input
--- Ààrẹ Buhari ló lè yóhùn padà lórí ètò kónílégbélé – Mínísítà
Mínísítà fún ètò ìlera lórílèèdè Nàìjíríà, Osagie Ehanire ti sọ̣̣̀rọ̀ lọ̣̣́jọ́ Àìkú pé, ààrẹ̣̣ Mohammadu Buhari nìkan ló leè sọ̣̣ ìgbà tétò kónílé-gbélé táárùn Corona (COVID-19) dásílẹ̀ lórílèèdè Nàìjíríà yóò parí.
Mínísítà tún tẹ̀síwájú pétò kónílé-gbélé tó ń lọ̣ lọ̣̣́wọ́ yìí wà nípa bétò ìlànà tí gbogbo orílẹ̀ àgbáyé làsílẹ̀.
"Ó ní, ""Ààrẹ̣̣ yóò lọ̣̣gbọ̣̣́n rẹ̀ láti sọ̣̣ bétò kónílé-gbélé yóò se dópin lórílèèdè yìí."
--- COVID-19: Àwọ̣̣n ènìyàn mẹ̣́tàdínláàdọ̣̣́rùn ún (87) míràn tún jẹ̣̣yọ lórílẹ̀ èdè Nàìjíríà
Àwọ̣̣n ènìyàn mẹ̣̣́tàdínláàdọ́rùn ún (87) míràn tún ti jẹyọ tí wọ̣̣́n ní ààrùn Corona (COVID 19 ) lórílẹ̀ èdè Nàìjíríà ní èyí tí ó jẹ́ kí iye àwọ̣̣n tó ní ààrùn Corona jẹ́ méjìlélọ̣̣́gọ̣̣́sànánlélẹ́gbẹ̣̣̀rún (1182), nígbà tí àwọ̣̣n ènìyàn bi ọ̣̀kànlénígba àti méjí (222 ) ti gba ìwòsàn , tí àwọ̣̣n ènìyàn márùndínlógójì (35) sì ti jẹ́ Ọlọ́run nípè.
Àjọ̣ tó ń gbógun ti àjàkálẹ̣̀ ààrùn lórílẹ̀ èdè Nàìjíríà (NCDC) ló kéde yìí lórí ẹ̀rọ Twitter wọ̣̣n, @NCDC. gov. Nínú ènìyàn mẹ́tàdínláàdọ̣̣́rùn ún (87) tí wọ̣́n ṣ̣ẹ̣̣̀ṣ̣ẹ̀ jẹ̣̣yọ̣̣ ọ̣̣̀hún , mẹ̣̣́tàlélọ̣̣́gbọ̣̣̀n ( 33) ní ìpínlẹ̀ Eko , méjìdínlógún (22) ní ìpínlẹ̀ Borno , méjìlá ( 12) ìpínlẹ̀ Ọ̀sun, mẹ́sàn án (9) ní ìpínlẹ̀ Katsina, ẹ̣yọ̣ mẹ́rin (4) ní ìpínlẹ̀ Kánò àti Èkìtì , ẹ̣̣yọ̣̣ mẹ́ta (3) ní ìpínlẹ̀ Edo ati Bauchi , ẹ̣̣yọ̣ kan (1) ní ìpínlẹ̀ Imo.
--- Àjọ̣̣ WHO yan Okonjo-Iweala láti jẹ́ aṣ̣ojú ikọ̀ tó ń gbógun ti ààrùn COVID-19
Àjọ àgbáyé fún ètò ìlera , (World Health Organisation, WHO) ti yan mínísítà fún ètò ìnáwó tẹ̣́lẹ̣̀rí lórílẹ̀ èdè Nàìjíríà, Ngozi Okonjo-Iweala gẹ̣̣́gẹ́ bí aṣ̣ojú ikọ̀ tuntun tí yóò máa mójútó irinsẹ́ àti ohun èlò fún ìtọ́jú ààrùn COVID-19.
Ọ̣̣̀mọ̣̣̀wé Okonjo-Iweala ni yóò máa ṣ̣iṣ̣ẹ́ pọ̀ pẹ̣̀lú onísòwò ará ilẹ̀ Britain, Andrew Witty, láti máa darí àwọ̣̣n iṣ̣ẹ́ àkànṣ̣e láti fi gbógun ti ààrùn COVID-19 fún àjọ̣̣ àgbáyé.
Olùdarí àjọ̣̣ náà,Tedros Ghebreyesus, ló sọ̣̣̀rọ̀ yìí lórí ẹ̣̀rọ̣ ayélujára lásìkò tí wọ̣̣́n ṣe ìdásílẹ̀ ikọ̀ ọ̀hún ní Geneva.
Ghebreyesus sọ pé “Mo fẹ́ dúpẹ́ púpọ̀ lọ̣̣́wọ̣̣́ Andrew Witty àti Ngozi Okonjo-Iweala láti jẹ́ adarí ikọ̀ tí yóò máa mójútó àwọ̣̣n irinsẹ̣̣́ àti ohun èlò fún gbígbógun ti ààrun COIVD-19.
"Ó tún ní , ""Iṣ̣ẹ́ àkànṣ̣e yìí jẹ́ ìfọ̣̣wọ̣̣́sowọ̣̣́pọ̣̣̀ àjọ̣̣ àgbáyé láti pèsè àwọ̣̣n irinsẹ́, òògùn , abẹ́ṛ̣ẹ́ àjẹsára , ohun ìtọ́jú fún gbígbógun ti ààrùn COVID-19 àti láti máa pín káàkiri gbogbo orílẹ̀ èdè àgbáyé. """
Lọ̣́sẹ̀ tó kọ̣̣já ni adarí àjọ ètò àgbáyé lórí ọ̀rọ̀ owó yíyá, Kristalina Georgieva, tún yan Ngozi Okonjo Iweala gẹ̣̣́gẹ̣́ bí ọ̀kan lára ikọ̀ tí yóò máa ṣ̣àmójútó ètò ìnáwó fún àjọ̣̣ náà.
Ikọ̀ náà yóò máa ṣ̣èpàdé lóòrè-kóòrè ḷ̣ọ̣̣́dún láti máa sàlàyé nípa ìdàgbàsókè àti ètò ìlànà tí wọ́n ti sẹ.
--- COVID-19: Ìyàwó ààrẹ Buhari pín àwọn ohun ilé-ìwòsàn
Ìyàwó ààrẹ orílẹ̀ èdè Nàìjíríà, ìyáàfin Aisha Buhari ti pín àwọn ohun èlò ilé-ìwòsàn fún ìrànwọ́ láti gbógun ti ìtànkálẹ̀ ààrùn Corona ìyẹn COVID-19.
Ìyáàfin Bùárí fi àìdùnú rẹ̀ hàn sí bí ààrùn aṣekúpani COVID 19 ṣe ń tàn kálẹ̀ káàkiri tìbú tòòró orílẹ̀ èdè Nàìjíríà èyí sì ti mú kí ó dìde sí à ti kó àwọn ohun ìrànwó jọ láti kojú ààrùn náà.
Ìyáàfin Buhari wá fi ìdùnnú rẹ̀ hàn sí gbogbo àwọn tó pèsè ìrànwọ̣̣́ fún gbígbógun ti ìtànkálẹ̀ ààrùn ọ̣̣̀hún náà, Ó ní, “orílẹ̀ èdè Nàìjíríà yóò jẹ̣̣̀gbádùn àwọ̣̣n ètò ìrànwọ̣̣̣́ tí ẹ pèṣ̣̣è.
Ìyáàfin Bùárí wá pe àwọn ọmọ Nàìjíríà láti wà láìléwu kí wọn sì máa fi ààyè sílẹ̀ láàrín ara wọn láti leè borí àjàkálẹ̀ àrùn yìí.
Ó tún rọ “àwọn ìpínlẹ̀ tí wọ́n jẹ àǹfààní ohun ìrànwọ́ wọ̀nyí láti lò wọ́n dáradára”
Olùrànlọ́wọ́ pàtàkì fún ìyáàfin ààrẹ Buhari lórí ètò ìlànà iṣẹ́ ati ìgbáyé-gbádùn àwọn obìnrin, Hajo Sani ló ṣojú ìyàwó ààrẹ Buhari lásìkò ayẹyẹ láti pín àwọn ohun èlò ọ̀hún nílùú Àbújá.
Lára àwọn ohun èlò tí wọ́n pín ọ̀hún ni; àwọn ọṣẹ ìfọwọ́ á-pa kòkòrò, àwọn òògùn òyìnbó, ohun èlò ìdáàbò bo ara, irinsẹ́, ìbọ̀wọ́ àti aṣọ ìdáàbò bò.
Àwọn ohun míràn tún ni aṣọ ìbọ̀wọ́, gíláásì ìbòjú, àwọn ohun ìbùsùn abbl.
Àwọn ìpínlẹ̀ mẹ́ta ni wọ́n fún ní àwọn ohun èlò wọ̀nyí, àwọn ìpínlẹ̀ náá ní Bauchi, Gombe àti ìlú Àbújá, Federal Capital Territory (FCT).
Adarí ẹ̀ka tó ń mójútó isẹ́ àkànse fún ètò ìlera àti ìgbáyé –gbádùn àwọn ènìyàn, nílùú Àbújá ,Mathew Ashikeni, ló tẹ́wọ́gba àwọn ohun èlò ọ̀hún fún mínísítà ìlú Àbújá.
Dókítà Ashikeni ní; “Àwọ̣n ohun èlò ìrànwọ́ náà yóò wúlò láti gbógun ti ààrun COVID-19 ní olú-ìlú orílẹ̣̀ èdè Nàìjíríà, tó wà nílùú Àbújá.
Ó wá fi àwọn aṣojú ọ̀hún lójú pé àwọn yóò lo ohun èlò náà bó se tọ́ àti bó se yẹ.
--- COVID-19: Àwọn ènìyàn mẹ́rìnléláàdọ́fà (114) míràn tún jẹyọ lórílẹ̀ èdè Nàìjíríà, iye àwọn tó ní ààrun Corona jẹ́ márùndínlọ́gọ́rùńlélẹ́gbẹ̀rún (1095)
Àwọn ènìyàn mẹ́rìnléláàdọ́fà (114) míràn tún ti jẹyọ tí wọ́n ní ààrun Corona (COVID 19 ) lórílẹ̀ èdè Nàìjíríà ní èyí tí ó jẹ́ kí iye àwọn tó ní ààrun Corona jẹ́ márùndínlọ́gọ́rùńlélẹ́gbẹ̀rún (1095), nígbà tí àwọn ènìyàn bí méjídínláàdọ́fà (208 ) ti gba ìwòsàn , tí àwọn ènìyàn méjìlélọ́gbọ̀n (32) sì ti jẹ́ Ọlọ́run nípè.
Àjọ tó ń gbógun ti àjàkálẹ̀ ààrùn lórílẹ̀ èdè Nàìjíríà (NCDC) ló kéde yìí lóríẹ̀rọ Twitter wọn, @NCDC. gov ní déédé aago méjìlá kọjá ìsẹ́jú márùndínlọ́gbọ̀n,lọ́jọ́ Ẹtì ,ọjọ́ kẹrìnlélógún, Osù kẹrin,ọdún, 2020.
Nínú ènìyàn mẹ́rìnléláàdọ́fà (114) tí wọn sẹ̀sẹ̀ jẹyọ ọ̀hún , ọgọ́rin ( 80) ní ìpínlẹ̀ Èkó , mọ́kànlélógún (21) ní ìpínlẹ̀ Gombe , márùn ún ( 5) ní ilu Àbújá, Federal Capital Territory (FCT), méjì (2) ní ìpínlẹ̀ Zamfara àti Edó, ẹyọ kan (1) ní ìpínlẹ̀ Ògùn, Ọ̀yọ́, Kàdúná àti ìpínlẹ̀ Sókótó.
--- Abba Kyari jẹ́ olóòótọ́ fún ààrẹ Buhari àti agbẹnusọ rere fún Amẹ́ríkà: Ìjọba Amẹ́ríkà
Ìjọba orílẹ̀ èdè Amẹ́ríkà ti ṣàpéjúwe olóògbé Abba Kyari gẹ́gẹ́ bí ó ṣe jẹ̣̣́ olóòótọ́ adarí òṣìṣẹ́ ìjọba fún ààrẹ Buhari àti agbẹnuṣọ rere fún ìjọba orílẹ̀ èdè Amẹ́ríkà.
Nínú ọ̀rọ̀ ìbánikẹ́dùn rẹ̣̀ sí ààrẹ Muhammadu Buhari, igbákejì akọ̀wé àgbà ìpínlẹ̀ tó ń mójútó ètò ilẹ̀ Áfíríkà, Tibor Nagy, ló gbósùbà fún ìwà akínkanjú tí olóògbé Kyari,wù pàápàá jùlọ, nípa bí orílẹ̀ èdè Amẹ́ríkà ṣe dá owó tí iye rẹ̀ jẹ́ ọ́ọ̀dúnrún mílíọ̀nù dọ́là ($300 million) tí olóògbé Sani Abacha jígbé lọ sí orílẹ̀ Amẹ́ríkà padà fún orílẹ̀ Nàìjíríà.
Nagy sọ pé Kyari jẹ́ olóòótọ́ adarí òṣìṣẹ́ ìjọba fún ààrẹ Buhari àti agbẹnuṣọ rere fún ìjọba orílẹ̀ èdè Amẹ́ríkà pàápàá jùlọ adarí rere fún ikọ̀ wa tó wà nílùú Àbújá.
Inú wa dùn láti bá olóògbé Kyari ṣe àwọn iṣ̣ẹ́ gidi-gidi papọ̀ pàápàá jùlọ, nípa bí wọ́n ṣe dá ọ́ọ̀dúnrún mílíọ́nù dọ́là ($300 million) tí olóògbé Sani Abacha jígbé lọ sí orílẹ̀ èdè Amẹ́ríkà padà fún orílẹ̀ èdè Nàìjíríà.
Ó dábàá pé kí wọ́n pín owó ọ̀hún sí ọ̀nà mẹ́ta láti fi ṣe àwọn iṣẹ́ àkànṣe ohun amáyédẹrùn, ní èyí láti lèè jẹ́ kí ìsọ̀kan àti ètò ọrọ̀ ajé túbọ̀ fẹsẹ̀ múlẹ̀ lórílẹ̀ èdè Nàìjíríà.
Nagy sọ̀rọ̀ yìí lásìkò tó ń kẹ́dùn pẹ̀lú ìjọba àti àwọn ọmọ orílẹ̀ èdè Nàìjíríà àti ẹbí Kyari , ó ní ìjọba ̀orílẹ̀ èdè Améríkà ti ṣèlérí láti dúró ti orílẹ̀ èdè Nàìjíríà láti gbógun ti ìtànkálẹ̀ ààrun Corona.
Ààrẹ tún rí ìwé ìkẹ́dùn gbà láti ọwọ́ mínísítà fún Niger Delta, Usani Uguru Usani, olókoòwò láti ìlú Kánò, Alhaji Sabiu Bàkó àti adarí àwọn òṣìṣẹ́,
--- COVID-19: Àwọn ènìyàn méjìdínláàdọ́fà (108) míràn tún jẹyọ lórílẹ̀ èdè Nàìjíríà
Àwọn ènìyàn méjìdínláàdọ́fà (108) míràn tún ti jẹyọ tí wọ́n ní ààrun Corona (COVID 19) lórílẹ̀ èdè Nàìjíríà.
Ní èyí tí ó jẹ́ kí iye àwọn tó ní ààrùn Corona jẹ́ mọ́kàndílógúndínlẹ́gbẹ̀rún (981)
Àjọ tó ń gbógun ti àjàkálẹ̀ ààrùn lórílẹ̀ èdè Nàìjíríà (NCDC) ló kéde yìí lórí ẹ̀rọ Twitter wọn, @NCDC. gov.
Nínú ènìyàn mọ́kàndílógúndínlẹ́gbẹ̀rún (981) tí wọ́n ṣẹ̀ṣẹ̀ jẹyọ ọ̀hún , méjìdínlọ́gọ́rin (78) ní ìpínlẹ̀ Èkó , márùn ún (5) ní ìpínlẹ̀ Katsina , mẹ́rìnlá ( 14) ní ìlú Àbújá, Federal Capital Territory (FCT), márùn ún (5) ní ìpínlẹ̀ Ògùn, mẹ́rin (4) ní ìpínlẹ̀ Gombe, mẹ́ta (3) ní ìpínlẹ̀ Borno, méjì (2) ní ìpínlẹ̀ Akwa Ibom, ẹyọ kan (1 )ní ìpínlẹ̀ Kwara ati ẹyọ kan (1 ) ní ìpínlẹ̀ Plateau.
--- Ilé-iṣẹ́ ológun òfúrufú ṣe ìdánilẹ́kọ̀ọ́ fún àwọn nọ́ọ̀sì rẹ̀ nípa ṣíṣe ìtọ́jú àwọn tó bá farapa
Ilé-iṣẹ́ ológun òfúrufú orílẹ̀ èdè Nàìjíríà (NAF) ti ṣ̣e ìdánilẹ́kọ̀ọ́ fún àwọn nọ́ọ̀sì ọkọ̀ òfúrufú àti àwọn awakọ̀ òfúrufú.
ìdánilẹ́kọ̀ọ́ yìí wà lára àwọn ètò ìlànà tí ilé-iṣẹ́ ológun òfúrufú là sílẹ̀ fún àwọn ikọ̀ ọmọ ogun wọn nípa bí wọn yóò ṣe máa kó àti ṣe ìtọ́jú àwọn ọmọ ogun tó bá farapa lójú ogun.
Adarí ẹ̀ka ìròyìn àti ìbáṣepọ̀ tí ikọ̀ ọmọ ogun òfúrufú ọ̀hún (NAF) Air Commodore Ìbíkúnlé Dáramólá sọ pé ìdánilẹ́kọ̀ọ́ ọlọ́sẹ̀- kan parí nípa lílo ọkọ òfúrufú C-130H tó wà ní pápá ọkọ̀ òfúrufú Nnamdi Azikwe tó ń mójútó írínájó ilẹ̀ òkèèrè tó wà nílùú Àbújá, ní èyí láti jẹ́ kí àwọn ikọ̀ ọmọ ogun ọ̀hún ní ìmọ̀ tó gbóhúnjẹ-fẹ́gbẹ́, gbàwobọ̀ nípa ṣíṣe ìtọ́jú nínú ọkọ̀ òfúrufú fún àwọn ọmọ ogun tó bá farapa lójú ogun láti du ẹ̀mí wọn títí tí wọn yóò fi gbé wọn dé ilé-ìwòsàn.
Dáramólá ní wọn ti se ọkọ̀ òfúrufú NAF C-130H lọ́nà tí àwọn ohun èlò tí àwọn tó bá farapa tàbí aláìsàn leè lò láti gba ìtọ́jú pàjáwìrì.
Adarí ilé-iṣẹ́ ológun ọkọ̀ òfúrufú lórílẹ̀ èdè Nàìjíríà, ọ̀gágun Sadique Abubakar, wá fi ìdùnnú rẹ̀ hàn nípa ìdánilẹ́kọ̀ọ́ ọ̀hún bí àwọn nọ́ọ̀ṣì tí yóò máa wà nínú ọkọ̀ òfúrufú náà ṣe fakọyọ.
Ó tẹ̀síwájú pé wọ́n tún leè lo àwọn irinṣẹ́ àti ohun èlò ọ̀hún fún gbígbé àwọn aláìsàn ààrun COVID-19 tó bá nílò ìtọ́jú ní kíákíá.
Adarí ọ̀hún tún ní láti bí ọdún mẹ́rin àti ààbọ̀ sẹ́yìn ní ilé-iṣẹ́ ikọ̀ ọmọ ogun òfúrufú ti ń gbìyànjú láti ṣètò ìdálẹ́kọ́ọ̀ fún ikọ̀ òṣìṣẹ́ elétò ìlera tó jẹ́ ọmọ ogun ọkọ̀ òfúrufú nípa pípèsè ìtọ́jú ètò ìlera fún àwọn ikọ̀ omọ ogun, ẹbí wọn àti àwọn tó bá farapa lójú ogun.
--- Ilé-iṣẹ́ ológun run agbègbè ti ikọ̀ ọmọ ogun ọlọ̀tẹ̀ fi ń ṣe ibùgbé ní ìpínlẹ̀ Borno
Ilé-isẹ́ ológun orí afẹ́fẹ́, ìyẹn Air Task Force of Operation LAFIYA DOLE, ti run gbogbo àwọn agbègbè tí adarí ikọ̀ ọmọ ogun ọlọ̀tẹ̀ Boko Haram fi ń ṣe ibùgbé ní Bulawa nínú igbó Sambisa tó wà ní ìpínlẹ̀ Borno pátápátá.
Agbẹnusọ fún ẹ̀ka ìròyìn ilé-iṣẹ́ ọ̀hún, ọ̀gágun John Enenche sọ pé“ ọkọ̀ ogun òfúrufú bẹ̀rẹ̀ sí ní máa ju àdó olóró sí àwọn agbègbè tí adarí ikọ̀ ọlọ́tẹ̀ Boko Haram wà nípaṣẹ̀ ìròyìn tí àwọn gbọ́ pé agbègbè náà ni ó farapamọ́ sí.
Ọ̀gágun John Enenche tún ní kí ó tó di pé ikọ̀ ọlọ̀tẹ̀ Boko Haram tó máa gbáradì láti kojú ìjà pẹ̀lú ikọ̀ ọmọ -ogun òfúrufú tó ń ju àdó olóró ní kíkan-kíkan sí agbègbè, ni àwọn ti fi àdó olóró ṣe wọ́n bí ọṣẹ́ ṣe ń ṣojú.
--- Ààrẹ Bùhárí fi ìkíni ránṣẹ́ sí àwọn Mùsùlùmí bí Ramandan ṣe bẹ̀rẹ̀
Ààrẹ orílẹ̀ èdè Nàìjíríà, Muhammadu Buhari ti fi ìkíni rẹ̀ ránṣẹ́ sí gbogbo àwọn mùsùlùmí tó wà lórílẹ̀ èdè yìí àti ni gbogbo àgbáyé látàrí bí wọ́n ṣe rí òṣùpá láti bẹ̀rẹ̀ ààwẹ̀ ọgbọ̀njọ́.
Ààrẹ Buhari ní ó ṣeni láàànù pé ààwẹ̀ ọdún yìí wáyé lásìkò tí gbogbo àgbáyé ń kojú
ìpèníjà àjàkálẹ̀ ààrùn COIVD-19, ní èyí tí ó ti tàn ká igba (200) orílẹ̀ èdè tó wà lágbàáyé, tí gbogbo orílẹ̀ èdè sì ń pariwo pé kí àwọn ènìyàn yàgò fún ìpéjọpọ̀, kí wọ́n sì máa dá gbàdúrà àti ìsírun wọn tàbí pẹ̀lú ẹbí wọn.
"Ààrẹ tún tẹ̀síwájú pé ""Lásìkò Ramadan yìí, ìbásepọ̀ tí ẹ máa ń ṣe tẹ́lẹ̀ ti di ohun tí ààrun Corona ṣọ di ewu báyìí,"" ààrẹ wá rọ gbogbo àwọn mùsùlùmí láti sọ́ra , kí wọ́n sì yàgò fún àwọn ìpéjọpọ̀ nípa oúnjẹ àti gbígbàdúrà papọ̀, ní èyí tí àwọn adarí ẹlẹ́sìn ti fòpin si báyìí ní gbogbo àgbáyé."
Ààrẹ Buhari tún wá rọ gbogbo àwọn mùsùlùmí láti farada ìṣẹ̀lẹ̀ ààrun Corona tó ń jà lórílẹ̀ èdè yíí sùgbọ́n kí wọn máa ṣe lo ìsẹ̀lẹ̀ ọ̀hún láti fi yẹra nípa kíkópa nínú ààwẹ̀ Ramadan àyàfi tí wọ́n bá ní ìdí kan pàtàkì tó ní ṣe pẹ̀lú ètò ìlera tàbí èyí tí adarí ẹ̀sìn bá là sílẹ̀ láti máa kópa nínú ààwẹ̀ ọ̀hún.
Ó wá kí gbogbo àwọ̣n mùsùlùmí lórílẹ̀ èdè yìí àti ní gbogbo àgbáyé pé gbogbo ìbùkún inú ààwẹ̀ mímọ́ yìí yóò jẹ́ ti wọn.
--- COVID-19: Àwọn ènìyàn mọ́kànléláàdọ́rùn ún (91) míràn tún jẹyọ lórílẹ̀ èdè Nàìjíríà
Àwọn ènìyàn mọ́kànléláàdọ́rùn ún (91) míràn tún ti jẹyọ tí wọ́n ní ààrùn Corona (COVID 19 ) lórílẹ̀ èdè Nàìjíríà.
Ní èyí tí ó jẹ́ kí iye àwọn tó ní ààrùn Corona jẹ́ mẹ́tàléláàdọ́rinléníẹgbẹ̀rin(873), nígbà tí àwọn ènìyàn bí mẹ́tàdínnígba (197 ) ti gba ìwòsàn , tí àwọn ènìyàn márùndínlọ́gbọ̀n (25) ṣì ti jẹ́ Ọlọ́run nípè.
Nínú ènìyàn mọ́kànléláàdọ́rùn ún (91) tí wọ́n ṣẹ̀ṣẹ̀ jẹyọ ọ̀hún , mẹ́rìnléláàdọ́rin ( 74) ní ìpínlẹ̀ Èkó , márùn ún (5) ní ìpínlẹ̀ Katsina ,ẹyọ kan ( 1) ní ìlú Àbújá, Federal Capital Territory (FCT), mẹ́rin (4) ní ìpínlẹ̀ Ògùn, méjì (2) ní ìpínlẹ̀ Delta ati Edo ,ẹyọ kan (1) ní ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́, Kwara àti Adámáwá.
--- Ilé igbimo Aṣ̣òfin ti ìpínlè̩ Èkó bẹ̀bẹ̀ fún ìfaradà ìpèníjà sísémó̩lé látàrí ààrùn Kòrónà.
Ilé Ìgbìmọ̀ Aṣ̣òfin ti ìpínlẹ̀ Èkó ti rọ̣ àwọn olùgbé ìpínlẹ̀ Èkó láti jọ̀wọ́ farada ìpèníjà tí ó wáyé látàri ìgbélé tó wáyé láti fi òpin sí ìtànkálè̩ ààrùn Kòrónà.
Ìgbìmọ̀ tó ń mójútó ètò ìlera àti Ìgbìmọ̀ tó ń mójútó ètò ìròyìn nínú ilé ìgbìmọ̀ aṣòfin rawọ́ ẹ̀bẹ̀ nígbàtí wọ́n ń bá àwọn oníròyìn sọ̀rọ̀ lórí àkíyèsí wọ̣n níbi àyẹ̀wò àwọn ohun èelò tí wọn pèsè fún ìtọ́jú àrùn ‘COVID-19’ ní Ìpínlẹ̀ Èkó.
Alága Ìgbìmọ̀ tó ń mójútó ètò ìlera nínú ilé ìgbìmọ̀ aṣòfin ti ìpínlẹ̀ Èkó, aṣòfin Hakeem, tí ó ṣáájú ikọ̀ náà sọ pé ó ṣe pàtàkì kí àwọn ará ìlú tẹ̀lé òfin kónílé-gbélé tí ìjọba ṣe yìí láti leè dẹ́kun ìtànkálẹ̀ àrùn kòrónà yìí.
Àwọn ọmọ ilé ìgbìmọ̀ Aṣòfin tó wà níbẹ̀ ni Alága ìgbìmọ̀ tó ń mójútó ètò ìròyìn àti ètò òṣ̣èlú nínú Ilé Ìgbìmọ̀ Aṣòfin náà, aṣòfin Túndé Braimoh; aṣòfin Desmond Elliot, aṣòfin Tèmítọ́pẹ́ Adéwálé.
Àwọn ìgbìmọ̀ náà ṣe àbẹ̀wò sí Ilé-ìwòsàn àjàkálẹ̀ àrùn ní agbègbè Yaba; gbọ̀ngàn ìdánidúró fún àyẹ̀wò ní àgbègbè Mobọ́lájí Johnson ní Oníkàn; gbọ̀ngàn ìdánidúró fún àyẹ̀wò ní àgbègbè Victoria Island ní Ìjọba Ìbílẹ̀ Etí-Ọ̀sà àti Ilé-Ìwòsàn gbogboògbò ní Gbàgádà.
Ìgbìmọ̀ náà wòye pé àwọn ohun èèlò fún ìtọ́jú àrùn náà àti iṣẹ́ wọn níbẹ̀ dúró dáradára láti kojú ìtànkálẹ̀ àrùn kòrónà ní Ìpínlẹ̀ Èkó, tí ìjọba àpapọ̀ ṣe àtìlẹyìn fún.
Wọ́n ṣe ìlérí pé àwọn ìpèníjà díẹ̀díẹ̀ tí wọ́n ń kojú ní àwọn ilé-ìwòsàn yìí tó níi ṣ̣e pẹ̀lú àìtó àwọn ohun èèlò tí àwọn òṣìṣẹ́ náà fi ń dáàbò bo ara wọn.
Àti pé gbogbo ipá ni ìjọba ń sà láti gbógun ti ààrùn yìí, ṣùgbọ́n àwọn ará ìlú ní láti ṣàtìlẹyìn fún àṣeyọrí èyí.
Nínú ọ̀rọ̀ tí Aṣòfin Shókúnlè so̩, ò̩nà kan pàtàkì tí ó rò láti dènà ìtànkálẹ̀ ààrùn yìí ni ìkéde kónílé-gbélé.
"Mo mọ̀ pé eléyìí kò rọrùn, sùgbọ́n nígbà miíràn, tí a bá ní kí á wo ìpalára irú ààrùn ""Coronavirus"", a ó rii pé ó ṣe pàtàkì làti ṣe èyí."
Aṣòfin Túndé Bramoh náà rọ àwọn ará ìlú láti túnbọ̀ ní sùúrù díẹ̀, níwọ̀n tó jẹ́ pé àìròtẹ́lẹ̀ ní gbgbo ọ̀rọ̀ yìí ṣẹlẹ̀, ó sì nílò ọwọ́ kunkun láti fi mú u. Ó ní:
A rọ àwọn ènìyàn wa, nítorí ọ̀rọ̀ ààrùn COVID-19, ọ̀rọ̀ ìrọ̀rùn àwọn ará ìlú náà wà lọ́tọ̀.
Ó yẹ kí á mọ̀ pé ọ̀rọ̀ ààrùn kòrónà yìí níí ṣe pẹ̀lú ẹ̀mí ẹ̀dá, ni ó fi ṣe pàtàkì kí á kọ́kọ́ yanjú ọ̀rọ̀ ààrùn yìí ná.
Ìgbìmọ̀ Aṣòfin náà s̩e àbẹ̀wò sí àwọn gbọ̀gàn ìtọ́jú Kòrónà mẹ́rẹ̀ẹ̀rin nípìnínlẹ̀ Èkó, wọ́n sì pèsè àwọn èèlò pẹ̀lú àwọn òṣìṣẹ́ tó yẹ, tí ààyè ìbùsùn síì fè̩ dáadáa.
--- Gómìnà ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́ dáròo onídàjọ́ àgbà tẹ́lẹ̀rí– Mákindé
Gómìnà ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́, Sèyí Mákindé ti fi ikú olóògbé onídàájọ́ àgbà, Richard Akínjídé tó ti fìgbà kan jẹ́ Mínísítà fún ètò ìdájọ́ ní orílẹ̀ èdè Nàí̀íríà wé àdánù ńlá fún ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́, orílẹ̀ èdè Nàìjíríà àti àgbáyé lápapọ̀.
Gómìnà Sèyí Mákindé, ẹni tí ó tún fi àìdùnnú rẹ̀ hàn sí ikú onídàájọ́ àgbà Akínjídé hàn nínú ọ̀rọ̀ ìbánikẹ́dùn rẹ̀, eléyìí tí ó fi sọwọ́ sí ẹbí olóògbé ọ̀hún láti ọwọ́ amúgbálẹ́gbẹ́ rẹ̀ lórí ọ̀rọ̀ ìròyìn, Táíwò Àdìsá, ló sọọ́ di mímọ̀ pé olóògbé Akínjídé ti fi ìgbà ayé rẹ̀ sin orílẹ̀ èdè Nàìjíríà tọkàn -tọkàn.
Mákindé tún tẹ̀síwájú pé, ikú olóògbé náà wá lásìkò tí ọmọ orílẹ̀ èdè Nàìjíríà nílò láti mu nínú omi ọgbọ́n rẹ̀ eléyìí tó ti fihàn nínú onírúurú ọ̀nà bí i , ìṣèjọba àti ẹ̀ka òfin eléyìí tó le tan ìmọ́lẹ̀ fún wọn láti jẹ́ adarí tó ṣeé mú yangàn lágbàáyé.
"Mákindé tún sàlàyé pé: ""Ìròyìn ikú bàbá wa, adarí ati ẹnìkanṣoṣo tó tayọ lara àwọn olóṣèlú orílẹ̀ èdè Nàìjíríà, Olóyè Richard Akínjídé jẹ́ ìyàlẹ́nu ńlá nítorí pé, bàbá kò fẹ́ kí ẹnikẹ́ni lára mọ̀ pé ọlọ́jọ́ ti dé, títí ó fi mí èémì ìkẹyìn, bàbá sì ń sọ̀rọ̀ lórí àwọn ìsẹ̀lẹ̀ tó ń lọ, tó sì ń gba ìjọba nímọ̀ràn ní oríṣiríṣi ọ̀nà, bàbá dúró gẹ́gẹ́ bí òpómúléró nínú òṣèlú àti ọ̀rọ̀ òfin. """
Ikú rẹ̀ jẹ́ àdánù ńlá fún ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́, orílẹ̀ èdè Nàìjíríà àti àgbáyé lápapọ̀, nítorí ó jẹ́ asíwájú rere tí se ọmọ bíbí ilẹ̀ Ìbàdàn ní ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́, tí kò fi ẹlẹ́yàmẹ̀yà ṣe, tó fi ọjọ́ ayé rẹ̀ sin orílẹ̀ èdè Nàìjíríà pẹ̀lú agbára rẹ̀ 
Gómìnà wá fi àsìkò ọ̀hún bá àwọn ọmọ olóògbé náà tó tún jẹ́ ògbóǹtarìgì nínú ẹgbẹ́ òṣèlú Peoples Democratic Party (PDP), olóyè Jùmọ̀ké Akínjídé àti gbogbo ọmọ bíbí inú bàbá yòókù láìyọ ẹnìkankan sílẹ̀ àti nínú òṣèlú kẹ́dùn.
Ó wá tún fi àsìkò náà bá gbogbo ọmọ bíbí ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́ àti ọmọ orílẹ̀ èdè Nàìjíríà kẹ́dùn lórí ikú ẹ̣ni rere tó dágbére fáyé. olóògbé Richard Akínjídé jẹ́ ẹni ọdún Méjìdínláàdọ́rùń kí ó tó jáde láyé.
--- Ilé-isẹ́ ológun gbẹ̀mí àwọn ọmọ-ogun ọlọ̀tẹ̀ mọ́kànlélógún ní ìpínlẹ̀ Zamfara
Ilé-isẹ́ ọmọ ogun orílẹ̀ èdè Nàìjíríà, Operation Hadarin Daji ti gbẹ̀mi àwọn ọmọ ogun ọlọ̀tẹ̀ tí kò dín ní mọ́kànlélógún tí wọ́n bá wọ̀yá ìjà ní Zurmi ní ìjọba ìbílẹ̀ Zurmi ní ìpínlẹ̀ Zamfara.
Agbẹnusọ fún ilé-isẹ́ ìròyìn ,ọ̀gágun John Enenche, ló sọ̀rọ̀ yìí lọ́jọ́rú nílùú Àbújá,pé ọmọ ogun orílẹ̀ èdè Nàìjíríà mẹ́rin ló kú níbi ìṣẹ̀lẹ̀ ọ̀hún.
Enenche tẹ̣̀síwájú pé àwọn yóò tún máa sọ bí ìgbésẹ̀ tí ó kàn nípa ìṣẹ̀lẹ̀ ọ̣̀hún ní àgbègbè náà ṣ̣e ń lọ sí.
Ó tún ní ikọ̣̀ ọmọ ogun náà yóò tún tẹ̀síwájú láti máa gbogún ti ikọ̀ ọḷọ̀tẹ̀ tó wà ní àgbègbè náà.
--- COVID-19: ìpínlẹ̀ Kánò bẹ̀rẹ̀ oúnjẹ pínpín fụ́n àwọn ará ìlú
Ìjọba ìpínlẹ̀ Kánò yóò bẹ̀rẹ̀ sí ní máa pín oúnjẹ láti fi ṣe ètò ìrànwọ́ fún àwọn ọmọ ìpínlẹ̀ náà, kí ó le dín wàhálà tí wọ́n ń kojú lásìkò ètò kónílé-gbélé kù nípasẹ̀ ààrùn COVID-19
Olùrànlọ́wọ́ ìjọba ìpínlẹ̀ náà lórí ìròyìn, Salihu Tanko Yakasai ló kéde lórí ẹ̀rọ twitter rẹ̀ láásálẹ́ ọjọ́ Àìkú.
Ó tẹ̀síwájú pé àwọn yóò máa pín ouńjẹ náà káàkiri gbogbo ìjọba ìbílẹ̀ méjìlélógójì tó wà ní ìpínlẹ̀ ọ̀hún.
Gómìnà ìpínlẹ̀ Kánò, Abdullahi Gàndújè ló ti kọ́kọ́ kéde ètò kónílé-gbélé fún ọ̀sẹ̀ kan gbáko lọ́jọ́bọ̀ ní déédé aago mẹ́ẹ́wá àsálẹ́ pé ètò kónílé-gbélé yóò bẹ̀rẹ̀ ní Ọjọ́rú.
Àmọ́ṣá Gàndújè ní ó se é se kí àtúnṣe bá ètò ọ̀hún.
Ìgbìmọ̀ ìjọba ìpínlẹ̀ Kánò tó ń sètò owó ìrànwọ́ fún ààrùn COVID-19, ní èyí tí ọ̀jọ̀gbọ́n Muhammad Yahuza Bello jẹ́ alákòóso rẹ̀ sọ pé ìgbìmọ̀ náà ti rí owó tó lé ní irinwó mílíọ́nù gbà àti orísi oúnjẹ mẹ́ẹ̀dógún.
--- COVID-19: Àwọn ènìyàn mẹ́rìndínláàdọ́rùn ún (86) míràn tún jẹyọ lórílẹ̀ èdè Nàìjíríà
Àwọn ènìyàn mẹ́rìndínláàdọ́rùn ún (86) míràn tún ti jẹyọ tí wọ́n ní ààrùn Corona (COVID 19 ) lórílẹ̀ èdè Nàìjíríà
Ní èyí tí ó jẹ́ kí iye àwọn tó ní ààrùn Corona jẹ́ mẹ́tàdínlọ́gbọ̀nléníẹgbẹ̀ta(627), nígbà tí àwọn ènìyàn bí àádọ́sàn án (170 ) ti gba ìwòsàn , tí àwọn ènìyàn mọ́kànlélógún (17) ṣì ti jẹ́ Ọlọ́run nípè. Àjọ tó ń gbógun ti àjàkálẹ̀ ààrùn lórílẹ̀ èdè Nàìjíríà (NCDC) ló kéde yìí lórí ẹ̀rọ Twitter wọn, @NCDCgov ní déédé aago méjìlá ku ìsẹ́jú mẹ́wàá àṣálẹ́ ọjọ́ kọkàndínlógún , osù kẹrin , ọdún 2020.
Nínú ènìyàn mẹ́rìndínláàdọ́rùn ún (86) tí wọ́n sẹ̀sẹ̀ jẹyọ ọ̀hún , àádọ́rin ( 70) ní ìpínlẹ̀ Èkó ,mẹ́ta (3) ní ìpínlẹ̀ Katsina ,méje ( 7) ní ìlú Àbújá, Federal Capital Territory (FCT) ẹyọ mẹ́ta (3) ní ìpínlẹ̀ Akwa Ibom, ẹyọ kàn (1) ní ìpínlẹ̀ Bauchi, Jigawa àti Borno.
--- Abba Kyari: Ààrẹ Buhari bá ìpínlẹ̀ Borno kẹ́dùn
Ààrẹ Muhammadu Buhari ti bá ìpínlẹ̀ Borno kẹ́dùn , nígbà tí ààrẹ pe gómìnà ìpínlẹ̀ ọ̀hún, ọ̀jọ̀gbọ́n Babagana Zulum, olórí agbègbè Banki, àwọn ọba ìpínlẹ̀ ọ̀hún àti ẹ̀gbọ́n olóògbé Mallam Abba Kyari, Zanna Baba Shehu Arjinoma, lọ́jọ́ Àìkú.
Nínú ọ̀rọ̀ tí ààrẹ ń bá àwọn sọ lórí ẹ̀rọ̀ ìbánisọ̀rọ̀, ààrẹ bá olórí ẹbí àti àwọn ẹbí rẹ̀ ; Shehu ti Borno, Shehu Abubakar Ibn Umar Garbai El-Kanemi; Shehu ti Bama, Shehu Kyari ibn Umar ibn Ibrahim Elkenemi kẹ́dùn ikú olóògbé ọ̀hún.
Ààrẹ Buhari ṣàpèjúwe olóògbé ọ̀hún gẹ́gẹ́ bí àdánù ńlá fún orílẹ̀ èdè Nàìjíríà, ó wá rọ ìjọba ,àwọn ọmọ ìpínlẹ̀ Borno àti ẹbí olóògbé náà láti máa ṣe bọkànjẹ́ nítorí olóògbé Mallam Kyari lo ìgbé ayé tó dára.
Ó ní, Abba jẹ́ ẹni tí a fẹ́ràn jùlọ.
Ó ṣe ǹkan tí ó jẹ́ kí orílẹ̣̀ èdè Nàìjíríà di ńlá.
Àwọ̣n ènìyàn láti orílẹ̀ èdè Nàìjíríà àti nílẹ̣̀ òkèèrè sì ń pe ààrẹ láti báa kẹ́dùn lórí ikú adarí òsìsẹ́ rẹ̀.
Lára àwọn tí ó fìwé ìkíni ránsẹ́ sí ààrẹ ni: ààrẹ orílẹ̀ èdè Nàìjíríà tẹ́lẹ̀rí , ọ̀gágun Ibrahim Bàbáńgídá; Gómìnà ìpínlẹ̀ Rivers, Nyesom Wike, Enugu, Ifeanyi Ugwuanyi, Yobe, Mai Mala Buni, Taraba, Darius Dickson Ishaku àti àwọn akẹẹgbẹ́ rẹ̀ tí wọ́n jọ lọ sí ilé ẹ̀kọ́ lọ́dún 1953.
Ààrẹ tún rí ìwé gbà láti ọ̀dọ̀ ààrẹ ìgbìmọ̀ àjọ àgbáyé, Ambassador (Prof. ) Tijjani Muhammad-Bande, ẹgbẹ́ àwọn akọ̀ròyìn àgbáyé (the global network of Editors, the International Press Institute, IPI, ààrẹ àwọn ẹgbẹ́ Nigerian Guild of Editors, Mustapha Isa, Emir ti ìpínlẹ̀ Kánò, Àmínù Ado Bayero, olórí ẹbí àwọn Dantata ní ìpínlẹ̀ Kánò, Alhaji Àmínù Dantata, adarí ẹgbẹ́ Izala religious movement lórílẹ̀ èdè Nàìjíríà, Alhaji Bala Lau àti igbákejì adarí ilé ìgbìmọ̀ aṣòfin àgbà, Bala Ibn Na’Allah.
Àwọn mííràn tún ni : Aṣojú orílẹ̀ èdè Nàíjíríà fún orílẹ̀ èdè Amẹ́ríkà (USA), adájọ́ Sylvanus Adiewere Nsofor, Emir ti Zamfara, ọba Alhaji Attahiru Muhammad Ahmad, aṣòfin Umaru Kurfi, Burhan Karabult, Nigeria’s Turkish partner in the Defence Industries Corporation, DICON, ọ̀jọ̀gbọ́n James Momoh, igbákejì alága fún ilé-isẹ́ tó ń mójútó iná mọ̀nà-mọ́ná( Nigerian Electricity Regulatory Commission) àti ajíhìnrere láti ìpínlẹ̀ Kánò, Ustashi Tijjani Bala Kalarawi.
--- Àwọn ènìyàn mẹ́tàdínláàdọ́ta pàdánù ẹ̀mí wọn lórí ìkọlù tó ṣẹlẹ̀ ní ìpínlẹ̀ katsina
Ààrẹ Muhammadu Buhari ti fi àìdùnnú rẹ̀ hàn lórí ìkọlù tó ṣẹlẹ̀ ní ìjọba ìbílẹ̀ mẹ́ta kan ní ìpínlẹ̀ katsina níbi tí àwọn ènìyàn mẹ́tàdínláàdọ́ta ti pàdánù ẹ̀mí wọn.
Ààrẹ Buhari ṣọ̀rọ̀ yìí lásìkò tó ń dáhùn ìbéèrè nípa ìṣẹ̀lẹ̀ burúkú tó wáyé lọ́jọ́ Àìkú. Ààrẹ ní inú òun bàjẹ́ nípa ìkọlù ọ̀hún.
"Ó wá rọ gbogbo ọmọ orílẹ̀ èdè Nàìjíríà láti fọkànbalẹ̀ pé ""ị̀jọba yìí ti pinnu láti gbógun àti fìyà jẹ gbogbo àwọn ọ̀daràn tí wọ́n bá ń lo àsìkò kónílé-gbélé láti fi hu ìwà ìbàjẹ́ sí àwọn aláìsẹ̀ ""."
Ààrẹ Buhari ní òun kò ní faramọ́ bí àwọn ọ̀daràn ṣe ń pa àwọn aláìsẹ̀ àti pé “gẹ́gẹ́ bí ìpinnu mi láti mójútó ètò ààbò àwọn ará ìlú,àwọn ìkọlù yìí ni a óò ri pé a gbógun tìì. ”
Ààrẹ wa pàsẹ fún gbogbo àwọn agbófinró láti máa ṣe káárẹ̀ nípa gbígbógun ti àwọn ọ̀daràn kí wọ́n sì fi wọ́n jófin.
Ààrẹ wa bá àwọn ẹbí tó pàdánù ènìyàn wọn kẹ́dùn , ó wá rọ gbogbo àwọn ènìyàn láti jẹ́ ojú ni alákàn fi ń ṣọ́rí , kí wọ́n sì máa fi tó gbogbo àwọn agbófinró létí, tí wọ́n bá fura sí àwọn ọ̀daràn ní àgbègbè wọn.
--- Ilé ìgbìmọ̀ aṣojú kẹ́dùn ikú Abba Kyari
Abẹnugan ilé ìgbìmọ̀ aṣojú lórílẹ̀ èdè Nàìjíríà, ọ̀gbẹ́ni Fémi Gbàjàbíàmílà ti sàpèjúwe ikú adarí òṣìṣẹ́ ààrẹ̣, Malam Abba Kyari gẹ́gẹ́ bi èyí tó bani lọ́kànjẹ́.
Nínú ọ̀rọ̀ ìkíni tí olùrànlọ́wọ́ rẹ̀, Láńre Làsísì fọwọ́sí, abẹnugan ilé ìgbìmọ̀ aṣojú, Gbàjàbíàmílà sọ pé, ó se ni láàánú pé ààrùn COVID-19 tí ó ń jà káàkiri gbogbo àgbáyé ni ó pa Abba Kyari
Ó tẹ̀síwájú pé orúkọ̣ Abba Kyari yóò wà nínú ìwé ìrántí orílẹ̀ èdè Nàìjíríà gẹ́gẹ́ bí akínkanjú àti olùfọkànsì ènìyàn sí ààrẹ Buhari àti orílẹ̀ èdè Nàìjíríà.
Nínú ọ̀rọ̀ ìkíni tirẹ̀, igbákejì abẹnugan ilé ìgbìmọ̀ aṣojú, Alhaji Idris Ahmed Wase wá kẹ́dùn pẹ̀lú àarẹ Muhammadu Buhari lórí ikú adarí òṣìṣẹ́ rẹ̀, Mallam Abba Kyari.
Ó wá fi ọ̀rọ̀ ìkẹ́dùn rẹ̀ ránsẹ́ sí àwọn ẹbí olóògbé ọ̀hún àti ìjọba ìpínlẹ̀ Borno.
Adarí ọmọ ẹgbẹ́ tó kéré jùlọ nílé ìgbìmọ̀ aṣojú, Ndudi Elumelu, náà wá sàpèjúwe ikú Abba Kyari gẹ́gẹ́ bí àdánù ńlá fún orílẹ̀ Nàìjíríà pàápàá jùlọ ní irú àsìkò tí a wà yìí.
--- Erín wó! Ààrùn Corona(COVID-19) pa adarí òṣìṣẹ́ ààrẹ Buhari
Adarí òṣìṣẹ́ fún ààrẹ orílẹ̀ èdè Nàìjíríà, Abba Kyari ni ààrùn (COVID-19) ti pa báyìí.
Olùrànlọ́wọ́ ààrẹ Buhari lórí ìròyìn àti ìkéde, Fémi Adésínà ló kéde yìí ní òwúrọ̀ ọjọ́ Àbámẹ́ta pé Mallam Kyari dágbére fáyé lọ́jọ́ Ẹtì (Friday) ọjọ́ kẹtàdínlọ́gbọ̀n ,oṣù kẹrin, ọdún, 2020.
Tí a ò bá gbàgbé pé Mallam Kyari ni wọ́n rí ààrùn COVID-19 lára rẹ̀, tí ó sì ń gba ìwòsàn , kí ó tó di pé ó dágbére fún ayé pé ò dìgbòóse.
Adésínà ni àwọn yóò kéde ètò ìsìnkú láìpẹ́, Ó wá gbàdúrà pé kí Ọlọ́run tẹ̣́ olóògbé náà sí afẹ́fẹ́ ire.
--- COVID-19: Àwọn ènìyàn mọ́kànléláàdọ́ta (51) míràn tún jẹyọ lórílẹ̀ èdè Nàìjíríà
Àwọn ènìyàn mọ́kànléláàdọ́ta (51) míràn tún ti jẹyọ tí wọ́n ní ààrùn Corona (COVID 19 ) lórílẹ̀ èdè Nàìjíríà
Àwọn ìpínlẹ̀ mọ́kàndínlógún ní ààrùn COIVD-19 tí jẹyọ báyìí.
--- COVID-19: Mínísítà ro̩mo̩ Nàìjíríà láti s̩àfihàn àwo̩n a-lo-ò̩nà-àìtó̩ wo̩ e̩nubodè.
Mínísítà fún ètò ọ̀rọ̀ abẹlé, ọ̀gbé̩ni Rauf Aré̩gbé̩ṣolá, ti rọ ọmọ Nàìjíríà láti tú àṣírí àwo̩n a-lo-ò̩nà-àìtó̩ wo̩ ẹnubodè sí Nàìjíríà fún àjọ amójútó ètò ẹnu ibodè ní orílèèdè Nàìjíríà.
Arégbésolá sọ̀yí lásìkò táwọn ikò̩ ìjọba àpapọ̀ amójútó ààrùn COIVD-19 ń dáhùn ìbéèrè lọ́wọ́ àwọn akọròyìn nílùú Àbújá lọ́jọ́bọ̀.
Ó ní ó lòdì sí òfin pé kí ẹnikẹ́ni kó ààrùn COVID-19 wọ orílẹ̀ èdè kan, lásìkò tí àwọn ọmọ orílẹ̀ èdè ọ̀hún sì ń kojú ìpèníjà òfin kónílé-gbélé tí ìjọba àpapọ̀ ṣe.
“Nàìjíríà ti s̩e làálàá púpò̩ láti kápa COVID-19 a sì gbo̩dò̩ kíyèsára ìwo̩lé-àìtó̩, èrè yìí wá pè̩lú ìdojúko̩ ńlá ó sì ti ní ipá lórí ètò o̩rò̩ ajé, ìbás̩epò̩ pè̩lú O̩ló̩run àti ìbás̩epò̩ láwùjo̩ wa.
“A gbó̩dò̩ kín orílèèdè wa lé̩yìn láti dáàbòbò ìlú wa, ìkónimó̩ra àti ìfé̩ni wa èyí tí ó je̩ orílè̩ èdè Nàìjíríà lógún jùlo̩ kò gbo̩dò̩ dí ohun àtè̩mó̩lè̩,” Ó so̩.
Sísò̩rò̩ lórí ìdárìjì ìjo̩ba àpapò̩ sí àwo̩n e̩lé̩wò̩n tí wó̩n tú ú lè̩, Aré̩gbé̩s̩o̩lá ni àádó̩rin e̩lé̩wò̩n ìjo̩ba àpapò̩ ló jàǹfààní ìyò̩nda yìí, tí e̩gbè̩tàlá sì jé̩ tìpínlè̩.
Aré̩gbé̩s̩o̩lá ní Ààre̩ Muhammadu Buhari tin í kí adájó̩ tó ń rísí èyí sowó̩pò̩ pè̩lú àwo̩n ìpínlè̩ láti yò̩nda àwo̩n e̩lé̩wò̩n e̩gbè̩tàlá.
Ó ní pé ìjo̩ba àpapò̩ ń wá ò̩nà láti s̩e àdínkù o̩gbà è̩wò̩n.
Mínísítà wá gbós̩ùbà fún àwo̩n o̩mo̩ Nàìjíríà, pàápàá jùlo̩ àwo̩n àjo̩ elétò ìlera fún ìgbìyànjú wo̩n láti dé̩kun ààrùn COVID-19.
Ó ké sí àwọn ìpínlẹ̀ bíi Èkó, Sókótó, Cross Rivers áti Niger tó ní ààlà pẹ̀lú àwọn orílẹ̀ èdè mííràn láti ri pé wó̩n ń s̩o̩ e̩nu ibodè dáadáa kí àjèjì má baà wo̩ orílè̩ èdè Nàìjíríà ní àkókò yìí.
--- COVID-19: FCTA gbé ìlànà tuntun jáde lásìkò òfin kónílé-gbélé
Ìjọba ìlú Àbújá (The Federal Capital Territory Administration, FCTA) ti gbé ètò ìlànà tuntun jáde lásìkò òfin kónílé-gbéle yìí láti dẹ̣́kun ìtànkálẹ̀ ààrùn COVID-19 nílùú Àbújá.
Gẹ́gẹ́ bí àtẹ̀jáde kan tí ilé-isẹ́ tí ó ń mójútó ìlú Àbújá gbé jáde lórí ẹ̀rọ twitter wọn pé àwọn ti ṣètò ìlànà tuntun lórí ètò kónílé-gbélé ọ̀hún.
Lára àwọn ètò ìlànà tuntun tígbìmọ̀ elétò ààbò ìlú Àbújá alámòójútó ààrùn COVID-19, tí mínísítà FCT, Malam Muhammad Musa Bello jólùdarí ní:
Àwo̩n o̩jó̩ o̩jà ni o̩jó̩rú àti àbámé̩ta nìkan. Ra nǹkan ló̩jà tó súnmó̩ re̩.
Ìdádúró ò̩kadà ní Kubwa àti Dutse.
Ìdásílè̩ ilé-e̩jó̩ alágbèéká láti dájó̩ àwo̩n arúfin.
--- Ààrẹ Buhari bádarí ìjọba Gè̩é̩sì, Johnson yọ̀ fún bíborí Corona
Ààrẹ Nàìjíríà Muhammadu Buhari kí adarí ìjọba Gè̩é̩sì, Boris Johnson kóorííre lé̩yìn tí wó̩n yò̩nda rè̩ níléèwòsàn nítorí kòrónà.
Nínú lé̩tà ìkíni rẹ̀ tó fi ránsẹ́ ní April 14, 2020, sí ọ̀gbẹ́ni Johnson, ààrẹ̀ Buhari ní, “Inú mi dùn lásìkò tí mo gbọ́ròyìn ayọ̀ pé ó kúrò nílé-ìwòsàn àìlárùn kòrónà mó̩.”
Ààrẹ Buhari gbàdúrà fún adarí ọ̣̀hún, pé kỌlọ́run fun lálàáfíà pípé ní gbogbo ọjọ́ ayé rẹ̀.
--- COVID-19: China ló báààrùn kòrónà jà kì í s̩e o̩mo̩ Nàìjíríà tàbí aláwò̩dúdú ní China – Mínísítà
Ìjọba orílèèdè Nàìjíríà ní ìjo̩ba China ló ń kojú ààrùn kòrónà kìí s̩e pé wó̩n kórìíra tàbí s̩àìda sí o̩mo̩ Nàìjíríà tàbí aláwò̩dúdú tó ń gbe Guangzhou ní China.
Mínísítà fún ètò ọ̀rọ̀ ilẹ̀ òkèèrè, ọ̀gbẹ́ni Geoffrey Onyeama, àti aṣojú orílẹ̀ èdè China ní Nàìjíríà, Zhou Pingjian,ní wọn sọ̀rọ̀ yìí fún àwọn akọ̀ròyìn nílùú Àbújá.
Okùnfà ni fídíò kan tí àwo̩n o̩mo̩ Nàìjíríà fihàn káàkiri, tó ń s̩àfihàn ohun búburú tí àwo̩n o̩mo̩ China fojú wa rí ló̩hùn-ún.
Mínísítà tẹ̀síwájú pé arábìnrin kan tó ń ta oúnjẹ nílùú Guangzhou, ní China, alárùn COVID-19 lọ́dún 2019 pẹ̀lú àwọn ọmọ Nàìjíríà tí wọ́n ra oúnjẹ ló̩dò̩ rè̩ fara káása ààrùn kòrónà, wó̩n fé̩ fi wó̩n sí ìgbélé s̩ùgbó̩n tí ò̩rò̩ gbabòmíràn nípasè̩ àìgbó̩nràn.
Mínísítà tún ní ìbásepọ̀ tó mọ́nyán lórí wà láàrín orílẹ̀ èdè China àti orílẹ̀ èdè Nàìjíríà, orílẹ̀ èdè méjèèjì yìí sí ti ń fọwọ́sowọ́pọ̀ láti yanjú wàhálà ọ̀hún.
--- COVID-19: Ààrẹ Buhari gbósùbà fún akọ̀ròyìn, àjọ elétò ààbò àti ì̀lera
Ààrẹ Muhammadu Buhari ti dúpẹ́ lọ́wọ́ àwọn akọ̀ròyìn, àjọ tó ń mójútó ètò ìlera, àwọn ilé-isẹ́ ètò ààbò fún gudu gudu méje yàyà mẹ́fà tí wọ́n ń ṣe lórílẹ̀ èdè yìí láti dẹ́kun ìtànkalẹ̀ ààrùn COVID-19.
Lákòókò ìgbóhùnsáfẹ́fẹ́ sí àwo̩n ọmọ orílẹ̀-èdè Nàìjíríà ló̩jó̩ ajé, Ààre̩ ní:
Mo gbó̩dò̩ mo̩ rírì àwọn òṣìsẹ́ ètò ìlera àti àwọn tí ó fara wọn jìn ní jákèjádò orílẹ̀ èdè Nàìjíríà, pàápàá jùlọ ní ìpínlẹ̀ Èkó, Ògùn àti ní olú ìlú Nàìjíríà, ìye̩n Abuja.
“Ẹ̀yin ni akọni wa gẹ́gẹ́ bí orílẹ̀-èdè, fún o̩jó̩ ayé wa gbogbo lá máa dúpẹ́ lọ́wọ́ yín fún ìfarajìn yin lásìkò ìpèníjà yìí.
A máa pèsè ohun amóríwú fún àwọn òṣìṣẹ́ ètò ìlera, léyìí táa kéde lọ́sẹ̀ tó ń bọ̀.
Mo tún dúpẹ́ lọ́wọ́ gbogbo ilé-isẹ́ ìròyìn , àwọn gbajú-gbajà òṣ̣èré àti àwọn ènìyàn pàtàkì láwùjọ fún iṣẹ́ ribi-ribi wọn láti máa la àwọn ènìyàn lọ́yẹ̀ nípa ìmọ́tótó, yìyẹra àti ohun tó ní ṣe pẹ̀lú ìpéjọ.
Látàrí àwọn àtìlẹyìn àti ìfọwọ́sowọ́pọ̀ yìí, ọ̀pọ̀lọpọ̀ àwọn àseyọrí ni a ti ṣe lásìkò ètò kónílé-gbélé ọjọ́ mẹ́rìnlá tí a ṣe.
Àwọn ẹ̀ṣọ́ ètò ààbò àti agbófinró náà kò gbẹ́yìn láti kojú ìpèníjà yìí, mo kan sáárá sí wọn.
Mo rọ̀ wọ́n láti túbọ̀ máa ṣ̣e ojúṣe wọn bíi iṣẹ́ lásìkò ètò kónílé-gbélé yìí, kí wọ̣́n sì tún máá gbàgbé ojúṣe wọn.
Àwọn adarí orílẹ̀ èdè yìí nígbàgbọ́ pé ìgbésẹ̀ tí wọ́n ń gbé yìí ní láti dẹ́kun ìtànkálẹ̀ ààrùn COVID-19.
--- Ọwọ́ ọlọ́pàá tẹ ọ̀daràn tó pa ajíhìnrere Grace Ajíbọ́lá nílùú Ìbàdàn
Ilé- iṣẹ ọlọ́pàá ní ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́ ti se àfihàn afurasí ọ̀daràn kan, Abégúndé Oláníyì tó lọ́wọ́ nínú ikú Abilékọ Grace Ajíbọ́lá tí ṣe ajíhìnrere ní ilé ìjọsìn ọmọlẹ́yìn Kristi kan ní agbègbè Olúyọ̀lé ní ìlú Ìbàdàn tó wà ní ẹkùn Gúsù ìwọ̀ oòrùn orílẹ̀ èdè Nàìjiríà ní ọjọ́ kẹtàdínlógún oṣù kẹta ọdún 2020 yìí.
Nínú àlàyé rẹ̀, kọmísọ́nà ọlọ́pàá, Shínà Olúkólù jẹ́ kí ó di mímọ́ pé afurasí ọ̀daràn yìí pa abilékọ Grace Ajíbọ́lá lẹ́yìn tí ó gba owó tó lé ní mílíọ́nù méjì náírà nínú àpò ìfowópamọ́ rẹ̀.
Sùgbọ́n ọwọ́ pálábá afurasí yìí ségi nígbà tí ọ̣wọ́ ilé-isẹ́ ọlọ́pàá ìpínlẹ̣̀ Ọ̀yọ́ gbáa mú, tí wọ̣́n sì fi kélé òfin gbé e.
Ilé- iṣẹ ọlọ́pàá tún rí àwọn nǹkan bíi oríṣi káádì ilé –ìfowópamọ́ mẹ́ta tí wọ́n fi ń gba owó lẹ́nu ẹ̀rọ pọwó-pọwó (ATM) gbà, ẹ̀rọ ìléwọ́ ìbáraẹni sọ̀rọ̀ Techno, orísiirísii aṣọ àti igi tí ó fi pa arábìnrin náà gbà.
Bákan náà, ní Ilé- isẹ́ ọlọ́pàá ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́ tún ṣe àfihàn àwọn afurasí mọ́kàndínlógún míràn tí wọ́n lọ́wọ́ nínú onírúurú ìwà ọ̀daràn bíi ìjínigbé, ìjínipa àti ìdigunjalè ní àwọn àgbègbè kan ní ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́.
Lára àwọn ohun tí Ilé-isẹ́ ọlọ́pàá tún rí gbà lọ́wọ́ àwọn afurasí wọ̀nyí ni ìbọn- ìléwọ́ méjì; ohun ìjà mẹ́ta; kẹ̀kẹ́ alùpùpù tí a mọ̀ sí ọ̀kadà mẹ́fà àti àwọn ohun mìràn bíi: ọ̀bẹ kan; àdá ẹyọ kan; àti owó tó lé díẹ̀ ní ọ̀kẹ́ Mẹ́rìndínlógún àti ààbọ̀ náírà.
Kọmísánà Ilé- iṣẹ ọlọ́pàá, Shínà Olúkólù wá fi kún ọ̀rọ̀ rẹ̀ pé kí àwọn ènìyàn ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́ máṣe fòyà nítorí Ilé- isẹ́ ọlọ́pàá tí setán láti pèsè ètò ààbò tó péye fún ẹ̀mí àti dúkìá wọn ní pàtàkì jùlọ ní àsìkò ìkéde kónílé- ó- gbélé tó ń lọ lọ́wọ́ látàrí ìtànkálẹ̀ àjàkálẹ̀ ààrùn COVID-19 tó ń bá gbogbo orílẹ̀ èdè àgbáyé wọ̀yá ìjà.
--- COVID-19. A ò ní foríjin ẹni tó bá tàpá sófin kónílé-gbéle- Kọmísọ́nà ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́
Kọmísọ́nà àwọ̣n ọlọ́pàá ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́, Shina Olúkolú ti fi ìpè síta pé àwọn kò ní foríjin ẹni tó bá tàpá sófin kónílé-gbélé ní ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́.
Ó tẹ̀síwájú pé ẹ̣ni tó bá fọwọ́ pa idà ìjọba lójú yóò fojú ba ilé-ẹjọ́ láti jẹ ìyà tó bá tọ́ lábẹ́ òfin.
Kọmísánà àwọn ọlọ́pàá ló ṣíṣọ lójú ọ̀rọ̀ yí lásìkò tí ó ń se àfihàn àwọn afurasí ọ̀daràn tí kò dín ní ogún ní olú- ilé isẹ́ ọlọ́pàá ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́ tó wà ní agbègbè Ẹlẹ́yẹlé ní ìlú Ìbàdàn tó wà ní ẹkùn gúsù ìwọ̀ oòrùn orílẹ̀ èdè Nàìjíríà.
Nínú àlàyé rẹ̀ komísánà jẹ́ kí ó di mímọ̀ pé Gómìnà ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́, Sèyí Mákindé se àgbékalè òfin kónílé ó gbélé ní ara ọ̀nà láti dènà ìtànkálẹ̀ àjàkálẹ̀ ààrùn Corona virus tí a mọ̀ sí COVID-19.
Òfin kónílé ó gbélé yìí ní Gómìnà ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́ ti fi múlẹ̀ láti ọjọ́ kọkàndínlọ́gbọ̀n osù kẹta ọdún 2020 yìí, nínú èyí tí ìjọba fi òfin de ẹnikẹ́ni láti máse jáde síta láti aago méje alẹ́ títí di aago mẹ́fà àárò ọjọ́ kejì.
Òfin yìí kò fi ààyè gba ẹnikẹ́ni lábẹ́ bó ti wù kórí láti se ohunkóhun lẹ́yìn aago méje alẹ̣́ lójoojúmọ́.
Sùgbọ́n komísánà wá fi àìdùnnú rẹ̀ hàn sí ìwà àìgbọràn tí àwọn kan ń hù láti máa bá àwọn ọlọ́pàá wọ̀yá ìjà tó bẹ́ẹ̀ tí wọ́n fi di èrò ilé- ìwòsàn.
--- COVID-19: Àwọn ènìyàn márùn ún (5) míràn tún jẹyọ lórílẹ̀ èdè Nàìjíríà
Àwọn ènìyàn márùn ún (5) míràn tún jẹyọ tíwọ́n ní ààrùn Corona (COVID 19 ) lórílẹ̀ èdè Nàìjíríà, ní èyí tí ó jẹ́ kíiye àwọn tó ní ààrùn Corona jẹ́ mẹ́tàlélógúnlélọ́ọ̀dúnrún (323), nígbà tí àwọn ènìyàn bíi márùndínláàdọ́rùnún (85) ti gba ìwòsàn , tí àwọn ènìyàn mẹ́wàá (10) ṣì ti j́ẹ Ọlọ́run nípè. Àjọ tó ń gbógun ti àjàkálẹ ààrùn lórílẹ̀ èdè Nàìjíríà (NCDC) ló kéde yìí lórí ẹ̀rọ Twitter wọn, @NCDCgov,.
Nínú àwọn mẹ́jọ tí wọ́n ṣẹ̀ṣẹ̀ jẹyọ ọ̣̀hún ,méjì ( 2) ní ìpínlẹ̀ Kwara ,méjì (2) ní ìpínlẹ̀ Èkó ,ẹyọ kan ( 1 ) ní ìpínlẹ̀ Katsina. Ìpínlẹ̀ tí ààrùn Corona ti jẹ yọ lórílẹ̀ èdè Nàìjíríà ti jẹ́ ìpínlẹ̀ mọ́kàndínlógún (19) báyìí. Adémọ́lá Adépọ̀jù.
--- COVID-19: Ẹ máa lo òṣèlú fún akitiyan ìjọba nípa ààrùn Corona-IBB
Ajagunfẹ̀yìntì , tó tún jẹ́ ààrẹ tẹ́lẹ̀rí fún orílẹ̀ èdè Nàìjíríà , Ibrahim Badamasi Babangida ti rọ gbogbo àwọn tí ọ̀rọ̀ láti máá ṣe fi lo òṣèlú fún akitiyan ìjọba nípa ààrùn Corona.
Ó wá gbósùbà fún àwọn òṣìṣẹ́ ìjọ̣ba lórí akitiyan wọn láti dẹ́kun ààrùn Corona. Ajagunfẹ̀yìntì, Ibrahim Bàbángídá sọ̀rọ̀ yìí lọ́jọ́ Àìkú nílùú Minna, ní ìpínlẹ̀ Niger, ó tún wá gbósùbà fún àwọn gómìnà ìpínlẹ̀, àwọn àjọ elétò ìlera fún ipa pàtàkì tí wọ́n ń kó láti dẹ́kun ààrùn Covid-19 lórílẹ̀ èdè Nàìjíríà , bó tilẹ̀ jẹ́ pé iye àwọn tó ní ààrùn ọ̀hún sì ń pọ̀ si lójoojúmọ́.
Ó wá rọ gbogbo ọmọ orílẹ̀ èdè Nàìjíríà láti máa tẹ̀lé gbogbo ìlànà tí àwọn àjọ elétò ìlera àti àjọ tó ń gbógun ti ìtànkálẹ̀ ààrùn (NCDC) bá là sílẹ̀ láti dẹ́kun ààrùn COIVD-19.
--- Easter: Abẹnugan ìpínlẹ̀ Ọ̀ṣun rọ Nàìjíríà láti ní ìrètí nínú Ọlọ́run
Abẹnugan ilé ìgbìmọ̀ aṣòfin ti ìpínlẹ̀ Ọ̀sun, ọ̀gbẹ́ni Timothy Owóèye,ti rọ gbogbo àwọn ọmọ lẹ́yìn Krísít̀i àti orílẹ̀ èdè Nàìjíríà láti mú ìrètí wọn dúro ṣinṣin bó tilẹ̀ jẹ́ pé àjàkálẹ̀ wà lórílẹ̀ èdè Nàìjíríà.
Owóèye sọ̀rọ̀ yìí lọ́jọ́ Àbámẹ́ta nínú àtẹ̀jáde rẹ̀ fún àjọ̀dún Ọjọ́ Àjíǹde , ó ní kì í ṣe ààrùn Corona ni yóò jẹ́ kí òpin ayé dé.
Ó wá rọ̣ àwọn ojúlówó ọmọ orílẹ̀ èdè Nàìjíríà láti ṣèrànwọ́ ohun ìdẹ̀rùn fún àwọn tó nílò ìrànlọ́wọ́.
Ó tẹ̀síwájú pé: A gbọdọ̀ jẹ́ kí àjọ̀dún Àjíǹde ti Krísítì yìí ní ipa pàtàkì nínú ìbásepọ̀ pẹ̀lú àwọn ẹlòmíràn.
A kò gbọdọ̀ dá ètò ìrànwọ́ fún àwọ̣n ènìyàn lásìkò ààrùn COVID-19 yìí dá ìjọba àti àwọn olósèlú nìkan.
Kò sí àríyànjiyàn pé àsìkò tí a wà yìí le púpọ̀ sùgbọ́n a gbọdọ̀ mú ìgbàgbọ́ wa dúró sinsin nínú Ọlọ́run, kí a sì ní ìrètí pé,bó tilẹ̀ wù kí ó le tó, ìgbà sì ń bọ̀ wá dẹ̀ .
--- Ààrùn COVID-19
Ààrun COVID-19 jẹ́ ààrùn asekúpani , tó tún jẹ́ kí gbogbo ètò ọrọ̀ ajé orílẹ̀ èdè àgbáyé dojúbolẹ̀.
Èyí ló mú kí ìjọba àpapọ̀ orílẹ̀ èdè Nàìjíríà gbé ìgbéṣẹ̀ láti sòfin kónílé-gbélé ní ìpínlẹ̀ Èkó, Ògùn àti Àbújá, láti dáàbò bò ẹ̀mí tonílé-tàlejò tó wà lórílẹ̀ èdè Nàìjíríà.
Nípa títẹ̀lé ètò ìlànà tí àjọ tó ń mójútó ètò ìlera là sílẹ̀ àti ìgbọràn sí òfin ìgbélé nìkan ló leè mú wa borí.
--- Easter: Ẹ jẹ́ kí ìgbàgbọ́ yín duro ṣinṣin – Sèyí Mákindé, Oyo State Governor
Góm̀inà ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́ , Sèyí Mákindé ti rọ àwọn ọmọ lẹ́yìn Krísítì láti mú ìgbàgbọ́ wọn dúró ṣiniṣin nínú agbára Àjíǹde Krísítì páàpáà jùlọ lásìkò tí gbogbo àgbáyé ń kojú ìpèníjà ààrùn Corona.
Góm̀inà ṣọ̀rọ̀ yìí nínú ọ̀rọ̀ Àjíǹde tí ó fi ránṣẹ́ sí àwọn ọmọ ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́.
Mákindé tún sọ pé, “Ayẹyẹ Àjíǹde, máa ń ran àwa ọmọ lẹ́yìn Kristi létí nípa ìgbàgbọ́ wa, Ìgbàgbọ́ nínú agbára Àjíǹde.
A gbọ́dọ̀ nígbàgbọ́ nípa ohun tí a kò fojúrí ,pàápàá jùlọ lásìkò tí gbogbo àgbáyé wà nínú ewu ààrùn COVID-19.
Ó tẹ̀síwájú pé bó tilẹ̀ jẹ́ pé àjàkálẹ̀ ààrùn Corona ti jẹ́ kí àwọn ọmọ ìpínlẹ̀ náà wà nínú ìgbélé , tí kò sì leè jẹ́ kí wọ́n lọ sí ibi iṣẹ́ òòjọ́ wọn, tí ó tún jẹ́ kí ó nira fún púpọ̀ àwọn ọmọ ìpínlẹ̀ náà láti pèsè fún àwọn ẹbí wọn gẹ́gẹ́ bí ìṣe wọn.
Gómìnà Mákindé wá ṣèlérí pé ìjọba yóò mú ìgbáyé-gbádùn àwọn ará ìpínlẹ̀ náà lọ́kùńkúndùn.
Gómìnà wá rọ àwọn ọmọ ìpínlẹ̀ náà láti dúró sínú ilé wọn, kí wọ́n sì wà ní àlàáfíà.
--- Ọ̀RỌ̀ ÀÀRẸ MUHAMMADU BUHARI FÚN AYẸYẸ ỌJỌ́ ÀJÍǸDE KRISTI FÚN ỌDÚN 2020 SÍ GBOGBO ỌMỌ ORÍLẸ̀ ÈDÈ NÀÌJÍRÍÀ
Mo bá àwọn arákùnrin, arábìnrin ọmọ lẹ́yìn kristi àti gbogbo ọmọ orílẹ̀ èdè Nàìjirià yọ̀ lórí ayẹyẹ ọjọ́ Àjíǹde Kristi ti ọdún yìí.
Ìrántí Àjíǹde ọdún yìí wáyé lásìkò tí ìtànkálẹ̣̀ ààrùn COVID-19 jẹyọ ní gbogbo àgbáyé.
Bó tilẹ̀ jẹ́ pé gbogbo àwọn ọmọ lẹ́yìn Kristi ní wọn bá ara wọn láti ṣe ayẹyẹ ọjọ́ Àjíǹde ní ọ̀nà ìrẹ̀lẹ̀ yàtọ̀ si bí wọ́n ṣẹ máa ń ṣe ayẹyẹ ọ̀hún nílé-ìjọ́sìn wọn.
Eleyìí jẹ́ kàyéfì àti ìbànújẹ́ púpọ̀.
Síbẹ̀síbẹ̀, Mo fẹ́ rọ gbogbo àwọn ọmọ lẹ́yìn kristi láti mú ìgbàgbọ́ wọn dúró ṣinṣin nínú Kristi, tí ó borí inúnibíni, àwọn ìjìyà àti ìfaradà, àti ju gbogbo rẹ̀ lọ, ìwà-bí-Ọlọ́run.
Jésù Kristi dúró fún agbára ènìyàn láti farada àwọn ìrora ìgbà díẹ̀ ní ìrètí ògo ayérayé.
Mo rọ̀ yín láti gbé ìgbé ayé ìrẹ̣̀lẹ̀, ìbáwí, ìfaradà, ìrúbọ àti ìgbọràn, ní èyí tí Jésù Kristi ṣe àfihàn rẹ̀ lákòókò tó wà nílé ayé.
Kò sí ànfààní tí ó dára ju eléyìí lọ fún gbogbo àwọn Krìstìẹ́nì, ní pàtàkì jùlọ, gbogbo àwọn ọmọ orílẹ̀ èdè Nàìjíríà lápapọ̀, láti jẹ́ olóòtítọ́, kí wọ́n tún ní ìrètí pé, pẹ̀lú àdúrà gbígbà àti nípasẹ̀ ìdúróṣinṣin yálà lọ́kọ̀ọ̀kan tàbí lápapọ̀, ó di dandan kí orílẹ̀-èdè wá borí awọn ìpèníjà wọ̀nyí.
Èmi kò ní iyèméjì pé tí gbogbo àwọn alábàṣepọ̀, ẹnì-kọ̀ọ̀kan àti àwọn ẹgbẹ́, ba sa ipá wọn ní kíkún, tí a sì tẹ̀lé ìmọ̀ràn láti ọ̀dọ̀ àwọn onímọ̀-ìjìnlẹ̀ àti àwọn tó ní òye nípa ìṣòògùn tó lè dẹ́kun ààrùn COVID-19, ó dájú pé ìpinnu tí àwọn ènìyàn wá ní, yóò jẹ́ kí a borí.
Gẹ́gẹ́ bí mo ti ṣàlàyé sẹ́yìn nínú ìgbóhùnsáfẹ́fẹ́ tí mo ṣe fún orílẹ̀-èdè yìí lọ́jọ́ Àìkú, Ọjọ́ kọkàndínlọ́gbọ̀n, ọdún 2020, pé , níwọ̀n ìgbà tí kò sí abẹ́rẹ́ àjẹsára tí a mọ̀ lọ́wọ́lọ́wọ́ tó lè gbógun ti ààrùn náà, ọ̀nà tí ó dára jùlọ àti tí ó múnádóko ni láti yàgò fún ààrùn ọ̀hún nípasẹ̀ ṣíse ètò ìmọ́tótó déédé àti nípa yíyẹra fún ìpéjọ àpapọ̀.
Mo tún ń lo ànfààní yìí láti gbósùbà fún ìgbìmọ̀ ìjọba àpapọ̀ fún àwọn ìlànà tí wọ́n ń gbé láti dẹ́kun ààrùn COVID-19.
Mo mọ̀ nípa àwọn ìníra àti ìjìyà tí ẹnìkọ̀ọ̀kan àti àwọn ènìyàn ń dojúkọ nípasẹ̀ ìgbésẹ̀ bíí ìgbélé àti bí a kò ṣe jẹ́ kí wọ́n lọ síbi isẹ́ òòjọ́ wọn.
Bó se jẹ́ pé ó níí ṣe pẹ̀lú “ọ̀rọ̀ ìyè àti ikú,” àwọn ìpèníjà wọ̀nyí la ní láti kojú fún ìfẹ́ ara wa láti gba orílẹ̀-èdè yìí lọ́wọ́ àjàkálẹ̀ ààrùn.
Ìgbáyé-gbádùn àwọ̣n ènìyàn mi ló jẹ mí lógún jùlọ.
Nítorí náà, ìdàgbàsókè ètò ọrọ̀ ajé orílẹ̀ èdè yìí ṣe pàtàkì nínú èròǹgbà wa, A ó sì tún gbìyànjú láti pèsè àwọn ohun tí ẹnu ń jẹ fún àwọn ènìyàn.
Lákòókò tí a rí àjàkálẹ̀-ààrùn COVID-19, tó jẹ́ ìpèníjà káríayé, ìjọba yìí kò saláìmọ̀ gbogbo wàhálà tí àwọn oníjàgídíjàgan àti ọlọ̀tẹ̀ ń fà lórí ètò ààbò orílẹ̀-èdè wa.
Wọ́n le loo àǹfààní yìí láti ṣe àwọn ìkọlù kan sí orílẹ̀ èdè wa.
Ṣùgbọ́n àwọn ikọ̣̀ olóógun, àwọn àjọ elétò ààbò àti àjọ tó ń ṣe ìtọpinpin sì dúró ṣinṣin láti máa gbógun ti gbogbo ìkọ̣lù tó bá fẹ́ sẹlẹ̀.
Bíi a ṣe ń sàmì sí ọjọ́ Àjíǹde ti ọdún yìí, ohunkóhun tó bá wù kó jẹ́, Mo gbà yín níyànjú làti ṣàmúlo ipò tí a wà yìí , kí a sì gbiyànjú láti sètọ́jú ara wa , kí a sì wà ní àìléwu.
Mo kí gbogbo yín kú àjọ̀dún ọjọ́ àjíǹde Kristi.
Muhammadu Buhari Ààrẹ orílẹ̀ èdè Nàìjirià
--- Ó gbóná fẹli-fẹli:Ìjàm̀bá iná ṣẹlẹ̀ nílé-iṣẹ́ ìsirò –owó
Ilé-isẹ́ paná-paná ti ní àwọn ti pa iná tó ń jó ilé- iṣẹ́ ìṣirò –owó orílẹ̀ èdè Nàìjíríà (Accountant General of the Federation).
--- COVID-19: Àwọn ènìyàn mẹ́fà (6) míràn tún jẹyọ lórílẹ̀ èdè Nàìjíríà
Àwọn ènìyàn mẹ́fà (6) míràn tún jẹyọ tí wọ́n ní ààrùn Corona (COVID 19 ) lórílẹ̀ èdè Nàìjíríà
Ní èyí tí ó jẹ́ kí iye àwọn tó ní ààrùn Corona jẹ́ òjìlénígba dín méjì (238), nígbà tí àwọn ènìyàn bí márùndínlógójì(35) ti gba ìwòsàn , tí àwọn ènìyàn márùn ún (5) sì ti jẹ́ Ọlọ́run nípè.
--- Ẹ pín ìrẹsì tí ẹ gbà lọ́wọ́ àwọn fàyàwọ́ fún ọmọ orílẹ̀ èdè Nàìjíría-Buhari
Ààrẹ̣ orílẹ̀ èdè Nàìjíría, Muhammadu Buhari ti pàṣẹ pé kí ilé-iṣẹ́ aṣọ́bodè pín ọkọ̀ àádọ́jọ (150) ìrẹsì tí wọ́n gbá sílẹ̀ lọ́wọ́ àwọn fàyàwọ́ fún gbogbo ìpínlẹ̀ tó wà lórílẹ̀ èdè Nàìjíría.
Mínísítà fún ètò ìnáwó, ìsúná àti ètò ìlànà , abilékọ Zainab Ahmed ló sọ̀rọ̀ yìí pẹ̀lú àwọn akọ̀ròyìn , nílùú Àbújá.
Ahmed tún sọ pé gbogbo àwọ̣n ọkọ̀ ìrẹsì ọ̀hún ni wọ́n ti fi ránsẹ́ sí àjọ tó ń mójútó ètò ọmọnìyàn àti ìṣẹ̀lẹ̀ pàjáwìrì láti pín àwọn ìrẹsì náà káàkiri.
Ahmed ní ààrẹ tún ti fọwọ́sí àwọn ètò ìrànwọ́ irúgbìn tí wọn yóò kó lọ sí àwọn apá ibìkan lórílẹ̀ èdè Nàìjíríà.
Mínísítà tún tẹ̀síwájú pé ìjọba ti dín owó tí àwọn àgbẹ̀ máa ń fi ra ajílẹ̀ láti ẹgbẹ̀rún márùn ún ààbọ̀ sí ẹgbẹ̀rún márùn ún náírà fún báàgì ajílẹ̀ kan.
Ó tún sọ̣ pé àwọn ètò ìrànwọ́ míiràn yóò tún wá fún gbogbo àwọn ọmọ orílẹ̀ èdè Nàìjíríà.
--- Ọjọ́ Àjíǹde kristi: Ìjọba orílẹ̀ èdè Nàìjíríà pàṣẹ ọjọ́ Ẹtì, Ajé fún ìsinmi
Ìjọba orílẹ̀ èdè Nàìjíríà ti pàṣẹ pé kí ọjọ́ Etì, ọjọ́ kẹwàá, oṣù kẹrin (April 10) àti ọjọ́ kẹtàlá , ọjọ́ Aje ́ jẹ́ ìsinmi láti fi sayẹyẹ àjọ̀dún Àjíǹde ti krisiti.
Mínísítà fún ètò abẹ̣́lé, ọ̀gbẹ́ni Rauf Arégbéṣọlá ló kéde yìí nípasẹ̀ ìjọba àpapọ̀ lọ́jọ́ Ajé, nílùú Àbújá.
Arégbéṣọlá wá rọ gbogbo àwọn ọmọlẹ́yìn kristi láti máa ṣàwòkọ́ṣẹ ìwà àti àbùdá Jésù kristi nípa fífi ẹ̀mí ìfẹ́, àlááfìa àti àànú hàn nínú ìwà àti ìṣe wọn.
Arégbéṣọlá tún wá gbogbo ọmọ lẹ́yìn kristi láti lo àsìkò ayẹyẹ ọ̀hún fi gbàdúrà fún orílẹ̀ èdè Nàìjíríà àti gbogbo àgbáyé lápapọ̀ páàpáà jùlọ lásìkò àjàkálẹ̀ ààrùn COVID-19 tó gba gbogbo ayé kan.
Mínísítà tún rọ̣ gbogbo ọmọ orílẹ̀ èdè Nàìjíríà láti máa sàtìlẹyìn fún gbogbo ìgbìyànjú ìjọ̣ba àpapọ̀ nípa gbígbógun ti ààrùn Corona.
Ó wá rán gbogbo ọmọ orílẹ̀ èdè Nàìjíríà létí nípa àwọn ètò ìlànà tí àwọn aláṣẹ ti là sílẹ̀ lọ́nà àti dẹ́kun ìtànkálẹ̀ ààrùn Corona lórílẹ̀ èdè yìí pàápàá jùlọ nípa yíyẹra fún ènìyàn àti ṣíṣe ìmọ́tótó lásìkò ayẹyẹ ọ̀hún.
Arégbéṣọlá wá kí gbogbo àwọn omọ lẹ́yìn kristi kú ayẹyẹ àjọ̀dún Àjíǹde.
--- COVID-19: Gómìnà ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́ yege àyẹ̀wò, yóò bẹ̀rẹ̀ iṣẹ́ lónìí
Gómìnà ìpínlẹ̣̀ Ọ̀yọ́, Ṣ̣èyí Mákindé ti ní òun yege níbi àyẹ̀wò kejì tí wọ́n ṣe fún òun nípa ààrùn Corona, ó wá ṣèlérí láti bẹ̣̀rẹ̀ iṣẹ́ rẹ̣̀ lónìí, tó jẹ̣́ ọjọ́ Ajé.
Mákindé sọ̀rọ̀ yìí láṣàálẹ́ ọjọ́ Àìkú lórí ẹ̀rọ Twittre rẹ̀ lásìkò tí o gba àbájáde èsì àyẹ̀wò kejì ọ̀hún.
Ọgbọ̀ọjọ́ oṣù kẹta ni gómìnà Mákindé sọ̀rọ̀ lórí ẹ̀rọ Twitter rẹ̀ pé, òuń ní ààrùn Conona, ìyẹn COVID-19.
Láti ìgbà yẹn ni gómìnà ọ̀hún ti wà nínú ìgbélé, kí ó tó di pé ó gba àbájáde èsì kejì nípa ààrùn Corona, ní èyí tí ó sọ pé kò ní ààrùn yìí.
--- COVID-19: Àwọn ènìyàn mẹ́jọ (8) míràn tún jẹyọ lórílẹ̀ èdè Nàìjíríà
Àwọn ènìyàn mẹ́jọ (8) míràn tún jẹyọ tí wọ́n ní ààrùn Corona (COVID 19 ) lórílẹ̀ èdè Nàìjíríà, ní èyí tí ó jẹ́ kí iye àwọn tó ní ààrùn Corona jẹ́ òjìlénígbadínmẹ́jọ (232).
Àjọ tó ń gbógun ti àjàkálẹ̀ ààrùn lórílẹ̀ èdè Nàìjíríà (NCDC) ló kéde yìí lórí ẹ̀rọ̀ Twitter wọn, @NCDCgov,ní àṣálẹ́ ọjọ́ Àìkú,ọjọ́ karùn ún, oṣù kẹrin (Sunday 5th April ) ní déédé aago Mẹ́sàn án ààbọ̀( 9:30 P. m,Local Time).
Nínú àwọn mẹ́jọ tí wọ́n ṣẹ̀ṣẹ̀ jẹyọ ọ̀hún ,márùn ún ( 5) ní ìpínlẹ̀ Èkó ,ẹyọ kan ( 1 ) ní ìlú Àbújá, Federal Capital Territory (FCT) àti ẹyọ kan (2) ní ìpínlẹ̀ Kàdúná.
--- COVID-19: Gómìná ìpínlẹ̀ Èkó yóò tẹ̀síwájú nípa ètò ìrànwọ́
Gómìná ìpínlẹ̀ Èkó,ọ̀gbẹ́ni Babájídé Sanwó-Olú, ti kéde pé àwọn kò ní dáwọ́ ètò ìrànwọ́ tí wọ́n ń pèsè fún àwọn tó kù díẹ̀ fún àti àwọn tí kò rọ́wọ́ họrí tí òfin ìgbélé ọjọ́ mẹ́rínlà tí ìjọba àpapọ̀ kéde rẹ̀ leè pa wọ́n lára.
Sanwó-olú sọ̀rọ̀ yìí lẹ́yìn ìpàdé ìgbìmọ̀ aláákóso fún ètò ààbò tó wáyé ní ilé-gomínà ní ìpínlẹ̀ Èkó, pé gbogbo gbèsè tí àwọn aláìsàn, aláboyún àwọn tó wà nínú ewu pàjáwìrì, àwọn tí wọ́n fẹ́ ṣe iṣẹ́ abẹ fún tí wọ́n wà nílé-ìwòsàn alábọ́dé tàbí tí ìjọba ìpínlẹ̀ lásìkò òfin ìgbélé yìí ni àwọn ti san gbogbo owó tí wọ́n jẹ nílé ìwòsàn.
Sanwó-Olú ní àwọn gbé ìgbésẹ̀ yìí láti jẹ́ kí ara tu àwọn aláìsàn , tí òfin ìgbélé ọ̀hún pa iṣẹ́ wọn lára lásìkò ààrùn COVID-19.
Ó wá rọ̣ àwọn ọmọ ìpínlẹ̀ Èkó láti túnbọ̀ mú sùúrù fún ìjọba, Sanwo-Olu ní òfin ìgbélé náà tí ń so èso rere, ní èyí tí ó jẹ́ kí àjọ ètò ìlera àti àjọ tó ń gbógun tí ààrùn lórílẹ̀ èdè yìí leè máa tọpinpin àwọn tó ní ààrùn Corona, tí wọ́n tì si ń gba ìtọ́jú ní ilé –ìtọ́jú àwọn aláìsàn tó wà ní, Yaba.
Sanwó-Olú wa tẹpẹlẹ mọ́ ìgbesẹ̀ ìjọba láti túbọ̀ máa dáàbò bo ẹ̀mí àti dúkìá àwọn ará ìlú.
Ó wá kìlọ̀ fún àwọn jàǹdùkú tí wọ́n leè fẹ́ máa lo àsìkò yìí láti da omi àlàáfíà rú, pé àwọn ti sọ fún agbófinró láti pèsè ètò ààbò fún ìpìnlẹ̀ náà fún wákàtí mẹ́rìnlélógún.
--- COVID-19: Àwọn ènìyàn mẹ́wàá (10) míràn tún jẹyọ lórílẹ̀ èdè Nàìjíríà
Àwọn ènìyàn mẹ́wàá (10) míràn tún jẹyọ tí wọ́n ní ààrùn Corona (COVID 19 ) lórílẹ̀ èdè Nàìjíríà, ní èyí tí ó jẹ́ kí iye àwọn tó ní ààrùn Corona jẹ́ okòólénígba àti mẹ́rìn (224).
Nínú àwọn mẹ́wàá tí wọ́n ṣẹ̀ṣẹ̀ jẹyọ ọ̀hún ,mẹ́fà ( 6) ní ìpínlẹ̀ Èkó ,méjì ( 2 ) ní ìlú Àbújá, Federal Capital Territory (FCT) àti méjì (2) ní ìpínlẹ̀ Edó.
--- COVID-19: Àwọn ènìyàn márùn ún míràn tún jẹyọ lórílẹ̀ èdè Nàìjíríà
Àwọn ènìyàn márùn ún míràn tún jẹyọ tí wọ́n ní ààrùn Corona (COVID 19 ) lórílẹ̀ èdè Nàìjíríà, ní èyí tí ó jẹ́ kí iye àwọ̣n tó ní ààrùn Corona jẹ́ okòólénígba dín mẹ́fa (214).
Àjọ tó ń gbógun ti àjàkálẹ̀ ààrùn lórílẹ̀ èdè Nàìjíríà (NCDC) ló kéde yìí lórí ẹ̀rọ Twitter wọn, @NCDCgov,lásàálẹ́ ọjọ́ Àbámẹ́ta ní déédé aago Mẹ́wàá kọjá ìsẹ́jú mẹ́wàá( 10:10 p. m,Local Time).
Nínú àwọn márùn ún tí wọn ṣẹ̀ṣẹ̀ jẹyọ ọ̀hún, mẹ́ta ( 3) ní ìpínlẹ̀ Bauchi (Àríwá ìlà oòrùn ) àti méjì ( 2 ) ní ìlú Àbújá, Federal Capital Territory (FCT).
--- A ó sa ipá wa láti gbógun ti ààrùn Corona ní Nàìjíríà- Chikwe Ihekweazu
Ìgbìmọ̀ ìjọba àpapọ̀ tó ń mójútó gbígbógun ti ààrùn Covid-19 ti rọ̣ àwọn olùdarí ilé-iṣẹ́ ìjọba àti aládàáni láti máa tẹ̣̀lé gbogbo ìlànà àti àyẹ̀wò tó ní ṣe nípa dídẹ́kun ààrùn Corona.
Akọ̀wé àgbà fún ìjọba àpapọ̀ lórílẹ̀ èdè Nàìjíríà (SGF) àti alága ìjọba àpapọ̀ tó ń mójútó gbígbógun ti ààrùn Covid-19 , Boss Mustapha ló sọ̀rọ̀ yìí nílùú Àbújá pẹ̀lú àwọn akọ̀ròyìn lọ́jọ́bọ̀.
Ọ̀gbẹ́ni Mustapha ní ààrùn Corona yìí lágbára láti fi ẹ̣̀mí àwọn ènìyàn àti ètò ọrọ̀ ajé, ètò ààbò orílẹ̀ èdè Nàìjíríà sínú ewu.
Ó wá rọ̣ gbogbo ọmọ orílẹ̀ èdè yìí pé kí wọ̣n rí gbogbo ìgbésẹ̀ tí ìgbìmọ̀ ọ̀hún ń gbé gẹ́gẹ́ bíi ọ̀nà láti dáàbò bo ìgbésí ayé tẹrú-tọmọ tó wà lórílẹ̀ èdè Nàìjíríà.
Mínísítà fún ètò ìlera lórílẹ̀ èdè Nàìjíríà, Osagie Ehanire, tó jẹ́ ọ̀kan lára ìgbìmọ̀ ọ̀hún sọ pé:
A rọ gbogbo ọmọ orílẹ̀ èdè Nàìjíríà láti dúró sínú ilé wọn, kí wọ́n sì mójútó ètò ìlera wọn, nípa títẹ̀lé ètò ìlànà tí àjọ ètò ìlera làà sílẹ̀ àyàfi ẹni tí ó bá ṣẹ̀ṣẹ̀ dé láti ìrìnàjò nìkan ló ní àǹfààní láti rìn padà lọ sínú ilé rẹ̀ .
Olùdarí àjọ tó ń gbógun tí ààrùn kòkòrò lórílẹ̀ èdè Nàìjíríà, (National Center for Disease Control, NCDC), Chikwe Ihekweazu ní:
Lójoojúmọ́ ni à ń fi àwọn òṣìṣẹ́ àti ohun èlò ránṣẹ́ sí ìpínlẹ̀ tí ààrùn Corona bá gbé jẹyọ ,a sì ń gbìyànjú láti sa ipá wa lọ́nà tí a óò fi dẹ́kun ààrùn Corona lórílẹ̀ èdè Nàìjíríà, bó tilẹ̀ jẹ́ pé àwọn nílò owó, irinsẹ̀,àwọn olùrànlọ́wọ́ ,ohun èlò àti àwọn nǹkan míràn.
Ìgbìyànjú yìí kò rọrùn rárá, sùgbọ́n a fi ń dá gbogbo ìpínlẹ̀ tó wà lórílẹ̀ èdè Nàìjírìá lójú pé , a ò ní káá àárẹ̀ láti sa ipá wa nípa dídẹ́kun ààrùn Corona ní àwọn ìpínlẹ̀ tí ààrùn yìí bá ti gbé ń jẹyọ.
--- COVID-19: Ìpínlẹ̀ Anambra àti ìpínlẹ̀ míràn ti bẹ̀rẹ̀ gbígba owó ìrànwọ́
Ìjọba àpapọ̀ ti ní ìpínlẹ̀ Anambra,Katsina àti Nasarawa yóò bẹ̀rẹ̀ sí ní máa gba owó ìrànwọ́ láti ọ̀dọ̀ àjọ tó ń mójútó ètò ọmọnìyàn, ìjàm̀bá pàjáwìrì àti ìdàgbàsókè àyíká.
Mínísítà fún àjọ tó ń mójútó ètò ọmọnìyàn, ìjàm̀bá pàjáwìrì àti ìdàgbàsókè àyíká lorilẹ èdè Nàìjíríà, ọ̀dọ̀ àjọ tó ń mójútó ètò ọmọnìyàn, ìjàm̀bá pàjáwìrì àti ìdàgbàsókè àyíká , Sadiya Umar Farouq ṣàlàyé pé ètò tí ìrànwọ́ owó tí àwọn ń ṣe ọ̀hun wà lára ìlérí tí ààrẹ Muhammadu Buhari ṣe láti pèsè ètò ìrànwọ́ lásìkò ìgbélé lọ́nà àtidẹ́kun ààrùn Covid-19.
Ètò ìrànwọ́ náà wáyé ní ìpínlẹ̀ Anambra , ní ìjọba ìbílẹ̀ Anyamelum (Wọọdu Anaku 1 & 2; Omor 1 & 2; Umerum Umumbo; Igbakwu; Ifite Ogwari 1 & 2; Umueje ati Omasi).
Ètò ìrànwọ́ owó ọ̀hún tún wáyé ní àwọn ibi mẹ́ta kan ní Wamba, Wayo àti Nakere ní ìpínlẹ́ Nasarawa ,tó jẹ́ ààrin gbùngbùn orílẹ̀ èdè Nàìjíríà.
Bákan náà, wọ̣n tún rí ìrànwọ́ owó yìí gba ní ìjọ̣ba ìbílẹ̀ mẹ́tàlélọ́gbọ̀n ní ìpínlẹ̀ Katsina.
Àwọn ìjọba ìbílẹ̀ náà ni Bakori, Bindawa, Baure, Batagarawa, Dandume, Ingawa, Kaita, Mani, Musawa, Rimi ati Kankara.
--- COVID-19: Ẹ máa san owó oṣù àwọn òṣìṣẹ́ lásìkò – ààrẹ Buhari
Ààrẹ Nàìjíríà, Muhammadu Buhari ti pàṣẹ fún àjọ amojuto ètò ìnáwó àti ètò ìlànà lórílèèdè láti máa sanwó oṣù àwọn òṣìṣẹ́.
Ààrẹ sọ̀rọ̀ yìí nílé ààrẹ tó wà nílùú Àbújá lásìkò tó ń ṣèpàdé pẹ̣̀lú ìgbìmọ̀ ààrẹ tó ń mójútó ààrùn COVID-19, nípa ètò ọrọ̀ ajé orílẹ̀èdè yìí.
Ààrẹ tún wá pàṣẹ fún àjọ ọ̣̀hún láti mójútó ètò amáyédẹrùn bíi àwọn ojú pópó ọkọ̀ àti ojú ọkọ̀ irin, kí wọ́n ṣì máa ṣe àmúlò àwọn irinsẹ́ orílẹ̀ èdè yìí.
Alága ìgbìmọ̀ ọ̀hún, mínísítà fún ètò ìnáwó, ìsúná àti ìlànà orílẹ̀èdè, Zainab Ahmed, lásìkò tó ń báwọn akọ̀ròyìn ilé ààrẹ sọ̀rọ̀, lẹ́yìn ìpàdé náà.
"Ahmed alága ìgbìmọ̀ náà ní ""Ààrẹ tún pàsẹ pé kí ìgbìmọ̀ náà rí i pé wọ́n ṣètò ìlànà tí yóò leè dáàbò bò àwọn akús̩è̩é̩ àti abarapá láwùjọ. """
Nínú àlàyé rè̩ sí àwo̩n akò̩rò̩yìn, ó nígbìmò̩ náà ti so̩ ìs̩è̩lè̩ ló̩wó̩ló̩wó̩ káàkiri àgbáyé fún ààre̩ nítorí COVID-19 àti ipa tó ní ló̩rò̩ jé wa.
Ó ní, “lóòótó ni Ààre̩ ti ní kí wó̩n sanwó os̩ù àwo̩n òs̩ìs̩é̩, kí wó̩n sì mójútó àwo̩n ètò amáyéde̩rùn bíi àwo̩n ojú pópó o̩kò̩, àti ojú o̩kò̩ irin kí wó̩n sì s̩àmúlò irins̩é̩ orílèèdè yìí
Kí iyì wa má baà so̩nù. Bákan náà, kí wó̩n s̩ètò ìrò̩rùn fún aláìní àti abarapá láwùjo̩.
Lórí ìdí abájo̩ ìpàdé náà, ó ní, “èrèdí ìpàdé náà ni láti sò̩rò̩ s̩ókí fún ààre̩ lórí bí ìs̩è̩lè̩ àsìkò yìí s̩e ń gbóhun tuntun yo̩ lójoojúmó̩.
Bí ìpèníjà ìlera s̩e ń gbòòrò si, ó sì ń s̩àkóbá fún ìpínlè̩ gbogbo àti ìgbélé tó wà láti kápa gbígbòòrò ìpèníjà ìlera yìí.
“Ìjìyà ìgbélé ni mímú ò̩rò̩ ajé náà fà bí ìgbín àti ìgbésè̩ tí ó ye̩ ní gbígbé láti lè dènà okùnfà búburú lórí fífà bíi ìgbín àwo̩n o̩jà òun òkòwò.”
Ọ̀kan lára ìgbìmọ̀ ọ̀hún, ìye̩n mínísítà ìpínlẹ̀ fún ètò epo rọ̀bì lórílẹ̀èdè yìí, Timipre Sylva, ní ètò ọrọ̀ ajé orílẹ̀ èdè yìí kò fararọ nítorí ààrùn COVID-19, àti pé, owó epo ń jábó̩ lójoojúmó̩, èyí ló s̩e okùnfà ìso̩nís̩ókí fún ààre̩ lóòrèkóòrè.
Aláákóso ilé-ìfowópamọ́ tìjọba àpapọ̀ (CBN), Godwin Emefiele, ní ètò ọ̣rọ̀ ajé orílẹ̀ èdè Nàìjíríà kò rẹ́ẹ́rìń rárá yàtọ̀ sí báwọn ènìyàn ṣe rò ó lọ́kàn.
Ó ní,”ètò o̩rò̩ ajé lágbàáyé gan-an, báa s̩e mò̩, yóò jìyà àwo̩n ìs̩òro ìdàgbàsókè ó sì tún lè mú àkùdé bá ètò o̩rò̩ ajé lágbàáyé.
Nítorí náà, à ń gbìyànjú láti rí ohun tá lè s̩e gé̩gé̩ bíi orílèèdè láti borí ìs̩òro ló̩wó̩ló̩wó̩ ká má ba ko̩rí só̩nà àìda tó̩pò̩ lo̩.
“Kò ní ro̩rùn s̩ùgbó̩n a kàn le fi da àwo̩n ènìyàn wa lójú pé à ń s̩is̩é̩ gan-an lórí rè̩ àti pé a óò wa ojútùú si, àwo̩n o̩mo̩ orílè̩-èdè Nàìjíríà á sì s̩e rere síi.
Àwọn tó wà níbi ìgbìmọ̀ ọ̀hún náà ni mínísítà ìpínlẹ̀ fún ètò ìsúná àti ètò ìlànà orílẹ̀ èdè, Clement Àgbà àti aláà́kóso ilé-iṣẹ́ epo rọ̀bì (NNPC), Mela Kyari.
--- Alákóso àwọn asọ́bodè gbósùbà fún àwọn òsìsẹ́ rẹ̀
Alákóso àwọn asọ́bodè lórílẹ̀ èdè Nàìjíríà ti gbósùbà fún àwọn òṣìsẹ́ rẹ̀ bí wọ́n ṣe fakọyọ àti ìwà akínkanjú tí wọ́n ń hù lásìkò ti òfin ìgbélé láti dẹ́kun ààrùn Corona ti wọ ọjọ́ mẹ́ta báyìí.
Ọ̀gbẹ́ni Àlí ní àwọn ìròyìn tí òun ń gbọ́ nípa àwọn òṣìṣẹ́ rẹ̀ nípa ìwà akínkanjú tí wọ́n ń hù lásìkò ìpèníjà tó ń dojúkọ orílẹ̀ èdè Nàìjíríà nípasẹ̀ ààrùn Corona, pàápàá jùlọ láti dáàbò bo àwọn ibùdó ọkọ̀ ojú omi.
Ó wá rọ àwọn òṣìṣẹ́ rẹ̀ láti máa tẹ̀lé ìlànà tí àwọn òṣìṣẹ́ ètò ìlera là sílẹ̀ nípa fífọ ọwọ́ wọn, yíyẹra fún àwọn ènìyàn àti nípa lílo ọsẹ a-pa kòkòrò lóòrè-kóòrè.
Ó wá gbàdúrà pé kí Ọlọ́run wo àwọn tí ààrùn COVID-19 mú fún ìwòsàn kíákíá, kí Ọlọ́run sì tún wo orílẹ̀ èdè Nàìjíríà àti àgbáyé sàn.
--- COVID-19: ilé-iṣẹ́ ológun ní irọ̣́ ni fídíò tí wọ́n ń gbé káàkiri
Ilé-iṣẹ́ ológun ti ní irọ́ ni fídíò tí àwọn ènìyàn ń gbé káàkiri lórí ẹ̀rọ ayélujára àti ní ilé-iṣẹ́ ìròyìn láti ba ilé-isẹ́ ọ̀hún lórúkọ jẹ́.
Olùdarí ẹ̀ka ìròyìn àti ìkéde fún ilé-isẹ́ náà, ọ̀gágun John Enenche ló sọ̀rọ̀ yìí lọ́jọ́rú pé ìṣẹ̀lẹ̀ tó wà nínú fídíò tí àwọn ènìyàn ń gbé káàkiri náà wáyé lọ́dún 2012 àti 2013, ní èyí tí àwọn ẹni ibi ń lò lásìkò tí ìjọba orílẹ̀ èdè yìí pàṣẹ pé kí àwọn ọmọ ogun wà lára àwọn òṣìṣẹ́ elétò ààbò láti ràn wọ́n lọ́wọ́ lásìkò òfin ìgbélé, láti dẹ́kun ìtànkálẹ̀ ààrùn COVID-19.
Ọ̀gágun John Enenche ni Mo wá rọ gbogbo àwọn ọmọ orílẹ̀ èdè Nàìjíríà láti rí fídíò tí wọ́n ń gbé káàkiri gẹ́gẹ́ bí iṣẹ́ ọwọ́ àwọn ẹni ibi láti ba ilé-isẹ́ ológun lórúkọ jẹ́.
Ilé-iṣẹ́ ológun kò ní ká à árẹ̀ nípa ojúṣe rẹ̀ láti máa tẹ́lẹ̀ òfin orílẹ̀ èdè Nàìjíríà áti láti máa dáàbò bo àwọn omọ orílẹ̀ èdè yìí.
--- COVID-19: Àwọn mẹ́tàlélógún(23) mìíràn tún jẹyọ lórílẹ̀ èdè Nàìjíríà
Àwọn mẹ́tàlélógún (23) mìíràn tó jẹ́ ọmọ orílẹ̀ èdè Nàìjíríà ni wọ́n tún ní ààrùn Corona, (COVID-19) báyìí.
Àwọn kan tó ní ààrùn Corona tún jẹyọ ní ìpínlẹ̀ Èkó, ìlú Àbújá, Akwa Ibom, Kaduna ati Bauchi.
Gẹ́gẹ́ bí àjọ tó ń gbógun tí ààrùn kòkòrò (Nigerian Centre for Disease Control, NCDC,)ṣe sọ pé , wọ́n rí mẹ́sàn án( 9) ní ìpínlẹ̀ Èkó,méje (7)ní ìlú Àbújá, FCT, márùn ún (5) ní ìpínlẹ̀ Akwa Ibom, ẹyọ kan (1) ní ìpínlẹ̀ Kàdúná àti ẹyọ kan (1) ní ìpínlẹ̀ Bauchi.
Gbogbo àwọn tó ti ní ààrùn Corona lórílẹ̀ èdè Nàìjíríà wá jẹ́ mẹ́rìnléláàdọ́sàn án (174) tí àwọn mẹ́sàn án yege àti àwọn méjì sì ti gbẹ́mì mìì.
--- COVID-19: Ẹ wo ìlú Àbújá bó se pa lọ́lọ́
Tó bá jẹ́ pé al̀ùfáà tàbí babaláwo tó mọfá-mọ̀pẹ̀lẹ̀ ló jíṣẹ́ fún gbogbo ọmọ orílẹ̀ èdè Nàìjíríà pé, ààrun kan ń bọ̀ , tí yóò jẹ́ kí tẹrú-tọmo, tonílé, tàlejò fìdìí mọ́lẹ́ wọn.
Pé ààrùn kan ń bọ̀, tí yóò jẹ́ kí onísòwò ti sọ́ọ̀bù rẹ̀ pa, pé ààrùn kan ń bọ̀ tí yóò jẹ́ kí gbogbo àwọn tó máa ń tẹkọ̀ létí lọ sí ilẹ̀ òkèèrè nítorí ẹ̀fọ́rí tàbí àìsàn ráńpẹ́, kọ̀ láti sálọ bíi ìṣe wọn, pé wọn yóò jókòó sílé , mo mọ̀ dájú pé gbogbo ọmọ orílẹ̀ èdè Nàìjíríà ni wọn yóò sọ pé kí onítọ̀hún tàbí fún babaláwo ọ̀hún pé ifá rẹ̀ kọ̀ fọ rere.
Àmọ́sá, ṣé bó ṣe wu olúwa ló ń ṣọlá, bó ṣe wu aṣẹ̀dàá ló ń hùwà. Ààrùn COVID-19, ààrùn Corona wọ orílẹ̀ èdè Nàìjíríà, gbogbo wa pa lọ́lọ́, ààrùn tí kò mọ olówó, tálákà, kó dà ààrùn tí kò mọ ibi tó ti wá, lórílẹ̀ èdè China.
Ohun tí ó dá mi lójú ni pé, lábẹ́ bó ti wù kó rí, orílẹ̀ èdè Nàìjíríà yóò yege, orílẹ̀ èdè Nàìjíríà yóò bọ́ lọ́wọ́ ààrùn Corona.
Ó di dandan ká bọ̣́ lọ́wọ́ ààrùn corona.
Tí ààrùn Corona bá kúrò lórílẹ̀ èdè Nàìjíríà, ó yẹ kí gbogbo ọmọ orílẹ́ èdè Nàìjíríà kọ́ ọgbọ́n kan tàbí ìkejì níbẹ̀ pé, ẹni tí Ọlọ́run kò leè mú, ó dájú pé Ọlọ́run kò tíì dá onítọ̀hún.
Ó yẹ kí gbogbo wa lórílẹ̀ èdè Nàìjíríà kọ́ ọgbọ́n pé, àjò kò dà bíi ilé, bí ọkọ̀ sì ròkun, rọ̀sà, ilé náà sì ni àbọ̀simi oko.
Tó bá jẹ́ pé, a ti tún gbogbo ilé-ìwòsàn ìjọba yálá ti ìjọba àpapọ̀ tàbí ti ìpínlẹ̀, gbogbo ilé ìtọ́jú yálà alábọ́dé tàbí gbogbo àwọn ilé-ìwòsàn fásitì tó wà lórílẹ̀ èdè wa jẹ́ ojúlówó, jẹ́ èyí tó wà ní ìbámu pẹ̀lú gbogbo àwọn ilé-ìwòsàn tó wà nílẹ̀ òkèèrè, tí àwọn olówó wa máa ń sálọ lásìkò tí wọ́n bá ní àìsàn ráńpẹ́,tó bá jẹ́ pé gbogbo àwọn ilé-ìwòsàn wa gbóuńjẹ fẹ́gbẹ́ gbàwobọ̀, ìwọ̀nba ni wàhálà àti ìdààmú tí ààrùn Corona kó wa sí lórílẹ̀ èdè Nàìjíríà ìbá jẹ́.
Ìmọ̀ràn mi ni wí pé, kí gbogbo wa forí-korí, fikùn lukùn, nítorí pé àgbájọwọ́ la fi ń sọ̀yà, ọwọ́ kan kò gbẹ́rù dórí, Kí á gbìyànjú láti yanjú gbogbo àwọn kùdìẹ̀-kudiẹ tó wà lórílẹ̀ èdè yìí, yálà nílé ìwòsàn wa gbogbo, tàbí nípa ètò ọrọ̀ ajé, kí orílẹ̀ èdè wa leè gòkè àgbà.
Àbọ̀ ọ̀rọ̀ là ń sọ fọ́mọlúàbí, tó bá dénú tán, yóò di odidi. ẹ sẹ́ púpọ̀.
--- Títìpa: ìjọba àpapọ̀ bẹ̀rẹ̀ pínpín ogún ẹgbẹ̀rún náírà nílùú Àbújá
Lọ́nà àtimú ìrọ̀rùn bá àwọn ènìyàn tó ń gbé nílùú Àbújá nípasẹ̀ òfin ìgbélé ti ààrẹ Muhammadu Buhara kéde rẹ̀, ìjọba orílẹ̀ èdè Nàìjíríà ti bẹ̀rẹ̀ sí ń pín ogún ẹgbẹ̀rún náírà owó ìrànwọ́ fún àwọn tó ń gbé ní ìjọba ìbílẹ̀ Kwali.̀
Mínísítà fún ètò ọmọnìyàn, ìṣẹ̀lẹ̀ pàjáwìrì àti ìdàgbàsókè àwùjọ, Hajiya Sadiya Umar Farouq ló sọ eléyìí lásìkò tí wọ́n ń pín owó ọ̣̀hún ní òwúrọ̀ ọjọ́rú.
Ilé akéde Nàìjíríà sọ pé, àwọn ènìyàn tí iye wọn jẹ́ àádọ́wàá (190) ni wọ́n ti jẹ àǹfààní ogún ẹgbẹ̀rún (N20,000 ) ni ìjọba ìbílẹ̀ Kwali báyìí.
Hajiya Farouk ní àwọn ènìyàn tí wọ́n jẹ àǹfààní owó ọ̀hún ló jẹ́ pé ẹgbẹ̀rún ún márùn ún, ni wọ́n máa ń gbà tẹ́lẹ̀, lóṣooṣù, tí wọ́n wá fún wọn ní ogún ẹgbẹ̀rún lásìkò yìí fún owó oṣù mẹ́rin lẹ́èkan náà fún wọn.
Ó tẹ̀síwájú pé ẹgbẹ̀rún márùn ún àwọn ènìyàn ni yóò jẹ àǹfààní owó ìrànwọ́ ọ̀hún nílùú Àbújá.
--- Owó epo ọkọ̀ ayọ́kẹ́lẹ́ tún ti dínkù sí N123.50
Ìjọba orílẹ̀ èdè Nàìjíríà tún ti fọwọ́sí àdínkù owó epo ọkọ̀ ayọ́kẹ́lẹ̀ lórílẹ̀ èdè Nàìjíríà sí náírà mẹ́tàlélọ́gọ́fà ààbọ̀ (N123. 50, per Litre) fún líta kan.
Alákòóso àgbà fún ilé-iṣẹ́ tó ń ṣàmójútó owó orí epo ọkọ̀ ayọ́kẹ́lẹ́ lórílẹ̀ èdè Nàìjíríà,(Petroleum Products Pricing Regulatory Agency) Abdulkadir Saidu, ló kéde yìí láṣàálẹ́ ọjọ́ Ìsẹ́gun.
Sàídù ní àdínkù owó epo ọ̀hún yóò bẹ̀rẹ̀ ní ọjọ́ kíńní, oṣù kẹrin, Ọdún 2020 (April 1 2020), gbogbo ilé-iṣẹ́ tí wọ́n gbé ń ta epo ọkọ̀ ayọ́kẹ́lẹ́ ní jákè-jádò orílẹ̀ èdè Nàìjíríà ló gbọdọ̀ tẹ̀lé ìfilọ̀ yìí.
--- COVID-19 : Àwọn méjìlá míràn tún jẹyọ lórílẹ̀ èdè Nàìjíríà
Àwọn alárùn kòrónà ní Nàìjíríà (COVID-19 ) ti di mọ́kànléláàdọ́jọ ( 151) lórílẹ̀ èdè Nàìjíríà báyìí.
Àjọ tó ń mójútó àjàkálẹ̀ ààrùn lórílẹ̀ èdè Nàìjíríà tún tikéde lórí ẹ̀ro Twitter wọn @NCDCgov, , pé àwọn mẹ́sàn án (9) mìíràn tún ti jẹyọ ní ìpínlẹ̀ Ọ̀sun, méjì (2) ní ìpínlẹ̀ Ẹdó, ẹyọ kan(1) ní ìpínlẹ̀ Èkìtì.
--- COVID-19: Ààrẹ Buhari dúpẹ́ lọ́wọ́ àwọn ènìyàn, ilé-iṣẹ́ fún àtìlẹ́yìn
Ààrẹ Muhammadu Buhari ti fi ìdúpẹ́ àtinúwá rẹ̀ hàn sí ìs̩e rere àwọn olúdarí ilé-iṣẹ́, àwọn ajíhìnrere, àwọn olórin àti ẹnìkọ̀ọ̀kan tó ṣàtìlẹ́yìn fún ìjọba láti gbógun ti àjàkálẹ̀ ààrùn COVID-19 tó kọlu ètò ọrọ̀ ajé àgbáyé.
Ààrẹ dúpẹ́ lọ́wọ́ ilé-iṣe tó ń ta epo rọ̀bì to fọwọ́sowọ́pọ̀ pẹ̀lú ilé-isẹ́ (NNPC) láti fun won ni ọgbọ́n mílíọ́nù dọ́là, ó tún dúpẹ́ lọ́wọ́ ọ̀kan lára àgbà ẹgbẹ́ (APC), Asíwájú Bólá Tinubu, Dr Mike Adénúgà, ìyáàfin Fólórunshó Alákijà tó ti ilé-epo Famfa , àti Dr Emeka Offor, tí ò darapọ̀ mọ́ àwọn ọmọ Nàìjíríà láti ṣèrànwọ́ ètò ìlera àti ilé-ẹ̀kọ́.
Ààrẹ tún fi inú dídùn dúpẹ́ lọ́wọ́ àwọn onínú rere wọ̀nyí, ilé-ìfowópamọ́ Zenith Bank PLC, tí ó pèsè ìrànwọ́ níbi ètò ìlera. Ààrẹ tún dúpẹ́ lọ́wọ́ ilé –ìfowópamọ́ Keystone bank, First Bank Plc àti olùdarí ilé-ìjọ́sìn Dunamis International Gospel Centre, Dr Paul Enenche, àti ìyàwó rẹ̀, Dr Becky Enenche.
Ààrẹ tún dúpẹ́ gidigidi lọ̣́wọ́ ilé-iṣẹ́ Stallion Group àti àjọ̣ tó mójútó ètò ìgbafẹ́ àti ìdárayá pàápàá jùlọ akọrin ìlú mọ̀-ọ́n-ká, Innocent Idibia Tuface fún ìrànlọ́wọ́ wo̩n.
Ìtúns̩e ètò ìlera
Ààrẹ Buhari wá fi dá gbogbo ọmọ orílẹ̀ èdè Nàìjíríà lójú pé, àwọn yóò lo owó náà bó se tọ́ láti fi gbogun ti ìtànkálè̩ COVID-19 àti fúntùnúns̩e ilé-ìwòsàn.
Ó ro̩ gbogbo afúnni láti fowó náà ráns̩é̩ sí ikò̩ ààre̩ amójútó ààrùn kòrónà (COVID-19).
Ààrẹ tún wá rọ̣ àwọn ọmọ orílẹ̀ èdè Nàìjíríà kí wó̩n tè̩lé ìlànà tí ilé-is̩é̩ ìlera, ìjo̩ba ìpínlè̩ àti ikò̩ amújótó ààrùn lóríléèdè (NCDC), tí òs̩ìs̩é̩ rè̩ ń s̩is̩é̩ ló̩sàn-án lóru kí gbogbo ènìyàn lórílèèdè le wà ní àlááfíà.
Ó ní ìpèníjà tí ó ń dojúko̩ orílè̩ èdè wa, àti àwo̩n orílè̩ èdè yòókù lágbàáyé, yóò nílò àtile̩yìn owó, ìrònú ati èròjà látò̩dò̩ ilé-is̩é̩ àti ènìyàn, pè̩lú ìfo̩wó̩sowó̩pò̩ o̩mo̩ Nàìjíríà láti lè kápa ìtànkálè̩ ààrùn kòrónà náà.
--- Covid-19: Ìgbìmọ̀ yóò tẹ̀lé ìlàna kí wọ́n tó ṣèrànwọ́ lásìkò ìgbélé
Akọ̀wé àgbà ti ìjọba àpapọ̀, Boss Mustapha ní ìgbìmọ̀ kò ní pẹ́ s̩e àgbéjáde ètò ìlànà tí wọn yóò tẹ̀lé láti ṣe ìrànwọ́.
Ààrẹ Muhammadu Buhari ti fọ̣wọ́sí yíyan ìgbìmọ̀ tí yóò máa ṣe àmojútó ètò okòòwò ní orílẹ̀ èdè Nàìjíríà, ní èyí tí igbákejì ààrẹ, Yemí Òsínbàjò yóò máa darí rẹ̀.
Akọ̀wé àgbà fún ìjọba àpapọ̀, Mr Boss Mustapha ló sọ̀rọ̀ eléyìí lásìkò ìfilọ́lẹ̣̀ ti ìgbìmọ̀ náà ní ìlú Àbújá.
Akọ̀wé àgbà náà tún sọ pé ìjọba yan ìgbìmọ̀ ọ̀hún láti lee máa fún àwọn ènìyàn tára ń ni nílùú Àbújá, Èkó àti Ògùn lásìkò ìgbélé yìí, kí ó lè dẹ́kun ìtànkálẹ̀ ààrùn Covid-19 ní Nàìjíríà.
A ṣẹ̀ṣẹ̀ bẹ̀rẹ̀ ni, a ò tíì mọ ìgbà tí ìṣẹ̀lẹ̀ yìí máa tán, sùgbọ́n mo nígbàgbọ́ pé, a ó bẹ̀rẹ̀ ètò náà láìpẹ́, àwọn ètò ìlànà
Òun, ìgbìmọ̀ náà yóòọ̀ kéde láìpé̩ ìlànà tí wọn yóò tẹ̀lé.
--- Ìgbélé COVID-19: Àwo̩n Gómìnà s̩èlérí mímójútó ìlo̩kiri e̩rù pàtàkì
Ẹgbẹ́ àwọn gómìnà Nàìjíríà (NGF) ti ṣèlérí pé àwọn yóò mójútó bí àwọn ẹrù tó ṣe pàtàkì yóò ṣe máa lo̩kiri lóríléèdè Nàìjíríà lásìkò ìgbélé láwọn ìpínlẹ̀ kò̩ò̩kan wò̩nyí.
Nínú àtẹ̀jáde kan tí ẹgbẹ́ náà kọ pé lásìkò ìpàdé tí wọ́n ṣe lórí ẹ̀rọ ayélujára lọ́jọ́ Àìkú, ní èyí tálága ẹgbẹ́ ọ̀hún, Gómìnà ìpínlẹ̀ Èkìtì, Káyòdé Fáyẹmí fọwọ́ṣí.
Àtẹ̀jáde ọ̀hún tó te̩ àwọn akò̩ròyìn ló̩wó̩ lójó̩ ajé ní Abuja so̩ pé àwo̩n gómìná s̩èpàdé lórí è̩ro̩ ayélujára, sò̩rò̩ lórí ìtànkálè̩ kòrónà káàkiri orílèèdè Nàìjíríà.
Nínú abala àtè̩jáde náà, ó so̩ pé: “àwo̩n gómìnà ti s̩e ìlérí láti rí i dájú pé àwo̩n è̩rù pàtàkì lo̩ káàkiri orílè̩ èdè yìí ní àkókò ìgbélé.
Ní Se̩kitáríàtì NGF, òfin gbígbé àwo̩n e̩rù pàtàkì káàkiri yóò jáde wo̩n á sì fi fún gbogbo ìjo̩ba ìpínlè̩ ní orílè̩-èdè.
E̩gbé̩ tó s̩e àte̩numó̩ ìdí fún fo̩wó̩sowó̩pò̩ láàrin ètò ìlèra ìjo̩ba àpapò̩, àjo̩ amójútó ààrùn ní Nàìjíríà (NCDC) àti àwo̩n ilé-is̩é̩ ní ìpínlè̩ láti kí́n ìgbésè ìdènà ìtànkálè̩ ààrùn náà.
Àwọn gómìnà tún fẹnukò láti máa ṣèpàdé pọ̀ lóòrè-kóòrè àti lọ́sẹ̀-ọ̀sẹ̀ lórí ẹ̀rọ̣ ayélujára lórí ààrùn corona àti ìgbésẹ̀ tí wọn ń gbé lórí rẹ̀.
Fáyemí sọ fún àwọn gómìnà nípa ìgbésẹ̀ tÍkò̩ ìjọba àpapọ̀ amójútó ààrùn Korona ń gbé àti àwọn ilé-iṣẹ́ aládàáni, nípasè̩ ìpèsè oúnje̩, ohun mímú àti e̩gbé̩ olóògùn èyí té̩gbé̩ a-sohun-títà ti Nàìjíríà (MAN) darí.
Àwo̩n Ilé-iṣẹ́ aládàáni yòókù ni MTN Foundation àti àwo̩n e̩gbé̩ a-fi-nǹkan lè̩ èyí tí Aliko Dangote àti Herbert Wigwe darí.
Àtẹ̀jáde náà ní àwo̩n gómìnà tún gba ìròyìn láìpé̩ láti ò̩do̩ mínísítà fún ètò ìlera, Dr Osagie Ehanire, àti olùdarí àjọ NCDC, Dr Chikwe Ihekweazu, lórí ìgbésẹ̀ tí ìjọba àpapọ̀ ń gbé láti dẹ́kun ìtànkálè̩ ààrùn COVID-19 lórílèèdè.
Ó fikún-un pé àwo̩n méjéèjì fún àwo̩n gómìnà níròyìn lóòrèkóòrè lórí ètò láti mú ibi àyè̩wò àti ìtó̩jú alárùn kòrónà ní àwo̩n ìpínlè̩ gbòòrò si.
--- COVID-19: Olùdarí òs̩ìs̩é fún Ààre̩ Bùhárí sò̩rò̩ lórí ipò rè̩
Olùdarí òṣìṣẹ́ fún ààrẹ orílẹ̀ èdè Nàìjíríà, Abba Kyari, ti ní kò sí ohun tó ṣe ìlera òun sùgbọ́n òun yóò lọ fún àyẹ̀wò ààrùn Corona mìíràn ní ìpínlẹ̀ Èkó.
Adarí ọ̀ún sọ̀rọ̀ lọ́jọ́ Àìkú lórí ẹ̀rọ twitter rẹ @NGRPresident sọ pé òun ti ṣètò ìtọ́jú fún ara òun láti leè dín wàhálà àwọn òṣ̣ìṣ̣ẹ́ elétò ìlera tí wó̩n bò kù.
“Mo ní àwo̩n alábòójútó tèmi nítorí àtilè dín wàhálà èto ìlera ìlú kù, tí wó̩n ń kojú ìpèníjà,” Kyari ló so̩ èyí.
Kyari ní ara òun balè̩ àti pé òun kò ní ìrírí gbígbóná àti àwo̩n ohun àìléra mìíràn tó rò̩ mó̩ àrùn ò̩hún.
“Gẹ́gẹ́ bí ọ̀pọ̀lọpọ̀ ènìyàn tó jé̩ alárùn kòrónà, èmi kò tíì ní ìrírí ìgbónára tàbí àwọn ohun àìléra mííràn tó níí ṣe pẹ̀lú ààrùn Corona.
Mo ń ṣe iṣẹ́ mi láti ilé, mo sì ní ìrètí pé màá tètè padà sẹ́nuuṣ̣ẹ́.
Mo láwọn ọ̀dọ́ , onímò̩, ọló̩gbó̩n àti afìfé̩s̩is̩é̩ alábàás̩is̩é̩pò̩ , tí wọ́n sì ń s̩iṣẹ́ lọ́jọ́ méje láàrín ọ̀sẹ̀ , tí kò sọjọ́ kan fún ìsinmi.
A ó tún tẹ̀síwájú bí a ti ń ṣe láti bí ọdún márùnún sẹ́yìn láti máa sin ààrẹ àti àwọn ènìyàn orílẹ̀ èdè Nàìjíríà.” Kyari s̩àfikún.
Ò̩rò̩ láti e̩nu Olùdarí àwo̩n òs̩ìs̩é̩ ti Ààre̩, nípa ipò ìlera rè̩:
Ara rè̩ balè̩ o sì wàpa– Lílo̩ sí Èkó fún àyè̩wò àti ìtó̩jú si – “Mo ní àwo̩n alábòójútó tèmi nítorí àtilè dín wàhálà èto ìlera ìlú kù, ti wó̩n ń kojú ìpèníjà.”
Ó tún dúpẹ́ lọ́wọ́ àwọn òṣ̣ìṣ̣ẹ́ elétò ìlera tó ń s̩is̩é̩ jákè-jádò Nàìjíríà, tí wọ́n ń fẹ̀mí ara wọn wéwu fún o̩mo̩ Nàìjíríà gbogbo. Ó tún gbós̩ùbà fun ọmọ Nàìjíríà nítorí ìtọ́jú tí wọn fun aláìní.
Kyari ro̩ o̩mo̩ Nàìjíríà fún sùúrù nígbà ìgbaninímò̩ràn lórí ìmó̩tótó ara, gbigba ìmò̩ràn rere látò̩dò̩ àwo̩n adarí, ko̩tíikún sí àwo̩n ìròyìn oníró̩ àti títèlé ìtó̩só̩nà ìjìnnà-síra-e̩ni.
--- COVID-19: Àwọn tí wón s̩àyèwò fún tó sì ní ààrun corona ni Nàìjíríà ti di mọ́kànléláàdọ́fà (111)
Ilé- iṣẹ́ tó ń gbógun ti àjàkálẹ̀ ààrùn (NCDC) lórílèèdè Nàìjíríà ti kéde pé àwọn mẹ́rìnlá mìíràn ti ní ààrùn Corona (COVID-19) lórílèèdè yìí. Àwọ̣n mẹ́sàn án ní ìpínlẹ̀ Èkó àti márùn ún ní FCT, Àbújá.
Láti aago mẹ́sàn-án ààbọ̀, lọjọ́ kọkàndínlọ́gbọ̀n, àwọn tó ní ààrùn Corona ti di mọ́kànléláàdọ́fà, ò̩kán kú, s̩ùgbó̩n ìpínlẹ̀ Èkó ló sì ń gbégbá orókè báyìí pẹ̀lú alárùn ènìyàn tó jẹ́ méjìdínláàdọ́rín.
--- COVID-19:Àar̀ẹ Buhari pàsẹ pé kí wọ́n ti Èkó, Ògùn àti Àbújá (FCT) pa
Lọ́nà àti dẹ́kun ààrùn Corona , tí a mọ̀ ṣí COVID-19 , ààrẹ orílẹ̀ èdè Nàìjíríà, Muhammadu Buhari ti pàsẹ pé kí ó máa sì wíwọlé tàbí jíjáde yálà àwọn ènìyàn tàbí ọkọ̀ nílùú Èkó , Ògùn àti Àbújá.
Ààrẹ sọ̀rọ̀ yìí lásìkò tó ń se ìgbóhùnsáfẹ́fẹ́, lááṣáálẹ́ ọjọ́ Àìkú, pé òfin wíwọlé tàbí jíjáde yóò bẹ̀rẹ̀ ní aago mọ́kànlá, ọgbọ̀ọjọ́, oṣù kẹta, ọdún 2020.
Nípa ìmọ̀ràn láti ọ̀dọ̀ àwọn àjọ tó ń mójútó ètò ìlera àti àjọ tó ń mójútó gbígbógun ti ààrùn lórílẹ́ èdè Nàìjíríà, nítorí náà mo pàṣẹ, pé kó ní sí wíwọlé tàbí jíjáde nílùú Èkó, Ògùn àti FCT Àbújá fún odidi ọjọ́ mẹ́rìnlá gbáko bẹ̀rẹ̀ láti aago mọ́kànlá, ọgbọ̀ọjọ́, oṣù kẹta,ọdún 2020.
Ohun tó fàá ti ìpínlẹ̀ Ògùn ni pé ìpínlẹ̀ náà súnmọ́ ìpínlẹ̀ Èkó àti bí àwọn ọkọ̀ ṣe pọ̀ ní àwọn ìpínlẹ̀ méjèèjì náà.
Gbogbo àwọ̣n tó wà ní àwọn ìpínlẹ̀ wọ̀nyí gbọ́dọ̀ wà nínú ìgbélé. Kò ní sí ètò ìrìnnà láti ìpínlẹ̀ kan ṣí èkejì.
Gbogbo ilé-iṣẹ́ àti ọ́fíísì tó wà ní àwọn agbègbè yìí gbọ́dọ̀ wà ní títì pa lásìkò yìí.
Ààrẹ Buhari ní àwọn gómìnà ìpínlẹ̀ Èkó, Ògùn àti mínísítà ìlú Àbújá ti mọ̣̀ nípa ìgbélé yìí.
Bákan náà, gbogbo àwọn adarí ilé-iṣẹ́ elétò ààbò àti ìtọpinipin ti mọ̀ nípa ètò ọ̀hún.
Ààrẹ ní ìjọba òun yóò lo àsìkò ìgbélé ọ̣̀hún láti ṣe ìtọpinpin àwọ̣n tí wọ́n ti ṣalábàápàdé àwọn tó ní ààrùn Korona náà.
Ààrẹ ní òfin náà kò mú àwọn ilé-ìwòsàn àti àwọn elétò ìlera àti ilé-iṣẹ́ epo àti pín egbòogi òyìnbó.
Bákan náà, gbogbo àwọn ilé-iṣẹ́ tó ń pèṣè àti àwọn tó ń ta ouńjẹ, ilé-epo rọ̀bì àti ilé-iṣẹ́ tó ń ta epo ọkọ̀ ayọ́kẹ́lẹ́, ilé-iṣẹ́ mọ̀nà-mọ́ná àti ilé-iṣẹ́ aládàáni alámòójútó ètò ààbò.
Ààrẹ ní bó tilẹ̀ jẹ́ pé òfin ètò ìgbélé kò mú àwọn ilé-iṣẹ́ wọ̀nyí síbẹ̀ ètò yóò wà nípa ibi tí wọn leè lọ.
Àwọn òṣìṣẹ́ ilé-iṣẹ́ tó ń mójútó ẹ̀rọ ìbáraẹni-sọ̀rọ̀ àti ìpè, ilé-iṣẹ́ ìròyìn yálà rédíò, móhùn-máwòrán tábi lórí ẹ̀rọ ayélujára tí kò bá leè ṣe iṣẹ́ láti ilé rẹ̀, ni wọn yóò gbà láàyè láti rìn, sùgbọ́n irúfẹ́ àwọn ènìyàn báyìí gbọdọ̀ leè fi káàdì ìdánimọ̀ wọn hàn.
--- O̩gọ́ta ọjọ́ lepo lè dé -NNPC
Ilé–iṣẹ́ a-tepo-rọ̀bì lórílẹ̀èdè Nàìjíríà (NNPC) ti rọ àwọn ọmọ Nàìjíríà láti máa ṣe bẹ̀rù nípa ríra epo ayọ́kẹ́lẹ́, nítorí pé ilé-iṣẹ́ náà ni epo tí Nàìjíríà leè lò fún oṣù méjì gbáko.
Ọ̀gbẹ́ni Mele Kyari, tó jẹ́ aláákóso ilé –iṣẹ́ ọ̀hún, ló sọ ọ̀rọ̀ ìdánilójú lásìkò tó bá àwon akọ̀ròyìn sọ̀rọ̀ lọ́jọ́ Àìkú, nílùú Àbújá.
Kyari wá rọ̣ gbogbo ọmọ orílẹ̀ èdè Nàìjíríà láti yàgò fún títò lẹ́sẹsẹ nílé- ìtajà epo, bí omíyalé.
Ó ní: “kò sí àìní níbì Kankan; o̩ja wa kún, a ní epo tí yóò tó orílèèdè fún os̩ù méjì láì repo.
“Lóòótó̩, è̩yin ènìyàn, nítorí ìtànkálè̩ ààrùn, a dúró sílé, e lè gbìyànjú láti s̩e epo kù, e kò nílò láti s̩e èyí.
Ó ro̩ àwo̩n o̩mo̩ Nàìjíríà láti má bo ilé-epo gbogbo nítorí kò sí ìdí fún èyí.
Sísò̩rò̩ lóri às̩e̩ NARTO fún àwo̩n oló̩kò̩ agbépo kí wó̩n kúrò nísò̩ wo̩n, Kyari ní ilé-is̩é̩ ò̩hún a túnbò̩ máa rán wó̩n káàkiri.
"Ó tè̩síwájú pé, ""Bí a ṣe ń sọ̀rọ̀ báyìí, kò sí ìdíwọ́ fún àwọn awakọ̀ epo ọkọ̀ ayọ́kẹ́lẹ́, nítorí pé wọ́n rí epo wọn gbà déédé, kò sí nínú èròǹgbà ilé –iṣẹ́, láti dá iṣẹ́ dúró""."
--- Ààre̩ Buhari yóò bá Nàìjíríà sò̩rò̩ ní Súńńdè
Ààre̩ Muhammadu Buhari yóò bá o̩mo̩ Nàìjíríà sò̩rò̩ lónìí Súnńdè, March 29 ní aago méje alé̩.
Olùgbanímò̩ràn sí Ààre̩ orílèèdè Nàìjíríà ti Ìròyìn àti ìpolongo, Fé̩mi Adés̩ìnà so̩ èyí nínú ò̩rò̩ rè̩.
O gba àwo̩n ilé-is̩é̩ telifís̩àn, àti ilé-is̩é̩ rédíò pè̩lú ò̩nà ìsò̩rò̩yìn mìíràn níyànjú láti darapò̩ mó̩ Ilé-is̩é̩ Telifís̩àn àkó̩kó̩ (NTA) àti Ilé-is̩é̩ Rédíò Àpapò̩ ti Nàìjíríà (FRCN) fún ò̩rò̩ Ààre̩ ò̩hún.
Ohun Nàìjíríà yóò máa já geere ní ààyè lóri è̩ro̩ Twitter wa @voiceofnigeria.
--- COVID-19: Gómìnà Èkìtì pàsẹ ìgbélé, ti gbogbo e̩nuubodè
Gómìnà Káyòdé Fáyemí ti kéde lọ́jọ́ Àìkú pé wọ̣n yóò ti ìpínlẹ̀ Èkìtì pa, kí ó le dẹ́kun ìtànkalẹ̀ ààrun Korona.
Gómìnà nínú ò̩rò̩ rè̩, pàs̩e̩ kí gbogbo okòwò gbogbo dúró gbo̩in bákan náà ni ti ìrìnàjò yòówù, àfi àwo̩n tó ń lokiri nítorí o̩jà pàtàkì.
Ó ní eni tí ó bá tàpá ṣi òfin tuntun ọ̀hún tí ó wà láti dé̩kun ìtànkálè̩ kòrónà ní ìpínlè̩ náà yóò fẹ̀wọ̀n oṣ̣ù mẹ́fà júra.
Gómìnà fàìdùnnú rè̩ hàn sáwo̩n ìgbésè̩ ìs̩áájú láti kápá ààrùn yìí s̩ùgbó̩n àwo̩n ènìyàn mò̩-ó̩n-ò̩n ketí ikún si.
O ní: “ó s̩eni láàánú gidgidi pé ìs̩esí àwo̩n kan tutu, àì-kobi-ara-si tàbí fífojú té̩ḿbé̩lú pípa àwo̩n ìlànà tí ó ro̩rùn àmó̩ tó kójú òs̩ùnwò̩n kíkápá kòrónà àti ìjìnnà sí ara e̩ni láwùjo̩ láti lè dáàbòbò ara wo̩n àti s̩e àdínkù ìtànkálè̩ àrùn náà ní àwo̩n ìgbéríkó wo̩n.”
“Bí mo s̩e mo̩ rírí ìfàyàrán wa, ìrètí tí ò le ye̩ àti ìdúrós̩ins̩in nínú è̩mí gé̩gé̩ bi ènìyàn, ó s̩e pàtàkì ká dó̩gba èyí pè̩lú ìrònú àti ìgbésè̩ kíákíá tó lè dáàbòbò è̩mí e̩bí àti ìgbéríko wa.
”Tá ò bá gbégbèésẹ̀ tó ye̩ láti dẹ́kun ààrùn yìí, ó s̩eés̩e kó borí ilé-iṣẹ́ ètò ìlera wa, ṣètò ọrọ̀ ajé wa níjàm̀bá, kí ó sì ìjàm̀bá púpọ̀ bá Èkìtì.
“Gé̩gé̩ bí a s̩e mo̩, ipò tí ìpínlè̩ yìí wa kò dára nítorí owó pò̩ lápò ìlú, èyí ti ipa ààrùn kòrónà kó níbè̩ àti sí o̩rò̩ ajé lágbàáyé pè̩lú owó epo rò̩bì tó ti lo̩lè̩ gan-an.
“Nítorí náà, a kò le fààyè àìléra láwùjo̩.
“Ìdí nìyí tí ó jé̩ àkíyèsí pàtàkì láwùjo̩ pé, nípasè̩ ojú ewé 8 ti ìs̩e ìsénimó̩lé, ofin ìjo̩ba àpapò̩ Nàìjíríà, o̩dún 2004 àti ìwé òfin ìjo̩ba àpapò̩ ti Nàìjíríà, o̩dún 1999 (pè̩lú àtúns̩e) so̩ ìgbélé láìrí ènìyàn kan tí ó ń rìnkiri di kànńpá ní ìpínlè̩ Èkìtì.
“Ìdí fún ìgbélé náà ni láti dẹ́kun bí wọn yóò ṣe máa kó àwọn ènìyàn àti ẹrù láàrín ìpínlẹ̀ ọ̀hún fún odidi ọjọ́ mẹ́rìnlá gbáko.
“Nítorí náà, láti 1:59pm ló̩sàn-án lọ́jọ́ Ajé, March 30, 2020 dé 11:59pm lálé̩ lójọ́ Ajé, April 13, 2020, ènìyàn kankan kò gbọdọ̀ rìnkiri ní Èkìtì, kí gbogbo e̩nuubodè náà ṣì wà ní títì pa.
“Èyí ni ìsémó̩lé pátápátá ní ìpínlè̩ Èkìtì, àti ìgbélé fún wákàtí méjìlá láti aago méje alẹ́ titi di aago méje òwúrọ̀.
Gbogbo o̩mo̩ ìpínlè̩ Èkìtì ní a rò̩ láti dúró sílé wo̩n.
“À ń s̩àmúlò ìs̩e ìsénimó̩lé láti dáàbòbò gbogbo o̩mo̩ ìlú Èkìtì. Nítorí náà, e̩ jé̩ só̩ kó yé yékéyéké.
Tí o kò bá lo̩ tàbí dúró sílé fún o̩jó̩ mé̩rìnlá bè̩rè̩ ló̩jó̩ ajé, 30 March, 2020, o lè sanwó ìtanràn re̩pe̩te̩ tàbí fè̩wò̩n júra.
Ó ní, “Lásìkò ìgbélé ọ̀hún, lílọ sí ìjọba ìbílẹ̀síbìílẹ̀, ìlúsíìlú, ìletò sí letò ti di èèwọ̀ ní ìpínlẹ̀ Èkìtì; Bákan náà, gbogbo àwọn tó bá wà ní ìpínlẹ̀ Èkìtì lásìkò ìgbà náà, ni ètò ìgbélé náà mú.”
Ó tún sọ pé gbogbo ilé-iṣẹ́ ni kó wà ní títì pa, àyàfi àwọn tó bá ń ṣe isẹ́ tó nííṣe pẹ̀lú ẹ̀mí àwọn ènìyàn.
Àwọn ọjà, ilé –ìtajà ńlá àti kékeré ló gbọ́dọ̀ wà ní títìpa àyàfi ibi ì-ta-o̩jà-pàtàkì, wọ́n sì gbọdọ̀ wà ní ìmọ́tótó káàrùn COVID-19 má tàn mó̩ àwo̩n ènìyàn.
Gbogbo ilé ìjọ́sìn, bí i ibi àdúrà òun ìyìn, ìsọ́-òru, ìdàpò̩ ojúlé, àti ìpàdé NASFAT; àpéjo̩pò̩ ènìyàn bíi ayẹyẹ okú, ìgbéyàwó, ìpàdé ẹbí àti ilé-ijó, ilé-ọtí, ìpàdé òṣèlú, ìwọ́de, ìpàdé ẹgbẹ́ wọ́ọ̀dù àti àwọn ìpàdé àti ètò ayẹyẹ lóríṣiríísi ni ó ti di èèwọ̀ báyìí pẹ̀lú ètò ìlànà yìí.
Ìpéjopọ̀ bíi ìsìnkú nìkan ni a ò gbà láàyè, sùgbọ́n ìpéjọpọ̀ náà kò gbọdọ̀ ju ènìyàn ogún lọ, kò gbọdọ̀ sí ìṣọ́-òru tàbí ayẹyẹ.
Gbogbo enubodè Èkìtì ni yóò wà ní títìpa lásìkò yìí àyàfi awakọ̀ epo rọ̀bì, àwọn olóúnjẹ, egbòogi òyìnbó àtàwọn ọjà aṣepàtàkì.
Gbogbo àwọn tí kìí ṣe ọmọ ìpínlẹ̀ Èkìtì sùgbọ́n tí wọ́n dé sí ìpínlẹ̀ náà lásìkò tàbí lẹ́yìn òfin ìgbélé náà gbọdọ̀ wà níbi tí wọ́n ń gbé ní ìpínlẹ̀ ọ̀hún fún ọjọ́ mẹ́rìnlá ìkéde náà, wọn yóò sì tún ṣàyẹ̀wò ààrùn COVID-19, bákan náà ní wọn yóò tún wà ní ìgbélé, tí ó bá jẹ́ dandan fún wọn.
“Gbogbo àwo̩n awakò̩ bíi bó̩ò̩sì, ayó̩ké̩lé, ò̩kadà àti kè̩ké̩ márúwá, ni kò gbo̩dò̩ s̩is̩é̩; àfi àwo̩n tí ó ń jáde nítorí is̩é̩e̩ kò̩s̩émás̩e, yí wó̩n ń gbà e̩rù pàtàkì, wíwá ìtó̩jú, aye̩ye̩ òkú àti gbígba owó ìrànwó̩ fun oúnje̩ àbí ohun mìíràn.
Àwo̩n tó bá ń s̩e is̩é̩ pàtàkì ní wo̩n yóò fún láyè látì máa lokiri, pàápàá jùlo̩ àwo̩n òs̩ìs̩é̩ ètò ìlera, s̩ùgbó̩n olóri ilé-is̩é̩ wo̩n gbo̩dò̩ fún wo̩n ní káàdì ìdánimò̩.
Fáye̩mí s̩àlàyé pé àwo̩n tófin ìgbélé ò mú kò ju àwo̩n ènìyàn kò̩ò̩kan àtilé-is̩é̩ tó ń pèsè ohun pàtàkì:
Àwọn ni ọmọ ilé – ìgbìmọ̀ aṣojú, ìjọba ìpínlẹ̀ àti ilé-ẹjọ́.
Àwọn mìíràn ni olùs̩e, olùpín àti olùta ouńjẹ àti ohun mímu, ilé-ìtajà egbòogi òyìnbó, ilé –ìtàwé àti abọ́, alámòjútó àyíká àti ìmọ́tótó, òṣìṣẹ́ mọ̀nà-mọ́ná, omi, ilé-ìbára-ẹni-sọ̀rọ̀, ilé-iṣẹ́ òǹtajà lóri ẹ̀rọ ayélujára àtàwọn olùpèsè ẹ̀rọ ayélujára.
Àwọn mìíràn ní òṣìṣẹ́ elétò ààbò tí wó̩n gbés̩é̩ fún, òṣìṣẹ́ àwo̩n ilé-ìfowópamọ́, èyí tí ó jo̩ ó̩ àti òṣìṣẹ́ àwo̩n ilé-epo rọ̀bì.
Gómìnà ní, “e̩ni tó bá rúfin yìí yóò jè̩bi è̩sun náà, nígbà tí wó̩n bà sì dalé̩bi, ó lè sanwó ìtanràn tàbí lo̩ è̩wò̩n tí ò tó os̩ù mé̩fà tàbí sanwó ìtanràn kó sì lo̩ è̩wò̩n bákan náà”.
Fáyemí, ní òun mọ̀ pé ìgbésẹ̀ yìí yóò mú ìníra dání fún okòwò àti mò̩lé̩bí, ó sì ní ohun ìrànwó ń lo̩ ló̩wó̩ fún àwo̩n ọ̣mọ ìpínlẹ̀ Èkìtì, pàápàá jùlọ àwọn abarapá.
--- COVID-19: Mé̩tàdínló̩gò̩rún lálàrún kòrónà dì ní Nàìjíríà
Ó ti di ènìyàn mẹ́tàdínlọ́gọ́rùn tó ti ní ààrùn Corona báyìí ní Nàìjíríà.
Àjọ agbógunti ààrùn ló kéde àwọn mẹ́jọ tó tún ṣ̣ẹ̀ṣẹ̀ jẹyọ pé “ní déédé 10:40am lóòórò̩, 28th, March làwọn àlárùn Korona lórílẹ̀ èdè yìí ti di mẹ́tàdínlọ́gọ́rùn, ò̩kan sì ti kú.
“Báyìí; Èkó- 59, FCT - 16 Ògùn- 3 Enugu- 2 Èkìtì- 1 Oyo- 7 Edo- 2 Bauchi- 2 Òṣun-2 Rivers-1 Benue- 1 Kaduna- 1”
Àwo̩n alárùn kòrónà mé̩jo̩ tún ti je̩yo̩ lórílè̩ èdè Nàìjíríà; 2 ní FCT, 4 ní Ò̩yó̩, 1 ní Kàdúná àti 1 ní ìpínlè̩ Ò̩s̩un
Ní déédé 10:40am lóòórò̩, 28th, March làwọn àlárùn Korona lórílẹ̀ èdè yìí ti di mẹ́tàdínlọ́gọ́rùn, ò̩kan sì ti kú.
--- COVID-19: Ààrẹ Nàìjíríà pàs̩e̩ títi pápá o̩kò̩ òfurufú àti e̩nuubodè
Láti dẹ́kun ìtànkálè̩ ààrùn as̩ekúpani kòrónà, ààrẹ orílẹ̀ èdè Nàìjíríà, Muhammadu Buhari ti pàṣẹ títi pápá ọkọ̀ òfurufú ilẹ̀ òkèèrè ní Nàìjíríà àti e̩nuubodè ní kíákíá fún ọ̀sẹ̀ mẹ́rin gbáko.
Ààrẹ so̩ èyí lórí Twitter rẹ @MBuhari lálé̩ o̩jó̩bò̩, ó ní ìgbésè̩ náà wà láti ran ìjo̩ba ló̩wó̩ nípa fífi gbogbo ìlànà tó ye̩, ìgbésè̩ ló̩ló̩kan-ò-jò̩kan, ohun amáyéde̩rùn láti lè kápá alárùn afunrasí àti èyí tí a ti s̩àwárí ní ilé, láì mu burú sí i pè̩lú èyí tó ń tòkèèrè wá.
Ààrẹ fàìdùnnú hàn sí ìnira tí títí pápá ọkọ̀ òfúrufú àti e̩nuubodè ti fún àwọn ọmọ Nàìjíríà tó fé̩ wálé, ó sì fi kún un pé “ó pondandan fún àǹfààní wa, mo dúpé̩ fún ìfọwọ́sowọ́pọ̀ àti ìgbó̩niye gbogbo yín.
Mo ti pàṣẹ pé ọkọ̀ ojú –omi e̩lé̩rù, o̩ló̩jó̩ mé̩rìnlá ó lé, lórí òkun nìkan, ni yóò dé sí ibùdókò wo̩n, lẹ́yìn tí àjọ elétò ìlera tolómi bá ti ṣàyẹ̀wò fún ikò̩ ọ̀hún tí wó̩n sì rárìídájú pé wo̩n ò lárùn.
Ó s̩àlàyé pé, “ìgbélé o̩jó̩ - mé̩rìnlá yìí kò níí s̩e pè̩lú àwo̩n tó ń gbé epo rò̩bì àti afé̩fé̩ gáàsì níwò̩n tí ìfarakínra pè̩lú ènìyàn kéré.
Ààrẹ Buhari tún dá ìlo̩kiri ọkọ̀ ojú-irin dúró láti lè s̩e àdínkù ìtànkálè̩ ààrùn náà sí è̩yà tí ó kù ní orílè̩-èdè.
Owó ìrànwọ́ – Ààre̩ Buhari tún pàṣẹ kí wọ́n yò̩nǹda owó ìrànwó̩ bílíọ̣́nù mẹ́wàá náírà fún ìpínlè̩ Èkó, nítorí ibè̩ ni ibùdó ìtànkálè̩ Kòrónà ní Nàìjíríà, gé̩gé̩ bí ó s̩e so̩.
Owó ìrànró̩ yìí máa mú Èkó láàyè sí láti kápá àti dènà ìtànkálè̩, yóò sì tún ránpìnlé̩ yòókù ló̩wó̩ nípa kíkó̩lé gbígbóòrò, ó s̩àlàyé.
Ààrẹ tún wá pa às̩ẹ yíyó̩ǹda bílíọ́nù márùn-ùn owó ìrànwó̩ tí wó̩n ya só̩tò̩ fún àjo̩ amójúto ìtànkálè̩ ààrun (NCDC) fún ríra irinsẹ́, ìmúgbòòrò àti wíwá kún àwo̩n òs̩ìs̩é̩ sí ilé-is̩é̩ àti àwo̩n ibi-àyè̩wò wo jákèjádò orílè̩-èdè.
“Mo ti pàs̩e̩ kí NCDC pé gbogbo òs̩ìs̩é̩ fè̩yìntì láìpé̩ padà sí e̩nuus̩é̩ láti lè kín àwo̩n òs̩ìs̩é̩ wa ló̩wó̩ ní ìfèsì sí ìtànkálè̩ náà”.
Síwájú sí i, gbogbo àwo̩n òs̩ìs̩é̩ NCDC tó wà lé̩nu ìkó̩s̩é̩ àti lé̩nu is̩é̩ lókè òkun padà wá sílé ní kíákíá.
Fún ìjáfáfá nínú is̩é̩ yìí, ààre̩ Nàìjíríà ní ikò̩ òfurufú ológun ti Nàìjíríà (NAF) ti ń s̩ètò àwo̩n o̩kò̩ wo̩n fún ikò̩ ààre̩ amójútó kòrónà, láti lè s̩àmúlò káàkiri orílè̩-èdè fún àmójútó tó yè kooro.
“Ló̩wó̩ló̩wó̩, ikò̩ òfurufú ológùn Nàìjíríà (NAF) ń gbégbèésè̩ láti kó àwo̩n onímò̩ ìjìnlè̩ wa tó wà ní Central Africa wálé, láti fo̩wó̩ kún ètò tó ń lo̩ ló̩wó̩ló̩wó̩”, ó fikún-un.
Ètò ìnáwó – “Ó gbóríyìn fún àwo̩n è̩ka tó ń mójútó owó fún ìrànló̩wó̩ tí wó̩n s̩e fún àwo̩n ilé-is̩é̩ aládàáni ”ní irú àkókò líle yìí”.
Ààre̩ ní ìjo̩ba yóò wá ò̩nà láti pèsè owó ìtura fún aráàlú láti lè dín ipa búburú tí àjàkálè̩ yìí s̩e ní ìgbé-ayé ogunló̩gò̩ o̩mo̩ orílè̩-èdè Nàìjíríà.
Gé̩gé̩ bí e̩ s̩e mò pé ìgbésè̩ lórí àtúnyè̩wò ètò ìsúnná lóríléèdè ti bè̩rè̩. E̩ máa gbàbò̩ ò̩nà àbáyo̩ gbàrà tí àtúnyè̩wò ètò ìsúnná bá ti parí.
Ní àkókò yìí, mo ti pàs̩e̩ fún Mínísítà alábòójútó ilé-is̩é̩ ìs̩òwò àti ìdókòwò, láti s̩is̩é̩ pè̩lú e̩gbé̩ olùs̩e-ohun-títà ti Nàìjíríà (MAN), láti rí i dájú pé pípèsè ohun pàtàkì bí i oúnje̩, onírúurú òògùn ń tè̩síwájú láì sí ìdíwó̩.
Ìmò̩ àti àtile̩yìn – Ààre̩ Buhari so̩ pé ìjo̩ba òun ti ń tàkurò̩so̩ pè̩lú ò̩ré̩ àti alábàás̩e òkèèrè láti pín ìmò̩ àti gbígba ìrànwó wo̩n lórí ìtànkálè̩ ààrùn yìí.
“A mo̩yì yín lórí àtìle̩yìn tí a ti rí gbà báyìí – A ti ń gba àwo̩n e̩rù kò̩ò̩kan tí ó wà fún ríran ìgbìyànjú wa ló̩wó̩”.
“E̩ jé̩ n fi tò̩wò̩tò̩wò̩ dúpé̩ pè̩lú gbígbóríyìn fún is̩é̩ ako̩ni òun ribiribi tí òs̩ìs̩é̩ ìlera, NCDC, òs̩ìs̩é̩ ìlera olómi, àjo̩ elétò ààbò, ìjo̩ba ìpínlè̩, àti gbogbo òs̩ìs̩é̩ àrà pè̩lú òs̩ìs̩é̩ ò̩fé̩ ti s̩e”.
Ìjayà àti Ìròyìn àhésọ - Ààrẹ Buhari rọ̣ àwọn ọmọ Nàìjíríà láti sọ́ra fún àwọn tó fẹ́ dá ìpayà àti àhéso̩ sílẹ̀ láti fàpòrúúru lásìkò yìí.
“A gbó̩dò̩ té̩tí sí ohun pàtàkì tí àwo̩n as̩ojù-ìjo̩ba tí ó s̩is̩é̩ ló̩sàn-án lóru láti lè mú ìròyìn tí ó tè̩wò̩n fún arááyé gbó̩”.
“Mo máa tún ro̩ gbogbo wa láti tè̩lé gbogbo ìlànà àti ìtó̩só̩nà ìlera tí ìjo̩ba àpapò̩ àti ìjo̩ba ìpínlè̩ làkalè̩ lórí ìmó̩tótó ara àti jíjìnnà sí ènìyàn nílé àti lóko.
“Àtúnṣe a máa je̩yo̩ lórí àwọn ìlànà wò̩nyí lóòrèkóòrè, bímọ̀ràn àtìtọ́jú tuntun bá s̩e ń wo̩lé.
“Ní báyìí, mo fé̩ fi dá gbogbo o̩mo̩ orílè̩-èdè Nàìjíríà lójú pé, ìjo̩ba àpapò̩ kò kè̩rè̩ láti dáàbò bò yín.
A nílò àtìle̩yìn àti ìfo̩wó̩sowó̩pò̩ yín lásìkò àìdè̩rùn yìí.
Bí a bá fo̩wó̩sowó̩pò̩, ó dájú pé a ó borí ààrùn yìí”.
--- COVID-19: Nàìjíríà tún s̩àwárí ènìyàn mẹ́rìnlá
Àjọ amójútó ààrùn kòrónà lórílèèdè Nàìjíríà (NCDC) tún ti s̩àwárí ènìyàn alárùn kòrónà mẹ́rìnlá tí a tún mọ̀ sí COVID-19.
Àjọ NCDC ló gbé èyí jáde lòrì ẹ̀rọ Twitter wọn pé, wó̩n rí alárùn Kòrónà kan ní FCT, ẹyọ kan ní Bauchi àti méjìlá ni ìpínlẹ̀ Èkó.
“Nínú mé̩rìnlá, wó̩n s̩àwárí mé̩fà lórí omi, mé̩ta jé̩ arìnrìnàjò tó ń padàbò̩ àti méjì tó súnmó̩ ara wo̩n ni wó̩n s̩àwárí”, NCDC s̩àlàyé.
Èyí mú gbogbo alárùn kòrónà as̩àwárí ní Nàìjíríà jé̩ márùndínláàdọ́rin, pè̩lú mé̩ta tí wó̩n fiílè̩, ò̩kan sì papòdà.
A rí às̩ìs̩e nínú ìròyìn wan í 8:35pm, ó ye̩ kó jé̩:
Wó̩n s̩e àwárí alárùn kòrónà mé̩rìnlá ní Nàìjíríà; ò̩kan ní FCT, ò̩kan náà ní Bauchi àti méjìlá ní ìlú Èkó.
Nínú mé̩rìnlá, wó̩n s̩àwárí mé̩fà lórí omi, mé̩ta - arìnrìnàjò tó ń padàbò̩ àti méjì tó súnmó̩ ara wo̩n ni wó̩n s̩àwárí – NCDC (@NCDCgov) March 26,2020.
--- COVID-19: Igbákejì ààrẹ, Ọ̀sínbàjò kò láàrùn Kòrónà
Igbákejì ààrẹ Nàìjíríà, ọ̀jọ̀gbọ́n Yemí Ọ̀sínbàjò, ti yege àyẹ̀wò ààrùn Kòrónà.
Èyí hàn nínú àyẹ̀wò tí wọ́n ṣe fúngbàkejì ààrẹ.
Agbẹnusọ igbákejì ààrẹ, Láolú Àkàndé, ló fi ọ̀rọ̀ ọ̀hún múlẹ̀ lákòókò ìfèsì sí ò̩rò̩ akòrò̩yìn nípaa rẹ̀.
Nínú èsì ti Àkàndé gbé jáde, ó ní: “Ẹ káàrọ́ọ̀ ẹ̀yin ọkùnrin àti obìnrin: Ọ̀pọ̀lọpọ̀ ìpè ni mo ti ń gbà bóyá igbákejì ààrẹ ṣàyẹ̀wò COVID-19 àti èsì àyẹ̀wò ọ̀hún.
Bẹ́ẹ̀ni, igbákejì ààrẹ ṣàyẹ̀wò, sùgbọ́n kò ní ààrùn Kòrónà, Ẹ̣ sé”.
Àkàndé sò̩rò̩ ló̩jò̩ó̩s̩é̩gun lórí Twitter pé igbákejì ààre̩ ti ń dágbé ó sì ń tilé s̩is̩é̩.
--- COVID-19: Igbákejì ààrẹ Òsínbàjò ń dágbé.
Igbákejì ààrẹ orílẹ̀ èdè Nàìjíríà, ọ̀jọ̀gbọ́n Ye̩mí Òsínbàjò ti fi ara rẹ̀ sínú ìgbélé láti tẹ̀lé ìlànà àjọ tó ń sàmójútó ààrùn (NCDC).
Agbẹnusọ igbákejì ààrẹ, Láolú Àkàndé, ló sọ̀rọ̀ yìí lọ́jọ́ Ìṣẹ́gun láti orí ẹ̀rọ twitter rẹ̀ @akandeoj.
Àkàndé ní: “Igbákejì ààrẹ lánàá (Mó̩ńdè) s̩èpàdé nínú ọ́físìì rẹ̀ lórí fídíò akóyànjo̩ láti tè̩lé ìlànà yíye̩ra fún ènìyàn.
“Ní òní, ó tè̩síwájú nínú is̩é̩ rè̩ láti ilé, nítorí ó wà ní ìgbélé ní ìlànà pè̩lú òfin NCDC”.
Àkàndé kó sọ̀rọ̀ lé̩kùnúnré̩ré̩ nípa àwọn tí igbákejì ààrẹ̀ ti s̩e alábàápàdé pè̩lú kí ó tó di pé ó lo̩ ṣe ìgbélé araa rè̩.
Igbákejì ààrẹ Osinbajo lánàá s̩e ìpàdé nínú ọ́físìì rẹ̀ lórí fídíò akóyànjo̩ láti tè̩lé ìlànà yíye̩ra fún ènìyàn.
Lónìí, ó tè̩síwájú nínú is̩é̩ rè̩ láti ilé, nítorí ó wà ní ìgbélé ní ìlànà pè̩lú òfin NCDC”.
Ló̩jó̩ ajé, ò̩jò̩gbó̩n Òsínbàjò ye̩ kó s̩e ìfiló̩lè̩ National Traffic Road ní Olú ilé-is̩é̩ àjo̩ amójútó ò̩nà ti ìjo̩ba àpapò̩, FRSC, Wuse, Abuja.
Wó̩n fagi lée, wo̩n ò si so̩ ìdí kan pàtó fúnté̩sìwájú rè̩.
---Ààmì ìpinlẹ́mìí ni ìkọlù t’ó wáyé ní Garkida – Ààrẹ Buhari.
Ààrẹ Muhammadu Buhari ti dá ikọ̀ ọlọ̀tẹ̀ Boko Haram lẹ́bi látàrí ìkọlù t’ó wáyé ní wáyé ní ìlú Garkida ní ìpínlẹ̀ Adamawa, Àríwá-ìlà-oòrùn orílẹ̀-èdè Nàìjíríà.
Ààrẹ Buhari sọ nínú àtẹ̀jáde kan: “Àwọn ìkọlù t’ó ń wáyé ní àwọn agbègbè kan láti ọwọ́ ikọ̀ Boko Haram jẹ́ àpẹẹrẹ pé ọkàn ikọ̀ Boko Haram kò balẹ̀ mọ́, nítorí pé ìjọba mi ti ṣẹ́ ìyẹ́ apá ikọ̀ ọmọ-ogun ọlọ̀tẹ̀ Boko Haram láti ya wọ agbègbè láì ní ìkọjú.
Ààrẹ wá bá àwọn ẹbí tó farapa nínú ìṣẹ̀lẹ̀ náà kẹ́dùn, ó sì ṣèlérí fún àwọn ọmọ orílẹ̀-èdè wí pé kò sí agbègbè tí àwọn yóò dá dá kádàrá wọn.
“Ó yẹ kí a gbóṣùbà fún àwọn akínkanjú ikọ̀ ológun wa fún kíkojú ikọ̀ àwọn akọluni ṣùgbọ́n wọ́n gbọdọ̀ ṣe ju èyí lọ.
Wọ́n ní àtìlẹyìn wa láti túbọ̀ kọlu ikọ̀ ọlọ̀tẹ̀ náa, kí wọ́n sì fimú wọn fọn fèrè.
Mò fẹ́ fọkàn ọmọ orílẹ̀ èdè náà balẹ̀ pé àwọn ọlọ̀tẹ̀ yóò túbọ̀ máa kọjú àpapọ̀ agbára ikọ̀ ọmọ ogun títí tí wọn yóò fi ronúpìwàdà níbi àṣìṣe wọn.
"Ààrẹ Buhari wá ní láti ìgbà tí ìjọba yìí ti dé orí àlééfà, akitiyan ikọ̀ Boko Haram láti dótì tàbí gba orílẹ̀ èdè Nàìjíríà, k’á má sọ ti ríri asia wọn mọ́lẹ̀, ni ó ti já sí pàbo.
---Ọmọ ogun bàbujá ìkọlù Boko Haram ní Adamawa.
Ikọ̀ ọmọ ogun Ẹgbẹ́-ọmọ-ogun 232 ti Ẹgbẹ́-ológun Ìhámọ́ra 23 lábẹ́ LAFIYA DOLE tí wọ́n kó lọ sí Garkida, ní ìjọba ìbílẹ̀ Gombi ní ìpínlẹ̀ Adamawa ti ba ète ìkọlù Boko Haram jẹ́.
Gẹ́gẹ́ bí àtẹ̀jáde kan ti Igbákejì Olùdarí Alukoro Ikọ̀ Ọmọ-ogun Ẹgbẹ́-ológun 23 ti Yola, Major Haruna Mohammed Sani, ṣe sọ, àwọn ikọ̀ ọlọ̀tẹ̀ náà wá sí àgbègbè ọ̀hún pẹ̀lú àwọn Ọkọ̀ Ìbọn ìjagun t’ó tó méje, pẹ̀lú àwọn oríṣiiríṣii ọkọ̀ alùpùpù, tí wọ́n sì bẹ̀rẹ̀ sí ń tiná bọ àwọn ilé kọ̀ọ̀kan, tí ó fa ìbẹ̀rù-bojo ní àárín ìlú náà.
Gẹ́gẹ́ bí Major Sani ṣe ṣ’àlàyé “àwọn ikọ̀ ọmọ ogun anígboyà yìí wọ̀yá ìjà pẹ̀lú àwọn ọ̀daràn awa-ìkógunkiri tí wọ́n sì daná bolẹ̀ gan-an tí púpọ̀ nínú àwọn ọ̀darànmọràn náà sì gbẹ́mìí mì tí àwọn kàn sì tún túká, tí ọ̀pọ̀lọpọ̀ wọn f’arapa yánna-yànna pẹ̀lú ẹ̀ri ipa ẹ̀jẹ̀ lọ́nà ibi tí wọ́n sá gbà.”
“Ó ṣ’eni láàánú, pé ọ̀kan nínú àwọn ikọ̀ ọmọ ogun anígboyà kan sọ ẹ̀mí rẹ nù, tí omiran f’arapa yánna-yànna lójú. Ọmọ ogun tí ó f’arapa náà sì ti ń gba ìwòsàn lọ́wọ́-lọ́wọ́ báyìí nílé ìwòsàn ológun.
Ní kété tí ìsẹ̀lẹ̀ náà wáyé ní ọjọ́ Kéjìlélógún oṣù kejì ọdún, 2020, ni Apàṣẹ ogun Ẹgbẹ́-ológun Ìhámọ́ra 23, Ọ̀gágun Sani Gambo Mohammed ti ṣe àbẹ̀wò sí ikọ̀ náà ní Garkida
Nígbà tí ó ṣe àbẹ̀wò rẹ̀ tán, t’ó sì gbóṣùbà fún ikọ̀ náà fún ìforítì, ìṣọ́ra àti ìjà fitafita tí ó mú wọn ṣẹ́gun ọta.
Ó tún wá rọ ikọ̀ ọ̀hún náà láti má ṣe káàrẹ́ẹ̀ nítorí pé ó se é se, kí ikọ̀ ọlọ̀tẹ̀ náà tún fẹ́ padà wá sí àgbègbè ọ̀hún.
Láfikun, Ọ̀gágun náà tún wá rọ, àwọn tó ń gbé àgbègbè náà láti máa fi tó ikọ̀ ológun létí ní kété tí wọn bá gbúròó àwọn afurasí tàbí àwọn ènìyàn tí ọwọ́ wọn kò mọ́ ọn.
Ó wá fi dá àwọn ènìyàn àgbègbè Garkida náà lójú pé ikọ̀ ọmọ ogun orílẹ̀ èdè Nàìjíríà kò ní káàrẹ́ẹ̀ láti máa dáàbò bo dúkìá àti ẹ̀mí àwọn ará ìlu.
---Ààrẹ Buhari dúpẹ́ lọ́wọ́ àwọn ‘Dókítà Láìní Ààlà’ fún àtìlẹ́yìn wọn ní Nàìjíríà.
Ààrẹ Muhammadu Buhari ti ní ìjọba mọ rírì ìfaradà àti ìgbìyànjú ẹgbẹ́ Medecins Sans Frontieres (Dokita Láìní Ààlà) ní àwọn agbègbè tí rògbòdìyàn ti ń wáyé l’órílẹ̀ èdè Nàìjíríà.
Lásìkò tí ààrẹ Buhari ń tẹ́wọ́gba Dókítà Christos Christou, t’ó jẹ́ ààrẹ ẹgbẹ́ ọ̀hún nílé ààrẹ, nílùú Àbújá, lọ́jọ́ Ọjọ́bọ̀, Ààrẹ ní ìgbìyànjú àti ìfaradà tí ẹgbẹ́ náà ń se pàápàá jùlọ láìgba owó, jẹ́ èyí tí ó yanilẹ́nu.
Ààrẹ Buhari ní ìjọba àpapọ̀ náà kò káàrẹ́ẹ̀ nínú ìgbìyànjú rẹ̀ bó tilẹ̀ jẹ́ pé wọ́n ń sọ ọ̀pọ̀lọpọ̀ ọ̀rọ̀ àbùkù sí ìjọba òun.
Ààrẹ ní “a mọ ipò tí àwọn ọmọdé tí kò mọ ibi tí àwọn òbí wọn wà, tàbí àwọn àgbègbè tí wọ́n ti wá, àti pé ìdí nìyí tí a fi dá Ilé-iṣẹ́ tó ń mójútó ọmọnìyàn, Ìṣàkóso àjálù, áti Ìdàgbàsókè àwùjọ sílẹ̀.
Èyí ni láti ṣ’ètò ìrànwọ́ fún irú àwọn ènìyàn báyìí.
Ààrẹ wá ṣèlérí pé ìjọba yóò fọwọ́sowọ́pọ̀ pẹ̀lú àwọn ògbóǹtarìgì ọmọ bíbí orílẹ̀ èdè yìí, àwọn ilé-iṣẹ́ ńlá àti àwọn ẹgbẹ́ ilẹ̀ òkèèrè láti pèsè ètò ìrànwọ́ fún àwọn àgbègbè tí rògbòdìyàn ti ṣe lọ́sẹ́.
---Mínísítà fún ètò ìròyìn ṣ’àlàyé nípa Ẹ̀yáwó Ẹ̀ẹ́dẹ́gbẹ̀ta mílíọ̀nù dọ́là láti China
Mínísítà fún ètò ìròyìn àti àsà, Alhaji Lai Mohammed ti sọ pé ẹ̀ẹ́dẹ́gbẹ̀ta mílíọ̀nù dọ́là tí wọ́n fẹ́ yá láti orílẹ̀-èdè China kì í ṣe fún ilé-iṣẹ́ móhùn-máwòrán ti orílẹ̀ èdè Nàìjíríà (NTA) nìkan.
Mínísítà fún ètò ìròyìn àti àsà s’ọ̀rọ̀ náà nígbàtí ó ń bá akọ̀ròyìn s’ọ̀rọ̀ nílùú Àbújá, tí ṣe olú-ìlú orílẹ̀-èdè Nàìjíríà lórí àhesọ ọ̀rọ̀ lórí owó tí wọ́n fẹ́ yá ọ̀hún fún àwọn iṣẹ́ àkànṣe.
Mohammed ní ẹ̀yáwó náà wà fún iṣẹ́ àkànse pàtàkì mẹ́ta tí wọ́n ṣe l’órílẹ̀ èdè Nàìjíríà tí ó yàtò sí awuyewuye ilé-iṣẹ́ akọ̀ròyìn.
Ó ní àwọn ilé-iṣẹ́ akọ̀ròyìn kan gbé àhesọ ọ̀rọ̀ náà jáde lásìkò tí òun wà nílé ìgbìmò aṣòfin láti sọ nípa ètò ẹ̀yáwó ọ̀hún, pé àwọn owó ọ̀hún láti leè jẹ́ kí ilé-iṣẹ́ NTA máa figa-gbága pẹ̀lú ilé-iṣẹ́ móhùn-máwòrán, America’s Cable Network News, CNN.
Mínísítà wá ṣ’àlàyé pé ètò ẹ̀yáwó náà yóò jẹ́ lílò fún kíkọ́ àwọn olú ilé-iṣẹ́ agbóhùn sáfẹ́fẹ́ (ITS), tí ó jẹ́ irinṣẹ́ apin-afẹ́fẹ́ ká ti Ìjọba Àpapọ̀ àti àwọn ohun-èlò ìbọ́sórí-ẹ̀rọ Ìgbóhùnsáfẹ́fẹ́ Ìgbàlódé (DSO).
Bákan náà, ó ní wọn yóò tún lo owó náà láti fi kọ́ ilé-iṣẹ́ ìgbàlódé fún ilé-ẹ̀kọ́ ìròyìn fún àwọn akọ̀ròyìn àti oníròyìn nílùú Ìkòròdú, ní ìpínlẹ̀ Èkó, tí ó ibi eré ìtàgé ilé/òde, Ìṣàwòrándààyè àti Ẹ̀kọ́ Ìmọ̀ Ẹ̀kọ́ Ìkọ̀ròyìn.
Mohammed tún pé wọn yóò tún lo owó náà fún pípèsè ilé-iṣẹ́ sinimá Ìgbàlódé, Ilé–ìtura Oníràwọ̀ Mẹ́rin, Gbọ̀ngàn eré- ìtàgé ńlá àti Ibi ìṣere.
Mínísítà tún tẹ̀síwájú pé àwọn yóò tún lo owó náà láti fi ra irinṣẹ́ ìgbàlódé fún ìyàwòràn fún yíyá àti ìpèsè iná mọ̀nà-mọ́ná.
Ó ní Ìlú Ilé-ẹ̀kọ́ Ìkọ́ròyìn ni ìkejì irú rẹ̀ tó wà ní Ilẹ̀-Adúláwọ̀ tí àkọ́kọ́ wà ní orílẹ̀ èdè Egypt.
Mínísítà tún sọ pé àwọn yóò tún lo owó ọ̀hún láti fi pèsè irinṣẹ́ ìgbàlódé fún ilé-iṣẹ́ móhùn-máwòrán NTA tó wà nílùú Àbújá àti ẹkùn méjìlá àti ní gbogbo ibi tí ilé-iṣẹ́ náà wà ní gbogbo ìpínlẹ̀ tó wà l’órílẹ̀ èdè Nàìjíríà.
---Ààrẹ Buhari fọkàn ìpínlẹ̀ Plateau balẹ̀ lórí ètò àlàáfíà àti àṣeyọrí.
Ààrẹ orílẹ̀ èdè Nàìjíríà, Muhammadu Buhari ti fọkàn àwọn ènìyàn ìpínlẹ̀ Plateau balẹ̀ pé ìjọba kò ní káàárẹ̀ láti túbọ̀ máa ṣètò ìránẁọ fún wọn nípa pípèsè ètò àlàáfíà, àṣeyọrí àti ìfọ̀kànbalẹ̀ fún wọn.
Lásìkò tí ààrẹ Buhari ń tẹ́wọ́gba gómìnà ìpínlẹ̀ Plateau ọ̀hún, Simon Lalong àti àwọn tí ọ̀rọ̀ kàn ní ìpínlẹ̀ Plateau lọ́jọ́ Ọjọ́bọ̀, Ààrẹ Buhari wá rọ àwọn olùgbé àti ọmọ ìpínlẹ̀ náà láti máa sàtìlẹyìn fún ètò ìdàgbàsókè tí gómínáà náà dáwọ́lé lórí.
Gómìnà náà wá rọ ààrẹ Buhari láti ṣètò pópó ọ̀nà ọkọ̀ tí yóò máa gba àwọn ọkọ̀ púpọ̀, ìrànwọ́ fún àwọn tí ogun àti ìjà lé kúrò ní àgbègbè wọn, àtúnṣe lórí ilé –iṣẹ́ ìwádìí lórí ànàmọ́.
Ààrẹ Buhari wá sọ fún àwọn aṣojú ọ̀hún pé, inú òhun dùn lórí ìdàgbàsókè tó wà nípa ètò ààbò àti ìdàgbàsókè àwùjọ tí gómìnà náà ń ṣe ní ìpínlẹ̀ náà
Lára àwọn èníyàn t’ó wà pẹ̀lú gómìnà Lalong ní ìgbákejì gómìnà, ọ̀jọ̀gbọ̀n Sonni Tyoden àti àwọn ògbóntàrigìì olósèlú tó wá láti ìpínlẹ̀ náà
---Ìgbìmọ̀ aṣòfin yóò ṣe ìwádìí bí ilé-iṣẹ́ ẹ̀rọ ìbánisọ̀rọ̀ alágbèéká ṣe ń ja Nàìjíríà lólè lórí ìpè.
Lọ́jọ́rú yìí n ilé ìgbìmọ̀ aṣòfin ti bẹ̀rẹ̀ ìwádìí lórí owó tí àwọn ilé-iṣẹ́ tó ń pèsè ẹ̀rọ ìbánisọ̀rọ̀ alágbèéká àti ìpè bí wọ́n ṣe ń ja àwọn ọmọ orílẹ̀ èdè lólè lórí ìpè tí àwọn ènìyàn kò jẹ̀gbádùn rẹ̀ sùgbọ́n tí wọ́n ń gbà owó lọ́wọ́ oníbárà wọn.
Gẹ́gẹ́ bí alága ìgbìmọ̀ aṣòfin tó ń mójútó ètò ìbánisọ̀rọ̀, aṣòfin Olúrèmí Tinubu, se sọ pé “Bí àwọn ilé-iṣẹ́ ẹ̀rọ ìbánisọ̀rọ̀ ṣe ń já owó lórí ìpè tí àwọn oníbàráà wọn kò lò àti àwọn ìwà mííràn tí wọ́n ń lò láti ja àwọn oníbàráà wọn lólè jẹ́ ìwà ìbàjẹ́.
Irú ìwà ti ilé-isẹ́ ìbánisọ̀rọ̀ MTN ń hu lórílẹ̀ èdè Nàìjíríà kó leè ṣẹlẹ̀ lórílẹ̀ èdè South Africa.
Ó yẹ kí ìgbìmọ̀ ṣe ìwádìí sí gbogbo owó tí àwọn ilé-isẹ́ ẹ̀rọ ìbánisọ̀rọ̀ ń gbà lọ́wọ́ oníbàráà wọn láìjẹ́ pé wọ́n jẹ àǹfààní ohun tí wọ́n san owó náà fún.
Àwọn orílẹ̀ èdè mìíràn máa ń dá owó padà.
Sùgbọ́n níbí ẹ fi dùn wá ti ẹ sì ní fún wa ní Kọ́bọ̀.
“Irú ọjá tó wà ní orílẹ̀ èdè Nàìjíríà, kò sí irú rẹ̀ ní àgbáyé.
Nígbàtí àwọn ọmọ orílẹ̀ èdè Nàìjíríà mìíràn yóò ní káàdì ìpè mẹ́ta, síbẹ̀ a kò tún ní jẹ àǹfààní sí ohun tí a sanwó fún.
Abẹnugan wá rọ ilé-iṣẹ́ tó ń mójútó gbogbo ẹ̀rọ ìbánisọ̀rọ̀ lórílẹ̀ èdè Nàìjíríà (NCC) láti mójútó ojúse wọn, pàápàá jùlọ bí àwọn ilé-isẹ́ tó ń pèsè ìpè àti ayélujára se ń já àwọn oníbàráà wọn lólè lórílẹ̀ èdè yìí.
---Coronavirus: Ìjọba Nàìjíríà ti múra sílẹ̀.
Ìjọba orílẹ̀ èdè Nàìjíríà ti ní òhun ti múra sílẹ̀ láti gbógun tí ààrùn corona tí a mọ̀ sí COVID-19, lọ́gán tí wọ́n bá gb́uròó rẹ̀ lórílẹ̀ èdè yìí.
Mínísítà fún ìròyìn àti àsà lórílẹ̀ èdè Nàìjíríà, Lai Mohammed ló sọ̀rọ̀ yìí pẹ̀lú àwọn akọ̀ròyìn lọ́jọ́ Ìsẹ́gun lásìkò tí wọ́n ń se àyẹ̀wò ohun èlò tí wọ́n pèsè sílẹ̀ láti fi gbógun ti àrùn corona.
Mínísítà tún sọ pé àwọn àjọ àti ilé-iṣẹ́ ìjọba tí ń bá ara wọn ṣiṣẹ́ papọ̀ láti gbógun ti àrùn corona ní kété tó bá wọ orílẹ̀ èdè Nàìjíríà.
Ó ní ìgbìmọ̀ tí ìjọba àpapọ̀ yàn ti fọkàn orílẹ̀ èdè Nàìjíríà balẹ̀ pé kò séwu lóko lóngẹ́ nípa ètò ìlera, àmọ́sá wọn kò ní dáwọ́ ìgbìyànjú náà dúró.
Àwọn mínísítà mẹ́rin orílẹ̀ èdè yìí ló wà níbi ètò àyẹ̀wò náà, Mínísítà fún ètò ọkọ̀ ojú òfuurufú, Mínísítà ìpínlẹ̀ fún ètò ìlera, Mínísítà fún ètò ọmọníyán, àjálù àti ìdàgbàsókè àwùjọ, ni wọ́n jọ wà ní pápá òfúrufú fún ètò àyẹ̀wọ̀ ọ̀hún.
Lai mohammed tún ní àwọn ilé-iṣẹ́ ìròyìn ìjọba orílẹ̀ èdè yìí, ilé-iṣẹ́ ìròyìn àti móhùn-máwòrán orílẹ̀ èdè Nàíjíríà, ilé-iṣẹ́ agbóhùn sáfẹ́fẹ́ orílẹ̀ èdè Nàíjíríà, ilé-iṣẹ́ akọ̀ròyìn ti ìjọba orílẹ̀ èdè Nàíjíríà, Ohùn Nàíjíríà àti ilé-iṣẹ́ elétò ìlanilọ́yẹ̀ náà kò gbẹ́yìn láti máa ṣe ìpolongo àti ìlanilọ́yẹ̀ fún àwọn ará ìlú lórí àrùn corona ọ̀hún.
Ó tún tẹ̀ síwájú pé ètò ìlanilọ́yẹ̀ ọ̀hún ni wọ́n tún ń sọ ní èdè abínibí.
Ilé ìgbìmọ̀ aṣòfin Nàìjíríà àti Iran yóò fọwọ́sowọ́pọ̀
Ilé ìgbìmọ̀ aṣòfin orílẹ̀ èdè Nàìjíríà ti ní orílẹ̀ èdè Nàíjíríà yóò fọwọ́sowọ́pọ̀ pẹ̀lú ilé ìgbìmọ̀ asòfin orílẹ̀ èdè Iran.
Abẹnugan Fẹ́mi Gbàjàbíàmílà sọ̀rọ̀ yìí lásìkò tó ń gba aṣojú orílẹ̀ èdè Iran sí Nàìjíríà, ọ̀gbẹ́ni Morteza Rahimi Zarchi, lálejò nílùú Àbújá, ó sọ pé ìbásepọ̀ láàrin ilé ìgbìmọ̀ aṣòfin orílẹ̀ èdè Nàíjíríà àti Iran yóò túnbọ̀ gbilẹ̀ síi láàrin orílẹ̀ èdè méjèèjì ọ̀hún.
Abẹnugan Gbàjàbíàmílà ní “Inú wa máa ń dùn láti tẹ́wógba àwọn àlejò láti ilẹ̀ òkèèrè, nítorí pé ó máa ń jẹ́ kí ìbásepọ̀ tó wà láàrín orílẹ̀ èdè Nàìjíríà àti orílẹ̀ náà tún túnbọ̀ múná-dóko.
“Mo mọ̀ pé orílẹ̀ èdè Iran ń la ìpèníjà kọjá bíi orílẹ̀ èdè Nàìjíríà.
Sáájú èyí ni, ọ̀gbẹ́ni Zarchi sọ pé lẹ́yìn ìbásepọ̀ pẹ̀lú ilé ìgbìmọ̀ aṣòfin orílẹ̀ èdè méjéèjì ọ̀hún, ó tún jẹ́ dandan pé kí orílẹ̀ èdè méjèèjì náà ní ìbásepọ̀ lórí ètò ọrọ̀ ajé àti àsà."
Ó ní orílẹ̀ èdè Iran ti ṣe gudugudu méje, yàyà mẹ́fà láti gbógun ti ikọ̀ ọlọ̀ọ̀tẹ̀ pàápàá jùlọ ní ẹkùn wọn.
---Ilé ìgbìmọ̀ aṣòfin fòǹtẹ̀ lu adarí ilé–iṣẹ́ ọkọ̀ òfuurufú tuntun.
Ilé ìgbìmọ̀ aṣòfin ti fòǹtẹ̀ lu adarí ilé-iṣẹ́ ọkọ̀ òfúrufú tuntun, Nigerian Civil Aviation Authority, NCAA,Captain Musa Shuaibu Nuhu gẹ́gẹ́ bi adarí tuntun fún àjọ náà.
Èyí wáyé lẹ́yìn àyẹ̀wò tí ìgbìmọ̀ aṣòfin tó ń mójútó ilé-iṣẹ́ ọkọ̀ òfúrufú ṣe fún, Musa Shuaibu Nuhu, tí ó sì yege níbẹ̀.
Alága ìgbìmọ̀ ọ̀hún, Smart Adéyẹmí, sọ pé “Àwon yàn, Musa Shuaibu Nuhu nítorí ìmọ̀ àti ẹ̀kọ́ tí ó ní nípa ọkọ̀ òfuurufú.
Lọ́jọ́ kejìdínlọ́gbọ̀n oṣù kínní, ọdún 2020, ni abẹnugan ilé ìgbìmọ̀ aṣòfin, Ahmad Lawan, ka ìwé tí ààrẹ Muhammadu Buhari fi ránsẹ́ sí ilé ìgbìmọ̀ aṣòfin nípa yíyan Captain Musa Shuaibu Nuhu gẹ́gẹ́ bíi adarí tuntun fún àjọ náà.
Captain Musa Shuaibu Nuhu jẹ́ ògbóǹtarìgì awakọ̀ òfuurufú, tí ó sì tún ṣe iṣẹ́ náà fún ọgbọ̀n ọdún.
---Abẹnugan ilé ìgbìmọ̀ asòfin, Ahmad Lawan ti se ìfilọ́lẹ̀ ìta gbangba láti jẹ́ kí àwọn ará ilú wá sọ̀rọ̀ nípa ìwà ìfipá bánilòpọ̀.
Aṣòfin Lawan ní ìwà ìfipá-bánilòpọ̀ àti ìdúnkookò mọ́ni láti fipá bá ènìyàn lòpọ̀ jẹ́ ìwà ọ̀daràn.
Nítorí náà, àwọn tí ọ̀rọ́ kàn gbọdọ̀ leè foríkorí láti ṣòfin tí yóò fìyà tó tọ́ jẹ ẹni tó bá hu ìwà ìbàjẹ́ ọ̀hún.
---Ilé-iṣẹ́ Ààrẹ rọ ọmọ orílẹ̀ èdè Nàìjíríà láti yàgò fún àwọn akọ̀ròyìn ayédèrú
Ilé-iṣẹ́ Ààrẹ ti rọ ọmọ orílẹ̀ èdè Nàìjíríà láti yàgò fún àwọn ìròyìn ẹlẹ́jẹ̀ àti àhesọ ti àwọn akọ̀ròyìn kán gbé jáde pé ààrẹ Muhammadu Buhari yóò tẹ ọkọ̀ létí lọ sí ilẹ̀ òkèèrè láti ọjọ́rú, osù kejì ọjọ́ kọkàndínlógún títí di ọjọ́ kẹrin, osù kẹrin.
Olùrànwọ́ ààrẹ lórí ìròyìn àti ìkéde, Fẹ́mi Adésínà lọ́ sọ̀rọ̀ yìí lọ́jọ́ Ajé pẹ̀lú àwọn akọ̀ròyìn pé irọ́ pátápátá ni àwọn ìròyìn tó jáde lórí ẹ̀rọ ayélujára lọ́jọ́ Àìkú.
Ó ní: “Ìròyìn t’ó jáde pé ààrẹ orílẹ̀ èdè Nàìjíríà, Muhammadu Buhari fẹ́ lọ sí United Kingdom fún oguń ọjọ́, yóò sì gba ibẹ̀ lọ sí orílẹ̀ èdè Saudi Arabia, tún lọ sí orílẹ̀ èdè Austria, irọ́ tó jìnnà sí òtítọ́ ni èyí, láti ọ̀dọ̀ àwọn ẹni ibi.
Agbẹnusọ ààrẹ tún ní àwon ènìyàn ibi yìí kò tún fi mọ lórí ààrẹ nìkan, wọ́n tún ń sọ àwọn àhesọ ọ̀rọ̀ wọ̀nyí nípa ẹbí àti àwọn tí wɔ̣́n jọ́ ń se ìjọba.
“Wọ́n tún gbé ìròyìn ẹlẹ́jẹ̀ jáde pé, àwon jàndùkú kọlu ọkọ̀ ojú irin tí mínísítà fún ètò ìrìnnà, Rótìmí Amaechi wà níbẹ̀ ní Rigasa ní ìpínlẹ̀ Kàdúná, wọ́n tún sọ pé ọmọ ààrẹ Buhari, Zahra, gba iṣẹ́ nílé ìtajà epo rọ̀bì orílẹ̀ èdè yìí gẹ́gẹ́ bí igbákejì adarí ilé-iṣẹ́ náà, irọ́ tó jìnnà sí òtítọ́ ni èyí.
---Gómìnà Borno sàbẹ̀wò ṣí Niger láti gba àwọn àtìpó tó wà níbẹ̀ padà
Gómìnà ìpínlẹ̀ Borno, ọ̀jọ̀gbọ́n Babagana Umara-Zulum ti ṣe àbẹ̀wò sí Diffa, ní orílẹ̀ èdè Niger, láti wá ọ̀nà sí bí àwọn tí ogun Boko Haram lé kúrò ní agbègbè, tí wọ́n sì ń ṣe àtìpó ní orílẹ̀ èdè Niger, padà sí ìpínlẹ̀ Borno.
Lásìkò tí gómìnà ṣe àbẹ̀wò sí àwọn àtìpó ọ̀hún, tí wọ́n lé ní ọgọ́fà, tó sì jẹ́ pé púpọ̀ nínú wọn ló wá láti apá ìwọ̀ oòrùn ìpínlẹ̀ Borno.
Àwon àtìpó ọ̀hún ló jẹ́ ọkùnrin, obìnrin àti àwọn ọmọdé, tí wọ́n sá kúrò ní agbègbè wọn nítorí ìkọlù láti ọwọ́ Boko Haram láti ọdún 2014, ní èyí tí ó ti sọ ọ̀pọ̀lọpọ̀ wọn di ẹni tí kò nílé lórí.
Ìròyìn sọ pé púpọ̀ nínú àwọn àtìpó náà ló rin ona jínjìn sí àwọn orílẹ̀-èdè agbègbè.
Gómìnà Diffa, Isa Lameen, tó jẹ́ olùgbàlejò ni ó darí gómìnà Zulum, àti abẹnugan ilé ìgbìmò asòfin ìpínlẹ̀ Borno, Abdulkarim Lawan.
Ọ̀jọ̀gbọ́n Zulum wá fi ìdùnnú rẹ̀ hàn sí ìjọba ẹkùn Diffa, ìjọba orílẹ̀ èdè Niger àti àwọn agbègbè tó wà ní orílẹ̀ èdè náà fún ìwà ìfi-ọmọnìyàn ṣe tí wọ́n hù sí àwọn ọmọ ìpínlẹ̀ Borno.
Gómìnà ìpínlẹ̀ Katsina, Aminu Masari ti kìlọ̀ fún àwọn ènìyàn agbègbè ìpínlẹ̀ náà láti má ṣe dájọ́ láti ọwọ́ ara wọn nítorí wàhálà tó bẹ́ sílẹ̀ ní ìpínlẹ̀ náà.
Masari sọ̀rọ̀ yìí lọ́jọ́ Àìkú ní Malumfashi lásìkò tó ń pín àwọn ohun èlò ìrónilágbára tí asòfin Bello Mandiya pèsè fún àwọn ènìyàn tó ń gbé ní ẹkùn Funtua ní ìpínlẹ̀ ọ̀hún.
Masari tẹ̀síwájú pé pípa àwọn ènìyàn ọgbọ́n tó ń gbé ní agbègbè Tsanwa àti Dankar ní ìjọba ìbílẹ̀ Batsari wá láti ọwọ́ àwọn ọlọ́tẹ̀ tí wọ́n wà nínú igbó Zamfara láti gbẹ̀san.
Gómìnà náà wá rọ àwọn tó ń gbé nínú agbègbè náà láti máa hu ìwá tí wọn yóò fi gbẹ̀san sùgbọ́n tí wón bá fura sí àwọn ènìyàn tí ọwọ́ wọn kò mọ́, kí wọn fi tó àwọn agbófinró létí.
Masari tún wá rọ̀ wọ́n láti mú sùúrù pé ìjọba àti àwọn àjọ ẹ̀sọ́ elétò ààbò sì ń ṣe isẹ́ lórí ìṣẹ̀lẹ̀ náà.
Ó wá bá àwọn agbègbè méjì tó kábàámọ̀ nínú ìṣẹ̀lẹ̀ náà kẹ́dùn.
Ó ní àwọn ọ̀daràn tí wọ́n wá láti ìpínlẹ̀ Zamfara ni wọ́n wá sí àgbègbè Tsanwa àti Dankar lọ́jọ́ Ẹtì, níbi tí wọ́n ti pa ènìyàn ọgbọ̀n, pàápàá jùlọ àwọn obìnrin àti ọmọdé, kó tó di pé wón dáná sun àwọn àgbègbè ọ̀hún.
Ilé-iṣẹ́ ọlọ́pàá ìpínlẹ̀ náà ti ní àwọn ti mú ọ̀kan lára ọ̀daràn ọ̀hún.
---Mínísítà pè fún ìbálẹ̀ọkàn ní ìpínlẹ̀ Bayelsa-.
Mínísítà ìpínlẹ̀ fún ọ̀rọ̀ epo rọ̀bì, Timipre Sylva ti rọ àwọn ọmọ ìpínlẹ̀ Bayelsa láti yàgò fún ìwà jàgídí-jàgan, ipá àti àìbọ̀wọ̀ fún òfin.
Sylva sọ̀rọ̀ yìí lọ́jọ́ Àìkú nínú àtẹ̀jáde kan tí ó gbé síta nílùú Àbújá.
“Mo fẹ́ lo àsìkò yìí láti rọ gbogbo ọmọ ìpínlẹ̀ Bayelsa láti yàgò fún ìwà jàgídí-jàgan, ipá àti àìbọ̀wọ̀ fún òfin.
“Mo tún fẹ́ lo àsìkò yìí láti fi tọrọ àforíjìn lọ́wọ́ ààrẹ orílẹ̀ èdè Nàìjíríà, Muhammadu Buhari, lórí ìṣẹ̀lẹ̀ burúkú tó wáyé, ní èyí tí ó mú kí ààrẹ yí ìpinnu rẹ̀ padà láti wá sí ìpínlẹ̀ Bayelsa.
Silva tún wá rọ àwọn ọmọ ìpínlẹ̀ Bayelsa ọ̀hún pé, àwọn adarí ẹgbẹ́ APC tí ń ṣe iṣẹ́ takun-takun láti rí i pé wọn yanjú wàhálà tó bẹ́ sílẹ̀ ní ìpínlẹ̀ náà, ní èyí tí wọn ti darí àwọn agbẹjọ́rọ̀ wọn láti gbé ìgbẹ́sẹ̀ lórí rẹ̀.
Ààrẹ Buhari kí Nasir el-Rufai kú orí-ire ọgọ́ta ọdún.
Ààrẹ orílẹ̀ èdè Nàíjíríà, Muhammadun Buhari ti darapọ̀ mọ́ ìgbìmọ̀ ìjọba àti gbogbo ọmọ ìpínlẹ̀ Kaduna láti bá gómìnà ìpínlẹ̀ Kaduna Nasir el-Rufai sàjọyọ̀ ọgọ́ta (60) ọdún tí yóò pé lọ́jọ́ Àìkú.
Nínú àtẹ̀jáde kàn tí, ààrẹ Buhari gbé jáde láti fi kí gómìnà náà kú orí-ire fún iṣẹ́ takun-takun tí ó ti gbé ṣe fún ìdàgbàsókè orílẹ̀ èdè Nàìjíríà.
Ààrẹ tún sàlàyé pé bó tilẹ̀ jẹ́ pé gómìnà náà bá ara rẹ̀ lẹ́nu iṣẹ́ ìjọba láìròtẹ́lẹ̀ sùgbọ́n ipa ribi-ribi tí ó ti kó lórílẹ̀ èdè kò láfiwé rárá.
Igbákejì Ààrẹ orílẹ̀ èdè Nàìjíríà, Ọ̀jọ̀gbọ́n Yẹmí Òsínbàjò ti ní òun ní ìgbẹ́kẹ̀lé nínú ọgbọ́n, ìmọ̀ àti òye àwọn ọmọ orílẹ̀ èdè yìí láti yanjú ìsoro tó ń dojúkọ orílẹ̀ èdè Nàìjíríà ĺài nílò ìrànwọ́ láti ilẹ̀ òkèèrè.
Ọ̀jọ̀gbọ́n Yẹmí òsínbàjò ní pẹ̀lú àṣeyọrí ti àwọn ọmọ orílẹ̀ èdè Nàìjíríà yìí ti ṣe nílẹ̀ yìí àti ní ilẹ̀ òkèèrè fihàn pé àwọn ọmọ orílẹ̀ èdè yìí leè yanjú ìṣòro àti ìpèníjà tó ń dojúkọ orílẹ̀ èdè yìí fúnra wọn.
Ọ̀jọ̀gbọ́n Òsínbàjò sọ̀rọ̀ yìí lásìkò tó ń gba ikọ̀ àwọn onísẹ́ abẹ láti ilé -ẹ̀kọ́ West African College of Surgeons (WACS), nílé-iṣẹ́ rẹ̀ lálejò lọ́jọ́ Ẹtì.
Àwọn ọmọ orílẹ̀ èdè Nàìjíríà tó ń ṣe iṣẹ́ abẹ ni wọ́n dá ilé ẹ̀kọ́ náà sílẹ̀ ní ọgọ́ta (60) ọdún sẹ́yìn, sáájú ìgbà tí wọn dá àjọ ilẹ̀ áfíríkà sílẹ̀.
Ọ̀jọ̀gbọ́n Ibrahim Yakasai, ló darí ikọ̀ náà wá sílé ààrẹ láti sọ nípa àwọn ojúṣe àti akitiyan ilé -ẹ̀kó náà àti láti sọ nípa ìpàdé ọgọ́ta ọdún àjọ náà, ní èyí tí yóò wáyé nílùú Àbújá.
Ọ̀jọ̀gbọ́n Yakasai ni olùdarí ayẹyẹ ọ̀hún.
Ọ̀jọ̀gbọ́n King-David Yawe, tó jẹ́ ààrẹ ilé-ẹ̀kọ́ náà tẹ́lẹ̀rí sàlàyé nípa àwọn aseyọrí tí WACS ti ṣe pàápàá jùlọ nípa àwọn ìwòsàn ọ̀fẹ́ tí wọ́n ti ṣe ní púpọ̀ nínú àwọn agbègbè tó wà lórílẹ̀ èdè Nàìjíríà.
---Orílẹ̀ èdè Nàìjíríà gba orísirísi ìlànà láti tún ojú pópó ṣ̣e.
Mínísítà fún èto iṣẹ́ àti ilẹ̀ lórílẹ̀ èdè Nàìjíríà, Babátúndé Fásholá ti fìdí rẹ̀ múlẹ̀ pé láti wá orísirísi ìlànà fún ìtọ́jú ojú pópó ní jákè –jádò orílẹ̀ èdè Nàíjíríà nìkan ló le jẹ́ kí gbogbo ọ̀nà ojú pópó wa leè gbóúnjẹ-fẹ́gbẹ́ gbàwo bọ̀ lọ́dọọdún.
Mínísítà sọ̀rọ̀ yìí ní Ugep tó wà ní ìjọba ìbílẹ̀ Yakurr, tó jẹ́ agbègbè tí ó tóbi jùlọ nílẹ̀ Áfíríkà lásìkò ètò àyẹ̀wò iṣẹ́ ojú pópó ní ìpínlẹ̀ Cross River.
Fáṣọlá, tí àwon òṣìṣẹ́ rẹ̀ jọ kọ́wọ̀ọ́rìn tún sọ pé ìtọ́jú ojú pópó pàápàá jùlọ lásìkò òjò jẹ́ ojúṣe gbogbo àwọn ènìyàn.
“A dúró ní ojú ọ̀nà Calabar-Itu, tí ó máa ń jẹ́ wàhálà fún àwọn ọlọ́kọ̀ àti ènìyàn láti gbà lásìkò òjò gẹ́gẹ́ bí ojú ọ̀nà Calabar-Ikom-Ogoja.
Nítorí náà gbogbo ojú ọ̀nà tó máa ń fa wàhálà fún àwọn ọlọ́kọ̀ láti gbà lásìkò òjò, àwọn bíi Numanchan tó lọ sí Taraba, Calabar-Itu, Abéòkúta sí Òttà-Lagos – a óò wá ètò ìlànà tí yóò jẹ́ kí àwọn agbaṣẹ́ṣe leè máa ro ti àwọn tó ń wa ọkọ̀ lásìkò tí wọn bá ń ṣe isẹ́ wọn.
Olùdarí ilé–iṣẹ́ SEMATECH, Isioma Eziashi sọ pé àwọn ìpèníjà tí ó máa ń dojúkọ wọn ni owó tí àwọn kò tètè máa rí gbà bó tilẹ̀ jẹ́ ilé-iṣẹ́ náà ti ṣetán láti tètè parí isẹ́ náà lásìkò tí wọn fún wọn.
---Àjọ elétò ìdìbò orílẹ̀ èdè Nàìjíríà,( Independent National Electoral Commission ,INEC) ti fún Duoye Diri tó jẹ́ olùdíje fún ipò gómìnà lábẹ́ ẹgbẹ́ òṣèlù Peoples Democratic Party (PDP) ní ìwé ẹ̀rí gẹ́gẹ́ bí gómìnà to jáwé olúborí nínú ìdìbò tó wáyé ní ìpínlẹ̀ Bayelsa lọ́dún 2019, ní ìbámu pẹ̀lú ìdájọ́ tí ilé-ẹjọ́ gíga tó wà l’órílẹ̀ èdè Nàìjíríà dá.
Kọmíṣánà fún àjọ INEC ní ẹkùn ìlà ìwọ̀ oòrùn arabìnrin May Agbamuche-Mbu ló fún Diri ní ìwé ẹ̀rí ọ̀hún lọ́jọ́ Ẹtì nílùú Àbújá tó jẹ́ olú-ìlú àjọ náà tó wà ní orílẹ̀ èdè Nàìjíríà.
Sáájú èyí ni alága àjọ INEC, ọ̀jọ̀gbọ́n Mahmood Yakubu, ti kéde pé Diri gẹ́gẹ́ bí olúborí nínú ìdìbò gómìnà ìpínlẹ̀ náà.
Diri wá gbósùbà fún àjọ INEC àti ilé-ẹjọ́ fún bí wọ́n ṣe jẹ́ “Èyí tí àwọn ènìyàn leè ní ìgbẹkẹ̀lé nínú wọn.
"Diri tún ní “kí Ọlọ́run wo ilẹ̀ Bayelsa sàn àti orílẹ̀ èdè Nàìjíríà lápapọ̀. Ọlọ́run ti mú wa rin ojú ọ̀nà, tí a ó máa gbà láti leè bá ara wa ṣe papọ̀.
Lọ́jọ́bọ̀ ní ilé-ẹjọ́ tó ga jùlọ lórílẹ̀ èdè Nàìjíríà yọ David Lyon ati Biobarakuma Degi-Eremienyo kúrò gẹ́gẹ́ bí gómìnà ìpínlẹ̀ Bayelsa
---Ààrẹ Buhari dé sí New York fún Ìpàdé Àpérò Àjọ UN.
Ààrẹ orílẹ̀-èdè Nàìjíríà Muhammadu Buhari wà ní New York, fún Àpérò Àjọ Ìṣòkan Àgbáyé tí ó jẹ́ ìkẹrìnléláàdọ́rin (74) ìpàdé àpérò irú rẹ̀.
Ààrẹ Buhari, ẹni tí ó dé sí New York ní ọ̀gànjọ́ ọjọ́ Àìkú, tí aṣojú orílẹ̀-èdè Nàìjíríà fún ilẹ̀ Amẹ́ríkà, Sylvanus Adiewere, Mínísítà fún ọ̀rọ̀ òkèèrè, Geoffrey Onyama àti Mínísítà fún ètò ìlera, Osagie Ehanire àti àwọn mìíràn wá pàde rẹ̀.
Ààrẹ Buhari ni ẹnití yóò jẹ́ ìkarùn-ún nínú àwọn ti yóò máa sọ̀rọ̀ níbi Ìpàdé Àpérò Àjọ Ìṣòkan Àgbáyé ọ̀hún, ní èyí tí yóò bẹ̀rẹ̀ lọ́jọ́ Ìṣẹ́gun.
Ààrẹ Buhari yóò máa sọ̀rọ̀ lórí ìṣèjọba àti ìpinnu mẹ́ta tí ó fẹ́ gúnlẹ̀ níbi ìṣèjọba rẹ̀ lẹ́yìn tí ọ̀pọ̀ ọmọ Nàìjíríà fìbò dá a padà sórí àléfà.
Yóò sì ṣàlàyé àwọn ipò tí orílẹ̀-èdè Nàìjíríà wà lórí àwọn ọ̀ràn tí ó kan gbogbo àgbáyé gbọ̀ngbọ̀n.
Ìkópa Ààrẹ nínú ìpéjọ àwọn olórí orílẹ̀-èdè àgbáyé ọdún yìí ṣe pàtàkì nítorí ó ṣe pẹ̀kínrẹ̀kí pẹ̀lú Orílẹ̀-èdè Nàìjíríà gẹ́gẹ́ bí Ààrẹ Ìpàdé Àpérò Àjọ UN.
Àkórí ìpàdé Àpérò Àjọ Ìṣòkan Àgbáyé ẹlẹ́ẹ̀kẹrìnléláàdọ́rin (UNGA74) náà ni, ‘Ìgbìyànjú Nílopo-ọ̀nà láti Mú Òṣì Kúrò, Ètò Ẹ̀kọ́ tó yè Kooro àti Mímójútó Ìyípadà Ojú-ọjọ́ àti Ìfi-àwọn-ènìyàn-gbogbo-kun-ètò-gbogbo.
---Àrùn Ebola àkọ́kọ́ ṣẹlẹ̀ ní ìlú Goma ní Orílẹ̀-èdè Ìjọba Àwarawa Olómìnira Congo.
Àwọn aṣojú ìjọba sọ wí pé, àrùn Ebola àkọ́kọ́ ṣẹ́yọ ní ìlú Goma ní ìlà-oòrùn Orílẹ̀-èdè Ìjọba Àwarawa Olómìnira Congo, ní ọjọ́ Àìkú, tí ó ń bà wọ́n lẹ́rù nítorí ó ṣe é ṣe kí àrùn ọlọ́jẹ̀ náà ó tàn kíá ní agbègbè tí ó mú àlà pẹ̀lú orílẹ̀-èdè Rwanda.
Ó tó àádọ́ta-ọ̀kẹ́ kan àwọn ènìyàn tó ń gbé ìlú Gómà, t’ó súnmọ́ bèbè adágúndò, tó ìbùsọ̀ 350 ní gúúsù apá ibí tí ó ṣìkejì agbègbè tí àrùn Ebola tí ó pọ̀ j ù lọ ti ṣẹ́yọ ní bí ọdún kan sẹ́yìn.
Ṣùgbọ́n àrùn ibà ọlọ́jẹ̀ náà tí ń ṣe wérewère tàn ká dé gúúsù, tí ó ti ran àwọn ènìyàn 2,500 tí ó sì pa àwọn 1,600.
Bí àrùn Ebola ṣ̣e wọ ìlú Goma
Gẹ́gẹ́ bí àwọn òṣìṣẹ́ ilé–ìwòsàn náà ṣe sọ, àlùfáà ni ẹni tí ó lugúdẹ àrùn náà lásìkò t’ó wá sí ìlú Butembo, ìbùsọ̀ 200 sí àríwá Goma, níbi tí ó ti ṣàgbákò àwọn ènìyàn tó ní àrùn Ebola.
Àwọn àmì àrùn náà bẹ̀rẹ̀ sí ní máa jẹyọ lọ́sẹ̀ t’ó kọ́ja lásìkò kí ó t ó wọ́kọ akéròpúpọ̀ lọ sí Goma lọ́jọ́ Ẹtì. Nígbà tí ó dé Goma lọ́jọ́ Àìkú ni ó lọ sílé ìwòsàn, níbi tí àyẹ̀wò ti fi hàn pé ó ní àrùn Ebola.
Gẹ́gẹ́ bí iléeṣẹ́ ètò ìlera ṣe sọ “látàrí ìjáfara kẹ́fin alárùn náà àti bí ó ti ṣe wà ní ìyàsọ́tọ̀ọ̀tọ̀, àti ìṣèdánimọ̀ gbogbo àwọn èrò ọkọ̀ láti Butembo, ewu ìfọ́nká sí àwọn agbègbè tí ó kù ní Goma kéré.” wọn ní gbogbo ibùdókọ̀
Ìlú Goma ti ń gbaradì fún àrùn Ebola láti ọdún tó kọjá, ṣíṣètò ibi tí àwọn ènìyàn náà yóò ti máa fi omi fọ ọwọ́, tí wọ́n sì tún ṣe àrídájú pé àwọn awakẹ̀kẹ́-alùpùpù kò yá ara wọn ní akoto.
Àmọ́ ní àwọn ìgbèríko, àrùn ọlọ́jẹ̀ náà ti ṣòro láti kápá. Àìfọkàntán àwọn òṣìṣẹ́ elétò ìlera àti ìjà ìgboro ti di àwọn akitiyan ìkápá lọ́wọ́, ó sì tí fa kí àwọn tí ó lùgbàdì ó pọ̀ sí i.
Àrùn Ebola máa ń fa àrùn ìgbẹ́ gbuuru, èébì, àti àrùn ibà ẹlẹ́jẹ̀ tí ó lè ràn nípase oje ara.
Àjàkálẹ̀ kan ní àárín ọdún 2013 àti 2016 pa ju ènìyàn tí ó lé ní ẹgbẹ̀rún mọ́kànlá (11,300) ní Ìwọ̀-oòrùn Ilẹ̀-Adúláwọ̀.
WHO fèsì
Ìṣẹ̀lẹ̀ àrùn Ebola àkọ́kọ́ irú ẹ̀ ní Orílẹ̀-èdè Ìjọba Àwarawa Olómìnira Congo ní ìlà-oòrùn ìlú Goma jẹ́ ìṣípòpadà tí ó ṣe kókó nínú ìpele àjàkálẹ̀ náà, Olóyè Tedros Adhanom Ghebreyesus Àjọ Elétò Ìlera Àgbáyé sọ.
Tedros sọ wí pé òun nírètí pé kò ní sí ìtànkálẹ̀ àrùn náà ní ìlú náà, ṣùgbọ́n ó ń k ó àwọn ìgbìmọ̀ pàjáwìrì àjọ WHO jọ láti ṣe ìpinnu bóyá àjàkálẹ̀ náà jẹ́ ètò ìlera pàjáwìrì àgbáyé.
— Àjọ Elétò Ìlera Àgbáyé (WHO)
Ibi Ìwòsàn àrùn Ebola ní Goma, DRC, ti ń ṣiṣẹ́ láti oṣù Èrèlé, tí onítọ̀hún sì ti ń gba ìtọ́jú níbẹ̀. Gẹ́gẹ́ bí ìgbaradì náà, òṣìṣẹ́ elétò ìlera 3000 ni a ti bupá fún ní ìlú náà nìkan.
---NMA dá àwọn Ìpínlẹ̀ lẹ́bi fún ipò àìdára ètò ìlera abẹ́lé
Ẹgbẹ́ àwọn Òṣìṣẹ́ Oníṣègùn Òyìnbó orílẹ̀-èdè Nàìjíríà, (Nigeria Medical Association, NMA), ti bẹnu àtẹ́ lu bí àwọn gómìnà ìpínlẹ̀ ṣe pa ilé ìwòsàn abẹ́lé orílẹ̀-èdè náà tì sẹ́gbẹ̀ẹ́ kan.
Ààrẹ ẹgbẹ́ NMA, Dr Francis Faduyile, ló sọ fún àwọn akọ̀ròyìn nílùú Àbújá pé, bí àwọn gómìnà Ìpínlẹ̀ lórílẹ̀-èdè Nàìjíríà kò ṣe kọbiara sí ilé-ìwòsàn abẹ́lé ló fà á tí àwọn ilé-ìwòsàn náà ṣe dẹnu kọlẹ̀.
Ó sọ pé àwọn ìjọba ìpínlẹ̀ ti pa ilé ìwòsàn abẹ́lé àwọn ìpínlẹ̀ náà tì, tí ó ń tẹnu mọ́ ọ wí pé wọ́n ti jẹ́ kí ó ní ìfàsẹ́yìn tí ó pọ̀.
Gẹ́gẹ́ bí ó ti ṣe sọ, ìkáwọ́ àwọn ìjọba ìpínlẹ̀ ni àwọn ilé ìwòsàn abẹ́lé wà àti pé àkàtà wọn ni àwọn ilé ìwòsàn gbogbó wà, tí ìjọba ìpínlẹ̀ kò sì ṣe tó ati sa ipá ní ti èyí.
Ó sọ pé NMA ti jára mo àgbàwí, yóò sì ìjíròrò pẹ̀lú ìjọba ìpínlẹ̀ láti wá ojútùú sí ipò adójútini náà.
“A nírètí láti lọ sí Àpérò Àwọn Gómìnà nígbà mìíràn tí wọ́n bá ní ìpàdé láti ṣíjú wọn sí àwọn ohun tí ó kàn gbọ̀ngbọ̀n.
Ètò ìlera abẹ́lé jẹ́ kọnti nínú àtúnṣe ètò ìlera ní orílẹ̀-èdè.”
Faduyile sọ pé kí Ìjọba Àpapọ̀ ó wá nnkan ṣe sí ti ìwàgbẹ ọpọlọ tí ó lè ṣe ìgbàpadà ẹ̀ka ìlera.
Gẹ́gẹ́ bí ààrẹ ẹgbẹ́ NMA ṣe sọ, a ti ṣ’àkíyèsí wí pé ìjọba kò ṣe dáadáa nínú ẹ̀ka ìlera.
Faduyile sọ pé lára àwọn ìgbésẹ̀ láti ṣe ìgbàpadà ẹ̀ka ìlera, NMA ti gbé ìgbésẹ̀ láti gbárùkù ti Ètò Mádàánilófò Àwùjọ.
Ó sọ pé àjọ náà yóò ṣe àtìlẹ́yìn fún àwọn ìpínlẹ̀ tí wọ́n ń ṣe àgbékalẹ̀ ètò mádàánilófò ìlera ti wọn, wọ́n rọ̀ wọ́n láti béèrè fún ìtọ́nà lọ́wọ́ NMA ní ọ̀nà tí ó yẹ.
---Nàìjíríà tún ìpinnu rẹ̀ sọ láti ṣe ìgbélárugẹ ẹ̀tọ́ ọmọnìyàn
Ìjọba orílẹ̀-èdè Nàìjíríà ti ní òun kò ní fi àyè gba lílọ ìwà ìjìyà ìpalára láti gba ìjẹ́wọ́ lọ́wọ́ ẹni tàbí ìfìyàja ẹni tí a fi ẹ̀sùn kàn mọ́.
Agbẹjẹ́rò Àgbà fún Orílẹ̀-èdè àti Akọ̀wé Àgbà ní ilé–iṣẹ́ Ètò Ìdájọ́, Ọ̀gbẹ́ni Dayọ̀ Akpata l’ó s’ọ̀rọ̀ yìí nílùú Àbújá, níbi ayẹyẹ láti sàmì sí àjọ̀dún Àjọ Ìṣọ̀kan Àgbáyé ọdún 2019 ní Àtìlẹ́yìn fún Àwọn tí ó ń Jìyà ìpalára.
Ọ̀gbẹ́ni Akpata ẹni tí ó jẹ́ onímọ̀-egbò inú ọpọlọ sọ wí pé ètò òmìnira ìjìyà ìpalára kì í ṣe ohun ìdúnàdúrà.
Akọ̀wé Àgbà náà ní ẹgbẹẹgbẹ̀rún awon ènìyàn, ebi ati àwọn lẹ́gbẹ́lẹ́gbẹ́ jákèjádò ilé-ayé ń jìyà ara àti egbò-inú ọpọlọ látàrí ìjìyà ìpalára.
Ó ní, “gbogbo ọmọ orílẹ̀-èdè Nàìjíríà l’ó ní ẹ̀tọ́ sí ìbọ̀wọ̀fún ìyìn ọmọ-ènìyàn, láti ìhín lọ, kò sí ẹnikẹ́ni kò gbọdọ̀ fì̀yà jẹ ẹlòmíràn tàbí ìwà àìṣènìà."
Ní ọ̀rọ̀ rẹ̀, “orílẹ̀-èdè Nàìjíríà jẹ́ ọ̀kan lára orílẹ̀-èdè tí ó t’ọwọ́bọ ìwé àjọ UN l’órí ìjìyà ìpalára tí ó ka ìjìyà ìpalára léèwọ̀.
"“Òfin orílẹ̀-èdè Nàìjíríà ti fún Ilé-Iṣẹ́ ètò ìdájọ́ l’ágbára láti mú àbá d’òfin ìtako ìwà ìpalára ṣe."""
Ọ̀gbẹ́ni Hamza l’ó ṣójú fún ọ̀gbẹ́ni Akpata níbi ayẹyẹ náà .
---Igbákejì Ààrẹ Ọ̀ṣínbájò yóò ṣèpàdé pẹ̀lú Mike Pence, àti àwọn t’ó kù l’órílẹ̀-èdè Amẹ́ríkà
Igbá-kejì Ààrẹ Yẹmí Ọ̀ṣínbájò ń lọ sí orílẹ̀ Amẹ́ríkà, United States níbi tí yóò ti máa ṣẹ̀pàdè pẹ̀lú akẹgbẹ́ rẹ̀ tí ó jẹ́ igbá-kejì Ààrẹ orílẹ̀-èdè Amẹ́ríkà ọ̀gbẹ́ni Mike Pence, àti àwọn ènìyàn jàǹkàn-jàǹkàn lorílẹ̀-èdè náà.
Àtẹ̀jáde kan tí ó wà láti ilé-iṣẹ́ igbá-kejì Ààrẹ sọ pé “Igbá-kejì Ààrẹ ọ̀jọ̀gbọ́n Yẹmí Ọ̀ṣínbájò yóò kọ́kọ́ ṣe ìpàdé pẹ̀lú ìgbìmọ̀ aláṣẹ lórí ọ̀rọ̀ tó jẹ mọ́ ti ilẹ̀ òkèèrè lọ́jọ́ Ajé ní New York, kí ó tó máa ṣèpàdé pẹ̀lú igbá-kejì Ààrẹ orílẹ̀-èdè Amẹ́ríkà ní Washington DC ní ọjọ́ Ọjọ́rú.
“Lára nǹkan tí igbá-kejì Ààrẹ, Yẹmí Ọ̀ṣínbájò yóò máa bá akẹgbẹ́ rẹ̀ jíròrò ni lórí bí ìdàgbàsókè yóò ṣe túbọ̀ máa gbilẹ̀ sí i lórí ìbáṣẹpọ̀ t’ó wà láàárín orílẹ̀-èdè méjèèjì, bákan náà, ni igbákejì Ààrẹ Ọ̀ṣínbájò yóò tún máa sọ̀rọ̀ lórí ètò ọ̀rọ̀ ajé.
"Igbákejì Ààrẹ fi ìlú sílẹ̀ ní ọ̀sán ọjọ́ Àbámẹ́ta, ìrètí wa pé yóò padà sí Àbújá ní ọjọ́ Ọjọ́bọ̀.
---Muhammad-Bande di Ààrẹ Àpérò Àjọ UN
Aṣojú orílẹ̀-èdè Nàìjíríà fún Àjọ Ìṣòkan Àgbáyé (United Nations) Tijjani Muhammad-Bande ni ó ti jáwé olúborí gẹ́gẹ́ bí Ààrẹ kẹrìnléláàádọ́rin Àpérò Àjọ Ìṣòkan Àgbáyé.
Muhammad-Bande, nìkan l’ó díje fún ipò yìí, a dìbò yàn án nípasẹ̀ pípa ohùn pọ̀ lásìkò ìpàdé àpérò àjọ àgbáyé kẹ́tàdínláàdọ́rùn-ún t’ó wáyé ni New York lọ́jọ́ Ìṣẹ́gun, ọjọ́ kẹrin oṣù kẹfà.
Òun ni yóò jẹ́ ọmọ Nàìjíríà kejì tí yóò di ipò náà mú lẹ́yìn tí ajagun fẹ̀yìn tì Joseph Garba tí ó jẹ́ aṣojú tẹ́lẹ̀ rí àti ọgbọ́n òṣèlú, ẹni tí ó darí ikọ̀ náà láàárín ọdún 1980 sí 1990.
Oṣù Kesan-an ọdún 2019 ni ó bẹ̀rẹ̀ iṣẹ́.
---Awon ọmọ orílẹ̀-èdè Nàìjíríà ní ẹ̀yìn odi ń ṣ’alágbàáwí fún ìdìbò láti ìlú òkèèrè.
Wọ́n ti rọ gbogbo àwọn ọmọ orílẹ̀-èdè Nàìjíríà tó ń gbé ní ìlú òkèèrè láti ṣe àgbáwí fún òfin tí yóò gbà wọ́n láàyè láti máa dìbò lásìkò ètò ìdìbò níbikíbi lẹ́yìn odi.
Alága, Àjọ Àwọn Ọmọ orílẹ̀-èdè Nàìjíríà nílẹ̀ òkèèrè, tí ó tún jé Olùdámọ̀ràn Pàtàkì fún Ààrẹ Muhammadu Buhari, Àbíkẹ́ Dábírí-Erewa, l’ó pe ìpè yìí lásìkò àpèjẹ tí wọ́n ṣe fún àwọn aṣojú ọmọ ẹgbẹ́ APC t’ó ń gbé nílùú òkèèrè, ní ìlú Àbújá, orílẹ̀-èdè Nàìjíríà.
 ẹ ṣéun púpọ̀ tí ẹ wá sílé nítorí wí pé ẹ fẹ́ wá darapọ̀ mọ́ ètò ìfinijoyè Ààrẹ Buhari."
Gbogbo yín ni ẹ ti ṣe iṣẹ́ takuntakun fún àṣeyọrí rẹ̀, pẹ̀lú oore-ọ̀fẹ́ Ọlọ́run àti ìpinnu, Ààrẹ bá a yín sọ̀rọ̀ lánàá, kò ní já gbogbo yín kulẹ̀.
"Ó ní "" Oun tí mo lérò pé ìlépa tí ó ṣe Pàtàkì jù lọ fún wa ni àṣeyege ìdìbò láti ìlú òkèèrè."
Gbogbo wa ni a ní lati ṣiṣẹ́ pọ̀ lati ṣe àṣeyọrí.
Ó sọ “Mo fẹ́ rọ̀ gbogbo yín, bí Àpéjọ kẹsàn-án ṣe ń ilé wọlé, ẹ jẹ́ kí á bẹ̀rẹ̀ lẹ́sẹ̀kẹsẹ̀, kí á gbìyànjú láti lọ sí Ìgbìmọ̀-aṣòfin, k’á sì kó sí wọn lẹ́mìí láti rí i dájú wí pé àwọn ọmọ orílẹ̀-èdè Nàìjíríà ní ẹ̀yìn odi láti lè dìbò, nítorí náà ó ṣe kókó”.
Ó sọ “ní báyìí ẹ ti ní Àjọ Ọmọ orílẹ̀-èdè nílẹ̀ òkèèrè, ẹ fọwọ́sowọ́pọ̀ pẹ̀lú Àjọ náà, kí èyí ba lè di mímúṣẹ, bí àwọn orílẹ̀-èdè kéréjekéréje bá leè ṣe é, mi kò rí ìdí kan tí àwọn Ọmọ orílẹ̀-èdè Nàìjíríà kò leè dìbò”.
"Ó tẹnumọ "" yóò jẹ́ ogun tí ó ṣòro láti jà, ṣùgbọ́n a gbọdọ̀ ṣe àrídájú wí pé ìdìbò lẹ́yìn odi di àmúṣẹ”."
---Ààrẹ Buhari forílé orílẹ̀-èdè Saudi Arabia fún Ìpàdé àpérò OIC.
Ààrẹ Muhammadu Buhari ti fi Abuja sílẹ̀ láti lọ fún Ìpàdé àpérò Ẹgbẹ́ Àjùmọ̀ṣe àwọn Ẹlẹ́sìn Islam, OIC nílùú Makkah ní orílẹ̀-èdè Saudi Arabia.
Ìpàdé àpérò gbogbogboò OIC ẹlẹ́ẹ̀kẹrìnlá irú rẹ̀, tí yóò wáyé lọ́jọ́ Ẹtì (Friday) ọjọ́kankàndínlọ́gbọ̀n, oṣù Karùn-ún, tí Ọba Salman Abdulaziz Al Saud yóò gbàlejò, tí àwọn Olórí orílẹ̀-èdè tí wọn jẹ́ ọmọ ẹgbẹ́ àjọ náà yóò lọ fún.
"Gẹ́gẹ́ bí ilé-iṣẹ́ Akọ̀wé ẹgbẹ́ OIC ṣe fi léde, àkórí ìpàdé àpérò naa ni: “Àpérò Makkah al-Mukarramah: Ìfọwọ́sọwọ́pọ̀ fún ọjọ́-ọ̀la "" láti mú ìdàgbàsókè bá ìṣọ̀kan àwọn ẹlẹ́ṣin Mùsùlùmí lágbàáyé."
Ààrẹ Buhari yóò sọ̀rọ̀ níbi ìpàdé náà àti ìmẹ́nuba ìdí tí àwọn orílẹ̀-èdè tí wọn jẹ́ ọmọ ẹgbẹ́ àjọ náà fi gbọdọ̀ fìmọ̀-ṣọ̀kan, láti ṣiṣẹ́ papọ̀ láti gbógun ti àwọn ìpèníjà bí i ìwà ìdúnkookò-mọ́ni àti làásìgbò àwọn alákata-kítí.
---Nàìjíríà rawọ́ ẹ̀bẹ̀ ìrànwọ́ sí U.S láti kojú ìṣòro àìríṣẹ́ṣe.
Orílẹ̀-èdè Nàìjíríà ń béèrè fún ìrànlọ́wọ́ láti ọ̀dọ̀ orílẹ̀-èdè Ìpínlẹ̀ Ìṣọ̀kan Amẹ́ríkà láti gbógun ti ìṣòro àìríṣẹ́ lorílẹ̀-èdè náà.
"Akọ̀wé Àgbà fún Àjọ tó-ń-rí-sí ètò iṣẹ́ àti Ìgbanisíṣẹ́ (Federal Ministry of Labour and Employment), William Alo, sọ pé orílẹ̀-èdè Nàìjíríà nilo ìrànlọ́wọ́ láti ọ̀dọ̀ U.S láti “dojú ìjà kọ ìpèníjà àìríṣé tó ń kojú orílẹ̀-èdè náà."""
Lásìkò t’ó ń gba ikọ̀ Èka ilé-iṣé ètò iṣẹ́ láti orílẹ̀-èdè Amẹ́ríkà, tí Kurt Petermeyer, ẹni tí ó jẹ́ Alábòójútó Èka Ìṣàkóso Ètò ààbò àtì Ìlera ṣe adarí, ọ̀gbẹ́ni Alo sọ pé ìrànlọ́wọ́ láti ọ̀dọ̀ U.S. láti mú àwọn ibi ìkọ́ni ní ọgbọ́n ìmọ̀ọ̀ṣe yóò ṣe ànfààní ribiribi fún orílẹ̀-èdè Nàìjíríà, ní ti ìmúdára ìpèsè iṣẹ́.
---Ààrẹ Buhari tẹ̀síwájú nínú ètò ìlànà ẹ̀sìn ní Makkah
Ààrẹ Muhammadu Buhari dé sí Makkah, ní Saudi Arabia, láti ìlú Madinah níbi tí ó ti bẹ̀rẹ̀ ìgbésẹ̀ tí ó ṣíwájú iṣẹ́ Umrah ní Ilẹ̀-ọba náà.
Lẹ́yìn àdúrà àṣálẹ́ ní Mọ́sálásí Òjíṣẹ́ ńlá, a mú Ààrẹ lọ sí ibojì òjíṣẹ́ ńlá Mohammed níbití ó ti gbàdúrà fún orílẹ̀ èdè, ẹbí rẹ̀ àti òun fúnra rẹ̀.
Gómìnà ẹkùn Madinah Prince Khalid Bin Faisal Al-Saud, sin ààrẹ jáde ní Pápákọ̀ Òfuurufú tí Prince Mohammed Bin Abdulaziz Madina International Airport.
Gómìnà agbègbè Makkah, Prince Khalid Bin Faisal Al-Saud ni ó kí Ààrẹ káàbọ̀ ní Makkah.
Bákannáà lára àwọn t’ó wá láti tẹ́wọ́gba Ààrẹ ni Aṣojú orílẹ̀ èdè Nàìjíríà ní Saudi Arabia, Onídájọ́ tóti fẹ̀yìntì Isa Dodo, ọ̀gá àgbà pátá fún Àjọ Ọ̀tẹlẹ̀múyẹ́, Aṣojú Ahmed Rufa’i Abubakar àti àwọn òṣìṣẹ́ Aṣojú ìjọba orílẹ̀ èdè Nigeria ní Jeddah.
Lẹ́yìn ìgbàlejò, lógán ni ó bẹ̀rẹ̀ iṣẹ́ Umrah ní àṣálẹ́ ọjọ́ ẹtì.
---Ààrẹ Buhari yóò wà ní Saudi Arabia láti ṣe àwọn ìlànà-ẹ̀sìn ti Umrah.
Ààrẹ orílẹ̀-èdè Nàìjíríà Muhammadu Buhari ti gba ìwé ìpè láti ọ̀dọ̀ Ọba ti Saudi Arabia, Salman Bin Abdulaziz, láti wá ṣe àwọn ìlànà-ẹ̀sìn Umrah (ìrìnàjò ilẹ̀-mímọ́ kékeré) ní orílẹ̀-èdè náà.
Lára àwọn ti yóò tẹ̀lé Ààrẹ lọ sí orílẹ̀-èdè Saudi Arabia ni àwọn olùrànlọ́wọ́ rẹ̀ pàtàkì, Ààrẹ yóò gúnlẹ̀ sí orílẹ̀-èdè Saudi Arabia ní ọjọ́ Ọjọ́bọ̀, ọjọ́ kẹrìndínlógún, oṣù Karùn-ún.
---Orílẹ̀-èdè Nàìjíríà àti Angola yóò fọwọ́sowọ́pọ̀ láti mú ètò ààbò agbègbè-ságbègbè gbópọn sí i.
Orílẹ̀-èdè Nàìjíríà àti Angola yóò fọwọ́sowọ́pọ̀ láti jọ mú kí ètò àlàáfíà ó ga sí i, ìdúróṣinṣin àti ètò ààbò ni ẹ̀kùn ilẹ̀-Adúláwọ̀ papàá jù lọ ní Ìwọ̀-oòrùn àti agbègbè Àárín-gbùngbùn ilẹ̀-Adúláwọ̀.
Orílẹ̀-èdè méjèèjì náà jọ t’ọwọ́bọ ìwé àdéhùn leyin ìpàdé kan láàárín Mínísítà tó ń rí sí ọ̀rọ̀ tó jẹ mọ́ ilẹ̀ òkèèrè, Geoffrey Onyeama àti Mínísítà fún Ìbáṣepọ̀ Orílẹ̀-èdè Òkèèrè ti Orílẹ̀-èdè Angola, Manuel Augusto, ni ọjọ́ Ọjọ́rú nílùú Àbújá.
Augusto àti Onyeama ni wọ́n jọ tọwọ́bọ ìwé àdéhùn náà.
Orílẹ̀-èdè méjèèjì náà jọ foríkorí lórí ọ̀nà tí wọn yóò gbà mú ètò ìṣèlú, àwùjọ àti ọrọ̀-ajé rinlẹ̀ àti àjọṣepọ̀ àṣà ní ìtẹ̀síwájú àgbéṣe ìdàgbàsókè orílẹ̀-èdè méjèèjì àti Ilẹ̀-Adúláwọ̀ náà.
Àwọn orílẹ̀-èdè méjèèjì ti gba àwọn wàhálà, àwọn ìpèníjà ìyípadà ojú-ọjọ́ àti ìwà ìpànìyàn.
Wọ́n pinnu lórí kókó àjọṣepọ̀ ìgbésẹ̀ láti gbógunti, gbogbo ìrókẹ́kẹ́ ìmúró ìdàgbàsókè àwọn orílẹ̀-èdè méjèèjì àti Ilẹ̀-Adúláwọ̀.
Àwọn orílẹ̀-èdè méjèèjì náà yóò tún jọ máa jíròrò lórí pípèsè ètò àlàáfíà to yí dandé, ìdúróṣinṣin àti ètò ààbò ní agbègbè náà.
---Ilé ìgbìmọ̀ aṣòfin f’ọ̀ǹtẹ̀ lu Àbíké Dábírí-Erewa gẹ́gẹ́ bí adarí Àjọ Ẹ̀yìn odi
Ilé ìgbìmọ̀ aṣòfin ti f’ọ̀ǹtẹ̀ lu ìpinnu Ààrẹ Muhammadu Buhari láti fi Àbíkẹ́ Dábírí-Erewa ṣe Ọ̀gá-àgbà/Alága Àjọ Ọ̀rọ̀-tó-jẹ-mọ́-ilẹ̀-òkèèrè pàápàá jùlọ ọ̀rọ̀ t’ó bá kan ọmọ orílẹ̀-èdè Nàìjíríà nílẹ̀ òkèèrè.
Ìyáàfin Dábírí-Erewa, t’ó jẹ ọmọ ilé ìgbìmọ̀ aṣojú tẹ́lẹ̀rí, ni Olùrànlọ́wọ́ Pàtàkì lórí ọ̀rọ̀ tó jẹ mọ́ ilẹ̀ òkèèrè fún Ààrẹ Buhari lọ́wọ́lọ́wọ́.
"Ó ní “lẹ́yìn tí ìgbìmọ̀ aṣòfin ti parí ìwádìí fínnífínní wọn tán lórí ìwé ẹ̀rí ẹ̀kọ́-àtiṣẹ́ àti àwọn ìwé mìíràn nípa àwọn ẹni-a-yàn, tí òtítọ́ rẹ̀, ìríta, ìbámu, ìkájú-òṣùwọ̀n àti ìrírí rẹ̀ nínú ètò òṣèlú àti iṣẹ́ ìlú sì tẹ́ wọn lọ́rùn, ìgbìmọ̀ náà rí Ẹni-ọ̀wọ̀ Àbíkẹ́ Dábírí Erewa bí ẹni tí ó dántọ́ àti ẹni tí ipò alága/ọ̀gá-àgbà yányán Àjọ ọ̀rọ̀ ọmọ orílẹ̀-èdè Nàìjíríà ni ilẹ̀ òkèèrè""."
Ó ní pé Dábírí-Erewa yege láti bọ́ sí ipò náà lẹ́yìn tí àwọn ìgbìmọ̀ ti ṣe àyẹ̀wò fínnífínní ní ìbámu pẹ̀lú àlàálẹ̀ òfin orílẹ̀-èdè Nàìjíríà.
Aṣòfin Oko ṣ’àfikún wí pé ẹni-a-fà-sílẹ̀ náà gba ìmọ̀ ìjìnlẹ̀ nínú Ọnà (èdè Gẹ̀ẹ́sì) lọ́dún 1983; ó tẹ̀síwájú nínú ẹ̀kọ́ ìmọ̀ ìjìnlẹ̀ láti tún gba oyè mìíràn nínú ẹ̀kọ́ Ìbáraẹnisọ̀rọ̀ Ọlọ́pọ̀ lọ́dún 1986, ó sì tún ní ìwé-ẹ̀rí akọ́ṣẹ́mọṣẹ láti Iléèwé ìmọ̀ ẹ̀kó Ìṣèjọba John Kennedy, ti Fáfit̀i Harvard, lórílẹ̀-èdè United States, ní oṣù kẹfà Ọdún 2002.
---Ìjì-líle kọlu ìlú ilé-ìsìn l’órílé-ẹ̀dè India lẹ́yìn tí ọ̀pọ̀ ènìyàn sá kúrò níbùgbé wọn
Ọ̀pọ̀ ènìyàn ni ó ti pàdánù ibùgbé wọn, tí àwọn míìrán sì pàdánù ohun ìní wọn ní agbègbè Puri, lórílé-èdè India látàrí ìṣèlè ìjì líle tí ó wáyé lọ́jó Ẹtì, Iròyìn fi múlẹ̀ pé, ìjì líle náà ba àwọn ohun amáyéderùn jẹ́ púpọ̀ bíi òpó iná mọ̀nà-mọ́ná, òpó ẹ̀rọ ìbánisọ̀rọ̀ abbl.
Gẹ́gẹ́ bí àjọ tó ń mójútó ìṣẹ̀lẹ̀ pàjáwìrì, wọ́n ní ìṣẹ̀lẹ̀ ìjì líle náà kọ́kọ́ ṣọṣẹ́ ní ẹ̀ka ìlà oòrùn ìlú Bengal kí ó tó sún lọ sí Ìpínlẹ̀ Odisha ní aago mẹ́jọ òwúrọ̀.
---Ọ̀pọ̀ farapa yánayàna, ẹnìkan pàdánù ẹ̀mí rẹ̀ nínú ìkọlù Venezuela.
Nínú ìkọlù tí ó wáyé lórílẹ̀-èdè Venezuela láàárín ọmọ-ogun ìjọba orílè-èdè náà àti àwọn olólùfẹ́ ẹgbẹ́ òṣèlú alátakò ní ọjọ́ Ọjọ́rú, ìròyìn fi múlẹ̀ pé ọmọbìnrin kan pàdánù ẹ̀mí rẹ̀ látàrí ọta ìbọn tí ó fara gbà, tí ọ̀pọ̀ ènìyàn sì farapa yánayàna.
Adarí ẹgbẹ́ òṣèlú alátakò ọ̀hún, Juan Guaidó ti pè láti ṣàwárí àwọn tí ó bá wà nídìí ikú ọmọbìnrin ọmọ ọdún mẹ́tàdínlọ́gbọ̀n náà.
Ó wá rọ àwọn òṣìṣẹ́ ní ọjọ́ Ọjọ́bọ̀ láti wá fi èhónú wọn hàn, eléyìí tí ó sì le è ṣ’okùnfà ìdásílẹ̀.
Ọ̀gbẹ́ni Guaidó kéde ara rẹ̀ gẹ́gẹ́ bi olùdarí ìjọba orílè-èdè Venezuela lóṣù Kinní ọdún tí a wà yìí, bẹ́ẹ̀ sì ni ọ̀pọ̀ orílè-èdè tí ó làmìi-laaka lágbàáyé bí ilẹ̀ Amẹ́ríkà, UK abbl ṣàtilẹ́yìn fún láti túkọ̀ orílè-èdè náà.
Ààrẹ bẹnu àtẹ lu ìròyìn àhẹ́sọ kan tí ó sọ pé Òun fẹ́ fi orílè-èdè òun sílẹ̀, bẹ́ẹ̀ sì ni ó tún fẹ̀sùn kan orílè-èdè Amẹ́ríkà fún dídá ọ̀rọ̀ náà lọ́nà tí ò tọ̀.
---Ìpàdé àpérò lórí ìdàgbàsókè ètò ọrọ̀-ajé láàárín orílẹ̀-èdè Nàìjíríà-UK wáyé nílùú Àbújá.
Igbákejì Ààrẹ orílẹ̀-èdè Nàìjíríà, Ọ̀jọ̀gbọ́n Yẹmí Òsínbàjò, ti ní púpọ̀ nínú àwọn oníṣòwò l’ó ti nífẹ̀ẹ́ láti dá ètò okòòwò sílẹ̀ lorílẹ̀-èdè Nàìjíríà báyìí.
Igbákejì Ààrẹ sọ̀rọ̀ yìí lásìkò ìpàdé àpérò lórí ètò ọrọ̀ ajé láàárín orílẹ̀-èdè Nàìjíríà àti UK, ní èyí tí ó jẹ́ àkọ́kọ́ irú rẹ̀ tí ó wáyé ní Ilé Agbára Ààrẹ, nílùú Àbújá.
Oṣù kéje ọdún 2018 ni Ààrẹ Muhammadu Buhari àti olùdarí ìjọba nílùú London, Theresa May, tọwọ́bọ ìwé àdéhùn lásìkò Ìpàdé àpérò lórí ìdàgbàsókè ètò ọrọ̀-ajé láàárín orílẹ̀-èdè Nàìjíríà àti orílẹ̀-èdè United Kingdom.
Gẹ́gẹ́ bí Igbákejì Ààrẹ ṣe sọ, “àwọn oníṣòwò tí wọ́n nífẹ̀ẹ́ láti dá okòòwò wọn sílẹ̀ lorílẹ̀-èdè Nàìjíríà tún ti pọ̀ si báyìí láàárín ọdún 2017 si ọdún 2018.
---Ààrẹ Buhari p’àṣẹ fún Adájọ́ Àgbà orílẹ̀-èdè Nàìjíríà láti dá sí ọ̀ràn Zainab
Ààrẹ Muhammadu Buhari ti p’àṣẹ fún Adájọ́ Àgbà orílẹ̀-èdè àti Mínísítà fún Ètò ìdájọ́ ọ̀gbẹ́ni Abubakar Malami, láti wá wọ̀rọ̀kọ̀ fi ṣàdá nípa gbígbé ìgbésẹ̀ lórí bí wọn yóò ṣe yọ arábìnrin Zainab Aliyu, tó jẹ́ akẹ́kọ̀ọ́, tí àwọn ọ̀daràn kan kó sínú wàhálà nípa gbígbé oògùn olóró sínú ẹrù rẹ̀, tí ó sì wà ní ìgbèkùn ìjọba orílẹ̀-èdè Saudi Arabia.
Nínú àtẹ̀jáde kan tí Abdur-Rahman Balógun, olùrànlọ́wọ́ lórí Ìròyìn fún Ẹni-ọ̀wọ̀ Àbíkẹ́ Dábírí, Olùdámọ̀ràn Pàtàkì Àgbà fún Ààrẹ lórí Ọ̀rọ̀ ọmọ Nàìjíríà ní ilẹ̀ òkèèrè, gbé jáde nílùú Àbújá sọ wí pé Ààrẹ pa àṣẹ náà ní ọ̀sẹ̀ méjì sẹ́yìn nígbàtí ọ̀ràn náà tó òun létí.
“Ààrẹ Muhammadu Buhari pa àṣẹ náà níkété tí ó gbọ́ ìṣẹ̀lẹ̀ ọ̀hún ní ọ̀sẹ̀ méjì sẹ́yìn.
“Ibi-iṣẹ́ mi ti ń ṣiṣẹ́ pẹ̀lú Adájọ́ Àgbà orílẹ̀-èdè Nàìjíríà àti Àjọ t’ó ń rí sí ọ̀rọ̀ t’ó jẹmọ́ ti ilẹ̀ òkèèrè lórí ọ̀rọ̀ náà”.
Olùrànlọ́wọ́ Ààrẹ fi dánilójú wí pé iṣẹ́ ń tẹ̀síwájú nínú ọ̀ràn Zainab, pẹ̀lú àwọn méjì mìíràn tí ó wà nínú ipò kan náà ní ilẹ̀ Saudi Arabia.
Dábírí-Erewa sọ wí pé, lóòótọ́ Zainub wà ní àtìmọ́lé, ìjọba ilẹ̀ Saudi Arabia kò tíì fi ojú rẹ̀ ba ilé ẹjọ́. Tí ó sì le láti gba ẹ̀rí wí pé wọ́n ti mú àwọn tí wọ́n kó bá a gbọ́, ẹjọ́ tí ó lágbára ni a fẹ́ pe àwọn aláṣẹ Saudi.
Àjọ JAMB ṣe ìdánwò ní orílẹ̀-èdè méje ní ìlú òkèèrè.
Àjọ tó ń mójútó ìdánwò fún àwọn t’ó fẹ́ wọ fáfitì, ilé-ẹ̀kọ́ gbogbonìṣe àti ilé-ẹ̀kọ́ àwọn olùkọ́ l’órílẹ̀-èdè Nàìjíríà ti ṣe ìdánwò fún àwọn ọmọ orílẹ̀-èdè yìí tó wà nílùú òkèèrè àti àwọn ọmọ orílẹ̀-èdè mìíràn tí wọ́n fẹ́ tẹ̀síwájú nípa ẹ̀kọ́ wọn ní orílẹ̀-èdè Nàìjíríà.
Ìgbìmọ̀ náà ní àwọn ṣètò ìdánwò yìí láti jẹ́ kí gbogbo àwọn ọmọ orílẹ̀-èdè Nàìjíríà t’ó wà nílẹ̀ òkèèrè àti àwọn ọmọ orílẹ̀-èdè mìíràn tó nífẹ̀ẹ́ láti kẹ́kọ̀ọ́ ní Ilẹ́ẹ̀kọ́-gíga t’ó yé kooro l’órílẹ̀ èdè Nàìjíríà ní àǹfààní kan náà.
Àwọn orílẹ̀-èdè tí àjọ náà ti ṣe ìdánwò náà ní orílẹ̀-èdè Ghana, United Kingdom, Cameroon, Benin Republic, Cöte d’Ivoire, South Africa àti Ilẹ̀-oba Saudi Arabia.
Àjọ náà sọ èyí di mímọ̀ nínú àtẹ̀jáde kan tí Alukoro àjọ náà, Ọ̀mọ̀wé Fabian Benjamin gbé jáde.
Àjọ náà ní “Ó lé ní igba àwọn akẹ́kọ̀ọ́ t’ó ṣe ìdánwò UTME tí ó wáyé nígbàkanáà ní ọjọ́ Àbámẹ́ta, ọjọ́ kẹ́tàdínlọ́gbọ̀n, oṣù kẹ́rin, ọdún, 2019 ní àwọn ibi gbogbo tí a dárúkọ tẹ́lẹ̀.
Àjọ náà tún tẹnpẹlẹ mọ́ ọ̀rọ̀ rẹ̀ pé, èsì ìdánwò UTME ti ọdún 2019 kò tíì jáde.
"Ó wá rọ àwọn ènìyàn pàápàá jùlọ àwọn òbí àti àkẹ́kọ̀ọ́ náà pé kí wọ́n ṣọ́ra fún àwọn oníjìbìtì, tí wọn á sọ pé wọ́n fẹ́ lo ọ̀nà ẹ̀bùrú láti ràn wọ́n lọ́wọ́ fún èsì ìdánwò tí wọ́n ṣe.
Àjọ náà tún sọ pé “Àjọ náà yóò polongo èsì ìdánwò náà, nígbà tí ó bá jáde
Ọwọ́ àwọn agbófinro ti tẹ àwọn ọ̀daràn kan, ní èyí tí wọ́n ṣì ń wá àwọn yòókù"
Amẹ́ríkà kan sáárá sí fọwọ́sowọ́pọ̀ pẹ̀lú orílẹ̀-èdè Nàìjíríà láti fòpin sí àìsàn ibà.
Ìjọba orílẹ̀-èdè Amẹ́ríkà ti fi ìdùnnú hàn bí wọ́n ṣe fọwọ́sowọ́pọ̀ àti láti ṣàtìlẹyìn fún orílẹ̀-èdè Nàìjíríà nípá gbígbógun ti àìsàn ibà.
"Aṣojú orílẹ̀-èdè Amẹ́ríkà sí orílẹ̀-èdè Nàìjíríà, W. Stuart Symington l’ó sọ̀rọ̀ yìí l’ásìkò ayẹyẹ láti fi sàmì àyájọ́ Ọjọ́ Àìsán ibà Lágbàáyé tí wọ́n pe àkórí rẹ̀ ní: “Láti gbógun ti àìsàn ibà bẹ̀rẹ̀ láti ọ̀dọ̀ mi""."
Aṣojú Symington wá gbóṣùbà fún àwọn àjọ elétò ìlera orílẹ̀-èdè Nàìjíríà fún akitiyan wọn láti orí àwọn òṣìṣẹ́ elétò ìlera, dé orí àwọn ìyá, àwọn apòògùn òyìnbó, awakọ̀, akọ̀ròyìn, àwọn oníwàdìí, olùkọ́ dé orí àwọn alákòóso ilé-ìkónnkanpamọ́ àti gbogbo àwọn tó kó ipa pàtàkì láti gbógun ti àìsàn ibà lorílẹ̀-èdè Nàìjíríà.
Aṣojú Symington sọ pé gẹ́gẹ́ bí àwùjọ àgbáyé, wọ́n ti ṣe àṣeyọrí nípasẹ̀ ìgbógunti àrùn náà.
---Ààrẹ Buhari fẹ́ ìmóríyá fún àwọn àgbẹ̀.
Ààrẹ Muhammadu Buhari ti ní ṣíṣe ìmóríyá fún àwọn àgbẹ̀ lórílẹ̀-èdè Nàìjíríà ni yóò jẹ́ ohun akọ́kọ́ tí ó wà lọ́kàn òun láti ṣe nínú ìjọba rẹ̀.
"Ààrẹ sọ pé òun ti pàsẹ fún Àjọ tó ń mójútó Iṣẹ́ Ọ̀gbìn àti Ilé-Ìfowópamọ́ tí Ijọba Orílẹ̀-èdè Nàìjíríà láti yọ àwọn ìṣòro àti ìdíwọ́ tí kò jẹ́ kí àwọn àgbè rí owó yá láti fi ṣe iṣẹ́ ọ̀gbìn kúrò níbẹ̀, ní èyí tí ó pè ní “Ìwà àmúnisìn burúkú""."
Fífòpin sí ìwà fàyàwọ́
Ààrẹ Buhari wá bẹnu àtẹ́ lu ìwà fàyàwọ́ tí ó ń ṣàkóbá fún ohun ọ̀gbìn àti iṣẹ́ àgbẹ̀ lórílẹ̀-èdè Nàìjíríà, ó sì ṣèlérí pé òun kò ní káàárẹ̀ láti túbọ̀ máa gbógun ti ìwà burúkú yìí pẹ̀lú gbogbo agbára tó bá wà ní ìkáwọ́ òun.
Ààrẹ ni ìjọba òun yóò túbò máa sa ipá rẹ̀ lórí ètò ààbò, ìdàgbàsókè ètò ọrọ̀-ajé àti gbígbógun ti ìwà ìbàjẹ́, sáà tuntun ìjọba òun yóò tẹnpẹlẹ mọ́ ètò ẹ̀kọ́ àti ìlera.
Ààrẹ sọ fún àwọn ọmọ ẹgbẹ́ náà pé “Mo mọ ìsòro wa. Mo mọ ojúṣe mi sí Ọlọ́run àti orílẹ̀-èdè mi. N ó máa tẹ̀síwájú láti sa ipá mi.”
"Ṣáájú èyí ni adarí ikọ̀ náà, Ọ̀mọ̀wé Arabo Ibrahim Báyọ̀, ní àwọ́n wá sí orílẹ̀-èdè Nàìjíríà nítorí ìfẹ́ tí àwọn ní sí ìdàgbàsókè orílẹ̀-èdè yìí àti ìgbàgbọ́ tí wọ́n ní sí ìṣèjọba Ààrẹ Muhammadu Buhari.
Àwọn ọmọ ẹgbẹ́ náà wá ṣèlérí àtìlẹ̀yìn wọn fún Ààrẹ láti ṣe ohun málegbàgbé lorílẹ̀-èdè Nàìjíríà.
---Orílẹ̀-èdè Nàìjíríà pè fún ètó ààbò lórí ìmọ̀ ẹ̀rọ ìgbàlódé.
Ààrẹ orílẹ̀-èdè Nàìjíríà Muhammadu Buhari ti rọ àwọn adaŕi orílè èdè àgbáyé láti wá wọ̀rọ̀kọ̀ fi ṣàdá lórí bí ìmọ̀ ẹ̀rọ ìgbàlódé yóò ṣe wà lárọ̀wọ́tó àwọn ènìyàn àti èyí tí ètò ààbò tó péye yóò tún wà níbẹ̀.
Nínú ọ̀rọ̀ rẹ̀ níbi Ìpàdé ètò Okoòwò ti ọdún 2019 (AIM) t’ó wáyé ní ìlú Dubai lọ́jọ́ Ajé, Ààrẹ ní ètò ìlànà gbọdò wà nípa èyí tí yóò máa dáàbò bo ìmọ̀ ẹ̀rọ ìgbàlódé lórí ètò ọrọ̀ ajé.
Àkórí ìpàdé àpérò náà ni: ‘Wíwá ọjọ́ iwájú tó dára fún ètò okoòwò: Mímú ìdàgbàsókè bá ètò okoòwò àgbáyé nípa lílo Ìmọ̀-ẹ̀rọ ìgbàlódé.
’’Ààrẹ orílẹ̀-èdè Nàìjíríà ni pípèsè ètò ìlànà fún lílo ìmọ̀ ẹ̀ro ìgbàlódé nìkan ló lè dín wàhálà àti ìsòro tó máa ń wáyé nípa rẹ̀.
Ààrẹ fi àìdunnú rẹ̀ hàn nípa bí wọ́n ṣe ń lo ìmò èrọ ìgbàlódé láti ṣe ayédùrú ètò ìdìbò, ni èyí tí ó tako ẹ̀tọ̀ ọmọnìyàn, tí ó sì tún máa ń dá rògbòdìyàn sílẹ́ láàrín ìlú.
Ààrẹ Buhari, wá rọ àwọn adarí ilé-iṣẹ́ ìjọba àti ilé-iṣẹ́ aládàáni láti fọwọ́sowọ́pọ̀ láti wá ojútùú sí wàhálà àti ìsoro tó máa ń wáyé nípa lílo ìmọ̀ èrọ ìgbàlódé.
---ilẹ̀-rírì lórílè-èdè Indonesia: ó tó ènìyàn màrúndínlógún tí ó ti kú lẹ́yìn ọ̀pọ̀ ọdún ìjàmbá
Ikọ̀ aláàbò tó ń mójútò ìṣèlẹ̀ pàjáwìrì lórílé-èdé Indonesia ti ń wá àwọn ènìyàn tí ó fara káásà nínú ìṣẹ̀lẹ̀ ìjàmbá ilẹ̀ rírì tí ó gba ẹ̀mí ènìyàn màrúndínlógún lọ́jọ́ Ọdún Tuntun, lẹ́yìn irúfẹ́ ìṣẹ̀lẹ̀ náà tí ó wáyé lọ́dún kan ṣẹ́yìn ti o ṣekúpa ọ̀gọ̀rọ̀ ènìyàn.
Ókéré tán ogún ènìyàn ni ó pàdánù ẹ̀mí wọn sínú ìṣẹ̀lẹ̀ ọ̀hún, bẹ́ẹ̀ sì ni ilé ọgbọ̀n sì bá ìṣẹ̀lẹ̀ náà lo nílùú Sukabumi.
Gẹ́gẹ́ bí agbẹnusọ̀rọ̀ ikọ̀ aláàbò náà, Sutopo Purwo Nugroho ṣe sọ,“Ó le púpọ̀ fún àwọn òṣìṣẹ́ oníṣẹ̀lẹ̀ pàjáwìrì láti gba àwọn ènìyàn sílẹ̀ lásìkò ìṣẹ̀lẹ̀ ilè rírì.”
Wàyìí o, àrọ̀rọ̀ dá òjò tí ó rọ̀ lọ́jọ́ Ìṣégun ọ̀hún ni ó dènà iṣẹ́ àwọn aláàbó náà.
Ìṣẹ̀lẹ̀ ìjàm̀bá ilẹ̀ ríri jẹ́ ohun tí ó máa ń ṣẹlẹ̀ lọ́pọ̀lọpọ̀ lórílè-èdè Indonesia, eléyìí tí o sì ṣekúpa ẹgbẹ̀rún mẹ́ta ènìyàn ní àwọn agbègbè lóríṣiríṣi lọ́dún 2018.
---Orílẹ̀-èdè Korea fún Nàìjíríà ni ẹ̀gbẹ̀rún lọ́nà ẹ̀ẹ́dẹ́gbẹ̀ta owó dọ́là.
Ètò Oúnjẹ Àjọ Ìṣọ̀kan Àgbáyé Orílẹ̀-èdè Nàìjíríà ti fi ẹgbẹ̀rún lọ́nà ẹ̀ẹ́dẹ́gbẹ̀ta dọ́là owó ilẹ̀ òkèèrè ran àwọn ènìyàn tí iye wọn dín ní ẹ̀ẹ́dẹ́gbéje ẹ̀gbẹ̀rún fún àwọn ìpínlẹ̀ Borno, Adamawa àti Yobe tí ikọ̀ ọlọ́tẹ̀ Boko Haram sọ di aláìnílé lórí.
Aṣojú orílẹ̀-èdè Korea fún orílẹ̀-èdè Nàìjíríà ajagun fẹ̀yìnti In-Tae Lee, ló sọ pé ìjọba orílẹ̀-èdè Korea ti ń gbìyànjú láti wá ọ̀nà tí yóò gbé ṣèrànwó fún àwọn ènìyàn tí ikọ̀ ọmọ gun Boko Haram sọ di aláìnílé lórí.
Ó ní ìjọba orílẹ̀-èdè Korea yóò fọwọsowọ́pọ̀ pẹ̀lú ìjọba orílẹ̀-èdè Nàìjíríà láti gbógun ti àìsàn ebi àti òṣì lórílẹ̀-èdè Nàìjíríà.
Aṣojú Àjọ Àgbáyé ní orílẹ̀-èdè Nàìjíríà, Myrta Kaulard wá gbósùbà fún orílẹ̀-èdè Korea fún ètò ìránwó tí wọ́n ṣe fún orílẹ̀-èdè Nàìjíríà, pé irú ètò báyìí yóò tún jẹ́ kí ìgbé ayé ìdẹ̀rùn bá àwọn ọmọ orílẹ̀-èdè Nàìjíríà.
---Èka èdè Yorùbá, Ohùn Nàìjíríà (VON) bẹ̀rẹ̀ ìgbòhùn sáfẹ́fẹ́ ní ìlú Àbújá.
Ohùn Nàìjíríà (Voice of Nigeria) ní ẹ̀ka èdè Yorùbá ti bẹ̀rẹ̀ ìgbóhùn sáfẹ́fẹ́ láti ìlú Àbújá.
Adarí ẹ̀ka èdè Yorùbá ní ìlú Àbújá Abíọ́dún Pópóọlá sọ fún àwọn ènìyàn pé, ọ̀pọ̀lọpọ̀ ètò ni àwọ́n ti yà sọ́tọ̀ fún ìgbádùn àwọn olólùfẹ́ jákè-jádò àgbáyé.
Ó tẹ̀síwájú pé Ìfẹ́ àwọn olùgbọ́ wa ló jẹ wá lógún, ìdí nìyí tí àwọn aláṣẹ Ohùn Nàìjíríà, Voice of Nigeria ṣe bẹ̀rẹ̀ ìgbóhùn sáfẹ́fẹ́ láti ìlú Àbújá."
Bákan náà, ni a ti ya àwọn ọ̀pọ̀lọpọ̀ ètò sílẹ̀ fún ìgbádùn àwọn tó ń gbọ́ wa, pàápàá jùlo ilẹ̀ Áfíríkà.
"Ewe, tí ó jẹ́ adarí ìmọ̀ ẹ̀rọ lábẹ́ ẹ̀ka Yorùbá náà tún sọ pé bí ẹ̀ka èdè Yorùbá ṣe bẹ̀rẹ̀ ìgbóhùn sáfẹ́fẹ́ láti ìlú Àbújá jẹ́ ohun tí yóò tún jẹ́ kí àwọn olùgbọ Ohùn Nàìjíríà láti ilẹ̀ òkèèrè tún máa gbọ́ wọn yéké-yéké.
Ó ní kò sí ohun tó dára jùlọ pé kí inú àwọn ènìyàn tó ń gbọ́ wa láti ilé akéde dùn láti máa tẹ́tí sí wọn.
Lára àwọn òṣìṣẹ́ tí yóò máa kópa lórí ètò ọ̀hún náà ni ìyáàfin Adérónkẹ́ Ọ̀súndíyà, Tóbi Ṣàngótọ́lá àti Maryam Yusuf.
Ẹ ó máa gbọ́ Ohùn Nàíjíríà láti ìkànnì 31m 9690khz ní déédé aago mọ̀kànlá ààbọ̀ òwúrọ̀ títí di aago mọ̀kànlá kọjá ìṣẹ́jú márùndínláàdọ́ta àti ní ìrọ̀lẹ́ ní déédé aago màrún kọjá ìṣẹ́jú màrúndínlógún tít́i di aago màrún ààbọ̀.
---Igbákejì Ààrẹ yóò kópa níbi ìpàdé Africa-Europe ni Austria.
Igbákejì Ààrẹ orílẹ̀-èdè Nàìjíríà Yemí Ọ̀sínbàjò yóò máa darapọ̀ mọ àwọn akẹgbẹ́ rẹ̀ láti orílẹ̀-èdè Áfíríkà àti Europe níbi ìjíròrò tí yóò wáyé ní Viénna lórílẹ̀-èdè Austria lọ́jọ́ Ajé, oṣù Kejìlá, ọjọ́ kej̀idínlógún àti ọjọ́ kẹrìndínlógún.
Nínú àtẹ̀jáde kan t’ó wá láti Ibi-iṣẹ́ igbákej̀i Ààrẹ, ó sọ pé Ọ̀jọ̀gbọ́n Ọ̀ṣínbàjò yóò máa sọ̀rọ̀ lórí àkórí ’Gbígbé àjùmọ̀ṣe dé orí ẹ̀rọ ìgbàlódé’ ní ìpàdé náà tí ìjọba orílẹ̀-èdè Austria jẹ́ olùgbàlejò tí ó dúró fún Àjọ Europe àti Àjọ Africa.
Àpérò àwọn èèyàn jànkànjànkàn náà yóò ṣe ìgbélárugẹ ìdàgbàsókè ìmọ̀ ẹ̀rọ ìgbàlódé àti ọgbọ́n àtinudá bí àwọn olùṣètò ní EU àti AU, “gẹ́gẹ́ bí àwọn ohun t’ó ṣe onígbọ̀nwọ́ ìdàgbàsókè ọjọ́ ọ̀la wa, kí gbogbo ènìyàn ó lè jẹ àǹfààní tí ènìyàn yóò jẹ láti ara àwọn àyípadà ìmọ̀ ẹ̀rọ ìgbàlódé.”
Ìpàdé náà yóò tún máa wo bí ìbaṣepọ tó wà láàárín Europe àti Áfíríkà ṣe lọ́wọ́ sí alépa yìí, àṣekún ìmúṣe tí ó ń lọ lọ́wọ́ tí wọ́n fẹnukò lé lórí níbi ìpàdé Abidjan tó wáyé lọ́dún 2017 àti àwọn nǹkan mìíràn, wọn yóò tún máa jíròrò lórí ipa pàtàkì tí ìmọ̀ ẹ̀rọ ìgbàlódé yóò tún fi wúlò fún ìdàgbàsókè ètò ọrọ̀ ajé fún Europe àti Áfíríkà."
Ó lépa ìdásí Àjọṣe fún Ìmúrò Ìdókoòwò àti ìpèsè Iṣé.”
Lásìkò ìrìnàjò rẹ̀ lọ sí Vienna, Ọ̀jọ̀gbọ́n Ọ̀ṣínbàjò yóò máa ṣe ìpàdé abẹ́lé pẹ̀lú àwọn ọmọ orílè Nàìjíríà t’ó ń gbé ní orílẹ̀-èdè Austria; bákan náà ni yóò tún máa ṣe ìpàdé pọ̀ pẹ̀lú àwọn olórí orílẹ̀-èdè Europe, lára wọn ni Adarí ìjọba ti orílẹ̀-èdè Czech Republic, Andrej Babis; Adarí ìjọba ti orílẹ̀-èdè Finland, H.E. Juha Petri Sipilä; Ọba orílẹ̀-èdè Austria, alayé jùlọ, Sebastian Kurz; àti Mínísítà ilẹ̀ aláwọ̀ funfun (UK ) tó ń sojú fún ilẹ̀ Africa, Harriet Baldwin.
Ọ̀jọ̀gbọ́n Ọ̀ṣínbànjò yóò tún máa ṣèpàdé pọ̀ pẹ̀lú àwọn òṣìṣẹ́ àgbà ilé iṣẹ́ Bill àti Melinda Gates Foundation.
Igbákejì Ààrẹ fi ìlú Àbújá sílẹ̀ l’áṣàlẹ́ ọjọ́ Àìkú, yóò sì padà wá sí orílẹ̀-èdè Nàìjíríà lọ́jọ́ Ìṣẹ́gun.
---Ààrẹ Buhari ṣèbọ̀wọ̀ fún àwọn tó pàdánù ẹ̀mí wọn lásìkò Ìṣẹ̀lẹ̀-ìpaninípakúpa.
Ààrẹ orílẹ̀-èdè Nàìjíríà Muhammadu Buhari ti lọ sí ibi tí wọ́n ń kó àwọn Ilé-ọnà ohun àlùmọ́ọ́ni àti àmì ìdàgbére sí ni Auschwitz-Birkenau àti Oświęcim láti lọ bọ̀wọ̀ fùn àwọn tó pàdánù ẹ̀mí wọn lásìkò ogun.
Lẹ́yìn wákàtí kan àti ìṣéjú mẹ́wàá tí Ààrẹ ti rin Ilé-ọnà, fún àwọn tí wọ́n pàdánù ẹ̀mí wọn lásìkò Ogun Àgbáyé kejì, Ààrẹ Buhari tún tọwọ́bọ ìwé láti bọ̀wọ̀ fún àwọn akọni náà nínú ìwé àlejò, tí ó sì lo ọ̀rí ‘Julius Caesar ti Shakespeare:
"Ìwà burúkú tí àwọn ènìyàn ba wù, máa ń tẹ̀lé wọn; ṣùgbón ìwà rere máa ń wọnú eegun lọ."""
Ààrẹ tún gbé òdódó ibojì si Ilé kejì ti ilé-ọnà, tí a mọ̀ sí “Ilé ikú.”
Gẹ́gé bí wọ́n ṣe kọ sórí Ilé ikú náà: ’’Àwọn ẹlẹ́wọ̀n l’ọ́kùnrin àti l’óbìnrin láti gbogbo ilé ìpàgọ́ náà ni wọ́n kó sínú ilé yìí...lẹ́yìn ìfọ̀rọ̀wánilẹ́nuwo ìjìyà, ti wọ́n sí dá wọn lẹ́jọ́ ìyìnbọn pa.”
"Lẹ́yìn ti Ààrẹ kúrò níbẹ̀ tán, ló ń bẹ̀rẹ̀ sí ń dáhùn ìbéèrè láti ọ̀dọ àwọn akọ̀ròyìn tí ó tẹ̀lẹ́ láti ilé –iṣé Ààrẹ pé àwọn tó ń dá wàhálà sílẹ̀ lorílẹ̀-èdè Nàìjíríà’’ jẹ́ aláìlẹ́kọ̀ọ́ àti aláìmọ̀kan.
Ààrẹ lọ fún ìrìnàjọ̀ ọlọ́jọ́ mẹ́rin sí orílẹ̀-èdè Poland, níbi tí yóò ti darapọ̀ mọ́ ìpàdé Àpérò Àyípadà Ojú-ọjọ́ ti UN àgbáyé ní Katowice, ó ṣe àgbékalẹ̀ ọ̀rọ̀ orílẹ̀-èdè rẹ̀ ní ìpàdé ọlọ́jọ́ méjìlá ti COP24, ṣèpàdé pẹ̀lú àwọn olórí àgbáyé tí wọ́n sì bẹ ibi àfihàn orílẹ̀-èdè Nàìjíríà ní àpérò ojú-ọjọ́ náà."
Ààrẹ tún bá àwọn ọmọ orílẹ̀-èdè Nàìjíríà tí wọ́n wà ní Poland sọ̀rọ̀ lọ́jọ́ kejì tí ó dé sí orílẹ̀-èdè Poland.
---Nàìjíríà bá Amẹ́ríkà kẹ́dùn lórí ikú George Bush.
Ààrẹ Muhammadu Buhari ti darapọ̀ mọ́ àwọn adarí orílẹ̀-èdè lágbàáyé láti bá orílẹ̀-èdè Amẹ́ríkà kẹ́dùn lórí ikú Ààrẹ àna George H. Bush, tí ó gbé ìgbé ayé rẹ̀ láti fi sin ìlú àti àwọn ènìyàn.
Ààrẹ Buhari fi ìwé ìkẹ́dùn náà ránṣé sí àwọn ọmọ orílẹ̀-èdè Amẹ́ríkà, ọ̀rẹ́ àti ẹbí olóògbé náà, tí ó jẹ́ Ààrẹ ìkọkànlélógójì ní orílẹ̀-èdè náà, ẹni tí gbogbo àwọn ènìyàn ń kan sáárá sí fún ipa pàtàkì tí ó kó lágbàáyé.
Ààrẹ tún tẹ̀síwájú pé ikú George H. Bush, kìí ṣe orílẹ̀-èdè Amẹ́ríkà nìkan ni yóò dùn,ṣùgbọ́n àjọ gbayé àti àwọn ènìyàn tí ó ti ko ipa rere ní ìgbésí ayé wọn pẹ̀lú.
Ààrẹ wá gbóṣùbà fún ipa rere tí olóògbé náà tí kó ní ìgbésí ayé àwọn ọmọ rẹ̀, ní èyí tí ó ń ràn wọ́n lọ́wọ́ láti kó ipa pàtàkì nínú ipò adarí lágbàáyé.
Ààrẹ wá gbàdúrà pé kí Ọlórun dun orílẹ̀-èdè náà, ẹbí, ọ̀rẹ́ olóògbé náà nínú, àti ìsinmi fún ẹ̀mi rẹ̀.
---Nàìjíríà kò ní pẹ́ gbé àwọn àkọsílẹ̀ ìwé àṣà fún ìdàgbàsókè ìgbáfẹ́ jáde.
Àjo tó ń mójútó àṣà àti ìgbáfẹ́ lorílẹ̀-èdè Nàìjíríà ti sọ pé àwọn kò ní pẹ́ gbé ìwé àkosílè ti yóò sàfihàn gbogbo àwọn àṣà tó wà jákè-jádò orílẹ̀-èdè Nàìjíríà síta láti lè mú ìdàgbàsókè bá àṣà àti ìgbáfẹ́ lorílẹ̀-èdè yìí.
Mínísítà fún ìlanilóye àti àṣà lorílẹ̀-èdè Nàìjíríà, Lai Mohammed ló sọ̀rọ̀ yìí ni Istanbul, lorílẹ̀-èdè Turkey níbi ayẹyẹ àṣà àti ìgbáfẹ́ tí àjọ àgbáyé (UNWTO/UNESCO World Conference on Tourism and Culture) ṣe,eléyìí ló jẹ́ ìkẹta irú rẹ̀ tí àjọ àgbáyé yóò ṣe.
Mínísítà sọ pé o lé ni aárùndínláàdọ́rinlé ọ́ọ̀dúnrún ni àwọn àṣà tó wà ní jákè-jádò orílẹ̀-èdè Nàìjíríà, ìyẹn ni pé orílẹ̀-èdè yìí lè e ṣe àṣà kan lójúmọ́ kan, ní èyí tí yóò jẹ́ kí ìdàgbàsókè bá ètò ìgbafẹ́ àti ọ̀rọ̀ ajé orílẹ̀-èdè yìí.
Àṣà oríṣiríṣi Alhaji Mohammed ni orílẹ̀-èdè Nàìjíríà fìdí múlẹ̀ nínú èdè àti àṣà ni èyí ti àwọn àṣà mííràn tún ti jẹyọ bi I Durbar, iṣu tuntun, Ẹ̀yọ̀ àti ọdún egúngún abbl.
Ó tẹ̀síwájú pé àwọn ìjọba ni gbogbo ẹ̀ka lorílẹ̀-èdè Nàìjíríà ń sa gbogbo ipá ní agbègbè wọn láti gbé àṣà láruge, bákan náà ni ìjọba àpapò náà sì ń ṣètò iranwọ láti fún wọn ní agbègbè tó ṣe é gbé, ní èyí tí yóò mú itẹ̀síwájú bá àṣà lorílẹ̀-èdè yìí.
Mínísítà tún tẹ̀síwájú pé ayẹyẹ àjọ̀dún àṣà tí ó máa ń wáyé nílùú Àbújá jẹ́ ohun tí ó wá láti gbé àṣà lárugẹ, ní èyí tí gbogbo àwọn ìpínlẹ̀ mẹ́rìndínlógójí àti ìlú Àbújá tó wà lorílẹ̀-èdè Nàìjíríà máa ń kópa níbẹ̀.
Ó ní ayẹyẹ àjọ̀dún àṣà kìí ṣe fún eré ìdárayá nìkan, bí kìí ṣe láti tún pèsè iṣẹ́ àti ìdàgbàsókè fún ètò ọrọ̀-ajé lọrílẹ̀-èdè Nàìjíríà.
Àwọn Mínísítà tó lé lọ́gbọ̀n ló wà níbi ayẹyẹ ajọdún agbaye yìí, ọjọ́ mẹ́ta gbáko ni wọn yóò fi se ayẹyẹ yìí.
---WANEP, AU ṣe ìdánilẹ́kọ̀ọ́ nípa ààbò lásìkò ìjàm̀bá ètò ìdìbò.
Gẹ́gẹ́ bí ètò ìdìbò ọdún 2019 ṣe ń súnmọ́ etílé àjọ tó ń mójútó ètò àlàáfíà lórílẹ̀-èdè Áfíríkà West Africa Network for Peace building àti Àjọ Áfíríkà àti àjọ Ecowas ti ṣe ìdánilẹ̀kọ̀ fún àwọn ènìyàn tó lé ní ọgọ́rin, pàápàá jùlọ àwọn ilé-iṣẹ́ aládàáni tí kì í ṣe ti ìjọba láti kọ́ wọn lọ́nà tí wọn yóò fi lè máa dáàbò bo ara wọn nígbà tí ìjàm̀bá bá wáyé lásìkò ètò ìdìbò.
Ẹgbẹ́ náà sọ pé àwọn olùkópa níbi ìdánilẹ́kọ̀ọ́ náà wá láti gbogbo ìpínlẹ̀ mẹ́rìndínlógójì tó wà lórílẹ̀-èdè Nàìjíríà àti ìlú Àbújá.
Ẹgbẹ́ náà sọ pé àwọn ṣe ìdánilékọ̀ọ́ yìí fún àwọn ènìyàn tí yóò kópa láti mójútó ètò ìdìbò, ní pàtàkì jùlo ní ìgbèríko àti ní ìpínlẹ̀ tó wà lorílẹ̀-èdè Nàìjíríà.
Ẹgbẹ́ WANEP tún tẹ̀síwájú pé ọ̀pọ̀lọpọ̀ àwọn ènìyàn ni ẹ̀rú ti ń bà nítorí ètò ìdìbò tó ń bò , pàápàá jùlọ nípa ètò ààbò tí kò fẹsẹ̀ múlẹ̀ , bi àwọn olóṣèlú ṣe ń bú ara wọn àti bí wọ́n ṣe ń dún ìkookò mọ́ ara wọn.
Alákòóso ẹgbẹ́ yìí Chukwuemeka Eze tún ni àwọn ẹ̀gbẹ mẹ́tẹ̀ẹ̀ta yìí fọwọ́sowọ́pọ̀ láti ṣe ìdánilẹ́kọ̀ọ́ yìí láti lè dénà àwọn ìjàm̀bá tó máa ń ṣẹlẹ̀ lásìkò ètò ìdìbò.
Eze tún sọ pé “WANEP, ECOWAS/AU ti ní àwọn yóò gbé àwọn iṣẹ́ àkànṣe kan dìde lórí èrọ ayélujára, ní èyí tí yóò máa jábọ̀, tí yóò sì tún máa tọpinpin bí ètò ìdìbò ṣe ń lọ sí.
Bákan náà, ni ẹgbẹ́ náà yóò tún gbé iṣẹ́ àkànṣe mìíràn dìde tí yóò ran àwọn ti ọ̀rọ̀ kàn lọ́wọ́ láti lèe gbógun ti ìjàm̀bá tó bá lèe wáyé lásìkò ètò ìdìbò , àwọn bí i àjọ elétò ìdìbò, ilé-iṣẹ́ ọlọ́pàá,àjọ tó ń mójútó ọ̀rọ̀ tó jẹ mọ́ ìlù, ẹgbẹ́ onígbàgbọ́ (kristeni) ẹgbẹ́ àwọn mùsùlùmí àti àjọ tó ń pèsè àlàáfíà.
Ààrẹ Buhari ní òun kì í ṣe ẹda.
Ààrẹ Muhammadu Buhari ti sọ̀rọ̀ nígbà àkọ́kọ́ láti tako àhesọ ọ̀rọ̀ pé òun kì í ṣe ènìyàn, pé ẹ̀dà ni òun.
Ó tako ọ̀rọ̀ yìí lọ́jọ́ Àìkú ní orílẹ̀-èdè Poland lásìkò tó ń bá àwọn ọmọ orílẹ̀-èdè Nàìjíríà tó wà ni orílẹ̀-èdè Poland sọ̀rọ̀.
Ọmọ orílẹ̀-èdè Nàìjíríà tó wà ni Poland fẹ́ mọ̀ bóyá Ààrẹ jẹ́ ènìyàn tàbí ẹ̀dà, láti fi òtítọ́ ọ̀rọ̀ tí wọ́n ń sọ múlè, eléyìí wáyé ní gbọ̀ngán tó wà ní Krakow lọ́jọ́ Àìkú.
Ààrẹ Buhari ní ọ̀pọ̀lọ́pọ̀ àwọn ènìyàn ni wọ́n fẹ́ kí òun ti kú lásìkò tí ò ń ṣàìsàn.
"Ó ṣàpèjúwe àwọn tí ó ń sọ̀rọ̀ yìí gege bi ""Aláìmọ̀kan àti aláìlẹ́sìn."
"Ààrẹ sọ pé: “Ọ̀pọ̀lọpọ̀ àwọn ènìyàn ni wọ́n fẹ́ kí n kú lásìkò tí mo ń ṣàìsàn.
Èmi kò ní pẹ́ ṣe ayẹyẹ ọjọ́ ìbí kẹrìndínlọ́gọ́rin mi.
Ìpàdé yìí tún fún àwọn aláṣẹ orílẹ̀-èdè yìí láti jíròrò pẹ̀lú àwọn ọmọ orílẹ̀-èdè Nàìjíríà tó ń gbé ní Poland, eléyìí ni yóò jẹ́ àkọ́kọ́ irú rẹ̀ tí Ààrẹ yóò wá sí ìpàdé àwọn ìgbìmọ̀ tó wà lára àjọ àgbáyé tí wọ́n ń rí sí bí ojú ọjọ́ ṣe ń yí padà (COP24 of Climate Change (UNFCCC), ní èyí tí yóò wáyé ní ọjọ́ kejì sí ọjọ́ kẹ́rin, oṣù kejìlá ọdún yìí."
Ààrẹ fi ìdùnnú rẹ̀ hàn pẹ̀lú ìròyìn tí aṣojú orílẹ̀-èdè Poland Eric Adagogo Bell-Gam sọ nípa àwọn ọmọ orílẹ̀-èdè Nàìjíríà tó ń gbé inú ìlú náà.
Lórí ètò ọrọ̀-ajé, ààrẹ ní ìjọba òun ti dá kíkó oúnjẹ láti òkè òkun wá sí orílẹ̀-èdè Nàìjíríà dúró, pàápàá jùlọ ìrẹsì.
“Mò ń gbìyànjú láti má ṣe owó orílẹ̀-èdè yìí báṣubàṣu, mò ń jáde nígbà tí ó bá pọn dandan.”
Inú mi kìí dùn nígbà tí mo ń bá rí àwọn ọmọdé tí wọ́n tọrọ owó àti oúnjẹ lójú títì.
---Ikọ̀ ọmọ-ogun ọlọ̀tẹ̀ Taliban ṣekú-pa ọlọ́pàá Afghan méjìlélógún.
Ó kéré tán ọlọ́pàá méjìlélógún l’ó pàdánù ẹ̀mí wọn nínú ìkọlù ikọ̀ ọmọ ogun ọlọ́tẹ̀ Taliban sílé-iṣẹ́ ọlọ́pàá Afghan lágbègbè Farah lọ́jọ́ Àìkú.
Agbẹnusọ̀rọ̀ fún ilé-iṣẹ́ ọlọ́pàá Afghan, Mohebullah Moheb ló jábọ̀ ọ̀rọ̀ náà ṣùgbọ́n ti ṣàlàyé bí ọ̀rọ̀ ọ̀hun ṣe lọ lẹ́kùnrẹ́rẹ́.
Agbenusọ̀rọ̀ ikọ̀ ọlọ́tẹ̀ Taliban, Qari Yousuf Ahmadi sọ pé, ọlọ́pàá márùndínlógbọ́n tí o fi mọ àwọn ọ̀gá àgbà ọlọ́pàá ni wọ́n ṣekú-pa, tí wọ́n sì dáná sun ọkọ̀ ọlọ́pàá mẹ́rin.
Ẹ̀wẹ̀, agbenusọ̀rọ̀ nílé ìwòsàn tí wọ́n gbé àwọn tí ó fara kaasa ìkọlu ọ̀hún ló sọ pé, ènìyàn méjìlélógún ni wọ́n ti gbé wọ ilé ìwòsàn náà láti ibi tí ìṣ̀ẹ̀lẹ̀ ọ̀hún ti wáyé.
Ìpàdànù náà ti ń wáyé ní lemọ́-lemọ́, tí ó fi jẹ́ pé òṣìṣẹ́ akọ̀ròyìn ilẹ̀ Améríkà sílùú Afghan ti pè fún ìjíròrò àlááfíà pẹ̀lú ikọ̀ ọlọ́tẹ̀ Taliban.
---Ààrẹ Buhari gbà àmì ẹ̀yẹ fún akitiyan láti dénà àrùn rọmọlápá-rọmọlẹ́sẹ̀.
Ààrẹ Muhammadu Buhari ti gba àmì ẹ̀yẹ ti àrùn rọmọlaparọmọlẹ́sẹ̀ fún gudugudu méje, yàyà mẹfà tí ìjọba rẹ̀ ti ṣe láti gbógun ti ààrùn yìí l’órílẹ̀-èdè Nàìjíríà.
Ààrẹ ẹgbẹ́ Rotary International, Barry Rassin, tí ó wá fún ìrìnàjò ọlọ́jọ́ mẹ́rin sí orílẹ̀-èdè Nàìjíríà, l’ó gbé àmì ẹ̀yẹ náà fi dá Ààrẹ Buhari lọ́lá nílé Ààrẹ t’ó wà lorílẹ̀-èdè Nàìjíríà, ní ọjọ́ Ọjọ́bọ̀.
Ẹgbẹ́ Rotary international ti máa ń fún àwọn adarí orílẹ̀-èdè àti ilé iṣẹ́ tí ó bá fakọyọ nínú ìgbìyànjú wọn láti dénà àrùn rọ́mọ-lapa-rọ́mọ-lẹ́sẹ̀ l’órílẹ̀-èdè wọn.
Ẹni t’ó gba àmì ẹ̀yẹ ọ̀hún kẹ́yìn ni Justin Trudeau, tí ọ́ jẹ́ Adarí Ìjọba orílẹ̀-èdè Canada.
Lára àwọn ènìyàn tí ó tún ti gba àmì ẹ̀yẹ ọ̀hún ni adarí ì̀jọba orílẹ̀-èdè Japan Shinzo Abe, adarí orílẹ̀-èdè Germany Angela Merkel àti akòwe àgbà fún àjọ àgbáyé tẹ́lẹ̀rí Ban Ki-Moon.
Nígbà tí Ààrẹ ń tẹ́wọ́gba àmì ẹ̀yẹ yìí, ó dúpẹ́ lọ́wọ́ ẹgbẹ́ Rotary Internàtional fún àmì ẹ̀yẹ tí wọn fi da a lọ́lá.
’’Ìran mi mọ́ ẹgbẹ́ Rotary International bí ẹní m’owó. Ní t’òóto, iṣẹ́ yín ní í ṣe pẹ̀lú ọmọnìyàn; kò sí iye ohunkóhun tí ó lè san àwọn iṣẹ́ ribi-ribi tí ẹ̀ ń gbé ṣe, a dúpẹ́ lọ́wọ́ yín gidi gan-an.
‘‘Inú mi dùn sí ipa pàtàkì tí ẹ̀ ń kó láwùjọ, ẹ jẹ́ alágbára fún àwọn tí kò lágbára, mo gbàdúrà pé kí Ọlọ́run san àwọn oore tí ẹ ń ṣe wọ̀nyín fún un yín ní ìlópo fún iṣẹ́ ọmọnìyàn yín.
Ààrẹ ní “inú mi dùn pé mo ní akọ́ṣẹ́mọṣẹ́ Mínísítà fún ètò ìlera, tí ó ń bójútó iṣẹ́ náà.
’’Ọ̀gbẹ́ni Rassin wá gbóṣùbà fún Ààrẹ Buhari fún iṣẹ́ gudu gudu méje yàyà mẹfà tí ó ń ṣe láti dẹ́kun àrùn rọmọlápárọmọlẹ́sẹ̀ l’órílẹ̀-èdè Nàìjíríà.
Ó tún rọ Ààrẹ láti túbọ̀ mú kí ètò ìṣèlú àti owó àyàsọ́tọ̀ ó gbé fúkẹ́ sí i kí gbogbo ìpele fún ètò ìbupá àti ìlera abélé ó ba kẹ́sẹjárí.
---Trump yóò yan ọ̀gágun tẹ́lẹ̀rí gẹ́gẹ́ bí aṣojú sílẹ̀ Saudi Arabia.
Ààrẹ ilẹ̀ Amẹ́ríkà, Donald Trump ti yan ọ̀gágun ikọ̀ ọmọ ogun orílé-èdè náà tí ó ti fẹ̀yìn tì gẹ́gẹ́ bí aṣojú ilẹ̀ Amẹ́ríkà sí orílé-èdè Saudi Arabia, gẹ́gẹ́ bí ìlú Washington náà ṣe ń kojú ìdojúkọ látàrí ikú akọ̀ròyìn ọmọbíbí ilẹ̀ Saudi, Jamal Khashoggi tí ó kú sí Ilé-iṣẹ́ Aṣojú Ìjọba Saudi ní Istanbul.
Ilé-iṣẹ́ Ààrẹ sọ̀rọ̀ ọ̀hún di mímọ̀ pé Ààrẹ Trump ti yan ọ̀gágun tẹ́lẹ̀rí ọ̀hún, John Abizaid, lẹ́ni tí ó tukọ̀ ọmọ ogun ilẹ̀ Amẹ́ríkà lásìkò ogun pẹ̀lú orílé-èdè Iraq.
Ní báyìí, ìrètí wà pé ilé ìgbìmọ̀ aṣòfin ilẹ̀ Amẹ́ríkà yóò ṣèpàdé láti bọwọ́lu ìyànsípò tuntun náà.
Ní àfikún sí ikú Khashoggi, ilẹ̀ Washington fẹ̀sùn kan àwọn aṣòfin ilẹ̀ Amẹ́ríkà fún ṣíṣe àtìlẹ́yìn fún ikọ̀ ọmọ ogun ilẹ̀ Saudi Arabia nínú ogun ilẹ̀ Yemen.
Orílé-èdè Amẹ́ríkà kò ì tíì ní aṣojú sílẹ̀ Saudi Arabia láti ìgbà tí Ààrẹ Trump ti gorí àlééfà lọ́dún 2017.
Olùgbani-nímọ̀ràn lórí ètò ààbò nílé iṣẹ́ Ààrẹ Trump John Bolton sọ lọ́jọ́ ìṣẹ́gun pé, òun kò rò pé àwọn àkásílẹ̀ àwòran tí ó rọ̀ mọ́ ikú Khashoggi, ti àwọn àra ilẹ̀ Turkey ń pín káàkiri, lọ́wọ́ ọmọọba ilẹ̀ Saudi, Mohammed bin Salman nínú.
Nàìjíríà fẹ́ ìjìyà tó nípọn fún àwọn t’ó ń ṣe owó ìlú mọ́kumọ̀ku.
Ààrẹ orílé-èdè Nàìjíríà, Muhammadu Buhari ní Paris lọ́jọ́ Àìkú, pè fún ìgbésẹ̀ ìjìyà tí ó gbópọn fún àwọn oníjìbìtì owó, títí kan ìségi ọwọ́ pálábá àwọn ibi ìbapamọ́ wọn.
Ó kìlọ̀ pé àbálé-àbálé ìwà kòsẹ́nimáamfúmi yóò túbọ̀ mú kí ìṣe owó ìlú mọ́kumọ̀ku ó pọ̀ sí i tí ó máa ń ṣe àkóbá fún àwọn mẹ̀kúnnù àti àwọn ará ìlú.
Ààrẹ sọ̀rọ̀ yìí lásìkò ìpàdé tó wáyé ní Paris, Ààrẹ ní orílẹ̀-èdè Nàìjíríà ti ṣàtúnṣe sí àwọn òfin àti ìlànà rẹ̀ láti gbógun ti ìwà ìbàjẹ́ àti láti gba àwọn owó tí àwọn oníwà ìbàjẹ́ kán kó sálọ sí orílẹ̀-èdè mìíràn, kí wọn sì tún fi imú àwọn ọ̀bàyéjẹ́ náà jófin.
Ọ̀rọ̀ Ààrẹ dá lórí “Ìbàjẹ́ ṣíṣe owó ìlú báṣu-bàṣu ati Rìbà: Ìpèníjà lórí Ìṣèjọba Àgbáyé’’ èyí tí àwọn àádọ́rin adarí orílẹ̀-èdè àgbáyé àti ìjọba wà níbi ìpàdé náà.
“A gbọ́dọ̀ gbógun ti ìwà ìbàjẹ́ ní gbogbo ọ̀nà.
Ààrẹ tún sọ pé “mo ti bá àwọn ẹgbẹ́ agbófinró, ilé–ìfowópamọ́, àwọn òṣìṣẹ́ ìjọba àti àwọn mìíràn sọ̀rọ̀ láti ṣàtìlẹ́yìn fún ìjọba nípa gbígbógun ti ìwà ìbàjẹ́.
“Ìrírí wà lorílẹ̀-èdè Nàìjíríà ti fihàn pé ìwà ìbàjẹ́ nípa ṣíṣe owó ìlú kúmọ-kùmọ máa ń jẹ́ kí àwọn ènìyàn jẹ èrè níbi tí wọn kò ṣiṣé sí tí ìjìyà lílọ sí ẹ̀wọ̀n kò tó láti jẹ́ kí àwọn oníwà ìbàjẹ́ wọ̀nyí ronú pìwàdà
"Adarí orílẹ̀-èdè Nàìjíríà wá rọ àwọn adarí ìjọba àgbáyé láti tẹpẹlẹ mọ́ ìlànà tí wọ́n tọwọ́bọ̀ nibi ìpàdé tó wáyé nílùú London lọ́dún 2016 nípa gbígbógun ti ìwà ìbàjẹ́.
Ààrẹ ni àwọn orílẹ̀-èdè Áfíríkà ti gbóṣùbà fún òun nípa ìgbésẹ̀ tí ó ń gbé láti gbókun ti ìwà ìbàjẹ́ lorílẹ̀-èdè Nàìjíríà, ní èyí tí ó ti jẹ́ kí ìbáṣepọ̀ láàárín àwọn orílẹ̀-èdè Áfíríkà wọn tún gún régé.
Ààrẹ Buhari tún ní ètò tí ìjọba òun fi gúnlẹ̀ láti máa ṣòfófó àwọn t’ó bá jí owó ìlú, ti so èso rere nípa pé ọ̀pọ̀lọpọ̀ owó bílíọ́nù ni wọ́n ti rí gbà padà lọ́wọ́ àwọn ọ̀bàyéjẹ́, ní èyí tí wọ́n ti lọ láti pèsè àwọn ohun amáyédẹrùn àti ètò tí àwọn ọmọ orílẹ̀-èdè Nàìjíríà yóò jẹ ànfààní rẹ̀ àti àfojúba àwọn Ìmúró Ìlépa Ìdàgbàsókè.
Adaríkùnrin àti Adaríbìnrin ti Cornwall dé sí orílẹ̀-èdè Nàìjíríà.
Ọmọoba Wales, tó tún jẹ́ àrẹ̀mọ sí ipò ọba ní orílẹ̀-èdè Britain, Charles àti Adaríbìnrin Cornwall, Camilla ti dé sí ìlú Àbújá.
Wíwá sí orílẹ̀-èdè Nàìjíríà wà lára ìrìnàjò rẹ̀ lọ sí ìlú Áfíríkà.
Àwọn ètò tí wọn yóò ti máa kópa. Àwọn ọmọọba yìí yóò máa kópa nínú àwọn ètò ọlọ́kan-ò-jọ̀kan nílùú Àbújá àti ní ìlú Èkó.
Wọn yóò máa bá àwọn ọ̀dọ́ orílẹ̀-èdè yìí sọ̀rọ̀ àti àwọn ọba aládé, àwọn oníṣòwò, àwọn ọmọ–ológun, àwọn ayàwòrán, àwọn oníṣe-òwò àti àwọn ilé-iṣé tí kìí ṣe ti aládàáni.
Lára àwọn ohun tí orílẹ̀-èdè méjèèjì náà yóò máa jíròrò ni bi ìbáṣepọ̀ wọn yóò ṣe tún túbọ̀ máa tẹ̀síwájú, okoòwò, ẹ̀kọ́ fún àwọn obìnrin àti omidan àti nǹkan mìíràn.
Eléyìí ni yóò jẹ́ ìgbà kẹta tí Ọmọọba Wales náà yóò wa ṣe ìbẹ̀wò ní orílẹ̀-èdè Nàìjíríà, ó kọ́kọ́ wá sí orílẹ̀-èdè Nàìjíríà lọ́dún 1990, 1999, àti ọdún 2006, ṣùgbọ́n ìgbà àkọ̀kọ́ nìyí fún Adarí-obìnrin ti ìlú Cornwall láti wá sí orílẹ̀-èdè Nàìjíríà.
---Nàìjíríà ṣèlérí láti jẹ́ kí àwọn ènìyàn jẹ̀gbádùn ètò ìjọba tiwa-n-tiwa.
Ìjọba orílẹ̀-èdè ti ní ohun kò ní káàrẹ́ẹ̀ láti túbọ̀ lọ́wọ́ nínú ìdàgbàsókè ohun amáyédẹrùn jákè-jádò orílẹ̀-èdè Nàìjíríà.
Ààrẹ Muhammadu Buhari lọ́ sọ eléyìí lọ́jọ́ Ajé, níbi ọ̀rọ̀ ìkẹyìn tó sọ nílé Ààrẹ t’ó wà nílùú Àbújá lásìkò ètò ìdágbére ti wọn ṣe fún asojú orílẹ̀-èdè Britain, Paul Arkwright tí ó ń padà lọ sílùú rẹ̀.
Ó sọ pé: “Ìfojúsùn wá ni láti mú ìdàgbàsókè bá ohun amáyéderùn; ojú-pópó, ojú irin, iná mọ̀nà-mọ́ná, àti àwọn ohun mìíràn.
Inú mi ìbá dùn púpọ̀ t’ó bá jẹ́ pé, a ti ṣe gbogbo eléyìí nígbà tí a ní owó lọ́wọ́
Ó sọ̀ wí pé pẹ̀lú owó tó wọlé sí àpò ìṣúná orílẹ̀-èdè yìí láti ọdún 1999 sí 2014 wà nínú àkọsílẹ̀ ṣùgbọ́n wọn kò lo owó yìí dára-dára láti fi pèsè ohun amáyéderùn nígbà náà.
Ààrẹ Buhari wá gbóṣùbà fún Aṣojú orílẹ̀-èdè Britan fún gudu-gudu, méje yàyà mẹfà tí ó ṣe lásìkò ìgbà tí ó jẹ́ aṣojú orílẹ̀-èdè yìí.
Ààrẹ tún ní “Mo máa ń rí ọ ní gbogbo àwọn ìpínlẹ̀ orílẹ̀-èdè yìí.
 Arkwright, t’ó ti lo ọdún mẹ́ta lorílẹ̀-èdè Nàìjíríà náà sọ pé òhún ti lọ sí ìpínlẹ̀ ọgbọ̀n nínú ìpínlẹ̀ mẹ́rìndínlógójì, ó sì ní àwọn ọmọ orílẹ̀-èdè yìí jẹ́ ọlọ́pọlọ t’ó nífẹ̀ẹ́ àlejò, ó wá ṣèlérí pé orílẹ̀-èdè Britain yóò túbọ̀ máa ṣètò ìràńwọ́ fún agbègbèkágbègbè ní orílẹ̀-èdè náà."
Ó wá dúpẹ́ lọ́wọ́ Ààrẹ Buhari fún àtìlẹ́yìn rẹ̀, ó ní ìbáṣepọ̀ tó wà láàárín orílẹ̀-èdè Britain àti orílẹ̀-èdè Nàìjíríà ti tún ní ìdàgbàsóké ju bí ó ṣe wà tẹ́lẹ̀ lọ láàárín ọdún mẹ́ta.
---Àwọn tó ń wa ekùsà l’órílẹ̀-èdè Nàìjíríà yóò jẹ́ àǹfààní bílíọ́nù márùn-ún owó ìrànwó.
Ìjọba àpapọ̀ ti fi orúkọ ẹgbẹ́ àwọn tó ń wa ekùsà lórílẹ̀-èdè Nàìjíríà sí ara àwọn tí yóò jẹ àǹfààní bílíónù márùn-ún tí wọ́n yà sọ́tọ̀ láti fi ran àwọn oníṣẹ́–ọwọ́ àti oníṣòwò kéékèèké lọ́wọ́ ní jáke–jádò orílẹ̀-èdè.
Ìgbìmọ̀ aláṣẹ náà sọ pé ìjọba àpapọ tí ṣèlérí láti fi ẹgbẹ́ náà sí ara àwọn tí yóò jẹ àǹfààní bílíọ́nù márùn ún náà.
Ààrẹ ẹgbẹ́ náà, Alhaji Sani Shehu ló sọ eléyìí nílùú Àbújá pé àjọ tó ń mójútó wíwa ekùsà àti irin lorílẹ̀-èdè Nàìjíríà ni wọ́n gbé ìgbésẹ̀ yìí.
Ó ní bí wọ́n ṣe fi ẹgbẹ́ náà sínú ìpinnu wọn yóò jẹ́ kí ìdàgbàsókè túbọ̀ ba àwọn tó ń wa ekùsà lorílẹ̀-èdè Nàìjíríà.
Egbẹ́ tó ń wa ekùsà lorílẹ̀-èdè Nàìjíríà ti kọ́kọ́ fi ẹ̀dùn ọkàn wọn nípa ìṣòro tí ẹgbẹ́ wọn ń dojúko láti rí owó gbà láti ọ̀dọ̀ Báńkì tó ń mójú tó ọ̀rọ̀ tó jẹ mọ́ ìdàgbàsókè iṣẹ́, tí ó lẹ́tọ̀ọ́ láti fi owó ràn wọn lọ́wọ́ fún ìdàgbàsókè iṣẹ́ wọn.
Ìdàgbàsókè ilé-iṣẹ́ ìgbésè náà wà lára ìpinnu ìjọba àpapọ̀ láti ran àwọn ilé-iṣẹ́ kéékéékè lọ́wọ́, ní èyí tí ìdàgbàsókè yóò fi dé ba ètò ọrọ̀-ajé orílẹ̀-èdè yìí.
Ìgbésẹ̀ yìí tún wà lára ìpinnu ìjọba láti tán ìṣòro t’ó máa ń dojúko àwọn oníṣẹ́ ọwọ́ àti àwọn oníṣòwò ìwakùsà kéékéékè.
Ó ní àjọ náà ti rí ìṣòro tí ó ń dènà àwọn tó ń wa èkùsà láti máa jẹ́kí wọ́n rí àǹfààní èyáwó òhún.
Ó tún sọ pé “ìjọba ti fún wa ní àǹfààní láti lọ́wọ́ níbi etò ẹ̀yáwó náà, wọ́n sí ti ṣèlérí pé àwọn ọmọ ẹgbẹ́ wa yóò jẹ àǹfààní ètò ẹ̀yáwó ọ̀hún.
Ó sọ pé “inú wa dùn sí èyí, àjọ tó ń mójútó ọ̀rọ̀ tó jẹ mọ́ wíwá ekùsà àti irin, báńkì tó ń rí sí ọ̀rọ̀ tó jẹ mọ́ ilé-iṣẹ́ àti ẹgbẹ́ wa yóò fọwọ́sowọ́pọ̀ láti ṣe ìpinnu lórí ọ̀nà tí àwọn ọmọ ẹgbẹ́ wa yóò ṣe máa jẹ àǹfààní ètò èyáwó náà.”
Shehu tún sọ pé gbogbo ìgbésẹ̀ ni àwọn ti gbé báyìí láti rí i pé wọ́n rí ètò èyáwó náà gbà, bákan náà ni ẹgbẹ́ náà ni yóò dúró fún ọmọ ẹgbẹ́ wọn láti yá owó náà.
---NIBUCAA: Àjọ Ìṣọ̀kan Àgbáyé yóò sàtìlẹ́yìn fún Nàìjíríà láti gbógun ti àrùn kògbóògùn.
Àjọ àgbáyé ti ní ààrùn kògbóògùn HIV/AIDS ní í ṣe pèlú ìlera àwọn ènìyàn, nítorí náà, àjọ àgbáyé ti ṣetán láti ṣe àwọn ètò tí yóò máa ṣàtìlẹ́yìn fún orílẹ̀-èdè Nàìjíríà, ni èyí tí yóò fi dẹ́kun ìtànkálẹ̀ ààrùn kògbóògùn lorílẹ̀-èdè Nàìjíríà.
Aṣojú àjọ àgbáyé ní ẹ̀ka ètò tó ń rí sí gbígbógun tí àrùn kògbóògùn Erasmus Murah l’ó sọ̀rọ̀ yìí níbi ètò tí àjọ t’ó ń gbógunti àrùn kògbóògùn lorílẹ̀-èdè Nàìjíríà NIBUCAA ṣe nílùú Àbújá, lọ́jọ́Rú ọ̀ṣẹ̀ yìí.
Musa Shuabu, alága ìgbìmọ̀ àjọ NiBUCAA náà sọ pé ìpinnu láti jẹ́ kí àwọn ilé-iṣẹ́ aládàáni lorílẹ̀-èdè Nàìjíríà fọwọ́sowọ́pọ̀ pẹ̀lú ìjọba àpapọ̀ láti gbógun ti àrùn kòkòrò inú ẹ̀jẹ̀ àti àrùn kògbóògùn (HIV/AIDS) bẹ̀rẹ̀ ní ọdún màrúndínlógún ṣéyìn lásìkò ìjọba Ààrẹ àna olúṣégun Ọbásanjọ́.
"Musa Shuabu sọ pé ""a ti mú ìpinnu wá ṣẹ, nítorí ìfẹ́ tí a ní sí orílẹ̀-èdè Nàìjíríà láti dá àjọ kan sílẹ, ti yóò máa gbógun ti ìtànkálẹ̀ àrùn kògbóògùn."
Ajọ NIBUCAA tí àwọn kán dá sílẹ̀ ní ọdún màrúndínlógún sẹ́yìn, ni ó ti di gbajú-gbajà káàkiri gbogbo àgbáyé.
Musa Shuabu wá dúpẹ́ lọ́wọ́ gbogbo àwọn ilẹ́-iṣẹ́ àti àjọ fún àtileyin wọn láti bí i ọdún màrúndínlógún ṣẹ́yìn láti gbógun ti ìtànkálẹ̀ àrùn kògbóògùn lorílẹ̀-èdè Nàìjíríà, bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé àwọn ìpẹ̀níjà kán wà tó ń kojú àjọ náà.
Ó tún wà rọ̀ wọn láti má káàárẹ láti túbọ̀ máa ṣe àtìlẹ́yìn fún àjọ NIBUCAA, nítorí pé iṣẹ́ si tún ń bẹ láti ṣe.
Alákóòso àjọ NIBUCAA, Gbénga Àlàbí náà tún sọ pé ìfọwọ́sowọ́pọ̀ àwọn ilé-iṣẹ́ aládàáni pẹ̀lú ìjọba láti gbógun ti àrùn kògbóògùn ṣe pàtàkì púpọ̀ nítorí pé ọwọ́ kan kò gbẹ́rù dórí.
A ti ní ọmọ ẹgbẹ́ mẹ́tàdínlógójì báyìí síbẹ̀ àǹfààní ṣì wà láti gba àwọn ọmọ ẹgbẹ́ tuntun tó bá fẹ́ darapọ̀ mọ́ wa, kí a lè jọ gbógunti ìtànkálẹ̀ àrùn kògbóògùn lorílẹ̀-èdè Nàìjíríà.
Ọ̀gbẹ́ni Gbénga Àlàbí tún tẹ̀síwájú pé àjọ NIBUCAA tún ń fọwọ́sowọ́pọ̀ pẹ̀lú ilé-iṣẹ́ NACA lorílẹ̀-èdè Nàìjíríà láti gbógun ti àrùn kògbóògùn, bẹ́ẹ̀ sì ni ọ̀pọ̀lọpọ̀ àwọn àṣeyọrí ni wọ́n ti ṣe nípa ìfọwọ́sowọ́pọ̀ yìí.
Ó wá rọ àwọn ilé-iṣẹ́ aládàáni láti má káàárẹ̀ nípa ìrànwọ́ wọn láti túbọ̀ gbógun ti àrùn kògbòógùn lorílẹ̀-èdè Nàìjíríà
Ó tún tẹ̀síwájú pé ọ̀pọ̀lọpọ̀ àṣeyọrí ni àjọ NiBUCAA ti ṣe láti dẹ́kun ìtànkálẹ̀ àrùn kògbóògùn lorílẹ̀-èdè Nàìjíríà.
Àlàbí sọ pé “Àjọ NIBUCAA pẹ̀lú ìbáṣepọ̀ àwọn olùrànlọ́wọ́ ti ṣe gudu-dudu méje, yàyà mẹfà lórílẹ̀-èdè Nàìjíríà, láti gbógun ti àrùn kògbóògùn.
Àjọ NIBUCAA ti ran àwọn ìpínlẹ̀ wọ̀nyí lọ́wọ́.
Àwọn ìpínlẹ̀ náà ni: Abia, Anambra, Akwa-Ibom, Cross River, Edo, FCT, Kaduna, Katsina, Èkìtì, Imo, Enugu, Katsina, Plateau àti ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́.
Lẹ́yìn ìjíròrò ni àwọn ilé–iṣẹ́ aládàáni, ilé-iṣẹ́ ìjọba àti àwọn tí ọ̀rọ̀ kàn fẹnukò lórí ípinnu wọ̀nyìí,:
---Orílẹ̀-èdè Nàìjíríà ṣèlérí láti pèsè ètò ìrànwọ́ fún Sao Tome àti Principe.
Orílẹ̀-èdè Nàìjíríà ti ṣèlérí láti pèsè ètò ìránwọ́ lórí iṣẹ́ àkànṣe fún orílẹ̀-èdè Sao Tome àti Principe lásìkò ètò ìdìbò ilé ìgbìmọ̀ aṣojú-ṣòfin orílẹ̀-èdè náà, ti yóò wáyé ní ọjọ́ keje oṣù Kẹwàá ọdún yìí
Mínísítà fún ọrọ̀ ilé òkèèrè lorílẹ̀-èdè Nàìjíríà, ọ̀gbẹ́ni Geoffrey Onyeama ló sọ̀rọ̀ yìí lásìkò ìfọ̀rọ̀wérò, pẹ̀lú àwọn akọròyìn láti fi ṣe ayẹyẹ ìfẹ̀yìntì lẹ́nu iṣẹ́ fún Olúkúnlé Bámgbóṣé, t’ó jẹ́ akọ̀wé àgbà fún àjọ tó ń mójútó ọ̀rọ̀ tó jẹ mọ́ ilẹ̀ òkèèrè.
Ọ̀gbẹ́ni Onyeama sọ pé, òun lọ ṣojú Ààrẹ orílẹ̀-èdè Nìàjíríà, Muhammadu Buhari ní orílẹ̀-èdè Sao Tome àti Principe nípa ọ̀nà tí wọn yóò gbà láti pèsè ètò ìrànwọ́ iṣẹ́ àkànṣe fún orílẹ̀-èdè náà.
Ọ̀gbẹ́ni Onyeama ṣ’àlàyé pé “nípa ọ̀nà tí a ó gbà láti pèsè ètò ìrànwọ́ iṣẹ́ àkànṣe fún orílẹ̀-èdè Sao Tome àti Principe ni a ṣe rán mi lọ síbẹ̀.
"Ó tún tẹ̀síwájú pé, “Ààrẹ nígbàgbọ́ láti pèsè ètò ìrànwọ́ fún àwọn orílẹ̀-èdè tó fẹ̀gbẹ́kẹ̀gbẹ́ pẹ̀lú orílẹ̀-èdè Nàìjíríà, ìdí nìyí tí Ààrẹ ṣe pèsè ètò ìrànwọ́ fún wọn.”
Mínísítà wá gbóṣùbà fún akọ̀wé àgbà àná, Bámgbóṣé, fún iṣẹ́ ribi-ribi tí o ṣe láti mú ìdàgbàsókè bá àjo náà."
“Ó jẹ́ akínkanjú ènìyàn, tí ó fẹ́ láti fi gbogbo ọkàn rẹ̀ ṣe iṣẹ́ rẹ̀, ó ní gbogbo ìwà àbùdá ènìyàn rere, ó jẹ́ olóòótọ́ lẹ́nu iṣẹ́, mo sì fẹ́ràn rẹ̀.
Ó sọ pé “Mo fẹ́ràn irú ènìyàn báyìí láti bá ṣe iṣẹ́ papọ̀, tí kò bá fẹ́ nǹkan kan, yóò ṣàlàyé fún mi, á sì tún gbà mí nímọ̀ràn, ìdí tí kò ṣe fẹ́ irú rẹ̀, nítorí náà, a fẹ́ràn ara wa.
"Bámgbóṣé náà wá sọ pé, inú òun dùn láti jẹ́ akòwé àgbà fún àjọ náà, àti pé gbogbo ìpinnu òun, ni òún mú sẹ fún àjo náà lásìkò tó wà lórí ipò náà.
“Mo wà láti wá pẹ̀lú “ìborí wéréwéré”, láàárín ọdún kan, gbogbo ìpinnu mi, ni mo mú ṣe, nítorí náà, mò ń lọ gẹ́gẹ́ bí Akọ̀wé Àgbà aláṣeyọrí.
“Èmi ò lọ gẹ́gẹ́ bí ẹni tí inú rẹ̀ ń bàjẹ́, mo ti ṣe ohun t’ó yẹ kí n ṣe.
“Inú mí dùn pé, mo kọjú àwọn ìpèníjà tí mo bá lẹ́nu iṣẹ́ yìí, mo sc sẹ àṣeyọrí lórí rẹ̀.”
Ní ọ̀rọ̀ tirẹ̀ “ohun tí ó ṣe kókó ni pé iṣẹ́ ń tẹ̀síwájú, mo ti ṣe tèmi, àwọn yòókù yóò ṣe ti wọn, tí o bá ṣe ìwọn tìrẹ, iṣẹ́ yóò lọ síwájú.
Mò ń rọ èyin t’ó wà lẹ́yìn mi, láti tẹ̀lẹ́ gbogbo ìlànà tí mo ti là sílè."
“Pẹ̀lú àjọṣepọ̀, a le è ṣe àṣeyọrí lórí àwọn ìpèníjà tí a ń dojúko nílé iṣẹ́ wa.
Akòwe àgbà tí ó ń lọ náà wá rọ àwọn òṣìṣẹ́ àjọ náà, láti má káàárẹ̀ lórí ìgbìyànjú wọn, kí wọ́n sì fi àpẹẹrẹ rere lélẹ.
Aṣojú Olúkúnlé Bámgbóṣé ń fẹ̀yìntì lẹ́yìn ọdún márùndínlógójì tí ó lò lẹ́nu iṣẹ́ ìjọba ní àjọ náà.
---Àwọn orílẹ̀-èdè t’ó wà lábẹ́ ECOWAS ṣèlérí láti ṣe okoòwò pẹ̀lú China.
Ààrẹ Muhammadu Buhari ti sọ pé orílẹ̀-èdè tó wà lábẹ́ àjọ ECOWAS yóò tẹ̀síwájú láti máa ṣe okòòwò pẹ̀lú orílẹ̀-èdè China nítorí ìbáṣepọ tó dán mọ́ọ́rán tó wà láàárín wọn àti àwọn orílẹ̀-èdè Asian.
Ó sọ̀rọ̀ yìí lọ́jọ́ Ajé, gẹ́gẹ́ bí Alága àjọ ECOWAS níbi ìpàdé tó wáyé láàárín àwọn ọmọ orílẹ̀-èdè China àti àwọn adarí orílẹ̀-èdè Áfíríkà ní China.
Ààrẹ Muhammadu Buhari ni ìrìnàjo ààrẹ orílẹ̀-èdè China Xi Jinping ti ṣàlàyé ni pàtàkì ìbáṣepọ̀ rẹ̀ pẹ̀lú àwọn orílẹ̀-èdè Áfíríkà.
Ààrẹ sọ pé: “Àjọ ECOWAS yóò tún tẹ̀síwájú láti máa ṣe ohun ìwúrí fún àwọn t’ó bá dá okoòwò sílẹ̀ láti ilẹ̀ òkèèrè.
Nítorí náà, àwọn ọmọ ẹgbẹ́ ECOWAS ń fẹ́ kí orílẹ̀-èdè China fún wọn ní àǹfààní láti máa rà tàbí ta ọjà sí orílẹ̀-èdè China.
"Ètò Ìlànà tuntun gẹ́gẹ́ bi ààrẹ Xi Jinping ṣe sọ, ó ní àjọ ECOWAS kò ní pẹ́ gbé ètò ìlànà kan jáde ni èyí tí yóò tún jẹ́ kí àwọn ọmọ ẹgbẹ́ ECOWAS tún wá ọ̀nà mìíràn nípa ètò ọrọ̀-ajé àti láti máa ṣe okoòwò pẹ̀lú orílẹ̀-èdè China.
“Àwọn ọmọ ẹgbẹ́ ECOWAS ti ń ṣ̀etò ìlànà ti yóò tún jẹ kí ètò ọrọ̀-ajé wọn ní ìdàgbàsókè sii.
Ọmọ ẹgbẹ́ ECOWAS tún fẹ́ kí àwọn ọmọ orílẹ̀-èdè China wá fún eré ìgbáfẹ́ lorílẹ̀-èdè Áfíríkà.
Àwọn ẹ̀kùn wa ní ọ̀pọ̀lọpọ̀ ohun nǹkan ìgbáfẹ́.
Pẹ̀lú ìrànwọ́ orílẹ̀-èdè China àwọn ibi ìgbáfẹ́ yóò tún ní ìdàgbàsókè sí i, ní èyí tí yóò ṣe máa pèsè iṣẹ́ lọ́pọ̀ janturu àti èyí tí yóò tún jẹ́ ki òṣì di ohun àfìsẹ́yìn tí eégún ń fi aṣọ.
Alága ECOWAS dúpẹ́ lọ́wọ́ orílẹ̀-èdè China fún ètò okoòwò wọn nílẹ̀ Áfíríkà.
“Láti ọ̀dọ̀ ì̀jọba, àwọn ọmọ orílẹ̀-èdè Nàìjíríà, àwọn Aláṣẹ àti ìjọba àjọ ECOWAS, mo fẹ́ fi ìdúpé wa hàn si ìjọba àti àwọn ọmọ Ilẹ̀ Olómìnira awon Ènìyàn China fún bí wọ́n ṣe gbà wá ní àlejò nígbà tí a dé sí orílẹ̀-èdè China.
“Orílẹ̀-èdè China lónìí, ni oludokoowo t’ó ga jùlọ ni ẹ̀kùn ìlé Áfíríkà yálà ní ilé-iṣẹ́ aládàáni àti ilé-iṣẹ́ ìjọba, tí wọn sì lọ́wọ́ nínú; ohun amáyédẹrùn, iná mọ̀nà-mọ́ná, ètò àgbẹ̀, ohun àlùmọ́nì -ilẹ̀, ìyípadà ọjọ́ àti ètò ìlera.
“China tún ń pèsè ètò ìrànwọ́ fún àwọn aláìní.
ọ̀pọ̀lọpọ̀ iṣẹ́ àkànṣe l’ó ń lọ lọ́wọ́ tí ó sì jẹ́ pé àwọn ọmọ orílẹ̀-èdè China ni wọ́n ń ṣe àwọn iṣẹ́ àkànṣe bí i ojú-irin, iná mọ̀nà-mọ́ná, ọkọ̀ ojú òfuurufú àti ọ̀pọ̀lọpọ̀ ojú ònà ọkọ̀ t’ó jẹ́ owó orílẹ̀-èdè China.
Ààrẹ Muhammadu Buhari tún rán orílẹ̀-èdè China létí nípa kíkọ́ ilé-iṣẹ́ àjọ ECOWAS tuntun, Ààrẹ wá ṣèlérí pé àwọn ọmọ ẹgbẹ́ ECOWAS yóò máa ṣe ohun ìwúrí láti jẹ́ kí àwọn oníṣòwò ilè òkèèrè wá dá ilé-iṣẹ́ sílẹ́ ní ẹ̀kùn wọn.
Ó ní́: “ọlọ́lá jùlọ, a dúpẹ́ fún ìpàdé tó wáyé láàárín orílẹ̀-èdè China àti àjọ ECOWAS, a tún dúpẹ́ lọ́wọ́ Ààrẹ Xi Jinping fún ìlérí tí ó ṣe láti kọ́ ilé-iṣẹ́ ECOWAS tuntun fún àjọ náà.
Jordan kìlò lórí ohun tó lè ṣẹlẹ̀ tí Amẹ́ríkà bá fòpin sí ìrànlọ́wọ́ Palestine.
Mínístà fún ọ̀rọ̀ ilẹ̀ òkèèrè ni Jordan, ti ṣe ìkìlọ̀ pé ó léwu tí Amẹ́ríkà bá fòpin sí ìrànlọ́wọ́ yìí nítorí pé àjọ tó ń rísí ọ̀rọ̀ àwọn aṣàtìpó Palestine UNRWA kò ní agbára láti pèsè ohun tó yẹ fún wọn lásìkò yìí.
Báyìí, ó lé ní mílíọ́nù méjì aṣàtìpó tí wọn ń sàtipo láti àárín gbungbùn ilà oòrùn ní èyí tí yóò yọ sílẹ̀ ní kété tí Amẹ́ríkà bá ti yọwọ́ kúrò.
Ayman Safadi tó jẹ́ mínísítà fún ilẹ̀ òkèèrè ni ó bani lọ́kàn jẹ́ pé Washington yọwọ́ owo ìrànwọ́ ìrànlọ́wọ́ Àjọ ìṣọ̀kan Àgbáyé àti Iṣẹ́ (UNRWA) tí wọ́n ń pèsè fún Palestine.
Mínísítà náà ní ìjọba yóò túbọ̀ máa gbìyànjú láti máa wa àwọn olùrànlọ́wọ́ míràn láti fòpin sí ìṣòro tí àjọ náà ń kojú báyìí fún owó níná.
---Ohun tó kọ iwájú sí ẹnìkan ni ọ̀rọ̀ náà nítorí mínísítà ọ̀tẹlẹ̀múyẹ́ fún Isreal, Isreal Katz yòmbó ìgbésẹ̀ Ààrẹ Amẹ́ríkà láti dá gbogbo owó ìrànwọ́ àjọ UNRWA – t’ó ń ṣàfikún sí ìṣoro àwọn ogúnléndé Palestine.
Àjọ UNRWA, tí ó bẹ̀rẹ̀ iṣẹ́ láti ọdún 1950 ní èyí tí ó ti pèsè ìrànlọ́wọ́ fún ó lè ní mílíọ́nù márùn-ún ogúnléndé Palestine.
Nàìjíríà, Germany àti UN yóò ṣèpàdé lórí ikọ̀ ọlọ́tẹ̀ Boko haram.
Orílẹ̀-èdè Nàìjíríà, Germany, Norway, àti àjọ àgbáyé (United Nàtions)ti pàdé ní Berlin, lọ́jọ́ Ajé láti “ṣèpàdé lórí ikọ̀ ọlọ́tẹ̀ boko haram."
Ìpàdé ti yóò wáyé ni Berlin láti ọjọ́ kẹta sí ìkẹrin lo jẹ́ pé àwọn orílẹ̀-èdè mẹ́ta àti àjọ àgbáyé (UN) ló ṣe onígbọ̀wọ́ rẹ̀, ìpàdé ọ̀hún ní èyí tí ó lágbára jùlọ lọ́dún 2018 fún ẹ̀kùn Lake Chad.
Ìpàdé náà ni yóò dá lórí pípèsè ètò ìrànwọ́ owó mílíọ́nù kan lé ní mẹ́rìndínlọ́gọ́ta dọ́là fún àwọn ẹ̀kùn ti ọ̀fọ̀ ṣẹ̀ sí àti pípèsè ètò ààbò.
bákan náà ni ìpàdé yìí yóò tún pèsè ètò ìrànwọ́ fún àwọn ẹ̀kùn Ìlà -oòrùn Àríwá lórílẹ̀-èdè Nàìjíríà àti apá ibìkan lórílẹ̀-èdè Niger, Chad àti Cameroon tí ikọ̀ Boko Haram ti ṣọṣẹ́ sí.
Níbi ìpàdé náà ni, wọn yóò tún máa jíròrò nípa èròǹgbà, ìmọ̀ràn àti ìrànwọ́ láti ọ̀dọ àwọn ilé-iṣẹ́ tí kì í ṣe ti ìjọba àti ọ̀nà tí wọn yóò gbà láti máa fọwọ́sowọ́pọ̀ pẹ̀lú àwọn orílẹ̀-èdè tí àjálù náà kọlù àti àwọn ẹgbẹ́ tí wọ́n ti ń pèsè ètò ìràwọ́ fún àwọn orílẹ̀-èdè wọ̀nyí.
Ọ̀jọ̀gbọ́n Tijjani Bándé, t’ó jẹ́ aṣojú orílẹ̀-èdè Nàìjíríà ní àjọ UN ló ṣojú orílẹ̀-èdè Nàìjíríà níbi ìpàdé náà tó wáyé ní Berlin.
Aṣojú orílẹ̀-èdè Nàìjíríà ní orílẹ̀-èdè Nàìjíríà ti ṣètò ìlànà owó tó lé ní bílíọ́nù méje dọ́là láti fi ṣàtúnṣe sí àwọn ẹ̀kùn tí ikọ̀ boko Haram bàjẹ́.
Ó sọ pé ìfọwọ́sowọ́pọ̀ àti ìbáṣepọ̀ láàárín àwọn orílẹ̀-èdè tó wà ní lake Chad àti àwọn tí yóò pèsè ètò ìrànwọ́ ṣe pàtàkì púpọ̀.
Àwọn ẹ̀kùn Lake Chad gbọ́dọ̀ le è pèsè ohun amáyédẹrùn, iṣẹ́ lọ́pọ̀ janturu àti iṣẹ́ kíkọ́, lọ́nà tí yóò fi dín wàhálà t’ó ń ṣẹlẹ̀ ní àwọn ẹ̀kùn náà kù.
Láti le ṣe àṣeyorí nípa àwọn ètò ìdàgbàsókè wọ̀nyí, àjọ àgbáyé bí i ilé ìfowópamọ́ àgbáyé, ilé ìfowópamọ́ ti orílẹ̀-èdè Áfíríkà àti àwọn ilé-iṣẹ́ mìíràn ti ṣetán láti ṣètò ìrànlọ́wọ́ fún àwọn orílẹ̀-èdè yìí, tí wọ́n bá lèe fọwọ́sowọ́pọ̀ láti le gbógun ti àwọn ìṣòro tó ń dojú kọ wọ́n.
Àjọ UN ti ní òun yóò pèsè ètò ìràwọ́ fún àwọn tí iye wọn lé ní mílíọ́nù mẹ́fà lorílẹ̀-èdè Nàìjíríà , tí ikọ̀ Boko Haram kọlù ní ẹ̀kùn Ìlà -oòrùn Àríwá lorílẹ̀-èdè Nàìjíríà kí ọdún 2018 ó tó parí.
Edward Kallon, t’ó jẹ́ aṣojú àjọ UN ni ẹ̀ka ètò ìrànwọ́ fún orílẹ̀-èdè Nàjíríà sọ̀rọ̀ ní New York níbi ìpàdé kan pé orílẹ̀-èdè Nàìjíríà ń kojú àwọn ìṣòro púpò.
Ó lé ní mílíọ́nù mẹ́wàá àwọn ènìyàn tó wà ní ìpínlẹ̀ mẹ́ta lorílẹ̀-èdè Nàìjíríà tó wà ní ẹ̀kùn Ìlà -oòrùn Àríwá tí wọ́n nílò ètò ìrànwọ́.
August 30, 2018 --- Gómìnà ìpínlẹ̀ Èkó gba adarí ìjọba Britain lálejò.
Gómìnà ìpínlẹ̀ Èkó, Akínwùnmí Ambode gba adarí ìjọba orílẹ̀-èdè Britain, Theresa May lálejò , ó sọ fún un pé ìpínlẹ̀ Èkó jẹ́ ibi tí àwọn oníṣòwò tẹ̀dó sí.
Gómìnà fi ìdùnnú rẹ̀ hàn láti tẹ́wọ́ gba adarí ìjọba orílẹ̀-èdè Britain ni àlejò, ó só pé ìbáṣepọ̀ tó wà láàárín orílẹ̀-èdè Nàíjíríà àti Britain ti wà láti ọjọ́ pípẹ́.
Ó ní ìmọ̀ ẹ̀kọ́, àṣà, ìṣèlú ti àwọn ọmọ orílẹ̀-èdè Nàìjíríà ń múlò, ló jẹ́ pé láti orílẹ̀-èdè Britain ni wọ́n ti kọ́ọ.
Ibi tí ó dára láti dá okoòwò sílẹ̀, Ambode fi kún ọ̀rọ̀ rẹ̀ pé, ìlú Èkó fi ààyè gba àwọn oníṣòwò láti dá ilé-iṣẹ́ wọn sílẹ̀, pàápàá jùlọ ,wọ́n ní ètò ìṣèjoba tí ó fẹsẹ̀ múlẹ̀, bí ètò ọrọ̀-ajé ìlú Èkó ṣe tóbi púpọ̀ sí, iye àwọn ènìyàn tó ń gbé inú ìlú náà, ìbọ̀wọ̀ fún òfin àti ètò ìdájọ́ tó fẹsẹ̀ múlẹ̀.
Ó sọ pé “a jíròrò pẹ̀lú adarí ìjọba orílẹ̀-èdè Britain, pàápàá jùlọ lórí bí àwọn oníṣòwò orílẹ̀-èdè Britain yóò ṣe mú ìdàgbàsókè bá et̀ò okoòwò nílùú Èkó.
Gẹ́gẹ́ bí ẹ ṣe mọ̀ pé ìlú Èkó ni ibi tí àwọn oníṣòwò gúnlẹ̀ sí lorílẹ̀-èdè Nàìjíríà.
Ọ̀pọ̀ àwọn ọmọ orílẹ̀-èdè Britain ló ní okoòwò nílùú Èkó.
"Gómìnà tún sọ pé bí May ṣe wá sílùú Èkó, yóò tún jẹ́ kí ètò okoòwò àti ààbò tún ní ìdàgbàsókè sí i.
Ó ní àwọn ọmọ orílẹ̀-èdè Britain ní àǹfààní láti lọ́wọ́ nínú ọ̀pọ̀lọpọ̀ okoòwò tó wà nílùú Èkó, bi i ètò agbára, ìmọ̀ ẹ̀rọ, ètò ìṣúná owó, ohun amáyé-dẹrùn àti ilé–iṣẹ́.
Ọ̀pọ̀lọpọ̀ ìgbésẹ̀ ni ìlú Èkó ti ń gbé láti mú ohun ìwùrí dé bá àwọn oníṣòwò láti dá okoòwò sílẹ̀.
Ọ̀pọ̀lọpọ̀ iṣẹ́ lati ṣe, lórí ètò ìdájọ́, inú adarí ìjọba orílẹ̀-èdè Britain sì dùn sí eléyìí.
Ó sì ti ṣetán láti ṣe àtìlẹyìn fún wa láti ṣèrànwọ́ ètò èyáwó àti ìdàgbàsókè lórí ètò ìnáwó.
Ètó ìbáṣepọ̀ Gómìnà sọ pé ìjọba òhun yóò gbìyànjú láti ṣe ohun tó wà níkàwọ́ọ́ rẹ̀ láti túbọ̀ feṣè ìbáṣepọ̀ tó wà láàárín ìlú Èkó àti Britain múlẹ̀ sí i."
Ó sọ pé ‘a ti sọ̀rọ̀ nípa ìmọ̀ ẹ̀rọ, ohun amáyédẹrùn àti ìdásílẹ̀ ilé-iṣẹ́.
Ìbáṣepọ̀ tó wà láàárín ìlú Èkó àti orílẹ̀-èdè Britain bẹ̀rẹ̀ láti ọ̀pọ̀lọpọ̀ ọdún ṣ́eyìn.
Bí ẹ ti mọ̀ pé, ìlú Èkó ni orílẹ̀-èdè Britain fi ṣe olú-ìlú lásìkò ìjọba amúnisìn, Ìdí nìyí tí a gbọ́dọ̀ ṣe ri i pé ọ̀pọ̀lọpọ̀ okoòwò láti orílẹ̀-èdè Britain ló gbọ́dọ̀ wà nílùú Èkó.
Adarí ìjọba orílẹ̀-èdè Britain ti lọ yíká ìlú Èkó, ó sì ti ṣetán láti tún fọwọ́sowọ́pọ̀ pẹ̀lú wa, láti tún jẹ́ kí àwọn ọmọ orílẹ̀-èdè Britain tún dá okoòwò sílẹ̀ si i.
"Adarí ìjọba orílẹ̀-èdè Britain fi ìdùnnú rẹ̀ hàn nígbà tí ó ń bá àwọn akọròyìn sọ̀rọ̀ ni pápá bàálù tó wà nílùú Èkó, pé inú òhun dùn láti wá sí orílẹ̀-èdè Nàìjíríà pàápàá jùlọ sí ìlú Èkó láti rí bí àwọn ilé iṣẹ́ ṣe ń ṣe àṣeyọrí.
Ó sọ pé “Inú mi dùn láti wá sí orílẹ̀-èdè Nàìjíríà, pàápàá jùlọ sí ìlú Èkó, ìbáṣepọ̀ tó dán mọ́nrán wà láàárín orílẹ̀-èdè Nàìjíríà àti Britain, a sì ní ọ̀pọ̀lọpọ̀ nǹkan pàtàkì láti ṣe lọ́jọ́ iwájú.
Mo gbádùn ìlú Àbújá àti Èkó, inú mi sì dùn bi ètò ọrọ̀-ajé ṣe ń ṣe àṣeyọrí níbẹ̀.
“A fẹ́ kí ìdàgbàsókè bá ètò ọrọ̀-ajé orílẹ̀-èdè Nàìjíríà àti Uk, kí a dá ọ̀pọ̀lọpọ̀ iṣẹ́ sílẹ̀ lorílẹ̀-èdè Nàìjíríà, iṣẹ́ tó wà lorílẹ̀-èdè Britain yóò wúlò lorílẹ̀-èdè Nàìjíríà.
Mo dúpẹ́ lọ́wọ́ gómìnà ìpínlẹ̀ Èkó.
’’Ó ní ìlú Èkó ti ṣe gudugudu méje, yàyà mẹfà láti leè mú ìwúrí bá àwọn oníṣòwò ní ìpínlẹ̀ náà.
Arábìnrin May, sọ pé àwọn ti ṣètò èyáwó tí iye rẹ̀ tó mílíọ́nù ẹ̀ẹ́dẹ́gbẹ̀rinléláàdọ́ta owó pọ́ùn tí ìlú Èkó náà sì le è jẹ àǹfààní rẹ̀.
Adarí ìjọba orílẹ̀-èdè Britain tún sọ pé òun wà pẹ̀lú àwọn aṣojú rẹ̀ tó ní ìmọ̀ ẹ̀rọ, ní èyí tí ìlú Èkó lèe jẹ àǹfààní rẹ̀.
Dídá okoòwò sílẹ̀. Ó tún sọ pé orílẹ̀-èdè Britain ti ṣetán láti ran ìlú Èkó lọ́wọ́ nípa ètò okoòwò àti pé orílẹ̀-èdè Nàìjíríà ni wọ́n ti ṣe aṣo jáákẹ́tì tí òun ń wọ̀.
Lára àwọn tó wá pàdé adarí ìjọba orílẹ̀-èdè Britain nígbà tó dé sí pápá ọkọ̀ òfuurufú ní déédé aago mẹ́rin àbọ̀ ọ̀san, ni gómìnà àti Igbákejì Gómìnà, Ọ̀mọ̀wé Olúrántí Adébulé, akọ̀wé ìjọba ìpínlẹ̀, Ọ̀gbẹ́ni Túnjí Bello àti olùrànlọ́wọ́ pàtàkì ìjọba àti olùdarí ọ̀rọ̀ t’ó jẹ mọ́ ti ilẹ̀ òkèère, ọ̀jọ̀gbọ́n Adémọ́lá Abass.
---Ààrẹ Buhari ṣe ìpàdé bòńkẹ́lẹ́ pẹ̀lú Adarí ìjọba orílẹ̀-èdè Britain.
Ààrẹ orílẹ̀-èdè Nàíjíríà Muhammadu Buhari àti Adarí ìjọba orílẹ̀-èdè Britain, Theresa May ṣe ìpàdé bòńkẹ́lẹ́ nílé Ààrẹ t’ó wà nílùú Àbújá.
Ìpàdé náà bẹ̀rẹ̀ ní ófíísì ile Ààrẹ, ní kété tí May dé sí ilé–Ààrẹ ní déédé aago méjìlá ọ̀sán.
Ààrẹ Buhari àti àwọn Adarí ilé-iṣẹ́ ìjọba àpapọ̀ ni wọ́n wá pàdé May.
Ìpàdé náà ni yóò dá lórí ọ̀nà tí ìbáṣepọ̀ orílẹ̀-èdè Nàìjíríà àti Britain yóò ṣe túbọ̀ fẹsẹ̀ múlẹ̀ sii.
Orílẹ̀-èdè méjèèjì yìí, ni yóò tún máa tọwọ́bọ ìwé ìgbọ́ra-ẹni yé (ìbáṣepọ̀) lórí ètò ààbò àti ìdàgbàsókè.
Orílẹ̀-èdè Nàìjíríà wà lára orílẹ̀-èdè tí May fẹ́ kàn sí nílẹ̀ Áfíríkà.
---Turkey ti àwọn afurasí mọ́lé látàrí ìkọlù sílé aṣojú orílẹ̀-èdè Améríkà.
Ilé-iṣẹ́ ọlọ́pàá lórílẹ̀-èdè Turkey tún ti mú àwọn afurasí méjì mííràn látàrí ẹ̀sùn tí wọ́n fi kàn wọ́n pé, wọ́n lọ́wọ́ sí ìkọlù sílé aṣojú orílẹ̀-èdè Amẹ́ríkà (United States embassy) èyí tí ó wáyé lọ́jọ́ Ajé ní olú-ìlú orílẹ̀-èdè ọ̀hún tí ń ṣe Ankara.
Gẹ́gẹ bí ìròyìn ṣe sọ, ìkọlù náà ni àwọn tọ́rọ̀ kàn sọ pé, ó ṣeéṣe kó jẹ́ pé àwọn ọmọ ogun ọlọ́tẹ̀ NATO ni ó wà nídì rẹ̀.
Ni báyìí, àpapọ̀ àwọn afurasí tí ó wà nínú àtìmọ́lé jẹ́ mẹ́rin pẹ̀lú àwọn méjì tí ó ṣẹ̀ṣẹ̀ darapọ̀ mọ́ wọn.
Ilé-iṣẹ́ ọlọ́pàá sọ pé, méjì nínú àwọn afurasí náà mu otí àmupara lásìkò ìkọlù náà.
Ẹ̀wẹ̀, ìròyìn tún fi múlẹ̀ pé ẹnikẹ́ni kò farapa nínú ìkọlù náà.
---Àwọn ènìyàn méjì ni ó kú níbi ìdíje eré ìdárayá orí ẹ̀rọ agbáwòrán ní ìpínlẹ̀ Florida.
Olùkópa kan nínú ìdíje ere-ìdárayá orí ẹ̀rọ agbáwòrán nílùú Jacksonville, ní ìpínlẹ̀ Florida, lórílẹ̀-èdè Amẹ́ríkà tí gbẹ̀mí ara rẹ̀ lẹ́yìn tí ó yìnbọn mọ́ ènìyàn méjì tí wọ́n sí pàdánù ẹ̀mí wọn lẹ́sẹ̀kẹsẹ̀.
Gẹ́gẹ bí ilé-iṣẹ́ ọlọ́pàá ṣe sọ, wọ́n ní, orúkọ afurasí ọ̀hún ń jẹ́ David Katz, ọmọ ọdún mẹ́rìnlélógún tí ó wá láti ìlú Baltimore.
Bákan náà, ènìyàn mọ́kànlá mìíràn tún farapa yánayàna ní gbàgede ìgbáfẹ́ lágbègbè Jacksonville lọ́jọ́ Àìkú (Sunday).
Gẹ́gẹ́ bí àwọn tí ìṣẹ̀lẹ̀ ọ̀hún ṣojú wọn, wọ́n fi múlẹ̀ pé, inú ló bí Katz látààrí pé kò jáwé olúborí nínú ìdíje bọ́ọ̀lù Amẹ́ríkà ọ̀hún (American football eSports event), ní èyí tí ó mú wu ìwà lọ́nà àìtọ́.
Ní báyìí, wọn kòì tíì kéde orúko àwọn tí ó fara kááṣá ìjàmbá náà, di ìgbà tí wọ́n bá tó fojúri àwọn ẹbí wọn, bí ó ti lè jẹ́ pé àwọn mìíràn tí ń ṣèdárò lórí ibùdó-ìtakùn esport.
Oríṣiríṣi ìjàmbá ló tí ń wáyé ní ìpínlẹ̀ Florida láti ọdún mélòó kan ṣẹ́yìn, tí ó fi mọ́ ìjàmbá tí ó wáyé ní gbàgede ìgbáfẹ́ alẹ́ nílùú Orlando lọdún 2016 (Pulse nightclub), ìṣẹ̀lẹ̀ tí ó ṣekú pa ènìyàn mọ́kàndínláàdọ́ta, bẹ́ẹ̀ sì ni ìṣẹ̀lẹ̀ tí ó tún ṣekú pa ènìyàn mẹ́tàdínlógún nílé ìwé Marjory Stoneman Douglas ní agbègbè Parkland nínú oṣù kejì oṣù yìí.
---Iran ṣèlérí láti ṣàtìlẹyìn fún àtúnṣe orílẹ̀-èdè Syria.
Orílẹ̀-èdè Iran ti ṣèpinnu láti mú ìlérí rẹ̀ ṣẹ lójúnà láti sàtìlẹyìn fún àtúnṣe orílẹ̀-èdè Syria nípasẹ̀ pípèsè ètò ìṣúná, òṣèlú tí ó fẹsẹ̀ múlẹ̀ àti àtìlẹyìn ikọ̀ ọmọ ogun.
Amir Hatami tí ó jẹ́ Mínísítà tó ń mójútó ètò ààbò lorílẹ̀-èdè Iran ló jábọ̀ ọ̀rọ̀ náà fún àwọn akọròyìn lásìkò ìpàdé rẹ̀ pẹ̀lú Ààrẹ orílẹ̀-èdè Syria Bashar al-Assad àti Mínísítà tó ń mójútó ètò ààbò, Ali Abdullah Ayyoub lórílẹ̀-èdè náà.
Orílẹ̀-èdè méjèèjì jọ ní àdéhùn pé wọn yóò jọ fọwọ́sowọ́pọ̀ mú àtunṣe bá ilẹ̀ Syria, tí wọn kò sì ní fàyè gba orílẹ̀-èdè mìíràn láti lọ́wọ́ sí àtunṣe ọ̀hún.
Hatami sọ pé,“Syria wà ní ìkoríta tí ó ṣe pàtàkì báyìí, nítorí àwọn ohun tí orílẹ̀-èdè yìí ti làkọjá ṣẹ́yìn lágbára púpọ̀, bẹ́ẹ̀ sì ni ojúnà láti bẹ̀rẹ̀ àtúnṣe ni Ó wà lọ́wọ́lọ́wọ́,Gẹ́gẹ́ bi ẹ̀ka tó ń mójúto ètò ọrọ̀-ajé ìlú àti ọrọ̀ àyíká nínú àjọ ìṣokan àgbáyé, wọ́n fi múlẹ̀ pé orílẹ̀-èdè Syria ti pàdánù ọ́ọ̀dúnrún bílíọ́nù ó lé méjídínláàdọ́rù- ún owó dollar ($388bn) látààrí onírúurú ìjàm̀bá àti ogun tí ó tí ń wáyé láti ọdún 2011 sẹ́yìn."
Nínú oṣù tí ó kọjá, Ààrẹ Assad ṣàlàyé pé, láti ṣe àtúnṣe sí ilẹ̀ Syria ló jẹ òun lógún jùlọ, lẹ́yìn tí ogúnlógó àwọn ọmọ orílẹ̀-èdè Iran ti pàdánù ẹ̀mí wọn ti àwọn mìíràn sì pàdánù ilé àti àwọn ohun ìní wọn sínú ọlọ́kan-ò-jọ̀kan ìjàm̀bá náà.
---Ọkọ̀ òfuurufú tí wọ́n jígbé ní Seattle-Tacoma ti já l’Érèkùsù kan.
Òṣìṣẹ́ ọlọ́kọ̀ òfuurufú kan tó’ jí bàálù kan gbé ní pápákọ̀ òfuurufú Seattle l’órílẹ̀-èdè Amẹ́ríkà ti lọ forí ṣọ́npọ́n ní Èrèkùsù kan.
Àwọn aláṣe ní bàálù náà gbéra lọ́jọ́ Etì láìgba àṣẹ láti gbéra kúrò ní pápákọ̀ òfuurufú ní èyí t’ó jẹ́ kí ìjọba ti pápákọ̀ Seattle-Tacoma pa.
Àwọn ọkọ̀ òfuurufú ajagun méjì F15 ni wọ́n yàn láti tẹ̀lé àti lọ wá bàálù náà kí wọ́n tó gbọ́ bó ṣe já pẹ̀lú ariwo ńlá.
Ọ̀ga ọlọ́pàá agbègbè náà, Pearl Pasor ní kì í ṣe àwọn agbẹ́sùnmómi l’ó jí i bíkòṣe ọlọ́kọ̀ òfuurufú ọmọ ọdún mọ́kàndínlọ́gbọ́n.
Àwòrán ojúìwò kan fihàn pé wọ́n ti ń rọ ọkùnrin náà k’ó balẹ̀ l’álàáfíà k’ó tó di pé ọkọ̀ òfuurufú náà já.
Ìwé ìròyìn The Seattle Times ṣàpèjúwe ọkùnrin náà gẹ́gẹ́ bí ẹni tí kò nání nǹkankan t’ó ti fi ọ̀pọ̀lọpọ̀ àwòrán-olóhùn sórí ayélujára níbi t’ó ti ń fi ọkọ̀ òfuurufú Q400 kan tó jẹ́ ti Alaska Airlines dárà lóríṣiiríṣi.
Leah Morse, t’ó ya àwòrán bí ọkọ̀ òfuurufú náà ṣe ń balẹ̀ ni òun ṣàkíyèsí pé nǹkankan ń ṣe ọkọ̀ náà lójú òfuurufú k’ó tó wá balẹ̀ nítòsí ilé òun pẹ̀lú ariwo ńlá.
---Ìjọba Nàìjíríà yóò gbé àwọn oníbàrá ìrinnà ọkọ̀ òfuurufú Russia lọ sílé ẹjọ́.
Ìjọba àpapọ̀ orílẹ̀-èdè Nàìjíríà ti pinnu láti gbé àwọn oníbàrá ọkọ̀ òfuurufú tó kó àwọn olólùfẹ́ lọ sí orílẹ̀-èdè Russia ṣùgbọ́n tí wọ́n kùnà láti kó wọn adà sí orílẹ̀-èdè Nàìjíríà, ní èyí tí ó jẹ́ kí àwọn ènìyàn náà di alárìnká lẹ́yìn ife ẹ̀yẹ bọ́ọ̀lù 2018 tó wáyé ní orílẹ̀-èdè Russia.
Aṣojú orílẹ̀-èdè Nàìjíríà sí orílẹ̀-èdè Russia ọ̀jọ̀gbọ́n Steve Ugba l’ó sọ̀rọ̀ yìí lórí ẹ̀rọ fídíò ayélujára, ní èyí tí ó fi ránṣẹ́ sí agbẹnusọ̀rọ̀ àjọ t’ó ń rí sí ọ̀rọ̀ ilẹ̀ òkèkèrè, Tope Elias-Fàtile lọ́jọ́ Àìkú, nílùú Àbújá.
Ugba jẹ́ kí àwọn olólùfẹ́ ọmọ orílẹ̀-èdè Nàìjíríà tó wà ní Moscow, ní Russia mọ̀, ipò tí ìjọba wà, kí ó tó lọ sí orílẹ̀-èdè Nàìjíríà.
Ó lé ní àádọ́jọ (150) olólùfẹ́ eré bọ́ọ̀lù tí wọn jẹ ọmọ orílẹ̀-èdè Nàìjíríà tí àwọn oníbàrá ọkọ̀ òfúrufú kùnà láti kó padà wá sí orílẹ̀-èdè Nàìjíríà, ní èyi tí àwọn ènìyàn náà lọ sí ilé-iṣẹ́ tó ń ṣojú orílẹ̀-èdè Nàìjíríà ní Moscow lọ́jọ́ kejìlá oṣù keje, láti bèèrè fún ìrànlọ́wọ́ láti ọ̀dọ àjọ náà lẹ́yìn tí eré bọ́ọ̀lù ìdárayá t’ó wáyé lọ́dún yìí parí.
Lọ́jọ́ kẹrìndínlógún ni Ààrẹ orílẹ̀-èdè Nàìjíríà Muhammadu Buhari ti pàṣẹ fún Mínísítà tó ń rí sí ilẹ̀ òkèèrè Geoffrey Onyeama àti akẹgbẹ́ rẹ̀, t’ó ń rí sí ọ̀rọ̀ tó jẹ mọ́ ọkọ̀ òfuurufú Hadi Sirika, láti kó gbogbo àwọn ọmọ orílẹ̀-èdè Nàìjíríà padà wá sí ìlú Àbújá ní kíákía.
Ṣáájú ọjọ́ náà ni bàálù Ethiopia ti kó àwọn ènìyàn márùndínlọgọ́jọ wá sí ìlú Àbújá ní ogúnjọ́ oṣù keje.
Àwọn ènìyàn náà kò sàì fi ìdùnnú wọn hàn sí Ààrẹ orílẹ̀-èdè Nàìjíríà Muhammadu Buhari láti rí i pé àwọn ènìyàn náà padà wá sílé.
Ugba, ní ìjọba orílẹ̀-èdè yìí kò ní jẹ́ kí àwọn ọ̀daràn náà lọ ní àlááfíà, ó wá rọ àwọn olólùfẹ́ eré ìdárayá tó jẹ́ ọmọ orílẹ̀-èdè Nàìjíríà láti fi ìwé àkọsílẹ̀ wọn ránṣẹ́ sí ilé-iṣẹ́ wọn, láti lè jẹ́ kí ìjọba mú àwọn ọ̀daràn náà.
“Ẹ fún wa ní ìwé àkọsílẹ̀ tí ẹ ni nípa àwọn ènìyàn tó lù yín ní jìbìtì, tàbí tí wọ́n gbé e yín lówó lọ, kí a lè fìyà tó tọ́ jẹ wọn ní orílẹ̀-èdè Nàìjíríà.
A ò ní jẹ́ kí wọn lọ láì jìyà.
Nítorí náà, ẹ fún wa ni ìwé àkọsílẹ̀ ti ẹ ni nípa wọn.
Ó tún sọ pé “à ń dúró de wọ́n ní orílẹ̀-èdè Nàìjíríà, irú ìwá tí ẹ hù yìí, fihàn pé ẹ jẹ́ ọmọlúàbí, pé ẹ tún ní ìbọ̀wọ̀ fún ara yín àti orílẹ̀-èdè yín.
“Kì í ṣe ìwà ọ̀daràn ni pé, ẹ wá sí orílẹ̀-èdè Russia, kí ó wá jẹ́ ìwà ọ̀daràn láti padà sílé.
“Ìwà ọ̀daràn ni, fún ẹni tí o ta ìwé ìrìnnà fún un yín, ṣ̀ugbọ́n tí ó kùnà láti kó o yín padà wá sílé, lẹ́yìn tí ó ti gba owó láti kó yín padà, nítorí náà, kì í ṣe ẹ̀bi yín.
Ó tún sọ̀ pé “A ó ri i pé a fìyà jẹ àwọn tó hu irú ìwà yìí, lábẹ òfin, tó fi jẹ pe lọ́jọ́ mìíràn, wọn kò ní hu irú ìwà bẹ́ẹ̀ mo.
’’Ugba tún sọ pé orílẹ̀-èdè Nàìjíríà gbóṣùbà fún àwọn olólùfẹ́ yìí bí wọ́n ṣe lọ sí orílẹ̀-èdè Russia láti lo yẹ àwọn Super Eagles sí lorílẹ̀-èdè Russia.
Ó ní ìwà tí wọ́n hù yìí, tí jẹ kí orílẹ̀-èdè Nàìjíríà jẹ́ ọ̀rẹ́ pàtàkì pẹ̀lú orílẹ̀-èdè Russia.
---Ààrẹ Trump yóò ṣàtúnṣe sí bàálù òfuurufú ti ààrẹ.
Ààrẹ orílẹ̀-èdè Amẹ́ríkà, Donald Trump ti sọ pé òhun yóò ṣàtúnṣe sí bàálù òfuurufú ti ilé-iṣẹ́ ààrẹ nípa kíkùn ún ní pupa, funfun àti búlúù.
"Trump ní pé ""ó dára kí bàálù tuntun Boeing jẹ́ kíkùn sí ọ̀dà pupa, funfun àti àwọ̀ aró."
Ààrẹ àná orílẹ̀-èdè Amẹ́ríkà, John F Kennedy àti ìyàwó rẹ̀, ni wọ́n mú ọ̀dà yìí lọ́dún 1960.
Ìpílẹ̀ tuntun àmọ́ṣá ìpílẹ̀ tuntun yìí yóò parí lọ́dún 2021.
Trump sọ̀rọ̀ yìí ní Scotland lọ́jọ́ ìsinmi ọ̀sẹ̀ yìí pé, bàálù náà yóò tún wúlò fún àwọn’’ ààrẹ lọ́jọ́ iwájú’’’nítorí ọ̀pọ̀lọpọ̀ ọdún ti yóò lò.
Trump tún sọ pé “a ó ní ọ̀pọ̀lọpọ̀ Ààrẹ, tí wọn yóò jẹ ànfààní yìí.
"Àtúnṣe sí bàálù òfuurufú náà yóò dára púpọ̀, yóò tún jẹ́ èyí tó dára jùlọ ní àgbáyé""."
Ilé-iṣẹ́ ọmọ ogun orí òfuurufú orílẹ̀-èdè Amẹ́rikà ní bàálù méjì̀.
Lọ́dún 1959 ni Ààrẹ Dwight D Eisẹnhowe lo bàálù àkọ́kọ́, t’ó àwọ̀ pupa àti wúrà ṣùgbọ́n láyé Ààrẹ Kennedy bàálù náà tún lo àwọ̀ aró àti funfun, títí di òní yìí.
Àwọn alátakò tí ń sọ̀rọ̀ lórí ìṣàmúlò ẹ̀rọ twitter rẹ̀ pé bàálù orílẹ̀-èdè Russia, China àti France náà ní ọ̀dà pupa, funfun àti àwọ̀ aró, nítorí náà kí Trump fi ọ̀dà náà sílẹ̀ bó ṣe wà.
Ilé-iṣẹ́ akoròyìn ní orílẹ̀-èdè Amẹ́ríkà sọ pé Ààrẹ Trump tí ń gbèrò láti ṣe àtúnṣe sí bàálù náà.
"Ìròyìn tún sọ pé ààrẹ̀ Trump fẹ́ kí bàálù náà tún dà bíi tuntun ""kó dà bí ti Amẹ́ríkà, kò yí kúrò ní èyí tó dà bí i ti ọ̀dà Jackie Kennedy’’, ní èyí tí Raymond Loewy sọ pé ó dà bí ọkọ̀ ojú omi."
Bàálù òfuurufú náà ti lo ọgbọ̀n ọdún, Ààrẹ George H W Bush, ni wọ́n kọ́kọ́ fi gbé.
Nígbà tí ààrẹ̀ Trump jáwé olúborí gẹ́gẹ́ bi ààrẹ̀ orílẹ̀-èdè Amẹ́ríkà, ó sọ̀rọ̀ lórí ìṣàmúlò twitter rẹ̀ pé, láti ra bàálù tí yóò máa gbé ààrẹ̀ yóò na wọn ni bílíọ́nù mẹ́rin dọ́là, ní èyí tí ó fagilé.
---Ààrẹ Buhari dé sí Hague fún ìpàdé àgbáyé ICC.
Ní ìrọ̀lẹ́ ọjọ́ Àìkú ni Ààrẹ orílẹ̀-èdè Nàìjíríà Muhammadu Buhari dé sí orílẹ̀-èdè Netherlands ṣáájú ìrìnàjò rẹ̀ lọ sí ilé-ẹjọ́ àgbáyé fún ìwà ọ̀daràn, ICC nílùú Hague.
Bàálù Ààrẹ balẹ̀ sí Rotterdam ní pápá òfúrufú Hague ní déédé aago méje kọjá ìṣẹ́jú mẹ́tàlélógún ọ̀sán, àkókò orílẹ̀-èdè Nàìjíríà.
Ààrẹ ilé-ẹjọ́ àgbáyé ICC, adájọ́ Chile Eboe-Osuji, àti igbákejì rẹ̀ fún ilé-ẹjọ́ náà, Marc Perrin de Brichambut àti Mínísítà fún ọ̀rọ̀ ilẹ̀ òkèèrè, Geoffrey Onyeama, ni wọn jọ lọ pàdé Ààrẹ ní pápá òfúrufú náà.
Lára àwọn tó tún wà ní pápá òfúrufú náà ni Oji Ngofa, aṣojú orílẹ̀-èdè Nàìjíríà fún orílẹ̀-èdè Netherlands,ọ̀gbẹ́ni Robert Petri tó jẹ́ aṣojú orílẹ̀-èdè Netherlands fún orílẹ̀-èdè Nàìjíríà , ọ̀gágun Veenhuijzen,olùrànlọ́wọ́ ọba orílẹ̀-èdè Netherlands àti àwọn ọ̀gá àgbà fún ilé-iṣẹ́ tó ń rí sí ọ̀rọ̀ ilẹ̀ òkèèrè lórílẹ̀-èdè Netherlands.
Olùràlọ́wọ́ Ààrẹ lórí ìròyìn àti ìpolongo, Fẹ́mi Adésínà sọ pé Ààrẹ yóò lo àǹfààní náà láti tún sọ̀rọ̀ níbi ayẹyẹ àjọ̀dún ogún ọdún tí orílẹ̀-èdè Rome wà lára ilé-ẹjọ́ àgbáyé tó ń rí sí ìwà ọ̀daràn.
Ààrẹ yóò tún máa lo àǹfààní náà láti rí arábìnrin Fatou Bensouda t’ó tún jẹ́ agbẹjọ́rò fún àjọ ICC.
Fẹ́mi Adésínà tún sọ pé “òun nìkan ni Ààrẹ tí wọ́n pè fún ayẹyẹ àjọ̀dún ogún ọdún àti pé àwọn ọ̀gá àgbà ilé-iṣẹ́ lorílẹ̀-èdè Nàìjíríà rí pípè yìí gẹ́gẹ́ bi ọ̀nà láti fi dúpẹ́ lórí àtìlẹyìn tí orílẹ̀-èdè Nàìjíríà ń ṣe fún àjọ náà.
Kí Ààrẹ tó dé sí Hague ni aṣojú orílẹ̀-èdè Nàìjíríà ti bá àwọn akọ̀ròyìn sọ̀rọ̀ pé b’ó tilẹ̀ jẹ́ pé àwọn kan ń tako ilé-ẹjọ́ àgbáyé tó ń rí sí ìwà ọ̀daràn síbẹ̀ Ààrẹ Buhari nígbàgbọ́ pé iṣẹ́ tí ilé-ẹjọ́ àgbáyé náà ń ṣe yóò dẹ́kun àwọn ìwà ọ̀daràn l’órílẹ̀-èdè àgbáyé.
‘Láti bi ogún ọdún ṣẹ́yìn ni orílẹ̀-èdè Nàìjíríà tí ń jẹ́ igi lẹ́yìn ọgbà fún ilé-ẹj̀ọ àgbáyé, pàápàá jùlọ l’órílẹ̀-èdè Áfíríkà.
Nítorí náà, ìrìnàjò Ààrẹ wá sí ilé-ẹjọ́ àgbáyé jẹ́ ọ̀nà láti fi ìfẹ́ hàn sí àtìlẹ́yìn rẹ̀.
Aṣojú náà tún sọ pé ‘‘ìdánilójú wà pé ìrìnàjò Ààrẹ yóò tún fihàn pé orílẹ̀-èdè Nàìjíríà jẹ́ alátìlẹyìn fún ìpinnu Rome.
---Ààrẹ Buhari dárò ikú aṣòfin Longjan
Ààrẹ Muhammadu Buhari ti bá ilé ìgbìmọ̀ aṣòfin, ìjọba àti àwọn ènìyàn ìpínlẹ̀ Plateau dárò lórí ikú aṣòfin Ignatius Longjan tó ń ṣojú fún ilà Gúúsù ìpínlẹ̀ Plateau.
Ààrẹ bá ẹbí, ọ̀rẹ́ àti àwọn ìsọ̀ngbè aṣòfin náà tí ó jẹ́ igbákejì gómìnà lọ́dún 2011-15, t’ó tún jẹ́ aṣojú orílẹ̀ èdè Nàìjíríà fún ọ̀pọ̀lọpọ̀ ọdún kẹ́dùn.
Ààrẹ wá gbàdúrà pé kí Ọlọ́run tẹ́ olóògbé náà sí afẹ́fẹ́ ire.
---Ilé-iṣẹ́ ọlọ́pàá kò ní kàárẹ̀ láti túbọ̀ máa gbógun ti ìwà ọ̀daràn.
Ilé-iṣẹ́ ọlọ́pàá l’órílẹ̀ èdè Nàìjíríà ti ní òhun kò ní kàárẹ̀ láti túbọ̀ máa gbógun ti ìwà ọ̀daràn l’órílẹ̀ èdè yìí.
Adarí ilé-iṣẹ́ ọlọ́pàá lórílẹ̀ èdè Nàìjíríà, Mohammed Adamu ló sọ̀rọ̀ yìí lásìkò tó ń ṣe àbẹ̀wò sí àwọn akínkanjú ọlọ́pàá tó farapa nígbà tí wọn ń wọ̀yá ìjà pẹ̀lú àwọn ọ̀daràn nínú igbó Kuduru tó wà ní ìjọba ìbílẹ̀ Birnin Gwari, ní ìpínlẹ̀ Kaduna.
Igbákejì adarí ilé–iṣẹ́ ọlọ́pàá, Abdulmajid Ali tó ṣojú fún adarí ilé-iṣẹ́ ọlọ́pàá orílẹ̀ èdè yìí ni adarí ilé-iṣẹ́ ọlọ́pàá ló ní kí òun wá wo àwọn akínkanjú ọlọ́pàá náà, tí wọn farapa níbi ìṣẹ̀lẹ̀ tó wáyé pẹ̀lú àwọn ọ̀daràn ọ̀hún.
Ó ní inú òun dún pẹ̀lú ìtọ́jú tí àwọn ọlọ́pàá náà ń gbà nílé ìwòsàn, ó ní. “Àwọn dókítà ń tọ́jú àwọn tó farapa náà, nítorí náà kò sí ìbẹ̀rù nípa ìtọ́jú tí wọn ń gbà“.
Ó wá fi dá àwọn tó farapa náà lójú pé, wọn yóò gba ìtọ́jú tó péye.
Igbákejì adarí ilé–iṣẹ́ ọlọ́pàá náà ní ó seni láàánú pé àwọn ọlọ́pàá méjì ló gbẹ́mìí mì. Orúkọ àwọn ọlọ́pàá tí wọn kú náà ní Muhammad Abubakar àti Sergeant Idris
---Àjọ tó ń mójútó ètò ìlera ní àgbáyé ti rọ orílẹ̀ èdè Nàìjíríà láti mójútó gbogbo ẹnu ibodè ati ibùdó ọkọ tó wà lórílẹ̀ èdè yìí nípa gbígbógun ti ìwà ààrùn ohun ọsin, coronavirus, pàápàá jùlọ ní àwọn ìpínlẹ̀ mẹ́sàn án tó wà lórílẹ̀ èdè yìí.
Alákòsóo ètò àkànse fún ètò pàjáwìrì ní ẹka àjọ WHO, arábìnrin, Dhamari Naidoo sọ̀rọ̀ yìí lásìkò ìfọ̀rọ̀wánilẹ́nuwò pẹ̀lú àwọn akọ̀ròyìn nílùú Àbújá.
Ó tẹ̀síwájú pé àwọn ìpínlẹ̀ tó wà nínú ewu láti ní ààrun coronavirus lórílẹ̀ èdè yìí ni: Àbújá, Èkó, Kano, Cross River, Akwa Ibom, Port Harcourt, Enugu, Delta, ati Bayelsa.
Ó tún sọ pé àjọ WHO ti ṣètò ìrànwọ́ àyẹ̀wò ní àwọn ilé ìwòsàn tó wà ní Gaduwa nílùú Àbújá àti LUTH tó wà nílùú Èkó.
Arábìnrin Naidoo tún sọ pé àwọn orílẹ̀ èdè mẹ́tàlá ló wà nínú ewu àrùn coronavirus, nítorí bí ọ̀pọ̀ ènìyàn ṣe ń yawọ àwọn orílẹ̀ èdè yìí, Algeria, Angola, Cote d’Ivoire, Democratic Republic of Congo, Ethiopia, Ghana, Kenya, Mauritius, Nigeria, South Africa, Tanzania, Uganda àti Zambia.
Arábìnrin Charity Warigon tó jẹ́ alákòóso ẹka tó ń mójútó ètò ìròyìn ni àjọ WHO wá rọ àwọn akọ̀ròyìn láti máa ṣèwádìí ìròyìn wọn kí wọn tó gbée jáde, pàápàá jùlọ nípa ààrùn coronavirus, nítorí ìròyìn tí wọ́n bá gbé jáde ni àwọn ènìyàn máa ń gbẹ́kẹ̀le.
---Orílẹ̀ èdè Germany ti ní ohun ṣetán láti fọwọ́sowọ́pọ̀ pẹ̀lú orílẹ̀ èdè Nàìjíríà láti mójútò ìṣoro ìṣikirí.
Mínísítà ìpínlẹ̀ fún orílẹ̀ èdè Germany àti kọmísọ́nà fún ọ̀rọ̀ tó jẹ mọ́ sísá kúrò lórílẹ̀ èdè, ṣíṣe àtìpó àti ìbágbépọ̀, ọbabìnrin Annette Widmann-Mauz, ló sọ̀rọ̀ yìí lásìkò tó ṣe àbẹ̀wò sí orílẹ̀ èdè Nàìjíríà.
Mínísítà ìpínlẹ̀ fún orílẹ̀ èdè Germany ní “ Orílẹ̀ èdè Nàìjíríà tí ń kó ipa pàtàkì láti ṣe àtìpò fún àwọn ọmọ orílẹ̀ èdè wọn tó wà nílùú Germany, ìdí nìyí tí a ṣe fẹ́ fọwọ́sowọ́pọ̀ láti bá wọn ṣe iṣẹ́ papọ̀, mo sì ní ìtara láti rí.
Ọbabìnrin tún ṣàlàyé pé, wọn yóò gbé ìgbésẹ̀ ní kíákíá láti leè wá ojútùú sí èrèdí ohun tó ń fá kí àwọn ènìyàn máa sá kúrò ní orílẹ̀ èdè wọn.
Ó tún tẹ̀síwájú pé “Láti leè gbé ìgbésẹ̀ nípa bí àwọn ènìyàn ṣe ń sá kúrò lórílẹ̀ èdè wọn, a nílò olùbásepọ̀ tó múná-dóko, ìdí nìyí tí a fi ní orílẹ̀ èdè Nàìjíríà tó jẹ́ alábàásisẹ́pọ̀ pẹ̀lú wa”.
Ṣáájú èyí ni kọmísọ́nà tó ń mójútó, àtìpó, sísá kúrò lórílẹ̀ èdè àti àwọn tí ogun lé kúrò ní ibùgbé wọn, Aṣòfin Basheer Garba Mohammed náà sọ pé orílè èdè Nàìjíríà ń ṣiṣẹ́ ètò ìlànà nípa ti ìṣínípòkiri.
Ilé ìgbìmọ̀ aṣòfin ń ṣe ìpàdé bòǹkẹ́lẹ́ pẹ̀lú adarí àwọn ọlọ́pàá Nàìjíríà.
Ilé ìgbìmọ̀ aṣòfin orílẹ̀ èdè Nàìjíríà ti wà ní ìpàdé bòǹkẹ́lẹ́ pẹ̀lú adarí àwọn ọlọ́pàá orílẹ̀ èdè yìí, Mohammed Adamu láti wa sọ̀rọ̀ nípa ìṣoro tó ń dojúkọ ètò ààbò lórílẹ̀ èdè yìí.
---Ilé-iṣẹ́ ààrẹ ti ní ìgbésẹ̀ tí ẹgbẹ́ àwọn onígbàgbọ́ Christian Association of Nigeria (CAN) gbe ́ jẹ́ ẹ̀tọ̀ gbogbo ọmọ orílẹ̀ èdè Nàìjíríà láti fi ẹ̀hónú hàn nípa èròǹgbà wọn lórí ẹ̀sìn, ìlànà iṣẹ́ àti àwùjọ.
Ọlùrànwọ́ ààrẹ Buhari lórí ìròyìn àti ìkéde, Garba Shehu ní ààrẹ bá àwọn onígbàgbọ́ kẹ́dùn, bẹ́ẹ̀ sìni inú ààrẹ tún bàjẹ́ lórí bí Boko Haram ṣe pa pásítọ̀ Lawan Andimi.
---Ìjọba orílẹ̀ èdè Amẹ́ríkà, ti gbósùbà fún ààrẹ Buhari lórí ipa tí ó ń kó láti gbógun ti ìwà ìbàjẹ́ lórílẹ̀ èdè Nàìjíríà.
Nínú àtẹ̀jáde kàn tí Morgan Ortagus, tí ó jẹ́ agbẹnusọ fún ilé-isẹ́ ọ̀telẹ̀múyẹ́ fún orílẹ̀ èdè Amẹ́ríkà kọ̀, lẹ́yìn tí ìjọba orílẹ̀ èdè Amẹ́ríkà, Bailiwick of Jersey àti ìjọba orílẹ̀ èdè Nàìjíríà tọwọ́bọ ìwé àdéhùn láti dá mílíọ́nù $308 owó ti olóògbé Sani Abacha jí kó pamọ́ sí orílẹ̀ Amẹ́ríkà padà fún orílẹ̀ èdè Nàìjíríà, orílẹ èdè Amẹ́ríkà tún ṣèlérí láti túbọ̀ máa ṣàtìlẹyìn fún orílẹ̀ èdè Nàìjíríà nípa gbígbógun ti ìwà ìbàjẹ́.
Olùrànwọ́ ààrẹ Buhari lórí ìròyìn àti ìkéde, Garba Shehu ló sọ̀rọ̀ yìí lásàálẹ́ ọjọ́ Ìsẹ́gun nínú ìwé àtẹ̀jáde kàn.
---Ààrẹ Muhammadu Buhari kẹ́dùn ikú ààrẹ orílẹ̀ èdè Kenya tẹ́lẹ̀rí, Arap Moi.
Ààrẹ Muhammadu Buhari ti sàpéjúwe ààrẹ orílẹ̀ èdè Kenya tẹ́lẹ̀rí, Daniel Arap Moi gẹ́gẹ́ bí asíwájú rere , tí ó fi ohun gbogbo tí ó dára jùlọ fún ìdàgbàsókè orílẹ̀ èdè rẹ̀.
Ó ní Moi jẹ́ ọ̀kan pàtàkì nínú àwọn tó jẹ́ kí ìdàgbàsókè bá ẹkùn ìlà oòrùn Áfíríkà.
Ààrẹ tún bá ààrẹ orílẹ̀ èdè Kenya, Uhuru Kenyatta, ìjọba àti àwọn ènìyàn orílẹ̀ èdè Kenya kẹ́dùn lórí ikú olóògbé náà, Ààrẹ Buhari ní: “Láti ìdílé tí kò rí ọwọ́ họrí (ó jẹ́ olùkọ́), olóògbé Arap Moi di olósèlú, kí ó tó di ààrẹ orílẹ̀ èdè náà.
Ààrẹ wá gbàdúrà pé kí ọlọ́run tẹ́ olóògbé náà sí afẹ́fẹ́ ire.
---Mínísítà sọ wípé ìgbóhùn sáfẹ́fẹ́ èdè Nàíjíríà, ọ̀kan nínú ohun tó ní òmìnira jùlọ.
Ìjọba orílẹ̀ èdè Nàíjíríà ti ní orílẹ̀ èdè yìí ló fi ààyè gba òmìnira nípa ọ̀rọ̀ sísọ jù fún àwọn ènìyàn ní àgbáyé.
Ìjọba ní bó tilẹ̀ jẹ́ pé orílẹ̀ èdè Nàìjíríà fún àwọn ènìyàn ni òmìnira láti leè sọ ọ̀rọ̀ tó bá wù wọ́n, púpọ̀ nínú wọn ni kò mọ ẹ̀tọ́ rẹ nípa ọ̀rọ̀ sísọ.
Mínísítà fún ìròyìn àti àṣà lórílẹ̀ èdè Nàìjíríà, Lai Mohammed, ló sọ̀rọ̀ yìí lọ́jọ́ Ajé nígbà tí ó ń gba aṣojú orílẹ̀ èdè Finland, Jyrki Pulkkinen, àti aláákóso tó ń mójútó ọ̀rọ̀ ilẹ̀ òkèèrè ní ẹka ètò ọgbọ́n àtinúdá fún orílẹ̀ Finland, Jarmo Sareva, wá sí ilé-isẹ́ rẹ̀ fún ìpolongo òmìnira ọ̀rọ̀ sísọ.
Mínísítà tún sọ pé àjọ tó ń mójútó ètò ìròyìn àti àsà yóò se ìpàdé pọ̀ pẹ̀lú àwọn tọ́rọ̀ọ́kàn lósù yìí láti ṣe àgbéyẹ̀wò ẹ̀tọ́ nípa lílo ìmọ̀ ẹ̀rọ ayélujára, lọ́nà tí wọn kò fi ní tẹ òmìnira nípa ọ̀rọ̀ sísọ àti ẹ̀tọ́ ọmọnìyàn mọ́lẹ̀.
Ó ní inú ìjọba orílẹ̀ èdè Nàìjíríà kò dùn si bí àwọn kàn se ń lo ìmọ̀ ayélujára láti fi gbé àwọn ìròyìn ẹlẹ́jẹ̀ àti ọ̀rọ̀ tó leè dá wàhálà sílẹ̀ jáde láti fa èdè àìyedè.
---Gómìnà ẹgbẹ́ òṣèlú APC yóò fi àtúnṣe ètò òfin ránsẹ́ sí ilé ìgbìmọ̀ aṣòfin.
Àwọn gómìnà ẹgbẹ́ òṣèlú APC, lábẹ́ igbimọ gómìnà tó ń mójútó ètò ìtẹ́síwájú fún àwọn gómìnà, Progressive Governors Forum, PGF ti ń ṣe àgbéyẹ̀wò òfin láti ṣe àtúnṣe sí ètò òfin tí yóò mú ìgbáyé-gbádùn àti ìṣèjọba rere bá gbogbo ìpínlẹ̀ lórílẹ̀ èdè Nàìjíríà, ní èyí tí wọ́n yóò fi ránsẹ́ sí ilé ìgbìmọ̀ asòfin.
Philip Shuaibu tó jẹ́ aṣojú gómìnà ìpínlẹ̀ Edo Godwin Obaseki ló sọ̀rọ̀ yìí lásìkò tó ń bá àwọn akọ̀ròyìn sọ̀rọ̀ nílùú Àbújá, lẹ́yìn ìpàdé tí ìgbìmọ̀ PGF ṣe.
Ó tún tẹ̀síwájú pé ìgbìmọ̀ ọ̀hún yóò yẹ ìwé àkọsílẹ̀ tí gómìnà ìpínlẹ̀ Kaduna Nasir El-Rufai kọ̀, lásìkò tí ó ń darí ìgbìmọ̀ tó ń ṣàgbéyẹ̀wò àtúnṣe òfin.
Ọ̀gbẹ́ni Shuaibu tún sọ pé ìgbìmọ̀ náà ń ṣe iṣẹ́ papọ̀ pẹ̀lú gbogbo àwọn gómìnà tí ó wà nínú ẹgbẹ́ òṣèlú APC, àwọn ìgbìmọ̀ aṣòfin àti ẹgbẹ́ òṣèlú ọ̀hún láti leè ṣe àwọn ètò àti ìlànà tí yóò mú ìgbáyé-gbádùn bá gbogbo ìpínlẹ̀ tó wà lórílẹ̀ èdè Nàìjíríà.
Ọ̀kan lára ọmọ ẹgbẹ́ ilé ìgbìmọ̀ asòfin, Yahaya Abdullahi, tó wà níbi ìpàdé ọ̀hún, tún sọ pé ìgbìmọ̀ tẹ̀ẹ́kótó náà yóò sàgbéyẹ̀wò ìwé àkọsílẹ̀ tí El-Rufai kọ, ní èyí tí ilé ìgbìmọ̀ aṣòfin yóò fẹnukò lé lórí pàápàá júlọ nípa ètò ìgbáyé-gbádùn àti ìṣèjọba rere lórílẹ̀ èdè Nàìjíríà.
--- Anthony Joshua ń jíròrò lórí ibi ìgbáradì ṣaájú ìfigagbága pẹ̀lú Jarrell Miller.
Ní báyìí, ẹlẹ́ṣẹ̀ẹ́ ọmọ ilẹ̀ Bìrìtìkó, Anthony Joshua ti ń ṣe ìpàdé lórí gbàgede ìgbáradì tí yóò lò kí ó tó lọ kojú ẹlẹ́ṣẹ̀ẹ́ ilẹ̀ New York, Jarrell Miller nínú ìtakàǹgbọ̀n fún àmì-ẹ̀yẹ àgbááyé.
Bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé, Anthony Joshua kò fìgbà kankan túra sílẹ̀, lẹ́yìn ìgbáradì ọlọ́jọ́ pípẹ́ fún ìfigagbága náà.
Ìròyìn fi ìdí rẹ̀ múlẹ̀ pé, Joshua ń dúró de àrídájú ìfigagbága náà láàrín òun àti Miller ní gbàgede Madison Square, nínú oṣù kẹfà ọdún yìí.
Bákan náà ni, akẹẹgbẹ́ rẹ̀ tí ó pàdánù, Eddie Hearn ṣe ìpàdé pẹ̀lú Dillian Whyte lórí bóyá ìfigagbága wọn yóò di àtúngbékalẹ̀.
--- Martial sún àkókò rẹ̀ síwájú nínú ikọ̀ Manchester United.
Atamátàsé ọmọ orílẹ̀-èdè France, Anthony Martial tí ó jẹ́ agbábọ́ọ̀lù ikọ̀ Manchester United ti buwọ́ lu ìwé àdéhùn ìṣiṣẹ́ ọlọ́dún márùn-ún láti sún àkókò rẹ̀ síwájú nínú ikọ̀ Manchester United di ọdún 2024.
Bí ó ti lẹ̀ jẹ́ pé, oríṣiríṣi àhesọ ọ̀rọ̀ ló gba ojú-ọjà kan pé, ó ṣeéṣe kí agbábọ́ọ̀lù náà ó kúrò nínú ikọ̀ Manchester United.
Ní báyìí, Martial ti gbá àpapọ̀ bọ́ọ̀lù mẹ́wàá sáwọ̀n ní sáà yìí, tí ó sì ṣe ìrànwọ́ ayọ̀ kan nínú ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ márùndínlọ́gbọ̀n ní sáà yìí.
Ọ̀pọ̀lọpọ̀ nínú àwọn agbábọ́ọ̀lù ọ̀hún ni ó gbóríyìn fún adelé akọ́nimọ̀ọ́gbá ikọ̀ Manchester United, Ole Gunnar Solskjaer fún iṣẹ́ takuntakun àti ipa tí ó kó láti ìgbà tí ó ti rọ́pò akọ́nimọ̀ọ́gbá ikọ̀ náà tẹ́lẹ̀, Jose Mourinho.
Gẹ́gẹ́ bí Martial ṣe sọ, Mo dúpẹ́ lọ́wọ́ Ole gidi gan àti àwọn akọ́nimọ̀ọ́gbá yòókù fún ìgbàgbọ́ wọn nínú mi, nítorí pé wọ́n rànmí lọ́wọ́ púpọ̀ láti mú ìgbèrú bá bí mo ṣe ń kópa sí.
A mọ ikọ̀ agbábọ́ọ̀lù Manchester United sẹ́yìn gẹ́gẹ́ bí, ikọ̀ tí ó nífẹ̀ẹ́ láti máa gba ife ẹ̀yẹ lọ́pọ̀lọpọ̀, ó dá mi lójú pé, láìpẹ́ a ó tún gba ife ẹ̀yẹ.
"Anthony Martial dara pọ̀ mọ́ Manchester United lọ́dún 2015 láti inú ikọ̀ agbábọ́ọ̀lù Monaco pẹ̀lú mílíọ́nù mẹ́rìndínlógójì £36 million ($47m), láti ìgbà náà ni ó ti ń rí ara rẹ̀ gẹ́gẹ́ bí ọ̀kan lára agbábọ́ọ̀lù ọ̀dọ́ tí ó dára jùlọ.
Akọ́nimọ̀ọ́gbá ikọ̀ ọ̀hún, Solskjaer náà fi àìdùnnú rẹ̀ hàn lẹ́yìn tí Martial tún buwọ́ lu ìwé àdéhùn nínú ikọ̀ náà.
Anthony wà lára agbábọ́ọ̀lu ọ̀dọ́ tí ó dára jùlọ fún ikọ̀ náà, ó sì jẹ́ agbábọ́ọ̀lù tí akọ́nimọ̀ọ́gbá yòówù yóò nífẹ̀ẹ́ láti ní nínú ikọ̀ rẹ̀, nítorí pé, ó rọrùn láti bá ṣiṣẹ́pọ̀,"
--- Sarri- Mi ò dí Hazard lọ́wọ́ tó bá fẹ́ lọ
Akọ́nimọ̀ọ́gbá ikọ̀ agbábọ́ọ̀lù Chelsea, Maurizio Sarri ti jẹ́ kí Eden Hazard mọ̀ pé òun kò dá a dúró, tí ó bá pinnu láti máa lọ.
Sarri sọ pé lòótọ́ òun fẹ́ kí Hazard ó ṣì wà nínú ikọ̀ Chelsea, ṣùgbọ́n òun kò ní dí i lọ́wọ́ tí ó bá fẹ́ fi ikọ̀ agbábọ́ọ̀lù náà sílẹ̀.
A ó rántí pé, ikọ̀ agbábọ́ọ̀lu Real Madrid ti ń fẹ́ ki Hazard ó dara pọ̀ mọ́ ikọ̀ ọ̀hún ní orílẹ̀-èdè Spain.
Tí Hazard fúnra rẹ̀ ti sọ pe ó wu òun láti dara pọ̀ mọ́ ikọ̀ Real Madrid, bí ikọ̀ ọ̀hún bá ṣetán láti ra òun.
Ní báyìí, ikọ̀ agbábọ́ọ̀lù Chelsea fẹ́ kí Hazard tọwọ́ bọ ìwé àdéhùn tuntun kí àdéhùn tilẹ̀ ó tó tán lọ́dún tó ń bọ̀.
Hazard dara pọ̀ mọ́ Chelsea lọ́dun 2012, ó sì ti gbá àpapọ̀ ayò mẹ́wàá sáwọ̀n fún ikọ̀ Chelsea nínú ìdíjé premier league ti sáà yìí.
--- Ikọ̀ agbábòọ̀lù obìnrin Dream Stars ṣàfihàn akọ́nimọ̀ọ́gbá tuntun.
Ikọ̀ agbábọ́ọ̀lù obìnrin Dream Stars ti ìpínlẹ̀ Èkó ti ṣàfihàn akọ́nimọ̀ọ́gbá àgbà tuntun, ọ̀gbẹ́ni Felix Nwosu, ṣaájú ìdíje sáà 2018/2019 ìdíje Líìgì àwọn obìnrin orílẹ̀-èdè Nàìjííríà.
Ikọ̀ tí ó fi ìlú ẹ̀kọ́ ṣe ibùgbé tí ó sì ṣẹ̀ṣẹ̀ gba ìgbéga ọ̀hún nìgbẹ̀yìngbéyín ti gba ìlúmọ̀ọ́ká akọ́nimọ̀ọ́gbá ọmọ bíbí ìpínlẹ̀ Anambra yìí.
Felix Nwosu jẹ́ òjìmì akọ́nimọ̀ọ́gbá tí ó ti ṣiṣẹ́ pẹ̀lú ikọ̀ FC Talanta lórílẹ̀-èdè Kenya, Heegan FC ní Somali, FIN FA nílùú Enugu, FIN Angels, Ambassador Child Youth Club /Angels nílùú Enugu rí.
Nínú ìfanikalẹ̀ fun àmì ẹ̀yẹ, ó jẹ́ fífàkalẹ̀ àti kíkàsí láti lọ́wọ́ ikọ̀ Arsenal/ilé iṣẹ́ WorldRemit gẹ́gẹ́ bí ọ̀kan lára àwọn akọ́nímọ́ọ̀gbá ọ̀dọ́ tí ó dáńgájíá jùlọ jákè-jádò ilẹ̀ Adúláwọ̀, ó wà lára akọ́nimọ̀ọ́gbá márùndínlọ́gbọ̀n àkọ́kọ́ nínú àpapọ̀ akọ́nimọ̀ọ́gbá tí ó lé ní ẹ̀ẹ́dẹ́gbẹ̀rin
Ẹni tí ó jẹ́ Alága ikọ̀ agbábọ́ọ̀lù Dream Stars Ladies, Ọ̀gbẹ́ni AbdulRahmon Àbọ̀lọrẹ sọ pé; “Ikọ̀ náà yà sí Nwosu torí àgbọ́ǹgbẹ ìrírí tí ó ní àti pé ó dá òun lójú pé agbábòọ̀lù ọwọ́ ẹ̀yin ikọ̀ Gor Mahia tẹ́lẹ̀rí ọ̀hún lè ṣe ìrànwọ́ fún ikọ̀ náà láti sọ èròńgbà rẹ̀ di mímúṣẹ.
“Àfojúsùn wa ni láti kópa dáradára pẹ̀lú ìgbéga wa yìí sí inú ìdíje líìgì, a kò sì fẹ́ da òkuta kan sí láìbì lulẹ̀.
--- Kò sí ìdánilójú ìṣàwárí Emiliano Sala tó di àwáàrí.
Ọ̀gá àgbà ilé-iṣẹ́ tó ń rí sí ìṣẹ̀lè pàjáwìrì àti ọkọ̀ òfurufú tí ó bá di àwáti sórí erékùsù, Ọ̀gbẹ́ni John Fitzgerald ti sọ pé, kò sí ìrètí pé Sala yóò di ṣíṣàwárí mọ́.
Emiliano Sala ọmọ orílẹ̀-èdè Argentina, tó jẹ́ ẹni ọdún méjìdínlọ́gbọ̀n wà pẹ̀lú awakọ̀ òfurufú nínú ọkọ̀ bàálù kan tí ó di àwátì lánàá ọjọ́ ajé (Monday).
Ṣíwájú si, ikọ̀ adóòlà ẹ̀mí ti tẹ̀síwájú nínú wíwá ọkọ̀ òfúrufú náà àti àwọn èrò inú rẹ̀ lọ́jọ́rú (Wednesday).
Ìròyìn kán fi léde pé Sala fi àtẹ̀jíṣẹ́ ẹ̀rọ ayélujára whatsapp ránṣẹ́ sí ọ̀rẹ́ rẹ̀ kan àti àwọn mọ̀lẹ́bí pé Ẹ̀rù ń ba òun pẹ̀lú bí ọkọ̀ òfúrufú náà ṣe ń ṣe lójú ofurufú.
"Gẹ́gẹ́ bí ilé-iṣẹ́ akọ̀ròyìn l’orílẹ̀-èdè Argentina ṣe sọ, Sala sọ fún àwọn mọ̀lẹ́bí rẹ̀ báyìí pé ""Mo wà nínú ọkọ̀ òfurufú kan tó dàbí ẹni pé ó fẹ́ ní ìjàm̀bá."
Wàyíí o ní nǹkan bí aago mọ́kànlá ààbọ̀ òwúrọ̀, ile-iṣẹ́ ọlọ́pàá ni Guernsey sọ pé, ọkọ̀ òfúrufú mẹ́ta àti bàálù kékeré kan wà lójú òfurufú, bí wọ́n ṣe ń wá bàálù Piper Malibu.
Bákan náà ni àwọn ọlọ́pàá sọ pé àwọn ti ń ṣàyẹ̀wò àwọn ìtàkùrọ̀sọ orí ẹ̀rọ ìbánisọ̀rọ̀ láti mọ̀ bóyá ó lè ṣe ìrànwọ́
Ṣùgbọ́n títí di àsìkò yìí, kò tí ì sí ìròyìn kankan nípa bàálù tó di àwáti ọ̀hún
Olú ìlú orílẹ̀-èdè Welsh ni Sala ń lọ lẹ́yìn tó bọwọ́lu ìwé àdéhùn iṣẹ́ mílíọ́nù mẹ́ẹ̀ẹ́dógún owó pounds pẹ̀lú ikọ̀ agbábọ́ọ̀lù Bluebirds.
--- Petr Cech ti ikọ̀ Arsenal ṣetán àti fẹ̀yìntì nípàrí sáà yìí.
Lẹ́yìn ogún ọdún gẹ́gẹ́ bí akọ́ṣẹ́mọṣẹ́, Amùlé àkọ́kọ́ ikọ̀ agbábọ́ọ̀lù Arsenal Petr Cech ti ṣetán láti fẹ̀yìntì ní ìparí sáà 2018/2019 ìdíje Premier League ilẹ̀ Gẹ̀ẹ́sì.
Ọmọ ọdún mẹ́rìndínlògòjì ọ̀hún tí ó dara pọ̀ mọ́ ikọ̀ Arsenal ní oṣù kẹfà ọdùn 2015 láti ikọ̀ agbábọ́ọ̀lù Chelsea kéde èyí lóri ìkànnì twitter rẹ̀ @petrcech ní ọjọ́ ìṣégun.
“Èyí ni sáà ogún mi gẹ́gẹ́ bí akọ́ṣẹ́mọṣẹ́ agbábọ́ọ̀lù, ó sì ti pé ogún ọdún tí mo tọwọ́ bọ ìwé àdéhùn mi àkọ́kọ́ gẹ́gẹ́ bí akọ́ṣẹ́mọṣẹ́.
--- Omeruo- máa nífẹ̀ẹ́ láti dara pọ̀ mọ́ ikọ̀ agbábọ́ọ̀lù CD Leganes fún àdéhùn ọlọ́jọ́ pípẹ́.
Agbábọ́ọ̀lù ọwọ́ ẹ̀yìn ikọ̀ Super Eagles, Kenneth Omeruo ti sọ pé òun yóò gba sìsọ àdéhùn àyálò òun di àdéhùn ọjọ́ pípẹ́ nínú ikọ̀ agbábọ́ọ̀lù CD Leganes ní tọwọ́-tẹsẹ́ nítorí ikọ̀ agbábọ́ọ̀lù ìdíje La Liga ọ̀hún rí bí ilé.
Omeruo wà nínú àdéhùn aláyàálò láti inú ikọ̀ Chelsea di ìparí sáà yìí, ó sì ti di ará ilé nínú ikọ̀ Leganes ọ̀hún tí ó ṣe dára gidi gan láti jìnnà sí ìfìdírẹmi.
“Ní báyìí, o dà bí ẹni pé mo wà ní ilé lẹ́yìn títì káàkiri pẹ̀lú oríṣìíríṣìí àdéhùn aláyàálò kí n tó dé inú ikọ̀ agbábọ́ọ̀lù orílẹ̀-èdè Spain yìí.” Agbábọ́ọ̀lù ọwọ́ ẹ̀yìn ikọ̀ Super Eagles ọ̀hún ló sọ èyí di mímọ̀ fún àwọn oníròyìn.
Ó dá bí àlá tí ó wá sí ìmúṣe fún mi gẹ́gẹ́ bí a ṣe mọ̀ pé ìdíje La Liga jẹ́ ọ̀kan lára àwọn ìdíje tí ó tóbi jùlọ lágbàáyé
Mi ò ní rò ó lẹ́ẹ̀mejì láti tọwọ́ bọ ìwé pẹ̀lú ikọ̀ yìí, tí oore-ọ̀fẹ rẹ̀ bá yọ.
"Ikọ̀ agbábọ́ọ̀lù ìlú Madrid ọ̀hún yóò ní láti ya mílíọ́nù márùn-ún owó Euros sọ́tọ̀ láti ra Omeruo ọmọ ọdún mẹ́ẹ̀ẹ́dọ́gbọ̀n fún àdehùn ọlọ́jọ́ pípẹ́.
--- Àjọ NFF yan pápá ìṣeré Keshi fún ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ Seychelles àti Egypt.
Àjọ tó ń mójú tó bọ́ọ̀lù àfẹsẹ̀gbá lórílẹ̀-èdè Nàìjííríà (NFF) ni ìgbàgbọ́ wà pé wọ́n ti yan pápá ìṣeré Keshi ní ìlú Asaba, ìpìnlẹ́ Delta láti gbàlejò ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ ọlọ́rẹ̀ẹ́sọ́rẹ̀ẹ́ àgbááyé láàrin ikọ̀ agbábọ́ọ̀lù Super Eagles àti ikọ̀ agbábọ́ọ̀lù Pharaoh ti orílẹ̀-èdè Egypt tí ó fi mọ́ ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ ìpegedé kẹyìn fún ìdíje ife ẹ̀yẹ ilẹ̀ Adúláwọ̀ ọdún 2019 tí wọn yóò gbá pẹ̀lú orílẹ̀-èdè Seychelles.
Àgbà ọ̀jẹ̀ kan ní Olú ilé-iṣẹ́ àjọ NFF nílùú Àbújá sọ ọ́ yanya pé, aáyan láti gbàlejò àwọn ìdíje méjéèjì ní ìlú Àsàbà ti fẹ́ yọrí nítorí pé ìjọba ìpínlẹ̀ Delta ti gbà láti gbé ìdá àádọ́rin nínú ọgọ́rùn-ún iye owó tí àwọn ìfẹsẹ̀wọsẹ̀ ọ̀hún yóò ná wọn.
“A ti dé abala ìkẹyìn ìjíròrò wa, gbogbo ètó sì ti tò pẹ̀lú bí pápá ìṣeré Asaba yóò ṣe gbàlejò àwọn ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ náà tí gbogbo nǹkan yóò sì ṣe yémú.” ni ó wí.
Ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ ọlọ́rẹ̀ẹ́sọ́rẹ̀ẹ́ pẹ̀lụ́ Egypt yóò ní àwọn agbábọ́ọ̀lù jàǹkànjàǹkàn bí i Mohammed Salah ti ikọ̀ Liverpool, Mohammed El-Shenawy àti Ahmed Hegazi."
Ìsèjọba Gómínà Ifeanyi Okowa ti jẹ́ èyí tí ó nífẹ̀ẹ́ ìrìn-àjò ìgbafẹ́ eré ìdárayá, bákan náà ni àbẹ̀wò àwọn agbábọ́ọ̀lù jàǹkànjàǹkàn ìdíje Premiership ilẹ̀ Gẹ̀ẹ́sì náà yóò mú ìgbèrú bá ọrọ̀ ajé ìlú Asaba àti àwọn ìlú agbègbè rẹ̀ ní àárín ìpínlẹ̀ náà.
--- Orílẹ̀-èdè Egypt ni ààyò láti gbàlejò ìdíje AFCON ti ọdún 2019.
Orílẹ̀-ẹ̀dè Egypt, ilẹ̀ onígun aborí sóńsó ni ó ṣeéṣe kí ó gbàlejò ìdíje ife ẹ̀yẹ ilẹ̀ Adúláwọ̀ ti ọdún 2019, Àjọ CAF ti fi léde pé àwọn orílẹ̀-èdè tó ku ní ilẹ̀ náà lè sẹ́rí lọ sí orílẹ̀-èdè tí kì í fi eré bọ́ọ̀lù àfẹsẹ̀gbá ṣeré ọ̀hún ní ọdún tó ń bọ̀.
Ní ìgbà kẹyìn tí orílẹ̀-èdè Egypt gbàlejò ìdíje ife ẹ̀yẹ ilẹ̀ Adúláwọ̀, ikọ̀ Super Eagle parí pẹ̀lú ipò kẹta; pẹ̀lú gbígba àmì ẹ̀yẹ bàbà fún ìgbà kẹta léra wọn nínú ìdíje ọ̀hún mẹ́ta ní tèléǹtẹ̀lé.
Gẹ́gẹ́ bí ìròyin ṣe sọ, Àjọ CAF ti ṣetán láti sègbè ìfẹ́ orílẹ̀-èdè Egypt láti gbàlejò ìdíje AFCON ọdún 2019.
Ààrẹ ìgbìmọ̀ tó ń mójú tó ìdíje AFCON, Amaju Pinnick ṣe é lálàyé pé, àwọn orílẹ̀-èdè tí agbára wọ́n gbé àtigbàlejò ìdíje náà nìkan ni ìgbìmọ̀ àwọn yóò wò ṣe.
Àjọ CAF yóò kéde orílẹ̀-èdè tí yóò gbàlejò ìdíje AFCON ọdún 2019 ọ̀hún ní ọjọ́ kẹsàn-án oṣù kínní ọdún.
--- Mbappe gba àmì-ẹ̀yẹ agbábọ́ọ̀lù orílẹ̀-èdè France tí ó dára jùlọ.
Agbábọ́ọ̀lù ọwọ́ iwájú ikọ̀ Paris Saint-Germain, Kylian Mbappe ti gba àmì-ẹ̀yẹ agbábọ́ọ̀lù orílẹ̀-èdè France tí ó dára jùlọ fún ìgbà àkọ́kọ́
Ọmọ ogún ọdún ọ̀hún tí ó kópa ribiribi fún orílẹ̀-èdè France láti gba ife-ẹ̀yẹ ìdíje àgbàáyé lórílẹ̀-èdè Russia ní sáà tó kọjá gbádun mérìírí ọdun 2018 yìí.
Mbappe ran ikọ̀ Les Bleus ọ̀hún lọ́wọ́ láti wẹ̀ yán kànhìnkànhìn pẹ̀lú àkitiyan àdáṣiṣẹ́ kára tí ó fi rí àwọ̀n he nínú ìjáwé olúborí àṣekágbá àmi ayò mẹ́rin sí méjì pẹ̀lú ikọ̀ Croatia.
Mbappe ti gbá bọ́ọ̀lù mẹ́rìndínlógún sáwọ̀n nínú ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ mọ́kàndínlógún tí ó ti gbá fún ikọ̀ agbábọ́ọ̀lù PSG ní sáà yìí, pẹ̀lú bí ikọ̀ náà tún ṣe ń tẹ̀síwájú láti máa lépa ife ẹ̀yẹ nílé àti lẹ́yìn odi.
Ó parí pẹ̀lú ipò kẹrin nínú àbájáde ìdìbò àmì ẹ̀yẹ agbábọ́ọ̀lù tí ó dára jùlọ lágbàáyé lọ́dún 2018, pẹ̀lú ipò gíga yìí gẹ́gẹ́ bí ọmọ kékeré, èyí gbé e ṣaájú Lionel Messi Agbábọ́ọ̀lù tí ó ti gba àmì ẹyẹ ọ̀hún lẹ́ẹ̀marùn-ún ọ̀tọ̀ọ̀tọ̀.
Mbappe jẹ́ fífún ní apata yìí láti ọ̀wọ́ Àjọ Eré Bọ́ọ̀lù ilẹ̀ France, lẹ́yìn tí ó ta Raphael Varane àti Antoine Griezmann yọ.
Ó jogún àmì ẹ̀yẹ yìí lọ́wọ́ agbábọ́ọ̀lù ọwọ́ àárín ikọ̀ Chelsea, NGolo Kante, tí ó mókè jùlọ lọ́dún 2017.
---Atamátàsé Ọmọ Ààrẹ Weah yóò dara pọ̀ mọ́ ikọ̀ agbábọ́ọ̀lù Celtic pẹ̀lú àyálò.
Timothy Weah yóò kúrò nínú ikọ̀ aṣáájú ìdíje bọ́ọ̀lù ilẹ̀ Faransé nnì Paris St Germain (PSG), láti dara pọ̀ mọ́ Celtic ikọ̀ agbábọ́ọ̀lù ilẹ̀ Scotland.
Weah sọ ọ́ di mímọ̀ lọ́jọ́ ìṣẹ́gun (Tuesday).
Gẹ́gẹ́ ilé-iṣẹ́ ìròyìn ilẹ̀ Bìrìtìkó ṣe sọ, ọmọ ọdún méjìdínlógún ọ̀hún ti ṣetán láti dara pọ̀ mọ́ ikọ̀ aṣáájú ìdíje bọ́ọ̀lù ilẹ̀ Scotland ìyẹn Celtic.
Weah ti kópa fún ikọ̀ agbábọ́ọ̀lù PSG nígbà mẹ́ta pére ní sáà yìí, látàrí àwọn olórúkọ sàǹkò bíi Neymar, Kylian Mbappe àti Edinson Cavani tí ó dín oore-ọ̀fẹ́ àtiwọ ikọ̀ àkọ́kọ́ rẹ̀ kù.
Nínú àtẹ̀jíṣẹ́ tí a kọ lédè Faransé lórí ìkànnì Instagram rẹ̀, Weah dúpẹ́ lọ́wọ́ àwọn àkẹẹgbẹ́ rẹ̀ nínú ikọ̀ PSG, àwọn akọ́nimọ̀ọ́gbá àti àwọn olólùfé ikọ̀ náà fún àǹfààní tí wọ́n fún un láti jẹ́ ọ̀kan lára ẹ̀bí náà.
Weah jẹ́ ọmọbíbí inú agbábọ́ọ̀lù tẹ́lẹ̀rí fún orílẹ̀-èdè Liberia, ikọ̀ agbábọ́ọ̀lù PSG àti AC Milan, George Weah, tí ó jẹ́ Ààrẹ̀ orílẹ̀-èdè Liberia báyìí.
--- Èyí ni àtúpalẹ̀ àwọn ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ ìdíje EPL tí ó wáyé lópin ọ̀sẹ̀.
Ikọ̀ agbábọ́ọ̀lù Crytsal Palace fàgbà han Manchester City pẹ̀lú àmì ayò mẹ́ta sí méjì nínú ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ ìdíje premier league ilẹ̀ Gẹ̀ẹ́sì tí ó wáyé lópin ọ̀sẹ̀.
Bákan náà, ikọ̀ agbábọ̀ọ̀lu Leicester City fẹ̀yìn Chelsea bẹ́lẹ̀ pẹ̀lú àmì ayò kan sí òdo.
Nínú inú àwọn ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ àkọ́kọ́ tí ó wáyé ṣaájú lọ́jọ́ àbámẹ́tà, ikọ̀ agbábọ́ọ̀lù Arsenal fàgbà han Burnley pẹ̀lú àmì ayò mẹ́ta sóókan
Ikọ̀ agbábọ́ọ̀lù Southampton fàgbà han Huddersfield pẹ̀lú àmì ayò mẹ́ta sóókan ọpẹ́ pàtàkì lọ́wọ́ àmì ayò tí Michael Ọbáfẹ́mi gbá sáwọ̀n.
Bákan náà Watford lu West Ham pẹ̀lú àmì ayò méjì sí òdo Bournemouth na Brighton pẹ̀lú àmì ayò méjì sí òdo
--- ÀTẸ ÀJỌ FIFA: Ikọ̀ Super Eagles parí ọdún 2018 sípò kẹrìnlélógójì.
Ikọ̀ agbábọ́ọ̀lù Super Eagles parí ọdún 2018 pẹ̀lú dídi ipò kẹrìnlélógójì wọn mú síbẹ̀ nínú àtẹ àjọ FIFA tuntun tí wọ́n gbé jáde lọ́jọ́bọ (Thursday).
Ikọ̀ agbábọ́ọ̀lù yìí tí ó ti gba ife ẹ̀yẹ ilẹ̀ Adúláwọ̀ lẹ́ẹ̀mẹta ọ̀tọ̀òtọ̀ tún di ipò kẹrin wọn mú ní ilẹ̀ Adúláwọ̀ síbẹ̀.
Ikọ̀ agbábọ́ọ̀lù orílẹ̀-èdè Senegal dipò kínní wọn mú síbẹ̀ pẹ̀lú bí ikọ̀ orílẹ̀-èdè Tunisia, Morocco, Nàìjíríà àti DR Congo ṣe pajú ikọ̀ márùn-ún àkọ́kọ́ ní ilẹ̀ náà dé.
Belgium ni ó di ipò kínní mú síbẹ̀, France ipò kejì síbẹ̀, Brazil ipò kẹta síbẹ̀ Crotia wà ní ipo kẹrin, nígbà tí England wà ní ipò karùn-ún lágbàáyé.
Ipò àtẹ àjọ FIFA/Coca-Cola mìíràn yóò tún jáde lọ́jọ́ keje, oṣù kejì, ọdún 2019.
--- Mourinho kí mi káàbọ̀ padà sínú ìdíje Premier League - Ranieri
Claudio Ranieri sọ lọ́jọ́bọ (Thursday) pé Jose Mourinho ni akọ́nimọ̀ọ́gbá àkọ́kọ́ tí ó kí òun káàbọ̀ padà sínú ìdíje Premier League nígbà tí wọ́n yan òun gẹ́gẹ́ bí akọ́nimọ̀ọ́gbá ikọ̀ Fulham lóṣù tó kọjá.
Ikọ̀ Fulham yóò tẹkọ̀ létí lọ sí pápá ìṣeré Old Trafford ní ọjọ́ Àbámẹ́ta (Saturday), níbi tí ìrètí wà pé ikọ̀ Manchester United yóò ti jáwé olúborí nínú ìdíje Premier League fún ìgbà àkọ́kọ́ nínú ìfẹsẹ̀wọnṣẹ̀ márùn-ún ọ̀tọ̀ọ̀tọ̀, èyí tí yóò tún gbé àwọn akọ́nimọ̀ọ́gbá méjéèjì pàdé ara wọn láti ìgbà tí Ranieri ti fi ikọ̀ Leicester sílẹ̀.
Àmọ́ ṣá, akọ́nimọ̀ọ́gbá ikọ̀ Fulham ti sọ pé “Òun ni ẹni àkọ́kọ́ tó kọ́kọ́ fi àtẹ̀jíṣẹ́ ránṣẹ́ sími láti sọ pé ‘káàbọ̀ padà’
Ọ̀rẹ́ mi dạ́adáa ló jẹ́.
Mo ti mọ̀ ọ́n láti ọjọ́ tó ti pẹ́, láti ìgbà tí ó wá sínú ikọ̀ Chelsea láti orílẹ̀-èdè Italy, o ń ṣe dáradára sími.
Akínkanjú ọkùnrin, akọ́nimọ̀ọ́gbá àti Alákòóso ni ó jẹ́.
Ikọ̀ agbábọ́ọ̀lù Fulham tí ó wà ní ìsàlẹ̀ tábìlì kópa tí ó wúni lórí nínú ọ̀mì àmì ayò kọ̀ọ̀kan pẹ̀lú ikọ̀ agbábọ́ọ̀lù Leicester lọ́jọ́rùú (Wednesday), èyí fún Ranieri ẹni ọdún mẹ́tàdínláàádọ́rin ní ìjáwé olúborí kan, ọ̀mì kan àti ìpàdánù kan pẹ̀lú ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ mẹ́ta tí ó ti tukọ̀.
--- Ilé-iṣẹ́ Ààrẹ, Àjọ NFF lọ pàdé ikọ̀ Super Falcons ní ìlú Àbújá.
Olórí òṣìṣẹ́ Ọba sí Ààrẹ Alhaji Abba Kyari, léwájú ìgbìmọ̀ àwọn ènìyàn jàǹkàn-jàǹkàn àti àwọn ọ̀gá àgbà nínú àjọ tó ń mójú tó bọ́ọ̀lù àfẹsẹ̀gbá lórílẹ̀-èdè Nàìjííríà (NFF) tí ó lọ pàdé ikọ̀ Super Falcons bí wọ́n ṣe dé sí ìlú Àbújá nírọ̀lẹ́ ọjọ́ Àìkù (Sunday).
Ikọ̀ agbábọ́ọ̀lù Super Falcons tí ó ti gba ife ẹ̀yẹ àwọn Obìnrin ilẹ̀ Adúláwọ̀ ní ẹ̀ẹ̀mẹsàn-án ọ̀tọ̀ọ̀tọ̀ balẹ̀ sí pápákọ̀ òfurufú àgbááyé Nnamdi Azikiwe ní aago mẹ́rin ku ìṣẹ́jú díẹ̀.
Lára àwọn ọmọ ẹgbẹ́ ikọ̀ Super Falcons tí ó wọ ìlú Àbújá ni akọ̀wé àpapọ̀ àjọ NFF, Dókítà Mohammed Sanusi, tí ó fi mọ́ àwọn òṣìṣẹ́ àjọ NFF mìíràn.
Ní ọjọ́ Àbámẹ́ta (Saturday), ní pápá ìṣeré Accra, ikọ̀ agbábọ́ọ̀lù Falcons gbo ewúro sí ikọ̀ Banyana Banyana ti orílẹ̀-èdè South Africa lójú pẹ̀lú àmì ayò mẹ́rin sí mẹ́ta nínú golí-wò-mi-n-gbá-a-sí-ọ lẹ́yìn ọgọ́fà ìṣẹ́jú láìráwọ̀n he láti gba ife ẹ̀yẹ àwọn Obìnrin tí ó tóbi jù nilẹ̀ Adúláwọ̀ yìí ní ìgbà mẹ́ta lé ara wọn tí ó sì fi pé mẹ́sàn-án ní àpapọ̀.
Ní orúkọ Ààrẹ, ẹni tí kò sí nílùú lọ́wọ́lọ́wọ́ báyìí, a kí gbogbo yín káàbọ̀ padà, ẹ sì tún kú iṣẹ́.
Kódà, bí a ṣe ń kúrò ní pápákọ̀ ofurufú, àwọn ọmọ orílẹ̀-èdè Nàìjííríà jàǹkàn méjì ọ̀tọ̀ọ̀tọ̀ pè wọ́n fún ṣètọrẹ àádọ́ta míllíọ́nù náírà (N50m) àti mílíọ́nù márùndínlọ́gbọ̀n náírà (N25m) fún ikọ̀ yìí.
Ẹ jọ̀wọ́, ẹ sinmi dáradára.
A ó kàn si yín lórí àwọn ẹ̀tọ́ tí a ti là kalẹ̀ fun yín láìpẹ́
Akọ̀wé àpapọ̀ àjọ NFF, Mohammed Sanusi sọ báyìí pé, “Ní orúkọ àwọn adarí àjọ NFF, a mọ rírì àtìlẹyìn láti ọ̀dọ̀ ìjọba ilẹ̀ Nàìjííríà, èyí tí ó ran ikọ̀ yìí lọ́wọ́ láti ṣàṣeyọrí nínú ìdíje ifẹ ẹ̀yẹ náà.
Àwọn ọmọbìnrin yìí ti wá ṣèlérí sísa gbogbo ipá wọn láti sojú orílẹ̀-èdè náà dáradára nínú ìdíje ife ẹ̀yẹ àgbááyé ọdún 2019.
--- Berhalter ti di kíkéde gẹ́gẹ́ bí akọ́nimọ̀ọ́gbá ikọ̀ agbábọ́ọ̀lù àwọn ọkùnrin orílẹ̀-èdè US.
Akọ́nimọ̀ọ́gbá ikọ̀ Columbus Crew tẹ́lẹ̀rí Gregg Berhalter ni wọ́n ti kéde gẹ́gẹ́ bí akọ́nimọ̀ọ́gbá tíṣé kan fún ikọ̀ agbábọ́ọ̀lù àwọn ọkùnrin orílẹ̀-èdè US ní ọjọ́ àìkú (Sunday)
Berhalter ẹni ọdún márùndínláàádọ́ta rọ́pò akọ́nimọ̀ọ́gbá fìdíhẹ̀ẹ́ Dave Sarachan láti di ẹni tí ó kẹ́rẹ́ jù tí yóò tu ikọ̀ náà láti àkókò Steve Sampson lọ́dun 1995.
“Inú wa dùn lọ́pọ̀lọpọ̀ láti yàn Gregg gẹ́gẹ́ bí gẹ́gẹ́ bí akọ́nimọ̀ọ́gbá ikọ̀ agbábọ́ọ̀lù àwọn ọkùnrin orílẹ̀-èdè US” nínú ọ̀rọ̀ Ààrẹ ìgbìmọ̀ Eré Bọ́òlù ilẹ̀ náà Carlos Cordeiro.
Gẹ́gẹ́ bí agbábọ́ọ̀lù ikọ̀ tẹ́lẹ̀rí tí ó ní ọ̀pọ̀lọpọ̀ ìrírí, àti òjìmì akọ́ṣẹ́mọṣẹ́ akọ́nimọ̀ọ́gbá, ó dá wa lójú pé òun ni ẹni tí ó tọ́ láti tẹ̀ wá síwájú.
À ń fojúsọ́nà láti ṣafihàn rẹ̀ lọ́jọ́ ìṣẹ́gun (Tuesday) nílùú New York.
Berhalter yóò di fífihàn nínú ìpàdé àwọn oníròyìn kan ní agogo mẹ́jìlá ọ̀sán ọjọ́ ìṣẹ́gun (Tuesday)
Agbábọ́ọ̀lù ikọ̀ yìí tẹ́lẹ̀rí, Berhalter wà nínú àlakalẹ̀ ikọ̀ náà fún ife ẹ̀yẹ àgbááyé ọdún 2002 àti ọdún 2006.
--- Ààrẹ Buhari kí ikọ̀ Super Falcons kú oríire gbígba ife ẹ̀yẹ ilẹ̀ Adúláwọ̀.
Ààrẹ Muhammadu Buhari lálẹ́ àna kí ikọ̀ agbábọ́ọ̀lù Super Falcons ti orílẹ̀-èdè Nàìjííríà kú oríire jíjáwé olúborí pẹ̀lú ikọ̀ Banyana Banyana ilẹ̀ South Africa lọ́jọ́ àbámẹ́ta (Saturday) nínú àṣekágbá ìdíje bọ́ọ̀lù àfẹsẹ̀gbá àwọn obìnrin nílẹ̀ Áfíríkà (AWCON) ẹ̀ẹ̀kọkànlá irú rẹ̀ Ghana 2018.
Ààrẹ fi ìdùnnú rẹ̀ hàn púpọ̀ látàrí iṣẹ́ ìfọmọlúàbíṣe àti ìfarajìn ikọ̀ agbábọ́ọ̀lù àwọn àgbà obìnrin pẹ̀lú bí akẹẹgbẹ́ wọn láti orílẹ̀-èdè South Africa ṣe gbóná gidigidi.
O tẹnu mọ́ ọ pé ikọ̀ Super Falcons ti kọ́kọ́ pegedé láti ṣojú orílẹ̀-èdè Nàìjííríà nínú ìdíje Ife ẹ̀yẹ àgbááyé àwọn Obìnrin tí yóò wáyé ní orílẹ̀-èdè France ní ọdún tó ń bọ̀, Ààrẹ ṣàpèjúwe ìjáwé olúborí ìdíje AWCON yìí fún ìgbà kẹta léra wọn tí ó sì fi pé mẹ́sàn-án ní àpapọ̀ gẹ́gẹ́ bí “oyin inú àkàrà náà”
Nígbà tí ó ń gbóríyìn fún ikọ̀ obìnrin orílẹ̀-èdè yìí fún ṣíṣeé mú yangàn àti ìjẹgàba lórí ilẹ̀ Adúláwọ̀, ó rọ̀ wọ́n láti lọ sínú ìdíje France 2019 pẹ̀lú àfojúsùn ńlá àti ìpinnu láti yege ní ìpele àgbááyé.
Ààrẹ Bùhárí tún gbóríyìn fún àwọn ikọ̀ akọ́nimọ̀ọ́gbá, àjọ tó ń mójú tó bọ́ọ̀lù àfẹsẹ̀gbá lórílẹ̀-èdè Nàìjííríà (NFF), àwọn alátìlẹyìn àti gbogbo àwọn ọmọ ìlú tí wọ́n jẹ́ olólùfẹ́ eré bọ́ọ̀lù àfẹsẹ̀gbá fún ìgbáradì tó mọ́yánlórí àti àtìlẹyìn wọn fún àwọn agbábọ́ọ̀lù, ó rọ àwọn alẹ́nulọ́rọ̀ láti máse wararo lórí ìgbìyànjú láti rí i pé àwọn ikọ̀ tí ó sojú orílẹ̀-èdè náà nínú eré bọ́ọ̀lù àfẹsẹ̀gbá ń tẹ̀síwájú. Ẹ̀wẹ̀, ààrẹ tún gbóṣùbà káre fún àwọn akọ́nimọ̀ọ́gbá wọn gbogbo, àjọ NFF àti àwọn olólùfẹ́ jákèjádò lágbàáyé kú iṣẹ́ ribiribi eléyìí ti ́ó fara hàn nínú bí wọ́n ṣe kópa sí.
“Èmi kì í ṣe iyèméjí lórí ìyege àwọn ọmọ orílẹ̀-èdè Nàìjííríà tí a bá fún wọn ní àtìlẹyìn tó yẹ” èyí ni ó tẹnu mọ́ nígbà tí ó ń ṣèlérí ìfarajìn ìjọba àpapọ̀ fún ìdàgbàsókè eré ìdárayá gẹ́gẹ́ bí ohun èlò ìṣọ̀kan.
--- Rohr ṣàlàyé ohun tí ó ń dùn ún nínú nípa ọwọ́ iwájú ikọ̀ Super Eagles.
Bí orílẹ̀-èdè Nàìjííríà ṣe ń gbáradì fún àwọn ojúṣe wọn lọ́dún tó ń bọ̀ lẹ́yìn tí wọ́n ti pegedé fún ife ẹ̀yẹ ilẹ̀ Adúláwọ̀ ti ọdún 2019, Akọ́nimọ̀ọ́gbá ikọ̀ àgbà orílẹ̀-èdè Nàìjííríà Gernot ti fi ìdùnnú rẹ̀ hàn lórí àwọn agbábọ́ọ̀lù tí ó wà nílẹ̀ fún un láti gbá ọwọ́ iwájú.
Lẹ́yìn ọ̀mì àmì ayò kọ̀ọ̀kan pẹ̀lú ikọ̀ South Africa, ikọ̀ Nàìjííríà yóò bẹẹrẹ ìgbáradì fún ìdíje AFCON tó ń bọ̀ ní inú oṣù kẹta nígbà tí wọn yóò ma wàákò pẹ̀lú ikọ̀ Seychelles, ọgangan pàtàkì nínú ikọ̀ ọ̀hún tí kò kọ akọ́nimọ̀ọ́gbá yìí lóminú ni àwọn agbábọ́ọ̀lù tí ó wà nílẹ̀ fún un láti gbá ọwọ́ iwájú.
Rohr tún tún un sọ pé Ikọ̀ Nàìjííríà ní àwọn agbábọ́ọ̀lù tí yóò mú kí ikọ̀ náà ó ta sánsán ní ọwọ́ iwájú.
“A ní àwọn agbábọ́ọ̀lù ayárabí àṣá lẹ́gbẹ̀ẹ́. Àwọn ọmọkùnrin tuntun wònyí ń ṣe dáadáa. Ẹ ní Kálu, Simon Chukwueze, Victor Osimhen àti Collins tó rí àwọn he ní ọjọ́ àìkú (Sunday). Mo fẹ́ràn ifagagbága náà. Bí àpẹẹrẹ, Kálu lè di ẹ̀yìn mú, ó sì le gbá ọwọ́ iwájú léyìí tí ó jẹ́ oríire fún ikọ̀ náà” ni akọ́nimọ̀ọ́gbá ọ̀hún wí.
--- Pinnick gbóríyìn fún ilé ìfowópamọ́ Zenith fún ìpegedé AFCON ọdún 2019
Ààrẹ àjọ NFF, Ọ̀gbẹ́ni Amaju Pinnick ti gbóríyìn fún ilé ìfowópamọ́ Zenith fún ìpegedé sí ìdíje ife ẹ̀yẹ ilẹ̀ Adúláwọ̀ (AFCON) ọdún 2019 tó yóò wáyé ní orílẹ̀-èdè Cameroon
Lásìkò tí ó ń ṣe ìfifúnni aṣọ ìgbábọ́ọ̀lù ikọ̀ Super Eagle tí a ti bọwó lù fún Olùdarí/Ọ̀gá àgbà ilé ìfowópamọ́ Zenith, ìyẹn Ọ̀gbẹ́ni. Peter Amangbo gẹ́gẹ́ bi ìdúpé láti ọ̀dọ̀ gbogbo àwọn agbábọ́ọ̀lù fún àtìlẹyìn ilé ìfowópamọ́ náà lórí ìpegedé wọn fún ìdíje AFCON ọdún 2019, Pinnick dúpẹ́ lọ́wọ́ ilé ìfowópamọ́ náà fún àtilẹ́yìn gbogbo ìgbà wọn lórí ìdàgbàsókè eré bọ́ọ̀lù àti eré ìdárayá lápapọ̀ ní orílẹ̀-èdè náà.
Ó tẹnu mọ́ ọn pé ọ̀tọ̀ ni ohun tí a ò bá máa sọ bí kì í bá ṣe ìrànlọ́wọ́ àti àtìlẹyìn ilé ìfowópamọ́ náà, tí ó jẹ́ pé láìsí tàbí ṣùgbọ́n ó ṣe pàtàkì sí ìpegedé ikọ̀ agbábọ́ọ̀lù Super Eagle fún ìdíje AFCON ọdún 2019 lẹ́nu lọ́ọ́lóọ́ yìí.
Nígbà tí ó ń fèsì, Amangbo tún fi àrídájú ìfarajìn ilé ìfowópamọ́ náà múlẹ̀ lórí àtìlẹyìn fún gbogbo ikọ̀ agbábọ́ọ̀lù orílẹ̀-èdè, ó sì tún ṣe ìlérí láti mú àwọn ìlérí tirẹ̀ ṣe lójúnà àtimú kí àwọn ikọ̀ agbábóọ̀lù ilẹ̀ Nàìjííríà ó ṣe é mú yangàn lágbàáyé.
--- Ikọ̀ Super Falcons pegedé sí àṣekágbá ìdíje AWCON
Ikọ̀ Super Falcons orílẹ̀-èdè Nàìjííríà ti pegedé sí àṣekágbá ìdíje ife ẹ̀yẹ àwọn obìnrin tí ó ń lọ lọ́wọ́ ní orílè.-èdè Ghana.
Ikọ̀ Super Falcons fàgbà han ikọ̀ Cameroon pẹ̀lú àmì ayò mẹ́rin sí méjì nínú Golí-wò-mí-n-gbá-a-sí-ọ lẹ́yìn ọgọ́fà ìṣẹ́jú ìfigagbága.
Pẹ̀lú èsì yìí, orílẹ̀-èdè Nàìjííríà ti pegedé sí àṣekágbá ìdíje AWCON ọdún 2019.
--- Didier Drogba fẹ̀yìntì nínú eré bọ́ọ̀lù àfẹsẹ̀gbá
Agbábọ́ọ̀lù ọwọ́ iwájú ikọ̀ Chelsea àti Ivory Coast tẹ́lẹ̀ rí Didier Drogba ti kéde ìfẹ̀yìnti rẹ̀ gẹ́gẹ́ bí agbábóọ̀lù.
Ọmọ ogójì odun ọ̀hụ́n gbá àmì-ayò mẹ́rìnlẹ́lọ́gọ́jọ sáwọ̀n nínú ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ ọ̀rìnlélọ́ọ̀ọ́dúnrúnlékan fún ìṣí ẹ̀ẹ̀méji ọ̀tọ̀ọ̀tọ̀ tí ó fi kópa fún ikọ̀ agbábọ́ọ̀lù Chelsea, èyí tí ó ràn wọ́n lọ́wọ́ láti gba Ife ẹ̀yẹ Premier League ilẹ̀ Gẹ̀ẹ́sì lẹ́ẹ̀mẹrin àti ife ẹ̀yẹ Champions League ní ọdún 2012, tí ó fi mọ́ ife ẹ̀yẹ FA àti ife Líìgì mẹ́ta.
Drogba ti ń gbá bọ́ọ̀lù ní sáà yìí ní orílẹ̀-èdè United States pẹ̀lú ikọ̀ Phoenix Rising, ikọ̀ onípele kejì tí òun pẹ̀lú wà lára àwọn tí ó ni í. Ògbóhùntarìgì agbábọ́ọ̀lù ọwọ́ iwájú yìí ni wọ́n ti lérò pé yóò feyìntì lẹ́yìn ìpàdánù àṣekágbá ife ẹ̀yẹ Líìgì United Soccer sọ́wọ́ Louisville City ní ìbẹ̀ẹ̀rẹ̀ oṣù yìí.
Tí èrí sì padà jáde ní ìrọ̀lẹ́ ọjọ́rùú (Wednessday) pẹ̀lú bí Drogba ṣe gbé àwòrán ìgbà kékeré rẹ̀ sí orí ìkànnì ayélujára rẹ̀ tòhun ti ọ̀rọ̀ ìdágbére.
--- Ìdíje AWCON ọdún 2018: Ikọ̀ Super Falcons lu ikọ̀ Shepolopolo orílẹ̀-èdè Zambia pẹ̀lú àmì ayò mẹ́rin sí òdo
Ikọ̀ Super Falcons orílẹ̀-èdè Nàìjííríà lu ikọ̀ Shepolopolo orílẹ̀-èdè Zambia pẹ̀lú àmì ayò mẹ́rin sí òdo ní ọjọ́rùú (Wednessday) ní Cape Coast ní orílẹ̀-èdè Ghana láti tẹ̀síwájú nínú ìdíje ìkọkànlá ife ẹ̀yẹ àwọn obìnrin ilẹ̀ Adúláwọ̀.
Ikọ̀ tí ife ẹ̀yẹ náà wà lọ́wọ́ rẹ̀ yìí tí ó kọ́kọ́ pàdánù ìfẹsẹ̀wọnṣẹ̀ ìṣíde wọn lójọ́ Àìkú (Sunday) tún agbára mú wá pẹ̀lú ìjáwé olúborí tó jọjú léyìí tí ó gbé wọn sí òkè téńté tábìlì ìpín wọn fún ìgbà díẹ̀ náà.
Desire Oparanozie gbá àmi ayò ìṣíde wọlé láti léwájú pẹ̀lú àmì ayò kan sí òdo ní sáà àkọ́kọ́, nígbàtí Francesca Ordega fi àmì ayò ìkejì kun un ní ìṣẹ́jú díẹ̀ tí abala kejì bẹ̀rẹ̀.
Oparanozie tún fi òmíràn kún un láti sọ ọ́ di àmì ayò mẹ́ta sí òdo, nígbà tí Amarachi Okoronkwo tí wọ́n gbé wọlẹ́ tọ́ oyin sí ẹ̀gbẹ́ àkàrà pẹ̀lú àmì ayò rẹ̀ láti sọ ọ́ di mẹ́rin sí òdo.
Ìjáwé olúborí yìí ni ó jẹ́ kí Ikọ̀ Nàìjííríà ó gbọ́n ikọ̀ Zambia kúrò bí ipò kíní lórí tábìlì ṣaájú ìdíje ikọ̀ South Africa àti ikọ̀ Equatorial Guinea tí yóò wáyé láìpẹ́ lónìí.
Ikọ̀ Falcons yóò wá máa bá ikọ̀ Equatorial Guinea wàákò nínú ìdíje ìkẹyìn àbala àkọ́kọ́ ní ọjọ́ àbámẹ́ta (Saturday), nígbà tí ikọ̀ Shepolopolo yóò kojú ikọ̀ South Africa ní ọjọ́ yìí kan náà.
--- Ààrẹ Buhari kí ikọ̀ Super Eagles kú oríire ìpegedé sínú ìdíje AFCON ọdún 2019
Ààrẹ Muhammadu Buhari ti kí ikọ̀ Super Eagles orílẹ̀-èdè Nàìjííríà kú oríire ìpegedé sínú ìdíje ife ẹ̀yẹ ilẹ̀ Adúláwọ̀ ọdún 2019 tí yóò wáyé ní orílẹ̀-èdè Cameroon.
Ọ̀rọ̀ rẹ̀ jáde lẹ́yìn òmì tí wọ́n ta pẹ̀lú ikọ̀ Bafana Bafana orílẹ̀-èdè South Africa ní ìlú Johannesburg ní ọjọ́ àbámẹ́ta (Saturday).
Ààrẹ kùn ọ̀gọ̀ọ̀rọ̀ àwọn olólùfẹ́ eré bọ́ọ̀lù ọmọ orílẹ̀-èdè Nàìjííríà láti gbósùbà fún ikọ̀ náà fún ìṣiṣẹ́ pẹ̀lú ìpinu àti ìfọmọlúàbíṣe wọn nínú ìfigagbága pẹ̀lú ògbóǹtarìgì aṣòrokọlù ikọ̀ yìí, èyí tí ó mú wọn pegedé lẹ́yẹòsọkà tí ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ ìkẹyìn wọn pẹ̀lú ikọ̀ Seychelles sì jẹ́ àgbáṣeré.
Ààrẹ Bùhárí tún gbóríyìn fún àwọn ikọ̀ akọ́nimọ̀ọ́gbá, àjọ tó ń mójú tó bọ́ọ̀lù àfẹsẹ̀gbá lórílẹ̀-èdè Nàìjííríà (NFF), àwọn alátìlẹyìn pàápàá jùlọ àwọn ọmọ orílẹ̀-èdè Nàìjííríà tí wọn ń gbé ní orílẹ̀-èdè South Africa tí wọ́n tú jáde láti wú àwọn agbábọ́ọ̀lù náà lórí, fún iṣẹ́ takuntakun yìí.
Ààrẹ Bùhárí fi àtilẹ́yìn gbogbo ìgbà Ìjọba Àpapọ̀ dá ikọ̀ Super Eagle lójú.
--- Belgium dúró ṣinṣin nínú ìdíje Líìgi UEFA Nations.
Michy Batshuayi fi ara rẹ̀ hàn gẹ́gẹ́ bí ẹni tì ó kọjá bẹ́ẹ̀ láti rọ́pò Romelu Lukaku tí ó fara pa ní ọjọ́bọ (Thursday) nígbà tí ó gbá àmì ayò méjì wọlé nínú ìjáwé olúborí pẹ̀lú àmì ayò méjì sóódo ikọ wọn àti ikọ̀ agbábọ́ọ̀lù Iceland nínú ìdíje Líìgi UEFA Nations.
Lẹ́yìn Ìṣẹ́jú márùndínláàdọ́rin tí wọ́n ti ń dárí sọ ọwọ́ ẹ̀yìn ikọ̀ Iceland, Balógun ikọ̀ Eden Hazard ṣàwárí Thomas Meunier ní apá ọtún orí pápá tí agbábọ́ọ̀lù ẹ̀gbẹ́ ikọ̀ Paris Saint-Germain ọ̀hụ́n nà á sí Batshuayi láti gbá bọ́ọ̀lù ayò náà wọlé.
Àmì ayò kejì tìlẹ̀ rọrùn fún agbábọ́ọ̀lù tí ó wà nínú ikọ̀ Valencia pẹ̀lú àdéhùn àyálò yìí pẹ̀lú bí ó ṣe ta bọ́ọ̀lù sáwọ̀n nígbà tí ayò tí Hans Vanaken gbá padà wá sí ọ̀dọ̀ rẹ̀.
Belgium ní àmì mẹ́sàn-án nínú ìdíje mẹ́ta tí wọ́n ti gbá nínú ìpín kejì ṣaájú ikọ̀ Switzerland.
Òmì pẹ̀lú ikọ̀ Orílẹ̀-èdè Switzerland ti tó láti mú ikọ̀ Belgium wà lára àwọn ikọ̀ mẹ́rin àkọ́kọ́ ní inú oṣù kẹfà. Ikọ̀ Iceland pàdánù gbogbo ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ mẹ́rẹ̀ẹ̀rin wọn, wọ́n sì ti fìdírẹmi.
--- ìdíje Líìgì UEFA Nations: Croatia fìyà jẹ Spain
Ikọ̀ Croatia báyìí yóò fò tọ kọ́sọ́ lọ sí ìlú London nígbà tí ikọ̀ Spain ti di fífi sẹ́yìn pẹ̀lú ìfojúwiná ìfìdírẹmi lábẹ́ akónimọ̀ọ́gbá tuntun Luis Enrique.
Spain pàdánù oore-ọ̀fẹ́ àti tẹ̀síwájú níní àṣekágbá ìdíje Líìgì UEFA yìí pẹ̀lú bí wọ́n ṣe pàdánù pẹ̀lú àmì ayò mẹ́ta sí méjì sọ́wó orílẹ̀-èdè Croatia ní ọjọ́bọ (Thursday), èyí tí ó wáyé pẹ̀lú àmì ayò ìṣẹ́jú kẹtàléláàádọ́rùn-ún tí Tin Jedvaj gbá wọlé.
Àmì ayò ọwọ́ ìparí Jedvaj’s ni ó sí ilẹ̀kùn ọ̀wọ́ kẹrin sílẹ̀ gbayawu ṣaájú ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ kẹyìn tí yóò wáyé ní àárín ikọ̀ orílẹ̀-èdè England àti ikọ̀ orílẹ̀-èdè Croatia ní ọjọ́ àìkú (Sunday).
Ikọ̀ tí ó bá jáwé olúborí yóò pegedé, pẹ̀lú bí ó tún ṣe ṣeéṣe kí ikọ̀ Spain ó tún padà pegedé tí ìdíje yìí tí yóò wáyé ní pápá ìṣeré Wembley bá parí sí ọ̀mì. Croatia ni ó yẹ kí ó borí ní Zagreb, níbi tí Jedvaj ti rí àwọn he lẹ́ẹ̀mejì – àmì ayò rẹ̀ àkọ́kọ́ nínú ìdíje àgbááyé – pẹ̀lú ìjáwé olúborí mánigbàgbé lẹ̀yìn ìfagagbága tó gbóná girigiri yìí.
Ikọ̀ Croatia báyìí yóò fò tọ kọ́sọ́ lọ sí ìlú London nígbà tí ikọ̀ Spain ti di fífi sẹ́yìn pẹ̀lú ìfojúwiná ìfìdírẹmi lábẹ́ akónimọ̀ọ́gbá tuntun Luis Enrique, pẹ̀lú ìpadánù tí ó yani lẹ́nu yìí tí ó jẹ́ irú àbájáde kan náà nínú ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ pẹ̀lú orílẹ̀-èdè England ní ilé wọn ní oṣù tó kọjá.
Spain ti bọ́ lọ́wọ́ ìfìdírẹmi, èyí tí a kò lè fi ògún rẹ̀ gbárí fún ikọ̀ England tàbí Croatia, tí wọ́n ṣì lè parí pẹ̀lú ipò kínní tàbí ipò ìkẹyìn, èyí wà lọ́wọ́ àbájáde alẹ́ ọjọ́ àìkú (Sunday). England yóò fìdí rẹmi tí wọ́n bá pàdánù tàbí tí wọ́n ta ọ̀mì. Croatia yóò bọ́ rẹ́lẹ̀ tí wọ́n bá lù wọ́n tàbí ta ọ̀mì òdo sí òdo.
--- Djokovic po Zverev mọ́lẹ̀ nínú àṣekágbá ìdìje ATP
Novak Djokovic àkọ́kọ́ nínú àwọn Onítẹníìsì àgbááyé ṣẹ́ jáde lọ́nà tó lágbára láti fẹ̀yìn alásọ iná ọmọ orílẹ̀-èdè Germany nnì Alexander Zverev bẹ́lẹ̀ nínú àṣekágbá ìdìje ATP lójọ́rùú (Wednesday).
Ọmọ orílẹ̀-èdè Serbia yìí, fi ọdún mẹ́wàá ju alátakò rẹ̀ tí ó fi ojú rẹ̀ winá lẹ́yìn alátakò yìí tí ó ti kọ́kọ́ gbìyànjú ní abala àkọ́kọ́, gbogbo ìgbìyànjú Zverev ní pápá ìṣeré O2 Arena forí sánpọ́n pẹ̀lú bí Djokovic ṣe borí pẹ̀lú àmì méfà sí mẹ́rin, mẹ́fà sí ọ̀kan.
Ìjáwé olúborí yìí ni ó jẹ́ kí Ẹni tí ó ti gba àmì ẹyẹ yìí ní ẹ̀ẹ̀marùn-ún ọ̀tọ̀ọ̀tọ̀ láti tọ kọ́sọ́ sí ìpele tí ó kángun sí àṣekágbá.
Djokovic, tí yóò parí ọdún yìí gẹ́gẹ́ bí ẹni-ipò kíní lágbàáyé fún ìgbà karùn-ún nínú ìgbésí ayé rẹ̀ lẹ́yìn abala kejì sáà yìí tí ó gbóná girigiri ni ó síwájú ọ̀wọ́ Gustavo Kuerten.
Èyí ni ó mú ọmọ orílẹ̀-èdè Serbia yìí jáwé olúborí fún ìgbà ìkẹtàlélọ́gbọ̀n nínú ìfigagbága márùndínlógójì tí ó ti gbá sẹ́yìn.
--- IÌfẹsẹ̀wọnsẹ̀ pẹ̀lú Bafana: Musa, Balogun, àti àwọn ogún mìíràn gbáradì ní Asaba
Gernot Rohr ti ní agbábọ́ọ̀lù mẹ́jìlélógún tí ó ń gbáradì lọ́wọ́ ní pápá ìṣeré Stephen Keshi ní ìlú Àsàbà nínú àwọn agbábọ́ọ̀lù tí ó fìwé pè, pẹ̀lú bí wọ́n ṣe bẹ̀ẹ̀rẹ̀ ìmúrasílẹ̀ fún ìdíje ìpegedé sí ife ẹ̀yẹ ilẹ̀ Adúláwọ̀ ọdún 2019 pẹ̀lú ikọ̀ Bafana Bafana ní pápá ìṣeré FNB ní ìlú Johannesburg.
Àtàmátàsé ikọ̀ Bordeaux Samuel Kalu, tí wọn ń retí ní ìpàgọ́ lónìí nìkan ni kò sí nínú ìgbáradì náà.
Nínú wọn ni Balogun Ahmed Musa pẹ̀lú àwọn aṣọ́lé Daniel Akpeyi, Theophilus Afelokhai àti Ikechukwu Ezenwa àti àwọn adiẹ̀yìnmú Olaoluwa Aina, Adeleye Aniyikaye, Semi Ajayi, Bryan Idowu, William Troost-Ekong, Leon Balogun, Kenneth Omeruo àti Jamilu Collins pèlú gbára dì.
Lára wọn tún ni àwọn agbábọ́ọ̀lù ọwọ́ àárín Oghenekaro Etebo, John Ogu àti Mikel Agu, àti àwọn ọwọ́ iwájú Kelechi Iheanacho, Moses Simon, Victor Osimhen, Henry Onyekuru, Alex Iwobi, Isaac Success àti Samuel Chukwueze.
Nínú ífẹsẹ̀wọnsẹ̀ àkọ́kọ́ ìpegedé, South Africa jáwé olúborí pẹ̀lú àmì ayò méjì sí òdo pẹ̀lú ayò láti ọwọ́ Tokelo Rantie àti Percy Tau ní inú pápá ìṣeré Godswill Akpabio, pẹ̀lú bi akọ́nimọ̀ọ́gbá Gernot Rohr ṣe lo àwọn agbábọ́ọ̀lù orílẹ̀-èdè kéékèèké tí wọn kò tíi ní ìrírí.
--- A kò bẹ̀ẹ̀rù ikọ̀ Nàìjííríà, Baxter tún un sọ.
Akọ́nimọ̀ọ́gbá ikọ̀ Bafana Bafana Stuart Baxter sọ ọ́ yanya pé òun àti ikọ̀ òun ò fòyà rárá láti kojú ikọ̀ Super Eagle orílẹ̀-èdè Nàìjííríà lọ́jọ́ àbámẹ́ta (Saturday) nínú ìdíje ìpegedé sí ife ẹ̀yẹ ilẹ̀ Adúláwọ̀ ọdún 2019 tí yóò wáyé ní pápá ìṣeré FNB ní ìlú Johannesburg. .
Baxter, tí ó ń lépa àtiborí fún ìgbà kẹta nígbà tí ikọ̀ Bafana bá kojú ikọ̀ Super Eagles, lérò kí ikọ̀ tí ó ti gba Ife ẹ̀yẹ ilẹ̀ Adúláwọ̀ lẹ́ẹ̀mẹta ọ̀tọ̀ọ̀tọ̀ yìí ní ète ìgbẹsan lọ́kàn ṣaájú ìfigagbága náà..
Ọmọ ilẹ̀ Bìrìtìkó yìí kó ikọ̀ South Africa borí ikọ̀ Nàìjííríà pẹ̀lú àmì ayò méjì sí ọ̀kan ní ọdún 2004 níní ìfigagbága fún Mandela kí ó tó di pé ó fìyà jẹ ikọ̀ Super Eagles pẹ̀lú àmì ayò méjì sí òdo 2-0 nínú ìdíje ìpegedé sí ife ẹ̀yẹ ilẹ̀ Adúláwọ̀ ọdún 2019 ní Uyo nínú oṣù kẹfà ọdún 2017 – ìdíje àkókọ́ rẹ̀ nínú ìṣí ẹ̀ẹ̀kejì nínú ikọ̀ náà.
-- Ikọ̀ Flying Eagles yóò kojú ikọ̀ orílẹ̀-èdè Ghana, àti ikọ̀ orílẹ̀-èdè Benin nínú ìdíje WAFU
Ikọ̀ agbábọ́ọ̀lù àwọn ọ̀dọ́ tí ọjọ́ orí wọn kò ju ogún ọdún lọ yóò máà wàákò pẹ̀lú akẹẹgbẹ́ wọn láti orílẹ̀-èdè Ghana, Niger Republic àti Benin Republic ní ìpín B ìdíje kòmẹsẹ̀óyọ ife ẹ̀yẹ́ WAFU àwọn ọ̀dọ́ tí ọjọ́ orí wọn kò ju ogún ọdún lọ tí yóò wáyé ní Lome lórílẹ̀-èdè Togo, láti ọjọ́ kẹfà sí ọjọ́ kẹrìndínlọ́gún oṣù kejìlá.
Àwọn Alákòóso ètò ti to àwọn ìdíje wọ̀nyí ní ìmurasílẹ̀ pàtàkì de àwọn ikọ̀ márààrún láti ẹkùn kọ̀ọ̀kan tí wọ́n ti pegedé láti kópa nínú ìdíje ife ẹ̀yẹ́ WAFU àwọn ọ̀dọ́ tí ọjọ́ orí wọn kò ju ogún ọdún lọ ní orílẹ̀-èdè Tanzania láti Ọjọ́ kejì sí ọjó kẹtàdínlógún oṣù kejì ọdún 2019.
Ikọ Nàìjííríà tí ó ti gba ife idíje yìí ní ẹ̀ẹ̀meje ọ̀tọ̀ọ̀tọ̀ yóò máa kópa nínú ìdíje kòmẹsẹ̀oyọ̀ ọlọ́jọ́ mọ́kànlá yìí pẹ̀lú àwọn ikọ̀ bíi ikọ̀ Senegal, Burkina Faso, Ghana àti ikọ̀ Niger Republic ní Lome. Ikọ̀ Burundi àti Angola tí wọ́n gbàlejò ìdíje yìí yóò kún àwọn orílẹ̀-èdè márùn yìí.
Ikọ̀ Flying Eagles wàákò pẹ̀lú ikọ̀ Young Squirrels ti orílẹ̀-èdè Benin nínú ìdíje àkọkọ wọn fún kòmẹsẹ̀oyọ náà ní ọjọ́ keje oṣù kejìlá, kí wọ́n tó kọlu ikọ̀ Junior Mena ti orílẹ̀-èdè Niger Republic ní ọjọ́ kẹsàn-án oṣù kejìlá àti ikọ̀ Black Satellites orílẹ̀-èdè Ghana ní ọjọ́ kejìlá oṣù kejìlá.
--- Ikọ̀ orílẹ̀-èdè China dara pọ̀ mọ́ àwọn tí wọn ń lépa àtira Victor Moses
Ọjọ́ iwájú Victor Moses nínú ikọ̀ Chelsea kò dájú lẹ́yìn tí akọ́nimọ̀ọ́gbá wọn Maurizo Sarri yọ orúkọ rẹ̀ kúro nínú ikọ̀ rẹ̀ tí yóò máa kojú Bate Borisov nínú ìdíje Líìgì Europa.
Sarri sọ ọ́ kan Moses lójú pé ó lè fi ikọ̀ náà sílẹ̀ nínú oṣù kínní ọdún nígbà tí fèrèsé ojú ọjà bá ṣí sílẹ̀. Láti ìgbà yìí ni ọmọ orílẹ̀-èdè Nàìjííríà kò tí rí ọ̀kankan nínú àwọn ìdíje wọn gbá.
Ikọ̀ Crystal Palace àti ikọ̀ Wolverhampton Wanderers ti fi ìfẹ wọn hàn sí ìṣọwọ́ṣiṣẹ́ rẹ̀ bẹ́ẹ̀ sì ni ìròyìn tí ó jáde ní yàjóyàjó láti ọwọ́ OwngoalNàìjííríà.com sọ ọ́ di mímọ̀ pé Ikọ̀ Líìgì ilẹ̀ China Shanghai SIPG ti dara pọ̀ láti máa lépa àtirà á.
--- Rohr mú Afelokhai gẹ́gẹ́ bí arọ́pò Uzoho
Akọ́nimọ̀ọ́gbá ikọ̀ Nàìjííríà Gernot Rohr ti fi késí Asọ́lé ikọ̀ Enyimba Theophilus Afelokhai gẹ́gẹ́ bí arọ́pò Uzoho fun ìdíje ìpegedé sínú ife ẹ̀yẹ ilẹ̀ Adúláwọ̀ pẹ̀lú ikọ̀ South Africa àti ìdíje ọlórẹ̀ẹ́sọ́rẹ̀ẹ́ àgbááyé pẹ̀lú ikọ̀ Uganda nínú oṣù yìí.
Uzoho fi agídí kúro nínú àlàkalẹ̀ àwọn agbábọ́ọ̀lù ikọ̀ Super Eagles látàrí èṣe tí ó ṣe lópin ọ̀sẹ̀ tó kọjá tí yóò fi wà létíi pápá ná fún ọ̀ṣẹ̀ mẹ́rin ókéré tán.
Ikọ̀ Nàìjííríà yóò kojú ikọ̀ South Africa ní Johannesburg lọ́jọ́ kẹtàdínlógún oṣù kọkànlá kí ó tó di pé wọn ó pàdé ikọ̀ Uganda lẹ́yìn ọjọ́ kẹta ní ìlú Asaba.
--- Ikọ̀ Man City gòkè lẹ́yìn ìfakọyọ ńlá
Ògbónhùntarìgì ikọ̀ agbábọ́ọ̀lù Manchester City ti gba ipò àkọ́kọ́ wọn padà nínú ìdíje Premier League ilẹ̀ Gẹ̀ẹ́sì tí ó wáyé lálẹ́ àná lẹ́yìn tí wọ́n lu ikọ̀ Southampton ní àlùbami, ikọ̀ tí Pep Guardiola kó sòdí yìí jáwé olúborí pẹ̀lú àmì ayò mẹ́fà sí ọ̀kan ní ilé wọn pẹ̀lú bí Raheem Sterling ṣe rí àwọn he lẹ́ẹ̀mejì nínú ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ náà. Lápá ibòmìírà, Ikọ̀ Chelsea di orogún tí ó súnmọ́ wọn jùlọ lẹ́yìn tí wọ́n fi ara balẹ̀ fìyàjẹ ikọ̀ Crystal Palace pẹ̀lú àmì ayò mẹ́ta sí ọ̀kan.
--- Ìdìje Ìpege AFCON: Bafana Bafana dárúkọ ikọ̀ tí yóò kojú orílẹ̀-èdè Nàìjííríà
Akọ́nimọ̀ọ́gbá ikọ̀ Bafana Bafana Stuart Baxter ti pe agbábọ́ọ̀lù ọwọ́ àárín Thulani Serero ti ikọ̀ SBV ní orílẹ̀-èdè Netherlands sínú ikọ̀ rẹ̀ fún ìfẹsẹ̀wọnṣẹ̀ àìgbọdọ̀máborí ìdíje ìpegedé sínú ife ẹ̀yẹ ilẹ̀ Adúláwọ̀ (AFCON) ọdún 2019 wọn pẹ̀lú ikọ̀ orílẹ̀-èdè Nàìjííríà ní pápá ìṣeré FNB Stadium ní ọjọ́ kẹtàdínlógún oṣù kọkànlá.
--- Ikọ̀ Nàìjííríà yóò pegedé sí ìdíje ife ẹ̀yẹ ilẹ̀ Adúláwọ̀ (AFCON) ọdún 2019 : Rohr
Akọ́nimọ̀ọ́gbá Gernot Rohr gbàgbó pé ikọ̀ rẹ̀ lè borí tàbí kí wọ́n ta ọ̀mì nínú ìdíje pẹ̀lú orílẹ̀-èdè South Africa láti pegedé sínú ìdíje ife ẹ̀yẹ ilẹ̀ Adúláwọ̀ (AFCON) ọdún 2019.
Ikọ̀ agbábọ́ọ̀lù Super Eagles ti wà lókè téńté tábìlì pẹ̀lú àmì mẹ́sàn-án nínú ìpín E, wọn yóò sì kojú ikọ̀ Bafana Bafana ní ọjọ́ kẹtàdínlógún oṣù kọkànlá ní ìlú Johannesburg lórílẹ̀-èdè South Africa
Ọ̀mì tàbí ìjáwé olúborí ti tó fún àgbà ikọ̀ apá ìwọ̀ oòrùn ilẹ̀ Adúláwọ̀ yìí láti rí ààyè nínú ìdíje tí orílẹ̀-èdè Cameroon yóò gbàlejò rẹ̀ yìí.
--- Ikọ̀ orílẹ̀-èdè Nàìjííríà gòkè, ipò kẹrìnlélógójì ni wọ́n wà báyìí lórí àtẹ ipò FIFA
Ikọ̀ Super Eagles orílẹ̀-èdè Nàìjííríà ti tẹ àkàbà mẹ́rin gòkè síi sí ipò kẹrìnlélógójì lágbàáyé nínú àtẹ Cocacola FIFA tí osù kẹwàá.
Ní orí àtẹ tábìlì tí wọ́n gbé jáde lórí ìkànnì ìgbìmọ̀ àpapọ̀ eré bọ́ọ̀lù lágbàáyé ní ọjọ́bọ (Thursday), orílẹ̀-èdè Nàìjííríà ní ààmì àmì òjìlélégbèjedínmẹ́sàn-án ju àmì òkòólégbèjedínmárùn-ún tí wọ́n ní nínú oṣù kẹsàn-án.
Ìgbéga yìí ti wá gbé ikọ̀ Nàìjííríà gẹ́gẹ́ bí onípòkẹta ní ilẹ Adúláwò lẹ́yìn ikọ̀ orílẹ̀-èdè Tunisia àti ikọ̀ Senegal.
Ó ṣe pàtàkì láti rántí pé ní àkókò yẹn ni ikọ̀ Nàìjííríà dáná ìyà fún ikọ̀ Lybia pẹ̀lú àmì ayò mẹ́rin sí òdo ní ilé wọn àti àmì ayò mẹ́ta sí méjì ní àjò nínú ìdíje ìpegedé sínú ife ẹ̀yẹ ilẹ̀ Adúláwọ̀.
Tunisia ni ó wà ní ipò kejìlélógún nígbà tí Senegal wà ní ipò karùndínlógbọ̀n.
Ikọ̀ Congo DR (wà ní ipọ̀ kẹrìndínláàádọ́ta tí Morocco jẹ́ ìkẹtàdíláàádọ́ta tí àwọn orílẹ̀-èdè ilẹ̀ Adúláwọ̀ mìíràn sì wà nínú aádọ́ta àkọ́kọ́.
Káàkiri àgbááyé, Belgium ni ó wà ní ipò kínní báyìí ṣíwájú France tí ó fi tíntinní yẹ̀sílẹ̀ pẹ̀lú àmì kan péré nínú àtẹ Cocacola FIFA tí ó jáje lónìí. Ikọ̀ Belgium ní àmì Òjìlélẹ́ẹ̀ẹ́dẹ́gbèsándínméje, tí France sì ní àmì Òjìlélẹ́ẹ̀ẹ́dẹ́gbèsándínmẹ́jọ.
Àwọn méjèèjì di ọ̀kè téńté mú síbẹ̀ lẹ́yìn oṣù kan tí àwọn méjéèjì ti ń fi ìjáwéolúborí àti òmì panu, pẹ̀lú bí ikọ̀ Belgium ṣe na ikọ̀ Switzerland kò jẹ́ kí ikọ̀ yìí kúrò ní ipò kẹjọ bẹ́ẹ̀ sì ni lílù tí France lu Germany nínú ìdíje Líìjì UEFA Nations jẹ́ kí wọn ó jábọ́ lẹnu àkàsọ méjì lọ sí ipò kẹrìnlá. Brazil dipò kẹta mú pẹ̀lú àmì ọ̀tàlélẹ́gbèjọlémẹ́sàn-án, tí Croatia ipò kẹrin pẹ̀lú àmì òjìlélẹ́gbèjọlémárùn-ún lórí tábìlì, England ipò karùn-ún àmì okòólélẹ́gbẹ̀jọ-dín-ọ̀kan nígbà tí ikọ̀ agbábọ́ọ̀lù Argentina Leo Messi wà ní ipò kejìlá lórí tábìlì.
--- Pliskova yege sínú ìpele tó kángun sí àṣekágbá ìdíje WTA
Ọmọ orílẹ̀-èdè Czech Karolina Pliskova ti yege bọ́ sínú ìpele tó kángun sí àṣekágbá ní ọjọ́bọ (Thursday) lẹ́yìn tí ó ó lu Petra Kvitova akínkanjú tí ó ti gba ìdíje ọ̀hún rí tí ó sì yọwọ́ kílàńkó rẹ̀ kúrò nínú àṣekágbá ìdíje WTA tí yóò wáyé ní ìlú Singapore.
Pliskova di aláyò àkọ́kọ́ tí ó kọ́kọ́ pegedé sínú àṣekágbá ẹlẹ́ni mẹ́rin ọ̀hún lẹ́yìn tí ó borí pẹ̀lú àmì ayò mẹ́fà sí mẹ́ta, mẹ́fà sí mẹ́rin ní ẹ̀tàlélọ́gọ́rin ìṣẹ́jú.
Kvitova nílò láti láti jáwé olúborí kanlẹ̀ láti lè tẹ̀síwájú àti máa fakọyọ ṣùgbọ́n ó jà fitafita ni láti lè parí ìfigagbága ìpele náà fún ìgbà àkọ́kọ́ láti ọdún 2015, àbájáde ìfigagbága yìí da jìnnìjìnnì bo Caroline Wozniacki tí àmì ẹyẹ ìdíje náà wà lọ́wọ́ rẹ̀ lọ́wọ́lọ́wọ́, ẹni tí ó nílò láti lu Elina Svitolina kanlẹ̀ láti lè di àmì ẹ̀yẹ yìí mú síbẹ̀.
Pliskova aláyò àkọ́kọ́ nínú ìdíje náà nígbàkanrí wá ààyè fún ara rẹ̀ ní ìpele tó kángun sí àṣekágbá fún ìgbà kejì léra wọn.
--- Messi di yíyọ sẹ́gbẹ̀ẹ́ fún ọ̀sẹ̀ mẹ́tà látàrí èṣe apá.
Balógun ikọ̀ Barcelona yóò máa gbélẹ̀ wòran fún ọ̀sẹ̀ mẹ́ta gbáko látàrí èṣe apá ọ̀tún rẹ̀ nínú ìjáwé olúborí ìdíje La liga wọn lórí ikọ̀ Sevilla pẹ̀lú àmì ayò mẹ́rin sí méjì ní ọjọ́ àbámẹ́ta (Saturday). Àtẹ̀jáde ikọ wọn kan ló sọ eléyìí di mímọ̀.
Ifarapa yìí yọ ọ́ kúrò nínú ikọ̀ tí yóò kojú orogún Real Madrid nínú ìfigagbága ‘Clasico’ tí yóò wáyé ní ọjọ́ kejìdínlọ́gbọ̀n oṣù kẹwàá.
Ousmane Dembele rọ́pò Messi ní ìṣẹ́jú mẹ́ẹ̀ẹ́dọ́gbọ̀n tí ìdíje náà bẹ̀ẹ̀rẹ̀ lẹ́yìn tí Dókítà ti yẹ̀ ẹ́ wò tán létí ìlà látàrí ìkọlù òun Franco Vazquez ọmọ ikọ̀ Sevilla.
Ní àfikún sí ìfigagbága ‘Clasico’ Agbábọ́ọ̀lù tí o rí àwọn he jùlọ fún ikọ̀ Barca yìí kò tún ní sí lórí pápá lọ́jọ́rùú (Wednesday) nínú ìdíje UEFA Champions League ní ilé wọn pẹ̀lú ikọ̀ Inter Milan.
--- Mikel Obi gbósùnbà fún ikọ̀ Eagles
Balógun ikọ̀ Super Eagles Mikel Obi ti gbósùbà fún ikọ̀ náà lẹ́yìn ikọ̀ náà gbo ewúro sí ikọ̀ Libya lójú pẹ̀lú àmì ayò mẹ́rin sí òdo ní ọjọ́ àbámẹ́ta (Saturday) nínú ìdíje ìpegedé sínú ife ẹ̀yẹ ilẹ̀ Adúláwọ̀ (AFCON) ọdún 2019 wọn ní ìlú Uyo. Mikel tí kò sí nínú ìdíje náà látàrí ìfarapa fún ikọ̀ náà ki ikọ̀ náà fún ìpinnu wọn bákan náà Odion Ighalo akọni ọjọ́ náà tó rí àwọn he lẹ́ẹ̀mẹta.
--- ìdíje ìpegedé (AFCON) ọdún 2019: Ìpàgọ ikọ̀ Eagles di ṣíṣí lónìí.
Ìpàgọ́ ikọ̀ Super Eagles yóò di ṣíṣí padà lónìí pẹ̀lú bí Gernot Rohr ṣe ń retí okéré tán agbábọ́ọ̀lù mẹ́rìndínlógún láti balẹ̀ sí olú ìlú ìpínlẹ̀ Akwa Ibom láti leè bẹ̀ẹ̀rẹ̀ igbáradì ṣaájú ìfigagbága pàtàkì ìdíje ìpegedé sínú (AFCON) ọdún 2019 tí wọ́n ní pẹ̀lú ikọ̀ Libya lọ́jọ́ àbámẹ́ta (Saturday).
Àwọn ìbejì ikọ̀ Leicester City lórílẹ̀-èdè England Kelechi Iheanacho àti Wilfred Ndidi, tí ó fi mọ́ adiẹ̀yìnmú fún ikọ̀ Udinese, William Troost-Ekong ni ìgbàgbọ́ wà pé wọn ó léwájú àwọn agbábọ́ọ̀lù mẹ́tàlá mìíràn wá sínú àgọ́ ikọ̀ Super Eagles lónìí, àwọn alákòóso ló fi ìdí èyí múlẹ̀. Atamátàsé ikọ̀ Watford, Isaac Success ti dé sí ìlú Èkó lánàá ìgbàgbọ́ sì wà pé yóò tẹ ọkọ̀ ofurufú létí lọ tààrà sí Uyo kí ọjọ́ tó kanrí.
Adiẹ̀yìnmú ikọ̀ Hapoel Beer Sheva orílẹ̀-èdè Israel, tí ó ran ikọ̀ rẹ̀ lọ́wọ́ láti fi òpin sí ọ̀dá ìjáwé olúborí nínú Líìgì ilẹ̀ Israeli lọ́jọ́ àbámẹ́ta (Saturday) pẹ̀lú ìjáwé olúborí àmì ayò mẹ́rin sí ọ̀kan nílé wọn pẹ̀lú ikọ̀ Maccabi Petach Tikva fi ìdí rẹ̀ múlẹ̀ pé òun yóò wọ àgọ́ lónìí.
Lára àwọn tí wọ́n tún ń retí ní àgọ́ Super Eagles ni àwọn agbábọ́ọ̀lù bíi Kenneth Omeruo, Leon Balogun, William Troost-Ekong, Shehu Abdullahi, Oghenekaro Etebo, Ahmed Musa, Moses Simon, Henry Onyekuru, Semi Ajayi, Ikechukwu Ezenwa àti Ola Aina.
--- Rafael Nadal dúró lókè téńtè síbẹ̀ lórí àtẹ ATP
Rafael Nadal ọmọ orílẹ̀-èdè Spain ti tẹ̀síwájú láti dipò aṣaájú mú lórí àtẹ Egbé àwọn Aláyò Tẹníìsì Àgbááyé (ATP) ti àwọn ọkùnrin tí wọ́n gbé jáde ní ọjọ́ ajẹ́ (Monday) pẹ̀lú ẹgbọ̀kànlélógójì àmì ṣaájú akẹẹgbẹ́ rẹ̀ ọmọ orìlẹ̀-èdè Switzerland.
--- Musa gba àmì-ẹ̀yẹ agbábọ́ọ̀lù ọ̀sẹ̀ tí ó dára jùlọ nílẹ̀ Saudi.
Agbábọ́ọ̀lù ẹ̀gbẹ́ ikọ̀ Super Eagles, Ahmed Musa ti gba àmì-ẹ̀yẹ agbábọ́ọ̀lù tí ó dára jùlọ ní abala kẹta Líìgì apapọ̀ ilẹ̀ Saudi, CompletesportsNàìjííríà.com ló jábọ eléyìí.
Agbábọ́ọ̀lù ikọ̀ Leicester City àti CSKA Moscow tẹ́lẹ̀rí ọ̀hún, tún gba ẹgbẹ̀rún mẹ́wà Riyal owó ilẹ̀ Saudi tí í ṣe ọ̀kẹ́méjìdínláàádọ́dalélẹ́gbààrúnlélárúndínláàádọ́ta owó náírà fún iṣe takun-takun rẹ̀, gẹ́gẹ́ bí ìkànì ikọ̀ agbábọ́ọ̀lù náa ṣe fi léde.
Musa tí ó ń ta sánsán lọ́wọ́ tún jẹ́ ẹni tí gbogbo ènìyàn rí iṣẹ́ rẹ̀ fún ikọ̀ Super Eagles nínú ìdíje ìpegedé sínú ife ẹ̀yẹ ilẹ̀ Adúláwọ̀ (AFCON) ọdún 2019 wọn pẹ̀lú ikọ̀ orílẹ̀-èdè Seychelles èyí tí ó parí pẹ̀lú àmì ayò mẹ́ta sí òdo.
--- ìdíje AFCON àwọn ọ̀jẹ̀ wẹ́wẹ́: Àjọ NFF yóò fún Eaglets ní ìmúrasílẹ̀ tó mọ́nyánlórí.
Lẹ́yìn tí wọn ti pegédé láti ìhà ìwọ̀ oorùn ilẹ̀ Adúláwọ̀ sínú ìdíje ìpegedé sínú ife ẹ̀yẹ ilẹ̀ Adúláwọ̀ àwọn ọ̀jẹ̀ wẹ́wẹ́. Ààrẹ Àjọ tó ń mójú bọ́ọ̀lù Afẹsẹ̀gbá lórílẹ̀-èdè Nàìjííríà (NFF), Amaju Pinnick sọ pé ikọ̀ Golden Eaglets yóò di fífún ní ìmúrasílẹ̀ tó mọ́nyánlórí, kí wọn ó lè gba ife ẹ̀yẹ ìdíje náà ní orílẹ̀-èdè Tanzania lọ́dún tó ń bọ̀.
Ikọ̀ Eaglets lu ikọ̀ Ghana pẹ̀lú àmì ayò mẹ́ta sí ọ̀kan pẹ̀lú lálẹ́ ọjọ́ àbámẹ́ta (Saturday) láti pegedé.
Samson Tijani ni ó gba àmì ẹ̀yẹ agbábọ́ọ̀lù tó ta sánsán jù lọ nígbà tí Olakunle Olusegun gba ti ẹni tí ó rí àwọn he jùlọ pẹ̀lú àmì ayò mẹ́rin.
“Àwọn tí a ní báyìí jẹ́ àwọn agbábọ́ọ̀lù tí wọ́n jẹ́ ọ̀dọ́ lóòótọ́ tí wọ́n sì ní ọjọ́ iwájú tó dára.
Ní ti àwa nínú àjọ wa, a ti fẹnu kò láti máa ṣe wọ́n bí ikọ̀ Super Eagles láti ìpele yìí.
A fẹ́ kí wọ́n ní ìrònú àti ọpọlọ tó suwọ̀n gẹ́gẹ́ bí wọ́n ṣe ń dàgbà. Bí a ṣe pèsè ikọ̀ Eagles fún ìdije ife ẹ̀yẹ àgbááyé ní Russia bẹ́ẹ̀ náà ni a ó pèsè wọn sílẹ̀ fún ìdíje ní Tanzania.
À ń wò tayọ Tanzania pẹ̀lú.
À ń wo ọjọ́ iwájú, àkókò yìí sì ni a ní láti bẹ̀ẹ̀rẹ̀ sí tọ́ àwọn ọmọ náà sọ́nà.
Ó sọ pé ikọ̀ Eaglets yóò rin ìrìn àjò ìgbafẹ́ káàkiri ìlú Qatar àti ìlú Jordan kí wọ́n ó tó lọ sínú ìdíje ní Tanzania.
--- Eaglets lu ikọ̀ Niger, wọn yóò kojú ikọ̀ Starlets Ghana ní aṣekágbá
Ikọ̀ Nàìjííríà ni ó jáwé olúborí pẹ̀lú àmì ayò méjì sí ọ̀kan lórí ikọ̀ Niger tí ó gbàlejò wọn lọ́jọ́ru (Wednessday) láti lọ kọlu ikọ̀ Ghana tí yóò tún iná orogún ọdún mẹ́tàdínláàádọ́rin dá.
Ìjáwé olúborí yìí túmọ̀ sí pè ikọ̀ Golden Eaglets yóò kojú ikọ̀ Black Starlets ní Niamey lọ́jọ́ àbáméta (Saturday) fún àtirí ààyè nínú ìdìje ife ẹ̀yẹ ilẹ̀ Adúláwọ̀ tí àwọn ọ̀dọ́ tí ọjọ́ orí wọn ò ju mẹ́tàdínlógún lọ tí wọ́n ṣètò láti wáyé lórílẹ̀-èdè Tanzania.
Ikọ̀ Eaglets mú ara gidi wọ́n sì ṣiṣẹ́ wọn bí iṣẹ́ pẹ̀lú bí wọ́n ṣe lu ikọ̀ Niger Republic tí ó gbàlejò wọn pẹ̀lú àmì ayò méjì sí òdo nínú ìfigagbaga yìí tí ó gbóná girigiri ní pápá ìṣeré General Seyni Kountche.
Wọ́n gbá àmì ayò méjì wọlé nínú ìpadánù alámì ayò méjì sí mẹta pẹ̀lú ikọ̀ Burkina Faso nínú ìfigagbága ìṣíde wọn kí wọ́n ó tó dáná ìyà fún ikọ̀ Cote d’Ivoire pẹ̀lú àmì ayò márùn-ún sí ọ̀kan ní ọ̀sẹ̀ tó kọjá.
--- Weah padà wá lọ́nà tó ya gbogbo àgbááyé lẹ́nu nínú ìdíje pẹ̀lú Nàìjííríà……lẹ́ni ọdún mọ́kànléláàádọ́ta!
Ààrẹ orílẹ̀-èdè Liberia àti àgbábọ́ọ̀lù tó ta sánsán jùlọ lágbàáyé nígbà kan rí George Weah padà sínú ìfigagbága àgbááyé lọ́nà tí ó yani lẹ́nu púpọ̀ ní ìlú Monrovia lọ́jọ́ ìṣẹ́gun (Tuesday), ó gbá bọ́ọ̀lù nínú ìpádánù alámì ayò méjì sí ọ̀kan sọ́wọ́ ikọ̀ Nàìjííríà.
Ìdíje yìí wá lẹ́yìn ọ̀ṣẹ̀ díẹ̀ tí ó ṣe ayẹyẹ ọjọ́ ìbí ọdún méjìléláàádọ́ta tí orílẹ̀-èdè Liberia sì ṣètò ìdíje náà láti fi ẹ̀yin Weah, gbajúgbajà aláṣọ ìgbábọ́ọ̀lù nọ́ḿbà ẹ̀rìnlá tì.
Bákan náà, àwọn alátìlẹyìn wà ní ipò ìyàlẹ́nu nígbà tí wọ́n rí atamátàsé yìí tí ó tún gbé aṣọ gánrùn ṣíwájú ikọ̀ orílẹ̀-èdè náà wọ orí pápá lẹ́yìn ọdún mẹ́rìndínlógún tí ó ti fara hàn gbẹ̀yìn.
Ìròyìn fi léde pé Weah, tí ó gbá ọwọ́ iwájú pátápátá tí ó sì pitú rẹpẹtẹ irú èyí tí ó sọ orúkọ rẹ̀ di tọ́ọ́rọ́ fọ́n kálé káàkiri àgbááyé gba ìdúró kíni láti ọ̀dọ̀ àwọn alátìlẹyìn nígbà tí wọ́n rọ́pò rẹ̀ ní ìṣẹ́jú kọkàndínlọ́gọ́dọ́rin.
Àmì ayò láti ọwọ́ Henry Onyekuru àti Simeon Nwankwo ni ó ran órílẹ̀-èdè Nàìjííríà lọ́wọ́ láti léwájú pẹ̀lú àmì ayò méjì sí òdo kí ó tó di pé ikọ̀ tí ó wà nílé yìí dá ọ̀kan padà pẹ̀lú gólì-wò-mí-n-gbá-a-sí-ọ láti Kpah Sherman ní ọwọ́ ìparí ayò náà.
Weah gbádùn ìgbésí ayé rẹ̀ ní ilè Europe tí ó fẹ́rẹ̀ẹ́ lò tó ọdún mẹ́wàá àbọ̀ èyí tí ó mú u kópa fún àwọn ikọ̀ bíi Monaco, Paris Saint-Germain àti Marseille ní orílẹ̀-èdè France, AC Milan ní orílẹ̀-èdè Italy.
Ó tún kópa fún ikọ̀ ilẹ̀ Gẹ̀ẹ́sì Manchester City àti Chelsea.
Weah ní ó di kíkéde gẹ́gẹ́ bí agbábọ́ọ̀lù tí ó ta sánsán jùlọ lágbàáyé lọ́dún 1995 bákan náà ni ó gba àmì ẹ̀yẹ Ballon d’Or ní ọdún yìí kan náà òun sì ni ọmọ ilẹ̀ Adúláwọ̀ kan ṣoṣo tí ó ṣì gba àwọn àmì ẹ̀yẹ́ méjéèjì yìí.
--- Hiddink jẹ́ yíyàn gẹ́gẹ́ bí akọ́nimọ̀ọ́gbá ikọ Olympic orílẹ̀-èdè China
Guus Hiddink ti di fífún ní ojúṣe láti rí i pé ikọ̀ China pegedé sí àṣekágbá ìdíje Olympic ọdún 2020 lẹ́yìn tí wọ́n fa ikọ̀ ọ̀dọ́ tí ọjọ́ orí wọn kò ju mọ́kànlélógún lọ lé akọ́nimọ̀ọ́gbá ikọ̀ Real Madrid àti ikọ̀ orílẹ̀-èdè Netherlands tẹ́lẹ̀rí ọ̀hún lọ́wọ́ lọ́jọ́ ajé (Monday).
Hiddink, ẹni ọ̀kànléláàládọ́rin ọdún, ni akọ́nimọ̀ọ́gbá ńlá tí ó tuntun jù tí yóò kọjá sí orílẹ̀-èdè China láti ìgbà tí ààrẹ orílẹ̀-èdè náà, Xi Jinping, ti fi ìfẹ́ hàn láti sọ orílẹ̀-èdè náà di ilè agbára eré bọ́ọ̀lù àgbááyé.
Ọmọ orílẹ̀-èdè Neitherland yìí dara pọ̀ mọ́ akẹẹgbẹ́rẹ̀ tí ó ti gba ife ẹ̀yẹ ní ilẹ̀ Europe rí ìyẹn Marcello Lippi lórí àtẹ ìsanwó àjọ CFA, pẹ̀lú bí akọ́nimọ̀ọ́gbá tí ó kó ikọ̀ Italy gba ife ẹ̀yẹ àgbááyé yìí ń tirẹ̀ ṣe ń pèsè ikọ̀ àgbà ilẹ̀ náà sílẹ̀ lọ́wọ́lọ́wọ́ fún àṣekágbá ìdíje Ife ilẹ̀ Asia tí yóò wáyé ní United Arab Emirates ní inú oṣù kínní.
Àwọn akọ́nimọ̀ọ́gbá ńláńlá bíi Luiz Felipe Scolari, Fabio Capello, Manuel Pellegrini àti Andre Villas Boas pẹ̀lú ti ní nǹkan ṣe pẹ̀lú àwọn ẹgbẹ́ agbábọ́ọ̀lù nínú ìdíje Chinese Super League.
--- ÀWỌN ÀWÒRÁN: Ikọ̀ Super Eagles ń yá òòrùn ilẹ̀ Seychelles’
Ikọ̀ Super Eagles ti ṣetán láti kojú ikọ̀ Seychelles nínú ìdíje kàkà-kéku-ó –jẹ-èsé tí yóò wáyé ní ìlú Victoria ní ọjọ́ àbámẹ́ta (Saturday).
Pẹ̀lú bí ilé ṣe kún fọ́fọ́, ikọ̀ Nàìjííríà tí ń gbádùn oor̀un àràn yẹ́ẹ́ tí ó gba orí erékùsù yìí kan
--- LÍÌGÌ UEFA NATION: France ta ọ̀mị̀ òdo sí òdo pẹ̀lú Germany
France tí ife ẹ̀yẹ́ àgbááyé wà lọ́wọ́ rẹ̀ kò bóde pàdé ó sì nílò láti dúpẹ́ lọ́wọ́ aṣọ́lé kẹta wọn Alphonse Areola fún ọ̀mị̀ òdo sí òdo tí wọ́n gbá pẹ̀lú Germany nínú ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ ìdíje Líìgì UEFA Nations lọ́lẹ̀ lọ́jọ́bọ (Thursday), àkọ́kọ́ irú ẹ̀ láti ìgbà tí wọ́n ti gbé igbá oró ife ẹ̀yẹ agbááyé sókè.
Ní inú òjò lálẹ́ ọjọ́ yìí, ikọ̀ Germany tún iyì wọn rà padà lẹ́yìn ìjákúrò láti abala àkọ́kọ́ nínú ìdíje ife ẹ̀yẹ́ àgbááyé tí ó yani lẹ́nu gbáà ní orílẹ̀-èdè Russia, èyí tí ó yára jù nínú ìdíje náà láti bí ọgọ́rin ọdún sẹ́yìn.
“Ó jẹ́ ìdíje tí ó gbóná girigiri pẹ̀lú bí a ṣe ń fakọyọ jù wọ́n lọ tí àwọn náà sì ń fakọyọ jù wá lọ nígbà mìíràn.,” ni Didier Deschamps akọ́nimọ̀ọ́gbá ikọ̀ France wí.
--- ìdíje AFCON àwọn ọjẹ wẹ́ẹ́wẹ́: ikọ̀ Eaglets fojú sun ìjáwé olúbori lórí ikọ̀ Burkina Faso
Mohammed Sanusi, akọ̀wé àpapọ̀ àjọ tí ó ń mójú tó bọ́ọ̀lù afẹsẹ̀gbá lórílẹ̀-èdè Nàìjííríà (NFF), ní ọjọ́ àìkú (Sunday) fi ìdánilójú rẹ̀ hàn pé ikọ̀ Golden Eaglets yóò na ikọ̀ Burkina Faso ní ọ̀la.
Ìdíje ìpegedé Àjọ tí ó mójútó bọ́ọ̀lù àfẹsẹ̀gbá ní ìhà ìwọ̀ oòrùn ilẹ̀ Adúláwọ̀ (WAFU) ti àwọn ọ̀dọ́ tí ọjọ́ orí wọn ò ju mẹ́tàdínlógún ìpín B yóò bẹ̀ẹ̀rẹ̀ ní orílẹ̀-èdè Niger Republic lọ́jọ́ ajé (Monday)
Sanusi sọ pé ikọ̀ tí Manu Garba kó ṣòdí yìí dáńtọ́, wọ́n sì ṣetán àtibi ikọ̀ yóòwù tí ó jẹ́ alátakò wọn ní ìhà ìwọ̀ oòrùn ilẹ̀ Adúláwọ̀ wó.
Ó ní àwọn ti ṣetán láti dá ògo eré bọ́ọ̀lù ikọ̀ àwọn ọ̀dọ́ orílẹ̀-èdè Nàìjííríà tí ọjọ́ orí wọn ò ju mẹ́tàdínlógún padà lágbàáyé.
“A nílò láti kún fún àdúrà, ní ti ọgbọ́n àwọn ọmọ wa ní ọgbọ́n lórí ṣùgbọ́n a nílò ìdásí Ọlọ́run,” èyí ni òsìṣẹ́ ìjọba àpapọ̀ yìí wí.
Ikọ̀ àwọn ọ̀dọ́ tí ọjọ́ orí wọn ò ju mẹ́tàdínlógún ti orílẹ̀-èdè Nàìjííríà yóò kojú ikọ̀ méjì látàrí yíyọ ikọ̀ Benin Republic dànù.
Mẹ́wàá nínú ogún àwọn agbábọ́ọ̀lù ikọ̀ Benin Republic ni wọn kò pegedé pẹ̀lú ìdánwò àyẹ̀wò inú ara (MRI), èyí tí wọ́n fi yọ ikọ̀ náà dànù bí ẹni yọ jìgá.
Ní báyìí ikọ̀ Cote d’ Voire àti ikọ̀ Burkina Faso nìkan ni yó ku ikọ̀ Nàìjííríà kù nínú ìpín wọn.
Ikọ̀ Golden Eaglets bákan náà yóò máa wàákò lọ́jọ́ Ajé (Monday) láago mẹ́rin ọ̀sán aago abẹ́lé pẹ̀lú ikọ̀ Burkina Faso.
Ìdíje ìpegedé (WAFU) yìí jẹ́ ìpegedé fún ife ẹ̀yẹ ilẹ̀ Adúláwọ̀ (AFCON) àwọn ọ̀dọ́ tí ọjọ́ orí wọn ò ju mẹ́tàdínlógún tí yóò wáyé ní orílẹ̀-èdè Tanzania èyí tí ó tún jẹ́ òsùwọ̀n ìpegedé sí ìdíje ife ẹ̀yẹ àgbááyé àwọn ọ̀dọ́ tí ọjọ́ orí wọn ò ju mẹ́tàdínlógún èyí tí yóò wáyé ní orílẹ̀-èdè Peru lọ́dún 2019.
--- Ikọ̀ Nàìjííríà gbéra lọ sí Idíje Ajẹmáyòtẹníísì àgbááyé.
Ikọ̀ tí ó sojú Nàìjííríà níbi Idíjẹ Ajẹmáyòtẹníísì kúrò ní Èkó lọ sí ibi ìdíje Ajẹmáyòtẹníísì àgbááyé ní ìlú Beijing.
Ikọ̀ yìí tí ó ní obìnrin kan àti ọkùnrin mẹ́ta gbéra kúrò lórílẹ̀-èdè pẹ̀lú ọkọ̀ òfurufú Ethiopian
Obìnrin kan ṣoṣo yìí ni Faith Obazuaye, nígbà tí àwọn ọkùnrin akẹẹgbẹ́ rẹ̀ jẹ́ Nasiru Bello, Tajudeen Agunbiade àti Olufemi Alabi.
Ìdíje yìí yóò bẹ̀ẹ̀rẹ̀ ní ọjọ́ kẹtàdínlọ́gbọ̀n oṣù kẹjọ yóò sì parí ní ọjọ́ kẹta oṣù kẹsàn-án.
Bankole, nígbà tí ó ń sọ̀rọ̀ kí wọ́n tó gbéra, so pé àwọn aláyò yìí ti múra gidigidi fún iṣẹ́ tí ó wà níwájú wọn.
“A nígbàgbọ́ nínú wọn àti ohun tí wọ́n lè ṣe, mo sì ní ìgbàgbọ́ pé wọn yóò mú orílẹ̀-èdè wa yangàn. Kí àwọn pẹ̀lú fi ara balẹ̀ gbá gbogbo ayò náà pẹ̀lú àfojúsùn.
Bankole, tí ó jẹ́ Kọmíṣánnà Ọlọ́pàá, bákan náà pàrọwà sí àwọn ọmọ orílẹ̀-èdè Nàìjííríà tí wọ́n ń gbé ní orílẹ̀-èdè China láti wá wú àwọn olùfọkànsìn wọ̀nyí lórí.
--- Mà á ríi pé mo dúró pé nínú ikọ̀ City – Kompany
Balógun ikọ̀ Manchester City Vincent Kompany sọ pé àbùdá àdámọ́ òun láti máa ṣe dáadáa le mú kí òun ó fa ọjọ́ òun gùn nínú ikọ̀ aṣaájú ìdíje Premier League ilẹ̀ Gẹ̀ẹ́sì náà.
Ọmọ ọdún méjìlélọ́gbọ̀n adiẹ̀yìnmú ikọ̀ agbábọ́ọ̀lù Belgium yìí ti gbìyànjú lọ́pọ̀ láti jàjà bọ́ lọ́wọ́ oríṣìíríṣìí ìfarapa láti nǹkan bí ọdún mẹ́wàá tí ó ti wà nínú ikọ̀ náà..
“Mo wòye pé ohun tí àwọn ènìyàn ò tíì fi taratara mọ̀ nípa mi ni pé yàtọ̀ sí níní àwọn ìfarapa, mó rí oore-ọ̀fẹ́ jíjẹ́ alábùdá àdámọ́ eré sísá gbà.
“Nítorí náà, eré ṣì ṣì wà lẹ́sẹ̀ mi,” Kompany, tí àdéhùn rẹ̀ yóò tẹnu bẹpo ní sáà tó ń bọ̀ ló sọ fún ìkànnì àyélujára ikọ̀ agbábọ́ọ̀lù náà.
Kompany jẹ́ gbígbé wọlé nínú ìjáwé olúborí àmì ayò méjì sí òdo pẹ̀lú ikọ̀ Arsenal nínú ìdíje àkọ́kọ́ wọn, ṣùgbọ́n ó bẹ̀ẹ̀rẹ̀ pẹ̀lú ikọ̀ tí ó fìyà jẹ ikọ̀ Huddersfield Town pẹ̀lú àmì ayò mẹ́fà sí ọ̀kan ní òpin ọ̀sẹ̀ tó kọjá.
--- Ayò Hockey: Ìdíje Líìgì ọdún 2018 yóò bẹ̀ẹ̀rẹ̀ lọ́ àbámẹ́ta (Saturday)
Fatai Atanda, ọmọ ẹgbẹ́ ìgbìmọ̀ ìmọ̀ ẹ̀rọ àjọ tó ń mójú tó ìdíje Hocky lórílẹ̀-èdè Nàìjííríà (NHF), sọ ní ọjọ́bọ (Thursday) pé Líìgì ayò Hockey ti ọdún 2018 yóò bẹ̀ẹ̀rẹ̀ ní ọjọ́ àbámẹ́ta (Saturday) ní pápá ìṣeré ìjọba àpapọ̀, Abuja.
Atanda sọ pé ìpín mẹ́rin ni wọn yóò pín ìdíje náà sí, ó sì sọ pé ikọ̀ mẹ́rìndínlógún ikọ̀ ọkùnrin mẹ́jọ àti obìnrin mẹ́jọ ni yóò kópa.
Lọ́dún tó kọjá, Kada Queens ìlú Kaduna ni ó gbé ife ti àwọn obìnrin lọ ilé nígbà tí Niger Flickers gba ti àwọn ọkùnrin.
Ìdíje yìí wà ní ìbámu pẹ̀lú àlàkalẹ̀ àjọ yìí láti tẹ ayò hockey síwájú lórílẹ̀-èdè Nàìjííríà, pàápàá jùlọ láàrin àwọn ọ̀dọ́ láti lè ṣe àlékún iṣẹ́ ọwọ́.
--- Ikọ̀ Falconets lè lu ikọ̀ Spain – Garba Manu
Akọ́nimọ̀ọ́gbá ikọ̀ Golden Eaglet Manu Garba sọ pé ó dá òun lójú pé Ikọ̀ Falconets ní agbára àti lu akẹẹgbẹ́ wọn láti orílẹ̀-èdè Spain nínú ìfigagbága ìpele kejì sí àṣekágbá ife ẹ̀yẹ àgbááyé àwọn ọ̀dọ́bìnrin tí ọjọ́ orí wọn kò ju ogún ọdún lọ ní ìlú France.
Garba, tí ó fi àrídájú yìí hàn ní ìlú Abuja, sọ pé ikọ̀ Falconets ti ṣe iṣẹ́, wọ́n sì ti pinnu láti lè jẹ́ kí ògo ife ẹ̀yẹ àgbááyé yìí jẹ́ tiwọn.
“Ikọ̀ Falconets ti ṣiṣẹ́ takuntakun láti múra sílẹ̀ fún ìdíje àṣekágbá ife ẹ̀yẹ àgbááyé àwọn ọ̀dọ́bìnrin tí ọjọ́ orí wọn kò ju ogún ọdún lọ.
“ìpele kejì sí àṣekágbá jẹ̀ ìpele tí a ti ń jára ẹni bọ́, ó sì ṣeéṣe láti na ikọ̀ Spain tí àwọn ọmọbìnrin wa bá le mú àlékú bá ìṣọwọ́wọlé lọ́wọ́ iwájú wọn, ni Garba wí.
Akọ́nimọ̀ọ́gbá yìí fi àtìlẹyìn orílẹ̀-èdè yìí dá ikọ̀ Falconets lójú, ó sọ pé àwọn ọmọ Nàìjííríà wà lẹ́yìn wọn.
Ó sọ pé ikọ̀ yìí pẹ̀lú ìrànlọ́wọ́ Ọlọ́run àti iṣẹ́ takuntakun yóò pegedé sí ipele tí ó kángun sí àṣekágbá.
Ikọ̀ Falconets lọ́jọ́ ajé (Monday) ta ọmì àmì ayò kọ̀ọ̀kan pẹ̀lú ikọ̀ orílẹ̀-èdè China láti pegedé sí ìpele kejì sí àṣekágbá.
--- Ìpè fún ìṣonígbọ̀wọ́ ti jẹ́ fífi síta fún àwọn eré ìdárayá lórílẹ̀-èdè Nàìjííríà.
Àwọn ilé iṣẹ́ àti àwọn ènìyàn tí wọ́n lágbára láti náwó lé orí eré-ìdárayá ní orílẹ̀-èdè Nàìjííríà ti jẹ́ rírọ̀ fún ìṣonígbọ̀wọ́.
Ọ̀gbẹ́ni Bukola Olapade, ọ̀kan nínú àwọn ọmọ ìgbìmọ̀ tí ó ń rí sí àwọn ìdíje orí pápá ní ilẹ̀ Adúláwọ̀, èyí tí wọ́n ń pè ní African Athelethics Championship ti ọdún 2018 tí ó wáyé ní ilú Asaba, ìpínlẹ̀ Delta state ni ó sọ èyí lásìkò tí ó ń bá àwọn oníròyìn sọrọ̀ ní ìlú Asaba, Ọ̀gbẹ́ni Olapade ní báyìí wá lo iṣẹ́ rere ilé-iṣẹ́ Rite foods limited gẹ́gẹ́ bí àpẹẹrẹ lórí bí wọ́n ṣe pèsè ohun jíjẹ àti ohun mímu fún àwọn olùdíje.
Nígbà tí a fi ìṣonígbọ̀wọ́ lọ̀ wọ́n, lẹ́sẹ̀kẹsẹ̀ ni wọ́n fi ìfẹ́ hàn sí i, wọ́n sì kópa délẹ̀ nínú ìṣonígbọ̀wọ́ ìdíje orí pápá náà.
Ọ̀gbẹ́ni Olapade tún ṣàlàyé síwájú sí i pé níbi ìdíje náà ọ̀pọ̀ àwọn ènìyàn tí wọ́n wà níbi ayẹyẹ ìṣíde ní wọ́n pèsè ohun jíjẹ àti ohun mímu láti ọ̀dọ̀ Rites foods fún, bẹ́ẹ̀ ni wọ́n pèsè ẹlẹ́rìndòdò àti ìpanu fún àwọn ọmọ kéékèèké níbi ìdíje náà.
Olùbẹ̀wọ̀ àgbà fún ilé-iṣẹ́ Rite Foods Ltd, Ọ̀gbẹ́ni Saleem Adegunwa fi ìdí rẹ̀ múlẹ̀ pé ilé-iṣẹ́ náà ń gbìyàjú gbogbo ipá rẹ̀ láti ṣàtìlẹyìn ohun tí yóò gbé ògo Nàìjííríà jáde.
‘A nígbàgbọ́ pé àwọn ènìyàn wa lè dá àwọn àrà ọ̀tọ̀ pẹ̀lú ẹ̀bùn wọn, àtìlẹ́yìn wa oríṣiríṣi, ìṣonígbọ̀wọ́, ìṣàtìlẹyìn pẹ̀lú ìlù, àti àwọn ohun mìíràn.
Ó sọ ọ́ di mímọ̀.
Ọ̀gbẹ́ni Adegunwa sọ pé ilé-iṣẹ́ Rite foods ti ná nǹkan bí ọgbọ̀n mílíọ́nù náírà (N30 million) lórí ohun jíjẹ àti ohun mímu tí wọ́n pèsè fún àwọn aláyò wọ̀nyí ẹ̀yí tí ó sọ pé àwọn ṣe gẹ́gẹ́ bí àtìlẹyìn fún eré ìdárayá ní orílẹ̀-èdè Nàìjííríà àti ilẹ̀ Adúláwọ̀ lápapọ̀.
Olùbẹ̀wọ̀ àgbà fún ilé-iṣẹ́ yìí fi dá wa lójú pé, lóòótọ́ ni ìdíje yìí ń wá sí òpin ní ọjụ́ àìkú (Sunday), ṣùgbọ́n ilé-iṣẹ́ Rite foods yóò tẹ̀síwájú akitiyan rẹ̀ láti máa ṣàtìlẹyìn ìdíje náà. Ó sọ pé ìdí pàtàkì àtìlẹyìn ilé-iṣẹ́ Rite Foods fún ìdíje yìí ni ìlú Àsaba lọ́dún 2018 ni láti pèsè ohun jíjẹ fún àwọn ajáwé olúborí.
Ó sọ pé àwọn ohun jíjẹ yìí yóò sọ okun wọn dọ̀tun bí wọ́n tún ṣe ń díje sí i.
--- E ṣé o – Ta Lou relishes ìjáwé olúborí Asaba, ó dú pé lọ́wọ́ àwọn alátilẹyìn
Látàrí ìjáwé olúborí rẹ̀ nínú ìdíje ọlọ́gọ́rùn mítà ní àṣekágbá ìdíje àwọn Àgbà Asáré orí pápá ilẹ̀ Adúláwọ̀ ọdún 2018 ní ìlú Asaba, Gbajúgbajà ẹlẹ́ṣẹ̀ ehoro ọmọ ilẹ̀ Ivory coast Ta Lou Marie Josée‏ ti fi ẹ̀mí ìmoore rẹ̀ hàn fún àtilẹ́yìn ńlá láti ọ̀dọ̀ àwọn olólùfẹ́ eré ìdárayá lórílẹ̀-èdè.
Marie Josee Ta Lou lọ́jọ́bọ (Thursday) gba àmì ẹyẹ wúrà ìdíje náà pẹ̀lú eré ìṣẹ́jú àáyá mọ́kànlá-lé-ìṣẹ́jú-iná-mẹ́ẹ̀ẹ́dógún 11.15 tí ó fi na Janet Amponsah ọmọ orílẹ̀-èdè Ghana tí ó sá tirẹ̀ ní ìṣẹ́jú àáyá méjìlá-dín- ìṣẹ́jú-iná-mẹ́fa 11.54 seconds; nígbà tí ọ̀dọ́mọdebìnrin ọmọ Nàìjííríà Udo Joy-Gabriel pári tirẹ̀ pẹ̀lú ìṣẹ́jú àáyá méjìlá-dín- ìṣẹ́jú-iná-méjì
Pẹ̀lú bí ó se ti gba àmì ẹ̀yẹ ìdíje ọlọ́gọ́rùn mítà sápò rẹ̀, Ta Lou yóò gbìyàjú láti mú ìgbèrú bá ìkópa ipò rẹ̀ lágbàáyé nípa kíkópa dáradára nínú ìdíje IAAF tí yóò wáyé láìpẹ́ yìí.
--- Àkàndá ẹ̀dá oníjó gba àwọn ọmọ orílẹ̀-èdè Kenya níyànjú.
Àjọ Elétò Ilera Àgbááyé ti sọ pé ó lé ní ọ̀kànlélọ́gọ́rin mílíọ̀nù àwọn ọmọ ilẹ̀ Adúláwọ̀ tí ó jẹ́ Àkàndá, bẹ́ẹ̀ni ọ̀pọ̀ nínú wọn sì ń fojú winá ìrẹ̀wẹ̀sì ọkàn àti ìkórìíra, léyìí tí ó ń ṣe àkóbá fún àǹfààní wọn láti kópa nínú ètò ẹ̀kọ́, iṣẹ́ àti ìgbáyégbádùn.
Fún ènìyàn láti jó lójú ofurufú jẹ́ ọ̀kan lára àwọn ijó tí ó wọ́pọ̀ láàárín àwọn àkàndá lórílẹ̀-ède Kenya.
Nicholas Ouma Odhiambo sọ pé ikọ̀ yìí fún òhun ní oore-ọ̀fẹ́ láti lè kópa nínú ìdíje ijó jíjó náà
--- Ìdí tí mo fi gba iṣẹ́ ikọ̀ Juventus – Ronaldo
Atamátàsé ikọ̀ orílẹ̀-èdè Portugal Christiano Ronaldo sọ pé òun dara pọ̀ mọ́ ògbóhùntarìgì ikọ̀ orílẹ̀-èdè Italy torí pé òun fẹ́ ràn ikọ̀ 'old lady' ọ̀hún lọ́wọ́ láti túbọ̀ máa gba ife ẹ̀yẹ sí i pàápàá jùlọ ìfẹ́ ẹ̀yẹ UEFA Champions League.
Nígbà tí ó ń bá àwọn oníròyìn sọ̀rọ̀ lẹ́yìn ìgbà tí a ṣí aṣọ lójú rẹ̀, Ronaldo sọ pé òun fẹ́ ní ipa nínú ìdíje Serie A.
"Mo fẹ́ràn ìfigagbága, mo sì mọ̀ pé èyí yóò le.
Ìdúrókíni tí mo gbà ní Allianz níbi jọ mí lójú."
Ronaldo ṣèlérí láti fi òpin sí ọ̀dá ife European tí ó bá ikọ̀ Juventus.
Ronaldo dara pọ̀ mọ́ ikọ̀ Juventus láti ikọ̀ Real Madrid pẹ̀lú àdéhùn owó tí ó lé ọgọ́rùn-ún owó pounds.
Láàárín ọdún mẹ́sàn-án Ronaldo gba ife ẹ̀yẹ UEFA Champions league mẹ́rin àti ife La Liga méjì.
--- VON gba àmì ẹyẹ ìdíje Teníìsì orí tábìlì Obìnrin tí NUJ gbé kalẹ̀.
Kissit Golit ti Voice of Nigeria tí gbé igbá orókè nínú ìdíje Teníìsì orí tábìlì Obìnrin tí NUJ gbé kalẹ̀ ẹlẹ́ẹ̀kkejì irú rẹ.
Ìdíje ọlọ́dọọdún yìí tí ó tí wọ ẹ̀ẹ̀kejì irú rẹ̀ jẹ́ gbígbá ní ọjọ́ àbámẹ́ta (Saturday), Ọjọ́ kẹrìnlá, Oṣù keje ọdún 2018 ní gbongan ilé àṣà ilẹ̀ China ní ìlú Abuja.
Ilé àṣà ilẹ̀ China ń ṣe àṣepọ̀ pẹ̀lú Ẹgbẹ́ àwọn Òníròyin Nàìjíríà (NUJ) ẹ̀ka ti olú ìlú ilẹ̀ Nàìjíríà.
Tokumbo Adesanya ni ó gbaàmì ẹyẹ ìdíje Teníìsì orí tábìlì Ọkùnrin tí NUJ gbé kalẹ̀, ẹlẹ́ẹ̀kejì ti ẹ̀ka sí ẹ̀ka. Òun ló ṣojú àjọ oníròyìn ilẹ̀ Nàìjíríà láti na aṣojú ilé-iṣẹ́ ọ̀rọ̀ ìròyìn tí àmì ẹyẹ yìí wà lọ́wọ́ rẹ̀, Onosanya, Sangotola Tobi yìí wà lára àwọn mẹ́ta tí wọ́n ṣojú Voice of Nigeria ṣùgbọ́n kò bóde pàdé pẹ̀lú bí wọ́n ṣe yọwọ́ kílàńkó rẹ̀ ní ìpele kejì sí àsekágbá.
Lára àwọn tí ó tún ṣojú Voices of Nigeria ni Comfort Babatunde tí wọ́n já kúrò ní ìpele àkọ́kọ́.
--- Ìròhìn gbangba: Ronaldo dara pọ̀ mọ́ ikọ̀ Juventus pẹ̀lú àdéhùn àrùnlélọ́gọ́rùn-ún mílíọ́nu owó pounds.
Atamátàsé ọmọ orílẹ̀-èdè portugal Cristiano Ronaldo ti kúrò ní inú ikọ̀ Real Madrid bọ́ sí inú akínkanjú ikọ̀ orílẹ̀-èdè Italy Juventus ti ìlú Turin pẹ̀lú àrùnlélọ́gọ́rùn-ún mílíọ́nu owó pounds.
Ní nínú ọ̀rọ̀ kan tí a fi léde lọ́jọ́ ìṣẹ́gun (Tuesday), Real Madrid sọ pé àwọn ta Ronaldo sí inú ikọ̀ Juventus ní ìbámu pẹ̀lú ìfẹ́ ọmọ ẹ̀tàlélọ́gbọ̀n ọdún ọ̀hún.
“Real Madrid fẹ́ fi ẹ̀mí ìmoore wọn hàn sí agbábọ́ọ̀lù tí ó ti fi ara rẹ̀ hàn gẹ́gẹ́ bí agbábọ́òlù tí ó dára jùlọ lágbàáyé tí ó sì ti nípa lórí àwọn àsìkò tí ó dára fún wa jùlọ nínú ìtàn bọ́ọ̀lù àfẹsẹ̀gbá lágbàáyé.
“Yàtọ̀ sí àwọn àmì ẹyẹ yìí, àwọn ife ẹ̀yẹ tí ó gbà àti àwọn ìjáwé olúborí rẹ̀ lórí pápá láàrin ọdún mẹ́sàn-án yìí, Cristiano Ronaldo ti jẹ́ àpẹẹrẹ ìfarajìn, ìṣojúṣe, ẹ̀bùn àti ìlọsíwájú.” nínú ọ̀rọ̀ náà.
Ronaldo kúro ní olú ìlú orílẹ̀-èdè Spaini yìí lẹ́yìn tí ó ti di ẹni tí ó rí àwọn he jùlọ nínú ìtàn ikọ̀ Real Madrid pẹ̀lù àmì ayò ọ̀tàlénírinwódínmẹ́sàn-án nínú ifẹ̀sẹ̀wọnsẹ̀ òjìlénírinwódín-méjì.
Ní àpapọ̀ ó gba ife ẹ̀yẹ mẹ́rìndínlógún nínú wọn ni ife European mẹ́rin, méta jẹ́ léra wọn nígbà tí ìkẹrin jẹ́ sáà márùn-ún sẹ́yìn.
--- Mahrez tọwọ́ bọ ìwé àdéhùn ọdún márùn-ún pẹ̀lú ikọ̀ Man City
Agbábọ́ọ̀lù ọmọ orílẹ̀-èdè Algeria Riyad Mahrez parí ìtọkọ́sọ́ rẹ̀ lọsí ikọ̀ aṣáájú ìdíje Premier League, Manchester City lọ́jọ́ ìṣẹ́gun (Tuesday), lẹ́yìn oṣù méje tí ó ti sọ̀rètí nù làtàrí pé ikọ̀ City kọ̀ láti san owó tí ikọ̀ Leicester ń bèèrè fún.
Ní àsìkò yìí, ikọ̀ Leicester so pẹ́ àwọn tà á ní iye owó tí ó wọn inú ìwé ìtàn ikọ̀ náà, tí àwọn ìròyìn kan sì ń ní I lérò pé ikọ̀ aṣáájú yìí san ọgọ́ta mílíọ́nù owó pounds (Ọgọ́rin mílíọ́nù dín díẹ̀ Owó dọ́là) léyìí tí yóò sọ ọ́ di èyí tí ó ń wọ inú ìwé ìtàn.
Ọmọ ọdún mẹ́tàdínlọ́gbọ̀n yìí tí ó jẹ́ èèkàn nígbà tí ikọ̀ Leicester gba ife Premier League lọ́nà ìyanu lọ́dún 2016 tọwọ́ bọ adéhùn ọdún márùn-ún.
“Inú mi dùn láti dara pọ̀ mọ́ ikọ̀ City, ikọ̀ tí ó ń gbá bọ́ọ̀lù tó ta sánsán lábẹ́ Pep Guardiola.
Wíwò wọ́n lókèèrè jẹ́ oun tí ó máa ń wù mí..
Pep jẹ́ ẹni tí ó fi ara sí títi bọ́ọ̀lù síwájú, léyìí tí ó ṣe régí pẹ̀lú mi, bẹ́ẹ̀ sì ni ìṣọwọ́ṣiṣẹ́ Cítì ní sáà tó lọ kò lẹ́gbẹ́” èyí ni Mahrez wí.
---Spain yan Luis Enrique gẹ́gẹ bí akọ́nimọ̀ọ́gbá tuntun.
Àjọ tó ń mójú tó bọ́ọ̀lù àfẹsẹ̀gbá lórílẹ̀-èdè Spain ti sọ pé akọ́nimọ̀ọ́gbá ikọ̀ Barcelona tẹ̀lẹ̀rí Luis Enrique ti di yíyàn gẹ́gẹ́ láti gba àkóso ikọ̀ orílẹ̀-èdè náà.
Ó rọ́pọ̀ Julen Lopetegui, tí wọ́n yọ níṣẹ́ ní ife ẹyẹ àgbááyé ku ọ̀la lẹ́yìn tí ó gba iṣẹ́ nínú ikọ̀ Real Madrid, nígbà tí Fernando Hierro ti ń tukọ̀ àwọn ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ ní Russia fún igbà díẹ̀.
Luis Enrique tọwọ́ bọ àdéhùn ọdún méjì.
--- Ife ẹ̀yẹ àgbááyé di ṣíṣàfihàn ní Moscow
Àjọ tó ń ṣàfihan nǹkan ìṣèmbayé eré ìdárayá FIFA yóò pàtẹ ìfe ẹ̀yẹ olùjáwé olúborí ọdún 2018 fún odidi ọjọ́ àìkú (Sunday) ní ìlú Moscow.
Yóò jẹ́ ṣíṣàfihàn pẹ̀lú ife ẹ̀yẹ irú rẹ̀, ife Jules Rimet, tí wọ́n kọ́kọ́ fún ẹni tí ó gba ìdìje náà lọ́dún 1930 nígbà tí ìdíje náà bẹ̀ẹ̀rẹ̀.
Ìṣàfihàn yìí tí a mọ̀ sí, “Àwọn Akọ̀tàn”, yóò wáyé ní yàrá àwòrán ilé-iṣẹ́ Hyundai Motorstudio ní agbègbè New ní ìlú Moscow.
Ìṣàfihàn yóò parí lẹ́yìn ọjọ́ karùn-ún ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ àsekágbá ife ẹ̀yẹ àgbááyé ọdún 2018 lórílẹ̀-èdè Russia lọ́jọ́ kẹẹ̀ẹ́dógún oṣù keje.
Àjọ tó ń mójú tó bọ́ọ̀lù àfẹsẹ̀gbá lágbàáyé, FIFA, sọ nínú ọ̀rọ̀ kan lọ́jọ́ àbámẹ́ta (Saturday) pé ọ̀fẹ́ ni ìwọlé sí ibi Ìṣàfihàn yìí, ó fi kún un pé wọ́n gba àwọn oníróyìn láàyè láti wọlé, láti ya àwòrán àti láti ká àwòrán sílẹ̀ níbẹ̀.
“Ibi ìṣàfihàn yìí jẹ́ ìmọrírì ìfẹ́ àti ìkọbiarasí àwọn alátìlẹyìn káàkiri àgbááyé àti ipa wọn lórí ríra iyì fún ife ẹ̀yẹ FIFA àgbááyé.
“Níbẹ̀, àwọn olùbẹ̀wò le rí àtẹ̀jíṣẹ́ láti ọ̀dọ̀ àwọn alátìlẹyìn àwọn orílẹ̀-èdè méjìlélọ́gbọ̀n tí wọn ń figa gbága àti àfihàn àwọn bọ́ọ̀lù tí wọn lò fún ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ mẹ́rìnlélọ́gọ́ta ife ẹ̀yẹ FIFA àgbááyé ọdùn 2018 lórílẹ̀-èdè Russia tí ilé iṣẹ́ adidas pèsè.
“Lẹ́yìn ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ kọ̀ọ̀kan, bọ́ọ̀lù tí ó bá bẹ̀ẹ̀rẹ̀ ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ náà yóò di fífikún ara àwọn àfihàn yìí”,’’ ní ọ̀rọ̀ tí Moritz Ansorge alákòóso Àjọ tó ń ṣàfihan nǹkan ìṣèmbayé eré ìdárayá FIFA ṣe lálàyé.
--- Tite gba àdéhùn ọdún mẹ́rin mìíràn.
Àjọ tó ń mójú tó bọ́ọ̀lù àfẹsẹ̀gbá lórílẹ̀-èdè Brazil (CBF) ń fi àdéhùn ọdún mẹ́rin mìíràn lọ akọ́nimọ̀ọ́gbá àgbà ikọ̀ náà Tite tòhun tẹnu ìjakúrò nínú ife ẹ̀yẹ agbááyé lẹ́ẹ̀marùn-ún ọ̀tọ̀ọ̀tọ̀ láti ìpele kejì sí àṣekágbá.
Gẹ́gẹ́ bí Globo ìtàkùn ilẹ̀ Brazil ṣe sọ, Ìṣọwọ́ṣiṣẹ́ akọ́nimọ̀ọ́gbá àgbà yìí tẹ́ Àjọ CBF lọ́rùn, wọ́n sì ń fi àdéhùn mìíràn lọ̀ ọ́.
Ẹni ọdún mẹ́tàdínlọ́gọ́ta gba àkóso ikọ̀ Brazil ní inú oṣù kẹfà ọdún 2016, ó si ran ikọ̀ náà lọ́wọ́ láti pegedé sí inú ife ẹ̀yẹ àgbááyé FIFA ọdún 2018 pẹ̀lú ipò kíní láti inú àwọn orílẹ̀-èdè ilẹ̀ Guusu America.
Lábẹ́ àkóso Tite, ikọ̀ Brazil ti jáwé olúborí ní ìgbà ogún, wọ́n ta ọ̀mì mẹ́rin wọ́n sì pàdánù lẹ́ẹ̀mejì péré, nínú rẹ̀ ni ìpàdánù ọjọ́ ẹtì (Friday) pẹ̀lú ikọ̀ Belgium.
[Ìròyìn tó tẹ̀wá lọ́wọ́] Luz Mely Reyes tí ìṣẹ̀lẹ̀ náà ṣe ojúu rẹ̀, fi tó wa létí nípa bí àwọn Agbófinró SEBIN ṣe yẹ ilée Díaz pẹ̀lú ilée Soto náà wò.
Ìsọ̀kan àwọn Oníròyìn náà fẹ ọ̀rọ̀ náà lójú:
NÍ KÍÁKÍÁ Ní dédé àsìkò yìí, ní dédé agogo 3:00 òwúrọ̀ kùtùkùtù, ìgbìmọ̀ láti àjọ Amúninípá dé ilé oníròyìn àti ajà-fún- ẹ̀tọ́ọ ọmọ ènìyàn Luis Carlos Díaz, tí ó ti di ẹni àwátì láti agogo 5:30 ìrọ̀lẹ́ #NiboNiLuisCarlosWa.
Àwọn ajàfúnẹ̀tọ́ ọmọnìyàn àti àjọ òmìnira ọ̀rọ̀ sísọ náà darapọ̀ mọ ìpolongo yìí pẹ̀lú #DondeEstaLuisCarlos (Níbo ni Luis Carlos wà?), tí ó jẹ́ pé, ní báyìí, ni àkọlé tí ó gbajúmọ̀ ní orí ìkànnì ayélujára Twitter ti Orílẹ̀ Èdè Venezuela.
Díaz jẹ́ ajábọ̀ ìròyìn àti a-jà-fún-ẹ̀tọ́-ọmọ ènìyàn tí ó jẹ́ ògbólógbòó ajàfúnẹ̀tọ́ òmìnira ọ̀rọ̀ sísọ tí wọ́n sì mọ ìṣe rẹ̀ fún un l'órílẹ̀ èdè Venezuela àti òkè òkun fún ìdásọ́rọ̀ àti ìtakò ìjọba Nicholas Maduro.
Ó ti tó ìgbà díẹ̀ kan tí ó ti ń ṣiṣẹ́ pẹ̀lú ìyàwó rẹ̀ àti olùdásọ́rọ̀ òṣèlú tí ó gbajúmọ̀ n nì, Naky Soto, tí wọn sì ń ṣe ìgbéjáde àwọn fídíò àti ètò Ìgbóhùnsáfẹ́fẹ́ lórí ayélujára èyí tí ó dá lórí ìṣèlú àti ẹ̀tọ́ ọmọ ènìyàn ní Venezuela.
Ó ti ṣiṣẹ́ gẹ́gẹ́ bí akọ́ni àti olùgbé-lárúgẹ ìdásílẹ̀ àyè ọ̀tọ̀ fún àwọn ará ìlú àti àwọn àkànṣe eto ìgbóhùn sáfẹ́fẹ́ tí kò lọ́wọ́ ìjọ̀ba nínú.
Díaz tún jẹ́ olùkópa nínú ẹgbẹ́ Ohùn Àgbáyé fún ọdún mẹ́wàá.
Lọ́dọ̀ tèmi, Luis Carlos jẹ́ onílàákàyè ẹ̀dá kan, ó gbọ́njú nínú ìròyìn gbígbà àti ìkànsì-ara-ẹni nínú Venezuela ti wa yìí tí kò fara rọ.
Ó ti ṣe àwárí ìjápọ̀ nínú ìlú (láti ìtakò sí ibi ìṣẹ̀ṣe) #NiboniLuisCarlosWa.
Láàrin ọjọ́ péréte tó ṣíwájú ìpòóráa rẹ̀, ètò ìkàn-sára- ẹni ti ìjọba Con el Mazo Dando ṣàfihàn fídíò tí Díaz sọ̀rọ̀ nínúu rẹ̀.
Atọ́kùn ètò ọ̀hún, olóṣèlú Diosdado Cabello, rò kàn pé Díaz lọ́wọ́ sí ìfẹ̀hónú hàn àìsí ináa mọ̀nàmọ̀nà tí ò lọ jákèjádò orílẹ̀ èdè èyí tí ó mú kí àwọn ọmọ Venezuela máa gbé nínú òkùnkùn fún ó lé ní wákàtí mẹ́rin lé lógún lọ́jọ́ 7 àti 8 Oṣù Ẹrẹ́nà
Kò sí ẹ̀rí tí ó fi ẹsẹ̀ rinlẹ̀.
Wákàtí méje ti ré kọjá lọ tí Luis Carlos Díaz ti di àwátì.
[Díaz] jẹ́ oníròyìn fún ilé iṣẹ́ ìgbóhùnsáfẹ́fẹ́ Unión Radio Noticias , ó sì tún jẹ́ ajàfúnẹ̀tọ́ ọmọnìyàn.
Àwa ní olú ilé iṣẹ́ẹ SEBIN headquarters àti pé wọ́n ní àwọn kò ní í [ní àhámọ́ àwọn] #NiboNiLuisCarlosWa.
[Ìròyìn tí ó tẹ̀ wá lọ́wọ́: they wọ́n pàpà jẹ́wọ́ wípé [Diaz wà ní akolóo wọn]
Akọ̀ròyìn Vladimir Villegas sọ wípé kò rí bẹ́ẹ̀ mọ́ wípé ìjọba ni ó fi ọwọ́ agbára mú u:
radionet Luis Carlos Díaz, ti wà nínú àtìmọ́lé agbófinró Ìlú.
A bá a kẹ́dùn ipò tí ó wà.
A béèrè fún ìtọ́sọ́nà nípa mímọ ibi tí ó wà, àti ìbọ̀wọ̀ fún ẹ̀tọ́ ọmọnìyàn-an rẹ̀.
Ẹgbẹ́ Ohùn Àgbáyé dúró ṣinṣin pẹ̀lú Luis Carlos, ẹbíi rẹ̀, àti oníròyìn aládàáṣiṣẹ́ gbogbo àwọn tí ó ń mú ìjọba ṣe bí ó ti yẹ ní Venezuela.
À ń retíi rẹ̀ kí ó dé kíákíá ní àlàáfíà ara àti ẹ̀mí, a ó máa gbé àwọn ìròyìn síta nípa ìròyìn yìí bí ó ba ṣe ń tẹ̀ wá lọ́wọ́.
Ìwé àbádòfin ìlò ẹ̀rọ alátagbà yóò pa òmìnira ọ̀rọ̀ sísọ lórí ayélujára ní Nàìjíríà
Ìwé àbádòfin náà yóò fi àṣẹ fún ìṣánpa ẹ̀rọ ayélujára ní Nàìjíríàj
Aṣojú Mohammed Sani Musa ni agbátẹrùu ìwé àbádòfin ìlò ẹ̀rọ alátagbà. Àwòrán àgékù láti ibùdó Channel Television You Tube .
"Lọ́jọ́ 20 oṣù Belu, Ìwé Àbádòfin tí ó fi Ààbò fún Irọ́ àti Màkàrúrù tí ó rọ̀ mọ́ ọn ti ọdún-un 2019, tí a mọ̀ sí ""ìwé àbádòfin ìlò ẹ̀rọ alátagbà"", tí Aṣojú kan tí orúkọ rẹ̀ ń jẹ́ Mohammed Sani Musa ṣe agbátẹrùu rẹ̀, ti di kíkà nínú ìgbìmọ̀ fún ìgbà kejì."
Èròńgbà ìwé àbádòfin ìlò ẹ̀rọ alátagbà náà ni láti dẹ́kun àwọn àhesọ àti gbólóhùn tí kì í ṣe òtítọ́ lórí ẹ̀rọ ayélukára bí ajere.
Bí-ó-ti-lẹ̀-jẹ́-wípé, kì í ṣe láti fi òfin de ìlò ẹ̀rọ alátagbà ni ìwé àbádòfin náà dá lé lórí, àmọ́ ṣá, ó máa pa òmìnira ọ̀rọ̀ sísọ lórí ayélujára, ìsọ alátakò ìjọba di ọ̀daràn àti fífi àtìpà ẹ̀rọ ayélujára fúngbà díẹ̀ sínú ìwé òfin.
Àtẹ̀pa bí erín bá tẹ koríko ni àwọn ọmọ Nàìjíríà tẹ irú ìwé àbádòfin báyìí pa ní ọdún-un 2016.
Ẹ̀ṣẹ̀ ni bí o bá gbó ìjọba lẹ́nu (tako ìjọba)
"Gẹ́gẹ́ bí Abala 1A ti ṣe ṣàlàyé, èròńgbà ìwé àbádòfin yìí ni láti ""[máà jẹ́] kí ìgbéjáde ọ̀rọ̀ tí kò ní òtítọ́ kan nínú tàbí èyí tí ẹ̀ríi rẹ̀ kò f'ẹsẹ̀ rinlẹ̀ tó ó jáde ní Nàìjíríà""."
"Yóò yọ ọwọ́ kílàńkó àwọn àtẹ̀jáde irọ́ tí ó lè kó orílẹ̀ èdèe Nàìjíríà sí ""ìyọnu"", láwo láì gbàgbée àwọn ọ̀ràn bíi ètò ìlera gbogboògbò, ààbòo gbogboògbò, ""ìbalẹ̀-ọkàn-an gbogboògbò tàbí ìṣúná owóo gbogboògbò"" àti ""àwọn ìbáṣepọ̀ orílẹ̀-èdèe Nàìjíríà pẹ̀lú àwọn orílẹ̀ èdè mìíràn""."
"Abala 1c sọ bí ìwé àbádòfin náà yóò ṣe ""mú, ṣàkóso àti fi ààbò bo ìlònílòkulò àwọn ìṣàmúlò àti ẹ̀rọ adánìkanṣiṣẹ́ orí ẹ̀rọ ayélujára""."
Ní àlàyé síwájú sí i, kò sí ohun tí ojú òfin tuntun náà kò leè tó bí ó bá ti jẹ́ lórí ayélujára — lábẹ́ àbùradà à ń gbógun ti àhesọ àti irọ́ pọ́nbẹ́lẹ́.
"Ọ̀run ń ya bọ̀ ni ìwé àbádòfin ìlò ẹ̀rọ alátagbà náà, kò yọ ẹnìkan sílẹ̀, gbogbo ọmọ orílẹ̀ èdèe Nàìjíríà ni yóò bá, kò kan agbègbè tàbí ibi tí ènìyàn fi ṣe ibùgbé, máà ṣe é l'oògùn máà mọ́, ọwọ́ àwọn ológìnní ojú tólé ojú tóko ni ""gbólóhùn irọ́ tí kò ní ẹ̀rí"" tí ó bá gba òpópónà ẹ̀rọ ayélukára bí ajere Nàìjíríà yóò bọ́ sí."
Abala 3a sí b(i) ti ìwé àbádòfin ìlò ẹ̀rọ alátagbà sọ wípé:
Ẹnikẹ́ni kò gbọdọ̀ wu ìwà kíwà kan nínú tàbí lẹ́yìn odi Nàìjíríà láti tari gbólóhùn tí kò ní òtítọ́ kan tí a kò leè fi ẹ̀ríi rẹ̀ múlẹ̀ síta; àti àgbésórí afẹ́fẹ́ ayélujára gbólóhùn t'ó lè kó orílẹ̀ èdèe Nàìjíríà síta bí ọmọ ọjọ́ mẹ́jọ nípa ti ààbò ìlú.
"Ọ̀ràn-an ti ""ààbò orílẹ̀-èdè"" ni orí Èṣù tí òfin náà dúró lé láti pa ẹ̀tọ́ sí òmìnira ọ̀rọ̀ sísọ mọ́."
Àmọ́ kò tán síbẹ̀, kò sí ẹní tó lè tako ìjọba Nàìjíríà tàbí gbó o lẹ́nu nítorí kì í ṣ'àṣìṣe.
Ní Abala 3b(vi), gbólóhùn tí ó bá yẹpẹrẹ “ojúṣe tàbí ìṣe, tí ó jẹ́ ti ìjọba lójú ará ìlú” kò leè la orí ayélujára kọjá.
"Gẹ́gẹ́ bí Abala 3b(v) ti ṣe fi hàn, èyí ní í ṣe pẹ̀lú gbólóhùn tí ó: ""fa ìmúnilọ́tàá, tí a sọ sí ẹnìkan tàbí ìtara láàárín àwọn ènìyàn""."
Èyí léwu nítorí ó fi àyè gba àwọn onípò àṣẹ láti lo agbára nílòkulò.
Ta ní í sọ bóyá gbólóhùn kan lè fa rògbòdìyàn?
Ìyẹn túmọ̀ sí wípé lílo inú kan tàbí mímú àwọn olóṣèlúu mú ìléríi wọn ṣe lè já sí ìkórìíra lójúu wọn.
Owó ìtanràn fún ẹni tí ilé ẹjọ́ bá dá lẹ́bi tó láàárín ẹgbẹ̀rún 200 àti ẹgbẹẹgbẹ̀rún 10 owó naira [tí ó tó $556 sí $28,000 owó orílẹ̀ èdèe United States], ìtìmọ́lé fún ọdún mẹ́ta tàbí méjèèjì.
Àṣẹ fún Àjọ Agbófinró láti ṣán ẹ̀rọ ayélujára pa fúngbà díẹ̀
"Ìwé àbádòfin ìlò ẹ̀rọ alátagbà náà fún ìjọba lágbára bí ó ṣe hù wọ́n láti ṣán ẹ̀rọ ayélukára bí ajere pa nígbàkúùgbà tí ó bá lérò wípé ó tọ́, nípasẹ̀ ""Àṣẹ Ìdígàgá Ìráyè"" láti lo ayélujára bí ó ti ṣe wà ní Abala 12, òǹkaye 3:"
Ẹ̀ka Agbófinró leè fi àṣẹ fún Àjọ Ìgbóhùnsáfẹ́fẹ́ Nàìjíríà NCC [Nigerian Communications Commission – tí ó ń ṣe bòńkárí ìtàkùrọ̀sọ orí ẹ̀rọ ayárabíàṣá] láti pa á láṣẹ fún apèsè àyè sí ìlò ẹ̀rọ ayélujára kí ó gbé ìgbésẹ̀ lójú ẹsẹ̀ tí ò ní mú àwọn òǹlò rí àyè lo ayélujára ní Nàìjíríà.
Àwọn apèsè ayélujára gbọdọ̀ tẹ̀lé òfin ìdígàgá yìí tàbí kí wọ́n ó sanwó ìtanràn tí ó tó ẹgbẹẹgbẹ̀rún 5 sí 10 owó naira [$14,000-28,000 USD].
"Ní àfikún, ìwé àbádòfin náà fi àrídájú ààbò bo àwọn apèsè iṣẹ́ ẹ̀rọ ayélujára tí kò ní mú wàhálà ""ará ìlú tàbí bẹ́ẹ̀ "" tí kò bá à lè jáde láti ìdájọ́ kan tí ẹnikẹ́ni kò bá pè wọ́n fúnopé ""wọ́n tẹ̀lé òfin ìdígàgá ìráyé"" sí ayélujára, ìyẹn bí abala 12, òǹkaye 5 ṣe fi lélẹ̀."
Ìtẹ́rí ẹ̀tọ́ ọmọnìyàn náà ṣ'ókùnkùn sí i nítorí wípé òfin náà gba àwọn ọlọ́pàá láyè lábẹ́ òfin láti pa àṣẹ ìdígàgá-àyè bí ó ti ṣe hù wọ́n.
"Abala 15a sọ wípé “iṣẹ́ ọpọlọ” ọlọ́pàá ní àsìkò ""ìṣèwádìí ẹ̀rí tó dájú"" jẹ́ kókó láti fagilé ìṣánpá ẹ̀rọ ayélujára ní orílẹ̀ èdè náà."
Ní ìparí, “kò sí àyè fún ẹjọ́ọ kò tèmi lọ́rùn ní Ilé-ẹjọ́ Gíga” [Abala 13(2)] tí eẹnikẹ́ni lè fi yẹ ìdígàgá sílẹ̀ láì máà kọ́kọ́ tọ ọlọ́pàá lọ láti fagilé òfin ìdígàgá náà.
Ipa èyí hàn gbàgàdà — ẹnikẹ́ni kò ní leè gba ilé ẹjọ́ lọ fún ìgbèjà ìfẹ̀tọ́ ẹni dunni yìí tí ìdígàgá náà ṣì wà.
Àwọn aṣojú-ṣòfin tí ó wà lẹ́yìn ìwé àbádòfin ẹ̀rọ alátagbà náà
Àwọn aṣojú-ṣòfin mẹ́ta kan ni ó gbé ìwé àbádòfin náà sórí nínú ìgbìmọ̀, ilé ìgbìmọ̀ àgbà: Mohammed Sani Musa (agbátẹrùu ìwé àbádòfin), Abba Moro àti Elisha Abbo.
Ilé-iṣẹ́ẹ Mohammed Sani Musa, Activate Technologies Limited, ni ó kó ẹ̀rọ Ìwé-pélébé Ìdìbò Alálòpẹ́ (PVCs) tí a lò fún ìbò ọdún-un 2019, nígbà tí ó jẹ́ òǹdíjedupò lábẹ́ ẹgbẹ́ olóṣèlúu tí ó ń tukọ̀ ètò ìṣèlú lọ́wọ́ All Progressives Congress (APC) fún Aṣojú Ìlà-Oòrùn Niger, ìyẹn gẹ́gẹ́ bí ilé iṣẹ́ aṣèwádìí, Premium Times ṣe tẹ̀ ẹ́ jáde.
Àjọ Elétò (INEC) gba ẹ̀sùn náà mọ́ra.
Ọ̀ràn yìí fi hàn pé àwọn alákòóso ìbò tí ó kọjá kò ṣiṣẹ́ láì lọ́wọ́ àwọn alágbára ń'nú.
Ishaku Elisha Abbo ti ẹgbẹ́ alátakò People’s Democratic Party (PDP) jẹ́ aṣojú tí ó ń ṣojú Ẹkùn-un Àríwá Adamawa ní Ìpínlẹ̀ Adamawa, ní ìlà-oòrùn àríwá orílẹ̀ èdèe Nàìjíríà.
Nínú oṣù Agẹmọ 2019, ní ìṣojú ọlọ́pàá, Abbo ṣe àṣemáṣe pẹ̀lú òṣìṣẹ́bìnrin kan nínú ìsọ̀ ohun ìbálòpọ̀ ní olú-ìlú Nàìjíríà ní Abuja.
Lẹ́yìn tí àwòrán càṣemáṣe náà fọ́n ká sórí ẹ̀rọ alátagbà, Abbo offered mọ ìwàa rẹ̀ lẹ́bí, ó sì bẹ̀bẹ̀.
Abba Moro, tí í ṣe ọmọ ẹgbẹ́ẹ PDP, ni aṣojú fún ẹ̀ka Gúúsù Benue, àárín gbùngbùn àríwá Nàìjíríà.
Ní ọjọ́ 15, oṣù Ẹrẹ́nà, ọdún-un 2014, Moro, tí í ṣe ọ̀gá pátápátá ètò abélé, ló wà nídìí ìṣẹ̀lẹ̀ abanilọ́kànjẹ́ Ìgbanisíṣẹ́ Ẹ̀ṣọ̀ aṣọ́bodè Nàìjíríà tí àwọn ọ̀dọ́langba tí ó tó bíi ẹgbẹẹgbẹ̀rún 6 tó fẹ́ àyè iṣẹ́ ẹgbẹ̀rún 4 tí ó ṣí sílẹ̀ nínú iléeṣẹ́ Ẹ̀ṣọ̀ Aṣọ́bodè Nàìjíríà tí wọ́n kóra jọ níbi orísìírísìí jákèjádò orílẹ̀ èdè náà.
Ìṣẹ̀lẹ̀ tí ó burúkú jáì náà tí ó ṣekú pa ogún ènìyàn àti ìpalára fún ọ̀pọ̀ èèyàn.
Moro gbà nínú of owó ìwáṣẹ̀ tí àwọn awáṣẹ́ san tí ó ń lọ bíi ẹgbẹẹgbẹ̀rún 675 owóo naira [ $1.8 USD].
Moro kó owó sápòo rẹ̀ bẹ́ẹ̀ náà ó fo òfin ìgbanǹkan Aṣọ́bodè dá.
Kò nílò ìdákẹ́ jẹ́jẹ́, ìbẹ̀rù bojo tàbí ìkáàánú-araẹni – #SayNoToSocialMediaBill!
Nípa lílo àmì #SayNoToSocialMediaBill, àwọn ọmọ orí ayélujára orílẹ̀ èdèe Nàìjíríà bọ́ sóríi Twitter láti sọ èrò ọkàn-an wọn:
"Nínú gbólóhùn kan, Amnesty International fajúro sí lílo ""àwọn òfin tí ó ń fìdìí ìfojú ẹ̀tọ́ ọmọnìyàn gbolẹ̀ múlẹ̀ "" nítorí pé kò ní pa àwọn ọmọ Nàìjíríà lẹ́nu mọ́ ""láti máà sọ èrò ọkàn-an wọn"" tí yóò sì tún ""rán wọn lọ s'ẹ́wọ̀n fún wípé wọ́n ṣe bẹ́ẹ̀ ""."
Lábẹ́ àbùradà à ń dẹ́kun gbólóhùn irọ́ àti ọ̀rọ̀ àhesọ, ń gbèrò ìṣòfin tí kò ní ìfẹ́ ará ìlú lọ́kàn.
Ó jẹ́ ohun ìyàlẹ́nu, àwọn olóṣèlúu ló léwájú níbi ká gbé gbólóhùn irọ́ sórí ayélujára.
Ẹgbẹ́ olóṣèlúu tí ó ń jẹ lọ́wọ́ àti ẹgbẹ́ alátakò gbòógì sọ Twitter di pápá ogun fa ọ̀rọ̀ ìkórìíra ẹlẹ́yàmẹ́lẹ́yá, ìròyìn tí kò pójú òṣùwọ̀n àti ọ̀rọ̀ ẹ̀tàn lásìkò ìdìbò ààrẹ ọdún-un 2019.
Kà síwájú sí i:
Ẹ̀rọ alátagbà fa ọ̀rọ̀ ìkórìíra ẹlẹ́yàmẹ́lẹ́yá, ìròyìn tí kò pójú òṣùwọ̀n àti ọ̀rọ̀ ẹ̀tàn lásìkò ìdìbò ààrẹ ọdún-un 2019
Twitter di pápá ogun fún gbólóhùn irọ́ lásìkò ìdìbò orílẹ̀-èdèe Nàìjíríà ọdún-un 2019
Ní àkókò bíi ti òmìnira ọ̀rọ̀ sísọ ní Nàìjíríà tí a wà yìí, ọ̀rọ̀ ọlọ́pọlọ láti ẹnu òǹkọ̀wé orílẹ̀-èdèe Amẹ́ríkà Toni Morrison tí ó mú ìrétí dání:
‎Èyí ni ìgbà tí àwọn ayàwòrán ń ṣiṣẹ́. Kò sáyé fún ìsọ̀rètínù, kò sáyé fún ìkáàánú-ara, kò nílò ìdákẹ́ jẹ́jẹ́, kò sí àyè fún ìbẹ̀rù bojo.
A sọ, a kọ, a p'èdè.
Ìwé àbádòfin ìlò ẹ̀rọ alátagbà náà ti jẹ́ kíkà ní ìgbà kejì nínú ìgbìmọ̀ Aṣojú-ṣòfin.
Kí ó tó di òfin, ó gbọdọ̀ gba ìgbìmọ̀ kan tí àwọn aṣojú-ṣòfin yóò yẹ̀ ẹ́ wò. Ìgbìmọ̀ọtẹ̀ẹ́kótó náà yóò sì jábọ̀ àbájáde àyẹ̀wòo rẹ̀ fún Ìgbìmọ̀ àgbà, láti gbé e yẹ̀ wò, tí wọn yóò tẹ òmíràn jáde fún àyẹ̀wò tí ó kẹ́yìn, kí ààrẹ ó tó bu ọwọ́ lù ú.
A gbọdọ̀ fajú ro sí ìgbésẹ̀ Ìgbìmọ̀ kí wọ́n ba ju ìwé àbádòfin ìlò ẹ̀rọ alátagbà náà dànù sígbó.
Nítorí orílẹ̀ èdèe tí ó gbajúmọ̀ jù lọ nílẹ̀ Adúláwọ̀ yóò yẹ̀ gẹ̀rẹ̀ sí ìjọba ìfipámúnisìn ní kété tí òmìnira ọ̀rọ̀ sísọ bá di títẹ̀ bọlẹ̀.
Ilé ẹjọ́ gíga Tanzania pa á láṣẹ fún ìfòpinsí ìsoyìgì láàárín àgbàlagbà àti ọmọdé láì wo ti ìgbésẹ̀ ìmúpadàa rẹ̀
Èyí ni ìpinnu tí ó dára jù lọ tí ilé-ẹjọ́ yóò ṣe
Àwọn Ọmọiléèwé ọmọdébìnrin ní Tanzania dúró fún àwòrán lọ́jọ́ 10 oṣù Agẹmọ ọdún-un, 2007. Fanny Schertzer ni ó ya àwòrán, a lò ó pẹ̀lú àṣẹ láti Wikimedia Commons, CC BY 2.0.
Nínú oṣù Ọ̀wàrà 2019, ilé ẹjọ́ gíga Tanzania ṣe ìdímú ṣinṣin ìdájọ́ ọdún-un 2016 tí ó pàṣẹ ó kéré jù, ọmọbìnrin àti ọmọkùnrin gbọdọ̀ pé ọmọ ọdún méjìdínlógún kí ó tó ṣe ìgbéyàwó.
Àjọ ọba orílẹ̀ èdèe Tanzania gbéègbésẹ̀ láti ṣe ìmúpadà ìpinnu yìí, nítorí wípé àwọn ọmọdébìnrin ń yára bàlágà àti wípé ààbò ni ìgbéyàwó jẹ́ fún ọ̀dọ́bìnrin aláboyún.
Àmọ́ ní ọjọ́ 23 oṣù Ọ̀wàrà ọdún-un 2019, ìjọba orílẹ̀ èdèe Tanzania pàdánù ẹjọ́ọ kòtẹ́milọ́rùnun rẹ̀ tí àṣẹ ilé ẹjọ́ gíga ṣì dúró: akọ àtabo gbọdọ̀ pé ọjọ́ orí méjìdínlógún kí wọn ó tó ṣe ìgbéyàwó, tí èyí sì ń fi agbára kún ìgbẹ́sẹ̀ ìsoyìgì ọmọdé ní Tanzania.
Gẹ́gẹ́ bí United Nations Population Fund (UNFPA) ti ṣe wí, Tanzania ni ìsoyìgì ọmọdé pọ̀ sí jù lọ lágbàáyé.
Àwọn ọmọ orí ayélujára ṣíra láti fi ìdùnnúu wọn hàn lóríi ìdájọ́ náà.
Àwọn kan kí Rebeca Z. Gyumi, aláfisùn àti ẹni tí ó lé wájú nínú ọ̀ràn ìsoyìgì àwọn ọmọdé náà.
Gyumi ni olùdásílẹ̀ àti alákòóso àgbà Msichana Initiative (Ètò fún àwọn Ọ̀dọ́mọbìnrin), iléeṣẹ́ tí kì í ṣe tìjọba tí ó ń ró àwọn ọmọdébìnrin lágbára nípasẹ̀ ti ẹ̀kọ́ ìwé.
Ìgbésẹ̀ láti fòpin sí ìsoyìgì ọmọdé ní Tanzania
Lọ́dún-un 2016, Gyumi na ọwọ́ ìka àbùkù sí agbára Òfin Ìgbéyàwó; Law of Marriage Act, 2002 (LMA) tí ó gba obìnrin tí kò tó ọmọ ọdún méjìdínlógún láyè láti ṣe ìgbéyàwó.
Gẹ́gẹ́ bí ìwádìí nípa ìlera Tanzania Demographic and Health Survey (TDHS) ṣe ti ṣàlàyé, ìdá 36 obìnrin tí ọjọ́ oríi wọ́n wà ní 25-49 ní í ṣe ìgbéyàwó kí wọn ó tó pé ọmọ ọdún méjìdínlógún, tí àwọn akẹgbẹ́ẹ wọn lọ́kùnrin sí jẹ́ ìdá 5.
Òfin LMA fi àyè gba ọmọdébìnrin tí ọjọ́ oríi wọn kò ju ọdún mẹ́rìnlá lọ láti ṣe ìgbéyàwó pẹ̀lú ìlọ́wọ́sí ilé-ẹjọ́, ìlọ́wọ́sí òbí fún ọmọ ọdún márùn-ún-dínlógún, nígbà tí ọdún méjìdínlógún jẹ́ ọjọ́ orí tí ó kéré jù lọ fún ọmọkùnrin.
Nípasẹ̀ àwọn aṣojú rẹ̀, Gyumi ṣàlàyé wípé àlàálẹ̀ LMA kọ iyán obìnrin kéré nítorí pé ó fún àwọn ọkùnrin ní àǹfààní ju àwọn obìnrin lọ.
Nítẹ̀síwájú, wọ́n sọ wípé àlàálẹ̀ náà fi ẹ̀tọ́ dídọ́gba ọmọ ènìyàn yí ẹrẹ̀fọ̀ àti pé wọn fi ẹ̀tọ́ àǹfààní sí ẹ̀kọ́ ìwé dun àwọn ọmọdébìnrin.
Gyumi rọ Ilé-ẹjọ́ Gíga láti gbé àlàálẹ̀ LMA tì sẹ́gbẹ̀ẹ́.
Ilé-ẹjọ́ Gíga kò ṣe bẹ́ẹ̀.
Àmọ́ wọ́n rí i lóòótọ́ wípé kò bá òfin mu wọ́n sì fún ìjọba lọ́dún kan láti ṣe àtúnṣe sí ohun tí kò tọ̀nà nínú àlàálẹ̀ LMA.
Nípasẹ̀ aṣojú àgbà àwọn adájọ́, a pa ìjọba láṣẹ láti gbé ọjọ́ orí ìgbéyàwó sí ọdún méjìdínlógún fún obìnrin àti ọkùnrin.
Síbẹ̀, aṣojú àgbà àná banújẹ́ sí ìdájọ́ náà ó sì kọ ìwé àtúnpè-ẹjọ́ sí Ilé-ẹjọ́ Gíga náà:
Pẹ̀lú ìfọwọ́sí àṣẹ ìjọba: mo ti gba ìwé àtúnpè-ẹjọ́ lóríi ẹjọ́ #childmarriage. Ẹjọ́ òǹkaye 204 ti oṣù Ọ̀wẹwẹ̀ ọdún-un 2017.
Kà síwájú sí i: Mozambique sọ ìsoyìgì ọmọdé di ìwà ọ̀daràn
Àyè fún àtúnpè-ẹjọ́
Láàárín oṣù mẹ́rin ìgbẹ́jọ́, ìjọba gbèrò láti ṣe àtúnpè-ẹjọ́ ọdún-un 2016 tí yó ṣe àtúnṣe sí àlàálẹ̀ LMA èyí tí ó fi àyè gba ọmọdébìnrin ọlọ́jọ́-orí márùn-úndínlógún gẹ́gẹ́ bí ẹni tí ó ti bàlágà fún ìgbéyàwó.
Atẹ́jọ́pè, tí ó jẹ́ aṣojú àwọn adájọ́ ìpínlẹ̀, Mark Mulwambo àti Alesia Mbuya, ṣe àgbékalẹ̀ ìyàtọ̀ ìwà ẹ̀dá obìnrin àti ọkùnrin tí wọ́n sì fi àṣà ìbílẹ̀ àti òfin ẹ̀sìn Ìmàle gbá àtúnpè-ẹjọ́ náà nídìí.
"Ms. Mbuya sọ wípé ìyàtọ̀ ìwà ẹ̀dá fi ọmọdékùnrin àti ọmọdébìnrin sí ""ìsọ̀rí ọ̀tọ̀ọ̀tọ̀ "" àti pé, òfin fi ojú ọ̀tọ̀ọ̀tọ̀ wò wọ́n."
Ó sọ síwájú sí i wípé nítorí àwọn ọmọdébìnrin máa ń tètè bàlágà ju ọmọdékùnrin lọ ni òfin fi la àlàálẹ̀ bẹ́ẹ̀. Ó sọ wípé ìgbéyàwó lè fi ààbò bo ọmọdébìnrin tí kò sí nílé ọkọ tí ó ti di abaraméjì láì tó ọjọ́ orí tí ó tọ́.
Ó sọ síwájú sí i wípé ilé ẹjọ́ kùnà bí ó ṣe “ṣe ìmúdọ́gbandọ́gba ọjọ́ orí ọmọ àti ọjọ́ orí tí ó yẹ fún ìgbéyàwó”, èyí tí ó túmọ̀ sí wípé ọ̀tọ̀ ni ti tọ́lú ọ̀tọ̀ ni ti tọ́lùú wò, ọ̀tọ̀ ni ó yẹ kí ilé ẹjọ́ ó là kalẹ̀ fún ọjọ́ orí ìgbéyàwó ọkùnrin àti obìnrin.
Àwọn ọmọ orí ayélujára ti yára bu ẹnu àtẹ́ lu ìdí tí àtẹ́jọ́pè fi sílẹ̀ nínú ìgbẹ́jọ́.
Kà síwájú sí i: Mozambique, Cote d'Ivoire gbé ìgbésẹ̀ akọni fún ẹ̀tọ́ àwọn obìnrin àti ọmọdé
Dídọ̀gba abo atakọ
Ìdájọ́ ilé ẹjọ́ náà jẹ́ atọ́ka sí ìfòpinsí àwọn àṣà tí ó ń mú ìpalára bá àwọn ọmọdébìnrin àti onírúurú ẹlẹ́yàmẹyà tòun ìfọwọ́rọ́sẹ́yìn àwọn ọmọdébìnrin ní Tanzania.
Ní ti àjọ United Nations, kí a tó lè yege níbi ti dídọ́gba abo atakọ ní ọdún-un 2030, ìjọba ní láti ṣe àyípadà òfin ìyàsọ́tọ̀ọtọ̀ àti ṣíṣe àmúlò ìṣòfin tí yóò mú ìmúdọ́gba tí à ń sọ wáyé.
Àbájáde ìwádìí ṣe àfihàn-an rẹ̀ wípé ọjọ́ orí tí ó tọ́ láti ṣe ìgbéyàwó bá ìpele ìwé tí ènìyàn kà àti ọrọ̀ tí ènìyán ti kó jọ (TDHS 201) tan.
Ní Tanzania, ó ní ìyàtọ̀ ọdún mẹ́fà tí ó wà láàárín ọmọdébìnrin tí kò lọ sí ilé ìwé àti àwọn tí ó ka ìwé gíga tàbí ìwé gíga jù lọ.
Ní Tanzania, ohun tí kò bá òfin mu ni kí a fẹ́ tàbí fún akẹ́kọ̀ọ́bìnrin lóyún, ẹ̀wọ̀n ọgbọ̀n ọdún ni ẹní bá tasẹ̀ àgẹ̀rẹ̀ sófin yóò fi gbára.
Akẹ́kọ̀ọ́bìnrin tí ó bá lóyún kì í padà sí ilé ìwé pàápàá tí ó bá bímọ tán.
Ìfòfinde ìsoyìgì pẹ̀lú ọmọdé máa ń fi ààbò fún àwọn ọmọdébìnrin, láì ro bí wọ́n ṣe wọ ilé ìwé.
Ní Tanzania, ìgbéyàwó ọmọdébìnrin kì í jẹ kí ọmọdébìnrin ó kàwé tí wọn kò sì ní àǹfààní láti parí ẹ̀kọ́ọ wọn, gẹ́gẹ́ bí èsì ìwádìí láti Tanzania National Survey, 2017 ṣe ní i lákọsílẹ̀.
Ìfòfinde ìsoyìgì yìí ṣe àgbékalẹ̀ ìgbé ayé tó dára fún akẹ́kọ̀ọ́bìnrin láti parí ẹ̀kọ́ọ wọn láì sí ìdádúró.
Pẹ̀lú bẹ́ẹ̀, akẹ́kọ̀ọ́bìnrin tí ó bá fẹ́rakù ṣì ń kojú òfin tí ó ní wọn kò gbọdọ̀ padà wá sílé ìwé.
Ààmì ìdánimọ̀ orílẹ̀ èdèe Jamaica tí Kanye West lò di awuyewuye tí ó dá fìrìgbagbòó lórí ‘ìsààmì’
Ẹrù ọjà pẹ̀lú àkórí nípa Jamaica di títà lórí ayélujára
Kanye West ń kọrin níbi ayẹyẹ ọlọ́dọọdún Ilé-ọnà ti Ọnà Ìgbàlódé ní Garden benefit, New York City, ọjọ́ 10, oṣù karùn-ún, 2011. Àwòrán láti ọwọ́ọ Jason Persse, CC BY-SA 2.0.
"Ọ̀kọrin tàkasúfèé tí ó jẹ́ ọmọ orílẹ̀ èdèe Amẹ́ríkà Kanye West gbé àríyá ""Ìsìn Ọjọ́ Ọ̀sẹ̀ "" pop-up concert wá sí Kingston, Jamaica, ní kété tí ìsinmi ọjọ́ ọ̀sẹ̀ fún Àyájọ́ Ọjọ́ Àwọn Málegbàgbé Ọmọ Orílẹ̀-èdè náà (19-21, oṣù Ọ̀wàrà ọdún-un 2019) yóò bẹ̀rẹ̀."
Èyí ni ìgbà àkọ́kọ́ tí ọ̀kọrin náà yóò kó ẹgbẹ́ akọrin ìyìnrere rẹ̀ kúrò ní Amẹ́ríkà, ní ìjẹ́pèe ti agbè fún ìjọba orílẹ̀ èdèe kan tí ó Ja kí ó gbé ètò náà wá sílùú òun.
Síbẹ̀, àríyá náà tí rí ìtakò láti ìbẹ̀rẹ̀ pẹ̀pẹ̀, tí ó Ho forí sọlẹ̀ pẹ̀lú àmì ìdánimọ̀ọ orílè-èdèe Jamaica tí West we lórí ọjà tí ó ń tà lóríi ibùdó ìtakùn àgbáyée rẹ̀ láì gba àṣẹ láti lò ó.
Láàárín ọjọ́ méjì ni ìkéde fi lọ síta, inúu gbàgede Emancipation Park tó wà ní Kingston, olú ìlú orílẹ̀ èdè náà ni bẹbẹ́ ti wáyé — ojú ibi tí ó mú àwọn sọ̀rọ̀sọ̀rọ̀ kan wí tẹnu wọn látàrí àwọn ọ̀rọ̀ tó mú àríyànjiyàn dání tí West sọ nípa òwò ẹrú nínú ìfọ̀rọ̀wánilẹ́nuwò kan báyìí lóṣù karùn-ún ọdún-un 2018.
"Ọdún-un 2002 ni gbàgede náà di lílò ní ìbọ̀wọ̀ fún ""òmìnira dójú àmì"" fún àwọn ẹrú 300,000 ní Jamaica lọ́jọ́ 1, oṣù kẹjọ ọdún-un 1838."
Ó lè jẹ́ èyí gan-an ni oun àkọ́kọ́ nípa àríyá orin náà, ṣùgbọ́n òun kọ́ ni ó gbẹ̀yìn.
"Pàápàá jù lọ bí Olóòtú Ètò Àṣà Olivia ""Babsy"" Grange ṣe bẹnu-àtẹ́ lu àwọn alátakò nígbà tí ó sọ wípé orílẹ̀ èdè náà ṣe àbápín nínú èrè àríyá náà, ní èyí tí aṣagbátẹrù orin kan lérò wípé àríyá náà tí ó ṣe é wò lójú ẹsẹ̀ bí ó ṣe ń lọ lóríi ìtakùn àgbáyée Ìsìn Ọjọ́ Ọ̀sẹ̀, ""gba"" àwọn ètò tí ó rọ̀ mọ́ àṣà ìbílẹ̀ tí ó jẹ́ ti Ìsinmi àwọn Málegbàgbé Ọmọ orílẹ̀ èdè sẹ́gbẹ̀ẹ́."
Láfikún, àwọn olùgbée Kingston, tí ó bá súnkẹrẹ fàkẹrẹ kòdìmú lọ́sẹ̀ yẹn, fọ àfọ̀tẹ́lẹ̀ làásìgbò àti rọ̀tìrọti bí àwọn tó ṣíwọ́ iṣẹ́ bá ń darí lọ sílé nírọ̀lẹ́.
Láì sí àní-àní, àríyá náà lọ ní ìrọwọ́-ìrọsẹ̀, ẹgbẹẹgbẹ̀rún lọ́nà ẹgbẹ̀rún àwọn Nev orílẹ̀-èdèe Jamaica gbádùn-un àríyá náà tí àwọn iléeṣẹ́ agbóhùnsáfẹ́fẹ́ orílẹ̀ èdèe Jamaica náà gba ìgbóríyìn fún iṣẹ́ takuntakun tí wọ́n ṣe:
Ìròyìn etíìgbọ́ ìgboro ni wípé ó ṣeé ṣe kí ìgbésẹ̀ wà láti (Ìsìn Ọjọ́-àìkú) láti gba àsẹ èmi-ni-monií/ẹ̀tọ́ oníhun ààmì ìdánimọ̀ọ Kingston, orílẹ̀ èdè Jamaica àti ti ẹyẹ olùlànà onírù gígùn.
Mo ti ṣe àwọn ìwádìí kan lórí ayélujára tí mo sì ṣe àwárí láti fi ti ẹ̀rí lẹ́yìn àmọ́ kádàrá kò ṣe mí lóore, mo ṣalábàápàdé ọjàa wọn tí wọ́n ń tà lórí ayélujára tó ní àwọn ààmi ìdánimọ̀ wọ̀nyí, tí ó sì ṣe dọ́gba-n-dọ́gba pẹ̀lú àríyá náà...
Òtítọ́ orílẹ̀ èdèe Jamaica ni wípé àwọn ìjọba àná kò fi ìgbàkan kọbiara sí ìgbéró èto ọrọ̀ Ajée ‘Jamaica’ tàbí àwọn ààmi ìdánimọ̀ tó jẹ́ ti wọn bíi àsíá àti àsíá apata.
Bákannáà ni ó rí fún orin wa àti ohun tí ó rọ̀ mọ́, Ska, Mento, Rock Steady, Reggae àti bẹ́ẹ̀ bẹ́ẹ̀ lọ.
Ilẹ̀ Jamaica kò tètè lajú sí òwò aṣọ ṣíṣe tí ó ní ààmì pàtàkì erékùṣù tí yóò mú àwọn ènìyàn rà á wìtìwìtì.
Bí a bá fi ètò àríyá ṣe ìgbélárugẹ àwọn ọjà wọ̀nyí nínúu gbàgede Emancipation Park tí ó mú ìlọsíwájú bá ohun tí ó ju aṣọ lọ láti ọ̀dọ̀ ìjọba àti àwọn ọmọ orílẹ̀ èdèe Jamaica náà, pẹ̀lú lílo àwọn ààmìi orílẹ̀ èdè náà ní ọ̀nà àrà.
Mo ti ṣe àkíyèsí wípé Iléeṣẹ́ Ètò Àṣà àti Olùdarí ìlúu Kingston ti ń gbé ìgbésẹ̀ẹ pàjáwìrì láti ra nǹkan padà. Kí àwọn méjèèjì mọ̀ pé àtúnṣe kì í ṣe nǹkan tó ma yá kíákíá.
Mo lérò wípé ìjọba ní àwọn agbẹjọ́rò tó ká ojú òṣùwọ̀n.
Lóòótọ́, àwọn agbẹjọ́rò ṣì níṣẹ́ láti ṣe láti tú kókó awuyewuye etí aṣọ ti lílo àsíá orílẹ̀ èdèe Jamaica.
Ìrọ́lù ọlọ́pàá tí í mú ikú bá ‘ni ní Guinea bí Ààrẹ Alpha Condé ṣe kọ̀ láì gbé’ jọba sílẹ̀
Ọ̀pọ̀lọpọ̀ ìlú ti kọ̀yìn síjọba lórí ìgbésẹ̀ yìí
Àgékù ohun tí ó ń ṣẹlẹ̀ ní Guinea láti ìròyìn ránpẹ́ France 24 kan.
Ìwà ipá bẹ́ sílẹ̀ ní Guinea lọ́jọ́ 14 oṣù Ọ̀wàrà, tí ó ti fa ikú ọ̀pọ̀lọpọ̀ ènìyàn tí wọ́n sì ń kó àwọn ènìyàn kiri lẹ́yìn ìyíde ìféhónúhàn tí ó tako ìjọba ààrẹ tí ó wà lórí oyè ìyẹn Alpha Condé, ẹni tí ó ń gbèrò láti yí ìwé-òfin padà kí ó bá fi ààyè gba òun láti lọ fún ìgbà kẹta.
Ojúu pópó olú ìlú náà, Conakry, àti àwọn ìlú tó kù ti di ojú ogun láàárín àjọ agbófinró àti àwọn ọmọ ìlú tó ń fi èhónú hàn.
Iléeṣẹ́ ọlọ́pàá ti lo àǹfààní tuntun tí ó fún wọn láṣẹ láti lo ohun ìjà aṣekúpani bí ó bá dé ojú ẹ̀.
Àwọn afẹ̀hónúhàn ti rán ẹni mẹ́fà sí ọ̀run àjànto, ní èyí tí ó jẹ́ pé ọlọ́pàá kan wà nínúu àwọn tí ó jẹ́ Ògún nípè, ọ̀pọ̀ èèyàn ló sì fi ara pa.
Kà síwájú sí i: Àwọn ẹ̀ṣọ́ aláàbò ní Guinea ti ní àṣẹ láti lo ohun ìjà aṣekúpani
Àwọn afẹ̀hónúhàn kò lọ́wọ́ sí kílàńkó àyípadà sí ìwé-òfin tí wọ́n rí gẹ́gẹ́ bí ìgbésẹ̀ ààrẹ láti wà lórí ipò fún ẹlẹ́ẹ̀kẹ́ta.
Ní tòótọ́, ìwé-òfin náà fi ààyè ọdún méjì gba ẹni tí ó bá wà ní ipò ààrẹ láti ṣèjọba. Condé, ẹni ọdún 81, yẹ kí sáà rẹ̀ ó parí ní oṣù Ọ̀wàrà ọdún-un 2020.
Àwọn afẹ̀hónúhàn ni a lè ṣá lọ́gbẹ́ jù lọ nítorí wípé wọ́n tasẹ̀ àgẹ̀rẹ̀ sí òfin náà bí Human Rights Watch ṣe pè fún àkíyèsí:
Ìtúmọ̀ Ìtúnwí-ọ̀rọ̀ Ọlọ́rọ̀ gan-an
Human Rights Watch sọ lónìí wípé, ìjọba orílẹ̀-èdèe Guinea ti gbẹ́sẹ̀ lé ìfèhònúhàn l'ójúu pópó fún ọdún kan, ó tọ́ka sí ìdojú-ìjà-kọ ààbò ìlú.
Àwọn aláṣẹ ìjọba ìbílẹ̀ ti fọ́n ó tó bíi ogún ìfèhònúhàn ẹgbẹ́ òṣèlú àti àwọn mìíràn ká yángá.
Àwọn ẹ̀ṣọ́ aláàbò ti sọ tajútajú sí àárín àwọn tí kò gbọ́ràn láti tú wọn ká, wọ́n sì kó àìmọye ènìyàn.
Ní ti ìṣẹ̀lẹ̀ òṣèlú náà, àjọ ọba náà ń kéde iṣẹ́-ìjẹ́ tí ó ń tako ara wọn: Ní ọjọ́ 13, oṣù Ọ̀wàrà Ààrẹ Condé fẹ́ ìsọ̀rọ̀-ní-tùnbí-ǹ-nùbí:
Ìtúmọ̀ Ìtúnwí-ọ̀rọ̀ Ọlọ́rọ̀ gan-an
Alpha Condé ti pè fún ìsọ̀rọ̀ ní tùnbíǹnùbí ó sì fẹ́ kí ìjókòó gẹ́gẹ́ bí tọmọtìyá tí yóò fi pẹ̀lẹ́pùtù yanjú gbọ́nmi-síi-omi-ò-tóo tí ó ń ṣẹlẹ̀ àti ọ̀nà àbáyọ sí àwọn ìpèníjà tí ó ń kojú orílẹ̀-èdè náà.
Síbẹ̀, Ahmed Tidiane Traoré, olùdámọ̀ràn ipò ààrẹ, sọ lọ́jọ́ tí ó tẹ̀lé e, ìyẹn ní ọjọ́ 12 oṣù Ọ̀wàrà, — ọjọ́ méjì kí ìfẹ̀hònúhàn ó tó bẹ̀rẹ̀, — fún àwọn èrò tó jẹ́ ọ̀dọ́ langba RPG ẹgbẹ́ olóṣèlúu [ruling Reunion of the People of Guinea]:
Ìtúmọ̀ Ìtúnwí-ọ̀rọ̀ Ọlọ́rọ̀ gan-an
A rọ àwọn ọ̀dọ́ ẹgbẹ́ òṣèlú náà láti kún fún ìṣọ́ra ní ojúu pópó.
Àwọn [tí àwọn jẹ́ ajìjàngbara alátakò] ti fa ìṣòro, a pe àwọn ìpẹ́ẹ̀rẹ́ láti inú ẹgbẹ́ náà láti wá ọ̀nà àbáyọ sí ìṣòro tó wà nílẹ̀, àmọ́ kí ẹ máà dojú ìjà kọ ẹnikẹ́ni, kí ẹ máà ba dúkìá kankan jẹ́, ju ìdáàbò bo ara yín lọ.
Gbogbo àwọn oníṣẹ́-ibi ni ó di àwárí tí a ó fi ojúu wọn hàn f'áráyé rí.
Ẹnu méjì àwọn tí ó ń tukọ̀ ìlú ti túbọ̀ mú inú bí ẹgbẹ́ alátakò àti àwọn àjàfẹ́tọ̀ọ́ ọmọnìyàn, ó ní bí ìtakùn globalguinee.info ṣe sọ:
Ìtúmọ̀ Ìtúnwí-ọ̀rọ̀ Ọlọ́rọ̀ gan-an
Ọjọ́ 14 oṣù Ọ̀wàrà ọdún-un 2019 jẹ́ ọjọ́ Ajé burúkú Èṣù gbomi mu, ní ti ìfèsì sí ìpè àjọ FNDC [Àwọn tí ó ń lé wájú ń'nú Ìdáàbò bo Ìwé-òfin Orílẹ̀-èdè], àwọn ọmọ Guinea tú yáyá tú yàyà sí ojúu títì láti tako ìgbésẹ̀ àtúnṣe sí ìwé-òfin.
Ìkọlù wáyé ní àwọn agbègbè tí ó wà ní àárín olú ìlú orílẹ̀-èdè náà.
Káràkátà dẹnu kọlẹ̀ ní àárín gbùngbùn ibi ìṣàkóso ìlú ní Kalou.
Àwọn tí ó wà ní Àárín àti Odò orílẹ̀ èdè Guinea náà gbọ́ ìpè, wọ́n sì darapọ̀ mọ́ àwọn ọmọ ìlú tó kù.
Ènìyàn díẹ̀ ni ó jáde ní ìgbèríko àti Òkèe Guinea.
Àmọ́ ṣá, ọ̀pọ̀lọpọ̀ ìlú ti kọ̀yìn síjọba lórí ìgbésẹ̀ yìí.
Ní oríi benbere.org, gbàgede ìtàkùrọ̀sọ fún àwọn ọ̀dọ́ ní Mali, akọ̀ròyin búlọ́ọ̀gù Adam Thiam kọ:
Ìtúmọ̀ Ìtúnwí-ọ̀rọ̀ Ọlọ́rọ̀ gan-an
Nǹkan kàyèéfì ń lọ lọ́wọ́ lọ́wọ́ báyìí ní Guinea, pẹ̀lú ìrógbàmù tí ó ń wáyé, ọta ìbon ti fọ́ sí ara àwọn afẹ̀hónúhàn tí ó sì ti ṣekú pa ọ̀pọ̀lọpọ̀ọ wọn, ẹ̀jẹ̀ ní ojúu pópó, ìdígàgá ní gbogbo, iná ẹsẹ̀ ọkọ̀ọ sísun àti tajútajú nínú afẹ́fẹ́.
Àwọn ọmọ ìlú orí ayélujára fajúro sí ìṣẹ̀lẹ̀ náà lórí ẹ̀rọ alátagbà:
Bíi ti Blaise Compaoré [olóṣèlúu Burkinabé] Alpha Condé ń forí lé ibi ìparun, ǹjẹ́ yó leè gbóhùn inúbíbí àwọn aráa rẹ̀ bí?
Ó di ọjọ́ iwájú kí á tó mọ̀. Ní báyìí ṣá, ọkọ̀ ojú omi ti ń ré.
Lọ́jọ́ 15 oṣù Ọ̀wàrà, akọ̀ròyin Guinea Bhiye Bary kọ:
Ilé ìtòògùn Hamdallaye (#Conakry): àwọn ọlọ́pàá ló jí àwọn ọmọ ìlú kan lójú oorun ní òwúrọ̀ yìí.
Gẹ́gẹ́ bí ẹnìkan ti ṣe sọ, àwọn ọlọ́pàá ń jálẹ̀kùn tí wọ́n sì ń kó ẹrù nílé onílé.
S. Nkola Matamba, òǹkọ̀wé àti ajàfẹ́tọ̀ọ́ ọmọnìyan tí ó jẹ́ ọmọ Ìlú Olómìnira Ìjọba ara wa ti Congo, fi ìbánújẹ́ ọkàn hàn:
Ọmọ ẹgbẹ́ alátakò ìgbàkan, tí ó wá fẹ́ yí òfin padà nítorí ìfẹ́ ara rẹ̀ kí ó ba ṣèjòba fún ìgbà kẹta, bóyá kí ó bá jẹ gàba títí tí Ọlọ́jọ́ yóò fi dé, Alpha Condé gan-an ni àpẹẹrẹ ibi tí ó ń fa ìfàsẹ́yìn fún Ilẹ̀-Adúláwọ̀ !
Ẹ̀yin aráa Guinea, ẹ mú ọkàn le!
#GUINÉE – ó jẹ́ ohun ìyàlẹ́nu. Ìfẹ̀hònúhàn ìtako ìṣèjọba Condé fún ìgbà kẹta ọjọ́ kan ṣoṣo tí mú ẹ̀mí àwọn ènìyàn lọ.
Sísíwín àwọn olóṣèlú tí ó fẹ́ kú sórí ipò ààrẹ yìí ti ń pọ̀ jù Amoulanfe— Cheikh Fall™ (@cypher007) ọjọ́ 14, oṣù Ọ̀wàrà 2019
Ajìjàǹgbara Guinea Macky Darsalam sọ ti ìgbésẹ̀ láti tọwọ́ bọ èròńgbà àwọn ará ìlú lójú:
Ẹgbẹ́ alátakò Guinea náà kò ní ààbò tí ó lè fi bo araa rẹ̀ lásìkò ìkọlù: àwọn aṣojú aláṣẹ ẹgbẹ́ alátakò gbogbo kò dá sí àríyànjiyàn ìgbìmọ̀ ìjọba mọ́ láti ọjọ́ 11, oṣù Ọ̀wàrà 2019.
Ìwà ipá sí àwọn ẹgbẹ́ olóṣèlú wọ̀nyí ti gba ọ̀nà àrà, bẹ́ẹ̀ ni ibùdó ìtakùn mediaguinee.org ṣe kọ:
Ìtúmọ̀ Ìtúnwí-ọ̀rọ̀ Ọlọ́rọ̀ gan-an
...ní olú iléeṣẹ́ Union of Republican Forces (URF) tí agbègbè Sidya Touré, ìjá wáyé láàárín àwọn ọmọ ẹgbẹ́ alátakò kan àti àwọn tí ó ń fẹ́ ti ìjọba tí ó ti ṣètò tí kò ní jẹ́ kí ìyíde ìfẹ̀hónúhàn náà ó wáyé lọ́jọ́ kan sí ọjọ́ ìfẹ̀hónúhàn ní àwọn agbègbè tí wọ́n ti lẹ́nu.
Ìkọlù náà wá sí òpin lẹ́yìn-in ìkólọ iléeṣẹ́ URF náà tí àwọn ènìyàn mẹ́fà tí kò sí ẹni tó mọ orúkọ àti ẹgbẹ́ olóṣèlú tí wọ́n ń bá ṣe di èrò àtìmọ́lé.
#SexForGrades: Ètò Alálàyé-afẹ̀ríhàn tú àṣìírí ìwà ìyọlẹ́nu ìbálòpọ̀ ní àwọn Ifásitìi Ìwọ-oòrùn Ilẹ̀-Adúláwọ̀
Ìtìjú mú àwọn tí ìṣẹ̀lẹ̀ ṣẹlẹ̀ sí máà leè sọ
Boniface Igbeneghu, ọ̀jọ̀gbọ́n Ifásitìi Èkó, Nàìjíríà ti bá ẹni tí ó wọ ìbòjú yìí ṣe erée gélé ní àìmọye ìgbà (Àwòrán láti BBC #SexForGrades)
#SexForGrades, ètò alálàyé afẹ̀ríhàn-an BBC kan tí ó dá fìrìgbagbòó lóríi àṣemáṣe eré ìfẹ́ tí àwọn ọ̀jọ̀gbọ́n ifásitì pẹ̀lú àwọn akẹ́kọ̀ọ́bìrin ní Nàìjíríà àti Ghana ti ràn bíi pápá inú ọyẹ́ ní orí ayélujára tí ó sì ti fa àwọn ìbéèrè ọlọ́kanòjọ̀kan nípa ọ̀nà tí a leè gbà dẹ́kùn àṣemáṣe ọ̀hún láwùjọ:
Àgbà iṣẹ́ ìwádìí náà, tí ó di gbígbé jáde ní ọjọ́ kéje oṣù Ọ̀wàrà 2019, tí akọ̀ròyin Kiki Mordi tí kò parí ẹ̀kọ́ọ rẹ̀ látàríi wípé kò fẹ́ ṣe àṣemáṣe pẹ̀lú olùkọ́ní ifásitì rẹ̀ tí ó ń fi ìdíi rẹ̀ rẹmi nínú ìdánwò nítorí wípé kò fún un ṣe ṣe atọ́kùn-un rẹ̀:
Boniface Igbeneghu, Ifásitì Èkó, tí a ká ìwà àṣemáṣe pẹ̀lú àwọn akẹ́kọ̀ọ́bìrin nínú ìwádìí abẹ́lẹ̀ tí BBC ṣe.
Àwòrán láti BBC #SexForGrades.
Ìwádìí tí ó pé wákàtí kan tú àṣìírí ìwà àṣemáṣe ti “eré ìfẹ́ fún ojú-àmì ẹ̀kọ́” ní ifásitì Ìwọ̀-oòrùn Ilẹ̀ Adúláwọ̀ méjì: University of Lagos (UNILAG) ti Nàìjíríà àti University of Ghana.
Boniface Igbeneghu, tí í ṣe kòfẹ́sọ̀ ní ẹ̀ka iṣẹ́ ọnà ti UNILAG, tí ó sì tún jẹ́ àlùfáà Ìjọ Foursquare Gospel, ní Èkó, ń bẹ nínú àwọn olùkọ́ tí òkété bórù mọ́ lọ́wọ́.
A rí Igbeneghu nínúu ètòo BBC náà tí ó kọ ẹnu ìfẹ́ sí ọmọdébìnrin tí ó díbọ́n gẹ́gẹ́ bí ọmọ ọlọ́jọ́ orí mẹ́tàdínlógún tí ó ń wà ìgbanisílé ẹ̀kọ́ láì fura wípé ajábọ̀ ìròyìn tí ó ń ṣe iṣẹ́ ìwádìí abẹ́lẹ̀ fún BBC ni ó ń ṣe. Igbeneghu sọ báyìí wípé:
Ṣé o kò mọ̀ wípé ọmọbìnrin arẹwà ni ọ́ ?
Ǹjẹ́ o mọ̀ wípé àlùfáà ìjọ ẹlẹ́sìn ìgbàgbọ́ ni mo jẹ́, àti pé mo tó ẹni àádọ́ta ọdún ṣùgbọ́n bí mo bá fẹ́ ọmọ ọdún mẹ́tàdínlógún ọ̀rọ̀ dídùn àti owó ni ó máa jẹ...
Níbi ìpàdé kan láàárín àwọn méjèèjì, Igbeneghu ṣẹ́ iná pa, ó sì ní kí ọmọdébìnrin náà ó fẹ́nu ko òhun lẹ́nu, tí ó sì tún dì mọ́ ọn gbádígbádí nínúu iyàraa iṣẹ́ẹ rẹ̀ tí ó wà ní títì pa.
"Ìjọ Ajíhìnrere Foursquare ti dá Igbeneghu dúró ""lẹ́nu iṣẹ́ ìhìn rere""."
"Bákan náà, Ifásitì Èkó ti lé Igbeneghu kúrò ní ilé ìwé wọ́n sì ti sún ìpèré sí ẹ̀hìn ilẹ̀kùn ilé òṣìṣẹ́ tí wọ́n ń pè ní ""yàrá tútù"", tí àwọn ọ̀gá olùkọ́ni ti máa ń ṣe àríyá níbi tí wọ́n ti máa ń gba àwọn ọ̀ṣọ́rọ̀ ọmọge lálejò."
Àwọn ìṣẹ̀lẹ̀ ìbànújẹ́ ọdún sẹ́yìn
Àkàrà tí ó tú sépo yìí ti fi gọ̀ngọ̀ fa kòmóòkùn ọ̀rọ̀ jáde lẹ́nu ọ̀gọ̀rọ̀ ọmọ orílẹ̀-èdèe Nàìjíríà ní orí ayélujára pẹ̀lú àmìi #SexForGrades ní oríi Twitter.
Púpọ̀ nínú àwọn òǹlò tí ó jẹ́ abo ní oríi Twitter fi ẹ̀dùn ọkàn-an wọn hàn nípa ìríríi wọn lóríi ìwà erée gélé ti ìbálòpọ̀:
"Lọlá Ṣónẹ́yìn, alátinúdáa àjọ̀dún ìwé àti òǹkọ̀wé, ṣàlàyé ""ìtìjú ńlá"" tí òhún rí nígbà tí amúgbálẹ́gbẹ̀ẹ́ ọ̀gá pátápátá ifásitì kan (DVC) fọwọ́ kan ibi tí kò yẹ kí ó fọwọ́ kàn lára òun:"
Àwọn ọ̀jọ̀gbọ́n oníṣìná ilé ẹ̀kọ́ gíga Nàìjíríà ti ba ti àwọn obìnrin jẹ́.
Síbẹ̀síbẹ̀, nítorí ìtìjú àwọn tí ó fi ara pa kì í leè sọ̀rọ̀ síta èyí kò sì jẹ́ kí ó rọrùn láti dá sẹ̀ríà fún àwọn awùwà ìbàjẹ́.
"Ní ọdún-un 2016, Ìgbìmọ̀ Àṣòfin mú àbá ẹ̀wọ̀n ọdún márùn-ún wá fún olùkọ́ní tí ilé ẹjọ́ bá dá lẹ́bi àṣemáṣe pẹ̀lú akẹ́kọ̀ọ́ nínú ""Ìwé àbádòfin Ìfòpin sí ìwà ìbàjẹ́ ìbálòpọ̀ ní Ilé Ìwé Gíga""."
Síbẹ̀, Àjọ Olùkọ́ni Ifásitìi Nàìjíríà kọ ẹ̀yìn sí ìwé àbá yìí, wọ́n ní ó kọ iyán àwọn kéré, nítorí ó kọjú ìjà sí àwọn olùkọ́ àti wípé ó yẹpẹrẹ àṣẹ àti agbára ilé ẹ̀kọ́ gíga.
Ìsọtasí ìwé àbá náà pa òfin náà ní àpakú finínfinfín — èyí kò sì jẹ́ kí ààrẹ ó bu ọwọ́ lù ú.
Ṣé Eré ìfẹ́ fún ojú-àmì Ẹ̀kọ́ #SexForGrades ni ìjìjàngbara ilé ìjọsìn #ChurchToo tuntun?
Nínú oṣù kéje ọdún yìí, gbajúgbajà ayàwòrán-an nì, Bùsọ́lá Dakolo, fi ẹ̀sùn kan Bíọ́dún Fátóyìnbó, àlùfáà àgbà ìjọ Commonwealth of Zion Assembly (COZA), wípé ó fi ipá bá òun ní àjọṣepọ̀ nígbà tí òhún wà ní ọmọ ọdún mẹ́rindínlógún.
Kà síwájú sí i: Àlùfáà tàbí apanijẹ bí ẹ̀pa?
Ajíhìnrere Oníwàásù nínúu wàhálà ẹ̀sùn ìfipábánilòpọ̀
Fún ọdún mẹ́fà tí ó ré kọjá lọ, Fátóyìnbó aródẹ́dẹ́ ti rí ìfẹ̀sùnkàn ìfipábánilòpọ̀ ọ̀kan-ò-jọ̀kan.
Síbẹ̀, ìfọ̀rọ̀wánilẹ́nuwò tí Dakolo ti fẹ̀sùn kan Fátóyìnbó dá awuyewuye sílẹ̀ lórí ayélukára bí ajere.
Fún ọjọ́ díẹ̀, ilé ìjọsìn náà; #ChurchToo — tí í ṣe àpẹẹrẹ èmi náà ní àgbáyé #MeToo — gba ayélujára kan ní Nàìjíríà.
Ẹ̀sùn yìí fò fẹ̀rẹ̀ láti orí ayélujára sí ìfẹ̀hónúhàn lóríi òpópónà ní àwọn ìlú ńlá ní Nàìjíríà bíi Èkó àti Abuja.
Ìpèsí àkíyèsí ilé ìjọsìn náà #ChurchToo movement rọ ìjọba láti da “ọ̀ràn-an ìjìyà obìnrin àti ọmọdébìnrin dúrò.”
"Ilé ìjọsìn náà #ChurchToo ṣípayá ìdákẹ́ rọ́rọ́ àmọ́ ""ìbàjẹ́ àṣà ìfipábánilòpọ̀ tí ó ń gbèrú, pàápàá jù lọ ní agbo ìjọsìn"" ní Nàìjíríà."
Ó fún àwọn obìnrin ní àǹfààní láti wí ti ẹnu wọn.
Bíi ti #ChurchToo, ìké tantan eré ìfẹ́ fún ojú-àmì ẹ̀kọ́ #SexForGrades ti fẹ ìdí ìlòkulò agbára tí ó bí ìwà àṣemáṣe ti ìbánilájọ̀ṣepọ̀ tí àwọn obìnrin kò fi tọkàntọkàn fẹ́ síta gbangba.
Ǹjẹ́ àmì orí ayélujára yìí yóò ṣe amọ̀nàa ìgbèjà ẹ̀tọ́ tí kì í ṣe ti orí ayélujára tí yóò béèrè fún àtúnṣe tí yóò sọ ilé ẹ̀kọ́ gíga ifásitì di ibi ààbò fún àwọn obìnrin bí?
Ìgbà àti àkókò nìkan ni yóò sọ.
Ilé ẹ̀kọ́ ìmọ̀ orin kíkọ kan ṣoṣo ní Zanzibar ti fẹ́ di títì pa
Ilé-ẹ̀kọ́ Orin Kíkọ Àwọn Orílẹ̀-èdè Dhow f'orin ṣègbélárugẹ àṣàa Swahili
Àwọn akẹ́kọ̀ọ́ láti Iléèwé Orin kíkọ Àwọn Orílẹ̀-èdèe Dhow (DCMA) ń fi qanun, fèrè, ìlù àti dùrù ní Ilé Àwọn Ẹ̀ṣọ́ Aṣọ́bodè Àtijọ́, ní Stone Town, Zanzibar, 2019. DCMA ló ni àwòrán.
Ẹgbẹẹgbẹ̀rún àlejò tí ó ń rọ́ wìtìwìtì wá sí ìlú Stone Town, Zanzibar tí ó kún fún ìṣẹ̀lẹ̀ àtẹ̀yìnwá, ti tẹ̀lé ìró orin Iléèwé Orin kíkọ Àwọn Orílẹ̀-èdèe Dhow (DCMA), ilé ẹ̀kọ́ orin kíkọ tí ó ń ṣe ìgbélárugẹ àti ìpamọ́ àwọn àṣà orin erékùṣù náà tí ó sún mọ́ Swahili ní ẹ̀báa Omi Òkun India.
Láti ọdún-un 2002, ilé ẹ̀kọ́ náà ti ṣe ìgbélárugẹ àti ìpamọ́ àkójọpọ̀ orin Lárúbáwá, India àti Ilẹ̀ Adúláwọ̀ tí kò lẹ́lẹ́gbẹ́.
Lẹ́yìn-in ọdún kẹtàdínlógún, iléèwé náà kò rí owó tí ó tówó nínú àpò ìkówó sí tí ó sì leè fa kí iléèwé náà ó di títì pa.
Nínú ìwé ìgbéròyìnjáde tí àwọn aláṣẹ DCMA tẹ̀ jáde, ìdá àádọ́rin nínú àwọn ọgọ́rin akẹ́kọ̀ọ́ ni kò rí owó iléèwé wọn tí ó tó bíi $13 USD lóṣù san.
Pẹ̀lú àtìlẹ́yìn àwọn onínúure tí ó ti dáwó fún iléèwé náà, owó tí ó kù ní sísan ṣì pọ̀ tó bẹ́ẹ̀ tí ó fi jẹ́ wípé, ó ṣe é ṣe kí ilẹ̀kùn-un iléèwé náà tí ó wà nínú Ilé Àwọn Ẹ̀ṣọ́ Aṣọ́bodè Àtijọ́.
Láìsí owó tí ó tówó nílẹ̀ láti tẹ̀síwájú, àwọn akẹ́kọ̀ọ́ DCMA àti òṣìṣẹ́ ń fòyà kí ìró amọ́kànbalẹ̀ tí ó ń sun jáde láti inúu gbọ̀ngán olókìkí ilé ẹ̀kọ́ yìí tí ó mú erékùṣù yìí kọrin — leè wọ òkùnkùn.
Orin àti ìgbélárugẹ àṣà àti àjogúnbá nìkan kọ́ ni ilé ẹ̀kọ́ náà fi gbajúmọ̀, àmọ́ ó jẹ́ ilé fún àwọn ọ̀dọ́ tí ó ń wà ibi tí wọn yóò ti fi ìmọ̀ kún ìmọ̀.
Akẹ́kọ̀ọ́ DCMA kan ń kọ́ qanun, ohun èlò orin ayédáadé orin taarab. Àwòrán láti iléèwé DCMA.
A [ti bẹ̀rẹ̀] sí í ní rí ìdojúkọ ìgbà tí ó nira, alákòóso àgbàa DCMA, Alessia Lombardo sọ, nínúu àwòrán fídíò DCMA kan.
"Láti ìsinsìnyí lọ títí di oṣù mẹ́fà sí àsìkò yìí, a kò rí àrídájú tí ó rinlẹ̀ wípé a ó leè san owó oṣù àwọn olùkọ́ni àti òṣìṣẹ́ẹ""."
Ní àkókò tí a wà yìí, àwọn àkàwé-gboyè olùkọ́ 19 àti àwọn òṣìṣẹ́ mìíràn ti ṣiṣẹ́ fún oṣù mẹ́ta gbáko láì gba owó lọ sílé nítorí àìsí owó nínúu kóló iléèwé.
Gẹ́gẹ́ bí Ilé Ìfowópamọ́ Àgbáyé ṣe ti ṣàlàyé wípé, pẹ̀lú bí a ti ṣe mọ agbègbè tí iléèwé náà wà fún ibi ìrìn-àjò ìgbafẹ́ nítorí àwọn etíkun àtijọ́ àti ilé ìtura olówó ńláńlá tí ó kángun síbẹ̀, ọ̀gọ̀rọ̀ àwọn ọmọ ìbílẹ̀ ló ń bá àìníṣẹ́ lọ́wọ́ pò ó pàápàá bí ìṣẹ́ ṣe ti gbé fúkẹ́ ju ti ìgbà kan lọ.
Fún ọdún mẹ́tàdínlógún, DCMA ti ṣiṣẹ́ àṣekúdórógbó nípa lílo orin ṣe ìgbélárugẹ tòun ìpamọ́ ọ̀rọ̀ àjogúnbá àti àṣà Zanzibar.
Orírun àwọn olóhùn-iyò akọrin taarab, Siti Binti Saad àti Fatuma Binti Baraka, tí a tún mọ̀ sí Bi. Kidude, Zanzibar ni ilé èyí-ò-jọ̀yìí orin tí ó ti inúu ìbàṣepapọ̀ àṣà àti àjọṣe ọlọ́dún gbọgbọrọ tí ó wà láàárín àwọn àdúgbò ẹ̀ka Swahili.
Láyé òde òní, akẹ́kọ̀ọ́ leè kọ́ orin ìbílẹ̀ bíi taarab, ngoma àti kidumbak, pẹ̀lú àfikún àwọn ohun èlò ìkọrin bíi ìlù ní oníranànran, qanun àti oud, gẹ́gẹ́ bí alápamọ́ — àti òǹgbifọ̀ — àṣà àti ìṣe.
Neema Surri, a ta violin ní DCMA, ti ń kọ́ bí a ti ṣe ń ta ohun èlòo violin láti ọmọdún mẹ́sàn-án mẹ́nu lé ọ̀rọ̀ nínú àwòrán fídíò DCMA náà.
Mo mọ àwọn ọ̀dọ́mọdé tí ó máa nífẹ̀ẹ́ sí kíkọ́ orin ṣùgbọ́n wọn kò leè san owó ìmẹ̀kọ tí ó jẹ́ owó iléèwé nítorí wípé wọn kúṣẹ̀ẹ́ wọn kò sì ní iṣẹ́ lọ́wọ́ .
Àwọn akẹ́kọ̀ọ́ọ DCMA ń fi ohun èlò ìkọrin olókùn tín-ín-rín kọrin nínú Ilé Àwọn Ẹ̀ṣọ́ Aṣọ́bodè Àtijọ́, níbití iiléèwé náà fi ìkàlẹ̀ sí, ní Stone Town, Zanzibar, lọ́dún-un 2019. Àwòrán jẹ́ ti iléèwée DCMA.
Ní ìparí àwọn ìdánilẹ́kọ̀ọ́ọ DCMA, tí wọ́n ti gba ìwé ẹ̀rí àti ní òpin ẹ̀kọ́ ọlọ́dún kan, púpọ̀ nínú àwọn akẹ́kọ̀ọ́ọ DCMA ni ó ti di àgbà ọ̀jẹ́ tí wọ́n sì í ṣeré lórí ìtàgé kárí ayé.
"Ọmọ bíbíi Zanzibar, tí ó jẹ́ akẹ́kọ̀ọ́ọ DCMA nígbà kan rí, tí ó jẹ́ olùkọ́ni ní iléèwé kan náà báyìí, Amina Omar Juma tòun ti ìlú mọ̀ọ́ká ẹgbẹ́ akọrin rẹ̀, tí ó ń ""fi àṣà ìró orin ìbílẹ̀ "" taarab papọ̀ mọ́ ti ìgbàlódélonígbàńlò kọrin, ìyẹn ""Siti àti Ẹgbẹ́ "", ṣẹ̀ṣẹ̀ padà wọ̀lú láti ìrìnàjò orin kíkọ kan ní orílẹ̀-èdèe South Africa."
"Òun, àwọn díẹ̀ nínú ẹgbẹ́ akọrin rẹ̀ àti àpapọ̀ àwọn akẹ́kọ̀ọ́ DCMA ní ìgbà kan rí ṣe àgbéjáde àwo orin wọn àkọ́kọ́, ""Fusing the Roots"", ní ọdún-un 2018, tí ó mú wọn oi ng o òǹwòran lára yá ní Sauti za Busara, tí í ṣe àjọ̀dún orin kíkọ tí ó gbàràdá jù lọ ní Ìlà-oòrùn Ilẹ̀ Adúláwọ̀."
Híhàyín ni orin Siti àti Ẹgbẹ́ “Nielewe” (“Gbó mi yéké”) àti àwòrán orin náà, tí ó ṣe àfihàn-an àwòrán-an, tí ó sọ ìtàn obìnrin kan tí ó ń rí ìdojúkọ abẹ̀-ilé, tí ó sì ń dárò ara rẹ̀. Ìtàn náà jọ ti Omar Juma fúnra rẹ̀:
Kà síwájú sí i: Àwọn akọrin lóbìnrin Ìlà-Oòrùn Ilẹ̀ Adúláwọ̀ kọrin tako àìfààyè gba obìnrin àwọn ọkùnrin.
Ìtàn nípa àyálò àṣà àti àjọṣepọ̀
Ó tó ẹgbẹ̀rún mẹ́ẹ̀ẹ́dógún àlejò ni ó ti wo eré, gba ìdánilẹ́kọ̀ọ́ àti bá àwọn akọrin lóríṣiírísí ọjọ́ ọ̀la ní iléèwé olókìkí náà ní gbólóhùn rí.
"Iléèwé náà ti ṣe àyálò àti àmúpapọ̀ ọ̀kan-ò-jọ̀kan àṣà ""àwọn orílẹ̀-èdè dhow"", tí ó wà ní ìtòsíi Òkun India àti Ọ̀gbùn-un Persia."
"Agbègbèe Omani Sultanate, tí ó jẹ́ "" ibi gbòógì àwọn alágbára atukọ̀ orí omi ní ọgọ́rùn-ún Ọdún-un kẹtàdínlógún sí kọkàndínlógún sẹ́yìn"", gbé àga agbára rẹ̀ láti Muscat sí Zanzibar ní ọdún-un 1840."
Láti Stone Town, àwọn ọba Omani ń tukọ̀ọ okòwò orí omi ìgbà náà tí ó fẹjú, títí kan kànáfùrù, wúrà, àti aṣọ , látàrí àwọn ìjì líle tí ń tu àwọn ọkọ̀ ìbílẹ̀ẹ Lárúbáwáa — dhows — ní oríi Òkun Indian, láti India sí Oman títí lọ dé Ìlà-Oòrùn Ilẹ̀ Adúláwọ̀.
Àwọn ọ̀dọ́ ní Zanzibar mọ rírìi ìṣẹ̀lẹ̀ àtẹ̀yìnwá tí ó ní ohun ńlá ní í ṣe fún ọjọ́ ọ̀la wọn, ni wọ́n fi ń ṣe àdàlù èyí tí a rí nínú àwọn orin òde òní tí wọn ń gbé jáde.
"Àwọn akẹ́kọ̀ọ́ àti olùkọ́ni DCMA ṣe ìdásílẹ̀ẹ ""TaraJazz"" láì pẹ́ yìí, èyí tí ó jẹ́ àdàlù orin ìbílẹ̀ taarab àti orin Jazz òde òní."
Ata violin, Felician Mussa, ọmọ ogún ọdún, ti ń kọ́ ohun èlò ìkọrin olókùn tín-ín-rín náà fún ọdún mẹ́ta àtààbọ̀; TaraJazz jẹ́ ọ̀kan nínú àwọn ẹgbẹ́ akọrin tí ó àwọn ènìyàn máa ń pè sí òde jù lọ ní àwọn erékùṣù náà, ni ó wà nínú àwòrán tí ayàwòrán tí Aline Coquelle yà:
Agbègbèe Swahili sọ ìtàn pàṣípààrọ àṣà ìbílẹ̀ tí DCMA ṣì ń tẹ̀síwájú nínúu rẹ̀ pẹ̀lú àjọṣepọ̀ àwọn orin-in rẹ̀ .
"Lọ́dọọdún, iléèwé náà máa ń gbàlejò fún ètò tí a pè ní ""Ìkọlù Swahili"", tí ó mú àgbárijọpọ̀ọ àgbà akọrin láti Ilẹ̀-Adúláwọ̀, Ìlú Abẹ́-àkóso Lárúbáwá, Ilẹ̀ Éróòpù àti Àríwá Amẹ́ríkà pẹ̀lú àwọn akẹ́kọ̀ọ́ DCMA láti ṣe orin láàárín ọ̀sẹ̀ kan."
"Ní ìgbẹ̀yìngbẹ́yín ""ìkọlù"" náà, àgbárijọpọ̀ tuntun náà yóò ta bí elégbé ní Sauti za Busara, tí àjọṣepọ̀ wọ̀nyí yóò sì di ìbáṣepọ̀ ọlọ́jọ́ pípẹ́ tí kò mọ ìyàtọ̀ èdè àti àṣà, tí ó fi hàn gbangba wálíà wípé èdè kan náà tí gbogbo ayé gbọ́ ni orin."
DCMA máa ń ṣe àgbékalẹ̀ ètò orin kíkọ tí ó ń ṣe ìgbélárugẹ ẹ̀bùn orin kíkọ àwọn akẹ́kọ̀ọ́ àti àfihàn àjọṣepọ̀ pẹ̀lú ọ̀kọrin àlejò hàn ní, Stone Town, Zanzibar, 2019. DCMA ni ó ni àwòrán.
DCMA mọ rírì orin gẹ́gẹ́ bí ohun tí ó leè ró àwọn ènìyàn lágbára àti gẹ́gẹ́ bí ohun tí ó lè mú ìṣọ̀kan àti ìrẹ́pọ̀ bá àwọn ènìyàn láì wo ti àṣà — ó sì tún ń pèsè àǹfààní iṣẹ́ fún àwọn ọ̀dọ́ tí ó ní ẹ̀bùn àmọ́ tí ó ń tiraka láti jẹ.
Fún àwọn akẹ́kọ̀ọ́ 1,800 tí ó ti gba ìdánilẹ́kọọ́ ní DCMA, èyí nìkan ni ibi ilé orin tí wọ́n mọ̀, níbi tí wọ́n ti ń kọ́ ẹ̀kọ́ tí wọ́n sì ti ń ní àlékún ìmọ̀ nípa iṣẹ́ orin kíkọ àti bí a ṣe ń di òǹkọrin.
"Arìnrìn-àjò kan láti Spain, tó bẹ DCMA wò ní kò pẹ́ yìí, kọ sí oríi TripAdvisor: ""Ní tèmi, ìṣalábàápàdée àwọn akọrin ni ìgbà tí ó meet jù lọ fún mi ní erékùṣù yìí""."
Bí ẹ̀ka ìrìn-àjò afẹ́ẹ Zanzibar ṣe ń gbèrò sí i, DCMA nígbàgbọ́ wípé orin ní ipa kan gbòógì ní í ṣe nínú àjọyọ̀, ìpamọ́ àti ìgbélárugẹ tòun ìpolongo àṣà, àjogúnbá àti ìṣẹ̀lẹ̀ àtẹ̀yìnwáa Swahili.
Zanzibar ju àwọn etíkun àti ilé ìtura olówó iyebíye rẹ̀ lọ — ó jẹ́ ibi tí ó kún fún àwọn ènìyàn ọlọ́pọlọ tí ó ní ẹ̀bùn ní poolo orí wọn látàrí àjọṣepọ̀ ọlọ́jọ́ pípẹ́ tí ó mú agbègbè náà dá yàtọ̀ gedegbe.
Ìfiyèsí Alákòóso Ìwé Títẹ̀: Òǹkọ̀wé àtẹ́jádé yìí ti ṣiṣẹ́ ọ̀fẹ́ pẹ̀lú DCMA.
Ìṣọdẹ-àjẹ́ ṣì ń gba ẹ̀mí àwọn ènìyàn ní ìgbèríko India
Superstition and lack of awareness behind witch-hunting in India
Ìletò kan ní ẹ̀báa Jamshedpur ní Jharkhand. Àwòrán láti ọwọ́ọ Anumeha Verma
Ní ọjọ́ 20 oṣù Agẹmọ, àgbájọ àwọn ènìyànkéènìà gba ẹ̀mí àwọn àgbàlagbà mẹ́rin kan láì dá wọn lẹ́jọ́ ní agbègbèe Gumla ní Jharkhand, India lẹ́yìn tí a fi ẹ̀sùn-un àjẹ́ kàn wọ́n.
Gẹ̀gẹ̀ bí ìjábọ̀ ìròyìn, àwọn àgbàlagbà wọ̀nyí ṣe ikú pa ọkùnrin kan, ni ìgbìmọ̀ abúlée Panchayat ṣe dá wọn lẹ́bi.
Wọ́n wọ́ àwọn àgbàlagbà mẹ́rin wọ̀nyí jáde síta ilée wọn, àwọn ọkùnrin tí ó bòjú sì fi igi lù wọ́n títí tí ẹ̀mí fi bọ́ lára wọn.
Mẹ́jọ nínú àwọn ènìyànkéènìà wọ̀nyí ti wà ní akóló ọlọ́pàá.
Gẹ̀gẹ̀ bí àkọsílẹ̀ ọlọ́pàá tí Times of India tẹ̀jáde, ìṣọdẹ-àjẹ́ ní Jharkhand ti rán àwọn ènìyàn 123 sọ́run àpàpàǹdodo ní àárín-in oṣù Èbìbí ọdún-un 2016 sí oṣù Èbìbí ọdún-un 2019.
Jákèjádò, ènìyàn 134 di ẹni ẹbọra-ń-bá-jẹun látàrí èsùn-un lílo “ògùngùn” ní ọdún-un 2016, ìyẹn gẹ̀gẹ̀ bí Àjọ Aṣàkọsílẹ̀ Ẹ̀ṣẹ̀ Orílẹ̀-èdè náà ṣe kọ́ ọ sílẹ̀.
Àrùn T’ó Ń Peléke Sí i
Ìṣọdẹ-àjẹ́ kò jẹ́ tuntun ní Jharkhand, Prem Chand, Olúdásílẹ̀ àti Alága Free Legal Aid Committee (FLAC) ní Jharkhand, sọ nínúu ìfọ̀rọ̀wánilẹ́nuwò orí ẹ̀ro-ìbánisọ̀rọ̀ kan.
FLAC ti ń ṣe àtọ́nàa ìṣòfin tí ó tako ìṣọdẹ-àjẹ́ ní Jharkhand.
Iléeṣẹ́ náà bẹ̀rẹ̀ iṣẹ́ ní agbègbè yìí ní ọdún-un 1991 nígbà tí àwọn aládùúgbò fi ẹ̀sùn kan obìnrin kan pé ó lọ́wọ́ nínú ikú ọmọdékùnrin kan.
Àgbájọ àwọn ènìyànkéènìà kan dìgbò lù ú, wọ́n sì pa ọkọ àti ọmọ rẹ̀ ọkùnrin.
Òún fi ara pa.
Nígbàtí Prem Chand àti àwọn ẹlẹgbẹ́ẹ rẹ̀ ṣe ìbẹ̀wò sí àwọn ẹlẹ́ṣẹ̀ wọ̀nyí nínúu túbú, wọ́n bá ìpèníjà:
Wọ́n sọ fún wọn wípé àwọn dúró lé oríi ẹ̀sùn tí wọ́n fi kan àwọn.
Wọ́n sì tún gbàgbọ́ wípé bí ẹ̀jẹ̀ẹ ẹni tí a pè ní àjẹ́ bá kan ilẹ̀ ọ̀gẹ́rẹ́, yóò pàdánù agbára ẹlẹyẹ rẹ̀.
Prem Chand sọ wípé ó kan apá kan nínú àwọn ọmọ ìlú:
Nígbàgbogbo, àwọn obìnrin tí kò lárá tí ó tálákà ní í máa ń fi ara kááṣá.
Àwọn tí ó f’ara kááṣá wọ̀nyí ni àwọn Adivasis, Harijans àti Dalits.
Ìfojú iyì àwọn obìnrin àti ìtasẹ̀ àgẹ̀rẹ̀ sí òfin ẹ̀tọ́ sí ayé iyì fún gbogbo ọmọ ènìyàn.
Òtítọ́ Àwùjọ àti Ìṣèlú
Àwọn ajìjàngbara sọ wípé ìgbàgbọ́-asán tí ó rinlẹ̀ ní ìgbèríko ni ó ń fa ìwà pálapalà náà.
Àìgbẹ̀kọ́, ètò ìlera tí ò pójú òṣùwọ̀n àti kòlàkòṣagbe tí ó ń gb’àgbègbè tí ìwà pálapalà wọ̀nyí ti gbalẹ̀ bí i ìtàkùn ni ó fi wọ́pọ̀.
Ọ̀ràn wọ̀nyí ti fi hàn wípé àhesọ ni ó máa fi ń bẹ̀rẹ̀ .
Pẹ̀lú òfin àwọn ìpínlẹ̀ India tí ó ka ìṣọdẹ-àjẹ́ sí ohun tí ó lòdì sófin, àwọn akópa ọ̀ràn wọ̀nyí rí i gẹ́gẹ́ bí ọ̀nà ìdáààbò-ara-ẹni.
Bákan náà ni wọ́n ń wí àwáwí fún gbígba ohun ìní àwọn obìnrin, fi agbára gbẹ̀san tàbí fi ipá bá obìnrin lò pọ̀.
Gẹ́gẹ́ bí Prem Chand ṣe ti sọ:
Àtètèròtẹ́lẹ̀ ni wípé ní kété tí o bá ti pe obìnrin ní àjẹ́, o lè tẹríi rẹ̀ ba fún ìlòkulò.
Síbẹ̀síbẹ̀, ó ṣe kókó láti mọ̀ wípé wọn máa ń lo ìwà pálapàla yìí fi gba tara àwọn obìnrin, kò sì kìí ṣe ìdí tí ó ń fà á pàtó.
Ní ti ẹ̀fẹ̀, láì wí tó, panchayat náà sábà máa ń lọ́wọ́ sí ìpènìyàn ní àjẹ́ pàápàá bí kò bá pàṣẹ ìjìyà t'ó tọ́.
Ní àfikùn sí panchayat tí ìbó yàn, àwọn kan ńbẹ tí wọ́n pe ara wọn ní panchayat ipò-ìsàlẹ̀ láì ní àṣẹ kankan tí ó fún wọn lágbara níbikíbi ní orílẹ̀-èdè.
Àwọn ẹgbẹ́ yìí máa ń dájọ́ àti fi ìyà jẹ ènìyàn tí kò sì sí ẹni tí ó ká wọn lápá kò.
Ìṣẹ̀lẹ̀ kan ní agbègbèe Ajmer ní Rajasthan lọ́dún-un 2017 jábọ̀ ìlọ́wọ́sí panchayat ipò-ìsàlẹ̀ tí ó ṣ’okùnfa ikú obìnrin ogójì ọdún kan.
Gẹ́gẹ́ bí òfin, ilé ẹjọ́ lé gbé ìgbésẹ̀ tí ó tako irúu ìdájọ́ báwọ̀nyí yálà láti ọ̀dọ̀ àwọn panchayat tí ìbó yàn àti panchayat ipò-ìsàlẹ̀.
Síbẹ̀síbẹ̀, àwọn tí ó fara kááṣá ò tilẹ̀ ní àǹfààní sí ilé-ẹjọ́ òfin kí àgbájọ-àwọn-ènìyànkéènìà ó tó kojúu wọn.
Ìṣọdẹ-àjẹ́ jákèjádò India
Jharkhand ti ṣe àkọsílẹ̀ iye ẹṣẹ̀ àwọn ènìyán ṣẹ̀ tí ó pọ̀ jù lọ tí ó tan mọ́ ìṣọdẹ-àjẹ́ àmọ́ kì í ṣe ìpínlẹ̀ náà nìkan.
Ọ̀ràn-an ìṣọdẹ-àjẹ́ ti wà l’ákọsílẹ̀ ní Chattisgarh, Odisha, Gujarat, West Bengal Assam, Bihar, Maharashtra àti Rajasthan pẹ̀lú.
Nígbà ìṣẹ̀lẹ̀ kan ní 2014, Debjani Bora, ẹlẹ́sẹ̀ ehoro ọmọ bíbíi orílẹ̀-èdèe India ti fi ara kááṣá rí.
Gẹ́gẹ́ bí ọ̀rọ̀ọ Debjani, a f’ẹ̀sùn-un ìgbẹ̀mí ènìyàn púpọ̀ kàn án ní abúlée Cherekali tí ó wà ní kìlómità 180 láti Guwahati, olú-ìlúu India ti apáa ìlà-oòrùn.
Olóríi gbọ̀gán àdúrà abúlé l’ó dárúkọ rẹ̀ tí àwọn ará abúlé sí fi ìyà jẹ́ ẹ.
Ìṣẹ̀lẹ̀ 2017 ní ipínlẹ̀ Rajasthan.
Lára èyí ni, ọmọbìnrin ogójì ọdún kan Kanya Devi rí ìkọlù tí a sì lù ú pa lẹ́yìn tí mọ̀lẹ́bíi rẹ̀ fi ẹ̀sùn kàn án ní agbègbèe Ajmer.
Àwọn Ẹni-tó-fara-kááṣá àti Ẹni-tórí-kó-yọ
Àwọn ènìyàn ń f’ẹ̀sùn kan àwọn ẹlẹyẹ fún iṣẹ́-ibi ọwọ́ọ wọn: ikú ènìyàn tàbí ẹranko, ọ̀dá òjò, àìso jìngbìnnì irúgbìn, àti bẹ́èbẹ́è lọ.
Ìkọlù tí ó kọ lu àwọn obìnrin wọ̀nyí (àti àwọn ọkùnrin kan) rorò bí ẹranko ẹhànnà.
Nígbà mìíràn, àwọn èsùn náà àti ìjìyà ẹṣé máa wá láti ọ̀dọ̀ mọ̀lébíi wọn.
Àwọn kan ń gbé tí wọ́n sì ń sọ ìtàn-an wọn tí wọ́n sì ń jà fún ẹ̀tọ́ọ wọn.
Chutni Mahato ti Saraikela ní Jharkhand jẹ́ ọ̀kan lára wọn.
"Àwọn ènìyàn láti agbègbè náà máa ń pè é ní ""tigress""."
Wọ́n fi ẹ̀sùn-un àjẹ́ kàn-án ní ọdún-un 1995. Láti ìgbà náà, ó ti yírapadà di ajìjàǹgbara olùtako ìfìyàjẹ àwọn obìnrin pẹ̀lú àtìléyìn Ilé-iṣẹ́-tí-kìí-ṣe-tìjọba.
Chutni sọ bí àìsí àtìlẹ́yìn tó késejárí ṣe mú u nira láti jà tako ìwà pálapàla yìí.
Ìbájẹ́pé àtìlẹ́yìn tó tó wá láti ọwọ́ àwọn oníṣẹọba àti ìjọba fún iṣẹ́ tí à ń ṣe níbí.
Síbẹ̀síbẹ̀, mo ti jìyà nítorí ìwà pálapàla yìí.
Bí ènìyàn bá tọ̀ mí wá fún ìrànlọ́wọ́, mo máa dúró tì wọ́n gbágbágbá, ó sọ nínúu ìfọ̀rọ̀wánilẹ́nuwò orí ẹ̀ro-ìbánisọ̀rọ̀ kan.
Dídá Ohùn Gbogboògbò Sí i
Àwọn ẹni-tórí-kó-yọ àti ajàfẹ́tọ̀ọ́-ènìyàn rò wípé àwọn ènìyàn gbogbo kò ti ìfòpin sí ìṣọdẹ-àjẹ́ lẹ́yìn.
Àwọn ajàfẹ́tọ̀ọ́-ènìyàn tí a fọ̀rọ̀ wá lẹ́nu wò lórí ìṣẹ̀lẹ̀ yìí jẹ́ kí á mọ̀ wípé àbùkù ìrànwọ́ ìjọba àti àwọn onímọ̀ ni kò mú ìwà àìbójúmu náà ṣíra kásẹ̀ ńlẹ̀.
Ohun tí ó dára jù lọ ni wípé àwọn tí ó ń tako ìwà burúkú yìí gbàgbọ́ wípé àyípadà lè dé.
Ní ọ̀rọ̀ọ Prem Chand:
Akitiyan láti f’òpin sí ìṣọdẹ-àjẹ́ lè tẹ̀lé ìlànà tí ìjọba fi polongo ètò mímọ̀ọ-kọ-àti-mímọ̀ọ-kà.
Bákan náà, àwọn onímọ̀ ní láti f’ọwọ́ sí i k’áwọn ènìyàn ó ba f’ohùn sí i.
B. Vijay Murty, akọ̀ròyìn àti olùgbé Jharkhand ni ó gbọ̀rọ̀ sílẹ̀ lẹ́nu àwọn tí ọ̀rọ́ kàn.
Ìtọ́jú àwọn erin aláìlóbìíi Myanmar
Òṣìṣẹ́ àgọ̀ kan ń rọ Ayeyar Maung ní oúnjẹ. / Aung Kyaw Htet / The Irrawaddy
Àpilẹ̀kọ jẹ́ ti Aung Kyaw Htet tí ó kọ́ fún The Irrawaddy, iléeṣẹ́ oníròyìnin orí ayélujára ní Myanmar, tí Ohùn Àgbáyé ṣe àtúntẹ̀jádée rẹ̀ ní ìbámu pẹ̀lú àdéhùn ìbáṣepọ̀ tí ó wà láàárín wọn.
Nígbà tí àwọn òṣìṣẹ́ alábòójútó igbó rí i nínú ijù tí ó sún mọ́ Etí-omi Irrawaddy, oṣù mẹ́ta ni Ayeyar Sein nígbà náà.
Ẹsẹ̀ẹ rẹ̀ kan ti lu páḿpẹ́ àwọn ajérangbépa.
Àwọn onígẹdú ìjọba ló dóòlà ẹ̀míi rẹ̀, wọ́n sì gbé e lọ sí àgọ́ erin kan ní Agbègbèe Bago fún ìtọ́jú.
Òhun ni ọ̀dọ̀ erin kẹjọ tí yóò rí ààbò ní Wingabaw, ibi ààbò fún àwọn erin Myanmar tí kò lóbìí.
Ọ̀dọ́ erin mìíràn, Ayeyar Maung náà rí nǹkan.
Kí ó tó di èròo àgọ́ náà, erin oṣù mẹ́fà náà ti lu okùn.
Ó sì há sí àárín àwọn òkúta nínú ijù kan náà tí a ti rí Ayeyar Sein, àwọn ọ̀wọ́ọ rẹ̀ tó kù fi í sílẹ̀ lọ.
Síbẹ̀, àwọn alábòójútó ijù tú u sílẹ̀, ó sì di aráa àgọ́ náà ní ọdún tó kọjá.
Àwọn méjèèjì ni erin aláìlóbìíi tí ó kéré jù lọ nínú àgọ́ náà; ọdún mẹ́rin ni erin tí ó dàgbà jù gbà lọ́wọ́ọ wọn.
Gbogbo wọn ni ó ní ìtàn kan tàbí òmíràn tí ó jẹ mọ́ ìjìyà láti ọwọ́ ẹ̀dá ọmọ ènìyàn adáríhununrun.
Àwọn kan kò rí ọ̀wọ́ọ wọn tí wọ́n jọ ń jẹ̀ mọ́, àwọn mìíì di aláìlóbìíi lẹ́yìn tí àwọn tí ó ń pa ẹran nínú ìgbẹ́ nípakúpa pa òbíi wọn.
Ní àgọ́ tí ó wà ní Wingabaw, àwọn ọ̀dọ́ erin tí kò ní òbí náà gbẹ́kẹ̀lé oúnjẹ ọmọ ìkókó tí àwọn alábòójútó ijù ń pèsè fún wọn lójoojúmọ́.
Ààyé gbà wọ́n láti jẹ̀ nínú ijù ní òwúrò, wọn yóò sì wẹ̀ nínú odò kékeré kan nítòsí kí wọn ó tó padà sí àgọ́.
Lọ́wọ́ lọ́wọ́ báyìí, Myanmar yóò fẹ́rẹ̀ẹ́ ní tó erin ẹgàn 1,500.
Àmọ́ ó jẹ́ ohun tí ó bani lọ́kàn jẹ́ nítorí pé àwọn tí ó ń dá ẹ̀míi wọn légbodò kò jẹ́ kí wọn ó gbé ayé, erin kan lọ́sẹ̀ kan ni wọ́n ń pa.
Iyùn Tobago tí ó ti ń pàwọ̀dà fi hàn gbàgàdàgbagada pé kò sí ọ̀nà mìíràn ju kíkojú àyípadà ojú-ọjọ́
"The island's reefs are on ""Bleaching Alert Level One"""
Iyùn bí ìwo àgbọ̀nrín tí ó ti pàwọ̀dà. Àworán láti ọwọ́ọ Matt Kieffer, CC BY-SA 2.0.
Iyùn-un abẹ́ òkúta òkun jẹ́ ohun tí a ò leè fọwọ́ rọ́ sẹ́yìn nínú àwọn àmúṣọrọ̀ tí ó ń mú ọrọ̀ Ajé Tobago àti àwọn àyíká erékùṣù náà gbòòrò.
Ibùgbé ọ̀kan-òjọ̀kan ẹ̀yà ẹ̀dá inú omi (àti ibi ẹja pípa fún àwọn apẹja ìbílẹ̀), tí ó sì tún ń dá ààbò bo èbúté, èyí tí kò mú kí àwọn ìjì líle etí omi ó pọ̀ kọjá àlà ni à ń sọ.
Òkúta inú òkun Buccoo Reef tí o gbajúmọ̀ bí ìṣáná ẹlẹ́ta tí àwọn arìnrìn-àjò afẹ́ máa ń wọ́ tùùrùtù níbẹ̀ náà kò gbẹ́yìn.
"Àmọ́ lẹ́yìn àtẹ̀jáde kan sí ilé ìròyìn tí Àjọ tí ó ń ṣàkóso Omi orílẹ̀ èdè náà (IMA) tẹ̀ jáde ní ọjọ́ 22, oṣù Ògún ọdún-un 2019, èyí tí ó kìlọ̀ wípé – ìwádìíi National Oceanic and Atmospheric Administration (NOAA) Coral Reef Watch sọ wípé — iyùn abẹ́ òkúta òkun Tobago ti bọ́ sì abẹ́ ìṣọ́ láti ṣe òfíntótó ""Ìkéde Ìpàwọ̀dàa Ìpele Ìkíni"", gbogbo ojú ló ń wo erékùṣù náà."
A ì í ṣe é mọ̀, ìpàwọ̀dà náà lè fò fẹ̀rẹ̀ sí ìpele kejì láàárín ọ̀sẹ̀ díẹ̀, tí yóò sì fa àkóbá fún ìwàláàyè àwọn iyùn wọ̀nyí, àwọn ẹ̀dá inú omi mìíràn àti àwọn olùgbé erékùṣù náà.
Kí ni ohun tí ń pàwọ̀dà ní pàtó?
Alábàágbé àti alájọṣe iyùn ni àwọn ewé inú omi tí ó máa ń bá a kó ohun aṣaralóore pamọ́ àti da èérí ara nù.
Ewé wọ̀nyí yóò sì fún iyùn ní okun tí ó nílò fún ìdàgbàsókè, àmọ́ àyípadà ìgbóná inú omi ń dí àjọṣepọ̀ yìí lọ́wọ́.
Bí omi bá gbóná ju bí ó ṣe yẹ lọ (tàbí bí ó bá tutù jù) àwọn iyùn yóò lé ewé omi — tí yóò sì pàdánù ọwọ́ tí ó ń fi oúnjẹ nù ún.
Àṣèyìnwá àṣẹ̀yìnbọ̀, ebi yóò pa iyùn kú; àwọ̀ ara tí yóò yí padà ni àmì tí a ó fi mọ̀, ìpàwọ̀dà láti àwọ̀ olómi-ọkà àti ewéko sí funfun egungun.
Ìkéde Ìpàwọ̀dà Ìpele Kìíní ń kéde wípé bí a kò bá wá nǹkan ṣe sí i, àwọn iyùn náà yóò bẹ̀rẹ̀ sí í pàwọ̀dà.
IMA dábàá wípé kí àwọn onímọ̀ ìṣẹ̀dá àti ọmọ ìlú ó máa ṣọ́ àwọn ẹ̀dá inú omi náà fún àwọn àmì ìpàwọ̀dà ní àárín-in ọ̀sẹ̀ mẹ́sàn-án sí méjìlá tí ó ń bọ̀.
Ìpele ìpàwọ̀dà kejì yóò jẹ́ ìtọ́ka sí ìpàwọ̀dà iyùn kárí ayé àti ikú iyùn.
Kí ló fa sábàbí?
Gẹ́gẹ́ bí onímọ̀ àyíká ìbílẹ̀ Anjani Ganase ti ṣe ṣàlàyé, ọ̀dádá tí ó dá ìpàwọ̀dà iyùn-un Tobago ni ìwọ̀n ìgbóná omi tí ó re òkè — tí í ṣe arapa àyípadà ojú-ọjọ́.
Nínú ímeèlì, Ganase ṣàlàyé wípé òkun máa ń fa èyí tí ó pọ̀ nínú ooru inú afẹ́fẹ́ mu, tí ó sì ń fa kí omi — pàápàá jù lọ àwọn ibú omi jínjìn gbungbunrungbun bíi Ọ̀sàa Caribbean — ó gbóná janjan.
Kódà, ìṣọ́ ọlọ́sẹ̀ méjìláa NOAA Tobago tan pinpin àyípadà yìí dé iyùn Lesser Antilles.
Àwọn òkúta tí ó wà ní agbègbè náà, bíi Greater Antilles àti Cuba, ti wà ní Ìpele Kejì Ìkéde Ìpàwọ̀dà:
Kí ni arapa rẹ̀?
Ohun tí ó léwu ni ìpàwọ̀dàa iyùn.
Nítorí wípé iyùn máa fún ẹja ní oúnjẹ, òun náà ni ó dúró gẹ́gẹ́ bí ilé fún àwọn ẹja àti fún àwọn ọmọ ẹja tí kòì tíì lè wẹ̀ nínú alagbalúgbú omi, nítorí ìdí èyí, bí a bá pàdánùu wọn, ẹja náà yóò bá wọn lọ.
Bí ẹjá bá sì tán lómi, iṣẹ́ bọ́ lọ́wọ́ àwọn apẹja nìyẹn.
Tobago gbẹ́kẹ̀lé iléeṣẹ́ ìrìnàjò afẹ́ ìbílẹ̀; ìdá 40 àwọn arìnrìn-àjò afẹ́ erékùṣù yìí ni ó máa ń wá láti wo àwọn iyùn omi wọ̀nyí.
Bí ìpàwọ̀dà bá tẹ̀síwájú, àwọn ènìyàn kò ní rí òkúta iyùn, owó dollar ìrìnàjò afẹ́ yóò fìdí jálẹ̀, tí yóò sì kó bá àwọn iléeṣẹ́ agbàlejò bíi: ilé ìtura, ilé ìjẹun, iṣẹ́ ìgbòkègbodò ọkọ̀ àti ilé iṣẹ́ aṣàkóso ìrìnàjò.
Bí ìjì líle bá ń pọ̀ sí i látàrí ségesège ojú-ọjọ́, òkúta iyùn-ún níṣẹ́ pàtàkì ní ṣíṣe láti fa agbára àwọn ìgbé omi àti ìdúró gẹ́gẹ́ bí alárinà láàárín òkun àti etí òkun — àmọ́ ìgbóná àgbáńlá ayé ń dí i lọ́wọ́ láti ṣiṣẹ́ẹ rẹ̀.
Ìwádìí ti fi ìdíi rẹ̀ múlẹ̀ wípé òkúta iyùn ní ń gba ìdá 90 etídò Tobago sílẹ̀-lọ́wọ́ ọ̀gbàrá tí ìgbé omi ń fà.
Ní ibi ètò Àyájọ́ Ọdún Òkúta iyùn ní Ifásitì West Indies ní ọdún-un 2018, Ọ̀jọ̀gbọ́n John Agard sọ wípé iṣẹ́ yìí yóò pọ̀ sí i bí ìjì ṣe ń pọ̀ sí i àti bí ọ̀sà ṣe ń kún sókè.
Kí ni a lè ṣe láti dẹ́kun rẹ̀?
Ganase ní pé àìmójútò omi wọ̀nyí bí ó ti tọ́ ló fa ẹja pípa kọjá àlà àti ìbàjẹ́ àyíká ni eku ẹdá tí ó fa ìpàwọ̀dà iyùn-un Tobago.
Bí ó bá ń bá a lọ bẹ́ẹ̀, títẹmpẹlẹ mọ́ ìṣàkóso àti ààbò òkúta iyùn nìkan ló lè mú kí wọn ó padà bọ̀ sípò àti dàgbà:
Ó yẹ kí òkúta iyùn ó di ohun tí yóò pamọ́ fún àwọn èrò, kí iṣẹ́ ìràpadà ó fẹsẹ̀ múlẹ̀ kí ọ̀wọ́ ẹja onílera àti omi tí ó dára tí yóò mú kí iyùn ó dàgbà ó padà.
Ó sọ síwájú sí i:
Ojúṣe oníkálukú ni láti dín èéfín inú àyíká kù, bẹ́ẹ̀ náà ni ọmọ aráyé ní ẹ̀tọ́ láti béèrè fún iṣẹ́ ìlọsíwájú láti ọ̀dọ̀ àwọn ìjọba kí wọn ó pèsè ohun tí yóò mú nǹkan sún pẹ́lí, ohun èlò àti ìdánilẹ́kọ̀ọ́ nípa ìpamọ́ àti ìfikọ́ra.
Ó pọn dandan kí a ṣàkóso àti ìpamọ́ ohun àlùmọ́ọ́nì wa, bóyá ìjọba ni o tàbí iléeṣẹ́ ńláńlá tí ó ń lo àwọn àlùmọ́ọ́nì wọ̀nyí.
Ó ti di ṣíṣe fún ìjọba ti erékùṣù agbègbè kan náà láti kéde nípa ojúṣe àgbáyé ní ti ìgbógunti ìṣòro àyípadà ojú-ọjọ́.
Ní ọjọ́ 11, oṣù Ọ̀wẹwẹ̀, ọdún-un 2019, Olùdarí Barbadia Mia Mottley mẹ́nu lé ìṣòro yìí ní olú iléeṣẹ́ Àjọ Àgbáyé ní Geneva, ó ń rọ àwọn orílẹ̀-èdè ńlá kí wọn ó gbé ìgbésẹ̀ akin láti kọjúu àyípadà ojú-ọjọ́.
"Ó sọ wípé, erékùṣù Caribbean, ""kò ní àsìkò tí ó pọ̀ nítorí [à] ń ṣiṣẹ́ ìyè lọ́wọ́ ""."
Ganase gbà wípé ọ̀ràn náà gba àtúnṣe ní kíákíá.
"Ohun gbogbo tí ó bá gbà láti gba òròmọdìẹ ojú-ọjọ́ lọ́wọ́ àyípadà àti ìdẹ́kun ìpàwọ̀dà iyùn ni kí á fi fún un, ó sọ wípé, pàápàá jù lọ ""iṣẹ́ ń bẹ"" fún àwọn tí ó ń ṣe òṣèlú:"
Bí a ṣe ń wò ó, kò ní jẹ́ ohun tí ó rọrùn, àmọ́ ọ̀nà àbáyọ mìíràn ń bẹ.
Ìrìn-àjò: Ìpẹ̀kun eré-ìdárayá fún Ọmọ-adúláwọ̀
Ìṣèbéèrè fún ìwé ìrìnnà dà bíi ẹbọ fún àwọn òòsà
Àwòràn olójìjì láti ọwọ́ọ Natasha Sinegina (CC BY-SA 4.0).
Àwòrán ojú-ewé ìwé ìrìnnà látọwọ́ọ Jon Evans (CC BY 2.0).
Àtúntò àwòrán-an látọwọ́ọ Georgia Popplewell.
Ní ọdún-un 2019, a kò fún Tèmítáyọ̀ Ọlọ́finlúà, òǹkọ̀wé àti ọ̀mọ̀wé ọmọbíbí orílẹ̀-èdèe Nàìjíríà, ní ìwé ìrìnnà láti lọ sí Àpérò Lórí Ẹ̀kọ́ Ilẹ̀ Adúláwọ̀ ní Éróòpù tí ó wáyé ní Edinburgh, UK.
Ìgbìmọ̀ Àgbà Sórílẹ̀-èdè Britain ní Nàìjíríà sọ wípé àwọn kò “sí àrídájú” tí ó tẹ̀ àwọn lọ́rùn wípé Ọlọ́finlúà yóò fi UK sílẹ̀ lẹ́yìn tí ètó bá parí.
Ilé-iṣẹ́ UK Nílé pe àìfúni ní ìwé ìrìnnà náà padà. Ọlọ́finlúà lọ, ó bọ̀ padà sí Nàìjíríà, kò b'ọmọ jẹ́.
Àwọn mìíràn kò rí àǹfààní báyìí. Nínúu oṣùu Igbe ọdún-un 2019, àwọn aláṣẹ ìwé ìrìnnà UK kò jẹ́ kí ọmọ adúláwọ̀ 24 nínúu àwọn onímọ̀ ìjìnlẹ̀ 25 tí ó ń ṣiṣẹ́ lóríi àrùn àkóràn ó darapọ̀ mọ́ àwọn akẹgbẹ́ẹ wọn níbi àpérò London School of Economics Africa Summit.
Àwọn onímọ̀ tí wọ́n lakakì tí wọ́n sì ní ìmọ̀ pípé láti kojúu àrùn tí ó ń bá ilẹ̀ adúláwọ̀ fínra, kò rí ìwé ìrìnnà tí yóò mú wọn kópa nínúu àpérò nípa “ìpèníjà ìpọnmisílẹ̀-de-oǹgbẹ àjàkálẹ̀ àrùn” gbà.
‘O kò ní padà!’
Kékeré nìkan kọ́ ni ìdójútì tí àìfàyègba Ọmọ-adúláwọ̀ láti wọ àwọn illú kan ń mú dání — bẹ́ẹ̀ náà ni ó ń tọ́ka sí ìgbékalẹ̀ ẹlẹ́yàmẹyà tí ó ń ṣe àtillẹ́yìn fún ìgbàgbọ́ wípé àwọn akọ́ṣẹ́mọṣẹ Ọmọ-adúláwọ̀ àti alátinúdá ò ṣe é fi ọkàn tàn lọ títí ni ti ìbọ̀wọ̀ fún òfín dé.
"Abala 13 ti Ìkéde Káríayé Fún È̩Tó̩ O̩mo̩nìyàn wípé ""E̩nì kọ̀ọ̀kan ló ní ẹ̀tọ́ láti kúrò lórìlẹ̀‐èdè yòówù kó jẹ́, tó fi mọ́ orílẹ̀‐èdè tirẹ̀, kí ó sì tún padà sí orílẹ̀‐èdè tirẹ̀ nígbà tó bá wù ú""."
Òtítọ́ ibẹ̀, síbẹ̀síbẹ̀, bí kò bá sí ìwé-àṣẹ-ọmọìlú-fún-ìrìnnà àti ìwé ìrìnnà tí ó wúlò, kò rọrùn láti lò.
Ìrọ̀rùn ni ìbéèrè fún ìwé ìrìnnà ní àwọn orílẹ̀-èdè kan, kò sì rí bẹ́ẹ̀ ní orílẹ̀-èdè mìíràn.
Ní oríi 2019 Henley Passport Index, Japan àti Singapore ni orílẹ̀-èdè tí ó rọrùn fún jù lọ láti ríwèé gbà wọ̀lú oríṣìíríṣi, nígbàtí Angola, Egypt àti Haiti wà ní ìsàlẹ̀.
Kà síwájú sí i: ‘Kò Sí Àpòpọ̀ Ìwé Ìrìnnà': Àwọn ìràwọ̀ olórin orílẹ̀-èdè Tanzania ò rí ìwé ìrìnnà wọ àjọ̀dún orin ní US
"Òǹkọ̀wée ọmọbíbíi Kenya Ciku Kimeria ṣe àlàyé gbígbé láìsí iyì ""ẹ̀tọ́ sí ìwé-ẹ̀rí-ọmọìlú-fún-ìrìnnà""."
"Obìnrin náà sọ wípé ìwé ìrìnnà nìkan kò gbé ènìyàn wọ orílẹ̀-èdè mìíràn nítorí pé ""o ní láti dáhùn àwọn ìbéèrè bíi, ‘Kí ló wa síbí wá ṣe?"""
tí àwọn òṣìṣẹ́ ibodè yóò béèrè, bí èsì ìbéèrè kò bá tẹ́ wọn lọ́rùn, arìnrìn-àjó lè bá ara rẹ̀ ní ẹnu ìloro àlọ.
Fún àwọn Ọmọ-adúláwọ̀ tí ó fẹ́ ṣe ìrìnàjò jáde lọ sí orílẹ̀-èdè tí kìí ṣe ti adúláwọ̀, ìbéèrè fún ìwé ìrìnnà ìwọ̀lú máa ń dà bíi ṣíṣe ẹbọ fún òòṣà tí ebi ń pa.
Adéṣínà Ayẹni (Ọmọ Yoòbá), alákòóso Ohùn Àgbáyé ní èdèe Yorùbá, sọ ìríríi rẹ̀ nígbà tí ó ṣe ìbéèrè fún ìwé ìrìnnà ìwọ̀lúu Lisbon, Portugal, fún àpéròo àwọn alátinúdá 2019 Creative Commons Summit:
Ìdùnnù ǹlá gba ọkàn-an mi nígbà tí mo gba ìròyìn tẹl mí lọ́wọ́ wípé n ó máa sọ̀rọ̀ àkórí ètò níbi Àpérò CC ọdún-un 2019 ní Lisbon. . . .
Lọ́jọ́ 18 oṣù Igbe, 2019, ọjọ́ díẹ̀ sí àyájọ́ ọjọ́ ìbíì mi, mo kó àwọn ohun tí wọn béèrè fún ìwé ìrìnnà láti wọ̀lúu Lisbon ki n ba kópa nínúu àpérò náà sílẹ̀ ní ilé-iṣẹ́ẹ VFS Global ní ìdádò Lekki, ní Èkó.
Ọjọ́ 9 sí 11 ọdún-un 2019 ni àpérò náà ṣùgbọ́n ọjọ́ márùnúndínlógún ni yó gbà fún ìwé ìrìnnà láti jáde fún gbígbà.
Lọ́jọ́ tí ó yẹ kí n kúrò nílé fún Portugal, n kòì tí ì rí ìwé-ẹ̀rí-ọmọìlú-fún-ìrìnnà mi gbà padà...
ọjọ́ mọ́kànlá lẹ́yìn tí àpérò ti di àfìsẹ́yìn ti eégún aláré ń fiṣọ, mo gba iṣẹ́-ìjẹ́ kí n wá gba ìwé-ẹ̀rí-ọmọìlú-fún-ìrìnnà mi ní VFS.
Awọn àgbá bọ̀, inú dídùn l’ó ń mú orí yá.
Ìṣòro kan ni ti àìrí ìwé ìrìnnà gbà, òmíràn ni ti owó ìrìnàjò ọ̀fẹ́ gọbọi tí ó wọlẹ̀ nítori n kò le è lọ si àpérò.
Ìbànújẹ́ gba ọkàn mi poo látàríi àlàálẹ̀ Ilé-Ìfowópamọ́ Àgbà orílẹ̀-èdè Nàìjíríà tí kò mú ìfowó ránṣẹ́ sí òkè òkun rọrùn; n kò le è dá owó ìrìnàjò ọ̀fẹ́ tí ó pọn dandan láti dá padà padà fún àwọn tí ó ni owó.
Ó dùn mí wọ akínyẹmí ara wípé wọ́n gbẹ́sẹ̀ lé ẹ̀tọ́ọ mi gẹ́gẹ́ bí olómìnira láti darapọ̀ mọ́ àwọn akẹgbẹ́ẹ̀ mi.
Wọ́n pa ohùn mọ́ mi lẹ́nu!
Ìṣòro: Fún àwọn Ọmọ-adúláwọ̀ tí ó ń ṣe ìrìnàjò nínúu Ilẹ̀-adúláwọ̀
Ó ṣòro fún ọmọ-adúláwọ̀ láti ṣe ìrìnàjò jáde kúrò ní Ilẹ̀-adúláwọ̀ — ṣùgbọ́n bẹ́ẹ̀ náà ni ó nira láti ṣe ìrìnàjò nílẹ̀ náà.
Àwọn ọmọ onílùú àìmọye orílẹ̀-èdè tí ó wà ní Àríwá àgbáńlá ayé lè ṣe ìrìnàjò lọ sí ọ̀pọ̀ orílẹ̀-èdè ní ilẹ̀-adúláwọ̀ láì ní ìwé ìrìnnà, tàbí pẹ̀lú hìhámọ́ tí ò tó nǹkan, àmọ́ ọ̀pọ̀lọpọ̀ Ọmọ-adúláwọ̀ ni ó nílòo ìwé ìrìnnà ìwọ̀lú láti ṣe ìrìnàjò sí ìdajì àwọn orílẹ̀-èdè tí ó kù.
"Aládàásí Ohùn Àgbáyé ọmọbíbí orílẹ̀-èdè Nàìjíríà Rosemary Àjàyí ṣe àpèjúwe ""ìlàkàkà àwọn ọmọ-adúláwọ̀ tí ó ń ṣe ìrìnàjò ní àárín ilẹ̀-adúláwọ̀ "":"
Inúu mi dùn nítorí wípé à ń gbé ọ̀ràn ohun tí ojú àwọn ọmọ-adúláwọ̀ máa ń rí ní wọ́n bá béèrè fún ìwé ìrìnnà wọ Orílẹ̀-èdè òyìnbó àti ohun ti ó tan mọ́ ọn yè wò.
Èyí kò gbé mi lọ́kàn bíi ti ìlàkàkà àwọn ọmọ-adúláwọ̀ tí ó ń ṣe ìrìnàjò nínúu ilẹ̀-adúláwọ̀.
Ní RightsCon tí ó wáyé ní Tunis, àti GlobalFact tí ó wáyé ní Cape Town, mo bi àwọn Ọmọ-adúláwọ̀ bóyá wọ́n ti nílòo ìwé ìrìnnà.
Ní ọjọ́ ìsinmi tí a wà yìí, mo gbọ́ wípé oníṣẹ́-ìròyìn ọmọ Nàìjíríà kan kò le è wà níbí GlobalFact nítorí wípé kò ní ìwé ìrìnnà.
Kí a máà sọ ti àwọn ọmọ-adúláwọ̀ tí ó fò kúrò nílẹ̀-adúláwọ̀ kí wọn ó tó lè wọ Tunis.
Ní oṣù ti ó kojá, mo ṣe alábàápàdé oníṣẹ́-ìròyìn tí ó wá láti Ìlà-oòrùn Ilẹ̀-adúláwọ̀ tí ó ń ṣe ìbéèrè fún ìwé ìrìnnà wọ Nàìjíríà. Wọ́n ní kí ó pèsèe ìwé-ẹ̀rí ìwákọ̀ọ ti akọ́ṣẹ́mọṣẹ́ awakọ̀ tí yóò wá gbé e bí ó bá balẹ̀ ní pápá-ọkọ̀-òfuurufú!
Bí Rosemary ti sọ, ìrìnàjò nínúu ilẹ̀-adúláwọ̀ máa ń gba ṣíṣèrìnàjò kúrò ní ilẹ̀-adúláwọ̀ kí aṣèrìnàjò ó tó le è dé ibi tí ó ń lọ ní àárín Ilẹ̀-adúláwọ̀.
Ní ibi àpérò òṣìṣẹ́ ọkọ̀-òfuurufú agbègbè tí Àjọ Ìgbókègbódò Ọkọ̀-òfuurufú Àgbáyé (IATA) gbé kalẹ̀ tí ó wáyé ní Accra nínúu oṣù Òkúdù, Igbákejì Ààrẹ Orílẹ̀-èdèe Ghana, Oníṣègùn Mahamudu Bawumia pohùnréré-ẹkún látàríi wípé “ó yẹ oníṣòwò láti Freetown [Sierra Leone], fún àpẹẹrẹ, láti ṣe ìrìnàjò fún ọjọ́ méjì gbáko láti lọ sí Banjul (nípasẹ̀ẹ orílẹ̀-èdè kẹ́ta) fún ìrìnàjò tí kò ju wákàtí kan lọ.“
Ìpòyì lórí òfuurufú náà gbọ́mọ pọn pẹ̀lú owó kanangú fífò lókè láàárín Ilẹ̀-adúláwọ̀.
Ǹjẹ́ òtítọ́ ni wípé ó ṣeéṣe kí Ọmọ-adúláwọ̀ ó máà padà wálé?
Iṣẹ́ ìdóòlà-ẹ̀mí ní oríi omi Erékùsù Canary ní 2006.
Àwòrán láti ọwọ́ọ Noborder Network. (CC BY 2.0)
Ni àárín-n ọdún-un 2010-2017, àwọn aṣípòkiri láti àwọn orílẹ̀-èdè tí ó wà lábẹ́ Ìlú Gúúsù Aṣálẹ̀ Sahara ni ó ṣepò tí ó tẹ̀lé Syria gẹ́gẹ́ bí ìlú tí ó ní ènìyàn tó pọ̀ jù nínú àwọn aṣípòkiri lágbàáyé.
Ọ̀pọ̀lọpọ̀ Ọmọ-adúláwọ̀ ń sá kúrò nílùú nítorí ebi àti rògbòdìyàn, láti wábi forípamọ́síeek, didi ogúnlémidébí tàbí didi agbélùú ní Àréwá Amẹ́ríkà tàbí ní Éróòpù.
"Àbájáde Ìwádìí Pew ọdún-un 2018 sọ wípé iye àwọn aṣípòkiri láti Ìlú Gúúsù Aṣálẹ̀ Sahara ""ti fi ìdá 50 lọ sókè tàbí jù bẹ́ẹ̀ lọ ní àárín-in ọdún-un 2010 àti 2017, ju gbogbo rẹ̀ lọ wọn ju ìdá 17 lọ káríayé ní àsìkò kan náà""."
Awọn ọmọ-adúláwọ̀ tí ó wá láti Ìlú Gúúsù Aṣálẹ̀ Sahara náà ń ṣí kiri orílẹ̀-èdè jákèjádò àgbáyé.
Ní ọdún-un 2014, ó tó aṣíkiri 170,000 tí ò ní ìwé-àṣẹ lábẹ́ òfin ni ó ń wọ ọkọ̀ gba orí òkun Mediterranean lọ sí orílẹ̀-èdè Italy.
Ọ̀gọ̀rọ̀ ló wá láti àwọn Ìlú Gúúsù Aṣálẹ̀ Sahara.
"Ní oṣù Ọ̀pẹ ọdún-un 2018, Ọlọ́pàá Brazil dóòlà ẹ̀mí èèyàn 25 ọmọ-adúláwọ̀ tí ó wá láti Ìlú Gúúsù Aṣálẹ̀ Sahara ""tí ó ti wà lọ́rí omi òkun Atlantic fún oṣù kan gbáko""."
"Àwọn arìnrìnàjòó san ""ẹgbẹlẹmùkù owó lọ́wọ́ ẹnìkọ̀ọ̀kan"" fún ìrìnàjò láti Cape Verde. Ní oṣù Òkúdù ọdún-un 2019, US Customs Àjọ Aṣọ́bodè àti Ààbò Ibodè US ní Del Rio, Texas, USA, fi ọwọ́ọ ṣìkún òfin mú àwọn ọmọ-adúláwọ̀ 500 tí ó wà láti Ilẹ̀-olómìnira Congo, Democratic Republic of Congo, àti Angola, tí wọn ń fẹ́ gba omi Odò Rio Grande wọ USA."
Onírúurú ìròyìn ni ó ti rò ó wípé Ilẹ̀-adúláwọ̀ ni àárín-ín gbùngùn òtòṣì àti ogun, síbẹ̀síbẹ̀, Marie-Laurence Flahaux àti Hein De Haas, àwọn onímọ̀ láti Ifásitì ti Oxford àti Ifásitì ti Amsterdam, ní ṣísẹ̀ntèlé, kò gbà pé bẹ́ẹ̀ ní ó rí.
"Flahaux àti De Haas jiyàn wípé kò rí bí ìròyín ti ṣe rò ó sí etígbọ̀ọ́ ọmọ aráyé pàápàá ""àwọn ilé iṣẹ́ àti olóṣòlú"" àti àwọn ọlọ́gbọ́n náà."
"Iṣẹ́ ìwádìí fi yé wípé àwọn ìṣípòkiri láti Ilẹ̀-adúláwọ̀ kò déédéé wáyé, ohun tí ó fà á ni ""ìlànà ìdàgbàsókè àti ìyípadà àwùjọ"" èyí tí ó ń mú ṣíṣíkiri lọ sí àwọn agbègbè àgbáyé wu Ọmọ-adúláwọ̀ — tí kò yàtọ̀ sí aṣípòkiri láti ibòmìíràn lágbàáyé."
Àwọn ìròyìn abanilórúkọjẹ́ wọ̀nyí, ni ó ń fa sábàbí ìlànà-iṣẹ́ ìwé ìrìnnà:
Ọ̀pọ̀lọpọ̀ orílẹ̀-èdè ni ó nígbàgbọ́ wípé gbogbo arìnrìnàjò tí ó bá jẹ́ Ọmọ-adúláwọ̀ ni kò ní padà sí orílẹ̀-èdèe rẹ̀, àfi bí arìnrìnàjó bá ní ẹ̀rí tí ó yanrantí tó ni ó lè rí ìwé ìrìnnà ìwọ̀lú gbà.
Kò rọrùn láti ṣí ojú àwọn tí kì í ṣe ọmọ-adúláwọ̀ lójú nípa orúkọ búburú tí wọn ti sọ orílẹ̀-èdè tí ó wá láti Ilẹ̀-adúláwọ̀.
Níbàyìí, àwọn orílẹ̀-èdè Ilẹ̀-adúláwọ̀ níṣẹ́ láti ṣe sí ètò lílọ-àti-bíbọ̀ àwọn ọmọadúláwọ̀. Ìwé-ẹ̀rí-ọmọìlú-fún-ìrìnnà kan ṣoṣo fún gbogbo orílẹ̀-èdè ní Ilẹ̀-adúláwọ̀ jẹ́ ọ̀nà àbáyọ — àmọ́ kò tó.
Single African Air Transport market náà (SAATM), àti Continental Free Trade Agreement náà, tí a fi lọ́lẹ̀ lọ́dún tí ó kọjá, ti se àlàálẹ̀ ìgbésẹ̀ wọ̀nyí, ṣùgbọ́n ìmúṣẹ ṣì kù díẹ̀ káàtó.
Lásìkò yìí, gẹ́gẹ́ bíi Ọmọ-adúláwọ̀, ìyànjú láti rìnrìnàjò ni láti ní ìrírí ìrẹnisílẹ̀ tí àwọn tí ó ń se ìrìnàjò lọ sí òkè-òkun ń rí — tàbí jẹ́ títají nínú àlà ìsọ̀kan Ilẹ̀-adúláwọ̀ tí kò sí.
Èyí kéyìí tí ò báà jẹ́, òòsà ìwé ìrìnnà ń béèrè ẹbọ sí i, tí kọ̀ sì yé é gbẹbọ.
Ẹ̀rọ Alátagbà ni a fi gbé àwọn ìròyìn irọ́ àti ọ̀rọ̀ ẹlẹ́yàmẹyà jáde lásìkò ìdìbò orílẹ̀-èdèe Nàìjíríà
Irọ́ tí ó ti ara ẹlẹ́yàmẹyà sú yọ lórí ẹ̀rọ alátagbà lásìkò ìbò
Ìbò ààrẹ ti ọjọ́ 28, oṣù kẹta ọdún-un 2015 bí ó ṣe ń lọ lọ́wọ́ ní Abuja, Nàìjíríà. Àwòrán láti Iléeṣẹ́ Aṣojúu Ètò Ìrìnàjò sí orílẹ̀-èdèe US ní Nàìjíríà/ Idika Onyukwu [Ìgbóríyín fún òǹlàwòrán: Àìsí-fọ̀rọ̀-ajé 2.0 Àìlámì (CC BY-NC 2.0)]
Èyí ni àkọ́kọ́ nínú ìròyìn oníṣísẹ̀ntẹ̀lé ẹlẹ́ka-méjì tí ó dá fìrìgbagbòó lóríi ọ̀rọ̀ ìkórìíra ẹni, ìròyìn ẹlẹ́jẹ̀ àti irọ́ lórí ayélujára ní Nàìjíríà lásìkò ìbò ọdún-un 2019.
O leè ká apá kejì ìròyìn náà níbí.
Ọjọ́ 23, oṣù kejì ọdún-un 2019 ni àwọn ọmọ orílẹ̀-èdèe Nàìjíríà gba ẹ̀ka ìdìbò lọ láti dìbò yan ààrẹ àti ọmọ ìgbìmọ̀ tuntun sípò.
"Àwọn méjì gbòógì òǹdíjedupò sí ipò ààrẹ, Ààrẹ tí ó wà lórí àléfà kó ìbò ẹgbẹẹgbẹ̀rún 15 tí ó mú u borí olórogún-un rẹ̀ pẹ́kípẹ́kí, Atiku Abubakar, pẹ̀lú ""àlàfo idà 56 sí ìdá 41""."
A ṣe ìbúra fún Buhari fún sáà kejì ọlọ́dún mẹ́rin lọ́jọ́ 29, oṣù karùn-ún, 2019.
Kà sí i: #NigeriaDecides2019: Ohun gbogbo tí ó yẹ kí o mọ̀ nípa ìdìbò gbogboògbò ti ọdún nìí
Síbẹ̀, ohun gbogbo tí ó gbà ni wọ́n fi ṣe ìpolongo ìbò náà, láì yọ bíbẹ ẹ̀rọ alátagbà lọ́wẹ̀ sílẹ̀.
Ọ̀rọ̀ ìkórìíra tẹ̀gbintẹ̀gbin tòun ìwà ẹlẹ́yàmẹyà àti ìròyìn irọ́ ràn bíi pápá inú ọyẹ́ ní orí ẹ̀rọ ayélujára, pabambarì lóríi gbàgede Twitter.
Ìkórìíra Ẹ̀yà ní Nàìjíríà
Ẹ̀yà onírúurú – tí ó tó bíi 250 àti èdè 500 – ti fi ìgbà kan jẹ́ orísun àìbalẹ̀ọkàn dípòo ìfọ̀kànbalẹ̀.
Èyí fi ojú hàn lásìkò ìbò nígbàtí àwọn olóṣèlú lo ẹlẹ́yàmẹ́lẹ́yá fi polongo ìbò.
Láti ilẹ̀, ìtàkùrọ̀sọ lórí ayélujára ní Nàìjíríà kò lọ láì sí ìkórìíra.
Kà sí i: Nàìjíríà: Gbígbógun ti àpọ̀jù ìkórìíra ẹ̀yà tẹ̀gbintẹ̀gbin — lójúkorojú àti lórí ayélujára
Lásìkò ìbò ọdún-un 2015, fún àpẹẹrẹ, gbàgede Twitter ní orílẹ̀-èdèe Nàìjíríà di ibi ìkorò àti ibi ìdíje ìjuwọ́ láàárín àwọn alátìlẹ́yìn àwọn òǹdíje méjì ìgbà náà, Goodluck Jonathan (PDP, ọmọ lẹ́yìn Krístì tó jẹ́ ọmọ Ijaw) àti Muhammadu Buhari (APC, Ìmàle, Hausa, Fulani).
Twitter di irinṣẹ́ fún ìgbéròyìn ìkórìíra ẹ̀yà tẹ̀gbintẹ̀gbin jáde àti ohun èlò fún ẹgbẹ́ olóṣèlú.
Àwọn kan lérò wípé ọdún-un 2019 yóò yàtọ̀ nítorí pé Buhari ti ẹgbẹ́ẹ Àjọ Ìtẹ̀síwájú Gbogboògbò (APC) àti Abubakar láti Ẹgbẹ́ olóṣèlú Ìjọba-tiwantiwa Àwọn Ènìyàn (PDP) tí àwọn méjèèjì sì jẹ́ Hausa, Fulani Ìmàle, àmọ́ bẹ́ẹ̀ kọ́ ló rí.
Àwọn amúgbálẹ́gbẹ̀ẹ́ wọn – Yẹmí Ọṣìńbàjò (APC), ọmọ Yoruba, àti Peter Obi (PDP), ọmọ Igbo, jẹ́ Ọmọ-lẹ́yìn-in-krístì — àmọ́ láti ẹ̀yà ọ̀tọ̀ọ̀tọ̀.
Ó fẹ́ jọ àtúnwáyé ìṣẹ̀lẹ̀ 2015 ṣùgbọ́n pẹ̀lú atakànàngbọ̀n mìíràn.
Ohun gbogbo nípa ìṣèlú Nàìjíríà wọṣọ ẹlẹ́yàmẹ́lẹ́yá ní 2017, ọdún méjì kí ìbò ó tó bẹ̀rẹ̀, tí ó sì fa àìgbàgbọ́ nínú ètò ìṣèlú.
Ẹgbẹ́ ajìjàngbara ọmọ ìbílẹ̀ Biafra Indigenous People of Biafra (IPOB), tí ó jẹ́ àgbáríjọpọ̀ àwọn ọmọ ìbílẹ̀ ìlà-oòrùn orílẹ̀-èdèe Nàìjíríà tí Nnamdi Kanu jẹ́ olórí, dá kún rògbòdìyàn tí ó ń rọ́ tìtì.
Kà sí i: Bí ọ̀rọ̀ ìkórìíra tẹ̀gbintẹ̀gbin ṣe ń peléke sí i, àwọn òǹkọ̀wée Nàìjíríà náà múṣẹ́ ṣe
Ìdi-aṣálẹ̀-ilẹ̀ ní àríwá Nàìjíríà ló mú kí àwọn ọlọ́sìn-ẹran tí ó jẹ́ darandaran tí ó ń bá àwọn àgbẹ̀ jà ó wà sí apá gúúsù.
Àwọn Ọmọ-lẹ́yìn-in-krístì kan “rí gbígba àwọn Fulani darandaran tí ó jẹ́ Ìmàle tọwọ́tẹsẹ̀ wọlé sí apáa gúúsù gẹ́gẹ́ bíi ìgbésẹ̀ láti 'Sọnidìmàlè' ní tipátipá.
"Ìkọ̀jálẹ́ ìjọba Nàìjíríà láti ṣe ìwádìí sí àwọn ìkọlù tí ó ń wáyé àti ""fífimú àwọn tí ó ṣẹ̀ sófin dánrin"", tí ìkọlù náà sì fa ikú àwọn ènìyàn tí ó tó bíi ẹgbẹ̀rún 4 láti ọdún-un 2015 sí 2018, gẹ́gẹ́ bí iléeṣẹ́ Amnesty International ti ṣe ní i lákọsílẹ̀."
Láti ìhín lọ, ẹlẹ́yàmẹyà ti ń peléke sí i kí ó tó di àsìkò ìbò ààrẹ ọdún-un 2019.
Àìnígbàgbọ́ tí ó wà nílẹ̀ ló fi àyè gba ìgbéjáde ìròyìn irọ́ – lójúkorojú àti lórí ayélujára – lásìkò ìbò.
Ìbò àti ìgbàgbọ́ ọ̀rọ̀ orí ẹ̀rọ ayélujára ní Nàìjíríà
Iye àwọn òǹlò ẹ̀rọ ayélujára ní Nàìjíríà fò fẹ̀rẹ̀ sókè láti ẹgbẹẹgbẹ̀rún 98.3 ní ọdún-un 2017 sí ẹgbẹẹgbẹ̀rún 100.5 ní 2018.
Facebook ló léwájú gẹ́gẹ́ bí i gbàgede ààyò ọ̀pọ̀ ọmọ orílẹ̀-èdèe Nàìjíríà pẹ̀lú òǹlò ẹgbẹẹgbẹ̀rún 22, tí gbàgede àwòrán-àtohùn YouTube (ẹgbẹẹgbẹ̀rún 7 àti jù bẹ́ẹ̀ lọ) tẹ̀lé e, Twitter (ẹgbẹẹgbẹ̀rún 6) àti Instagram (ẹgbẹẹgbẹ̀rún 5.7).
Ọ̀dọ́ ni ọ̀pọ̀lọpọ̀ àwọn olùdìbò orílẹ̀-èdèe Nàìjíríà. Lára ẹgbẹẹgbẹ̀rún 84 àwọn olùdìbò tí ó forúkọsílẹ̀ fún Ìbò Àpapọ̀ ọdún-un 2019, tí ìdajì — ìdá 51 — jẹ́ ọ̀dọ́ òǹdìbò tí ọjọ́ oríi wọ́n tó ọdún 18 àti 35, tí ìdá 30 sì jẹ́ ẹni ọdún 36 àti 50.
Àwọn ọjọ́-orí méjèèjì yìí, tí ó ní onímọ̀ nípa ìlò ẹ̀rọ ayárabíàṣá àti àwọn aṣípò sórí ẹ̀rọ ayárabíàṣá, ni ó pọ̀ jù lọ nínú àwọn olùdìbòo Nàìjíríà.
Torí ìdí èyí, kò yanilẹ́nu wípé ẹ̀rọ ayárabíàṣá jẹ́ gbàgede kan gbòógì fún fífi ìpolongo ìbò ọdún-un 2019 sọta ìjà lura ẹni.
Látàrí èyí, ó mú u ṣòro láti gbọ́kàn tẹ àwọn ìròyìn orí ayélukára-bí-ajere lásìkò ètò ìdìbò tó wáyé lọ́dún-un 2019.
Ìròyìn irọ́ tí kò ní gbọ́ngbọ́n nínú ni wọ́n polongo gẹ́gẹ́ ìhìn rere tòótọ́, tí àwọn alátìlẹ́yìn ẹgbẹ́ olóṣèlú méjèèjì tí ó gbajúmọ̀ jù lọ ní orílẹ̀-èdèe Nàìjíríà sì lukoro rẹ̀: Àjọ Ìtẹ̀síwájú Gbogboògbò All Progressive Congress (APC) àti Ẹgbẹ́ olóṣèlú Ìjọba-tiwantiwa Àwọn Ènìyàn People's Democratic Party (PDP).
Gẹ́gẹ́ bí ìkíyèsí ẹ̀yà tí ó wáyé láàárín ọjọ́ 28 oṣù kẹwàá, 2018, àti ọjọ́ 29, oṣù karùn-ún 2019, ọ̀rọ̀ ìkórìíra ẹ̀yà tẹ̀gbintẹ̀gbin jẹ́ irinṣẹ́ fún ìròyìn tí kò ní gbọ́ngbọ́n ń'nú tí ó kún fún irọ́ láti sàkání ẹgbẹ́ olóṣèlú méjèèjì ní oríi Twitter ti Nàìjíríà lásìkò ìbò ààrẹ 2019.
A ká àwọn ìkíyèsí yìí sílẹ̀ láti orí ayélujára ní àsìkò yìí.
Tí a bá sọ nípa ìròyìn irọ́ nípa ti ẹlẹ́yàmẹyà, àwọn agbárùkù ti ẹgbẹ́ olóṣèlúu APC yọ ẹnu ìwọ̀sí sí Obi lára nítorí pé ó dá àwọn ará òkè Ọya padà nígbà tí ó wà lórí ipò gẹ́gẹ́ bí aláṣẹ Ìpínlẹ̀ Anambra, ní ìlà-oòrùn gúúsù orílẹ̀-èdèe Nàìjíríà.
Túwíìtì tàn kárí ilé kárí oko tí ó sọ pé àwọn ọmọ Yorùbá ń tiná bọ ìsọ̀ àwọn oníṣòwò tí ó jẹ́ ẹ̀yà Igbo ní Èkó. Irọ́ funfun báláwú ni àwọn ìròyìn wọ̀nyí, a ó gbé e yẹ̀ wò síwájú sí i nínú Apá kejì àròkọ yìí.
Àwòrán 1: Túwíìtì irọ́ ti Festus Keyamo
Àwòrán 2: Àṣírí bi tí àwòrán tí Keyamo tari síta wà ní ti òtítọ́.
Fún àpẹẹrẹ òmíràn, a lo àwòrán kan báyìí lọ́nà tí kò yẹ. Lọ́jọ́ 28, oṣù kẹwàá, ọdún-un, 2018, Festus Keyamo, olùdarí ètò ìkéde àná fún Iléeṣẹ́ Ìpolongo fún Buhari, túwíìtì àwòrán kan (Aworan 1) ti igi kan tí ó ń wù láàárín ojú irin kan tí ó ti di àpatì:
Bí igí ṣe ń wù sí àárín ojú irin ní 1999 sí 2015...
Báyìí, ‘Sáà Ìparí iṣẹ́’ rè é, àwọn ojú irin náà ti ń jí padà sáyé.” Ìjọba PDP ló ń tukọ̀ ètò ní 1999 sí 2015.
Lẹ́yìn-ò-rẹyìn, òǹlò Twitter kan tí ó jẹ́ ọmọ orílẹ̀-èdèe Nàìjíríà tọ ipasẹ̀ẹ àwòrán náà sí túwíìtì kan lédèe Lárúbáwá (Àwòrán 2) tí ẹnìkan tari síta nínú oṣù yẹn.
Túwíìtì náà jẹ́rìí wípé Lebanon ni àwòrán ọ̀hún ti ṣẹ̀ wá.
Ohun tí Keyamo fẹ́ ṣe ni láti fi hàn wípé ìṣàkóso ìjọba Buhari ti gbé ìgbésẹ̀ àtúnṣe sí àwọn ọ̀nà ọkọ̀ọ ojú irin tí ìjọba àná pa tì.
"Àmọ́ ṣá, àwòrán orílẹ̀-èdè mìíràn tí ó lò láti fi sọ ""ìtẹ̀síwájú"" náà, fọ́ gbogbo rẹ̀ lójú."
Àwòrán 3: Ọ̀rọ̀ ìkórìíra ẹ̀yà tẹ̀gbintẹ̀gbin
Àwòrán 4: El-Rufai tọrọ àforíjì fún túwíìtì “tí ó lè dá wàhálà sílẹ̀” náà tí ó wà ń'nú Àwòrán 3.
Ọ̀rọ̀ ìkórìíra ẹ̀yà tẹ̀gbintẹ̀gbin ṣẹ́ yọ kí ọjọ́ ìbò ó tó kò, lásìkò ìbò àti lẹ́yìn ìbò.
Túwíìtì ẹlẹ́yàmẹyà kan (Àwòrán 3) Bashir El-Rufai, ọmọ Aláṣẹ Ìpínlẹ̀ Kaduna, wí pé ẹ̀yà Igbo ló fi ìbínú tan iná ọ̀tẹ̀ tí ó fa Ogun Abẹ́lée Nàìjíríà.
Láàárín 1967 sí 1970, orílẹ̀-èdèe Nàìjíríà ja ogun kíkorò kan pẹ̀lú ìlúu Biafra tí í ṣe àwọn ẹ̀yà Igbo tí ó wà ní apá ìlà-oòrùn gúúsù, tí ó ń gbèrò láti pín yà kúrò lábẹ́ ìṣàkóso ìjọba Nàìjíríà.
Síbẹ̀, gẹ́gẹ́ bí Bashir El-Rufai ti ṣe sọ, àbájáde ìbò ọdún-un 2019 tí ẹgbẹ́ẹ rẹ̀, APC, gbégbà-orókè. Ó yẹ kí a rí i bíi “ẹ̀san” láti apá ọ̀dọ̀ àwọn ẹ̀yà Hausa, Fulani.
"Ó padà wá á tọrọ àforíjì, lẹ́yìn tí a ti bu ẹnu àtẹ́ lù ú, fún túwíìtì ""tí ó lè dá wàhálà sílẹ̀ "" bí a ti rí i nínú Àwòrán."
Bákan náà ni ó mú túwíìtì ìsọkúsọ náà wálẹ̀ (Àwòrán 3).
Ìròyìn irọ́ tí ó ti ara ẹlẹ́yàmẹyà wá lórí ẹ̀rọ-alátagbà lásìkò ìbò ṣe é pín sábẹ́ ẹ̀ka méjì: ìròyìn tí kò ní gbọ́ngbọ́n nínú àti ìròyìn irọ́.
"Miroslav Tudjman àti Nives Mikelic, ọ̀mọ̀wé nípa ìtàkùrọ̀sọ ní Ifáfitì ti Zagreb, Croatia, túmọ̀ ìròyìn tí kò ní gbọ́ngbọ́n nínú sí ""ìròyìn àmọ̀ọ́mọ̀ tari síta láti ṣi àwọn ènìyàn lọ́kàn""."
Ète títari ìròyìn irọ́ síta bí òtítọ́, ló ya ìròyìn tí ó ń ṣini lọ́kàn àti ìròyìn irọ́ sọ́tọ́.
Tudjman àti Mikelic sọ wípé ọ̀nà ìtànkálẹ̀ ìròyìn fẹ̀jú ju ìròyìn àmọ̀ọ́mọ̀ tari síta láti ṣini lọ́kàn tàbí ìròyìn irọ́ lọ.
"Ìdí ni pé ọ̀nà ìtànkálẹ̀ ìròyìn ""máa ń yí ìhùwàsí ẹni padà"" nípasẹ̀ ""ìṣẹ̀lẹ̀ àìròtẹ́lẹ̀ kan tàbí ìgbésẹ̀ àmọ̀ọ́mọ̀ dá lásìkò ìtari ìtàkùrọ̀sọ [náà] síta""."
Bí irú èyí, ọ̀nà ìtànkálẹ̀ ìròyìn máa ń tẹ̀sí apá kan tàbí àìpé ìròyìn fún àǹfààní ọ̀rọ̀ òṣèlú àti yíyí ìrònú padà níparí.
"Ìbẹ̀rùbojo ọkàn bẹ́ sílẹ̀ látàrí ìbò ọdún-un 2019 nítorí ìròyìn irọ́ àti ọ̀nà ìtànkálẹ̀ ìròyìn ń ṣe àgbédìde àìbalẹ̀ ọkàn tí ó ti ọ̀rọ̀ ìbò bẹ̀rẹ̀ àmọ́ tí ó ń fa ""ìdẹ́rùbà fún ìparí-ìjà tí ìbòó bá kásẹ̀ ńlẹ̀ ""."
Apá kejì àròkọ yìí yóò ṣe àgbéyẹ̀wò bí èyí ṣe wáyé lórí ayélujára, pàápàá lóríi gbàgede Twitter, pẹ̀lú àwọn àpẹẹrẹ mélòó kan.
Àpilẹ̀kọ yìí jẹ́ ara àtẹ̀jádé ìròyìn oníṣísẹ̀ntẹ̀lé tí ó ń ṣe àgbéyẹ̀wò ìṣúsí pẹ̀lú ẹ̀tọ́ ìlò ẹ̀rọ-ayárabíàṣá nípa àwọn ìlànà bíi ìṣánpa ìṣàsopọ̀ ẹ̀rọ ayélukára-bí-ajere àti ìròyìn ẹlẹ́jẹ̀ lásìkò ètò ìṣèlú tí ó pọn dandan ní orílẹ̀-èdè méje ní Ilẹ̀-Adúláwọ̀: Algeria, Ethiopia, Mozambique, Nàìjíríà, Tunisia, Uganda, àti Zimbabwe.
Africa Digital Rights Fund àti The Collaboration on International ICT Policy for East and Southern Africa (CIPESA) ni agbátẹrù iṣẹ́ àkànṣe yìí.
Ní Kenya àti Ethiopia, àwọn ọkùnrin wọ̀nyí ríran ‘àwòrán-ìtọ́nà’ àt'ọ̀run wá láti gbẹ́ ihò nísàlẹ̀ ilẹ̀
Àwọn ọkùnrin méjèèjì sọ wípé Ọlọ́run ló yọ sí àwọn
Ihò nísàlẹ̀ ilẹ̀ẹ Dunbar ní gúúsù Ethiopia tí Mohammed Yiso Banatah gbẹ́ jáde pẹ̀lú ọwọ́ọ rẹ̀ láì lo ohunkóhun.
Allah l'ó pa á láṣẹ láti gbẹ́ ilé Ọlọ́run fún ètò ìgbéyàwó sísàlẹ̀ ilẹ̀.
Àwòrán láti ọwọ́ọ Amanda Leigh Lichtenstein, a fi àṣẹ lò ó.
Lọ́jọ́ 26 oṣù Ọ̀pẹ, BBC Swahili gbé àwòrán-àtohùn kan tí ó ṣe àfihàn-an Francisco Ouma, ẹni àgbà kan láti Busia, ìlà-oòrùnun Kenya, ẹni tí ó gbọ́ ohùn Ọlọ́run láti gbẹ́ ihò nísàlẹ̀ ilẹ̀ jáde.
Ìran náà wá nípasẹ̀ àwòrán ìtọ́nà tí ó rí lójú àwọn àláa rẹ̀.
Láti inú oṣù kejì ọdún-un 1967, ni Ouma ti ń tọ ipasẹ̀ẹ ìtọ́nà látọ̀run wá náà tí ó gbà Iójú àláa rẹ̀.
Lónìí, ihò nísàlẹ̀ ilẹ̀ẹ rẹ̀ ti ní yàrá 24 tí ó sì ń lé sí i.
Àgékù àwòrán-an Francis Ouma, tí ó gbọ́ ohùn Ọlọ́run láti gbẹ́ ihò sísàlẹ̀ ilẹ̀ tí ó ní 24 ìyàrá lóríi BBC Swahili / Instagram.
Láti ayébáyé, ọ̀pọ̀ ènìyàn ló ti ní kò sí ẹ̀rí tí ó dájú wípé ìran àt'ọ̀run wá ni àwọn irú àlá báwọ̀nyí, tí wọn ń dẹ́jàá ìlera ọpọlọ irú ẹni bẹ́ẹ̀ tí ó pé òún ríran lójú àlá.
Àmọ́ àwọn òjíṣẹ́ ẹ̀sìn Ìmàle, Júù àti Onígbàgbọ́ gbogboó ti jẹ́rìí sí ìran láti ọ̀dọ̀ Ọlọ́run ent tí ó wá lójú àlá fún ẹgbẹẹgbẹ̀rún ọdún.
Ọlọ́run fi nǹkankan bí àwòrán-ìtọ́nà hàn mí, Ouma sọ fún BBC Swahili.
Nígbà yẹn, nígbà tí mò ń wa ilẹ̀, àwòrán-ìtọ́nà yìí ni mo tẹ̀lé.
Kì í ṣe nígbà tí mò ń walẹ̀ nìkan, ó dára jù kí n máa walẹ̀ lọ, rárá.
Ìtúlẹ̀ àti ọwọ́ọ rẹ̀ méjèèjì ni ó lò, Ouma kan àwọn òkúta abẹ́lẹ̀ tí kò mú ìwalẹ̀ náà rọrùn fún un.
Àṣẹ̀yìnwá àṣẹ̀yìnbọ ó rí ibi tí yóò ti mú àwòrán-ìtọ́nà ihò nísàlẹ̀ ilẹ̀ẹ Ọlọ́run tí ó wà ní ọkàn-an rẹ̀ wá sí ìmúṣẹ.
Nínú ìyẹ̀wù kan, ó ní òkúta kan tí a kọ ọ̀rọ̀ọ Jésù sí lára.
Jésù Kristì ni ẹni tí ó mú ìròyìn yìí wá fún mi, Ouma sọ, ó sì ṣàlàyée rẹ̀ fún mi gẹ́gẹ́ bí ó ti ṣe ṣe fún Mósè.
Ouma gbàgbọ́ wípé òun ń mú májẹ̀mú mìíràn pẹ̀lú Ọlọ́run padà wá sílé ayé.
Ìpele kejì ń bọ̀ lọ́nà.
Èyí ni ìpele àkọ́kọ́ ti májẹ̀mú náà.
Ìkejì ń bọ̀ lọ́nà.
Mi ò leè sọ ní pàtó ohun tí yóò jẹ́ báyìí nítorí bí mo bá kédee rẹ̀, mo lè máa yan ìṣẹ̀dá ẹ̀dá ọmọ ènìyàn jẹ.
Toríi bẹ́ẹ̀, mo máa dúró fún ìjábọ̀ náà bí ó bá tó àsìkò, Ouma wí fún BBC Swahili.
Àwòrán-àtohùn-un BBC Swahili ti di wíwò fún ìgbà 50,000 pẹ̀lú èsì tí ó tó 100 tí ó sì ń lé sí í.
Níwọ̀n-ọn bí àwọn kan ti sọ nípa àìlera ọpọlọ àwọn t'ó ń sọ pé àwọn gbọ́hùn Ọlọ́run lójú àlá, tí ọ̀pọ̀lọpọ̀ èsì àdásí gbè lẹ́yìn àwọn ẹni Ọlọ́run tí ó sọ sí ìran ojú àlá.
Òǹlòo Instagram kan kọ:
Ìtúmọ̀ Ìtúnwí-ọ̀rọ̀ Ọlọ́rọ̀ gan-an
Fún èmi, àwọn ènìyàn báyìí, mo máa ń gbà wọ́n gbọ́ gidi gan-an, ju àwọn tí ó máa ń fi ọ̀rọ̀ Ọlọ́run [rọ] wá nílé ìjọsìn, fún ọdún 52 èèyàn-án wa ilẹ̀ — bí kò bá tẹ̀lé ọkàn-an rẹ̀, ṣé kò yẹ kí àdúgbòo rẹ̀ àti ìjọba ó dá a mọ̀?
Kò tilẹ̀ béèrè fún ìrànwọ́ fún katakata tàbí owó fún làálàáa rẹ̀. A kò gbọdọ̀ dájọ́ ẹni yìí.
Mohammed Yiso Banatah lọ́dún-un 2012 ṣàlàyé àlá mẹ́wàá tí Allah yọ sí òun lójú àlá láti gbẹ́ ilé Ọlọ́run fún ìgbéyàwó sábẹ́ ilẹ̀.
Àwòrán láti ọwọ́ọ Amanda Leigh Lichtenstein.
Ilé Ọlọ́run fún ètò ìgbéyàwó Ethiopia
Ní gúúsù Ethiopia, ẹ̀rí tí ó jọra á wá láti àgbàlagbà kan tí orúkọ rẹ̀ ń jẹ́ Mohammed Yiso Banatah, tí ó ní lọ́dún-un 2012 wípé Allah yọ sí òun ní ọdún 33 sẹ́yìn lójú àlá lẹ́ẹ̀mẹwàá ọ̀tọ̀ọ̀tọ̀.
Lójú àwọn àlá náà, ó gbọ́ ohùn-un Allah láti gbẹ́ ihò ilé Ọlọ́run fún ètò ìgbéyàwó nísàlẹ̀ ilẹ̀.
Ihò nísàlẹ̀ ilẹ̀ẹ Dunbar ni a mọ̀ ọ́ sí, ilé Ọlọ́run fẹ̀nfẹ̀ wọ̀nyí wà ní ẹ̀bá ọ̀nàa Banatah tí í ṣe ìlàjì ọ̀nàa Hawassa àti Shashamene.
Banatah sọ wípé nínú àláa rẹ̀ kẹ́ta ni ó ti rí àwòṣe fún àwọn ilé Ọlọ́run wọ̀nyí.
O lè ka ẹ̀kúnrẹ́rẹ́ àkọsílẹ̀ àláa Banatah ní ṣísẹ̀-n-tẹ̀lé àti ohun tí ó gùn ún kí ó tó bẹ̀rẹ̀ iṣẹ́ ìwalẹ̀ ayée rẹ̀ níbí:
Lójú àláa àsèkágbáa rẹ̀, èyí tí ó jẹ́ ìkẹwàá nínú àkọsílẹ̀ oníṣísẹ̀ntẹ̀lé ọdún-un 1979, ọkùnrin kan fara hàn tí ó mú Mohammed lọ sí ibi igi kékeré kan nínúu ọgbàa rẹ̀, ó sì tọ́ka sí egbòo rẹ̀.
Ọkùnrin náà fi ojú ibi tí yóò ti bẹ̀rẹ̀ ìwalẹ̀, ó sì tún sọ fún un pé lórí iṣẹ́ ìwalẹ̀ náà ni yóò ti là.
Ní ọ̀gànjọ́, ó ríran rí wúrà.
Agbègbè tí ó sún mọ́ jìnà, àwọn ohun tí ó jìnà di fífà sún mọ́ ọ.
A sọ ibi tí yóò ti bẹ̀rẹ̀ ìwalẹ̀, ìgbà tí yó bẹ̀rẹ̀ àti bí yóò ṣe bẹ̀rẹ̀ .
Lọ́jọ́ kejì, nígbà tí ó lajú sáyé, ó bẹ̀rẹ̀ síí gbẹ́lẹ̀ pẹ̀lú ọwọ́ọ rẹ̀ nìkan láì lo ìtúlẹ̀.
Ihò nísàlẹ̀ ilẹ̀ tí ìmọ́lẹ̀ oòrùn tán sínúu rẹ̀ wọ̀nyí ti di ibi ìgbafẹ́ olówó kékeré fún àwọn èèyàn láti ṣe ìrinsẹ̀ máìlì mẹ́rin lábẹ́ ilẹ̀ tí ó pa lọ́lọ́.
Àwọn àfẹ́sọ́nà kan ti ṣe ètò ìgbéyàwó níbé.
Bí a ṣe kọ́ àwọn ìyẹ̀wù wọ̀nyí fi iṣẹ́ ọpọlọ àti itú ọwọ́ọ Mohammed hàn – ó ti fi ìfarabalẹ̀ lọ ọ̀pọ̀lọpọ̀ wákàtí fún gbígbẹ́, dídán, àti ṣíṣe iṣẹ́ ọnà sí gbogbo kọ́lọ́fín inú iyàrá àti ògiri, pẹ̀lú àwọn tìmùtìmù, àti pẹpẹ tí a fi iyẹ̀pẹ̀ mọ nínúu rẹ̀, tí àwọn yàrá mìíràn ní fèrèsé tí ìmọ́lẹ̀ oòrùn ń tàn gbà láti ibi tí ẹnìkan kò mọ̀.
Láti ayébáyé ni ihò nísàlẹ̀ ilẹ̀ ti jẹ́ ibi àpẹẹrẹ tí a kà sí gẹ́gẹ́ bí ibi ti ẹ̀mí.
"Odindin ìwé kan gbáko tí a pè ní ""Al Kahf"" tàbí ""Ihò nísàlẹ̀ ilẹ̀ "" jẹyọ nínúu ìwé mímọ́ọ Kuran."
"Nínúu rẹ̀ ni a ti bá ìtàn Ẹ̀sìn ìgbàgbọ́ kan tí a mọ̀ sí ""Àwọn ẹni Ihò-òkúta"", which nínú èyí tí àwọn ọ̀dọ́, jìyà àìṣẹ̀ nítorí ìgbàgbọ́ọ wọ́n sá kúrò nílùú, wọ́n sì wá ibi ihò-òkúta kan sùn sí."
Nígbà tí wọ́n jí, wọ́n padà sílé, wọ́n sì ṣàkíyèsí wípé gbogbo ọmọ ìlú ti di ònígbàgbọ́.
Kíni ìdí irẹ̀ tí Donald Trump ṣe l'ókìkí ní Nàìjíríà?
Trump ní ọ̀pọ̀lọpọ̀ olólùfẹ́ ní gúúsù orílẹ̀-èdèe Nàìjíríà
Ààrẹ Donald Trump padà sí Ilé Agbára Funfun ní Washington lọ́jọ́ 19 oṣù Ògún, ọdún-un 2018.
Àwòrán láti ọwọ́ọ Samira Bouaou/The Epoch Times, CC BY 2.0.
Ààrẹ orílẹ̀-èdèe Amẹ́ríkà Donald Trump ti ré sí ipò ìsàlẹ̀ lójú àwọn ènìyàn kárí ayé látàrí àwọn òfin rẹ̀ àti bí ó ṣe ń ṣe ìṣàkóso ọ̀ràn tí ó jẹ mọ́ orílẹ̀-èdèe òkèèrè — àmọ́ kò rí bẹ́ẹ̀ ní àwọn orílẹ̀-èdè bíi Nàìjíríà.
"Ní kò pẹ́ kò pẹ́ yìí ni ìwádìí àyẹ̀wò tí Pew Research Centre ṣagbátẹrùu rẹ̀ fi hàn wípé ọ̀gọ̀rọ̀ ọmọ Nàìjíríà ""fi Ògún-un rẹ̀ gbárí"" wípé Trump ""yóò gbé ìgbésẹ̀ tí ó lààmìlaka nípa ti ọ̀ràn àgbáyé""."
Orí ẹ̀rọ-ìbánisọ̀rọ̀ àti ìfọ̀rọ̀wánilẹ́nuwò ojúkorojú ni Gallup – iléeṣẹ́ aṣàgbéyẹ̀wò fínnífínní àti iléeṣẹ́ olùdámọ̀ràn tí ó wà ní Washington, DC fi gba èsì jọ nínú ìwádìí àyẹ̀wò èrò àwọn ènìyàn-an fún Pew.
Àgbéyẹ̀wò Tweepsmap kan tí ó dá lóríi iye àwọn tí ó ń tẹ̀lé Trump lóríi ẹ̀rọ alátagbà Twitter ṣe òfófó wípé ipò karùn-ún ni Nàìjíríà dúró sí nínú àwọn orílẹ̀-èdè márùn-ún lágbàáyé:
"Òǹkọ̀wé tí í ṣe ọmọ bíbí orílẹ̀-èdèe Nàìjíríà Adaobi Tricia Nwaubani làdíi rẹ̀ fún àgbáyé lórí ètò ẹ̀rọ agbóhùnsáfẹ́fẹ́ kan tí ó jẹ́ àbáṣepọ̀ pẹ̀lú BBC, wípé ìrísíi Trump gẹ́gẹ́ bí ""ọkùnrin alágídí"" mú kí àwọn ọmọ orílẹ̀-èdè tí ó kún fún ènìyàn jù lọ ní Ilẹ̀-Adúláwọ̀ ó fẹ́ràn-an rẹ̀ dé góńgó:"
Àwọn ènìyàn fẹ́ràn-an ìhùwàsí alágídíi rẹ̀ àti pé àìfọ̀rọ̀ sábẹ́ ahọ́n-ọn rẹ̀ dùn ún gbọ́ sétí.
Àwọn ọmọ Amẹ́ríkà rí i bí àkàndá ènìyàn.
Ìhùwàsíi rẹ̀ kò bá tayé mu.
Kì í ṣe ẹni tí wọ́n sọ pé ó jẹ́.
Àmọ́ irú olórí tí kì í lọ́ra sọ̀rọ̀ bí ó ti wù ú kò jẹ́ tuntun sí wa.
Torí ìdí èyí, ìhùwàsíi rẹ̀ kò bàjẹ́ tó bẹ́ẹ̀ bí àwọn ọmọ Amẹ́ríkà ṣe ń rí i.
Ìdí mìíràn ni ẹ̀sìn.
Àwọn Ọmọ lẹ́yìn-in Krístì nífẹ̀ẹ́ẹ Trump
Cheta Nwanze, Olórí Ìwádìí ní SBM Intelligence sọ fún Ohùn Àgbáyé:
Ó hùn mí láti mọ IBI tí wọ́n ti ṣe ìwádìí-àyẹ̀wò yìí ní Nàìjíríà.
Mo mọ̀ dájú wípé kì í ṣe káríi gúúsù orílẹ̀-èdèe Nàìjíríà, tí ó ṣàlàyé ìfẹ́ tí ọmọ Nàìjíríà ní sí Trump.
Ọ̀pọ̀ nínú àwọn olólùfẹ́ẹ rẹ̀ l'ó jẹ́ Onígbàgbọ́, tí wọ́n ń gbójú sókè wò ó bí àwòkọ́ṣe rere.
Nàìjíríà, pẹ̀lú iye ènìyàn ìlú tí ó tó ẹgbẹẹgbẹ̀rún 200 èèyàn, ní ẹ̀sìn méjì tí àwọn ènìyàn-án ń ṣe jù: ẹ̀sìn Ìgbàgbọ́ àti Ìmàle.
Ìmàle àti Ìgbàgbọ́ kó ìdá 50 àti ìdá 48 iye gbogbo ènìyàn t'ó ń gbé Nàìjíríà.
"Ìlànà ìwádìí náà fi hàn wípé ""iléeṣẹ́ ìjọba Ìpínlẹ̀ tí wọ́n sì pín àwọn ènìyàn sí agbègbè"" ni wọ́n ti ṣe ìwádìí àyẹ̀wò yìí."
Bí ó ti wù kíó rí, kò sí ohùn àwọn Adamawa, Borno, àti ìpínlẹ̀ Yobe ní àríwá ìlà-oòrùn Nàìjíríà nínú àbájáde ìwádìí náà nítorí ọ̀rọ̀ ààbò.
Nàìjíríà ní ìjọba ìbílẹ̀ 774, tí í ṣe ẹ̀ka aláṣẹ ìjọba ìbílẹ̀. Bákan náà ni ó ní ẹ̀ka àkóso mẹ́fàá.
Àárín gbùngbùn Àríwá, Àríwá Ìlà-oòrùn, Àríwá Ìwọ̀-oòrùn, Àjìǹdò-gúúsù, Ìwọ̀-oòrùn gúúsù, àti Ìlà-oòrùnun gúúsù.
Ọ̀rọ̀ọ Nwanze pé àwọn Onígbàgbọ́ ní gúúsù Nàìjíríà ló pọ̀ jù lọ nínú ìwádìí àyẹ̀wò Pew Research kò ṣe é má gbàgbọ́.
"Ìwádìí àyẹ̀wò náà tún fi hàn pé ọ̀pọ̀ ọmọ lẹ́yìn Krístì ní Nàìjíríà ""rí orílẹ̀-èdèe US bí ìlú tí ó dára (ìdá 69) ju bí àwọn Ìmàlé ṣe rí i lọ (ìdá 54)""."
"Lẹ́yìn tí orílẹ̀-èdèe Amẹ́ríkà pa Ọ̀gágun ọmọ Iran Qasem Soleimani, ọ̀gá ọlọ́pàá tẹ ìkéde ìṣọ́ra ẹni jákèjádò orílẹ̀-èdèe Nàìjíríà jáde kí ó ba ti ilẹ̀kùn ""ogun""."
"Ẹgbẹ́ Ẹ̀sìn Ìmàle ní Nàìjíríà ṣàpèjúwe ikú oró òjò ọta ìbọn láti òkè wá tí US fi pa Soleimani gẹ́gẹ́ bí ""ìpè ogun sí Ìran""."
A ti ṣe àpèjúwe Trump gẹ́gẹ́ bí “ọ̀kan lára àwọn olórí àgbáyé sáà tí a wà yìí tí ó ní ọkàn líle.”
Síbẹ̀, ọ̀pọ̀ ọmọ Nàìjíríà ló fẹ́ràn-an Trump.
Twitter di pápá ìròyìn ayédèrú lásìkò Ìdìbò ọdún-un 2019 ní Nàìjíríà
Ọ̀rọ̀ Ìkórìíra Ẹ̀yà àti Ayédèrú Ìròyìn tàn ká lórí Twitter
Àtòpọ̀ àwòrán láti ọwọ́ Nwachukwu Egbunike
Èyí ni apá kejì ìròyìn nínú àkọsílẹ̀ ẹlẹ́ka méjì lórí ọ̀rọ̀ ìkórìíra ẹ̀yà lórí ayélujára, ìròyìn ayédèrú àti ìsọkiri lásìkò ìdìbò ọdún-un 2019 lórílẹ̀-èdèe Nàìjíríà.
O lè ka apá kìíní níbí.
Ní orílẹ̀-èdèe Nàìjíríà, àwùjọ ìbánisọ̀rọ̀ orí ayélujára jẹ́ ibi tí ìròyìn ìtakora-ẹ̀yà tẹ̀gbintẹ̀gbin àti ìsọkiri ti máa ń gbilẹ̀ bíi ṣẹ́lẹ̀rú lásìkò ìdìbò.
Ní àsìkò ìdìbò ọdún-un 2015, Twitter Nàìjíríà kó sí ìjà àti ìsọ̀rọ̀-takora láàárín àwọn alátilẹyìn olùdíje-dupò méjèèjì tí ó lérò lẹ́yìn jù lọ lásìkò náà, ìyẹn Goodluck Jonathan (ọmọ ẹgbẹ́ẹ PDP tí ó jẹ́ kìrìsìtẹ́nì àti ọmọ Ijaw) àti Muhammadu Buhari (ọmọ ẹgbẹ́ APC tí ó jẹ́ Mùsùlùmí àti ọmọ Hausa-Fulani).
Túwítà di ohun èlò fún ìsọkiri ọ̀rọ̀ ìkórìíra ẹ̀yà àti ọ̀rọ̀ ẹgbẹ́ òṣèlú.
Àsìkò ìdìbò ọdún 2019 ò yàtọ̀ rárá.
"Ní ọjọ́ 15, oṣù Èrèlé ẹgbẹ́ Ajábọ̀ Ìròyìn Láìsí Àlà (RSF) ṣe àkọsílẹ̀ kan tí ó ń ṣe àfihàn èròo wọn lórí ìpolongo ìdìbò tí ""ìròyìn ayédèrú ti mú bàjẹ́ ""."
Àwọn ọmọ orílẹ̀-èdèe Nàìjíríà náà fi èròo wọn hàn.
Akọ̀ròyìn Abdulbaqi Jari túwíìtì pé:
Ìròyìn ayédèrú àti ìṣèlú ní àwọn orílẹ̀-èdè ilẹ̀ Adúláwọ̀
"Ìwádìí ọdún-un 2019 kan láti ọwọ́ Dani Madrid-Morales ní Ilé-ẹ̀kọ́ gíga Huston àti Herman Wasserman ní ilé-ẹ̀kọ́ gíga Cape Town fẹnukò pé ""ìròyìn irọ́ àti ìròyìn ayédèrú ni wọ́n ti máa ń lò láti fi mú ìfẹ́-inú àwọn olóṣèlú ṣẹ"" ní orílẹ̀-èdèe Nàìjíríà, Kenya àti South Africa."
"Ọ̀pọ̀ Ìròyìn ayédèrú lórí àwọn àwùjọ ìbánisọ̀rọ̀ orí ayélujára pàápàá lásìkò ìpolongo ìbò máa ń fa ""àìgbara-eni-gbọ́ "" láàárín àwọn tí wọ́n ń lo àwùjọ ìbánisọ̀rọ̀ orí ayélujára ""nítorí pé ibẹ̀ ni wọ́n ti ń rí 'ìròyìn ayédèrú' lọ́pọ̀ ìgbà"", Madrid-Morales sọ̀rọ̀."
Ìwádìí mi lórí onírúurú ẹ̀yà láàárín ọjọ́ 28, oṣù Ọ̀wàrà ọdún-un 2018 àti ọjọ́ 29 oṣù Èbìbí, ọdún-un 2019 lórí ìdìbò ọdún-un 2019 lórílẹ̀-èdèe Nàìjíríà tó wáyé ní ọjọ́ 23, oṣù Èrèlé (láti dìbò yan ààrẹ àti aṣòfin sí ilé ìgbìmọ̀ aṣòfin ti orílẹ̀-èdè) àti ọjọ́ 9, oṣù Erénà (láti yan gómìnà àti aṣòfin sí ilé-ìgbìmọ̀ aṣòfin ti ìjọba ìpínlẹ̀) ṣe àfihàn ìṣẹ̀lẹ̀ ìròyìn ayédèrú méjì pàtàkì kan: ìròyìn ayédèrú tó tako ẹ̀yà kan àti ìsọkiri láti mú èrò inú àwọn olóṣèlú ṣẹ.
Ìròyìn Ayédèrú tó tako ẹ̀yà
Peter Obi, igbá kejì Atiku Abubakar tí ó jẹ́ òǹdíje-dupò ẹgbẹ́ òṣèlú (PDP) jẹ́ ẹni tí ó dojú kọ ìpalára ìròyìn ayédèrú tó tako ẹ̀yà lásìkò ìdìbò tó kọjá.
Obi jẹ́ gómìnà ìgbà kan rí ní ìpínlẹ̀ Anambra ní gúúsù-ìlà oòrùn Nàìjíríà.
Ìkànni Túwítà kan tí ó ń ṣe àtìlẹyìn ìpolongo fún Buhari-Osinbajo, Coalition of Buhari-Osinbajo Movement pín Túwíìtì kan (Atọ́ka 1) tí ó ń fẹ̀sùn kan Obi pé ó “lé àwọn ará àríwá orílẹ̀-èdèe Nàìjíríà kúrò ní ìpínlẹ̀ Anambra nígbà tí ó jẹ́ gómìnà.
Àwòrán 1: Àwòrán Túwíìtì kan láti ọwọ́ Coalition of Buhari-Osibanjo Movement tí ó ń fẹ̀sùn kan òbí pé ó ṣe ‘ìdápadà’ àwọn ará àríwá sí ìlúu wọn.
Atọ́ka 2: Àwòrán Túwíìtì kan láti ọwọ́ Nasir El-Rufia
"Gómìnà ìpínlẹ̀-ẹ Kaduna àti ọmọ ẹgbẹ́ òṣèlú tí ó ń ṣè ìjọba lọ́wọ́, Nasir El-Rufai, mú ẹ̀sùn yìí rinlẹ̀ sí i, ó túwíìtì (Atọ́ka 2) pé Obi jẹ́ ""ẹni tí ó ń ṣe ìyàtọ̀ọ̀tọ̀ ẹ̀yà""."
Ohun tí El-Rufai sọ yìí ò mú kí ipò igbákejì ààrẹ tọ́ fún Obi.
Kà sí i: Gómìnà kan ní Nàìjíríà kìlọ̀ fún ìjọba ilẹ̀ òkèèrè: Ẹ dá sí ọ̀rọ̀ ìdìbò wa kí 'ẹ padà sí ìlú yín ní òkú'
Kí ni ohun tí ó ṣẹlẹ̀ gan-an?
"Ilé-iṣẹ́ ìwé ìròyìn Vanguard jábọ̀ wípé ní oṣù Agẹmọ ọdún-un 2013, ọmọ Nàìjíríà 67 tí ọ̀pọ̀lọpọ̀ wọn wá láti ilẹ̀-ẹ Igbo ni ""wọ́n dá padà láti Èkó tí wọ́n sì pa wọ́n tì sí ibi kan náà ní agbègbè Upper Iweka"" tí ó gbajúmọ̀ ní Onitsha, Ìpínlẹ̀ Anambra."
"Obi, tí ó jẹ́ gómìnà ìpínlẹ̀ Anambra ní ìgbà náà, ṣàpèjúwe ìhùwàsí yìí tí akẹgbẹ́-ẹ ‘ẹ̀ Túndé Fáṣọlá ní ìpínlẹ̀ Èkó hù gẹ́gẹ́ bí ""ohun tí kò bá òfin mu àti ìrúfin ẹ̀tọ́ ọmọnìyàn àwọn ẹni tí ó di èrò ìlúu wọn""."
Lẹ́yìn ìbínúu gbogboògbò tí ọ̀rọ̀ yìí fà, Premium Times jábọ̀ pé Obi náà jẹ̀bi irú ọ̀rọ̀ bẹ́ẹ̀:
Ní 2011, ó lé àwọn atọrọbárà tó jẹ́ ọmọdé padà sí ìpínlẹ̀ Ebonyi àti Akwa Ibom, ní apá gúúsù orílẹ̀-èdèe Nàìjíríà.
Atọ́ka 3: Àwòrán Túwíìtì kan láti ọwọ́ Jubril A. Gawat
Nígbà tí Obi dá àwọn oníbárà padà sí àwọn ìpínlẹ̀ ní Gúúsù Nàìjíríà lóòótọ́, kò lé àwọn ará Àríwá, ẹ̀sùn tí ìṣàmúlò-o Twitter ẹgbẹ́ alátìlẹ́yìn-in Coalition of Buhari-Osinbajo Movement túwíìtì (Atọ́ka 1) kò gún régé.
"Kódà Túndé Fáṣọlá ti ẹgbẹ́ APC ni ó ""ṣe ìdápadà àwọn ará Àríwá 70 sí ìpínlẹ̀-ẹ Kano nítorí wọ́n tọrọ bárà"" gẹ́gẹ́ bí ìwé ìròyìn aṣèwádìí lórí ayélujára Sahara Reporters ṣẹ jábọ̀."
Bẹ́ẹ̀ àwọn agbèsẹ́yìn egbẹ́ òṣèlú APC ni wọ́n ṣàmúlò ìròyìn ayédèrú tó tako ẹ̀yà kan yìí láti fi bu ẹnu àtẹ́ lu òǹdíje-dupò lábẹ́ àsíá ẹgbẹ́ tó tako ẹ̀gbẹ́ẹ wọn.
Fún àpẹẹrẹ, Jubril Gawat tí wọ́n ṣẹ̀ṣẹ̀ yàn sípò aṣèrànwọ́ Gómìnà pàtàkì lórí ẹ̀rọ ìgbéròyìnjáde ìgbàlódé tuntun túwíìtì pé (Atọ́ka 3) ìbò kan fún òǹdíje-dupò ẹgbẹ́ atako Atiku Abubakar “jẹ́ ìbò fún ẹ̀yà Igbo.”
Nàìjíríà jẹ́ orílẹ̀-èdè kan tí ọ̀rọ̀ ẹ̀yà ti rinlẹ̀ gan-an.
"Àwọn olóṣèlú sì máa ń sa ẹ̀yàmẹyà yìí bí oògùn ní àsìkò ìdìbò nítorí wọ́n máa ń nílò láti pín àwọn ènìyàn sí ẹgbẹ́ “àwa” pẹ̀lú ""wọn""."
Nítorí náà, wọ́n ní í lọ́kàn láti fi ẹ̀sùn tí wọ́n fi kan Obi pé ó lé àwọn ará Àríwá padà sí ìlú wọn rú inúnibíni tí ó ti wà tẹ́lẹ̀ láàárín ẹ̀yà Igbo àti Hausa tí ó fa Ogun Abẹ́lée Nàìjíríà.
Èròǹgbà wọn pẹ̀lú ìpolongo àwọn ìròyìn ayédèrú yìí ni láti ṣe àfihàn Obi gẹ́gẹ́ bí ajìjàǹgbara fún ẹ̀yà Biafra.
Ẹ̀yà tó wà ní Gúúsù-ìwọ̀ oòrùn Nàìjíríà, tí ọ̀pọ̀lọpọ̀ wọn jẹ́ ọmọ Igbo gbìyànjú láti ya kúrò lára orílẹ̀-èdè nípasẹ̀ ogun abẹ́lé tí ó wáyé fún ọdún mẹ́ta láàárín ọdún 1967 sí 1970.
"Fún ìdí èyí, wọ́n ní í lọ́kàn láti lo àkọsílẹ̀ inú atọ́ka 3 tí ó sọ pé ""Ìbò kan fún Atiku jẹ́ ibo fún ẹ̀yà Igbo..."" fi jí òkú ìkórìíra ẹ̀yà tẹ̀gbintẹ̀gbin tí ó ti wà láàárín ẹ̀yà Hausa àti Igbo."
Ní àsìkò ìdìbò ọdún-un 2019, èyí túmọ̀ sí pé Atiku jẹ́ agbèsẹ́yìn ẹ̀yà Igbo tí wọ́n ti fìgbà kan gbìyànjú láti pínyà kúrò nínú orílẹ̀-èdèe Nàìjíríà.
Àkọsílẹ̀ inú atọ́ka 1 dé 3 ń ṣe àfihàn àwọn èrò tí ó lágbára láti jí ìṣẹ̀lẹ̀ àtijọ́ tí ó ti relẹ̀, tí kòì tí ì tán nínú àwọn ẹ̀yà méjèèjì.
"Àjọ UNESCO sọ pé ìròyìn ayédèrú báyìí máa ń lapa lára àwọn “tí ó mọ̀ díẹ̀ káàtó tí ìpalára lè bá tí ó ń gbà á” yóó sì sọ wọ́n di ""aláriwo àti alápìínká ìròyìn náà""."
Ìpolongo ìbò tí ó bá ti ń tako ẹ̀yà kan máa ń fi ẹ̀tanú tó rinlẹ̀ sínú ọkàn àwọn tí ó ń gbọ́ ọ, ó sì máa ń sọ àwọn olùgbọ́ yìí di alápìínká ìròyìn ayédèrú.
Irọ́ tí wọ́n pa pé àwọn Yorùbá ń tiná bọ ìsọ̀ àwọn ọmọ Igbo nílùú Èkó
Atọ́ka 4: Àwòrán Túwíìtì kan [ti Twitter lòdì sí tí wọ́n sì yọ kúrò] láti ọwọ́ Chioma tí ó ń ṣe ìtànká ìròyìn ayédèrú pé àwọn Yorùbá ń dáná sun ìsọ̀ àwọn Igbo nílùú Èkó.
Bákan náà, àwọn agbèsẹ́yìn ẹgbẹ́ẹ PDP náà lo ọ̀rọ̀ ìdójúkọ ẹ̀yà yìí láti kó ìbò ju ẹgbẹ́ẹ APC lọ ní ìpínlẹ̀ Èkó.
Atọ́ka 4 àti 5 ń ṣàfihàn àwòrán Túwíìtì láti ọwọ́ abánikẹ́dùn PDP kan tí ó ń sọ pé àwọn Yorùbá ti ń ti iná bọ ìsọ̀ àwọn ọmọ Igbo nílùú Èkó.
Irọ́ ni àwọn ìròyìn náà, Àjọ Ọlọ́pàá ìpínlẹ̀ Èkó sì tètè fi òtítọ́ hàn láti pa á rẹ́.
Àkọsílẹ̀ orí Facebook kan tí ó fẹ́rẹ̀ẹ́ ṣàmúlò gbogbo ọ̀rọ̀ inú àwòrán atọ́ka 4, pẹ̀lú àwòrán ibi tí wọ́n ti fi táyà tó ń jó dí ọ̀nà náà ṣe àpínká ìròyìn irọ́ náà.
African Check jábọ̀ pé àwòrán tí wọ́n lò yìí jẹ́ àwòrán kan lati ibi ìfẹ̀hónúhàn kan ni ọjọ́ 24 oṣù Èrèlé ọdún 2017 tí ó wáyé ní agbègbè kan nítòsí Pretoria ní orílẹ̀ èdè South Africa.
Atọ́ka 5: Àwòrán Túwíìtì kan tí ó ń ṣe ìtànká ìròyìn ayédèrú kan pé àwọn Yorùbá ń tiná bọ ìsọ̀ àwọn ọmọ Igbo nílùú Èkó II
Ìsọkiri láti mú èrò inú àwọn olóṣèlú ṣẹ
Ní ọjọ́ 13 oṣù Èrèlé, olùṣàmúlò Túwítà kan Souljah túwíìtì (Atọ́ka 6) pé Ballard Partners, tí ó jẹ́ iléeṣẹ́ Alukoro kan tí wọ́n gbà síṣẹ́ tí ó kalẹ̀ sí Washington DC, láti ṣe ìpolongo fún Abubakar gẹ́gẹ́ bí Ààrẹ, ṣe ìwádìí àyẹ̀wò lábẹ́lẹ̀ kan tí ó ti ṣàpẹẹrẹ ìfìdírẹmi òǹdíje-dupò lábẹ́ àsiá ẹgbẹ́ alátakò, ìyẹn PDP.
Ní ọjọ́ 5, oṣù Èrèlé, ìwé àbájáde ìwádìí náà tí Brian Ballard, adaríiléeṣẹ́ Ballard Partners buwọ́lù tẹ Olúṣọlá Saraki, tí ó jẹ́ adarí pátápátá fún ìpolongo ìbò Abubakar lọ́wọ́.
Túwíìtì Souljah tàn káàkiri tí ènìyàn ẹgbẹẹgbẹ̀rún kan fẹ́ràn-an rẹ̀, tí ẹgbẹẹgbẹ̀rún ènìyàn-án sì ṣe àtúnpín-in rẹ̀ fún ìdí tí ò f'ara sin.
Wọ́n gbé ọjọ́ ìdìbò láti yan ààrẹ sí ọjọ́ 16 oṣù Èrèlé (tí wọ́n padà sún un síwájú sí ọjọ́ 23 oṣù Èrèlé), nǹkan ò bá bàjẹ́ fún ẹgbẹ́ asàtakò PDP pẹ̀lú àbájáde ìwádìí tí ó ń fara hàn ní ọjọ́ mẹ́ta kí ìdìbò ó tó wáyé yìí..
Kà sí i: Nàìjíríà sún ìdìbò gbogboògbò ọdún-un 2019 síwájú nígbà tí ìdìbò kú ìwọ̀n-ọn wákàtí nítorí ọ̀rọ̀ 'ètò àti ìlànà ìmúṣẹ́ṣe'
Atọ́ka 6: Àwòrán Túwíìtì kan láti ọwọ́ Souljah
"Sùgbọ́n ní ìrólẹ́ ọjọ́ 13 oṣù Èrèlé, Ballard Partners ní àbájáde ìwádìí náà kò rí bẹ́ẹ̀ (Atọ́ka 7) tí wọ́n ṣe àpèjúwe rẹ̀ gẹ́gẹ́ bí i ""jìbìtì"", wọ́n sì fi ìdíi rẹ̀ múlẹ̀ pé àwọn kò ""ṣe ìwádìí kankan fún ẹgbẹ́ òṣèlú PDP""."
"Ose Anenih, tí ó jẹ́ agbèsẹ́yìn ẹgbẹ́ PDP ṣe ìfisùn lára àwọn ará APC orí Túwítà tí wọ́n ṣe ìtànká àbájáde ìwádìí náà sí ìkànni àwọn ọlọ́pàá orílẹ̀-èdèe Nàìjíríà àti àjọ tí ó ń ṣe àmójútó ọ̀rọ̀ ìdìbò, INEC fún “ìwà ọ̀daràn àti ohun tí ó lòdì sófin” tí ó ń gbìyànjú ""láti dí ìdìbò tí ó yẹ kí ó lọ nírọ̀rùn lọ́wọ́ ""."
Ṣùgbọ́n èyí kì í ṣe ìgbà àkọ́kọ́ tí wọ́n máa fi ìròyìn ayédèrú mú èrò inú àwọn olóṣèlú ṣẹ lórí ayélujára ní àsìkò ìdìbò.
Atọ́ka 7: Àwòrán Túwíìtì kan láti ọwọ́ iléeṣẹ́ Ballard and Partners tí í sẹ́ ayédèrú ìwádìí tí wọ́n purọ́ mọ́ wọn pé wọ́n ṣe.
Ọ̀pọ̀lọpọ̀ irọ́ olùrànlọ́wọ́ ààrẹ
Atọ́ka 8: Àwòrán Túwíìtì kan by Lauretta Onochie, láti ọwọ́ Lauretta Onochie, tí ó jẹ́ olùrànlọ́wọ́ fún ààrẹ
Ní ọjọ́ 4, oṣù Ọ̀pẹ, ọdún-un 2018 Lauretta Onochie, tí ó jẹ́ olùrànlọ́wọ́ fún Buhari [tí ó jẹ́ òǹdíje-dupò ààrẹ lásìkò náà] túwíìtì (Atọ́ka 8) àwòrán kan pẹ̀lú oúnjẹ àti owóo náírà 500 tí wọ́n ní wọ́n pín fún àwọn èrò lọ́jọ́ kejì ìrìnde ìpolongo ìdìbò fún Abubakar gẹ́gẹ́ bí ààrẹ ní Sokoto, apá àríwá-ìlà oòrùn orílẹ̀-èdèe Nàìjíríà ní àná ọjọ́ náà.
Irọ́ pátápátá ni àwọn ẹ̀sùn Onochie. Kódà, níbi òde kan tí kò tan mọ́ “ọ̀rọ̀ ìdìbò” ni a ti ya àwòrán náà nínú “oṣù Èrèlé ọdún-un 2017″, Chuba Ugwu tan ìmọ́lẹ̀ sí èyí nínú èsì sí túwíìtì rẹ̀ kan.
"Onochie jẹ́ ògbóǹtarìgì níbi ká máa ṣe àpínká ìròyìn ayédèrú. Iléeṣẹ́ agbéròyìnjáde orí ayélujára kan tí ó ń ṣe ìwádìí ìjábọ̀ ìròyìn (ICIR), ti ṣe àgbéyẹ̀wò àwòrán tó ju 1,000 lọ tí Onochie ti pín sórí Twitter láàárín ọjọ́ 1, oṣù Ògún ọdún-un 2018 àti ọjọ́ 31, oṣù Agẹmọ ọdún-un 2019. Àgbéyẹ̀wò náà fi hàn pé ó kéré tán ""ìgbà méjìlá"" ni Onochie ""ti lo àwòrán tí kò yẹ""."
Ọ̀rọ̀ Àtakò lórí Ayélujára: ọ̀ràn ní Nàìjíríà
"Abala 26 òfin Nàìjíríà nípa ọ̀ràn orí ayélujára kọ ""lílérí ìjà àti lílo ọ̀rọ̀ èébú sí àwọn èèyàn nítorí ẹ̀yàa wọn, ẹ̀sìn-in wọn, àwọ̀-ọ wọn, ìràn-an wọn tàbí orílẹ̀-èdèe wọn""."
Àwọn ẹni tí adé ìwà náà bá ṣí mọ́ lórí á fi ẹ̀wọ̀n ọlọ́dún-márùn-ún gbára tàbí kí wọ́n san owó ìtanràn tí kò dín ní ẹgbẹẹgbẹ̀rún 10 owóo naira [tí ó ń lọ bí i $28,000] tàbí méjèèjì.
Ní oṣù Ẹrẹ́nà ọdún yìí, Enough is Enough Nigeria (EIE), tí ó jẹ́ àkójọpọ̀ àwọn ọ̀dọ́ kan àti Paradigm Initiative (PI), tí ó jẹ́ ẹgbẹ́ aṣòfin àti ajàfẹ́tọ̀ọ́ ẹni lórí ẹ̀rọ-ayárabíàṣá, ṣe ìfilọ́lẹ̀ ìpèlẹ́jọ́ Onochie àti Gbénga Ọlọ́runpomi tí ó jẹ́ olùrànlọ́wọ́ gómìnà ìpínlẹ̀-ẹ Kogi lẹ́jọ́ ní Ilé-ẹjọ́ kan ní Abuja.
"Àjọ méjèèjì yìí ""ṣe àkópọ̀ àwọn ọ̀rọ̀ àtakò tí ó jẹ́ ọ̀rọ̀ Onochie àti Ọlọ́runpomi lórí ayélujára"" tí wọ́n rí i pé ó rú òfin orílẹ̀-èdèe Nàìjíríà nípa ọ̀ràn orí ayélujára ti 2015."
Kà sí i: Báwo ni ìsọkiri yóò ṣe to ìdìbò ààrẹ orílẹ̀-èdèe Nàìjíríà ti 2019?
Àkójọpọ̀ àwọn ajagun orí Twitter tí wọ́n ń ṣe àpínká irọ́
Púpọ̀ nínú àwọn àpẹẹrẹ tí a ṣe lókè yìí kì í ṣe ohun tí wọn kò mọ̀-ọ́n-mọ̀ ṣe. Wọ́n dìídì gbìyànjú láti ṣe àpínká irọ́ bí i pé òótọ́ ni.
"Èyí kò yani lẹ́nu rárá nítorí a rí i pé APC àti PDP ni wọ́n di ajagun orí ayélujára láti lè ṣe ""ìmúwálẹ̀ ìjábọ̀ búburú"" lórí ayélujára nípa wọn tàbí láti “gbèjà” níbi ìdojúkọ lásìkò ìpolongo ìbò."
"Ẹgbẹ́ méjèèjì ni ó ṣe àmúlò ""ajagun orí ayélujára"" — ""àwọn akópa nínú ìjọba tàbí ẹgbẹ́ òṣèlú tí wọ́n fún ní iṣẹ́ láti tọwọ́bọ ọpọlọ àwọn ará ìlú láti yí èròo wọn padà lórí ayélujára""."
Ìdìbò ọdún yìí jẹ́ àṣẹtúnṣe ti 2015, níbi tí APC àti PDP ti kópa nínú ìtànká ìròyìn ayédèrú àti irọ́ pẹ̀lú ìsọkiri láti mú èrò àwọn olóṣèlú ṣẹ “nínú àwọn ìpolongo wọn lórí àwùjọ ayélujára tí wọ́n “fara balẹ̀ ṣètò láti fi tan àwọn olùdìbò tí kò fura, “báyìí ni Eshemokha Austin Maho, tí ó jẹ́ ọ̀mọ̀wé Nàìjíríà kan nípa ìkéde àti ìgbéròyìnjáde ṣe sọ.
"Wọ́n rí èyí ṣe nípasẹ̀ “ìdásílẹ̀ àwọn ìkànnì irọ́ lórí ayélujára ""níbi tí wọ́n ti ń pín “ọ̀rọ̀ ibanilórúkọjẹ́ "" àti ""ìròyìn tí kò ṣe é fọkàn tán pẹ̀lú ìsọkiri láti mú èrò àwọn olóṣèlú ṣẹ""."
Àbájáde tí ipa wọn kó ni pé Twitter di pápá ìròyìn ayédèrú tí ó ń ṣe ẹlẹ́yàmẹyà àti ìsọkiri láti mú èrò àwọn olóṣèlú ṣẹ ṣáájú àsìkò ìdìbò, ní àsìkò ìdìbò àti lẹ́yìn ìdìbò ọdún-un 2019 lórílẹ̀-èdèe Nàìjíríà.
Àròkọ yìí jẹ́ apá kan nínú ọ̀wọ̀ọ́ àwọn àkọsílẹ̀ tí ó ń ṣe àgbéyẹ̀wò ìkọlura pẹ̀lú ẹ̀tọ́ ẹni lórí ayélujára nípasẹ̀ àwọn ìlànà bí i pípa òpó ìbánisọ̀rọ̀ àti ìròyìn ayédèrú ní àsìkò tí ọ̀rọ̀ ìṣèlú pàtàkì bá ń wáyé ní orílẹ̀-èdè ilẹ̀ Adúláwọ̀ méje: Algeria, Ethiopia, Mozambique, Nigeria, Tunisia, Uganda, and Zimbabwe.
Àjọ tí ó ń ṣàmójútó ẹ̀tọ́ ẹni lórí ẹ̀rọ Africa Digital Rights Fund ti The Collaboration on International ICT Policy for East and Southern Africa (CIPESA) ni ó ṣe agbátẹrù iṣẹ́ yìí.
Ilẹ̀-Adúláwọ̀ rí àbọ̀ ẹgbẹẹgbẹ̀rún-lọ́nà-ẹgbẹ̀rún owóo dollar láti ọ̀dọ̀ Ilé-ìfowópamọ́sí ńláńlá fún ìgbéfúkẹ́ Iléeṣẹ́ ọgbọ́n àtinudá
Àwọn ọlọ́gbọ́n àtinudá Ilẹ̀-Adúláwọ̀ gbọdọ̀ 'ká èso ọrọ̀ tí ó pọ̀ tí ó ń dúró fún kíká'
Àgékù àwòrán ọ̀kọrin ọmọ orílẹ̀-èdèe Nàìjíríà D'banj ń sọ̀rọ̀ níbi ètò Ọjọ́ Ìsinmi CAX ní Cairo, Egypt, ọdún-un 2018. Dbanj sọ fún olùdókoòwò wípé “iṣẹ́ àtinúdá ni epo rọ̀bì tí ọpọ́n sún kàn” tí ó sì yẹ kí a bu ìyìn fún.
Ó ti pẹ́ tí àwọn iléeṣẹ́ ìgbélárugẹ àṣà àti ọgbọ́n àtinudá ti ń ṣe ohun mèremère ní ti ìdàgbàsókè ọrọ̀ Ajé, ní ti ipa tí wọ́n ń kó àti agbára tí ó wà níkàáwọ́ wọn láti mú àyípadà dé bá àwùjọ àti ìpàṣípààrọ̀ àṣà.
Lọ́dún-un 2013, iléeṣẹ́ ìgbélárugẹ àṣà àti ọgbọ́n àtinudá (CCI) rí owó ẹgbẹẹgbẹ̀rún-lọ́nà-ẹgbẹ̀rún 2,250 dollar ti Ìṣọ̀kan Orílẹ̀-èdèe Amẹ́ríkà àti iṣẹ́ tí ẹgbẹẹgbẹ̀rún 29.5 kárí ayé [àmọ́] ìdá 3 àwọn iṣẹ́ wọ̀nyí wá láti Ilẹ̀-Adúláwọ̀ àti Àárín gbùngbùn Ìlà-Oòrùn tí ó jẹ́ agbègbè àwọn aráa Lárúbáwá, ìyẹn gẹ́gẹ́ bí ìwádìí àyẹ̀wò fínnífínní Àjọ Ìṣọ̀kan Àgbáyé fún Ẹ̀kọ́, Ìwádìí Ìjìnlẹ̀ àti Àṣà (UNESCO) ọdún-un 2013 tí a pè ní “Àsìkò Àṣà” kan ti ṣe fi hàn.
"Torí ìdí èyí, Ilé-ìfowópamọ́sí Ọjà títa sókè òkun-àti-kíkó ọjà wọlé (Afreximbank) pẹ̀lú àbáṣepọ̀ọ UNESCO àti Ẹgbẹ́ Ilé-ìfowópamọ́sí Ìdàgbàsókè Ilẹ̀-Adúláwọ̀, ṣe àgbékalẹ̀ Ìpàṣípààrọ̀ Ọgbọ́n Àtinudá Ilẹ̀-Adúláwọ̀ – Creative Africa Exchange (CAX) tí yóò ""dúró gẹ́gẹ́ bíi ohun tí yóò ṣe àmúpapọ̀ àwọn nǹkan ọrọ̀ àti àlùmọ́nì tí ó wà nínú iléeṣẹ́ ọgbọ́n àtinudá"" tí yóò ṣe àgbéró, mú owó wọlé àti lapa rere lára àwọn ọlọ́gbọ́n àtinudá àti àwọn oníṣẹ́ àṣà, bí ibùdó ìtakùn àgbáyé CAX ṣe ní i lákọsílẹ̀."
Ọdún-un 2018 ni ìfilọ́lẹ̀ CAX wáyé ní ibi Ìpàtẹ Ọjà Inú Ilẹ̀-Adúláwọ̀ ní ìlúu Cairo, orílẹ̀-èdèe Egypt, nínú oṣù Ọ̀pẹ̀ ọdún-un 2018.
Àwọn ọlọ́gbọ́n àtinudá gbogbo láti ẹ̀ka orin kíkọ, iṣẹ́ ọnà, àwòṣe, ẹ̀ṣọ́, ewì, ìwé títẹ̀, àwòrán-olóhùn àti òṣìṣẹ́ ẹ̀rọ amóhùnmáwòràn parojọ fún Ọjọ́ Ìsinmi Ìpàṣípààrọ̀ Ọgbọ́n Àtinudá ní Kigali, ní orílẹ̀-èdèe Rwanda, ní ọjọ́ 16-18 oṣù kìíní, Ọdún-un 2020.
"Ó polówó araa rẹ̀ gẹ́gẹ́ bíi ""ayẹyẹ àkọ́kọ́ tí yóò kó àwọn ọmọ ilẹ̀ adúláwọ̀ jọ tí ń ṣe ìgbélárugẹ ìpàṣípààrọ̀ láàárín àwọn ọlọ́gbọ́n àtinudá àti aṣàgbélárugẹ àṣà ní Ilẹ̀-Adúláwọ̀ "", tí ó ní àwọn akópa tí ó tó bíi 2,000 láti orílẹ̀-èdè 68."
"Ní ọjọ́ kejì ayẹyẹ náà ní Kigali, ọ̀jọ̀gbọ́n Benedict Oramah, ààrẹ Ilé-ìfowópamọ́sí Ọjà títa sókè òkun-àti-kíkó wọlé (Afreximbank) kéde owó ìrànwọ́ ẹgbẹẹgbẹ̀rún 500 owó dollar Amẹ́ríkà ""tí yóò ṣe àtìlẹ́yìn ìgbéjáde àti káràkátà nǹkan tí ó jẹ mọ́ ti àṣà àti ọgbọ́n àtinudá Ilẹ̀-Adúláwọ̀ "" fún ọdún méjì gbáko, New Times Rwanda jíyìn ìròhìn."
Omarah gbé e sí àwọn àlejò tí ó wà níkàlẹ̀ níbi ayẹyẹ náà létí wípé owó ìrànwọ́ náà, tí yóò bù kún iṣẹ́ tí Ilé-ìfowópamọ́sí náà ti ń ṣe tẹ́lẹ̀, yóò wà ní àrọ̀wọ́tó ní àwọn Ilé-ìfowópamọ́sí, tí yóò jẹ́ lílò fún àwọn tí ó fẹ́ ẹ.
Ó sọ wípé bí Ilẹ̀-Adúláwọ̀ ti ṣe ní ọ̀pọ̀lọpọ̀ ọlọ́gbọ́n àtinudá tó, kò sí ohun èlò tí yóò mú kí wọn ó ká èso ọrọ̀ tí ó pọ̀ tí ó ń dúró fún kíká, ìyẹn bí Afreximbank ti ṣe ṣàlàyé.
Ó sọ̀rọ̀ síwájú sí i :
Nítorí àìtó ìdókoòwò nínú iléeṣẹ́ ọgbọ́n àtinudá àti àṣà, Ilẹ̀-Adúláwọ̀ kò sí nínú ọjà iṣẹ́ ọpọlọ, àti ìdáraáwò púpọ̀ gẹ́gẹ́ bí a ti fi hàn nínú orin, eré ìtàgé, ewì, àwòrán-àtohùn àti ètò orí ẹ̀rọ amóhùnmáwòrán àgbáyé.
Àwọn orílẹ̀-èdè Ilẹ̀-Adúláwọ̀ máa ń kó ọjà ọgbọ́n àtinudá wọlé ju èyí tí wọ́n tà sókè òkun tàbí láàárin ara wọn.
"Ó gbóṣùbàa sàńdákátà fún orílẹ̀-èdèe Egypt ní ti “ìdàgbàsókèe ìtàsókè òkun ọgbọ́n àtinudá láàárín ọdún mẹ́wàá tí ó ré kọjá""."
Nínú oṣù Ọ̀pẹ̀ ọdún-un 2019, a dá Afreximbank lọ́lá níbi Ìfàmìẹ̀yẹdánilọ́lá Ìṣaralọ́ṣọ̀ọ́ Àgbáyé International Fashion Awards (IFA) ní Cairo fún ipa tí ó ń kó níbi ti ìtìlẹ́yìn-in iléeṣẹ́ ọgbọ́n àtinudá Ilẹ̀-Adúláwọ̀.
Bákan náà ni Omarah gbóríyìn fún iléeṣẹ́ eré orí ìtàgé Nollywood ti Nàìjíríà.
Lóríi gbàgede Twitter, àwọn òṣèré tó wà níbi àpérò náà dúpẹ́ fún àpéjọ náà tí ó wáyé ní gbọ̀ngan Intare tí ó wà ní Kigali:
Nínú ọ̀rọ̀-ọ rẹ̀ níbi ayẹyẹ Ọjọ́ Ìsinmi CAX 2018 ní Cario, ọ̀kọrin ọmọ orílẹ̀-èdèe Nàìjíríà D'Banj sọ fún àwọn òṣìṣẹ́ Ilé-ìfowópamọ́sí àti olùdókoòwò:
Ohun tí a nílò láti ọ̀dọ̀ọ yín ní fún un yín láti lóye wípé iṣẹ́ àtinudá ni epo rọ̀bì tí ọpọ́n sún kàn tí ó sì yẹ kí a bu ìyìn fún iléeṣẹ́ náà.
Ọ̀sẹ̀-ẹ CAX tí yóò ṣe pẹ̀kí-ǹ-rẹ̀kí pẹ̀lú Ìpàtẹ Ọjà Inú Ilẹ̀-Adúláwọ̀ (IATF2020) láti Ọjọ́ 1-7 kẹsàn-án ní Kigali, yóò tẹ̀lé Ọjọ́ Ìsinmi CAX 2020 tí ó ṣẹ̀ṣẹ̀ tẹnu bọ epo.
Sọ̀rọ̀sọ̀rọ̀ ní Nàìjíríà darapọ̀ mọ́ àwọn akẹgbẹ́-ẹ wọn láti sààmì ayẹyẹ Ọjọ́ Ẹ̀rọ-ìgbóhùnsáfẹ́fẹ́ Àgbáyé ọdún-un 2020
Rédíò — ohun èlò fún ìdàgbàsókè tí kò hàn, tí ó sì ṣe é gbé kiri.
Ọkùnrin kan gbé ẹ̀rọ-ìgbóhùnsáfẹ́fẹ́ tí máa ń rin ọ̀nà jínjìn dání. Àwòrán láti ọwọ́ọ Muhammadtaha Ibrahim Ma'aji tí ó jẹ́ àṣẹ ìlò CC BY 2.0.
Kò sí irọ́ kan níbẹ̀ wípé Ẹ̀rọ-ìgbóhùnsáfẹ́fẹ́ jẹ́ ohun èlò ìgbéròyìn ká tí ó ti ṣiṣẹ́ ribiribi fún ìdàgbàsókè àgbà-ńlá ayé.
"Àwọn Yorùbá ní, kí a gbé oyè fún olóyè, kí á gbádé fún ẹni tí ó ni adé"", èyí ló mú Àjọ Ìṣọ̀kan Àgbáyé tí ó ń rí sí Ètò Ẹ̀kọ́, Ìmọ̀ Ìjìnlẹ̀ àti Àṣà (UNESCO) ya ọjọ́ 13 oṣù Èrèlé sọ́tọ̀ gẹ́gẹ́ bíi Ọjọ́ Ẹ̀rọ-ìgbóhùnsáfẹ́fẹ́ Àgbáyé."
UNESCO yà ọjọ́ yìí sọ́tọ̀ láti ṣí ojú àwọn ènìyàn sí ipa tí ẹ̀rọ-ìgbóhùnsáfẹ́fẹ́ ń kó ní ìgbésí ayé — tí ó jẹ́ ọ̀nà ìgbéròyìnká tí kò hàn, tí ó sì ṣe é gbé kiri.
Àwọn sọ̀rọ̀sọ̀rọ̀-ọ orílẹ̀-èdèe Nàìjíríà darapọ̀ mọ́ àwọn sọ̀rọ̀sọ̀rọ̀ orí ẹ̀rọ-ìgbóhùnsáfẹ́fẹ́ lágbàáyé láti sààmì ọjọ́ náà àti láti fọn rere iṣẹ́ ìdàgbàsókè àgbà-ńlá ayé tí ẹ̀rọ-ìgbóhùnsáfẹ́fẹ́ ń ṣe.
Ẹ̀rọ ìgbéròyìnjáde ń yí bí a ti ṣe ń ṣe nǹkan padà, síbẹ̀síbẹ̀ ẹ̀rọ-ìgbóhùnsáfẹ́fẹ́ ṣì ni ó ṣì wúlò jù lọ fún ọ̀gọ̀rọ̀ ènìyàn láti gbọ́ ìròyìn ohun tí ó ń lọ lọ́wọ́, òhun ṣì ni ohun èlò tí ó máa ń lapa tí ó pọ̀ jù nínúu gbogbo ọ̀nà tí àwọn oníròyìn máa ń lò nítorí ó lágbára láti dé ibi jínjìn àti ìgbèríko tí ó jẹ́ ibi kọ́lọ́fín…  Àlùfáà George Bako sọ̀rọ̀, nígbà tí ó ń ṣíde ètò níbi Àpérò Ọjọ́ Ẹ̀rọ-ìgbóhùnsáfẹ́fẹ́ Àgbáyé. Bako ti fi ìgbà kan rí jẹ́ Ọ̀gá-Àgbà pátápátá fún Iléeṣẹ́ Alájọṣepọ̀ Ìgbóhùnsáfẹ́fẹ́ Ìjọba Àpapọ̀ Orílẹ̀-èdèe Nàìjíríà (FRCN).
Àlùfáà George Bako sọ̀rọ̀ níbi àpérò Ọjọ́ Ẹ̀rọ-ìgbóhùnsáfẹ́fẹ́ Àgbáyé ní Èkó, orílẹ̀-èdèe Nàìjíríà.
Àwòrán láti ọwọ́ọ Ọmọ Yoòbá, tí a gba àṣẹ láti lò.
FRCN — tí a tún ń pè ní Radio Nigeria — ni ó léwájú nínúu iṣẹ́ẹ ẹ̀rọ-ìgbóhùnsáfẹ́fẹ́ ní orílẹ̀-èdèe Nàìjíríà, pẹ̀lú ẹgbẹlẹmùkù àwọn olólùfẹ́ tí ó ń gbọ́ ọ jákèjádò Ìpínlẹ̀ Èkó th oríi ìkànnì mẹ́ta ọ̀tọ̀ọ̀tọ̀, tí orúkọ wọ́n jẹ́: Radio One 103.5 FM, Metro 97.7 FM àti aláràa gbàyídá inúu wọn Bond 92.9 FM.
Ọ̀kọ̀ọ̀kan ìkànnì yìí — ní àwọn olólùfẹ́ẹ rẹ̀ àti àwọn tí ó ń gbọ́ ọ — tí ó ń fi èdèe Gẹ̀ẹ́sì, Àdàlùmọ́-Gẹ̀ẹ́sì, Hausa, Igbo àti èdèe Yorùbá.
Ẹ̀rọ-ìgbóhùnsáfẹ́fẹ́ ṣì ni ọ̀nà tí ó dára jù lọ fún ìfọ́nká ìròyìn ní Nàìjíríà. FM (Ìgbóhùnsáfẹ́fẹ́ Aláṣeéyípadà) ni ó wọ́pọ̀ jù lọ, AM (Ìgbóhùnsáfẹ́fẹ́ Títóbi) tẹ̀lé e gbọ̀ngbọ̀ngbọn, gẹ́gẹ́ bí iléeṣẹ́ Media Landscape ti European Journalism Centre ní i lákọsílẹ̀ — tí ìgbóhùnsáfẹ́fẹ́ orí ẹ̀rọ ayélujára sì ti di gbajúmọ̀.
Ní ọdún-un 2019, Nigeria Diary Radio Stations Ratings ti oṣù Ògún fi hàn wípé Bond FM ló di ipò kìíní mú ní Ìpínlẹ̀ Èkó gẹ́gẹ́ bí ìkànnì tí ó ní olùgbọ́ jù lọ.
Látàrí ayẹyẹ náà, àwọn sọ̀rọ̀sọ̀rọ̀ jákèjádò orílẹ̀-èdèe Nàìjíríà fi gbàgede Twitter kéde ìfẹ́ ẹ wọn fún rédíò:
"Dan Manjang, alákòóso fún oọ̀rọ̀ ìgbóhùnsáfẹ́fẹ́ àti ìkéde ti Ìpínlẹ̀ Plateau, kí àwọn sọ̀rọ̀sọ̀rọ̀ níbi gbogbo fún ""gbogbo akitiyan, ìgbìyànjú àti àsìkò"" tí wọ́n fi ń kéde ìròyìn àti onírúurú ètò akọ́nilọ́gbọ́n:"
Ìgbóhùnsáfẹ́fẹ́ ní Nàìjíríà bẹ̀rẹ̀ ní ọdún-un 1933 pẹ̀lú Ìtàn káàkiri Rédíò Ìjọba Amúnisìn (RDS), tí ó jẹ́ wípé gbé àwọn ẹ̀rọ-gbohùngbohùn sí ìta gbangba níbi tí àwọn ènìyàn yóò ti tẹ́tí sí ìròyìn òkèèrè ti Iléeṣẹ́ Ìgbóhùnsáfẹ́fẹ́ Ìjọba Gẹ̀ẹ́sì.
Ní ọdún-un 1950, RDS gbé aṣọ tuntun wọ̀ — ó di Iléeṣẹ́ Ìgbóhùnsáfẹ́fẹ́ Orílẹ̀-èdèe Nàìjíríà (NBS) — nígbà tí ó ṣe, ó di Iléeṣẹ́ Alájọṣepọ̀ Ìgbóhùnsáfẹ́fẹ́ Orílẹ̀-èdèe Nàìjíríà (NBC), pẹ̀lú ìkànnì ìgbóhùnsáfẹ́fẹ́ ní àwọn ẹ̀ka tí Nàìjíríà pín sí. NBC pàpà paradà di Iléeṣẹ́ Alájọṣepọ̀ Ìgbóhùnsáfẹ́fẹ́ Ìjọba Àpapọ̀ Orílẹ̀-èdèe Nàìjíríà (FRCN) lọ́dún-un 1978.
"Iléeṣẹ́ Rédíò àkọ́kọ́ ní Nàìjíríà tí a dá sílẹ̀ ní Ìbàdàn ní ọdún-un 1939.
Ìkànnì-i Kano ló tẹ̀lée ní 1944, gẹ́gẹ́ bí iléeṣẹ́ ìròyìn oríaayélujára Legit ti ṣe ṣàlàyé."
Legit ṣàlàyé wípé RayPower FM, ni rédíò aládàáni àkọ́kọ́ ní orílẹ̀-èdèe Nàìjíríà, ọdún-un 1994 ni a dá a sílẹ̀, nígbàtí ó mmáa fi di ọdún-un 2007, àwọn olùgbọ́ ti ń gbọ́ ìròyìn kárí ayé.
Rédíò ti ṣiṣẹ́ gẹ́gẹ́ bíi ohun èlò àyẹ̀wò fún àwọn tí ó wà nípò àṣẹ, ìfìdírinlẹ̀ òfin àti ìpèsè ìkéde tí yóò lapa dáadáa lára àwọn ènìyàn.
Ní ọdún-un 2019, Ìgbìmọ̀ Ètò Ìgbóhùnsáfẹ́fẹ́ Orílẹ̀-èdèe Nàìjíríà (NBC) ṣán African Independent Television àti RayPower FM pa nítorí wípé ó ṣe àgbéjáde ètò tí ó tako ìjọba.
Bákan náà ní ọdún- 2019, Jay FM tíó wà ní Port Harcourt di ṣíṣánpa lẹ́yìn tí a fi ẹ̀sùn ìtako ìjọba kàn án.
"Ọkọ̀ọ Radio Nigeria ṣe ìpolówó ara rẹ̀ gẹ́gẹ́ bíi ""iléeṣẹ́ ìgbóhùnsáfẹ́fẹ́ ẹgbẹẹgbẹ̀rún ọdún,"" tí ó sì darapọ̀ mọ́ àwọn òṣìṣẹ́ rédíò kárí ayé fún ìsààmì ayẹyẹ Ọjọ́ Ẹ̀rọ-ìgbóhùnsáfẹ́fẹ́ Àgbáyé ọdún-un 2020."
Àwòrán láti ọwọ́ọ Muhammadtaha Ibrahim Ma'aji, tí a gba àṣẹ láti lò ó ní ìbámu pẹ̀lú àṣẹ CC BY 2.0.
Rédíò tí ó ń mú ìsọdọ̀kan àti ìgbéga wáyé
UNESCO rọ ìlú gbogbo láti sààmì ayẹyẹ Ọjọ́ Ẹ̀rọ-ìgbóhùnsáfẹ́fẹ́ Àgbáyé nípasẹ̀ ṣíṣe àwọn ètò àjọṣe pẹ̀lú iléeṣẹ́ ìgbóhùnsáfẹ́fẹ́, iléeṣẹ́ ìjọba, iléeṣẹ́ aládàáni àti iléeṣẹ́ tí kì í ṣe ti ìjọba kárí ayé.
"Àkórí Àyájọ́ Ọjọ́ Ẹ̀rọ-ìgbóhùnsáfẹ́fẹ́ Àgbáyé ti ọdún yìí, tí í ṣe ìkẹrìnlá irú ẹ̀ ni ""Ẹ̀rọ-ìgbóhùnsáfẹ́fẹ́ àti Onírúurú."""
Rédíò ẹlẹ́rọ-amìtìtì orílẹ̀-èdèe Nàìjíríà ń jí gìrì sí ọ̀rọ̀ àṣàròo rẹ̀ tí ó ní ìgbésókè àwọn ènìyàn àti ṣíṣe ìsọdọ̀kan ètò afúnilóye, akọ́nilẹ́kọ̀ọ́ àti aṣínilétí tó ń ró àwọn ọmọ orílẹ̀-èdèe Nàìjíríà lágbára láti ní ìfẹ́ ìlú ẹni.
Èyí wúlò ní àsìkò tí ìpínyà àti ìyapa ẹ̀yà, àìbalẹ̀-ọkàn látàrí ọ̀rọ̀ òṣèlú tó ń kojúu orílẹ̀-èdèe Nàìjíríà.
Ìpín ipò Ìlú tí ó rọrùn láti fọ́ ọdún-un 2019 fi Nàìjíríà sí ipò kẹrìnlá lágbàáyé, ìkẹsàn-án ní Ilẹ̀-Adúláwọ̀.
Láti ọdún-un 2011, Boko Haram, ajìjàǹgbara ẹ̀sìn Ìmàle ní Ìlà-oòrùn àréwá orílẹ̀-èdèe Nàìjíríà, ti fi ẹ̀rù sí ọkàn àwọn ènìyàn àti bí àwọn ìkọlù tó rorò wọ́n ti ṣe fa ikú láì rò tẹ́lẹ̀ ìpí àwọn ènìyàn, tí ọ̀pọ̀ọ́ sì ti di àwátì.
Kà síwájú sí i: Nàìjíríà: Ìlú tí ó kùnà — òótọ́ tàbí ìwòye?
Ní ìtẹ̀síwájú ìgbésókè orílẹ̀-èdèe Nàìjíríà, àwọn aláṣẹ FRCN Ẹ̀ka ti Èkó ṣe àgbékalẹ̀ ọkànòjọ̀kan ètò láti sààmì Àyájọ́ Ọjọ́ Ẹ̀rọ-ìgbóhùnsáfẹ́fẹ́ Àgbáyé ọdún-un 2020.
"Eré gbogboó bẹ̀rẹ̀ pẹ̀lú ìdíje àròkọ ọlọ́rọ̀ 1,200 tí ó dá lóríi ""ìdí tí mo fi nífẹ̀ẹ́ sí láti máa gbọ́ rédíò"" fún àwọn akẹ́kọ̀ọ́ iléèwé gíga."
Àwọn akẹ́kọ̀ọ́ ìmọ̀ iṣẹ́ ìròyìn náà ṣe ètò alálàyé oníṣẹ̀ẹ́jú 5 tí ó dá fìrìgbagbòó lóríi pàtàkìi ẹ̀rọ-ìgbóhùnsáfẹ́fẹ́ fún ìmúṣẹ àwọn ìlépa ìmúdúró ìdàgbàsókè. Àwọn àkópa méjì ló jáwé olúborí.
Olúborí ìdíje àròkọ Ìlọ̀rí Olúwatóbi ti iléèwé Mater Christi Catholic Girls' High School, Ìgede Èkìtì, Ìpínlẹ̀ Èkìtì, mú u wá sí ìrántí ìgbà àkọ́kọ́ tí òùn-ún ṣalábàápàdée rédíò nígbà tí òùn-ún wà ní ọmọ ọdún 5:
Ó dà bí ẹni pé ọmọ ọdún 5 ni mí nígbà tí mo kọ́kọ́ ní ẹ̀rọ-ìgbóhùnsáfẹ́fẹ́ẹ̀ mi.
Mo tẹ àwọn ohun-àtẹ̀-àṣẹ ara rẹ̀, ó sì tàn.
"Ìyàlẹ́nu ló jẹ́ fún mi bí mo ṣe ń gbọ́ ohùn tí ó ń ti inúu ""àpótí"" yìí jáde tí mo sì rò wípé àwọn èèyàn ló wà nínúu rẹ̀."
Ẹ̀rú bá mi mo sì béèrè lọ́wọ́ọ bàbáà mi ohun tí ó jẹ́, ó sì ṣàlàyé ohun tí rédíò jẹ́ fún mi.
Ní ọjọ́ 12 oṣù Èrèlé, àwọn akẹ́kọ̀ọ́ ilé ẹ̀kọ́ gíga, akẹ́kọ̀ọ́ ìmọ̀ iṣẹ́ ìròyìn, ọ̀jẹ̀ sọ̀rọ̀sọ̀rọ̀ àti àwọn alẹ́nulọ́rọ̀ nínú iṣẹ́ ìròyìn àti àwọn olólùfẹ́ẹ̀ rédíò péjúpésẹ̀ sí Lekki Coliseum ní Èkó fún àpérò láti jíròrò nípa pàtàkìi ẹ̀rọ-ìgbóhùnsáfẹ́fẹ́ fún ìdàgbàsókè.
Ní ọjọ́ 12 oṣù Èrèlé, àwọn akẹ́kọ̀ọ́ ilé ẹ̀kọ́ gíga, akẹ́kọ̀ọ́ ìmọ̀ iṣẹ́ ìròyìn, ọ̀jẹ̀ sọ̀rọ̀sọ̀rọ̀ àti àwọn alẹ́nulọ́rọ̀ nínú iṣẹ́ ìròyìn àti àwọn olólùfẹ́ẹ̀ rédíò péjúpésẹ̀ sí Lekki Coliseum ní Èkó fún àpérò láti jíròrò nípa pàtàkìi ẹ̀rọ-ìgbóhùnsáfẹ́fẹ́ fún ìdàgbàsókè.
Àwòrán láti ọwọ́ọ Ọmọ Yoòbá, a gba àṣẹ láti lò ó.
Ní ìgbàtí ọjọ́ rọ̀, àwọn ògbóǹtarìgì sọ̀rọ̀sọ̀rọ̀, àwọn aṣojú the Ọba Èkó, Ọ̀túnba Gani Adams, Ààrẹ Ọ̀nà Kakanfò ilẹ̀ẹ Yorùbá àti àwọn àlejò mìíràn péjọ sí Lekki Coliseum fún àpèjẹ alẹ́ àti ìfàmìẹ̀yẹ dánilọ́lá Àyájọ́ Ọjọ́ Ẹ̀rọ-ìgbóhùnsáfẹ́fẹ́ Àgbáyé.
Àwọn àgbà ọ̀jẹ̀ẹ sọ̀rọ̀sọ̀rọ̀ bíi Cordelia Okpei àti àwọn tó kù wá sí ayẹyẹ náà.
Àmì-ẹ̀yẹ̀ẹ̀ fún akíkanjú lẹ́nu iṣẹ́ àti ìṣiṣẹ́sìnlú lọ sí ọ̀dọ̀ àwọn ẹni tí ó tọ́ sí.
Ọ̀kan-ò-jọ̀kan ètò náà wá sópin pẹ̀lú ìṣójú òpó sílẹ̀ láti gba ìpè àwọn olùgbọ́ wọlé sórí afẹ́fẹ́, níbi tí wọ́n ti ní kí àwọn ènìyàn ó sọ wípé “ẹ kú Àyájọ́ Ọjọ́ Ẹ̀rọ-ìgbóhùnsáfẹ́fẹ́ Àgbáyé” ní àwọn onírúurú ọ̀kan-ò-jọ̀kan èdè àti ahọ́n:
Kò sẹ́ni tí kò kópa nínú ayẹyẹ náà. Ohùn àwọn ikọ̀ Ohùn Àgbáyé náà bọ́ sórí afẹ́fẹ́ ní orí ìkànnì Metro 97.7FM. Àwọn sọ̀rọ̀sọ̀rọ̀ tí ó ti fẹ̀yìntì ló ka ìròyìn tí wọ́n sì tọ́kùn ètò.
Àkọ́kọ́ irú ‘ẹ̀ ni Àyájọ́ Ọjọ́ Ẹ̀rọ-ìgbóhùnsáfẹ́fẹ́ Rédíò Orílẹ̀-èdèe Nàìjíríà ọdún-un 2020 àmọ́ àwọn òṣìṣẹ́ àti olólùfẹ́ẹ̀ rédíò lérò wípé ayẹyẹ náà yóò máa wáyé lọ́dọọdún.
Olóyè yìí nírètí wí pé àwọn ọmọ Yorùbá yóò tẹ́wọ́ gba 'alífábẹ́ẹ̀tì t'ó ń sọ̀rọ̀ ' tí òun hu ìmọ̀ rẹ̀
Ǹjẹ́ ìlànà ìṣọwọ́kọ Yorùbá tuntun yóò di lílò lọ́jọ́ iwájú bí?
Olóyè Tolúlàṣẹ Ògúntósìn dúró lẹ́gbẹ̀ẹ́ ọba ilẹ̀-Yorùbá káàfàtà, Ọọ̀ni ti Ilé-Ifẹ̀, lórí ìjókòó.
Olóyè Ògúntósìn ló yànda àwòrán.
Lẹ́yìn ìpolongo kárí ayé nípa Ọdún Èdè Ìbílẹ̀ Àgbáyé ní ọdún 2019 àti ìkéde Ọdún mẹ́wàá Èdè Ìbílẹ̀ Àgbáyé 2022-2032, púpọ̀ nínú àwọn ọmọ Ilẹ̀-Adúláwọ̀ ló ti bẹ̀rẹ̀ ọ̀kan-ò-jọ̀kan àkànṣe iṣẹ́ tó ní ṣe pẹ̀lú ìdàgbàsókè àwọn èdè Ilẹ̀-Adúláwọ̀.
Lílo àyálò ìlànà Látíìnì fún kíkọ èdè Yorùbá yóò di àfìsẹ́yìn tí eégún aláré ń fiṣọ láì pẹ́ ní èyí tí ọmọ Káàárọ̀-o-ò-jí-ire kan, Olóyè Tolúlàṣẹ Ògúntósìn, ẹni tí ó ń gbé ní Ilẹ̀ Olómìnira Bẹ̀nẹ̀, Ìwọ̀-oòrùn Ilẹ̀-Adúláwọ̀, ti hu ìmọ̀ ìlànà tí a ó máa lò fún kíkọ èdè Yorùbá.
Alífábẹ́ẹ̀tì Yorùbá tuntun náà ti ń gbàlú kan pẹ̀lú ìrètí wí pé yóò pààrọ ti Látíìnì tí ó ti jẹ́ lílò fún ọgọ́rùn-ún ọdún àti jù bẹ́ẹ̀ lọ.
Gẹ́gẹ́ bí Olóyè Ògúntósìn ti ṣe rò fún Ohùn Àgbáyé nínú ìfọ̀rọ̀wánilẹ́nuwò lórí WhatsApp, ojú àlá ni alífábẹ́ẹ̀tì àràmàndà wọ̀nyí ti f'ara hàn sí òun.
"Ní báyìí, níṣe ni ó máa ń ṣe ìrìnàjò jákèjádò Ilẹ̀-Yorùbá — láti Bẹ̀nẹ̀ títí dé Nàìjíríà — láti polongo ""alífábẹ́ẹ̀tì tí ó ń sọ̀rọ̀ "" rẹ̀ bí àwọn alálẹ̀ ti ṣe fi rán an."
Olóyè Ògúntósìn nígbàgbọ́ wí pé Odùduwà, tí ó jẹ́ bàbá-ńlá ìran Yorùbá lo alífábẹ́ẹ̀tì náà ní ayé àtijọ́ — àmọ́ ó ti di ohun ìgbàgbé.
25 ni gbogbo àwọn àmì wọ̀nyí lápapọ̀.
Àwọn onímọ̀ nípa èdè ní Ilẹ̀-Adúláwọ̀ sọ wí pé kí ìlọsíwájú ó tó dé bá Ilẹ̀ Adúláwọ̀, ó pọn dandan kí ó ní ìlànà ìṣọwọ́ kọ èdè tàbí ìlànà kíkọ tí ó jẹ́ tirẹ̀.
Èdè tí ó wà lábẹ́ ìsọ̀rí Niger-Congo tí ó jẹ́ èdè ìran tí ó ti wà lọ́jọ́ tó ti pẹ́ tí ó sì lajú bí èdè Yorùbá ò gbọdọ̀ gbọ́kàn tẹ ìlànà àyálò fún kíkọ èrò àti ìmọ̀ ìrírí ayé rẹ̀.
Kà sí i: Ọ̀rọ̀ àyálò nínú èdè Yorùbá: Bí èdè ṣe yí padà
Ní ọdún 1843, Àlùfáà Sámúẹ́lì Àjàyí Crowther òṣìṣẹ́ Ẹgbẹ́ Iṣẹ́ Ìránṣẹ́ Ẹ̀sìn Ìgbàgbọ́ (CMS) ṣe àgbékalẹ̀ ìlànà ìṣọwọ́kọ èdè Yorùbá nípa yíya ìlànà Látíìnì lò pẹ̀lú àfikún àwọn àmì ohùn — tàbí àmì ìró ọ̀rọ̀.
Láti ìgbà náà, ẹgbẹẹgbẹ̀rún ìwé ti jẹ́ títẹ̀ jáde ní èdè Yorùbá nípasẹ̀ lílo ìlànà kíkọ Látíìnì dípò Ajami, tí í ṣe ìlànà ìṣọwọ́kọ Lárúbáwá tí ó ti jẹ́ lílò tẹ́lẹ̀tẹ́lẹ́ rí fún kíkọ èdè Ìwọ̀-oòrùn Ilẹ̀-Adúláwọ̀ bí i èdè Yorùbá àti Haúsá kí ó tó di 1843.
Àwọn alágbàwí èdè gbà wí pé lílo ìlànà Látíìnì, tí ó jẹ́ ìṣọwọ́kọ láti ilẹ̀ òkèèrè, fún kíkọ àwọn èdè Ilẹ̀-Adúláwọ̀ sílẹ̀, fi ilẹ̀ náà sínú ipò ẹrú.
Ìpolongo ìlànà ìṣọwọ́kọ tuntun yìí wáyé ní ìbámu pẹ̀lú àwọn ìṣọwọ́kọ ayébáyé Ilẹ̀-Adúláwọ̀, bí i hieroglyphics ti Íjípìtì, Àkójọ Adrinka ti ìran Akan ní Ghana, Ge'ez ti Ethiopia, ìṣọwọ́kọ ìyàwòrán Nsibidi ti Àárín Gbùngbùn Ìwọ̀-oòrùn Ilẹ̀-Adúláwọ̀ tí ó ti wà fún bí 5000 ọdún k'á tó bí Jésù, àti alífábẹ́ẹ̀tì Vai ni Ilẹ̀-Adúláwọ̀ jẹ́ orísun wọn.
Ìṣàyèwò 'alífábẹ́ẹ̀tì tó ń sọ̀rọ̀ '
Alákòóso Ohùn Àgbáyé lédè Yorùbá, Ọmọ Yoòbá fi ọ̀rọ̀ wá Olóyè Ògúntósìn lẹ́nu wò, nípasẹ̀ iṣẹ́-ìjẹ́ ohùn lórí ẹ̀rọ iìtàkùrọ̀sọ WhatsApp, láti mọ̀ sí i nípa bí ó ti ṣe rí alífábẹ́ẹ̀tì tuntun yìí.
Olóyè Ògúntósìn, tó jẹ́ ọmọ ọdún 43 báyìí, ṣàlàyé wí pé òun kò lè ka ju ilé gíga lọ lẹ́yìn ìpapòdà bàbá òun ní ọdún 1997, tí òun sì ní láti ṣe ojúṣe bí bàbá gẹ́gẹ́ bí àkọ́bí láti tọ́jú àwọn àbúrò rẹ̀.
Síbẹ̀, bí olóyè Yorùbá tí ó jẹ́, iṣẹ́ ìgbélárugẹ àṣà rẹ̀ dá lórí ìṣọ̀kan àwọn ọmọ Odùduwà jẹ́ ohun tí ó gbé e lọ́kàn gidi gan-an, tí ó sì ń ṣe bí olùlàjà láàárín wọn.
Bí iṣẹ́ ìgbélárugẹ àṣà yìí ṣe ń gbòòrò sí i, kò tẹ́ ẹ lọ́rùn tó bí ó ṣe fẹ́.
Lọ́dún 2011, ó fi eéjì kún eéjì, ó fi ẹẹ́ta kún ẹẹ̀ta, ó gba oko aláwo lọ.
Babaláwo náà, Olókun Awópẹ̀tu, wí fún un pé kí ó lọ sí ojúbọ ìdílé rẹ̀ tí ó wà ní agbègbè Farasìnmí ní Àgbádárìgì (Badagry), Ìpínlẹ̀ Èkó, orílẹ̀ èdè Nàìjíríà, wí pé yóò rí atọ́nà tí yóò tọ́ka sí ohun tí Elédùmarè rán an wá ṣe láyé ní ojúbọ náà.
Ní ojúbọ náà, ó rí “nǹkan àjèjì” kan tí ó mú padà sí ilé rẹ̀ ní Porto-Novo, Bẹ̀nẹ̀.
Nígbà tí ó délé, òkùnkùn bo iyàrá birimùbirimù.
Kò sí iná amọ́roro nínú yàrá ìgbàlejò, ìmọ́lẹ̀ ìtànṣán ẹ̀rọ àmóhùnmáwòrán ni ó máa ń fi ríran.
Ó gbé nǹkan àjèjì náà sí orí àga ìgbénǹkanlé, ó sì tan ẹ̀rọ àmóhùnmáwòrán, kàyéfì ló jẹ́ fún un, ohun tí ó gbé sórí àga di àwátì.
Ó tú gbogbo ilé kí ó tó wá rí i ní kọ̀rọ̀ ilé.
Lálẹ́ ọjọ́ yẹn, ó fi nǹkan àjèjì náà sábẹ́ ìgbèrí sùn. Ó sọ fún Ohùn Àgbáyé:
Mo lálàá wí pé mo lọ sí inú oòrùn.
Nígbà tí mo débẹ̀, ó òkùnkùn ṣú bolẹ̀, a sì fi alífábẹ́ẹ̀tì náà hàn mí ní àpẹẹrẹ ìmọ́lẹ̀.
Ìgbàkúùgbà tí mo bá sùn, àlá yìí kan náà ni ní ọ̀nà àrà, mò ń lọ láti agbègbè kan sí agbègbè mìíràn, tí mo sì ń kọ́ àwọn ènìyàn bí a ti ṣe ń lo ìṣọwọ́kọ tuntun náà...
Fún ọdún mẹ́ta, kò yé lálàá nípa alífábẹ́ẹ̀tì náà, kò yé ríran léraléra, síbẹ̀ kò ṣe nǹkankan sí i.
Lásìkò yìí, ní ọdún 2016, mo tún lọ sí inú oòrùn, mo ṣalábàápàdé ọkùnrin kan, Lámúrúdu, tí ó kọ́ mi ní ìró alífábẹ́ẹ̀tì náà, tí ó sì pa á láṣẹ fún mi pé kí tan ìmọ́lẹ̀ ìmọ̀ kíkọ àti kíkà àmì ìṣọwọ́kọ̀ náà kárí ayé.
Mo máa ń jọ arúgbó lójú àlá — tí yóò sì rẹ̀ mí — bí mo bá jí lójú oorun.
Ó wá bẹ̀rẹ̀ sí ní di ẹ̀rù fún Olóyè Ògúntósìn — ó ń rẹ̀ ẹ́ látinú wá, ó wí fún Ohùn Àgbáyé.
Ó pinnu láti rọ́ àwọn àlá náà fún Oníkòyí, Alájàṣẹ́ ti Àjàṣẹ́ ní Port-Novo, ẹni tí ó là á lóye pé kí ó ṣe bí a ti pa á láṣẹ lójú àlá.
Látàrí ìdí èyí, ó ń ṣe ìrìnàjò láti agbègbè kan dé òmíràn ní Ilẹ̀-Yorùbá láti tan ìmọ̀ alífábẹ́ẹ̀tì Odùduwà náà.
Àwòrán-àtohùn àwọn olùkọ́ni tí ó kọ́ àwọn akẹ́kọ̀ọ́ bí a ti ṣe ń kọ alífábẹ́ẹ̀tì Odùduwà ní yàrá-ìgbẹ̀kọ́ kan ní Bẹ̀nẹ̀:
Ìgbélárugẹ alífábẹ́ẹ̀tì Yorùbá náà
Lọ́dún 2017, Olóyè Ògúntósìn, pẹ̀lú àwọn ọba Aláṣẹ igbá-kejì òrìṣà Ilẹ̀-Yorùbá nílé àti lẹ́yìn odi, ṣe àbẹ̀wó to sí Ọ̀gbẹ́ni Rauf Arẹ́gbẹ́ṣọlá, ẹni tí ó fi ìgbà kan rí jẹ́ alákòóso Ìpínlẹ̀ Ọ̀ṣun, ní olú ìpínlẹ̀ náà th Òṣogbo, e one- èdè Nàìjíríà, láti béèrè fún àtìlẹ́yìn fún alífábẹ́ẹ̀tì Odùduwà tuntun náà.
Arẹ́gbẹ́ṣọlá ni Mínísítà fún Ètò Abélé fún orílẹ̀-èdè Nàìjíríà ní sáà ti a wà yìí.
Ìwé tí a kọ ránṣẹ́ sí gómìnà ìpínlẹ̀ Ọ̀ṣun ní ìrántí àwọn ìpinnu kíkọ́ alífábẹ́ẹ̀tì tuntun náà tí kò tíì wá sí ìmúṣẹ.
Ọdún mẹ́ta ti lọ, ó bani lọ́kàn jẹ́, ìlérí tí gómìnà àná Arẹ́gbẹ́ṣọlá ṣe láti rí dájú wí pé alífábẹ́ẹ̀tì tuntun náà jẹ́ kíkọ́ ni àwọn iléèwé tí ó ń bẹ ní Ìwọ̀-oòrùn gúúsù ilẹ̀ Nàìjíríà kò tíì di múmú ṣẹ.
Lójúnà kí alífábẹ́ẹ̀tì Odùduwà náà ó ba di ìlúmọ̀ọ́ká, Olóyè Ògúntósìn ti kọ ìwé kan, ó sì ti ká àwòrán-àtohùn alálàyé kan tí ó tú pẹrẹpẹ́ẹ̀rẹ̀ ìṣọwọ́kọ alífábẹ́ẹ̀tì tuntun náà sílẹ̀ — fún mùtúmùwà láti wò ní abalaabala lórí ayélujára — bákan náà ni ẹ̀patìrì iṣẹ́ akọ́nilọ́gbọ́n kàtúùnù fún àwọn èwe tí kò s'ówó láti parí i rẹ̀ náà ò gbẹ́yìn.
"Olóyè Ògúntósìn ń lo gbàgbé YouTube, WhatsApp àti Ẹgbẹ́ orí Facebook: ""Ẹ̀kọ́ Aèébáèjìogbè Odùduwà"" àti “Alífábẹ́ẹ̀tì Odùduwà” fi ṣe ìgbélárugẹ àti kọ́ àwọn akẹ́kọ̀ọ́ tí ó nífẹ̀ẹ́ sí kíkọ́ ìlànà ìṣọwọ́kọ náà."
Ó rọ gbogbo ẹni tí ọ̀ràn kan láti dìde sí ti ìgbélárugẹ àwárí tí yóò gbá ìlànà ìṣọwọ́kọ Àmúnisìn tì sẹ́gbẹ̀ẹ́ tí yóò sì fún ìran Yorùbá ní ìdánimọ̀ tí ó tọ́ tí ó ní ṣe pẹ̀lú ìdàgbàsókè èdè.
"Ọkùnrin onínúure kan, Sunday Adéníyì, ṣe agbátẹrù ìtẹ̀jáde 1,000 ẹ̀da ìwé ìgbẹ̀kọ́ ""Alífábẹ́ẹ̀tì Aèébáèjìogbè Odùduwà"" fún àwọn ọmọ iléèwé alákọ̀ọ̀bẹ̀rẹ̀."
Kà sí i: Sísọnù sínú ògbufọ̀: Ìdí tí Atúmọ̀ Google ṣe ń kùnà — nínú títúmọ̀ èdè Yorùbá — àti àwọn èdè mìíràn
Ẹ̀da ìwé ẹ̀kọ́ alífábẹ́ẹ̀tì náà wà ní èdè Igbo, Hausa, English, àti Faransé lẹ́sẹẹsẹ. Síbẹ̀síbẹ̀, àtìlẹ́yìn kì í pọ̀ jù fún ìpínkárí alífábẹ́ẹ̀tì náà.
Ìgbésẹ̀ tí ó mú ìwúrí dání ni alífábẹ́ẹ̀tì Odùduwà náà.
Ṣùgbọ́n, sísún láti ìlànà Látíìnì sí ìlànà tuntun ni yóò mú ìpèníjà ńlá lọ́wọ́.
Kò jẹ́ bó ṣe jẹ́, ohun tí yóò mú ìlọsíwájú àti ìdàgbàsókè bá èdè Yorùbá ni alífábẹ́ẹ̀tì Odùduwà — ohun tí ìran Yorùbá yóò pè ni tiwa-ń-tiwa.
Ọ̀rọ̀ àyálò nínú èdè Yorùbá: Bí èdè ṣe yí padà
Ṣé àkàrà ni ò ń pè àbí bean cake?
Àkàrà tàbí beans cake ní Nàìjíríà jẹ́ oúnjẹ àárọ̀ ní Nàìjíríà, ọjọ́ 11, oṣù kéje, ọdún 2013. Àwòrán láti ọwọ́ Atimukoh láti orí i Wikimedia Commons, àṣẹ CC BY 2.0.
Àjọṣepọ̀ láàárín onírúurú èdè ti wà láti ayébáyé.
"Fún àkàwé, kí á wo gbólóhùn bí i ""restaurant,"" tí ó jẹ́ ọ̀rọ̀ tí a yá láti inú èdè Faransé wá sínú èdè Gẹ̀ẹ́sì."
Lóde òní, ọ̀rọ̀-àyálò yìí — ìyẹn gbólóhùn tí a gbà lò láti inú èdè kan sí inú èdè mìíràn láì tú ìmọ̀ rẹ̀ — kò l'óǹkà nínú èdè Gẹ̀ẹ́sì àfi bí ẹni pé kì í ṣe ọ̀rọ̀ tí a yá lò.
Àwọn èdè àyálò wọ̀nyí wáyé látàrí àbápàdé onírúurú ènìyàn kárí ayé, bí wọ́n ṣe ń ṣíkiri, ṣe ọrọ̀ Ajé, àti káràkátà.
Látàrí ìtàkùrọ̀sọ tí ó wáyé láàárín àwọn onírúurú ènìyàn wọ̀nyí, èdè wọnú èdè, gbólóhùn àti àpólà ọ̀rọ̀ di àyálò.
Ìṣẹ̀lẹ̀ yìí kò yọ ìran Yorùbá sílẹ̀.
Ó tó ẹgbẹẹgbẹ̀rún ènìyàn 40 tíó ń fọ èdè Yorùbá ní orílẹ̀ èdè Nàìjíríà, irú èdè Yorùbá ti dàpọ̀ mọ́ ṣapala èdè Gẹ̀ẹ́sì, tí í ṣe èdè ìjọba amúnisìn àná láti ọdún 1914 sí 1960.
"Ó tó ìdajì gbólóhùn èdè Gẹ̀ẹ́sì tí a yà lò nínú èdè Yorùbá. Kí a wo ọ̀rọ̀ bí i ""cup"" Ó di kó̩ò̩pù."
"A pe ""phone"" ní fóònù, ""ball"" di bó̩ò̩lù, ""television"" ni te̩lifís̩ó̩ò̩nù, àti bẹ́ẹ̀ bẹ́ẹ̀ lọ."
"Àwọn gbólóhùn ""àyálò"" wọ̀nyí mú èdè Yorùbá fẹjú sí i."
Bákan náà ni àwọn ọ̀rọ̀ àyálò inú èdè Hausa tí àwọn ẹgbẹẹgbẹ̀rún 44 ènìyàn ní Àríwá ilẹ̀ Nàìjíríà ń sọ lọ sua.
"Èdè yìí yá ọ̀kẹ́ àìmọye ọ̀rọ̀ lò láti inú èdè Lárúbáwá, àwọn ọ̀rọ̀ bí i àlùbáríkà (""ìbùkún""), àlbásà (""àlùbọ́sà"") àti wàhálà (""ìyọnu"")."
Ohun tí ó jẹ́ ìwúrí ní ti àwọn ọ̀rọ̀ àyálò nínú èdè Yorùbá ni bí àwọn ènìyàn ṣe ń lò wọ́n nínú ìtàkùrọ̀sọ lójoojúmọ́ bí wọ́n ṣe ń ṣàn wọ inú èdè náà.
"Wà á gbọ́ gbólóhùn bí i, Bá o̩mo̩ ye̩n mú bó̩ò̩lu è̩ tàbí ""Help the child take the ball"" lédè Gẹ̀ẹ́sì."
Adi, ọmọ-ọ̀rọ̀ tí a falà sí lábẹ́ bó̩ò̩lu jẹ́ tiwantiwa nínú èdè Yorùbá, àwọn aṣàfọ̀ mọ bí wọ́n ṣe ń lò ó.
Ìpèníjà kan tí èdè Yorùbá ní nípa ti ọ̀rọ̀ àyálò ò ju ti ògbufọ̀ ọ̀rọ̀ wuuru tí àwọn aṣàfọ̀ èdè Yorùbá máa ń ṣe láti túmọ̀ àwọn gbólóhùn èdè Yorùbá sí ti Gẹ̀ẹ́sì tí wọ́n máa ń lò nínú ìpèdè dípò ojúlówó èdè Yorùbá.
Fún àpẹẹrẹ, àkàrà — tí àwọn ọmọ Yorùbá ti túmọ̀ sí bean cake — pàápàá nínú ìfọ̀rọ̀jomitoro-ọ̀rọ̀ pẹ̀lú àlejò.
Lílo ọ̀rọ̀ ní èdè pọ́nbélé máa ń mú kí àṣà — ó gbòòrò — tí yóò sí máa jẹ́ kí èdè ó di ìtẹ́wọ́gbà.
Bí a bá wò ó báyìí, kò s'ẹ́ni jẹ́ pe sushi Japan lórúkọ mìíràn — sushi ni sushi ń jẹ́.
Bí èyí bá rí bẹ́ẹ̀ fún àwọn ọ̀rọ̀ Yorùbá náà, èdè àti àṣà rẹ̀, yóò gbilẹ̀ kọjá orílẹ̀-èdè Nàìjíríà àti ibi tí wọ́n ti ń fọ èdè Yorùbá kárí ayé.
Fún àpẹẹrẹ, àmàlà jẹ́ oúnjẹ tí ó ilẹ̀ Yorùbá lókìkí, pàápàá ní òkè òkun.
Gbólóhùn yìí ti rá pálá wọnú ìlò ọ̀rọ̀ èdè mìíràn bí àwọn aṣàfọ̀ Yorùbá bá tẹnu mọ́ ọn.
"Títúmọ̀ rẹ̀ sí ""yam flour"" dín agbára ìpèdè náà kù — yóò sọ ""ipò Yorùbá nù."""
"Bí a bá wo gbólóhùn èdè Gẹ̀ẹ́sì tí a yí padà sí èdè Yorùbá ""fanimorious"", tí ó ti ń lókìkí tí ó sì ti wà nínú Ìwé Ìtumọ̀ Ìgbàlódé."
Ó túmọ̀ sí “bójúmu,” tàbí “rẹwà,” tí ó súyọ láti fanimó̩ra tí í ṣe gbólóhùn Yorùbá.
Èyí f'ara pẹ́ ìbáṣepọ̀ fonọ́lọ́jì àti mọfọ́lọ́jì: èdè Yorùbá kì í fàyè gba ìhunpọ̀ kọ̀nsónántì àti kí ọ̀rọ̀ parí pẹ̀lú kọ̀nsónántì.
Torí ìdí èyí, a fi àfòmọ́ ìparí -ious èdè Gẹ̀ẹ́sì kún ọ̀rọ̀ ìpìlẹ̀ Yorùbá.
Síbẹ̀, òtítọ́ farahàn wípé láti ara èdè Yorùbá ni ó ti sú yọ. Ìgbéga ni èyí jẹ́ fún Yor Yorùbá.
Ní kò pẹ́ kò pẹ́ yìí, ọ̀gọ̀rọ̀ èdè Gẹ̀ẹ́sì bí a ti ṣe ń lò ó ní Nàìjíríà di àfikún nínú ìwé ìtúmọ̀ èdè Gẹ̀ẹ́sì ti Oxford.
Ọpọ́n èdè Yorùbá yóò sún síwájú bí àwọn tó ń fọ èdè náà bá lọ́wọ́ sí ìdàgbàsókè rẹ̀; ìlò rẹ̀ nínú iṣẹ́ ìkọ̀ròyìn pọn dandan ní ìbámu pẹ̀lú bí ayé ṣe ń lu jára wọn bí ajere lóde òní.
Ní ìparí, èyí yóò túbọ̀ mú kí iṣẹ́ ìwádìí èdè Niger-Congo ó rinlẹ̀.
Sísọnù sínú ògbufọ̀: Ìdí tí Atúmọ̀ Google ṣe ń kùnà — nínú títúmọ̀ èdè Yorùbá — àti àwọn èdè mìíràn
Ọ̀pọ̀lọpọ̀ ògbufọ̀ tí ẹ̀rọ ṣe ni kò nítumọ̀.
Aṣàmúlò Ẹgbẹ́ Wikimedia Orílẹ̀-èdè Nàìjíríà, oṣù Ọ̀wàrà ọdún 2018 láti orí Wikimedia Commons CC.BY.2.0.
"Èdè Gẹ̀ẹ́sì ti jẹ gàba lórí ìbánisọ̀rọ̀ tí ó ń wáyé ní orí ẹ̀rọ ayélukára-bí-ajere gẹ́gẹ́ bí èdè ""gbogbo àgbáyé"" fún ìtàkùrọ̀sọ láti ìbẹ̀rẹ̀ pẹ̀pẹ̀ ẹ̀rọ ayélujára."
Nínú oṣù Èrèlé ọdún 2020, gẹ́gẹ́ bí WebTech3 ti ṣe fi hàn, ìdajì ibùdó ìtakùn àgbáyé tó wà lórí ayélujára ni a kọ ní èdè Gẹ̀ẹ́sì.
Àmọ́ bí ọ̀pọ̀lọpọ̀ ènìyàn tí ó ń sọ oríṣìíríṣìí èdè àgbáyé ṣe ń bọ́ sórí ayélukára-bí-ajere, ó ṣẹ́ ẹtà ìjà fún èdè ẹni — ìráàyè sí ìṣògbufọ̀ sí onírúurú èdè tí yóò ṣẹ̀ ní mọnawáà.
Ọ̀pọ̀lọpọ̀ iléeṣẹ́ onímọ̀ ẹ̀rọ ti ṣe iṣẹ́ ribiribi ní ti ìṣàkọsílẹ̀ àwọn ọ̀rọ̀ tí kì í ṣe èdè Gẹ̀ẹ́sì sórí ayélujára, tí ó ń ṣe olùlànà onírúurú èdè lórí ẹ̀rọ ayárabíàṣá lọ́nà ìgbàlódé. Google, Yoruba Names, Masakhane MT àti ALC jẹ́ àpẹẹrẹ àwọn iléeṣẹ́ ńlá àti àwọn iléeṣẹ́ kéréje tí ó ṣẹ̀ṣẹ̀ bẹ̀rẹ̀ tí ó ti mú ìmọ̀-ẹ̀rọ ṣiṣẹ́ pọ̀ pẹ̀lú àwọn èdè tí kì í ṣe èdè Gẹ̀ẹ́sì.
Kí oṣù Èrèlé ọdún 2020 ó tó tẹnu bepo, Google filọ̀ wípé òun yóò fi èdè tuntun márùn-ún kún iṣẹ́ Atúmọ̀ Google rẹ̀, àwọn èdè náà ni Kinyarwanda, Uighur, Tatar, Turkmen àti Odia, lẹ́yìn ìsinmi ọdún mẹ́rin tí wọ́n fi èdè tuntun kún un kẹ́yìn.
Ọkùnrin kan ń wò bí ẹni tí ó nídààmú nígbà tí ó ń ka gbólóhùn ọ̀rọ̀ lórí ayélujára. Àwòránlláti ọwọ́ Ọládiméjì Ajégbilẹ̀, àṣẹ-àtúnlò láti orí Pexels.
Àmọ́ ṣe o ti ṣíra tẹ àṣàyàn ìtumọ̀ rí tí ó ṣàkíyèsí wípé, bákan, ló dára jù lọ?
Bákan náà, ló kù díẹ̀ káàtó, kò ṣe déédéé?
Orísìírísìí àríyànjiyàn àti ìṣòro ló máa ń wáyé bí ó bá kan irú ìtumọ̀ èdè báyìí àti rírí i lò.
Twitter máa ń ṣe ìtumọ̀ èdè Yorùbá sí èdè Gẹ̀ẹ́sì nípasẹ̀ lílo Atúmọ̀ Google bí ó ti ṣe fàyè gbà wọ́n, tí àbájáde rẹ̀ sì kù díẹ̀ káàtó nígbàgbogbo — tí àwọn ọ̀rọ̀ kọ̀ọ̀kan sì ṣe déédéé.
Ohun tí ó fa àwọn ìpeníjà wọ̀nyí ó ju pé orí ayélujára ni àwọn iléeṣẹ́ onímọ̀ ẹ̀rọ ti máa ń ṣe àkójọ èdè wọn for tí wọ́n ń fi ṣe ògbufọ̀ gbólóhùn ọ̀rọ̀.
Àwọn àkójọ gbólóhùn ọ̀rọ̀ wọ̀nyí lè ṣiṣẹ́ fún àwọn èdè kan, àmọ́ èdè bí i Yorùbá àti Ìgbò, jẹ́ èdè méjì ní orílẹ̀-èdè Nàìjíríà, tí ìpèníjà yìí bá, látàrí àìpọ̀tó gbólóhùn ọ̀rọ̀ àti gbólóhùn tí a ò yán lórílábẹ́ dáadáa tí yóò tọ́ka sí ìró ohùn.
Láti fèsì sí ohun tí ó fa sábàbí tí ó fi gba Google ní ọdún mẹ́rin kí ó tó ṣe àfikún èdè tuntun márùn-ún kún tilẹ̀, agbẹnusọ iléeṣẹ́ náà ṣe ìṣípayá:
Orí ìtakùn àgbáyé ni Atúmọ̀ Google ti máa ń ṣa gbólóhùn tí a ti túmọ̀ jọ, àmọ́ bí èdè kò bá ní gbólóhùn ọ̀rọ̀ tí ó pọ̀ tó lórí ayélujára, ó nira fún ẹ̀rọ wa láti ṣe àtìlẹ́yìn tí ó lákaakì fún irú àwọn èdè bẹ́ẹ̀
Síbẹ̀, látàrí ìlọsíwájú àbùdá kíkọ́ ẹ̀rọ lẹ́kọ̀ọ́ wa, àti àwọn aṣiṣẹ́ Ìtumọ̀ Google lọ́fẹ̀ẹ́, ecent advances in our machine a ti fi àtìlẹ́yìn fún àwọn èdè wọ̀nyí.
Bákan náà, ọ̀pọ̀ ènìyàn ni kò mọ bí a ṣe ń kọ ọ̀rọ̀ dájúdánu — tàbí pípe ọmọ-ọ̀rọ̀ — inú àwọn èdè wọ̀nyí.
Torí náà, ògbufọ̀ tí ó kúnjú òṣùwọ̀n kò jẹ́ àkópọ̀ nítorí kò sí bí a ṣe lè dá àwọn àṣìṣe wọ̀nyí mọ̀.
Púpọ̀ nínú ògbufọ̀ tí ẹ̀rọ ṣe ni kò ní ìtumọ̀, pàápàá jù lọ àwọn gbólóhùn tí ó rọ̀ mọ́ àṣà tí ó ní ju ìtúmọ̀ kan ṣoṣo lọ.
Fún àpẹẹrẹ, gbólóhùn Yorùbá bí i ayaba àti ọbabìnrin ní ìtumọ̀ tó yàtọ̀.
"Ọ̀pọ̀lọpọ̀ ẹ̀rọ ní í máa tú ìmọ̀ gbólóhùn méjèèjì sí ""queen""."
"Síbẹ̀, tí a bá ti ọ̀nà ìṣe-àti-àsà wò ó, ó ṣe kókó láti sọ wí pé ìtúmọ̀ ayaba and ọbabìnrin yàtọ̀ síra wọn: Ọbabìnrin túmọ̀ sí ""queen"" lédè Gẹ̀ẹ́sì nígbà tí ayaba jẹ́ ""wife of the king""."
Pẹ̀lú àwọn àìṣedéédéé wọ̀nyí, ìmọ̀-ẹ̀rọ ti ṣe ìrànwọ́ fún ìdàgbàsókè àwọn èdè Ilẹ̀-Adúláwọ̀ lórí àwọn gbàgede orí ayélujára, tí ó ti mú ìṣẹ̀dá ọ̀rọ̀ tuntun wáyé.
Èdè Ilẹ̀-Adúláwọ̀ ti gòkè àgbà látàrí àwọn lílo àwọn ẹ̀rọ ìgbàlódé tuntun bí i ẹ̀rọ-ìléwọ́ àti ẹ̀rọ ọpọ́n ayárabíàṣá, tí ó sì ń bí àwọn gbólóhùn tuntun tí a fi ń pe àwọn irinṣẹ́ ìmọ̀-ẹ̀rọ tuntun wọ̀nyí.
Èyí sì ti fẹ bí a ti ṣe ń lo àwọn èdè wọ̀nyí lójú.
Látàrí àwọn ẹ̀rọ tuntun wọ̀nyí, ìpèdè ọ̀pọ̀lọpọ̀ èdè Ilẹ̀-Adúláwọ̀ ti lé kún sí i.
"Fún àpẹẹrẹ, èdè Yorùbá ní àwọn gbólóhùn tí ó ní ṣe pẹ̀lú ìmọ̀-ẹ̀rọ bí i ẹ̀rọ-amúlétutù (""air conditioner""), erọ-ìbánisọ̀rọ̀ (""phone"") and ẹ̀rọ-ìlọta (""grinder"")."
"Ẹ̀wẹ̀wẹ̀, èdè Igbo náà ní ọ̀rọ̀ bí i ekwè nti (""telephone"") àti ugbọ̀ àlà (""vehicle"")."
A ṣẹ̀dá àwọn orúkọ yìí ní ìbámu pẹ̀lú iṣẹ́ tí wọ́n ń ṣe.
Nínú ẹ̀kọ́ ìmọ̀ ìgbóhùnsáfẹ́fẹ́ àti ètò ìpolówó ọjà lédè Yorùbá, àwọn akẹ́kọ̀ọ́ ti kọ́ wí pé ẹ̀rọ-amóhùnmáwòrán ni oọ̀pọ̀lọpọ̀ ènìyàn ń pe TV.
Ìṣẹ̀dá ọ̀rọ̀ yìí fa àwọn onírúurú ìbéèrè àti èrò — àwọn akẹ́kọ̀ọ́ kan jiyàn wí pé a lè pe ẹ̀rọ-ayàwòrán náà ní ẹ̀rọ-amóhùnmáwòrán nítorí iṣẹ́ tí wọ́n ń ṣe.
Àwọn ìpèníjà t'ó tara ìmọ̀-ẹ̀rọ wá yìí ni yóò mú ìdàgbàsókè bá èdè — ó máa ń fa àròjìnlẹ̀ fún ìgbéga èdè àti ìmọ̀-ẹ̀rọ.
"Lọ́dún 2019, gẹ́gẹ́ bí CNN ti ṣe ròyìn, Google ṣí ibiṣẹ́ ìwádìí AI àkọ́kọ́ irú ẹ̀ sí Accra, Ghana, tí ó ń lépa láti mú kí ""Atúmọ̀ Google ó gba àwọn èdè Ilẹ̀-Adúláwọ̀ jọ kí ó lọ geere""."
"Onímọ̀ ìjìnlẹ̀ nípa iṣẹ́ ìwádìí Moustapha Cisse, tó jẹ́ olórí iṣẹ́ Google AI ní Ilẹ̀-Adúláwọ̀, nígbàgbọ́ wí pé ó tọ́ sí ""ilẹ̀ tí ó ní ju ẹ̀ka-èdè 2,000 lọ láti jẹ́ àǹfààní iṣẹ́,"" — CNN jábọ̀."
Mozilla àti BMZ kéde àjùmọ̀ṣe wọn láti ṣe agbátẹrù iṣẹ́ àkànṣe tí ó dá fìrìgbagbòó lórí ìmọ̀-ẹ̀rọ alohùn fún thei èdè Ilẹ̀-Adúláwọ̀. Pẹ̀lú àwọn iṣẹ́ àtinudá bí eléyìí, ọjọ́ iwájú ìwádìí èdè Ilẹ̀-Adúláwọ̀ dára.
Àwọn Iléèjọsìn ní Greece àti Àríwá Macedonia kọ̀ láti yí ọwọ́ àwọn ìlànà-ìsìn wọn padà k'ó ba má fàyè gba àjàkálẹ̀ àrùn COVID-19 t'ó ń ràn ká
Àjọ Oúnjẹ Alẹ́ Olúwa, àwòrán tí a kùn lódà ní 1442 láti ọwọ́ Fra Angelico. Àwòrán tí kò ní olóhun láti orí Wikipedia.
Bí àwọn tí ó ti kó àrùn COVID-19 ṣe ń pọ̀ọ́ sí i ní Balkans, àwọn ilé ìjọsìn kan kò yí ọwọ́ àwọn ìlànà ìsìn tí ó lè mú kí àrùn Coronavirus ó ràn bí i pápá inú ọyẹ́ padà.
Ìlànà ìsìn tí a mọ̀ sí Jíjẹara àti mímu ẹ̀jẹ̀ Olúwa tàbí Oúnjẹ Ìkẹyìn ní èyí tí àwọn ọmọ lẹ́yìn Krístì tí ó ń tẹ̀lé ìlànà ìsìn àtijọ́ yóò máa pín wáìnì tí a ti sọ di mímọ́ mu pẹ̀lú ṣíbí kan náà, àwọn Ìjọ Àgùdàá máa ń jẹ ẹ̀bẹ àkàrà fẹ́lẹ́fẹ́lẹ́ tí wọ́n fi ẹnu gbà lọ́wọ́ àlùfáà.
Àjọ Ìlera Àgbáyé (WHO) rọ̀ wá láti jìnà gbégbérégbé sí ibi tí àwọn èròó bá pitì sí, kí a sì káràmásíkì sí ìlera ara wa kí á ba dín àrànká àrùn ẹ̀jẹ̀ tí ènìyàn lè kó nípasẹ̀ ìfọwọ́kàn, ìfarakan omi tó sun lára ẹlòmíràn, àti láti inú afẹ́fẹ́.
Nínú àtẹ̀jáde ọjọ́ 9, Iléèjọsìn Àtijọ́ Greek sọ wí pé òun kò ní yí ọwọ́ ìlànà-ìsìn padà kí ó bá ìgbésẹ̀ ààbò mu.
"Bákan náà ni ó sọ wí pé ""a kò leè kó ààrùn coronavirus láti ara Jíjẹ ara-àti-mímu-ẹ̀jẹ̀ Olúwa, àti pé kí àwọn ọmọ Ọlọ́run ó gbàdúrà gidi nítorí ààrùn apànìyàn náà""."
Bíṣọ́ọ̀pù ti GOC Klimis, ti Àárín gbùngbùn Peristeri, lábẹ́ agbègbè tó sún mọ́ Athens, sọ wí pé ọ̀rọ̀-òdì sí Olúwa ni bí ẹnikẹ́ni bá sọ pé ìlànà ẹ̀sìn lè mú kí ààrùn ó ràn:
Ìyè ni Ara-jíjẹ àti ẹ̀jẹ̀ mímu.
Iṣẹ́ ìyanu ni.
Ọ̀rọ̀-òdì sí Olúwa ni láti ní ìgbàgbọ́ wí pé ènìyàn lè tara Jíjẹ ara-àti-mímu-ẹ̀jẹ̀ Olúwa kó ààrùn.
Ènìyàn 89 ló ti lùgbàdì COVID-19 ní Greece, láìsí ẹni tó kù.
Àwọn aláṣẹ Greek, tí ó ti ṣán àwọn iléèwé pa, tí ó sì ti f'òfin de àpéjọ lójú ọ̀nà àti dènà àjàkálẹ̀, rọ Iléèjọsìn náà láti ṣe àtúnwò.
Àmọ́ àwọn aṣojú ìjọba tìkarawọn ń tàpá sí òfin ìdènà ààrùn yìí. Lọ́jọ́ ìsinmi ajẹmẹ́sìn kan lọ́jọ́ Ọ̀sẹ̀ tó kọjá, ààrẹ àti àwọn onípò nínú ìṣèjọba rẹ̀ lọ sí ìsìn kan.
Ní ìlú tó múlé gbe Greece, ó jọ pé North Macedonia, Iléèjọsìn Àtijọ́ ti Macedonia – Ohrid Archbishopric náà ń tọ ipasẹ̀ kan náà.
Bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé Iléèjọsìn náà kò tíì ṣe ìfilọ̀ kankan nípa àjàkálẹ̀ náà, ó sì ń fún àwọn ọmọ ìjọ ní Ara jẹ àti ẹ̀jẹ̀ mu bí ó ti máa ń ṣe.
"Ìròyìn kàn nígbà tí ojúlé ibùdó ìtakùn Prespa-Pelagonia Diocese ṣe àtẹ̀jáde ògbufọ̀ article àrọko ibùdó ìtakùn tó jẹ́ ti Russia ìyẹn Pravoslavie.ru (ìtumọ̀ ""Ẹ̀sìn Ìgbàgbọ́ Àtijọ́ "") tó ń sọ wí pé ""kò lè ṣe é ṣe kí àwọn onígbàgbọ́ ó k'árùn láti ara ìlànà-ìsìn ìjọ""."
Àlùfáà Sergey Adonin ti Russia ló buwọ́ lu àpilẹ̀kọ náà, ẹni tó sọ pé òun ní ìmọ̀ nípa ìṣẹ̀dá ẹ̀dá oníyè àìfojúrí pẹ̀lú ìrírí iṣẹ́ ní iléèwòsàn.
"Ó sọ síwájú sí i nínú àpilẹ̀kọ náà wí pé lílo ṣíbí kan náà bí wọn ti ṣe fi lọ́lẹ̀ ní ọgọ́rùn-ún ọdún kéje ayé Bizantium ò fa ìpalára, nítorí ""ìgbàgbọ́ nínú Ọlọ́run ń fi ìṣọ́ ààbò bo àlùfáà àti ọmọ ìjọ""."
Ní North Macedonia, àwọn tí ó ń mú ṣe ti ìlànà-ìsìn náà ní kò sí aburú nínú ìlànà iléèjọsìn náà.
Fún àpẹẹrẹ, atọ́kùn ètò lórí ẹ̀rọ amóhùnmáwòrán tó jẹ́ adàṣà-àtijọ́-mú-ṣinṣin — ajìjàǹgbara ẹni tó ti fi ìgbà kan rí ṣe ìpolongo ìtako ìbupá — fúnnu lórí Twitter wí pé òun ti kópa nínú àwọn ìlànà-ìsìn ajẹmẹ́sìn tó léwu:
Túwíìtì: Mo jẹ Ara Olúwa mu ẹ̀jẹ̀ Olúwa lọ́jọ́ Àìkú tó kọjá nínú Iléèjọsìn Holy Annunciation tí ó wà nínú Iléèwòsàn ti Skopje tí n ó sì tún ṣe é!
Kí ni ìṣòro rẹ̀?
Àkọlé adarí: Pẹ̀lú gbogbo ẹ̀bẹ̀ àjọ tó ń rí sí ètò ìlera: Àwọn onígbàgbọ́ jẹ Ara mu ẹ̀jẹ̀ Olúwa láì fòyà fún ààrùn coronavirus.
"Sladjana Velkov, ẹni tó gbajúmọ̀ gẹ́gẹ́ bí alátakò-ìbupá tó ń ṣiṣẹ́ ní Serbia àti Àríwá Macedonia, sọ láì pẹ́ yìí wí pé nǹkan kò ""le tóyẹn"" àti pé ""ọ̀fìnkìn lásán ni, èyí tí kò yàtọ̀ sí ọ̀fìnkìn tí a ti mọ̀ tẹ́lẹ̀, tó máa ń ṣe àwọn àgbàlagbà tàbí àwọn tí ìlera ara wọn kò pé tó""."
Ní orílẹ̀-èdè Italy, níbi tí 631 ẹ̀mí èèyàn 631 ti bọ́ tí àwọn tí ó tó 10,000 ti lùgbàdì àrùn náà, aṣàmúlò kan túwíìtì:
Bí á bá kà á ní méníméjì, ó ti tó ẹni méje tí ó ti kó àrùn COVID-19 ní North Macedonia; 25 ní Slovenia; 13 ní Croatia; mẹ́fà ní Albania; fi márùn-ún ní Serbia; márùn-ún ní Bosnia; òdo ní Montenegro.
Ó ti tó ẹni 28 tó ti kó o ní Romania, mẹ́fà ní Bulgaria.
Onígbàgbọ́ níbi gbogbo
Ilé ayé ti rí bí coronavirus àkọ́kọ́ irú ẹ̀ ṣe lè ràn níbi ìpéjọ ajẹmẹ́sìn.
Lóṣù tó kọjá, ọ̀pọ̀ ènìyàn tí ó tó 7,400 ni a gbọ́ wí pé ó ti ní àrùn apànìyàn COVID-19 ní South Korea — orílẹ̀-èdè tí ó jọ pé ó ti ń gbá àrùn náà mọ́lẹ̀ — rí àrùn náà lára Iléèjọsìn ẹgbẹ́ Shincheonji ti Jésù.
A fi ẹ̀sùn ọ̀daràn kan ẹgbẹ́ náà — tí wọ́n máa ń pè ní igbẹ́-ìmùlẹ̀ — olórí ẹgbẹ́ náà tí í ṣe ẹni 8-ọdún wá síta láti ṣe ìtọrọ àforíjì.
Ní tirẹ̀, Àjọ Ìlànà-ìsìn Àtijọ́ ti Korea ṣe ìfilọ̀ nípa àwọn àyípadà tó dé bá ìsìn rẹ̀ ní ìbámu pẹ̀lú àfilélẹ̀ Iléeṣẹ́ Ètò Ìlera:
1. Gbogbo onígbàgbọ́ yóò wọ ìbomúbẹnu lásìkò tí ìsìn bá ń lọ lọ́wọ́.
2. Kí wọ́n ó wọ Iléèjọsìn, wọ́n yóò fi apakòkòrò tó wà lẹ́nu àbáwọlé Iléèjọsìn ra ọwọ́ wọn.
3. Wọn kò ní gba ẹnìkan lọ́wọ́.
4. Wọn kò ní f'ẹnu ko Àlùfáà ìjọ lọ́wọ́.
5. Wọn kò ní fẹnu ko àwọn Ère, àmọ́ wọn ó tẹríba níwájú wọn.
6. Wọn kò ní lo àwọn ìwé àdúrà nígbà ìsìn.
7. Wọn kò ní gba Àkàrà lọ́wọ́ Àlùfáà ìjọ, àmọ́ fúnra wọn bí wọ́n bá ń jáde kúrò nínú iléèjọsìn.
8. Oúnjẹ Àpèjẹ Ifẹ̀ kò ní jẹ́ pínpín lọ́jọ́ Àìkú.
9. Àwọn ìpàdé ẹlẹ́gbẹ́jẹgbẹ́ àti ti àwọn tó ń kọ́ ìsìn Ọlọ́run kò ní wáyé.
Àwọn ilé ìjọsìn kan ní Ilẹ̀ Gẹ̀ẹ́sì ti ń ṣe àyípadà sí ìlànà ìsìn wọn, bí i ìjọ Àgùdà ti Italy.
Àjọ ẹ̀sìn ìgbàgbọ́ Croatia náà en ti ṣ'òfin tó dá lé àrùn náà, ní France, ibi ìrìnàjò mímọ kan ní ìlú Lourdes ti di títì pa.
"Iléèjọsìn Ìlànà-ìsìn Àtijọ́ ti Romania fi òfin kan síta ""tó jẹ́ àwọn ìgbésẹ̀ tí ènìyàn yóò tẹ̀lé bí àjàkálẹ̀ bá dúkokò"":"
Àwọn onígbàgbọ́ tíbẹ̀rùbojo àrùn apànìyàn náà ti sojo s'ọ́kan wọn yóò pa ìfènuko àwọn ère inú ilé ìjọsìn lára.
Bí ó bá wù wọ́n, wọ́n leè sọ fún àlùfáà wí pé ṣíbí ti wọn ni àwọn fẹ́ lò fi gba Ẹ̀jẹ̀ Olúwa mu.
Lẹ́yìn tí Italy pàṣẹ pé kí gbogbo orígun mẹ́rẹ̀ẹ̀rin ìlú ó di sísé pa, àwọn alámùúlégbè, bí i Ilẹ̀ Olómìnira Czech náà gbé àwọn àgbékalẹ̀ kan lọ́jọ́ 10, oṣù Ẹrẹ́nà tí wọ́n ṣán àwọniiléèwé pa.
Ìjọba North Macedonia kéde ipò ìlú ò f'ara rọ, ó sì ti àwọn jẹ́léósinmi, iléèwé, títí kan iléèwé gíga jù lọ Ifásitìi pa fún ọ̀sẹ̀ méjì.
Check Yẹ àwọn iṣẹ́ àkànṣe Ohùn Àgbáyé lórí arapa COVID-19 lágbàáyé.
Orílẹ̀-Èdè Nàìjíríà fi òfin de ìrìn-àjò lójúnà ìṣàmójútó àwọn tó ti kó kòkòrò àìfojúrí COVID 19
Ìfòfindèrìnàjò àwọn orílẹ̀-èdè 13 tí ènìyàn tó ti kó COVID-19 ju 1,000 lọ
Àwòrán láti ọwọ́ Pete Linforth ní Pixabay. Ìlò àwòrán pẹ̀lú àṣẹ Pixabay, fún ìlò gbogboògbò.
Yẹ àkọsílẹ̀ àkànṣe Global Voices wò lórí ipa COVID-19 lágbàáyé.
Gẹ́gẹ́ bí àjò tí ó ń kápá ìtànkálẹ̀ àrùn ní Nàìjíríà ṣe sọ, àwọn èèyàn márùn-ún mìíràn ni wọ́n ti fìdí rẹ̀ múlẹ̀ pé wọ́n ti kó kòkòro àrùn COVID-19, àròpọ̀ iye àwọn tí wọ́n ní àrùn náà ní Nàìjíríà wá jẹ́ mẹ́jọ.
"Iye àwọn ẹni tí ó ní kòkòrò àrùn náà di mẹ́jọ ní ọjọ́ méjì lẹ́yìn tí dókítà E. Osagie Ehanire fìdí i rẹ múlẹ̀ ní ọjọ́ 16, oṣù Ẹrẹ́na pé wọ́n ti rí ẹni kẹ́ta tí ó kó kòkòrò àìfojúrí COVID-19, ìyen ""ọmọ orílẹ̀-èdè Nàìjíríà kan tí ó lé ní ẹni ọgbọ̀n tí ó ṣẹ̀ṣẹ̀ dé láti United Kingdom ní ọjọ́ 13, oṣù Ẹrẹ́na""."
Aláìsàn náà ya ara rẹ̀ sọ́tọ̀ fún ọjọ́ 14 ní ìlú Èkó, láàárín àsìkò yìí ni ó bẹ̀rẹ̀ sí i ní àmì àìsàn ibà àti ikọ̀.
Aláìsàn náà wà ní ilé ìwòsàn tí wọ́n ti ń ṣètọ́jú Kòkòro àkóràn ní Yaba, ní Ìpínlẹ̀ Èkó.
Ara rẹ̀ ti ń balẹ̀, ó sì ń dáhùn sí ìtọ́jú dáadáa.
Bí í iye àwọn ènìyàn tí ó kó kòkòrò àrùn COVID-19 ṣe ń pọ̀ sí i ni Nàìjíríà, ìjọba àpapọ̀ ti gbọ́ ohun tí àwọn aráàlú sọ ní ọjọ́ 18, oṣù Ẹrẹ́na nípa fífi òfin de àwọn tí ó ń rin ìrìn àjò láti orílẹ̀ èdè 13 bí i: China, Italy, Iran, South Korea, Spain, Japan, France, Germany, Norway, United States, United Kingdom, Netherlands àti Switzerland tí ó ní ju ènìyàn 1000 lọ tí ó ti kó kòkòrò àrùn Kòrónà láti má wọ orílẹ̀-èdè Nàìjíríà.
Àwọn tí wọ́n ti wọ Nàìjíríà tẹ́lẹ̀ láti àwọn orílẹ̀ èdè tí a dárúkọ yìí gbọ́dọ̀ ya ara wọn sọ́tọ̀ fún ọjọ́ 14.
Ọjọ́ 27 ni oṣù Èrèlé ní a fìdí rẹ̀ múlẹ̀ pé ọmọ orílẹ̀ èdè Italy kan tí ó rìn ìrìnàjò wá sí orílẹ̀ èdè Nàìjíríà jẹ́ ẹni àkọ́kọ́ tí ó ní kòkòrò àrùn COVID-19.
Kà sí i: Ọmọ orílẹ̀ èdè Italy kan tí ó rìn ìrìnàjò wá sí orílẹ̀ èdè Nàìjíríà ni ó kọ́kọ́ ní kòkòrò àrùn COVID-19
Ẹni kejì tí a fìdí rẹ̀ múlẹ̀ pé ó ní kòkòrò àrùn yìí, gẹ́gẹ́ bí NCDC ṣe sọ jẹ́ ẹni tí ó rìnnà pàdé ẹni àkọ́kọ́ tí ó kó àrùn náà, tí ara rẹ̀ sì ti yá báyìí lẹ́yìn tí àyẹ̀wò méjì ti fi hàn pé àyẹ̀wò náà kò sí lára rẹ̀ mọ́.
Ẹnìkejì yìí ò ní àrùn náà mọ́, wọ́n sì ti fi í sílẹ̀ kí ó máa lọ sílé ní ọjọ́ 13 oṣù Ẹrẹ́na, ọdún 2020, gẹ́gẹ́ bíi àjọ NCDC ṣe sọ.
Bí wọ́n ṣe ń bójú tó àrùn COVID-19 kò tẹ́ ọ̀pọ̀ aráàlú lórí ayélujára lọ́rùn, wón sì ti ń béèrè fún àwọn ìgbésẹ̀ tí ó lágbára láti dẹ́kun ìtànkálẹ̀ àrùn náà ní orílẹ̀ èdè Nàìjíríà.
"Ọmọ ìlú lórí ayélujára, Ayobami kéde pé ìgbésẹ̀ NCDC falẹ̀. Ó gbà wọ́n nímọ̀ràn pé ""kí wọ́n dẹ́kun ṣíṣe àṣehàn lórí ayélujára kí wọ́n sì bẹ̀rẹ̀ iṣẹ́!"""
"Gideon sọ pé ""ó yẹ kí ó bà wá lẹ́rù"" pé ṣíṣe àyẹ̀wò fún kòkòrò àrùn COVID-19 ń falẹ̀ ní Nàìjíríà."
Ẹ fi òfin de àwọn arìnrìn-àjò tí ó fẹ́ wọlé láti àwọn orílẹ̀ èdè mìíràn pàápàá jù lọ àwọn tí ó wá láti àwọn orílẹ̀ èdè tí àrùn náà ti gbilẹ̀, akọ̀ròyìn Bayo Olupohunda náà tẹnumọ:
Dr. Whitewalker náà tẹnpẹlẹ mọ́ ọn pé kò sí ohun tí ó burú nínú fífi òfin de àwọn arìnrìn-àjò ní àkókò tí wọ́n ṣiṣẹ́ ìṣàdínkù ìtànkálẹ́ àrùn láti lè dẹ́kun àkóràn ní àsìkò ìtànkálẹ́ àrùn bí i irú èyí.
"Dr. Chikwe Ihekweazu, olórí àjọ NCDC, bẹ̀bẹ̀ pé àwọn ń ""gbìyànjú GIDI láti rí i pé àwọn ṣe gbogbo ohun tí ó yẹ kí àwọn ṣe"":"
Ní ọjọ́ 17 oṣù Ẹrẹ́na, ilé ìgbìmọ̀ aṣòfin àgbà ti kọ́kọ́ sọ pé kí wọ́n fi òfin de àwọn ọkọ̀ òfurufú tí ó ń bọ̀ láti àwọn orílẹ̀ èdè tí àrùn náà ti gbilẹ̀ bí i United Kingdom àti China, kí wọ́n tó dúró di ọjọ́ kejì kí wọ́n tó fi òfin náà múlẹ̀.
Cable Nigeria jábọ̀ gbogbo àwọn tí wọ́n wá láti àwọn orílẹ̀-èdè tí àrùn náà ti gbilẹ̀ ni wọ́n máa yà sọ́tọ̀ pẹ̀lú àbójútó fún ọjọ́ mẹ́rìnlá.
Ìjọba àpapọ̀ sì fi òfin de fífún àwọn ènìyàn ní visa Nàìjíríà.
Ìfòfindèrìnàjò náà bẹ̀rẹ̀ ní àbámẹ́ta ọjọ́ 21, oṣù Ẹrẹ́nà, ọdún 2020, yóò sì wà fún ọ̀sẹ̣̀ mẹ́rin tí ó ṣe é ṣe kí wọ́n sún un síwájú lẹ́yìn àpérò.
Kà sí i: COVID-19 ní ilẹ̀ Adúláwọ̀: ‘Ìgbáradì tí a kò rí irú rẹ̀ rí’ bí àwọn orílẹ̀-èdè ṣe ń múra sílẹ̀ fún ìtànkálẹ̀ àrùn
Ọ̀pọ̀ àwọn orílẹ̀-èdè ní ilẹ̀ Adúláwọ̀ ti ń gbé ìgbésẹ̀ láti ṣe àdínkù ìtànkálẹ̀ kòkòrò àrùn COVID-19.
Lára àwọn ìgbésẹ̀ yìí ni fífi òfin de ìrìn-àjò láti àwọn orílẹ̀ èdè tí kòkòrò àrùn COVID-19 náà ti gbilẹ̀ láti má ṣe wọ orílẹ̀ èdè wọn.
Ìṣàmójútó tí kò péye tó
Àwọn ìjábọ̀ kan wà nípa bí ìṣàmójútó àwọn òṣìṣẹ́ elétò ìlera kò ṣe péye tó lórí àwọn tó ní kòkòrò àrùn COVID-19 ni orílẹ̀-èdè Nàìjíríà.
Obìnrin kan tí ó jẹ́ ẹni ọdún 70 tí ó ti lo oṣù márùn-ún ní United Kingdom padà sí Nàìjíríà ní ọjọ́ 11 oṣù Ẹrẹ́na.
Lẹ́yìn ìgbà díẹ̀ tí ó dé, ó bẹ̀rẹ̀ sí ní àmì àìsàn kòkòrò àrùn COVID-19 bí i òtútù àti ikun tí ó pọ̀ lápọ̀jù ní ọjọ́ 13, oṣù Ẹrẹ́na, wọ́n sì sáré gbé lọ sí Teaching Hospital ti ìpínlẹ̀ Enugu (ESUTH) Colliery Parklane, ní gúúsù ìlà-oòrùn Nàìjíríà.
Wọ́n yà á sọ́tọ̀ ní ESUTH Colliery Parklane, wọ́n sì fi àyẹ̀wọ̀ tí wọ́n ṣe fun un ṣọwọ́ sí àjọ NCDC ní ọjọ́ 14, oṣù Ẹrẹ́na fún àyẹ̀wò.
Ní ọjọ́ 15, oṣù Ẹrẹ́na, obìnrin náà kú lẹ́yìn tí àjọ NCDC jábọ̀ pé kò ní kòkòrò àrùn COVID-19.
"Bẹ́ẹ̀, nínú lẹ́tà tí wọ́n kọ sí gómìnà ìpínlẹ̀ Enugu, ọmọ obìnrin náà fẹ̀sùn kan àwọn òṣìṣẹ́ ilé ìwòsàn náà pé ""tàbùkù"" ìyá òun, wọ́n gbé e sínú ""ilé àkọ́kù"" tí ó kún fún koríko."
Ọ̀rọ̀ ẹnìkan tí ó ní kòkòrò àrùn COVID-19 tí wọn kò ṣe àbójútó tó péye fún wáyé ní ìpínlẹ̀ Èkó tí ó jẹ́ olú-ìlú ìdókòòwò ní orílẹ̀-èdè Nàìjíríà.
Ní ọjọ́ 17, oṣù Ẹrẹ́na, David Hundeyin tí ó jẹ́ akọ̀ròyìn pẹ̀lú News Wire, jábọ̀ nípa ìṣàmójútó tí kò gúnrégé tó lórí ọ̀rọ̀ ẹni tí wọ́n furasí pé ó ní kòkòrò àrùn COVID-19 ní ilé iṣẹ́ Dangote ní Ibeju-Lekki, ní Ìpínlẹ̀ Èkó, tí ó sì ti ń fa ìpayà láàárín àwọn òṣìṣẹ́ ibẹ̀.
Ní ọjọ́ kejìlá oṣù Ẹrẹ́nà, òṣìṣẹ́ iléeṣẹ́ Dangote kan tí ó jẹ́ ọmọ ilẹ̀ India tí ó ń tún ọ̀pá omi ṣe wá sí orílẹ̀-èdè Nàìjíríà láti Mumbai, lẹ́yìn tí ó dúró díẹ̀ ní Cairo, ní orílẹ̀-èdè Egypt.
"Ìwádìí Hudeyin fi hàn pé ọkùnrin náà tí ó ń tún ọ̀pá omi ṣe bẹ̀rẹ̀ sí i ní ""ibà, ikọ́ gbígbẹ, ọ̀fun dídùn àti àìlè mí délẹ̀ "", ní ọjọ́ kejì tí ó dé láti India."
"Síbẹ̀, ""kò tí ì hàn bóyá ẹnikẹ́ni ní iléeṣẹ́ Dangote ti gbìyànjú láti kàn sí"" àwọn elétò ìlera tí ọ̀rọ̀ náà kàn."
"Hudeyin sọ̀rọ̀ síwájú pé ilé iṣẹ́ náà ń lo àǹfààní ""àyíká òfin tí kò múnádóko tó"" ní Nàìjíríà ""láti fi èrè tirẹ̀ síwájú"", èyí sì ń fi ẹ̀mí àwọn òṣìṣẹ́ rẹ̀ àti gbogbo àwùjọ sínú ewu."
Ìròyìn yìí mú kí iléeṣẹ́ náà gbé èrò wọn jáde pé àwọn ti gbé aláìsàn náà lọ sí ilé ìwòsàn tí wọ́n ti ń ṣètọ́jú kòkòrò Àkóràn ní Yaba, ní ìpínlẹ̀ Èkó.
Ọ̀nà wo ni àrùn COVID-19 ń gbà ṣe àtúnṣe sí ètò ìṣèlú àti ẹ̀yìn-ọ̀la Orílẹ̀-èdè China lágbàáyé?
"Àwòrán tó ń fi ààlà-ilẹ̀ orílẹ̀-èdè China hàn lórí ọmọ ọ̀rọ̀ mẹ́rin tí kíkà rẹ̀ jẹ́ 武汉肺炎 tí ó túmọ̀ sí ""àrùn ẹ̀dọ̀fóró Wuhan"" (tí ó ṣì jẹ́ lílo ní èdè Chinese), gẹ́gẹ́ bí a ti ṣe mọ àjàkálẹ̀ náà ní ìbẹ̀rẹ̀ pẹ̀pẹ̀, kí ó tó yí orúkọ padà sí COVID-19."
A gba àṣẹ láti lo àwòrán.
Ohun tí ó bẹ̀rẹ̀ nínú ọjà oúnjẹ inú odò, gẹ́gẹ́ bí i ọ̀ràn àìlera ìbílẹ̀, ti wá di nǹkan tó rànká Orílẹ̀-èdè China.
Lẹ́yìn ìfẹsẹ̀múlẹ̀ ìjẹyọ kòkòrò àìfojúrí kòrónà ní Wuhan nínú Oṣù Kejìlá Ọdún 2019, ọ̀pọ̀lọpọ̀ ìṣẹ̀lẹ̀ ló ṣẹ̀ ní ṣísẹ̀-n-tẹ̀lé ló ṣú yọ tó sì fi àwùjọ ilẹ̀ Chinese làkàlàkà tí ó sì tún dojú ìpèníjà kọ ìdúróṣinṣin ètò ìṣèlú Beijing.
Kíkúndùn ìṣàkóso ìròyìn ti fún ìjọba lọ́rùn, àti ìjọba ìbílẹ̀ àti ìjọba àpapọ̀ ní àárín gbùngbùn, ló máa ń fa ìdádúró fún àgbéjáde ìròyìn tí yóò ṣe ará ìlú láǹfààní fún ọ̀sẹ̀ pípẹ́.
Nígbà tí wọ́n wá sọ jí láti ṣe ìkéde lórí àwọn ọ̀nà tí yóò dẹ́kun ìtànká àjàkálẹ̀ náà, ó ti bọ́ sórí, nítorí ayẹyẹ ọdún tuntun ìran Chinese ọlọ́dọọdún ti gbérasọ.
Àwọn Dókítà àti àwọn onímọ̀ ìjìnlẹ̀ sì ń ṣe ìwádìí àti ìfọ̀rọ̀jomitoro-ọ̀rọ̀ lórí ohun tí ó lè jẹ́ orísun àrùn tí wọ́n mọ̀ nígbà náà lọ́hùn-ún gẹ́gẹ́ bí kòkòrò àìfojúrí kòrónà ti Wuhan, tí ó padà wá ṣe okùnfà COVID-19, kòkòrò àìfojúrí tó ń mú kí ènìyàn má leè mí sókèsódò tí ó sì ń fa àrùn ẹ̀dọ̀fóró.
Ìdámọ̀ràn ohun tí ó lè fa sábàbí àrùn náà kan fi yé wí pé kòkòrò àìfojúrí kòrónà jẹ yọ látàrí ẹran ejò tàbí ẹran àdán tí àwọn ará China máa ń jẹ l'óúnjẹ, tí wọ́n ń tà ní ọjà Huanan wet ní agbègbè Wuhan níbi tí ọ̀pọ̀lọpọ̀ ní èrò wí pé ibẹ̀ ni orísun kòkòrò àìfojúrí yìí.
Ìbéèrè kan tí ó nílò ìdáhùn ni ti ọ̀nà ìtànkálẹ̀ àrùn yìí: bóyá ó leè rànká láti ara èèyàn kan sí ìkejì, àti ìyè èèyàn mélòó ló leè kó àìsàn yìí látara ẹni tí ó bá ti ní i.
Ẹ̀rí láti ìmọ̀ ìlera tó fẹsẹ̀múlẹ̀ ṣe ìṣípayá àrànkán láti ara ènìyàn kan sí ìkejì, tí ó fi jẹ́ wí pé kòkòrò náà yóò ti wà lágọ̀ọ́ ara fún ìgbà díẹ̀ kí ẹni tí ó kó o ó tó máa rí àwọn ààmì rẹ̀ lára, tí èyí ò sì mú mímọ ẹni tí ó bá ti lu gúdẹ àrùn náà rọrùn.
Ní ti bí àrùn náà ti ń ràn, èyí tí àwọn onímọ̀ nípa àjàkálẹ̀ àrùn ń pè ní “òǹkà ìpìlẹ̀ ìbísí“, gbà pé ó wà láàárín 2 sí 3 ní ìparí Oṣù Kìn-ín-ní, ẹni tí ó ní i yóò kó o ran ẹni méjì sí mẹ́ta, ṣùgbọ́n ìfikùnlukùn àti ìwádìí kò dúró, ìyẹn bí àwọn ìwífún-alálàyè tí ó wúlò bá wà ní àrọ́wọ́tó.
Bí òǹkà àwọn tí wọ́n ti ní kòkòrò yìí ṣe ń lọ sókè sí i lójoojúmó, àáríngbùngbùn Orílẹ̀-èdè China tí i ṣe Hubei àti Olú-ìlú rẹ̀ tí í ṣe Wuhan ti ní ìdojúkọ tó gogò lórí ètò ìlera, tí àpapọ̀ àwọn tí wọ́n ń gbé lágbègbè yìí sì jẹ́ ẹgbẹ̀rún-lọ́nà-ẹgbẹ́rùn ní ìlọ́po 60.
Bí iye àwọn tí ó ti kó àrùn yìí ṣe ń pọ̀ káàkiri Orílẹ̀-èdè China, àwọn òṣìṣẹ́ elétò ìlera ti wà digbí, tí wọ́n sì tún kóná mọ́ ètò ìlera tí kò sùwábọ̀ tó fún ìtọ́jú àwọn ọ̀kẹ́ àìmọye arúgbó tó kún ìlú.
Ṣùgbọ́n àrùn kòkòrò àìfojúrí kòrónà Wuhan náà kì í ṣe ìkọlù ètò ìlera lásán, ó jẹ́ àkókò òtítọ́ ètò ìṣèlú tí ó lákaakì.
Ìgbẹ́kẹ̀lé ìjọba tí ó sọ fún àwọn ará ìlú wí pé kò s'éwu l'óko àfi gìrì àparò ní ìbẹ̀rẹ̀ pẹ̀pẹ̀, títí tí ẹ̀pa ò fi bóró mọ́, tí àwọn ará ìlú kò sì ní ìfọkàntán nínú àwọn ìjọba wọn mọ́, àti pé, kì í ṣe ní agbègbè Hubei nìkan ni èyí ti ṣẹlẹ̀.
Àwọn ará ìlú bu ẹnu àtẹ́ lu ìjọba Beijing fún ọwọ́ yẹpẹrẹ tí wọ́n fi mú ọ̀rọ̀ àjàkálẹ̀ àrùn èémí SARS tó ṣú yọ ní ọdún 2002 sí 2003, bí ó ti ṣe fi ìròyìn tó péye lórí rẹ̀ pamọ́ fún Àjọ Elétò Ìlara Lágbàáyé (WHO).
Olórí Orílẹ̀-èdè China àgbà Xi Jinping dákẹ́ rọrọ lórí àjàkálẹ̀ àrùn yìí àyàfi ìgbà tí ó di ọjọ́ 20, Oṣù Kìn-ín-ní Ọdún, tí ó kéde fún ará ìlú lẹ́yìn oṣù kan tí àrùn náà ti ń ṣọṣẹ́, pé ọ̀ràn náà ti kọjá àfẹnusọ.
Agbára lórí ìṣàkóso àtẹ̀jáde ìròyìn fẹsẹ̀ múlẹ̀ rìnrìn ní orílẹ̀-èdè China, àti pé, ìwọ̀yáàjà ètò káràkátà pẹ̀lú Orílẹ̀-èdè Amẹ́ríkà, àti bí ọrọ̀-ajé wọn ṣe ń dẹnukọlẹ̀, bí wọ́n bá ṣe yanjú ìṣòro kòkòrò àìfojúrí kòrónà ti Wuhan náà ni yóò forí lé ní ọdún 2020.
Àwọn Ilé Iṣẹ́ ẹ̀rọ-ìbánisọ̀rọ̀ ní Mozambique àti Cape Verde tẹ́ pẹpẹ ètò ẹ̀dínwó fún ayélujára lórí ẹ̀rọ alágbèéká láti mú kí àwọn ọmọ-ìlú ó dúró sílé
Ojú ọ̀nà Santa Maria, Cape Verde. Àwòrán láti ọwọ́ọ Miccaela, Wikimedia Commons. CC-BY 3.0
Yẹ àkànṣe iṣẹ́ tí Ohùn Àgbáyé’ ti ṣe lórí ipa tí kòkòrò àìfojúrí kòrónà COVID-19 ń kó lágbàáyé
Gẹ́gẹ́ bí àṣẹ kónílégbélé ṣe ń múlẹ̀ ní ilẹ̀ Adúláwọ̀ látàrí àjàkálẹ̀ àrùn COVID-19, àwọn ilé iṣẹ́ ẹ̀rọ-ìbánisọ̀rọ̀ ti Ìpínlẹ̀ ní Orílẹ̀-èdè Mozambique àti Cape Verde ń fún àwọn ará ìlú ní ẹ̀dínwó lórí owó-ìlò-ayélujára ní orí ẹ̀rọ-ìbánisọ̀rọ̀ alágbèéká.
Di àsìkò yìí, Orílẹ̀-èdè Mozambique ti ní àkọsílẹ̀ ènìyàn 10 tí ó ti kó àrùn COVID-19, ṣùgbọ́n tí kò tí ì sí ẹni tí ó ti bá àìsàn náà lọ, àmọ́ ẹni 6 ló ti kó àrùn náà ní Cape Verde tí ẹnìkan sì ti di ẹni ẹbọra ń bá jẹun.
Ní ọ̀sẹ̀ tí ó kọjá, Orílẹ̀-èdè méjèèjì ti pàṣẹ òfin pàjáwìrì ìlú-ò-f'ara-rọ olóṣù kan látàrí àjàkálẹ̀ àìsàn tó gbayé kan, ó sì ṣe é ṣe kí wọ́n ṣe àfikún-un rẹ̀.
Gẹ́gẹ́ bí ilé iṣẹ́ oníròyìn kan ti Orílẹ̀-èdè Portugal Lusa ti ròyìn:
Ìtúmọ̀ Ìtúnwí-ọ̀rọ̀ Ọlọ́rọ̀ gan-an
Lónìí Ilé Iṣẹ́ ẹ̀rọ-ìbánisọ̀rọ̀ ti Cape Verde méjèèjì, CV Móvel àti Unitel T+, ṣe ìfilọ̀ ìpolongo alájúmọ̀ṣe tí yóò mú kí MB ẹgbẹ̀rún 2 ó jẹ́ ti àwọn ará ìlú fún ìwúrí láti leè mú wọn dúró sílé lójúnà ìdíná ìtànká àjàkálẹ̀ àrùn COVID-19 láwùjọ.
Tí àkọ́lée rẹ̀ jẹ́ “Fica em Casa” (“ẹ̀bùn ìdúró sílé” ní èdè Yorùbá), ìpolongo náà ni àwọn ilé iṣẹ́ méjèèjì gbé jáde sórí ẹ̀rọ agbọ́rọ̀káyé tí a kọ báyìí pé àwọ́n ti f'oríkorí láti “ṣiṣẹ́ àjàmọ̀ṣe” tí yóò mú kí àwọn ará orílẹ̀ Cape Verde “ó jókòó sílé”.
Ẹ̀bùn pàtàkì yìí wà fún oníbàárà ilé iṣẹ́ méjèèjì, àti pé ní àfikún sí MB ẹgbẹ̀rún 2 tí wọ́n yóò fún wọn, owó ìpè ọ̀fẹ́ fún ìsẹ́jú 15 yóò wà lófò fún pípe èyíkéyìí òpó ẹ̀rọ ìbánisọ̀rọ̀ orílẹ̀-èdè náà tí ó sì gbọdọ̀ jẹ́ lílò kí ó tó d'ọjọ́ 30, Oṣù Kẹrin.
COVID-19: Ìpolongo àǹfààní ìrànwọ́ MB ẹgbẹ̀rún 2 láti mú kí àwọn ará ìlú Cape Verde ó jókòó kalé kí òfin kónílégbélé ó bá f'ẹsẹ̀rinlẹ̀.
Ọ̀gọ̀rọ̀ ará ìlú Cape Verde ti yọ ṣùtì ẹnu sí ìpolongo yìí, nítorí ségesège ni afẹ́fẹ́ ẹ̀rọ ayélujára náà máa ń ṣe:
Àwàdà ńlá ni!!!
Ẹni mélòó nínú ará ìlú Cape Verde l'ó ní afẹ́fẹ́ ẹ̀rọ ayélujára tó já geere?
Ní Cape Verde, agbègbè erékùṣù tí ó ní èèyàn tó tó ẹgbẹ̀rún 560, tí idà 57 wọn ń lo ẹ̀rọ-ayélujára, ìyẹn gẹ́gẹ́ bí ìwádìí tí Ilé Ìfowópamọ́ Àgbáyé ṣe ní ọdún 2017 ti ṣe fi hàn.
Lọ́dún náà, ìdá 50 ni ìdá àwọn tó ń lo ayélujára tó pọ̀jù lágbàáyé.
"Ní Mozambique, níbi tí àwọn ènìyàn tí ó ń lo ayélujára ò ti tó nǹkan – Ilé Ìfowópamọ́ Àgbáyé kan yìí náà fi hàn nínú ìwádìí pé ìdá 10 àwọn ará ìlú nínú èèyàn ẹgbẹẹgbẹ̀rún ló ní ẹ̀rọ-ayélujára ní àrọ́wọ́tó – ilé iṣẹ́ ẹ̀rọ ìbánisọ̀rọ̀ TmCel tí ó jẹ́ ti ọmọ onílùú náà ti se ìfilọ́lẹ̀ ìpolongo ""kónílégbélé"" yìí kan náà."
Ìpolongo náà kún fún àwọn ọ̀kan-ò-jọ̀kan àǹfààní ẹ̀bùn ọ̀fẹ́ láti GB 1 sí GB 5, tí owóo rẹ̀ jẹ́ 25 sí 100 meticals (0.37 sí 1.50 owó US).
Mú àǹfààní ẹ̀bùn #StayAtHome yìí lò fún 25 meticals láàárín oṣù kan.
Tẹ *219# láti se àṣàyàn ẹ̀bùn tí ó fẹ́, kí o sì dúró sílé pẹ̀lú TmCel. Fún àlàyé lẹ́kùnúnrẹ́rẹ́ kàn sí:
Bí-ó-ti-lẹ̀-jẹ́-pé àǹfààní ẹ̀bùn jẹ́ ohun àtẹ́wọ́ gbà láwùjọ, díẹ̀ lára àwọn òǹṣàmúlò gbàgede Twitter se àgbéjáde àwọn ìbéèrè kan:
Ìgbésẹ̀ tí ó dáa ni.
Sé ó jẹ́ ojúlówó bákan náà?
Dídúró sílé yìí kì í se ohun tó bá àwọn onísẹ́ ọwọ́ àti oníṣẹ́ ìgbẹ́mìíró tí ó ń gbé ní Mozambique àti Cape Verde lára mú rárá. Ajàfẹ́tọ̀ọ́ ọmọ-ènìyàn Tomás Queface túwíìtì:
Àìsàn #coronavirus yìí ti ṣípayá ìwà àìdọ́gba tí ó wà láwùjọ wa.
Bí òfin kónílé ó gbélé #StayAtHome ṣe jẹ́ oore ọ̀fẹ́ fún àwọn kan, níṣe l'ó ń mú àwọn tí ò rọ́wọ́họrí láwùjọ fajúro látàrí fi f'ọwọ́ múkan: nínúu dídúró sílé láì rí oúnjẹ jẹ, tàbí ṣíṣiṣẹ́ kí àlàáfíà ara ó di fíafìa tàbí fífi ìlera àwọn ará ìlú tó kù wéwu.
COVID-19 ṣe àgbéǹde ìṣẹ̀lẹ̀-àtẹ̀yìnwá tó burú jáì nípa ìdánwò egbògi ní Ilẹ̀-Adúláwọ̀
Ilẹ̀-Adúláwọ̀ kì í ṣe iyàrá àyẹ̀wò'
Olóyè ọmọ-ogun. 1st Class Marites Cabreza, olùtọ́jú ọmọ tí ó ń ṣiṣẹ́ pẹ̀lú 354th Civil Affairs Brigade, Special Functioning Team, Combined Joint Task Force-Ìho Ilẹ̀-Adúláwọ̀, ń tọ́jú aláìsàn lọ́jọ́ 29, oṣù kẹta, ọdún-un 2008, lásìkò àkànṣe iṣẹ́ ìwòsàn ìlú ní Goubetto, Djibouti.
Àwòrán láti àkàtà Ọmọ-ogún Òfuurufú US Ẹ̀ka ìmọ̀ ẹ̀rọ , Jeremy T. Lock. Ìlò gbogboògbò.
Yẹ àkànṣe ìròyìn-in ‘Ohùn Àgbáyé’ lórí ipa tí COVID-19 ń kó lágbàáyé.
Arée pànpàlà bí o ò lọ ó yàgò tí ń ṣẹlẹ̀ láàárín àwọn onímọ̀ ìjìnlẹ̀ àti oníṣẹ́ ìwádìí kò ṣẹ̀yìn ìgbésẹ̀ láti ṣe àyẹ̀wò àwọn oògùn tí wọ́n rò pé ó lè wo àrùn COVID-19 sàn lára ọmọ ènìyàn ti ń dá gbọ́nmisíi-omi-ò-tóo sílẹ̀ ní Ilẹ̀-Adúláwọ̀.
Lọ́jọ́ 1, oṣù kẹrin, àwọn oníṣẹ́ ìwádìí ọmọ ilẹ̀ Faransé méjì, Oníṣègùn Jean-Paul Mira, àti Camille Locht, dá a lábàá lórí ètò kan ní orí ẹ̀rọ-amóhùnmáwòrán wí pé Ilẹ̀-Adúláwọ̀ ni ó yẹ kí wọn ó ti kókó dán egbògi àjẹsára tí yóò ká apá àrùn kòkòrò àìfojúrí kòrónà sàn wò, gẹ́gẹ́ bí Al-Jazeera ti ṣe jíyìn ìròyìn náà.
Oníṣègùn Mira, olórí ẹ̀ka ìtọ́jú àfẹ́jù ti Cochin Hospital tí ó wà ní Paris, fi ọ̀rọ̀ náà wé “àwọn ìwádìí àyẹ̀wò fún Àrùn Kògbóògùn ÉÈDÌ, tí ó jẹ́ wí pé lára àwọn olówòo nàbì ni a ti kọ́kọ́ dán an wò, a gbìyànjú àwọn nǹkan kan nítorí a mọ̀ dájú wí pé wọn kì í dá ààbò bo ara wọn, àti pé ó rọrùn fún àrùn ìbálòpọ̀ láti lúgọ sí ara wọn.”
Àwọn oníṣẹ́ ìwádìí méjèèjì mẹ́nu lọ́rọ́ nígbà tí àsọgbà ọ̀rọ̀ kan wáyé lórí ìṣàyẹ̀wò egbògi àjẹsára BCG fún ikọ́-àwúpẹ̀jẹ̀ ní Yúróòpù àti Australia láti mọ̀ bóyá yóò ṣiṣẹ́ ìwòsàn fún kòkòrò àìfojúrí kòrónà àkọ́kọ́ irú ẹ̀.
Ní Australia, àyẹ̀wò ti ń lọ lórí àwọn oníṣẹ́ ìlera ẹgbẹ̀rún 4.
Ìṣesí àwọn oníṣẹ́ ìwádìí wọ̀nyí jẹ́ gbohùngbohùn ìṣẹ̀lẹ̀-àtẹ̀yìnwá ọlọ́jọ́ pípẹ́ tí ó ní ṣe pẹ̀lú ìdánwò àti fífọwọ́ọlá gbá ọmọ Adúláwọ̀ ní ojú, tí ó ṣe wí pé àwọn adarí Ilẹ̀-Adúláwọ̀ ti pàdí-àpò-pọ̀ pẹ̀lú àwọn iléeṣẹ́ apooògùntà — tí ó fi Yúróòpù tàbí ilẹ̀ Amẹ́ríkà ṣe ibùgbé — láti wá ṣe àyẹ̀wò ní ara àwọn tí kò rí já jẹ láwùjọ.
"Lẹ́sẹ̀kẹsẹ̀ ni ìṣọ̀rọ̀sí àwọn oníṣẹ́ ìwádìí wọ̀nyí rí ìdálẹ́bi àti ìbínú àwọn ènìyàn, tí ó mú àpólà ọ̀rọ̀ kan, ""Ọmọ ilẹ̀-Adúláwọ̀ kì í ṣe eku ẹmọ́."" gbajúmọ̀ lórí ẹ̀rọ-agbọ́rọ̀káyé."
Ìràwọ̀ agbábọ́ọ̀lù ọmọ orílẹ̀-èdè Ivory Coast Didier Drogba túwíìtì:
"Nígbà tí ó di ọjọ́ 3, Oṣù Kẹrin, Oníṣègùn Mira ti ṣe ìtọrọ àforíjì fún àwọn ọ̀rọ̀ tí ó sọ, àmọ́ lẹ́yìn tí àwọn ẹgbẹ́ SOS Racisme kọ ẹ̀yìn sí i ni ó ṣe èyí. Òṣìṣẹ́ẹ oníṣègùn Locht, bákan náà, da àwọn ẹ̀hónú orí Twitter dànù gẹ́gẹ́ bí i ""ìròyìn ẹlẹ́jẹ́ "", nítorí wí pé àwọn ọ̀rọ̀ náà kò rí bí wọ́n ti ṣe ń sọ ọ́."
"Ní àárín ọ̀sẹ̀ yẹn kan náà, onímọ̀ nípa àrùn àìfojúrí ọmọ orílẹ̀-èdè Congo Jean-Jacque Muyembe, tí ó ń léwájú nínú ìgbógunti àjàkálẹ̀ àrùn ibà ìdà ẹ̀jẹ̀ Ebola ní orílẹ̀-èdè Ìlú Ìjọba Àwaarawa Olómìnira Congo, filọ̀ wí pé DR Congo ""ti ṣe tán láti kópa nínú irúfẹ́ ìdánwò egbògi tí yóò pa kòkòrò àìfojúrí kòrónà tí kò bá à wáyé lọ́jọ́ iwájú"", bí News 24 ti jábọ̀."
Muyembe, olórí ìgbìmọ̀ amúṣẹ́ṣe lórí àjàkáyé àrùn náà àti Iléeṣẹ́ ètò ìlera orílẹ̀-èdè náà, sọ níbi àpérò àwọn oníròyìn kan:
Wọ́n ti yàn wá láti ṣe àwọn àyẹ̀wò wọ̀nyí...
Ìlú Ìṣọ̀kan Amẹ́ríkà tàbí Canada tàbí ní China ni a ó ti ṣe egbògi àjẹsára náà.
Àwa ni ẹni ayàn fún iṣẹ́ àyẹ̀wò náà níbí.
Lẹ́ẹ̀kan sí i, àwọn ọ̀rọ̀ wọ̀nyí fa ìrúnú àwọn ọmọ Congo àti àwọn ọmọ orí ayélujára jákèjádò ilé ayé tí wọ́n dá Oníṣègùn Muyembe ní ẹ̀bí nítorí ó faramọ́ ìṣàyẹ̀wò egbògi ní DR Congo, níbi tí iye àwọn tí ó ti kó àrùn COVID-19 kò tí ì fi bẹ́ẹ̀ pọ̀.
Láàárín wákàtí díẹ̀, Oníṣègùn Muyembe yànnàná ọ̀rọ̀ọ rẹ̀ nínú àwòrán-àtohùn kan, tí ó fi ìdíi rẹ̀ múlẹ̀ wí pé ó di ìgbà tí wọ́n bá ti kọ́kọ́ yẹ iṣẹ́ egbògi náà wò ní US àti China ni yóò tó jẹ́ lílò ní DR Congo:
Ìṣẹ̀lẹ̀-àtẹ̀yìnwá tó burú jáì nípa ìdánwò egbògi ní Ilẹ̀-Adúláwọ̀
"Ìdánwò egbògi ní Ilẹ̀-Adúláwọ̀ — tí ó sábà máa ń wáyé lábẹ́ ẹ̀tàn ""ìfẹ́ẹ gbogboògbò” tí ó pọn dandan ní ojúnà àti wá ìwòsàn fún àrùn aṣekúpani bí i àrùn yírùnyírùn àti àrùn kògbóògùn HIV/AIDS — ti lu agogo ìtanijí ìwà-ọmọlúwàbí fún àìníye ọdún — pàápàá jù lọ lórí ìgbàṣẹ lọ́wọ́ àwọn ènìyàn kí wọn ó tó ṣe ìdánwò àti ìlànà ìṣètò ìlera onítúláàsì."
Àwọn iléeṣẹ́ tí ó jẹ́ asíwájú nínú ètò ìlera lágbàáyé bí i Àjọ Elétò Ìlera Àgbáyé, Àjọ Aṣàkóso Àrùn ti orílẹ̀-èdè Amẹ́ríkà àti Iléeṣẹ́ Ètò Ìlera Ìjọba Àpapọ̀ ni ó máa ń kó owó sílẹ̀ fún irú àwọn iṣẹ́ báyìí.
Ní orílẹ̀-èdè Zimbabwe, ní àárín àwọn ọdún tí ó ré kọjá kí a tó wọ Ẹgbàá ọdún, ó lé ní 17,000 àwọn obìnrin tí ó ní àrùn kògbóògùn ni ó ṣe ìdánwò láì fi àṣẹ fún àwọn elétò ìdánwò wí pé àwọn fi ọwọ́ si í kí wọn ó lo àwọn fún iṣẹ́ ìwádìí àyẹ̀wò egbògi-agbógunti ìtànká àrùn kògbóògùn AZT lágọ̀ọ́ ara tí CDC, WHO àti NIH kó owó lé lórí.
Bákan náà ẹ̀wẹ̀, àgbà ọ̀jẹ̀ iléeṣẹ́ apooògùntà Pfizer dán oògùn kan wò tí a pè ní Trovan ní ara àwọn èwe 200 ní Ìpínlẹ̀ Kano, orílẹ̀-èdè Nàìjíríà, nígbà tí àjàkálẹ̀ àrùn yírùnyírùn ṣẹ́ yọ.
Ọ̀pọ̀lọpọ̀ ìdílé ni ó pe Pfizer ní ẹjọ́ lórí àìgbàṣẹ lọ́wọ́ àwọn kí wọn ó tó lo àwọn ọmọ àwọn fún ìdánwò.
Ìdánwò egbògi kì í ṣe èyí tí ó dá lórí ìṣẹ̀lẹ̀-àtẹ̀yìnwá nípa ti ẹlẹ́yàmẹyà àti ìfipámúnisìn nìkan — bákan náà ni ó ń ṣe okùnfàa ìṣòro àìfọkàn tán láàárín àwọn aṣojú ètò ìlera àti ará ìlú.
"Patrick Malloy kọ sí inú àpilẹ̀kọ ajẹmákadá tí a pe àkọ́lée rẹ̀ ní, ""Èròjà Iṣẹ́-ìwádìí àti Ìbókùúsọ̀rọ̀: Ìgbéyẹ̀wò ìrònú nípa ètò Ìṣèlú-tòun Ọrọ̀-ajé tí ó ní ṣe pẹ̀lú ìṣoògùn ìgbàlódé ní ayé ìfipámúnisìn ní Tanganyika"" pé ""Àti ìfipámúnisìn àti ìṣoògùn ìgbàlódé ní í jọ ń parapọ̀ ṣe, tí ìk-ín-ní ń kín ìlọsíwájú ìkejì lẹ́yìn."""
"Láti ayée àmòdi sí ayé irú àwọn ""àjàkálẹ̀-àrùn báwọ̀n-ọnnì"", àwọn aṣojú ìjọba ìfipámúnisìn sábà máa ń fi àwọn Ọmọ Adúláwọ̀ ṣe ohun èlò fún ìdánwò láì gba àṣẹ, Malloy kọ pé ""...ẹ̀jẹ̀ Ọmọ Adúláwọ̀ ni ó dára jù lọ láti fi bọ́ iṣẹ́ ìwádìí egbògi ayé ìjọba amúnisìn""."
Ó tẹ̀síwájú nínú ọ̀rọ̀ọ rẹ̀:
Ní Tanganyika àti ní apá ibòmíràn ní Ilẹ̀-Adúláwọ̀, èyí túmọ̀ sí wí pé ní ìgbàkúùgbà ni àwọn amúnisìn leè ké sí àwọn tí wọ́n ń jẹ gàba lé lórí láti yànda àwọn pádi ẹ̀jẹ̀, tí ó dúró fún ẹ̀yà àbùdá ara wọn fún aṣojú ètò ìlera tí yóò jẹ́ lílò fún ìdánwò.
"Àwọn ìṣẹ̀lẹ̀ báwọ̀nyí kò yàtọ̀ sí gbọ́yìí-sọ̀yìí ọ̀rọ̀ tí àwọn ènìyàn ń jẹ ní ẹnu ní Ìlà-oòrùn Ilẹ̀-Adúláwọ̀ nípa ""àwọn ẹgbẹ́ "" tí ó ń ṣiṣẹ́ fún àwọn Òyìnbó tí iṣẹ́ẹ ti wọn kò ju kí wọn ó máa jí Ọmọ Adúláwọ̀ gbé lọ láti gba ẹ̀jẹ̀ tí wọn yóò fi ṣe oògùn kan bí òjíá tí a pè ní mumiani."
Ọ̀rọ̀ ìperí ní èdèe Swahili àkàwé oògùn náà ni “amùjẹ̀” tàbí “agbẹ̀jẹ̀-fún-ìwòsàn” — tí ó ti di “ìmórí-ẹni-sábẹ̀” báyìí.
Ìṣẹ̀lẹ̀-àtẹ̀yìnwá tí ó burú jáì yìí ti gbin èso àìfọkàn tán nínú àwọn egbògi àjẹsára, ìṣàyẹ̀wò àti ìdán oògùn wò ní Ilẹ̀-Adúláwọ̀, tí ó sì ń farahàn nínú iṣẹ́ àwọn aṣojú ètò ìlera tí ó ń ṣiṣẹ́ papọ̀ pẹ̀lú ìjọba àti àwọn iléeṣẹ́ alooògùntà ní àgbáyé.
Ìdánwò oògùn àrùn yírùnyírùn ìgbàa nnì ní Kano, orílẹ̀-èdèe Nàìjíríà, gbin ọ̀pọ̀lọpọ̀ àìnígbágbọ̀ tí kò mú kí ìpolongo ìdánwò oògùn àrùn rọmọlápárọmọlẹ́sẹ̀ ó rinlẹ̀.
Àhesọ nípa egbògi àjẹsára agbógunti àrùn rọmọlápárọmọlẹ́sẹ̀ fọ́n ká sí ìgboro. Àwọn àhesọ ọ̀rọ̀ náà di pínpín ká bí ìròyìn tí ó ṣe atọ́nà ètò ìmúlò ìjọba agbègbè tí ó f'òfin de ìlòo egbògi àrùn rọmọlápárọmọlẹ́sẹ̀ ní orílẹ̀-èdèe Nàìjíríà ní ọdún-un 2003.
Ìmúláradá lẹ́yìn ‘orí fífọ́’ ìfipámúnisìn
Pẹ̀lú ohun tí a ti sọ, kí ni gbogbo ìwọ̀nyí yóò fà fún ìdánwò egbògi àrùn COVID-19 ní Ilẹ̀-Adúláwọ̀ ?
"Àwọn ènìyàn ní orí ayélujára àti ajìjàngbara gbogbo ló ti pẹnupọ̀ wí pé ""àwọn Ọmọ Adúláwọ̀ kì í ṣe eku ẹmọ́ òyìnbó""."
"Ọ̀gá àgbà Àjọ Ètò Ìlera Àgbáyé (WHO) Tedros Adhanom Ghebreyesus ti pe ìhùwàsí àwọn oníṣègùn méjèèjì náà sí ""orí fífọ́ "" tí ó dá lórí “làákàyè ìfipámunisìn”, ó sì fi léde:"
Kò leè jẹ́ Ilẹ̀ Adúláwọ̀ àti pé kì í ṣe Ilẹ̀ Adúláwọ̀ ni yóò jẹ́ ibi ìdánwò fún èyíkéyìí irúfẹ́ egbògi.
Síbẹ̀, ìbẹ̀rùbojo àti àìfọkàn tán ìdánwò egbògi ti mú kí dídá àwọn ẹni tí ó ti lùgbàdè àrùn àfòmọ́ kòkòrò àìfojúrí kòrónà mọ́ láwùjọ àti ìṣàyẹ̀wò ó nira fún àwọn òṣìṣẹ́ elétò ìlera.
Ní orílẹ̀-èdèe Côte d'Ivoire ní ọjọ́ 6, Oṣù kẹrin, àwọn afẹ̀hónúhàn ti iná bọ ibi àyẹ̀wò àrùn COVID-19 kan, ìdí tí wọ́n fi ṣe bẹ́ẹ̀ ni wí pé agbègbè tí èró pọ̀ sí ni wọ́n sọrí ibi àyẹ̀wò náà sí tí kò sì bójúmu.
"Iléeṣẹ́ BBC jábọ̀ wí pé, ""ìkọlù náà “mú ‘ni rántí ìhùwàsí àwọn ènìyàn ní àsìkò tí àrùn ibà Ebola ń jà rọ̀ìnrọ̀ìn ní Ìwọ̀-oòrùn àti Àárín gbùngbùn Ilẹ̀ Adúláwọ̀ níbí tí àwọn kan ti ya bo àwọn oníṣẹ́ ètò ìlera, pẹ̀lú ìmúfuradání wí pé wọn ń kó àrùn náà wọ àdúgbòo àwọn, bókànràn-an kí wọ́n fún àwọn ní ìtọ́jú tí ó lẹ́tikẹ""."
"Jù bẹ́ẹ̀ lọ, nínú rògbòdìyàn àjàkálẹ̀-àrùn ibà Ebola ọdún-un 2018 ní DR Congo, àwọn àyẹ̀wòkan àyẹ̀wòkàn tí a ṣe ní ara àwọn ẹni tí ó ti lu gúdẹ àrùn Ebola ""tí ó tẹ̀lé àlàkalẹ̀ ìwà-ọmọlúwàbí kan"" — lábẹ́ ìtọ́nàa Oníṣègùn Muyembe àti ìjọba orílẹ̀-èdèe DR Congo — dóòlà ẹ̀mí àwọn ènìyàn níkẹyìn."
Nígbà tí ó máa fi di Oṣù Kọkànlá ọdún-un 2019, tí a ti ṣe àyẹ̀wò fún ọmọ orílẹ̀ èdèe Congo tí ó ju ẹgbẹ̀rún lọ, a fi òǹtẹ̀ lu egbògi àjẹsára kan.
Ó yẹ kí WHO ó ṣe ìkéde wí pé àrùn ibà ìdà ẹ̀jẹ̀ Ebola kò sí ní DR Congo mọ́ ní ọjọ́ 12 Oṣù Kẹrin, ṣùgbọ́n lẹ́yìn 50 ọjọ́ tí kò sí ẹni tí ó lùgbàdìi àrùn yìí, ọmọkùnrin tí ọjọ́ oríi rẹ̀ jẹ́ ọdún 26 kó àrùn ibà ìdà ẹ̀jẹ̀ Ebola ó sì filẹ̀ ṣ'aṣọ bora ní ọjọ́ 10 Oṣù Kẹrin.
Ní báyìí, ní àfikún Ebola àti awuyewuye ọ̀rọ̀ ẹ̀tọ́ ọmọnìyàn tí ó ń m'ìgboro tìtì lọ́wọ́lọ́wọ́, orílẹ̀-èdèe DR Congo ní láti kọ ojú sí dídẹ́kun ìgbodikan àjàkálẹ̀-àrùn kòkòrò àìfojúrí kòrónà tí ó ń gbilẹ̀ bí ọ̀gẹ̀dẹ̀.
Àwọn ìgbésẹ̀ 62 tí ó ń gbèrò láti wá egbògi àjẹsára fún àrùn COVID-19 ló ń lọ lọ́wọ́. Àyẹ̀wò àti ìdánwò egbògi àjẹsára tí yóò ṣiṣẹ́ dé góńgó tí a gbé ṣe lọ́nà tí ó bá ìwà-ọmọlúwàbí mu máa ń gba àsìkò.
Ǹjẹ́ àwọn iléeṣẹ́ apooògùntà ńlá yóò dìrọ̀ mọ́ àwọn òfin ìwà-ọmọlúwàbí ní Ilẹ̀-Adúláwọ̀ bí wọ́n ti ṣe ń ṣe bí wọ́n bá ń ṣe ìdánwò ní Ilẹ̀ òyìnbó?
Ní Burundi, àwọn akọ̀ròyìn mẹ́rin tí a fi sátìmọ́lé ń dúró de ìpinnu ẹjọ́ kòtẹ́milọ́rùn
Ẹ̀sùn ìlọ́wọ́sí ìdúkokò mọ́ ààbò ìlú ni a fi kan àwọn akọ̀ròyìn náà
Iléeṣẹ́ Oníròyìn náà ní Bujumbura, níbi tí a yọ àwọn ilé ìgbóhùnsáfẹ́fẹ́ kúrò lórí ìlà. Ọjọ́ 19 oṣù Èbìbí 2010.
Àwọn akọ̀ròyìn mẹ́rin — Agnès Ndirubusa, Christine Kamikazi, Térence Mpozenzi àti Egide Harerimana — ni a dá lẹ́jọ́ ìgbésẹ̀ láti yẹpẹrẹ ààbò ìlú tí a sì rán wọn lọ sí ẹ̀wọ̀n nínú oṣù Kìn-ín-ní ọdún-un 2020.
Àwọn mẹ́rẹ̀ẹ̀rin tí ó ń ṣiṣẹ́ pẹ̀lú ìwé ìròyìn Iwacu kò fi méní pe méjì níṣe ni wọn sọ wí pé àwọn kò ṣẹ̀ sófin.
Ní báyìí wọ́n ń dúró de ìpinnu ẹjọ́ kòtẹ́milọ́rùn lórí àtìmọ́lé wọn, lẹ́yìn ìgbẹ́jọ ọjọ́ 6 oṣù Karùn-ún.
Antoine Kaburahe, olùdásílẹ̀ ìwé ìròyìn tí ó ń gbé ní ẹ̀yin odi, kọ:
Ní yàjóyàjó: Òpin ìgbẹ́jọ́ ní Bubanza. Iwacu bọ́rí.
Ẹ̀sùn tí a kà sí àwọn akọ̀ròyìn náà lọ́rùn kì í ṣe tiwọn.
Iṣẹ́ẹ wọn ni àwọn akọ̀ròyìn náà ń ṣe: ìkóròyìnjọ.
Ọkàn-án balẹ̀ !
Àmọ́ adájọ́ kò tíì dájọ́, àbálọ-bábọ̀ ọ̀rọ̀ di lẹ́yìn oṣù kan.
Ẹ dúró ṣinṣin!
Àtìmọ́lé fún ìkóròyìnjọ
Ní ọjọ́ 22, oṣù Ọ̀wàrà, àwọn ẹ̀ṣọ́ aláàbò Burundi wà á kò pẹ̀lú ẹgbẹ́ agbébọrìn alátakò ìjọba kan — tí à ń pè ní RED-Tabara, tí ó fi Democratic Republic of Congo ṣe ilé — ní agbègbè ibodè igbó Kibira.
Àwọn ẹgbẹ́ ọlọ́tẹ̀ agbébọrìn ti máa ń fi ibí yìí kiri àgbègbè náà.
Nínú ìjà akátá náà, àwọn agbébọrìn 14 ni ikú pa, tí ẹ̀ṣọ́ aláàbò 10 sì bá a lọ.
Ní ọjọ́ yẹn náà, àwọn ọlọ́pàá fi àwọn akọ̀ròyìn Iwacu mẹ́rin àti awakọ̀ wọn Adolphe Masabaakiza sí àtìmọ́lé, nígba tí wọn lọ kóròyìn jọ ní àdúgbò Musigati, ní Bubanza, níbi tí wọ́n ti fẹ́ bá àwọn ènìyàn tí ó sá kúrò ní àdúgbò nígbà tí ìjà náà bẹ́ sílẹ̀.
Lákọ̀ọ́kọ́, a fi wọn sí àtìmọ́lé láì fi ẹ̀sùn kàn wọ́n, tí a sì lu Christine Kamikazi nígbà tí wọ́n mú wọn.
Ọlọ́pàá gba ẹ̀rọ-ìbánisọ̀rọ̀ àti àwọn ohun èlò iṣẹ́ wọn tí àwọn ọ̀tẹlẹ̀múyẹ́ sí béèrè fún gbólóhùn ìfiwọlé sí orí ẹ̀rọ wọn láti yẹ̀ ẹ́ wò fínnífínní.
Àwọn akọ̀ròyìn náà di ẹni tí à ń gbé kiri lọ sí túbú mìíràn tí kò sunwọ̀n.
"Ní ọjọ́ 26 oṣù Kẹwàá, ní Bubanza, a jàjà fẹ̀sùn ""Ìlọ́wọ́sí ìdúkokò mọ́ ààbò ìlú"" kàn wọ́n."
Ní ọjọ́ 31, oṣù Kẹwàá, abánirojọ̀ náà fi ẹ̀rí èyí lélẹ̀ ó sì fẹ̀sùn kàn wọ́n ní pé wọ́n mọ̀ sí ìkọlù àwọn kọ̀lọ̀rànsí ẹ̀dá náà.
Àwọn iléeṣẹ́ ní ẹ̀ka-ò-jẹ̀ka ni ó ti pè fún ìdásílẹ̀ wọn, títí kan Human Rights Watch, International Federation of Journalists, Olucome, African Journalists’ Federation àti Àjọ Burundaise des Radiodiffuseurs.
Síbẹ̀, Iléeṣẹ́ Ìgbóhùnsáfẹ́fẹ́ Àpapọ̀ sọ wí pé àwọn kò tíì lè sọ sí ọ̀ràn náà báyìí.
Iwacu bu ẹnu àtẹ́ ohun tí àjọ náà sọ, ní pé wọn kò fẹ̀sùn kankan kàn wọ́n nígbà tí wọ́n mú wọn àti pé ojúṣe àjọ náà ni láti gbèjà àwọn akọ̀ròyìn.
Ọ̀pọ̀ àwọn ènìyàn ní ó gbè lẹ́yìn àwọn akọ̀ròyìnnáà tí wọ́n sì fi ọwọ́ bọ ìfẹ̀sùnkàn lórí ẹ̀rọ-ayélujára. Àwọn iléeṣẹ́ oníròyìn ríi gẹ́gẹ́ bí ìfojú-ẹ̀tọ̀ sí òmìnira oníròyìn gbolẹ̀, tí Iwacu sì ń tọ okùn ọ̀ràn náà lọ pẹ́kípẹ́kí.
Akọ̀ròyìn Esdras Ndikumana túwíìtì:
"Burundi: àwọn akọ̀ròyìn Iwacu mẹ́rin (àti awakọ̀ wọn) ni a fi ẹ̀sùn ""ìlọ́wọ́sí ìdúkokò mọ́ ààbò ìlú"" kàn nítorí wọ́n lọ kó ìròyìn ìkọlù tí ó wá sáyé tí wọ́n sì di ẹ̀rọ ọgbà ẹ̀wọ̀n Bubanza (Àwòrán láti ọwọ́ Yaga)"
Lẹ́yìn tí wọ́n ti ní ẹjọ́ tí ó fi àwọn sí inú àtìmọ́lé náà kò tẹ́ àwọn lọ́rùn, a dá ọjọ́ ìgbẹ́jọ́ wọn sí ọjọ́ 18, oṣù Kọkànlá, kàyéfì ni ó jẹ́ fún wọn nígbà tí wọ́n gbé wọn lọ sílé ẹjọ́ ní ọjọ́ 11, oṣù Kọkànlá kí wọn ó wá gbọ́wọ́ pọ̀nyìn rojọ́ níwájú adájọ́ — láì sí àwọn agbẹ́jọ́rò.
Wọ́n kọ̀ wọn kò fèsì nítorí kò sí àwọn agbẹ́jọ́rò wọn níkàlẹ̀, wọ́n sì dá wọn padà sí àtìmọ́lé, kí ọjọ́ 18 tí a dá fún ìgbẹ́jọ́ ó kò.
Ní ọjọ́ 20 oṣù Kọkànlá, ìpinnu dé tí wí pé àwọn akọ̀ròyìn mẹ́rẹ̀ẹ̀rin yóò padà sínú àtìmọ́lé, àmọ́ wọ́n dá awakọ̀ sílẹ̀.
Ìdájọ́ tí a fún wọn tó ọdún 15 nínú ẹ̀wọ̀n.
Ààrẹ Pierre Nkurunziza sọ níbi àpéjọ àwọn akọ̀ròyìn kan tí ó wá sáyé ní ọjọ́ 26 oṣù Kejìlá wí pé ohun ohun kò ní fẹ́ dídijú mọ́rí dájọ́ àmọ́ ó dìgbà tí a bá ti ṣánpá tí kò ṣe é ṣán mọ́ ni òun yóò tó ká a lérí, pẹ̀lú pé ó lè fi àṣẹ tí ó ń bẹ ní ìkáwọ́ rẹ da ẹjọ́ náà nù.
Lọ́jọ́ 30, oṣù Kìn-ín-ín ní Bubanza, a rán to àwọn akọ̀ròyìn mẹ́rẹ̀ẹ̀rin náà lọ sí ẹ̀wọ̀n ọdún méjì àti àbọ̀ pẹ̀lú kí ẹnìkọ̀ọ̀kan ó sanwó ìtanràn ẹgbẹẹgbẹ̀rún owó francs ($521 owó orílẹ̀ èdè Amẹ́ríkà) lábẹ́ òfin 16 ti Òfin Ọ̀daràn, tí awakọ̀ sì gba ilé-e rẹ̀ láì sanwó ìtanràn.
"Ìdájọ́ náà kò fi hàn ní pàtó wí pé àwọn akọ̀ròyìn náà mọ ohunkóhun nípa ìṣẹ̀lẹ̀ náà, látàrí èyí ẹ̀sùn náà yíra padà di ""ìgbésẹ̀ ìlọ́wọ́sí ìdúkokò mọ́ ààbò ìlú tí kò ṣe é ṣe"", ìyẹn ni pé — wọ́n pète láti dúnmọ̀rurumọ̀ruru mọ́ ààbò ìlú àmọ́ ó ṣòro láti gbé ṣe."
Iwacu ṣàlàyé wí pé àwọn akọ̀ròyìn náà lọ síbi ìṣẹ̀lẹ̀ náà lẹ́yìn tí àwọn aláṣẹ tí fi léde, wọ́n gba ìwé àṣẹ kò sì sí òfin tí ó ní kẹ́nìkan ó máa dé agbègbè ìṣẹ̀lẹ̀ náà.
"Ẹ̀rí kan ṣoṣo tí wọ́n rí dìmú tí ó kó àwọn akọ̀ròyìn náà sí yáwúyáwú ni àtẹ̀jíṣẹ́ orí WhatsApp tí ọ̀kan lára àwọn akọ̀ròyìn náà fi ṣọwọ́ sí ọ̀rẹ́ẹ rẹ̀ kan, tí ó sọ wí pé àwọn fẹ́ lọ ""ran àwọn ọlọ́tẹ̀ ìjọba náà lọ́wọ́ ""."
Àmọ́ ẹ̀fẹ̀ lásán ni wọ́n fi ṣe — ìjọba ti máa ń sábà kó àwọn alátakò, ẹgbẹ́ olóṣèlú àti àwọn agbébọnrìn papọ̀ láti jàre irú ìgbésẹ̀ báyìí. the àtẹ̀jíṣẹ́ náà ni a fi kàn wọ́n mọ́lẹ̀.
Reporters Without Borders (RSF) sọ wí pé àwọn akọ̀ròyìn náà lẹ́tọ̀ọ́ láti jábọ̀ ìròyìn tí ó kan gbogbo ìlú gbọ̀ngbọ̀n láì fòyà ìgbẹ̀san, papàá ní ìgbaradì ìbò orílẹ̀-èdèe Burundi ọjọ́ 20 oṣù karùn-ún tí ó ń bọ̀ lọ́nà.
Wọ́n kọ ìwé ìfẹ̀sùnkànni kan tí ó ń pè fún ìdásílẹ̀ wọn, èyí tí ènìyàn tí ó tó 7,000 tọwọ́bọ̀ ní ìbẹ̀rẹ̀ oṣù Karùn-ún.
Àwọn igbá-kejì àjọ European Union, Ìgbìmọ̀ ìjọba Yúróòpù, àti àwọn àgbà UN nípa ẹ̀tọ́ ọmọnìyàn wà lára àwọn tí ó ti pè fún ìdásílẹ̀ wọn.
Lọ́jọ́ 20 oṣù Kejì, àwọn akọ̀ròyìn náà ní ìdájọ́ náà kò-tẹ́ àwọn lọ́rùn, tí wọ́n sọ wí pé aláìṣẹ̀ ni wọ́n ń fìyà jẹ, àti àyípadà pàjáwìrì tí ó déédéé bá ẹ̀sùn tí wọ́n kọ́kọ́ fi kàn wọ́n.
Lọ́jọ́ 6, oṣù karùn-ún, àwọn akọ̀ròyìn náà fojú hàn nílé ẹjọ́ kòtẹ́milọ́rùn kan, lẹ́yìn tí wọ́n ti fi ẹ̀wọ̀n oṣù mẹ́fà jura.
"Ní ìfèsìpadà sí ẹ̀sùn náà látàrí iṣẹ́-ìjẹ́ orí WhatsApp, ní èyí tí akọ̀ròyìn kan sọ wí pé àwọn ọlọ́tẹ̀ náà ń bọ̀ wá ""dí àlàáfíà lọ́wọ́ ""."
RFI tún ọ̀rọ̀ agbẹ́jọ́rò wọn, Clément Retirakiza wí, wípé kkò sí ẹ̀rí tí dájú nípa ẹ̀sùn tí a fi kan àwọn akọ̀ròyìn náà, wọ́n kàn fẹ́ fi ọwọ́ ọlá gba aláìṣẹ̀ lójú ni.
Ọjọ́ ti pẹ́ tí Iwacu ti wà gedegbe gẹ́gẹ́ bí ohùn tí ó fajúro sí jágídíjàgan ìṣèlú — òun ni iléeṣẹ́ oníròyìn tí ó kẹ́yìn lẹ́yìn ìgbẹ́sẹ̀lé ọdún-un 2015.
Ìṣẹ̀lẹ̀ àtẹ̀yìnwá nípa ìjìyà akọ̀ròyìn
Lẹ́yìn ètò ìdìbò tí ó dá wàhálà sílẹ̀ ti ọdún-un After 2015 — èyí tí ó gbé Nkurunziza padà sípò fún ìgbà kẹta tí àwọn ènìyàn sọ wí pé ó tasẹ̀ àgbẹ̀rẹ̀ sófin — ìfipágbàjọba tí kò yọrí sí rẹ. Iṣẹ́ àwọn akọ̀ròyìn de polúkúmuṣu.
Ọ̀pọ̀lọpọ̀ iléeṣẹ́ agbóhùnsáfẹ́fẹ́ — tí àwọn ènìyàn fẹ́ràn fún ẹ̀kúnrẹ́rẹ́ ìròyìn tí kò figbákanbọ̀kan ní Burundi — ni a ṣán pa. Ọ̀pọ̀lọpọ̀ akọ̀ròyìn lló júbà ehoro tí àwọn mìíràn bíi Esdras Ndikumana jẹ mo-yó-ìyà
Ọ̀gọ̀rọ àwọn akọ̀ròyìn ni ó ti ní ìrírí ìyà lọ́wọ́ àwọn ẹ̀sọ́ agbófinró ìlú, pàápàá jù lọ bí wọ́n ń bá kó ìròyìn tí ó “pọn dandan” jọ.
Ní ìparí ọdún 2015, ọlọ́pàá pa òǹyàwòrán Christophe Nkezabahizi pẹ̀lú àwọn ọmọ-lẹ́bí mẹ́ta, ní àsìkò ìbò tí ìfẹ̀hónú wá sáyé.
Nínú oṣù Keje ọdún 2016, Jean Bigirimana di àwátì, ó ṣe é ṣe kí ó jẹ́ wí pé iléeṣẹ́ ọ̀tẹlẹ̀múyẹ́ (SNR) ló gbé e, láì jẹ́ kí àwọn ọlọ́pàá ó ṣe ìwádìí ìfínìdíikókò bó ṣe yẹ.
Lọ́dún yìí, ní ọjọ́ 16 oṣù Kìn-ín-ní, akọ̀ròyìn Blaise-Pascal Kararumiye pẹ̀lú Radio Isanganiro (Meeting Point Radio) di èrò akánrán ọlọ́pàá lẹ́yìn ìròyìn kan nípa owó ìjọba ìbílẹ̀ kan. Lọ́jọ́ 28, oṣù kẹrin, ọlọ́pàá kan na akọ̀ròyìn Jackson Bahati níbi tí ó ti ń ṣiṣẹ́ ìkóròyìn jọ.
Àwọn iléeṣẹ́ oníròyìn àgbáyé náà ò gbẹ́yìn, a gbẹ́sẹ̀ lé iṣẹ́ BBC ati VOA ní 2019. RSF to Burundi sí ipò 160 nínú orílẹ̀èdè 180 fún òmìnira oníròyìn — ó fi 15 láti 2015.
Àwọn obìnrin ní Nàìjíríà kojú àdó-olóró àgbẹ́sẹ̀léró àgbàwí ọ̀rọ̀ ìṣèlú lórí ẹ̀rọ-ayélujára
#BringBackOurGirls àti #ArewaMeToo ṣe àtúntò sí ìgbàwí ètò ìṣèlú ní orílẹ̀ èdè Nàìjíríà
Àwọn ọmọ ẹgbẹ́ Mother's Savings Club, Nàìjíríà. I'm Àwòrán láti ọwọ́ Karen Kasmauski / USAID ní Ilẹ̀-Adúláwọ̀ ní orí United States government work, public domain.
Ní Nàìjíríà, àdó-olóró àgbẹ́sẹ̀léró ni gbàgede àgbàwí ọ̀rọ̀ òṣèlú.
Àgbàwí àti ọ̀rọ̀ ìṣèlú sábà máa ń fi ti ọ̀rọ̀ ẹ̀sìn àti ẹlẹ́yàmẹyà ṣe.
"Àwọn alágbàwí tí ó gbajúmọ̀ lórí ẹ̀rọ-alátagbà — pàápàá jù lọ lórí Twitter — ní láti lè fi ara gba ọ̀pọ̀lọpọ̀ gbas gbos (èdè àdàlù-mọ́-Gẹ̀ẹ́sì Nàìjíríà fún ""ìkànṣẹ́"") ní orí ẹ̀rọ-ayárabíàṣá."
Àwọn alágbàwí tí ó jẹ́ obìnrin — ní àfikún sí títẹ àwọn ohun ìdánimọ̀ tí ó ń mú ìpalára wá mọ́lẹ̀ — bákan náà ni wọ́n ń kojú ìkọlù tí ó ti ara ìkórìíra tẹ̀gbintẹ̀gbin ẹ̀yà jẹ yọ.
Báwo ni àwọn alágbàwí l'óbìnrin ní Nàìjíríà ṣe ń farada ìkorò orí ẹ̀rọ-ayélujára bíi ìsọ̀rọ àlùfànṣá síni, ọ̀rọ̀ ìkórìíra tẹ̀gbintẹ̀gbin àti ìmọ̀ọ́mọ̀ yí-ọ̀rọ̀ wọn dà?
Báwo ni wọ́n ṣe ń tẹ̀síwájú nínú iṣẹ́ wọn tàbí fọnrere iṣẹ́ wọn?
Àwọn ajìjàgbara orí ẹ̀rọ alátagbà méjì ní Nàìjíríà fi ìrírí àwọn àgbàwí àti ìkórìíra ìwà abo hàn: #BringBackOurGirls, tí Dókítà Oby Ezekwesili jẹ́ aṣíwájú; àti #ArewaMeToo, tí Fakhriyyah Hashim jẹ́ agbátẹrù, gbogbo wọn ni wọ́n ní ìrírí ìkórìíra tẹ̀gbintẹ̀gbin abo nínú agbo òṣèlú tí ó ń fa ìlọsíwájú wọn sẹ́yìn.
Ìjàgbara #BringBackOurGirls (#BBOG)
Ọdún mẹ́fà sẹ́yìn, ní ọjọ́ 15, Oṣù Igbe ọdún 2014, ó tó 200 àwọn ọmọdébìnrin tí ọjọ́ orí wọn ò ju ọdún 15 àti 18 lọ, láti iléèwé Gíga Ìjọba Obìnrin ní Chibok ẹ̀bà Maidiguri, ní àríwá-ìlà-oòrùn Nàìjíríà ni ẹgbẹ́ afẹ̀míṣòfò èlẹ́sìn Mùsùlùmí Boko Haram sọ di ẹni tí a fi túláàsì mú sí ìgbẹ̀sìn.
Ìjínigbé àwọn ọmọdébìnrin Chibok náà ṣe okùnfà ìlọ́wọ́sí àwọn orílẹ̀ èdè kárí àgbá ńlá ayé.
Iléeṣẹ́ oníròyìn BBC jábọ̀ wí pé nínú oṣù Igbe ọdún 2014, #BringBackOurGirls náà gbajúmọ̀ ní orí Twitter pẹ̀lú nǹkan bíi àwọn ènìyàn ẹgbẹẹgbẹ̀rún 3.3 tí ó tún túwíìtì náà túwíìtì, ìdá 27 àwọn túwíìtì wọ̀nyí ni ó wá láti Nàìjíríà, ìdá 26 láti orílẹ̀ èdè Amẹ́ríkà àti ìdá 11 láti Ilẹ̀ Gẹ̀ẹ́sì.
Dókítà Oby Ezekwesili ń dáhùn ìbéèrè níbi ètò àwọn obìnrin àjọ UN pẹ̀lú àwọn alákòóso ìpolongo #BringBackOurGirls.
Àwòrán láti ọwọ́ UN Women/Ryan Brown, ọjọ́ 14, oṣù Ọ̀wẹwẹ̀ ọdún 2014. (CC BY-NC-ND 2.0)
Dókítà Obiageli (Oby) Ezekwesili, igbá-kejì ààrẹ Ilé ìfowópamọ́ Àgbáyé ìgbà kan, àti mínísítà ètò ẹ̀kọ́ orílẹ̀ èdè Nàìjíríà nígbà kan rí, bẹ̀rẹ̀ sí túwíìtì nípa àwọn ọmọdébìnrin Chibok ní ọjọ́ tí wọ́n jí wọn gbé gan-an gan-an.
Ìṣẹ̀lẹ̀ kan tí ó ti ṣẹlẹ̀ tí àwọn àjínigbé jí àwọn ọmọdékùnrin gbé ní iléèwé Kọ́lẹ̀jì ìjọba Àpapọ̀ ti Buni Yadi ní Ìpínlẹ̀ Yobe, àríwá-ìlà-oòrùn Nàìjíríà lọ́jọ́ 25, oṣù Èrèlé ọdún 2014 ló ṣí i lójú sí ìpolongo yìí.
Àwọn ọmọdékùnrin kankàndínlọ́gọ́ta ni ó ti ara ọta ìbọn àti ọgbẹ́ ọbẹ̀ kú, nígbà tí iná sì jó àwọn mìíràn pa.
Síbẹ̀síbẹ̀, àfi ìgbà tí ó di ọjọ́ 23, oṣù Igbe, nígbà tí àjọ UNESCO gbà á lálejò ní Port Harcourt, ibi tí ó kún fún epo-rọ̀bì ní agbègbè Niger Delta, ni ó ti ké gbàjarè fún ìdásílẹ̀ àwọn ọmọdébìnrin tí ó fi di ohun tí gbogbo orílẹ̀ èdè àgbáyé gbà bí igbá ọtí:
Ní ọjọ́ 7 oṣù Èbìbí ọdún 2014, aya ààrẹ orílẹ̀-èdè Amẹ́ríkà ọ̀gábìnrin Michelle Obama ṣe àtẹ̀jáde àwòrán kan tí ó ti mú àmì “Ẹ dá àwọn ọmọdébìnrin wa padà” #BringBackOurGirls lọ́wọ́.
Bákan náà ni ó tari àwòrán-olóhùn kan láti inú Ilé Funfun síta — tí ìgbésẹ̀ yìí sì sọ ìṣẹ̀lẹ̀ ìjínigbé náà di ọ̀ràn tí gbogbo àgbáyé fẹ́ rí àbálọ-bábọ̀ rẹ̀.
Ọdún méjì ni ó gba àwọn ọmọ ogun orílẹ̀ èdè Nàìjíríà láti gba ọmọdébìnrin kan sílẹ̀, nínú oṣù Òkúdù ọdún-un 2016.
Nígbà tí ó máa fi di oṣù Ọ̀wàrà ọdún-un 2016, àwọn ọmọdébìnrin 21 darapọ̀ mọ́ àwọn mọ̀lẹ́bí wọn. Ní oṣù Èbìbí 2017, ikọ̀ Boko Haram dá àwọn ọmọdébìnrin 82 sílẹ̀ nínú ìgbẹ̀sìn.
Síbẹ̀síbẹ̀, ó tó ọmọdébìnrin 112 tí ó di àwátì bí abẹ́rẹ́ tí ó sì jọ pé àwọn 13 tí ṣègbé, ìyẹn gẹ́gẹ́ bí ìwádìí ọdún 2018 kan ṣe tọ pinpin.
Ezekwesili àti àjọṣepọ̀ àwọn ènìyàn kan ni ó dá ìgbésẹ̀ ìjà fún ẹ̀tọ́ àwọn ọmọdébìnrin #BBOG tí ó kó àwọn ènìyàn jọ lágbàáyé fún ìdásílẹ̀ àwọn ọmọdébìnrin Chibok.
Nígbà tí ó ṣe, ìgbésẹ̀ náà yírapadà di igi àràbà tí ẹnìkan kò leè ṣí nídìí tí ó fi ara da igbàgede ètò ìlú Nàìjíríà t'ó rorò.
Àmọ́ ṣá o, àṣeyọrí akitiyan yìí kò ṣẹ̀yìn-in ìnáwónára Ezekwesili.
Ní wéré kí ètò ìdìbò ààrẹ ọdún 2015 ó wá sáyé ni ìṣẹ̀lẹ̀ ìjínigbé àwọn ọmọdébìnrin Chibok ṣẹ̀, tí èyí sì mú kí àwọn kan ó máa fi ojú ìgbèlẹ́yìn ẹgbẹ́ olóṣèlú kan wo ìgbàwí tí Ezekwesili ń bá ká lórí ayélujára.
Bí wọ́n ti fi ojú òtítọ́ inú rẹ̀ gbolẹ̀ ni wọ́n fa gbogbo aṣọ iyìi rẹ̀ ya pẹ́rẹpẹ̀rẹ.
Àwọn mìíràn sọ wípé gbogbo kùkùgẹ̀gẹ̀ akitiyan #BBOG rẹ kò ju kí ó ba lẹ́nu nínú ìṣèlú lọ.
"Reno Omokri, olùrànlọ́wọ́ ààrẹ àná, fi ẹ̀sùn kan Ezekwesili wí pé ẹgbẹ́ olóṣèlú APC ni ó ń lò ó fi ba ìjọba tí ó wà lórí àpèré jẹ́ àti láti ""yẹpẹrẹ"" ìjọba Ààrẹ Jonathan, nípa èyí náà ni ó fi lànà fún APC láti ""gba ọ̀pá àṣẹ""."
"Ní ọdún-un 2014 àwọn alátìlẹ́yìn Ààrẹ àná ààrẹ Jonathan àti ẹgbẹ́ olóṣèlú Peoples’ Democratic Party (PDP) fi ""àwọn ọ̀kan-ò-jọ̀kan irọ́ "" léde ní orí ẹ̀rọ-ayélujára láti tako Ezekwesili. Dókítà náà sọ nínú àtẹ̀jáde àwòrán-olóhùn Twitter kan ti ọjọ́ 14, oṣù Igbe ní ìsààmì ọdún mẹ́fà tí àwọn ọmọdébìnrin náà ti di àwátì wí pé: “kí á má purọ́ wọ́n tàbùkù mi, wọ́n sì ṣe kèéta."
Àwọn ẹlẹ́nu èké sọ wí pé ìgbónára àì rí ipò nínú ìjọba Jonathan ló ń mú Ezekwesili tẹpẹlẹ mọ́ ìgbárùkù ti ọ̀ràn àwọn ọmọ tí ajínigbé jí gbé.
"Bí ó ti ṣe sọ, àwọn tí ó kọ ẹnu ẹ̀gbin sí i lórí ayélukára-bí-ajere lérò ""wí pé torí kí wọ́n ba fi òun j'òye mínísítà ni òun ò fi mẹ́nu kúrò lọ́ràn àwọn ọmọdébìnrin Chibok""."
Báwo ni yó ṣe jẹ́ bẹ́ẹ̀ lẹ́yìn tí mo kọ ipò mínísítà ní ọdún mẹ́ta sẹ́yìn kí àwọn ọmọdébìnrin Chibok ó tó di ìgbẹ̀sìn?
Ezekwesili wí nínú àwòrán-olóhùn Twitter náà.
Ó di ọ̀kan nínú àwọn òǹdíje sí ipò ààrẹ ọdún-un 2018, ṣùgbọ́n ó ju ọwọ́ sílẹ̀ nígbà ó yá.
"Ní orí Twitter, Ezekwesili mú ìbànújẹ́ rẹ̀ wá sí ìrántí: ""Ẹ̀dùn ọkàn ni fún mi pé àwọn ọmọdé tí a rán nílé ìwé di pípa bí ẹran dé ibi wí pé àwọn òbí wọn kò lè dá àwọn ọmọ wọn mọ̀ ""."
Àmọ́ ìṣààta ti olóṣèlú nípa ìgbésẹ̀ ìpolongo #BBOG ti gbé ìbínú tòun t'ìbánújẹ́ rẹ̀ mì.
#ArewaMeToo àti NorthNormal
Ní ọjọ́ 3, oṣù Èrèlé ọdún-un 2019, ọ̀dọ́bìnrin kan tí orúkọ rẹ̀ ń jẹ́ Khadijah Adamua gbójúgbóyà láti túwíìtì nípa ìlòkulò ajẹmára tí ọ̀rẹ́kùnrin rẹ̀ ìgbà kan lo òun.
Adamua, ẹni tí ó ń gbé ní ìpínlẹ̀ Kano tí í ṣe àríwá-ìlà-oòrùn orílẹ̀ èdè Nàìjíríà, ti ṣáájú kọ búlọ́ọ̀gù nípa ìrírí rẹ̀ tí ó banilẹ́rù.
Ọmọ Nàìjíríà rere Fakhriyyah Hashim túwíìtì àtìlẹ́yìn rẹ̀ fún Adamua pẹ̀lú lílo àmì #ArewaMeToo:
#ArewaMeToo di ẹ̀dà ìgbésẹ̀ Èmi Náà àgbáyé #MeToo ní àríwá Nàìjíríà. (Árẹ̀wá ni èdè-ìperí fún “Àríwá” ní èdè Haúsá) — tí ó tan ìjì àsọgbà ọ̀rọ̀ lórí ìfipábánilòpọ̀ àti irú àwọn ìwà-ipá sí àwọn obìnrin ní orí ẹ̀rọ ayélukára-wọn-bí-ajere.
Ìwà-ipá sí obìnrin wọ́pọ̀ jákèjádò orílẹ̀-èdèe Nàìjíríà. Síbẹ̀, Relief Web sọ wí pé ní àárín oṣù Belu ọdún-un 2014 àti oṣù Ṣẹẹrẹ ọdún un 2015, àríwá-ìlà-oòrùn Nàìjíríà, pàápàá jù lọ Ìpínlẹ̀ Borno, ní àkọsílẹ̀ ìwà-ipá sí obìnrin ti pọ̀ jọjọ.
Ní agbègbè àríwá tí àwọn Mùsùlùmí pọ̀ sí jù lọ, àsọgbà nípa orí ọ̀rọ̀ èèwọ̀ wọ̀nyí ṣòro, tí ó máa pàpà sọ àwọn tí ó ń jìyà ìpalára sì ìpa kẹ́kẹ́.
Ìbínú #ArewaMeToo ní orí ẹ̀rọ-ayélujára ṣe àtọ́nà ìyíde ìfẹ̀hònúhàn ìta gbangba NorthNormal ní Bauchi, Kano, àti Niger.
Ìyíde ọlọ́jọ́ mẹ́ẹ̀ẹ́dógún ti NorthNormal wá sáyé nínú oṣù Belu ọdún t'ó kọjá ní àwọn ìpínlẹ̀ mẹ́jọ ní òkè Ọya àti ní Abuja.
"Wọ́n rí ipa rere látàrí ìyíde tí àwọn aṣòfin ""sì rí ìdí tí ó fi yẹ kí àwọn gbọ́ sí àwọn ọ̀dọ̀ ìbílẹ̀ "" lẹ́nu torí wọ́n ń “lé iwájú nínú ìjà fún VAPP,” Hashim ṣàlàyé ọ̀rọ̀."
"Hashim tẹ̀síwájú wí pé,” síbẹ̀, ní Ìpínlẹ̀ Sokoto, ìjọba ń kó àwọn tí ó ń yíde NorthNormal""."
Àwọn ọlọ́pàá ṣe ọ̀kan lára àwọn olórí ìbílẹ̀ tí í ṣe alágbèékalẹ̀ ìyíde náà ṣìbáṣìbo.
Lẹ́yìn wá, ọba Sokoto, tí í ṣe olórí àwọn Mùsùlùmí orílẹ̀ èdè Nàìjíríà fagilé ìwọ́de.
"Gẹ́gẹ́ bí Hashim ti ṣe wí, NorthNormal súyọ láti ara àmì #ArewaMeToo, tí ó sì ní èta méjì: ìgbàwí fún ""ìṣàmúlò Ìfòfinde Ìwà-ipá sí àwọn Ènìyàn (VAPP)"", àti ìléwájú nínú ìtàkùrọ̀sọ ""onírúurú ìwà-ipá sí obìnrin àti àṣà ìfipábánilòpọ̀ jákèjádò àríwá Nàìjíríà""."
Àbà Òfin Ìwà-ipá sí Àwọn Ènìyàn (Ìfòfindè) ọdún-un 2015 di títọwọ́bọ̀ lọ́jọ́ 23, oṣù Èbìbí, ọdún-un 2015.
Lábẹ́ Àbá VAPP — ìlọsíwájú òfin ìjìyà ẹ̀ṣẹ̀ orílẹ̀ èdè Nàìjíríà — àbá ìwà-ipá sí àwọn obìnrin jẹ́ ẹ̀ṣẹ̀ lábẹ́ òfin.
Lára rẹ̀ ni ìfipábánilòpọ̀, nína aya, ìfipálé aya jáde nílé, ìfipá sọ obìnrin di adábùkátà gbọ́ tàbí ìjìyà ti ọrọ̀-ajé, àṣà opó tí ó ń fa ìpalára, dídábẹ́ fún obìnrin tàbí gígé ida, àti/tàbí ìkọ̀sílẹ̀ ọmọ.
Ní Nàìjíríà, ẹ̀wọ̀n gbére ni ìjìyà ìfipábánilòpọ̀. Ọmọdé lè fi ara gbá ẹ̀wọ̀n ọdún 14.
Bí ó bá jẹ́ ọ̀ràn ìfipábánilòpọ̀ ẹni púpọ̀, ẹ̀wọ̀n ọdún 20 ni àwọn ẹlẹ́sẹ̀ yóò fi gbára láì san owó ìtanràn.
Síbẹ̀, Abala 47 ti Àbá òfin VAPP fi lélẹ̀ wí pé Abuja, olú ìlú orílẹ̀ èdè Nàìjíríà nìkan ni òfin yìí ti f'ẹsẹ̀ rinlẹ̀. NorthNormal àti àwọn iléeṣẹ́ mìíràn ti ń polongo kí gbogbo ìgbìmọ̀ aṣòfin ìpínlẹ̀ 36 ó sọ àbá yìí d'òfin.
Àtakò àwọn alágbàwí
Ọdún kan lẹ́yìn tí #ArewaMeToo gba ìgboro, Hashim sọ fún Ohùn Àgbáyé wí pé adi ìgbàwí wọn tí ó tú “ìbàjẹ́ àwùjọ jáde,” ó sì tún ní arapa tirẹ̀.
"Hashim ní ìrírí ìyọlẹ́nu lórí ayélujára nígbà tí ẹgbẹ́ rẹ̀ kojú ""ẹnìkan tí ó máa bá àwọn ọmọdé lò ní ṣísẹ̀ntẹ̀lé kiri àdúgbò"" ẹni tí ó ń ṣiṣẹ́ ní iléeṣẹ́ ìṣúná-owó gẹ́gẹ́ bí ìgbàwí orí ayélujára wọn."
Ó sọ fún Ohùn Àgbáyé:
A ṣe ìfilọ́lẹ̀ ìpolongo tako rẹ̀ [abọ́mọdé sùn], kí ó bá gba ìwé ìyọniníṣẹ́ láti ọwọ́ mínísítà; àwọn kan kò fẹ́ bẹ́ẹ̀ torí ìdí èyí ni wọ́n ṣe gbé ìgbésẹ̀ ìpolongo ìyọlẹ́nu orí ayélujára láti sọ #ArewaMeToo di èyí tí ó lòdì sí òfin.
Gẹ́gẹ́ bí Hashim ṣe sọ, àwọn ayọnilẹ́nu gbèrò láti sọ ArewaMeToo di ohun tí ó tasẹ̀ àgẹ̀rẹ̀ sí òfin nípa síso ArewaMeToo pọ̀ mọ́ LGBTQ [obìnrin-tó-ń-fẹ́-obìnrin, ọkùnrin-tí-ó-ń-fẹ́-ọkùnrin, àwọn abo àti akọ tí ó yíra padà di akọ tàbí abo àti àwọn ènìyàn tí ó ṣe àjèjì tí kò sí ní ìbámu] àti ète wọ́n ṣiṣẹ́ bí ìyọlẹ́nu orí ayélujára ṣe ń lékún sí i.
Ní orílẹ̀ èdè Nàìjíríà, ìgbéyàwó láàárín ọkùnrin àti ọkùnrin lòdì sófin bẹ́ẹ̀ náà ní abẹ́ òfin Sẹ́ríà àti òfin ìfìyàjẹ ẹlẹ́sẹ̀, ìbálòpọ̀ ihò ìdí àti ìbálòpọ̀ láàárín obìnrin àti obìnrin ní ìjìyà ní àwọn ìpínlẹ̀ kan.
Nípasẹ̀ dída ìgbésẹ̀ ìpolongo Hashim papọ̀ mọ́ ẹ̀tọ́ LGBTQ, àwọn ènìyàn ní orí ẹ̀rọ-ayélujára lọ́ ìpolongo wọn po wọ́n sì pe #ArewaToo àti NorthNormal ní ohun tí kò tọ́.
Bí-ó-ti-wù-kí-ó-rí, Ohùn Àgbáyé kò rí àyè sí àwọn túwíìtì tí ó sọ ìgbésẹ̀ ìpolongo Hashim ní ìjà fún ẹ̀tọ́ LGBTQ.
Síbẹ̀, Hashim ṣe àtẹ̀jáde àwọn ọ̀rọ̀ ìrètí sí orí Twitter:
Fakhriyyah Hashim, ọ̀kan lára àwọn olùdásílẹ̀ #ArewaToo àti NorthNormal (a gba àṣẹ láti lo àwòrán rẹ̀.
Ó sọ wí pé gbogbo ìrírí yìí ran òun lọ́wọ́ láti “ní ìfarada tí ó pọ̀”:
Ìrírí mi nípa ìgbóhùnsókè lórí ọ̀rọ̀ òṣèlú ní orí Twitter fún ìṣèjọba tí ó dára, ti kọ́ mi ní ìfaradà, àmọ́ ìyẹn kò mú mi gbaradì fún ọ̀kan-ò-jọ̀kan ìtakò tí a fojú rí látàrí ìpolongo ArewaMeToo àti NorthNormal.
Àmọ́pé mo fi gbogbo rẹ̀ ṣe osùn mo fi para n ò sì jẹ́ kí ó fà mí sẹ́yìn, mo bẹ̀rẹ̀ sí ní í ní ìrẹ̀wẹ̀síọkàn nípa ìṣèjọba Àríwá orílẹ̀ èdè Nàìjíríà àti bí wọ́n ṣe fi ọwọ́ mú ìwà ìfipábánilò...
Lẹ́yìn ìkọlù kọ̀ọ̀kan, a máa ń ní okun àti agbára láti tẹ̀síwájú nítorí ìtakò mú wa rí bí àṣà ìdákẹ́ rọrọ ti ṣe rinlẹ̀ tó ní àwùjọ àti pé bí a bá fi àyè gba ìpanumọ́, a jẹ́ wí pé oko ìparun ni à ń fi orí lé.
Ó ṣeni láàánú, Hashim àti Ezekwesili ṣì ń janpata pẹ̀lú ìyà “àìsí àánú ọmọlàkejì” tí ó dìrọ̀ mọ́ ọ̀ràn ìwà ìjìyà àwọn obìnrin lórí ayélujára àti lójú ayé tòótọ́.
"Ní ti Hashim, ""ìmọ̀ọ́mọ̀ ṣààta ìgbésẹ̀ tí ó ń gbèrò láti fi ohùn fún àwọn tí ó ń jìyà ìfarapa"" nira láti gbá mú."
"Àròkọ yìí jẹ́ ọ̀kan lára àkànṣe iṣẹ́, ""Orísun ìdánimọ̀: òfin gbàgede orí ẹ̀rọ-ayélujára bí ajere tí ń gbégi dínà ìdàgbàsókè ọ̀rọ̀ sísọ ní Ilẹ̀ Adúláwọ̀""."
Àtẹ̀jáde yìí ṣe ìbéèrè ipa ìdánimọ̀ ọ̀rọ̀ ìkórìíra tẹ̀gbintẹ̀gbin tàbí ìyàsọ́tọ̀ọ̀tọ̀ tí ó dá fìrìgbagbòó lórí èdè tàbí agbègbè ilẹ̀ ayé, àṣìwífún àti ìyọlẹ́nu (pàápàá jù lọ ìyọlẹ́nu àwọn ajàfẹ́tọ̀ọ́ ọmọnìyàn àti akọ̀ròyìn l'óbìnrin) lórí ẹ̀rọ ayélujára bí ajere tí ó wọ́pọ̀ ní orílẹ̀ èdè Ilẹ̀ Adúláwọ̀ méje: Algeria, Cameroon, Ethiopia, Nigeria, Sudan, Tunisia àti Uganda.
Africa Digital Rights Fund ti Collaboration on International ICT Policy for East and Southern Africa (CIPESA) ni ó kówó fún à kànṣe iṣẹ́ yìí.
Ní àwọn ìlú tí ó wà lábẹ́ ìsàkóso Assad ní ilẹ̀ Syria, àwọn alákòóso sọ báyìí pé ‘kò sí ìṣẹ̀lẹ̀ ààrùn kòrónà kankan’
Lẹ́yìn ọdún mẹ́sàn-án ogun abẹ́lẹ́ tó gbóná girigiri, ètò ìlera ní orílẹ̀-èdè Syria ò ṣe bẹ́ẹ̀ gbópọn mọ́.
Ní àwọn ìlú tí ó wà lábẹ́ ìsàkóso Ààrẹ Bashar al-Assad, àwọn Aláṣẹ wọn ti tako ìṣẹ̀lẹ̀ ààrun COVID-19.
Gẹ́gẹ́ bí Fáfitì John Hopkins ̣ sọ, Orílẹ̀-èdè ọ̀hún ti sàwárí ìsẹ̀lẹ̀ Òjìlénírinwó-dínkan pẹ̀lú ikú ènìyàn mọ́kànlélógún títí di ọjọ́ kẹẹ̀ẹ́dógún osù Agẹmọ.
Ṣùgbọ́n àwọn ìròyìn tí ó wà nílẹ̀ báyìí tí ṣe àfihàn bí ilẹ̀ náà ṣe takú wọnle tí wọ́n sì ń ṣẹ́ ìdánilójú pé ààrùn COVID-19 wà lóòótọ́.
Walid Abdullah ọmọ ọdún mẹ́tàlélógún, sọ ọ́ di mímọ̀ pé ìlẹ̀ yìí tilè ṣe é débi pé wọ́n ń dába gbígba ẹ̀mí àwọn aláàárẹ̀ tí wọ́n bá funra sí pé wọ́n ní COVID-19.
Ohùn Àgbáyé ń lo orúkọkórúkọ láti dààbò bó.
Nínú ìtàkùrọsọ pẹ̀lú Ohùn Àgbáyé lórí ago, Abdullah ṣe é ní àlàyé pé ní ọjọ́ kẹtàlá ọsù èbìbí, òun pé Ilé ìwòsàn Àpapọ̀ ti Daraa ní ìha Gúúsù ilẹ̀ Syria láti fi ìṣẹ̀lẹ̀ ààrun kòrónà kan tó wọn létí.
"Gẹ́gẹ́ bí Abdullah ṣe sọ, nígbà tí ó bèèrè ìgbésè tí ó yẹ ní gbígbé, òṣìṣẹ́ ìjọba tí ó gbé ìpè náà sọ pé "" Yìnbọn pà á, a kò ní ìwòsàn fún"""
Ó yára fi òpin sí ìpè náà.
Dájú, kò sí ọ̀rọ̀ nínú yíyin ìbọn pa ẹni tí a fura sí pé ó ní àrun COVID-19.
"Abdullah sọ fún Ohùn Àgbáyé ""Ikú nípasẹ̀ COVID-19 sàn ju dídá ẹsẹ̀ wọ ilé ìwòsàn ìjọba lọ"""
Èrí ìbanilọ́kanjẹ́ eléyìí tún kín in lẹ́yìn láti àwọn orísun mìíràn.
"Àtẹ̀jáde ọjọ́ kẹwàá, oṣù Ẹrénà kan ti The Voice of the Capital, Iwé ìròyìn Olómìnira kan ní ilẹ̀ Syria sọ di mímọ̀, pé àwọn elétò ìlera láti Ilé-iṣẹ́ Ètò Ìlera ilẹ̀ Syria sọ pé ""Iṣẹ́ Ìmọ̀-ọ́n-mọ̀ṣekúpani ń wáyé ní ilé ìwòsàn ìjọba Al-Mujtahid ní olú ìlú ilẹ̀ náà, Damascus, fún àwọn tí wọ́n ní ìgbàgbọ́ pé wọ́n ní àrùn ọ̀hún ní tòótọ́, nípa fífún wọn ní àpọ̀jù oògùn tí ó máa ń rani níy""è."
Èyí pẹ̀lú fi ara hàn ní orí ìkànnì alátagbà:
Ẹlòmìíràn láti ilé ìwòsàn Mouwasat ni Damascus ni ọ̀rọ̀ rẹ̀ tún jẹ́ dídì mọ́ ọwọ́ nínú àtẹ̀jáde kan náà tí ó sọ pé:
Iṣẹ́ Ìmọ̀-ọ́n-mọ̀ṣekúpani ń wáyé ní ibi kọ́lọ́fín pátápátá, àwọn dókìtà tí wọ́n ṣe iṣẹ́ ìtọpinpin àrùn ọ̀hún ni wọ́n sì ń ṣe é.
Ìgbésẹ̀ sáà ìṣèjọba Assad sí ìdẹ́kun àrùn COVID-19 yìí burú jáì, ó fi ara jọ ète tí wọ́n lò nígbà Ogun abẹ́lé Assad tí ó gba èmí ènìyàn tí ó lé díẹ̀ ní mílíọ̀nù, tí Ẹgbẹ̀rún lónà ọgọ́rùn-ún tí ó wà látìmọlé parẹ́ síbẹ̀, tí mílíọ́nù márùn-ún àbọ̀-ó-lẹ́ sì di ogunléndé káàkiri àwọn orílẹ̀-èdè àgbáyé.
Ìbẹ́sílẹ̀ Àjàkálẹ̀ Àrùn àti Ìtèsíwájú Ìsèjọba
Sáà ìṣèjọba Assad yìí ti sọ ọ̀pọ̀lọpọ̀ àwọn ìlú tí ó yí i ká sínú ìdààmú tí ó fi mọ́ orílẹ̀-èdè Iran náà, pẹ̀lú bí ó ṣe jẹ́ pé ilẹ̀ Syria ni ọ̀pọ̀lọpọ̀ àwọn ìlú tí ó yí i ká fi ń mí.
Ní osù Èrèlé, Orílẹ̀-èdè Iran di ọ̀kan nínú àwọn orílè-èdè tí Covid-19 ti ṣọṣẹ́ jùlo, ìbi tí ààrùn náà gbà wọ ilẹ̀ wọn ni ó ṣeéṣe kí ó jẹ́ Lebanon, Iraq àti Syria, níbi tí ìfarayíra ti ṣelẹ̀ nípasẹ̀ àjọṣepọ̀ àwọn Ológun.
Ní àfikún, àwọn Arìnrìnàjò-ẹ̀sin àti àwọn Arìnrìnàjò-ìgbafẹ́ láti Iran náà tẹ̀síwájú láti máa ṣe àbẹ̀wọ̀ sí àwọn ojúbọ ní Damascus títí di ọ̀ṣẹ̀ kíní osù ẹrénà (march) gẹ́gẹ́ bí Zaki Mechy tí ó jẹ́ ara àwọn Òǹkòwé March Study ti London School of Economics and Political Science (LSE) ṣe sọ.
Síbẹ̀, Ìṣèjọba Assad ń tẹpẹlẹ mọ́ sísọ òfegè ìròyìn àti irọ́ lórìṣirísi bẹ́ẹ̀ ni ó tún ṣe àdínkù iye àwọn ènìyàn tí wọ́n ti ní COVID-19.
Ní ìfọ̀rọ̀wánilẹ́nuwọ̀ pẹ̀lú ẹ̀ka ìròyìn ìjọba ilẹ̀ Syria ní ọjọ́ kẹtàlá Osù Ẹrẹ́nà, Mínísítà ètò ilera ilẹ̀ náà Nizar Al-Yaziji kọ̀jálẹ̀ lórí pé kò sí ìṣẹ̀lẹ̀ COVID-19 ní ilẹ̀ Syria, ó sọ pé:
"A dúpé̩ ló̩wó Ọló̩run pé àwọn È̩ka Ológun ti fọ ilè̩ Syria mó kúrò ló̩wó̩ àrùnkárùn:”
Mínísítà ètò ìlera ilè̩ Syria kò tilè̩ kéde ìṣè̩lè̩ ààrùn COVID-19 àkó̩kó̩ ilè̩ náà títí di ọjó̩ kejìlélógún Osù Ẹré̩nà (March 22), èyí si ń fa ìbínú àti ìtutọ́sókè fojú gbà á ní àárín àwọn ọmọ ilẹ̀ Syria tí wọ́n ṣe àkíyèsí pé ìṣèjọba Assad ń parọ́, ó si ń tako ìròyìn ododo.
Nínú ìwé àpilẹ̀kọ tí wọ́n fi sí orí ẹ̀rọ alátagbà-oníròyìn kan ní ilẹ̀ náà, ọ̀kan nínú àwọn ará ìlú fèsì sí ọ̀rọ̀ Yaziri, ó sọ pé “ṣé o kò sọ nínú ọ̀rọ̀ rẹ tẹ́lẹ̀ pé gbogbo àrùn ni ó ti jẹ́ fífọ̀ kúrò ni"
Síbẹ̀ náà ìṣèjọba yìí ti bẹ̀rẹ̀ sí ní sí ṣe àdíkù òǹkà iye àwọn tí wọ́n ní àrùn náà nínú àtẹ̀jáde wọn.
Nínú àtẹjáde kan tí ọjọ́ kíní osù Igbe Àjọ tí ó pè fún Àtúnṣe Ìṣejọba Syria àti àwọn Ẹgbẹ́ Alátakò késí àwọn orílẹ̀-èdè àgbáyé láti fíná mọ́ ìṣejọba ọ̀hún, pé kí wọn ó gbé òótọ́ òǹkà iye àwọn tí wọ́n ní àrùn COVID-19 jáde.
Ó gbé èrò rẹ̀ jáde lórí iye tí ó yẹ kí ó jẹ́ òótọ́, àjọ náà kọ báyìí pé:
Ètò ìlera tí ó ti dẹnu kọlẹ̀
Gbígbà pé àjàkálẹ̀ ààrun yìí wà lóòótọ́ bu ìsejọba Assad kù nítorí pé òhun ni yóò jẹ́ kí àwọn aláṣe wọn ó fi tipá gbà lóòtọ́ pé wọn kò ní èka ètò ìlera.
Gẹ́gẹ́ bí London School of Economics and Political Science (LSE) ṣe sọ, àpapọ̀ iye àwọn aláàárẹ̀ COVID-19 tí wọ́n le wò ní ilẹ̀ náà kò ju ẹgbẹ̀rún mẹ́fà ààbọ̀ lọ (6500) nínú ọ̀gọ̀rọ̀ èníyán tí ó tó mílíọ̀nù mẹ́tàdínlógún àbọ̀ tí ó ń gbé ní ilẹ̀ náà.
Ó ní bí iye àwọn aláàrẹ́ bá ti ju iye yìí lọ, ipá orílè-èdè náà ti pin nìyẹn, omi sì le tẹ̀yìn wọ̀gbín lẹ́nu.
Ní àsìkò ogun abélé náà, àwọn ológun ti ṣe ìkọlù tí ó lágbára sí ẹ̀ka ètò ìlera wọn.
Àkọsílẹ̀ láti ọdọ̀ Àjọ́ WHO àti Ilé-iṣẹ́ ètò ilera ilẹ̀ Syria sọ ọ́ di mímọ̀ pé méjìdínlọ́gọ́ta nìkan ni ètò iṣẹ́ rẹ̀ pé nínú ilé ìwòsàn ìjọba ọ̀kànléláàádọ́fà tí ó wà ní ilẹ̀ náà.
Àkọsílẹ̀ yìí tún fi hàn pé ó tó ìdá àádọ́rin nínú ọgọ́rùn-ún àwọn òṣìṣẹ́ elétò ìlera ilẹ̀ náà tí wọ́n ti kúrò láti di àtìpó àti ogúnléndé sí ilẹ̀ ibòmìíràn.
COVID-19 wà lára àjálù tí ó ń kujú ọmọnìyàn
Ó ṣeéṣe kí ó jẹ́ pé ohun tí ó jẹ́ ìdojúkọ àwọn ọmọ ilẹ̀ Syria jùlọ ni bí àwọn àjálù yìí ṣe rọ́ lu ara wọn; ogun, àjàkálẹ̀-àrùn àti iyàn.
Àjọ Ìsọkan Àgbáyé ṣe ìkìlọ̀ ní ọjọ́ kẹrìndínlọ́gbọ̀n osù Okudù pé Syria ń fojú winá ebi àpafẹ́ẹ̀ẹ́kú, ìgbẹ́sẹ̀ níkíá sì nílò láti dèènà ìtànkálẹ̀ COVID-19
Gẹ́gẹ́ bí Àjọ Elétò Ounjẹ Àgbááyé ṣe sọ, òwọ́ngọ́gọ́ bá ounjẹ pẹ̀lú ìdá mọ́kànlá iye rẹ̀ tẹ́lẹ̀ ní oṣù Èbìbí yàtọ̀ sí ti oṣù Igbe, ó sì wọ́n sí i ní ìwọ̀n mẹ́tàléláàádóje nígbà tí wọ́n gbé e wò sí ti ọdun 2019.
"Gẹ́gẹ́ bí ètò ọrọ̀ ajẹ́ wọ́n ṣe dẹnukọlẹ̀. Ali al-Ahmed (orúkọkórúkọ ni èyí náà, gẹ́gẹ́ bí ẹni yìí ṣe bèèrè fún ìdáàbòbò orúkọ rẹ̀) láti ìlu Daraa sọ fún Ohùn Àgbáyé ní orí ago pé ""nǹkan burú jáì, kò sí irú iṣẹ́ tí o lè ṣe, kódà kí wọn ó máa san Egbẹ̀rún mẹ́wàá owó ilẹ̀ Syria (láàrin Dọ́là kan sí márùn-ún) fún ènìyàn, kò le tóó ná""."
Ahmed ní ọ̀pọ̀ àwọn ẹrù ni àwọn ènìyàn ti kọ̀ sílẹ̀ láìgbà látàri ọ̀wọ́ngógó owó ìgbẹrù.
Lásìkò tí ètò ìlera wọn ti dẹnikọlẹ̀ yìí látàari ewu ogun tí ó wu wọ́n tí ètò ọ̀rọ̀ ajé tí ó forí sánpọ́n sì ti sọ ọ̀pọ̀ ọmọ ilè Syria di Akúṣẹ̀ẹ́, Àjàkálẹ̀ ààrùn tí ò jà kiri yìí tún ti ti ìlú yìí sínú ewu àìkàsí àti ìdibàjẹ́.
Ìdánowò YKS ń lọ lọ́wọ́ pẹ̀lú mílíọ́nù méjì àbọ̀ akẹ́kọ̀ọ́ ládúrúu gbogbo ìkìlọ̀: Ìjìnàsíra-ẹni láwùjo gan-an di àwátì.
Àìgbọ́raẹniyé Ìdànwò YKS tuntun: ìwà rere
Kì í ṣe COVID-19 nìkan ni famínfà tí ó yí Ìdánowò YKS ká ní ọdún 2020.
Ọ̀pọ̀lọpọ̀ àwọn ọ̀rọ̀ ló ti ń jà rànhìnrànhìn láti ìbẹ̀ẹ̀rẹ̀ oṣù keje èyí tí ó nííṣe pẹ̀lú ìwé àyọkà fún ìdánwò èdè Turkish.
Ọ̀kan nínú àwọn ìbéèrè abẹ́ rẹ̀ tọ́ka sí “Fırtınadayım, (mo wà nínú ìjì), orin olórin tàka-n-súfèé kan Mabel Matiz ọmọ ẹgbẹ́ LGBTQ.
Ìbéèrè lórí ìtumọ̀ “Gözümün gördüğü, göğsümün bildiği ile bir değil” (tí a le tú sí ohun tí ojú mi rí kọ́ ni ohun tí aya mí mọ̀) ti ń da àwọn ìkànnì àwùjọ rú gùdùgùdù nítorí Mabel jẹ́ ẹni tí àwọn ọdọ́ mọ̀ bí ẹni mọ owó (Ọ̀pọ̀ àwọn fọ́nrán rẹ̀ ní ó máa ń ní olùwò tí ó tó àádọ́ta mílíọ́nù) àti ìṣe rẹ̀ lórí àwọn ohun tí ó jẹmọ́ akọ àti abo.
Ní ìbámu pẹ̀lú fàmínfà orí ìkànni Twitter, Halis Aygün Ààrẹ Center for Measurement, Selection and Placement (ÖSYM), ẹ̀ka ìjọba tí ó bójú tó ìṣètò ìdánwò sọ nínú ìfọ̀rọ̀wánilẹ́nuwọ̀ pẹ̀lú àgbà òṣìṣẹ́ ìròyìn kan, Yeni Akit. Níbẹ̀ ni ó ti sọ pé wọn yóò ṣe ìwádìí ọ̀rọ̀ náà, gbogbo àwọn tí wọ́n bá sì lọ́wọ́ nínú fífi ìwé náà si abẹ́ ìdánwò ọ̀hún ni wọ́n yóò lé kúrò lẹ́nu iṣẹ́.
Ìdánwò YKS ọdún 2020 kẹ́sẹ járí kákàkiri àwọn ibùdó ìdánwò méjìdínnígbà (188) ní ìṣí ẹ̀ẹ̀mẹta, tí àwọn akópa nínú rẹ̀ sì ń lọ bíi mílíọ́nù méjì àbọ̀.
Àwọn ìdánwò rẹ̀ jẹ́ èyí tí àwọn onímọ̀ akadá káàkiri àwọn fáfitì orílẹ̀-èdè wa ṣètò.
Ìkíyèsí àwọn ẹ̀kọ́ ilé àti ọgbọ́n ìbágbépò láwùjọ fùn àwọn ilé-ìwé gíga wa máa ń jẹ́ kíkíyèsí.
Wọ́n ti fi ìdí ìwádìí lọ́lẹ̀ lórí àkóónú àwọn ìbéèrè tí ó nííṣe pẹ̀lú ìdánwò èdè Turkish ti ìdánwò YKS ọdún 2020 [èyí ká ọ̀kan nínú àwọn abala ìdánwò YKS].
Àwọn òṣìṣẹ́ tí èyí bá ṣí mọ́ lórí ni wọn yóò di gbígbọ́n dànù kúrò nínú ìṣètò ìdánwò.
Fún àwọn asàmúlò ìkànnì Twitter kan, ìdájọ́ yìí kò tó:
[Òkè] Ààrẹ ÖSYM sọ̀rọ̀ fún ìgbà àkọ́kọ́ lẹ́yìn ìdánwò! “
Wọ́n ti fi ìdí ìwádìí lọ́lẹ̀ láti wo ibi tí ìṣòro náà ti wọ́wá.
Àwọn tí wọ́n bá lọ́wọ́ nínú rẹ̀ yóò di gbígbọ́n dànù kúrò nínú ìṣètò ìdánwò.”
[Ìsàlẹ̀] Kò tó [lá ti yọ ọ́] nìkan, Ààrẹ tí kò ka nǹkan sí náà gbọdọ̀ jẹ́ yíyọ kúrò nínú ìṣàkósọ gbogbo kí ojú rẹ̀ le wálẹ̀.
Ọ̀wọ́ àwọn alẹ́nulọ́rọ̀ láwùjọ náà tún rí wí sí ìpinnu àti ṣètò irú ìbéèrè báyìí:
Nínú ìdánwò YKS2020 tí ó wáyé lónìí, ẹ kò rí ẹlòmìíràn fi ṣe àpèjúwe fún àwọn ọmọdé wọ̀nyí àfi ọkùnrin oníbálòpọ̀-akọsíakọ nnì Mabel Matiz
(Ènìyàn tí ó gbé àkólé tí ó fi ń polongo pé “Oníbálòpọ̀-akọsíakọ ni àwa” Kí ni ẹ̀ ń gbìyànjú láti ṣe?
Èrò àwọn aṣàmúlò ìkànni Twitter kò ṣọ̀kan pẹ̀lú bí àwọn mìíràn ṣe ń tọ́ka sí àwọn àṣeyọrí Mabel Matiz àti bí ó ṣe lókìkí sí:
Èyin ọmọ ìgbìmọ̀ aṣèwádìí. Mo fẹ́ kí ẹ wo àwọn fọ́nrán Mabel Matiz. Nítorí pé a kò ní eléré mìíràn tí ó ti ṣe àmúlò àṣà wa tó báyìí ní ọ̀pọ̀ ọdún sẹ́yìn. Ìdí nìyẹn tí mabelmatiz ṣe jẹ́ ìsúra wa.
Àwọn netizen pé àkíyèsí sí i pé fífi ojú sun olórin tí ó jẹ́ oníbálòpọ̀-akọsíakọ, àwọn olóṣèlú yóò pa àwọn ọ̀rọ̀ tí ó ṣe kókó tì:
Kò sí ẹni tí ó figbe ta lórí àwọn afipábánilòpọ̀, síbẹ̀ ìwádìí Mabel Matiz ni wọ́n ń gbà bí ẹni ń gba igbá ọtí.
Ẹ sọ pé “ìdààbò bo ìṣe wa” ṣùgbọ́n Mabel Matiz ni ẹni tí ó ṣe ìgbéjáde àṣà wa jùlọ.
Ó wa yẹ kí ìwádìí ó dá lé àwọn èyí tí ó tàbùkù Mabel Matiz tí wọ́n sì ṣẹlẹ́yàmẹ́yá rẹ̀.
Èsì Mabel Matiz sí àìgbọ́raẹniyé náà.
Ní ọjọ́ kẹta oṣù keje, bí fàmínfà náà ṣe ń gbóná sí i, Matiz padà la ohùn:
Ẹ ǹlẹ́ o:) Inú mi dùn pé orin mi jẹ́ lílò fún irú ìdánwò pàtàkì bí èyí.
Ní báyìí, ìyàlẹ́nu lójẹ́ fún mi bí ìgbéayé mi ṣe di ohun tí ó kan ìdánwò tí à ń sọ yìí.
Ẹ wo ohun tí a fi dán mi wò..bí a ṣe gbé ààmi kan ní ìfẹ̀gbẹ́kẹ̀gbẹ́ pẹ̀lú orúkọ mi.
Kò burú, Ìdánwò ayé kò lópin:) Iyán tún di àtúngún wàyí.
Mo ka ọ̀pọ̀lọpọ̀ àwọn àtẹjáde tí ó ṣègbè lẹ́yín mi.
Òhun tí mo fẹ́ sọ nínú orin yẹn yémi, mó nímọ̀ pé ó yé ẹ̀yin náà, ara mi sì tún yá gágá sí i.
N ó tẹ̀síwájú láti máa kọ orin sí i, láti máa sọ ìtàn àti láti jẹ́ ọmọ orílẹ̀-èdè yìí.
Ká tún pàdé nínú ìdánwò mìíràn…
Matiz sì lókìkí síbẹ̀: lẹ́yìn ọjọ́ kan tí Aygun sọ̀rọ̀ sáfẹ́fẹ́.
Ó gba àmì-ẹ̀yẹ méjì nínú ìdíje àmì-ẹ̀yẹ kan nípasẹ̀ ìbò tí ó pọ̀jù.
Ó gba àmì-ẹyẹ ipele méjì.
“Orin tí mùṣèmúṣè rẹ̀ dá múṣé jùlọ” àti “Olórin ọkùnrin tí mùṣèmúṣè rẹ̀ dá múṣé jùlọ” ní ìdíje àmìẹyẹ Pantene Golden Butterfly ẹlẹ́ẹ̀kẹrìndínláàádọ́ta irú rẹ̀.
Èyí fi hàn pé ọ̀pọ̀ ènìyá̀n ni wọ́n wà lẹ́yìn rẹ tako ọ̀rọ̀ ìbálòpọ̀-akọsíakọ tí ìjọba àti àwọn alẹ́nulọ́rọ̀ tí ìjọba ń sọ.
Ní ọjọ́ karùn oṣù keje, Mabel Matix tún túwíìtì:
Mo gba àmì-ẹyẹ “Fọ́nrán orin tí mùṣèmúṣè rẹ̀ dá múṣé jùlọ” àti “Olórin ọkùnrin tí mùṣèmúṣè rẹ̀ dá múṣé jùlọ” nínú ìdíje àmì-ẹyẹ Pantene Golden Butterfly ẹlẹ́ẹ̀kẹrìndínláàádọ́ta irú rẹ̀
. Inú mi dùn! Ẹ ṣé gan ẹ̀yin olùgbọ́ mi gbogbo. Màá fẹ́ láti dúpẹ́ lọ́wọ́ Erhan Arik àti DOP Meryem Yavuz. Àwọn tí wọ́n darí fọ́nrán [orin mi] “I Have a Red in My Wipe” tẹ́lẹ̀.
Ní orílẹ̀-èdè Turkey, ẹgbẹẹgbẹ̀rún méjì àbọ̀ àwọn akẹ́kọ̀ọ́ ni wọ́n jókòó ṣe ìdánwò ìgbaniwọlẹ́ sí Ifásitì
Ìdánwò ọdún yìí wáyé nínú àìgbọ́raẹniyé—àti pé kì í ṣe nítorí àjàkálẹ̀
Àtẹ̀jáde ìtúmọ̀ 15 Ògún 2020 8:07 GMT
Àwòrán ojú ìwò àwòrán-olóhùn orí YouTube ti orin kan láti ọwọ́ Mabel Matiz pẹ̀lú ọ̀rọ̀ orin náà ní àárín àìgbọ́raẹniyé tí ó súyọ látàrí Ìdánwò Ìgbaniwọlé sí Ilé Ẹ̀kọ́ Gíga (YKS):
"Gözümün gördüğü, göğsümün bildiği ile bir değil (ohun tí ojú mi rí kọ́ ni ọkàn mi mọ̀ "")"
Ní orílẹ̀-èdè Turkey, orílẹ̀-èdè tí ó lé ní ẹgbẹẹgbẹ̀rún mẹ́tàlélọ́gọ́rin ènìyàn (83 million), ènìyàn ní láti peregedé nínú ìdánwò ìgbaniwọlé tí wọn ń pè ní Yükseköğretim Kurumları Sınavı ní èdè ilẹ̀ Turkey láti wọlé sí Fáfitì.
Pẹ̀lú bí àjàkẹ́lẹ̀ COVID-19 ṣe ń jà rànhìn rànhìn, ìdánwò yìí sì jẹ́ ṣíṣe lójútáyé, ẹgbẹẹgbẹ̀rún méjì àbọ̀ ènìyàn (2.5 million) ni wọ́n jókòó ṣe ìdánwò náà.
Ní ọjọ́ 26 osù Kẹta, àjọ àwọn ilé-ìwé gíga ilẹ̀ náà kéde ọjọ́ ìdánwò YKS yìí gẹ́gẹ́ bi ọjọ́ 25 sí ọjọ́ 26 oṣù Keje.
Ṣùgbọ́n ní ọjọ́ 4 oṣù karùn-ún, Ààrẹ ilẹ̀ Turkey Recep Erdoğan yí ọjọ́ náà sí ọjọ́ 27 sí ọjọ́ 28 oṣù Keje.
Àyípadà yìí àti àìdájú ìdánwò yìí ti ń kọ àwọn ènìyàn ilẹ̀ Turkey lóminú, ní ààrín ìgboro ìlú àti ní orí àwọn èrọ alátagbà lórí pé:
Báwo ni ọjọ́ yíyí ṣe ní ipá lórí ìrònú àwọn akẹ́kọ̀ọ́ tí wọn ń múra sílẹ̀ de ìdánwò láti bí osù mélòó kan?
Báwo ni àwọn àlàkalẹ̀ àti òfi ìdèènà ìtànkálẹ̀ COVID-19 yóò ṣe di títẹ̀lé (Jíjìnnà síra ẹni láwùjọ, ìwọn ìgbọ́nà/tutù, ìlò ạṣọ ìbomú) bí a bá ń kó ènìyàn tí ó tó mílíọ́nù méjì àbọ̀ papọ̀.
Ní ọdún 2019, ìdá mẹ́rìnléláàádọ́rin ó lé díẹ̀ ni àwọn olùṣèdánwò tí wọ́n pegedé nínú ìdánwò náà, nígbà tí ìdá mọ́kàndínlógójì pegedé sí ìpele ìkejì ìdánwò náà.
Orílẹ̀-èdè Turkey ṣe àkọsílẹ̀ ìṣẹ̀lẹ̀ COVID-19 àkọ́kọ́ wọn ní ọjọ́ 11 oṣù kẹta ọdún, ní ìgbà tí ó fi máa di ọjọ́ 15 oṣù keje ẹ̀nìyàn ẹgbẹ̀rún márùn-ún àbọ̀ ti pàdánù ẹ̀mí wọn sí ọwọ́ ààrùn náà bẹ́ẹ̀ sì ni iye ènìyàn tí ó ti ní ààrùn náà ti lé ní igba ẹgbèrún.
Ní ọjọ́ 1 oṣù keje, Ìjọba gùnlé àwọn ìgbéṣẹ̀ ìdẹ́kun lóríṣiríṣi:
Àwọn ilé oko-òwò bi ilé ounjẹ, àwọn oko òwò ẹ̀rọ ayélujára, ilé ìṣàfihàn eré, gbọ̀ngàn ạyẹyẹ ìgbeyàwó tí wọ́n tì pa fún bíi oṣù mẹ́ta ni wọ́n ti tún ṣí padà báyìí, àmọ́ ṣá pẹ̀lú àtẹ̀lé ìjíjìnà síra ẹni láwùjọ.
Àwọn olùbẹ̀wò báyìí nílò láti máa bo imú wọ, wọn yóò sì máa ṣe àyẹ̀wò ìgbóná/tutù wọn.
Bí àwọn akẹ́kọ̀ọ́ tilẹ̀ fi ìpè síta pé kí ìdánwò YKS ó di sísún síwájú, ìjọba ò tẹ̀tì nínú àlàkalẹ̀ rẹ̀:
Ní ìparí oṣù keje mílíọ̀nù méjì àbọ̀ ni ó jókòó ṣe ìdánwò náà..
Gẹ́gẹ́ bí a ṣe rí i ní inú túwíìtì yìí, tí ó nííṣe pẹ̀lú àsujù lórí ìmúnitẹ̀lẹ́ ìjìnnà sí ara ẹni láwùjọ:
Ìdánowò YKS ń lọ lọ́wọ́ pẹ̀lú mílíọ́nù méjì àbọ̀ akẹ́kọ̀ọ́ ládúrúu gbogbo ìkìlọ̀: Ìjìnàsíra-ẹni láwùjo gan-an di àwátì.
Àìgbọ́raẹniyé Ìdànwò YKS tuntun: ìwà rere
Kì í ṣe COVID-19 nìkan ni famínfà tí ó yí Ìdánowò YKS ká ní ọdún 2020.
Ọ̀pọ̀lọpọ̀ àwọn ọ̀rọ̀ ló ti ń jà rànhìnrànhìn láti ìbẹ̀ẹ̀rẹ̀ oṣù keje èyí tí ó nííṣe pẹ̀lú ìwé àyọkà fún ìdánwò èdè Turkish.
Ọ̀kan nínú àwọn ìbéèrè abẹ́ rẹ̀ tọ́ka sí “Fırtınadayım, (mo wà nínú ìjì), orin olórin tàka-n-súfèé kan Mabel Matiz tí í ṣe LGBTQ “Fırtınadayım” (“I am in the storm”):
Ìbéèrè lórí ìtumọ̀ “Gözümün gördüğü, göğsümün bildiği ile bir değil” (tí a le tú sí ohun tí ojú mi rí kọ́ ni ohun tí aya mí mọ̀) ti ń da àwọn ìkànnì àwùjọ rú gùdùgùdù nítorí Mabel jẹ́ ẹni tí àwọn ọdọ́ mọ̀ bí ẹni mọ owó (ọ̀pọ̀ àwọn àwòrán-àtohùn rẹ̀ ní ó máa ń ní ìwò tí ó tó àádọ́ta mílíọ́nù) àti ìṣe rẹ̀ lórí àwọn ohun tí ó jẹmọ́ akọ́ṣebíabo.
Ní ìbámu pẹ̀lú fàmínfà orí ìkànni Twitter, Halis Aygün Ààrẹ Center for Measurement, Selection and Placement (ÖSYM), ẹ̀ka ìjọba tí ó bójú tó ìṣètò ìdánwò sọ nínú ìfọ̀rọ̀wánilẹ́nuwọ̀ pẹ̀lú àgbà òṣìṣẹ́ ìròyìn kan, Yeni Akit.
Níbẹ̀ ni ó ti sọ pé wọn yóò ṣe ìwádìí ọ̀rọ̀ náà, gbogbo àwọn tí wọ́n bá sì lọ́wọ́ nínú fífi ìwé náà si abẹ́ ìdánwò ọ̀hún ni wọ́n yóò lé kúrò lẹ́nu iṣẹ́:
Ìdánwò YKS ọdún 2020 kẹ́sẹ járí kákàkiri àwọn ibùdó ìdánwò méjìdínnígbà (188) ní ìṣí ẹ̀ẹ̀mẹta, tí àwọn akópa nínú rẹ̀ sì ń lọ bíi mílíọ́nù méjì àbọ̀.
Àwọn ìdánwò rẹ̀ jẹ́ èyí tí àwọn onímọ̀ akadá káàkiri àwọn fáfitì orílẹ̀-èdè wa ṣètò.
Ìkíyèsí àwọn ẹ̀kọ́ ilé àti ọgbọ́n ìbágbépò láwùjọ fùn àwọn ilé-ìwé gíga wa máa ń jẹ́ kíkíyèsí.
Àwọn òṣìṣẹ́ tí èyí bá ṣí mọ́ lórí ni wọn yóò di gbígbọ́n dànù kúrò nínú ìṣètò ìdánwò.
Fún àwọn asàmúlò ìkànnì Twitter kan, ìdájọ́ yìí kò tó:
[Òkè] Ààrẹ ÖSYM sọ̀rọ̀ fún ìgbà àkọ́kọ́ lẹ́yìn ìdánwò!
Wọ́n ti fi ìdí ìwádìí lọ́lẹ̀ láti wo ibi tí ìṣòro náà ti wọ́wá. Àwọn tí wọ́n bá lọ́wọ́ nínú rẹ̀ yóò di gbígbọ́n dànù kúrò nínú ìṣètò ìdánwò.
[Ìsàlẹ̀] Kò tó [lá ti yọ ọ́] nìkan, Ààrẹ tí kò ka nǹkan sí náà gbọdọ̀ jẹ́ yíyọ kúrò nínú ìṣàkósọ gbogbo kí ojú rẹ̀ le wálẹ̀.
Ọ̀wọ́ àwọn alẹ́nulọ́rọ̀ láwùjọ náà tún rí wí sí ìpinnu àti ṣètò irú ìbéèrè báyìí:
Nínú ìdánwò #YKS2020 tí ó wáyé lónìí, ẹ kò rí ẹlòmìíràn fi ṣe àpèjúwe fún àwọn ọmọdé wọ̀nyí àfi ọkùnrin oníbálòpọ̀-akọsíakọ nnì Mabel Matiz?
"(Ènìyàn tí ó gbé àkólé tí ó fi ń polongo pé ""Oníbálòpọ̀-akọsíakọ ni àwa"""
Kí ni ẹ̀ ń gbìyànjú láti ṣe?
Èrò àwọn aṣàmúlò ìkànni Twitter kò ṣọ̀kan pẹ̀lú bí àwọn mìíràn ṣe ń tọ́ka sí àwọn àṣeyọrí Mabel Matiz àti bí ó ṣe lókìkí sí:
Èyin ọmọ ìgbìmọ̀ aṣèwádìí. Mo fẹ́ kí ẹ wo àwọn fọ́nrán Mabel Matiz.
Nítorí pé a kò ní eléré mìíràn tí ó ti ṣe àmúlò àṣà wa tó báyìí ní ọ̀pọ̀ ọdún sẹ́yìn.
Ìdí nìyẹn tí mabelmatiz ṣe jẹ́ ìsúra wa.
Àwọn èèyàn lórí ayélujára pé àkíyèsí sí i pé fífi ojú sun olórin tí ó jẹ́ oníbálòpọ̀-akọsíakọ, àwọn olóṣèlú yóò pa àwọn ọ̀rọ̀ tí ó ṣe kókó tì:
Kò sí ẹni tí ó figbe ta lórí àwọn afipábánilòpọ̀, síbẹ̀ ìwádìí Mabel Matiz ni wọ́n ń gbà bí ẹni ń gba igbá ọtí.
Eléyìí kó gbogbo rẹ̀ nílẹ̀:
"Ẹ sọ pé ""ìdààbò bo ìṣe wa"" ṣùgbọ́n Mabel Matiz ni ẹni tí ó ṣe ìgbéjáde àṣà wa jùlọ."
Ó wa yẹ kí ìwádìí ó dá lé àwọn èyí tí ó tàbùkù Mabel Matiz tí wọ́n sì ṣẹlẹ́yàmẹ́yá rẹ̀. #MabelMatizisnotalone [Àtẹ̀jáde òkè]
Èsì Mabel Matiz sí àìgbọ́raẹniyé náà
Ní ọjọ́ 3 oṣù Keje, bí fàmínfà náà ṣe ń gbóná sí i, Matiz padà la ohùn:
Ẹ ǹlẹ́ o:) Inú mi dùn pé orin mi jẹ́ lílò fún irú ìdánwò pàtàkì bí èyí.
Ní báyìí, ìyàlẹ́nu lójẹ́ fún mi bí ìgbéayé mi ṣe di ohun tí ó kan ìdánwò tí à ń sọ yìí.
Ẹ wo ohun tí a fi dán mi wò..bí a ṣe gbé ààmi kan ní ìfẹ̀gbẹ́kẹ̀gbẹ́ pẹ̀lú orúkọ mi.
Kò burú, Ìdánwò ayé kò lópin:)
Iyán tún di àtúngún wàyí.
Mo ka ọ̀pọ̀lọpọ̀ àwọn àtẹjáde tí ó ṣègbè lẹ́yín mi.
Òhun tí mo fẹ́ sọ nínú orin yẹn yémi, mó nímọ̀ pé ó yé ẹ̀yin náà, ara mi sì tún yá gágá sí i.
N ó tẹ̀síwájú láti máa kọ orin sí i, láti máa sọ ìtàn àti láti jẹ́ ọmọ orílẹ̀-èdè yìí.
Ká tún pàdé nínú ìdánwò mìíràn...
Matiz sì lókìkí síbẹ̀: lẹ́yìn ọjọ́ kan tí Aygun sọ̀rọ̀ sáfẹ́fẹ́, ó gba àmì-ẹ̀yẹ méjì nínú ìdíje àmì-ẹ̀yẹ kan nípasẹ̀ ìbò tí ó pọ̀jù.
Ó gba àmì-ẹyẹ ipele méjì, “Orin tí mùṣèmúṣè rẹ̀ dá múṣé jùlọ” àti “Olórin ọkùnrin tí mùṣèmúṣè rẹ̀ dá múṣé jùlọ” ní ìdíje àmìẹyẹ Pantene Golden Butterfly ẹlẹ́ẹ̀kẹrìndínláàádọ́ta irú rẹ̀.
Èyí fi hàn pé ọ̀pọ̀ ènìyá̀n ni wọ́n wà lẹ́yìn rẹ tako ọ̀rọ̀ ìbálòpọ̀-akọsíakọ tí ìjọba àti àwọn alẹ́nulọ́rọ̀ tí ìjọba ń sọ.
Ní ọjọ́ 5 oṣù Keje, Mabel Matix tún túwíìtì:
"Mo gba àmì-ẹyẹ ""àwòrán-àtohùn orin tí mùṣèmúṣè rẹ̀ dá múṣé jùlọ"" àti “Olórin ọkùnrin tí mùṣèmúṣè rẹ̀ dá múṣé jùlọ” nínú ìdíje àmì-ẹyẹ Pantene Golden Butterfly ẹlẹ́ẹ̀kẹrìndínláàádọ́ta irú rẹ̀, Inú mi dùn!"
Ẹ ṣé gan ẹ̀yin olùgbọ́ mi gbogbo.
Màá fẹ́ láti dúpẹ́ lọ́wọ́ Erhan Arik àti DOP Meryem Yavuz, àwọn tí wọ́n darí àwòrán-àtohùn [orin mi]
I Have a Red in My Wipe clip tẹ́lẹ̀.
---Àjọ̀dún òṣìṣẹ́: Abẹnugan ilé-ìgbìmọ̀ as̩ojú rọ òṣìṣẹ́ láti tẹramọ́ iṣẹ́ fún àbájáde rere.
Abẹnugan ilé-ìgbìmọ̀ aṣ̣ojú ti Nàìjíríà, Fẹ́mi Gbàjàbíàmílà, ti kí àwọn òṣìṣẹ́ orílẹ̀-èdè yìí kú orííre fún ti àjọ̀dún àyájọ́ àwọn òsìsẹ́ lágbàáyé.
Ọ̀gbẹ́ni Gbàjàbíàmílà ní bó tilẹ̀ jẹ́ pé ayẹyẹ yìí wáyé láìsí ariwo ní gbogbo àgbáyé nítorí àṣe̩ kónílé–gbélé látàrí ìtànkálẹ̀ aàrun COVID-19, ohun tí a lè rántí pọ̀ nípa àwọn ìrúbọ ti àwọn òṣìṣẹ́ Nàìjíríà̀ ṣe.
Nínú àtẹ̀jáde tó ń sàmì ọjọ́ àwọn òṣìṣẹ́ èyí tí Olùdámọ́ràn rẹ̀ Pàtàkì lórí ìròyìn àti ìkéde fo̩wó̩sí, Láńre Làsísì, Abẹnugan gbóṣùbà fún àwọn òṣìṣẹ́ Nàìjíríà nítorí ìfarajìn àti ipa ribiribi tí wọ́n kó fún ọ̀pọ̀ ọdún sẹ́yìn, èyí tó mú ìyípadà rere bá Nàìjíríà.
Síbè̩, ó ro̩ àwọn òṣìṣé Nàìjíríà kí wọ́n túnbọ̀ máa so èso rere nísisìnyí àti gbogbo ìgbà, nítorí àṣeyorí àná nílò ìtẹ̀síwájú kí a ṣiṣẹ́ síi kí ọrílẹ̀-èdè yìí leè ní àṣeyọrí síi.
‘Mo fẹ́ kí àwọn òṣìṣé Nàìjíríà fún ọkàn-akin, àwọn tí wọ́n ti fi gbogbo ipá wọn ṣiṣé.
Nítòótọ́, Nàìjíríà àti àwọn ọmọ Nàìjíríà fi yín yangàn.
Mo rọ àwọn òṣìṣẹ́ Nàìjíríà láti fikún okun wọn ní irú àkókò ìdàgbàsókè orílẹ̀ èdè wa yìí.
Wọ́n gbọ́dọ̀ tẹ̀síwájú láti fi gbogbo agbára wọn ṣe iṣé tí wọ́n ń ṣe fún àǹfààní orílẹ̀ èdè’
--- Àyájọ́ àwọn Òṣìṣẹ́: Olóri ilé-ìgbìmọ̀ aṣòfin àgbà kí àwọn òṣìṣẹ́ Nàìjíríà
Ààrẹ ilé-ìgbìmọ̀ aṣòfin àgbà ti Nàìjíríà, Ahmad Lawan, kí àwọn òṣìṣẹ́ orílẹ̀-èdè yìí bí wọ́n ṣe sowó̩pò̩ pè̩lú àwọn akẹgbẹ́ wọn lágbàáyé láti s̩e àjọ̀dún o̩jó̩ àwọn òṣìṣẹ́.
Aṣòfin Lawan tún gbóṣùbà fún àwọn òṣìṣẹ́ fún gudugudu méje, yàyà mẹfà tí wọ́n ń ṣe láti mú orílẹ̀-èdè kúrò nínú òṣì àti àìní idàgbàsókè àti kíkojú àwo̩n ìpèníjà amúnibè̩rù lẹ́nu iṣẹ́ onírúurú.
Ó mọ rírì ipa àwọn òṣìṣẹ́ gẹ́gẹ́ bíi ẹni tó ń mú ọrọ̀ wá sí àwùjọ, ó tẹnumọ wípé èyí ni a ṣe gbọ́dọ̀ mo rírì wọn ní gbogbo ìgbà.
"Ó tẹ̣̀síwájú pé ""ọ̀nà tó dára jùlọ̣ láti mọ̣ rírì ipa ribiribi tí àwọ̣̣n òṣìṣẹ́ kó ní láti mójútó ètò ìgbáyé-gbádùn wọ̣̣n."
"Lawan sọ wípé, ""Gẹ̣́gẹ́ bí ilé-ìgbìmọ̀ aṣ̣òfin, a ti ṣ̣etán láti fọwọ̣́sowọ̣́pọ̀ pẹ̣̀lú ẹ̣̣gbẹ̣́ àwọ̣̣n òṣ̣ìṣ̣ẹ́ láti ṣòfin tó lòdì sí ìwà ìbàjẹ́ sí òṣìṣẹ lẹ́nu iṣẹ́""."
Ààrẹ ilé-ìgbìmọ̀ aṣòfin àgbà sọ wípé, gégẹ́ bíi ara akitiyan ilé-ìgbìmọ aṣòfin kẹsàn-án láti fi okun fún ètò ọrọ̀ ajé àti láti mú ìgbé-ayé àwọn ènìyàn dára síi, ti pinu láti mú kí ètò ìsúúná ọdún yìí ṣee dáadáa nípa títètè bu ọwọ́ lu ìwé ètò ìsúná ọdún 2020.
Nínu ọ̀rọ̀ Aṣòfin Lawan, ilé-ìgbìmọ̀ aṣòfin àgbà bakan náà ti ṣe àtúnṣe sí àwọn òfin kò̩ò̩kan láti ri wípé ìmúlò ètò ìsúná náà lo̩o̩ bí ó ti yẹ.
Ó sọ wípé àwọn Aṣòfin yóò máa lọ ní ìlànà yìí láìwo àwọn ìpèníjà àjàkálẹ̀ ààrùn COVID-19.
Ààrẹ ilé-ìgbìmọ̀ aṣòfin ṣe àkíyèsí wípé ayẹyẹ ọjọ́ àwọn òṣìṣẹ́ ti ọdún yìí wáyé lásìkò tí gbogbo orílẹ̀ èdè àgbáyé ń kojú àjàkálẹ̀ ààrùn òjiijì COVID-19.
"Ó wípé ""Ọkàn akínkanjú àti ẹ̀mí tí kìí kú tí àwọn ènìyàn Nàìjíríà níí ni yóò ran iṣẹ́ ìjọba lọ́wọ́ láti leè borí àjàkálẹ̀ ààrùn náà"""
”Ààrẹ ilé ìgbìmọ̀ aṣòfin wá rọ àwọn òṣìsẹ́ lórílẹ̀ èdè Nàìjíríà bí wọ́n ṣe ń sàmì ọjọ́ wọn, láti máa tẹ́lé ìlànà ètò ìlera láwùjọ, fífi ààyè sáàrín ara wa, kí a máa wọ ìbòjú, kí a máa lo oun èlò ìfọwọ́ apakòkòrò, kí a máa ṣe ìmọ́tótó ara wa àti láti máa dúrọ sílé kí a sì dáàbò bo ara wa.
--- COVID-19: Àwọn ènìyàn mẹ́rìnlélógún (24) mìíràn tún jẹyọ lórílẹ̀ èdè Nàìjíríà
Àwọn ènìyàn mẹ́rìlélógún (24) mìíràn tún ti jẹyọ tí wọ́n ní ààrùn Corona (COVID 19) lórílé̩èdè Nàìjíríà, èyí tó jẹ́ kí iye àwọn tó ní ààrùn Corona jẹ́ o̩gbò̩nlélé̩è̩dé̩gbàá lé méjì (1932), nígbà tí àwọn ènìyàn bí mọ́kàndínlógúnlélọ́ọ̀dúnrún (319) ti gba ìwòsàn, tí àwọn ènìyàn méjìdínlọ́gọ́ta (58) sì ti jẹ́ Ọlọ́run nípè. Àjọ tó ń gbógun ti àjàkálẹ̀ aàrùn ti Nàìjíríà (NCDC) ló kéde yìí lórí ẹ̀rọ Twitter wọn, @NCDC. gov.
--- COVID-19: A ti gba ìròyìn díẹ̀ lórí ìṣẹ̀lẹ̀ ní Kánò- Dókítà Osagie
Mínísítà fún ètò ìlera ti Nàìjíríà, Dókítà Osagie Ehanire ti ní àwọn ri ìròyìn díẹ̀ gbà nípa ìṣẹ̀lẹ̀ onírúurú ní ìpínlẹ̀ Kánò.
Mínísítà sọ̀rọ̀ yìí lásìkò ètò ìfọ̀rọ̀wánilẹ́nuwò ojoojúmó tí ìgbìmọ̀ ìjọba àpapọ̀ tó ń mójútó gbígbógun ti aàrùn COVID-19 ń ṣe pẹ̀lú àwọn akọ̣̣̣̣̣̀ròyìn nílùú Àbújá.
Ó tún tẹ̀síwájú pé àwọ̣n ṣí ń retí gbogbo ìròyìn nípa ìṣẹ̣̀lẹ̀ ikú òjijì tó wáyé ní ìpínlẹ̣̀ Kánò, eléyìí yóò ràn ìgbéṣẹ̀ pípèsè ètò ìrànwọ́ ìrìnsẹ̀ , àwọn onímọ̀ àti ètò ẹ̣̀kọ́ tí wọn yóò fún ìpínlẹ̀ Kánò láti dẹ́kun aàrùn COVID-19.
Dókítà Ehanire , wá rọ̣ àwọ̣n òṣìṣẹ̣́ ètò ìlera làti maa tẹ̀ḷé ètò ìlànà láti dáàbò bò ara wọn nígbà gbogbo kí wọ̣n máa bàa lùgbàdì aàrùn COVID-19 tàbí fi ara wọ̣n sínú ewu.
--- Nàìjíríà ṣàwárí àwọn alárùn COVID-19 mé̩rìnlélúgba
Nàìjíríà ti ní àkosílẹ̀ ènìyàn mẹ́rìnlélúgba tí wọ́n ní ààrun kòrónà tí a mọ̀ sí COVID – 19, èyí tó mú gbogbo akárùn náà jé̩ o̩gbò̩nlélé̩è̩dé̩gbàá lé méjì (1932).
Okòóléló̩ò̩dúnrún dín ò̩kan (319) gba ìwòsàn, méjìdínlọ́gọ́ta sì kú.
Àjo̩ a-gbógun-ti-àjàkálẹ̀-ààrun ti Nàìjíríà (NCDC) ló so̩ èyí lórí ẹ̀rọ abẹ́yẹfò @NCCDCgov;
Alárùn COVID-19 mé̩rìnlélúgba ti farahàn;
Ọgọ́rin-Kano, márùndínláàdọ́ta-Èkó, méjìlá-Gombe, mẹ̩́sàn-án-Bauchi, mé̩sàn-án-Sokoto, méje-Borno, méje-Edo, méfà-Rivers, méfà-Ògùn, mẹ́rin-Àbújá, mẹ́rin-Akwa Ibom, mẹ́rin-Bayelsa, mẹ́ta-Kaduna, méjì-Òyó, méjì-Delta, méjì-Nasarawa, Ò̩kan-Òǹdó, Ò̩kan-Kebbi. Ní agogo méjìlá ku ìṣéjú mẹ́wàá, ọgbọ̀n ọjo oṣú igbe – 1932 alárùn Covid-19 farahàn ní Nàìjíríà.
--- COVID-19: Ikò̩ òṣìṣé mínísítà ti Kano s̩àgbékalè̩ ìròyìn gbà-á-gbè̩
Ikò̩ ọ̀ṣìṣẹ́ mínísítà lóri is̩é̩ ìwádìí sí Kano, ti s̩e àgbékalè̩ ìròyìn gbà-á-gbè̩ fun ilé-iṣẹ́ ìjọba àpapọ̀ ti ìlera, lórí ìdí, okun àti àìlera ọ̀nà tí ìpínlẹ̀ Kano ṣe ń dáhùn.
Mínísítà fún ìlera, Dókítà Osagie Ehanire sò̩yí nínú ìpàdé àpapọ̀ pẹ̀lú àwọn oníròyìn èyí tí ìgbìmọ̀ ìjọba àpapọ tó ń mójútó COVID-19 ní Àbújá ṣe.
Ó ní bí ilé-iṣé ìjọba àpapọ s̩e ń retí ìròyìn kíkún, ìròyìn gbà-á-bè̩ yìí yóò jẹ́ ató̩nà nínú ìrànwọ́ fún ikò̩ agbógunti Covid-19 ti Kano pèlú èròja to ye̩, ìdánilé̩kò̩ó̩ àti àwo̩n ènìyàn araniló̩wó̩.
“ Lára àwọn ohun ìrànwọ́ ni kíkó àti rírán àwọn ẹgbẹ́ onímọ̀ láti FMOH àti àwọn onímọ̀ nípa kòkòrò ààrùn láti ilé-ìwòsàn Irrua Specialist Hospital láti darapọ̀ mọ́ ẹgbẹ́ onímọ̀ ilé-iṣẹ́ ètò ìlera ní ìpínlẹ̀ Èkó tí ó ti ń ṣiṣẹ́ ní ìpínlẹ̀ Kano nítorí Gómìnà ìpínlẹ̀ Kano”
Gé̩gé̩ bi ìdáhùn, ó tún so̩ pé àwọn onímọ̀ onírìírí yóò pò̩ jaburata ní ìkàlè̩ láti kin àwo̩n òs̩ìs̩é̩ ìs̩áájú lé̩yìn ní ìpínlẹ̀ Kano.
“E̩gbẹ́ oníṣègùn tó ń dáhùn ìpè pàjáwìrì lati FMOH ti kúrò ní Àbújá pẹ̀lú àwo̩n áḿbúlàǹsì, márùn-ún ni àjọ ẹ̀ṣọ́ ojú pópó (FRSC) fi to̩re̩, lọ́nà láti lọ sí ìpínlẹ̀ Kano fún ìdáhùn pàjáwìrì látàríi àṣẹ kónílégbélé.
Dókítà Ehanire tún sọ̀dí tí àwọn òṣìṣé ìlera ṣe gbọ́dọ̀ tẹ̀lé àwọn ìlànà ìpara-ẹni-mọ́ fún ààrùn ní gbogbo ìgbà, kí wọ́n máa sì fi ẹ̀mí wọn wéwu.
“A kò leè gbà láti pàdánù àwọn òṣìṣẹ́ pàtàkì nírú àkókò báyìí; gbogbo ènìyàn ni wọ́n gbọ́dọ̀ tó̩jú pẹ̀lú ìfura tó ga fún COVID-19 sùgbọ́n kí wọ́n tójú gbogbo ènìyàn láì s̩ojús̩àájú kí àwọn elòmíràn pẹ̀lú àìsàn má baà jìyà àìdásí tàbí kí wọ́n má tó̩jú wọn.”
Ó wípé, “Ó jẹ́ ohun àìdára láti lé àwọn ènìyàn lọ láìsí ìmọ̀ràn nípa ètò ìlera tàbí kí á fi ìtọ́jú du ẹni tí ó nílò ìtọ́jú ní pàjáwìrì.”
--- S̩ís̩í àwo̩n ilé-è̩kó̩ kò tíì farahàn - Mínísítà
Mínísítà ìpínlẹ̣̀ fún ètò ẹ̣̀kọ̣́, Emeka Nwajiuba ní òun kò leè sọjọ́ tàbí ìgbà tí wọn yóò padà ṣí ilé-è̩kó̩.
Mínísítà tẹ̣̀síwájú pé ṣíṣí àwọn ilé-è̩kó̩ yóò jẹ́ ní sísẹ̀-n-tẹ̀lé pẹ̀lú bí Ààrẹ Muhammadu Buhari ṣe ń gbẹ́sẹ̀ kúrò lórí àṣẹ kónílé–gbélé tí ó wà láti kápá ààrùn kòrónà.
Nwajiuba, nínú ọ̀rọ̀ rẹ̀ lójojúmọ́ ti sọ s̩áájú wípé ìjọ̣̣ba kò ṣetán láti fi ẹ̣̀mí àwọ̣̣̣̣n o̩mo̩ wéwu, ó wá kìlọ̀ wípé ilé-è̩kó̩ kọkan kò gbọdọ̀ bẹ̀rẹ̀ ètò ẹ̀kọ́ nílé-è̩kó̩ wọ̣̣n àyàfi ọjọ́ tí ìjọ̣̣ba bá kéde rẹ̀ pé kí ilé-è̩kó̩ wọlé.
“Ní kúkurú, kò sí èyíkèyí nínú àwo̩n ilé-è̩kó̩ yìí tó le s̩í lé̩yìn odi.
Mínísítà tún so̩ pé gbogbo àwọ̣̣n ìdánwò ìgbaniwọlé tí wọ́n ti sún síwájú ni yóò di ṣíṣe nígbà tí ìjọba bá ri dájú pé gbogbo ètò-ẹ̀kọ́ tí wó̩n gbékalè̩ ló yé àwọn akẹ́kọ̀ó̩.
Mínísítà ṣe àlàyé pé ìdánwò àwọn akẹ́kọ̀ọ́ oníwèémẹwàá (WAEC) àti àwọn ìdánwò àpapọ̀ (NECO) pẹ̀lu NABTEB ni kò ì di fífagilé sùgbọ́n tí wó̩n sún síwájú.
Ó sọ̀rọ̀ nípa ìpèníjà tí ẹ̀kọ́ orí ayélujára tí a ṣẹ̀ṣẹ̀ mú wọlé àti bí a ṣe mú ètò ẹ̀kọ́ gbogboogbò ní ìpínlẹ̀ lò.
Gẹ́gẹ́ bí ó ṣe sọ, “A mọ̀ wípé àwọn kan kò ni àǹfààní àti àìkò ní àǹfààní yìí nítorí àìkò ní ẹ̀rọ tó kún ojú òsùwọ̀n, àwọn kan le tẹsíwájú nínú ẹ̀kọ́ wọn lórí rédíò, àwọn kan lórí te̩lifís̩àn, àwọn kan sì ń lo ẹ̀rọ ayára-bí-àsá pẹ̀lú ayélujára, nítorí náà à ń ṣe èyí pẹ̀lú àjọṣiṣẹ́pọ̀ ìjọba ìpínlẹ, èyí túmọ̀ sí pé gbogbo àlàfo tí a fe̩ dí tó nííṣe pẹ̀lú ẹ̀kọ́ àwọn ọmọ jákèjádò orílẹ̀-èdè yìí, a nílò láti gba ọ̀dọ̀ Gómìnà ìpínlẹ̀ kọ̀ọ̀kan nípaṣè àjọ ẹ̀kọ́ alákọ̀ọ́bẹ̀rẹ̀ káríayé SUBEBS”
"Ní báyìí a ti ní ètò ìlànà ẹ̣̀kọ̣́ fún àwọ̣̣n ìpínlẹ̀ mọ̣́kànlélọ̣́gbọ̀n nínú ìpínlẹ̀ mẹ̣̣́rìndínlógóji, èyí túmọ̀ sí wípé láti orí rédíò tàbí te̩lifís̩àn, ìkọ́ni àti ìkẹ́kọ̀ọ́ n lọ, èyí jẹ́ àwo̩n ìlànà ìkẹ́kò̩ọ́ tó dára fún ìpínlẹ kọ̀ọ̀kan sùgbọ́n ìjọba àpapọ̀ ti ṣe ìlànà láti orí ayélujára.”
Nwajiuba sọ wípé “Lílo àwo̩n SUBEB, ọ̀nà tí à ń gbà momi o̩gbó̩n wo̩n ni a ṣe fi pín kíkọ́ àti mímọ̀ yìí lórí ẹ̀rọ ayélujára. Ìjọba àpapọ̀ sì sọ wípé wọ́n leè lo àwọn ilé-iṣẹ́ ìgbóhùn sáfẹ́fẹ́ ti ìpínlẹ̀ wo̩n tó dára fún un”.
Mínísítà s̩àfikún pé àjàkálẹ̀ ààrùn COVID-19 ti ran àwọn olókoòwò gbogbo lọ́wọ́ láti túnramú, ó sì ti ran ẹnìkọ̀ọ̀kan láti bọ́ sójú iṣẹ́.
Nígbà tó ń sọ̀rọ̀ lórí ìmúdúró ẹ̀kọ́ lórí ayélujára, mínísítà sọ wípé ìjọba yóò túnbọ̀ ṣàmúlò àwọn olùkọ́ akọ́ṣẹ́mọṣẹ́ tí yóò ṣàṣepé ètò náà tí yóò leè mú u wúlò lẹ́yìn ìpèníjà ààrun kòrónà tó kojú àgbááyé.
Bákan náà, ilé-iṣẹ́ ẹ̀kọ́ tó ń ṣàmójútó àwọn ilé-è̩kó̩ ní olú-ìlú FCTA, ṣe ìkìlọ̀ fún àwọn ilé-è̩kó̩ aládàáni tí wọ́n ń dájọ́ ìwọlé táàmù kẹta fún 2019/2020 lórí ẹ̀rọ ayélujára fún àwọn òbí àti akẹ́kọ̀ọ́.
Akọ̀wé ilé-iṣẹ́ àjọ tó ń mójútó ilé-è̩kó̩, Umaru Marafa sọ nínú àtẹ̀jáde ọjọ́ ìṣẹ́gun wípé kò sí iṣẹ́ ìkẹ́kọ̀ọ́ kọ̀kan ní ilé-è̩kó̩ kọ̀ọ̀kan lọ́nàkọnà tó gbọ́dọ̀ bẹ̀rẹ̀ títí di ìgbà tí àṣẹ s̩ís̩í ilé ìwé bá jáde.
Marafa so̩ pé, “Ìtumò̩ èyí ni pé nígbà tí àwọn ilé-è̩kó̩ yóò bá di s̩ís̩í padà, ìfilọ̀ tí ó yé̩ ni yóò ti wà lórí táàmù kejì tí kò parí, àti ò̩nà àti runmó̩ táàmù kẹta bí ó ti yẹ. Ìgbésè̩ tó bá lòdì sí èyí ṣeéṣe kó kóbá ètò ẹ̀kọ́ àwọn ilé-è̩kó̩ tó kàn.
Wó̩n ro̩ àwọn ọ̀gá ilé-è̩kó̩ aláàdáni láti sowé-agbéjé̩-mó̩wó̩ kí ilé-è̩kó̩ wò̩n sì wà látìpa, kí wọ́n má s̩e si ní ọ̀nàkọnà títí ìjò̩ba yóò fi sohun mìíràn.
Àwọn tí wọ́n bá ṣe lòdì sí àṣẹ yìí yóò dojúkọ ìdájọ́ òfin pó̩nńbélé;
Marafa tún sọ wípé ilé-iṣẹ́ ẹ̀kọ́ ìjọba àpapọ̀ ti parí gbogbo ètò láti leè mú ètò ẹ̀kọ́ lórí ayélujára w̩onú èto ẹ̀kọ́ yálà lóri rédíò tàbí te̩lifís̩àn kí àwọn akẹ́kọ̀ọ́ leè máa ṣiṣẹ́ nígbogbo ìgbà tí kónílé gbélé bá fiwà.
--- Kò gbọ̣̣̣̣̣dọ̣̀ ṣí ilé-ìwé aládàáni kankan tó gbọ̣́dọ̣̀ bẹ̣̀rẹ̣̀ isẹ̣́ – Mínísítà FCT
Mínísítà fún olú-ìlú Nàìjíríà, Alhaji Muhammad Músá Bello ti ṣ̣èkìlọ̀ fún gbogbo àwọ̣̣n olùdarí ilé-ìwé aládàáni tó wà nílùú Àbújá tí wọ́n ti ń sọ̣̣ fún gbogbo àwọ̣̣n òbí àti akẹ̣̣́kọ̣̀ọ́ pé wọ̣̣n kò ní pẹ́ bẹ̣̀rẹ̣̀ iṣ̣ẹ́ láìpẹ̣́ fún sáà kẹ̣̣ta fún ti ọ̣dún 2019/2020 tí a wàyìí láti ṣ̣ọ̣̣́ra, kí wọ̣̣́n máa ba fojụ winá òfin ìjọ̣̣ba.
Akọ̣̣̀wé àgbà fún ètò ẹ̣̣̀kọ́ nílùú Àbújá, Umaru Máráfá ló sọ̣̣̀rọ̣̣̀ yíì nínú àtẹ̀jáde kan tí ó gbé jáde lọ̣̣́jọ́ ìṣ̣ẹ̣̣́gun pé ètò ẹ̣̣̀kọ́ kò ní tíì bẹ̣̣̀rẹ̀ nílé ìwé kankan tó wà nílùú Àbújá báyìí àyàfi ọjọ́ tí ilé-iṣ̣ẹ́ akọ̀wé àgbà fún ètò ẹ̣̣̀kọ́ bá fọ̣̣wọ̣̣́si.
À ń rọ̣̣ gbogbo àwọ̣̣n olùdarí ilé-è̩kó̩ aládàáni láti jẹ́ kí ilé-è̩kó̩ wà ní títìpa, wọn kò gbọ̣̣̣dọ̣̣̀ gbìyànjú láti ṣí ilé-è̩kó̩ náà àfi tí àṣ̣ẹ̣̣ tàbí ìlànà bá wá láti ọ̀dọ̀ ilé-iṣ̣ẹ́ FCTA."""
Gbogbo àwọ̣̣n tó bá tàpá ṣófin yìí ni yóò fojú winá òfin ìjọ̣̣ba.
Máràfá tẹ̀síwájú pé ilé-iṣ̣ẹ́ FCTA tí ó ń mójútó ètò ẹ̣̀kọ́ ti s̩e ètò láti bẹ̀rẹ̀ ètò ẹ̀kọ́ nípa lílo ìmọ̀ ayélujára, àti s̩ís̩e àmúlò te̩lifís̩àn láti fi kọ̣́ àwọn akẹ́kọ̀ọ́ ní àkókò kónílé-gbélé.
--- Ọ̀RỌ̀ ÀÀRẸ MUHAMMADU BUHARI LÓRI TE̩LIFÍS̩ÀN SỌ́MỌ NÀÌJÍRÍÀ
Ọ̀RỌ̀ ÀÀRẸ ORÍLẸ̀-ÈDÈ NÀ̀ÌJÍRÍÀ, MUHAMMADU BUHARI, NÍPA ÒFIN KÓNÍLÉ-GBÉLÉ NÍ ÌPÍNLẸ̀ ÈKÓ, ÒGÙN ÀTI ÌLÚ ÀBÚJÁ, FCT, LÓRI ÌTÀNKÁLẸ̀ ÀÀRÙN COVID- 19, NÍ ÈYÍ TÍ Ó WÁYÉ NÍ ÌLÚ ÀBÚJÁ LỌ́JỌ́ AJÉ, ỌJÓ̩ KẸTÀDÍNLỌ́GBỌ́N, OSÙ KẸRIN ,ỌDÚN 2020 (MONDAY, 27th APRIL, 2020).
1.O̩mọ Nàìjíríà
2.Màá bẹ̀rẹ̀ pè̩lú gbígbós̩ùbà fun yín nítorí ìwà akínkanjú àti ìjólóòótọ́ yín èyí tẹ s̩àfihàn nínú ìjà àjùmò̩jà sí ìpèníjà ìlera tó gajù, tó ń kojú ìran wa.
3.Níwòyí àná, 26th April 2020, àgbáyé s̩àwárí àwo̩n alárùn Covid-19 míĺiọ̣́nù mẹ́ta, tí ẹ̀ẹ́dẹ́gbààrún ló̩nà e̩gbè̩rún ènìyàn sì ti gbàwòsàn. Ó ṣeni láàánú pé igba ló̩nà e̩gbè̩rún ènìyàn ló tipasè̩ ààrùn náà papò̩dà.
4.Ètò ìlera àti ọrọ̀ ajé ọ̀pọ̀lọpọ̀ orílẹ̀ èdè ni ó sì ń tiraka látàrí àjàkálẹ́ ààrùn kòkòrò kòrónà.
5.Nàìjíríà ń tẹ̀síwájú láti máa mọ àwọn òótọ́ titun tó ń súyo̩ lágbàáyé lójoojúmó̩. Lónìí, n ó sọ àwọn òtítọ́ bó ṣe jẹ́, n ó sì ṣàl̀àyé àwọn ètò wa fún àwọn oṣu tó ń bọ̀ nígb̀atí a tí mọ̀ wípé àwọn ohun kan lè yípadà láwọn ọjọ́ àtọ̀sẹ̀ tó ń bọ̀.
6.Ní déédé ọ̀sẹ̀ méjì sẹ́yìn, oníkòrónà okòóléló̩ò̩dúnrún lé mé̩ta ni wó̩n s̩àwárí nípìnínlè̩ ogún àti olú-ìlú.
7.`Lówùúrọ̀ yìí, Nàìjíríà ti lákọsílẹ̀ àádó̩rinlélè̩é̩gbé̩fà-lé-mé̩ta alárùn nípìnínlè̩ méjìlélọ́gbọ̀n àti olú-ìlú. Ó ṣeni láànú pé ogójì ló ti papòdà.
8.Mò ń lo àǹfààní yìí láti fi ìbánikẹ́dùn wa hàn pẹ̀lú àwọn ẹbí ọmọ orílè̩-èdè Nàìjíríà gbogbo tí wọ́n pàdánù àwọn olólùfẹ́ wọn látàrí àjàkálẹ̀ ààrùn COVID-19. Èyí jẹ́ àdánù wa papọ̀, a sì pín nínú ìbànújẹ́ yín.
9.Àwòye ìbè̩rè̩ ni pé Nàìjíríà máa ní e̩gbàá àko̩sílè̩ alárùn ní oṣù àkọ́kọ́ lé̩yìn tí wọ́n rí alárùn àkó̩kó̩.
10.Èyí ni pé bí iye àwọn tí àyẹ̀wò so̩ pé wọ́n ní ààrùn kòrónà ní ọ̀sẹ̀ méjì sẹ́yìn ti pọ̀ tó, àwọn ohun ta ti ṣàgbékalè̩ ti mú èso rere jáde lòdì síwòye àná.
11.Iye alárùn kòrónà tó tòkè òkun wá ti dínkù sìdá mó̩kàndínlógún nínú o̩gó̩rùn-ún àwo̩n alárùn titun, èyí fihàn pé títi e̩nubodè sèso rere. Ò̩pò̩lo̩pò̩ ni àwo̩n o̩mo̩ Nàìjíríà tó ń padabò̩ wálé. A ó tẹ̀síwájú nínú títe̩pe̩le̩ mó̩ ìlànà gbígba àwo̩n as̩è̩s̩è̩dé gé̩gé̩ bi ọ̀nà láti gbógun tààrùn yìí.
12.Lónìí, àjọ amójútó àjàkálẹ̀ ààrùn lórílẹ̀ èdè Nàìjíríà ti fi ọwọ́ sí àwọn ilé ìyẹ̀wò mẹ́ẹ̀dógún tó lè ṣe àyẹ̀wò fún ènìyàn tó tó è̩é̩dé̩gbè̩tàlá lójúmọ́ jákèjádò orílẹ̀ èdè.
13.Látàrí èsì yín, ìjọba ìpínlẹ̀ Èkó àti ìlú Àbújá pẹ̀lú àtìlẹ́yìn àjọ agbógun ti àjàkálẹ̀ ààrùn ti ṣe àgbékalẹ̀ ibùdó ìgbàyèwò onírúúurú. Wọ́n tún ṣàgbéyẹ̀wò ète ìs̩àyè̩wò ní àwo̩n yàrá àyè̩wò láti lè mú kí àyè̩wò s̩ís̩e pò̩ sí pè̩lú ibùdó àyè̩wò aládàáni tí ó kojú òs̩ùnwò̩n tí wó̩n fo̩wó̩sí.
14.Ọ̀pọ̀ àwọn ilé-ìtójú gidi àti ìbùdó ìyàsọ́tọ̀ titun tìbè̩rè̩ iṣẹ́ jákèjádò orílẹ̀-èdè yìí, èyí sì mú kí iye ìbùsùn fé̩ tó ẹgbẹ̀é̩dógún.
15.Mo yin àwo̩n Gómìnà ìpínlẹ̀ fúndàásílẹ̀ ibùdó ìdásí ní pàjáwìrì nípìnínlẹ̀, ìdásílẹ̀ àwọn ibùdó ìtójú tuntun àti ète bíba àwo̩n ènìyàn sò̩rò̩ gidigidi lórí ewu tó wà.
16.E̩gbẹ̀rún mẹ́wàá òṣìṣẹ́ ìlera lé, la ti kọ́. Fún ààbò won, àwọn èlò ìdáàbòbò mìíràn la ti fi s̩o̩wó̩ sáwo̩n ìpínlẹ̀.
17.Nítòótọ́ a ti ní ìrírí àwọn ìpèníjà kan, a dúró digbi lóri s̩ís̩àgbékalè̩ ìpèsè tí ó múnádoko kí àwo̩n òs̩ìs̩é̩ yìí s̩is̩é̩ láìsí ewu pè̩lú ìs̩o̩ra pípé.
18.́Ni mímú ìlérí ìjọba wa ṣe láti mú kí ìgbé ayé àwọn òṣìṣẹ́ ìlera wa dára si, a ti fi ọwọ́ sí ìwé àdéhùn olóye fún ìpèsè owó ìfẹ̀míwewu àti àwọn owó mìíràn pẹ̀lú àwọn ẹgbẹ́ akọ́ṣẹ́mọṣẹ́ ẹ̀ka ètò ìlera tí ó ṣe kókọ.
19.A ti s̩ètò ìdójútòfò fún àwọn òṣìṣẹ́ ìlera tó ń léwájú bíi ẹgbẹ̀rún márùn-ún. Níkòóríta yìí mo gbọ́dọ̀ kí àwọn òṣìṣẹ́ adójútòfò fún àtìlẹyìn wọn ní ṣíṣe èyí láàrín àkókò díè.
20.Nàìj́iríà sì ń gbàrànlọ́wọ́ láti àwọn orílẹ̀ àgbáyé láti àwọn ilé-iṣẹ́ káàkiri, ẹgbẹ́ aládàáni àti ẹnìkọ̀ọ̀kan. Àtìlẹyìn yìí ti jẹ́ káwọn irinṣẹ́ àtohun èlò ta fi ń dóòlà ẹ̀mí, èyí tó sò̩wọ́n ní àgbáyé ti wà fún Nàìjírị́à látipaṣẹ̀ àwọn àjọ tó ń ṣe irinṣẹ́ gidi àtètò ìjọba-sí-ìjọba.
21.Pínpín àti ìgbòòrò àwọn ohun ìtura lásìkò kónílé -gbélé tí mo sọ nínú ìkéde ìs̩áájú sì ń tẹ̀síwájú láìléèérú nínú. Mo mọ ìsúni tí àwọn ọmọ orílẹ-èdè yìí tó ń retí rẹ̀ ń kojú. Mo ṛo̩ gbogbo ẹ̀yin anípìn-ín nínú rẹ̀ láti ni ́sùúrù bí a ti ń wá ọ̀nà tó dára láti pín pẹ̀lu àwọn ìjọba ìpínlẹ̀.
22.Àwọn òṣìṣẹ́ alábòò wa tẹ́síwájú láti dìde sípèníjà àsìkò ajo̩nilójú yìí. Bó tilè̩ jé̩ pé ìs̩è̩lè̩ ààbò ibùdó ìyàsó̩tò̩ dùn wá gan-an, mo fẹ́ fiyé ọmọ Nàìjíríà pé ààbò àti è̩s̩ó̩ yín jé̩ àkó̩kó̩ sí wa, pàápàá jùlọ ní àkókò líle òun àìmò̩ yìí.
23.Bá ṣe ń bójútó ààbò è̩mí àti dúkìá a kò ní fààyè gba ì-tẹ-ẹ̀tọ́-ọmọnìyàn mólẹ̀ láti ọ̀dọ̀ òṣìṣẹ́ aláàbò. Àwọn ìròyìn ìṣẹ̀lẹ̀ díẹ̀ tá a gbọ́ jẹ́ èyí tó ṣeni láàánú, mo sì fẹ́ fi dáa yín lójú pé a ó mú àwọn ọ̀daràn náà láti kojú ìdájọ òfin.
24.Mo rọ gbogbo ọmọ Nàìjíríà láti tẹ̀síwájú nínú ìfọwọ́sowọ́pọ̀ àti ìfòyehàn nínú ìpàdé wo̩n àti òṣìṣẹ́ aláàbò. Síwájú si, fún ààbò wọn, mo ti pàṣẹ pé kí wó̩n fún àwọn òṣìṣẹ́ aláàbò wọ̀nyí ní irinṣẹ́ ìdáàbòbò ara wo̩n lọ́wọ́ àkóràn ààrùn yìí.
25.Bá ti ń tẹ̀síwájú láti mú àdínkùn bá ìdáhùn wa láwọn ibùdó tÈkó àtÀbújá, ìṣẹ̀lẹ̀ ní Kánò láìpẹ́ yìí tún bàmí-nínú-jẹ́. Bó tilẹ̀ jẹ́ pé ìwá̀díi kíkún ń tẹ̀síwájú, a ti pinnu láti s̩àfikún òṣìṣẹ́ ìjọba àpapọ̀, ohun èlò àti ìrànwó̩ peléke láti kín àti s̩àtìlẹ́yìn akitiyan ìjọba ìpínlẹ̀, ní ló̩gán.
26.Ní Kánò, àti ìpínlẹ̀ yòókù tó ń s̩àkọsílẹ̀ alárùn tuntun, ìwádìí àkọ́kọ́ so pé àwọn èsì àyẹ̀wò yìí níí s̩e pè̩lú ìrìnàjò ìpínlẹ̀sípìnínlẹ̀ àti ìtànkálè̩ ààrùn nílùú kan.
27.Lati inú èyí, mo rọ gbogbo ọmọ Nàìjíríà kí wọ́n ó tẹ̀síwájú láti máa tẹ̀lé ìmọ̀ràn àwọn ikọ̀ amúṣẹ́ṣe ààrẹ àti àwọn àjo tí ó ń mójútó ààrùn
28.Àwọn èyí ni, fífọwọ́ lóòrèkóòrè, jíjìnà síra e̩ni, lílo ìbomú nígbangba, yíyàgò fún òde ìwò̩fún pè̩lú ìrìnàjò àti yíyàgò fún ìpéjọpọ̀ elérò púpọ̀.
29.Ẹ̣̣̀yin ọmo Nàìjíríà, fún bí ọ̀sẹ̀ mẹ́rin sẹ́yìn lọ̀pọ̀lọpọ̀ ibì lórílẹ̀èdè wa lábẹ àṣẹ kónílégbélé ti ìjọba àpapọ̀ tàbí ti ìjọba ìpínlẹ̀. Bí mo s̩e sọ ṣáájú, àwọn ìgbésẹ̀ yìí ṣe pàtàkì àti pé ó tún kópa nínu mímú àdínkù bá ìtànkálè̩ Kòrónà lórílẹ̀èdè wa.
30.Síbẹ̀síbẹ̀, irú àṣẹ kónílé gbélé náà ti wà pẹ̀lú ètò ìsúnná tó pọ̀. Ọ̀pọ̀lọpọ̀ ọmọ orílẹ̀èdè wa ti pàdánù ọ̀nà ìjẹun. Ọ̀pọ̀lọpọ̀ iṣẹ́ ló ti dúró. Kò sí orílẹ̀èdè tó lè gba gbogbo àkóbá kónílé-gbélé se nígbà à ń retí èsì ayò̩ lórí abẹ́rẹ́ àjẹsára.
31.Nínú ọ̀rọ̀ àsọkẹ́yìn, mo ní ìjọba àpapọ yóò ṣàgbékalẹ̀ ète àti òfin tí yóò dáàbòbò è̩mí á sì ló̩ràá ìgbé-ayé.
32.Láàrín ọ̀sẹ̀ méjì yìí, ìjọba àpapọ àti ìpínlẹ̀ ti ṣiṣẹ́ takuntakun papọ̀ lóríi ọ̀nà láti ṣe ìdó̩ó̩gba dídábòòbò ìlera àti tító̩jú ìgbé ayé, ní ìdó̩gba pẹ̀lu bí wọ́n ti ń ṣe ní gbàáyé pẹ̀lu ìrántí awon ohun ìyàtọ̀ wa.
33.A ṣàgbéyẹ̀wò bí àwọn ilé-iṣẹ, ọjà, oníṣòwò àti àwọn awakọ̀ wa ṣe leè tèsíwájú nínú ṣiṣẹ́ bákan náà kí wọ́n tèlé ìlànà àjo̩ amójútó ààrùn lórílèèdè yìí làkalè̩ lórí ìmó̩tótó àti jíjìnnà síra e̩ni.
34.A ṣe àgbéyẹ̀wò ìtẹ̀síwájú ìké̩kò̩ó̩ àwo̩n o̩mo̩ wa láì s̩e àkóbá ìlera wo̩n.
35. A yiiri ò̩nà tí àwo̩n àgbè̩ wa s̩e lè gbìn kí wó̩n sì kórè ní àkókò òjò kí á lè rip é ìpèsè oúnje̩ kò ní àkóbá. Síwájú sí, a tún sò̩rò̩ lóri ìgbóúnje̩ aláìléwu láti ìgbèríko lo̩ sí àwo̩n ilé-iṣẹ́ ìs̩ááyan rẹ̀ àti ibùdó ìje̩un gbòógì.
36.Àfojúsùn wa ni ká wá ò̩nà tá á lò ti yóò jé̩ kí o̩rò̩ ajé wa máa tè̩síwájú nígbà tí à ń wá ìdáhùn atè̩wò̩n sájàákálè̩ ààrùn kòrónà. Ìpinnu líle yìí làwo̩n olórí gbogbo lágbàááyé ń dojúko̩.
37.Nítorí èyí àti ìyànjú àwọn ikọ̀ ààrẹ lórí COVID-19, orísirísi ìgbìmọ̀ ìjọba àpapọ tó ti gbé ọ̀rọ̀ ìsúnná yẹ̀wò àti ìgbìmọ̀ àwọn gómìnà Nàìjíríà, mo ti fọwọ́ sí kí òfin kónílé-gbélé nílùú Àbújá, Èkó, àti ìpínlẹ̀ Ògùn kí ó máa lọlẹ̀ díẹ̀díẹ̀ kí ó sì bè̩rè̩ láti ọjọ́ ajé, ọjọ́ kẹrin, oṣù karùn-ún, 2020.
38.Síbè̩, àyè̩wò s̩is̩é àti s̩ís̩àwárí àwo̩n alábàápàdé alárùn kòrónà yóò máa lo̩ ní kánkán, a ó sì mú ìpadàbòsípò bá ètò ọrọ̀ ajé àtokòòwò láwo̩n ibì kan.
39.Síwájú síi, òfin tuntun táa s̩àgbékalè̩ káàkiri orílèèdè nìwọ̀nyí;
a.Àkókò àìjáde wà láti 8am si 6am. Èyí túmọ̀ sí wípé rírìn káàkiri yóò di èèwọ̀ láàrin àkókò yìí àfi àwọn òs̩ìs̩é̩ pàtàkì.
b.Kò ní sááyè fún ìrìnàjò aláìs̩epàtàkì láarin ìpínlẹ̀síìpínlẹ̀ títí di àkókò àìmò̩.
c.Gbígbé ẹrù alámòójútó láàrin ìpínlẹ̣̀síìpínlẹ̀ yóò wà díẹ̀ láti leè máa gbé àwọn ẹrù láti ilé-iṣé lọ sọ́dọ̀ àwọn tí yóò lò wọn.
d.A ó ri dájú wípé a fi dandan sí lílo ìbòjú ní ìta pẹ̀lú bí a ṣe ń fi ààyè sáàrín ara wa àti ìmọ́tótó. Ìjọba ìpínlẹ̀, àwọn onílé iṣẹ́ ńlá àti àwọn ẹlẹ́yinjú àánú la rọ̀ láti ṣe ìrànwọ ní pípèsè àwọn aso ìbòmú fún àwọn ọmọ orílẹ̀ èdè yí.
40.Nítorí iyèméjì, òfin kónílé-gbélé nílùú Àbújá, ìpínlẹ̀ Èkó àti Ògùn yóò wà títí di ìgbà tí àwọn òfin mìíràn yóó fi bẹ̀ẹ̀rẹ̀ lỌ́jọ́ ajé, ọjọ́ kẹrin oṣù karùn-ún, 2020.
41.Àwọn ikọ̀ ààrẹ yóò pèsè àwọn àlàyé kan fún ìmúra sílẹ̀ ìjọba, àwọn olókoòwò àti ilé iṣẹ́.
42.Níbàámu àwọn ìlànà òkè wò̩nyí, ìjọba ìpínlẹ̀ leè yàn láti faramọ́ àti láti fẹ̀ẹ́ lójú sii lórí onírúurú ìs̩è̩lè̩ àrò̩ò̩tò̩ tó bá súyo̩ kí wọ́n sáà ti wà níbàámu pẹ̀lú ìlànà àgbékalè̩ yìí.
43.Láti s̩èrànwó fún olókoòwò àtàwọn ọlọ́jà wa, àwọn tó wà nídìí owó yóò darí ìpèsè tó yẹ kíṣẹ́ leè tẹ̀síwájú, ká sì múṣẹ́ padàbò̩ sípò.
44.Àwọn ìlànà wọ̀nyí kò ní kan ìpínlẹ̀ Kano.
45.Níti ìpínlẹ̀ Kano, mo ti pàṣẹ kónílé-gbélé pátápátá fún òṣẹ̀ méjì ní kíákíá. Ìjọba àpapọ̀ yóò kó àwọn ènìyàn, ohun èlò àti àwọn irinṣẹ́ tí wọ́n nílò láti ran ìpínlẹ̀ náà lọ́wọ́ ní kíkápá àti bíborí àjàkálẹ̀ ààrùn kòrónà yìí pè̩lú dídènà rè̩ láti máa ràn lọ sí àwọn ìpínlẹ̀ tó múlé tìí.
46.Léèkan si, mo fẹ́ káwọn òṣìṣẹ́ tó ń léwájú jákèjádò orílèèdè yìí, àwọn tí wọ́n ń fi ohun gbogbo wéwu lójojúmọ́ láti borí ìjà yìí. Sáwọn tó kó ààrùn lójú iṣẹ́ wọn, ẹ fọkànbalẹ̀ wípé ìjọba yóò ṣohun gbogbo tó gbà láti ràn ẹ̀yin àti ẹbí yín lọ́wọ́ lákòókò tó le rékọjá yìí. Mo tún fẹ́ lo àǹfàní yìí láti fi dáa yín lójú wípé ààbò àti ìgbé-ayé àlàáfíà yín ló jẹ ìjọba yìí lógún.
47.Mo tún mo rírì àtìlẹyìn ta ti rígbà láti ọ̀dọ̀ àwọn Ọba wa, àwọn ẹgbẹ́ ọmọlẹ́yìn Krístì ní Nàìjíríà, àjọ tó gajù tó ń rí sí Islam àti àwọn àjọ ẹlẹ́sìn pẹ̀lú àwọn olórí agbègbè. Ìfọwọ́sowọ́pọ̀ àti àtìlẹyìn yín ti ran àseyọrí tí a ní lọ́wó
48.Màá rọ gbogbo yín láti jọ̀wọ́ tẹ̀síwájú láti máa sọ̀rọ̀ lórí ààrùn Kòrónà ní àárín àwọn olùjọ́sìn àti àwọn olùgbé agbègbè yín wípé kí wọ́n kíyèsí gbogbo ìmọ̀ràn àti ìmọ́tótó láwùjọ.
49.Mo dúpẹ̣́ lọ̣́wọ́ ẹ̣̣gbẹ̣́ àwọ̣n gómìnà, ikò̩ ìgbìmọ̀ ìjọba àpapọ̀ amójútó ààrùn COVID-19 fún iṣ̣ẹ́ ribiribi títí dòní. Pẹ̣̀lú ìfọwọ́sowọ́pọ̀ yìí, mo ní ìdánilójú pé, àseyọrí yóò wà.
50.Mo tún fẹ́ dúpẹ́ lọ́wọ́ àwọ̣̣n ilé-iṣ̣ẹ́ ńlá, aláàánú, àjọ̣ ìṣ̣ọ̣̣kan àgbáyé, àjọ̣ aláwọ̀ funfun, ọ̣̀rẹ́ orílèèdè yìí, akọ̣̣ròyìn àtàwọ̣̣n olùrànlọ̣́wọ́ wa fún àtìlẹ́yìn tí wọ̣̣n ń ṣ̣̣e fún wa.
51.Nípàárí, màá tún dúpẹ́ lọ̣́wọ́ gbogbo àwọ̣̣n ọ̣̣mọ̣ Nàìjíríà lé̩è̩kan si fún sùúrù àti ìfọ̣̣wọ̣́sowọ̣́pọ̀ lásìkò ìpèníjà yìí. Mo fi da yín lójú pé ìjọ̣̣ba yóò sa gbogbo ipá rẹ̀ láti gbégbèésẹ̀ nípa dídáàbò bò ẹ̀mí àtìwàláàyè gbogbo tonílé-tàlejò orílèèdè yìí.
52.Mo dúpẹ́ pé ẹ fetí sílẹ̀ fún mi, kỌ̣lọ́run bùkún fún orílèèdè Nàìjíríà.
--- Ààbò ọ̣̣mọ̣ Nàìjíríà ló jẹ̣ mí lógún jùlọ – Ààrẹ Buhari
"Ààrẹ orílèèdè Nàìjíríà, Muhammadu Buhari ti sọ pé ètò ààbò ọmọ orílèèdè Nàìjíríà ló jẹ òun lógún jùlọ ""pàápàá jùlọ̣ ní àsìkò tí ìpèníjà àti àìròtẹ́lẹ̀ wọ̀nyí wà""."
Ààrẹ̣ sọ̀yí lórí te̩lifís̩àn lásìkò tó ń bá ọ̣̣mọ̣ Nàìjíríà sọ̣̀rọ̀ lọ̣́jọ́ Ajé, 27th of April, 2020.
Ààrẹ Buhari níjọ̀ó̩ba òun rí sáàbò ẹ̣̀mí àti dúkìá àwọ̣̣n ènìyàn, ìjọba òun kò sì ní fààyè gba ìwà títẹ̣ ẹ̣̀tọ́ọ̣̣́mọ̣̣nìyàn lójú látọ̣wọ́ àwọ̣̣n agbófinró.
Ìròyìn tí mo gbọ́ banújẹ́ lọ̣̣́pọ̣̀lọ̣̣pọ̣̀, mo fi ń dá ọmọ orílèèdè Nàìjíríà lójú pé, àwọn ẹ̣̣lẹ̣́sẹ̀ kò ní lọ̣ láìjìyà lábẹ́ òfin.
Ààrẹ wá rọ̣ gbogbo ọ̣̣mọ̣ orílèèdè Nàìjíríà láti fọ̣̣wọ̣́sowọ̣́pọ̣̀ pẹ̣̣̀lú àwọ̣̣n agbófinró lásìkò ìpàdé pè̩lú wọ̣̣n.
--- COVID-19: Ààrẹ Buhari pàṣ̣ẹ ètò kónílé-gbélé nípìnínlẹ̀ Kánò
Ààrẹ̣ Nàìjíríà, Muhammadu Buhari ti pàṣ̣ẹ kétò kónílé-gbélé bẹ̣̀rẹ̀ nípìnínlẹ̀ Kánò, Àríwá Ìwọ̣̀-Oòrùn Nàìjíríà látàrí báwọ̣̣n ènìyàn se ń kúkú òjijì nípìnínlẹ̀ náà.
Ààrẹ Buhari so̩ ọ̣̀rọ̣̀ yíi lórí ẹ̣̀rọ̣ a-móhùn-máwòrán pé ètò kónílé-gbélé ọ̣̀hún yóò wà fún ọ̣̀sẹ̀ méjì gbáko ní kánkán, ní ìpínlẹ̣̀ Kánò.
"Ààrẹ̣ tún sọ̣ pé ""Ìjọ̣̣ba àpapọ̀ yóò fàwọ̣̣n irinṣ̣ẹ́ àti òṣ̣ìṣ̣ẹ́ ránsẹ́ sí ìpínlẹ̀ Kánò láti ran ìpínlẹ̀ ọ̀hún lọ̣́wọ̣́, lọ̣́nà àtidẹ̣́kun ààrùn Kòrónà, kó má baà tàn lọ̣ sí ìpínlẹ̀ mìíràn tó sún mọ́ wọ̣̣n."""
Ààrẹ̣ tún sọ̣ pé àwọ̣̣n arìnrìnàjò láti ìpínlẹ̀ kan lọ̣ sí ìpínlẹ̀ mìíràn ló fa ìtànkálẹ̀ ààrùn tí ó wáyé ní ìpínlẹ̀ Kánò.
--- NIS gbo̩mọ̣̣̣̣ Nàìjíríà mẹ́tàlá tó ń ti Tógò bò̩
Ile-iṣ̣ẹ́ amójútó arìnrìnàjò Nàìjíríà (NIS) ní àwọ̣̣n ọ̣̣mọ̣ orílèèdè yìí mẹ́tàlá làwọ̣̣n ti rí gbà láti orílèèdè Lòmè, Tógò àti Seme-Krake.
Agbẹnusọ̣ NIS náà, ọ̣̀gbẹ́ni Sunday James ló sọ̣̣̀yí nínú àtẹ̣̀jáde kan lọ̣́jọ́ Àìkú nílùú Àbújá, láwọ̣̣n tó padà wá sílé jẹ́ akọ́sẹ́mọsẹ́ tí wọ̣̣n lọ̣ ṣ̣iṣ̣ẹ́ nílées̩ẹ́ kan ni Tógò.
Gẹ́gẹ́ bí ọ̣̀gbẹ́ni James ṣ̣e ṣ̣ọ, ó làwọ̣̣n ènìyàn mẹ́tàlá ọ̣̀hún ni wọ̣́n ti fà fún eléètò ìlera Èkó fún àyẹ̣̀wò Corona.
"Ó ní, ""Bákan náà la tún sọ̣ fún wọ̣̣n pé kí wọ̣̣́n wà nígbèèélé gẹ́gẹ́ bílànà àjọ̣ agbógun tàjàkálẹ̀ ààrùn (NCDC) ṣ̣̣e làá sílẹ̀ fún àwọ̣̣n tí wọ̣́n bá ṣ̣ẹ̣̀ṣẹ̀ dé láti ilẹ̀ òkèèrè, lèyí láti dẹ́kun ààrùn Corona."""
James lẹ́nubodè Seme-Krake jẹ́ ojú ọ̀nà tó gba Nàìjíríà wọ̣̣lé tàbí jáde, tó sì tún pààlà pẹ̀lú orílèèdè Benin. Ó ní NIS kò káàrẹ́ láti mójútó àwọ̣̣n ẹ̣nubodè wọ̀nyí.
Ó ní NIS máa mú àwọ̣̣̣n tí ó bá fẹ́ gba ọ̀nà ẹ̀bùrú láti wọ̣̣̣lé sí orílè̩ èdè Nàìjíríà, nítorí náà iye àwo̩n tó ń gba e̩nu ibodè Seme-Krake ti peléke si.
Ó ní adarí NIS gbogboòògbò, ìye̩n ọ̀gbẹ́ni Muhammad Bàbándédè ti rọ̣ àwọ̣̣n arìnrìnàjò tó ń padabò̩ wá sí orílèèdè Nàìjíríà láti ṣ̣ọ̣́ra nípa gbígba ọ̀nà ẹ̀bùrú, nítorí àwọ̣n ọ̀daràn àti oníṣẹ́-ibi tí ó leè ṣe wọ̣̣̣́n ní ìjàmbá.
--- Ààrẹ Buhari yóò bọ́mọ orílèèdè sọ̀rọ̀ lágogo mẹ́jọ àsálẹ́.
Ààrẹ Muhammadu Buhari yóò bá o̩mo̩ orílèèdè Nàìjíríà sọ̣̀rọ̣̀ lónìí Mó̩ńdè, April 27, ni aago mé̩jo̩ alé̩.
Àwo̩n ilé-is̩é̩ Te̩lifís̩àn, Rédíò àti àwọn ẹ̀rọ agbóhùnsáfé̩fé̩ mìíràn ni wó̩n rò̩ láti darapọ̀ mọ́ ẹ̀rọ alátagbà amóhùnmáwòrán ti àkó̩kó̩ ní orílè̩ èdè Nàìjíríà (NTA) àti asọ̀rọ̀mágbèsì ìjọba àpapọ̀ (FRCN) fún ìkéde yìí.
Ohun Nàìjíríà náà yóò gbesáfé̩fé̩ lórí ẹ̀rọ abẹ́yẹfò.
Ẹ tèlé wa lórí VON Social Media handles:
--- Ààrẹ Buhari yóò bá Nàìjíríà ṣ̣ọ̣̀rọ̀ lónìí: Ǹjẹ́ ààrẹ yóò fòpin ṣí òfin kónílé -gbélè tàbí yóò tún fi ọjọ́ kún un
Ààrẹ Nàìjíríà, Muhammadu Buhari yóò máa bá orílèèdè Nàìjíríà sọ̣̀rọ̣̀ lónìí yìí, Monday, April 27, 2020 ni 8pm.
Gbogbo ọ̣mọ̣̣ Nàìjíríà ni wọ̣́n fẹ́ gbọ́ ohun tíi ààrẹ Buhari yóò sọ̣ nípa ètò kónílégbélé.
Olùrànlọ̣́wọ́ ààrẹ lórí ìròyìn àti ìkéde ló kéde yìí.
--- Ilé-ìgbìmọ̀ aṣ̣ojú yóò padà sẹ̣́nusẹ́ ní April 28
Ilé-ìgbìmọ̀ aṣ̣ojú Nàìjíríà yóò padà ṣ̣ẹ̣́nuṣ̣ẹ́ ló̩jó̩ ìs̩e̩gun lẹ̣́yìn ìsinmi oṣ̣̣ù kan tí wọ̣́n wà látàrí ààrùn Covid-19 tó ṣ̣ẹ̣̣lẹ̀ lórílẹ̀ èdè Nàìjíríà.
Lọ̣́jọ́ kẹ̣̣rìnlélógún, oṣ̣ù kẹ̣̣ta nilé ìgbìmọ̀ asojú kọ́kọ́ bẹ̣̣̀rẹ̀ ìsinmi ọlọ́sẹ̀ méjì wọ̣́n láti leè jẹ́ kígbìmọ̀ tó ń mójútó ilé –asòfin pèsè ààbò tó múnádóko tí yóò dẹ̣́kun ìtànkálẹ̀ ààrùn COIVD-19 nilé-asòfin ọ̀hún sùgbọ̣́n lẹ̣́yìn ọ̣̀sẹ̀ kan tí wọ́n bẹ̀rẹ̀ ìsinmi nìjọba àpapọ̀ pàsẹ pé kí ètò kónílé-gbélé bẹ̣̀rẹ̀ nílùú Àbújá àtàwọ̣n ìpínlẹ̀ méjì táàrùn COIVD-19 ń bá wọ̀yá ìjà.
Nínú àtẹ̀jáde kan tákọ̀wé ilé-ìgbìmọ̀ asojú ọ̀hún, ọ̀gbẹ́ni Patrick Gíwá gbéjáde láti gbàwọ̣̣n ọ̣̣mọ̣̣ ìgbìmọ̀ aṣ̣ojú náà nímọ̀ràn láti tẹ̣̣̀lé ètò ìlànà tíjọ̣̣ba àpapọ̀ àtàjọ̣̣ tó ń gbógun tàjàkálẹ̀ ààrùn ní Nàìjíríà là sílẹ̀ àtètò ìlànà tílé-ìgbìmọ̀ aṣ̣ojú làà sílẹ̀, léyìí táwọ̣̣n yóò fi ránṣ̣ẹ́ sáwọ̣̣n ọ̣̣mọ̣̣ ilé-ìgbìmọ̀ asojú ọ̣̣̀hún.
"Àtẹ̣̣̀jáde náà ní káwọ̣̣n olùrànlọ̣̣́wọ̣̣́ àtòṣ̣ìṣ̣ẹ́ ilé-ìgbìmọ̀ aṣ̣òfin sì dúró sílé láti máa ṣ̣iṣ̣ẹ́ wọ̣̣n àti pé ""a ó pè wọ̣̣́n ta bá nílò ìrànlọ́wọ́ wọ̣̣n fúnsẹ́ pàtàkì kan níléesẹ́."""
Táwọ̣n ọ̣̣mọ̣̣ ilé –ìgbìmọ̀ aṣ̣ojú ọ̀hún bá wọ̣̣lé, wọ̣̣n yóò máa jíròrò lórí ìgbésẹ̀ láti gbógun ti ààrùn Corona àti lórí ètò ọ̣̀rọ̣̀ ajẹ́ orílèèdè yìí.
--- Ìjọba àpapọ̣̣̀ ń ṣe ìwádìí alárùn kòrónà ní ìpínlẹ̀ Kánò- Mínísítà
Mínísítà fún ètò ìlera ní orílè̩ èdè Nàìjíríà, Osagie Ehanire, ti sọ pé ìjọ̣̣ba àpapọ̣̣̀ àti ìjọ̣̣ba ìpínlẹ̀ Kánò ti ń s̩e ìwádìí ní Kano pè̩lú às̩e̩ wo̩n, ó ní ilé-is̩é ò̩hún yóò rán àwo̩n adarí awérìí nínú ìwádìí.
Ehanire ní ikò̩ tó ń s̩is̩é̩ ìwé̩rìí nínú ìwádìí yóò ṣ̣e ìpàdé pẹ̣̣̀lú gómìnà Kánò láti so̩ irú ìs̩è̩lè̩ ọ̀hún, ó sì fi kún-un pé kò dájú pé kòrónà ni.
Ehanire tún láwọ̣̣n ikọ̀ náà yóò máa ṣàyẹ̀wò, ìyàsọ̣́tọ̀, ìtọpinpin àwọ̣̣n alárùn ọ̀hún, láti mọ̀nà tí wọ̣̣n yóò gbà láti métò ìdàgbàsókè báwọ̣̣n ètò ìlànà àti yàrá àyẹ̀wò tó ti wá ní ìpínlẹ̀ náà.
Kánò kò nírìírí nípa ààrùn COVID-19 tẹ̣́lẹ̣̀rí, ìyàlẹ̣̣́nu ló sì ye̩ kó jẹ́ fún wa báàrùn COVID-19 se tànkálẹ̀.
Ó se é se, kí a leè dẹ́kun ààrùn yìí tí a bá lo àwọ̣̣n irinṣẹ́ àti àwọ̣̣n ènìyàn tó múná-dóko.
Mínísítà ní Èkó tó lérò bíi ìpínlẹ̀ Kánò láwọ̣̣n irinṣ̣ẹ́ tó múnádóko àti pé ìpínlẹ̀ Èkó tètè dojúkọ̣̣ ààrùn Corona nítorí ìrírí tí wọ̣̣́n ní nípa ààrùn Èbólà tó ṣ̣ẹ̣̣lẹ̀ lọ́dún 2014.
Mínísítà tẹ̣̣̀síwájú pé àwọ̣̣n èròjà àti irinṣ̣ẹ́ típìnínlẹ̀ Kánò ní, bó tilẹ̀ jẹ́ pé wọ̣́n ń gbìyànju, a kò le fi ìpínlẹ̀ Èkó wé ìpínlẹ̀ Kánò, nítorí pé àwọ̣̣n òṣ̣ìṣ̣é àtirinṣ̣ẹ́ tí ìpínlẹ̀ Èkó ní, ìpínlẹ̀ Kánò kò níi.
Ehanire ní ogójì òṣ̣ìṣ̣ẹ́ ètò ìlera ni wọ̣̣̣́n ti láárùn kòrónà ní Nàìjíríà, s̩ùgbó̩n ibi-is̩é̩ kó̩ ni wó̩n ti kó o.
Ilé-iṣẹ́ Agbóhùnsáfẹ́fẹ́ Ìbílẹ̀ Fagilé Ìfọ̀rọ̀wọ́rọ̀ pẹ̀lú àwọn ajìjàǹgbara LGBT lẹ́yìn ìhalẹ̀mọ́ sí olóòtú
Àwọn ajìjàǹgbara ní Madrid fi ẹ̀hónú hàn lórí ìrúfin ẹ̀tọ́ LGBT ní Russia
Ilé-iṣẹ́ Echo ti Moscow ní Yaroslavl tí ó jẹ́ ẹ̀ka ilé-iṣẹ́ Agbóhùnsáfẹ́fẹ́ Echo ti Moscow ìsopọ̀ tí ó ti dá dúró fún ìgbà pípẹ́ ní Russia fagi lé ìfọ̀rọ̀wọ́rọ̀ pẹ̀lú àwọn ajìjàǹgbara LGBT lẹ́yìn tí wọ́n gba ìhalẹ̀ láti ọ̀dọ̀ àwọn tí ó kórìíra-ìbálòpọ̀-láàárín-akọ-àti-akọ, olóòtú ilé-iṣẹ́ náà Lyudmila Shabuyeva sọ̀rọ̀ nínú àkọsílẹ̀ Facebook kan:
Ìtúmọ̀ Ìtúnwí-ọ̀rọ̀ Ọlọ́rọ̀ gan-an
Ní àná, a gba ìhàlẹ̀ kan tí ó ń lérí mọ́ àwa àti àwọn àlejòo wa tí a bá tẹ̀síwajú pẹ̀lú ètò ìfọ̀rọ̀wọ́rọ̀ọ wa nípa LGBT.
Mò ń fagi lé ètò náà.
Gẹ́gẹ́ bí ìwé ìròyìn tí ò sí ní abẹ́ ìṣàkóso ìjọba Novaya Gazeta ti ṣe sọ, ó yẹ kí ètò náà tí yóò ṣe àfihàn àwọn ajìjàǹgbara LGBT ní Yaroslavl wáyé ní òwúrọ̀ Ọjọ́rú 23, ní oṣù Ṣẹẹrẹ.
Àwọn ajìjàǹgbara yìí kan náà ṣẹ̀ṣẹ̀ fi ẹ̀hónú hàn ní gbàgede ìlú láti tako ìfìyàjẹ àwọn aṣe-ìbálòpọ̀-akọ-àti-akọ ní Russia, pàápàá jùlọ ní orílẹ̀ Chechnya.
Ilé-iṣẹ́ agbóhùnsáfẹ́fẹ́ náà pè wọ́n láti fi ọ̀rọ̀ wá wọn lẹ́nu wò nípa ìfẹ̀hónúhàn àti ìrírí wọn fún jíjáde sí gbangba gẹ́gẹ́ bíi aṣe-ìbálòpọ̀-akọ-àti-akọ ní ẹ̀ka-ìlúu Russia.
Ìkéde Shebuyeva àkọ́kọ́ nípa ètò náà fa ẹgbẹlẹmùkù èébú ìkórìíra-ìbálòpọ̀-láàárín-akọ́-àti-akọ nínú àwọn èsì, tí èsì sì wá láti ọ̀dọ̀ àwọn òṣìṣẹ́ ọba kan bákan náà, ṣùgbọ́n ìyẹn ò mú ọkàn-an rẹ̀ kúrò, ó sọ fún Novaya Gazeta.
Ṣùgbọ́n ní alẹ́ ọjọ́ tí ètò náà ku ọ̀la, Shabuyeva sọ̀rọ̀ pé òun gba ìpè àjèjì láti orí òpó ẹ̀rọ-ìbánisọ̀rọ̀ kan tí kò ṣe é dámọ̀, ẹni náà sì sọ fún òun pé bí òun bá tẹ̀síwajú pẹ̀lú ètò náà bí ó ṣe ti pinnu, wọ́n máa fi igi ìgbábọ́ọ̀lù-afọwọ́jù pàdé àwọn àlejò rẹ ní ìta ilé-iṣẹ́ náà.
Òun náà sì lè kojúu wàhálà, onípè àjèjì náà léríléka.
Nítorí ìbẹ̀rù fún ààbò àwọn àlejòo rẹ̀, Shabuyeva fagilé ìfọ̀rọ̀wánilẹ́nuwò náà tí ó sì fi ètò mìíràn rọ́pòo rẹ̀.
Ìfẹ̀hónúhàn tí ó wáyé ní gbàgede ìlú wà lára ìkéde gbogboògbò #saveLGBTinRussia tí wọ́n fi ń polongo ìyà tí ó rorò tí wọ́n fi ń jẹ àwọn ènìyàn aṣe-ìbálòpọ̀-akọ-àti-akọ ní orílẹ̀ Chechnya.
Àwọn ìwọ́de àti ìfẹ̀hónúhàn irú èyí wáyé ní àwọn ìlú mìíràn ní Russia.
Ìlú ń ké pe àwọn ọmọ rẹ̀ (àwọn ọmọ ìlú) láti dojú ìjà kọ ìwà elẹ́yàmẹyà àti ìtẹ̀mọ́lẹ̀ ní Russia òde-òní.
Jẹ́ kí ìpèe rẹ̀ ta ọ́ jí!
[àmì náà ń sọ pé: Ẹ̀KA ÌṢÈDÁJỌ́ TI ORÍLẸ̀-ÈDÈE RUSSIA Ò RÍ ÀWỌN AṢE-ÌBÁLÒPỌ̀-AKỌ-ÀTI-AKỌ NÍ CHECHYA.
WỌ́N WÀ NÍBẸ̀: NÍNÚ ÀWỌN ỌGBÀ Ẹ̀WỌ̀N ÀTI IBOJÌ-ÒKÚ.
#SAVELGBTINRUSSIA Ẹ̀TANÚ ÌBÁLÒPỌ̀-LÁÀÁRÍN-AKỌ-ÀTI-AKỌ = ÌJỌBA AFIPÁMÚNI
Nínú oṣù Igbe 2017, Novaya Gazeta jábọ̀ pé àwọn aláṣẹ ní Chechnya, ti ìlú oníjọba Ìmọ́lẹ̀ tí ó ń rí ìdààmú jù ní gúúsù Russia tí ajagun fẹ̀yìntì Ramzan Kadyrov, ń ṣe olóríi rẹ̀, ń ṣe ìpolongo tí ó rorò tí ó ń tako ìtẹ̀mọ́lẹ̀ àwọn ènìyàn tí í ṣe LGBT tí ó ń gbé nínúu rẹ̀.
"Ìròyìn tí ó jáde ní àìpẹ́ sọ pé ""ìfọ̀mọ́ "" náà le gidi gan-an ni, pẹ̀lú ikú èèyàn méjì ó kéré tán àti ogunlọ́gọ̀ àwọn tí ó wà ní àtìmọ́lé tí ó lòdì sí òfin."
#FreeAmade: Akọ̀ròyìn tí a mú tí a sì dá lóró lẹ́yìn tí ó kọ ìròyìn lórí ìwà jàgídí jàgan tí ó ń ṣẹlẹ̀ ní Àríwá Mozambique
Àwọn ẹni-orí-kó-yọ tí wọ́n pàdánù ẹbí àti ilé ń sinmi níta gbangba lẹ́yìn ìkọlù ọjọ́ 5 oṣù Òkúdù ní abúlé Naunde ní Cabo Delgado nílùú Mozambique.
Àwòrán láti ọwọ́ Borges Nhamira pẹ̀lú àṣẹ ìlò.
Wọ́n mú akọ̀ròyìn Mozambique kan ní ọjọ́ 5 oṣù Ṣẹẹrẹ níbi tí ó ti ń jábọ̀ ìròyìn nípa ìkọlù tí ó ń dé bá àwọn abúlé kéréje ní ìgbèríko Cabo Delgado ní Mozambique.
Cabo Delgado wà ní àríwá orílè-èdè Mozambique, ó kún fún àwọn ohun àlùmọ́nì bí i òkúta iyebíye, èédú àti afẹ́fẹ́ gáàsì tí wọ́n rí ní Rovuma, ilẹ tí omí yí ká.
Àwọn olùkíyèsí sọ pé ẹgbẹ́ tí ó ń darí ìkọlù yìí ní i lọ́kàn láti máa jí àwọn ohun àlùmọ́nì yìí kó.
Láti oṣù Ọ̀wàrà 2017, àìmọye ìkọlù ni ó ti wáyé ní oríṣiríṣìí ìgbèríko ní Cabo Delgado láti ọwọ́ àwọn ẹgbẹ́ jàndùkú kan náà.
Ọ̀pọ̀lọpọ̀ àwọn iléeṣẹ́ ìròyìn ni wọ́n ti jábọ̀ lórí àwọn ìkọlù yìí ṣùgbọ́n kò tilẹ̀ wu àwọn ìjọba láti sọ̀rọ̀ lé e tàbí kí wọ́n fi ìdí àrídájú ẹ̀rí múlẹ̀ nínú àwọn ọ̀rọ̀ yìí.
Ní 2018, èèyàn tó lé lọ́gọ́rùn-ún ni wọ́n bá ṣẹjọ́ lórí àwọn ọ̀ràn yìí. Ó yẹ kí ẹjọ́ọ wọn ó parí lọ́dún yìí.
#FreeAmade: Ìpolongo láti gba Akọ̀ròyìn Mozambique sílẹ̀
Amade Abubacar ń ṣiṣẹ́ pẹ̀lú Mozambican Social Communication Institute, ó sì ń ṣiṣẹ́ gẹ́gẹ́ bí akọ̀ròyìn pẹ̀lú ibùdó ìròyìn orí ayélujára Zitamar àti iléeṣẹ́ ìgbóhùnsáfẹ́fẹ́ ìbílẹ̀ Nacedje.
Àwọn ọlọ́pàá ìjọba àpapọ̀ Mozambique mú akọ̀ròyìn náà ní ọjọ́ 5 níbi tí ó ti ń ya àwòrán àwọn ẹni-orí-kó-yọ nínú ìkọlù kan ní Cabo Delgado, wọ́n sì tì í mọ́lé.
Lẹ́yìn náà, wọ́n mú Amade lọ sí ibùdó àwọn ológun Mozambique ní ìgbèríko Mueda láìjẹ́ ọmọ ẹgbẹ́ ológun.
Lẹ́yìn ọ̀sẹ̀ díẹ̀, wọ́n gbé e lọ sí ẹ̀wọ̀n gbogboògbò láti mú kí àtìmọ́lé rẹ̀ bá òfin mu ní Pemba, olú ìlú Cabo Delgado.
Lẹ́yìn tí ó dé ẹ̀wọ̀n gbogboògbò, Amade pe ẹgbẹ́ àwọn agbẹjọ́rò Mozambique tí ó sì sọ bí ó ṣe ti jìyà tó lọ́wọ́ àwọn ológun Mozambique tí ó ní wọ́n na òun tí wọ́n sì fi ebi pa òun.
Ọ̀pọ̀lọpọ̀ èèyàn àti ẹgbẹ́ ajàfómìnira ti sọ̀rọ̀ síta láti gbèjà Abubacar tí wọ́n sọ pé mímú tí wọ́n mú un àti àtìmọ́lée rẹ̀ ti dẹ́rùba òmìnira ẹni láti sọ̀rọ̀.
Ìfilọ́lẹ̀ Agbéròyìn Sáfẹ́fẹ́ ti Gúúsù Ilẹ̀ Adúláwò, tí ó ń ṣe àbójútó ẹ̀tọ́ agbéròyìn sáfẹ́fẹ́ àti iṣẹ́ wọn ní agbègbè náà sọ̀rọ̀ tako àtìmọ́lé Amade:
Títì tí àwọn ológun ti Abubacar mọ́lé jẹ́ ìpalára fún ẹ̀tọ́ rẹ pẹ̀lú mímú tí wọ́n mú un láìsí ìdí tí wọ́n fi ìdí ẹ múlẹ̀.
Ìjọba Mozambique ti ń ṣe àfihàn ìṣáájú burúkú nípa ṣíṣe ìdíwọ́ ẹ̀tọ́ ẹni láti sọ̀rọ̀ àti rírí ọ̀nà gbọ́ ìròyìn ní agbègbè náà.
Amnesty International náà sọ̀rọ̀:
Ìtúmọ̀ Ìtúnwí-ọ̀rọ̀ Ọlọ́rọ̀ gan-an
Amade Abubacar Amade Abubacar jẹ́ gbajúgbajà akọ̀ròyìn tí ó ń gba ẹ̀rí sílẹ̀ lẹ́nu àwọn ẹni tí wọ́n bọ́ nínú ìkọlù ní Cabo Delgado nígbà tí àwọn ọlọ́pàá mú un.
Èyí jẹ́ àfihàn àìkàsí àwọn aláṣẹ Mozambique sí òmìnira láti sọ̀rọ̀ àti òmìnira àwọn oníròyìn... [àwọn aláṣẹ] rí akọ̀ròyìn gẹ́gẹ́ bí alátakò wọn [fún ìdí èyí] wọ́n ń ṣe wọ́n bí ọ̀daràn.
Ìpolongo náà ti tàn lórí Twitter, pẹ̀lú ìṣẹ̀dá àwọn àsopọ̀ ọ̀rọ̀ bí i #FreeAmade láti jà fún ìdásílẹ̀ Amade.
Fún ìgbà àkọ́kọ́ ní orílẹ̀-èdèe Brazil, ọmọ ìbílẹ̀ lóbìnrin di ọmọ ìgbìmọ̀ ìjọba
Joenia ni ọmọ ìbílẹ̀ lóbìnrin àkọ́kọ́ tí ó kẹ́kọ̀ọ́ gboyè nínú ẹ̀kọ́ ìmọ̀ òfin ní Brazil.
Àwòrán: Àwòrán tí wọ́n yà nínú fídíò kan láti ọwọ́ọ United Nations Web TV.
Ní ọdún-un 1997, Joenia Wapichana di obìnrin àkọ́kọ́ tí yóò gboyè nínú ẹ̀kọ́ ìmọ̀ òfin ní Brazil.
Lẹ́yìn ọdún kọ́kànlá, òun ni ọmọ ìbílẹ̀ àkọ́kọ́ tí ó gbẹjọ́rò ní ilé-ẹjọ́ gíga jùlọ.
Ní oṣù Ọ̀wàrà ọdún-un 2018, Joenia tún gbajúmọ̀ sí i nígbà tí ó di ọmọ ìbílẹ̀ lóbìnrin àkọ́kọ́ tí wọn yóò yàn sípò nínú ìgbìmọ̀ ìjọba.
Ìbòo 8,491 tí wọ́n dì fún un ni wọ́n fi yàn án sípò kan nínúu mẹ́jọ tí ó tọ́ sí ìpínlẹ̀ Roraima tí ó ti wá.
Ìgbà kan ṣoṣo tí Brazil ní ọmọ ìbílẹ̀ gẹ́gẹ́ bí ọkàn lára àwọn ìgbìmọ̀ ìjọba ni ọdún-un 1986 — Mario Juruna, tí ó wá láti ẹ̀yà Xavante, wọ́n yàn án sípò ní ọdún-un 1983.
A bí Joana sínú ẹ̀yà Wapichana, ó lọ sí Boa Vista tí ó jẹ́ olú-ìlú Roraima nígbà tí ó wà ní ọmọ ọdún mẹ́jọ.
Ó ń kọ́ ẹ̀kọ́ọ rẹ̀ nínú ìmọ̀ òfin bí ó ṣe ń ṣiṣẹ́ ní ọ́fíìsì àwọn oníṣirò kan, ó sì sọ ọ́ nínú ìfọ̀rọ̀wánilẹ́nuwò kan láìpẹ́, pé òun ṣetán ní ilé-ẹ̀kọ́ ní ọdún kan ṣáájú ìgbà tí ó yẹ kí òun ṣetán tí òun sì gbé ipò karùn-ún nínúu kíláàsìi rẹ̀ àti láàárín-in àwọn ọmọ ọlọ́lá ní Roraima.
Ní oṣù Ọ̀pẹ ọdún-un 2018, gẹ́gẹ́ bí ọmọ ẹgbẹ́ ìgbìmọ̀ tí wọ́n dìbò yàn, Joenia gba àmì ẹ̀yẹ ìdánimọ̀ UN fún ìjàfẹ́tọ̀ọ́ ẹ̀dá lórí àṣeyọrí tí ó ṣe nínú ìpolongo ẹ̀tọ́ àwọn ọmọ ìbílẹ̀.
Wọ́n ti fi àmì-ẹ̀yẹ ìdánimọ̀ yìí kan náà fún Nelson Mandela àti Malala rí.
Joenia Wapichana níbi tí ó ti ń gbè lẹ́yìn ọ̀rọ̀ ìbílẹ̀ kan ní ilé-ẹjọ́ gíga jùlọ.
Àwòrán: Àwòrán tí wọ́n yà nínú fídíò YouTube ilé-ẹjọ́ gíga jùlọ ti Brazil.
Joênia ṣe àfikún ìtàn ní ọdún-un 2008 nígbà tí ó gba ẹjọ́ ẹgbẹ́ ìbílẹ̀ márùn-ún kan rò, pé kí wọn ya ilẹ̀ẹ wọn sọ́tọ̀ gẹ́gẹ́ bí ilẹ̀ abínibí, irú òfin tí yóò fún àwọn abínibí ilẹ̀ náà ní ẹ̀tọ́ láti pàṣẹ lórí àwọn ilẹ̀ ìlúu wọn.
Ilé ẹjọ́ dá ẹjọ́ tí ó gbè lẹ́yìn àwọn ẹgbẹ́ ìbílẹ̀ náà tí wọ́n ti wá di òǹnilẹ̀ kánrin-kése fún àwọn ilẹ̀ abínibí tí ó tóbi jù ní Brazil — ilẹ̀ẹ Raposa Terra do Sol, tí ó wà ní ìpínlẹ̀ Roraima.
Bẹ́ẹ̀, Jair Bolsonaro tí ó jẹ́ ọmọ ẹgbẹ́ ìgbìmọ̀ ní àkókò náà ti fi ìwọ̀sí lọ ajàfẹ́tọ̀ọ́ ìbílẹ̀ kan tí ó wá sí ibi gbígbọ́ ìdájọ́ nípa ìyàsọ́tọ̀ Raposa Terra do Sol ní ìyẹ̀wù àwọn igbá-kejì.
"Bolsonaro sọ̀rọ̀ báyìí ní ọjọ́ náà pé ""ó yẹ kí o jáde síta láti lọ jẹ koríko pẹ̀lú àwọn alálẹ̀ẹ yín""."
Kò pẹ́ lẹ́yìn tí ó jáwé olúborí nínú ìdìbò 2018, Bolsonaro tún mú ọ̀rọ̀ Raposa Terra do Sol bọnu gẹ́gẹ́ bí àpẹẹrẹ agbègbè ìbílẹ̀ tí ó yẹ kí àwọn jẹ àǹfààní ètò ọrọ̀-ajée rẹ̀.
Ó sọ fún àwọn akọ̀ròyìn pé:
Ìtúmọ̀ Ìtúnwí-ọ̀rọ̀ Ọlọ́rọ̀ gan-an
Ó jẹ́ agbègbè kan tí ó lọ́rọ̀ jù ní àgbáyé. Èèyàn lè jẹ àǹfààní rẹ̀ lọ́nà tó mọ́gbọ́n dání.
Nípa ti àwọn ọmọ bíbí ibẹ̀, à á fún wọn ní ohun tí ó tọ́ sí wọn, à á sì dà wọ́n pọ̀ mọ́ àwùjọ.
Lọ́dún mẹ́wàá sẹ́yìn, pẹ̀lú ọ̀dà pupa lójúu rẹ̀, ní ìbámu pẹ̀lú àṣà ẹ̀yàa rẹ̀ ni Joenia lo èdè Portuguese àti ẹ̀ka-èdèe rẹ̀ láti rán àwọn adájọ́ létí pé bíi mílíọ̀nù dọ́là US lọ́nà mẹ́ta ni ó ń kárí àwọn ilẹ̀ wọ̀nyí láìsí pé wọ́n kópa nínú ètò ọrọ̀-ajée Brazil.
"Ó ní ""wọ́n ń sọ̀rọ̀ bà wá lórúkọ jẹ́, bẹ́ẹ̀ ni wọ́n ń ṣe ìyàtọ̀ọ̀tọ̀ ẹ̀yà pẹ̀lúu wa ní ilẹ̀ẹ wa""."
Àwòrán: Àjọ tí ó ń rí sí ààbò gbogboògbò, CC 2.0
Alátakò tí kò ṣe é borí
Bí ó ṣe ń gbaradì láti gba ìjókòó rẹ̀ nínú ìgbìmọ̀ ìjọba gẹ́gẹ́ bí alátakò fún ìjọba Bolsonaro, ó sọ fún àwọn akọ̀ròyìn Folha de São Paulo, tí ó jẹ́ ilé iṣẹ́ oníwèé ìròyìn tó gbajúgbajà ní orílẹ̀-èdè pé:
Ìtúmọ̀ Ìtúnwí-ọ̀rọ̀ Ọlọ́rọ̀ gan-an
Kí ló dé tí ó [Bolsonaro] ṣe ń ṣe inúnibíni sí àwọn ọmọ ìbílẹ̀ tó báyìí?
Kí ni ìdí fún ìkórìíra àti òǹgbẹ fún ìṣubúu wa?
A ní ètò ìrìnàjò ìgbafẹ́, òògùn ìbílẹ̀ àti àwọn ohun mèremère tí ó pín yẹ́lẹyẹ̀lẹ káàkiri ilẹ̀ẹ wa.
A nílò láti ṣe àyípadà ìgbàgbọ́ pé à ń ṣe ìdíwọ́ fún ìdàgbàsókè tàbí pé à ń ṣe ìpalára fún ẹnikẹ́ni.
Àwa náà ní láti di aṣíwájú fún ara wa.
Ìfẹsẹ̀múlẹ̀ tí ó ń lọ
Ìgbìmọ̀ Brazil gba ipò ní oṣù Èrèlé 2019, Joênia sì bẹ̀rẹ̀ sáà rẹ̀ gẹ́gẹ́ bí olùdarí ẹgbẹ́ òṣèlú rẹ̀, Rede Sustentabilidade (tí ó túmọ̀ sí Ẹgbẹ́ Alágbèéró lédè Portuguese) ní ìyẹ̀wù àwọn igbá-kejì ti ilé ìgbìmọ̀ aṣòfin kékeré.
Olùṣàkóso fún ètò àyíká tẹ́lẹ̀ rí Marina Silva, tí orúkọ rẹ̀ gbajúmọ̀ nínú ìjàfẹ́tọ̀ọ́ agbègbè ni ó dá Rede sílẹ̀ pẹ̀lú bí ó ti ṣe fìdírẹmi tó nínú ètò ìdìbò ààrẹ lẹ́ẹ̀mẹ́ta léraléra.
"Lẹ́yìn àjálù ìdídò ní Brumadinho, tí ó pa àwọn èèyàn tí ó lé ní 160, tí ó sì mú ìbàjẹ́ bá gbogbo ayé tí ó wà ní odò Paraopeba, Joenia ṣe àgbékalẹ̀ àkọsílẹ̀ àbá òfin rẹ̀ àkọ́kọ́, tí ó ń ka àwọn ọ̀ràn tí ó ń ṣe ìpalára fún agbègbè àti ìlera pẹ̀lú ẹ̀mí àwọn èèyàn gẹ́gẹ́ bí ""ọ̀ràn ńlá"" tí ó ní ìjìyà tí ó pọ̀ nínú."
Ní ó-ku-ọ̀la tí yóò gba ipò, arábìnrin inú ìgbìmọ̀ náà sọ fún Folha de Boa Vista, ilé-iṣẹ́ ìròyìn ìbílẹ̀ kan tí ó ti ìpínlẹ̀ẹ rẹ̀ wá pé àbá òfin náà ń dojúkọ ìwà àìbìkítà àwọn iléeṣẹ́ àdáni sí agbègbè:
Ìtúmọ̀ Ìtúnwí-ọ̀rọ̀ Ọlọ́rọ̀ gan-an
Ohun tí ó kàn wá ni ètò ìmúlò tí ìjọba fi ń ṣe àdínkù agbára àwọn àtòpọ̀ ẹ̀rọ tí a ṣẹ̀dá láti dáàbò bo àyíká tó ní ìlera, gẹ́gẹ́ bí a ti rí i nínú ìwé òfin àti àwọn ipa tí ó ń kó láwùjọ.
Fún àpẹẹrẹ [lára àwọn àtòpọ̀ ẹ̀rọ yìí], a ní ètòo gbígba ìwé àṣẹ ní àwọn agbègbè yìí [tí ó ń bá wa dènà] àìlègbẹ̀rí àwọn iléeṣẹ́ jẹ́ àti àìtó agbára ìjọba láti kápáa wọn nínú ìpínlẹ̀ náà.
Nínú ọ̀rọ̀ọ rẹ̀ pẹ̀lú BBC, Joenia sọ pé ohun tí ó ṣe pàtàkì sí òun jùlọ nínú ìgbìmọ̀ náà ni ìyàsọ́tọ̀ àwọn ilẹ̀ abínibí:
Ìtúmọ̀ Ìtúnwí-ọ̀rọ̀ Ọlọ́rọ̀ gan-an
Tí o bá ní èèyàn ńláńlá mẹ́fà ní ọwọ́ kan, tí ọwọ́ kejì sì ní àìmọye àwọn èèyàn tí wọn ò jámọ́ nǹkan tí wọ́n ń rí mi gẹ́gẹ́ bí aṣojú wọn níbẹ̀.
Wọ́n jẹ́ ọ̀wọ́ àwọn tí ó nílò aṣojú. Ètò ìṣèlú àtẹ̀yìnwá wáyé nípasẹ̀ àwọn èèyàn tí wọ́n ń ro ohun tí ó máa jẹ́ èrèe tiwọn níbẹ̀, èmi máa mú iyì tí ó kárí wá.
Burundi: Kọ Ìkọkúkọ sórí àwòrán Ààrẹ — kí o wẹ̀wọ̀n
Àwọn oníkọkúkọ ní ìṣọ̀kan
Ààrẹ Jacob Zuma bẹ Burundi wo ní 25, oṣù Èrèlé ọdún 2016.
Orísun àwòrán: ìjọba ZA. Flickr, àṣẹ CC.
Akẹ́kọ̀ọ́ mẹ́fà di ẹni àtìmọ́lé lọjọ́ Ìṣẹ́gun 12, oṣù Ẹrẹ́nà ní agbègbè Kirundo ní Àríwá Ìlà-oòrùn Burundi fún ẹ̀sùn-un kíkọ ìkọkúkọ sórí àwòrán Ààrẹ Pierre Nkurunziza nínú àwọn ìwé ìkọ́ni márùn-ún.
"Wọ́n fi ẹ̀sùn ""títa àbùkù bá Ààrẹ orílẹ̀-èdè"" kan àwọn akẹ́kọ̀ọ́ náà."
Ẹgbẹ́ Àwọn Àjọ tí ó ń ṣe Àmójútó ìwàlálàáfíà Àwọn ọmọdé ní Burundi (FENADEB) jábọ̀ pé wọ́n ti fi akẹ́kọ̀ọ́ kan tí ó jẹ́ ọmọ ọdún mẹ́tàlá sílẹ̀ lẹ́sẹkẹsẹ̀ nítorí pé ó ṣì kéré, kò sì tí ì tó ọdún mẹ́ẹ̀dógún.
Wọ́n jábọ̀ pé wọ́n ṣe ìdásílẹ̀ àwọn akẹ́kọ̀ọ́ mẹ́ta lọ́jọ́ Ẹtì, 15 oṣù Ẹrẹ́nà ṣùgbọ́n àwọn mẹ́ta yòókù ṣì wà ní àtìmọ́lé.
Àwọn ọmọ náà tí wọn kò ju ọmọ ọdún 15 sí 17 yóò ṣe ẹ̀wọ̀n ọdún márùn-ún bí wọ́n bá jẹ̀bi ẹ̀sùn ìtàbùkù bá Ààrẹ orílẹ̀-èdè.
Ìwé ìròyìn iwacu jábọ̀ pé àwọn ìdílé tí ọ̀rọ̀ náà kàn wà nínú ìdààmú gidi.
Ìkọkúkọ [lórí àwòrán Ààrẹ] jẹ́ ẹ̀ṣẹ̀ tí ó mú ìjìyà dání lábẹ́ òfin ilẹ̀ Burundi gẹ́gẹ́ bí àbọ̀ ìwádìí Reuters kán ṣe sọ.
Bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé ọjọ́-orí àwọn ọ̀daràn náà lè jẹ́ ìdí fún ṣíṣe àdínkù ìjìyà ẹ̀sẹ̀ nínú ìgbẹ́jọ́ àwọn akẹ́kọ̀ọ́ yìí.
Gẹ́gẹ́ bí olùkọ́ kan tí kò dárúkọ araa rẹ̀ ṣe sọ, wọn kò yẹ àwọn ìwé ìkọ́ni wọ̀nyí wò fún àìmọye ọdún, àwọn akẹ́kọ̀ọ́ sì máa ń pín in lò ni, fún ìdí èyí ó nira láti mọ ẹni tí ó kọ nǹkan sí i ní pàtó.
Ìṣẹ̀lẹ̀ tó fara jọ èyí ṣẹlẹ̀ ní 2016, lẹ́yìnin rògbòdìyàn sáà kẹ́ta Ààrẹ náà, nígbà tí àwọn akẹ́kọ̀ọ́ nílé ẹ̀kọ́ kọ ìkọkúkọ sórí àwòrán (Ààrẹ) Nkurunziza nínú ìwé ìkọ́ni.
Àwọn aláṣẹ rí èyí gẹ́gẹ́ bí ìwọ̀sí gidi tí wọ́n sì lé ọgọọgọ̀rún akẹ́kọ̀ọ́ kúrò ní àwọn ilé ẹ̀kọ́ lóríṣìíríṣi káàkiri orílẹ̀-èdè náà.
"Akẹ́kọ̀ọ́ mọ́kànlá ni wọ́n fẹ̀sùn ""ìtàbùkù bá adarí ìlú"" àti ""ìhàlẹ̀ mọ́ ààbò ìlú"" kàn, bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé wọ́n padà dá wọn sílẹ̀."
Wọ́n bu ẹnu àtẹ́ lu ìwà yìí gidigidi.
Zeid Ra'ad Al Hussein, tí ó jẹ́ aṣàkóso fún ẹ̀ka ìjàfẹ́tọ̀ọ́ ènìyàn lábẹ́ United Nations gbé àkọsílẹ̀ kan jáde ní 29, oṣù Òkúdù 2016:
Ẹ̀rù ń bà mí pẹ̀lú àwọn ìròyìn tí mò ń gbọ́ nípa lílé tí wọ́n ń lé àwọn ọmọ ní ilé-ẹ̀kọ́ àti bí wọ́n ṣe ń tì wọ́n mọ́lé nítorí ìkọkúkọ tí wọ́n kọ sórí àwòrán Ààrẹ nínú àwọn ìwé ìkọ́ni.
Nkurunziza,’ Adarí ayérayé tó ga jù’
Pierre Nkurunziza ti jẹ ààrẹ ilẹ̀ Burundi láti ọdún 2005.
Ní ọdún 2015, àwọn ẹgbẹ́ òṣèlúu rẹ̀ tún gbé e sípò fún sáà kẹ́ta lórí oyè.
Ní oṣù Ẹrẹ́nà ọdún tó kọjá, Nkurunziza gba orúkọ tuntun lọ́dọ̀ àwọn ẹgbẹ́ òṣèlúu rẹ̀, Àjọ Agbèjà Òmìnira Àwọn Ológun – Fún Ìgbéga Ìjọba Oníbò (CNDD-FDD), wọ́n pè é ní “adarí ayérayé tó ga jù”.
Akọ̀wé gbogboògbò fún CNDD-FDD, Evariste Ndayishimiye ṣàlàyé ìdí tí orúkọ náà ṣe di ti Nkurunziza:
Olùdaríi wa ni, kò sí eni tí a lè fi wé e nínú ẹgbẹ́ẹ wa.
Òun ni òbíi wa, òun ni ó ń gbà wá nímọ̀ràn.
Ìdí nìyí tí mo ṣe ní kí gbogbo ọmọ ẹgbẹ́ pọ́n ọn lé nítorí pé ojúkójú ni ẹnikẹ́ni lè fi wo ilé tí kò ní olórí.
Ní tiwa, olórí tó dára jù ni a ní.
"Bí àwọn CNN-FDD ṣe gbé oyè náà ní yẹpẹrẹ tó ipò agbára Nkurunziza gẹ́gẹ́ bí ""adarí ayérayé tó ga jù"" ti jẹ́ kí ó nira fún ẹnikẹ́ni láti kọ ohunkóhun tí ó bá yàn láti ṣe, títí mọ́ ìgbésẹ̀ rẹ̀ láti ṣe àyípadà òfin sáà méjì fún ipò adarí tí ó wà nínú ìwé òfin orílẹ̀-èdè náà."
Èyí ń ṣe àfihàn àdálò tí ẹgbẹ́ òṣèlú tó wà lórí oyè ń dá agbára lò pẹ̀lú Nkurunziza àti àwọn alátìlẹyìn-in rẹ̀ pẹ̀lú bí ẹgbẹ́ òṣèlú náà ṣe ń darí àwọn ìdásílẹ̀ ìjọba.
Àwọn oníkọkúkọ ní ìṣọ̀kan
Àwọn ọmọ ìlú tí wọ́n ń ṣàmúlò ayélujára ti bẹ̀rẹ̀ ìkọkúkọ sórí àwòrán ààrẹ Nkurunziza nínú ìfẹ̀hónúhàn pẹ̀lú àmì ìdámọ̀: #Nkurunziza àti #Burundi:
Ìfòfinlíle mú àtakò
Ìjọba Burundi ti bẹ̀rẹ̀ sí í fi ìkanra mú ìwà àtakò láti ọdún 2015, lẹ́yìn ìjákulẹ̀ ìṣọ̀tẹ̀ kan, ìdojúkọ pẹ̀lú àwọn ẹgbẹ́ adìtẹ̀ kan, àtakò lórí ìlòkulò ẹ̀tọ́, òfin kànńpá, ìnira pẹ̀lú ètò ọrọ̀-ajé àti rògbòdìyàn àwọn asásàálà.
European Union pẹ̀lú United Nations tako ìgbésẹ̀ Nkurunziza fún sáà kẹ́ta, wọ́n sì béèrè fún ìdápadà ìlọdéédé kí àsìkò ìdìbò ó tó dé.
Pẹ̀lú àwọn ìdojúkọ wọ̀nyí, “ipò náà” le sí i, àti àwọn aláṣẹ sì ń fi ìkanra mú gbogbo ìhàlẹ̀ tí wọ́n ń rí.
Ìjábọ̀ pàtàkì ti àjọ ajàfẹ́tọ̀ọ́ ènìyàn ṣe ní oṣù Èbìbí 2018 rí i pé àwọn èṣọ́ aláàbò ní Burundi, àwọn afòyeṣiṣẹ́ àti àwọn ọmọ ẹgbẹ́ òṣèlú tí ó wà nípò, àwọn ẹgbẹ́ Imbone… ń kọlu àwọn alátakò àti àwọn ẹni tí wọ́n fura sí gẹ́gẹ́ bí alátakò pẹ̀lú ajàfẹ́tọ̀ọ́ ènìyàn àti akọ̀ròyìn.
Wọ́n pa èèyàn tó tó 1700, bẹ́ẹ̀ ni wọ́n sì ń fi ipá lé àwọn ẹlòmíìn, wọ́n ń fi ipá bá wọn ní ìbálòpọ̀, wọ́n ń fi ìyà jẹ wọ́n, wọ́n ń tì wọ́n mọ́lé, bẹ́ẹ̀ ni wọ́n sì ń dẹ́rùba àìmọye àwọn mìíràn.
Èyí ti dá wàhálà ìsásàálà sílẹ̀, a ti rí àwọn ará Burundi tí wọ́n sá lọ sí Tanzania, Rwanda, Congo àti Uganda.
Bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé ẹgbẹẹgbẹ̀rún ti padà sílé, alákòóso United Nations fún ìsásàálà ti ṣe àkọsílẹ̀ àwọn asásàálà tí ó wá láti Burundi tí wọ́n lé ní 347,000 ní oṣù Èrèlé 2019, UNHCR fìdí ẹ̀ múlẹ̀:
...Làásìgbò nínú òṣèlú Burundi le sí i ní ọdún 2015 lẹ́yìn tí ààrẹ́ kéde èròńgbàa rẹ̀ láti lọ fún sáà kẹ́ta.
Ìfẹ̀hónúhàn àwọn èèyàn láti tako èròńgbà fa ìkọlura, ọgọọgọ̀rún àwọn èèyàn sì sá lọ sí àwọn orílẹ̀-èdè ìtòsí láti fi oríi wọn pamọ.”
Ní ìbẹ̀rẹ̀ oṣù yìí, ìjọba Burundi ti ọ́fíìsì ẹ̀ka àwọn ajàfẹ́tọ̀ọ́ ènìyàn lábẹ́ United Nations tí wọ́n sì sọ pé àwọn kò nílòo wọn mọ́.
"Ìjọba náà ń bínú sí alákòóso tẹ́lẹ̀-rí ẹ̀ka náà, Zeid Ra'ad Al Hussein tí ó ṣàpèjúwe Nkurunziza ti Burundi gẹ́gẹ́ bí ọkàn lára ""àwọn apanilẹ́kúnjayé ènìyàn tí ó ń gbèrú sí i láìpẹ́ yìí"" ní oṣù Èrèlé 2018."
Àtìpa àwọn Ilé-iṣẹ́ Akọ̀ròyìn, ìyọlẹ́nu àwọn alátakò, ìfòfinlílẹ̀ mú àwọn ìdásílẹ̀ tí kì í ṣe ti ìjọba (NGOs) àti ìdiwọ́ fún àwọn mìíràn láti sọ̀rọ̀ tàbí ṣe àfihàn ara wọn ní ààyè òṣèlú.
Fún àpẹẹrẹ, wọ́n dájọ́ ẹ̀wọ̀n ọdún méjìlélọ́gbọ̀n fún ajàfẹ́tọ̀ọ́ ènìyàn Germain Rukiki fún ìdarapọ̀ mọ́ ìgbìyànjú ìrúlùú, jíjin ètò ààbò ìlú lẹ́sẹ̀, àti ìṣọ̀tẹ̀ ní 2018 nítorí pé ó ṣe àkọsílẹ̀ àwọn ọ̀nà tí ìjọba Nkurunziza ń gbà fìyà jẹni.
Àwọn àìṣedede kan dá ìgbẹ́jọ́ Rukiki dúró, ó sì wáyé ní ọ̀sẹ̀ mélòó kan ṣáájú àríyànjiyàn ìdìbò abófinmu náà.
Ọ̀rọ̀ ìkọkúkọ náà ń ṣe àfihàn ìdúróṣánṣán ìjọba náà tí kò yẹ̀ àti ọ̀nà tí wọ́n ń gbà ṣe ẹ̀tọ́ọ wọn, títí mọ́ ṣíṣe ìgbéyàwó kànńpá fún àwọn tọkọtaya tí wọ́n ń gbépọ̀ láìṣe ìgbéyàwó ní 2017, ìfòfinlíle mú òwòo panṣágà àti agbe ṣíṣe.
Wọ́n fagi lé ìfìwépè Adarí iléeṣẹ́ tó ń ṣètò Ìṣàjò-papọ̀-wa-ọkọ̀-kí-n-wa-ọkọ̀ sí iléeṣẹ́ tẹlifíṣàn Russia lẹ́yìn tí olóòtú ètò rí i pé obìnrin ni
"Àwọn elétò náà sọ pé ó ""nírú ẹ̀yà"" tí àwọn olugbọ́ àwọn ń fẹ́."
Àgékúrò àwòrán adarí iléeṣẹ́ náà, Irina Reyder ní ọ́fíìsì iléeṣẹ́ BlaBlaCar ti Russia. Àwòrán láti orí Ojú ewé. Facebook
Irina Reyder tí ó jẹ́ adarí iléeṣẹ́ BlaBlaCar ní Russia ní wọ́n fagi lé ìfìwépè òun sí ìfọ̀rọ̀wọ́rọ̀ kan pẹ̀lú iléeṣẹ́ amóhùnmáwòrán-an ti ìjọba, Channel One lẹ́yìn tí olóòtú náà rí i pé obìnrin ni òun.
Reyder kọ nípa ìṣẹ̀lẹ̀ náà sójú ìwé Facebook rẹ̀. Ó ní òun gbọ́ ọ̀rọ̀ inú ìpè olóòtú ètò náà pẹ̀lú aṣojú ilé iṣẹ́ BlaBlaCar fún ìbánisọ̀rọ̀ pẹ̀lú àwùjọ tí òun sì gba ohùn-un wọn sílẹ̀:
Ìtúmọ̀ Ìtúnwí-ọ̀rọ̀ Ọlọ́rọ̀ gan-an
E (Olóòtú ètò “Ojúmọ́ Ire”): Báyìí ni a ṣe gbèrò láti ṣe é; akọ̀ròyìn-in wa á máa wa ọkọ̀ bí yóò ṣe máa fi ọ̀rọ̀ wá ọ̀rọ̀ lẹ́nu alámọ̀dájúu yín.
PR (Aṣojú iléeṣẹ́ BlaBlaCar fún ìbánisọ̀rọ̀ pẹ̀lú àwùjọ): Bẹ́ẹ̀ ni, Ìyẹn dára
E: Ta ni yóò wá jẹ́ alámọ̀dájú náà?
PR: Adarí iléeṣẹ́ wa ni, Irina Reyder
E: Ẹ̀n... Ẹ ti fìgbà kan ní ọkùnrin tó dára ní ipò náà, àbí bẹ́ẹ̀ kọ́?
PR: Bẹ́ẹ̀ ni, a ti ní Alexey Lazorenko gẹ́gẹ́ bí Adarí, Irina Reyder ni nísẹ̀yín.
E: Bẹ́ẹ̀ ni, mo mọ̀ nípa àyípadà tí ó wáyé nínú ìdarí iléeṣẹ́ yín lọ́dún tó kọjá.
Ṣùgbọ́n Irina kò ní le è wúlò gẹ́gẹ́ bí alámọ̀dájú.
Ó nírú ẹni tí àwọn olùgbọ́ọ wa máa ń nífẹ̀ẹ́ sí.
Fún àpẹẹrẹ, tí a bá ní agbẹjọ́rò gidi kan.
Ó ń láti jẹ́ ọkùnrin.
Tàbí ẹni tí ó mọ̀ nípa ọkọ̀ lọ́pọ̀lọpọ̀ – ọkùnrin ni, kó má jẹ̀ ẹ́ obìnrin.
Bóyá kí ìwọ Sergey ó ṣe ìfọ̀rọ̀wọ́rọ̀ náà?
Lẹ́yìn tí aṣojú iléeṣẹ́ náà fún ìbánisọ̀rọ̀ pẹ̀lú àwùjọ, Sergey sọ fún olóòtú ètò náà pé kò sí alámọ̀dájú ọkùnrin kankan ní iléeṣẹ́ naa, ó ní olóòtú ètò náà ṣe ìlérí láti padà wá lẹ́yìn tí ó bá ti bá olóòtú àgbà ètòo wọn sọ ọ́.
Nínú ìpè kan lẹ́yìn ìgbà náà, wọ́n sọ fún aṣojú iléeṣẹ́ BlaBlaCar pé ètò náà ti yí padà, pé àwọn á máa ṣe ìfọ̀rọ̀wọ́rọ̀ pẹ̀lú àwọn oníbàáràa wọn dípò wọn.
“Kí lẹ rò?
Ṣé àwọn alámọ̀dájú tuntun yìí á mọ̀ dájú dánu?
Reyder ń béèrè ìbéèrè ìkẹ́gàn náà lọ́wọ́ àwọn èèyàn-an rẹ̀.
Nínú èsì kan sí TJournal, tí ó jẹ́ iléeṣẹ́ onímọ̀-ẹ̀rọ àti ìròyìn ẹ̀rọ alátagbà àti orí ayélujára.
Ẹ̀ka ìròyìn Channel One ò fi òtítọ́ ìtàkùrọ̀sọ yìí pamọ́, ṣùgbọ́n wọ́n tẹnu mọ́ ọn pé ọ̀rọ̀ náà kò ṣègbè lẹ́yìn akọ.
Bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé àlàyé wọn kò fìdí èyí múlẹ̀ tó:
Ìtúmọ̀ Ìtúnwí-ọ̀rọ̀ Ọlọ́rọ̀ gan-an
Akọ̀ròyìn méjì, ọkùnrin àti obìnrin kan ń gbèrò láti ṣàfihàn ìyàtọ̀ tí ó wà nínúu bí ọkùnrin àti obìnrin ṣe ń hùwà sí ìfowópamọ́.
Akọ̀ròyìn lóbìnrin á ní láti fọ̀rọ̀wọ́rọ̀ pẹ̀lú alámọ̀dájú ọkùnrin kan nígbà tí Akọ̀ròyìn lọ́kùnrin á ní ìfọ̀rọ̀wọ́rọ̀ pẹ̀lú àwọn obìnrin.
Nítorí pé èròńgbà Akọ̀ròyìn obìnrin yẹn ni láti wo bí wọ́n ṣe ń tọ́jú owó bí wọ́n bá gbé ọkọ̀, a nílò láti bá aṣojú iléeṣẹ́ tó ń ṣètò ìrìnnà-papọ̀-wa-ọkọ̀-kí-n-wa-ọkọ̀ kan sọ̀rọ̀ (bẹ́ẹ̀ ni, nítorí àlàkalẹ̀ ètò náà ni, kì í ṣe nítorí àìfẹ́dọ̀ọ́gba akọ àtabo, ó ní láti jẹ́ ọkùnrin).
Channel One ò sọ bí ìyàtọ̀ ṣe wà láàárín bí ọkùnrin àti obìnrin ṣe ń ronú sí ìfowópamọ́.
Ṣùgbọ́n ọ̀rọ̀ náà kò yí àwọn èèyàn lọ́kàn padà, wọ́n sì ń sọ̀rọ̀ tako ìhùwàsí iléeṣẹ́ tẹlifíṣàn yìí.
Adarí iléeṣẹ́ BlaBlaCar, Irina Reyder sọ pé wọ́n fagi lé ìfìwépè òun wá sórí ètò Ojúmọ́ Ire lórí Channel One lẹ́yìn tí olóòtú rí i pé obìnrin ni òún jẹ́.
Ó yani lẹ́nu pé àwọn ohun kan ṣì wà nínú ìyírí àwọn Channel One tí a kò mọ̀.
Pẹ̀lú ọ̀rọ̀ burúkú tí Channel One gbọ́ lórí ayélujára, Russia sì ní iṣẹ́ ńlá láti ṣe lórí ọ̀rọ̀ ìbádọ́gbà akọ àti abo.
Russia wà ní ipò 75 nínú àwọn orílẹ̀-èdè 149 tí Àjọ tó-ń-ṣètò-ọrọ̀-Ajé Lágbàáyé ṣàyẹ̀wò fún lọ́dún 2018 nínú Ìjábọ̀ Àlàfo tó wà láàárín Akọ àti Abo Lágbàáyé, ó ń ṣe dáadáa ní ti ìbádọ́gbà nínú rírí ètò ìlera àti ètò ẹ̀kọ́ lò fún àwọn obìnrin, ṣùgbọ́n wọ́n ń fà sẹ́yìn nínú ètò ìṣòfin láti jà fún ẹ̀tọ́ọ wọn.
Àwọn ajàfẹ́tọ̀ọ́ abo ní Russia máa ń sábàá lo gbàgede ẹ̀rọ alátagbà àti ẹ̀fẹ̀ láti tan ìmọ́lẹ̀ sí ìhùwàsí àti ìṣe àwọn tí ó ń ṣègbè lẹ́yìn ẹ̀yà ènìyàn kan.
Ìpolongo ìtakò Kérésìmesì ìlú China mú yíyan àjọyọ̀ le fún ọmọ-ìlú
"Ohun tí a kọ sí ojú pátákó: ""Gbé Ìgbésẹ̀ kí o sì kọ àjọ̀dún Òyìnbó"" àti ""Ṣe ìgbélárugẹ àṣà ìbílẹ̀, kọ àjọ̀dún Òyìnbó""."
Àwòrán láti Weibo.
Kérésìmesì ń sún mọ́ dẹ̀dẹ̀ ṣùgbọ́n kàkà kí inú àwọn tí ó ń gbé ní orí-ilẹ̀ ìlú China ò dùn, ọ̀pọ́ ti fi ẹ̀hónú-u wọn hàn lórí ìpolongo tí ó tako ayẹyẹ Kérésìmesì tí ó kà á sí àjọ̀dún Òyìnbó.
"Ní ọdún 2017, ìgbìmọ̀ àgbà àti àjọ ìpínlẹ̀ lábẹ́ ẹgbẹ́ olóṣèlú Communist ìlú China kọ ìwé àṣẹ kan tí a pe àkọlée rẹ̀ ní ""Ìmọ̀ràn lórí imúdiṣíṣẹ iṣẹ́ ìgbélárugẹ àti ìdàgbà àṣà ìbílẹ̀ China dé ibi gíga""."
Wọ́n la àwọn àkànṣe iṣẹ́ ìsọjí àṣà bíi Ọdún Òṣùpá Tuntun àti Àjọ̀dún Àtùpà sílẹ̀, láì pa ìyìókù tì, gẹ́gẹ́ bí ìpàgọ́ tí ó jẹ mọ́ ti àṣà tí ó lákaakì.
Kí òfin yìí lè di àmúṣẹ, ìjọba China ti ṣe ìfilọ́lẹ̀ àwọn ètò ìpolongo kéékèèké mélòó kan fún ìkọ̀yìn sí àwọn ayẹyẹ tí kì í ṣe ti ìbílẹ̀ China.
Ọdún nìín, ọjọ́ díẹ̀ sí Kérésìmesì, ìjọba ní àwọn ìlú ńlá bíi Langfang, ní agbègbèe Hebei, ti pa á ní àṣẹ fún ìsọ̀ gbogbo láti yọ ẹ̀ṣọ́ ọdún Kérésìmesì kúrò lójú títí àti fèrèsé.
Ọ̀rọ̀ àlùfànṣá tí ó dá lórí ìtako àjọ̀dún Òyìnbó ti gba ẹ̀rọ-alátagbà ìlú China kan, èyí mú kí yíyan ayẹyẹ Kérésìmesì láàyò le koko fún àwọn tí ó rò wípé ní ìkọ̀kọ̀ ni ayọ̀ àwọn gbọdọ̀ wà.
Ònlo Weibo Long Zhigao ya àwòrán ìròyìn orí WeChat ti rẹ̀ ní orí Weibo ní ìfihàn àríyànjiyàn.
Kókó ìròyìn àkọ́kọ́
1. Àjọ̀dún Òyìnbó ń bọ̀ lọ́nà dẹ̀dẹ̀.
Kí a ṣe àjọyọ̀ àbí kí á máà ṣe é, ìbéèrè yen ni ìyẹn.
2. Ọmọ China ni mí n kò sì kí ń ṣe àjọyọ̀ Òyìnbó.
3. Sọ pé rárá fún ìṣàjọyọ̀ àjọ̀dún Òyìnbó nínú ọgbà ilé-ìwé.
4. Ẹgbẹ́ òṣèlú-ìpínlẹ̀ ti kọ ẹ̀yìn sí àjọ̀dún Òyìnbó.
Àjọyọ̀ àjọ̀dún ti wá di ọ̀rọ̀ ìṣèlú.
Láfikún-un Kérésìmesì, àkàsílẹ̀ àwọn àjọ̀dún Òyìnbó kò yọ Àyájọ́ Ọjọ́ Olólùfẹ́, Àjíǹde àti Halowíìnì, àti bẹ́ẹ̀ bẹ́ẹ̀ lọ sí ẹ̀yìn.
"Ọ̀pọ̀lọpọ̀ ènìyàn ni ó ka àjọ̀dún sí ""ìgbógunti àṣà"" tàbí ""ìrẹ̀sílẹ̀ ìlú""."
Fún àpẹẹrẹ, ọ̀kan tí ó ràn ká bí ìgbà tí iná bá ń jó pápá inú ọyẹ́ sọ wípé:
Ìtúmọ̀ Ìtúnwí-ọ̀rọ̀ Ọlọ́rọ̀ gan-an
Bí àwọn ènìyàn ìlú kan bá mú àjọyọ̀ àjọ̀dún ìlú mìíràn ní òkúnkúndùn ju bí ó ṣe yẹ, èyí fi hàn wípé orílẹ̀-èdè náà ń jẹ ìyà ìgbógunti àṣà.
Bí ẹlẹ́gbẹ́ olóṣèlú kò bá mọ èyí, a jẹ́ wípé wọn kò ní ìkọbiarasí ìṣèlú wọ́n sì ti pàdánù ìlọsíwájúu wọn.
Awuyewuye náà tọ́ka sí ìṣẹ̀lẹ̀-àtẹ̀yìnwá Eight-Nation Alliance, ẹgbẹ́ ìṣọ̀kan tí a dá ní ìdáhùnsí Tẹ̀mbẹ̀lẹ̀kun Akànṣẹ́ ní China láàárín-in ọdún 1899 àti 1901 nígbàtí àwọn àgbẹ̀ rokoroko fi ẹ̀hónú hàn sí ìjọba amúnisìn, ètò ìṣèlú ní ìlànà Krìstẹ́nì àti àṣà.
Síwájú sí i, ó ní wípé ọjọ́ ìbíi Mao Zedong, bàbá ìsàlẹ̀ Ìlú-tí-kò-fi-ọba-jẹ ti Èèyàn-an China, ni ó yẹ kí a kà sí Kérésìmesì ìlú China:
Ìtúmọ̀ Ìtúnwí-ọ̀rọ̀ Ọlọ́rọ̀ gan-an
Alága àkọ́kọ́ Ìlú-tí-kò-fi-ọba-jẹ ti China Mao Zedong ti yọ àwọn ènìyàn nínú ìṣòro.
A gbọdọ̀ sọ ọjọ́ ìbíi rẹ̀ di Kérésìmesì China.
Gbé ìgbésẹ̀ kí o kọ àjọ̀dún Òyìnbó.
Àmọ́ àwọn ènìyàn kan lórí Weibo kò rí ọ̀rọ̀ ọlọgbọ́n kankan nínú àríyànjiyàn wọ̀nyí.
Ẹnìkan sọ pé:
Ìtúmọ̀ Ìtúnwí-ọ̀rọ̀ Ọlọ́rọ̀ gan-an
Bí àwọn Òyìnbó bá ń ṣe àjọyọ̀ Ọdún Òṣùpá Tuntun, àwọn aráa China á gbéraga wọ́n á sì rí èyí gẹ́gẹ́ bí ìdàgbà ìsọjí àṣà ìbílẹ̀ China...
Bí àwọn aráa China bá ṣe àjọyọ̀ àjọ̀dún Òyìnbó, kí ni ìdí tí a fi kà wọ́n sí ìgbógunti àṣà?
Àwọn ọ̀dọ́ máa ń ṣe àjọyọ̀ àjọ̀dún Òyìnbó nítorí àríyá àti fún ayọ̀.
Àwọn àjọ̀dún wọ̀nyí lè mú ìkóúnjẹjẹ gbòòrò, kí ni ó burú nínú ìyẹn?
Àwọn kan gbèrò wọ́n fẹ́ gbé àjọyọ̀ Kérésìmesì fi ẹ̀gbẹ́ kan ẹ̀gbẹ́ pẹ̀lú ìrẹ̀sílẹ̀ ìlú tí ó wáyé ní ọgọ́jọ ọdún sẹ́yìn.
Fún kí ni?
Ẹgbẹ́kíkó, ìkóraẹni-níjàánu
Àgbàrá òdì ọ̀rọ̀ sí Kérésìmesì ti ṣàn gba orí ẹ̀rọ-alátagbà ó sì ti mú kí àwọn òǹlò kan ó kó ara wọn ní ìjánu.
Ònlo Weibo kan fi ẹ̀hónú hàn:
Ìtúmọ̀ Ìtúnwí-ọ̀rọ̀ Ọlọ́rọ̀ gan-an
Kérésìmesì ń bọ̀ lọ́nà dẹ̀dẹ̀.
Ní agbo ọ̀rẹ́ẹ wa, àgọ́ alòdìsí àjọ̀dún Òyìnbó àti alòdìsí alòdìsí àjọ̀dún Òyìnbó ń ṣe àríyànjiyàn.
Kò kan ẹnikéni bóyá èèyàn féràn àjọyọ̀ tàbí kò fẹ́, kí ni ó dé tí àwọn ènìyàn ṣe fẹ́ràn láti máa fi túláàsì mú ẹlòmíràn gba èròńgbà ti wọn?
Ojú kan tí gbogbo ènìyàn dúró sí ti kún.
Fún àwa tí a wà láàárín, kí a ba mú un dọ́gba, a ní láti dúró sí ẹ̀gbẹ́ kejì.
Ìkìlọ̀ lórí ìtako àjọ̀dún Òyìnbó ní inú ọgbà ilé-ìwé.
Awuyewuye ti kọjáa ti gbàgede orí ẹ̀rọ-alátagbà, ó kàn dé ilé-ìwé àti àjọ ìlú.
Àwọn òǹlo Weibo kan ti pín ìkìlọ̀ ilé-ìwé ti a fún akẹ́kọ̀ọ́.
"Ọ̀kan nínú ìkìlọ̀ náà (ọ̀tún) ń tọ́ka sí òfin ""Ìmọ̀ràn"" ó sì rọ olùkọ́ àti akẹ́kọ̀ọ́ láti kọ àyájọ́ tí ó fi ara jọ ti Òyìnbó sílẹ̀."
Bákan náà ni ìkìlọ̀ rọ akẹ́kọ̀ọ́ láti fọ́n iṣẹ́-ìjẹ́ òdì-ọ̀rọ̀ ìgbógunti àṣà Òyìnbó ká sí ọ̀rẹ́ àti ojúlùmọ̀ lórí WeChat àti lórí àwọn irinṣẹ́ iṣẹ́-ìjẹ́ ẹ̀rọ-alátagbà mìíràn.
Ìyàlẹ́nu ni ó jẹ́ fún ìyá kan nígbàtí ọmọọ rẹ̀ kọ ẹ̀bùn Kérésìmesì. Ìyá kọ sórí Weibo:
Ìtúmọ̀ Ìtúnwí-ọ̀rọ̀ Ọlọ́rọ̀ gan-an
Ìyá: Ọmọ mi, ẹ̀bùn wo lo fẹ́ fún Kérésìmesì?
Ọmọ: Èmi ò ní ṣe àjọyọ̀ àjọ̀dún Òyìnbó kì í ṣe àjọ̀dún ìlúu China.
Ó dáa, dájúdájú onígbọràn ọmọ ẹgbẹ́ òṣèlú àti àwọn ará ìlú ni ọ́.
Síbẹ̀, àwọn akẹ́kọ̀ọ́ ilé-ẹ̀kọ́ gíga ṣe àròjinlẹ̀.
Akẹ́kọ̀ọ́ kan ní ìbéèrè lórí òfin ilé-ìwé lórí Weibo:
Ìtúmọ̀ Ìtúnwí-ọ̀rọ̀ Ọlọ́rọ̀ gan-an
Ilé-ìwé ti gbé ẹsẹ̀ lé ìṣẹ̀ṣọ́ọ Kérésìmesì nínú ọgbà ó sì ti sọ pàṣìpàrọ̀ ẹ̀bùn di èèwọ̀ ní ìpolongo ìtako àjọ̀dún Òyìnbó.
Ǹjẹ́ fún ìdàgbàsókè àṣà ilẹ̀ China ni gbogbo ọ̀nà yìí tàbí àmì ìpàdánù ìgbẹ́kẹ̀lé àṣà ìbílẹ̀ ẹni?
Àwọn kan ti yan ìṣàjọyọ̀ àjọ̀dún náà ní ìkọ̀kọ̀. Òǹlo Weibo kan sọ:
Ìtúmọ̀ Ìtúnwí-ọ̀rọ̀ Ọlọ́rọ̀ gan-an
Ilé-iṣẹ́ ti sọ ayẹyẹ àjọyọ̀ àjọ̀dún Òyìnbó di èèwọ̀. Ṣùgbọ́n akọ̀wé láti ẹ̀ka ètò-òṣìṣẹ́ ti fi òró Kérésìmesì (ẹ̀bùn Kérésìmesì tí ó wọ́pọ̀) fún àwọn òṣìṣẹ́ ní ìkọ̀kọ̀.
Ẹ jẹ́ kí a fẹ́ àlàáfíà.
Òǹlo Weibo mìíràn fi èròǹgbàa rẹ̀ hàn pẹ̀lú ohun tí ó fẹ́ fún Kérésìmesì:
Ìtúmọ̀ Ìtúnwí-ọ̀rọ̀ Ọlọ́rọ̀ gan-an
Ẹ kú ọdún Kérésìmesì!
Mo nífẹ̀ẹ́-ẹ̀ rẹ olúwa!
Bàba Kérésìmesì, jọ̀wọ́ fún mi ní ìbọsẹ̀ nílá gbàǹgbà pẹ̀lú òmìnira nínúu rẹ̀.
Òṣìṣẹ́ inú ọkọ̀ òfuurufú olóbìnrin nìkan wọ ìwé ìtàn ní Mozambique
Ikọ̀ awakọ̀ òfuurufú olóbìnrin àkọ́kọ́ irúu rẹ̀ ní Mozambique | A lo àwòrán pẹ̀lú àṣẹ láti ọwọ́ Meck Antonio.
Ọjọ́ ìtàn ni ọjọ́ yìí: ojú yìí ni ogunlọ́gọ̀ ọmọ-ìlú Mozambique fi wo ìṣẹ̀lẹ̀ ọjọ́ 14, oṣù Ọ̀pẹ ọdún 2018 nígbà tí, fún ìgbà àkókọ́ nínú ìtàn ìgbésí ayé ètò ọkọ̀ òfuurufú ìlú náà, tí obìnrin jẹ́ atukọ̀.
Ikọ̀ bàlúù TM112/3, tí ó rin ìrìn àjò láti olú ìlú, Maputo, àti Manica — tí jíjìn sí ara wọn tó máìlì 442 — ni a tí rí atukọ̀ Admira António, atukọ̀ kejì Elsa Balate, olóyè ọkọ̀ Maria da Luz Aurélio, àti òṣìṣẹ́ inú ọkọ̀ Débora Madeleine.
Àwọn obìnrin wọ̀nyí wà nínú ẹgbẹ́ MEX, ilé-iṣẹ́ tí a dá sílẹ̀ gẹ́gẹ́ bíi Ẹ̀ka Iṣẹ́ Àkànṣe LAM — Linhas Aéreas de Moçambique.
Ní 1995, ó bẹ̀rẹ̀ iṣẹ́ bíi ilé-iṣẹ́ ọkọ̀ òfuurufú aládàáni , Mozambique Express.
Àtẹ̀jáde ìkíni orí Facebook láti ọwọ́ ajàfúnẹ̀tọ́ obìnrin Eliana Nzualo, ti ní ìsọsí tí ó tó 450, tí a ti pín tó ìgbà 460, àti pé ọ̀pọ̀ èsì tí ó tó 2,000 ni ó gbà:
Ìtúmọ̀ Ìtúnwí-ọ̀rọ̀ Ọlọ́rọ̀ gan-an
ỌJỌ́ ÌTÀN – Ikọ̀ ọkọ̀ òfuurufú
MEX kú oríire!
Ikọ̀ ẹ kú oríire!
Mozambique, kú oríire!
Fún ọ̀pọ̀lọpọ̀ obìnrin nínú iṣẹ́ gbogbo.
"Àjàfúnẹ̀tọ́ ìkẹ́gbẹ́ Mauro Brito sọ ní tirẹ̀ wípé obìrin gbọ́dọ̀ ní ìgbéraga ""nígbàtí [wọ́n] bá jẹ́ aṣojú nínú iṣẹ́ gbogbo"":"
Ìtúmọ̀ Ìtúnwí-ọ̀rọ̀ Ọlọ́rọ̀ gan-an
Obìnrin kò pọ̀ nínú iṣẹ́ ọkọ̀ òfuurufú, bẹ́ẹ̀ ni ó sì ṣe rí káríayé.
Mo rò ó wípé àwọn obìnrin tí ó ronú láti ṣe iṣẹ́ tí ọkùnrin máa ń ṣe, gbọdọ̀ gbéraga.
Mozambique nìkan kọ́.
Ní oṣù Ògún ọdún 2018, nínú ọkọ̀ òfuurufú ìlú apá Gúúsù Ilẹ̀-Adúláwọ̀ SAA, ìrìnàjò ìlú dé ìlú pẹ̀lú ikọ̀ olóbìnrin fò ní ojú sánmà wọ́n sì kó èrò láti Johannesburg sí Sao Paulo, Brazil.
Oṣù méjìlá sẹ́yìn, ní oṣù Ọ̀pẹ ọdún 2017, Ilé-iṣẹ́ Ọkọ̀ òfuurufú Ethiopia fún ìgbà àkókọ́ gbé ikọ̀ òṣìṣẹ́bìnrin fò.
Awọn atukọ̀ títí kan òṣìṣẹ́ gbogbo, ọkọ̀ òfuurufú láti Addis Ababa ní Ethiopia sí Èkó ní Nàìjíríà — jẹ́ obìnrin pátápátá porongodo.
Kí ló dé tí ìjọba Ilẹ̀-Adúláwọ̀ ń f'òfin de ọ̀rọ̀ sísọ orí-ayélujára? Nítorí wọ́n bẹ̀rù agbára rẹ̀.
Akẹ́kọ̀ọ́ Ifásitì Haromaya ní Ethiopia ń fi àmì ìtako ìjọba hàn.
Àwòrán tí a pín lórí ẹ̀rọ-alátagbà.
Ọ̀rọ̀ sísọ lórí ayélujára ti ń rí ìfúnpa láti ọwọ́ ìjọba díẹ̀ díẹ̀.
Nínú ìlànà òfin àti ọ̀rọ̀ Ajé, iye òmìnira ọ̀rọ̀ ń dìde kárí Ilẹ̀-Adúláwọ̀.
Nígbà tí àwọn ìjọba kan mọ rírì ètò ìjọba àwa-arawa nípasẹ̀ ṣíṣe ìbò pẹ̀lú ọlọ́pọ̀-ẹgbẹ́ òṣèlú àti sọ nígbangba nípa àjọṣe, nínú ìṣe, ọ̀pọ̀ máa ń lo àṣẹ tí ò ṣe é yí padà — wọ́n sì ń lo agbára àṣẹ yìí lórí ẹ̀rọ-ayárabíàṣá bí ọjọ́ ṣe ń gun orí ọjọ́.
Cameroon, Tanzania, Uganda, Ethiopia, Nigeria, àti Benin ti ní Ìtìpa Ẹ̀rọ-ayélujára, ìjọba ti fi owó-orí lé lílo búlọ́ọ̀gù àti ẹ̀rọ-alátagbà, wọ́n sì ti fi ọwọ́ ṣìgún òfin mú oníròyìn.
Òṣìṣẹ́ ìròyìn àti àwọn ọmọ-ìlú ti di èrò àtìmọ́lé lórí ẹ̀sùn àtẹ̀jáde “ìròyìn irọ́” títí kan ìkóròyìn ìkòkọ̀ ìlú sí etí ìgbọ́ ẹgbẹ́ afẹ̀míṣòfò.
Ní ibi Àpérò Òmìnira Ẹ̀rọ-ayélujára ní Ilẹ̀-Adúláwọ̀ (FIFA) tí ó wáyé ní Accra, Ghana, ikọ̀ akópa láti àwọn ìlú ilẹ̀ Adúláwọ̀ pátá sọ wípé kò ní ṣe ẹnu rere bí ìjọba bá fi òfin de ọmọ-ìlú tí ó ń lo ẹ̀rọ-ayárabíaṣá.
Ọ̀pọ̀ orílẹ̀-èdè ló ní àwọn òfin àti àbádòfin tí ó fún ọmọ ènìyàn ní ẹ̀tọ́ sí òmìnira ọ̀rọ̀ sísọ.
Ní Nàìjíríà, fún àpẹẹrẹ, Àbádòfin Òmìnira Ọ̀rọ̀ fún ọmọ ìlú ní òmìnira láti béèrè fún ìwífun lọ́wọ́ àjọ ìjọba.
"Abala 22 ìwé òfin ọdún 1999 pèsè fún ẹ̀tọ́ òmìnira ìròyìn àti Abala 39 fi lélẹ̀ wípé ""gbogbo ènìyàn ni ó ní ẹ̀tọ́ sí òmìnira ọ̀rọ̀ sísọ, títí kan òmìnira láti gbá ìròyìn mú àti gba ọgbọ́n àti ìwífun láì sí ìdíwọ́..."""
Síbẹ̀, Nàìjíríà tí tẹ àwọn òfin kan tí ó tẹ orí àwọn ẹ̀tọ́ òkè yìí bọlẹ̀.
"Abala 24 Òfin Ẹ̀ṣẹ̀ orí-ayélujára fi ẹ̀sùn kan ""ẹnikẹ́ni tí ó bá tan iṣẹ́-ìjẹ́ tí kò ní òótọ́ kan nínú, tí ó lè fa ìbínú, ìnira, ewu, ìdíwọ́, àfojúdi, ìdáyàfò ọ̀daràn, ọ̀tá, ìkórìíra, tàbí ìbínú láì ní ìdí sí ẹlòmíràn ká tàbí fa kí a fi irúfẹ́ iṣẹ́-ìjẹ́ bẹ́ẹ̀ ránṣẹ́."""
"Ìṣòfin àìdájú àti àwọn gbólóhùn bíi ""ìnira"" tàbí ""ìwọ̀sí"" jẹ́ nǹkan tí a ní láti mójútó."
Ìjọba àti àwọn àjọ rẹ̀ máa ń sábà fi èyí ṣe bójúbójú fún ìtẹríbọlẹ̀ òmìnira ọ̀rọ̀ sísọ.
Ta ni ẹni tí ó ń sọ bóyá ọ̀rọ̀ kan jẹ́ àfojúdi?
Ǹjẹ́ ó yẹ kí òṣìṣẹ́ ìjọba ó ṣe ìmúdàgbà àwọ̀-ara tí ó ní ipọn?
Ní àgbáyé, ọmọ-ìlú ní ẹ̀tọ́ láti wá àìṣedéédé aláṣẹ ìjọba.
Kí ló dé tí Ilẹ̀-Adúláwọ̀ kò ní ẹ̀tọ́ láti ṣẹ̀ gẹ́gẹ́ bí ẹ̀ka tí ó ṣe pàtàkì nínú òmìnira ọ̀rọ̀ sísọ?
Ní ọdún 2017 àti 2016, oníròyìn orí-ayélujára ọmọ bíbí ìlú Nàìjíríà àti akọbúlọ́ọ̀gù Abubakar Sidiq Usman àti Kẹ́mi Olúnlọ́yọ̀ọ́ tí ta ẹsẹ̀ àgẹ̀rẹ̀ sí òfin nípasẹ̀ ṣíṣe iṣẹ́ ìkóròyìnjọ lóríi Òfin Ẹ̀ṣẹ̀ orí-ayélujára.
Má jìyà nínú Ìdáké̩ró̩ró̩ — máa wí lọ
Ìwà tí ó jẹ́ gbòògì àwọn ìpèníjà wọ̀nyí gẹ́gẹ́ bíi ti òfin ń sọ fún ọmọ-ìlú pé ohùn-un wọn ṣe kókó.
"Kí a mú un láti Ìdádúró Tanzania tí ó dá lóríi ìtànká ""ìròyìn irọ́, ìtànjẹ, tàbí ìròyìn tí ò pé ojú òṣùwọ̀n"" lórí ayélujára títí kan owó-orí Uganda fún ìlò ẹ̀rọ-alátagbà fún ìgbógunti ""àhesọ"", ariwo orí ẹ̀rọ-ayárabíaṣá ń já àwọn ìjọba aninilára láyà. Ní ìgbà mìíràn, ó máa mú wọn pa àwọn ìwàa wọn tì."
Ìrírí akọbúlọ́ọ̀gù Zone9 ìlú Ethiopia jẹ́ àpẹẹrẹ.
Ní ọdún 2014, àwọn òǹkọ̀wé ọmọ bíbí Ethiopia mẹ́sàn-án lọ sí ẹ̀wọ̀n àti jìyà oró látàrí iṣẹ́ àjọṣepọ̀ tí wọ́n jọ kọ nípa ìtẹsẹ̀ àgẹ̀rẹ̀ sí ẹ̀tọ́ ọmọ-ènìyàn ìjọba àná ìlú Ethiopia, kí òótọ́ ó di mímọ̀.
"Ìjọba pe ẹgbẹ́ yìí ni ""afẹ̀míṣòfò"" nítorí àtẹ̀jáde orí ẹ̀rọ-ayélujára wọn a sì ti wọ́n mọ́lé fún oṣù 18."
Àwọn ọmọ ẹgbẹ́ Zone9 Mahlet (òsì) àti Zelalem (ọ̀tún) ń dunnú fún ìdásílẹ̀lẹ́wọ̀n Befeqadu Hailu (ẹnìkejì láti ọwọ́ òsì, pẹ̀lú sícáàfù) ní oṣù kẹwàá ọdún 2015.
Orí Twitter ni Zelalem Kiberet ti pín àwòrán yìí.
Àwọn mẹ́fà lára àwọn ẹgbẹ́ náà tí ó ti gba òmìnira báyìí ṣe ìtàkùrọ̀sọ àgbáyé àkọ́kọ́ ní ìlú Ghana ní àsìkò àpérò FIFA: Atnaf Berhane, Befeqadu Hailu Techane, Zelalem Kibret, Natnael Feleke Aberra, àti Abel Wabella náà wá sí àpérò.
Jomanex Kasaye, ẹni tí ó ti bá ẹgbẹ́ náà ṣiṣẹ́ kí àtìmọ́lé ó tó ṣẹlẹ̀ (àmọ́ tí a kò fi àṣẹ mú) náà kò gbẹ́yìn níbi àpérò.
Ọ̀pọ̀lọpọ̀ nínú ẹgbẹ́ yìí ti bá Ohùn Àgbáyé ṣe pọ̀ láti kọ àti ṣe ìtúmọ̀ ìròyìn sí èdè Amharic.
Gẹ́gẹ́ bí ọmọ ẹgbẹ́ Ohùn Àgbáyé ṣe ìpolongo àti ìpanupọ̀ ajàfúnẹ̀tọ́ ọmọnìyàn àgbáyé gẹ́gẹ́ bi agbẹnusọ láti ọjọ́ tí wọ́n dé akoto ọba.
Lẹ́yìn ọ̀pọ̀lọpọ̀ oṣù tí a tẹ ọ̀kanòjọ̀kan ìròyìn jáde àti ìgbélárugẹ ìtàkùrọ̀sọ ọ̀ràn wọn lórí Twitter, ìdálébi ìfàṣẹmú àti àtìmọ́lé gba ojúlé ìjọba àti àwọn alẹ́nulọ́rọ̀ ajàfúnẹ̀tọ́ ọmọnìyàn ní àgbáyé kọjá, láì gbàgbé àwọn ọgọọ́gọ̀rún àti ẹgbẹẹ̀gbẹ̀rún alátìlẹ́yìn orí ẹ̀rọ-ayélujára.
Láti orígun mẹ́rẹ̀ẹ̀rin àgbáyé, igbe ńlá ni ó gba àwọn akọbúlọ́ọ̀gù Zone9 sílẹ̀ lọ́wọ́ ìjọba ilẹ̀ Ethiopia.
Nínú ọ̀rọ̀ wọn ní FIFA, àwọn akọbúlọ́ọ̀gù náà sọ wípé ìkẹ́gbẹ́ẹ wọn nínú Ohùn Àgbáyé ṣe gudugudu méje yàyà mẹ́fà ní àsìkò tí àwọn ń fi aṣọ pénpé ro oko ọba.
Ní ètò ìtàkùrọ̀sọ wọn, wọ́n gbé orí yìn fún ìpolongo Ohùn Àgbáyé tí ó ṣe iṣẹ́ ribiribi tí ó mú àwọn wà láyé.
Berhan Taye, atọ́kùn ìtàkùrọ̀sọ, bi ẹgbẹ́ yìí ní ìbéèrè ìrírí wọn ní inú túbú.
Bí wọ́n ti ṣe sọ, iná amọ́roro ìtàgé wálẹ̀ díẹ̀.
Ohùn-un wọn mú kí iyàrá ètò pa lọ́lọ́.
Abel Wabella, alákòóso Ohùn Àgbáyé ní ‘ Èdè Amharic , kò fi etí ẹ̀gbẹ́ẹ rẹ̀ kan gbọ́ràn já geere mọ́n láti ara ìjìyà oró tí ó jẹ́ nítorí pé ó kọ̀ láti ti ọwọ́ bọ ìwé ìjẹ́wọ́.
Atnaf Berhane rántí wípé òún jẹ ìyà oró di aago méjì òru tí òún padà sí lẹ́yìn oorun díẹ̀.
Ọ̀kan lára àwọn agbófinró tí ó mú Zelalem Kibret ti fi ìgbà kan rí jẹ́ akẹ́kọ̀ọ́ Kibret ní Ifásitì tí ó ti ń ṣe iṣẹ́ olùkọ́.
Jomanex Kasaye náà ṣe ìrántí ìwàyáìjà ọpọlọ tí ó ní í ṣe pẹ̀lú ìrònú ìfìlú Ethiopia sílẹ̀ kí wọ́n ó tó fi ọwọ́ òfin mú àwọn ọ̀rẹ́ẹ rẹ̀ — ìrora àìlágbára — ìlàkàkà ọkàn àti àìfẹ̀dọ̀lórí òróòró àti ìbẹ̀rù wípé àwọn ọ̀rẹ́ òhun ò ní jáde láàyè.
Àpapọ̀ Akọbúlọ́ọ̀gù Zone9 ní Addis Ababa, ní ọdún 2012. Láti ọwọ́ ọ̀tún: Endalk, Soleyana, Natnael, Abel, Befeqadu, Mahlet, Zelalem, Atnaf, Jomanex.
Endalk Chala ni ó ni àwòrán.
Pẹ̀lú ìrẹ̀lẹ̀, àwọn akọbúlọ́ọ̀gù Zone9 sọ wípé:
A kò kí ń ṣe ẹni tí ó ní okun tàbí ìgboyà... inúu wa dùn nítorí wípé a fún àwọn ènìyàn mìíràn ní ìmísí ni.
Síbẹ̀, akọbúlọ́ọ̀gù Zone9 ṣe àtúnlò ìfẹ́-ìlú-ẹni nínú ọ̀rọ̀ àti ìṣe.
Ó gba ìgboyà láti fẹ́ràn ìlú ẹni pàápàá lẹ́yìn ìjìyà nítorí wípé a sọ̀rọ̀ síta.
Oníròyìn ọmọ Uganda Charles Onyango-Obbo, tí òun náà wà ní FIFA, mẹ́nu ba òwe Igbo tí gbajúgbajà òǹkọ̀wée nì Chinua Achebe mú di mímọ́ tí ó sọ wípé:
Níwọ̀n ìgbà tí òde ti já ọgbọ́n àtamátàsè, ẹyẹ Eneke náà ti kọ́ fífò láì bà.
Ní àkótán, ohun tí ó fẹ́ sọ ní wípé láti mú ayélujára wà ní ipò ọ̀fẹ́ àti ààbò, àwọn tí ó ń jà fún èyí nílò láti wá ọgbọ́n mìíràn dá.
Àwọn ajàfúnẹ̀tọ́ tí ó ń lé iwájú nínú òmìnira ọ̀rọ̀ sísọ ní ìlú-Gúúsù-Aṣálẹ̀-Sàhárà àti káríayé kò gbọdọ̀ ṣe aláì máà wá wọ̀rọ̀kọ̀ fi ṣ'àdá lórí ọ̀ràn yìí.
Pẹ̀lú agbára àti àjọṣe wa, ẹ̀rọ-ayélujára yóò di ibi òmìnira fún ìtẹ̀síwájú ìjọba àwa-arawa.
Ìjàm̀bá Àwọn Ológun Mauritania 28 tí wọ́n pa ní ọjọ́ Òmìnira tí a kò sọ
Àwòrán àwọn Ológun 28 tí wọ́n pa lọ́jọ́ òmìnira – Ibrahima Sow ni ó ṣe àtẹ̀jáde fídíò.
Ní ọjọ́ kejìdínlọ́gbọ̀n oṣù Belu ọdún 1990, àwọn ẹgbẹ́ ológun yẹgi fún ọkùnrin méjìdínlọ́gbọ̀n tí a fi ìfarabalẹ̀ ṣà lọ́kọ̀ọ̀kan láti pa nínú ẹ̀wọ̀n láàárín òru, ní Inal ní orílẹ̀-èdè Mauritania lẹ́yìn tí a fi ẹ̀sùn ìpète-lati-gba-ìjọba kàn wọ́n.
Ọjọ́ yìí, tún jẹ́ àyájọ́ ọjọ́ tí orílẹ̀-èdè Mauritania gba òmìnira lọ́wọ́ France ní ọdún 1960, lé góńgó sọ́kàn àwọn ọmọ orílẹ̀-èdè Mauritania kan tí wọ́n ń wá ìdájọ́ òdodo fún ìpakúpa tí wọ́n pa àwọn ọkùnrin 28 yìí, tí gbogbo wọn sì jẹ́ aláwọ̀ dúdú.
Orílẹ̀-èdè Mauritania ti Ìwọ̀-oòrùn Ilẹ̀-Adúláwọ̀ jẹ́ ìdàpọ̀ àwọn Lárúbáwá àti àwọn aláwọ̀ dúdú, àwọn ẹgbẹ́ ajàfẹ́tọ̀ọ́ ọmọnìyàn sọ pé àwọn aláwọ̀ dúdú ti ń dojúkọ ìyàsọ́tọ̀ àti ìlòkulò fún ìgbà pípẹ́.
Ààrẹ Ìgbìmọ̀ àwọn Inal-France, Youba Dianka, ṣàlàyé:
Ìtúmọ̀ Ìtúnwí-ọ̀rọ̀ Ọlọ́rọ̀ gan-an
Mo fẹ́ fi hàn wípé àpẹẹrẹ ni Inal jẹ́; ọ̀pọ̀ ọmọ ‘Inal’ ni ó ti wà ní Mauritania.
Àwọn ìṣẹ̀lẹ̀ abanilẹ́rù ti wáyé ní Azlatt, Sony Malé, Wothie, Walata, Jreida àti nínú àfonífojì.
Nínú ọgbà àwọn ológun ní Inal àti àgbègbè rẹ̀, wọ́n pín àwọn ológun yẹ́lẹyẹ̀lẹ, wọ́n rì wọ́n mọ́lẹ̀ ní òòyẹ̀, wọ́n yìnbọn lù wọ́n, wọ́n sì yẹgi fún wọn ní ìrántí òmìnira orílẹ̀-èdè náà lọ́dún 1990.
Ní àyájọ́ ọjọ́ òmìnira ti ọdún yìí, àwọn ọmọ orílẹ̀-èdè Mauritania fi ọkàn sí yíyàn tí a yan ẹgbẹ́ agbábọ́ọ̀lù orílẹ̀-èdè wọn sí àṣekágbá ìdíje Ife-ẹ̀yẹ ti àwọn orílẹ̀-èdè Ilẹ̀-Adúláwọ̀ (CAF) ju bí wọ́n ṣe ṣe sí àwọn ẹni ìgbàgbé, àwọn ológun tí wọ́n wà nínú kòtò àìmọ̀ ...
tí wọ́n ṣì ń dúró de ìsìnkú tí ó yẹni, Kaaw Elimane Bilbassi Toure tí í ṣe olóòtú ibùdó ìròyìn orí ayélujára Le Flambeau ti Mauritania kọ.
Kiné-Fatim Diop, adarí ìpolongo Amnesty International ní Ìwọ̀-oòrùn Ilẹ̀-Adúláwọ̀, sọ̀rọ̀ ní ọdún yìí nípa ìtakora tí ó wà ní àárín ohun tí ó yẹ kí ó jẹ́ ọjọ́ ìṣèrántí-dunnú àti ohun tí ọ̀pọ̀lọpọ̀ ẹbí àwọn olùfarapa ń rò:
Ìtúmọ̀ Ìtúnwí-ọ̀rọ̀ Ọlọ́rọ̀ gan-an
Lọ́dọọdún, bí àwọn tí wọ́n dipò mú ṣe ń ṣe ìrántí ìgùnkè wọn sí ipò gíga pẹ̀lú ìdùnnú, ẹbí àwọn olùfarapa máa ń sunkún, tí wọ́n sì máa ń fi ẹhónú hàn pẹ̀lú ìbànújẹ́ fún àtúnṣe àti ìdájọ́ òdodo.
Àwọn tí ó wà nípò àṣẹ kàn ń gbìyànjú láti ri apá òmìnira tí kò farahàn yìí mọ́lẹ̀, gẹ́gẹ́ bí wọ́n ṣe dìbò yan òfin ìdáríjì ìjọba ní ìkọ̀kọ̀ lọ́dún 1993 tí wọ́n sì fìdí ìgbàgbé ìjọba múlẹ̀ nípa ìpakúpa àwọn ológun náà lọ́gbọ̀n ọdún sẹ́yìn.
Àjọ tí ó ń tako àìjìyà ẹlẹ́ṣẹ̀ àti àìṣòdodo ní orílẹ̀-èdè Mauritania Forum Against Impunity and Injustice fi ìbànújẹ́ hàn lórí ìjàm̀bá àwọn tẹ̀gbọ́n-tàbúrò kan tí a yẹgi fún lálẹ́ ọjọ́ burúkú Èṣù gb'omi mu yìí:
Ìtúmọ̀ Ìtúnwí-ọ̀rọ̀ Ọlọ́rọ̀ gan-an
Láìsí àní-àní, èpè ja àwọn ológun 28 yẹn lóru ọjọ́ náà. Bí i ti àwọn tẹ̀gbọ́n-tàbúrò, Diallo Oumar Demba àti àbúròo rẹ̀ Diallo Ibrahima tí a yẹgi fún pẹ̀lú àkọsílẹ̀ nọ́ḿbà tí ó tẹ̀lé ara wọn tí a fi gègé kọ sí wọn lára.
Ohun tí ó mú èyí bani nínú jẹ́ jù ni fún ẹni láti rí ikú tí ó pa ẹ̀gbọ́n ẹni.
Àwọn apani ṣe iṣẹ́ wọn pé, wọn kò sì dáwọ́ dúró lẹ́yìn tí wọ́n yẹgi fún wọn, wọ́n tún wọ́ òkúu wọn nílẹ̀ bẹ́ẹ̀ náà ni wọ́n sì ń jókòó lé wọn lórí.
Àwọn Ẹni-orí-kó-yọ sọ̀rọ̀ síta
Ẹ̀rí túbọ̀ ń tẹnu àwọn ẹni-orí-kó-yọ jáde lẹ́yìn ọgbọ̀n ọdún.
Mamadou Sy jẹ́ apàṣẹ ẹgbẹ́-ológun nínú ẹgbẹ́ ológun Mauritania, ó ti jẹ́ igbákejì apàṣẹ, kí ó tó wá di apàṣẹ ẹgbẹ́ ológun ẹ̀ka kan kí wọ́n tó mú un ní alẹ́ ọjọ́ yẹn.
Nínú ìwée rẹ̀, “Ọ̀run-àpáàdì ní Inal“, tí a tẹ̀ jáde ní ọdún 2000, ó ṣàpèjúwe ìjìyà-oró tí ó jẹ, nígbà tí àwọn apàṣẹ ológun dì í lójú, so ó mọ́lẹ̀, tí wọ́n sì jù ú sínú omi ìdọ̀tí rírùn.
Ológun mìíràn tí orí kó yọ lálẹ́ ọjọ́ burúkú yìí tiraka gba France lọ fún ìtọ́jú lẹ́yìn tí ó kúrò ní ọgbà ẹ̀wọ̀n pẹ̀lú ìrànwọ́ àwọn Àjọ Onígbàgbọ́ tí ó ń tako Ìfìyàjẹni (ACAT lédè Faransé).
Ní ipò àìlórúkọ, ó jẹ́rìí sí ìyàsọ́tọ̀ ẹ̀yà tí ó rí láàárín ọdún mẹ́rìnlélógún tí ó fi ṣiṣẹ́ ológun:
Ìtúmọ̀ Ìtúnwí-ọ̀rọ̀ Ọlọ́rọ̀ gan-an
Gẹ́gẹ́ bí mo ṣe rántí, nígbà tí ó bẹ̀rẹ̀ sí í yé mi, mo ti máa ń ṣàkíyèsí pé àwọn aláwọ̀ dúdú kì í ní ẹ̀tọ́ kankan, ṣùgbọ́n àwọn aláwọ̀ funfun ará Mauritania máa ń ní àǹfààní tí ó pọ̀.
Níbí, nínú ogún àwọn adarí ipò ìjọba, ìdá mẹ́rin péré ni wọ́n jẹ́ aláwọ̀ dúdú. Nínú ẹgbẹ́ ológun, aláwọ̀ dúdú kan ṣoṣo ni ó máa ń wà láàárín ológun mẹ́wàá.
Nígbà ìkọ́ṣẹ́, bí ọmọ Mauritania aláwọ̀ funfun kan kò bá ṣe dáadáa, wọn á ṣì borí aláwọ̀ dúdú mìíràn. A ò sì gbọdọ̀ fi ẹhónú hàn…
Ó ṣe àpèjúwe àwọn ìfìyàorójẹni tí òun pẹ̀lú àwọn ológun mìíràn rí:
Ìtúmọ̀ Ìtúnwí-ọ̀rọ̀ Ọlọ́rọ̀ gan-an
Fún àpẹẹrẹ, wọ́n gbẹ́ kòtò sínú iyẹ̀pẹ̀, wọ́n sì rì wá mọ́lẹ̀ dé ibi ọrùn, orí wa ò ṣe é yí, ojú wa sì wà ní ìhà oòrùn.
Tí a bá sì gbìyànjú láti pa ojú dé, àwọn ẹ̀ṣọ́ á da iyẹ̀pẹ̀ sí wa. Wọ́n á sì wọ ìbòjú padà.
Maimouna Alpha Sy, akọ̀wé gbogboògbò fún Ẹgbẹ́ Ọ̀ràn Opó àti Aṣàánù ọmọ-ènìyàn, ti fi ìgbà kan rí jẹ́ aya Ba Baïdy Alassane, tí ó jẹ́ adarí àwọn ẹ̀ṣọ́ ibodè tẹ́lẹ̀.
Alpha Sy sọ pé ọkọ rẹ̀ tí ó ti di olóògbé wà lára àwọn tí wọ́n pa lọ́dún 1990.
Ìtúmọ̀ Ìtúnwí-ọ̀rọ̀ Ọlọ́rọ̀ gan-an
Oṣù mẹ́ta àti ọjọ́ mẹ́wàá ni a fi wá ọkọ mi, ṣùgbọ́n pàbó ni ó já sí ...
Àwọn ẹ̀ṣọ́-ibodè sọ fún wa pé àìsàn ọkàn ló pa á, tí èyí kò sì jẹ́ òtítọ́.
Wọ́n mú àwọn tó jẹ́rìí pẹ̀lú rẹ̀, wọ́n so wọ́n, wọ́n sì fi ìyà oró jẹ wọ́n pẹ̀lú rẹ̀.
Ní iwájú wọn ni wọ́n ti pa á.
‘Kò tún gbọdọ̀ ṣẹlẹ̀ mọ́’
Lọ́dún yìí ni ọjọ́ kejìdínlọ́gbọ̀n, àwọn ọmọ Mauritania tí wọ́n jẹ́ aṣíkiri fi ẹ̀hónú hàn níwájú Ẹ́mbásì Mauritania ní ìlú Paris, ní orílẹ̀-èdè France, lórí àìfiyèsí ìjọba nípa ìṣẹ̀lẹ̀ oró yìí.
Kardiata Malick Diallo, tí ó jẹ́ igbákejì, sọ ọrọ àròjinlẹ̀ ní ilé Ìgbìmọ̀ aṣòfin Mauritania láti máà jẹ́ kí àwọn ènìyàn gbàgbé, tí ó sì fi ẹ̀sùn kàn ààrẹ tí ó wà lórí oyè pé ó ń dáàbò bo àwọn oníṣẹ́-ibi náà, tí wọ́n ṣì ń dipò gíga mú nínú ìjọba nígbà tí wọn kò tí ì wá nǹkan ṣe sí ẹ̀tọ́ àwọn olùfarapa:
Ìtúmọ̀ Ìtúnwí-ọ̀rọ̀ Ọlọ́rọ̀ gan-an
Bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé ìwọ kọ́ ni o ṣe iṣẹ́-ibi tí ó kó àbààwọ́n ba gbogbo ọjọ́ 28 oṣù Belu jẹ́, ìwọ ni ó yẹ kí o wá ojútùú sí ẹ̀tọ́ àwọn olùfarapa sí òtítọ́ àti òdodo...
"Àwọn orílẹ̀-èdè olókìkí àti àwọn èèyàn ńlá kì í gbìyànjú láti pa ìṣẹ̀lẹ̀ aburú inú ìtàn-an wọn rẹ́, dípò èyí wọ́n máa ń fi han ayé kí gbogbo ènìyàn lè rántí kí wọ́n sì sọ pé ""KÒ TÚN GBỌDỌ̀ ṢẸLẸ̀ MỌ́ ""."
Ọ̀gbẹ́ni ààrẹ, àkósoò rẹ ti ṣe àmúlò òfin ìyàsọ́tọ̀ àti ìyọkúrò ẹ̀yà.
Ní oṣù Ọ̀wàrà ọdún 2018, nínú àwọn adarí ipò ìjọba 24, márùn-ún péré ni àwọn tí ó jẹ́ aláwọ̀ dúdú àti elẹ́yà-méjì, tí wọ́n ń ṣojú ìdá 70 àwọn mẹ̀kúnù.
Ọ̀pọ̀ àwọn mẹ̀kúnù ni wọ́n kò ní aṣojú láàárín àwọn aṣojú tí wọ́n dìbò yàn, láàárín àwọn ẹgbẹ́ àbò àti àwọn adarí ipò ìjọba ìbílẹ̀.
Mauritania ni orílẹ̀-èdè tí ó gbẹ́yìn láti pa òwò-ẹrú rẹ ní àgbáyé ní ọdún 1981, ṣùgbọ́n wọn kò fi ìdíi rẹ̀ múlẹ̀ títí di ọdún 2007, ìdá 20 àwọn ènìyàn ni wọ́n ṣì ń gbáyé ìṣẹrúsìn tí púpọ̀ nínú wọn sì jẹ́ aláwọ̀ dúdú tàbí elẹ́yà-méjì.
Nítorí ìyàsọ́tọ̀ ẹ̀yà yìí ṣì ń ṣẹlẹ̀ ní orílẹ̀-èdè Mauritania, ìdájọ́ òdodo kò sí ní àrọ́wọ́tó fún àwọn ẹni orí-kó-yọ àti àwọn ìdílé wọn.
100 ọjọ́ fún Alaa: Ẹbí ajàfúnẹ̀tọ́ ọmọ Íjípìtì ń ka ọjọ́ fún ìdásílẹ̀ẹ rẹ̀ nínú ẹ̀wọ̀n
Alaa Abd El Fattah, àwòrán láti ọwọ́ Nariman El-Mofty.
Lẹ́yìn tí ó ti lo ọdún 5 nínú ẹ̀wọ̀n, akọbúlọ́ọ̀gù ọmọ Íjípìtì àti ajàfúnẹ̀tọ́ Alaa Abd El Fattah yóò gba ìdásílẹ̀ nínú ẹ̀wọ̀n ní ọjọ́ 7, oṣù Ẹrẹ́nà, ọdún 2019.
"Ní ọjọ́ 8 oṣù Ọ̀pẹ, ẹbíi rẹ̀ ti ṣe àgbékalẹ̀ ìpolongo –""100 ọjọ́ fún Alaa"" — kí àtìmọ́lée rẹ̀ ó ba wá s'ópin ní mọnawáà."
Ìdásílẹ̀ẹ rẹ̀ nínú oṣù Ẹrẹ́nà kì í ṣe ìsààmì òpin ìgbà Alaa ní ẹ̀wọ̀n, ṣùgbọ́n ìṣíkúrò sí ipò tí ó jẹ́ àṣekágbá àtìmọ́lée rẹ̀.
Lẹ́yìn ìdásílẹ̀ẹ rẹ̀, Alaa yóò máa wá sun oorun alẹ́ ní àgọ́ ọlọ́pàá ìbílẹ̀ẹ rẹ̀ fún àfikún ọdún márùn-ún gbáko.
Abẹ́ ìṣọ́ ọlọ́pàá ni yóò wà fún àkókò yìí.
A fi ọwọ́ọ ṣìgún òfin mú Alaa a sì mú u kúrò ní ilé ẹbíi rẹ̀ nínú oṣù Belu ọdún 2013.
"Ọdún kan kọjá, nínú oṣù Èrèlé ọdún 2015, a gbé e re ilé ẹjọ́ a sì rán an ní ẹ̀wọ̀n ọdún márùn-ún fún ""àgbékalẹ̀ "" ìyíde kiri ìfẹ̀hànnúhàn lábẹ́ òfin ìyíde kiri ìfẹ̀hànnúhàn ọdún 2013 tí kò fi àyè gba ìyíde láìgbàṣẹ."
Ní tòótọ́ ni ó kópa nínú ìyíde kiri tí ó ń tako ẹjọ́ tí àwọn ológun dá mẹ́kúnnú ní ọjọ́ 26 oṣù Belu ọdún 2013, Alaa kò kó ipa nínú àgbékalẹ̀ẹ rẹ̀.
Ilé ẹjọ́ Cassation ti Íjípìtì fi ẹsẹ ẹ̀wọ̀n-ọn rẹ̀ múlẹ̀ nínú oṣù Belu ọdún 2017.
Omar Robert Hamilton, olùkùu Alaa, to àwọn ète ìpolongo náà lẹ́sẹẹsẹ lóríi Twitter:
Láti mú kí àwọn ọmọ ìbílẹ̀ àti ọmọ àgbáyé ó fi ọkàn sí ìdájọ́ àti fún ìdásílẹ̀ẹ Alaa ní ọjọ́ 17 oṣù Ẹrẹ́nà.
Láti gbé ìrò المراقبة (‘ìṣọ́nikiri’ tàbí ‘ìdásílẹ̀-lẹ́wọ̀n-kọ́jọ́-ìdásílẹ̀-tó-pé’) sínú làákàyè àwọn ènìyàn gbogbo.
"Lẹ́yìn ìdásílẹ̀, Alaa ṣì tún ní láti sun ọrùn alẹ́ nínú àgọ́ ọlọ́pàá ìbílẹ̀ẹ rẹ̀ fún ""ọdún márùn-ún""."
A ní láti ṣe iṣẹ́ ìpìlẹ̀ fún ìtako èyí.
Gbogbo olórí orílẹ̀-èdè Íjípìtì ni ó ti ṣe ìwádìí tàbí rán Alaa ní ẹ̀wọ̀n ní ojú ayée rẹ̀.
Ní ọdún 2006, a fi ọwọ́ọ ṣìgún òfin mú u fún ipa tí ó kó nínú ìyíde kiri ìfẹ̀hànnúhàn tí kò fa ìdíwọ́ fún ẹnikẹ́ni.
Ní ọdún 2011, ó lo oṣù méjì ní ẹ̀wọ̀n, àkókò yìí ni ìyàwóo rẹ̀ bí àkọ́bíi rẹ̀, Khaled.
Ní ọdún 2013, a mú u a sì fi sínú àhámọ́ fún ọjọ́ 115 láì ṣe ìgbẹ́jọ́.
Ó ti pẹ́ tí Alaa ti ń ṣiṣẹ́ lóríi ìjìnlẹ̀ ìmọ̀-ẹ̀rọ àti òṣèlú pẹ̀lú ìyàwóo rẹ̀, Manal Hassan.
Ìdílé gbajúgbajà ajàfúnẹ̀tọ́ ọmọnìyàn ni ó ti wà, adájọ́ ajàfúnẹ̀tọ́ ọmọnìyàn Ahmed Seif El Islam, ni bàbáa Alaa, ẹni tí a ti rán lọ ní ẹ̀wọ̀n láì mọye ìgbà ní abẹ́ àṣẹ Hosni Mubarak.
Ẹ̀gbọ́n-bìrin méjèèjì Abd El Fattah, Mona àti Sanaa Seif, jẹ́ agbèjà ẹ̀tọ́ ọmọnìyàn bákan náà tí wọ́n sì ti ṣe ìpolongo alátakò ìjìyà mẹ́kúnnú lọ́wọ́ọ àwọn ológun ní ìlú náà.
Ní ọdún 2016, Sanaa lo oṣù mẹ́fà ní ẹ̀wọ̀n nítorí wípé ó sọ̀rọ̀ àfojúdi sí alás̩e̩ ìjọba.
Àdánwòo Alaa jọ ti ọ̀pọ̀lọpọ̀ ọmọ orílẹ̀-èdè Íjípìtì tí ó wà ní ẹ̀yin gádà nítorí akitiyan wọn nípa ẹ̀tọ́ ọmọnìyàn.
Ẹgbẹ́ ajàfúnẹ̀tọ́ ọmọnìyàn sọ wípé, àwọn tí ìjọba rán ní ẹ̀wọ̀n ní Íjípìtì á tó 60,000.
Gbogbo ẹni tí ìjọba bá fi ọwọ́ọ ṣìgún òfin mú ní Íjípìtì ní í jẹ ìyà oró, ìfarasin, àtìmọ́lé ọjọ́ pípẹ́ àti àdánìkangbé inúu túbú.
Dídarapọ̀ mọ́n ìpolongo #FreeAlaa
Ní inú ìwé tí a kọ sí àwọn àlejò tí ó wá sí RightsCon, àpérò tó dá lórí ẹ̀tọ́ irinṣẹ́ ẹ̀rọ-ayárabíaṣá tí ó wáyé ní Toronto nínú oṣù Èbìbì ọdún 2018, Alaa rọ àwọn alátìlẹ́yìn láti “ṣe àtúnṣe sí ìjọba àwa-arawa ti wọn”.
"Èyí ti fi ìgbà pípẹ́ jẹ́ ìdáhùn mi sí ìbéèrè náà ""báwo ni a ṣe lè ṣe ìrànwọ́?"" Mo ṣì ní ìgbàgbọ́ wípé [àtúnṣe ìjọba àwa-arawa] ni ìdáhùn kan ṣoṣo."
Kì í ṣe ibi tí ò ń gbé nìkan, ṣiṣẹ́, san owó orí àti ṣe àkóso ibi tí ó ti ní ipa, àmọ́ ìfàsẹ́yìn fún ẹ̀tọ́ ọmọnìyàn nínú ibi tí ìjọba àwa-arawa ti fi ẹsẹ̀ rinlẹ̀ lè di lílò fún ìrúfin ẹ̀tọ́ ní àwọn agbègbè tí ẹ̀tọ́ ọmọnìyàn kò fi bẹ́ẹ̀ fi ẹsẹ̀ múlẹ̀.
Mo mọ̀ wípé àwọn ìṣẹ̀lẹ̀ tí ó ń ṣẹlẹ̀ ní òde òní jẹ́ ẹ̀rí wípé àtúnṣe pọ̀ láti ṣe.
Mo ń retí ìmísí ọ̀nà tí ẹ ó gbà tún un ṣe.
"Kí ẹni tí ó bá fẹ́ darapọ̀ mọ́ ìpolongo ""100 ọjọ́ fún Alaa"" ó fi ""àròkọ, àwòrán tàbí ìṣe ìlọ́wọ́sí ìpolongo"" ṣọwọ́ tí a lè tún tẹ̀ jáde sórí ibùdó-ìtàkùn-àgbáyé ìpolongo náà:"
Ìpolongo orísun-ọ̀fẹ́ – a óò máa tẹ àwọn ọgbọ́n àtinúdá tuntun síta, àmọ́ a nílò láti gba èrò tuntun àti agbára tuntun wọlé bákan náà.
Torí ìdí èyí máa bá wa ronú!
Bí ìgbà gbogbo, àmì ìpolongo ni #FreeAlaa – jọ̀wọ́ darapọ̀ mọ́ wa fún ìpalẹ̀mọ́ ìdásílẹ̀ẹ Alaa.
Ìwọ́de afẹ́ àwọn abódiakọ-akọ́diabo àkọ́kọ́ lè tú èrò nípa wọn ní Pakístánì ká
Jannat Ali Pẹ̀lú àwọn alágbèékalẹ̀ láti ilé-iṣẹ́ Sathi àti Track-T.
Àwòrán láti ọwọ́ọ Syed Noman. A lò ó pẹ̀lú àṣẹ.
Fún ìfẹsẹ̀múlẹ̀ ẹ̀tọ́ àti imúdiṣíṣẹ ìbéèrè wọn lábẹ́ òfin, ìwọ́de Afẹ́ Abódiakọ-akọ́diabo wáyé ní Lahore, Pakistan, lọ́jọ́ 29 oṣù Ọ̀pẹ ọdún 2018.
Fún ìgbà àkọ́kọ́ nínú ìtàn ìlúu nì, àwọn Abódiakọ-akọ́diabo kò bẹ̀rù láti jáde síta nínú ibi ìkòkọ̀ wọn àti fún ìjọba láti mú òfin Ààbò Ẹ̀tọ́ Abódiakọ-akọ́diabo Ènìyàn ọjọ́ 24, oṣù Èbìbì 2018.
Transgender Pride march takes place in Pakistan
Trans people in Pakistan staged the country's first Transgender Pride march.
"Ìwé òfin ìlú Pakistan sọ wípé ""A kò gbọdọ̀ fi ẹ̀tọ́ ìgbé ayé tàbí òmìnira du ẹnikẹ́ni ní ìbámu òfin,"" tí ó wà lábẹ́ Àwọn Ẹ̀tọ́ ọmọ ìlú."
Síbẹ̀, Abódiakọ-akọ́diabo ènìyàn ní ìtàn mìíràn láti sọ bí ó bá kan ti ẹ̀tọ́ àti ìgbé ayé; wọ́n ti jìyà oró, ìfipábánilòpọ̀, dáná sun wọ́n ní ààyè, bẹ́ wọn lórí àti yin ìbọn pa wọ́n, ìjọba kò fi torí gbogbo èyí ràn wọ́n lọ́wọ́ pẹ̀lú pé Ìjọba ti tari òfin Ààbò Ẹ̀tọ́ Abódiakọ-akọ́diabo Ènìyàn wọlé nínú oṣù Ẹrẹ́nà ọdún 2018.
Jannat Ali, tí orúkọ ìnagijẹ rẹ̀ ń jẹ́ Lahore's Trans Diva, ni olùdásílẹ̀ Abódiakọ-akọ́diabo Track Transgender àti Olùdarí Ètò fún Ilé-iṣẹ́ Sathi tí ó ṣe àgbékalẹ̀ Ìwọ́de Afẹ́ náà.
Àwọn Abódiakọ-akọ́diabo mìíràn àti àwọn tí kì í ṣe Abódiakọ-akọ́diabo àmọ́ tí ó jẹ́ alátìlẹ́yìn náà kó ipa nínú ìyíde náà àti àṣeyọríi rẹ̀.
Ilé-iṣẹ́ ìpìlẹ̀ Sathi jẹ́ ilé-iṣẹ́ fún àlàáfíà àti ìmójútó ààbò ẹgbẹ́ abódiakọ-akọ́diabo ní Pakistan.
Ìwọ́de Afẹ́ Abódiakọ-akọ́diabo ní Lahore, oṣù Ọ̀pẹ, ọdún 2018.
Syed Noman ni ó ní àwòrán.
A lò ó pẹ̀lú àṣẹ.
Ènìyàn Abódiakọ-akọ́diabo tí ó tó bí 250 láti agbègbè jákèjádò ìlú Pakistan.
Gbajúmọ̀ nínú wọn ni Kami Sid, Bebo láti Sindh, Nadra láti KPK, Anmol láti Agbègbè Sahiwal, Nayab láti Okara, Sunaina Khan (Oníjó ìbílẹ̀), Naghma àti Lucky (Akọrin Coke Studio), Laila Naz àti Neeli Rana.
Ìpàdé oníròyìn ni a fi bẹ̀rẹ̀ ètò ní Ilé Ẹgbẹ́ Akọ̀ròyìn ní Lahore níbi tí wọ́n ti fi ẹ̀dùn ọkàn-an wọn hàn; lẹ́yìn náà ni wọ́n yíde kiri dé Ilé Àṣà Al Hamra níbi tí wọ́n ti jó, kọrin lọ́nà, kí wọn ó tó fọ́nká lẹ́yìn tí wọ́n jẹun tán.
Pẹ̀lú pé ìpàdé fún oníròyìn wáyé ní Ilé Ẹgbẹ́ Akọ̀ròyìn Lahore, Ìyíde Ìgbéraga náà ó jáde nínú ìròyìn.
Bí ó tilẹ̀ jé pé àwọn alágbèékalẹ̀ fi ìwé pe aláṣẹ ìlú, bí i Punjab MNA Saadia Sohail láti Pakistan Tehreek e Insaf, àwọn aláṣẹ kò yọjú.
Ìyíde ọ̀hún fa awuyewuye lórí ẹ̀rọ-alátagbà níbi tí àwọn ènìyàn gbé oríyìn fún ìyíde kiri náà nígbà tí àwọn ènìyàn kan fẹ́ mọ ìdí tí ilé iṣẹ́ oníròyìn kò ṣe rò nípa rẹ̀.
Ni ọ̀rọ̀ọ rẹ̀ alágbèékáa Jannat Ali ní:
The aim was to show positive and progressive image of Pakistan and how the country is slowly accepting us and we are gaining more space in the society.
Pakistan is not only about terrorism and a conservative society there is more to us.
We promoted our march along with our KhawajaSara (transgender) culture and traditions it was not the same type of march as it is held in US.
Ìyíde náà tún tẹnu mọ́ ìlọsíwájú àti ìbáṣepọ̀ rere láàárín ẹgbẹ́ abódiakọ-akọ́diabo; bákan náà ni ó tẹnu mọ́ ìyàsọ́tọ̀ àti rògbòdìyàn.
Nítorí wípé kò sí iṣẹ́ fún wọn, àwọn abódiakọ-akọ́diabo ènìyàn kò ní ṣíṣe ju kí wọn ó ṣe òwò nọ̀bì láti rí oúnjẹ òòjọ́.
Látàrí ìbálòpọ̀ tí kò ní ààbò, ọ̀pọ̀ l'ó ti kó àrùn kògbéwékògbègbó HIV àti AIDS.
Ìdánilẹ́kọ̀ọ́ ṣe kókó fún àjọ ọlọ́pàá àti oníṣègùn nítorí àwọn ni kì í mú ayé rọrùn fún Abódiakọ-akọ́diabo ènìyàn tí ó bá ra ọwọ́ ẹ̀bẹ̀ tàbí nílò ìrànlọ́wọ́ ètò ìlera.
A ti fi ẹ̀tọ́ àwọn abódiakọ-akọ́diabo yí iyẹ̀pẹ̀.
Láti ọdún 2015, abódiakọ-akọ́diabo tí ó tó 500 ni a ti rán lọ sí ọ̀run alakákeji ní Pakistan , Jannat Ali sì tún sọ wípé Abódiakọ-akọ́diabo 60 ni a dá ẹ̀mí wọn ní ẹ̀gbodò ní ọdún tí ó kọjá.
Asad Zaidi túwíìtì nípa ojú tí àwọn ènìyàn Pakistan fi wo ẹgbẹ́ Abódiakọ-akọ́diabo:
Nínú ọ̀rọ̀ọ rẹ̀ ní TEDxLahore ní ọdún 2017, Jannat Ali ṣe àlàyé ìrìnàjòo rẹ̀ gẹ́gẹ́ bí abódiakọ-akọ́diabo ní Pakistan lẹ́yìn ìgbà tí ó fi irú ènìyàn tí òun ń jẹ́ han ẹbí àti àwọn ènìyàn.
Òfin Ẹ̀tọ́ Ààbò Abódiakọ-akọ́diabo Ènìyàn ọdún 2018 tí a bu ọwọ́ lù nínú ilé ìgbìmọ̀ aṣòfin fi àṣẹ fún ọmọ ẹgbẹ́ náà láti gba ìwé àṣẹ ọkọ̀ wíwà, ìwé ìrìnnà, ní ẹ̀tọ́ láti pààrọ ìṣẹ̀dá ẹni nínú àkọsílẹ̀ ìlú àti Àjọ Ìforúkọsílẹ̀ (NADRA), ìfòpinsí ìjìyà, àyè láti kàwé, iṣẹ́ nínú káràkátà àti ètò ìlera láì sí ìyàsọ́tọ̀.
Òfin náà ní ìjọba yóò pèsè àyè ilé ààbò fún Abódiakọ-akọ́diabo ènìyàn, ètò ìlera àti ohun èlò ẹ̀kọ́ àti ilanilọ́yẹ.
Wọ́n máa lè jẹ ogún àti ẹ̀tọ́ láti di ìbò.
Nayaab Ali (ní ìdúró), abódiakọ-akọ́diabo àkọ́kọ́ tí ó dújedupò nínú ìbò àpapọ̀ ọdún 2018, àti Neeli Rana, tí òun náà jẹ́ gbajúgbajà abódiakọ-akọ́diabo ènìyàn.
Ayàwòrán Ikọ̀ Afẹ́ Abódiakọ-akọ́diabo ni ó ní àṣẹ, a gba àṣẹ àtúnlò lọ́wọ́ọ rẹ̀.
Pakistan ti ń sún kẹ́rẹ́ ní ti ìgbé ayé Abódiakọ-akọ́diabo.
Díẹ̀ lára àwọn abódiakọ-akọ́diabo ènìyàn du ipò ìjọba nínú Ìbò ọdún 2018 fún ìgbà àkọ́kọ́.
Ilé iṣẹ́ amóhùnmáwòrán ìbílẹ̀ kan gba Abódiakọ-akọ́diabo àkọ́kọ́ sí iṣẹ́ gẹ́gẹ́ bí atọ́kùn; Coke Studio, ètò orin, àwọn Abódiakọ-akọ́diabo méjì ni ó ti kópa ní orí ètò náà.
Bí nǹkan ṣe ń ṣe ẹnu ire fún àwọn ọmọ ẹgbẹ́ Abódiakọ-akọ́diabo a sì ń gbà wọ́n gẹ́gẹ́ bí ènìyàn, ìrìnàjò náà kò yàrá.
Síbẹ̀, ọ̀gọ̀rọ̀ ènìyàn ni ó ní ìgbàgbọ́ wípé àyípadà ọ̀tún ń bọ̀ fún àwọn ènìyàn wọ̀nyí láti gbé ìgbé ayé ìfọkànbalẹ̀ nígbà tí ẹ̀tọ́ ọmọnìyàn gbogbo ní ìlú á wà ní ọ̀gbọọgba ní ojú àwọn ènìyàn àti ní abẹ́ òfin.
‘Ẹ Yé é Pa Àwọn Òbìnrin’ – ìpolongo tuntun tí ó ń tako ìjìyà inú ìgbéyàwó ní Angola
Manifestação em Luanda: #Paremdematarasmulheres | foto Simão Hossi
Ìfè̩hònúhàn hàn ní Luanda, Angola, pẹ̀lú àmì ìpolongo #Paremdematarasmulheres ní èdè Portuguese, tabí ‘ẹ yé é pa obìnrin’, àwòrán láti ọwọ́ọ Simão Hossi, a lò ó pẹ̀lú àṣẹ.
Nígbà tí wọ́n bá òkú agbẹjọ́rò tí ó jẹ́ ẹni ọdún 26, Carolina Joaquim de Sousa da Silva nínú ilée rẹ̀ ní ọjọ́ 3, oṣù Ọ̀pẹ ọdún 2018, ọkọ rẹ̀ jẹ́wọ́ ọ̀ràn náà, ó sì di èrò àhámọ̀ ẹ̀ka tí ó ń ṣe ìwádìí ìwà ọ̀daràn ti Angola tí a mọ̀ sí SIC.
Láàárín ọ̀sẹ̀ kan náà, ìròyìn ikú obìnrin kan ni ó jáde láti ilé-iṣẹ́ Amóhùn-máwòrán Gbogboògbò orílẹ̀-èdè Angola tí ó ní wípé ọ̀rẹ́kùnrin ìgbà-kan-rí obìnrin náà ni ó gún un pa.
"Àwọn ọ̀ràn ìwà ọ̀darànmọràn yìí ti mú ọ̀pọ̀lọpọ̀ àwọn obìnrin ní orílẹ̀-èdè Angola dúró gírígírí, èyí sì fa ìpolongo tuntun kan tí ó ń tako ìjìyà abẹ́lé tí wọ́n pe àkóríi rẹ̀ ní ""Ẹ Yé é Pa àwọn Obìnrin"" tí Ẹgbẹ́ Ondjango tí ó jẹ́ àjọ ajàfúnẹ̀tọ́ obìnrin tí kì í ṣe ti ìjọba ṣe àgbékalẹ̀ẹ rẹ̀."
Wọ́n ṣe àmúlò Facebook gẹ́gẹ́ bí ohun èlò ìkórajọ wọn, èròńgbà wọn ni láti jẹ́ kí àwọn ènìyàn mọ̀ nípa àwọn ìjìyà obìnrin ní orílẹ̀-èdè Angola:
Ìtúmọ̀ Ìtúnwí-ọ̀rọ̀ Ọlọ́rọ̀ gan-an
Àsìkò yìí jẹ́ èyí tí ó le.
Lóòótọ́, fún àwa obìnrin ọ̀pọ̀lọpọ̀ ọjọ́ ni ó le tí ó sì ń dùn èèyàn nítorí pé a ṣì wà ní ipò tí ó jẹ́ pé a máa ń yẹra fún ìjìyà lọ́nà kan tàbí òmíràn.
Láìpẹ́ yìí gan-an pàápàá, ó dunni láti máa kojú àwọn ìhùwàsí tí ó ń jáde lẹ́yìn ọ̀rọ̀ ti Carolina...
Lóòótọ́ ni ìjìyà àwọn obìnrin, ó wà lóòótọ́.
Kì í ṣe ohun tí ó kàn wá lórí àwọn ajàfúnẹ̀tọ́ obìnrin, kì í sì í ṣe ọ̀rọ̀ àgbélẹ̀rọ tàbí ọ̀rọ̀ òfìfo, LÓÒÓTỌ́ NI!
Ó ṣeni láàánú pé ti Carolina kún ìṣirò tí ó ti wà nílẹ̀, ọ̀pọ̀ ọ̀ràn báyìí ti wáyé kí tirẹ̀ ó tó ṣẹlẹ̀ tí àwọn ènìyàn gbọ́ sí, bẹ́ẹ̀ sì ni ẹgbẹẹgbẹ̀rún àwọn ọ̀ràn mìíràn tí àwọn èèyàn ò mọ̀ sí.
Ó jẹ́ ìṣòro kan tí ó ti wà níbẹ̀ lẹ́nu ọ̀nà níwájú wa.
Ó sì jẹ́ ìṣòro tí ó ń ro ti ìbáṣe láàárín tọkọtaya – ìṣòro àtilẹ̀wá ni.
Ètò ìpìlẹ̀ kan wà tí ó ń pàṣẹ tí ó sì ń rẹ àwọn obìnrin sílẹ̀ sí ipò ẹ̀yìn tí èyí sì sọ wọ́n di olùfaragbá ìjìyà lóríṣiríṣi àti ní gbogbo ọ̀nà.
Ètò fífi akọ ṣe olórí yìí tí ó ti kọ́ wa lọ́rùn tipẹ́ tí ọ̀pọ̀lọpọ̀ sì ń kọ̀ pé kò rí bẹ́ẹ̀ – ìyẹn kò sì ṣe é rí – ohun tí ó ń ṣe rè é: ó ń sọni di aláàbọ̀-ara, ó ń ba ayé àwọn obìnrin jẹ́, bẹ́ẹ̀ ló ń pani.
"Àwa obìnrin lọ́kọ̀ọ̀kan àti àpapọ̀ọ wa, a máa tẹ̀síwajú láti máa pariwo kí ""ẹ yéé pa wá"" kí ẹ sì ""yéé ṣe wá léṣe""."
À ń fẹ́ àwọn òfin tí yóò dáàbò bò wá tí wọn yóò sì kún ojú ìwọ̀n, a fẹ́ àwọn ètò àmúlò gbogboògbò tí yóò mú àpọ́nlé wa lọ sí àwọn ìtàkùrọ̀sọ àti àwọn ìdásílẹ̀.
A fẹ́ àwùjọ tí ẹ̀rù àtijáde ò ti ní bà wá!
A máa tẹ̀síwajú láti béèrè fún àwùjọ tí a óò ti ní òmìnira ti ara, òmìnira ìmọ̀lára, òmìnira ìrìn àti òmìnira ríronú bí a ṣe fẹ́.
A máa tẹ̀síwajú láti béèrè fún àwùjọ tí a ti lè gbáyé pẹ̀lú ààbò tó péye.
Bẹ́ẹ̀, ìpolongo yìí mú èsì tí ó ń takoni wá láti ọ̀dọ̀ àwọn ọkùnrin kan tí wọ́n rí ìdí fún ìdáláre fún ìrúkèrúdò fífi ìyà jẹ obìnrin.
"Wọ́n pe ìpolongo wọn ní ""Ẹ Yé é Dà Wá"", wọ́n gbà pé ìwà ọ̀dàlẹ̀ jẹ́ ìdí tí ó tọ́ láti máa fìyà jẹ obìnrin."
Bíótilẹ̀jẹ́pé èrò wọn ò tí ì máa rinlẹ̀, Olórin Angola, Gill Slows Allen Russell náà sọ̀rọ̀;
Ìtúmọ̀ Ìtúnwí-ọ̀rọ̀ Ọlọ́rọ̀ gan-an
“Ẹ yé é da ẹlòmíràn, ẹ jọ̀wọ́ a ò fẹ́ aláìṣòdodo aya mọ́.
À ń ké tantan, ẹ̀yin obìnrin bí ẹ kò bá nífẹ̀ẹ́ wa mọ́, ẹ béèrè fún ìtúká kí ẹ tó máa dà wa, ẹ máa lọ.
Onímọ̀ àwùjọ Mbangula Kemba sọ̀rọ̀ tako ojú tí wọ́n fi wo ọ̀rọ̀ yìí, ó tẹnumọ́ọ pé wọn ò gbọdọ̀ fi ìfìyàjẹni yanjú ìṣòro nínú ìgbéyàwó.
Angola fi ìdí òfin tí ó ń de ìfìyàjẹni tí wọ́n mọ̀ sí 25/11 múlẹ̀ ní ọdún 2011 tí ó ń sọ onírúurú ìfìyàjẹni abẹ́lé di ìwà ọ̀daràn ní gbangba.
Síbẹ̀síbẹ̀, ìdájọ́ òfin yìí kò le tó, ìtìmọ́lé ọdún méjì sí mẹ́jọ.
Sizaltina Cutaia, tí í ṣe ajìjàgbara àti ajàfẹ́tọ̀ọ́ obìnrin ní Angola; tí ó jẹ́ ìlúmọ̀ọ́ká fún iṣẹ́ẹ rẹ̀ lórí ẹ̀tọ́ obìnrin béèrè fún ìṣàmúlò òfin náà lórí àwọn gbàgede ìtàkùrọ̀sọ lórí ẹ̀rọ-alátagbà:
Ìtúmọ̀ Ìtúnwí-ọ̀rọ̀ Ọlọ́rọ̀ gan-an
Àfikún ọdún ẹ̀wọ̀n kò tó, arábìnrin igbá-kejì Ààrẹ MPLA [Àjọ Àwọn ènìyàn tó fẹ́ ìdásílẹ̀ Angola], Ó nílò kí orílẹ̀-èdè ṣe ìdásílẹ̀ àwọn ìlànà àtilẹ̀wá tí yóò kojú ìpanilára – Àwọn ohun tí wọ́n fara mọ́ ní 2007 nípa àjọsọ ìlànà Maputo ní láti di ṣíṣe.
Bákan náà ni ti èyí, ó nílò kí wọ́n ṣe ìdásílẹ̀ òfin arọ́pò tí yóò mú ẹ̀tọ́ àwọn obìnrin rinlẹ̀.
Lára èyí ni gbogbo òfin tí ó de obìnrin ní ti ìbálòpọ̀ àti ẹ̀tọ́ ọmọ bíbí wà.
Kò sí ìwúlò ìsọ̀rọ̀ tako ìjìyà abẹ́lé kí ó wá di ẹ̀yìn wá kí a máa ṣe ìgbèlẹ́yìn àwọn òfin tí ó fi àṣẹ fún agbófinró láti yẹ̀yẹ́ obìrin ní títì ní ojúmọ́, kò bá ara mu!
Kò wúlò kí a máa sọ̀rọ̀ tako ìjìyà abẹ́lé kí a sì tún máa gbèlẹ́yìn àṣàrò ìnáwó tí kò ní ṣe ààbò ètò àwùjọ, ìṣúná àìtó tí gbogbo wa mọ̀ pé ipa òdì ni ó ń kó nínú ayé àwọn obìnrin.
Ó ṣe pàtàkì kí a fi ọgbọ́n kún àwọn ọ̀rọ̀ náà pẹ̀lú ṣíṣe gidi.
Ẹ fi owó yín sí ibi tí ẹnu yín wà.
# ẹyéé pa àwọn obìnrin
Ajàfẹ́tọ̀ọ́ obìnrin Cecelia Kitombé sọ̀rọ̀ sí àwọn tí ó ń ṣe àtìlẹyìn ìbáṣepọ̀ tí ó níyà nínú:
Ìtúmọ̀ Ìtúnwí-ọ̀rọ̀ Ọlọ́rọ̀ gan-an
Lára wa tí à ń tẹnumọ́ ọn pé ó pọ̀jù [láti sọ̀rọ̀ síta tako ìjìyà Abẹ́lé] náà ni ẹni tí ó ń gba àwọn ọmọbìnrin, arábìnrin àti ìbátan lóbìnrin níyànjú láti máa fi ara da ìbáṣepọ̀ tí ó ń pani lára pẹ̀lú ọ̀rọ̀-ẹ̀tàn pé ọ̀rọ̀ tọkọtaya ò ṣe é dá sí, àwọn mìíràn á ní kí o tẹ̀síwajú bẹ́ẹ̀, bí ọ̀rọ̀ lọ́kọláya ṣe rí nìyẹn...
"Àwọn kan tilẹ̀ rò pé obìnrin lè ṣe gbogbo nǹkan, ṣùgbọ́n wọn ò gbọdọ̀ gbàgbé ""ojúṣe"" wọn."
Ẹ yéé pa wá!!!
Bí àpamọ́ àlọ́ àti ìtàn àtọwọ́dọ́wọ́ ṣe mú ọ̀rọ̀ àyíká di mímọ̀ ní Mekong
Adágún omi Mekong. Àwòrán tí a mú láti Ibùdó-ìtàkùn-àgbáyé iṣẹ́ Ìtàn Àwọn Ènìyàn.
A lò ó pẹ̀lú àṣẹ.
Ní ọdún 2014, ogunlọ́gọ̀ ìbílẹ̀ ní Mekong bẹ̀rẹ̀ sí ní í ṣe àkọsílẹ̀ àwọn àlọ́ àti ìtàn àtọwọ́dọ́wọ́ọ wọn pẹ̀lú ìrànlọ́wọ́ ẹgbẹ́ aṣèwádìí kan tí ó ń ṣe àyẹ̀wò fínnífínní sí bí ìtàn wọ̀nyí ṣe lè ṣe ìrànwọ́ tí yóò tú àṣìírí ìmúdìbàjẹ́ àyíká tí àwọn iṣẹ́ ńláǹlà ń fà ní agbègbè náà.
Mekong jẹ́ ọ̀kan nínú àwọn odò ńlá Ásíà tí ó ṣàn gba orílẹ̀-èdè mẹ́fà: China, Myanmar, Thailand, Laos, Cambodia, àti Vietnam.
Ó ní ọ̀pọ̀lọpọ̀ ọrọ̀ ìṣẹ̀dá abẹ̀mí àti ewéko tí ó jẹ́ ohun ìsayéró fún ẹgbẹẹ̀gbẹ̀rún àgbẹ̀ àti apẹja.
Ní ọdún díẹ̀ sẹ́yìn, ọ̀pọ̀lọpọ̀ iṣẹ́ ńláǹlà bíi kòtò ìdarí-omi ṣíṣàn fún Ìpèsè Iná Mànàmáná ti lé àwọn olùgbé jìnà ó sì ń ṣe àkóbá fún nnkan ìṣẹ̀dá odò náà.
Ọ̀kanòjọ̀kan ìfẹ̀hónúhàn kò ṣe nǹkan kan, àwọn iṣẹ́ ìdarí-omi ṣíṣàn ṣì ń lọ, pàápàá jù lọ ní Laos àti Thailand.
Pẹ̀lú àjọṣepọ̀ Mekong Watch, ẹgbẹ́ kan ní Jápáànì ń jà fún ìdàgbàsókè ní agbègbè náà, ọ̀pọ̀lọpọ̀ àwọn àgbà ní Mekong ti bẹ̀rẹ̀ sí ní ṣe àkọsílẹ̀ àlọ́, ìṣẹ̀lẹ̀ àti ìtàn àtọwọ́dọ́wọ́ọ wọn tí ó ní íṣe pẹ̀lú ìṣẹ̀dá.
"Mekong Watch gbàgbọ́ wípé àwọn ìtàn wọ̀nyí ""ti kó ipa ribiribi ní ti ìdáàbò ìṣẹ̀dá nípa dídẹ́kun ìwà àìbìkítà fún ọrọ̀ ìṣẹ̀dá."""
"Mekong Watch sọ wípé ohun ìṣẹ̀dá nìkan kọ́ ni a ní láti dáàbò bò àmọ́ àti àwọn ""nǹkan àjogúnbá tí-a-kò-le-è-rí-dìmú"" tí a lè pín àti rí lò."
Toshiyuki Doi, olùdámọ̀ràn àgbà fún Mekong Watch, ní èyí láti sọ:
Ó pọn dandan fún wa láti ka ìtàn àwọn ènìyàn Mekong kún, kí a dá wọn mọ̀, àti bọ̀wọ̀ fún wọn, papàá jù lọ ní òde òní tí wọ́n ti ń pàdánù àyè wọn ní ìrọ́pò ilé iṣẹ́ oníròyìn ìgbàlódé, tí wọn kò sì fi àjogúnbá lé ìran tí ó ń bọ̀ lọ́wọ́.
Àwọn agbègbè ní Mekong níbi tí àwọn oníṣẹ́-ìwádìí ti ṣe iṣẹ́. 1. Kmhmu’ ní àríwá àti àárín gbùngbùn Laos;; 2. Siphandon ní gúúsù Laos; 3. Akha ní àríwá Thailand; 4. Thai So atí Isan ní àríwá-ìwọ̀-oòrùn Thailand; 5. Bunong ní àríwá-ìwọ̀-oòrùn Cambodia.
A lò ó pẹ̀lú àṣẹ.
Ẹgbẹ́ náà ṣe gudugudu méje yàyà mẹ́fà kí ó tó kó oríṣiríṣi ìtàn 102 jọ ní Cambodia, Laos, àti Thailand.
A ṣe àkọsílẹ̀ àwọn ìtàn wọ̀nyí, dà á kọ sílẹ̀ sínú ìwé, àti ìtúmọ̀ ìtàn sí àwọn èdè orílẹ̀ Thailand, Laos, àti Cambodia kí ó tó kan ẹ̀da ti èdè Gẹ̀ẹ́sì.
Mekong Watch tẹ àwọn ìtàn wọ̀nyí jáde sórí ìwé ìròyìn pélébé àti sórí ẹ̀rọ ayárabíàṣá, wọ́n sì tún lò ó ní ìdánilẹ́kọ̀ọ́ nípa àyíká ní àwọn ìlú náà.
Láti ìparí ọdún 2016, a ti fi ìtàn àwọn ènìyàn ṣe ìdánilẹ́kọ̀ọ́ àyíká fún àwọn èwe ní ìgbèríko Laos àti Thailand.
A ti ṣe àgbékalẹ̀ ìdánilẹ́kọ̀ọ́ ní ilé-ìwé àti ní ìlú ìbílẹ̀ láti tọ́ àwọn èwe sọ́nà, àti àwọn àgbà nígbà mìíràn, láti ṣe àkọsílẹ̀ ìtàn ẹnu àwọn àgbàlagbà, fi ìtàn náà kọ́gbọ́n, àti láti sọ wọ́n di kíkà.
Àpẹẹrẹ ìdánilẹ́kọ̀ọ́ kan ni ìtúnsọ àlọ́ ‘Òwìwí àti Àgbọ̀nrín‘ àwọn aráa Kmhmu ní àárín gbùngbùn àti àríwá Laos.
Àlọ́ náà dá lóríi òwìwí tí kò ríran ní ọ̀sán nítorí ó yan àgbọ̀nrín jẹ.
Níbi ìdánilẹ́kọ̀ọ́ kan, a bi àwọn èwe tí ó kópa:
Irúfẹ́ ẹranko wo ni a bá nínú àlọ́ náà?,
Ǹjẹ́ a lè rí àwọn ẹranko wọ̀nyí ní abúlée yín bí?, àti
bóyá àwọn ẹranko wọ̀nyí ti dínkù sí ti ìgbà kan, kí ni ìwọ rò wípé ó ti ṣẹlẹ̀?
Lẹ́yìn èyí, a gba àwọn akópa ní ìyànjú láti so àlọ́ náà mọ́ ìdìbàjẹ́ àyíká ní ìlúu wọn.
Ní agbègbè Champasak, gúúsù Laos, ìtàn àtọwọ́dọ́wọ́ọ ẹranko omi tí ó ti ń dínkù Irrawaddy dolphin àti ẹyẹ Sida ni a ń lò fi ṣe àpèjúwe bí iṣẹ́ ìdarí-omi-ṣíṣàn ṣe ń ṣe àkóbá fún ẹja inú odò Mekong.
Àlọ́ mìíràn láti gúúsù Laos ní àwọn ìlànà tí ó kọ́ni nípa ìmọrírìi ìbójútó ọrọ̀ ìṣẹ̀dá:
A ṣe àkọsílẹ̀ àlọ́ Orí Erinmi ní ọjọ́ 16, oṣù Belu, ọdún 2014, ní etídò Songkran ní àríwá-ìwọ̀-oòrùn Thailand.
Mun Kimprasert, ẹni ọdún 68. ni asọ̀tàn, Mekong Watch ló ni àwòrán, a lò ó pẹ̀lú àṣẹ.
Ní ìgbà kan, ológun kan wọ inú igbó iwin kan.
Ó ṣe alábàápàdé ọ̀pọ̀lọpọ̀ ewé kátabá níbẹ̀ ó sì ṣẹ́ wọn.
Àmọ́ ṣá, bí ó ti fẹ́ẹ́ jáde nínú igbó náà, ọ̀nà dí mọ́n ọn ní ojú, kò sì mọ ọ̀nà mọ́.
Nítorí wípé ó ṣẹ́ ewé kátabá tí ó pọ̀ ju èyí tí ó lè lò lọ ni kò fi mọ ọ̀nà mọ́n.
Ó wá ọ̀nà títí kò rí.
Ẹ̀rí-ọkàn bẹ̀rẹ̀ sí ní jẹ́ ẹ fún ohun tí ó ṣe, ó pinnu láti dá àwọn ewé kátabá náà padà sí ibi tí ó ti gbé ṣẹ́ ẹ.
Wéré tí ó sọ ọ́ sílẹ̀, logan ni ó rí ọ̀nà ní iwájúu rẹ̀.
Ní àríwá Thailand, àlọ́ àwọn aráa Akha kan nípa ìpilẹ̀ṣẹ̀ swing tí ó sọ iṣẹ́ takuntakun ìfaraẹnisílẹ̀ t'ẹ̀gbọ́ntàbúrò tí ó mú ayé rọrùn.
Ní àríwá ìwọ-oòrùn Thailand, àlọ́ kan tí ó dá lórí Ta Sorn tí Tongsin Tanakanya sọ ṣe ìgbélárugẹ ìṣọ̀kan láàárín aládùúgbò ní ìlú iṣẹ́ àgbẹ̀.
Ìtàn mìíràn ṣe ìrántí bí pípa àgbànrere kan ṣe fa iyọ̀ títà ní apá orílẹ̀-èdè yìí.
Ní Bunong, tí ó wà ní àríwá ìwọ-oòrùn Cambodia, àwọn àlọ́ tí ó sọ nípa ètùtù fún àtúnṣe sí ìgbéyàwó tí kò ní adùn àti ètùtù ìfọ́nrúgbìn àti ìkórè tí Khoeuk Keosineam jẹ́ asọ̀tàn.
Bákan náà ni ìtàn àtọwọ́dọ́wọ́ọ erin tí Chhot Pich sọ ṣe àfihàn bí àwọn òrìṣà ṣe sọ àwọn ará abúlé tí ó fi májèlé sí inú odò di erin.
Ó sọ ìdí tí ó fi rọrùn fún erin láti máa gbé pẹ̀lú àwọn ènìyàn àmọ́, lẹ́yìn ọ̀pọ̀lọpọ̀ ìran, wọ́n gbàgbé ìpìlẹ̀ wọn, wọ́n lọ ń gbé nínú igbó.
Hea Phoeun ti abúlé Laoka, Senmonorom, agbègbè Mondulkiri ní Cambodia ń ṣàlàyé ètùtù ìgbéyàwó tí kò ládùn ní abúlé.
Àwòrán láti ọwọ́ọ Mekong Watch, a lò ó pẹ̀lú àṣẹ.
Fún Mekong Watch àti àwọn agbègbè ní ìlú náà tí àkóbá ti bá, ìpamọ́ àwọn ìtàn wọ̀nyí ṣe kókó nínú ìpolongo ìkọjú-ìjà sí àwọn iṣẹ́ tí yóò lé ẹgbẹẹgbẹ̀rún olùgbé Mekong kúrò ní ilée wọn:
Ìtàn wọ̀nyí lè di ìdánimọ̀ọ wọn gẹ́gẹ́ bí ọmọ ìlú àti ìbáṣepọ̀ t'ó dán mánrán pẹ̀lú àyíká.
Nípasẹ̀ẹ ìtàn, ìlú yóò wá ọ̀nà ìgbàmọ́ra àti/tàbí ìkọjú-ìjà sí ìyípadà tí ó ń ṣẹlẹ̀ ní odò Mekong.
Mọ àwọn òǹdíje sí ipò ààrẹ Nàìjíríà ọdún 2019
Àwọn òǹdíje sí ipò ààrẹ Nàìjíríà ọdún 2019 [Àkópọ̀ àwòrán láti ọwọ́ọ Nwachukwu Egbunike].
Nàìjíríà, orílẹ̀-èdè tí ó ní ènìyàn tí ó pọ̀ jù ní Ilẹ̀-Adúláwọ̀, yóò di ìbò ipò ààrẹ ní ọjọ́ 16, oṣù 2019.
"Bí-ó-ti-lẹ̀-jẹ́-wípé àwọn òǹdíje sí ipò ààrẹ t'ó 73, eré Àpáta Agbára – ibùjókòó ààrẹ orílẹ̀-èdè Nàìjíríà – yóò wáyé ní àárín-in ẹgbẹ́ olóṣèlú méjì tí ó ti ń figagbága ní ọjọ́ tí ó ti pẹ́ àti àwọn òǹdíje tí a pè ní ""agbára ìkẹta"", ìyẹn àwọn ẹgbẹ́ a ṣẹ̀ṣẹ̀ dé sínú ìṣèlú orílẹ̀-èdè Nàìjíríà."
Muhammad Buhari, Ààrẹ orílẹ̀-èdè Nàìjíríà. Creative Commons.
Ẹgbẹ́ méjèèjì tí ó gbajúmọ̀ jù lọ, Ìpéjọ Ìlọsíwájú Gbogboògbò APC àti Ẹgbẹ́-olóṣèlú Ìjọba-àwa-arawa PDP, láì ṣe àní-àní, yóò tari òǹdíje wọn sí gbangba wálíà:
Muhammadu Buhari
Ààrẹ lọ́wọ́lọ́wọ́ tí ó jẹ́ òǹdíje lábẹ́ àsíá APC, Buhari ló jáwé olúborí nínú ìbò ààrẹ ti ọdún 2011 tí ààrẹ ìgbà kan Goodluck Jónátánì sí pàdánù.
Nítorí irú ènìyàn tí Buhari ń ṣe àti èrò wípé yóò gbógun ti ìjẹgúdújẹrá àti ìgbáwọlẹ̀ ẹgbẹ́ afẹ̀míṣòfò Boko Haram ni àwọn ará ìlú fi gbé e sórí àlééfà.
Síbẹ̀, lábẹ́ ìṣàkóso rẹ̀, ààbò ẹ̀mí kò sí pẹ̀lú ìkọlù láàárín darandaran àti àgbẹ̀ bí àwọn darandaran láti àríwá ṣe ń wọ gúúsù láti wá koríko fún ẹran ọ̀sìn-in wọn.
Bákan náà, ẹ̀tọ́ ọmọnìyàn ti wó lulẹ̀ nínú ìṣàkóso ìjọba rẹ̀, pẹ̀lú àìjẹ̀yà àti ìṣowó-ìlú-mọ̀kumọ̀ku ní ibi gíga nínú ìjọba.
Atiku Abubakar [Àwòrán Ibùdó-ìtàkùn-àgbáyé Ilé-iṣẹ́ ìpolongo].
Atiku Abubakar
Abubakar ni igbá-kejì ààrẹ ìgbà kan àti òǹdíje lábẹ́ àsíá PDP.
Ó ti gbìyànjú sẹ́yìn láti di ààrẹ àmọ́ orí kò ṣe ní oore.
Bíótiwùkíórí, ìpolongo rẹ̀ jẹ́ ìgbàwọlé nítorí ìparí ìjà tí ó wà ní àárín òun àti ọ̀gáa rẹ̀, Ààrẹ ìgbà kan rí Olusegun Obasanjo — tí ó sọ wípé ìṣàkóso ìjọba Buhari kùnà.
Gẹ́gẹ́ bí amúgbálẹ́gbẹ̀ẹ́, Abubakar ni ó ṣe bònkárí ìsọhun-ìjọba-di-àdáni àti títa ọ̀kẹ́ àìmọye ilé iṣẹ́ tí ó jẹ́ ti ìjọba tí kò pa owó sí àpò ìjọba.
Àwọn mìíràn tí ó ní ìrètí sí ipò ààrẹ Nàìjíríà ni:
Oby Ezekwesili [Àwòrán tí àwọn alágbèékalẹ̀ ìpolongo tari síta]
Obiageli [Oby] Ezekwesili
Ezekwesili, obìnrin kan ṣoṣo tí ó ń du ipò nínú eré ìbò sísá ti ọdún tí a wà yìí, ti ṣe mínísítà ọrọ̀ líle inú-ilẹ̀ àti ètò ẹ̀kọ́ ní àsìkò ìjọba Olusegun Obasanjo ní àárín ọdún 1999 sí 2007.
Ó sì ti ṣe amúgbálẹ́gbẹ̀ẹ́ ààrẹ Ilé ìfowópamọ́ Àgbáyé ẹ̀ka ti Ilẹ̀ Adúláwọ̀ ìgbà kan láti oṣù Igbe ọdún 2007 sí oṣù Igbe ọdún 2012.
Ezekwesili ti ṣe bẹbẹ nínú akitiyan ìdásílẹ̀ àwọn akẹ́kọ̀ọ́-bìnrin 200 tí ọmọ ẹgbẹ́ afẹ̀míṣòfo Ẹlẹ́sìn ìmale jí gbé ní ọdún 2014.
Ó jẹ́ ọ̀kan lára olùdásílẹ̀ Ìpolongo #BringBackOurGirls (BBOG).
Bákan náà ni ó jẹ́ òǹdíje sí ipò ààrẹ ní abẹ́ ẹgbẹ́ olóṣèlú Allied Congress Party ti Nàìjíríà.
Kingsley Moghalu [Àwòrán láti ibùdó ìpolongo].
Kingsley Moghalu
Moghalu jẹ́ onímọ̀ nínú ìdókòwò àgbáyé àti òfin gbogbo ènìyàn ní ilé ìwé Òfin àti Ọgbọ́n Fletcher ní Ifásitì Tufts ní Massachusetts, USA.
Moghalu ti ṣiṣẹ́ rí ní United Nations láti ọdún 1992 sí 2008.
Ó ti ṣe igbá-kejì gómìnà Ilé Ìfowópamọ́ Àgbà ti Nàìjíríà láti ọdún 2009 sí 2014, níbi tí “ó ti tukọ̀ ọ àwọn àgbà iṣẹ́ àtúnṣe nínú ètò ìkówóoamọ́ orílẹ̀ èdè Nàìjíríà lẹ́yìn ìgbà tí ọrọ̀ Ajé àgbáyé ti ṣe òjòjò tán.”
Òun ni òǹdíje ní abẹ́ àsíá Ẹgbẹ́ Olóṣèlú Ìtẹ̀síwájú Ọ̀dọ́ – YPP.
Ọmọ́yẹlé Sowóre [Àwòrán ìfọ̀rọ̀wánilẹ́nuwò ní orí CNBCAfrica, ní ọjọ́ 13, oṣù Ọ̀pẹ, ọdún 2018].
Omoyole Sowore
Sowore ni olùdásílẹ̀ àti atẹ̀wéjáde SaharaReporters (SR), ilé-iṣẹ́ oníròyìn aṣèwádìí orí-ayélujára.
SR ni à ń pè ní Wikileaks Ilé Adúláwọ̀.
Ajà-fún-ẹ̀tọ́-ọmọnìyàn yìí ń jáde lábẹ́ àsíá African Action Congress.
Aré ti ń lọ fún ọjọ́ iwájú orílẹ̀ èdè Nàìjíríà
Buhari àti Abubakar ni afigagbága ìdíje ìbò aré yìí.
Àwọn méjèèjì ti ń figagbága nínú ìbò Nàìjíríà ní ọjọ́ tí ó ti pẹ́.
"Ní ọ̀nà kejì, Ezekwesili, Moghalu, Sowore, àwọn ""agbára ìkẹ́ta"", jẹ́ ẹgbẹ́ tí ó ń wọ inú ètò ìṣèlú fún ìgbà àkọ́kọ́."
Iṣẹ́ ìṣàkóso Buhari ọdún mẹ́ta ni yóò gbè é lẹ́yìn àti pé yóò bá ìfi Nàìjíríà sí ipò olú orílẹ̀-èdè tí ìṣẹ́ ti pọ̀ jù.
"Ìwé ìròyìn Punch ṣe ìfojúsùn ""ìpèsípò"" gẹ́gẹ́ bí ""àìròtẹ́lẹ̀ "" àti pé ó ti pín ìlú yẹ́bẹyẹ̀bẹ."
Ètò ìgbógunti ìwà àjẹbánu rẹ̀ fì sí ẹ̀gbẹ́ kan.
"Ìgbésẹ̀ tí ó gbé láì pẹ́ yìí láti ṣe ìgbẹ́jọ́ Adájọ́ Àgbà orílẹ̀ èdè — tí ó ti sún mọ́ ìbò ààrẹ — ni Àjọ Adájọ́ orílẹ̀ èdè Nàìjíríà Nigerian Bar Association pè ní ""àwòṣe ìkọlù ní lemọ́lemọ́ ní orí àwọn àgbà ẹ̀ka ìjọba méjèèjì tí-kò-gbáralé ìjọba"" ní abẹ́ ìṣàkóso Buhari."
"Abubakar, ní ọ̀nà kejì, ń dúró lórí ""ìgbẹ́kẹ̀lé"" àwọn ""ẹgbẹlẹmùkù okòwò tí ó ní èrè lóríi rẹ̀ ""."
Bíótiwùkíórí, ó ní láti bá agbára ìwàlóríoyè afigagbága rẹ̀ takọ̀ngbọ̀n.
Ẹni yòówù tí ó bá gbégbá-orókè nínú ìdíje sí ipò ààrẹ ọdún 2019 ní iṣẹ́ ìmúgbòòrò ọrọ̀ Ajé, ààbò ní àárín ìlú, àtúntò agbára àti ìmúkárí agbára, àti ìṣèlú elẹ́yàmẹyà làti ṣe.
Fún ìyọsọ́tọ̀ tí wọ́n yọ òun nìkan láti yẹ ara rẹ̀ wò ní ilé ìtajà ìgbàlódé kan ní Serbia, gbajúgbajà ìràwọ̀ òṣèré orí-ìtàgé Roma fi ẹ̀sùn ìwà elẹ́yàmẹyà kan ilé ìtajà náà
Nataša Tasić Knežević, photo by Dzenet Koko, used with permission.
Ìràwọ̀ òṣèré orí-ìtàgé ìlú Serbia Nataša Tasić Knežević, àwòrán láti ọwọ́ọ Dzenet Koko, a lò ó pẹ̀lú àṣẹ.
Àwọn gbàgede ìtàkùrọ̀sọ ẹ̀rọ-alátagbà ìlú Serbia gbaná lẹ́yìn tí olórin àti òṣèré ìbílẹ̀ Nataša Tasić Knežević, tí ó jẹ́ ọmọ bíbí ilẹ̀ Roma fi ẹ̀sùn kan ilé ìtajà-ìgbàlóde kan tí ó wà ní ìgboro Novi Sad fún ìwà ìyàsọ́tọ̀ ẹ̀yà nínú ìgbóhùnsáfẹ́fẹ́ ojú-ẹsẹ̀ kan lórí Facebook.
Nínú fídíò náà, tí ó gbé-sórí-áfẹ́fẹ́ ní ọjọ́ 29, oṣù Ọ̀pẹ lẹ́yìn tí ìṣẹ̀lẹ̀ náà ṣẹ̀, arábìnrin Tasić Knežević ṣàlàyé pé bí òun ṣe ń jáde síta nínú ilé ìtajà ńlá náà pẹ̀lú ọ̀pọ̀ àwọn òǹrajà mìíràn ni ẹ̀rọ adènà àfọwọ́rá dún.
Bí àwọn ènìyàn yòókù ṣe ń jáde síta, àwọn ẹ̀ṣọ́-aláàbò ilé ìtajà náà ní kí ó dúró tí wọ́n sì tẹ̀síwajú láti yẹ ara rẹ̀ wò ní gbangba tí àwọn òǹwòran bẹ̀rẹ̀ sí í fi ṣe yẹ̀yẹ́.
Ìwé orin, ìwé àti àpò-àpawómọ́-ìléwọ́ ni wọ́n rí nínú àpò-àgbékọ́yìn-in rẹ̀.
Ní ìbẹ̀rẹ̀ oṣù Ṣẹẹrẹ ọdún 2019, fídíò náà dédé pòórá pẹ̀lú àlàyé ránńpẹ́ nípa arábìnrin Knežević.
Bíótilẹ̀jẹ́pé kòì tíì wá sí gbangba kí ó ṣàlàyé ohun tí ó ṣẹlẹ̀, àwọn ẹlòmíràn ń sọ pé fúnra rẹ̀ ni ó yọ ọ́ kí ọ̀ràn tó wà nílẹ̀ lè tán bọ̀rọ̀.
Láàárín ọjọ́ díẹ̀, àwọn ènìyàn tí ó tó bíi ẹgbẹ̀rún 60 ti wo fídíò rẹ̀, tí wọ́n sì pín in lọ́nà 350, tí ó sì gba èsì tí ó tó 700.
Ilé-iṣẹ́ Ìkóròyìnjọ Orí-ayélujára Olómìnira Bulka ni ó kọ́kọ́ ro ìyìn ìṣẹ̀lẹ̀ náà ṣáájú àwọn ilé-iṣẹ́ ìròyìn Bulka mìíràn.
Akọrin-olóhùn-òkè ni arábìnrin Tasić Knežević ní Gbọ̀ngan Eré-ìtàgé ti orílẹ̀-èdè Serbia tí ó wà ní Novi Sad, ìlú kejì tí ó tóbi jù lọ ní orílẹ̀-èdè náà.
Tẹ́lẹ̀ rí, ó ṣiṣẹ́ ní Belgrade Atelje 212.
Ó tún jẹ́ akọrin-ṣeré àti àdánìkànkọrin tí ó gbajúmọ̀, ó sì máa ń kọ orin àdánìkànkọ nípa àṣà Roma tí ó jẹ́ orírun rẹ̀.
Nínú fídíò náà, arábìnrin Knežević sọ pé alábòójútó ilé ìtajà náà bẹ̀bẹ̀ lẹ́yìn tí òun ṣe àròyé nípa ìwọ̀sí náà, ṣùgbọ́n pé inú òun kò dùn sí bí àwọn èrò tí ó pé jọ lé òun lórí ṣe yẹ̀yẹ́ òun.
"Ó ní ọkùnrin àgbàlagbà kan pariwo pé kí wọ́n ""kó pàǹtí yẹn jáde"", ìyẹn túmọ̀ sí wípé kí àwọn òṣìṣẹ́ ó ju òun jáde síta nínú ilé ìtajà náà nítorí pé òun jẹ́ ọmọ ìbílẹ̀ Rome."
"A mọ ẹni tí ó fẹ́ràn láti máa jalè níbí jẹ́ gbólóhùn kan láti inú eré ""Ta ni ó ń kọrin níbẹ̀ yẹn!"" nípa àwọn ìṣẹ̀lẹ̀ tí ó ń ṣẹlẹ̀ ní ọjọ́ 5, oṣù Èbìbí ọdún 1971."
Lẹ́yìn ọdún 77, èyí [èrò ìyàsọ́tọ̀] ò tí ì kúrò ní ìrònúu wa.
Ilé-iṣẹ́ [tí ó ni ilé ìtajà Maxi] náà jẹ́ ti àwọn Dutch-Belgian ṣùgbọ́n àwọn ènìyàn-an wa ni àwọn òṣìṣẹ́ẹ wọn!
Ohun ìtìjú! Àtìlẹyìn fún obìnrin gidi àti òṣèré yìí @NatasaTasicKnez.
Ta ni ó ń kọrin níbẹ̀ yẹn? jẹ́ eré Yugoslavia ayé ìgbà 1980 tí ó sì di ipò ẹgbẹ́-ìmùlẹ̀ láàárín àwọn Balkan.
Nínú ìtàn náà, wọ́n ṣèṣì fẹ̀sùn olè kan àwọn olórin Roma méjì, orí ni ó kó wọn yọ lọ́wọ́ ìjìyà láìsí ìdájọ́.
Ilé-iṣẹ́ tí ó ni ilé ìtajà-ìgbàlóde Maxi, Delez Srbija, ṣe àgbéjáde àkọsílẹ̀ ìtúúbá lọ́jọ́ kan náà.
Ó sọ pé àwọn “gbàgbọ́ pé èyí á wà bí ìṣẹ̀lẹ̀ ìyàsọ́tọ̀ tí ó mú ìfura ẹni tí kò yẹ dání pé irú ìṣẹ̀lẹ̀ bẹ́ẹ̀ ò ní wáyé mọ́ lọ́jọ́ iwájú.
Ilé-iṣẹ́ náà fi kún un pé àwọn á ṣe ìdánilẹ́kọ̀ọ́ fún àwọn òṣìṣẹ́ wọn lórí bí a ṣe ń hùwà bí wọ́n bá fura sí olè jíjà.
Ní ọjọ́ kejì, Miloš Nikolić tí ó jẹ́ adarí ọ́fíìsì tí ó ń ṣe àfikún Novi Sad mọ́ Roma sọ̀rọ̀ tako ìṣẹ̀lẹ̀ náà.
Ó ní; gbogbo ìwádìí tí wọ́n ṣe fi hàn pé àwọn ará Roma lọ́kùnrin lóbìnrin ni ẹ̀yà tí a yà sọ́tọ̀ jù lọ ní orílẹ̀-èdèe wa.
A ní láti ṣiṣẹ́ pọ̀ láti yí i padà!
Ní 31 oṣù Ọpẹ, Igbá-kejì Alákòóso Ìgbìmọ̀ Ìjọba àti Ààrẹ Àjọ-tí-ó-ń-fètò-sí Ìmúdọ́gba Akọ-àtabo ní àwùjọ, Zorana Mihajlović náà sọ̀rọ̀ tako àwọn òṣìṣẹ́ ilé ìtajà Maxi pé “ìwà ìbanilórúkọjẹ́ ni wọ́n hù àti pé wọ́n jẹ̀bi.
Kò sọ̀rọ̀ nípa àwọn ohun tí ó yẹ kí wọ́n ṣe sí ìyàsọ́tọ̀ àwọn ọmọ Roma ní Serbia.
Bíótilẹ̀jẹ́pé ó dàbí ẹni pé arábìnrin Knežević ti yọ ara rẹ̀ kúrò lórí Facebook, bóyá láti lè jẹ́ kí ọ̀ràn náà ó silẹ̀, ó fi àlàyé-nípa-ara rẹ̀ orí Twitter sílẹ̀.
Ní alẹ́ ọjọ́ tí ó ṣíwájú Ọdún Tuntun, ó fi àtẹ̀jáde ṣókí sọ nípa ìṣẹ̀lẹ̀ náà.
Ẹ̀yin ọ̀rẹ́ẹ̀ mi ọ̀wọ́n, ìṣẹ̀lẹ̀ tí kò dùn mọ́ni nínú kan ṣẹlẹ̀ ní ọjọ́ mélòó kan sẹ́yìn, ṣùgbọ́n mo nírètí pé irú ìṣẹ̀lẹ̀ náà á pín pẹ̀lú ọdun 2018 àti pé irú ìṣẹ̀lẹ̀ bẹ́ẹ̀ ò ní wáyé mọ́.
Ẹ jẹ́ kí a jẹ́ ènìyàn ẹlẹ́ran ara, ohun tí ó dára jù ní ayé yìí nìyẹn. <3
Ìjà láàárín ìràwọ̀ akọrin soca Trinidad àti Tobago jẹ́ àmì tí ó dára fún orin àtijọ́
Ìràwọ̀ akọrin soca ìlú Trinidad Machel Montano ń ṣeré ní Àjọ̀dún OVO ní Toronto ní ọdún 2016. ÀWÒRÁN: The Come Up Show (CC BY-ND 2.0)
Gbólóhùn asọ̀ láàárín ẹni méjì ní ọ̀nà àrà tí ó gbà di ìjà ìgboro — papàá nínú iṣẹ́ orin kíkọ.
Ìjà mo jù rẹ́ lọ láàárín àwọn ọ̀jẹ̀ bíi ti Kanye West àti Taylor Swift àti ọmọ Jamaica Mavado àti Vybz Kartel, títí kan ìjà ìbílẹ̀ ọdún 2004 ní àárín-in akọrin soca ìlú Trinidad méjì Destra àti Denise Belfon, ìjà mo jù ọ́ lọ àwọn gbajúgbajà sábà máa ń já sí ìpolongo fún akọrin àti orin wọn.
Wàyí, ọpẹ́ fún asọ̀ tí ó wà ní àárín-in akọrin adìde Trinidad àti Tobago méjì Machel Montano àti Neil “Iwer” George, orin soca wọ ìròyìn fún ìgbà àkọ́kọ́ ní ọdún 2019.
Ayẹyẹ ijó ìta-gbangba ọlọ́dọọdún Trinidad àti Tobago tí ọdún yìí wáyé ní ọjọ́ 4 àti 5 oṣù Ẹrẹ́nà, tí ó sì jẹ́ àkókò fún orin soca.
Ọ̀jẹ̀ olórée soca bíi Montano àti George ti gba ìpè láti ṣeré níbi ètò ijó ìta-gbangba kí ọjọ́ ó tó kò rárá.
Wọn yóò gbé orin tuntun jáde ní ìpalẹ̀mọ́ fún ẹni tí yóò gbégbáorókè nínú ìdíje Ìwọ́de Ojúná, tí ó ń gbé ẹ̀bùn owó sílẹ̀ fún akọrin tí a bá kọ orin rẹ̀ jù lọ nínú Ijó ìta-gbangba.
Àwòrán ìràwọ̀ akọrin soca ti Trinidad Iwer George ní Ìdápadà Fête ní Toronto ní ọdún 2018 tí a mú láti fídíò orí Vimeo.
"Àwọn olólùfẹ́ẹ orin Soca ṣe àkíyèsí àròyé ọ̀tẹ̀ láàárín-in akọrin méjèèjì nígbà tí George gbé orin àkọ́ṣe ọdún 2019 jáde, ""Ìwọ́de Ojúná Bacchanal 2""."
Orin náà kò fi igbákanbọ̀kan nínú nípa ìkùnsínú tí ó wà nílẹ̀ látàrí ìpàdánù ìfigagbága ọdún 2018 tí Montana jáwé olúborí.
"Orin rẹ̀ tí a pè ní ""Savannah"", bá ti ẹnìkejì figagbága, ṣùgbọ́n Montana tí pàdí-àpò-pọ̀ pẹ̀lú ògbóǹtarigi akọrin soca Superblue wọ́n sì ṣe àgbéjáde ""Soca Kingdom"", tí ó gba oyè orin Ìwọ́de Ojúná ọdún 2018."
"Iye ìgbà 336 ni a kọ orin “Soca Kingdom”, a sì kọ ""Savannah"" fún iye ìgbà 140."
Ìpàdánù oyè yìí ni ó fa ìbínú ní ìta-gbangba, George fi orin fẹ̀sùn kan “jàndùkú soca” – ìyẹn àkójọpọ̀ òṣìṣẹ́ ilé iṣẹ́ agbóhùnsáfẹ́fẹ́ àti olùdaríI wọn – fún ìpàdíàpòpọ̀ tí ó mú wọn kọ orin “Soca Kingdom” ní àsìkò ìdájọ́ láti yan ẹni tí ó jáwé olúborí.
Ó kọrin:
"Lórí ìtàgé ni eré tí ó kàn-án wà, àwọn DJ àti wọn ń kọ ""Savannah"""
"Ṣùgbọ́n nígbà tí àwọn jàndùkú dé, wọ́n sún láti ""Savannah"" sí ‘Kingdom’"
Wọ́n pawọ́pọ̀ láti borí ìjà ńlá náà... lọ́dún yìí ẹ ní láti pawọ́pọ̀ pẹ̀lú Jésù Kristì ọmọ Màríà
"Nínú ẹ̀dà orin náà mìíràn , George fi ẹ̀sùn kan Montana pé ó ń ""sọ ọ̀rọ̀ àlùfànṣá"" sí òun, ó sì fi ẹnu tẹ́ oyè ọ̀mọ̀wé tí Montano ṣẹ̀ṣẹ̀ gbà ní Ifásitì Trinidad àti Tobago látàrí ipa tí ó kó ní ti ìgbélárugẹ orin soca."
"Kò pẹ́ tí a gbé orin George jáde, Montano fèsì pẹ̀lú orin tí a pe àkọlée rẹ̀ ní ""Dr. Mashup"", nínúu rẹ̀ ni ó ti sọ màdàrú tí wọ́n ṣe níbi ìdíje Ìwọ́de Ojúná:"
"Kò tán síbẹ̀: níbi ayẹyẹ Ijó ìta-gbangba tuntun, ""Hydrate"", ní ọjọ́ 13 oṣù Ṣẹrẹ, àwọn akọrin méjèèjì ṣeré. George lé orin rẹ̀ tuntun Montano náà sọ ọ̀rọ̀ ìkẹyìn:"
Lẹ́yìn eré, alábòójútó Montano, Anthony Chow Lin On, tari àwòrán kan sí orí Instagram tí ó fi ara jọ ẹ̀fẹ̀ ìtúká ẹni méjì tí ó ń jà:
Àtẹ̀jáde náà mú ìfura dání bóyá ìjà tòótọ́ ni tàbí ète lásán-làsàn:
"Ète tàbí bẹ́ẹ̀ kọ́, ọ̀pọ̀lọpọ̀ òǹlo ẹ̀rọ-alátagbà tó ń tẹ̀lé awuyewuye náà ti tọ́ka sí irúfẹ́ àríyànjiyàn orin báyìí (tí a mọ̀ sí ""orin ìjà"") kò jẹ́ tuntun; àti pé, ó bá orísun orin calypso mu, ó sì jẹ́ àmúlùmálà, soca."
"Nínú ìfọ̀rọ̀wánilẹ́nuwò kan, George fúnra rẹ̀ sọ òtítọ́ ibẹ̀ wípé òun kàn ń ""ṣe àkópamọ́ ìṣẹ̀lẹ̀ àtijọ́ "" gẹ́gẹ́ ""bí ó ṣe máa ń ṣe"", títọpa àwọn ènìyàn jàǹkàn-jàǹkàn tí ó ti kọ orin calypso sẹ́yìn."
Orin calypso jẹ́ ìlúmọ̀nánká tí ó máa ń sọ nípa àwùjọ àti ìṣèlú, ní ìbẹ̀rẹ̀ pẹ̀pẹ̀ orin náà ni ìsọ̀rọ̀ síra ẹni méjì tí ó fi ara pẹ́ ogun ọ̀rọ̀ tí ó ń lọ ní àárín-in George àti Montano.
"Abẹ́ àtíbàbà orin Calypso, níbi tí àwọn eléré calipso ti máa ń ṣeré ní àsìkò Ijó ìta-gbangba, gbajúmọ̀ fún ""ogun àìròtẹ́lẹ̀ "", ìdíje tí àwọn akọrin yóò kọrin èébú sí ara wọn láì rò tẹ́lẹ̀ lójú ẹsẹ̀, tàbí lórí àkọ́lé kan."
"Ìfigagbága àwọn akọrin wọ̀nyí ni a mọ̀ sí ""picong""."
"Irúfẹ́ eré wọ̀nyí máa ń fi àyè gba ìdásí, tí àwọn olùwòràn yóò máa gbe orin, ọ̀kan tí ó wọ́pọ̀ jù lọ ni ""Santimanitay!"", tí ó jẹ́ ẹ̀dà àbọ̀-ọ̀rọ̀ Faransé “sans humanité”, tàbí “àìláàánú”."
Àmọ́ àwọn òǹwòrán kò ì tíì rí irú èyí rí nínú orin soca tí a ti ká sílẹ̀.
Ó jẹ́ òtítọ́ tàbí kò jẹ́ òtítọ́, àwọn olólùfẹ́ẹ George/Montano dá sí ogun àìròtẹ́lẹ̀ wọn gẹ́gẹ́ bí olùwòràn, ní Ijó ìta-gbangba àti lórí ayélujára.
George àti Montano yô, láì sí àní-àní, nínú ìdíje Ìwọ́de Ojúná ọdún 2019 àti èyí tí ó kéré jù lọ, awuyewuye ìjà gẹ́gẹ́ bí ìdárayá gidi àti orin.
Àwọn olólùfẹ́ẹ Soca kò le è béèrè ju bẹ́hẹ̀ lọ.
Spiny Babbler, ẹyẹ orílẹ̀-èdè Nepal, fa àwọn onímọ̀-nípa-ẹyẹ àti olólùfẹ́ ẹyẹ mọ́ra
Spiny Babbler
Spiny Babbler, ẹyẹ tí a kò le è rí níbòmìrán àyàfi ní Nepal. Àwòrán láti ọwọ́ọ Sagar Giri. A lò ó pẹ̀lú àṣẹ.
Bí-ó-ti-lẹ-jẹ́-pé ẹ̀yà ẹyẹ orílẹ̀ èdè Nepal ju 800 lọ, ẹyẹ Spiny Babbler (Turdoides nipalensis) jẹ́ ẹ̀dá tí kò sí ní ibòmíràn àyàfi orílẹ̀ èdè náà.
Ẹyẹ aláwọ̀ eérú-àti-pupa-rẹ́súrẹ́sú náà, tí à ń pè ní Kaande Bhyakur ní èdè ìbílẹ̀ Nepali, ń fi igbó ṣe ìtẹ́ a sì lè fi ojú bà á bí ó bá ń fò lókè lálá láti ìwọ̀n mítà 500 sí mítà 2135.
Bí ó ti lẹ̀ jẹ́ pé Spiny Babbler náà ti fa àwọn onímọ̀-nípa-ẹyẹ àgbáyé mọ́ra fún ọdún pípẹ́, ìbàjẹ́ àyíká ti ń ṣe ìdẹ́rùbà àkàndá, ẹyẹ tí àwọn ènìyàn fẹ́ràn yìí.
Ìwée nì The Status of Nepal’s Birds: The National Red List Series sọ wípé:
Ó máa ń wá kòkòrò nínú koríko ilẹ̀, ẹ̀kànànkan ni a sì máa ń rí i.
Spiny Babbler máa ń bà lé ẹ̀ka koríko àti igi kéékèèké láti kọrin, àgógó ẹnu ẹyẹ yóò wà ní òkè irú ní ìsàlẹ̀.
Ó dára ní wíwò, iké oríṣiríṣi. Orin rẹ̀ ni a fi ń mọ ibi tí ó wà, àárín oṣù Ọ̀wẹwẹ̀ àti Ọ̀wàrà. Ẹ̀dá ẹyẹ yìí máa ń fò sókè lálá nínú àwọn àkókò kan nínú ọdún.
Ẹyẹ Spiny Babbler, tí a lè rí ní Nepal nìkan, ti fa àwọn onímọ̀-nípa-ẹyẹ àti olólùfẹ́ ẹyẹ káríayé mọ́ra. Don Messerschmidt kọ nípa àkọsílẹ̀ tí onímọ̀-nípa-ẹyẹ S. Dillon Ripley ṣe nípa ẹyẹ náà nínú ìwée rẹ̀ Ìṣàwárí ẹyẹ Spiny Babbler:
Ó jẹ́ ọ̀wọ̀ ẹyẹ tí kò ka àwọn onímọ̀ ìjìnlẹ̀ sáyẹ́ǹsì sí fún ọdún gbọgbọrọ, láti ọdún 1843 tàbí 1844.
Ní ìgbà yẹn àwọn aṣiṣẹ́ fún Brian Hodgson tí ó jẹ́ aṣèwádìí Nepali tí ṣe àkójọ onírúurú àpẹẹrẹ, ó kọ.
Ẹyẹ Spiny Babbler ti jẹ́ ẹranko tí ó ju ìmọ̀ ènìyàn lọ ní ọjọ́ tí ó ti pẹ́, ọ̀kan nínú ọ̀wọ̀ ẹyẹ márùn-ún ní India, pẹ̀lú Àparò Òkè gíga, kò sí lórílẹ̀ ayé mọ́n.
Ṣùgbọ́n bí èrò mi bá jẹ́ òtítọ́, ó ń fò kiri níbi ní gẹ̀rẹ́gẹ̀rẹ́ òkè Rekcha.
Bẹ́ẹ̀ gẹ́gẹ́, ikọ̀-ọba orílẹ̀-èdè America tẹ́lẹ̀ sí ìlú Nepal Scott DeLisi fi ọ̀pọ̀ ọdún wá ẹyẹ yìí àti láti ya àwòrán-an rẹ̀.
Ẹyẹ náà ti ń dínkù látàrí ìgbẹ́ pípa fún iṣẹ́ ọ̀gbìn àti ìtẹ́lọ ìgbèríko di ìgboro.
Bí a bá yọ ti agbègbè ààbò kúrò, nígbà mìíràn pípa ẹyẹ yìí fún oúnjẹ, ní òkè kékeré tí ó yí àfonífojì Kathmandu ká ti mú kí ẹyẹ Spiny Babbler dínkù ni iye.
Síbẹ̀, ohun tí ó ń fa àdánù ní agbègbè kan náà lè mú wọn pọ̀ ní agbègbè mìíràn.
Bí igbó ṣe ń dínkù látàrí ìgbẹ́ pípa àti igi gẹdú gígé jákèjádò orílẹ̀ èdè náà, igbó tí wọ́n fi ṣe ilé ti di ti nǹkan mìíràn.
Àmọ́ ṣá ìgbà àti àkókò ni yóò sọ ohun tí yóò ṣẹlẹ̀ sí àwọn ẹyẹ ìlú Nepal tí kò sí ní ibòmíràn.
Àwọn ọ̀gágun ajagun fẹ̀yìntì orílẹ̀-èdè Nàìjíríà wọ̀yáàjà láti nípa lórí ètò ìdìbò ọdún-un 2019
Olúṣẹ́gun Ọbásanjọ́, Ààrẹ àná orílẹ̀-èdè Nàìjíríà.
Bí orílẹ̀-èdè Nàìjíríà ṣe ń múra fún ètò ìdìbò sí ipò Ààrẹ nínú Oṣù Èrèlé, àwọn ọ̀gágun tí ó ti jagun fẹ̀yìntì tí wọn di olóṣèlú, jẹ́ igi gbòógì fún òye ètò òṣèlú orílẹ̀-èdè Nàìjíríà.
Àwọn ọ̀gágun tí ó ti fẹ̀yìntì tàbí àwọn tí wọn ṣe àtìlẹ́yìn fún láti dé orí ipò ni ó ti ń tukọ̀ orílẹ̀-èdè Nàìjíríà láti ọdún 1999 tí ìjọba tiwantiwa ti padà.
Asọ̀ tí ó wáyé láìpẹ́ yìí láàárín Ààrẹ àná, Olúsẹ́gun Ọbásanjọ́ àti Ààrẹ tí ó wà lórí àlééfà, Ààrẹ Muhammadu Buhari – tí àwọn méjèèjì jẹ́ ajagun fẹ̀yìntì afipásèjọba ológun –ní ipa tí ó pọ̀ lórí ètò ìdìbò oṣù tí ó ń bọ̀.
Nínú ìwé àpilẹ̀kọ kan tí a kò rí irúu rẹ̀ rí tí ó kọ ránṣẹ́ sí Buhari, Ọbásanjọ́ fi ẹ̀sùn kàn-án wípé ó ní ètè láti ṣe èrú ìbò. Ó kọ ọ́ sínú ìwé náà wípé:
Ìtìjú ńlá gbáà ló jẹ́ fún ìjọba tiwantiwa, bí ètò ìbò tí o yẹ kí ó lọ ní ìrọwọ́-ìrọsẹ̀ láì fi ti apá kan ṣe, ṣùgbọ́n tí ìṣesíi wọn kò fi ìṣedéédé hàn, àìmúdọ́gba tí ó hàn kedere, ẹ̀tàn àti ìjòye àwòdì máà le è gbẹ́dìẹ.
"Ọbásanjọ́ tẹnu mọ́ ọn wípé Buhari kò leè ""ṣe ètò ìbò tí ó kẹ́sẹjárí"", àti wípé ìsèjọba tiwantiwa ní abẹ́ ìṣàkóso Buhari ni a lè fi wé tí ìjọba ológun fàmílétè-kí-n-tutọ́ọ ti Gen. Sani Abacha."
Ní ọdún 1998, Sani Abacha, tí ó jẹ́ ológun apàṣẹwàá ní ìgbà náà, pè fún ìbò gbogboògbò ṣùgbọ́n tí ó hàn ketekete pé Abacha kò ṣetán láti gbé ìjọba sílẹ̀ fún alágbádá.
Ní àsìkò tí à ń sọ̀rọ̀ọ rẹ̀ yìí, àwọn ẹgbẹ́ òṣèlú márùn-ún ọ̀tọ̀ọ̀tọ̀ ni ó fọwọ́ síi wípé kí Abacha ó jẹ́ olùdíje fún ipò Ààrẹ nínú ẹgbẹ́ òṣèlúu wọn.
Ní báyìí ó ti ṣípò-padà, òkìkí Abacha tàn káàkiri ó sì di ìlú-mọ̀-ọ́-ká nípa ìtẹrí ẹ̀tọ́ ọmọ-ènìyàn mọ́lẹ̀ àti ìjẹgùdùjẹrà.
"Ọbásanjọ́ tẹnumọ́ọ wípé ""ipasẹ̀ "" Abacha ní ọjọ́ kínní àná náà ni Buhari ń tọ́ báyìí ""láì wo ẹ̀yìn wò."""
Shehu Garba, tí ó jẹ́ olùrànlọ́wọ́ pàtàkì fún Ààrẹ Buhari lórí gbígbé ìròyìn jáde, bu ẹnu àtẹ́ lu ìwé àpilẹ̀kọ Ọbásanjọ́:
Ètò ìdìbò tí yóò wáyé nínú osù tí ó ń bọ̀ yìí yóò lọ ní pẹ̀lẹ́-kùtù, gẹ́gẹ́ bí Ààrẹ Buhari ti ṣe ìlérí fún ọmọ orílẹ̀-èdè yìí àti àgbáyé.
Ọbásanjọ́, òǹkọ̀wé àpilẹ̀kọ?
Olúṣẹ́gun Ọbásanjọ́, tí ó jẹ́ Ààrẹ ìjọba ológun àná (láti ọdún 1976 sí 1979), tí ó sì tún ṣe Ààrẹ ìjọba alágbádá tí ìbò gbé wọlé (ní ọdún 1999 sí 2007), kúndùn láti máa bu ẹnu àtẹ́ lu àwọn ètò ìjọba Ààrẹ orílẹ̀-èdè Nàìjíríà tí ó jẹ tẹ̀lé e.
"Ní èṣí, Ọbásanjọ́ gba Buhari ni ìmọ̀ràn láti má díje fún ipò Ààrẹ fún ìgbà kejì, ṣùgbọ́n kí ó ""da ìfẹ̀yìntì rò nítorí ọjọ́ oríi rẹ̀ ""."
Àmọ̀ràn yìí dá yánpọnyánrin sílẹ̀ ní orílẹ̀-èdè Nàìjíríà nítorí wípé Ọbásanjọ́ jẹ́ alátìlẹ́yìn àgbà fún Buhari gẹ́gẹ́ bí òǹdíje nínú ìbò ipò Ààrẹ ni sáà àkọ́kọ́ ní ọdún 2015.
Ṣáájú àsìkò yìí, Ọbásanjọ́ ti bá ìjọba Goodluck Jónátánì wí nínú ìwé àpilẹ̀kọ tí ó kọ ránṣẹ́ sí i ní ọdún 2013, Ọbásanjọ́ fi ẹ̀sùn kan Jónátánì wípé ó ń darí orílẹ̀-èdè Nàìjíríà lọ sí oko ìparun pẹ̀lú bí ó ṣe fi àyè gba ẹ̀tàn, ìjẹ́gùdùjẹrà, ìbápín àìgbẹ́kẹ̀lé láti fa aṣọ iyì àti ìtẹ̀síwájú orílè-èdè náà ya pẹ́rẹpẹ̀rẹ.
Ní àpárá, Ọbásanjọ́ ti Goodluck Jónátánì lẹ́yìn nínú ètò ìdìbò tí ó wáyé ní ọdún 2011. Àti wípé ni ọdún 2007, òun yìí kan náà ni ó ti Umaru Musa Yar'Adua tí ó jẹ kí Jónátánì ó tó jẹ lẹ́yìn digbídigbí.
Ṣùgbọ́n tí ó pa ìdí ọ̀rẹ́ dá sí Yar'Adua lẹ́yìn ìgbátí ó bẹ̀rẹ̀ àìsàn tí kò sì gbé ètò ìṣe ìjọba fún igbákèjì rẹ̀ tii ṣe Goodluck Jónátánì.
Ààrẹ orílẹ̀-èdè Nàìjíríà àná Goodluck Jonathan with pẹ̀lú Ààrẹ tí ó ṣẹ̀ṣẹ̀ gorí àlééfà Muhammadu Buhari níbi ayẹyẹ ìfilọ́lẹ̀ ìjọba tuntun ní ọjọ́ 29, oṣù Èbìbì, ọdún 2015.
Àworan Ìkápá Gbogboògbò láti ẹ̀ka ìjọba US.
Ọ̀gágun tí ó ti jagun fẹ̀yìntì kì í sinmi ní orílẹ̀-èdè Nàìjíríà
Abẹ ìgbèkùn àwọn ọ̀gágun tí ó ti jagun fẹ̀yìntì àti àwọn asọ́mogbée wọn ni orílẹ̀-èdè Nàìjíríà wà. Bí àpẹẹrẹ, Ọbásanjọ́ jẹ́ alẹ́nulọ́rọ̀ tí ó mọ àludé tòun àpadé bí àwọn Ààrẹ ṣe ń gba ipò láti ọdún 2007 sí 2015.
Bíótiwùkíórí, láì jọ ti àwọn alágbádá – Yar'Adua àti Jónátánì – tí ó gbé ní arugẹ, tí ó sì tún yẹpẹrẹ wọn, ti Buhari dá yàtọ̀ gedegbe.
Bí ó ti lẹ̀ jé pé Ọbásanjọ́ ti Buhari lẹ́yìn láti leè yege ní ọdún 2015, a kò leè sọ pé àtìlẹyìn rẹ̀ nìkan ni ó gbé e dé ipò Ààrẹ.
Nítorí ohun tí ó jẹ́ kí ó ṣeé ṣe ò ju bí Buhari ṣe fi ọwọ́ wẹ ọwọ́ pẹ̀lú ẹgbẹ́ òṣèlú ìgbàanì Action Congress of Nigeria (ACN) ti Bọ́lá Tinubu.
Ẹgbẹ́ òṣèlú Congress for Progressive Change (CPC) ti Buhari jẹ ọmọ ẹgbẹ́ ní ìgbẹ̀yìngbẹ́yín parapọ̀ mọ́ ACN, wọ́n sì di ọkàn nínú oṣù Kejì ọdún 2013, èyí tí ó ṣe okùnfà ìdásílẹ̀ ẹgbẹ́ òṣèlú tuntun tí orúkọ rẹ̀ ń jẹ́ Àjọ Ìtẹ̀síwájú Gbogboògbò (APC).
Ní àfikún, Buhari tí ó ṣe olórí ìjọba ológun ní ọdún (1983 sí 1985) jẹ́ ọ̀kan lára àwọn ọmọ ‘ẹgbẹ́’ ọ̀gágun tí ó ti fẹ̀yìntì tí ó ti takú ti ètò òṣèlú orílẹ̀-èdè Nàìjíríà.
Fún ìdí èyí, bí Ọbásanjọ́ ṣe tàbùkù Buhari ní gbangba tó, ó níí ṣe pẹ̀lú agbára àti ipò ẹgbẹ́ tí àwọn méjèèjì wà gẹ́gẹ́ bí ọ̀gágun tí ó ti jagun fẹ̀yìntì.
Ọbásanjọ́ nìkan sì kọ́ ni ọ̀gágun tí ó ti jagun fẹ̀yìntì tí ó ń tàbùkù Buhari.
"Theophilus Danjuma, tí òun náà jẹ́ ọ̀gágun tí ó ti jagun fẹ̀yìntì ní oṣù kẹ́ta ọdún tí ó kọjá fi ẹ̀sùn kan ""ẹgbẹ́ ológun orílẹ̀-èdè Nàìjíríà wípé ó ń gbárùkù ti ìpànìyàn nípakúpa tí ó ń lọ ní orílẹ̀-èdè Nàìjíríà""."
Danjuma, tí ó jẹ olórí àwọn ológun, tí o si tún jẹ́ mínísítà fún ètò abo ní ìgbà kan rí, bu ẹnu àtẹ́ lu ẹgbẹ́ ológun bí wọ́n ṣe ń gbé lẹ́yìn apá kan dá apá kan sí nínú aáwọ̀ tí ó wáyé láàárín àwọn darandaran àti àgbẹ̀, pàápàá jù lọ èyí tí ó wáyé ní ilée rẹ̀ tí í ṣe ìpínlẹ̀ Taraba.
Ìrí-bá-kan-náà, Danjuma fi ariwo ta nípa ète bí àwọn “ọlọ́pàá àti ológun” ṣe ń gbìmọ̀pọ̀ láti ṣe ẹ̀rú nínú ìbò ọdún 2019.
Bákan náà ẹ̀wẹ̀wẹ̀, nínú Oṣù Kejì ọdún tí ó kọjá, ajagun fẹ̀yìntì tí ó tún jẹ́ olórí orílẹ̀-èdè Nàìjíríà láyé ológun, Ibrahim Babangida gba Ààrẹ Buhari ní ìyànjú láti máà du ìje fún ipò Ààrẹ fún ìgbà kejì, nítorí wípé ọgọ́rùn-ún ọdún 21 tí Nàìjíríà wà yìí jẹ́ àsìkò àwọn ọ̀dọ́ tí ó ní ìrírí ìgbàlódé.
Ó gbàgbọ́ wípé ìgbàkanìgbàkàn “ohun tí yóò jẹ́ àǹfààní gbogbo ará ìlú gbọdọ̀ bo orí àǹfààní ti ara ẹni.”
"Pẹ̀lú bí gbogbo nǹkan ṣe ń lọ, yóò fẹ́rẹ̀ẹ́ pẹ́ díẹ̀ kí orílẹ̀-èdè Nàìjíríà ó tó le è ní Ààrẹ tí kò ní nǹkan ṣe pẹ̀lú, tàbí tí kò ní àtìlẹ́yìn ""ẹgbẹ́ "" àwọn ọ̀gágun ajagun fẹ̀yìntì."
Òwìwí kan kọ̀ kò kúrò nínú ilé ìgbìmọ̀ ìjọba Tanzania. Àmìi kí ni èyí?
"Gbàgede Nyerere Square ní Dodoma, olú-ìlú orílẹ̀-èdè Tanzania, àti ilé ìgbìmọ̀ aṣòfin, ""Bunge""."
Àwòrán láti ọwọ́ọ Pernille Bærendtsen, a lò ó pẹ̀lú àṣẹ.
Ní ọjọ́ 29 oṣù Ṣẹrẹ, nígbà tí àwọn àjọ ìjọba Tanzania (Bunge) péjọ ní Dodoma fún ìjókòó ìpàdé tí ó ṣáájú nínú ọdún-un 2019, ẹyẹ òwìwí kan fò wọ inú ilé ìpàdé, ó sì bà sí orí ajá, níbi tí ó ti ń wo ìpéjọ láti òkè téńté.
Ìṣẹ̀lẹ̀ náà di ìròyìn tí ó sì tàn kálékáko, tí ó sì ń mú àwọn ènìyàn ṣe onírúurú ìbéèrè láti orí ẹ̀rọ-alátagbà àti ìwé ìròyìn.
Àpẹẹrẹ wo ni ti òwìwí nínú ilé ìgbìmọ̀ ?
Ẹyẹ òwìwí náà ti jẹ́ rírí nínúu gbọ̀ngan ilé ìgbìmọ̀ ìlú Dodoma ní ẹ̀rìnmejì. Àpẹẹrẹ wo ni èyí túmọ̀ sí?
Àmì burúkú? ìwé ìròyìn ẹkùn-ìlú ọlọ́sẹ̀ọ̀sẹ̀, Ìlà-oòrùn Afrika, dá ìmọ̀ràn.
Akọbúlọ́ọ̀gù ọmọ Gẹ̀ẹ́sì àti onímọ̀ kíkún nípa iṣẹ́ ìròyìn, Ben Taylor, sọ síwájú sí i:
Àwòrán-ẹ̀fẹ̀ láti ọwọ́ọ Samuel Mwamkinga (Joune), a lòó pẹ̀lú àṣẹ.
"Ayàwòrán-ẹ̀fẹ̀ ọmọ bíbíi Tanzania, Samuel Mwamkinga (Joune), lẹ́yìn wá, ya àpẹẹrẹ àwòrán ìṣẹ̀lẹ̀ náà pẹ̀lú ìtọ́ka sí ìsọlọ́rúkọ ní èdè Gẹ̀ẹ́sì ""àkójọpọ̀ àwọn òwìwí"" látàrí ìmọ̀ àwọn Gíríìkì tí ó ní wípé ọlọ́gbọ́n ni ẹyẹ òwìwí (pẹ̀lú àṣẹ ni a fi lo àwòrán àpẹẹrẹ)."
Síbẹ̀, ojú nǹkan búburú, àmì ikú àti òfo ní Tanzania ni àwọn ènìyàn fi wò ó.
Àti pé — òwìwí náà ti pinnu láti dúró sí Bunge, gẹ́gẹ́ bí Ọmọọ̀lú Náà ti wí:
Òwìwí, ẹyẹ òru, kò le è kúrò... pẹ̀lú gbogbo ọ̀nà tí àwọn àjọ ọba gbà láti lé e jáde.
Ẹyẹ òwìwí kì í ṣe ẹyẹ rere ní Tanzania, àti pé, bẹ́ẹ̀ ni Tanzania kì í ní ìgbàgbọ́-asán. Ìwò káàkiri ọdún-un 2010 kan fi hàn wípé ìdá 94 ọmọ bíbí Tanzania ní ìgbàgbọ́ nínú agbára Àjẹ́.
Ìpàdé ìgbìmọ̀ lásán kọ́
Fún ti ìpàdé yìí, ẹyẹ òwìwí nínúu ìpàdé ní ìtúmọ̀ tí ó ní àpẹẹrẹ, pàápàá fún àwọn tí kò ní ìgbàgbọ́-asán, tí ó le pátápátá láti mú ojú kúrò.
Ní orí ìlànà ètò ìpàdé àkọ́kọ́ ìgbìmọ̀ọ Tanzania ọdún-un 2019 ni ìdámọ̀ràn àtúnṣe sí Òfin Ẹgbẹ́ Òṣèlú, tí ó ti ní àríyànjiyàn lemọ́lemọ́ nínúu ìṣèlú tí nǹkan kò ṣe ẹnu re.
Tanzania wọ ìwé ìtàn ní ọdún-un 1992 gẹ́gẹ́ bíi orílẹ̀-èdè àkọ́kọ́ ní Ilẹ̀-adúláwò tí yóò dá ètò ẹgbẹ́ òṣèlú púpọ̀ sílẹ̀, èyí tí ó fi àyè gba ẹgbẹ́ ìkọjúsí.
Òfin Ẹgbẹ́ Òṣèlú náà (rè é níbi pẹ̀lú àtúnṣe tí a gbà ní ìmọ̀ràn) bákan náà di lílò ní ọdún-un 1992, ó sì ti rí àtúnṣe ní ọ̀pọ̀ ìgbà bíi àtúnṣe ti ọdún-un 2009.
Pẹ̀lú wípé òwìwí wọ̀ sí òkè téńté nínúu ìpàdé, kò dí ìpinnu àwọn ìgbìmọ̀ lọ́wọ́ láti ṣe àtúnṣe sí òfin — ìgbésẹ̀ tí àwọn atàbùkù ní wípé ó sọ ètò ẹgbẹ́ òṣèlú púpọ̀ Tanzania, àti ìjọba tiwantiwa bákan náà di yẹpẹrẹa
Gẹ́gẹ́ bí Reuters ti ṣe wí, ìsọdituntun òfin náà ti fi agbára tí ó pọ̀ sí ọwọ́ àwọn akọ̀wé ìrántí tí ìjọba-yàn láti da ìwé àṣẹ ẹgbẹ́ òṣèlú nù àti láti fi ìyà ìfisẹ́wọ̀n jẹ ẹgbẹ́ olóṣèlú tí ó bá ṣẹ̀ sí òfin.
Ní àpẹẹrẹ, bí ó bá ṣe ìdánilẹ́kọ̀ọ́ ìlú tí ó ní í ṣe pẹ̀lú ìforúkọsílẹ̀ òǹdìbò àti àgbékalẹ̀ ètò mìíràn tí ó ní í ṣe pẹ̀lú ìṣèlú.
Ọ̀pọ̀ ilé-ìròyìn ni ó ṣe àtúnwí ọ̀rọ̀ Zitto Kabwe, olórí ẹgbẹ́ òṣèlú alátakò ACT-Wazalendo, ẹni tí ó jẹ́ wípé nínú oṣù Ògún ọdún-un 2017 bu ẹnu àtẹ́ lu ìdámọ̀ràn àtúnṣe òfin náà, wípé ó ṣe é ṣe kí ó rọ́ ẹ̀tọ́ òṣèlú sẹ́yìn.
Kabwe wá fi wé Àbádòfin Iṣẹ́ Ìròyìn ọdún-un 2016, èyí tí ó fi òmìnira fún ilé iṣẹ́ ìròyìn tí ó sì dá ilé ìròyìn aládàánialáìgbáralé-ìjọba padà. Wàyí, Kabwe pe àkíyèsí sí ìjì lẹ́sẹ̀ tí àtúnṣe Òfin Ẹgbẹ́ Òṣèlú dá sílẹ̀:
A kò le è ní ìwé-òfin tí ó fi ẹ̀tọ́ fún òmíràn ìkẹ́gbẹ́ kí ó tún wá fún ẹnìkan ní agbára láti mú ẹ̀tọ́ òmìnira ìkẹ́gbẹ́ kúrò.
Ní ẹnu ọdún mélòó kan sẹ́yìn, òfin orílẹ̀-èdè Tanzania ti ń yí padà di aláfagbára ṣe, arapa rẹ̀ sì ń fa àìrí àyè fún ẹgbẹ́ òṣèlú mìíràn àti ilé iṣẹ́ ìròyìn aláìgbáralé-ìjọba láti ṣe bí ó ṣe ní abẹ́ òfin.
Ní báyìí, àwọn aṣàyẹ̀wò fínnífínní ti sọ wípé àtúnṣe Òfin Ẹgbẹ́ Òṣèlú kò ní mú un rọrùn fún ètò ìṣèlú tí ó jẹ́ pàtàkì fún Ààrẹ àti Chama Cha Mapinduzi (Ẹgbẹ́ Àyípadà Náà), tí ó ti wà ní orí àlééfà láti ìgbà tí òmìnira dé ní ọdún-un 1961.
Ìtakò jẹ́ dandanàndan nínú ìjọba tiwantiwa tí ó yé kooro. Alátakò gidi yóò ṣe àyẹ̀wò fínnífínní sí ètò ìjọba, yóò sì pè é ní ìjà.
Bí kò bá sí alátakò, ó ṣe é ṣe kí ojú àwọn onírúurú ìyàtọ̀ ohun tí ọmọ-ìlú nílò ó máa jẹ́ ṣíṣe bí ó ti ṣe tọ́.
Nínú túwíìtì 15, akẹ́kọ̀ọ́ ìmọ̀ ìṣègùn Rachel McLellan la àwọn ènìyàn ní òye nípa èrèdíi òfin tuntun náà, àti irú ibi tí ìtako tí ó mú ọpọlọ dání yóò ti wúlò :walked readers through possible consequences of the new act, and characterizes a situation where a critical opposition will find itself cornered:
Ìgbàgbọ́-asán ni tàbí bẹ́ẹ̀ kọ́ – àwọn tí ó ń ṣe àgbéyẹ̀wò ìṣèjọba àfagbáraṣe orílẹ̀-èdè Tanzania rí ìdánilójú awuyewuye wọn pẹ̀lú ti ẹyẹ òwìwí tí ó wọ inú ilé ìgbìmọ̀ àti ìgbésẹ̀ gbogbo láti lé e dánú àmọ́ tí kò bọ́ sí i.
Òwìwí náà ta kété. Agbẹnusọ Ìgbìmọ̀, Job Ndugai, gbìyànjú láti yí ìgbàgbọ́ ìbílẹ̀ padà pẹ̀lú àlàyé tí ó ní iyè nínú:
Ẹ̀yin Ọmọ Ìgbìmọ̀ Ọlọ́lá, a ti ń rí ẹyẹ òwìwí kan nínú Ilé yìí láti òwúrọ̀ àmọ́ nínú ìgbàgbọ́ ìbílẹ̀ Dodoma, òwìwí tí a bá rí ní ojú-ọjọ́ kò ní ohunkóhun ń ṣe fún ẹnikẹ́ni.
Èyí jásí wípé kò sí ìbẹ̀rù.
Fún àwọn tí ó ń wá àṣìṣe, síbẹ̀, kò sí ohun tí ó ní iyè nínú nípa òfin tuntun náà.
Pẹ̀lú àìbalẹ̀-ọkàn tí ó ń pọ̀ sí i ní ìmúra ìbò ààrẹ ọdún-un 2019, Ọmọ orílẹ̀-èdè Nàìjíríà ń bẹ̀rùu pípa ẹ̀rọ-ayélujára
Ìbẹ̀rùbojo gba orílẹ̀-èdè Nàìjíríà kan látàrí awuyewuye pé ó ṣe é ṣe kí ẹ̀rọ ayélukára-bí-ajere ó di pípa ní àsìkò ìbò ààrẹ ọdún-un 2019.
Ẹ̀rù ti ń tàn ká orílẹ̀-èdè Nàìjíríà wípé ó ṣe é ṣe kí ìjọba ó pa ẹ̀rọ-ayélujára ní àsìkò ìbò ààrẹ nínú oṣù Èrèlé ọdún-un 2019.
Ohun tí ó bẹ̀rẹ̀ bí àhesọ lásán ti ń di ohun tí ó ń gbé àwọn ènìyàn ní ọkàn bí ìbò ṣe ń sún mọ́lé. Yomi Kamez ti Quartz Africa ṣàlàyé :
A lè sọ wípé ìbẹ̀rùbojo nípa pípa ẹ̀rọ-ayélujára ń gbilẹ̀ sí i ní orílẹ̀-èdè tí àwọn ọmọ-ìlú ń wá ìlànà tí yóò mú wọn wà ní orí ayélukára-bí-ajere bí ìdígàgá bá wáyé.
Ní ìsinmi tí ó kọjá lọ, ìtọ́sọ́nà bí a ṣe lè wà ní orí ayélukára-bí-ajere ti Quartz Africa kó jọ bí ìdígàgá ẹ̀rọ-ayélujára tàbí ẹ̀rọ-alátagbà bá wáyé ni ìròyìn-in wá tí àwọn òǹkàròyìn kà jù lọ, tí ọ̀pọ̀ sì jẹ́ ọmọ orílẹ̀-èdè Nàìjíríà.
Ọ̀gọ̀rọ̀ ènìyàn ni ó sọ ní orí ẹ̀rọ-alátagbà wípé a kì í ṣe é mọ̀, Nàìjíríà lè tọ ipa ẹsẹ̀ àwọn orílẹ̀-èdè Adúláwọ̀ [bíi Sudan, Zimbabwe] tí ìjọba ti dígàgá ẹ̀rọ-alátagbà tàbí pa ẹ̀rọ-ayélujára ní àpapọ̀ ní ìrí ọ̀ràn ààbò.
Àwọn ìṣẹ̀lẹ̀ tí ó jẹ́ mọ́n ẹ̀rọ-alátagbà, ọ̀rọ̀ ìkórìíra, ìdádúró lẹ́nu iṣẹ́ àti ìrọ́pò adájọ́, àti àìgbàgbọ́ nínú ilé iṣẹ́ ìròyìn ni ó parapọ̀.
Yíyọ-eyín onídàájọ́ àti ìdọ́gba lábẹ́ òfin
Ní ọjọ́ 25, oṣù Ṣẹrẹ ọdún-un 2019, ìyàlẹ́nu ni ó jẹ́ fún ọmọ orílẹ̀-èdè Nàìjíríà nígbà tí Ààrẹ Muhammad Buhari ní òun nìkan dá Adájọ́ Àgbà Orílẹ̀-èdè Nàìjíríà, Onídàájọ́ Walter Onnoghen dúró ní ẹnu iṣẹ́, tí ó sì yan ẹlòmíràn ní kíákíá, ìyẹn Ibrahim Tanko Muhammad ẹni tí a búra fún gẹ́gẹ́ bíi aṣiṣẹ́ bíi Adájọ́ Àgbà Orílẹ̀-èdè Nàìjíríà (CJN).
Ẹ̀sùn àìbìkítà àti ìṣowó-ìlú-mọ́kumọ̀ku ni a fi kan Onnoghen.
Síbẹ̀, àwọn alátakò sọ wípé ẹ̀sùn wọ̀nyí jẹ́ ìgbésẹ̀ láti di àjọ onídàájọ́ ní ẹnu ní ìpalẹ̀mọ́ ìbò, àti dáyàfo ẹ̀ka ìjọba tí ó kù.
Ìdádúróo Onnoghen ta ìpá sí òfin Orílẹ̀-èdè Nàìjíríà ọdún-un 1999 fún ìyọkúrò àwọn adájọ́ .
Àlàálẹ̀ Ìkẹta, Apá 1, ti ìwé òfin ọdún-un 1999 sọ wípé Àjọ Onídàájọ́ (NJC) nìkan ni ó ní àṣẹ láti lè rọ adájọ́ ní oyè. Apá IV ìwé òfin náà túbọ̀ sọ síwájú nípa òfin yìí.
Ààrẹ orílẹ̀-èdè Nàìjíríà Muhammadu Buhari kò tẹ̀lé àwọn àlàálẹ̀ wọ̀nyí.
Ó fi ipá gba agbára lọ́wọ́ NJC tí ó ní àṣẹ ní abẹ́ òfin láti sọ bóyá kí a rọ adájọ́ tàbí aṣojú-ṣòfin (ilé ìgbìmọ̀ àgbà) ní oyè, tí yóò sì fi ohùn sí irúfẹ́ ìgbésẹ̀ náà.
Ìwà ìfagbáraṣèjọba ni ààrẹ hù, bẹ́ẹ̀ ni kò sì bá òfin mú.
Ìrò olóòtú ìwé ìròyìn Punch pe ìhùwàsíi Buhari gẹ́gẹ́ bíi ti apàṣẹ-wàá àti pé ìwà náà lè fa rògbòdìyàn-an ti òfin:
Ìhùwàsíi Buhari burú jáyì, ó ní ẹ̀tàn nínú, kò sì ní orí kò sì ní ìdí.
Ìwà àkóso ìjọba fàmílétèntutọ́, tí ìwé òfin lè di ìfọwọ́rọ́tìsẹ́gbẹ̀ẹ́...
Ní ti òtítọ́, ìwà àdánìkanṣe ààrẹ lè da ìwé òfin orílẹ̀-èdè Nàìjíríà rú yányán, bóyá, ó lè da ìrìnàjò ogún ọdún ìjọba tiwantiwa rú.
Èyí kò yàtọ̀ sí àwọn ìwà ìfagbáraṣèjọba àti ìtàpá sí ìjọba àwa-arawa tí a ti mọ ìṣàkóso ìjọba náà mọ́n, kódà bí a bá kà á sí ìwàa kò kàn mí, tí ó nípa tí ó pọ̀ àti tí a kò lérò.
Ìjọba orílẹ̀-èdè Amẹ́ríkà àti United Kingdom náà sọ̀rọ̀ òdì sí ìdìgbòlùu àjọ onídàájọ́.
Ní oríi gbàgede ẹ̀rọ-alátagbà Twitter, àwọn ènìyàn ń sọ.
Ìgbógunti ọ̀rọ̀ ìkórìíra ni gbólóhùn tuntun ‘ààbò orílẹ̀-èdè’
Àmì mìíràn tí ó ń tọ́ka sí wípé ó lè bọ́ sí kí wọn ó ti ayélujára pa ni èròńgbà ìjọba láti pa òmìnira ọ̀rọ̀ sísọ orí ayélujára mọ́n ní ìbámu pẹ̀lú dídáàbobo orílẹ̀-èdè.
"Ní kò pẹ́ kò pẹ́, ìjọba pa àṣẹ fún àwọn agbófinró láti ""wá wọ̀rọ̀kọ̀ fi ṣ'àdá lórí ọ̀rọ̀ ìkórìíra, pàápàá ní orí ẹ̀rọ-alátagbà""."
"Èyí, gẹ́gẹ́ bí ìròyìn láti ọwọ́ọ Cable ti ṣe sọ, yóò jẹ́ mímú ṣẹ nípasẹ̀ ṣíṣe alamí aṣàmúlò ẹ̀rọ-alátagbà ""ọmọ orílẹ̀-èdè Nàìjíríà tí ó lókìkí""."
Nínúu oṣù Agẹmọ ọdún-un tí ó kọ́ja, Olórí Ẹ̀ka tí ó ń rí sí Ètò Gbígbé Ọ̀rọ̀ Síta fún Orílẹ̀-èdè Nàìjíríà Láí Mohammed ní wípé ewu ńlá ni ìbísí àhesọ ìròyìn àti ọ̀rọ̀ ìkórìíra tí ó ń gbilẹ̀ yóò mú bá ààbò orílẹ̀-èdè.
Ní ọdún méjì sẹ́yìn, Nasir El-Rufai, gómìnà ìpínlẹ̀ Kaduna, sọ wípé àhesọ àti ọ̀rọ̀ ìkórìíra jẹ́ “ìṣòro ńlá” tí ó lè fa ìfọ̀kànbalẹ̀, ààbò ẹ̀mí àti dúkìá orílẹ̀-èdè yà.
Bí ó ti wù kí ó rí, pẹ̀lú ẹ̀gàn ni ó jẹ́ pé ọ̀ràn-an àhesọ àti ọ̀rọ̀ ìkórìíra kan Lai àti El-Rufai gẹ́gẹ́ bíi ìṣòro ààbò orílẹ̀-èdè Nàìjíríà.
Bí olóṣèlú ẹgbẹ́ alátakò, àwọn méjèèjì kò ní ẹ̀rí tí ó dájú tí yóò fi ìdí ẹ̀sùn tí ó fi kan ìjọba àná múlẹ̀.
Fún àpẹẹrẹ, Nassir El-Rufai, gómìnà ìpínlẹ̀ẹ Kaduna lọ́wọ́lọ́wọ́ tẹnu mọ́ ọn ní ọdún-un 2014 — láìsí ẹ̀rí — wípé “ẹni kéje ni òun jẹ́ nínú àwọn tí [Ààrẹ Jónátàànì Goodluck] fẹ́ ṣe ikú pa ”.
El-Rufai tún sọ wípé nígbà tí Goodluck ń tu ọkọ̀ gẹ́gẹ́ bí ààrẹ, jẹ́ agbátẹrù ẹgbẹ́ apani-ní- ìfọnná-finṣu Boko Haram. Bẹ́ẹ̀ náà ni Láí Mohammed tí ó ti ṣe Akọ̀wé Alukoro Orílẹ̀-èdè rí fún ẹgbẹ́ òṣèlú APC ti ṣe sọ.
Gẹ́gẹ́ bíi olóṣèlú alátakò, àwọn òṣìṣẹ́ ọba ti fi hàn wípé àwọn gan-an ni adárúgúdù tí ó ń dá àhesọ àti ọ̀rọ̀ ìkórìíra sílẹ̀, tí ó ń lo ẹ̀rọ-alátagbà fi dá rúgúdù sílẹ̀.
Àmọ́ wọn kò rí ìwàa wọn gẹ́gẹ́ bíi ewu fún ààbò àti àlàáfíà orílẹ̀-èdè; wọn kò di ẹni à ń fi ọwọ́ọ ṣìgún òfin mú tàbí mú kí a pa ayélujára nítorí ìwàa wọn.
Ẹ̀rọ-alátagbà àti ìbò orílẹ̀-èdè Nàìjíríà
Ìjà fún ìyàtọ̀ ìgbé-ayé ní orílẹ̀-èdè Nàìjíríà ọdún-un 2012 #OccupyNigeria àti ìpolongo ọdún-un 2014 #BringBackOurGirls mi gbogbo àgbáyé tìtì nítorí wípé àwọn ènìyàn ṣe àmúlò ẹ̀rọ-alátagbà fún ìpolongo ẹ̀dùn ọkàn-an wọn.
Ní ọdún-un 2015, ẹ̀rọ-alátagbà kó ipa ribiribi nínú ìbò orílẹ̀-èdè Nàìjíríà nígbà tí Twitter di ibi ìkorò àti gbàgede ìjà ìpínyà ní àsìkò ìpolongo, a sì mú u lò fún ìtànká ọ̀rọ̀ ìkórìíra àti ìròyìn tí kò ní òtítọ́ kan nínú.
Ní ọdún tí a wà yìí, ó ti ṣe ojúṣe gẹ́gẹ́ bíi ọ̀nà kan tí àwọn ọ̀dọ́ọ Nàìjíríà yàn láti ní ẹnu nínú ọ̀rọ̀ ìṣèlú.
Àwọn tí ó ń lo ẹ̀rọ-ayárabíaṣá ti ṣe àmúlò ẹ̀rọ-alátagbà láti fi pe ìjọba sí àkíyèsí, bíi ti ìdádúró-lẹ́nu-iṣẹ́ ti CJN, bí bẹ́ẹ̀ kọ́, kò bá ti máà jẹ́ mímọ̀ fún ọmọ ìlú.
Àwọn ọmọ bíbí orílẹ̀-èdè Nàìjíríà fi orí ẹ̀rọ-alátagbà sọ ohun tí ó ń gbé wọn ní ọkàn, bẹ́ẹ̀ náà ni wọ́n lò ó fi yọ ìjọba lẹ́nu láti pa èròńgbàa rẹ̀ tì àti fún ìfẹ̀hónúhàn:
Bó yá ayélujára wà ní àsìkò ìbò tàbí kò ní í wà, ìdí tí ó dájú ń bẹ láti ní ìgbàgbọ́ wípé ọ̀rọ̀ òṣèlú ní orí ayélukára-bí-ajere àti ní ojú òpópónà yóò jẹ́ ohun tí ìjọba yóò fi ojú sí.
‪Ta ni yóò jáwé olúborí nínú Ayẹyẹ ijó ìta-gbangba orílẹ̀-èdè Trinidad àti Tobago ọdún-un 2019?‬
Aparadà ijó ìta-gbangba kan fò sókè sí orin soca ní orí ìtàgé ní Queen's Park Savannah, ní Ijó ìta-gbangba ọjọ́ Ìṣẹ́gun, ọdún-un 2009.
Àwòrán láti ọwọ́ọ Georgia Popplewell, a lò ó pẹ̀lú àṣẹ.
Àwọn alárìíyá máa ń gba títì kan ní ọdọọdún fún Ijó ìta-gbangba Ijó ìta-gbangba Trinidad àti Tobago, tí wọn ń ṣe pẹ̀lú orin.
Àwọn àṣàyàn orin tí wọ́n máa ń jó sí máa ń jẹ́ àkójọpọ̀ orin soca tí ó mi ìgboro títì nínú ọdún yẹn, àmọ́ Ìwọ́de Ojúnà — orin náà tí máa ń jẹ́ jíjó jù lọ ní àwọn ibi kọ̀ọ̀kan ní ojú ọ̀nà ìyíde — jẹ́ oyè tí ó mú ẹ̀bùn àti iyì ìgbélárugẹ àjogúnbá ohun àtijọ́.
Fún àwọn òṣèré soca, kí ni kan ní í máa mú ni jáwé olúborí nínú Ìwọ́de Ojúnà, kò ju, dídáńgájíá ní oríi òpópónà.
Ní ọdún mẹ́wàá sẹ́yìn tàbí nnkan bẹ́ẹ̀ ni wọ́n sọ pé ìdíje náà ní màgòmágó nínú — pẹ̀lu ìlọ́wọ́sí àwọn alẹ́nulọ́rọ̀ tí ó ni ilé iṣẹ́ ìgbóhùnsáfẹ́fẹ́, afiorin-tí-a-ti-ká-sílẹ̀ dá àwọn ènìyàn lára dá àti àwọn aláṣẹ ilé iṣẹ́ orin kíkọ tí a mọ̀ sí “jàndùkú soca” — kò ì yọ́ ìgbàgbọ́ wípé Ìwọ́de Ojúnà jẹ́ ohun àwọn ènìyàn.
"Ìràwọ̀ òṣèrée soca Machel Montano, ẹni tí ó ṣe ojúkòkòrò jáwé olúborí nínú Ìwọ́de Ojúnà ní ẹ̀rìnmẹ́sàn-án, ṣe àpèjúwe rẹ̀ gẹ́gẹ́ bí ""orin tí ó máa ń mú àwọn ènìyàn ní ìdùnnú àti tí máa ń mú àwọn ènìyàn jáde nínú ara wọn"" — akọrin wo ni kò ní fẹ́ gba irú oyè bẹ́ẹ̀?"
Àmọ́ kí ẹnikẹ́ni máà rò wípé iṣẹ́ ọpọlọ nìkan ni ìrìnàjò sí Ìwọ́de Ojúnà.
Orin Ìwọ́de Ojúnà gbọdọ̀ ní àwọn èròjà tí ó ṣe kókó nínú kí ó tó lè kópa:
1. Ó gbọdọ̀ ṣe é jó sí, síbẹ̀ ó ní láti dùn ún ní etí àwọn ènìyàn tí yóò “mú wọn gbàgbé ara” ní orí ìtàgé, pẹ̀lú ọ̀rọ̀ orin tí yóò mú ayọ̀ jáde, èyí tí a mọ Ijó ìta-gbangba mọ́.
2. Ègbè tí àwọn òǹwòran lè kọ tẹ̀lé orin, ní ìdásí àti ìdáhùn tí í ṣe àṣà calinda, tí calypso — àti àdàlù ìgbàlódé, soca — ti wáyé.
3. Orin tí a gbé jáde ní ìgbà tí ó yẹ.
Bí orín bá tètè jáde, tí kò sí dúró pẹ́ títí ní ìgboro, orin mìíràn tí ó ń bá a figagbága lè rọ́ ọ sí ẹ̀gbẹ́.
Ní ọ̀nà mìíràn, bí orin tí ó dára gan-an bá pẹ́ jù kí ó tó jáde, àwọn ayírapadà lè máà ní àyè tí ó tó fún wọn láti mọ ọ̀rọ̀ orin náà ní ìgbáradì kí ọjọ́ Ijó ìta-gbangba ó tó dé.
Ní ìgbà mìíràn ẹ̀wẹ̀wẹ̀, ìdíje Ìwọ́de Ojúnà máa ń ní orin àyànfẹ́ tí kò ní afigagbága rárá; kò sí rí bẹ́ẹ̀ nígbà mìíràn, ìfigagbága náà máa ń le dé ibi wípé ó máa ń ṣòro láti yan olúborí.
Láì wípé ọ̀kan ju ọ̀kan lọ, àwọn wọ̀nyí ni orin tí a rò wípé yóò figagbága nínú Ijó ìta-gbangba Ìwọ́de Ojúnà Trinidad àti Tobago ọdún-un 2019...
"1. ""Savannah Grass"" láti ọwọ́ọ Kes"
Pápáa Queen's Park Savannah, ibi tí ó ní ewéko bíi kàá-sí-nǹkan ní àárín gbùngbùn olú ìlú Trinidad, ni ibi tí ayẹyẹ Ijó ìta-gbangba àti ilé ìtàgé àjọ̀dún náà.
Orin yìí dá lóríi agbègbè ayẹyẹ náà, àti ìrántí tí ó ti mú bá àwọn ayírapadà tí ó ti ń kópa láti ọdúnmọ́dún.
Orin náà ń fi ọ̀wọ̀ wọ agbègbè náà: bí ẹni wípé Agbègbè Papa náà ni oòrùn ní àárín àgbá-ńlá Ijó ìta-gbangba àti ohun tí ó kù ń yí i ká.
Savannah Grass jẹ́ ìpè sí ìrírí idán ayée àjọ̀dún yìí.
Bẹ́ẹ̀ kọ́, àmọ́ bẹ́ẹ̀ náà ni, ìlù orin náà ba orin náà mú gẹ́gẹ́ bí àwọn olólùfẹ́ẹ Ijó ìta-gbangba tí ó máa ń gbádùn un Ijó ìta-gbangba ṣe máa ń fẹ́ ẹ.
Orin náà dún dáadáa ní etí àti pé ó mú èèyàn gbàgbé ara rẹ̀, ní ọ̀nà tí ó ń mú kí àwọn ayírapadà ó máa gbé ẹsẹ̀ ní ọ̀kọ̀ọ̀kan bí wọ́n ṣe ń rìn/jó ní ojú ọ̀nà.
Orin náà ṣe àmúlò àti àfikún àwòrán ìlànà Ijó ìta-gbangba bí a ti ṣe mọ̀ ọ́ ni ìgbà-dé-ìgbà, fídíò orin náà túbọ̀ ṣe àfihàn ìdàgbàsókè orin soca láti ìpilẹ̀ṣẹ̀ tí í ṣe orin calypso.
"Bí kò bá ti ẹ̀ jáwé olúborí nínú ìdíje Ìwọ́de Ojúnà (bí ó ti lẹ̀ jé pé ó ní àyè tí ó pọ̀!), ""Savannah Grass"" yóò wà nínú àkópamọ́ orin soca gẹ́gẹ́ bí orin ìgbà-dé-ìgbà tí ó mú inú àwọn olólùfẹ́ẹ Ijó ìta-gbangba ní ibi gbogbo dùn."
"2. ""Rag Storm"" láti ọwọ́ọ Super Blue, pẹ̀lú àjọṣepọ̀ 3 Canal"
"Ìwà tí ó dùn mọ́ni ti ""playing mas'"" àti jíjó sí orin ni wípé ní bákan, àwọn èèyàn máa ń ju ọwọ́ sí òkè, pẹ̀lú ohunkóhun tí wọ́n bá mú ní ọwọ́, títì kan ohun-mímu àti aṣọ inujú."
"Aṣọ inujú yìí ni wọ́n máa ń pè ní ""àkísà"", èyí tí wọn máa fi ń nu àágùn bí wọ́n bá ń ""fò sókè"". Ìlànà Ijó ìta-gbangba náà kò sọnù ní ara Super Blue, ẹni tí ó kọ ""Get Something and Wave"", orin tí ó jáwé olúborí nínú Ìwọ́de Ojúnà ọdún-un 1991."
"Ó fọnrere àtinúdá náà ní ọdún tí ó tẹ̀lé oyè tí ó gbà pẹ̀lú ""Bacchanal Time"", tí ó pa àṣẹ fún àwọn ayírapadà láti máa ""fi ọwọ́ "" bí àwọn afọnfèrè brass ṣe ń kọrin ""F-jam"" tí gbogbo ènìyàn mọ̀ tàbí ""tantana"" tí ó ń dún ní abẹ́lẹ̀."
"Super Blue tí ṣe àgbékalẹ̀ ìlànà fún irúfẹ́ orin kan tí ó dára fún ojú ọ̀nà: ó tún jáwé olúborí ní èèkàn sí i ní ọdún-un 1995 pẹ̀lú orin-in rẹ̀ ewì sí agbábọ́ọ̀lù kríkẹ́ẹ̀tì Brian Lara, tí ó pa á ní àṣẹ fún àwọn olùwòran láti ""na pátákóo wọn sí òkè kí wọn ó ṣe àríyá""."
Ìjì Àkísà ní àwọn ohun tí ó mú soca yàtọ̀ — bíi irúfẹ́ lavway ìpè-àti-ìfèsì, pẹ̀lú àyè tí ó fẹ́ fún àwọn ènìyàn láti fi àkísà.
Orin tí ó dára lórí ìtàgé fún àwọn ayírapadà láti tú ara sílẹ̀ àti “ṣeré tìkára wọn”, lè fi hàn kedere wípé kò kì í ń ṣe wàsá láti fi ọwọ́ rọ́ sí ẹ̀gbẹ́ nínú ìdíje Ìwọ́de Ojúnà ti ọdún nìí.
"3. ""Famalay"" lọ́wọ́ọ Machel Montano, Bunji Garlin àti Skinny Fabulous"
Bí ó bá ní orin kan tí ń fi gbogbo ọ̀nà wá oyè Ìwọ́de Ojúnà ti ọdún yìí, ni orin yìí tí ó ní àyè láti jáwé olúborí:
"ìlù ""soca tí ó tani jí"", ọ̀rọ̀ orin tí ó sọ nípa ìṣọ̀kan tí àjọ̀dún náà máa ń mú wá, àti ègbé ọlọ́pọlọ tí ó kó gbogbo ẹ̀yà tí ó ń kópa nínú Ijó ìta-gbangba náà pọ̀ — tí ó ń bá òṣìṣẹ́ akọrin kiri, tàbí bí àwọn ọmọ ìbílẹ̀ Trinbago ṣe máa ń sọ, “famalay” rẹ (kí a máà ṣèṣì fi wé “ẹbí”) :"
Ṣé ẹ rí i , ẹ jẹ́ kí n sọ fún un yín ní ẹ̀rìnkan sí i, famalay ni famalay ń jẹ́ àti pé ó yàtọ̀ sí ẹbí tí ènìyàn ti wá
Àwọn kan ní ẹ̀jẹ̀ ni àmọ́ wọn kò fẹ́ rí oòrùn
Famalay kì í bẹ̀rù láyé láti tì ọ́ lẹ́yìn ní ìgbà gbogbo...
"Láì pa àṣẹ (yàtọ̀ sí abala kan tí Skinny kọ ""fi ọwọ́ọ̀ rẹ hàn mí"" àti ""wá tẹ̀lé mi"", orin náà dàbí orin ológun."
Ègbé soca tí ó dùn ní etí, pẹ̀lú ọ̀rọ̀ orin dancehall díẹ̀díẹ̀, ti ń da orí àwọn ènìyàn rú ní ìtaja Ijó ìta-gbangba.
"Bí ó ti lẹ̀ jé pé ó ní àríyànjiyàn bóyá ""Famalay"" yóò kópa nínú Ìwọ́de Ojúnà tàbí kò ní í kópa, nítorí Skinny wá láti St. Vincent àti Grenadines, òfin sọ wípé bí “ọ̀pọ̀ àwọn akọrin tí ó ń lé orin” yẹ kí ""ó jẹ́ ṣíṣe láti ọwọ́ọ ọmọ bíbíi Trinidad àti Tobago"", orin náà lè jẹ́ afigagbága – eléyìí sì jẹ́ ọ̀kan."
Èyí kì í ṣe wípé orin mẹ́ta péré ni ó ń du oyè. Ó ku bí ọ̀sẹ̀ mẹ́ta kí Ijó ìta-gbangba ó wáyé, àwọn orin wọn mìíràn — tí ó ní akọrin obìrin Destra Garcia àti Patrice Roberts —tí yóò mú ìdíje le fún àwọn ọkùnrin, àti bí àwọn akọrin soca ṣì ń gbé àwo orin tuntun jáde, ìfigagbága Ìwọ́de Ojúnà ọdún-un 2019 ṣì ń lọ lọ́wọ́.
Jẹ́ kí àwọn òkú ó sọ ìtàn nípa Hong Kong
Òpópónà Ilé-ìsìn òrìṣà, Yau Ma Tei, Hong Kong. ÀWÒRÁN: David Yan (CC BY 2.0)
Ìkìlọ̀: ìròyìn yìí ní àwọn àwòrán tí ó ń ṣe àfihàn ikú àti ipá. Medium ti ṣe àtẹ̀jáde ẹ̀dàa ìròyìn yìí ṣáájú èyí.
Bí o bá ti rìnrìn àjò lọ sí Hong Kong, o ṣe é ṣe kí o dé Yau Ma Tei, agbègbè ọjà alẹ́ tí ó jẹ́ ìlúmọ̀nánká níbi tí àwọn ènìyàn ti máa ń lọ ra ọjà àti oúnjẹ ẹ̀gbẹ́ẹ títì.
Yau Ma Tei jẹ́ ọ̀kan lára àwọn agbègbè tí èró pọ̀ sí jù lọ ní Hong Kong.
"Láti ọdún-un 2016, ẹ̀ka- ìlú náà ti di ibùdó fún ""20,000 ọ̀nà láti gbà kú ní Yau Ma Tei"", ìtọ́nà ""ìrìnàjò afẹ́ ìpànìyàn"" tí Melody Chan àti èmitìkarami ṣe olùdásílẹ̀, tí ó ti ń gbé àdúgbò náà fún ọdún púpọ̀."
Nípasẹ̀ ìrìnàjò afẹ́ náà, a fẹ́ mọ bí ayé àti ìgbé ayé ṣe rí ní Hong Kong.
Ìrìnàjò afẹ́ ojúnà oní kìlómítà 1.5 náà lọ láti arẹwà àti gúúsù Yau Ma Tei, àti ìrìnàjò dé ibi tí a ti pa ènìyàn 12 ní àárín-in wákàtí méjì.
A bẹ̀rẹ̀ ẹ rẹ̀ gẹ́gẹ́ bíi ètò Halowíìnì láti kó owó jọ fún ilé-iṣẹ́ ìbílẹ̀ kan.
Èsì tí a gbà dára tó bẹ́ẹ̀ ni ó mú wa tẹ̀síwájú nínú ìrìnàjò alẹ́ nínú oṣù tí yìnyín bá ń bọ́ tí ojú ọjọ́ bá tútù.
Oníṣẹ́ ìlú ni àwọn amọ̀nà, olùkọ́, oníṣègùn àti àwọn onímọ̀ mìíràn.
Bí a bá kà á ní ẹníméjì, ó ti tó ènìyàn 500 tí ó ti ṣe ìrìnàjò náà.
Àwọn ọ̀ràn ìpànìyàn tí a yàn wáyé ní àárín-in ọdún-un 2012 to 2016. Nínú ìwé ìròyìn ni a ti ṣa àwọn ìròyìn àti àkọsílẹ̀ láti ọwọ́ọ ilé ẹjọ́ Oníwàádìí-ẹni-tí-ó-kú.
Ní ìsàlẹ̀ ni àwòrán-eré ránpẹ́ ìrìnàjò afẹ́ ọdún-un 2017 ní oríi YouTube:
Ó súnmọ́, síbẹ̀ ó jìnà
Iye ènìyàn tí ó ń gbé ní ilẹ̀-tí-omí-fẹ́rẹ̀ẹ́-yíká Kowloon tó bíi èèyàn 40,000 ní orí ìwọ̀n kìlómítà kọ̀ọ̀kan, àti bí i ènìyàn 20,000 ni ó ń gbé Yau Ma Tei.
Ọ̀pọ̀lọpọ̀ ńláǹlà ni a pín sí kéékèèké. Àwọn ènìyàn ń gbé súnmọ́ ara wọn, àmọ́ síbẹ̀, wọ́n jìnà sí ara wọn.
Àìmọye àwọn ènìyàn tí ó wà nínú ìrìnàjò afẹ́ náà jẹ́ àgbàlagbà.
Bàbá arúgbó kan pa ara rẹ̀ nígbà tí ó bẹ́ láti ojúu fèrèsé ilé alájà-mẹ́rin pẹ̀lú okùn tí ó so mọ́ ọrùn.
Òkúu rẹ̀ ń fì ní ìta ògiri ilé náà ní títì ní àárín alẹ́, àmọ́ kò sí ẹni tí ó se àkíyèsí àfi ní ìgbà tí ó di fẹ̀ẹ̀rẹ̀ nígbà tí àwọn alùgbé ilé òdì kejì ṣí fèrèsée wọn.
Òmíràn ní í ṣe pẹ̀lú àwọn àgbàlagbà méjì tí a bá òkúu wọn nínú ilé, ọ̀kan kú ikú ebi.
Àsẹ̀yìnwá ni ó tó yé wípé ọkọ náà ni ó ṣe olùtọ́jú aya, ẹni tí ó arán ń ṣe.
Ọkọ náà kọsẹ̀ nínú yàrá ìgbàlejò, ó sì kú, ebí sì ṣe wẹ́rẹ́ pa ìyàwó sí orí ibùsùn.
Ó jẹ́ ohun ìbànújẹ́ wípé kò sí ẹni tí ó fura sí irú ìgbé ayé ìjìyà àwọn àgbàlagbà méjì.
Gẹ́gẹ́ bí ètò ìkànìyàn ọdún-un 2016, mílíọ̀nù èèyàn 1.16 million ni ọmọ ọdún 65 àti jù bẹ́ẹ̀ lọ ní Hong Kong— ìyẹn 15.9 ìdá gbogbo ènìyàn.
Ẹgbẹ̀rún 150 àwọn ènìyàn wọ̀nyí ni ó ń dá gbé.
HK$5,780 (US$720) ni owó oṣù àwọn àgbàlagbà tí í ṣe òṣìṣẹ́-fẹ̀yìntì ní ọdún-un 2016 — àti owó ìrànwọ́ ìjọba lápapọ̀.
Lọ́wọ́lọ́wọ́ báyìí, owó oṣù tí ó kéré jù lọ nínú tó HK$16,800 (US$2,200) dollars.
Àmọ́ gbígbé pẹ̀lú ẹbí tàbí ọ̀rẹ́ kò kan ti ìtìlẹyìn. Ìjàmbá oríṣi ni ó máa ń ṣẹlẹ̀ nínú ẹbí ní ìlú, pàápàá jù lọ ní àárín àwọn tí ó ń ṣiṣẹ́.
Ìṣẹ̀lẹ̀ kan wáyé, ọmọdébìnrin ọmọ ọdún 15 ni olóògbé tí ó máa ń múra bí ẹ̀dá-inú ìtàn tí a mọ̀ sí cosplay.
Ó f'akọyọ nínú ẹ̀kọ́ọ rẹ̀ àmọ́ ó bá ẹbíi rẹ̀ ní gbólóhùn asọ̀ nítorí olólùfẹ́ẹ rẹ̀.
Àbálọ àbábọ̀, ó kúrò ní ilé-ìwé, ó sì di ẹni-àpẹẹrẹ àwòrán láti so ẹ̀mí àti ara ró. Ẹni tí ó ṣiṣẹ́ fún tí ó san owó ọ̀yà HK$500 dollars (US$65) fún un ni ó pa a.
Òmíràn jẹ́ òkú ọmọ-ọwọ́ kan tí ìwọ́ọ rẹ̀ ṣì wà ní a ara rẹ̀, tí obìrin kan tí ó ń ṣe ìmọ́tótó ìbùdókọ̀ abẹ́-ilẹ̀ ní Yau Ma Tei bá nínú àpò kan.
Lẹ́yìn ìwádìí, àwọn ọlọ́pàá ṣe àrídájú wípé ọmọ-ọ̀dọ̀ kan láti ilẹ̀ òkèèrè tí ó ń bẹ̀rù wípé ọ̀gá òun yóò lé òun ni ẹnu iṣẹ́ bí ó bá mọ̀ wípé òun ní oyún ni ìyáa rẹ̀. Obìrin náà jẹ èrè iṣẹ́ ọwọ́ọ rẹ̀ ní ẹ̀wọ̀n.
Ní abala ìrìnàjò afẹ́ yìí, amọ̀nà ṣe ìbéèrè: ṣé àwọn ọ̀gá obìnrin náà kò jẹ̀bi bí?
Kò sí bí ó ṣe lè ṣẹlẹ̀ kí wọn ó máà mọ̀ wípé ẹni tí ó ń ṣiṣẹ́ fún wọn ní ojúmọ́ ní oyún ní inú.
Ọmọ-ọ̀dọ̀ tí ó wà ní Hong Kong ju 370,000 lọ, òfin ṣì fi àyè gbà wọ́n kí ó máa gbé nínú ilé ọ̀gáa wọn.
Èyí ni àyè fi sílẹ̀ láti lè rí wọn bá sùn bí wọn bá ń ṣiṣẹ́ fún wákàtí púpọ̀, láì jẹun tí ó ṣe ara ní oore, àti bẹ́ẹ̀ bẹ́ẹ̀ lọ.
Lẹ́yìn ọdún kan tí ìṣẹ̀lẹ̀ yẹn wáyé, ọmọ-ọ̀dọ̀ ilẹ̀-òkèèrè mìíràn gba ìdádúró ní ẹnu iṣẹ́ fún oyún tí ó ní.
Ó gba obìnrin náà ní ọdún méjì gbáko nílé ẹjọ́ láti jà fún ìdádúró láì bá òfin mu ní ẹnu iṣẹ́.
Ìpànìyàn ní àárín àwọn ènìyàn
Ọ̀gọ̀rọ̀ ìpànìyàn ní Yau Ma Tei jẹ́ ẹsẹ̀ tí ó ti ọwọ́ àwọn ènìyàn fún ra wọn wá, tí ó jẹ́ ẹsẹ̀ tí wọn kò gbèrò tàbí pa ète rẹ̀ tẹ́lẹ̀, tí àwọn tí ó dá ẹ̀ṣẹ̀ sì ṣe àṣìṣe.
Ó ní ìṣẹ̀lẹ̀ tí ọkùnrin kan pa ẹ̀gbọ́n-ọn rẹ̀ ọkùnrin ní ìta gbangba ní ojúu títì pẹ̀lú ọbẹ̀ ìwọ̀n ínṣì mẹ́sàn-án tí ó wọ inú ẹ̀dọ̀ fóró ẹ̀gbọ́n-ọn rẹ̀ lọ.
Ẹ̀bùn ni ó yẹ kí ọbẹ̀ náà jẹ́ fún ẹ̀gbọ́n náà.
Apànìyàn kan takú sí ibi ìpànìyàn lẹ́yìn tí ó pa ènìyàn tán; òmíràn fi ìwé pẹlẹbẹ ìdánimọ̀ọ rẹ̀ gba iyàrá tí ó tọ́jú òkú ẹni tí ó pa sí.
Ìpànìyàn mìíràn wáyé ní ilé ìtaja-ohun-èlò-inú-ilé.
Ẹ̀rọ-ayàwòrán amóhùnmáwòrán ká ìṣẹ̀lẹ̀ náà sílẹ̀.
Onírìn àjò ìgbafẹ́ tí ó ń lo ìwé-ìrìnnà Orílẹ̀-èdè Canada ni apànìyàn náà, ẹni tí ó gún òǹtajà ìsọ̀ náà nígbà tí òǹtajà bíi léèrè ìdí tí ó fi kó ọjà láì san owó.
Àlábàápàdé àwọn ẹ̀mí àti òjìjíi wọn
Ọ̀pọ̀ àwọn arìnrìn-àjò afẹ́ jẹ́ akẹ́kọ̀ọ́ ilé-ẹ̀kọ́ gíga.
Àwọn kan kópa nítorí wọ́n fẹ́ rí àrídájú; àwọn mìíràn rí i bí ọ̀nà láti fi ìmọ̀ kún ìmọ̀.
Oníṣègùn kan tí í ṣe ikọ̀ òṣìṣẹ́ ìlera tí ó ṣe ìrìnàjò náà sọ wípé:
Ẹni ọ̀ràn yìí dà bíi àwọn aláàárẹ̀ tí a máa ń bá pàdé nínú ìyára ìtọ́jú àwọn tí ó ní ìjàmbá àti ìtọ́júu pàjàwìrì – àwọn tí egbògi olóró tí sọ di ìdàkudà, àwọn tí ó ń sun títì, àwọn ogún-lé-mi-dé.
Iṣẹ́ẹ gbogbo wa ni láti dóòlà ẹ̀míi wọn ní yàráa pàjàwìrì.
Àmọ́ wọ́n máa ń kanra nígbà mìíràn.
Kì í rọrùn bí a bá ń ṣe ìtọ́júu wọn, nítorí náà a máa sọ sùúrù nù.
Ìrìnàjò afẹ́ yìí rán wa létí wípé a nílòo sùúrù bí a bá ń dá àwọn aláàárẹ̀ lóhùn.
Àti pé ayé ìrora ni wọ́n ń gbé, wọ́n sì ń tiraka láti gbé.
Onírúurú ikú ni yóò pa gbogbo àwọn olùgbée 20,000 Yau Ma Tei.
Ìgbàgbọ́ọ wa ni wípé bí ikú bá kanlẹ̀kùn, ẹ̀míi wọn yóò máa ráre kiri ní àárín-in àdúgbò àti ní òpópónà, láti máa rán àwọn ènìyàn létí nípa ìtúmọ̀ ìwà láyé.
Ìrìnàjò yìí ń lépa láti pèsè àyè fún àwọn òjìjí láti sọ ìtàn ara wọn.
Ohun tí ó ń fa ikú ni ìbàjẹ́ ọkàn tí a ò wò sàn.
Ìbàjẹ́ ọkàn ní ìwòsàn, a sì lè dènà ìpànìyàn.
Ó lè rí ìrànwọ́ fún àwọn tí ó ń bá ìparaẹni fà á àti àwọn tí ó wà nínú ìbàjẹ́ ọkàn.
Lọ sí Befrienders.org fún ojú òpó ìbánisọ̀rọ̀ ìdènà ìparaẹni ní orílẹ̀-èdèe rẹ.
Olórí orílẹ̀-èdè Azerbaijan tàkùrọ̀sọ àkọ́kọ́ ní orí amóhùnmáwòrán lẹ́yìn ọdún 15 ní orí àlééfà. Ó lè lo ọ̀nà mìíràn.
Ìfọ̀rọ̀wọ́rọ̀ Ààrẹ Ilham Aliyev àti amóhùnmáwòran REAL TV ní Oṣù Èrèlé 12.
Àpá àwòrán wá láti REAL TV ẹ̀rọ-alátagbà YouTube channel.
Ẹ̀rìn mélòó ló yẹ kí ààrẹ orílẹ̀ èdè ní ìtakùrọ̀sọ pẹ̀lú ilé ìgbéròyìn jáde tí ìlúu rẹ̀?
Ẹẹ̀kan l'ọ́sẹ̀?
Ẹẹ̀kan l'óṣù?
Àwọn olórí orílẹ̀ èdè afipá ṣe ìjọba máa ń ṣe ìtakùrọ̀sọ pẹ̀lú àwọn ilé ìgbéròyìn jáde ní èèkàn l'ọ́dún tàbí kí ó kéré jù bẹ́ẹ̀ lọ.
Ìdáhùn sí ìbéèrè yìí kọyọyọ ní Azerbaijan.
Ní ìbẹ̀rẹ̀ oṣù yìí, Ààrẹ Ilham Aliyev, tí ó di olórí ilẹ̀ Azerbaijan ní Oṣù Ọ̀wàrà ọdún 2003, ṣe ìtakùrọ̀sọ alákọ̀ọ́kọ́ọ rẹ̀ pẹ̀lú ilé ìṣẹ́ amóhùn-máwòrán ti ìlúu rẹ̀.
Ìfọ̀rọ̀-wáni-lẹ́nuwò oníwákàtí kan ọ̀hún tí ó wáyé lọ́jọ́ 12 oṣù yìí, pẹ̀lú oníròyìn ìjọba Mirshahin Aghayev — tí a ti mọ̀ tẹ́lẹ̀ rí fún ìdúróṣinṣin aìfi òlò p'ohùn — di gbígbésáfẹ́fẹ́ ní ilé ìṣẹ́ amóhùn-máwòrán aládàáni agbè fún ìjọba REAL TV.
Ó gbọn òǹgbẹ ni Azerbaijan, ilẹ̀ tí àwọn ará ìlú ti máa ń gbọ́ kí Aliyev sọ̀rọ̀ lórí afẹ́fẹ́, àmọ́ tí wọn kò sì rí i rí kó tàkùrọ̀sọ pẹ̀lú oníbèèrè.
Kódà ìṣàmúlò Twitter Aliyev dà gẹ́gẹ́ bí wèrè aládàásọ̀rọ̀ ju ìgbìyànjú ìbá ará ìlú sọ̀rọ̀ lọ.
Ní ìgbẹ̀yìn-gbẹ́yín, ìfọ̀rọ̀-wáni-lẹ́nuwò ọ̀hún jẹ́ àkọ́ṣe tí ó kọyọyọ.
Púpọ̀ àwọn tí ó wà lórí ẹ̀rọ ayélujára gbogbo sọ̀rọ̀ lórí aìkọbì-ara sí bí ààrẹ ṣe gbé ara rẹ̀, bí ó ṣe múra àti àwọn kókó tí ilé ìṣe ìgbóhùn sáfẹ́fẹ́ ìjọba sọ̀rọ̀ lé lórí.
Gẹ́gẹ́ bí a ti mọ̀ pé kò pọn dandan kí Aliyev ṣàfihàn ara rẹ̀ bí ó ṣe tó — Azerbaijan kòì tí ì dìbò tí kò sí kọ́mí-n-kọ́họ lẹ́yìn ọdún 37 tí ó ti gba òmìnira — kíni ó mú u ṣe èyí?
Ìfọ̀rọ̀wánilẹ́nuwo Ààrẹ Ilham Aliyev's pẹ̀lú REAL TV ní ọjọ́ 12, oṣù Èrèlé.
Àwòrán láti orí ẹ̀rọ-alátagbà YouTube ti REAL TV.
Àwọn kókó ìtakùrọsọ ọ̀hún dá lórí — ìjàkú akátá pẹ̀lú Armenia lóríi Nargono- Karabakh, iṣẹ́ ìlú, àtúnṣe sí ètò ọrọ̀ Ajé, àti ìbáṣepọ̀ pẹ̀lú Ẹgbẹ́ Aláṣẹpọ̀ Eurasian àti Ẹgbẹ́ Aláṣẹpọ̀ Europe.
A kò rí ohun tuntun kan gbámu.
Lẹ́yìn ìgbà tí fídíò ọ̀hún gba kòbákùngbé ìjábọ̀ bíi “Kọ̀wé fipò sílẹ̀” àti “A kò fẹ́ àlọ́ atanijẹ mọ́” pẹ̀lú ọ̀pọ̀lọpọ̀ àìní ìfẹ́ràn ní ọjọ́ àkọ́kọ́ tí a gbé e sórí ayélujára, ìkànnì REAL TV ní oríi YouTube ti ìsọsí pa.
"Olóṣèlú alátakò Azer Gasimli sọ pé ìfọ̀rọ̀-wáni-lẹ́nuwò ọ̀hún fi hàn pé ""ìfoyà ti dé bá"" ìjọba láàárín bí àwọn ará ìlú ò ṣe gba ti wọn àti ọ̀rọ̀ ajé ìlú tí ó ń ṣ'òjòjò."
Mo wo ìtàkùrọsọ àkọ́kọ́ tí Ilham Aliyev ṣe pẹ̀lú oníròyìn ilẹ̀ yìí kan.
Mo rò pé kò mọ́gbọ́n dání láti sọ tàbí kọ nǹkan kan l’ ésì si ohun tí Ààrẹ sọ.
Nítorí pé a ti ń fún un l'ésì fún ọdún pípẹ́.
Kò sí hóró òótọ́ kán nínú ìtàkùrọsọ ọ̀hún.
Ààrẹ àti oníròyìn ọ̀hún rán mi l'étí nípa “ọkọ̀ tó léfòó lórí irọ́ ”.
Ní àkótán: ara ò rọ ìjọba!
Habib Muntazir, aládàádúró oníròyìn kan fi ẹ̀dùn ọkàn-an rẹ̀ hàn pé ìtàkùrọsọ ọ̀hún kò gbóòkàn:
"Nǹkan kan ṣo tí mo gbọ́ ni ""Ìyá àgbà Saray""."
"Ó dá mi lójú pé ""Ìyá àgbà"" yìí yóò ṣòro tí ó wúni lórí ju Ilham Aliyev lọ."
Ìfakùn ọ̀rọ̀ “Ìyá àgbà Saray” tí Muntazir mẹ́nubà dá lórí àbẹ̀wò ìbánidárọ tí Aliyev bá lọ sí Agbègbè Shamakhi tí Azerbaijan, níbi tí ìporùrù ayé tí bá ọ̀pọ̀lọpọ̀ ilé ìgbé jẹ́ ní ìbẹ̀rẹ̀ oṣù yìí, tí ọ̀kan nínú rẹ̀ jẹ́ ti obìrin ọlọ́mọdún 92 tí orúkọ rẹ ń jẹ́ Saray.
Ajábọ̀ iṣẹ́ ìjọba ti fúnpá lórí ìpàdé tí Aliyev ní pẹ̀lú Saray, ẹni tí ó ti gba oríyìn gẹ́gẹ́ bí àwòkọ́ṣe rere fún ìfaradà àti ìgbàgbọ́ tí ó ní sí ọjọ́ iwájú orílẹ̀-èdè Azerbaijan lẹ́yìn-in ìṣẹ́lẹ̀ náà.
Ilham Aliyev pàdé Ìyá àgbà Saray. Àwòrán láti qafkaz.info.
Bí a ṣe lè ri lára ìtú ìmọ̀ ìfọ̀rọ̀wọ́rọ̀ agbóhùnsáfẹ́fẹ́ REAL TV l'órèfé, Aliyev sọ àsọdùn ọ̀rọ̀ nínú ìgbóríyìn fún arúgbó ọ̀hún, bí ò tí ṣe perí rẹ ní sísẹ̀ntẹ̀lé:
Irú ìyá àgbà àti àwọn ìyá, gẹ́gẹ́ bíi Ìyá àgbà Saray ti ń ṣakitiyan ìpamọ́ àwọn ìṣe orílẹ̀ wa àti ẹ̀mí-àìrí fún àìní ye ọgọ́rùn-ún ọdún.
Gbogbo obìnrin Azerbaijan ni ó fẹ́ fi ìwà jọ ìyá àgbà Saray.
Wò ó, obìrin ọmọ ọdún 92 èyí tí ilé rẹ̀ ti di ìlẹ̀ẹ́lẹ̀, ìrètí gidi wo ló tún wà fún un mọ́!
Ìyá àgbà Saray ní ìfọkàntẹ̀ pé ìjọba yóò dúró tì òun.
Kámáparọ́, nínú ìrìnàjò kékeré lọ sí Shamakhi, n kò rò ó tì tẹ́lẹ̀ pé n ó ṣe àlábàpáàdé Ìyá àgbà Saray.
Mo yẹ àwọn ilé tí ìporùrù ilẹ̀ ọ̀hún bà wò fínnífínní, mo sì rí àrító ohun tí ó ṣẹlẹ̀ níbẹ̀.
Gẹ́gẹ́ tí mo rí Ìyá àgbà Saray, àrídájú mi lórí bí àwọn ọmọ Azerbaijan ṣe ṣ'èèyàn sí l'ékún sí i.
Àwọn ọmọ ilẹ̀ wa á máa mú ìwúrí báni.
Ó wà nínú ìṣòro; ilée rẹ̀ ti wó.
Ó jọ pé kò mọ̀ pé ẹnìkan yóò wá ṣe ìrànwọ́ fún òun.
Kò mọ̀ bóyá ilé òun yóò dí àtúnkọ́ tàbí wọn yóò dà á wó pátápátá kọ́ òmíràn.
Àwọn ìyá àgbà bíi Saray ní ẹ̀mí ìforítì òun ìlọra tí ó mú àwọn ọmọ Orílẹ̀ Azerbaijan yàtọ̀.
Oníròyìn aládàádúró mìíràn, Sevinc Osmangizi, fi ṣe àgbékalẹ̀ ìpè kan ní oríi YouTube tí ó ń pè fún ìda-ọ̀rọ̀-wo lórí ìfọ̀rọ̀wáni-lẹ́nuwo ọ̀hún lẹ́yìn tí Ìgbóhùnsáfẹ́fẹ́ parí.
Àwọn tí wọ́n wò ó sọ àwọn nǹkan tí kò tẹ́ wọn lọ́run, wón sì tún pè fún àyípadà.
Ọ̀kan ní:
N kò le è wo ìfọ̀rọ̀wọ́rọ̀ náà ju ibi mo wò ó dé lọ, mo sì pa ẹ̀rọ amóhùn-máwòrán.
Nítorí pé, òfé lásán ni olùbéèrè Mirshahin Aghayev àti ìbéèrè rẹ̀.
Àdéhùn wọn kò wúlò fún wa mọ́.
Èké àti irọ́ wọn ti sú àwọn èèyàn.
Àwọn ará ìlú ń fẹ́ ohun tuntun àti àtúntò tòótọ́.
Akẹ́kọ̀ọ́bìrin kan tí ó jẹ́ ọmọ Tibet-Canada rí ìkọlu lórí ayélujára lẹ́yìn tí ó já ewé olú borí nínú ìdìbò àjọ-ìgbìmọ̀ akẹ́kọ̀ọ́.
Ó rò pé, Beijing ló yẹ á bá wí.
Àwòrán wá láti ọwọ́ọ Chemi Lhamo láti ìbáwọlé The Stand News.
Leung Hoi Ching ni ó kọ́kọ́ kọ ìròyìn yìí tí a sì tẹ̀jáde ní èdèe Chinese lórí ilé ìgbéròyìn jáde ará ìlú Hong Kong, The Stand News ní ọjọ́ karùn-ún-dínlógún, Oṣù Èrèlé, ọdún-un 2019.
Zhao Yunlin ni ó tú ìmọ̀ọ rẹ̀ sí èdèe Gẹ̀ẹ́sì.
Ní ọjọ́ kẹsàn-án Oṣù Èrélé, àwọn akẹ́kọ̀ọ́ ti Ifáfitì Toronto, ọgbà Scarborough dìbò yan ọmọ ọdún méjìlél'ógún kan tí ìlú abínibíi rẹ̀ jẹ́ Tibet, gẹ́gẹ́ bí ààrẹ ìgbìmọ̀ àwọn akẹ́kọ̀ọ́.
Lẹ́yìn ọjọ́ mélòó kan tí a kéde èsì ìdìbò ọ̀hún, ogunlọ́gọ̀ àwọn ọmọ China tí wọ́n ń kẹ́kọ̀ọ́ l'ókè òkun fi òǹtẹ̀ lu àpilẹ̀kọ ìfi-èhónú kan ní orí ẹ̀rọ-ayélujára, tí wọ́n sì ń t'ọ́ka àbùkù sí Lhamo pé ó ń l'ẹ̀díàpòpọ̀ pẹ̀lú àwọn àjọ tó ń jà fún òmìnira Tibet.
Wọn rọ àwọn aláṣẹ ilé-ìwé ọ̀hún láti yọ ọ́ kúrò l'órí òye náà.
Kòbákùngbé ìfèsì ọ̀rọ̀ láti ẹnu àwọn akẹ́kọ̀ọ́ tí ó ń gbé ní òkè òkun gbùngbùn òkè-odò China.
Ìṣàmúlò ẹ̀rọ-alátagbàa ti Lhamo kún fún àwọn kòbákùngbé ìjábọ̀-ọ̀rọ̀ àti èyí tí ó ń pè fún ìwàa jàgídíjàgan, èyí tí kò ṣẹ̀yìn àwọn akẹ́kọ̀ọ́ òkè-òkun tí ó ń gbé gbùngbùn China.
Bí àwọn ilé ìgbéròyìn sáfẹ́fẹ́ àgbàńlá-ayé gbogbo ṣe tán ìròyìn-in rẹ̀ ká, àwọn akẹ́kọ̀ọ́ tí ó wà láti Hong Kong àti Taiwan gbìnnàyá láti gbéjàa Lhamo.
Nínú ìfọ̀rọ̀wáni-lẹ́nuwo orí ẹ̀rọ ìbánisọ̀rọ̀ pẹ̀lú Stand News, Chemi Lhamo sọ pé òun nígbàgbọ́ pé ohun tí ó ṣẹlẹ̀ kò sẹ́yìn àwọn àjọ tí wọ́n ń bá Ìjọba China ṣe, ẹ̀sùn èyí tí àwọn òṣìṣẹ́ àgbà àjọ ọba China ti sẹ́ lé lórí.
Kí a tó dìbò yìí, a ti yàn mí gẹ́gẹ́ bí igbá-kejì ààrẹ ìgbìmọ̀ akẹ́kọ̀ọ́ fún oṣù mẹ́jọ gbáko, kò sì sí ohun kan tí ó ṣẹlẹ̀.
Ní ìdakèjì, lẹ́yìn gbogbo ìṣẹ̀lẹ̀ẹ pàjáwìrì wọ̀nyìí, kò sí àní-àní pé àjọ kan ń gbìyànjú láti tìka bọ ìṣẹ̀lẹ̀ wọ̀nwọ̀nyí ní bírípó.
Ó pani lẹ́rìn-ín pé láti ìgbà yìí wá tí mo ti ń ṣiṣẹ́ gẹ́gẹ́ bí igbá-kejì ààrẹ, bí mo ti ṣe ń ṣe ètò oríṣiríṣi tí n ò sì yé fi àwọn àṣàyàn ìhùwàsí mi l'éde, ṣùgbọ́n kò sí ẹni tí ó ti wádìí nípa àwọn ọ̀nà òṣèlú tí mo yàn ní ààyò.
Ó tẹ̀ síwájú sí i pé ìwà àwọn akẹ́kọ̀ọ́ akẹgbẹ́ òun láti gbùngbùn China tí ń yí padà.
Ọ̀kàn nínú àwọn akẹgbẹ́ẹ rẹ̀ tí ó wá láti gbùngbùn China fi ìwàǹwara pè é níjà láti fi èrò rẹ s'óde lórí gbígba òmìnira Tibet.
"Ó tún gba àwọn ìpè kan, èyí tí ó ń kọ ""orin pupa"" (orin ọ̀tẹ̀ tí ó ń yín Ẹgbẹ́ Òṣèlú Chinese Communist Party)."
Àwọn orin wọ̀nyìí kò yé Lhamo, bó ṣe jẹ́ pé kò mọ èdèe Mandarin Ilẹ̀ China sọ.
Bí àkànlù àtakò àti ìjàbọ̀ ṣe ń lọ lọ́wọ́ lórí ayélujára, àpapọ̀ àwọn akẹ́kọ̀ọ́ kan tí gbógun lọ sí ọ́fíìsì ìgbìmọ̀ akẹ́kọ̀ọ́ láti lọ pè fún gbígbé èsì ìdìbò ọ̀hún yẹ̀wò.
Ìgbìmọ̀ akẹ́kọ̀ọ́ sì ti ti ìyàrá ìpàdée wọn pa fún ìgbà díẹ̀, nítorí ọ̀rọ̀ àbò.
Chemi Lhamo ti jẹ́ ajàjàǹgbara akẹ́kọ̀ọ́ fún ọdún mélòó kan.
Ó jẹ́ ọmọ ẹgbẹ́ tó ní áápọn ní ìlú àjọgbé àwọn Tibet tí ó wà ní Toronto àti pé ó ti kópa nínú ìjàfẹ́tọ̀ọ́ kan tí ó wáyé níta Akànkọ́ Ilé Ẹ̀kọ́ Confucius tí fáfitì ọ̀hún, ẹ̀ka ìbílẹ̀ àjọ ìsọdọ̀kan àṣà Ilẹ̀ China tí ìjọba China ń ṣe agbátẹrù fún lọ́nà tí ó fi ń mú kí China lágbára sí i ní ilẹ̀ òkèèrè.
Ní ìgbà yìí wá, ó ti fi èrò ọkàn-an rẹ̀ hàn pẹ̀lú àwọn ajàfẹ́tọ̀ọ́ ìlú láti Hong Kong àti Taiwan lórí kókó ọ̀rọ̀ tó jẹ mọ̀, òmìnira ọ̀rọ̀ sísọ, ìdá-gbé nǹkan ṣe, ìjọba àwarawa àti àwọn kókó tó jọ mọ́ ọ ní ìpàdé ìta gbangba.
Lhamo ò fi ìgbà kan bẹ̀rù láti sọ èrò ọkàn-an rẹ̀ jáde rí tàbí fi ara rẹ̀ hàn gẹ́gẹ́ bí ọmọ Tibet- ó má ń wọ Chuba, aṣọ ìbílẹ̀ àwọn ọmọ Tibet, ní gbogbo ọjọ́ Ọjọ́rú.
Títí di ìgbà ìdìbò, kò gbó-òórùn inúnibíni kán rí láti ọ̀dọ àwọn akẹgbẹ́ẹ rẹ̀ tí wọ́n jẹ́ ọmọ China.
Èyí ni ó mú u fura pé ìkoni síta bíi ọmọ ọjọ́ mẹ́jọ yìí kò sẹ́yìn àwọn aláṣẹ China.
Láti èèyàn ogúnléndé aláìníbùgbé sí olórí ìgbìmọ̀ akẹ́kọ̀ọ́
Kí ó tó rin ìrìnàjò lọ sí Canada ní ọmọ ọdún mọ́kànlá , Chemi Lhamo jẹ́ ẹni ogúnléndé tí kò rí ibùgbé kan gbé ní India.
Àwọn òbíi rẹ̀ àgbà sá kúrò ní ilẹ̀ẹ wọn pẹ̀lú Dalai Lama ní ọdún-un 1959. Nínú hàhámọ́ ìnira tí wọ́n wà yìí, kò sí ibi tí òun àti mọ̀lẹ́bí rẹ̀ lọ, tí wọ́n kà wọ́n kún.
"Nígbàkúùgbà tí wọ́n bá bí mí léèrè pé : ""Ibo lo ti wá?"""
Ara mi máa ń kótì láti dáhùn – Ìgbà mìíràn mà á pé India ni mo ti wá, ṣùgbọ́n wọn kò fún mi ní ìwé ìgbèlùú; nígbà mìíràn ẹ̀wẹ̀ mà á dáhùn pé Tibet ni mo ti wá, ṣùgbọ́n tí wọ́n bá béèrè pé báwo ni Tibet ṣe rí, n ò mọ bí n ó ṣe dáhùn-un rẹ̀, ìdí ni pé China ò fún mi ní ìwé ìgbèlùú lọ sí Tibet.
Ṣùgbọ́n ìrírí mi bí wọ́n ṣe ń rí mi bíi atọ̀húnrìnwá ti jẹ́ kí n ní ìmọ̀ nípa àṣà àwọn èèyàn mi: àṣà Tibet.
Llamo sọ̀rọ̀ nípa ìrìnàjòo rẹ̀ lọ sí Canada, ọmọ kékeré akẹ́kọ̀ọ́ tuntun kan tí ó wá láti Tibet tí ó bá wá sí ìyàrá ìkẹ́ẹ̀kọ̀ọ́.
Ara rẹ̀ yá gágá, inú rẹ̀ dùn láti ṣe alábàpàdé àwọn ọ̀rẹ́ tí ó wá láti ilẹ̀ẹ rẹ̀, bẹ́ẹ̀ ló mọ̀ pé ó lé sọ èdè Tibet.
Síbẹ̀síbẹ̀, nínú ìfún-ojúpọ̀, ó sọ fún un pé: “Tí a kò bá sọ èdè Tibet ńkọ́ ?
Mo lè sọ Gẹ̀ẹ́sì.”
N ò mọ̀ bóyá ojú ń tì í ni tàbí ẹ̀rí ọkàn ń jẹ́ ẹ.
N ò mọ̀.
Ṣùgbọ́n ìgbà náà ni mo tó mọ̀ pé àwọn ọ̀dọ́ Tibet kan ò fẹ́ sọ èdè wọn bí ẹni pé wọn kàn-án nípa fún wọn láti sọ èdè elédè.
Ní ìgbà yẹn, Lhamo jẹ́ ọmọ ọdún 12.
Ẹ̀míi rẹ̀ ò lé ‘lẹ̀ nípa ìdánimọ̀ọ rẹ̀, ó yìí ọkàn àwọn òbí rẹ̀ padà láti kó lọ sí àdúgbò tí àwọn ọmọ Tibet ń gbé.
Láti ìgbà náà wá, ó kọ́ nípa èdè, àṣà àti ìṣẹ̀ṣe Buddha ti Tibet, ó sì di àjà-fún-ẹ̀tọ́ ọmọ ènìyàn.
Àwọn àdáyanrí ìwà Tibet bíi ìní elẹgbẹ́ ẹni lọ́kàn, ìbọ̀wọ̀ fún àgbà, àìmọ̀kan ní ìpilẹ̀ ìbàjẹ́, ti fún mi ní ìgboyà.
Bí ìmọ̀ mi ṣe ń lé kún sí i nínú àṣà ìbílẹ̀ẹ mi, ní ìgboyà mi ṣe ń pọ̀ sí i.
Agbára àti ìgboyà yìí, bí ó ṣe sọ, tí mú u láti lè sọ̀rọ̀ akin gẹ́gẹ́ bí atọ̀hùn-rìnwá àti ọmọ Tibet:
Ó le láti jẹ́ atọ̀hùn-rìnwá, ṣùgbọ́n ìjàjàǹgbara yìí ní ó sọ mí di bí mo ṣe wà.
Lónìí, mò ń sọ̀rọ̀ ní ohùn ìrara nípa àwọn ará Tibet ní kíkankíkan àti ìwúrí ọlọ́pẹ́ tí ìdánimọ̀ọ mi gẹ́gẹ́ bí ọmọ Tibet fún mi.
Nígbà tí à ń dìbò ìgbìmọ̀ akẹ́kọ̀ọ́, mo máa ń tẹnu mọ ọn pé ó yẹ kí àwọn tí wọ́n ayàsọ́tọ̀ ní aṣojú nígbà ìdìbò.
À ń fẹ́ aṣojú tí yóò rí i wípé à ń rí ẹtọ wa gbà lóòrèkóòrè.
Ìjìyà yóò wá sópin
Fún Lhamo, ayé tí ó pé pérépéré ni èyí tí kò sí ìdálọ́wọ́kọ́ tàbí ìyàsọ́tọ̀ — Òmìnira Tibet àti ìdádúróo rẹ̀ kọ́ ni ohun tí ó hún jẹ wá lẹ́sẹ̀.
Ìmísí ọjọ́ ọ̀la mi sí Tibet kan náà ni mo ní sì gbogbo àgbá-ńlá-ayé: Mo fẹ́ jẹ́ kí ẹ̀tọ́ tí àwọn ará Tibet ń jẹ gbádùn máà yàtọ̀ sí ti àwọn Canada, àwọn ni òmìnira láti lè sọ èrò ọkàn ẹni, òmìnira láti ní ìgbàgbọ́, òmìnira láti máà fi òṣèlú pá ẹniẹlẹ́ni lẹ́kún.
N ò ṣe ojúṣàájú fún àwọn ará Tibet láti ní àwọn ẹ̀tọ́ wọn yìí nìkan, ó wù mí kí àwọn tí wọ́n wá láti Hong Kong àti Taiwan, ìwọ̀-oòrùn Turkey, àwọn ẹgbẹẹgbẹ̀rún lọ́nà ẹgbẹ̀rún ní ìlọ́po méjì 60 ẹni ogúnléndé tí ó wà ní kárí ayé àti fún gbogbo àwọn ènìyàn láti jàǹfààní ẹ̀tọ̀ wọ̀nyí.
Ọ̀pọ̀ àwọn èèyàn láti Hong Kong ní ìgbàgbọ́ pé China tí ń lo agbára tìkúùkú, wọ́n sì ń lo ètò ìlú láti ṣẹ́ àwọn ọ̀tá àti àwọn ẹ̀yà tí kò pọ̀ lẹ́yìn.
Kódà ni Hong Kong, àyè láti sọ ọ̀rọ̀ ẹnu ẹni jáde àti láti bá èèyàn ṣe pọ̀ ti jákulẹ̀.
Àwọn ìpèníjà òṣèlú tí ó ń kojú wọn ní Hong Kong lẹ́yìn Àkójọpọ̀ Ẹgbẹ́ Alábùradà; 2014 Umbrella Movement kò ṣe àjòjì sí Chemi Lhamo, ṣùgbọ́n ó bá àwọn ará Hong Kong kẹ́dùn, ó pẹ̀tù sí wọn lọ́kàn pé kò kí wọ́n máà ṣe juwọ́ sílẹ̀:
Mo kọ́ ẹ̀kọ́ kan nínú àṣà àwọn Tibet nípa àìwàfúnìgbàpípẹ́: gbogbo nǹkan ni òpin yóò dé bá. Mo ní ìgbàgbọ́ pé ìjìyà gbogbo ń bọ̀ wá dópin…Mo ní ìrètí pé ọjọ́ kan ń bọ̀ tí mo máa wọ aṣọ Chuba mi lọ sí Tibet.
Àfilé iye owó fún gbígba ìwé ẹ̀rí ọmọ-ìlú-fún-ìrìnnà mú àwọn ọmọ Angola fi ẹ̀hónú hàn
"Ní ibi ìfẹ̀hónúhàn ní Luanda, àmì náà sọ pé ""30.500 Kwanzas kì í ṣe kékeré""."
Àwòrán láti ọwọ́ọ Fernando Gomes, a gba àṣẹ láti lò ó.
Inú ń bí àwọn ọmọ orílẹ̀-èdè Angola látàrí iye owó ìwé ẹ̀rí ọmọ-ìlú-fún-ìrìnnà tuntun 30,500 kwanzas (ó tó 97 owó dollar) tí ìjọba ṣẹ̀ṣẹ̀ polongo ní ọjọ́ 21 oṣù Ṣẹẹrẹ.
2500 kwanzas (owó dollar orílẹ̀-èdè US mẹ́jọ) ni ó jẹ́ tẹ́lẹ̀tẹ́lẹ̀.
Ní àfikún, ìjọba ti pín iye owó irúfẹ́ ìrìnàjò tí ó wà sí ọ̀tọ̀ọ̀tọ̀, ó tò ó ní ẹsẹẹsẹ.
Lábẹ́ ìlànà tuntun yìí ni ìjọba yóò ti máa gba 45,250 kwanzas fún ìwé ìwọ̀lú ìdúró-sí-ìlú; 21,350 fún ìwé ìwọ̀lú ìrìnàjò-afẹ́; 36,500 fún ìwé ìwọ̀lú àgbàníbodè; 38,125 fún ìsúnsíwájú ìwé ìwọ̀lú iṣẹ́; 15,250 fún ìwé ìwọ̀lú ọ̀rọ̀ ìlera ara; àti 30,500 fún ìwé pélébé ìgbélùú.
Agbẹnusọ fún Ẹ̀ka Ìjọba tí ó ń ṣe àbójútó ètò ìforúkọsílẹ̀, Valdemar José, sọ fún àwọn akọ̀ròyìn ìbílẹ̀ Angola pé ìdíyelé fún ìwé ìrìnnà ìwọ̀lú lásán-làsàn lọ sí òkè nítorí owó gegere ni ó ń jẹ láti ṣe ìwé náà:
Ìtúmọ̀ Ìtúnwí-ọ̀rọ̀ Ọlọ́rọ̀ gan-an
Ìjọba rí i wípé ó tó àsìkò láti sún owó ìwé ẹ̀rí ọmọ-ìlú-fún-ìrìnnà, ó sì ti yọ ọwọ́ọ Kílàńkóo rẹ̀ kúrò nínú kíkó owó lé e lórí, kí ó ba lè ṣe, fún àpẹẹrẹ, pèsè omi, ináa mànàmáná àti àwọn ohun amáyérọrùn mìíràn.
Ohun èlò fún ìwé ẹ̀rí ọmọ-ìlú-fún-ìrìnnà máa ń gbọ́n owó mì, nítorí iṣẹ́ ìdáàbòbò oríi rẹ̀, tí àjọ ọba ń kówó lé lórí tẹ́lẹ̀ kí ó tó di ìgbà yìí.
Èyí jẹ́ ìrántí ohun tí ojú àwọn ọmọ Mozambique rí ní ìparí ọdún-un 2018, nígbàtí ìjọba pinnu láti fi owó kún ìwé àṣẹ gbogbo, bẹ́ẹ̀ náà ni ó bá ìwé àṣẹ ọkọ̀ wíwà, tí ìdíyelée rẹ̀ fi ìdá 500 gbéwó lórí.
Àfilé iye owó náà ti dá awuyewuye sílẹ̀.
Ìfẹ̀hónúhàn ọ̀dọ̀ tí ó tó bíi 100 wáyé ní ọjọ́ kẹ́rin oṣù Èrèlé, pẹ̀lú àtìlẹ́yìn ẹgbẹ́ àwọn ọmọ ìlú kan tí ó rí ìgbésẹ̀ ìjọba gẹ́gẹ́ bí ọ̀nà láti gbẹ́sẹ̀ lé ẹ̀tọ́ àwọn ènìyàn fún ìrìnàjò ṣíṣe.
Ìfẹ̀hónúhàn náà
Ìfẹ̀hónúhàn ní Luanda (ọjọ́ kẹrin oṣù Èrèlé).
Àwòrán láti ọwọ́ọ Simão Rossi, a lò ó pẹ̀lú àṣẹ.
Ní ọjọ́ kẹrin oṣù Èrèlé, Global Voices bá Fernando Gomes, ajìjàǹgbara ọmọ orílẹ̀ èdè Angola tí ó jẹ́ ọ̀kan lára àwọn alátìlẹ́yìn ìfẹ̀hónúhàn náà tàkùrọ̀sọ, láti mọ ohun gbogbo tí ó rọ̀ mọ́ ìṣẹ̀lẹ̀ náà.
Ó sọ fún wa:
Ìtúmọ̀ Ìtúnwí-ọ̀rọ̀ Ọlọ́rọ̀ gan-an
Èyí [ni ọ̀nà kan] fún ìpèsí àkíyèsí ìjọba João Lourenço, wípé àfilé ìdíyelé kò yẹ nírú àsìkò yìí, nítorí owó náà ti ṣe gegere ju fún àwọn ọmọ ìlú.
"Àti pé ""iṣẹ́ ìdàgbàsókè ọrọ̀ Ajé orílẹ̀-èdè Angola"" kò lé wáyé nípasẹ̀ àfilé owó orí, nítorí wípé àwọn ọmọ ìlú ni ó ń fi orí kó o, àwọn tí ó wà ní ipò ìjọba ní àǹfààní tí ó pọ̀ ní ìkáwọ́ọ wọn, tí ó ṣe pé àpò ará ìlú tí ó ń rùnpà ni wọ́n ti ń mú owó tí wọ́n ń ná."
Àwọn alátakò ti sọ pé ó ṣe pàtàkì láti rántí wípé ìwé ẹ̀rí ọmọ-ìlú-fún-ìrìnnà dúró fún ìdánimọ̀ ọmọ ìlú ní òkè òkun, torí ìdí èyí, kò ṣe é yẹ̀ sílẹ̀ fún wọn.
Ìtúmọ̀ Ìtúnwí-ọ̀rọ̀ Ọlọ́rọ̀ gan-an
A máa wà ní ojú òpópónà ní olú ìlú fún oṣù Èrèlé, ní àwọn ọjọ́ kọ̀ọ̀kan tí a yàn, ọjọ́ kẹrin oṣù Èrèlé ni ìwọ́de náà bẹ̀rẹ̀, àmọ́ ní ọjọ́ kéje ni a máa padà sí ojú òpópónà, tí a óò tún wà ní ọjọ́ kankànlá, tí a ó sì jábọ̀ ní ọjọ́ kẹtàlá, bí ìjọba kò bá yí ohùn padà.
"Àwọn akọrin ewì-alohùn ráàpù, Lilo Kwanza àti Adérito Gonçalves, kọ orin kan, tí wọ́n sì ya àwòrán-an orin tí ó dá lóríi ìwọ́de ìfẹ̀hónúhàn yìí, ""Ìwé ẹ̀rí ọmọ-ìlú-fún-ìrìnnà 30,000"" ni àkọlé orin náà, tí ó ń ṣe ẹ̀fẹ̀ lórí iye owó tabua tí ọmọ-ìlú yóò san fún ìwé ìrìnnà."
Ó ku ọjọ́ díẹ̀ kí ìwọ́de náà ó kò, ajàfúnẹ̀tọ́ ọmọ orílẹ̀-èdè Angola Pedrowski Teca sọ wípé ìwé ẹ̀rí ọmọ-ìlú-fún-ìrìnná pọn dandan ju ìwé ìdánimọ̀ pélébé lọ, ó rọ àwọn ènìyàn láti kọ́wọ̀ọ́ rìn, nítorí àìkọ́wọ̀ọ́ rìn, ní í ṣe ikú pa ọmọ ejò:
Ìtúmọ̀ Ìtúnwí-ọ̀rọ̀ Ọlọ́rọ̀ gan-an
Àwọn àjọ àgbáyé ti dẹ̀yìn kọ Òfin Ìṣíkúrò tí ó pàṣẹ àfilé ìdíyelé tí ó gbéra nílẹ̀ fìrì tí ó sì lọ òkè lálá.
OBS: Ìwé ìdánimọ̀ pélébé (B.I) wúlò gẹ́gẹ́ bí àmì ìdánimọ̀ ní àárín ìlú Angola.
Ní ẹ̀yìn odi ìlú Angola, pánda tí kò wúlò ni ìwé ìdánimọ̀ pélébé, kò sí àmì ìdánimọ̀ kan tí ó wà bí kò ṣe ìwé ẹ̀rí ọmọ-ìlú-fún-ìrìnnà.
Àwa, tí a wà nínú ìlú, ni a ó fi ààbò bò tí a ó sì ké pe àwọn aráa wa ní òkè òkun, kí àwọn náà ó ké gbàjarè, nítorí ìwé ẹ̀rí ọmọ-ìlú-fún-ìrìnnà ṣe kókó fún wọn.
Kí ìròyìn náà ó ba hó ye létí àwọn ènìyàn, ajàfúnẹ̀tọ́ọ nì àti akẹ́kọ̀ọ́ Ifáfitì, David Mendes, kọ, ní ọjọ́ ìwọ́de náà, iṣẹ́-ìjẹ́ fún ààre orílẹ̀-èdè Angola João Lourenço:
Ìtúmọ̀ Ìtúnwí-ọ̀rọ̀ Ọlọ́rọ̀ gan-an
Ọmọ-ẹgbẹ́ ààrẹ João Lourenço, kì í ṣe nítorí èyí ni àwọn aráa Angola ṣe yàn ọ́ sípò, kò sí ibi tí o ti sọ nínú ìpolongo ìléríi rẹ, o kò sọ pé ìwé ẹ̀rí yóò gbówó lórí, síbẹ̀ kí ni ò ń rò?
Kí ni ẹ fi ṣe ohùn àwọn mẹ̀kúnnù?
A ti rí ìrora látàrí àwọn àfilé ìdíyelé, ǹjẹ́ o mọ ìṣòro tí ó ń fà fún àwọn ará ìlú?
A kò tilẹ̀ mọ ẹni náà tí ó tọ́ láti tukọ̀ orílẹ̀-èdè Angola, báwo ni ọ̀dọ́ tí kò níṣẹ́ tí kò lábọ̀ yóò ṣe rí owó gba ìwé ẹ̀rí?
Pẹ̀lú gbogbo rẹ̀, ìjọba kò ì tíì sọ tó, tàbí kí ó kéde láti sọ bóyá òun yóò mú ìdíyelé náà wálẹ̀.
Àyájọ́ Ọjọ́ Òmìnira ní Trinidad àti Tobago — àmọ́ ǹjẹ́ orílẹ̀-èdè náà ní òmìnira bí?
Citizens examine what stands in the way of true freedom
Ère Orin Ìràpadà, Ọgbà Òmìnira, Jamaica. Àwòrán láti ọwọ́ọ Mark Franco, a gba àṣẹ láti lò ó.
Ọjọ́ 1 oṣù Ògún ni ọ̀pọ̀ agbègbè tí ó wà ní Caribbean mọ̀ sí Àyájọ́ Ọjọ́ Òmìnira, tí í ṣe ọjọ́ tí a máa ń sààmi ìgbòmìnira àwọn ọmọ Adúláwọ̀ t'ó jìyà ní àsìkò okòwò ẹrú orí òkun atlantic.
Trinidad àti Tobago jẹ́ àkọ́kọ́ nínú àwọn orílẹ̀-èdè ní àgbáyé tí yóò ya ọjọ́ sọ́tọ̀ láti fi sọríi ìfòpin sí òwò ẹrú, àmọ́ lẹ́yìn-in 34 ọdún tí ìsinmi àpapọ̀ náà fi ẹsẹ̀múlẹ̀ àti ọdún 185 lẹ́yìn-in tí Àbá òfin Ìfòpin sówò-ẹrú kọ́kọ́ wáyé, awuyewuye ṣì ń lọ lóríi wípé bóyá erékùṣù-ìbejì olómìnira náà ní òmìnira tàbí kò ní.
"Nínú ọ̀rọ̀ọ rẹ̀ nípa òmìnira ní ọjọ́ 27, ọdún-un, Alákòóso Ìlú Dókítà. Keith Rowley ṣàkíyèsí wípé ní àárín àwọn ọmọ bíbíi Trinidad àti Tobago, àwọn tí ó jẹ́ ọmọ Adúláwọ̀ ""kol ṣe dáadáa tó bí ó ṣe yẹ""."
"Rowley sọ wípé ìwà-ipá tí í ṣe ti ènìyàn dúdú, ìrírí ọ̀dọ̀, ní láti máa ṣe ìwúrí fún àwọn ọmọìlú láti ""fiyèsí, ṣe àfihàn àti ṣe ìtàkùrọ̀sọ pàtàkì nípa ibi tí a wà gẹ́gẹ́ bí orílẹ̀-èdè""."
Alága Ìgbìmọ̀ Àtìlẹ́yìn Òmìnira ti orílẹ̀-èdè náà, Khafra Khambon, gbà.
Àwọn ìwé àpilẹ̀kọ kan sí olóòtú fi àwọn àpẹẹrẹ okòwò ẹrú ìgbàlódé láwùjọ hàn èyí tí ó fi hàn wípé òmìnira tòòtọ́ ṣì ku díẹ̀ káàtó, nígbà tí àwọn mìíràn gbìyànjú láti sọ ọ́ di ọ̀rọ̀ òṣèlú, bí wọ́n ṣe ń tako àwọn iṣẹ́ ìlú àti àṣà.
Ìwé ìròyìn Trinidad Express yàn láti kọ èròo rẹ̀ nípa Àyájọ́ Ọjọ́ Òmìnira tí ó dábàá wípé Rowley, Kambon, àti ajàfẹ́tọ̀ọ́ ọmọ-ènìyàn Pearl Eintou Springer ṣì sọ nígbàtí wọ́n sọ ìdí tí àwọn ọmọìlú Trinidad àti Tobago tí ó jẹ́ ènìyàn dúdú ò fi ṣe dáadáa tó:
Ó rọrùn fún ẹgbẹ́ tí ó dúró ṣinṣin láti dá ètòo ẹlẹ́yàmẹyà àti ìtẹ̀bọlẹ̀.
Àwọn tí kò bá ètò náà lọ yóò di aláìṣetó tí wọ́n á sì di ẹni àgbésẹ́yìn sí ipò kejì tàbí èyí tí ó burú ju bẹ́ẹ̀ lọ.
Ọ̀pọ̀lọpọ̀ àwọn ètòo wa, ẹ̀kọ́ tí í ṣe baba, ń gbé àwọn ènìyàn sí ipòo tálákà, kò sì fún wọn ní àǹfààní lẹ́ẹ̀kan sí i.
Gbogbo ètò ni ó ní òṣùwọ̀n, tí ó ṣì jìnà gbégbérégbé sí òkè.
Àwọn tó bá ara wọn ní ìsàlẹ̀ ní ìṣòro láti bá àwọn tí ó wà ní òkè ṣe.
Iyì-ara-ẹni máa ń relẹ̀, tí èyí yóò sì mú wọn hu ìwà-ipá láti jà fún ẹ̀tọ́ọ wọn láwùjọ.
Ajábọ̀-ìròyín Arthur Dash gbóríyìn fún “ìṣẹ̀lẹ̀-àtẹ̀yìnwá ìdàgbàsókè” orílẹ̀-èdè náà ní ti ọ̀ràn-an ẹ̀yà, àmọ́ ó tún dá àbá wípé ìṣòro náà ju bí àwọn ti ṣe rò lọ, ó sì mú u ní àbá pé ó yẹ kí ọ̀rọ̀ alákòóso ìlú jẹ́ ìwúrí fún ọmọìlú láti ṣe ìwádìí fínnífínní sí bí ẹlẹ́yàmẹyà nínú ilé-iṣẹ ṣe ń pín àwọn ènìyàn sọ́tọ̀ọ̀tọ̀.
Àwọn òǹlò ẹ̀rọ-alátagbà sọ ti wọn. Òǹlò Facebook Adrian Raymond sọ:
Ní ọjọ́ òní a ṣe ìrántí àti ìsààmì òmìnira àwọn babańláa wa nínú ìgbèkùn ara ti òwò ẹrú.
Ní òní, lẹ́yìn ọ̀pọ̀lọpọ̀ ọdún, àwa ọmọ ẹrú tí à ń jà fitafita fún àjogúnbá ìjọba amúnisìn.
Àwọn àjogúnbá tí ó gbèèrú àti tí ó ní ìmúgbòrò ti di gbẹndẹ́kẹ: A ò kí ń ṣe òǹrorò, a ò kí ń ṣe oníjàgídíjàgan, a ò kí ń ṣe apanijẹ, a ò kàn kí ń ṣe ọ̀daràn àti ọmọ-ìta.
Olórí ni wa, aronújinlẹ̀ ni wa, ọlọ́pọlọ pípé ni wa, onímọ̀ ni wa.
Obama ni wá, Garvey ni wa, Marley ni wa, Angelou ni wa, Walcott ni wa.
Ẹ jẹ́ ká mọ̀ wípé ìyàsọ́tọ̀ọ̀tọ̀ nípa ti àwọ̀ ara ni ogún tí ó ń pín wa níyà.
Ẹ jẹ́ kí á ṣe ìṣèlú tó kún fún ọ̀wọ̀; ẹ dẹ́kun à ń ba dúdú jẹ́ ní etí àwọn ènìyàn...
Ẹ jẹ́ ká ṣ’àjọyọ̀ àtúnrí àwọn ìgbàgbọ́ọ wa.
Wọ́n gba ẹ̀sìn àwọn babańláa wa, wọ́n mú ìgbàgbọ́ àti ohun iyìi wa kúrò ní ọkàn-an wa.
Ní ayé òde òní tí ẹ̀rọ ayélujára mú iṣẹ́ ìwádìí rọrùn, ó yẹ kí o ṣe àyẹ̀wò sí ìgbàgbọ́ àwọn babańláa wa, ìbọ̀wọ̀ àti ìmọrírì àgbà, gbígba ìwùsàsí ẹni ìtẹnumọ́ ẹwùn àti èrè ìwà ẹni, ìgbàgbọ́ ń bẹ nínú ẹbí, nínúu mọ̀lẹ́bí, nínú ìletò, nínúu àdúgbó.
Òmìnira yìí faramọ́ ẹni tí o jẹ́, ibi tí o ti ṣẹ̀ wá, ẹ̀jẹ̀ àti ìṣẹ̀lẹ̀-àtẹ̀yìwá tí ó wà nínú iṣan-ẹ̀jẹ̀.
Gbá iyìi rẹ̀ mú, àṣàà rẹ, àti ìdánimọ̀ọ rẹ.
Àwọn ọmọ Bangladeshi lo ẹ̀rọ-alátagbà fi gbógun ti àjàkálẹ̀ àìsàn ibà-ẹ̀fọn
Ọ̀gọ̀rọ̀ l’ó ń d'orí kọ ẹ̀rọ-alátagbà lọ láti gba ẹ̀jẹ̀
Ẹ̀fọn Aedes albopictus, tí ó máa ń gbé kòkòrò ibà ká.
Àwòrán láti oríi Wikipedia, James Gathany, CDC ni ó ni àwòrán, àwòrán Òde.
Ní àárín ọdún, mélòó kan tí ó kọjá, pàápàá ní àsìkò ìjì ọdọọdún monsoon, iye àwọn tí àìsàn-an ibàa ẹ̀fọn ti kọlù ní Bangladeshì ti lékún síi.
Ní ọdún yìí, àwọn tí àìsàn-an ibàá kọlù tó bíi 7,179, àwọn - 2800 ní sáà kínní osùu Agẹmọ nìkan.
Bí ètò ìjọba ò ṣe dántọ́ tó láti borí àjàkálẹ̀ àìsàn ibà tí ó gbòde yìí, àwọn ènìyàn ń gbẹ́kẹ̀le ẹ̀rọ-alátagbà láti fi sọ ẹ̀dùn-un ọkàn-an wọn, pín àlàyé nípa ìtànkálẹ̀ kòkòrò náà, àti ṣe ìkéde nípa bí àwọn ènìyán ṣe le dá ààbò bo ara wọn.
Àkọsílẹ̀ Àìsàn Pọ̀ Sí i Ní Osù Agẹmọ
Ilé ìwòsàn gba àwọn aláìsàn ibà ẹ̀fọn 403 tí ó pọ̀ jù lọ ní ọjọ́ 22 osù Agẹmọ.
Gẹ́gẹ́ bí àwọn onímọ̀ kan ṣe rò, ipa ìyípadà ojú-ọjọ́, òjò àìdágbá kan, ojú-ọjọ́ tó ń ṣe ségesège, àti àìṣèmọ́tótó ni ọ̀dádá tí ó ń dá àtànkálẹ̀ ibà sílẹ̀.
Àwọn mìíràn sọ wípé ibà ẹ̀fọn ti ọdún nìí ń ṣekú paon ju ti ẹ̀yìn wá lọ. Ní ti òǹlò Twitter Md. Saif:
Ibà-ẹ̀fọn àti àmìi rẹ̀ ní ọdún yìí ti yàtọ̀ nítorí ìdí èyí ni o fi ní láti tọ oníṣègùn rẹ̀ lọ ní kété tí o bá ti ní ibà náà – gẹ́gẹ́ bí ògbólògbó onímọ̀ ìlera ti Ilé-ìwòsàn Bangabandhu ti sọ.
Àwọn ẹ̀yà ara àwọn aláìsàn tí amodi tẹ̀ ti ń daṣẹ́ sílẹ̀ – a kò gbọ́ èyí rí.
Nínú ìfọ̀rọ̀wánilẹ́nuwò pẹ̀lú ìwé ìròyìn Bangla Tribune, Dókítà Gulzar sọ wípé kò sí bí a ṣe lè wo ibà ẹ̀fọn yìí nígbà àkọ́kọ́ tó, kí ó máà tún ṣeni lẹ́ẹ̀ẹkejì.
Ìtúmọ̀ Ìtúnwí-ọ̀rọ̀ Ọlọ́rọ̀ gan-an
Ibà-ẹ̀fọn ti ọdún yìí jẹ́ tuntun, ó sì yára pa ènìyàn.
Ó sì ń fa àmì ìfòyà.
Ohun tí ó lè fà á lè pọ̀ – ọ̀pọ̀ ni ó kó àìsàn ní ọdún tí ó kọjá, tí wọn kò fura.
Bí ó bá tún tẹ̀ wọ́n ní ẹ̀rìn kejì, sààárè ń sún mọ́ nìyẹn.
Ìròyìn nípa àjàkálẹ̀ àìsàn yìí ń gba gbogbo orí ẹrọ-alátagbà kan tí ó sì ń mú àìbalẹ̀ara àti ọkàn bá ọ̀pọ̀lọpọ̀ àwọn òǹlo ẹ̀rọ-alátagbà.
Shofiq Ahmed pín Túwíìtì kan nípa ìròyìn àìsàn tuntun:
Àwọn dókítà méjì kan náà kú látàrí ibà-ẹ̀fọn, èyí sì ti ń mú kí àwọn ènìyàn ó máa bẹ̀rù.
Ilé-ẹjọ́ Gíga Dhaka ti fi àṣẹ pe Ọ̀gá Àgbà Ètò Ìlera ti ìjọba.
Àwọn tí ó ń kú nh pọ̀ ọ́ sí i.
Ǹjẹ́ ìjọbá ń ṣe tó?
Ojú-ìwé Facebook ti BBC Bangla rọ àwọn òǹkàwée rẹ̀ láti jábọ̀ àwọn ìgbésẹ̀ akin tí àwọn òníṣẹ́ ìlú Dhaka ń gbé láti gbógun ti ẹ̀fọn.
Òǹlò Mohammad Mynuddin jábọ̀ ìfàsẹ́yìn láti ọwọ́ àwọn òṣìṣẹ́ ìjọba láti kápá àjàkálẹ̀ náà:
A ò tíì rí nǹkan.
Òṣìṣẹ́ Àjọ Ìlú kan ti sọ wípé yóò tó ọ̀sẹ̀ mélòó kan kí egbògi ìdáààbòbò tí yó sì dín ẹ̀fọn kù.
Ó yà mí lẹ́nu 🤔🤔
Àwọn kan lérò wípé ìjọba ò mú kiní ibà-ẹ̀fọn ọ̀hún ní kanpá, àwọn ọmọìlú ń lo ẹ̀rọ-alátagbà mú kí àwọn ènìyàn ó mọ̀ nípa kòkòrò náà.
Health Barta gbé fídíò kan sí oríi YouTube tí ó ń ṣe àlàyé lẹ́kùnúnrẹ́rẹ́ ohun tí ó pọn dandan láti ṣe bí èèyán bá ní ibà-ẹ̀fọn:
Ọ̀gọ̀rọ̀ l’ó ń d'orí kọ ẹ̀rọ-alátagbà lọ láti gba ẹ̀jẹ̀ fún àwọn aláìsàn.
Òǹlo Sajid Islam Khan túwíìtì pé òún nílò ẹ̀jẹ̀ fún àbúrò òun tí ibà-ẹ̀fọn ń bá fínra.
Hannan Gazi náà se àgbéjáde tirẹ̀:
Àmì ibà-ẹ̀fọn àti àtiṣe..
Ní àárín-in àjàkálẹ̀ náà, Alákòóso-ìlú Àríwá Dhaka ti fagilé ìsinmi ránpẹ́ àwọn ikọ̀ tí ó ń rí sí pàntí kíkó àti ìgbégidínà àpọ̀si ẹ̀fọn.
Síbẹ̀síbẹ̀, fún ìdáààbò àwọn ènìyàn, ṣíṣe ṣì kú.
Àdàwólulẹ̀ ilé ayé-àtijọ́ ọlọ́dún-un 150 fi àìkáràmáìsìkí ìjọba sí àwọn ibi àjogúnbáa Bangladesh hàn
Ilé àjogúnbá náà di àwópalẹ̀ pẹ̀lú bí Ilé-ẹjọ́ Gíga ṣe pa àṣẹ.
Ẹgẹrẹmìtì “Jahaj Bari” kí ó tó di àdàwólulẹ̀.
Òun ni ilé àkọ́kọ́ àyàgbé ní olú-ìlú Bangladeshi, Dhaka, a kọ́ ọ ní ọdún-un 1870. Àwòrán láti ọwọ́ọ Shakil Ahmed, a fi àṣẹ lò ó.
Ní Dhaka, ilé àjogúnbá ọlọ́gọ́rùn-ún ọdún kan di àdàwólulẹ̀ pátá ní alẹ́ ọjọ́ Ìtunu Àwẹ̀ 5, oṣù Òkúdù 2019.
"Ní nǹkan bíi ọdún-un 1870 ni a kọ́ ilé náà tí ó fẹ́ẹ́ dà bíi ọkọ̀ ojú-omi, tí àwọn ọmọ ìbílẹ̀ ń pè ní ""Jahaj Bari"", òun sì ni ilé àyágbé àkọ́kọ́ ni olú-ìlúu Bangladesh."
Àdàwólulẹ̀ tí a da ilé yìí ti mú kí àwọn ọ̀pọ̀ ènìyàn ó sọ ẹ̀dùn ọkàn-an wọn síta lórí àìbìkítà fún àwọn ilé tí ó jẹ́ ohun ìṣúra Dhaka.
Ìròyìn fi yé wípé àwọn ọmọ ẹgbẹ́ òṣèlú tí ó wà lórí ipò ìyẹn Awami League (AL) gbé ẹ̀rọ tatapùpù wá sí ibẹ̀, wọ́n sì da ilé náà wó.
Àwọn tí ó wá ṣiṣẹ́ náà sọ wípé olóríi àwọn, ọmọ ìgbìmọ̀ ìbílẹ̀ (Dhaka-7) Haji Md. Salim, ti ra ilẹ̀ náà láti fi kọ́ ilé alájà tó pọ̀ sí ibùdó náà.
Bákan náà àwọn alátìlẹ́yìn AL sọ wípé ilé àtijọ́ náà kò sí lóríi àwọn ibi àjogúnbá tí ó wà nínú àkọsílẹ̀.
Ní ọjọ́ 13, oṣù Ògún ọdún-un 2018, Ilé-ẹjọ́ Gíga Dhaka pàṣẹ fún àjọ ìjọba tí ó ń rí sí ètò ìdàgbàsókè ìlú ní ìlànà tìgbàlódé ní Dhaka láti máà wó tàbí tún àwọn ilé àjogúnbá tí ó wà ní olú-ìlú náà tó bíi 2,200 kọ́.
Jahaj Bari wà nínú àwọn ilé àkọ́pọ̀ Waqf (mortmain) tí kò ṣe é tà.
Gẹ́gẹ́ bí alákòóso Bangladesh Waqf Administratioń ṣe sọ, gbígba àṣẹ pọn dandan láti gbé iṣẹ́ sílẹ̀, tà tàbí ṣe àtúnṣe sí ohunkóhun tí ó bá jẹ́ ti Waqf.
Èyí kò rí bí ajàfẹ́tọ̀ọ́ AL náà ti ṣe wí, kò sí ohun tó jọ ọ́, kò sí àṣẹ tí ó ní kí wọ́n tà tàbí wó ilé tí à ń sọ̀rọ̀ọ rẹ̀ yìí.
Nínú oṣùu Ẹrẹ́nà ọdún-un 2019, a gbé ìgbésẹ̀ kan láti da ilé náà wó lulẹ̀.
Urban Study Group, ẹgbẹ́ aṣiṣẹ́ ọ̀fẹ́-tí-kò-ní-èrè tí ó máa ń fi ààbò fún àwọn ohun àjogúnbá Dhaka Àtijọ́ fi ìwé ẹ̀dùn ìdáwọ́dúróo àdàwólulẹ̀ náà ránṣẹ́ sí àwọn tí ọ̀rán kàn, tí ó sì mẹ́nu ba àṣẹ Ilé-ẹjọ́ Gíga.
Síbẹ̀, bí ìwé ìròyìn ṣe jábọ̀, díẹ̀ lára àwọn ọmọ ìbílẹ̀ ń yọ̀ fún àdàwólulẹ̀ ilé náà.
Wọ́n ò mọ̀ pé ilé náà ti di ẹgẹrẹmìtì, ó sì lè wò lulẹ̀ kí ó wó lù wọ́n—tí í ṣe àpẹẹrẹ àìmọ̀kanmọ̀kàn àwọn ènìyàn sí ìpamọ́ ohun àjogúnbá àti àtìlẹ́yìn fún àtúnṣe sí ilé àtijọ́ tí ó wà ní Bangladesh.
Àjogúnbá Ìṣẹ̀lẹ̀ Àtẹ̀yìnwá —ọ̀rọ̀ tí ò jẹ́ mọ́ nǹkan
Ọ̀pọ̀ ènìyàn l'ó fi ẹ̀dùn ọkàn-an wọn hàn nígbà tí wọ́n gbọ́ nípa àmúdipẹ̀tẹ́lẹ̀ ilé náà.
Shuvra Kar kọ sí oríi Facebook:
Ìtúmọ̀ Ìtúnwí-ọ̀rọ̀ Ọlọ́rọ̀ gan-an
Àjogúnbá , ìtàn-ìṣẹ̀lẹ̀-àtẹ̀yìnwá, àṣá jẹ́ ọ̀rọ̀ tí kò já mọ́ nǹkan ní orílẹ̀-èdè yìí!
Òǹkọ̀wé Tania Kamrun Nahar tan ìmọ́lẹ̀ sí ìdí tí kò fi yẹ kí ilé yìí di àdàwólulẹ̀:
Ìtúmọ̀ Ìtúnwí-ọ̀rọ̀ Ọlọ́rọ̀ gan-an
Ilé alájà-mẹ́ta náà “Jahaj Bari” ní àwọn iṣẹ́ ọnà tí ó yàrà ọ̀tọ̀ lára ní ara irin àgbọ́wọ́lé gun àkàsọ̀ .
Iṣẹ́ ọnà aláràbarà ti orí òrùlé ibi ìbojúwòta gígùn.
Ọ̀kanòjọ̀kan ọnà ni ó wà ní ara ilé náà — àwọn àràbarà ọnà abẹ́ àjà àti bẹ́ẹ̀ bẹ́ẹ̀ lọ.
Àwọn òpó ní àwòṣe ọnà ilée ionic àti Corinthian.
Ọnà ara ilé náà kọjá àfẹnusọ tí a kò le è rí lára àwọn ilé mìíràn ní àwọn agbègbè àtijọ́ọ Dhaka.
Fún ìdí èyí, kò yẹ kí ilé náà di àdàwólulẹ̀.
Ọdún-un 1610 ni Dhaka di olú-ìlúu Bengal, ìyẹn ogójì ọdún sẹ́yìn.
Ní sáàa Mughal àti ìjọba amúnisìn British, ọ̀pọ̀lọpọ̀ ilé tí a kọ́ ni ó ní ìtàn-ìṣẹ̀lẹ̀-àtẹ̀yìnwá àti àjogúnbá ìlú náà kan tí ó rọ̀ mọ́ ọn.
Àmọ́ púpọ̀ nínú àwọn ilé wọ̀nyí ni ó ti wó láti ọjọ́ pípẹ́.
Àwọn tí ó ṣì ń dúró ti di ẹgẹrẹmìtì, èyí á mú kí àwọn kan ó máa lọ (ṣe ayédèrú ìwé láti) gbẹ́sẹ̀ lé ilé wọ̀nyí.
Àpẹẹrẹ kan ni Bara Katra, àrágbáramúramù ilé tí ó ní ìtàn-ìṣẹ̀lẹ̀-àtẹ̀yìnwá tí Mir Abul Qasim, Diwan (alága ètò ìṣúná) ti ó jẹ́ ọmọba Shah Shuja Mughul kọ́ ní nǹkan bíi 1644 àti 1646.
Ó jẹ́ nǹkan ìbànújẹ́ wípé ilé náà ti ṣe tán, ó lè wó nígbàkigbà látorí àìṣàtúnṣe, àìkáràmáìsìkí ohun àjogúnbá, àti ìbàjẹ́ tí àwọn tí ó gbé ilé láì gba àṣẹ ń fà.
Bara Katra, àwòṣe ilé kíkọ́ ìbílẹ̀ Àárín gbùngbùn Asian caravanserais ni a fi kọ́ ọ, ó sì ní ọwọ́ọ àwòṣe Mughal náà.
Ragib Hassan ni ó ní àwòrán ní oríi Wikipedia. CC BY 2.5
Muntasir Mamun ti kọ àìmọye ìwé lóríi ìtàn-ìṣẹ̀lẹ̀-àtẹ̀yìnwá àti àjogúnbá ìlúu Dhaka.
Ó kọ sínú ìwé ìròyìn ìbílẹ̀ẹ Bhorer Kagoj:
Ìtúmọ̀ Ìtúnwí-ọ̀rọ̀ Ọlọ́rọ̀ gan-an
Mo ti rawọ́ ẹ̀bẹ̀ sí àwọn aláṣẹ fún ogójì ọdún tí ó kọjá láti gba àwọn ilé àjogúnbá bíi Bara Katra àti Choto Katra sílẹ̀ lọ́wọ́ àwọn tí ó fẹ́ pa ìtàn àtẹ̀yìnwá rẹ́.
Ṣùgbọ́n kò sí ẹni tí ó dá mi lóhùn.
Kí ni ká sọ? Nígbà tí ẹ̀ka tí ó ń ṣe àkópamọ́ sítám̀pù ti wo ògiri àtijọ́ àmọ̀káyée Lalbagh Fort láti fi ṣe àyè ìgbọ́kọ̀sí.
Báwo ni a ó ṣe dojú ìjà kọ ìwà òmùgọ̀?
Ilé oníròyìn orí-ayélujára kan ti ṣe àtẹ̀jáde àbájáde ìwádìí tí ó jinlẹ̀ nípa àìkáràmáìsìkí ìjọba lóríi àwọn ilé àjogúnbá àti àwọn alẹ́nulọ́rọ̀ tí ó ń gbìyànjú láti da àwọn ilé tí ó kù wó:
Ìtúmọ̀ Ìtúnwí-ọ̀rọ̀ Ọlọ́rọ̀ gan-an
Ilé tí ó wà ní ipò.14 ní orí ìwé àkọsílẹ̀ àjogúnbá ti di wíwó.
Apá kan lára àwọn ilé àwòṣífìlà tí ó wà ní Sutrapur kò ṣe é rí mọ́n.
Iṣẹ́ àtúnṣe sí àwọn àjogúnbá ìgbàa Mughal ní mọ́ṣálááṣí Bangshal Mukim Bazar Jam-e àti mọ́ṣálááṣí Siddique Bazar Jam-e ti di ohun ìgbàgbé nítorí ojú àpá ò le è jọ ojú ara, ó ti yàtọ̀.
Àmọ́ ṣá, ó ní àṣẹ ìjọba tí ó fi ààbò bo àwọn ilé àjogúnbá, àwọn agbèfúnjọba ti agbègbèe Rajdhani Unnayan Kartripakkha àti Àjọ Ìlúu Dhaka kò ṣe ohun tí ó yẹ kí wọn ó ṣe.
Àìṣojúṣe wọn ni ó fà á tí àwọn olóṣèlú olójúkòkòrò ṣe ń gba àwọn ilé àtijọ́ tí wọ́n sì ń dà wọ́n wó lulẹ̀.
Ẹgbẹ́ Urban Study ti ṣe àgbékalẹ̀ ìwọ́de àti àkójọ àwọn ènìyàn tí yóò fi ẹ̀hónú àdàwólulẹ̀ wọ̀nyí hàn.
Bẹ́ẹ̀ náà ni wọ́n gbèrò láti ṣe ìkéde nípa ìdààbò bo àwọn ilé àjogúnbá tí ọ̀rán kàn.
Àwòrán ìsàlẹ̀ yìí ni àwọn ilé àjogúnbáa Bangladeshi tí àdàwólulẹ̀ ń bá:
Ilée Zamindar àtijọ́ kan ní Nazira Bazar ní agbègbèe Àtijọ́ọ Dhaka ti ń di wíwó lulẹ̀. Àwòrán láti ọwọ́ọ Shakil Ahmed. A lò ó pẹlú àṣẹ.
Aàfin Nimtali, òun ni ibùgbé Gómìnà Dhaka ní ayée Ìjọba Mughal.
Ìloro àbáwọlé ìwọ̀-oòrùn-un ààfin náà nìkan ló ṣì ń dúró.
Àwòrán láti ọwọ́ọ Shakil Ahmed, a lò ó pẹlú àṣẹ.
ShankhaNidh Èyí ni ilé ọgọ́rùn-ún ọdún sẹ́yìn mìíràn ní Dhaka.
Láìsí àmójútó, ilé yìí ṣì dúró.
Àwòrán láti ọwọ́ọ Shakil Ahmed. A lò ó pẹlú àṣẹ.
Northbrook Hall tàbí Lal Kuthi – Fritz Kapp ni ó ya àwòrán yìí ní ọdún-un 1904.
Ilé yìí ṣì ń dúró lónìí.
Oríi Wikipedia ni àwòrán yìí wà. Ojú Òde
China fi ọwọ́ọ ṣìnkún òfin mú ayàwòrán eré orí ìtàgé nítorí pé ó tún àwòrán ìgò ọtí-líle kan tí ó ń tọ́ka sí Ìpanìyànnípakúpa Tiananmen pín
Àwọn ìgòo Baijiu ń ṣe ìrántí ìpànìyànnípakúpa Tiananmen náà.
Jennifer Creery ni ẹni tí ó kọ ìròyìn yìí, tí Ilé Iṣẹ́ Atẹ̀wé Olómìnira Hong Kong sì tẹ̀ ẹ́ jáde ní ọjọ́ 24 oṣù Èbìbí ọdún-un 2019.
Ohùn Àgbáyé ṣe ẹ̀dàa ìròyìn náà ní abẹ́ ìtọwọ́bọ̀wé àjọṣe pọ̀ ìkóròyìnjọ.
"Àwọn aláṣẹ ìjọba China ti fi ayàwòrán eré aṣakọ̀sílẹ̀-ìṣẹ̀lẹ̀ Deng Chuanbin sí àtìmọ́lé lẹ́yìn tí ó ṣe túwíìtì àwòrán ìgò ọtí-líle kan tí a sààmìi ""64"" sí lára – tí ó ń tọ́ka sí ọjọ́ burúkú Èṣù gbomi mu Ìpaninípakúpa tí ó wáyé ní Tiananmen Square ní ọjọ́ 4, oṣù Òkúdù ọdún-un 1989."
Ìgò ọtí-líle 64
Ọdún-un 2016 ni a ṣe ìgòo ọtí-líle náà, ìyẹn ní ìrántí ọdún kẹtàdínlọ́gbọ̀n tí ìṣẹ̀lẹ̀ láabi ọjọ́ 4 oṣù Òkúdù wáyé.
"Orúkọ tí a pe ọtí-líle náà ni ""8 wine 64""."
"Bí a ti ṣe ń pe ""wine"" ní èdèe Putonghua náà ni à ń pe ""9""."
"Ààmì ara ìgò náà ní àwòrán ""Ọkùnrin ọkọ̀-ogun"" tí a kọ ""Máà ṣe gbàgbé, máà ṣe sọ̀rètí nù""."
Ó sì tún fi han gbangbagbàngbà pé Beijing ni a ti ṣe ọtíi wáìnì náà tí ó ní ìdá 64 iye ọtí-líle nínú tí ó sì ti wà nílé ìtajà fún ọdún mẹ́tadínlọ́gbọ̀n.
A fi ọwọ́ọ ṣìnkún òfin mú àwọn ọmọkùnrin orílẹ̀ èdèe China mẹ́rin, Fu Hailu, Zhang Jinyong, Luo Fuyu àti Chen Bing, ní ọdún-un 2016 fún ìṣẹ̀lẹ̀ ìgò ọtí-líle tí a sì fi ẹ̀sùn-un “rírú ìṣẹ́po agbáraiìlú sókè”.
Ìgbẹ́jọ́ Fu, Zhang àti Luo's wáyé ní ibìkan ní Ilé-ẹjọ́ Àwọn Ènìyàn Agbedeméjì Chengdu nínú oṣù Igbe.
Ọ̀kọ̀ọ̀kan wọn gba ìdájọ́ ìgbà ọdún mẹ́ta ní ẹ̀wọ̀n pẹ̀lú ìdádúró ọdún mẹ́rin sí márùn-ún.
Nítorí pé Chen kò gbà wípé òun dá ẹ̀ṣẹ̀, ó sì wà lábẹ́ẹ ṣìgún òfin.
Pẹ̀lú ìdádúró ìránlẹ́wọ̀n, àwọn mẹ́tẹ̀ẹ̀ta ṣì wà lábẹ́ ìṣọ́:
Ìfọwọ́ọ ṣìnkún òfin múni nítorí àtúnpín túwíìtì
Ní ìpalẹ̀mọ́ ìsààmì ọgbọ̀n ọdún tí ìṣẹ̀lẹ̀ ọjọ́ 4, ayàwòrán eré orí ìtàgé Deng Chuabin ti di ẹni tí ọ̀rọ̀ ìgò ọtí-líle 64 ń dá sẹ̀ríà fún lọ́wọ́lọ́wọ́.
Ọlọ́pàá Sichuan fi ọwọ́ọ ṣìgún òfin mú Deng ní ilée rẹ̀ ní Yibin ní ọjọ́ Ẹtì tí ó kọjá, lẹ́yìn wákàtí díẹ̀ tí ó ṣe àtúnpín àwòrán-an Twitter kan tí ó jẹ́ ti ìgò ọtí-líle 64, gẹ́gẹ́ bí Iléeṣẹ́-tí-kìí-ṣe-tìjọba, Adáààbòbo Ẹ̀tọ́ Ọmọ ènìyàn ti China (CHRD).
Ayàwòrán náà gba ìpè àwọn ọlọ́pàá lẹ́yìn-in ọgbọ̀n ìṣẹ́jú lẹ́yìn tí ó túwíìtì àwòrán náà pẹ̀lú wípé lẹ́sẹ̀kẹsẹ̀ ni ó mú un wálẹ̀, bẹ́ẹ̀ ni CHRD ṣe ti sọ.
Àwọn ọlọ́pàá fi agbára gba ẹ̀rọ ìbánisọ̀rọ̀ alágbèéká mẹ́ta, ẹ̀rọ ayárabíàṣá kọ̀mpútà kan, ẹ̀rọ ayárabíàṣá àgbélétan kan, iPad, ike pélébé ìrántí àti ẹ̀rọ ayàwòrán kékeré kan nígbà tí wọ́n wá sí ilée rẹ̀.
Deng ti wà ní Àtìmọ́lé Agbègbè Nanxi nítorí wípé “ó ń bá ìjà bọ̀” – ẹ̀sùn tí wọ́n sábà máa ń kà mọ́ àwọn ènìyàn tí ó ń takò ìjọba lẹ́sẹ̀.
CHRD sọ wípé fún wákàtí kan gbáko, àwọn ọlọ́pàá padà láti yẹ ilée Deng wò, wọ́n sì kó àwọn ẹ̀rọ lóríṣiríṣi:
18 people are talking about this
Ọ̀rọ̀ tí ó ń lọ nípa #Deng Chuabin: Ní ọjọ́ 20 oṣù Èbìbì ọdún-un 2019: Àwọn ọlọ́pàá àgọ́ọ Peizhi ránṣẹ́ sí bàbáa Deng.
Àwọn kan tẹ̀lée padà sílé, wọ́n sì ya àwòrán nínú ilée wọn.
Wọ́n tú yàráa Deng Chuabin wò fún bíi wákàtí kan, wọ́n sì gbé ẹ̀rọ 20 àti agbaná sí ara ẹ̀rọ.
Wọ́n tún ṣe bẹ́ẹ̀, wọ́n mú okùn ìkòkò ìse-ìrẹsì.
Ní ọjọ́ 21, àwọn ọlọ́pàá sọ fún àwọn òbíi Deng láti máà gba agbẹjọ́rò fún un.
Deng, tí a tún mọ̀ sí Huang Huang, tí ó jẹ́ ayàwòrán aládàádúró tí ó ti bá òǹyàwòrán Beijing, Ai Weiwei ṣiṣẹ́ papọ̀.
Ó sọ wípé òun ti ní ìdojúkọ ìjọba, pẹ̀lú àtìmọ́lé ní ọdún-un 2015 láti dénà dè é kí ó máà lọ sí ìdánilẹ́kọ̀ọ́ ẹ̀tọ́ ọmọnìyàn ní Geneva.
Oṣù tí ó ń bọ̀ ni ó sààmì ọgbọ̀n ọdún tí ìpaninípakúpa Tiananmen Square wáyé.
Lọ́dọọdún, àwọn aláṣẹ China fi ọwọ́ agbára mú ìrántí ìṣẹ̀lẹ̀ náà, tí wọ́n sì fi àwọn agbọ̀rọ̀dùn sí àtìmọ́lé.
Ojúṣe láti ṣe ìrántí: ọgbọ̀n ọdún lẹ́yìn Tiananmen
Òǹyàwòrán ọmọ bíbí Taiwan Shake ni aṣàgbékalẹ̀, àwòrán Ọkùnrin Ọkọ̀ Ogun tí ó wà ní àárín gbùngùn-un Taipei ni ìmísí àgbékalẹ̀ náà.
Filip Noubel ni ó ya àwòrán èyí, a fi àṣẹ lò ó.
Ó ti tó 30 ọdún sí ìgbà ìgbérí sókè àti ìṣubú Ẹgbẹ́ Olóṣèlú Ìjọba Àwa-ara-wa 89 (八九民运) ní China tí ó kóra jọ di Ìpaninípakúpa Gbàgede àìlókìkí Tiananmen Square ní ọjọ́ 4 oṣù Òkúdù, 1989.
Ní ọjọ́ yẹn, ikọ̀ ogun orílẹ̀-èdè China ṣíná bolẹ̀ fún àwọn akẹ́kọ̀ọ́ tí ó ń ṣe ìwọ́de ìfẹ̀hónúhàn àtúnṣe ètò ìjọba àwaarawa.
Àjọ Alágbèélébùú Pupa ní yóò tó ọmọ orílẹ̀ 2,700 tí wọ́n pa, àmọ́ àwọn mìíràn nípé ó jù bẹ́ẹ̀ lọ.
Àkọpamọ́ kan tí ó jẹ́ ti ìjọba US jábọ̀ ní ọdún-un 2014 wípé àyẹ̀wò tí ó wáyé nínú China sọ wípé yóò fẹ́rẹ̀ẹ́ tó ọmọ orílẹ̀ 10,454 tí wọ́n pa.
Ẹgbẹ́ Olóṣèlú The Communist Party ti China kò fi ìgbà kan sọ ọ́ ní gbangba rí wípé òún mọ̀ wípé ìṣẹ̀lẹ̀ wọ̀nyí ṣẹ̀ tàbí ṣe ìwádìí fínnífínní síwájú sí i.
Kò sí ìtọ́ka kankan sí Ẹgbẹ́ Olóṣèlú Ìjọba Àwa-ara-wa 89 nínú ìwé àkọsílẹ̀ ìṣẹ̀lẹ̀ àtẹ̀yìnwá kankan, àwọn ọmọ ilé ìwé tí ó ga jù lọ ní China kò gbọ́ nípa ìpaninípakúpa náà, kò ta sí wọn létí rí.
Ohùn Àgbáyé ti ń jábọ̀ ìròyìn lórí ìṣẹ̀lẹ̀ yìí fún ọdún mẹ́wàá.
Ní ọdún yìí ni a sààmì ọgbọ̀n ọdún ohun tí ó fa sábàbí ìpaninípakúpa ọjọ́ 4 oṣù Òkúdù àti láti ṣe ojúṣe wa láti rán àwọn ènìyàn létí, pẹ̀lú gbogbo ọ̀nà àgàbàgebè tí Beijing ń gbà láti fi eérú bo òtítọ́ mọ́lẹ̀.
Ìpinnu Beijing kò ju láti pa ohun gbogbo tí ó bá tan mọ́n ìṣẹ̀lẹ̀ ọjọ́ 4 oṣù Òkúdù rẹ̀ lórí ayélujára.
Ní oṣù Igbe, ìpolówó òkè òkun kan tí ó ní àwòrán Ọkùnrin Ọkọ̀ Ogun fọ́nká sí orí ẹ̀rọ alátagbà orílẹ̀ èdèe China kí a tó mú un wálẹ̀.
Òmíràn nínú àwọn ìròyìn-in wa ṣàlàyé bí àwọn ọmọ orílẹ̀ èdèe China tí ó wà lórí ayélujára ṣe máa ń fi ìpalẹ́numọ́ ṣeré àti wá ọ̀nà àrà tí wọ́n máa ń gbà sọ nípa ìṣẹ̀lẹ̀ náà láì dárúkọ rẹ̀, bí wọ́n bá sì fi ọwọ́ọ ṣìgún òfin mú wọn, ìjìyà ojú ẹsẹ̀ tí ó kọjáa kékeré ni onítọ̀hún yóò jẹ ní agodo ọba.
Èyí ni àyíká tí ó mú ìkóròyìnjọ nira àti di ohun tí kò ṣe é ṣe nítorí gbogbo ìròyìn ní láti gba Asẹ́ Ńlá ìpalẹ́numọ́ orílẹ̀ èdèe China kọjá.
Bẹ́ẹ̀ náà ni ìfojúṣùnnùnkùn wo ọ̀rọ̀ lórí ẹ̀rọ alátagbà ní ẹ̀yin odi orílẹ̀ èdèe China náà mú ewu tirẹ̀ lọ́wọ́, gẹ́gẹ́ bí o ti ṣe kà nínú ìròyìn yìí.
Àtìmọ́lé àti ifipámúni ni èrè ẹ̀ṣẹ̀ ẹni tí ó bá sọ èròńgbà tirẹ̀ tí ó yàtọ̀ sí ti Ẹgbẹ́ olóṣèlú ìjọba, bí a ṣe ṣàpèjúwe níbí.
Irú ìpalẹ́numọ́ onísànánjúpa Beijing báwọ̀nyí ti ń kárí ayé, títí kan Hong Kong.
Síbẹ̀ ojúṣe láti rántí kò dẹ́kun fífi ìmísí sí ọkàn àwọn ènìyàn àti àwọn ọmọ orílẹ̀ èdè káàkiri àgbáyé.
Àwọn tí ìṣẹ̀lẹ̀ náà ṣe ojúu wọn fọ ohun tí ó ń gbé wọn lọ́kàn síta nínú ìfọ̀rọ̀wọ́rọ̀, bí àwọn akọni òǹkọ̀ròyìn ní Hong Kong ṣe ń kọ ìròyìn nípa ọjọ́ 4 oṣù Òkúdù.
Níṣe ni Hong Kong kún fún àwòrán ìdánimọ̀ ẹgbẹ́ náà, òrìṣà abo ti Àwaarawa ní ìta gbangba.
Ní Taiwan, àgbékalẹ̀ẹ ọnà alágbára kan tí a gbé sí àárín gbùngbùn Taipei ń ṣe ìrántí àwọn ìṣẹ̀lẹ̀ ọdún-un 1989.
Àwọn ọmọ orí ayélujára Àgbáyé, títí kan àwọn tí ó ń lo Reddit, náà ń lo ẹ̀fẹ̀, ọnà àti àwòrán orí ayélujára tí a fi àyọkà sínúu rẹ̀ rán ni létí nípa ìjàgbara ọ̀rọ̀ ìjọba àwaarawa.
‘Ohùn-un Jamaica fún Àyípadà Ojú-ọjọ́’ fi orin jíṣẹ́ẹ wọn
Àwòrán láti fídíò oríi YouTube “Ohùn fún Àyípadà Ojú-ọjọ́ fún Ẹ̀kọ́ Àyípadà Ojú-ọjọ́ – Ìpolongo ọdún 2019,” tí Panos Caribbean tẹ̀ jáde.
Iléeṣẹ́ náà ti ṣe ìfilọ́lẹ̀ ìpolongo ìkéde àyípadà ojú-ọjọ́ ní agbègbè mẹ́rin ní àárín-in Jamaica: Rocky Point àti Lionel Town ní ẹ̀ka ìlúu Clarendon, Ridge Red Bank ní St. Elizabeth àti White River ní St Ann.
Bí orin reggae àti dancehall ṣe ń lọ ni àwọn ìpolongo tí ó ń sọ nípa ohun gbogbo láti ọṣẹ ìfọṣọ àbùfọ̀ sí oúnjẹ àsèsílẹ̀, orin ni ènìyán lè gbà dé ọkàn ọmọ Jamaica — èyí ló mú Panos Caribbean, ẹni tí ó ní ilé iṣẹ́ ìròyìn tí kì í ṣe ti ìjọba, láti fi orin kéde nípa ọ̀rọ̀ àyíká.
Iléeṣẹ́ náà ti yege nínúu ìtànká àwọn ìkéde tí ó ṣe kókó nípasẹ̀ẹ iṣẹ́ Ohùn fún Àyípadà Ojú-ọjọ́.
Kedere ni ohùn ń jáde láti inú ilé àpérò ìlú-mọ̀ńká United Nations Conference ní Paris (COP21) lọ́dún-un 2015.
Níbẹ̀, ọ̀kọrin ọmọ Jamaica Aaron Silk darapọ̀ mọ́ àwọn olórin mìíràn — pẹ̀lú eléré Belizean Adrian Martinez — láti ṣe alágbàáwí ìdínkù fún ìgbóná àgbáyé sí ìwọ̀n-ọn ojúàmì 1.5.
Ìfiránṣẹ́ olórin náà, tí ó ṣe àtìlẹ́yìn, ipòo ti ìdásílẹ̀ Ìpínlẹ̀ Erékùṣù Kéékèèké Tí-ó-ń-gòkè, jẹ́ ohun àfiyèsí, tí ó ń ní ipa nínúu ìwé-ìpamọ́ ìkẹyìn-in ti COP21.
Ọdún gorí ọdún, iṣẹ́ “1.5 túbọ̀ ń rinlẹ̀ sí i ní ìlà-oòrùn Caribbean, níbi tí àwọn ọ̀kọrin ti ṣe àlọ́pọ̀ ọ̀rọ̀ akéwì St. Lucian Kendel Hippolyte’s pẹ̀lú orin-in ti wọn láti ṣe àrídájú wípé iṣẹ́ náà dé ibi tí ó yẹ kí ó dé.
Olùyàwòrán agbègbè Sammy Junior, láti Rocky Point, Clarendon (agbègbè tí ìrúsókè-odò ọ̀sà àti àgbàrá ibi tí ó súnmọ́ omi ti kó bá) níbi ìdánilẹ́kọ̀ọ́ tí ó dá lóríi Ìfiṣẹ́ránṣẹ́ Àyípadà Ojú-ọjọ́ ní Jamaica ní ọjọ́ 14 oṣù Ẹrẹ́nà, ọdún-un 2019.
Àwòrán-an Emma Lewis, pẹ̀lú àṣẹ ni a fi lò ó.
Wàhálà àyípadà ojú-ọjọ́ ní ọdún-un 2019 jẹ́ ohun tí ó nílò àbójútó kíákíá ju ti ìdúnrin lọ, àti ní Jamaica, àwọn ará ìgbèríko tí ó jẹ́ àgbẹ̀, àwọn apẹja ń gbọ́ ìpè itanijí yìí.
Akọrin, ọmọ ilé ìwé àti àwọn aládùúgbò péjọ ní — Kingston, Lionel Town, Ridge Red Bank àti White River — fún ìdánilẹ́kọ̀ọ́ ọlọ́jọ́ mẹ́rin nínúu oṣù Ẹrẹ́nà àti Igbe.
Níbẹ̀, wọ́n fi ẹ̀kọ́ kún ẹ̀kọ́ ìmọ̀ ìtàkùrọ̀sọ àti kọ́ nípa ipa àyípadà ojú-ọjọ́.
Ọ̀rọ̀ orin tí ó lágbára gbérí, ọgbọ́n ń tayọ àti ìrìnàjò ìṣíjú ojú ẹsẹ̀:
Ìtúmọ̀ Ìtúnwí-ọ̀rọ̀ Ọlọ́rọ̀ gan-an
Ìyá Ilẹ̀-ayé ń ké tantan
Nínú igbó kìjikìji níbi tí àwọn igi ń wó sí
Wo òkúta ìsàlẹ̀ òkun, wo ẹja bí ó ṣe kéré
Fún wọn ní àsìkò, jẹ́ kí wọ́n dàgbà àti ga
Àwọn akọrin láti Kingston, Clarendon àti Spanish Town ń ṣiṣẹ́ pọ̀ lóríi ọ̀rọ̀ orin níbi ìdánilẹ́kọ̀ọ́ Ìfiṣẹ́ránṣẹ́ Àyípadà Ojú-ọjọ́.
Àwòrán-an Emma Lewis, a lò ó pẹ̀lú àṣẹ.
Pẹ̀lú ìfilọ́lẹ̀ẹ Panos fún àkòrí orin tuntun fún Caribbean fún Àyájọ́ Ilẹ̀-ayé, ẹgbẹ́ẹ Jamaica náà ti ṣe tán láti ṣe eré ní iléèwé àti ní àdúgbò, láì yọ Kàwé Jákèjádò Jamaica sílẹ̀ àti iṣẹ́ igi gbíngbìn.
Àwọn orin báwọ̀nyí, tí a kọ sí orí ìlú reggae àtijọ́ tí a fi àlùjó kún, ṣe kẹ̀rẹ̀kẹ̀rẹ̀ mi ìgboro:
Ìyá Ìṣẹ̀dá ń kérora fún ìwàláàyè
Bí àwọn iléeṣẹ́ ṣe ń ṣiṣẹ́, ìyá ń ké.
Ìgbà wo ni a óò kọ́ ẹ̀kọ́, tí a ó fi gbọ́n?
Bí omi-dídì ilé ayé ṣe ń yọ́, òkun ń kún.
Pẹ̀lú ìdásílẹ̀ àwọn akọ̀ròyìn-in Reuters, ẹ̀ṣẹ̀ ní òmìnira ọ̀rọ̀ sísọ ṣì jẹ́ ní Myanmar
Akọ̀ròyìn Reuters méjì Wa Lone àti Kyaw Soe Oo rìnrìn òmìnira lẹ́yìn tí a dá wọn sílẹ̀ ní ẹ̀wọ̀n Insein ní Yangon.
Àwòrán àti ọ̀rọ̀ abẹ́-àwòrán láti ọwọ́ọ Myo Min Soe / Irrawaddy náà ń bá Ohùn Àgbáyé ṣiṣẹ́ ìròyìn.
Àwọn ẹgbẹ́ iléeṣẹ́ oníròyìn àti ajà-fún-ẹ̀tọ́ ọmọnìyàn ń ṣe àjọyọ̀ọ ti ìdásílẹ̀ lẹ́wọ̀n-ọn akọ̀ròyìn Reuters Wa Lone àti Kyaw Soe Oo tí ó lò ju ọjọ́ 500 ní àtìmọ́lé fún ipa tí wọ́n kó nínú ìwádìí òfíntótó ìṣẹ̀lẹ̀ ìpanípakúpa àwọn olùgbée Rohingya kan ní gúúsù Myanmar.
Àmọ́ pẹ̀lú ìdásílẹ̀ tí wọ́n dá wọn sílẹ̀, ipò yẹpẹrẹ ni òmìnira ọ̀rọ̀ sísọ ní ìlú náà nítorí wípé ìtìmọ́lé àti ìfìyàjẹ àwọn akọrin, akọ̀ròyìn, àti ajìjàǹgbara ṣì wà síbẹ̀ sẹpẹ́.
Ka àwọn ọ̀ràn ìsàlẹ̀ yìí síwájú:
Ìfẹ̀sùn Ìbanilórúkọjẹ́ kan Irrawaddy Náà
Ẹ̀ka ológun Agbègbè Yangon kọ ìwé ẹ̀sùn-un ìbanilórúkọjẹ́ sí olóòtú èdèe-Burmese U Ye Ni wípé ibùdó-ìtakùn-àgbáyé akọ̀ròyìn náà gbè lẹ́yìn ẹnìkan nínú ìròyìn ìkọlù láàárín-in ọmọ-ogun ìjọba àti àwọn adárúgúdù sílẹ̀ Ọmọ ogun Arakan ní Ìpínlẹ̀ Rakhine tí ó tẹ̀ jáde.
Irrawaddy Náà sọ wípé òun kò ṣe àṣemáṣe ju jíjábọ̀ọ ìwọ̀yáàjà tí ó bẹ́ sílẹ̀ ní sàkání náà láti ìbẹ̀rẹ̀ ọdún-un 2019.
Èsì tí U Ye Ni fún àwọn ọmọ ajagun rè é :
Ó ká mi lára nípé iṣẹ́ẹ wa kò yé ikọ̀ ajagun yékéyéké.
Nínú ìmọ̀ ìjìnlẹ̀ iṣẹ́ ìkọ̀ròyìn ni ó ti fi lélẹ̀ wípé a gbọdọ̀ tànmọ́lẹ̀ sí ìjìyà àwọn ènìyàn ní ibi tí rògbòdìyàn bá wà.
Èròńgbà wa tí a fi tẹ̀lé ìròyìn náà ó ju láti fa àkíyèsí àwọn tí yóò tán ìṣòro sí ìjìyà àwọn ènìyàn.
Àjọṣepọ̀ tí ó dán mọ́nrán ń bẹ ní àárín-in Ohùn Àgbáyé àti Irrawaddy.
Àjùsẹ́wọ̀n fún yẹ̀yẹ́
Ìyẹn bẹ́ẹ̀, àwọn ọmọ ẹgbẹ́ẹ ajótà Ìran Ọ̀kín Thangya márùn-ún di èrò ẹ̀wọ̀n tí ó wà ní Insein títí di ìgbà tí wọn yóò lọ sí ilé ẹjọ́ fún ẹ̀fẹ̀ tí wọ́n fi ológun ṣe. Eré ìtàgé tí ó ní àkójọpọ̀ orin abínibí, ijó àti ewì ni a mọ Thangyat mọ́.
Ẹ̀gbẹ́ alájòótà yìí ti tasẹ̀ àgẹ̀rẹ̀ sí òfin abala 505(a) tí ó ní wípé ọ̀daràn ni ẹni tí ó bá polongo ọ̀rọ̀, àyesọ, tàbí jábọ̀ irúu rẹ̀ pẹ̀lú èrò láti mú kí ikọ̀ ajagun ó máà ka ojúṣe rẹ̀ kún tàbí kùnà láti ṣe ojúṣee rẹ̀.
Ọ̀kan lára ẹni tí a fi ẹ̀sùn kàn, Zeyar Lwin, sọ pé:
Gbogbo ẹ̀sùn tí wọ́n fi kàn wá jẹ́ ti òṣèlú torí ìdí èyí ó yẹ kí wọ́n ṣe àtúnṣe gẹ́gẹ́ bíi ọ̀rọ̀ òṣèlú.
Bákan náà, mo máa sọ wípé gbogbo wa ní láti darapọ̀ mọ́ iṣẹ́ àtúnṣe sí ìwé òfin ọdún-un 2008 tí ó ń lọ lọ́wọ́ nínú ìgbìmọ̀ ìjọba.
Ní tèmi, gbogbo ọ̀ràn yìí pátá yóò jẹ́ yíyẹ̀ lulẹ̀ bí a bá le è ṣe iṣẹ́ àkọ́bẹ̀rẹ̀ ti àtúnṣe sí ìwé òfin.
Zeyar Lwin ń tọ́ka sí ìwé òfin ọdún-un 2008 tí ọ̀pọ̀lọpọ̀ àwọn atúnǹkanká gbàgbọ́ wípé a ṣe é to láti fi agbára fún ìṣèjọba ikọ̀ ajagun pàápàá lẹ́yìn tí alágbáda gba ìjọba.
Aya-eré-ìtàgé aláàárẹ̀ nínú àtìmọ́lé
Ọ̀ràn aya-eré-ìtàgé Min Htin Ko Ko Gyi tún fi ìrísí ìhámọ́ tí a há àwọn akọrin pàtàkì mọ́.
Ìwé ẹ̀sùn tí ọ̀físà jagunjagun kọ nípa àwọn àtẹ̀jáde ‘ìbanilórúkọjẹ́’ tí aya-eré-ìtàgé gbé sí orí Facebook tí ó fà á tí a fi fi òfin mú un.
Min Htin Ko Ko Gyi ni olùdásílẹ̀ iléeṣẹ́ Àjọ̀dún Eré Ajàfẹ́tọ̀ọ́ Iyì Ọmọnìyàn àti ìlúmọ̀nánká alátakò ìlọ́wọ́sí ikọ̀ ajagun nínú òṣèlú.
Àwọn alátìlẹ́yìn-in rẹ̀ ń pè fún ìtúsílẹ̀ẹ rẹ̀ lóríi ẹ̀tọ́ ọmọnìyàn, látàrí wípé a ti yọ àbọ̀ ẹ̀dọ rẹ̀ nítorí àrùn jẹjẹrẹ àti àrùn ọkàn àti ìṣòro kíndìnrín.
Àjọṣe Eré Ẹ̀tọ́ Ọmọnìyàn, tí ó jẹ́ àjọṣepọ̀ àjọ̀dún eré ajàfẹ́tọ̀ọ́ ọmọnìyàn 40 kárí ayé, fi lẹ́tà ṣọwọ́ sí ìjọba:
Gẹ́gẹ́ bí ẹgbẹ́ ajìjàǹgbara àgbáyé tí ọ̀rán kàn, a tọrọ ìdánilójú ìjọba Myanmar láti ríi dájú wípé Abala 66 (d), tí ó yẹ kí ó sún ìtẹ̀síwájú ẹ̀rọ ayárabíàṣá síwájú, tí kò ní jẹ́ lílò fún ìpalẹ̀mọ́ ọmọ ìlúu Myanmar tí ó fẹ́ sọ èròo ọkàn-an wọn àti lọ́wọ́ sí ètò ìṣèlú ìjọba àwa-arawa ní Myanmar.
Lẹ́tà náà tọ́ka sí ti àríyànjiyàn Abala 66(d) tí ó sọ nípa òfin ìbánilórúkọjẹ́ tí àwọn aláṣẹ ń lò láti to fi ẹ̀sùn ìtakò, ìjìjàgbara, àti akọ̀ròyìn.
Ilé ẹjọ́ ìbílẹ̀ kọ ìwé ẹ̀dùn tí Min Htin Ko Ko Gyi kọ fún béèlì. Ìgbẹ́jọ́ọ rẹ̀ tún di ọjọ́ 9, oṣù Èbìbì ọdún-un 2019.
“Kò yẹ kí wọ́n di èrò ẹ̀wọ̀n ní ìbẹ̀rẹ̀.”
A rán Wa Lone àti Kyaw Soe Oo sí ẹ̀wọ̀n ọdún méje fún rírú òfin Ìkọ̀kọ̀ sáà-akónilẹ́rú.
Ilé Ẹjọ́ Àgbà di ìdálẹ́jọ́ tí wọ́n ṣe ní oṣù Igbe tí ó kọjá àmọ́ a dá wọn sílẹ̀ lẹ́yìn ìdáríjì ààrẹ ní àsìkò Ọdún Tuntun ìbílẹ̀ orílẹ̀ èdè náà.
Àwọn ẹgbẹ́ bíi Southeast Asian Press Alliance kí Wa Lone àti Kyaw Soe Oo káàbọ̀ lẹ́yìn-in tí a dá wọn sílẹ̀ àmọ́ wọ́n sọ ìyànjẹ tí ó kojú àwọn akọ̀ròyìn méjèèjì:
Kò yẹ kí wọ́n di èrò ẹ̀wọ̀n ní ìbẹ̀rẹ̀, nítorí wọn kò jẹ̀bi ẹ̀sùn tí wọ́n fi kàn wọ́n.
Nígbàtí a gba ìdàgbàsókè yìí wọlé, ẹjọ́ọ Wa Lone àti Kyaw Soe Oo jẹ́ ẹ̀rí wípé ẹ̀mí àwọn akọ̀ròyìn tí ó ń ṣe àyẹ̀wò sí ìṣèlú wà nínú ewu ìgbẹ̀san òṣèlú.
Àwọn ọmọ ìbílẹ̀ Brazili ra ìpín ìdókòòwò ní iléeṣẹ́ reluwé láti bá a wí fún ìkùnà ojúṣe àyíkáa rẹ̀
Àwọn ọmọ ìbílẹ̀ sọ wípé iṣẹ́ tuntun fífẹ reluwé ń kóbá àwọn ẹranko agbègbè náà àti ààbòo wọn.
Àwòrán: Pedro Biava, tí a fi àṣẹ lò.
Ní ọjọ́ 24 oṣù Igbe, ìpàdé akópìnín Rumo Logística, ìgbìmọ̀ reluwé orílẹ̀ èdèe Brazili, gba àwọn àlejò àìròtẹ́lẹ̀ tuntun: ẹgbẹ́ ẹlẹ́ni márùn-ún ìbílẹ̀ kan tí ó wá láti ẹ̀yà Guarani àti Tupi tí ó ṣẹ̀ṣẹ̀ ra ìpín ìdókòwò mẹ́fà iléeṣẹ́ náà.
Ọ̀kọ̀ọ̀kan wọ́n jẹ́ aṣojú Ilẹ̀ Ìbílẹ̀ tí ìjọba fọwọ́ sí ní gúúsù ìlà oòrùn ìpínlẹ̀ São Paulo tí reluwé akẹ́rù aláàdọ́run ọdún iléeṣẹ́ Rumo ń kó bá, ní ọdún-un 2014, bẹ̀rẹ̀ sí í fẹ̀ sí i.
"Láti san owóo gbà máà bínú fún ìbàjẹ́ tí ìmúgbòòrò sí i ilé iṣẹ́ náà kó bá agbègbèe náà, ìpínlẹ̀ ti fi ẹ̀tọ́ fún iiléeṣẹ́ reluwé náà láti ""kọ́ ilé tuntun, ibùdó ìwúre, afárá, ọgbà àti ra ẹ̀rọ ìṣánko kékeré"" fún àwọn agbègbè náà."
Ó tó bíi ẹgbẹ̀rún márùn-ún ènìyàn tí ó ń gbé jákèjádò Ilẹ̀ Ìbílẹ̀ tí fífẹ̀ reluwé kó bá.
Ṣùgbọ́n àwọn aṣojú ìbílẹ̀ sọ wípé iléeṣẹ́ náà ti kùnà láti ṣe irú ẹ̀tọ́ náà, gẹ́gẹ́ bíi ìròyìn láti ọwọ́ Folha de São Paulo.
Ọ̀fíìsì Abánirojọ̀ Ìjọba Àpapọ̀ jẹ́rìí sí i èyí: 63 nínúu iṣẹ́ àtúnṣe 97 ìwé àdéhùn ìfìmọ̀ṣọ̀kan ti di àpatì.
Ní ọjọ́ 19 oṣù Igbe, àwọn afẹ̀sùnkanni pa á láṣẹ fún Ibama, àjọ ètò àyíká orílẹ̀ èdè Brazili, láti ṣíra dá iṣẹ́ reluwé tuntun náà dúró, wọ́n sì gba ìwé àṣẹ Rumo.
Bákan náà ni wọ́n tún gba àjọ náà níyànjú láti mú kí Rumo ó san owó ìtanràn mílíọ̀nù 10 owóo reais (ìyẹn mílíọ̀nù 2,5 owóo dọ́là orílẹ̀ èdèe US).
Nínúu lẹ́tà tí a kà níbi àpèjọ ọjọ́ 24 oṣù Igbe, àwọn aràpín-ìdókòòwò ìbílẹ̀ náà ṣàlàyé ẹ̀dùn-un ọkàn-an wọn.
Wọ́n ti ṣe àlàyé ìjàmbá tí àwọn ọkọ̀ ojú irin náà ti fà fún ẹranko inú ìgbẹ́ tí ó wà ní agbègbè náà, àti dín àwọn ọmọ ènìyàn lọ́wọ́ láti fọ́n ká sí agbègbè.
"Ní àfikún, wọ́n ti jábọ̀ akitiyan ìtàkùrọ̀sọ wọn pẹ̀lú Rumo, tí wọ́n sì bu ẹnu àtẹ́ lu Àtẹ̀jáde Ìgbéró Ọlọ́dọọdún-un iléeṣẹ́ náà, tí ó sọ pé Rumo ""ń ṣe ojúṣe rẹ̀ bí ó ti tọ́ àti bí ó ti ṣe yẹ, ní ọ̀nà tí ó fa àwọn ọmọ ìbílẹ̀ wọ inú iṣẹ́ ""."
Nígbà tí ó ń bá Pedro Biava ajábọ̀-ìròyìn ìwé ìròyìn Brasil de Fato fọ̀rọ̀jomitoro, Adriano Karai, tí ó wà láti agbègbè Guarani, sọ wípé ìlépa àwọn alájọpín ìdókòòwò ìbílẹ̀ náà ni láti mú kí ohùn-un wọn ó dé etí ìgbọ́ àwọn olùdókòòwò iléeṣẹ́ náà dípòo kí wọn ó jèrè láti ara ìdókòòwò náà (èyí tí wọ́n ra ọ̀kọ̀ọ̀kan-an ní 17 owó reais, tí ó tó bíi 4,30 owóo dọ́là US).
Karai tún ṣe àpèjúwe bí iṣẹ́ẹ fífẹ reluwé tuntun náà ti ṣe kóbá agbègbèe rẹ̀ Tenondé, tí ó wà ní ìlúu Paralheiros:
Ìtúmọ̀ Ìtúnwí-ọ̀rọ̀ Ọlọ́rọ̀ gan-an
Ariwo ọkọ̀ ojú irin náà, tí ó máa ń gbalẹ̀ kan títí lálẹ́.
Àwọn ọmọ ẹranko kì í jẹ́ sí ibi ìdẹ mọ́ bíi tẹ́lẹ̀ .
A kò ní alẹ́ àìláriwo.
Bákan náà ni wọ́n máa ń gbé ọ̀pọ̀lọpọ̀ ọkàn tí ó máa ń dànù káàkiri ilẹ̀, a sì mọ́ wípé oúnjẹ yẹn kì í ṣe ojúlówó, tí àtọwọ́dá ni.
Ẹ̀mí àwa gan-an alára ń bẹ nínú ewu: ọkọ̀ ojú irin náà ń gba ilẹ̀ àjogúnbáa wa kọjá, níbi tí àwọn àpá ẹsẹ̀ àwọn àlejò afẹsẹ̀ rìn tọ́.
A wà nínú ewu ńlá ìjàmbá ikú ọkọ̀ ojú irin, nítorí ọkọ̀ ojú-irin ń pa ènìyàn nínúu ìṣẹ́jú mẹ́wàá mẹ́wàá báyìí.”
Gẹ́gẹ́ bíi ìròyìn Folha, ní àkọ́kọ́, àwọn agbègbè ìbílẹ̀ ti gbèrò pẹ̀lú Rumo wípé kí ó gbé iṣẹ́ àtúnṣe náà fún ìgbìmọ̀ tí ó jẹ́ ọmọ ìbílẹ̀.
Ní ti Ọ́fíìsì Abánirojọ̀, iléeṣẹ́ náà ti kọ́kọ́ gba àbá náà wọlé, ṣùgbọ́n ní kété tí ó di ẹ̀yìn-in ìbò oṣù Ọ̀wẹwẹ̀ ọdún-un 2018 tí ó gbé Ààrẹ Jair Bolsonaro tí kò fi bò wípé òun kórìíra ti ìbílẹ̀ sí orí àlèèfà, àyípadà dé bá ìpinnu ìgbésè ti ó wà nílẹ̀ tẹ́lẹ̀tẹ́lẹ́rí.
Ní ọjọ́ 20 oṣù Belu, Rumo ṣàì dédé fagi lé ìkópa pẹ̀lú àwọn agbègbè ìbílẹ̀, tí kò ì tíì tún yọjú níbi ìpàdé láti ìgbà náà.
Nínú ìtàkùrọ̀sọ pẹ̀lú Folha, iléeṣẹ́ náà sọ wípé òun kò fi ìgbà kan t'ọwọ́ bọ ìwé àdéhùn pẹ̀lú àwọn agbègbè ìbílẹ̀ náà láti gbé iṣẹ́ àtúnṣe náà fún wọn ṣe.
Àpéjọ àwọn alájọpín ìdókòòwò tí ó wáyé lọ́jọ́ 24 oṣù Igbe wá sí òpin láì sí ìpinnu tí ó lórí, àmọ́ àwọn aṣojú Rumo sọ wípé ọ̀rọ̀ ti ìbílẹ̀ náà yóò jẹ́ sísọ nínú ìpàdé ti abẹ́nú tí yóò wáyé nínú oṣù Èbìbì.
Iṣẹ́ àtúnṣe bẹ̀rẹ̀ ní 2014. Àwọn ọmọ ìbílẹ̀ tí ó ń gbé ní agbègbè náà tó bíi 5,000.
Àwòrán: Pedro Biava, pẹ̀lú àṣẹ ni a fi lò ó.
Ìjàgbara Alájọpín-ìdókòòwò
"Àwọn ọmọ ìbílẹ̀ Guarani àti Tupi nìkan kọ́ ni ó ṣe ohun tí a pè ní ""ìjàgbara alájọpín- ìdókòòwò"", tí ó jẹ́ ohun tuntun ní Brazil."
Ní ọdún-un 2010, ẹgbẹ́ Ìmọ́rọ̀-yéni-yékéyéké àwọn tí ọ̀ràn-an Vale náà kàn (Articulação dos Atingidos e Atingidas pela Vale) ra ìpín ìdókòòwò iléeṣẹ́ náà láti lè bá wọn jókòó ní àjọ wọn.
Vale ni ọkàn lára iléeṣẹ́ awakùsà ní àgbáyé, òun sì ni ó ṣe àkóso ìdídò tí ó ba ìlúu Brumadinho jẹ́ nínú oṣùu Ṣẹẹrẹ ọdún-un 2019, tí ó mú ẹ̀mí èèyàn-an 236 lọ (tí 34 ṣì ti di ẹni àwátì).
Ní ọjọ́ 30 oṣù Igbe, ọjọ́ ìpàdé alájọpín ìdókòòwò, àwọn ọmọ ẹgbẹ́ Ìmọ́rọ̀-yéni-yékéyéké lẹ ìwé-àlẹ̀mógiri tí a tẹ orúkọ àwọn tí ó ti re ọ̀run àrìnmabọ̀ mọ́ ara ògiri olú-ilé-iṣẹ́ẹ Vale, gẹ́gẹ́ bí ìwé ìròyìn O Globo ti rò ó.
Nítorí àìdéènà-pa-ẹnu ọ̀ràn tí ó kàn wọ́n gbọ̀ngbọ̀n nínú àwọn ìpàdé wọ̀nyẹn, ó di dandan kí àwọn iléeṣẹ́ náà ó kọ ohun tí àwọn ajìjàgbara náà ń fẹ́ sílẹ̀ nínú ìpàdée wọn.
Obìnrin kan lára àwọn ọmọ ẹgbẹ́ Ìmọ́rọ̀-yéni-yékéyéké, Carolina de Moura, tí òun náà ní ìpín nínú ìdókòòwò Vale, sọ fún O Globo:
Ìtúmọ̀ Ìtúnwí-ọ̀rọ̀ Ọlọ́rọ̀ gan-an
A kò ní dẹ́kun láti máa sọ ohun tí ó ń gbé wa lọ́kàn síta fún aráyé gbọ́.
Iléeṣẹ́ náà gbọdọ̀ lo èrè tí wọ́n bá rí fi tún àwọn odòo wa ṣe àti ṣíṣe àbójútó ẹ̀mí ọmọ ènìyàn.
Ìjọba Tanzania fi Ajìjàgbara Ọmọ Orílẹ̀-èdèe Uganda sí àtìmọ́lé, wọ́n sì lé e kúrò nílùú
Dókítà Wairagala Wakabi [Àwòrán láti CIPESA tí a fi àṣẹ lò]
Wairagala Wakabi, àgbà ọ̀jẹ̀ ajàfẹ́tọ̀ọ́ ẹ̀rọ ayárabíàṣá tí ó wá láti Uganda, di ẹni àtìmọ́lé ní Pápákọ̀ òfuurufú Julius Nyerere International Airport ní Dar es Salaam, Tanzania lọ́jọ́ 25 oṣù Igbe.
A fi ìwé pe Wakabi kí ó wá á sọ̀rọ̀ níbi ètò Àyájọ́ Àwọn Olùgbèjà Ẹ̀tọ́ Ọmọnìyàn ní Tanzania ọlọ́dọọdún tí Àgbáríjọ Olùgbèjà Ẹ̀tọ́ Ọmọnìyàn ti Tanzania (THRDC) jẹ́ olùgbàlejò.
Wakabi ni Olùdarí Àgbà Ìfọwọ́sowọ́pọ̀ Ètò-ìmúlò Ìmọ̀-ẹ̀rọ Gbogboògbò fún Ìlà-Oòrùn àti Gúúsù Ilẹ̀ Adúláwò (CIPESA), ọ̀kan gbòógì nínú ilé-iṣẹ́ tí ó ń ṣe ètò tí ó dá lórí ètò-ìmúlò ẹ̀rọ ayélujára àti òmìnira ọ̀rọ̀ sísọ ní orí ayélujára ní ilẹ̀ Adúláwò.
Lẹ́yìn ọ̀pọ̀lọpọ̀ wákàtí tí a fi ọ̀rọ̀ wá Wakabi lẹ́nu wò, tí wọn kò sì jẹ́ kí ó rí agbẹjọ́rò, a dá a padà sí Uganda.
"Àwọn aṣojú láti Àgbáríjọ Olùgbèjà Ẹ̀tọ́ Ọmọnìyàn gbìyànjú láti jà fún un, àmọ́ a sọ fún wọn wípé fún ""àǹfààní ìlú"" ni a fi dá Wakabi padà sí ìlúu rẹ̀:"
Bí ó ti lẹ̀ jẹ́ pé ìṣẹ̀lẹ̀ náà kò ju wákàtí díẹ̀ lọ, ó mú ìjáyà ńlá bá àwọn ajàfẹ́tọ̀ọ́ ní agbègbè náà, tí ọ̀ràn ìwà àìtọ́ tí orílẹ̀-èdèe Tanzania ń wù sí àwọn ajìjàgbara àti oníṣẹ́-ìròyìn ń peléke sí i.
Nínú oṣù Belu ọdún tí ó ré kọjá, àwọn òṣìṣẹ́ Ìgbìmọ̀ tí ó ń Dáàbò bo Oníṣẹ́-ìròyìn, Angela Quintal àti Muthoki Mumo di ẹni àtìmọ́lé fún ọ̀pọ̀ wákàtí ní Dar es Salaam, Tanzania, tí ìwé ẹ̀rí ọmọ-ìlú-fún-ìrìnnàa wọ́n di gbígbà lọ́wọ́ọ wọn.
"Human Rights Watch sọ wípé lábẹ́ ìṣàkóso ìjọba Ààrẹ John Magufuli Tanzania ti rí ""ìrésílẹ̀ ìbọ̀wọ̀ fún òmìnira ọ̀rọ̀ sísọ, ìkẹ́gbẹ́ àti àpéjọ dé ojú àmì""."
Ní ọdún-un 2015, Orílẹ̀èdè Olómìnira Ìṣọ̀kan Tanzania kéde Ìgbésẹ̀ Ìrúfin Orí Ẹ̀rọ Ayélujára.
Ní àárín ọdún kan tí a kéde òfin yẹn, ó ti tó bí ọmọ orílẹ̀ èdèe Tanzania 14 tí òfín ti mú tí a sì ti dálẹ́jọ́ lábẹ́ òfin fún pé wọ́n sọ̀rọ̀ mọ́ṣààsí sí ààrẹ lórí ẹ̀rọ alátagbà.
Pẹ́pẹ́yẹ gbé ọmọ pọ̀n nínú oṣù Ẹrẹ́nà ọdún-un 2018 nígbàtí a gba Ìlànà Ẹ̀rọ Ayárabíàṣá (Ohun orí ayélujára) àti Ìtàkùrọ̀sọ Ìfìwéránṣẹ́ wọlé tí ó mú un ní túláàsì fún àwọn akọbúlọ́ọ̀gù láti fi orúkọ sílẹ̀ tí wọ́n á sì san owó orí tí ó tó bíi US $900 lọ́dún kí wọn ó tó lè gbé àtẹ̀jáde sí orí ayélujára.
Èyí mú kí ọ̀pọ̀lọpọ̀ búlọ́ọ̀gù aládàádúró ó wọ òkùnkùn.
Ìpalẹ́numọ́ iléeṣẹ́ akọ̀ròyìn aládàádúró nípasẹ̀ àwọn àdàlù ìṣíwèé fún ilé iṣẹ́ akọ̀ròyìn àti ìrókẹ́kẹ́ mọ́ oníṣẹ́-ìròyìn ti di ìdẹ́rùbà, ìkóra-ẹni-ní-ìjánu àti ìbẹ̀rù láti sọ èrò ọkàn ẹni nípa àwọn olórí orílẹ̀ èdè náà.
Àtìmọ́lé àti ìdápadà Wakabi sí Uganda jẹ́ ìtẹ̀síwájú ìdojú-ìjà-kọ òmìnira ọ̀rọ̀ tòun èrò ọkàn ẹni ní Tanzania.
Oníròyìn Orí ẹ̀rọ-alátagbà Luis Carlos Diaz di àwátì ní Venezuela
Níbo ni Luis Carlos wà?
Àwòrán ìpolongo orí ayélujára tí Provea taari síta.
Wọ́n sọ ìgbà tí a pè é kẹ́yìn àti túwíìtì tí ó tẹ̀ kẹ́yìn nínú àwòrán náà.
Ní ìrọ̀lẹ́ ọjọ́ 11, oṣù Ẹrẹ́nà olùfèsì sí ọ̀rọ̀ ìṣèlú Naky Soto tí ó tún jẹ́ aya akọ̀ròyìn àti ajììjàǹgbara iṣẹ́ ìròyìn tí ó jẹ́ ọmọ orílẹ̀ Venezuela, Luis Carlos Díaz túwíìtì pé òun ti ń wá ọkọ òun fún wákàtí márùn-ún.
[Ìròyìn tí ó tẹ̀ wá lọ́wọ́] Àjọ àwọn Òṣìṣẹ́ Ìròyìn (SNTP lédè Spanish) jábọ̀ pé àwọn Agbófinró Ọ̀tẹlẹ̀múyẹ́ Bolivaria (SEBIN) ti fi Luis Carlos sí àtìmọ́lé.
PÀJÁWÌRÌ Àjọ Sebin kan fìdíi rẹ̀ múlẹ̀ pé akọ̀ròyìn Luis Carlos Diaz ti wà ní àhámọ́ àwọn ọlọ́pàá yẹn.
Wọ́n yọ àwọn ohun ìjà ti akọ̀ròyìn Marco Ruiz, Luz Mely Rehes àti Federico Black [pẹ̀lú àwọn ọmọ ẹgbẹ́ òṣìṣẹ́ ìròyìn.
Wákàtí díẹ̀ sẹ́yìn, Soto túwíìtì pé àwọn ti ń wá Luis Carlos Díaz fún wákàtí márùn-ún:
@LuisCarlos wà ní orí kẹ̀kẹ́ẹ rẹ̀, ṣùgbọ́n láti aago 5:30 ni mi kò ti gbúròó rẹ̀ mọ́, bẹ́ẹ̀:
– Kò sí ní ilé iṣẹ́ ìgbóhùnsáfẹ́fẹ́ náà
– Kò sí nílé
– Kò tíì túwíìtì
– Kò gbé ìpèe rẹ̀
– Kò fèsì sí àtẹ̀jíṣẹ́ tàbí iṣẹ́-ìjẹ́ oríi WhatsApp
---‘Boca de Rua': Ìwé ìròyìn ilè brazil láti ọwọ́ àwọn ènìyàn tí ó ń gbé ní ojú òpópónà
Lẹ́yìn ọdún 19, Boca ṣì ń ròyìn nípa àwọn olùgbé títì
Marcos Scher ń ta ìwé ìròyìn náà nínú ìdádúró iná adarí ọkọ̀ kí àjákálẹ́ àrùn ó tó bẹ̀rẹ̀. Àwòrán: Charlotte Dafol/ a gba àṣẹ kí a tó lò ó
Ní ọdún mọ́kàndínlógún sẹ́yìn ní Porto Alegre, ní gúúsù orílẹ̀-èdè Brazil, ìwé ìròyìn kan tí àgbáríjọ àwọn tí wọn ń sun ìta àdúgbò ẹsẹ̀kùkú náà bẹ̀rẹ̀ iṣẹ́ ìròyìn títẹ̀ jáde.
Boca de Rua (Ẹnu Asùnta, tí a tún mọ̀ sí ìwé ìròyìn Boca) jẹ́ ọgbọ́n orí ọ̀wọ́ àwọn akọ̀ròyìn kan láti pèsè ọ̀nà tí àwọn asùnta àdúgbò yìí fi lè máa fi sọ̀rọ̀ fún ara wọn.
Ní ọdún 2000 ni wọ́n bẹ̀rẹ̀ iṣẹ́ àkànṣe yìí, lẹ́yìn ọdún kan lásìkò ìpàdé àkọ́kọ́ Ẹgbẹ́ Àwùjọ Àgbáyé, ni wọ́n ṣe ìfilọ́lẹ̀ àkọ́kọ́já ewé rẹ̀.
Ní òní, ìwé ìròyìn yìí nìkan ni ó jẹ́ ọmọ ẹgbẹ́ Àwọn Ìwé Ìròyìn Ẹsẹ̀kùkú Àgbáyé (INSP) tí àwọn ẹni tí ó ń sùnta ń ṣe jáde.
Àwọn asùnta wọ̀nyí tìkara wọn ni ó pilẹ̀ àwọn ọgbọ́n ìkọ̀tàn, ìfọ̀rọ̀wánilẹ́nuwò àti ti ìbéèrè.
Àwọn akọ̀rọ̀yìn méjì kan tí wọ́n ti ń tì kín àwọn asùnta wọ̀nyí lẹ́yìn láti ìgbà tí iṣẹ́ àkànṣe náà ti bẹ̀rẹ̀ ni wọ́n máa ń ṣe gbogbo àwọn àtẹ̀jáde tuntun.
Ọ̀wọ́ àwọn afínúfẹ́dọ̀ṣiṣẹ́ kan náà máa ń ṣe àtìlẹyìn nípa gbígba ohùn ìpàdé sílẹ̀, níní àwọn ajábọ̀ ìrọ̀yìn níran àwọn ohun tí ó ṣe kókó àti kíkọ ohùn tí a ká sílẹ̀ ní ọ̀rọ̀ sórí èrọ-ayárabíàṣá.
Ìgbàdégbà oṣù mẹ́tamẹ́ta ni ìwé ìròyìn náà ń jẹ́ títẹ̀ jáde.
Àwọn ibi tí Boca na ìyẹ́ dé bèrè lórí ìfìyàjẹ tàbí ìjìyà àwọn tí wọ́n wà ní àárín ojú pópó títí kan àwọn ìròyìn rere mìíràn.
Láàárin oṣù méta, òwọ́ yìí, pinnu àwon ohun tí wọn yóò kọ nípa rẹ̀, wọ́n jáde lọ sí oko ìwádìí, wọ́n fi ọ̀rọ̀ wá àwọn ènìyàn lẹ́nu wò, wọ́n ya àwòrán, wọ́n sì kó àwọn ẹ̀rí jọ fún àwọn ìròyìn wọn.
Àwọn ọmọ ẹgbẹ́ jáde lọ́pọ̀ yanturu fún iṣẹ́ yìí, ó fẹ́rẹ̀ẹ́ tó ènìyàn 50 tí wọn ń ṣiṣẹ́ lórí àtẹ̀jáde kọ̀ọ̀kan ní àpapọ̀ lórí ìwé ìròyìn ẹlẹ́ẹ̀mẹrin lọ́dún yìí.
Lẹ́yìn tí wọ́n bá tẹ ìwé ìròyìn náà jáde tán, àwọn ọmọ ẹgbẹ́ yóò gbá ìpín láti lọ tà ní àárín àdúgbò Porto Alegre, tí èrè yóò sì lọ sí ọ̀dọ̀ àwọn akọ̀ròyìn/atàwé-ìròyìn.
Àtẹ̀jádè yìí tún máa ń rí ìgbọ̀wọ́ láti ọ̀dọ̀ àwọn olólùfẹ́ ìwé ìròyìn yìí, ọ̀pọ̀ nínú wọn ni kò fẹ́ kí orúkọ wọn ó di mímọ̀.
Rosina Duarte, ọ̀kan nínú àwọn tí wọ́n ń ṣẹ̀dá Boca de Rua àti Ilé-ṣẹ́ tí-kìí-ṣe-ti-ìjọba ALICE (Àjọ òfẹ́ fún ètò ìgbéròyìnsíta, ijọ́mọìlú àti ètò ẹ̀kọ́-ìwé) èyí tí ìwé ìròyìn yìí so mọ́ sọ pé ohun tí àwọ́n gbà lérò tẹ́lẹ̀ ni “láti fi ohùn fún àwọn tí ko ní ohùn”.
Ó sọ wí pé, lẹ́yìn èyí ni àwọ́n ṣẹ̀ṣẹ̀ wá rí i pé ìlérò lásánlàsàn ni, nítorí kò sí ìgbà tí àwọn ènìyàn kì í fọhùn, àwùjọ ló kàn kọ̀ láti tẹ́tí sí wọn.
Nínú ìfọ̀rọ̀wánilẹ́nuwò orí ẹ̀rọ-ìbánisọ̀rọ̀ pẹ̀lú Ohùn Àgbáyé, Rosina sọ pé:
Ìtúmọ̀ Ìtúnwí-ọ̀rọ̀ Ọlọ́rọ̀ gan-an
Nígbà tí a bẹ̀rẹ̀, a maá ń lo àwọn ọ̀rọ̀ tí ó lẹ́wà gan-an ni, èyí tí ó mú kí ọ̀pọ̀lọpọ̀ àwọn ènìyàn abẹ́lé ó maa hu ìwà yíyin ẹni láìgba tẹni ọ̀hún” bi mo ṣe lè pè é nìyẹn, tí í ṣe ọ̀nà tí yóò jẹ́ ìrànlọ́wọ́ fún wọn.
Ṣùgbọ́n a rí i pé àwa ni ó yẹ kí a di ọ̀mọ̀wẹ́ èdè àmúlò àwùjọ wọn.
Wọn kò ní ìmọ̀-mọ̀-ọ́n-kọ mọ̀-ọ́n-kọ̀ bẹ́ẹ̀ ni àwa náà kò sì ní òye ìgbéayé àwọn tí wọ́n ń gbé ní títì rárá.
Catarina àti Daniel wọ aṣọ ìbomúbẹnu tí ó ní àmì ìdámọ̀ Boca lára | Àwòrán: Luiz Abreu / a gba àṣẹ kí a tó lò ó
Èrò àwọn akọ̀ròyìn yìí ní ìbẹ̀rẹ̀pẹ̀pẹ̀ ni láti ṣe ìdásílẹ̀ ètò orí rédíò tí wọn yóò sì darí afẹ́fẹ́ ètò náà sórí àwọn gbohùngbohùn tí wọn yóò gbé sí orí àwọn òpó iná ẹ̀bà títì ní àárín ìgboro.
Ṣùgbón nígbà tí wọ́n bá ọ̀wọ́ àwọn ènìyàn kan tí wọn kò tilẹ̀ nílé lórí sọ̀rọ̀, wọ́n ranrí pé àwọn kò fẹ́, ariwo: “A fẹ́ ìwé ìròyìn tí yóò máa sọ nípa wa” ni wọ́n ń pa.
Rosina sọ pé èrò yìí kọ́kọ́ kọ òun lóminú, ṣùgbọ́n ó padà bùṣe gàdà.
Ìtúmọ̀ Ìtúnwí-ọ̀rọ̀ Ọlọ́rọ̀ gan-an
Nígbà tí wọ́n sọ pé àwọn fẹ́ ìwé ìròyìn, a bẹ̀rẹ̀ sí ní wá owó kiri, bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé inú òkùnkùn ni a wà tí a kò sì mọ ohun tí a ó gbámú ṣe.
Sùgbọ́n èyí padà dópin lọ́jọ́ kan: pẹ̀lú bí a ṣe ròyìn ohun tí ó ń lọ ní ojú pópó, wọ́n bẹ̀rẹ̀ sí ní gbé ìròyìn yìí kiri.
Bí wọ́n bá sì ti mọ̀ nípa rẹ̀, ọ̀nà à á gbà di lílà fúnra rẹ̀ nìyẹn.
Ìdí ni pé gbogbo ìgbà ni a máa ń ṣiṣẹ́ lórí ìròyìn.
Àwọn kan ń ṣe é láì fi-igbá-kan-bọ-ìkan-nínú, àwọn kan kò sì náání òtítọ́, ṣùgbọ́n à ń ṣe é.
Nígbà tí ó yá, ìwé ìròyìn yìí di ohun tí a lè pè ní ẹgbẹ́ àwùjọ.
Ẹgbẹ́ náà ń pàdé lọ́sọ̀ọ̀ọ̀sẹ̀ láti jíròrò lórí ìbèèrè fún ẹ̀tọ́ àti àwọn ọ̀nà tí wọ́n lè gbà ran àwọn ọmọ ẹgbẹ́ lọ́wọ́.
Wọ́n tilẹ̀ so pọ̀ mọ́ oríṣìíríṣìí ẹgbẹ́ bí i Movimento Nacional da População de Rua (Àgbáríjọ àwọn ènìyàn ojú u títì lórílẹ̀-èdè) àti Amada Massa (Loving Dough) ilé-iṣẹ́ adínkàrà tí èròǹgbà rẹ jé láti sọ àwọn tí wọ́n ti pẹ́ ní àdúgbo esẹ̀kùkú Porto Alegre di òmìnira ara wọn.
Ní ìbàmu pẹ̀lú àkóónú ìwé ìròyìn náà, Rosina sọ pé:
Ìtúmọ̀ Ìtúnwí-ọ̀rọ̀ Ọlọ́rọ̀ gan-an
Ó fara jọ ìyà ni kì í ṣe ìyà, ó fojú jọ ìṣòro ni kì í ṣe ìṣoro.
A ti ṣàwárí ayọ̀ yìí, ìtakò yìí, nínú rẹ̀ bẹ́ẹ̀ ni a mọ rírì agbára dáradára tí kò jẹ́ kí ó kú, kì í ṣe pé ti àìkú rẹ̀ nìkan bíkò ṣe mímú ìrètí, ayọ̀ àti àwọn ohun mìíràn tí ó ti wà pẹ̀lú rẹ̀ wà láàyè.
Ohùn láti àdúgbò ẹsẹ̀kùkú
Nínú ìfọ̀rọ̀wánilẹ́nuwò orí ẹ̀rọ-ìbánisọ̀rọ̀ pẹ̀lú Ohùn Àgbáyé, Elisângela Escalante, tí ó dara pọ̀ mọ́ ẹgbẹ́ náà ní ọdún mẹ́fà sẹ́yìn nígbà tí òun náà ń sun ìta tẹnumọ́ ipa tí ìwé ìròyìn náà ti kó nínú ayé òun.
Ìtúmọ̀ Ìtúnwí-ọ̀rọ̀ Ọlọ́rọ̀ gan-an
Mẹ́wàá ṣẹlẹ̀ sí mi láti ara ìwé ìròyìn yìí.
Òhun ni kò jẹ́ kí n sun ìta mọ́.
Ìdí ni pé ìta ni mò ń sùn fún odidi ọdún mẹ́ta àti ààbọ̀, mi ò sì sun ìta mọ́ lẹ́yin bí oṣù mélòó kan tí mo dara pọ̀ mọ́ ìwé ìròyìn yìí.
Mo bẹ̀rẹ̀ sí ní fi owó pamọ́ láti gba ilé tí èmi náà yóò máa gbé.
Tẹ́lẹ̀, mi ò ní ọ̀nà ìpawówọlé kankan, ọkọ mi ni mo máa ń wojú rẹ̀ fún ohun gbogbo.
Ó yí ayé mi padà torí èmi pẹ̀lú fẹ́ ní owó ti ara mi.
Ojúewé ìta ìtẹ̀jáde tí ó ṣe àgbéyẹ̀wò ìpèníjà tí ó ń kojú àwọn ìyá tí ó ń gbé ní títì.
Àwòrán: Agência ALICE/Boca de Rua, a gba àṣẹ kí a tó lò ó.
Elisângela rántí ọ̀kan pàtó nínú àwọn àtẹ̀jáde ìgbàdégbà wọn èyí tí àkọ́lé òke rẹ̀ jẹ́: “Kí ló dé tí a ò le jẹ́ ìyá?
Àtẹ̀jáde yìí sọ̀rọ̀ lórí ìṣòro tí àwọn obìnrin tí ó ń tọ́ ọmọ ní ojú òpópónà ń kojú.
Elisângela sọ pé: Nígbà tí a ń ṣe èyí lọ́wọ́ àwọn tí wọ́n jẹ́ ìyá nínú àwọn ọmọ ẹgbẹ́ gbìyànjú láti kàn sí àwọn ọmọ wọn tí wọn kò bá sọ̀rọ̀ láti àìmọye ọdún sẹ́yìn.
Ìtúmọ̀ Ìtúnwí-ọ̀rọ̀ Ọlọ́rọ̀ gan-an
Mo lérò wí pé òtítọ́ ni ohun tí a sọ [ìyẹn nínú ìwé ìròyìn].
Ó jẹ́ ìrírí àti ohun tí à ń là kọjá ní àárín àwùjọ.
Bí kò bá sí Boca, kò bá tí sí ọ̀nà mìíràn tí n ó gbé èyí gbà tí ọ̀pọ̀ ènìyàn ó sì gbọ́ mi tó báyìí.
Pẹ̀lú rẹ̀ mo jẹ ọ̀pọ̀ àǹfààní, mo sì ṣe ìrànlọ́wọ́ fún ọ̀pọ̀ ènìyàn bákan náà.
Fún ìgbà àkọ́kọ́ nínú ìtan, ìwé ìròyìn yìí di èyí tí a kò le tà ní àárín àdúgbò látàrí àjàkálẹ̀ àrùn COVID-19.
Nínú akitiyan láti ṣe ìgbésókè sí owó tí ó ń wọlé fún àwọn ajábọ̀ ìròyìn, Boca de Rua ti gbé aṣọ tuntun wọ̀, ó ti bọ́ sórí ẹ̀rọ ìgbàlódé fún kíkà lórí ẹ̀rọ ayélujára.
Pẹ̀lú ìdáwójọ iye òwó tí ó tó 20BRL owó ilẹ̀ Brazil (tí ó ń lọ bi 3.75 owó dọ́là ilẹ̀ America) ní osù mẹ́tamẹ́ta àwọn ọ̀nkàwé máa ń rí àyè ka àgbéjáde Boca tuntun náà, tí ó fi mọ́ ti tẹ́lẹ̀ àti àwọn nǹkan mìíran.
Ohun tí ó ṣe pàtàkì jù fún àwọn aládàásí àti àwọn ajábọ̀ ìròyìn ni pé ohùn àwọn tí ó fi títì ṣe ibùgbé ń di gbígbọ́ ketekete síbẹ̀ ní àsìkò àjàkálẹ̀ àrùn yìí.
Nínú ìtàkùrọ̀sọ orí ẹ̀rọ-ìbánisọ̀rọ̀ nípa ohun tí ó rí sí ìwé ìròyìn náà, Marcos Sher, ọmọ ọdún 13 tí ó jẹ́ ògbóntarìgì Boca sọ báyìí pé:
Ìtúmọ̀ Ìtúnwí-ọ̀rọ̀ Ọlọ́rọ̀ gan-an
Ní tèmi ó dára, ó dára gidi ni.
Ẹ̀yín náà rí i pé èmí náà kò gbé e tì, àbí irọ́ ni mo pa?
Nígbà mìíràn mo máa ń pa á tì, ṣùgbọ́n mà á tún bẹ̀rẹ̀ rẹ̀ padà níbi tí mo fi tì sí.
Ní tèmi, ìwé ìròyìn yìí jẹ́ ọ̀nà láti bọ́ kúrò nínú oògùn olóró gbígbé ó sì dá mi padà sí ẹnu iṣẹ́.
Ó dára nítorí pé ènìyàn ń rí nǹkan ṣe tí ènìyàn bá kúrò nílé.
Rírí nǹkan máa ṣe bí iṣẹ́ ṣe pàtàkì sími púpọ̀.
Ìfiyèsí olóòtú: Talita Fernandes ń ṣiṣẹ́ pẹ̀lú ìwé ìròyìn Boca de Rua (Porto Alegre, Rio Grande do Sul) ó sì kọ àpilẹ̀kọ kan “Ojú títì, ọ̀rọ̀-orúkọ ti ìwà obìnrin: àwọn obìnrin nínú ìgbésẹ̀ àti ìjà-fún-ẹ̀tọ́ sí ti ara ní ìlú”, láti ọwọ́ Ifásitì Ìjọba Àpapọ̀ Rio Grande do Sul (UFRGS).
Àwọn ìdílé l’órílẹ̀-èdè Kenya fi ara kááṣá látàrí ipa ìfọjọ́-kún ilé-ìwé tí ó wà ní títì pa
Kenya tí pa ẹ̀kọ́-ìwé kíkọ́ tì, àlàkalè wọ́n báyìí nílò ìṣàmúlò ẹ̀rọ-ìgbàlódé tí ọ̀pọ̀ kò ní àǹfààní sí.
Ọ̀rọ̀ Olóòtú: Àgbéjádè yìí jẹ́ àjùmọkọ aládàásí Ohùn Àgbááyé Bonface Witaba, aládàásí àlejò Sri Ranjini Mei Hua, aṣèwádìí àti òǹkọ̀wé láti Singapore.
Ní oṣù Èrèlé, ìjọba ilẹ̀ Kenya kéde àfàró àwọn ilé-ìwé ilẹ̀ náà gẹ́gẹ́ bí ọ̀kan nínú àwọn ọ̀nà láti dẹ́kun ìtànkálẹ̀ àrùn COVID-19.
Ìkéde yìí da àwọn àlàkálẹ̀ ẹ̀kọ́ ní àwọn ilé-iwé ilẹ̀ náà rú, léyìí tí ó ṣe àkóbá fún ẹgbẹẹgbẹ̀rún 18 àwọn akẹ́kọ̀ọ́ jákèjádò orílẹ̀-èdè náà.
Ó gbégi dínà ìtẹ̀síwájú sísọ ètò-ẹ̀kọ́ di tọ́rọ́ fọ́n kálé, ìdọ́gba àti ètò-ẹ̀kọ́ tó mọ́nyánlórí gẹ́gẹ́ bí ó ṣe wà nínú Àgbéṣe 4 ti Ìgbéró Ìlépa Ìdàgbàsókè Àjọ Ìsọ̀kan Àgbáyé.
Lára àwọn ìgbìyànjú wọn láti rí i pé ẹ̀kọ́kíkọ́ ń tẹ̀síwájú bí wọ́n ṣe ń dáàbò bo ìlera, ìgbéláìléwu, àti ìgbáyégbádùn àwọn akẹ́kọ̀ọ́ àti olùkọ́, ni Ilé-iṣẹ́ Ètò-ẹ̀kọ́ ilẹ̀ náà pẹ̀lú àjọṣepọ̀ àwọn àjọ elétò ẹ̀kọ́ mìíràn ṣe ìdásílẹ̀ Àjọ elétò ẹ̀kọ́ ìpìlẹ̀, abetíwéré sí ìṣẹlẹ pàjáwìrì COVID-19 ti ilẹ̀ Kenya pẹ̀lú èròǹgbà láti mú ìdàgbàsókè bá ẹ̀kọ́ àtẹ̀yin yàrá ìkẹ́kọ̀ọ́ kọ́ pẹ̀lú ìṣàmúlò ẹ̀rọ asọ̀rọ̀mágbèsì, amóhùnmáwòran, ìgbéṣẹ́ sórí àwọ̀-sánmà, àti àwọn ẹ̀rọ ìbánisọ̀rọ̀ ìléwọ́ alágbèéká.
Ní ọ̀ní, pẹ̀lú akitiyan Àjọ tí o ń mú ìdàgbàsókè bá àlàkalẹ̀ ètò-ẹ̀kọ́ ní ilẹ̀ Kenya (KICD) láti fẹ ìkẹ́kọ̀ọ́ orí ẹ̀rọ ayárabíàṣá lójú sí i, ìdá 80 àwọn akẹ́kọ̀ọ́ ni àwọn tí kò rí àǹfààní ẹ̀kọ orí afẹ́fẹ́ yìí jẹ síbẹ̀, gẹ́gẹ́ bí èsì ìwádìí tí Àgbéṣe Usawa gbé jáde (gbàgede ajẹmẹ́kọ̀ọ́ orí ẹ̀rọ-ayélujára).
Èyí wáyé látàrí àìdógba oore-ọ̀fẹ́ sí ìlò irinṣẹ́ ìmọ̀-ẹ̀rọ amúṣẹ́yá bí i ẹ̀rọ-ayárabíàṣá, ẹ̀rọ ayárabíàṣá àgbélétantẹ̀, tàbí àwọn èrọ̀-ìbánisọ̀rọ̀ ìléwọ́ ayárabíàṣá tí ó fi mọ́ ọ̀hángógó iye owó ìṣàmúlò èrọ ayélujára àti kùdìẹ̀kudiẹ nídìí ìṣàmúlò ẹ̀rọ ayélujára pàápàá jùlọ fún àwọn akẹ́kọ̀ọ́ láti àwọn ìdílé tí wọn kò rí jájẹ àti àwọn ìlú tí wọn kò kàsí.
Kódà níbi tí ẹ̀rọ ti wà lárọ̀ọ́wọ́tó gan-an, àìmáatọ́ àwọn ọmọ sọ́nà nídìí ìṣàmúlò ẹ̀rọ ayélujára gan-an alára jẹ́ ohun tí ó ń kọ ènìyàn lóminú.
Kí ìtípa yìí tó bẹ̀rẹ̀, àwọn akẹ́kọ̀ọ́ ní ooreọ̀fẹ́ sí ouńjẹ ọ̀fé ní ilé-ìwé.
Àwọn omọdébìnrin inú wọn ní oore-ọ̀fẹ́ sí aṣọ ìlédìí ìsé-nǹkan-àlejò ti ètò kan fún ìpèsè àṣọ ìsé-nǹkan-àlejò.
Pẹ̀lú bí ìtìpa yìí ṣe ti gùn sì, Akọ̀wé Ìgbìmọ̀ Ètò-ẹ̀kọ́ George Magoha ti kéde pé àwọn àlàkalè ilé-ìwé ti “bómi lọ”, tí ó túnmọ̀ sí wí pé àwọn ilé-ìwé yóò wà ní títìpa síbẹ̀ títí di ọdún 2021, léyìí tí yóò sọ ọ̀pọ̀ àwọn akẹ́kọ̀ọ́ sí ipò òṣì pẹ̀lú bí àwọn ẹbí wọn kò ṣe lè pèsè ouńjẹ àti àwọn ohun èlò tí ó ṣe kókó látàrí àìríṣẹ́ṣe ẹnu lọ́wọ́lọ́wọ́ yìí.
Ní ìlú Kibra, fún àpẹẹrẹ, agbègbè tí wọ́n rí gẹ́gẹ́ bí ibi tí ìṣẹ́ àti ìyà sodo sí jùlọ ní Nairobi (àti ní ilẹ̀ Adúláwọ̀) ọ̀pọ̀ àwọn akẹ́kọ̀ọ́ ni wọn kò ní oore-ọ̀fẹ́ sí àlàkalẹ̀ ẹ̀kọ́ àtẹ̀yìn yàrá ìkẹ́kọ̀ọ́ kọ́ àjọ KCID, bẹ́ẹ̀ ni ọ̀pọ̀ kò tilẹ̀ ní ibi tí wọn ó ti kẹ́kọ̀ọ́ áḿbèlètàsé ibi eré ìdarayá.
(Láti ọ̀pọ̀ ọdún séyìn, agbègbè yìí ti ń jẹ́ pípẹ̀ ní “Kibera” tí í ṣe àṣìpè Kibra tí ó túmọ̀ sí “igbó kìjikìji” ní èdè Nubia. Fífi ọmọ peni lérú ni àwọn ará agbègbè Nubia ní Kenya máa ń rí lílo “Kibera” sí)
Nínú ìfọ̀rọ̀wánilẹ́nuwò lórí Skype pẹ̀lú Asha Jaffar, akọ̀rọ̀yìn tí ó ń gbé ní Kibra, ẹni tí ó gbé ìròyìn nípa ewu tí ó wu àwọn agbègbè Kibra, Jaffar sọ fún Ohùn Àgbáyé pé àwọn yàrá ìkàwé lọ́fẹ̀ẹ́ tí ó lè gba àwọn akẹ́kọ̀ọ́ mẹ́wàá ní ẹ̀ẹ̀kan ṣoṣo kò tó nǹkan.
Àmọ́, àwọn akẹ́kọ̀ọ́ wọ̀nyí ní láti máa fi àyè wọn sílẹ̀ lẹ́yìn bíi wákàtí kan kí ọ̀wọ́ àwọn akẹ́kọ̀ọ́ mìíràn lè ṣàmúlò àwọn àyè náà.
Ó fi kún un pé iná ètò fún owó ilé-ìwé ọ̀fẹ́ fún àwọn akẹ́kọ̀ọ́ ní láti jó rẹ̀yìn nítorí òfin jíjìnnà síraẹni láwùjọ tí ìjọba àti àwọn ikọ̀ elétò ìlera kàn nípá.
Asha Jaffar, akọ̀rọ̀yìn àti olùgbé Kibra ń nawọ́ sí àwọn ibùgbé Kibra.
Àwòrán láti Ètò ìpèsè Ouńjẹ ọ̀fé Kibra, Oṣù Ògún, ọdún 2020, àwòrán jẹ́ lílò pẹ̀lú ìyọ̀nda.
Ipa ìtìpa ọlọ́jọ́ gbọọrọ àwọn ilé-ìwé náà ti ń kọjá agbára bẹ́ẹ̀ ni ó sì ń lapa burúkú lórí àwọn ìdílé tí wọn kò rọ́wọ́ họrí.
Pẹ̀lú bí aáyan àtijẹ-àtimu ṣe borí aáyan ètò- ẹ̀kọ́, àwọn akẹ́kọ̀ọ́ pàápàá àwọn omọdébìnrin àti àwọn abilékọ kékèké láti àwọn ìdílé tí ìṣẹ́ ń bá fínra nílò láti ṣe iṣẹ́ oko dídá àti àwọn iṣẹ́ ilé tàbí iṣẹ́ àgbàtọ́ dípò ẹ̀kọ́ ìwé kíkọ́.
Èyí wáyé nínú ìtìpa yìí tí ó ṣe déédé pẹ̀lú àkókò tí ọ̀gbìn ṣíṣe wọ́pọ̀ jùlọ ní oṣù Ẹrẹ́nà.
Àwọn ọmọdébìnrin mìíràn gan-an lè tibẹ̀ ti kékeré lọ́kọ léyìí tí yóò sọ wọ́n sínú ewu pípa ilé-ìwé tì láti ara oyún àpàpàndodo.
Nítorí náà, ètò-ẹ̀kọ́ nínú àwọn ìdílé tí ìṣẹ́ ń bá fínra yóò lami, ìdí ni pé ọ̀pọ̀ nínú wọn ni kò rí ìdí pàtàkì tí ó fi yẹ kí wọn ó darí àwọn ọmọ wọn padà sí ilé-ìwé tí àwọn ilé-ìwé bá di ṣísí padà.
Ní oṣù Ẹrénà, Jaffar ṣe ìfilọ́lẹ̀ Ìpèsè Ouńjẹ ọ̀fé Kibra, láti lé ebi jìnà sí agbègbè Kibra pẹ̀lú fífi àpọ̀ kékèké tí ó kún fún oríṣìíríṣìí oúnjẹ ta àwọn ìdílé kòlàkòṣagbe lọ́ọrẹ.
Ó bẹ̀rẹ̀ pẹ̀lú wíwá àwọn ìtọrẹ àánú lórí M-pesa (àpò owó orí èrọ ìbánisọ̀rọ̀ alágbèéká) pẹ̀lú èrọ̀ngbà láti bọ́ àwọn ìdílé tí kò ń ọ̀pọ́n pọ́n là 100 fún ọ̀ṣẹ̀ kan, ṣùgbọ́n pẹ̀lú bí àwọn tí wọ́n nílò ìrànlọ́wọ́ ṣe ń pọ̀ si, ètò yìí ti bọ́ ìdílé tí ó tó 2400 títí di Ọjọ 5, Oṣù Ògún.
Jaffar rí i mọ̀ pé ìpèsè oúnjẹ ọ̀fẹ́ kò tó nítorí pé àwọn ìdílé yìí nílò àtìlẹ́yìn láti bẹ̀rẹ̀ oko-òwò kéékèèké.
Àmọ́ ṣá o, orọ̀ ajé agbègbè yìí dùró gbọhin pẹ̀lú bí káràkátà ṣe ti wara ro.
Afínúfẹ́dọ̀ pín oúnjẹ fún àwọn ènìyàn ibùgbé Kibra láti Ètò ìpèsè Ouńjẹ ọ̀fé Kibra, Kenya, Oṣù Ògún, ọdún 2020.
Àwòrán láti Ètò ìpèsè Ouńjẹ ọ̀fé Kibra, àwòrán jẹ́ lílò pẹ̀lú ìyọ̀nda.
Kenya ń retí ọdún ètò-ẹ̀kọ́ tuntun nì ọdún 2021— Ṣùgbọ́n èyí tún wà lọ́wọ́ iye ènìyàn tí àrùn COVID-19 bá kọlù — gẹ́gẹ́ bí ọ̀rọ̀ Magoha, Akọ̀wé Ìgbìmọ̀ Ètò-ẹ̀kọ́.
Ọ̀pọ̀ àwọn amòye nídìí ètò ẹ̀kọ́ sọ báyìí pé àkókò yìí jé oore-ọ̀fẹ́ fún ìjọba láti ṣe ìgbéléwọ̀n ètò-ẹ̀kọ́, kí wọn ó sì tún iná ìpèsè ẹ̀kọ́ fún tẹ̀rútọmọ dá gẹ́gẹ́ bí àfojúsùn àjọ elétò ẹ̀kọ́ ìpìlẹ, abetíwéré sí ìṣẹ̀lè pàjáwìrì COVID-19 ti ilẹ̀ Kenya.
Ìgbésẹ̀ àkọ́kọ́, yóò jẹ́ ìya owó sọ́tọ̀ láti mú ìdàgbàsókè bá ilé-ìwé nípa ìpèsè iná, àwọn tábìlì ìkàwé, àga ìjókòó àti iná mọ̀nàmọ́ná tó ṣeé fọkàn tán, pàápàá jùlọ ní àwọn ìgbèríko.
Léyìn èyí, ìjọba lè mú àdínkù bá owó iná àti owó omi ní àwọn ilé ìwé nítorí pé bí ó ṣe gbérí yìí ń pa iṣẹ́ wọn lára.
Léyin bí àwọn ohun tí ó ṣe kókó wọ̀nyí bá ti di yíyanjú nìkan ni ìgbìyànjú le bẹ̀rẹ̀ lórí Iṣẹ́ àkànṣe ìkàwé ìgbàlódé alápilẹ̀rọ tí ìjọba gbé jáde ni ọdún 2013.
Ètò Mọ̀ọ́kọ-mọ̀ọ́kà Ẹ̀rọ-ayárabíàṣá yìí gbèrò láti rí i wí pé àwọn akẹ́kọ̀ọ́ ilé-ìwé alákọ̀ọ́bẹ̀rẹ̀ (onípò 1-3) lè lo àwọn èrọ ìgbàlódé àti àwọn ohun èlò ìbáraẹnisọ̀rọ̀ pẹ̀lú èròǹgbà láti mú kí ètò ẹ̀kọ́ ilẹ̀ Kenya ó bá ti ọgọ́rùn-ún ọdún 21 mu.
Iṣẹ́ àkànṣe náà fẹ́rẹ̀ẹ́ má gbéra sọ bí wọ́n ṣe kọ́kọ́ múra sí i tó pẹ̀lú bí àwọn àfojúsùn wọn ṣe kùnà àti bí ìmúrasílẹ̀ àwọn olùkọ́ ṣe mẹ́hẹ.
Láti le kẹ́sẹ járí, ètò yìí nílò kí wọn ó dá àwọn olùkọ́ lẹ́kọ̀ọ́ ìlò àwọn ẹ̀rọ ìgbàlódé kí wọn ó bà lè ṣàmúlò àwọn ẹ̀rọ náà bí ó ti yẹ.
Ọ̀pọ́n Orílẹ̀-èdè Kenya ti sún láti ìṣètò Ẹ̀kọ́ alákọ̀ọ́bẹ̀ẹ̀rẹ̀ káàkiri àgbáyé (UPE) sí àgbéṣe Ẹ̀kọ́-ìwé fún gbogbo ènìyàn (EFA).
UPE tí ó jẹ́ Ìlépa kejì Ilépa ìdàgbàsókè ti Ẹgbẹ̀rún ọdún Àjọ Ìsọ̀kan Àgbáyé tí ó gbèrò láti rí i wí pé nígbà tí ó bá fi máa di ọdún 2015, gbogbo ọmọ ní jákèjádò àgbáyé ni wọn ó ti parí ilé-ìwé alákòóbẹ̀ẹ̀rẹ̀, ṣùgbọ́n EFA ní tirẹ̀ jẹ́ ìpolongo àgbáyé tí àjọ UNESCO léwájú rẹ̀, pẹ̀lú èròǹgbà láti mú àǹfààní ẹ̀kọ́-ìwé tọ “gbogbo ọmọ ìlú ní gbogbo àwọn àwùjọ ” àgbáyé lọ.
Pẹ̀lú àwọn àǹfààní wọ̀nyí, orílẹ̀-èdè Kenya ò gbọdọ̀ fa ọwọ́ aago ìdàgbàsókè yìí sẹ́yìn.
Ìpènijà tí ó kángun sí orílẹ̀-èdè Kenya báyìí ni láti rí i wí pé àwọn akẹ́kọ̀ọ́ ní oore-ọ̀fẹ́ sí àwọn iṣẹ́ àkànṣe ìkàwé ìgbàlódé tí kì í ṣe ẹ̀kọ́-ìwé nìkan ni yóò máa kọ́ni, sùgbọ́n àpapọ̀ ẹ̀kọ́ tí yóò tún máa kọ́ni lọ́gbọ́n àtiṣe lóríṣìiríṣìi, ìmọ̀ àtilèdádúró láti lè bá àfojúsùn wọn àti ìmúṣẹ ìlepa ìgbérò ìdàgbàsókè tí ó bá fi máa di ọdún 2030.
Ìlàkàkà láti fi òpin sí òkúrorò SARS ẹ̀ka ilé-isẹ́ ọlọ́pàá ilẹ̀ Nàìjííríà ń tẹ̀síwájú.
Àwọn ọ̀dọ́ Nàìjíríà ń tẹ̀síwájú ìfẹ̀hónúhàn jákèjádò orílèèdè náà
Àtẹ̀jáde ìtúmọ̀ 15 Ọ̀wàrà 2020
Ka àtẹ̀jáde yìí ní Français, Español, English
Àwọn afẹ̀hónúhàn kóra jọ láti fi òpin sí ikọ̀ SARS ní Ọjọ́ 13, Oṣù Òwàrà, Ọdún 2020, ní Ikeja, Èkó.
Àwòrán láti ọwọ́ Nora Awolowo, s̩ís̩àmúlò pẹ̀lú ìyọ̀nda.
Láti ọ̀sẹ̀ tó ti kọjá, àwọn ọ̀dọ́ ọmọ orílẹ̀-èdè Nàìjííríà ti gbéra sọ lọ́pọ̀ yanturu láti gbógun ti ẹ̀ka kan lábẹ Ilé-Iṣẹ́ Ọlọ́pàá Orílẹ̀-èdè Nàìjííríà tí a mọ̀ sí Ikọ̀ Agbógunti Ìdigunjalè (SARS), èyí tí wó̩n gbajúgbajà fún ìṣekúpani, ìlọ́nilọ́wọ́gbà, ìjínigbé, ìfipábánilòpọ̀ láti ọdún 1992 tí wọ́n ti dáwo̩n sílẹ̀.
Ó lé ní o̩gó̩rùn-ún ènìyàn tí Ikọ̀ SARS ti ṣekú pa láti bí ọdún mẹ́rin sí márùn-ún sẹ́yìn gẹ́gẹ́ bí Amnesty International ṣe jábọ̀.
Àwọn ọ̀dọ́ ọmọ orílẹ̀-èdè Nàìjííríà ­— tí ó máa ń jẹ́ àfojúsùn ikọ̀ SARS lọ́pọ̀ ìgbà — ti figbe ta láìmọye ìgbà pé kí wọn ó pa ẹ̀ka náà rẹ́ pátápátá ṣùgbọ́n wó̩n ko̩tí o̩gbó̩in si.
Ṣùgbọ́n ní báyìí, ìfipáńpẹ́-ọba-gbé àti ìṣekúpani tó ń peléke sí i lẹ́nu lọ́ọ́lọ́ yìí ní ìpínlẹ̀ Èkó ni ó tún ta àwọn ènìyàn jí láti rí i pé ó wá sí ìmúṣẹ —lẹ́yìn tí Ikọ̀ SARS ti kọ́kọ́ di tíkúkà ní ẹ̀ẹ̀mẹrin ọ̀tọ̀ọ̀tọ̀ láàárín ọdún mẹ́rin — ti fa ìwó̩de ọ̀pọ̀lọpọ̀ ènìyàn nígboro.
KÀ SÍWÁJÚ: ‘Ò̩lẹ’ ọ̀dọ́ orílẹ̀-èdè Nàìjííríà kó ìfẹ̀hónúhàn #EndSars (FI ÒPIN SÍ IKỌ̀ SARS) jọ láti orí ẹ̀rọ alátagbà títí dé àárín ìgboro.
Ìgbógunti ìwà òkúrorò àwọn ọlọ́pàá yìí tún di ohun tí gbogbo ènìyàn ń gbà bí ẹni gba igbá ọtí, ó sì tún di kókó ọ̀rọ̀ ọ̀pọ̀lọpọ̀ ìtàkùrọsọ lórí gbàgede ẹ̀rọ alátagbà
Ìfẹ̀hónúhàn ti gbéra sọ ní ó kéré tán ìpínlẹ̀ méjìlá nínú ìpínlẹ̀ mé̩rìndínlógójì orílẹ̀-èdè Nàìjííríà tí ó fi mọ́ Abuja, olú-ìlú orílẹ̀-èdè náà àti Èkọ́, níbi tí àwọn afẹ̀hónúhàn ti dí àwọn ẹnu ibodè asanwó-kí-a-tó-kọjá àti àwọn pápákọ̀ òfuurufú ní ìpínlẹ̀ náà, pẹ̀lú ìrètí àtimú kí ó fa ètò ọrọ̀ ajé sẹ́yìn kí àwọn adarí tí a yàn lè gbọ́ sí àwọn àfẹ̀hónúhàn lẹ́nu láifi àkókò ṣòfò.
Èyí ni àwọn ohun tí àwọn afẹ̀hónúhàn ń fẹ́:
Àwọn ọmọ orílẹ̀-èdè Nàìjííríà lẹ́yìn odi náà ti fọ́n sígboro láti fi àìdùnnú wọn hàn sí ikọ̀ ògbólógbo SARS yìí, tí ó ti ń hu oríṣiríṣi ìwa láabi láti àìmọye ọdún sẹ́yìn.
Àwọn afẹ̀hónúhàn ti kóra jọ ní London, England, Dublin, Ireland, Ottawa, àti Toronto, Canada, Cologne, Germany, Moscow, Russia, Pretoria, South Africa tí ó fi mọ́ Texas àti Washington, DC ní ilẹ̀ Amẹ́ríkà láti bu ẹnu àtẹ́ lu ikọ̀ SARS.
Ó kéré tan àwọn afẹ̀hónúhàn mé̩wàá ni wọ́n ti ṣekú pa ní àsìkò ìfẹ̀hónúhàn, gẹ́gẹ́ bí Amnesty International ṣe sọ.
Lára àwọn tí wọ́n pa ni Jimoh Isiaq, tí wọ́n pa ní ìlú Ògbómò̩s̩ó̩, Ìpínlẹ̀ Oyo, àti Ikechukwu Ilohamauzo tí wọn pa ní àsìkò ìfẹ̀hónúhàn Sùúrùlérè ní Èkó, tí orúkọ wọn gba orí àwọn ìkànnì ìbánidọ́rẹ̀ẹ́ orí ẹ̀rọ alátagbà kan.
Àwọn oníṣègùn òyìnbó tí ń kọ́wọ̀ọ́ rìn pẹ̀lú àwọn afẹ̀hónúhàn tórí bí ìṣẹ̀lẹ̀ pàjáwìrì bá wáyé.
Àwon afẹ̀hónúhàn kóra jọ láti bu ẹnu àtẹ́ lu ikọ̀ SARS ní Ọjọ́ kejìlá, Oṣù Ọ̀wàrà, Ọdún 2020 ní Yaba, Èkó.
Àwòrán láti ọwọ́ Aremu Adeola Jr, s̩ís̩àmúlò pẹ̀lú ìyọ̀nda.
Ọ̀gá àgbà Ọlọ́pàá nílẹ̀ Nàìjííríà Muhammad Adamu tú ikọ̀ náà ká ní bí ọjọ́ mélòó kan sẹ́yìn, ṣùgbọ́n ìgbésẹ̀ yìí kò tẹ́ àwọn ọmọ orílẹ̀-èdè Nàìjííríà lọ́rùn nítorí pé àwọn ìgbésẹ̀ tí wọ́n ti gbé ṣáájú nípa ikọ̀ náà kò so èso rere.
Ní ọjọ́ Ajé, Ààrẹ orílẹ̀-èdè President Nàìjííríà Muhammad Buhari fi ọkàn àwọn ọmọ orílẹ̀-èdè balẹ̀ pé ìgbésẹ̀ ì-tú-ikọ̀ náà ká yóò fẹsẹ̀ múlẹ̀ ní kíá, bẹ́ẹ̀ sì ni ìgbìmọ̀ àtúndá ilé iṣẹ́ ààrẹ yóò rí sí ìgbáyégbádùn àwọn ọlọ́pàá àti àwọn nǹkan mìíràn tí ó tun ṣe pàtàkì, ó ń fi àrídájú hàn pé àwọn ìbéèrè àwọn ará ìlú yóò di mímú ṣe.
Àwọn amòfin tí wọ́n tún jẹ́ ajàfẹ́tọ̀ọ́ ọmọnìyàn àti àwọn ọ̀dọ́ ajàfẹ́tọ̀ọ́ tí ń ṣiṣẹ́ kárakára láti rí i pé wọ́n tú àwọn afẹ̀hónúhàn tí wọ́n tì mólé sílẹ̀.
Àwọn afẹ̀hónúhàn ti sọ ọ́ yanya pé ìjà fitafita láti fi òpin sí ikọ̀ SARS kò lọ́wọ́ òṣèlú nínú, bẹ́ẹ̀ ni wọ́n ṣe ìkìlọ̀ fún àwọn olóṣèlú tí ó fi mọ́ àwọn alátìlẹ́yìn ẹgbẹ́ òṣèlú alátakò láti má ṣe gbé ìfẹ̀hónúhàn ọ̀hún karí nítorí àtirí èrè nínú ẹgbẹ́ òṣèlú tàbí ti òṣèlú gan pàá.
Àwọn afẹ̀hónúhàn tákú pé kò sí adarí nínú ìfẹ̀hónúhàn wọn, wí pé ẹnikẹ́ni tí ó bá jáde láti wá fẹ̀hónú hàn jẹ́ adarí àti ọmọ ẹ̀yìn pèlú.
Wọ́n takú pé kí ààrẹ àti/tàbí Ọ̀gá Àgbà Ilé iṣẹ́ Ọlọ́pàá dojú ọ̀rọ̀ kọ gbogbo àwọn tí inú ń bí ní ẹ̀ẹ̀kan ṣoṣo ni kì í ṣe pé kí wọn ó ṣa àwọn kan bá sọ̀rọ̀.
Ìbéèrè lórí ẹni tí ó ń darí àwọn ọlọ́pàá àti ikọ̀ SARS kò tíì ní ìdáhùn tí ó jé̩ ìté̩wó̩gbà.
Ìwé òfin ilẹ̀ náà gbé agbára ìdárí ọlọ́pàá lé ààrẹ lọ́wọ́ lábẹ́ ìbòjútó ọ̀gá àgbà ilé iṣẹ́ ọlọ́pàá.
Àmọ́ pé ẹ̀wọ̀n-àṣe àti ìdarí yẹn ti já.
Bí àpẹẹrẹ, láti jọ̀wọ́ àwọn afẹ̀hónúhàn ní Sùúrùlérè, ní ìpínlẹ̀ Èkó, èyí gba ìpè láti ọ̀dọ̀ Gómìnà ìpínlẹ̀ Èkó Babájídé Sanwó-Olú, Abẹnugan ilẹ́ Ìgbìmọ̀ Aṣojúṣòfin Fẹ́mi Gbàjàbíàmílà, ọmọ ilé ìgbìmọ̀ aṣòfin ìpínlẹ̀ Èkó tí ó ń ṣojú ẹkùn Sùúrùlérè Desmond Elliot àti àwọn agbẹjórò díẹ̀.
Ní Ọjọ́ kejìlá, Oṣù Òwàrà, Gómìnà Ìpínlẹ̀ Rivers Nyesom Wike, kéde láti orí túwíìtì kan pé kò sí ààyè fún ìfẹ̀hónúhàn kankan — pàápàpá jùlọ ti #EndSARS protest — ní ìpínlẹ̀ òun.
Èyí kò dùn mọ́ ọ̀pọ̀ àwọn ọmọ ìlú nínú.
Ọ̀pọ̀ àwọn ènìyàn ni wọ́n dá èsì padà lórí àwọn ìkànnì ẹ̀rọ àwùjọ pé ìwé òfin tí ó gbé gómínà dé orí ipò náà ni ó fún àwọn ọmọ ìlú ní ẹ̀tọ́ láti fi ẹ̀hónú hàn.
Síbẹ̀, Wike yóhùn padà ó sì padà bá àwọn afẹ̀hónúhàn sọ̀rọ̀, níbi tí ó ti fi àtìlẹ́yìn rẹ̀ hàn sí ìpè wọn
Ìfẹ̀hónúhàn yìí tẹ̀síwájú ní ọ̀pọ̀lọpọ̀ ìlú ní orílẹ̀-èdè náà tí ó fi mọ́ ìpínlẹ̀ Rivers. Àwọn afẹ̀hónúhàn ti ṣèlérí pé àwọn ò ní tẹ̀tì àyàfi bí àwọn bá rí ààmì ìyípadà ní ọ̀dọ̀ àwọn ọlọ́pàá àti ọ̀dọ̀ ìjọba àpapọ̀.
Ní ọjọ́ Ìṣẹ́gun, Ọjọ́ ke̩tàlá, Oṣù Òwàrà, àwọn afẹ̀hónúhàn ròyìn lórí Twitter pé ní Ìwó Road, Ìbàdàn, àwọn ọmọ ológun orí ilẹ̀ ń kọ́wọ̀ọ́rìn pẹ̀lú àwọn afẹ̀hónúhàn pẹ̀lú ìsọ̀kan.
Bákan náà ní Ọjọ́ ke̩rìnlá, Oṣù Ò̩wàrà, Gómìnà Ìpínlẹ̀ Èkó Babàjídé Sanwó-Olú kọ́wọ̀ọ́rìn pẹ̀lú àwọn afẹ̀hónúhàn, níbi tí ó tún ti fi ìdánilójú àtìlẹyìn ìjọba hàn láti dé̩kun ohun aburú yìí.
Ìjọba ìpínlẹ̀ Èkó ní àwọn ènìyàn méwàá tó farakáásáá níbi ìsẹ̀lẹ̀ iná tó sẹlẹ̀ ní ọjọ́ kẹ̀rin oṣù Agẹmọ ní ìlú Ìjegun lóti dágbéré fún áyé bótijépé iná ohun ti jó wọn kọjá sísọ.
Akọ̀wé ìjoba lórí ètò ìlera Dókítà Títílayò Goncalves tò bá àwọn Akọ̀ròyìn sọ̀rọ̀ ní mẹ́ta lára wọn lókú ní ilé ìwòsàn ẹ̀kọ́ṣẹ́ ètò ìlera Lagos State University Teaching Hospital Ikeja tí àwọn méje míì sì pàdánù ẹ̀mí ní Gbàgádà General Hospital Léèkó.
Nínú ọ̀rọ̀ rẹ̀, ó ní àwọn ènìyàn méjìlélógún tí wọ́n fi Ọkọ̀ pàjáwìrì gbé níbi ìṣẹ̀lẹ̀ ọ̀hún ni wọ́n gbé ènìyàn mẹ́sàn án sí LASUTH, tí méjìlá sì wà ní ẹka ìjàmbá iná Gbàgádà General Hospital tí ẹ̣nìkan sì wà ni Àlímòṣọ́ General Hospital.
Dókítà Titilayo ní gbogbo ìgbìyànjú làwọn wa láti máse pàdánù ẹ̀mí Kankan mọ́. Bákanáà lóní ara àwọn tó kù ti ń yá.
Ààrẹ tintun orílẹ̀ èdè Greece’s, Mrkyriakos Mitsotakis ti ní òun ò ní já àwọn ará ìlú ní tàn-án mọ̀n lẹ́hìn tí Ìjọba ti bọ́si lọ́wọ́.
Mr Mitsotakis tófi ẹ̀yìn akegbẹ́ jọnlẹ̀ pẹ̀lú àbájáde egbelemùkú ìbò.
Prime minister yìí tún ní òun yóò ṣe ìjọba àlááfíà lórí gbogbo ará ìlú.
Bákannáà lótún ṣe ìlérí láti sè ìpàdé pẹ̀lú àwọn Olókòwò Greece láti leè fàyè gba ọ̀pọ̀lọpọ̀ owó síi ìlú.
Ààrẹ Mohammedu Buhari ti padá sí Àbújá lọ́jọ́ ajé lẹ́hìn ìpàdè ẹlẹ́ẹ̀kejìlá àpèjọ àrà ọ̀tọ̀ pẹ̀lú Àjo Africa Union ní Niamey Niger Republic.
Àjọ Akọ̀ròyìn News Agency of Nigeria jábọ̀ pé ọkọ̀ òfurufú tó gbé Ààrẹ àti àwọn tí wọ́n jọ kọ́ọ̀wọ̀rìn balè igun pápákọ̀ Nnamdi Azikwe International Airport Abuja ní aago kan kọjá ìṣẹ́jú mẹ́ẹ̀dógún.
Ààrẹ fọwọ́sí ìwé àdéhùn pẹ̀lú AfCFTA gẹ́gẹ́ bí Ààre ketàlélọ́gọ́ta tí yóò tí owọ́ bọ ìwé yìí lágbàáyé.
Ààre dá ìwé yí dúró de osú karùn-ún ọdún 2019.
Ìdádúró tí wọ́n fi àyè gbà àwọn Alẹ́nulọ́rọ̀, Onímọ̀ ìjìnlẹ̀ láti jábọ̀ ìwádìí wọn bí Nigeria se gbaradì láti darapọ̀ mọ́ wọn.
Ìpolongo àti ìkéde lórí ẹ̀tò láàrín àwọ̀n ọkùnrin sí Obìrinbi kìí ṣe fún ìfi igagbága bíkòsepé kí takọ tabo ilẹ̀ yìí le kópa nínú ìlọsíwájú orílẹ̀ èdè wa.
Ọ̀rọ̀ yìí ni mínísítà fún ètò iṣé dokita Nike Akande sọ níbi ètò kan tí Ìjọba ìpínlẹ̀ Èkò gbé kalẹ̀ láti sàmì àyájọ́ Àwọn Obìnrin lágbàáyé [IDW].
Ó fi kún ọ̀rọ̀ rẹ̀ pé ìwòye ọjọ́ iwájú Orílẹ̀ èdè yìí ni ìṣèjọba tí àwọn tó dántọ́ ṣe àkóso rẹ̀ àti ibi tí ètò ìdájọ́, Ìsọ̀kan àti Orí ò ju orí wà.
Nínú Ọ̀rọ́ tí Gómìnà Ìpínlẹ̀ Èkó Ọ̀gbẹ́ni Akíwùnmí Ambode tí Kómísóná fún ọ̀rọ̀ àwọn Ọ̀dọ́ àti Ìdàgbàsókè Àwùjọ, Agboọlá Dábírí tó sojú fún, ni tí a bá wo inú agbo òsèlú, ipa ribiribi làwọn Obìrin ńkó pèlu ètò ọrọ Ajé Ìpínlè, bákan náà lótún rọ àwọn Òbí àti Alágbàtọ́ láti ma gba àwọn ọ̀dọ́ ĺámọ̀ràn pàápàá àwọn Ọ̀dómọbìnrin láti ni ìwà ọmọlúwàbí kí wọ́n lè jẹ́ aṣíwájú rere lẹ́yìn ọ̀la.
Asojú ni ilé Ìgbìmọ̀ asòfin tó ń sojú ekùn Etì ọ̀sà kejì, Ọ̀gbẹ́ni Gbóláhàn Yishawu ti gbóríyìn fún àwọn òṣìṣẹ́ fún àtìlẹyìn wọn láti gbé Orílẹ̀ èdè yìí ga.
Ọ̀gbẹ́ni Yishawu nínú ìwé Àpilẹ̀ko tó fi kí àwọn òṣìṣẹ́ tó sì dúpẹ́ lọ́wọ́ Àjo Àwọn òṣìṣẹ́ pẹ̀lú àjo tó n mú ojútó Ayédáadé Òṣìṣẹ́ àti Àjo Olókòwò bí wọ́n ṣe ja Àjàyè lórí èkúnwó owó oṣù àwọn òṣìṣẹ́.
Aṣòfin tún múu dá àwọn òṣìṣẹ́ lójú pé ìsèjoba Ààrẹ Mohammadu Buhari mọ rírì wọn tó sìjẹ́ kó buwólu ìbéèrè wọn tó sì ti di òfin.
Ọ̀gbẹ́ni Yishawu tún rọ àwọn Oníléeṣẹ́ tó sì ńjẹ àwọn òṣìṣẹ́ wọn lówó osú láti san Owó wọn fún wọn lásìkò.
Bí gbogbo òṣìṣẹ́ lágbàáyé se ń sàmì àyájó àwọn òṣìṣẹ́ ní gbogbo ìpele láti ṣe ètò ilé olówópókú ,ètò ìlera tó jíire lówó tí kò ganilára àti sísan owó Àjemọ́nú àwọn òṣìṣẹ̀ fẹ̀hìntì lásìkò.
Ìpè yìí wá láti ọ̀dọ̀ Alága fún Àjo Akọ̀ròyìn ẹ̀ka ti ìpínlẹ̀ èkó Ọ̀gbẹ́ni Qazeem Akínretí ló sọ ọ̀rọ̀ yíí fún àwọn aṣojú oníròyìn wa.
Dokita Akinreti tún ní lẹ́yìn ìbuwọ́lù owó oṣù òṣìṣẹ́ to kéré ju ọ̀pọ̀lọ̀pọ̀ nǹkan amáyédẹrùn lóye ki ìjoba o mójútó láti mú ìgbé ayé ìrọ̀rùn bá àwọn òṣìṣẹ́.
Ẹni tó jáwé olúborí ní ọjọ́ àbámẹ́ta tó kọjá nínú ìdìbò abẹ́lé ti Káńsílọ̀ ní Ọ̀bẹ̀lẹ́ Oníwàálà lágbègbè Sùúrùlérè ni Ìpínlẹ̀ eko, Ọ̀gbẹ́ni Kazeem Béllò ní Àjo elétò ìdìbò ìpínlẹ̀ Èkó LASIEC ti fun ní ìwé ẹ̀rí láti padà si Ófíìsì lẹ́ẹ̀kan si.
Alága Àjo ọ̀hún onídàájó Àyòtúndé Phillips kí Ọ̀gbẹ́ni Bello kú oríire tó sì tún gbàá lámọ̀ràn làti teramọ́ isẹ́ Ìdàgbàsókè agbègbè
Onídàájọ́ Phillips níbi tó ti jábọ̀ fún Komisọ́nà fún Àjọ òhún Hon Olúségun Ayédùn wòye pé Àjọ ọ̀hún fi ìfara ẹnijì hàn láti kó ipa pàtàkì láàrín ẹgbẹ́ òṣèlù tó ń díje.
Alága yìí tó fi èhónú rẹ̀ hàn bí àwọn Olùdìbò ṣe kọ̀ láti jáde kópa nínú eto ìdìbò ọ̀hún.
Alága tún dúpẹ́ púpọ̀ lọ̀wọ̀ àwọn elétò ààbò pàápàá àwọn Agbófinró atì àwọn Eléto ààbò ìpínlè (DSS) pẹ̀lú Civil Defence.
Àjo tó ń kojú ìsẹ̀lẹ̀ pàjáwìrì ìyen Lagos Management Agency (LAGSEMA) ti ro àwọn Awakọ̀ àti àwọn tó ń wa kẹ̀kẹ́ ẹlẹ́sẹ̀ mẹ́ta láti máa se jẹ́jẹ́ lójú pópó kí ìfẹ̀mí sòfò lójú pópó ó lè di ohun àfìsẹ́yìn nílẹ̀ yìí pàápàá lásìkò tí wọ́n bá ń sodá lójú irin (Railway)
Ọ̀gbẹ́ni Adésínà Tìámíyù tó jẹ́ ọ̀gá Àgbà fún Àjo tó ń kojú ìsẹ̀lẹ̀ pàjáwìrì ìyen Lagos Management Agency (LAGSEMA)gba àwọn oníkèké márúwá lámọ̀ràn látàrí ìṣẹ̀lẹ̀ burúkú kan tó ṣẹlẹ̀ nígbàtí oníkèké márúwá kan sáré sẹ́nu ọkọ̀ ojú irin tó ńkọjá lọ́ ní agbègbè Shina Peters ní Ìjú Ìshàá ní agbègbè Èkó ní ibi tí àwọn ènìyàn mẹ́rin ti jẹ́ ọlọ́run nípè tí ọlọ́run sì kó ẹnìkan yọ láì farapa
Ọ̀̀gbẹ́ni Tìámíyù ní tó bá sepé dẹ́rẹ́bà yìí mú sùúrù tó tún tẹ̀lé ìlànà òfin, irúfẹ́ ìsèlè yìí ìbátí wáyé.
Bákanáà ló tún ń rò wọ́n láti dẹ́kun ìfẹ̀mí àti dúkìá sòfò látàri eré àsápajúdé àti àìní sùúrù.
Mohammed Buhari ti ní kí gbogbo Òṣìṣẹ́ ólọ fi okàn balẹ̀ nítorí pé ìsèjoba òun yìí yóò mú ìdẹ̀rùn bá àwọn òṣìṣẹ́ ní gbogbo ọ̀nà èyì ni isé ìkíni ìwúrí tó fi ránsẹ́ sí àwọn òṣìṣẹ́ níbi tí Mínísítà fún ètò ìgbani sí iṣẹ́ Dókítà Chris Ngige tilo sojú fun Ààrẹ, ònì òwà nínú èrò àti ìpinu rere fun àwọn òṣìṣẹ́ lori ìdókòwò ti yoo mú ọrọ̀ ajé Nigerians gbéra sókè .
Nínú isẹ́ ìkíni ti Olórí ilé ìgbìmọ̀ asòfin Dokita Bukola Saraki tó fi gbóríyìn fún àwọn òṣìṣẹ́ fún ipa tí wón nko nínú ìdàgbàsókè ilẹ̀ wa, ninu àtèjáde ti akọ̀wé fún Dókítà Saraki buwọ́lù ìyen Ogbeni Yusuph Olaniyonu ló ti gbóríyín fún àwọn tó gbèrò láti jóòko ìpàdé pọ̀ pẹ̀lú ìjoba láti so àsoyèpọ̀ lórí ìdàmú tó n kójú àwọn òṣìṣẹ́.
Sàràkí múu dá wọn lójú pé ìgbà ọ̀tun ńbò ṣùgbọ́n ki àwọn òṣìṣẹ́ o ri dájú pé wọn n sa ipá wọn pàápá lẹ́nu isẹ́ òòjó wọn.
Àwọn Òṣìṣí ìpìnlẹ́ yìí lóti kórajo si pápá ìseré Agege láti sàmì àyájọ́ àwọn òṣìṣẹ́.
Komisona fun Ìdáṣẹ́sílẹ̀, ìkọ́ni àti ìfẹ̀yìntì Ogbeni Akintola Benson gbóríyín fún Àjo tó ń mójútó ìgbáyé gbádùn òṣìṣẹ́ bí wọ́n se ń bèrè fún ohun amáyédẹrùn fun àwọn Òṣìṣẹ́.
Óní ìjoba pẹ́lú yóò tún bọ̀ ma tẹ̀síwájú láti mú ìgbé ayé ìdẹ̀rùn bá àwọn òṣìṣẹ́ àti pé pípèsè iṣé yóò jẹ ìjọba lógún
Ọ̀gbẹ́ni Francis Ògúnrèmí tó jẹ́ alága fún àwọn Onísòwò pe Gómìná Akinwunmi Ambode láti bẹ̀rẹ̀ síní san owó osú òṣìṣẹ̀ tó kéré jù nínú Oṣù Karùn ún Ọdún Bákan náà ni wọn tún béèrè fún owó àjẹmọ́nú ti Oṣù kẹrin ọdún.
Ẹ̀wẹ̀ lásìkò tí wón ń pe ìjoba sí àkíyèsí Ọ̀gbẹ́ni Ògúnrẹ̀mí tún rawó ẹ̀bẹ̀ sí ìjoba láti dákun dábọ̀ jẹ́ kí owó oṣù àwọn òṣìṣẹ̀ ní sísan lọ dédé àti àwọn owó ìfẹ̀yìntì náà, Ó tún wá rawọ́ ẹ̀bẹ̀ síí ìjọba Ìpínlẹ̀ pé kí wọn ṣe ìdíwòn dédé sí àwọn òṣìṣẹ́ kíákíá àti àwọn kongílá
Ilé Ìgbìmọ̀ Aṣòfin àgbà ẹlẹ́kẹ̀jọ lábẹ́ Aàre wọ́n Dókítà Bùkọ́lá Sàràkí àti aka ẹgbẹ́ rè ọ̀gbẹ́ni Yakubu Dogara tí wón ń ṣojú nílé ìgbìmọ̀ aṣojú-ṣòfín kékeré ni wọ́n ti júwe gẹ́gẹ́bí aṣíwájú rere tósí ń fẹ́ ìlọsíwájú ilẹ̀ yí.
Ọ̀mọ ilé ìgbìmọ̀ Aṣojú-ṣòfin tó ń ṣojú Àgbádárìgì Ọ̀gbẹ́ni Joseph Bamgbose ló sọ ọ̀rọ̀ yí lásìkò tó ńgbé o ríyìn fún wọ̣n pé èróngbà ìjọba ló mumú láyà àwọn aka ẹgbẹ́ ilé ìgbìmọ̀ aṣòfin ẹlẹ́ẹ̀kẹjọ, Óní gẹ́gẹ́ bíí ọmọ ilé ìgbìmọ̀ aṣòfin ọ̀hún tisa ipa ribiribi láti mú ayé dẹrùn fún àwọn ènìyàn agbègbè rẹ̀ látàrí ètò ìrónilágbára lórí ètò Ọ̀gbìn, isẹ́ ọnà ti ọ̀pọ̀lọpọ̀ oníṣẹ́-ọwọ́ náà si rí gbà láti jábọ̀ fún àwọn tó lọ sojú fún labuja bákan náà, Ódúpẹ́ púpọ̀ lọ́wọ́ àwọn agbègbè rẹ̀ fún ore-òfẹ́ tí wọn fún láti ṣojú wọn ní ilé ìgbìmọ̀ aṣòfin ósì ṣ̣e ìlérí pé òun kò ní já àwọn ènìyán náà kulẹ̀ lọ́jọ́-kọ́jọ́.
Àjọ tó ń gbógun ti ìwà ìbàjé, ẹ̀ka ti ìjọba àpapọ̀ tí jáwé adámọlẹ́kun fún àwọn ọmọ gànfé tó ń gba owó kòtọ́ lọ́wọ́ àwọn Awakọ̀ àjàgbé Àpápá
Ọ̀gá Àgbà wọn Ọ̀gbẹ́ni Káyọ̀de Ọpéifá tó sọ̀rọ̀ yìí wí pé Ààrẹ ti fún wọn ní gbèdéke wíwẹ̀ yán kẹ̀yìnkẹ̀yìn tí Ọjọ́ náà sì ti pé lónìí.
Ọpeifa ní gbogbo kàànda ọ̀hún tó sì tún ṣe kìlọ̀-kìlọ̀ fún àwọn lọ́gà-lọ́gà láti darí àwọn Awakọ sí ibi ìgbọ́kọ̀sí tí ìjọba ti yà sọ́tọ́ fún wọn
Bí ọdún se ń súnmọ́ ni àwọn olùgbé ìpínlè Èkó ti fajúro bí ojà se gbé owó lérí tósì gaju agbára wọn lọ.
Lára àwọn ènìyàn tobá iléeṣẹ́ Bond FM sọ̀rọ̀ sọ pé ohun gbogbo ló gbe owó lórí kọ́já sísọ.
Wọ́n rawọ́ ẹ̀bẹ̀ sí ìjoba Àpapọ̀ láti wa ǹkan se síi
Àjọ tó ń mójútó ìkólẹ̀-ḱdọ̀tí ti Ìpínlẹ̀ Èkó ti ro àwọn olùgbé látí tọ́jú àwọn ilẹ̀ lásìkò ọdún yìí láti fi dènà àjàkálẹ́ àrún
Igbá kejì ọ̀ga àgbà àti alámòjútó Abilékọ Fọláshadé Kádírì ní ètò gbogbo ló ti wà nílẹ̀ láti ri wípé àgbègbè tí àwọn ènìyàn tí ń ṣe àjọyọ̀ ọdún wàní mímọ́
Arábìnrin náà tún wá sọ pé Àjọ LAWMA yóò pín àpò ìdàdọ̀tí sí ní ọ̀fẹ́ fún àwọn olùgbé agbègbè yìí láti kó àwọn ìdọ̀tí náà síi ní àsìkò pọ̀pọ̀sìsì ọdún.
Ilé Isẹ́ Olọ́ọ̀pá ti fi ọwọ́ sí yíyọ àwọn Ọ̀gá agbófinró mẹ́sàn án lẹ́yẹ ò sọkà látàri ìwà ìbàjẹ́ wọ́n.
Níbi àbájáde ìpàdé tó wáyé ní ìlú Àbújá ní ojọ́-kẹrìndínlọ́gbọ̀n àti kẹ́tàdínlọ́gbọ̀ oṣù ketà ọdún 2019, lábẹ́ Alága ìyen Ọ̀gá Àgbà tẹ́lẹ̀rí fún àwọn Ọlọ́ọ̀pá Ọ̀gbẹ́ni Musiliu Smith, ó fi kún pé àjọ náà buwọ́lu ìjìyà ọlọ́kan ò jọ̀kan fún àwọn òṣìṣẹ́ Ọlọ́ọ̀pá méwàá tó tasẹ̀ àgèẹ̀rẹ̀ sí òfin.
Látàrí ọ̀rọ̀ tí wọn fi léde, Àwọn tí wọn dá dúró ni, Abdul Ahmed, Adamu Abare, Osondu Christian,Samson Ahmadu,Pius Timiala,Agatha Usman,Esther Yahya,Idris Sheu,Usman Dass.
Àjọ náà tọrọ lọ́wọ́ Ọ̀gá àgbà Ọlọ́ọ̀pá pé kí wọn ṣàlàyé lẹ̀kúnrẹ́rẹ́ irú ìjìyà tí wọn fijẹ èyíkéyìí agbófinró tí adárúkọ nínú ìwádìí àwọn ọlọ́ọ̀pá.
ÌJÀǸBÁ ẸNU IṢẸ́
Ó ju Mílíònù méjì ó lé léèédégbèrín ènìyàn ló ń pàdánù ẹ̀mí wọn látàrí ìjànbá ẹnu isẹ́ àti àrùn tó fara pẹ́ isẹ́ ṣíṣe lọ́dọdún ní àgbáyé
Akowé àgbà fún ètò ìgbani sí iṣẹ́ Ogbeni William Alo ní òdiwọ̀n aláèlẹ́gbẹ́ ni ìyà tí àílàbò tó fí ń jẹ àwọn òṣìṣẹ́ àti gbígbìnyànjú ìlera àti ìdojúkọ tó ṣe faradà
Ò ní àwọn túnbọ̀ ma tẹ̀síwájú àti láti ṣe àgbéyèwò ìlànà, òfin àti àwọn ètò tó lágbára láti ripé ìlọsíwájú bá ètò àbò àti ìlera tó làmìlaka ní ẹnu isẹ́
Nínú ọ̀rọ̀ tí Ọ̀gá àgbà fún Àjo tó ń mójútó ọ̀rọ̀ àwọn òṣìṣe lágbàáyé, ẹ̀ka ti Orílẹ̀ èdè wa (Internàtional Labour Organisàtion Organisàtion) iyen Ọ̀gbẹ́ni Denis Zulu ni Orílẹ̀ èdè wa kúndún láti ma sàmì àyájó yìí láti lè fi mọ ìtẹ̀síwájú àti ibi tóyẹ ki wọn dojú isẹ́ ko nípa èto àbò ti ìlera lẹ́nu isẹ́.
Ẹ̀SỌ́ ALÁÀBÒ
Àwọn awakò kẹ̀kẹ́ elẹ́sẹ̀ mẹ́ta àti àwọn Olọ́kadà tó bá lòdì sí òfin ìrìnnà ìpínlẹ̀ Èkó ni wọn yóò o kólọ sí ibi tí wọ́n ti ń yẹ àrùn ọpọlọ wò, tí ìjoba yóò sì gbẹ́sẹ̀ lé kẹ̀kẹ́ tàbí irúfẹ́ ọ̀kadà bẹ́ẹ̀.
Olùdarí fún Àjo Ẹ̀ṣọ́ Àrìnyè Ọ̀gbẹ́ni Hyginus Omeje ló kéde ọ̀rọ̀ yìí lásìkò tí wọ́n ńṣe ètò ìdánilẹ́ẹ̀kọ́ tí ìjọba gbé kalẹ̀ pẹ̀lú àwọn Oníkẹ̀kẹ́,Ọlọ́kadà àti àwọn èrò wọn ní Ìjoba Ìbílẹ̀ Ìfàkọ̀ Ìjàyè.
Ogbeni Ofure-Ihenacho tó sojú fún-ún níbi ètò ọ̀wún ni àwọn awakọ̀ yí ní ẹ̀tọ́ sí ojú òpópónà tósì tún nbẹ̀ wọ̀n láti lo ọ̀nà gẹ́gẹ́bí ọmọlúwàbí.
Ọ̀gá àgbà yìí tún ránsẹ́ pé kí wọ́n ri dájú pé àwọn èrò tí wọ́n bá gbé jóòkó bótitọ́.
Nínú ọ̀rọ̀ Alága Kansulu yìí Apostle Ọlọruntoba Òkè lóti ńrọ àwọn Ọlọ́kadà àti oní kẹ̀kẹ́ láti yíí ìwà wọn padà kí wọn sì rí iṣẹ́ wọn bíi iṣẹ́ ẹlẹgẹ́ pẹ̀lú àwọn tí wọn jọ ńlo ojú ọ̀nà.
Àjọ Africa Union ní ò seni láàánu pé àwọn Ológun omo ilẹ̀ Sudan kọ̀ láti gbé ìjoba ilẹ̀ náà fún Alágbádá.
AU ti fún àwọn ológun ní gbèndéke ọjọ́ méẹ̀dógún láti gbé ìjọba fún Alágbádá lẹ̀yín tí wọ́n ti gba ìjoba lọ́wọ́ Ààrẹ Omar al-Bashir ní ọ̀sẹ̀ mẹ́tta sẹ́yín.
Bákan náà ni wọ́n tun fún olórí adìtẹ̀ gbàjọba ní ọgọ́ta ọjọ́ láti gbé ìjọba sílẹ̀ fún alágbádá, bí wọ́n bá kùnà àwọn yóò yọ orílèdè sudan kúrò ní Africa Union.
Ẹ̀wẹ̀ àwọn olori Ológun naa sì ti ń ṣe ìfọ̀rọ̀wérọ̀ pẹ̀lú olórí àwọn ajìjàgbara àti àwọn alátakò bí wọn ṣe leè gbé ìjọba fún àwọn tí wọn ó fìbò yàn
BANGBOSE/AṢOJÚ ILÉ ÌGBÌMỌ̀ AṢÒFIN
Ilé Ìgbìmọ̀ Aṣòfin ẹlẹ́èkẹ̀jọ lábẹ́ Aàre wọ́n Dókítà Bùkọ́lá Sàràkí àti Aka ẹgbẹrẹ rẹ̀ Yakubu Dogara tí wọ́n ń ṣojú nílé ìgbìmọ̀ aṣojú ṣofín ni wọ́n ti júwe gẹ́gẹ́bí aṣíwájú rere tó si ń fẹ́ ìlọsíwájú ilẹ̀ yíì.
Ọ̀mọ ilé ìgbìmọ̀ Aṣojú-ṣòfin tó ń ṣojú Àgbádárìgì Ọ̀gbẹ́ni Joseph Bamgbose ló sọ ọ̀rọ̀ yí lásìkò tó ńgbé o ríyìn fún wọ̣n pé èróngbà ìjọba ló mumú láyà àwọn aka ẹgbẹ́ ilé ìgbìmọ̀ aṣòfin ẹlẹ́ẹ̀kẹjọ, Óní gẹ́gẹ́ bíí ọmọ ilé ìgbìmọ̀ aṣòfin ọ̀hún tisa ipa ribiribi láti mú ayé dẹrùn fún àwọn ènìyàn agbègbè rẹ̀ látàrí ètò ìrónilágbára lórí ètò Ọ̀gbìn, isẹ́ ọnà ti ọ̀pọ̀lọpọ̀ oníṣẹ́-ọwọ́ náà si rí gbà láti jábọ̀ fún àwọn tó lọ sojú fún labuja bákan náà, Ódúpẹ́ púpọ̀ lọ́wọ́ àwọn agbègbè rẹ̀ fún ore-òfẹ́ tí wọn fún láti ṣojú wọn ní ilé ìgbìmọ̀ aṣòfin ósì ṣ̣e ìlérí pé òun kò ní já àwọn ènìyán náà kulẹ̀ lọ́jọ́-kọ́jọ́.
Ọ̀gá Ọlọ́ọ̀pá Mohammed Adamu tí bèrè fún ìjìyà tó gbópọn lórí àwọn ajínigbé, Idúnkokò mọ́ni tàbí ìwà-Ọ̀daràn míì.
Adamu sọ̀rọ́ níbi ìpàdé àwọn Aṣojú Ọmọ ìpínlẹ̀ Nasarawa ẹ̀ka ti Èko lábẹ́ Alhaji Aminu Muasu Maifata lásìkò ọdún Sallah.
O ní látì ìgbà tí wọ́n ti ṣe ìgbékalẹ̀ Puff Addent ni Ọjọ́ karun ún oṣù kerin ọdún 2019 ni Àjọ ọ̀hún ti gba ènìyàn bi métàlélọ́góta kalè lọ́wọ́ àwọn ajínigbé.
Ó fikún ọ̀rọ̀ rẹ̀ pé púpọ̀ lára àwọn ẹ̀sùn tówà nílé ẹjọ́ ni ìwáàdí nlọ lórí ẹ̀ àti àwọn ẹ̀sùn míì.
Ọ̀gá ọlọ́ọ̀pá gbóṣùbà ràbàndẹ̀ fún olùtónisónà rẹ̀ fún iṣẹ́ ribiribi ó sì tẹ̀síwájú pé ohun náà lófa ti àṣeyọrí àwọn ọlọ́ọ̀pá olùgbanisílẹ̀ tí wọn rí àwọn ọ̀daràn mú pẹ̀lú àwọn oun ìjà tí wọn rígbà.
Lójúnà àti mú ìdàgbàsékè bá ètò lílọ bíbọ̀ ọkọ̀ ojú omi ní ìrọ̀rùn ló mú Nigeria Maritime Administràtion and safety Agency (NIMASA) ṣe ìfilọ́lẹ̀ àwọn ọkọ̀ ńlá-nlá ayára bí àṣá lórí omi tó jẹ́ ti àwọn Apẹja tó sì ní ohun èlò ìgbàlódé nínú láti mú ìdàgbàsókè bá ẹ̀ka yìí.
Ògá àgbà àjọ òhún Dókítà Dakuku Peterside ló ṣíṣọ lórí ìwé èrí ní ìlú èkó ní àsìkò ìfikùn-lukùn pẹ̀lú àwọn oní ọkọ̀ ojú omi náà.
Ọ̀mọ̀wé Dakuku ṣàlàyé pé ọkọ̀ ojú omi orílèdè Nigeria wà ní ipò kejì ní áfíríkà báyìí àti mẹ́rìn-dín-ní-àdọ́ọ́ta ní àgbáyé gẹ́gẹ́ bí international maritime organization ṣe fi léde nínú ìgbéléwọ̀n wọn. Ní ìgbẹ̀yìn ìfọ̀rọ̀wánilénu wò tó lékenkà, Àwọn ọlọ́kọ̀ ojú omi fi ìdùnú wọn hàn láti bá àjọ NIMASA ṣiṣé papọ̀, láti leè ṣàṣeyọrí nínú èròńgbàwon láti jẹ́kí ọkọ̀ ojú omi tiwatiwa jẹ́ ìtẹ́wọ́gbà ní àgbáńlá ayé.
Ọ̀gbẹ́ni Bayọ lsinyẹmi tó jẹ́ Olùbádámọ̀ràn Gomina Sanwo-Olu lórí ọ̀rọ̀ ìjọba ìbílẹ̀ àti oyè jíjẹ ni Olóyè Abdul Raman Rafiu Apena ti ṣe àpèjúwe rẹ̀ gẹ́gẹ́bi Olóṣèlú tó ṣe fi Ọkàn tán tó sì ń kó ipa rere láti ran àwọn aláèní lọ́wọ́ pàápàá jùlọ nínú Ẹgbẹ́ òṣẹ̀lú All Progressive Congress Mushin àti Ojúwòyè ní agbègbè ìpínlẹ̀ Èkó.
Ọ̀rọ̀ apinlẹ̀kọ yìí wá láti ẹnu àgbà olóṣèlú Olóyè Abdul Ramon Rafiu Apena ni ó júwe Ọ̀gbẹ́ni Bayọ lsinyẹmi bẹ́ẹ̀ nínú iṣẹ́ ìkíni kú ayẹyẹ Àádọ́rin ọdún wọn.
Alhaji Apena tí ó jẹ́ Balogun Ododowo Ojúwòyẹ̀ fi ìdùnú rẹ̀ hàn lórí ìgbé ayé ìrẹ̀lẹ̀ àti ti ọmọlúàbí tí ọlọ́jọ́ ìbí náà ń gbé, ìgbéayé tó ṣe tẹ̀lé ni, Alhaji Apena tún tẹ̀síwájú láti ṣe àdúrà fún ọlọ́dún náà.
Alágá ìdàgbàsókè Ìkòsì Ìṣhẹ́ri Ọmọbabìnrin Samiat Badà ṣe ìlérí fún àwọn ènìyan rẹ pé Àlàáfíà àti ìdùnnú wọn loún yóò wá ni ìgbà gbogbo o so ọ̀rọ̀ yìí nígbà tí ó ṣe ìbúra fún igbákejì ẹ Alhaji Mukaila Adisa àti pe ètò ìrónilágbára onígbà dégbà fún àwọn opó, àgbàlagbà àti àwọn ọ̀dọ́ bákan náà ló tún rọ àwọn olùgbé láti máa san owó orí lásìkò ki wọn lè ma jẹ ìgbádùn ìjọba síwájú si.
Ó dúpẹ́ lọ́wọ́ gbogbo àwọn àgbà ẹgbẹ́ APC ti àgbègbè kòsòfẹ́ federal constituency fún ìfọwọ́sowọ́pọ̀ wọn. Bíbúra fún igbákejì alága wáyé látàrí ìpapòdà alága àná, Alhaji Abdul-fatai Oyesanya tósì jásí ìgbéga igbákejì alága, Nígbàtí àyè alága sófo.
Aya Gómìnà ìpìnlẹ̀ Èkó Dọ́kítà Ìbíjọkẹ́ Sanwó-Olú ti rọ gbogbo ẹlẹ́sìn Mùsùlùmí láti máṣe yẹ̀ kúrò nínu ìwà rere tí wón gbéwọ làsìkò Ramadan tó kásè ńlẹ̀, kí wọn jẹ́ kójẹ yọ nínú àwon ìwà wọn, àti ìhùwàsí wọn ní àwùjọ àti ní àrin ara wọn.
Dókítà Sanwo-Olu rọ̀ wọ́n níbi Ìrun Odún Eild-el-fitri ní Aláùsá ní Ìkẹjà, ó ní kí wọn máṣe gbàgbé ẹ̀kọ̀ ti osú Lamulana kọ́wa nípa ìfẹ́, Àláafíà àti ìpamọ́ra láìní ẹlẹ́yàmẹyà nínú.
Nínú ọ̀rọ̀ Gómìnà Sanwó-Olú ló ti dúpẹ́ lọ́wọ́ àwọn olúgbé fún ìfọwọ́sopọ̀ wọn tó sì tún ṣe ìlérí pé láìpẹ́ ojú òpó kan máa tó jáde fún ará ìlú láti máa fi kàn sí ìjọba bákan náà lótún óní gẹ́gẹ́ bí ẹṣe mọ̀ pé ìjọba yìí kònífi àyè gba ìgbàkugbà fún àwọn tó ń dalẹ̀ sí ibi tí kòtọ́ àti àwọn tí wọn ń rú òfin ìrìnà gómìnà tún ní ìjọba òun kòní káàárẹ̀ láti rii pé àgbékalẹ̀ òfin àti àfojúsùn òun múnádóko.
Akọ̀rọ̀hìn jábọ̀ pe nibe wọn gbàdúrà fún ìṣèjọba àlàáfià ìpìnlẹ̀ Èkó àti Nigeria láti ẹnu aládarí àwọn lèmọ́mù, tí wọn sì tún ṣe kóríyá fún àwọn ọ̀dọ́ tó díje nínú kíka àkọ́sórí Qurani àti ìdíje ìwé.
Àjọ JAMB ní àwọn kò ì tí kéde iye Gbèndéke máàkì tí àwọn tó ṣe ìdánwò àṣewọlé sí ilé èkó Ifásitì, bí àhesọ ṣe lùgborokan.
Olórí Àjọ Jamb ti ẹka Ìròyìn àti ìpolongo, Dọ́kíta Febian Benjamin ló jẹ́ kí èyí di mímọ̀ nígbàtí ń bá àwọn Akọ̀ròyìn sọ̀rọ̀ ní ìlú Èkó, ó ní kòsí òtítọ́ nínú ọ̀rọ̀ tí àwọn akẹ́kọ̀ọ́ náà ń gbọ́ kiri ó sì gbà wọ́n ní Ìmọ̀ràn pé kí wọn da ọ̀rọ̀ náà nù sígbó. Dókítà náà tún tẹ̀síwájú láti ṣàlàyé pé ọjọ́ kọkànlá oṣú kẹfà ni ìpàdé míràn máá wáyé lórí máàkì tí wọn yóò fi ṣe gbèndéke.
Ò ní Àjọ Jamb yóò ma fi tó wọn létí bí nǹkan bá ṣe ń lọ lẹ́sẹsẹ.
Olúpolongo ìbò sí ipò Agbẹnugan ilé ìgbìmọ̀ Aṣòfin ẹlẹ́ẹ̀kẹsàn án Ọ̀gbẹ́ni Fẹ́mi Gbàjàbíàmílà ti tako ẹ̀sùn Ọ̀daràn tí wọ́n fi kàn án.
Abdulmumuni tó jẹ́ Ọ̀gá àgbà fún ìpolongo ìbò fún Fẹ́mi Gbàjàbíàmílà ìyẹn Ahmed Wase, ní kò sí ilé ẹjọ́ tó fún Gbàjàbíàmílà ní ìwé ìpẹ̀jọ́ láti wá jẹ́jọ́ àti wi pe níwọ̀n ìgbà tí kò ní ẹ́jọ kankan láti jẹ́ o lẹ́ẹ̀tọ́ làbẹ́ òfin láti kópa nínú ètò ìdì̀bò ọjọ́ kọkànlá oṣù kẹfà Ọdún yìí.
Ọ̀gbẹ́ni Jubrin ní Ọ̀gá àgbà Ọlọ́ọ̀pá lẹ́jọ́ kósì rii pé ó tẹ̀lé àwọn adarí ẹgbẹ́ òṣèlú parapọ̀ láti rí I pé ó ṣe ìwáàdí ibi tí wọn tí rí àhesọ ọ̀rọ̀ wọn àti pe àwọn wo ni agbẹ̀yìnbẹbọjẹ́ láti ọ̀dọ̀ ìjọba àpapọ̀ tó ń ṣiṣẹ́ pẹ̀lú wọn.
Ẹ̀wẹ̀ Gbàjàbíàmílà náà ti darí ikọ̀ amòfin rẹ̀ ní ìlànà òfin láti tawọn lójì lórí ìbanilórukọjẹ́.
Omo ilé ìgbìmọ̀ aṣójú-ṣòfin tẹ́|ẹ̀rí fún Kòṣọ̀fẹ́ Ọ̀gbẹ́ni Dayọ Bash Alébíoṣù ní kí gbogbo Ẹlẹ́sìn Islam, o kọ́ ìṣe àti ìwà Òjíṣẹ́ ńlá Mohammed.
Ọ̀gbẹ́ni Dayo Bash sọ èyí di mímọ̀ nígbà tó ń bá àwọn akọ̀ròyìn sọ̀rọ̀ lásìkò pọ̀pọ̀ṣìnṣìn ọdún Eid-el-fitri tí afi sorí ìparí àwẹ̀ olóṣù kan Ramadan.
Bash ni kí gbogbo Aṣíwájú ẹ̀sìn ó máa gbádùrá fún Ààrẹ Buhari àti Gómìnà Sanwo-Olu ti ìpìnlẹ̀ èkó.
Ò tún rọ̀ àwọn ará ìlú láti mágba àdúrà fún Orílẹ̀ èdè wa láti lo àsìkò yìí láti gbàdúrà fún àlááfíà àti ìṣòkan Nigeria.
Gómìnà ìpínlẹ̀ Èkó Ọ̀gbẹ́ni Sanwó-Olú titún jẹ́ kí ìfarajì rẹ̀ pẹ̀lú àwọn olùgbé ìpínlẹ̀ èkó fún àṣeyọrí gbogbo àfojúsùn àti ètò ìṣèjọba yìí
Gomina sọ̀rọ̀ yìí lásìkò tó n gba àwọn Ẹlẹ́sìn Musulumi Òdodo lálejò nínu Ọgbà ìjọba Aláùsá ní Ìkẹjà láti sàmì Eid-el-fitri tó sí ṣe ìlérí pé ojú kan máa tó jáde ti àwọn ara ìlú yóò malò láti lè mafi tó ìjọba létí lórí àwọn ojúnà tó nílò àtúnṣe kí wọn le tètè tunṣe. Ò tún rọ̀ wọn láti bẹ Ọlọ́run fún àlááfíà.
Àwọn ọlọ́ọ̀pá ti pe àkíyèsí àwọn Oníṣòwò ilé ìtura láti máa wà ní ojúlalákàn fi ńṣọ́rí nígbà gbogbo láti má wo lílọ bíbọ̀ àwọn ọmọ ẹlẹ́gbẹ́ òkùnkùn bóṣe jẹ́pé ilé ìtura nibi ìpàdé wọn.
Olùdarí àwọn Ẹ̀sọ́ tó ń gbógun ti ẹgbẹ́ òkùnkùn Ọgbẹ́ni Udom Udoak lo kéde ọ̀rọ̀ nígbà tó n ṣe ìpàdé pelu àwọn Olórí àdúgbò àti Onílé-ìtura àti àwọn Ọdẹ ní agbègbè Gbàgádà lórí akitiyan àwọn ọlọ́ọ̀pá láti dẹ́kun ṣíṣe ẹgbẹ́ òkùnkùn
Uduak rọ gbogbo àwọn tó ní ilé ìtura láti máa lo ẹ̀rọ ònmọ̀ CCTV kí wọ́n si ma fi tó àwọn ọlọ́ọ̀pá létí nígbàkigbà tí wọ́n bá kẹ́ẹ́fín wọn.
Àjọ olómi ìpìnlẹ̀ Èkó ni Ojúnà tí wọ́n ń ṣe ní Ojúnà márosẹ̀ Èkó sí Abéòkúta ló ṣe ìdíwọ́ fún omi tíkò já gaara fún àwọn olùgbé Ìyànà-Ìpájà, Ẹgbẹ́dá,Dọ̀pẹ̀mú,Orílé Agége,Ìdímù,Ìshẹri Olófin àti àwọn agbègbè tó kù.
Nínú ọ̀rọ̀ tí Olùdarí àgbà fún àjọ Olómi Ọ̀gbéni Muminu Badmus ṣe lálàyé pé àwọn ọ̀pá omi tó gbé omi sí àwọn ìlú yìí lóti bàjẹ́ lásìkò iṣẹ́ ojúnà.
Ó rọ̀ àwọn olùgbé láti máse bínú kí wọ́n mú sùúrù pé láìpé omi tójágara má tó padà sí ọ̀dọ̀ wọn.
Alága àjọ elétò ìdìbò nì ilẹ̀ yìí Ọ̀jọ̀gbọ́n Mahmood Yakub ti ṣe àpéjùwe ìgbésẹ̀ fún ìgbaradì ètò ìdìbò èyí ti àwọn kan ńlòdì sí òfin.
Ó ní ìgbèsẹ́ tuntun yìí ni láti lè jẹ́ kí ohun gbogbo lọ bótitọ́ tó sì bá ìlànà ètò ìdìbo mu.
Ọ̀jọ̀gbọ́n Yakubu sọ ọ̀rọ̀ yìí níbi ìpàdè Àjọ àwọn elétò ìdìbò ẹlẹ́kejìlá irúu rẹ̀ tó wáyé ní Jos olú ìpìnlẹ̀ Pleateu.
Alága tí àwọn lọ́ọ̀gálọ́ọ̀ga lọ ṣojú fún bí Alága àjọ tó ń ṣe àmójútó, Alága fún àwọn kọmíṣọ́ná àti Olùpolongo àti ọ̀gá lẹ́ka ìkọ́èkọ́ nípa ètò ìdìbò, Ọ̀gbéni Festus ní ìlànà yìí fé ní ọwọ́ àbòsí nínú tí kò sì fẹ́ jẹ́ ḱi àwọn ènìyàn ní ìgbàgbọ́ nínú wọn.
Ó ní Àjọ yìí ń ṣe àtúngbéyẹ̀wò tí yóò yanjú gbogbo àwọn awuyewuye tí ó ńṣẹ́ yọ kí á tó dìbò, ó kéré tán Ọgọ́ta ọjọ́ sí ìdìbò.
Ọ̀jọ̀gbọ̀n Yakubu ní eni tí Ẹgbẹ́ bá yàn ní ètọ̀ láti má gbaradì fún ìdìbò.
Ọ̀gá àgbà yìí tún ṣe kìlọ̀-kìlọ̀ pé yíyọ Orúkọ àti àmì ẹgbẹ́ òṣèlú àti pípàrọ̀ orúko aṣojú ẹgbẹ́ títí dí ọjọ́ kejì ìbò ní ìdarí àṣẹ ilé-ẹjọ́ àti polongo jẹ́ wàhálà àti ìdàmú.
A nílò láti máa gbé nínú ìrẹ́pọ̀ kí ìdàgbàsókè ó lè dé àgbègbè wa.
Gbólóhùn yìí ló ti ẹnu Alága ìdàgbàsókè Òjokòro Ọ̀gbẹ́ni Hammed Ìdòwú Tìjání wá, níbi wáàsí Àwè tó wáyé nínú ogbà káńsùlù wọn tó sì ń pàrọwà fún àwọn Òṣìṣè láti fi Ìmọ̀ sọ̀kan.
Alága gbé oríyìn fún gbogbo ọmọ ẹgbẹ́ tí ń ṣe iṣẹ́ mùsùlùmí òdodo pẹ̀lú ìwà pẹ̀lẹ́ ní gbogbo ìgbà niwọ́n má ń tọ́jú ara wọn pẹ̀lú ìbáṣepọ̀ tó dán mánrán tíwọn gbé ṣe pẹ̀lú àwọn ẹgbẹ́ ẹlẹ́sìn míràn, tún rán wọn létí pé àsìkò Ramadan jẹ́ èyí tí a fí nfọ Ọkàn àti ara mọ́ àti pẹ̀lú kámá ní ìwà rere sí omolàkejì láì wo ti Ẹ̀sìn tàbí Ìwà.
Bákań náà ló tún rọ̀ wọ́n láti má ṣe àtìlẹ́yìn tóyẹ ju ti tẹ́lẹ̀ lọ fún ìṣèjọba òun kí àwọn le ṣe àṣeyorì nítorí pé (Ẹnikan ki jẹ Awade)
Ọ̀gbẹ́ni Tijani kò ṣàì dúpẹ́ lọ́wọ́ Ọníwáàsí ọjọ́ náà ìyẹn Fadiilat Sheik Ajani Bello fún Oúnjẹ èmí t́i wọ́n fi bọ́ wọ́n.
Àarẹ Mohammadu Buhari ti ṣe ìfilọ́lẹ̀ àwọn tí yóò máa ṣe àmójútó ìdàgbàsókè Àríwá Gúsù tó sì ti yan Ajagun fẹ̀yìntì Paul Tarfa gẹ́gẹ́ bí alága wọn.
Nínú ọ̀rọ̀ Àarẹ ló ti ní ó yẹ kí irú àgbékalẹ̀ yìí ó wà lágbègbè ọ̀hún kí wọ́n le mójútó bí wọn yóò ṣe ṣẹ́gun àwọn Apanilékún Boko Haram tó ńda àlááfìa ilù wọn láàmú.
Ààrẹ ni àwọn ṣe èyí láti fi ẹ̀mí ìmoore hàn sí àwọn Ènìyàn yìí fún bí wọ́n ṣe fi ìbò gbé òwun wọlé 2015 àti 2019 ó sọ ọ̀rọ̀ ìfẹ̀mímoore hàn nígbà tó ńṣe ìbúra fún àwọn ikọ̀ yìí .
Aarẹ Buhari ní àwọn ikọ̀ yìí o ma jábọ̀ fún ìjọba tí wọ́n o ṣì maa ṣe ètò ìlanilóyẹ ìrónílágbára àti amáyédẹrùn tí àwọn dúkià ìjọba kò fi ní maa ṣòfò mọ́.
Ó tẹnúmọ pe ìgbésè yíyan àwọn ènìyàn tí yóò ma ṣóju ìjọba, àti pé ó wà lára ìlérí tòún ṣe lásìkò ìpolongo ìbò láti mú ìdàgbàsókè bá ọrọ̀ ajé wọn kí ìpín tí́wọ́n náà le tẹ̀wọ́n lọ́wọ́ lẹ́yìn tí wọ́n bá ti rẹ́yìn àwọn ikọ̀ Boko-Haram.
Àjọ tó ń gbógún ti ìṣowó ìlú mọ́ku-mọ̀ku tí ní àwọn ṣì ńtẹ̀síwájú nínú ìwáàdí bí Àarẹ ilé ìgbìmọ̀ aṣòfin, Bukola Saraki, ṣe ná owó nígbà tó ṣe Gómìnà ìpínlè Kwara lọ́dún 2003 si 2011.
Àjọ yìí ní àwọn ò ní dẹ̀yìn níbi ìwáàdí ìwà àjẹbánu láì wo irúfẹ́ ipò tàbí àyè tí t̀í eni ọ̀hún lè jẹ́.
Ténìyàn ò ba ṣe ohun Etùfù kòyẹ kó kíyèsí èhìnkùléni Àjọ yìí sọ fún Ààrẹ ilé ìgbìmọ̀ Aṣòfin.
Tony Oríkóládé tó jẹ́ Olórí léka ìròyìn fún àjọ (EFCC) ní àwọn yóò ṣe ìwá ìfín ìdikóko bí ó ṣe náa owó ìpìnlẹ̀ Kwara nígbà tó ńṣe Gómìnà ní ìpìnlẹ̀ kwara.
(Ọmọ aifọ lorò ńgbé) lómú Aṣòfin Bùkọ́lá Sàràkí fèsì pé Ìròyìn àgbélẹ̀ro àti ìbanilórúkó jẹ́ lásán ni ọ̀rọ̀ yìí.
Àwọn Aṣòfin ti yan igbákejì Ọ̀gá àgbà tẹ́lẹ̀rí fún ilé ìfowópamọ́ Erinlónibú orílẹ̀ èdè wa Ọ̀gbẹ́ni Túndé Lemo gẹ́gẹ́bí Alága fún Àjọ tó ńṣe àtúnṣe àwọn òpópónà tó jẹ́ ti ìjọba àpapọ̀, Àwọn aṣòfin tẹ́wọ́gba àbọ̀ áwọn ìgbìmọ̀ (FERMA) tí wọ́n fi ẹnu kòsí yíyan Lema gẹ́gẹ́bí alága wọn pẹ̀lú àwọn méje mìíràn láti máa ṣe ìṣàkóso.
Nurudeen Rafindadi ni wọ́n yàn sí ipò Olùdarí Àgbà fún àjọ yìí àti àwọn tí wọn yóò jọ ṣiṣé pọ̀ bí Buba Abdulahi Babangana Aji,Sha Abdulahi,Lorreta Aniagholu,Mujideen Dako àti Ọ̀gbẹ́ni Vincent Kọ́láwọlé.
Alága Ìgbìmọ̀ yìí Senator Magnus Abe ní, nínú ìwáàdí làwọn tí ríi pé àwọn ènìyàn yìí yẹ ní ipò Aládarí yìí.
Àjọ orílẹ̀ èdè tì buwọ́lu owó rọ̀gùn-rọ́gún Ọgọ́rùnmẹ́sà án Million Naira láti fi kọ́ ilé tó bójúmu fún àwọn Aṣọ́bodè ilẹ̀ wa.
Ḿinísítà fún ètò Ìṣúná Abilékọ Zainab Ahmeed ló kéde ọ̀rọ̀ yìí lẹ́yìn ìpàdé ìfẹnukò láàárín Àjọ yìí pèlú Àarẹ Mohammadu Buhari ní ilé ìjọba láàbújá.
Ahmeed ní àwọn Aṣọ́bodè ti ń bèèrè fún ilé olówópọ́ọ́kú aládàáni méjìlélógójì tí iye tí yóò si parí ọ̀kòokan jẹ́ Ọgọ́rùn-ùn-márùn-ùn lélàáadọ́ta mílíònù fún igun kọ̀òkan tí àpapọ̀ ẹ sì jẹ́ búlókù méfà.
Ó ṣe àfikún pé àwọn ẹ̀ṣó aṣọ́bodè yìí léètó sí àwọn èèlò ìkàn síraeni bíi Rédíò aláàgbéká,Ẹ̀̀ro ìbánisọ̀rọ̀ aláàgbérín,okùn afainá àti èròjà míì tí iye owó rẹ̀ jé Mílíònù Méjì Náírà.
Mínísítà ní àwọn èèlò yìí yóò ṣe ìrànwọ́ fún àwọn ẹṣọ́ yìí láti dá àwọn Onífàyàwó lẹ́kun àti wíwọlé sílẹ̀yí lọ́nà tí kò bá òfin mu.
Àjọ àgbáyé tó ń ṣe ìgbéléwọ̀n ilé kíkọ́ lórílẹ̀ èdè yìí (ICC-NNC)ọ̀gá àgbà kan léka yìí Ọ̀gbẹ́ni Joseph Otejere ní títẹ̀lé ìlànà àjọ yìí ni a filè dẹ́kun ilé wíwó.
Otejere ní ọ̀pọ̀ àwọn ọ̀ṣìṣẹ́ kọ́lé-kọ́lé àti àwọn Agbalékọ (DEVELOPER)ni wọn kìí tẹ̀lé ìlànà ilé kíkọ́, ọ̀rọ̀ yìí ló sọ fún àwọn Akọ̀ròyìn níbi ìṣẹ̀lẹ̀ ilé kan tó dàwó lulẹ̀ ní ìpìnlẹ̀ Èkó nìgbá tì òjò ńlá bèrè.
Ó sọ nínú ọ̀rọ̀ rè pé oríṣiríṣi ọ̀nà là ńlò fi kọ́lé nílè wa pàápàá àwọn ilé tóbájẹ́ gogoro lóyẹ kí wọ́n ya àwòrán fún un kó lè yé wọn dáadáa kó tó di pé wọn o bẹ̀rẹ̀ síní kọ́ọ àti pé títèlé ìlànà òfin ilé kíkọ́ ṣe pàtàkì.
Ó ní ó yẹ kí wọ́n máa tọ àwọn Akọ́ṣẹ́mọṣẹ́ lọ láti mọ̀ nípa ìlànà àti òfin, ó tún gba wọ́n níyànjú pé àwọn ìlànà ìkọ́lé ni àwọn ìlu ńlá-ńlá tí àwa náà lè máa lò láti fi kọ́lé tí yóò fi wá lọ́kàn balẹ̀ nígbà òjò tàbi nígbà ẹ̀ẹ̀rùn.
Ó ṣàlàyé nípa ìṣẹ̀lè ilé kan tó wó ní ìlu Port Harcourt ó ní ìwáàdí ló jẹ́ kí wọ́n mọ̀ pé àìkúnjú òṣùwọ̀n àgbaṣẹ́se ló fa ìṣẹ̀lẹ̀ òhun.
Adarí fún Orílẹ̀ èdè olómìnira Korea sí ilẹ̀ wa Nigeria Ọ̀gbẹ́ni Jon Tong Chol ti pe fún ìfọwọ́sowọ́pọ̀ ṣiṣẹ́ láàárín ilẹ̀ Korea àti Nàìjíríà fún ìdàgbàsókè tó lọ́ọ̀ọ̀riin
Ó pe ìpè yìí níbi Àpèjẹ ọjọ́ ìbí ọdúnmétàdínláàdọ́fà tí wọn ṣe fún Kim II Sung tí ilé àwọn ilè àṣe ì́lu òhún tó wà ní ílù Àbújá ṣe fún.
Ọ̀gbẹ́ni Jon tó gbẹnusọ fún Kim Chin ll tó jé Akọ̀wé àti Ògbùfọ̀ ni, ó ti pẹ̀ tí àjọṣepọ̀ ti wà láàárín orílẹ́ èdè méjèjì yìí àti pé wọ́n fẹ́ kó tún fi ẹsẹ̀ rinlẹ̀ ju ti àtẹ̀yìnwá lọ.
Agbẹnusọ yìí ní táabá wò dáadáa a o ri pé nínú Àsía orílè èdè Korea àti Nàìjíríà ní ìbádọ̀rẹ́ ọlójọ́ pípé tiwà láti ayé Kim ll Sung àti Kim Jon tí wọ́n jẹ́ bàbá ń́lá wọn.
Láàkótán ó ní, ìbáṣepò Àṣà àti ìdọ́ọrépọ̀ wa sì n tèsíwájú.
Àwọn jagun-jagun tí wọ́n dìtẹ̀ gbà ìjoba ti ṣe ìlérí pé gbígbà tí àwọn gba ìjọba ní ìbámu pẹ̀lú ìfẹ́-inú àwọn ara ilú.
Wọ́n ní ọwọ́ ará ilú ni àṣẹ wà bóyá wọ́n ṣì ń fẹ́ Àarẹ yìí nítorí pé àwọn ni wọ́n bọ́síta láti ṣe ìfi èhónú hàn pé kí wọ́n yọ Aarẹ Ọrílẹ̀ èdè wọn, ìyẹn Omar al Bashir.
Àwọn olùwọ́de kó ara wọn jọ sí agbègbè kan ní àdúgbò Khartoum, bí wọ́n ṣe ńfura pé olórí àwọn adìtẹ̀ gba ìjọba ọ̀hún leè súnmọ́ ọ̀gbẹ́ni Bashir pẹ́kípẹ́kí.
Àwọn Ológun ní àwọn ò ní tẹ̀lé ẹ̀sùn tí àjọ Àgbáyé fi kàn án ní ilé ẹjọ́ pé ó ńṣi agbára lò lórí àwọn ara ilú lágbègbè Sudan Darfur lọ́dún 2003 sí 2008.
Nítorí náà, wọn leè fàá fún ìjẹ́jọ́ ní inú ìlú sudan, gẹ́gẹ́ bí àlàkalẹ̀ ìgbìmọ̀ tí ológun adìtẹ̀ gbàjọba gbé kalẹ̀
Ìṣubú ìjọba yìí ni wọ́n ní kòsé lẹ́yìn òwón gógó ọjà tó ti ń ṣẹlẹ̀ láti ọṣù díẹ̀ sẹ́yìn, tí ènìyàn méjìdínlógójí sì ti bá ìṣẹ̀lẹ̀ òhún lọ.
Àwọn jagun-jagun ní àwọn yóò ma darí ilú títí tí ìdìbò yóò fi wáyé tósì tún kéde kónílégbélé olóṣù mẹ́ta.
Ológun ni yóò ma darí fún Odún méjì, ṣùgbọ́n wọ́n ní ólè máju osù kan lọ tí ọ̀rọ̀ àwọn Olóṣèlu bá yé ra wọn lásìkò.
Ó dín díè Lógóje-Ẹgbẹ̀rún ọkọ̀ ló ti lu òfin ìrìnà ní ipìnlẹ̀ Èkó, tí àwọn ọkọ̀ yìí sì jẹ́ ti àwọn Kọmíṣọ́ná, Aṣòfin, Òjíṣẹ́ Olúwa àti àwọn míì ní wọ́n tiṣẹ̀ sí òfin ìrìnnà ọkọ̀ ìpìnlẹ̀ èkó láàárín oṣù kínní sí ìkẹta ọdún 2019 tí ẹ̀rọ titun tí mú nọ́uńbà ọkọ̀ sì mú nóuńbà ọkọ̀ wọn silẹ̀.
Ọ̀gbẹ́ni Gbọ́láhàn Toríọlá tó jẹ́ olùdarí àwọn ẹ̀ṣọ́ yìí ní ẹ̀rọ tó ń ṣọ́ lílọ bíbọ̀ ọkọ̀ ló ti mú nóuńba àwọn ọkọ̀ yìí sílẹ̀ nígbà tí wọ́n ṣẹ̀ sí òfin ìrìnnà ó ní ẹ̀rọ yìí náà ló jẹ́kí wọ́n mọ orúkọ àti irúfẹ́ àwọn ènìyàn tí wọ́n jẹ́.
Toríọlá ní, tí arúfin kan bákọ̀ láti wá jẹ́jọ́ lẹ́yìn ọjọ́ méje pé, wọn ó fi orúkọ rẹ̀ sí ìwé ìbanilórúkọ jẹ́ wọn ósì tún gbée lọ ilé-ẹjọ́ aláágbéká pelu ẹ́kúnwó ìtanràn rè yóò tún lé sí ìdá/ọgọ́rùn-ùn.
Ó ní lẹ́yìn àyẹ̀wò agbára ẹ̀rọ yìí lómú káwọn ṣe ìfilọ́lẹ̀ sí ojúnà ìpínlẹ̀ Èkó.
Fífi òfin de àwọn ọlọ́kadà àti kẹ́kẹ́ ẹlẹ́sẹ̀ mẹ́ta ní ìjọba ti ṣe àpèjúwe bí ojúnà ìdábò bò ará ìlú Eko áti dúkìá wọn.
Àkó ọ̀rọ̀ yìí Alága ìdàgbàsókè ìwọ̀-òòrùn Àgbádárìgì Ọgbẹ́ni joseph Gbenú Henugbe nigbati o n dahun sii ibere àwọn Akọròyìn nípa ìnira tí òfin ọ̀hun múbá ará ìlú.
Lóòótó Ọ̀kadà àti kẹ̀kẹ́ ẹlẹ́sẹ̀ mẹ́ta ni ó jẹ́ ọ̀nà tí ó yára fún àwọn èniyàn láti bọ́ lọ̀wọ̀ súnkẹrẹ- fàkẹ̀rẹ lójú pópó síbẹ̀ kíì ṣe ojúùtú sí ìṣòro.
Alága ní pẹ̀lú àwọn Àkànṣe ọ̀nà tí Gómìnà Sanwó-Olú ń ṣe yìí o mú ìdàgbàsókè àti ìrọ̀rùn bá arà ìlú.
Ìjọba ìpínlẹ̀ ti ké gbàǹjarè sí etí àwọn arìn-ìrìn àjò sí orílẹ̀ Ọ̀jọ̀gbọ́n tàbí ní ìbáṣepọ̀ pẹ̀lú Ọmọ ilẹ̀ China, kó tètè jọ̀wọ́ ara sí ibùdó àyẹ̀wò látárí àìsàn Corona-virus tó ti China wa.
Kọmísọ́na fún ètò ìIera Ọ̀jọ̀gbọ́n Akin Àbáyòmí ní dídá ṣe ìtọ́jú ẹni léwu pùpọ́ lórí àìsàn Corona tí àwọn arìnrìn àjò ń ṣe òun ni ìgbésẹ̀ kínní láti kó àrùn yìí.
O ní wọn sọ èyí láti dáàbòbo olúkúlùkù àti láti máa bá gbá áìsàn yii láàyè.
O tẹ̀síwájú pé ẹnikẹ́ni tó bá fẹ́ ṣe ìtọ́jú fún ara rẹ̀ gbódọ̀ jóòko sílé láìgba àlejò tábí lọsí àwùjọ ọ̀pọ̀ ènìyàn, Ó gbọdọ̀ sáfún àwùjọ ọ̀pọ̀ ènìyàn kò sì gbọdọ̀ wọ ọkọ̀ èrò tàbí ọkọ̀ ojú òfurufú.
Ọ̀jọ̀gbọ́n Àbáyọ̀mí rọ àwọn ará ìlu láti kọ̀yìn sí ìròyìn tí kò báti ọ́físì Àjọ elètò ìlera jáde.
Àwọn ọmọ ìsọ̀ta tí n ṣọbà lórí ilẹ̀ tí wọ́n yà sọ́tọ̀ fún ilé ẹ̀kọ́ Girama ní Òtúmarà ni èbúté mẹ́ta ní ìlú èkó ni wọ́n ti gbà ní ìmòràn pé kí wọn kúrò ní orí ilẹ̀ náà.
Baálẹ̀ Kẹhinde Kalẹ̀jayé ló gba àwọn Oníròyìn nímọ̀ràn ọ̀rọ̀ yìí ní ìlú èkó.
O ní, ilẹ̀ yìí ni ìjọba ti yàà sọ́tọ̀ fùn ilé ìwé aláàkọ́bẹ̀rẹ̀ mẹ́fà lásìkò ìṣèjọba Jakande tósì jẹ́pé méjì ní wọn le parí nínú rẹ̀.
Olóyè Kalẹ̀jayé ní ó wá jẹ́ ohun ìyàlẹ́nu pe ìyókùn nínú ilẹ̀ náà ni àwọn ọmọ asùnta ti wá sọ ibẹ̀ di ibùgbé.
O tako ìròyìn kan tóní wọn ti ya ilẹ̀ náà sọ́tọ̀ fún ilẹ̀ Ọjà, Kalẹjaye ní irọ́ pátápátá gbáni.
Baálẹ̀ gbóríyìn fún Gómìnà Sanẃó-Olu, Alaga Dainland Abilékọ Ọmọlọlá Essien àti Ọ̀gbẹ́ni Adekanye fún àdúrótì wọn lórí ètò yìí.
Ìjọba ìpínlè Èkó ti tún bẹ̀rẹ̀ ìtanijí lórí àwọn ilẹ̀ olómi fún àwọn nǹkan Àlùmọ́nì tó nbẹ nínú rẹ̀.
Ọ̀gbẹ́ni Bello ní ìpínlẹ̀ Èkó fi àsìkò yìí la àwọn ènìyàn lọ́yẹ̀ lórí iwúlò àti Àlùmọ́nì tó fi ara sin sínú omi, wọn w ápè àwọn àgbègbè tókùn kí wọn wá darapọ̀ mọ́ wọn nínú ìgbélárugẹ oun àlùmọ́nì tó fara sin sínú omi.
O tẹ̀síwájú pé ìkẹ́ ni àwọn ilẹ̀ yìí jẹ́ fún àláàdúgbò tó bá wà nítorí pé ó dára fún Ọ̀gbìn ewébẹ̀, iṣẹ́ ọnà àti àwọn nǹkan mère mère míràn bíi ibi ìgbàfẹ́.
Ọ̀gbẹ́ni Bello ní ìjọba yóò dá ètò ìmójútó àti ìpolongo sílẹ̀ láti ríi pé àwọn ènìyàn jànkàn jànkàn láwùjọ yóò fọwọ́sowọ́pọ̀ pẹ̀lú wọn láti dáàbò bo oun alumoni ti ipinlẹ yii ri ninu omi.
Alága ẹgbẹ́ àwọn awakọ RTEAN lórílè èdè yìí Alhaji Musa Mohammed ti kìlọ̀ fún àwọn Awakọ̀ láti máṣe gbé owó lé ọkọ̀ látàrí kíkó tí ìjọba kó kẹ̀kẹ́ Marwa kúrò nílẹ̀
Ó sọ ọ̀rọ̀ yìí níbi tí ilé ẹ̀kó ìpoògùn ti ìjọba ìpínlẹ̀ Èkò tí wọn tún fi àmì ẹ̀ye dá Gómìnà lọ́lá tí òun naa sì tún se ìlérí pé òun yóò túnbọ̀ teramọ ìgbélárugẹ ètò ẹ̀kọ́.
Ilé ìgbìmọ̀ aṣòfin ti páláṣẹ fún àwọn ẹ̀ṣọ́ aláàbò ti pápákọ̀ òfurufú ti ìjọba Àpapọ̀ láti se ìmójútọ́ àti fífi ara balẹ̀ ṣe ìwáàdí àwọn tó n gbé egbògi olóró àti lẹ́ka mìíràn tí iṣè wọn jẹmọ́ o.
Àwọn Aṣòfin ní àwọn tí àyẹ̀wò bá kún ojú òṣùwọ̀n nìkan lóní ẹ̀tó láti dúró láwọn agbègbè yìí.
ilé ìgbìmọ̀ Aṣòfin buwó lu àbá tí Aṣòfin Ibrahim Olúlégba gbé sí iwájú wọn, tí àwọn aṣòfin méje mìí tún kín n lẹ́yìn, bákan náà lótún mú ẹnu ba ṣíṣì tí wọn ṣí Ọmọdébìrin Zainab Aliyu mú ní Saudi Arabia pé ó gbé egbògi olóró.
Ò fi ìdùnnú rẹ̀ hàn bí orí ṣe kó Aliyu àti àwọn meji mìí yọ lọ́wọ́ ikú àìmọ̀dí lẹ́yìn ìwáàdí tó fìdí rẹ̀ múlẹ̀ pé wọn kòmọ bí egbògi olóró náà ṣe dé inú àpamọ́ wọn.
Àtúnṣe ojúnà Àgbádárìgì ti tún bẹ̀rẹ̀.
Igbákejì Gòmìnà Dókítà Ọbáfẹ́mi Hamsat ní àtúnṣe ọ̀hún bẹ̀rẹ̀ láti ọjà ńlá Trade fair lòjúnà márosè Àgbádárìgì.
Dókítà Hamsat ìṣíkejì ọ̀nà yóò láàrín Agboju sí traid fair.
Ó ní ọ̀nà náà yóò fẹ̀ẹ̀ láti abala mẹ́rin tówà tẹ́lẹ̀ losí abala mẹ́ẹ̀wá.
Ó ṣe ìlérí pé àtúnṣe ọ̀wun yí parí nínú oṣù kejìlá ọdún.
lgbákejì Gómìnà rọ àwọn Awakọ̀ láti faradà ìnira tí àtúnṣe òhún le ma mú bá wọn .
Bákan náà ló ní kí wọn máa tẹ̀lé òfin kí wọ́n máṣe sáré àsápajúdé kí wọ́n sì rántí àwọn ẹlẹ́sè, kí àwọn ẹlẹ́sẹ̀ náà ó ṣẹ pẹ̀lẹ́-pẹ̀lẹ́ làsìkò àtúnṣe ọ̀nà yìí.
Ó fikún ọ̀rọ̀ rẹ̀ wí pé ìfọwọ́sowọ́pọ̀ tiwà láàrín àwọn òṣìṣẹ́ẹ́ Àjọ atún ọ̀nà ṣe tó jé ti ìjọba Àpapọ̀ láti ṣe àtúnse ọ̀nà igbó elérin jáde sí Àgbárá.
Akọ̀wé àjọ Amúṣẹ́ṣe dúpé, Ọ̀gbẹ́ni Olujimi Hotonu ní, láti bí ọdún méwàá sẹ́yìn ni ọ̀nà yí ti nílò àtúnṣe.
Ẹgbẹ́ òṣẹ̀lú People Democtic Party (PDP) ẹkà t‘èkó ti ní ó yẹ kí Ìjọba se ìrànwọ́ fún àwọn ebí àwọn èrò tó pàdánù èmí wọn nínú Ọkọ̀ ojú-omi ni Agbègbè Bádóre Ìkòròdú
Nínú ọ̀rọ̀ ti Agbẹnusọ fún ẹgbẹ́ yìí, Ọ̀gbẹ́ni Taofik Gani ní Ẹgbẹ́ Òṣèlú bere fún ìwáàdí múnádóko lórí ìṣẹ̀lẹ̀ yíi.
Ó fi ọ̀rọ̀ náà léde pé ọkọ̀ ojú omi tí ó ń dànù lemọ́lemọ́ ní ẹka ojú ọ̀nà orí omi ti ṣe ikú pa ọ̀pọ̀lọpọ̀ ènìyàn.
Báakan náà lótún gba Gómìnà Sanwó-Olú lámòràn láti pèsè àwọn ohun èèlò ààbò ìrìnnà ọkọ̀ ojú omi bí aṣọ ìdáàbòbò, ọkọ̀ ìdóòlà èmí àti iná ọba tó mọ́lẹ̀ rokoṣo pẹ̀lú àwọn akọ́ṣẹ́mọṣẹ́ awakọ̀ ojú omi.
Ó tẹ̀síwájú pé kí Gómìnà Sanwó-Olú mójútó àwọn kùdìẹ-kùdìẹ ní tó nkójú àwọn olúgbé ìpínlẹ̀ èkó.
Ipa ribiribi ní isẹ́ ọwọ́ àti Ọgbọ́n àtinúdá ń mú bá ìdàgbàsókè ọrọ̀ ajé.
Olùdarí Àgbà fún ilé Ẹ̀kọ ìgbóhùn sáfẹ́fẹ́ Arákùnrin Abíólá Ajíbólá tó tẹnumọ́ ọ̀rọ̀ yìí nígbà tó ń ṣojú Ọ̀gá Àgbà pátá-pátá fún ilé isé Rédíò Ìjọba Àpapọ̀ Dọ́kítà Maosur Liman níbi ètò tí wọ́n fi ṣíde ìgbẹ̀kọ́ ọ̀wọ́ kejì àwọn akẹ́ẹ̀kọ́ nípa ìgbóhùn sáfẹ́fẹ́ tó wáyé nínú ọgbà ilé ẹ̀kọ́ òhún ní GRA Ìkẹjà.
Arákùnrin Ajibọla rọ àwọn Akẹ́ẹ̀kọ́ pé kí wọn ríi pé wọn ṣiṣẹ́ takuntakun láti ríi pé wọn dá iṣẹ́ ti ara wọn sílẹ̀ kí wọn leè kojú ìṣòro àíríṣẹ ṣe tó débá orílèdè yìí, Ó sì ṣe ìlérí pé òun yóò dá ìdánilẹ́ẹ̀kọ́ kan sílẹ̀ láàrin ẹ̀kọ́ ọlọ́sẹ̀ mẹ́sàn án tí wọn ń ṣe lọ́wọ́
Bákan náà lótún rọ àwọn Akẹ́ẹ̀kọ́ láti jẹ́ Ọmọlúwàbí kí wọ́n siì jìnnà sí ẹgbẹ òkùnkùn nítorí pé ẹgbẹ́kẹ́gbẹ́ ń ba ìwà rere jẹ́.
Nínú ọ̀rọ̀ ti Ọ̀gá Àgbà fún gbogbo ẹ̀ka Abílekọ Nkiruka Okiche lòun ti ka ìlànà òfin iléìwé ọhún sí ẹtíìgbọ́ wọn.
Ọ̀gbẹ́ni Tanko Abdulahi tóun jẹ́ Ọ̀gá léka Ìgbẹ̀kọ́ naa gbà wọ́n níyànjú láti ní ẹ̀mí àti máa ṣe ìwádìí lóòrèkórè.
Gomina Sanwó –Olú ti fi ọwọ́ ṣọ̀yà fún àwọn Agbábọ́ọ̀lù ikọ̀ Fífà pé kí wọ́n lọ fi ọkàn balẹ̀ pé ètò ààbò tó péye, lóri lílọ-bíbọ̀ ní ìrọ̀rùn, ilé ìgbè tó fini lọ́kàn balẹ̀ àti ṣíṣe àkóso láàrin ogunlọ́gọ̀ ènìyàn, ní ìlú Èkó, tí orílèdè Nàíjíríà bá gbé gbá orókè láti ọwọ́ Àjọ FIFA pé kí wọn lọ ṣe kòkárí àti gba ìdíje àwọn ọmọbìnrin tí ọjọ́ orí wọn kòju ogún ọdún wá sílẹ̀ lọ
Ọ̀rọ̀ yìí ló jáde lásìkò tí àwọn ikọ̀ tí ń ṣàbẹ̀wò láti Àjọ FIFA tí alága àwọn agbábọ́ọ̀lù ní orílèdè yìí NFF Amaju Pinnik darí wọn lọ ṣe àbẹ̀wò sí gómìnà lọ́ọ́fìsì rẹ̀ ní Ìkẹjà.
Ó ní Ọriĺẹ̀-èdè yìí ti gbaradì fún eré Ìdárayá ẹlẹ́ẹ̀kẹrìndínlógún irú rẹ̀ tí wọ́n sì ti pèsè àyè sí ílu Benin city, Asaba àti Uyo.
Sanwó-Olú ní ìpínlè Èkó pẹ̀lú ẹgbẹlẹmùkú ènìyàn tó lé ní Ogún mílíònù óní ìlú Èkó ní agbára, àti àwọn Ọ̀dọ́ lọ́lọ́kan òjòkan àti ọ̀yàyà láti gba àlejò, gẹ́gẹ́ bí ìlú kan gbòógì tí wọ́nti yà sọ́tọ̀ fún ìdíje tó ń bọ̀ yìí.
Gómìnà, tún mú ẹnu ba ti ìpalẹ̀mọ́ Orin tó ń bò láìpẹ́ yìí, ó tún jẹ́ ọ̀nà ìmúgbòòrò ọrọ̀ ajé nípa ìrìn àjọ ìgbafẹ́.
Amaju Picnic tó jẹ́ Ààrẹ fún Ẹgbẹ́ agbábóòlù ilẹ́ wa dúpẹ́ lọ́wọ́ Gómìnà fún ọ̀rọ̀ ìyànjù oníyebíye tóbá àwọn agbábọ́ọ̀lù Ọkùnrin àgbà sọ, ó tún fi kún pé àwọn ikọ̀ yìí wá fún ìrànwọ̀ ìjọba láti jẹ́ kí eré ìdárayá bọ́ọ̀lú aláfẹsẹ̀gbá ó tún mú òkè si.
Àwọn Òǹkọ̀tàn wa ni wọ́n ti pè láti jígìrì kí Ìtàn, Àṣà àti Ìṣẹ̀ǹbáyé wa ó má bàá parun.
Ọ̀rọ ̀ìrántí yìí ni Gómìnà Ìpínlẹ̀ Èkó Ọ̀gbẹ́ni Babájídé Sanwó-Olú pe gbogbo ènìyàn śi níbi ìfilọ́lẹ̀ ìwé mánigbàgbé kan tí wọ́n pè ní MÁTIKÚ tó wáyé ní Akọkà Yaba.
Gomina dúpẹ́ lọ́wọ́ òǹkọ̀tàn yìí fún bí o ṣe kọ ìwé ọ̀hún nípa ìtàn Ìpínlẹ̀ Èkó ó tún ṣe ìlérí pé ìjọba yóò ma lé iwájú nínú Ìfẹ́ Ìṣọ̀kan àti ṣíṣe àgbélárugẹ àṣà.
Abilékọ Abọ́sèdé Adélafà tó jé Akọ̀wé fún Àjọ elétò ìrìnàjò ìgbafé àti Àṣà tó lọ ṣojú Gómìnà níbẹ̀ ní gómìnà níìfẹ́ púpọ̀ śi ìwé tóbá ní ṣe pẹ̀lú ̀itàn nítorí pé lára ìrànwọ̀ àti jẹ́ kí àṣà wa ó le pé kárin kése ní, kó sì tún le ṣe àtìlẹ́yìn fún ìjọba.
Ṣé oníìkàn laajẹ́ ó ṣe, Oǹkọ̀tàn yìí Ọ̀gbéni Ẹlésin tó kọ ìwé yìí ní ojúṣe àwọn oǹkọ̀tàn ni láti má kọ ìtàn mánigbàgbé àti èròńgbà lórí ìwé yìí pé yóò se àfihàn ojúlówó ọmọ èkó tòóótó.
Bákán náà lótún rọ àwọn ọ̀dọ́ láti máṣe gbàgbé ìtán ibi tí wọ́n t́i ṣẹ̀ wá nítorí pé orírun wọn nìyẹn àti àmì ìdánimọ̀ wọn.
Ilé ẹjọ́ to ńgbọ́ ẹjó lẹ́yìn ìdìbò (PEPT) ni wọn yóò ṣe ìfilọ́lẹ̀ ìgbẹ́jọ́ ẹ̀ka ti olú ìlú Àbújá ní ilé ẹjọ́ kò tẹ́milọ́rùn.
Tí wọ́n sì ti to ẹjọ́ mérin tí wọ́n kọ́kọ́ fé gbọ́ sì́lẹ̀ ,
Àkọ́kọ́ ni ti Ẹgbẹ́ Òṣèlú Hope Democràtic Party (HPD) àti Ọ̀gbẹ́ni Ambrose Owuru, tó ń polongo ara rẹ̀ ní olùdíje fún Ààrẹ ẹgbẹ́ náà
Ẹlẹ́èkejì ni ti Ẹgbẹ́ Ọ̀ṣèlù (PDP) tí Alhaji Àtiku Abubakar sì jẹ́ Olùdíje fún ipo Ààrẹ.
Coalition for Change ni ejọ́ tóun jẹ́ ẹlẹ́èkẹ́ta, tí Jeff Ojinika Ẹni tó ń polongo ararẹ̀ gẹ́gẹ́ bíi olùdíje Ààrẹ ẹgbẹ́ náà
Ìgbẹ́jọ́ tó ṣìkẹrin ni ti Ẹgbẹ́ People’s Democràtic Movement (PDM) eleyìí ti òjíṣẹ́ Olúwa Aminchi Abu tóun náà ń polongo ara rẹ̀ gẹ́gẹ́ bíi olùdíje fún ipò Ààrẹ ẹgbẹ́ náà
Ààrẹ Buhari ti tún fi ọwọ́ sọ̀yà pé òun ò ní já ọmọ Orílẹ̀ èdè yìí kulẹ̀ ní ìgbà kan-kan lórí Ìdánilẹ́èkọ́ nípá ìwùwà sí asájú, Ètò ààbò tó péye àti ìgbé ayé ìrọ̀rùn fún gbogbo Ọmọ ilẹ̀ yìí.
Ọ̀rọ̀ yìí ni Aàrẹ sọ ní Mósháláshí ńlá tó wà Lábùjá lásìkò tí wọn ń sàmì oṣù Ramadan ó ní òun yóò ṣe Ìjọba tí yóò mú ìdẹ̀rùn bá Ọmo Ọrilé-èdè Nàìjíríà. Akọ̀ròyìn fún Àare wa Mallam Garba Ṣheu ní Àarẹ dúpẹ́ lọ́wọ́ gbogbo Ọmọ Nàìjíríà tí wọ́n fi àyè gba òun láti ṣiṣẹ́ sin ìlú lẹ́lẹ̀kejì.
Ààrẹ rọ àwọn Mùsùlùmí láti máa ní Ìkóra ẹni ní Ìjánu làsìkò lámú-lánà.
Imam Mọshalashi yìí Sheik Abdul-Waheed Sulaimon naa tún pàrọwà fún ìrònúpìwàdà àti àdúrà kí orílẹ̀̀-edè wa ba lè ní ààbò tó peye.
Bí ọdún se n súnmọ́ ni àwọn olùgbé ìpínlẹ̀ Eko ti fajúro bí ojà se gbé owó lérí tó sì gaju agbára wọn lọ, tí kòsì mú ayé dẹrùn fún mùtúmùwà.
Lára àwọn ènìyàn tí ó bá iléṣe Bond FM sọ̀rọ̀ so pé ohun gbogbo ló gbe owó lórí kọ́já sísọ ní ọjà tí ósì jẹ́ kí àti la irúfẹ́ àkókò yìí kojá nira fún àwọn ènìyàn.
Wọ́n rawọ́ ẹ̀bẹ̀ sí ìjoba Àpapọ̀ láti wá nǹkan ṣe síi, àtipé lílọbíbọ̀ owó láàrin ìlú leè jẹ́ kí ọrọ̀ ajé lọ sókè síi, ásì tún jẹ́kí ìgbé ayé ìdẹ̀rùn wà fún gbogbo mùtúmùwà.
Akínrógun ìlú Èpé Ọ̀túnba Dẹngẹ Anífowóṣe ti késí gbogbo ọmọ orílẹ̀-èdè yìí ĺáti sowópọ pẹ̀lú Ààrẹ Buhari fún ìyípadà rere fún ilẹ̀ wa.
Ó ní èròńgbà àti tún ìlú ṣe èyí tó ṣe ìrànwọ́ fún un láti wọlé lẹ́lẹ́kèejì.
Ọ̀túnba Anífowóṣe ní sáà kejì yóò mú ìyípadà ọ̀tun wá bí Àarẹ ṣe ti fi ipa rẹ̀ lélẹ̀ fún orílèdè yìí.
Ó tún dúpẹ́ lọ́wọ́ àwọn olùgbé ìpínlẹ̀ Èkó bí wọ́n ṣe dìbò lópò yanturu fi gbé Gómìnà Sanwó-Olú wọlé àti pé gómìnà yìí ní ìmọ̀ ìjìnlẹ̀ láti leè ṣọ ìpínlẹ̀ Èkó di ìlú àpéwò fún àwọn Oníṣòwò.
Ọ̀tùnba Dẹngẹ nígbà tó ń kí Gómìnà tó kógbá wọlé, ìyẹn Akinwunmi Ambọde pé ìtẹ̀síwájú rẹ̀ á dára àti pé Sanwó-Olú yóò ma tẹ̀síwájú nínú àlàálẹ̀ Asíwáju wọn.
Ìjọba ìpínlẹ̀ Èkó ti ń ṣe ètò lábẹ́nú láti kọ́ ẹ̀kún ilé ìwòsán ìjọba tó wà ní ìdàgbàsókè Àmúwò-Ọdòfin.
Igbá kejì Ọ̀gá àgbà àjọ elétò ìlera Dókítà Olúfúnmilọla Èṣhọ́ ló sọ ọ̀rọ̀ yìí níbi ìpàdé tó lọ ṣe ní́ ilé ìwòsàn yìí lẹ́ka ti ìgbẹ̀bí àti ọmọ wẹ́wẹ́ ‘
Dókítà Ẹ̀shọ́ ní ìjọba ń gbèrò láti kọ́ ẹ̀kún ilé ìwòsàn yìí kí ó le tó lò fún àwọn olùgbé àgbègbè náà.
Bẹ́ẹ̀ lótún rọ àwọn tórí jájẹ lágbègbè ọ̀hún láti kún ìjọba lọ́wọ́, kí wọn fi leè pèsè ìwòsàn tó yanrantí, tí owó rẹ̀ kò sì gunpá fún àwọn ènìyàn.
Àjọ tó ńṣe ètò ìforúkọ sílẹ̀ àwọn Olùkó ti ní kò sí ìpadà sẹ́yìn nínú gbèdéke tí wọ́n fún wọn pé tóbá di ọjọ́ kọkànlélọ́gbọ̀n oṣù kejìlá ọdún yìì làwọn ó yọ àwọn Olùkó tí kò kúnjú òṣùwọ̀n danù bí ení yọ jìgá láwọn ilé ẹ̀kọ́ wa. Ọ̀jọ̀gbọ́n Ṣẹ́gun Ajíbóyè tó jẹ́ Akọ̀wé àjọ yìí lósọ bẹ́ẹ̀ níìlú ìbàdàn pé (Awífún ni kót́ó dáni àgbà ìjakàdi ni) ó ní ó tí pẹ tí wọ́n ti ń kéde fún àwọn olùkọ́ náà láti lọ fi orúkọ̀ sílẹ̀ lábẹ́ àjọ̀ yìí kí wọ́n sì gba òǹtẹ̀ àṣẹ.
Ó ní ọjọ́ keje nínú oṣù kẹfà ni Àjọ tó ń ṣe àkóso ẹ̀kọ́ nílẹ̀yí ti fi ìwé ṣọwọ́ sí gbogbo Aláṣe ilé ẹ̀kọ́ pátá-pátá láti da àwọn Olùkọ́ tí kò kúnjú òṣùwọ̀n dúró jákè-jádò ilẹ̀ yìí.
Ó rọ àwọn tí kòì forúkọ sílẹ̀ láti lọ fi orúkọ sílẹ̀ kí àsìkò tí wọ́n fún wọn tó pé.
Wọ́n ti rọ àwọn Ọ̀gá nínú eré ìdárayá láti má mójútó àwọn ọ̀dọ́ agbábọ́ọ̀lùjẹun láti kìlò fún won nídi lílo egbògi olóró pàápàá bí wọ́n ṣe ń gbe láwọn ẹsẹ̀ kùkú àti pé kò le rorún fún ìjọba nìkan láti dáwọn lẹ́kun ìwà yìí.
Ògbóntàrigì nínú ẹgbẹ́ òṣèlù (APC) Ọ̀gbẹ́ni Wálé Adélànà ló ké gbànjarè ọ̀rọ̀ yìí níbi àyájọ́ gbígbé Ogunti Oògùn olóró eléyìí tí àjọ àgbáyé yà sọ́tọ̀.
Ọ̀gbẹ́ni Adélàná ní (ilèkùn àjọ kàn lọ̀rọ̀ yìí) tí ó sì ti dan-dan fún gbogbo ojúlówó ọmọ orílẹ̀ èdè yìí láti sowọ́pọ̀ pẹ̀lú àjọ tó ń kìlọ̀ ìwà ìbàjẹ́ nítorí pé àwọn ọ̀dọ́ èní laṣiwajú orílẹ̀ èdè yìí tóbá di lọ́la.
Bákan náà lótún pe àwọn Òbí àti Alágbàtó sí àkíyèsí láti wo irúfẹ́ àwọn ọ̀rẹ́ tí ọmọ wọn ń bá rìn.
Ṣí́ṣe ìmójútó àṣà wa àti ṣíṣe àkọsílè ẹ̀ ni wọ́n ní ó tidi dan-dan fún ọmọ Nàìjíríà, láti leè fi ran àwọn ìran tó ńbọ̀ lọ́wọ́
Igbákej̀i Gómìnà ìpínlẹ̀ Ògun Onímọ̀-Ẹ̀rọ Noimọt Sàlàkọ́ Oyèdélé ló pe ìpè ìtaníjí yìí níbi ìfilọ́lẹ̀ ìwé tí wọ́n pè ní “Ìlú Ọ̀tà Àwórì” tó wáyé ní Maryland ìpínlẹ̀ Èkó.
Oyèdélé to gbóṣùbà fún Òǹkọ̀wé tó sì tún ní kí àwọn òǹkọ̀wé tókù ó kọ́ṣe lára wọn káwọn náá ò kọ ìtàn mánigbàgbé tí yòò wúlò fún àṣà wa lọ́jọ́́ iwájú.
Lọ̀rọ̀ tí kábíyèsí Ọba Abdu Kabir Adéyẹmí Oba Lánlẹ́gẹ́ (Ọlótà ti ilú Ọ̀tà) tó ní ìlú Ọ̀tà ni àkọ́kọ́ nínú ilẹ̀ Àwórì tó kọ́kọ́ ṣe ìwé ìtàn.
Nínú ọ̀rọ̀ tí Sínétọ̀ tó ń ṣojú fún Ìwọ̀-Oòrùn ìpínlẹ̀ Ogun Aṣòfin Tolú Ọdẹ́bíyìí lóti rọ àwọn ẹ́ka ètò ẹ̀kọ́ láti má kọ́ àwọn akẹ́kọ̀ọ̀ ní ìtàn ilẹ̀ wa tó sì tún késí àwọn òbi láti má sọ ìtàn fún àwọn ọmọ wọn.
Ọ̀gbẹ́ni Frank Akinọlá ní ó yẹ kí àwọn ẹ̀yà Àwórì ó mọ orírun àti Àṣa wọn èyí tó sì jẹ́ ìwúrí fún un láti ka ìwé òhun lákà tún kà.
Ìròyìn yájó yàjó tó désí yàrá ìròyìn wa ní pe, ilé Alájà méta kan tó ẁa ní agbègbè Fágbà ìjú ní ìpínlẹ̀ èkó ti dà wó lulẹ̀.
Nínú ìròyìn tó tẹ̀wá lọ́wọ́ ni pé àwọn ènìyàn tí ìjànbá náà kọlù ni wọ́n tikó kúrò níbẹ̀ tí wọn sìti gbé àwọn tó farapa lọsí ilé ìwòsàn níbi tí wọ́n tí ń gba ìtọ́jú.
Wọ́n ní ìṣẹ̀lẹ̀ yìí kò gba ẹ̀mí kọkan tí àwọn ẹ̀ṣọ́ aláàbò ni ẹ̀ka elétò pàjáwìrì sì ti wà níbẹ̀
Ìròyìn fiyé wa wí pé ilé ọ̀hún ni ìjọba máa wolulẹ̀ fún ìfọ̀kànbalẹ̀ àwọn olùgbé àgbègbè yìí.
Nàíjíríà yóò gba ikọ̀ ọmọ ogun tuntun.
Orílẹ̀ èdè Nàíjíríà ti setán láti gba ikọ̀ ọmọ ogun tuntun láti fi kún àwọn ọmọ ogun tó wà nílẹ̀ láti le gbógun ti ìdúnkoòkò àti ètò ààbò tó ń ṣe sége-sège.
Igbákejì ààrẹ orílẹ̀ èdè Nàíjíríà, ọ̀jọ̀gbọ́n Yemí Òsínbàjò ló sọ̀rọ̀ yìí lásìkò ìpàdé tí ó se pẹ̀lú ẹgbẹ́ àwọn àlùfáà láti ìlà oòrùn, Arewa Pastors Forum for Peace, nílé ààrẹ tó wà nílùú Àbújá, lọ́jọ́ Ajé.
Ọ̀jọ̀gbọ́n Òsínbàjò tún ní; “ À ń sa ipá wa lórí ètò ààbò.
“Gẹ́gẹ́ bí ẹ se mọ̀ pé, à ń sa ipá wa lórí ètò ààbò lórílẹ̀ èdè yìí, nípa kíkó àwọn ikọ̀ ọmọ ogun lọ sí ìlà oòrùn láti kojú ikọ̀ ọlọ̀tẹ̀ Boko Haram.
Ní báyìí, a fẹ́ gba àwọn ọmọ ogun tuntun láti fi kún àwọn tó wà nílẹ̀, a tún ti ya owó kan sọ́tọ̀ láti fi ra irinsẹ́ ogun.
"Ọ̀jọ̀gbọ̀n Òsínbàjò tún ní ìjọba ààrẹ Muhammadu Buhari kò káàrẹ́ẹ̀ láti máa mójútó ètò ààbò lórílẹ̀ èdè yìí.
Igbákejì ààrẹ wá rọ ẹgbẹ́ àwọn àlùfáà náà pé ‘Ẹ̀yin ènìyàn Ọlọ́run, ẹ wá ètò tí ìjọba yóò máa tẹ̀lé láti mójútó ètò ààbò."
Ààrẹ ẹgbẹ́ náà, Bisobu Mbayo Japhet náà sọ pé àwọn wá sílé ààrẹ láti wá sàtìlẹyìn fún ìjọba láti tún wá sàpèjúwe ọ̀jọ̀gbọ́n Òsínbàjò gẹ́gẹ́ bí ènìyàn àlááfíà.
A ò ní fowó kún ọkọ̀ ojú irin nítorí àwọn mẹ̀kúnù- Rotimi Amaechi.
Bí àwọn ènìyàn se ń pè láti jẹ́ kí wọ́n fi owó kún iye tí àwọn ènìyàn ń wọ ọkọ̀ ojú irin, kí ìjọba leè tètè san owó tí wọ́n ya padà láti fi ra ọkọ́ ojú irin náà sùgbọ́n mínísítà fún ètò ìrìnnà, Rotimi Amaechi ti ní ìjọba kò ní dẹ́kun láti máa sèrànwọ́ nípa fífi owó kún ọkọ̀ ojú irin láti Àbújá sí Kaduna.
Amaechi, sọ̀rọ̀ yìí lásìkò tó ń bá àwọn akọrọ̀yìn sọrọ̀, pé ní gbogbo àgbáyé kò sí ibi tí wọ́n ti ń lo ọkọ̀ ojú irin láti pa owó sápò ìjọba.
"Amaechi ní “Tí a bá fi owó kún iye tí àwọn ènìyàn ń wọ ọkọ̀ ojú irin, Báwo ni àwọn mẹ̀kúnù tí wọn ń se isẹ́ ní Àbújá, sùgbọ́n tí wọn ń gbé ní Kàdúná nítorí owó ilé""."
Nítorí náà, láti wá ojútùú sí ìpèníjà tó wà níbi ríra ìwé ìrìnnà ọkọ̀ ojú irin láti Àbújá sí Kàdúná, mínísítà ní ilé-isẹ́ tó ń mójútó ọkọ̀ ojú irin Nigeria Railway Corporation (NRC) yóò tún pèsè àwọn ọkọ̀ ojú irin tuntun.
Ọkọ̀ ojú irin láti Èkó sí Ìbàdàn Mínísítà kò fésìì lórí ìgbà tí ọkọ̀ ojú irin láti Èkó sí Ìbàdàn yóò parí.
Amaechi ní “Ohun tí wọn sọ fún wa ni pé wọn yóò parí isẹ́ náà ní osú kẹrin, ọdún 2020.
Sùgbọ́n wọ́n ní ìpèníjà.
Wọn kò tí ì rí ẹrù wọn gbà láti èbúté ọkọ̀ ojú omi.
--- Orílẹ̀ èdè Amerika àti Nàíjíríà yóò tọwọ́bọ ìwé àdéhùn láti da $321m padà.
Ìjọba orílẹ̀ èdè Nàíjíríà ti gbaradi láti tọwọ́bọ ìwé àdéhun pẹlu ilu New Jersey ati United States of America nípa dídá $321m owó orílẹ̀ èdè Nàíjíríà tí wọ́n jí kó pamọ́ si orílẹ̀ èdè naa.
Ìwé àdéhùn náà wa lára ìgbìyànjú orílẹ̀ èdè Nàíjíríà láti rí i pé gbogbo owó tí àwọn ọ̀bàyéjẹ́ kan kó sálọ sí ilẹ̀ òkèèrè ni wọ́n dá padà sí orílẹ̀ èdè Nàíjíríà.
Mínístà fún ètò ìdájọ́ lórílẹ̀ èdè Nàíjíríà, Abubakar Malami ní yóò máa tọwọ́bọ ìwé àdéhùn ọ̀hún lórúkọ orílẹ̀ èdè Nàíjíríà, ni ó ti fi orílẹ̀ èdè Nàíjíríà sílẹ̀ lọ sí orílẹ̀ èdè America, lọ́jọ́ Àìkú.
Ìpàdé ọ̀hún ló máa ń wáyé lọ́dọọdún láàrin orílẹ̀ èdè Nàíjíríà àti America láti se àgbéyẹ̀wò nípa ìbásepọ̀ orílẹ̀ èdè méjèèjì, lọ́nà tí ìbásepọ̀ wọn yóò tún se leè múná-dóko sii.
Lára àwọn tó lọ sojú orílẹ̀ èdè Nàíjíríà nílẹ̀ America níbi ìpàdé náà ní: Mínísítà fún ọ̀rọ̀ ilé-isẹ́, ètò isẹ́ àti okoòwò Otúnba Adéníyì Adébáyò, Mínísítà fún ètò abbo, Maj.-Gen.Bashir Magashi (rtd), Mínísítà fún ilẹ́ ókeeré, Geoffrey Onyeama, olùdámọ̀ràn fún ìjọba àpapọ̀ lórí ètò aabo, Maj.-Gen.Babagana Monguno (rtd) àti mínísítà fún ètó ọmọnìyàn, àjálù àti ìdàgbàsókè àwùjọ.
--- Gómìnà pàsẹ láti mú àwọn adarí agbègbè, bí ẹ̀mí se ń sòfò ní ìpínlẹ̀ Plateau.
Ẹ̀mí tó ti sọnù ní ìpínlẹ̀ Plateau ti di méjìlélógún báyìí, bi ìwà ìpànìyàn se ń tẹ̀síwájú.
Gomina Simon Lalong lo sọ eleyii lasiko to n se ipade pẹlu awọn adari agbegbe lọjọ Ìsẹ́gun nile gomina to wa ni Jos, to jẹ olú-ìlú ipinlẹ Plateau.
Ó wá fi àìdùnnú rẹ̀ hàn lori ọwọ́ tí àwọn ọlọ́pàá, agbófinró àti adarí agbègbè ọ̀hún se mú ìsẹ̀lẹ̀ náà, ní èyí tí ó tún jẹ́ kí ìwà ìpàìyàn náà tún fi lee si ́i ju ti àtẹ̀yìnwá lọ.
Gómìnà tún fi àìdùnnú rẹ̀ hàn sí bí àwọn agbébọn kan se kọlu àgbègbè Ruboi àti Marish ní ìjọba ìbílẹ̀ Bokkos tó wà ní ìpínlẹ̀ náà.
Lásìkò ìsẹ̀lẹ̀ burúkú yìí ènìyàn mẹ́ẹ̀dógún ló pàdánù ẹ̀mí wọn, nígbà tí ènìyàn márùn ún farapa, tí ọ̀pọ̀lọpọ̀ dúkìá àti ilé sì jóná.
Lásìkò ìpàdé ọ̀hún ni Lalong wá ka ìwé òfin sí etí àwọn tó bá tún fẹ́ gbìmọ̀ràn láti dá wàhálà mííràn sílẹ̀.
Ó wá pàsẹ pé kí wọn mú àwọn adarí àgbègbè níbi tí wàhálà náà ti wáyé, títí tí wọn yóò fi mú àwọn afurasí tó lọ́wọ́ nínú wàhálà náà.
Kọmísọ́nà ọlọ́pàá fún ìpínlẹ̀ Plateau, Isaac Akínmóyèdé, jẹ́ ọ̀kan lára àwọn tó wà níbi ìpàdé ọ̀hún.
Ó wá kìlọ̀ fún àwọn adarí àgbègbè ọ̀hún láti máa se gba ìwà ọ̀daràn láàyè ní agbègbè wọn.
Ìpàdé náà wáyé lẹ́yìn ìsẹ̀lẹ̀ tí ó gba ẹ̀mí àwọn ènìyàn mẹ́tàlá ní àgbègbè Kwatas ní ìjọba ìbílẹ̀ Bokkos ní ìpínlẹ̀ Plateau.
Gẹ́gé bí àwọn ọlọ́pàá se sọ pé, àwọn ọ̀daràn daran-daran ló wá se ọsẹ́ ní agbègbè ọ̀hún ní àsálẹ́ ọjọ́ Àìkú.
--- Ìjàḿbà iná ní ọjà Balogun nílùú Eko.
Ìjàḿbà iná ń sẹlẹ lọ́wọ́-lọ́wọ́ ní ọjà Balogun nílùú Eko báyìí,.
Eléyìí wáyé lẹ́yìn ìjàm̀bá iná kan tí ó sẹlẹ̀ ni ọjà Mushin ní ọjọ karun un sẹ́yìn níbi tí àwọn ọlọ́jà ti pàdánù ọ̀kẹ́ àìmọye dúk̀ía wọn.
--- Àwọn agbébọ́n pa ènìyàn mẹ́tàlá ní ìpínlẹ̀ Plateau.
Ààrẹ orílẹ̀ èdè Naijiria , Muhammadu Buhari ti fi àìdùnú rẹ̀ hàn sí bí àwọn agbébọn se pa ènìyàn mẹ́tàlá ní ìpínlẹ̀ Plateau, ààrẹ wá fi dá àwọn ọmọ ìpínlẹ̀ náà lójú pé,gbogbo ìwà ìpànìyàn, ìdígunjalè, ìjínigbé àti àwọn ìwa ọ̀daràn mìíràn kò ní pẹ́ di àfisẹ́yìn tí eégún ń fi asọ.
“Ààrẹ Buhari wá rọ àwọn ènìyàn náà pé “ kò sí ànfààní níbi ẹ̀san, ìkórìíra àti ìwà ipá níbi tí ẹlẹ́yà púpọ̀, ẹlẹ́sìn àti àṣà orísìírìsí bá wà, gẹ́gẹ́ bí orílẹ̀ èdè Nàíjíríà, tí a wà yíí.
’’ Ààrẹ wá rọ àwọn adarí ẹlẹ́sìn àti adarí agbègbè náà láti rọ àwọn ọ̀dọ́ wọn nípa ìbásepọ̀ àlááfíà.
Ààrẹ Buhari wá bá àwọn ẹbí àti ìjọba ìpínlẹ̀ Plateau kẹ́dùn lórí ìsẹ̀lẹ̀ burúkú ọ̀hún.
--- Nàíjíríà àti Netherland yóò fọwọ́sowọ́pọ̀ lórí ètọ ẹ̀kọ́.
Ìjọba orílẹ̀ èdè Nàíjíríà àti Netherlands ti fohùnsọ̀kan láti fọwọ́sowọ́pọ̀ lórí ètọ ẹ̀kọ́, kí ìbásepọ̀ orílẹ̀ èdè méjéèjì náà tún le fẹsẹ̀ múlẹ̀ síi.
Akọ̀wé ìjọba àjọ tó ń mójútó ètò ẹ̀kọ́, Sonny Echono, ló sọ̀rọ̀ nílùú Àbújá, lásìkò tí ikọ̀ ilé-ẹ̀kọ́ orílẹ̀ èdè Netherlands Institute of International Relations Clingendael, tí ọ̀gbẹ́ni Monika Sie Dhian Ho, jẹ́ adarí rẹ̀, yọjú síí.
Akọ̀wé ìjọba fún àjọ ọ̀hún ní orílẹ̀ èdè Nàíjíríà yóò jẹ́ ànfààní púpọ̀ nípa ìfọwọ́sowọ́pọ̀ náà.
"Gẹ́gẹ́ bí akọ̀wé náà se sọ ó ní, “Orísìírísìí ọ̀nà nípa ètò ẹ̀kọ́ ló nílò ìrànwọ́ láti ọ̀dọ̀ àwọn olókoòwò láti ilẹ̀ òkèèrè""."
Sonny Echono sọ pé ìjọba orílẹ̀ èdè Nàíjíríà ti ṣetán láti bá àwọn tó bá nífẹ̀ẹ́ sí ètò okòowó lórí ẹ̀kọ́ lórílẹ̀ èdè yìí ṣe.
Echono tún wá rọ ìjọba orílẹ̀ Dutch láti tún fọwọ́sowọ́pọ̀ pẹ̀lú ìjọba orílẹ̀ èdè Nàíjíríà lórí ètò ọ̀gbìn, ìròyìn àti ị̀mọ̀ ẹ̀rọ àti ètò ẹ̀kọ́ nípa isẹ́ ọwọ́.
Sáájú èyí ni, olùdarí ilé -ẹ̀kọ́ ọ̀hún, Monika Sie Dhian wá sọ pé ìjọba orílẹ̀ Dutch, ló rán àwọn wá sí orílẹ̀ èdè Nàíjíríà láti wá béèrè ọ̀nà tí ìjọba ọ̀hún yóò fi leè fọwọ́sowọ́pọ̀ pẹ̀lú ìjọba orílẹ̀ èdè Nàíjíríà.
--- Ilé ìgbìmọ̀ asòfin yóò sàgbéyẹ̀wò ètò ààbò, òfin epo rọ̀bì àti ìdìbò.
Ilé ìgbìmọ̀ asòfin lórilẹ̀ èdè Nàíjíríà ti se ìpinnu fún ọdún 2020, láti mójútó ètò ààbò, òfin fún epo rọ̀bì àti àtúnse òfin lórí ètò ìdìbò, ní kété tí wọ́n bá ti wọlé lọ́jọ́ Ìsẹ́gun.
Abẹnugan ilé ìgbìmọ̀ asòfin, Ahmad Lawan ní òhun wòye bí ẹsẹ̀ ètò ààbò lórílẹ̀ èdè yìí se ń se sége-sège bí ẹsẹ̀ télọ̀ jẹ́ ojúse gbogbo wọn yálà, ìjọba àpapọ̀, ilé ìgbìmọ̀ asòfin àti gbogbo àwọn ìpele ìjọba tí ó wà, ìjọba ìpínlẹ̀ àti ìjọba ìbílẹ̀ ní láti mójútó.
Ó tẹ̀síwájú pé, nígbà tí ilé ìgbìmọ̀ asòfin bá wọlé lọ́jọ́ Ìsẹ́gun ọjọ́ kejìdínlọ́gbọ̀n, Ọdún 2020 wọn yóò tún sún ìjokòó ọ̀hún síwájú di ọjọ́Rú ni ìbámu pẹ̀lú ìlànà wọn láti bu ọlá fún ọ̀kan nínú wọn tí ó jẹ́ Ọlọ́run nipé lásìkò àjọ̀dún kérésìmesì ní Dubai, ìyẹn olóògbé Muhammadu Gawo, tó ń sojú fún Garki/Babura ní ìpínlẹ̀ Jigawa.
--- Ìjọba ìpínlẹ̀ Cross River ń fẹ́ àtìlẹ́yìn fún ìbùdó omi òkun.
Ìjọba ìpínlẹ̀ Cross River ti rọ ìjọba àpapọ̀ láti sàtìlẹyìn fún ojú ọ̀nà márosẹ̀ àti ìbùdó omi òkun tó wà ní Bakasi tí ìpínlẹ̀ náà ti dawọ́lé.
Gómìnà ìpínlẹ̀ ọ̀hún, ọ̀jọ̀gbọ́n Ben Ayádé lọ bẹ̀bẹ̀ yìí lọ́jọ́ Ajé, nílé ààrẹ tó wà nílùú Àbújá, lẹ́yìn ìpàdé tí ó se pẹ̀lú ààrẹ Muhammadu Buhari.
Gómìnà náà sọ pé isẹ́ àkànṣe méjì ní ìjọba òhun tí gùnlé, ní èyí tí ó se pàtàkì sí ìpínlẹ̀ Cross River àti orílẹ̀ èdè Nàíjíríà.
Ó ní: “Mo gbóróyìn fún ààrẹ Buhari fún ètò ìrànlọ́wọ́ rẹ̀ sí gbogbo ọmọ orílẹ̀ èdè Nàíjíríà àti pàápàá jùlọ fún ìpínlẹ̀ Cross River.
Síbẹ̀síbẹ̀ ìjíròrò wa kìí se lórí ìgbàgbọ́ tí a ní nínú ìsèjọba yìí nìkan sùgbọ́n a tún jíròrò nípa ohun tí ó ju epo rọ̀bì lọ.
Gómìnà Ayade wá fọkàn gbogbo àwọn ́ọmọ ìpínlẹ̀ Rivers balẹ̀ pé, òun yóò túbọ̀ máa tẹpẹlẹ mọ́ àwọn isẹ́ àkànse tí àwọn ènìyàn yóò máa jẹ ìgbádùn rẹ̀.
Ó tẹ̀síwájú pé ìjọba ìpínlẹ̀ náà tí pinnu láti fún ẹgbẹ̀rún méjì àwọn ọ̀dọ́ ní isẹ́ nípa ètò ìdàgbàsókè ohun ọ̀gbìn.
Gómìnà tún sọ pé ààrẹ Buhari kò ní pẹ́ wá sí ìpínlẹ̀ náà láti wá se ìfilọ́lẹ̀ àwọn ètò ìrónilágbára fún àwọn ọ̀dọ́ bí i ‘ètò G-Money ’.
--- Ilé-isẹ́ ogun òfurufú ti dáná sun ibùdó ikọ̀ ọlọ̀tẹ̀ (ISWAP) ní ìpínlẹ̀ Borno.
Ilé-isẹ́ ikọ̀ ọmọ ogun òfurufú (Nigerian Air Force NAF) ti dáná sun ibùdó ikọ̀ ọlọ̀tẹ̀, Islamic State of West Africa Province, (ISWAP) tó wà ní Gashigar ní ìpínlẹ̀ Borno.
Ilé-isẹ́ NAF sọ pé wọn tún se ìkọ̀lù sí ibi tí àwọn ikọ̀ ọlọ̀tẹ̀ ń sá pamọ́ sí ní àwọn agbègbè Tumbun Rego tó wà ní Lake Chad àti Bula Bello ní agbègbè igbó Sambisa ní ìpínlẹ̀ Borno.
Air Commodore Ìbíkúnlé Dáramólá, NAF tó jẹ́ adarí ẹka ìbára-ẹni-sepọ̀ àti ìròyìn ló sọ̀rọ̀ yìí nílùú Àbújá láti sọ nípa ìkọlù orí afẹ́fẹ́ ti ikọ̀ ọmọ ogun òfurufú, Air Task Force (ATF) of Operation LAFIYA DOLE se láti fi dáná sun ikọ̀ ọlọ̀tẹ̀.
--- Ìjọba àpapọ̀ kò nilò láti ya owó nílẹ̀ òkèèrè – SGF.
Akọ̀wé àgbà fún ìjọba àpapọ̀ lórílẹ̀ èdè Naijiria, Boss Mustapha ti ní ti ìjọba bá leè máa rí owó nípa sísan owó –orí, wọn kò nílò láti tún yá owó mọ́.
Boss Mustapha sọ̀rọ̀ yìí ni ọ́fíìsì rẹ̀ lásìkò tí alága ilé-isẹ́ tó ń mójútó ètò bí owó se ń wọlé lórílẹ̀ èdè Nàíjíríà (FIRS), Mohammed M. Nami se ẹ́ -kááre, ẹ -ǹ- lẹ́- níbẹ̀ -yẹn sii.
Boss Mustapha tẹ̀síwájú pé ìjọba àpapọ̀ nílò gbogbo owó láti leè jẹ́ kí ó se ojú rẹ̀.
Ó wá kí alága àti ìgbìmọ̀ rẹ̀ kú orí –ire fún ipò tuntun wọn.
--- Ààrẹ Buhari pàsẹ láti kọlu jàǹdùkú,ọ̀daràn àti olè lórí afẹ́fẹ́ ní ìpínlẹ̀ Niger.
Ààrẹ Muhammadu Buhari ti pàsẹ pé kí àwọn ọmọ ogun orí òfurufú bẹ̀rẹ̀ ìkọlù orí afẹ́fẹ́ láti gbógun ti gbogbo àwọn jàǹdùkú,ọ̀daràn àti olè tí wọ́n ń lo inú igbó láti se isẹ́ ibi wọn ní àwọn ìpínlẹ̀ Kaduna, Niger ati Zamfara Ààrẹ ti rí ìdánilójú pé bí eruku ojú ọjọ́ ṣe ń kúrò lójú òfurufú, àwọn ikọ̀ ọmọ ogun orí afẹ́fẹ́ yóò bẹ̀rẹ̀ lọ́sẹ̀ yìí láti maa ṣe ikọlu si gbogbo ibi ti àwọn ọ̀daràn daran-daran máa n sa pamọ́ sí láti se àwọn ènìyàn ní ìjàm̀bá pàápàá jùlọ ni agbègbè Dogon Gona ni ipinlẹ Niger,tó jẹ́ ààrin gbùngbùn orílẹ̀ èdè Nàíjíríà.
Ààrẹ Buhari wá sàpèjúwe àwọn ìkọlù tó ń wáyé ní agbègbè ọ̀hún, ní èyí tí ọ̀pọ̀lọpọ̀ àwọn ènìyàn ti pàdánù ẹ̀mí wọn bí “òfò fún orílẹ̀ èdè yìí.
"Ní ìbámu ìlànà yìí, ilé-isẹ́ ọmọ ogun òfurufú àti agbófinró orílẹ̀ èdè Nàíjíríà ti setán láti bẹ̀rẹ̀ iṣẹ́ ní pẹrẹu láti ṣe ìkọlù sí àwọn ọ̀daràn nílùú Minna, ní ìpínlẹ̀ Niger láti pèsè ìrànwọ́ fún ikọ̀ ọmọ ogun òfurufú.
Ààrẹ Buhari wá bá ìjọba ìpínlẹ̀ Niger àti àwọn ọmọ ìpínlẹ̀ Niger kẹ́dùn lórí ìkọlù àti òfò ẹ̀mí tó sẹlẹ̀ ní ìpínlẹ̀ náà.
Ààrẹ wá fi dá àwọn tó farapa níbi ìsẹ̀lẹ̀ náà lójú pé orílẹ̀ èdè Nàíjíríà kò ní gbàgbé wọn.
--- India yóò ran Nàíjíríà lọ́wọ́ nípa ètò ajé, okòòwò, ààbò,ẹ̀kọ́.
Orílẹ̀ èdè India ti sọ pé òhun setán láti túbọ̀ fọwọ́sowọ́pọ̀ pẹ̀lú orílẹ̀ èdè Nàíjíríà nípa ètò ajé, okòòwò, ààbò, ẹ̀kọ́, ọkọ̀ òfurufú àti ètò ìgbafẹ́ nípa ìlera fún àǹfààní orílẹ̀ èdè méjéèjì.
Asojú orílẹ̀ èdè Inidia ní Nàíjíríà, Arákùnrin Abhay Thakur sọ̀rọ̀ yìí lásìkò tí orílẹ̀ èdè ọ̀hún ń se ayẹyẹ àádọ́rin ọdún tí wọń gba òmìnira àti ọgọ́ta ọdún tí orílẹ̀ èdè méjèèjì náà ń bá ara wọn se papọ̀, ní èyí tó wáyé nílùú Àbújá, lórílẹ̀ èdè Nàíjíríà.
Abhay Thakur sàlàyé pé “India jẹ́ alábàáṣepọ̀ nínú ètò ìṣòwò tí ó tóbi jùlọ pẹ̀lú orílẹ̀ èdè Nàíjíríà, àti Nàíjíríà náà sì jẹ́ alábàáṣepọ̀ tí ó tóbi jùlọ lórílẹ̀ èdè India ní Afirika.
Àwọn pàṣípààrọ̀ lórí ètò okoòwò láàrin orílẹ̀ méjèèjì ọ̀hún ti gòkè àgbà láàrin oṣù mẹ́jọ àkọ́kọ́ lọ́dún 2019-20.
Orílẹ̀ èdè India ti pèsè ètò ìrànlọ́wọ́ fún Nàíjíríà nípa gbígbógun ti ikọ̀ ọlọ̀tẹ̀ Boko Haram.
 Mínísítà ìpínlẹ̀ fún ọ̀rọ̀ òkèèrè lórílẹ̀ èdè Nàíjíríà, Zubairu Dada, náà tẹpẹlẹ mọ́ ìfọwọ́sowọ́pọ̀ orílẹ̀ èdè Nàíjíríà pẹ̀lú India lọ́nà tí ìbásepọ̀ àwọn orílẹ̀ méjèèjì náà yóò se tún leè tẹ̀síwájú sii:"
"Zubairu sọ pé “ Bí orílẹ̀ èdè Nàíjíríà àti India se ń se ayẹyẹ ọgọ́ta ọdún lórí ìbásepọ̀ wọn, tí Inidia náà sì ń se ayẹyẹ àádọ́rin ọdún tí wọn ti gba òmìnira, Nàíjíríà yóò tẹpẹlẹ mọ́ ìfọwọ́sowọ́pọ̀ pẹ̀lú India lọ́nà tí ìbásepọ̀ àwọn orílẹ̀ méjèèjì náà yóò se tún leè tẹ̀síwájú síi:"""
Láti osù kọkànlá, ọdún 1958 ni orílẹ̀ èdè India àti Nàíjíríà ti ń bá ara wọn se papọ̀.
--- Àwọn àáfà gbàdúrà fún àlàáfíà orílẹ̀ èdè Nàíjíríà.
Àpèjọ àdúrà náà wáyé lásìkò ìgbéyàwó àbúrò ààrẹ Muhammadu Buhari, Hajiya Hadiza Lawal àti Muhammad Tukur Ibrahim, tí ó wáyé ní Mọsalasi ìlú Àbújá, ní èyí tí ààrẹ Muhammadu Buhari náà wà níbẹ̀.
Ààrẹ Buhari lo àsìkò ayẹyẹ náà láti gbàdúrà fún tọkọ-taya, bákan náà ni àwọn àáfà lo ànfààní náà láti gba ọ̀pọ̀lọpọ̀ àdúrà fún ètò àlàáfíà, ìdúrósinsin àti ìdàgbàsókè orílẹ̀ èdè Nàíjíríà.
Lára àwọn tó wà níbi ìgbéyàwó ọ̀hún tí wọn sojú ẹbí ààrẹ níbi ìgbéyàwó náà ni Mínísítà ìlú Àbújá, Muhammed Bello pẹ̀lú Dan Madamin Daura àti Alhaji Musa Haro.
--- Nàíjíríà ti fẹnukò pẹ̀lú Marco láti dá àwọn ẹlẹ́wọ̀n padà sílé.
Ààrẹ orílẹ̀ èdè Nàíjíríà Muhammadu Buhari ti fẹnukò pẹ̀lú ìjọba orílẹ̀ èdè Republic of China láti da àwọn ọmọ orílẹ̀ èdè Nàíjíríà sùgbọ́n tí wọ́n wà lọ́gbà ẹ̀wọ̀n lórílẹ̀ èdè China padà sí orílẹ̀ èdè Nàíjíríà.
Ìpinnu yìí wá lára ohun tí ìgbìmọ̀ ìjọba àpapọ̀ fẹnukò lé lórí ní ọjọ́ kínní, oṣù kejì, ọdún, 2018, ìgbìmọ̀ Ìjoba pàsẹ fún àdájọ́ orílẹ̀ èdè Nàíjíríà tí ó tún jẹ́ mínísítà fún ètò ìdájọ́, Abubakar Malami láti se ìwé àdéhùn tí ààrẹ yóò bọwọ́lù.
Olùràlọ́wọ́ ààrẹ fún ìròyìn àti ìkéde, Fémi Adésínà ti fi tó àwọn oníròyìn létí pé ààrẹ ti bọwọ́lu ìwé àdéhùn náà.
--- Àjọ EFCC yóò mu ́àwọn tó bá lọ́wọ́ nínú ìwà ìbàjẹ̀ padà sórílẹ̀ Nàíjíríà- Magu.
Àjọ tó ń gbógun ti síse owó ìlú kúmọ-kúmọ lórílẹ̀ èdè Nàíjíríà, the Economic and Financial Crimes Commission(EFCC), ti ní gbogbo àwọn ènìyàn jàǹkàn-jàǹkàn tó bá lọ́wọ́ nínú ìwà ìbàjẹ́ sùgbọ́n tí wọ́n sálọ sókè òkun, ni àwọn yóò mú wá padà sórílẹ̀ èdè Nàíjíríà láti wá jẹ́jọ́.
Adelé àjọ EFCC, ọ̀gbẹ́ni Ibrahim Magu sọ̀rọ̀ yìí lọ́jọ́ Ìṣẹ́gun nílùú Ìlọrin, ní ìpínlẹ̀ Kwara pẹ̀lú àwọn akọ̀ròyìn.
Magun tún ṣàlàyé pé àjọ náà àti ẹgbẹ́ àwọn àgùnbánirọ̀ yóò ṣe ìkéde ìfẹ̀hónúhàn nípa ewu tó wà níbi ìwà ìbàjẹ́ káàkiri orílẹ̀ èdè Nàíjíríà lọ́jọ́ kẹrìnlá osù kejì ọdún.
Magun tún tẹ̀síwájú pé gbogbo ẹ̀sùn nípa ìwà ìbàjẹ́ tí àjọ náà gùnlé ni wọn yóò ri i pé wọn yanjú rẹ̀, tí àwọn afuarasí ọ̀hún yóò fojú balé ẹjọ́, ní kété tí wọn bá ti parí ìwádìí wọn.
Magu ní kìí se pé àwọn dá ọfíísì àjọ EFCC sílẹ̀ ní Ìlọrin láti máa mú àwọn aláìsẹ̀.
Ó wá rọ́ àwọn akọ̀ròyìn láti fọwọ́sowọ́pọ̀ pẹ̀lú àjọ náà kí wọn leè se àseyọrí.
--- Ilé -ẹjọ́ gíga da Simon Lalong láre gẹ́gẹ́ bi gómìnà ìpínlẹ̀ Plateau.
Ilé -ẹjọ́ gíga tó wà ní ìlú Àbújá, orílẹ̀ èdè Nàíjíria ti fòntẹ̀ lu Simon Lalong gẹ́gẹ́ bíi gómìnà ìpínlẹ̀ Plateau tí wọ́n dìbò yàn.
Ilé -ẹjọ́ gíga ọ̀hún ní wọn dá ẹjọ́ Jeremiah Useni tí ó jẹ́ olùdíje fún ipò gómìnà lábẹ́ ẹgbẹ̀ òsèlú Peoples Democratic Party (PDP) tí ó gbé wá sílé ẹjọ́ ọ̀hún nù, pé kò fẹsẹ̀ múlẹ̀ láti tako ìbò tó gbé Simon Lalong wọlè gẹ́gẹ́ bíi gómìnà ìpínlè ọ̀hún.
Nínú ẹjọ́ tí adájọ́ Adamu Galinje dá ni ó ti sọ pé olùfẹ̀sùnkàn náà kò ní ẹ̀rí tó leè fi òtítọ́ ẹ̀sùn rẹ̀ múlẹ̀.
---Ilé ẹjọ́ gíga da ẹjọ́ kòtémilọ́rùn tí́ wọn pè tako àṣeyọrí Tambuwal’s gẹ́gẹ́ bíi gómìnà ìpínlẹ̀ sokoto
Aminu Tambuwal olùdíje fún ipò gómìnà láti inú ẹgbẹ́ alábùradà (PDP) ní ilé ẹjọ́ gíga ti gbà gẹ́gẹ́ bíi ẹni tó jáwé olúborí nínú ìdìbò gómìnà ti ọdùn 2019
Nínú ìdájọ́ tí adájọ́ Abba-Aji kà sóde, Adájọ́ náà dá ẹjọ́ kòtẹ́milọ́rùn ti ẹgbẹ́ òṣèlú olóṣùṣùọwọ̀ (APC) àti olùdíje fún ẹgbẹ́ náà Ahmad Aliyu pè dànù látàrí pé ẹjọ́ náà kòmúnádóko tó.
Ní ọjọ́ kejìlélógún osù kọkànlá ọdún 2019 àwọn ìgbìmọ̀ ẹlẹ́nu márùn ún ilé ẹjọ́ kòtẹ́milọ́rùn, tí Adájọ́ Usaini Murkhtar ṣe aládarí wọn da ẹjọ́ náà sígbó.
Ilé ẹjọ́ kòtẹ́milọ́rùn náà sọ pé olùpẹ̀jọ́ náà kòní ẹ̀rí tó múnádóko láti fi yíí àwọn adájọ́ náà lọ́kàn padà ìdí nìyí tí wọn fi da ẹjọ́ náà sígbó.
--- Ilé -ẹjọ́ gíga da Abdullahi Ganduje láre gẹ́gẹ́ bi gómìnà ìpínlẹ̀ Kano.
Ilé -ẹjọ́ gíga lorílẹ̀ èdè Nàíjíríà ti fòntẹ̀ lu Abdullahi Ganduje gẹ́gẹ́ bi gómìnà ìpínlẹ̀ Kano tí wọ́n dìbò yàn.
Ilé -ẹjọ́ gíga ọ̀hún ni wọ́n dá ẹjọ́ tí Abba Yusuf tó jẹ́ olùdíje fún ipò gómìnà lábẹ́ ẹgbẹ́ òsèlú Peoples Democratic Party gbé wá sílé ẹjọ́ ọ̀hún ni pé kò fẹsẹ̀ múlẹ̀.
--- Ẹ jẹ́ onítara àti ọmọ orílẹ̀ èdè Nàíjíríà rere: Lai Mohammed.
Mínísítà fún ìròyìn àti àsà, Alh. Lai Mohammed ti rọ gbogbo àwọn ọmọ orílẹ̀ èdè Nàíjíríà láti jẹ olùfọkànsìn àti onítara, kí orílẹ̀ èdè leè ní ìdàgbàsókè tó ní ìtumọ̀.
Mínísítà pe ìpè yìí lọ́jọ́ Àbámẹ́ta pẹ̀lú àwọn akọ̀ròyìn lásìkò ètò ìgbéyàwó tó wáyé ní ilé-isẹ́ àwọn ọmọ ológun orí afẹ́fẹ́, nílé ìjọ́sìn protestant tó wà nílùú Èkó.
Ó ní ìyípadà tí àwọn ọmọ orílẹ̀ èdè Nàíjíríà ń fẹ́ láti ọ̀dọ̀ ìjọba gbọdọ̀ bẹ̀rẹ̀ láti ilé ẹnìkọ̀ọ̀kan.
Mínísítà tún tẹ̀síwájú pé “A mọ̀ rírì ohun tí àwọn ọmọ orílẹ̀ èdè Nàíjíríà ń fẹ́, ìjọba kò sì ní káàrẹ́ láti mú gbogbo ìlérí tí ó se sẹ́, páàpáà jùlọ nípa ètò ọrọ̀ ajé àti láti pèsè isẹ́ lọ́pọ̀ janturu.
“Gbogbo ènìyàn gbọdọ̀ mọ ojúse rẹ̀ láti jẹ onítara àti láti máa dáwọ́le ohun tí ó le dá wàhálà sílẹ̀ láàrin ara wa tàbí sí ìjọba.
--- Ìdàgbàsókè ti dé bá orílẹ̀ èdè Nàíjíríà láti bí ogún ọdún sẹ́yìn- Lawan.
Abẹnugan ilé ìgbìmọ̀ asòfin orílẹ̀ èdè Nàíjíríà, Ahmad Lawan sọ pé ìyàtọ̀ ńlá àti ìdàgbàsókè ló ti dé bá orílẹ̀ èdè Nàíjíríà láti bí ogún sẹ́yìn , lẹ́yìn tí orílẹ̀ èdè Nàíjíríà ti padà sí ìjọba tiwa-n-tiwa lọ́dún 1999.
"Asòfin Ahmad Lawan sọ̀rọ̀ yìí nínú ìwé apilẹ̀kọ rẹ̀ níbi ìdánilẹ́kọ̀ọ́ ìkẹtàdínlógún ti ilé –isẹ́ akọ̀rọ̀yìn Daily Trust Dialogue se àgbékalẹ̀ rẹ̀, tí wọn pe àkòrí rẹ̀ ní “Ogún ọdún ìjọba tiwa-n-tiwa lorílẹ̀ édé Nàíjíríà: Agbára, Aláìlágbára àti àwọn ànfààní rẹ̀ "", tí ó wáyé nílùú Àbújá lọ́jọ́BỌ̀."
Aliyu Sabi Abdullahi, tí ó jẹ́ igbákejì alámòjútó ètò, nílé ìgbìmọ̀ asòfin ló sojú abẹnugan ilé ìgbìmọ̀ asòfin, Lawan, tí ó jẹ́ àlejò pàtàkì níbi ayẹyẹ ọ̀hún.
Abẹnugan ilé ìgbìmọ̀ asòfin tún tẹpẹlẹ mọ́ àwọn ìgbésẹ̀ tí ilé ìgbìmọ̀ asòfin ti gbé láti mú ìdàgbàsókè bá ètò ọ̀rọ̀ ajé orílẹ̀ èdè Nàíjíríà.
Ó ní ilé ìgbìmọ̀ asòfin ti se ọ̀pọ̀lọpọ̀ òfin, ní èyí tí ó ti jẹ́ kí owó tó ń wọlé sí àpò òsùwọ̀n orílẹ̀ èdè yìí tún pọ̀ síi.
Lára àwọn ènìyàn pàtàkì tó wà níbi ayẹyẹ ọ̀hún ni igbákejì ààrẹ orílẹ̀ èdè Nàíjíríà tẹ́lẹ̀rí, Mohammed Namadi Sambo, tí ó jẹ́ alága ayẹyẹ náà; Gómìnà ìpínlẹ̀ Èkìtì àti alága àwọn gómìnà lórílẹ̀ èdè Nàíjíríà, Káyòdé Fáyemí, àti alága ẹgbẹ́ òsèlú All Progressive Congress (APC) tẹ́lẹ̀rí, olóyè John Oyegun.
--- Ìpínlẹ̀ Nasarawa ti ń jẹ̀gbádùn ètò ààbò tó péye – Abdullahi Sule.
Gómìnà ìpínlẹ̀ Nasarawa, Abdullahi Sule ti sọ pé ètò ààbò ti fẹsẹ̀ múlẹ̀ si ní ìpínlẹ̀ ọ̀hún, nípa ìgbésẹ̀ tí wọ́n gbé láti gbógun ti ìwà ọ̀daràn.
Ó sọ̀rọ̀ yìí lásìkò tó ń bá àwọn akọ̀ròyìn ilé akéde sọ̀rọ̀ nílùú Àbújá lẹ́yìn ìpàdé tí ó se pẹ̀lú ààrẹ Muhammadu Buhari.
Ó ní: “Gẹ́gẹ́ bí ọ̀kan lára ọmọ ẹgbẹ́ òsèlú APC, tí mo sì tún jẹ́ gómìnà tó ń sojú ẹgbẹ́ náà, mo wá láti rí adarí ẹgbẹ́ wa, ààrẹ Buhari láti sọ nípa bí ìpínlẹ̀ míì, tí ó ní ànfààní láti súnmọ́ ìlú Àbújá se ń lọ síi, ìyẹn Nasarawa.
Mo ní ànfààní láti sọ fún ààrẹ Buhari nípa bí ìpínlẹ̀ Nasarawa se ń lọ, bí i ètò ààbò àti ìdàgbàsókè tí ó ti dé bá ìpínlẹ̀ Nasarawa ‘’
Gómìnà Sule ní òun wá rí ààrẹ Buhari láti wá dúpẹ́ lọ́wọ́ rẹ̀ fún bí ó ṣe dá ilé-ẹkọ́ àwọn ọlọ́pàá sílẹ̀ ní ìpínlẹ̀ ọ̀hún.
--- Ààrẹ Buhari yan Kingsley Obiora gẹ́gẹ́ bi igbákejì gómìnà CBN.
Ààrẹ orílẹ̀ èdè Nàíjíríà, Muhammadu Buhari ti forúkọ Kingsley Isitua Obiora ránsẹ́ sí ilé ìgbìmọ̀ asòfin àgbà gẹ́gẹ́ bí igbákejì gómìnà fún ilé-ìfowópamọ́ ti ìjọba àpapọ̀ (CBN).
Nínú ìwé tí ààrẹ Buhari fi ránsẹ́ sí abẹnugan ilé ìgbìmọ́ asòfin, Ahmad Lawan, láti yan Kingsley Isitua Obiora gẹ́gẹ́ bí igbákejì gómìnà fún ilé-ìfowópamọ́ ti ìjọba àpapọ̀ (CBN) wà ní ìbámu pẹ̀lú òfin 8(1) (2) tí ó dá banki CBN sílẹ̀ (Establishment) Act 2007.
Ọ̀mọ̀wé Obiora, ni yóò dípò Joseph Nnanna, tí ó fẹ̀yìntì ní ọjọ́ kejì, osú kejí, ọdún 2020.
Ọ̀mọ̀wé Obiora gba oyè Bachelor’s degree nínú ìmọ̀ ètò ìnáwó (Economics) àti ìsirò láti fásitì Benin, ó tún ní ìmọ̀ ìjìnlẹ̀ nínú ètò ìnáwó (Masters in Economics) láti Fásitì ìlú Ìbàdàn, ó tún gba oyè ọ̀mọ̀wé nínú Monetary and International Economics, láti fásitì ìlú Ìbàdàn.
Ọ̀mọ̀wé Obioraje jé ọ̀kan lára àwọn adarí nílé ìfowópamọ́ àgbáyé International Monetary Fund (IMF) ni Washington DC, lórílẹ̀ èdè United States of America (USA).
--- Ìdásilẹ̀ Àmọ́tẹ́kùn lòdì sí òfin orílẹ̀-èdè Nàíjiríà ọdún 1999 – Malami.
Ìjọba orilẹ̀-èdè Naijiria ti ní ikọ̀ elétò ààbò tuntun ti àwọn gómìnà ẹkùn Gúsù orílẹ̀-èdè Nàíjiríà dá sílẹ̀ iyẹn, Àmọ̀tẹ́kùn lòdì sí òfin orílẹ̀-èdè Nàíjiríà.
Nínú àtẹ̀jáde kàn tí olùbádámọ̀ràn pàtàkì lóri ìròyìn àti ìbára -ẹni sepọ̀, Umar Gwandu sọ pé, Àmọ̀tẹ́kùn dídásílẹ̀ ẹgbẹ́ kìí ṣe èyi to ba òfin orílẹ̀-èdè Nàíjiríà mu.
Agbẹjọ́rò àgbà fún ìjọba àpapọ̀ Abubakar Malami (SAN) sàlàyé pé, ọ̀rọ̀ ààbò jẹ ojúṣe ìjọba àpapọ níkàn ni.
"Àtẹjáde náà ka bayìí pé "" ìwé òfin orílẹ̀-èdè Nàíjíríà ti ọdún 1999 ti fi idí rẹ̀ múlẹ̀ pé, ọmọ–ogun orí-ilẹ̀, ọmọ–ogun ojú omi, àti ọmọ–ogun ojú ofurufu, ọlọpàá àti àwọn to farapẹ́ nìkàn ló wà fún ètò ààbò Nàíjíríà àti pé ìjọba àpapọ̀ nìkan ni òfin gbáà láàyè láti ṣe ìdásílẹ̀ wọn."
"Nítorí ìdí èyí kò si Gómìnà yálà ẹyọ kan tàbi lápapọ̀ to ni ẹ̀tọ tàbi agbára láti ṣe ìdásílẹ̀ ilé iṣẹ́ tàbí àjọ kankan to níṣe pẹ̀lú èètò ààbo.
--- Ilé -ẹjọ́ gíga orílẹ̀ èdè Nàíjíríà yọ gómínà Imo, Emeka Ihedioha.
Ilé-ẹjọ́ gíga lórílẹ̀ èdè Nàíjíríà ti ní kí wọ́n yọ gómínà ìpínlẹ̀ Imo , Emeka Ihedioha, kí àjọ elétò ìdìbò sí kéde Hope Uzodinma olùdíje fún ipò gómìnà lábẹ́ ẹgbẹ́ òṣèlú, All Progressive Party (APC) gẹ́gẹ́ bí gómìnà tuntun fún ìpínlẹ̀ náà.
Nínú ẹjọ́ tí ìgbìmọ̀ ẹlẹ́nu méje tí adájọ́ àgbà lórílẹ̀ èdè Nàíjíríà, Tanko Muhammed darí rẹ̀, ni adájọ́, Kudirat Kekere-Ekun pàsẹ fún àjọ elétò ìdìbò orílẹ̀ èdè Nàíjíríà, Independent Electoral Commission (INEC) láti gba ìwé ẹri gẹ́gẹ́ bí gómìnà ìpínlẹ̀ Imo lọ́wọ́ Ihedioha kí wọń sì fún Uzodinma gẹ́gẹ́ bí gómìnà tuntun fun ìpínlẹ̀ náà.
--- Ìdájọ́ ètò ìdìbò ìpínlẹ̀ Kano: Adájọ́ ilé-ẹjọ́ gíga subú lu àìsàn lójijì.
Ilé-ẹjọ́ gíga tó wà nílùú Àbújá, ti sún ìdájọ́ lórí ètò ìdìbò gómìnà ìpínlẹ̀ Kano 2019 síwájú, nítorí ọ̀kan lára adájọ́ méje tó wà nílé-ẹjọ́ náà subú lu àìsàn lójijì lásíkò ti ẹjọ́ ń lọ lọ́wọ́.
Adájọ́ àgbà fún ilé-ẹjọ́ gíga náà, Tanko Mohammad, ló kéde yìí lẹ́yìn tí agbẹjọ́rò fún Abbah Yusuf tó jẹ́ ọmọ ẹgbẹ́, peoples Democratic party, Gboyega Awomolo rọ ilé-ẹjọ́ náà láti dá ẹjọ́ ọ̀hún.
Tanko Mohammad ní ilé-ẹjọ́ nílò láti sún ẹjọ́ náà síwájú di ojó kerìnlá, osù kínní, odún 2020.
--- Ìrántí àwọn ológun: Osinbajo gbósùbà fún àwọn tó fẹ̀mí wọn lélẹ̀.
Igbákejì ààrẹ orílẹ̀ èdè Nàíjíríà, ọ̀jọ̀gbọ́n Yemí Òsínbàjò ní oriĺẹ̀ èdè Nàíjíríà jẹ oriĺẹ̀ èdè tó ní ẹ̀yà, àsà àti èdè orísirísi, nítorí ipa tí àwọn akínkanjú kan tó fi ara wọn se ìrúbọ nígbà kan sẹ́yìn àti níbàyìí ti kó.
Igbákejì ààrẹ sọ̀rọ̀ yìí níbi ìsìn ayẹyẹ àyájọ́ ọdún fún àwọn ológun tó subú lójú ogun ti ọdún 2020, ní èyí tí ó wáyé nílé-ìjọ́sìn, National Christian Centre, tó wà nílùú Àbújá.
Igbákejì ààrẹ tún sọ pé, ààrẹ Muhammadu Buhari kò ní káàrẹ́ láti túbọ́ máa mójútó ìgbáyé-gbádùn ilé-isẹ́ ológun.
Nínú ìwásù tí àkòrí rẹ́ jẹ́ “Ìpè láti sìn tí oníwàásù ìjọ Church of Christ in Nations (COCIN) Reverend Dr. Dachollom Chumang Datiri sọ pé ọlọ́run pe gbogbo wa lá́ti wa sìn òun àti àwọn ènìyàn."
Adarí ilé-isẹ́ ológun fún ètò ààbò lórílẹ̀ èdè Nàíjíríà, ọ̀gágun Gabriel Olanisakin, ni ó ka ẹ̀kọ́ kíkà àkọ́kọ́ láti Genesis 3-1-19, nígbà tí igbákejì abẹnugan ilé ìgbìmọ̀ asòfin àgbà fún ọmọ ẹgbẹ́ tó kéré jùlọ, Peter Okpatasai, ka ẹ̀kọ́ kejì láti inú, John 1:1-19.
Alága ètò náà, arábìnrin, Olu Mustapha wá dúpẹ́ lọ́wọ́ Ọlọ́run àti àwọn ènìyàn pàtàkì tó wà níbi ayẹyẹ náà fún ìdàgbàsókè wọn lórílẹ̀ èdè Nàíjíríà.
--- Ètò ìdájọ́ gómìnà ní ìpínlẹ̀ Sokoto: Ọlọ́pàá pèsè ààbò tó nípọn.
Ilé-isẹ́ ọlọ́pàá tó wà ní ìpínlẹ̀ Sokoto, ti ní ọlọ́pàá tí kò dín ní ẹgbẹ̀rún kan, mọ́ èyí tí kò wọsọ ni àwọn ti pín káàkiri gbogbo orígun ìpínlẹ̀ Sokoto.
Láti mójútó ìdájọ́ tí ilé-ẹjọ́ gíga yóò da lónìí yìí láàrin gómìnà ìpínlẹ̀ náà, Aminu Waziri Tambuwal tó jẹ́ ọmọ ẹgbẹ́ òsèlú, Peoples Democratic Party ( PDP) àti Alhaji Ahmed Aliyu Sokoto , ọmọ ẹgbẹ́ òsèlú, Progressives Congress (APC) láti tako ìdájọ́ ìgbìmọ̀ tó ń se ìtọpipin ètò ìdìbò dá láti fi gbé ìbò tó gbé Aminu Waziri Tambuwal wọlé gẹ́gẹ́ bi gómìnà ìpínlẹ̀ Sokoto.
Kọmísọ́nà ọlọ́pàá fún ìpínlẹ̀ náà, Ibrahim Kaoje, ni Ilé-isẹ́ ọlọ́pàá gbé ìgbésẹ̀ náà láti rí i pé ètò ààbò tó péye wà ní ìpínlẹ̀ náà lásìkò àti lẹ́yìn ìdájọ́ ọ̀hún, tí yóò wáyé lónìí yìí.
--- Àwọn àjòjì ló ń se fàyàwọ́ wọnú orílẹ̀ èdè Nàíjíríà: Emir ti Yashkira.
Emir ti Yashkira, tó wà ní ìjọba ìbílẹ̀ Baruteen ní ìpínlẹ̀ Kwara, ni ààrin gbungbun orílẹ̀ èdè Nàíjíríà, Alhaji Umar Sariki Sabikpasi II, ti ní ohun ti fi tapá –titan sí ìgbésẹ̀ ìjọba àpapọ̀ láti ti ààlà orílẹ̀ èdè yìí pa, ó ní púpọ̀ nínú àwọn ìwà fàyàwọ́ tó ń sẹlẹ̀ lórílẹ̀ èdè yìí ló jẹ́ pé àwọn àjòjì ló ń fàá.̀
Emir sọ̀rọ̀ yìí ní ààfin rẹ̀ lásìkò tí adarí àwọn ikọ̀ tó ń mójútó ààlà orílẹ̀ èdè Comptroller Mohammed Uba Garba wá sí ààfin emir náà fún ìpolongo àti ìlanilọ́yẹ̀ nípa bí ìjọba se ti ààlà orílẹ̀ èdè yìí pa.
Ó tẹ̀síwájú pé orílẹ̀ èdè Nàíjíríà kò leè fọwọ́rọ́ ilé-iṣẹ́ asọ́bodè sẹ́yìn nípa pípa owó sí àpò òsùwọ̀n orílẹ̀ èdè yìí.
Emir náà tún tẹ̀síwájú pé ìgbésẹ̀ tí ìjọba gbé láti ti ààlà orílẹ̀ èdè yìí pa yóò jẹ́ kí ìdàgbàsókè bá ètò ọrọ̀ ajé orílẹ̀ èdè yìí.
Ó wá rọ ìjọba láti gbé ìgbésẹ̀ tó lágbára lórí àwọn ọ̀bàyéjẹ́ tó ń fa aago ètò ọrọ̀ ajé orílẹ̀ èdè yíí sẹ́yìn, kí ìjọba sì tún fi ọwọ́ òfin mú àwọn ilé-isẹ́ tó ń ta epo rọ̀bì ṣùgbọ́n tí wọn kò gba ìwé àsẹ láti bẹ̀rẹ̀ isẹ́ wọn.
--- Gómìnà Nasiru El-Rufai ti ilé –ìtajà afẹ́fẹ́ gáàsì pa..
Gómìnà ìpínlẹ̀ Kaduna, Nasiru El-Rufai ti pàsẹ pé kí ní kíákíá, ní wàrà-sesà ni kí wọn ti ilé –ìtajà afẹ́fẹ́ gáàsì tó wà ní agbègbè ibi tí àwọn ènìyàn kọ́lé wọn sih, pa.
Gómìnà tún wá rọ àwọn olùgbé àgbègbè náà láti máa fi ìròyìn náà tó àwọn alásẹ létí lórí irú ìgbésẹ̀ bẹ́ẹ̀.
Nasiru El-Rufai sọ̀rọ̀ yìí lọ́jọ́ Àbámẹ́ta lásìkò tí ìjàmbá iná kan sẹlẹ̀ ní àgbègbè Sabon Tasha, ní ìpínlẹ̀ Kaduna.
Ó ní ìjọba yóò gbé ilé-iṣẹ́ afẹ́fẹ́ gáàsì náà kúrò lọ sí ibi tí wọn pèsè fún àwọn ilé-isẹ́, Nasiru El-Rufai tún sọ pé“Ó seni láànú pé irú ìsẹ̀lẹ̀ báyìí tún wáyé.
Èyí ti fihàn pé afẹ́fẹ́ gáàsì léwu fún àwọn ènìyàn, ní èyí tí kò yẹ kí irú ilé-ìtajà bẹ́ẹ̀ wà ní àgbègbè tí àwọn ènìyàn ń gbé.
“A o ko wọn kúrò níbi tí wọn wà yìí, a ó fún wọn nílẹ̀ tí wọn yóò gbé máa ta afẹ́fẹ́ gáàsì, ní èyí tí yóò fi dènà irú ìsẹ̀lẹ̀ báyìí.
"Gómìnà wá bá àwọn ẹbí, ọ̀jọ̀gbọ́n Simon Mallam kẹ́dùn, tí ó kú níbi ìjàmbá iná afẹ́fẹ́ gáàsì ná, Ó tún kàn sí àwọn tó farapa níbi ìsẹ̀lẹ̀ ọ̀hún, tí wọn ń gba ìtọ́jú nílé ìwòsàn, Gerald hospital, tó wà ní ìpínlẹ̀ Kaduna.
Ó tún gbàdúrà fún àwọn tó pàdánù ẹ̀mí wọn níbi ìsẹ̀lẹ̀ ọ̀hún, pé kí Ọlọ́run tẹ́ wọn sí afẹ́fẹ́ ire.
--- Kwara da mílííọ̀nù mọ́kànlélógún naira padà fún àwọn arìnrìnàjò Hajj.
Gómìnà ìpínlẹ̀ Kwara, Mallam AbdulRahman AbdulRasaq ti fi mílííọ̀nù mọ́kànlélógún náírà sílẹ̀ fún àwọn arìnrìnàjò tó lọ sí ilẹ̀ mímọ́ Hajj lọ́dún 2019.
Akọ̀wé àgbà fún ìrìnàjò ilẹ̀ mímọ́ Hajj ní ìpínlẹ̀ Kwara, Alhaji Tunde Jimoh ló sọ̀rọ̀ yìí lọ́jọ́ Ajé lásìkò tó ń bá àwọn akọ̀ròyìn sọ̀rọ̀ nílùú Ìlọrin.
Gẹ́gẹ́ bí ó sẹ sọ, ó ní ìjọba orílẹ̀ èdè Saudi Arabia ló dá owó náà padà fún wọn, nítorí pé wọn kùnà láti pèsè àwọn ètò tó yẹ kí wọn se fún àwọn arìnrìnàjò lọ́dún náà.
Lọ́jọ́Rú ọ̀sẹ̀ tó ń bọ̀ ni àwọn tó ń gbé ní ìwọ̀ oòrùn Ìlọrin yóò gba owó tiwọn, tí àwọn tó ń gbé láti Asà àti ìlà Gúsù Ìlorin yóò gba owó tiwọn lọ́jọ́Bọ̀, tí àwọn tó ń gbé ní ìlà oòrùn Ìlorin àti Mòro yóò gba owó tiwọn ní ọjọ́ Ẹtì, Jimọh yìí.
Àwọn tó ń gbé láti Gúsù Kwara ní wọn yóò gba owó tiwọn lọ́jọ́ Ajé tó ń bọ̀ yìí, ṣùgbọ́n àwọn tó ń gbé láti Baruten, Patigi, Edu, Kaiama ni wọn yóò gba owó tiwọn lọ́jọ́ Ìsẹ́gun, tí àwọn tí kìí se ọmọ ìlọrin yóò gba owó tiwọn lọ́jọ́Rú tó ń bọ̀.
Alhaji Jimoh wá rọ́ àwọn arìnrìnàjò 2019 ọ̀hún láti wà pẹ̀lú àwọn ìwé ìdánimọ̀ ayélujára, ìwé ìrìnnà àti ẹ̀dà ìwé owó tí wọn fi sanwó ìrìnàjò lọ sí Hajj ti ọdún náà.
--- Gómìnà ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́ sèfilọ́lẹ̀ ọjọ́ ìrántí àwọn ológun pẹ̀lú mílíọ̀nù Mẹ́ta naira.
Gómìnà ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́, Seyi Makinde ti sèfilọ́lẹ̀ ọjọ́ ìrántí àwọn ológun ti ọdún 2020 àti àmì ẹ̀yẹ pẹ̀lú ẹ̀bùn owó mílííọ̀nù mẹ́ta náírà.
Mákindé wá gbósùbà fún àwọn ọmọ -ogun orílẹ̀ èdè yìí, tí wọn fi ẹ̀mí wọn lélẹ̀ láti jẹ́ kí àlááfíà àti ìsọ̀kan jọba lórílẹ̀ èdè Nàíjíríà.
Ó wá rọ àwọn ọmọ orílẹ̀ èdè Nàíjíríà láti túbọ̀ máa sàtìlẹyìn fún àwọn ẹbí tí àwọn olóògbé náà fi sílẹ̀.
“Ó yẹ kí á máa sàtìlẹyìn fún àwọn ọmọ -ogun tó farapa, àwọn opó àti ọmọ àwọn akínkanjú ọmọ-ogun tí wọn subú lójú ogun.
Gómìnà Mákindé, ẹni tí igbákejì rẹ̀, Rauf Olaniyan, sojú fún ló sọ̀rọ̀ yìí ní ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́ tó jẹ́ ìlà Gúsù, orílẹ̀ èdè Nàíjíríà, sáájú èyí ni, alága ẹgbẹ́ àwọn ọmọ- ológun tó ti fẹ̀yìntì, Michael Fajimi, sọ pé, lára ètò síse ìrántí ọmọ -ológun orílẹ̀ èdè yìí ni láti se ìrànwọ́ owó fún àwọn tó farapa lójú ogun, ṣùgbọ́n tí wọn sì wà láyé àti fún àwọn opó àti ọmọ àwon olóògbé tó subú lójú ogun."
--- A ó mójútó ètò ààbò àti àlàáfíà nílẹ̀ Afrika: Buhari.
Ààrẹ Muhammadu Buhari ti ní ohun yóò túbọ̀ tẹpẹlẹ mọ́ ètò ààbò, ìdàgbàsókè àti àseyọrí nílẹ̀ Afirika.
Ààrẹ Buhari sọ̀rọ̀ yìí lásìkò tí ààrẹ Umaro Muhktar Sissoco Embalo ti orílẹ̀ èdè Guinea Bissau sẹ̀sẹ̀ yàn wá dúpẹ́ lọ́wọ́ rẹ̀.
Ààrẹ Buhari tún wá gbósùbà fún ààrẹ, José Mário Vaz, tó ń sẹ̀sẹ̀ ń fi ipò sílẹ̀ fún àtìlẹyìn tí o sé fún ààrẹ tuntun ọ̀hún lásìkò ètò ìdìbò.
Ààrẹ Buhari sọ pé ìtàn àti orílẹ̀ èdè Guinea Bissau kò ní gbàgbé ipa ribiribi tí ààrẹ Jose Mario Vaz kó lásìkò ètò ìdìbò, ní èyí tí ó gba láti jẹ́ kí ìfẹ́ orílẹ̀ èdè Guinea Bissau ju ìfẹ́ ọkàn rẹ̀ lọ.
Ààrẹ Embalo tí ó jẹ́ onísòwò, kí ó tó di olósèlú, ti fi ìgbà kan jẹ́ adarí ìjọba orílẹ̀ èdè Guinea Bissau lábẹ́ àkóso ààrẹ Jose Mario Vaz láàrin ọdún 2016 sí 2018.
Ó tún jẹ́ ọmọ ẹgbẹ́ òsèlú ruling African Party of Independence of Guinea àti Cape Verde (PAIGC) lásìkò tí ó dá ẹgbẹ́ Movement for Democratic Alternative (MADEM-G15), sílẹ̀, ní èyí tí ó fí díje fún ipò ààrẹ, tí ó sì jáwé olúborí.
-- Orílẹ̀ èdè Nàíjíríà yóò ti di ògbóntarìgì nípa ẹ̀rọ ìgbàlódé láàrin ọdún mẹ́wàá.
Ìjọba orílẹ̀ èdè Nàíjíríà ti ní láàrin ọdún mẹ́wàá tí a wà yìí, o dájú pé gbogbo ọmọ orílẹ̀ èdè Nàíjíríà ni yóò ti ní ìmọ̀ nípa ẹ̀rọ ìgbàlódé.
Mínísítà fún ètò ìbánisọ̀rọ̀ àti ìmọ̀ ẹ̀rọ ìgbàlódé Isa Pantami ló sọ̀rọ̀ yìí pẹ̀lú àwọn akọ̀ròyìn nílùú Àbújá pé kó tó di ọdún mẹ́wàá sí àsìkò tí a wá yìí, gbogbo àwọn ọmọ orílẹ̀ èdè Nàíjíríà yóò ti di ògbóǹtarìgì nínú ìmọ̀ èrọ ìgbàlódé, nípa ìgbésẹ̀ tí ìjọba yìí ń gbé lórí ìmọ̀ ẹ̀rọ.
Mínísítà tún tẹ̀síwájú pé gbogbo àwọn ọmọ orílẹ̀ èdè Nàíjíríà ni yóò jẹ ànfààní ẹ̀kọ́ nípa ìmọ̀ ẹ̀rọ.
--- Pa Adama Aduku di olóògbé.
Ààrẹ Muhammadu Buhari ti bá ẹbí, ọ̀rẹ́ àti ìjọba ìpínlẹ̀ Kogi kẹ́dùn ikú Adama Aduku Adamu jẹ́ ọ̀kan lára àwọn ọmọ-ogun orílẹ̀ èdè Nàíjíríà, tó ja ogun àgbáyé kejì,(world war 11), ọmọ ọdún mọ́kànlélọ́gọ́rùn ún (101) Adama Aduku kó tó fi ayé sílẹ̀.
Ààrẹ wá gbàdúrá pé kí Ọlọ́run tẹ́ olóògbé náà sí afẹ́fẹ́ ire, kí Ọlọ́run sì tu àwọn ẹbí́ olóògbé náà nínú.
--- Ọlọ́pàá mẹ́rìnléláàdọ́rin gba ìgbéga lẹ́nu isẹ́ ní ìpínlẹ̀ Kaduna.
Kọmísọ́nà àwọn ọlọ́pàá ní ìpínlẹ̀ Kaduna, Ali Janga ti ṣe àwọn ọlọ́pàá mẹ́rìnléláàdọ́rin (74) tí wọ́n sẹ̀sẹ̀ gba oyè ìgbéga lẹ́nu isẹ́, lọ́sọ̀ọ́.
Ali ní ìgbéga náà jẹ́ ara akitiyan adarí ilé-isẹ́ ọlọ́pàá lórílẹ̀ èdè Nàíjíríà, láti ṣe móríyá fún àwọn ọlọ́pàá tí o ti ṣe gudu gudu méje, yàyà mẹfà lẹ́nu iṣẹ́, nípa gbígbógun ti ìwà ọ̀daràn lorílẹ̀ èdè Nàíjíríà.
Kọmísọ́nà náà tún sọ pé ìgbéga náà wà lára ìlànà ilé-isẹ́ ọlọ́pàá orílẹ̀ èdè yìí láti jẹ́ kí ètò ààbò tún fẹsẹ̀ múlẹ̀ síi lorílẹ́ èdè Nàíjíríà.
Kọmísọ́nà náà wá gbósùbà fún àwọn ènìyàn ìpínlẹ̀ náà àti akọ̀ròyìn fún àtìlẹyìn wọn fún ilé-iṣẹ́ ọlọ́pàá pàápàá jùlọ fún ìròyìn àti ẹ̀sùn tí wọn fi ń tó wọn létí.
--- Amina Mohammed gba àmì ẹ̀yẹ àgbáyé.
Ààrẹ Mohammadu Buhari ti kí mínísítà àná fún ètò àyíká, Amina Mohammed fún àmì ẹ̀yẹ àgbáyé lórí mímú ìgbé ayé ìdẹ̀rùn bá àwọn ènìyàn, pàápàá jùlọ fún ipa pàtàkì tí ó ń kó lórílẹ̀ èdè Nàíjíríà nípa bí ó se ń ran àwọn tó kù díẹ̀ kí wọ́n fọwọ́-họrí lọ́wọ́.
Ààrẹ Buhari wá gbósùbà fún igbákejì akọ̀wé àgbà fún àjọ àgbáyé UN fún ipa ribi-ribi tí ó ń kó láti mú ìpinnu àjọ àgbáyé wá sí ìmúsẹ, nípa mímú àwọn ènìyàn kúrò nínú ìsẹ́ àti òṣì, kí ó tó di ọdún 2030.
Ààrẹ Buhari wá rọ igbákejì akọ̀wé àgbà náà láti máa káàrẹ́ẹ̀ nípa síse ìrànwọ́ fún àwọn ènìyàn lọ́nà àtiyọ wọn kúrò nínú ìṣẹ́.
--- Ènìyàn mọ́kàndínlógún pàdánù ẹ̀mí wọn ní ìpínlẹ̀ Kogi.
Ààrẹ Muhammadu Buhari ti fi àìdùnnú rẹ̀ hàn lórí ìwà ìpànìyàn tó wáyé ní agbègbè Tawari ní ìpínlẹ̀ Kogi, níbi tí àwọn agbébọn kan ti pa àwọn ènìyàn mọ́kàndínlógún.
Nígbà tí ààrẹ Buhari ń sọ̀rọ̀ lórí ìsẹ̀lẹ̀ náà, ó ní: “Kò sí àwáwí tàbí ẹjọ́ kankan fún ẹnìkan tàbí ẹgbẹ́ nípa gbiǵba ẹ̀mí àwọn áláìsẹ̀.
’’ “Gbígba ẹ̀mí tábi gbígbẹ̀san nípa gbígba ẹ̀mí máa ń jẹ́ kí ìwà ipá gbilẹ̀ sìí ni, ní èyí tí ó leè se àkóbá fún ètò ààbò.
Ààrẹ wá rọ gbogbo àwọn ènìyàn láti máa yanjú aáwọ̀ wọn ni ìtùbí-ìnùbí dípò síse ara ẹni ní ìjàmbá.
--- Ẹ sàtìlẹ́yìn fún ìjọba Buhari: Abiola Ajimobi.
Gómìnà àná fún ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́ Abiola Ajimobi ti rọ gbogbo ọmọ orílẹ̀ èdè Nàíjíríà láti túbọ̀ máa sàtìlẹyìn fún ìjọba Muhammadu Buhari, kí wọ́n sì ní ìgbàgbọ́ nínú ìsejọba rẹ̀.
Ajímọ̀bi ní ààrẹ Muhammadu Buhari tí ń se gudu gudu méje, yàyà mẹfà láti rí i pé àtúnse débá ètò ọrọ̀ ajé orílẹ̀ èdè yìí.
Ajímòbi sọ̀rọ̀ yìí láti ẹnu agbẹnusọ rẹ̀, Bolaji Tunji, ó tún lo àsìkò náà lati rọ gbogbo ọmọ ẹgbẹ All Progressives Congress, APC, to wa ni ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́ láti gba àtúnse tí wọn fẹ́ se nínú ẹgbẹ́ náà láàyè fún ànfààní ẹgbẹ́ àti àwọn ọmọ ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́.
Nínú àtẹ̀jáde kan tí Ajímòbi gbé jáde, ó ní, “Mo fẹ́ fi dá gbogbo ọmọ orílẹ̀ èdè Nàíjíríà lójú pé, ìfẹ́ orílẹ̀ èdè yìí ń gbóná lọ́kàn ààrẹ Buhari, ó sì ti pinnu pé òun yóò fi àpẹẹrẹ rere lélẹ̀ tí àwọn ìran tó ń bọ̀, yóò leè máa ròyìn rẹ̀.
"Ó tún sọ pé, “Ọ̀pọ̀ àwọn ènìyàn ló ti ṣẹ̀ mí, èmi náà sì ṣẹ ọ̀pọ̀ àwọn ènìyàn.
Ṣùgbọ́n kí á leè gba àtúnse láàyè, a gbọdọ̀ dáríjin ara wa, kí a sì jẹ́ kí ohun tí ó ti kọjá lọ, bá ọdún 2019 lọ.
--- Mínísítà fún àwọn ọmọ ọgọ́fà tí wọ́n bí lọ́jọ́ ọdún tuntun lẹ́bùn.
Minisita ìpínlẹ̀ fún, FCTA Nigerian Federal capital territory administration, Ramatu Tijjani Aliyu, ti fi ẹ̀bùn orísirísi àti owo fun awọn ọmọ ọgọ́fà ti wọn bi lasiko ọdún tuntun yìí ni àwọn ilé ìwòsàn alábọ́dé tó wà ní ni ìjọba ìbílẹ̀ mẹ́fẹ́ẹ̀fà tó wà nílùú Àbújá.
Mínísítà ti adelé akọ̀wé àgbà fún ilé ìwòsàn alábọ́dé sojú rẹ̀, Iwot Ndaeyo dúpẹ́ lọ́wọ́ àwọn òbí fún ìtọ́jú ọmọ wọn, nígbà tí ó sì ń tẹnumọ pé ẹ̀bùn láti ọ̀dọ̀ Ọlọ́run ni ọmọ.
Aliyu wá lo àsìkò náà láti fi ran àwọn òbí létí nípa gbígba abẹ́rẹ́ àjẹsára fún àwọn ọmọ lóòrè-kóòrè, kí wọn tó pé ọmọ ọdún méjì, kí wọn sì ri i pé wọn tọ́jú káàdì ọ̀hún.
Ikọ̀ mínísítà ọ̀hún tún lọ sí ilé ìwòsàn alábọ́dé ti Kutunku àtijọ́ tó wà ní ìjọba ìbílẹ̀ Gwagwalada, ilé ìwòsàn alábọ́dé ti Kunchigoro tó wà ní ìjọba ìbílẹ̀ Àbújá Municipal Area Council (AMAC), ilé ìwòsàn alábọ́dé ti Ushafa tó wà ní ìjọba ìbílẹ̀ Bwari, ilé ìwòsàn alábọ́dé ti Dabi Bako tó wà ní ìjọba ìbílẹ̀ Kwali àti ilé ìwòsàn alábọ́dé tó wà ní ìjọba ìbílẹ̀ Abaji.
--- Ọdún 2020: Ààrẹ Buhari bá Nàíjíríà yọ̀, ṣàlàyé nípa àṣeyọrí rẹ̀.
Ààrẹ orílẹ̀ èdè Nàíjíríà, Muhammadu Buhari ti bá àwọn ọmọ orílẹ̀ èdè Nàíjíríà yọ àyájọ́ ọdún tuntun 2020;
Nínú ìwé àtẹ̀jáde kan tí ààrẹ fi ránsẹ́ sí gbogbo ọmọ orílẹ̀ èdè Nàíjíríà, lọ́jọ́ kínní, ọdún 2020, pé àtúnṣe ńlá ló ti dé bá iṣẹ́ àgbẹ̀ lórílẹ̀ èdè yìí lásìkò ìjọba rẹ̀.
Ààrẹ ní: “Bí a ṣe ń jẹ tàbí mu pẹ̀lú àwọn ọ̀rẹ́ àti ẹbí wa nínú àsìkò ìsinmi yìí, tí tábìlì ouńjẹ wa kún fún oúnjẹ tí à ń pèsè fúnra wa, fún ìgbà àkọkọ lórílẹ̀ èdè yìí, láìjẹ́ pé a kó àwọn ouńjẹ yìí wá láti òkè –òkun.
Èyí jásí pé àyípadà àti àtúnse ti débá isẹ́ ọ̀gbìn ni gbogbo orígun mẹ́rẹ̀ẹ̀rin orílẹ̀ èdè Nàíjíríà.
A tún ti tọwọ́bọ ìwé àdéhùn mííràn pẹ̀lú orílẹ̀ èdè Morocco, Russia àti àwọn orílẹ̀ èdè mííràn, láti ràn wá lọ́wọ́ nípa isẹ́ ọ̀gbìn lórílẹ̀ èdè yìí.
Ààrẹ tún sọ̀rọ̀ nípa ètò ìrìnnà lórílẹ̀ édé yìí: “Lórí ètò ìrìnnà, a ti gbìyànjú láti se àseyọrí lórí rẹ̀ bí i afárá kejì ti Niger,
Ojú ọ̀nà márosẹ̀ tó wà ní Lagos – Ìbàdàn àti èyí tó wà ní ìlú Àbújá sí Kánò.
A ó tún gbé ìgbésẹ̀ lọ́dún 2020 yìí láti se isẹ́ lórí ojú ìrìnnà ọkọ̀ ojú irin ti ìpínlẹ̀ Èkó sí Kánò.
isẹ́ ti lọ lójú pópó ti Àpápá-Òwòròǹshòkí.
Àbújá àti Port Harcourt ti ní ibùdó ọkọ̀ ojú òfurufú tuntun, bákan náà ni á ò tún tẹ̀síwájú láti se èyí ní ìpínlẹ̀ Èkó àti Kánò lọ́dún 2020.
Tí a bá parí àwọn isẹ́ àkànse yìí, yòó tún jẹ́ kí ètò ọrọ̀ ajé orílẹ̀ èdè gbóunjẹ fẹ́gbẹ́ -gbàwobọ̀.
“Wàhálà lórí ìná mọ̀nà-mọ́ná ti wà láti ìgbà ìwásẹ̀.
A ti gbé ìgbésẹ̀ láti bá àwọn tí ọ̀rọ̀ náà kàn sọ̀rọ̀ láti wá ojútùú sí ìṣòro ọ̀hún.
Ààrẹ Buhari tún sàlàyé lórí ìpinnu rẹ̀ láti gbógun ti ìsẹ́ àti òṣì lórílẹ̀ èdè Nàíjíríà."
“Lásìkò àjọ̀dún ètò ìjọba tiwa-n-tiwa, mo sèlérí pé ọgọ́rùn ún mílíọ̀nù ọmọ orílẹ̀ èdè yii ni maa yọ kuro ninu ìsẹ́ ati òṣì láàrin ọdún mẹ́wàá.
A oò tún tẹ̀síwájú láti ṣe àwọn àtúnse tó mọ́nyán lórí nípa ètò ẹ̀kọ́, ilé-ìwòsàn alábọ́dé àti omi.
A ó túbọ̀ máa fọwọ́sowọ̀pọ́ pẹ̀lú ìjọba ìpínlẹ̀ àti ìbílẹ̀.
Owó osù àwọn òsìsẹ́ yóò se wọ́n ní ànfààní, a ó sì tún mójútó àwọn òsìsẹ́ tó ti fẹ̀yìntì lẹ́nu isẹ́ wọn.
A ti bẹ̀rẹ̀ sí ní máa san àwọn owó tí wọn jẹ àwọn òsìsẹ́ fẹ̀yìntì fún ìgbà pípẹ́ báyìí.
--- Ọdún 2020: Abẹnugan ilé ìgbìmọ̀ asòfin ni ọrọ̀ ajé Nàíjíríà yóò búrẹ́kẹ́ síi.
Abẹnugan ilé ìgbìmọ̀ asòfin lórílẹ̀ èdè Nàíjíríà Ahmad Lawan ti ńi òun nígbàgbọ́ pé ọdún 2020 yóò tún jẹ́ kí ìsọ̀kan àti ìdàgbàsókè fẹsẹ múlẹ̀ síi lórílẹ̀ èdè Nàíjíríà.
Nínú ìròyìn ọdún tuntun tí abẹnugan ọ̀hún gbé jáde láti kí gbogbo ọmọ orílẹ̀ èdè Nàíjíríà fún ìbẹ̀rẹ̀ ọdún 2020.
Abẹnugan gbósùbà fún gbogbo ọmọ orílẹ̀ èdè Nàíjíríà fún ẹ̀mí ìsọ̀kan àti ìdàgbàsókè orílẹ̀ èdè ọ̀hún àti àtìlẹ́yìn wọn fún ìjọba Muhammadu Buhari.
Abẹnugan wá fi dá gbogbo ọmọ orílẹ̀ èdè Nàíjíríà lójú pé, ilé ìgbìmọ̀ asòfin kò ní káàrẹ́ẹ̀ láti máa sòfin tí yóò mú ìgbáyé-gbádùn bá gbogbo ọmọ orílẹ̀ èdè Nàíjíríà.
Asòfin Lawan tún ní ilé ìgbìmọ̀ asòfin yóò túbọ̀ máa fọwọ́sowọ́pọ̀ pẹ̀lú ìjọba àpapọ̀ kí ìbásepọ̀ wọn tún leè gún régé fún ànfààní gbogbo ọmọ orílẹ̀ èdè Nàíjíríà.
Abẹnuga wá kí gbogbo ọmọ orílẹ̀ èdè Nàíjíríà nílé, lóko àti lájò kú ọdún tuntun.
--- Ọdún tuntun: Abẹnugan ilé ìgbìmọ̀ asojú bá Nàíjíríà yọ̀, ó pè fún ẹ̀mí ìsọkan.
Abẹnugan ilé ìgbìmọ̀ asojú lórílẹ̀ èdè Nàíjíríà, Fẹmi Gbajabiamila ti bá gbogbo ọmọ orílẹ̀ èdè Nàíjíríà yọ ayọ̀ ọdún 2020.
Gbajabiamila ní ọpọ̀lọpọ̀ nǹkan ribi-ribi ló sẹlẹ̀ ní orílẹ̀ èdè Nàíjíríà lọ́dún 2019 , lára rẹ̀ ni ètò ìdìbò tó wáyé ni ìrọwọ́-ìrọsẹ̀, ó ní òun nígbàgbọ́ pé ọdún 2020 yóò dára fún orílẹ̀ èdè Nàíjíríà.
Abẹnugan sọ̀rọ̀ yìí láti ẹnu olùrànlọ́wọ́ rẹ̀ fún ìròyìn àti ìkéde, Lanre Lasisi, ó wá rọ gbogbo ọmọ orílẹ̀ èdè Nàíjíríà láti gba ẹ̀mí ìsọ̀kan láàyè.
"Ó tẹ̀síwájú pé""A kò gbọdọ̀ dákẹ́ àdúrà wa pàápàá jùlọ fún ìsọ̀kan àti ìbágbépọ̀ orílẹ̀ èdè yìí."
Kí Ọdún 2020 jẹ́ ọdún àseyọrí fún gbogbo ọmọ orílẹ̀ èdè Nàíjíríà.
"Abẹnugan Gbàjàbíàmílà tún sọ pé ilé ìgbìmọ̀ asòfin kò ní káàrẹ́ẹ̀ láti máa ṣòfin tí yóò túbọ̀ mú ìgbáyé-gbádùn bá àwọn ọmọ orílẹ̀ èdè Nàíjíríà.
--- Gómìnà ìpínlẹ̀ Benue bọwọ́lu àbádòfin ètò ìsúná ọdún 2020.
Gómìnà ìpínlẹ̀ Benue, Samuel Ortom ti tọwọ́bọ ìwé ètò ìsúná ọdún 2020 ti iye rẹ̀ lé ní biliọnu mọ́kàndínláàdọ́wàá. (N189.43 billion) láti sọọ́ di òfin.
Lásìkò tí Ortom ń tọwọ́bọ ìwé ètò ìsúná ọdún 2020 ọ̀hún tí ó pè ní “Ìtẹ̀síwájú, Ìdàgbàsókè àti ìmúgbòòrò lọ́jọ́ Ajé ni Makurdi, ó sèlérí láti jẹ́ ḱi gbogbo àwọn ènìyàn lọ́wọ́ nínú ìsejọba rẹ̀."
Ortom gbé àbádòfin ètò ìsúná lọ síwájú ìgbìmọ̀ asojú ìpínlẹ̀ náà ní ọjọ́ kejìlá, Osù kọkànlá.
Ortom ní ètò ìsúná náà yóò mú ìgbé ayé ìdẹ̀rùn àwọn ènìyàn àti ìdàgbàsókè bá ètò ẹ̀kọ́, ètò ìlera, omi àti àwọn ohun amáyédẹrùn.
--- Gómìnà ìpínlẹ̀ Ọ̀sun bọwọ́lu àbádòfin ètò ìsúná ọdún 2020.
Gómìnà ìpínlẹ̀ Ọ̀sun Gboyega Oyetọla ti bọwọ́lu àbádòfin ètò ìsúná ọdún 2020 ti iye rẹ̀ lé ní díẹ̀ ní bílíọ̀nù mọ́kàndínlọ́gọ́fà (N119.5 billion), ní èyí tí ó sèlérí láì mú ètò ìsúná náà lò.
Gómìnà tọwọ́bọ ìwé ètò ìsúná náà láti sọọ́ di òfin lẹ́yìn tí abẹnugan ilé ìgbìmọ̀ asojú ìpínlẹ̀ Ọ̀ṣun, Timothy Owóẹ̀yẹ gbé àbádòfin ètò ìsúná náà gbé fún un.
Ọjọ́ kẹ́rìnlélógún, oṣú kejìlá, ọdún yìí ní ilé ìgbìmọ̀ aṣojú náà fẹnukò lórí ètò ìsúná náà.
Oyetola ní, ohun jẹ́ kí ètò ìṣúná náà wà ní ìbámu pẹ̀lú bí ètò ọrọ̀ ajé ìpínlẹ̀ náà se rí lásìkò yìí, lọ́nà àtimú ètò ìsúná náà wá sí ìmúsẹ.
Gómìnà Oyetola wá sèlérí láti mójútó àwọn ohun tí yóò mú ìdàgbàsókè bá ìpínlẹ̀ náà, ní èyí tí àwọn olùgbé ìpínlẹ̀ náà yóò leè jẹ ànfààní rẹ̀ lọ́dún 2020.
Ó tẹ̀síwájú pé ìjọba yóò gbìyànjú láti mú ètò ìdàgbàsókè bá gbogbo ẹka tó wà ní ìpínlẹ̀ náà.
--- Ìjọba Nàíjíríà ti sanwó oúnjẹ àwọn ọmọ ilé –ìwé fún ọdún 2020.
Ìjọba orílẹ̀ èdè Nàíjíríà ti san owó oúnjẹ tí àwọn ọmọ ilé-iwé yóò máa jẹ ní osù kinni,ọdún 2020 fún àwọn agbasẹ́se, eléyìí wà lára ètò tí ìjọba àpapọ̀ yà sílẹ̀ láti máa fún àwọn akẹ́kọ̀ọ́ tí iye wọ́n lé ní miliọnu mẹ́sàn án tó wà ní jákè-jádò orílẹ̀ èdè Nàíjíríà àti ìpínlẹ̀ FCT.
Mínísítà fún ètò ọmọnìyàn, àjálù àti ìdàgbàsókè àwùjọ, Hajiya Sadiya Umar Farouq ló kéde yìí nílùú Àbújá pé, ìjọba ti san owó tí yóò pèsè ouńjẹ fún àwọn ọmọ ilé-ìwé tó wà ní ìpínlẹ̀ mẹ́tàlélọ́gbọ̀n lorílẹ̀ èdè Nàíjíríà.
Mínísítà tún sọ pe ijọba apapọ san owo naa ni osu kejila, ọdun yii fun awọn agbasẹse ti yoo pese ounjẹ ati eroja ounjẹ fun awọn akẹkọọ ọhun.
Minista wá kìlọ̀ pé ìjọba kò ní fàyè gba ounjẹ ti eroja rẹ ko ba dara tó tàbí tí kò ní àwọn ohun a-fún-ara-lóore fun àwọn ọmọ ilé –iwé náà.
--- Ààrẹ orílẹ̀ èdè Nàíjíríà ń se ìpàdé pẹ̀lú àwọn adarí àjọ elétò ààbò.
Ààrẹ orílẹ̀ èdè Nàíjíríà, Muhammadu Buhari ń se ìpàdé pẹ̀lú àwọn adarí ilé –isẹ́ elétò ààbò lọ́wọ́-lọ́wọ́ báyìí nílé ààrẹ tó wà nílùú Àbújá.
--- Ẹ jẹ́ ká wá ojú rere Ọlọ́run fún ìdàgbàsókè orílẹ̀ èdè Nàíjíríà: NYCN.
Ẹgbẹ́ àwọn ọ̀dọ́ lórílẹ̀ èdè Nàíjíríà, (The National Youth Council of Nigeria NYCN) ti rọ gbogbo ọmọ orílẹ̀ èdè yìí láti wà nínú àwẹ̀ àti àdúrà ọlọ́jọ́ mẹ́ta fún ìsọ̀kan, àlàáfíà àti ìdàgbàsókè orílẹ̀ èdè Nàíjíríà.
Nínú àtẹ̀jáde kan tí ààrẹ ẹgbẹ́ náà, Solomon Adodo gbé jáde nílùú Àbújá, pé kí gbogbo ọmọ orílẹ̀ èdè Nàíjíríà wà nínú àdúrà àti àwẹ̀ ọlọ́jọ́ mẹ́ta láti ọjọ̀ kínní di ọjọ́ kẹta osù kínní,( Jan.1 to Jan) ọdún 2020.
Adodo tún wá rọ wọn láti jáwọ́ nínú ẹ̀sẹ̀, kí wọn sì wá ojú rere Ọlọ́run.
“Gbogbo àwọn orílẹ̀ èdè tí wọn wá ojú rere ọlọ́run fún ìdàgbàsókè orílẹ̀ èdè wọn, ní ìdàgbàsókè ti dé bá.
“A ní ìgbàgbọ́ pé, tí a bá wá ojú rere Ọlọ́run nípa ìṣòro tó ń dójúkọ orílẹ̀ èdè yìí, ó dájú pé ìṣòro náà yóò di pẹ̀tẹ́lẹ̀.
Gẹ́gẹ́ bí ó se sọ, ó ní kí àwọn ọmọ lẹ́yìn kristi péjọ nílé ìjọ́sìn wọn fún àdúrà lásìkò àwẹ̀, kí àwọn mùsùlùmí náà péjọ ní mọ́sálásí láti gbàdúrà lásìkó àwẹ̀ tíwọn náà.
--- Ẹ pa ọlọ̀tẹ̀ àti àwọn alákatakítí ẹlẹ́sìn run lórílẹ̀ èdè Nàíjíríà: Tukur Buratai.
Adarí ilé-isẹ́ ológun lórílẹ̀ èdè Nàíjíríà, Lt.-Gen.Tukur Buratai ti rọ àwọn ikọ̀ ọmọ -ogun Operation Lafiya Dole (OPLD) tí wọ́n ń kó lọ sí Madagali ní ìpínlẹ̀ Adamawa láti máa fún àwọn ikọ̀ ọlọ̀tẹ̀ ní ìsinmi rárá.
Buratai, sọ̀rọ̀ yìí lásìkò tó ń kàn sí ikọ̀ ọmọ ogun náà lọ́jọ́ Àìkú, ó wá rọ wọn láti túbọ̀ máa gbógun ti ikọ̀ ọlọ̀tẹ̀ ni agbègbè náà, kí wọn máa sì rẹ̀wẹ̀sì rárá nínú ojúse wọn.
Buratai tún ní ìjọba ti sèlérí láti sàtìlẹyìn fún wọn, ní èyí tí yóò fi leè ràn lọ́wọ́ láti borí ikọ̀ ọlọ̀tẹ̀ tó ń da omi àlàáfíà orílẹ̀ èdè yìí rú.
Ó tún wá gbósùbà fún ikọ̀ náà fún gudugudu méje, yàyà mẹfà tí wọn se láti gbógun ti ikọ̀ Boko Haram àti àwọn ọlọ̀tẹ̀ alákatakítí ẹlẹ́sìn mùsùlùmí, Islamic State of West Africa Province (ISWAP) ní ẹkùn náà.
“Inú mi dún ùn láti wà níbí yìí, nítorí àgbègbè yìí gan ni mo mọ̀ pé ó léwu púpọ̀ fún ikọ̀ Operation Lafiya Dole (OPLD) láti se isẹ́ wọn.
“Ẹ ti se gudu gudu méje, yàyà mẹfà láti gbógun ti ìwà ọ̀daràn,ikọ̀ Boko Haram àti ISWAP.
“Ẹ máa se fún wọn ní ìsinmi rárá.
Èyí ni pé ẹ ó máa gbógun tì wọ́n yálà ní òwúrọ̀, ọ̀sán àti àsálẹ́, nígbà òjò tábi nínú òòrùn.
--- Èmi ò ní yọ ẹnìkankan sílẹ̀ níbi ìsàkoso mi: Ahmed Lawan.
Abẹnugan ilé ìgbìmọ̀ asòfin, Ahmed Lawan ti sèlérí láti máa fa orí apá kan, dá apá kan sí níbi ìsàkoso rẹ̀.
Lawan sọ̀rọ̀ yìí lọ́jọ́ Àbámẹ́ta ni Damaturu níbi ayẹyẹ láti fi se àyẹ́sí fún abẹnugan ilé ìgbìmọ̀ asòfin àti mínísítà ìpínlẹ̀ fún isẹ́ àkànse àti ilé lórílẹ̀ èdè Nàíjíríà, Abubakar Aliyu.
Lawan tún sọ pe “Mo ti pinnu láti se ìsàkóso mi, ní èyí tí yóò kó gbogbo ọmọ ilé ìgbìmọ̀ asòfin mọ́ra, ní èyí tí ẹgbẹ́ òsèlú kò ní leè nípa lórí ohun tí a bá se.
Gbogbo ohun tí a bá fẹ́ se ni ó gbọdọ̀ jẹ́ èyí tí gbogbo ọmọ orílẹ̀ èdè Nàíjíríà yóò jẹ ànfààní rẹ̀.
"“Gbogbo ọmọ orílẹ̀ èdè Nàíjíríà, yálà ó wà nínú ẹgbẹ́ òsèlú kan tàbí kò sí níbẹ̀, ló fẹ́ kí ìdàgbàsókè bá ètò ọrọ̀ ajé orílẹ̀ èdè yìí""."
Lawan wá rọ gbogbo ọmọ orílẹ̀ èdè Nàíjíríà láti se àtìlẹyìn fún ilé ìgbìmọ̀ asòfin lórí àseyọrí wọn.
Ó tún wá dúpẹ́ lọ́wọ́ ilé ìgbìmọ̀ asòfin fún àtìlẹyìn tí wọn ń se fún un.
Nínú ọ̀rọ̀ rẹ̀ gómìnà ìpínlẹ̀ Yobe, Maimala Buni, ó gbósùbà fún abẹnugan ilé ìgbìmọ̀ asòfin fún ìbásepọ̀ tó múná-dóko tó wà láàrin ọmọ ẹgbẹ ilé ìgbìmọ̀ asòfin àti ìjọba àpapọ̀.
--- Gómìnà ìpínlẹ̀ Adamawa gbósùbà fún ilé-isẹ́ ológun fún ìpèsè àlàáfíà.
Gómìnà ìpínlẹ̀ Adamawa, Fintiri ti gbósùbà fún ilé-isẹ́ ológun orílẹ̀ èdè Nàíjíríà láti gbógún ti ikọ̀ ọlọ̀tẹ̀ Boko Haram tó ń da omi àlà́afíà ìpínlẹ̀ náà láàmú pàápàá jùlọ ní ìwọ oòrùn Àríwá tó wà ní ìpínlẹ̀ Adamawa láti pèsè ètò àlà́afíà níbẹ̀.
Fintiri ẹni tí igbákejì rẹ̀, oloye Seth Crowther sojú fún, ló gbósùbà fún ilé-isẹ́ ológun náà lásìkò tí wọn ń se ìfilọ́lẹ̀ isẹ́ àkànse tí owó rẹ̀ lé ní ẹgbẹgbẹ̀rún mílíọ́nù fún ibùdó àwọn ọmọ ológun ọ̀hún, ní Gibson Jalo, tó wà ní Yola, lọ́jọ́ Àbámẹ́ta.
Ó tún tẹ̀síwájú pé ìgbésẹ̀ ń lọ lọ́wọ́ láti ṣe àtúnse sí ètò ààbò ní ìpínlẹ̀ náà, nípa pípèsè àwọn ọkọ̀ ayọ́kẹ́lẹ́, kíkọ́ ilé-ẹ̀kọ́ fún àwon ọmọ ilé –ìwé àti àwọn irinsẹ́ tí yóò leè ran àwọn àjọ elétò ààbò lọ́wọ́ láti fòpin sí ìwà ìdúnkookò mọ́ni, tí yóò sì tún fi ọkàn àwọn ènìyàn ìpínlẹ̀ náà balẹ̀.
Nínú ọ̀rọ̀ tirẹ̀ adarí ilé-isẹ́ ológun orílẹ̀ èdè Nàíjíríà, Lt.-Gen. Tukur Buratai, náà sọ pé isẹ́ àkànse náà wà lára ètò láti mú ìgbé ayé ìdẹ̀rùn bá gbogbo ọmọ ológun orílẹ̀ èdè yìí àti ẹbí wọn.
--- Gómìnà ìpínlẹ̀ Sokoto bọwọlu àbádòfin ètò ìsúná ọdún 2020.
Gómìnà ìpínlẹ̀ Sokoto, Aminu Waziri Tambuwal ti bọwọ́lu àbádòfin ètò ìsúnáọdún2020 ti iye rẹ̀ lé ní méjìlènígba biliọnu naira (N202.4 billion) tí ilé ìgbìmọ̀ asojú ìpínlẹ̀ náà fẹnukò lé lórí láti sọọ́ di òfin.
Lásìkò tí gómìnà náà ń tọwọ́bọ ìwé àbadòfin fún ètò ìsúná náà, Tambuwal wá gbósùbà fún ilé ìgbìmọ̀ asojú ìpínlẹ̀ náà, tí púpọ̀ nínú wọn jẹ́ ọmọ ẹgbẹ́ alátakò- All Progressive Congress (APC), fún àtìlẹyìn wọn fún ìlọsíwájú ìpínlẹ̀ náà.
"Gomina Tambuwal tún sọ pé ""Bó tilẹ̀ jẹ́ pé ẹgbẹ́ alátakò APC ló pọ̀jù nílé ìgbìmò asojú ìpínlẹ̀ yìí, síbẹ̀ wọ́n tún ń sàtìlẹyìn fún ìjọba láti rí i pé wọ́n se ojúṣe wọn fún ìlọsíwájú ìpínlẹ̀ yìí ""."
"Abẹnugan ilé ìgbìmọ̀ asojú ìpínlẹ̀ Sokoto, Aminu Muhammad Achida wá gbósùbà fún ìjọba ìpínlẹ̀ náà fún gbogbo akitiyan wọn láti rí i pé wọ́n se àseyọrí ní ìpínlẹ̀ náà, bó tilẹ̀ jẹ́ pé wọ́n ní ìjákulẹ̀ owó.
--- Ẹ máa jẹ́ kí àwọn ọlọ̀tẹ̀ pín Nàíjíríà yẹ́lẹ-yẹ̀lẹ – Ààrẹ Buhari.
Ààrẹ orílẹ̀ èdè Nàíjíríà Muhammadu Buhari ti rọ àwọn ọmọ orílẹ̀ èdè yìí láti máa jẹ́ kí ̀àwọn ọlọ̀tẹ̀ pín orílẹ̀ èdè Nàíjíríà yẹlẹ-yẹlẹ nitori ẹsin.
Ààrẹ Buhari tún sọ pé: “Inú mi bàjẹ́ nípa ikú àwọn omọ orílẹ̀ èdè yìí tí wọ́n kú sí ibi ìhámọ́ láti ọwọ́ àwọn alákatakítí ẹlẹ́sìn, àwọn apanìyàn tí wọ́n ń ba orúkọ ẹ̀sìn mùsùlùmí jẹ́ nípa ìwà burúkú wọn.
“Lábẹ́ bó ti wù kórí, a ò gbọdọ̀ gba àwọn ọlọ̀tẹ̀ láàyè láti da omi àlááfíà orílẹ̀ èdè yìí rú nípa dídá ìjà sílẹ̀ láàrin àwọn ẹlẹ́sìn mùsùlùmí àti ìgbàgbọ́, nítorí àwọn apànìyàn yìí kì í se ẹlẹ́sìn mùsùlùmí rárá.
“Gẹ́gẹ́ bí ààrẹ orílẹ̀ èdè yìí, ojúṣe mi ni láti mójútó ètò ààbò gbogbo ọmọ orílẹ̀ èdè Nàíjíríà, nítorí náà ikú àwọn aláìsẹ̀ yálà mùsùlùmí tàbí onígbàgbọ́ máa ń bà mí nínú jẹ́.
’’Ààrẹ tún sọ pé ohun tí àwọn ọlọ̀tẹ̀ ní lọ́kàn ni láti máa ṣe iṣẹ́ ibi wọn, láti máa ta ẹ̀jẹ̀ àwọn aláìsẹ̀ sílẹ̀, ní èyí tí ó lòdì sí ìmọ̀ ẹ̀kọ́ ẹ̀sìn mùsùlùmí àti ìgbàgbọ́.
--- Nàíjíríà yan ìgbìmọ̀ alámójútó fún iná mọ̀nà-mọ́ná.
Ìgbìmọ̀ alámójútó lábẹ́ ìsàkoso mínísítà ilé-isẹ́ mọ̀nà-mọ́ná lórílẹ̀ èdè Nàíjíríà, ni ìjọba ti yàn láti máa mójútó iná mọ̀nà-mọ́ná lórílẹ̀ èdè yìí, ní èròǹgbà láti rí i pé àtúnse tó mọ́nyán lórí bá iná mọ̀nà-mọ́ná.
Lasiko ti Sale Mamman to jẹ minisita fun iná mọ̀nà-mọ́ná lórílẹ̀ èdè Nàíjíríà n se ifilọlẹ ìgbìmọ̀ naa , ó rọ̀ wọ́n lati mojuto ọna ti atunse yoo se lee ba iná mọ̀nà-mọ́ná, ní èyí tí àwọn ọmọ orílẹ̀ èdè Nàíjíríà yoo se maa jẹ̀gbádùn iná mọ̀nà-mọ́ná ọ̀hún.
Mamman tún sọ pé ìgbìmọ̀ náà ni yoo tun jẹ olugbanimọran lori eto ilana ati imọ ẹrọ tuntun lori iná mọ̀nà-mọ́ná.
Ó tún tẹ̀síwájú pé ọdún méjì ni ìgbìmọ̀ náà, ní láti fi isé wọn, lára ojúṣe wọn sì ni láti sètò ìlànà, tí yóò mú àtúnse tó mọ́nyán lórí nípa iná mọ̀nà-mọ́ná, ní èyí tí ìjọba orílẹ̀ èdè Nàíjíríà yóò máa tẹ̀lé.
Ọ̀jọ̀gbọ́n Abubakar Sani Sambo, ni alága ìgbìmọ̀ náà.
--- Ààrẹ Buhari bọwọ́lu ètò ìsúná ọdún 2020.
Ààrẹ orílẹ̀ èdè Nàíjírià Muhammadu Buhari ti tọwọ́bọ ètò ìsúná ọdún 2020 lọ́jọ́ Ìsẹgun, lati sọ́ di òfin, ní èyí tí iye rẹ̀ lé ní tiriọnu mẹ́wàá (N10.594).
Ní ọjọ́ karùn ún, osù kejìlá ọdún yìí, ní ilé ìgbìmọ̀ asòfin parí ìjíròrò wọn lórí ètò àbádòfin ìsúná láti sọọ́ di òfin, ní èyí tí wọn sì fẹnukò pé kí ìjọba àpapọ̀ kò gbọdọ̀ ná ju tírílíọ̀nù mẹ́wàá ló.
Ní ọjọ́ kẹwàá osù kẹjọ, ọdún 2020 ní ààrẹ orílẹ̀ èdè Nàíjírià Muhammadu Buhari gbé àbádòfin ètò ìsúná wá sí ilé ìgbìmọ̀ asòfin.
Bí ààrẹ Buhari ṣe tètè bọwọ́lu ètò ìṣúná 2019 ọ̀hún, ni yóò tún jẹ́ kí orílẹ̀ èdè Nàíjírià tún padà sí osù kínní sí osù kejìlá tí ó jẹ́ ìbẹ̀rẹ̀ ọdún, tí ààrẹ orílẹ̀ èdè Nàíjírià máa ń bọwọ́lu ètò ìsúná ọ̀hún.
Lásìkò tí ayẹyẹ ètò ọ̀hún, ààrẹ ní ilé ìgbìmọ̀ asòfin ti fi owó tó lé ní igba bílíọ̀nù (N263.95 billion) kún ìwé ìsúná tí òun gbé wá sílé ìgbìmọ̀ asòfin.
--- Ilé ìgbìmọ̀ asòfin yóò gbogun ti òsì àti ìsẹ́.
Ilé ìgbìmọ̀ asòfin ti ní àwọn kò ní kàárẹ̀ láti túbọ̀ máa gbógun ti òsì àti ìsẹ́, kí ìgbé ayé ìdẹ̀rùn leè bá gbogbo ọmọ orílẹ̀ èdè Nàíjíríà.
Abẹnugan ilé ìgbìmọ̀ asòfin Ahmad Lawan ló sọ̀rọ̀ ìdánilòjù yìí, lọ́jọ́ Ajé lásìkò tó ń bá àwọn akọ̀ròyìn sọ̀rọ̀ nílùú Àbújá.
Lawal, tún tẹ̀síwájú pé ilé ìgbìmọ̀ kẹsàn án yóò sètò òfin tí yóò gbógun ti òsì àti ìsẹ́, àjàkálẹ̀ ààrùn, ìwà ọ̀daràn, ìwà ìbajẹ́, ní èyí tí abẹnugan náà sàpèjúwe wọn, gẹ́gẹ́ bí ọ̀tá ìlú.
Ó tún sọ pé ilé ìgbìmọ̀ asòfin tètè se isẹ́ lórí ètò ìsúná ọdún 2020, tí ààrẹ Buhari gbé wá síwájú wọn, kí o lè bá ìgbà àti àkókò (January and December) tí orílẹ̀ èdè Nàíjíríà máa ṣètò lórí ìṣúná ọdọọdún wọn.
Asòfin Lawan, ní gbogbo kùdìẹ̀-kudiẹ tó wá bí wọn se ta gbogbo ohun ìní orílẹ̀ èdè yìí, pàápàá jùlọ nípa iná mọ̀nà-mọ́ná ni àwọn yóò mójútó.
Abẹnugan ilé ìgbìmọ̀ asòfin tún rọ àwọn akọ̀ròyìn láti máa fárí apá kan, dá apá kan sí, nínú ìròyìn wọn, ṣùgbọ́n kí wọn máa kọ ìròyìn tí ó leè mú ìdàgbàsókè bá orílẹ̀ èdè Nàíjíríà.
Adarí ọmọ ẹgbẹ́ tó kéré jùlọ nílé ìgbìmọ̀ asòfin, asòfin Eyinanya Abaribe tún fi dá àwọn ọmọ orílẹ̀ èdè Nàíjíríà lójú pé, bó tilẹ̀ jẹ́ pé ẹgbẹ́ ọ̀tọ̀tọ̀ ni àwọn asòfin wà, síbẹ̀.
Ìgbìmọ̀ asòfin kò ní jẹ́ kí ẹgbẹ́ ọ̀tọ̀tọ̀ náà da àárín wọn rú, láti máa se òfin tí yóò mú ìgbáyé –gbádùn bá gbogbo ọmọ orílẹ̀ édé Nàíjíríà.
--- Boris Johnson di adarí́ ìjọba orílẹ̀ èdè United Kingdom, UK.
Ààrẹ orílẹ̀ èdè Nàíjíríà Muhammadu Buhari ti kí adarí ìjọba tuntun fún orílẹ̀ èdè United Kingdom, Boris Johnson kú orí –ire bó se jáwé olúborí nínú ètò ìdìbò tí wọ́n dì kọjá lórílẹ̀ èdè náà.
Ààrẹ Buhari ní orílẹ̀ èdè Britain ti ń se gudu gudu méje, yàyà mẹ́fà láti fi ṣe àtìlẹyìn fún orílẹ̀ èdè Nàíjíríà, pàápàá jùlọ lórí ètò ààbò àti bí wọ́n se ń ran orílẹ̀ èdè Nàíjíríà lọ́wọ́ láti dá àwọn owó àti ohun ìní tí wọ́n jí kó lọ sí orílẹ̀ èdè UK padà wá sí orílẹ̀ èdè Nàíjíríà.
Ààrẹ Buhari ni òun fojúsọ́nà láti bá adarí ìjọba tuntun náà sisẹ́ papọ̀, ní èyí tí ìbásepọ̀ tó wà láàrin orílẹ̀ èdè méjéèjì náà, pàápàá jùlọ nípa bí ètò ọrọ̀ ajé, yóò se túbọ̀ ní ìdàgbàsókè síi.
--- Nàíjíríà yóò jáwọ́ láti máa ra epo rọ̀bì láti ilẹ̀ òkèèrè lọ́dun 2023.
Ìjọba orílẹ̀ èdè Nàíjíríà ti ní òhun yóò jáwọ́ láti máa ra epo rọ̀bì láti ilẹ̀ òkèèrè lọ́dún 2023.
Adarí ilé-isẹ́ tó ń mójútó epo rọ̀bì lórílẹ̀ èdè Nàíjíríà , (Nigerian National Petroleum Corporation ,NNPC), Mele Kyari ló sọ eléyìí di mímọ̀ láṣìkò tó ń tọwọ́bọ ìwé àdéhùn nípa ìdásílẹ̀ ibi tí wọn yóò gbé máa tún epo rọ lórílẹ̀ èdè Nàíjíríà.
Ètò náà ni wọ́n ní ìrètí pé yóò fòpin ṣí rira epo láti ilẹ̀ òkèèrè.
Bó tilẹ̀ jẹ́ pé lọ́dún 2017, ni ìjọba orílẹ̀ èdè Nàíjíríà ti sèpinnu láti fòpin ṣí ríra epo rọ̀bì láti ilẹ̀ òkèèrè lọ́dún 2019.
--- Ààrẹ Buhari padà sí Nàíjíríà lẹ́yìn ìpàdé àpérò àlàáfíà lórílẹ̀ èdè Egypt.
Ààrẹ Muhammadu Buhari ti padà sí ìlú Àbújá lẹ́yìn ìpàdé àpérò àlàáfíà àti ìdàgbàsókè Afirika, ní èyí tí ó wáyé ní ọjọ́ kọkànlá àti ìkejìlá, oṣù kejìlá lórílẹ̀ èdè Egypt.
Ọkọ̀ òfurufu ààrẹ balẹ̀ sí pápá ofurufu ààrẹ, Nnamdi Azikiwe International Airport, tó wà nílùú Àbújá, ní aago 13.30 GMT.
Mínísítà fún ìlú Àbújá, Federal Capital Territory, Mohammed Bello àti àwọn adarí elétò ààbò lórílẹ̀ èdè Nàíjíríà ló tẹ́wọ́gba ààrẹ ní pápá òfurufu ọ̀hún.
Ìpàdé ọ̀hún ló dá lórí ọ̀nà tí ilẹ̀ Afirika yóò ṣe gbà mójútó ètò àlááfíà àti ìdàgbàsókè, ìpàdé àpérò yìí ló tún jẹ́ àkọ́kọ́ irú rẹ̀ nílẹ̀ Afirika.
Ààrẹ Muhammadu Buhari àti ààrẹ orílẹ̀ èdè Egypt, Abdelfattah el-Sisi, tún jọ jíròrò láti gbógun tí ìwà ọ̀daràn àti ọlọ̀tẹ̀ lórílẹ̀ èdè wọn.
Lára àwọn tó tẹ̀lé ààrẹ ni mínísítà fún ètò ààbò, Gen.Bashir Magashi (Rtd); Mínísítà fún ọ̀rọ̀ ilẹ̀ òkèèrè fún ìpínlẹ̀, Amb.Zubairu Dada; Olùgbani-nímọ̀ràn lórí ètò ààbò lórílẹ̀ èdè yìí, Maj.-Gen. Babagana Monguno (Rtd); àti alákòsóo ilé-isẹ́, tó ń ṣe ìtọpinpin lórílẹ̀ èdè Nàíjíríà, (National Intelligence Agency), Amb. Ahmed Abubakar.
--- Ẹ jáwọ́ lórí ẹ̀sun Sowore: AGF Abubakar.
Adájọ́ àgbà lórílẹ̀ èdè Náíjíríà (Attorney General of the Federation), Justice Abubakar Malami ti pàsẹ fún ilé-isẹ́ ọ̀tẹlẹ̀múyẹ́ (Department of State Services, DSS) láti jáwọ́ lórí ẹ̀sun Omoyẹle Sowore ní kíákíá.
--- ilé -ẹjọ́ ní Magu le di alága àjọ EFCC.
Adájọ́ ilé ẹjọ́ gíga lórílẹ̀ èdè Nàíjíríà tó wà nílùú Àbújá, Justice Ijeoma Ojukwu, ti yí ẹjọ́ tó wà níwájú rẹ̀ dànù bí omi-ìsanwọ́ láti máa jẹ́ kí Ibrahim Mustapha Magu adelé àjọ tó ń gbógun ti ìwà síṣe owó ìlú kúmọ-kumọ̀ lórílẹ̀ èdè yìí, Economic and Financial Crimes Commission, EFCC di alága àjọ náà, pé ẹjọ́ ọ̀hụn kò lẹ́sẹ̀ nílẹ̀.
Ìpẹ̀jọ́ náà ló wáyé làsíkó tí ilé ìgbìmọ asòfin kẹjọ lábẹ́ abẹnugan, Bùkọ́lá Sàràkí nígbà tí ilé ìgbìmọ̀ náà fàáké kọ́rí pé wọn kò ní jẹ́ kí adelé ọ̀hún di alága àjọ EFCC.
Nínú ìdájọ́ rẹ̀, adájọ́ Ojukwu ní, “Ẹjọ́ yìí kò ní ẹ̀rí láti gbe ẹ̀sùn rẹ̀ lẹ́sẹ̀ nítorí náà, ilé-ẹjọ́ da ẹjọ́ náà nú.
Adájọ́ náà tún tẹ̀síwájú pé ààrẹ Muhammadu Buhari, ni “ọ̀bẹ àti iṣu lọ́wọ́, tí ó sì ní agbára láti fi ṣe ohun tí ó bá wùú, nítorí náà, òfin kò sọọ́ nípàtó iye àkókò tàbí àsìkò tí ààrẹ leè fi yan adelé sórí ipò."
"Adájọ́ Ojukwu tún tẹ̀síwájú pé ilé ìgbìmọ asòfin kò ní agbára lábẹ́ òfin láti sọ adelé si alága nípa ti alága àjọ EFCC.
--- Láìsí káàdì ìdánimọ̀, kò sí àǹfààní láti jókòó fún ìdánwò ilé-ẹ̀kọ́ gíga-Jamb.
Àjọ tó ń mọjútó ìdánwò lọ ṣí ilé- ẹ̀kọ́ gíga lórílẹ̀ èdè Nàíjíríà,The Joint Admissions and Matriculation Board, JAMB ,ti yan ẹgbẹ̀sán (1800)àwọn òsìsẹ́ wọn láti lọ ṣe àyẹ̀wò fínní-fínní lóri bí àwọn akẹ́kọ̀ọ́ tó ń gbáradì fún ìdánwò yóò se máa lo káádì ìdánimọ̀ wọn nínú àtẹ ìforúkọsílẹ̀ ẹ̀rọ ìgbàlódé ti àjọ JAMB àti ilé-isẹ́ tó ń pèsè káàdì ìdánimọ̀ lórílẹ̀ èdè Nàíjíríà ,National Identity Management Commission,jọ ṣe agbátẹrù rẹ̀.
Ajọ JAMB ní àwọn òsìsẹ́ tí àwọn yàn náà yóò lọ káàkiri gbogbo orílẹ̀ èdè Nàíjíríà láti se àyẹ̀wò náà , ní èyí tí yóò se leè rọ àwọn akẹ́kọ̀ọ́ to fẹ ṣe ìdánwò si ilé-ẹ̀kọ́ gíga, Unified Tertiary Matriculation Examination, ti ọdun 2020 náà lọ́rùn.
Àwọn òsìsẹ́ náà yóò wo àséyọrí àti ìpèníjà tí àwọn akẹ́kọ̀ọ́ náà le dojúkọ àti ọ̀nà tí wọn leè gbà láti wá ojútùú sí irú ìpèníjà ọ̀hún.
--- Abẹnugan ilé ìgbìmọ̀ asòfin ìpínlẹ̀ Taraba kọ̀wé fipò sílẹ̀.
Abẹnugan ilé ìgbìmọ̀ asòfin ìpínlẹ̀ Taraba, Taraba, ọ̀gbẹ́ni Abel Peter Diah, ló fárígá pé òun kò se abẹnugan mọ́ lọ́jọ́ Àìkú yìí.
Bó tilẹ̀ jẹ́ pé awuye-wuye ti ń lọ lọ́wọ́ pé gomina ìpínlẹ̀ náà, Darius Ishaku ti ń gbèrò láti yọ òun àti akẹgbẹ́ rẹ̀ nípò bi í jìgá.
Lórí ẹ̀rọ ìbánisọ̀rọ̀ lásàálẹ́ ọjọ́ Àìkú ló ti sọ pé ohun ti pinnu “láti kọ̀wé fipò sílẹ̀ gẹ́gẹ́ bi abẹnugan ilé ìgbìmọ̀ asòfin ìpínlẹ̀ Taraba fún ìdí kan tàbí ìdí kejì.
Diah wá dúpẹ́ lọ́wọ́ àwọn ilé ìgbìmọ̀ asòfin fun ìfọẃọsowọ́pọ̀ wọn lásìkò tó ń darí wọn, ó tún wá rọ̀ wọ́n láti túbọ̀ máa fọwọ́sowọ́pọ̀ pẹ̀lú ìjọba ìpínlẹ̀ náà, ní èyí tí ìtẹ̀síwájú yóò ṣe débá ìpínlẹ̀ náà."
--- Ẹ wá wọkọ̀ ojú-irin ọ̀fẹ́ láti Èkó lọ sí Ìbàdàn.
Ìjọba orílẹ̀ èdè Nàíj́́ríà ti ní àwọn yóò bẹ̀rẹ̀ ọkọ̀ ojú irin ọ̀fẹ́ tí yóò máa gbé àwọn arìnrìnàjò láti Eko lọ sí Ìbàdàn lọ́fẹ̀ẹ́.
Ọkọ̀ ojú irin yìí yóò máa gbéra láti Iju nílùú Eko tí yóò si máa balẹ̀ sí ìlú Ìbàdàn.
Mínísítà fún ètò ìrìnnà lórílẹ̀ èdè Nàíjíríà, Rotimi Amaechi ni ó sọ̀rọ̀ yìí lásìkò tó ń se ìfilọ́lẹ̀ ètò ọkọ̀ ojú irin náà.
Amaechi ní ọkọ̀ ojú irin ọ̀fẹ́ náà yóò parí ní osù kẹta ọdún, 2020.
Amaechi ni ètò ọkọ̀ ojú irin ọ̀fẹ́ naa yóò bẹrẹ ni ọjọ́ kejì sí ọjọ́ kọ́kàndínlógún , oṣ̀u kéjìlá, ọdun, 2019 nígbà tí èyí tí yóò máa gberá láti Agege sí ìlú Ìbàdàn ńi ọjọ́ kọ́kànlélógún.
--- Dino Melaye fìdìí rẹmi nínú ètò ìdìbò asòfin ní ìpínlẹ̀ Kogi.
Olùdíje fún ipò asòfin àgbà nínú ẹgbẹ́, All Progressives Congress (APC),asòfin Smart Adeyemi,ni ó jáwé olúborí nínú ètò ìdìbò asòfin tó wáyé ní apá ilà Gúsù ní ìpínlẹ̀ Kogi.
Olùdarí ètò ìdìbò ní ìpínlẹ̀ Kogi Ọ̀jọ̀gbọ́n Olajide Lawal, ni ó kéde àbájáde ètò ìdìbò náà lọ́jọ́ Àbámẹ́ta ni ìpínlẹ̀ Kogi.
Gẹ́gẹ́ bí àbájáde ètò ìdìbò náà l se lọ, Ọ̀jọ̀gbọ́n Ọlajide ni asofin Smart Adeyemi ni iye ibo 88,373 láti fìdìí ẹnìkejì rẹ̀ Dino Melaye láti inú ẹgbẹ́ òsèlú People’s Democratic Party (PDP) janlẹ̀ nígbà tí òun ní iye ìbò 62,133.
Ambassador Rufus Aiyenigba to jẹ ọmọ ẹgbẹ Social Democratic Party (SDP) ni o gbe ipo kẹta nigba ti o ni iye ìbò 659 ,John Olabode àti Adeyemi Taiwo tí wọn jẹ ọmọ ẹgbẹ African Democratic Congress (ADC) àti Nigeria Elements Progressive Party (NEPP ) ni iye ìbò 262 ati 119 bákan náà.
Àjọ elétò ìdìbò lórílẹ̀ èdè Nàíjíríà, The Independent National Electoral Commission (INEC) ti kéde pé olùdíje fún ipò asòfin àgbà Smart Adeyemi, tí ó jẹ́ ọmọ ẹgbẹ́ APC ló jáwé olúborí fún ipò asòfin àgbà.
--- ASUU le bẹ̀rẹ̀ ìyansẹ́nlódì láìpẹ́.
Ilé ìgbìmọ̀ asòfin orílẹ̀ èdè Nàíjíríà , ti ní tí àwọn kò bá tètè dá sí wàhálà tó ń sẹlẹ̀ láàrin ẹgbẹ́ olùkọ́ lórílẹ̀ èdè Nàíjíríà, Academic Staff Union of Universities (ASUU) àti ìjọba àpapọ̀, pé kí ìjọba máa fi àwọn olùkọ́ fáfitì sínú ètò ìlànà IPPIS.
Abbas Tajuddeen tó ń sojú fún ìpínlẹ̀ Kaduna, tó tún jẹ́ ọ̀kan lára ọmọ ìgbìmọ̀ asòfin nílùú Àbújá ló pe àkíyèsí ilé ìgbìmọ̀ asòfin láti dá sí ọ̀rọ̀ yìí.
Tajudeen ní ìgbésẹ̀ tí ìjọba àpapọ̀ fẹ́ gbé yìí dára púpọ̀.
Ó ní “Bí ẹgbẹ́ ASUU se ń fáríga láti ḿaa tẹ̀lé ètò ìlànà ti ́ ìjọba àpapọ̀ là sílẹ̀ nípa sísan owó osù wọn, leè fa ìyansẹ́lódì, ní èyí ti ́ó leè tún dákún ìsoro tó ń kojú àwọn akẹ́kọ̀ọ́ àti òbí wọn.
"Àmọ́sá, ìjọba àpapọ̀ ti ní àwọn fásitì mọ́kànlélógójì ni wọ́n ti forúkọ sílẹ̀ sínú ètò ìlànà yìí, bó tilẹ̀ jẹ́ pé ẹgbẹ́ ASUU sì kọ etí ikún láti tẹ̀lé ètò ìlànà ọ̀hún.
--- Ààrẹ Buhari bẹnu àtẹ lu wàhálà tó sẹlẹ̀ ní ìpínlẹ̀ Cross River.
Ààrẹ orílẹ̀ èdè Nàíjíríà ,Muhammadu Buhari ti bu ẹnu àtẹ lu wàhálà tó ń sẹlẹ̀ ní ìjọba Boki tó wà ní agbègbè ìpínlẹ̀ Cross River, ní èyí tí ó ti bẹ̀rẹ̀ ní wákàtí mẹrinlelogun sẹ́yìn sùgbọ́n tí wọ́n kò leè sọ iye ẹ̀mí tí wọ́n ti pàdánù báyìí nínú ìkọlù náà.
Nínú àtẹ̀jáde kan tí olùrànlọ́wọ́ ààrẹ fún ìròyìn àti ìkédè Garba Shehu gbé jáde lọ́jọ̀Rú pé:
“Ní báyìí ìpànìyàn àti ilé sísun ń lọ́wọ́ ní agbègbè Nsadop àti Boje.
Bákan náà, ní a ó tíì mọ ohun tó fa ìsẹ̀lẹ̀ burúku yìí.
Àmọ́sá, ààrẹ Buhari fi àìdùnnú rẹ̀ hàn lórí ìsẹ̀lẹ̀ yìí pé, kò sí irú ìbínú tó yẹ kí ènìyàn gba ẹ̀mí ẹnìkejì rẹ̀.
Àwọn ọmọ orílẹ̀ èdè Nàíjíríà gbọ́dọ̀ máa kọ́ bí wọn se ń gbé ní ìrẹ́pọ̀ àti àlááfíà.
Orílẹ̀ èdè Nàíjíríà kò nífẹ̀ẹ́ sí ogun abẹ́lé.
“Ààrẹ Buhari mọ̀ pé àwọn agbófinró àti ẹ̀sọ́ aláàbò ti ń yanjú isoro náà, ní èyí tí yóò mú kí àlàáfíà tètè pàdà sí agbègbè naa.
Ààrẹ tún ti bá gómìnà ipinlẹ River àti alásẹ ìjọba ìbílẹ̀ Boki sọ̀rọ̀ lórí ìpè láti gbé ìgbésẹ̀ bí wọn yóò se leè tètè yanjú wàhálà náà kíákíá.
--- Nàíjíríà bá orílẹ̀ èdè Kenya ati DR Congo kẹ́dùn ìjàm̀bá omíyalé.
Àarẹ orílẹ̀ èdè Nàíjíríà Muhammadu Buhari ti bá orílẹ̀ èdè Kenya àti DR Congo kẹ́dùn ìjàm̀bá omíyalé ati ilẹ riri tó ṣe ìjàm̀bá lórílẹ̀ èdè náà.
Nínú ìwẹ́ àtẹ̀jáde tí àarẹ Muhammadu Buhari kọ sí orílẹ̀ èdè méjéèjì náà, ààrẹ ni: “orílẹ̀ èdè Nàíjíríà ba ẹyin ati àwọn ènìyàn ti ìjàm̀bá omíyalé àti ilẹ̀ rírì náà sẹlẹ̀ sí kẹ́dùn púpọ̀"""
Àarẹ tún sọ fún àwọn adarí orílẹ̀ èdè Kenya àti the Democratic Republic of Congo pé orílẹ̀ èdè Nàíjíríà yóò fi wọ́n sọ́kàn láti máa gbàdúrà fún wọn.
--- Ààrẹ Buhari màá fímu àwọ́n tó pa Achejuh Abuh jófin
Arábìnrin Achejuh Abuh tó jẹ́ ògbóǹtarìgì adarí àwọ́n obìnrin fún ẹgbẹ́ oselu People’s Democratic Party (PDP) ní ìjọba ìbílẹ̀ Wada/ Aro, tí àwọ́n oníjàm̀bá àti ọ̀daràn kan dáná sun nínú ilé rẹ̀ lásìkò ètò ìdìbò gómìnà tó wáyé ní ìpínlẹ̀ Kogi.
--- Ẹ se àtúnṣe si gbogbo àwọn ilé-ìwòsàn alábọ́dé lórílẹ̀ èdè yìí: Buhari.
Ààrẹ Muhammadu Buhari ti pàsẹ fún gbogbo àwọn àjọ tàbí ilé-isẹ́ ìjọba tó ń mójútó gbogbo ilé-ìwòsàn alábọ́dé tó wà jákè –jádò orílẹ̀ èdè yìí, pé kí wọ́n tètè wá wọ̀rọ̀kọ̀ fi sàd́a láti mu àtúnse dé bá wọn ní kíákíá.
"Ààrẹ sọ̀rọ̀ yìí lásìkò tó ń tẹ́wọ́ gba àbájáde ìròyìn lórí: “Ètò ìnáwó lórí àwọn ilé-ìwòsàn alábọ́dé lórílẹ̀ èdè Nàíjíríà"" ní èyí tí adarí ilé-ẹ̀kọ́ ètò ìlànà àti iṣẹ́ ìjìnlẹ̀ ọpọlọ (National Institute for Policy and Strategic Studies, NIPSS), Kúrú, ọ̀jọ̀gbọ́n Habu Galadima gbe fún un, nílùú Àbújá."
Ní ìparí ọdún 2018 ni ààrẹ ti bọwọ́lu ìwádìí lórí ètò àtúnse sí ilé-ìwòsàn alábọ́dé tó wà lórílẹ̀ èdè Nàíjíríà fun ọdún 2019 láti wá ojútùú sí àwọn ìpèníjà tó ń dojúkọ ètò ìlera, ní ọ̀nà àti mú ìdàgbàsókè bá ètò ìlera lórílẹ̀ èdè Nàíjíríà.
Ààrẹ tún fi dá ilé-ẹ̀kọ́ náà lójú pé gbogbo àwọn ilé-isẹ́ tàbí àjọ ìjọba tó ń mójútó ètò ìlera alábọ́dé lórílẹ̀ èdè Nàíjíríà ni yóò ṣe àmúlò ètò àtúnse tó wà nínú àbájáde ìwé náà.
--- Ilé ìgbìmọ̀ asòfin fẹnukò lórí àtúnse sí owó -orí sísan lórílẹ̀ èdè Nàíjíríà.
Ilé ìgbìmọ̀ asòfin àgbà lórílẹ̀ èdè Nàíjíríà ti gba àbá ìjọba àpapọ̀ wọlé nípa ṣíse àtúnse sí owó –orí sísan lórílẹ̀ èdè yii.
Asòfin Olamilekan Adeola, tó jẹ́ alága ìgbìmọ̀ náà, ní tí ìjọba àpapọ̀ bá ti bu ọwọ́ lu àtúnse sí owó- orí náà ńipa sísọ ọ́ di òfin, yóò pèsè àwujọ tó dára fún àwọn tó bá fẹ́ dá isẹ́ sílẹ̀ lórílẹ̀ èdè Nàíjíríà, àti pé yóò tún jẹ́ kí àwọn ilé-isẹ́ olókoòwò kékèkèé tún búrẹkẹ̀ sii.
Nínú ọ̀rọ̀ tirẹ̀, abẹnugan fún Ilé ìgbìmọ̀ asòfin àgbà lórílẹ̀ èdè Nàíjíríà, Ahmad Lawan, ní àtúnse sí òfin owó- orí yóò tún jẹ́ kí owó tó ń wọlé sí àpò òṣùwọ̀n orílẹ̀ èdè Nàíjíríà tún pọ̀ síi, ní èyí tí ìjọba yóò máa lo láti leè pèsè àwọn ohun amáyédẹrùn lórílẹ̀ èdè Nàíjíríà.
--- Mínísítà fún ìròyìn fẹ̀dùn ọkàn rẹ hàn lórí ikú olóògbé olóyè Alex Akinyele
Mínísítà fún ìròyìn àti àsà lórílè èdè Nàíjíríà, Lai Mohammed ti fẹ̀dùn ọkàn rẹ hàn lórí ikú olóògbé olóyè Alex Akinyele, tí ó jẹ́ mínísítà àná fún ìròyìn lórílè èdè Nàíjíríà.
Nínú àtèjáde kàn tí Mínísítà gbé jáde lọ́jọ́ Etí pé ikú olóyè Alex Akinyẹle jẹ́ àdánù mále-gbàgbé fún ẹbí, gbogbo àwon omo ìpínlè Ondo àti orílè èdè Nàíjíríà lápapọ̀.
Mínísítà sápéjùwe olóògbé Alex Akinyele gẹ́gẹ́ bí olùfokànsìn àti ẹni tó nífẹ̀ẹ́ orílè èdè Nàíjíríà púpọ̀.
Olóògbé Akínyẹlé ti jẹ́ mínísítà fún ìròyìn lórílè èdè Nàíjíríà àti alága àjọ tó ń sàmójútó eré ìdárayá lórílè èdè Nàíjíríà tẹ́lẹ̀rí nígbà ayé rẹ̀.
Mínísítà wá gbàdúrà pé kí Ọlọ́run tẹ́ olóògbé náà sí afẹ́fẹ́ ire.
--- Nàíjíríà yóò yàá ọgọ́ta biliọnu dọla fún ìdàgbàsókè ohun amáyédẹrun láti ilẹ̀ Amẹrika.
Ààrẹ orílè èdè Nàíjíríà Muhammadu Buhari ti ní kàkà kéku máa jẹ sèsé yóò fi sàwàdànù ni, òun yóò wá wọ̀rọ̀kọ̀ fi sàdá láti wá owó tí yóò lò fún ìdàgbàsókè ohun amáyédẹrùn lórílẹ̀ èdè yìí.
Ààrẹ Buhari sọ̀rọ̀ yìí lásìkò tó ń sèpàdé pẹ̀lú akọ̀wé owó fún orílẹ̀ èdè Amerika, Steven Mnuchin ni Riyadh lórí bí ìdàgbàsókè yóò ṣe dé bá ètò ọrọ̀ ajé lórílẹ̀ èdè Nàíjíríà, nípa ṣíṣe ètò ìrànwọ́ owó fún orílẹ̀ èdè yìí.
Àjọ orílẹ̀ èdè Amerika tó ń rí sí pípèsè ètò ìrànwọ́ owó tí wọn ń pè ní United States International Development Finance Corporation (USIDFC) ti ya ọgọ́ta bílíọ́nù dọ́là sọ́tọ̀ fún ìdàgbàsókè ohun amáyédẹrùn fún àwọn orílẹ̀ èdè tí ó kù díẹ̀ kí wọn fọwọ́ họrí.
--- Mobọ́lájí Johnson di olóògbé.
Gómìnà ìpínlẹ̀ Èkó Babajide Sanwo-olu ti fi ẹ̀dùn ọkàn rẹ̀ hàn lórí ikú olóògbé ajagunfẹ̀yìntì, Mobólájí Johnson tí ó jẹ́ gómìnà ológun àkọ́kọ́ fún ìpínlẹ̀ Èkó.
Sanwo-Olu sàpèjúwe olóògbé Mobólájí Johnson gẹ́gẹ́ bí onírẹ̀lẹ̀ òṣìṣẹ́ ológun, tí ó sì tún ní ìfẹ́ ìlú Èkó lọ́kàn.
Olóògbé Mobólájí Johnson kó ipa pàtàkì fún ìdàgbàsókè ìlú Èkó àti lórílẹ̀ èdè Nàíjíríà lápapọ̀.
Sanwo –Olu tún tẹ̀síwájú pé nígbà tí olóògbé Mobólájí Johnson jẹ gómìnà àkọ́kọ́ ní ìpínlẹ̀ Èkó lásìkò ìjọba ológun láàrin osùn Karùn-ún ọdún 1967 sí osù keje ,ọdún 1975 ni ètò ìdàgbàsókè wà ní ìpínlẹ̀ náà.
Gómìnà ìpínlẹ̀ Èkó wá rọ gbogbo àwọn ‘Lagosians’ pé ọ̀nà láti fi ẹ̀mí ìmoore hàn sí olóògbé náà ní láti jẹ́ kí ètò ìsèjọba rere tàn yíká ní àgbègbè àti àwùjọ wa.
Olóògbé Mobólájí Johnson jẹ́ Ọlọ́run nípè lẹ́yìn àìsàn díẹ̀, ọmọ ọdún mẹ́tàlélọ́gọ́rin (83) ni olóògbé náà, kí ó tó jáde láye.
--- Ọgọ́rùn ún miliọnu ọmọ orílẹ̀ èdè Nàíjíríà ni yóò jẹ̀gbádùn ètò ìlera alábọ́dé.
Orílẹ̀ èdè Nàíjíríà ti ní kàkà kéku máa jẹ sèsé yóò fi sàwàdànù ni, nípa síse àtúnse sí àwọn ilé- ìwòsàn tó pèsè ètò ìlera alábọ́dé ẹ̀gbẹ̀rún mẹ́wàá ti awọn ọgọ́rùn ún miliọnu ọmọ orílẹ̀ èdè Nàíjíríà yóò fi leè jẹ̀gbádùn ètò-ìlera alábọ́dé láàrin ọdún mẹ́wàá.
Àjọ tó ń rí sí ètò ìlera lorílẹ̀ èdè Nàíjíríà ló sọ̀rọ̀ yìí lọ́jọ́ Ìsẹgun níbi ìpàdé tí ìgbìmọ̀ ìjọba àpapọ̀ tó ń mójútó ètò ọrọ̀ ajé se, nílùú Àbújá , ní èyí ti ́igbákejì ààrẹ , Yẹmi Osinbajo darí rẹ̀.
Nígbà tí gómìnà ìpínlẹ̀ Anambra, Willy Obiano ń bá àwọn akọ̀ròyìn ilé-isẹ́ ààrẹ sọ̀rọ̀ lẹ́yìn ìpàdé pé “Bí orílẹ̀ èdè Nàíjíríà ṣe ṣe àṣeyọrí lórí ààrùn rọmọ lápá-rọmọ lẹ́sẹ̀, síbẹ̀ isẹ́ sì pọ̀ láti ṣe nípa fífi òpin sí ìtànkálẹ̀ ààrùn ọ̀hún.
"Obiano sọ pé àjọ ọ̀hún wá ń bẹ̀bẹ̀ fún ètò ìrànwọ́ lọ́wọ́ ìgbìmọ̀ tó ń rí sí ètò ọrọ̀ ajé láti pèsè owó ìrànwọ́ kí orílẹ̀ èdè Nàíjíríà leè tẹ̀síwájú nínú àwọn àṣeyọrí tí ó ti se nípa pípèsè ilé-ìwòsàn alábọ́dé lórílẹ̀ èdè yìí.
--- E máse fààyè gba ìrẹ̀wẹ̀sì okàn- Ààre Buhari gba àwon omo orílè-èdè Nàíjíríà níyànjú.
Ààre Muhammadu Buhari gbósùbà káre láí fún ikọ̀ agbábóòlù Nàíjíríà, tọ́jọ́ orí wọn kòju mẹ́tàdínlógún lọ (Golden Eaglets) fún iṣẹ takun-takun wọn, lẹ́yìn tí ikọ̀ náà gbo ewúro ìyà sójú ikọ̀ akaẹgbẹ́ won láti orílẹ̀-èdè Ecuador lánàá ọjọ́ ìṣẹ́gun (Tuesday), nínú ìdíje bọ́ọ̀lù àgbáyé tàwọn ọ̀dọ́ tọ́jọ́ orí wọn kòju mẹ́tàdínlógún lọ tó ń lọ lọ́wọ́ lórílẹ̀-èdè Brazil (FIFA Under 17 World Cup in Brazil).
Ààrẹ wá lo ìwà akínkanjú àwọn ọ̀dọ́ náà láti fi gba àwọn ọmọ orílẹ̀-èdè Nàíjíríà níyànjú láti mú ìwà náà lò nínú gbogbo ohun tí wọn bá ń dáwọ́ lé, pàápàá jùlo fún ìdàgbàsókè orílẹ̀-èdè Nàíjíríà."
--- Wón tẹ́ Olóògbé Augustina Okechukwu sáfẹ́fẹ́ rere nílùú Enugu.
Olóògbé Augustina Okechukwu, ayaaba olùdarí àgbà ilé-iṣẹ́ akọ̀ròyìn Voice of Nigeria (VON), ọ̀gbẹ́ni Osita Okechukwu, ti wọ ilẹ̀ sùn báyìí nílùú rẹ̀ tín ṣe Eke, níjọba ìbílẹ̀ Udi Local Government nípínlè Enugu, lọ́jọ́ àbáméta (Saturday).
Lásìkò ìwàásù nílé ìjọ́sìn St.Paul’s Catholic Church, nílùú Eke, òjíṣé olúwa alàgbà Nnamdi Nwankwo, nínú ọ̀rọ̀ rẹ̀, Ó rọ àwon onígbàgbó láti gbé ìgbéayé tí yóò mú ayérorùn fún àwon tí ó wà láyìíká won gbogbo, kí won sì tún jẹ́ olùfokán sín nílé Olúwa.
Nínú ọ̀rọ̀ ìdúpé, ọkọ olóògbé náà, tí ó tún jẹ́ olùdarí àgbà ilé-iṣẹ́ VON, ọ̀gbẹ́ni Okechukwu dúpẹ́ lọ́wọ́ àwon ènìyàn fún ìfẹ́ tí wón fi hàn sí òun àti àpapọ̀ ẹbí lásìkò ìsìnkú náà.
Ẹ̀wẹ̀, lára àwọn tí ó kópa nínú ìsùnkú náà ni Bisobu Anaezichukwu Obodo, tí ó jé Bisobu ilé-ìjósìn Catholic Diocese, ní ìpínlẹ̀ Enugu, akòwé àgbà ìjoba àpapọ̀ ọ̀gbẹ́ni Boss Mustapha, ẹni tí akọ̀wé àgbà àjọ tó ń rí sí ọ̀rọ̀ abẹ́lé ìyáàfin Georgina Ekeoma-Nwaiwu ló ṣojú fún.
Bákan náà, ìgbàkejì gómìnà ìpínlẹ̀ Enugu, ìyáàfin Cecila Ezeilo àti mínísítà tẹ́lẹ̀rí fún ọ̀rọ̀ ilẹ̀-òkèrè, ọ̀gbéni Dubem Onyia, tí ó fi tún mọ àwọn ènìyàn jànkàn-jànkàn mííràn.
--- Àjọ FIFA fòfin de adarí ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ bọ́ọ̀lù ọmọ orílẹ̀-èdè Kenya títí láí.
Adarí ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ bọ́ọ̀lù ọmọ orílẹ̀-èdè Kenya tí ó yẹ kí ó darí ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ níbi Ife ẹ̀yẹ àgbááyé tí ó ń lọ lọ́wọ́ lórílẹ̀-èdè Russia ni wọ́n ti fi òfin dè títí láí lẹ́yìn tí wọ́n gbá a mú pẹ̀lú gbígba owó ìbọ̀ọ̀nú.
Aden Marwa di kíkásílẹ̀ lásìkò tí ó ń gba ẹgbẹ̀ta owó dollar lásìkò iṣẹ́ àkànṣe Àjọ tó ń mójú tó bọ́ọ̀lù àfẹsẹ̀gbá ní ilè Adúláwọ̀ (CAF) lórílẹ̀-èdè Ghana.
Ó wà lára àwọn méjìlélógún tí àjọ CAF fòfin dè nínú ìpàdé ìfọ̀wà-ìbàjẹ́-nù tí wọ́n pè lópin ọ̀sè tó kọjá.
Marwa, tí ó wà ní ìpamọ́ ní àṣekágbá ìdíje ọdún 2014 lórílẹ̀-èdè Brazil ni wọ́n ti kọ́kọ́ yọ kúrò lára àwọn tí yóò darí ìdíje ní orílẹ̀-èdè Russia.
Ìfòfindè títí lái yìí jẹ́ ṣíṣe láti ọwọ́ ìgbìmọ̀ tí ó ń ṣèdájọ́ ìwà-ìbàjẹ́ àjọ CAF, èyí tí ó tún fi òfin de àwọn adarí ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ bọ́ọ̀lù mẹ́wàá mìíràn fún ọdún méjì sí ọdún mẹ́wàá fún irúfẹ́ ẹ̀sùn kan náà.
--- Pinnick jẹ́ yíyàn gẹ́gẹ́ bí igbákejì ààrẹ àjọ CAF
Ààrẹ Àjọ tó ń mójú tó bọ́ọ̀lù àfẹsẹ̀gbá lórílẹ̀-èdè Nàìjííríà (NFF) Amaju Pinnick ti jẹ́ yíyàn gẹ́gẹ́ bí igbákejì ààrẹ àkọ́kọ́ Àjọ tó ń mójú tó bọ́ọ̀lù àfẹsẹ̀gbá ní ilè Adúláwọ̀ (CAF).
Ìwé náà kà báyìí pé” Látàrí ìkọ̀wéfipòsílẹ̀ igbákejì ààrẹ àkọ́kọ́, Ọ̀gbẹ́ni Kwesi Nyantakyi àti òkè téńté tí Àjọ tó ń mójú tó bọ́ọ̀lù àfẹsẹ̀gbá lórílẹ̀-èdè Nàìjííríà wà Ààrẹ Àjọ CAF, lẹ́yìn tí ó fi ọ̀rọ̀ lọ àwọn ọmọ ìgbìmọ̀ ìṣẹ̀lẹ̀ pàjáwìrì, yan Ọ̀gbẹ́ni Amaju Melvin Pinnick gẹ́gẹ́ bí igbákejì ààrẹ àkọ́kọ́.
”Ìgbésẹ̀ yìí wà ní ìbámu pẹ̀lú àpilẹ̀kọ kẹtàdínlọ́gbọ̀n, ìpínrọ̀ kejì léyìí tí ìgbìmọ̀ ìṣàkóso yóò fọwọ́ sí ní ìjókòó tí wọ́n ti fi sí ọjọ́ kẹtàdínlọ́gbọ̀n àti ìkejìdínlọ́gbọ̀n oṣù kẹsàn-án ọdún 2018.” nínú ọ̀rọ̀ inú àtẹ̀jáde, okùn mìíràn ni ìyànsípò yìí jẹ́ fún Amaju pẹ̀lú bí ó ṣe jẹ́ olórí ìgbìmọ̀ Ife ẹ̀yẹ ilẹ̀ Adúláwọ̀ tí yóò mójú tó ayẹyẹ ìṣíde.
Ó tún jẹ́ ọ̀kan lára ọmọ ìgbìmọ̀ fún ìṣètò fún Ife ẹ̀yẹ àgbááyé FIFA.
--- Quadri gba ipò ogún lágbàáyé, àkọ́kọ́ ní ilẹ̀ Adúláwọ̀.
Aruna Quadri gòkè sí i pẹ̀lú àkàsọ̀ méji lọ sí ipò ogún lórí àtẹ àgbááyé àjọ agbáyòtẹníìsì-orí-tàbìlì tí ó sì di ipò kínní mú ní ilẹ̀ Adúláwọ̀ ṣaájú ọmọ orílẹ̀-èdè Egypt Omar Assar tí ó di ipò náà mú ní ilẹ̀ Adúláwọ̀ tẹ́lẹ̀.
Ṣaájú kí àtẹ yìí tó jáde, ipọ̀ èjìlélógún ni Quadri wà ní inú oṣù kẹfà. Pẹ̀lú àmì òjìlélẹ́gbọ̀kànléláàádọ́ta-o-dín-mẹ́fà, Quadri ṣíwájú Assar tí òun ní àmì òjìlélẹ́gbọ̀kànléláàádọ́ta-o-dín-méje ní orí àtẹ tuntun, ó sì ti já láti ipò kẹ́tàdínlógún sípò kọ́kànlélógún lórí ipò àtẹ náà.
Èyí ni ìgbàkejì nínú ọdún yìí tí Quadri yóò wà lára àwọn ogún àkọ́kọ́ lágbàáyé, pẹ̀lú bí ó ṣe ti wà ní ipò yìí kan náà ní inù oṣù kínní ọdún 2018, tí ó jẹ́ ọmọ orílẹ̀-èdè Nàìjííríàn àkọ́kọ́ láti rí èyí ṣe.
Fan Zhendong ọmọ orílẹ̀-èdè China di ipò àkọ́kọ́ rẹ̀ mú lágbàáyé síbẹ̀ fún osù mẹ́rin léra wọn àti fún ìgbà àkọ́kọ́ nínú ìtàn iṣẹ́ rẹ̀.
Bákan náà, Ma Long, gbajúgbajà aṣáájú nínú ìdíje Olympic tí ó tún jẹ́ aṣáájú lágbàáyé, nǹkan ò ṣenu ire fún un; pẹ̀lú bí ó ṣe já láti ipò kejì sí ipò kẹfà.
Òun ni ó wà nípò kẹrin láti orílẹ̀-èdè China nínú àwọn tí ó ga jùlọ. Lin Gaoyuan gòkè láti ipò karùn-ún sí ipò kẹta; Xu Xin já pẹ̀lú àkàsọ̀ kan sí ipò kẹfà.
Bákan náà ní ti orílẹ̀-èdè Germany. Timo Boll gòkè pẹ̀lú àkàsọ̀ méjì, ó wà ní ipò kejì báyìí; Dimitrij Ovtcharov rébọ́ pẹ̀lú àkàsọ kan, ó wà ní ipò kẹrin báyìí.
--- Ẹ ṣé o! – Mikel dúpẹ́ lọ́wọ́ àwọn Ọlọ́pàá fún dídóòlà bàbá rẹ̀
Balógun ikọ̀ Super Eagles John Mikel Obi ti fi ẹ̀mí ìmoore hàn sí àwọn ọlọ́pàá ilẹ̀ Nàìjííríà fún dídóòlà bàbá rẹ̀ nínú ìgbèkùn.
Bàbá àgbà Michael Obi, pẹ̀lú awakọ̀ rẹ̀ ni àwọn agbébọn tí a kò mọ̀ jígbé ní ọjọ́ kọkàndínlọ́gbọ̀ oṣù kẹfà, ní ó ku wákàtí díẹ̀ sí ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ ìfe ẹ̀yẹ́ agbááyé orílẹ̀-èdè Nàìjííríà àti orílẹ̀-èdè ní St. Petersburg, ní orílẹ̀-èdè Russia.
Ṣùgbọ́n àwọn ikọ̀ Ọlọ́pàá ẹ̀ka ti ìpínlẹ̀ Enúgun dóòlà rẹ̀ lọ́jọ́ ajé (Monday), láwọn tí wọ́n dáná ogun ìbọn yá àwọn ajínigbé wọ̀nyí.
“Mà á fẹ́ dúpẹ́ lọ́wọ́ àwọn aláṣẹ ile-iṣẹ́ ọlọ́pàá tí wọ́n lọ́wọ́ nínú ìpadàbọ̀ bàbá mi láyọ̀ àti àlááfíà lẹ́yìn ìninilára ọ̀sẹ̀ yìí,” Mikel sọ èyí lórí ìkànnì Twitter rẹ̀.
Ó tún dúpẹ́ lówọ́ àwọn ọmọ orílẹ̀-èdè Nàìjííríà fún àdúrà àti àtìlẹyìn wọn.
“Èmi àti àwọn ẹbí mi mọ rírì o,” ló fi parí ọ̀rọ̀ rẹ̀
Pẹ̀ú èyí, Mikel lọ láti gbá ìdíje náà láìsọ ohun tí ó ń bá a fínra fún ẹnikẹ́ni.
Èyí ni ó fi jẹ́ ìgbà kejì láàrin ọdún méje tí Bàbá àgbà Michael Obi ti di jíjígbé.
--- Mohamed Salah to̩wó̩ bò̩wé tuntun pẹ̀lú Liverpool.
Atamátàsé ikọ̀ agbábọ́ọ̀lù Liverpool, tí ó tún jẹ́ ọmọ orílẹ̀ èdè Egypt, Mohamed Salah ti sún ìbásiṣẹ́pọ̀ rẹ̀ síwáju nínú ikọ̀ agbábọ́ọ̀lù Liverpool.
Agbábó̩ò̩lù iwájú fún orílè èdè Egypt tí sún àkókò rè̩ pè̩lú ikò̩ Liverpool síwájú si nípa títo̩wó̩ bò̩wé, lé̩yìn bi o̩dún kan tí ó ti ikò̩ AS Roma dé ikò̩ Liverpool.
--- Fídíò: Russia fìdùnnú hàn lẹ́yìn tí wọ́n já Spain.
Ọ̀pọ̀ ènìyàn kò lérò pé ikọ̀ agbábọ́ọ̀lù orílẹ̀ èdè Russia yóò ní àǹfààní láti jáde kúrò nípele kínní ìdíje bọ́ọ̀lù àgbáyé tó ń lọ lọ́wọ́, eléyìí tí orílẹ̀-èdè Russia ọ̀hún ṣagbátẹrù rẹ̀.
Àmó̩, ikọ̀ ọ̀hún ya gbogbo ènìyàn lé̩nu nípa jíjá Spain nípele kejì ìdíje pẹ̀lú bọ́ọ̀lù àgbésílẹ̀-gbá.
--- IHF yóò ṣèdánilẹ́kọ̀ọ́ fún àkọ́nimọ̀ọ́gbá bò̩ó̩lù-àfo̩wó̩gbá wa.
Ààrẹ àjọ amójútó bọ́ọ̀lù-àfọwọ́gbá lórílẹ̀-èdè Nàìjííríà, Sam Ocheho sọ pé ètò ń lọ lọ́wọ́ pẹ̀lú àjọ amójútó bọ́ọ̀lù-àfọwọ́gbà tìlú òkèrè láti dáwo̩n akọ́nimọ̀ọ́gbá wa lé̩kò̩ó̩.
Ocheho, sọ ọ̀rọ̀ yìí dí mímọ̀ ní àsìkò àsekágbá ìdíje Sam Ocheho International Invitational Handball Championships, ní àjo̩ ò̩hún ti pinnu láti mu ìmò̩ àwo̩n akọ́nimọ̀ọ́gbá wa àti àwo̩n òs̩ìs̩é̩ ìdárayá yòókù peléke sí i.
Ó fikún ọ̀rọ̀ rẹ̀ pé, orílẹ̀-èdè Nàìjííríà ti ṣetán láti mú àyípadà ọ̀tún dé bá eré ìdárayá ọ̀hún àti àwọn akónimọ̀ọ́gbá rẹ̀ lórílẹ̀-èdè yìí, tesiwaju si, Ocheho ní, ìdanilẹ́kọ̀ọ́ náà yóò wáyé ní ìpínlẹ̀ Èkó, bẹ́ẹ̀ sì ni ikọ̀ obìnrin yóò wà ní ìpàgọ́ wọn fún ọ̀sẹ̀ méjì, ní ọ̀nà láti tún máa ṣàmójútó àwọn olùkópa ṣaájú ọ̀kan-ò-jọ̀kan ìdíje tó ń bọ̀ lọ́nà.
O ní, báyìí, ọ̀rò̩ ń lọ lọ́wọ́ pẹ̀lú àjọ IHF láti ràn wá lọ́wọ́ fún ìdánilẹ́kọ̀ọ́ àwọn akọ́nimọ̀ọ́gbá wa gbogbo.
Ìdánilẹ́kọ̀ọ́ náà yóò wáyé kí ọdún yìí tó parí, nítorí a fẹ́ kí àwọn akọ́nimọ̀ọ́gbá wa ní ìmọ̀ ló̩wó̩ló̩wó̩ nínú eré ìdárayá náà, èyí tí á nípa lórí àwo̩n agbábò̩ò̩lù.
--- Ìdíje bọ́ọ̀lù àgbááyé: Belgium lu England.
Àmì-ayò kan ṣoṣo Adnan Januzaj ló mú ikò̩ Belgium je̩gàba lórí England ikò̩ G.
Agbábọ́ọ̀lù tẹ́lẹ̀rí Manchester United gbámì-ayò náà wọlé níṣẹ̀ẹ́jú péréte kí ìfẹ́sẹ̀wọnsẹ̀ ọ̀hún tó wá síparí, èyí tó sì mú ikò̩ Belgium lé tété níkò̩ wo̩n àfi tíkò̩ England bá mi àwò̩n bákan náà.
È̩wè̩, látàarí pípegedé ikọ̀ agbábọ́ọ̀lù orílè̩-èdè méjéèjì, oríṣiríṣi àtúnṣe nikọ̀ kọ̀ọ̀kan ṣe, èyí ó sì han bóyá ikò̩ yòówù fé̩ jáwé olúborí nínú ìfe̩sè̩wo̩nsè̩ wo̩n.
Belgium ti gba àpapọ̀ káàdì pélébé ólómi ọsàn márùn-ún tí orílẹ̀ èdè England sì ti gba méjì péré.
Èyí tó jásí pé, tí ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ ọ̀hún bá parí sámì dọ́gba-dọ́gba, England yóò parí sípò kinni ṣaájú ikọ̀ akẹegbẹ́ wọn tí wo̩n kò bá mi àwò̩n ara wo̩n.
--- Àjọ NFF sàjọyọ̀ ayẹyẹ ọjọ́-ìbí pẹ̀lú Rohr àti Balogun.
Àjọ amójútó bọ́ọ̀lù ní Nàìjííríà (NFF), sàjọyọ̀ ọjọ́-ìbí pẹ̀lú akó̩nimò̩ó̩gbá, Gernot Rohr, tó s̩ayẹyẹ ọjọ́-ìbí ọdún márùndínláàdọ́rin lEssentuki, Russia lọ́jọ́bọ.
Wọ́n bí Rohr lọ́jọ́ kéjídínlọ́gbọ̀n oṣù kẹfà, ọdún 1953 ni Mannheim, Germany.
Akọ́nimọ̀ọ́gbá OGC Nice té̩lè̩, lạ̀jọ NFF yàn gẹ́gẹ́ bí akọnimọ̀ọ́gbá Super Eagles lọ́dún 2016 ó sì rankọ̀ ọ̀hún lọ́wọ́ láti lo̩ ìdíje bọ́ọ̀lù àgbááyé tó ń lọ lọ́wọ́ lórílẹ̀-èdè Russia.
NFF sún ìbáṣiṣẹ́pọ̀ pẹ̀lú Rohr síwájú di ọdún 2020.
Kú ayẹyẹ ọjọ́-ibi akó̩nimò̩ó̩gbá Super Eagles, Gernot Rohr.
“Àwọn òṣìṣẹ́ tí wọ́n jọ ń ṣiṣẹ́ pò ní ìpàgọ́ ikọ̀ ọ̀hún nílùú Essentuki, pèsè àkàrà òyìnbó àti òdòdó láti fi ṣàjọyọ̀ o̩jó̩ rẹ̀,” NFF sò̩yí lóri twitter, pè̩lú àwò̩rán Rohr tó dunnú táwo̩n òs̩ìs̩é̩ sì yiká.
Rohr atùkọ̀ Super Eagles gbá ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ ogún, ó borí mẹ́sàn-án, ó pàdánù mẹ́fà, ó sì gbá ò̩mì márùn ún.
Àjọ NFF tún kí agbábọ́ọ̀lù ọwọ́ ẹ̀yìn ikọ̀ Super Eagles, Leon Balogun tí ó pé ogbọ̀n ọdún lọ́jọ́bọ̀ (Thursday).
Wọ́n bí Balogun lọ́jọ́ kéjídínlọ́gbọ̀n oṣu ̀kẹfà, ọdún 1988 sílùu Berlin, lórílẹ̀-èdè Germany.
--- Amúyangàn wá niyín - CAF, FIFA gbóríyìn fún Super Eagles.
Akọ̀wé àgbà àjọ FIFA, Fatma Samoura, àjọ CAF àti ọ̀gọ̀ọ̀rò̩ àwọn olólùfẹ́ ikọ̀ agbábọ́ọ̀lù ló gbà pé ikọ̀ agbábọ́ọ̀lù Super Eagles mú ilè̩ adúláwò̩ dùn pè̩lú bí wó̩n se pàdánù ìfe̩sè̩wo̩nsè̩ wo̩n.
Àmì-ayò kan sódo ni ikò̩ Argentina ni ìfe̩sèwo̩nsè̩ ikò̩ ìke̩yìn (Group D) ni pápá ìs̩iré Saint Petersburg, èyí tó mú wo̩n wà nípò ke̩ta pè̩lú àmì mé̩ta lé̩yìn Argentina tó mí àmì mé̩rin.
Argentina tí Lionel Messi jé̩ balógun wo̩n, yóò darapọ̀ mọ́ Croatia tó parí ìfigagbága ọ̀hún sípò kínní pẹ̀lú àmì mẹ́sàn-án, nígbà tí Iceland às̩è̩s̩è̩dé yóò lo̩lé pè̩lú ikò̩ Gernot Rohr.
Bákan náà, àjọ CAF, ti adúláwò̩, sọ lórí ẹ̀rọ ayélujára wọn pé, ikọ̀ Super Eagles gbìyànjú lọ́pọ̀lọpọ̀, bẹ́ẹ̀ sì ni wọ́n mú orí àwọn wú.
Àwo̩n olós̩èlú kan ní Nàìjíríà fi so̩wó̩ lórí twitter láti yìn ikò̩ Nàìjíríà.
Ààrẹ ilé ìgbìmọ̀ aṣòfin, Dókítà Bukola Saraki túwíìtì pé: Iṣẹ́ takun-takun ni ikọ̀ Super Eagles ṣe.
A sa ipa púpọ̀.
Síbè̩, ènìyàn borí níwò̩n, kùnà níwò̩n.
E̩ s̩o̩kàn o̩kùnrin, nítorí e̩ dàwò̩ko̩s̩e fún o̩gó̩sàn-án mílíò̩nù. E s̩eun”.
"Aṣòfin Ben Murray Bruce ní: Iṣẹ́ ribiribi lẹ ṣe.
Èsì ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ yìí kò yí ìfẹ́ yín lọ́kàn wa padà.
A jo̩ borí papò̩, a jo̩ kùnà papò̩. E s̩e múyangàn.
Pè̩lú Egypt, Morocco àti Tunisia tí wó̩n ti lo̩lé, Senegal nìkan lorílè̩èdè adúláwò̩ kan tó kù, wo̩n á fe̩sè̩wo̩nsè̩ pè̩lú Colombia ni ìfe̩sè̩wo̩nsè̩ tó ké̩yìn ikò̩ H ló̩jó̩bò̩.
--- Croatia yóò gbé àwọn ojúlówó agbábọ́ọ̀lù jókòó.
Akọ́nimọ̀ọ́gbá àgbà ikò̩ Croatia, Zlatko Dalic s̩etán láti gbé àwọn ojúlówó agbábọ́ọ̀lù mẹ́jọ jókòó nínú ìfigagbága ìkẹyìn ìpele àkọ́kọ́ ìdíje Russia pẹ̀lú orílẹ̀-èdè Iceland.
Ẹ̀wẹ̀, ikò̩ Dalic tí ní àmì tí ó ye̩ fún ìpele tó tè̩le ní ìdíje̩ ò̩hún, ìrètí wà pé, Ivan Rakitic, Mario Mandzukic, Luka Modric, Dejan Lovren àti Ante Rabic wọn kò ní bẹ̀rẹ̀ ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ náa.
Dalic ní, Ó wù mí láti wà lókè téńté tábìlì, s̩ùgbó̩n a gbọdọ̀ ṣe àtúnṣe síkọ̀ wa, látàrí àwọn agbábọ́ọ̀lù kọ̀ọ̀kan tó ti gba káàdì olómi-ọsàn, fúndìí èyí màá sàtúnṣe sáwọn agbábọ́ọ̀lu mì.
--- Saudi Arabia fàgbà han Egypt pẹ̀lú àmì-ayò méjì sóókan.
Egypt fún ọmọ ọdún márùndínláàdọ́ta aṣọ́lé wo̩n, Essam El-Hadary láǹfààní láti dile, èyí tó sọ́ daṣọ́lé tó dàgbà jùlọ nítàn bọ́ọ̀lù àgbááyé.
Egypt àti Saudi Arabia ló pàdánù ìfe̩sè̩wo̩nsè̩ méjì wo̩n àkó̩kó̩.
Al Dawsari gbámì ayò mìíràn wọ̀lé, eléyìí tó ran Saudi Arabia lọ́wọ́ láti jáwé olúborí, tí wọ́n sì parí sípò kẹta nípele náà.
--- Ìdíje àgbááyé: Uruguay gbonwúro sójú Russia 3-0.
Adùn ìdíje àgbáyé fún Russia forís̩ánpó̩n ló̩jó̩ ajé bí Uruguay s̩e fàgbà han ikọ̀ náà pẹ̀lú 3-0.
Atamátàsé agbábọ́ọ̀lù ọwọ́ iwájú fún Uruguay, Luiz Suarez ló gbá àmì-ayò kínní wọlé nísè̩ẹ́jú mẹ́wàá sáà àkọ́kọ́ tí ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ náà bẹ̀rẹ̀ láti mukò̩ ò̩hún darí.
Ikọ̀ agbábọ́ọ̀lù Russia s̩apá wọn láti dámì-ayò ọ̀hún padà, ṣùgbọ́n omi pọ̀ ju ọkà lọ.
Níṣẹ̀ẹ́jú mẹ́tàlélógún Diego Laxalt sọ àmì ayò ọ̀hún di méjì sóódo, èyí tí bó̩ò̩lù rè̩ bá Cheryshev láti mú ikò̩ gúúsù Amé̩ríkà lékè.
Agbábó̩̀ò̩lù amúlé, Akinfeev ti bó̩ò̩lù àgbáwo̩lé s̩ùgbó̩n Cavani tun gba wo̩lé ó sì jé̩ igbà àkó̩kó̩ tá mi àwò̩n nídìíje ò̩hún ní àádọ́rùn-ún iṣẹ́jú
Uruguay lé téńté group A, pẹ̀lú àmì mẹ́sàn-án láì màwò̩n wo̩n.
Wo̩n yóò kojú ikọ̀ tó bá tè̩lé adarí group B, tí Russia agbanilálejò kojú.
--- Ààrẹ Buhari kí ikọ̀ Super Eagles.
Ààrẹ orílè̩ èdè Nàìjíríà Muhammadu Buhari ti kí ikọ̀ Super Eagles ti Nàìjííríà fún àṣeyọrí wo̩n ní o̩jọ́ ẹtì lóri ikò̩ Iceland nínú ìfẹsèwọnsẹ̀ wo̩n ẹlẹ́ẹ̀kejì nínú ìdíje àgbáyé 2018 ní Russia.
Ààre̩ s̩e àfihàn ìdùnnú rè̩ sí ìgboyà, ìsé̩ra-e̩ni, ìṣọ̀kan àti è̩mí àìlekùnà tí àwo̩n agbábó̩ò̩lù ò̩dò̩ Nàìjíríà s̩e àfihàn.
Ààrẹ wá rọ̀ wó̩n láti má fojú kéré ara wo̩n s̩ùgbó̩n kí wó̩n tẹ̀síwájú nípa jíjáwé olúborí lórí ikò̩ Argentina, níbi ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ ò̩sẹ̀ tó ń bọ̀.
Gẹ́gẹ́ bó s̩e sọ:ọkàn mí balẹ̀ tíkọ̀ wa bá nígbàgbọ́ nínú ara wọn, dandan ni kí wọ́n pegedé níbi ìpele líle yìí, kí wọ́n sì rìn jìnnà nídìíje náà, “Ó fi kún-un, “pẹ̀lú ìfọkànsìn, kò sáìṣe."
Ààrẹ wá rọ gbogbo ọmọ orílẹ̀ èdè Naijiria láti túbọ̀ máa gbárùkù ti àwọn aṣojú yìí pẹ̀lú àdúrà àti àtìlẹyìn ọlọ́kan-ò-jọ̀kan.
Nàìjííríà lu ikọ̀ Iceland pẹ̀lú àmi ayò méjì sí òdo, Ahmed Musa ló gbá àmì-ayò méjì ọ̀hún wọlé ní ìpele kejì eré ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ náà.
--- Dalung: Eagles yóò ṣe dáadáa nífẹsẹ̀wọnsẹ̀ wọn yòókù.
Mínísítà amójú eré-ìdárayá, Solomon Dalung, ní òun nídàánilójú pé ikọ̀ agbábọ́ọ̀lù Super Eagles yóò ṣe dáradára nífẹsẹ̀wọnsẹ̀ wọn yòókù.
Solomon Dalung so̩ fún VON, Rafat Salami pé gbogbo ìrètí kó̩ ló ti so̩nù bó tilè̩ jé̩ pé ikò̩ ò̩hún so̩ ìfe̩sèwo̩nsè̩ wo̩n àkó̩kó̩ nù nídìj́ié àgbáyé.
Ó so̩yí ní pápákọ̀ òfurufú Nnamdi Azikiwe nílùú Àbújá, bí ó s̩e ti Germany dé.
--- Russia 2018: Japan fàgbà han Colombia.
Japan tó fàgbà hàn Colombia, só̩ di ìgbà àkó̩kó̩ tí wo̩n yóò borí alátakò̩ láti gúúsù ìwọ̀ oòrùn Amerika.
Ò̩pò̩ àwọn olólùfé̩ bó̩ò̩lù àfẹsègbá, tí wón ń ta té̩té́ ló gbówó lórí orílè̩-èdè Colombia pé wọn yóò borí.
Ò̩kan lára àmì-ayò tí Japan gbáwọlé, ló wá látojú bọ́ọ̀lù agbésílẹ̀gbá́.
Wó̩n rí bọ́ọ̀lù agbésílẹ̀gbà lé̩yìn tagbé̩yìn fún Colombia, Carlos Sanchez dènà s̩ó̩ò̩tì à-mi-àwò̩n látò̩do̩ Yuya Osako ti Japan.
--- Super Eagles bẹ̀èrẹ̀ ìgbáradì ní kíkún fún ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ Croatia.
Ikò̩ Super Eagles bẹ̀ẹ̀rẹ̀ ìgbáradì wo̩n lónìí ní 10:15am àárò̩.
Ìgbáradì náà s̩íde nís̩è̩é̩jú mé̩è̩dógún àkó̩kó̩, wó̩n sì gùnlé ète ikò̩ náà.
--- Canada, U.S, Mexico yóò ṣagbáterù ìdíje àgbáyé 2026.
Amẹ́ríkà, Canada àti Mexico yóò ṣagbátẹrù ìdíje àgbááyé ló̩dún 2026, lẹ́yìn tí wọ́n jáwé olú́borí pè̩lú ò̩kándínláàdó̩rin ibò láàrin wo̩n sí orílẹ̀-èdè Morocco tí òun náà ń gbèrò láti ṣagbátẹrù ìdíje ọ̀hún, èyí tíkò̩ máa di méjìdínláàdo̩ta fúngbà àkó̩kó̩.
--- Lopetegui rọ́pọ̀ Zidane ni Madrid.
Ikọ̀ Real Madrid ti yan akọ́nimọ̀ọ́gbá Spain, Julen Lopetegui gẹ́gẹ́ bí akọ́nimọ̀ọ́gbá tuntun sáà tó ń bọ̀.
Lopetegui, ọmọ ọdún mọ́kànléláàdọ́ta (51), rọ́pò Zinedine Zidane, lẹ́ni tó kò̩ láti tè̩síwájú gé̩gé̩ bi akó̩nimò̩ó̩gbá wo̩n, lẹ́yìn to ran ikò̩ ọ̀hún lọ́wọ́ láti gbafe-ẹ̀yẹ ìdíje UEFA Champions League nígbà mẹ́ta léra ọ̀tọ̀ọ̀tọ̀.
Julen Lopetegui ni yóò jẹ́ akọ́nimọ̀ọ́gbá àgbà ikọ̀ Real Madrid lẹ́yìn ìdíje àgbááyé 2018.
"Lopetegui bẹ̀ẹ̀rẹ̀ sí ní tukọ̀ agbábọ́ọ̀lù Spain láti ọdún 2016.
Bẹ́ẹ̀ sì ni ó fìgbà kan jẹ́ akónimọ̀ọ́gbá ikọ̀ agbábọ́ọ̀lù FC Porto.
Ó tún kópa fúnkọ̀ Real Madrid àti Barcelona.
--- Russia 2018: Germany gunlè̩ fún ìdíje àgbáye.
Àwọn agbábọ́ọ̀lù English Premier League pàdé Erdogan nílùú London lóṣù tó kọjá, èyí tó mú Gundogan fẹ̀wù ìgbábọ́ọ̀lù ikọ̀ Manchester City rẹ̀ ránsẹ́ sáàrẹ rè̩.
Germany balẹ̀ sí Moscow lọ́jọ́ ìṣé̩gun, pè̩lú èròǹgbà láti dààbò bò ife-ẹ̀yẹ àgbááyé tó wà lọ́wọ́ wọn, pè̩lú ìrètí láti mọ́kàn kúrò nínú gbogbo awuyewuye òṣèlú tó rò̩ mó̩ Mesut Ozil àti Ilkay Gundogan.
Nínú gbogbo ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ ọlọ́rẹ̀ẹ́jọ̀rẹ́, làwọn olólùfẹ́ ikọ̀ náà bẹnu àté̩ lu Ozil àti Gundogan tí wọ́n jágbá́bọ́ọ̀lù Germany ṣùgbọ́n wọ́n tan mó̩ Turkey fún pípàdé ààrẹ ilẹ̀ Turkey RecepTayyip Erdogan.
--- Òṣìṣé̩ àjọ Ghana fis̩é̩ FIFA sí̀̀lè̩ nítorí ìfè̩sùn ìwàbàjé̩ kàn-án.
Òṣìṣé̩ àjọ FIFA, Kwesi Nyantakyi, ti fipò sílẹ̀ lájọ FIFA, látàrí ẹ̀sùn ìwàbàjé̩ tí wọ́n fi kàn án, ìwádìí sì ń lo̩ lábé̩lè̩ ní Ghana lórí ìwàbàjé̩̩.
Ààrẹ àjọ CAF, Ahmad náà fikún un pé, Nyantakyi tún kọ̀wé fipò rẹ̀ sílẹ̀ gẹ́gẹ́ bí igbákejì ààrẹ àjọ ọ̀hún.
Ahmad wá kéde ètòòdìbò ni Egypt lọ́gbọ̀n ọjọ́, oṣù kẹsàn-án ọdún 2018, fún àádọ́ta (50) àwọn àjọ amójútó bó̩ò̩lù àfe̩sè̩gbá nílè̩ Áfíríkà, fún ipò tó ṣófo.
Olùdíje yóò wá láti orílè̩-èdè tó ń so̩ Gè̩é̩sì, ààre̩ CAF sò̩yí.
Ló̩sè̩ tó kọjá lẹ̀rọ amóhùnmáwòrán ṣàfihàn Nyantakyi tó gba $65,000 só̩wó̩, ló̩wó̩ akò̩ro̩yìn tó mò̩-ó̩n-mò̩ s̩e bí olókòwò, láti rójú rere ààrẹ Ghana, Nana Akufo-Addo àtàwọn òṣìsé̩ ìjọba mìíràn.
--- Nadal fàgbà han Thiem láti gba ife-ẹ̀yẹ French Open.
Rafael Nadal bori nínú àṣekágbá ìdíje French Open, lé̩yìn tí ó yanjú akẹẹgbé̩ rè̩ Dominic Thiem ti Austria pèlú àmì-àyò 6-4, 6-3, 6-2 pè̩lú ìs̩elés̩e adérùbani rè̩ lópin ìdíje náà ló̩jó̩ Áìkú.
O̩mọ ọdún méjílélọ́gbọ̀n (32) tó mò̩-ó̩n gbá jùlọ ti gbàpapọ̀ ifeẹ̀yẹ mẹ́tàdínlógún, mé̩ta péré lalátakò rè̩ kòríkòsùn Roger Federer fi jùú.
Nadal fàyànrán ìdíje náà dé òpin, àmó̩ ó nílò ìtó̩jú ní ìpele ke̩rin nígbà tí ó fọwọ́ ṣèse ní ìpele kẹta ìdíje ò̩hún, kí ó tó fakọyọ láti gbon ewúro sí Thiem lójú nínú àṣekágbá ìdíje náà lárà ọ̀tọ̀.
Nadal ní, “Ìfigagbága yìí lágbára púpọ̀, mo wò̩yá ìjà ńlá pè̩lú alátakò tó mò̩-ó̩n gba.”
Láti gbafe è̩yẹ ìdíje yìí nígbà mọ́kànlá (11) ọ̀tọ̀ọ̀tọ̀, jóhun tí mi ò ronú kàn.
Mo nígbàgbó̩ rírí gbogbo yín ló̩dún tí ó ń bò̩.
Nadal darapò̩ mó Margaret Court ti Australia bi òǹdíje tó gba ifeẹ̀yẹ ò̩hún nígbà mọ́kànlá.
Jíjáwé olú́borí Nadal náà mú ìfigagbága rẹ̀ ni Roland Garros di ajáwé-olúborí mé̩rìndínláàdó̩rùn-ún (86), tó sì kùnà lé̩è̩mejì.
Pè̩lú àwọn òǹwò̩ran gbajúgbajà bíi òs̩èré Hugh Grant àti Tim Roth, àtàwo̩n òs̩èré o̩mo̩ Faransé Marion Cottillard ati Jean Dujardin tí wó̩n ń wòran bí Nadal s̩e bè̩rè̩.
--- Del Potro fàgbà hàn Cilic, láti lọ kojú Nadal.
Del Potro ti Argentina, kópá ribiribi láti borí Marian Cilic èyí tó mu yege fúnpele sè̩mí ní French Open fúngbà àkó̩kó̩ lé̩yìn o̩dún mé̩sàn-án ló̩jó̩bò̩, tójò síì dáfigagbága 7-6, 5-7, 6-3 at̀i 7-5 ò̩hún dúro.
Del Potro nílò àmì ayò méjì péré láti kó̩kó̩ borí ìpele kìn-ín-ní tí Cilic sì s̩e ń kó̩kó̩ borí pè̩lú 5-6.
Cilic o̩mo̩ Croatia kò kópa dáradára nígbà tó kó̩kó̩ pàdánù àmì-ayò níbè̩rè̩, ó sì ń s̩às̩ìs̩e̩ pé̩é̩pè̩è̩pé̩, ṣùgbọ́n ó ní àǹfààní láti tún s̩íde nígbà tó ti ń kápá Del Potro, àkókò yìí ní ó sì ní àmì-ayò tó dó̩gbá pè̩lú rè̩.
--- Nàìjííríà jáwálẹ̀ nínú́ àtẹ tuntun àjọ FIFA.
Nínú ipò àtẹ tuntun àjọ FIFA tó ṣèṣẹ̀ jáde, orílẹ̀-èdè Nàìjííríà ti jawálẹ̀ láti ipò mẹ́tàdínláàdọ́ta (47) sípò méjídínláàdọ́ta (48) lágbàáyé, bẹ́ẹ̀ sì ni láti ipò kẹfà sí ipò keje nílẹ̀ Afrika.
Àjọ FIFA ní, ò̩kan-ò-jòkan ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ ọlọ́rẹ̀ẹ́jọ̀rẹ́ wà lára ohun tí wọ́n ṣàgbéyẹ̀wò rè̩ fún àbájáde ipò àtẹ tuntun náà.
Ẹ̀wẹ̀, nínú ipò àtẹ tuntun ọ̀hún lágbàáyé, orílẹ̀-èdè Germany, Brazil àti Belguim síì dipò wọn mú ní ìtẹ̀léǹtẹ̀lé, bẹ́ẹ̀ sì ni, Russia, Poland ati Uruguay láǹfààní láti wà láàrin ipò kínní sí ogún.
Argentina dipò karùn-ún mú, Croatia dipò ogún mú, bẹ́ẹ̀ sì ni Iceland wà nípò méjìlélógún.
Ní Afíríkà, Tunisia jáwálè̩ láti ipò ke̩rìnlá tí wó̩n wà tè̩lé̩ dé ìko̩kànlélógún gé̩gé̩ bi o̩mo̩ Afíríkà tó wà nípò tó ga jù lágbàáyé.
Senegal tè̩lée nípò ke̩tàdínló̩gbò̩n (27), tí DR Congo sì dúró sípò kejìdínlógójì, tí Morrocco sì wà nípò ko̩kànlélógójì àti Egypt ní ipò karùndínláàdó̩ta.
Ghana, Aláìkópa nídije àgbááyé náà wà nípò kẹ́tàdínláàdọ́ta wọ́n sì dipò kẹfà mú lÁfíríkà.
Ipò àtẹ tuntun mìíràn yóò jáde ní July 19.
--- Putin kìlò̩ fún àwo̩n gómìnà – Ẹ má sàyíká pápáṣèré dilé-ìtajà.
Ààrẹ ni kí wó̩n má s̩e sọ àwọn ìpàgó̩ ìgbábó̩ò̩lù tàbí àyíká pápá ìṣeré Russia tí wọn yóò lò fún ìdíje bó̩ò̩lù àgbááyé di ilé ìtajà.
--- Ẹ tají! Agbábó̩ó̩lù tẹ́lẹ̀rí pe Eagles níjà bíborí
Lé̩yìn ìkùnà 1-0 ikò̩ Nàìjííà só̩wó̩ ikò̩ Czech Republic ní pápá-ìs̩iré Rudolf-Tonn-Stadion ni Austria, àwọn agbábò̩ò̩lù té̩lè̩rí ti ikọ̀ Super Eagles ṣèkìlò̩ títají wo̩n tí wó̩n bá fé̩ nípa nínú ìdíje àgbááyé Russia 2018.
Agbábó̩ò̩lù è̩gbé̩-iwájú té̩lè̩rí fúnkò̩ Super Eagles Emmanuel Amunike s̩èkìlò pé tíkò̩ ò̩hún kò bá fé̩ já nídìíje FIFA 2018 ní ìpele àkó̩kó̩, tí wó̩n ò bá yípadà nífe̩sè̩wo̩nsè̩ wo̩n onírúurú kí wo̩n tó figagbága pè̩lú Croatia ní ìfe̩sè̩wo̩nsè̩ ìs̩íde.
Bíbá Complete Sports sò̩rò̩, Amúníke s̩àpèjúwe ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ ikò̩ Eagles pè̩lú Czech Republic bíi “àìdára rárá”
Garba Lawal kín ihà Àmúníke ko̩ sèyí, ó s̩àkíyèsí pékò̩ Nàìjíríà kò bè̩rè̩ dáadáa láwo̩n ìfe̩sè̩wò̩nsè̩ èyí tí pípàdánù àwọn ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ o̩ló̩rè̩é̩jó̩rè̩é̩ sì fà á.
--- Nàìjííría kéde agbábọ́ọ̀lù mọ́kànlá tá kojú Czech Republic.
Akọ́nimọ̀ọ́gbá àgbà Gernot Rohr ti kéde agbábó̩ò̩lù mọ́kànlá fún ìfe̩sè̩wo̩nsè̩ o̩ló̩rè̩é̩jó̩rè̩é̩ ló̩sàn-án ojórú pè̩lú ikò̩ Czech Republic ní orílè̩-èdè Austria.
Ó ti wá fara hàn gbangbagbangba báyìí pé, aṣọ́lé ikọ̀ agbábọ́ọ̀lù Deportivo de La Corua, Francis Uzoho ni yóò jẹ́ aṣọ́lé kínní ikọ̀ ọ̀hún fún ìdíje àgbááyé náà, lẹ́yìí tí yóò tún ṣọ́lé nínú ìfigagbága náà.
Àwọn agbábó̩ò̩lù ọwó̩-ẹ̀yìn ni Abdullahi Shehu, Leon Balogun, William Troost-Ekong àti Brian Idowu.
Agbábó̩ò̩lù márùn-ún tí wó̩n yàn fún o̩wó̩-àárín ni John Ogu, Wilfred Ndidi, John Obi Mikel, Alex Iwobi àti Victor Moses, ó túmò̩ sí pé Joel Obi àti Eddy Onazi yóò jókòó lé̩yìn ìgbábó̩ò̩lù tí kò wúnilórí pèlú England.
Agbábó̩ò̩lù dáadáa fún Watford té̩lè, ìye̩n Odion Ighalo, Kelechi Iheanacho àti Simeon Tochukwu Nwankwo ló ní àǹfààní láti gbówó̩-iwájú.
Agbábọ́ọ̀lù mọ́kànlá ọ̀hún: Uzoho, Shehu, Troost-Ekong, Balogun, Idowu, Ogu, Ndidi, Iwobi, Mikel, Moses, Ighalo.
--- Lichtsteiner darapò̩ mó̩ Arsenal.
Arsenal ti ra agbábọ́ọ̀lù ọwọ́-ẹ̀yìn alágbárà Italy, Juventus, o̩mo̩ Switzerland, Stephan Lichtsteiner, ló̩fè̩é̩ èyí tó di mímò̩ ló̩jó̩ ìs̩é̩gun láte̩nu ikò̩ Arsenal.
Ọmọ ọdún mẹ́rìnlélọ́gbọ̀n náà gbápapò̩ ìfẹsè̩wọnsè̩ àádó̩tálélúgba fúnkò̩ Juve, ó sì gbafe-è̩yẹ ìdíje Serie A fún ìgbà méje ò̩tò̩ò̩tò̩ tó fi wà níbè̩.
Wó̩n só̩ di balógun ikò̩ Switzerland lọ́dún 2016, ó sì ti gbápapò̩ ìfe̩sè̩wọnsè̩ mọ́kàndínlọ́gọ́rùn-ún fún wo̩n.
Òun lagbábó̩ò̩lù kìíní takó̩nimò̩ó̩gbá tuntun Arsenal, Unai Emery ráà lé̩yìn tó gbaṣé̩ ló̩wó̩ Arsene Wenger lóṣù tó kọjá.
Stephan mú ìrírí àtidarí àìlé̩gbé̩ wánú e̩gbé̩ yìí.
Ó jé̩ agbábó̩ò̩lù tó dára gan-an tó sì ní ìs̩esí àti ìfojúsùn tó dáa.”
Emery so̩ pé, “Stephan yóò rankò̩ yìí ló̩wó̩ yálà lórí pápá tàbí níbò mìíràn”.
Lábala Lichtsteiner, ó fìdùnnú rè̩ hàn láti darapò̩ mó̩ agbábó̩ò̩lù ihà àríwá London.
Pè̩lú è̩ro̩ twitter rè̩, ó ní, “Inúu mí dùn, mo sì mo̩ iyì rè̩ láti je̩ o̩mo̩ Gunner! Màá s̩iṣé̩ takuntakun lójoojúmó̩ láti ríi dájú pé, a mú gbogbo àfojúsùn wa pátá sí ìmúṣẹ”.
Lichtsteiner bẹ̀rẹ̀ iṣé̩ agbábó̩ò̩lù rè̩ nínú ikò̩ Grasshoppers Zurich ti Switzerland ló̩dún 2001, ó tè̩síwájú ní Lille ti France, àti Lazio ní Italy kó tó lo̩ Juventus ló̩dún 2011.
--- Russia 2018: Iran kanlè̩ sí Russia.
Ikò̩ agbábó̩ó̩lù Iran jé̩kò̩ àkó̩kó̩ tí yóò balẹ̀ sí orílẹ̀-èdè Russia ló̩jó̩ ìṣẹ́gun, ṣaájú ìdíje bó̩ò̩lù àgbááyé tí yóò bè̩è̩rè̩ ní pápáàṣeré Luzhniki ló̩jó̩ ke̩rìnlá, oṣù kẹfà ọdún táa wà yìí.
Iran yóò kojú Morocco nínú ìfẹsè̩wo̩nsè̩ kìíní wọn ló̩jó̩ karùndínlógún, oṣù kẹfà ní pápáàṣeré Nizhny Novgorod. Ìgbàkarùn-ún Iran rèé, FIFA sì fi wó̩n sípò ke̩rìndínlógójì.
Bákan náà, wọn yóò rìnrìnàjò lo̩ Kazan ní June 20 láti kojú agbéfe àná ikò̩ Spain, kí wó̩n tó pajú rè̩ dé pè̩lú Portugal ni June 25.
Iran pàdánù ìfẹsè̩wọnsè̩ ọló̩rè̩é̩́jò̩ré̩ pè̩lú Turkey, pè̩lú àmì-ayò 2:1 ni May 28, wọn a tún gbáfẹsè̩wọnsè̩ ọlọ́rè̩é̩jò̩ré̩ mìíràn pè̩lú Lithuania ló̩jó̩ ke̩jo̩, oṣù kẹfà.
--- Rohr ní Uzoho dára, a kò níṣòro asó̩lé rárá.
Akọ́nimọ̀ọ́gbá àgbà fún ikò̩ agbábó̩ò̩lù àgbà ti Nàìjíríà, Gernot Rohr ti ṣe àfihàn àbùdá pàtàkì jùlo̩ tí ó rí lára asó̩lé ò̩dó̩ ti ikò̩ ò̩hún, Francis Odinaka Uzoho, ó sì tún ní ikò̩ Super Eagles ko níṣòro aṣó̩lé rárá.
Rohr sò̩rò̩ ò̩hún lé̩yìn ìfe̩sè̩wọnsè̩ ọló̩rè̩é̩jò̩ré̩ tíkò̩ náà pàdánù só̩wó̩ England pè̩lú àmì-ayò kan sí méjì, ó ní kò sí wàhálà kankan pè̩lú as̩o̩lé kí ìdíjé àgbááyé ní Russia tó bè̩rè̩, ó te̩numó̩o̩ pé àwo̩n as̩ó̩lé mé̩ta rè̩ tó gbangba sùn ló̩yé̩ ní Russia.
“Mo ní ìgbé̩kè̩lé pè̩lú àwo̩n as̩ó̩lé wa, bí ó tilè̩ jé̩ pé mo gbó̩ ìkùnsínú òun awuyewuye ló̩dò̩ àwo̩n onífèé bó̩ò̩lù pé ikò̩ wa ní ìs̩òro pè̩lú àwo̩n as̩ó̩lé”, Rohr ló sò̩yí.
“Ó ṣe dáradára nínú ìfẹsè̩wọnsè̩ pè̩lú England, a sì ń ṣiṣé̩ síi pè̩lú rè̩ láti túbò̩ ràn án ló̩wó̩ síi, èyí tó ṣokùnfà ìdí tí a fi rán akó̩nimò̩ó̩mú ikò̩ yìí lọ sí Deportivo La Coruna láti lọ ràn án ló̩wó̩ nínú àwọn kùdìè̩-kudiẹ rè̩ tó kù.
As̩ó̩lé ke̩ta ló jé̩ ní La Coruna ó sì ń gbìyànjú.
E̩ni jé̩jé̩ ni, ó ga, ó máa ń jáde, o dára nílà rè̩ ó sì nílò is̩é̩ si.
Ohun tí mo fé̩ràn jù nípaa rè̩ ni ìwà ìrè̩lè̩,” ó sò̩yí.
--- England àti Naijiria: Mikel àti Iheanacho ń gbèrò fífakọyọ.
Àwọn ọmọ ẹgbé̩ agbábó̩ò̩lù Super Eagles ti Nàìjíríà ti fìrètí hàn pé dídùn lọsàn á so nínú ìdíje ọló̩rè̩só̩rè̩é̩ tí wó̩n fé̩ gbá pè̩lú Three Lions ti England ní London ló̩jó̩ Àbámé̩ta.
Ò̩pò̩ ọmọ Nàìjíríà be̩nu àté̩ lu ẹgbé̩ agbábó̩ò̩lù Super Eagles fún ìs̩o̩wó̩gbá ìdíjé o̩ló̩rè̩é̩jó̩rè̩é̩ wo̩n pè̩lú Leopard ti DR Congo nílùú Port Harcourt ló̩jó̩ ajé tó parí pè̩lú ò̩mì.
Ìdíje tí wọ́n gbá pẹ̀lú Poland náà kò wúni lórí tó nítorí agídí ni wọ́n fi gbá 1-0 tí Serbia si nà wọ́n pẹ̀lú 2-0 ní London.
Sísò̩rò̩ láti ìlú London, balógun Eagles Mikel Obi níkò̩ ò̩hún ti ṣàtúnṣe gbogbo àṣìṣe wọn, ó sì ti s̩e̩tán fún ìfigagbága pè̩lú alátakò bíi wó̩n.
--- Ìdíje ò̩dó̩ nílè̩ Adúláwò̩: Kwara káwọn 26 lọ̀pàgó̩ fúngbàáradì.
Eléré sísá mé̩rìndínló̩gbò̩n nípìnínlè̩ Kwara ti kó lọ sípàgó̩ fúngbàáradì de ìdíje oríṣìí eré ìdárayá mé̩wàá tí yóò wáyé ní eré àwọn ò̩dó̩ ilè̩ Adúláwò̩ ní Algiers ni orílè̩ èdè Algeria láìpé̩.
Pípèsè àwo̩n akó̩pa fún eré-ìdárayá náà fún àwo̩n akò̩rò̩yìn eré-ìdárayá, olùdarí eré-ìdárayá nípìnínlè̩ náà, ìye̩n Mallam Tunde Kazeem, ní àwo̩n akó̩nimò̩ó̩gbá mé̩ta náà, Tajudeen Sulaiman (Badminton), Sidiq Bolaji (Wushu Kung Fu) àti Sulaiman Abdulkareem Angulu (Rugby) ti gbàpè láti s̩ègbáradì fún àwo̩n akópá ìdíje ò̩hún.
Mallam Tunde Kazeem, tó tún jé̩ alága fún adarí eré-ìdárayá ní Nàìjíríà, gbà wó̩n nímò̩ràn láti fìdí yíyàn wo̩n múlè̩, kí wó̩n sì fi ìpínlè̩ wo̩n yangàn níbi ìdíje tó fé̩ wáyé ní orílèèdè yìí.
--- NTTF ń sọ̀fọ̀ Seun Ajetunmobi tó ti di olóògbé.
Ajetunmobi, tí wó̩n bí Oct 10, ọdún 1985 lo kú ló̩jó̩bò̩ nílùú Èkó látàrí afé̩fé̩ gáàsì.
Anderson Bankole, ò̩kan lára àwọn ọmọò̩gbìmò̩ ìṣàkóso NTTF, sísò̩rò̩ nílùú Èkó so̩ pájo̩ ò̩hún so̩ ò̩kan lára àwo̩n ògbóǹtirigi wo̩n nù.
Samson Ajayi, ò̩kan lára àwọn akó̩nimò̩ó̩gbá ní ìpínlè̩ Èkó ròyìn akitiyan olóògbé náà fún ìdàgbàsókè eré ìdárayá yìí kí o̩ló̩jó̩ tó dé wá mú.
--- Rohr ṣàgbékalẹ̀ ẹ̀rọ ìgbàlódé GPS trackers tí yóò ṣàfihàn ipa àwọn agbábọ́ọ̀lù lórí pápá."
Akọ́nimọ̀ọ́gbá ikọ̀ Super Eagles, Gernot Rohr ti pàṣẹ fún àwọn agbábọ́ọ̀lù rẹ̀ láti máa wọ ẹ̀wù ìgbàlódé, kí wọn ó tó bẹ̀rẹ̀ ìgbáradì, tí a mọ̀ sí (GPS trackers), èyí tí yóò máa ṣàfihàn bí agbábọ́ọ̀lù kọ̀ọ̀kan ṣe ń kópa sí nínú ìgbáradì ọlọ́kan-ò-jọ̀kan wọn.
--- Odion Ighalo dara pọ̀ mọ́ àwọn akẹẹgbẹ́ rẹ̀ nílùú Uyo.
Odion Ighalo balẹ̀ sí ìpínlẹ̀ Èkó láti ìlú London lọ́jọ́ ìṣẹ́gun (Tuesday), láti dara pọ̀ mọ́ àwọn akẹẹgbẹ́ rẹ̀ fún ìgbáradì ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ ọlọ́rẹ̀ẹ́jọ̀rẹ́ èyí tí ikọ̀ ọ̀hún yóò gbá pẹ̀lú ikọ̀ agbábọ́ọ̀lù DR Congo.
Ìrètí wà pé, ikọ̀ Super Eagles yóò gbáradì ní òwúrọ̀ òní fún ìfigagbága ọlọ́rẹ̀ẹ́jọ̀rẹ́ mìíràn tí yóò wáyé láàrin ikọ̀ ọ̀hún àti ikọ̀ agbábọ́ọ̀lù Atletico de Madrid, tí ó ń kópa nínú ìdíje La Liga lórílẹ̀-èdè Spain, ní pápá ìṣeré Godswill Akpabio láago mẹ́fa ìrọ̀lẹ́ òní.
"Ighalo sọ̀rọ̀ ṣaájú ìfigagbága ọlọ́rẹ̀ẹ́jọ̀rẹ́ tí wọn yóò gbá pẹ̀lú England, ""England ní àwọn agbábọ́ọ̀lù tí ó dára púpọ̀, bẹ́ẹ̀ sì ni, a ò ní fojú tẹ́ńbẹ́lú wọn rárá."
"Mò ń fojú sọ́nà fún ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ náà torí pé, mo ti kópa rí nínú ìdíje ilẹ̀ Gẹ̀ẹ́sì EPL, tí mo sì fẹ́ràn láti rí àwọn ojú tí a jọ wà tẹ́lẹ̀.
--- Iwobi fẹnu ko pẹ̀lú ilé-iṣẹ́ LG láti jẹ́ aṣojú wọn.
Atamátàsé ikọ̀ agbábọ́ọ̀lù Super Eagles, Alex Iwobi ti bọwọ́ lu ìwé ìbásepọ̀ pẹ̀lú ilé-iṣẹ́ tó ń rí sí ìpèsè ẹ̀rọ ìgbàlódé LG Electronics, láti jẹ́ aṣojú ilé-iṣẹ́ náà.
Gẹ́gẹ́ bí olùdarí ilé-iṣẹ́ LG Electronics nílẹ̀ Áfíríkà, Taeick Son ṣe sọ: Kí a tó yan Alex Iwobi gẹ́gẹ́ bí aṣojú wa, a fikùnlukùn lọ́pọ̀lọpọ̀ láti wo ipa rẹ̀ tí ó ń kó lórí pápá, àti ní pàápàá jùlọ bí àwọn ènìyàn ṣe nífẹ̀ẹ́ rẹ̀ sí jákèjádò.
--- Chelsea fàgbà hàn Manchester United láti gba ife-ẹ̀yẹ ìdíje FA Cup.
Chelsea fàgbà han Manchester United láti gba ife-ẹ̀yẹ ìdíje FA Cup, nínú ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ tí ó wáyé ní pápá ìṣeré Wembley lọ́jọ́ Àìkú (Saturday).
Bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé, jíjáwé olúborí nínú àṣekágbá ìdíje náà kò tíi tó láti fẹsẹ̀ àkọ́nimọ̀ọ́gbá ikọ̀ ọ̀hún, Antonio Conte múlẹ̀, lẹ́ni tí ìrètí wà pé wọn yóò gba iṣẹ́ lọ́wọ́ rẹ̀ tí sáà ìdíje yìí bá parí, látàrí àìṣe déédé ikọ̀ náà, tí wọn kò sì tún pegedé fún ìdíje UEFA champions league ti sáà tó ń bọ̀, lẹ́yìn tí wọ́n parí sípò karùn-ún lórí tábìlì ìdíje EPL.
Ní báyìí, pípàdánù ife-ẹ̀yẹ ìdíje FA ọ̀hún sọ́wọ́ ikọ̀ agbábọ́ọ̀lù Chelsea, ló fihàn pé, ikọ̀ agbábọ́ọ̀lù Manchester United parí sáà yìí láìgba ife-ẹ̀yẹ kankan.
Gẹ́gẹ́ bí balógun ikọ̀ ọ̀hún, Gary Cahill ṣe sọ, A ṣisẹ́ takuntakun láti gba ife ẹ̀yẹ yìí, láti yẹ́ sáà wa tọdụ́n yìí sí, látàrí àìṣe déédé wa nínú ọ̀kan-ò-jọ̀kan ìdíje yòókù tí a kópa nínú rẹ̀.
Romelu Lukaku tí ó jẹ́ ẹni tí ó gbá bọ́ọ̀lù ságbọ̀n júlọ̀ fún ikọ̀ Manchester United ni sáà yìí, kò láǹfààní láti bẹ̀ẹ̀rẹ̀ ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ náà látàrí ìfarapa ráńpẹ́ tí ó ní."
--- Dalung- Super Eagles nílò àtìlẹyìn tí ó péye ṣaájú ìdíje àgbááyé.
Mínísítà tó ń rí sí ọ̀rọ̀ ere ìdárayá àti ìdàgbàsókè àwọn ọ̀dọ́ ní Nàìjííríà, ọ̀gbẹ́ni Solomon Dalung ti pè fún àtìlẹyìn tí ò lẹ́gbẹ́ látọwọ́ àwọn ọmọ orílẹ̀-èdè Nàìjííríà fún àṣeyọrí ikọ̀ agbábọ́ọ̀lù Super Eagles ṣaájú ìdíje àgbááyé tó ń bọ̀ lọ́nà lórílẹ̀-èdè Russia.
Dalung sọ nínú ọ̀rọ̀ rẹ̀ eléyìí tí amúgbálẹ́gbẹ̀ẹ́ pàtàkì rẹ̀ lóri ́ọ̀rọ̀ ìgbódegbà àti ìfitónilétí, Nneka Ikem-Anibeze, gbé jáde lọ́jọ́bọ (Thursday) nílùú Abuja, Ó gbóríyìn fún ikọ̀ ọ̀hún fún gbogbo akitiyan wọn, ìbáṣepọ̀ àti ìwà akínkanjú tí wọ́n ní ṣaájú ìdíje náà tó ń ti ń sún mọ́lé báyìí.
Ó wá rọ, àpapọ̀ ikọ̀ ọ̀hún àti àwọn tọ́rọ̀ kàn nínú ikọ̀ náà pé, kí wọ́n ríi dájú láti kópa dáradára nínú ọ̀kan-ò-jọkan ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ ọlọ́rẹ̀ẹ́jọ̀rẹ́ wọn tí wọn yóò gbá fún ìgbáradì ní kíkún ṣaájú ìdíje ńlá náà.
Mo gbósùbà káreláí fún ìjọba àpapọ̀ látàrí àtìlẹyìn wọn lọ́lọ́kan-ò-jọ̀kan fún ikọ̀ yìí.
Ìjọba fi dá àwọn ọmọ orílẹ̀-èdè lójú láti ṣètò bí ó ti tọ́ àti bí ó ti yẹ ṣaájú àwọn ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ ọlọ́rẹ̀ẹ́jọ̀rẹ́ wa yòókù tí a ó gbá pẹ̀lú, DR Congo, England àti Czech Republic.
Bákan náà, mínísítà tuń kí àjọ NFF, àwọn òṣìṣẹ́ tí ó fi mọ́ àwọn akọ́nimọ̀ọ́gbá gbogbo fún akitiyan wọn, bẹ́ẹ̀ sì ni, Ó rọ̀ wọ́n láti pa ọkàn wọn pọ̀ sójúkan fún ìgbáradì ìdíje náà.
--- DR Congo kéde agbábọ́ọ̀lù méjídínlọ́gbọ̀n tí yóò kojú Super Eagles.
--- Nàìjíríà dípò mẹ́tàdínláàdọ́ta mú nínú ipò àtẹ àjọ FIFA.
Gẹ́gẹ́ bí àbájáde ipò àtẹ àjọ FIFA tí ó jáde lọ́jọ́bọ (Thursday), Nàìjíiríà dipò mẹ́tàdínláàdọ́ta mú lágbàáyé nínú ipò àtẹ àjọ ọ̀hún tí ó ṣẹ̀ṣẹ̀ jáde.
Ipò àtẹ ọ̀hún ni àjọ FIFA gbé jáde lórí ẹ̀rọ ayélujára wọn lọ́jọ́bọ (Thursday), eléyìí tí orílẹ̀-èdè mẹ́tàdínláàdọ́ta di ipò wọn mú gẹ́gẹ́ bí wọ́n ṣe wà tẹ́lẹ̀.
Orílẹ̀-èdè Germany, Brazil àti Belgium wà lórí òkè téńté tábìlì ọ̀hún ní ìtẹ̀léǹtẹ̀lé, bẹ́ẹ̀ sì ni Argentina, Croatia àti Iceland wà ní ipò karùn-ún, ipò kejìdínlógún àti ipò kejìlélógún.
Ipò àtẹ mìíràn yóò tún jáde lọ́jọ́ keje oṣù kẹfà ọdún tí a wà yìí.
--- Oborududu yóò dara pọ̀ mọ́ àwọn akẹẹgbẹ́ rẹ̀ ní New York.
Blessing Oborududu tí ó ní òṣùwọ̀n kílógíràmù méjìdínláàádọ́rin (68kg), ti balẹ̀ sílùú New York láti dara pọ̀ mọ́ àwọn akẹẹgbẹ́ rẹ̀ yòókù fún ìdíje ìfigagbága tí yóò wáyé lọ́jọ́ kẹtàdínlógún oṣù karùn-ún ọdún tí a wà yìí.
Oborududu kò láǹfààní láti bá àwọn akẹẹgbẹ́ rẹ̀ lọ lọ́jọ́ Àìkú (Sunday), látàrí ìdojúkọ ìwé ìrìn àjò tí ò ní.
Ó dara pọ̀ mọ Ọdúnayọ Adékúoróyè tí ó ní òṣùwọ̀n kílógírámù mẹ́tàdínlọ́gọ́ta (57kg) àti Aminat Adéníyì tí ó ní òṣùwọ̀n kìlógírámù méjílélọ́gọ́ta (62kg), fún ìfigagbága tí yóò wáyé ní gbàgede
"Gẹ́gẹ́ bí Purity Akuh, tí ó jẹ àkọ́nimọ̀ọ́jà ikọ̀ náà,""Inú mi dùn púpọ̀ pé, ikọ̀ mi ti pé báyìí."
Mo ń fojú sọ́nà fún ìdíje World Championships tí yóò wáyé lórílẹ̀-èdè Hungary, bẹ́ẹ̀ sì ni ìfigagbága yìí yóò ṣe àǹfààní fún wa láti fi gbáradì ṣaájú ìdíje àgbááyé ọ̀hún.
--- Atletico fàgbà han Marseille pẹ̀lú àmì-ayò mẹ́ta sóódo.
Atamátàsé agbábọ́ọ̀lù ọwọ́ iwájú fún ikọ̀ agbábọ́ọ̀lù Atletico Madrid, Antoine Griezmann ti ran ikọ̀ rẹ̀ lọ́wọ́ láti gba ife ẹ̀yẹ ìdíje Europa League fún ìgbà kẹta báyìí, lẹ́yìn tí wọ́n fàgbà han ikọ̀ agbábọ́ọ̀lù Olympique de Marseille pẹ̀lú àmì-ayò mẹ́ta sóódo (3-0), lọ́jọ́rú (Wednesday).
Ẹ̀wẹ̀, àmì-ayò kínni wáyé látàrí àṣìṣe agbábọ́ọ̀lù ẹ̀yìn Marseille Andre-Frank Zambo Anguissa, eléyìí tí balógun ikọ̀ Madrid, Gabi já gbà kí ó tó ṣè ìrànwọ́ àmì-ayò ọ̀hún fún Griezmann ní ìṣẹ́jú kọkànlélógún sáà àkọ́kọ́ ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ náà.
Marseille pàdánù àǹfàaní lóríṣiriṣi láti dá àmì-ayò náà padà, ṣùgbọ́n ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ náà tún wá burú jáì lẹ́yìn tí agbábọ́ọ̀lù àárín ikọ̀ náà, Dimitri Payet fara pa, tí ó sì jáde níṣẹ̀ẹ́jú kọkànlélọ́gbọ̀n sáà kínní ọ̀hún.
Ní ìṣẹ́jú mẹ́rin gbàrà tí sáà kejì bẹ̀ẹ̀rẹ̀, Koke tún ṣe ìrànwọ́ àmì-ayò mìíràn fún Griezmann.
Gabi gbá àmì ayò mìíràn wọ̀lé láti sọ àpapọ̀ èsì ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ ọ̀hún di mẹ́ta sóódo (3-0).
--- Brazil kéde agbábọ́ọ̀lu mẹ́tàlélógún fún ìdíje bọ́ọ̀lù àgbááyé.
--- Rohr kéde ọgbọ̀n agbábọ́ọ̀lù tí yóò kópa fún ìdíje bọ́ọ̀lù àgbááyé.
Akọ́nimọ̀ọ́gbá àgbà ikọ̀ agbábọ́ọ̀lù Super Eagles, Gernot Rohr ti kéde àwọn agbábọ́ọ̀lù tí yóò lọ ṣojú orílẹ̀-èdè Nàìjííríà nínú ìdíje bọ́ọ̀lù àgbááyé tó ń bọ̀ lọ́nà lórílẹ̀-èdè Russia.
--- Nàìjííríà yóò kojú Argentina, Turkey nínú ìdíje àgbááyé FIBA.
Nàìjíírìà yóò máa kojú ikọ̀ Australia, Argentina àti Turkey nínú ìpele kejì ìyíkoto ìfigágbaga ìdíje àgbááyé 2018 FIBA Women Basketball tí yóò bẹ̀ẹ̀rẹ̀ lọ́jọ́ kejìlélógún oṣù kẹsàn-án títí di ọgbọ̀n ọjọ́ ọdún tí a wà yìí, nílùú Tenerife, lórílẹ̀-èdè Spain.
Australia dipò kẹrin mú nínú ipò àtẹ àjọ FIBA tí ó ṣẹ̀ṣẹ̀ jáde, Turkey wà ní ipò keje, bẹ́ẹ̀ sì ni Argentina dipò karùndínlógún mú lágbàáyé.
Ikọ̀ Tigress wà ní ipò mẹ́tàdínlógójì lágbàáyé, tí wọ́n sì di ipò karùn-ún mú nílẹ̀ Áfíríkà.
Senegal bọ́ sí ìpele kẹrin, tí wọn yóò sì máa kojú Latvia, USA àti China.
Nàìjííríà pegedé fún ìdíje àgbáyé FIBA fún ìgbà àkọ́kọ́ lọ́dún 2006, ṣùgbọ́n wọn kò jáwé olúborí nínú ìfigagbága kankan tí wọ́n fi já kúrò nínú ìdíje ọ̀hún.
Bákan náà, gẹ́gẹ́ bí àjọ NBF (Nigeria Basketball Federation), wọ́n ní, ikọ̀ Tigress yóò pàgọ́ sílùú Atlanta, Georgia, lórilẹ̀-èdè USA fún ìgbáradì ìdíje náà ní kíkún.
Agbẹnusọ̀rọ̀ àjọ ọ̀hún, ọ̀gbẹ́ni Afọlábí Òní sọ pé, wọn yóò kéde àpapọ̀ ikọ̀ tí yóò máa kópa fún ìdíje ọ̀hún ní kété tí ìdíje bọ́ọ̀lù àgbááyé Russia 2018 bá parí.
--- Mancini fiṣẹ́ sílẹ̀ gẹ́gẹ́ bí akọ́nimọ̀ọ́gbá ikọ̀ agbábọ́ọ̀lù Zenit.
Akọ́nimọ̀ọ́gbá àgbà ikọ̀ agbábọ́ọ̀lù Zenit St Petersburg, Roberto Mancini ti gbà láti fiṣẹ́ sílẹ̀ lẹ́yìn tí ó fẹnu kò pẹ̀lú àdéhùn tí ó rọ̀ mọ́ ìfisẹ́ sílẹ̀ náà.
Ọmọ ọdún mẹ́tàlélógójì ọ̀hún ni ìrètí wà pé yóò bẹ̀rẹ̀ iṣẹ́ láìpẹ́ gẹ́gẹ́ bí akọ́nimọ̀ọ́gbá ikọ̀ agbábọ́ọ̀lù orílẹ̀-èdè Italy.
Bákan náà, Ó tukọ̀ agbábọ́ọ̀lù Manchester City, Inter Milan, kí ó tó dara pọ̀ mọ́ ikọ̀ agbábọ́ọ̀lù Zenit lọ́dún 2017, tí ó sì ran ikọ̀ ọ̀hún lọ́wọ́ láti parí ìdíje sáà yìí sípò karùn-ún lórí tábìlì.
Zenit àti Roberto Mancini fẹnu kò láti fòpin sí ìbáṣepọ̀ wọn.
Ní báyìí, Mancini yóò kúrò nínú ikọ̀ ọ̀hún láìgba owó gbàmábìínú kankan.
--- Edmund fàgbà han Djokovic nínú ìdíje Madrid open.
Kyle Edmund gbádùn ọkàn lára ìfigagbága rẹ̀ tí ó ti ń gbá láti ìgbà tí ó ti ń díje nínú eré ìdárayá bọ́ọ̀lù àfigigbá, lẹ́yìn tí ó fàgbà han òǹdíje tí ó dára jùlọ tẹ́lẹ̀rí nínú eré ìdárayá ọ̀hún, Novak Djokovic nínú ìfigagbága ìsọ̀rí-ìsọ̀rí pẹ̀lú àmì ayò mẹ́fà sí mẹ́ta (6-3), méjì sí mẹ́fà (2-6) àti mẹ́fa sí mẹ́ta (6-3) nínú ìpele kejì ìdíje Madrid Open.
--- Tiger Woods yóò kópa nínú ìdíje British open.
Tiger Woods ti sọ pé, òun yóò kópa nínú ìdíje mẹ́tàdínláàdọ́jọ British Open tí ìgbìmọ̀ náà yóò ṣagbátẹrù rẹ̀, eléyìí tí yóò wáyé ní gbàgede Carnoustie lọ́jọ́rú.
Woods, ọmọ ọdún méjílélógójì náà, ẹni ti ó ti gba ife ẹ̀yẹ ìdíje ọ̀hún fún ìgbà mẹ́ta ọ̀tọ̀ọ̀tọ̀, ṣùgbọ́n kò tíì láǹfààní láti kópa nínú ìdíje náà láti ọdún 2015 látàrí ìfarapa tí ó ní.
Bákan náà, Woods tí gba ife ẹ̀yẹ mẹ́rìnlá ọ̀tọ̀ọ̀tọ̀, bẹ́ẹ̀ sì ni, Ó tún kópa nínú ìfigagbága méje ọ̀tọ̀ọ̀tọ̀ lọ́dún yìí, lẹ́yìn àṣeyọrí iṣẹ́ abẹ́ ọ̀pá ẹ̀yìn èyí tí ó làkọjá nínú oṣù kẹrin ọdún tí ó kọjá.
Ní ìparí, ìdíje British Open náà yóò bẹ̀ẹ̀rẹ̀ lọ́jọ́ kọkàndínlógún, oṣù keje títí di ọjọ́ kejìlélógún oṣù kan nàà ọdún tí a wà yìí (July 19 to July 22).
--- Àṣìṣe aṣọ́lé ikọ̀ Ac Milan, Gianluigi ṣokùnfà bí ikọ̀ ọ̀hún ṣe pàdánù.
Àṣìṣe aṣọ́lé ikọ̀ agbábọ́ọ̀lù Ac Milan Gianluigi Donnarumma ti ṣokùnfà bí ikọ̀ ọ̀hún ṣe pàdánù ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ àṣekágbá ìdíje Coppa Italia sọ́wọ́ ikọ̀ agbábọ́ọ̀lù Juventus nínú ìfigagbága tí ó wáyé lọ́jọ́bọ (Thursday).
Agbábọ́ọ̀lù ọwọ́̀ ẹ̀yìn Juventus Medhi Benatia, gbá àmì ayò méjì wọlé, bẹ́ẹ̀ sì ni Douglas Costa gbá àmì ayò mìíràn wọlé.
Nikola Kalinic ṣe àṣìṣe gbá àmì ayò kan mìíràn wọnú agbọ̀n rẹ̀, láti sọ àpapọ̀ èsì ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ náà di àmì ayò mérin sóódó.
--- Dennerby kéde agbábọ́ọ̀lù mẹ́rìndínlọ́gbọ̀n tí yóò kojú Gambia.
Ikọ̀ agbábọ́ọ̀lù Super Falcons yóò bẹ̀ẹ̀rẹ̀ ìgbáradì ní kíkún fún ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ ìpegedé ìdíje bọ́ọ̀lù ilẹ̀ Áfíríkà 2018 táwọn obìnrin tó ń bọ̀ lọ́nà, eléyìí tí wọn yóò gbá pẹ̀lú ikọ̀ agbábọ́ọ̀lù orílẹ̀-èdè Gambia.
Ní báyìí, akọ́nimọ̀ọ́gbá àgbà ikọ̀ ọ̀hún, Thomas Dennerby ti pe agbábọ́ọ̀lù mẹ́rìndínlọ́gbọ́n, tí ó fi mọ́ àwọn tí ó fi ilẹ̀ òkèrè ṣe ibùgbé.
--- Ribery sún àsìko rẹ̀ síwájú sí nínu ikọ̀ agbabọ́ọ̀lù Bayern Munich.
Atamátàsé ikọ̀ agbábọ́ọ̀lù Bayern Munich, Franck Ribery ti sún àsìkò rẹ̀ síwájú síi nínú lkọ̀ agbábọ́ọ̀lù Bayern lẹ́yìn tí ó bọwọ́lu ìwé ìṣiṣẹ́ pọ̀ ọlọ́dún kan.
Ọmọ ọdún márùnlélọ́gbọ̀n ọ̀hún ní àmì ayò márùn-ún péré nínú ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ mọ́kàndínlógún tí ó gbá ní sáà yìí láti gba ife ẹ̀yẹ kẹjọ ìdíje Bundesliga.
Gẹ́gẹ́ bí adarí ẹ̀ka ètò ìdárayá fún Bayern, Hasan Salihamidzic ṣe sọ, Inú wa dùn púpọ̀ pé Franck ṣì fẹ́ dúró tìwá.
"Ẹ̀wẹ̀, Ribery dara pọ̀ mọ́ ikọ̀ agbábọ́ọ̀lù Bayern lọ́dún 2007 láti ikọ̀ agbábọ́ọ̀lù Olympique de Marseille.
Ribery sọ pé, inú mi dùn pé máa tún kópa fún ikọ̀ agbábọ́ọ̀lù yìí fún sáà kan sí i,
Munich ti jẹ́ ilé fún èmi àti ẹbí mi láti ọjọ́ pípẹ́, bẹ́ẹ̀ sì ni ó jẹ́ ìwúrí fún mi.
--- Eagles ṣetán fún ìdíje bọ́ọ̀lù àgbááyé – Balogun
Atamátàsé agbábọ́ọ̀lù ọwọ́ ẹ̀yìn ikọ̀ Super Eagles, Leon Balógun sọ pé, ó jẹ́ ohun ìwúrí pé àwọn akẹẹgbẹ́ òun kò ní ìfarapa kankan ṣááju ìdíje àgbááyé tó ń bọ̀ lọ́nà.
Nínú ìdíje àgbááyé náà, eléyìí tí ikọ̀ agbábọ́ọ̀lù Super Eagles jẹ́ ikọ̀ kínní tí ó kọ́kọ́ pegedé fún ìdíje ọ̀hún nílẹ̀ Áfíríkà, ni wọn yóò máa wàákò pẹ̀lú Argentina, Croatia àti Iceland.
Balógun wa sọ pé, kí okun àwọn agbábọ́ọ̀lù pé yóò ran ikọ̀ náà lọ́wọ́ púpọ̀ láti ṣàṣeyọrí nínú ìdíje àgbááyé ọ̀hún.
A ní ikọ̀ tí o le fakọyọ ní Russia, bẹ́ẹ̀ sì ni a lè dé ìpele tí ó lápẹrẹ tí a bá ní okun àti ìlera tí ó pé.
Mo mọ̀ pé, ìfarapa máa ń wáyé nípasẹ̀ kíkópa lórí pápá, tí a bá sì ní oreọ̀fẹ́ láti má nìí ìfarapa kankan tí ìdíje náà yóó fi bẹ̀rẹ̀, èyí yóò ṣe ìrànwọ́ fún wa lọ́pọ̀lọpọ̀.
Nínú irúfẹ́ ìdíje ọ̀hún tí ó wáyé sị̀kẹyìn, eléyìí tí balogun ikọ̀ náà tẹ́lẹ̀rí, Joseph Yobo àti Vincent Enyeama tukọ̀ rẹ̀, ikọ̀ ọ̀hún dé ìpele kejì nínú ìdíje ni Brazil kí ikọ̀ agbábọ́ọ̀lù France kó tó já wọn kúro."
Bákan náà, ni ikọ̀ Super Eagles yóò tún kojú England lọ́jọ́ kejí oṣù kẹfà ọdún tí a wà yìí, ní pápá ìṣeré Wembley ṣaájú ìfigagbága ọlọ́rẹ̀ẹ́jọ̀rẹ kẹyìn pẹ̀lú Czech Republic lọ́jọ́ kẹfà sí ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ ọ̀hún.
--- Èsì ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ ìdíje bọ́ọ̀lù àfẹsẹ̀gbá orílẹ̀-èdè Nàìjííríà (NPFL).
Èyí ni èsì ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ ìdíje bọ́ọ̀lù àfẹsẹ̀gbá orílẹ̀-èdè Nàìjííríà Nigeria Professional Football League (NPFL), tí ó wáyé lópin ọ̀sẹ̀:
--- Super Eagles yóò fakọyọ lórílẹ̀-èdè Russia – Yobo
Balógun ikọ̀ agbábọ́ọ̀lù Super Eagles tẹ́lẹ̀ rí, Joseph Yobo, sọ pé, òun ní ìgbàgbọ́ pé ikọ̀ Super Eagles yóò fakọyọ nínú ìdíje bọ́ọ̀lù àgbááyé tó ń bọ̀ lọ́nà lórílẹ̀-èdè Russia.
Yobo gba ikọ̀ ọ̀hún níyànjú láti má ṣe jáyà fún ikọ̀ akẹẹgbẹ́ wọn kankan tí wọn yóò jọ máa figagbága, tí ń ṣe Croatia, Argentina àti Iceland.
Agbábọ́ọ̀lù ọwọ́ ẹ̀yìn náà tẹ́lẹ̀rí, Yobo gbóríyìn fún akọ́nimọ̀ọ́gbá àgbà ikọ̀ ọ̀hún, Gernot Rohr, fún akitiyan rẹ tí ó sà láti kó ọ̀kan-ò-jọ̀kan agbábọ́ọ̀lu tí ó dáńtọ́ jọ láti figagbága fún ààyè ṣaájú ìdíje ọ̀hún.
Yobo wá yànàná ìdojúkọ tí ikọ̀ ọ̀hún kojú ní ẹ̀ka agbábọ́ọ̀lù aṣólé, pé ikọ̀ náà yóò la ìdojúkọ ọ̀hún kọjá tí wọn yóò sì fakọyọ lórílẹ̀-èdè Russia.
Gẹ́gẹ́ bí Yobo ṣe sọ, Mo ní ìgbàgbọ́ pé ikọ̀ Super Eagles yìí yóò fakọyọ lórílẹ̀-èdè Russia.
Ó fikún un pé, agbábọ́ọ̀lù ọ̀dọ́ tí ó pọ̀ nínú ikọ̀ náà yóò ran ikọ̀ náà lọ́wọ́ lọ́pọ̀lọpọ̀ nínú ìdíje náà.
--- Roberto Mancini fẹnu kò pẹ̀lú àjọ FA láti tukọ̀ agbábọ́ọ̀lù orílẹ̀-èdè Italy.
Roberto Mancini ti fẹnu kò pẹ̀lú àjọ tó ń rí sí bọ́ọ̀lù àfẹsẹ̀gbá orílẹ̀-èdè Italy láti jẹ́ akọ́nimọ̀ọ́gbá àgbà ikọ̀ agbábọ́ọ̀lù orílẹ̀-èdè ọ̀hún.
Akọ́nimọ̀ọ́gbá àgbà ikọ̀ agbábọ́ọ̀lù Zenit St Petersburg náà, ṣe ìpàdé pọ̀ pẹ̀lú aṣojú àjọ FA orílẹ̀-èdè Italy, Alessandro Costacurta àti olùdarí àgbà ikọ̀ agbábọ́ọ̀lù náà, Gabriele Oriali fún wákàtí méjì gbáko nílùú Rome nírọ̀lẹ́ ọjọ́ Ajé.
"Gẹ́gẹ́ bí ilé-iṣẹ́ akọ̀ròyìn Gazzetta,""Mancini bọwọ́ lu ìwé láti ṣe iṣẹ́ ọlọ́dún méjì, èyí tí yóò mú un wà nínú ikọ̀ ọ̀hún títí di ọdún 2020, tí yóò sì máa gba mílíọ́nù mẹ́rin owó ilẹ̀ òkèrè euro lọ́dọọdún."
Gẹ́gẹ́ bí Mancini ṣe sọ, ó jẹ́ ohun ìwúrí fún mi lọ́pọ̀lọpọ̀ láti jẹ́ akọ́nimọ̀ọ́gbá àgbà ọ̀kan lára ikọ̀ agbábọ́ọ̀lù orílẹ̀-èdè tí ó lààmìlaaka jùlọ nínú eré bọ́ọ̀lù àfẹsẹ̀gbá lágbàáyé,
Ní báyìí, ìrètí wà pé, Mancini yóò bẹ̀ẹ̀rẹ̀ iṣẹ́ rẹ̀ ní kété tí ìdíje orílẹ̀-èdè Russia bá parí ní ọjọ́ kẹtàlá oṣù karùn-ún ọdún tí a wà yìí.
Ẹ̀wẹ̀, fún gbogbo sáà ọdún mẹ́tàdínlógún tí Mancini ti yan iṣẹ́ akọ́nimọ̀ọ́gbá láàyò, Ó tukọ̀ agbábọ́ọ̀lù Manchester City gba ife ẹ̀yẹ́ ìdíje ilẹ̀ Gẹ̀ẹ́sì EPL fún ìgbà àkọ́kọ́ lọ́dún mẹ́rìnlélógójì ní ọdún 2012.
Bẹ́ẹ̀ sì ni, Ó tún gba ife ẹ̀yẹ ìdíje Serie A mẹ́ta pẹ̀lú ikọ̀ agbábọ́ọ̀lù Inter Milan, tí ó sì tún tukọ̀ agbábọ́ọ̀lù Fiorentina àti Lazio.
Lára àwọn akọ́nimọ̀ọ́gbá mìíran tí wọ́n rò pé wọ́n kójú òṣùwọ̀n láti tukọ̀ ọ̀hún ni: Antonio Conte àti Claudio Ranieri.
--- Real Madrid pegedé sínú àṣekágbá ìdíje UEFA champions league.
Ikọ̀ agbábọ́ọ̀lu Real Madrid ti pegedé sínú aṣekágbá ìdíje UEFA champions league fún ìgbà kẹta léra wọn báyìí.
Èsì ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ ọ̀hún parí sí àmì-ayò méjì-méjì (2-2), tí àpapọ̀ àmì ayò náà sì jẹ́ àmì ayò mẹ́rin sí mẹ́ta (4-3).
Joshua Kimmich ló gbá àmì ayò kínní wọlé, tí Karim Benzema sì dá àmì- ayò ọ̀hún padà ní ìṣẹ́jú mẹ́jọ sí àmì ayò àkọ́kọ́.
Ẹ̀wẹ̀, ní kété tí sáà kejì ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ ọ̀hún bẹ̀ẹ̀rẹ̀, àṣìṣe aṣọ́lé ikọ̀ agbábọ́ọ̀lù Bayern, Sven Ulreich ni ó ṣokùnfà bí Benzema tún ṣe gbá àmì-ayò kejì wọlé.
Bí ó ti lẹ̀ jẹ́ pé, James Rodriguez gbá àmì ayò mìíràn wọ̀lé, ṣùgbọ́n omi pọ̀ju ọkà lọ.
Ní báyìí, Real Madrid yóò kojú ikọ̀ agbábọ́ọ̀lù tí ó bá jáwé olúborí nínú ikọ̀ agbábọ́ọ̀lù AS Roma tabi Liverpool, èyí tí yóò wáyé ní pápá ìṣeré Stadio Olympico nílùú Rome ní àṣálẹ́ ọjọ́rú.
--- Wọn yóò ṣàmúlò ẹ̀rọ ìgbàlódé VAR nínú ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ Nàìjííríà àti England - Pinnick
Ààrẹ àjọ tó ń rí sí bọ́ọ̀lù àfẹsẹ̀gbá lórílẹ̀-èdè Nàìjííríà, Amájù Pinnick, ti kéde pé, wọ́n yóò ṣàmúlò ẹ̀rọ ìgbàlódé Fọ́ńrán tí a mọ̀ sí, Video Assistant Referee (VAR) nínú ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ ọlọ́rẹ̀ẹ́jọ̀rẹ tí yóò wáyé láàrin ikọ̀ agbábọ́ọ̀lù Super Eagles àti orílẹ̀-èdè England lọ́sẹ̀ tó ń bọ̀ ní pápá ìṣeré Wembley.
Ẹ̀wẹ̀, ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ ọ̀hún yóò wáyé lọ́jọ́ kejì oṣù kẹfà ọdún tí a wà yìí, fún ìgbáradì ní kíkún ṣaájú ìdíje bọ́ọ̀lù àgbáyé tó ń bọ̀ lọ́nà.
Gẹ́gẹ́ bí Pinnick ṣe sọ, Wọn yóò ṣàmúlò ẹ̀rọ ìgbàlódé VAR nínú ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ ọlọ́rẹ̀ẹ́jọ̀rẹ wa pẹ̀lú orílẹ̀-èdè England.
"Bákan náà, akọ́nimọ̀ọ́gbá àgbà ikọ̀ ọ̀hún, Gernot Rohr náà bọwọ́lù ṣíṣe àmúlò ẹ̀rọ ìgbàlódé ọ̀hún pé, yóò ṣàtìlẹyìn ńlá fún olùdarí ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ náà.
--- Dalung fẹ́ kí ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀¸ ọlọ́rẹ̀ẹ́jọ̀rẹ Eagles àti DR Congo wáyé nílùú Abuja.
Mínísítà tó ń rí sí eré ìdárayá àti ìdàgbàsókè àwọn ọ̀dọ́ lórílẹ̀-èdè Nàìjííríà, Solomon Dalung, ti fi múlẹ̀ pé, ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ ọlọ́rẹ̀ẹ́jọ̀rẹ́ tí yóò wáyé láàrin ikọ̀ agbábọ́ọ̀lù Super Eagles àti Congo DR yóò wáyé ní pápá ìṣeré mìíràn, tí àtúnṣe tó ń lọ lọ́wọ́ ní pápá ìṣeré ìlú Abuja kò bá tíi wá sí ìparí kí ó tó di àsìkò ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ náà.
Dalung sọ ọ̀rọ̀ náà di mímọ̀ lásìkò tó ń bá àwọn akòròyìn sọ̀rọ̀, lẹ́yìn ayẹyẹ ìṣíṣọ lójú eégún ìdíje eré ìdárayá abẹ́lé tí yóò wáyé nílùú Abuja lọ́jọ́ Ajé.
Dalung fikún un pé, ìdí pàtàkì tí òun ṣe fẹ́ jẹ́ kí, ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ ọ̀hún kó wáyé nílùú Abuja, ni láti fi yẹ́ ikọ̀ Super Eagles sí, ṣaájú ìrìn àjò ikọ̀ ọ̀hún lọ sí orílẹ̀-èdè Russia fún ìdíje àgbáyé tó ń bọ̀ lọ́na, àti pé bóyá ààrẹ Muhammadu Buhari yóò wá yẹ́ ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ ọ̀hún sí.
Ní báyìí, A ń wo pápá ìṣeré ìlú Port Harcourt, tí àtúnṣe pápá ìṣeré ìlú Abuja kò bá tíi parí.
Ẹ̀wẹ̀, Super Eagles yóò máa gbáradì láti gbá ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ ọlọ́rẹ̀ẹ́jọ̀ré pẹ̀lú orílẹ̀-èdè Czech Republic, England àti DR Congo fún ìpalẹ̀mọ́ ìdíje àgbááyé náà."
--- Ó di dandan kí ìfigagbága pẹ̀lú Anthony Joshua kó wáyé – Wilder
Òǹdíje olùjà ọmọ orílẹ̀-èdè Amẹ́ríkà, Deontay Wilder sọ pé, òun kò lérò pé ìfigagbága pẹ̀lú Anthony Joshua kò ní wáyé, bí ó tilẹ̀ jé pé, òun kó àádọ́ta mílíọ́nù owó dọ́là sílẹ̀ fún ìfigagbága ọ̀hún, èyí tí ikọ̀ náà kọ̀ láti gbá.
Ní ọ̀sẹ̀ yìí, Wilder kó àádọ́ta mílíọ́nù owó dọ́là ($50m) sílẹ̀ fún Joshua láti figagbága pẹ̀lú rẹ̀, tí ó sì fi gbèdéke ọjọ́bọ (Thursday) sílẹ̀ láti ṣè’pinnu.
Bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé, Joshua gbà láti kojú Wilder, lẹ́yìn tí ó fẹnu kò pẹ̀lú rẹ̀ lórí ẹ̀rọ ayélujára Instagram, pàpàsíbẹ̀ ọjọ́ ìfigagbága ọ̀hún wáyé, tí ó sì tún ré kọjá lọ.
Ẹ̀wẹ̀, pẹ̀lú gbogbo ìdúnàádúrà ìfigagbága náà, Wilder ní ìgbàgbọ́ pé ìfigagbága ọ̀hún yóò sì wáyé.
--- Ancelotti kọ̀ láti ṣiṣẹ́ gẹ́gẹ́ bí akọ́nimọ̀ọ́gbá ikọ̀ agbábọ́ọ̀lù orílẹ̀-èdè Italy.
Gẹ́gẹ́ bí ilé-iṣẹ́ akọ̀ròyìn ṣe sọ lọ́jọ́ Àìkú (Sunday), wọ́n ní, Carlo Ancelotti ti kọ̀ láti ṣiṣẹ́ gẹ́gẹ́ bí akọ́nimọ̀ọ́gbá àgbà ikọ̀ agbábọ́ọ̀lù orílẹ̀-èdè Italy.
Ikọ̀ agbábọ́ọ̀lù Italy ti wà láìsí akọ́nimọ̀ọ́gbá kankan tí ó ń tukọ̀ ikọ̀ ọ̀hún láti oṣù mélòó kan sẹ́yìn, èyí tí ikọ̀ ọ̀hún ti gba iṣẹ́ lọ́wọ́ Gian Piero Ventura látàrí àìṣe déédé ikọ̀ náà, tí ikọ̀ ọ̀hún kò sì tún pegedé fún ife ẹ̀yẹ ìdíje àgbááyé tó ń bọ̀ lọ́nà yìí.
Ancelotti, tí ó jẹ́ akọ́nimọ̀ọ́gbá ikọ̀ agbábọ́ọ̀lu Bayern Munich tẹ́lẹ̀ rí, ṣe ìpàdé pọ̀ pẹ̀lú àwọn òṣìṣẹ́ àjọ tó ń rí sí bọ́ọ̀lù àfẹsẹ̀gbá orílẹ̀-èdè Italy ní Rome lósẹ̀ tí ó kọjá.
Gẹ́gẹ́ bí ilé-iṣẹ́ akọ̀ròyìn Corriere dello, wọ́n ní, bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé, ọmọ ọdún méjídínlọ́gọ́ta ọ̀hún fi ọjọ́ méjì ronú láti sọ ìpinnu rẹ̀, ṣùgbọ́n ibi pẹlẹbẹ náà lọ̀rọ̀ ọ̀hún jásí.
Bákan náà, ó ṣeéṣe kí ikọ̀ agbábọ́ọ̀lù Arsenal tún fiṣẹ́ akọ́nimọ̀ọ́gbá lọ Ancelotti, lẹ́yìn tí akọ́nimọ̀ọ́gbá ikọ̀ ọ̀hún Arsene Wenger ti pinnu láti fi ikọ̀ náà sílẹ̀ bí sáà yìí bá parí.
Ẹ̀we, oríṣiríṣi ikọ̀ agbábọ́ọ̀lù ni Ancelotti ti tukọ̀ rẹ̀, tí ó fimọ́ ife ẹ̀yẹ lọ́lọ́kan-ò-jọ̀kan, Ó tukọ̀ agbábọ́ọ̀lu Chelsea, Real Madrid, AC Milan, Juventus, Roma àti Paris Saint-Germain.
Bẹ́ẹ̀ sì ni Ó gba ife ẹ̀yẹ ìdíje Champions League mẹ́ta ni France, Germany àti England.
Àwọn akọ́nimọ̀ọ́gbá mìíràn tí àjọ ọ̀hún tún ní lọ́kàn láti pè ni: Roberto Mancini, Antonio Conte àti akọ́nimọ̀ọ́gbá ikọ̀ agbábọ́ọ̀lù Leicester rí, Claudio Ranieri, lẹ́ni tí ó ń tukọ̀ agbábọ́ọ̀lù Nantes báyìí.
--- Èsì ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ ìdíje orílẹ̀-èdè Nàìjííríà (NPFL).
--- Ìdíje NNL yóò bẹ̀ẹ̀rẹ̀ lọ́jọ́ Àbámẹ́ta.
Gẹ́gẹ́ bí ọ̀kan lára àwọn tọ́rọ̀ kàn gbòngbòn nínú ìgbìmọ̀ tó ń sàkóso ìdíje Nigeria National League (NNL), Lawrence Katken, sọ pé, ìdíje sáà 2017/2018 yóò bẹ̀ẹ̀rẹ̀ lọ́jọ́ Àbáméta.
Ìdíje ọ̀hún ni ìrètí wà tẹ́lẹ̀ pé, yóò bẹ̀ẹ̀rẹ̀ nínú oṣù kẹta ọdún yìí, ṣùgbọ́n wọ́n sún un síwájú látàrí àfikún àwọn ikọ̀ agbábọ́ọ̀lù mìíràn tí ó dara pọ̀ mọ́ ìdíje ọ̀hún.
Lọ́dún tó kọjá ikọ̀ agbábọ́ọ̀lù méjìlélọ́gbọ́n ló kópa nínú ìdíje yìí, ṣùgbọ́n lọ́dún yìí ikọ̀ agbábọ́ọ̀lù ogójì ni yóò kópa nínú ìdíje náà.
Àwọn ikọ̀ agbábọ́ọ̀lù tuntun ti yóò dara pọ̀ mọ́ ìdíje náà, ni ó wá láti inú ìdíje Nigeria Professional Football League (NPFL).
Bẹ́ẹ̀ sì ni àwọn mìíràn gbà ìgbéga láti inú ìdíje Nationwide League One (NLO), tí àwọn mìíràn sì ra ààyè ikọ̀ agbábọ́ọ̀lù mìíràn láti dara pọ̀ mọ́ ìdíje ọ̀hún.
Àwọn ikọ̀ agbábọ́ọ̀lù mìíràn ọ̀hún ni: Kada Football Club, Malumfashi FC, Bimo FC, Real Stars FC, Stores FC àti Rovers FC.
"Ó fikún un pé, ìgbìmọ̀ tó ń sàkóso ìdíje náà gbà láti jẹ́ kí àwọn ikọ̀ agbábọ́ọ̀lù tuntun darapọ̀ mọ́ ìdíje ọ̀hún, ní pàápàá jùlọ láti mú òfin mìíràn, èyí tí yóò dá ìdíje ọ̀hún dúró gbàrà tí ìdíje bọ́ọ̀lù àgbááyé bá bẹ̀ẹ̀rẹ̀.
A ṣe ìfilọ́lẹ̀ òfin tuntun náà láti fi àyè sílẹ̀ fún ìdíje bọ́ọ̀lù àgbááyé 2018tí yóò wáyé lórílẹ̀-èdè Russia.
A ó gba ìsinmi ráńpẹ́ ní kété tí ìdíje bọ́ọ̀lù àgbááyé bá bẹ̀ẹ̀rẹ̀, tí a ó sì bẹ̀ẹ̀rẹ̀ padà tí ìdíje náà bá wá sí ìparí.
--- Real Madrid fàgbà han Bayern pẹ̀lú àmì-ayò méjì sóókan.
--- Super Eagles yóò gbáradì ní kíkún fún ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ pẹ̀lú England - Mikel
Balógun ikọ̀ agbábọ́ọ̀lù Super Eagles, Mikel Obi sọ pé, Super Eagles gbáradì sílẹ̀ fún ìfẹsẹ̀wọnse ọlọ́rẹ̀ẹ́jọ̀rẹ́ tí ikọ̀ ọ̀hún yóò gbá pẹ̀lú orílẹ̀-èdè England, èyí tí yóò wáyé ní pápá ìṣeré Wembley nílùú London, lọ́jọ́ kejì inú oṣù kẹfà ọdún tí a wà yii.
Kò sí ọ̀nà mìíràn fún wa ju pé, kí á gbáradì ní kíkún sílẹ̀ fún ìdíje bọ́ọ̀lù àgbááyé náà tó ti ń súnmọ́ etílé.
Ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ ọlọ́rẹ̀ẹ́jọ̀rẹ́ ọ̀hún yóò wáyé ní ọ̀sẹ̀ méjì sí ìdíje FIFA bọ́ọ̀lù àgbááyé ọ̀hún.
Nàìjííríà yóò wàákò pẹ̀lú Croatia nínú ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ àkọ́kọ́ ìdíje àgbááyé ọ̀hún, ní pápá ìṣeré Kaliningrad lọ́jọ́ kẹrìndínlógún oṣù kẹfà ọdún tí a wà yìí.
Bákan náà, ìfigagbága pẹ̀lú Iceland yóò wáyé ní pápá ìṣeré Volgograd lọ́jọ́ kejìlélógún inú oṣù kẹ̀fà.
Ẹ̀wẹ̀, ìwé pélébé ìwòran fún ìfẹsèwọnsẹ̀ tí yóò wáyé láàrín England àti Nàìjíría ti wà lọ́jà fún títà báyìí, tí ìye rẹ̀ jẹ́ pounds márùndínlógójì (35 pounds) owó ilẹ̀ òkèrè.
--- Rohr Uzoho yóò fakọyọ nínú ìdije bọ́ọ̀lù àgbááyé.
Akọ́nimọ̀ọ́gbá àgbà ikọ̀ Super Eagles, Gernot Rohr fọwọ́ sọ̀yà pé, aṣọ́lé tuntun fún ikọ̀ Super Eagles Francis Uzoho yóò kópa dáradára nínú ìdíje bọ́ọ̀lù àgbááyé tó ń bọ̀ lọ́nà lórílẹ̀-èdè Russia.
Rohr sọ pé, Mi ò lérò pé, ìṣòro aṣọ́lé ni ikọ̀ Super Eagles ní láti ìgbà tí Carl Ikeme ti wà nípò àìsàn, a lérò pé ìṣòro aṣọ́lé ni a ní, ṣùgbọ́n Ikechukwu Ezenwa ṣe dáradára nínú àwọn ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ ìpegedé tí a gbá, pàpà síbẹ̀ a sì ń wà asọ́lé mìíràn.
Mi ò lérò pé Uzoho yóò ní ìṣòro kankan láti kojú irú agbábọ́ọ̀lù bi Messi àti àwọn agbábọ́ọ̀lù jàǹkànjàǹkàn mìíràn, nítorí pé lẹ́yìn tí ó kojú Lewandowski, Aguero àti Di Maria, Ó ṣe dáradára, èyí ni ó fún mi ní ìdánilójú pé yóò fakọyọ nínú ìdíje náà.
Ẹ̀wẹ̀, Rohr fikún ọ̀rọ̀ rẹ̀ pé, òun yóò ṣètò àpapọ̀ àgbábọ́ọ̀lù márùndínlógójì tí yóò kópa nínú ìdíje náà fún àjọ NFF lọ́jọ́ kẹrin oṣù karùn-ún ọdún tí a wà yìí."
--- Òpin sáà - Arsene Wenger yóò fi ipò rẹ̀ sílẹ̀ gẹ́gẹ́ bí akọ́nimọ̀ọ́gbá Arsenal.
Lẹ́yìn ọdún mejìlélógún ti akọnímọ̀ọ́gbá àgbà ikọ̀ agbábọ́ọ̀lù Arsenal, Arsene Wenger ti ń tukọ̀ ikọ̀ agbábọ́ọ̀lù ọ̀hún, Wenger ti kéde báyìí láti fi ikọ̀ náà sílẹ̀ lópin sáà tó ń lọ lọ́wọ́ yìí.
Mo dúpẹ́ lọ́pọ̀lọpọ̀ fún àǹfààní láti sin ikọ̀ yìí fún ọ̀pọ̀lọpọ̀ ọdún.
Mo tukọ̀ yìí tọkàn-tọkàn pẹ̀lú oyè kíkún.
Mo fé dúpẹ́ lọ́wọ́ àwọn òṣìṣẹ́, àwọn agbábọ́ọ̀lù, olùdarí gbogbo, àti pàápàá jùlọ àwọn olólùfẹ́ ikọ̀ yìí, fún àtìlẹyìn àti ìfẹ́ wọn tí ò lẹ́gbẹ̀ tí wọ́n fi hàn sí mi láti ìgbà tí mo ti ń tukọ̀ ikọ̀ yìí.
Mo rọ àwọn olólùfẹ́ wa láti túbọ̀ dúró ṣinṣin pẹ̀lú ikọ̀ yìí láti pàri sí ibi tí ó lápẹrẹ lórí tábìlì ní sáà yìí.
Sí àwọn olólùfẹ́ wa, ẹ ri dájú láti ṣe ìtọ́jú àwọn ohun ìní wa gbogbo.
Ifẹ́ mi àti àtìlẹyìn mi fún ikọ̀ yìí, yóò wà títí ayérayé.
--- Antonio Conte gbóríyìn fún Victor Moses.
Akọ́nimọ̀ọ́gbá àgbà ikọ̀ agbábọ́ọ̀lù Chelsea, Antonio Conte ti gbósùbà káreláí fún agbábọ́ọ̀lù rẹ̀ ọmọ bíbí àti agbábọ́ọ̀lù kan gbòógì nínú ikọ̀ Super Eagles Nàìjíríà, Victor Moses.
Moses gbá àmì ayò kan wọlè, tí ó sì ṣẹ̀ ìrànwọ́ àmì-ayò kan láti ran ikọ̀ agbábọ́ọ̀lù Chelsea lọ́wọ́ láti jáwé olúborí nínú ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ pẹ̀lú ikọ̀ agbábọ́ọ̀lù Burnley ní pápá ìṣeré Turf Moor.
Bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé, Ashley Barnes dá àmì-ayò kan padà, láti sọ èsì ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ ọ̀hún di àmì ayò kan sí méji (1-2), ṣùgbọ́n omi pọ̀ ju ọkà lọ.
"Gẹ́gẹ́ bí Antonio Conte ṣe sọ,""A kópa ribiribi lónìí, bẹ́ẹ̀ sì ni, a ní ẹ̀tó sí àmì mẹ́tẹ̀ẹ̀ta ọ̀hún, ní pàápàá jùlọ, Moses ṣe gudugudu méje ọ̀hún yààyà mẹ́fa, léyìn tí ó gbá àmì-ayò kan wọlé tó sì tún ṣe ìrànwọ́ àmì-ayò kan."
"Ẹ̀wẹ̀,"" jí jáwé olúborí nínú ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ ọ̀tọ̀ọ̀tọ̀ méji léra yóò ṣe ìrànwọ́ ńlá fún wa láti kópa dáradára nínú àwọn ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ wa mìíràn tó ń bọ̀ lọ́nà."
"Ní báyìí, Chelsea yóò lọ kojú Southampton nínú ìfigagbága ìpele kejì sí àṣekágbá ìdíje FA lọ́jọ́ Àìkú.
Fún àwọn eré ìdárayá mìíràn ní èdè Gẹ̀ẹ́sì kan síi.
--- Djoliba já MFM kúrò nínú ìdíje CAFCC.
Ikọ̀ agbábọ́ọ̀lù MFM FC tílù Èkó, lórílẹ̀-èdè Nàìjííríà ti jáde kúrò nínú ìdíje CAF Confederation Cup (CAFCC), bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé, èsì ìfigagbága ẹsẹ̀ kejì náà parí sí ọ̀mì ayò (0-0) pẹ̀lú ikọ̀ agbábọ́ọ̀lù Djoliba torílẹ̀-èdè Mali.
Ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ ọ̀hún wáyé ní pápá ìṣeré Modibo Keita ní Bamako, lẹ́yìn tí ikọ̀ agbábọ́ọ̀lù Djoliba ti fàgbà han MFC tẹ́lẹ̀ nínú ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ àkọ́kọ́ pẹ̀lú àmì ayò kan sóódo(1-0).
Bákan náà, oríṣiríṣi àǹfààní ni Oumar Kida, Siaka Bagayoko àti Mohammed Cisse pàdánù láti tún gbá àmì ayò wọlé.
Ẹ̀wẹ̀, ikọ̀ agbábọ́ọ̀lù Enyimba FC tìlú Abá nìkan ló kù tí yóò máa sojú orílẹ̀-èdè Nàìjííríà nínú ìdíje náà, lẹ́yìn tí ikọ̀ agbábọ́ọ̀lù Plateau United àti Akwa United ti já kúrò ṣaájú.
Plateau United pàdánù pẹ̀lú àmì-ayò mẹ́rin sóódo (4-0) sọ́wọ́ USM Alger torílẹ̀-èdè Algeria lọ́jọ́ Ìṣẹ́gun, tí àpapọ̀ èsì ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ ọ̀hún sì parí sí àmì ayò márùn-ún sí méji (5-2).
Bákan náà, bí ó tilẹ̀ jẹ́pé wọ́n jaẃé olúborí pẹ̀lú àmì ayò mẹ́ta sóókan nínú ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ ẹsẹ̀ kejì pẹ̀lú ikọ̀ agbábọ́ọ̀lù Al Hilal, ṣùgbọ́n ikọ̀ náà já kúrò nínú ìdíje ọ̀hún látàrí èsì ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ àkọ́kọ́, eléyìí tí ó parí sí àmì ayò méjì sóódo.
--- SWAN ẹ̀ka ìpínlẹ̀ Kwara ki Ọlárìnóyè kú oríire.
Ẹgbẹ́ tó ń rí sí ṣíṣe akọọ́lẹ̀ ọrọ eré ìdárayá ní Nàìjííríà, Sports Writers Association of Nigeria (SWAN), ti panupọ̀ pẹ̀lú ẹbí, ọ̀rẹ́, ará láti ki Dókítà Ayọ̀dèjì Ọlárìnóyè, kú oríire ìyànsípò tuntun gẹ́gẹ́ bí alákòóso ẹ̀tò ìlera àwọn agbábọ́ọ̀lù fún àjọ tó ń rí sí bọ́ọ̀lù àfẹsẹ̀gbá lágbàáyé FIFA Doping Control Officer (DCO), ẹni tí ó jẹ́ dókítà tí ó ń ṣàkóso ìlera ikọ̀ agbábọ́ọ̀lù ọ̀dọ́ Nàìjííríà tọ́jọ́ orí wọn kòju mẹ́tadínlógún lọ (Nigeria national Under-17 team).
SWAN sọ nínú ọ̀rọ̀ rẹ̀ èyí tí igbákejì akọ̀wé ẹgbẹ́ ọ̀hún, Abdulrosheed Okiki gbé jáde nílùú Ìlọrin pé, ìyànsípò dókítà náà níí ṣe pẹ̀lú iṣẹ́ takuntakun tí ó ń gbése àti àṣeyọrí rẹ̀ nínú ojúṣe tórílẹ̀-èdè yàn fún un.
SWAN fikún-un pe, ìyànsípò dókítà Ayọ̀dèjì Ọlárìnóyè ni ó jẹ́ àkọ́kọ́ ọmọ orílẹ̀-èdè Nàìjííríà tí yóò ṣe irú àṣeyọrí báyìí, bẹ́ẹ̀ sì ni wọ́n gbàdúrà pé Ọlọ́run yóò fún un ní ọgbọ́n àti òye láti kojú àwọn ìṣòro lọ́lọ́kan-ò-jọ̀kan bí ó bá ṣe ń wá sí iwájú rẹ̀.
Lára àṣeyọrí Dókítà Ọlárìnóyè tí SWAN tó kà sí, ni iṣẹ́ takuntakun rẹ̀ tí ó ṣe nínú ìdíje bọ́ọ̀lù àgbááyé tàwọn ọ̀dọ́ náà, tọdún 2013 àti 2015, èyí tí ikọ̀ Golden Eaglets gba ife-ẹ̀yẹ ìdíje ọ̀hún wálé.
Dókítà Ọlárìnóyè jẹ́ ọmọ bíbí adarí ẹ̀ka àwọn agbábọ́ọ̀lù ilẹ̀-òkèrè nínú àjọ NFF tẹ́lẹ̀rí, Dókítà Steve Ọlárìnóyè.
--- Ipo ̀atẹ FIFA: Nàìjííríạ̀ bọ́ sí ipò mẹ́tàdínláàdọ́ta lágbàáyé.
Nínú ipò àtẹ àjọ tó ń rí sí bọ́ọ̀lù àfẹsẹ̀gbá lágbàáyé FIFA, tí ó ṣẹ̀sẹ̀ jáde, Nàìjííríà bọ́ sí ipò mẹ́tàdínláàdọ́ta lágbàáyé, tí wọ́n sì di ipò kẹfà mú nílẹ̀ Áfíríkà pẹ̀lú àpapọ̀ àmì Òjìlélẹ́gbẹ̀ta-dín-márùn-ún tí ikọ̀ ọ̀hún ní.
Nínú ipò àtẹ kẹyiǹ tí ó jáde, Nàìjííríà wà ní ipò méjílélógójì lágbàáyé pẹ̀lú àmì ẹgbẹ̀wa-ó-lé mẹ́sàn-án lórí tábìlì.
Ẹ̀wẹ̀, orílẹ̀-èdè Tunisia ni ó wà lókè jùlọ ṣaájú orílẹ̀-èdè mìíràn nílẹ̀ Áfíríkà, lẹ́yìn tí wọ́n di ipò kẹrìnlá mú lágbàáyé, tí Senegal àti DR Congo sì di ipò méjídínlọ́gbọ̀n àti ipò méjídínlógójì ní ìtẹ̀léǹtẹ̀lé.
Germany sì dúro lókè téńté tábìlì ipò àtẹ lágbàáyé, tí Brazil sì tẹ̀lé wọn, Belgium bọ́ sí ipò kẹta láti ipò karùn-ún tí wọ́n wà tẹ́lẹ̀.
Bákan náà, àwọn orílẹ̀-èdè tí Nàìjííríà yóò máa wàákò pẹ̀lú nínú ìdíje bọ́ọ̀lù àgbááyé 2018 tó ń bọ̀ lọ́nà, Argentina, Croatia àti Iceland wà ní ipò karùn-ún, ipò kejìdínlógún àti ipò kejìlélógún ní ìtẹ̀lẹ́ǹtẹ̀lé.
Ipò àtẹ́ àjọ FIFA mìíràn yóò tún jáde lọ́jọ́ kẹtàdínlógún oṣù karùn-ún ọdún tí a wà yìí.
--- Real Madrid áti Bayern pegedé sípele kejì àṣekágbá ìdíje UEFA.
--- Pápá ìṣeré Jos yóò parí fún lílò nínú oṣù karùn-ún.
Adarí àgbà Ilé-iṣẹ́ ìkọ́lé, BCC Tropical Nig. Ltd, ọ̀gbẹ́ni Plamen Iliev, tó ń kọ́ pápá ìṣeré ultra-modern stadium nílùú Jos sọ pé, iṣẹ́ yóò parí lórí pápá ìṣeré ọ̀hún nínú oṣù karùn-ún ọdún tí a wà yìí.
Iliev sọ ọ̀rọ̀ ọ̀hún fún gómìnà ìpínlẹ̀ Plateau, Simon Lalong, lásìkò àbẹ̀wò rẹ̀ sí pápá ìṣeré náà, Ó sì fikún un pé gbogbo ohun èlò ni ìpèsè rẹ̀ ti wà nílẹ̀ báyìí láti kọ́ pápá ìṣeré ọ̀hún ní ìbámu pẹ̀lú ìlànà tí àjọ CAF fi sílẹ̀.
Ẹ̀wẹ̀, ikọ̀ agbábọ́ọ̀lù Pleateau United tí wọ́n wà lórí òkè téńté tábìlì ìdíje NPFL báyìí, ni àjọ CAF ti fòfin dè láti má se gbá ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ kankan lórí pápá náà, látàrí ipò tí ò bójú mu tí papa ìṣeré ọ̀hún wà báyìí, àyàfi bí wọ́n bá ṣàtúnṣe sí pápá ìṣeré náà, ní èyí tí iṣẹ́ sì ti ń lọ lórí rẹ̀ báyìí.
Àwọn olólùfẹ́ ikọ̀ agbábọ́ọ̀lù Pleateau united ti bu ẹnu àtẹ́ lu bí ikọ̀ náà ṣe pàdánu ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ ẹsẹ̀ kejì wọn nínú ìdíje CAF Champions League látàrí pápá ìṣeré ìpínlẹ̀ Kano tí ikọ̀ ọ̀hún ti lọ gbá ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ náà, èyí tí ó jìnà sí ilé wọn.
Ọ̀gbẹ́ni Iliev, tí ìsàkóso bí àtúnṣe yóò se bá pápá ìṣeré ọ̀hún wà lọ́wọ́ rẹ̀, ṣàlàyé fún gómìnà Simon Lalong pé, ìyàrá ìtúnraṣe (dressing room), àwọn àga ìjókòó (the seats), àwọn iyàrá ìgbọ̀nsẹ̀, balùwè àti bẹ́ẹ̀ bẹ́ẹ̀ lọ ni gbogbo rẹ̀ yóò ti wà ní títún ṣe kí ó tó di inú oṣù karùn-ún ọ̀hún.
Gómìnà Simon Lalong, sọ pé ìjọba yóò ri dájú láti mú àtúnṣe bá pápá ìṣeré ọ̀hún gẹ́gẹ́ bí ìlànà tí àjọ NPFL fi sílẹ̀ láti tẹ̀lé ṣaájú kí ìdíje CAF mìíràn ó tó bẹ̀ẹ̀rẹ̀.
--- Òǹdíje ọmọ orílẹ̀-èdè Cameroon márùn-ún sọnù ní Commonwealth Games.
Òǹdíje ọmọ orílẹ̀-èdè Cameroon márùn-ún tó ń kópa nínú ìdíje Commonwealth Games tó ń lọ lọ́wọ́ lórílẹ̀-èdè Australia, ni wọn kò rí mọ́ báyìí.
Gẹ́gẹ́ bí alákòóso ikọ̀ tó ń sojú Cameroon nínú ìdíje náà.
Ògbẹ́ni Victor Agbor Nso, ṣe sọ lásìkò tó ń bá àwọn akọ̀rọ̀yìn CRTV sọ̀rọ̀ lọ́jọ́ Ìṣẹ́gun, Nso sọ pé, òǹdíje nínú ìrin gbígbé, Olivier Matam, oluja Ndzie Tchoyi àti Simplice Fotsala ni wọ́n yẹ kí wọ́n figagbága lọjọ́ Ìṣẹ́gun (Tuesday), ṣùgbọ́n tí wọn kò rí wọn.
Nso fikún ọ̀rọ̀ rẹ̀ pé, àwọn òǹdíje olùgbé irin mìíràn, tí a mọ̀ sí (weightlifters), Aka Angeline Filji ati Mikoumba Petit David, ni wọn kò rí ní Gold Coast.
Sụ̀gbọ́n, ní báyìí ọ̀rọ̀ ọ̀hún ti wà lọ́wọ́ àwọn ọlọ́pàá Australia.
Nso tẹnu mọ́ ọn pé, A ti fi ọ̀rọ̀ ọ̀hún tó àwọn tọ́rọ̀ọ́ kàn gbangban tí ó rán wa wábí létí, tí àjọ tó ń rí sí eré ìdárayá, tí ó fi mọ́ ààrẹ ìgbìmọ̀ tó ń rí sí ṣísàkóso ìdíje Olympic ní Cameroon (National Olympic Committee of Cameroon)""."
Bákan náà, ni a ti ṣe ohun tí ó tọ́, láti fi ọ̀rọ̀ náà tó àwọn agbófinró létí ti Australia.
"Ẹ̀wẹ̀, ìròyìn fi múlẹ̀ pé, èyí kìí ṣe ìgbà àkọ́kọ́ tí àwọn òǹdíje aṣojú orílẹ̀-èdè Cameroon yóò sọnù nínú irúfẹ́ ìdíje báyìí.
Lọ́dún 2012, òǹdíje márùn-ún nínú ìfigagbága ìjà (five male boxers), agbábọ́ọ̀lù obìnrin kan àti olụ̀wẹ̀ ọkùnrin kan ni wọ́n di àwátì nílùú London.
--- Jurgen Klopp-Ìdíje Champions League ní ń ṣe pẹ̀lú èsì.
Akọ́nimọ̀ọ́gbá àgbà ikọ̀ agbábọ́ọ̀lù Liverpool, Jurgen Klopp ti gbósùbà káreláí fún ikọ̀ rẹ̀ lẹ́yìn tí wọ́n já ikọ̀ agbábọ́ọ̀lù akẹẹgbẹ́ wọn Manchester City kúrò nínú ìdíje Uefa Champions League pẹ̀lú àmì-ayò méjì sóókan (2-1), láti pegedé sípele kejì sí àṣekágbá ìdíje ọ̀hún.
Lẹ́yìn tí Liverpool jáwé olúborí nínú ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ àkọ́kọ́ pẹ̀lú àmì-ayò mẹ́ta sóódo (3-0) ní pápá ìṣeré Anfield.
Bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé, City gbá àmì-ayò kínní wọlé ní kété tí ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ ọ̀hún bẹ̀ẹ̀rẹ̀, ṣùgbọ́n omi pọ̀ ju ọkà lọ, lẹ́yìn tí Liverpool dá àmì-ayò méjì padà gbàrà tí sáà kejì ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ náà bẹ̀ẹ̀rẹ̀ ní pápá ìṣeré Etihad Stadium.
Gẹ́gẹ́ bí Klopp ṣe sọ,Inú mí ò dùn rárá fún bí a ṣe kópa ní sáà kínní ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ ọ̀hún."
"A ò ṣe dáradára rárá, ṣùgbọ́n Mo bá àwọn agbábọ́ọ̀lù mi sọ̀rọ̀ láti pa ọkàn pọ̀ sójú kan, inú mí sì dùn pé a jáwé olúborí níkẹyìn!""Ìdíje Uefa Champions League kò nííṣe pẹ̀lú bí ikọ̀ agbábọ́ọ̀lù ṣe dára sí tàbí ṣe kópa si, bí kì í bá ṣe èsì ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ tí ó bá wáyé lẹ́yìn sáà ìfigagbága méjèèjì,"
Ní báyìí, ikọ̀ agbábọ́ọ̀lù Real madrid yóò gbàlejò Juventus ni pápá ìṣeré Santiago, bẹ́ẹ̀ sì ni, Bayern Munich yóò gbàlejò Sevila ní pápá ìṣeré Alliance Arena.
--- Oyema fakọ yọ nínú ìwe-ìtàn, Ezuruike, Ndidi gbà àmì-ẹ̀yẹ góòlù.
Ikọ̀ Nàìjííríà ń kópa ribiribi nínú ìdíje Commonwealth games tó ń lọ lọ́wọ́ lórílẹ̀-èdè Australia.
Esther Oyema fìtàn balẹ̀ lágbàáyé nínú eré ìdárayá irin gbígbé (Para powerlifter), Ó fìtàn balẹ̀ lẹ́yìn tí ó gba àmì-ẹ̀yẹ góòlù ṣaájú àwọn akẹẹgbẹ́ rẹ̀ tí wọ́n jọ kópa.
Oyema gbé ìkún irin tí ó lé lọ́kànlélógóje Kílò (141.6kg), ṣaájú akẹẹgbẹ́ rẹ̀ Lucy Ejike, tí ó gbé ìkùn irin tí ó lé lọ́kànléláàádóje Kílò (131.4kg).
Bákan náà, nínú ẹ̀ka irin gbígbé tàwọn ọkùnrin, Roland Ezuruike tukọ̀ Nàìjííríà gba àmì-ẹ̀yẹ góòlù, lẹ́yìn tí ó gbé ìkún irin ìwọ̀n tí ó lé lókòólénígba-ó-lé-mẹ́rin Kílò (224.3kg).
Akẹẹgbẹ́ rẹ̀, Paul Kẹ́hìndé gba àmì-ẹ̀yẹ ipò kẹta tí ń ṣe, silver lẹ́yìn tí ó gbé ìkún irin ìwọ̀n tí ó le lókòólénígbadínkan Kílò (219.9kg).
Ẹ̀wẹ̀, ní ẹ̀ka irin wúwo gbígbé, Ndidi Nwosu gba àmì-ẹyẹ góòlù láti sọ àpapọ̀ àmì-ẹyẹ ikọ̀ Nàìjííríà di mẹ́jọ, góòlù mẹ́rin àti Silver mẹ́rin lápapọ̀.
--- Harry Kane: Ìrètí wà pé màá bá Salah láìpẹ́.
Agbábọ́ọ̀lù ọwọ́ iwájú fún ikọ̀ agbábọ́ọ̀lù Tottenham Hotspur, Harry Kane ní ìrètí pé láìpẹ́ láìjìnà òun yóò ṣaájú akẹẹgbẹ́ rẹ̀ tó ń kópa fún ikọ̀ agbábọ́ọ̀lù Liverpool FC, Mohamed Salah nínú ìdíje dupò agbábọ́ọ̀lù tí yóò gba bọ́ọ̀lù ṣágbọ̀n jùlọ (Golden Boot award) nínú ìdíje bọ́ọ̀lù ilé Gẹ̀ẹ́sí (English Premier League) ti sáà 2017/2018 tó ń lọ lọ́wọ́ yìí.
Bákan náà, ní kane tún ń gbérò láti ran ikọ̀ àgbábọ́ọ̀lù rẹ̀ lọ́wọ́ láti parí ìdíje sáà EPL tọdún yìí sípò tí ó dára lórí tábìlì, bẹ́ẹ̀ sì ni.
Kane ń gbèrò láti parí ìdíje sáà yìí gẹ́gẹ́ bí agbábọ́ọ̀lù tí ó gbá bọ́ọ̀lù ságbọ̀n jùlọ fún ìgbà kẹta léra wọn.
Gẹ́gẹ́ bí Kane ṣe sọ lásìkò tó ń bá àwọn akọ̀ròyìn sọ̀rọ̀, Mo ní ìgbàgbọ́ pé mo ṣì lè ṣe é, tí mo bá le pa ọkàn pọ̀ nínú àwọn ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ tí ó kù.
Spurs yóò máa wàákò pẹ̀lú ikọ̀ agbábọ́ọ̀lù Manchester City nínú ìdíje EPL lọ́jọ́ Àìkú, oṣù kẹrin, kí wọn ó tó kojú ikọ̀ Manchester United nínú ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ ipele kejì sí àṣekágbá ìdíje FA Cup.
--- Ìfigagbága ipele kẹta sí àṣekágbá ìdíje UEFA Champions League.
--- Ahmed Musa, Moses Simon dara pọ̀ mọ́ ìgbìmọ̀ tó ń ṣàkóso DW sports.
Ahmed Musa àti akẹẹgbẹ́ rẹ̀ Moses Simon ti dara pọ̀ mọ́ ìgbìmọ̀ tó ń ṣàkóso DW sports.
Ní báyìí èyí túmọ̀ sí pé, àwọn méjéèjì yóò wà lára ìṣàkóṣo kátàkára ikọ̀ agbábọ́ọ̀lù tí àwọn agbábọ́ọ̀lù bá fẹ́ kópa fún.
Ẹ̀wẹ̀, látàrí dídara pọ̀ mọ́ ìgbìmọ̀ iṣàkóso DW sport ọ̀hún, èyí ló fòpin sí ìbáṣepọ̀ Musa àti Tony Harris, lẹ́ni tí ìṣàkóso kátàkárà Ahmed Musa láti dara pọ̀ mọ́ ikọ̀ agbábọ́ọ̀lù lóríṣiríṣi wà lọ́wọ́ rẹ̀, bẹ̀ẹ̀rẹ̀ láti ìgbà tí ó kúrò nínú ikọ̀ agbábóòlù Kano Pillars lọ sí ilẹ̀ òkèrè.
Bákan náà, Moses Simon wà lábẹ́ ìṣàkóso kátàkára Tony Harris.
DW sports fi ìdùnnú wọn hàn láti ní ìbáṣepọ̀ pẹ̀lú àwọn agbábọ́ọ̀lù méjèèjì lórí ẹ̀rọ ayélujára Twitter wọn.
Dídara pọ̀ mọ́ ìgbìmọ̀ ọ̀hún ni yóò di agbábọ́ọ̀lù Super Eagles méje tí yóò máa ṣiṣẹ́ papọ̀ pẹ̀lú DW sports.
Àwọn agbábọ́ọ̀lù Super Eagles mìíràn tí wọ́n jọ máa ṣiṣẹ́ papọ̀ báyìí ni: Bryan Ìdòwú, Shehu Abdulahi, Henry Onyekuru, Oghenekaro Etebo, àti Mikel Agu.
--- Ikọ̀ mẹ́rìnlélọ́gọ́ta (64) yóò kópa nínú eré ìdíje bọ́ọ̀lù Mike Okonkwo.
Ikọ̀ agbábọ́ọ̀lù mẹ́rìnlélọ́gọ́ta ni wọ́n ti bọwọ́ lù báyìí pé wọn yóò kópa nínú eré ìdíje bọ́ọ̀lù Bishop Mike Okonkwo Football Championship 2018, èyí tí yóò wáyé ní pápá ìṣeré National Stadium tìlú Èkó, bẹ̀ẹ̀rẹ̀ lọ́jọ́ karùn-ún oṣù karùn-ún ọdún tí a wà yìí.
Gẹ́gẹ́ bí àwọn tí ó ṣagbátẹrù ìdíje náà, ìdíje ọ̀hún ni ikọ̀ agbábọ́ọ̀lù obìnrin ọ̀tọ̀ọ̀tọ̀ mẹ́jọ yóò kópa nínú rẹ̀ fún ìgbà àkọ́kọ́.
Gẹ́gẹ́ bí alága ìgbìmọ́ tí ó ṣagbátẹrù ìdíje ọ̀hún, ọgbẹ́ni Malachy Ndubuzor, Ó ṣe é lálàyé pé, wọn yóò ríi dájú láti fojú sílẹ̀ mú àwọn agbábọ́ọ̀lù tí ó bá fakọyọ nínú ìdíje náà sínú ikọ̀ agbábọ́ọ̀lù TREM Football Academy.
Àṣekágbá ìdíje ẹ̀ka méjéèjì, tí ń ṣe ikọ̀ ọkùnrin àti tobìnrin, yóò wáyé ní ilé-ìwé gíga fáfìti onímọ̀-ẹ̀rọ̀ Yaba College of Technology lọ́jọ́ kínní oṣù kẹsàn-án ọdún tí a wà yìí nílùú Èkó.
"Agbábọ́ọ̀lù ikọ̀ Super Eagles tẹ́lẹ̀rí, Waheed Akanni, tí ó jẹ́ àlejò pàtàkì lásìkò ìyíkoto ìfigagbága ìdíje ọ̀hún, gbórìyìn púpọ̀ fún Bishop Mike Okonkwo fun akitiyan tó ń kò láti gbé ìdíje ọ̀hún lárugẹ lọ́dọọdún.
Ò fikún-un pé, ìdíje ọ̀hún yóò ṣe ìrànwọ́ láti ṣàwárí àwọn ọ̀dọ́ tí ò lẹ́bùn eré bọ́ọ̀lù àfẹsẹ̀gbá.
--- Arsenal, Atletico gbé ẹnu lé ìpele kejì sí àṣekágbá Europa League.
Ikọ̀ agbábọ́ọ̀lù Arsenal kópa dáradára nínú ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ ìpele kẹta sí àṣekágbá ìdíje Europa League, lẹ́yìn tí ó fàgbà han ikọ̀ agbábọ́ọ̀lù CSKA Moscow pẹ̀lú àmì-ayò mẹ́rin sóókan (4-1) nínú ìfigagbága àkọ́kọ́ ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ náà, bákan náà sì ni, ikọ̀ agbábọ́ọ̀lù Atletico Madrid kò gbẹ́yìn, lẹ́yìn tí ikọ̀ ọ̀hún náà fàgbà han Sporting Lisbon pẹ̀lú àmì-ayò méjì sóódo (2-0) lọ́jọ́bọ (Thursday).
Ikọ̀ agbábọ́ọ̀lù Lazio náà gbo ewúro sójú Salzburg pẹ̀lú àmì-ayò mẹ́rin sí méji (4-2), bẹ́ẹ̀ sì ni ikọ̀ agbábọ́ọ̀lù RB Leipzig fạ̀gbạ̀ han Olympique de Marseille pẹ̀lú àmì-ayò kan sóódo (1-0).
Koke gbá àmì-ayò kínní wolé níṣẹ̀ẹ́jú péréte tí ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ ọ̀hún bẹ̀ẹ̀rẹ̀, kí Antoine Griezmann kó tó fọba lé e kí sáà àkọ́kọ́ ó tó wá sí ìparí.
--- Commonwealth 2018: Nàìjííríà fàgbà han Malaysia nínú ìfigagbága bọ́ọ̀lù orí tábìlì.
Ikọ̀ agbábọ́ọ̀lù orí tábílì Nàìjííríà ti bẹ̀ẹ̀rẹ̀ ìfigagbága wọn nínú ìdíje Commonwealth Games tó ń lọ lọ́wọ́ lórílẹ̀-èdè Australia.
Ikọ̀ Nàìjííríà fàgbà han Malaysia àti Belize nínú ìfigagbága àkọ́kọ́ tí ó wáyé lọ́jọ́bọ̀.
Olájídé Ọmọ́táyò fàgbà han Chee Feng olùkópa fún Malaysia pẹ̀lú àmì-ayò mẹ́tàlá sí mọ́kànlà (13-11), márùndínlógún sí mẹ́tàlá (15-13), mọ́kànlá sí méje (11-7) ní ìtẹ̀léǹtẹ̀lé.
Ní báyìí, Abiodun yóò lọ kojú Javen Choong láti Malaysia àti Terry Su láti Belize, bẹ́ẹ̀ sì ni Jamiu náà yóò lọ kojú Rohit Pagarani láti Belize.
Ìdíje Commonwealth Games yìí, ni yóò di ìgbạ̀ kẹtàlá tí Nàìjíírìà yóò kọpà nínú rẹ̀ láti ọdún 1950.
Ẹ̀wẹ̀, ikọ̀ Nàìjííríà yóò máa fojú sọ́nà láti tún fìtàn mìíràn balẹ̀ tí yóò kọjá èyí tí orílẹ̀-èdè ọ̀hún ní tẹ́lẹ̀ nínú irúfẹ̀ ìdíje náà tí ó wáyé lọ́dún 1994 ní Canada, lẹ́yìn tí wọ́n gba àmì-ẹ̀yẹ mẹ́tàdínlógójì nínú ìdíje náà.
Bákan náà, nínú ìdíje Commonwealth Games tí ó wáyé ní Glasgow, lórílẹ̀-èdè Scotland lọdún 2014, Nàìjííríà gba àmì-ẹ̀yẹ mẹ́rìndínlógójì, tí ń ṣe (11 Gold, 11 silver ati 14 bronze).
Ní ìparí, ìdíje Commonwealth 2018 ọ̀hún tí ó bẹ̀ẹ̀rẹ̀ lọ́jọ́rú, ní ìrètí wà pé yóò parí lọ́jọ́ karùndínlógún oṣù kẹrin ọdún tí a wà yìí.
--- Sally Pearson: Ìbànújẹ́ ló jẹ́ pé mi ò ní tẹ̀síwájú nínú ìdíje Commonwealth.
Sally Pearson ọmọbíbí orílẹ̀-èdè Australia, tí ó tún jẹ olùkópa tí ó dára jùlọ lágbàáyé nínú eré sísá hurdles ni kò ní tẹ̀síwájú nínú ìdìjé Commonwealth Games tó ń lọ lọ́wọ́ látàrí ìfarapa tí ó ní lẹ́sẹ̀, léyìí tí ó sì mú yébà kíkópa nínú eré-ìdárayá ọ̀hún fún ọ̀dún kan.
--- Dalung rọ ikọ̀ Nàìjííríà láti lọ fakọyọ nínú ìdíje Commonwealth.
Mínísítà tó ń rí sí eré-ìdárayá àti ìdàgbàsóke àwọn ọ̀dọ́ ní Nàìjììríà, ọ̀gbẹ́ni Solomon Dalung, ti rọ ikọ̀ Nàìjííríà tí yóò lọ sojú nínú onírúurú ìdíje eré-ìdárayá Commonwealth Games tí yóò wáyé lórílẹ̀-èdè Australia láti kópa dáradára.
Nínú ọ̀rọ̀ àgbélẹ̀kọ̀ rẹ̀, èyí tí àmúgbálẹ́gbẹ̀ẹ́ pàtàkì sí mínísítà ọ̀hún ní ẹ̀ka ìròyìn àti ọ̀rọ̀ ìfitóniléti ṣe sọ, ogbeni Nneka Ikem-Anibeze, Ó ní, mínísítà gbà wọ́n níyànjú láti lọ sojú orílẹ̀-èdè Nàìjííríà dáradára.
Ò sọ̀rọ̀ náà di mímọ̀ ní kété tí wọ́n parí ayẹyẹ ìṣíṣọ lójú eégún láti bẹ̀ẹ̀rẹ̀ ìdíje ọ̀hún, tí wọ́n sì kéde ikọ̀ tí yóò máa sojú Nàìjííríà.
Mo ríi pé, ẹ ti ń fojú sọ́nà láti bẹ̀ẹ̀rẹ̀ síní ń kópa, léyìí tí ó fara hàn pé, ẹ ti gbáradì lọ́pọ̀lọpọ̀ fún ìdíje yìí.
Ni fikún un pé, ìrètí ààrẹ Buhari ni láti ríi pé, orúkọ Nàìjííríà gòkè àgbà, kí orílẹ̀-èdè ọ̀hún sì fakọyọ nínú ìdíje náà.
Ayẹyẹ ìṣíṣọ lójú eégún ọ̀hún ni ó wáyé láti ṣe ìkíni káàbọ̀ àwọn ikọ̀ orílẹ̀-èdè kọ̀ọ̀kan tí yóò máa kópa nínú ìdíje ọ̀hún pẹ̀lú orin, ìlù àti ijó látọwọ́ ẹgbẹ́ oníjó Munujali.
Ẹ̀wẹ̀, olùkópa tí ó bá gba àmì-ẹ̀yẹ góòlù (Gold) yóò láǹfààní sí ẹ̀ẹ́dẹ́gbààta owó dọ́là ($5,000), àmì-ẹ̀yẹ̀ ipò kejì (Silver) yóò gba ẹ̀ẹ́dẹ́gbàajì owó dọ́là ($3,000), bẹ́ẹ̀ sìni àmì-ẹ̀yẹ ipò kẹta (bronze) yóò gba ẹgbàá owó dọ́là ($2,000).
Lára àwọn ènìyàn jàǹkànjàǹkàn tí ó tún yẹ́ ayẹyẹ ìdíje ọ̀hún sí la ti rí aṣojú Nàìjííríà sórílẹ̀-èdè Australia, ọ̀gbẹ́ni Bello Husseini , bẹ́ẹ̀ sì ni ààrẹ tẹ́lerí àti ààrẹ tí ó wà lórí àléfà báyìí ti ìgbìmọ̀ tó ń rí sí ìdíje Olympic ní Nàìjííríà Nigeria Olympic Committee (NOC), náà kò gbẹ́yìn, Sani Ndanusa àti Habu Gumel.
Ayẹyẹ láti bẹ̀ẹ̀rẹ̀ ìdíje XXI Commonwealth Games náà yóò wáyé láago méje ọjọ́rùú, ní pápá ìṣeré Carrara ní Gold Coast, Australia.
--- Cristiano Ronaldo dúpé lọ́wọ́ àwọn olólùfẹ́ Juventus.
--- Ìfẹsẹ̀wọ̀nṣẹ̀ ìdíje bọ́ọ̀lù àfẹsẹ̀gbá NPFL tí yóò wáyé lónìí.
Èyí ni àwọn ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ tí yóò máa wáyé nínú ìdíje orílẹ̀-èdè Nàìjííríà NPFL lónìí:
--- West Brom àti Alan Pardew fẹnu kò láti fòpin sí ìbaṣepọ̀ wọn.
Pardew ni ikọ̀ ọ̀hún gbà ní oṣù mẹ́rin sẹ́yìn ní ìrètí pé yóò mú àyípadà ọ̀tun dé bá ikọ̀ náà lórí tábìlì ìdíje (EPL), ṣùgbọ́n omi pọ̀ ju ọkà lọ.
--- Ògúnbọ̀wálé, Azubuike rán ikọ̀ wọn lọ́wọ́ láti jáwé olúborí.
Àríkẹ́ Ògúnbọ̀wálé ran ikọ̀ agbábọ́ọ̀lù àfọ́wọ́gbá rẹ̀ Notre Dame láti gba ife-ẹ̀yẹ ìdíje National Collegiate Athletic Association (NCAA) tọdún 2018 pẹ̀lú àmì-ayò ọ̀kànlélọ́gọ́ta sí mẹ́jìdínlọ́gọ́ta (61-58) láti fàgbà han Mississippi State.
Ẹ̀wẹ̀, ìṣẹ́jú péréte díẹ̀ tókù kí ìfigagbága ọ̀hún wá sí ìparí ni Ògúnbọ̀wálé ju bọ́ọ̀lù wọlé sínú agbọ̀n Mississippi State láti ran Notre Dame lọ́wọ́ gba ife-ẹ̀yẹ ìdíje NCAA tàwọn obìnrin àkọ́kọ́ láti ọdún 2001, èyí tí ó sì di èèkejì irú rẹ̀ tí ikọ̀ ọ̀hún ti gbà báyìí.
Lẹ́yìn tí ikọ̀ ọ̀hún fàgbà han Connect cut lọ́jọ́ Ẹtì (Friday) nínú ìpele kejì sí àṣekágbá ìdíje náà, jíjáwé olúborí lọ́jọ́ Àìkú Sunday nínú àṣekágbá ìdíje náà jẹ́ ohun ìyàlẹ́nu tí ó sì tún fìtàn balẹ̀ nínú ìwé ìtàn ìdije náà.
Ògúnbọ̀wálé sọ pé,Láti ṣe irú eléyìí nínú ọ̀sẹ̀ kan péré, ó jẹ́ ohun ìtàn nínú ìdíje bọ́ọ̀lù àfọwọ́gbá yìí,"" Ògúnbọ̀wálé ju bọ́ọ̀lù àmì mẹ́tàdínlọ́gbọ̀n wọlé nínú ìpele kejì àṣekágbá ọ̀hún lọ́jọ́ Ẹti ̀(Friday), léyìí tí ó mú un gba àmì-ẹ̀yẹ olùkópa tí ó tayo jùlọ nínú ìdíje ọ̀hún."
Mo ti gbáradì púpọ̀ fún irú àkókò yìí, ọ̀pọ̀ olùkópa ló ń fẹ́ láti lọ́wọ́ nínú àmì-ayò tí yóò ran ikọ̀ rẹ̀ lọ́wọ́ gba ife-ẹ̀yẹ, ṣùgbọ́n gbígbáradì ṣaájú ìfigagbága ṣe pàtàkì.
"Bàbá Ògúnbọ̀wálé, Gregory, jẹ́ ọmọbíbí Nàìjííríà, tí ó sì fẹ́ràn bọ́ọ̀lù àfẹsẹ̀gbá àti bọ́ọ̀lù àfọwọ́gbá (rugby), bẹ́ẹ̀ sìni ìyá rẹ̀, Yolanda, jé ọmo bíbí Amẹ́ríkà tí ó sì tún jẹ́ olùkọ́.
Bákan náà, nínú irúfẹ́ ìdíje NCAA tàwọn ọkùnrin, ikọ̀ agbábọ́ọ̀lù Kansas, tí Udoka Azubuike ǹ kópa fún, pàdánù ìpele kejì sí àṣekágbá ìdíje ọ̀hún sọ́wọ́ Villanova pẹ̀lú àmì-ayò márùndínlọ́gọ́rùn-ún sí mọ́kàndínlọ́górin (95-79).
--- Ẹ̀kọ́ ńlá ni pípàdánù sọ́wọ́ Serbia jẹ́ fún wa – Dalung
Mínísítà tó ń rí sí eré ìdárayá àti ìdàgbàsókè eré ìdárayá ní Nàìjíríà, Solomon Dalung sọ pé, inú ìjọba kò bàjẹ́ rárá látàrí pípàdánù ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ ọlọ́rẹ̀ẹ́jọ̀ré kejì sọ́wọ́ Serbia lọ́jọ́ Ìṣẹ́gun (Tuesday).
Mínísítà sọ̀rọ̀ náà di mímọ̀ fún àwọn akọ̀ròyìn lẹ́yìn ìpàdé àpérò ìgbìmọ̀ ìjọba tọ́rọ̀ kàn gbàngbàn Federal Executive Council (FEC) tí wọ́n ṣe pẹ̀lú ààrẹ Muhammadu Buhari.
Gẹ́gẹ́ bí Ó ṣe sọ, Ó ní, pípàdánù ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ náà ṣe àfihàn àwọn kùdìẹ̀-kudiẹ tó kù fún akọ́nimọ̀ọ́gbá ikọ̀ náà àti àwọn òṣìṣẹ́ àjọ NFF ní láti ṣe ṣáájú ìdíje àgbááyé ọ̀hún tó ń bọ̀ lọ́nà.
Bóyá ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ Super Eagles ọ̀hún tẹ́milọ́rùn tàbí kò tẹ́milọ́rùn, tèmi ni pé, mo ní ìgboyà fún ikọ̀ náà.
Bí a ṣe pegedé fún ìdíje àgbááyé yìí kò rọrùn rárá, bẹ́ẹ̀ sì ni a kò le máa jáwé olúborí nínú gbogbo ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ wa.
--- Diego Costa- Olùgbàlà ni Messi jẹ́ fún Argentina.
Atamátàsé ikọ̀ agbábọ́ọ̀lù Atletico Madrid, tí ó tún ń kópa fún Spain, Diego Costa ti rọ Argentina láti dúpẹ́ pé ikọ̀ náà ní agbábọ́ọ̀lù bí Lionel Messi nínú ikọ̀ ọ̀hún.
Diego Costa ní ìgbàgbọ́ pé, jíjáwé olúborí Spain nínú ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ ọlọ́rẹ̀ẹ́jọ̀rẹ́ pẹ̀lú Argentina láìsí atamátàsé ọ̀hún, Messi nínú ikọ̀ náà ṣe àfihàn bí Messi ṣe ṣe pàtàkì fún Argentina tó.
Spain fàgbà han Argentina pẹ̀lú àmì-ayò mẹ́fà sóókan (6-1), tí àwọn ayò ọ̀hún sì wá láti ọwọ́: Costa, Thiago Alcantara, Iago Aspas áti Isco tí ó gbá àmì-ayò mẹ́ta wọlé.
Bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé, ọ̀pọ̀ ló ń bu ẹnu àtẹ́ lu Messi pé, kò tíì kópa dáradára tó fún orílẹ̀-èdè rẹ̀ bí ó ṣe máa ń gbá bọ́ọ̀lu fún ikọ̀ kejì tí ń ṣe Barcelona, ṣùgbọ́n ní báyìí, Costa rọ àwọn olólùfẹ́ ikọ̀ agbábọ́ọ̀lù Argentina láti dúpẹ́ pé wọ́n ní Messi láàárín wọn, tí ó sì fikún ọ̀rọ̀ rẹ̀ pé, ipa Messi nínú ikọ̀ náà kò ṣe é yẹ̀ sílẹ̀ rárá.
Costa sọ pé, Ó fara hàn gbangba gbangba pé, bí Messi kò bá kópa nínú ikọ̀ Argentina, ó máa ń nira fún ikọ̀ ọ̀hún láti ṣiṣẹ́ pọ́, léyìí tí ó wà lára bí a ṣe fàgbà hàn wọ́n pẹ̀lú àmì-ayò tí ó tóyìí.
irú agbábọ́ọ̀lù bí Messi kò ṣe é bu ẹnu àtẹ́ lú."
Ó yẹ kí wọ́n máa dúpẹ́ pé wọ́n ní Messi lára wọn ni.
Ẹ̀wẹ̀, inú Costa dùn púpọ̀ láti padà sínú ikọ̀ Spain, lẹ́yìn tí o kópa fún ikọ̀ náà lásìkò àwọn ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ ìpegedé fún ìdíje àgbááyé náà látàrí wàhálà tí ó kojú lásìkò rẹ̀ nínú ikọ̀ agbábọ́ọ̀lù Chelsea.
--- Ìpínlẹ̀ Kano mú ìgbèrú bá ikọ̀ àgbábọ́ọ̀lù mọ́kànlélógójì (41).
Ìjọba ìpínlẹ̀ Kano ti ṣe ìtọrẹ mílíọ́nù mẹ́tàlá ààbọ̀ náírà (N13.5m) fún ikọ̀ agbábọ́ọ̀lù mọ́kànlélógójì (41) tí wọ́n fi ìpínlẹ̀ náà ṣe ibùgbé.
Àwọn Ikọ̀ agbábọ́ọ̀lù méje tí ó wà ní ẹ̀ka kìnnì kọ̀ọ̀kan láǹfạ̀ạ̀ní láti gba owó tí ó tó ẹgbẹ̀rún lọ́nà ẹ̀ẹ́dẹ́gbẹ̀ta (N500,000), bẹ́ẹ̀ sìni ikọ̀ agbábọ́ọ̀lù márùndínlógún tí ó wà ní ẹ̀ka kejì kọ̀ọ̀kan ọ̀kẹ́ mẹ́tàdínlógún-lélẹ́gbàarùn-ún (N350,000), tí ikọ̀ agbábọ́ọ̀lù mọ́kàndínlógún tí ó bọ́ sí ẹ̀ka kẹta sì láǹfààní láti gba ọ̀kẹ́ méjìlá-lélẹ́gbàarùn-ún (N250, 000).
Gomina Abdullahi Ganduje sọ pé, ṣíṣe ìtọrẹ owó ọ̀hún ni ó wáyé ni ọ̀nà láti mú ìdàgbàsókè tí ó yèkooro bá ikọ̀ kọ̀ọ̀kan ní ìpínlẹ̀ náà.
Inú mí dùn pé ikọ̀ agbábọ́ọ̀lù yín ṣe dáradára, gẹ́gẹ́ bí ìjọba, ojúṣe wa ni láti ran ikò kọ̀ọ̀kan lọ́wọ́ láti túbọ̀ máa ṣe dáradára síi. A fi ń dáa yín lójú pé a ó ṣe àtìlẹ́yìn tí ó tó fún-un yín.
Bákan náà, kò tí ì pẹ́ rárá tí a tún ṣe ìtọrẹ àwọn ohun èlò ìgbá bọ́ọ̀lù fún ikọ̀ agbábọ́ọ̀lù tí ó tó ẹ̀ẹ́dẹ́gbéje ní ìpínlẹ̀ yìí, eléyìí tí ó wà lára èrò wa láti mú ìgbèrú bá eré-ìdárayá ni í̀pínlẹ̀ yìí.
"O fi kún un pé, bọ́ọ̀lù àfẹsègbá jẹ́ eré ìdárayá kan gbòógi tí kò ṣe é fọwọ́ yẹperẹ mú láwùjọ, ó máa ń fi ààyè ìbáṣepọ̀ tí ó dánmọ́rán sílẹ̀ láàrin àwọn ọ̀dọ́ àti àwọn ènìyàn lápapọ̀.
Gómìnà náà wá rọ ikọ̀ agbábọ́ọ̀lù kọ̀ọ̀kan ní ìpínlẹ̀ náà láti túbọ̀ tẹpá mọ́ṣẹ́ wọn síi, bẹ́ẹ̀ sì nì O fi ń dá wọn lójú pé, ìṣàkóso ọ̀un yóò sa ipá rẹ̀ láti ṣàtìlẹyìn tí ó tó fún wọn nígbà kúùgbà àti lóòrèkóòrè.
--- Àwọn olóyè nínú àjọ NFF ṣàbẹ̀wò sí Carl Ikeme.
Àwọn tọ́rọ̀ kàn gbọ́ngbọ̀n nínú àjọ NFF ti lọ ṣàbẹ̀wò sí amúlé ikọ̀ agbábọ́ọ̀lù Super Eagles, Carl Ikeme tí ó ń gba ìtọ́jú nílé ìwòsàn Christie Clinic, Manchester.
Ikeme ni àwọn dókítà sàyẹ̀wò pé Ó ní àìsàn jẹjẹrẹ nínú oṣù keje ọdún 2017, tí ó sì ti ń gba ìtọjú láti ìgbà náà.
Nínú ọ̀rọ̀ wọn, agbẹnusọ̀ àjọ NFF, Tóyìn Ìbítóyè sọ pé, ààrẹ àjọ NFF, Amaju Pinnick ni ó dari àwọn ìgbìmọ̀ ọ̀hún, tí ó kún fún igbákejì ààrẹ kìnní àjọ NFF, Ṣèyí Akínwùnmí, akọ̀wé àgbà àjọ náà Mohammed Sanusi, olùṣàkóso ikọ̀ Super Eagles, Dayọ̀ Enebi àti akọ́nimọ̀ọ́mú Alloy Agu lọ sí ilé ìwòsàn náà.
Pinnick sọ pé, A mú ìkínni wá fún Ọ láti ọwọ́ ìjọba, àjọ NFF lápapọ̀, láti wá ṣàbẹ̀wò mọ ibi tí àwọn dókítà bá ìtọ́jú dé. Ní pàápàá jùlọ láti sọ fún Ọ pé a kò gbàgbé rẹ nígbà kankan, bẹ́ẹ̀ sìni O ṣì dúró digbí nínú ikọ̀ Super Eagles.
Bákan náà, ni a tún wá bèèrè bóyá O lè jẹ́ àlejò wa pàtàkì nínú ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ ọlọ́rẹ̀ẹ́jọ̀rẹ́ tí Super Eagles yóò gbá pẹ̀lú England ní pápá ìṣeré Wembley lọ́jọ́ kejì oṣù kẹfà. A fẹ́ jẹ́ kó kópa láti ṣíṣọ lójú eégún kí ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ ọ̀hún ó tó bẹ̀ẹ̀rẹ̀.
Ikeme dáhùn pé, Inú mí dùn púpọ̀ fún ìfẹ́ ńlá tí àjọ NFF àti ìjọba fi ń hàn mí.
Mo sì dúpẹ́ lọ́pọ̀lọpọ̀ fún àwọn ọmọ Nàìjííríà fún oríṣiríṣi àdúrà àtẹ̀jíṣẹ́ tí wọ́n máa ń fi ránṣẹ́ sí mi lórí ẹ̀rọ ìbánisọ̀rọ̀ mi.
--- CAF, NFF ṣàjọyọ̀ ọdún merinlelogoji(44) fún Tàríbò West.
Àjọ tó ń rí sí bọ́ọ̀lù àfẹsẹ̀gbá nílẹ̀ Áfíríkà (CAF) ti panu pọ̀ pẹ̀lú àjọ tó ń rí si bọ́ọ̀lù àfẹsẹ̀gbá ní Nàìjííríà (NFF) láti ṣàjọyọ̀ ayẹyẹ ọdún mẹ́rìnlélógójì agbábọ́ọ̀lù ikọ̀ Super Eagles tẹ́lẹ̀rì Taribo West lọ́jọ́ Ajé (Monday).
Àjọ CAF àti NFF ṣe ìkínni ọ̀hún lórí ẹ̀rọ ayélujára wọn láti kí atamátàsé tẹ́lẹ̀rí náà.
Ẹ̀wẹ̀, West bẹ̀ẹ̀rẹ̀ ayé rẹ gẹ́gẹ́ bí agbábọ́ọ̀lù nínú ikọ̀ Obanta United kí ó tó dara pọ̀ mọ́ ikọ̀ agbábọ́ọ̀lù mìíràn lóríṣiríṣi Ó kópa fún Sharks, Enugu Rangers, Julius Berger, Auxerre, Internazionale, AC Milan, Derby County, Kaiserslautern, Partizan, Al-Arabi àti Plymouth Argyle.
Taribo West wà lára ikọ̀ Super Eagles tí ó gba ife-ẹ̀yẹ ìdíje bọ́ọ̀lù àgbááyé tàwọn ọ̀dọ́ tọ́jọ́ orí wọn kòju ọ̀dún mẹ́tàlélógún lo U-23̣, 1996 Atlanta Olympic, bẹ́ẹ̀ sì ni Ó tún kópa nínú ìdíje Africa Cup of Nations àti ìdíje bọ́ọ̀lù àgbááyé.
--- ìlera Nadal ti pé báyìí láti figagbága nínú ìdíje Davis Cup.
Atamátàsé agbábọ́ọ̀lù àfigigbá tí ó dára jùlọ sìkejí lágbàáyé, Rafael Nadal ní Spain ti kéde báyìí pé yóò figagbága nínú ìpele kẹta sí àṣekágbá ìdíje Davis Cup tí wọn yóò gbá pẹ̀lú Germany nílùú Valencia lóṣù tó ń bọ̀.
Ọmọ ọdún mọ́kànlélọ́gbọ̀n(31) ọ̀hún ni kò tíi kópa nínú ìdíje náà láti ìgbà tí ó ti ran Spain lọ́wọ́ láti gba ife-ẹ̀yẹ ọ̀hún nígbà márùn-ún ọ̀tọ̀ọ̀tọ̀, èyí tí ó gbà kẹ́ỳin lọ́dún 2016 lórílẹ̀-èdè India.
Nadal ni akọ́nimọ̀ọ́gbá àgbà ikọ̀ Spain Sergi Bruguera ti yàn papọ̀ pẹ̀lú Pablo Busta, Bautista Agut, David Ferrer àti Feliciano Lopez láti kópa nínú ìdíje náà.
Nadal, ṣíwọ́ láti tẹ̀síwájú nínú ìdíje Australian Open nínú oṣù kínní ọdún látàrí ìfarapa tí ó ní.
Ẹ̀wẹ̀, bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé, ìrètí wà pé, yóò padà wá kópa nínú ìdíje Mexican Open nínú oṣù kejì, ṣùgbọ́n Ó kọ̀ láti kópa, léyìí tí ó sọ ọ́ di ìdíje márùn-ún ọ̀tọ̀ọ̀tọ̀ tí kò tíi kópa léra wọn báyìí.
Ní ìparí, ìfigagbága ìpele kẹta sí àṣekágbá ìdíje Davis Cup ọ̀hún yóò wáyé lọ́jọ́ kẹfà sí ọjọ́ kẹjọ inú oṣù kẹrin ọdún tí a wà yìí.
--- Ìfigagbága pẹ̀lú Parker yóò lágbára gan-an – Joshua
Olùjà ọmọ bíbí ilẹ̀ Bìrìtìkó, ẹni tí àmì-ẹ̀yẹ bẹ́lítì ìgbàdí WBA àti IBF wà lọ́wọ́ rẹ̀ báyìí, Anthony Joshua sọ pé ìfigagbága ọ̀un pẹ̀lú Joseph Parker tí yóò wáyé ní gbàgede Principality Stadium ní Cardiff lọ́jọ́ àbámẹ́ta (Saturday) yóò lágbára gan-an.
Ìròyìn sọ pé, Joshua kò tíì pàdánù ìfigagbága kankan látẹ̀yìn wá, bẹ́ẹ̀ sìni ìgbàgbọ́ wà pé ó ṣeéṣe kí Ó jáwé olúborí nínú ìfigagbága ọ̀hún látàrí ìrírí rẹ̀ tí ó ní ní gbàgede Principality.
Ẹ̀wẹ̀, ẹnìkejì rẹ̀ ọmọ bíbí orílẹ̀-èdè New Zealander, Parker náà kò tíì pàdánù ìfigagbága kankan nínú ìfigagbága mẹ́rìnlélógún tí ó ti jà báyìí, bẹ́ẹ̀ sìni yóò gbé bélíìtì ìgbàdí WBO tí ó gbà kẹ́yìn wá fi díje nínú ìfigagbága náà.
--- Rohr ṣàtúnṣe sí ikọ̀ tí yóò kojú Serbia.
Akọ́nimọ̀ọ́gbá àgbà ikọ̀ Super Eagles, Gernot Rohr ti ṣe àtúnṣe si ikọ̀ tí ó fàgbà hàn ikọ̀ agbábọ́ọ̀lù Poland, léyìn tí ó rọ́pò agbábọ́ọ̀lù mẹ́rin lára ikọ̀ tí yóò kojú orílẹ̀-èdè Serbia.
Gẹ́gẹ́ bí ẹ̀rọ ayélujára own goal Nigeria ṣe sọ, Rohr ti ṣe àtúnṣe sí ikọ̀ tí ó fàgbà han ikọ̀ agbábọ́ọ̀lù Poland lọ́jọ́ Ẹtì (Friday)."
Ní báyìí, Leon Balógun kò ní kópa látàri ìfarapa tí ó ní, bẹ́ẹ̀ sì ni Shehu Abdullahi, Kelechi Iheanacho, àti Odion Ighalo kò ní bẹ̀ẹ̀rẹ̀ ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ ọ̀hún.
Ẹ̀wẹ̀, Kenneth Omeruo, Ogenyi Onazi, Tyronne Ebuehi àti Ahmed Musa yóò rọ́pò wọn ṣaájú ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ náà, ṣùgbọ́n Francis Odinaka Uzoho, Joel Obi àti Brian Ìdòwú yóò di ipò wọ́n mú bí ó ṣe wà tẹ́lẹ̀.
Ikọ̀ mọ́kànlá tí yóò kojú Serbia ni: Francis Odinaka Uzoho (GK), Tyronne Ebuehi, Brian Ìdòwú, William Troost-Ekong, Kenneth Omeruo, Joel Obi, Wilfred Ndidi, Ogenyi Onazi (C), Alex Iwobi, Ahmed Musa, Victor Moses.
--- Ibrahimovic fi ikọ̀ Manchester United silẹ̀ láti dara pọ̀ mọ́ LA Galaxy.
Zlatan Ibrahimovic ti pinnu láti fi ikọ̀ Manchester United silẹ̀ láti dara pọ̀ mọ́ ikọ̀ agbábọ́ọ̀lù LA Galaxy.
“kòsí òhun tí ó ní ìbéèrè tí ò lópin, àsìkò tí tò ní báyìí láti tún tẹ̀síwájú nínú ìrín-àjo bọ́ọ̀lù àfẹsẹ̀gbá mi, lẹ́yìn sáà méjì tí mo lò pẹ̀lú ikọ̀ agbábọ́ọ̀lù Manchester United.
Mo dúpé púpọ̀ fún ikọ̀ náà, àwọn olólùfẹ́, àwọn akẹẹgbẹ́ mi, àwọn akọ́nimọ̀ọ́gbá gbogbo àti àwọn òṣìṣẹ́ pátápátá fún àṣeyọrí mi nínú ikọ̀ yìí.
"Akọ́nimọ̀ọ́gbá àgbà ikọ̀ Manchester United, Jose Mourinho náà ti sọ tẹ́lẹ̀rí pé, Ibrahimovic yóò kúrò nínú ikọ̀ náà tí ìwé ìṣiṣẹ́ rẹ̀ náà bá wá sí ìparí ní sáà yìí.
--- Mi ò ní kópa fún Spain mọ́ lẹ́yìn ìdíje bọ́ọ̀lù àgbááyé - Iniesta
Ṣaájú ìfigagbága ọlọ́rẹ̀ẹ́jọ̀rẹ́ tí ikọ̀ agbábọ́ọ̀lù Spain yóò gbá pẹ̀lú Germany lọ́jọ́ Ẹtì (Friday), Iniesta, ti gbá ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ mẹ́tàlélọ́gọ́fà (123) fún Spain báyìí, ṣùgbọ́n tí kò tíì bá tàwọn aṣaájú rẹ̀ tí wọ́n ti fẹ̀yìntì bí: Andoni Zubizarreta, Xavi, Sergio Ramos ati Iker Casillas.
Ní báyìí, tí Iniesta bá láǹfààní láti kópa nínú ọ̀kan-ò-jọ̀kan ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ ọlọ́rẹ̀ẹ́jọ̀rẹ́ fún Spain, èyí yóò mú ṣaájú akẹẹgbẹ́ rẹ̀ tẹ́lẹ̀rí, Xavi lẹ́ni tí ó jẹ́ ẹnikẹta tí ó kópa jùlọ fún ikọ̀ agbábọ́ọ̀lù Spain kí ó tó fẹ̀yìntì ní ọmọ ọdún mẹ́rìnlélọ́gbọ̀n.
Ní báyìí, ó fara hàn gbangba gbàǹgbà pé, ìdíje àgbááyé tó ń bọ yìí ni yóò jẹ́ ìkẹyìn tí màá kópa nínú rẹ̀ fún Spain, Iniesta jẹ́ ọ̀kan lára agbábọ́ọ̀lù ikọ̀ Spain tí ó ṣàṣeyọrí jùlọ nínú ìtàn ikọ̀ ọ̀hún, lẹ́yìn tí ó ràn wọ́n lọ́wọ́ láti gba ife-ẹ̀yẹ European Championship ní sáà 2008 ati 2012, bẹ́ẹ̀ sì ni Ó tún kópa fún ikọ̀ náà nínú ìdíje àgbááyé lọ́dún 2010, tí ó sì tún gba ife-ẹ̀yẹ ìdíje náà.
--- Poland/Nigeria ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ ọlọ́rẹ̀ẹ́jọ̀ré: Agbábọ́ọ̀lù Super Eagles méjìlélógún (22) balẹ̀ sípàgọ́ Wroclaw.
Ilé ìtura ikọ̀ agbábọ́ọ̀lù Super Eagles, Radisson Blu Hotel gbàlejò rẹpẹtẹ lọ́jọ́ Í̀ṣẹ́gun (Tuesday), lẹ́yìn tí agbábọ́ọ̀lù méjìlélógún bálẹ ṣípàgọ́ ikọ̀ náà tí ń ṣe Wroclaw, fún ìgbáradì ní kíkún ṣaájú ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ ọlọ́rẹ̀ẹ́jọ̀ré tí yóò wáyé lọ́jọ́ Ẹtì (Friday) pẹ̀lú orílẹ̀-èdè Poland.
Àwọn ọ̀ṣìṣẹ́ ìkọ́ ọ̀hún, tí o fimọ́ àwọn akọ́nimọ̀ọ́gbá wọn gbogbo, pẹ̀lú agbábọ́ọ̀lù mẹ́fà ní ó ṣíde ìpàgọ́ ọ̀hún lọ́jọ́ Ajé (Monday), kí àwọn yòókù ó tó wá dara pọ̀ mọ́ wọn, Ní báyìí, àwọn agbábọ́ọ̀lù tí ó ti wà níkàlẹ̀ ni: Francis Uzoho, Kenneth Omeruo, Elderson Echiejile, Stephen Eze, Abdullahi Shehu, Chidozie Awaziem, midfielders Joel Obi, John Ogu, Ogenyi Onazi, Uche Agbo, Wilfred Ndidi, Ahmed Musa, Moses Simon, Odion Ighalo, Kelechi Iheanacho ati Victor Moses.
Amúlé ikọ̀ náà, Ikechukwu Ezenwa àti Daniel Akpeyi nìrètí wà pé, wọn yóò dara pọ̀ mọ́ wọn lónìí tí ń ṣe ọjọ́rùú (Wednesday).
Ẹ̀wẹ̀, balógun ikọ̀ ọ̀hún Mikel John Obi ni kò tíì wà pẹ̀lú àwọn akẹẹgbẹ́ rẹ̀ ní Wroclaw látàrí iṣẹ́ tó ń ṣe lọ́wọ́ láti sọ ìwé ìṣiṣẹ́ rẹ̀ ní China di ọ̀tun nínú ikọ̀ agbábọ́ọ̀lù rẹ̀ Tianjin Teda.
Ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ náà yóò bẹ̀ẹ̀rẹ̀ gbàrà láago mẹ́jọ ààbọ̀ (8.45pm), lojo Eti (Friday).
--- Saunders sún ìfigagbága WBO ṣíwájú látàrí ìfarapa.
Olùdíje nínú ìfigagbága (WBO) Billy Saunders, tí ó tún jẹ́ ẹni tí ó gba ife ẹ̀yẹ okùn ìgbàdí (Belt) ọ̀hún kẹ́yìn, ti sún ìfigagbága tí yóò wáyé láàárín rẹ̀ àti Martin Murray sínú oṣù tó ń bọ̀ látàrí ìfarapa ọwọ́ tí ó ní lásìkò ìgbáradì.
Ẹ̀wẹ̀, ìfigagbága náà nìrètí wà tẹ́lẹ̀ pé, yóò wáyé ní gbàgede London O2 Arena lọ́jọ́ kẹrìnlá oṣù kẹrin ọdún yìí, ṣùgbón ní báyìí yóò wáyé lọ́jọ́ kẹtàlélógún inú oṣù kẹfà ọdún tí a wà yìí.
Saunders gba okùn ìgbàdí ọ̀hún fún ìgbà mẹ́tà báyìí, tí ó sì fàgbàhan David Lemieux nínú ìfagagbága kẹ́yìn tí ó wáyé ní Canada.
Mo ní ìfarapa lásìkò ìgbáradì mi, ti mo sì nílò láti ṣètọ́jú níkíá láìfi falẹ̀ rárá."
Gẹ́gẹ́ bí akọ́nimọ̀ọ́já mi, Dominic Ingle, Ó ni, Mi ò ní lè jà fún ọ̀sẹ̀ mẹ́rin, àfi tí ìlera ara mi bá pé kí ó tó di inú oṣù kẹ̀fa.
--- Argentina bẹ̀rẹ̀ ìgbáradì fún ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ ọlọ̀rẹ̀ẹ́jọ̀rẹ́ pẹ̀lú Italy.
Lionel Messi dara pọ̀ mó àwọn akẹẹgbẹ́ rẹ̀ lọ́jọ́ Ìṣẹ́gun (Tuesday) ní pápá ìṣeré Manchester City láti gbáradì fún ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ ọlọ́rẹ̀ẹ́jọ̀rẹ́ pẹ̀lú ikọ̀ agbábọ́ọ̀lù Italy.
Ikọ̀ agbábọ́ọ̀lu Argentina ló ń ṣàmúlò pápá ìṣeré ọ̀dọ́ ikọ̀ Manchester City fún ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ ọ̀hún tí yóò wáyé lọ́jọ́ Ẹtì (Friday).
Ẹ̀wẹ̀, Sergio Aguero náà dara pọ̀ mọ́ wọn, ṣùgbọ́n kò kópa látàrí ìfarapa tí ó ní.
Bákan náà, àwọn tí ó tún kópa nínú ìgbáradì ọ̀hún ni: Nicolas Otamendi, Gonzalo Higuain, Angel Di Maria, Javier Mascherano ati Marcos Rojo.
--- Agbábọ́ọ̀lù mẹ́rìnlá gúnlẹ̀ sípàgọ́ Super Eagles.
Agbábọ́ọ̀lụ̀ mẹ́rìnlá (14) tí ikọ̀ agbábọ́ọ̀lù Super Eagles ló ti gúnlẹ̀ sí ìpàgọ́ ikọ̀ ọ̀hún ṣaájú ìfigagbága ọlọ̀rẹ̀ẹ́jọ̀rẹ́ pẹ̀lú ikọ̀ agbábọ́ọ̀lù Poland tí yóò wáyé lọ́jọ́ Ẹtị̀ (Friday), ní pápá ìṣeré Municipal, Wroclaw.
Ìpàgọ́ ọ̀hún ni wọ́n ṣí lọ́jọ́ Ajé (Monday), tí àwọn agbábọ́ọ̀lù mẹ́jọ̀ sì gúnlẹ̀ lọ́jọ́ kannáà kí àwọn mìíràn ó tó wá dara pọ̀ mọ́ wọn lọ́jọ́ kejì.
Ní báyìí, lára àwọn agbábọ́ọ̀lù tí ó ti gúnlẹ̀ sí ìpàgọ́ náà ni: Moses Simon, Joel Obi, Elderson Echiejile , Stephen Eze, Shehu Abdullahi, John Ogu àti Kenneth Omeruo.
Bákan náà, ìrètí wà pé, àwọn akónimọ̀ọ́gbá ikọ̀ Super Eagles àti amúlé ikọ̀ ọ̀hún, Ikechukwu Ezenwa yóò tẹkọ̀ létí lọ sórílẹ̀-èdè Poland lónìí láti lọ bẹ̀ẹ̀rẹ̀ ìgbáradì ní kíkún.
Àwọn agbábọ́ọ̀lù tí ó ti balẹ̀ sípàgọ́ ní kíkún: Francis Uzoho, Elderson Echiejile, Stephen Eze, Joel Obi, Shehu Abdullahi, John Ogu, Moses Simon, Kenneth Omeruo, Troost Ekong, Alex Iwobi, Ola Aina, Tyronne Ebuehi, Brian Idowu, Leon Balogun.
--- Chiellini kò ní kópa nínú ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ ọlọ́rẹ̀ẹ́jọ̀rẹ́.
Agbábọ́ọ̀lù ọwọ́ ẹ̀yìn ikọ̀ Juventus àti orílẹ̀-èdè Italy, Giorgio Chiellini kò ní kópa nínú ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ ọlọ́rẹ̀ẹ́jọ̀rẹ́ tí ikọ̀ agbábọ́ọ̀lù Italy yóò gbá látàrí ìfarapa ẹ̀yí tí ó ní. Ikọ̀ agbábọ́ọ̀lù Juventus ló sọ̀rọ̀ ọ̀hún di mímọ̀ lórí ẹ̀rọ ayélujára ikọ̀ ọ̀hún lọ́jọ́ Ajé (Monday).
Ikọ̀ agbábọ́ọ̀lù Italy, tí àwọn èèyàn tún mọ̀ sí The Azzurri, nìrètí wà pé, wọn yóò kojú ikọ̀ agbábọ́ọ̀lù Argentina ní pápá ìṣeré Manchester lọ́jọ́ Ẹtì (Friday), bẹ́ẹ̀ sì ni wọn yóò tún lọ kojú England ní pápá ìṣeré Wembley lọ́jọ́ kẹrin sí ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ àkọ́kọ́.
Adelé akọ́nimọ̀ọ́gbá orílẹ̀-èdè ọ̀hún, Luigi Di Biagio ló gba iṣẹ́ lọ́wọ́ Gian Piero Ventura nínú oṣù kọkànlá ọdún tí ó kọjá, látàrí kíkùnà láti pegedé fún ìdíje bọ́ọ̀lù àgbááyé fún ìgbà àkọ́kọ́ láti ọdún 1958.
Juventus yóò máa kojú ikọ̀ agbábọ́ọ̀lù AC Milan lọ́jọ́ kọkànlélọ́gbọ̀n (31) oṣù kẹ̀ta, bẹ́ẹ̀ sì ni wọn yóò tún lọ gbá ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ àkọ́kọ́ ìdíje UEFA Champions League pẹ̀lú Real Madrid lọ́jọ́ kẹta inú oṣù kẹ̀rin.
--- Cadbury, NFF tọwọ́ bọ ìwé ìbáṣepọ̀ ọlọ́dún mẹ́ta.
Ilé iṣẹ́ Cadbury Nigeria Plc tí wọ́n ń pèsè ohun lílá ẹlẹ́rìndòdò TomTom pẹ̀lú àjọ́ NFF ti tọwọ́bọ ìwé ìbáṣepọ̀ ọlọ́dún mẹ́ta ní ọ̀nà láti gbé ikọ̀ agbábọ́ọ̀lù Super Eagles lárugẹ sìi.
Gẹ́gẹ́ bí adari àgbà ilè-iṣẹ́ Cadbury Nigeria Plc ṣe sọ, ọ̀gbéni Amir Shamsi lásìkò ìpàdé náà, Inú wa dùn púpọ̀ láti kéde ìbáṣepọ̀ ọlọ́dún mẹ́ta síi pẹ̀lú àjọ NFF. Ọdún yìí jẹ́ ọdún kẹwàá tí a ti ń ṣiṣẹ́ pọ̀ pẹ̀lú àjọ NFF.
"Adarí àgbà ẹ̀ka ìtajà ilé-iṣẹ́ Cadbury nílẹ̀ Áfíríkà, iyáàfin Iwadiae Chidinma sọ pé: Iṣẹ́ tí Tom Tom ṣe lára kò lóǹkà. …jẹ́ ọ̀kan gbòógì láàrin àwọn akẹẹgbẹ́ rẹ̀ lọ́jà. Tom-Tom jẹ́ ẹlẹ́rìndòdò tí ó ṣe Pàtàkì fún ikọ̀ Super Eagles.
Ààrẹ àjọ NFF, Amaju Pinnick gbóríyìn bàǹtàbanta fún ilé-iṣẹ́ Cadbury Nigeria Plc fún ìbáṣepọ̀ àti àtìlẹyìn wọn tó gbòòrò ní ọ̀nà láti mú ìgbèrú bá ikọ̀ Super Eagles A dúpé fún TomTom lọ́pọ̀lọpọ̀ fún ọ̀kan-ò-jọ̀kan àtilẹyìn wọn."
"Adarí àgbà nínú ilé-iṣẹ́ náà nílẹ̀ Áfíríkà, ọ̀gbẹ́ni Aruleba Olúmìídé sọ pé, Inú ilé-iṣẹ́ Cadbury Nigeria Plc, dùn púpọ̀ láti ṣàtìlẹyìn fún Super Eagles, bẹ́ẹ̀ sì ni Ó kín wọn lẹ́yìn láti lọ kópa tí ó tayọ ní Russia. Tom-Tom nífẹ̀ẹ́ Super Eagles púpọ̀.
--- Yaya Toure pinnu láti padà sínú ikọ̀ Ivory Coast.
Agbábọ́ọ̀lù ikọ̀ Manchester City, ọmọ orílẹ̀-èdè Ivory Coast, Yaya Toure ti pinnu láti padà sínú ikọ̀ agbábọ́ọ̀lù orílẹ̀-èdè rẹ̀, lẹ́yìn ìsinmi ọdún mẹ́ta tí ó ti kópa fún ikọ̀ ọ̀hún tí ó wáyé nínú ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ ọlọrẹ̀ẹ́jọ̀rẹ́ pẹ̀lú orílẹ̀-èdè France.
Toure tí yóò pé ọmọ ọdún márùnlélọ́gbọ̀n(35) nínú oṣù kaàrún, tí ó tún tukọ̀ ọ̀hún gba ife-ẹ̀yẹ ìdíje African Nations Cup lọ́dún 2015, kéde ìpinnu ọ̀hún nínú oṣù kejìlá ọdún tí ó kọjá pé òun yóò padà máa kópa, bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé ikọ̀ náà kò pegedé fún ìdíje bọ́ọ̀lù àgbááyé tí yóò wáyé lórílẹ̀-èdè Russia nínú ọdún tí a wà yìí.
Bákan náà, ni adelé akọ́nimọ̀ọ́gbá ikọ̀ agbábọ́ọ̀lù Ivory Coast, Ibrahim Kamara kéde Eric Bailly, Wilfried Zaha sára ikọ̀ tí yóò kojú Togo àti Moldova, bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé, wọn ṣẹ̀ṣẹ̀ padà sórí pápá látàrí ìfarapa tí wọ́n ní ni..
--- UCL: Bayern jáwé olúborí nínú ìfigagbága pẹ̀lú Besiktas.
Bayern Munich gbo ewúro sí ikọ̀ agbábọ́ọ̀lù Besiktas lójú nínú ìfigagbága ìdíje UEFA Champions League, pẹ̀lú àmì-ayò mẹ́ta sóókan (3-1). Ní báyìí, àpapọ̀ àmì-ayò mẹ́jọ sóókan (8-1), ni ikọ̀ Bayern Munich fi pegedé sínú ìpele kẹta sí àṣekágbá ìdíje náà.
Ẹ̀wẹ̀, jíjáwé olúborí nínú ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ ọ̀hún, ló sọ ọ́ di ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ mọ́kànlá tí ikọ̀ Bayern ti yege léra wọn.
Thiago Alcantara, gbá àmì-ayò kínní wọlé nísẹ̀ẹ́jú méjìdínlógún sáà àkọ́kọ́ ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ náà láti fòpin sí ìrètí Besiktas, bóyá wọ́n lè pegedé síwájú síi.
Ní báyìí, ìyíkoto ìpele kẹta yóò wáyé lọ́jọ́ Ẹtì (Friday).
--- Venus j́awé olúborí nínú ìfigagbága ọ̀mọ-ìyá.
Venus Williams ti fàgbà han àbúrò rẹ̀ Serena, nínú ìfigagbága sípele kẹta ìdíje Indian Wells pẹ̀lú àmì-ayò mẹ́fà sí mẹ́ta (6-3), àmì-ayò mẹ́fà sí mẹ́rin (6-4).
Bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé, ọ̀pọ̀ èèyàn sọ pé, kíkùnà Serena láti jáwé olúborí ò níiṣe pẹ̀lú ọmọ tí ó ṣẹ̀ṣẹ̀ bí, ṣùgbón ìfigagbága ọ̀hún ló di ìgbà mọ́kàndínlọ́gbọ̀n (29) tí àwọn ọmọ-ìyá méjéèjì máa pàdé, tí Venus sì jáwé olúborí ìgbà márùndínlọ́gbọ̀n.
Ní báyìí, Venus yóò ló kojú ọmọ ilẹ̀ Latvia Anastasija Sevastova, lẹ́ni tí ó fàgbà han Julia Goerges láti pegedé sípele tí ó kàn.
--- Halep fàgbà han Wang láti pegedé sínú ìpele kẹta ìdíje Indian Wells.
Olùkópa obìnrin tí ó dára jùlọ lágbàáyé nínú eré-ìdárayá bọ́ọ̀lù àfigigbá, Simona Halep fàgbà han akẹẹgbẹ́ rẹ̀ Wang Qiang pẹ̀lú àmì-ayò méje sí márùn-ún (7-5), mẹ́fà sí óókàn (6-1), ní pápá ìṣeré BNP Paribas lọ́jọ́ Ìṣẹ́gun (Tuesday) láti pegedé sípele kẹta ìdíje Indian Wells.
Ní báyìí, yóò gbáradì láti kojú Petra Martic nílùú California.
Bí ó ti lẹ̀ jẹ́ pé, oríṣiríṣi aṣemáṣeni Simona fi bẹ̀ẹ̀rẹ̀ ìfigágbaga ọ̀hún, kí akọ́nimọ̀ọ́gbá rẹ̀, Darren Cahill kó tó ṣí i níyè láti tẹpá mọ́ṣẹ́ síi, kí ó sì fòpin sí aṣemáse náà.
Simona Ọmọ ọdún mẹ́rìndínlọ́gbọ̀n (26) ọ̀hún, kò kópa bí ẹni tó ní ìfarapa rárá, lẹ́yìn tí ó kọ̀ láti tẹ̀síwájú nínú ìdíje Qatar Total Open nílùú Doha lóṣù tí ó kọjá.
Ẹ̀wẹ̀, Simona gba irúfẹ́ ife-ẹ̀yẹ ìdíje ọ̀hún tí ó wáyé lọ́dún 2015.
Mo ní láti tẹpámọ́ṣẹ́ nínú ìpele tí ó kàn, nítorí Petra Martic dára púpọ̀ ,."
Karolina Pliskova fi agbára rẹ̀ fàgbà han ọmọ ọdún mẹ́rìndínlógún Amanda Anisimova.
--- Maria Sharapova àti Sven Groeneveld fòpin sí ìbáṣépọ́ wọn.
Maria Sharapova sẹtán láti fòpin sí ìbáṣepọ̀ ọ̀un àti akọ́nimọ̀ọ́gbá rẹ̀, Sven Groeneveld.
Groeneveld bẹ̀ẹ̀rẹ̀ síní ṣisẹ́ pẹ̀lú Sharapova láti ọdún 2014, tí ó sì rà án lọ́wọ́ láti gba ife-ẹ̀yẹ ìdíje French Open fún sáà náà.
Bákan náà, àwọn méjèèjì ṣì jọ wà papọ̀ fún oṣù márùndínlógún(15) tí àjọ tó ń rí sí eré-ìdárayá ọ̀hún ní Russia fòfin dè, látàrí lílo ògùn èyìnbó afúnilókun tí a mọ̀ sí meldonium lọ́dún 2016.
Ṣùgbọ́n, ọmọ ọgbòn(30) ọdún náà ti yege ìfigagbága márùn-ún(5) lọ́dún yìí, tí ó sì pàdánù ìfigagbága àkọ́kọ́ nínú ìdíje Indian Wells nínú ọ̀sẹ̀ yìí.
Sharapova fikún un pé, Ìṣiṣẹ́pọ̀ ọlọ́dún mẹ́rin àti oríṣiríṣi ìdojúkọ la ti jọ là kọjá láti ọdún mẹ́rin sẹ́yìn.
"Bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé, A ti jọ fẹnu kò láti pínyà fún àkọ́kọ́ yìí, bẹ́ẹ̀ sìni àǹfààní ńlá ló jẹ́ fún mi láti ṣiṣẹ́ papọ̀ pẹ̀lù rẹ̀ fùn ọdún mẹ̀rin gbàko,""."
Akọ̀nimọ̀ọ̀gbà ọmọ orìlẹ̀-èdè Holland ọ̀hún, ti ṣiṣẹ́ papọ̀ pẹ̀lú oríṣirìṣi olùkòpa nínú erè-ìdàrayà yìí bíi: Monica Seles, Arantxa Sanchez Vicario, Ana Ivanovic, Caroline Wozniacki àti Greg Rusedski.
Gẹ́gẹ́ bí Groeneveld ṣe sọ Maria jẹ́ ọ̀kan gbòógì, akíkanjú, ẹni tó ń ṣiṣẹ́ kárakára lára àwọn tí mo ti bá ṣiṣẹ́ pọ̀ sẹ́yìn, bẹ́ẹ̀ sìni Mo ní ọ̀wọ̀ púpọ̀ fùn un.
--- Serena ṣàjọyọ̀ jíjáwé olúborí lẹ́yìn ìsinmi oṣù mẹ́rìnlá.
Serena Williams ti fi ìdùnnú rẹ̀ hàn púpọ̀ lẹ́yìn jíjáwé olúborí nínú ìfigagbága WTA, lẹ́ni tí ó ṣẹ̀ṣẹ̀ padà sínú ìdíje látàrí ìsinmi oṣù mẹ́rìnlá ọmọ tí ó ṣèṣẹ̀ bí.
Williams fàgbà han akẹẹgbẹ́ rẹ̀ Zarina Diyas pẹ̀lú àmì-ayò méje sí márùn-ún (7-5), mẹ́fà sí mẹ́ta (6-3), nínú ìfigagbága kínní tí ó wáyé lórílẹ̀-èdè India.
"Bákan náà, Mi ò tí́i ṣetàn láti fẹ̀yìntì bàyìí.
Serena Williams, ọmọ ọdún mẹ́rìndínlógójì ọ̀hún, bí ọmọ obìnrin Alexis Olympia nínú oṣù kejìla lọ́dún tí ó kọjá.
Serena yóò wàákò pẹ̀lú Kiki Bertens nínú ìfigagbága kejì, tí ó sì tún mọ̀ pé, òun yóò tún kojú àbúrò rẹ̀ Venus nípele kẹta.
--- Ìdíje Europa: Arsenal fàgbà han AC Milan 2-0
Arsenal fàgbà han ikọ̀ agbábọ́ọ̀lù AC Milan mọ́lé pẹ̀lú àmì-ayò méjì sóódo (2-0), nínú ìdíje Europa tí ó wáyé lánàá òde yìí.
Mkhitaryan gbá àmì-ayò àkọ́kọ́ wọlé fún Arsenal, tí Aaron Ramsey sì gbá àmì-ayò kejì wọlé.
--- Ààrẹ Muhammadu Buhari gbàlejò ife-ẹ̀yẹ ìdíje bọ́ọ̀lù àgbááyé FIFA.
Ààrẹ Muhammadu Buhari gbàlejò ife-ẹ̀yẹ ìdíje bọ́ọ̀lù àgbááyé, lẹ́yìn tí ife-ẹ̀yẹ ọ̀hún balẹ̀ sílùú Abuja tí ń ṣe olú-ìlú Nàìjíríà lọ́jọ́ru (Wednesday).
Ẹ̀wẹ̀, lẹ́yìn tí ife-ẹ̀yẹ ọ̀hún ti lọ káàkiri ọgbọ́n orílẹ̀-èdè láti inú oṣù kínní tí ó ti bẹ̀ẹ̀rẹ̀ ìrìn àjò rẹ̀, ife-ẹ̀yẹ tí ó gbayì jùlọ ọ̀hún padà balẹ̀ sílùú Abuja, lẹ́yìn tí Christian Karembeu ṣàgbékalẹ̀ rẹ̀ fún ará-ìlú àkọ́kọ́ lórílẹ̀-èdè yìí.
Peter Njonjo, tí ó jẹ́ ààrẹ Coca-Cola nílẹ̀ Áfíríkà ló darí ìgbìmọ̀ àjọ FIFA látì ṣàgbékalẹ̀ ife-ẹ̀yẹ ọ̀hún fún Ààrẹ Buhari àti àwọn mìíràn tọ́rọ̀ọ́ kàn gbọ̀ngbọ̀n lórílẹ̀-èdè Nàìjííríà.
Gẹ́gẹ́ bí ọ̀rọ̀ Ààrẹ Buhari, Ó jẹ́ ohun ìwúrí fún mi pé, Nàìjííríà jẹ́ orílẹ̀-èdè adúláwọ̀ àkọ́kọ́ tí ó kọ́kọ́ pegedé fún ìdíje àgbááyé yìí, Ìjọba àpapọ̀ yóò ri dájú láti ṣàtìlẹyìn, ṣèpèsè àwọn ohun èlò fún ikọ̀ Super Eagles láti kópa dáradára nínú ìdíje náà, lórílẹ̀-èdè Russia."
"Ife-ẹ̀yẹ tí ó gbayì jùlọ lágbàáyé nínú ife-ẹ̀yẹ ìdíje àjọ FIFA ọ̀hún, ni wọn yóò ṣàfihàn rẹ̀ fún àwọn ará ìlú, ní pápá ìṣeré Old Parade Ground, Garki nílùú Abuja lọ́jọ́bọ (Thursday).
Ife-ẹ̀yẹ ọ̀hún ni Coca-Cola yóò tún gbé káàkiri àwọn orílẹ̀-èdè yòókù mìíràn, kí ó tó padà sórílẹ̀-èdè Russia fún ìfigagbága rẹ̀.
--- Rohr pe agbábọ́ọ̀lù márùndínlọ́gbọ̀n(25) fún ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ Poland, Serbia.
Akọ́nimọ̀ọ́gbá àgbà ikọ̀ Super Eagles, Gernot Rohr, ti pe agbábọ́ọ̀lù márùnlélógún fún ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ ọlọ́rẹ̀ẹ́jọ̀rẹ́ tí ikọ̀ náà yóò gbá pẹ̀lú Poland àti Serbia, fún ìgbáradì ìdíje bọ́ọ̀lù àgbááyé tó ń bọ̀ lọ́nà, lórílẹ̀-èdè Russia.
Ẹ̀wẹ̀, lẹ́yìn ọjọ́ kẹrin sí ìfigagbága pẹ̀lú orílẹ̀-èdè Poland, Super Eagles yóò lọ kojú Serbia ní pápá ìṣeré The Hive, ní London.
ÀWỌN IKỌ̀ AGBÁBỌ́Ọ̀LÙ Ọ̀HÚN NÍ KÍKÚN:
Àwọn Aṣọ́lé (Goalkeepers): Francis Uzoho (Deportivo La Coruna, Spain); Ikechukwu Ezenwa (Enyimba FC) àti Daniel Akpeyi (Chippa United, South Africa).
Àwọn Agbábọ́ọ̀lù ọwọ́-ẹ̀yìn (Defenders): Abdullahi Shehu (Bursaspor FC, Turkey); Tyronne Ebuehi (Ado Den Haag, The Netherlands); Ọláolúwa Àìná (Hull City, England); Elderson Echiejile (Cercle Brugge KSV, Belgium) àti Brian Ìdòwú (Amkar Perm, Russia).
Chidozie Awaziem (Nantes FC, France); William Ekong (Bursaspor FC, Turkey); Leon Balogun (FSV Mainz 05, Germany); Kenneth Omeruo (Kasimpasa FC, Turkey) ÀTI Stephen Eze (Lokomotiv Plovdiv, Bulgaria).
Àwọn Agbábọ́ọ̀lù ọwọ́-àárín (Midfielders): Mikel John Obi (Tianjin Teda, China); Ogenyi Onazi (Trabzonspor FC, Turkey); Wilfred Ndidi (Leicester City, England); Oghenekaro Etebo (Las Palmas, Spain); John Ogu (Hapoel Beâ€™er Sheva, Israel); Uche Agbo (Standard Liege, Belgium) ati Joel Obi (Torino FC, Italy).
Àwọn Agbábọ́ọ̀lù ọwọ́-iwájú (Forwards): Ahmed Musa (CSKA Moscow, Russia); Kelechi Iheanacho (Leicester City, England); Moses Simon (KAA Gent, Belgium); Victor Moses (Chelsea FC, England); Odion Ighalo(Changchun Yatai, China); Alex Iwobi (Arsenal FC, England); Junior Ajayi (Al Ahly, Egypt) ati Gabriel Okechukwu (Akwa United).
--- Dalung: Eré-ìdárayá nílò ìsúná tó múná dóko fún ìdàgbàsókè.
Mínísítà tó ń rí sí eré-ìdárayá àti ìdàgbàsókè àwọn ọ̀dọ́ lórílẹ̀-èdè Nàìjííríà, Solomon Dalung sọ pé ìsúná tó múná dóko ṣe pàtàkì láti mú ìgbèrú débá eré ìdárayá ní ìpínlẹ̀ wa kọ̀ọ̀kan.
Dalung sọ̀rọ̀ ọ̀hún di mímọ̀ lásìkò ayẹyẹ ọdún eré-ìdárayá kejì ìpínlẹ̀ Akwa Ibom, 2nd Akwa Ibom State Youth Sports Festival tí ó wáyé lọ́jọ́ ìṣẹ́gun (Tuesday), ni olú-ìlú ìpínlẹ̀ ọ̀hún, Uyo.
Akọ̀wé àgbà nínú àjọ náà, ìyá àfin Esther Àlùkò ló ṣojú fún mínísítà ọ̀hún nínú ayẹyẹ náà.
Dalung sọ pé, Ṣíṣe ayẹyẹ ọdún eré-ìdárayá ní ìpínlẹ̀ ṣe pàtàkì láti mú ìgbèrú bá ṣíṣe déédé nínú ọ̀kan-ò-jọ̀kan ètò ìdárayá.
Ó gbóríyìn fún gómìnà ìjọba ìpínlẹ̀ Akwa Ibom, Udom Emmanuel fún àǹfààní tí ó fún àwọn ọdọ́ láti fẹ̀bùn wọn hạ̀n nípasẹ ayẹyẹ ọ̀hún.
Gomina Udom Emmanuel sọ pé, A kò wá síbí láti wá polongo ẹgbẹ́ òṣèlú, tàbí ṣe ìkéde ìbò.
--- US tennis club mú ìgbèrú bá bọ́ọ̀lù àfigigbá ní Nàìjííríà.
Ẹgbẹ́ Springdale Area Recreation, tó ń rí sí eré-ìdárayá odò wíwẹ̀ àti bọ́ọ̀lù àfigigbá tí ó fi North Carolina lórílẹ̀-èdè Amẹ́ríkà ṣe ibùgbé, ti pèsè àwọn ohun èlò lóríṣiríṣi fún àwọn olùkópa Nàìjííríà nínú eré-ìdárayá náà láti mú ìgbèrú bá eré-ìdárayá ọ̀hún lórílẹ̀-èdè Nàìjíìríà.
Ọládélé Michael, ẹni tí ó gba àmì-ẹyẹ eré-ìdárayá ọ̀hún fún ìgbà méjì lórílẹ̀-èdè yìí, tí ó tún jẹ́ akọ́nimọ̀ọ́gbá àgbà nínú ẹgbẹ́ Springdale Area Recreation, ló pín àwọn ohun èlò náà fún àwọn olùkópa ní ìpínlẹ̀ Èkó.
Ẹ̀wẹ, lára àwọn ohun èlò ọ̀hún láti rí: igi ìgbá bọ́ọ̀lù, bàtà, àkẹtẹ̀, bọ́ọ̀lù, àwọn ohun ìdẹra abbl.
Ó sọ pé, Nígbàtí Mo bẹ̀ẹ̀rẹ̀ sí ní ń gbá bọ́ọ̀lù àfigigbá, oríṣiríṣi ìdojúkọ ni Mo là kọjá; Mi ò ní àwọn ohun èlò kankan. Lẹ́yìn rẹ̀ ni mo ní àǹfààní láti tẹkọ̀ létí lọ sílẹ̀ Amẹ́ríkà láti tẹ̀síwájú nínú ẹbùn eré-ìdárayá náà. Ní báyìí, Èmi ni akọ́nimọ̀ọ́gbá àgbà ẹgbẹ́ Springdale Area Recreational, èyí tí ó fún mi láǹfàání láti bèèrè fún ìrànwọ́ àwọn ohun èlò lọ́wọ́ ẹgbẹ́ náà láti pín fún àwọn ọ̀dọ́ tó ń kópa nínú eré-ìdárayá yìí.
Ó sọ pé, láìpẹ́ láìjìnà àwọn ọ̀dọ́ orílẹ̀-èdè Nàíjííríà yóò tún ní àǹfààní sí àwọn ohun èlò mìíràn lóríṣiríṣi.
--- Falconets bọ́ sí ìkòkò kejì nínú ìyíkoto ìdíje bọ́ọ̀lù àgbááyé.
Ikọ̀ agbábọ́ọ̀lù obìnrin Super Falconets orílẹ̀-èdè Nàìjííríà, ti bọ́ sí ìkòkò kejì nínú ìyíkoto ìfigagbága ìdíje bọ́ọ̀lù àgbááyé tàwọn obìnrin tó ń bọ̀ lọ́nà lórílẹ̀-èdè France, FIFA U-20 Women World Cup France 2018.
Nínú irúfẹ́ ìdíje náà tí ó wáyé lọ́dún 2010 àti 2014, Falconets pàrí ìdíje náà sípele kejì sí àṣekágbá, bẹ́ẹ̀ sì ni lọ́dún 2012 wọ́n parí sípò karùn-ún.
Ní báyìí, Falconets yóò máa wàákò pẹ̀lú USA, Mexico àti Zealand.
Nínú ìkòkò kínní, orílẹ̀-èdè France tí yóò ṣagbátẹrù ìdíje náà, yóò máa wàákò pẹ̀lú Germany, Korea àti Japan. Bákan náà, nínú ìkòkò kẹta Brazil, Spain, Ghana àti China yóò jọ máa figagbága.
Nínú ìkòkò kẹrin, England, Paraguay, Haiti àti orílẹ̀-èdè Netherland ni wọn yóò jọ máa figagbága.
Ẹ̀wẹ̀, èyí jẹ́ ìgbà karùn-ún tí Nàìjííríà àti Ghana yóò lọ sojú ilẹ̀-Áfíríkà nínú ìdíje náà.
Sarai Bareman, tí ó jẹ́ òṣìṣẹ́ àjọ FIFA àti akẹẹgbẹ́ rẹ̀ Rhiannon Martin ni wọn yóò jọ máa ṣàkóso ìyíkoto ọ̀hún. Bẹ́ẹ̀ sì ni, àwọn mìíràn tí wọn yóò jọ ṣiṣẹ́ papọ̀ nínú yíyíkoto náà ni: Mikael Silvestre, Camille Abily, Damien Seguin àti Aela Mocaer.
ìdíje ọ̀hún yóò wáyé nílùú mẹ́rin lórílẹ̀-èdè France: Vannes, Concarneau, Dinan-Lehon àti Saint-Malo, bẹ̀ẹ̀rẹ̀ láti ọjọ́ karùn-ún oṣù kẹjọ di ọjọ́ kẹrìnlélógún ọdún tí a wà yìí.
--- CCL: Etoile Sahel fàgbà han Plateau United FC 4-2
Nínú ìdíje CAF Champions League tó ń lọ lọ́wọ́, Plateau United FC pàdánù ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ àkọ́kọ́ sọ́wọ́ Etoile du Sahel torílè-èdè Tunisia pẹ̀lú àmì-ayò mẹ́rin sí méjì (4-2), nínú ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ tí ó wáyé lọ́jọ́ ìṣẹ́gun (Tuesday) ní pápá ìṣeré Sousse.
Ìdíje onípele méjì ọ̀hún ni yóò mú ikọ̀ agbábọ́ọ̀lù Etoile du Sahel wá gbá ìfigagbága kejì nílùú Jos, láti mọ ikọ̀ tí yóò pegedé sínú ìpele tí ó kàn nínú ìdíje náà.
Bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé, ikọ̀ agbábọ́ọ̀lù Plateau United FC pàdánù ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ náà, àyè ṣì wà fún ikọ̀ ọ̀hún láti yí èsì ọ̀hún padà, tí ikọ̀ náà bá ṣe dáradára nínú ìfigagbága kejì.
Amr Marey ló gbá àmì ayò kínní wọlé níṣẹ̀ẹ́jú méjì gbàrà tí sáà àkọ́kọ́ ìfẹsẹ̀wọnsẹ ọ̀hún bẹ̀ẹ̀rẹ̀, kí Amine Chemiti ó tó gbá àmì-ayò méjì mìíràn wọlé láìpẹ́ sí ara wọn.
Ẹ̀wẹ̀, Aikhali Bangoura gbá àmì-ayò kẹrin wọlé, kí Plateau United ó tó tara jí láti gbá àmì kan wọlé pẹ̀lú bọ́ọ̀lù àgbésílẹ̀gbá, bẹ́ẹ̀ sì ni Tósìn Ọmọ́yẹlé gbá àmì-ayò mìíràn wọlé kí ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ ọ̀hún ó tó wá sí ìparí.
--- Farah ṣe pò kínní nínú ìfigagbága eré ìje Big Half.
Mo Farah, ọmọ bíbí ilẹ̀ Bìrìtìkó ti ṣepò kínní nínú ìdíje eré ìje máìlì mẹ́tàlá Big Half lọ́jọ́ Àìkú (Sunday), ṣaájú ìgbáradì fún ìdíje eré-ìje tí yóò wáyé nílùú London.
Nínú eré-ìje ọ̀hún tí ó wáyé lágbègbè Greenwich, Farah ṣepò kínní ṣaájú àwọn akẹẹgbẹ́ rẹ̀, Daniel Wanjiru, ọmọ orílẹ̀-èdè Kenya tí ó ṣepò kínní nínú ìdíje eré-ìje nílùú London lọ́dún tí ó kọjá àti Scot Callum Hawkins tí òun ṣi ṣe ipò kẹta.
Farah ọmọ ọdún mẹ́rìnlélọ́gbọ̀n(34) ọ̀hún ti ń gbáradì lórílẹ̀-èdè Ethiopia, kí ó tó balẹ̀ sílùú London lọ́jọ́bọ (Thursday) ṣaájú ìfigagbága eré ìje náà.
Gẹ́gẹ́ bí Farah Ó ṣi mọ níwọ̀n, Mo sì ní eré-ìje mìíràn níwájú tí ó tó méjì irú máìlì tí mo sá yìí, iṣẹ́ ṣì pọ̀ fún mi láti ṣe.
Farah bẹ̀ẹ̀rẹ̀ sí ní fakọyọ nínú ọ̀kan-ò-jọ̀kan eré-ìje láti ìgbà tí ó ti gba àmì-ẹ̀yẹ góòlù nígbà méjì ọ̀tọ̀ọ̀tọ̀ lọ́dún 2012 àti ọdún 2016 nínú ìdíje Olympic."
Bákan náà ni Ó sì tún fojúsọ́nà fún ìdíje 2020 Olympic eléyìí tí yóò wáyé ní Tokyo.
--- Shehu Dikko dara pọ̀ mọ́ ìgbìmọ̀ àjọ FIFA.
Alága ẹgbẹ́ LMC, tí ó tún jẹ́ igbákejì ààrẹ àjọ NFF tẹ́lẹ̀rí, Shehu Dikko ni àjọ FIFA ti yàn báyìí sára ìgbìmọ̀ àwọn tọ́rọ̀ kàn gbọ̀ngbọ̀n nínú àjọ ọ̀hún, lẹ́yìn tí ó kópa nínú ìpàdé àpérò àkọ́kọ́ ìgbìmọ̀ ọ̀hún tí ó wáyé ní Zurich, lórílẹ̀-èdè Switzerland tí ń ṣe olú-ìlú àjọ FIFA lọ́jọ́ru (Wednesday), Ààrẹ àjọ FIFA, Gianni Infantino àti igbákejì rẹ̀, Victor Montagliani lẹ́ni tí ó tún jẹ́ ààrẹ àjọ CONCACAF ni wọ́n pawọ́ pọ̀ láti ṣèfilọ́lẹ̀ ìgbìmọ̀ tuntun náà.
Infantino ṣèfilọ́lẹ̀ Dikko, ẹni tí ó tún dípò alága kátàkárà, onígbọ̀wọ́ àjọ NFF, láti dara pọ̀ mọ́ ìgbìmọ̀ ọ̀hún ṣaájú ìpàdé àpérò àjọ FIFA kẹta tí yóò tún wáyé.
Ẹ̀wẹ̀, Shehu Dikko dara pọ̀ mọ́ ìgbìmọ́ àjọ FIFA nínú oṣù kọkànlá ọdún 2017. Bákan náà ni ó tún jẹ́ ọmọ ẹgbẹ́ ìgbìmọ̀ àjọ CAF.
--- Èsì ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ ìdíje NPFL tí ó wáyé lópin ọ̀sẹ̀.
Èyí ní èsì ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ ìdíje NPFL, Nigeria Professional Football League tí ó wáyé lọ́jọ́ Àìkú (Sunday):Heartland FC 0-1 Lobi StarsNasarawa United 1-0 Wikki TouristsRivers United 1-1 FC IfeanyiUbahAbia Warriors 1-0 Kwara UnitedEl-Kanemi Warriors 0-0 Niger TornadoesKano Pillars 2-0 Go Round FCSunshine Stars 1-1 Rangers International.
--- Onome Ebi bọwọ́ lu ìwé-ìṣiṣẹ́pọ̀ ikọ̀ agbábọ́ọ̀lù Henan Huishang FC.
Atamátàsé ikọ̀ agbábọ́ọ̀lù obìnrin orílẹ̀-èdè Nàìjíríà, Ọ̀nọ̀mẹ Ebí tí bọwọ́lu iwé-ìṣiṣẹ́pọ̀ ikọ̀ agbábọ́ọ̀lù Henan Huishang FC, tí ó ń kópa nínú ìdíje orílẹ̀-èdè China.
Onome Ebi tí ó gba ife-ẹ̀yẹ ìdíje African Women Championships (AWC) ní ìgbà mẹ́ta ọ̀tọ̀ọ̀tọ̀ tí padà sórí pápá báyìí, lẹ́yìn ìfarapa tí ó ní nínú àṣekáágbá ìdíje AWC lọ́dún 2016 pẹ̀lú ikọ̀ agbábọ́ọ̀lù orílẹ̀-èdè Cameroon.
Koye Ṣówẹ̀mímọ́, tí ó jẹ́ olórí ẹ̀ka eré-ìdárayá nílé iṣẹ́ Temple Management Company (TMC), fí ìdùnnú rẹ̀ hàn púpọ̀ láti rí Ebi padà lórí pápá.
Mo dúpẹ́ lọ́wọ́ Ọlọ́run fún àǹfààní yìí.
--- Ààrẹ Buhari yóò gbàlejò ife-ẹ̀yẹ agbááyé.
Ní báyìí, gbogbo ètò ló ti tò sílẹ̀ fún Ààrẹ Muhammadu Buhari, ìgbìmọ̀ àjọ NFF àti àwọn tọ́rọ̀ kàn gbọ̀ngbọ̀n láti gbàlejò ife-ẹ̀yẹ bọ́ọ̀lù àgbááyé ní Náìjíríà, èyí tí ó jẹ́ ojúṣe àjọ tó ń rí sí bọ́ọ̀lù lágbàáyé FIFA láti lọ ṣàfihàn ìfe-ẹ̀yẹ ọ̀hún lórílẹ̀-èdè kọ̀ọ̀kan tí yóò máa kópa nínú ìdíje àgbááyé náà Bákan náà, ni àwọn olólùfẹ́ bọ́ọ̀lù àfẹsẹ̀gbá nílùú Abuja àti Èkó yóò ní àǹfààní láti yàwòrán pẹ̀lú ife-ẹ̀yẹ àgbááyé ọ̀hún.
Ẹ̀wẹ̀, èyí yóò tún ta ikọ̀ agbábọ́ọ̀lù Super Eagles jí, láti lọ ṣojú orílẹ̀-èdè yìí dáradára lórílẹ̀-èdè Russia, kí wọn kó sì gba ife-ẹ̀yẹ ọ̀hún padà wá sílé.
--- NFF ṣe ìfilọ́lẹ̀ ìgbìmọ̀ tuntun.
Ààrẹ àjọ NFF, Amaju Pinnick ṣe ìfilọ́lẹ̀ ìgbìmọ̀ tí yóò máa ṣàmójútó wíwọlé àti bí owó ṣe ń jáde àti ìgbìmọ̀ ìṣàkóso mìíràn nínú àjọ ọ̀hún, lọ́jọ́ Ìṣẹ́gun (Tuesday) nílé ìpàdé àjọ ọ̀hún nílùú Abuja.
Pinnick gbóríyìn fún ọ̀kan lára àwọn tọ́rọ̀ kàn gbọ̀ngbọ̀n nínú ìgbìmọ̀ ọ̀hún, ọ̀gbẹ́ni Sunday Délé-Àjàyí, fún iṣẹ́ takuntakun rẹ̀ tí ó ń gbése ní ọ̀nà láti mú ìgbèrú bá eré-ìdárayá, bẹ́ẹ̀ sì ni Ó tún kí I ṣáájú ayẹyẹ ọjọ́ ìbí rẹ̀ ọgọ́ta ọdún tí yóò wáyé lọ́sẹ̀ tó ń bọ̀.
Ó sọ pé, Ọtúnba kójú òṣùwọ̀n láti dárí ìgbìmò náà látàrí ìrírí rẹ̀ gbogbo, bẹ́ẹ̀ síní ìwùwà rẹ̀ sì yááyì, Ó tún jẹ́ oníwà tútù bí àdàbà abbl.
Ààrẹ tún sọ pé, ìgbìmọ̀ ìṣàkóso yìí, yóò máa ṣe àkọ́lé gbogbo iṣẹ́, èròǹgbà àjọ NFF lápapọ̀ fún ìdàgbásókè bọ́ọ̀lù àfẹsẹ̀gbá ní Nàìjííríà.
Pinnick fikún un pé Alága ìgbìmọ̀ ọ̀hún, Alhaji Abba Yola kò nílò ṣíṣe àfihàn rẹ̀ rárá. Ó jẹ́ ẹni tí ó lóye ìṣàkóso eré ìdárayá. Bẹ́ẹ̀ sìni, A kí i lọ́pọ̀lọpọ̀ fún gbígbà rẹ̀ láti fara jìn fún àjọ yìí.
--- Parker:- Máa fàgbà han Joshua nínú ìfigagbága Cardiff.
Joseph Parker, ọmọ orílẹ̀-èdè New Zealand ti sọ̀rọ̀ pẹ̀lú ìgboyà ṣaájú ìfigagbága heavyweight title pẹ̀lú Anthony Joshua, èyí tí yóò wáyé lọ́jọ́ kẹtàlélọ́gbọ̀n(31) oṣù kẹta.
Parker, ẹni tí okùn ìró mọ́-dìí (WBO) wà lọ́wọ́ rẹ̀, bẹ́ẹ̀ sì ni akẹẹgbẹ́ rẹ̀ Joshua ti gba okùn ìró mó-dìí (IBF) àti (WBA), wọn yóò jọ wọ̀yá ìjà ní pápá-ìṣeré Principality ní Cardiff nínú oṣù tó ń bọ̀.
Bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé, Joshua ni àwọn olólùfẹ́ eré ijà ọ̀hún fojú sí lára pé yóò yege, ṣùgbọ́n Parker ti fọwọ́-sọ̀yà pé, òun yóò fàgbà hàn ań nínú ìfigagbága náà. Parker sọ pe, Mo lè fàgbà han Anthony Joshua. Bẹ́ẹ̀ sìni, Mo lérò pé Mo ní ẹ̀bùn àrà ọ̀tọ̀ láti kojú rẹ̀.
Èyí ni ó mú inú mi dùn púpọ̀ pé, Máa fi ara mi hàn nínú ìfigagbága ńlá yìí.
"Bákan náà, ni àǹfààní láti jà níwájú ogunlọ́gọ̀ àwọn ènìyàn tún jẹ́ ohun ìwúrí.
Bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé, ọ̀pọ̀ ló sọ pé, Màá máa bẹ̀rù, ṣùgbọ́n mo rí ìjà ọ̀hún pẹ̀lú ojú mìíràn pé, A ó jọ wàákò nínú ìfigagbága ọ̀hún ni.
Akọ́nimọ̀ọ́jà Parker, Kevin Barry náà ti fọwọ́-sọ̀yà pé, òun náà nígboyà pé Parker yóò fàgbà han Joshua nínú ìfigagbága náà."
--- Agbábọ́ọ̀lù Spain tẹ́lẹ̀rí Enrique Castro jáde láyé.
Erin wó, Àjànàkú sùn bí òkè, lẹ́yìn tí agbábọ́ọ̀lù ikọ̀ Barcelona àti Spain tẹ́lẹ̀rí, Enrique Castro tí àwọn èèyàn mọ̀ sí “Quini” jáde láyé lọ́jọ́ Ìṣẹ́gun (Tuesday). Atamátàsé ọmọ ọdún mẹ́rìndínláàádọ́rin ọ̀hún, gbá ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ ọgọ́rùn-ún fún ikọ̀ Barcelona pẹ̀lú àmì-ayò mẹ́rìnlélógójì, bẹ́ẹ̀ sì ni Ó gba ife-ẹ̀yẹ Copa del Rey méjì ní sáà (1981, 1983), àti ife-ẹ̀yẹ ìdíje UEFA Cup ní sáà (1982).
Ó dolóògbé lẹ́yìn tí ó ṣàárẹ̀ ààrùn-ọ̀kan.
Bákan náà, ni ikọ̀ agbábọ́ọ̀lù Sporting Gijon FC kẹ́dùn ikú atamátàsé olóògbé ọ̀hún, lẹ́ni tí ó kópa fún ikọ̀ náà fún sáà ọ̀tọ̀ọ̀tọ̀ méji. Kí Ọlọ́run kí ó tẹ́ ẹ sí afẹ́fẹ́ rere.
Castro tún kópa fún orílẹ̀-èdè rè, Spain nínú ìdíje bọ́ọ̀lù àgbááyé lọ́dún 1978 àti 1982, bákan náà ló tún kópa nínú ìdíje European Championship lọ́dún 1980. Ó gbá àmì-ayò mẹ́jọ wọlé nínú ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ márùnlélọ́gbọ̀n tí ó gbá fún orílẹ̀-èdè Spain.
--- Infantino: A ń jíròrò lórí ìṣámúlò ẹ̀rọ VAR nínú ìdíje àgbááyé.
Ààrẹ àjọ FIFA, Gianni Infantino sọ pé, òun kò tíi ní iyè méjì nípa ṣíṣàmúlò ẹ̀rọ ìgbàlódé fọ́nrán, video assistant referee (VAR) nínú ìdíje bọ́ọ̀lù àgbááyé tó ń bọ̀ lọ́nà, pẹ̀lú gbogbo àríyànjiyàn lílo ẹ̀rọ ọ̀hún tó ń lọ lábẹ́lẹ̀.
Bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé, òn dupò akẹẹgbẹ́ rè, Aleksander Ceferin sọ pé, wọn kò ní ṣe àmúlò ẹ̀rọ ìgbàlódé náà nínú ìdíje UEFA Champions League ní sáà tó ń bọ̀.
Ẹ̀rọ VAR ọ̀hún ló ń ṣiṣẹ́ láti ran olùdarí ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ lọ́wọ́ fún àǹfààní ṣíṣe àtúnyẹ̀wò àwọn ọ̀kan-ò-jọ̀kan ìṣẹ̀lẹ̀ lórí pápá.
Èyí tí wọ́n ti ṣe àmúlò ẹ̀rọ náà nínú oríṣiríṣi ìdíje lágbàáyé.
Ìgbìmọ̀ tó ń ṣe ìfilọ́lẹ̀ ìlànà bọ́ọ̀lù àfẹsẹ̀gbá nílẹ̀ òkèèrè, IFAB nìrètí wà pé wọn yóò fẹnu kò sójúkan lọ́jọ́ àbámẹ́ta (Saturday) bóyá láti máa ṣamúlò ẹ̀rọ ọ̀hún.
Infantino wá sọ̀ pé, tí ìgbìmọ̀ náà bá bọwọ́lu lílo ẹ̀rọ VAR, wọn yóò ṣàmúlò rẹ̀ nínú ìdíje àgbááyé lórílẹ̀-èdè Russia.
--- Ilé-iṣẹ́ ìwé ìròyìn The SUN fún Pinnick lámì-ẹ̀yẹ Ó káre láí.
Ilé-iṣẹ́ ìwé ìròyìn The SUN fi àmì-ẹ̀yẹ Sports Personality of the Year dá ààrẹ àjọ NFF, Amaju Melvin Pinnick lọ́lá, fún ìgbàkejì lọ́dún méjì sẹ́yìn, lọ́jọ́ Àìkú (Sunday). Ayẹyẹ ìgbàmì ẹ̀yẹ ọ̀hún ló wáyé nílé ìtura Eko Hotels and Suites, Victoria Island, nílùú Èkó. Níbití ilé-iṣẹ́ ìwé ìròyìn náà ti ń ṣayẹyẹ ọdún márùndínlógún tí wọ́n ṣàgbékẹ̀lé rẹ̀. Nínú ìgbàmì-ẹ̀yẹ ọ̀hún, àwọn èèyàn jàǹkàn-jàǹkàn mìíràn tí wọ́n tún fi àmì-ẹ̀yẹ dá lọ́lá ni, ààrẹ àgbà ilé ìgbìmọ̀ aṣóju-sòfin, Dókítà Bùkọ́lá Sàràkí, pẹ̀lú àmì-ẹ̀yẹ olóṣèlú to tayọ jùlọ (Outstanding Politican of the Year), Gómìnà ìpínlẹ̀ Èkó, ọ̀gbẹ́ni Akinwunmi Ambode gba àmì-ẹyẹ (Man of the Year), Gómìnà ìpínlẹ̀ Rivers, Nyesom Wike (Governor of the Year), Emir ìpínlẹ̀ Kano, Alhaji Muhammad Sanusi (Courage in Leadership Award), adarí àgbà àjọ NDDC, Nsima Ekere (Public Service Award), adarí àgbà ilé ìfowópamọ́ Zenith, Peter Amangbo (Banker of the Year), Dókítà Emeka Okwuosa (Investor of the Year); Dókítà Samuel Adédoyin (Lifetime Achievement Award); adarí àgbà ilé ìfowópamọ́ àgbà CBN, Godwin Emefiele (Public Service Award), bẹ́ẹ̀ sì ni aṣòfin Osita Izunaso àti Dókìtà gba àmì-ẹ̀yẹ ìsọmọnìyàn (Humanitarian Service Award).
Ẹ̀wè, lásìkò ìgbàmì-ẹ̀yẹ náà, Pinnick fi àǹfààní ọ̀hún gbóríyìn fún akọ́nimọ̀ọ́gbá àgbà ikọ̀ agbábọ́ọ̀lù Super Eagles, Gernot Rohr látàrí iṣẹ́ takuntakun rẹ̀ nínú ikọ̀ náà. Bákan náà, Ó tún gbóṣùbà fún àwọn tí ó ṣagbátẹrù ìgbàmì ẹ̀yẹ ọ̀hún àti àwọn ọmọ ẹgbẹ́ àjọ NFF fún ìfọwọ́sowọ́pọ̀ wọn pátápátá ní ọ̀nà láti mú ìgbèrú bá eré bọ́ọ̀lù àfẹsẹ̀gbá lórílẹ̀-èdè Nàìjííríà.
Àwọn mìíràn tí ó tún kópa nínú ìgbàmì-ẹ̀yẹ ọ̀hún ni, amòfin Sèyí Akínwùnmí, tí ó jẹ́ igbákejì ààrẹ NFF tẹ́lẹ̀rí, bákan náà ni àwọn ọmọ ẹgbẹ́ mìíràn, alága àwọn tọ́rọ̀ kàn gbọ̀ngbọ̀n nínú àjọ NFF, Mallam Shehu Dikko, abbl.
Gernot Rohr ni ó kùnà láti kópa nínú ìpàdé àpérò náà látàrí ìpàdé ìgbáradì ìdíje bọ́ọ̀lù àgbááyé tí ó lọ fún lórílẹ̀-èdè Russia.
--- Èsì ìdíje bọ́ọ̀lù ilẹ̀-Gẹ̀ẹ́sì tí ó wáyé lópin ọ̀sẹ̀.
Èyí ni èsì ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ ìdíje English Premier League (EPL), tí ó wáyé lópin ọ̀sẹ̀: Leicester City 1 â€“ 1 Stoke CityAFC Bournemouth 2 â€“ 2 Newcastle UnitedBrighton & Hove Albion 4 â€“ 1 Swansea CityBurnley 1 â€“ 1 SouthamptonLiverpool 4 â€“ 1 West Ham UnitedWest Bromwich Albion 1 â€“ 2 Huddersfield TownWatford 1 â€“ 0 EvertonCrystal Palace 0 â€“ 1 Tottenham HotspurManchester United 2 â€“ 1 Chelsea Bákan náà, èsì ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ àṣekágbá ìdíje EFL Ikọ̀ agbábọ́ọ̀lù Manchester City fàgbà han Arsenal FC pẹ̀lú àmì ayò mẹ́ta sóódo (3-0).
--- Èsì ìdíje NPFL tí ó wáyé lópin ọ̀sẹ̀.
Èyí ni èsì ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ ìdíje Nigeria Professional Football League (NPFL), tí ó wáyé lọ́jọ́ Àìkú (Sunday):MFM FC 0-0 Lobi Stars FCEnyimba International 2-1 Sunshine Stars FCKwara United 0-1 Rivers UnitedWikki Tourists 1-1 Katsina UnitedRangers International 1-1 Kano PillarsYobe Desert Stars 2-0 El-Kanemi WarriorsNiger Tornadoes 2-0 Abia WarriorsFC IfeanyiUbah 1-0 Nasarawa United.
--- Mikel jẹ́ ọ̀kan lára agbábọ́ọ̀lù Nàìjííríà tó ṣàṣeyọrí jùlọ Siasia.
Agbábọ́ọ̀lù àti akọ́nimọ̀ọ́gbá àgbà ikọ̀ Super Eagles tẹ́lẹ̀rí, Samson Siasia sọ pé, kò sí nǹkan tí ó ṣe pàtàkì nínú ìfẹ́ tí òun ní sí balógun ikọ̀ Super Eagles, Mikel Obi.
Siasia yànàná ọ̀rọ̀ yìí látàrí awuyewuye mímú Obi lọ kópa nínú ìdíje 2016 Olympic, èyí tí ó sì gba àmì-ẹyẹ ipò kẹta silver wálé.
Kò sí nǹkan tí ó ṣe pàtàkì láàrin èmi pẹ̀lú Ò̀bí; ó kàn jẹ́ pé mo nífẹ̀ẹ́ rẹ̀ púpọ̀ gẹ́gẹ́ bí agbábọ́òlù.
Bẹ́ẹ̀ sìni Ó jẹ́ ọ̀kan lára àwọn agbábọ́ọ̀lù Nàìjííríà tí ó ti ṣàṣeyọrí nínú eré bọ́ọ̀lù lágbàáyé.
Òbí kópa fún ikọ̀ agbábọ́ọ̀lù tí ó lààmìlaaka láti ọjọ́ kékeré ayé rẹ̀, bẹ́ẹ̀ sì ni ó ti gba oríṣiríṣi ife-ẹ̀yẹ gẹ́gẹ́ bí agbábọ́ọ̀lù, ó sì tún jẹ́ akínkanjú ẹni tó ń fara jìn fún iṣẹ́ rẹ̀.
"Bákan náà, ipa rẹ̀ nínú ikọ̀ Super Eagles kò ṣe é yẹ̀ sílẹ̀, fún ìdí èyí, tani kò ní nífẹ̀ẹ́ sí irú agbábọ́ọ̀lù yìí,""."
Ó fikún un pé, Obi ti kópa dáradára nínú ikọ̀ rẹ̀ nílẹ̀ òkèèrè àti ikọ̀ agbábọ́ọ̀lù Super Eagles.
Ní ìgbà kan rí, Siasia fi Obi wé agbábọ́ọ̀lù ọwọ́ àárín ikọ̀ agbábọ́ọ̀lù Real Madrid, Luka Modric àti àwọn agbábọ́ọ̀lù jàǹkànjàǹkàn mìíràn lágbàáyé.
Mikel lọ sojú Nàìjííríà nínú ìdíje bọ́ọ̀lù àgbááyé tàwọn ọ̀dọ́ tọ́jọ́ orí wọn kò ju ogún ọdún lọ, FIFA U-20 World, tí Ó sì gba àmì ẹ̀yẹ agbábọ́ọ̀lù kẹta tí ó kópa jùlọ nínú ìdíje náà tẹ̀lé Lionel Messi, bẹ́ẹ̀ sí ni ó bẹ̀ẹ̀rẹ̀ sí ní kópa fún Super Eagles lọ́jọ́ kẹtàdínlógún oṣù kẹjọ ọdún 2005.
--- Morocco yóò ṣagbátẹrù ìdíje bọ́ọ̀lù àgbááyé lọ́dún 2026 - Blatter.
Ààrẹ àjọ FIFA tẹ́lẹ̀rí, Sepp Blatter ti gbè sí orílẹ̀-èdè Morocco lẹ́yìn láti ṣagbátẹrù ìdíje bọ́ọ̀lù àgbááyé lọ́dún 2026, lẹ́yìn tí ó fọwọ́ sọ̀yà pé orílẹ̀-èdè ọ̀hún ti ó kángún sí àríwá gúsú ilẹ̀ Áfíríkà tó gbangba sùn lọ́yẹ́.
Morocco ti ń gbèrò láti ṣagbátẹrù ìdíje bọ́ọ̀lù àgbááyé fún ìgbà karùn-ún báyìí, bákan náà wọn tún gbìyànjú láti ṣagbátẹrù ìdíje náà lọ́dún 1994, 1998, 2006 àti ọdún 2010.
Àwọn orílẹ̀-èdè mìíràn tí ó tún gbèrò láti ṣagbátẹrù ìdíje yìí papọ̀ lórílẹ̀-èdè U.S, Canada àti Mexico, èyí tí ìgbìmọ̀ tó ń rí sí bọ́ọ̀lù àfẹsẹ̀gbá lágbàáyé FIFA yóò ṣe ìpàdé àpérò rẹ̀ nínú oṣù kẹfà, ní Moscow láti mọ orílẹ̀-èdè tí ó kójú òsùwọ̀n jùlọ láti ṣagbátẹrù ìdíje náà.
Ìdíje bọ́ọ̀lù àgbááyé ọdún 2026: gbìgbìmọ̀pọ̀ láti ṣagbátẹrù ìdíje bọ́ọ̀lù àgbááyé kò jẹ́ ìtẹ́wọ́gbà fún àjọ FIFA, lẹ́yìn èyí tí ó wáyé lọ́dún 2002.
"Ní báyìí: Morocco ni ó ṣì láǹfààní báyìí láti ṣagbátẹrù rẹ̀, tí yóò sì tún fàyèsílẹ̀ fún ilẹ̀-Áfíríkà!"""
Blatter, tí ó jẹ́ ààrẹ àjọ FIFA láti ọdún 1998 sí 2015, kò tẹ́wọ́ gba àpapọ̀ ṣíṣe agbátẹrù ìdíje bọ́ọ̀lù àgbááyé yìí láàrin orílẹ̀-èdè méjì, lẹ́yìn èyí tí ó ti wáyé lọ́dún 2002 ní Japan àti South Korea, èyí tí ó sì jẹ́ ìgbà àkọ́kọ́ rẹ̀ tí orílẹ̀-èdè méjì yóò gbìmọ̀pọ̀ láti ṣagbátẹrù ìdíje náà.
Ọmọ ọgọ́rin ọdún ọ̀hún, Blatter fipò rẹ̀ sílẹ̀, tí wọ́n sì tún fòfin dè é fún ọdún mẹ́fà látàrí títàpá sí ìlànà ìgbìmọ̀ àjọ FIFA.
Irúfé ìdíje ńlá yìí tí o wáyé kẹ́yìn nílẹ̀ Áfíríkà, wáyé lórílẹ̀-èdè South Africa lọ́dún 2010, èyí tí Blatter kòsí kábàámọ̀ pé ilẹ̀-Áfíríkà ṣagbátẹrù rẹ̀.
--- Russia 2018: Aiteo gbóríyìn fún ètò NFF fún ìpalẹ̀mọ́ ìdíje bọ́ọ̀lù àgbááyé.
Onígbọ̀wọ́ ikọ̀ agbábọ́ọ̀lù Super Eagles, ilé-iṣẹ́ epo rọ̀bì Aiteo ti fi ìdùnnú rẹ̀ hàn fún ètò àti ìpalẹ̀mọ́ ọlọ́kan-ò-jọ̀kan tí àjọ tó ń rí sí bọ́ọ̀lù àfẹsẹ̀gbá ní Nàìjííríà, NFF ti ń pèsè sílẹ̀ ṣaájú ìdíje bọ́ọ̀lù àgbááyé tó ń bọ̀ lọ́nà lórílẹ̀-èdè Russia.
Igbákejì adarí ilé-iṣẹ́ Aiteo, Francis Peters, Nínú ọ̀rọ̀ rẹ̀ lásìkò ìpàdé ìgbàmì-ẹ̀yẹ èyí tí ó wáyé nílùú Èkó lọ́jọ́ Ajé (Monday), Ó ní inú ilé-iṣẹ́ Aiteo dùn lọ́pọ̀lọpọ̀ fún àwọn ètò àjọ NFF tí wọ́n ṣẹ̀ṣẹ̀ kéde fún ìpalẹ̀mọ́ ìdíje ńlá yìí.
Ó fikún un pé Ní pàtàkì inú wá dùn púpọ̀ fún ìpalẹ̀mọ́ àjọ NFF ṣaájú ìdíje bọ́ọ̀lu àgbááyé yìí, èyí tí ó fara hàn gbangba gbàǹgbà pé ikọ̀ Super Eagles náà ti ṣetán fún ìdíje náà.
Èrò wa ni láti rí Super Eagles kí ó kópa dáradára kọjá èròńgbà wa.
AITEO tí ó jẹ́ onígbọ̀wọ́ ikọ̀ agbábọ́ọ̀lù Super Eagles yóò wà ní digbí lórílẹ̀-èdè Russia fún àtìlẹyìn tí ò lẹ́gbẹ́ àti igbani-níyànjú.
Láti ṣàfihàn mímú ikọ̀ yìí lọ́kùn-únkúndùn, pàápàá jùlọ fún ikọ̀ náà láti lọ ṣàṣeyọrí nínú ìdíje yìí, à ti san ọgbòn ọ̀kẹ́ owo dollar ($600,000) àti okòólélọ́ọ̀ọ́dúnrún mílíọ́nù owo Naira (N320 million) láti pèsè àwọn ohun èlò lọ́lọ́kan-ò-jọ̀kan fún ìgbáradì ní kíkún fún ìdíje bọ́ọ̀lù àgbáyé yìí.
"Peters tèsíwájú pé, inú òun dùn púpọ̀, bẹ́ẹ̀ sìni ó jẹ́ ohun ìwúrí láti rí àwọn olùdarí àgbà tuntun àjọ tó ń rí sí bọ́ọ̀lù àfẹsẹ̀gbá nílẹ̀ Áfírík̀a CAF fún àtìlẹyìn àti akitiyan wọn láti gbé bọ́ọ̀lù ẹ̀yà Afrika dé ìpele tí ó lápẹẹrẹ, bákan náà, àjọ FIFA fún ìgbèrú tí ó ṣeé yẹ̀ sílẹ̀ tí wọ́n mú bá bọ́ọ̀lù àfẹsẹ̀gbá lágbàáyé.
Peters tún gbóríyìn fún Gómìnà ìpínlẹ̀ Èkó, Ọ̀gbẹ́ni Akínwùmí Ambode àti ìjọba rẹ̀ fún àtìlẹyìn wọn láti mú ìgbèrú bá bọ́ọ̀lù àfẹsẹ̀gbá ní Nàìjííríà àti ní ilẹ̀ Áfíríkà.
--- MFM FC pegedé sínú ìpele kejì ìdíje CAF Champions League.
MFM FC ilú Èkó, nínú ìfigagbága ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ tí ó wáyé lọ́jọ́ru (Wednesday), ikọ̀ ọ̀hún pegedé sínú ìpele kejì ìdíje CAF Champions League, léyìn tí wọ́n fàgbà han ikọ̀ agbábọ́ọ̀lù AS Bamako orílẹ̀-èdè Mali pẹ̀lú àmì-ayò kan sóódo (1-0).
MFM pegedé lápapọ̀ àmì-ayò ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ ọ̀hún, lẹ́yìn tí ikọ̀ ọ̀hún gbá àmì-ayò kọ̀ọ̀kan nínú ìfigagbága àkọ́kọ́ tí ó wáyé lórílẹ̀-èdè Mali, kí wọn ó tó wá gbá àmì-ayò kan sóódo ní pápá ìṣeré Agége.
Akuneto Chijioke ló gbá àmì ayò kan ṣoṣo ọ̀hún wọlé ní sáà kejì ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ náà, èyí tí Lawal Àbáyọ̀mí ọmọ ọdún mẹ́rìndínlógún ṣì ṣe ìrànwọ́ àmì-ayò ọ̀hún.
Ó fikún un pe, Àwọn agbábọ́ọ̀lù mi ti fi ara wọn hàn pé àwọn tó gbangba sùn lọ́yẹ́.
Bẹ́ẹ̀ sì ni, a fi ń da àwọn olólùfẹ́ wa àti ìjọba ìpínlẹ̀ Èkó lójú pé, a kò ní jáwọn kulẹ̀ nígbà kankan.
Ẹ̀wẹ̀, àwọn agbábọ́ọ̀lù tí kò kópa fún MFM FC nínú wọn la ti rí, Sikiru Ọlátúnbọ̀sún, Akila /Jesse, Ṣhọlá Brossa àti Waheed Àkànní, èyí sì wáyé látàrí ìdojúkọ tí ó wáyé lásìkò ìforúkọsílẹ̀ fún ìdíje náà."
--- Infantino:-Russia ṣetán láti ṣagbátẹrù ìdíje bọ́ọ̀lù àgbááyé.
Ààrẹ àjọ FIFA, Gianni Infantino sọ̀rọ̀ lórí ìgbésẹ̀ ìgbáradì tí Russia ti gbé láti gbàlejò ìdíje lọ́dún yìí.
--- Ààrẹ FIFA- Bọ́ọ̀lù àfẹsẹ̀gbá ní Nàìjííríà ju ọ̀rọ̀ ẹ̀sìn lọ.
Ààrẹ àjọ FIFA, Gianni Infantino ti ṣàlàyé bọ́ọ̀lù àfẹsẹ̀gbá ní Nàìjííríà gẹ́gẹ́ bí ohun tí ó ju ọ̀rọ̀ ẹ̀sìn lọ.
Nínú ìpàdé ìgbàmì ẹ̀yẹ ọ̀hún tí ó wáyé nílé ìtura Eko Hotels and Suites, ni wọ́n ti fi àmì-ẹ̀yẹ agbábọ́ọ̀lù tí ó dára jùlọ tí àjọ NFF dá agbábọ́ọ̀lù ikọ̀ Chelsea FC, Victor Moses lọ́lá.
Bákan náà, Moses tún gba ife-ẹ̀yẹ ìdíje EPL fún ikọ̀ agbábọ́ọ̀lù Chelsea ní sáà 2016/2017, tí ó sì kópa nínú ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ ogójì fún ikọ̀ náà.
Àwọn agbábọ́ọ̀lù tí ó tún gba onírúurú àmì-ẹ̀yẹ mìíràn ni: Rasheedat Ajíbádé, agbábọ́ọ̀lù obìnrin AITEO-NFF tí ó dára jùlọ Player of the Year (Women), Ikouwon Udoh, àmì-ẹ̀yẹ agbábọ́ọ̀lù tí ó kéré jùlọ Young Player of the Year (Women).
Ann Chiejine, akọ́nimọ̀ọ́gbá tí ó dára jùlọ Coach of the Year (Women), tí agbábọ́ọ̀lù ikọ̀ MFM FC, Sikiru Ọlátúnbọ̀sún gba àmì-ẹ̀yẹ àmì ayò tí ó dára jùlọ
Kennedy Bòbóyè, tí ó jẹ́ akọ́nimọ̀ọ́gbá àgbà ikọ̀ agbábọ́ọ̀lù Plateau United FC tìlùú Jos.
"Channels Television gba àmì-ẹ̀yẹ Developmental Award""."
All-Time Legendary Awards lọ sọ́dọ̀ Chiejine, Christian Chukwu, Uche Okechukwu, Austin Eguavoen, Felix Owólabí, Austin Okocha, Nwankwo Kanu, Ṣẹ́gun Ọdẹ́gbàmí, Adokie Amaesimaka, Mercy Udoh ati Thompson Usiyen.
The Platinum Award lọ sọ́dọ̀ Ààrẹ àjọ FIFA Infantino
--- Tennis: Roger Federer gba ife-ẹ̀yẹ Rotterdam Open.
Roger Federer ṣayẹyẹ ìpadàsípò kínni rè lágbàáyé pẹ̀lú gbígba ife-ẹ̀yẹ Rotterdam Open lọ́jọ́ Àìkú (Sunday), èyí tí ó jẹ́ ife-ẹ̀yẹ mẹ́tàdínlógórun lápapọ̀ tí ó ti gbà báyìí.
Ọmọ ọdún mọ́kàndínlógójì náà, tí ó sì tún jẹ́ olùkópa tí ó dàgbà jùlọ nínú ìtàn ìdíje ATP, fàgbà han akẹẹgbẹ́ rẹ̀ láti orílẹ̀-èdè Bulgaria, Grigor Dimitrov pẹ̀lú àmì-ayò mẹ́fà sí mẹ́ji (6-2), nínú àṣekágbá ìfigagbága ẹ̀ẹ̀kan ṣoṣo ọ̀hún.
Ẹ̀wẹ̀, olùkópa ọmọ bíbí orílẹ̀-èdè Amẹ́ríkà, Jimmy Connors nìkan ní àpapọ̀ ìfe-ẹ̀yẹ tí ó gbà jù ti Federer lọ, lẹ́yìn tí ó ti gba ife-ẹ̀yẹ tí ó lé ní ọgọ́rùn-ún.
Federer, ẹni tí ó ti gba àmì-ẹ̀yẹ Grand Slam ní ìgbà ogún báyìí, yóò tún gba ipò kínní rẹ̀ padà tí ipò àtẹ tuntun ATP mìíràn bá jáde lọ́sẹ̀ tí a wà yìí.
--- Ọmọ Didier Drogba dara pọ̀ mọ́ ikọ̀ agbábọ́ọ̀lù Guingamp.
Ikọ̀ agbábọ́ọ̀lù ọ̀dọ́ Guingamp tó ń kópa nínú ìdíje orílẹ̀-èdè Faransé, tọ́jọ́ orí wọn kò ju mọ́kàndínlógún lọ, Guingamp U19 ti ra Isaac Drogba, ọmọ atamátàsé ikọ̀ agbábọ́ọ̀lù Chelsea tẹ́lẹ̀rí, tí ó tún jẹ́ ọmọ orílẹ̀-èdè Cote dIvoire, Didier Drogba wá sínú ikọ̀ náà báyìí.
Ikọ̀ agbábọ́ọ̀lù Guingamp sọ̀rọ̀ ọ̀hún di mímọ̀ lórí ẹ̀rọ ayélujára lọ́jọ́ Ajé (Monday).
Ọmọ ọdún mẹ́tàdínlógún ọ̀hún, Isaac Drogba yóò tún lọ kópa fún ikọ̀ agbábọ́ọ̀lù Guingamp, tí bàbá rẹ̀ ti kópa fún lọ́dún mẹ́rìndínlógún sẹ́yìn.
"Drogba fi ìdùnú rẹ̀ hàn lẹ́yìn tí ó kí ọmọ rẹ̀ kú oríire lórí ẹ̀rọ ayélujára Instagram,""ó jẹ́́ ohun ìwúrí fún mi láti ríi pé Isaac dara pọ̀ mọ́ Guingamp""."
Didier Drogba kópa fún ikọ̀ agbábọ́ọ̀lù Guingamp fún sáà kan, kí ó tó lọ dara pọ̀ mọ́ ikọ̀ agbábọ́ọ̀lù Le Mans lọ́dún 2002.
Ẹ̀wẹ̀, Drogba tún fikọ̀ agbábọ́ọ̀lù Marseille sílẹ̀, tí ó sì tún lọ dara pọ̀ mọ́ ikọ̀ agbábọ́ọ̀lù Chelsea, níbi tí ó ti gba ife-ẹ̀yẹ ìdíje EPL àti ìdíje UEFA Champions League.
--- Wọn yóò ṣàmúlò ẹ̀rọ ìgbàlódé VAR nílẹ̀ Áfíríkà.
Ní báyìí, fún ìgbà àkọ́kọ́ wọn yóò lo ẹ̀rọ ìgbàlódé Fonran, Video Assistant Referee [VAR] nílẹ̀ Áfíríkà ní pápá ìṣeré Stade Mohammed V, Casablanca lọ́jọ́ Àbámẹ́ta (Saturday).
Àjọ tó ń rí sí bọ́ọ̀lù àfẹsẹ̀gbá nílẹ̀ Áfíríkà CAF, ló sọ ọ̀rọ̀ ọ̀hún di mímọ̀ pé, wọn yóò lo ẹ̀rọ ìgbàlódé náà nínú ìdíje 2018 Caf Super Cup, èyí tí yóò wáyé láàrin ikọ̀ agbábọ́ọ̀lù Wydad Athletic Club àti TP Mazembe lọ́jọ́ Àìkú (Saturday).
Ìfigagbága ìdíje 2018 CAF Super Cup , ni ó máa ń wáyé láàrin ikọ̀ tí ó bá gba ife-ẹ̀yẹ 2017 Caf Champions League àti ikọ̀ agbábọ́ọ̀lù tí ó bá gba ife-ẹ̀yẹ 2017 Caf Confederation Cup.
Ẹ́̀wẹ̀, látàrí ṣíṣe àmúlò ẹ̀rọ ìgbàlódé ọ̀hún nínú ìdíje African Nations Championship tí ó wáyé lórílẹ̀-èdè Morocco, àjọ Caf, ìgbìmọ̀ tó ń rí sí bọ́ọ̀lù àfẹsẹ̀gbá nílẹ̀-òkèrè, International Football Association Board (IFAB) àti àjọ tó ń rí sí bọ́ọ̀lù àfẹsẹ̀gbá lágbàáyé FIFA, ti fẹnukò papọ̀ láti tún ṣàmúlò ẹ̀rọ VAR ọ̀hún nínú ìdíje 2018 Caf Super Cup tó ń bọ̀ lọ́nà.
Gẹ́gẹ́ bí akọ̀wé àgbà àjọ CAF, Amr Fahmy.
Èyí jẹ́ ohun ìtàn nínú eré ìdárayá bọ́ọ̀lù àfẹsẹ̀gbá nílẹ̀ Áfíríkà.
"Bákan náà, alákòóso olùdarí àwọn ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ àjọ CAF, Eddy Maillet fi ìdùnú rẹ̀ hàn fún ìfilọ́lẹ̀ ṣíṣe àmúlò ẹ̀rọ ìgbàlódé náà nílẹ̀ Áfíríkà.
Ó tẹ̀síwájú pé, àwọn ti ṣetán láti ṣe àmúlò ẹ̀rọ VAR náà nínú ọ̀kan-ò-jọ̀kan ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ CAF tí yóò máa wáyé.
--- Ganduje yóò buyi-kùn àṣekágbá ìdíje Ramat Cup.
Gómìnà ìpínlẹ̀ Kano, ọ̀gbẹ́ni Abdullahi Umar Ganduje, yóò jẹ́ àlejò pàtàkì nínú àṣekágbá mẹ́rìndínlógójì ìdíje Ramat Cup, èyí tí ìjọba ìpínlẹ̀ Kano àti àjọ tó ń rí sí bọ́ọ̀lù àfẹsẹ̀gbá àti ìdàgbàsókè àwọn ọ̀dọ́ lórílẹ̀-èdè Nàìjííríà ṣagbátẹrù rẹ̀.
Gẹ́gẹ́ bí ààrẹ YSFON, Násírù Gawuna ṣe sọ, Ó ní yàtọ̀ sí gómìnà ìpínlẹ̀ Kano, àwọn tí wọn yóò tún máa retí láti buyì kún àṣekágbá ìdíje náà, èyí tí wọ́n ṣàgbékalẹ̀ rẹ̀ láti ṣèrántí olóògbé Gen. Murtala Mohammed ni àwọn ọmọ ẹgbẹ́ ìgbìmọ̀ aṣòfin ìpínlẹ̀ ọ̀hún àti àwọn èèyàn jàǹkàn-jàǹkàn lóríṣiríṣi nípìnlẹ̀ náà àti lórílẹ̀-èdè Nàìjííríà.
Gawuna ṣàlàyé pé, Gomina Ganduje fẹ́ láti kópa nínú àṣekágbá ìdíje náà látàrí ìfẹ́ tí ó ní fún ìdàgbàsókè àwọn ọ̀dọ́ àti fún eré-ìdárayá.
Ganduje jẹ́ Gómìnà tí ó fẹ́ràn eré-ìdárayá púpọ̀, tí ó sì máa ń setán láti ran àwọn ọ̀dọ́ lọ́wọ́ nípasẹ̀ kíkún wọn lọ́wọ́ láti mú ìgbèrú bá ẹ̀bùn tí wọ́n ní fún àǹfààní àwọn ará-ìlú àti ìdàgbàsókè orílẹ̀-èdè.
Nínú ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ ìpele kejì sí àṣekágbá ìdíje Ramat Cup ọ̀hún, ikọ̀ agbábọ́ọ̀lù kano fàgbà han Kwara pẹ̀lú àmì-ayò kan sóódo (1-0), bẹ́ẹ̀ sì ni ìpínlẹ̀ Èkó jẹ oore-ọ̀fẹ́ aṣemáse tí ìpínlẹ̀ Kebbi ṣe, lẹ́yìn tí ikọ̀ ọ̀hún lo agbábọ́ọ̀lù ti ́kò lẹ́tọ̀ọ́ láti kópa nínú ìdíje náà, èyí tí ó ṣokùnfa bí ìpínlẹ̀ Èkó ṣe yege sínú àṣekágbá ìdíje ọ̀hún.
Ẹ̀wẹ̀, Kano tí ó ṣagbátẹrù ìdíje ọ̀hún, yóò máa wàákò pẹ̀lú ìpínlẹ̀ Èkó nínú ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ tí yóò máa wáyé ní pápá ìṣeré ikọ̀ agbábọ́ọ̀lù Kano Pillars, Sabon Garri, Kano.
--- NPFL: Abia Warriors fàgbà han Yobe Desert Stars.
Ikọ̀ agbábọ́ọ̀lù Abia Warriors FC lọ́jọ́ Àìkú (Sunday) gbo ewúro sí akẹẹgbẹ́ wọn lójú láti ìpínlẹ̀ Yobe, Yobe Desert Stars FC pẹ̀lú àmì-ayò mẹ́ta sóókan (3-1), ní pápá ìṣeré Umuahia Township Stadium.
Atamátàsé ikọ̀ ọ̀hún Effiong Ndifereke ló gbá àmì-ayò kínní wọlé níṣẹ̀ẹ́jú mọ́kàndínlọ́gbọ̀n sáà àkọ́kọ́ ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ ọ̀hún, béẹ̀ sì ni Sam Obi gbá àmì-ayò kejì wọlé kí sáà àkọ́kọ́ ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ náà ó tó wá sí ìparí.
Bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé, ikọ̀ Yobe Desert ṣe gudugudu méje òhun yàhàyà mẹfà láti gba àmì-ayò kan wọlé níṣẹ̀ẹ́jú mọ́kàndínlọ́gọ́rin sáà kejì ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ náà, ṣùgbọ́n omi pọ̀ ju ọkà lọ, lẹ́yìn tí Abia Warrios tún gbá àmi-ayò mìíràn wọ̀lé, ẹ̀yí tí ó kásẹ̀ ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ náà nílẹ̀.
Gẹ́gẹ́ bí akọ́nimọ̀ọ́gbá ikọ̀ Yobe Stars, Ganaru Mohammed ṣe sọ,Èsì ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ yìí bàmí nínú jẹ́ púpọ̀."
Akọ́nimọ̀ọ́gbá àgbà Abia Warriors Emmanuel Deutsch gbósùbà káre láí fún ikọ̀ rẹ̀ lẹ́yìn tí wọ́n jáwé olúborí nínú ìfigagbága náà.
--- Nàìjííríà já wálẹ̀ nínú ipò àtẹ àjọ FIFA.
Nàìjííríà já wálẹ̀ nínú ipò àtẹ tuntun àjọ FIFA, èyí tí ìgbìmọ̀ tó ń rí sí bọ́ọ̀lù àfẹsẹ̀gbá lágbàáyé gbé jáde lọ́jọ́bọ (Thursday).
Gẹ́gẹ́ bí àtẹ̀jáde àjọ FIFA tí ó jáde nínú ẹ̀rọ ayélujára wọn lọ́jọ́bọ (Thursday) ṣe sọ, Ikọ̀ agbábọ́ọ̀lù Super Eagles tí ó wà ní ipò mọ́kànléláàádọ́tà lágbàáyé pẹ̀lú àmì ọ̀tàlélẹ́gbẹ̀ta-dín-,mẹ́ta nínú oṣù-kínní ọdún yìí.
Ikọ̀ Nàìjííríà sepò kejì nínú ìdíje CHAN tí ó wáyé lórílẹ̀-èdè Morocco.
Ẹ̀wẹ̀, lẹ́yìn tí ikọ̀ ọ̀hún já wálẹ̀ nínú àtẹ̀jáde ipò àtẹ FIFA lósù tí ó kọjá látàrí dídín àmì ikọ̀ náà tí wọ́n fi pegedé fún ìdíje bọ́ọ̀lù àgbááyé, ọ̀pọ̀ nínú àwọn olólùfẹ́ ikọ̀ Super-Eagles ló fọkàn si pé, ipò àtẹ mìíràn yóò wá sókè, ṣùgbọ́n tí kò rí bẹ́ẹ̀.
Ní báyìí, Super Eagles dipò keje mú nílẹ̀ Áfíríkà, tí orílẹ̀-èdè Tunisia, Senegal, DR Congo, Morocco, Egypt àti Cameroon sì tẹ̀léra wọn.
Orílẹ̀-èdè Ghana, Burkina Faso àti Algeria náà tẹ̀léra wọn pẹ̀lú ipò kẹjọ, kẹsàn-án àti ìkẹwà-á lórí ipò àtẹ túntún ọ̀hún.
Ipò àtẹ tuntun mìíran yóò tún jáde lọ́jọ́ karùndínlógún oṣù kẹta .
--- Ronaldo fìtàn balẹ̀ nínú ìdíje Uefa Champions League gbígbá ọ̀gọ́rùn-ún àmì-ayò. wọ̀lé
Atamátàsé ikọ̀ agbábọ́ọ̀lù Real-madrid, Cristiano Ronaldo di agbábọ́ọ̀lù àkọ́kọ́ tí yóò gbá ọ̀gọ́rùn-ún àmì-ayò wọ̀lé nínú ìtàn ìdíje Uefa Champions League fún ikọ̀ kan-náà, lẹ́yìn tí ó gbá àmì-ayò méjì wọ̀lé nínú ìfagagbága pẹ̀lú ikọ̀ agbábọ́ọ̀lù Paris Saint-German lọ́jọ́rú (Wednesday).
Ẹ̀wẹ̀, bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé, ikọ̀ agbábọ́ọ̀lù PSG ló kọ́kọ́ gbá àmì-ayò àkọ́kọ́ wọlé, ṣùgbọ́n ikọ̀ Real Madrid padà jáwé olúborí pẹ̀lú àmì-ayò mẹ́ta sóókan (3-1) ní pápá ìṣeré Santiago Bernabeu.
--- Pápá ìṣeré Akwa-Ibom gba àmì-ẹ̀yẹ pápá tí ó dára júlọ.
Iṣẹ́ àkànṣe ìjọba ìpínlẹ̀ Akwa-Ibom lórí kíkówó lé pápá ìṣeré ìpínlẹ̀ ọ̀hún láti le gbèrú sí àti fífigagbága láàrin àwọn akẹẹgbẹ́ rẹ̀ yòókù ní ìpínlẹ̀ kọ̀ọ̀kan lórílẹ̀-èdè Nàìjíríà, pàápàá jùlọ lágbàáyé ti so èso rere, lẹ́yìn tí pápá ìṣeré ọ̀hún gba àmì-ẹ̀yẹ National Sports Summit Award, léyìí tí ó jẹ́ pápá ìṣeré tí ó ní àwọn ohun èlò ìdárayá ìgbàlóde tí ó pọ̀jùlọ láàrín àwọn akẹẹgbẹ́ rẹ̀ lórílẹ̀-èdè yìí.
Àmì-ẹ̀yẹ ọ̀hún náà fi ta ìpínlẹ̀ náà lọ́rẹ lásìkò ayẹyẹ tí ó wáyé nílùú Abuja tí ilé-iṣẹ́ tó ń rí sí eré-ìdárayá àti ìdàgbàsókè àwọn ọ̀dọ́ lórílẹ̀-èdè yìí ṣagbátẹrù rẹ̀.
Mínísítà eré-ìdárayá, Solomon Dalung ni adarí àgbà tó ń rí sí ṣíṣètò onírúurú nínú àjọ náà, ìyà-afin Hauwa Kulu-Akinyemi ló sojú rẹ̀, èyí tí kọmíṣọ́nà tó ń rí sí ọ̀rọ̀ ìfitónilétí ní ìpínlẹ̀ Akwa-Ibom, ọ̀gbẹ́ni Charles Udoh gba àmì-ẹ̀yẹ náà fún ìjọba ìpínlẹ̀ Akwa Ibom.
Ẹ̀wẹ̀, àmì-ẹ̀yẹ ọ̀hún ló jẹ́ ọ̀kan lára àmì-ẹ̀yẹ mẹ́ta tí ìpínlẹ̀ náà gbà nínú ayẹyẹ ọ̀hún.
Ìpínlẹ̀ náà tún gba àmì-ẹ̀yẹ Diamond fún ìpínlẹ̀ tó ń ṣagbátẹrù ètò lọ́lọ́kan-ò-jọ̀kan fún ìdàgbàsókè eré-ìdárayá jùlọ, bẹ́ẹ̀ sì ni wọ́n tún gba àmì-ẹ̀yẹ akínkanjú, òǹfara jìn olólùfẹ́ eré-ìdárayá lórílẹ̀-èdè yìí.
"Gẹ́gẹ́ bí Udoh ṣe sọ,""Gbígba àmì-ẹ̀yẹ mẹ́ta náà ṣàfihàn iṣẹ́ rere tí Gómìnà Udom Emmanuel gbé ṣe láti mú eré-ìdárayá lọ́kùn-únkúndùn ní ìpínlẹ̀ náà,""."
"Ó tẹnumọ́ ọn pe, gbogbo ohun tí a ti ṣe ló ti so èso rere báyìí, tí ó fi mọ́ ṣíṣe àṣeyọrí agbátẹrù ìpolongo ikọ̀ agbábọ́ọ̀lù Super Eagles tí yóò kópa nínú ìdíje bọ́ọ̀lù àgbááyé, bẹ́ẹ̀ sì ni tí a tún ní ikọ̀ agbábọ́ọ̀lù méjì nínú ìdíje bọ́ọ̀lù àfẹsẹ̀gbá tọkùnrin àti tobìnrin torílẹ̀-èdè yìí,"""
Ní ìparí, alága ayẹyẹ ìgbàmì-ẹ̀yẹ ọ̀hún, Philips Asiegbu sọ pé, títẹ́wọ́ gba ikọ̀ Super Eagles àti ọ̀kan-ò-jọ̀kan àtìlẹyìn ìjọba ìpínlẹ̀ náà àti àwọn olólùfẹ́ rẹ̀ ṣokùnfá ṣíṣe àṣeyọrí àti jíjáwé olúborí nínú ìfigagbága ìpegedé ìdíje àgbááyé náà.
--- Ìpàdé Àjọ FIFA yóò wáyé nílùú Èkó.
Àjọ tó ń rí si eré-ìdárayá bọ́ọ̀lù àfẹsẹ̀gbá lórílẹ̀-èdè Nàìjííríà, NFF sọ pé, ìpàdé àwọn tọ́rọ̀ kàn gbọ̀ngbọ̀n nínú Àjọ tó ń rí sí bọ́ọ̀lù àfẹsẹ̀gbá lágbàáyé, FIFA yóò wáyé nílùú Ékó, lórílẹ̀-èdè Nàìjííríà, èyí tí yóò jẹ́ ìpàdé kejìlá irúfẹ́ ìpàdé ọ̀hún báyìí, 12 FIFA Executive Football Summit (EFS).
"Gẹ́gẹ́ bí Ààrẹ àjọ NFF, Amaju Pinnick ṣe sọ lásìkò tó ń bá àwọn akọ̀ròyìn sọ̀rọ̀ nílùú Abuja,""Ìpàdé náà ni ìrètí wà tẹ́lẹ̀ pé yóò wáyé nínú oṣù kọkànlá ọdún 2017 sí oṣù kẹta ọdún 2018."
"Ẹ̀wẹ̀, àwọn tí yóò máa kópa nínú ìpàdé ọ̀hún nìrètí wà pé, wọn yóò mú ọ̀kan-ò-jọ̀kan ìrírí àti ìdojúkọ tí orílẹ̀-èdè wọn là kọjá, eléyìí tí wọn yóò kojú nínú ìpàdé ọ̀hún.
Ìròyìn sọ pé, lára àwọn èèyàn pàtàkì tí yóò máa kópa nínú ìpàdé ọ̀hún ni: Ààrẹ àjọ CAF, Ahmad Ahmad, akọ̀wé àgbà àjọ FIFA, Fatima Samba Samoura, Ààrẹ àjọ tó ń rí sí bọ́ọ̀lù afẹ́sẹ̀gbá lórílẹ̀-èdè Netherland, Michael Van Praag àti Slavisa Ikokezia, tí ó jẹ́ ààrẹ tuntun àjọ bọ́ọ̀lù afẹsẹ̀gbá lórílẹ̀-èdè Serbia.
Pinnick fikún ọrọ rẹ̀ pé, Ààrẹ àjọ FIFA, Gianni Infantino yóò gúnlẹ̀ sí Nàìjííríà lọ́jọ́ Ajé (Monday) fún ìpàdé ọlọ́jọ́ mẹ́ta ọ̀hún, bẹ́ẹ̀ sìni yóò mú àwọn akọ̀ròyìn lágbàáyé wá sórílẹ̀-èdè Nàìjííríà,"
--- Ìfigagbága Ìdíje UEFA CHAMPIONS LEAGUE.
Champions League ÌPELE IKỌ̀ MẸ́RÌNDÍNLÓGÚN February 1320:45 Basel ?
Tottenham Hotspur February 14 20:45 FC Porto ?
Liverpool 20:45 Real Madrid ?
--- Ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ ìdíje NPFL (Nigeria Professional Football League).
Èyí ni àwọn ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ tí yóò wáyé nínú ìdíje NPFL(Nigeria Professional Football League), lọ́jọ́ àìkú (Sunday):Enugu Rangers ?
Heartland Owerri 16:00 Kwara United ?
Katsina United 16:00 Niger Tornadoes ?
--- Ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ tí yóò máa wáyé nínú ìdíje bọ́ọ̀lù ilẹ̀-okèèrè lọ́kan-ò-jọ̀kan.
Èyí ni àwọn ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ tí yóò wáyé nínú ìdíje bọ́ọ̀lù ilẹ̀-òkèrè lọ́lọ́kan-ò-jọ̀kan lọ́jọ́ àbámẹ́ta (Saturday) àti Àìkú (Sunday):English Premier League: February 10Tottenham Hotspur ?
--- NFF ń kẹ́dùn ikú Mgbolu.
Àjọ tó ń rí sí bọ́ọ̀lù àfẹsẹ̀gbá lórílẹ̀-èdè Nàìjííríà , NFF ti ṣe ìkẹ́dùn ikú agbẹnusọ̀rọ̀ àjọ ọ̀hún tẹ́lẹ̀rí, Austin Mgbolu.
"Ẹ̀wẹ̀, nínú ọ̀rọ̀ tí agbẹnusọ̀rọ̀ àjọ náà Adémọ́lá Ọlájíire sọ,""Mgbolu ṣiṣẹ́ gẹ́gẹ́ bí agbẹnusọ̀rọ̀ àjọ (NFA) fún sáà 1993 sí 2001. Ó fi kún ọ̀rọ̀ rẹ̀ pé,"" Ó jé akínkanjú ènìyàn, bẹ́ẹ̀ sì ni Mgbolu fi ara rẹ̀ jìn fún iṣẹ́, tí ó sì fi àpẹẹrẹ rere sílẹ̀ kí ó tó jáde láyé""."
Bákan náà, akọ̀wé àgbà àjọ (NFF), Mohammed Sanusi ṣàlàyé pé, ìròyìn sọ pé Mgbolu ṣe iṣẹ́-abẹ lóṣù tí ó kọjá, léyìí tí ó sì fara hàn pé ara rẹ̀ ti mókun, ṣùgbọ́n tí àìsàn ọ̀hún tún peléke sí lọ́jọ́ru (Wednesday) léyìí tí ó ṣokùnfa ilé-ìwòsàn tí ó ti jáde láye.
--- Nike ṣàfihàn àwọn ohun èlò tuntun tí Eagles yóò lò.
Nike ti ṣàfíhan àwọn ohun èlò tuntun tí ikọ̀ agbábọ́ọ̀lù Super Eagles yóò lò nínú ìdíje bọ́ọ̀lù àgbááyé tó ń bọ̀ lọ́nà lórílẹ̀-èdè Russia lọ́jọ́rùú (Wednesday), nílùú London.
Ẹ̀wẹ̀, aṣọ̀ tuntun ọ̀hún ló ṣàfihàn ẹ̀wù tí ikọ̀ Super-Eagles wọ̀ nínú ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ ìpegedé ìdíje àgbááyé USA 94.
Alex Iwobi àti Sophia Omidiji wà lára àwọn tí o ṣàfihàn ẹ̀wù bọ́ọ̀lù tuntun ọ̀hún.
Ní báyìí, Eagles yóò lo ẹ̀wù tuntun náà fún ìgbà àkọ́kọ́ nínú ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ ọlọ́rẹ̀ẹ́jọ̀rẹ́ tí yóò wáyé láàrin ikọ̀ náà àti orílẹ̀-èdè Poland, kí wọn ó tó tẹkọ̀ létí lọ gbá ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ àkọ́kọ́ pẹ̀lú Croatia nínú ìdíje àgbááyé.
Nǹkan tí ikọ̀ le yí padà lórílẹ̀-èdè Nàìjííríà ni ìfẹ́ eré bọ́ọ̀lù àfẹsẹ̀gbá.
Bẹ́ẹ̀ sìni, ẹ̀wù tuntun ọ̀hún ni Nike pèsè láti buyì kún àṣà orílẹ̀-èdè yìí.
--- Rohr mú agbábọ́ọ̀lù CHAN Eagles méjì fún ìdíje bọ́ọ̀lù àgbááyé.
Akọ́nimọ̀ọ́gbá àgbà ikọ̀ agbábọ́ọ̀lù Super Eagles, Gernot Rohr ti mú agbábọ́ọ̀lù méjì lára ikọ̀ CHAN Eagles láti kópa nínú ìdíje bọ́ọ̀lù àgbááyé tó ń bọ̀ lọ́nà. Àwọn méjì ọ̀hún ni balógun ikọ̀ náà Ikechukwu Ezenwa àti agbábọ́ọ̀lù ọwọ́ ẹ̀yìn Stephen Eze.
Gẹ́gẹ́ bí ọ̀kan gbòógì lára òṣìṣẹ́ NFF ṣe sọ, Rohr ti pinnu láti mú Ezenwa àti Eze láti kópa nínú àwọn ikọ̀ rẹ̀ tí yóò kó lọ fún ìdíje bọ́ọ̀lù àgbááyé. Ó fikún ọ̀rọ̀ rẹ̀ pé, ò wá kù sọ́wọ̀ àwọn méjèèjì láti jà fún ààyè wọ̣n nínú ikọ̀ náà.
" Nàìjííríà pegedé sínú àṣekágbá ìdíje CHAN tí ó wáyé lórílẹ̀-èdè Morocco, ṣùgbọ́n wọ́n pàdánù ife-ẹ̀yẹ ọ̀hún sọ́wọ́ Morocco.
Ẹ̀wẹ̀, Rohr ti kéde pé òun yóò mú àwọn agbábọ́ọ̀lù tí yóò kópa fún òun nínú àwọn ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ ọlọ́rẹ̀ẹ́jọ̀rẹ́ ọlọ́kan-ò-jọ̀kan tí ikọ̀ Super-Eagles bá gbá fún ìgbáradì ìdíje àgbááyé ọ̀hún tó ń bọ̀ lọ́nà.
Ní báyìí, Super-Eagles yóò lọ kojú Poland lọ́jọ́ kẹtàlélógún oṣù kẹta ọdún tí a wà yìí, bẹ́ẹ̀ sì ni wọn yóò tún kojú Serbia lọ́jọ́ kẹtàdínlọ́gbọ̀n oṣù kẹta nílùú London.
--- Netherland yan Koeman gẹ́gẹ́ bí akọ́nimọ̀ọ́gbá àgbà tuntun.
Ronald Koeman ni orílẹ̀-èdè Netherland ti yàn báyìí gẹ́gẹ́ bí akọ́nimọ̀ọ́gbá àgbà tuntun ikọ̀ ọ̀hún.
Ní báyìí, ọmọ-ọdún mẹ́rìnléláàádọ́ta akọ́nimọ̀ọ́gbá tuntun ọ̀hún ló di akọ́nimọ̀ọ́gbá keje tí yóò tukọ̀ ikọ̀ agbábọ́ọ̀lù orílẹ̀-èdè náà láti ọdún mẹ́jọ sẹ́yìn.
Mo lérò pé, orílẹ̀-èdè Netherland yẹ kó pegedé bẹ́ẹ̀ sìni, ó yẹ kí o ́máa kópa fún ọ̀kan-ò-jọ̀kan ìdíje, mo rí àpẹẹrẹ tí ó dára fún ọjọ́ iwájú, eléyìí tí ó ṣokùnfà ìdí tí mo fi gba iṣẹ́ yìí.
Orílẹ̀-èdè Netherland ṣe ipò kejì nínú irúfẹ́ ìdíje bọ́ọ̀lù àgbááyé ọ̀hún tí ó wáyé lọ́dún 2010, bẹ́ẹ̀ sìni wọ́n tún ṣe ipò kẹta lọ́dún 2014, ìdíje bọ́ọ̀lù àgbááyé tí ó wáyé lórílẹ̀-èdè.
Ẹ̀wẹ̀, ìrètí yóò wà pé Ronald Koeman yóò ran ikọ̀ náà lọ́wọ́ láti pegedé fún ìdíje Euro 2020, bákan náà ìdíje àgbááyé ọdún 2022 lórílẹ̀-èdè Qatar.
Ní báyìí, Koeman yóò wàákò pẹ̀lú ikọ̀ agbábọ́ọ̀lù England nínú ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ ọlọ́rẹ̀ẹ́jọ̀rẹ́ ní pápá ìṣeré Amsterdam Arena lọ́jọ́ kẹtàlélógún oṣù kẹta ọdún tí a wà yìí, bákan náà, yóò tún máa wàákò pẹ̀lú ikọ̀ agbábọ́ọ̀lù Portugal nínú ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ ọlọ́rẹ̀ẹ́jọ̀rẹ́ lọ́jọ́ kẹta sí ìfigagbága pẹ̀lú orílẹ̀-èdè England.
Koeman tukọ̀ Ajax Amsterdam gba ife-ẹ̀yẹ ìdíje Eredivisie lórílẹ̀-èdè Netherland tí sáà (2001-02, 2003-04), bẹ́ẹ̀ sì ni Ó tún tukọ̀ PSV Eindhoven gba irúfẹ́ ife-ẹ̀yẹ náà lọ́dún (2006-07).
Ní àfikún, Koeman ti tukọ̀ agbábọ́ọ̀lù Vitesse Arnhem, Benfica, Valencia, AZ Alkmaar, Feyenoord àti Southampton.
--- Djokovic bẹ̀ẹ̀rẹ̀ ìgbáradì padà lẹ́yìn iṣẹ́-abẹ tí ó là kọjá.
Ní báyìí, atamátàsé agbábọ́ọ̀lù àfigigbá ọmọ orílẹ̀-èdè Serbia, Djokovic ti bẹ̀ẹ̀rẹ̀ ìgbáradí ní kíkún padà láti bí oṣù mẹ́rin sẹ́yìn t́í ó ti farapa, léyìí tí ó sì ṣe iṣẹ́-abẹ láti fi padà bọ̀ sípò. Ẹ̀wẹ̀, ìròyìn sọ pé, Djokovic ti bẹ̀ẹ̀rẹ̀ ìgbáradì báyìí láti kópa nínú ìdíje Australian Open.
Ó tẹnu mọ́ ọn pé, Mo ti ní ìpalára yìí láti ọdún méjì sẹ́yìn, bẹ́ẹ̀ sìni ni gbogbo àkókò yìí, mo ti ń rí oríṣiríṣi dókítà.
Kò rọrùn fún mi láti mọ ohun tí màá ṣe tàbí ibi tí màá lọ báyìí."
--- Nàìjííríà gba ipò kejì nínú ìdíje CHAN.
Bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé, ikọ̀ agbábọ́ọ̀lù CHAN Eagles torílẹ̀-èdè Nàìjííríà sa gbogbo ipá wọn dénú àṣekágbá ìdíje CHAN 2017 tí ó wáyé lórílẹ̀-èdè Morocco, ṣùgbọ́n omi pọ̀ ju ọkà lọ nínú ìfigagbága ọ̀hún, lẹ́yìn tí ikọ̀ CHAN torílẹ̀-èdè Morocco tí ó ṣagbátẹrù ìdíje náà gbo ewúro sí ikọ̀ ọ̀hún lójú pẹ̀lú àmì-ayò mẹ́rin sóódo (4-0), nínú ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ tí ó wáyé ní pápá ìṣeré Casablanca.
Ẹ̀wẹ̀, àmì-ayò méjì wáyé láti ọwọ́ Zakaria Hadraf, bẹ́ẹ̀ sì ni Walid El Karti àti Ayoub El Kaabi gbá àmì-ayò kọ̀ọ̀kan wọlé.
Ní àfikún, ikọ̀ agbábọ́ọ̀lù Sudan jáwé olúborí nínú ìfigagbága ìdupò kẹta, lẹ́yìn tí wọ́n fàgbà han orílẹ̀-èdè Libya.
--- Èsí ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ ìdíje bọ́ọ̀lù àfẹsẹ̀gbá torílẹ̀-èdè Nàìjííríà.
Èyí ni èsì ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ ìdíje bọ́ọ̀lù àfẹsẹ̀gbá torílẹ̀-èdè Nàìjííríà NPFL tí ó wáyé lópin ọ̀sẹ̀: Abia Warriors 0 – 0 Enugu RangersAkwa United 4 – 0 Wikki TouristEl Kanemi Warriors 0 – 0 EnyimbaKano Pillars 2 – 0 MFM FCKatsina United 2 – 0 Niger TornadoesPlateau United 5 – 0 Sunshine StarsRivers United FC 1 – 0 Go RoundHeartland Owerri 2 – 0 Kwara UnitedLobi Stars 1 – 0 Ifeanyi Ubah UnitedEwe, ìfẹsẹ̀wọnsẹ méjì yòókù yóò wáyé láàrín ikọ̀ agbábọ̀ọ̀lù Nasarawa United ? Yobe Desert Stars, láago mẹ́rin òní, bẹ́ẹ̀ sìni ọ̀kan yòókù yóò wáyé lọ́la láàrin ikọ̀ agbábọ́ọ̀lù Niger Tornadoes àti Heartland Owerri.
--- Barcelona fàgbà han Chelsea láti pegedé sípele tí ó kàn.
Lionel Messi gbá àmì-ayò méjì wọlé, bẹ́ẹ̀ sìni Ó ṣe ìrànwọ́ àmì-ayò kan fún akẹẹgbẹ́ rẹ̀ Ousmane Dembele, láti fàgbà han Chelsea pẹ̀lú àmì-ayò mẹ́ta sóódo (3-0), lọ́jọ́rùú (Wednesday).
Gẹ́gẹ́ bí ọ̀rọ̀ akọ́nimọ̀ọ́gbá àgbà Chelsea, Antonio Conte: Nínú ìfigagbága méjèèjì, a ń sọ nípa agbábọ́ọ̀lù tí ó dára jùlọ lágbàáyé, Lionel Messi ni ó tayọ jùlọ, tí ó sì mú ìyàtọ̀ wà nínú ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ ọ̀hún.
A ní láti lọ gbáradì fún ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ wa pẹ̀lú ikọ̀ agbábọ́ọ̀lù Leicester tí yóò wáyé lọ́jọ́ Àìkú (Sunday) báyìí.
Àwọn Àpéjọ Tá A Ṣe Ní Orílẹ̀-Èdè Àǹgólà Ní Ibùdó Àwọn Tó Ń Wá Ibi Ìsádi Ní Èdè Lingala àti Tshiluba
Iṣẹ́ Ń Lọ Lọ́wọ́ Lórí Ẹ̀ka Ọ́fíìsì Tuntun Tí À Ń Kọ́ ní Kamẹrúùnù
Ìròyìn: Iṣẹ́ Ti Ń Lọ Gan-an Lórí Ẹ̀ka Ọ́fíìsì Tuntun ní Kamẹrúùnù
Àwọn Ẹlẹ́rìí Jèhófà Mú Ìwé Mímọ́ Kristẹni Lédè Gíríìkì Jáde Lédè Bassa ní Orílẹ̀-èdè Kamẹrúùnù
Àwọn Ará ní Àríwá Ìlà Oòrùn Kóńgò Sá Torí Àwọn Tó Ń Jà
Àrùn Ebola Ń Jà Ràn-ìn Lórílẹ̀-Èdè Congo
Wọ́n Ti Lo Ọdún Mẹ́ẹ̀ẹ́dọ́gbọ̀n (25) Lọ́gbà Ẹ̀wọ̀n ní Eritrea
Arábìnrin Kan Kú Nínú Jàǹbá Ọkọ̀ Òfúrufú Ethiopian Airlines
Àkànṣe Ìwàásù Lórílẹ̀-Èdè Gabon
Àwọn Adigunjalè Wá sí Hòtẹ́ẹ̀lì Kan ní Kenya
Àwa Ẹlẹ́rìí Jèhófà Mú Bíbélì Mímọ́ ti Ìtumọ̀ Ayé Tuntun Jáde Lédè Luo Lórílẹ̀-Èdè Kẹ́ńyà
A Ya Ilé Ẹ̀kọ́ Ètò Ọlọ́run Kan Sí Mímọ́ ní Kẹ́ńyà
Ìjì Cyclone Ava Kọlu Madagásíkà
Àwa Ẹlẹ́rìí Jèhófà Kọ Lẹ́tà Nítorí Àwọn Ará Wa ní Rọ́ṣíà​—Láti Màláwì
Ìjì Líle Kenneth Jà ní Àríwá Mòsáńbíìkì
“Ìdùnnú Ṣubú Layọ̀”—A mú Bíbélì Ìtumọ̀ Ayé Tuntun Tá A Tún Ṣe Jáde Lédè Méjì ní Nàìjíríà
Òjò Àrọ̀ọ̀rọ̀dá Rọ̀ ní Nàìjíríà
Òjò Àrọ̀ọ̀rọ̀dá Fa Omíyalé ní Nàìjíríà
Ẹ̀ka Ọ́fíìsì Wa ní Rùwáńdà Bẹ̀rẹ̀ Sí Í Túmọ̀ Ìwé Bíbélì sí Èdè Adití Lọ́nà ti Rùwáńdà
Wọ́n Rántí Ìpẹ̀yàrun Tó Ṣẹlẹ̀ Ní Rùwáńdà Lẹ́yìn Ọdún Márùndínlọ́gbọ̀n
Òjò Oníjì Líle Ṣọṣẹ́ ní Rùwáńdà
Àwa Ẹlẹ́rìí Jèhófà Ṣe Àpéjọ Àgbègbè Lédè Adití Fún Ìgbà Àkọ́kọ́ Ní Rùwáńdà
Ilẹ̀ Ya, Ó Sì Pa Àwọn Èèyàn ní Siria Lóònù
Àpéjọ Àgbáyé “Ìfẹ́ Kì Í Yẹ̀ Láé”! Ti Ọdún 2019 Tí A Ṣe Ní Ìlú Johannesburg, Lórílẹ̀-Èdè South Africa
Àwa Ẹlẹ́rìí Jèhófà Mú Ìwé Mímọ́ Kristian Lédè Griki ní Ìtumọ̀ Ayé Titun Jáde Lédè Kwanyama
A Mú Bíbélì Ìtumọ̀ Ayé Tuntun Jáde ní Èdè Mẹ́ta ní Àpéjọ Àgbáyé Tá A Ṣe Lórílẹ̀-Èdè South Africa
Òjò Àrọ̀ọ̀rọ̀dá àti Omíyalé ní South Africa
Àkúnya Omi Wáyé Lórílẹ̀-Èdè Tógò
Àwa Ẹlẹ́rìí Jèhófà Mú Bíbélì Ìtumọ̀ Ayé Tuntun Tá A Tún Ṣe Jáde Lédè Shona
Iṣẹ́ Ti Bẹ̀rẹ̀ Lórí Ẹ̀ka Ọ́fíìsì Tuntun ní Ajẹntínà
A Wàásù Lákànṣe Níbi Térò Pọ̀ sí Nígbà Eré Ìdárayá Òlíńpíìkì Tó Wáyé ní Ajẹntínà Lọ́dún 2018
Ọmọ Ọdún Mẹ́ẹ̀ẹ́dọ́gbọ̀n (25) Ni Arábìnrin Cecilia Alvarez, Àmọ́ Ó Ti Ṣe Iṣẹ́ Abẹ Mẹ́tàlélógójì (43) Láì Gba Ẹ̀jẹ̀
Ilẹ̀ Ya Lórílẹ̀-Èdè Bolivia, Ó sì Ba Nǹkan Jẹ́ Nílùú La Paz
Àpéjọ Àgbáyé “Ìfẹ́ Kì Í Yẹ̀ Láé”! Tá A Ṣe ní 2019—São Paulo, Brazil
Àwọn Ará Wa Ṣèrànwọ́ Lẹ́yìn Tí Àkúnya Omi Ṣọṣẹ́ Lórílẹ̀-èdè Brazil
Ibi Tó Ń Gba Omi Dúró Ya Lulẹ̀ ní Brazil
Iná Ńlá Sọ Nílùú Manaus, ní Brazil
Ilé Ẹjọ́ Gíga Jù Lọ ní Kánádà Dá Àwa Ẹlẹ́rìí Jèhófà Láre
Ilé Ẹjọ́ Gíga Jù Lọ ti Kánádà Kọ̀ Láti Dá sí Ètò Ìyọlẹ́gbẹ́
Ìrántí Ikú Kristi Tá A Ṣé Lọ́dún 2020​—Orílẹ̀-èdè Kánádà
Omíyalé Ṣẹlẹ̀ ní Kánádà
Ọkàn Wọn Balẹ̀ Lásìkò tí Àrùn COVID-19 Ń Jà
Àpéjọ Àgbáyé “Ìfẹ́ Kì Í Yẹ̀ Láé”! Tá A Ṣe ní 2019—Toronto, Kánádà
Wọ́n Fún Àwa Ẹlẹ́rìí Jèhófà ní Ìwé Ẹ̀rí Torí Bá A Ṣe Ń Kọ́ Àwọn Ẹlẹ́wọ̀n Lẹ́kọ̀ọ́ Bíbélì ní Kòlóńbíà
Ìjì Líle Fa Àjálù Ńlá ní Cuba
Ìdílé Ẹlẹ́rìí Jèhófà Kan Kú Sínú Jàǹbá Ọkọ̀ Òfuurufú ní Cuba
Àpéjọ Àgbáyé “Ìfẹ́ Kì Í Yẹ̀ Láé”! Tá A Ṣe ní 2019​—Guayaquil, Ecuador
Àwọn Ẹlẹ́rìí ní Ecuador Ń Wàásù Fáwọn Èèyàn Láì Kúrò Nílé
Òkè Ayọnáyèéfín Bú Gbàù ní Guatemala
Ìmìtìtì Ilẹ̀ Wáyé ní Àríwá Ilẹ̀ Haiti
Ìjì Tí Wọ́n Pè Ní Lidia Jà ní Orílẹ̀-Èdè Mẹ́síkò
Ìmìtìtì ilẹ̀ tó lágbára tí ìwọ̀n rẹ̀ jẹ́ 7.1 wáyé ní àárín gbùngbùn orílẹ̀-èdè Mẹ́síkò
Hurricane Max jà ní gúùsù orílẹ̀-èdè Mẹ́síkò
Àwọn Ẹlẹ́rìí Jèhófà Parí Ètò Ìrànwọ́ ní Amẹ́ríkà Àárín Lẹ́yìn Ìmìtìtì Ilẹ̀ Tó Wáyé
Àwọn Ẹlẹ́rìí Jèhófà Ti Ṣe Tán Láti Bẹ̀rẹ̀ Àtúnṣe Sáwọn Ilé Tí Ìmìtìtì Ilẹ̀ Bà jẹ́ ní Guatemala àti Mexico
Àpéjọ Àgbáyé “Ìfẹ́ Kì Í Yẹ̀ Láé”! Tá A Ṣe ní 2019—Monterrey, Mẹ́síkò
Ìmìtìtì Ilẹ̀ Wáyé ní Mẹ́síkò
Wọ́n Fi Ipá Lé Àwọn Ẹlẹ́rìí Jèhófà tó Jẹ́ Huichol Kúrò Nílé Wọn ní Jalisco, Orílẹ̀-Èdè Mexico
Ìjì Líle Jà Tẹ̀ Léra ní Mẹ́síkò
Àwa Ẹlẹ́rìí Jèhófà Mú Bíbélì Mímọ́ ti Ìtumọ̀ Ayé Tuntun Jáde Lédè Guarani
Àkúnya Omi Ṣẹlẹ̀ Lórílẹ̀-Èdè Paraguay
Àkànṣe Ìwàásù Dé Ọ̀dọ̀ Àwọn Tó Ń Sọ Èdè Aymara Nílùú Puno, Lórílẹ̀-Èdè Peru
Ilé Iṣẹ́ Ìjọba Thailand “Gbóríyìn àti Òṣùbà” Fáwọn Ẹlẹ́rìí Jèhófà Nílẹ̀ Peru Torí Wọ́n Ṣèrànwọ́ Fáwọn Ọmọ Ilẹ̀ Thailand Tó Wà Lẹ́wọ̀n
Àwọn Ẹlẹ́rìí Jèhófà Ní Orílẹ̀-èdè Peru Mú Kí Iṣẹ́ Ìwàásù Níbi Térò Pọ̀ Sí Gbòòrò Yíká Ibi Àwọn Eré Ìdárayá
Ìròyìn Tá a kọ́kọ́ gbọ́ nípa ìjì ńlá kan tí wọ́n pè ní Hurricane Maria
Ìròyìn láti Puerto Rico Lẹ́yìn ìjì líle Hurricane Maria
Àwọn Ẹlẹ́rìí Jèhófà Tó Wà ní Amẹ́ríkà Ń Bá Ìgbòkègbodò Wọn Nìṣó Lẹ́yìn Ìjì Líle Hurricane Harvey
Ojú Ọjọ́ Tí Kò Bára Dé Ba Nǹkan Jẹ́ Láwọn Ibì Kan Lórílẹ̀-Èdè Amẹ́ríkà
Ìmìtìtì Ilẹ̀ Ṣọṣẹ́ Ní Gúúsù California
Àpéjọ Àgbáyé “Ìfẹ́ Kì Í Yẹ̀ Láé”! ti Ọdún 2019 Tí A Ṣe Ní St. Louis Lórílẹ̀-Èdè Amẹ́ríkà
Ìmìtìtì Ilẹ̀ Tó Lágbára ní Alaska
Ìjì Lílé Ṣọṣẹ́ Láwọn Agbègbè Kan Lórílẹ́-èdè Amẹ́ríkà
Ìjì Líle Tó Ń Jẹ́ Dorian Ṣọṣẹ́ Lórílẹ̀-èdè Bahamas
Ìjì Líle Michael, Ọ̀kan Lára Èyí Tó Le Jù Tó Tíì Jà Nílẹ̀ Amẹ́ríkà Ba Nǹkan Jẹ́ Lápọ̀jù
Àpéjọ Àgbáyé “Ìfẹ́ Kì Í Yẹ̀ Láé”! Tá A Ṣe ní 2019​—Houston, Orílẹ̀-èdè Amẹ́ríkà (Gẹ̀ẹ́sì)
Iná Runlérùnnà ní Ìpínlẹ̀ California
Àpéjọ Àgbáyé “Ìfẹ́ Kì Í Yẹ̀ Láé”! Tá A Ṣe ní 2019—Atlanta, Orílẹ̀-èdè Amẹ́ríkà
Òkè Ayọnáyèéfín Tó Ń Bú Gbàù ní Hawaii Ba Nǹkan Jẹ́, Ó sì Ti Lé Àwọn Èèyàn Kúrò Nílé
Àpéjọ Àgbáyé “Ìfẹ́ Kì Í Yẹ̀ Láé”! Tá A Ṣe ní 2019—Miami, Orílẹ̀-èdè Amẹ́ríkà (Gẹ̀ẹ́sì)
Iná Runlé-rùnnà ní Àríwá California
Ìròyìn Àkọ́kọ́ Nípa Ìjì Líle Tí Wọ́n Pè ní Irma
Ìròyìn nípa Hurricane Irma
Iná Ńlá Tí Wọ́n Pè ní Carr Ṣọṣẹ́ Nítòsí Redding, Ìpínlẹ̀ California
ÌRÒYÌN TÓ KỌ́KỌ́ DÉ | Iná Tó Ṣẹ́ Yọ Ní California
Ìjì Líle àti Àkúnya Omi Ṣọṣẹ́ Ní Gúúsù Ìpínlẹ̀ Texas
Ìrántí Ikú Kristi Tá A Ṣé Lọ́dún 2020—Orílẹ̀-Èdè Amẹ́ríkà
Ìròyìn Lọ́ọ́lọ́ọ́ Nípa Ibi Tí Ètò Ìrànwọ́ Dé Lẹ́yìn Ìjì Hurricane Harvey
Ijì Lílé Tó Ń Jẹ́ Dorian Runlé-rùnnà
Ìròyìn Lọ́ọ́lọ́ọ́ Nípa Iná Runlé-rùnnà Tó Ṣẹ́yọ Ní California
Omíyalé Ba Nǹkan Jẹ́ Láàárín Agbègbè Ìwọ̀ Oòrùn Amẹ́ríkà
Ìjì Líle Ṣọṣẹ́ ni Gúúsù Ìpínlẹ̀ California
A Ya Gbọ̀ngàn Ìjọba Àkọ́kọ́ Sí Mímọ́ Lẹ́ẹ̀kan Sí I Lẹ́yìn Ọdún Márùnlélọ́gọ́rin (85)
Àwọn Iná Tó Jó ní Ìgbèríko California Ba Agbègbè Náà Jẹ́
Ẹnì Kan Yìnbọn ní Ilé Ìwé Kan ní California, Lórílẹ̀-Èdè Amẹ́ríkà
Àpéjọ Àgbáyé “Ìfẹ́ Kì Í Yẹ̀ Láé”! Tá A Ṣe ní 2019​—Phoenix, Orílẹ̀-Èdè Amẹ́ríkà
Ìpàtẹ Àwọn Nǹkan Ìṣẹ̀ǹbáyé Ti Wà Báyìí ní Oríléeṣẹ́ Wa Lédè Adití
Àpéjọ Àgbáyé “Ìfẹ́ Kì Í Yẹ̀ Láé”! Tá A Ṣe ní 2019—Miami, Orílẹ̀-èdè Amẹ́ríkà (Èdè Spanish)
Ìjì Líle Tó Ń Jẹ́ Barry Gbo Gúúsù Amẹ́ríkà Jìgìjìgì
Ọ̀pọ̀ Èèyàn Ló Fara Gbọta Nílùú Virginia Beach Lórílẹ̀-Èdè Amẹ́ríkà
Ìjì Líle Tó Lé Ní Ọgọ́rùn-ún Ṣọṣẹ́ Láwọn Ibì Kan Lórílẹ̀-èdè Amẹ́ríkà
Ìjì Líle Florence Ṣọṣẹ́ ní Gúúsù Ìlà Oòrùn Ilẹ̀ Amẹ́ríkà
Ìjì Líle Jà ní Gúúsù Ìlà Oòrùn Ilẹ̀ Amẹ́ríkà
fenesuela, oro aje denu kole, ko si owo, eto iranlowo, fidio
Ìròyìn Láti Fẹnẹsúélà: Àwọn Ẹlẹ́rìí Jèhófà Túbọ̀ Tẹra Mọ́ Ìjọsìn Ọlọ́run Láìka Ìṣòro Sí
Àwọn Ẹlẹ́rìí Jèhófà Lórílẹ̀-èdè Fẹnẹsúélà Ń Kọ́ Àwọn Èèyàn Lẹ́kọ̀ọ́ Bíbélì Nìṣó Láìfi Ọrọ̀ Ajé Tó Dẹnu Kọlẹ̀ Pè
Ìjì Líle Hato Jà Nílùú Hong Kong àti Macau
Ẹ̀mí Ṣòfò Nígbà Tí Òkè Ya Lulẹ̀ Lápá Gúúsù-Ìwọ̀ Oòrùn Ilẹ̀ Íńdíà
Àwọn Ẹlẹ́rìí Jèhófà Mú Bíbélì Jáde ní Èdè Telugu ní Orílẹ̀-Èdè Íńdíà
Àrọ̀ọ̀rọ̀dá Òjò Mú Kí Omi Ya Wọ Ìwọ̀ Oòrùn Íńdíà
Omíyalé Ṣẹlẹ̀ ní Íńdíà
Ìjì Líle Jà ní Íńdíà
Òjò Alátẹ́gùn Tó Lágbára Gan-an Ba Ìlú Mumbai Jẹ́
Àwọn Atúmọ̀ Èdè ní Orílẹ̀-èdè India Ń Báṣẹ́ Lọ Láìka Ti Àjàkálẹ̀ Àrùn Tó Gbòde Kan Sí
Ìmìtìtì Ilẹ̀ Wáyé ní Erékùṣù Kan ní Indonéṣíà
Ìmìtìtì Ilẹ̀ àti Omíyalé Ṣọṣẹ́ ní Sulawesi, Indonéṣíà
Omíyalé Ṣẹlẹ̀ ní Indonesia
Ìjì Líle Trami: Ìjì Líle Tó Jà Lẹ́nu Àìpẹ́ Yìí ní Japan
Àwọn Ẹlẹ́rìí Jèhófà Ṣèrànwọ́ Fáwọn Tí Omíyalé Dà Láàmú ní Japan
Omíyalé Ba Nǹkan Jẹ́ ní Ìwọ̀ Oòrùn Ilẹ̀ Japan
Ìmìtìtì Ilẹ̀ Wáyé ní Hokkaido,Japan
Àkúnya Omi Ṣọṣẹ́ Lórílẹ̀-Èdè Japan
Ìjì Líle Tó Ń Jẹ́ Tapah Rọ́ Lu Apá Gúúsù Orílẹ̀-Èdè Japan
Ìjì Líle Jebi Jà ní Japan
A Mú Bíbélì Ìtumọ̀ Ayé Tuntun Tá A Tún Ṣe Jáde Lédè Japanese
Ìjì Líle Tí Wọ́n Pè Ní Typhoon Bualoi Ṣọṣẹ́ Lórílẹ̀-Èdè Japan
Ìjì Líle Tó Ń Jẹ́ Faxai Ṣọṣẹ́ ní Orílẹ̀-Èdè Japan
Wọ́n Ti Dá Teymur Akhmedov Sílẹ̀ Lẹ́wọ̀n Lórílẹ̀-èdè Kazakhstan ní April 4, 2018
Àwọn Ẹlẹ́rìí Jèhófà ní Kazakhstan Pe Àwọn Èèyàn Wá Ṣèbẹ̀wò Sáwọn Gbọ̀ngàn Ìjọba
Teymur Akhmedov Lo 441 Ọjọ́ Lẹ́wọ̀n​—A Fọ̀rọ̀ Wá Òun àti Mafiza Ìyàwó Rẹ̀ Lẹ́nu Wò
Ìtẹ̀síwájú Lórí Ọ̀ràn Ẹjọ́ Nílùú Osh, Lórílẹ̀-èdè Kyrgyzstan
Àwọn Ẹlẹ́rìí Jèhófà Ti Lómìnira Ẹ̀sìn ní Mòǹgólíà: Ìjọba Pa Dà Forúkọ Ẹ̀sìn Wọn Sílẹ̀ Lábẹ́ Òfin
Àkúnya Omi àti Ilẹ̀ Yíya Ba Orílẹ̀-èdè Nepal Jẹ́
Omíyalé Ṣọṣẹ́ Lórílẹ̀-Èdè Philippines
Àpéjọ Àgbáyé “Ìfẹ́ Kì í Yẹ̀ Láé!” Manila, Philippines—2019
Ìjì Líle Vongfong Jà Lórílè-èdè Philippines Lásìkò Tí Ìjì Sábà Máa Ń Jà
Òjò Alátẹ́gùn Rọ́ Lu Orílẹ̀-Èdè Philippines
Ìjì Líle Yutu Tún Ṣọṣẹ́, Ó Jà ní Philippines
Ìrántí Ikú Kristi ti Ọdún 2020
Àwa Ẹlẹ́rìí Jèhófà Mú Bíbélì Ìtumọ̀ Ayé Tuntun Jáde Lédè Mẹ́ta ní Philippines
Ìmìtìtì Ilẹ̀ Ṣọsẹ́ Ní Orílẹ̀-Èdè Philippines
Iná Ńlá Tó Sọ ní Philippines Jó Ọ̀pọ̀ Ilé
Ó Ṣeé Ṣe Kí Òkè Ayọnáyèéfín Tó Wà Lórílẹ̀-Èdè Philippines Bú Gbàù
Ìjì Líle Ba Apá Kan Orílẹ̀-èdè Philippines Jẹ́
Iná Sọ Àwọn Ilé Di Eérú ní Philippines
Ìjì Líle Jà ní Ìlà Oòrùn Orílẹ̀-Èdè Philippines, Ó Mú Kí Ilẹ̀ Ya, Ó sì Fa Omíyalé
Ìjì Méjì Ṣọṣẹ́ ní Philippines
Ìmìtìtì Ilẹ̀ Tó Pọ̀ Gan-an Wáyé ní Apá Gúúsù Orílẹ̀-Èdè Philippines
“Wọn Ò Jẹ̀bi”
Ilé Ẹjọ́ Gíga Jù Lọ Nílẹ̀ South Korea Gbọ́ Tẹnu Àwọn Èèyàn Lórí Ọ̀rọ̀ Àwọn Tí Ẹ̀rí Ọkàn Ò Jẹ́ Kí Wọ́n Ṣiṣẹ́ Ológun
Wọ́n Ti Dá Gbogbo Ẹlẹ́rìí Jèhófà Tó Wà Lẹ́wọ̀n Torí Pé Ẹ̀rí Ọkàn Ò Jẹ́ Kí Wọ́n Ṣiṣẹ́ Ológun Sílẹ̀ ní South Korea
Ilé Ẹjọ́ Ìjọba South Korea Ṣèpinnu Tá A Ti Ń Retí Tipẹ́​—Wọ́n Gbèjà Àwọn Tí Ẹ̀rí Ọkàn Ò Jẹ́ Kí Wọ́n Ṣiṣẹ́ Ológun
Ilé Ẹjọ́ Gíga Jù Lọ Nílẹ̀ South Korea Dá Ẹjọ́ Mánigbàgbé
Iná Ńlá Sọ Nínú Igbó Létí Ìlà Oòrùn South Korea
Ìdájọ́ Tó Ṣàrà Ọ̀tọ̀ ní Ilé Ẹjọ́ Tó Ń Rí Sí Ẹ̀tọ́ Ọmọnìyàn Nílẹ̀ Korea: Kò Bófin Mu Bí Kò Ṣe Sí Iṣẹ́ Míì Téèyàn Lè Fi Sìnlú
Wọ́n Dá Àwọn Arákùnrin Wa Sílẹ̀ Lẹ́wọ̀n ní Korea
Àwọn Ẹlẹ́rìí Jèhófà Pàtẹ Ìwé Tó Dá Lórí Bíbélì Níbi Ìdíje Òlíńpíìkì àti Ìdíje Fáwọn Aláàbọ̀ Ara ti Ọdún 2018
Àwọn Ẹlẹ́rìí Jèhófà Ṣe Àkànṣe Àpéjọ Fúngbà Àkọ́kọ́ ní Siri Láńkà
Wọ́n Mú Bíbélì Ìtumọ̀ Ayé Tuntun Tá A Tún ṣe Jáde Lédè Chinese
Ìmìtìti Ilẹ̀ Ṣọṣẹ́ ni Taiwan
Wọ́n Fi Arákùnrin Jovidon Bobojonov Sẹ́wọ̀n Ọdún Méjì Lórílẹ̀-èdè Tajikistan
Àwọn Aláṣẹ Ìlú Tajik Ju Arákùnrin Shamil Khakimov, Ẹni Ọdún Méjìdínláàádọ́rin (68) Sẹ́wọ̀n Ọdún Méje Àtààbọ̀ Lọ́nà Tí Kò Tọ́
A Mú Ìwé Mímọ́ Kristian Lédè Griki ní Ìtumọ̀ Ayé Titun Jáde Lédè Laotian
Ilé Ẹjọ́ Orílẹ̀-Èdè Turkmenistan Fi Arákùnrin Dovletov Sẹ́wọ̀n Ọdún Mẹ́ta Nítorí Ẹ̀rí Ọkàn Rẹ̀ Kò Jẹ́ Kó Ṣiṣẹ́ Ológun
Ọ̀pọ̀ Èèyàn Wá Sáwọn Ibi Tá A Ti Ṣe Ìrántí Ikú Kristi Káàkiri Orílẹ̀-Èdè Uzbekistan
Àwọn Ilé Ẹjọ́ Gíga ní Uzbekistan Dájọ́ Pé Àwọn Ẹlẹ́rìí Jèhófà Lẹ́tọ̀ọ́ Láti Ní Àwọn Ìwé Tó Dá Lórí Bíbélì
Àpéjọ Àgbáyé “Ìfẹ́ Kì Í Yẹ̀ Láé” ti Ọdún 2019 Tí A Ṣe Ní Melbourne, Lórílẹ̀-Èdè Ọsirélíà
Òjò Àrọ̀ọ̀rọ̀dá Mú Kí Àgbàrá Ya Bo Ìlú Queensland ní Ọsirélíà
Iná Jó Ọ̀pọ̀ Ibi ní Ọsirélíà
Ìjì Líle Harold Ba Ọ̀pọ̀ Nǹkan Jẹ́ Láwọn Erékùṣù Vanuatu àti Fíjì
A Túbọ̀ Ń Wàásù Níbi Térò Pọ̀ sí Lórilè-Èdè Israel Bí Ẹgḅẹẹgbẹ̀rún Èèyàn Ṣe Ń Ṣèbẹ̀wò Sílùú Tel Aviv
Ilé Ẹjọ́ Ẹ̀tọ́ Ọmọnìyàn ti Ilẹ̀ Yúróòpù Dá Orílẹ̀-èdè Armenia Lẹ́bi Ẹjọ́ Tí Wọ́n Dá Fáwọn Arákùnrin Méjìlélógún (22) Tí Ẹ̀rí Ọkàn Wọn Kò Jẹ́ Kí Wọ́n Ṣiṣẹ́ Ológun
Ilé Ẹjọ́ ní Azerbaijan Dá Ọ̀kan Lára Àwọn Arákùnrin Wa Lẹ́bi Torí Pé Ó Kọ̀ Láti Wọṣẹ́ Ológun
Àwọn Ẹlẹ́rìí Jèhófà Ti Forúkọ Ẹ̀sìn Wọn Sílẹ̀ Lábẹ́ Òfin Nílùú Baku, ní Azerbaijan
Àpéjọ Agbègbè Mánigbàgbé Wáyé Ní Azerbaijan
Ẹni Tí Ẹ̀rí Ọkàn Ò Jẹ́ Kó Ṣiṣẹ́ Ológun ní Azerbaijan Máa Pe Ẹjọ́ Kòtẹ́milọ́rùn sí Ilé Ẹjọ́ Gíga Jù Lọ
Àwọn Ẹjọ́ Tá A Jàre Nílé Ẹjọ́ Gíga Jù Lọ Dáàbò Bo Ẹ̀tọ́ Táwọn Ẹlẹ́rìí Jèhófà Ní Láti Ṣe Ẹ̀sìn Wọn ní Bọ̀géríà
Àwa Ẹlẹ́rìí Jèhófà Mú Bíbélì Ìtumọ̀ Ayé Tuntun Tá A Tún Ṣe Jáde Lédè Czech àti Slovak
Ìṣẹ̀lẹ̀ Mánigbàgbé Nínú Ìtàn Àwa Ẹlẹ́rìí Jèhófà: A Mú Ìwé Mímọ́ Kristian Lédè Griki Jáde Ní Èdè Icelandic
Àwọn Ẹlẹ́rìí Jèhófà Ṣí Ibi Tuntun Tí Wọ́n Kó Onírúurú Bíbélì Sí Lórílẹ̀-Èdè Denmark
Àpéjọ Àgbáyé “Ìfẹ́ Kì Í Yẹ̀ Láé”! Tá A Ṣe ní 2019—Copenhagen, Denmark
Àwọn Ẹlẹ́rìí Jèhófà Tu Àwọn Èèyàn Nínú lẹ́yìn Ìpànìyàn tó wáyé nílùú Turku, lórílẹ̀-èdè Finland
Àkànṣe Àpéjọ Àkọ́kọ́ Tó Wáyé Nílùú Tbilisi, ní Jọ́jíà
A Ṣe Ètò Ìpàtẹ Kan Nílùú Kassel, Lórílẹ̀-èdè Jámánì Láti Ṣayẹyẹ Àádọ́rin Ọdún Àpéjọ Mánigbàgbé Kan Tó Wáyé Níbẹ̀
Àpéjọ Àgbáyé “Ìfẹ́ Kì Í Yẹ̀ Láé”! Tá A Ṣe ní 2019​—Berlin, Jámánì
Kì Í Ṣẹni Táwọn Èèyàn Ò Mọ̀ Mọ́: Wọ́n Ṣèrántí Max Eckert ní Ibi Ìrántí Tó Wà ní Àgọ́ Ìṣẹ́niníṣẹ̀ẹ́ Ìlú Dachau
Ojúkò Àgọ́ Ìṣẹ́niníṣẹ̀ẹ́ Kan Ṣàfihàn Bí Wọ́n Ṣe Pọ́n Àwọn Ẹlẹ́rìí Jèhófà Lójú ní Jámánì
Ìlú Munich Ṣàfihàn Bí Ìjọba Násì Ṣe Pọ́n Àwọn Ẹlẹ́rìí Jèhófà Lójú
Ìtàn Mánigbàgbé: A fi Odindi Àádọ́ta Ọdún Jà fún Ẹ̀tọ́ Tá A Ní Láti Wàásù
Iná Sọ Nínú Igbó Nílẹ̀ Gíríìsì
Àpéjọ Àgbáyé “Ìfẹ́ Kì Í Yẹ̀ Láé”! Tá A Ṣe ní 2019—Athens ní Gíríìsì
Ọ̀pọ̀ Dókítà Nífẹ̀ẹ́ sí Títọ́jú Aláìsàn Láìlo Ẹ̀jẹ̀ Níbi Àpérò Pàtàkì Méjì Táwọn Onímọ̀ Ìṣègùn Ṣe Lórílẹ̀-Èdè Ítálì
Ilé Ẹjọ́ Kan Nílùú Sicily Túbọ̀ Fìdí Ẹ̀ Múlẹ̀ Pé Àwọn Ẹlẹ́rìí Jèhófà Lẹ́tọ̀ọ́ Láti Pinnu Irú Ìtọ́jú Tí Wọ́n Fẹ́ Nílé Ìwòsàn
Ìmìtìtì Ilẹ̀ Ṣẹlẹ̀ ní Erékùṣù Kan Lórílẹ̀-Èdè Ítálì
Ilé Ẹjọ́ Gíga Jù Lọ ní Ítálì Fọwọ́ Sí I Pé Àwọn Ẹlẹ́rìí Jèhófà Lẹ́tọ̀ọ́ Láti Yan Ìtọ́jú Ìṣègùn Tó Wù Wọ́n
Lórílẹ̀-Èdè Ítálì, Wọ́n Ṣí Aṣọ Lójú Àmì Tó Ń Ránni Létí Àwọn Ẹlẹ́rìí Jèhófà tí Ẹgbẹ́ Òṣèlú Násì àti Ìjọba Aláṣẹ Oníkùmọ̀ Ṣe Inúnibíni Sí
A Ti Ń Kọ́ Ẹ̀ka Ọ́fíìsì Tuntun Lórílẹ̀-Èdè Ítálì
Àpéjọ Àgbáyé “Ìfẹ́ Kì Í Yẹ̀ Láé”! Tá A Ṣe ní 2019—Utrecht, Netherlands
Wọ́n “Sọdá Wá sí Makedóníà” fún Àkànṣe Ìwàásù
Àpéjọ Àgbáyé “Ìfẹ́ Kì Í Yẹ̀ Láé”! Tá A Ṣe ní 2019​—Warsaw, Poland
Iná Tó Tíì Pààyàn Jù Lọ ní Portugal
Àpéjọ Àgbáyé “Ìfẹ́ Kì Í Yẹ̀ Láé”! Tá A Ṣe ní 2019—Lisbon ní Pọ́túgà
Wọ́n Dá Àwọn Arákùnrin Mẹ́fà Míì Lẹ́bi, Wọ́n Sì Jù Wọ́n Sẹ́wọ̀n ní Orílẹ̀-Èdè Rọ́ṣíà
Ilé Ẹjọ́ ní Rọ́ṣíà Dẹ́bi fún Dennis Christensen Láìṣẹ̀ Láìrò, Wọ́n sì Rán An Lẹ́wọ̀n Ọdún Mẹ́fà
Ìjọba Rọ́ṣíà Gbẹ́sẹ̀ Lé Dúkìá Àwa Ẹlẹ́rìí Jèhófà Tí Iye Rẹ̀ Ju Mílíọ̀nù Mẹ́tàdínlọ́gọ́ta (57) Owó Dọ́là Lọ
Ilé Ẹjọ́ Ilẹ̀ Rọ́ṣíà Dá Ẹ̀wọ̀n Ọdún Mẹ́fà fún Arákùnrin Klimov, Ìdájọ́ Tó Burú Jù Lọ Láti Ọdún 2017
Dennis Christensen Máa Sọ̀rọ̀ Ìkẹyìn Láti Gbèjà Ara Rẹ̀ Nílé Ẹjọ́ ní May 23
Ilé Ẹjọ́ Wọ́gi Lé Ìdájọ́ Tí Wọ́n Ṣe fún Arákùnrin Akopyan Tẹ́lẹ̀ ní Rọ́ṣíà
Ilé Ẹjọ́ Kan ní Rọ́ṣíà Rán Arákùnrin Alushkin Lọ sí Ẹ̀wọ̀n Ọdún Mẹ́fà
Ó Ti Tó Ọdún Mẹ́ta Báyìí Tí Wọ́n Ti Fi Arákùnrin Dennis Christensen Sẹ́wọ̀n Ní Rọ́ṣíà, Síbẹ̀ Ó Jẹ́ Olóòótọ́ Ó Sì Ń Láyọ̀
A Pe Ẹjọ́ Kòtẹ́milọ́rùn Kí Wọ́n Má Bàa Gbẹ́sẹ̀ Lé Ẹ̀ka Ọ́fíìsì Wa Àtijọ́ ní Rọ́ṣíà
Àwọn Aṣojú Kárí Ayé Ti Àwọn Ará Wa ní Rọ́ṣíà Lẹ́yìn Níbi Ìgbẹ́jọ́ Tó Wáyé ní Ilé Ẹjọ́ Gíga Jù Lọ
Látinú Ẹ̀wọ̀n Sínú Má Jáde Nílé
Ilé Ẹjọ́ Kòtẹ́milọ́rùn Fara Mọ́ Ọn Pé Kí Dennis Christensen Lọ Sẹ́wọ̀n
Rọ́ṣíà Dájú Sọ Àwọn Àgbàlàgbà Ẹlẹ́rìí Jèhófà, Títí Kan Àwọn Tó Ti Lé ní Àádọ́rin Ọdún
Ilé Ẹjọ́ Kòtẹ́milọ́rùn Fagi Lé Ìdájọ́ Tí Ilé Ẹjọ́ Kan Ṣe Lòdì sì Arákùnrin Alushkin Àtàwọn Márùn-ún Míì. Ìgbà Àkọ́kọ́ Rèé Tírú Ẹ̀ Máa Ṣẹlẹ̀ Ní Rọ́ṣíà
Wọ́n Máa Dá Ẹjọ́ Dennis Christensen ní February 6, 2019
Ilé Ẹjọ́ ní Rọ́ṣíà Dá Dennis Christensen Lẹ́bi, Wọ́n sì Rán An Lẹ́wọ̀n Ọdún Mẹ́fà
Ilé Ẹjọ́ Kan Lórílẹ̀-Èdè Rọ́ṣíà Dá Arákùnrin Dennis Christensen Sílẹ̀ Lẹ́wọ̀n
Ilé Ẹjọ́ Lórílẹ̀-Èdè Rọ́ṣíà Dá Arákùnrin Yevgeniy Aksenov Lẹ́bi Pẹ̀lú Ẹ̀wọ̀n Ọdún Méjì Ní Ìpamọ́
Ilé Ẹjọ́ Lórílẹ̀-Èdè Rọ́ṣíà Dá Arákùnrin Yevgeniy Aksenov Lẹ́bi Pẹ̀lú Ẹ̀wọ̀n Ọdún Méjì Ní Ìpamọ́
Wọ́n Dá Àwọn Ẹlẹ́rìí Jèhófà Lóró Nílùú Surgut, Lórílẹ̀-Èdè Rọ́ṣíà
Wọn Ò Gba Ẹjọ́ Kòtẹ́milọ́rùn Táwọn Ẹlẹ́rìí Pè Wọlé, Ó sì Mú Kí Àwọn Aláṣẹ Rọ́ṣíà Gbẹ́sẹ̀ Lé Ẹ̀ka Ọ́fíìsì Wa Àtijọ́
Àwùjọ Àwọn Onímọ̀ Ìjìnlẹ̀ Tó Wà Lábẹ́ Àjọ Ìṣọ̀kan Àgbáyé Sọ Pé Ìjọba Rọ́ṣíà Ti Tẹ Òfin Àwọn Orílẹ̀-Èdè Lójú, Bí Wọ́n Ṣe Fi Ẹlẹ́rìí Jèhófà Méjìdínlógún Sátìmọ́lé
Àwùjọ Àwọn Onímọ̀ Ìjìnlẹ̀ Tó Wà Lábẹ́ Àjọ Ìṣọ̀kan Àgbáyé Sọ Pé Ìjọba Rọ́ṣíà Ti Tẹ Òfin Àwọn Orílẹ̀-Èdè Lójú, Bí Wọ́n Ṣe Fi Ẹlẹ́rìí Jèhófà Méjìdínlógún Sátìmọ́lé
Wọ́n Dájọ́ Ẹ̀wọ̀n Ọdún Mẹ́fà Àtààbọ̀ fún Arákùnrin Gennady Shpakovskiy Lórílẹ̀-Èdè Rọ́ṣíà
Ilé Ẹjọ́ ní Rọ́ṣíà Dẹ́bi fún Arkadya Akopyan Tó Jẹ́ Ẹni Àádọ́rin Ọdún
Wọ́n Fẹ̀sùn Kan Arákùnrin Mikhail Popov àti Ìyàwó Rẹ̀, Yelena Ní Rọ́ṣíà—À Ń Retí Ohun Tí Ilé Ẹjọ́ Máa Sọ Ní February 13, 2020
Wọ́n Ti Dá Arákùnrin Vladimir Alushkin Sílẹ̀ Lẹ́wọ̀n
Arákùnrin Gennady Shpakovskiy Lè Lọ Sẹ́wọ̀n Ọdún Méjé Àtààbọ̀ Lórílẹ̀-èdè Rọ́ṣíà
Wọ́n Dá Arákùnrin Valeriy Moskalenko Sílẹ̀ Lẹ́wọ̀n
Ilé Ẹjọ́ Kòtẹ́milọ́rùn Pàṣẹ Pé Kí Wọn Jẹ́ Kí Arákùnrin Andrey Suvorkov Lómìnira Láti Jáde Kúrò Nílé
Wọ́n Dá Arákùnrin Andrzej Oniszczuk Sílẹ̀ Lẹ́wọ̀n Lẹ́yìn Tó Ti Lo Oṣù Mọ́kànlá ní Àhámọ́
Wọ́n Tún Dẹ́bi fún Ẹlẹ́rìí Jèhófà Míì ní Rọ́ṣíà
Gbajúgbajà Onímọ̀ Nípa Ẹ̀sìn Jẹ́rìí Gbe Àwọn Ẹlẹ́rìí Jèhófà ní Ìlú Saratov
Ilé-Ẹjọ́ Orílẹ̀-Èdè Rọ́ṣíà Dá Arákùnrin àti Arábìnrin Popov Lẹ́bi, Wọ́n Sì Ní Kí Wọ́n Sanwó Ìtanràn
Ọ̀rọ̀ Àsọkágbá Arákùnrin Valeriy Moskalenko
Ìgbìmọ̀ Àwọn Ọ̀jọ̀gbọ́n Ti Àjọ Ìṣọ̀kan Àgbáye Sọ Pé Kò Bófin Mu Bí Ìjọba Rọ́ṣíà Ṣe Fi Arákùnrin Mikhaylov Sẹ́wọ̀n
Ó Ti Fẹ́rẹ̀ẹ́ Tó Ọdún Kan Tí Arákùnrin Andrzej Oniszczuk Ti Wà Látìmọ́lé
Ìyàwó Àwọn Ẹlẹ́rìí Jèhófà Tó Wà Lẹ́wọ̀n ní Rọ́ṣíà Fi Lẹ́tà Ránṣẹ́ sí Agbani-nímọ̀ràn Putin
Ilé Ẹjọ́ ECHR Sáré Fèsì Ìwé Tá A Kọ Lórí Ẹjọ́ Arákùnrin Tí Wọ́n Fìyà Jẹ ní Rọ́ṣíà
ÌRÒYÌN LỌ́Ọ́LỌ́Ọ́—Wọ́n Ti Gbé Dennis Christensen Lọ Sí Ọgbà Ẹ̀wọ̀n Tó Wà Ní Àdádó, Síbẹ̀ Ó Ṣì Jẹ́ Olóòótọ́
December 21 Ni Ọjọ́ Tó Kẹ́yìn Tí Arákùnrin Arkadya Akopyan Máa Fara Hàn Nílé Ẹjọ́
Ìfọ̀rọ̀wánilẹ́nuwò: Àwọn Arábìnrin Márùn-ún Ròyìn Bí Àwọn Ọlọ́pàá Ṣe Já Wọlé Àwọn ní Ìlú Ufa, Lórílẹ̀-Èdè Rọ́ṣíà
Wọ́n Dá Arakùnrin Stupnikov Sílẹ̀ Látìmọ́lé
Ilé Ẹjọ́ Kan Ní Rọ́ṣíà Dájọ́ Pé Arákùnrin Aleksandr Solovyev Jẹ̀bi Ẹ̀sùn Tí Wọ́n Fi Kàn Án
Wọ́n Ṣì Ń Kó Ọ̀pọ̀ Àwọn Ará Wa, Wọ́n sì Ń Fi Wọ́n sí Àtìmọ́lé ní Rọ́ṣíà
Ẹjọ́ Kòtẹ́milọ́rùn Christensen Ò Ní Pẹ́ Parí
Wọ́n Parọ́ Mọ́ Àwọn Ẹlẹ́rìí Jèhófà ní Rọ́ṣíà Pé Wọ́n Ká Ohun Ìjà Mọ́ Wọn Lọ́wọ́ Tí Wọ́n Fi Ń Ṣiṣẹ́ Agbawèrèmẹ́sìn
Ilé Ẹjọ́ Orílẹ̀-Èdè Rọ́ṣíà Máa Dá Ẹjọ́ Arákùnrin Moskalenko Lọ́sẹ̀ Tó Ń Bọ̀
Àwọn Èèyàn Ń Ti Dennis Christensen Lẹ́yìn Kárí Ayé
Ilé Ẹjọ́ ní Rọ́síà Tú Àwọn Arákùnrin Méjì Tó Kù Látìmọ́lé Sílẹ̀ ní Ìlú Surgut
Ilé Ẹjọ́ Orílẹ̀-Èdè Rọ́ṣíà Ní Kí Arákùnrin Aleksey Metsger San Owó Ìtanràn Ẹgbẹ̀rún Lọ́nà Ọgọ́rùn-ún Mẹ́ta àti Ààbọ̀ Ruble (350,000 Rubles), Kò sì Gbà Pẹ̀lú Agbẹjọ́rò Ìjọba Pé Kí Wọ́n Fi Sẹ́wọ̀n Ọdún Mẹ́ta
Wọ́n Fẹ̀sùn Ìwà Ọ̀daràn Kan Arákùnrin Yevgeniy Aksenov Torí Pé Ó Sọ̀rọ̀ Nípa Bíbélì
A Máa Gbé Ẹjọ́ Dennis Christensen Lọ sí Ilé Ẹjọ́ Ẹ̀tọ́ Ọmọnìyàn ti Ilẹ̀ Yúróòpù
Tọkọtaya Ẹlẹ́rìí Tí Wọ́n Kọ́kọ́ Jù Sẹ́wọ̀n ní Rọ́ṣíà
Ilé Ẹjọ́ Tú Ọ̀kan Lára Àwọn Ẹlẹ́rìí Jèhófà Mẹ́ta Tó Wà Látìmọ́lé Sílẹ̀ Nílùú Surgut, Lórílẹ̀-èdè Rọ́ṣíà
Ilé Àwọn Ará Tó Ju Ẹgbẹ̀ta (600) Ni Àwọn Ọlọ́pàá Ilẹ̀ Rọ́ṣíà Ti Fipá Ya Wọ̀
Àpéjọ Àgbègbè Àkọ́kọ́ Tá A Ṣe Ní Èdè Rómánì (Ìlà-Oòrùn Slovakia)
Ìṣẹ̀lẹ̀ Mánigbàgbé: Àwọn Ẹlẹ́rìí Jèhófà Mú Bíbélì Mímọ́ ti Ìtumọ̀ Ayé Tuntun Tá A Tún Ṣe Jáde Lédè Sípáníìṣì
Àpéjọ Àgbáyé “Ìfẹ́ Kì Í Yẹ̀ Láé”! ti Ọdún 2019 Tí A Ṣe Ní Madrid Lórílẹ̀-èdè Spain
Àkúnya Omi Ṣọṣẹ́ ní Apá Ìlà Oòrùn Sípéènì
Ìjọba Orílẹ̀-Èdè Sweden Sọ Pé Ẹ̀sìn Tó Ń Ran Aráàlú Lọ́wọ́ Làwọn Ẹlẹ́rìí Jèhófà
Wọ́n Fòfin De Àwọn Ẹlẹ́rìí Jèhófà ní “Donetsk People’s Republic”
Ìṣọ̀kan àti Aájò Àlejò Wà Láàárín Àwọn Ẹlẹ́rìí Jèhófà Nígbà Àkànṣe Àpéjọ ní Ukraine
Àwa Ẹlẹ́rìí Jèhófà Lórílẹ̀-Èdè Ukraine Ṣàfihàn Bíbélì
Iṣẹ́ Ìkọ́lé Ẹ̀ka Ọ́fíìsì Ti Ilẹ̀ Gẹ̀ẹ́sì Ti Fẹ́rẹ̀ẹ́ Parí
Ní May 25 àti 26, 2019, a ṣé àpéjọ àyíká “Jẹ́ Alágbára!” ní èdè Lingala àti Tshiluba ní ibùdó àwọn tó ń wà ibi ìsádi to wà nílùú Lóvua.
Ibùdó yìí fi kìlómítà ẹgbẹ̀rún kan àti méjìlélógún (1,022) jìn sí Luanda, tó jẹ́ olú ìlú Àǹgólà.
Nígbà tá a ṣe àpéjọ yẹn, akéde ọgọ́rùn-ún kan àti mẹ́tàdínlọ́gọ́rin (177) tó fi mọ́ àwọn ìdílé wọn ló wà ní ibùdó Lóvua.
Síbẹ̀, ọgọ́rùn-ún mẹ́ta àti ọgọ́rin (380) èèyàn ló gbádùn àpéjọ tá a ṣe ní èdè Lingala, àwọn mẹ́ta sì ṣe ìrìbọmi, nígbà tó jẹ́ pé ọgọ́rùn-ún mẹ́fà àti ọgbọ̀n (630) èèyàn ló gbádùn ìtòlẹ́sẹẹsẹ tá a ṣe ní èdè Tshiluba, àwọn mẹ́fà sì ṣe ìrìbọmi.
Ọ̀pọ̀ àwọn ará wa tó sá wá sí Lóvua ṣe bẹ́ẹ̀ torí ìwà ipá tí ò mú kí ìlú fara rọ ní orílẹ̀-èdè Kóńgò.
Àwọn ará wa tó wà ní Lóvua ò lè lọ́ sí àwọn ìlú míì láti ṣe ìpàdé, torí wọ́n fòfin de àwọn tó wà ní ibùdó láti rìnrìn àjò.
Torí náà, ẹ̀ka ọ́fíìsì ṣètò pé kí wọ́n ṣe àpéjọ yẹn nínú ibùdó náà, wọ́n sì tún kọ́ Gbọ̀ngàn Ìjọba méjì tó ṣe é lò fúngbà díẹ̀.
Ìjọ mẹ́rin ló ń lo Gbọ̀ngàn Ìjọba méjèèjì yìí, mẹ́ta ní èdè Tshiluba àti ọ̀kan ní èdè Lingala
Ní May 24, 2019, alábòójútó àyíká àti aṣojú láti ẹ̀ka ọ́fíìsì rìnrìn àjò lọ sí ibùdó Lóvua kí wọ́n lè rí i pé pèpéle àti ẹ̀rọ tá a fi ń gbóhùn sáfẹ́fẹ́ wà létòlétò.
Láìka àwọn ìpèníjà tí àwọn ara wa tó wà ni ibùdó àwọn tó ń wà ibi ìsádi ń kojú sí, síbẹ̀ wọ́n fi àwọn nǹkan bíi tapólì, òpó, okùn, ìṣó àtàwọn ohun èlò míì tí wọ́n nílò ṣètìlẹ́yìn.
Lẹ́yìn ìtòlẹ́sẹẹsẹ náà, arákùnrin Honoré Lontongo, tó jẹ́ ìránṣẹ́ iṣẹ́ òjíṣẹ́ nínú ọ̀kan lára àwọn ìjọ tó wà ní Tshiluba nínú ibùdó àwọn tó ń wà ibi ìsádi náà, sọ pé:
“Bí a ṣe rí àwọn àpéjọ tá a ṣe nínú ibùdó àwọn tó ń wà ibi ìsádi yìí, láìka àwọn ipò tí kò rọrùn rárá tá a wà sí, jẹ́ ká rí i pé Jèhófà nífẹ̀ẹ́ wa, kì í ṣe àwùjọ wa lódindi nìkan ló nífẹ̀ẹ́, àmọ́, ó tún nífẹ̀ẹ́ wa lẹ́nì kọ̀ọ̀kan pẹ̀lú.”
Inú mi dùn gan-an!
Àádọ́ta (50) ni àwọn tó ń fi gbogbo àkókò wọn ṣiṣẹ́ ní Bẹ́tẹ́lì tó wà nílùú Douala, lórílẹ̀-èdè Kamẹrúùnù.
Láìpẹ́, wọ́n máa ní ẹ̀ka ọ́fíìsì tuntun, torí pé a máa tó kọ́ ẹ̀ka ọ́fíìsì tuntun sí àdúgbò Logbessou, èyí tó máa rọ́pò àwọn ọ́fíìsì tí wọ́n ń lò lọ́wọ́lọ́wọ́ báyìí ní àdúgbò Bonabéri.
Ti pé a fẹ́ kọ́ ẹ̀ka ọ́fíìsì tuntun fi hàn pé ìlọsíwájú ń bá ọ̀rọ̀ ìjọsìn Ọlọ́run lórílẹ̀-èdè Kamẹrúùnù. Lọ́dún 2017, ó lé ní ẹgbẹ̀rún lọ́nà ọgọ́rùn-ún (100,000) èèyàn tó wá síbi Ìrántí Ikú Kristi, iye yẹn sì ju ìlọ́po méjì àwọn akéde lọ.
Àwọn ará wa ń ri ohun tí kò ní jẹ́ kí mànàmáná ṣọṣẹ́.
Ẹ̀gbẹ́ Gbọ̀ngàn Àpéjọ kan ni ibi tá a ń kọ́ ẹ̀ka ọ́fíìsì náà sí wà.
Àwọn òṣìṣẹ́ ti bẹ̀rẹ̀ sí í ṣètò ìpìlẹ̀ ilé náà.
Tá a bá ti kọ́ ilé náà tán, àwọn ilé gbígbé tó wà níbẹ̀ máa rí bíi tàwọn ilé tó wọ́pọ̀ ládùúgbò náà, àwọn ọ́fíìsì sì máa wà lọ́tọ̀ bó ṣe wà nínú fọ́tò tó wà lókè yìí.
Ètò tá a ṣe lọ́wọ́lọ́wọ́ báyìí ni pé, títí ìparí ọdún 2019, ìdílé Bẹ́tẹ́lì máa lè kó lọ síbẹ̀.
Díẹ̀ lára àwọn ará lọ́kùnrin lóbìnrin tó lé ní ẹgbẹ̀rún méjì àti ọgọ́rùn-ún mẹ́jọ (2,800) tó wá síbi àkànṣe ìpàdé tí wọ́n ti kọ́ bí wọ́n ṣe lè ṣèrànwọ́ lẹ́nu iṣẹ́ ìkọ́lé náà.
Gilles Mba, tó jẹ́ ara ìdílé Bẹ́tẹ́lì ní Kamẹrúùnù, tó ń bá Ẹ̀ka Tó Ń Gbéròyìn Jáde ṣiṣẹ́, sọ pé, “Ó wú wa lórí láti rí ẹgbẹẹgbẹ̀rún àwọn ará wa lọ́kùnrin lóbìnrin tí wọ́n ti yọ̀ǹda ara wọn láti ṣèrànwọ́ lẹ́nu iṣẹ́ ìkọ́lé náà, táwọn náà ní irú ẹ̀mí tí Aísáyà ní.” (Aísáyà 6:8)
Ó fi kún un pé, “Bí iṣẹ́ ṣe ń lọ ní pẹrẹu yìí jẹ́ kóríyá fún gbogbo àwa tá à ń ṣiṣẹ́ ní ẹ̀ka ọ́fíìsì láti tẹra mọ́ṣẹ́.
Ara wa ti wà lọ́nà láti bẹ̀rẹ̀ sí í lo àwọn ọ́fíìsì tuntun tá à ń kọ́ yìí fún ète tá a fi ń kọ́ ọ, ìyẹn láti bọlá fún orúkọ Jèhófà.”
Lọ́dún tó kọjá, iṣẹ́ bẹ̀rẹ̀ lórí ẹ̀ka ọ́fíìsì tuntun lórílẹ̀-èdè Kamẹrúùnù.
Bó ṣe wà nínú àwòrán tó wà lókè yìí, iṣẹ́ ti ń lọ lórí àwọn ilé gbígbé mẹ́rẹ̀ẹ̀rin àtàwọn ọ́fíìsì.
A retí pé ọgọ́ta (60) èèyàn láá máa gbé ní ẹ̀ka ọ́fíìsì tuntun yìí, ó sì máa ní àyè tó gba àwọn mọ́kànléláàádọ́rin (71) láti ṣiṣẹ́.
Ètò tó wà nílẹ̀ fi hàn pé iṣẹ́ máa parí lórí àwọn ilé náà títí ìparí oṣù December 2019.
Àwọn fọ́tò tó tẹ̀ lé e yìí máa jẹ́ kẹ́ ẹ rí ibi tí iṣẹ́ náà dé. Àwòrán bí ẹ̀ka ọ́fíìsì náà ṣe máa rí tíṣẹ́ bá parí.
Àwọn Ẹlẹ́rìí Jèhófà mú Ìwé Mímọ́ Kristẹni Lédè Gíríìkì ní Ìtumọ̀ Ayé Tuntun jáde lédè Bassa ní àpéjọ agbègbè tó wáyé nílùú Douala, lórílẹ̀-èdè Kamẹrúùnù ní August 2, 2019.
Ó gbà tó oṣù méjìdínlógún (18) kí iṣẹ́ tó parí lórí iṣẹ́ ìtumọ̀ Ìwé Mímọ́ yìí.
Ìgbà àkọ́kọ́ sì nìyí tí àwọn Ẹlẹ́rìí Jèhófà máa tú Bíbélì sí èdè tí àwọn èèyàn Kamẹrúùnù ń sọ.
Arákùnrin Peter Canning, tó jẹ́ ọ̀kan lára Ìgbìmọ̀ Ẹ̀ka ọ́fíìsì Kamẹrúùnù ló mú Bíbélì yìí jáde ní ọjọ́ àkọ́kọ́ àpéjọ agbègbè tó wáyé ní Gbọ̀ngàn Àpéjọ tó wà ní Logbessou. Ẹgbẹ̀rún méjì ó lé mẹ́ẹ̀ẹ́dógún (2,015) èèyàn ló wà níbẹ̀.
Ṣáájú ká tó mú Ìwé Mímọ́ Kristẹni Lédè Gíríìkì yìí jáde, Bíbélì tí wọ́nwó, tó sì ṣòro lóye ní àwọn arákùnrin àti arábìnrin wa tó ń sọ èdè Bassa ń lò.
Ọ̀kan lára àwọn atúmọ̀ èdè tó ṣiṣẹ́ lórí ìtumọ̀ Bíbélì yìí sọ pé: “Ìtumọ̀ Bíbélì tí a ṣẹ̀ṣẹ̀ mú jáde yìí máa ran àwọn akéde lọ́wọ́ láti lóye Bíbélì dáadáa.
Ó tún máa fi kún ìfẹ́ tí wọn ní fún Jèhófà àti ètò rẹ̀.”
Àwọn tó fẹ́rẹ̀ẹ́ tó ẹgbẹ̀rún lọ́nà ọgọ́rùn-ún mẹ́ta (300,000) ló ń sọ èdè Bassa ní Kamẹrúùnù.
Ẹgbẹ̀rún kan, ọgọ́rùn-ún mẹ́sàn-án àti mẹ́sàn-án (1,909) akéde tó ń sọ èdè Bassa ló wà ní Kamẹrúùnù.
Láti December 2017, ìjà abẹ́lé tó ń wáyé láàárín àwọn Hema àti Lendu lágbègbè Ituri ní Orílẹ̀-èdè Olómìnira ti Kóńgò ti yọrí sí ikú ọ̀pọ̀ èèyàn, ẹgbẹẹgbẹ̀rún èèyàn ni ò sì nílé lórí mọ́.
Ṣe ni ìjà yìí ń le sí i, ọ̀pọ̀ àwọn ará wa lọ́kùnrin lóbìnrin sì wà lára àwọn tó ń fara gbá àbájáde rẹ̀.
Ẹgbẹẹgbẹ̀rún àwọn tí ogun lé wá sí Kóńgò, tó fi mọ́ àwọn akéde igba ó dín mẹ́jọ (192) tó ń gbé ní ibùdó méjì nítòsí ààlà Kóńgò, ti sá lọ sí Ùgáńdà láti forí ara wọn pa mọ́.
Nígbà tó fi máa di June 2018, ẹgbẹ̀rún kan ó lé méjìdínlọ́gọ́rùn-ún (1,098) Ẹlẹ́rìí Jèhófà ló ti sá kúrò níbi táwọn èèyàn ti ń jà lọ sí Bunia, tó jẹ́ olú-ìlú Ituri.
Ó dùn wá pé tọkọtaya kan àtàwọn ọmọ kékeré mẹ́ta táwọn òbí wọn ti ṣèrìbọmi ṣaláìsí, torí pé wọ́n ṣàìsàn.
Àmọ́ àwọn tó ń para wọn nípakúpa náà ò rí ìkankan nínú àwọn ará wa lọ́kùnrin àti lóbìnrin pa.
Àwọn ará lọ́kùnrin lóbìnrin tó sá kúrò láwọn agbègbè lóríṣiríṣi nílùú Ituri rèé nínú àyíká Gbọ̀ngàn Àpéjọ ní Bunia.
Àwọn jàǹdùkú ti fọ́ ilé ọ̀pọ̀ àwọn ará tó sá lọ, ṣe ni wọ́n tiẹ̀ jó àwọn ilé kan kanlẹ̀.
Bákan náà, wọ́n ba ọ̀pọ̀ irè oko àwọn ará náà jẹ́, bẹ́ẹ̀ torí kí wọ́n lè fi gbọ́ bùkátà ni wọ́n ṣe gbìn wọ́n.
Àtìgbà tí ìjà náà ti bẹ̀rẹ̀ làwọn akéde tí kò sí níbi tí wọ́n ti ń jà ti ń ṣèrànwọ́ fáwọn ará wọn tọ́rọ̀ yìí kàn.
Àwọn kan gbé ọkọ̀ wọn sílẹ̀ kí wọ́n lè fi kó àwọn ará lọ síbi tí kò séwu (wo àwòrán ìbẹ̀rẹ̀).
Yàtọ̀ síyẹn, àwọn ìdílé Ẹlẹ́rìí Jèhófà tíye wọn jẹ́ igba ó lé márùn-ún (205) láti ìlú Bunia fi owó àti oúnjẹ ránṣẹ́, kódà wọ́n gba àwọn ará wọn sílé, bó tiẹ̀ jẹ́ pé àwọn fúnra wọn ò fi bẹ́ẹ̀ ní lọ́wọ́.
Lóòótọ́, ibùdó méjì tó tóbi déwọ̀n àyè kan wà nílùú Bunia táwọn tí ogun lé wá lè dé sí, àmọ́ gbogbo àwọn akéde tó sá kúrò ní Kóńgò làwọn ará wọn tó jẹ́ Ẹlẹ́rìí Jèhófà ní Bunia ti gbà sílé.
Ìgbìmọ̀ Ẹ̀ka orílẹ̀-èdè Kóńgò ṣètò ìgbìmọ̀ kan tó ń ṣètò ìrànwọ́ nígbà àjálù, ìgbìmọ̀ yìí sì ti pèsè àwọn ohun kòṣeémáàní fáwọn ará wa.
Aṣojú kan láti ẹ̀ka ọ́fíìsì tún bẹ àwọn ará tọ́rọ̀ kàn wò, ó sì fi ọ̀rọ̀ Ọlọ́run gbé wọn ró.
Bó tiẹ̀ jẹ́ pé àwọn ará lọ́kùnrin lóbìnrin tó sá lọ sí Bunia àtàwọn ibòmíì ò nílé tara wọn, síbẹ̀ wọ́n ń kóra jọ láti jọ́sìn pẹ̀lú àwọn ìjọ tó wà lágbègbè náà, wọ́n sì ń fìtara wàásù ìhìn rere fáwọn èèyàn.
Láti February sí April 2018, ó lé ní igba àti àádọ́rin (270) èèyàn táwọn ará bẹ̀rẹ̀ sí í kọ́ lẹ́kọ̀ọ́ Bíbélì níbi táwọn tí ogun lé kúrò nílùú ń gbé.
Bó tiẹ̀ jẹ́ pé nǹkan ò fara rọ lórílẹ̀-èdè Congo, tí ìjà sì ń ṣẹlẹ̀, àrùn Ebola bẹ̀rẹ̀ sí í jà níbẹ̀ láti oṣù August 2018.
Lágbègbè North Kivu àti Ituri, ó lé ní ẹgbẹ̀rún kan (1,088) èèyàn tó ti kó àrùn yìí, àwọn tó sì ti pa jẹ́ ọgọ́rùn-ún mẹ́fà ó lé márùndíláàádọ́rin (665).
Ó dùn wá pé àrùn yìí jà dé ọ̀dọ̀ àwọn ará wa.
Ẹ̀ka ọ́físì wa ní Congo (Kinshasa) sọ pé, àrùn yìí pa ẹni mẹ́wàá tó ti dàgbà àti ọmọdé méjì láàárín àwọn ará.
Àrùn náà ran arákùnrin kan, àmọ́ ara rẹ̀ ti kọ́fẹ pa dà.
Ká lè kọ́ àwọn ará ní bí wọ́n ṣe lè dènà àrùn yìí, ẹ̀ka ọ́fíìsì wa ní Congo (Kinshasa) gba àyè lọ́dọ̀ Ìgbìmọ̀ Olùṣekòkáárí láti ṣe fídíò kan pẹ̀lú àsọyé kan.
Fídíò náà kọ́ni láwọn àbá tó wúlò, irú bíi pé kí wọ́n láwọn ibi téèyàn ti lè fọwọ́ káàkiri, ìyẹn la sì ṣe ní gbogbo ìjọ.
Àwọn àbá tó wúlò yìí ti jẹ́ ká lè dín bí ààrùn náà ṣe ń gbilẹ̀ kù.
Ohun tá a ṣe yìí mú kí àwọn òṣìṣẹ́ ètò ìlera méjì kọ̀wé ìmọrírì sí ẹ̀ka ófíìsì wa torí àpẹẹrẹ tó dáa àti ìfọwọ́sowọ́pọ̀ tí wọ́n rí láàárín àwọn Ẹlẹ́rìí Jèhófà lásìkò tí àrùn Ebola fi ń jà.
Ìgbà kan wà tí àwọn ará wa kan ò lè jáde nílé fún ọ̀pọ̀ ọ̀sẹ̀ láwọn ìlú kan.
Kódà, torí kí àrùn yìí má bàa túbọ̀ ràn lásìkò náà, ẹ̀ka ọ́fíìsì ní kí àyíká méjìlá sún àpéjọ àgbègbè wọn síwájú.
Ẹ̀ka ọ́fíìsì wá ṣètò pé kí àwọn ará tó wà láwọn ìjọ tọ́rọ̀ náà kàn wo fídíò àpéjọ àgbègbè tá a ti gbà sílẹ̀ ní Gbọ̀ngàn Ìjọba wọn, kí wọ́n má bàa pàdánù oúnjẹ tẹ̀mí.
Orílẹ̀-èdè Eritrea jẹ́ ọ̀kan lára àwọn ibi tí wọ́n ti ń ṣe inúnibíni tó gbóná janjan sí àwọn Ẹlẹ́rìí Jèhófà láwọn ọdún àìpẹ́ yìí.
Ní September 17, 2019, àwọn arákùnrin mẹ́tẹ̀ẹ̀ta wọ̀nyí, Paulos Eyasu, Isaac Mogos, àti Negede Teklemariam ti wà lẹ́wọ̀n fún ọdún mẹ́ẹ̀ẹ́dọ́gbọ̀n.
Láfikún sí i, àwọn arákùnrin wa mọ́kàndínlógójì (39) àtàwọn arábìnrin mẹ́wàá míì ní wọn ti jù sẹ́wọ̀n.
Gbogbo àwọn arákùnrin àtàwọn arábìnrin wa tí wọ́n wà lẹ́wọ̀n báyìí ni ìjọba ilẹ̀ náà kò gbọ́rọ̀ wọn lọ ilé ẹjọ́, bẹ́ẹ̀ sì ni ilé ẹjọ́ kankan ò dá wọn lẹ́bi.
Wọn ò mọ ìgbà tí wọ́n máa dá wọn sílẹ̀.
Àwọn arákùnrin mẹ́rin ló ti kù sínú ọgbà ẹ̀wọ̀n, nígbà tí àwọn mẹ́tà míì kú lẹ́yìn tí wọ́n dá wọn sílẹ̀, torí ìyà tí wọ́n fi jẹ wọ́n nígbà tí wọ́n wà lẹ́wọ̀n.
Inúnibíni ní Eritrea bẹ̀rẹ̀ sí gbóná sì i ní October 25, 1994 tó jẹ́ nǹkan bí ọdún kan ààbọ̀ lẹ́yìn tí orílẹ̀ èdè Eritrea gbòmìnira lọwọ́ orílẹ̀ èdè Ethiopia.
Ààrẹ orílẹ̀ èdè tuntun níbẹ̀ sọ pé gbogbo àwọn ọmọ ìbílẹ̀ orílẹ̀ èdè Eritrea tí wọ́n jẹ́ Ẹlẹ́rìí Jèhófà, ní wọn kìí ṣe ọmọ ìbílẹ̀ orílẹ̀ èdè náà mọ́, kìkì ní torí pé, wọ́n dúró láìyẹsẹ̀ lórí ìpinnu wọn gẹ́gẹ́ bí Kristẹni láti má ṣe dá sí tọ̀tún tòsì.
Ààrẹ náà tún fi àwọn ẹ̀tọ́ tí wọ́n ní dù wọ́n.
Lára àwọn ẹ̀tọ́ tí wọ́n tún fi dù wọ́n ni pé àwọn Ẹlẹ́rìí Jèhófà kò lè lọ sílé ìwé, wọn ò lè dá okòwò tiwọn sílẹ̀ tàbí rìnrìn àjò kúrò lórílẹ̀ èdè náà.
Láwọn ọdún àìpẹ́ yìí, àwọn ẹgbẹ́ ajàfẹ́tọ̀ọ́ ọmọnìyàn tó lórúkọ láwùjọ ti sọ léraléra pé ó ń ká àwọn lára bí ìjọba orílẹ̀ èdè Eritrea ṣe fọwọ́ rọ́ ìlànà nípa ẹ̀tọ́ ọmọnìyàn lágbàáyé sẹ́yìn tí wọ́n sì ń fojú àwọn Ẹlẹ́rìí gbolẹ̀.
Ìjọba orílẹ̀-èdè Eritrea ti kọ̀ jálẹ̀ láti tẹ̀ lé ohun tí àwọn àjọ yìí sọ..
Wo: “ÀKÀNṢE ÌRÒYÌN: Wọ́n Ń Ṣenúnibíni Sáwọn Ẹlẹ́rìí Jèhófà Lórílẹ̀-Èdè Eritrea”
Àá máa bá a lọ láti máa sọ fún àwọn aláṣẹ ìjọba àtàwọn míì tó wà nípò àṣẹ nípa bí nǹkan ṣe rí ní Eritrea.
Ní Sunday, March 10, ọkọ̀ òfúrufú 302 ti Ethiopian Airlines gbéra ní Addis Ababa tó jẹ́ olú ìlú orílẹ̀-èdè Etiópíà, àmọ́ kò pẹ́ lẹ́yìn tó gbéra tó fi ko jàǹbá.
Gbogbo àwọn mẹ́tàdínlọ́gọ́jọ (157) tó wà nínú ẹ̀ ló sì kú.
Ó dùn wá pé arábìnrin wa kan tó ń jẹ́ Rosemary Mumbi wà lára àwọn tó kú nínú jàǹbá ọkọ̀ náà. Ìròyìn ikú arábìnrin yìí dùn wá gan-an.
Ẹni ọdún mẹ́rìndínláàádọ́rin (66) ni Arábìnrin Mumbi, ó sì máa ń lo èyí tó pọ̀ jù lára àkókò rẹ̀ lẹ́nu iṣẹ́ ìwàásù, ìjọ Roma Manzoni Inglese ló wà ní ìlú Rome, lórílẹ̀-èdè Ítálì.
Láti lè dé àwọn ìpínlẹ̀ tí a kì í sábà ṣe lórílẹ̀-èdè Gabon, ẹ̀ka ilé iṣẹ́ wa lórílẹ̀-èdè Cameroon ṣètò ìwàásù àkànṣe láti June 1 sí August 31, 2019.
Àfojúsùn náà jẹ́ láti wàásù dé ọ̀dọ́ àwọn tó ń gbé làwọn ìlú ńlá mẹ́wàá tí èrò pọ̀ sí jùlọ, ìyẹn Franceville, Koulamoutou, Lambaréné, Libreville, Makokou, Moanda, Mouila, Oyem, Port-Gentil, àti Tchibanga.
Láti onírúurú orílẹ̀-èdè làti kọ́wọ́ ti iṣẹ́ ìwàásù yìí, torí pé ọgọ́rùn-ún mẹ́rin (400) àwọn olùyọ̀ǹda-ara-ẹni ló wá láti Belgium, Kánádà, France, àti orílẹ̀-èdè Amẹ́ríkà.
Èèyàn tó lé ní mílíọ̀nù méjì ló ń gbé lórílẹ̀-èdè Gabon.
Àwọn tó tó ìdá mẹ́jọ nínú mẹ́wàá ló ń sọ èdè Faransé tó jẹ́ èdè àjùmọ̀lò, tí ìdá mẹ́ta nínú mẹ́wàá sì lè sọ èdè Fang tó jẹ́ èdè ìbílẹ̀ wọn.
Torí náà, èdè méjèjì la lò láti wàásù.
Ẹnìkan tó ń sọ èdè Fang, tó nífẹ̀ẹ́ Bíbélì, tó sì ń gbé lágbègbè Bissegue nílùú Libreville sọ pé: “Ìgbà àkọ́kọ́ nìyí tí màá gbọ́ ọ̀rọ̀ Ọlọ́run lédè mi!”
Arábìnrin kan tó kópa nínú ìwàásù náà sọ pé: “Iṣẹ́ ìwàásù yìí jẹ́ àpẹẹrẹ ìfẹ́ àti ìṣọ̀kan tó wà nínú ètò Jèhófà.
Ní January 15, 2019, ó kéré tán, èèyàn mọ́kànlélógún (21) ló kú nígbà táwọn adigunjalè wá sí hòtẹ́ẹ̀lì àti ọ́fíìsì kan ní ìlú Nairobi, lórílẹ̀-èdè Kenya.
Ẹ̀ka ọ́fíìsì wa ní Kenya ròyìn pé kò sí ìkankan nínú àwọn akéde tó kú tàbí tó fara pa nígbà ìṣẹ̀lẹ̀ yìí. Ibi tí ìṣẹ̀lẹ̀ yìí ti wáyé tó ìrìn kìlómítà méje (máìlì mẹ́rin) sí ẹ̀ka ọ́fíìsì wa.
Ó ju mẹ́wàá lára àwọn ará wa tó ń ṣiṣẹ́ nínú ọgbà Dusit, táwọn adigunjalè náà ti ṣọṣẹ́.
Lásìkò táwọn adigunjalè náà wá, méje lára àwọn ará náà ò sí níbi iṣẹ́; àwọn èèyàn tó kù sì jáde níbẹ̀ ní àlàáfíà.
Arákùnrin kan àti arábìnrin kan tó fara pa mọ́ fún wákàtí méjìlá wà lára àwọn tí wọ́n kó jáde níbẹ̀ ní àlàáfíà.
Ní August 30 2019, àwa Ẹlẹ́rìí Jèhófà mú Bíbélì Mímọ́ ti Ìtumọ̀ Ayé Tuntun jáde lédè Luo ní àpéjọ agbègbè tó wáyé nílùú Kisumu, lórílẹ̀-èdè Kẹ́ńyà.
Arákùnrin Remy Pringle, tó jẹ́ ọ̀kan lára Ìgbìmọ̀ Ẹ̀ka lórílẹ̀-èdè Kẹ́ńyà ló mú Bíbélì yìí jáde lọ́jọ́ àkọ́kọ́ àpéjọ náà.
Àwọn tó wá sí àpéjọ náà, pa pọ̀ pẹ̀lú àwọn tó wà níbi àpéjọ àgbègbè méjì míì tí àtagbà ètò náà dé, jẹ́ ẹgbẹ̀rún méjì, ọgọ́rùn-ún mẹ́rin àti mọ́kànlélọ́gọ́rin (2,481).
Nǹkan bí ọdún mẹ́ta ni wọ́n fi ṣiṣẹ́ lórí ìtúmọ̀ Bíbélì yìí kó tó parí.
Ọ̀kan lára àwọn atúmọ̀ èdè tó ṣiṣẹ́ náà sọ pé: “Ó máa nípa tó pọ̀ lórí àwọn arákùnrin àti arábìnrin tí wọn ti ń fojú sọ́nà fún Bíbélì Ìtumọ̀ Ayé Tuntun lódindi lédè Luo.
Ọ̀pọ̀ ìdílé tá a jọ wà nínú ìjọ ni kò le ra odindi Bíbélì fún gbogbo àwọn tó wà nínú ìdílé wọn. Torí náà, ìbùkún lèyí jẹ́ fún wọn láti ní ẹ̀dà kọ̀ọ̀kan.
Ìyẹn nìkan kọ́, èdè òde òní tá a fi túmọ̀ Bíbélì yìí á mú kó rọrùn láti lóye, bákan náà, á mú kí ìgbàgbọ́ wa túbọ̀ lágbára bá a ṣe ń lò ó fún ìdákẹ́kọ̀ọ́ àti ìjọsìn ìdílé.”
A ti túmọ̀ Bíbélì Ìtumọ̀ Ayé Tuntun lódindi tàbí ní apá kan sí èdè mẹ́rìnlélọ́gọ́sàn-án (184), mẹ́ẹ̀ẹ́dọ́gbọ̀n (25) nínú wọn jẹ́ àtúnṣe lódindi, tá a gbé ka ẹ̀dà Gẹ̀ẹ́sì tá a tún ṣe lọ́dún 2013.
Akéde tó tó nǹkan bí ẹgbẹ̀rún kan àti ọgọ́rùn-ún mẹ́jọ (1,800) ló ń sọ èdè Luo ní Kẹ́ńyà, ó sì dá wa lójú pé Bíbélì tá a ṣẹ̀ṣẹ̀ mú jáde yìí á ràn wọ́n lọ́wọ́ láti túbọ̀ sún mọ Jèhófà.
Á tún ràn wọ́n lọ́wọ́ láti wàásù fún àwọn èèyàn tó lé ní mílíọ̀nù márùn-ún tó ń sọ èdè Luo.
Ní November 9, 2019, a ya ilé tuntun kan tá a kọ́ fún ilé ẹ̀kọ́ ètò Ọlọ́run sí mímọ́ ní Eldoret, lórílẹ̀-èdè Kẹ́ńyà.
Arákùnrin Bengt Olsson tó jẹ́ ọ̀kan lára Ìgbìmọ̀ Ẹ̀ka orílẹ̀-èdè Kẹ́ńyà ló sọ àsọyé ìyàsímímọ́ náà. Àwọn ẹgbẹ̀rún kan àti igba ó dín kan (1,199) títí kan ọgọ́rùn-ún márùn-ún (500) àwọn òjíṣẹ́ alákòókò kíkún tí wọ́n wá láti onírúurú ibi lórílẹ̀-èdè náà ló pésẹ̀ síbẹ̀.
Ilé Ẹ̀kọ́ Àwọn Ajíhìnrere Ìjọba Ọlọ́run (SKE) àti Ilé Ẹ̀kọ́ Àwọn Alábòójútó Àyíká Àtàwọn Ìyàwó Wọn la fẹ́ máa lo ibẹ̀ fún.
Ó kéré tán, àwùjọ àwọn akẹ́kọ̀ọ́ SKE mẹ́rin la retí pé á máa kẹ́kọ̀ọ́ yege níbẹ̀ lọ́dọọdún.
Àwọn ilé tí ẹ̀ka ọ́fíìsì ń lò tẹ́lẹ̀ àmọ́ tá a ti tún ṣe la sọ di ilé ẹ̀kọ́ yìí. Ilé táwọn míṣọ́nnárì ń gbé tẹ́lẹ̀ la sọ di ibi tí wọ́n á ti máa fọṣọ, ilé ìdáná àti ilé ìjẹun.
A sì sọ Gbọ̀ngàn Ìjọba kan di kíláàsì táwọn akẹ́kọ̀ọ́ á máa lò. April 1, 2019 la bẹ̀rẹ̀ iṣẹ́ yìí, a sì parí èyí tó pọ̀ jù níbẹ̀ ní September 9.
Nígbà tí Arákùnrin Olsson ń sọ bí ilé ẹ̀kọ́ yìí ṣe ṣe pàtàkì tó, ó sọ pé: “Ẹ̀rí fi hàn pé ọ̀pọ̀ àwọn tó ń gbé ní Ìlà Oòrùn Áfíríkà ni wọ́n fẹ́ mọ Ọlọ́run. Ó dá wa lójú pé ìdálẹ́kọ̀ọ́ táwọn akẹ́kọ̀ọ́ máa gbà nílé ẹ̀kọ́ yìí á mú kí wọ́n túbọ̀ já fáfá láti ran ọ̀pọ̀ èèyàn lọ́wọ́ kí wọ́n lè rọ́ wá sórí òkè Jèhófà.”
Ní January 5, 2018, ìjì líle Cyclone Ava kọlu orílẹ̀-èdè Madagásíkà. Àwọn òṣìṣẹ́ ìjọba ròyìn pé nǹkan bí èèyàn mọ́kànléláàádọ́ta [51] ló kú sínú ìṣẹ̀lẹ̀ náà, ẹgbẹẹgbẹ̀rún èèyàn ló sì ti di ẹni tí kò nílé lórí mọ́.
Ìròyìn tá a gbọ́ láti ẹ̀ka ọ́fíìsì wà ní Madagásíkà jẹ́ ká mọ̀ pé kò sí ọ̀kankan nínú àwọn ará wa tó kú sínú ìṣẹ̀lẹ̀ náà.
Àmọ́ ilé márùndínláàádọ́ta [45] ló ti bà jẹ́, títí kan Gbọ̀ngàn Ìjọba mẹ́fà.
Ìjì yẹn tún ba ohun ọ̀gbìn jẹ́, ohun tí púpọ̀ nínú àwọn ará wa sì fi ń gbọ́ bùkátà ara wọn nìyẹn.
A ṣètò pé kí Ìgbìmọ̀ Tó Ń Ṣètò Ìrànwọ́ Nígbà Àjálù bójú tó àwọn ará tí àjálù náà bá, wọ́n pèsè oúnjẹ, aṣọ, wọ́n tún ṣètò ibi táwọn ará lè forí pamọ́ sí fún ìgbà díẹ̀.
Àwọn arákùnrin méjì láti ẹ̀ka ọ́fíìsì tún rìnrìn àjò lọ síbẹ̀ láti ṣe ìpàdé àkànṣe pẹ̀lú àwọn tí àjálù náà dé bá, wọ́n fi Bíbélì gbé wọn ró.
Owó táwọn ará wa kárí ayé fi ṣe ìtìlẹyìn fún iṣẹ́ kárí ayé ni Ìgbìmọ̀ Olùdarí lò láti pèsè ìrànwọ́ fáwọn ará wa tí àjálù dé bá kárí ayé, irú èyí tó ṣẹlẹ̀ ní Madagásíkà.
Àdúrà wa ni pé kí Jèhófà máa báa lọ láti jẹ́ orísun ààbò fáwọn ará wa ní Madagásíkà lásìkò tó nira yìí.
Gbọ́ ìrírí àwọn arákùnrin àti arábìnrin wa ní Màláwì, tí wọ́n kọ lẹ́tà nítorí àwọn ará wa ní Rọ́ṣíà.
Àwọn kan sọ̀rọ̀ nípa ìgbà tí irú ohun tó ṣẹlẹ̀ ní Rọ́síà ṣẹlẹ̀ lórílẹ̀-èdè wọn, láwọn àkókò kan láàárín ọdún 1970 sí 1979.
Máà bínú, ètò tó o fi ń wo fídíò kò ṣiṣẹ́. Wa Fídíò Yìí Jáde
Ní April 25, 2019, ìjì líle kan tí wọ́n pè ní Kenneth jà ní àríwá orílẹ̀-èdè Mòsáńbíìkì.
Ìgbà kejì nìyí tí ìjì líle tún jà léyìn Ìjì Líle Idai tó jà lóṣù March lórílẹ̀-èdè náà.
Ìjì tó jà kẹ́yìn yìí fa omíyalé tó pọ̀, ó ba ọ̀pọ̀ ilé àti ọ̀nà jẹ́, kódà ńṣe ló mú kí nǹkan túbọ̀ nira lágbègbè tó ti jà.
Nǹkan bíi ọgọ́rùn-ún mẹ́ta (300) akéde ló ń gbé ní agbègbè Cabo Delgado, àmọ́ kò sí ìkankan lára wọn tí ìjì líle náà ṣe lẹ́se tàbí tó pa.
Síbẹ̀, ìjì náà ba mẹ́sàn-án lára ilé àwọn ará wa jẹ́ kọjá àtúnṣe, ó sì tún ba ilé mẹ́rìndínlógún (16) míì jẹ́ díẹ̀.
Yàtọ̀ síyẹn, ó ba Gbọ̀ngàn Ìjọba kan jẹ́ pátápátá, ó sì tún ba mẹ́ta míì jẹ́ díẹ̀.
Alábòójútó àyíká tó wà lágbègbè náà àti aṣojú kan láti Ẹ̀ka Tó Ń Yàwòrán Ilé Tó sì Ń Kọ́ Ọ pẹ̀lú arákùnrin méjì láti ọ́fíìsì àwọn atúmọ̀ èdè lọ sọ́dọ̀ gbogbo àwọn ìjọ tí àjálù náà kàn, wọ́n sì fún wọn ní ìṣírí.
Ní January 12, 2019, àwọn ará wa lórílẹ̀-èdè Nàìjíríà ṣe àkànṣe ìpàdé kan ní Gbọ̀ngàn Àpéjọ tó wà ní ìlú Benin.
Nínú ìpàdé náà, Arákùnrin Geoffrey Jackson, ọ̀kan lára Ìgbìmọ̀ Olùdarí kéde pé a ti mú Bíbélì Mímọ́ ti Ìtumọ̀ Ayé Tuntun tá a tún ṣe jáde ní èdè Isoko àti Yorùbá.
Àwọn tó wà níbi ìpàdé náà àtàwọn tó wò ó láwọn ibi tá a ta àtagbà rẹ̀ sí jẹ́ ẹgbẹ̀rún lọ́nà ọgọ́ta, ọgọ́rùn-ún mẹ́fà àti méjìléláàádọ́rin (60,672).
A ta àtagbà ìpàdé náà sí Gbọ̀ngàn Ìjọba mẹ́rìndínláàádọ́fà (106) àti Gbọ̀ngàn Àpéjọ mẹ́sàn-án ní Nàìjíríà àti láwọn ibì mélòó kan lórílẹ̀-èdè Benin.
Arákùnrin Jackson àti ìdílé kan ní Gbọ̀ngàn Àpéjọ tó wà ní ìlú Benin lórílẹ̀-èdè Nàìjíríà
Arákùnrin Gad Edia tó wà ní ẹ̀ka ọ́fíìsì ní Nàìjíríà sọ pé: “Ọdún mẹ́ta àti oṣù méjì ni wọ́n fi túmọ̀ Bíbélì yìí sí èdè Isoko, ó sì gba ọdún mẹ́ta àti oṣù mẹ́ta kí wọ́n tó parí rẹ̀ lédè Yorùbá.”
Ó wá sọ pé: “Ní Nàìjíríà, ó lé ní ẹgbẹ̀rún márùn-ún (5,000) àwọn ará tó ń sọ èdè Isoko, àwọn tó ń sọ èdè Yorùbá tí wọ́n sì ń kà á lé ní ẹgbẹ̀rún lọ́nà àádọ́ta (50,000). Nígbà táwọn ará gba Bíbélì tá a tún ṣe yìí, ẹnì kan sọ bó ṣe rí lára àwọn tó wà níbẹ̀ pé ‘ìdùnnú ṣubú layọ̀.’ Torí náà, a lè fi gbogbo ẹnu sọ pé ìsapá náà tó bẹ́ẹ̀, ó jù bẹ́ẹ̀ lọ!”
Ní lọ́wọ́lọ́wọ́ báyìí, àwa Ẹlẹ́rìí Jèhófà ti mú Bíbélì Ìtumọ̀ Ayé Tuntun jáde lódindi tàbí lápá kan ní èdè mọ́kàndínlọ́gọ́sàn-án (179).
Òjò rọ̀ gan-an ní gúúsù ìwọ̀ oòrùn orílẹ̀-èdè Nàìjíríà láti July 6 sí July 12, 2017, ó sì mú kí omi yalé àwọn èèyàn ní ìpínlẹ̀ Èkó, Niger àti Ọ̀yọ́. Ìròyìn tá a gbọ́ ni pé, ó kéré tán, èèyàn méjìdínlógún [18] ni ẹ̀mí wọn ti lọ sí ìṣẹ̀lẹ̀ yìí.
Ẹ̀ka ọ́fíìsì àwọn Ẹlẹ́rìí Jèhófà ní Nàìjíríà ti wádìí, wọ́n sì ti rí i pé Ẹlẹ́rìí Jèhófà kankan ò kú sínú ìṣẹ̀lẹ̀ yìí, ìkankan ò sì fara pa, bó tiẹ̀ jẹ́ pé mẹ́rin nínú wọn ò nílé lórí mọ́.
Yàtọ̀ síyẹn, ilé Ẹlẹ́rìí Jèhófà méjì ló bà jẹ́, ilé ẹnì kan sì wà tó bà jẹ́ pátápátá.
Àwọn Ẹlẹ́rìí Jèhófà tó wà ní Nàìjíríà ń ṣèrànwọ́ fáwọn ará wọn àtàwọn aládùúgbò wọn tí kì í ṣe Ẹlẹ́rìí, táwọn kan nínú wọn náà ò nílé lórí mọ́.
Òjò àrọ̀ọ̀rọ̀dá ti fa omíyalé lọ́pọ̀ ibi ní àárín gbùngbùn orílẹ̀-èdè Nàìjíríà àti láwọn agbègbè tó wà ní gúúsù.
Odò Benue àti odò Niger, àwọn odò méjèèjì tó la orílẹ̀-èdè náà já ti kún kọjá ààlà wọn, èyí ti lé ọ̀pọ̀ èèyàn kúrò níbi tí wọ́n ń gbé, ó sì lé ní ọgọ́rùn-ún (100) èèyàn tó pa.
Ìròyìn tá a kọ́kọ́ gbọ́ sọ pé kò sí ìkankan lára àwọn ará wa tó bá àjálù náà lọ tàbí tó fara pa.
Àmọ́, ó kéré tán, ẹgbẹ̀rún méjì (2,000) akéde ni omíyalé náà lé kúrò níbi tí wọ́n ń gbé, ó sì ju ẹgbẹ̀rún kan (1,000) lára wọn tó nílò ìrànlọ́wọ́.
Èyí tó pọ̀ jù lára àwọn tó sá kúrò nílé wọn yìí ló ti ń gbé lọ́dọ̀ àwọn ará láwọn agbègbè tí àjálù náà ò dé.
A ti ní kí Ìgbìmọ̀ Tó Ń Ṣètò Ìrànwọ́ Nígbà Àjálù bẹ̀rẹ̀ iṣẹ́ láti pèsè àwọn nǹkan tí àwọn ará nílò, kí wọ́n sì fún wọn níṣìírí nípa tẹ̀mí.
Méjì lára Ìgbìmọ̀ Ẹ̀ka ní Nàìjíríà àti alábòójútó àyíká kan pẹ̀lú àwọn arákùnrin tó ń ṣiṣẹ́ ní Ẹ̀ka Iṣẹ́ Ìsìn àti Ẹ̀ka Tó Ń Yàwòrán Ilé Tó sì Ń Kọ́ Ọ lọ ṣèbẹ̀wò sọ́dọ̀ àwọn akéde tó wà láwọn agbègbè tọ́rọ̀ kàn, láti ràn wọ́n lọ́wọ́.
Bó tiẹ̀ jẹ́ pé àjálù yìí ti fa ọ̀pọ̀lọpọ̀ ìṣòro, Baba wa ọ̀run, Jèhófà, ṣì ‘ni odi ààbò wa ní àkókò wàhálà.
Ọjọ́ pẹ́ táwọn Ẹlẹ́rìí Jèhófà ti ń sọ Ọ̀rọ̀ Ọlọ́run fáwọn èèyàn Rùwáńdà, àmọ́ èyí tí wọ́n ṣe ní September 2018 tún ṣàrà ọ̀tọ̀ : Wọ́n bẹ̀rẹ̀ sí í túmọ̀ àwọn ìwé tó dá lórí Bíbélì sí Èdè Adití Lọ́nà ti Rùwáńdà (RWS).
Ohun tí wọ́n ṣe yẹn máa mú káwọn mẹ́tàléláàádọ́fà (113) arákùnrin àti arábìnrin tó jẹ́ adití túbọ̀ lóye ẹ̀kọ́ Bíbélì, á sì jẹ́ kí wọ́n túbọ̀ já fáfá láti wàásù fáwọn adití àtàwọn tí kò fi bẹ́ẹ̀ gbọ́rọ̀, tó lé lẹ́gbẹ̀rún lọ́nà ọgbọ̀n (30,000) lórílẹ̀-èdè náà.
Àwọn atúmọ̀ èdè RWS yìí ti túmọ̀ ìwé Tẹ́tí sí Ọlọ́run Kó O Lè Wà Láàyè Títí Láé, wọ́n túmọ̀ fídíò kúkúrú Kí Nìdí Tó Fi Yẹ Kó O Kẹ́kọ̀ọ́ Bíbélì? àti ọ̀pọ̀ ìwé àṣàrò kúkúrú tó wà nínú Àpótí Ìkọ́nilẹ́kọ̀ọ́ wa.
A máa gbé àwọn ìtẹ̀jáde yìí sórí ìkànnì wa láìpẹ́.
Inú ilé kan tí kò fi bẹ́ẹ̀ jìnnà sí ẹ̀ka ọ́fíìsì wa nílùú Kigali làwọn atúmọ̀ èdè RWS yìí ti ń ṣiṣẹ́ wọn, kódà kò ju ìrìn ìṣẹ́jú márùn-ún lọ.
Mẹ́rin làwọn atúmọ̀ èdè náà, ọkùnrin méjì àti obìnrin méjì, odi sì ni ọ̀kan lára àwọn arákùnrin náà.
Àwọn mẹ́rẹ̀ẹ̀rin ló ti gba ìdálẹ́kọ̀ọ́ ọlọ́sẹ̀ mẹ́rin tó ń jẹ́ kéèyàn mọ àwọn ìlànà tó rọ̀ mọ́ títúmọ̀ èdè.
Ọ́fíìsì àwọn atúmọ̀ èdè náà rèé, kò fi bẹ́ẹ̀ jìnnà sí ẹ̀ka ọ́fíìsì orílẹ̀-èdè Rùwáńdà.
Arákùnrin Rwakibibi Jean Pierre tó jẹ́ ọ̀kan lára àwọn atúmọ̀ èdè RWS ṣàlàyé ohun tó fà á tó fi máa ń ṣòro láti túmọ̀ sí èdè adití tá a bá fi wé títúmọ̀ sáwọn èdè míì tó ṣeé kà, Ó ní: “Ọwọ́ àti ojú làwọn tó jẹ́ adití fi máa ń bá ara wọn sọ̀rọ̀, torí náà fídíò la máa ń lò láti mú káwọn adití lóye ọ̀rọ̀ tí wọ́n kọ sínú ìwé.
Lẹ́yìn tá a bá ti lóye ohun tí òǹkọ̀wé sọ lédè òyìnbó, àá ya onírúurú àwòrán sórí pátákó ìkọ̀wé funfun kan, kó lè rọrùn fún wa láti fara ṣàpèjúwe ohun tí òǹkọ̀wé ń sọ lédè adití.
Kó lè dá wa lójú pé ohun tí òǹkọ̀wé ń sọ gan-an la gbé jáde àti pé a ò fi irú pe ìrù, a sábà máa ń pe àwọn ará tó jẹ́ adití láti ṣàyẹ̀wò rẹ̀ kí wọ́n sì sọ èrò wọn nípa ẹ̀.”
Ọ̀gbẹ́ni Augustin Munyangeyo tó jẹ́ ọ̀gá àgbà àjọ Rwanda National Union of the Deaf.
Ọ̀gbẹ́ni Augustin Munyangeyo tó jẹ́ ọ̀gá àgbà àjọ àdáni kan tó ń bójú tó ọ̀rọ̀ àwọn adití lórílẹ̀-èdè Rùwáńdà, ìyẹn Rwanda National Union of the Deaf, sọ bó ṣe mọyì iṣẹ́ táwọn atúmọ̀ èdè yẹn ń ṣe. Ó sọ pé: “A dúpẹ́ lọ́wọ́ ẹ̀yin Ẹlẹ́rìí Jèhófà gidigidi fún iṣẹ́ ribiribi tẹ́ ẹ̀ ń ṣe. Ẹ̀yin lẹ̀ ń jẹ́ káwọn adití mọ Ọlọ́run torí pé ẹ̀ ń ṣe ìwé Bíbélì àti fídíò lédè Adití lọ́nà ti Rùwáńdà.”
Tá a bá kà á ní ení, èjì, èdè adití táwa Ẹlẹ́rìí Jèhófà ń túmọ̀ ìwé wa sí láwọn ibi ọ̀tọ̀ọ̀tọ̀ láyé ti lé ní àádọ́rùn-ún (90), yàtọ̀ síyẹn, a tún ní ètò ìṣiṣẹ́ kan ta á dìídì ṣe fún àǹfààní gbogbo èèyàn láìbéèrè kọ́bọ̀, ìyẹn JW Library Sign Language®, oríṣiríṣi ìtẹ̀jáde tá a gbé karí Bíbélì ló wà ní àwọn èdè adití tó lé láàádọ́rùn-ún (90) yẹn.
Báwọn ìtẹ̀jáde yìí ṣe wà lónírúurú èdè adití mú kó ṣeé ṣe fáwọn ará wa lọ́kùnrin àti lóbìnrin níbi gbogbo láyé láti wàásù ìhìn rere fún “gbogbo orílẹ̀-èdè àti ẹ̀yà àti èdè àti èèyàn.”​—Ìfihàn 14:​6, àlàyé ìsàlẹ̀.
Lọ́dún tó ṣáájú ọdún tí wọ́n bẹ̀rẹ̀ sí í túmọ̀ àwọn ìtẹ̀jáde wa sí RWS, ẹ̀ka ọ́fíìsì orílẹ̀-èdè Rùwáńdà ṣètò Ilé Ẹ̀kọ́ Àwọn Aṣáájú-Ọ̀nà ní ọ̀sẹ̀ September 4 sí 9, 2017.
Èdè Adití Lọ́nà ti Rùwáńdà ni wọ́n fi ṣe ilé ẹ̀kọ́ náà, ìyẹn sì ni àkọ́kọ́ irú ẹ̀. Àwọn mẹ́tàlélógún (23) ló wá sílé ẹ̀kọ́ náà, wọ́n sì kọ́ bí wọ́n ṣe lè túbọ̀ mọ̀ọ̀yàn kọ́, pàápàá bí wọ́n ṣe lè kọ́ àwọn adití lẹ́kọ̀ọ́ Bíbélì, títí kan àwọn tí kò fi bẹ́ẹ̀ gbọ́rọ̀.
Ìlànà ẹ̀kọ́ nípa béèyàn ṣe lè kọ́ àwọn adití lẹ́kọ̀ọ́ làwọn olùkọ́ ilé ẹ̀kọ́ náà tẹ̀ lé. A ti tẹ àwọn ìlànà yìí sínú ìwé kan tá a pè ní “Ṣàṣeparí Iṣẹ́ Òjíṣẹ́ Rẹ ní Kíkún.”
A tún ṣe ìwé ilé ẹ̀kọ́ kan lákànṣe fún àwọn akẹ́kọ̀ọ́, èyí táá jẹ́ kí wọ́n lóye ẹ̀kọ́ Bíbélì, kí wọ́n sì lè fi kọ́ni lédè adití.
Bí àpẹẹrẹ, àwòrán la fi gbé àwọn kókó pàtàkì inú ẹ̀kọ́ Bíbélì jáde dípò ọ̀rọ̀, a sì tún fàyè sílẹ̀ fáwọn akẹ́kọ̀ọ́ láti ya àwòrán tiwọn fúnra wọn, èyí táá mú kí wọ́n lè máa rántí ẹ̀kọ́ tí wọ́n kọ́.
Orílẹ̀-èdè Amẹ́ríkà la ti kọ́kọ́ ṣe Ilé Ẹ̀kọ́ Àwọn Aṣáájú-Ọ̀nà ní December 1977, kẹ̀rẹ̀kẹ̀rẹ̀ ó di ohun tá à ń ṣe nígun mẹ́rẹ̀ẹ̀rin ayé.
Lọ́dún iṣẹ́ ìsìn 2018 nìkan, ìyẹn láti September 2017 sí August 2018, ilẹ̀ mẹ́tàlélọ́gọ́rin (83) ọ̀tọ̀ọ̀tọ̀ la ti ṣe ilé ẹ̀kọ́ náà.
Arákùnrin Ricardo Braz, tó jẹ́ ọ̀kan lára àwọn olùkọ́ Ilé Ẹ̀kọ́ Àwọn Aṣáájú-Ọ̀nà ń fọ̀rọ̀ wá akẹ́kọ̀ọ́ kan lẹ́nu wò, ìyẹn Arákùnrin Nyandwi Jean de Dieu.
Ìpẹ̀yàrun tó ṣẹlẹ̀ sáwọn ẹ̀yà Tutsi lórílẹ̀-èdè Rùwáńdà jẹ́ ọ̀kan lára èyí tó tíì yára kánkán tó sì tíì bani lẹ́rù jù lọ nínú ìtàn òde òní.
Àjọ Ìṣọ̀kan Àgbáyé tiẹ̀ fojú bù ú pé láàárín ọgọ́rùn-ún (100) ọjọ́ péré, ó tó ẹgbẹ̀rún lọ́nà ọgọ́rùn-ún mẹ́jọ (800,000) sí mílíọ̀nù kan (1,000,000) èèyàn tí wọ́n pa.
Àwọn ẹ̀yà Tutsi gan-an ni wọ́n dájú sọ, àmọ́ wọ́n tún pa àwọn ẹ̀yà Hutu tí kò bá wọn lọ́wọ́ sí ìpẹ̀yàrun náà.
Ìyẹn túmọ̀ sí pé gbogbo àwọn Ẹlẹ́rìí Jèhófà tí iye wọn jẹ́ ẹgbẹ̀rún méjì àti ẹ̀ẹ́dẹ́gbẹ̀ta (2,500) tó wà ní Rùwáńdà ni ẹ̀mí wọn wà nínú ewu.
Àwọn arákùnrin àtàwọn arábìnrin tó tó nǹkan bí irínwó (400) ní Rùwáńdà ló kú nígbà ìpẹ̀yàrun náà, èyí tó sì pọ̀ jù lọ lára wọn jẹ́ ẹ̀yà Tutsi.
Àmọ́, àwọn Ẹlẹ́rìí míì tó jẹ́ ẹ̀yà Hutu kú torí pé wọ́n kọ̀ láti pa ẹlòmíì lára àti pé wọ́n fẹ́ dá ẹ̀mí arákùnrin tàbí arábìnrin wọn sí.
Arákùnrin Charles Rutaganira tó jẹ́ ara ẹ̀yà Tutsi mórí bọ́ nígbà ìpẹ̀yàrun tó wáyé lọ́dún márùndínlọ́gbọ̀n (25) sẹ́yìn, ó sọ pé òun rántí àárọ̀ ọjọ́ Sunday kan tóun ti gbà pé wọ́n máa pa òun, àmọ́ àwọn arákùnrin rẹ̀ gba ẹ̀mí rẹ̀ là torí pé wọ́n ní ìfẹ́ ìfara-ẹni-rúbọ.
Ẹ̀rù ba arákùnrin Rutaganira gan-an nígbà tí nǹkan bí ọgbọ̀n èèyàn ya bo ilé rẹ̀.
Ó sọ pé: “Aládùúgbò mi ni ọ̀pọ̀ lára wọn. Ojoojúmọ́ la máa ń ríra wa.”
Àmọ́ nígbà táwọn jàǹdùkú yìí wá sílé ẹ̀ láàárọ̀ ọjọ́ yẹn, ó rí i pé wọ́n ò rí bóun ṣe mọ̀ wọ́n tẹ́lẹ̀ mọ́.
Ó sọ pé “Ojú wọn pọ́n, wọ́n sì bẹ̀rẹ̀ sí í wò òun tìkà-tẹ̀gbin.
Wọ́n rí bí àwọn ẹranko tó ń wá ẹran tí wọ́n fẹ́ pa jẹ.”
Àwọn jàǹdùkú náà fi àdá ṣá Arákùnrin Rutaganira, wọ́n fi ọ̀kọ̀ gún un, wọ́n sì fi ọ̀pá tó ní ìṣó lára gbá a, kò sí ìdí méjì ju pé ó jẹ́ ẹ̀yà Tutsi.
Lẹ́yìn náà, wọ́n wọ́ ọ sójú títì, wọ́n sì fi í síbẹ̀ kó lè kú.
Ó ti fẹ́ẹ̀ kú tán níbi tí wọ́n wọ́ ọ sí, ẹ̀jẹ̀ sì ń dà lára ẹ̀ gan-an, kò pẹ́ sákòókò yẹn láwọn òṣìṣẹ́ kan kó ṣọ́bìrì wá síbẹ̀ kí wọ́n lè sin òkú ẹ̀.
Ó jọ pé ọ̀kan lára wọn mọ Arákùnrin Rutaganira sí Kristẹni tó jẹ́ èèyàn àlàáfíà, ó wá béèrè pé “Kí nìdí tí wọ́n fi pa Ẹlẹ́rìí Jèhófà yìí?” Kò sẹ́ni tó dá a lóhùn.
Kò pẹ́ sígbà yẹn ni òjò ńlá kan bẹ̀rẹ̀ sí í rọ̀, bí wọ́n ṣe kúrò níbẹ̀ nìyẹn.
Nígbà tí Arákùnrin Samuel Rwamakuba tó jẹ́ ọ̀kan lára ẹ̀yà Hutu tó ń gbé nítòsí gbọ́ ohun tó ṣẹlẹ̀ sí Arákùnrin Rutaganira, ó ní kọ́mọ òun ọkùnrin lọ gbé arákùnrin náà wá sílé òun nínú òjò tó lágbára yẹn.
Láìka bí ìgboro ṣe léwu lákòókò yẹn sí, àwọn arákùnrin méjì míì tó jẹ́ ẹ̀yà Hutu fìgboyà jáde, wọ́n sì lọ mú oògùn àti aṣọ tí wọ́n fi máa ń di ọgbẹ́ wá.
Àwọn apààyàn yẹn wá bẹ̀rẹ̀ sí í wá Arákùnrin Rutaganira.
Nígbà tí wọ́n rí i nílé ẹnì kan tó jẹ́ ẹ̀yà Hutu, olórí wọn bá halẹ̀ pé: “Gbogbo yín la máa wá pa láàárọ̀ ọ̀la.”
Àwọn Arákùnrin tó jẹ́ ẹ̀yà Hutu yẹn mọ̀ pé wọ́n lè pa àwọn torí ẹ̀yà Tutsi kan tí wọ́n ṣàánú.
Arákùnrin Rutaganira sọ pé: “Tó o bá lọ dá ẹ̀mí ẹni kan tí wọ́n fẹ́ pa sí, ìwọ àtẹni náà ni wọ́n jọ máa pa.”
Torí pé ẹ̀yà Hutu ni Arákùnrin Rwamakuba, ó ṣeé ṣe kó má ṣòro fún un láti sá lọ kó sì gba ibi táwọn ẹ̀ṣọ́ tó dìhámọ́ra ti gbégi dínà tí wọ́n sì ń ṣọ́ ojú ọ̀nà látàárọ̀ ṣúlẹ̀.
Àmọ́ kò fi arákùnrin ẹ̀ tó jẹ́ ẹ̀yà Tutsi tó ti ṣèṣe yìí sílẹ̀, ó sọ fún un pé: “Mi ò ni fi ẹ́ sílẹ̀.
Ibi tó o bá kú sí lèmi náà máa kú sí.”
Láàárọ̀ ọjọ́ kejì, àwọn sójà bẹ̀rẹ̀ sí í bá àwọn apààyàn yẹn jà, bí gbogbo wọn ṣe sá lọ nìyẹn.
Lẹ́yìn tí ọgbẹ́ ara Arákùnrin Rutaganira san, ó pa dà sílé kó lè lọ bá àwọn ará ìjọ rẹ̀ tó ń ṣọ̀fọ̀ àwọn olólùfẹ́ wọn tí wọ́n pa láìnídìí, ọpọ̀ lára wọn ló ní ìdààmú ọkàn àti ìrora tó lágbára torí bí wọ́n ṣe fìyà jẹ wọ́n, tí wọ́n sì fipá bá àwọn míì lò pọ̀.
Arákùnrin Rutaganira sọ pé: “Nǹkan nira gan-an lẹ́yìn oṣù díẹ̀ tí ìpẹ̀yàrun yẹn dáwọ́ dúró.”
Àmọ́ torí pe àwọn arákùnrin tó jẹ́ ẹ̀yà Hutu àti Tutsi nífẹ̀ẹ́ ara wọn, wọ́n sì fòye bára wọn lò, ó jẹ́ kí wọ́n lè ran ara wọn lọ́wọ́ láti borí ìbànújẹ́ tí wọ́n ní.
Ó sọ pé: “Wọ́n ṣiṣẹ́ kára kó má bàa sí àgàbàgebè tàbí èrò ‘ẹ̀yà tèmi lọ̀gá,’ tàbí ìyapa láàárín wọn.”
Ní April 2019, wọ́n ṣe àfihàn kan ní Ojúkò Tó Wà fún Ẹ̀tọ́ Ọmọnìyàn ní ìlú Atlanta lórílẹ̀-èdè Georgia tó níṣe pẹ̀lú ìtàn àwọn arákùnrin àtàwọn arábìnrin tó la ìpẹ̀yàrun tó wáyé lórílẹ̀-èdè Rùwáńdà já àtàwọn tó kú
Bó tilẹ̀ jẹ́ pé ìdààmú ọkàn bá àwọn Ẹlẹ́rìí Jèhófà káàkiri orílẹ̀-èdè Rùwáńdà, wọ́n bẹ̀rẹ̀ sí í lọ sáwọn ìpàdé Kristẹni, wọ́n sì ń wàásù.
Wọ́n rí ọ̀pọ̀ èèyàn tó nílò ìtùnú àti ìrètí lójú méjèèjì.
Ọ̀pọ̀ èèyàn ni wọ́n fìyà jẹ gan an torí bí wọ́n ṣe pa àwọn èèyàn wọn nípa ìkà.
Ṣe ni ẹ̀rí ọkàn àwọn ẹlòmíì ń dá wọn lẹ́bi torí ohun burúkú tí wọ́n ṣe.
Ó dun ọ̀pọ̀ èèyàn lórílẹ̀-èdè Rùwáńdà gan an torí báwọn aládùúgbò wọn, àwọn olóṣèlú, pàápàá jùlọ báwọn aṣáájú ẹ̀sìn ṣe já wọn kulẹ̀.
(Wo àpótí náà “ Bí Àwọn Oníṣọ́ọ̀ṣì Náà Ṣe Kópa Nínú Ìpẹ̀yàrun Tó Ṣẹlẹ̀ Ní Rùwáńdà.”)
Àmọ́, ọ̀pọ̀ àwọn ará Rùwáńdà kíyè sí i pé àlàáfíà wà láàárín àwọn èèyàn Jèhófà, ohun tó sì mú kí wọ́n ṣàrà ọ̀tọ̀ nìyẹn.
Ìdílé Ẹlẹ́rìí Jèhófà kan fi olùkọ́ ilé ìwé Kátólíìkì kan tó jẹ́ ẹ̀yà Tutsi àtàwọn ọmọ rẹ̀ mẹ́fà pamọ́, bó tiẹ̀ jẹ́ pé olùkọ́ náà ò fi bẹ́ẹ̀ mọ ìdílé náà rí.
Olùkọ́ náà sọ pé: “Mo bọ̀wọ̀ fáwọn Ẹlẹ́rìí Jèhófà gan an. . . .
Ọ̀pọ̀ èèyàn ló mọ̀ pé wọn ò lọ́wọ́ sí ìpẹ̀yàrun náà.”
Lẹ́yìn tí ìpẹ̀yàrun náà parí, ọ̀pọ̀ àwọn ará Rùwáńdà rọ́ wá sínú Gbọ̀ngàn Ìjọba.
Ní ìpíndọ́gba, akéde kọ̀ọ̀kan darí ìkẹ́kọ̀ọ́ Bíbélì mẹ́ta.
Láàárín ọ́dún iṣẹ́ ìsìn 1996, ìdá ọgọ́ta nínú ọgọ́rùn-ún ni àwọn Ẹlẹ́rìí Jèhófà tó wà ní Rùwáńdà fi pọ̀ sí i, ìdí ni pé ìwàásù táwọn èèyàn gbọ́ ń tù wọ́n nínú, wọ́n sì nífẹ̀ẹ́ sí i.
Ọdún yìí ló pé ọdún márùndínlọ́gbọ̀n (25) tí ìpẹ̀yàrun yẹn wáyé, ọpọ̀ èèyàn ló ń ronú jinlẹ̀ nípa ìpẹ̀yàrun tó ṣẹlẹ̀ náà, pàápàá jùlọ àwọn tó là á já.
Ó dá Arákùnrin Rutaganira àtàwọn míì tí ìṣẹ̀lẹ̀ yẹn ṣojú wọn lójú pé ojúlówó ìfẹ́ Kristẹni lágbára ju ìkórìíra tó wà láàárín àwọn ẹ̀yà lọ.
Arákùnrin Rutaganira sọ pé, “Jésù Kristi kọ́ àwọn ọmọ ẹ̀yìn rẹ̀ olóòótọ́ pé kí wọ́n nífẹ̀ẹ́ ọmọnìkejì wọn ju ara wọn lọ.
Ìdí tí mo fi wà láàyè lónìí ni pé irú ìfẹ́ yìí wà láàárín àwọn èèyàn Jèhófà lóòótọ́.”​—Jòhánù 15:13.
Ìwé Christianity and Genocide in Rwanda sọ pé, ìdá àádọ́sàn-án nínú ọgọ́rùn-ún èèyàn tó ń gbé ní Rùwáńdà ló ń lọ sí Ṣọ́ọ̀ṣì, ìyẹn túmọ̀ sí pé ó fẹ́rẹ̀ẹ́ jẹ́ gbogbo èèyàn ló sọ pé Kristẹni làwọn ní Rùwáńdà.
Òǹṣèwé kan tórúkọ rẹ̀ ń jẹ́ Timothy Longman sọ pé, nígbà ìpẹ̀yàrun yẹn, ọ̀pọ̀ àwọn ará ṣọ́ọ̀ṣì, títí kan àwọn aṣáájú ṣọ́ọ̀ṣì tó jẹ́ ẹ̀yà Hutu ló pa àwọn ọmọ ìjọ wọn tó jẹ́ ẹ̀yà Tutsi.
Ó béèrè pé: “Tí wọ́n bá jẹ́ olóòótọ́ sí ṣọ́ọ̀ṣì wọn àtàwọn onígbàgbọ́ bíi tiwọn, kí . . . nìdí táwọn Kátólíìkì fi ń pa Kátólíìkì, táwọn Pùròtẹ́sítáǹtì sì fí ń pa Pùròtẹ́sítáǹtì?”
Ọjọ́ ti pẹ́ táwọn oníṣọ́ọ̀ṣì ti ń kópa nínú ìjà kẹ́lẹ́yàmẹ̀yà.
Ní ọ̀pọ̀ ọdún ṣáájú ìpẹ̀yàrun yẹn, àwọn aṣáájú ṣọ́ọ̀ṣì àtàwọn olóṣèlú ní Rùwáńdà gbìmọ̀ pọ̀ kí wọ́n má bà a kúrò nípò àṣẹ.
Ọ̀kan lára ọ̀nà tí wọ́n lò ni pé, wọ́n gbin ẹ̀mí ẹ̀tanú àti kẹ́lẹ́yàmẹ̀yà sọ́kàn àwọn èèyàn. Síbẹ̀, Ọ̀jọ̀gbọ́n Longman kọ̀wé pé: “Lórílẹ̀-èdè Rùwáńdà, àwọn aṣáájú ṣọ́ọ̀ṣì ò kọ́ àwọn èèyàn lẹ́kọ̀ọ́ nípa ‘ìfẹ́ àti bí wọ́n ṣe lè fara rora pẹ̀lú àwọn ẹlòmíì.’”
Nígbà táwọn tó gbin ẹ̀mí ìkórìíra sọ́kàn àwọn ẹ̀yà Hutu lòdì sí ẹ̀yà Tutsi dórí àlééfà, ńṣe làwọn aṣáájú ṣọ́ọ̀ṣì ń tì wọ́n lẹ́yìn.
Nígbà tí ìpẹ̀yàrun náà bẹ̀rẹ̀, dípò káwọn aṣáájú ẹ̀sìn yìí dẹ́bi fún ìwà ipá àti ẹ̀tanú tó gbilẹ̀, ṣe ni wọ́n sọ fáwọn ọmọ ìjọ wọn pé kí wọ́n ṣe ohunkóhun táwọn olóṣèlú bá ní kí wọ́n ṣe.
Ọ̀jọ̀gbọ́n Longman sọ pé “Èrò ọ̀pọ̀ àwọn tó ń lọ sí ṣọ́ọ̀ṣì ni pé àwọn aṣáájú ṣọ́ọ̀ṣì ló fọwọ́ sí ìpẹ̀yàrun náà.
Ó tiẹ̀ sọ àpẹẹrẹ àwọn apààyàn kan tí wọ́n máa ń kọ́kọ́ gbàdúrà lórí pẹpẹ ṣọ́ọ̀ṣì kí wọ́n tó jáde lọ pààyàn.
Ìtẹ̀jáde tó ń jẹ́ Rwanda: Death, Despair, and Defiance sọ nínú ìròyìn tí wọ́n gbé jáde pé “Ìpẹ̀yàrun tó wáyé ní Rùwáńdà fi hàn lọ́nà tó ṣe kedere pé àwọn aṣáájú ìsìn tó wà ní ọ̀pọ̀ ṣọ́ọ̀ṣì kò níwà rere, wọn ò sì mọ Ọlọ́run.”
Nígbà tí wọ́n gbé àwọn aṣáájú ṣọ́ọ̀ṣì ní Rùwáńdà lọ sílé ẹjọ́ torí pé wọ́n lọ́wọ́ sí ìpẹ̀yàrun, àwọn oníròyìn kan kíyè sí i pé: “Àwọn Ẹlẹ́rìí Jèhófà nìkan ni wọn ò fi ẹ̀sùn èyíkéyìí kan.”
Nígbà tí J. J. Carney tó jẹ́ ọ̀jọ̀gbọ́n nínú ẹ̀kọ́ ìsìn ń ṣàlàyé nípa ìwà àwọn Ẹlẹ́rìí Jèhófà, ó sọ pé “ọ̀kan pàtàkì lára ohun táwọn Ẹlẹ́rìí Jèhófà gbà gbọ́ ni pé ìwà ipá kò dára.”
John Roth tó jẹ́ ọ̀mọ̀wé nípa ìpẹ̀yàrun sọ pé, àwọn Ẹlẹ́rìí Jèhófà gbà pé ó ṣe pàtàkì kéèyàn ṣègbọràn sí Ọlọ́run ju kéèyàn ṣègbọràn sáwọn olóṣèlú.”
Arákùnrin Tharcisse Seminega, táwọn ará tó jẹ́ ẹ̀yà Hutu dáàbò bo ìdílé rẹ̀ sọ ohun míì tó mú káwọn onígbàgbọ́ bíi tiẹ̀ jẹ́ èèyàn àlàáfíà tó sì mú kí wọ́n máa ṣiṣẹ́ ìgbẹ̀mílà: Ojúlówó ìfẹ́ Kristẹni ni.
Ó sọ pé “Irú ìfẹ́ yìí nìkan ló lágbára láti dáàbò bo ọkàn àti ìrònú èèyàn lọ́wọ́ oró ẹ̀tanú.”
Ní October 26 àti 29, 2019, òjò oníjì líle ṣọṣẹ́ ní ibi tó pọ̀ ní apá àríwá orílẹ̀-èdè Rùwáńdà, ó sì kan ọ̀pọ̀ àwọn Ẹlẹ́rìí Jèhófà.
Ó dùn wá pé omi gbé ọmọbìnrin kan tó jẹ́ ọmọ ọdún mẹ́tàlá (13) lọ. Ẹlẹ́rìí Jèhófà làwọn òbí ẹ̀, àdúgbò Musanze ní apá Àríwá ni wọ́n sì ń gbé.
Ní agbègbè Ngororero tó wà ní apá Ìwọ̀ Oòrùn, ilé àwọn Ẹlẹ́rìí kan bà jẹ́, ìdílé mẹ́sàn-án ló sì pàdánù irè oko wọn.
Ẹ̀ka ọ́fíìsì Rwanda ń pèsè ìrànwọ́ fún àwọn tí àjálù bá ní agbègbè yẹn, wọ́n sì ń pèsè ohun tí wọ́n nílò nípa tara àti nípa tẹ̀mí.
Àdúrà wa ni pé kí Jèhófà tu àwọn ará tí ìṣẹ̀lẹ̀ yìí kàn nínú.​—2 Tẹsalóníkà 2:16, 17.
Ní August 16 sí 18, 2019, àwọn arákùnrin wa ṣe àpéjọ agbègbè lédè adití ti Rùwáńdà nílùú Kigali, lórílẹ̀-èdè Rùwáńdà, ìgbà àkọ́kọ́ tírú ẹ̀ máa wáyé rèé.
Ọgọ́rùn-ún mẹ́fà àti ogún (620) èèyàn ló wà sí àpéjọ náà, àwọn adití mẹ́jọ ló sì ṣèrìbọmi.
Àwọn tó wá sí àpéjọ náà ń fi èdè adití kọ orin Ìjọba Ọlọ́run
Àwọn àlejò láti iléeṣẹ́ ìjọba méjì ló wà ní àpéjọ yìí lọ́jọ́ Sunday, àwọn ni: Ọ̀gbẹ́ni Jean Damascène Bizimana tó jẹ́ ọ̀kan lára àwọn olùdarí Ẹgbẹ́ Àwọn Adití Ilẹ̀ Rùwáńdà àti Ọ̀gbẹ́ni Emmanuel Ndayisaba tó jẹ́ akọ̀wé àgbà fún Àjọ Tó Ń Bójú Tó Àwọn Aláàbọ̀ Ara lórílẹ̀-èdè Rwanda.
Yàtọ̀ síyẹn, iléeṣẹ́ ìwé ìròyìn tó ń jẹ́ Ukwezi náà wà níbẹ̀ lọ́jọ́ Sunday, wọ́n sì gbé ìròyìn tó wúni lórí jáde lórí ìkànnì wọn.
Arábìnrin kan ń túmọ̀ ìtòlẹ́sẹẹsẹ àpéjọ náà fún ẹnì kan tó fọ́jú tó sì tún yadi. Ó ń fi ọwọ́ ṣe àmì ohun tí wọ́n sọ sí i lọ́wọ́
Ọ̀gbẹ́ni Bizimana sọ pé: “Àpéjọ yìí ti dáa jù! Ẹ wo bí àwọn adití láti onírúurú agbègbè lórílẹ̀-èdè yìí ṣé jọ wà papọ̀ — Ẹ ṣeun.
A dúpẹ́ gan-an lọ́wọ́ àwọn Ẹlẹ́rìí Jèhófà fún bí wọ́n ṣe ń ti èdè àwọn adití lẹ́yìn.
Ó yẹ káwọn aláṣẹ ìjọba wa wo irú àpéjọ tó ń fi bí àwọn èèyàn ṣe wà níṣọ̀kan báyìí hàn, kí wọn sì ṣe irú rẹ̀.”
Lọ́dún méjì sẹ́yìn, àwọn ohun mánigbàgbé méjì kan tún wáyé láàárín àwọn tó ń sọ èdè adití tí Rùwáńdà.
Ní September 2017, ẹ̀ka ọ́fíìsì Rùwáńdà ṣe ilé-ẹ̀kọ́ àwọn aṣáájú-ọ̀nà lédè adití ti Rùwáńdà fún ìgbà àkọ́kọ́.
Nígbà tó tún di September 2018, ẹ̀ka ọ́fíìsì bẹ̀rẹ̀ sí tú àwọn ìtẹ̀jáde wa sí èdè adití ti Rùwáńdà.
Arákùnrin Jean d’Amour Habiyaremye, tó jẹ́ aṣojú tí ẹ̀ka ọ́fíìsì rán wá sí àpéjọ àwọn adití yìí sọ pé: “A láyọ̀ láti rí ìtẹ̀síwájú tó ń bá iṣẹ́ ìwàásù láàárín àwọn tó ń sọ́ èdè adití ti Rùwáńdà, títí kan àpéjọ agbègbè yìí.
Àkòrí àpéjọ náà ni ‘Ìfẹ́ Kì Í Yẹ̀ Láé!,’ a sì rí i pé lóòótọ́ ni àwa Ẹlẹ́rìí Jèhófà fi ìfẹ́ yìí hàn sí gbogbo èèyàn títí kan àwọn adití.”
Bí iṣẹ́ ìwàásù ṣe ń tẹ̀síwájú láàárín àwọn tó ń sọ èdè adití jẹ́ ẹ̀rí tó ṣe kedere pé Jèhófà ń bù kún wa!​—Sáàmù 67:1.
Láàárọ̀ August 14, 2017, àkúnya omi àti ilẹ̀ yíya ba àwọn ṣọ́ọ̀bù, àwọn ojú ọ̀nà àtàwọn ilé jẹ́ nílùú Freetown, tó jẹ́ olú ìlú Siria Lóònù, jàǹbá yìí kọjá sísọ.
Ó lé ní ọgọ́rùn-ún mẹ́rin [400] èèyàn tí wọ́n ti rí pé ó kú, nǹkan bí ọgọ́rùn-ún mẹ́fà [600] àwọn míì ni wọn ò sí tíì mọ ibi tí wọ́n wà.
Ẹ̀rù ń ba àwọn aláṣẹ pé àwọn òjò míì tí wọ́n ti gbọ́ pé ó máa rọ̀ tún máa fa àjálù kún èyí tó wà nílẹ̀.
Ẹ̀ka ọ́fíìsì tó wà lórílẹ̀-èdè Siria Lóònù sọ pé kò sí Ẹlẹ́rìí Jèhófà kankan tó kú tàbí tó fara pa nínú àjálù yìí.
Àmọ́, ìdílé méjì ni omi gbalé wọn.
Àwọn alàgbà ìjọ tó wà lágbègbè náà ń fi ọ̀rọ̀ Ọlọ́run gbé àwọn Ẹlẹ́rìí Jèhófà bíi tiwọn ró.
Yàtọ̀ síyẹn, àwọn alàgbà náà ń sọ ohun táwọn èèyàn lè ṣe láti dáàbò bo ara wọn tí àkúnya omi bá tún ṣẹlẹ̀.
Agbẹnusọ fún Àwa Ẹlẹ́rìí Jèhófà:
Kárí Ayé: David A. Semonian, Office of Public Information.
Déètì: September 6 sí 8, 2019
Ibi Tí A Ti Ṣe É: Gbọ̀ngàn Ìwòran FNB ní ìlú Johannesburg, South Africa
Èdè: Gẹ̀ẹ́sì, Sesotho, Zulu
Àwọn Tó Wá: 58, 149
Àwọn Tó Ṣèrìbọmi: 476
Àwọn Tó Wá Láti Ilẹ̀ Òkèèrè: 6,000
Àwọn Ẹ̀ka Ọ́fíìsì Tá A Pè: Bòlífíà, ilẹ̀ Gẹ̀ẹ́sì, Central Europe, Kóńgò (Kinshasha) Finland, Hong Kong, Hungary, Ísírẹ́lì, Japan, Kẹ́ńyà, Kòríà, Làìbéríà, Madagásíkà, Màláwì, Paraguay, Peru, Uganda, Amẹ́ríkà, Sáńbíà, Sìǹbábúwè.
Ìrírí: Àwọn aláṣẹ ọgbà ẹranko tó ń jẹ́ Lion and Safari Park, tó jẹ́ ọ̀kan lára ibi tí wọ́n ṣètò fún àwọn àlejò láti gbafẹ́ lọ, ṣàlàyé pé àwọn ò tíì rí i rí kí ọ̀pọ̀ èèyàn tí àṣà ìbílẹ̀ àti èdè wọn yàtọ̀ síra bẹ́ẹ̀ máa bọ́ sílẹ̀ látinú ọkọ̀ kan náà tó sì jẹ́ pé wọ́n ò bá ara wọn jiyàn, bẹ́ẹ̀ ni wọ́n ò sì bá ara wọn jà.
Orí àwọn aláṣẹ náà wú gan-an nígbà tí wọ́n rí i bí àwọn àlejò yẹn ṣe tẹ̀ lé ìtọ́ni tí wọ́n sì fọwọ́sowọ́pọ̀ pẹ̀lú àwọn òṣìṣẹ́ wọn, wọ́n sọ pé: “Inú wá dùn pé wọ́n wá.”
Ní August 16, 2019, àwa Ẹlẹ́rìí Jèhófà mú Ìwé Mímọ́ Kristian Lédè Griki ní Ìtumọ̀ Ayé Titun jáde lédè Kwanyama níbi àpéjọ agbègbè tó wáyé ní Ondangwa, lórílẹ̀-èdè Namibia.
Arákùnrin Franco Dagostini, tó jẹ́ ara Ìgbìmọ̀ Ẹ̀ka orílẹ̀-èdè South Africa ló mú Bíbélì yìí jáde lọ́jọ́ àkọ́kọ́ àpéjọ náà ní gbọ̀ngàn tó ń jẹ́ Ondangwa Trade Fair Hall.
Ọ̀kan lára àwọn atúmọ̀ èdè náà sọ pé: “Ìwé Mímọ́ Kristian Lédè Griki ní Ìtumọ̀ Ayé Titun yìí máa rọrùn fáwọn èèyàn láti kà, wọ́n á sì lóye àwọn ọ̀rọ̀ inú ẹ̀ lọ́nà tó ṣe kedere.
Inú àwọn arákùnrin àti arábìnrin wa máa dùn láti rí orúkọ Jèhófà ní gbogbo ibi tó yẹ kó wà.”
Ní ìpínlẹ̀ tí Ẹ̀ka ọ́fíìsì South Africa ń bójú tó, nǹkan bí ọgọ́rùn-ún márùn-ún ó dín mẹ́wàá (490) akéde ló ń sọ èdè Kwanyama.
Wọ́n ń wàásù fún àwọn èèyàn tó fẹ́rẹ̀ẹ́ tó mílíọ̀nù kan àtààbọ̀ tó ń sọ èdè Kwanyama ní orílẹ̀-èdè Àǹgólà àti Nàmíbíà.
A ti mú Bíbélì Ìtumọ̀ Ayé Tuntun jáde lódindi tàbí lápá kan ní èdè mẹ́rìnlélọ́gọ́sàn-án (184), mẹ́ẹ̀ẹ́dọ́gbọ̀n (25) lára rẹ̀ sì jẹ́ odindi Bíbélì tá a tún ṣe látinú ẹ̀dà tó jáde lédè Gẹ̀ẹ́sì lọ́dún 2013.
Inú wa dùn pé àwọn arákùnrin àti arábìnrin wa máa lo Bíbélì yìí láti sọ Ọ̀rọ̀ Ọlọ́run fún ọ̀pọ̀ èèyàn lédè Kwanyama.​—Ìṣe 2:37.
Ní September 6, 2019, a mú Bíbélì Mímọ́ ti Ìtumọ̀ Ayé Tuntun jáde ní èdè Venda, Afrikaans àti Xhosa níbi àpéjọ àgbáyé tá a ṣe nílùú Johannesburg lórílẹ̀-èdè South Africa, ó sì ju mílíọ̀nù mẹ́rìndínlógún (16) èèyàn lọ tó ń sọ àwọn èdè yẹn.
Arákùnrin Anthony Morris, tó jẹ́ ọ̀kan lára Ìgbìmọ̀ Olùdarí ló kéde fáwọn èèyàn tó tó ẹgbẹ̀rún mẹ́rìndínlógójì, ọgọ́rùn-ún mẹ́jọ àti márùndínláàádọ́rin (36,865) tó kóra jọ sí pápá ìṣeré FNB pé a ti mú Bíbélì náà jáde.
Àwọn èèyàn tó tó ẹgbẹ̀rún mọ́kànléláàádọ́ta àti igba ó lé mọ́kàndínlọ́gbọ̀n (51,229) míì wo ìtòlẹ́sẹẹsẹ náà bó ṣe ń lọ lọ́wọ́ ní ibi mẹ́jọ ọ̀tọ̀ọ̀tọ̀ ti wọ́n ta àtagbà ètò náà sí, títí kan orílẹ̀-èdè Lesotho, Namibia àti Saint Helena.
Nígbà tí atúmọ̀ èdè kan ń sọ̀rọ̀ lórí ohun tó ṣàrà ọ̀tọ̀ nínú Bíbélì náà, ó sọ pé: “Inú wa dùn gan-an pé a lè ka Bíbélì látòkèdélẹ̀ ní èdè tó wọni lọ́kàn!” Atúmọ̀ èdè míì sọ pé: “Ní pàtàkì jùlọ, [Bíbélì tá a ṣẹ̀ṣẹ̀ mú jáde yìí] máa jẹ́ ká lè sún mọ́ Jèhófà torí pé léraléra ló lo orúkọ Ọlọ́run.”
Bíbélì yìí tún máa ran àwọn ará wa lọ́wọ́ nígbà tí wọ́n bá ń wàásù. Ọ̀kan lára àwọn tó túmọ̀ èdè Xhosa sọ pé: “Bíbélì Ìtúmọ̀ Ayé Tuntun tá a tún ṣe yìí máa ràn wá lọ́wọ́ nínú iṣẹ́ ìwàásù.
Àwọn èèyàn máa gbọ́ ohun tí Bíbélì fi kọ́ni lọ́nà tó ṣe kedere láìsì pé à ṣẹ̀ṣẹ̀ ń ṣàlàyé ìtumọ̀ ọ̀rọ̀ kọ̀ọ̀kan.”
Ọ̀kan lára àwọn atúmọ̀ èdè Afrikaans fi kún un pé: “Ní báyìí, ó ti ṣeé ṣe láti ka Bíbélì kó sì yé ẹ yékéyéké.”
Inú wa dùn pé àwọn ara wa ní Bíbélì tó rọrùn-ún ka, táá sì jẹ́ kí wọ́n sún mọ́ Ọlọ́run wa.​—Jémíìsì 4:8.
Òjò tó rinlẹ̀ gan-an rọ̀ lọ́wọ́ ìparí oṣù April 2019 láwọn ibi tó kángun sí ìlà oòrùn orílẹ̀-èdè South Africa.
Òjò àrọ̀ọ̀rọ̀dá náà fa omíyalé àti àbàtà láwọn ibì kan ní ìlú Durban àti ní agbègbè KwaZulu-Natal.
Ìròyìn fi hàn pé ó kéré tán, àádọ́rin (70) èèyàn ló kú.
Ẹ̀ka ọ́fíìsì wa ní South Africa sọ pé kò sí ìkankan lára àwọn ará wa tó kú tàbí tó fara pa nínú ìṣẹ̀lẹ̀ náà.
Àmọ́, ó kéré tán, ilé àwọn ìdílé mọ́kàndínlógún (19) ni omíyalé àti àbàtà náà bà jẹ́.
Omíyalé náà tún ba Gbọ̀ngàn Ìjọba mẹ́ta jẹ́ ó kéré tán.
Ìgbìmọ̀ Tó Ń Ṣètò Ìrànwọ́ Nígbà Àjálù ti ṣètò àwọn ará tó yọ̀ǹda ara wọn láti ṣiṣẹ́ pẹ̀lú Ẹ̀ka Tó Ń Yàwòrán Ilé Tó sì Ń Kọ́ Ọ kí wọ́n lè ṣèwádìí bí ilé kọ̀ọ̀kan ṣe bà jẹ́ tó.
Láwọn ibi tí ẹ̀mí àwọn ará ti wà nínú ewu, wọ́n ṣètò láti kó wọn lọ síbòmíì.
Ó dá wa lójú pé Jèhófà ò ní yéé ran àwọn ará wa ní South Africa lọ́wọ́ bí wọ́n ṣe ń kojú ìṣòro tó le gan-an yìí.—Sáàmù 34:19.
Òjò àrọ̀ọ̀rọ̀dá tó wáyé lórílẹ̀-èdè Tógò ní àsìkò òjò ọdún 2019 fa àkúnya omi ní ibi púpọ̀ láwọn ìgbèríko ìlú Lome, lórílẹ̀-èdè Tógò.
Àwọn akéde ọgọ́rùn-ún méjì ó lé mẹ́tàdínlọ́gọ́ta (257) tó wà ní ìjọ méje ọ̀tọ̀ọ̀tọ̀ ló fara gbá nínú ìṣẹ̀lẹ̀ náà.
Ẹ̀ka ọ́fíìsì tó ń bójú tó orílẹ̀-èdè náà ti ń pèsè ìrànwọ́ fún àwọn akéde yìí.
Láwọn ibì kan tí àkúnya omi náà ti ṣẹlẹ̀, omi náà fẹ́ẹ̀ mu èèyàn dé ìbàdí, èyí mú kó pọndandan kí àwọn ará tó jẹ́ mọ́kànléláàádọ́ta (51) sá kúrò nílé.
Àwọn akéde tó wà nítòsí ti gba àwọn ará yìí sílé, wọ́n sì ń bójú tó wọn.
Àgbàrá òjò ti ba díẹ̀ lára àwọn omi tó ṣeé lò ní agbègbè yẹn jẹ́.
Ìgbìmọ̀ Ẹ̀ka Benin tó ń bójú tó iṣẹ́ wa ní Tógò ti ṣètò pé kí alábòójútó àyíká àtàwọn alàgbà pín àwọn nǹkan táwọn ará wa lè lò fún wọn.
Lára ẹ̀ ni oògùn tó ń pa kòkòrò inú omi, kẹ́míkà apakòkòrò àti kẹ́míkà tí wọ́n fi ń sọ aṣọ di funfun tí wọ́n ń pè ní bleach.
A gbàdúrà pé kí Jèhófà bù kún àwọn ará wa ní Tógò bí wọ́n ṣe ń fi ìfẹ́ ìfara-ẹni-rúbọ hàn síra wọn.—Jòhánù 13:34, 35.
Ní March 17, 2019, Arákùnrin Kenneth Cook tó jẹ́ ara Ìgbìmọ̀ Olùdarí mú Bíbélì Ìtumọ̀ Ayé Tuntun tá a tún ṣe jáde lédè Shona níbi àkànṣe ìpàdé kan tí wọ́n ṣe ní Gbọ̀ngàn Àpéjọ Harare lórílẹ̀-èdè Sìǹbábúwè.
Ọdún mẹ́ta sẹ́yìn ni iṣẹ́ ìtúmọ̀ Bíbélì tá a mú jáde yìí bẹ̀rẹ̀.
Nǹkan bí ẹgbẹ̀rún méjì ààbọ̀ (2,500) àwọn ará ló wá sí Gbọ̀ngàn Àpéjọ náà fún àkànṣe ìpàdé yìí.
A ta àtagbà rẹ̀ sí ọgọ́rùn mẹ́ta ó dín márùn-ún (295) Gbọ̀ngàn Ìjọba àti Gbọ̀ngàn Àpéjọ mẹ́rin, iye àwọn tó sì wá síbẹ̀ tó ẹgbẹ̀rún mẹ́tàlélógójì (43,000).
Arákùnrin kan sọ pé: “Ó wù mí kí n ti máa lo Bíbélì tá a tún ṣe náà lóde ẹ̀rí.
Ọ̀rọ̀ rẹ̀ rọrùn, ó sì dùn mọ́ni, èyí kìí jẹ́ kéèyàn fẹ́ gbé e sílẹ̀ tó bá ń kà á.
Ọpẹ́ ni fún Jèhófà torí ẹ̀bùn yìí.”
Bíbélì tá a tún ṣe yìí máa wúlò gan-an fún ẹgbẹ̀rún méjìdínlógójì (38,000) àwọn ará tó ń sọ èdè Shona.
Tá a bá pín mílíọ̀nù mẹ́sàn-án (9,000,000) èèyàn tó ń gbé ní Sìǹbábúwè sọ́nà mẹ́wàá, àwọn tó ń sọ èdè Shona tó nǹkan bí ìdá mẹ́jọ, torí náà Bíbélì yìí máa mú kó rọrùn fáwọn ará láti wàásù.
Bíbélì kọ̀ọ̀kan tá à ń mú jáde ń fi ẹ̀rí hàn pé Jèhófà ń bù kún iṣẹ́ ìtumọ̀ tá à ń ṣe kárí ayé.
Inú wa dùn pé Ọ̀rọ̀ Ọlọ́run ti ń wà lóríṣiríṣi èdè àbínibí kí àwọn púpọ̀ sí i lè rí i kà.—Ìṣe 2:8.
Lóṣù August 2018, iṣẹ́ ìkọ́lẹ́ bẹ̀rẹ̀ lórí ẹ̀ka ọ́fíìsì wa tuntun tó wà ní ìlú Buenos Aires, lórílẹ̀-èdè Ajẹntínà.
Ilé tuntun yìí máa ní àyè ibi iṣẹ́ mẹ́rìndínlógóje (136) àti ilé gbígbé méjì tó ní yàrá méjìndínlọ́gọ́rùn-ún (98).
Ilé yìì yàtò sáwọn ilé tó wà káàkiri tí à ń lò fún ẹ̀ka ọ́fíìsì lọ́wọ́lọ́wọ́ báyìí torí pé ibì kan náà ni ilé tuntun yìí wà, èyí máa mú kí iṣẹ́ yá, kó sì túbọ̀ rọrùn.
Nínú àwọn fọ́tò tó wà nísàlẹ̀ yìí, ẹ máa rí bí iṣẹ́ náà ṣe lọ sí nígbà tí wọ́n bẹ̀rẹ̀ rẹ̀.
Ilẹ̀ náà fẹ̀ tó 91,758 ẹsẹ̀ bàtà, ẹ̀yìn òde ìlú Buenos Aires, tó jẹ́ olú ìlú Ajẹntínà ló sì wà.
Ní October 6 sí 18, 2018, àwọn ará wa wàásù lákànṣe láwọn ibi térò pọ̀ sí nígbà Eré Ìdárayá Òlíńpíìkì Ọdún 2018 tó wáyé ní ìlú Buenos Aires, lórílẹ̀-èdè Ajẹntínà.
Àwọn eléré ìdárayá láti erékùṣù Saint Kitts àti Nevis wá síbi àtẹ náà.
Ọgọ́rọ̀ọ̀rún ìtẹ̀jáde làwọn èèyàn ń gbà lójoojúmọ́ lásìkò ìwàásù àkànṣe náà.
Àwọn tó kópa nínú eré ìdárayá tó wà fáwọn ọ̀dọ́ náà lé ní ẹgbẹ̀rún mẹ́rin (4,000), wọ́n wá láti igba ó lé mẹ́fà (206) orílẹ̀-èdè, àwọn èèyàn gbà pé eré ìdárayá yìí ló tóbi jù lọ láyé, torí oríṣiríṣi eré ìdárayá tó wà fáwọn ọ̀dọ́ tí ọjọ́ orí wọn wà láàárín ọdún mẹ́ẹ̀ẹ́dógún (15) sí méjìdínlógún (18) ni wọ́n ṣe níbẹ̀.
Kí ọ̀pọ̀ àwọn eléré ìdárayá àtàwọn àlejò tó wá láti oríṣiríṣi ilẹ̀ yìí lè gbọ́ nípa ẹ̀kọ́ Bíbélì, ó ju ẹgbẹ̀rún mẹ́fà ó lé ọgọ́rùn-ún mẹ́rin (6,400) Ẹlẹ́rìí Jèhófà tó kópa nínú ìwàásù náà.
Àwọn ará wa lo ọgọ́rùn-ún mẹ́ta ó lé àádọ́rùn-ún (390) àtẹ ìwé ní nǹkan bí ibi ọgọ́rùn-ún (100) ọ̀tọ̀ọ̀tọ̀.
Torí pé àwọn ọ̀dọ́ ni eré ìdárayá náà wà fún, àwọn ará lo ìwé Awọn Ìbéèrè Tí Awọn Ọ̀dọ́ Ń Béèrè​—Awọn Ìdáhùn Tí Ó Gbéṣẹ́ apá méjèèjì àti ìwé pẹlẹbẹ Ìdáhùn Àwọn Ìbéèrè 10 Táwọn Ọ̀dọ́ Ń Béèrè.
Àwọn ìwé náà wà níbẹ̀ lóríṣiríṣi èdè, irú bíi Lárúbáwá, Chinese, Gẹ̀ẹ́sì, Faransé, German, Korean, Potogí, Russian, Sípáníìṣì àti Èdè Àwọn Adití Lọ́nà ti Ajẹntínà. Nǹkan bí ọgọ́rùn-ún méje ó lé àádọ́rùn-ún (790) ìtẹ̀jáde làwọn èèyàn ń gbà lójoojúmọ́ lásìkò eré ìdárayá náà.
Inú àwọn ará tó kópa nínú iṣẹ́ ìwàásù náà dùn gan-an láti sọ ìrètí tó wà nínú Bíbélì fún tọmọdé tàgbà.—Sáàmù 110:3.
Orílẹ̀-èdè Argentina ni wọ́n bí Arábìnrin Cecilia Alvarez sí.
Ó sì ti kojú ọ̀pọ̀ ìṣòro àìlera tó le gan-an.
Kò ju ọmọ ọjọ́ mẹ́rìndínlógún (16) lọ nígbà tó ṣe iṣẹ́ abẹ àkọ́kọ́. Ní May 18, 1994, àwọn dókítà ní orílẹ̀-èdè Argentina ṣiṣẹ́ abẹ láti ṣàtúnṣe sí àléébù kan tó wà lórí ọ̀pá ẹ̀yìn àti awọ fẹ́lẹ́ tó bo egungun ẹ̀yìn rẹ̀.
Ní báyìí, Cecilia ti pé ẹni ọdún mẹ́ẹ̀ẹ́dọ́gbọ̀n (25), ó ti ṣe iṣẹ́ abẹ mẹ́tàlélógójì (43), ọ̀pọ̀ nínú rẹ̀ ló sì jẹ́ nígbà tó wà lọ́mọdé.
Ó tiẹ̀ ṣe iṣẹ́ abẹ kan láìpẹ́ yìí níbi tí wọ́n ti ṣàtúnṣe egungun ìbàdí apá òsì rẹ̀.
Bíi tàwọn iṣẹ́ abẹ míì tó ti ṣe tẹ́lẹ̀, wọ́n ṣe èyí náà láṣeyọrí láì fa ẹ̀jẹ̀ sí i lára.
1999: Cecilia nígbà tó wà lọ́mọ ọdún márùn-ún ní ilé ìwòsàn àwọn ọmọdé, ìyẹn Juan P. Garrahan Children’s Hospital
Cecilia sọ pé: “Ọ̀pọ̀ iṣẹ́ abẹ tí mo ti ṣe sẹ́yìn àtàwọn ìtọ́jú tí mo ti gbà tán mi lókun gan-an.”
Àmọ́, ọkàn ẹ̀ balẹ̀, ó sì gbára lé Jèhófà.
Pẹ̀lú ìrànlọ́wọ́ àwọn òbí rẹ̀, ó ń sapá láti ṣe àwọn ohun tí àwọn dókítà bá sọ pé kó ṣe.
Cecilia sọ pé: “Ohun kan tí mo máa ń fọwọ́ pàtàkì mú ni pé, mó máa ń múra sílẹ̀ fún iṣẹ́ abẹ.
Ìyẹn gba pé kí n lo àwọn oògùn ẹ̀jẹ̀, kí n sì jẹ àwọn oúnjẹ tí á mú kí sẹ́ẹ̀lì pupa inú ẹ̀jẹ̀ pọ̀ sí i.”
Nígbà tí Cecilia ń sọ̀rọ̀ nípa bí àwọn onímọ̀ ìṣègùn ṣe ràn án lọ́wọ́ láti ọdún yìí wá, ó sọ pé: “Mo mọyì iṣẹ́ wọn gan-an, kì í ṣe torí pé wọn gba ẹ̀mí mi là nìkan, ṣùgbọ́n torí pé wọn tún fi ọ̀wọ̀ hàn fún ìpinnu mi láti má ṣe gba ẹ̀jẹ̀.”
Dókítà Ernesto Bersusky, ẹni tó ti fẹ̀yìn tì lẹ́nu iṣẹ́ ìṣègùn egungun ẹ̀yìn tó lábùkù
Àwọn onímọ̀ ìṣègùn tó tọ́jú Cecilia bọ̀wọ̀ fún òun àtàwọn ará tó ràn án lọ́wọ́.
Dókítà Ernesto Bersusky, tó ti fìgbà kan rí jẹ́ olórí àwọn tó ń tọ́jú egungun ẹ̀yìn ní ilé ìwòsàn àwọn ọmọdé tó ń jẹ́ Juan P. Garrahan Children’s Hospital nílùú Buenos Aires, tó ti ṣiṣẹ́ abẹ egungun ẹ̀yìn fún Cecilia lọ́pọ̀ ìgbà sọ pé: “Kò sígbà tí mo fẹ́ ṣiṣẹ́ abẹ fún Cecilia, tí kì í wú mi lórí láti rí bó ṣe fọwọ́ pàtàkì mú ìpinnu rẹ̀ àti bó ṣe máa ń ṣàlàyé ìgbàgbọ́ rẹ̀ láì fìkan pe méjì.
Mo ti bá a sọ̀rọ̀ láìmọye ìgbà, tí màá sì ṣàlàyé àwọn ohun tí mo fẹ́ ṣe, ìyẹn nìkan kọ́, máà tún fi í lọ́kàn balẹ̀ pé a ò ní fàjẹ̀ sí i lára.”
Dókítà Susana Ciruzzi, agbẹjọ́rò àti onímọ̀ nípa ìlànà ìwà híhù nílé ìwòsàn
Dókítà Susana Ciruzzi, tó jẹ́ agbẹjọ́rò àti ọkàn lára ìgbìmọ̀ tó ń rí sí ìwà tó yẹ káwọn oníṣègùn máà hù ní ilé ìwòsàn ọmọdé tó ń jẹ́ Juan P. Garrahan Children’s Hospital sọ pé: “Ìfọwọ́sowọ́pọ̀ tó wà láàárín àwọn Ẹlẹ́rìí Jèhófà àtàwọn onímọ̀ ìṣègùn kì í ṣe kékeré.
A ti ṣiṣẹ́ pọ̀ pẹ̀lú àwọn Ẹlẹ́rìí Jèhófà, a sì ti fi ara wa jìn láti yí èrò, ọgbọ́n àti ìmọ̀ ìjìnlẹ̀ pa dà, nípa bẹ́ẹ̀, èyí ti jẹ́ ká ṣàwárí àwọn ìtọ́jú míì téèyàn lè yàn dípò fífa ẹ̀jẹ̀ síni lára.”
Gẹ́gẹ́ bí Cecilia ṣe sọ, láfikún sí báwọn akọ́ṣẹ́mọṣẹ́ onímọ̀ ìṣègùn ṣe sapá ribiribi, ó tún gbóríyìn fún bí àwọn onígbàgbọ́ ẹlẹgbẹ́ rẹ̀ ṣe dúró tì í gbá-gbá-gbá, ó sọ pé: “Mi ò mọ bí mi ò bá ṣe dúpẹ́ fún iṣẹ́ takuntakun tí Ìgbìmọ̀ Alárinà Ilé Ìwòsàn (HLC) àti Ẹgbẹ́ Tó Ń Bẹ Àwọn Aláìsàn Wò ṣe.
Láìka pé àwọn arákùnrin yìí ní ìdílé tiwọn àtàwọn nǹkan míì tí wọ́n ń bójú tó sí, síbẹ̀ wọ́n ló okun àti àkókò wọn, torí kò sígbà tá a nílò wọn tí wọ́n sọ pé ó sú àwọn rí, mo mọyì wọn gan-an.”
Bó tiẹ̀ jẹ́ pé, gbogbo ìgbà ni ara máa ń ro Cecilia tó sì jẹ́ pé orí kẹ̀kẹ́ arọ ló máa ń wà nígbà gbogbo, ó ti pé ẹni ọdún mẹ́ẹ̀ẹ́dọ́gbọ̀n (25) báyìí síbẹ̀ ó gbà pé ọ̀la ń bọ̀ wá dáa, kò sì ro ara rẹ̀ pin. Kódà, ó tiẹ̀ sọ pé: “Mo mọ̀ pé àwọn ohun tó ṣẹlẹ̀ sí mi yìí ti túbọ̀ sọ mí di ẹni ọ̀tún, ó sì ti jẹ́ kí n lè máa gbé àwọn ànímọ́ Kristẹni yọ.”
July 2019: Cecilia wà lóde ẹ̀rí pẹ̀lú aṣáájú ọ̀nà ẹlẹgbẹ́ rẹ̀
Cecilia tún sọ pé: “Lẹ́yìn ọ̀kan lára àwọn iṣẹ́ abẹ tí mo ṣe, ọkàn lára Ìgbìmọ̀ Alárinà Ilé Ìwòsàn bẹ̀ mí wò, ó sì tọ́ka sí Òwe 10:22 tó sọ pé: ‘Ìbùkún Jèhófà ló ń sọni di ọlọ́rọ̀, kì í sì í fi ìrora [tó máa wà títí láé] kún un.’
Kò sígbà tí mi ò kì í rántí àwọn ọ̀rọ̀ yìí.”
Ní May 1, 2019, Arábìnrin Cecilia rí ìbùkún àrà ọ̀tọ̀ kan gbà nígbà tí ètò Ọlọ́run fọwọ́ sí i pé kó di aṣáájú-ọ̀nà déédéé.
Ó hàn kedere pé, Jèhófà ti tu arábìnrin wa ọ̀wọ́n yìí nínú, ó sì tún fún un lókun.
Nípa bẹ́ẹ̀, òun náà ń fi tayọ̀tayọ̀ sọ̀rọ̀ ìtùnú tó wà nínú Ọ̀rọ̀ Ọlọ́run fún àwọn ẹlòmíì.
A nígbàgbọ́ pé bí Jèhófà ṣe tú Cecilia nínú, bẹ́ẹ̀ náà láá máa tu gbogbo wa nínú láìka onírúurú ìpọ́njú tó lè dé bá wa sí.​—2 Kọ́ríńtì 1:4.
Ilẹ̀ tó ya ní ìlú La Paz lórílẹ̀-èdè Bolivia ba nǹkan jẹ́ gan-an lágbègbè San Jorge Kantutani ní April 30, 2019.
Ọ̀pọ̀lọpọ̀ èèyàn ló ní láti kúrò níbi tí wọ́n ń gbé.
Bó tiẹ̀ jẹ́ pé kò sí ìkankan lára àwọn ará wa tí àjálù yìí pa tàbí tó ṣe léṣe, ẹ̀ka ọ́fíìsì wa ní Bolivia sọ pé ó ba ilé méjì tó jẹ́ tàwọn ará wa jẹ́ pátápátá.
Bákan náà, ìdílé mọ́kànlá (11) àwọn ará wa ló ń gbé lágbègbè tọ́rọ̀ yìí ti ṣẹlẹ̀, àmọ́ kò fi bẹ́ẹ̀ sí nǹkan kan tó ṣe àwọn ilé wọn.
Ẹ̀ka ọ́fíìsì ṣètò Ìgbìmọ̀ Tó Ń Ṣètò Ìrànwọ́ Nígbà Àjálù, ìgbìmọ̀ yìí pẹ̀lú àwọn alábòójútó àyíká àtàwọn alàgbà tó wà lágbègbè náà ń fáwọn ará níṣìírí, wọ́n sì ń pèsè àwọn ohun tí wọ́n nílò.
Àwọn ará tó wà lágbègbè yìí wà lójúfò gan-an, torí ó ṣeé ṣe kí ilẹ̀ tún ya níbẹ̀ tí òjò míì bá rọ̀.
A dúpẹ́ pé àwọn ará wa ò fara pa, wọ́n sì ti ń rí ìrànlọ́wọ́ tí wọ́n nílò.—Gálátíà 6:10.
Déètì: July 12 sí 14, 2019
Ibi Tá A Ti Ṣe É: São Paulo Expo ní São Paulo, Brazil
Èdè: Èdè Adití ti Brazil, Gẹ̀ẹ́sì, Faransé, Italian, Potogí, Sípáníìṣì
Àwọn Tó Wá: 36,624
Àwọn Tó Ṣèrìbọmi: 291
Àwọn Tó Wá Láti Ìlẹ̀ Òkèèrè: 7,000
Áwọn Ẹ̀ka Ọ́fíísì Tó Wá: Àǹgólà, Ajẹntínà, Belgium, Czech-Slovak, Faransé, Ítálì, Mòsáńbíìkì, Pọ́túgà, Scandinavia, Suriname, Trinidad and Tobago, Amẹ́ríkà, Fẹnẹsúélà
Ìrírí: Maria Luiza Gonçalves ló máa ń ṣètò bí wọ́n ṣe ń báwọn tó ń wá sí ọgbà ẹranko tó wà ní São Paulo Zoo sọ̀rọ̀, nígbà tó ń kí àwọn tó wá sí àpéjọ káàbọ̀, ó ní: “Ọ̀pọ̀ àwọn tó ń wá ṣe nǹkan níbí ni mo ti bá pàdé.
Jálẹ̀ ọdún ni wọ́n sì máa ń wá, àmọ́ tiyín yàtọ̀, mi ò tíì ráwọn tó pọ̀, síbẹ̀ tí wọ́n lọ́yàyà, tí wọ́n sì wà létòlétò bíi tiyín rí.
Ẹ mà nífẹ̀ẹ́ ara yín ò! Ó hàn nínú bẹ́ ẹ ṣe ń gbáni mọ́ra, bẹ́ ẹ ṣe ń ṣe síra yín àti nínú àwọn orin yín.”
Láti January 18, 2020 ni àrọ̀ọ̀rọ̀dá òjò ti ń rọ̀ ní ìpínlẹ̀ Espírito Santo àti Minas Gerais lórílẹ̀-èdè Brazil, ìyẹn sì fa àkúnya omi tó lágbára gan-an.
Omi tó ń ya wọnú ìlú ba ọ̀pọ̀ ilé jẹ́, ó gbé ọ̀pọ̀ ọkọ̀ lọ, ó sì hú àwọn igi dà nù.
Àwọn aláṣẹ sọ pé, ẹgbẹẹgbẹ̀rún èèyàn ló ti sá fi ilé wọn sílẹ̀, ó sì ju ọgọ́ta (60) èèyàn tó ti pàdánù ẹ̀mí wọn.
Nílùú Iconha àti Alfredo Chaves, àkúnya omi náà ba ilé àwọn Ẹlẹ́rìí Jèhófà mẹ́sàn-án jẹ́, àwọn arákùnrin àtàwọn arábìnrin mẹ́tàdínlọ́gbọ̀n (27) ló sì ń gbébẹ̀.
Inú wá dùn pé kò sí ará wa kankan tó fara pa tàbí tó kú nínú ìṣẹ̀lẹ̀ náà.
Nǹkan bí ọgọ́rùn-ún (100) èèyàn tí wọ́n jẹ́ Ẹlẹ́rìí láti agbègbè yẹn ló yọ̀ǹda ara wọn kí wọ́n lè ṣèrànwọ́ fáwọn ará tí àkúnya omi náà ba ilé wọn jẹ́.
Àwọn alàgbà bójú tó bí wọ́n ṣe pín oúnjẹ, omi àti aṣọ táwọn ará fi ṣètìlẹ́yìn.
Yàtọ̀ síyẹn, àwọn ará tún ilé àwọn arákùnrin àtàwọn arábìnrin wọn ṣe, títí kan ilé àwọn aládùúgbò tí kì í ṣe Ẹlẹ́rìí Jèhófà.
Kò sí ará wa kankan tó fara pa tàbí tó kú nínú ìṣẹ̀lẹ̀ náà.
Àmọ́, Gbọ̀ngàn Ìjọba márùn-ún ló bà jẹ́, ó sì fẹ́rẹ̀ẹ́ tó àádọ́ta (50) ìdílé Ẹlẹ́rìí Jèhófà tó sá kúrò nílé wọn.
Àkúnya omi náà ká àwọn ará wa kan mọ́ débi pé ọkọ ojú omi ni wọ́n fi gbé wọn láti àjà kejì ilé wọn.
Gbogbo àwọn arákùnrin àtàwọn arábìnrin tí àkúnya omi náà ba ilé wọn jẹ́ ni àwọn Ẹlẹ́rìí Jèhófà míì gbà sílé.
Ẹ̀ka ọ́fíìsì yan Ìgbìmọ̀ Tó Ń Ṣètò Ìrànwọ́ Nígbà Àjálù ní ìpínlẹ̀ Espírito Santo àti Minas Gerais, ìgbìmọ̀ yìí ló ń ṣètò bí wọ́n ṣe máa pèsè ìrànwọ́ fáwọn tí àjálù náà bá.
Ìgbìmọ̀ Tó Ń Ṣètò Ìrànwọ́ Nígbà Àjálù láwọn ìpínlẹ̀ yìí máa ṣiṣẹ́ pẹ̀lú àwọn alábòójútó àyíká àtàwọn alàgbà láti pèsè ohun táwọn ará tí àjálù náà bá nílò nípa tara, kí wọ́n sì fi Bíbélì tù wọ́n nínú.
A ò ní jẹ́ kó sú wa láti máa gbàdúrà fáwọn ará tí àkúnya omi náà fìyà jẹ.
A dúpẹ́ pé Jèhófà ń lo ẹgbẹ́ ará wa láti fún wọn lókun, láti tù wọ́n nínú àti láti máa pèsè àwọn ohun tí wọ́n nílò.​—Sáàmù 28:7.
Ní Friday, January 25, 2019, ibi tó ń gba omi dúró fáwọn tó ń wa kùsà ya lulẹ̀ ní ìlú Brumadinho, ìpínlẹ̀ Minas Gerais, lórílẹ̀-èdè Brazil, ó sì mú kí àbàtà tó pọ̀ gan-an ya wọ̀lú.
Ó kéré tán àádọ́jọ (150) èèyàn ló kú, àwọn méjìlélọ́gọ́sàn-án (182) míì sì wà tí wọ́n ṣì ń wá títí di báyìí.
Ìjọ méjì ló wà ní ìlú Brumadinho, àwọn Ẹlẹ́rìí tó wà níbẹ̀ ń lọ sí bí ọgọ́sàn-án (180), ilé iṣẹ́ tó ń wa kùsà náà sì ni púpọ̀ wọn ti ń ṣiṣẹ́.
Àwọn arákùnrin mẹ́wàá ló ń ṣiṣẹ́ níbi tó ń gba omi dúró náà nígbà tó ya lulẹ̀.
Mẹ́sàn-án lára wọn ò fara pa, àmọ́ ó dùn wá pé a ò tíì rí ẹnì kan tó kù tó jẹ́ alàgbà títí di báyìí.
Yàtọ̀ síyẹn, ìdílé márùn-ún ó kéré tán ló ní láti kúrò ní ilé wọn, kódà ńṣe ni ọ̀kan lára àwọn ilé náà bà jẹ́ pátápátá.
Ọ̀kan lára Ìgbìmọ̀ Ẹ̀ka ní Brazil àtàwọn alábòójútó àyíká tó wà lágbègbè náà lọ wo àwọn tí ọ̀rọ̀ yìí ṣẹlẹ̀ sí, kí wọ́n lè fún wọn níṣìírí nípa tẹ̀mí, kí wọ́n sì pèsè ohun tí wọ́n nílò.
Àdúrà wa ni pé kí Baba wa ọ̀run tu àwọn tí àjálù yìí kan nínú kó sì pèsè ohun tí wọ́n nílò fún wọn.—Róòmù 15:5.
Láàárọ̀ kùtù December 18, iná sọ nínú ìlú Manaus lórílẹ̀-èdè Brazil, ó sì ba ó kéré tán ọgọ́rùn-ún mẹ́fà (600) ilé jẹ́.
Bó tiẹ̀ jẹ́ pé a ò gbọ́ pé iná náà pa ẹnì kankan, àwọn mẹ́rin fara pa, ó sì lé ní ẹgbẹ̀rún méjì (2,000) èèyàn tó ní láti kúrò níbi tí wọ́n ń gbé.
Ìròyìn tá a gbọ́ láti ẹ̀ka ọ́fíìsì wa ní Brazil fi hàn pé kò sí ìkankan lára àwọn ará tí iná náà pa tàbí tó ṣe léṣe.
Àmọ́, ilé mẹ́wàá tó jẹ́ tàwọn ará wa ló bà jẹ́, ìyẹn sì mú kí akéde méjìdínlógún (18) pẹ̀lú àwọn mọ̀lẹ́bí wọn tí kì í ṣe Ẹlẹ́rìí kúrò níbi tí wọ́n ń gbé.
Ẹ̀ka ọ́fíìsì ti dá Ìgbìmọ̀ Tó Ń Ṣètò Ìrànwọ́ Nígbà Àjálù sílẹ̀ kí wọ́n lè pèsè ohun táwọn akéde tí ọ̀rọ̀ náà kàn nílò.
Ó dá wa lójú pé àwọn ará wa tí ìjàǹbá iná yìí kàn ní Brazil kò ní jẹ́ kó sú wọn bí wọ́n ṣe ń gbẹ́kẹ̀ lé Jèhófà tó jẹ́ ‘ibi ààbò wa ní àkókò wàhálà.’—Sáàmù 9:9, 10.
Ní May 31, 2018, Ilé Ẹjọ́ Gíga Jù Lọ ní ilẹ̀ Kánádà sọ ìpinnu tí wọ́n fẹnu kò sí pé wọ́n fàyè gba àwa Ẹlẹ́rìí Jèhófà pé a lè yọ ẹnì kan lẹ́gbẹ́ láìsí pé à ń gbàyè nílé ẹjọ́.
Inú wa dùn gan-an sí bí wọ́n ṣe dá àwọn ìlànà òdodo Jèhófà láre yìí.​—Aísáyà 33:22.
Nínú ẹjọ́ Highwood Congregation of Jehovah’s Witnesses (Judicial Committee) v. Wall, Ilé Ẹjọ́ Gíga Jù Lọ ti Kánádà fohùn ṣọ̀kan ní May 31, 2018 pé “àwọn ẹlẹ́sìn lómìnira láti pinnu ẹni tí wọ́n bá fẹ́ kó wà nínú ẹ̀sìn wọn, wọ́n sì lómìnira láti ṣe òfin tí wọ́n á máa tẹ̀ lé nínú ẹ̀sìn wọn,” èyí sì fi hàn pé wọ́n fọwọ́ sí i pé ilé ẹjọ́ ò gbọ́dọ̀ dá sí ètò táwọn Ẹlẹ́rìí Jèhófà ṣe nípa yíyọ ẹnì kan lẹ́gbẹ́.
Ilé Ẹjọ́ Gíga Jù Lọ ti Kánádà (àwòrán apá òsì) ní Ottawa.
Ibi tí Ilé Ẹjọ́ náà parí èrò sí ni pé ìlànà táwọn Ẹlẹ́rìí Jèhófà máa ń tẹ̀ lé lórí ọ̀rọ̀ ẹni tó dá ẹ̀ṣẹ̀ tó burú jáì “kì í ṣe èyí tó ní ìkórìíra nínú, kàkà bẹ́ẹ̀, ṣe ló máa ń jẹ́ kí wọ́n lè ran ẹni náà lọ́wọ́ kó lè pa dà di ara Ìjọ,” Ilé Ẹjọ́ náà sì dájọ́ pé àwọn ilé ẹjọ́ yòókù ò gbọ́dọ̀ dá sí irú ọ̀rọ̀ bẹ́ẹ̀, torí kì í ṣe nǹkan gbogboogbò, ọ̀rọ̀ ẹ̀sìn ni.
Adájọ́ Malcolm Rowe tó jẹ́ adájọ́ Ilé Ẹjọ́ Gíga Jù Lọ ṣàlàyé ìdí tí ìgbìmọ̀ ẹlẹ́ni mẹ́sàn-án tó gbọ́ ẹjọ́ náà fi ṣèdájọ́ yẹn, ó ní: “Àwọn ìlànà àti òfin tí ẹ̀sìn pàtó kan ń tẹ̀ lé lè wé mọ́ ohun kan tí wọ́n gbà gbọ́, bá a ṣe rí i nínú ẹjọ́ yìí.
Kò sí agbára lọ́wọ́ ilé ẹjọ́, bẹ́ẹ̀ ni wọn ò láṣẹ láti ṣèpinnu lórí irú àwọn ọ̀rọ̀ báyìí tó jẹ mọ́ ọ̀rọ̀ ẹ̀sìn torí wọn ò mọ kúlẹ̀kúlẹ̀ nípa ohun tí wọ́n gbà gbọ́.”
Philip Brumley, tó jẹ́ agbẹjọ́rò àgbà fáwọn Ẹlẹ́rìí Jèhófà sọ pé: “Ìpinnu tí Ilé Ẹjọ́ Gíga Jù Lọ ti Kánádà ṣe yìí mú kí wọ́n fohùn ṣọ̀kan pẹ̀lú àwọn ilé ẹjọ́ gíga ní Ajẹntínà, Brazil, Hungary, Ireland, Ítálì, Peru, Poland àti Amẹ́ríkà, pé àwọn fọwọ́ sí i pé a lẹ́tọ̀ọ́ lábẹ́ òfin láti tẹ̀ lé ìlànà tó wà nínú Ìwé Mímọ́ tó bá dọ̀rọ̀ ká pinnu ẹni tó tóótun láti jẹ́ Ẹlẹ́rìí Jèhófà.”—1 Kọ́ríńtì 5:11; 2 Jòhánù 9-11.
Ìjọ Iqaluit wà ní ọ̀kan lára àwọn erékùṣù tí yìnyín ti máa ń jábọ́ gan-an lápá àríwá orílẹ̀-èdè Kánádà, àwọn akéde mẹ́tàdínlógún (27) ló wà nínú ìjọ yẹn, nínú àwọn ẹni márùndínlọ́gọ́ta (55) tí wọ́n ń kọ́ lẹ́kọ̀ọ́ Bíbélì, méjìlá (12) ló dara pọ̀ mọ́ wọn lórí ẹ̀rọ ayélujára láti gbọ́ àsọyé Ìrántí Ikú Kristi, inú wọn sì dùn gan-an pé àwọn ṣe bẹ́ẹ̀.
Látilẹ̀, kò lè rọrùn rárá fún èyí tó pọ̀ lára àwọn tí wọ́n ń kọ́ lẹ́kọ̀ọ́ Bíbélì láti wá sí Ìrántí Ikú Kristi, ó tiẹ̀ lè má ṣeé ṣe rárá ni.
Ìdí sì ni pé ìpínlẹ̀ ìwàásù ìjọ náà tóbí gan-an, ó bẹ̀rẹ̀ láti ìlú Kimmirut lọ sí ìyànníyàn ìlú Grise Fiord tó jẹ́ apá ibi tó jìnnà jù lọ ní apá àríwá orílẹ̀-èdè Kánádà.
Ọdún yìí ni ìgbà àkọ́kọ́ táwọn tá à ń kọ́ lẹ́kọ̀ọ́ Bíbélì dara pọ̀ mọ́ wa láti ṣe Ìrántí Ikú Kristi.
Ẹnì kan tá à ń kọ́ lẹ́kọ̀ọ́ Bíbélì ní agbègbè Grise Fiord pe àwọn mẹ́rin míì, bó ṣe di pé àwọn márùn-ún ló dara pọ̀ mọ́ wa láti ṣe Ìrántí Ikú Kristi, bó tiẹ̀ jẹ́ pé ọ̀nà wọn jìn gan-an sí wa.”
Bí nǹkan ṣe rí lásìkò tí àrùn COVID-19 gbòde yìí mú kí ọ̀pọ̀ lára àwọn arákùnrin àtàwọn arábìnrin tó wà ní ìjọ Iqaluit rí bó ti ṣe pàtàkì tó pé ká mọ onírúurú ọ̀nà tá tún lè gbà wàásù.
Arábìnrin Kathy Burechailo sọ pé: “À ń pe àwọn èèyàn tó wà láwọn agbègbè oníyìnyìn ní ìlà òòruń orílẹ̀-èdè yìí lórí fóònù, a sì ń báwọn sọ̀rọ̀.
Inú mi dùn gan-an pé mo lè bá àwọn èèyàn tó wà làwọn ọ̀nà jíjìn yẹn sọ̀rọ̀ Jèhófà! Ìdí sì ni pé wọn ò lè jáde nílé, wọ́n nílò ẹni tó máa tù wọ́n nínú.”
Arábìnrin Laura McGregor sọ pé: “Nǹkan ò rọrùn rárá fún wa ní ìlú Iqaluit látìgbà tí oníkálùkù wa ti wà nílé nítorí àrùn tó gbòde yìí.
Kò sówó lọ́wọ́, ẹ̀rù sì tún ń bà ọ̀pọ̀ èèyàn torí pé wọn ò mọ ohun tó lè ṣẹlẹ̀ bọ́jọ́ ṣe ń gorí ọjọ́.
Ìgbà àkọ́kọ́ rèé tá a màá ṣe búrẹ́dì Ìrántí Ikú Kristi ní ìdílé wa.
Àmọ́ a gbádùn bá a ṣe jọ wà pa pọ̀, ó jẹ́ ká túbọ̀ mọyì bí ètò Ìrántí Ikú Kristi ṣe rọrùn tó àti bí kò sì la ariwo lọ, a dúpẹ́ lọ́wọ́ Jèhófà pé ohun tá a nílò wà lárọ̀ọ́wọ́tó, kò sì ṣòro ṣe.”
Arákùnrin Demeester fi kún un pé: “Òótọ́ ni pé àrùn COVID-19 yìí kò jẹ́ ká lè wà pa pọ̀ bá a ṣe máa ń ṣe látẹ̀yìn wá, síbẹ̀ ìyàlẹ́nu ló jẹ́ pé a túbọ̀ sún mọ́ra gan-an lásìkò Ìrántí Ikú Kristi yìí.
Mánigbàgbé ni Ìrántí Ikú Kristi tọdún yìí jẹ́!”
Àwọn ará tó wà ní ìjọ Iqaluit nírètí pé àwọn náà máa ní Gbọ̀ngàn Ìjọba tiwọn láìpẹ́, tí ipò nǹkan bá ti yí pa dà sí rere.
Ní báyìí ná, ó dá wa lójú pé Jèhófà máa bù kún gbogbo ìsapá wọn láti rí i pé ìhìn rere Ìjọba Ọlọ́run dé àwọn ibi tó jìnnà jù lọ lápá àríwá orílẹ̀-èdè Kánádà, tó jẹ́ ọ̀kan lára ibi tó jìnnà jù lọ ní ayé!​—Ìṣe 1:8.
Lórílẹ̀-èdè Kánádà, ẹgbẹẹgbẹ̀rún àwọn tó ń gbé ní agbègbè New Brunswick, Ontario, àti Quebec ni omíyalé ti lé kúrò nílé.
Lágbègbè Quebec nìkan, nǹkan bí ẹgbẹ̀rún mẹ́sàn-án (9,000) èèyàn ló ní láti kó kúrò níbi tí wọ́n ń gbé.
Ẹ̀ka ọ́fíìsì wa ní Kánádà sọ pé ní Quebec, ilé mẹ́rìnlélógójì (44) àwọn ará wa ló bà jẹ́.
Ní New Brunswick àti Ontario, a ò tíì gbọ́ pé ó ba nǹkan kan jẹ́, àmọ́ omíyalé náà kò tíì dáwọ́ dúró.
Àwọn alábòójútó àyíká tó wà láwọn agbègbè tọ́rọ̀ kàn ń ṣiṣẹ́ pẹ̀lú àwọn alàgbà tó wà níbẹ̀ láti tu àwọn ará nínú.
Bákan náà, aṣojú kan láti ẹ̀ka ọ́fíìsì lọ ṣẹ̀bẹ̀wò sáwọn apá ibi tí omíyalé náà ti pọ̀ gan-an kó lè fún wọn níṣìírí nípa tẹ̀mí.
Ní agbègbè Beauce, àwọn ará ti palẹ̀ ìdọ̀tí àti àbàtà mọ́ kúrò nínú ogún (20) ilé tó jẹ́ tàwọn ará wa.
Ìgbìmọ̀ Tó Ń Ṣètò Ìrànwọ́ Nígbà Àjálù ti bẹ̀rẹ̀ iṣẹ́ ní Sainte-Marthe-sur-le-Lac, wọ́n ń ran àwọn tí ilé wọn bà jẹ́ lọ́wọ́.
Àdúrà wa ni pé kí àwọn ará wa tí àjálù yìí kàn má ṣe dẹ́kun láti gbẹ́kẹ̀ lé Jèhófà, ẹni tó jẹ́ ‘okun àti agbára wọn.’—Ẹ́kísódù 15:2.
Arákùnrin Jean-Yves Mudaheranwa àti ìyàwó rẹ̀ tó ń jẹ́ Vasthie wà lára àwọn oníṣègùn tó ń bójú tó àwọn tó ní àrùn Corona nílùú Montreal lórílẹ̀-èdè Kánádà.
Arákùnrin Mudaheranwa jẹ́ dókítà tó ń tọ́jú àwọn tó níṣòro èémí, ọ̀kan lára ilé ìwòsàn tó wà nílùú Montreal ló sì ti ń ṣiṣẹ́, ní ti ìyàwó rẹ̀, nọ́ọ̀sì ni, ọ̀kan lára ibi tí wọ́n ti ń tọ́jú àwọn tó ní àrùn COVID-19 lòun ti ń ṣiṣẹ́ ní tiẹ̀.
Ẹ̀yìn náà mọ bí àrùn yìí ṣe ń mú káwọn èèyàn kọ́kàn sókè, àmọ́ ọ̀kan tọkọtaya yìí balẹ̀ torí pé Jèhófà ń fún wọn lókun, ó sì ń mú kí “ayọ̀ kún inú ọkàn” wọn bó ti ṣèlérí nínú Bíbélì Ọ̀rọ̀ rẹ̀.​—Àìsáyà 65:14.
Arákùnrin Mudaheranwa sọ pé: “Ńṣe lẹ̀rù ń bá àwọn tá a jọ ń ṣiṣẹ́, bóyá ni mo rí kí wọ́n bẹ̀rù bẹ́ẹ̀ rí.”
Arábìnrin Mudaheranwa sọ pé: “Bá a ṣe ń dá kẹ́kọ̀ọ́ wà lára ohun tó mú kí ọkàn wa balẹ̀, aṣàṣàrò lórí àmì tí Bíbélì sọ pé a fi máa mọ̀ pé a ti wà láwọn ọjọ́ ìkẹyìn, a sì rán ara wa létí ìlérí Jèhófà pé òun máa wà pẹ̀lú wa, òun ò sì ní fi wá sílẹ̀.
Àdúrà tún wà lára ohun tó fi wá lọ́kàn balẹ̀.
Kí n tó kúrò nílé lọ síbi iṣẹ́, mo kọ́kọ́ máa ń gbàdúrà, ìyẹn sì máa ń jẹ́ kára tù mí pẹ̀sẹ̀.”
Arákùnrin àti arábìnrin Mudaheranwa dara pọ̀ mọ́ àwọn ará yòókù nípàdé látorí ẹ̀rọ
Arákùnrin Mudaheranwa sọ pé: “Orílẹ̀-èdè Rùwáńdà ni mo ti wá, ojú mi sì rí màbo nígbà ogun kan tí wọ́n ti fẹ́rẹ̀ẹ́ pa odindi ẹ̀yà kan run.
Lórílẹ̀-èdè Kánádà tá a wà yìí, kò sóhun tó jọ bẹ́ẹ̀, téèyàn ò bá sì ṣọ́ra èèyàn lè má rántí pé ọjọ́ ìkẹyìn la wà yìí.
Kí n sòótọ́, kì í ṣe ìgbà gbogbo ni mo máa ń rántí pé ọjọ́ Jèhófà ti sún mọ́lé. Àmọ́, àrùn tó gbòde yìí ti mú kó túbọ̀ dá mi lójú pé ọjọ́ ìkẹyìn la wà yìí.
Yàtọ̀ síyẹn, ó ti mú kí n túbọ̀ mọyì Bíbélì, ó sì ti mú kí n túbọ̀ gbà gbọ́ pé kò sí àsọtẹ́lẹ̀ Bíbélì kan tó máa lọ láìṣẹ.”
Ojú tí Arákùnrin àti Arábìnrin Mudaheranwa fi wo ohun tó ń ṣẹlẹ̀ làwọn èèyàn Jèhófà níbi gbogbo láyé náà fi ń wò ó, ìyẹn sì mú kí ọkàn gbogbo wọn balẹ̀ láìka àrùn COVID-19 tó gbayé kan sí.​—Àìsáyà 48:18.
Déètì: July 19-21, 2019
Ibi Tí A Ti Ṣe É: Exhibition Place, Toronto, Ontario, Canada
Èdè: Gẹ̀ẹ́sì, Potogí, Sípáníìṣì
Àwọn Tó Wá: 46,183
Àwọn Tó Ṣèrìbọmi: 317
Àwọn Tó Wá Láti Ilẹ̀ Òkèèrè: 5,000
Àwọn Ẹ̀ka Ọ́fíísì Tá A Pè: Amẹ́ríkà, Brazil, Britain, Central America, Finland, India, Japan, Korea, Philippines, Ukraine
Ìrírí: Laura Purdy tó jẹ́ ọ̀gá àgbà ní ẹ̀ka tó ń pawó wọlé tó sì ń bójú tó ayẹyẹ ní gbọ̀ngàn tá a lò sọ pé: “Gbogbo ohun tí ìgbìmọ̀ àpéjọ [àwọn Ẹlẹ́rìí Jèhófà] sọ pé àwọn máa ṣe nínú gbọ̀ngàn yìí láti buyì kún un ni wọ́n ṣe pátá.
A ṣe ìwádìí díẹ̀ fúnra wa nípa àwọn Ẹlẹ́rìí Jèhófà, a sì bá àwọn olùdarí àwọn gbọ̀ngàn ayẹyẹ tí wọn ti lò rí fún àpéjọ wọn sọ̀rọ̀. Irú ìrírí kan náà tá a ní pẹ̀lú wọn báyìí làwọn náà ní.”
Ms. Purdy tún sọ pé: “Àpéjọ náà gbádùn mọ́ni ó sì tuni lára.
Tọkàntọkàn ni màá fi gba àwọn míì tó ń bójú tó ibi ayẹyẹ bí irú èyí níyànjú láti gba àwọn Ẹlẹ́rìí Jèhófà tọwọ́tẹsẹ̀ sí ìlú wọn kí wọn lè ṣe àpéjọ wọn níbẹ̀.”
Ìwé ẹ̀rí tí àjọ Paulo Freire Educational Center fi mọyì ẹ̀kọ́ Bíbélì tá à ń ṣe ní ọgbà ẹ̀wọ̀n tó wà ní ìlú Valledupar.
Ó ti lé ní ogun (20) ọdún báyìí táwọn ará wa ti ń kọ́ àwọn ẹlẹ́wọ̀n lẹ́kọ̀ọ́ Bíbélì lọ́fẹ̀ẹ́ ní kòlóńbíà.
Ní November 30, 2018, àjọ Paulo Freire Educational Center fún àwa Ẹlẹ́rìí Jèhófà ní ìwé ẹ̀rí kan láti kan sáárá sí wa torí bá a ṣe ń kọ́ àwọn ẹlẹ́wọ̀n lẹ́kọ̀ọ́ Bíbélì ní ọgbà ẹ̀wọ̀n tó wà ní ìlú Valledupar.
Lọ́wọ́lọ́wọ́ báyìí, àádọ́ta (50) lára àwọn ẹlẹ́wọ̀n tó wà níbẹ̀ ló ń kẹ́kọ̀ọ́ Bíbélì.
Káàkiri orílẹ̀-èdè Kòlóńbíà, ọgbà ẹ̀wọ̀n márùndínláàádọ́rin (65) làwa Ẹlẹ́rìí Jèhófà ti ń kọ́ àwọn èèyàn lẹ́kọ̀ọ́ Bíbélì, iye àwọn tá a sì ń kọ́ lẹ́kọ̀ọ́ jẹ́ ọgọ́rùn-ún méje àti méjìlélọ́gọ́rin (782).
Látọdún 1996, iye àwọn tó ṣèrìbọmi lára wọn ti di ọgọ́ta (60).
Ọgbà ẹ̀wọ̀n ni Néver Antonio Cavadía ti kẹ́kọ̀ọ́ Bíbélì, ó sì ti di alàgbà nínú ìjọ rẹ̀ báyìí.
Òun rèé pẹ̀lú ìyàwó rẹ̀, Lety Cavadía.
Ọgbà ẹ̀wọ̀n ni Néver Antonio Cavadía ti kẹ́kọ̀ọ́ Bíbélì, ó sì ṣèrìbọmi ní 1998.
Nígbà tó yá, wọ́n tú u sílẹ̀ ní ọgbà ẹ̀wọ̀n tó wà ní ìlú Valledupar lọ́dún 2007.
Nígbà tó ń mẹ́nu kan àǹfààní tí ẹ̀kọ́ Bíbélì ṣe fóun, ó ní: “Àwọn ìlànà Bíbélì dáàbò bò mí, ó sì jẹ́ kí n ní ọgbọ́n tó wúlò nígbà tí mo wà lẹ́wọ̀n.
Ó tún mú kí n ṣe àwọn ìyípadà tó lágbára nínú ayé mi, kí n sì nírètí.”
Gbogbo ìsapá wa láti kọ́ àwọn ẹlẹ́wọ̀n lẹ́kọ̀ọ́ kárí ayé bá ìfẹ́ Jèhófà mu pé, “ká gba onírúurú èèyàn là, kí wọ́n sì ní ìmọ̀ tó péye nípa òtítọ́.”—1 Tímótì 2:4.
Ní January 27, 2019, ìjì líle kan jà nílùú Havana tó jẹ́ olú ìlú orílẹ̀-èdè Cuba.
Ìjì náà lágbára gan-an (322 km/h), ó yára débi pé ó lè fa igi tu, kó sì gbé mọ́tò sọ nù kódà, òun ni ìjì tó lágbára jù lọ tó tíì jà nílùú yẹn láti bí ọgọ́rin (80) ọdún sẹ́yìn, àwọn nǹkan tí ìjì náà bà jẹ́ ò lóǹkà, ọ̀pọ̀ ilé ló wó, ó sì fa omíyalé.
Ó kéré tán, èèyàn mẹ́rin ló kú, àwọn ọgọ́rùn-méjì ó dín márùn-ún (195) sì fara pa.
Kò sí arákùnrin tàbí arábìnrin tó kú tàbí tó ṣèṣe nínú ìṣẹ̀lẹ̀ náà.
Síbẹ̀, ilé mẹ́rìndínlọ́gbọ̀n (26) tó jẹ́ tàwọn ará wa ni ìjì náà bà jẹ́, wọ́n sì máa ń lo mẹ́ta lára àwọn ilé náà fún ìpàdé.
Ètò ti bẹ̀rẹ̀ ní pẹrẹu láti ṣàtúnṣe ilé àwọn ará tí ìjì náà bà jẹ́.
Àwọn alábòójútó arìnrìn àjò ti ń pèsè ìrànwọ́ tẹ̀mí fáwọn ará tí àjálù yìí dé bá.
Àdúrà wa ni pé kí Jèhófà tu àwọn ará yìí nínú kó sì fún wọn lókun kí wọ́n lè fara da àdánù ńlá yìí.​—Nọ́ńbà 6:26.
Ní Friday, May 18, 2018, ọkọ̀ òfuurufú kan tí wọ́n ń pè ní Boeing 737 já bọ́ láìpẹ́ sígbà tó gbéra nílùú Havana lórílẹ̀-èdè Cuba.
Nínú gbogbo àwọn mẹ́tàléláàádọ́fà (113) tó wọkọ̀ òfuurufú náà, ẹnì kan péré ló yè é. Ìṣẹ̀lẹ̀ yìí ni jàǹbá ọkọ̀ òfuurufú tó burú jù tó tíì wáyé lórílẹ̀-èdè yìí láti ọ̀pọ̀ ọdún sẹ́yìn.
Ó dùn wá pé ìdílé ẹlẹ́ni mẹ́ta kan tí wọ́n jẹ́ Ẹlẹ́rìí Jèhófà (ìyẹn bàbá, ìyá àti ọmọkùnrin wọn ọlọ́dún méjìlélógún (22)) wà lára àwọn tó bá ìṣẹ̀lẹ̀ náà lọ.
A ti sin òkú wọn ní Saturday, May 26, 2018.
Àwọn alàgbà tó wà nílùú náà ò fi tẹbí-tọ̀rẹ́ àwọn tí àjálù ṣẹlẹ̀ sí sílẹ̀, wọ́n sì ń fi ọ̀rọ̀ Bíbélì tù wọ́n nínú. Bẹ́ẹ̀ náà làwọn aláṣẹ ìlú ń fìfẹ́ ṣèrànwọ́.
Ó dá wa lójú pé Jèhófà ò ní yéé ‘tu gbogbo àwọn tó ń ṣọ̀fọ̀ nínú’ lásìkò tí nǹkan nira yìí.​—Aísáyà 61:1, 2.
Déètì: June 14 sí16, 2019
Ibi Tá A Ti Ṣe É: Pápá ìṣeré Estadio Monumental Banco Pichincha ní ìlú Guayaquil, Ecuador
Èdè: Èdè Adití ti Ecuador, Gẹ̀ẹ́sì, Sípáníìṣì
Àwọn Tó Wá: 53,055
Àwọn Tó Ṣèrìbọmi: 702
Àwọn Tó Wá Láti Ìlẹ̀ Òkèèrè: 5,300
Áwọn Ẹ̀ka Ọ́fíísì Tó Wá: Ajẹntínà, Belgium, Bolivia, Central America, Kòlóńbíà, Cuba, Kazakhstan, Korea, Moldova, Myanmar, Poland, Sípéènì, Amẹ́ríkà
Ìrírí: José Francisco Cevallos, ààrẹ ẹgbẹ́ agbábọ́ọ́lù Barcelona tó ni pápá ìṣeré tá a ti ṣe àpéjọ náà sọ pé: “Ẹ ò fún wa ní wàhálà kankan nígbà tẹ́ ẹ ṣe àpéjọ yín láwọn ọdún tó kọjá, tọdún yìí náà ò sì yàtọ̀.
Èyí fi hàn pé oníwà tútù ni yín àti pé gbogbo àpéjọ yín ló máa ń wà létòlétò.
Kò rọrùn, àmọ́ ẹ máa ń sapá gan-an láti ṣètò kí nǹkan lè lọ bó ṣe yẹ láwọn àpéjọ yín.
Èèyàn dáadáa ni yín​—ẹ gbẹ̀kọ́, ìwà yín dáa, ẹ sì wà létòlétò.
Ìmọ̀ràn wa ni pe káwọn ìlú àtàwọn orílẹ́-èdè míì máa gba àwọn Ẹlẹ́rìí Jèhófà lálejò.”
Ibi gbogbo láyé làwọn ará wa ti ń lo àwọn ọ̀nà míì láti máa wàásù nítorí àrùn COVID-19 tí kò jẹ́ kí wọ́n lè máa wàásù bí wọ́n ti ń ṣe tẹ́lẹ̀.
Àwọn ará wa tó wà ní orílẹ̀-èdè Ecuador ń lo onírúurú ọ̀nà láti wàásù ìhìn rere fún ọ̀pọ̀lọpọ̀ èèyàn.
Àpẹẹrẹ kan ni ti ọ̀dọ́bìnrin ọlọ́dún méje kan tó ń gbé ní ìlú Ambato, pẹ̀lú ìrànlọ́wọ́ màmá rẹ̀, ó kọ àtẹ̀jíṣẹ́, ó sì fi ránṣẹ́ sáwọn tíṣà ilé ìwé rẹ̀.
Lára ohun tó kọ nìyí: “Ẹ káàárọ̀.
Mò fi àtèjíṣẹ́ yìí ránṣẹ́ sí yín láti tù yín nínú nítorí pé àsìkò tá a wà yìí nira gan-an.
Bíbélì fi wá lọ́kàn balẹ̀ nínú ìwé Ìfihàn 21:4 pé ọ̀la máa dáa.
Ìlujá tí mo fi ránṣẹ́ máa gbé yín lọ síbi tẹ́ ẹ ti máa rí àlàyé tó pọ̀ sí i.”
Ọ̀kan lára àwọn tíṣà rẹ̀ dá èsì pa dà, ó ní: “O ṣeun gan-an ni, ọmọ dáadáa.
Ọmọdé ni ẹ́, àmọ́ ọ̀rọ̀ tó o sọ yìí mọ́gbọ́n dání gan-an.”
Ẹlòmíì dúpẹ́ lọ́wọ́ rẹ̀ gan-an, ó sì béèrè bóyá òun lè rí Ìwé Ìtàn Bíbélì, èyí tó wà lórí ẹ̀rọ.
Ó sọ fún ọmọ náà pé òun ní ìwé yẹn tẹ́lẹ̀ àmọ́ òun yá ọmọ iléèwé kan.
Ọ̀dọ́bìnrin náà wá ṣàlàyé fún tíṣà yẹn pé ó lè rí ìwé náà lórí ìkànnì jw.org.
Àpẹẹrẹ míì ni tọkọtaya kan tó ń gbé nílùú Quevedo, wọ́n wá orúkọ àwọn tí kì í ṣe Ẹlẹ́rìí Jèhófà tó wà lórí fóònù wọn, wọ́n sì fi àtẹ̀jíṣẹ́ ránṣẹ́ sí wọn, ohun tí wọ́n sọ rèé: “Ẹlẹ́rìí Jèhófà ni mí
Kò ṣeé ṣe fún wa láti máa wàásù láti ilé dé ilé bá a ti máa ń ṣe nítorí àrùn tó ń jà ràn-ìn nílẹ̀ wa àti kárí ayé, síbẹ̀, inú wa máa dùn tá a bá lè bá yín sọ̀rọ̀ lórí ẹ̀rọ ayélujára.”
Ọ̀pọ̀ ló gbà láti ṣe bẹ́ẹ̀.
Obìnrin kan tí kì í gbà káwa Ẹlẹ́rìí Jèhófà bá òun sọ̀rọ̀ Ọlọ́run gbóríyìn fáwọn tọkọtaya náà pé òun mọrírì bí wọ́n ṣe ń gbìyànjú láti tu àwọn èèyàn nínú.
Ó sọ fún wọn pé ọ̀kan òun ò balẹ̀ nítorí ìṣòro tó gbòde kan yìí.
Ni tọkọtaya náà bá fi ìwé ìròyìn wa kan ránṣẹ́ sí i, ìyẹn Jí!, No. 1 2020, tó ní àkòrí náà, “Bó O Ṣe Lè Ní Ìbàlẹ̀ Ọkàn.”
Nígbà tí wọ́n tún jọ ráyè sọ̀rọ̀, obìnrin náà sọ pé òun gbádùn ìwé náà gan-an, ó sì jẹ́ kí wọ́n mọ̀ pé òun ti ka ìwé náà lọ́pọ̀lọpọ̀ ìgbà.
Àpẹẹrẹ ẹlòmíì ni arábìnrin adití kan tó ń jẹ́ Johana tó ń gbé ní Santo Domingo de los Tsáchilas. Arábìnrin yìí fi àwòrán * “kọ̀wé” sáwọn èèyàn.
Ó fọwọ́ ya onírúuru àwòrán, ó ya fọ́tò àwọn àwòrán náà, ó sì fi í ránṣẹ́ sáwọn ojúlùmọ̀ ẹ̀ tó jẹ́ adití.
Àmọ́, obìnrin kan tí kì í ṣe adití wà lára àwọn tó fi àtẹ̀jíṣẹ́ náà ránṣẹ́ sí.
Kò pẹ́ tí obìnrin yẹn rí àtẹ̀jíṣẹ́ náà gbà ló fèsì pa dà, tó sì ń béèrè ọ̀pọ̀ ìbéèrè.
Àmọ́ Johana ò lóyé àwọn ìbéèrè yẹn, torí náà ó sọ fún arábìnrin aṣáájú-ọ̀nà kan tí kì í ṣe adití tí orúkọ rẹ̀ ń jẹ́ Rhonda pé kó dáhùn àwọn ìbèérè obìnrin náà.
Obìnrin yẹn sọ fún Arábìnrin Rhonda pé àwọn àwòrán tí Johana fi ránṣẹ́ sí òun ya òun lẹ́nu gan-an.
Ó wá béèrè bóyá àwọn ẹsẹ Ìwé Mímọ́ míì tún wà tó ṣàlàyé ìdí táwọn nǹkan burúkú fi ń ṣẹ̀lẹ̀ láyé.
Arábìnrin Rhonda ka Lúùkù 21:​10, 11 fún un, ó sì fi ìlujá fídíò Kí Nìdí Tí Ọlọ́run Fi Gbà Pé Ká Máa Jìyà? àti Kí Ni Ìdí Tí Ọlọ́run Fi Dá Ayé? ránṣẹ́ sí i. Obìnrin náà sọ pé òun á fẹ́ káwọn tún jọ sọ̀rọ̀ Bíbélì nígbà míì.
Bíi ti àpọ́sítélì Pọ́ọ̀lù tí kò dẹ́kun àtimáa “jẹ́rìí kúnnákúnná nípa Ìjọba Ọlọ́run” bó tiẹ̀ wà lẹ́wọ̀n, àwọn ará wa náà ń ṣe gbogbo ohun tí wọ́n lè ṣe láti máa wàásù báwọn náà ò tiẹ̀ lè jáde nílé.​—Ìṣe 28:23.
^ ìpínrọ̀ 7 Ọ̀pọ̀ àwọn adití ló máa ń ṣòro fún láti lóyé ìwé téèyàn bá kọ, torí náà dípò káwọn ará wa tó gbọ́ èdè adití kọ̀wẹ́ sílẹ̀ fún ẹni tó jẹ́ adití, àwòrán ni wọ́n sábà máa ń yà láti fi ṣàlàyé ọ̀rọ̀ fẹ́ni tó jẹ́ adití.
Ní Sunday, June 3, 2018, òkè ayọnáyèéfín tí wọ́n ń pè ní Volcan de Fuego bú gbàù ní orílẹ̀-èdè Guatemala.
Eérú gbígbóná tú jáde, èéfín tó ń jáde níbẹ̀ sì fẹ́rẹ̀ẹ́ ga tó kìlómítà mẹ́sàn-án.
Ó kéré tán, ìjọ mẹ́wàá ló wà níbi tí ìṣẹ̀lẹ̀ yìí ti wáyé. Àmọ́ a dúpẹ́ pé ìkankan nínú àwọn ará wa lọ́kùnrin àti lóbìnrin ò fara pa, bó tiẹ̀ jẹ́ pé àwọn mẹ́jọ nínú wọn la ti ní kí wọ́n kúrò níbi tí wọ́n ń gbé torí àtidáàbò bò wọ́n.
Ọ̀rọ̀ inú 2 Kọ́ríńtì 8:14 àti 15 ti mú kí àwọn àyíká tó wà nítòsí ṣèrànwọ́ láti pèsè oúnjẹ, ilé àti ohun ìrìnnà fáwọn tí àjálù ṣẹlẹ̀ sí.
Ní Saturday, October 6, 2018, ìmìtìtì ilẹ̀ kan tó lágbára wáyé ní agbègbè àríwá ilẹ̀ Haiti, ó pa èèyàn mẹ́tàdínlógún (17), ó sì ju ọgọ́rùn-ún mẹ́ta (300) tó fara pa.
Ìròyìn tá a gbọ́ fi hàn pé kò sí ìkankan lára àwọn ará wa tó kú; àmọ́ àwọn méjì ṣèṣe.
Ìròyìn tá a kọ́kọ́ gbọ́ látọ̀dọ̀ àwọn alábòójútó àyíká fi hàn pé ilé mẹ́rìnlélógójì (44) àti Gbọ̀ngàn Ìjọba mẹ́rin ló bà jẹ́.
Ní ìlú Port-de-Paix, nǹkan bí àádọ́ta (50) àwọn ará àti ìdílé wọn ló ní láti kúrò níbi tí wọ́n ń gbé torí àwọn ilé náà lè wó nígbàkigbà.
Àwọn ará inú ìjọ tó wà lágbègbè náà ló ń tójú àwọn ìdílé yìí.
Ọ̀kan lára Ìgbìmọ̀ Ẹ̀ka nílẹ̀ Haiti pẹ̀lú arákùnrin méjì tó ń ṣiṣẹ́ ní Ẹ̀ka Tó Ń Yàwòrán Ilé Tó sì Ń Kọ́ Ọ lọ sáwọn ibi tí àjálù náà ti ṣẹlẹ̀ kí wọ́n lè mọ bó ṣe tó, kí wọ́n sì fún àwọn ara níṣìírí.
Ìgbìmọ̀ Tó Ń Ṣètò Ìrànwọ́ Nígbà Àjálù ti bẹ̀rẹ̀ iṣẹ́ níbẹ̀ láti pèsè àwọn nǹkan tó ṣe pàtàkì.
Ọkàn wa wà lọ́dọ̀ àwọn ará wa ní Haiti, a sì ń gbàdúrà fún wọn.
Ìjì kan tí wọ́n pè ní Lidia jà ní Ìyawọlẹ̀ Omi Baja California lórílẹ̀-èdè Mẹ́síkò ní September 1.
Bó tilẹ̀ jẹ́ pé ó ti rọlẹ̀ nígbà tó fi máa di ọjọ́ Saturday, síbẹ̀ òjò tó rọ̀ pọ̀ gan-an, kò tíì sí irú ẹ̀ láti ọdún 1933.
Ó kéré tán, èèyàn márùn-ún ló kú nínú ìjì náà.
Ẹ̀ka ọ́fíìsì àwa Ẹlẹ́rìí Jèhófà tó wà ní Mexico City fi tó wa létí pé arábìnrin Ẹlẹ́rìí kan kú, ọ̀gbàrá òjò tó ń ya mù-ún mù-ún ló gbé e lọ nígbà tó ń rìn lọ sílé.
Ọ̀gbàrá yẹn gbé àwọn mẹ́ta míì lọ, àmọ́ wọ́n rí wọn yọ nínú ẹ̀.
Láfikún sí i, ìjì náà ba ilé mẹ́jọ jẹ́ pátápátá.
Gbogbo àwọn tí àjálù yìí ṣẹlẹ̀ sí ló rí ìtọ́jú gbà látọ̀dọ̀ àwọn mọ̀lẹ́bí wọn tàbí látọ̀dọ̀ àwọn Ẹlẹ́rìí Jèhófà tó wà ládùúgbò wọn.
Ìgbìmọ̀ Olùdarí àwọn Ẹlẹ́rìí Jèhófà ló ń bójú tó ètò ìrànwọ́ nígbà àjálù láti oríléeṣẹ́ wọn, ọrẹ táwọn èèyàn fi ṣètìlẹ́yìn fún iṣẹ́ kárí ayé ni wọ́n sì ń lò.
Agbẹnusọ fún Àwa Ẹlẹ́rìí Jèhófà: Kárí Ayé: David A. Semonian, Ọ́fíìsì Agbéròyìnjáde, +1-845-524-3000 Mexico: Gamaliel Camarillo, +52-555-133-3048
Ní September 19, 2017, ìmìtìtì ilẹ̀ tó lágbára gan-an tí ìwọ̀n rẹ̀ jẹ́ 7.1 wáyé ní àárín gbùngbùn orílẹ̀-èdè Mẹ́síkò, ó sì pa èèyàn tó lé ní ọgọ́rùn-ún méjì [200].
Ìròyìn tá a kọ́kọ́ gbọ́ láti ẹ̀ka ọ́fíìsì Central America rèé: Ó dùn wá gan-an pé ọ̀kan lára àwọn arábìnrin wa ní Mexico City kú sínú ìṣẹ̀lẹ̀ náà.
Arábìnrin kan tún wà tí a ṣì ń wá títí di báyìí lẹ́yìn tí ilé rẹ̀ wó.
Arábìnrin kan fara pa yánayàna ní ìlú kan tó ń jẹ́ Puebla, a tún gbọ pé arábìnrin míì fara gbọgbẹ́ ó sì wà nílé ìwòsàn ní State of Mexico.
A kọ́kọ́ kó ìdílé Bẹ́tẹ́lì kúrò ní ẹ̀ka ọ́fíìsì wa, àmọ́ wọ́n ti pa dà sẹ́nu iṣẹ́ báyìí.
A dúpẹ́ pé ẹnikẹ́ni ò fara pa, ọ́fíìsì náà ò sì bà jẹ́.
À ń bá a lọ láti máa gbàdúrà fún àwọn arákùnrin àtàwọn arábìnrin wa bá a ṣe ń gbé ní àkókò tó le koko yìí, ó dájú pé Jèhófà mọ “wàhálà ọkàn” wọn, á sì bójú tó wọn.—Sáàmù 31:7.
Agbẹnusọ fún Àwa Ẹlẹ́rìí Jèhófà: Kárí Ayé: David A. Semonian, Ọ́fíìsì Agbéròyìnjáde, +1-845-524-3000 Mexico: Gamaliel Camarillo, +52-555-133-3048
Ní September 14, 2017, ìjì ńlá kan tí wọ́n pè ní Hurricane Max jà ní gúùsù etíkun Pàsífíìkì lórílẹ̀-èdè Mẹ́síkò, ó sì fa ìjì líle.
Ìjì náà mú kí atẹ́gùn tó lágbára fẹ́, ó sì tún fa omíyalé tó ba ọ̀pọ̀ nǹkan jẹ́.
Ìwádìí ṣì ń lọ lọ́wọ́ láti mọ bí ìjì náà ṣe ṣọṣẹ́ tó.
Àmọ́, ó bani nínú jẹ́ láti gbọ́ pé ìjì náà pa ọ̀kan lára àwọn arákùrin wa níbi tó ti ń gbìyànjú láti ran aládùúgbò rẹ̀ kan lọ́wọ́.
Ẹ̀ka ọ́fíìsì wa tó wà ní Mexico ṣètò ìrànwọ́, wọ́n sì ṣiṣẹ́ pọ̀ pẹ̀lú àwọn ìjọ àdúgbò láti pèsè ìrànwọ́ fún àwọn tí ìjì náà ṣe lọ́ṣẹ́.
Agbẹnusọ fún Àwa Ẹlẹ́rìí Jèhófà: Kárí Ayé: David A. Semonian, Ọ́fíìsì Agbéròyìnjáde, +1-845-524-3000 Mexico: Gamaliel Camarillo, +52-555-133-3048
Lọ́dún 2017, ìmìtìtì ilẹ̀ méjì tó lágbára wáyé lórílẹ̀-èdè Guatemala àti Mẹ́síkò.
Àwọn ará wa parí ètò ìrànwọ́ tí wọ́n ṣe ní gbogbo agbègbè náà lóṣù December 2018.
Ẹ̀ka ọ́fíìsì wa ní Amẹ́ríkà Àárín bẹ̀rẹ̀ ètò ìrànwọ́ yìí nígbà tí wọ́n ṣe onírúurú ìpàdé láti fún àwọn ará tí àjálù náà ṣẹlẹ̀ sí níṣìírí.
Wọ́n ṣe ìpàdé náà ní ìpínlẹ̀ Chiapas, Morelos, Oaxaca, àti Puebla, kódà wọ́n tún ṣe é ní ìlú Mexico City.
Ìgbìmọ̀ Ẹ̀ka dá ìgbìmọ̀ mọ́kàndínlógójì (39) tó ń ṣètò ìrànwọ́ sílẹ̀, àwọn ìgbìmọ̀ yìí ló sì ṣètò bí wọ́n ṣe tún gbogbo àwọn nǹkan tó bà jẹ́ ṣe.
Arákùnrin Jesse Pérez, ọ̀kan lára Ìgbìmọ̀ Ẹ̀ka ní Amẹ́ríkà Àárín bá àwọn akéde tí àjálù náà kàn ṣèpàdé ní ìpínlẹ̀ Morelos.
Arákùnrin méjì ń ṣiṣẹ́ lórí òrùlé Gbọ̀ngàn Àpéjọ kan tí wọ́n tún kọ́ nígbà ètò ìrànwọ́ náà.
Lórílẹ̀-èdè Mẹ́síkò, ó ju ẹgbẹ̀rún méjìlélógójì (42,000) akéde tó yọ̀ǹda ara wọn láti ìpínlẹ̀ mẹ́wàá kí wọ́n lè bá àwọn tó ń ṣètò ìrànwọ́ ṣiṣẹ́.
Àwọn ará yìí tún ilé ọgọ́rùn-ún mẹ́fà ó lé mọ́kàndínlógún (619) kọ́ pẹ̀lú Gbọ̀ngàn Ìjọba márùn-ún àti Gbọ̀ngàn Àpéjọ méjì.
Wọ́n tún ṣàtúnṣe sí ọgọ́rùn-ún márùn-ún ó lé méjì (502) ilé àti Gbọ̀ngàn Ìjọba mẹ́tàléláàádọ́ta (53).
Yàtọ̀ síyẹn, wọ́n tún ilé mẹ́wà kọ́ ní Guatemala.
Ara àwọn tí wọ́n ṣèrànlọ́wọ́ fún ni ìdílé Hernández àti Santiago.
Ìdílé Hernández níwájú ilé wọn, àwọn tó ṣètò ìrànwọ́ ló bá wọn tún ilé náà kọ́.
Ìlú Chalco ni ìdílé Hernández ń gbé, ibẹ̀ ò ju ogójì (40) kìlómítà sí ìlú Mexico City.
Ìmìtìtì ilẹ̀ tó wáyé ní September 19, 2017 ba ilé wọn jẹ́ kọjá àtúnṣe.
Arábìnrin Ana María Hernández sọ pé: “Ní gbogbo àsìkò wàhálà yìí, a ò ṣaláìní ohunkóhun tá a nílò.
Àwọn ará tọ́jú wa gan-an.
Mo ṣì rántí bí ilé wa tẹ́lẹ̀ ṣe rí nígbà tó wó, àmọ́ tí nǹkan bí àádọ́ta àwọn tó yọ̀ǹda ara wọn wá láti bá wa kọ́ ilé wa tuntun.
Títí dòní, ohun táwọn ará yẹn ṣe fún wa ṣì máa ń ya àwọn ará àdúgbò wa lẹ́nu.” Yàtọ̀ sí ìrànlọ́wọ́ tí ìdílé Hernández rí gbà yìí, aṣojú kan láti ẹ̀ka ọ́fíìsì ní Amẹ́ríkà Àárín wá sọ́dọ̀ wọn, ó sì fi Bíbélì fún wọn níṣìírí.
Ìdílé Santiago níwájú ilé wọn tuntun.
Ìmìtìtì ilẹ̀ tó wáyé ní September 7, 2017 kan ìdílé Santiago tó ń gbé ní ìlú Juchitán, ìpínlẹ̀ Oaxaca.
Ó ba ilé wọn jẹ́ débi pé kò ṣeé gbé mọ́.
Àmọ́ láàárín oṣù mẹ́fà, àwọn tó ń ṣiṣẹ́ ìrànwọ́ bá wọn kọ́ ilé tuntun míì.
Olórí ìdílé náà, Arákùnrin Victor Santiago sọ pé: “Bí ètò Jèhófà ṣe yára pèsè àwọn ohun tá a nílò fún wa wú mi lórí púpọ̀.
Mo rí i pé ọwọ́ Jèhófà la wà, òun ló sì ń bójú tó wa.” Arákùnrin Jesse Pérez, ọ̀kan lára Ìgbìmọ̀ Ẹ̀ka ní Amẹ́ríkà Àárín, sọ pé: “Ọṣẹ́ ti ìmìtìtì ilẹ̀ méjèèjì tó wáyé ṣe pọ̀ gan-an.
Àmọ́ ètò ìrànwọ́ tó wúlò tá a ṣe tẹ̀ lé e fún àwọn ará láǹfààní láti yọ̀ǹda ara wọn.
Ọ̀pọ̀lọpọ̀ àwọn akéde ló ṣèrànlọ́wọ́, èyí sì fi hàn pé wọ́n nífẹ̀ẹ́ àwọn ará.
December 1 ni ìṣẹ́ ìrànwọ́ yìí bẹ̀rẹ̀, a máa ná tó mílíọ̀nù mẹ́wàá dọ́là [$10 million].
A máa tún ilé tó tó ọgọ́rùn-ún márùn-ún [500] àti Gbọ̀ngàn Ìjọba mẹ́rìndínlógún [16] ṣe, àtàwọn ilé míì tí ìjì lílé tó wáyé lẹ́ẹ̀mejì ti bà jẹ́ ní Guatemala àti Mexico lóṣù September.
MEXICO CITY—Ìgbìmọ̀ Ẹ̀ka ti Central America máa bẹ̀rẹ̀ àtúnṣe tó pọ̀ gan-an ní Guatemala àti Mexico ní December 1, 2017, láti pèsè ìrànwọ́ síwájú sí i nítorí ìmìtìtì ilẹ̀ méjì tó wáyé ní oṣù September.
Gbàrà lẹ́yìn tí ìmìtìtì ilẹ̀ yẹn ti wáyé ni ẹ̀ka ọ́fíìsì ti ṣètò ìrànwọ́, wọ́n pèsè omi, oúnjẹ, oògùn àti aṣọ fáwọn arákùnrin wa tí àjálù yẹn dé bá.
Ohun míì tí wọ́n tún máa bẹ̀rẹ̀ báyìí ni bí wọ́n ṣe máa tún Gbọ̀ngàn Àpéjọ, Gbọ̀ngàn Ìjọba àti ilé àwọn arákùnrin wa kọ́.
Ní ìpínlẹ̀ Chiapas àti Oaxaca ní Mexico, àwọn arákùnrin àti arábìnrin ọgọ́rùn mẹ́fà àti àádọ́ta lé ní márùn-ún [655] ni kò nílé lórí mọ́ lẹ́yìn tí ìjì líle kan wáyé ní September 7.
Ohun tí wọ́n gbèrò láti ṣe ni pé kí wọ́n tún ilé ọgọ́rùn mẹ́ta àti mẹ́ẹ̀ẹ́dógún [315] kọ́, wọ́n sì máa tún Gbọ̀ngàn Ìjọba mẹ́ẹ̀ẹ́dógún [15] kọ́.
Yàtọ̀ sáwọn yẹn, àwọn ilé tó bàjẹ́ tí wọ́n fẹ́ tún ṣe tó ẹgbẹ̀rún kan àti mọ́kàndínlógójì [1,039], Gbọ̀ngàn Ìjọba tó tó ọgọ́rùn kan ó lé mẹ́jọ [108] àti Gbọ̀ngàn Àpéjọ mẹ́ta.
Ní Mexico City àti ní Morelos àti Puebla, àwọn arákùnrin àtàwọn arábìnrin ọgọ́rùn mẹ́rin ó lé ọgọ́ta àti mẹ́ta [463] ni ìjì líle tó wáyé ní September 19 ba ilé wọn jẹ́.
Ilé tó tó méjìdínlọ́gọ́jọ [158] ni wọ́n máa tún kọ́, wọ́n tún máa tún ilé ọgọ́rùn mẹ́fà [600] ṣe, wọ́n á sì tún ṣàtúnṣe sí Gbọ̀ngàn Ìjọba mọ́kàndínlógójì [39] àti Gbọ̀ngàn Àpéjọ kan.
Ìjì líle tó wáyé ní September 7 ní Guatemala sọ àwọn arákùnrin àti arábìnrin mẹ́rìndínlógójì [36] di aláìnílé lórí.
Láàárín oṣù díẹ̀ sí i, àwọn ìránṣẹ́ ìkọ́lé àti àwọn arákùnrin tó wà ládùúgbò máa tún ilé mẹ́sàn-án àti Gbọ̀ngàn Ìjọba kan kọ́.
Wọ́n máa tún ilé ogún [20] kọ́, wọ́n sì máa tún Gbọ̀ngàn Ìjọba mẹ́rin kọ́.
Ìgbìmọ̀ Ẹ̀ka sọ pé àwọn ìgbìmọ̀ tó ń bójú tó ètò ìrànwọ́ mọ́kàndínlógójì [39] ló máa bójú tó iṣẹ́ yìí, ó máa ná wọn tó mílíọ̀nù mẹ́wàá owó dọ́là [$10 million] iṣẹ́ náà sì máa gbà tó oṣù márùn-un sí mẹ́fà.
Àwọn ìránṣẹ́ ìkọ́lé ọgbọ̀n [30] ló ti ń gbara di láti lọ sí àwọn ibi tí àjálù yẹn ti wáyé, àwọn ará tó tó ẹgbẹ̀rún kan ó dín ọgbọ̀n [970] ló sì ti yọ̀ǹda ara wọn láti lọ́wọ́ sí iṣẹ́ àtúnṣe yìí.
Ó dá wa lójú pé Jèhófà máa bù kún iṣẹ́ yìí àtàwọn tó yọ̀ǹda ara wọn láti ní ìpín nínú ètò ìrànwọ́ tá a ṣe fáwọn ará wa tí àjálù yìí dé bá.—2 Kọ́ríńtì 8:4.
Déètì: June 7 sí 9, 2019
Ibi Tá A Ti Ṣe É: Pápá ìṣeré BBVA Bancomer Stadium ní ìlú Monterrey, Mẹ́síkò
Èdè: Gẹ̀ẹ́sì, Èdè Adití ti Mẹ́síkò, Sípáníìṣì
Àwọn Ibi Tí Wọ́n Ta Àtagbà Rẹ̀ sí: Ibi méjìdínlógójì (38) ní orílẹ́-èdè mẹ́fà (Costa Rica, Guatemala, Honduras, Mẹ́síkò, Nicaragua àti Panama)
Àwọn Tó Wá: 39,099
Àwọn Tó Ṣèrìbọmi: 393
Àwọn Tó Wá Láti Ìlẹ̀ Òkèèrè: 4,682
Áwọn Ẹ̀ka Ọ́fíísì Tó Wá: Ajẹntínà, Brazil, Kòlóńbíà, Faransé, Ítálì, Japan, Netherlands, Paraguay, Peru, Sípéènì, Amẹ́ríkà
Ìrírí: Roberto Valero tó jẹ́ aṣojú ìjọba ìlú Guadalupe lọ sí ibi tá a ti ṣe àpéjọ lọ́jọ́ Sátidé. Ó sọ pé: “Ohun tó ṣe pàtàkì jù sí ìjọba ilẹ̀ wa ni bí àwọn èeyàn á ṣe wà ní àlááfíà àti ààbò. Ẹ̀yin Ẹlẹ́rìí Jèhófà ń kópa tó jọjú nínú mímú kí èyí ṣeé ṣe. Gbogbo ará ìlú yìí ló sì mọ̀ bẹ́ẹ̀.”
Ní ìrọ̀lẹ́ ọjọ́ Thursday, September 7, ìmìtìtì ilẹ̀ tó lágbára gan-an wáyé ní apá gúùsù Etí Òkun Pàsífíìkì ní orílẹ̀-èdè Mẹ́síkò.
Ìmìtìtì ilẹ̀ yẹn ló le jù nínú àwọn èyí tó ti wáyé rí ní orílẹ̀-èdè Mẹ́síkò ní ọ̀pọ̀ ọdún sẹ́yìn, èèyàn márùnlélógójì [45] ló pa.
Ó dùn wá pé a gba ìsọfúnni pé arákùnrin wa kan àti àwọn arábìnrin wa méjì wà lára àwọn tó kú.
Ní àfikún sí ìyẹn, ìsọfúnni tá a kọ́kọ́ gbà fi hàn pé ọ̀pọ̀ ilé àwọn ará wa àti àwọn Gbọ̀ngàn Ìjọba kan ló bàjẹ́ tàbí tó bàjẹ́ pátápátá.
Gbọ̀ngàn Àpéjọ méjì ní Ìpínlẹ̀ Chiapas náà bàjẹ́.
Àmọ́ wọ́n ṣì ń bá àyẹ̀wò lọ.
A ó túbọ̀ máa gbàdúrà fún àwọn arákùnrin àti àwọn arábìnrin wa, a nígbàgbọ́ pé Jèhófà máa tù wọ́n nínú, á sì fún wọn lókun.—2 Tẹsalóníkà 2:16, 17.
Agbẹnusọ fún Àwa Ẹlẹ́rìí Jèhófà: Kárí Ayé: David A. Semonian, Ọ́fíìsì Agbéròyìnjáde, +1-845-524-3000 Mexico: Gamaliel Camarillo, +52-555-133-3048
MEXICO CITY​—Ní December 4, 2017, àwọn kan kóra jọ ní àdúgbò Tuxpan de Bolaños, tó wà nítòsí àwọn àpáta ní Jalisco, Mexico, wọ́n sì lé àwọn ará wa méjìlá [12] tí wọ́n jẹ́ ọmọ Huichol kúrò nílé, papọ̀ pẹ̀lú àwọn mẹ́rìndínlógójì [36] míì tó máa ń wá sí ìpàdé.
Àwọn èèyàn yẹn ń bínú pé àwọn ará wa ò bá àwọn lọ́wọ́ sí àwọn àṣà ẹ̀sìn tí àwọn Huichol máa ń ṣe.
Torí ohun tí wọ́n ṣe yìí, àwọn ará wa ti lọ bá àwọn aláṣẹ pé kí wọ́n ran àwọn lọ́wọ́.
Wọ́n jí ẹrù àwọn ará wa kó, wọ́n sì ju àwọn míì síta.
Ìjọba Mexico ò kóyán àwọn àṣà Huichol kéré rárá, torí náà, dé ìwọ̀n àyè kan, ìjọba fún wọn lómìnira láti ṣe bó ṣe wù wọ́n.
Ṣe làwọn tó ń rí sí àṣà àwọn Huichol ni káwọn èèyàn wá lé àwọn ará wa kúrò nílé wọn, wọ́n tún jà wọ́n lólè, wọ́n yọ ilẹ̀kùn wọn lọ, wíńdò àti òrùlé wọn.
Wọ́n tún da àwọn ẹrù wọn míì sínú omi.
Lẹ́yìn náà, wọ́n mú àwọn ará wa lọ sínú igbó kan, wọ́n sì sọ pé àwọn máa pa wọ́n tí wọ́n bá pa dà wálé.
Àwọn Ẹlẹ́rìí tí wọ́n jẹ́ ẹ̀yà Huichol níwájú Gbọ̀ngàn Ìjọba.
Aṣojú kan láti ẹ̀ka ọ́fíìsì wa ní Mexico rìnrìn àjò láti lọ bá àwọn tí wọ́n lé kúrò nílé, kí wọ́n lè fi Bíbélì ràn wọ́n lọ́wọ́, kí wọ́n sì bá wọn ṣètò ilé tí wọ́n lè forí pamọ́ sí.
Àwọn tó ń bójú tó ọ̀rọ̀ ẹjọ́ láti ẹ̀ka ọ́fíìsì àwa Ẹlẹ́rìí Jèhófà ti lọ rí àwọn aláṣẹ ìlú Jalisco, ẹni tó ń rí sí ọ̀rọ̀ ẹ̀tọ́ ọmọnìyàn, agbẹjọ́rò fún ìjọba lágbègbè yẹn, àti ẹni tó ń rí sí ọ̀rọ̀ àwọn tá a hùwà ìkà sí.
Àwọn yìí ti ń ṣe ìwádìí lórí ohun tí wọ́n ṣe sáwọn ará wa yìí.
Arákùnrin Gamaliel Camarillo, tó jẹ́ agbẹnusọ fún àwa Ẹlẹ́rìí Jèhófà ní Mexico sọ pé: “Ó dùn wá gan-an pé wọ́n ń gbéjà ko àwọn ará wa tó jẹ ẹni àlàáfíà tó sì ń bọ̀wọ̀ fún àṣà àwọn míì, torí pé wọn ò bá wọn lọ́wọ́ nínú àwọn àṣà ẹ̀sìn tí kò bá ẹ̀rí ọkàn wọn mu.
A gbà pé àwọn aláṣẹ máa ṣe nǹkan sí ọ̀rọ̀ àwọn tó ń ṣe inúnibíni sáwọn ará wa nítorí ẹ̀sìn.” À ń gbàdúrà fún àwọn ará wa tó ti pàdánù ilé àtàwọn nǹkan ìní wọn, ó dá wa lójú pé Jèhófà á máa lo ètò rẹ̀ láti pèsè ìrànlọ́wọ́ táwọn ará wa nílò.​—Aísáyà 32:2.
Agbẹnusọ fún Àwa Ẹlẹ́rìí Jèhófà: Kárí Ayé: David A. Semonian, Ọ́fíìsì Agbéròyìnjáde, +1-845-524-3000 Mexico: Gamaliel Camarillo, +52-555-133-3048
Ní October 23, àjálù méjì ṣẹlẹ̀ lórílẹ̀-èdè Mẹ́síkò, ìyẹn ni Ìjì Vicente àti Ìjì Líle Willa.
Ìjì Vicente fa omíyalé tó lágbára, ó sì mú kí ẹrẹ̀ ya ní gúúsù Mẹ́síkò débi pé ó pa èèyàn mọ́kànlá (11).
Ìjì líle Willa ṣọṣẹ́ gan-an ní etí Òkun Pàsífíìkì ní Mẹ́síkò, òjò àrọ̀ọ̀rọ̀dá rọ̀, ọwọ́ atẹ́gùn ibẹ̀ sì le gan-an. Èèyàn tó tó ẹgbẹ̀rún mẹ́rin ó lé igba àti àádọ́ta (4,250) ló sì sá kúrò nílé torí ìjì líle náà.
Ẹ̀ka ọ́fíìsì Central America, tó ń bójú tó iṣẹ́ àwa Ẹlẹ́rìí Jèhófà ní Mẹ́síkò, ròyìn pé kò sí ìkankan lára àwọn ará wa tó kú, wọn ò sì fara pa nígbà tí ìjì méjèèjì jà.
Àmọ́ ní ìpínlẹ̀ Nayarit, akéde méjìdínlọ́gọ́fà (118) ló sá kúrò nílé lọ sí agbègbè olókè.
Nílùú Sinaloa, omi ya wọ Gbọ̀ngàn Ìjọba kan àti ilé ọ̀pọ̀ àwọn ará.
Omi tún ya wọ ilé àwọn ìdílé Ẹlẹ́rìí Jèhófà márùn-ún nílùú Michoacán.
Àmọ́ àwọn ará tó wà níbẹ̀ ṣàtúnṣe tó yẹ sí ilé wọn àti Gbọ̀ngàn Ìjọba tí omi wọ̀ náà.
Àdúrà wa ni pé kí àwọn ará wa tí àwọn ìjì yìí ṣe ní jàǹbá ní Mẹ́síkò máa fara dà á, kí wọ́n sì máa rántí pé gbogbo wa la jọ ń retí ọjọ́ iwájú tí àjálù ò ní ṣẹlẹ̀ mọ́.—2 Kọ́ríńtì 6:4.
Ní August 16 2019, àwa Ẹlẹ́rìí Jèhófà mú Bíbélì Mímọ́ ti Ìtumọ̀ Ayé Tuntun jáde lédè Guarani níbi àpéjọ agbègbè tí wọ́n ta àtagbà rẹ̀ látinú gbọ̀ngàn Bẹ́tẹ́lì tó wà nílùú Capiatá, lórílẹ̀-èdè Paraguay.
Arákùnrin Daniel González, tó jẹ́ ọ̀kan lára Ìgbìmọ̀ Ẹ̀ka orílẹ̀-èdè Paraguay ló mú Bíbélì yìí jáde lọ́jọ́ àkọ́kọ́ àpéjọ agbègbè náà.
Wọ́n sì wo ìtòlẹ́sẹẹsẹ náà bó ṣe ń lọ lọ́wọ́ láwọn ibi mẹ́tàlá (13) ọ̀tọ̀ọ̀tọ̀ míì, àròpọ̀ gbogbo àwọn péjọ nígbà tá a mú Bíbélì náà jáde sì jẹ́ ẹgbẹ̀rún márùn-ún, ọgọ́rùn-ún mẹ́fà àti mọ́kànlélọ́gbọ̀n (5,631).
Bó tiẹ̀ jẹ́ pé èdè Sípáníìṣì làwọn èèyàn ń sọ lórílẹ̀-èdè Paraguay, àmọ́ ó kéré tán, èèyàn mẹ́sàn-án nínú mẹ́wàá ló ń sọ èdè Guarani tó jẹ́ èdè ìbílẹ̀ ibẹ̀.
Ìdí nìyẹn tó fi jẹ́ pé ní gbogbo Latin America, orílẹ̀-èdè Paraguay nìkan ni ọ̀pọ̀ èèyàn ti ń sọ èdè ìbílẹ̀ kan náà.
Ọ̀kan lára àwọn atúmọ̀ èdè tó ṣiṣẹ́ lórí ìtúmọ̀ Bíbélì yìí sọ pé kí wọ́n tó mú Bíbélì yìí jáde, ọ̀pọ̀ àwọn arákùnrin àtàwọn arábìnrin ló jẹ́ pé èdè Guarani tó jẹ́ èdè ìbílẹ̀ wọn ni wọ́n fi máa ń gbàdúrà sí Jèhófà..
Ó sọ pé: “Ní báyìí, Jèhófà náà á máa bá wa sọ̀rọ̀ lédè Guarani. A mọ̀ pé Jèhófà nífẹ̀ẹ́ wa, ó sì mọyì wa. Ó ti túbọ̀ dá mi lójú pé Jèhófà ni Bàbá mi.”
Ó dá wa lójú pé Bíbélì èdè Guarani yìí máa ṣèrànwọ́ fún àwọn akéde ẹgbẹ̀rún mẹ́rin, ọgọ́rùn-ún mẹ́sàn-án àti mẹ́rìnlélọ́gbọ̀n (4,934) tó ń sọ èdè Guarani lórílẹ̀-èdè Paraguay, ó sì máa jẹ́ kí ìfẹ́ àti ìmọrírì tí wọ́n ní fún Jèhófà àti ètò rẹ̀ túbọ̀ lágbára sí i.
Ó dá wa lójú pé Bíbélì yìí máa jẹ́ káwọn tó ń kà á mọ òtítọ́ tó ṣeyebíye tó wà nínú ọ̀rọ̀ Ọlọ́run wa.
Láti ìparí oṣù April 2019 ni òjò tó rinlẹ̀ tó ń rọ̀ ní Paraguay ti ń mú kí àkúnya omi ṣẹlẹ̀ láwọn agbègbè tó wà ní etí odò Paraguay River.
Ó kéré tán, èèyàn mẹ́fà ni àkúnya omi náà pa.
Ẹ̀ka ọ́fíìsì wa ní Paraguay ròyìn pé àjálù yìí kan métàdínlógóje (137) lára àwọn ará wa lóríṣiríṣi ìlú.
Ní ìlú Asunción tó jẹ́ olú ìlú orílẹ̀-èdè náà, omi yìí wó ògiri Gbọ̀ngàn Ìjọba kan, ó sì ya wọlé, ibẹ̀ ni wọ́n máa ń lò fún Ilé Ẹ̀kọ́ Àwọn Ajíhìnrere.fara pa.
Àmọ́, a dúpẹ́ pé kò sẹ́ni tó fara pa.
Ẹ̀ka ọ́fíìsì kó nǹkan ránṣẹ́ sáwọn ará tọ́rọ̀ náà kàn, irú bí oúnjẹ, omi àtàwọn nǹkan míì tí wọ́n nílò.
Torí pé àkúnya omi náà ò tíì lọ, ẹ̀ka ófíìsì ṣì ń wo bí nǹkan ṣe ń lọ sí fáwọn ará, bákan náà wọ́n ń rí sí i pé àwọn ará rí ohun tí wọ́n nílò, wọ́n sì ń ṣèrànwọ́ nípa tara àti nípa tẹ̀mí.
À ń gbàdúrà fún àwọn ará wa tí àkúnya omi yìí kàn ní Paraguay. A mọ̀ pé Jèhófà máa jẹ́ “ibi olódi” fún wọn lásìkò ìṣòro yìí.​
Láti May 1 sí August 31, 2019, ẹ̀ka ọ́fíìsì orílẹ̀-èdè Peru ṣètò àkànṣe ìwàásù kan kí wọ́n lè wàásù ọ̀rọ̀ Ọlọ́run fún àwọn ará Peru tí wọ́n ń sọ èdè ìbílẹ̀ tó ń jẹ́ Aymara.
Àkànṣe ìwàásù náà kẹ́sẹ járí gan-an ni.
Àwọn tó lọ́wọ́ nínú ẹ̀ fi ìwé ẹgbẹ̀rún méje, ọgọ́rùn-ún mẹ́jọ àti mẹ́tàléláàádọ́rùn-ún (7,893) sóde, wọ́n sì fi fídíò wa han àwọn èèyàn ní ìgbà ẹgbẹ̀rún méjì àti ọgọ́rùn-ún márùn-ún (2,500).
Nígbà tí àkànṣe ìwàásù náà fi máa parí, àwọn ará wa ti bẹ̀rẹ̀ ìkẹ́kọ̀ọ́ Bíbélì pẹ̀lú ọgọ́rùn-ún mẹ́ta àti mọ́kànlélọ́gọ́rin (381) èèyàn.
Àwọn tó ń sọ èdè Aymara lórílẹ̀-èdè Peru tó ẹgbẹ̀rún lọ́nà àádọ́ta-lé-ní-irínwó (450,000), ó sì fẹ́rẹ̀ẹ́ tó ẹgbẹ̀rún lọ́nà ọ̀ọ́dúnrún (300,000) lára wọn tó ń gbé ní ìlú Puno.
Ní báyìí, iye àwọn akéde tó ń sọ èdè Aymara jẹ́ ọgọ́rùn-ún mẹ́ta àti mọ́kànlélọ́gbọ̀n (331), wọ́n wà ní ìjọ méje àti àwùjọ mẹ́jọ.
Ìpínlẹ̀ ìwàásù tó wà lórílẹ̀-èdè Peru fẹ̀ ju ohun tí àwọn akéde tó wà níbẹ̀ lè kárí lọ, torí náà àwọn akéde tó ń sọ èdè Aymara lórílẹ̀-èdè Chile wá dara pọ̀ mọ́ wọn fún àkànṣe ìwàásù náà.
Kí àwọn ará lè dé ọ̀dọ̀ àwọn tó ń sọ èdè Aymara, ìgbà míì wà tí wọ́n máa ń gun òkè tó fi ẹgbẹ̀rún márùn-un (5,000) mítà ga ju ìtẹ́jú òkun lọ, wọ́n á sì wàásù níbi tó tutù bíi yìnyín.
Àwùjọ kan fi ọ̀pọ̀ wákàtí rìn lọ sí agbègbè kan tí àwọn tó ti abúlé míì wá ti wá ṣe ìsìnkú kan.
Àwọn ará lọ́kùnrin àti lóbìnrin fi ìlérí tí Ọlọ́run ṣe nípa àwọn tó ti kú hàn wọ́n nínú Bíbélì.
Àwọn aláṣẹ abúlé náà àti ìdílé tí ọ̀fọ̀ ṣẹ̀ dúpẹ́ lọ́wọ́ àwọn arákùnrin àti arábìnrin náà fún gbogbo ìsapá tí wọ́n ṣe kí wọ́n lè wá fi Bíbélì, Ọ̀rọ̀ Ọlọ́run tù wọ́n nínú.
Ní apá ibòmíì, àwọn arákùnrin àti arábìnrin wa rí àwùjọ àwọn èèyàn kan tí wọ́n ń pàdé lẹ́ẹ̀mejì lọ́sẹ̀ láti kẹ́kọ́ọ̀ Bíbélì.
Àwọn akéde náà rí i pé ìwé Ọkunrin Titobilọla Julọ Ti O Tii Gbé Ayé Rí àti Ìwé Ìtàn Bíbélì tí wọ́n gbà lọ́wọ́ ìbátan wọn kan lórílẹ̀-èdè Bòlífíà ni wọ́n ń lò.
Bí àwọn èèyàn yìí ṣe rí i pé àwa Ẹlẹ́rìí Jèhófà la tẹ àwọn ìwé tí wọ́n ń lò yìí ni ọ̀pọ̀ lára wọn ti bẹ̀rẹ̀ síí kẹ́kọ̀ọ́ Bíbélì, tí wọ́n sì ń wá sí àwọn ìpàdé wa.
Arákùnrin Albert Condor, alàgbà kan tó ṣe kòkáárí ọ̀kan lára àwọn àwùjọ náà sọ pé: “Inú èmi àti ìyàwó mi dùn gan-an pé ó ṣeé ṣe fún wa láti lọ́wọ́ nínú àkànṣe ìwàásù yìí.
Ó ti jẹ́ ká túbọ̀ nígbàgbọ́ nínú Jèhófà torí pé nígbà tá a kọ́kọ́ ń lọ sí ìlú náà, a ò mọ bá ṣe máa débẹ̀, torí pé ìrìn-àjò náà nira gan-an.
Nígbà tá a débẹ̀, a gbàdúrà sí Jèhófà pé kó jẹ́ ká rí ibi tá a máa sùn sí, ó sì gbọ́ àdúrà wa.
Àwọn àdúrà tá a gbà yẹn fún mi lókun gan-an, bí mo tún ṣe rí bí àwọn ará yòókù ṣe gbẹ́kẹ̀ lé Jèhófà náà tún fún mi lókun.”
Inú àwọn ará lọ́kùnrin àti lóbìnrin dùn pé àwọn wàásù Ọ̀rọ̀ Ọlọ́run tó lè mú kéèyàn jogún ìyè àìnípẹ̀kun, fún àwọn ará ìlú Puno tí wọ́n ń sọ èdè Aymara lórílẹ̀-èdè Peru.​
Ní June 26, 2018, àwọn aṣojú Ilé Iṣẹ́ Ìjọba ilẹ̀ Thailand ní Peru wá sí ẹ̀ka ọ́fíìsì àwa Ẹlẹ́rìí Jèhófà tó wà ní Lima, tó jẹ́ olú ìlú ilẹ̀ Peru.
Wọ́n dìídì wá ni láti dúpẹ́ lọ́wọ́ àwọn ará wa torí pé wọ́n ṣèrànwọ́ fún àwọn ọmọ ilẹ̀ Thailand tó wà lẹ́wọ̀n nílẹ̀ Peru.
Ọdún 2007 làwọn Ẹlẹ́rìí Jèhófà ní Peru ti bẹ̀rẹ̀ sí í lọ wo àwọn ẹlẹ́wọ̀n kí wọ́n lè kọ́ wọn lẹ́kọ̀ọ́ Bíbélì.
Àmọ́ látọdún 2013, àwọn ará bẹ̀rẹ̀ sí í lọ sí ọgbà ẹ̀wọ̀n kan tí àwọn ọmọ ilẹ̀ Thailand wà.
Inú aṣojú ilẹ̀ Thailand yìí dùn gan-an sí ìfẹ́ táwọn ará dìídì fi hàn yìí, ló bá kàn sí ẹ̀ka ọ́fíìsì pé òun máa fẹ́ wá síbẹ̀.
Àwọn ará lọ́kùnrin àti lóbìnrin ń jáde bọ̀ láti ọgbà ẹ̀wọ̀n kan tí wọ́n ti lọ kọ́ àwọn ẹlẹ́wọ̀n lẹ́kọ̀ọ́ Bíbélì.
Àwọn tí wọ́n wá láti ọ́fíìsì ìjọba ni Ọ̀gbẹ́ni Angkura Kulvanij tó jẹ́ aṣojú mínísítà; Ọ̀gbẹ́ni Pathompong Singthong tó jẹ́ akọ̀wé àgbà àti Pradthana Pongudom tó jẹ́ olùrànlọ́wọ́ aṣojú ilé iṣẹ́.
Bí wọ́n ṣe ń rìn káàkiri ẹ̀ka ọ́fíìsì náà, àwọn arákùnrin tó wà nínú Ìgbìmọ̀ Ẹ̀ka jẹ́ kí wọ́n rí iṣẹ́ ribiribi tí à ń ṣe lẹ́nu iṣẹ́ ìtumọ̀, lára ẹ̀ ni bá a ṣe ń túmọ̀ àwọn ìtẹ̀jáde wa sí èdè ìbílẹ̀ mẹ́sàn-án.
Àwọn aṣojú Ilé Iṣẹ́ Ìjọba Thailand ń wo arákùnrin kan bó ṣe ń túmọ̀ ìtẹ̀jáde wa sí Èdè Àwọn Adití Lọ́nà ti Peru.
Nínú lẹ́tà tí wọ́n kọ láti ọ́fíìsì ìjọba sí ẹ̀ka ọ́fíìsì wa, wọ́n sọ pé, wọ́n “gbóríyìn àti òṣùbà” fún àwọn ará wa lórí iṣẹ́ takuntakun tí wọ́n ṣe láti ṣèrànwọ́ fún “àwọn aláìní àtàwọn tí ò léèyàn ní Peru, láìka ohun tí wọ́n gbà gbọ́ àti àṣà wọn sí.”
Ilé iṣẹ́ ìjọba tún sọ̀rọ̀ nípa “iṣẹ́ ribiribi àti ìtìlẹyìn táwọn òṣìṣẹ́ Association of Jehovah’s Witnesses ní ẹ̀ka ọ́fíìsì Peru ń ṣe láti ṣèrànwọ́ fún àwọn ọmọ ilẹ̀ Thailand tó wà lẹ́wọ̀n nílẹ̀ Peru.”
Ohun táwọn ará wa ní Peru ń ṣe jẹ́ ká rí àyípadà rere tó máa ń wáyé tá a bá ń kọ́ gbogbo èèyàn lẹ́kọ̀ọ́ Bíbélì.
Àwọn arákùnrin àti arábìnrin tó tó ẹgbẹ̀rún mẹ́ta (3,000) ló wà níbi àkànṣe iṣẹ́ ìwàásù níbi térò pọ̀ sí ní àkókò eré ìdárayá tí wọ́n ṣètò fún àwọn ará Amẹ́ríkà àtàwọn míì, ìyẹn Pan American Games and Parapan American Games, èyí tó wáyé ní ìlú Lima ní Peru.
Eré ìdárayá náà bẹ̀rẹ̀ ní July 26, 2019, ó sì parí ní September 1.
Àwọn tó kópa nínú àwọn eré ìdárayá náà lé ní ẹgbẹ̀rún mẹ́jọ àti ààbọ̀ (8,500), àwọn arìnrìn-àjò afẹ́ tó wá síbẹ̀ sì tó ọ̀kẹ́ méjìlá ààbọ̀ (250,000).
Láti lè wàásù fún ọ̀pọ̀ àlejò tó ń bọ̀, àwọn akéde gbé ọgọ́rùn-ún kan (100) àtẹ ìwé sí ibi mẹ́tàléláàádọ́ta (53) ọ̀tọ̀ọ̀tọ̀.
Àwọn ìwé tí wọn tẹ̀ lédè Aymara, Gẹ̀ẹ́sì, Faransé, Potogí, Quechua (tí a tún mọ̀ sí Ayacucho) àti Sípáníìṣì ni a kó sórí àwọn àtẹ ìwé náà.
Àwọn fídíò tí a ṣe ní Èdè Àwọn Adití Lọ́nà ti Peru tún wà níbẹ̀ pẹ̀lú fún àǹfààní àwọn àlejò tó jẹ́ adití.
Arákùnrin Kemps Moran Hurtado, tó ń ṣe kòkáárí iṣẹ́ ìwàásù yìí sọ pé: “Ètò tí a ṣe yìí á mú ká lè wàásù fún onírúurú èèyàn tí àṣà ìbílẹ̀ wọn yàtọ̀ nítorí pé orílẹ̀-èdè ọ̀tọ̀ọ̀tọ̀ ni àwọn èèyàn ti máa wá.
Iṣẹ́ ìwàásù níbi térò pọ̀ sí jẹ́ apá pàtàkì nínú iṣẹ́ kíkọ́ni lẹ́kọ́ọ́ Bíbélì tí à ń ṣe, nítorí ó ń jẹ́ káwọn èèyàn rí àwọn Ẹlẹ́rìí Jèhófà tí wọ́n ń wàásù láwọn ibi térò pọ̀ sí.”
Inú wa dùn láti gbọ́ nípa ìgbòkègbodò iṣẹ́ ìwàásù tó ń gbòòrò sí i yìí. Ó dá wa lójú pé Jèhófà á máa bá a lọ láti bù kún àwọn arákùnrin àti arábìnrin wa ní Peru, bí wọ́n ṣe ń tẹ̀ síwájú láti wàásù fún àwọn èèyàn níbi gbogbo tí a ti lè rí wọn.​
Ní Wednesday, September 20, 2017, ìjì ńlá kan tí wọ́n pè ní Hurricane Maria jà, ó sì bá nǹkan jẹ́ gan-an ní Puerto Rico.
Èyí ni ìjì karùn-ún tó lágbára jù lọ nínú èyí tó tíì jà lórílẹ̀-èdè Amẹ́ríkà.
Lọ́wọ́lọ́wọ́ báyìí, kò sí iná mọ̀nàmọ́ná ní gbogbo erékùṣù náà, ìjọba sì ti ṣòfin pé ẹnikẹ́ni kò gbọ́dọ̀ rìn níta láti aago mẹ́fà ìrọ̀lẹ́.
Àwọn ará wa kankan kò fara pa. A sì ti ń ṣètò láti pèsè ìrànwọ́ fún wọn.
Gbọ̀ngàn Ìjọba kan tí kò bà jẹ́ la máa gbé, ibẹ̀ náà làá ti máa pín àwọn ohun ìrànwọ́ fáwọn èèyàn.
Ìjì náà ba apá kékeré kan jẹ́ ní ẹ̀ka ọ́fíìsì wa tó wà ní ìlú San Juan.
Àwọn ìdílé Bẹ́tẹ́lì wà ní àláàfíà, kò sí ẹnì kankan tó fara pa.
Àmọ́ íńtánẹ́ẹ̀tì ti bà jẹ́, jẹnẹrátọ̀ ni wọ́n sì ń lò.
Ó dájú pé àwọn ará wa ń rí ìtùnú gbà bí wọ́n ṣe rí iṣẹ́ ribiribi tí ètò Jèhófà ń ṣe láti pèsè ìrànwọ́ fún wọn.
Ní September 25, 2017, ohun tá a gbọ́ látẹnu àwọn alábòójútó àyíká mẹ́ẹ̀ẹ́dógún [15] lára àwọn alábòójútó àyíká mọ́kàndínlógún [19] tó wà nílùú Puerto Rico ni pé arákùnrin wa kan ṣoṣo ló fara pa nígbà tí ìjì líle Hurricane Maria ṣọṣẹ́.
A ò tíì rí àwọn alábòójútó àyíká mẹ́rin tó kù tí wọ́n wà ní apá ìwọ̀ oorùn ìlú náà bá sọ̀rọ̀ láti mọ bí nǹkan ṣe ń lọ sí níbẹ̀.
Àwọn arákùnrin wa tó wà láwọn àyíká tó wà nítòsí ti lọ wá àwọn ọ̀kadà àtàwọn ọkọ̀ tó rọ́kú, kí wọ́n lè fi rìnrìn-àjò lọ wo àwọn ara wa tó wà ní ìwọ̀ oòrùn ìlú náà.
A ó máa bá a nìṣó láti gbàdúrà fún àwọn arákùnrin àti arábìnrin wa ọ̀wọ́n yìí.
Àfikún ìsọfúnni: Ó dùn wá gan-an pé ìjì líle Hurricane Harvey pa arábìnrin wa kan tó jẹ́ àgbàlagbà.
NEW YORK—Lọ́jọ́ Friday, August 25, 2017, ìjì runlérùnnà kan tí wọ́n ń pè ní Hurricane Harvey ṣọṣẹ́ lágbègbè Rockport, Texas, tó wà létíkun.
Nígbà tó máa fi di ọjọ́ Sunday, ìjì náà ti rọlẹ̀ díẹ̀, àmọ́ ó ṣì ń ṣọṣẹ́ lọ láwọn ibì kan ní Texas títí di ọjọ́ Wednesday, August 30.
Ẹ̀ka ọ́fíìsì àwa Ẹlẹ́rìí Jèhófà tó wà lórílẹ̀-èdè Amẹ́ríkà ti ṣèwádìí láti mọ bí ìṣẹ̀lẹ̀ náà ṣe nípa tó lórí àwọn arákùnrin àti arábìnrin wa.
Nǹkan bí 84,000 àwọn Ẹlẹ́rìí Jèhófà ni ìjì líle náà ṣàkóbá fún.
Kò sí arákùnrin tàbí arábìnrin wa kankan tó kú sínú ìṣẹ̀lẹ̀ yìí, àmọ́ àwọn mẹ́sàn-án ló fara pa, àwọn márùn-ún sì ń gba ìtọ́jú nílé ìwòsàn.
Àwọn Ẹlẹ́rìí Jèhófà tí iye wọn jẹ́ 5,566 ni ìṣẹ̀lẹ̀ yìí ti sọ di aláìnílé lórí.
Ilé àwọn ará wa tí ó tó 475 ni ìjì yẹn bà jẹ́ gan-an; láfikún síyẹn, ilé àwọn ará wa míì tí iye rẹ̀ jẹ́ 1,182 ló tún bà jẹ́.
Àwọn alábòójútó àyíká tó wà ní ìlú Austin, Dallas, àti San Antonio ló ń ṣe kòkáárí bí àwọn tí ìṣẹ̀lẹ̀ yìí ṣàkóbá fún ṣe máa rí ìrànwọ́ gbà.
Ọ̀pọ̀ àwọn ará wa tó wà láwọn ìlú yìí ló gba àwọn ará tó wá láti Houston àti Texas Gulf Coast tí ilé wọn bà jẹ́ sílé.
Àwọn ará wa míì fi òbítíbitì oúnjẹ ránṣẹ́, wọ́n tún fi omi àtàwọn nǹkan míì tó ṣe pàtàkì ṣètìlẹ́yìn fáwọn tí ìṣẹ̀lẹ̀ náà ṣàkóbá fún.
Àwọn alábòójútó àyíká jẹ́ ká mọ̀ pé gbogbo àwọn ìjọ tó wà láwọn ìlú náà ló ti bẹ̀rẹ̀ sí í bá àwọn ìgbòkègbodò tẹ̀mí wọn nìṣó.
Àwọn tó wà nínú Ìgbìmọ̀ Ẹ̀ka ọ́fíìsì wa lóríllẹ̀-èdè Amẹ́ríkà ti ń ṣètò bí wọ́n ṣe máa lọ ṣèbẹ̀wò sáwọn àgbègbè tí ìjì náà ti ṣọṣẹ́ kí wọ́n lè tù wọ́n nínú, kí wọ́n sì ṣètìlẹ́yìn tó bá yẹ fún wọn.
David A. Semonian tó jẹ́ agbẹnusọ fún àwa Ẹlẹ́rìí Jèhófà sọ pé: “A bá àwọn tí ìjì líle Harvey ṣàkóbá fún kẹ́dùn gan-an ni, a sì tún dúpẹ́ lọ́wọ́ gbogbo àwọn tó yọ̀ǹda ara wọn láti ṣèrànwọ́ lẹ́yìn tí ìṣẹ̀lẹ̀ náà wáyé.
À ń gbàdúrà fún àwọn arákùnrin àti arábìnrin wa tí ìṣẹ̀lẹ̀ yìí ṣàkóbá fún.
A tún ń rọ̀ wọ́n pé kí wọ́n máa bá a nìṣọ́ láti gbẹ́kẹ̀ lé Jèhófà, Ọlọ́run ìfẹ́.”
Lóṣù May 2019, ìròyìn fi hàn pé ojò púpọ̀ tó rọ̀ àti ọgọ́rùn márùn-ún (500) ìjì líle tó jà ní Amẹ́ríkà ba nǹkan jẹ́ gan-an.
Ojú ọjọ́ tí kò bára dé yìí kan àwọn Ẹlẹ́rìí Jèhófà tó wà ní ìpínlẹ̀ Arkansas, Indiana, Mississippi, Missouri, Ohio, Oklahoma, Pennsylvania àti Texas.
Kò sí ìkankan lára àwon ará wa tó bá àjálù náà lọ. Àmọ́, mẹ́fà lára wọn fara pa, mẹ́rin nínú wọn sì wà nílé ìwòsàn.
Yàtọ̀ síyẹn ilé mẹ́fà àwọn ará wa ló bà jẹ́ pátápátá, ilé méjìdínlọ́gọ́rùn-ún (98) àti Gbọ̀ngàn Ìjọba méjìlá sì bà jẹ́.
Gbogbo èyí mú kí àwọn ará mẹ́rìnlélọ́gọ́rin (84) kúrò níbi tí wọ́n ń gbé.
Báwọn ará ṣe ń yẹ àwọn nǹkan tó bà jẹ́ wò, wọ́n ń pèsè oúnjẹ, omi àti ibùgbé fáwọn tọ́rọ̀ náà kàn.
Àwọn alàgbà ìjọ àtàwọn alábòójútó àyíká tó wà lágbègbè náà ń fún àwọn ará níṣìírí, wọ́n sì ń gbà wọ́n níyànjú.
A ò ní ṣíwọ́ ìrànwọ́, a ò sì ní dákẹ́ àdúrà fáwọn ará wa bí wọ́n ṣe ń fara da ìṣòro tí ìjì tó jà ti dá sílẹ̀.
Láti July 4, 2019, àwọn ìmìtìtì ilẹ̀ tó lágbára wáyé ní Gúúsù California ní agbègbè aṣálẹ̀ Mojave.
Ọ̀kan nínú àwọn ìmìtìtì ilẹ̀ náà lágbára tó 7.1 lórí ìwọ̀n, wọ́n sì gbà pé ó wà lára àwọn ìmìtìtì ilẹ̀ tó tíì lágbára jù lọ ní agbègbè yìí láti ogún (20) ọdún sẹ́yìn.
Àwọn ìmìtìtì ilẹ̀ náà wáyé nítòsí ìlú ńlá Ridgecrest níbi tí àwọn akéde igba ó lé mẹ́ẹ̀ẹ́dógún (215) ń gbé.
A dúpẹ́ pé kò sí ẹnì kankan nínú wọn tó ṣèṣe gan-an, bó tilẹ̀ jẹ́ pé àwọn akéde mẹ́ta fara pa díẹ̀.
Yàtọ̀ síyẹn, ìsọfúnni tí a gbà fi hàn pé àwọn akéde méje ló di aláìnílé mọ́.
Bákan náà, ilé méje tó jẹ́ tàwọn ará wa bà jẹ́ gan-an, tí márùndínlógójì (35) sì bà jẹ́ díẹ̀.
Ní àfikún, Gbọ̀ngàn Ìjọba méjì ló bà jẹ́ díẹ̀.
Àwọn alábòjútó àyíká méjì ló ń bojú tó ètò ìrànwọ́ fún àwọn tí àjálù bá ní agbègbè náà.
Àwọn alábòjútó àyíká yìí àti àwọn alàgbà tún ń ṣèbẹ̀wò olùṣọ́ àgùntàn sọ́dọ̀ àwọn arákùnrin àti arábínrin tí àjálù náà bá.
Àdúrà wa ni pé kí Jèhófà fún àwọn ará wa lọ́gbọ́n tí wọ́n nílò láti kojú àwọn àjálù bí èyí.​
Ọjọ́ Tí A Ṣe É: August 16 sí 18, 2019
Ibi Tí A Ti Ṣe É: Ilé Olórùlé Rìbìtì tí wọ́n ń pè ní “The Dome” tó wà ní St. Louis, Missouri, lórílẹ̀-èdè Amẹ́ríkà
Èdè: Gẹ̀ẹ́sì, Croatian
Àwọn Tó Wá: 28,122
Àwọn Tó Ṣèrìbọmi: 224
Àwọn Tó Wá Láti Ilẹ̀ Òkèèrè: 5,000
Àwọn Ẹ̀ka Ọ́fíìsì Tá A Pè: Argentina, Australasia, ilẹ̀ Gẹ̀ẹ́sì, Kánádà, Central Europe,, Kòlóńbíà, Croatia, Czech-Slovak, Finland, Faransé, Japan, Philippines, Poland, Portugal, Scandinavia, Serbia, South Africa
Ìrírí: Martin Gulley, tó jẹ́ agbẹnusọ fún iléeṣẹ́ Metrolink sọ pé:n.
“O lè sọ pé o nífẹ̀ẹ́ ẹnì kan tàbí ohun kan.
Àmọ́, ó dìgbà tó o bá fi ìfẹ́ yẹn hàn ká tó mọ̀ pé kì í ṣe ọ̀rọ̀ orí ahọ́n lásán ni.
Bí ẹ̀yin Ẹlẹ́rìí Jèhófà ṣe ń ṣe fi hàn pé lóòótọ́ lẹ nífẹ̀ẹ́.
Onírẹ̀lẹ̀ ni yín, ó ṣe tán, ìfẹ́ máa ń jẹ́ kí èèyàn rẹ ara ẹ̀ sílẹ̀ ni, kì í jẹ́ kó gbéra ga.
Báàjì tó wà láyà mi ló jẹ́ kẹ́ ẹ mọ̀ pé òṣìṣẹ́ Metrolink ni mi, àmọ́ ìfẹ́ la fi ń dá ẹ̀yin Ẹlẹ́rìí Jèhófà mọ̀.”
Jerry Vallely ni ọ̀gá àgbà tó jẹ́ agbẹnusọ fún ilé-iṣẹ́ Bi-State Development (ìyẹn, àjọ elétò ìrìnnà kan tó ń rí sí ìdàgbàsókè ọrọ̀-ajé ní agbègbè St. Louis). Ó sọ pé:
“Ìṣẹ́ tí ẹ̀ ń ṣe kọ́ ló jẹ́ bàbàrà fún un yín, ohun tó jẹ yín lógún ni àǹfààní táwọn èèyàn máa rí látinú iṣẹ́ náà, ìyẹn àwọn àlejò tó ń bọ̀, àwọn tí ẹ̀ ń bá ṣiṣẹ́ nínú ìlú, àti àwa òṣìṣẹ́ Metrolink tí a wà níbí.
Ẹ̀ n ronú nípa bí inú gbogbo àwọn tí ẹ̀ ń bá ṣiṣẹ́ ṣe máa dùn, bí gbogbo nǹkan ṣe máa gún régé, tá á sì sunwọ̀n sí i.”
Ní November 30, 2018, ìmìtìtì ilẹ̀ tó lágbára ṣẹlẹ̀ nítòsí ìlú Anchorage, ìpínlẹ̀ Alaska.
Bí ó tiẹ̀ jẹ́ pé kò sẹ́ni tó bá ìmìtìtì ilẹ̀ náà lọ, àwọn oníròyìn sọ pé ó ba àwọn ọ̀nà jẹ́ gan-an.
Ẹ̀ka ọ́fíìsì wa ní Amẹ́ríkà ròyìn pé àwọn akéde méje fara pa díẹ̀ nígbà tí ìṣẹ̀lẹ̀ yìí wáyé.
Ilé mẹ́rìndínlógún (16) àwọn ará wa àti Gbọ̀ngàn Ìjọba méjì ló bà jẹ́.
Àwọn alábòójútó àyíká ṣètò bí àwọn ìjọ á ṣe máa pèsè oúnjẹ, aṣọ omi àti ilé fún àwọn ará tó nílò wọn.
Yàtọ̀ síyẹn, àwọn alàgbà tó wà lágbègbè náà ń fi Bíbélì tu gbogbo àwọn tí àjálù náà kàn nínú.
À ń rántí àwọn ará wa tí ìmìtìtì ilẹ̀ yìí kàn nínú àdúrà wa.
Ó dá wa lójú pé Jèhófà máa jẹ́ agbára àti ibi ààbò fún àwọn èèyàn rẹ̀ bí wọ́n ṣe ń gbẹ́kẹ̀ lé e.
Arákùnrin Albert Barnett àti ìyàwó rẹ̀, Arábìnrin Susan Barnett, ń dara pọ̀ mọ́ ìjọ West nílùú Tuscaloosa, ìpínlẹ̀ Alabama Ní January 11 àti 12, 2020, Ìjì lílé kan jà, ó sì ṣọṣẹ́ làwọn agbègbè kan ní orílẹ̀-èdè Amẹ́ríkà.
Ọṣẹ́ kékeré kọ́ ní àrọ̀ọ̀rọ̀dá òjò, ìjì tó fẹ́ atẹ́gùn àti ìjì líle tó ṣẹlẹ̀ fún odindi ọjọ́ méjì ṣe ní ọ̀pọ̀ ìpínlẹ̀ lórílẹ̀-èdè yẹn.
Ó bani nínú jẹ́ pé Arákùnrin Albert Barnett ẹni ọdún márùndínláàádọ́rùn-ún (85) àti ìyàwó rẹ̀, Arábìnrin Susan Barnett, tó jẹ́ ẹni ọdún márùndínlọ́gọ́rin (75) kú nígbà tí ìjì líle náà kọlu ilé wọn.
Ẹ̀ka ọ́fíìsì orílẹ̀-èdè Amẹ́ríkà ròyìn pé, ó kéré tán ilé àwọn ará wa mẹ́rin àti Gbọ̀ngàn Ìjọba méjì ni ìjì náà kọlù, àmọ́ àwọn ilé náà kò fi bẹ́ẹ̀ bà jẹ́ púpọ̀.
Yàtọ̀ síyẹn, ìjì líle náà ba ilé tí arákùnrin wa kan ti ń tajà jẹ́ gan-an.
Àwọn alàgbà àtàwọn alábòójútó àyíká ń ṣe gbogbo ohun tí wọ́n lè ṣe láti ṣèrànwọ́ fáwọn tí àjálù náà bá, wọ́n sì ń fún wọn níṣìírí látinú Bíbélì.
A mọ̀ pé Baba wa ọ̀run Jèhófà ń pèsè ìtùnú fáwọn arákùnrin àtàwọn arábìnrin wa tó ń ṣọ̀fọ̀ nítorí àjàlù yìí.​
Ìjì líle tó ń jẹ́ Dorian ni ìjì tó lágbára jùlọ tó tíì jà lórí Òkun Àtìláńtíìkì. Erékùṣù Abaco lápá àríwá Bahamas ló ti wáyé láàárọ̀ Sunday September 1, 2019.
Ohun tó mú kí ìjì lílé Dorian burú gan-an ni pé, ìjì náà kìí sáré, ó máa ń fẹ́ atẹ́gùn tó le, àrọ̀ọ̀rọ̀dá òjò sì máa ń rọ̀.
Ìjì náà fẹ́ lọ sí erékùṣù Leewards Islands lórílẹ̀-èdè Puerto Rico àti erékùṣù Virgin Islands, àmọ́ kò fi bẹ́ẹ̀ ṣọṣẹ́ púpọ̀ níbẹ̀.
Ẹ̀ka ọ́fíìsì orílẹ̀-èdè Amẹ́ríkà ń kó ìsọfúnni jọ nípa bí ìjì líle náà ṣe ṣèpalára fáwọn ará wa àtàwọn dúkìá ètò Ọlọ́run.
Ìròyìn tó tó wa létí báyìí ni pé kò sí akéde kankan tó fara pa nínú àwọn akéde mẹ́rìndínláàádọ́ta (46) tó wà ní ìjọ méjì tó wà ní erékùṣù Great Abaco Island.
Àmọ́, ìjì náà ti ba Gbọ̀ngàn Ìjọba kan ṣoṣo tó wà ní erékùṣù náà jẹ́.
Ìjọ mẹ́rin ló wà ní erékùṣù Grand Bahama Island, wọ́n sì ní ọgọ́rùn-ún mẹ́ta àti mẹ́rìnlélọ́gọ́ta (364) akéde.
Ìròyìn tá a kọ́kọ́ gbọ́ ni pé àwọn arákùnrin àtàwọn arábìnrin tó tó igba ó dín mẹ́rin (196) ló sá fi ilé wọ́n sílẹ̀, ilé méjìlélógún (22) ló bà jẹ́ díẹ̀.
Ilé mẹ́ta ló sì bà jẹ́ kọjá àtúnṣe.
Ẹ̀ka ọ́fíìsì ti fún àwọn alábòójútó àyíká àtàwọn alàgbà tó wà níbi tí àjálù náà ti ṣẹlẹ̀ ní ìtọ́ni kí ìjì náà tó wáyé.
Ẹ̀ka ọ́fíìsì sọ fáwọn ará pé kí wọ́n kó lọ sí olú ìlú Nassau tàbí agbègbè míì tí kò léwu.
Gbogbo ìgbà là ń gbàdúrà fáwọn arákùnrin àtàwọn arábìnrin wa tó wà níbi tí ìjì líle yìí ti ṣọṣẹ́.
A mọ̀ pé Jèhófà ń rí ìyà tó ń jẹ wọ́n, ó sì máa fún wọn lókun tá á jẹ́ kí wọ́n lè fara da àkókò wàhálà yìí.​
Ní October 10, 2018, ìjì líle kan tí wọ́n pè ní Michael jà ní ìpínlẹ̀ Florida lórílẹ̀-èdè Amẹ́ríkà, ó sì ba nǹkan jẹ́ gan-an láwọn ìpínlẹ̀ tó wà ní gúúsù ìlà oòrùn Ilẹ̀ Amẹ́ríkà.
Ìjì yìí le gan-an, wọ́n sì sọ pé ó wà lára àwọn ìjì tó le jù tó tíì jà lórílẹ̀-èdè Amẹ́ríkà, tó sì ba ọ̀pọ̀lọpọ̀ nǹkan jẹ́.
Ìjì líle yìí tún pa ó kéré tán, èèyàn méjìdínlógún (18).
Ìjì líle yìí kan àwọn ará wa ní ìjọ mẹ́rìnléláàádọ́rùn-ún (94) àti àyíká mẹ́tàlá (13).
Kò sí ìkankan lára àwọn ará wa tó kú nínú àjálù yìí, àmọ́ àwọn mẹ́ta fara pa.
Ọgọ́rùn-ún márùn-ún ó lé méjìdínlọ́gbọ̀n (528) ilé àwọn ará wa àti Gbọ̀ngàn Ìjọba mẹ́rìnlélọ́gbọ̀n (34) ni ìjì yìí bà jẹ́, bákan náà, ó ba iná jẹ́ ní Gbọ̀ngàn Ìjọba mọ́kàndínlógójì (39).
Ẹ̀ka Ọ́fíìsì wa lórílẹ̀-èdè Amẹ́ríkà àti Ìgbìmọ̀ Tó Ń Ṣètò Ìrànwọ́ Nígbà Àjálù ń ṣiṣẹ́ pẹ̀lú ogójì (40) alábòójútó àyíká láti ṣètò ohun táwọn ará nílò.
Iṣẹ́ yìí gba pé kí wọ́n pèsè oúnjẹ, oògùn, ilé àti omi fáwọn ará, kí wọ́n ta tapolíìnì sórí ilé wọn, kí wọ́n sì palẹ̀ mọ́ gbogbo pàǹtírí táwọn igi tó wó lu nǹkan dá sílẹ̀.
Wọ́n tún ṣètò láti ṣèrànwọ́ fáwọn ará nípa tẹ̀mí, kí wọ́n sì ṣèbẹ̀wò olùṣọ́ àgùntàn sọ́dọ̀ wọn.
Bó tiẹ̀ jẹ́ pé àwọn ohun burúkú tó ń ṣẹlẹ̀ nínú ayé yìí, títí kan àwọn ìṣòro tí àjálù ń fà, ń kan àwọn ará wa, wọ́n gbẹ́kẹ̀ lé Ọlọ́run pátápátá pé á máa ran àwọn lọ́wọ́.
Déètì: July 12-14, 2019
Ibi Tá A Ti Ṣe É: Pápá Ìṣeré NRG ní Houston, ìpínlẹ̀ Texas, lórílẹ̀-èdè Amẹ́ríkà
Èdè: Gẹ̀ẹ́sì àti Korean
Àwọn Tó Wá: 50,901
Àwọn Tó Ṣèrìbọmi: 401
Àwọn Tó Wá Láti Ilẹ̀ Òkèèrè: 5,000
Àwọn Ẹ̀ka Ọ́fíìsì Tá A Pè: Australasia, Belgium, Brazil, Britain, Kánádà, Kòlóńbíà, Czech-Slovak, Faransé, Íńdíà, Ítálì, Japan, Kòríà, Philippines àti Scandinavia
Ìrírí: Inú Sylvester Turner tó jẹ́ olórí ìlú Houston dùn láti rí ẹgbẹ̀rún lọ́nà àádọ́ta (50,000) àwọn Ẹlẹ́rìí Jèhófà àtàwọn àlejò tó wá sí ìlú Houston fún àpéjọ náà.
Ó sọ pé: “A ò lè sọ bí inú wa ṣe dùn tó torí ńṣe lara tù wa pẹ̀sẹ̀.
Ìdí nìyẹn tí a fi gbà wọ́n tọwọ́tẹsẹ̀.
Tẹ́yin Ẹlẹ́rìí Jèhófà bá lè máa wá lẹ́ẹ̀mejì lọ́dún, tayọ̀tayọ̀ là á máa kí i yín káààbọ̀ sí ilú Houston.
Àá ma retí yín lọ́dún tó ń bọ̀ àtèyí tó tẹ̀ lé e.
Ìròyìn Lọ́ọ́lọ́ọ́: Ó ṣeni láàánú pé ẹ̀ka ọ́fíìsì wa lórílẹ̀-èdè Amẹ́ríkà ti rí àrídájú pé iná Camp Fire tún gbẹ̀mí arákùnrin kan tó jẹ́ ẹni àádọ́rin (70) ọdún tó wá láti ìlú Paradise, ní agbègbè àríwá ìpínlẹ̀ California.
Ó kéré tán, èèyàn méjìdínláàádọ́ta (48) ló kú látàrí iná runlérùnnà tó jó lẹ́ẹ̀mẹta ní ìpínlẹ̀ California lrílẹ̀-èdè Amẹ́ríkà, ọ̀pọ̀lọpọ̀ nǹkan ló sì bà jẹ́.
Èyí tó le jù nínú iná mẹ́tẹ̀ẹ̀ta ni wọ́n ń pè ní iná Camp Fire, iná yìí ṣì ń jo lọ ní àríwá California, ó ti jó ibi tó fẹ̀ tó ẹgbẹ̀rún mẹ́tàdínlọ́gọ́fà (117,000) éékà, nǹkan bí ẹgbẹ̀rún méje ó lé ọgọ́rùn-ún kan (7,100) ilé ló ti run, ilé gbígbé ló sì pọ̀ jù níbẹ̀.
Ní gúúsù ìpínlẹ̀ California, ẹ̀ẹ̀mejì ni iná jó, wọ́n pe ọ̀kan ní Hill Fire, ìkejì Woolsey Fire, iná méjèèjì yìí jó ibi tó fẹ̀ tó éékà ẹgbẹ̀rún lọ́nà àádọ́rùn ó lé mẹ́rin àtààbọ̀ (94,500), ilé tó sì run tó ọgọ́rùn-ún mẹ́rin ó lé márùndínlógójì (435).
Ìròyìn kan sọ pé, tá a bá pa orílẹ̀-èdè Belgium àti Luxembourg pọ̀, kò tíì tó gbogbo ibi tí iná jó ní ìpínlẹ̀ California.
Ìròyìn tá a kọ́kọ́ gbọ́ láti ẹ̀ka ọ́fíìsì wa lórílẹ̀-èdè Amẹ́ríkà ni pé iná Camp Fire lé àwọn akéde tó tó ọgọ́rùn-ún mẹ́rin àti mẹ́tàdínlọ́gbọ̀n (427) kúrò nílùú Chico àti Paradise.
Ó dùn wá pé iná yẹn pa arábìnrin àgbàlagbà kan láti Ìjọ Ponderosa.
A tún rí àrídájú pé lọ́wọ́lọ́wọ́ báyìí, ó kéré tán, mẹ́rìnléláàádọ́rùn-ún (94) ilé àwọn ará wa ni iná yẹn ti run, òmíì nínú wọn sì ti bà jẹ́ gidi gan-an.
Gbọ̀ngàn Ìjọba kan tó wà nílùú Paradise náà run pátápátá.
Nǹkan bí akéde ọgọ́rùn-ún mẹ́rin ó lé ogún (420) tó ń gbé nílùú Oxnard, Simi Valley àti Thousand Oaks ló ti kúrò nílùú nítorí àwọn iná tó jó yìí.
Ó ṣeni láàánú pé arákùnrin kan àti ìyá rẹ̀ tí kì í ṣe Ẹlẹ́rìí kú nílùú Malibu níbi tí wọ́n ti ń sá fún iná náà.
Ìròyìn tá a kọ́kọ́ gbọ́ fi hàn pé ilé mọ́kànlélógún (21) àwọn ará wa ló bà jẹ́, tó fi mọ́ Gbọ̀ngàn Ìjọba kan. Ẹ̀ka ọ́fíìsì dá Ìgbìmọ̀ Tó Ń Ṣètò Ìrànwọ́ Nígbà Àjálù méjì sílẹ̀, kí wọ́n lè pèsè ohun táwọn ará wa nílò.
Àwọn alábòójútó àyíká ṣètò àwọn alàgbà láti lọ ṣèbẹ̀wò sọ́dọ̀ àwọn akéde tí iná yìí ṣe ní jàǹbá, kí wọ́n sì pèsè ìrànwọ́ nípa tara fún àwọn tí àjálù náà dé bá.
Ní Saturday, November 10, wọ́n ṣe àkànṣe ìpàdé kan nílùú Chico fún àwọn ará tó lé ní igba àti àádọ́rin (270).
Ọ̀kan lára Ìgbìmọ̀ Ẹ̀ka Orílẹ̀-èdè Amẹ́ríkà àtàwọn alábòójútó àyíká fi Ìwé Mímọ́ fún àwọn ará ibẹ̀ níṣìírí.
Àdúrà wa ni pé kí Jèhófà tu àwọn ará wa tó ń kojú ìṣòro tó nira yìí nínú, kó sì fún wọn lókun.
A tún gbàdúrà pé kí wọ́n máa rántí pé láìpẹ́, Jèhófà máa nu gbogbo omijé wa kúrò, á sì gbé ikú mì títí láé.​
Déètì: May 17 sí 19, 2019
Ibi Tá A Ti Ṣe É: Pápá Ìṣeré Mercedes-Benz Stadium nílùú Atlanta, ìpínlẹ̀ Georgia, Amẹ́ríkà
Èdè: Amharic, Gẹ̀ẹ́sì, Russian
Àwọn Tó Wá: 46,374
Àwọn Tó Ṣèrìbọmi: 314
Àwọn Tó Wá Láti Ìlẹ̀ Òkèèrè: 5,000
Áwọn Ẹ̀ka Ọ́fíísì Tó Wá: Australasia, Brazil, Britain, Kánádà, Chile, Kòlóńbíà, Etiópíà, Finland, ilẹ̀ Faransé, Gíríìsì, Hong Kong, Israel, Ítálì, Japan, Kazakhstan, Netherlands, Pọ́túgà, Ròmáníà, Scandinavia, Trinidad and Tobago
Èyí ni àkọ́kọ́ lára ìtọ́wò mẹ́rìnlélógún (24) àwọn àpéjọ àgbáyé ọdún 2019 tá a máa gbé sí abala Ìròyìn lórí ìkànnì jw.org/yo bí àpéjọ kọ̀ọ̀kan bá ṣe ń parí.
Láti May 3, 2018, òkè ayọnáyèéfín Kilauea tó ń bú gbàù ní Erékùṣù Ńlá Hawaii lórílẹ̀-èdè Amẹ́ríkà ti lé àwọn tó fẹ́rẹ̀ẹ́ tó ẹgbẹ̀rún méjì (2,000) kúrò nílé wọn, ó sì ti ba, ó kéré tán, ilé mẹ́rìndínlógójì (36) jẹ́.
Ara àwọn tó ti kúrò nílé wọn ni ìdílé Ẹlẹ́rìí Jèhófà mẹ́rin àti arábìnrin àgbàlagbà kan.
Bó tiẹ̀ jẹ́ pé àwọn nǹkan gbígbóná tó ń ru jáde látinú òkè yẹn ò ba Gbọ̀ngàn Ìjọba kankan jẹ́, ìmìtìtì ilẹ̀ kan tó wáyé ní May 4 ba Gbọ̀ngàn Ìjọba kan jẹ́ díẹ̀.
Ìgbìmọ̀ Tó Ń Ṣètò Ìrànwọ́ Nígbà Àjálù àtàwọn ará lọ́kùnrin lóbìnrin tó wà nílùú yẹn ń bójú tó àwọn akéde tọ́rọ̀ náà kàn.
Tí nǹkan bá ti lójú déwọ̀n àyè kan, ìgbìmọ̀ náà máa pinnu ìrànwọ́ míì táwọn akéde náà bá tún máa nílò.
A ò dákẹ́ àdúrà lórí àwọn ará wa lọ́kùnrin lóbìnrin tọ́rọ̀ kàn torí àjálù tó ń ṣẹlẹ̀ lọ́wọ́ yìí, ó dá wa lójú pé Jèhófà máa jẹ́ odi agbára wọn lásìkò wàhálà yìí.
Déètì: July 5 sí 7, 2019
Ibi Tá A Ti Ṣeé: Marlins Park ní Miami, Florida, Lórílẹ̀-èdè Amẹ́ríkà
Èdè: Gẹ̀ẹ́sì àti Chinese Mandarin
Àwọn Tó Wá: 28,000
Àwọn Tó Ṣèrìbọmi: 181
Àwọn Tó Wá Láti Ilẹ̀ Òkèèrè: 5,000
Àwọn Ẹ̀ka Ọ́fíìsì Tá A Pè: Australasia, Brazil, Britain, Kánádà, Kòlóńbíà, Dominican Republic, Fíjì, Gánà, Gírí ìsì, Hong Kong, Israel, Japan, Netherlands, Scandinavia, South Africa, Sípéènì, Taiwan, Trinidad and Tobago, Ukraine
Ìrírí: Alákòóso ìlú Miami tórúkọ rẹ̀ ń jẹ́ Francis X. Suarez wá sí àpéjọ náà lọ́jọ́ Sunday, ó sì sọ pé: “Inú mi dùn pé ‘Ìfẹ́ Kì Í Yẹ̀ Láé’! ni àkòrí àpéjọ tẹ́ ẹ ṣe yìí. Àkòrí yẹn tuni lára gan-an.”
"Ó wá fi kún un pé: “Ó máa dáa tẹ́ ẹ bá lè ṣe irú àpéjọ yìí láwọn ìlú tó wà ní Amẹ́ríkà àti láwọn ibòmíì kárí ayé.”"""
Àwọn panápaná ṣì ń bá iná runlérùnnà jà ní Southern California, iná yìí ti jó ibi tó lé ní ẹgbẹ̀rún lọ́nà ọgọ́rùn-ún méjì àti ààbọ̀ [250,000] éékà ní àwọn àgbègbè mẹ́fà bíi Los Angeles, Riverside, San Diego, Santa Barbara, àti Ventura.
Ìròyìn tá a kọ́kọ́ gbọ́ jẹ́ ká mọ̀ pé àwọn akéde ọgọ́rùn-ún mẹ́rin, àti àádọ́rin lé mẹ́rin [484] ti sá kúrò nílé, wọ́n sì lọ ń gbé pẹ̀lú àwọn arákùnrin míì tàbí pẹ̀lú àwọn mọ̀lẹ́bí wọn tó ń gbé ní apá ibi tí àlááfíà wà.
Yàtọ̀ síyẹn, mẹ́fà nínú ilé àwọn arákùnrin wa ló jóná, ilé mẹ́ta míì sì bàjẹ́.
Àwọn alàgbà àti àwọn alábòójútó àyíká ń fi Ọ̀rọ̀ Ọlọ́run pèsè ìtùnú fún àwọn ará wa ti àjálù náà bá, wọ́n sì tún ń bójú tó àìní wọn nípa tara
Gbogbo ìgbà là ń gbàdúrà fún àwọn arákùnrin àti arábìnrin wa, a sì tún fojú sọ́nà fún ìgbà tí ọ̀rọ̀ tó wà nínú Òwe 1:33 máa ní ìmúṣẹ:
“Ní ti ẹni tí ń fetí sí mi, yóò máa gbé nínú ààbò, yóò sì wà láìní ìyọlẹ́nu lọ́wọ́ ìbẹ̀rùbojo ìyọnu àjálù.”
Agbẹnusọ fún Àwa Ẹlẹ́rìí Jèhófà: David A. Semonian, Ọ́fíìsì Agbéròyìnjáde, +1-845-524-3000
Ìjì líle kan tó mi ilẹ̀ tìtì wáyé ní September 5, 2017, ó sì wà lára àwọn ìjì líle tó lágbára jù lọ tó wáyé ní àgbègbè Òkun Àtìláńtíìkì.
Ó ti ba ọ̀pọ̀ àwọn erékùṣù tó wà ní agbègbè Caribbean jẹ́.
Títí di báyìí, a kò tíì gbọ́ pé ẹnì kankan nínú àwọn arákùnrin àtàwọn arábìnrin wa ṣèṣe tàbí pé wọ́n kú nínú ìṣẹ̀lẹ́ yìí.
Gbọ̀ngàn Ìjọba kan tó wà ní La Désirade, Guadeloupe; Gbọ̀ngàn Ìjọba kan ní St. Barts àti Gbọ̀ngàn Àpéjọ kan ní St. Martin la gbọ́ pé ìjì líle náà bà jẹ́.
Ìjì líle náà ṣọṣẹ́ lọ́nà tó le gan-an ní erékùṣù Barbuda, bí ìdajì àwọn tó ní ilé ní erékùṣù náà ni kò nílé lórí mọ́.
Gbogbo àwọn tó ń gbé níbẹ̀, tó fi mọ́ àwọn arákùnrin wa mọ́kànlá [11] ni ìjọba ti sọ fún pé kí wọ́n tètè kúrò ní àgbègbè yẹn, kí wọ́n máa lọ sí Antigua torí wọ́n fura pé ìjì líle míì tí wọ́n pè ní José tún máa jà ní agbègbè Caribbean yẹn ní òpin ọ̀sẹ̀.
Ọ̀pọ̀ nǹkan ní àwọn arákùnrin tó wà lágbègbè yẹn ti ṣe kí wọ́n lè fi àwọn nǹkan kòṣeémánìí ránṣẹ́ sí àwọn ará bí ìjì líle tí wọ́n pè ní Irma ṣe ń jà lọ sí apá gúùsù Bahamas, Cuba àti gúúsù ìlà oòrùn orílẹ̀-èdè Amẹ́ríkà.
Ara ohun tí wọ́n ṣe ni pé wọ́n ti ń ṣètò ilé sílẹ̀ fún àwọn ará tó ṣeé ṣe kí ìjì náà ba ilé wọn jẹ́.
Agbẹnusọ fún àwa Ẹlẹ́rìí Jèhófà: David A. Semonian, Ọ́fíìsì Agbéròyìnjáde, +1-845-524-3000
A gbọ́ròyìn nípa bí nǹkan ṣe ń lọ sí fún àwọn arákùnrin àtàwọn arábìnrin wa tó wà ní àgbègbè Caribbean àti gúúsù ìlà oòrùn Amẹ́ríkà lẹ́yìn tí ìjì líle Hurricane Irma ṣoṣẹ́.
Ó dùn wá gan-an pé arákùnrin àgbàlagbà kan nílùú Florida àti arábìnrin kan ní Georgia kú sínú ìṣẹ̀lẹ̀ náà.
Bákan náà, àwọn arákùnrin méjì fara pa ní ìlú Tortola.
Ilé àwọn ará wa tó bà jẹ́ ní gbogbo àgbègbè Caribbean lé ní ogójì [40], ó kéré tán àwọn arákùnrin wa tí iye wọn jẹ́ ogójì [40] ló ti sá kúrò nílé wọn.
Àwọn ará wa ṣì ń bá iṣẹ́ nìṣó láti mọ bí nǹkan ṣe ń lọ sí láwọn àgbègbè míì tí ìjì yẹn ti ṣọṣẹ́.
A kẹ́dùn gan-an pẹ̀lú àwọn tí èèyàn wọn kú sínú ìṣẹ̀lẹ̀ náà, tó fi mọ́ ọ̀pọ̀ àwọn míì tí ìṣẹ̀lẹ̀ náà ṣàkóbá fún láwọn ọ̀nà míì.
A nígbàgbọ́ pé Jèhófà á máa tù wá nínú nìṣó nípasẹ̀ ìjọ rẹ̀.
Agbẹnusọ fún Àwa Ẹlẹ́rìí Jèhófà: David A. Semonian, Ọ́fíìsì Agbéròyìnjáde, +1-845-524-300
Iná ńlá kan tó sọ ní July 23, 2018 ṣì ń jó nítòsí agbègbè Redding, ní ìpínlẹ̀ California títí di báyìí.
Orúkọ ibi tí iná yìí ti sọ ni wọ́n fi pe iná náà, ó ti pa èèyàn mẹ́jọ, ó sì lé ní ẹgbẹ̀rún lọ́nà ọgọ́rùn-ún ó lé mẹ́wàá (110,000) éékà ilẹ̀ tó ti jó, kódà àwọn ilé tó bà jẹ́ lé ní ẹgbẹ̀rún kan ó lé ọgọ́rùn-ún mẹ́ta (1,300).
Kò sí ìkankan lára àwọn akéde tó ń gbé láwọn ibi tí iná ti ṣọṣẹ́ yìí tó fara pa kọjá bó ṣe yẹ, bó tiẹ̀ jẹ́ pé iná náà jó arákùnrin wa kan lára níbi tó ti ń fi ọkọ̀ katapílà lànà fáwọn panápaná kí wọ́n lè ríbi kápá iná náà.
Bákan náà, ọgọ́rùn-ún mẹ́rin àti àádọ́ta ó lé mẹ́rin (454) akéde wa lọ́kùnrin lóbìnrin ni wọ́n kúrò níbi tí wọ́n ń gbé, tí wọ́n sì lọ sọ́dọ̀ àwọn mọ̀lẹ́bí wọn tàbí sọ́dọ̀ àwọn ará fúngbà díẹ̀.
Iná náà ba ilé ìdílé méjìlá jẹ́ lára àwọn ará wa.
Gbogbo àwọn akéde la ti gbúròó wọn, àwọn alábòójútó àyíká pẹ̀lú àwọn alàgbà ìjọ sì ń ṣètò bí wọ́n ṣe máa pèsè ohun táwọn ará nílò nípa tara àti nípa tẹ̀mí lásìkò wàhálà yìí.​
Ìgbìmọ̀ Ẹ̀ka orílẹ̀-èdè Amẹ́ríkà ti fún wa láwọn ìsọfúnni yìí nípa àwọn arákùnrin wa tí ìjàǹbá iná ṣẹlẹ̀ sí ní Northern California àti iná igbó tó ń yára ṣọṣẹ́ gan-an ní Southern California.
Northern California: Ẹ̀ka ọ́fíìsì orílẹ̀-èdè Amẹ́ríkà ti kàn sí àwọn alábòójútó àyíká tó wà lágbègbè Mendocino, Napa àti Sonoma, wọ́n sì sọ fún wa pé gbogbo àwọn ará wa ti kúrò níbi tó léwu, bó tilẹ̀ jẹ́ pé akéde kan fara pa.
Àwọn ará tó tó ọgọ́rùn-ún méje (700) ti fi ilé wọn sílẹ̀, àwọn ẹgbẹ̀rún méjì (2,000) sì ti múra tán láti lọ tó bá ṣẹlẹ̀ pé ipò nǹkan burú sí i.
Àwọn ará tó wà níbi tí kò séwu ti gba àwọn tó sá kúrò níbi tí ewu wà sílé wọn.
A gbọ́ pé Gbọ̀ngàn Ìjọba kan àti ilé àwọn ará mẹ́ta ló bà jẹ́ pátápátá.
Láfikún sí i, ilé méjìlélógún (22) ló bà jẹ́ gan-an, ilé méjìlélọ́gbọ̀n (32) sì bà jẹ́ díẹ̀.
Àwọn alábòójútó àyíká ń mú ipò iwájú láti fún àwọn ará ní ìṣírí àti ìtìlẹ́yìn tí wọ́n nílò.
Southern California: Lágbègbè Anaheim, ìdílé àwọn Ẹlẹ́rìí mẹ́ẹ̀ẹ́dọ́gbọ̀n (25) ni wọ́n ti sá kúrò nílé wọn, àmọ́ kò sẹ́nì kankan tó fara pa.
Àwọn ará tó wà níbí tí kò léwu ti gba gbogbo àwọn ará yìí sílé wọn.
Kò sí ilé àwọn ará tàbí Gbọ̀ngàn Ìjọba kankan tó bà jẹ́.
Ó dá wa lójú pé Jèhófà máa jẹ́ “ibi gíga ààbò” fún gbogbo àwọn tọ́rọ̀ kàn lásìkò wàhálà yìí.
Ní June 24, 2019, ìjì líle àti òjò àrọ̀ọ̀rọ̀dá ṣọṣẹ́ gan-an ní gúúsù Texas.
Ìròyìn fi hàn pé ọgọ́rọ̀ọ̀rún ilé ni ọ̀gbàrá òjò náà bà jẹ́, ó sì ju ọgọ́rùn-ún èèyàn tí wọ́n kó kúrò lágbègbè náà.
Bó tilẹ̀ jẹ́ pé kò sí akéde kankan tó fara pa nibi ìjì náà, àmọ́ àkéde mẹ́tàdínláàádọ́ta (47) ni ò nílé mọ́ rárá.
Yàtọ̀ síyẹn, ìjì náà ba ilé àwọn ará márùndínláàádọ́rin (65) jẹ́, ó sì tún bá ilé kan tá a kọ́ mọ́ Gbọ̀ngàn Ìjọba kan jẹ́.
Àwọn alábòójútó àyíká àtàwọn alàgbà ń ṣèbẹ̀wò sọ́dọ̀ àwọn ará tí àjálù náà bá.
Bákan náà, Ìgbìmọ̀ Tó Ń Ṣètò Ìrànwọ́ Nígbà Àjálù ti ń ṣètò ilé, oúnjẹ, omi àti aṣọ fáwọn ará.
Yàtọ̀ síyẹn, iṣẹ́ ń lọ lórí àtúnṣe àwọn ilé àti Gbọ̀ngàn Ìjọba tó bà jẹ́.
A ò ní fi àwọn arákùnrin àtàwọn arábìnrin wa ní gúúsù Texas sílẹ̀, inú wa dùn pé Jèhófà ni wọ́n gbára lé, ó sì dájú pé á ràn wọ́n lọ́wọ́ láti fara da àjálù yìí.​
Ọgbà ẹ̀wọ̀n méjì tó wà ní Palm Beach County, ní Florida ṣe àtagbà àsọyé Ìrántí Ikú Kristi àwọn tó lé ní ẹgbẹ̀rún kan ó lé ọgọ́rùn-ún (1,100) èèyàn tó wà nínú ọgbà ẹ̀wọ̀n nírọ̀lẹ́ April 7, bó tiẹ̀ jẹ́ pé kò sí Ẹlẹ́rìí Jèhófà kankan tó lè lọ síbẹ̀ láti darí ìtòlẹ́sẹẹsẹ náà.
Ọ̀kan lára àwọn méjìlá (12) tó máa ń lọ wàásù lọ́gbà ẹ̀wọ̀n lọ́sọ̀ọ̀sẹ̀ sọ pé: “Ó yà wá lẹ́nu gan-an pé gbogbo ètò náà lọ dáadáa bó ṣe yẹ.
Kò sí àní-àní pé Jèhófà fẹ́ káwọn tó wà lẹ́wọ̀n yìí gbọ́ àsọyé Ìrántí Ikú Kristi.” Àwọn ará ti gbàṣẹ lọ́dọ̀ alábòójútó ọgbà ẹ̀wọ̀n tó wà níbẹ̀ láti sọ àsọyé Ìrántí Ikú Kristi láwọn ọgbà ẹ̀wọ̀n méjì yìí.
Àmọ́ kò ṣeé ṣe mọ́ torí òfin tí Ìjọba ṣe nípa àrùn COVID-19 tó ń jà.
Ṣùgbọ́n káwọn ará tó rí ojútùú sí ọ̀rọ̀ náà, alábòójútó ọgbà ẹ̀wọ̀n náà bi wọ́n pé ṣé wọ́n lè fún òun ní àsọyé Ìrántí Ikú Kristi tí wọ́n ti gbohùn ẹ̀ sílẹ̀.
Ó ti ṣètò bí wọ́n ṣe máa ta àtagbà àsọyé náà ní ọgbà ẹ̀wọ̀n méjèèjì.
Yàtọ̀ sí fídíò yẹn, àwọn arákùnrin yẹn ti ń ṣètò bí wọ́n ṣe máa fi ìkésíni Ìrántí Ikú Kristi ránṣẹ́ sí alábòójútó ọgbà ẹ̀wọ̀n náà kó lè fún àwọn ẹlẹ́wọ̀n tàbí kó lẹ̀ ẹ́ sójú pátákó fún wọn.
Àmọ́, ó tún yà wọ́n lẹ́nu lẹ́ẹ̀kan sí i pé alábòójútó ọgbà ẹ̀wọ̀n náà ti lẹ ìsọfúnni nípa Ìrántí Ikú Kristi káàkiri àwọn ọgbà ẹ̀wọ̀n náà.
Nígbà tó máa fi di ìrọ̀lẹ́ ọjọ́ Ìrántí Ikú Kristi, gbogbo àwọn tó wà nínú ẹ̀wọ̀n ló ti láǹfààní láti wo àsọyé yẹn.
Lẹ́yìn Ìrántí Ikú Kristi, alábòójútó ọgbà ẹ̀wọ̀n yẹn sọ fún àwọn ará pé kí wọ́n fún òun ní Bíbélì tó pọ̀ sí i kóun lè fún àwọn tó wà nínú ẹ̀wọ̀n.
Gbogbo Bíbélì tí wọ́n kó sí ọgbà ẹ̀wọ̀n ni wọ́n ti gbà tán.
Kódà, Bíbélì náà ò kárí àwọn tó ń béèrè fún un.
Inú wa dùn pé kò sóhun tó lè ní káwọn èèyàn má gbọ́rọ̀ Ọlọ́run, kódà ọgbà ẹ̀wọ̀n gan-an ò dí i lọ́wọ́.​
NEW YORK​—Lẹ́yìn tí ìjì líle tí wọ́n ń pè ní Hurricane Harvey jà, tó sì sọlẹ̀ ní tòsí àgbègbè Corpus Christi ní August 25, 2017, ràbọ̀ràbọ̀ ẹ̀ ti ń tán lára àwọn tó ń gbé nílùú Texas lórílẹ̀-èdè Amẹ́ríkà.
Ìgbìmọ̀ méjì tó ń ṣètò ìrànwọ́ nígbà àjálù ló ń darí bí ẹgbẹẹgbẹ̀rún àwọn ará lọ́kùnrin àti lóbìnrin tí àjálù ṣẹlẹ̀ sí ṣe máa rí ìrànwọ́ gbà.
Arákùnrin kan ń wá àwọn Ẹlẹ́rìí Jèhófà níbì kan tí wọ́n ti ń ṣètò ìrànwọ́ ní Houston, nílùú Texas.
Ó lé ní ẹgbẹ̀rún méje [7,000] èèyàn tó yọ̀ǹda ara wọn láti ṣèrànwọ́ nígbà tí wọ́n kọ́kọ́ bẹ̀rẹ̀ àtúnṣe gbàrà tí ìjì náà jà tán. Ara ibi tí wọ́n tún ṣe ni ilé àwọn akéde tó jẹ́ ẹgbẹ̀rún méjì àti ọgọ́rùn-ún mẹ́ta [2,300].
Lọ́sọ̀ọ̀sẹ̀, àwọn tó fẹ́rẹ̀ẹ́ tó ẹgbẹ̀rún kan [1,000] ló ń yọ̀ǹda ara wọn láti ṣèrànwọ́ lẹ́nu iṣẹ́ tó ṣì ń lọ lọ́wọ́, ìyẹn kíkọ́ àwọn ilé tí ìjì náà bà jẹ́.
Gbọ̀ngàn Ìjọba méjìdínláàádọ́ta [48] ni wọ́n ti tún ṣe tán báyìí, àwọn ilé tí wọ́n sì ṣètò pé wọ́n máa tún ṣe láàárín oṣù díẹ̀ sí i lé ní ọgọ́rùn-ún márùn-ún àti márùndínláàádọ́ta [545].
A retí pé a máa ná tó mílíọ̀nù mẹ́jọ ààbọ̀ owó dọ́là sórí iṣẹ́ tá a máa ṣe ní àdúgbò yìí nìkan, iṣẹ́ náà á sì parí títí June 30, 2018.
Láti ìparí oṣù August 2017, àwọn aṣojú ẹ̀ka méjìlélógún [22], tó fi mọ́ àwọn méje tó wà lára Ìgbìmọ̀ Ẹ̀ka, ló ti ṣèbẹ̀wò sí àwọn ibi tí àjálù náà ti ṣẹlẹ̀ kí wọ́n lè fi ọ̀rọ̀ Ọlọ́run gbé àwọn akéde tí àjálù ṣẹlẹ̀ sí ró.
Àdúrà wa ni pé kí gbogbo àwọn tó ń lọ́wọ́ sí ètò ìrànwọ́ yìí rí okun gbà kí wọ́n lè ṣiṣẹ́ náà yọrí.​
Àwọn tó ń ṣètò ìrànwọ́ ní Aransas Pass, nílùú Texas.
Ìjì líle tó ń jẹ́ Dorian yìí kọ́kọ́ jà ní àwọn erékùṣù tó wà ní Bahamas, ó sì ba nǹkan jẹ́ níbẹ̀ gan-an. Ẹ̀yìn ìyẹn ló wá rọ́ lọ sí àwọn etíkun tó wà ní ìlà oòrùn Amẹ́ríkà.
Ní àárọ̀ Friday, September 6, 2019, ó kọjá ní ìlú Cape Hatteras ní North Carolina, ó sì fa àkúnya omi tó ń ru gùdù, èyí tó ya wọ ilé àti àwọn ilé ìtajà káàkiri.
Ní September 7, 2019, ìjì náà fa ẹ̀fúùfù líle gan an nílùú Nova Scotia, ní orílẹ̀ èdè Kánádà.
Àwọn akéde láti Nassau wá kí àwọn arákùnrin àti arábìnrin wọn tí wọ́n kó kúrò ní erékùṣù Great Abaco káàbọ̀ ní pápákọ̀ òfuurufú Ẹ̀ka ọ́fíìsì wa ní orílẹ̀ èdè Amẹ́ríkà ròyìn pé lára àwọn akéde tó tó ẹgbẹ̀rún kan, ọgọ́rùn-ún méje àti méjìlélógójì (1,742) tó wà ní Bahamas, arábìnrin kan ṣoṣo ló kàn fara pa díẹ̀.
Ní àsìkò tá a ń kọ ìròyìn yìí, ilé méjìdínláàádọ́ta (48) tó jẹ́ ti àwọn ará wa ni ìjì náà bà jẹ́ nígbà tí ilé mẹ́jọ bàjẹ́ kọjá àtúnṣe.
Ọ̀pọ̀ lára àwọn akéde tó ń gbé ní erékùṣù Great Abaco ni ẹ̀ka ọ́fíìsì ṣètò pé kí wọ́n kó lọ sí ìlú Nassau, tó jẹ́ olú ìlú Bahamas.
Àwọn arákùnrin àti arábìnrin tó sì wà níbẹ̀ kí wọn káàbọ̀ tayọ̀tayọ̀ ní pápá ọkọ̀ òfuurufú.
Àwọn arákùnrin àti arábìnrin ń ṣètò àwọn nǹkan ìrànwọ́ ní gbọ̀ngàn àpéjọ tó ń jẹ́ West Palm Beach Christian Convention Center Ìgbìmọ̀ Tó Ń Ṣètò Ìrànwọ́ Nígbà Àjálù àti alábòójútó àyíká tó wà ní agbègbè náà ń ṣètò ìtọ́jú pàjáwìrì, wọ́n sì tún ń ṣètò ìbẹ̀wò olùṣọ́ àgùntàn fún àwọn akéde tí àjálù dé bá.
Àwọn arákùnrin láti ẹ̀ka ọ́fíìsì orílẹ̀ èdè Amẹ́ríkà náà rìnrìn àjò lọ sí agbègbè náà kí wọ́n lè pèsè àwọn ohun tí àwọn ará yìí nílò kí wọ́n sì fi Bíbélì tù wọ́n nínú.
Àwọn nǹkan ìrànwọ́ tí wọ́n fi ọkọ̀ òkun kó láti gbọ̀ngàn àpéjọ West Palm Beach Christian Convention Center dé sí Freeport ní Bahamas.
Àwọn ará tó wà níbẹ̀ ń kó àwọn páálí ẹrù náà sínú ọkọ̀ tó máa pín in kiri Ní orílẹ̀ èdè Amẹ́ríkà, apá Àríwá àti Gúúsù Carolina ni ìjì náà ti ṣọṣẹ́ jùlọ.
Ko sí arákùnrin tàbí arábìnrin kankan tó fara pa nínú àjálù náà, àmọ́ àwọn ará tó tó ọgọ́rùn-ún méje àti mẹ́tàdínlógójì (737) ló ni láti sa fi ilé wọn sílẹ̀.
Ọ̀pọ̀ lára wọn ní ìgbìmọ̀ náà ṣètò pé kí wọ́n kó kúrò fúngbà díẹ̀ títí dìgbà tí wọ́n a fì lè pa dà sílé.
Bákan náà, àádọ́ta (50) ilé àti gbọ̀ngàn ìjọba méjìlá (12) ló bà jẹ́.
A ò gbọ́ ìròyìn pé ẹnikẹ́ni lára àwọn ará wà ní Kánádà fara pa. Ìjì náà ba àwọn nǹkan díẹ̀ jẹ́ lára ilé àwọn arákùnrin wa kan, bẹ́ẹ̀ ló sì ba iná mànàmáná wọn jẹ́.
Àwọn arákùnrin àti arábìnrin tó wà nínú ìjọ ládùúgbò yẹn ṣe ìrànlọ́wọ́ fún àwọn ará tí àjálù náà dé bá.
A mà dúpẹ́ o, pé Jèhófà ń gbọ́ “ẹ̀bẹ̀ [àwọn ará wa] fún ìrànlọ́wọ́,” bí wọ́n ṣe ń gbọ́kàn lé e ní àkókò tí nǹkan lè koko yìí.​
Wọ́n ti ń kápá iná runlérùnnà tó ń jó lọ́nà tó kàmàmà ní California.
Nínú ìsọfúnni díẹ̀ tá a rí gbà látọ̀dọ̀ Ìgbìmọ̀ Ẹ̀ka ti Orílẹ̀-Èdè Amẹ́ríkà nípa àwọn arákùnrin wa tó wà lágbègbè yẹn, kò sí arákùnrin wa tàbí arábìnrin wa kankan tó kú, àmọ́ àwọn arákùnrin mẹ́jọ ṣèṣe, àwọn ẹgbẹ̀rún kan àti ọgọ́rùn-ún mẹ́rin [1,400] ló sì ti sá kúrò nílé.
Yàtọ̀ síyẹn, ilé àwọn arákùnrin wa mọ́kàndínlọ́gbọ̀n [29] ló ti bàjẹ́ pátápátá.
Àwọn tó sá kúrò nílé torí ìṣẹ̀lẹ̀ burúkú yìí ń rí ìtọ́jú gbà látọ̀dọ̀ àwọn ará tó wà ní ìjọ àti àyíká míì tó wà nítòsí wọn, púpọ̀ nínú àwọn arákùnrin wa ló sì ti pa dà sílé wọn.
Lásìkò tí iná yẹn ṣì ń ṣọṣẹ́, àwọn aṣojú láti ẹ̀ka ọ́fíìsì lọ́ ṣèbẹ̀wò sáwọn Alábòójútó àyíká, Ìgbìmọ̀ Tó Ń Ṣètò Ìrànwọ́ Nígbà Àjálù àtàwọn tó yọ̀ǹda ara wọn láti ṣèrànwọ́ fáwọn tí àjálù dé bá.
Wọ́n tún ṣèbẹ̀wò sọ́dọ̀ àwọn tó pàdánù ilé wọn sínú ìjàǹbá yẹn.
Yàtọ̀ síyẹn, wọ́n tún ṣe ìpàdé àkànṣe kan pẹ̀lú àwọn àyíká méjì tí àjálù yẹn dé bá gan-an kí wọ́n lè fi Bíbélì tù wọ́n nínú, kí wọn sì ràn wọ́n lọ́wọ́.
Ó dá wa lójú pé Jèhófà á máa báa lọ láti pèsè ìtùnú fáwọn arákùnrin wa tó wà nínú ìṣòro yìí.
Òjò àrọ̀ọ̀rọ̀dá àti yìnyín tó yọ́ fa omíyalé ní ìpínlẹ̀ Nebraska àti Iowa lóṣù March 2019.
Omíyalé náà mú kí àwọn odò tó wà lágbègbè náà kún kọjá ààlà, àwọn ibi tó ń gba omi dúró ya lulẹ̀, ó ba ọ̀pọ̀lọpọ̀ ilé jẹ́, ó sì pa ó kéré tán èèyàn mẹ́rin.
Ẹ̀ka ọ́fíìsì wa ní Amẹ́ríkà sọ pé kò sí ìkankan lára ẹgbẹ̀rún márùn-ún àti mẹ́tàlélọ́gọ́fà (5,123) akéde tó wà níbẹ̀ tó kú tàbí tó fara pa.
Àmọ́ akéde mẹ́rìnlélọ́gọ́rin (84) ní láti kúrò níbi tí wọ́n ń gbé.
Yàtọ̀ síyẹn, ilé mẹ́jọ àwọn ará wa bà jẹ́ gan-an, ilé mẹ́rìnlélọ́gbọ̀n (34) míì sì bà jẹ́ díẹ̀.
Àwọn ará ìjọ lágbègbè náà ti bẹ̀rẹ̀ sí í yọ̀ǹda ara wọn láti palẹ̀ ìdọ̀tí mọ́, wọ́n sì ń ṣiṣẹ́ pẹ̀lú àwọn ará tó wà ní Ẹ̀ka Tó Ń Yàwòrán Ilé Tó sì Ń Kọ́ Ọ.
Àwọn alábòójútó àyíká tó wà lágbègbè tí àjálù náà ti ṣẹlẹ̀ ń fáwọn ará tọ́rọ̀ kàn níṣìírí.
Àdúrà wa ni pé kí ìrànlọ́wọ́ táwọn ará wa rí gbà nípa tara àti nípa tẹ̀mí tù wọ́n nínú lásìkò ìṣòro yìí.
Ní January 9 lórílẹ̀-èdè Amẹ́ríkà, ìjì líle kan jà ní gúúsù ìpínlẹ̀ California. Ìjì yẹn ló fa ọ̀gbàrá púpọ̀ gan-an tó sì han àwọn ará ìlú léèmọ̀.
Ìròyìn jẹ́ ká mọ̀ pé àwọn mọ́kànlélógún [21] ló pàdánù ẹ̀mí wọn sínú ìṣẹ̀lẹ̀ burúkú yẹn, ọ̀pọ̀ ilé ló wó, àwọn míì sì bàjẹ́.
Kò sí ọ̀kankan nínú àwọn ará wa tó kú sínú ìṣẹ̀lẹ̀ náà.
Àmọ́ ní ìlú Burbank, ìjì yẹn ba ilé àtàwọn nǹkan ìní akéde kan jẹ́. Bákan náà, ní ìlú Ventura ìdílé mẹ́jọ ló ti sá kúrò nílé.
Gbọ̀ngàn Ìjọba kankan kò bàjẹ́.
Àwọn Alábòójútó àyíká pẹ̀lú Ìgbìmọ̀ Tó Ń Ṣètò Ìrànwọ́ Nígbà Àjálù àti àwọn aṣojú láti Ẹ̀ka Tó Ń Yàwòrán Ilé Tó sì Ń Kọ́ Ọ jọ ń ṣiṣẹ́ pọ̀ láti ṣèrànwọ́ fáwọn tí àjálù dé bá.
Ní irú àsìkò tí nǹkan nira yìí, àá máa báa lọ láti rántí àwọn arákùnrin àtàwọn arábìnrin wa nínú àwọn àdúrà wa, ó dá wa lójú pé Jèhófà máa fún wọn lókun tí wọ́n nílò.​
Ọdún 1935 ni ìṣẹ̀lẹ̀ amọ́kànyọ̀ yìí kọ́kọ́ wáyé.
Arákùnrin Joseph F. Rutherford, tó jẹ́ ààrẹ Watch Tower Society nígbà yẹn wà níbẹ̀ nígbà tí wọ́n bẹ̀rẹ̀ sí í kọ́ Gbọ̀ngàn Ìjọba tó wà ní ojúlé 1228 ní Pensacola Street, ìlú Honolulu, ìpínlẹ̀ Hawaii.
Kò ní yà yín lẹ́nu pé ilé kékeré tí wọ́n kọ́ nígbà yẹn ni ilé ìjọsìn àwa Ẹlẹ́rìí Jèhófà tá a kọ́kọ́ pè ní “Gbọ̀ngàn Ìjọba.” Àtìgbà yẹn làwa èèyàn Jèhófà ti ń pe àwọn ibi tá a máa ń kóra jọ sí láti jọ́sìn ní Gbọ̀ngàn Ìjọba, ìyẹn sì ti lé lọ́gọ́rin (80) ọdún báyìí.
Ní báyìí, àwọn ìjọ mẹ́rin ló ń ṣèpàdé nínú Gbọ̀ngàn Ìjọba yẹn, èdè márùn-ún ni wọ́n sì fi ń ṣèpàdé níbẹ̀, títí kan èdè Hawaii Pidgin.
* Gbọ̀ngàn Ìjọba tá a ṣẹ̀ṣẹ̀ tún kọ́ ní 1228 Pensacola Street, Honolulu, Hawaii Ní February 11 sí 15, 2020, ìyẹn kí àrùn COVID-19 tó gbayé kan, lẹ́yìn tá a ti tún Gbọ̀ngàn Ìjọba àkọ́kọ́ yẹn kọ́, àwọn ará wa pe àwọn ará ìlú, àwọn aṣojú ìjọba àtàwọn olùkọ́ láti wá ṣèbẹ̀wò kí wọ́n sì rín yí ká ilé náà.
Àwọn ará wa mú àwọn àlejò náà rìn yí ká ilé náà, kí wọ́n lè rí onírúurú fọ́tò àtàwọn àkọ́sílẹ̀ ìtàn nípa ilé náà. Yàtọ̀ síyẹn, àwọn arákùnrin tún ṣàlàyé àwọn nǹkan táwa Ẹlẹ́rìí Jèhófà ń gbé ṣe lóde òní fún wọn.
Nígbà tó di February 16, Arákùnrin David H. Splane tó jẹ́ ọ̀kan lára Ìgbìmọ̀ Olùdarí àwa Ẹlẹ́rìí Jèhófà wá fọba lé e pẹ̀lú àsọyé ìyàsímímọ́.
Arábìnrin kan tó wà lára àwọn tó ṣe àwọn ìmúrasílẹ̀ kan kí ètò náà lè kẹ́sẹ járí sọ pé: “Bó tiẹ̀ jẹ́ pé kì í ṣe torí àtiwàásù fáwọn èèyàn náà la ṣe ní kí wọ́n wá ṣèbẹ̀wò, a gbà pé ẹ̀rí ńlá ni ìbẹ̀wò náà jẹ́ fún ọ̀pọ̀ èèyàn tó ṣeé ṣe kí wọ́n má mọ̀ nípa àwa Ẹlẹ́rìí Jèhófà.” Ètò tá a ṣe pé káwọn èèyàn rìn yí ká Gbọ̀ngàn Ìjọba yẹn mú káwọn ará wa lọ́kùnrin àti lóbìnrin túbọ̀ lóye ìtàn àwa Ẹlẹ́rìí Jèhófà láwọn erékùṣù Hawaii, ó sì mú kí wọ́n rí ìmúṣẹ Ọ̀rọ̀ Ọlọ́run tó sọ pé: “Ní àwọn erékùṣù òkun, wọ́n máa yin orúkọ Jèhófà, Ọlọ́run Ísírẹ́lì lógo.
^ ìpínrọ̀ 2 Lásìkò tí àrùn COVID-19 gbòde, orí ẹ̀rọ ayélujára ni gbogbo ìjọ àwa Ẹlẹ́rìí Jèhófà lórílẹ̀-èdè Amẹ́ríkà ti ń ṣèpàdé dípò kí wọ́n máa kóra jọ nínú Gbọ̀ngàn Ìjọba.
Ní oṣù díẹ̀ sẹ́yìn, àwọn iná kan jó ní ìpínlẹ̀ California, ó sì ba agbègbè tó tó ọgọ́rùn-ún mẹ́ta ó lé ọgọ́ta àti méjì kìlómítà jẹ́ níbùú àti lóòró (362 square kilometers).
Ẹ̀ka ọ́fíìsì wa ní Amẹ́ríkà ròyìn pé àwọn ará tó lé ní ẹgbẹ̀rún kan ó lé ọgọ́rùn-ún méje (1,700) ló ti sá kúrò nílé nítorí àwọn iná tó jó léraléra náà.
A ò tíì gbọ́ pé ẹnikẹ́ni fara pa tàbí kú.
Ní October 10, 2019, iná tó jó àdúgbò Sandalwood tó wà ní Calimesa ba ilé ọ̀kan lára àwọn arákùnrin wa jẹ́.
Bákan náà, èéfín ba àwọn ilé kan jẹ́ díẹ̀.
Ó fẹ́rẹ̀ẹ́ jẹ́ gbogbo àwọn tó sá kúrò nílé ló ti pa dà sílé.
Ọ̀kan lára àwọn alàgbà tó ń gbé láwọn ibi tí iná náà ti jó sọ pé: “Ó ṣe pàtàkì gan-an pé ká máa tẹ̀ lé ìtọ́ni tí irú nǹkan báyìí bá ṣẹlẹ̀, kódà, ó yẹ ká tẹnu mọ́ ọn dáadáa.
Ẹsẹ̀kẹsẹ̀ làwọn ará wa ti kúrò láwọn ibi tí iná náà ti ń jó, ìyẹn sì jẹ́ kó rọrùn fáwọn panápaná láti gbájú mọ́ bí wọ́n ṣe máa pa iná náà dípò kí wọ́n máa wá àwọn èèyàn kiri.” Àwọn alábòójútó àyíká àti àwọn alàgbà tó ń gbé lágbègbè náà ń ṣe gbogbo ohun tí wọ́n lè ṣe láti pèsè ìrànwọ́ fún àwọn tó sá kúrò nílé.
Ìfẹ́ àti ẹ̀mí ọ̀làwọ́ tí àwọn akéde tó ń gbé lágbègbè yìí fi hàn bùáyà.
Torí ìfẹ́ tó jinlẹ̀ táwọn ará fi hàn, alábòójútó àyíká kan sọ pé: “Kò ṣòro fún wa rárá láti rí ilé táwọn tó sá kúrò nílé máa gbé.” A dúpẹ́ lọ́wọ́ Jèhófà torí àwọn tó “ti di orísun ìtùnú” fún àwọn arákùnrin àtàwọn arábìnrin wa tí iná yìí lé kúrò nílé.
Ní November 14, 2019, ọmọ ilé ìwé kan dàbọn bolẹ̀ láàárín àwọn ọmọ kíláàsì rẹ̀ ní ilé ẹ̀kọ́ girama tó wà nílùú Santa Clarita, ní California.
Ọmọ náà pa ọmọ ilé ìwé méjì, ó sì ṣe àwọn mẹ́ta léṣe, kó tó wá pa ara ẹ̀.
Ó bani nínú jẹ́ pé Dominic Blackwell, ọmọ arábìnrin wa kan wà lára àwọn ọmọ ilé ìwé tó yìnbọn pa.
Ọmọ ọdún mẹ́rìnlá (14) ni, ó sì máa ń lọ sí ìpàdé déédéé pẹ̀lú ìyá rẹ̀ tó ń jẹ́ Nancy Blackwell.
Bàbá, ìyá àti àbúrò mẹ́ta ni Dominic fi sílẹ̀.
Àwọn alàgbà ń pèsè ìtùnú látinú Ìwé Mímọ́ fún ìdílé yìí àtàwọn ará ìjọ wọn.
Ó bà wá nínú jẹ́ gan-an pé irú àjálù burúkú yìí ṣẹlẹ̀.
À ń retí ìgbà tí Ọlọ́run máa ‘nu gbogbo omijé kúrò tí ikú ò ní sí mọ́, tí kò sì ní sí ọ̀fọ̀ tàbí ẹkún tàbí ìrora mọ́.’
Déètì: August 9 sí 11, 2019
Ibi Tó Ti Wáyé: Chase Field ní Phoenix, Arizona, Orílẹ̀-èdè Amẹ́ríkà
Èdè: Gẹ̀ẹ́sì
Àwọn Tó Wá: 40,237
Àwọn Tó Ṣèrìbọmi: 352
Àwọn Tó Wá Láti Ilẹ̀ Òkèèrè: 5,000
Àwọn Ẹ̀ka Ọ́fíìsì Tá A Pè: Australasia, ilẹ̀ Gẹ̀ẹ́sì, Kánádà, Central Europe, Chile, Faransé, Gíríìsì, Íńdíà, Ítálì, Kòríà, Micronesia, Scandinavia, Sri Lanka, Tahiti, Thailand, Trinidad and Tobago, Tọ́kì
Ìrírí: Steve Moore tó jẹ́ ààrẹ àti Ọ̀gá àgbà iléeṣẹ́ kan tí wọ́n ń pè ní Visit Phoenix, ló bá wa ṣètò ibi tá a ti ṣe àpéjọ náà, àwọn òtẹ́ẹ̀lì àti ibi ìgbafẹ́ tá a ṣeré lọ ní ìlú Phoenix, ó sọ pé:
“Ọjọ́ pẹ́ gan-an tí mo ti ń ṣiṣẹ́ yìí, àmọ́ àpéjọ yín ló ṣì wà létòletò jù látìgbà tí mo ti ń ṣiṣẹ́ yìí. Inú mi dùn pé a jọ ṣiṣẹ́.
"Yàtọ̀ síyẹn, ẹ ṣèlérí pé ẹ máa jẹ́ kí pápá ìṣeré yìí wà ní mímọ́ kẹ́ ẹ tó kúrò, kò sẹ́ni tó sọ bẹ́ẹ̀ rí, àfẹ̀yin nìkan.”"""
Bẹ̀rẹ̀ láti January 2019, ó ti ṣeé ṣe fáwọn tó gbọ́ Èdè Adití ti Amẹ́ríkà (ASL) láti túbọ̀ gbádùn ìbẹ̀wò wọn sí oríléeṣẹ́ wa.
Arákùnrin Enrique Ford, tó jẹ́ alábòójútó Ẹ̀ka Àwọn Nǹkan Ìṣẹ̀ǹbáyé sọ pé: “Iṣẹ́ kékeré kọ́ ni ẹ̀ka ìtúmọ̀ èdè àti ti kọ̀ǹpútà ṣe láti mú káwọn ará wa lóye àwọn nǹkan ìṣẹ̀ǹbáyé yìí ní Èdè Adití ti Amẹ́ríkà (ASL)!
Torí náà, àwọn ará wa lọ́kùnrin àti lóbìnrin tí wọ́n jẹ́ adití tàbí tí wọn ò fi bẹ́ẹ̀ gbọ́rọ̀ tí wọ́n máa ń ṣèbẹ̀wò síbi ìpàtẹ wa máa gbádùn ẹ̀ dọ́ba báyìí. Á mú kí wọ́n túbọ̀ mọyì ohun tí wọ́n rí, á wú wọn lórí, á sì túbọ̀ kọ́ wọ́n lẹ́kọ̀ọ́ gan-an.” Arábìnrin Ana Barrios, tó jẹ́ adití tó sì ń ṣe aṣáájú-ọ̀nà déédéé nílùú New York, wà lára àwọn tó kọ́kọ́ ṣèbẹ̀wò síbi ìpàtẹ yìí.
Ẹ gbọ́ ohun tó sọ: “Nígbà tí mò ń wo àlàyé nípa àtẹ náà lédè adití lórí ẹ̀rọ tí wọ́n gbé fún mi, orí mi wú!
Kì í ṣe ìgbà àkọ́kọ́ tí mo máa wá síbí rèé, léraléra ni mo sì ti rí àwọn nǹkan tí wọ́n pàtẹ, síbẹ̀ ìgbà àkọ́kọ́ rèé tí ohun tí mo rí wọ̀ mí lọ́kàn gan-an, ó sì yé mi dáadáa ju ìgbà tí mo kàn ka èdè òyìnbó tí wọ́n fi ṣàlàyé ọ̀kọ̀ọ̀kan wọn.
Bí mo ṣe bẹ̀rẹ̀ sí í gbọ́ àlàyé náà lédè mi làwọn nǹkan wá túbọ̀ ṣe kedere sí mi.
Bí àpẹẹrẹ, mo wá lóye ohun tí orúkọ Jèhófà dúró fún, àṣé mi ò tiẹ̀ fi bẹ́ẹ̀ lóye ẹ̀ tẹ́lẹ̀! Yàtọ̀ síyẹn, ìpàtẹ yẹn jẹ́ kí n túbọ̀ lóye àwọn ànímọ́ Jèhófà, àlàyé yẹn wọ̀ mí lọ́kàn débi pé ṣe ni mo bẹ̀rẹ̀ sí í da omi lójú!” June 2017 niṣẹ́ títúmọ̀ àti ṣíṣètò bẹ̀rẹ̀ lórí ìpàtẹ àwọn nǹkan ìṣẹ̀ǹbáyé ní Èdè Adití ti Amẹ́ríkà.
Mẹ́tàlélógún (23) làwọn arákùnrin àti arábìnrin tó kópa nínu rẹ̀, adití ni mẹ́fà lára wọn, mẹ́fà míì sì láwọn òbí tó jẹ́ adití. Gbogbo wọn ló lọ́wọ́ nínú iṣẹ́ títúmọ̀ àwọn àlàyé yẹn sí ASL, wọ́n sì tún kópa nínú àwọn fídíò náà.
Fídíò tí wọ́n ṣe lé ní ọgọ́rùn-ún mẹ́sàn-án (900), wọ́n sì gùn tó nǹkan bíi wákàtí mẹ́sàn-án, kó lè bá àlàyé tá a ti gba ohùn rẹ̀ sílẹ̀ mu.
Ilé ìgbohùnsílẹ̀ mẹ́ta tó wà fún èdè adití la ti ṣe iṣẹ́ náà: Ọ́fíìsì àwọn atúmọ̀ Èdè Adití (ASL) ní Fort Lauderdale, ìpínlẹ̀ Florida; èyí tó wà ní ẹ̀ka ọ́fíìsì orílẹ̀-èdè Amẹ́ríkà ní Wallkill, ìpínlẹ̀ New York; àtèyí tó wà ní oríléeṣẹ́ wa ní Warwick, ìpínlẹ̀ New York.
Kó lè dá wa lójú pé kò sí tàbí-ṣùgbọ́n kankan nínú iṣẹ́ náà, a pe àwọn arákùnrin àti arábìnrin mélòó kan tí wọ́n jẹ́ adití, tọ́jọ́ orí wọn sì yàtọ̀ síra pé kí wọ́n bá wa fojú ṣùnnùkùn wò ó. A ṣiṣẹ́ lórí àwọn àkíyèsí wọn kó tó di pé a gbé e jáde níkẹyìn.
Díẹ̀ rèé lára àwọn arákùnrin àti arábìnrin tó túmọ̀ sí èdè adití nípa àwọn ohun ìṣẹ̀ǹbáyé tá a pàtẹ sí Warwick.
Ẹ̀ka Ìṣẹ̀ǹbáyé ra ẹ̀rọ ìgbàlódé alágbèéká mélòó kan tó lè jẹ́ káwọn tó ń sọ èdè adití (ASL) lóye àwọn nǹkan tí wọ́n ń rí bí wọ́n ṣe ń rìn yíká tí wọ́n sì ń fojú lóúnjẹ. Àlàyé kan náà táwọn tó ti nǹkan bọ etí ń gbọ́ nípa ìpàtẹ Warwick yìí làwọn náà ń wò lórí ẹ̀rọ tí wọ́n mú dání.
Yàtọ̀ sáwọn ẹ̀rọ téèyàn lè mú dání, Ẹ̀ka Ìṣẹ̀ǹbáyé tún ṣètò ohun tá a lè pè ní tẹlifíṣọ̀n gàdàgbà mẹ́rìnlá míì tó ń ṣàgbéyọ àwọn ohun ìṣẹ̀ǹbáyé náà, tó sì ń ṣàlàyé wọn lédè ASL.
Mark Sanderson, tó jẹ́ ọ̀kan lára Ìgbìmọ̀ Olùdarí Àwa Ẹlẹ́rìí Jèhófà sọ pé: “Kí nìdí tá a fi ṣètò ìpàtẹ àwọn ohun ìṣẹ̀ǹbáyé yìí? A fẹ́ kó fún gbogbo àwọn tó ń ṣèbẹ̀wò sí oríléeṣẹ́ wa níṣìírí, kó sì fún ìgbàgbọ́ wọn lókun.
Inú wa dùn pé èdè mẹ́rìnlá (14) ọ̀tọ̀ọ̀tọ̀ la fi ṣàlàyé onírúurú nǹkan tó wà níbi ìpàtẹ yìí, títí kan Èdè Adití ti Amẹ́ríkà (ASL). Torí náà, ó dùn mọ́ wa pé àwọn ará wa tó jẹ́ adití àtàwọn tí kò fi bẹ́ẹ̀ gbọ́rọ̀, títí kan àwọn tí kì í ṣe Ẹlẹ́rìí ló máa jàǹfààní.” Tá a bá ṣírò ẹ̀, ó lè ní ìlàjì mílíọ̀nù èèyàn tó ti wá ṣèbẹ̀wò sí oríléeṣẹ́ wa ní Warwick.
A ké sí ẹ̀yin ará wa níbi gbogbo láyé pé kẹ́ ẹ wá síbi, kẹ́ ẹ sì fojú ara yín rí àwọn nǹkan tá a pàtẹ síbi ìṣẹ̀ǹbáyé yìí. Ẹ̀gàn ni hẹ̀ẹ̀, á jẹ́ kẹ́ ẹ túbọ̀ mọyì àwọn ohun ribiribi táwa èèyàn Jèhófà ti gbé ṣe àtohun tó ti wáyé nínú ìtàn àwa Ẹlẹ́rìí Jèhófà.
Kò sí àní-àní, gbogbo àwọn tó ti wá síbí lo pinnu pé títí láé làwọn á máa “gbẹ́kẹ̀ lé Ọlọ́run.”—Sáàmù 78:7.
A ṣí i ní April 3, 2017, ìpàtẹ yìí pín sọ́nà mẹ́ta ní oríléeṣẹ́ wa tó wà nílùú Warwick, ní New York. Kò sí pé ẹnì kan ń mú èèyàn kiri ibẹ̀ tàbí kó máa ṣàlàyé fúnni.
“The Bible and the Divine Name” ṣàlàyé báwọn kan ṣe sapá fún ọ̀pọ̀ ọdún láti tẹ Ọ̀rọ̀ Ọlọ́run àti orúkọ rẹ̀ rì àtohun tí kò jẹ́ kí wọ́n ṣàṣeyọrí.
(Àìsáyà 40:8) Èèyàn á rí àwọn Bíbélì tó ṣọ̀wọ́n, tó lé lọ́gọ́rùn-ún (100) àtàwọn ohun ìṣẹ̀ǹbáyé míì tó jẹ mọ́ Bíbélì.
“A People for Jehovah’s Name” ṣe àfihàn ohun táwa Ẹlẹ́rìí Jèhófà gbé ṣe àtohun tó ṣẹlẹ̀ sí wa látọdún yìí wá.
Àwọn ohun ìṣẹ̀ǹbáyé àti ìrírí àwọn tọ́rọ̀ ṣojú wọn jẹ́ ká rí bí Jèhófà ṣe ń darí àwa èèyàn rẹ̀ látọdún yìí wá.
“World Headquarters—Faith in Action” ṣàlàyé ojúṣe ìgbìmọ̀ mẹ́fẹ̀ẹ̀fà ti Ìgbìmọ̀ Olùdarí àti bí wọ́n ṣe ń bójú tó onírúurú iṣẹ́ táwa Ẹlẹ́rìí Jèhófà ń ṣe kárí ayé.
“Courage to Stand Firm in a Time of Trial.” Wọ́n máa ń pààrọ̀ ohun tí wọ́n kó síbi ìpàtẹ yìí látìgbàdégbà.
Ó jẹ́ ká mọ bí nǹkan ṣe rí láàárín ọdún 1914 sí 1919, àdánwò ìgbàgbọ́ táwọn Akẹ́kọ̀ọ́ Bíbélì kojú lẹ́nì kọ̀ọ̀kan àti lápapọ̀.
Ìpàtẹ yìí ń jẹ́ káwọn tó ṣèbẹ̀wò rí àwọn fọ́tò tá a ti yà látọjọ́ gbọ́nhan, àwọn àkọsílẹ̀, àwòrán àtàwọn ìfọ̀rọ̀wánilẹ́nuwò tá a ti gbà sílẹ̀ tipẹ́tipẹ́. Àwọn tó ṣèbẹ̀wò lè tẹ́tí sí i tàbí kí wọ́n wò ó ní fídíò.
October 3, 2018 nibi ìpàtẹ yìí ti di àpéwò.
A máa fàwọn nǹkan tá a kó síbi ìpàtẹ yìí ránṣẹ́ sáwọn ẹ̀ka ọ́fíìsì wa míì káwọn náà lè pàtẹ wọn, àá wá pàtẹ àwọn nǹkan míì sí Warwick.
Déètì: May 24 sí 26, 2019
Ibi Tá A Ti Ṣe É: Marlins Park nílùú Miami, ìpínlẹ̀ Florida, Amẹ́ríkà
Èdè: Sípáníìṣì
Àwọn Tó Wá: 28,562
Àwọn Tó Ṣèrìbọmi: 230
Àwọn Tó Wá Láti Ìlẹ̀ Òkèèrè: 4,600
"Áwọn Ẹ̀ka Ọ́fíísì Tó Wá: Ajẹntínà, Bolivia, Brazil, Britain, Kánádà, Central America, Central Europe, Chile, Kòlóńbíà, Cuba, Ecuador, Paraguay, Peru, Philippines, Sípéènì"""
Ní Saturday, July 13, 2019, ìjì líle kan rọ́ lu ìlú Louisiana, kó tó di pé ọwọ́ wà rọlẹ̀ díẹ̀ tí wọ́n fi wá ń pè é ní Barry.
Ìjì líle yìí ba nǹkan jẹ́, ó fa àkúnya omi, ó sì jẹ́ kí iná mànàmáná lọ ní ibi púpọ̀ yí ká ìpínlẹ̀ Alabama, Louisiana, àti Mississippi.
Bí o tì lẹ́ jẹ́ pé kò sí akéde kankan tó fara pa tàbí kú nínú ìjì náà, àwọn mẹ́tàlélọ́gọ́fà (123) ni wọ́n di aláìnílé lórí.
Láfikún, ìjì líle náà ba ilé mẹ́tàdínlọ́gọ́rùn-ún (97) tó jẹ́ ti àwọn arákùnrin àti arábìnrin wa jẹ́, pẹ̀lú Gbọ̀ngàn Ìjọba márùn-ún.
Àwọn alábòójútó àyíká àti àwọn alàgbà ìjọ ń lọ bẹ àwọn tọ́rọ̀ náà kàn wò kí wọ́n lè fún wọn níṣìírí.
Bákan náà làwọn akéde láti àwọn ìjọ tó wà nítòsí ń pèsè omi, oúnjẹ àti ibùgbé níbi tí wọ́n ti nílò wọn.
Wọ́n ti ń ṣètò bí wọ́n á ṣe tún àwọn ilé tó nílò àtúnṣe ṣe.
Àá máa fi àwọn arákùnrin àti àwọn arábìnrin wa ní Gúúsù Amẹ́ríkà tí ìjì líle Barry ṣe lọ́ṣẹ́ sínú àdúrà wa, àá sì máa tì wọ́n lẹ́yìn.
Ní May 31, 2019, ọkùnrin kan bẹ̀rẹ̀ sí í ròjọ̀ ọta ìbọn lu àwọn tó ń ṣiṣẹ́ ní ọ́fíìsì ìlú Virginia Beach, ìpínlẹ̀ Virginia, lórílẹ̀-èdè United States.
Èèyàn méjìlá ló kú, àwọn mẹ́rin sì fara pa.
Ìròyìn tá a gbọ́ láti ẹ̀ka ọ́fíìsì wa ní Amẹ́ríkà fi hàn pé, ó ṣeni láàánú pé arábìnrin wa kan tó ń jẹ́, LaQuita Brown, wà lára àwọn tó kù nínú ìṣẹ̀lẹ̀ burúkú yìí.
Ẹni ọdún mọ́kàndínlógójì (39) ni Arábìnrin Brown, aṣáájú-ọ̀nà sì ni nínú Ìjọ Seaview tí wọ́n ti ń sọ èdè Faransé nílùú Norfolk, ìpínlẹ̀ Virginia.
Arábìnrin yìí máa ń yọ̀ǹda ara rẹ̀ láti ṣisẹ́ pẹ̀lú Ẹ̀ka Tó Ń Yàwòrán Ilé Tó sì Ń Kọ́ Ọ.
Àwọn alàgbà tó wà lágbègbè náà àti alábòójútó àyílká wọn ń fún tẹbítọ̀rẹ́ Arábìnrin Brown níṣìírí, wọ́n sì ń tù wọ́n nínú.
Ikú arábìnrin yìí dùn wá gan-an.
À ń retí àsìkò tí irú ìṣẹ̀lẹ̀ burúkú yìí ò ní wáyé mọ́, tí “ọ̀pọ̀lọpọ̀ àlàáfíà” á sì wá káàkiri ayé.
Ní April 12 àti 13, 2020, ó lé ní ọgọ́rùn-ún (100) ìgbà tí ìjì líle tí wọ́n ń pè ní tornado ṣoṣẹ́ ní apá gúúsù ìlà oòrùn orílẹ̀-èdè Amẹ́ríkà.
Àjọ Tó Ń Bójú Tó Ipò Ojú Ọjọ́ sọ pé ọ̀kan lára ìjì líle náà fẹ̀ tó kílòmítà mẹ́ta, ó wà lára àwọn ìjì líle tó tóbi jù tó tíì jà rí.
Ẹsẹ̀kẹsẹ̀ ni ẹ̀ka ọ́fíìsì kàn sí àwọn alábòójútó àyíká tó wà ní agbègbè yẹn kí wọ́n lè mọ bí nǹkan ṣe ń lọ sí pẹ̀lú àwọn ará wa.
Kò sí ìkankan nínú àwọn ará wa tí ìjì náà pa. Àmọ́, arábìnrin kan fara pa díẹ̀ nígbà tí ìjì náà fẹ́ lu ilé rẹ̀.
Àwọn akéde mẹ́tàlélọ́gọ́ta (63) ló ní láti kúrò nílé, ilé méjìlá (12) ló wó, ilé méjìdínlọ́gọ́ta (58) ló sì bà jẹ́.
Láfikún síyẹn, Gbọ̀ngàn Ìjọba márùn-ún ló bà jẹ́ díẹ̀, àmọ́ igi kan wó lu Gbọ̀ngàn Ìjọba kan, ó sì bà á jẹ́ gan-an.
Àwọn alàgbà àtàwọn alábòójútó àyíká ṣì ń kíyè sí bí nǹkan ṣe rí.
Wọ́n ń bójú tó ohun táwọn ará nílò nípa tara àti nípa tẹ̀mí, wọ́n sì ń pèsè ìtùnú fáwọn tí àjálù náà bá.​
Ìjì líle kan tí wọ́n pè ní Florence jà lọ́pọ̀ ibi ní ìpínlẹ̀ North Carolina, South Carolina àtàwọn ìpínlẹ̀ míì lórílẹ̀-èdè Amẹ́ríkà, omíyalé sì tún ṣẹlẹ̀ níbẹ̀.
Ìgbà kan wà tí ìjì líle tí wọ́n ń pè ní Florence yìí pa ó kéré tán, èèyàn méjìlélọ́gbọ̀n (32), tó sì sọ ẹgbẹẹgbẹ̀rún èèyàn di aláìrílégbé.
Ẹ̀ka ọ́fíìsì wa ní Amẹ́ríkà sọ pé kò sí ìkankan lára àwọn akéde wa tó bá ìṣẹ̀lẹ̀ náà lọ tàbí tó fara pa ju bó ṣe yẹ, bó tiẹ̀ jẹ́ pé ó lé ní ẹgbẹ̀rún mẹ́rin (4,000) Ẹlẹ́rìí Jèhófà tí ìjì náà lé kúrò níbi tí wọ́n ń gbé.
Lóòótọ́, ìjì náà ti jà tán, síbẹ̀ àwọn ibì kan ò tíì ṣeé dé torí omi tó bo gbogbo ibẹ̀.
Àyẹ̀wò tí wọ́n ṣe gbẹ̀yìn fi hàn pé ọgọ́rùn-ún mẹ́ta àti mọ́kànléláàádọ́ta (351) ilé àwọn ará wa pẹ̀lú Gbọ̀ngàn Ìjọba mọ́kànlélógún (21) ni ìjì náà bà jẹ́.
Ìgbìmọ̀ Tó Ń Ṣètò Ìrànwọ́ Nígbà Àjálù ń ṣiṣẹ́ lórí bí àwọn ará ṣe máa rí oúnjẹ, omi, ibùgbé àti ìtọ́jú ìṣègùn tí wọ́n nílò.
Àwùjọ méjì kan tún wà tó ń ṣèrànwọ́ láti kó àwọn igi tó wó lulẹ̀ kúrò lágbègbè náà.
Ohun tó kù báyìí ni bí wọ́n ṣe máa tún àwọn nǹkan tí omíyalé ti bà jẹ́ ṣe. Àwọn ará láwọn ìjọ tó wà níbẹ̀ àtàwọn tó wá láti ibòmíì ń yọ̀ǹda ara wọn láti bá Ìgbìmọ̀ Tó Ń Ṣètò Ìrànwọ́ Nígbà Àjálù náà ṣiṣẹ́.
Àwọn alàgbà ìjọ àti àwọn alábòójútó àyíká tó wà níbẹ̀ sì ń lọ sọ́dọ̀ àwọn tọ́rọ̀ náà kàn láti fún wọn níṣìírí.
À ń gbàdúrà fún àwọn ará wa tí nǹkan nira fún nítorí ìjì líle tó jà lẹ́nu àìpẹ́ yìí, a sì ń retí ìgbà tí ‘ẹ̀rù kankan’ ò ní bà wá mọ́.
Ní Sunday March 3, 2019, ìjì tó le gan-an jà láwọn apá ibì kan ní ìpínlẹ̀ Alabama, Florida àti Georgia, ó gbẹ̀mí èèyàn mẹ́tàlélógún (23), ọ̀pọ̀ èèyàn ló sì fara pa.
Ẹ̀ka ọ́fíìsì wa ní Amẹ́ríkà sọ pé kò sí ìkankan lára àwọn ará wa tó kú.
Àmọ́ arábìnrin wa kan fara pa nígbà tí ìjì líle ba ilé rẹ̀ jẹ́ pátápátá ní ìlú Fort Valley, ìpínlẹ̀ Georgia.
Wọ́n ti ń tọ́jú rẹ̀ nílé ìwòsàn kan tó wà nítòsí.
Yàtọ̀ síyẹn, ẹ̀ka ọ́fíìsì sọ pé ilé mẹ́fà àwọn ará wa ni ìjì náà bà jẹ́, ó sì wó ilé mẹ́rin míì pátápátá.
Àwọn alábòójútó àyíká tó wà lágbègbè náà ń ṣètò báwọn ará ṣe ń rí oúnjẹ, ibi tí wọ́n á gbé àti aṣọ, àwọn alàgbà sì ń fi Bíbélì fún wọn níṣìírí.
Àdúrà wa ni pé kí àwọn ará wa tí àjálù yìí kàn rí ìtùnú nínú ẹṣin ọdún wa ti 2019 tó sọ pé, “Má wò yí ká, nítorí èmi ni Ọlọ́run rẹ.
Bí ètò ọrọ̀ ajé ṣe túbọ̀ ń dẹnu kọlẹ̀ ní Fẹnẹsúélà nípa lórí àwọn ará wa lọ́kùnrin àti lóbìnrin.
Ọ̀sọ̀ọ̀sẹ̀ ni ìròyìn nípa àwọn ará wa tí wọ́n hùwà ọ̀daràn sí ń dé ẹ̀ka ọ́fíìsì wa ní Fẹnẹsúélà.
Bákan náà, ọ̀pọ̀ Gbọ̀ngàn Ìjọba lórílẹ̀-èdè náà ni wọ́n ti jí àwọn nǹkan tó wà nínu rẹ̀ kó lọ.
Àwọn ará wa ń fara dà á bó tiẹ̀ jẹ́ pé gbogbo nǹkan ló ti gbówó lérí, bẹ́ẹ̀ ni kò sí oúnjẹ, oògùn àtàwọn nǹkan tó ṣe pàtàkì míì.
Látọdún 2013, ó lé ní ọ̀kẹ́ kan (20,000) akéde tó ti sá lọ́ sáwọn orílẹ̀-èdè míì bíi, Ajẹntínà, Brazil, Chile, Kòlóńbíà, Ecuador, Ítálì, Peru, Pọ́túgà, Sípéènì àti Amẹ́ríkà.
* Láìka gbogbo ìṣòro yìí sí, nǹkan bí ẹgbẹ̀rún lọ́nà ogóje (140,000) Ẹlẹ́rìí Jèhófà tó wà ní Fẹnẹsúélà báyìí ń bá ìjọsìn wọn lọ.
Ẹ̀ka ọ́fíìsì wa ní Fẹnẹsúélà kò dáwọ́ dúró láti máa ṣètò ìrànwọ́ lórílẹ̀-èdè náà.
Lọ́wọ́lọ́wọ́ báyìí, ọgọ́ta (60) ìgbìmọ̀ tó ń ṣètò ìrànwọ́ ló ń ṣiṣẹ́ kára láti pín oúnjẹ fáwọn ará lọ́kùnrin àti lóbìnrin.
Títí di báyìí, ẹ̀ka ọ́fíìsì wa ní Fẹnẹsúélà pẹ̀lú èyí tó wà nílẹ̀ Brazil ti pín oúnjẹ tí àwọn ará kó jọ, tó sì kún ọ̀pọ̀lọpọ̀ ọkọ̀ akẹ́rù fún àwọn akéde tó lé ní ẹgbẹ̀rún mẹ́rìnlélọ́gọ́ta (64,000) láwọn ìjọ ẹgbẹ̀rún kan, ọgọ́rùn-ún mẹ́rin àti mẹ́tàdínlọ́gọ́rùn-ún (1,497).
Ẹ̀ka ọ́fíìsì wa ní Fẹnẹsúélà tún ń pèsè àwọn ohun táwọn ará nílò láti máa bá ìjọsìn wọn lọ.
Lọ́dún yìí, Àpéjọ Agbègbè “Jẹ́ Onígboyà”! méjìlélọ́gọ́fà (122) ni wọ́n ṣe káàkiri orílẹ̀-èdè náà, September 2, 2018 ni wọ́n parí èyí tó kẹ́yìn lára wọn.
Àpéjọ Agbègbè yìí túbọ̀ fún àwọn ará lókun gan-an nípa tẹ̀mí, ọ̀pọ̀ lára wọn ló sì tiraka gan-an kí wọ́n tó lè wá sí àpéjọ náà.
Àwọn ará ní Fẹnẹsúélà ń ṣiṣẹ́ kára láti fi ọ̀rọ̀ Bíbélì tu ọ̀pọ̀ àwọn tí wàhálà ti bá lórílẹ̀-èdè náà nínú.
Ní báyìí, iye ìkẹ́kọ̀ọ́ Bíbélì táwọn akéde ń darí lóṣooṣù fẹ́rẹ̀ẹ́ tó ọ̀kẹ́ mẹ́wàá (200,000).
Iye àwọn tó ń kẹ́kọ̀ọ́, tí wọ́n sì ń wá sípàdé ti pọ̀ sí i, àwọn ẹgbẹ̀rún méje ọgọ́rùn-ún mẹ́jì àti mọ́kàndínlọ́góta (7,259) ló sì ṣèrìbọmi.
Àwọn ìtẹ̀síwájú tí à ń rí yìí fi hàn pé ẹ̀mí Ọlọ́run ló ń fún àwọn ará wa ní Fẹnẹsúélà lágbára.
Àdúrà wa ni pé kí wọ́n gbára lé Jèhófà títí dìgbà tí Ìjọba rẹ̀ máa fòpin sí gbogbo wàhálà tí à ń kojú báyìí.—Òwe 3:5, 6.
Tó o bá fẹ́ mọ̀ sí i nípa ohun tó ń ṣẹlẹ̀ ní Fẹnẹsúélà, wo fídíò Fẹnẹsúélà—Wọ́n Ní Ìfẹ́ àti Ìgbàgbọ́ Bí Nǹkan Tiẹ̀ Nira.
^ ìpínrọ̀ 2 Láwọn àkókò tí ọrọ̀ ajé àti ètò ìṣèlú ò bá fara rọ, akéde kọ̀ọ̀kàn ló máa pinnu bóyá kí òun kúrò lórílẹ̀-èdè tóun ń gbé tàbí kóun dúró.
Ètò Ọlọ́run kì í pinnu fáwọn èèyàn bóyá kí wọ́n kúrò tàbí kí wọ́n dúró.
Ìlú ò fara rọ, ọrọ̀ ajé sì ti dẹnu kọlẹ̀ lórílẹ̀-èdè Fẹnẹsúélà.
Àwọn èèyàn ò rí oúnjẹ, omi, epo pẹtiróòlù, ati oògùn tí wọ́n máa lò torí kò sí lárọ̀ọ́wọ́tó, èyí tó wà sì gbówó lérí.
Àìsí iná ti mú kí oúnjẹ túbọ̀ ṣọ̀wọ́n, torí kò sí bí wọ́n á ṣe tọjú rẹ̀ kó má bàa bà jẹ́.
Ìwà ọ̀daràn sì ń peléke sí i.
Síbẹ̀, lójú gbogbo ìṣòro yìí, àwọn akéde ẹgbẹ̀rún mẹ́rìndínlógóje àtààbọ̀ (136,500) tó wà ní Fẹnẹsúélà ó yéé fìtara wàásù.
Bí àpẹẹrẹ, ní January 2019, bó tiẹ̀ jẹ́ pé iye àwọn akéde lórílẹ̀-èdè náà fi ẹgbẹ̀rún méje (7,000) dín sí tọdún tó kọjá, wákàtí tí wọ́n fi wàásù fi ẹgbẹ̀rún lọ́nà àádọ́rùn-ún (90,000) ju ti tẹ́lẹ̀ lọ.
Ní April 2019, ìkẹ́kọ̀ọ́ Bíbélì tí wọ́n ṣe fẹ́rẹ̀ẹ́ tó ẹgbẹ̀rún lọ́nà ọgọ́rùn-ún méjì (195,600).
Àwọn aṣáájú-ọ̀nà déédéé pọ̀ sí i, wọ́n ti lé ní ẹgbẹ̀rún lọ́nà ọgbọ̀n (30,000).
Àwọn ará kọ́wọ́ ti ẹ̀tò tá a ṣe kárí ayé láti pe àwọn èèyàn wá síbi Ìrántí Ikú Kristi, ìyẹn sì mú kí iye àwọn aṣáájú-ọ̀nà olùrànlọ́wọ́ di ẹgbẹ̀rún lọ́nà ogún ó lé ọgọ́rùn mẹ́rin (20,400).
Ìsapá tí wọ́n ṣe yìí mú kí nǹkan bí ẹgbẹ̀rún lọ́nà ọgọ́rùn-ún mẹ́rin ó lé mọ́kànléláàádọ́rin (471,000) èèyàn wá síbi Ìrántí Ikú Kristi, èyí sì ju ìlọ́po mẹ́ta iye àwọn akéde tó wà lórílẹ̀-èdè náà.
Bákan náà, ọ̀pọ̀ èèyàn ló ń wá sípàde, torí pé àwọn ará ò yéé kọ́ àwọn tó ń wá ojútùú sí ìṣòro wọn lẹ́kọ̀ọ́ Bíbélì.
Ẹ̀ka ọ́fíìsì wa ní Fẹnẹsúélà ṣètò iṣẹ́ ìrànwọ́ kí àwọn ará wa lè rí ohun tí wọ́n nílò jẹ.
Lọ́lá ìrànwọ́ láti àwọn ẹ̀ka tó wà láyìíká àti owó ìtìlẹyìn kárí ayé, oṣooṣù ni ẹ̀ka ọ́fíìsì wa ní Fẹnẹsúélà ń pín ọ̀pọ̀lọpọ̀ ẹrù oúnjẹ fún ẹgbẹ̀rún márùndínlọ́gọ́rin (75,000) akéde ní ìjọ ẹgbẹ̀rún kan ọgọ́rùn márùn-ún ó lé márùndínlọ́gọ́rùn-ún (1,595).
Ọ̀pọ̀ ìṣoro làwọn ará wa ní Fẹnẹsúélà ń fara dà, àmọ́ inú wa dùn pé wọ́n ń ‘yọ̀ gidigidi nínú Jèhófà, inú wọn sì ń dùn nínú Ọlọ́run ìgbàlà wọn.
ÌLÚ NEW YORK— Kárí ayé ni àwọn oníròyìn ti ń sọ nípa wàhálà tó ń bá orílẹ̀-èdè Fẹnẹsúélà nítorí ọrọ̀ ajé tó dẹnu kọlẹ̀.
Ìgbìmọ̀ Ẹ̀ka Ọ́fíìsì orílẹ̀-èdè Fẹnẹsúélà sọ pé wàhálà náà ò yọ àwọn arákùnrin àtàwọn arábìnrin wa sílẹ̀.
Àwọn ìròyìn yìí ò múnú Ìgbìmọ̀ Olùdarí dùn rárá.
Àwọn adigunjalè wọ àwọn Gbọ̀ngàn Ìjọba kan nígbà tí ìpàdé àárín ọ̀sẹ̀ ń lọ lọ́wọ́, wọ́n sì jí àwọn ẹ̀rọ̀ abánáṣiṣẹ́ àtàwọn nǹkan iyebíye míì.
Yàtọ̀ síyẹn, àwọn ìgbà míì wà tí àwọn ará máa ṣèpàdé ní ilé àdáni, torí pé àwọn tó ń bára wọn jà ò jẹ́ kí wọ́n rọ́nà dé Gbọ̀ngàn Ìjọba.
Ọ̀pọ̀ lára àwọn arákùnrin àtàwọn arábìnrin wa ló wà lára àwọn tí iṣẹ́ bọ́ mọ́ lọ́wọ́ torí pé ibi tí wọ́n ti ń ṣiṣẹ́ kógbá wọlé.
Ṣe ni àwọn ọ̀daràn àtàwọn jàǹdùkú tún ń dájú sọ àwọn tó níṣẹ́ ara wọn, ìyẹn lò fà á táwọn kan fi gbé okòwò wọn tà, tí wọ́n sì sá kúrò nílùú kí wọ́n lè rímú mí.
Ó bani nínú jẹ́ pé, láwọn ọdún àìpẹ́ yìí, ó kéré tán ọgọ́rùn-ún méje ó dín ogún [680] àwọn arákùnrin àtàwọn arábìnrin ni wọ́n ti jí gbé, ó lé ní ẹgbẹ̀rún mẹ́tàlá àti mẹ́rìndínláàádọ́jọ [13,146] nínú wọn tí àwọn adigunjalè jí nǹkan wọn, àwọn mẹ́rìnlélógóje [144] ni wọ́n sì ti fipá bá lò pọ̀ tàbí tí wọ́n fẹ́ ṣe bẹ́ẹ̀ fún.
Èyí tó burú jù ni ohun tí ìròyìn tó dé ní August 10, 2017 sọ, pé àwọn arákùnrin àtàwọn arábìnrin mẹ́tàdínláàádọ́ta [47] ni wọ́n ti pa.
Àwọn míì tiẹ̀ tún gbẹ́mìí mì torí pé wọn ò rí ìtọ́jú tó yẹ gbà.
Ìgbìmọ̀ Olùdarí ń wo bí nǹkan ṣe ń lọ sí lójú méjèèjì, wọ́n ń lo lára owó táwọn èèyàn fi ṣètọrẹ láti ran àwọn arákùnrin àtàwọn arábìnrin tí wọ́n nílò oúnjẹ, ilé gbígbé àtàwọn nǹkan míì lọ́wọ́.
Ìgbìmọ̀ Olùdarí tún ń bá àwọn Ẹ̀ka Ọ́fíìsì kárí ayé sọ̀rọ̀ kí wọ́n lè rí ọ̀nà tó dáa jù láti ran àwọn arákùnrin àtàwọn arábìnrin wa ní Fẹnẹsúélà lọ́wọ́, torí pé ó léwu kéèyàn sọ pé òun fẹ́ lọ síbẹ̀ lọ ràn wọ́n lọ́wọ́.
Ìgbìmọ̀ Ẹ̀ka orílẹ̀-èdè Fẹnẹsúélà ti yan ìgbìmọ̀ tó ń bójú tó ètò ìrànwọ́ pàjáwìrì sí ẹ̀ka ọ́fíìsì náà, ìgbìmọ̀ tí wọ́n yàn yìí sì ń bójú tó ìgbìmọ̀ kéékèèké mẹ́rìnlélógún [24] míì káàkiri orílẹ̀-èdè náà láti pèsè ohun tí àwọn ará nílò.
Kì í ṣe pé àwọn akéde tó lé ní ẹgbẹ̀rún lọ́nà ogóje ó lé mẹ́sàn-án [149,000] tó wà ní Fẹnẹsúélà ń fara da ìpọ́njú tó lágbára “ní àwọn ọjọ́ ìkẹyìn” yìí nìkan ni, wọ́n tún ń fi kún ìsapá wọn láti máa sọ ọ̀rọ̀ ìtùnú tó wà nínú Bíbélì fún àwọn aládùúgbò wọn.
(2 Tímótì 3:1-5; 2 Tímótì 4:2) Luis R. Navas tó jẹ́ agbẹnusọ láti ẹ̀ka ọ́fíìsì orílẹ̀-èdè Fẹnẹsúélà sọ pé: “A ò tíì lọ́rọ̀ nípa tẹ̀mí báyìí rí.
Àwọn tó ń wá sípàdé ìjọ ti pọ̀ sí i.
Ọ̀pọ̀ akéde ló ti bẹ̀rẹ̀ aṣáájú-ọ̀nà déédéé, wọ́n sì ń ṣọ́ra ṣe bí wọ́n ń wàásù.
Torí pé àwọn aládùúgbò wa mọ̀ pé a ò gbè sẹ́yìn ẹnikẹ́ni àti pé a ò lọ́wọ́ sí ìwà ọ̀daràn èyíkéyìí tó ń lọ lórílẹ̀-èdè náà, wọ́n tẹ́wọ́ gba ọ̀rọ̀ ìrètí àti ìtùnú tí à ń sọ fún wọn látinú Bíbélì.” Àwọn Ẹlẹ́rìí Jèhófà tó wà lórílẹ̀-èdè Fẹnẹsúélà á máa bójú tó ara wọn nìṣó lẹ́nì kọ̀ọ̀kan, wọ́n á sì máa tu àwọn aládùúgbò wọn nínú.
Kárí ayé, àwọn arákùnrin àtàwọn arábìnrin bíi tiwọn á máa tì wọ́n lẹ́yìn nìṣó, wọn ò sì ní dákẹ́ àdúrà lórí wọn.
Ní Wednesday, August 23, ìjì líle tó léńkekà kan tó ń jẹ́ Hato, jà ní apá gúúsù orílẹ̀-èdè Ṣáínà, ó sì dé ìlu Hong Kong àti Macau.
Kò sí ẹni kankan tá a gbọ́ pé ó kú nílùú Hong Kong, àmọ́ àwọn mẹ́tàlélógbọ̀n [34] ló fara pa.
Nílùú Macau, ó kéré tán àwọn mẹ́sàn-án ló kú, àwọn mẹ́tàléláàdọ́jọ [153] sì fara pa.
Ẹ̀ka ọ́fíìsì àwa Ẹlẹ́rìi Jèhófa ní ìlu Hong Kong, tó tún ń bójú tó iṣẹ́ àwa Ẹlẹ́rìí nílùú Macau, ròyìn pé kò sí Ẹlẹ́rìi kankan tó bá ìṣẹ̀lẹ̀ yìí lọ.
Àmọ́, ọ̀pọ̀ ni kò ní iná àti omi tí wọ́n máa lò nílùú Macau.
Ẹ̀ka ọ́fíìsì ń ṣètò pẹ̀lú àwọn Ẹlẹ́rìí lágbègbè yẹn láti pèsè omi àti àwọn ohun míì tí àwọn ará wọn tí àjálù yìí dé bá nílò.
Àwọn Ẹlẹ́rìi Jèhófa tó ju ẹgbẹ̀rún márùn-ún àti ọgọ́rùn márùn-ún [5,500] ló ń gbé nílùú Hong Kong, àwọn ọgọ́rùn-un mẹ́ta àti ógún [320] ló sì ń gbé nílùú Macau.
Ìjì líle tó máa ń bá òjò rìn jà ní ìpínlẹ̀ Kerala, lórílẹ̀-èdè Íńdíà, ó sì mú kí òkè ya lulẹ̀ níbi mẹ́ẹ̀ẹ́dọ́gbọ̀n (25), ìṣẹ̀lẹ̀ yìí gbẹ̀mí ó kéré tán, èèyàn márùndínlọ́gọ́rin (75).
Ẹ̀ka Tó Ń Ṣèwádìí Nípa Ojú Ọjọ́ Nílẹ̀ Íńdíà (India Meteorological Department) sọ pé ìjì líle tó máa ń jà lápá gúúsù ìwọ̀ oòrùn ayé ló tíì rọ òjò tó rinlẹ̀ jù lọ lápá ibí yìí nínú ìtàn.
Ó dùn wá gan-an nígbà tá a gbọ́ ìròyìn láti ẹ̀ka ọ́fíìsì wa nílẹ̀ Íńdíà pé nígbà àjálù yìí, tọkọtaya Ẹlẹ́rìí kan tí wọ́n ti lé ní lẹ́ni ọgọ́ta (60) ọdún àti akẹ́kọ̀ọ́ Bíbélì kan pàdánù ẹ̀mí wọn, bákan náà àwọn akẹ́kọ̀ọ́ Bíbélì méjì ṣèṣe gan-an, wọ́n sì ti ń gbàtọ́jú nílé ìwòsàn.
Yàtọ̀ síyẹn, arákùnrin wa kan tó jẹ́ ọmọ ọdún mẹ́tàdínlógún (17) bómi lọ níbi tó ti fẹ́ ran ará àdúgbò rẹ̀ lọ́wọ́.
A dá Ìgbìmọ̀ Tó Ń Ṣètò Ìrànwọ́ Nígbà Àjálù (DRC) sílẹ̀ kí wọ́n lè wo ibi tí nǹkan bà jẹ́ dé, kí wọ́n sì ṣètò ìrànwọ́.
Àwọn Gbọ̀ngàn Ìjọba kan ni wọ́n lò láti ṣe iṣẹ́ ìrànwọ́ yìí.
Ìròyìn tá a sì kọ́kọ́ gbọ́ fi hàn pé ó kéré tán, mẹ́rìndínláàádọ́ta (46) lára ilé àwọn ará wa ló wó tàbí tó bà jẹ́.
Nǹkan bí ìdílé márùnlélọ́gọ́rin (85) ìyẹn (akéde 475) ni ìṣẹ̀lẹ̀ yìí mú kí wọ́n kúrò níbi tí wọ́n ń gbé, tí wọ́n sì lọ ń gbé nílé àwọn ará tàbí àwọn mọ̀lẹ́bí wọn.
A gbọ́ pé omi ọ̀gbàrá ti mu àwọn Gbọ̀ngàn Ìjọba kan débì kan.
Ìgbìmọ̀ DRC ṣì wà ní sẹpẹ́ torí ìròyìn tá a gbọ́ ni pé òjò tó rinlẹ̀ ṣì máa tún rọ̀ láìpẹ́.
Àwọn aṣojú láti ẹ̀ka ọ́fíìsì àti alábòójútó àyíká kan lágbègbè náà pẹ̀lú àwọn alàgbà ìjọ ṣèbẹ̀wò sọ́dọ̀ àwọn ará lọ́kùnrin àti lóbìnrin kí wọ́n lè tù wọ́n nínú, kí wọ́n sì fún wọn níṣìírí nípa tẹ̀mí.
Ọkàn wa wà lọ́dọ̀ gbogbo àwọn tí ìṣẹ̀lẹ̀ yìí kàn, a sì ń gbàdúrà fún wọn.
À ń retí ìgbà tí gbogbo irú àjálù yìí àti gbogbo ìrora tó máa ń bá a rìn á dohun ìgbàgbé.​
Ní October 25, 2019, Arákùnrin Ashok Patel tó jẹ́ ọ̀kan lára Ìgbìmọ̀ Ẹ̀ka orílẹ̀-èdè Íńdíà mú Bíbélì Mímọ́ ti Ìtumọ̀ Ayé Tuntun jáde lédè Telugu ní àpéjọ agbègbè tá a ṣe ní International Convention Centre tó wà nílùú Hyderabad, lórílẹ̀-èdè Íńdíà.
Àwọn tó fẹ́rẹ̀ẹ́ tó mílíọ̀nù mọ́kànléláàádọ́rùn-ún (91,900, 000) ló ń sọ èdè Telugu, ìyẹn ló mú kó jẹ́ èdè kẹta tí àwọn èèyàn ń sọ jù ní Íńdíà lẹ́yìn èdè Hindi àti Bengali.
Ní báyìí, àwọn akéde tó tó ẹgbẹ̀rún mẹ́fà (6,000) ló ń sìn láwọn agbègbè tí wọ́n ti ń sọ èdè Telugu, àmọ́ ẹgbẹ̀rún mẹ́jọ àti méjìdínláàádọ́rin (8,868) làwọn tó wá sí àpéjọ náà.
Èyí fi hàn pé ọ̀pọ̀ àwọn èèyàn ló wà ní agbègbè yẹn tí wọ́n nífẹ̀ẹ́ sí òtítọ́, kódà àyíká méjì la ti dá sílẹ̀ lọ́dún yìí.
Ọ̀kan lára àwọn atúmọ̀ èdè tó wà lára àwọn tó túmọ̀ Bíbélì Telugu náà fún odindi ọdún márùn-ún kíyè sí i pé kì í rọrùn fáwọn ọ̀dọ́ láti lóye àwọn èdè àtijọ́ tí wọ́n lò nínú àwọn Bíbélì Telugu míì.
Ó wá sọ pé: “Pẹ̀lú ìtumọ̀ tuntun yìí, Jèhófà máa bá àwọn ọ̀dọ́ sọ̀rọ̀ ní tààràtà lọ́nà tó máa yé wọn dáadáa tí kò sì ní lọ́jú pọ̀.”
Atúmọ̀ èdè míì tún fi kún un pé: “Lóde ẹ̀rí, àwọn èèyàn á máa tètè lóye ẹsẹ Ìwé Mímọ́ tá a bá kà fún wọn torí pé ó rọrùn.”
Láfikún síyẹn, ọ̀pọ̀ lára àwọn Bíbélì tó wà lédè Telugu ló ti yọ orúkọ Ọlọ́run, ìyẹn Jèhófà kúrò nínú Bíbélì wọn, torí náà Bíbélì Ìtumọ̀ Ayé Tuntun máa ran ọ̀pọ̀ lọ́wọ́ láti mọ orúkọ Ọlọ́run Olódùmarè.
Ó tún máa jẹ́ kí wọ́n mọ ìtumọ̀ àwọn ọ̀rọ̀ bí ọkàn àti ẹ̀mí. Ìdí sì ni pé ìgbàgbọ́ ẹ̀sìn Hindu làwọn tó tú àwọn Bíbélì míì gbé ìtumọ̀ wọn kà.
Akéde kan sọ pé: “Mo mọ̀ pé Bíbélì Telugu yìí máa ran àwọn tó bá kà á lọ́wọ́ láti túbọ̀ rí i pé Jèhófà nífẹ̀ẹ́ wọn gan-an!” Ó ṣe kedere pé Bíbélì tuntun tá a mú jáde lédè Telugu yìí máa ran àwọn tó bá kà á lọ́wọ́ láti ‘tọ́ Jèhófà wò, kí wọ́n sì rí i pé ẹni rere ni.
Bí ìròyìn kan ṣe sọ, ó kéré tán, ọgọ́rùn-ún kan àti mọ́kàndínláàádọ́rin (169) èèyàn ló bá àkúnya omi tó ṣẹlẹ̀ láwọn ìpínlẹ̀ kan ní Ìwọ̀ Oòrùn Íńdíà lọ. Àwọn ìpínlẹ̀ tọ́rọ̀ kàn ni ìpínlẹ̀ Gujarat, Maharashtra, Karnataka àti Kerala.
Ìròyìn tó tẹ̀ wá lọ́wọ́ láti ẹ̀ka ọ́fíìsì wa lórílẹ̀-èdè Íńdíà fi yé wa pé kò sí ìkankan nínú àwọn arákùnrin àtàwọn arábìnrin wa tó bá àkúnya omi náà lọ tàbí tó fara pa.
Àlàyé tí ẹ̀ka ọ́fíìsì ṣe rèé:
Ìpínlẹ̀ Gujarat: Ní ìlú Vadodara, àwọn akéde márùnlélógóje (ni àkúnya omi náà ba ilé wọn jẹ́.
Àmọ́, mìmì kan ò mi ọ́fíìsì àwọn atúmọ̀ èdè Gujarati tó wà ní ìlú Vadodara.
Ìpínlẹ̀ Maharashtra: Ní ìlú Mumbai, ìdílé mẹ́fà ni àkúnya omi náà ba ilé wọn jẹ́.
Ní ìlú Sangli, tó wà ní nǹkan bíi 378 kìlómítà sí ìlú Mumbai, àwọn akéde mẹ́ẹ̀ẹ́dọ́gbọ̀n (25) ló sá fi ilé wọn sílẹ̀.
Àwọn ará ní ìlú kan tó wà nítòsí gbà wọ́n sílé.
Ìpínlẹ̀ Karnataka: Ìdílé mẹ́fà ni àkúnya omi náà ti mú kí wọ́n sá fi ilé wọn sílẹ̀.
Ìpínlẹ̀ yìí ni ẹ̀ka ọ́fíìsì wà, àmọ́ àkúnya omi yìí ò ṣe jàǹbá èyíkéyìí fún ẹ̀ka ọ́fíìsì náà.
Ìpínlẹ̀ Kerala: Nǹkan bíi ọgọ́rùn-ún kan (100) ìdílé ló ti ṣí lọ sáwọn ibi tó ga, wọ́n ń gbé pẹ̀lú àwọn ará wa tó wà níbẹ̀.
Ìgbìmọ̀ Tó Ń Ṣètò Ìrànwọ́ Nígbà Àjálù ti ń bójú tó ọ̀rọ̀ náà.
Ẹ̀ka ọ́fíìsì ti ń darí ètò ìrànwọ́ láwọn ibi tọ́rọ̀ kàn.
Àwọn alábòójútó àyíká àtàwọn aṣojú Ẹ̀ka Tó Ń Yàwòrán Ilé Tó Sì Ń Kọ́ Ọ náà sì ti ń ṣiṣẹ́ takuntakun lórí ọ̀rọ̀ yìí kí wọ́n lè ran àwọn arákùnrin àtàwọn arábìnrin wa tọ́rọ̀ kàn lọ́wọ́.
Wọ́n fún wọn láwọn ohun kòṣeémáàní bíi omi tó ṣé e mu, wọ́n ń fún wọn níṣìírí, wọ́n sì ń fi Ọ̀rọ̀ Ọlọ́run tù wọ́n nínú.
Àdúrà wa ni pé kí Jèhófà má ṣe fi àwọn ará wa yìí sílẹ̀.
À ń fojú sọ́nà fún ìgbà tó jẹ́ pé “ọ̀pọ̀lọpọ̀ àlàáfíà” ló máa wà níbi gbogbo dípò àjálù.​
Ó ti lé ní ọgọ́rùn-ún [100] ọdún báyìí tí ojú ọjọ́ ti yí pa dà láwọn ibì kan lórílẹ̀-èdè Íńdíà, èyí sì ti mú kí mànàmáná tó léwu gan-an máa kọ, kí òjò àrọ̀ọ̀rọ̀dá sì máa rọ̀, kódà àwọn ọ̀jọ̀gbọ́n sọ pé òjò ò rọ̀ tó bẹ́ẹ̀ rí lórílẹ̀-èdè náà.
Omi àti yẹ̀pẹ̀ tó ya ti ba nǹkan jẹ́ lọ́pọ̀ ìlú lórílẹ̀-èdè náà; àwọn tí ẹ̀mí wọn lọ sí i tó ọgọ́rùn-ún méje [700], ọ̀pọ̀ mílíọ̀nù èèyàn ni ò sì nílé lórí mọ́.
Títí di July 31, 2017, a ò tíì gbọ́ pé Ẹlẹ́rìí Jèhófà kankan ṣèṣe tàbí pé wọ́n fara pa yánnayànna.
Àmọ́, ó kéré tán, ilé mẹ́ta tó jẹ́ tàwọn Ẹlẹ́rìí ni omi ya wọ̀, ṣùgbọ́n kò bà jẹ́ kọjá àtúnṣe.
Àwọn ìjọ àwọn Ẹlẹ́rìí Jèhófà tó wà ní Íńdíà ń ṣèrànwọ́ fáwọn ará wọn tí àjálù ṣẹlẹ̀ sí.
Ní November 16, 2018, ìjì tí wọ́n pè ní Gaja ṣọṣẹ́ gan-an ní ìpínlẹ̀ Tamil Nadu lórílẹ̀-èdè Íńdíà.
Ó kéré tán, èèyàn mẹ́rìndínláàádọ́ta (46) ló kú, nǹkan bí ẹgbẹ̀rún lọ́nà igba ó lé àádọ́ta (250,000) ló sá fi ilé wọn sílẹ̀, ilé tó sì lé ní ẹgbẹ̀rún márùndínláàádọ́rùn-ún (85,000) ló bà jẹ́ díẹ̀ tàbí tó bà jẹ́ pátápátá.
Ilé ọ̀kan lára àwọn ará wa nílùú Mannargudi, ní Tamil Nadu rèé. Igi wó lu ilé náà.
Ẹ̀ka ọ́fíìsì tó wà ní Íńdíà jábọ̀ pé ìjì náà ò pa ìkankan nínú àwọn ará wa, kò sì ṣe wọ́n léṣe.
Àmọ́, ilé àwọn ará wa méjìdínlógójì (38) àti Gbọ̀ngàn Ìjọba méjì ló bà jẹ́.
Ẹ̀ka ọ́fíìsì ṣètò Ìgbìmọ̀ Tó Ń Ṣètò Ìrànwọ́ Nígbà Àjálù kí wọ́n ṣèrànlọ́wọ́ fún àwọn akéde tí àjálù náà ṣẹlẹ̀ sí, wọ́n pín oúnjẹ, omi àtàwọn nǹkan míì.
Àdúrà wa ni pé kí àwọn ará wa tí Ìjì Gaja ṣèpalára fún ní Íńdíà rí ìtùnú gbà látọ̀dọ̀ Jèhófà nípasẹ̀ àwọn alàgbà onífẹ̀ẹ́.
Heavy monsoon rains fell on Mumbai, India, during the week of August 28, leading to the deaths of 14 individuals.
The branch office of Jehovah’s Witnesses in India reports that there have been no casualties or serious injuries among Jehovah’s Witnesses.
However, several homes of Witnesses were flooded.
Local Witnesses provided food and assisted in cleaning up the damaged homes of their fellow believers.
The branch office continues to monitor the situation in Mumbai as well as other parts of India that have been affected by the floods.
Àrùn COVID-19 tó gbòde kan yìí kò fẹ́ mú nǹkan rọrùn fáwọn tó ń ṣiṣẹ́ ní ọ́fíìsì àwọn atúmọ̀ èdè (RTO) mọ́kànlá, níbi tí wọ́n ti ń túmọ̀ àwọn ìtẹ̀jáde wa sí èdè mẹ́rìndínlógójì (36).
Àmọ́ pẹ̀lú ìrànlọ́wọ́ Jèhófà, àwọn atúmọ̀ èdè yìí ń rí ojútùú sáwọn ìṣòro tó ń yọjú yẹn, wọ́n sì ń báṣẹ́ wọn nìṣó.
Iṣẹ́ ìtúmọ̀ èdè kì í ṣe iṣẹ́ tí ẹnì kan lè dá ṣe.
Àmọ́ bí àrùn COVID-19 ṣe túbọ̀ ń tàn kálẹ̀, ìjọba orílẹ̀-èdè India ṣe òfin kónílégbélé, wọ́n ò sì fọ̀rọ̀ náà ṣeré rárá, èyí ló wá mú kó ṣòro fún àwọn atúmọ̀ èdè yẹn láti wà papọ̀ níbi kan náà.
Bákàn náà, àwọn amojú ẹ̀rọ tó máa ń ṣiṣẹ́ lórí àwọn fídíò wa, tí wọ́n sì máa ń gba ohùn àwọn èèyàn sílẹ̀ kò lè ṣiṣẹ́ wọn nínú ọ́fíìsì àwọn atúmọ̀ èdè mọ́ bíi ti tẹ́lẹ̀.
Àtorí ẹ̀rọ ayélujára làwọn atúmọ̀ èdè yẹn ti máa ń bára wọn ṣiṣẹ́ báyìí dípò kí wọ́n jọ wà níbì kan náà, kódà tí wọ́n bá fẹ́ gba ohùn àwọn èèyàn sílẹ̀, ọ̀tọ̀ nibi tí ẹni tó ń mojú ẹ̀rọ àtẹni tó ń kàwé máa wà.
Èyí ló wá jẹ́ kó ṣeé ṣe fún àwọn ará tó wà ní àwọn orílẹ̀-èdè míì bíi Bangladesh àti Amẹ́ríkàláti ràn àwọn atúmọ̀ èdè tó wà ní India lọ́wọ́ lẹ́nu iṣẹ́ wọn.
Àwọn ará yẹn tún ti wá rí àwọn ọ̀nà míì tí wọ́n lè gbà ṣe àwọn fídíò tó wà fún àwọn adití, láì jẹ́ pé àwọn tó ń ṣiṣẹ́ náà sún mọ́ra wọn.
Àwọn atúmọ̀ èdè kan tiẹ̀ ti sọ iyàrá wọn di ibiṣẹ́ wọn, kódà wọ́n ti fi àwọn páálí àtàwọn nǹkan míì tó wà lárọ̀ọ́wọ́tó wọn ṣe àwọn nǹkan tó máa jẹ́ kí iṣẹ́ wọn jáde dáadáa, àwọn kan tiẹ̀ ń fi fóònù wọn ṣe fídíò dípò àwọn kámẹ́rà tó le nílẹ̀.
Àmọ́ yàtọ̀ sóhun táwọn atúmọ̀ èdè yẹn ṣe, ṣe ni wọ́n gbára lé Jèhófà pé ó máa ran àwọn lọ́wọ́ láti má ṣe rẹ̀wẹ̀sì,ó sì máa fún wọn lókun láti máa báṣẹ́ náà lọ.
Ẹ gbọ́ ohun táwọn kan lára wọn sọ: Arákùnrin Jose Francis láti ìlú Kolkata sọ pé, “Tí ìṣòro kan bá yọjú, àwa èèyàn máa ń ríi bí ògiri, àmọ́ Jèhófà mọ ọ̀nà àbáyọ.” Arábìnrin Bindu Rani Chandan láti ìlú Bangalore sọ pé, “Ohun tó ń fún mi láyò lásìkò tí nǹkan nira yìí ni pé Jèhófà ń lò mí, ó sì jẹ́ kí n wúlò fún òun.” Arábìnrin Rubina Patel láti ìlú Vadodara sọ pé, “Kò sí ohun tó lè dá Jèhófà àti ètò rẹ̀ dúró, kódà àrùn corona gan-an ò tó bẹ́ẹ̀.” Orí wa máa ń wú tá a bá rántí àwọn arákùnrin àtàwọn arábìnrin wa tó ń ṣiṣẹ́ takuntakun láti túmọ̀ àwọn ìtẹ̀jáde wa.
Ó dá wa lójú pé ẹ̀mí mímọ́ Jèhófà ló ń jẹ́ kí wọ́n ṣe gbogbo àṣeyọrí tí wọ́n ń ṣe lẹ́nu iṣẹ́ náà, ó sì máa jẹ́ kí àsọtẹ́lẹ̀ Jésù nímùúṣẹ, èyí tó sọ pé: “A ó sì wàásù ìhìn rere Ìjọba yìí ní gbogbo ilẹ̀ ayé tí à ń gbé, kó lè jẹ́ ẹ̀rí fún gbogbo orílẹ̀-èdè.
Ní ìparí oṣù July àti ìbẹ̀rẹ̀ oṣù August, ilẹ̀ mì tìtì léraléra ní erékùṣù Lombok lórílẹ̀-èdè Indonéṣíà, ó gbẹ̀mí ó kéré tán, ọgọ́rùn-ún mẹ́rin ó lé mẹ́rìndínlógójì (436) èèyàn, nǹkan bí ẹgbẹ̀rún lọ́nà ọgọ́rùn-ún mẹ́ta àti àádọ́ta (350,000) ló sì ní láti kúrò níbi tí wọ́n ń gbé.
Ọ̀kan lára ìmìtìtì tó wáyé náà lágbára gan-an, ṣe ni àwọn ilé wọlẹ̀ ráúráú, ọgọ́rọ̀ọ̀rún mílíọ̀nù owó dọ́là sì làwọn nǹkan tó bà jẹ́.
Ìròyìn tá a gbọ́ láti ẹ̀ka ọ́fíìsì wa nílùú Jakarta ni pé ìkankan nínú àwọn ará wa ò fara pa, ìkankan ò sì kú, bó tiẹ̀ jẹ́ pé ilé àwọn akéde kan bà jẹ́.
Bákan náà, ilé tí ìjọ kan ṣoṣo tó wà ní erékùṣù náà ti ń ṣèpàdé bà jẹ́, ogójì (40) akéde ló sì wà nínú ìjọ.
Aṣojú méjì láti ẹ̀ka ọ́fíìsì rìnrìn àjò lọ síbi tí àjálù ti ṣẹlẹ̀ yìí kí wọ́n lè mọ ìrànlọ́wọ́ tí àwọn ará ibẹ̀ máa nílò, kí wọ́n sì lè tù wọ́n nínú.
A ò dákẹ́ àdúrà lórí àwọn ará wa lásìkò tí nǹkan nira yìí, torí a mọ̀ pé Jèhófà lè ‘tù wọ́n nínú nínú gbogbo ìpọ́njú wọn.
Ní Friday, September 28, ìmìtìtì ilẹ̀ tó lágbára wáyé ní erékùṣù Sulawesi lórílẹ̀-èdè Indonéṣíà.
Ó ju ẹgbẹ̀rún kan ó lé ọgọ́rùn-ún mẹ́ta (1,300) èèyàn tí ìmìtìtì ilẹ̀ náà àti omíyalé tó tẹ̀ lé e pa, púpọ̀ lára wọn ló ń gbé ní ìlú Palu ní àárín erékùṣù Sulawesi.
Ẹ̀ka ọ́fíìsì tó wà ní ìlú Jakarta ní Indonéṣíà sọ pé kò sí ìkankan tó kú lára ọgọ́rin (80) àwọn ará wa tó wà níbi tí àjálù yìí ti ṣẹlẹ̀.
Àwọn díẹ̀ ló fara pa, wọ́n sì ní láti lọ sílé ìwòsàn.
Ìṣẹ̀lẹ̀ yìí ba ilé arákùnrin wa kan jẹ́ pátápátá, ọ̀pọ̀ àwọn ará wa míì sì wà tó ba ilé wọn jẹ́ gan-an.
Ilé tí Ìjọ Palu ti ń ṣèpàdé náà tún bà jẹ́.
Ẹ̀ka Tó Ń Ṣètò Ìrànwọ́ Nígbà Àjálù ní ẹ̀ka ọ́fíìsì wa ti ń ṣiṣẹ́ pẹ̀lú àwọn alábòójútó àyíká àtàwọn ìjọ tó wà nítòsí láti ṣètò bí wọ́n ṣe máa ran àwọn ará lọ́wọ́.
Torí pé àwọn ará tó wà níbi tí àjálù náà ti ṣẹlẹ̀ ò fi bẹ́ẹ̀ ní oúnjẹ, omi àtàwọn nǹkan míì tó ṣe pàtàkì, ẹ̀ka ọ́fíìsì ṣètò ìjọ mẹ́ta tí á máa pèsè àwọn nǹkan yìí fáwọn ará tó wà ní Palu.
Àwọn alàgbà ń pèsè ìrànlọ́wọ́ tẹ̀mí fáwọn ará, wọ́n ń tù wọ́n nínú, wọ́n sì ń jẹ́ kí wọ́n rí ohun tí wọ́n nílò láti gbé ẹ̀mí wọn ró.
Arákùnrin tó jẹ́ alábòójútó Ẹ̀ka Tó Ń Yàwòrán Ilé Tó sì Ń Kọ́ Ọ, tó sì tún jẹ́ ọ̀kan lára Ìgbìmọ̀ Ẹ̀ka pẹ̀lú alábòójútó àyíká ibẹ̀ máa dé ọ̀dọ̀ àwọn ará tí ìṣẹ̀lẹ̀ náà kàn kí wọ́n lè tù wọ́n nínú, kí wọ́n sì fún wọn níṣìírí.
À ń gbàdúrà fún àwọn ará wa ní Indonéṣíà, torí a mọ̀ pé Jèhófà á máa jẹ́ “ibi ìsádi àti okun” fún wọn lásìkò wàhálà yìí.
Òjò tó rọ̀ ní agbègbè Papua tó wà ní ìlà oòrùn orílẹ̀-èdè Indonesia ní March 16, 2019 kọjá wẹ́rẹwẹ̀rẹ.
Òjò yìí fa omíyalé, àwọn tó pa lé ní ọgọ́rùn-ún kan (100), ọ̀pọ̀ ilé ló sì gbá lọ.
Ẹ̀ka ọ́fíìsì wa ní Indonesia sọ pé omíyalé yìí náà dààmú ọ̀pọ̀ lára àwọn ará tó ń gbé ní ìlú Sentani lágbègbè Papua.
Ó dùn wá pé arákùnrin wa kan kú nígbà tí omi gbé ilé rẹ̀ lọ.
Omi náà sì tún ba ilé mẹ́ta míì tó jẹ́ ti àwọn ará wa jẹ́.
Ó ju ogójì (40) akéde tó ní láti kúrò níbi tí wọ́n ń gbé, ọ̀dọ̀ àwọn ará lèyí tó pọ̀ jù nínú wọ́n sì ń gbé báyìí.
A ti dá Ìgbìmọ̀ Tó Ń Ṣètò Ìrànwọ́ Nígbà Àjálù sílẹ̀ láti pèsè ohun táwọn ará nílò.
Àwọn aṣojú ẹ̀ka àti alábòójútó àyílá tó wà lágbègbè náà lọ sáwọn apá ibi tí àjálù náà ti ṣẹ̀lẹ̀ láti fún àwọn ará ní ìṣírí látinú Bíbélì.
Wọ́n sì tún wo bí ìránlọ́wọ́ táwọn ará nílò ṣe máa pọ̀ tó.
À ń rántí gbogbo àwọn ará tí àjálù yìí ṣẹlẹ̀ sí nínú àdúrà wa.
A retí pé láìpẹ́, Jèhófà máa “máa gbé ikú mì títí láé,” á sì “nu omijé kúrò ní ojú gbogbo èèyàn.
Ìjì líle kan tí wọ́n pè ní Trami jà ní gúúsù ilẹ̀ Japan nírọ̀lẹ́ ọjọ́ Sunday, September 30, 2018. Ọwọ́ ìjì náà lágbára gan-an, òjò tó sì rọ̀ pọ̀ púpọ̀.
Àmọ́ ìjì náà bẹ̀rẹ̀ sí í rọlẹ̀ kó tó dé apá àríwá lópin ọ̀sẹ̀ náà. Nígbà tó fi máa dọjọ́ Monday, October 1, ó dé ìlú Tokyo.
Èèyàn mẹ́ta ló kú, nǹkan bíi igba (200) ló fara pa, ó sì lé ní mílíọ̀nù kan àti ẹgbẹ̀rún lọ́nà ọgọ́rùn-ún mẹ́ta (1,300,000) ilé tí ìjì náà ba iná wọn jẹ́.
Ìròyìn tá a gbọ́ látọ̀dọ̀ àwọn alábòójútó àyíká fi hàn pé erékùṣù Okinawa, ní gúúsù ilẹ̀ Japan ni ìjì náà ti ba nǹkan jẹ́ jù.
Àyẹ̀wò àkọ́kọ́ tí wọ́n ṣe láwọn àyíká mẹ́tẹ̀ẹ̀ta tó wà ní Okinawa àtàwọn ibi tó wà nítòsí fi hàn pé kò sí ìkankan lára àwọn ará wa tó kú nínú àjálù yìí, àmọ́ àwọn mẹ́sàn-án fara pa.
Ìjì líle náà tún ba nǹkan bí ọgọ́fà (120) ilé àwọn ará wa jẹ́ àti Gbọ̀ngàn Ìjọba márùn-ún ní erékùṣù Okinawa.
Bákan náà, ọwọ́ ìjì yìí ba Gbọ̀ngàn Ìjọba mọ́kànlélógójì (41) jẹ́ káàkiri àwọn agbègbè míì nílẹ̀ Japan.
Àwọn alábòójútó àyíká tó wà láwọn agbègbè yìí àtàwọn tó wà ní Ẹ̀ka Tó Ń Yàwòrán Ilé Tó sì Ń Kọ́ Ọ ṣì ń ṣèwádìí kí wọ́n lè mọ bí àwọn nǹkan tó bà jẹ́ ṣe pọ̀ tó, wọ́n sì ń ṣètò bí àwọn ará á ṣe máa jọ́sìn Ọlọ́run nìṣó, kí wọ́n sì tún pèsè àwọn ohun tí wọ́n nílò fún wọn.
À ń gbàdúrà fún àwọn ara wa tí ìjì líle yìí kàn àtàwọn àjálù míì tó wáyé nílẹ̀ Japan.
Ó dá wa lójú pé Baba wa ọ̀run máa tu ọkàn àwọn ará wa yìí lára, á sì mú kí wọ́n mọ́kàn le.
Ó lé ní ẹgbẹ̀rún mẹ́tàdínláàádọ́ta (47,000) àwọn ará wa tó ń gbé láwọn agbègbè tó wà ní ìwọ̀ oòrùn orílẹ̀-èdè Japan tí omíyalé ti ṣọṣẹ́ lóṣù July 2018.
Kò pẹ́ lẹ́yìn náà tí àwọn ẹgbẹ̀rún mẹ́rin ó lé ọgọ́rùn-ún mẹ́sàn (4,900) tó yọ̀ǹda ara wọn láti ṣèrànwọ́ fi bẹ̀rẹ̀ iṣẹ́, wọ́n palẹ̀ ìdọ̀tí mọ́ kúrò nínú ilé àwọn ará àtàwọn Gbọ̀ngàn Ìjọba tó bà jẹ́, wọ́n sì tún wọn ṣe.
Àwọn ará yọ̀ǹda ara wọn láti palẹ̀ ìdọ̀tí mọ́ kúrò nínú Gbọ̀ngàn Ìjọba tó wà lókè.
Àwọn Ìgbìmọ̀ Tó Ń Ṣètò Ìrànwọ́ Nígbà Àjálù ṣètò bí àwọn ará ṣe palẹ̀ ìdọ̀tí mọ́ kúrò nínú Gbọ̀ngàn Ìjọba mẹ́sàn-án tí omíyalé náà bà jẹ́, wọ́n sì tún àwọn Gbọ̀ngàn Ìjọba náà ṣe.
Ní báyìí, àtúnṣe ń lọ lọ́wọ́ lórí Gbọ̀ngàn Ìjọba kan.
Bákan náà, ilé mẹ́rìnlélọ́gọ́sàn-án (184) àwọn ará wa ni wọ́n ti parí àtúnṣe rẹ̀ tàbí tí wọ́n ti tún ṣe díẹ̀ kó lè ṣeé gbé, àwọn ilé mọ́kànlá míì sì wà tí wọ́n ṣètò láti tún ṣe lọ́dún yìí.
Àwòrán Gbọ̀ngàn Ìjọba kan ṣáájú àti lẹ́yìn tí wọ́n tún un ṣe.
Àwòrán ìdílé Abe láti agbègbè Ehime lẹ́yìn táwọn ará parí títún ilé wọn tí omíyalé bà jẹ́ ṣe.
Ìdílé Taro àti Keiko Abe wà lára àwọn tí wọ́n ràn lọ́wọ́, ọmọ mẹ́ta ni wọ́n bí, agbègbè Ehime ni wọ́n sì ń gbé.
Ọjọ́ mẹ́ta péré lẹ́yìn tí omíyalé ba ilé wọn jẹ́, àwọn ará láti àyíká ibẹ̀ dé, wọ́n sì tún ilé náà ṣe, kódà wọ́n tún ilẹ̀ ilé náà ṣe torí omíyalé ti bà á jẹ́.
Kò mọ síbẹ̀ o, àwọn ará lágbègbè náà tún fún àwọn ọmọ wọn ní àwọn bẹ́ẹ̀dì àtàwọn tábìlì tuntun.
Ní September 20, 2018, Arákùnrin Geoffrey Jackson tó jẹ́ ara Ìgbìmọ̀ Olùdarí wá sí orílẹ̀-èdè Japan fún iṣẹ́ kan, ó sì fìyẹn sọ àsọyé kan níbi ìpàdé àkànṣe láti fún àwọn ará níṣìírí, Gbọ̀ngàn Ìjọba kan ní ìlú Okayama ni wọ́n ti ṣèpàdé náà.
Àpapọ̀ iye àwọn ará tó wá sípàdé náà jẹ́ ẹgbẹ̀rún mẹ́rìndínlógójì ó lé ọgọ́rùn-ún mẹ́fà àti mọ́kànléláàádọ́rùn-ún (36,691), lára wọn wá láti àwọn ibi tí ìjì líle àti ìmìtìtì ilẹ̀ ti ṣọṣẹ́ nígbà kan náà lẹ́nu àìpẹ́ yìí ní Japan, wọ́n gbọ́ bí Arákùnrin Jackson ṣe ṣàlàyé bí Jèhófà ṣe máa ń bójú tó àwọn èèyàn Rẹ̀, tó sì máa ń tù wọ́n nínú lásìkò wàhálà.
Arákùnrin Jackson tún fi àsìkò náà bá ọ̀kọ̀ọ̀kan àwọn tí àjálù náà kàn sọ̀rọ̀ ìtùnú.
Àwa àtàwọn ará wa ní Japan ń dúpẹ́ pé a wà nínú ètò Jèhófà, tó ń fìfẹ́ ṣe nǹkan, tó sì jẹ́ ká mọ bí ọ̀rọ̀ wa ṣe jẹ Baba wa ọ̀run lọ́kàn tó.—2 Kọ́ríńtì 1:3, 4.
Arákùnrin Geoffrey Jackson tó wà lára Ìgbìmọ̀ Olùdarí wà pẹ̀lú arábìnrin kan ní Okayama tí omíyalé ti ba nǹkan jẹ́ ní ìwọ̀ oòrùn Japan lóṣù July 2018.
Ó kéré tán, èèyàn mọ́kàndínláàádọ́sàn-án (169) ló ṣòfò ẹ̀mí ní ìwọ̀ oòrùn orílẹ̀-èdè Japan, kódà títí di báyìí, ó lé ní 255,000 agboolé tí ò rí omi tó dáa lò látàrí òjò àrọ̀ọ̀rọ̀dá tó fa omíyalé àti ilẹ̀ tó ya.
Bó tiẹ̀ jẹ́ pé kò sí Ẹlẹ́rìí Jèhófà kankan lára àwọn tó bá ìṣẹ̀lẹ̀ náà lọ, a kó ọgọ́rùn-ún méjì (200) lára wa kúrò níbi tí wọ́n ń gbé tẹ́lẹ̀, arábìnrin wa kan sì ṣèṣe.
Wọ́n tọ́jú arábìnrin wa tó fara pa yìí nílé ìwòsàn, ara rẹ̀ sì ti ń balẹ̀ báyìí.
Ó kéré tán ilé mẹ́tàlélọ́gọ́rùn-ún (103) àwọn ará wa ló bà jẹ́, kódà ọ̀kan tiẹ̀ wà tó jẹ́ pé ńṣe ló bà jẹ́ pátápátá.
Kò mọ síbẹ̀ o, omíyalé yìí tún ba Gbọ̀ngàn Ìjọba mọ́kànlá àti Gbọ̀ngàn Àpéjọ kan jẹ́.
A dá ìgbìmọ̀ mẹ́rin sílẹ̀ tó ń ṣètò ìrànwọ́ nígbà àjálù, kí wọ́n lè tu àwọn ará tọ́rọ̀ kàn nínú, kí wọ́n fún wọn níṣìírí nípa tẹ̀mí, kí wọ́n sì pèsè àwọn ohun tí wọ́n nílò lójú ẹsẹ̀, irú bí oúnjẹ, aṣọ àti omi tó ṣeé mu.
Àwọn ìgbìmọ̀ yìí á sì tún ṣètò ìrànlọ́wọ́ táwọn ará máa nílò lẹ́yìn náà, irú bí wọ́n ṣe máa fọ ilé àwọn ará, tí wọ́n á da oògùn apakòkòrò sí i, tí wọ́n á sì tún àwọn ibi tó bà jẹ́ níbẹ̀ ṣe.
À ń gbàdúrà fún àwọn ará wa tí àjálù yìí dé bá nílẹ̀ Japan bá a ṣe ń retí ìgbà tí Jésù máa fi agbára rẹ̀ fòpin sí gbogbo àjálù tó ń ṣẹlẹ̀ láyé pátápátá.​
"Ní September 6, 2018, ìmìtìtì ilẹ̀ tó lágbára wáyé ní Hokkaido, erékùṣù kan ní gúúsù orílẹ̀-èdè Japan.
Ìmìtìtì ilẹ̀ náà gbẹ̀mí èèyàn mọ́kànlélógójì (41), ó sì ba iná ìjọba jẹ́ gan-an, èyí mú kó ṣòro láti rí ọkọ̀ èrò wọ̀, ó sì tún mú kó ṣòro láti kàn sí àwọn tó wà ní erékùṣù náà.
Ẹ̀ka ọ́fíìsì wa ní Japan so pé bó tiẹ̀ jẹ́ pé kò sí ìkankan lára àwọn ará wa tó bá ìmìtìtì ilẹ̀ náà lọ, àwọn ará wa méje ló fara pa.
Ọgọ́rùn-ún (100) ilé àwọn ará wa àti Gbọ̀ngàn Ìjọba mẹ́rin ló bà jẹ́.
Gẹ́rẹ́ lẹ́yìn ìmìtìtì ilẹ̀ náà, ẹ̀ka ọ́fíìsì ṣètò pé kí àwọn ará kó oúnjẹ, omi àtàwọn nǹkan míì tó ṣe pàtàkì lọ fún àwọn ará tó wà lágbègbè tí àjálù yìí ti ṣẹlẹ̀.
A ṣètò Ìgbìmọ̀ Tó Ń Ṣètò Ìrànwọ́ Nígbà Àjálù láti wá bí àwọn ará wa níbẹ̀ ṣe máa rí àwọn nǹkan tí wọ́n máa nílò lọ́jọ́ iwájú.
Àdúrà wa ni pé kí Jèhófà máa fún àwọn ará wa tó wà níbi tí àjálù yìí ti ṣẹlẹ̀ ní ìbàlẹ̀ ọkàn.—Fílípì 4:6, 7."
"Ní August 28, ọdún 2019, òjò àrọ̀ọ̀rọ̀dá tó rọ̀ ní àgbègbè Kyushu lórílẹ̀-èdè Japan fa àkúnya omi tó lágbára gan-an.
Ṣe làwọn odò kún àkúnya, àwọn àgbègbè míì sì léwu torí pé ó ṣeé ṣe kí àwọn òkè ya lulẹ̀. Ìdí nìyẹn tí wọ́n fi sọ fún àwọn èèyàn tó ju ẹgbẹ̀rún lọ́nà ọgọ́rùn-ún mẹ́jọ (800,000) pé kí wọ́n kúrò lágbègbè yẹn.
Ẹ̀ka ọ́fíìsì tó wà lórílẹ̀-èdè Japan ròyìn pé, àwọn arákùnrin àtàwọn arábìnrin méjìlélọ́gọ́rin (82) ló fi ilé wọn sílẹ̀.
Ìròyìn tó dé kẹ́yìn sọ pé ogójì (40) ilé àwọn arákùnrin àtàwọn arábìnrin ló bà jẹ́ àti Gbọ̀ngàn Ìjọba kan tí kò fi bẹ́ẹ̀ bà jẹ́ púpọ̀.
Ẹ̀ka ọ́fíìsì náà dá Ìgbìmọ̀ Tó Ń Ṣètò Ìrànwọ́ Nígbà Àjálù sílẹ̀ kí wọ́n lè bójú tó àwọn akéde tí àjálù náà kàn.
Àwọn alábòójútó àyíká, àwọn alàgbà àtàwọn akéde pèsè ìtùnú àti ìṣírí látinú Bíbélì, wọ́n sì fún wọn láwọn nǹkan míì bí oúnjẹ àti aṣọ.
Inú wa dùn pé ìfẹ́ ń mú kí ọ̀pọ̀ èèyàn ran àwọn arákùnrin àtàwọn arábìnrin wa lọ́wọ́.​—2 Kọ́ríńtì 8:4."
"Ní September 21 sí 23, 2019, ìjì líle tí wọ́n ń pè ní Tapah rọ́ lu apá gúúsù orílẹ̀-èdè Japan pẹ̀lú atẹ́gùn àti òjò tó lágbára.
Ìjì yìí ò jẹ́ káwọn ọkọ̀ òfúrufú àtàwọn ọkọ̀ ojú irin lè rìn, kódà, àwọn ilé tó lé ní ẹgbẹ̀rún lọ́nà ọgbọ̀n (30,000) ni ìjì náà ba iná mànàmáná wọn jẹ́.
Ní ìlú Okinawa àti Kyushu, àwọn tó ju àádọ́ta (50) lọ ló fara pa.
Ẹ̀ka ọ́fíìsì Japan ròyìn pé àwọn akéde márùn-ún ló fara pa, wọ́n sì ní láti gbé arábìnrin kan lára wọn lọ sílé ìwòsàn.
Yàtọ̀ síyẹn, ilé àwọn arákùnrin wa tó bà jẹ́ lé ní àádọ́ta (50).
Ìgbìmọ̀ Tó Ń Ṣètò Ìrànwọ́ Nígbà Àjálù àti àwọn arákùnrin tó tóótun ti ń bójú tó ohun táwọn ará yìí nílò nípa tara àti nípa tẹ̀mí.
Ẹ̀ka ọ́fíìsì Japan á máa báa lọ láti ṣàyẹ̀wò àwọn ohun tí ìjì yìí bà jẹ́, wọ́n á sì máa pèsè ìrànwọ́ táwọn ará nílò.
Àdúrà wa ni pé kí àwọn ará wa ní Japan máa bá a lọ láti gbára lé Jèhófà, Ọlọ́run ìtùnú ní àkókò wàhálà yìí.​—Sáàmù 94:19."
"Ní Tuesday, September 4, 2018, ìjì líle kan jà ní ìwọ̀ oòrùn orílẹ̀-èdè Japan, ó ti lé lógún ọdún tírú ẹ̀ ti jà kẹ́yìn nílẹ̀ náà.
Àwọn aláṣẹ ní kí ọ̀pọ̀lọpọ̀ kúrò níbi tí wọ́n wà. Bó sì ṣe máa ń rí lọ́pọ̀ ìgbà, ohun tí ìjì líle náà bà jẹ́ kì í ṣe kékeré.
Ẹ̀ka ọ́fíìsì wa ní Japan sọ pé kò sí Ẹlẹ́rìí Jèhófà kankan tó bá ìṣẹ̀lẹ̀ náà lọ.
Àmọ́ ó kéré tán, àwọn ará mẹ́ẹ̀ẹ́dógún (15) ló fara pa, ilé tó sì bà jẹ́ tó ọgọ́rùn-ún márùn-ún àti méjìdínlógójì (538), ó kéré tán.
Àyẹ̀wò àkọ́kọ́ tí wọ́n ṣe fi hàn pé Gbọ̀ngàn Ìjọba mẹ́rìnlélógójì (44) ló bà jẹ́.
Ìgbìmọ̀ Tó Ń Ṣètò Ìrànwọ́ Nígbà Àjálù, tó wà ní ìlú Osaka àti ní Sakai ti jọ ń ṣiṣẹ́ lórí bí wọ́n á ṣe ṣèrànlọ́wọ́, títí kan bí wọ́n á ṣe tún àwọn ilé tó bà jẹ́ ṣe, tí wọ́n á sì bẹ àwọn tọ́rọ̀ náà kàn wò.
A dúpẹ́ pé Jèhófà mọ ìṣòro tí àwọn ará wa ń ní, ó sì ń lo ẹgbẹ́ ará láti ràn wọ́n lọ́wọ́.—Sáàmù 34:19."
"Ní Saturday, April 13, 2019, Arákùnrin Stephen Lett tó jẹ́ ara Ìgbìmọ̀ Olùdarí mú Bíbélì Mímọ́ ti Ìtumọ̀ Ayé Tuntun tá a tún ṣe jáde lédè Japanese.
Inú àkànṣe ìpàdé kan tí wọ́n ṣe ní Gbọ̀ngàn ìwòran tí wọ́n ń pè ní Noevir Stadium Kobe ní ìlú Kobe lórílẹ̀-èdè Japan la ti mú Bíbélì náà jáde, àwọn ẹgbẹ̀rún lọ́nà ogún ó lé ọgọ́rùn-ún mẹ́jọ àti méjìndínláàádọ́rin (20,868) ló sì wá síbẹ̀.
A ta àtagbà ìpàdé náà sí Gbọ̀ngàn Àpéjọ mẹ́jọ àti ọ̀pọ̀ Gbọ̀ngàn Ìjọba káàkiri àwọn agbègbè tó wà lábẹ́ ẹ̀ka ọ́fíìsì Japan.
Àwọn ará tí kò láǹfààní láti wo ìpàdé náà bó ṣe ń lọ lọ́wọ́ wò ó lọ́sàn-án ọjọ́ náà tàbí lọ́jọ́ kejì láwọn Gbọ̀ngàn Ìjọba.
Àpapọ̀ iye àwọn tó gbádùn ìpàdé yìí lópin ọ̀sẹ̀ náà jẹ́ ẹgbẹ̀rún lọ́nà ọgọ́rùn-ún méjì ó lé ogún, ọgọ́rùn-ún mẹ́rin àti mọ́kànléláàádọ́rùn-ún (220,491).
Gbọ̀ngàn ìwòran Noevir Stadium Kobe
A bá àwọn ará wa tó ń sọ èdè Japanese yọ̀ kárí ayé, láwọn ìjọ àtàwọn àwùjọ pẹ̀lú àwọn tí kò tíì di àwùjọ tí iye wọn fẹ́rẹ̀ẹ́ tó ẹgbẹ̀rún mẹ́ta (2,950), pé àwọn náà ti ní Bíbélì Ìtumọ̀ Ayé Tuntun, ẹ̀bùn pàtàkì ló jẹ́ látọ̀dọ̀ Jèhófà, ó sì wúlò téèyàn bá fẹ́ kẹ́kọ̀ọ́ àti lóde ẹ̀rí.—Hébérù 4:12.
Inú àwọn ará ń dùn bí wọ́n ṣe gba Bíbélì Ìtumọ̀ Ayé Tuntun tiwọn
Ọdún márùndínláàádọ́ta (45) sẹ́yìn la kọ́kọ́ mú Bíbélì Ìtumọ̀ Ayé Tuntun jáde lórílẹ̀-èdè Japan.
Arákùnrin Lyman Swingle tó jẹ́ ara Ìgbìmọ̀ Olùdarí nígbà yẹn ló mú Ìwé Mímọ́ Kristian Lédè Griki ní Ìtumọ̀ Ayé Titun jáde lédè Japanese ní Àpéjọ Àgbáyé “Ìsẹ́gun Àtọ̀runwá” tí wọ́n ṣe ní ìlú Osaka, lórílẹ̀-èdè Japan lọ́dún 1973.
Láàárín ọdún mẹ́sàn tá a mú un jáde, a pín ẹ̀dà mílíọ̀nù kan ó lé ẹgbẹ̀rún lọ́nà ogóje (1,140,000) fáwọn èèyàn, èyí sì fẹ́rẹ̀ẹ́ tó ìlọ́po márùndínlọ́gọ́rin (75) iye àwọn akéde tó wà ní Japan nígbà náà. Lọ́dún 1982, a mú Ìwé Mímọ́ ní Ìtumọ̀ Ayé Tuntun jáde lódindi, orílẹ̀-èdè Japan la ti tẹ̀ ẹ́, ibẹ̀ náà la sì ti dì í pọ̀.
Ní báyìí tá a ti mú Bíbélì tá a tún ṣe jáde lédè Japanese, ọdún 2019 yìí jẹ́ mánigbàgbé nínú ìtàn iṣẹ́ ìtumọ̀ Bíbélì táwa èèyàn Jèhófà ṣe ní Japan.
A ti mú Bíbélì Ìtumọ̀ Ayé Tuntun jáde lódindi tàbí lápá kan ní èdè mọ́kàndínlọ́gọ́sàn-án (179), méjìlélógún (22) lára rẹ̀ sì jẹ́ odindi Bíbélì tá a tún ṣe látinú ẹ̀dà tó jáde lédè Gẹ̀ẹ́sì lọ́dún 2013."
"Ní October 25 àti 26, 2019, ìjì líle kan tí wọ́n pè ní Typhoon Bualoi ṣọṣẹ́ ní apá ìlà oòrùn etíkun Japan.
Ohun tó gba àfiyèsí ni pé, ìjì yìí ni ìkẹta nínú àwọn ìjì tó jà ní ìlà oòrùn Japan láti September, lẹ́yìn tí ìjì líle tí wọ́n pè ní Typhoon Faxai àti Hagibis jà.
Ìjì líle tó ṣẹ̀ṣẹ̀ jà yìí mú kí àwọn odò kún àkúnya, èyí sì fa ọ̀pọ̀ omíyalé ní agbègbè náà.
Ó kéré tán, ilé mọ́kànlélọ́gọ́rin (81) tó jẹ́ tàwọn ará wa ló bà jẹ́.
A ò gbọ́ pé ará wa kankan kú, àmọ́ arábìnrin kan fara pa. Ìjì yìí ti kó àwọn arákùnrin àtàwọn arábìnrin wa tó ń gbé ní ìpínlẹ̀ Chiba sí ìdààmú gan-an.
Ìgbìmọ̀ mẹ́ta tó ń pèsè ìrànwọ́ nígbà àjálù ló ṣètò ìrànwọ́ láwọn agbègbè yìí nígbà tí ìjì Faxai àti Hagibis jà, àwọn náà ló sì ń pèsè ìrànwọ́ báyìí lẹ́yìn tí ìjì Bualoi jà.
Ẹ̀ka ọ́fíìsì wa tó wà ní Japan ń ti àwọn ìgbìmọ̀ yìí lẹ́yìn kí wọ́n lè pèsè ìtọ́jú ní kíákíá fáwọn ará wa.
Wọ́n ń bá wọn tún àyíká wọn ṣe, wọ́n ń pèsè àwọn oògùn tó ń pa kòkòrò, wọ́n sì ń tún àwọn ilé wọn tó bà jẹ́ ṣe.
Àwọn alábòójútó àyíká ń ṣe gbogbo ohun tí wọ́n lè ṣe láti fún àwọn ará ní ìṣírí, kí wọ́n sì tù wọ́n nínú.
Lákòókò tí nǹkan le yìí, à ń gbàdúrà fún àwọn ará wa tó wà ní Japan, a sì mọ̀ pé Jèhófà máa bójú tó àwọn ìránṣẹ́ ẹ̀ tí “àárẹ̀ bá ẹ̀mí wọn” nítorí àjálù yìí.—Sáàmù 34:18."
"Ní September 9, 2019 ìjì líle tó ń jẹ́ Faxai jà nítòsí Tokyo, lórílẹ̀-èdè Japan.
Afẹ́fẹ́ ìjì náà lágbára débi pé ó fẹ́ dé ibi tó jìnnà tó ọgọ́sàn-án (180) kìlómítà láàárín wákàtí kan péré, ó sì ba iná mànàmáná ilé tó tó ẹgbẹ̀rún lọ́nà ọgọ́rùn-ún márùn-ún ó lé ọgọ́rin (580,000) jẹ́.
Ó kéré tán èèyàn mẹ́ta ló pàdánù ẹ̀mí wọn.
Ẹ̀ka ọ́fíìsì wa ní Japan ròyìn pé kò sí akéde kankan tó kú, àmọ́ méje lára àwọn ará wa fara pa.
Àyẹ̀wò tí wọ́n kọ́kọ́ ṣe fi hàn pé ọgọ́rùn-ún mẹ́jọ àti márùndínlọ́gọ́rùn-ún (895) ilé àwọn ará ló bà jẹ́, Gbọ̀ngàn Ìjọba méjìdínlọ́gbọ̀n (28) àti Gbọ̀ngàn Àpéjọ kan tó wà ni Chiba sì bà jẹ́.
Ẹ̀ka ọ́fíìsì ṣì ń ṣàyẹ̀wò àwọn ohun tí ìjì náà bà jẹ́ kí wọ́n lè pèsè ohun táwọn ará nílò.
A gbàdúrà pé kí Jèhófà, “Ọlọ́run tó ń fúnni ní ìfaradà àti ìtùnú” máa tu àwọn ará wa yìí nínú, kó sì dúró tì wọ́n lásìkò àjálù yìí.​—Róòmù 15:5"
"Nursultan Nazarbayev tó jẹ́ ààrẹ orílẹ̀-èdè Kazakhstan ní kí wọ́n dá Teymur Akhmedov sílẹ̀, wọ́n sì mú un kúrò látìmọ́lé ní April 4, 2018.
Ṣáájú àkókò yẹn, ní March 27, 2018, àwọn aláṣẹ gba Arákùnrin Akhmedov láyè pé kó lọ ṣiṣẹ́ abẹ pàjáwìrì nílé ìwòsàn kan tó wà nílùú Almaty.
Ibẹ̀ ló wà báyìí, tí ara rẹ̀ ti ń yá díẹ̀díẹ̀.
Arákùnrin Akhmedov, ẹni ọdún mọ́kànlélọ́gọ́ta (61), ti wà lẹ́wọ̀n láti January 18, 2017, torí pé ó kàn ń ṣe ohun tó gbà gbọ́. Inú ẹ̀ dùn pé òun ti pa dà sílé báyìí lọ́dọ̀ àwọn mọ̀lẹ́bí òun.
Gbogbo wa là ń yọ̀ torí pé Jèhófà ti gba ìránṣẹ́ rẹ̀ olóòótọ́ sílẹ̀.​—2 Sámúẹ́lì 22:2."
"Bẹ̀rẹ̀ láti May 11 sí November 10, 2018, àwọn Ẹlẹ́rìí Jèhófà ní Kazakhstan pe àwọn èèyàn pé kí wọ́n wá ṣèbẹ̀wò sí Gbọ̀ngàn Ìjọba.
Lára àwọn tó tẹ́wọ́ gba ìkésíni náà ni àwọn òṣìṣẹ́ ìjọba, àwọn akọ̀ròyìn, àwọn ọ̀mọ̀wé àtàwọn míì, ètò yìí sì jẹ́ kí gbogbo wọn mọ púpọ̀ sí i nípa àwọn Ẹlẹ́rìí Jèhófà. Lápapọ̀, àwọn tó lé ní ẹgbẹ̀rún kan ààbọ̀ (1,500) ló lọ.
Àwọn ìlú tí Gbọ̀ngàn Ìjọba náà wà: (1) Öskemen, (2) Qaraghandy, (3) Qostanay, (4) Semey, (5) Shymkent, (6) Taldyqorghan àti (7) Taraz.
Àwọn Gbọ̀ngàn Ìjọba kan ni wọ́n ṣètò pé káwọn èèyàn náà wá, àwọn Gbọ̀ngàn Ìjọba náà sì wà ní ìlú méje ọ̀tọ̀ọ̀tọ̀, ìyẹn ní ìlú Öskemen, Qaraghandy, Qostanay, Semey, Shymkent, Taldyqorghan àti Taraz.
Àwọn tó wá síbẹ̀ rí àwọn nǹkan tó jẹ́ kí wọ́n mọ púpọ̀ sí i nípa ìtàn àwa Ẹlẹ́rìí Jèhófà ní Kazakhstan, èyí tó ti bẹ̀rẹ̀ láti ọdún 1892.
Wọ́n tún rí àwọn nǹkan tó jẹ́ kí wọ́n mọ̀ nípa ohun tá à ń gbé ṣe lóde òní, irú bíi Bíbélì Mímọ́ ti Ìtumọ̀ Ayé Tuntun tá a mú jáde lédè Kazakh lọ́dún 2014.
Arákùnrin Bekzat Smagulov tó ń ṣiṣẹ́ ní Ẹ̀ka Tó Ń Bójú Tó Ọ̀ràn Òfin àti Ẹ̀ka Tó Ń Gbéròyìn Jáde ní ọ́fíìsì àwa Ẹlẹ́rìí Jèhófà tó wà ní Kazakhstan sọ pé: “Ọ̀pọ̀ èèyàn ló tẹ́wọ́ gba ìkésíni náà láti wá ṣèbẹ̀wò, ìyẹn sì ràn wọ́n lọ́wọ́ láti mọ irú ẹni tá a jẹ́ gan-an.
Lára àwọn tó wá síbẹ̀ ni àwọn òṣìṣẹ́ láti Ẹ̀ka Tó Ń Rí sí Ọ̀rọ̀ Ẹ̀sìn lórílẹ̀-èdè Kazakhstan, àtàwọn akọ̀ròyìn láti ilé iṣẹ́ oníròyìn Kazakhstan-Öskemen, títí kan aṣojú láti ilé iṣẹ́ ìwé ìròyìn Rudnyi Altai àti Semei Vesti.”
Ẹnì kan tó jẹ́ olórí ní Ẹ̀ka Tó Ń Bójú Tó Ọ̀rọ̀ Ẹ̀sìn ní àgbègbè kan, pẹ̀lú àwọn òṣìṣẹ́ méjì míì láti ẹ̀ka yẹn wà lára àwọn tó wá sí Gbọ̀ngàn Ìjọba tó wà ní ìlú Taldyqorghan.
A tún rí ẹnì kan tó jẹ́ olóòtú ilé iṣẹ́ ìwé ìròyìn Zhetysu Dialog, nígbà tó yá, ẹni yìí gbé àpilẹ̀kọ kan jáde nínú ìwé ìròyìn níbi tó ti ṣe ìfọ̀rọ̀wánilẹ́nuwò fún àwọn kan tó yọ̀ǹda ara wọn ní Gbọ̀ngàn Ìjọba náà.
Yàtọ̀ síyẹn, àwọn ará wa tún pín Bíbélì Mímọ́ ti Ìtumọ̀ Ayé Tuntun tó lé ní ọgọ́rùn-ún márùn-ún ó lé lọ́gọ́ta (560) fáwọn èèyàn ní èdè Kazakh àti Russian, àwọn èdè tí wọ́n ń sọ jù ní Kazakhstan.
Inú wa dùn pé gbogbo nǹkan lọ bó ṣe yẹ, èyí sì mú ìyìn bá orúkọ Jèhófà, ó tún jẹ́ káwọn èèyàn mọ̀ nípa “àwọn iṣẹ́ rere” wa.—Mátíù 5:16."
"Lẹ́yìn tí Ààrẹ Nursultan Nazarbayev tó jẹ́ olórí orílẹ̀-èdè Kazakhstan dá Arákùnrin Teymur Akhmedov sílẹ̀, wọ́n mú un kúrò látìmọ́lé ní April 4, 2018. Gbogbo ọjọ́ tó lò lẹ́wọ̀n jẹ́ ọgọ́rùn-ún mẹ́rin ó lé mọ́kànlélógójì (441).
Torí pé ó kàn ń sọ ohun tó gbà gbọ́ fáwọn míì ni àwọn aláṣẹ ṣe mú un.
Kò pẹ́ lẹ́yìn tí wọ́n dá Teymur sílẹ̀ lẹ́wọ̀n tí Ọ́fíìsì Agbéròyìnjáde (ìyẹn OPI) tó wà ní oríléeṣẹ́ àwa Ẹlẹ́rìí Jèhófà nílùú Warwick, ìpínlẹ̀ New York, bá òun àti Mafiza ìyàwó ẹ̀ sọ̀rọ̀, àwọn méjèèjì ti pa dà báyìí sí ilé wọn nílùú Astana, tó jẹ́ olú ìlú Kazakhstan. Àwọn ohun tí wọ́n sọ la kọ sísàlẹ̀ yìí.
A ti gé e kúrú, a sì kọ́ ọ lọ́nà tó máa jẹ́ kó ṣe kedere.
OPI: Arákùnrin Akhmedov, a máa kọ́kọ́ fẹ́ mọ̀ sí i nípa yín.
Ìgbà wo lẹ di Ẹlẹ́rìí Jèhófà?
Teymur Akhmedov: October 9, 2005 ni mo ṣèrìbọmi.
Kí n tó kẹ́kọ̀ọ́ òtítọ́, mi ò gbà pé Ọlọ́run wà.
Ọ̀pọ̀ ọdún ni mi ò fi gba Ọlọ́run gbọ́, mi ò sì ṣe ẹ̀sìn kankan.
Nígbà tó yá, àwọn Ẹlẹ́rìí Jèhófà bẹ̀rẹ̀ sí í kọ́ ìyàwó mi lẹ́kọ̀ọ́, ó sì wù mí kí n mo ohun tí wọ́n jọ máa ń sọ.
Mo bá bẹ̀rẹ̀ sí í dúró sẹ́yìn ilẹ̀kùn, kí n lè máa fetí kọ́ ohun tí wọ́n ń sọ.
Nígbà tí mo mọ ohun tí wọ́n ń kọ́ ọ, ó yà mí lẹ́nu torí pé kìkì àwọn nǹkan rere-rere ni wọ́n jọ ń sọ.
Nígbà tó yá, àwọn Ẹlẹ́rìí fi mí mọ Arákùnrin Veslav tó wá láti Poland àmọ́ tó ń gbé ní Kazakhstan.
Lọ́jọ́ tá a kọ́kọ́ jọ sọ̀rọ̀, mo sọ fún un pé: ‘Ìbéèrè kan ṣoṣo ni màá bi ẹ́.
Tí ìdáhùn rẹ bá tẹ́ mi lọ́rùn, àá dọ̀rẹ́, àá sì jọ máa bá ọ̀rọ̀ wa lọ.
Àmọ́ tí mi ò bá gba ti ìdáhùn tó o fún mi, a ò ní lè jọ máa bọ́rọ̀ yìí lọ mọ́. O ò ní bínú sí mi, èmi náà ò sì ní bínú sí ẹ.’
Mo wá bi Arákùnrin Veslav léèrè ohun tó máa ń ṣẹlẹ̀ sí àwọn tó ti kú.
Ó ṣí Bíbélì sí Oníwàásù 9:​5, ó sì sọ pé, ‘Tó o bá ka ẹsẹ Bíbélì yìí, wàá mọ ohun tó máa ń ṣẹlẹ̀ sáwọn tó ti kú.’
Nígbà tí mo kà á, mo rí i pé òtítọ́ nìyí.
Torí náà mo gbà pé kó máa wá, kó sì máa kọ́ mi kẹ́kọ̀ọ́ Bíbélì.
Bẹ́ ẹ ṣe kẹ́kọ̀ọ́ Bíbélì nìyẹn, tẹ́ ẹ sì ṣèrìbọmi lọ́dún 2005.
Ẹ jẹ́ ká fi ìyókù lẹ̀ ná, ká sọ̀rọ̀ nípa ohun tó ṣẹlẹ̀ káwọn aláṣẹ tó mú yín.
Ní May 2016, ẹ pàdé àwọn ọkùnrin kan tí wọ́n láwọn nífẹ̀ẹ́ sí ohun táwọn Ẹlẹ́rìí Jèhófà gbà gbọ́.
Láàárín oṣù mélòó kan, ẹ máa ń lọ bá wọn jíròrò látinú Bíbélì.
Tẹ́ ẹ bá ronú pa dà sẹ́yìn sí àwọn ìgbà tẹ́ ẹ jọ máa ń jíròrò yẹn, ǹjẹ́ ẹ rántí ohunkóhun tí wọ́n sọ tàbí tí wọ́n ṣe tó mú ìfura lọ́wọ́?
TA: Bẹ́ẹ̀ ni, mo sọ fún wọn pé tá a bá ń ṣe ìkẹ́kọ̀ọ́ Bíbélì, a sábà máa ń fẹ́ kó jẹ́ ẹnì kọ̀ọ̀kan làá máa kọ́ lẹ́kọ̀ọ́ dípò kó jẹ́ àwọn kan tó kóra jọ.
Mo sọ pé á dáa kí kálukú wọn máa ṣe ìkẹ́kọ̀ọ́ yìí lọ́tọ̀ọ̀tọ̀, àmọ́ gbogbo ìgbà tí mo bá ti sọ bẹ́ẹ̀ ni wọ́n máa ń sọ pé rárá, ìjíròrò aláwùjọ yẹn làwọn fẹ́.
Yàtọ̀ síyẹn, ẹ̀ẹ̀mélòó kan wà tí wọ́n pe àwọn míì wá síbi tá a ti ń kẹ́kọ̀ọ́ pé kí wọ́n wá dara pọ̀ mọ́ wa, wọ́n á sì ní kí n tún ohun tá a jíròrò nígbà tá a kẹ́kọ̀ọ́ gbẹ̀yìn sọ.
Mafiza Akhmedov: Ìgbà kan wà témi náà wà níbi tí wọ́n ti ń ṣe ìkẹ́kọ̀ọ́.
Mo kíyè sí i pé wọ́n ń sọ̀rọ̀ nípa ẹ̀sìn ọ̀tọ̀ọ̀tọ̀, bó tiẹ̀ jẹ́ pé ó ti ṣe díẹ̀ tí wọ́n ti ń kẹ́kọ̀ọ́.
Mo tún kíyè sí i pé ilé tí wọ́n ń gbé gbówó lórí ju ilé tí ọ̀pọ̀ àwọn akẹ́kọ̀ọ́ máa ń lè sanwó ẹ̀.
Mo sọ fún wọn pé ìgbésí ayé olówó tí wọ́n ń gbé yàtọ̀ sí èyí tí ọ̀pọ̀ àwọn akẹ́kọ̀ọ́ ń gbé.
Àmọ́ mo rí i pé ohun tí mo sọ bà wọ́n, ara wọn ò sì lélẹ̀.
Nígbà tá à ń kúrò níbẹ̀ lọ́jọ́ yẹn, ṣe ni wọ́n pe Teymur sẹ́gbẹ̀ẹ́ kan, èmi lọ dúró dè é níta, wọ́n sì sọ fún un pé kó má mú mi wá síbẹ̀ mọ́ nígbàkigbà tó bá fẹ́ wá kọ́ àwọn lẹ́kọ̀ọ́.
Ìgbà wo lẹ wá mọ̀ pé kì í ṣe pé àwọn ọkùnrin tẹ́ ẹ̀ ń kọ́ lẹ́kọ̀ọ́ Bíbélì fẹ́ràn àwọn Ẹlẹ́rìí Jèhófà, pé àwọn ọlọ́pàá ọ̀tẹlẹ̀múyẹ́ ilẹ̀ Kazakhstan (ìyẹn KNB) ni wọ́n ń bá ṣiṣẹ́?
TA: Ìgbà tí ìgbẹ́jọ́ bẹ̀rẹ̀ ni mo tó mọ̀ pé àwọn ọlọ́pàá KNB ni wọ́n ń bá ṣiṣẹ́.
Báwo ló ṣe rí lára yín nígbà tí wọ́n mú yín, tí wọ́n sì fẹ̀sùn kàn yín pé ẹ̀ ń “mú kí àwọn èèyàn kórìíra ẹ̀sìn míì” ẹ sì ń “gbé [ẹ̀sìn] kan ga ju ẹ̀sìn míì lọ”?
TA: Ká sòótọ́, nígbà tí wọ́n mú mi, ṣe ni mo rò pé bí wọ́n ṣe sọ, wọ́n máa mú mi lọ sí àgọ́ ọlọ́pàá kí n lè ṣàlàyé tẹnu mi, kí wọ́n sì dá mi sílẹ̀.
Mo ṣe tán láti gbèjà ara mi, kí n sì ṣàlàyé ohun tí mo bá àwọn ọkùnrin náà sọ.
Àmọ́ ohun tó wá ṣẹlẹ̀ yà mí lẹ́nu, síbẹ̀ mi ò bẹ̀rù.
Ẹ̀sùn tí wọ́n fi kàn mí pé mò ń mú kí àwọn èèyàn kórìíra ẹ̀sìn míì, pé mo sì ń lọ́wọ́ sí iṣẹ́ agbawèrèmẹ́sìn yà mí lẹ́nu gan-an.
Ọ̀rọ̀ nípa Jèhófà làwa Ẹlẹ́rìí Jèhófà máa ń sọ, a ò sì fìgbà kankan ní ohunkóhun ṣe pẹ̀lú ìkórìíra tàbí ìyapa.
Ó dá mi lójú hán-ún hán-ún pé mi ò mọwọ́ mẹsẹ̀, mo sì mọ̀ pé Jèhófà máa ràn mí lọ́wọ́.
Òótọ́ ni pé ọkàn mi ò balẹ̀, àmọ́ mo rántí ìmọ̀ràn tó wà nínú Bíbélì, tó sọ pé, “ẹ . . . kó gbogbo àníyàn yín lé [Jèhófà], nítorí ó bìkítà fún yín.”​—1 Pétérù 5:7.
Nígbà tó di May 2, 2017, lẹ́yìn tẹ́ ẹ ti lo ohun tó lé ní oṣù mẹ́ta ní àtìmọ́lé, ilé ẹjọ́ kan nílùú Astana rán yín lọ sí ẹ̀wọ̀n ọdún márùn-ún, wọ́n sì tún fòfin dè yín pé ẹ ò gbọ́dọ̀ ṣe iṣẹ́ ìkọ́nilẹ́kọ̀ọ́ Bíbélì fún ọdún mẹ́ta.
Báwo ló ṣe rí lára yín?
TA: Nígbà tí ilé ẹjọ́ sọ bẹ́ẹ̀, mo gbà lọ́kàn ara mi pé tó bá pọn dandan, màá lo ọdún márùn-ún tí wọ́n dá fún mi pé.
Ohun tí mo rò ni pé: ‘Tó bá jẹ́ pé àdánwò ló délẹ̀ yìí, Jèhófà ń rí gbogbo ẹ̀, ó mọ bó ṣe máa pẹ́ tó àtìgbà tó máa dópin.’
Torí náà, mo pinnu pé bó ti wù kó pẹ́ tó, màá dúró.
Ilé tí wọ́n ti ń tún ìwà ẹni ṣe nílùú Pavlodar ní Kazakhstan, ibẹ̀ ni Arákùnrin Akhmedov ti ṣẹ̀wọ̀n.
Àmọ́ nígbà tí wọ́n fi yín sẹ́wọ̀n yẹn, a mọ̀ pé ẹ̀ ń bá àìsàn kan tó le fínra. Àbí bẹ́ẹ̀ kọ́?
TA: Bẹ́ẹ̀ ni, ara mi ò yá, mo sì ń gbàtọ́jú kó tó di pé wọ́n rán mi lọ sẹ́wọ̀n.
Àmọ́ nígbà tí wọ́n ti mú mi, wọ́n dá ìtọ́jú tí mò ń gbà dúró, àìsàn tó ń ṣe mí wá bẹ̀rẹ̀ sí í le sí i.
Arábìnrin Mafiza, báwo lọ̀rọ̀ yìí ṣe rí lára yín lásìkò yẹn?
MA: Ẹ̀rù bà mí gan-an, ìbànújẹ́ sì dorí mi kodò.
Kódà, ó nira fún mi láti máa dá ìpinnu ṣe látìgbà tí wọ́n ti fi Teymur sẹ́wọ̀n, torí pé láti ọdún méjìdínlógójì (38) tá a ti ṣègbéyàwó, nǹkan kan ò yà wá rí.
Àmọ́ Teymur sọ̀rọ̀ kan tó tù mí nínú, ó ní: ‘Fọkàn balẹ̀, ṣó o gbọ́? Ṣó o rí ọdún márùn-ún tá a máa fi pín yà yìí, ọdún mẹ́ẹ̀ẹ́dọ́gbọ̀n (25) ni Jèhófà máa fi rọ́pò ẹ̀ fún wa kí Ìjọba Ọlọ́run tó dé!’
Kí lohun míì tó tún ràn yín lọ́wọ́ nígbà tí ọkọ yín wà lẹ́wọ̀n?
MA: Àwọn ará lọ́kùnrin lóbìnrin ràn mí lọ́wọ́ gan-an.
Nígbà tí wọ́n fi Teymur sẹ́wọ̀n, kí n má parọ́, ṣe ni mo rò pé ẹ̀rù á máa ba gbogbo wọn láti wá wò mí torí ohun tó fà á táwọn aláṣẹ fi mú Teymur.
Kódà, àwọn ọ̀tẹlẹ̀múyẹ́ ń ṣọ́ ilé wa, wọ́n sì ń ṣọ́ àwọn nǹkan tá à ń ṣe.
Àmọ́ lọ́jọ́ kan, alàgbà kan àti ìyàwó ẹ̀ wá wò mí, ìṣírí ńlá gbáà ló jẹ́ fún mi.
Mo bi wọ́n pé, ‘Ṣé ẹ̀rù ò bà yín láti wá síbí ni?’
Wọ́n dáhùn pé, ‘Kí ló fẹ́ máa bà wá lẹ́rù?
Níbi táyé dé yìí, kò ṣòro rárá fáwọn aláṣẹ láti rí wa mú.
Tí wọ́n bá fẹ́ mú wa, kò ju kí wọ́n fi kọ̀ǹpútà wá àdírẹ́sì ibi tá a ti ń pè lórí fóònù.’
Àwọn alàgbà wá ṣèbẹ̀wò olùṣọ́ àgùntàn sọ́dọ̀ mi, wọ́n sì rọ̀ mí pé kí n má jẹ́ kí àdánwò tó délẹ̀ yìí kó ìrẹ̀wẹ̀sì bá mi, àmọ́ kí n jẹ́ kí ìgbàgbọ́ mi àti àjọṣe mi pẹ̀lú Jèhófà túbọ̀ lágbára.
Arákùnrin Teymur, kí ló ràn yín lọ́wọ́ tẹ́ ẹ fi fara da àdánwò yìí, tẹ́ ò sì sọ̀rètí nù?
Wọ́n de Arákùnrin Akhmedov mọ́ bẹ́ẹ̀dì nílé ìwòsàn ní Almaty kó tó di pé wọ́n tú u sílẹ̀.
Bó tiẹ̀ jẹ́ pé wọn ò kọ́kọ́ jẹ́ kó gbàtọ́jú, nígbà tí ìlera ẹ̀ di pé ó ń burú sí i, àwọn aláṣẹ gbà kí wọ́n tọ́jú rẹ̀.
TA: Àdúrà ni! Ojoojúmọ́ ni mo máa ń gbàdúrà pé kí Jèhófà tọ́ mi sọ́nà, kó fún mi lóye, kó sì jẹ́ kí n lókun kí n lè máa láyọ̀, kí n lè jẹ́ olóòótọ́, kí n má sì bọ́hùn lásìkò ìṣòro yìí.
Mo sì rí bó ṣe dáhùn àdúrà mi.
Kò fi mí sílẹ̀, torí mi ò mọ̀ ọ́n lára pé mo dá wà nínú ẹ̀wọ̀n.
Kíka Bíbélì náà ràn mí lọ́wọ́.
Nínú ọ̀kan lára àwọn ọgbà ẹ̀wọ̀n yẹn, Bíbélì wà lárọ̀ọ́wọ́tó mi ní gbogbo ìgbà.
Ní ọgbà ẹ̀wọ̀n míì tí wọ́n gbé mi lọ, wọ́n fi Bíbélì kan síbi ìkówèésí ní ọgbà náà, mo sì lè lọ máa kà á lẹ́ẹ̀kan lọ́sẹ̀.
Mo tún rántí ọ̀rọ̀ arákùnrin tó kọ́ mi lẹ́kọ̀ọ́ Bíbélì.
Ó máa ń sọ pé kò yẹ kí ìṣòro tá à ń kojú máa dẹ́rù bà wá.
Mo rántí pé mo bi wọ́n pé: ‘Báwo ni mi ò ṣe ní bẹ̀rù?
Tí ìṣòro yẹn bá le ńkọ́, tó sì ń dáyà já mi?’ Ó ní, Jèhófà ò ní jẹ́ ká dán wa wò kọjá ohun tá a lè mú mọ́ra, á sì fún wa lókun ká lè borí ìṣòro èyíkéyìí. (1 Kọ́ríńtì 10:13)
Torí náà, nígbà tí mo wà lẹ́wọ̀n, mi ò gbàgbé ọ̀rọ̀ tí wọ́n fà yọ látinú Ìwé Mímọ́ yẹn.
Báwo ló ṣe rí lára yín nígbà tẹ́ ẹ gbọ́ pé gbogbo àwọn ará kárí ayé ló ti gbọ́ ohun tó ṣẹlẹ̀ sí yín, àti pé gbogbo wọn lọ́kùnrin lóbìnrin ló ń gbàdúrà fún yín?
TA: Ó dá mi lójú pé Jèhófà ló lọ́wọ́ sí ọ̀rọ̀ yẹn torí pé òun náà ló ni ètò yìí.
Ìyẹn fi mí lọ́kàn balẹ̀ pé àwọn ará ò ní pa mí tì, àti pé lọ́jọ́ kan, Jèhófà máa kó mi yọ.
Kẹ́ ẹ sì máa wò ó o, ohun tó bà mí lẹ́rù jù ni kí wọ́n fi mí sẹ́wọ̀n.
Mo bẹ̀rù ọgbà ẹ̀wọ̀n gan-an.
Tí mo bá ń ka ìtàn àwọn ará wa tó wà lẹ́wọ̀n, ṣe ni mo máa ń gbàdúrà pé, ‘Jèhófà jọ̀ọ́, gbogbo nǹkan ni mo lè mú mọ́ra, àmọ́ bíi ti ẹ̀wọ̀n kọ́!’
Síbẹ̀, lẹ́sẹ̀ kan náà, ó máa ń wù mí gan-an láti lọ sọ́dọ̀ àwọn tó wà lẹ́wọ̀n, kí n lè kọ́ wọn lẹ́kọ̀ọ́ òtítọ́.
Mo béèrè nígbà kan bóyá a lè lọ máa wàásù lọ́gbà ẹ̀wọ̀n, àmọ́ àwọn àrá ṣàlàyé pé lọ́wọ́lọ́wọ́ báyìí, ìjọba ò fún wa láṣẹ láti máa lọ sáwọn ẹ̀wọ̀n tó wà ní Kazakhstan.
Nígbà tó wá di pé nǹkan yí bìrí fún mi, ẹ́rù ṣe ń bà mí náà ni mo tún ń rò ó pé ohun tó máa ń wù mí láti ṣe, ìyẹn láti máa wàásù fáwọn ẹlẹ́wọ̀n, máa wá di ṣíṣe báyìí.
Ṣé àǹfààní ẹ̀ wá yọ láti wàásù fún àwọn kan nígbà tẹ́ ẹ wà lẹ́wọ̀n?
TA: Bẹ́ẹ̀ ni. Ìgbà kan wà tí agbófinró kan ránṣẹ́ sí mi pé òun fẹ́ bá mi sọ̀rọ̀. Nígbà tí mo dé ọ́fíìsì ẹ̀, ó ní, ‘Mo ti mọ̀ pé Ẹlẹ́rìí Jèhófà ni ẹ́, má lọ rò ó pé o fẹ́ wàásù fún mi!’ Mo fèsì pé, ‘Mi ò ní in lọ́kàn láti wàásù fún yín.’
Ó wá bi mí pé, ‘Kí lorúkọ Ọlọ́run?’ Mo ní, ‘Jèhófà lorúkọ Ọlọ́run.’
Ó tún bi mí pé, ‘Ta wá ni Jésù? Ṣé òun kọ́ ni Ọlọ́run ni?’ Mo dáhùn pé, ‘Rárá, ọmọ Ọlọ́run ni.’
Ó wá béèrè pé, ‘Kí ló wá dé táwọn Oníṣọ́ọ̀ṣì Ọ́tọ́dọ́ọ̀sì fi gbà pé òun ni Ọlọ́run?’
Mo ní, ‘Àwọn náà ni wọ́n máa lè dáhùn ẹ̀.’
Nǹkan míì tún ṣẹlẹ̀ lọ́jọ́ kan tó jẹ́ kí n lè bá àwọn tó tó ogójì (40) tàbí jù bẹ́ẹ̀ lọ sọ̀rọ̀ lẹ́ẹ̀kan náà.
Dókítà kan tó jẹ́ afìṣemọ̀rònú ẹ̀dá wá ṣèbẹ̀wò sọ́dọ̀ àwọn ẹlẹ́wọ̀n.
Ọ̀rọ̀ nípa ìgbéyàwó là ń sọ lọ́jọ́ yẹn, ló bá bi wá pé kí lèrò wa nípa kéèyàn fẹ́yàwó púpọ̀.
Gbogbo wa la láǹfààní láti sọ èrò wa.
Nígbà tí wọ́n ní kí n sọ èrò mi, mo sọ fún wọn pé èmi fúnra mi ò ní nǹkan kan sọ sí i, àmọ́ á wù mí kí n sọ ohun tẹ́nì kan rò nípa ọ̀rọ̀ yìí fún gbogbo wọn.
Mo wá sọ pé: ‘Ìdí nìyẹn tí ọkùnrin yóò ṣe fi baba rẹ̀ àti ìyá rẹ̀ sílẹ̀ tí yóò sì fà mọ́ aya rẹ̀, wọn yóò sì di ara kan.’ (Jẹ́nẹ́sísì 2:24)
Dókítà náà béèrè pé, ‘Èrò ta nìyẹn?’ Mo ní, ‘Èrò Jèhófà Ọlọ́run ni, ẹni tó dá ọmọ aráyé.
Èèyàn méjì ló sọ pé wọ́n á ṣègbéyàwó; wọn ò ju méjì lọ.’
Dókítà náà wá bi mí pé, ‘Ṣé ìdí míì wà tó o fi rò pé ìyàwó kan ṣoṣo ló yẹ kí ọkùnrin ní?’
Mo fa ọ̀rọ̀ yọ látinú Mátíù 7:​12, tó sọ pé: “Nítorí náà, gbogbo ohun tí ẹ bá fẹ́ kí àwọn ènìyàn máa ṣe sí yín, kí ẹ̀yin pẹ̀lú máa ṣe bẹ́ẹ̀ gẹ́gẹ́ sí wọn.”
Mo ní: ‘Jésù ló sọ̀rọ̀ yìí.
Ẹ jọ̀ọ́, ẹ bi àwọn ọkùnrin tó jókòó síbí bóyá ó máa wù wọ́n kí àwọn àti ọkùnrin míì jọ máa fẹ́ ìyàwó wọn.
Tó bá jẹ́ pé àwọn ọkùnrin ò fẹ́ kí ìyàwó àwọn ní ọkọ míì, nígbà náà, ó dájú pé àwọn ìyàwó náà ò ní fẹ́ kí ọkọ àwọn níyàwó míì.’
Dókítà náà sọ pé nínú ọ̀rọ̀ tí gbogbo àwọn tó wà níbẹ̀ sọ, ọ̀rọ̀ tèmi lòun gbádùn jù.
Ìṣírí ló jẹ́ fún wa pé láìka bí nǹkan ṣe nira fún yín tó, ẹ ṣì wá àǹfààní láti wàásù fún àwọn tó wà nítòsí yín!
Lẹ́yìn táwọn ilé ẹjọ́ kọ̀ lọ́pọ̀ ìgbà láti fọwọ́ sí i pé kí wọ́n dá yín sílẹ̀, tó fi mọ́ Ilé Ẹjọ́ Gíga Jù Lọ ti Kazakhstan pàápàá, ṣe ló dà bíi pé kò sọ́nà àbáyọ mọ́ lábẹ́ òfin.
Síbẹ̀, wọ́n fún yín láǹfààní láti buwọ́ lùwé kan tẹ́ ẹ bá fẹ́ kí wọ́n dá yín sílẹ̀.
Ṣé ẹ lè sọ ohun tó ṣẹlẹ̀ fún wa àti ìdí tẹ́ ẹ fi kọ̀ láti buwọ́ lù ú?
TA: Òótọ́ ni pé àwọn ìgbà kan wà tí wọ́n ní kí n buwọ́ lùwé.
Ó jọ bíi pé ìrànlọ́wọ́ ni wọ́n fẹ́ ṣe fún mi, àmọ́ ohun tó wà nínú ìwé yẹn ni pé mo jẹ̀bi ẹ̀sùn tí wọ́n fi kàn mí àti pé mo tọrọ àforíjì fún ohun tí mo ṣe.
Nígbà tó yá, wọ́n ní kí n kọ̀wé míì fúnra mi láti jẹ́wọ́ ohun tí mo ṣe, kí n sì bẹ̀bẹ̀ pé kí wọ́n tú mi sílẹ̀.
Ohun táwọn aláṣẹ ní kí n kọ ni pé àṣìṣe ni mo ṣe bí mo ṣe bá àwọn míì sọ̀rọ̀ nípa ohun tí mo gbà gbọ́, àmọ́ pé ní báyìí, mo tọrọ àforíjì fún ohun tí mo ṣe, mo sì ń bẹ̀bẹ̀ pé kí wọ́n tú mi sílẹ̀ torí àìlera mi.
Mo kọ̀ láti kọ àwọn ọ̀rọ̀ yẹn, mo sì sọ fáwọn aláṣẹ pé ó pé mi kí n wà lẹ́wọ̀n pẹ̀lú ẹ̀rí ọkàn tó mọ́, ju kí wọ́n tú mi sílẹ̀ àmọ́ kí ẹ̀rí ọkàn mi máa dá mi lẹ́bi.
A mọyì àpẹẹrẹ ìgbàgbọ́ tẹ́ ẹ ní gan-an àti bẹ́ ẹ ṣe kọ̀ láti ṣe ohun tó máa ba ẹ̀rí ọkàn yín jẹ́.
Nígbà tó yá, ohun tá ò retí ṣẹlẹ̀. Ṣé ẹ lè sọ fún wa nípa bẹ́ ẹ ṣe mọ̀ pé ìjọba fẹ́ tú yín sílẹ̀ lẹ́wọ̀n?
TA: Lọ́jọ́ kan, ẹ̀ṣọ́ kan wá sí yàrá mi, ó sọ fún mi pé ẹnì kan fẹ́ bá mi sọ̀rọ̀ lórí fóònù.
Mo rò ó pé, ‘Ta ló lè fẹ́ bá mi sọ̀rọ̀?’
Nígbà tí mo gbé fóònù, obìnrin lẹni náà, ó sọ bóun ṣe jẹ́ fún mi, ó sì sọ pé òun ń bọ̀ wá tú mi sílẹ̀.
Kí n má parọ́, mi ò mọ ohun tí mi ò bá ṣe.
Nígbà tá a sọ̀rọ̀ tán lórí fóònù, mo pinnu pé màá sọ fún ọmọ mi ọkùnrin, mi ò fẹ́ sọ fún ìyàwó mi torí kí n má bàa kó o lọ́kàn sókè, a ò sì mọ̀ bóyá wọ́n á tú mi sílẹ̀ lóòótọ́, kí n má lọ fojú ẹ̀ sọ́nà.
Bí mo ṣe gbé fóònù náà kalẹ̀, ẹ̀ṣọ́ yẹn bi mí pé, ‘Kí ni wọ́n sọ fún ẹ lórí fóònù?’ Mo ní ẹnì kan ló ń bá mi dá àpárá jàre, torí ṣe ni obìnrin tí mo bá sọ̀rọ̀ kàn sọ pé òun ń bọ̀ wá tú mi sílẹ̀.
Mark Sanderson, tó jẹ́ ara Ìgbìmọ̀ Olùdarí, pẹ̀lú Teymur àti Mafiza Akhmedov lẹ́yìn tí wọ́n dá Arákùnrin Akhmedov sílẹ̀.
Ẹ̀ṣọ́ yẹn sọ fún mi pé kì í ṣọ̀rọ̀ eré o, òótọ́ lobìnrin yẹn ń sọ o.
Arábìnrin Mafiza, báwo ni ìròyìn amóríyá yìí ṣe rí lára yín?
MA: Nígbà tí ọmọ mi sọ fún mi, èmi náà rò pé ó ń ṣeré ni. Ọjọ́ pẹ́ tá a ti ń retí irú ìròyìn bẹ́ẹ̀!
Àwa ò lè mọ bínú ẹ̀yin méjèèjì ṣe máa dùn tó nígbà tí Arákùnrin Teymur pa dà sílé lẹ́yìn ohun tó lé ní ọdún kan táwọn aláṣẹ ti mú wọn lọ!
Tẹ́ ẹ bá ronú pa dà sẹ́yìn nípa àdánwò ìgbàgbọ́ tẹ́ ẹ kojú yìí, ẹ̀kọ́ wo lẹ lè sọ pé ẹ kọ́?
MA: Mo rántí bí ọ̀rọ̀ Arákùnrin Bahram [Hemdemov] àti [Arábìnrin] Gulzira Hemdemov ṣe máa ń pa mí lẹ́kún tó.
[Àwọn aláṣẹ ní Turkmenistan mú Arákùnrin Hemdemov ní March 2015.
Nígbà tó di May 19, 2015, wọ́n rán an lọ sí ẹ̀wọ̀n ọdún mẹ́rin lórí ẹ̀sùn èké tí wọ́n fi kàn án pé ó ń “mú kí àwọn èèyàn kórìíra ẹ̀sìn míì”, wọn ò sì tíì tú u sílẹ̀ lẹ́wọ̀n di báyìí.]
Kódà, kí wọ́n tó mú Teymur, mo ronú nípa bó ṣe máa nira tó fún Gulzira.
Ní báyìí, á wù mí báyìí kí n rí i, kí n gbá a mọ́ra, kí n sì jẹ́ kó mọ̀ pé mo nífẹ̀ẹ́ ẹ̀, mo sì wà lẹ́yìn ẹ̀.
Torí ohun tí ojú èmi àti Teymur ti rí yìí, á wù mí kí n sọ fún Gulzira pé mo bá a kẹ́dùn torí ohun tójú tiẹ̀ náà rí.
Mo mọ̀ pé bíi tèmi, Jèhófà àtàwọn ará lòun náà gbára lé.
Ọpẹ́ púpọ̀ lọ́wọ́ gbogbo àwọn ará tó tì wá lẹ́yìn, látorí àwọn ará ìjọ wa àti gbogbo ìjọ kárí ayé, tó fi mọ́ Ìgbìmọ̀ Olùdarí, àwọn agbẹjọ́rò àtàwọn ọmọkùnrin wa.
Arákùnrin Akhmedov di ìwé ẹ̀rí tí wọ́n fi dá a sílẹ̀ mú lẹ́yìn tó kúrò lẹ́wọ̀n.
TA: Ohun kan tí mo fẹ́ sọ ni pé gbogbo wa la máa kojú àdánwò.
Ó lè má jẹ́ gbogbo wa la máa lọ sẹ́wọ̀n.
Àdánwò táwọn míì máa kojú lè jẹ́ inúnibíni látọ̀dọ̀ mọ̀lẹ́bí wọn tó jẹ́ aláìgbàgbọ́.
Ní tàwọn míì, ó lè jẹ́ arákùnrin tàbí arábìnrin kan nínú ìjọ tó ṣòroó bá lò.
Ìṣòro tàbí àdánwò yòówù ká máa kojú, gbogbo wa la máa pinnu ohun tá a máa ṣe, bóyá ìlànà Ọlọ́run la fẹ́ rọ̀ mọ́ àbí ìdàkejì ẹ̀ la fẹ́ ṣe.
Tá a bá rọ̀ mọ́ àwọn ìlànà yẹn, a máa lè borí àdánwò.
Ohun tó dáa jù tá a le ṣe tá a bá ń kojú àdánwò ni pé, ká gbà pé àdánwò ló délẹ̀ yìí, ká sì máa rántí pé Jèhófà máa fún wa lókun ti àá fi borí ẹ̀.
Mo dúpẹ́ gan-an lọ́wọ́ ìdílé mi àtàwọn ọmọ mi, wọ́n kú àdúrótì.
Gbogbo àǹfààní tó bá yọ ni wọ́n fi ń wá wò mí, ìyẹn ò sì jẹ́ kí n rẹ̀wẹ̀sì.
Bákan náà, mo fẹ́ dúpẹ́ lọ́wọ́ ẹgbẹ́ ará fún gbogbo ohun tí wọ́n ṣe.
Mo mọrírì àdúrà wọn àtàwọn lẹ́tà tó ń gbéni ró tí wọ́n kọ sí mi.
Mi ò mọ̀ ọ́n lára pé wọ́n pa mí tì fún ìṣẹ́jú kan.
Ohun tó ṣẹlẹ̀ sí mi ti jẹ́ kí ìfẹ́ tí mo ní sí ẹgbẹ́ ará pọ̀ sí i, ó sì ti jẹ́ kí àjọṣe tí mo ní pẹ̀lú Jèhófà lágbára sí i."
"Ní November 30, 2018, Ilé Iṣẹ́ Ètò Ìdájọ́ lórílẹ̀-èdè Kyrgyzstan forúkọ ọ́fíìsì àwa Ẹlẹ́rìí Jèhófà tó wà ní ìlú Osh sílẹ̀, ìlú yìí ló tóbi ṣèkèjì lórílẹ̀-èdè Kyrgyzstan.
Àwọn ará wa jọlá bí ìjọba àpapọ̀ ṣe forúkọ ẹ̀sìn wọn sílẹ̀ ní Kyrgyzstan látọdún 1998, àmọ́ lẹ́yìn tí wọ́n gbé òfin kan nípa ẹ̀sìn jáde lọ́dún 2008, léraléra ni àwọn aláṣẹ tó wà láwọn ìlú ní agbègbè gúúsù orílẹ̀-èdè náà bẹ̀rẹ̀ sí í kọ̀ láti forúkọ ẹ̀sìn wọn sílẹ̀, apá ibẹ̀ sì ni ìlú Osh wà.
Nípa bẹ́ẹ̀, ńṣe làwọn aláṣẹ ìlú bẹ̀rẹ̀ sí í ka ìpàdé àwọn ará wa àti iṣẹ́ ìwàásù wọn sí ohun tí kò bófin mu.
Láwọn ìgbà kan àwọn ọlọ́pàá ya wọnú ilé tàbí ibi táwọn ará gbà láti pé jọ sí fún jọ́sìn.
Inú wa dùn pé ìyípadà yìí máa mú kí àwa Ẹlẹ́rìí Jèhófà túbọ̀ lẹ́tọ̀ọ́ lórílẹ̀-èdè Kyrgyzstan láti máa pé jọ fún ìjọsìn ká sì máa báwọn èèyàn sọ̀rọ̀ nípa Bíbélì láìsí wàhálà.—1 Tímótì 2:1-4."
"Ní June 14, 2018, àwọn Ẹlẹ́rìí Jèhófà tó wà nílùú Ulaanbaatar tó jẹ́ olú-ìlú orílẹ̀-èdè Mòǹgólíà, gba ìwé ẹ̀rí kan látọ̀dọ̀ Àjọ Tó Ń Rí sí Ọ̀rọ̀ Ìlú, pé ìjọba ti pa dà forúkọ ẹ̀sìn wọn sílẹ̀ lábẹ́ òfin lórílẹ̀-èdè náà.
Ìwé ẹ̀rí tó jẹ́ káwọn Ẹlẹ́rìí Jèhófà lè máa ṣe ẹ̀sìn wọn ní Ulaanbaatar.
Ìjọba sọ fáwọn ẹlẹ́sìn pé ọdọọdún ni kí wọ́n máa forúkọ ẹ̀sìn wọn sílẹ̀ ní Mòǹgólíà, àtìgbà táwọn ará wa sì ti kọ́kọ́ forúkọ ẹ̀sìn wọn sílẹ̀ lábẹ́ òfin lọ́dún 1999 ni wọ́n ti ń ṣe bẹ́ẹ̀.
Àmọ́ lọ́dún 2015, Àjọ Tó Ń Rí sí Ọ̀rọ̀ Ìlú ò gbà káwọn ará wa forúkọ ẹ̀sìn wọn sílẹ̀ ní Ulaanbaatar.
Nígbà tó di January 2017, Àjọ Tó Ń Rí sí Ọ̀rọ̀ Ìlú sọ pe ìjọba fagi lé àǹfààní tí àwọn ará ní láti ṣe ẹ̀sìn wọn.
Àwọn tó ṣojú fún Àjọ náà ò sọ ohunkóhun tó mú kí wọ́n ṣe ìpinnu yìí.
Làwọn ará bá sọ pé àwọn máa gbé ọ̀rọ̀ náà lọ sílé ẹjọ́.
Nígbà tí Ilé Ẹjọ́ ń gbọ́ ẹjọ́ náà, agbẹjọ́rò Àjọ Tó Ń Rí sí Ọ̀rọ̀ Ìlú gbìyànjú láti fi ẹjọ́ tí Ilé Ẹjọ́ Gíga Jù Lọ ní Rọ́ṣíà dá ṣe ẹ̀rí, ìyẹn bí wọ́n ṣe sọ pé kí ìjọba gbẹ́sẹ̀ lé àwọn àjọ tá a fi forúkọ ẹ̀sìn wa sílẹ̀ lábẹ́ òfin ní Rọ́ṣíà.
Àmọ́ àwọn agbẹjọ́rò wa jẹ́ kó ṣe kedere pé ọ̀pọ̀ orílẹ̀-èdè ni ò fara mọ́ ẹjọ́ tí ilé ẹjọ́ dá ní Rọ́ṣíà àti pé ọ̀rọ̀ náà ti dé àwọn ilé ẹjọ́ àgbáyé.
Wọ́n tún rán ilé ẹjọ́ létí pé ẹ̀yìn tí Àjọ Tó Ń Rí sí Ọ̀rọ̀ Ìlú ṣèpinnu tiwọn ni ọ̀rọ̀ ti Rọ́ṣíà wáyé, torí náà, Àjọ náà ò lè sọ pé ohun tó ṣẹlẹ̀ ní Rọ́ṣíà ló mú káwọn ṣèpinnu táwọn ṣe.
Ilé Ẹjọ́ fagi lé ìpinnu tí Àjọ Tó Ń Rí sí Ọ̀rọ̀ Ìlú ṣe, wọ́n ní àhesọ ọ̀rọ̀ lásán ni Àjọ náà gùn lé tí wọ́n fi ṣèpinnu, wọn ò sì rí ẹ̀rí kankan mú wá pé àwọn Ẹlẹ́rìí Jèhófà ṣe ohunkóhun tó léwu.
Ilé Ẹjọ́ náà tún rí i pé Àjọ Tó Ń Rí sí Ọ̀rọ̀ Ìlú fi ẹ̀tọ́ táwọn ará wa ní lábẹ́ òfin dù wọ́n, tó fi mọ́ òmìnira láti ṣe ẹ̀sìn wọn tàbí ohun tí wọ́n gbà gbọ́.
Jason Wise, tó jẹ́ ọ̀kan lára àwọn agbẹjọ́rò àwa Ẹlẹ́rìí Jèhófà nínú ẹjọ́ yìí sọ pé: “Bó tiẹ̀ jẹ́ pé kò di dandan kéèyàn ṣẹ̀ṣẹ̀ forúkọ ẹ̀sìn sílẹ̀ lábẹ́ òfin kó tó lè lo ẹ̀tọ́ ọmọnìyàn àti òmìnira tí òfin sọ pé ó ní, síbẹ̀ kì í sábà rọrùn láti jọ́sìn fàlàlà láìkọ́kọ́ forúkọ sílẹ̀.
Ara àwọn àǹfààní tá à ń rí bá a ṣe forúkọ ẹ̀sìn wa sílẹ̀ ni pé ó ń jẹ́ kó rọrùn fún wa láti kó Bíbélì àtàwọn ìwé tó dá lórí Bíbélì wọ̀lú, ká lè ní ibi ìjọsìn, ká sì lè yá àwọn ibi tá a ti máa ṣe àpéjọ.
Inú wa dùn pé Ilé Ẹjọ́ fagi lé ìpinnu tí Àjọ Tó Ń Rí sí Ọ̀rọ̀ Ìlú ṣe nílùú Ulaanbaatar, tí wọ́n sì gbà pé irú ìpinnu bẹ́ẹ̀ máa ṣàkóbá fún òmìnira tá a ní láti ṣe ẹ̀sìn wa àti òmìnira tá a ní láti pé jọ ní Mòǹgólíà.”"
"Òjò àrọ̀ọ̀rọ̀dá kan rọ̀ lórílẹ̀-èdè Nepal, ó sì fa àkúnya omi àti ilẹ̀ yíya, ìṣẹ̀lẹ̀ yìí sọ ẹgbẹẹgbẹ̀rún àwọn èèyàn di aláìnílé, ó sì pa àwọn èèyàn tó lé ní ogóje [140].
Àkúnya omi náà ba àwọn ojú títì jẹ́, ó sì ba iná mànàmáná jẹ́, èyí wá mú kó nira láti ran àwọn tọ́rọ̀ kàn lọ́wọ́.
Ẹ̀ka ọ́fíìsì àwọn Ẹlẹ́rìí Jèhófà tó wà lórílẹ̀-èdè Japan náà ló ń bójú tó iṣẹ́ àwọn Ẹlẹ́rìí Jèhófà tó wà ní Nepal, wọ́n sì sọ pé kò sí Ẹlẹ́rìí Jèhófà kankan tó fara pa tàbí tó kú nínú jàǹbá náà.
Àmọ́, ó di dandan fún ìdílé àwọn Ẹlẹ́rìí Jèhófà mẹ́rin láti filé wọn sílẹ̀, torí pé àkúnya omi tí bá àwọn ilé ọ̀hún jẹ́.
Àwọn Ẹlẹ́rìí Jèhófà tó wà lágbègbè náà ti ń ran àwọn ará bíi tiwọn lọ́wọ́, ìyẹn àwọn tómi gbalé wọn.
Agbẹnusọ fún Àwa Ẹlẹ́rìí Jèhófà:
Kárí Ayé: David A. Semonian, Ọ́fíìsì Agbéròyìnjáde, +1-845-524-3000
Ní August 28, 2019, àrọ̀ọ̀rọ̀dá òjò kan mú kí odò Talomo kún àkúnya, omi náà sí ya wọ ìlú Davao."
Ìròyìn látọ̀dọ̀ àwọn aláṣẹ fi hàn pé omíyalé tó tẹ̀ lé òjò yìí lé ìdílé tó tó nǹkan bí ọgọ́rùn-ún márùn-ún àti márùndínláàádọ́ta (545) kúrò nílé wọn.
Ẹ̀ka ọ́fíìsì Philippines ròyìn pé ọgọ́fà (120) akéde látì ìjọ márùn-ún ni àkúnya omi yìí ṣàkóbá fún.
Ọ̀pọ̀ àwọn akéde yìí ló fara pa mọ́ sí Gbọ̀ngàn Ìjọba.
Àkúnya omi náà wó ilé mẹ́ta, ó sì ba ilé mẹ́rin tó jẹ́ ti àwọn ará wa jẹ́.
Ẹ̀ka ọ́fíìsì gbé Ìgbìmọ̀ Tó Ń Ṣètò Ìrànwọ́ Nígbà Àjálù dìde láti bójú tó àìní àwọn arákùnrin àti arábìnrin tí ìṣẹ̀lẹ̀ yìí ṣàkóbá fún.
Ìgbìmọ̀ yìí rí i dájú pé àwọn tí ìṣẹ̀lẹ̀ náà ṣàkóbá fún rí àwọn ohun tí wọ́n nílò, wọ́n sì ṣètò láti ṣé ìmọ́tótó àwọn ilé tí omi ya wọ̀.
"Àdúrà wa ni pé kí ìfẹ́ táwọn ará ń fi hàn máa tu àwọn arákùnrin àti arábìnrin wa nílùú Davao nínú, pàápàá ní àkókò tó le koko yìí.​—Róòmù 12:10."""
"Ọjọ́: November 1-3, 2019
Ibi Tí Wọ́n Ti Ṣe é: Gbọ̀ngàn Mall of Asia Arena àti SMX Convention Center ní Manila, Philippines
Àwọn Èdè Tí Wọ́n Lò: English, Tagalog
Iye Àwọn Tó Wá: 26,245
Iye Àwọn Tó Ṣèrìbọmi: 145
Iye Àwọn Tó Wá Láti Ilẹ̀ Òkèèrè: 5,397
Àwọn Ẹ̀ka Ọ́fíìsì Tá a Pè: Australasia, Central Europe, France, Indonesia, Italy, Japan, Kazakhstan, Madagascar, Malaysia, Myanmar, Papua New Guinea, Solomon Islands, South Africa, Sri Lanka, Taiwan, Thailand, United States
Àwọn Ìrírí: Rogelio Jolongbayan tó jẹ́ máníjà tó ń rí sí ọ̀rọ̀ àwọn oníbàárà ní gbọ̀ngàn Asia Arena sọ pé: “Ẹ̀yin lẹ níwà ọmọlúwàbí jù nínú gbogbo àwọn tó ti ń lo ibí.
Inú wa dùn pé ẹ wá síbí.”
Ọ̀gá ọlọ́pàá kan lórílẹ̀-èdè Philippines náà sọ pé: “Ṣe làwọn àlejò náà tò lọ́wọ̀ọ̀wọ́ wọnú gbọ̀ngàn náà, ó sì wúni lórí gan an.
Mi ò rò pé wọ́n nílò wa níbí tó bá jẹ́ pé báyìí ni nǹkan ṣe ń lọ!”
Teofilo Labe Jr. tó jẹ́ olùrànlọ́wọ́ fún alábòójútó fún ọ̀rọ̀ ààbò ní Manila Hotel ni wọ́n ní kó rí sí bí àwọn àlejò ṣe máa rìnrìn àjò afẹ́.
Lẹ́yìn tó kíyè sí bí nǹkan ṣe ń lọ fúngbà díẹ̀, ó wá sọ pé: “Tí àwọn aláṣẹ bá ní kí n díwọ̀n bí ẹ ṣe ṣètò ara yín sí, màá sọ pé ẹ̀yin lẹ ṣe dáadáa jù.
Ẹ wà létòlétò gan an ni.”"
"Ìjì líle Vongfong (tí wọ́n tún ń pè ní Ambo) jà ní erékùṣù Samar ní May 14, 2020.
Ìgbà àkọ́kọ́ tí irú ìjì líle yìí máa jà lọ́dún 2020 nìyẹn, Ìwọ̀ Oòrùn Òkun Pàsífíìkì ló sì ti jà, ìjì náà ṣọṣẹ́ gan-an ní erékùṣù Samar.
Kódà, ẹgbẹẹgbẹ̀rún èèyàn ló kó kúrò lágbègbè yẹn, èyí ò sì rọrùn rara torí ìjọba ti ṣòfin pé káwọn èèyàn máa jìnnà síra torí àrùn tó wà lóde.
Bó tiẹ̀ jẹ́ pé kò sí ìkankan nínú àwọn ará wa tó fara pa, àwọn mọkàndínlọ́gọ́ta (59) ló ní láti fi ilé wọn sílẹ̀.
Àwọn kan lọ ń gbé ní iléèwé tí wọ́n ṣètò pé káwọn èèyàn sá sí, àwọn míì sì lọ ń gbé ní ilé àwọn Ẹlẹ́rìí Jèhófà bíi tiwọn.
Yàtọ̀ síyẹn, ilé àwọn ará méjìlélọ́gọ́rin (82) ni ìjì náà bà jẹ́.
Kódà, Gbọ̀ngàn Ìjọba márùn-ún ló bà jẹ́, ìkan sì wó lulẹ̀ pátápátá.
Ìgbìmọ̀ Ẹ̀ka orílẹ̀-èdè Philippines dá Ìgbìmọ̀ Tó Ń Pèsè Ìrànwọ́ Nígbà Àjálù sílẹ̀, kí wọ́n lè fún àwọn ará wa tí ìjì náà ṣàkóbá fún ní ohun tí wọ́n nílò nípa tara, kí wọ́n sì tún fún ìgbàgbọ́ wọn lókun.
A ò ní dákẹ́ àdúrà lórí àwọn ará wa ní Philippines, tí wọ́n ń fara da ọṣẹ́ tí ìjì líle àti àrùn corona ń fà.
Ó dá wa lójú pé Jèhófà tó jẹ́ “àpáta ayérayé” á máa pèsè ohun táwọn ará wa nílò lásìkò tí nǹkan le koko yìí.​—Àìsáyà 26:4."
"Ní ìbẹ̀rẹ̀ August 2019, òjò alátẹ́gùn bẹ̀rẹ̀ lórílẹ̀-èdè Philippines pẹ̀lú òjò rẹpẹtẹ àti ìjì líle, èyí sì fa àkúnya omi àti ilẹ̀ ríri.
Ó bani nínú jẹ́ pé ilẹ̀ tó rì náà pa arákùnrin kan tó ń sìn gẹ́gẹ́ bí aṣáájú-ọ̀nà àkànṣe onígbà díẹ̀ nílùú Natonin, lágbègbè Mountain Province.
Arákùnrin míì tí òun náà ń sìn gẹ́gẹ́ bí aṣáájú-ọ̀nà àkànṣe onígbà díẹ̀ fara pa díẹ̀ nínú ilẹ̀ ríri kan náà.
Nínú ìṣẹ̀lẹ̀ míì, àwókù pàǹtírí ṣe ọmọkùnrin ọlọ́dún mẹ́wàá kan léṣe, àmọ́ ó rí ìtọ́jú tó yẹ gbà.
Kò sí ilé àwọn arákùnrin wa tò bàjẹ́ jù.
Àmọ́, ìjì líle tó ṣọṣẹ́ ní Negros Occidental ba Gbọ̀ngàn Ìjọba kan jẹ́, ó sì ya lára òrùlé ilé náà lulẹ̀.
Ẹ̀ka ọ́fíìsì Philippines àti alábòójútó àyíká ń pèsè ìtùnú fún àwọn ìdílé tí ìṣẹ̀lẹ̀ náà kàn, wọ́n sì ń fi Bíbélì tù wọ́n nínú.
Ó bani nínú jẹ́ láti gbọ́ nípa àdánù ńlá yìí, à sì ń gbàdúrà fún àwọn tó ń ṣọ̀fọ̀ ikú arákùnrin wa.
À ń retí ọjọ́ iwájú kan nígbà tí àwọn ìṣẹ̀lẹ̀ burúkú “ò ní wá sí ìrántí.”​—Àìsáyà 65:17."
"Ìjì Líle Yutu tó ṣọṣẹ́ gan-an ní Àwọn Erékùṣù Northern Mariana ní October 24 tún jà ní erékùṣù Luzon ní Tuesday, October 30.
Erékùṣù yìí ló tóbi jù lórílẹ̀-èdè Philippines.
Òjò àrọ̀ọ̀rọ̀dá tó bá ìjì yẹn rìn fa omíyalé, ó mú kí ilẹ̀ ya, èyí sì pa àwọn èèyàn. Ẹgbẹẹgbẹ̀rún èèyàn ni wọ́n kó kúrò lágbègbè náà, èèyàn mọ́kànlá (11) ló sì kú.
Ìròyìn tá a gbọ́ láti ẹ̀ka ọ́fíìsì wa ní Philippines ni pé kò sí ìkankan lára àwọn ará wa tí ìjì náà pa tàbí tó ṣe léṣe.
Àmọ́ ilé mẹ́tàléláàádọ́rin (73) tó jẹ́ ti àwọn ará wa ló bà jẹ́, títí kan Gbọ̀ngàn Ìjọba mẹ́fà.
Ẹ̀ka ọ́fíìsì wa ní Philippines ti ń ṣètò ìrànwọ́ fáwọn tí àjálù náà ṣẹlẹ̀ sí.
A ò dákẹ́ àdúrà lórí àwọn ará wa ní Philippines, torí ó ti di ìjì líle méjìdínlógún (18) báyìí tó jà níbẹ̀ lọ́dún yìí.
Bí wọ́n ṣe gbẹ́kẹ̀ lé Jèhófà làwa náà gbẹ́kẹ̀ lé e, a sì mọ̀ pé ó máa gbé wa ró.—Sáàmù 55:22."
"Nílùú Davao lórílẹ̀-èdè Philippines, ó ju ẹgbẹ̀rún mọ́kànlélọ́gbọ̀n (31,000) èèyàn tí kì í ṣe Ẹlẹ́rìí Jèhófà tó dara pọ̀ mọ́ ìjọ́ kan láti wo Ìrántí Ikú Kristi tí wọ́n ṣètò látorí ẹ̀rọ.
Kò ṣeé ṣe fún àwọn ìjọ náà láti wà pa pọ̀ torí òfin tí ìjọba gbé kalẹ̀, torí náà wọ́n ṣàtagbà Ìrántí Ikú Kristi látorí ẹ̀rọ.
Ọ̀pọ̀ èèyàn ló dara pọ̀ mọ́ Ìrántí Ikú Kristi yìí torí pé ọ̀dọ́ kan tó jẹ́ aṣáájú-ọ̀nà sapá láti ké sí wọn.
Aṣáájú-ọ̀nà déédéé ni Daphane Jane tó jẹ́ ọmọ ọdún mẹ́tàdínlógún (17), tó ń gbé nílùú Davao.
Ọ̀pọ̀ ọdún ló ti ń bá àìsàn ojú tó lágbára fínra, èyí sì ti mú kó má ríran dáadáa mọ́.
Daphane wá pinnu pé òun máa sọ fún dókítà tó ń tọ́jú òun pé kó wo àkànṣe àsọyé àti Ìrántí Ikú Kristi tá a ṣàtagbà látorí ẹ̀rọ.
Ó wú dókítà náà lórí bí Daphane ṣe fi Bíbélì dáhùn àwọn ìbéèrè rẹ̀ àti bó ṣe bá a sọ̀rọ̀ nípa àwọn àpilẹ̀kọ tó wà lórí ìkànnì jw.org, torí náà dókítà náà gbà láti wo àwọn àsọyé náà.
Ní Sunday, April 5, dókítà yìí wo àkànṣe àsọyé náà, dókítà náà tún ké sáwọn dókítà àtàwọn nọ́ọ̀sì méjìlá (12) tí wọ́n jọ ń ṣiṣẹ́ pé kí wọ́n wo àsọyé náà.
Àwọn dókítà àtàwọn nọ́ọ̀sì yìí tún sọ fáwọn ẹlòmíì pé kí wọ́n wo àsọyé yìí.
Torí náà, èèyàn ọgọ́rùn-ún kan ó lé méjìdínlọ́gbọ̀n (128) ló wo àkànṣe àsọyé ọ̀hún.
Lẹ́yìn àsọyé yẹn, ọ̀kan lára àwọn dókítà náà sọ pé òun “kórìíra àwọn Ẹlẹ́rìí Jèhófà” tẹ́lẹ̀, òun sì máa ń ta kò wọ́n tí wọ́n bá ń wàásù.
Àmọ́, lẹ́yìn tó gbọ́ àkànṣe àsọyé yẹn, ó sọ pé: “Mo fẹ́ tọrọ àforíjì, torí pé mo jágbe mọ́ obìnrin kan lára yín, mo sì kàn-án lábùkù.
Ẹ ṣeun pé ẹ fún mi láǹfààní láti gbọ́ àsọyé yín.
Mo rọ̀ yín pé kẹ́ ẹ máa bá iṣẹ́ ìwàásù yín lọ.”
Dókítà tó ń tọ́jú Daphane tún pinnu pé òun máa wo àsọyé Ìrántí Ikú Kristi àti pé òun máa ké sí ọ̀pọ̀ dókítà tí wọ́n jọ ń ṣiṣẹ́ láti wò ó.
Torí pé ètò ìṣiṣẹ́ tí ìjọ náà fi ń ṣàtagbà kò fàyè gba ọ̀pọ̀ èèyàn láti wo àsọyé yìí, dókítà náà gbà láti bójú tó bí àwọn èèyàn ṣe máa dara pọ̀ mọ́ àsọyé náà, èyí sì mú kó ṣeé ṣe fún ọ̀pọ̀ èèyàn láti wò ó.
Nígbà tó di ọjọ́ Ìrántí Ikú Kristi, àwọn dókítà, àwọn nọ́ọ̀sì, àwọn ọlọ́pàá àtàwọn tó jẹ́ ọ̀gá lẹ́nu iṣẹ́ ìjọba wá wo àsọyé náà.
Kí àsọyé náà tó parí, ó ti ju ẹgbẹ̀rún mọ́kànlélọ́gbọ̀n èèyàn (31,000) tó wo ìtòlẹ́sẹẹsẹ náà látorí ẹ̀rọ tàbí ohùn tá a gbà sílẹ̀.
Dókítà kan dúpẹ́ lọ́wọ́ Daphane àtàwọn ará wa pé wọ́n ké sí òun, ó wá sọ pé: “A ò tiẹ̀ mọ̀ pé àwọn Ẹlẹ́rìí Jèhófà máa ń wàásù lórí ìkànnì.
Bẹ́ ẹ ṣe ń lo ẹ̀rọ ìgbàlódé dára gan-an.”
Ẹlòmíì sọ pé: “Ó ṣeé ṣe fún ọ̀pọ̀ àwa dókítà àti nọ́ọ̀sì láti gbọ́ àsọyé yìí.
Ó ti pẹ́ gan-an tá a ti gbọ́ àsọyé Bíbélì kẹ́yìn, ìgbà àkọ́kọ́ sì rèé tá a máa gbádùn rẹ̀ lórí ẹ̀rọ.
Ó yà wá lẹ́nu láti rí i pé àwọn Ẹlẹ́rìí Jèhófà ń jọ́sìn Ọlọ́run pa pọ̀ lọ́nà yìí.
A retí pé kẹ́ ẹ máa bá a nìṣó láti jẹ́ káwọn èèyàn wo àwọn àsọyé Bíbélì yín látorí ẹ̀rọ.
Ètò tẹ́ ẹ ṣe yìí ràn wá lọ́wọ́ gan-an, pàápàá lákòókò tí nǹkan túbọ̀ ń burú yìí.”
Àkànṣe àsọyé àti àsọyé Ìrántí Ikú Kristi wọ ọ̀pọ̀ èèyàn lọ́kàn gan-an.
Ọ̀kan lára àwọn tó wò ó sọ pé: “Ìgbà àkọ́kọ́ rèé tí màá sunkún bí mo ṣe ń gbọ́ àsọyé tó dá lórí Bíbélì.
Mo dúpẹ́ lọ́wọ́ ẹ, Daphane Jane pé o ké sí dókítà rẹ láti gbọ́ àsọyé yìí, àwa náà sì wà lára àwọn tó rí ìtùnú gbà.
Mo ti wá gbà báyìí pé Ọlọ́run wà, mo sì dúpẹ́ lọ́wọ́ ẹ fún bó o ṣe ràn mí lọ́wọ́ láti mọ̀ bẹ́ẹ̀.”
Lẹ́yìn tí Daphane Jane rí ọ̀nà tí Jèhófà gbà ràn án lọ́wọ́, ó wá pinnu pé òun á máa bá a lọ láti wàásù láìka ti àìsàn tó ń bá òun fínra àti òfin tí ìjọba ṣe torí àjàkálẹ̀ àrùn tó gbòde yìí.
Ìrírí Daphane yìí rán wa létí pé kò yẹ “kí a jáwọ́ nínú ṣíṣe rere, torí tí àkókò bá tó, a máa kórè rẹ̀ tí a ò bá jẹ́ kó rẹ̀ wá.”​—⁠Gálátíà 6:⁠9."
"Ní oṣù January 2019, Arákùnrin Mark Sanderson tó jẹ́ ara Ìgbìmọ̀ Olùdarí mú Bíbélì jáde lédè Cebuano, Tagalog àti Waray-Waray láwọn ibi àkànṣe ìpàdé kan.
Gbọ̀ngàn ìwòran Hoops Dome tó wà ní ìlú Lapu-Lapu ni wọ́n ti mú Bíbélì èdè Cebuano jáde ní January 12.
Lọ́jọ́ kejì, a mú ti èdè Waray-Waray jáde, wọ́n sì pín in ní Gbọ̀ngàn Leyte Academic Center tó wà ní ìlú Palo lágbègbè Leyte.
Ní January 20, a mú Bíbélì jáde lédè Tagalog ní Gbọ̀ngàn Àpéjọ Metro Manila tó wà ní ìlú Quezon City.
Ìdílé kan ń ka Bíbélì Ìtumọ̀ Ayé Tuntun tá a tún ṣe tí wọ́n ṣẹ̀ṣẹ̀ gbà lédè Cebuano.
Ọ̀pọ̀lọpọ̀ Gbọ̀ngàn Ìjọba la ta àtagbà àwọn àkànṣe ìpàdé náà sí, ó sì lé ní ẹgbẹ̀rún mẹ́tàlélọ́gọ́jọ (163,000) Bíbélì Ìtumọ̀ Ayé Tuntun tá a pín fáwọn tó wá.
Arákùnrin Dean Jacek tó wà ní ẹ̀ka ọ́fíìsì ní Philippines sọ pé: “Bíbélì Ìtumọ̀ Ayé Tuntun tá a tún ṣe la mú jáde lédè Cebuano àti Tagalog.
Ó lé lọ́dún mẹ́ta kí wọ́n tó parí iṣẹ́ lórí ọ̀kọ̀kan wọn.
A ti ní Ìwé Mímọ́ Kristẹni Lédè Gíríìkì tẹ́lè lédè Waray-Waray, àmọ́ ìgbà àkọ́kó nìyí táwọn tó ń ka èdè yìí máa ní odindi Bíbélì Ìtumọ̀ Ayé Tuntun.
Ó lé lọ́dún márùn-ún tí wọ́n fi ṣiṣẹ́ ìtúmọ̀ rẹ̀.”
Tá a bá pín àwọn tó ń gbé ní Philippines sọ́nà mẹ́wàá, àwọn tó ń sọ èdè Cebuano, Tagalog tàbí Waray-Waray lé ní ìdá mẹ́fà.
Lára wọn ni nǹkan bí ẹgbẹ̀rún lọ́nà ọgọ́jọ (160,000) àwọn ará wa àti ẹgbẹ̀rún lọ́nà ọgọ́rùn-ún méjì ó dín mẹ́ta (197,000) àwọn akẹ́kọ̀ọ́ Bíbélì.
Yàtọ̀ síyẹn, ní báyìí, ẹgḅẹẹgbẹ̀rún àwọn ọmọ ilẹ̀ Philippines tó ń gbé láwọn ilè míì náà máa lè gbádùn gbogbo ohun tó wà nínú Bíbélì Ìtumọ̀ Ayé Tuntun láwọn èdè yìí.
Arábìnrin Donica Jansuy tó wà ní ìjọ tí wọ́n ti ń sọ èdè Tagalog ní Amẹ́ríkà sọ bó ṣe rí lẹ́yìn tó wa Bíbélì náà jáde lórí íńtánẹ́ẹ̀tì pé: “Àwọn ọ̀rọ̀ inú Bíbélì tí wọ́n tún ṣe lédè Tagalog yìí rọrùn gan-an, ó ṣe kedere, ó sì jẹ́ kó tètè yéèyàn.
Ọ̀rọ̀ tó rọrùn tó wà nínú ẹ̀ ń jẹ́ kó ṣe wá bíi pé Jèhófà ń bá wa sọ̀rọ̀ lẹ́nì kọ̀ọ̀kan, ó sì mú kí ohun tó wà nínú Bíbélì túbọ̀ wọ̀ni lọ́kàn.”
Ní lọ́wọ́lọ́wọ́ báyìí, àwa Ẹlẹ́rìí Jèhófà ti mú Bíbélì Ìtumọ̀ Ayé Tuntun jáde lódindi tàbí lápá kan ní èdè mọ́kàndínlọ́gọ́sàn-án (179).
A dúpẹ́ lọ́wọ́ Jèhófà tó ń mú kí Ọ̀rọ̀ rẹ̀ tí wọ́n túmọ̀ lọ́nà tó ṣe kedere dé ọ̀dọ̀ àwọn ará wa àtàwọn tí wọ́n ń kọ́ lẹ́kọ̀ọ́ Bíbélì.—Ìṣe 13:48."
"Ní July 27, 2019, ìmìtìtì ilẹ̀ méjì tó jà ba ọ̀pọ̀ nǹkan jẹ́ ní erékùṣù kékeré Itbayat tó fẹ́rẹ̀ẹ́ tó ọgọ́rùn-ún méje ó dín mẹ́wàá (690) kìlómità sí Manila, lórílẹ̀ èdè Philippines.
Ìmìtìtì ilẹ̀ yìí kọjá kékeré, èèyàn mẹ́sàn-án ló kú, ò ṣe èèyàn mérìnlélọ́gọ́ta (64) léṣe, ó sì ba ilé ọgọ́rùn-ún méjì àti mẹ́rìndínláàádọ́rin (266) jẹ́.
Àwọn aláṣẹ ròyìn pé, ẹgbẹ̀rún mẹ́ta ó dín méjìlélọ́gbọ̀n (2,968) èèyàn ló fara gbá nínú ìmìtìtì ilẹ̀ náà.
Kò sí ìkankan lára àwọn ará wa tó kú nínú ìmìtìtì ilẹ̀ yìí.
Àmọ́ arábìnrin kan fara pa díẹ̀.
Bákan náà, àwọn arákùnrin wa méjì ni ilé wọn bàjẹ́ gan-an.
Ẹ̀ka ọ́fíìsì gbé Ìgbìmọ̀ Tó Ń Ṣètò Ìrànwọ́ Nígbà Àjálù dìde, àwọn ló sì ń bójú tó rírà àti pínpín àwọn ohun kòséémàní bí i oúnjẹ àti omi.
Àwọn aṣojú ẹ̀ka ọ́fíìsì máa ṣèbẹ̀wò sí àwọn arákùnrin àti arábìnrin tí ìṣẹ̀lẹ̀ yìí kan láti fi ọ̀rọ̀ Ọlọ́run tù wọ́n nínú àti láti pèsè ohun tí wọn nílò fún wọn.
Gbogbo ìgbà là ń gbàdúrà fún àwọn arákùnrin àti arábìnrin wa tó fara gbá nínú àwọn ìmìtìtì ilẹ̀ tó ṣẹlẹ̀ láìpẹ́ yìí.
A mọ̀ pé Jèhófà, “Ọlọ́run ìtùnú gbogbo,” á máa báa lọ láti bójú tó àìní àwọn ará wa.​—2 Kọ́ríńtì 1:3."
"Ní March 2019, iná ńlá kan sọ ní ìlú Calbayog City ní erékùṣù Samar Island lórílẹ̀-èdè Philippines, ó sì jó ilé méjìdínláàádóje (128).
Lóṣù kan sáájú àkókò yẹn, iná sọ láwọn ibì kan ní ìlú Taguig City tó wà ní erékùṣù Luzon.
Lápapọ̀, ilé àwọn Ẹlẹ́rìí Jèhófà méje ni iná náà jó.
Ọ̀dọ̀ àwọn Ẹlẹ́rìí míì tí iná náà ò dé làwọn ará wa yìí ń gbé báyìí.
Ẹsẹ̀kẹsẹ̀ ni ẹ̀ka ọ́fíìsì ṣètò tó yẹ, wọ́n sì pèsè oúnjẹ, omi àti aṣọ fáwọn tọ́rọ̀ kàn.
Àwọn alàgbà tó wà lágbègbè náà ń ṣèbẹ̀wò sọ́dọ̀ àwọn ará tí àjálù yìí kàn, wọ́n sì ń ràn wọ́n lọ́wọ́.
Ìgbìmọ̀ méjì tó ń ṣètò ìrànwọ́ nígbà àjálù àtàwọn tó ń ṣiṣẹ́ ní Ẹ̀ka Tó Ń Yàwòrán Ilé Tó sì Ń Kọ́ Ọ ti ń ṣètò bí wọ́n ṣe máa tún ilé àwọn ará wa tó bà jẹ́ kọ́.
Ó dá wa lójú pé Jèhófà ò ní yé jẹ́ ibi ààbò fún àwọn ará wa tí àjálù iná yìí ṣẹlẹ̀ sí.—Sáàmù 62:8."
"Ní January 12, 2020, òkè ayọnáyèéfín tó ń jẹ́ Taal ní ìlú Batangas lórílẹ̀-èdè Philippines tú eérú gbígbóná jáde, eérú gbígbóná náà rìn jìnnà sókè nínú òfúrufú gan-an, kódà ó fẹ́ẹ̀ tó òpó iná kan àtààbọ̀ tó fi lọ sókè.
Torí pé òkè Taal yìí ló burú jù lára àwọn òkè tó sábà máa ń bú gbàù ní orílẹ̀-èdè náà, ìjọba ti pàṣẹ pé kí gbogbo àwọn tó ń gbé lágbègbè tí òkè náà wà kúrò níbẹ̀ pátápátá.
Títí di àkókò yìí, àwọn arákùnrin àtàwọn arábìnrin wa tó lé ní ọgọ́rùn-ún márùn-ún (500) ló ti kó kúrò lágbègbè yẹn tí wọ́n sì lọ síbi tí kò séwu.
Ìròyìn fi hàn pé kò sí ìkankan nínú àwọn ará wa tó fara pa.
Kára lè tu àwọn ará wa yìí, Ìgbìmọ̀ Ẹ̀ka ti yan Ìgbìmọ̀ Tó Ń Ṣèrànwọ́ Nígbà Àjálù láti bójú tó ohun táwọn ará tó kúrò nílé wọn máa nílò.
Àdúrà wa ni pé kí ìgbàgbọ́ àwọn arákùnrin àtàwọn arábìnrin wa lórílẹ̀-èdè Philippines lágbára sí i, kó sì túbọ̀ dá wọn lójú pé Jèhófà ni Ọlọ́run “ààbò wa àti okun wa.”​—Sáàmù 46:​1-3."
"Ìjì líle typhoon Kammuri táwọn èèyàn Philippines tún ń pè ní Tisoy jà lórílẹ̀-èdè Philippines ní December 2, ọdún 2019.
Àgbègbè Bicol ní ìpínlẹ̀ Luzon ni ìjì náà ti jà. Bó tiẹ̀ jẹ́ pé kò sí Ẹlẹ́rìí Jèhófà kankan tó kú tàbí tó fara pa, ilé àwọn Ẹlẹ́rìí méjìdínláàádọ́fà (108) ló bà jẹ́ gan-an, nígbà tí ilé ọgọ́rùn-ún mẹ́rin ó lé méjìdínlọ́gọ́rin (478) bà jẹ́ díẹ̀.
Yàtọ̀ síyẹn, Gbọ̀ngàn Ìjọba mẹ́ẹ̀ẹ́dógún (15) ló bà jẹ́.
Torí bí ìjì náà ṣe ba nǹkan jẹ́ ní ibi tó pọ̀ gan-an, ẹ̀ka ọ́fíìsì orílẹ̀-èdè Philippines ṣètò Ìgbìmọ̀ mẹ́jọ Tó Ń Pèsè Ìrànwọ́ Nígbà Àjálù, kí wọ́n lè fi Ọ̀rọ̀ Ọlọ́run gbé àwọn ará ró kí wọ́n sì tún ràn wọ́n lọ́wọ́ nípa tara.
À ń gbàdúrà fún àwọn ará wa lórílẹ̀-èdè Philippines, à ń bẹ Jèhófà bíi ti onísáàmù tó sọ pé: “Kí Jèhófà dá ọ lóhùn ní ọjọ́ wàhálà. . . . Kó ràn ọ́ lọ́wọ́ láti ibi mímọ́.”—Sáàmù 20:1, 2."
"Ní August 5, 2017, iná sọ ní àgbègbè Agdao nílùú Davao tó wà ní etíkun erékùṣù Mindanao, ní gúúsù orílẹ̀-èdè Philippines.
Bó tiẹ̀ jẹ́ pé kò sí Ẹlẹ́rìí Jèhófà kankan tí iná yìí pa, ilé àwọn ìdílé mẹ́tàlá [13] ni iná náà ṣe báṣubàṣu, ó sì sọ àwọn mọ́kàndínlọ́gbọ̀n [29] tó ń gbé àwọn ilé náà di aláìnílélórí.
Àwọn Ẹlẹ́rìí Jèhófà ti gba àwọn ará wọn tí iná yìí sọ di aláìnílé sílé.
Ẹ̀ka ọ́fíìsì àwọn Ẹlẹ́rìí Jèhófà tó wà nílùú Manila ti yan ìgbìmọ̀ tó ń ṣètò ìrànwọ́ nígbà àjálù láti bójú tó bí wọ́n á ṣe pín àwọn nǹkan tó wà fún ìrànwọ́.
Ìgbìmọ̀ Olùdarí àwọn Ẹlẹ́rìí Jèhófà ló ń bójú tó iṣẹ́ ìrànwọ́ nígbà àjálù láti oríléeṣẹ́ wọn, owó táwọn èèyàn fi ṣètìlẹyìn fún iṣẹ́ ìwàásù àwọn Ẹlẹ́rìí Jèhófà kárí ayé ni wọ́n sì ń lò.
Agbẹnusọ fún Àwa Ẹlẹ́rìí Jèhófà:
Kárí Ayé: David A. Semonian, Ọ́fíìsì Agbéròyìnjáde,
Ní December 29, 2018, Ìjì Líle tí wọ́n pè ní Usman jà ní erékùṣù Samar, òun ni erékùṣù tó tóbi ṣèkẹta ní Philippines."
Ìjì náà fa òjò àrọ̀ọ̀rọ̀dá, ó mú kí ilẹ̀ ya, ó sì fa omíyalé.
Ó kéré tán, èèyàn mẹ́ẹ̀ẹ́dọ́gbọ̀n (25) ló kú, àwọn méjìlélógójì (42)sì fara pa.
Gbogbo ilé tó bà jẹ́ fẹ́rẹ̀ẹ́ tó ẹgbẹ̀rún mẹ́tàlélógún (22,835).
Ẹ̀ka ọ́fíìsì wa ní Philippines ròyìn pé, kò sí ìkankan lára àwọn ará wa tí ìjì líle náà pa.
Àmọ́ ó ba mẹ́ta lára ilé àwọn ará wa jẹ́ gan-an, ó sì ba ilé mẹ́rin míì jẹ́ díẹ̀.
Yàtọ̀ síyẹn, ó tún ba Gbọ̀ngàn Ìjọba kan jẹ́.
Ẹ̀ka ọ́fíìsì wa yan Ìgbìmọ̀ Tó Ń Ṣètò Ìrànwọ́ Nígbà Àjálù, ìgbìmọ̀ yìí sì pèsè ohun táwọn tí ọ̀ràn kàn nílò títí kan ibi tí wọ́n lè gbé fúngbà díẹ̀.
"Ó dá wa lójú pé àwọn ará wa tí àjálù yìí ṣẹlẹ̀ sí o ní yé gbẹ́kẹ̀ lé Jèhófà torí wọ́n mọ̀ pé ó máa fún wọn lókun, á sì sọ wọ́n di alágbára.—1 Pétérù 5:10."""
"Ìjì gbẹ̀mígbẹ̀mí méjì tí wọ́n ń pè ní Kai-tak (táwọn aráàlú mọ̀ sí Urduja) àti Tembin (táwọn aráàlú mọ̀ sí Vinta) jà lórílẹ̀-èdè Philippines, ó sì lé ọ̀pọ̀lọpọ̀ èèyàn kúrò nílé. Àwọn ìjì náà mú kí omi yalé, kí ẹrẹ̀ sì ya wọ̀lú lápá ìparí oṣù December.
Àwọn ìjì náà ba Gbọ̀ngàn Ìjọba méjì àti ilé mẹ́fà tó jẹ́ tàwọn Ẹlẹ́rìí Jèhófà jẹ́, ó sì di dandan káwọn igba ó lé mọ́kàlélọ́gọ́rin (281) ìdílé kó kúrò nílé wọn.
Ó dùn wá gan-an láti sọ pé nílùú Lanao del Norte, arábìnrin kan tó jẹ́ ọmọ ọdún mẹ́rìnlélógún (24) mumi yó, ó sì kú.
Àwọn Ẹlẹ́rìí Jèhófà tó wà lágbègbè náà ti dìde ìrànwọ́ fáwọn èèyàn.
Àwọn aṣojú láti ẹ̀ka ọ́fíìsì orílẹ̀-èdè Philippines ti ń múra láti lọ ṣèbẹ̀wò sí ibi tí àjálù ti ṣẹlẹ̀ kí wọ́n lè mọ àwọn nǹkan míì táwọn ará tún máa nílò, kí wọ́n sì lè fi Bíbélì tù wọ́n nínú kínú wọn lè máa dùn.
A bá gbogbo àwọn tọ́rọ̀ kàn, tí àjálù sì ṣẹlẹ̀ sí kẹ́dùn.
Bí iṣẹ́ ìrànwọ́ náà ṣe ń tẹ̀ síwájú, ó dá wa lójú pé Jèhófà ò ní yéé fi ẹ̀mí rẹ̀ àti ètò rẹ̀ tu àwọn èèyàn nínú, kó sì rà wọ́n lọ́wọ́.—Sáàmù 9:9; Aísáyà 51:12.
Agbẹnusọ fún Àwa Ẹlẹ́rìí Jèhófà:
Kárí Ayé: David A. Semonian, Ọ́fíìsì Agbéròyìnjáde, +1-845-524-3000
Láti October 16, 2019, léraléra ni ìmìtìtì ilẹ̀ tó lágbára wáyé ní apá gúúsù orílẹ̀-èdè Philippines, àwọn èèyàn mọ́kànlélógún (21) ló kú, àwọn tó lé ní irínwó (400) ló fara pa, àwọn tó lé ní ẹgbẹ̀rún lọ́nà márùndínlógójì (35,000) ló sì ní láti fi ilé wọn sílẹ̀."
Mẹ́ta lára àwọn ìmìtìtì ilẹ̀ náà lágbára gan-an, kódà ilẹ̀ ṣì ń mì lẹ́yìn ọ̀pọ̀ ọjọ́ tí ìṣẹ̀lẹ̀ náà ṣẹlẹ̀.
Bó tiẹ̀ jẹ́ pé arábìnrin kan fara pa díẹ̀, a dúpẹ́ pé kò sí ìkankan lára àwọn ará wa tó kú.
Ilé ìpàdé àwa Ẹlẹ́rìí Jèhófà mẹ́rin àti igba ó dín márùn-ún (195) ilé àwọn ará wa ló bà jẹ́ gan-an.
Ilé ìpàdé àwa Ẹlẹ́rìí Jèhófà mẹ́sàn-án (9) àti ọgọ́rùn-ún mẹ́ta ó lé mọ́kànléláàádọ́ta (351) ilé àwọn ará ló sì bà jẹ́ díẹ̀.
Torí pé ó léwu gan-an láti wà nínú ilé, inú àgọ́ lọ̀pọ̀ àwọn ará lọ forí pa mọ́ sí.
Ẹ̀ka ọ́fíìsì wa lórílẹ̀-èdè Philippines ti yan Ìgbìmọ̀ Tó Ń Ṣètò Ìrànwọ́ Nígbà Àjálù méjì láti bójú tó iṣẹ́ ìrànwọ́ náà.
Àwọn mẹ́fà tó jẹ́ aṣojú láti ẹ̀ka ọ́fíìsì tí mẹ́ta lára wọn wà lára Ìgbìmọ̀ Ẹ̀ka ti ṣèbẹ̀wò sí agbègbè náà kí wọ́n lè pèsè ìtùnú àti ìṣírí nípa tẹ̀mí.
"A gbàdúrà pé kí Jèhófà máa ran àwọn ará tí àjálù bá yìí lọ́wọ́.​—Sáàmù 70:5."""
"Ohun kan ṣẹlẹ̀ fún ìgbà àkọ́kọ́ nínú ìtàn orílẹ̀-èdè South Korea. Àwọn agbẹjọ́rò ìjọba pàrọwà fún ilé ẹjọ́ kòtẹ́milọ́rùn pé kí wọ́n wọ́gi lé ẹ̀sùn tí wọ́n fi kan márùn-ún lára àwọn arákùnrin wa kí wọ́n sì dá wọn sílẹ̀ lómìnira.
Wọ́n gba àrọwà àwọn agbẹjọ́rò ìjọba, wọ́n sì dá àwọn arákùnrin náà sílẹ̀ lómìnira.
Ìpinnu tí ilé ẹjọ́ yìí ṣe ló wọ́gi lé ìdájọ́ àwọn ilé ẹjọ́ ti tẹ́lẹ̀, ó sì fi ìdí ẹ̀ mulẹ̀ pé àwọn arákùnrin náà kò ní ẹ̀sùn lọ́rùn mọ́.
December 14, 2018 ni ilé ẹjọ́ kòtẹ́milọ́rùn ṣe ìpinnu tá à ń sọ yìí, ó sì ti wá di ìlànà òfin tá à ń tọ́ka sí láti fi pàrọwà fún àwọn ilé ẹjọ́ míì ní Korea pé kí wọ́n dá ọgọ́rùn-ún mẹ́sàn-án (900) àwọn arákùnrin wa sílẹ̀ lómìnira.
Ní báyìí, àwọn arákùnrin tí wọ́n dá sílẹ̀ ń retí kí ìjọba ṣètò iṣẹ́ àṣesìnlú tí wọ́n lè ṣe dípò kí wọ́n ṣiṣẹ́ ológun.
Ohun tí ilé ẹjọ́ kòtẹ́milọ́rùn wò ṣe ìpinnu wọn ni ìdájọ́ mánigbàgbé tí ilé ẹjọ́ méjì kan ṣe lọ́dún 2018, ìyẹn Ilé Ẹjọ́ Gíga Jù Lọ lórílẹ̀-èdè Korea àti Ilé Ẹjọ́ Tó Ń Rí Sí Ẹ̀tọ́ Ọmọnìyàn Nílẹ̀ Korea.
Ìdájọ́ méjèèjì yẹn ló fòpin sí ohun kan tó ti dàṣà láti ọgọ́ta ọdún ó lè márùn-ún (65) sẹ́yìn. Ní gbogbo àsìkò yẹn, bí ẹnì kan bá sọ pé ẹ̀rí ọkàn òun ò lè jẹ́ kóun ṣiṣẹ́ ológun, ẹ̀wọ̀n lonítọ̀hún máa bára ẹ̀, bó ti wù kí àlàyé tó ṣe lẹ́sẹ̀ nílẹ̀ tó.
Àwọn àjọ tó ń jà fún ẹ̀tọ́ ọmọnìyàn gbóṣùbà fún ilé ẹjọ́ méjèèjì yẹn torí ìpinnu tí wọ́n ṣe, ìpinnu yẹn mú kó ṣe kedere pé ó bẹ́tọ̀ọ́ mu tẹ́nì kan bá kọ̀ láti ṣiṣẹ́ ológun torí ẹ̀rí ọkàn rẹ̀, ó ṣe tán gbogbo èèyàn ló lẹ́tọ̀ọ́ láti kọ ohun tó lòdì sí ẹ̀rí ọkàn rẹ̀.
Àjọ Tó Ń Rí Sọ́ràn Ẹ̀tọ́ Ọmọnìyàn lórílẹ̀-èdè Korea sọ pé: “Ìpinnu táwọn adájọ́ Ilé Ẹjọ́ Gíga Jù Lọ lórílẹ̀-èdè Korea pa ẹnu pọ̀ ṣe yẹn mú ire wa, ó lé ní ọgọ́ta ọdún tí wọ́n ti ń fìyà jẹ àwọn tí ẹ̀rí ọkàn wọn kò gbà láyè láti ṣiṣẹ́ ológun. Látìgbà yẹn, àwọn bí ẹgbẹ̀rún lọ́nà ogún (20,000) ni wọ́n ti fimú ẹ̀ dánrin.
Àmọ́ ní báyìí, kò sohun tó jọ bẹ́ẹ̀ mọ́ . . . Àfi ká máa dúpẹ́ lọ́wọ́ àwọn tó ti fara da ìyà láti ọ̀pọ̀ ọdún yìí wá, a mọyì wọn gan-an, a sì dúpẹ́ lọ́wọ́ ìdílé wọn.”
Ohun tí ìjọba ń ṣe báyìí ni pé kẹ́nì kan tó lè sọ pé ẹ̀rí ọkàn òun ò gba òun láyè láti ṣiṣẹ́ ológun, ó gbọ́dọ̀ fi ẹ̀rí ohun tó gbà gbọ́ múlẹ̀ dáadáa.
Wọ́n ti fún àwọn adájọ́ ní ìtọ́ni pé kí wọ́n rí i dájú pé òótọ́ lọ̀rọ̀ ẹni náà, kì í ṣe pé ó kàn ń fi ẹ̀sìn bojú.
Ẹ gbọ́ bí Ilé Ẹjọ́ Gíga Jù Lọ ṣe sọ ọ́, ó ní: “Ó gbọ́dọ̀ hàn ní gbogbo apá ìgbésí ayé onítọ̀hún . . . pé òótọ́ ló ń fi ìlànà ẹ̀sìn rẹ̀ sílò.”
Bí adájọ́ ṣe ń bi àwọn arákùnrin wa léèrè ọ̀rọ̀, ṣe nìyẹn mú kí wọ́n ṣàlàyé ohun tó mú kí wọ́n pinnu pé àwọn ò ní ṣiṣẹ́ ológun àti ìdí tí wọn ò fi ní jagun.—1 Pétérù 3:15.
Ó lé ní ọgọ́ta ọdún tí ìjọba ti ń ju àwọn Ẹlẹ́rìí Jèhófà nílẹ̀ Korea sẹ́wọ̀n torí pé wọn ò fẹ́ ṣe ohun tó ta ko ẹ̀rí ọkàn wọn, Èyí mú kó túbọ̀ ṣe kedere pé èèyàn àlàáfíà ni wọ́n, àlàáfíà ìlú ni wọ́n sì ń wá, torí ẹ̀ ni wọn kì í dá sọ́ràn ìṣèlú àti ogun, ohun tó mú kí wọ́n ṣe bẹ́ẹ̀ ni pé wọ́n ń pa èkejì lára òfin méjì tó ga jù lọ mọ́, èyí tó sọ́ pé: “Kí o nífẹ̀ẹ́ ọmọnìkejì rẹ bí ara rẹ.”—Mátíù 22:39."
"Ní Thursday, August 30, 2018, Ilé Ẹjọ́ Gíga Jù Lọ Nílẹ̀ South Korea ṣe àpérò kan lórí ẹjọ́ àwọn Ẹlẹ́rìí Jèhófà mẹ́ta kan tí ẹ̀rí ọkàn wọn ò jẹ́ kí wọ́n ṣiṣẹ́ ológun, àwọn adájọ́ mẹ́tàlá ló sì gbọ́ ẹjọ́ náà.
Wákàtí mẹ́rin ni gbogbo àwọn adájọ́ mẹ́tàlá náà fi béèrè ọ̀rọ̀ lọ́wọ́ àwọn agbẹjọ́rò àwọn Ẹlẹ́rìí Jèhófà àtàwọn míì nípa ọ̀rọ̀ tó ti ń jà ràn-ìn nílẹ̀ tipẹ́tipẹ́ torí bí wọ́n ń ṣe ju àwọn tí ẹ̀rí ọkàn ò jẹ́ kí wọ́n ṣiṣẹ́ ológun sẹ́wọ̀n ní Korea.
Àwọn adájọ́ náà sọ̀rọ̀ gan-an nípa ẹjọ́ mánigbàgbé tí Ilé Ẹjọ́ Ìjọba dá ní June 28, 2018, tó fi pàṣẹ fún Ilé Ìgbìmọ̀ Aṣòfin Ilẹ̀ Korea pé kí wọ́n ṣètò iṣẹ́ àṣesìnlú míì fáwọn tó bá jẹ́ pé òótọ́ ni ẹ̀rí ọkàn wọn ò gbà wọ́n láyè láti ṣiṣẹ́ ológun dípò kí wọ́n máa jù wọ́n sẹ́wọ̀n bí ọ̀daràn.
Àwọn agbẹjọ́rò náà ní kí Ilé Ẹjọ́ dá àwọn arákùnrin mẹ́ta yìí láre, kí ọ̀rọ̀ wọn lè jẹ́ àpẹẹrẹ tó máa ṣeé tẹ̀ lé nígbà táwọn ilé ẹjọ́ míì bá fẹ́ yanjú irú ẹjọ́ yìí tó lé ní ọgọ́rùn-ún mẹ́sàn-án (900) tó ṣì wà nílẹ̀.
Ní báyìí, ó kù sọ́wọ́ Ilé Ẹjọ́ Gíga Jù Lọ láti sọ ìgbà tí wọ́n máa dá ẹjọ́ mẹ́tẹ̀ẹ̀ta tó lápẹẹrẹ tí wọ́n gbé yẹ̀ wò yìí àti ibi tí wọ́n máa jẹ́ kí ọ̀rọ̀ náà já sí.
Àwa àti àwọn arákùnrin wa olóòótọ́ tó lé ní ọgọ́rùn-ún (100) tó ṣì wà lẹ́wọ̀n kò ní jẹ́ kó sú wa bá a ṣe ń fi sùúrù dúró dé Ọlọ́run ìgbàlà wa.—Míkà 7:7."
Ní February 28, 2019, wọ́n dá ẹni tó gbẹ̀yìn lára àwọn Ẹlẹ́rìí Jèhófà tó wà lẹ́wọ̀n torí àìdá sọ́rọ̀ òṣèlú sílẹ̀ ní South Korea.
Gbogbo àwọn tí wọ́n dá sílẹ̀ náà dúpẹ́ torí òmìnira tí wọ́n rí gbà àti bí wọ́n ṣe sapá láti jẹ́ olóòótọ́ sí Jèhófà Ọlọ́run.
Lẹ́yìn ìdájọ́ tí Ilé Ẹjọ́ Gíga Jù Lọ ṣe ní November 1, 2018, tó fi hàn pé ẹni tí ẹ̀rí ọkàn rẹ̀ ò bá gbà láyè láti ṣiṣẹ́ ológun kì í ṣe ọ̀daràn, wọ́n ti dá arákùnrin márùndínláàádọ́rin (65) sílẹ̀.
Ìdájọ́ yìí ló fòpin sí bí wọ́n ṣe ń ju àwọn tí ẹ̀rí ọkàn wọn ò jẹ́ kí wọ́n ṣiṣẹ́ ológun sẹ́wọ̀n látọdún márùndínláàádọ́rin sẹ́yìn.
Ìgbàgbọ́ àti ìṣòtítọ́ àwọn ará wa ní Korean jẹ́ kóríyá fún gbogbo wa láti ‘túbọ̀ máa fi ìgboyà’ àti òtítọ́ sin Ọba wa àti ìjọba rẹ̀.
(Fílípì 1:14) À ń gbàdúrà fún àwọn ará wa tó ṣì wà lẹ́wọ̀n ní Eritrea, Rọ́ṣíà, Singapore àti Turkmenistan.—Hébérù 10:34.
Láti nǹkan bí ọdún márùndínláàádọ́rin (65) báyìí làwọn ọ̀dọ́kùnrin tí wọ́n jẹ́ Kristẹni lórílẹ̀-èdè South Korea ti ń fi ẹ̀wọ̀n gbára torí pé ẹ̀rí ọkàn wọn ò jẹ́ kí wọ́n ṣiṣẹ́ ológun.
Àmọ́ ní Thursday, June 28, 2018, ìpinnu mánigbàgbé tí Ilé Ẹjọ́ Tó Ń Rí Sọ́ràn Ẹ̀tọ́ Ọmọnìyàn ṣe jẹ́ kọ́rọ̀ náà lójú, torí wọ́n kéde pé ohun tó wà nínú Àpilẹ̀kọ 5, ìpínrọ̀ 1, nínú Ìlànà Iṣẹ́ Ológun (MSA) ò bá òfin ilẹ̀ South Korea mu torí pé ìjọba ò ṣètò iṣẹ́ àṣesìnlú míì dípò iṣẹ́ ológun.
Àwọn oníròyìn rèé níwájú ìta Ilé Ẹjọ́ Tó Ń Rí Sọ́ràn Ẹ̀tọ́ Ọmọnìyàn.
Kárí ayé làwọn oníròyìn ti ń tọ pinpin ibi tọ́rọ̀ náà dé.
Adájọ́ mẹ́sàn-án ló wà nínú ìgbìmọ̀ tó dá ẹjọ́ yìí, Adájọ́ Àgbà Lee Jin-sung sì ni alága ìgbìmọ̀ náà. Mẹ́fà nínú wọn ló fara mọ́ ìpinnu náà, àwọn mẹ́ta yòókù ta kò ó. Ìpinnu tí ilé ẹjọ́ ṣe yìí máa jẹ́ kí ìjọba ilẹ̀ náà ṣe ohun táwọn orílẹ̀-èdè yòókù ń ṣe káàkiri ayé, wọ́n á sì túbọ̀ jẹ́ káwọn èèyàn lómìnira láti ṣe ohun tí ẹ̀rí ọkàn wọn fẹ́, èrò ọkàn wọn àti ìgbàgbọ́ wọn.
Àwọn aṣojú àwọn Ẹlẹ́rìí Jèhófà ní Korea rèé nínú Ilé Ẹjọ́ Ìjọba kó tó di pé Ilé Ẹjọ́ náà ṣèpinnu.
Iye àwọn tí orílẹ̀-èdè South Korea ń fi sẹ́wọ̀n lọ́dọọdún torí pé wọn ò ṣiṣẹ́ ológun nítorí ẹ̀rí ọkàn wọn ju àpapọ̀ àwọn tó ń lọ sẹ́wọ̀n ní gbogbo orílẹ̀-èdè yòókù torí pé ẹ̀rí ọkàn ò jẹ́ kí wọ́n ṣiṣẹ́ ológun.
Ìgbà kan wà tó jẹ́ pé nǹkan bí ọgọ́rùn-ún márùn-ún (500) sí ọgọ́rùn-ún mẹ́fà (600) àwọn arákùnrin wa ló ń ṣẹ̀wọ̀n lọ́dọọdún.
Tí wọ́n bá sì dá wọn sílẹ̀ lẹ́wọ̀n, gbogbo wọn ni wọ́n máa ń níṣòro láwùjọ torí ẹ̀sùn ọ̀daràn tó ti wà lọ́rùn wọn, tí kò sì lè pa rẹ́.
Ara ohun tó sì máa ń yọrí sí ni pé kìí jẹ́ kí wọ́n ríṣẹ́ bọ̀rọ̀.
Àmọ́ nígbà tó di ọdún 2011, àwọn arákùnrin kan kọ̀wé sí Ilé Ẹjọ́ Tó Ń Rí Sọ́ràn Ẹ̀tọ́ Ọmọnìyàn láti fẹjọ́ sùn torí pé òfin ò ṣètò àfidípò fáwọn tí ẹ̀rí ọkàn ò jẹ́ kí wọ́n ṣiṣẹ́ ológun, àfi kí wọ́n ṣẹ̀wọ̀n.
Àtọdún 2012 làwọn adájọ́ kan ti bẹ̀rẹ̀ sí í wò ó pé kò tọ́ láti máa fìyà jẹ àwọn tó jẹ́ pé òótọ́ ni ẹ̀rí ọkàn wọn ò gbà á kí wọ́n ṣiṣẹ́ ológun.
Ni wọ́n bá bẹ̀rẹ̀ sí í gbé ẹjọ́ wọn lọ sí Ilé Ẹjọ́ Tó Ń Rí Sọ́ràn Ẹ̀tọ́ Ọmọnìyàn, kí ilé ẹjọ́ náà lè tún Ìlànà Iṣẹ́ Ológun gbé yẹ̀ wò.
Wọ́n ń fọ̀rọ̀ wá Hong Dae-il, tó jẹ́ agbẹnusọ fáwọn Ẹlẹ́rìí Jèhófà ní Korea lẹ́nu wò níwájú ìta ilé ẹjọ́ náà lẹ́yìn tí ilé ẹjọ́ ṣèpinnu Iṣẹ́ Ilé Ẹjọ́ Tó Ń Rí Sọ́ràn Ẹ̀tọ́ Ọmọnìyàn ni kí wọ́n máa wò ó bóyá òfin kan bá Òfin Ilẹ̀ Korea mu àbí ó ta kò ó. Bó tiẹ̀ jẹ́ pé ẹ̀ẹ̀mejì (ìyẹn lọ́dún 2004 àti 2011) ni ilé ẹjọ́ yìí ti fọwọ́ sí i pé Ìlànà Iṣẹ́ Ológun bá òfin ilẹ̀ náà mu, àwọn náà ti wá gbà báyìí pé ó yẹ kí àtúnṣe bá a. Ilé Ẹjọ́ náà pàṣẹ pé kí ìjọba South Korea tún òfin náà ṣe, kó lè ṣètò iṣẹ́ àṣesìnlú míì tó jẹ́ àfidípò tó bá fi máa di ìparí ọdún 2019.
Lára àwọn iṣẹ́ àṣesìnlú tí wọ́n lè ní káwọn èèyàn máa ṣe ni pé kí wọ́n máa ṣiṣẹ́ nílé ìwòsàn tàbí láwọn àjọ míì tó ń ṣèrànwọ́ fún aráàlú, àmọ́ tí kò sí lábẹ́ àwọn ológun.
Ká lè mọ bí ìpinnu yìí ti ṣe pàtàkì tó, Arákùnrin Hong Dae-il, tó jẹ́ agbẹnusọ fáwọn Ẹlẹ́rìí Jèhófà ní Korea sọ pé: “Ilé Ẹjọ́ Tó Ń Rí Sọ́ràn Ẹ̀tọ́ Ọmọnìyàn, tó jẹ́ ilé ẹjọ́ tó lágbára jù lórílẹ̀-èdè yìí tó ń gbèjà ẹ̀tọ́ ọmọnìyàn, ti fojú ọ̀nà àbáyọ kan hàn sọ́rọ̀ yìí.
Àwọn arákùnrin wa ń retí ìgbà tí wọ́n máa lè ṣiṣẹ́ sìnlú lọ́nà tí ò ní pa ẹ̀rí ọkàn wọn lára, tó sì máa bá ohun táwọn orílẹ̀-èdè yòókù kárí ayé ń ṣe mu.” Lára àwọn ọ̀rọ̀ pàtàkì míì tá a ṣì ń retí kó lójú ni ọ̀rọ̀ àwọn Ẹlẹ́rìí Jèhófà tí wọ́n jẹ́ igba ó dín mẹ́jọ (192) tó ń ṣẹ̀wọ̀n lọ́wọ́lọ́wọ́ torí pé ẹ̀rí ọkàn ò jẹ́ kí wọ́n ṣiṣẹ́ ológun, àtàwọn ẹjọ́ míì tó tó ọgọ́rùn-ún mẹ́sàn-án (900) tó ṣì wà láwọn ilé ẹjọ́ káàkiri orílẹ̀-èdè náà.
Ìpinnu mánigbàgbé tí Ilé Ẹjọ́ Tó Ń Rí Sọ́ràn Ẹ̀tọ́ Ọmọnìyàn ṣe máa jẹ́ kó túbọ̀ ṣeé ṣe fún Ilé Ẹjọ́ Gíga Jù Lọ láti dá àwọn tí wọ́n bá gbọ́ ẹjọ́ wọn lórí ọ̀rọ̀ yìí láre.
Ibi tí gbogbo àwọn adájọ́ Ilé Ẹjọ́ Gíga Jù Lọ bá fẹnu kò sí máa pinnu ohun tí ilé ẹjọ́ máa ṣe lórí ọ̀kọ̀ọ̀kan àwọn tọ́rọ̀ kàn.
A retí pé tó bá di August 30, 2018, Ilé Ẹjọ́ Gíga Jù Lọ máa ṣe àpérò kan láti jíròrò ọ̀rọ̀ náà, tó bá sì yá, wọ́n á ṣèpinnu.
Ìgbà àkọ́kọ́ nìyẹn máa jẹ́ láti ọdún mẹ́rìnlá (14) sẹ́yìn tí gbogbo àwọn adájọ́ Ilé Ẹjọ́ Gíga Jù Lọ máa gbé ọ̀rọ̀ àwọn tí ẹ̀rí ọkàn ò jẹ́ kí wọ́n ṣiṣẹ́ ológun yẹ̀ wò.
Kó tó dìgbà yẹn, Ilé Ìgbìmọ̀ Aṣòfin Ilẹ̀ Korea ti ń báṣẹ́ lọ lórí bí wọ́n ṣe máa ṣàtúnṣe sí Ìlànà Iṣẹ́ Ológun.
Arákùnrin Mark Sanderson tó jẹ́ ara Ìgbìmọ̀ Olùdarí sọ pé: “Ara wa ti wà lọ́nà láti gbọ́ ìpinnu tí Ilé Ẹjọ́ Gíga Jù Lọ máa ṣe.
Tinútinú làwọn arákùnrin wa ní Korea ti ń yọ̀ǹda bí wọ́n ṣe ń fi òmìnira wọn dù wọ́n, torí wọ́n mọ̀ pé ‘bí ẹnì kan, nítorí ẹ̀rí-ọkàn sí Ọlọ́run, bá ní àmúmọ́ra lábẹ́ àwọn ohun tí ń kó ẹ̀dùn-ọkàn báni, tí ó sì jìyà lọ́nà tí kò bá ìdájọ́ òdodo mu, èyí jẹ́ ohun tí ó ṣe ìtẹ́wọ́gbà.’ (1 Pétérù 2:19) A bá wọn yọ̀ torí ilé ẹjọ́ ti gbà báyìí pé ṣe ni wọ́n ń rẹ́ wọn jẹ látọdún yìí wá, àti pé wọ́n fìgboyà dúró lórí ohun tí ẹ̀rí ọkàn wọn fẹ́.
Ní Thursday, November 1, 2018, Ilé Ẹjọ́ Gíga Jù Lọ Nílẹ̀ South Korea dájọ́ pé ẹni tí ẹ̀rí ọkàn rẹ̀ ò bá jẹ́ kó ṣiṣẹ́ ológun ò hùwà ọ̀daràn kankan.
Àwọn adájọ́ mẹ́rin ò fara mọ́ ìdájọ́ yìí, àmọ́ àwọn mẹ́sàn-án ló fara mọ́ ọ. Ní báyìí, wọ́n máa fàyè gba ẹni tí ẹ̀rí ọkàn rẹ̀ ò bá gbà á láyè láti ṣiṣẹ́ ológun nítorí ẹ̀sìn rẹ̀.
Àwọn ilé ẹjọ́ lóríṣiríṣi nílẹ̀ Korea sì lè tẹ̀ lé ìdájọ́ mánigbàgbé tí Ilé Ẹjọ́ Gíga Jù Lọ ṣe yìí, kí wọ́n sì dá àwọn ará wa tó lé ní ọgọ́rùn-ún mẹ́sàn (900) láre nígbà tí wọ́n bá ń gbọ́ ẹjọ́ wọn tó wà nílẹ̀.
Ní oṣù mélòó kan sẹ́yìn, Ilé Ẹjọ́ Ìjọba Korea dájọ́ pé tó bá fi máa di oṣù December 2019, kí ìjọba ti ṣètò iṣẹ́ àṣesìnlú míì fún àwọn tí ẹ̀rí ọkàn wọn ò jẹ́ kí wọ́n ṣiṣẹ́ ológun.
Inú wa dùn, a sì yin Jèhófà nítorí ìdájọ́ tó ṣàrà ọ̀tọ̀ yìí.
Ní April 4, 2019, iná ńlá kan sọ létí ìlà oòrùn orílẹ̀-èdè South Korea ní agbègbè tí wọ́n ń pè ní Gangwon Province.
Kò pẹ́ rárá tí iná náà fi ràn, èyí sì mú kí ìjọba kéde pé wàhálà ti wọ̀lú káàkiri orílẹ̀-èdè náà.
Kí wọ́n tó lè kápá iná náà, ó ti jó ẹgbẹ̀rún mẹ́rin (4,000) eékà ilẹ̀, ó sì ti pa èèyàn méjì.
Ẹ̀ka ọ́fíìsì wa ròyìn pé kò sí ìkankan lára àwọn ará wa tó kú.
Àmọ́ iná náà jó ilé mẹ́jọ tí àwọn ará wa mẹ́tàdínlọ́gbọ̀n (27) ń gbé.
Ẹ̀ka ọ́fíìsì dá Ìgbìmọ̀ Tó Ń Ṣètò Ìrànwọ́ Nígbà Àjálù sílẹ̀, àwọn alábòójútó àyíká tó wà lágbègbè náà àtàwọn alàgbà ìjọ ń fáwọn tí àjàlù yìí kàn níṣìírí, wọ́n sì ń pèsè ohun tí wọ́n nílò fún wọn.
Ó dá wa lójú pé Jèhófà máa jẹ́ ‘ibi ààbò àti okun pẹ̀lú ìrànlọ́wọ́ tó wà lárọ̀ọ́wọ́tó ní àkókò wàhálà’ fáwọn ará wa yìí.—Sáàmù 46:1.
Ọjọ́ kejìdínlọ́gbọ̀n oṣù June, ọdún 2018 ni ìgbà àkọ́kọ́ nínú ìtàn ilẹ̀ South Korea tí Ilé Ẹjọ́ Tó Ń Rí Sí Ẹ̀tọ́ Ọmọnìyàn máa sọ pé apá kan lára Ìlànà Iṣẹ́ Ológun Ilẹ̀ Korea, ìyẹn “Korea’s Military Service Act (MSA)” kò bófin mu, torí pé kò gba àwọn tí ẹ̀rí ọkàn wọn ò jẹ́ kí wọ́n ṣiṣẹ́ ológún láyè láti ṣe iṣẹ́ míì.
Ìdájọ́ tó ṣàrà ọ̀tọ̀ yìí ló máa yí ìlànà “MSA” tó ti wà látọdún márùndínláàádọ́rin (65) sẹ́yìn pa dà, ìyẹn ìdájọ́ tó sọ pé kí àwọn tí ẹ̀rí ọkàn wọn ò jẹ́ kí wọ́n ṣiṣẹ́ ológun máa lọ sẹ́wọ̀n.
Láti ọdún 1953, ó ju ẹgbẹ̀rún mọ́kàndínlógún ó lé ọgọ́rùn-ún mẹ́ta (19,300) àwọn ará wa tí wọ́n ti rán lẹ́wọ̀n ẹgbẹ̀rún mẹ́rìndínlógójì ó lé ọgọ́rùn-ún méje (36,700) ọdún lápapọ̀.
Ilé Ẹjọ́ Gíga Jù Lọ Nílẹ̀ Korea á lè lo ìdájọ́ tí Ilé Ẹjọ́ yìí ṣe nínú ọ̀rọ̀ ọ̀kọ̀ọ̀kan àwọn tí ẹ̀rí ọkàn wọn ò jẹ́ kí wọ́n ṣiṣẹ́ ológun.
Yàtọ̀ síyẹn, ó ti wá di dandan pé káwọn tó wà nílé ìgbìmọ̀ aṣòfin ilẹ̀ Korea dá iṣẹ́ míì téèyàn lè fi sìnlú sílẹ̀, ó pẹ́ tán December 31, 2019.
Gbogbo wa la bá àwọn ará wa ní Korea yọ̀ pé ohun tó máa fòpin sí ìwà ìrẹ́jẹ tí wọ́n ti ń hù sí wọn láti ọ̀pọ̀ ọdún ti ṣeé ṣe.​—Òwe 15:30.
Ẹ̀ka ọ́fíìsì wa ní Korea ti fi tó wa létí pé ní November 30, 2018, mẹ́tàdínlọ́gọ́ta (57) nínú àwọn ará wa ni ìjọba dá sílẹ̀ lẹ́wọ̀n, tí wọ́n sì pa dà sọ́dọ̀ àwọn mọ̀lẹ́bí wọn.
Gbogbo ẹgbẹ́ ará kárí ayé ló ń yọ̀ torí ohun tá a ti ń retí tipẹ́ ló ṣẹlẹ̀ yìí, a dúpẹ́ lọ́wọ́ Jèhófà tó ṣojúure sí wa, tó sì bù kún wa.​—Nọ́ńbà 6:​24-26.
À ń gbàdúrà fún àwọn arákùnrin mẹ́jọ tó kù lẹ́wọ̀n, a retí pé àwọn aláṣẹ máa dá wọn sílẹ̀ tí wọ́n bá ti lo oṣù mẹ́fà nínú ẹ̀wọ̀n ọdún kan ààbọ̀ tí ìjọba dá fún wọn.
Àwọn arákùnrin tí wọ́n ṣẹ̀ṣẹ̀ dá sílẹ̀ pa dà sọ́dọ̀ àwọn òbí wọn (lọ́tùn-ún, lósì).
Àwọn oníròyìn ń fọ̀rọ̀ wá arákùnrin kan lẹ́nu wò níwájú ìta ọgbà ẹ̀wọ̀n náà (àárín).
Nígbà ìdíje Pyeongchang 2018 Olympic and Paralympic Winter Games, tó wáyé ní February 9 sí 25, 2018, àti March 9 sí 18, 2018, àwọn ará lọ́kùnrin lóbìnrin ní Korea ṣe àkànṣe ìwàásù láti jẹ́ kí àwọn àlejò lóríṣiríṣi tó wá láti ibi ọ̀tọ̀ọ̀tọ̀ lágbàáyé rí àwọn ìwé tó dá lórí Bíbélì gbà lọ́fẹ̀ẹ́.
Ó lé ní ẹgbẹ̀rún méje àti ọgọ́rùn-ún kan (7,100) àwọn ará lọ́kùnrin lóbìnrin káàkiri orílẹ̀-èdè náà tó kópa nínú àkànṣe ìwàásù yẹn.
Ọ̀pọ̀ nínú wọn ló wá láti ìlú Busan, Gwangju, Incheon, Seoul àti Suwon; àwọn kan tiẹ̀ wá láti Erékùṣù Jeju lọ́hùn-ún lọ́hùn-ún, ibi tó lé ní ọgọ́rùn-ún mẹ́ta (300) máìlì sí gúúsù Pyeongchang táwọn èèyàn ti sábà máa ń lọ gbafẹ́.
Àwọn ará wa gbé àtẹ méjìléláàádọ́jọ (152) síbi méjìdínláàádọ́ta (48) ọ̀tọ̀ọ̀tọ̀, títí kan ibi ìgbafẹ́ Gangneung Olympic Park àti Pyeongchang Olympic Plaza.
Wọ́n tún gbà wọ́n láyè kí wọ́n pàtẹ díẹ̀ lára àwọn ìwé wọn síbi àbáwọlé ọ̀kan lára àwọn ibi ìjọsìn tó wà ní Olympic Village.
Wọ́n gbé àtẹ ìwé méjì sí tòsí ẹnubodè àríwá ní Gangneung Olympic Park.
Yàtọ̀ síyẹn, àwọn aláṣẹ fún àwọn ará wa láyè láti gbé àtẹ ìwé wọn sí Gangneung Station Square tó jẹ́ ibùdókọ̀ tó gbẹ̀yìn fún ọkọ̀ ojú irin ayára-bí-àṣá tí wọ́n ṣẹ̀ṣẹ̀ ṣe tán, tí wọ́n ń pè ní KTX Gyeonggang Line, èyí tó máa ń gbérò láti ìlú Incheon àti Seoul lọ sí Pyeongchang.
Lọ́jọ́ tí wọ́n bẹ̀rẹ̀ ìdíje òlíńpíìkì, ó lé ní ẹgbẹ̀rún lọ́nà méjìdínlọ́gbọ̀n (28,000) èèyàn tó gba ibùdókọ̀ Gangneung Station kọjá.
Kí àwọn ará wa lè kàn sí àwọn àlejò tó fẹ́rẹ̀ẹ́ tó ẹgbẹ̀rún lọ́nà ọgọ́rin (80,000) tí wọ́n ń retí pé wọ́n á wá síbi ìdíje náà, wọ́n pàtẹ ìwé ńlá, ìwé pẹlẹbẹ, ìwé ìròyìn àti àṣàrò kúkúrú lédè tó tó ogún (20), títí kan èdè Chinese, Gẹ̀ẹ́sì, Kazakh, Korean àti Russian.
Bákan náà, àwọn ará lọ́kùnrin lóbìnrin tó gbọ́ Èdè Àwọn Adití Lédè Korea dáadáa lo àwọn àtẹ tó ní móhùn-máwòrán lára láti máa fi àwọn fídíò èdè adití han ọ̀pọ̀ àwọn adití tó wá síbi Ìdíje Fáwọn Aláàbọ̀ Ara.
Ìwé tí wọ́n pín lé ní ẹgbẹ̀rún lọ́nà mọ́kànléláàádọ́rin àti igba (71,200), títí kan ohun tó lé ní ẹgbẹ̀rún méjìlélógún (22,000) ìwé ìkésíni wá síbi Ìrántí Ikú Kristi.
Kárí ayé, àwọn Ẹlẹ́rìí Jèhófà ń lo àtẹ ìwé tó lé ní ẹgbẹ̀rún lọ́nà ọgọ́rùn-ún mẹ́ta (300,000) láti pàtẹ ìwé wọn láwọn orílẹ̀-èdè tó lé ní márùndínlógójì (35).
Èyí ń jẹ́ kí wọ́n lè wàásù fáwọn èèyàn níbikíbi tí wọ́n bá ti lè rí wọn, kí wọ́n sì ṣàṣeparí iṣẹ́ òjíṣẹ́ wọn ní kíkún.​—2 Tímótì 4:5.
Ẹgbẹẹgbẹ̀rún àwọn Ẹlẹ́rìí Jèhófà ló wá láti orílẹ̀-èdè méje ọ̀tọ̀ọ̀tọ̀ láti wá bá àwọn ará wọn lọ́kùnrin lóbìnrin ní orílẹ̀-èdè Siri Láńkà ṣe àkànṣe àpéjọ. Ìgbà àkọ́kọ́ tírú ẹ̀ máa wáyé nìyẹn ní orílẹ̀-èdè náà.
Ìlú Colombo tó jẹ́ olú-ìlú Siri Láńkà ni wọ́n ti ṣe àkànṣe àpéjọ náà, tí ẹṣin ọ̀rọ̀ ẹ̀ jẹ́ “Jẹ́ Onígboyà”! Pápá ìṣeré Sugathadasa National Sports Complex ni wọ́n lò, July 6 sí 8, 2018 ni wọ́n sì ṣe é. Àwọn ẹgbẹ̀rún mẹ́rìnlá ó lé mọ́kànlélọ́gọ́fà (14,121) ló wá sí àpéjọ náà.
Ara àwọn ohun mánigbàgbé tó wáyé níbi àpéjọ náà ni àwọn àsọyé tí ọ̀kan lára Ìgbìmọ̀ Olùdarí sọ, àwọn tó ṣèrìbọmi ní àpéjọ yìí ló tíì pọ̀ jù nínú gbogbo àpéjọ tó ti wáyé ní Siri Láńkà, àwọn ará sì fìfẹ́ gba àwọn bí ẹgbẹ̀rún mẹ́ta ààbọ̀ (3,500) lálejò lọ́nà tó ta yọ.
September 2017 ni wọ́n fi tó àwọn ará ní Siri Láńkà létí pé àkànṣe àpéjọ kan máa wáyé lọ́dún tó tẹ̀ lé e, àtìgbà yẹn ni ètò sì ti bẹ̀rẹ̀.
Yàtọ̀ sí gbogbo ètò tí wọ́n ṣe láti gbàlejò àwọn tó máa wá sí àpéjọ náà, pápá ìṣeré tí wọ́n fẹ́ lò nílò àtúnṣe tó pọ̀.
Ó máa gba pé kí wọ́n kùn ún, kí wọ́n kó ìdọ̀tí ibẹ̀, kí wọ́n tún àwọn àga tó ti bà jẹ́ ṣe, kí wọ́n sì dí àwọn ihò ojú ọ̀nà.
Nígbà tí àpéjọ náà ku ọ̀sẹ̀ mẹ́ta, ọ̀pọ̀ àwọn Ẹlẹ́rìí Jèhófà ló wá kọ́wọ́ ti iṣẹ́ àtúnṣe náà.
Ẹ̀ṣọ́ kan tiẹ̀ sọ pé ó máa gba àwọn òṣìṣẹ́ pápá ìṣeré náà ní ọdún mẹ́rin láti ṣe ohun táwọn ará wa ṣe láàárín àkókò kúkúrú yẹn.
Yàtọ̀ sí àwọn àsọyé Bíbélì tí wọ́n sọ ní àpéjọ náà, wọ́n mú àwọn àlejò lọ wo oríṣiríṣi ibi, wọ́n sì ṣe àwọn nǹkan lóríṣiríṣi tó jẹ mọ́ àṣà ìbílẹ̀ Siri Láńkà.
Àwọn ará ṣe ohun kan tó jẹ́ mánigbàgbé nírọ̀lẹ́ ọjọ́ kan, wọ́n jó ijó ìbílẹ̀, wọ́n sì kọrin ìbílẹ̀. Àwọn ọ̀dọ́ kan tó jẹ́ Ẹlẹ́rìí Jèhófà náà kọ àwọn orin Ìjọba Ọlọ́run.
Ashley Ferdinands tó jẹ́ aṣojú ẹ̀ka ọ́fíìsì tó wà ní Siri Láńkà sọ pé: “Ohun ńlá ni ètò Ọlọ́run ṣe fáwọn ará wa lórílẹ̀-èdè yìí pẹ̀lú bí wọ́n ṣe ṣètò pé ká ṣe àkànṣe àpéjọ, àǹfààní ló sì jẹ́ láti gba àwọn ará wa tó pọ̀ lálejò.
A mọyì ọ̀pọ̀ àwọn tó yọ̀ǹda ara wọn láti ṣèrànwọ́ kí nǹkan lè lọ dáadáa ní àpéjọ yìí.
Àmọ́ Baba wa ọ̀run ni gbogbo ọpẹ́ yẹ, torí àtọ̀dọ̀ ẹ̀ ni gbogbo ẹ̀bùn rere ti ń wá.”—Jémíìsì 1:17.
Ní July 5, 2019, a mú Bíbélì Ìtumọ̀ Ayé Tuntun tá a tún ṣe jáde lédè Chinese ní àpéjọ agbègbè kan tá a ṣe ní ìlú Taoyuan lórílẹ̀-èdè Taiwan.
Arákùnrin Kenneth Cook tó jẹ́ ọ̀kan lára Ìgbìmọ̀ Olùdarí ló mú Bíbélì náà jáde nígbà tó ń sọ àsọyé kan nínú Gbọ̀ngàn National Taiwan Sport University.
Àwọn ẹgbẹ̀rún-ún méjìlá, ọgọ́rùn-ún mẹ́fà àti mẹ́wàá (12,610) ló gbádùn ètò yìí. Àwọn kan gbádùn ẹ̀ nínú gbọ̀ngàn yẹn, wọ́n sì ta àtagbà ẹ̀ sáwọn àpéjọ agbègbè mẹ́rin míì.
Ọdún 1995 ni wọ́n kọ́kọ́ tẹ Ìwé Mímọ́ Kristẹni Lédè Gíríìkì ní Ìtumọ̀ Ayé Tuntun jáde lédè Chinese, wọ́n sì ṣe é lọ́nà méjì. Wọ́n lo ọ̀nà ìkọ̀wé tó wọ́pọ̀ ní Hong Kong àti Taiwan mu nínú tí àkọ́kọ́, wọ́n sì lo ọ̀nà ìkọ̀wé tá a mú kó túbọ̀ rọrùn tó wọ́pọ̀ ní Ṣáínà, Màléṣíà àti Singapore fún èkejì.
Lọ́dún 2001, wọ́n mú odindi Bíbélì Ìtumọ̀ Ayé Tuntun jáde. Ẹ̀dà méjì ni wọ́n tún fi ṣe, àkọ́kọ́ jẹ́ ọ̀nà ìkọ̀wé tó jẹ́ ti ìbílẹ̀, ìkejì sì jẹ́ ọ̀nà ìkọ̀wé tá a mú kó túbọ̀ rọrùn láti lóye.
Nígbà tó dọdún 2004, a tẹ ẹ̀dà kẹta jáde. Ọ̀nà ìkọ̀wé tá a mú kó túbọ̀ rọrùn láti lóye ni wọ́n lò nínú ẹ̀dà yìí, yàtọ̀ síyẹn, wọ́n tún lo ọ̀nà ìkọ̀wé kan tá à ń pè ní Pinyin kí wọ́n lè fi álífábẹ́ẹ̀tì èdè Róòmù kọ ọ̀rọ̀ kọ̀ọ̀kan.
Wọ́n wá mú Bíbélì Ìtumọ̀ Ayé Tuntun tá a tún ṣe jáde ní ẹ̀dà mẹ́ta ọ̀tọ̀ọ̀tọ̀.
Ti èdè ìbílẹ̀ àti èdè tá a mú kó túbọ̀ rọrùn láti lóye ni wọ́n tẹ̀ sínú ìwé àti sórí ẹ̀rọ, nígbà tí ẹ̀dà Pinyin wà lórí ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍŃTÁNẸ́Ẹ̀TÌ™ (ti Watchtower).
Ní gbogbo ayé, àwọn èèyàn tó lé ní bílíọ̀nù kan ló ń sọ èdè Chinese Mandarin. Òun sì ni èdè ìbílẹ̀ táwọn èèyàn ń sọ jù lọ láyé.
Ní àfikún sí àwọn tó ń sọ èdè Mandarin, ọ̀pọ̀ mílíọ̀nù èèyàn ló wà tó ń sọ àwọn èdè ìbílẹ̀ Chinese míì, wọ́n sì lè ka àwọn ọ̀rọ̀ tá a kọ lọ́nà ìkọ̀wé Chinese.
Ní báyìí, àwọn ará wa tó ń ṣiṣẹ́ ní ìpínlẹ̀ ìwàásù tó gbòòrò yìí lè fi Bíbélì Ìtumọ̀ Ayé Tuntun tá a tún ṣe ran ọ̀pọ̀ èèyàn láti mọ Jèhófà, kí wọ́n sì ní ìmọ̀ tó péye nípa Ọ̀rọ̀ rẹ̀.​—1 Tímótì 2:4.
Ní alẹ́ Tuesday, February 6, ìmìtìtì ilẹ̀ tó lágbára gan-an wáyé ní etíkun tó wà ní ìlà oòrùn orílẹ̀-èdè Taiwan.
Ìròyìn fi hàn pé àwọn mẹ́fà ló kú sí inú ìṣẹ̀lẹ̀ yìí, àwọn tó ju àádọ́talénígba [250] ló sì fara pa yánnayànna.
Yàtọ̀ síyẹn, àwọn mẹ́rìndínlọ́gọ́rin [76] míì ni wọ́n ṣì ń wá.
Kò sí arákùnrin tàbí arábìnrin wa kankan tó kú sínú ìṣẹ̀lẹ̀ náà, wọn ò sì fara pa. Àmọ́, ìmìtìtì ilẹ̀ yẹn ba ilé kan tí Gbọ̀ngàn Ìjọba àti ọ́fíìsì àwọn atúmọ̀ èdè Taiwanese jẹ́.
Ilé náà wà ní ìlú Hualien, ibẹ̀ wà lára àwọn ibi tí ìmìtìtì ilẹ̀ náà ti ṣọṣẹ́ jù.
Yàtọ̀ síyẹn, ilé tí àwọn kan lára àwọn atúmọ̀ èdè ń gbé bà jẹ́ gan-an, torí náà wọ́n ní láti kúrò ní ilé yẹn.
Ẹsẹ̀kẹsẹ̀ ni àwọn ará tó wà ní ìtòsí bá wọn ṣètò ibi tí wọ́n lè forí pamọ́ sí fúngbà díẹ̀, ẹ̀ka ọ́fíìsì tó wà ní Taiwan náà ń pèsè àwọn nǹkan míì tí wọ́n nílò fún wọn.
Àdúrà wa ni pé, kí Ọlọ́run fún àwọn ará wa tí àjálù náà dé bá ní ìbàlẹ̀ ọkàn ní àsìkò tí nǹkan dojú rú yìí, kí àwọn tí wọ́n sì yàn láti bójú tó wọn dà “bí ibi ìfarapamọ́sí kúrò lọ́wọ́ ẹ̀fúùfù.”—Aísáyà 32:2.
Ní April 2, 2020, ilé ẹjọ́ àwọn ológun tàwọn ará Tajik, tó wà ní ìlú Dushanbe tó jẹ́ olú ìlú orílẹ̀-èdè Tajikistan fi Arákùnrin Jovidon Bobojonov sẹ́wọ̀n ọdún méjì tórí pé ẹ̀rí ọkàn rẹ̀ kò gbà á láyè láti wọṣẹ́ ológun.
Ó máa pe ẹjọ́ kòtẹ́milọ́rùn.
Ní September 10, 2019, ilé ẹjọ́ ìlú Khujand ní Tajikistan fi Arákùnrin Shamil Khakimov sí ẹ̀wọ̀n ọdún méje àtààbọ̀ kìkì nítorí pé ó ń sọ ohun tó gbà gbọ́ fún àwọn míì.
Àwa Ẹlẹ́rìí Jèhófà ti pe ẹjọ́ kòtẹ́milọ́rùn lórí ọ̀rọ̀ yìí.
Ìbẹ̀rẹ̀ ọdún 2019 ni wọ́n bẹ̀rẹ̀ sí í fojú Arákùnrin Khakimov rí màbo.
Ní February 26, 2019, àwọn aláṣẹ mú Shamil, ẹni ọdún méjìdínláàádọ́rin (68), wọ́n sì fẹ̀sùn kàn án pé ó ń “mú kí àwọn èèyàn kórìíra ẹ̀sìn míì.” Ni ilé ẹjọ́ bá fi sí àtìmọ́lé láì tíì gbọ́ ẹjọ́ rẹ̀, oṣù mẹ́fà ló lò níbẹ̀.
Yàtọ̀ sí wàhálà ti pé wọ́n sọ Arákùnrin Khakimov sẹ́wọ̀n lọ́nà àìtọ́, àìsàn ẹ̀jẹ̀ ríru ń bá a fínra, èyí tó ṣì ń gba ìtọ́jú rẹ̀ lọ́wọ́.
Èyí ni ìgbà àkọ́kọ́ tí wọ́n máa ju ọ̀kan lára àwa Ẹlẹ́rìí Jèhófà sẹ́wọ̀n ní Tajikistan látọdun 2017. Nígbà yẹn wọ́n ju Danil Islamov tó jẹ́ ẹni ọdún méjìdínlógún (18) sí ẹ̀wọ̀n oṣù mẹ́fà torí pé ó kọ̀ láti wọ aṣọ ológun.
Tajikistan náà ti wà lára àwọn orílẹ̀-èdè márùn-ún tó ti ju ó kéré tán, ọ̀kan lára àwa Ẹlẹ́rìí Jèhófà sẹ́wọ̀n.
Àwọn orílẹ̀-èdè mẹ́rin tó kù ni Eritrea, Rọ́ṣíà, Singapore àti Turkmenistan.
Àdúrà wa ni pé kí Jèhófà máa báa lọ láti fún Arákùnrin Khakimov ní gbogbo ohun tó nílò láti fara da àdańwò yìí.​—Róòmù 15:5.
Àwa Ẹlẹ́rìí Jèhófà mú Ìwé Mímọ́ Kristian Lédè Griki ní Ìtumọ̀ Ayé Titun jáde lédè Laotian níbi àpéjọ agbègbè tí a ṣe ní Nong Khai, lórílẹ̀-èdè Thailand, ní August 16, 2019.
Arákùnrin Plakorn Pestanyee tó jẹ́ ọ̀kan lára Ìgbìmọ̀ Ẹ̀ka orílẹ̀-èdè Thailand, ló mú Bíbélì náà jáde lọ́jọ́ àkọ́kọ́ àpéjọ náà.
Ìgbìmọ̀ ẹlẹ́ni-mẹ́ta tó túmọ̀ Bíbélì náà lo ọdún kan ààbọ̀ lórí iṣẹ́ náà.
Ọ̀kan lára àwọn atúmọ̀ èdè náà sọ pé: “Ní báyìí, a ti ní ìtumọ̀ Bíbélì kan tó ṣàlàyé àwọn ọ̀rọ̀ inú Bíbélì lọ́nà tí àwọn tó ń sọ èdè Laotian gbà ń sọ̀rọ̀, síbẹ̀ ó gbé ìtumọ̀ àwọn ọ̀rọ̀ jáde lọ́nà tó pé pérépéré, kí àwọn akẹ́kọ̀ọ́ Bíbélì lè lóye ‘àwọn ohun ìjìnlẹ̀ Ọlọ́run.’ ”​—Jóòbù 11:7.
Bíbélì tuntun yìí ní àwọn ohun èlò ìwádìí bí atọ́ka, tó máa ran àwọn tó ń kà á lọ́wọ́ láti tètè rí àwọn ẹsẹ Bíbélì àti àlàyé ọ̀rọ̀ tó ń ṣàlàyé àwọn ọ̀rọ̀ Bíbélì.
Atúmọ̀ èdè míì tóun náà ṣe nínú iṣẹ́ ìtumọ̀ náà sọ pé: “Tá a bá fi Bíbélì yìí kọ́ àwọn èèyàn lẹ́kọ̀ọ́, àwọn akẹ́kọ̀ọ́ Bíbélì á lóye àwọn koko pàtàkì lọ́nà tó rọrùn ju ti tẹ́lẹ̀ lọ, á sì wọ̀ wọ́n lọ́kàn, èyí á sì jẹ́ kí wọ́n ní ìbátan tímọ́tímọ́ pẹ̀lú Jèhófà.” Ó dá wa lójú pé Ìwé Mímọ́ Kristian Lédè Griki ní Ìtumọ̀ Ayé Titun yìí á ran àwọn arákùnrin àti arábìnrin wa tó ń sọ èdè Lao lọ́wọ́ láti kí wọ́n lè “kúnjú ìwọ̀n dáadáa, kí wọ́n sì gbára dì pátápátá fún gbogbo iṣẹ́ rere.”​—2 Tímótì 3:​16, 17.
Ní November 12, 2019, Ilé ẹjọ́ kan ní orílẹ̀-èdè Turkmenistan dá Arákùnrin Serdar Dovletov lẹ́bi, ó sì fi sẹ́wọ̀n ọdún mẹ́ta. Ẹni ọdún mẹ́rìndínlọ́gbọ̀n (26) ni Arákùnrin Dovletov.
Arákùnrin Dovletov wà lára àwọn arákùnrin mẹ́wàá ní orílẹ̀-èdè náà tí wọ́n fi sẹ́wọ̀n nítorí pé ẹ̀rí ọkàn wọn ò gbà wọ́n láyè láti ṣiṣẹ́ ológun.
Àwọn méje ni wọ́n fi sẹ́wọ̀n ní 2019, wọ́n ti fi àwọn mẹ́ta yòókù sẹ́wọ̀n ní 2018.
Àkókò tí wọ́n ní kí wọ́n lò lẹ́wọ̀n jẹ́ láàárín ọdún kan sí mẹ́rin.
Ìlú Baýramaly ni Arákùnrin Dovletov ti wá, ní agbègbè Mary tó wà ní apá gúúsù ìlà oòrùn Turkmenistan.
Ẹlẹ́rìí Jèhófà ni Surya ìyàwó ẹ̀ àti Sonya màmá rẹ̀.
November 11, 2019 ni ìgbẹ́jọ́ Arákùnrin Dovletov bẹ̀rẹ̀.
Arákùnrin Dovletov sọ fún ilé ẹjọ́ náà pé ìsìn òun ló mú kí ẹ̀rí ọkàn òun kọ̀ láti ṣiṣẹ́ ológun.
Ní àfikún, àwọn dókítà mẹ́ta ló jẹ́rìí pé Arákùnrin Dovletov ní ọgbẹ́ inú ọlọ́jọ́ pípẹ́, ìyẹn náà sì wà lára ìdí tó fi yẹ kí wọ́n yọ̀ǹda ẹ̀ láti má ṣiṣẹ́ ológun.
Láìka àwọn ẹ̀rí yìí sí, adájọ́ náà sọ pé Arákùnrin Dovletov jẹ̀bi fífi “ọgbọ́n jìbìtì” sá fún iṣẹ́ ológun, ó sì sọ pé kí wọ́n fi sí àhámọ́.
Láìpẹ́, ó máa dara pọ̀ mọ́ àwọn arákùnrin mẹ́sàn-an tí wọ́n fi sẹ́wọ̀n ní àgọ́ ìṣẹ́niníṣẹ̀ẹ́ tó wà nílùú Seydi nínú aṣálẹ̀ kan lágbègbè Lebap.
Arákùnrin Dovletov máa pe ẹjọ́ kòtẹ́milọ́rùn lórí ìdájọ́ náà.
Bí àwọn arákùnrin wa ní Turkmenistan ṣe ń fara da ìwà ìrẹ́jẹ lórílẹ̀-èdè wọn, à ń gbàdúrà fún wọn pẹ̀lú ìgbàgbọ́ kíkún nínú ìlérí Jèhófà pé á tì wọ́n lẹ́yìn bí wọ́n ṣe ń fi ìgboyà di ìṣòtítọ́ wọn mú.​—Sáàmù 37:18, 24.
Látọdún bíi mélòó kan báyìí, April 19, 2019 nìgbà àkọ́kọ́ táwọn ará wa káàkiri orílẹ̀-èdè Uzbekistan ṣe Ìrántí Ikú Kristi tí ọ̀pọ̀ èèyàn sì láǹfààní láti wá síbẹ̀.
Ìlú Chirchik tó wà nítòsí ìlú Tashkent nìkan ló forúkọ ẹ̀sìn àwa Ẹlẹ́rìí Jèhófà sílẹ̀ lábẹ́ òfin ní gbogbo orílẹ̀-èdè Uzbekistan.
Láwọn ọdún tó kọjá, ńṣe làwọn ará wa tí kò sí ní ìlú Chirchik máa ń ṣe Ìrántí Ikú Kristi ní bòókẹ́lẹ́ káwọn ọlọ́pàá má bàa dà wọ́n láàmú.
Àmọ́ lọ́dún yìí, àwọn ará sọ fáwọn Ọlọ́pàá pé àwọn fẹ́ ṣe Ìrántí Ikú Kristi, wọ́n sì pè wọ́n pé kí wọ́n wá.
Àwọn ọlọ́pàá náà fèsì tó dáa, wọ́n sì gbé ìgbésẹ̀ láti pèsè ààbò tó yẹ fáwọn tó wá síbi Ìrántí Ìkú Kristi.
Àní láwọn ibì kan, àwọn ọlọ́pàá wà lára àwọn tó wá gbọ́ àsọyé.
Arákùnrin Mark Sanderson tó jẹ́ ara Ìgbìmọ̀ Olùdarí ló sọ àsọyé Ìrántí Ikú Kristi ní Gbọ̀ngàn Ìjọba tó wà ní ìlú Chirchik, bẹ́ ẹ ṣe rí i nínú àwòrán tó wà lókè yìí.
Wọ́n túmọ̀ àsọyé náà sí èdè Russian.
Àwọn tó wá jẹ́ ogọ́rùn-ún méje àti mọ́kànlélọ́gọ́rin (781).
Lẹ́yìn ìpàdé àkọ́kọ́ yìí, wọ́n ṣe ìpàdé méjì míì nínú Gbọ̀ngàn Ìjọba náà.
Lásìkò ìbẹ̀wò yìí, Arákùnrin Sanderson pẹ̀lú Arákùnrin Paul Gillies láti oríléeṣẹ́ wa àtàwọn arákùnrin méjì láti Central Asia ṣèpàdé pẹ̀lú àwọn ọ̀gá ní Ilé Iṣẹ́ Ètò Ìdájọ́ àti ní Ọ́fíìsì Àwọn Tó Ń Bójú Tó Ẹ̀tọ́ Ọmọnìyàn.
Nínú ìpàdé náà, wọ́n ní kí àwọn ará wa ṣàlàyé àwọn ohun tá a gbà gbọ́ àti ètò wa.
A retí pé ohun táwọn aláṣẹ náà ti mọ̀ nípa wa máa mú kí wọ́n ṣèrànwọ́ láti forúkọ ẹ̀sìn wa sílẹ̀ láwọn agbègbè tó kù lẹ́yìn ìlú Chirchik, èyí sì máa mú kó rọrùn fáwọn ará láti lè ní àwọn ibi tí wọ́n á ti máa jọ́sìn.
Arákùnrin Mark Sanderson pẹ̀lú àwọn ará tí wọ́n rán lọ rèé ní ìta Ilé Iṣẹ́ Ètò Ìdájọ́ Orílẹ̀-èdè Uzbekistan Ìrántí Ikú Kristi tí ọ̀pọ̀ èèyàn wá àti ìpàdé tá a ṣe pẹ̀lú àwọn aláṣẹ yìí jẹ́ ohun tuntun tó wáyé ní Uzbekistan.
Láti oṣù mẹ́fà báyìí, kò sí Ẹlẹ́rìí Jèhófà kankan tí wọ́n ya wọlé rẹ̀ tàbí tí wọ́n ní kó sanwó ìtanràn tàbí táwọn ọlọ́pàá mú.
Ní nǹkan bí ọdún kan sẹ́yìn, ní May 14, 2018, Ọ̀gbẹ́ni Javlon Vakhabov tó jẹ́ aṣojú orílẹ̀-èdè Uzbekistan lọ́dọ̀ ìjọba Amẹ́ríkà sọ ní lójú ọ̀pọ̀ èèyàn pé àwọn aṣòfin máa rí sí i pé wọ́n ṣe àwọn ìyípadà tó yẹ kó lè rọrùn fáwọn Ẹlẹ́rìí Jèhófà láti forúkọ ẹ̀sìn wọn sílẹ̀ lábẹ́ òfin.
Àdúrà wa ní pé kí Jèhófà bù kún ìsapá àwọn ará wa ní Uzbekistan bí wọ́n ṣe ń ‘gbé ìgbé ayé tó pa rọ́rọ́ nìṣó pẹ̀lú ìbàlẹ̀ ọkàn, tí wọ́n sì ń fi gbogbo ọkàn wọn sin Ọlọ́run.”—1 Tímótì 2:2.
Láàárín oṣù mẹ́fà, bẹ̀rẹ̀ láti March 2018, Ilé Ẹjọ́ Gíga Jù Lọ ní Uzbekistan àti Ilé Ẹjọ́ Ìjọba Karakalpakstan, agbègbè kan tó ní ìjọba tiẹ̀ lọ́tọ̀ ní Uzbekistan, sọ nínú àwọn ẹjọ́ kan tí wọ́n dá pé àwa Ẹlẹ́rìí Jèhófà lómìnira lábẹ́ òfin láti jọ́sìn.
Ilé Ẹjọ́ Gíga Jù Lọ yí ìdájọ́ mẹ́rin táwọn ilé ẹjọ́ kan ti ṣe fáwọn ará wa tẹ́lẹ̀ pa dà, Ilé Ẹjọ́ Ìjọba sì tún yí ẹjọ́ kan pa dà láfikún sí àwọn ẹjọ́ mẹ́rin náà.
Timur Satdanov, ọ̀kan lára àwọn ará wa tí Ilé Ẹjọ́ Gíga Jù Lọ dá láre ní Uzbekistan.
Ohun tó ṣẹlẹ̀ ni pé àwọn aláṣẹ gba àwọn ìwé tó dá lórí Bíbélì àtàwọn ẹ̀rọ alágbèéká tí Bíbélì wà nínú wọn lọ́wọ́ àwọn èèyàn, àwọn ọlọ́pàá ṣèwádìí nípa wọn, wọ́n sì gbé ọ̀rọ̀ náà lọ sí ilé ẹjọ́.
Àwọn ilé ẹjọ́ tó kọ́kọ́ gbọ́ ẹjọ́ náà dá àwọn ará wa lẹ́bi, wọ́n sì bu owó ìtanràn lé wọn, torí wọ́n gbà pé àwọn ará náà ti rú òfin táwọn kan sọ pé ó kà á léèwọ̀ fún ẹnikẹ́ni láti máa pín ìwé ẹ̀sìn kiri.
Àmọ́ a dúpẹ́ pé, ilé ẹjọ́ gíga dá àwọn ará wa láre lẹ́nu àìpẹ́ yìí, wọn ò sì ní sanwó ìtanràn náà mọ́.
Inú àwa Ẹlẹ́rìí Jèhófà kárí ayé dùn sí ohun tó ṣẹlẹ̀ yìí, a sì dúpẹ́ lọ́wọ́ àwọn aláṣẹ, àmọ́ a fi ọpẹ́ tó ga jù fún Jèhófà pé ó tọ́ wa sọ́nà, ó sì tì wá lẹ́yìn “bí a ṣe ń gbèjà ìhìn rere, tí a sì ń fìdí rẹ̀ múlẹ̀ lọ́nà òfin.’—Fílípì 1:7.
Ọjọ́ Tí A Ṣe É: November 22 sí 24, 2019
Ibi Tí A Ti Ṣe É: Pápá Ìṣeré Marvel ní Melbourne, Ọsirélíà
Èdè Tí A Lò fún Ìtòlẹ́sẹẹsẹ: Èdè Àwọn Adití Lọ́nà ti Ọsirélíà, Chinese Cantonese, Chinese Mandarin, Gẹ̀ẹ́sì, Korean, Sípáníìṣì, Tagalog, Vietnamese
Iye Àwọn Tó Pésẹ̀: Ẹgbẹ̀rún mẹ́rìndínláàádọ́ta ó lé ọgọ́rùn-ún márùn-ún àti méjìlélọ́gọ́rin (46,582)
Iye Àwọn Tó Ṣèrìbọmi: Ọgọ́rùn-ún mẹ́rin àti méje (407)
Iye Àwọn Aṣojú Tó Wá Láti Orílẹ̀-Èdè Míì: Ẹgbẹ̀rún mẹ́fà àti mẹ́tàlélọ́gọ́rin (6,083)
Àwọn Ẹ̀ka Tí Aṣojú Ti Wá: Ajẹntínà, Kánádà, Hong Kong, Íńdíà, Ítálì, Japan, Kòríà, Philippines, Solomon Islands, South Africa, Taiwan, Amẹ́ríkà
Ìrírí: Ọ̀gá àgbà Ọgbà Ẹranko Ballarat sọ pé: “Gbogbo ẹnu ni mo fi ń sọ pé láti bí ọdún mẹ́ẹ̀ẹ́dógún (15) tí mo ti ń ṣiṣẹ́ ní Ọgbà Ẹranko Ballarat, àwùjọ yín ni mo tíì gbádùn jù, òun ló sì wà létòlétò jù lọ nínú àwùjọ tí mo ti ń bá ṣiṣẹ́.
Mo dúpẹ́ púpọ̀ lọ́wọ́ yín àti lọ́wọ́ àwọn tó mú àwọn èèyàn káàkiri.” Ọ̀gá àgbà ilé ìtura tí àwọn àlejò bí ọgọ́rùn-ún mẹ́ta ó lé ogójì (340) dé sí sọ pé: “Gbogbo wọn máa ń kóra jọ láti yanjú ìṣòro.
Ṣe ni wọ́n dà bí ìdílé kan lójú mi tí gbogbo wọn jọ ń sọ̀rọ̀, tí wọ́n sì ń ti ara wọn lẹ́yìn.
Ká sòótọ́, inú mi dùn gan-an pé mo wà pẹ̀lú wọn.
Ọdún kọkànlá (11) tí mo ti ń ṣiṣẹ́ ìgbàlejò rèé, síbẹ̀ àwùjọ wọn ló jọ mí lójú jù.” Torí ohun tí ọ̀gá náà rí, ó lọ sí àpéjọ tá a ṣe lọ́jọ́ Saturday pẹ̀lú àwọn ará..
Àrọ̀ọ̀rọ̀dá òjò ti mú kí alagbalúgbú omi ya bo apá àríwá-gúúsù orílẹ̀-èdè Ọsirélíà.
Omíyalé yìí lé ẹgbẹẹgbẹ̀rún èèyàn nílé, ọ̀pọ̀ nǹkan ló sì bà jẹ́ títí kan iná ìjọba.
Ẹ̀ka ọ́fíìsì wa ní Ọsirélíà ròyìn pé akéde méjìdínlọ́gọ́ta (58) láti ìjọ mẹ́ta ni omíyalé yìí mú kí wọ́n lọ máa gbé lọ́dọ̀ àwọn mọ̀lẹ́bí wọn tàbí àwọn ará.
Ilé mẹ́wàá tó jẹ́ tàwọn ará wa ni àgbàrá ya wọ̀, ó sì ba méjì lára wọn jẹ́ pátápátá.
Ẹ̀ka ọ́fíìsì ti yan Ìgbìmọ̀ Tó Ń Ṣètò Ìrànwọ́ Nígbà Àjálù, alábòójútó àyíká àtàwọn alàgbà tó wà lágbègbè náà sì ń bójú tó àwọn akéde tọ́rọ̀ yìíkan.
Àdúrà wa ni pé kí àwọn araá wa máa fara dà á nìṣó, kí wọ́n sì rí ìtùnú lọ́dọ̀ àwọn alábòójútó onífẹ̀ẹ́ yẹn.—1 Pétérù 5:2
Tọkọtaya Ẹlẹ́rìí kan pàdánù ilé wọn nígbà tí iná tó jó léraléra nínú igbó sun mílíọ̀nù kan hẹ́kítà ilẹ̀ (nǹkan bíi mílíọ̀nù méjì ààbọ̀ éékà) jákèjádò ìpínlẹ̀ New South Wales àti ìpínlẹ̀ Queensland ní Ọsirélíà.
Kò sí ìkankan nínú àwọn ará wa tó kú tàbí tó fara pa nínú ìṣẹ̀lẹ̀ náà.
Kò sì sí Gbọ̀ngàn Ìjọba tàbí Gbọ̀ngàn Àpéjọ kankan tó bà jẹ́.
Àwọn aláṣẹ ìjọba ìpínlẹ̀ sọ pé ó ṣeé ṣe kó jẹ́ pé àwọn tó ń dáná sun ilé ló bẹ̀rẹ̀ àwọn kan lára iná náà.
Láti oṣù September tí iná náà ti bẹ̀rẹ̀ sí í jó, ó ti pa èèyàn mẹ́fà, ó sì ti jó ilé ó kéré tán ọgọ́rùn-ún mẹ́fà àti ààbọ̀ (650) run pátápátá.
Àwọn ará tó tó igba (200) lọ́kùnrin àti lóbìnrin ló ní láti fi ilé wọn sílẹ̀, àmọ́ wọ́n ti pa dà sílé báyìí.
Àwọn Ẹlẹ́rìí kan ti ń bójú tó tọkọtaya tí ilé wọn bà jẹ́.
Àwọn alàgbà ń fi Ọ̀rọ̀ Ọlọ́run tu àwọn tí ìṣẹ̀lẹ̀ náà kàn nínú.—Ìṣe 20:28.
Ìjì líle kan tó lágbára tí wọ́n ń pè ní Cyclone Harold jà ní apá àríwá àwọn erékùṣù tó wà ní Vanuatu ní April 5, 2020, ó sì ba ọ̀pọ̀ nǹkan jẹ́.
Lẹ́yìn ìyẹn, ní April 8, ó tún ṣọṣẹ́ ní àwọn erékùṣù tó wà ní Fíjì, ó sì tún ba ọ̀pọ̀ nǹkan jẹ́ níbẹ̀ náà.
Nínú ìròyìn tá a kọ́kọ́ gbọ́, kò sí èyíkéyìí lára àwọn arákùnrin wa tó ṣèṣe, a ò sì gbọ́ pé ẹnì kankan lára wọn kú.
Àwọn akéde tó tó ọgọ́rùn-ún méjì àti ọgọ́rin (280) ló ń gbé ní erékùsù Espiritu Santo, ìyẹn erékùṣù tó tóbi jù lápá àríwá Vanuatu.
Ńṣe làwọn ilé sùn lọ bẹẹrẹbẹ, ó sì ba àwọn nǹkan ọ̀gbìn jẹ́, ohun kan náà ló ṣe láwọn erékùṣù míì tó wà nítòsí.
Ní Fíjì, ó bá ilé àwọn ará wa bí ọgọ́rùn-ún méjì àti ọgọ́ta (260) jẹ́ gan-an.
Ohun tó ṣẹlẹ̀ yẹn ṣàkóbá gan-an, débi pé tipátipá ni wọ́n fi ń rí omi lo, iná ò sì, bẹ́ẹ̀ sì ni oúnjẹ ṣọ̀wọ́n.
Ẹ̀ka ọ́fíìsì wa tó wà ní Fíjì ń ṣètò báwọn ará wa ṣe máa rí àwọn ohun tí wọ́n nílò.
Bákan náà, àwọn alàgbà ìjọ ń ṣèbẹ̀wò sọ́dọ̀ àwọn ará lọ́kùnrin àti lóbìnrin kí wọ́n lè tù wọ́n nínú kí wọ́n sì fún wọn níṣìírí.
Inú wa dùn pé àwọn ará wa tó wà níbi tí ìjì ti jà yìí ń rí àbójútó torí pé wọ́n ń rí ìtùnú látinú Ọ̀rọ̀ Ọlọ́run, àwọn ohun kòṣeémáàní tí wọ́n nílò sì ń tẹ̀ wọ́n lọ́wọ́.​—Òwe 17:17.
Ní May 10 sí 19, àwa Ẹlẹ́rìí Jèhófà lórílẹ̀-èdè Israel sapá gan-an láti túbọ̀ wàásù láwọn ibi térò pọ̀ sí ní ìlú Tel Aviv.
Wọ́n fẹ́ ṣe àwọn ọdún ìbílẹ̀ kan ní ìlú náà, èyí sì mú kí àwọn tó ń wá sí ìlú náà ń pọ̀ sí i, torí náà a ṣètò láti wàásù láwọn ibi térò pọ̀ sí.
Bí àpẹẹrẹ, ní May 14 sí 18, wọ́n ṣe ìdíje orin Eurovision Song Contest ní ìlú Tel Aviv, àwọn tó sì wá síbẹ̀ tó ẹgbẹ̀rún mẹ́wàá.
Arákùnrin Gennadi Korobov tó bójú tó iṣẹ́ ìwàásù náà sọ pé: “Nígbà tá a gbọ́ pé ẹgbẹẹgbẹ̀rún èèyàn ló ń bọ̀ níbi ìdíje orin tó máa wáyé ní ìlú Tel Aviv, a gbà pé ó máa fún wa láǹfààní láti túbọ̀ wàásù láwọn ibi térò pọ̀ sí.
Ó wúni lórí láti rí àwọn akéde méjìdínláàádọ́sàn-án (168) tí wọ́n yọ̀ǹda ara wọn láti ìjọ méjìlélógún (22) lórílẹ̀-èdè Israel.” Ojoojúmọ́ làwọn ará yìí pàtẹ àwọn ìwé wa síbi mẹ́jọ ọ̀tọ̀ọ̀tọ̀ láti aago mẹ́sàn-án àárọ̀ títí di aago mẹ́sàn-án alẹ́.
Torí pé oríṣiríṣi orílẹ̀-èdè làwọn àlejò tí wá síbẹ̀, àwọn ará kó àwọn ìwé wa ní èdè mẹ́wàá síbi ìpàtẹ náà, ìyẹn: èdè Lárúbáwá, Chinese, Gẹ̀ẹ́sì, Faransé, Gámánì, Hébérù, Italian, Japanese, Russian àti Sípáníìṣì.
Ó dá wa lójú pé iṣẹ́ ìwàásù tá a mú gbòòrò sí i lórílẹ̀-èdè Israel yìí máa sèso rere.
Ó sì tún jẹ́ ẹ̀rí tó túbọ̀ ń fi hàn pé àwọn èèyàn Jèhófà ń yìn ín “nígbà gbogbo.”—Sáàmù 34:1, 2.
Ní December 5, 2019, Ilé Ẹjọ́ Ẹ̀tọ́ Ọmọnìyàn ti Ilẹ̀ Yúróòpù dájọ́ pé àwọn arákùnrin méjìlélógún (22) láti orílẹ̀-èdè Armenia tí wọ́n dá lẹ́bi pé wọ́n sá fún iṣẹ́ ológun kò jẹ̀bi rárá.
Ilé Ẹjọ́ náà sì ní kí wọ́n san owó gbà-má-bínú tó lé ní ẹgbẹ̀rún lọ́nà ọgọ́rùn-ún méjì ó lé méjìdínláàádọ́rin dọ́là ($267,000) fún àwọn arákùnrin náà.
Èyí ni owó tó pọ̀ jù tí Ilé Ẹjọ́ Ẹ̀tọ́ Ọmọnìyàn ti Ilẹ̀ Yúróòpù tíì bù rí pé kí wọ́n san fún àwọn arákùnrin wa tí wọ́n pè lẹ́jọ́ nítorí ẹ̀rí ọkàn wọn tí kò jẹ́ kí wọn ṣiṣẹ́ ológun.
Ní 2012, wọ́n dá àwọn arákùnrin yìí lẹ́bi torí ẹ̀rí ọkàn wọn ò jẹ́ kí wọ́n ṣiṣẹ́ ológun àti pé wọ́n tún kọ̀ láti ṣiṣẹ́ míì tí kì í ṣe iṣẹ́ ológun.
Ìdí tí wọ́n fi kọ̀ láti ṣiṣẹ́ míì tí kì í ṣe iṣẹ́ ológun ni pé lákòókò yẹn, àwọn ológun ló ń bójú tó iṣẹ́ náà. Torí náà, a ò lè sọ pé kì í ṣe iṣẹ́ ológun.
Nítorí náà, méjì péré nínú àwọn arákùnrin náà ni wọn ò jù sẹ́wọ̀n ṣáájú ọdún 2013, ìyẹn ọdún tí orílẹ̀-èdè Armenia ṣòfin pé kí iṣẹ́ míì wà, tó jẹ́ iṣẹ́ àṣesìnlú lóòótọ́, tí kì í ṣe iṣẹ́ ológun.
Nígbà tí Ilé Ẹjọ́ Ẹ̀tọ́ Ọmọnìyàn ti Ilẹ̀ Yúróòpù fẹ́ gbé ìdájọ́ ẹ̀ kalẹ̀ ní December 5, ó tọ́ka sí ìdáláre tí àwọn Ẹlẹ́rìí Jèhófà rí gbà ní 2017 nínú ẹjọ́ tó wà láàárín orílẹ̀-èdè Armenia àti Adyan pẹ̀lú àwọn ìyókù ẹ̀ (Adyan and Others v. Armenia).
Ilé Ẹjọ́ Ẹ̀tọ́ Ọmọnìyàn ti Ilẹ̀ Yúróòpù sọ pé orílẹ̀-èdè Armenia mọ̀ dáadáa pé ẹjọ́ 2017 yìí jọra gan-an pẹ̀lú ti àwọn arákùnrin méjìlélógún yìí àti pé ṣe ló yẹ kí orílẹ̀-èdè Armenia fìfẹ́ yanjú ọ̀rọ̀ náà.
Síbẹ̀, pẹ̀lú gbogbo bí àwọn arákùnrin wa ṣe sapá tó láti bí ọdún kan sẹ́yìn, ìjọba orílẹ̀-èdè Armenia kọ̀ láti fi wọ́n sílẹ̀.
Àmọ́ ní báyìí, Ilé Ẹjọ́ Ẹ̀tọ́ Ọmọnìyàn ti Ilẹ̀ Yúróòpù ti dá àwọn arákùnrin wa láre.
A dúpẹ́ pé ojú tí ìjọba orílẹ̀-èdè Armenia fi ń wo àwọn tó kọ̀ láti ṣiṣẹ́ ológun nítorí ẹ̀rí ọkàn wọn ti yàtọ̀ sí i láti 2013.
Wọn ò fi àwọn arákùnrin wa sẹ́wọ̀n mọ́, kò sì sí àkọsílẹ̀ mọ́ pé wọ́n jẹ́ ọ̀daràn nítorí wọn ò dá sí tọ̀tún-tòsì.
Láti bí ọdún méje sẹ́yìn, orílẹ̀-èdè Armenia ti ṣètò iṣẹ́ míì tí àwọn tí ẹ̀rí ọkàn wọn ò jẹ́ kí wọ́n ṣiṣẹ́ ológun lè ṣe, tí kò sì sí lábẹ́ ìdarí àwọn ológun rárá.
Àmọ́ ṣá o, Ilé Ẹjọ́ Ẹ̀tọ́ Ọmọnìyàn ti Ilẹ̀ Yúróòpù dá orílẹ̀-èdè Armenia lẹ́bi ní December 5 pé wọn ò tẹ̀ lé òfin àgbáyé ti ọdún 2012.
Pẹ̀lú ìdájọ́ yìí, Ilé Ẹjọ́ Ẹ̀tọ́ Ọmọnìyàn ti Ilẹ̀ Yúróòpù ń sọ fún gbogbo ayé pé òun máa fìyà tó tó ìyà jẹ orílẹ̀-èdè èyíkéyìí tó bá tẹ òfin ẹ̀tọ́ ọmọnìyàn àgbáyé lójú.
A dúpẹ́ lọ́wọ́ Jèhófà pé ó fún àwọn arákùnrin wa tó wà lórílẹ̀-èdè Armenia ní ìdáláre tó ṣàrà ọ̀tọ̀ yìí.
A gbàdúrà kí Jèhófà ṣí ọ̀nà sílẹ̀ fún àwọn arákùnrin wa lórílẹ̀-èdè míì láti má ṣe lọ́wọ́ nínú iṣẹ́ ológun tó jẹ́ dandan, kí wọ́n sì lè ní àǹfààní láti ṣe iṣẹ́ míì dípò iṣẹ́ ológun ní àwọn orílẹ̀-èdè tí kò tíì sí, bí Azerbaijan, South Korea, Turkey àti Turkmenistan.
Ní July 6, 2018, Ilé Ẹjọ́ Barda lórílẹ̀-èdè Azerbaijan fìyà jẹ ọ̀kan lára àwọn arákùnrin wa tó ń jẹ́ Emil Mehdiyev, wọ́n sì fún un láwọn òfin tó gbọ́dọ̀ máa tẹ̀ lé fún ọdún kan gbáko tí kò bá fẹ́ ṣẹ̀wọ̀n.
Ilé ẹjọ́ sọ pé ọmọ ọlọ́dún méjìdínlógún (18) tó ń jẹ́ Emil yìí jẹ̀bi torí pé ó lóun ò wọṣẹ́ ológun, àmọ́ wọn ò rán an lọ sẹ́wọ̀n.
Ní báyìí, kò lè kó kúrò níbi tó ń gbé láìsọ fáwọn aláṣẹ, wọn ò sì jẹ́ kó kúrò lórílẹ̀-èdè Azerbaijan.
Ní December 2017, wọ́n ránṣẹ́ pe Arákùnrin Mehdiyev ní Ẹ̀ka Tó Ń Gbani Síṣẹ́, Tó sì Ń Fani Wọṣẹ́ ní Agbègbè Barda.
Àmọ́ ó kọ̀ láti tọwọ́ bọ̀wé ìwọṣẹ́ ológun, torí ẹ̀rí ọkàn rẹ̀ ò jẹ́ kó ṣiṣẹ́ ológun.
Nígbà tí wọ́n tún ránṣẹ́ sí i, ó pa dà lọ ṣàlàyé fún wọn pé ẹ̀rí ọkàn òun ò ní jẹ́ kóun ṣiṣẹ́ ológun, ó sì ní kí wọ́n jẹ́ kóun ṣiṣẹ́ àṣesìnlú míì dípò iṣẹ́ ológun.
Wọ́n sọ fún un pé kò sírú iṣẹ́ yẹn, wọ́n sì sọ pé àwọn máa gbé ọ̀rọ̀ ẹ̀ lọ sí ọ́fíìsì olùpẹ̀jọ́ ìjọba ní Àgbègbè Barda.
Lẹ́yìn ọ̀pọ̀ atótónu nílé ẹjọ́ àti àìmọye sísún ẹjọ́ náà síwájú, Ilé Ẹjọ́ Barda dá a lẹ́bi, wọ́n sì fòfin dè é láwọn ọ̀nà kan.
Bó tiẹ̀ jẹ́ pé ilé ẹjọ́ ò rán Emil lọ sẹ́wọ̀n, ojú ọ̀daràn làwọn èèyàn á máa fi wò ó, kò sì rọ́gbọ́n dá sí i, torí pé ìjọba Azerbaijan ò tíì ṣètò iṣẹ́ àṣesìnlú títí di báyìí, bó tiẹ̀ jẹ́ pé tipẹ́tipẹ́ ni wọ́n ti ṣèlérí pé àwọn máa ṣe é.
Inú wa dùn pé Arákùnrin Mehdiyev ò yẹhùn lórí ìpinnu rẹ̀ láìka bí nǹkan ṣe nira fún un báyìí tó.—1 Pétérù 2:19.
Ní November 8, 2018, Àjọ Tó Ń Rí sí Ọ̀rọ̀ Iṣẹ́ pẹ̀lú Àwọn Ẹlẹ́sìn ní orílẹ̀-èdè Azerbaijan fọwọ́ sí i káwọn Ẹlẹ́rìí Jèhófà forúkọ ẹ̀sìn wọn sílẹ̀ lábẹ́ òfin délẹ̀délẹ̀ nílùú Baku, tó jẹ́ olú-ìlú Azerbaijan.
Àwọn ará wa ti wá ní ẹ̀rí tó lẹ́sẹ̀ nílẹ̀ lábẹ́ òfin láti máa jọ́sìn ní gbangba, kí wọ́n sì máa wàásù fàlàlà ní ìlú náà.
Àdúrà wa ni pé àṣeyọrí tá a ṣe lábẹ́ òfin yìí máa jẹ́ káwọn aláṣẹ gbà káwọn ará wa tó wà láwọn ibòmíì lórílẹ̀-èdè náà forúkọ ẹ̀sìn wọn sílẹ̀ lábẹ́ òfin.
A dúpẹ́ lọ́wọ́ Jèhófà pé àwọn aláṣẹ fojúure hàn sí wa, wọ́n sì fọwọ́ sí i kí òfin gbà wá láyè láti máa ṣe ìjọsìn wa nílùú Baku.​—Fílípì 1:7.
Ní July 26 sí 28 2019, àwọn Ẹlẹ́rìí Jèhófà tó wà ní orílẹ̀-èdè Azerbaijan ṣe àpéjọ tí wọ́n máa ń ṣe lọ́dọọdún ní Darnagul Ceremony House ní olú ìlú orílẹ̀-èdè náà tí wọ́n ń pé ní Baku.
Lọ́dún yìí tí ọ̀wọ́ àpéjọ àgbáyé mánigbàgbé wáyé, àpéjọ agbègbè tó wáyé ní Baku pẹ̀lú jẹ́ mánigbàgbé ní ti pé òun ni àpéjọ tó tóbi jù lọ tá a ṣe ní Azerbaijan.
Bákan náà, fún ìgbà àkọ́kọ́, àwọn ìjọ tó ń sọ èdè Azerbaijan àti ti Rọ́ṣíà ní orílẹ̀ èdè yẹn pàdé pọ̀ fún àpéjọ kan ṣoṣo.
Bó tiẹ̀ jẹ́ pé gbogbo akéde tó wà ni Azerbaijan kò ju ẹgbẹ̀rún kan àtààbọ̀ (1,500) lọ, síbẹ̀ ẹgbẹ̀rún kan, ọgọ́rùn-ún mẹ́sàn àti méjìdínlógójì (1,938) ló wá sí àpéjọ yìí.
Èèyàn mẹ́tàlélọ́gbọ́n (33) ló sì ṣe ìrìbọmi.
Wọ́n fún Arákùnrin Mark Sanderson ní àǹfààní àrà ọ̀tọ̀ láti wọlé sí orílẹ̀-èdè yìí kó lè sọ àsọyé ní àpéjọ náà.
Èyí ni ìgbà àkọ́kọ́ tí ọ̀kan lára Ìgbìmọ̀ Olùdarí máa ṣe àpéjọ pẹ̀lú àwọn ará ní Azerbaijan.
A dúpẹ́ lọ́wọ́ àwọn aláṣẹ fún ànfààní yìí.
Ìṣọ̀kan tó wà láàárín àwọn arákùnrin àti arábìnrin wa ń jẹ́rìí lọ́nà tó wúni lórí.
Olùdarí ibi tá a lò fún àpéjọ náà kíyè sí i pé àlàáfìà, ìfẹ́ àti inú rere jọba láàárin àwọn Ẹlẹ́rìí Jèhófà nígbà àpéjọ náà àti pé wọ́n ń fi ohun tí wọn ń wàásù ṣèwà hù.
Bó tìẹ̀ jẹ́ pé, wọ́n ṣì ń fojú òmìnira ìsìn àwọn Ẹlẹ́rìí Jèhófà gbolẹ̀ ní Azerbaijan, látìgbàdégbà làwọn aláṣẹ ń fún àwọn ará wa lómìnira tó pọ̀ sí i láti jọ́sìn.
Ní November 2018, ìjọba Azerbaijan fún àwọn Ẹlẹ́rìí Jèhófà láàyè láti forúkọ ẹ̀sìn wọn sílẹ̀ lábẹ́ òfin ní Baku.
Èyí ló sì fún àwọn ará wa ní òmìnira tó pọ̀ sí i lábẹ́ òfin láti jọ́sin ní gbangba ní ìlú náà.
A bá àwọn arákùnrin àti arábìnrin wa ní Azerbaijan yọ̀ fún àwọn ohun rere àti ìṣẹ̀lẹ̀ mánigbàgbé tó wáyé nínú ìtàn wọn.
Àdúrà wa ni pé kí Jèhófà bù kún ìsapá wa “bí a ṣe ń gbèjà ìhìn rere, tí a sì ń fìdí rẹ̀ múlẹ̀ lọ́nà òfin” ní ibi gbogbo lórílẹ̀-èdè Azerbaijan àti kárí ayé.​—Fílípì 1:7.
Ní October 31, 2018, Ilé Ẹjọ́ Kòtẹ́milọ́rùn nílùú Ganja lórílẹ̀-èdè Azerbaijan fọwọ́ sí ẹjọ́ tí ilé ẹjọ́ kan ti dá tẹ́lẹ̀ pé Arákùnrin Vahid Abilov, tó jẹ́ ọmọ ọdún mọ́kàndínlógún (19) jẹ̀bi torí pé ẹ̀rí ọkàn ò jẹ́ kó wọṣẹ́ ológun.
Bó tiẹ̀ jẹ́ pé wọn ò rán Vahid lọ sẹ́wọ̀n, wọ́n fi àwọn òfin máṣu-mátọ̀ kan dè é fún ọdún kan gbáko, tó túmọ̀ sí pé oríṣiríṣi nǹkan ni ò ní lè ṣe.
Bí àpẹẹrẹ, ọ̀sọ̀ọ̀sẹ̀ ló gbọ́dọ̀ máa yọjú sí agbófinró kan, wọn ò sì gbà á láyè kó kúrò ní Azerbaijan.
Vahid máa kọ̀wé pe ẹjọ́ kòtẹ́milọ́rùn sí Ilé Ẹjọ́ Gíga Jù Lọ báyìí, ìpele tó gbẹ̀yìn nìyẹn tó lè gbé ọ̀rọ̀ ẹ̀ dé lábẹ́ òfin ní Azerbaijan. May 2017 ni ìṣòro arákùnrin wa yìí ti bẹ̀rẹ̀.
Kò pẹ́ tó pé ẹni ọdún méjìdínlógún (18) ni wọ́n ní kó lọ sí iléeṣẹ́ ìjọba ní Aghdam tó ń rí sí bí àwọn èèyàn ṣe ń wọṣẹ́ ológun, tí wọ́n sì ń múra sílẹ̀ fún ogun.
Nígbà tó débẹ̀, ó fún wọn níwèé tó kọ, tó fi ṣàlàyé pé òun ò ní lè wọṣẹ́ ológun.
Ohun tó kọ rèé: “Ẹ̀rí ọkàn mi tí mo ti fi Bíbélì kọ́ ò ní jẹ́ kí n lè wọṣẹ́ ológun.
Kì í ṣe pé mò ń sá, tàbí pé mò ń ronú àtisá fún ojúṣe tó yẹ kí n ṣe fún ìlú.
Ohun tí mo kàn fẹ́ kẹ́ ẹ jọ̀ọ́ ṣe fún mi ni pé kẹ́ ẹ jẹ́ kí n ṣiṣẹ́ àṣesìnlú dípò iṣẹ́ ológun.” Àmọ́ àwọn aláṣẹ ò gbà fún Vahid, nígbà tó di July 9, 2018, wọ́n fẹ̀sùn kàn án pé ó ń sá fún iṣẹ́ ológun.
Nígbà tí Ilé Ẹjọ́ Kòtẹ́milọ́rùn nílùú Ganja ń gbọ́ ẹjọ́ náà, Arákùnrin Abilov tún ṣàlàyé ohun tó fà á tí òun ò fi fẹ́ wọṣẹ́ ológun.
Ó ka ìwé Àìsáyà 2:4 fún ilé ẹjọ́, ó sì ṣàlàyé pé àyẹ̀wò tí òun fúnra òun ṣe nínú Bíbélì jẹ́ kó dá òun lójú pé “kò tiẹ̀ yẹ kóun kọ́ bí wọ́n ṣe ń jà.” Láìka gbogbo àlàyé tó ṣe sí, ilé ẹjọ́ sọ pé ó jẹ̀bi.
A ò tíì mọ̀ bóyá Ilé Ẹjọ́ Gíga Jù Lọ máa fọwọ́ sí i kó ṣe ohun tó fẹ́.
Nígbà tí orílẹ̀-èdè Azerbaijan dara pọ̀ mọ́ Ìgbìmọ̀ Ilẹ̀ Yúróòpù lọ́dún 2001, wọ́n ṣàdéhùn pé àwọn máa ṣòfin tó máa fọwọ́ sí iṣẹ́ àṣesìnlú. Àmọ́ wọn ò tíì mú àdéhùn náà ṣẹ.
Èyí ń mú kí àwọn ará wa máa kojú ìṣòro léraléra lórí ọ̀rọ̀ pé ẹ̀rí ọkàn ò jẹ́ kí wọ́n ṣiṣẹ́ ológun.
Lọ́wọ́ ìbẹ̀rẹ̀ ọdún yìí, ilé ẹjọ́ kan ní Azerbaijan tún dá Emil Mehdiyev tó jẹ́ ọ̀kan lára àwọn ará wa lẹ́bi torí pé ó kọ̀ láti wọṣẹ́ ológun, wọ́n sì sọ pé kó wà lábẹ́ àyẹ̀wò fún ọdún kan.
Òun náà ti pe ẹjọ́ kòtẹ́milọ́rùn sí Ilé Ẹjọ́ Gíga Jù Lọ.
Yàtọ̀ síyẹn, ẹjọ́ mẹ́rin ló ṣì wà ní Ilé Ẹjọ́ Ẹ̀tọ́ Ọmọnìyàn ti Ilẹ̀ Yúróòpù lórí ọ̀rọ̀ àwọn ará wa tí ẹ̀rí ọkàn ò jẹ́ kí wọ́n ṣiṣẹ́ ológun.
Láìka àwọn ìṣòro yìí sí, àwọn ará wa ò yéé gbára lé Jèhófà kó lè ràn wọ́n lọ́wọ́ láti má se dá sí ọ̀rọ̀ ogun.—Jòhánù 15:19.
Lóṣù March 2019, Ilé Ẹjọ́ Gíga Jù Lọ ní Bọ̀géríà dá àwọn ará wa láre nínú ẹjọ́ mẹ́ta ọ̀tọ̀ọ̀tọ̀.
Àwọn ẹjọ́ tó lápẹẹrẹ yìí máa wúlò gan-an láti dáàbò bo ẹ̀tọ́ táwọn ará wa ní láti ṣe ẹ̀sìn wọn káàkiri orílẹ̀-èdè náà.
Nínú méjì lára àwọn ẹjọ́ náà, ńṣe làwọn ilé iṣẹ́ tó ń gbéròyìn jáde parọ́ mọ́ àwọn ará wa.
Lọ́dún 2012, ìwé ìròyìn Vseki Den gbé àpilẹ̀kọ kan jáde tó fi sọ̀rọ̀ tí kò dáa nípa ohun tá a gbà gbọ́.
Bákan náà, lọ́dún 2014, ilé iṣẹ́ tẹlifíṣọ̀n SKAT TV gbé ìròyìn èké jáde nípa ètò wa.
Nígbà táwọn ará wa sọ fún wọn pé kí wọ́n ṣàtúnṣe sí irọ́ tí wọ́n pa mọ́ wa, ńṣe ni ilé iṣẹ́ méjèèjì kọ̀ jálẹ̀.
Lẹ́yìn ọ̀pọ̀ ẹjọ́ tá a pè, títí dé àwọn ilé ẹjọ́ kòtẹ́miọ́rùn, a gbé àwọn ẹjọ́ náà lọ sí Ilé Ẹjọ́ Gíga Jù Lọ.
Ní March 18, 2019 Ilé Ẹjọ́ Gíga Jù Lọ dá ilé iṣẹ́ tẹlifíṣọ̀n SKAT TV lẹ́bi.
Ní March 26, Ilé Ẹjọ́ yìí tẹ̀ lé ìpinnu rẹ̀ nínú ẹjọ́ àkọ́kọ́, ó sì dẹ́bi fún ìwé ìròyìn Vseki Den pé ó lo “ọ̀rọ̀ tó fi hàn pé ó kórìíra.” Ẹjọ́ kẹta dá lé ìwà ìkà táwọn ọmọ ẹgbẹ́ òṣèlú VMRO-Bulgarian National Movement hù sáwọn ará wa.
Ní April 17, 2011, àwọn ará wa pé jọ láti ṣe Ìrántí ikú Jésù.
Àmọ́, ńṣe ni Georgi Drakaliev tó jẹ́ olórí nínú ẹgbẹ́ VMRO kó ọgọ́ta (60) jàǹdùkú jọ, wọ́n wá ṣe àwọn ará lésẹ, wọ́n sì dọ́gbẹ́ sí wọn lára.
Àwọn ará gbé ọ̀rọ̀ náà lọ sílé ẹjọ́.
Nígbà tó yá, ọ̀rọ̀ náà dé Ilé Ẹjọ́ Gíga Jù Lọ.
Ní March 20, 2019, Ilé Ẹjọ́ Gíga Jù Lọ dá Ọ̀gbẹ́ni Drakaliev lẹ́bi, wọ́n sì ní kó sanwó ìtanràn fáwọn ará wa.
Inú wa dùn gan-an torí bá a ṣe jàre nínú ẹjọ́ mẹ́tẹ̀ẹ̀ta yìí.
Àwọn ilé ẹjọ́ lè lo àwọn ìdájọ́ tó lápẹẹrẹ yìí láti dáàbò bo ẹ̀tọ́ táwọn ará wa ní láti “máa gbé ìgbé ayé tó pa rọ́rọ́ nìṣó pẹ̀lú ìbàlẹ̀ ọkàn, bí wọ́n ti ń fi gbogbo ọkàn wọn sin Ọlọ́run.”​—1 Tímótì 2:2.
Ní September 7, 2019, a mú Bíbélì Mímọ́ ti Ìtumọ̀ Ayé Tuntun tá a tún ṣe jáde lédè Czech àti Slovak.
Arákùnrin Stephen Lett tó jẹ́ ọ̀kan lára Ìgbìmọ̀ Olùdarí ló mú Bíbélì méjèèjì náà jáde níbi àkànṣe ìpàdé kan tá a ṣe nílùú Ostrava lórílẹ̀-èdè Czech Republic.
Ibi tó ju igba (200) ọ̀tọ̀ọ̀tọ̀ lọ ni wọ́n ti gbé àkànṣe ìpàdé náà sáfẹ́fẹ́ lórílẹ̀-èdè Czech Republic àti Slovakia, ẹgbẹ̀rún-ún márùndínlọ́gbọ̀n àti igba ó lé mẹ́rìnlélọ́gọ́rin (25,284) èèyàn ló sì pésẹ̀ síbẹ̀.
Ó ju ọdún mẹ́rin tí àwùjọ àwọn atúmọ̀ èdè kọ̀ọ̀kan fi ṣiṣẹ́ kí wọ́n tó lè mú àwọn ìtẹ̀jáde náà jáde.
Àǹfààní pàtàkì tó wà nínú àwọn ìtúmọ̀ Bíbélì tá a tún ṣe yìí ni pé, wọ́n rọrùn láti kà.
Ọ̀kan lára àwọn atúmọ̀ èdè Slovak sọ pé: “Àwọn èèyàn máa gbádùn Bíbélì yìí gan an, ó sì máa dùn-ún kà.
Torí pé àwọn ọ̀rọ̀ inú ẹ̀ ò le, ó sì rọrùn láti lóye, ẹni tó ń kà á kò ní fẹ́ fi í sílẹ̀ kó lè mọ ohun tó ṣẹlẹ̀ tẹ̀ lé e.” Àwọn Ẹlẹ́rìí Jèhófà tó wà lórílẹ̀-èdè Czech Republic ju ẹgbẹ̀rún márùndínlógún (15,000) lọ, àwọn Ẹlẹ́rìí tó wà ní Slovakia sì ju ẹgbẹ̀rún mọ́kànlá (11,000) lọ, gbogbo wọn ló sì máa gbádùn Bíbélì tuntun yìí.
Ọ̀kan lára àwọn atúmọ̀ èdè lórílẹ̀-èdè Czech sọ pé: “Ohun kan tó ṣe pàtàkì nínú Bíbélì Ìtumọ̀ Ayé Tuntun tá a tún ṣe yìí ni bá a ṣe lo àwọn gbólóhùn tí kò gùn jù tá a sì lo èdè tó bóde mu ká lè túmọ̀ èdè tí wọ́n fi kọ Bíbélì ní ìpilẹ̀ṣẹ̀ lọ́nà tó ṣe kedere.
Kì í ṣe àwọn tó ti di Ẹlẹ́rìí Jèhófà fún ọ̀pọ̀ ọdún nìkan ló máa lóye Bíbélì yìí, àmọ́ àwọn ọ̀dọ̀ àtàwọn tó ṣẹ̀ṣẹ̀ ń kẹ́kọ̀ọ́ òtítọ́ náà máa lóye rẹ̀.” Ní báyìí, a ti túmọ̀ Bíbélì Ìtumọ̀ Ayé Tuntun lódindi tàbí lápá kan sí èdè mẹ́rìnlélọ́gọ́sàn-an (184), èyí tá a tún ṣe lọ́dún 2013 la fi túmọ̀ mọ́kàndínlọ́gbọ̀n (29) lára ẹ̀.
Àdúrà wa ni pé kí Bíbélì tuntun yìí mú káwọn tó ń kà á túbọ̀ nífẹ̀ẹ́ sí òtítọ́ tó wà nínú Ọ̀rọ̀ Ọlọ́run.​—Lúùkù 24:32.
Ní July 19, 2019, Arákùnrin Stephen Lett tó jẹ́ ọ̀kan lára Ìgbìmọ̀ Olùdarí fi tayọ̀tayọ̀ mú Ìwé Mímọ́ Kristian Lédè Griki ní Ìtumọ̀ Ayé Titun jáde lèdè Icelandic ní àpéjọ àgbáyé tá a ṣe ní Copenhagen lórílẹ̀ èdè Denmark.
Lówùúrọ̀ Friday àpéjọ náà, alága sọ pé kí gbogbo àwọn tó wà làwọn ìjọ tó ń sọ èdè Icelandic wá sí yàrá kékeré kan tó wà nínú pápá ìṣeré náà ní àkókò ìsinmi ọ̀sán.
Níbi àkànṣe ìpàdé yìí ni Arákùnrin Lett ti fún àwọn ọgọ́rùn mẹ́ta àti mọ́kànlélógójì 341) arákùnrin àti arábìnrin tó wà níbẹ̀, tí wọn sì gbà á pẹ̀lú ẹ̀mí ìmoore.
Fún ọ̀pọ̀ ọdún ni àwọn ọmọ ìlú Iceland ti ṣiṣẹ́ láti tú Bíbélì sí èdè wọn.
Ní ọdún 1540, Oddur Gottskálksson tẹ̀ Ìwé Mímọ́ Kristẹni lédè Gíríìkì jáde ní èdè Iceland fún ìgbà àkọ́kọ́.
Láti ọdún 2010 ni àwọn ará wa tó ń sọ èdè Icelandic ti ń lo Bíbélì tó ń jẹ́ Bible of the 21st Century èyí tí àjọ Icelandic Bible Company tẹ̀ jáde.
Ní báyìí, ara àwọn arákùnrin àtàwọn arábìnrin wa tó ń lágbègbè tí wọ́n ti ń sọ èdè Icelandic ti wà lọ́nà láti lo Bíbélì tí a ṣẹ̀ṣẹ̀ mú jáde yìí láti sọ ìròyìn ayọ̀ náà fún àwọn tó lé ní ẹgbẹ̀rún lọ́nà ọgọ́rùn-ún mẹ́ta (300,000) tó ń sọ èdè yìí.
Arákùnrin kan tó jẹ́ ọkàn lára àwọn tó ṣe iṣẹ́ ìtumọ̀ náà sọ pé: “Ó fẹ́rẹ̀ẹ́ gbà tó ọdún mẹ́rin láti túmọ̀ Ìwé Mímọ́ Kristẹni lédè Gíríìkì sí èdè Icelandic.
Ohun tó mú kí ìtumọ̀ yìí ṣàrà ọ̀tọ̀ ni pé, ó dá orúkọ Jèhófà padà sí gbogbo ibi tó yẹ kó wà nínú Ìwé Mímọ́.
Èyí wà ní ìbámu pẹ̀lú àdúrà Jésù tó wà ní Jòhánù 17:26 tó sọ pé: ‘Mo ti jẹ́ kí wọ́n mọ orúkọ rẹ, màá sì jẹ́ kí wọ́n mọ̀ ọ́n.’ ” A dúpẹ́ pé Jèhófà ń bá a lọ láti bù kún iṣẹ́ tó gbé fún wa láti wàásù ìhìn rere dé gbogbo ilẹ̀ ayé tí à ń gbé pátá. Bá a ṣe ń túmọ̀ Bíbélì ti ràn wá lọ́wọ́ láti ṣe iṣẹ́ yìí yanjú.
Àdúrà wa ni pé kí àwọn èèyàn púpọ̀ sí i fẹ́ láti kẹ́kọ̀ọ́ nípa “àwọn ohun àgbàyanu Ọlọ́run” bí wọ́n ṣe ń ka ọ̀rọ̀ rẹ̀ ní èdè ìbílẹ̀ wọn.​—Ìṣe 2:11.
Ní July 2019, a ṣí ibi tuntun tí wọ́n kó onírúurú Bíbélì sí ní ẹ̀ka ọ́fíìsì àwọn Ẹlẹ́rìí Jèhófà tó wà ní Scandinavia, nílùú Holbæk lórílẹ̀-èdè Denmark, ibẹ̀ ò jú nǹkan bi kìlómítà márùndínláàádọ́rin (65) sí ìlú Copenhagen.
Àkòrí tí wọ́n kọ síbi tí wọ́n kó àwọn Bíbélì náà sí ni “The Bible and the Divine Name in Scandinavia” tó túmọ̀ sí Bíbélì àti Orúkọ Àtọ̀runwá Náà ní Scandinavia.
Níbẹ̀, wàá rí àtẹ kan tí wọ́n kó ọ̀pọ̀ Bíbélì tó ṣàrà ọ̀tọ̀ sí lédè Danish, Faeroese, Greenlandic, Icelandic, Norwegian, Saami àti Swedish.
Bíbélì tó wà nínú àtẹ yìí ju àádọ́ta (50) lọ.
Ọ̀kan lára ohun tó ṣe pàtàkì jù nínú àtẹ náà ni Bíbélì ìpilẹ̀ṣẹ̀ Gustav Vasa ti ọdún 1541.
Òun ni odindi Bíbélì àkọ́kọ́ tí wọ́n ṣe lédè Scandinavia.
Inú Bíbélì Gustav Vasa ni wọ́n ti mú èyí tó pọ̀ jù nínú gírámà àti ọ̀rọ̀ èdè àwọn ará Sweden.
Wọ́n tún lò ó láti fi túmọ̀ àwọn Bíbélì míì lédè Sweden fún ọgọ́rùn-ún mẹ́ta (300) ọdún tó tẹ̀ lé e. Wọ́n pàtẹ Bíbélì ìpilẹ̀ṣẹ̀ Gustav Vasa ti ọdún 1541 síbi tí wọ́n ń kó nǹkan ìṣẹ̀ǹbáyé sí Ohun tó tún ṣàrà ọ̀tọ̀ nínú àtẹ náà ni Bíbélì ìpilẹ̀ṣẹ̀ 1550 Christian III ti ọdún 1550.
Òun ni odindi Bíbélì àkọ́kọ́ tí wọ́n ṣe lédè Danish.
Ìlànà tí wọ́n fi kọ Bíbélì Christian III ni wọ́n lò nínú èdè Danish, kódà ọ̀rọ̀ inú ẹ̀ ti di ara èdè tí ọ̀pọ̀ lára àwọn ará Àríwá Yúróòpù ń lò báyìí.
Ẹ̀dà Bíbélì ìpilẹ̀ṣẹ̀ Christian III ti ọdún 1550 Erik Jørgensen tó wà ní ẹ̀ka ọ́fíìsì orílẹ̀-èdè Scandinavia sọ pé: “Ibi tuntun tí wọ́n ń kó onírúurú Bíbélì sí yìí ti jẹ́ ka rí i pé láti ọ̀pọ̀ ọdún sẹ́yìn làwọn ará Scandinavia ti ní ìfẹ́ tó jinlẹ̀ fún Ọrọ̀ Ọlọ́run àti orúkọ rẹ̀ tí kò lẹ́gbẹ́, ìyẹn Jèhófà.”
Déètì: July 19-21, 2019
Ibi Tí A Ti Ṣeé: Pápá Ìṣeré Brøndby àti Gbàgede Brøndby Hallen, ní Copenhagen, Denmark
Èdè: Danish, Èdè Adití ti Danish, Gẹ̀ẹ́sì, Icelandic, Èdè Adití ti Norway, Èdè Adití ti Sweden
Àwọn Tó Wá: 26,409
Àwọn Tó Ṣèrìbọmi: 141
Àwọn Tó Wá Láti Ilẹ̀ Òkèèrè: 7,000
Àwọn Ẹ̀ka Ọ́fíísì Tá A Pè: Amẹ́ríkà, Australasia, Brazil, Central America, Central Europe, Colombia, Dominican Republic, Finland, Georgia, India, Japan, Poland
Ìrírí: Christian Tidemand Andersen, tó jẹ́ olùṣekòkárí ayẹyẹ ní Pápá Ìṣeré Brøndby sọ pé: “Ọdún kan àtàbọ̀ sẹ́yìn la ti bẹ̀rẹ̀ sí múra sílẹ̀ fún àpéjọ àgbáyé àwọn Ẹlẹ́rìí Jèhófà yìí. Láti ọjọ́ àkọ́kọ́ tí a ti bẹ̀rẹ̀ ló ti jẹ́ pé ṣe ni àwùjọ méjèèjì máa ń gbọ́ ara wa yé ni, ó yà mi lẹ́nu gan-an ni.
Bá a ṣe jọ ń bọ̀wọ̀ fún ara wa tá a sì jọ ń fara balẹ̀ gbọ́ ara wa yé ló jẹ́ kí gbogbo ètò ayẹyẹ ńlá yìí yọrí sí rere láìka gbogbo àwọn ìṣòro tó yọjú lọ́tùn-ún lósì sí.
Kò wọ́pọ̀ láti rí iléeṣẹ́ tó wà létòlétò, tò sì ń ronú láti ṣe nǹkan fínnífínní bíi tiyín.
Nígbà tó sì wá di ọjọ́ àpéjọ náà, ò wúni lórí láti rí àwọn tó yọ̀ǹda ara wọ́n bí wọ́n ṣe ń ṣiṣẹ́ láti àárọ̀ ṣúlẹ̀ tí inú wọ́n ń dùn, tí wọ́n sì ń rẹ́rìn-ín músẹ́.
Àǹfààní ńlá ló jẹ́ fún wa pé a kópa nínú ètò ayẹyẹ ńlá yìí, a sì fẹ́ láti dúpẹ́ gan-an lọ́wọ́ Ìgbìmọ̀ Àpéjọ yín àti àwọn tó yọ̀ǹda ara wọn fún ìfọwọ́sowọ́pọ̀ wọn.
À ń retí ẹ̀yin àti àwọn àlejò yín nígbà míì ní Pápá Ìṣeré Brøndby.”
HELSINKI—Ní ọ̀ṣán Friday, August 18, 2017, afẹ̀míṣòfò kan pa ọ̀kan nínú àwon arábìnrin wa ní orílẹ̀-èdè Finland.
Ìwádìí ń lọ lọ́wọ́ nípa ìṣẹ̀lẹ̀ yìí, àmọ́ ẹ̀rí fi hàn pé àwọn obìnrin ni afẹ̀míṣòfò yìí dájú sọ.
Yàtọ̀ sí arábìnrin wa, afẹ̀míṣòfò yẹn tún pa obìnrin kan, ó sì ṣe èèyàn mẹ́jọ léṣe ní gbàgede ọjà ìlú Turku tó wà ní etíkun orílẹ̀-èdè Finland.
Ẹsẹ̀kẹsè tí ìṣẹ̀lẹ̀ náà wáyé ni àwọn aṣojú láti ẹ̀ka ọ́fíìsì Finland, alábòójútó àyíká àtàwọn alàgbà lọ pèsè ìrànwọ́ fáwọn tí ọ̀rọ̀ náà kàn, wọ́n sì tù wọ́n nínú.
Veikko Leinonen tó jẹ́ agbọ̀rọ̀sọ fún ẹ̀ka ọ́fíìsì àwa Ẹlẹ́rìí Jèhófà ní Finland, sọ pé: “Nǹkan burúkú gbáà ni ohun to ṣẹlẹ̀ yìí, ó sì bà wá nínú jẹ́ gan-an pé ọ̀kan lára arábìnrin wa tó jẹ́ aṣáájú ònà kú sínú ìṣẹ̀lẹ̀ náà níbi tó ti ń wàásù níbi táwọn èèyàn pọ̀ sí.
Èèyàn lè gbìyànjú láti sá fún ewu, ṣùgbọ́n nígbà míì èèyàn lè ṣe kòńgẹ́ ‘ìgbà àti ìṣẹ̀lẹ̀ tí a kò rí tẹ́lẹ̀,’ títí kan ọṣẹ́ táwọn àfẹ̀míṣòfò máa ń ṣe.
Síbẹ̀, àá máa báa lọ láti tu ara wa nínú lẹ́nì kìíní-kejì, pàápàá ìdílé arábìnrin tí ọ̀fọ̀ ṣẹ̀.
Àdúrà wa ni pé kí Jèhófà tu gbogbo àwọn tó ń ṣọ̀fọ̀ nínú, kó sì fún wọn ní àláàfíà rẹ̀.
Àá máa bá a lọ láti wà lójúfò, àá sì máa ṣọ́ra, síbẹ̀ a ò ní jẹ́ kí ìbẹ̀rù bò wá mọ́lẹ̀, àá sì máa fìtara wàásù nìṣó.”—Oníwàásù 9:11; Róòmù 15:13; Fílípì 4:6, 7.
Ẹ̀ka ọ́fíìsì tún kọ lẹ́tà sí gbogbo àwọn ìjọ tó wà lórílẹ̀-èdè Finland láti tu àwọn ará nínú.
Láfikún sí èyí, ẹ̀ka ọ́fììsì tún ṣètò ìpàdé àkànṣe láti pèsè ìṣírí fún nǹkan bí 135 arákùnrin àtàwọn arábìnrin wa tó ń ìwàásù níbi tí èrò pọ̀ sí ní Turku.
Àwọn aṣáájú ọ̀nà yìí fi hàn pé àwọn jẹ́ onígboyà bí wọ́n ṣe pinnu pé àwọn á máa wàásù nìṣó níbi tí èrò pọ̀ sí.
Ẹ̀rù ba ọ̀pọ̀ èèyàn tó ń gbé ní Turku gan-an torí ìṣẹ̀lẹ̀ yìí, ìdí sì ni pé wọ́n gbà pé orílẹ̀-èdè Finland jẹ́ ọ̀kan lára orílẹ̀-èdè tó ní ààbò jù lọ.
Láàrọ̀ ọjọ́ kẹjì tí ìṣẹ̀lẹ̀ náà wáyé, ńṣe làwọn ará ń bá ìwàásù wọn lọ láti ilé-dé-ilé. Wọ́n ń tu àwọn èèyàn nínú, wọ́n sì ń fún wọn níṣìírí.
Ẹ̀ka ọ́fíìsì wa ní Finland dúpẹ́ lọ́wọ́ ẹgbẹ́ ará kárí ayé fún àdúrà yín àti ìtìlẹ́yìn yín.
(1 Pétérù 2:17; 5:9) Àmọ́ ọpẹ́ wa tó ga jù lọ sọ́dọ̀ Jèhófà, “Ọlọ́run tí ń pèsè ìfaradà àti ìtùnú.”—Róòmù 15:5.
Tayọ̀tayọ̀ làwọn ará lọ́kùnrin lóbìnrin ní Jọ́jíà fi kí àwọn àlejò tó wá láti orílẹ̀-èdè méjìdínlógún (18) káàbọ̀ síbi àkànṣe àpéjọ “Jẹ́ Onígboyà”!
tó wáyé ní Tbilisi, olú-ìlú Jọ́jíà, ní July 20-22, 2018.
Ìgbà àkọ́kọ́ rèé tí àkànṣe àpéjọ máa wáyé ní Jọ́jíà, ọpọ̀ àsọyé tó ń gbéni ró, tó sì dá lórí Bíbélì ni wọ́n gbọ́ níbẹ̀, àwọn ará fìfẹ́ gba àwọn ará wọn lálejò, wọ́n sì ṣàfihàn àṣà ìbílẹ̀ wọn àti ìtàn orílẹ̀-èdè náà.
Ibi tí wọ́n ti ṣe àpéjọ náà ni Olympic Palace, gbọ̀ngàn ìṣeré kan tó wà nílùú Tbilisi, iye àwọn tó sì péjọ síbẹ̀ jẹ́ ẹgbẹ̀rún méje ó lé méjì (7,002).
Wọ́n ta àtagbà ìtòlẹ́sẹẹsẹ àpéjọ náà sí ibi ọgọ́rin (80) ọ̀tọ̀ọ̀tọ̀ káàkiri orílẹ̀-èdè náà, èyí mú kí àpapọ̀ àwọn tó gbádùn àpéjọ náà lé ní ẹgbẹ̀rún mọ́kànlélógún àti ọgọ́rùn-ún márùn-ún (21,500).
Ọ̀kan lára ohun mánigbàgbé tó wáyé ní àpéjọ náà ni àwọn igba ó lé mẹ́jọ (208) tó ṣe ìrìbọmi tí wọ́n sì di Ẹlẹ́rìí Jèhófà.
Yàtọ̀ sí àwọn àsọyé tó dá lórí Bíbélì tí wọ́n gbọ́, àwọn tó wá láti orílẹ̀-èdè míì gbádùn bí àwọn ará Jọ́jíà ṣe ṣàfihàn àṣà ìbílẹ̀ wọn.
Àwọn ará ní Jọ́jíà jó ijó ìbílẹ̀ fún wọn, wọ́n kọrin ilẹ̀ wọn, wọ́n tún ṣe oúnjẹ ìbílẹ̀ wọn, wọ́n sì mú àwọn àlejò náà rìn yí ká àwọn ibi àtijọ́ nílùú Tbilisi.
Tamaz Khutsishvili tó jẹ́ aṣojú ẹ̀ka ọ́fíìsì Jọ́jíà sọ pé: “Kì í kúkú ṣe pé a lómìnira ẹ̀sìn lọ títí lórílẹ̀-èdè wa.
Àmọ́ lọ́tẹ̀ yìí, àwọn aláṣẹ ìlú fọwọ́ sowọ́ pọ̀ pẹ̀lú wa, òun ló jẹ́ ká láǹfààní láti gba àwọn ará wa tó pọ̀ tó yìí lálejò ká lè jọ gbádùn àpéjọ yìí ní ìrọwọ́rọsẹ̀. A ò lè gbàgbé láé!”—Róòmù 15:7.
Ní July 1948, àwa Ẹlẹ́rìí Jèhófà ṣe àpéjọ kan ní ìlú Kassel lórílẹ̀-èdè Jámánì. Àpéjọ yìí ni àpéjọ térò tíì pọ̀ jù táwa Ẹlẹ́rìí ṣe nílẹ̀ Yúróòpù lẹ́yìn tí Ogun Àgbáyé Kejì jà.
Àwa Ẹlẹ́rìí Jèhófà wá ṣe ètò ìpàtẹ kan nílùú Kassel láti fi rántí bí àpéjọ náà ṣe wáyé ní àádọ́rin (70) ọdún sẹ́yìn.
Ní gbogbo ọjọ́ méjìlá (12) tí wọ́n fi ṣe ìpàtẹ yìí, àwọn tó lé ní ẹgbẹ̀rún méjì (2,000) ló wá síbẹ̀.
Kódà iléeṣẹ́ tẹlifíṣọ̀n kan gbé ètò náà sáfẹ́fẹ́, ọ̀pọ̀ àwọn oníwèé ìròyìn ló sì kọ̀ròyìn nípa rẹ̀.
Àwọn Ẹlẹ́rìí Jèhófà tó wà níbi àpéjọ ọdún 1948 sọ ìrírí wọn.
Mánigbàgbé ni àpéjọ tó wáyé lọ́jọ́ kìíní àná ní Kassel torí pé àwọn 23,150 ló pé jọ, tí ẹgbẹ̀rún kan ó lé igba (1,200) sì ṣèrìbọmi.
Bákan náà, ọ̀pọ̀ nínú àwọn tó sọ̀rọ̀ ní àpéjọ yẹn àtàwọn tó pé jọ ló jẹ́ àwọn tójú wọn ti rí màbo ní àgọ́ ìṣẹ́niníṣẹ̀ẹ́. Lára àwọn tó sọ̀rọ̀ ìbẹ̀rẹ̀ níbi ètò ìpàtẹ náà, ìyẹn Ọ̀mọ̀wé Gunnar Richter kan sárá sáwọn Ẹlẹ́rìí Jèhófà.
Òun ni alábòójútó ibi ìrántí tí wọ́n ṣe fáwọn tójú wọn rí màbo ní àgọ́ ìṣẹ́niníṣẹ̀ẹ́ Breitenau, nínú àlàyé rẹ̀, ó sọ bí ìjọba Násì ṣe fojú àwọn Ẹlẹ́rìí Jèhófà han èèmọ̀.
Àwọn arákùnrin àtàwọn arábìnrin ṣiṣẹ́ kára láti tún ilẹ̀ tí wọ́n lò fún àpéjọ náà ṣe, kòtò gìrìwò tó wà níbẹ̀ lé ní àádọ́ta (50). Lára àwọn fọ́tò tí wọ́n fi hàn níbi ìpàtẹ náà jẹ́ ká rí ọṣẹ́ tí Ogun Àgbáyé Kejì ṣe nílùú Kassel, kódà ìlú náà fẹ́rẹ̀ẹ́ pa run.
Nígbà táwọn ará ń ṣètò àpéjọ yẹn nígbà yẹn lọ́hùn-ún, pápá kan tí onírúurú bọ́ǹbù ti gbẹ́ kòtò gìrìwò sí láwọn aláṣẹ rí yọ̀ǹda fún wọn.
Arákùnrin Kurt Rex tí àpéjọ náà ṣojú rẹ̀ sọ iṣẹ́ àṣelàágùn táwọn ará ṣe fún nǹkan bí ọ̀sẹ̀ mẹ́rin kí wọ́n lè tún pápá náà ṣe, ó sọ pé: “Iṣẹ́ náà gbomi gan-an.
A kọ́kọ́ fi garawa gbọ́n àwọn omi tó dá rogún sínú àwọn kòtò gìrìwò náà.
Lẹ́yìn ìyẹn la ṣẹ̀ṣẹ̀ bẹ̀rẹ̀ sí í kó òkúta láti àwọn àwókù ilé tí bọ́ǹbù ti bà jẹ́ ká lè fi dí àwọn kòtò náà.
A ò ní ẹ̀rọ tó ń ki ilẹ̀, torí náà fúnra wa la tún bẹ̀rẹ̀ sí í ki ilẹ̀ náà kó lè tẹ́jú pẹrẹsẹ.
Torí pé àsìkò òjò ló bọ́ sí, òjò pa dẹndẹ sí wa lára, kódà gbogbo ìgbà laṣọ wa máa ń rin gbingbin.” Láìka àrọ̀ọ̀rọ̀dá òjò yìí sí, iyẹ̀pẹ̀ àti òkúta táwọn ará kó wá sí pápá náà máa kún ohun tó fẹ́rẹ̀ẹ́ tó ẹgbẹ̀rún mẹ́rin ó lé ọgọ́rùn-ún méje àti ọgọ́ta (4,760) ọkọ̀ típà.
Díẹ̀ lára àwọn tó ju 23,000 tó wá sí àpéjọ náà.
Wolfram Slupina tó jẹ́ aṣojú tí ẹ̀ka ọ́fíìsì àwa Ẹlẹ́rìí Jèhófà ní Jámánì rán wá ṣàlàyé ohun tó mú káwọn ará lo ara wọn tokuntokun fún iṣẹ́ náà, ó sọ nínú ọ̀rọ̀ rẹ̀ pé: “Lẹ́yìn táwọn arákùnrin àtàwọn arábìnrin yẹn jáde nínú àgọ́ ìṣẹ́niníṣẹ̀ẹ́, wọn ò bẹ̀rẹ̀ sí í káàánú ara wọn tàbí kí wọ́n máa bínú sáwọn aláṣẹ.
Dates: June 14-16, 2019
Location: Olympic Stadium in Berlin, Germany
Program Languages: English, German, Russian
Peak Attendance: 37,115
Total Number Baptized: 255
Number of International Delegates: 5,000
Invited Branches: Brazil, Britain, Canada, Ecuador, Finland, Greece, Poland, Scandinavia, Slovenia, United States
Local Experience: Delegates toured the famous Pergamon Museum in Berlin as part of the activities surrounding the convention.
After observing our brothers as they visited the museum, a guard stated: “Many people are hopeless because they do not have any faith.
It’s very obvious, however, that you do have faith and love among yourselves.” Another guard said: “With visitors like you, time flies by and I’m happy to work overtime.”
Nígbà ayẹyẹ kan tó wáyé ní May 7, ọdún 2018, ní Ibi Ìrántí Tó Wà ní Àgọ́ Ìṣẹ́niníṣẹ̀ẹ́ Ìlú Dachau, wọ́n ṣí aṣọ lójú àmì ìrántí kan tí wọ́n ṣe ní ìrántí Arákùnrin Max Eckert tí wọ́n fi sẹ́wọ̀n fún ohun tó lé ní ọdún méjì ní àgọ́ ìṣẹ́niníṣẹ̀ẹ́ tó ti wà ní ìlú Dachau nígbà kan rí, kó tó di pé wọ́n gbé e lọ sí àgọ́ ìṣẹ́niníṣẹ̀ẹ́ tó burú jáì tó wà ní ìlú Mauthausen lórílẹ̀-èdè Austria.
Ó tó igba (200) èèyàn tó rí àmì ìrántí náà.
Àgọ́ ìṣẹ́niníṣẹ̀ẹ́ yẹn ni Max Eckert kú sí. Bó tiẹ̀ jẹ́ pé ìwọ̀nba èèyàn ló mọ Arákùnrin Eckert kó tó kú, ó ti wá di ọkùnrin tí ọ̀pọ̀ èèyàn mọ̀ sí ẹni tí ìgbàgbọ́ rẹ̀ fẹsẹ̀ múlẹ̀ ṣinṣin.
Fọ́tò àgọ́ ìṣẹ́niníṣẹ̀ẹ́ ìlú Dachau àtijọ́ tí wọ́n yà láìpẹ́ yìí rèé, ibẹ̀ ni Max Eckert ti ṣẹ̀wọ̀n kí wọ́n tó mú un lọ sí Mauthausen.
Àgọ́ ìṣẹ́niníṣẹ̀ẹ́ Mauthausen, tí Max Eckert kú sí.
Àkọsílẹ̀ nípa Arákùnrin Eckert fi hàn pé ó pẹ́ tó ti jẹ́ adúróṣinṣin sí Ọlọ́run.
Ní ọdún 1935, wọ́n ní kí òun àti ìyàwó rẹ̀ sanwó ìtanràn torí pé wọ́n ń sọ ohun tí wọ́n gbà gbọ́ fún àwọn èèyàn.
Lẹ́yìn yẹn, iṣẹ́ bọ́ lọ́wọ́ rẹ̀ torí pé ó kọ̀ láti gbé àsíá tó ní àmì òṣèlú swastika.
Ní ọdún 1937, ó pẹ̀lú nǹkan bí ọgọ́rùn-ún mẹ́fà (600) Ẹlẹ́rìí Jèhófà onígboyà tí wọ́n jù sẹ́wọ̀n ní ìlú Dachau.
Ní ohun tó lé ní ọdún méjì lẹ́yìn náà, wọ́n gbé e lọ sí ìlú Mauthausen níbi tí, ó kéré tán, ọ̀kẹ́ mẹ́rin ààbọ̀ (90,000) ẹlẹ́wọ̀n kú sí torí ipò tó burú jáì.
Ní February 21, ọdún 1940, wọ́n tẹ wáyà ránṣẹ́ sí ìyàwó Arákùnrin Eckert, èyí tí wọ́n fi túfọ̀ ọkọ rẹ̀ fún un tẹ̀gàntẹ̀gàn pé: “Ọkọ rẹ kú lónìí ní àgọ́ ìṣẹ́niníṣẹ̀ẹ́.
Tó o bá fẹ́ àlàyé sí i, kàn sí àwọn ọlọ́pàá.” Ọmọ ọdún mẹ́tàlélógójì (43) ní nígbà tó kú.
Nígba tí Ọ̀mọ̀wé Gabriele Hammermann, tó jẹ́ alábòójútó Ibi Ìrántí Tó Wà ní Àgọ́ Ìṣẹ́niníṣẹ̀ẹ́ Ìlú Dachau ń bá àwọn èèyàn sọ̀rọ̀, ó ṣàlàyé pé: “Wọ́n ṣe inúnibíni sí Àwọn Akẹ́kọ̀ọ́ Bíbélì [bí wọ́n ṣe ń pe Àwọn Ẹlẹ́rìí Jèhófà nígbà yẹn] torí pé ohun tí wọ́n gbà gbọ́ ò jẹ́ kí wọ́n di ọmọ ẹgbẹ́ èyíkéyìí nínú ètò òṣèlú ìjọba Nazi, kò jẹ́ kí wọ́n máa kan sáárá sí Hitler tàbí kí wọ́n wọṣẹ́ ológun.” Ó fi kún un pé: “Àwọn tó wà lẹ́wọ̀n pẹ̀lú Àwọn Akẹ́kọ̀ọ́ Bíbélì bọ̀wọ̀ fún wọn torí ìwà ọmọlúwàbí wọn, wọ́n kì í sì í yé sọ̀rọ̀ nípa bí wọ́n ṣe jẹ́ adúróṣinṣin tó sì máa ń yá wọn lára láti ṣèrànlọ́wọ́.” Arákùnrin Wolfram Slupina, tó jẹ́ agbẹnusọ fún àwọn Ẹlẹ́rìí Jèhófà ní orílẹ̀-èdè Jámánì, sọ pé ọ̀pọ̀ lára àwọn tó wá síbi ayẹyẹ náà ni kò mọ Arákùnrin Eckert, kódà ó sọ pé: “A ò ní fọ́tò Max Eckert lọ́wọ́.” Ó wá fi kún ọ̀rọ̀ rẹ̀ pé, àmì ìrántí náà mú kó ṣeé ṣe láti “mọ bí [Arákùnrin Eckert] ṣe jẹ́ adúróṣinṣin tó àti bó ṣe pinnu láti má ṣe fi ìgbàgbọ́ rẹ̀ báni dọ́rẹ̀ẹ́​—àní títí dójú ikú.” Kò sí iyèméjì pé Jèhófà ò gbàgbé ìgbàgbọ́ àti ìwà títọ́ Max Eckert àti tàwọn Ẹlẹ́rìí Jèhófà míì tó kú nítorí ìgbàgbọ́ wọn.​—Hébérù 6:10.
Ibi tó jẹ́ ojúkò àgọ́ ìṣẹ́niníṣẹ̀ẹ́ ní Ravensbrück tó ti wá di ibi tí wọ́n ń kó àwọn nǹkan ìṣẹ̀ǹbáyé sí ti ṣe ètò kan tí wọ́n máa fi hàn ní àwọn ìlú káàkiri. Àkọlé ètò náà ni “Wọ́n Fòfin De Àwọn Ẹlẹ́rìí Jèhófà, Wọ́n sì Ṣe Inúnibíni sí Wọn ní Àgọ́ Ìṣẹ́niníṣẹ̀ẹ́ Ravensbrück àti Láwọn Ilé Ẹ̀wọ̀n Míì ní GDR.” Àfihàn náà jẹ́ ká rí bí wọ́n ṣe fìyà jẹ àwọn Ẹlẹ́rìí Jèhófà ní Jámánì lábẹ́ ìjọba Násì (1933-1945), lábẹ́ ìjọba German Democratic Republic (ìyẹn GDR tàbí East Germany; lọ́dún 1949 sí 1990) àti lábẹ́ ìjọba Weimar Republic (lọ́dún 1918 sí 1933).
(Wo àpótí náà “ Ohun Tí Àwọn Ẹlẹ́rìí Jèhófà Kojú Lábẹ́ Ìjọba Mẹ́ta ní Jámánì.”) Wọ́n bẹ̀rẹ̀ sí í ṣàfihàn yìí lọ́jọ́ Sunday, April 22, 2018, níbi ìkóhun ìṣẹ̀ǹbáyé sí ní àgọ́ ìṣẹ́niníṣẹ̀ẹ́ Ravensbrück tó wà nílùú Fürstenberg, ní Jámánì.
Lọ́dún 2019, wọ́n máa gbé àfihàn yìí lọ sí àwọn ìlú míì bí Erfurt, Rostock, àti Potsdam. Nílùú Potsdam, ilé ìjọba ìpínlẹ̀ Brandenburg ni wọ́n ti máa ṣe àfihàn náà.
Ìtàn ìgbésí ayé Adolf Graf níbi àfihàn náà, òun náà wà lára àwọn tó jìyà lábẹ́ ìjọba Násì àti Kọ́múníìsì.
Àfihàn náà sọ ìtàn méjìlá (12) lára àwọn ará wa tí wọ́n jìyà lábẹ́ ìjọba Násì àti ìjọba Kọ́múníìsì ti GDR.
Lára ohun táwọn èèyàn máa rí níbi àfihàn náà ni ọ̀rọ̀ iléeṣẹ́ rédíò tí wọ́n gbà sílẹ̀ tó dá lórí ìtàn àwọn ará wa àti lẹ́tà ìdágbére táwọn ará wa kọ nígbà tí wọ́n dájọ́ ikú fún wọn. Yàtọ̀ síyẹn, wọ́n tún máa rí àwọn ìwé ìròyìn tó jáde nígbà ìjọba Násì àtàwọn fáìlì pàtàkì míì tí wọ́n kọ nígbà yẹn lọ́hùn-ún.
Ọ̀pọ̀ àwọn èèyàn lásìkò yẹn ni wọ́n fi sẹ́wọ̀n nítorí ẹ̀yà tí wọ́n ti wá, ẹgbẹ́ òṣèlú tí wọ́n wà tàbí ìwà ọ̀daràn tí wọ́n hù. Àmọ́ àfihàn yẹn jẹ́ kó ṣe kedere pé wọ́n ju àwọn ará wa sẹ́wọ̀n nítorí ohun tí wọ́n gbà gbọ́.
Nígbà tí wọ́n ń ṣayẹyẹ ìbẹ̀rẹ̀ ètò náà, òpìtàn kan tó ń jẹ́ Ọ̀mọ̀wé Detlef Garbe sọ pé: “Àwọn ọlọ́pàá Násì kórìíra àwọn Ẹlẹ́rìí Jèhófà torí pé ìgbàgbọ́ àwọn Ẹlẹ́rìí yẹn lágbára, wọ́n wà níṣọ̀kan, wọn ò sì bọ́hùn láìka ohun tí wọ́n ṣe fún wọn sí.
Ìgbàgbọ́ àwọn Ẹlẹ́rìí Jèhófà fẹsẹ̀ múlẹ̀ kódà nínú àgọ́ ìṣẹ́niníṣẹ̀ẹ́ torí ó dá wọn lójú pé Ọlọ́run máa gbà wọ́n sílẹ̀ àti pé wọ́n ṣe ara wọn ní òṣùṣù ọwọ̀.” Bákan náà lónìí, tí ìjọba orílẹ̀-èdè kan bá bẹ̀rẹ̀ sí í ta ko àwọn Ẹlẹ́rìí Jèhófà tàbí tó fòfin de iṣẹ́ wa bá a ṣe rí i ní Rọ́ṣíà, ọkàn wọn máa ń balẹ̀ pé Jèhófà máa fún wọn lókun láti fara dà á.​—Àìsáyà 54:17.
Jákèjádò ilẹ̀ Jámánì làwọn àlùfáà ṣọ́ọ̀ṣì ti ń wá bí wọ́n á ṣe fòfin de iṣẹ́ àwọn Akẹ́kọ̀ọ́ Bíbélì, ìyẹn àwa Ẹlẹ́rìí Jèhófà.
Láti nǹkan bí ọdún 1922 ni wọ́n ti ń fẹ̀sùn kan àwọn ará wa pé wọ́n ń “ta ìwé láìgbàṣẹ, wọn ò sì san owó orí.” Ìyà burúkú ni wọ́n máa ń fi jẹ àwọn tí wọ́n bá dá lẹ́bi.
Kódà láàárín ọdún 1927 àti 1930, ó fẹ́rẹ̀ẹ́ tó ẹgbẹ̀rún márùn-ún (5,000) ẹjọ́ àwọn ará wa tí wọ́n gbé lọ sílé ẹjọ́.
Lọ́dún 1928, àwọn àlùfáà ṣọ́ọ̀ṣì mú kí ẹ̀ka iléeṣẹ́ ìjọba tó ń rí sí ọ̀rọ̀ owó orí yọ àjọ Watch Tower Bible and Tract Society kúrò lára àwọn àjọ tí ìjọba fọwọ́ sí pé kí wọ́n má san owó orí.
Àwọn oníṣọ́ọ̀ṣì yẹn tiẹ̀ sọ ní gbangba pé àwọn fẹ́ mú kó nira fáwọn Akẹ́kọ̀ọ́ Bíbélì láti máa wàásù.
Àwọn ará wa gbé ọ̀rọ̀ náà lọ sílé ẹjọ́, ilé ẹjọ́ sì dá wọn láre.
Ní November 1931, àwọn ọlọ́pàá nílùú Munich fòfin de ìwé àwọn Akẹ́kọ̀ọ́ Bíbélì ní agbègbè Bavaria.
Nígbà tó di February 1932, ìjọba ìpínlẹ̀ Upper Bavaria fọwọ́ sí ìfòfindè náà, àwọn ará wa sì pe ẹjọ́ kòtẹ́milọ́rùn. Àmọ́ nígbà tó di March ọdún yẹn, Ilé Iṣẹ́ Tó Ń Bójú Tó Ọ̀rọ̀ Abẹ́lé ní ìpínlẹ̀ Bavaria fọwọ́ rọ́ ẹjọ́ àwọn Akẹ́kọ̀ọ́ Bíbélì náà dà nù, wọ́n ní “kòlẹ́sẹ̀ nílẹ̀.”
Ni January 30, 1933, Adolf Hitler di alákòóso ìlú Jámánì, kò sì fàyè gba àwọn èèyàn láti máa pàdé pọ̀ tàbí kí wọ́n máa tẹ ìwé jáde.
Nígbà táwọn ará wa ń pín ìwé Crisis lákànṣe láti April 8 sí 16, ṣe ni ìjọba ìpínlẹ̀ Bavaria fòfin de iṣẹ́ wa.
Lẹ́yìn ìwàásù àkànṣe yẹn, àwọn ìjọba ìpínlẹ̀ míì náà fòfin de àwa Ẹlẹ́rìí Jèhófà.
Ọ̀pọ̀ àwọn àlùfáà ṣọ́ọ̀ṣì ló gbárùkù ti Hitler bó ṣe ń ṣe inúnibíni sáwa Ẹlẹ́rìí Jèhófà.
Ní April 20, 1933, nínú ètò kan tí wọ́n ṣe lórí rédíò láti ṣayẹyẹ ọjọ́ ìbí Hitler, àlùfáà ṣọ́ọ̀ṣì Lutheran kan tó ń jẹ́ Otto sọ pé: “Ṣọ́ọ̀ṣì Lutheran ti ìpínlẹ̀ Saxony ti ronú gan-an nípa ìjọba tuntun tó gorí àlééfà yìí, a sì ti pinnu pé a máa fọwọ́ sowọ́ pọ̀ pẹ̀lú ìjọba tuntun yìí láti mú kí orílẹ̀-èdè wa di alágbára, kí ẹ̀sìn Kristẹni sì gbèrú.
Àṣeyọrí kan tá a ṣe lẹ́nu ìgbà tá a bẹ̀rẹ̀ sí í fọwọ́ sowọ́ pọ̀ pẹ̀lú ìjọba ni ti ìfòfindè tí ìjọba ṣe lórí Ẹgbẹ́ Àwọn Akẹ́kọ̀ọ́ Bíbélì Onítara Kárí Ayé àtàwọn àjọ míì tó wà lábẹ́ rẹ̀ ní Saxony.” Nígbà tó fi máa di àárín ọdún 1933, ọ̀pọ̀ ìjọba ìpínlẹ̀ ló ti fòfin de àwa Ẹlẹ́rìí Jèhófà, (April 1, 1935 ni wọ́n kéde ìfòfindè àwa Ẹlẹ́rìí Jèhófà nílé lóko) àwọn ọmọ ogun Hitler sì gbẹ́sẹ̀ lé ẹ̀ka ọ́fíìsì wa.
Àìmọye ìgbà làwọn agbófinró tú ilé àwọn ará wa, ọ̀pọ̀ nínú wọn ni wọ́n sì mú.
Nígbà tí Ogun Àgbáyé Kejì fi máa parí, nínú nǹkan bí ẹgbẹ̀rún mẹ́ẹ̀ẹ́dọ́gbọ̀n (25,000) Ẹlẹ́rìí tó wà ní Jámánì, nǹkan bí ẹgbẹ̀rún mẹ́wàá àti ọgọ́rùn-ún méje (10,700) nínú wọn ni ìjọba Násì ṣe inúnibíni sí, ẹgbẹ̀rún méjì àti ọgọ́rùn-ún mẹ́jọ (2,800) ni wọ́n rán lọ sí àgọ́ ìṣẹ́niníṣẹ̀ẹ́, nǹkan bí ẹgbẹ̀rún kan ló sì pàdánù ẹ̀mí wọn.
Bó tiẹ̀ jẹ́ pé ìjọba yìí tí wọ́n tún ń pè ní ìjọba East Germany sọ pé ìṣàkóso àwọn kì í ṣe bóofẹ́ bóokọ̀ bíi táwọn Násì, síbẹ̀ àwọn náà fojú pọ́n àwa Ẹlẹ́rìí Jèhófà bíi ti ìjọba Násì.
Láàárín ọdún 1950 àti 1985, èyí tó jú ẹgbẹ̀rún márùn-ún àwọn Ẹlẹ́rìí ní wọ́n fẹ̀sùn kàn pé wọ́n ń “ṣiṣẹ́ lòdì sí ìjọba,” wọ́n ń “sọ̀rọ̀ lòdì sí ìjọba,” wọ́n sì ń “ṣagbátẹrù ogun.” Ẹ̀wọ̀n ọdún márùn-ún àtààbọ̀ ni wọ́n sábà máa ń bù lé àwọn ará wa lọ́kùnrin àti lóbìnrin.
Àwọn ará tó jẹ́ méjìlélọ́gọ́ta ni wọ́n kú sẹ́wọ̀n lábẹ́ ìjọba GDR.
Àjọ Munich Documentation Centre for the History of National Socialism ṣàfihàn fọ́tò àwọn Ẹlẹ́rìí Jèhófà àti àkọsílẹ̀ ohun tí ìjọba Násì fojú wọn rí. Ọgọ́ta (60) làwọn nǹkan tó dà bíi pátákó tí wọ́n fi ṣàfihàn náà, wọ́n sì gbé wọn kọ́ sára ògiri.
Àjọ kan tí wọ́n ń pè ní Munich Documentation Centre for the History of National Socialism ṣètò àkànṣe kan ní September 26, 2018, sí January 6, 2019, káwọn èèyàn lè mọ ohun ti ìjọba Násì fojú àwọn Ẹlẹ́rìí Jèhófà rí lásìkò tí wọ́n ń ṣàkóso.
Kò ní yà yín lẹ́nu pé orí ilẹ̀ kan náà tí oríléeṣẹ́ ẹgbẹ́ òṣèlú Násì wà nígbà yẹn lọ́hùn-ún ni àjọ yìí kọ́ ọ́fíìsì wọn sí.
Nígbà tí wọ́n ń ṣayẹyẹ ìṣílé ọ́fíìsì tuntun náà, Ọ̀mọ̀wé Hans-Georg Küppers tó jẹ́ abẹnugan nípa àṣà àti ìṣẹ̀dálẹ̀ ìlú Munich ṣàlàyé ìdí tí wọ́n fi ṣètò ìran àpéwò náà, ó ní: “Ó ṣe pàtàkì ká ṣe àkànṣe ètò yìí torí kì í ṣèní, kì í ṣàná làwọn èèyàn kan ti ń sọ pé kò sóòótọ́ nínú ìtàn tó sọ pé ìjọba Násì pọ́n àwọn Ẹlẹ́rìí Jèhófà lójú, wọ́n ní irọ́ funfun báláú ni.
Torí náà, a fẹ́ káwọn èèyàn lóye pé òótọ́ lọ̀rọ̀ náà, wọ́n á sì kà nípa àwọn tí ìjọba pọ́n lójú.” Wọ́n ṣàkọsílẹ̀ ohun tí ìjọba Násì fojú àwọn arákùnrin wa rí lásìkò yẹn, wọ́n ṣàlàyé bí wọ́n ṣe fìgboyà hàn, tí wọn ò sẹ́ ìgbàgbọ́ wọn, tí wọ́n sì fara dà á. Ọgọ́ta (60) làwọn nǹkan tó dà bíi pátákó tí wọ́n kọ àwọn ìtàn náà sí, wọ́n sì gbé wọn kọ́ sára ògiri.
Ìrírí Martin àti Gertrud Pötzinger wà nínú ọ̀kan lára ohun tí wọ́n gbé kọ́ náà, wọ́n sọ bí ìjọba ṣe mú àwọn méjèèjì, tí wọ́n sì fi wọ́n sí àgọ́ ìṣẹ́niníṣẹ̀ẹ́ tó yàtọ̀ síra. Bẹ́ẹ̀ sì rèé, kò ju oṣù mélòó kan péré tí wọ́n ṣègbéyàwó.
Ọdún mẹ́sàn-án gbáko ni wọn ò fi fojú kan ara wọn.
Àwọn méjèèjì la ìpọ́njú yẹn já, Arákùnrin Pötzinger sí wà di ọ̀kan lára Ìgbìmọ̀ Olùdarí Àwa Ẹlẹ́rìí Jèhófà nígbà tó yá.
Ìjọba Násì pa Therese Kühner ní October 6, 1944.
Òmíràn ni ti Arábìnrin kan tó ń jẹ́ Therese Kühner. Ọdún 1929 ló di Ẹlẹ́rìí Jèhófà, (Akẹ́kọ̀ọ́ Bíbélì là ń pè wọ́n nígbà yẹn).
Nígbà tí ìjọba Jámánì fòfin de iṣẹ́ àwa Ẹlẹ́rìí Jèhófà, arábìnrin yìí yọ̀ǹda pé káwọn ará máa ṣèpàdé nínú ilé òun láìjẹ́ kí ẹnikẹ́ni mọ̀. Yàtọ̀ síyẹn, wọ́n tún máa ń dọ́gbọ́n tẹ àwọn ìwé wa nínú ilé rẹ̀.
Lẹ́yìn tí àṣírí tú sí ìjọba Násì lọ́wọ́, wọ́n mú Therese, wọ́n sì fẹ̀sùn kàn án pé “ó ń tẹ ìwé tó ta ko ìjọba, ó ń pín ìwé náà kiri, ó sì ń dá ojora sílẹ̀ fáwọn ọmọ ogun ìjọba.” Láìka gbogbo ohun tí wọ́n fojú Arábìnrin Kühner rí, kò bọ́hùn, ṣe ló di ìgbàgbọ́ rẹ̀ mú títí dójú ikú.
October 6, 1944 ni wọ́n pa á.
Ohun míì téèyàn máa rí kà ni báwọn ará wa ṣe pinnu pé àwọn ò ní dá sọ́rọ̀ ìṣèlú àti ogun, tí wọ́n sì kọ̀ láti bẹ́rí fún Hitler. Ìpinnu wọn yẹn ló mú kí ìjọba dìídì dájú sọ wọ́n, tí wọ́n sì fimú wọn dánrin.
Lọ́dún 1934, Hitler búra pé òun máa rí i dájú pé kò sí Ẹlẹ́rìí Jèhófà kankan lórílẹ̀-èdè náà mọ́. Ó sọ pé: “Àwọn èèyànkéèyàn yìí máa pòórá bí isó nílẹ̀ Jámánì!” Kó lè mú ọ̀rọ̀ ẹ̀ ṣẹ, Hitler ṣe baba-ńlá inúnibíni sáwọn ará wa, àmọ́ wọ́n fara dà á. Ibo lọ̀rọ̀ náà wá yọrí sí?
Hitler àti ẹgbẹ́ òṣèlú rẹ̀ ni ò sí mọ́, àmọ́ àwọn ará wa ṣì wà nílẹ̀ Jámánì digbí, kódà wọ́n lé ní ẹgbẹ̀rún lọ́nà ọgọ́rùn-ún kan àti márùndínláàádọ́rin (165,000).
A dúpẹ́ lọ́wọ́ Jèhófà tó sọ ìmọ̀ràn wọn dòfo, torí pé báwọn èèyàn tiẹ̀ ń pọ́n wa lójú, Ọlọ́run mú ká nírètí tí kì í “yọrí sí ìjákulẹ̀.”—Róòmù 5:3-5.
Ọjọ́ ọ̀hún rèé bí àná, ìyẹn ní ọgọ́rin (80) ọdún sẹ́yìn, nígbà tí ìjọba gbé Arákùnrin Minos Kokkinakis wọ̀ọ́ sínú ọkọ̀ ojú omi tí wọ́n fi máa ń kó àwọn ẹlẹ́wọ̀n. Lọkọ̀ náà bá forí lé erékùṣù kan tí wọ́n ń pè ní Amorgós láàárín agbami òkun Aegean Sea, lórílẹ̀-èdè Gíríìsì.
Ilé ẹjọ́ kan ló dá a lẹ́bi pé ó rú òfin tó ní káwọn èèyàn má ṣe bá ẹlòmíì sọ̀rọ̀ ẹ̀sìn, ilé ẹjọ́ ò sì gbọ́ tẹ́nu ẹ̀ kí wọ́n tó dá a lẹ́bi.
Eré la pè é, bí ìjọba ṣe bẹ̀rẹ̀ sí í nawọ́ gán àwa Ẹlẹ́rìí Jèhófà nìyẹn o. Láàárín ọdún 1938 sí 1992, wọ́n mú ẹgbẹ̀rún mọ́kàndínlógún, ọgọ́rùn-ún kan ó lè mẹ́tàdínláàádọ́ta (19,147) àwọn ará wa.
Láwọn ọdún yẹn, àwọn ará wa lọ́kùnrin àti lóbìnrin ò dẹ́kun àtimáa wàásù ìhìn rere Ìjọba Ọlọ́run bí ìjọba tiẹ̀ ń fìyà jẹ wọ́n, tí wọ́n ń mú wọn, tí wọ́n sì ń jù wọ́n sẹ́wọ̀n.
Ẹni ọgbọ̀n (30) ọdún ni Arákùnrinr Kokkinakis nígbà tọ́rọ̀ yìí wáyé, àtìgbà yẹn náà ló ti ń jà fún ẹ̀tọ́ tó ní láti wàásù, odindi àádọ́ta (50) ló sì fi ja ìjà yìí.
Ó lè ní ọgọ́ta (60) ìgbà tí wọ́n mú un, ó sì lé lọ́dún mẹ́fà tó lò lẹ́wọ̀n àti láwọn erékùṣù tí wọ́n ń kó àwọn ẹlẹ́wọ̀n sí. Wọ́n fi ojú òun àtàwọn Ẹlẹ́rìí Jèhófà míì rí màbo ní gbogbo àsìkò yẹn.
Wọ́n tún mú un nígbà tó pé ẹni ọdún mẹ́tàdínlọ́gọ́rin (77). Ó pẹjọ́ kòtẹ́milọ́rùn àmọ́ ilé ẹjọ́ kò gba tiẹ̀ rò, ló bá gbọ́rọ̀ náà lọ sí Ilé Ẹjọ́ Gíga Jù Lọ ní Gíríìsì.
Nígbà táwọn yẹn tún da ẹjọ́ ẹ̀ nù, Arákùnrin Kokkinakis gbé ẹjọ́ náà lọ sí Ilé Ẹjọ́ Ẹ̀tọ́ Ọmọnìyàn ti Ilẹ̀ Yúróòpù (ECHR), pé orílẹ̀-èdè Gíríìsì ń fi ẹ̀tọ́ òun du òun bí wọn ò ṣe jẹ́ kóun sin Ọlọ́run bó ṣe fẹ́.
Nígbà tí ilé ẹjọ́ yẹn máa kéde ìdájọ́ wọn lọ́dún 1993, ṣe ni wọ́n dá Arákùnrin Minos Kokkinakis, ẹni ọdún mẹ́rìnlélọ́gọ́rin (84) láre.
* Ẹ wá rídìí tá a fi ń dáwọ̀ọ́ ìdùnnú, torí pé ọdún 2018 ló pé ọdún kẹẹ̀ẹ́dọ́gbọ̀n (25) tá a jagunmólú ẹjọ́ yẹn.
Ó ní ẹjọ́ Kokkinakis “jẹ́ ògúnnágbòǹgbò táwọn amòfin máa ń tọ́ka sí lára àwọn ìgbẹ́jọ́ tí Ilé Ẹjọ́ Ẹ̀tọ́ Ọmọnìyàn ti Ilẹ̀ Yúróòpù bójú tó lórí ọ̀ràn jíjà fún ẹ̀tọ́ ẹni tó bá kan ọ̀ràn ìsìn.” Àpẹẹrẹ ni ẹjọ́ Kokkinakis á máa jẹ́ nígbàkigbà, pàápàá lásìkò tàwọn ìjọba orílẹ̀-èdè alágbára, bíi Rọ́ṣíà, ń fẹ̀tọ́ àwọn èèyàn Jèhófà dù wọ́n, tí wọ́n ò jẹ́ kí wọ́n jọ́sìn Ọlọ́run wọn bó ṣe fẹ́.
Àwa èèyàn Jèhófà níbi gbogbo láyé mọyì bí Arákùrin Kokkinakis ṣe ní ìgbàgbọ́, tí kò sì jẹ́ kí ẹnikẹ́ni ṣí òun lọ́wọ́ wíwàásù Ọ̀rọ̀ Ọlọ́run, ẹ̀kọ́ gidi nìyẹn jẹ́ fáwọn tó kojú àtakò àti inúnibíni lẹ́nu iṣẹ́ ìwàásù.
A ò jẹ́ gbàgbé ìtara rẹ̀ àti bó ṣe di ìgbàgbọ́ rẹ̀ mú ṣinṣin lójú inúnibíni.—Róòmù 1:8.
^ ìpínrọ̀ 3 Minos Kokkinakis kú ní January 1999.
Lẹ́yìn òde ìlú Athens nílẹ̀ Gíríìsì, iná sọ nínú igbó, atẹ́gùn líle sì mú kó túbọ̀ ràn bí iná ọyẹ́. Iná yìí ṣèpalára fáwọn èèyàn, ó sì ba nǹkan jẹ́.
Ó kéré tán, èèyàn mẹ́rìndínlọ́gọ́rin (76) ni ẹ̀mí wọn lọ sí i, àwọn ọgọ́sàn-an ó lé méje (187) ló sì fara pa níbi tíná ti ń jó. Iná yìí ni wọ́n gbà pé ó tíì ṣọṣẹ́ jù lórílẹ̀-èdè náà láti ohun tó lé lọ́dún mẹ́wàá sẹ́yìn.
Ìròyìn tá a gbọ́ láti ẹ̀ka ọ́fíìsì àwọn Ẹlẹ́rìí Jèhófà tó wà ní Gíríìsì ni pé ìkankan nínú àwọn arákùnrin wa ò fara pa, ìkankan nínú wọn ò sì kú.
Àmọ́ ó gba pé kí gbogbo àwọn ará wa tó wà níbi tí àjálù náà ti wáyé kó kúrò lágbègbè náà, àwọn ará tó sì wà láwọn ìjọ itòsí sì ti gbà wọ́n sílé.
Yàtọ̀ síyẹn, ilé mẹ́rin tó jẹ́ tàwọn Ẹlẹ́rìí Jèhófà ló bà jẹ́ gan-an, ilé kan tiẹ̀ wà tó bà jẹ́ kọjá àtúnṣe.
A ò dákẹ́ àdúrà lórí àwọn ará wa tí àjálù yìí ṣẹlẹ̀ sí àtàwọn ará wa tí ìfẹ́ ará mú kí wọ́n gba àwọn Ẹlẹ́rìí Jèhófà bíi tiwọn sílé.
(Jòhánù 13:​34, 35) A mọ̀ pé Jèhófà á túbọ̀ máa gbé àwọn ará wa ró lásìkò wàhálà yìí.
Déètì: July 5 sí 7, 2019
Ibi Tá A Ti Ṣe É: Pápá ìṣeré Athens Olympic Stadium ní ìlú Athens, Greece
Èdè: Albanian, Gẹ̀ẹ́sì, Gíríìkì, Èdè Adití ti Gíríìkì, Romany (ti Gúúsù Greece), Russian
Àwọn Tó Wá: 36,873
Àwọn Tó Ṣèrìbọmi: 406
Àwọn Tó Wá Láti Ìlẹ̀ Òkèèrè: 6,000
Áwọn Ẹ̀ka Ọ́fíísì Tó Wá: Alibéníà, Àméníà, Australasia, Bọ̀géríà, Central America, Central Europe, Fíjì, Japan, Kyrgyzstan, North Macedonia, Tọ́kì, Amẹ́rikà
Ìrírí: Òṣìṣẹ́ kan tọ́ máa ń ṣètó ìrìn àjò sọ pé: “Látìgbà tí mo ti bẹ̀rẹ̀ iṣẹ́ síṣètò ìrìn àjò, mí ò tíì rí ibikíbi láyé tí wọ́n ti ń ṣètò tó dáà bí eléyìí, kí wọ́n sì tún bójú tó àwọn arìnrìn àjò.
Ńṣe ni mò ń wò yín lánàá, ẹ wú mi lórí gan-an!
Ẹ ṣètò ẹgbẹ̀rún méjì ó lé ọgọ́rùn-ún mẹ́fà (2,600) arìnrìn àjò láàárìn wákàtí díẹ̀ lọ́nà tó dáa ju ti àwọn akọ́ṣẹ́mọṣẹ́ lọ.
Èyí tó wú mi lórí jù ni ẹ̀rín músẹ́ tó wà lójú yín.
Kí n sọ̀ótọ́, ọ̀pọ̀ ọdún ni mo ti wà lẹ́nu iṣẹ́ yìí, mo sì máa ń mọ̀ tẹ́nì kan bá ń rẹ́rìn-ín látọkàn wá tàbí tó bá jẹ́ pé ẹ̀rín ẹ̀ ò dọ́kàn.
Àmọ́, gbogbo yín lẹ̀ ń rẹ́rìn-ín látọkàn.”
Àwọn dókítà ṣèbẹ̀wò síbi ìpàtẹ wa níbi àpérò SIAARTI tí wọ́n ṣe ni erékùṣù Palermo Ọ̀pọ̀ dókítà ló ń dúpẹ́ lọ́wọ́ ètò wa torí ìsọfúnni tá a pèsè kárí ayé nípa onírúurú ìtọ́jú ìṣègùn àti iṣẹ́ abẹ láìfa ẹ̀jẹ̀ síni lára.
Ẹ̀ka Tó Ń Pèsè Ìsọfúnni fún Àwọn Ilé Ìwòsàn (lórílẹ̀-èdè Ítálì), tó wà ní ẹ̀ka ọ́fíìsì àwa Ẹlẹ́rìí Jèhófà nílùú Róòmù wà lára ètò tá a dá sílẹ̀ kárí ayé.
Ní October 10 sí 13, 2018, ẹgbẹ́ kan lórílẹ̀-èdè Ítálì tá a mọ̀ sí Italian Society of Anesthesia, Analgesia, Resuscitation, and Intensive Care (SIAARTI) ṣe àpérò kan nílùú Palermo ní erékùṣù Sísílì.
Níbi àpérò náà, àwọn tó ń ṣojú fún Ẹ̀ka Tó Ń Pèsè Ìsọfúnni fún Àwọn Ilé Ìwòsàn (lórílẹ̀-èdè Ítálì) àtàwọn tó wà nínú Ìgbìmọ̀ Alárinà Ilé Ìwòsàn ṣètò ìpàtẹ kan. Lẹ́yìn tí wọ́n parí àpérò yẹn, àwọn arákùnrin wa tún gbé ìpàtẹ yẹn lọ síbi àpérò Joint Congress of the Scientific Societies of Surgery tí wọ́n ṣe ní gbọ̀ngàn àpérò “La Nuvola” nílùú Róòmù.
A máa ń lo àǹfààní àwọn àpérò yìí láti pèsè àwọn ìsọfúnni tuntun nípa ìtọ́jú ìṣègùn láìlo ẹ̀jẹ̀ fún gbogbo dókítà tó nífẹ̀ẹ́ sí i.
Àwọn dókítà tó ń pa ìrora nígbà iṣẹ́ abẹ tí iye wọn tó ẹgbẹ̀rún méjì àti ọgọ́rùn-ún mẹ́jọ (2,800) ló wá síbi àpérò tí wọ́n ṣe nílùú Palermo.
Ẹgbẹ̀rún mẹ́ta àti ọgọ́rùn-ún márùn-ún (3,500) dókítà tó ń ṣiṣẹ́ abẹ ló wá síbi àpérò tí wọ́n ṣe nílùú Róòmù. Ó sì jọ pé àpérò àwọn dókítà tó ń ṣiṣẹ́ abẹ tó tíì gbòòrò jù lọ tí wọ́n ṣe lórílẹ̀-èdè Ítálì nìyẹn.
Àwọn aṣojú láwọn ilé ìwòsàn tó lórúkọ ló pésẹ̀ síbi àpérò náà.
Títí kan gbogbo àwọn tó wà nínú ẹgbẹ́ tá a mọ̀ sí Italian associations of surgeons àti American College of Surgeons ti orílẹ̀-èdè Ítálì.
Ọ̀pọ̀ ilé iṣẹ́ ló sì ti ètò náà lẹ́yìn, irú bí Ilé Iṣẹ́ Ètò Ìlera.
Dókítà kan tó ń jẹ́ Vincenzo Scuderi láti Ilé Ìwòsàn Policlinico ti Catania ní erékùṣù Sísílì, wá síbi ìpàtẹ wa níbi àpérò tí wọ́n ṣe nílùú Palermo.
Ní January 18, 2019, dókítà náà ṣe iṣẹ́ abẹ pàjáwìrì fún Ẹlẹ́rìí Jèhófà kan tó ní àìsàn tí wọ́n ń pè ní aortic dissection.
Dókítà náà ṣe iṣẹ́ abẹ tó díjú yìí láìlo ẹ̀jẹ̀.
Dókítà Scuderi ṣàlàyé pé: “[Ìpàtẹ] tẹ́ ẹ ṣe níbi àpérò SIAARTI lọ́dún 2018 ràn mí lọ́wọ́ gan-an.
Àwọn ìsọfúnni tẹ́ ẹ fún wa sì gbéṣẹ́ gan an.” Ní báyìí, àwọn dókítà tó ju ẹgbẹ̀rún márùn-ún (5,000) lórílẹ̀-èdè Ítálì ti gbà láti máa tọ́jú àwọn aláìsàn tó jẹ́ Ẹlẹ́rìí Jèhófà nípa lílo ìlànà ìtọ́jú ìṣègùn àti iṣẹ́ abẹ tí kò léwu, tó gbéṣẹ́, tí kò sì nílò ìfàjẹ̀sínilára.
Lọ́dọọdún, ìpíndọ́gba àwọn aláìsàn tó jẹ́ Ẹlẹ́rìí Jèhófà tí iye wọn tó ẹgbẹ̀rún mẹ́rìndínlógún (16,000) ló ń gba ìtọ́jú láìlo ẹ̀jẹ̀ lórílẹ̀-èdè Ítálì.
Lẹ́yìn àpérò náà, àwọn dókítà tó ń fún èèyàn láwọn oògùn tó ń dín ìrora kù àtàwọn tó ń ṣiṣẹ́ abẹ sọ ìrírí tí wọ́n ní nígbà tí wọ́n tọ́jú àwọn aláìsàn tó jẹ́ Ẹlẹ́rìí Jèhófà.
“Ọ̀pọ̀ ọdún ni mo fi tọ́jú àwọn aláìsàn tó jẹ́ Ẹlẹ́rìí Jèhófà.
Àwùjọ kan wà nínú ẹgbẹ́ SIAARTI tó máa ń rí sí ọ̀rọ̀ àwọn tí kò fẹ́ gba ẹ̀jẹ̀ sára. Ní nǹkan bí ọdún mélòó kan sẹ́yìn, àwùjọ yìí fún àwọn dókítà tó ń pa ìrora nígbà iṣẹ́ abẹ ní ìtọ́ni tí wọ́n á máa tẹ̀ lé nígbà tí wọ́n bá fẹ́ ṣiṣẹ́ abẹ tó díjú fún aláìsàn kan. Èyí máa jẹ́ káwọn dókítà mọ ọ̀nà tó dáa jù lọ láti tọ́jú aláìsàn náà.
Ìtọ́ni náà ṣe kedere nínú Ìwé Òfin (Àpilẹ̀kọ 2, 13 àti 32), Ìpolongo Ẹ̀tọ́ Ọmọnìyàn Lágbàáyé, Àpéjọ Oviedo, àti nínú ìwé òfin Ẹ̀tọ́ Ọmọnìyàn ti Ilẹ̀ Yúróòpù.’ ” ​—⁠Antonio Corcione, tó jẹ́ olùṣekòkáárí ní ojúkò tí wọ́n ti ń pààrọ̀ ẹ̀yà ara ti agbègbè Campania. Òun ló ń bójú tó ẹ̀ka àwọn tó ń pa ìrora nígbà iṣẹ́ abẹ tó sì ń pèsè ìtọ́jú àkànṣe ní ilé ìwòsàn Monaldi. Ó sì tún fìgbà kan jẹ́ ààrẹ ẹgbẹ́ Italian Society of Anesthesia, Analgesia, Resuscitation, and Intensive Care (SIAARTI). “Ìrírí tí mo ní nígbà tí mo tọ́jú àwọn Ẹlẹ́rìí Jèhófà ti ran èmi àtàwọn dókítà míì títí kan àwọn nọ́ọ̀sì lọ́wọ́, ó ti jẹ́ ká ṣàtúnṣe sí ọ̀nà tá à ń gbà ṣiṣẹ́ abẹ kí ẹ̀jẹ̀ tó máa dànù lè dín kù gan-an. Nípa bẹ́ẹ̀, aláìsan náà ò ní nílò ìfàjẹ̀sínilára.
Èyí ti mú kó rọrùn láti tọ́jú àwọn tí kò fẹ́ gba ẹ̀jẹ̀ sára, bákan náà a lè lo ọ̀nà yìí láti tọ́jú àwọn míì tí ò kọ̀ láti gba ẹ̀jẹ̀.”​—⁠Ugo Boggi, tó jẹ́ ọ̀jọ̀gbọ́n nípa onírúurú iṣẹ́ abẹ ní University of Pisa (Ítálì), òun ni igbákejì ọ̀jọ̀gbọ́n nínú iṣẹ́ abẹ ní University of Pittsburgh (USA), òun tún ni ààrẹ tí wọ́n ṣẹ̀ṣẹ̀ yàn fún ẹgbẹ́ Italian Society for Organ Transplantation (SITO) “Nínú gbogbo ẹ̀yà ara, ẹ̀dọ̀ ló ṣòro pààrọ̀ jù lọ.
Ẹ̀jẹ̀ tó sì máa ń dà tá a bá ń ṣiṣẹ́ abẹ inú ẹ̀dọ̀ pọ̀ débi pé ó lè la ẹ̀mí lọ.
Àmọ́, torí ẹ̀rí wà pé ẹgbẹẹgbẹ̀rún iṣẹ́ abẹ yìí ló wáyé kárí ayé, títí kan ọgọ́rọ̀ọ̀rún iṣẹ́ abẹ tá a ti pààrọ̀ ẹ̀dọ̀, a lè fi gbogbo ẹnu sọ pé a ti mọ ọ̀nà tó gbéṣẹ́ tá a lè fi dènà ẹ̀jẹ̀ tó ń dà lára.
Ká sòótọ́, a ti rí i pé ọgbọ́n wà tá a lè dá ká lè dènà ẹ̀jẹ̀ tó ń dà lára nígbà iṣẹ́ abẹ.
A ti mọ bá a ṣe lè ṣe é láìfa ẹ̀jẹ̀ síni lára.
Ó fẹ́rẹ̀ẹ́ jẹ́ pé gbogbo iṣẹ́ abẹ inú ẹ̀dọ̀ títí kan iṣẹ́ abẹ tá a fi ń pààrọ̀ ẹ̀dọ̀ là ń ṣe láìsí pé wọ́n fa ẹ̀jẹ̀ síni lára.
Nígbà tá a bá ń ṣe iṣẹ́ abẹ inú ẹ̀dọ̀, a kì í sábà fa ẹ̀jẹ̀ síni lára mọ́, torí pé dípò ká lò ọ̀nà tá a máa ń lò lọ́dún díẹ̀ sẹ́yìn, ṣe la ń ṣe iṣẹ́ abẹ náà lọ́nà tá a jẹ́ ká kíyè sí iṣan kọ̀ọ̀kan tó ń gbẹ́ ẹ̀jẹ̀ káàkiri inú ara.
Mo dúpẹ́ lọ́wọ́ àwọn Ẹlẹ́rìí Jèhófà torí pé àwọn ló jẹ́ ká mọ̀ nípa ohun tá ò tiẹ̀ ronú kàn ní nǹkan bí ọdún mẹ́wàá sí mẹ́ẹ̀ẹ́dógún sẹ́yìn, ìyẹn bá ò ṣe ní máa fi ẹ̀jẹ̀ ṣòfò​—⁠Umberto Cillo, tó jẹ́ ọ̀jọ̀gbọ́n nípa onírúurú iṣẹ́ abẹ àti olùdarí ẹ̀ka tó ń tọ́jú ẹ̀dọ̀ tó sì ń pààrọ̀ rẹ̀ ní Yunifásítì Padua, òun tún ni ààrẹ ẹgbẹ́ Italian Society for Organ Transplantation (SITO) “Mo bọ̀wọ̀ fáwọn aláìsàn tó jẹ́ Ẹlẹ́rìí Jèhófà gan-an torí wọ́n ní ìgbàgbọ́ tó lágbára.
Ó sì jẹ́ ọ̀kan lára ohun tó jẹ́ kí n sapá láti ọ̀pọ̀ ọdún wá kí n lè ṣàtúnṣe, kí n sì ṣe ohun tó máa múnú wọn dùn.
Mo gbà pé wọ́n yẹ lẹ́ni téèyàn ń bọ̀wọ̀ tó jinlẹ̀ fún.
Kò wu àwọn Ẹlẹ́rìí Jèhófà pé kí wọ́n kú, àmọ́ ojúlówó ìtọ́jú ni wọ́n ń fẹ́.”​—⁠Francesco Corcione, tó jẹ́ ọ̀jọ̀gbọ́n nípa iṣẹ́ abẹ ní University of Naples Federico II, òun ni ààrẹ àgbà ẹgbẹ́ Italian Society of Surgery (SIC), olóyè pàtàkì sì tún ni nínú ẹgbẹ́ Académie Nationale de Chirurgie, ìlú Paris lórílẹ̀-èdè Faransé “Ohun tí mo kọ́ lára àwọn Ẹlẹ́rìí Jèhófà ti jẹ́ kí n túbọ̀ gbà pé ó yẹ káwọn dókítà àtàwọn nọ́ọ̀sì máa bọ̀wọ̀ tó jinlẹ̀ fún àṣà ìbílẹ̀ àti ẹ̀sìn àwọn aláìsàn.
Mo gbà pé orílẹ̀-èdè Ítálì náà ti fọwọ́ sí ìwé òfin kan, ìyẹn Law 219 of December 2017 tí wọ́n pè ní ‘Provisions for informed consent and advance directives.’ Òfin yìí sọ pé kí dókítà tàbí nọ́ọ̀sì tó bẹ̀rẹ̀ sí tọ́jú aláìsàn kan, aláìsàn náà gbọ́dọ̀ lóye irú ìtọ́jú tó fẹ́ gbà lẹ́kùn-ún-rẹ́rẹ́, ó sì gbọ́dọ̀ fọwọ́ sí i pé kí wọ́n fóun nírú ìtọ́jú bẹ́ẹ̀.’ Tí dókítà tó fẹ́ ṣiṣẹ́ abẹ náà bá ṣàlàyé bí ìtọ́jú náà ṣe máa rí lọ́nà tó yéni tó sí rọrùn, a jẹ́ pé dókítà àti aláìsàn náà ti jọ fọwọ́ sí ìtọ́jú náà, ìyẹn á sì jẹ́ kí aláìsàn náà túbọ̀ lómìnira láti ṣe ìpinnu tó bá wù ú. Nípa bẹ́ẹ̀, ìtọ́jú náà á túbọ̀ gbéṣẹ́.”​—⁠Luca Ansaloni, tó jẹ́ olùdarí ẹ̀ka onírúurú iṣẹ́ abẹ àti iṣẹ́ abẹ pàjáwìrì ní Ilé Ìwòsàn Bufalini ní Cesena, ó tún jẹ́ ààrẹ ẹgbẹ́ Italian Society of Surgical Physiopathology (SIFIPAC) “Àwọn Ẹlẹ́rìí Jèhófà ti ràn wá lọ́wọ́ gan-an láti jẹ́ ká mọ ọgbọ́n tó túbọ̀ gbéṣẹ́ táá mú ká yẹra fún ìfàjẹ̀sínilára.
Àwọn ẹ̀rọ ìgbàlódé tí wọ́n fi ń ṣiṣẹ́ abẹ ti ṣèrànwọ́ gan-an fáwọn dókítà tí wọ́n gbà láti bọ̀wọ̀ fún ìpinnu aláìsàn tó kọ̀ láti gba ẹ̀jẹ̀ sára torí ohun tó gbà gbọ́.
Kéèyàn tọ́jú aláìsàn láìlo ẹ̀jẹ̀ máa dín ìnáwó kù gan-an, òun ló sì dáa jù.”​—⁠Diego Piazza, tó jẹ́ ààrẹ ẹgbẹ́ Italian Medical Association of Catania, òun ni olùdarí ẹ̀ka tó ń tọ́jú àìsàn jẹjẹrẹ ní Ilé Ìwòsàn Garibaldi-Nesima ní ìlú Catania, òun sì ni ààrẹ ẹgbẹ́ Italian Association of Hospital Surgeons tẹ́lẹ̀ (ACOI) “Àwọn dókítà kan rò pé kò séwu nínú kéèyàn gba ẹ̀jẹ̀ sára. Wọ́n nífẹ̀ẹ́ sí ìfàjẹ̀sínilára torí pé ó rọrùn láti gbà, kò wọ́n rárá, ó sì rọrùn láti dábàá rẹ̀ fún aláìsàn. Ohun míì tó jẹ́ kí wọ́n fẹ́ láti máa fa ẹ̀jẹ̀ síni lára ni pé ó tètè máa ń jẹ́ kí èròjà hemoglobin nínú sẹ́ẹ̀lì pupa inú ẹ̀jẹ̀ lọ sókè lára aláìsàn. Ìdí nìyẹn tí ọ̀pọ̀ dókítà fi máa ń fa ẹ̀jẹ̀ síni lára.
Bó tilẹ̀ jẹ́ pé ọdọọdún la túbọ̀ ń rí ẹ̀rí tó fi hàn pé, ó léwu gan-an tá a bá fa ògidì sẹ́ẹ̀lì pupa inú ẹ̀jẹ̀ tàbí èyíkéyìí lára èròjà ẹ̀jẹ̀ síni lára.
Kódà, ọ̀pọ̀ ìwádìí fi hàn pé aláìsàn tó gba ẹ̀jẹ̀ sára máa ń níṣòro ju aláìsàn tí kò gba ẹ̀jẹ̀ sára lọ. Àwọn tó gba ẹ̀jẹ̀ sára tètè máa ń kú tàbí kí wọ́n tètè ṣàìsàn, wọ́n sì máa ń pẹ́ nílé ìwòsàn torí àìsàn rọpá rọsẹ̀, egbò inú kíndìnrín, ẹ̀jẹ̀ tó ń dì, kòkòrò inú ẹ̀jẹ̀ àti àìsàn tí kì í jẹ́ kéèyàn lè mí dáadáa.
Mo gbà pé ọ̀nà tá a gbà tọ́jú àwọn Ẹlẹ́rìí Jèhófà láti àádọ́ta (50) ọdún sẹ́yìn ti mú káwọn dókítà mọ bí wọ́n ò ṣe ní jẹ́ kí ẹ̀jẹ̀ ṣòfò nígbà tí wọ́n bá ń ṣiṣẹ́ abẹ àti bí wọ́n ṣe lè ṣiṣẹ́ abẹ láìlo ẹ̀jẹ̀.”​—⁠Giandomenico Biancofiore, tó jẹ́ olùdarí iṣẹ́ abẹ tó díjú ní ẹ̀ka anesthesia and resuscitation in transplants ní Pisa University Hospital, òun sì ni igbákejì ọ̀jọ̀gbọ́n ní ẹ̀ka anesthesiology and resuscitation ní University of Pisa
Ní April 6, 2018, Ilé Ẹjọ́ Termini Imerese nílùú Sicily lórílẹ̀-èdè Ítálì dájọ́ pé dókítà oníṣẹ́ abẹ kan jẹ̀bi ẹ̀sùn ọ̀daràn torí pé ó fipá fa ẹ̀jẹ̀ sí obìnrin kan tó jẹ́ Ẹlẹ́rìí Jèhófà lára.
Wọ́n ní kí dókítà náà san ẹgbẹ̀rún mọ́kànlá àti ọgọ́rùn-ún mẹ́fà ó lé márùn-ún owó dọ́là ti ilẹ̀ Amẹ́ríkà ($11,605 U.S.) fún obìnrin náà gẹ́gẹ́ bí owó gbà-máà-bínú, kó sì tún san ẹgbẹ̀rún márùn-ún àti ọgọ́rùn-ún mẹ́jọ ó lé mẹ́ta owó dọ́là ti ilẹ̀ Amẹ́ríkà ($5,803 U.S.) fún ọkọ obìnrin náà tóun náà jẹ́ Ẹlẹ́rìí Jèhófà.
Ìgbà àkọ́kọ́ rèé tí ilé ẹjọ́ ilẹ̀ Ítálì máa dájọ́ pé dókítà kan jẹ̀bi ẹ̀sùn ọ̀daràn torí pé ó fi ẹ̀tọ́ tí aláìsàn ní lábẹ́ òfin dù ú, níwọ̀n ìgbà tó jẹ́ pé èèyàn lẹ́tọ̀ọ́ láti pinnu ohunkóhun tó fẹ́ kí ẹlòmíì ṣe sí ara òun.
Ohun tó ṣẹlẹ̀ gan-an ni pé ní December 2010, wọ́n ṣiṣẹ́ abẹ fún arábìnrin tá à ń sọ̀rọ̀ ẹ̀ yìí níbi òróòro, àmọ́ àwọn ìṣòro kan jẹyọ lẹ́yìn iṣẹ́ abẹ náà.
Bó tiẹ̀ jẹ́ pé léraléra ló ń sọ pé òun ò gba èròjà inú ẹ̀jẹ̀ sára, agbára ẹ̀ ò ká dókítà náà, ó sì fipá fa àwọn sẹ́ẹ̀lì pupa inú ẹ̀jẹ̀ sí i lára.
Dókítà tó ṣiṣẹ́ abẹ náà parọ́ pé adájọ́ ilé ẹjọ́ ló fún òun láṣẹ láti ṣe bẹ́ẹ̀.
Nígbà tó yá, obìnrin náà àti ọkọ ẹ̀ fẹjọ́ sun Ọ́fíìsì Olùpẹ̀jọ́.
Ilé ẹjọ́ sì pinnu pé “tí Ẹlẹ́rìí Jèhófà kan bá ti dàgbà tó lábẹ́ òfin, tó sì ní làákàyè tó, .
dókítà ò gbọ́dọ̀ fún un nírú ìtọ́jú yìí” tí onítọ̀hún bá ti lóhun ò fẹ́.
Ilé ẹjọ́ tún kéde pé Òfin Orílẹ̀-èdè Ítálì ò fàyè gbà á kí dókítà fipá fún ẹnì kan ní irú ìtọ́jú kan pàtó tó bá ti lóun ò fẹ́, kódà kí dókítà sọ pé ó dáa kó gba irú ìtọ́jú bẹ́ẹ̀.
Bí ilé ẹjọ́ náà ṣe sọ, “ti pé dókítà rí i pé ìtọ́jú kan pọn dandan .
kì í ṣe àwáwí láti fipá mú kí aláìsàn gba ìtọ́jú tó ti fara balẹ̀ ṣàlàyé lọ́nà tó ṣe kedere pé òun ò fẹ́.” Daniele Rodriguez, tó jẹ́ ọ̀jọ̀gbọ́n ní Ẹ̀ka Ìmọ̀ Ìṣègùn Lábẹ́ Òfin àti Ìlànà Ìtọ́jú ní Yunifásítì Padua, tún jẹ́rìí sí ọ̀rọ̀ yìí nígbà tó ń jábọ̀ lórí ẹjọ́ náà. Ó kíyè sí i pé “[àpilẹ̀kọ] 32 nínú Òfin [Ítálì] jẹ́ kó ṣe kedere pé èèyàn lẹ́tọ̀ọ́ láti sọ pé òun ò gba irú ìtọ́jú kan pàtó.
Òfin sọ pé ‘a ò gbọ́dọ̀ fipá mú ẹnikẹ́ni láti gba irú ìtọ́jú kan pàtó àfi tí òfin bá fọwọ́ sí i.’” Amòfin kan lórílẹ̀-èdè Ítálì, tó sì tún jẹ́ ògbóǹkangí nínú òfin tó jẹ mọ́ ìlera, tórúkọ ẹ̀ ń jẹ́ Luca Benci sọ̀rọ̀ lórí ìpinnu tí ilé ẹjọ́ ṣe, ohun tó kọ nínú ìwé Quotidiano Sanità (Health Daily) rèé: “Kò sí òfin tó sọ pé ó pọn dandan kí aláìsàn gba ẹ̀jẹ̀ sára tó bá lóun ò fẹ́.
Ẹ̀tọ́ tí aláìsàn ní láti sọ pé òun ò gba irú ìtọ́jú kan borí ohun gbogbo.” Ọ̀kan lára àwọn agbẹjọ́rò àwọn Ẹlẹ́rìí Jèhófà tó ń jẹ́ Marcello Rifici sọ pé: “Inú wa dùn láti rí i pé ẹjọ́ tí ilé ẹjọ́ dá yìí bá ìlànà tí wọ́n ń tẹ̀ lé nílẹ̀ Yúróòpù mu, bí èyí tó hàn nínú àwọn ẹjọ́ tí Ilé Ẹjọ́ Ẹ̀tọ́ Ọmọnìyàn ti Ilẹ̀ Yúróòpù ti dá, tó jẹ́ kó ṣe kedere pé gbogbo aláìsàn ló lẹ́tọ̀ọ́ láti pinnu irú ìtọ́jú tí wọ́n fẹ́.
Kẹ́ ẹ sì máa wò ó, lọ́dún 2017, Ilé Ìgbìmọ̀ Aṣòfin Ilẹ̀ Ítálì ṣe òfin 219/2017, tí wọ́n mọ̀ sí ‘Òfin Ohun Tí Mo Fẹ́,’ (ìyẹn Living Will Law) àwọn ìlànà inú òfin yẹn sì bá ìpinnu tí ilé ẹjọ́ ṣe yìí mu.” Òmíì lára àwọn agbẹjọ́rò àwọn Ẹlẹ́rìí Jèhófà tó ń jẹ́ Lucio Marsella tún sọ pé: “Ìpinnu tí ilé ẹjọ́ ṣe yìí máa ṣèrànwọ́ fún gbogbo àwọn dókítà onígboyà tó ń ṣe gbogbo ohun tí wọ́n lè ṣe láti tọ́jú àwọn aláìsàn láìfi ẹ̀tọ́ tí wọ́n ní láti yan ìtọ́jú tí wọ́n fẹ́ dù wọ́n.”
Ní August 22, ìmìtìtì ilẹ̀ tó lágbára kan ṣẹlẹ̀ ní erékùṣù Ischia tó wà létíkun ìlú Naples, lórílẹ̀-èdè Ítálì. Ìmìtìtì ilẹ̀ náà ba ọ̀pọ̀lọpọ̀ ilé jẹ́, ó sì sọ nǹkan bí ẹgbẹ̀rún méjì ó lé ọgọ́rùn-ún mẹ́fà [2,600] èèyàn di aláìnílé.
Ó lé ní ogójì [40] èèyàn tó fara pa, àwọn méjì ló sì kú.
A ò tíì gbọ́ pé ìkankan nínú àwọn ọgọ́rùn-ún mẹ́fà ó lé mẹ́tàlélọ́gbọ̀n [633] Ẹlẹ́rìí Jèhófà tó ń gbé ní erékùṣù náà ko jàǹbá tàbí fara gbọgbẹ́, àmọ́ ilé àwọn ìdílé Ẹlẹ́rìí Jèhófà mẹ́sàn-án ló bà jẹ́.
Àwọn Ẹlẹ́rìí Jèhófà tó wà lágbègbè náà ti ń ran àwọn ará bíi tiwọn lọ́wọ́, ìyẹn àwọn tọ́rọ̀ yìí kàn, wọ́n sì ń fi ọ̀rọ̀ Ọlọ́run tù wọ́n nínú.
Agbẹnusọ fún Àwa Ẹlẹ́rìí Jèhófà: Kárí Ayé: David A. Semonian, Ọ́fíìsì Agbéròyìnjáde, +1-845-524-3000 Ítálì: Christian Di Blasio, +39-06-872941
Ní May 15, 2019, Ilé Ẹjọ́ Gíga jù Lọ ní Ítálì fọwọ́ sí i pé àwọn ará wa lẹ́tọ̀ọ́ láti pinnu irú ìtọ́jú ìṣègùn tó wù wọ́n.
Ilé ẹjọ́ náà mú kó ṣe kedere pé aláìsàn kan lẹ́tọ̀ọ́ láti yan aṣojú fún ọ̀rọ̀ ìtọ́jú ìṣègùn, tó sì máa gbèjà aláìsàn náà kí wọ́n má bàa fa ẹ̀jẹ̀ sí i lára.
Yàtọ̀ síyẹn, Ilé ẹjọ́ náà tẹnu mọ́ ọn pé ó bófin mu lórílẹ̀-èdè Ítálì kí aláìsàn kan yan ẹni tó máa ṣojú fúnni lórí ọ̀rọ̀ ìtọ́jú ìṣègùn tó bá ṣẹlẹ̀ pé aláìsàn náà dákú gbọnrangandan tàbí kò lè sọ̀rọ̀ mọ́.
Arákùnrin àti Arábìnrin Cappelli Ilé ẹjọ́ ṣe ìpinnu yìí nítorí àwọn ẹjọ́ tó wáyé nípa Arákùnrin Luca Cappelli tó jẹ́ alàgbà nínú ìjọ.
Ó ti tó ọdún mẹ́ẹ̀ẹ́dọ́gbọ̀n (25) báyìí tó ti ní ìṣòro inú iṣan tí ẹ̀jẹ́ ń gbà kọjá nínú ọpọlọ.
Àìsàn tó ń ṣe Arákùnrin Cappelli le débi pé ó nílò onírúurú ìtọ́jú ìṣègùn àti pé nígbà míì kò ní lè sọ̀rọ̀.
Kí wọ́n tó bẹ̀rẹ̀ sí í tọ́jú ẹ̀, ó rí i pé òun kọ̀rọ̀ kún káàdì Advance Medical Directive, ó sì yan ìyàwó rẹ̀ Francesca láti ṣojú fún un nínú ọ̀rọ̀ ìtọ́jú ìṣègùn.
Àmọ́, adájọ́ kan nílé ẹjọ́ kòtẹ́milọ́rùn kò gbà kí ìyàwó arákùnrin yìí sojú fún un nínú ọ̀rọ̀ ìtọ́jú ìṣègùn, torí náà kò sí bí Arákùnrin Cappelli ṣe lè dáàbò bo ara ẹ̀ kí wọ́n má bàa fa ẹ̀jẹ̀ sí i lára.
Wọ́n gbé ẹjọ́ Arákùnrin Cappelli dé Ilé Ẹjọ́ Gíga Jù Lọ ní February 16, 2017.
Ilé Ẹjọ́ Gíga Jù Lọ sì sọ pé àwọn ilé ẹjọ́ kéékèèké yìí tàpá sí Òfin orílẹ̀-èdè Ítálì àti ti European Convention of Human Rights, tó fún aláìsàn kan lẹ́tọ̀ọ́ láti ṣe ìpinnu fúnra ẹ̀.
Ohun tó wúni lórí níbẹ̀ ni pé, ilé ẹjọ́ náà sọ pé “ó ṣe pàtàkì, ó sì yẹ kí wọ́n fi da aláìsàn kan lójú pé wọ́n máa dáàbò bo ẹ̀tọ́ rẹ̀ tó bá sọ pé òun ò nífẹ̀ẹ́ sírú ìtọ́jú ìṣègùn kan nítorí ohun tó gbà gbọ́.” Ilé Ẹjọ́ Gíga Jù Lọ dájọ́ pé káwọn ilé ẹjọ́ tó wà lórílẹ̀-èdè Ítálì túbọ̀ máa bọ̀wọ̀ fún ìpinnu táwọn ará wa ṣe pé àwọn ò ní gba ẹ̀jẹ̀.
Kárí ayé ni inú àwa Ẹlẹ́rìí Jèhófà ti dùn sí ìdájọ́ Ilé Ẹjọ́ Gíga Jù Lọ yìí. Ìdí ni pé wọ́n dáàbò bo ẹ̀tọ́ táwọn ará wa lórílẹ̀-èdè Ítálì ní láti má ṣe gba ẹ̀jẹ́ torí pé kò bá ìgbàgbọ́ wọn mu.​—Ìṣe 15:29.
Àmì ìrántí tí wọ́n gbé sí abúlé Risiera di San Sabba, ní ìlú Trieste.
Àwọn Ẹlẹ́rìí Jèhófà tó wà ní àgọ́ ìṣẹ́niníṣẹ̀ẹ́ nígbà yẹn máa ń ní àmì onígun mẹ́ta aláwọ̀ àlùkò lára aṣọ wọn Ní May 10, 2019, àwọn aláṣẹ ìjọba, àwọn òpìtàn, àwọn akọ̀ròyìn, àti ọ̀pọ̀ àlejò míì wá síbi ètò kan tí wọ́n ti ṣí aṣọ lójú àmì tí wọ́n ṣe ní ìrántí ọ̀pọ̀ àwọn ará wa lọ́kùnrin àti lóbìnrin tí ẹgbẹ́ òṣèlú Násì àti Ìjọba Aláṣẹ Oníkùmọ̀ ṣe inúnibíni sí.
Ètò ìrántí náà wáyé ní abúlé Risiera di San Sabba ní ìlú Trieste, tó wà ní àríwá ìlà-oòrùn orílẹ̀-èdè Ítálì, abúlé yìí ni wọ́n ti ń fi ẹ̀rọ fẹ́ ìrẹsì tẹ́lẹ̀ kí wọ́n tó sọ ọ́ di àgọ́ ìṣẹ́niníṣẹ̀ẹ́ kan ṣoṣo lórílẹ̀-èdè Ítálì tó ní ibi tí wọ́n ti ń dáná sun òkú.
Àwọn ilé iṣẹ́ oníròyìn ti àdúgbò àti ti ìjọba náà wá síbi tí wọ́n ti ṣí aṣọ lójú àmì ìrántí náà, tó fi mọ́ Canale 5, tó jẹ́ ìkànnì tẹlifíṣọ̀n táwọn èèyàn ń wò jù lọ lórílẹ̀-èdè náà.
Àsọyé kan tó dá lórí ìdúróṣinṣin ni Christian Di Blasio, tó jẹ́ agbẹnusọ fún àwọn Ẹlẹ́rìí Jèhófà ni orílẹ̀-èdè Ítálì fi bẹ̀rẹ̀ ètò ìrántí náà.
Ó sọ pé: “Lára àwọn tí ìjọba Násì ṣe inúnibíni sí, àwọn ẹlẹ́rìí Jèhófà nìkan ṣoṣo ló jẹ́ pé kìkì nítorí ohun tí wọ́n gbà gbọ́ ni ìjọba Násì ṣe ṣe inúnibíni sí wọ́n.
Àwọn nìkan ni sì àwùjọ tó ní àǹfààní láti ṣe nǹkan kan tí ikú á fi yẹ̀ lórí wọn.
Kí wọ́n wulẹ̀ sẹ́ ìgbàgbọ́ wọn ni, kí wọ́n sì sọ pé ti ìjọba làwọn á ṣe.
Síbẹ̀, wọ́n ní ìgboyà tó mú kí wọ́n dúró lórí ìwà tó yẹ ká bá lọ́wọ́ Kristẹni, ìyẹn ni pé wọ́n ní jẹ́ adúróṣinsin sí Ọlọ́run, wọ́n sì tún nífẹ̀ẹ́ àwọn èèyàn.”
Lẹ́yìn yẹn ni Arákùnrin Di Blasio fi fídíò ìfọ̀rọ̀wánilẹ́nuwò pẹ̀lú Arábìnrin Emma Bauer han àwọn tó wà níkàlẹ̀, nínú fídíò náà, Arábìnrin Emma Bauer ròyìn bi òun àti ìdílé òun ṣe fojú winá inúnibíni nígbà Ogun Àgbáyé Kejì.
Ó ṣàlàyé pé àwọn Kristẹni tòótọ́ ò ní yẹsẹ̀ lórí ohun tó tọ́, kódà tó bá máa la ikú lọ.
Ní ìparí ètò ìrántí náà, olórí ìlú Trieste, Roberto Dipiazza, bá àwọn tó wá síbẹ̀ sọ̀rọ̀.
Ó ní: “Àmì ìrántí yìí dùn mọ́ mi nínú gan-an.
A gbọ́dọ̀ wá nǹkan ṣe kí irú inúnibíni bẹ́ẹ̀ má bàa ṣẹlẹ̀ mọ́ láé.” Ẹ̀yìn yẹn ni wọ́n wá ṣí aṣọ lójú àmì ìrántí náà.
Ọ̀pọ̀ ọ̀mọ̀wé àtàwọn ìlúmọ̀ọ́ká sọ̀rọ̀ lórí bí ètò ìrántí náà ti ṣe pàtàkì tó.
Bí àpẹẹrẹ, Giorgio Bouchard, ààrẹ àná fún Àgbájọ Àwọn Ṣọ́ọ̀ṣì Ajíhìnrere Lórílẹ̀-Èdè Ítálì sọ pé: “Yàtọ̀ sí àwọn Ẹlẹ́rìí Jèhófà, kò sí àwùjọ ẹ̀sìn náà táwọn ọmọ ìjọ rẹ̀ tíì fẹ̀mí ara wọn lélẹ̀ tó báyìí rí nítorí ohun tí wọ́n gbà gbọ́.
Àmọ́, ṣe ni ìrírí tó le koko táwọn Ẹlẹ́rìí ní yìí túbọ̀ mú kí wọ́n lágbára, wọ́n sì wá fìdí ẹ̀rí múlẹ̀ fáwọn èèyàn, àti fún Ọlọ́run pàápàá, pé àwọn ni ẹ̀sìn Kristẹni kan ṣoṣo tó ta ko èròǹgbà tí Ìjọba Násì gbé lárugẹ.” (Fún àlàyé síwájú sí i, wo àpótí tó wà nísàlẹ̀.)
A nírètí pé àwọn èèyàn tó tó ẹgbẹ̀rún lọ́nà ọgọ́fà (120,000 ) lá máa ṣèbẹ̀wò síbi àmì ìrántí pàtàkì tó wà ní abúlé Risiera di San Sabba yìí lọ́dọọdún.
Ẹnì kọ̀ọ̀kan tó bá wá síbẹ̀ á ní àǹfààní láti wo àmì yìí ní ìrántí ẹgbẹẹgbẹ̀rún àwọn Ẹlẹ́rìí Jèhófà tó dúró lórí ìgbàgbọ́ wọn tí wọn ò sì lọ́wọ́ sí òṣèlú, bó tilẹ̀ jẹ́ pé ẹgbẹ́ òṣèlú Násì àti ìjọba aláṣẹ oníkùmọ̀ ṣe inúnibíni sí wọn.​—⁠Ìfihàn 2:⁠10.
Sergio Albesano (Òpìtàn, ìlú Turin) Ìgbà tí mò ń ṣe ìwádìí nípa àwọn tó kọ̀ láti wọṣẹ́ ológun torí ohun tí wọ́n gbà gbọ́ ni mo wá mọ̀ nípa àwọn Ẹlẹ́rìí Jèhófà, ọ̀nà tí wọ́n gbà gbé ìgbé ayé wọn sì wú mi lórí gan-an.
Bó tilẹ̀ jẹ́ pé ẹlẹ́sìn Búdà ni mí, mo bọ̀wọ̀ fún wọn torí pé ìgbàgbọ́ wọn lágbára, ìgbàgbọ́ yẹn ni ò jẹ́ kí ọ̀pọ̀ tó kú lára wọn torí inúnibíni ìjọba Násì jáwọ́ nínú ohun tí wọ́n gbà gbọ́, tó sì mú kí wọ́n fẹ̀mí ara wọn lélẹ̀ kí wọ́n má bàa sẹ́ ìgbàgbọ́ wọn.
Luigi Berzano (Onímọ̀ nípa ìbágbépọ̀ ẹ̀dá, ọ̀jọ̀gbọ́n, Yunifásítì Turin; olóòtú ìwé ọdọọdún náà, Annual Review of the Sociology of Religion)
Ó ti pẹ́ jù káwọn èèyàn tó gbà pé òótọ́ ni Ìjọba Násì ṣe inúnibíni sí àwọn Ẹlẹ́rìí Jèhófà àti kí wọ́n tó máa fọ̀wọ̀ wọ̀ wọ́n pé wọn fara da inúnibíni náà, bó tilẹ̀ jẹ́ pé àwọn tí ọ̀rọ̀ ṣojú wọn àtàwọn àkọsílẹ̀ ìtàn tó ṣeé gbára lé wà tó jẹ́rìí sí ohun tó ṣẹlẹ̀ nígbà náà.
Lẹ́yìn-ọ̀-rẹyìn, àgbàyanu ìgbàgbọ́ àti ìwà ọmọlúwàbí àwọn Ẹlẹ́rìí tó lé ní ẹgbẹ̀rún mẹ́ẹ̀ẹ́dọ́gbọ̀n (25,000) tí wọ́n ṣenúnibíni sí lórílẹ̀-èdè Jámánì ti kúrò lóko ìgbàgbé.
Ohun tó ṣẹlẹ̀ sáwọn Ẹlẹ́rìí Jèhófà ti wá di ẹ̀rí tí kò lẹ́gbẹ́ pé, wọn ò fi ìgbàgbọ́ wọn nínú Ọlọ́run báni dọ́rẹ̀ẹ́, torí náà, wọ́n yẹ lẹ́ni àpọ́nlé, wọ́n sì níyì ju gbogbo àwọn míì tí ìjọba ṣenúnibíni sí lọ.
Giorgio Bouchard (Ààrẹ àná fún Àgbájọ Àwọn Ṣọ́ọ̀ṣì Ajíhìnrere ní Orílẹ̀-Èdè Ítálì) Bó tiẹ̀ jẹ́ pé gbágbáágbá làwọn ọmọ “ìjọ ńláńlá” (ṣọ́ọ̀ṣì Lutheran àti Kátólíìkì) rìn ní ìfẹ̀gbẹ́kẹ̀gbẹ́ pẹ̀lú àwọn ọmọ ogun Jámánì títí dé ìlú Stalingrad [Volgograd], ọ̀pọ̀ àwọn Ẹlẹ́rìí Jèhófà ló kú sínú ọgbà ẹ̀wọ̀n àtàwọn àgọ́ ìṣẹ́niníṣẹ̀ẹ́ torí pé wọn ò fẹ́ ṣe ohun tó lòdì sí ẹ̀rí ọkàn wọn.
Yàtọ̀ sí àwọn Ẹlẹ́rìí Jèhófà, kò sí àwùjọ ẹ̀sìn náà táwọn ọmọ ìjọ rẹ̀ tíì fẹ̀mí ara wọn lélẹ̀ tó báyìí rí nítorí ohun tí wọ́n gbà gbọ́.
Àmọ́, ṣe ni ìrírí tó le koko táwọn Ẹlẹ́rìí ní yìí túbọ̀ mú kí wọ́n lágbára, wọ́n sì wá fìdí ẹ̀rí múlẹ̀ fáwọn èèyàn, (àti fún Ọlọ́run pàápàá), pé àwọn ni ẹ̀sìn Kristẹni kan ṣoṣo tó ta ko èròǹgbà tí Ìjọba Násì gbé lárugẹ.”
Giuseppina Celloni (Onímọ̀ nípa ìrònú àti ìhùwàsí ẹ̀dá àti olùtọ́jú àrùn ọpọlọ, ìlú Trieste) Ó pẹ́ táwọn èèyàn ò ti ka inúnibíni tí ẹgbẹ́ òṣèlú Násì àti ìjọba aláṣẹ oníkùmọ̀ ṣe sáwọn Ẹlẹ́rìí Jèhófà sí.
Àmì ìrántí tá a gbé síbi pàtàkì nínú ìtàn yìí, ṣe àpọ́nlé ẹgbẹẹgbẹ̀rún àwọn Ẹlẹ́rìí Jèhófà tí wọ́n ti ní ìgboyà, tí wọ́n jẹ́ adúróṣinṣin tí wọ́n sì ní ìgbàgbọ́ nínú àwọn ìlànà rere táwọn Kristẹni ń tẹ̀ lé kí wọ́n lè máa gbé ìgbé ayé àlàáfíà.
Àwọn Ẹlẹ́rìí Jèhófà tó la inúnibíni náà já sapá láti borí ohun tí wọ́n fojú winá rẹ̀ bí wọ́n ṣe ń bá a nìṣó láti máa gbé ní ìrọ̀wọ́-rọsẹ̀ tí wọ́n sì ní ìgbàgbọ́ tó lágbára nínú “ọjọ́ tuntun” kan tó ń bọ́ lọ́nà, níbi tí kò ní sí ìjìyà mọ́ tí kò sì ní sí ẹni tó máa bí ara rẹ̀ pé, ‘Kí nìdí?’
Maurizio Costanzo (Akọ̀ròyìn àti olóòtú ètò orí tẹlifíṣọ̀n, ìlú Róòmù) A ò jẹ́ gbàgbé ẹgbẹẹgbẹ̀rún àwọn Ẹlẹ́rìí Jèhófà láti apá ibi ọ̀tọ̀ọ̀tọ̀ lórílẹ̀-èdè Yúróòpù tí wọ́n rán lọ sí àwọn àgọ́ ìṣẹ́niníṣẹ̀ẹ́.
Ẹ̀mí ẹgbẹ̀rún kan ààbọ̀ (1,500) lára wọn ló lọ sí i.
Ní ọwọ́ kejì ẹ̀wẹ́, kò yani lẹ́nu pé ẹgbẹ́ òṣèlú Násì àti ìjọba aláṣẹ oníkùmọ̀ ṣe inúnibíni sí àwọn Ẹlẹ́rìí Jèhófà, kì í ṣe torí ẹ̀yà tí wọ́n jẹ́, àmọ́ torí pé wọ́n ní ìgbàgbọ́, wọ́n jẹ́ ẹni àlàáfíà, wọn kì í sì í dá sí ọ̀rọ̀ òṣèlú, ìdí nìyẹn tí ìjọba fi kórìíra wọn.
Abala pàtàkì lèyí jẹ́ nínú ìtàn àwọn Ẹlẹ́rìí Jèhófà, torí náà, ó yẹ ká máa rántí rẹ̀ lọ́nà tá á fi hàn pé a mọyì wọn gan-an.
Annamaria Fiorillo (Igbá kejì agbẹjọ́rò ìjọba ní Kóòtù Àwọn Ọ̀dọ́ ti ìlú Milan)
Ó ṣe pàtàkì ká rántí pé Ìjọba Násì ò rí àwọn Ẹlẹ́rìí Jèhófà bí ọ̀rẹ́ torí ojú tí wọ́n fi ń wo ayé, pé ìwàláàyè jẹ́ mímọ́, èyí tó ta ko èròǹgbà ìjọba Násì pé ẹ̀yà Aryan ló yẹ kó máa ṣàkóso gbogbo ayé.
Àwọn Ẹlẹ́rìí Jèhófà tó kọ̀ láti wọṣẹ́ ológun torí ohun tí wọ́n gbà gbọ́, bó tilẹ̀ jẹ́ pé ó lè la ikú lọ fún wọn, síbẹ̀ tí wọ́n kọ̀ láti sẹ́ ìgbàgbọ́ wọn, ò wulẹ̀ kù ikú ẹ̀sìn lásán.
Lónìí, bó ṣe jẹ́ nígbà náà lọ́hùn-ún, a lè sọ pé wọ́n jẹ́ onígboyà, tó kọ̀ láti lọ́wọ́ sí ìwà ipá tó sì gbé àlàáfíà lárugẹ.
Àpẹẹrẹ rere ni wọ́n jẹ́ láàárín àwọn èèyàn, wọ́n sì mú káwọn ìran tó ń bọ̀ lọ́jọ́ iwájú nírètí.
Anna Foa (Ọ̀jọ̀gbọ́n Ìtàn Òde Òní, Yunifásítì La Sapienza, ìlú Róòmù) Àárín ọdún 1990 sí ọdún 1999 ni àwọn òpìtàn ṣẹ̀ṣẹ̀ bẹ̀rẹ̀ sí í ṣèwádìí nípa “àmì onígun mẹ́ta aláwọ̀ àlùkò” tí wọ́n sì wá ń rántí inúnibíni tí Ìjọba ṣe sí àwọn tó lo àmì náà.
Ìdí pàtàkì tí wọn ò fi mọ̀ tí wọn ò sì rántí wọn ni pé, lẹ́yìn ogun, ìjọba ṣì ń bá a nìṣó láti máa ṣe inúnibíni sáwọn Ẹlẹ́rìí Jèhófà ní Ìlà Oòrùn orílẹ̀-èdè Jámánì.
Wọ́n fi ẹ̀sùn kàn wọ́n pé wọ́n jẹ́ ọ̀tá ìjọba àjùmọ̀ní, aṣojú ìjọba agbókèèrè-jẹ-gàba ti ilẹ̀ Amẹ́ríkà àti amí, torí náà wọ́n tún pa dà jù wọ́n sẹ́wọ̀n, ìjọba ju ẹgbẹ̀rún mẹ́rin (4,000) lára wọn sẹ́wọ̀n, wọ́n sì fi ẹgbẹ̀rún kan (1,000) sẹ́wọ̀n láì gbọ́ tẹnu wọn nílé ẹjọ́.
Ẹ̀yìn ìgbà tí Ìlà Oòrùn àti Ìwọ̀ Oòrùn orílẹ̀-èdè Jámánì pa dà di ọ̀kan lọ́dún 1989 ní ìtàn wọn kúrò lóko ìgbàgbé táwọn èèyàn sì bẹ̀rẹ̀ sí í sọ̀rọ̀ nípa inúnibíni tí Ìjọba ṣe sí wọn.
Àwọn ọkùnrin nìkan kọ́ ni wọ́n ṣe inúnibíni sí, àmọ́ bí òpìtàn Adriana Lotto ṣe sọ, wọ́n ṣe inúnibíni sáwọn obìnrin náà, pàápàá àwọn tí wọ́n dìídì jù sẹ́wọ̀n torí kí wọ́n má bàa kọ́ àwọn ọmọ wọn lẹ́kọ̀ọ́ tí ò ní jẹ́ kí wọ́n fẹ́ wọṣẹ́ ológun.
Nígbà tí èyí bẹ̀rẹ̀, lọ́dún 1933, àwọn (yàtọ̀ sí àwọn obìnrin tó jẹ́ ẹgbẹ́ òṣèlú ìjọba orí-ò-jorí) ni àwùjọ kan ṣoṣo tó pọ̀ jù lọ láwọn àgọ́ ìṣẹ́niníṣẹ̀ẹ́, pàápàá jù lọ, àgọ́ ìṣẹ́niníṣẹ̀ẹ́ àwọn obìnrin ní Ravensbrück.
Wọ́n mọ̀ wọ́n bí ẹní mowó níbẹ̀ torí pé wọ́n kọ̀ láti ṣe iṣẹ́ tó bá jẹ mọ́ àwọn ọmọ ogun àti ogun (irú bíi rírán aṣọ àwọn ológun tàbí wíwá oúnjẹ fún àwọn ẹ̀ṣọ́ SS), wọ́n torí bẹ́ẹ̀ fìyà jẹ wọ́n gidigidi, tàbí nígbà míì, kí wọ́n dájọ́ ikú fún wọ́n.
Maria Fausta Maternini (Òjọ̀gbọ́n nípa Ìjọra Tàbí Àìdọ́gba Tó Wà Nínú Òfin Ẹ̀sìn, Yunifásítì ìlú Trieste)
Mo dara pọ̀ mọ́ wọn níbi ètò ìrántí tó bani nínú jẹ́ tó sì wọni lọ́kàn èyí tó wáyé ní abúlé Risiera di San Sabba, tó jẹ́ ká rí ìjẹ́pàtàkì bí àwọn Ẹlẹ́rìí Jèhófà ṣe dúró lórí ìgbàgbọ́ wọn, pé dípò kí wọ́n sẹ́ ohun tí wọ́n gbà gbọ́, wọ́n ṣe tán láti kú.
Bíi tìgbà yẹn, ṣe làwọn Ẹlẹ́rìí Jèhófà òde òní náà ń pa kún ṣíṣe ohun tó tọ́ tó sì yẹ, kí gbogbo èèyàn lè máa gbé ní àlàáfíà àti ní ìrẹ́pọ̀.
Ẹ ṣeun tẹ́ ẹ pè mí síbi ètò ìrántí yìí, mo sì fi ìmọrírì hàn fún àlàyé tó ṣe kedere tó sì wọni lọ́kàn tí ẹ̀yin Ẹlẹ́rìí Jèhófà ṣe.
Marzio Pontone (Agbẹjọ́rò, ìlú Turin) Ọdún mẹ́ẹ̀ẹ́dọ́gbọ̀n (25) ni mo fi gbẹnu sọ láwọn ilé ẹjọ́ ológun àti ti ìjọba nílùú Ítálì kí wọ́n lè fún àwọn Ẹlẹ́rìí ní “òmìnira láti ṣe ohun tí ẹ̀sìn wọn fàyè gbà.”
Láì ṣiyè méjì, mo lè sọ pé ànímọ́ mẹ́ta pàtàkì láwọn Ẹlẹ́rìí Jèhófà ní.
Wọ́n jẹ́: (1) adúróṣinṣin nínú ohun gbogbo, (2) wọn kì í yí pa dà, wọn (3) kì í sì í ṣiyè méjì tó bá di pé kí wọ́n tẹ̀ lé ohun tí Jèhófà pa láṣẹ fún wọn kí wọ́n sì bọ̀wọ̀ fún un.
Àwọn Ẹlẹ́rìí kan tiẹ̀ ti gbà láti kú kí wọ́n má bàá sẹ́ ìgbàgbọ́ wọn — Àmì “onígun mẹ́ta aláwọ̀ àlùkò” ló jẹ́ ẹ̀rí tó ṣeé fojú rí nípa àwọn tó ṣe irú ìpinnu bẹ́ẹ̀.
Mi ò rò pé àsọdùn ni tí mo bá sọ pé tá a bá ń wá “àwọn tó kú nítorí ohun tí wọ́n gbà gbọ́” àpẹẹrẹ tòótọ́ làwọn Ẹlẹ́rìí kan jẹ́.
Mi ò rí ohun àbùkù kankan sọ nípa àwọn Ẹlẹ́rìí Jèhófà torí mo mọ̀ pé wọn yẹ lẹ́ni àpọ́nlé lọ́dọ̀ gbogbo èèyàn, títí kan lọ́dọ̀ àwa tá a jẹ́ ẹlẹ́sìn míì (Kátólíìkì).
Guido Raimondi (Ààrẹ àná fún Ilé Ẹjọ́ Ẹ̀tọ́ Ọmọnìyàn ti Ilẹ̀ Yúróòpù)
Mo gbóṣùbà fún àwọn tó wà nídìí ètò ìrántí pàtàkì yìí, ó rán wa létí bí òṣìkà ìjọba Násì ṣe ṣenúnibíni sí àwọn Ẹlẹ́rìí Jèhófà tó sì dá ọ̀pọ̀ lára wọn lóró.
Ọpẹ́lọpẹ́ ìwà akin wọn tó gún wa ní kẹ́ṣẹ́ láwùjọ tá a fi dá ètò ìgbẹ́jọ́ ilẹ̀ Yúróòpù àti Ilé Ẹjọ́ Ẹ̀tọ́ Ọmọnìyàn ti Ilẹ̀ Yúróòpù sílẹ̀.
Gbogbo ọmọ ilẹ̀ Yúróòpù ló yẹ kó máa rántí wọn kí wọ́n sì máa ṣọpẹ́ torí ohun tí wọ́n ṣe.
Bruno Segre (Agbẹjọ́rò, akòròyìn, olóòtú ìwé ìròyìn L’Incontro, ìlú Turin) Ní orílẹ̀-èdè Ítálì, mo jẹ́ ọ̀kan lára àwọn tó ṣiṣẹ́ lórí àbádòfin tó fàyè gba ẹni tí ẹ̀rí ọkàn rẹ̀ ò bá yọ̀ǹda fún láti ṣiṣẹ́ ológun.
Mo ní àǹfààní láti ṣe agbẹjọ́rò fún ọ̀pọ̀ lára àwọn ọ̀dọ́ Ẹlẹ́rìí Jèhófà níwájú ilé ẹjọ́ ológun lórílẹ̀-èdè Ítálì.
Mo lè jẹ́rìí sí i pé àìṣàbòsí wọn, ẹ̀mí ìmúratán wọn àti bí wọn ṣe fìmọ̀ ṣọ̀kan ló mú kí ìgbàgbọ́ wọn fẹsẹ̀ múlẹ̀ ṣinṣin, ìyẹn sì mú kí n gba tiwọn ní gbogbo ọ̀nà.
Ilé tó wà nílùú Imola, níbi tí Ẹ̀ka Ìtúmọ̀ Èdè wà báyìí Ẹ̀ka ọ́fíìsì orílẹ̀-èdè Ítálì ti ń kó láti ìlú Róòmù lọ sí ìlú Bologna àti Imola.
Ìlú Bologna wà ní nǹkan bí ọgọ́rùn-ún mẹ́ta ó lè àádọ́rin (370) kìlómítà sí àríwá ìlú Róòmù, ìlú Imola sì wà ní nǹkan bíi kìlómítà méjìdínláàádọ́ta (48) sí ìlú Bologna.
Wọ́n ti ń ṣe àtúnṣe sí ilé alájà mẹ́sàn-án kan tó wà ní ìlú Bologna èyí tí ẹ̀ka máa fi ṣe ọ́fíìsì.
Láti ọdún 2018, àwọn òṣìṣẹ́ Bẹ́tẹ́lì tó lé ní ọgọ́ta (60) tí wọ́n ń ṣe iṣẹ́ atúmọ̀ èdè àtàwọn iṣẹ́ míì tó tan mọ́ ọn ti ń bá iṣẹ́ nìṣó nínú ilé tí wọ́n ṣẹ̀ṣẹ̀ ṣe àtúnṣe sí ní ìlú Imola.
Ká lè pèsè ibùgbé fún àwọn òṣìṣẹ́ ní Bẹ́tẹ́lì tí wọ́n ń kó lọ sí ìlú Bologna, a ti bẹ̀rẹ̀ sí í kọ́ ilé alájà-méje kan sí nǹkan bíi kìlómítà kan àtààbọ̀ (máìlì kan) sí ibi tá a kọ́ ọ́fíìsì sí. Ilé náà ní ibi ìgbọ́kọ̀sí abẹ́lẹ̀ tó jẹ́ ìpele mẹ́ta.
A ṣì tún máa wá àwọn ilé míì sí i ní agbègbè yẹn.
Àwòrán bí ilé gbígbé alájà-méje tí wọ́n ń kọ́ lọ́wọ́ náà ṣe máa rí Ọdún 1948 ni àwa Ẹlẹ́rìí Jèhófà ra ẹ̀ka ọ́fíìsì wa àkọ́kọ́ ní ìlú Róòmù tá a sì kó lọ síbẹ̀ láti ibi tá a ti ń ṣiṣẹ́ tẹ́lẹ̀ ní ìlú Milan.
Látìgbà yẹn wá, àwa Ẹlẹ́rìí Jèhófà ti pọ̀ sí i lọ́nà tó pabanbarì ní Ítálì.
Ní nǹkan bí ọdún 1945, àwọn akéde tó wà lórílẹ̀-èdè náà ò ju igba (200) lọ.
Lónìí, àwọn akéde tó wà níbẹ̀ ti lé ní ẹgbẹ̀rún lọ́nà àádọ́ta-lé-nígba (250,000).
Orílẹ̀-èdè yìí ló ní iye akéde tó pọ̀ jù nílẹ̀ Yúróòpù.
Bí iye àwọn akéde tó wà ní Ítálì ṣe ń pọ̀ sí i ni iye àwọn òṣìṣẹ́ ní Bẹ́tẹ́lì àti ẹ̀ka ọ́fíìsì náà ń pọ̀ sí i. Ní ọdún 2006, ilé mọ́kàndínlọ́gọ́rùn-ún (99) ọ̀tọ̀ọ̀tọ̀ là ń lò fún ẹ̀ka ọ́fíìsì ní Ítálì.
Tá a bá ti pa gbogbo iṣẹ́ pọ̀ sójú kan nílùú Bologna, iye àwọn òṣìṣẹ́ Bẹ́tẹ́lì máa dín kù, á wá ṣẹ́ ku ilé márùn-ún péré.
Àdúrà wa ni pé kí Jèhófà máa bá a lọ láti fi ìbùkún rẹ̀ sórí iṣẹ́ ìkọ́lé náà kí àwọn ọ́fíìsì tuntun náà sì ṣètìlẹ́yìn fún iṣẹ́ tá à ń ṣe ní Ítálì, pápá tó ‘funfun tó sì ti tó kórè.’​—Jòhánù 4:35.
Déètì: August 2 sí 4, 2019
Ibi Tá A Ti Ṣe É: Jaarbeurs Hallencomple, ìlú Utrecht, orílẹ̀-èdè Netherlands
Èdè: Lárúbáwá, Dutch, Èdè Àwọn Adití lọ́nà ti ilẹ̀ Jámánì, Gẹ̀ẹ́sì, Papiamento, Polish, Potogí, Sípáníìṣì, Twi
Àwọn Tó Wá: Ẹgbẹ̀rún méjìlélógójì, ọgọ́rùn-ún mẹ́ta àti márùn-ún dín lógójì (42,335)
Àwọn Tó Ṣèrìbọmi: Ọgọ́rùn-ún méjì àti méjìlá (212)
Àwọn Tó Wá Láti Ilẹ̀ Òkèèrè: Ẹgbẹ̀rún mẹ́fà (6,000)
Àwọn Ẹ̀ka Ọ́fíísì Tá A Pè: Australasia, Belgium, Brazil, Kánádà, Kòlóńbíà, Indonesia, Kòríà, Pọ́túgà, Ròmáníà, South Africa, Suriname, Orílẹ̀-èdè Amẹ́ríkà
Ìrírí: Alábòójútó ilé-iṣẹ́ tí Jaarbeurs Hallencomplex gbé iṣẹ́ ìmọ́tótó ọgbà náà fún pe arákùnrin wa tó jẹ́ ọ̀kan lára àwọn òṣìṣẹ́ rẹ̀ lórí fóònù, ó ní: “Àwọn kan wà níbí tó ń ṣe gbogbo iṣẹ́ tó yẹ ká ṣe láìjáfara, wọ́n ń tún àyíká ṣe, wọ́n sì tún ṣètò bí gbogbo nǹkan ṣe máa wà ní mímọ́ tónítóní.
Mo gbà pé wọ́n á fẹ́ẹ̀ fi ibí sílẹ̀ lọ́nà tó dáa ju bí wọ́n ṣe gbà á lọ́wọ́ wa lọ.
Mí ò rírú èyí rí, ó jọ mi lójú gan-an ni!
Kódà, wọ́n tún àwọn ibì kan nínú ilé oúnjẹ tá ò lò báyìí ṣe!
Èèyàn méjì ló máa ń wà lárọ̀ọ́wọ́tó níbi ilé ìtura, bí ohunkóhun bá sì ṣẹlẹ̀, kíá, wọ́n ti ṣàtúnṣe ẹ̀.
Kò ṣẹlẹ̀ rí!”
Ẹ̀ka ọ́fíìsì wa tó wà ní North Makedóníà ṣètò àkànṣe ìwàásù ní August 1 sí October 31, 2019, kí wọ́n lè wàásù fún àwọn tó ń sọ èdè Makedóníà àti èdè Alibéníà ní ìpínlẹ̀ ẹ̀ka ọ́fíìsì wọn.
Ní North Makedóníà, àwọn tó ń sọ èdè Makedóníà ju mílíọ̀nù kan àti ẹgbẹ̀rún lọ́nà ọgọ́rùn-ún mẹ́ta (1,300,000) lọ, àwọn tó sì ń sọ èdè Alibéníà ju ìdajì mílíọ̀nù kan lọ.
Àmọ́, nínú àwọn akéde ẹgbẹ̀rún kan ó lé ọgọ́rùn-ún mẹ́ta (1,300) tó ń sọ èdè Makedóníà lórílẹ̀-èdè yẹn, ẹgbẹ̀rún kan péré ló wà ní ìjọ tí wọ́n ti ń sọ èdè Makedóníà, ogún (20) akéde péré ló sì wà ní ìjọ tí wọ́n ti ń sọ èdè Alibéníà.
Torí náà, àwọn akéde ọgọ́rùn-ún mẹ́rin àti mẹ́rìndínlọ́gọ́rin (476) ló wá ṣèrànwọ́ fáwọn akéde yìí láti àwọn orílẹ̀-èdè méje ọ̀tọ̀ọ̀tọ̀.
Àwọn orílẹ̀-èdè náà ni Alibéníà, Austria, Belgium, Jámánì, Ítálì, Sweden àti Switzerland.
Ìwé Bíbélì Fi Kọ́ni lédè Makedóníà tí ọkùnrin tó ń da ewúrẹ́ náà gbà lọ́dún mẹ́wàá sẹ́yìn Nígbà àkànṣe ìwàásù yẹn, arákùnrin kan pàdé ọkùnrin kan tó ń da ewúrẹ́ lójú ọ̀nà.
Bí ọkùnrin tó ń da ewúrẹ́ náà ṣe rí i pé àwọn Ẹlẹ́rìí Jèhófà lòun ń bá sọ̀rọ̀, kíá ló yọ ìwé Bíbélì Fi Kọ́ni jáde nínú àpò rẹ̀, ó sọ pé ìgbà táwọn Ẹlẹ́rìí wá wàásù láti Ítálì ní ọdún mẹ́wàá sẹ́yìn ni wọ́n fún òun ní ìwé náà.
Ó tiẹ̀ sọ pé ojoojúmọ́ lòun ń ka ìwé náà, kódà òun ti há àwọn àkòrí kan sórí nínú ẹ̀.
Báwọn ará ṣe ṣètò fún ìpadàbẹ̀wò nìyẹn.
Báwọn ará tó ń sọ èdè Makedóníà àti Alibéníà ṣe tú yáyá tù yàyà láti ti àkànṣe ìwàásù yìí lẹ́yìn rán wa létí bí Pọ́ọ̀lù náà ṣe múra tán láti “sọdá wá sí Makedóníà.”—Ìṣe 16:9.
Déètì: August 9 sí 1l, 2019
Ibi Tó Ti Wáyé: Pápá Ìṣeré Municipal Stadium of Legia nílùú Warsaw àti Gbọ̀ngàn Ìwòran Torwar Hall, nílùú Warsaw, lórílẹ̀-èdè Poland
Èdè: Gẹ̀ẹ́sì, Polish
Àwọn Tó Wá: 32,069
Àwọn Tó Ṣèrìbọmi: 190
Àwọn Tó Wá Láti Ilẹ̀ Òkèèrè: 6,892
Àwọn Ẹ̀ka Ọ́fíìsì Tá A Pè: Central Europe, Chile, Ecuador, Finland, Faransé, Jọ́jíà, Hungary, Japan, Kòríà, Moldova, Romania, Ukraine, Amẹ́ríkà
Ìrírí: Ọ̀gbẹ́ni KamilKaźmierkiewicz tó jẹ́ ọ̀gá àgbà òtẹ́ẹ̀lì tí wọ́n ń pè ní Four Points by Sheraton ní ìlú Warsaw Mokotów (ó jẹ́ ọ̀kan lára òtẹ́ẹ̀lì tí wọ́n fi àwọn àlejò wọ̀ sí), kọ̀wé pé: “Ó rọrùn láti bá a yín ṣiṣẹ́, ó wù mí kí n tún láwọn àlejò tó jẹ́ onínúure tí wọ́n sì lẹ́mìí tó dáa bíi tiyín.
Mo kíye síi pé ẹ nífẹ̀ẹ́ ara yín gan an, ẹ sì wà níṣọ̀kan.
Bẹ́ ẹ ṣe ṣètò gbogbo nǹkan ní àpéjọ yìi wú mi lórí gan-an.” Ọ̀gbẹ́ni Kamil Lubański tó ni ilé iṣẹ́ KL Team tó bá wa ṣètò ọkọ̀ tó kó àwọn èèyàn sọ pé: “Látọjọ́ tí mo ti bẹ̀rẹ̀ sí bá àwọn Ẹlẹ́rìí Jèhófà ṣiṣẹ́ ni mo ti mọ̀ pé màá gbádùn àkókò tá a máa fi ṣiṣẹ́.
Wọ́n wà létòletò, wọ́n sì mọ́ nǹkan ṣe.
Wọ́n ti ṣètò tó nítumọ̀ fún àpéjọ ńlá yìí, wọ́n sì ti múra sílẹ̀ dáadáa.
Ọ̀pọ̀ àwọn olókìkí èèyàn la ti bá ṣiṣẹ́ nílé iṣẹ́ wa, títí kan àwọn òṣìṣẹ́ ìjọba, a sì ti ṣètò ìkórajọ káàkiri orílẹ̀-èdè yìí àti láwọn orílẹ̀-èdè tó wà ní Yúróòpù.
Àmọ́, mi ò tíì ráwọn èèyàn tó múra sílẹ̀ tó sì ṣe nǹkan létòletò bíi tiyín rí.
Kókó ibẹ̀ ni pé, gbogbo àwọn awakọ̀ wa àtàwọn òṣìṣẹ́ wa míì ló ń sọ ohun tó dáa nípa àwọn Ẹlẹ́rìí Jèhófà nígbà tí wọ́n jọ ṣiṣẹ́.
Lọ́jọ́ iwájú, ó wù wá ká tún jọ ṣiṣẹ́.”
"Ojú ọjọ́ tó ń gbóná kọjá sísọ àti ọ̀gbẹlẹ̀ tó lágbára ti yọrí sí iná lórílẹ̀-èdè Portugal, tọ̀tẹ̀ yìí ló sì tíì pààyàn jù lórílẹ̀-èdè náà.
Lóṣù June, èèyàn mẹ́rìnlélọ́gọ́ta [64] ló kú, èèyàn márùndínláàádọ́ta [45] ló sì kú lóṣù October, ní àárín oṣù October, ìgbà ọgọ́rùn-ún márùn-ún ó lé mẹ́tàlélógún [523] ni iná ṣẹ́ yọ.
Àjọ Tó Ń Bójú Tó Ọ̀rọ̀ Pàjáwìrì lábẹ́ ìdarí Ìgbìmọ̀ Ilẹ̀ Yúróòpù sọ pé, lọ́dún yìí, ó ti fẹ́rẹ̀ẹ́ tó mílíọ̀nù kan ààbọ̀ eékà ilẹ̀ tí iná ti jó, ó fi ìlọ́po mẹ́fà ju iye ilẹ̀ tó sábà máa ń jóná lórílẹ̀-èdè náà tẹ́lẹ̀, ìyẹn ẹgbẹ̀rún lọ́nà igba ó lé márùn-ún [205,000] eékà ilẹ̀
Ẹ̀ka ọ́fíìsì àwọn Ẹlẹ́rìí Jèhófà lórílẹ̀-èdè Portugal ròyìn pé iná náà gbẹ̀mí ọ̀kan nínú àwọn ará wa àti ìbátan rẹ̀ ọlọ́dún mẹ́rin.
Iná ọ̀hún tún ba ilé àwọn ará wa kan jẹ́, ó tiẹ̀ ba àwọn kan jẹ́ kọjá àtúnṣe, títí kan ilẹ̀ oko wọn àtàwọn irinṣẹ́ wọn, kódà, ó pa lára ẹran ọ̀sìn wọn.
Àwọn ará lọ́kùnrin lóbìnrin ti ń ṣiṣẹ́ kára láti ran ara wọn lọ́wọ́ kí wọ́n lè palẹ̀ àwọn ohun tí iná jó mọ́, kí wọ́n sì gbé àwọn igi tó ti jóná àtàwọn ìdọ̀tí míì kúrò.
A ṣètò Ìgbìmọ̀ Tó Ń Ṣètò Ìrànwọ́ Nígbà Àjálù sí àgbègbè náà kí wọ́n lè ṣèrànwọ́ fún àwọn tí àjálù ṣẹlẹ̀ sí.
Bákan náà, méjì lára Ìgbìmọ̀ Ẹ̀ka lórílẹ̀-èdè Portugal dara pọ̀ mọ́ àwọn alábòójútó àyíká àtàwọn alàgbà ìjọ láti máa bẹ àwọn ará wa lọ́kùnrin lóbìnrin wò kí wọ́n lè fún wọn níṣìírí.
Àdúrà wa ni pé kí Jèhófà túbọ̀ jẹ́ ká máa fìfẹ́ ti àwọn ará wa ní Portugal lẹ́yìn, kó sì máa tù wọ́n nínú kí wọ́n lè bọ́ nínú ìṣòro tí iná ọ̀gbálẹ̀-gbáràwé yìí dá sílẹ̀.—Sáàmù 71:21.
Agbẹnusọ fún Àwa Ẹlẹ́rìí Jèhófà:
Kárí Ayé: David A. Semonian, Ọ́fíìsì Agbéròyìnjáde, +1-845-524-3000
Portugal: João Pedro Candeias, +351-214-604-339"
"Déètì: June 28 sí 30, 2019
Ibi Tá A Ti Ṣe É: Pápá ìṣeré Sport Lisboa e Benfica Stadium ní ìlú Lisbon, Pọ́túgà
Èdè: Gẹ̀ẹ́sì, Èdè Potogí (Pọ́túgà), Èdè Adití ti Potogí, Sípáníìṣì
Àwọn Tó Wá: 63,390
Àwọn Tó Ṣèrìbọmi: 451
Àwọn Tó Wá Láti Ìlẹ̀ Òkèèrè: 5,300
Áwọn Ẹ̀ka Ọ́fíísì Tó Wá: Àǹgólà, Ọsirélíà, Brazil, Kánádà, Central America, Gánà, Íńdíà, Mòsáńbíìkì, Sẹ̀nẹ̀gà, Sípéènì, Amẹ́ríkà, Fẹnẹsúélà
Ìrírí: Ọ̀gbẹ́ni Santos wà lára àwọn awakọ̀ tó ń gbé àwọn àlejò tó wá sí àpéjọ. Nígbà tí arákùnrin tó ń ṣètò mọ́tò pè é wá sí àpéjọ náà, Ọ̀gbẹ́ni Santos sọ pé: “Mà á wá.
Látìgbà tí mo ti ń bá yín ṣiṣẹ́, mo ní ìfọ̀kànbalẹ̀ tó kojá àfẹnusọ.
Mi ò mọ bí ìfọ̀kànbalẹ̀ yìí ṣe ń wá, àmọ́ ó dá mi lójú ni pé ẹ̀ ń jẹ́ kí n ní ìfọ̀kànbalẹ̀.
Pápá ìṣeré ni màá wà jálẹ̀ ọjọ́ yẹn, torí náà màá wá.”
Lẹ́yìn tí Ọ̀gbẹ́ni Santos wá sí àpéjọ náà, ó sọ pé òun gbádùn ẹ̀ gan-an.
Abúlé kan níta ìlú Lisbon ló ti wá.
Nígbà tó wá sí àpéjọ, ó pàdé arákùnrin kan tó ń gbé ní tòsí abúlé ẹ̀.
Ọ̀gbẹ́ni Santos gbà pé kí arákùnrin yìí máa wá máa kọ́ òun lẹ́kọ̀ọ́ tí wọ́n bá ti pa dà sílé."
"Ní Thursday, September 19, 2019, ilé ẹjọ́ dá àwọn arákùnrin mẹ́fà láti ìlú Saratov, ní Rọ́ṣíà lẹ́bi wọ́n sì jù sẹ́wọ̀n, kìkì nítorí pé wọ́n jẹ́ Ẹlẹ́rìí Jèhófà.
Adájọ́ Dmitry Larin ti ilé ẹjọ́ Leninsky District Court of Saratov dájọ́ ẹ̀wọ̀n ọdún mẹ́ta àtààbọ̀ fún Arákùnrin Konstantin Bazhenov àti Arákùnrin Aleksey Budenchuk; ó dá ẹ̀wọ̀n ọdún mẹ́ta fún Arákùnrin Feliks Makhammadiyev; ó sì dá ẹ̀wọ̀n ọdún méjì fún Arákùnrin Roman Gridasov, Arákùnrin Gennadiy German, àti Arákùnrin Aleksey Miretskiy.
Yàtọ̀ síyẹn, ilé ẹjọ́ sọ pé lẹ́yìn tí gbogbo wọn bá ṣẹ̀wọ̀n tán, wọn ò ní lé mú ipò iwájú lẹ́nu iṣẹ́ ìjọba èyíkéyìí fún odindi ọdún márùn-ún.
Àwọn arákùnrin náà máa pe ẹjọ́ kòtẹ́milọ́rùn lórí ìdájọ́ yìí.
Ìgbà táwọn aláṣẹ ya wọ ilé méje táwọn Ẹlẹ́rìí ń gbé nílùú Saratov ní June 12, 2018 ni ìgbà àkọ́kọ́ tí wọ́n fi ẹ̀sùn ìwà ọ̀daràn kan àwọn arákùnrin mẹ́fà yìí.
Gbogbo àwọn arákùnrin wọ̀nyí ló ní ìdílé, àmọ́ Arákùnrin Budenchuk ní tiẹ̀ ní ọmọ méjì tí wọ́n ṣì wà ní ilé ìwé.
Arákùnrin Budenchuk, Arákùnrin Bazhenov àti Arákùnrin Makhammadiyev ti lo ohun tó fẹ́rẹ̀ẹ́ tó ọdún kan látìmọ́lé lẹ́yìn tí wọ́n mú wọn kó tó wá di pé wọ́n gbọ́ ẹjọ́ wọn.
Nínú ọ̀rọ̀ tí wọ́n sọ gbẹ̀yìn nílé ẹjọ́, àwọn arákùnrin mẹ́fà wọ̀nyí tọ́ka sí ọ̀pọ̀ àwọn ẹsẹ Bíbélì amóríyá tó sún wọn láti jẹ́ adúróṣinṣin, wọ́n sì fi kún un pé àwọn ò ní ẹ̀tanú èyíkéyìí sí ẹnikẹ́ni lára àwọn tó fẹ̀sùn kan àwọn.
Ní báyìí, ìjọba Rọ́ṣíà, ti dá àwọn arákùnrin wa méje lẹ́bi tí wọ́n sì ti jù wọ́n sẹ́wọ̀n. Ó ju igba ó lé àádọ́ta (250) àwọn arákùnrin àti àwọn arábìnrin wa ní Rọ́ṣíà tí wọ́n ti fẹ̀sùn ìwà ọ̀daràn kàn. Àwọn mọ́kànlélógójì (41) wà ní àtìmọ́lé (ìyẹn àwọn tí wọ́n tì mọ́lé láì tíì gbọ́ ẹjọ́ wọn tàbí àwọn tí wọ́n ti dá lẹ́bi tí wọ́n sì ti jù sẹ́wọ̀n), wọ́n ò sì gbá àwọn mẹ́tàlélógún (23) láyè láti jáde kúrò ní ilé wọn.
A gbàdúrà fún gbogbo àwọn arákùnrin àtàwọn arábìnrin wa olóòótọ́ àti onígboyà ní Rọ́ṣíà pé ‘kí agbára [Jèhófà] ológo fún [wọn] ní gbogbo agbára tí [wọn] nílò, kí [wọn] lè fara dà á ní kíkún pẹ̀lú sùúrù àti ìdùnnú.’​—Kólósè 1:11."
"Bá a ṣe sọ nínú ìròyìn tó jáde ní February 6, 2019, Ilé Ẹjọ́ Agbègbè Zheleznodorozhniy nílùú Oryol ti rán Arákùnrin Dennis Christensen lọ sí ẹ̀wọ̀n ọdún mẹ́fà torí pé ó ń jọ́sìn pẹ̀lú àwa Ẹlẹ́rìí Jèhófà.
Arákùnrin náà ti pe ẹjọ́ kòtẹ́milọ́rùn sí ilé ẹjọ́ gíga.
Ọ̀pọ̀ èèyàn kárí ayé ló kọminú sí ẹjọ́ tí wọ́n dá fún arákùnrin wa yìí. Bí àpẹẹrẹ, Ìgbìmọ̀ Ilẹ̀ Yúróòpù.
Àwùjọ Àwọn Orílẹ̀-Èdè Ilẹ̀ Yúróòpù, Àjọ Orílẹ̀-èdè Amẹ́ríkà Tó Ń Rí sí Òmìnira Ẹ̀sìn Kárí Ayé, Ọ́fíìsì Ọ̀gá Àgbà Àjọ Ìparapọ̀ Orílẹ̀-Èdè Tó Ń Rí sí Ẹ̀tọ́ Ọmọnìyàn àti onírúurú àwọn àjọ míì ló ti kéde pé ohun tí ìjọba Rọ́ṣíà ṣe fún Christensen kò bẹ́tọ̀ọ́ mu rárá àti pé wọ́n kàn ń fìyà jẹ aláìṣẹ̀ ni.
Ọ̀gá Àgbà Àjọ Ìparapọ̀ Orílẹ̀-Èdè Tó Ń Rí sí Ẹ̀tọ́ Ọmọnìyàn ìyẹn Michelle Bachelet sọ pé: “Ẹjọ́ tí wọ́n dá fún Christensen lè dá wàhálà sílẹ̀ torí pé láti ìsinsìnyí lọ, ilé ẹjọ́ lè fẹ̀sùn ọ̀daràn kan àwọn Ẹlẹ́rìí Jèhófà bó tiẹ̀ jẹ́ pé ìjọba sọ pé gbogbo èèyàn lómìnira láti ṣe ẹ̀sìn tó wù wọ́n.”
Ó wá gba ìjọba Rọ́ṣíà níyànjú pé kí wọ́n “ṣàyẹ̀wò òfin tó dá lórí Bí Wọ́n Ṣe Lè Gbéjà Ko Àwọn Agbawèrèmẹ́sìn kí wọ́n lè ṣàtúnṣe sí ìtumọ̀ tí wọ́n fún ọ̀rọ̀ náà ‘agbawèrèmẹ́sìn,’ kí wọ́n sì rí i dájú pé àwọn alákatakítí tó ń hùwà jàgídíjàgan ni wọ́n kà sí agbawèrèmẹ́sìn.”
Bachelet wá sọ ní ìparí ọ̀rọ̀ rẹ̀ pé kí àwọn aláṣẹ “wọ́gi lé ẹ̀sùn tí wọ́n fi kan àwọn tó ń lo òmìnira tí wọ́n ní láti ṣe ẹ̀sìn tó wù wọ́n, àwọn tó lómìnira láti gba ohun tó wù wọ́n gbọ́ àti láti pé jọ ní àlàáfíà, kí wọ́n sì dá àwọn tí wọ́n fi sẹ́wọ̀n sílẹ̀ lómìnira.”
Ọjọ́ méjì lẹ́yìn tí wọ́n dájọ́ Arákùnrin Christensen, àwọn gbajúgbajà mẹ́rin tí wọ́n jẹ́ ajàfẹ́tọ̀ọ́-ọmọnìyàn ní Rọ́ṣíà ṣètò ìpàdé kan pẹ̀lú àwọn oníròyìn nílùú Moscow.
Èrò kún fọ́fọ́ níbi tí wọ́n ti ṣèpàdé náà, àwọn tó sì lé ní ẹgbẹ̀rún mẹ́fà ló ń wo ètò náà bí wọ́n ṣe ń ṣe é látorí íńtánẹ́ẹ̀tì.
Gbogbo àwọn tó sọ̀rọ̀ níbi ìpàdé náà ló gbèjà àwọn Ẹlẹ́rìí Jèhófà, wọ́n sọ pé èèyàn àlàáfíà ni wọ́n, wọn kì í sì í dá wàhálà sílẹ̀ nílùú.
Ìpàdé àwọn oníròyìn nílùú Moscow ní February 8, 2019.
Lára àwọn tó wà níbi ìpàdé náà ni ìyàwó Arákùnrin Christensen, ìyẹn Irina; agbẹjọ́rò rẹ̀, Ọ̀gbẹ́ni Anton Bogdanov; àti aṣojú Àjọ Àwa Ẹlẹ́rìí Jèhófà nílẹ̀ Yúróòpù, ìyẹn Yaroslav Sivulskiy.
Gbogbo wọn ló sọ̀rọ̀ nípa ẹjọ́ àìtọ́ tí wọ́n dá fún Arákùnrin Christensen, wọ́n sì dáhùn ìbéèrè àwọn oníròyìn.
Bó tilẹ̀ jẹ́ pé Arákùnrin Christensen ti fẹ́rẹ̀ẹ́ lo ọdún méjì lẹ́wọ̀n, ó gbẹ́kẹ̀ lé Jèhófà, ó sì ń láyọ̀.
Nínú ọ̀rọ̀ àsọkẹ́yìn tó sọ nílé ẹjọ́ ní ọjọ́ díẹ̀ ṣáájú ọjọ́ tí wọ́n dájọ́ rẹ̀, Arákùnrin Christensen sọ pé: “Bópẹ́ bóyá, ohun tó jẹ́ òótọ́ máa hàn kedere, bó sì ṣe máa rí nínú ẹjọ́ yìí náà nìyẹn.”
Lẹ́yìn tó ka Ìfihàn 21:3-5, ó fi ìdánilójú sọ pé: “Àwọn ọ̀rọ̀ yìí . . . sọ nípa ìgbà tí Ọlọ́run máa ṣèdájọ́ òdodo, tá a sì fún gbogbo èèyàn ní òmìnira tòótọ́.
Ìdájọ́ òdodo ló ń mú kéèyàn ní òmìnira tòótọ́.
Ọlọ́run á sì rí i dájú pé gbogbo èèyàn rí ìdájọ́ òdodo gbà.”
Títí dìgbà tí wọ́n máa bẹ̀rẹ̀ ẹjọ́ kòtẹ́milọ́rùn, Arákùnrin Christensen ṣì máa wà ní àtìmọ́lé nínú ọgbà ẹ̀wọ̀n kan ní ìpínlẹ̀ Oryol, níbi tó ti wà láti nǹkan bí ọdún kan àti oṣù mẹ́jọ.
Àdúrà wa ni pé kí Jèhófà wà pẹ̀lú Arákùnrin Dennis Christensen àti ìyàwó rẹ̀. Kó sì tún dúró ti gbogbo àwọn ará wa lórílẹ̀-èdè Rọ́ṣíà.—1 Pétérù 3:12.
Máà bínú, ètò tó o fi ń wo fídíò kò ṣiṣẹ́.
Wa Fídíò Yìí Jáde
Nígbà tó ku ọjọ́ díẹ̀ tí wọ́n máa dájọ́ arákùnrin náà, ilé iṣẹ́ agbéròyìnjáde kan, ìyẹn RFE/RL ṣe fídíò kan tí wọ́n pè ní Russian Trial Called ‘A Litmus Test For Religious Freedom’ (ìyẹn, Ìgbẹ́jọ́ Kan ní Rọ́ṣíà Tó Máa Jẹ́ ‘Ìlànà Fáwọn Ẹjọ́ Míì Nípa Òmìnira Ẹ̀sìn’)."
"Látìgbà tí Ilé Ẹjọ́ Gíga Jù Lọ ní Rọ́ṣíà ti fòfin de àwa Ẹlẹ́rìí Jèhófà ní April 20, 2017, ni wọ́n ti ń ṣenúnibíni sáwọn arákùnrin àtàwọn arábìnrin wa, tí wọ́n sì ń fi wọ́n sẹ́wọ̀n.
Àtìgbà náà làwọn aláṣẹ ti gbẹ́sẹ̀ lé dúkìá àwa Ẹlẹ́rìí Jèhófà tí iye rẹ̀ tó mọ́kànléláàádóje (131).
Wọ́n sì tún ń sapá láti gbẹ́sẹ̀ lé ọgọ́ta (60) dúkìá míì. Àròpọ̀ gbogbo dúkìá náà ju mílíọ̀nù mẹ́tàdínlọ́gọ́ta (57) owó dọ́là lọ.
Ọ̀kan lára ohun ìní tí wọ́n gbẹ́sẹ̀ lé ni ilé Watch Tower Bible and Tract Society of Pennsylvania tó wà ní Solnechnoye, ìyẹn ẹ̀ka ọ́fíìsì wa ní Rọ́ṣíà tẹ́lẹ̀.
(wo àwòrán tó wà lókè lápá òsì.)
Tá a bá ṣírò iye tí ilé yìí nìkan jẹ́, ó tó ọgbọ̀n (30) mílíọ̀nù owó dọ́là. Dúkìá mẹ́tàlélógójì (43) míì tí wọ́n gbẹ́sẹ̀ lé jẹ́ ti àjọ ilẹ̀ òkèèrè tá a gbé kalẹ̀ lábẹ́ òfin tó wà ní Austria, Denmark, Finland, Netherlands, Nọ́wè, Pọ́túgà, Sípéènì, Sweden, àti Amẹ́ríkà.
Òótọ́ ni pé Ilé Ẹjọ́ Gíga ti fòfin dé àwa Ẹlẹ́rìí Jèhófà, àmọ́ ìyẹn ò fún ìjọba láṣẹ láti gbẹ́sẹ̀ lé àwọn ohun ìní wa tó jẹ́ ti ilẹ̀ òkèèrè, torí náà bí wọ́n ṣe gba àwọn dúkìá náà kò bófin mu.
Àwa Ẹlẹ́rìí Jèhófà ti kọ̀wé sí Ilé Ẹjọ́ Ẹ̀tọ́ Ọmọnìyàn ti Ilẹ̀ Yúróòpù (ECHR) lórí bí ìjọba ṣe gbẹ́sẹ̀ lé ẹ̀ka ọ́fíìsì tá à ń lò ní Rọ́ṣíà tẹ́lẹ̀.
Ìpinnu yòówù kí ECHR ṣe, Jèhófà la fọkàn tán, òun la sì gbára lé.
Àdúrà wa ni pé kí Jèhófà fún àwọn ará wa ní Rọ́ṣíà lókun kí wọ́n lè máa fìgboyà sin Jèhófà “ní ẹ̀mí àti òtítọ́” láìka bí ìjọba ṣe ń dà wọ́n láàmù, tí wọ́n ń mú wọ́n, tí wọ́n sì ń gbẹ́sẹ̀ lé àwọn Gbọ̀ngàn Ìjọba wa.​—Jòhánù 4:23."
"Ní November 5, 2019, ilé ẹjọ́ àgbègbè Oktyabrsky nílùú Tomsk ju Arákùnrin Sergy Klimov sẹ́wọ̀n ọdún mẹ́fà.
Dennis Christensen ni arákùnrin tí wọ́n kọ́kọ́ dá ẹ̀wọ̀n ọlọ́jọ́ gbọọrọ bẹ́ẹ̀ fún.
Àmọ́, ọ̀rọ̀ arákùnrin Klimov tún wá burú sí i torí pé ọ̀pọ̀ nǹkan ni ilé ẹjọ́ ká a lọ́wọ́ kò pé kò ní lè ṣe, èyí ló mú kí ìdájọ́ tiẹ̀ jẹ́ èyí tó le jù lọ tó tíì wáyé látìgbà tí Ilé Ẹjọ́ Gíga Jù Lọ ti fòfin de iṣẹ́ wa lọ́dún 2017.
Wọ́n mú arákùnrin Klimov ní June 3, 2018, nígbà táwọn agbófinró àtàwọn ẹ̀ṣọ́ aláàbò ya wọ ilé àwọn Elẹ́rìí Jèhófà méjì.
Nǹkan bí ọgbọ̀n (30) àwọn ará wa ni wọ́n mú kí wọ́n lè fọ̀rọ̀ wá wọn lẹ́nu wò. Kódà wọ́n mú arábìnrin kan tó jẹ́ ẹni ọdún mẹ́tàlélọ́gọ́rin (83).
Wọ́n dá àwọn tó kù sílẹ̀, àfi arákùnrin Klimov. Wọ́n fẹ̀sùn ọ̀daràn kàn án, ilé ẹjọ́ sì pàṣẹ pé kó ṣì wà látìmọ́lé fún oṣú méjì kí wọ́n tó dá ẹjọ́ rẹ̀.
Ẹ̀ẹ̀méje ọ̀tọ̀ọ̀tọ̀ ni wọ́n sún ẹjọ́ rẹ̀ síwájú, tó túmọ̀ sí pé kó tó bẹ̀rẹ̀ ẹ̀wọ̀n ọdún mẹ́fà tí wọ́n dá fún un, ó ti lo ọdún kan àti oṣù márùn-ún ní àtìmọ́lé láìfojú kan ìyàwó àti ìdílé rẹ̀.
Àwọn agbẹjọ́rò tó ń ṣojú fún arákùnrin Klimov máa pe ẹjọ́ kòtẹ́milọ́rùn lórí ẹjọ́ náà.
Yàtọ̀ síyẹn, ní August 20, 2018, wọ́n gbé ẹjọ́ nípa Klimov àti ilẹ̀ Rọ́ṣíà lọ síwájú Ilé Ẹjọ́ Ẹ̀tọ́ Ọmọnìyàn ti Ilẹ̀ Yúróòpù lórí bí wọ́n ṣe ń sún àsìkò tí wọ́n fẹ́ fi gbọ́ ẹjọ́ rẹ̀ síwájú.
Jálẹ̀ ọdún 2019, iye ilé àwọn ará wa táwọn aláṣẹ orílẹ̀-èdè Rọ́ṣíà lọ fọ́ túbọ̀ pọ̀ sí i, tó fi mọ́ iye àwọn tí wọ́n mú àtàwọn tí wọ́n ń fi sí àtìmọ́lé. Síbẹ̀, ìgbàgbọ́ àwọn ará wa ò mì rárá.
A ń rí ẹ̀rí tó fi hàn pé Jèhófà ń bù kún àwọn ará wa bí wọ́n ṣe gbẹ́kẹ̀ lé e, ìyẹn sì túbọ̀ ń fún wa níṣìírí.—Sáàmù 56:1-5, 9."
"Ní Thursday, May 16, 2019, ìgbẹ́jọ́ Dennis Christensen tẹ̀ síwájú gẹ́gẹ́ bí ilé ẹjọ ṣe sọ tẹ́lẹ̀.
Àwọn agbẹjọ́rò ìjọba àtàwọn tó ń gbèjà Dennis fẹnu ọ̀rọ̀ wọn jóná lọ́kọ̀ọ̀kan, wọ́n sì gba Dennis láyè pé kóun náà fi nǹkan bíi wákàtí kan gbèjà ara rẹ̀.
Àwọn aṣojú láti ilẹ̀ òkèèrè àtàwọn akọ̀ròyìn lóríṣiríṣi wà níbẹ̀, èyí fi hàn pé bó tiẹ̀ ti pọ́dún méjì báyìí tórọ̀ Dennis ti jáde nínú ìròyìn kárí ayé pé wọ́n tì í mọ́lé, àwọn èèyàn káàkiri ayé ṣì fẹ́ mọbi tọ́rọ̀ ẹjọ́ ẹ̀ máa já sí.
Ètò tí wọ́n kọ́kọ́ ṣe ni pé kí wọ́n parí ìgbẹ́jọ́ náà ní Friday, May 17. Àmọ́, àwọn adájọ́ sún ẹjọ́ náà sí aago mẹ́wàá àárọ̀ Thursday, May 23.
Wọ́n á fún Dennis láyè láti gbèjà ara rẹ̀ níwájú àwọn adájọ́, lẹ́yìn ìyẹn, àwọn adájọ́ náà á foríkorí kí wọ́n lè ṣèpinnu.
A ò tíì lè sọ bóyá May 23 yẹn náà ni ilé ẹjọ́ máa sọ ìpinnu rẹ̀ lórí ọ̀rọ̀ yìí àbí wọ́n máa mú ọjọ́ míì tí wọ́n á sọ ìpinnu tí ilé ẹjọ́ bá ṣe.
Bá a ṣe ń rí àwọn ará bíi Dennis Christensen àti Sergey Skrynnikov, tí wọn ò bọkàn jẹ́, tí wọ́n sì ń fi hàn pé àwọn ò ní yẹhùn, àpẹẹrẹ wọn ń fún wa nígboyà.
Ńṣe lohun tá à ń rò nípa àwọn ará wa ní Rọ́síà ṣọ̀kan pẹ̀lú ohun tí àpọ́síltélì Pọ́ọ̀lù sọ nipa àwọn ará Tẹsalóníkà, ó ní: “À ń fi yín yangàn láàárín ìjọ Ọlọ́run nítorí ìfaradà àti ìgbàgbọ́ yín nínú gbogbo inúnibíni àti àwọn ìṣòro tí ẹ̀ ń dojú kọ.”—2 Tẹsalóníkà 1:4."
"Ní March 1, 2019, Ilé Ẹjọ́ Gíga Jù Lọ ti Republic of Kabardino-Balkaria wọ́gi lé ìdájọ́ tí ilé ẹjọ́ kan fi dẹ́bi fún Arákùnrin Arkadya Akopyan.
Ó ti lé lọ́dún kan tí wọ́n ti ń gbọ́ ẹjọ́ rẹ̀, wọ́n fẹ̀sùn èké kàn án pé ó ń pín ìwé “àwọn agbawèrèmẹ́sìn,” ó sì ń ‘rúná sí ìkórìíra ẹ̀sìn.’
Ilé ẹjọ́ kan ti kọ́kọ́ sọ pé kí Arákùnrin Akopyan, ẹni àádọ́rin (70) ọdún lọ ṣe iṣẹ́ àṣesìnlú. Àmọ́ ìdájọ́ tí Ilé Ẹjọ́ Gíga Jù Lọ ṣe yìí wọ́gi lé ìdájọ́ ti tẹ́lẹ̀.
A dúpẹ́ lọ́wọ́ Jèhófà tó mú ká borí nínú ẹjọ́ yìí, a sì bá Arákùnrin Akopyan yọ̀. Àdúrà wa ni pé kí àwọn ará wa máa fi ìṣòtítọ́ fara dà á nìṣó.—2 Tẹsalóníkà 1:4."
Ní December 13, 2019, ilé ẹjọ́ dá ẹjọ́ Arákùnrin Vladimir Alushkin, wọ́n sì rán an lọ sí ẹ̀wọ̀n ọdún mẹ́fà.
Ojú ẹsẹ̀ níbẹ̀ ni wọ́n ti fí ṣẹkẹ́ṣẹkẹ̀ sí i lọ́wọ́ tí wọ́n sì mú un lọ.
Arákùnrin Alushkin máa pe ẹjọ́ kòtẹ́milọ́rùn lórí ìdájọ́ yìí.
"Bá a se ń sọ̀rọ̀ yìí, ó ti tó ọdún mẹ́ta tí wọ́n ti fi Arákùnrin Dennis Christensen sẹ́wọ̀n lọ́nà àìtọ́ lórílẹ̀-èdè Rọ́ṣíà.
Láti May 25, 2017 ni wọ́n ti mú Arákùnrin Christensen, àwọn ọ̀rẹ́ rẹ̀ kan béèrè lọ́wọ́ rẹ̀ nípa bí gbogbo wàhálà tó ń ṣẹlẹ̀ sí i yìí ṣe ń nípa lórí ìgbàgbọ́ rẹ̀.
Ohun kan náà ló ṣì fi ń dáhùn látìgbà yẹn: “Ṣe ni ìgbàgbọ́ mi ń lágbára sí i.”
Arákùnrin Christensen sọ pé: “Ohun tó wà nínú ìwé Jémíìsì orí kìíní ẹsẹ kejì sí ìkẹta ti ṣẹ sí mi lára, èyí tó sọ pé: ‘Ẹ̀yin ará mi, tí oríṣiríṣi àdánwò bá dé bá yín, ẹ ka gbogbo rẹ̀ sí ayọ̀, kí ẹ mọ̀ pé ìgbàgbọ́ yín tí a dán wò ní ti bó ṣe jẹ́ ojúlówó tó máa mú kí ẹ ní ìfaradà.’ ”
Ó wú wa lórí láti mọ̀ pé láìka gbogbo ìṣòro àti ìjákulẹ̀ tí Arákùnrin Christensen ti kojú sí, ńṣe ni ìgbàgbọ́ rẹ̀ ń lágbára sí i, tí inú rẹ̀ sì ń dùn.
Lẹ́yìn tí ìjọba mú Arákùnrin Christensen, kó tó di pé wọ́n mú un lọ sílé ẹjọ́, wọ́n fi sí àtìmọ́lé níbì kan tí kò fi bẹ́ẹ̀ jìnnà sí ilé rẹ̀ ní ìlú Oryol.
Kò pẹ́ sígbà yẹn, wọ́n gbà Irina ìyàwó rẹ̀ láyè láti máa wá bẹ̀ ẹ́ wò.
Ó lé ní ọdún méjì tí wọ́n fi ti Arákùnrin Christensen mọ́lé láì tíì gbọ́ ẹjọ́ rẹ̀.
Ní February 2019, wọ́n dájọ́ ẹ̀wọ̀n ọdún mẹ́fà fún Arákùnrin Christensen. Oṣù mẹ́ta lẹ́yìn náà, ó pe ẹjọ́ kòtẹ́milọ́rùn, àmọ́ wọn ò gbà á láyè.
Lẹ́yìn náà wọ́n gbé e lọ sí ẹ̀wọ̀n míì tó jìnnà tó máìlì mẹ́rìnlélọ́gọ́fà [124] (200km) sí ìlú Oryol tí ìyàwó rẹ̀ wà, èyí sì mú kí ibi táwọn méjèèjì wà túbọ̀ jìnnà síra.
Ó ti fẹ́rẹ̀ẹ́ tó ọdún kan báyìí tí Arákùnrin Christensen ti lẹ́tọ̀ọ́ láti béèrè pé kí wọ́n dá òun sílẹ̀ lẹ́wọ̀n, ó sì ti ṣe bẹ́ẹ̀ lẹ́ẹ̀mẹrin ọ̀tọ̀ọ̀tọ̀, àmọ́ ẹ̀ẹ̀mẹta ni ìjọba ti dá a lóhùn pé kò ṣeé ṣe.
Láìka gbogbo ìjákulẹ̀ yìí sí, Arákùnrin Christensen kò jẹ́ kí ìgbàgbọ́ rẹ̀ nínú Ọlọ́run dín kù.
Arákùnrin Christensen sọ pé: “Èmi àti Irina ìyàwó mi kì í ṣe eni pípé, àmọ́ a ti kọ́ bá a ṣe lè ní ìfaradà, ká má sì jẹ́ kí ayọ̀ wa dín kù nínú ìṣòro.
Ohun tó wá ṣe pàtàkì jù ni pé, a ti túbọ̀ sún mọ́ Bàbá wa àti Ọlọ́run wa, Jèhófà.”
A ò dáwọ́ àdúrà dúró, a sì gbà pé Jèhófà á máa báa lọ láti ṣèrànwọ́ fáwọn arákùnrin àtàwọn arábìnrin wa ní Rọ́ṣíà, kí wọ́n lè máa láyọ̀ bí wọ́n ṣe ń fara da inúnibíni.​—Mátíù 5:​11, 12."
Ní Thursday, May 3, 2018, ní aago mọ́kànlá ààbọ̀ àárọ̀, Ilé Ẹjọ́ Saint Petersburg máa gbọ́ ẹjọ́ kòtẹ́milọ́rùn tá a pè lórí ẹjọ́ tí ilé ẹjọ́ dá fún wa ní December 2017 pé kí àwọn aláṣẹ gbẹ́sẹ̀ lé àwọn ilé tá à ń lò fún ẹ̀ka ọ́fíìsì wa tẹ́lẹ̀ ní Rọ́ṣíà.
Tí wọn ò bá gba ẹjọ́ kòtẹ́milọ́rùn tá a pè wọlé, ìjọba lè gbẹ́sẹ̀ lé gbogbo ilé ńlá mẹ́rìnlá (14) tó wà ní ẹ̀ka ọ́fíìsì náà lójú ẹsẹ̀.
"NEW YORK—Ìgbìmọ̀ Olùdarí àwa Ẹlẹ́rìí Jèhófà ṣètò pé káwọn arákùnrin láti ilẹ̀ mẹ́ta ọ̀tọ̀ọ̀tọ̀ lágbàáyé rìnrìn àjò lọ sílùú Moscow láti ṣojú ẹgbẹ́ ará, kí wọ́n lè jẹ́ káwọn arákùnrin àtàwọn arábìnrin wa ní Rọ́ṣíà mọ̀ pé gbogbo àwa Ẹlẹ́rìí Jèhófà kárí ayé la wà lẹ́yìn wọn.
Nígbà táwọn aṣojú náà dé sí Rọ́ṣíà, tayọ̀tayọ̀ làwọn ará lọ́kùnrin lóbìnrin lọ pàdé wọn, Sàìbéríà lọ́hùn-ún lọ́hùn-ún làwọn kan tiẹ̀ ti rìnrìn àjò wá sí Moscow.
Àwọn aṣojú náà fi dá àwọn ará ní Rọ́ṣíà lójú pé ọ̀rọ̀ wọn ń ká àwọn lára gan-an, àwọn ará kárí ayé ò sì dákẹ́ àdúrà lórí wọn.
Ọ̀kan lára àwọn aṣojú náà sọ pé: “Ìgboyà táwọn ará mi ní Rọ́ṣíà ní wú mi lórí gan-an, torí wọn ò tiẹ̀ fi gbogbo ara retí pé ilé ẹjọ́ máa yí ẹjọ́ tí kò tọ́ tí wọ́n dá pa dà pé àwọn fòfin de iṣẹ́ wọn.”
Bó tiẹ̀ jẹ́ pé ibi pẹlẹbẹ lọ̀bẹ tún fi lélẹ̀ nígbà tí ìgbìmọ̀ ẹlẹ́ni mẹ́ta tún ẹjọ́ náà gbọ́, ṣe làwọn ará ṣera wọn lọ́kan nínú ilé ẹjọ́ náà, wọ́n sì ń fìfẹ́ tòótọ́ hàn síra wọn.
Ìbànújẹ́ dorí wọn kodò nígbà tí wọ́n gbọ́ bí àwọn èèyàn ṣe pẹ̀gàn orúkọ Jèhófà ní gbangba bẹ́ẹ̀, tí wọ́n sì mọ̀ pé àdánwò ìgbàgbọ́ ló délẹ̀ fáwọn Ẹlẹ́rìí Jèhófà ní Rọ́ṣíà yìí.
Síbẹ̀, báwọn ará ṣe fìfẹ́ hàn nílé ẹjọ́ lọ́jọ́ yẹn, tí wọ́n sì hùwà tọ̀wọ̀tọ̀wọ̀ ti tó láti ṣe ẹ̀rí pé irọ́ gbuu ni ẹ̀sùn “agbawèrèmẹ́sìn” tí wọ́n fi kan àwa Ẹlẹ́rìí Jèhófà, táwọn adájọ́ tó tún ẹjọ́ gbọ́ náà fọwọ́ sí.
Mark Sanderson, tó jẹ́ ara Ìgbìmọ̀ Olùdarí, ló ṣáájú àwọn ará tó rìnrìn àjò wá sí Rọ́ṣíà.
Ó fìfẹ́ gbé àwọn ará ró, ó ní kí wọ́n “jẹ́ alágbára àti onígboyà” bí wọ́n ṣe ń retí àwọn ohun tó máa ṣẹlẹ̀.
Nígbà táwọn aṣojú yìí ń kúrò nílé ẹjọ́, ṣe làwọn Ẹlẹ́rìí Jèhófà tó ń gbé ní Rọ́ṣíà ń dì mọ́ wọn, tí wọ́n sì ń sọ pé àwọn mọyì bí wọ́n ṣe wá ti àwọn lẹ́yìn lórí ọ̀rọ̀ pàtàkì tó wà nílẹ̀ yìí.
Àwọn aṣojú náà tún dé àwọn ọ́fíìsì aṣojú ìjọba orílẹ̀-èdè mọ́kànlélógún [21] tó wà nílùú Moscow kí wọ́n lè ṣe ẹ̀kúnrẹ́rẹ́ àlàyé fún wọn nípa bí inúnibíni tí àwọn aláṣẹ Rọ́ṣíà ń ṣe yìí ṣe ń nípa lórí àwọn Ẹlẹ́rìí Jèhófà.
Bí àpẹẹrẹ, àwọn èèyàn ń dáná sun ilé wọn, iṣẹ́ ń bọ́ lọ́wọ́ wọn, wọ́n ń halẹ̀ mọ́ àwọn ọmọ Ẹlẹ́rìí Jèhófà níléèwé, wọ́n sì ń fẹ̀sùn kan àwọn alàgbà ìjọ pé wọ́n ń ṣètò ìpàdé pẹ̀lú àwọn ará wọn, arákùnrin Dennis Christensen wà lára àwọn alàgbà yìí, ó ṣì wà látìmọ́lé di báyìí.
Àwọn aṣojú náà fi fídíò oníṣẹ̀ẹ́jú méjì kan tó ṣàlàyé ọ̀rọ̀ yìí ní ṣókí han àwọn aṣojú ìjọba.
Ìbéèrè tí ọ̀pọ̀ nínú àwọn aláṣẹ náà ń béèrè ni pé, ‘Ó ṣe wá jẹ́ àwọn Ẹlẹ́rìí Jèhófà?’
Àwọn ará wa wá fìyẹn jẹ́rìí lọ́nà tó wọni lọ́kàn, wọ́n ṣàlàyé pé àwọn ará wa kì í dá sí òṣèlú, iṣẹ́ ìwàásù tá à ń ṣe sì ti yí ìgbésí ayé ọ̀pọ̀ nínú àwọn ọmọ ilẹ́ Rọ́ṣíà pa dà sí rere.
Aṣojú kan sọ pé: “Ṣọ́ọ̀ṣì Ọ́tọ́dọ́ọ̀sì fẹ́ kẹ́ ẹ wá ọmọlẹ́yìn tiyín síwájú ni, wọn ò fẹ́ kẹ́ ẹ gba àwọn ọmọ ìjọ wọn.”
Ó lé ní mẹ́wàá nínú àwọn aṣojú ìjọba náà tó rán aṣojú lọ sílé ẹjọ́ kí wọ́n lè wà níbi ìgbẹ́jọ́ náà, wọn ò sì kúrò níbẹ̀ jálẹ̀ wákàtí mẹ́jọ tí ilé ẹjọ́ fi gbọ́ ẹjọ́ náà.
Nígbà tí àwọn arákùnrin káàkiri ayé tó wá sí Rọ́ṣíà fi máa kúrò níbẹ̀, ìgbàgbọ́ wọn ti lágbára sí i, bí àwọn ará wọn ní Rọ́ṣíà ṣe pinnu pé àwọn ò ní fi Jèhófà sílẹ̀ gbé wọn ró gan-an, inú wọn sì dùn pé àwọn láǹfààní láti jẹ́rìí fáwọn aláṣẹ lọ́nà tó gbéṣẹ́.
Agbẹnusọ fún Àwa Ẹlẹ́rìí Jèhófà:
Ọ́fíìsì Agbéròyìnjáde
Méjì lára àwọn arákùnrin tí wọn ò jẹ́ kí wọ́n jáde nílé rèé pẹ̀lú àwọn agbẹjọ́rò wọn. Láti ọwọ́ òsì sí ọ̀tún: agbẹjọ́rò Vitaly Svintsov, Vladimir Kochnev, Aleksandr Suvorov àti agbẹjọ́rò Egiazar Chernikov."
Ní August 3, 2018, Adájọ́ Inna Yangubayeva tó wà ní Ilé Ẹjọ́ Agbègbè Leninsky ti ìlú Orenburg, lórílẹ̀-èdè Rọ́síà, dájọ́ pé kí wọ́n má jẹ́ kí Arákùnrin Vladimir Kochnev àti Arákùnrin Aleksandr Suvorov jáde nílé wọn mọ́, bẹ́ẹ̀ ọ̀kọ̀ọ̀kan àwọn arákùnrin yìí ti lo ọjọ́ méjìdínlọ́gọ́rin (78) lẹ́wọ̀n.
Lọ́jọ́ kan náà, Ilé Ẹjọ́ Agbègbè Magadan ní kí wọ́n má jẹ́ kí Arákùnrin Konstantin Petrov jáde nílé mọ́, bẹ́ẹ̀ òun náà ti lo ọjọ́ mẹ́rìnlélọ́gọ́ta (64) látìmọ́lé.
A dúpẹ́ pé àwọn ará wa mẹ́tẹ̀ẹ̀ta yìí ò sí lẹ́wọ̀n mọ́, àmọ́ ẹjọ́ wọn ò tíì parí, tí wọ́n bá sì dá wọn lẹ́bi, wọ́n lè rán wọn lọ́ sẹ́wọ̀n nǹkan bí ọdún mẹ́wàá.
Títi di August 16, àwọn ará wa mẹ́sàn-án ni wọn ò jẹ́ kí wọ́n jáde nílé mọ́, àwọn mẹ́ẹ̀ẹ́dọ́gbọ̀n (25) sì wà lẹ́wọ̀n káàkiri ilẹ̀ Rọ́ṣíà.
Àwọn ọgbọ̀n (30) míì tún wà lára àwọn ará wa lọ́kùnrin àti lóbìnrin tí wọ́n ti mú kí wọ́n tọwọ́ bọ̀wé pé wọn ò gbọ́dọ̀ jáde nílé wọn láìgba àyè lọ́dọ̀ àwọn aláṣẹ ìlú.
"Ẹ jẹ́ ká máa gbàdúrà fún àwọn ará wa tó ń kojú wàhálà tó bani lẹ́rù yìí nílẹ̀ Rọ́ṣíà.​—2 Kọ́ríńtì 1:11."""
"Ní May 23, 2019, àwọn adájọ́ mẹ́ta ní Ilé Ẹjọ́ Agbègbè Oryol dá Dennis Christensen lẹ́bi nínú ẹjọ́ kòtẹ́milọ́rùn tó pè torí bí ilé ẹjọ́ kan ṣe rán an lẹ́wọ̀n ọdún mẹ́fà. Nǹkan bí ọgọ́rin (80) àwọn ará ló wá síbi ìgbẹ́jọ́ náà.
Àwọn aṣojú láti orílẹ̀-èdè Ọsirélíà àti Denmark náà wà níbẹ̀.
Àwọn ilé iṣé tó ń gbéròyìn jáde kárí ayé sì ti ń sọ̀rọ̀ nípa ìdájọ́ tí ilé ẹjọ́ ṣe yìí.
Oṣù February ni ilé ẹjọ́ rán Arákùnrin Christensen lẹ́wọ̀n.
Lááàrín oṣù mẹ́ta tó kọjá yìí, ìgbà márùndínlọ́gọ́fà (115) làwọn aláṣẹ ya wọ ilé àwọn Ẹlẹ́rìí Jèhófà, kódà iye ìgbà tí wọ́n fẹ̀sùn ìwà ọ̀daràn kàn wọ́n ti fi ìlọ́po mẹ́ta pọ̀ sí i tá a bá fi wé ti oṣù mẹ́ta tó ṣáájú.
À ń rántí Arákùnrin Christensen àtàwọn ará wa ní Rọ́ṣíà nínú àdúrà.
Ó dá wa lójú pé Jèhófà “wà nítòsí gbogbo àwọn tó ń ké pè é,” kò sì ní yéé ran àwọn ará wa lọ́wọ́ kí wọ́n lè dúró láìyẹhùn lójú inúnibíní—Sáàmù 145:18."
"Arákùnrin Boris Burylov, ẹni ọdún méjìdínlọ́gọ́rin (78) tí wọ́n fẹ̀sùn kàn pé ó jẹ́ agbawèrèmẹ́sìn ní ìlú Perm’
Ní May 2019, àwọn aláṣẹ agbègbè Arkhangel’sk àti Volgograd lórílẹ̀-èdè Rọ́ṣíà fẹ̀sùn ìwà ọ̀daràn kan arábìnrin wa méjì tó jẹ́ àgbàlagbà.
Ìwádìí ń lọ lọ́wọ́ lórí Arábìnrin Kaleriya Mamykina, ẹni ọdún méjìdínlọ́gọ́rin (78) tí àwòrán rẹ̀ wà lókè àti Arábìnrin Valentina Makhmadgaeva, ẹni ọdún mọ́kànléláàádọ́rin (71), wọ́n fẹ̀sùn kàn wọ́n pé wọ́n jẹ́ agbawèrèmẹ́sìn torí pé Ẹlẹ́rìí Jèhófà ni wọ́n.
Ní April 2018, àwọn aláṣẹ ìlú Vladivostok fẹ̀sùn ìwà ọ̀daràn kan Arábìnrin Yelena Zayshchukbrought, ẹni ọdún mẹ́rìnlélọ́gọ́rin (84) pẹ̀lú àwọn mẹ́rin míì tó jẹ́ Ẹlẹ́rìí Jèhófà.
Ní báyìí mẹ́wàá nínú àwọn ará wa lọ́kùnrin àti lóbìnrin tí wọ́n ti lé lẹ́ni àádọ́rin (70) ọdún ló ń jẹ́jọ́ lórí ẹ̀sùn ìwà ọ̀daràn torí pé wọ́n ń jọ́sìn Ọlọ́run láìda ẹnikẹ́ni láàmú lórílẹ̀-èdè Rọ́síà.
Bó tiẹ̀ jẹ́ pé kò sí ìkankan nínú wọn látìmọ́lé, kò rọrùn fún wọn rárá torí ara tó ti ń dara àgbà.
Tí ìwádìí náà bá ṣì ń bá a lọ, tí ilé ẹjọ́ sì dá wọn lẹ́bi, wọ́n lè bu owó ìtánràn lù wọ́n tàbí kí wọ́n rán wọn lẹ́wọ̀n.
Títí di June 17, 2019, iye àwọn ará wa tí wọ́n ń jẹ́jọ́ lórí ẹ̀sùn èké ìwà ọdaràn tí wọ́n fi kàn wọ́n jẹ́ igba ó lé mẹ́ẹ̀ẹ́dógún (215).
Ńṣe ni iye wọn sì ń pọ̀ sí i.
Ẹ jẹ́ ká máa rántí gbogbo àwọn ará wa ní Rọ́síà nínú àdúrà wa, ká sì máa dárúkọ wọn ní pàtó.
Ó dá wa lójú pé Jèhófà á máa mú kí ‘agbára rẹ̀ ológo fún wọn ní gbogbo agbára tí wọ́n nílò, kí wọ́n lè fara dà á ní kíkún pẹ̀lú sùúrù àti ìdùnnú.’​—Kólósè 1:11."
"Ní March 25, 2020, Ilé Ẹjọ́ Kòtẹ́milọ́rùn tó wà nílùú Penza fagi lé ìpinnu tí ilé ẹjọ́ kan ṣe níbi ìgbẹ́jọ́ Arákùnrin Vladimir Alushkin, Vladimir Kulyasov, Andrey Magliv àti Arákùnrin Denis Timoshin pa pọ̀ pẹ̀lú Arábìnrin Tatyana Alushkina àti Galiya Olkhova.
Torí náà, Ilé Ẹjọ́ Kòtẹ́milọ́rùn dá ẹjọ́ náà pa dà sí ilé ẹjọ́ àkọ́kọ́ pé kí wọ́n tún ẹjọ́ náà gbọ́.
Bọ́rọ̀ ṣe rí yìí, ó ṣe kedere pé lọ́jọ́ mélòó kan sí i, wọ́n máa dá Arákùnrin Alushkin sílẹ̀ lẹ́wọ̀n.
Àmọ́ títí dìgbà tí wọ́n máa tún ẹjọ́ náà gbọ́, òun àtàwọn yòókù rẹ̀ kò ní lè rìnrìn-àjò, wọ́n sì tún máa fi àwọn ẹ̀tọ́ kan dù wọ́n."
"Ilé Ẹjọ́ Agbègbè Zheleznodorozhniy tó wà ní ìlú Oryol ti parí gbígbọ́ ẹjọ́ Dennis Christensen, adájọ́ sì máa sọ ìdájọ́ rẹ̀ ní Wednesday, February 6, 2019.
Àtìgbà tí wọ́n ti mú Arákùnrin Christensen ní May 25, 2017 ló ti wà látìmọ́lé. Wọ́n bẹ̀rẹ̀ sí í gbọ́ ẹjọ́ ẹ̀sùn ìwà ọ̀daràn tí wọ́n fi kàn án ní February 19, 2018.
Tí ilé ẹjọ́ bá dá Arákùnrin Christensen lẹ́bi, àwọn tó fẹ̀sùn kàn án ti sọ pé kí wọ́n rán an lẹ́wọ̀n ọdún mẹ́fà àtààbọ̀.
Bó tiẹ̀ jẹ́ pé ó ti lé ní ogún (20) oṣù tí Arákùnrin Christensen ti wà lẹ́wọ̀n, kò bọkàn jẹ́, ó gbẹ́kẹ̀ lé Jèhófà ó sì mọyì àdúrà táwọn ará kárí ayé ń gbà fún òun.—2 Tẹsalóníkà 3:1, 2."
"Ní February 6, 2019, ilé ẹjọ́ kan lórílẹ̀-èdè Rọ́ṣíà dá Dennis Christensen lẹ́bi pé ó “ń ṣètò iṣẹ́ àjọ àwọn agbawèrèmẹ́sìn.”
Wọ́n sì rán an lẹ́wọ̀n ọdún mẹ́fà.
Àwọn oníròyìn láwọn ilẹ̀ míì ti sọ̀rọ̀ nípa ẹjọ́ tí kò tọ́ yìí, a sì máa pe ẹjọ́ kòtẹ́milọ́rùn.
A ò ní dákẹ́ àdúrà fún Dennis Christensen àti ìyàwó rẹ̀, Irina pẹ̀lú ọ̀pọ̀ àwọn ará wa ní Rọ́ṣíà bí wọ́n ṣe ‘fara balẹ̀, tí wọ́n sì gbẹ́kẹ̀ lé’ Jèhófà.—Àìsáyà 30:15."
Ní June 23, 2020, Ilé Ẹjọ́ Agbègbè Lgovskiy tó wà ní Kursk dá Arákùnrin Dennis Christensen sílẹ̀ kí ọdún tí wọ́n ní kó lò lẹ́wọ̀n tó pé.
Àwọn tó pe ẹjọ́ náà ní kí adájọ́ gba owó ìtanràn lọ́wọ́ Arákùnrin Christensen dípò ọdún tó kù tó yẹ kó lò lẹ́wọ̀n, adájọ́ wá ní kó san nǹkan bíi mílíọ̀nù méjì ààbọ̀ náírà (ìyẹn $5,759 owó Dọ́là).
Ẹ̀yìn ọjọ́ mẹ́wàá tí wọ́n kéde ìdájọ́ yìí ni Arákùnrin Christensen tó máa làǹfààní láti lọ bá ìyàwó rẹ̀, àwọn mọ̀lẹ́bí àtàwọn míì tí wọ́n jọ ń sin Jèhófà.
A dúpẹ́ lọ́wọ́ Jèhófà fún àṣeyọrí yìí!
Ní February 18, 2020, Ilé Ẹjọ́ Zheleznodorozhniy District Court tó wà ní ìlú Khabarovsk lórílẹ̀-èdè Rọ́ṣíà kéde pé Arákùnrin Yevgeniy Aksenov jẹ̀bi, wọ́n sì dájọ́ ẹ̀wọ̀n ọdún méjì fún un.
Lóòótọ́ kò ní lọ sẹ́wọ̀n báyìí, àmọ́ ṣe ni wọ́n á máa ṣọ́ ọ lọ́wọ́-lẹ́sẹ̀. Tí Arákùnrin Aksenov bá kó kúrò níbi tó ń gbé, tàbí tó jẹ̀bi ẹ̀sùn ìwà ọ̀daràn èyíkéyìí míì láàárín ọdún méjì náà, wọ́n máa fi sẹ́wọ̀n.
Fún oṣù mẹ́fà àkọ́kọ́, wọ́n á máa ṣọ́ ọ bóyá ó ń tẹ̀ lé ìtọ́ni ilé-ẹjọ́, á sì máa fara han àwọn aláṣẹ agbègbè náà lóṣooṣù.
Ní àfikún, ní àkókò tó fi wà lábẹ́ ìkálọ́wọ́kò náà, kò gbọdọ̀ jáde kúrò ní Khabarovsk tó jẹ́ ìlú ẹ̀, kò sì gbọdọ̀ jáde kúrò nínú ilé ẹ̀ lálẹ́. Arákùnrin Aksenov máa pe ẹjọ́ kòtẹ́milọ́rùn lórí ìdájọ́ yìí.
"Ọjọ́ mẹ́sàn-án péré lẹ́yìn tí wọ́n dá Arákùnrin Dennis Christensen lẹ́bi nílé ẹjọ́ kan ní Rọ́ṣíà, ó kéré tán àwọn méje míì lára àwọn Ẹlẹ́rìí Jèhófà ni àwọn agbófinró nílùú Surgut lágbègbè Siberia ti mú, tí wọ́n sì dá lóró.
Bí wọ́n ṣe ń dá àwọn ará wa yìí lóró, bẹ́ẹ̀ làwọn agbófinró yẹn ń halẹ̀ mọ́ wọn pé kí wọ́n sọ ibi tí wọ́n ti ń pàdé pọ̀ àti orúkọ àwọn Ẹlẹ́rìí míì.
Ìṣẹ̀lẹ̀ yìí wáyé ní àárọ̀ February 15, 2019 nígbà táwọn agbófinró fọ́n sígboro, tí wọ́n sì ń mú àwọn ará wa nílé wọn.
Wọ́n kó wọn lọ sí ọ́fíìsì Ìgbìmọ̀ Tó Ń Ṣèwádìí, wọ́n sì bẹ̀rẹ̀ sí í fọ̀rọ̀ wá wọn lẹ́nu wò.
Nígbà táwọn agbófinró náà rí i pé amòfin kan ṣoṣo tó wà níbẹ̀ ti lọ, ṣe ni wọ́n bẹ̀rẹ̀ sí dá àwọn ará wa lóró, tí wọ́n sì ṣe wọ́n bí ọṣẹ ṣe ń ṣojú.
Àwọn ará sọ ohun tí wọ́n ṣe fún wọn, wọ́n ní: àwọn agbófinró fi ọ̀rá bo ojú àwọn, wọ́n sì fi téèpù so ó pa, lẹ́yìn náà wọ́n so ọwọ́ wọn sẹ́yìn, wọ́n sì lù wọ́n nílùkulù.
Nígbà tó yá, wọ́n bọ́ wọn sí ìhòòhò, wọ́n yí omi dà sí wọn lára, wọ́n wá fi iná mànàmáná gbé wọn.
Ó dunni gan-an pé nǹkan bíi wákàtí méjì gbáko ni wọ́n fi hùwà ìkà burúkú yìí sáwọn ará wa.
Ó kéré tán, mẹ́ta nínú àwọn Ẹlẹ́rìí yìí ṣì wà lẹ́wọ̀n.
Àwọn tí wọ́n dá sílẹ̀ ti lọ sílé ìwòsàn torí pé wọ́n ṣèṣe gan-an. Wọ́n sì ti gbé ọ̀rọ̀ náà lọ sọ́dọ̀ àwọn àjọ tó ń jà fún ẹ̀tọ́ ọmọnìyàn.
Ó yani lẹ́nu pé lẹ́yìn táwọn agbófinró ti fojú àwọn ará wa rí màbo, wọ́n tún wá fẹ̀sùn ọ̀daràn kan àwọn Ẹlẹ́rìí mọ́kàndínlógún (19), wọ́n sọ pé wọ́n ń “dara pọ̀ mọ́ àwọn agbawèrèmẹ́sìn,” àti pé wọ́n ń “ṣagbátẹrù àjọ tó ń ṣètìlẹ́yìn fáwọn agbawèrèmẹ́sìn.”
Lábẹ́ òfin ìjọba Rọ́ṣíà, wọ́n máa ń fìyà jẹ ẹni tó bá lo àṣẹ tó ní láti dá ẹlòmíì lóró.
Yàtọ̀ síyẹn, ó yẹ kí ìjọba orílẹ̀-èdè Rọ́ṣíà tẹ̀ lé òfin tí àwọn àjọ àgbáyé gbé kalẹ̀ tó sọ pé kò yẹ kí ẹnikẹ́ni máa fi àṣẹ ìjọba dáni lóró.
Torí náà, a máa lo gbogbo ẹ̀tọ́ tá a ní láti gbé ọ̀rọ̀ yìí lọ sí ilé ẹjọ́ ní Rọ́ṣíà, àá sì gbé e lọ sáwọn àjọ àgbáyé míì ká lè rí i dájú pé wọ́n dá ẹjọ́ àwọn ará wa bó ṣe tọ́.
Lékè gbogbo ẹ̀, a mọ̀ pé Jèhófà ń rí bí wọ́n ṣe ń fojú pọ́n àwọn ará wa ní Rọ́ṣíà, ó sì máa gbé ìgbésẹ̀ gẹ́gẹ́ bí ‘olùrànlọ́wọ́ àti olùgbàlà wọn.’​—Sáàmù 70:5."
"Ní Thursday, May 3, 2018, Ilé Ẹjọ́ Saint Petersburg fọwọ́ sí ìpinnu tí ilé ẹjọ́ ti kọ́kọ́ ṣe ní December 2017, wọ́n ní ẹsẹ̀kẹsẹ̀ ni kí ìjọba orílẹ̀-èdè Rọ́ṣíà gbẹ́sẹ̀ lé ẹ̀ka ọ́fíìsì wa àtijọ́ tó wà ní Solnechnoye lórílẹ̀-èdè Rọ́ṣíà.
Bó tiẹ̀ jẹ́ pé a ò lè dá ìjọba orílẹ̀-èdè Rọ́ṣíà dúró kí wọ́n má gba ẹ̀ka ọ́fíìsì wa, Ilé Ẹjọ́ Ẹ̀tọ́ Ọmọnìyàn ti Ilẹ̀ Yúróòpù ti gbọ́ sí ẹjọ́ tí ilé ẹjọ́ dá fún wa lónìí, wọ́n sì ti ń gbé e yẹ̀ wò.
Ilé Ẹjọ́ Ẹ̀tọ́ Ọmọnìyàn ti kàn sí ìjọba Rọ́ṣíà pé ẹjọ́ wa wà lára ẹjọ́ táwọn kọ́kọ́ ń fún láfiyèsí.
Ojú Jèhófà, Ọlọ́run tó máa ń dá gbogbo ẹjọ́ bó ṣe tọ́ là ń wò báyìí. A retí pé tó bá tó àkókò lójú ẹ̀, ó máa yanjú ọ̀rọ̀ náà.​—Aísáyà 30:18."
"Àwùjọ àwọn onímọ̀ ìjìnlẹ̀ kan tó ń rí sí ẹ̀tọ́ ọmọnìyàn lábẹ́ Àjọ Ìṣọ̀kan Àgbáyé kọ ìwé kan tó ní ojú ìwé mẹ́ẹ̀ẹ́dógún (15). Nínú ìwé náà, wọ́n sọ pé ìjọba Rọ́ṣíà ti tẹ òfin àwọn orílẹ̀-èdè lójú, bí wọ́n ṣe fi àwọn Ẹlẹ́rìí Jèhófà méjìdínlógún (18) sátìmọ́lé láwọn ìlú ọ̀tọ̀ọ̀tọ̀, láti May 2018 sí July 2019. Wọ́n ní kí àwọn aláṣẹ orílẹ̀-èdè Rọ́síà dá àwọn ará wa tó wà látìmọ́lé sílẹ̀ lẹ́sẹ̀kẹsẹ̀, kí wọ́n sì máa lọ lómìnira.
Àwọn onímọ̀ ìjìnlẹ̀ náà gbé ìpinnu tí wọ́n kọ́kọ́ ṣe jáde ní May 15, 2020. Wọ́n máa tó gbé ibi tí wọ́n parí ọ̀rọ̀ náà sí jáde lórí ìkànnì Àjọ Ìṣọ̀kan Àgbáyé.
Ìgbà kẹta rèé lẹ́nu àìpẹ́ yìí, tí àwùjọ àwọn onímọ̀ ìjìnlẹ̀ tó ń rí sí ọ̀rọ̀ àwọn tí wọ́n fi sátìmọ́lé lọ́nà àìtọ́ máa gbèjà àwọn ará wa.
Nínú ìwé tí wọ́n kọ kẹ́yìn, wọ́n bẹnu àtẹ́ lu oríṣiríṣi ìwà ìkà tí ìjọba orílẹ̀-èdè Rọ́ṣíà ń hù sáwọn ará wa lọ́kùnrin àti lóbìnrin.
Àwùjọ náà sọ pé, kò sí ẹ̀rí tó lẹ́sẹ̀ nílẹ̀ tó fi yẹ káwọn ọlọ́pàá orílẹ̀-èdè Rọ́ṣíà fipá mú àwọn Ẹlẹ́rìí Jèhófà.
Wọ́n tún sọ pé, “kò sí ìkankan nínú [àwọn Ẹlẹ́rìí Jèhófà] tó yẹ kí wọ́n fi sátìmọ́lé, kò sì yẹ kí wọ́n gbé ìkankan nínú wọn lọ sí ilé ẹjọ́.”
Àwùjọ náà bẹnu àtẹ́ lu ẹ̀sùn tí wọ́n fi ń kan àwọn Ẹlẹ́rìí Jèhófà pé wọ́n jẹ́ agbawèrèmẹ́sìn.
Wọ́n ní ohun táwọn ará wa lọ́kùnrin àti lóbìnrin ń ṣe ò ju pé “wọ́n ń lo ẹ̀tọ́ tí wọ́n ní láti máa jọ́sìn láìdí ẹnikẹ́ni lọ́wọ́.”
Nínú ìwé tí wọ́n kọ, wọ́n tún jẹ́ kó ṣe kedere pé bí wọ́n ṣe ń gbọ́ ẹjọ́ àwọn ará wa nílé ẹjọ̀ kò tọ́ rárá.
Bí apẹẹrẹ, inú àhámọ́ ni wọ́n fi àwọn arábìnrin wa méjì sí nílé ẹjọ́ nígbà tí wọ́n ń gbọ́ ẹjọ́ wọn.
Nínú àlàyé táwọn onímọ̀ ìjìnlẹ̀ náà ṣe, wọ́n ní òfin àwọn orílẹ̀-èdè jẹ́ ká mọ̀ pé ẹ̀tọ́ ẹnì kọ̀ọ̀kan ni “pé kí wọ́n fojú aláìmọwọ́mẹsẹ̀ wò ó, títí wọ́n á fi rí i dájú pé onítọ̀hún jẹ̀bi ẹsùn tí wọ́n fi kàn án.”
Torí náà, kò yẹ kí wọ́n fi “ṣẹkẹ́ṣẹkẹ̀ sí àwọn arábìnrin wa lọ́wọ́ tàbí kí wọ́n fi wọ́n sínú àhámọ́ nígbà tí wọ́n ń gbọ́ ẹjọ́ wọn, torí ìyẹn á jẹ́ káwọn èèyàn máa fi ojú ọ̀daràn paraku wò wọ́n.”
Àwùjọ náà tún sọ pé kí ìjọba orílẹ̀-èdè Rọ́ṣíà wọ́gi lé àkọ́sílẹ̀ ẹ̀sùn ọ̀daràn tí wọ́n fi kan àwọn Ẹlẹ́rìí Jèhófà méjìdínlógún (18) náà.
Kí wọ́n sì tún san owó gbà-má-bínú fún wọn, bí òfin àwọn orílẹ̀-èdè ṣe sọ. Yàtọ̀ síyẹn, wọ́n ní kí ìjọba orílẹ̀-èdè náà “ṣèwádìí fínnífínní nípa ohun tó mú káwọn aláṣẹ hùwà àìtọ́ yìí,” kí wọ́n sì “gbé ìgbẹ́sẹ̀ lórí àwọn tó ń fi ẹ̀tọ́ [àwọn Ẹlẹ́rìí Jèhófà] dù wọ́n.”
Wọ́n tún sọ nínú ìwé náà pé àwọn Ẹlẹ́rìí Jèhófà méjìdínlógún (18) tí wọ́n mú wulẹ̀ jẹ́ díẹ̀ “lára ọ̀pọ̀ àwọn Ẹlẹ́rìí Jèhófà tó wà ní Rọ́ṣíà, tí wọ́n fi sátìmọ́lé, tí wọ́n sì fi ẹ̀sùn kàn pé wọ́n jẹ́ ọ̀daràn, torí pé wọ́n ń lo ẹ̀tọ́ tí wọ́n ní láti máa ṣe ìsìn wọn.”
Kẹ́ ẹ sì máa wò ó o, orílẹ̀-èdè Rọ́ṣíà wà lára àwọn tó fọwọ́ sí ẹ̀tọ́ yìí nínú àdéhùn táwọn orílẹ̀-èdè ṣe.
Bó tiẹ̀ jẹ́ pé ẹjọ́ àwọn ará wa méjìdínlógún (18) ni ìwé tí àwùjọ náà kọ dá lé, wọ́n tún jẹ́ kó ṣe kedere pé ohun tí wọ́n sọ “kan gbogbo àwọn míì tó wà nírú ipò yẹn.”
Kò sí ẹ̀rí tó dájú pé ìwé táwọn onímọ̀ ìjìnlẹ̀ yìí kọ máa mú kí àwọn aláṣẹ orílẹ̀-èdè Rọ́ṣíà dá àwọn ará wa sílẹ̀, àmọ́ a gbà pé ó ṣeé ṣe kó mú kí ọ̀rọ̀ náà yanjú déwọ̀n àyè kan.
À ń retí ohun táwọn aláṣẹ orílẹ̀-èdè Rọ́ṣíà máa ṣe sọ́rọ̀ yìí.
Ní báyìí ná, a mọ̀ pé àwọn arákùnrin àtàwọn arábìnrin wa tó wà ní Rọ́ṣíà á máa fara da inúnibíni tí wọ́n ń ṣe sí wọn, a sì mọ̀ pé Jèhófà, Baba wa onífẹ̀ẹ́, á jẹ́ kí wọ́n máa láyọ̀, kí ọkàn wọn sì balẹ̀, torí pé òun ni wọ́n gbẹ́kẹ̀ lé.​—Róòmù 15:13."
Lọ́jọ́ Tuesday, June 9, 2020, ilé ẹjọ́ Pskov City Court dẹ́bi fún Arákùnrin Gennady Shpakovskiy tó jẹ́ ẹni ọdún mọ́kànlélọ́gọ́ta (61), wọ́n sì dájọ́ ẹ̀wọ̀n ọdún mẹ́fà àtààbọ̀ fún un.
Ẹsẹ̀kẹsẹ̀ tí wọ́n dájọ́ fún un tán ni wọ́n mú un lọ sínú ẹ̀wọ̀n.
Iye ọdún tí wọ́n dá fún arákùnrin wa yìí ló ṣì pọ̀ jù láti ọdún 2017 tí Ilé Ẹjọ́ Gíga Jù Lọ ní Rọ́ṣíà ti ṣòfin pé ọ̀daràn ni ẹnikẹ́ni tí wọ́n bá rí tó ń ṣe ẹ̀sìn Ẹlẹ́rìí Jèhófà.
Arákùnrin Shpakovskiy máa pe ẹjọ́ kòtẹ́milọ́rùn lórí ẹjọ́ tí wọ́n dá fún un.
"Ní Thursday, December 27, Adájọ́ Oleg Golovashko ti Ilé Ẹjọ́ Agbègbè Prohladniy ní Rọ́ṣíà sọ ìpinnu ilé ẹjọ́ lórí ẹ̀sùn tí wọ́n fi kan Arákùnrin Arkadya Akopyan.
Ilé ẹjọ́ sọ pé Arákùnrin Akopyan, tó jẹ́ ẹni àádọ́rin (70) ọdún tó ti fẹ̀yìn tì nídìí iṣẹ́ télọ̀, máa fi ọgọ́fà (120) wákàtí ṣe iṣẹ́ ìlú torí ẹ̀sùn èké tí wọ́n fi kàn án pé ó rán àwọn tí kì í ṣe Ẹlẹ́rìí Jèhófà pé kí wọ́n lọ máa pín ìwé àwọn agbawèrèmẹ́sìn kiri.
Bó tiẹ̀ jẹ́ pé wọn ò rán Arákùnrin Akopyan lẹ́wọ̀n, ẹjọ́ tí wọ́n dá fún un yìí ta ko ẹ̀tọ́ ọmọnìyàn.
Nítorí náà, a máa pe ẹjọ́ kòtẹ́milọ́rùn sí ilé gíga.
Ní ọ̀sẹ̀ díẹ̀ sí i, à ń retí ìdájọ́ tí ilé ẹjọ́ máa ṣe lórí ẹjọ́ Arákùnrin Dennis Christensen.
Àdúrà wa ni pé kí Jèhófà máa ti àwọn ará wa ní Rọ́ṣíà lẹ́yìn, kó sì máa tù wọ́n nínú torí bí wọ́n ṣe ń fi wọ́n sẹ́wọ̀n nítorí ohun tí wọ́n gbà gbọ́.—2 Tẹsalóníkà 2:16, 17."
"A retí pé kí ilé ẹjọ́ Vilyuchinsk City Court sọ ìdájọ́ wọn lórí ọ̀rọ̀ Arákùnrin Mikhail Popov àti ìyàwó rẹ̀ Arábìnrin Yelena Popova lọ́jọ́ Thursday, February 13, 2020.
Wọ́n mú tọkọtaya yìí ní July 30, 2018 ní ìlú Kamchatka, àmọ́ wọ́n fi wọ́n sílẹ̀ ní August 9, 2018. Ẹ̀sùn tí wọ́n fi kàn wọ́n ni pé wọ́n ń lọ́wọ́ sí “iṣẹ́ agbawèrèmẹ́sìn.”
Mikhail àti Yelena gbára lé Jèhófà pátápátá bí wọ́n ṣe ń fara da ipò tó le koko yìí. Ó dá wa lójú pé Jèhófà á máa bá a lọ láti jẹ́ ‘ibi ààbò àti okun’fún wọn.—Sáàmù 46:1."
"A láyọ̀ láti sọ fún yín pé wọ́n ti dá Arákùnrin Vladimir Alushkin sílẹ̀ lẹ́wọ̀n ní March 30, 2020, inú òun àti ìyàwó ẹ̀ sì dùn gan-an pé àwọn tún jọ wà pa pọ̀.
Tẹ́ ò bá gbàgbé, a gbé ìròyìn kan jáde ní March 25 nípa bí Ilé Ẹjọ́ Kòtẹ́milọ́rùn tó wà nílùú Penza ṣe fagi lé ìpinnu tí ilé ẹjọ́ àkọ́kọ́ ṣe, tí wọ́n sì ní kí wọ́n tún ẹjọ́ náà gbọ́.
Ìpinnu ilé ẹjọ́ kejì jẹ́ kó ṣe kedere pé Arákùnrin Vladimir Alushkin, Vladimir Kulyasov, Andrey Magliv àti Arákùnrin Denis Timoshin kò jẹ̀bi ẹ̀sùn tí wọ́n fi kàn wọ́n, bákan náà lọ̀rọ̀ sì rí pẹ̀lú Arábìnrin Tatyana Alushkina àti Galiya Olkhova.
Nípa bẹ́ẹ̀, Ilé Ẹjọ́ Kòtẹ́milọ́rùn tó wà nílùú Penza ní kí ilé ẹjọ́ àkọ́kọ́ yan adájọ́ míì láti tún ẹjọ́ náà gbọ́.
Kó tó di pé wọ́n tún ẹjọ́ yẹn gbọ́, wọ́n fòfin de àwọn ará wa mẹ́fẹ̀ẹ̀fà yẹn pé wọn ò gbọ́dọ̀ rìnrìn-àjò, wọ́n sì tún fi àwọn ẹ̀tọ́ míì dù wọ́n.
Bó tiẹ̀ jẹ́ pé inú wa dùn gan-an pé wọ́n ti dá Arákùnrin Alushkin sílẹ̀ lẹ́wọ̀n, ó ká wa lára pé lọ́jọ́ méjì lẹ́yìn náà, wọ́n tún mú ọ̀kan lára àwọn arákùnrin wa lápá àríwá orílẹ̀-èdè Rọ́ṣíà nítorí ohun tó gbà gbọ́.
Títí dìgbà táwọn èèyàn fi máa ṣíwọ́ àtimáa fẹ̀sùn tí kò lẹ́sẹ̀ nílẹ̀ kan àwọn ará wa lọ́kùnrin àti lóbìnrin, ó dá wa lójú pé àwọn ará wa yìí á máa fi ọ̀rọ̀ tó wà nínú Náhúmù 1:7 sọ́kàn, èyí tó sọ pé: “Jèhófà jẹ́ ẹni rere, odi agbára ní ọjọ́ wàhálà. Ó sì mọ àwọn tó ń wá ibi ààbò lọ́dọ̀ rẹ̀.”"
"Ilé ẹjọ́ ìlú Pskov máa gbé ìdájọ́ ẹ̀ kalẹ̀ ní June 8, 2020, lórí ẹ̀sùn tí wọ́n fi kan Arákùnrin Gennady Shpakovskiy, ẹni ọdún mọ́kànlélọ́gọ́ta (61).
Wọ́n fẹ̀sùn agbawèrèmẹ́sìn kàn-án torí ìpàdé Kristẹni tí wọn ń ṣe nílé ẹ̀. Agbẹjọ́rò ìjọba ti sọ pé kí ilé ẹjọ́ rán Arákùnrin Shpakovskiy lọ sẹ́wọ̀n ọdún méje àtààbọ̀.
Ní ìbẹ̀rẹ̀ 2018, àwọn ọ̀lọ́pàá ọ̀tẹlẹ̀múyẹ́ orílẹ̀-èdè Rọ́ṣíà bẹ̀rẹ̀ sí yọ́ kẹ́lẹ́ fi ẹ̀rọ gbọ́ ohun tí wọ́n ń sọ nínú ilé Shpakovskiy, wọ́n sì ń ṣọ́ wọn lọ́wọ́ lẹ́sẹ̀ fún ọ̀pọ̀ oṣù.
Ní June 3, 2018, ní aago kan ku ìṣẹ́jú mẹ́ẹ̀ẹ́dógún lọ́sàn-án, àwọn ọlọ́pàá ọ̀tẹlẹ̀múyẹ́, papọ̀ pẹ̀lú àwọn ẹ̀ṣọ́ orílẹ̀-èdè náà, fi tipátipá ṣí ilẹ̀kùn iwájú ilé náà, níbi tí àwọn èèyàn péjọ sí láti ṣe ìpàdé ní wọ́ọ́rọ́wọ́, wọ́n sì wá gbogbo inú ilé náà fún wákàtí mẹ́fà.
Àwọn ọlọ́pàá ọ̀tẹlẹ̀múyẹ́ gbẹ́sẹ̀ lé tábílẹ́tì àti fóònù àwọn Ẹlẹ́rìí náà, wọ́n sì kó wọn lọ fún ìfọ̀rọ̀wánilẹ́nuwò.
Àwọn tó ń fọ̀rọ̀ wá wọn lẹ́nu wò bẹ̀rẹ̀ sí bú wọn, wọ́n sì ń halẹ mọ́ wọn pé wọ́n máa pàdánù iṣẹ́ wọn, wọ́n á sì lọ sẹ́wọ̀n.
Ó tó aago mẹ́wàá alẹ́ kí ìfọ̀rọ̀wánilẹ́nuwò Arákùnrin Shpakovskiy tó parí.
Ní March 19, 2019, wọ́n fẹ̀sùn kan Arákùnrin Shpakovskiy pé ó ń ṣètò ìgbòkègbodò ẹgbẹ́ agbawèrèmẹ́sìn.
Oṣù márùn-ún lẹ́yìn náà, wọ́n fi ẹ̀sùn míì kàn-án pé ó ń fi owó ṣe ìtìlẹ́yìn fún ìgbòkègbodò ẹgbẹ́ àwọn agbawèrèmẹ́sìn.
Bí ìgbẹ́jọ́ náà ṣe ń sún mọ́lé, a gbàdúrà pẹ̀lú ìgbẹ́kẹ̀lé kíkún pé Jèhófà máa ran ìdílé Shpakovskiy lọ́wọ́ láti dúró gbọin, a sì mọ̀ pé èrè wà fún ìfaradà wọn.​—2 Kíróníkà 15:7."
"Ní September 2, 2019, Ilé Ẹjọ́ Àgbègbè Zheleznodorozhniy ní ìlú Khabarovsk lórílẹ̀-èdè Rọ́ṣíà dájọ́ pé kí Arákùnrin Valeriy Moskalenko lọ ṣe iṣẹ́ àṣesìnlú fún ọdún méjì àti oṣù méjì.
Ẹ̀yìn ìyẹn ní wọ́n á wá máa ṣọ́ ọ lọ́wọ́ lẹ́sẹ̀ fún oṣù mẹ́fà. Ìyẹn túmọ̀ sí pé kò ní pa dà sẹ́wọ̀n mọ́.
Lẹ́yìn tí ilé ẹjọ́ kéde ìdájọ́ yìí, wọ́n dá Arákùnrin Moskalenko sílẹ̀ lẹ́wọ̀n, inú ìdílé àtàwọn ọ̀rẹ́ rẹ̀ sì dùn gan-an.
Láti August 2, 2018 ló ti wà lẹ́wọ̀n. Kí wọ́n tó fi í sẹ́wọ̀n, iṣẹ́ tó ń ṣe ni pé ó máa ń ran ẹni tó ń wa ọkọ̀ ojú irin lọ́wọ́, ó sì tún ń tọ́jú ìyá rẹ̀ tó ń ṣàìsàn.
Lára àwọn ìkálọ́wọ́kò tí wọ́n fún un lásìkò tí wọ́n fi ń ṣọ́ ọ lọ́wọ́ lẹ́sẹ̀ ni pé kò gbọdọ̀ jáde kúrò nílùú Khabarovsk, ó sì gbọ́dọ̀ máa lọ sí àgọ́ ọlọ́pàá lóṣooṣù kí wọ́n lè rí i pé kò ṣe ohunkóhun tí kò bófin mu.
Nínú ọ̀rọ̀ tí Arákùnrin Moskalenko sọ kẹ́yìn nílé ẹjọ́ ní August 30, ó sọ pé: “Mi ò ni ṣe ohun tó lòdì sí ìfẹ́ Ọlọ́run bó ṣe wà nínú Bíbélì láé.
Bó ti wù kí ilé ẹjọ́ yìí fìyà jẹ mí tó, kódà tí wọ́n bá dájọ́ ikú fún mi, mi ò ni fi Jèhófà, Ọlọ́run Olódùmarè àti Ẹlẹ́dàá ayé àtọ̀run sílẹ̀ láé.”
Yaroslav Sivulskiy, tó jẹ́ aṣojú Àjọ European Association of Jehovah’s Witnesses, sọ pé: “Bó tiẹ̀ jẹ́ pé a ò gbà pé a jẹ̀bi ẹ̀sùn náà, àmọ́ inú wa dùn pé Valeriy máa lè pa dà sílé.”
Yàtọ̀ sí Arákùnrin Moskalenko, àwọn arákùnrin wa méje míì wà ní ìlú Khabarovsk tó ń retí ìgbà tí wọ́n máa dá ẹjọ́ ẹ̀sùn ìwà ọ̀daràn tí wọ́n fi kàn wọ́n.
A dúpẹ́ lọ́wọ́ Jèhófà pé Arákùnrin Moskalenkodúró gbọin nígbà tó wà lẹ́wọ̀n.
Àdúrà wa ni pé kí Jèhófà túbọ̀ máa fún àwọn arákùnrin àtàwọn arábìnrin wa lókun bí wọ́n ṣe ń fara da inúnibíni nítorí ohun tí wọ́n gbà gbọ́.​—Àìsáyà 40:31."
Ní August 13, 2019, ilé ẹjọ́ kòtẹ́milọ́rùn tó wà ní ìlú Kirov dájọ́ pé kí wọn jẹ́ ki Arákùnrin Andrey Suvorkov tó jẹ́ ẹni ọdún mẹ́rìndínlọ́gbọ̀n (26) pé kò lómìnira láti jáde kúrò nílé.
Bó tiẹ̀ jẹ́ pé wọ́n fún Arákùnrin Suvorkov lómìnira tó pọ̀ si i, síbẹ̀ ẹ̀sùn ọ̀daràn tí wọ́n fi kàn án ṣì wà síbẹ̀.
Bó ṣe wà nínú ìròyìn tá a gbé jáde ṣáájú, ní October 9, 2018 àwọn ọlọ́pàá àtàwọn agbófinró tó fi nǹkan bojú ya wọ ilé mọ́kàndínlógún (19) lára ilé àwọn ará wa, ìgbà yẹn ni wọ́n mú Arákùnrin Suvorkov, ọkọ ìyá rẹ̀ àtàwọn arákùnrin mẹ́ta míì.
Arákùnrin Suvorkov sọ ohun tó ṣẹlẹ̀ nígbà tí wọ́n wá tú ilé rẹ̀, ó ní: “Wọ́n kó púpọ̀ nínú àwọn ohun ìní wa.
Àmọ́, èmi àti ìyàwó mi ò ronú nípa ìyẹn torí a ti jẹ́ kí ohun díẹ̀ tẹ́ wa lọ́rùn, a ò sì kì í ṣàníyàn púpọ̀ nípa àwọn nǹkan tara.
Ìmọ̀ràn tó wà ní Mátíù 6:21 ti ràn wá lọ́wọ́ gan-an, ó sọ pé, ‘ibi tí ìṣúra yín bá wà ibẹ̀ ni ọkàn yín náà máa wà,’ ìyẹn ni kò jẹ́ ká kọ́kàn sókè.”
Lẹ́yìn tí wọ́n tú ilé àwọn arákùnrin yìí, wọ́n fẹ̀sùn ìwà ọ̀daràn kan Arákùnrin Suvorkov, ọkọ ìyá rẹ̀ àtàwọn arákùnrin mẹ́ta míì, wọ́n ní torí pé wọ́n ń kọrin ìjọba Ọlọ́run, wọ́n ń ka àwọn ìtẹ̀jáde wa àti pé wọ́n tún ní Bíbélì Mímọ́ ti Ìtumọ̀ Ayé Tuntun lédè Rọ́ṣíà lọ́wọ́.
Wọ́n fi gbogbo wọ́n sí àtìmọ́lé tó wà fún gbà díẹ̀ títí ilé ẹjọ́ á fi sọ pé kí wọn dá wọ́n sílẹ̀ tàbí kí wọ́n wà lẹ́wọ̀n títí wọ́n á fi gbọ́ ẹjọ́ wọn.
Arákùnrin Suvorkov sọ ohun tójú ẹ̀ rí, ó sọ pé: “Ọjọ́ méjì ni mo lò ní àtìmọ́lé onígbà díẹ̀.
Mi ò dáwọ́ àdúrà dúró láti ìbẹ̀rẹ̀, torí ó dá mi lójú pé Jèhófà á gbọ́ mi, á sì tì mí lẹ́yìn. Mò rántí àwọn orin ìjọba Ọlọ́run kan, mo sì ń kọ wọ́n.
Lápapọ̀, mo rántí ohùn orin tó lé ní àádọ́ta (50) àti ọ̀rọ̀ inú wọn.”
Ilé ẹjọ́ wá sọ pé kí wọ́n fi Arákùnrin Suvorkov àti àwọn yòókù sẹ́wọ̀n títí wọ́n á fi gbọ́ ẹjọ́ wọn.
Ní ọ̀sẹ̀ àkọ́kọ́ tí Arákùnrin Suvorkov lò lẹ́wọ̀n, ṣé ló gbájú mọ́ bó ṣe máa ran àwọn míì lọ́wọ́.
Ó sọ́ pé: “Mo pinnu láti máa dárúkọ àwọn ará wa nínú àdúrà mi, mo sì ń kọ lẹ́tà tó ń fúnni lókùn sí àwọn tí mo rántí àdírẹ́sì ilé wọn.
Èyí fún mi láyọ̀ gan-an.”​—Ìṣe 20:35.
Lẹ́yìn ọ̀pọ̀ oṣù, wọ́n dá àwọn arákùnrin yìí padà sílé wọ́n, àmọ́ wọ́n pàṣẹ pé gbogbo wọn ò gbọdọ̀ jáde kúrò nílé, àfi Arákùnrin Andrey Oniszczuk nìkan ló lè jáde nílé.
Arákùnrin Suvorkov ni ẹni àkọ́kọ́ nílùú Kirov lára àwọn tí wọ́n ní wọn ò gbọdọ̀ jáde nílé tí wọ́n wá pa dà fún lómìnira láti jáde nílé.
Nígbà tí Arákùnrin Suvorkov rántí ohun tó ṣẹlẹ̀ sí i, ó sọ pé: “Inú mi dùn pé mo ní irú ìrírí tí mo ní lẹ́wọ̀n. . . .
Mi ò mọ ohun tó máa ṣẹlẹ̀ lọ́la, mi ò sì mọ̀ bóyá wọ́n ṣì tún máa sọ mí sẹ́wọ̀n.
Àmọ́ ní báyìí, ó ti wá dá mi lójú pé Jèhófà àti ètò rẹ̀ ò ní fi mí sílẹ̀, kódà tí mo bá wà lẹ́wọ̀n.
"Ohun kan ni pé, àyà mi ò já pé wọ́n lè sọ mí sẹ́wọ̀n.”"""
"Ní September 3, 2019, wọ́n dá Arákùnrin AndrzejOniszczuk sílẹ̀ lọ́gbà ẹ̀wọ̀n kan lórílẹ̀-èdè Rọ́ṣíà.
Láti October 9, 2018 ni wọ́n ti fi í sẹ́wọ̀n torí pé ó ń jọ́sìn Ọlọ́run.
Láàárín àkókò yẹn, wọ́n fi í sínú àhámọ́, wọn ò jẹ́ kó rí Anna ìyàwó rẹ̀, wọn ò tún jẹ́ kó o bá a sọ̀rọ̀.
Bó tiẹ̀ jẹ́ pé wọ́n ti jẹ́ kó pa dà sílé báyìí, àmọ́ àwọn aláṣẹ ò gbà á láyè láti lọ síbi tó wù ú.
Wọn ò sì tíì parí ẹjọ́ lórí ẹ̀sùn ìwà ọ̀daràn tí wọ́n fi kàn án.
Inú wa dùn pé Arákùnrin Andrzej Oniszczuk àti ìyàwó rẹ̀ dúró gbọin lákòókò tí nǹkan le koko yìí.
A dúpẹ́ pé Jèhófà ń dáhùn àwọn àdúrà tá a gbà nítorí àwọn tó wa nínú “ìdè ẹ̀wọ̀n.”​—Kólósè 4:​2, 3."
"Ní April 1, 2019 ilé ẹjọ́ tó rán Arákùnrin Dennis Christensen lẹ́wọ̀n ọdún mẹ́fà tún dẹ́bi fún Sergey Skrynnikov, ẹni ọdún mẹ́rìndínlọ́gọ́ta (56) torí pé ó ń ṣe ohun tó gbà gbọ́ gẹ́gẹ́ bíi Kristẹni Ẹlẹ́rìí Jèhófà.
Ilé ẹjọ́ bu owó ìtanràn tabua lé e lórí, wọ́n ní kó san ẹgbẹ̀rún márùn-ún àti ọgọ́rùn-ún mẹ́ta ó lé méjìdínláàádọ́ta owó dọ́là ($5,348.00).
Bó tiẹ̀ jẹ́ pé àwọn tó fẹ̀sùn kàn án fẹ́ kí ilé ẹjọ́ ran an lẹ́wọ̀n ọdún mẹ́ta, ilé ẹjọ́ ò rán an lẹ́wọ̀n.
Arákùnrin Skrynnikov àti ìyàwó rẹ̀, Nina bí ọmọbìnrin kan.
Wọ́n máa ń ran ọmọbìnrin wọn lọ́wọ́ pẹ̀lú ọkọ rẹ̀ láti tọ́jú ọmọ márùn-ún tí wọ́n bí.
Yàtọ̀ síyẹn, ìdílé Skrynnikov náà ló ń tọ́jú àwọn òbí Nina, ìyàwó ọmọ wọn, torí wọ́n ti dàgbà gan-an.
Tọ̀wọ̀tọ̀wọ̀ ni Arákùnrin Skrynnikov gbèjà ohun tó gbà gbọ́ nílé ẹjọ́, ọ̀rọ̀ rẹ̀ sì wọni lọ́kàn.
Lára ohun tó sọ ni pé: “Téèyàn bá fojú ẹni tí ò nígbàgbọ́ wo ọ̀rọ̀ yìí, ó máa bọkàn jẹ́. . . .
Àmọ́ torí pé Ẹlẹ́rìí Jèhófà ni mí, ojú ìgbàgbọ́ ni mo fi wo ohun tó ṣẹlẹ̀ yìí.
Tí Ọlọ́run bá fàyè gbà á pé kí wọ́n rán mi lẹ́wọ̀n, àfi kí n yáa gbà pé ọdún mẹ́ta yìí kì í ṣe tìyà, àmọ́ ó wà fún iṣẹ́ pàtàkì kan tí màá ṣe níbi tuntun!
Torí náà, mi ò bọkàn jẹ́. . . .
Ìkan náà ni Ọlọ́run, kò yí pa dà, à báà wà lómìnira tàbí a wà lẹ́wọ̀n.
Kò fi wá sílẹ̀.
Ó wà pẹ̀lú wa níbikíbi tá a bá wà, tá a bá ṣáà ti jẹ́ olóòótọ́ sí i.”
Ìgbàgbọ́ tó lágbára táwọn ará wa ní máa ń fún wa níṣìírí bíi ti Arákùnrin Skrynnikov.
Tá a ba ronú nípa àwọn àdánwò lílé tí wọ́n ń kojú, àwa náà máa gba irú àdúrà tí àpọ́sítélì Pọ́ọ̀lù gbà fáwọn ará pé: “Kí Ọlọ́run tó ń fúnni ní ìrètí fi gbogbo ayọ̀ àti àlàáfíà kún inú yín nítorí ẹ̀ ń gbẹ́kẹ̀ lé e, kí ìrètí yín lè túbọ̀ dájú nípasẹ̀ agbára ẹ̀mí mímọ́.”—Róòmù 15:13.
A túmọ̀ rẹ̀ láti èdè Russian
Lákọ̀ọ́kọ́, mo dúpẹ́ lọ́wọ́ Adájọ́ Àgbà Gleb Borisovich Noskov tí kò fi mí sátìmọ́lé kí wọ́n tó gbọ́ ẹjọ́ mi, èyí jẹ́ kí n lè wà pẹ̀lú ìdílé mi ní gbogbo àsìkò ìgbẹ́jọ́ yìí.
Bákan náà, mo fẹ́ dúpẹ́ lọ́wọ́ gbogbo àwọn ọ̀ṣìṣẹ́ ilé ẹjọ́ fún iṣẹ́ tí wọ́n ń ṣe.
Mo dúpẹ́ gan-an lọ́wọ́ agbẹjọ́rò ìjọba, Ìyáàfin Nadezhda Gennadiyevna Naumova, torí kò ni mí lára nígbà tó ń wádìí ọ̀rọ̀ wò lẹ́nu mi, ọ̀nà tó sì gbà bi mí léèrè ọ̀rọ̀ bọ́gbọ́n mu.
Mo tún dúpẹ́ lọ́wọ́ àwọn agbẹjọ́rò mi, Ìyáàfin Irina Aleksandrovna Krasnikova àti Ọ̀gbẹ́ni Anton Nikolayevich Bogdanov torí iṣẹ́ ribiribi tí wọ́n ṣe.
Ìyàlẹ́nu gbáà ló jẹ́ fún mi nígbà tí wọ́n mú akọ́ṣẹ́mọṣẹ́ kan wá láti ìlú Chelyabinsk.
Mo dúpẹ́ lọ́wọ́ gbogbo ẹ̀yín ọ̀rẹ́ mi àtàtà fún bẹ́ ẹ ṣe ń wá sílé ẹjọ́ láti fún mi níṣìírí ní gbogbo àsìkò ìgbẹ́jọ́, bó tiẹ̀ jẹ́ pé ẹ mọ̀ pé wọn ò ní jẹ́ kẹ́ ẹ wọlé.
Màmá mi, ẹ ṣé o, bó tiẹ̀ jẹ́ pé ara ò le, ẹ ò yéé wá sílé ẹjọ́ láti fún mi níṣìírí.
Ìyàwó mi àtàtà, o ṣé o, kú àdúrótì látọdún mẹ́tàdínlógójì (37), lọ́jọ́ dídùn àti lọ́jọ́ kíkan.
Jèhófà, Ọlọ́run mi ni ọpẹ́ tó ga jù lọ yẹ, òun ló ń fi mí lọ́kàn balẹ̀, tó sì fi ayọ̀ kún ọkàn mi.
Ó lè ṣòroó gbà gbọ́, àmọ́ kò sí ìbànújẹ́ tàbí ìbínú kankan lọ́kàn mi, ayọ̀ àti àlááfíà ló kún ọkàn mi.
Kọ́ríńtì Kejì 4:​8, 9 ló ṣe nínú ọ̀rọ̀ mi: “Wọ́n há wa gádígádí ní gbogbo ọ̀nà, àmọ́ kò le débi tí a ò fi lè yíra; ọkàn wa dà rú, àmọ́ kì í ṣe láìsí ọ̀nà àbáyọ rárá; wọ́n ṣe inúnibíni sí wa, àmọ́ a ò pa wá tì; wọ́n gbé wa ṣánlẹ̀, àmọ́ a ò pa run.”
Ọ̀rọ̀ yìí jẹ́ ká rí i pé wọ́n máa há àwọn ìránṣẹ́ Ọlọ́run mọ́, wọ́n á sì ṣenúnibíni sí wọn, àmọ́ iṣẹ́ tí Jésù Olúwa gbé lé wọn lọ́wọ́ ò ní dáwọ́ dúró, kàkà bẹ́ẹ̀, ńṣe láá tubọ̀ yára, táá sì túbọ̀ gbilẹ̀.
Gbogbo àwọn tó bá jẹ́ ọmọlẹ́yìn tòótọ́ fún Kristi lọ̀rọ̀ yìí kàn:
Mátíù 28:​19, 20 sọ fún wa pé “Torí náà, ẹ lọ, kí ẹ máa sọ àwọn èèyàn gbogbo orílẹ̀-èdè di ọmọ ẹ̀yìn, ẹ máa batisí wọn ní orúkọ Baba àti ti Ọmọ àti ti ẹ̀mí mímọ́, ẹ máa kọ́ wọn pé kí wọ́n máa pa gbogbo ohun tí mo pa láṣẹ fún yín mọ́.
Ẹ wò ó! Mo wà pẹ̀lú yín ní gbogbo ọjọ́ títí dé ìparí ètò àwọn nǹkan.”
Ẹ̀mí Jèhófà ló máa ń darí àwọn Kristẹni, tó ń fún wọn ní agbára tó kọjá ti ẹ̀dá, tó sì ń mú kí wọ́n lè ṣe iṣẹ́ tí Ọlọ́run yàn fún wọn bí wọ́n tiẹ̀ ń kojú inúnibíni.
Ọ̀rọ̀ yìí máa túbọ̀ dá wa lójú tá a bá wo ohun tó ṣẹlẹ̀ kọjá. Lọ́dún 1930 sí 1939, àwọn ìránṣẹ́ ọlọ́run fàyà rán iṣẹ́ ńlá kan tó dà bíi pé kò lè ṣeé ṣe, ìyẹn ni bí wọ́n ṣe máa wàásù Ìjọba Ọlọ́run ní gbogbo agbègbè tó wà lábẹ́ ìjọba Soviet Union.
Àmọ́ torí pé Kristi ló ń darí iṣẹ́ ìwàásù, ní nǹkan bí ogún (20) ọdún lẹ́yìn náà, ó ṣètò nǹkan lọ́nà tí ìjọba Soviet Union fúnra rẹ̀ fi kó ẹgbẹẹgbẹ̀rún ìdílé àwọn Ẹlẹ́rìí Jèhófà lọ sí Sàìbéríà lọ́fẹ̀ẹ́, kódà títí dé àwọn apá ibi tó jìnnà jù lọ lórílẹ̀-èdè náà.
Ó ti fẹ́rẹ̀ẹ́ pé ọgọ́ta (60) ọdún báyìí tọ́rọ̀ yìí ti ṣẹlẹ̀, àmọ́ kí ló ti yọrí sí?
Ìyàlẹ́nu ló ń jẹ́ fáwọn aláṣẹ ní Sàìbéríà bí wọ́n ṣe ń rí iṣẹ́ ìwàásù tó ń gbilẹ̀ lágbègbè náà.
Ọ̀kan lára àwọn olùṣèwádìí tó mọ ìtàn àwa Ẹlẹ́rìí Jèhófà dáadáa ní USSR sọ pé:
“Ńṣe lọ̀rọ̀ bí wọ́n ṣe ń gbógun ti àwọn Ẹlẹ́rìí Jèhófà dà bí ìgbà téèyàn bá fẹ́ atẹ́gùn lu òdòdó tí wọ́n ń pè ní dandelions.
Bí atẹ́gùn náà bá ṣe pọ̀ tó ni yẹtuyẹtu rẹ̀ tó máa gbọ̀n sílẹ̀ á ṣe pọ̀ tó, bẹ́ẹ̀ ni wọ́n sì ṣe máa rìn jìnnà tó.”
Bọ́rọ̀ ṣe rí fáwa Ẹlẹ́rì Jèhófà lóde òní nìyẹn.
Àwọn wo la sábà máa ń bá tá a bá ń wàásù láti ilé dé ilé?
Àwọn ìyàwó ilé àtàwọn tó ti fẹ̀yìn tì lẹ́nu iṣẹ́.
A kìí fi bẹ́ẹ̀ bá àwọn òṣìṣẹ́ nílé.
Bẹ́ẹ̀ náà ló ṣòro tàbí kó má tiẹ̀ ṣeé ṣe láti wàásù láwọn ilé tó ní fẹ́ǹsì gìrìwò, láwọn ọgbà ẹ̀wọ̀n, láwọn ilé ẹjọ́ àtì láwọn ibi tí wọ́n ti ń kó àwọn ẹlẹ́wọ̀n ṣiṣẹ́.
Àmọ́ torí pé Kristi ló ń darí iṣẹ́ ìwàásù àti pé ó [Jèhófà] ti fi í sọ́kàn Ilé Iṣẹ́ Ètò Ìdájọ́ láti ṣe ìfẹ́ Rẹ̀.
Èyí ti mú kí ilé Iṣẹ́ Ètò Ìdájọ́ àti Ìgbìmọ̀ Tó Ń Ṣèwádìí Nílẹ̀ Rọ́ṣíà pẹ̀lú ọ́fíìsì àwọn agbẹjọ́rò ìjọba àtàwọn agbófinró lóríṣiríṣi fọwọ́ ara wọn àtohun tí wọ́n ṣe mú kí iṣẹ́ ìwàásù àwa Ẹlẹ́rìí Jèhófà túbọ̀ gbilẹ̀. Lọ́nà wo?
Ohun tí wọ́n ṣe ti mú ká kéde orúkọ Ọba Aláṣe Ayé Àtọ̀run, Jèhófà Ọlọ́run láti agbègbè Kaliningrad títí dé ẹrékùṣù Sakhalin àti Kuril; láti ìlú Arkhangel’sk títí dé Crimea àti Yalta; láàárín àwọn ìdílé, láwọn ibi iṣẹ́, láwọn ọgbà ẹ̀wọ̀n, láwọn ilé ẹjọ́ àti láwọn ibi tí wọ́n ti ń kọ́ni ní béèyàn á ṣe yíwà pa dà.
Àwa Ẹlẹ́rìí Jèhófà ò rò ó rí pé iṣẹ́ ìwàásù wá á délédóko bó ṣe rí yìí.
Torí náà ilẹ̀kùn tuntun ló ṣí sílẹ̀ láti ìwàásù láwọn ibi tuntun àti lọ́nà tuntun.
Àǹfààní ńlá ló jẹ́ fáwa Ẹlẹ́rìí Jèhófà láti wàásù ìhìn rere láwọn ibi tuntun yìí.
Ọ́fíìsì àwọn agbẹjọ́rò ìjọba ló sì mú kí èyí ṣeé ṣe.
Ẹ jẹ́ ká wo bọ́rọ̀ yìí ṣe máa rí lọ́jọ́ iwájú.
Tá a bá fi máa rọ́dún mẹ́wàá sí i, tí ijọba bá ṣì ń ju àwa Ẹlẹ́rìí Jèhófà sẹ́wọn àtàwọn ibi tí wọ́n ti kó àwọn ẹlẹ́wọ̀n ṣiṣẹ́, á fẹ́rẹ̀ẹ́ tó ọgọ́rùn-ún méjì (200) Ẹlẹ́rìí Jèhófà tó máa wà ní ojúkò kọ̀ọ̀kan.
Ẹ wo bó ṣe máa rí tí ìjọ mẹ́rin bá wà ní ọgbà ẹ̀wọ̀n kọ̀ọ̀kan!
Ńṣe làwọn tó ń bójú tó ọgbà ẹ̀wọ̀n á máa bẹ Ilé Iṣẹ́ Ètò Ìdájọ́ pé kí wọ́n tú àwa Ẹlẹ́rìí Jèhófà sílẹ̀.
Kí lẹ rò pé èyí tó pọ̀ jù lára àwa Ẹlẹ́rìí Jèhófà á máa gbà ládùúrà?
“Olúwa, jọ̀ọ́, má jẹ́ kí ọkàn àwọn aláṣẹ rọ̀ o; má jẹ́ kí wọ́n tú mi sílẹ̀.
Inú ibí yìí ni ọ̀pọ̀ àwọn akẹ́kọ̀ọ́ Bíbélì mi àtàwọn tí mo lè bá sọ̀rọ̀ wà.”
Téèyàn bá fojú aláìnígbàgbọ́ wo ohun tó ń ṣẹlẹ̀ báyìí, ó máa bọkàn jẹ́.
Bíi kó sọ pé: “Mi ò pààyàn, mi ò gba nǹkan oníǹkan, mi ò sì jààyàn lólè.
Mi ò tiẹ̀ bá ẹnikẹ́ni fa ọ̀rọ̀.
Ẹ̀rí sì fi hàn bẹ́ẹ̀ nínú ìwé táwọn aláṣẹ agbègbè kọ.
Síbẹ̀, àwọn tó pè mí lẹ́jọ́ ṣáà fẹ́ kí wọ́n rán mi lẹ́wọ̀n ọdún mẹ́ta.”
Irú àsìkò yìí lèèyàn lè fẹ́ bọkàn jẹ́; àmọ́ torí pé Ẹlẹ́rìí Jèhófà ni mí, ojú ìgbàgbọ́ ni mo fi ń wo ohun tó ṣẹlẹ̀ yìí.
Tí Ọlọ́run bá fàyè gbà á pé kí wọ́n rán mi lẹ́wọ̀n, àfi kí n yáa gbà pé ọdún mẹ́ta yìí kì í ṣe tìyà, àmọ́ ó wà fún iṣẹ́ pàtàkì kan tí màá ṣe níbi tuntun!
Torí náà, mi ò bọkàn jẹ́.
Dípò bẹ́ẹ̀, mo wò ó bí àǹfààní ńlá láti lọ ṣiṣẹ́ Ọlọ́run níbi tí kò tíì sí Ẹlẹ́rìí Jèhófà kankan.
Àwọn ilé iṣẹ́ agbéròyìnjáde ti roko gbogbo agbègbè náà dè mí.
Àsìkò ti tó láti fún irúgbìn.
Ìkan náà ni Ọlọ́run, kò yí pa dà, à báà wà lómìnira tàbí a wà lẹ́wọ̀n.
Kò fi wá sílẹ̀.
Ó wà pẹ̀lú wa níbikíbi tá a bá wà, tá a bá ṣáà ti jẹ́ olóòótọ́ sí i.
Nínú ọ̀rọ̀ tèmi, ó dá mi lójú pé Ọlọ́run máa tọ́jú mi nípa tara àti nípa tẹ̀mí, tó bá sì wù ú, á fi sọ́kàn adájọ́ àgbà pé kó rán mi lẹ́wọ̀n bí àwọn tó pè mí lẹ́jọ́ ṣe fẹ́, ìyẹn Ìyáàfin Naumova.
Mò ń retí ọjọ́ kìíní oṣù April.
Hébérù 13:6 fi dá mi lójú pé: “Jèhófà ni olùrànlọ́wọ́ mi; mi ò ní bẹ̀rù.
Kí ni èèyàn lè fi mí ṣe?”
Jèhófà Ọlọ́run fúnra rẹ̀ máa ràn mí lọ́wọ́.
Ṣé ó tún yẹ kí n bẹ̀rù ẹnikẹ́ni?
Ní September 4, 2019, nígbà tí wọ́n ń gbẹ́jọ́ àwọn Ẹlẹ́rìí Jèhófà mẹ́fà ní ìlú Saratov, wọ́n ní kí onímọ̀ nípa ẹ̀sìn táwọn èèyàn mọ̀ bí ẹní mowó àti olùdámọ̀ràn fún ìjọba Orílẹ̀-Èdè Rọ́ṣíà, Sergey Igorevich Ivanenko, wá sọ ohun tó mọ̀ nípa àwọn Ẹlẹ́rìí Jèhófà níwájú ilé ẹjọ́."
Ọ̀mọ̀wé Ivanenko ló ṣe ìwé méjì tó wúlò fáwọn akẹ́kọ̀ọ́ èyí tó sọ̀rọ̀ nípa àwọn Ẹlẹ́rìí Jèhófà lórílẹ̀-èdè Rọ́ṣíà.
Ohun tá a kọ síbí yìí ni ẹ̀rí tó jẹ́ níwájú ilé ẹjọ́:
Ìgbésí ayé àwọn Ẹlẹ́rìí Jèhófà àti ìjọsìn wọn.
“Ohun kan tó mú káwọn Ẹlẹ́rìí yàtọ̀ gédégbé ni pé:
Wọn kì í tẹ̀ lé òfin gbòógì kankan tàbí ohun tí aṣáájú kan pàtó bá pa láṣẹ, ṣe ni wọ́n máa ń gbìyànjú láti ran ara wọn lọ́wọ́ kí wọ́n lè ní ẹ̀rí ọkàn tí wọ́n fi Bíbélì kọ́, kí ẹnì kọ̀ọ̀kan wọn sì lè dá ṣe ìpinnu tó bá Bíbélì mu.
“Àwọn Ẹlẹ́rìí Jèhófà máa ń gbìyànjú láti tẹ̀ lé ohun tó wà nínú Bíbélì, ni ìbámu pẹ̀lú àwọn ìlànà tí Jésù Kristi àtàwọn ọmọ ẹ̀yìn rẹ̀ gbé kalẹ̀ ní ọgọ́rùn-ún ọdún kìíní Sànmánì Kristẹni.
“Ọ̀nà tí wọ́n ń gbà ṣe ohun tí wọ́n jọ gbà gbọ́, ìyẹn kíkẹ́kọ̀ọ́ Bíbélì, dídáhùn àwọn ìbéèrè nípa Bíbélì àti kíkọ orin tó bá Bíbélì mu, jẹ́ kó ṣe kedere pé àwọn Ẹlẹ́rìí Jèhófà ń sapá gidigidi láti ṣe gbogbo nǹkan lọ́nà tó bá Bíbélì mu.
“Wọ́n tún gbà pé ìpàdé ìjọ wà lára ohun tí Kristẹni kan gbọ́dọ̀ máa pésẹ̀ sí.
Láwọn ìpàdé náà, àwọn Ẹlẹ́rìí Jèhófà máa ń ṣe àyẹ̀wò Májẹ̀mú Tuntun, ohun tó sọ nípa Jésù Kristi àtàwọn ọmọ ẹ̀yìn rẹ̀, àwọn ọmọlẹ́yìn rẹ̀ àti ìgbà tí ìjọ Kristẹni ṣẹ̀ṣẹ̀ bẹ̀rẹ̀. . . .
Àwọn Ẹlẹ́rìí Jèhófà gbà pé àwọn gbọ́dọ̀ máa sin Ọlọ́run pa pọ̀ gẹ́gẹ́ bí ìjọ.
“Wọ́n máa ń tẹnu mọ́ ọn pé ohun tá a fi ń dá àwọn ọmọ ẹ̀yìn Jésù Kristi mọ̀ ni ìfẹ́ tí wọ́n ní láàárín ara wọn.”
Iṣẹ́ ìwàásù àwọn Ẹlẹ́rìí Jèhófà.
“A tún ń fi iṣẹ́ ìwàásù àwọn Ẹlẹ́rìí Jèhófà dá wọn mọ̀.
Mo lérò pé kò sẹ́ni tó ń wàásù bí àwọn Ẹlẹ́rìí Jèhófà, kò sì sẹ́ni tó ní ìtara tó wọn.
Gbogbo wọn gbọ́dọ̀ wàásù kí wọ́n sì lo àkókò díẹ̀ lẹ́nu iṣẹ́ ìwàásù.
“Wọ́n sábà máa ń sọ pé, ‘Ohun tí Bíbélì sọ nìyí.’
Ẹnì kan lè ṣí Bíbélì kí òun fúnra rẹ̀ sì yẹ̀ ẹ́ wò.
Bó bá fara mọ́ ohun tí Bíbélì sọ, á dara pọ̀ mọ́ wọn.
Bí kò bá sì fara mọ́ ọn, kò ní dara pọ̀ mọ́ wọn.
Wọ́n kì í fipá múni.”
Ẹ̀sùn tí wọ́n fi kan àwọn Ẹlẹ́rìí Jèhófà pé wọ́n jẹ́ agbawèrèmẹ́sìn.
“Ohun tó mú kí ìjọba kọ́kọ́ sọ pé agbawèrèmẹ́sìn làwọn Ẹlẹ́rìí Jèhófà ni pé àwọn ọ̀jọ̀gbọ́n kan sọ pé àwọn ìwé wọn kan sọ pé àwọn Ẹlẹ́rìí Jèhófà nìkan ló ń ṣe ìsìn tòótọ́ àti pé àwọn ìsìn tó kù jẹ́ ìsìn èké.
Àwọn ẹlẹ́sìn míì náà máa ń sọ irú ọ̀rọ̀ bẹ́ẹ̀, àmọ́ àwọn Ẹlẹ́rìí Jèhófà ni wọ́n fẹ̀sùn kan nínú ẹjọ́ tó wà nílẹ̀ yìí.
Wọ́n ka ohun táwọn Ẹlẹ́rìí Jèhófà sọ pé ìsìn àwọn nìkan ni ìsìn tòótọ́ àti pé àwọn ìsìn tó kù jẹ́ èké sí ìpolongo ẹ̀tàn.
“Lójú tèmí gẹ́gẹ́ bí onímọ̀ nípa ẹ̀sìn, [ìpinnu ti ilé ẹjọ́ ṣe yìí] ò tọ̀nà, torí pé béèyàn bá yàn láti wádìí ọ̀rọ̀ náà wò, kò sí ẹlẹ́sìn tí ò ní sọ pé tòun ni ìsìn tòótọ́, ìsìn èké làwọn tó kù tàbí pé wọ́n ti ṣì wọ́n lọ́nà.
“Gbogbo ẹlẹ́sìn ló máa ń sọ pé tiwọn nìkan ni ìsìn tòótọ́, tí wọ́n á sì ka àwọn ẹ̀sìn tó kù sí ẹ̀sìn èké tàbí èyí tí kò fi taratara jóòótọ́.
Bó ṣe yẹ kó rí náà nìyẹn àfi bí wọ́n bá máa ṣe àgàbàgebè ló kù.
“Àmọ́, àwọn Ẹlẹ́rìí Jèhófà máa ń sapá nígbà gbogbo láti pa òfin ìjọba mọ́ bí kò bá ti forí gbárí pẹ̀lú òfin Ọlọ́run.
Ìdí nìyẹn tá a fi máa ń gbọ́ pé àwọn Ẹlẹ́rìí Jèhófà dá pọ́ọ̀sì tí wọ́n rí he pa dà, wọ́n sì sanwó ìtanràn tàbí owó orí bó tilẹ̀ jẹ́ pé wọ́n lè ṣàì ṣe bẹ́ẹ̀.
Ìpinnu àtọkànwá lèyí jẹ́ mi ò sì ní fi ẹ̀sùn kàn wọ́n pé wọ́n jẹ́ agbawèrèmẹ́sìn tó wulẹ̀ ń díbọ́n.”
Àwọn Ẹlẹ́rìí Jèhófà Máa Ń Lo Bíbélì.
“Ohun kan tó ṣàrà ọ̀tọ̀ nípa àwọn Ẹlẹ́rìí Jèhófà ni pé wọ́n máa ń lo onírúurú ìtumọ̀ Bíbélì fún ìkẹ́kọ̀ọ́ àti lẹ́nu iṣẹ́ ìwàásù wọn.
Wọ́n rí i bí ohun tó ṣe pàtàkì pé kí wọ́n mú káwọn èèyàn ní Bíbélì ní oríṣiríṣi èdè.
Wọn ò dà bí àwọn ẹlẹ́sìn yòókù torí pé wọ́n pọkàn pọ̀ sórí Bíbélì.
Àwọn aláṣẹ ka ìtumọ̀ Bíbélì wọn sí ìwé àwọn agbawèrèmẹ́sìn . . .
Bóyá àwọn tó ṣe ìpinnu yẹn rò pé àwọn Ẹlẹ́rìí Jèhófà ti fẹ́ràn Bíbélì wọn jù àti pé wọ́n á ṣíwọ́ iṣẹ́ ìwàásù tí wọn ò bá jẹ́ kí wọ́n lo Bíbélì yẹn mọ́.
Àṣìrò nìyẹn jẹ́.
Àwọn Ẹlẹ́rìí Jèhófà ò fọwọ́ rọ́ ìtumọ̀ Bíbélì kankan sẹ́yìn.”
Lílo àjọ tó ń bójú tó iṣẹ́ wa lábẹ́ òfin.
“Ìpinnu Ilé Ẹjọ́ Gíga Jù Lọ ti Orílẹ̀-Èdè Rọ́ṣíà fi hàn pé. . . èyí tó pọ̀ jù nínú ìjọ àwọn Ẹlẹ́rìí Jèhófà kò ní àjọ tó ń bójú tó iṣẹ́ wọn lábẹ́ òfin . . .
Torí náà, kò tọ̀nà láti sọ pé olúkúlùkù Ẹlẹ́rìí Jèhófà tó wà ní agbègbè pàtó kan gbọ́dọ̀ jẹ́ ara àjọ tó ń bójú tó iṣẹ́ wọn lábẹ́ òfin.
“Ní ti àwọn àjọ tó ń bójú tó iṣẹ́ wọn lábẹ́ òfin . . . , mo fara balẹ̀ ṣàyẹ̀wò ìwé òfin tí wọ́n fi dá wọn sílẹ̀, wọn ò dárúkọ alábòójútó, alàgbà, aṣáájú-ọ̀nà; irú àwọn ọ̀rọ̀ bẹ́ẹ̀ ò sí níbẹ̀.
Orúkọ àwọn olùdásílẹ̀ àjọ náà ló máa ń wà níbẹ̀, àwùjọ kéréje tí kì í ju nǹkan bí èèyàn mẹ́wàá lọ.
Àwọn tí orúkọ wọn ò sí nínú ìwé yẹn kọ́ ló ń ṣojú fún òfin, ohun tó jẹ mọ́ ọ̀rọ̀ ẹ̀sìn àwọn Ẹlẹ́rìí Jèhófà ni wọ́n ń bójú tó. . . .
Ohun táwọn Ẹlẹ́rìí Jèhófà ń ṣe ò sì yàtọ̀ síra láìka orílẹ̀-èdè tàbí ẹkùn ìpínlẹ̀ tí wọ́n wà sí.
“Ṣe ni àwọn Ẹlẹ́rìí Jèhófà gbìyànjú láti fara mọ́ [ìpinnu Ilé Ẹjọ́ Gíga Jù Lọ tó fi òfin de àjọ tó ń bójú tó iṣẹ́ wọn lábẹ́ òfin yìí] kí wọ́n má bàa ta ko ìpinnu Ilé Ẹjọ́ Gíga Jù Lọ náà délẹ̀délẹ̀.
Torí náà, wọ́n ń bá iṣẹ́ wọn nìṣó gẹ́gẹ́ bí ẹ̀sìn tí àwọn aláṣẹ ò fi òfin dè.
Wọ́n ń bá iṣẹ́ wọn lọ bí olùjọsìn tó wà láyè ara ẹ̀.
Lójú wọn àti bí ìwádìí nípa ẹ̀sìn ṣe fi hàn, iṣẹ́ wọn ò ta ko ìpinnu Ilé Ẹjọ́ Gíga Jù Lọ.”
Ojú tí àwọn Ẹlẹ́rìí Jèhófà fi ń wo gbígba ẹ̀jẹ̀.
“Bíbélì sọ pé ‘inú ẹ̀jẹ̀ ni ẹ̀mí wà’; torí náà ẹ kò gbọ́dọ̀ jẹ ẹ̀jẹ̀.
Ọ̀rọ̀ nípa irú oúnjẹ téèyàn ò gbọ́dọ̀ jẹ ni ibí yìí ń sọ, amọ́ wọ́n mú kí ìtumọ̀ rẹ̀ túbọ̀ gbòòrò.
Wọ́n gbà pé èèyàn ò gbọ́dọ̀ jẹ ẹ̀jẹ̀ ní ọ̀nà èyíkéyìí, yálà nínú oúnjẹ (wọn kì í jẹ sọ́séèjì tí wọ́n po ẹ̀jẹ̀ mọ́) tàbí nípa gbígbà á sára.
Ṣùgbọ́n, wọ́n máa ń lo àwọn ìpín kékeré látara èròjà ẹ̀jẹ̀.
Ẹnì kọ̀ọ̀kan ló máa pinnu ìyẹn . . .
Kì í ṣe pé wọ́n fẹ́ kú ni wọ́n ṣe ń sọ pé àwọn ò gbẹ̀jẹ̀, ṣe ni wọ́n fẹ́ ìtọ́jú tó péye àti àbójútó ìṣègùn tó dáa.
Wọ́n mọ̀, àwọn oníṣègùn náà sì gbà pé ìgbẹ̀jẹ̀sára léwu torí pé ẹni tó gbẹ̀jẹ̀ sára lè kó àrùn Éèdì tàbí irú àrùn míì.
Iṣẹ́ abẹ láìlo ẹ̀jẹ̀ ló fọkàn ẹni balẹ̀ jù, mo sì ti rí i nígbà tí mo ṣàyẹ̀wò àkọsílẹ̀ ìṣirò pé àwọn ọlọ́rọ̀ kì í sábà fẹ́ láti gbẹ̀jẹ̀ torí pé ìyẹn ni ò ní jẹ́ kí wọ́n kó àrùn tàbí kí wọ́n ní ìṣòro.”
Ojú tí àwọn Ẹlẹ́rìí Jèhófà fi ń wo ọrẹ.
“Ẹnì kan lè pinnu pé òun ò ní fi owó ṣètọrẹ.
Ó ṣeé ṣe kí ẹnì kan fi gbogbo ọjọ́ ayé rẹ̀ lọ sí ìpàdé àwọn Ẹlẹ́rìí Jèhófà kó má sì dá kọ́bọ̀.
Ọwọ́ ẹnì kọ̀ọ̀kan ló kù sí láti pinnu bóyá òun á fi owó ṣètọrẹ tàbí òun ò ní ṣe bẹ́ẹ̀.”
Bó tilẹ̀ jẹ́ pé ọ̀mọ̀wé Ivanenko fi ìdánilójú jẹ́rìí sí i pé àwọn Ẹlẹ́rìí Jèhófà kì í ṣe arúfin, wọ́n sì máa ń pa òfin mọ́, ilé ẹjọ́ kó àlàyé rẹ dà nù wọ́n sì ní kí àwọn arákùnrin mẹ́fẹ̀ẹ̀fà lọ lògbà tó yàtọ̀ síra lẹ́wọ̀n.
"Bí orílẹ̀-èdè Rọ́ṣíà ṣe ń bá a nìṣo láti máa fi ẹ̀sùn èké kan àwọn ará wa tí wọ́n sì ń fi wọ́n sẹ́wọ̀n láìtọ́, a ò ní yé gbàdúrà pé kí Jèhófà máa rọ̀jò ibùkún rẹ̀ sórí àwọn ará wa tí wọ́n jẹ́ onígboyà àti olóòótọ́ kí inú wọn lè máa dùn pé àwọn ní ìtẹ́wọ́gbà rẹ̀.—Sáàmù 109:2-4, 28."""
"Ní February 14, 2020, Ilé-Ẹjọ́ ìlú ńlá Vilyuchinsk dá Arákùnrin Mikhail Popov àti ìyàwó rẹ̀ Arábìnrin Yelena Popov lẹ́bi.
Ilé-Ẹjọ́ ní kí Arákùnrin Mikhail Popov san 350,000 rubles ($5,508 U.S.) owó ìtanràn, wọ́n sì ní kí ìyàwó rẹ̀ Arábìnrin Yelena Popov san 300,000 rubles ($4,722 U.S.), àmọ́ wọn ò fi wọ́n sẹ́wọ̀n rárá.
Àwọn méjèèjì máa pe ẹjọ́ kòtẹ́milọ́rùn lórí ìdájọ́ yìí.
Ìjọba mú Mikhail àti Yelena ní July 2018.
Kò sì pẹ́ tí wọ́n fi wọ́n sílẹ̀, wọ́n sì ní kí wọ́n máa dúró de ìdájọ́ wọn.
Láti ọdún 2019, ilé-ẹjọ́ orílẹ̀-èdè Rọ́ṣíà ti dá àwọn Ẹlẹ́rìí Jèhófà méjìdínlọ́gbọ̀n (28) lẹ́bi nítorí ìgbàgbọ́ wọn.
Nínú oṣù méjì tó kọjá nìkan, mẹ́wàá nínú àwọn arákùnrin àti àwọn arábìnrin wọ̀nyí ni wọ́n dá lẹ́bi. Àmọ́, wọn ò tíì fi wọ́n sẹ́wọ̀n báyìí."
"Ní Friday, August 30, 2019, Arákùnrin Valeriy Moskalenko sọ ọ̀rọ̀ àsọkágbá rẹ̀ fún ilé ẹjọ́.
Díẹ̀ rèé (tá a túmọ̀ láti èdè Rọ́ṣíà) lára ọ̀rọ̀ tó sọ níwájú ilé ẹjọ́:
Ọ̀gá Àgbà àti gbogbo ẹ̀yin ọlọ́lá tó wà níkàlẹ̀, ọmọ ọdún méjìléláàádọ́ta (52) ni mí, ọdún tó kọjá yìí ni wọ́n fi mí sí àtìmọ́lé.
Tàbí kí n kúkú sọ ní tààràtà pé ó ti lé ní ọdún kan báyìí.
Nínú ọ̀rọ̀ àsọkágbá mi fún ilé ẹjọ́ yìí, mo fẹ́ ṣàlàyé ṣókí fún yín nípa ara mi, ojú ti mo fi wo ẹ̀sùn ọ̀daràn tí wọ́n fi kàn mí àti ọwọ́ tí mo fi mú ìwàláàyè.
Ọ̀gá Àgbà, mo nírètí pé ẹ máa lóye ìdí ti mi ò fi ní sẹ́ ìgbàgbọ́ tí mo ní nínú Ọlọ́run àti ìdí kò fi sí ẹ̀ṣẹ̀ nínú kéèyàn gba Ọlọ́run gbọ́.
Ẹlẹ́rìí Jèhófà kọ́ ni mí látilẹ̀ wá.
Èèyàn rere làwọn òbí mi wọ́n sì kọ́ mi dáadáa, síbẹ̀ látìgbà tí mo ti wà lọ́mọdé ló ti máa ń dùn mí pé ìwà ìrẹ́jẹ kún ibi gbogbo.
Mo máa ń ronú pé, ‘Kì í ṣe bó ṣe yẹ kí nǹkan rí nìyí, àwọn ẹni ibi àtàwọn ẹlẹ́tàn ń gbèrú, àwọn olóòótọ́ àti ẹni rere sì ń jìyà.’
Nígbà tí mo wà lọ́mọ ọdún mẹ́rìnlélógún (24), mo ṣèwádìí gan-an nínú Bíbélì fún ọ̀pọ̀ oṣù, mo sì rí ìdáhùn sí àwọn ìbéèrè mi.
Àtìgbà ló ti jẹ́ pé kí n tó ṣe ìpinnu, mo kọ́kọ́ máa ń ronú nípa ojú tí Ọlọ́run á fi wo ohun tí mo fẹ́ ṣe, màá sì tún ronú nípa àwọn òfin àti ìlànà rẹ̀.
[Bíbélì] ṣàlàyé àwọn òfin àti ìlànà náà ní kíkún, èèyàn sì lè mọ púpọ̀ sí i nípa wọn téèyàn bá kẹ́kọ̀ọ́ nípa àwọn tó sin Ọlọ́run nígbà àtijọ́.
Inú ilé kan náà ni èmi àti màmá mi ń gbé.
Wọ́n ti dàgbà, ó sì yẹ kí n máa tọ́jú wọn.
Ní August 1, 2018, nígbà tí màmá mi nìkan wà nínú ilé, Àwọn Òṣìṣẹ́ Aláàbò ti Ìjọba (FSB) tí wọ́n ń ṣe iṣẹ́ ìwádìí sọ fún Àwọn Ọlọ́pàá Àkànṣe pé kí wọ́n fi ayùn rẹ́ ilẹ̀kùn iwájú ìta ilé wa kúrò lára férémù.
Ọ̀nà tí ẹni tó wá ṣèwádìí náà yàn láti gbà wọnú ilé mí nìyẹn o.
Ẹ̀rù ba màmá mi gan-an.
Lẹ́yìn tí Àwọn Ọlọ́pàá Àkànṣe tó da aṣọ bojú náà já wọnú ilé wa, àyà màmá mi jà débi pé wọ́n ní àrùn ọkàn wọ́n sì ní láti pe áńbúláǹsì kó wá gbé wọn.
Ọgbọ̀n ìṣẹ́jú lẹ́yìn tí mo gbọ́ pé àwọn ọlọ́pàá ti lọ sí ilé wa ni mo pa dà délé.
Nígbà tí mo rí ipò tí màmá mi wà, ìfúnpá tèmi náà ga sí i. Láìka gbogbo èyí sí, mi ò fi ṣèbínú, ṣe ni mo fọwọ́ wọ́nú.
Mò ń fi ìfẹ́ hùwà, bó ṣe yẹ kí Kristẹni ṣe.
Ohun tí Jèhófà, Ọlọ́run mi fi kọ́ mi nìyẹn, mi ò sì fẹ́ ṣe ohun tó máa mú un bínú.
Ẹ forí jì mí, Ọ̀gá Àgbà, èmi kì í sọ̀rọ̀ nípa ara mi tó báyìí.
Kì í ṣe ìwà mi, ọ̀rọ̀ ló bá mo-kó-mo-rò wá o.
Ó lé ní ọdún mẹ́ẹ̀ẹ́dọ́gbọ̀n (25) tí mo ti di Ẹlẹ́rìí Jèhófà.
Ẹ̀sìn tí mo fi èyí tó pọ̀ jù nínú ìgbésí ayé mi ṣe nìyẹn.
Látìgbà tí mo sì ti ń ṣe ẹ̀sìn náà, kò sẹ́ni tó kà mí sí agbawèrèmẹ́sìn rí.
Kàkà bẹ́ẹ̀, aládùúgbò rere làwọn èèyàn kà mí sí, ẹni tó ń fi tọkàntọkàn ṣiṣẹ́ àti ọmọ tó ń tọ́jú òbí ẹ̀.
Ṣàdédé ni wọ́n bẹ̀rẹ̀ sí í pè mí ní agbawèrèmẹ́sìn láti April 20, 2017.
Torí kí ni?
Ìwà búburú wo ní wọ́n bá lọ́wọ́ mi?
Ṣé mo ti ń hùwà àìdá ni? Rárá o.
Ṣé mo ti di oníwà ipá ni àbí mo ti di ẹni tó ń fi ìyà jẹ àwọn míì tó sì ń fa ìrora fún wọn? Rárá o.
Ṣé mi ò lẹ́tọ̀ọ́ láti jàǹfààní ohun tí Abala Kejìdínlọ́gbọ̀n nínú Òfin Orílẹ̀-Èdè Rọ́ṣíà sọ ni?
Rárá nìyẹn náà.
Orúkọ mi ò sí lára àwọn tí Ilé Ẹjọ́ Gíga Jù Lọ gbọ́ ẹjọ́ wọn.
Kò sẹ́ni tó gba ẹ̀tọ́ àtilo Òfin Orílẹ̀-Èdè Rọ́ṣíà lọ́wọ́ mi, pàápàá jù lọ Abala Kejìdínlọ́gbọ̀n.
Kí ló wá sọ mí di ẹni tó ń jẹ́jọ́ nílé ẹjọ́?
Nínú ọ̀rọ̀ tí èmi àti olùṣèwádìí jọ sọ, ó túbọ̀ ṣe kedere pé torí pé mo gba Jèhófà, Ọlọ́run Olódùmarè gbọ́ mo sì ń lo orúkọ rẹ̀ nínú àdúrà àti ọ̀rọ̀ mi ni wọ́n ṣe mú mi tí wọ́n sì fi mí sí àtìmọ́lé.
Àmọ́, ẹ̀ṣẹ̀ ò sí nínú ìyẹn.
Ọlọ́run ló sọ ara rẹ̀ lórúkọ, tó sì rí i dájú pé orúkọ náà wà nínú Bíbélì.
Mò ń sọ ọ́ léraléra pé mi ò ní ta ko ohun tí Ọlọ́run bá pa láṣẹ lọ́nà tó ṣe kedere nínú Bíbélì.
Bó sì ti wù kéèyàn yọ mí lẹ́nu tàbí kó jẹ mí níyà tó, kódà tí wọ́n bá dájọ́ ikú fún mi, mo fẹ́ kó di mímọ̀ pé mi ò ní fi Jèhófà Ọlọ́run, Ẹlẹ́dàá ayé òun ọ̀run sílẹ̀ láé.
Ọ̀gá Àgbà, ibi gbogbo kárí ayé ni wọ́n ti mọ àwọn Ẹlẹ́rìí Jèhófà sí ẹni tó dùn ún bá rìn àti ẹni tó nífẹ̀ẹ́ àlàáfíà.
Ní ọ̀pọ̀ orílẹ̀-èdè kárí ayé, wọ́n kì í fi ẹ̀tọ́ tí wọ́n ní láti gba Ọlọ́run gbọ́ dù wọ́n.
Ó máa wù mí pé ká má ṣe fi ẹ̀tọ́ àwọn Ẹlẹ́rìí Jèhófà dù wọ́n ní orílẹ̀-èdè Rọ́ṣíà náà, kò sì ní yẹ kí ilé ẹjọ́ yìí fi ẹ̀tọ́ tí mo ní láti gba Ọlọ́run gbọ́ dù mí.
Mi ò jẹ̀bi ẹ̀sùn tí wọ́n fi kàn mí, mo sì rọ ilé ẹjọ́ yìí láti má ṣe dá mi lẹ́bi!
Ẹ ṣeun!"
"Àwọn ọ̀jọ̀gbọ́n lórí ọ̀rọ̀ òfin ti àjọ Ìṣọ̀kan Àgbáyé ti sọ pé bí ìjọba Rọ́ṣíà ṣe fàṣẹ ọba mú Arákùnrin Dmitriy Mikhaylov tí wọ́n sì fi í sẹ́wọ̀n “nítorí ohun tó gbà gbọ́ fi hàn pé wọ́n hùwà àìtọ́ sí i,” wọ́n sì ti tẹ òfin àpapọ̀ àwọn ìjọba lójú.
Àwùjọ àwọn ọ̀jọ̀gbọ́n náà tún rọ ìjọba Rọ́ṣíà pé wọn ò gbọ́dọ̀ fẹ̀sùn ìwà ọ̀daràn èyíkéyìí kan Arákùnrin Mikhaylov mọ́.
Ó tó ojú ìwé méjìlá tí ìgbìmọ̀ tí wọ́n ń pè ní Working Group on Arbitrary Detention (WGAD) fi kọ èrò wọn nípa Arákùnrin Mikhaylov, wọ́n sọ pé “kò sígbà tó ṣe ohun tó dí àlàáfíà ìlú lọ́wọ́.”
Yàtọ̀ síyẹn, “kò sí ẹ̀rí kankan tó fi hàn pé òun tàbí Ẹlẹ́rìí Jèhófà èyíkéyìí lórílẹ̀-èdè Rọ́ṣíà jẹ́ oníwà ipá, wọn kì í sì í rọ àwọn míì pé kí wọ́n hùwà ipá.”
Ìgbìmọ̀ WGAD wá pinnu pé ńṣe ni Arákùnrin Mikhaylov “kàn lo ẹ̀tọ́ tó ní láti ṣe ìsìn tó wù ú” kò sì “yẹ kí wọ́n fàṣẹ ọba mú un débi tí wọ́n á fi jù ú sí àhámọ́ láìgbọ́ ẹjọ́ ẹ̀.”
Nítorí náà, ó yẹ kí ìjọba san owó ìtanràn fún un torí pé kò ráyè ṣiṣẹ́ ní gbogbo àkókò tó fi wà lẹ́wọ̀n, àti pé wọ́n jù ú sẹ́wọ̀n láì jẹ̀bi ẹ̀sùn tí wọ́n fi kàn án.
Ìgbìmọ̀ WGAD tún kíyè sí i pé kì í ṣe Arákùnrin Mikhaylov nìkan ni wọ́n ń fìyà jẹ nítorí ohun tó gbà gbọ́.
Òun náà jẹ́ “ọ̀kan lára àwọn Ẹlẹ́rìí Jèhófà lórílẹ̀-èdè Rọ́ṣíà tí wọ́n fàṣẹ ọba mú, tí wọ́n fi sẹ́wọ̀n, tí wọ́n sì ti fẹ̀sùn ìwà ọ̀daràn kàn nítorí pé wọ́n ń lo ẹ̀tọ́ tí wọ́n ní láti ṣe ìsìn tó wù wọ́n,” ó sì jẹ́ ẹ̀tọ́ tí òfin àpapọ̀ àwọn ìjọba fọwọ́ sí.
Torí náà, ìgbìmọ̀ WGAD jẹ́ kó ṣe kedere pé kì í ṣe Arákùnrin Mikhaylov nìkan lọ̀rọ̀ yìí kàn, ó tún kan bí wọ́n ṣe ń fi gbogbo àwọn Ẹlẹ́rìí Jèhófà sẹ́wọ̀n láìtọ́ “lọ́nà tó jọ ti Ọ̀gbẹ́ni Mikhaylov.”
Ọ̀dọ́ ni Arákùnrin Mikhaylov nígbà tó bẹ̀rẹ̀ sí kẹ́kọ̀ọ́ Bíbélì, ó sì ṣèrìbọmi nígbà tó pé ọmọ ọdún mẹ́rìndínlógún (16) lọ́dún 1993.
Lọ́dún 2003, ó fẹ́ Yelena, àwọn méjèèjì sì jọ ń sin Jèhófà.
Lọ́dún 2018, Arákùnrin àti Arábìnrin Mikhaylov kíyè sí i pé fún ọ̀pọ̀ oṣù làwọn aláṣẹ ti ń ṣọ́ wọn ni ti pé wọ́n ń tẹ́tí sí ọ̀rọ̀ wọn lórí fóònù, wọ́n sì tọ́jú kámẹ́rà sílé wọn.
Ní April 19, 2018, Ìgbìmọ̀ Tó Ń Ṣèwádìí ní Àgbègbè Ivanovo Lórílẹ̀-èdè Rọ́ṣíà fẹ̀sùn ìwà ọ̀daràn kan Arákùnrin Mikhaylov, làwọn ọlọ́pàá tó dira ogun bá lọ tú ilé rẹ̀ yẹ́bẹ́yẹ́bẹ́.
Kò ju oṣù kan lẹ́yìn ìyẹn, wọ́n fàṣẹ ọba mú un wọ́n sì jù ú sẹ́wọ̀n, wọ́n fẹ̀sùn kàn án pé ó ń fi owó ṣètìlẹ́yìn fáwọn “agbawèrèmẹ́sìn.”
Wọ́n tú u sílẹ̀ lẹ́yìn tó ti fẹ́rẹ̀ẹ́ lo oṣù mẹ́fà lẹ́wọ̀n.
Torí pé ìwádìí ṣì ń lọ lọ́wọ́ lórí ẹjọ́ rẹ̀, àwọn aláṣẹ ò jẹ́ kó rìnrìn-àjò, wọ́n sì ń ṣọ́ ọ lọ́wọ́ lẹ́sẹ̀ bó ṣe ń bá àwọn èèyàn sọ̀rọ̀.
Oṣù mẹ́fà ni ìjọba ilẹ̀ Rọ́ṣíà ní láti fèsì lórí ìpinnu tí ìgbìmọ̀ WGAD ṣe, wọ́n gbọ́dọ̀ jẹ́ kí ìgbìmọ̀ náà mọ̀ bóyá ẹ̀sùn ìwà ọ̀daràn tí wọ́n fi kan Mikhaylov ti parí, bóyá wọ́n ti san owó ìtanràn fún un, bóyá wọ́n sì ti ṣèwádìí nípa àwọn tó fìyà jẹ ẹ́ láìṣẹ̀.
Ó ṣeé ṣe kó jẹ́ pé ìpinnu tí ìgbìmọ̀ WGAD ṣe yìí ló mú kí ìjọba orílẹ̀-èdè Kazakhstan dá Arákùnrin Teymur Akhmedov sílẹ̀ lẹ́wọ̀n.
Lọ́dún 2017, wọ́n fàṣẹ ọba mú un, wọ́n sì rán an lọ sí ẹ̀wọ̀n ọdún márùn-ún torí pé ó ń sọ ohun tó gbà gbọ́ fáwọn ẹlòmíì láìfi dí àlàáfíà ìlú lọ́wọ́.
Gbogbo ilé ẹjọ́ tó wà ní Kazakhstan ni wọ́n gbé ẹjọ́ náà lọ, àmọ́ kò lójú, ni agbẹjọ́rò Arákùnrin Akhmedov bá gbé ẹjọ́ náà lọ sọ́dọ̀ ìgbìmọ̀ WGAD.
Nínú ìpinnu tí ìgbìmọ̀ WGAD ṣe ní October 2, 2017, wọ́n ní ìwà tí àwọn aláṣẹ orílẹ̀-èdè Kazakhstan hù kò dáa, wọ́n sì ní kí wọ́n tú Arákùnrin Akhmedov sílẹ̀.
Lẹ́yìn oṣù mẹ́fà, ààrẹ orílẹ̀-èdè Kazakhstan wá sọ ọ́ ní gbangba pé Arákùnrin Akhmedov kì í ṣe ọ̀daràn.
Ní April 4, 2018, wọ́n dá a sílẹ̀ lẹ́wọ̀n.
Yálà orílẹ̀-èdè Rọ́ṣíà máa ṣe ohun tí ìgbìmọ̀ WGAD ní kí wọ́n ṣe fún Arákùnrin Mikhaylov tàbí wọn ò ní ṣe bẹ́ẹ̀, ọkàn wa balẹ̀ torí Bíbélì sọ pé: “Aláyọ̀ ni ọkùnrin tí ó fi [Jèhófà] ṣe ibi ààbò.”
Àdúrà wa ni pé kí Jèhófà máa bójú tó àwọn arákùnrin àtàwọn arábìnrin wa tí wọ́n ń fi ẹ̀sùn ìwà ọ̀daràn kàn ní Rọ́ṣíà, kí wọ́n lè rí i pé gbogbo ẹni tó bá nígboyà tó sì gbẹ́kẹ̀ lé Jèhófà kò ní “ṣaláìní ohun rere.”​—⁠Sáàmù 34:​8, 10.
Ó jẹ́ ìgbìmọ̀ àwọn ọ̀jọ̀gbọ́n ẹlẹ́ni márùn-ún tí àjọ Ìṣọ̀kan Àgbáyé dá sílẹ̀, kí wọ́n lè máa ṣèwádìí àwọn tí ìjọba rán lọ sẹ́wọ̀n lọ́nà àìtọ́.
Ìgbìmọ̀ náà máa pinnu bóyá ìjọba ti tàpá sí òfin tí àpapọ̀ àwọn ìjọba là kalẹ̀ bó ṣe wà nínú Ìwé Ìpolongo Ẹ̀tọ́ Ọmọnìyàn Lágbàáyé àtàwọn ìwé míì.
Kí wọ́n ba à lè fìdí òtítọ́ múlẹ̀, ìgbìmọ̀ Working Group on Arbitrary Detention (WGAD) lẹ́tọ̀ọ́ láti wádìí ọ̀rọ̀ lọ́dọ̀ àwọn aláṣẹ àtàwọn iléeṣẹ́ tí kì í ṣe ti ìjọba kí wọ́n lè gba ìsọfúnni tí wọ́n nílò.
Ó tiẹ̀ lè gba pé kí wọ́n rí ẹni tí wọ́n fi sẹ́wọ̀n náà àti ìdílé rẹ̀. Lẹ́yìn náà, ìgbìmọ̀ WGAD á wá sọ ìpinnu àti àbá wọn fún ìjọba títí kan Àjọ Ẹ̀tọ́ Ọmọnìyàn ti Àjọ Ìṣọ̀kan Àgbáyé.
Bó tilẹ̀ jẹ́ pé ìgbìmọ̀ WGAD ò lè fi dandan lé e pé kí ìjọba tẹ̀ lé ìpinnu wọn, wọ́n máa ń jẹ́ kí gbogbo èèyàn lágbàáyé mọ ìpinnu tí wọ́n bá ṣe. Ìyẹn sì lè mú káwọn aláṣẹ tẹ̀ lé ìpinnu wọn."
"Láti October 9, 2018 táwọn agbófinró ti mú Anrzej Oniszczuk, tó jẹ́ ọmọ orílẹ̀-èdè Poland àti arákùnrin kan, wọn ò tíì gbọ́ ẹjọ́ wọn títí di báyìí.
Ẹ̀karùn-ún rèé tí wọ́n máa sún àkókò tó fi wà látìmọ́lé síwájú.
October 2 ni wọ́n ṣètò pé kó parí àtìmọ́lé rẹ̀, ìyẹn ọjọ́ díẹ̀ kó pé ọdún kan tó ti wà ní àhámọ́.
Arákùnrin Andrzej àti ìyàwó rẹ̀ Anna, ṣáájú kí wọ́n tó mú un lọ sí àtìmọ́lé.
Wọn ò gba Anna láyè láti rí ọkọ rẹ̀ láti oṣù mẹ́wàá sẹ́yìn
Àtìmọ́lé ni Andrzej wà látìgbà tí wọ́n ti mú un.
Orí ìdúró ló máa ń wà láti aago mẹ́fà àárọ̀ títí di aago mẹ́sàn-án alẹ́.
Ẹ̀ẹ̀kan lọ́sẹ̀ ni wọ́n fàyè gbà á láti fi omi tó ń lọ́ wọ́ọ́rọ́ wẹ̀ fún ìṣẹ́jú mẹ́ẹ̀ẹ́dógún.
Fún oṣù mẹ́wàá tó fi wà láhàámọ́, wọn ò jẹ́ kí Anna ìyàwó rẹ̀ rí i.
Lẹ́tà ni wọ́n fi ń bára wọn sọ̀rọ̀.
Ọ̀pọ̀ ìgbà ni Anna ti kọ̀wé sí àwọn aláṣẹ pé kí wọ́n gbà á láyè láti rí ọkọ rẹ̀, ṣùgbọ́n wọn ò dá a lóhùn.
Bá a ṣe sọ ṣáájú, ìgbà tí àwọn ọlọ́pàá àtàwọn ológun tó fi nǹkan bojú fipá ya wọ ilé Andrzej àtàwọn méjìdínlógún (18) míì nílùú Kirov ni wọ́n mú un.
Wọ́n fẹ̀sùn ọ̀daràn kàn àn torí ó ń kọrin ìjọba Ọlọ́run, ó sì tún ń ka ìtẹ̀jáde wa.
Lọ́dún tó kọjá, wọ́n mú Andrzej àtàwọn arákùnrin mẹ́rin míì nílùú Kirov (ìyẹn, Maksim Khalturin, ẹni ọdún mẹ́rìnlélógójì (44), Vladimir Korobeynikov, ẹni ọdún mẹ́rìndínláàádọ́rin (66), Andrey Suvorkov, ẹni ọdún mẹ́rìndínlọ́gbọ̀n (26) àti Evgeniy Suvorkov, ẹni ọdún mọ́kànlélógójì (41) sátìmọ́lé láì tíì gbọ́ ẹjọ́ wọn.
Àtìgbà yẹn ni wọ́n ti ní wọn ò gbọdọ̀ jáde nílé.
Ní báyìí, ẹjọ́ Andrzej àti tàwọn arákùnrin mẹ́rin yẹn ti wà ní Ilé Ẹjọ́ Ẹ̀tọ́ Ọmọnìyàn ti Ilẹ̀ Yúróòpù.
Lọ́dún yìí, ìjọba orílẹ̀-èdè Rọ́ṣíà tún ti fẹ̀sùn ọ̀daràn kan àwọn arákùnrin méje míì ní Kirov, Yevgeniy Udintsev tó jẹ́ ẹni àádọ́rin ọdún (70) ló dàgbà jù.
Ní báyìí, àwọn Ẹlẹ́rìí Jèhófà tí wọ́n ń kojú ẹ̀sùn ìwà ọ̀daràn ní Kirov nítorí ìgbàgbọ́ wọn ti di méjìlá (12).
Ohun tó ń ṣẹlẹ̀ sí Andrzej, Anna àtàwọn ará wa ọwọ̀n tó wà lórílẹ̀-èdè Rọ́ṣíà, ń rán wa létí ọ̀rọ̀ tí Ọlọ́run mí sí, tó sọ pé: “Ẹ máa rántí àwọn tó wà nínú ẹ̀wọ̀n, bí ẹni pé ẹ jọ wà lẹ́wọ̀n àti àwọn tí wọ́n ń fìyà jẹ, torí pé ẹ̀yin fúnra yín náà wà nínú ara.”​—⁠Hébérù 13:3."
Láàárọ̀ June 7, 2018, mẹ́wàá nínú ìyàwó àwọn Ẹlẹ́rìí Jèhófà mẹ́tàdínlógún (17) tó wà lẹ́wọ̀n lórílẹ̀-èdè Rọ́ṣíà fi lẹ́tà ránṣẹ́ sí Mikhail Fedotov, tó jẹ́ agbani-nímọ̀ràn Ààrẹ Putin àti alága Ìgbìmọ̀ Ààrẹ Lórí Ọ̀rọ̀ Aráàlú àti Ẹ̀tọ́ Ọmọnìyàn.
"Ní February 25, 2019 a kọ̀wé ránṣẹ́ sí Ilé Ẹjọ́ Ẹ̀tọ́ Ọmọnìyàn ti Ilẹ̀ Yúróòpù (ECHR), pé kí wọ́n tètè wá nǹkan ṣe sọ́rọ̀ Arákùnrin Sergey Loginov, ọ̀kan lára àwọn arákùnrin méje táwọn aláṣẹ fìyà jẹ ní ìlú Surgurt tó wà ní ìwọ̀ oòrùn ilẹ̀ Sàìbéríà.
Wọ́n ti tú àwọn arákùnrin mẹ́fà tó kù sílẹ̀, àmọ́ Arákùnrin Loginov ṣì wà látìmọ́lé látìgbà tí wọ́n ti mú un, bẹ́ẹ̀, wọn ò tíì gbọ́ ẹjọ́ rẹ̀, wọn ò sì jẹ́ kó lọ tọ́jú àwọn ọgbẹ́ tó wà lára rẹ̀.
Ní February 26, ìyẹn ọjọ́ kan lẹ́yìn tá a kọ̀wé sí Ilé Ẹjọ́ ECHR, wọ́n fèsì, èsì náà sì dáa gan-an.
Ilé Ẹjọ́ fọwọ́ sí ohun tá a béèrè, wọ́n sì pàṣẹ pé “ní kíá” kí ìjọba Rọ́ṣíà jẹ́ kí àwùjọ àwọn dókítà tó ń dá ṣiṣẹ́ ṣàyẹ̀wò Arákùnrin Loginov kí wọ́n lè mọ bí àkóbá tí ìyà tí wọ́n fi jẹ ẹ́ ṣe pọ̀ tó “nínú àgọ́ ara rẹ̀ àti nínú ọpọlọ rẹ̀” àti bóyá ara rẹ̀ ṣì le tó láti wà látìmọ́lé.
Títí di March 11, 2019, ìjọba Rọ́ṣíà ò ṣe nǹkan kan.
Ẹ̀ẹ̀kan lọ́gbọ̀n ni Ilé Ẹjọ́ ECHR máa ń ṣe irú ìdájọ́ kíákíá yìí, ó sì máa ń jẹ́ tí ẹ̀mí ẹni tọ́rọ̀ kàn bá wà nínú ewu, tí nǹkan sì lè bà jẹ́ kọjá àtúnṣe.
Ó dùn mọ́ni nínú pé Ilé Ẹjọ́ ECHR tètè wá nǹkan ṣe sọ́rọ̀ yìí láàárín ọjọ́ kan péré tá a kọ̀wé sí wọn.
Ilé Ẹjọ́ ECHR sì sọ pé wọ́n máa rí i dájú pé àwọn fojú sí bí wọ́n ṣe ń fìyà jẹ àwọn ará wa.
Lọ́wọ́lọ́wọ́ báyìí, Ẹlẹ́rìí mọ́kàndínlógún (19) ló ń jẹ́jọ́ ẹ̀sùn ìwà ọ̀daràn tí wọ́n fi kàn wọ́n ní ìlú Surgut, mẹ́ta lára wọn sì ti wà látìmọ́lé láì tíì gbọ́ ẹjọ́ wọn.
Bá a ṣe ń bá àwọn ará wa bẹ Jèhófà, ẹ jẹ́ ká máa fi ọ̀rọ̀ tó ń tuni nínú tí Jeremáyà sọ sọ́kàn pé: “Ìbùkún ni fún ọkùnrin tó gbẹ́kẹ̀ lé Jèhófà.”​—Jeremáyà 17:7."
"Ní June 6, 2019, ìyẹn ọ̀sẹ̀ méjì lẹ́yìn tí Arákùnrin Dennis Christensen pàdánù ẹjọ́ kòtẹ́milọ́rùn tó pè, àwọn alákòóso Rọ́ṣíà gbé e láti yàrá ìtìmọ́lé tó wà ṣáájú ìgbẹ́jọ́ rẹ̀ ní Oryol, lọ sí ọgbà ẹ̀wọ̀n tó wà ní àdádó, ìyẹn Penal Colony No. 3 nílùú Lgov.
Ìlú Lgov jìn tó igba (200) kìlómítà sí ibi tí àwọn ẹbí àti ọ̀rẹ́ Dennis ń gbé ní Oryol.
Nígbà tí Dennis kọ́kọ́ dé ọgbà ẹ̀wọ̀n náà, wọ́n fi àbùkù kàn án, wọ́n sì gbìyànjú láti mú kó sẹ́ ìgbàgbọ́ ẹ̀.
Àmọ́, ṣe ni Dennis gbára lé Jèhófà pátápátá, ó sì fi hàn pé òun jẹ́ alágbára àti onígboyà.​—⁠1 Pétérù 5:⁠10.
Ní Finland (láti apá òsì sí apá ọ̀tún): Mark Sanderson tó jẹ́ ara Ìgbìmọ̀ Olùdarí, Irina Christensen, àti Tommi Kauko láti Finland
Látìgbà tí wọ́n ti ti Dennis mọ́lé ni àwọn ara ti ń ti ìyàwó ẹ̀, Irina, lẹ́yìn tí wọ́n sì ń fi ìfẹ́ bójú tó o.
Ní June, Arákùnrin Mark Sanderson tó jẹ́ ọkàn lára Ìgbìmọ̀ Olùdarí àti àwọn arákùnrin míì tó ń mú ipò iwájú ṣètò bí wọ́n ṣe pàdé Irina ní Finland ki wọ́n lè fún un níṣìírí.
Ó ti tó oṣù kan báyìí tí Dennis tí wà lẹ́wọ̀n yìí.
Láìpẹ́ yìí ni wọ́n gba Irina láàyè láti máa bá Dennis sọ̀rọ̀ lẹ́ẹ̀kan lójúmọ́ lórí fóònù.
Wọ́n tún ti fọwọ́ sí i pé kó máa ṣèbẹ̀wò sọ́dọ̀ Dennis ní ọgbà ẹ̀wọ̀n.
Irina ń tún àwọn lẹ́tà tó ń fúnni níṣìírí tí Dennis kọ sí i kà
Pẹ̀lú gbogbo ohun tí Dennis àti Irina ti fara dà fún ọdún méjì sẹ́yìn, ìyẹn láti igba tí wọ́n ti mú u tí wọn sì tì í mọ́lé, síbẹ̀ wọ́n dúró láìyẹsẹ̀, wọ́n sì ń láyọ̀.
Irina sọ pé àwọn lẹ́tà tí Dennis ń kọ sí òun lọ́sọ̀ọ̀sẹ̀ máa ń gbé òun ro gan an ni.
Ọ̀kan wà lára àwọn lẹ́tà yẹn ti Irina fẹ́ràn gan an, Dennis kọ̀wé pé: “A máa ṣàṣeyọrí tá a bá ń fi ojú tó tọ́ wo nǹkan, bẹ́ẹ̀ sì rèé àìmọye nǹkan tó ń fún wa láyọ̀ la ní.”
Ó parí ọ̀rọ̀ rẹ̀ báyìí: “Torí ká lè fi hàn pé Jèhófà la fara mọ́ pé kó jẹ́ Ọba Aláṣẹ la ṣe wà láyé.
Mo mọ̀ pé ọnà wa ṣì jìn, a ò sì tíì ṣẹ́gun.
Àmọ́, mo mọ̀ pé bó pẹ́ bóyá, à máa ṣẹ́gun.
Ìyẹn dá mi lójú hán-ún hán-ún.”
Ní July 21, ní àpéjọ àgbáyé tí wọ́n ṣe ní Denmark, Arákùnrin Lett tó jẹ́ ọkàn lára Ìgbìmọ̀ Olùdarí ka lẹ́tà kan tí Dennis kọ.
Apá kan nínú lẹ́tà náà sọ pé: “Ó wù mí kí n wà pẹ̀lú yín ní àpéjọ yìí, ṣùgbọ́n ìyẹn ò ṣeéṣe báyìí torí pé mi ò tíì parí iṣẹ́ tí a yàn fún mi.
Àmọ́, ó máa ṣeéṣe lọ́jọ́ iwájú, mo sì ń wọ̀nà fún un.”
Nígbà tí Pọ́ọ̀lù wà ní àtìmọ́lé ní Róòmù, ó kọ̀wé pé: “Mò ń dúpẹ́ lọ́wọ́ Ọlọ́run mi ní gbogbo ìgbà tí mo bá rántí yín nínú gbogbo ìrawọ́ ẹ̀bẹ̀ mi lórí gbogbo yín.
Inú mi máa ń dùn ní gbogbo ìgbà tí mo bá ń rawọ́ ẹ̀bẹ̀,. . . ọ̀rọ̀ yín ń jẹ mí lọ́kàn, ẹ sì jẹ́ alájọpín pẹ̀lú mi nínú inú rere àìlẹ́tọ̀ọ́sí nínú àwọn ìdè ẹ̀wọ̀n mi àti nínú bí a ṣe ń gbèjà ìhìn rere, tí a sì ń fìdí rẹ̀ múlẹ̀ lọ́nà òfin.”​—Fílípì 1:​3, 4, 7."
"December 21, 2018 ni Arákùnrin Arkadya Akopyan, máa fara hàn kẹ́yìn nílé ẹjọ́.
Apá kan nílẹ̀ Rọ́ṣíà tí wọ́n ń pè ní Kabardino-Balkaria ni arákùnrin tó jẹ́ ẹni àádọ́rin (70) ọdún yìí ti wá, ó sì ti fẹ̀yìn tì nídìí iṣẹ́ télọ̀.
Ó ti lé lọ́dún kan tí ẹjọ́ rẹ̀ ti wà ní Ilé Ẹjọ́ Agbègbè Prohladniy, tó ń gbèjà ara rẹ̀ lórí ẹ̀sùn tí wọ́n fi kàn án pé ó ń pín ìwé àwọn tí wọ́n kà sí agbawèrèmẹ́sìn àti pé ó ń ṣagbátẹrù ìkórìíra ẹ̀sìn nínú àsọyé kan tó sọ nínú Gbọ̀ngàn Ìjọba.
Kò dájú pé adájọ́ máa dá ẹjọ́ rẹ̀ ní December 21.
Àmọ́ tí wọ́n bá dá Arákùnrin Akopyan lẹ́bi, wọ́n lè bu owó ìtanràn tó pọ̀ lé e tàbí kí wọ́n rán an lẹ́wọ̀n ọdún mẹ́rin.
Arákùnrin Akopyan wà lára àwọn Ẹlẹ́rìí Jèhófà tó lé ní ọgọ́rùn-ún (100) tí wọ́n fẹ̀sùn ọ̀daràn kàn ní Rọ́ṣíà nítorí ohun tí wọ́n gbà gbọ́.
Àdúrà wa ni pé kí gbogbo àwọn ará wa lọ́kùnrin àti lóbìnrin tí ìgbàgbọ́ wọn ò yẹsẹ̀ máa ní àlàáfíà tí Ọlọ́run nìkan lè fúnni.—Éfésù 6:11-14, 23."
"Láàárọ̀ kùtù April 10, ọdún 2018, àwọn tó ń ṣèwádìí àtàwọn ọlọ́pàá àrà ọ̀tọ̀, tí lára wọn fi nǹkan bojú tí wọ́n sì gbé ìbọn arọ̀jò ọta, já wọlé àwọn Ẹlẹ́rìí ní ìlú Ufa, olú ìlú Bashkortostan, lórílẹ̀-èdè Rọ́ṣíà, wọ́n tú gbogbo ilé wọn yẹ́bẹ́yẹ́bẹ́.
Wọ́n mú Arákùnrin Anatoliy (Tolya) Vilitkevich, àwọn aláṣẹ sì fì í sí àtìmọ́lé láì tíì gbọ́ ẹjọ́ rẹ̀.
Àwọn arábìnrin márùn-ún láti ìlú Ufa, tó fi mọ́ Alyona, ìyàwó Tolya ròyìn ohun tó ṣẹlẹ̀ nígbà tí wọ́n já wọlé wọn.
Máà bínú, ètò tó o fi ń wo fídíò kò ṣiṣẹ́.
Wa Fídíò Yìí Jáde"
"Ní July 2, 2019, ilé ẹjọ́ kan ní ìlú Krasnoyarsk, lórílẹ̀-èdè Rọ́ṣíà dájọ́ pé kí wọ́n fi Arákùnrin Andrey Stupnikov sílẹ̀, kí wọ́n má ṣe sé e mọ́lé mọ́.
Bó tilẹ̀ jẹ́ pé wọn ò sé e mọ́lé mọ́, àwọn aláṣẹ ṣì kà á sí ọ̀daràn, wọ́n sì ń bá ìwádìí lọ lórí ọ̀rọ̀ rẹ̀.
Arákùnrin Andrey Stupnikov
Ní July 3, 2018, bí ìdílé Stupnikov ṣe fẹ́ wọkọ̀ òfúrufú láàárọ̀ kùtù ní Pápákọ̀ Òfúrufú Krasnoyarsk, ní Yemelyanovo, lórílẹ̀-èdè Rọ́ṣíà.
Àwọn ẹ̀ṣọ́ aláàbọ̀ ìjọba méjì fàṣẹ ọba mú Arákùnrin Stupnikov.
Odindi oṣù mẹ́jọ ló lò ní ẹ̀wọ̀n láìjẹ́ pé wọ́n gbọ́ ẹjọ́ rẹ̀ rárá, lẹ́yìn náà ni wọ́n sé e mọ́lé láti ìparí oṣù February, 2019.
Bí arákùnrin Stupnikov ṣe sọ, ohun tójú ẹ̀ rí láàárín ọdún kan yìí ti jẹ́ kó mọ ọ̀pọ̀ nǹkan nípa ara ẹ̀ àti àjọṣe rẹ̀ pẹ̀lú Jèhófà.
Ó sọ pé: “[Èmi àti Olga] ti di Ẹlẹ́rìí Jèhófà fún ọ̀pọ̀ ọdún sẹ́yìn, àmọ́ a ò sún mọ́ Jèhófà tó báyìí rí láyé wa!
Láwọn ìgbà tí nǹkan nira gan-an, mo máa ń rí bí Bàbá wa ọ̀run ṣe ń tù mí nínú tó sì ń ràn mí lọ́wọ́.
Ó máa ń yà mí lẹ́nu láti rí bí Jèhófà ṣe ń dúró tì mí tó sì máa ń tètè dáhùn àdúrà mi!”
Arákùnrin Stupnikov parí ọ̀rọ̀ rẹ̀ pé: “Ju ti ìgbàkígbà rí lọ, ó ti wá dá mi lójú pé Jèhófà Bàbá mi lóye bí nǹkan ṣe ń rí lára mi torí pé ó mọ̀ mí dáadáa.
Ohun tó ṣẹlẹ̀ sí mi yìí ti jẹ́ kí n rí i pé ó yẹ kí n gbára lé Jèhófà pátápátá, kí n má sì máa da ara mi láàmú ju bó ṣe yẹ lọ nítorí inúnibíni.
Mo tún rí i pé èèyàn máa kábàámọ̀ tó bá pàdánù irú àjọṣe tímọ́tímọ́ bẹ́ẹ̀ pẹ̀lú Jèhófà.
Ó dá mi lójú pé tí Jèhófà bá wà pẹ̀lú wa, kò síṣòro tá ò ní lè borí.”
Láti July 1, ẹ̀sùn ìwà ọ̀daràn tí wọ́n ti fi kan àwọn arákùnrin àtàwọn arábìnrin wa lórílẹ̀-èdè Rọ́ṣíà ti tó igba ó lé mẹ́tàdínlógún (217).
Láwọn ipò kan, àwọn aláṣẹ orílẹ̀-èdè Rọ́ṣíà ti dín ìyà tí wọ́n fi ń jẹ àwọn ara wa kan kù.
Àmọ́, kì í ṣe àwọn aláṣẹ ilé ẹjọ́ la gbẹ́kẹ̀ lé, Jèhófà la gbẹ́kẹ̀ lé.
Àdúrà wa ni pé kí Jèhófà máa fún àwọn ará wa tó wà ní Rọ́ṣíà lágbára, kó sì máa dáàbò bò wọ́n.​—⁠Sáàmù 28:7."
"Ní Thursday, July 4, 2019, Ilé Ẹjọ́ Ordzhonikidzevskiy ní agbègbè Perm’ lórílẹ̀-èdè Rọ́ṣíà kéde pé Arákùnrin Aleksandr Solovyev jẹ̀bi ẹ̀sùn tí wọ́n fi kàn án, wọ́n sì ní kó san ìtanràn ohun tó fẹ́rẹ̀ẹ́ tó ẹgbẹ̀rún márùn-ún (4,731) owó dọ́là.
Ìrọ̀lẹ́ May 22, 2018 ni wọ́n fàṣẹ ọba mú Arákùnrin Solovyev ní ibùdókọ̀ ojú irin nígbà tí òun àti Anna ìyàwó rẹ̀ ń bọ̀ láti ìrìn-àjò tí wọ́n lọ lórílẹ̀-èdè míì.
Àwọn ọlọ́pàá fi ṣẹkẹ́ṣẹkẹ̀ sọ́wọ́ Arákùnrin Solovyev, wọ́n sì fi í sátìmọ́lé fúngbà díẹ̀.
Àwọn ọlọ́pàá tún mú Arábìnrin Solovyev, àmọ́ ọkọ̀ tí wọ́n fi gbé e yàtọ̀ sí ti ọkọ̀ ẹ̀.
Àwọn ọlọ́pàá tú ilé wọn yẹ́bẹ́yẹ́bẹ́ ní gbogbo òru, wọ́n sì kó àwọn fọ́tò wọn, àwọn ẹ̀rọ ìgbàlódé àti oríṣiríṣi Bíbélì.
Wọ́n da ìbéèrè bo Arábìnrin Solovyev, lẹ́yìn náà wọ́n tú u sílẹ̀, wọn ò sì fẹ̀sùn kàn án.
Àmọ́, wọ́n fẹ̀sùn ìwà ọ̀daràn kan Arákùnrin Solovyev, nígbà tó sì di May 24, wọ́n sé e mọ́lé títí di November 19, 2018.
Kó tó dìgbà tí wọ́n máa gbọ́ ẹjọ́ ẹ̀, wọ́n ò fún un lómìnira láti jáde bó ṣe fẹ́.
Agbẹjọ́rò Arákùnrin Solovyev máa pe ẹjọ́ kòtẹ́milọ́rùn lórí ẹjọ́ tí wọ́n dá fún un.
Wọ́n tún ti kọ̀wé sí Àjọ Ìṣọ̀kan Àgbáyé Tó Ń Gbógun Ti Fífini Sátìmọ́lé Lọ́nà Tí Kò Bójú Mu.
Bó tilẹ̀ jẹ́ pé inúnibíni tí wọ́n ń ṣe sáwọn ará wa lórílẹ̀-èdè Rọ́ṣíà àti láwọn orílẹ̀-èdè míì ń le sí i, a ò ní jẹ́ káwọn alátakò yìí “kó jìnnìjìnnì bá wa lọ́nàkọnà.”
Ó dá wa lójú pé Jèhófà á máa fún wa ní gbogbo ohun tá a nílò ká lè máa fara dà á títí táyé tuntun tá à ń retí fi máa dé.—Fílípì 1:28"
"Nínú oṣù October 2018, àwọn ọlọ́pàá ya wọ ilé tó ju ọgbọ̀n (30) lọ káàkiri ìwọ̀ oòrùn ilẹ̀ Rọ́ṣíà.
Wọ́n mú arákùnrin mẹ́fà àti arábìnrin méjì, wọ́n sì fi wọ́n sí àtìmọ́lé kí ilé ẹjọ́ tó gbọ́ ẹjọ́ wọn lórí ẹ̀sùn pé agbawèrèmẹ́sìn ni wọ́n.
Ní báyìí, àwọn ará lọ́kùnrin lóbìnrin tí wọ́n ti rán lọ sẹ́wọ̀n láìtọ́ jẹ́ mẹ́ẹ̀ẹ́dọ́gbọ̀n (25), wọ́n sì sọ fún àwọn méjìdínlógún (18) míì pé wọn ò gbọ́dọ̀ jáde nílé.
October 7, ní Sychyovka, Àgbègbè Smolensk​—Àwọn ọlọ́pàá àdúgbò àtàwọn agbófinró tó fi nǹkan bojú lọ tú ilé mẹ́rin, wọ́n sì mú arábìnrin méjì, ìyẹn Nataliya Sorokina tó jẹ́ ẹni ọdún mẹ́tàlélógójì (43) àti Mariya Troshina tó jẹ́ ẹni ọdún mọ́kànlélógójì (41).
Lẹ́yìn ọjọ́ méjì tí wọ́n mú wọn, Ilé Ẹjọ́ Leninsky rán àwọn arábìnrin wa lọ sí àtìmọ́lé títí di November 19, 2018.
Àmọ́ nígbà tó di November 16, 2018, Ilé Ẹjọ́ Leninsky fi oṣù mẹ́ta kún ọjọ́ táwọn arábìnrin wa máa lò látìmọ́lé, tó fi hàn pé wọ́n á wà níbẹ̀ títí di February 19, 2019 nìyẹn.
October 9, ní Kirov, Àgbègbè Kirov​—Ó kéré tán, ilé mọ́kàndínlógún (19) ni wọ́n ya wọ̀.
Wọ́n mú àwọn alàgbà ìjọ márùn-ún, wọ́n sì fi wọ́n sí àtìmọ́lé kí wọ́n tó gbọ́ ẹjọ́ wọn.
Ọmọ ilẹ̀ Rọ́ṣíà ni mẹ́rin lára wọn (ìyẹn Maksim Khalturin, Vladimir Korobeynikov, Andrey Suvorkov àti Evgeniy Suvorkov) ẹnì kan tó kù, ìyẹn Andrzej Oniszczuk, jẹ́ ọmọ ilẹ̀ Poland.
Yàtọ̀ sí Dennis Christensen tó jẹ́ ọmọ ilẹ̀ Denmark, Arákùnrin Oniszczuk ló máa jẹ́ ẹnì kejì tó wá láti orílẹ̀-èdè míì táwọn aláṣẹ Rọ́ṣíà máa mú sílẹ̀ ní Rọ́ṣíà torí ohun tó gbà gbọ́ gẹ́gẹ́ bíi Kristẹni.
October 18, ní Dyurtyuli, Republic of Bashkortostan​—Ó kéré tán, ilé mọ́kànlá (11) làwọn ọlọ́pàá ya wọ̀, wọ́n sì gba owó, káàdì tí wọ́n fi ń gbowó ní báǹkì, fọ́tò, àwọn lẹ́tà àdáni, kọ̀ǹpútà, fóònù alágbèéká àti síìmù.
Wọ́n mú Anton Lemeshev tó jẹ́ alàgbà, wọ́n sì fi sí àtìmọ́lé fún oṣù méjì kí wọ́n tó gbọ́ ẹjọ́ rẹ̀.
Nígbà tó di October 31, 2018, wọ́n dá a sílẹ̀ kó máa lọ sílé, àmọ́ wọ́n ní kò gbọ́dọ̀ jáde nílé, títí di bá a ṣe ń sọ yìí.
Láìka báwọn agbófinró ṣe ń ya wọ ilé àwọn ará, tí wọ́n sì ń gbẹ́sẹ̀ lé àwọn ohun ìní wọn lọ́nà tí kò bófin mu, àwọn ará lọ́kùnrin lóbìnrin láwọn àgbègbè yìí ń ṣèrànwọ́ tí wọ́n lè ṣe fáwọn tó wà látìmọ́lé àti ìdílé wọn, wọ́n sì ń gbàdúrà fún wọn.
Títí tí ọ̀rọ̀ yìí fi máa yanjú, ẹgbẹ́ ará kárí ayé ò ní yéé bẹ Jèhófà torí gbogbo àwọn ìránṣẹ́ rẹ̀ olóòótọ́ tó wà ní Rọ́ṣíà, kódà, àá máa dárúkọ àwọn kan nínú àdúrà wa.​—Éfésù 6:18."
"Ní Tuesday, May 7, 2019, Ilé Ẹjọ́ Agbègbè Oryol bẹ̀rẹ̀ ẹjọ́ kòtẹ́milọ́rùn tí Dennis Christensen pè torí bí wọ́n ṣe rán an lẹ́wọ̀n ọdún mẹ́fà nítorí ohun tó gbà gbọ́.
Àmọ́ ohun táwọn ilé ẹjọ́ ilẹ̀ Rọ́ṣíà sábà máa ń ṣe ni ilé ẹjọ́ yìí náà ṣe, wọn ò gba àwọn ẹ̀rí tí kò ṣeé já ní koro táwọn agbẹjọ́rò wa mú wá wọlé, wọn ò sì gbé wọn yẹ̀ wò láti rí i pé Dennis kò mọwọ́mẹsẹ̀.
Ó ṣeé ṣe kí àwọn adájọ́ mẹ́tẹ̀ẹ̀ta tó ń gbọ́ ẹjọ́ yìí sọ ìpinnu wọn títí ìparí ọ̀sẹ̀ yìí.
Ọ̀pọ̀ àwọn ará ló wá sí ilé ẹjọ́ yìí láti wá ṣètìlẹyìn fún Dennis lọ́jọ́ tí ìgbẹ́jọ́ náà bẹ̀rẹ̀.
Bákan náà, àwọn aṣojú láti oríṣiríṣi orílẹ̀-èdè wá síbẹ̀ àtàwọn akọ̀ròyìn pẹ̀lú àwọn tó ń jà fẹ́tọ̀ọ́ ọmọnìyàn.
Inú yàrá kékeré kan tí kò lè gbà ju èèyàn ogún (20) sí mẹ́ẹ̀ẹ́dọ́gbọ̀n (25) ni wọ́n ti bẹ̀rẹ̀ sí í gbọ́ ẹjọ́ náà, ìyẹ̀n sì mú kí nǹkan bí àádọ́ta (50) èèyàn dúró síta.
Àmọ́ ilé ẹjọ́ náà fara mọ́ àbá táwọn agbẹjọ́rò Dennis mú wá pé kí wọ́n jẹ́ kí gbogbo àwọn tó wá fún ìgbẹ́jọ́ náà lọ sí yàrá míì tó lè gba nǹkan bí ọgọ́rin (80) èèyàn.
Lẹ́yìn tí wọ́n lo wákàtí mẹ́ta péré lẹ́nu ìgbẹ́jọ́ náà, ilé ẹjọ́ sún ẹjọ́ náà síwájú.
Lọ́jọ́ kejì ìgbẹ́jọ́ náà, agbẹjọ́rò Dennis béèrè pé kí ilé ejọ́ náà ṣàtúnyẹ̀wò àwọn ẹ̀rí kan tó fi hàn pé Dennis ò mọwọ́mẹsẹ̀, àmọ́ àwọn adájọ́ kọ̀.
Èyí ò dáa rárá torí àwọn agbẹjọ́rò Dennis gbà pé àwọn ẹ̀rí yìí máa fi hàn pé ẹjọ́ tí ilé ẹjọ́ àkọ́kọ́ dá kò lẹ́sẹ̀ nílẹ̀.
Lópin ọjọ́ náà, ilé ẹjọ́ sọ pé ìgbẹ́jọ́ náà máa tẹ̀ síwájú ní Thursday, May 16 káwọn agbẹjọ́rò lè fẹnu ọ̀rọ̀ wọn jóná lọ́kọ̀ọ̀kan.
Àdúrà wa fáwọn ará wa ní Rọ́síà ni pé kí ọkàn wọn balẹ̀, kí ìgbàgbọ́ wọn má sì yẹ̀ nínú àwọn ìlérí tí Jèhófà ṣe pé òun máa gbà wọ́n pátápátá lọ́wọ́ àwọn tó kórìíra wọn.—Sáàmù 12:5."
"Àwọn ilé iṣẹ́ oníròyìn bíi mélòó kan gbé ìròyìn kan jáde pé, nígbà táwọn aláṣẹ ń wo ilé àwọn èèyàn ní agbègbè Kirov lórílẹ̀-èdè Rọ́ṣíà, wọ́n rí àwọn ohun kan tí wọ́n pè ní ohun ìjà tó jẹ́ ti àwọn Ẹlẹ́rìí Jèhófà.
Àmọ́ ẹni tí wọ́n rí ohun tí wọ́n pè ní ohun ìjà yìí nílé rẹ̀ kìí ṣe Ẹlẹ́rìí Jèhófà.
Àwọn àdó olóró tí wọ́n lò kù nígbà Ogun Àgbáyé Kejì ni ohun ìjà tí wọ́n láwọn rí yìí, méjì nínú wọn jẹ́ èyí tí wọ́n máa ń jù, ọ̀kan tó kù sì jẹ́ èyí tí wọ́n ń rì mọ́lẹ̀, gbogbo wọn ló ti dípẹtà, tí wọn ò sì ṣeé lò mọ́.
Ẹlẹ́rìí Jèhófà ni ìyàwó onílé yìí, kódà òun gan-an ò mọ̀ pé ọkọ òun nírú àwọn nǹkan bẹ́ẹ̀ lọ́wọ́.
Ọ̀gbẹ́ni tó ni àwọn nǹkan yìí ti fìgbà kan jẹ́ ọ̀gá nínú àwùjọ àwọn tó máa ń wá òkú àwọn ọmọ ogun tó kú nígbà Ogun Àgbáyé Kejì kí wọ́n lè sin wọ́n bó ṣe yẹ.
Tí wọ́n bá ń ṣiṣẹ́ lọ́wọ́, wọ́n sábà máa ń rí àwọn nǹkan tí wọ́n fi jagun nígbà yẹn, títí kan àwọn ohun ìjà tí kò wúlò mọ́.
Bí àwọn aláṣẹ nílẹ̀ Rọ́ṣíà ṣe ń hùmọ̀ irọ́ kí wọ́n lè bà wá lórúkọ jẹ́ pé a kìí ṣe èèyàn àlàáfíà yìí ń rán wa létí ọ̀rọ̀ tí Jésù sọ pé àwọn alátakò máa “parọ́ oríṣiríṣi ohun burúkú mọ́” àwọn ọmọlẹ́yìn òun.—Mátíù 5:11."
"Adájọ́ Ivan Belykh ti ilé ẹjọ́ agbègbè Zheleznodorozhniy ní Khabarovsk ti fi ìdájọ́ lórí ẹ̀sùn ọ̀daràn tí wọ́n fi kan Arákùnrin Valeriy Moskalenko tó jẹ́ ẹni ọdún méjìléláàádọ́ta (52) sí September 2, 2019.
August 2, 2018 ni wọ́n mú Arákùnrin Moskalenko nígbà tí àwọn Ẹ̀ṣọ́ Aláàbò Ìjọba àtàwọn ọlọ́pàá tó ń kó àwọn tó ń jà ìjà ìgboro ya wọ ilé rẹ̀.
Àwọn agbófinró gbọn ilé Arákùnrin Moskalenko yẹ́bẹ́yẹ́bẹ́ fún bíi wákàtí márùn-ún kí wọ́n tó mú un.
Àtìgbà yẹn ni wọ́n ti tì í mọ́lé láì tíì gbọ́ ẹjọ́ rẹ̀, pẹ̀lú bó ṣe jẹ́ pé ó ti wà lẹ́wọ̀n láì tíì gbọ́ ẹjọ́ rẹ̀ fún ohun tó lé ní ọdún kan báyìí, ọ̀pọ̀ ló ń ronú pé wọ́n lè dá a lẹ́bi, kí wọ́n sì fi sẹ́wọ̀n bíi ti Dennis Christensen.
Ní December 18, 2018, a kọ̀wé sí Ilé Ẹjọ́ Ẹ̀tọ́ Ọmọnìyàn ti Ilẹ̀ Yúróòpù lórí ẹjọ́ Moskalenko v. Russia..
Ẹ̀sùn tó lé ní àádọ́ta (50) ló wà níwájú ilé ẹjọ́ yìí lòdì sí ilẹ̀ Rọ́ṣíà, mẹ́rìnlélọ́gbọ̀n (34) nínú rẹ̀ sì ti dé etígbọ̀ọ́ ìjọba orílẹ̀-èdè Rọ́ṣíà.
À ń fi àwọn arákùnrin àti arábìnrin wa ní Rọ́ṣíà yangàn ‘nítorí ìfaradà àti ìgbàgbọ́ wọn nínú gbogbo inúnibíni àti àwọn ìṣòro tí wọ́n ń dojú kọ.’
Ó hàn gbangba pé Jèhófà ń tì wọ́n lẹ́yìn, ó sì ń bù kún wọn.
Àdúrà wa ni pé kí Jèhófà máa bá a lọ láti fún Arákùnrin Moskalenko ní okun tó nílò kó lè máa fara dà á pẹ̀lú ìdùnnú, láìka ohun tó lé jẹ́ àbájáde ìdájọ́ náà.​—2 Tẹsalóníkà 1:4."
"Arákùnrin Dennis Christensen ti lo ohun tó lé ní ọgọ́rùn-ún márùn-ún àti mẹ́ẹ̀ẹ́dọ́gbọ̀n (525) ọjọ́ lẹ́wọ̀n torí pé ó ń ṣe ohun tó gbà gbọ́, ó sì ti fẹ́rẹ̀ẹ́ tó àádọ́ta (50) ìgbà tó ti fara hàn nílé ẹjọ́.
Ilé Ẹjọ́ Zheleznodorozhniy nílùú Oryol ní Rọ́ṣíà, tó ń gbọ́ ẹjọ́ Dennis, ti ṣètò ìgbẹ́jọ́ náà sí àárín oṣù December.
Bó tiẹ̀ jẹ́ pé ó ti lé ní ọdún kan ààbọ̀ tí Dennis ti wà ní àtìmọ́lé, síbẹ̀ ó ṣì ń láyọ̀, ó sì gbà pé nǹkan á dáa.
Kò sí àní-àní pé Jèhófà ń gbọ́ àìmọye àdúrà tí ẹgbẹ́ ará wa kárí ayé ń gbà nítorí arákùnrin yìí, ó sì ń fún un lókun.
Ọgọ́rọ̀ọ̀rún káàdì àtàwọn ìwé tí wọ́n yàwòrán sí ni Dennis ti rí gbà látọ̀dọ̀ àwọn Ẹlẹ́rìí Jèhófà bíi tiẹ̀ ní Rọ́ṣíà àtàwọn orílẹ̀-èdè míì, tí wọ́n ń fìyẹn sọ fún un pé àwọn nífẹ̀ẹ́ rẹ̀, gbágbáágbá làwọn sì wà lẹ́yìn rẹ̀.
Níbi ìgbẹ́jọ́ rẹ̀ tí wọ́n ṣe ní October 30, Dennis fi díẹ̀ lára àwọn káàdì àtàwọn àwòrán táwọn ọmọdé fi ránṣẹ́ sí i han àwọn èèyàn látinú ẹ̀wọ̀n onígíláàsì táwọn aláṣẹ dé e mọ́, kí gbogbo àwọn tó bá wá kí i lè rí i, kó sì fún wọn níṣìírí.
Lásìkò ìsinmi ní October 30, 2018, tí ilé ẹjọ́ ń gbọ́ ẹjọ́ Dennis Christensen, ó ń fi díẹ̀ lára àwọn lẹ́tà ìṣírí táwọn ará fún un han àwọn èèyàn látinú ẹ̀wọ̀n onígíláàsì tí wọ́n dé e mọ́.
Kì í ṣe ẹgbẹ́ ará wa kárí ayé nìkan lọ̀rọ̀ Dennis ń ká lára, àwọn ẹlòmíì káàkiri ayé pàápàá ń sọ̀rọ̀ nípa rẹ̀.
Bí àpẹẹrẹ, ní July 21, 2017, Iléeṣẹ́ Ẹ̀tọ́ Ọmọnìyàn tó fìkàlẹ̀ sílùú Moscow kéde pé àwọn olóṣèlú ló fi Dennis sẹ́wọ̀n.
Ní June 20, 2018, Àjọ Tó Ń Rí sí Ẹ̀tọ́ Ọmọnìyàn ní Rọ́ṣíà sọ pé kí Ọ́fíìsì Olùpẹ̀jọ́ Ìjọba ṣèwádìí bóyá ó bófin mu láti máa fi àwọn Ẹlẹ́rìí Jèhófà sẹ́wọ̀n torí ohun tí wọ́n gbà gbọ́.
Nígbà tó tún di September 26, 2018, Àjọ Orílẹ̀-èdè Amẹ́ríkà Tó Ń Rí sí Òmìnira Ẹ̀sìn Kárí Ayé forúkọ Dennis sílẹ̀ gẹ́gẹ́ bí “ẹni tí wọ́n rán lọ sẹ́wọ̀n torí ohun tí ẹ̀rí ọkàn rẹ̀ gbà gbọ́.”
Gbangba ni ìjọba orílẹ̀-èdè Rọ́ṣíà ti sọ ọ́ nílé ẹjọ́ pé báwọn ṣe gbẹ́sẹ̀ lé àwọn ibi táwọn Ẹlẹ́rìí Jèhófà ti ń ṣe ẹ̀sìn wọn ò túmọ̀ sí pé àwọn máa dí Ẹlẹ́rìí Jèhófà kọ̀ọ̀kan lọ́wọ́ kó má ṣe ohun tó gbà gbọ́.
Àwọn agbófinró ìjọba ìbílẹ̀ àti ti ìjọba àpapọ̀ ò tẹ̀ lé ohun tí ìjọba sọ yẹn, wọ́n sì ti ṣi òfin lò kí wọ́n lè mú Dennis àti ọ̀pọ̀ àwọn míì, kí wọ́n sì fẹ̀sùn “agbawèrèmẹ́sìn” kàn wọ́n.
Lọ́dún yìí, ọ̀pọ̀ ilé àwọn Ẹlẹ́rìí ni àwọn aláṣẹ ti ya wọ̀ káàkiri orílẹ̀-èdè náà.
Lọ́wọ́lọ́wọ́ báyìí àwọn ará wa lọ́kùnrin àti lóbìnrin mẹ́ẹ̀ẹ́dọ́gbọ̀n (25) ló wà lẹ́wọ̀n, àwọn méjìdínlógún (18) wà nílé, wọ́n ní wọn ò gbọ́dọ̀ jáde nílé, àwọn míì tó sì lé ní ogójì (40) ni wọn ò jẹ́ kó lómìnira lọ́nà kan tàbí òmíì.
Ohun tó bá tẹ̀yìn ìgbẹ́jọ́ Dennis yọ ló máa pinnu ohun tó máa ṣẹlẹ̀ sáwọn Ẹlẹ́rìí Jèhófà míì tí wọ́n lé ní àádọ́rùn-ún (90), tí wọ́n wà láwọn àgbègbè tó tó ọgbọ̀n (30) ní Rọ́ṣíà, tí wọ́n ń retí èsì ìwádìí táwọn aláṣẹ ń ṣe lórí bóyá ọ̀daràn ni wọ́n lóòótọ́.
A mọ̀ pé àwọn ará wa kárí ayé ò ní dákẹ́ àdúrà sí Jèhófà, pé kó túbọ̀ máa pèsè okun fún àwọn ará wa tí wọ́n fẹ̀sùn kàn torí ohun tí wọ́n gbà gbọ́, kó sì máa bá wa gbé wọn ró, bí gbogbo wa ṣe ń retí ọjọ́ tó máa “mú kí a dájọ́ bó ṣe tọ́” fún wọn.​—Lúùkù 18:7."
"Ní April 9, 2019, Ilé Ẹjọ́ Ìlú Surgut pàṣẹ pé kí wọ́n tú Arákùnrin Yevgeniy Fedin àti Arákùnrin Sergey Loginov sílẹ̀ ní àtìmọ́lé.
Ìpinnu yìí wọ́gi lé ohun táwọn aláṣẹ ní Rọ́ṣíà béèrè pé kí wọ́n fi kún àsìkò táwọn arákùnrin yìí máa lò látìmọ́lé.
Bó tiẹ̀ jẹ́ pé ìwádìí ṣì ń lọ lọ́wọ́ lórí ẹ̀sùn ìwà ọ̀daràn tí wọ́n fi kan àwọn arákùnrin méjèèjì, wọ́n fún wọn láyè láti kúrò látìmọ́lé ní April 11.
Ìgbà táwọn aláṣẹ tú ilé ọ̀pọ̀lọpọ̀ èèyàn nílùú Surgut ní February 15, 2019 ni wọ́n mú Arákùnrin Fedin àti Arákùnrin Loginov, tí wọ́n sì tì wọ́n mọ́lé.
Lásìkò yẹn, àwọn Ẹlẹ́rìí mọ́kàndínlógún (19) làwọn aláṣẹ fẹ̀sùn ìwà ọ̀daràn kàn.
Wọ́n sì ju mẹ́ta lára wọn sátìmọ́lé láì tíì gbọ́ ẹjọ́ wọn, àwọn ni: Yevgeniy àti Sergey pẹ̀lú Arákùnrin Artur Severinchik.
Ní March 15, wọ́n tú Artur sílẹ̀.
Nígbà tí wọ́n ń kó àwọn èèyàn lóṣù February, àwọn agbofinró dá méje lára àwọn ará wa lóró, Arákùnrin Loginov sì wà lára àwọn tí wọ́n dá lóró náà.
A fi ẹjọ́ bí wọ́n ṣe dá àwọn ará wa lóró yìí sùn ní Ilé Ẹjọ́ Ẹ̀tọ́ Ọmọnìyàn ti Ilẹ̀ Yúróòpù.
Wọ́n sì ti ń gbé ọ̀ràn náà yẹ̀ wò.
Ó dá wa lójú pé Jèhófà ó ní yé fi hàn pé òun ń fiyè sí gbogbo àdúrà wa, bó ṣe ń fún àwọn ará wa olóòótọ́ lókun ní Rọ́ṣíà.—Sáàmù 10:17."
"Ní Thursday, November 14, 2019, ilé ẹjọ́ agbègbè Ordzhonikidzevskiy tó wà ní Perm dá Arákùnrin Aleksey Metsger lẹ́bi, kódà ó ní kó san owó ìtanràn ẹgbẹ̀rún lọ́nà ọgọ́rùn-ún mẹ́ta àtààbọ̀ Ruble (350,000 Rubles) ìyẹn sì fẹ́rẹ̀ẹ́ tó ẹgbẹ̀rún márùn-ún ó lé ọgọ́rùn-ún mẹ́rin àti ọgọ́ta owó dọ́là ilẹ̀ Amẹ́ríkà ($5,460 U.S.)
Arákùnrin yìí ni ẹni kejìlá (12) tí wọ́n dá lẹ́bi ní Rọ́ṣíà lọ́dún yìí lórí ẹ̀sùn tí kò jẹ́ òótọ́ tí wọ́n fi kàn wọ́n pé agbawèrèmẹ́sìn ni wọ́n.
Agbẹjọ́rò Arákùnrin Metsger máa pe ẹjọ́ kòtẹ́milọ́rùn nítorí ìdájọ́ yìí.
Ní April 25, 2019, wọ́n fi ẹ̀sùn ọ̀daràn kan Arákùnrin Metsger nítorí pé ó sọ pé ọ̀kan lára àwọn Ẹlẹ́rìí Jèhófà lòun.
Lára àwọn ẹ̀rí tí wọ́n lò lòdì sí Arákùnrin Metsger ni ọ̀rọ̀ tí òun àtàwọn kan jọ sọ nípa ẹ̀sìn táwọn yẹn sì gbohùn ẹ̀ sílẹ̀ ní bòńkẹ́lẹ́.
October 14, 2019 ni ìgbẹ́jọ́ náà bẹ̀rẹ̀, agbẹjọ́rò ìjọba sì ní kí wọ́n fi Arákùnrin Metsger sẹ́wọ̀n ọdún mẹ́ta.
Bó tilẹ̀ jẹ́ pé ilé ẹjọ́ kò sọ Arákùnrin Metsger sẹ́wọ̀n, wọ́n ti dá arákùnrin wa míì lẹ́bi, ó sì ṣeé ṣe kí wọ́n tún ṣe bẹ́ẹ̀ fún ọ̀pọ̀ lára àwọn ará wa torí ohun tí wọ́n gbà gbọ́.
Bí àwọn aláṣẹ orílẹ̀-èdè Rọ́ṣíà ṣe ń fúngun mọ́ àwọn arákùnrin wa láìnídìí, a mọ̀ pé Jèhófà máa tù wọ́n nínú, á sì máa fún wọn lókun.​—Sáàmù 119:76, 161."
"Ilé ẹjọ́ agbègbè Zheleznodorozhniy tó wà nílùú Khabarovsk máa dá ẹjọ́ Arákùnrin Yevgeniy Aksenov ní Friday, February 14, 2020, lórí ẹ̀sùn tí wọ́n fi kàn án.
Agbẹjọ́rò ìjọba fẹ́ kí wọ́n fi arákùnrin náà sẹ́wọ̀n ọdún mẹ́ta.
Ní April 21, 2018, Arákùnrin Aksenov péjọ pẹ̀lú àwọn ọ̀rẹ́ àti ojúlùmọ̀ ní yàrá àpérò ní hòtẹ́ẹ̀lì kan láti sọ̀rọ̀ nípa Bíbélì.
Níbi ìjíròrò yẹn, ó bá àwùjọ náà sọ̀rọ̀ nípa bí àwọn ìlànà Bíbélì ṣe lè mú kí ìdílé wà níṣọ̀kan.
Fún ìdí yẹn, wọ́n fẹ̀sùn “ìwà ọ̀daràn tó burú jáì” kàn án, wọ́n sì pè é lẹ́jọ́ fún “ṣíṣètò ìgbòkègbodò àwọn agbawèrèmẹ́sìn.”
Ìgbẹ́jọ́ náà bẹ̀rẹ̀ ní October 21, 2019.
Bí ìgbẹ́jọ́ Arákùnrin Aksenov ṣe ń parí lọ, àdúrà wa ni pé kí òun àti ìdílé ẹ̀ túbọ̀ gbára lé Jèhófà, kí wọ́n sì fọkàn sí ìlérí rẹ̀ pé àwọn ẹni ìdúróṣinṣin “kò ní ṣaláìní” ohunkóhun.​—Sáàmù 34:9."
"Bá a ṣe sọ nínú ìròyìn tó jáde ní May 23, 2019, Ilé Ẹjọ́ Agbègbè Oryol fara mọ́ ọn pé kí Dennis Christensen lọ sẹ́wọ̀n.
Torí náà, ẹjọ́ ẹ̀wọ̀n ọdún mẹ́fà tí wọ́n dá fún Arákùnrin Christensen ò tíì yí pa dà.
Ó ti lo ọdún méjì látìmọ́lé kí wọ́n tó dá ẹjọ́ rẹ̀, nínú òfin orílẹ̀-èdè Rọ́ṣíà, èyí ṣe rẹ́gí pẹ̀lú ọdún mẹ́ta nínú ẹ̀wọ̀n, torí náà ọ́dún mẹ́ta ló kù tí wọ́n retí pé kó lò lẹ́wọ̀n.
Ní ìrọ̀lẹ́ June 6, 2019, wọ́n mú Arákùnrin Christensen lọ sí ọgbà ẹ̀wọ̀n kan táwọn ẹlẹ́wọ̀n ti ń ṣiṣẹ́, kó lè lọ ṣẹ̀wọ̀n níbẹ̀.
A máa fi ìwé tá a kọ lórí bí wọ́n ṣe rán Arákùnrin Christensen lẹ́wọ̀n láìtọ́ ránṣẹ́ sí Ilé Ẹjọ́ Ẹ̀tọ́ Ọmọnìyàn ti Ilẹ̀ Yúróòpù (ECHR).
Ìwé tá a kọ ránṣẹ́ sí Ilé Ẹjọ́ ECHR lórí bí wọ́n ṣe tì í mọ́lé láì tíì gbọ́ ẹjọ́ rẹ̀ ṣì wà lọ́dọ̀ wọn.
A mọyì bí Arákùnrin Christensen ṣe ń fara dà á nìṣó láìka ìdájọ́ tí kò tọ́ tí wọ́n ṣe fún un sí.
Ó dá wa lójú pé Jèhófà ò ní fi í sílẹ̀, àtàwọn Ẹlẹ́rìí Jèhófà tó lé ní ẹgbẹ̀rún lọ́nà ọgọ́rùn-ún méjì (200) tí wọ́n fẹ̀sùn ìwà ọ̀daràn kàn ní lórílẹ̀-èdè Rọ́ṣíà.​—Sáàmù 27:1.
Ka ọ̀rọ̀ tí Dennis Christensen sọ ní Ilé Ẹjọ́ Agbègbè Oryol ní May 16, 2019.
Ka ọ̀rọ̀ tí Dennis Christensen sọ ní Ilé Ẹjọ́ Agbègbè Oryol ní May 23, 2019."
"Ní July 6, 2018, àwọn aláṣẹ ní ìlú Omsk, lórílẹ̀-èdè Rọ́ṣíà ju tọkọtaya kan tó jẹ́ Ẹlẹ́rìí Jèhófà sí àtìmọ́lé láì tíì gbọ́ ẹjọ́ wọn nílé ẹjọ́, Sergey àti Anastasia Polyakov lorúkọ wọn.
Èyí nìgbà àkọ́kọ́ tí wọ́n máa ju Ẹlẹ́rìí Jèhófà tó jẹ́ obìnrin sí ẹ̀wọ̀n ní Rọ́ṣíà látìgbà tí Ilé Ẹjọ́ Gíga Jù Lọ ti sọ pé kí wọ́n fòfin de iṣẹ́ àwa Ẹlẹ́rìí Jèhófà.
Nígbà tí Ilé iṣẹ́ kan tó máa ń ṣèwádìí, tí wọ́n ń pè ní SOVA Center for Information and Analysis ní ìlú Moscow, ń sọ̀rọ̀ nípa àwọn tí wọ́n jù sẹ́wọ̀n lẹ́nu àìpẹ́ yìí, ó ní:
“A gbà pé ìpinnu tí wọ́n ṣe yìí, irú bí wọ́n ṣe ń fìyà jẹ àwọn Ẹlẹ́rìí Jèhófà lápapọ̀, kò bófin mu, ẹ̀tanú ẹ̀sìn gbáà ló jẹ́.”
Lọ́wọ́lọ́wọ́ báyìí, àwọn mọ́kànlélógún (21) ọkùnrin àti obìnrin kan ló wà lẹ́wọ̀n lára àwọn ará wa ní Rọ́ṣíà torí ohun tí wọ́n gbà gbọ́.
Àdúrà wa ni pé kí wọ́n nígboyà, kó sì dá wọn lójú pé Jèhófà ni Olùrànlọ́wọ́ wọn gíga jù lọ.​—Hébérù 13:6."
"Ní March 7, 2019, Ilé Ẹjọ́ Kòtẹ́milọ́rùn tó wà ní ìlú Khanty-Mansiysk, lórílẹ̀-èdè Rọ́ṣíà wọ́gi lé ìpinnu tí Ilé Ẹjọ́ Ìlú Surgut ṣe pé kí wọ́n ti Arákùnrin Artur Severinchik mọ́lé.
Wọ́n sì tú u sílẹ̀ nínu àtìmọ́lé ní March 15.
Arákùnrin Severinchik wà lára àwọn arákùnrin mẹ́ta tí wọ́n jù sí àtìmọ́lé ní February 17, lẹ́yìn táwọn aláṣẹ ya wọlé àwọn èèyàn ní ìlú Surgut àti Lyantor.
Ilé ẹjọ́ ò fọwọ́ sí i pé kí wọ́n tú àwọn arákùnrin méjì tó kù sílẹ̀, ìyẹn Yevgeniy Fedin àti Sergey Loginov.
Ọ̀pọ̀ ìjọba àtàwọn oníròyìn kárí ayé ló ti gbọ́ nípa ọ̀rọ̀ yìí.
Ilé Ẹjọ́ Ẹ̀tọ́ Ọmọnìyàn ti Ilẹ̀ Yúróòpù pàṣẹ pé kí wọ́n jẹ́ káwọn dókítà ṣàyẹ̀wò ìlera Arákùnrin Loginov, torí bí wọ́n ṣe lù ú lálùbami nígbà tí wọ́n tì í mọ́lé.
A dúpẹ́ pé wọ́n tú Arákùnrin Severinchik sílẹ̀.
Àdúrà wa ni pé kí àwọn ará wa tó wà lẹ́wọ̀n ní Rọ́ṣíà gbẹ́kẹ̀ lé Jèhófà, kí wọ́n sì máa rántí pé bó ṣe ń ràn wọ́n lọ́wọ́, ‘mìmì kan ò ní mì wọ́n.’​—Sáàmù 16:8."
"Láàárín oṣù méjìdínlógún (18) tó kọjá, nǹkan bí ọgọ́rùn-ún mẹ́fà àti mẹ́tàlá (613) ilé àwọn arákùnrin wa ni àwọn ọlọ́pàá àti ẹ̀ṣọ́ aláàbò orílẹ̀-èdè Rọ́ṣíà, ìyẹn Federal Security Service (FSB) ti lọ gbọ̀n yẹ́bẹ́yẹ́bẹ́.
Nígbà tó fi máa di January 2019, ilé ọgọ́rùn-ún mẹ́ta àti méjìlélọ́gbọ̀n (332) ni àwọn aláṣẹ ti lọ tú, èyí sì ju àpapọ̀ ilé tí wọ́n tú ní 2018 lọ, tó jẹ́ ọgọ́rùn-ún méjì àti mọ́kànlélọ́gọ́rin (281).
Ṣe ni iye ilé àwọn ará wa táwọn agbófinró ń ya wọ̀ láwọn oṣù díẹ̀ sẹ́yìn túbọ̀ ń pọ̀ sí i.
Bí àpẹẹrẹ, ilé mọ́kànléláàádọ́rin (71) ni wọ́n ya wọ̀ lóṣù June, nígbà tí ti July jẹ́ méjìdínláàádọ́rin (68), èyí sì lọ sókè gan-an ní ìfiwéra pẹ̀lú iye ilé mẹ́tàlélógún àti ẹ̀sún mẹ́rin (23.4) ní ìpíndọ́gba tí wọ́n ya wọ̀ lóṣooṣù lọ́dún 2018.
Àwọn ọlọ́pàá orílẹ̀-èdè Rọ́ṣíà ń fipá wọ ilé kan ní Nizhniy Novgorod
Lọ́pọ̀ Ìgbà, ṣe ni ọ̀pọ̀ àwọn ọlọ́pàá tí wọ́n dira ogun tí wọ́n sì fi nǹkan bojú máa ya wọ ilé kan ṣoṣo.
Bí wọ́n bá ti rọ́nà wọlé, ọ̀pọ̀ ìgbà ni wọn máa ń na ìbọn sí àwọn ará wa títí kan àwọn àgbàlagbà àti àwọn ọmọdé bí i pé ògbólógbòó ọ̀daràn ni wọ́n wá mú.
Abájọ tí ọ̀pọ̀ àwọn ọ̀jọ̀gbọ́n fi gbà pẹ̀lú ohun tí Dókítà Derek H. Davis sọ.
Òun ni ọ̀gá tẹ́lẹ̀ ní ilé ẹ̀kọ́ J.M. Dawson Institute of Church-State Studies ní Baylor University níbi tí wọ́n ti ń kọ́ Ẹ̀kọ́ Nípa Àjọṣe Tó Wà Láàárín Ìsìn àti Ìjọba, ó sọ pé:
“Inúnibíni tó rorò tí ìjọba orílẹ̀-èdè Rọ́ṣíà ń ṣe sí àwọn èèyàn alálàáfíà bí i ti àwọn Ẹlẹ́rìí Jèhófà ti jẹ́ ká rí i pé ìjọba gan-an ni ‘agbawèrèmẹ́sìn.’”
Ó ṣeni láàánú pé, bí iye ilé tàwọn aláṣẹ ń ya wọ̀ ṣe ń pọ̀ sí i bẹ́ẹ̀ ni iye ẹ̀sùn ọ̀daràn tí wọ́n ń fi kan àwọn ará wa túbọ̀ ń pọ̀ sí i.
Àwọn ará wa tí iye wọn jẹ́ igba ó lé mẹ́rìnlélógójì (244) ni wọ́n fẹ̀sùn ọ̀daràn kàn ní orílẹ̀-èdè Rọ́ṣíà àti ní ilẹ̀ Crimea báyìí.
Èyí sì ju ìlọ́po méjì ẹ̀sùn ọ̀daràn tí wọ́n fi kàn wọ́n ní December 2018 lọ, èyí tó jẹ́ àádọ́fà (110) nígbà yẹn.
Nínú àwọn igba ó lé mẹ́rìnlélógójì (244) ará wa tó ń jẹ́jọ́, mọ́kàndínlógójì [39] nínú wọn ló wà ní àtìmọ́lé, wọ́n fòfin de àwọn mẹ́tàdínlọ́gbọ̀n (27) pé wọn ò gbọ́dọ̀ jáde nílé, nígbà tí wọ́n fún àwọn tó lé ní ọgọ́rùn-ún kan (100) ni onírúurú ìkálọ́wọ́kò.
Bó tilẹ̀ jẹ́ pé àwọn aláṣẹ orílẹ̀-èdè Rọ́ṣíà ṣì ń bá a lọ láti máa ṣe inúnibíni sáwọn ará wa, síbẹ̀ ‘àwọn ìpọ́njú yìí ò ní mú ká yẹsẹ̀.’
Kàkà bẹ́ẹ̀, àwọn ìròyìn tá à ń gbọ́ nípa bí àwọn ará wa ṣe jẹ́ adúróṣinṣin tí wọ́n sì ń lo ìfaradà túbọ̀ ń fún wa níṣìírí.
Torí náà, a dúpẹ́ lọ́wọ́ Jèhófà fún bó ṣe ń dáhùn àdúrà tá à ń gbà nítorí àwọn ará wa yìí, ó sì dá wa lójú pé á túbọ̀ máa gbọ́ àdúrà wa.​—1 Tẹsalóníkà 3:​3, 7."
"Ọ̀kan lára àwọn mọ́kàndínlógún (19) tó ṣèrìbọmi
Ní July 20 sí 21, 2019, àwọn ará wa ṣe àpéjọ àgbègbè àkọ́kọ́ ní èdè Rómánì ní Slovakia nínú pápá ìṣeré tí wọ́n ń pè ní Winter Stadium ní Michalovce.
Ẹgbẹ̀rún kan, ọgọ́rùn-ún méjì àti mẹ́rìndínlọ́gọ́rin (1,276) ló pésẹ̀ sí àpéjọ ọlọ́jọ́ méjì yìí, nígbà tí àwọn mọ́kàndínlógún (19) sì ṣèrìbọmi.
Àwọn ará láti orílẹ̀-èdè mẹ́rin ọ̀tọ̀ọ̀tọ̀ ló pésẹ̀ sí àpéjọ yìí, ìyẹn Belgium, Czech Republic, Great Britain àti Ukraine.
Ohun tó wú àwọn tó wá síbẹ̀ lórí jù ni bí wọ́n ṣe wo fíìmù Ìtàn Jòsáyà: Nífẹ̀ẹ́ Jèhófà; Kórìíra Ohun Búburú, ní èdè ìbílẹ̀ wọn.
November 2014 ni wọ́n dá ìjọ àkọ́kọ́ lédè Rómánì sílẹ̀ ní Slovakia, ọdún márùn-ún péré lẹ́yìn náà ni àpéjọ yìí sì wáyé.
Lọ́wọ́lọ́wọ́ báyìí, ìjọ mẹ́sàn-án, àwùjọ mẹ́wàá àti àwọn tó fẹ́ di àwùjọ mẹ́rìnlá (14) tó ń sọ èdè Rómánì ni ẹ̀ka ọ́fíìsì Czech-Slovak ń bójú tó.
Peter Tirpak, alábòójútó pápá ìṣeré náà sọ pé:
“Bí àwọn Ẹlẹ́rìí Jèhófà ṣe fọwọ́ sowọ́ pọ̀ pẹ̀lú wa wú wa lórí gan-an.
Ẹ máa ń dúró lórí ọ̀rọ̀ yín.
Inú wa máa dùn tẹ́ ẹ bá tún pa dà wá.”
Peter Varga, tó jẹ́ alábòójútó àpéjọ sọ pé: “Mí ò tíì ṣe irú àpéjọ yìí rí.
Mánigbàgbé ni àpéjọ yìí jẹ́ fún àwọn ará wa tó ń sọ èdè Rómánì.
Lẹ́yìn orin ìparí, ṣé ni wọ́n bẹ̀rẹ̀ sí í dì mọ́ra wọn bó tiẹ̀ jẹ́ pé wọn ò mọ ara wọn rí.
Ọ̀pọ̀ ló ń da omijé ayọ̀ lójú.”
A bá àwọn ẹgbẹ̀rún kan àti mẹ́wàá (1,010) akéde tó ń sọ èdè Rómánì ní Slovakia yọ̀. Àpéjọ yìí jẹ́ ká rí ojúlówó ìfẹ́ ará tó wà láàárín àwọn èèyàn Jèhófà.​—Jòhánù 13:34,35."
"Ní Friday, July 19, 2019, lọ́jọ́ àkọ́kọ́ Àpéjọ Àgbáyé tá a pe àkọlé rẹ̀ ní, “Ìfẹ́ Kì Í Yẹ̀ Láé”! tá a ṣe ní Madrid, lórílẹ̀-èdè Spain, àwọn Ẹlẹ́rìí Jèhófà mú Bíbélì Mímọ́ ti Ìtumọ̀ Ayé Tuntun tá a tún ṣe jáde lédè Sípáníìṣì.
Ọjọ́ pẹ́ tá a ti ń retí ẹ̀! Bíbélì tá a tún ṣe yìí ti wà lórí ìkànnì jw.org®, àwọn arákùnrin àtàwọn arábìnrin wa kárí ayé tó lé ní mílíọ̀nù méjì àtààbọ̀ tó ń sọ èdè Spanish lè kà á níbẹ̀ tàbí wà á jáde.
Àwọn tó ń sọ èdè yìí ló pọ̀ jù lọ nínú àwọn Ẹlẹ́rìí Jèhófà. *
Arákùnrin Gerrit Lösch, tó jẹ́ ọkàn lára Ìgbìmọ̀ Olùdarí mú Bíbélì yìí jáde nínú fídíò tí a ti gbà ohùn àti àwòrán rẹ̀ sílẹ̀ ní àpéjọ àgbáyé tó wáyé ní pápá Ìṣeré Wanda Metropolitano nílùú Madrid.
A ṣe àtagbà fídíò yìí sí ibi mọ́kànlá (11) míì ní orílẹ̀-èdè Spain.
Kété lẹ́yìn náà, a gbé fídíò náà sórí ètò JW Broadcasting®.
Inú àwọn tó pé jọ dùn nígbà tí a mú Bíbélì tí a tún ṣe jáde lédè Sípáníìṣì
Níbi àpéjọ náà, a ṣe àkànṣe ètò tó máa jẹ́ kí àwọn tó wà níbẹ̀ lè wa Bíbélì yìí jáde ní ẹ̀dà EPUB, JWPUB tàbí PDF lórí ìkànnì jw.org.
Àwọn arákùnrin àtàwọn arábìnrin tó wà láwọn ibi mọ́kànlá yòókù ní orílẹ̀-èdè Spain níbi tá a ṣe àtagbà ètò yìí sí ní àǹfààní láti wa ẹ̀dà Bíbélì yìí sórí fóònú tàbí ẹ̀rọ alágbèéká wọn nípa lílo ètò ìṣiṣẹ́ íńtánẹ́ẹ̀tì JW Box tí àwọn Ẹlẹ́rìí Jèhófà dìídì ṣe.
Ó lé ní ẹgbẹ̀rún kan àti ọgọ́rùn-ún méjì (1,200) àwọn tó yọ̀ǹda ara wọn tó ti wà ní sẹpẹ́ níbi àpéjọ àgbáyé yìí àti láwọn ibòmíì tá a ṣètò láti ṣèrànwọ́ fún àwọn tó wá kí wọ́n lè wa Bíbélì sórí fóònù wọn.
Àwọn arákùnrin àti arábìnrin ń wa Bíbélì tuntun tá a mú jáde ní èdè Sípáníìṣì sí orí ẹ̀rọ alágbèéká wọn
Ìpèníjà ńlá ni iṣẹ́ ìtumọ̀ Bíbélì ní èdè Sípáníìṣì jẹ́, torí ọ̀nà tí wọ́n gbà ń sọ èdè Sípáníìṣì kárí ayé yàtọ̀ síra.
Arákùnrin Pedro Gil, ọkàn lára Ìgbìmọ̀ Ẹ̀ka ní orílẹ̀-èdè Spain sọ pé: “Kárí ayé, nǹkan bí ẹ̀ẹ́dẹ́gbẹ̀ta ó lé mẹ́tàdínlọ́gọ́rin (577) mílíọ̀nù èèyàn ló ń sọ èdè Spanish, àmọ́ àwọn ọ̀rọ̀ àtàwọn àgbékalẹ̀ wọn ní ìtumọ̀ tó yàtọ̀ síra láti orílẹ̀-èdè kan sí òmíràn.
Yàtọ̀ sí ìyẹn, èdè Sípáníìṣì tí à ń sọ báyìí ti yàtọ̀ pátápátá sí bí àwọn èèyàn ṣe ń sọ ọ́ lọ́pọ̀ ọdún sẹ́yìn.”
Ọ̀dọ́ kan tó yọ̀ǹda ara rẹ̀, ń ran arábìnrin kan lọ́wọ́ láti wa Bíbélì tuntun yìí jáde.
Ká lè ran àwọn atúmọ̀ èdè lọ́wọ́ láti ṣe ìtumọ̀ tó péye tó sì rọrùn láti kà, a kàn sí nǹkan bí ọgọ́rùn-ún kan (100) àwọn arákùnrin àtàwọn arábìnrin tó wà ní orílẹ̀-èdè ọ̀tọ̀ọ̀tọ̀ láti ràn wá lọ́wọ́.
Gbogbo ẹ̀ gba nǹkan bí ọdún mẹ́rin àtààbọ̀ kó tó parí.
Arákùnrin Gil sọ pé: “Èdè tó bágbà mu tá a lò nínú Bíbélì Ìtumọ̀ Ayé Tuntun tá a tún ṣe lédè Sípáníìṣì yìí máa tètè yé àwọn tó bá kà á.
Nípa bẹ́ẹ̀, á rọrùn fún àwọn akéde láti lò lóde ẹ̀rí àti ní ìpàdé.
Inú wa dùn pé àtúnṣe yìí á jẹ́ kí àwọn arákùnrin àti àwọn arábìnrin tó ń sọ èdè Sípáníìṣì sún mọ́ Jèhófà sí i.”
A dúpẹ́ lọ́wọ́ Jèhófà fún ìtumọ̀ tuntun tó ń mú ìyìn bá orúkọ rẹ̀.
A nígbàgbọ́ pé Bíbélì tá a tún ṣe yìí máa ran àwọn Ẹlẹ́rìí Jèhófà lọ́wọ́ láti máa bá a lọ láti wàásù “dé ibi tó jìnnà jù lọ ní ayé.”​—Ìṣe 1:8.
ìpínrọ̀ 2 Iye Bíbélì tá a fẹ́ tẹ̀ jáde lédè yìí pọ̀ gan-an, torí náà, a ò pín ẹ̀dà Bíbélì tá a ṣẹ̀ṣẹ̀ mú jáde ní àpéjọ yìí.
Àmọ́, àwọn ìjọ tó ń sọ èdè Sípáníìṣì máa rí ẹ̀dà Bíbélì yìí gbà ní kété tó bá ti wà lárọ̀ọ́wọ́tó.
A máa gbé e sí orí JW Library® lẹ́yìn ọjọ́ Monday, July 22."
"Ọjọ́ Àpéjọ: July 19-21, 2019
Ibi Àpéjọ: Pápá Ìṣeré Wanda Metropolitano nílùú Madrid lórílẹ̀ èdè Spain
Àwọn Èdè Tí A Lò Fún Ìtòlẹ́sẹẹsẹ: Gẹ̀ẹ́sì, Sípáníìṣì, Èdè Adití Lọ́nà Ti Sípáníìṣì
Iye Àwọn Tó Wá: Ẹgbẹ̀rún méjìléláàdọ́ta, ọgọ́rùn-ún márùn-un àti mẹ́rìndínlógún (52,516)
Iye Àwọn Tó Ṣe Ìrìbọmi: Ọgọ́rùn-ún mẹ́rin àti mẹ́rìnlélọ́gbọ̀n (434)
Iye Àwọn Tó Wá Láti Orílẹ̀-Èdè Míì: Ẹgbẹ̀rún mẹ́fà àti ọgọ́rùn-ún mẹ́ta (6,300)
Àwọn Ẹ̀ka Ọ́fíìsì Tí Àlejò Ti Wá: Albania, Argentina, Bulgaria, Kánádà, Amẹ́ríkà Àárín, Dominican Republic, Gánà, Hungary, Kòríà, Netherlands, Peru, Slovenia, Taiwan, Tọ́kì àti Amẹ́ríkà
Ìrírí Tó Ṣẹlẹ̀ Lágbègbè Náà: César López, tó jẹ́ olùdarí òtẹ́ẹ̀lì tàwọn àlejò dé sí sọ pé: “Ìrírí àrà ọ̀tọ̀ lèyí jẹ́ fún wa.
Ọ̀kan lára àwọn nǹkan tàwọn òṣìṣẹ́ wa ò lè ṣe kí wọ́n má sọ̀rọ̀ nípa ẹ̀ ni irú ẹni tàwọn àlejò tó wá síbi ayẹyẹ yìí jẹ́, wọ́n ń rẹ́rìn-ín músẹ́, wọ́n nìwà ọmọlúàbí, wọ́n sì ṣeé sún mọ́.
Mo gbà pé àwọn àlejò yìí ti kọ́kọ́ kẹ́kọ̀ọ́ nípa àkòrí àpéjọ yín, ìyẹn “Ìfẹ́ Kì Í Yẹ̀ Láé” kí wọ́n tó wá síbí.
Gbogbo àwọn tó dé sí òtẹ́ẹ̀lì wa ni wọ́n fìfẹ́ hàn sí wa.
Inú wa máa dùn láti rí àwọn àlejò yín nígbà míì.”"
"Òjò àrọ̀ọ̀rọ̀dá ba nǹkan jẹ́ gan-an ní apá ìlà oòrùn Sípéènì láàárín oṣù September sí October 2019.
Èyí tó ṣọṣẹ́ jù ni èyí tó wáyé ní October 23 lágbègbè Tarragona nígbà tí Odò Francoli kún àkúnya.
Ó bani nínú jẹ́ pé èèyàn márùn-ún ló kú nínú ìṣẹ̀lẹ̀ yìí. Àwọn arákùnrin méjì tí wọ́n ń bọ̀ láti ìpàdé wà lára wọn.
Ṣe ni omi ṣàdédé gbé mọ́tò wọn lọ nígbà tí wọ́n fẹ́ kọjá lórí afárá kan.
Àwọn alàgbà ń tu àwọn ará nínú torí ìṣẹ̀lẹ̀ láabi tó ṣẹlẹ̀ sáwọn arákùnrin wa wọ̀nyìí.
Arákùnrin kan tó wà lára Ìgbìmọ̀ Ẹ̀ka orílẹ̀-èdè Sípéènì náà ti ṣèbẹ̀wò sí ìjọ yẹn kó lè túbọ̀ tù wọ́n nínú.
Àdúrà wa ni pé kí Jèhófà máa tu àwọn ará wa nínú lásìkò àdánwò yìí.—2 Kọ́ríńtì 1:3, 4."
"Láti January 1, ọdún 2000, ni ìjọba orílẹ̀-èdè Sweden ti ń lo Òfin Tó Wà fún Ṣíṣe Ìtìlẹ́yìn fún Ẹ̀sìn láti máa fowó ìjọba ṣètìlẹ́yìn fun àwọn ẹlẹ́sìn.
Àwọn ẹ̀sìn tí wọ́n ń fi owó tì lẹ́yìn láwọn ẹ̀sìn tó ń “fi ìlànà táá jẹ́ káwọn èèyàn máa gbé ní ìrẹ́pọ̀ kọ́ni, tí kì í jẹ́ kí irú ìlànà bẹ́ẹ̀ pa rẹ́” àti ẹ̀sìn“tó ṣeé gbára lé tó sì ń nípa rere lórí àwọn èèyàn.”
Bó tiẹ̀ jẹ́ pé èyí tó pọ̀ jù nínú ẹ̀sìn tó wà ní Sweden nìjọba ń fowó tì lẹ́yìn, láti ọdún 2007 ló ti kọ̀ láti máa fowó ṣètìlẹ́yìn fún àwọn Ẹlẹ́rìí Jèhófà, torí pé wọ́n kì í dá sí ọ̀rọ̀ òṣèlú.
Lẹ́yìn ọ̀pọ̀ ìsapá, àwọn ará gbé ìjọba orílẹ̀-èdè Sweden lọ sílé ẹjọ́ nígbà mẹ́ta ọ̀tọ̀ọ̀tọ̀.
Ìgbà mẹ́tẹ̀ẹ̀ta ni Ilé Ẹjọ́ Gíga dẹ́bi fún ìjọba orílẹ̀-èdè Sweden pé ohun tí wọ́n ṣe ò bófin mu bí wọ́n ṣe kọ̀ láti fi owó ìjọba ṣètìlẹ́yìn fún àwa Ẹlẹ́rìí Jèhófà, àti pé wọ́n gbọ́dọ̀ yí ìpinnu náà pa dà.
Níkẹyìn, ìjọba orílẹ̀-èdè Sweden yí ìpinnu wọn pa dà ní October 24, ọdún 2019, wọ́n sì gbà pé àwọn Ẹlẹ́rìí Jèhófà “kúnjú ìwọ̀n gbogbo ohun tí òfin béèrè fún” láti rí owó ìtìlẹ́yìn ìjọba gbà.
Irú ẹ̀ tún ṣẹlẹ̀ lẹ́nu àìpẹ́ yìí ní orílẹ̀-èdè Norway, níbi tí ìjọba ti máa ń fún gbogbo ẹ̀sìn, tó fi mọ́ àwọn Ẹlẹ́rìí Jèhófà, ní owó ìtìlẹ́yìn lóòrèkóòrè.
Ṣùgbọ́n, ní àwọn oṣù mélòó kan sẹ́yìn, wọ́n ní kí ìjọba tún yẹ̀ ẹ́ wò dáadáa bóyá ó yẹ kí wọ́n máa fi owó ìjọba ṣètìlẹ́yìn fún àwọn Ẹlẹ́rìí Jèhófà torí pé wọn kì í dá sí ọ̀rọ̀ òṣèlú.
Èyí wá mú kí àwọn ará wa fún àwọn aláṣẹ orílẹ̀-èdè Norway ní ìsọfúnni tó péye nípa ojú tá a fi ń wo ọ̀rọ̀ òṣèlú.
Wọ́n tún fún ìjọba ní ẹ̀dà àwọn ìwé tó ṣàlàyé bí Ilé Ẹjọ́ Ìṣàkóso Gíga Jù Lọ Lórílẹ̀-Èdè Sweden ṣe dá wa láre àti bí àwọn ilé ẹjọ́ míì ṣe dá wa láre ní orílẹ̀-èdè Jámánì àti Ítálì.
Inú wa dùn pé ní November 18, ọdún 2019, àwọn aláṣẹ orílẹ̀-èdè Norway sọ pé ìjọba gbódọ̀ máa fi owó ṣètìlẹyìn fáwọn Ẹlẹ́rìí Jèhófà, ohun tí wọ́n fi parí ọ̀rọ̀ wọn ni pé:
“Ẹ̀tọ́ àwọn ọmọ ìbílẹ̀ orílẹ̀-èdè Norway ló jẹ́ láti dìbò nígbà ìdìbò, àmọ́ kì í ṣe tipátipá fẹ́ni tí kò bá wù.
Ó jọ pé lára ohun táwọn Ẹlẹ́rìí Jèhófà gbà gbọ́ ni pé kò yẹ káwọn máa dìbò, . . . [ṣùgbọ́n] kò wá yẹ kí [ìjọba] rí èyí bí . . . ìdí tó bófin mu láti má ṣe fún àwọn Ẹlẹ́rìí Jèhófà ní owó tí ìjọba fi ń ṣètìlẹ́yìn.”
Nígbà tí Arákùnrin Dag-Erik Kristoffersen, láti ẹ̀ka ọ́fíìsì ilẹ̀ Scandinavia, ń sọ̀rọ̀ lórí ìpinnu yìí, ó ní:
“Inú wa dùn pé ìjọba ti wá rí i pé à ń ṣe ohun tó dáa fáwọn aráàlú.
A nírètí pé àwọn orílẹ̀-èdè míì tí ìjọba ti ń fowó ṣètìlẹ́yìn fáwọn ẹlẹ́sìn á kíyè sí ẹjọ́ tílé ẹjọ́ dá yìí.”
Ju gbogbo rẹ̀ lọ, a fi ọpẹ́ fún Jèhófà, Afúnnilófin wa Gíga Jù Lọ.—Àìsáyà 33:22."
"Ní September 26, 2018, Ilé Ẹjọ́ Gíga Jù Lọ ní “Donetsk People’s Republic” (DPR) sọ pé “agbawèrèmẹ́sìn” ni àjọ ẹ̀sìn àwọn Ẹlẹ́rìí Jèhófà, torí náà wọ́n fòfin de iṣẹ́ wa.
Kò sí ìkankan nínú àwọn tó pe ẹjọ́ yìí, títí kan Ilé tó dá ẹjọ́ náà tó béèrè ọ̀rọ̀ lẹ́nu Ẹlẹ́rìí Jèhófà kankan nígbà tí ẹjọ́ náà ń lọ lọ́wọ́.
Ìfòfindè yìí ni ìgbésẹ̀ tuntun tí wọ́n gbé nínú bí wọ́n ṣe ń ṣe inúnibíni sí àwọn Ẹlẹ́rìí Jèhófà lágbègbè yìí torí ẹ̀sìn wọn.
Láti àárín ọdún 2017 tí Ilé Ẹjọ́ Gíga Jù Lọ nílẹ̀ DPR ti sọ pé lára àwọn ìtẹ̀jáde wa jẹ́ ti àwọn “agbawèrèmẹ́sìn,” ńṣe ni nǹkan túbọ̀ ń burú sí i fún àwọn ará wa láwọn agbègbè kan ní Donetsk àti Luhansk, ní ìlà oòrùn ilẹ̀ Ukraine.
Kí ọdún yẹn tó parí, àwọn Ẹlẹ́rìí Jèhófà táwọn ọlọ́pàá mú kí wọ́n lè da ìbéèrè bò wọ́n lé ní àádọ́sàn-án (170).
Àwọn aláṣẹ agbègbè náà sì tún ṣètò bí wọ́n ṣe ń gba àwọn Gbọ̀ngàn Ìjọba ní kọ̀ọ̀kan.
Iye gbogbo Gbọ̀ngàn Ìjọba tí wọ́n ti gbà títí di August 29, 2018 jẹ́ mẹ́rìnlélógún (16).
Lójú gbogbo àtakò ẹ̀sìn yìí, àwọn ará wa láwọn agbègbè yìí gbẹ́kẹ̀ lé ‘Ọlọ́run ìgbàlà wa.’—Sáàmù 18:46."
"Ní July 6 sí 8, 2018, àwọn Ẹlẹ́rìí Jèhófà lórílẹ̀-èdè Ukraine kí ẹgbẹẹgbẹ̀rún àwọn ará káàbọ̀ síbi àkànṣe àpéjọ tó wáyé ní ìlú Lviv, lórílẹ̀-èdè Ukraine.
Ó ju ẹgbẹ̀rún mẹ́ta ó lé ọgọ́rùn-ún mẹ́ta (3,300) èèyàn láti orílẹ̀-èdè mẹ́sàn-án tó wá sí Ukraine láti wá gbádùn ètò tó dá lórí Bíbélì náà, àkòrí ètò náà ni “Jẹ́ Onígboyà”!
Àwọn ará ní Ukraine sì ṣaájò wọn gan-an.
Oṣù April 2017 ni wọ́n ti bẹ̀rẹ̀ sí í múra sílẹ̀ fún àpéjọ náà, lóṣù mẹ́ẹ̀ẹ́dógún (15) tó tẹ̀ lé e, àwọn ará tó wà lágbègbè náà yọ̀ǹda ara wọn láti ṣètò àpéjọ náà àti bí wọ́n ṣe máa bójú tó àwọn tó máa wá sí àpéjọ náà.
Àwọn tó wá síbi àpéjọ náà rí lára àwọn àṣà tó ṣàrà ọ̀tọ̀ táwọn èèyàn ilẹ̀ Ukraine ní, irú bí ijó àti orin wọn àtàwọn oúnjẹ ìbílẹ̀ wọn.
Wọ́n ṣètò báwọn èèyàn ṣe máa lọ síbi tí wọ́n ń ko àwọn nǹkan ìṣẹ̀ǹbáyé sí, àwọn ilé ńlá ayé àtijọ́ àti bí wọ́n ṣe máa lọ wo lára òkè Carpathian tó jẹ́ àwòṣífìlà.
Ètò kan tó tún ṣàrà ọ̀tọ̀ ni báwọn tó wá ṣe láǹfààní láti bá àwọn ará ní Ukraine lọ sóde ẹ̀rí.
Pápá ìṣeré kan ní ìlú Lviv ni wọ́n ti ṣe àpéjọ náà, àwọn tó wá síbẹ̀ sì ju ẹgbẹ̀rún mẹ́ẹ̀ẹ́dọ́gbọ̀n (25,000).
Wọ́n tàtaré àwọn apá tó jẹ́ lájorí nínú àpéjọ náà sí pápá ìṣeré mẹ́ẹ̀ẹ́dógún (15) míì àti ọ̀pọ̀lọpọ̀ Gbọ̀ngàn Ìjọba káàkiri orílẹ̀-èdè náà, iye gbogbo àwọn tó wá sí àpéjọ náà lé ní ẹgbẹ̀rún lọ́nà márùnlélọ́gọ́fà (125,000), àwọn ẹgbẹ̀rún kan ọgọ́rùn-ún mẹ́rin ó lé ogún (1,420) ló sì ṣèrìbọmi.
Ivan Riher tó jẹ́ aṣojú ẹ̀ka ọ́fíìsì ní Ukraine, sọ pé: “A ti ń fojú sọ́nà fún àpéjọ pàtàkì yìí, ó sì ń wù wá láti kí àwọn ará láti àwọn orílẹ̀-èdè míì káàbọ̀.
A gbádùn bí a ṣe fi àwọn nǹkan ilẹ̀ wa ṣe àwọn tó wá lálejò, èyí sì mú ká rí bí ìṣọ̀kan àti ìgboyà tó wà láàárín àwọn ará wa kárí ayé ṣe ń pọ̀ sí i.”—Sáàmù 133:1."
"Àwa Ẹlẹ́rìí Jèhófà lórílẹ̀-èdè Ukraine ṣe àfihàn kan tó ṣàrà ọ̀tọ̀ nípa Ìwé Mímọ́ Kristẹni Lédè Gíríìkì ní Ìtumọ̀ Ayé Tuntun tá a mú jáde ní Èdè Adití ti Rọ́síà, aṣeyọrí tó lápẹẹrẹ lèyí sì jẹ́ nínú iṣẹ́ ìtúmọ̀ tí à ń ṣe.
Àfihàn náà bẹ̀rẹ̀ ní October 7, 2018 ní ìlú Lviv, a sì ṣe é títí di June 7, 2019. Àwọn ìlú míì tá a ti ṣe àfihàn náà ni Kharkiv, Kyiv, Odesa àti Dnipro.
Kí a tó ṣe àfihàn yìí, àwọn ìjọ tó ń sọ èdè adití pín ìwé ìkésíni fáwọn adití àtàwọn tí kò gbọ́ran dáadáa lágbègbè tí àfihàn náà ti máa wáyé, wọ́n sì tún fàwọn fídíò hàn wọ́n.
Yàtọ̀ síyẹn, Ẹ̀ka Tó Ń Gbéròyìn Jáde ní ọ́fíìsì wa lórílẹ̀-èdè Ukraine pín ìwé ìkésíni fún àwọn onímọ̀ ẹ̀kọ́, àwọn oníròyìn àtàwọn aláṣẹ.
Àwọn tó wá síbi àfihàn tá a kọ́kọ́ ṣe ní Lviv City Deaf Club rí oríṣiríṣi àwọn ètò tá a ṣe táwọn adití lè lò láti fi kẹ́kọ̀ọ́ Bíbélì, irú bí ètò JW Library Sign Language®.
Àwọn tó wá tún rí àfihàn kan tó ní oríṣiríṣi Bíbélì tí wọ́n ti lò láti ọ̀pọ̀ ọgọ́rùn-ún ọdún, látorí àwọn ìwé àkájọ títí dé àwọn ìwé òde òní.
Ọ̀kan pàtàkì lára àwọn ohun tó wà níbẹ̀ ni Bíbélì kan tó ti wà látọdún 1927.
Inú wa dùn pé Ìwé Mímọ́ Kristẹni Lédè Gíríìkì ní Ìtumọ̀ Ayé Tuntun ti wà ní Èdè Adití ti Rọ́síà.
Ó dá wa lójú pé ó máa jẹ́ kó rọrùn fáwọn tó ń sọ èdè náà láti ní ìmọ̀ tó péye nípa Bíbélì.​—Mátíù 5:3."
"Iṣẹ́ ìkọ́lé ẹ̀ka ọ́fíìsì ti ilẹ̀ Gẹ̀ẹ́sì tó wà nítòsí Chelmsford, Essex ni a retí pé kó parí ní December 2019.
Ní báyìí, àwọn ọ̀mọ̀wé gbà pé àpẹẹrẹ tó yẹ kí àwọn èèyàn tẹ̀ lé tó bá di pé ká sọ ilẹ̀ dọ̀tun ló jẹ́.
Oríṣiríṣi pàǹtírí làwọn èèyàn ń dà sí ilẹ̀ ọ̀hún títí kan àwọn mọ́tò tó ti bà jẹ́ kí àwọn ará wa tó ra ilẹ̀ náà ní 2015.
Àwọn olùyọ̀ǹda ara ẹni ló hú àwọn ìdọ̀tí náà kúrò, wọ́n kó o dà nù, wọ́n sì tún àwọn kan tó ṣì lè wúlò ṣe, wọ́n tiẹ̀ hú ẹgbẹẹgbẹ̀rún àwọn táyà tọ́jọ́ wọ́n ti pẹ́ jáde níbẹ̀, kódà àwọn táyà kan ti wà níbẹ̀ látìgbà Ogun Àgbáyé Kejì.
Lẹ́yìn náà, wọ́n sẹ́ àwọn iyanrìn tó ti dọ̀tí, títí kan àwọn òkúta kéékèèké, wọ́n sì tún wọ́n ṣe fún lílò, wọ́n tiẹ̀ tún àwọn kan ṣe kí wọ́n lè lò wọ́n fún àwọn nǹkan míì, kò tán síbẹ̀ o, wọ́n tún lo àwọn iyanrìn tó mọ́ náà fún iṣẹ́ ìkọ́lé.
Ní àkópọ̀, ó lé ní ẹgbẹ̀rún mọ́kànlá (11,000) àwọn arákùnrin àti arábìnrin tí wọ́n yọ̀ǹda ara wọn láti ṣiṣẹ́ níbẹ̀, ó sì ju mílíọ̀nù mẹ́rin wákàtí lọ tí wọ́n fi ṣiṣẹ́ lórí ilẹ̀ hẹ́kítà mẹ́tàlélọ́gbọ̀n náà.
Òsì: Àwọn tó yọ̀ǹda ara wọn tá a ti dá lẹ́kọ̀ọ́ ń kó àwọn ìdọ̀tí tó wà nílẹ̀ náà kúrò lọ́dún 2015; Ọ̀tún: Fọ́tò ọ̀kan lára ọgbà tí wọ́n gbin onírúurú òdòdó sí
Tí wọ́n bá parí iṣẹ́ náà, ilẹ̀ náà máa ní ọgbà ọ̀gbìn tó rẹwà, adágún omi, onírúurú òdòdó ẹgàn àti ọgbà eléso tó jojú ní gbèsè.
Kì í ṣe pé ilẹ̀ tó tẹ́jú yìí kàn dùn ún wò nìkan ni.
Ó tún jẹ́ ibùgbé fún àwọn ẹranko ìgbẹ́, ó mú kó rọrùn láti ṣọ́ omi lò, ibẹ̀ tún jẹ ibi tó dáa láti dá àwọn igi ńláńlá àti kéékèèké sí, èyí sì mú kí àwọn ewéko tó pọ̀ wà níbẹ̀, kó sì túbọ̀ mú kí àdúgbò náà rẹwà fún àwọn tó ń gbé ibẹ̀.
Arákùnrin Paul Rogers, tó jẹ́ ọkàn lára àwọn ìgbìmọ̀ ìkọ́lé sọ pé: “Ilẹ̀ ti wọ́n ò lò, tí wọ́n sì ti pa tì fún ọ̀pọ̀ ọdún la rà.
Ilẹ̀ náà bẹ̀rẹ̀ sí jọjú nígbà tí ọ̀gọ̀ọ̀rọ̀ àwọn olùyọ̀ǹda ara ẹni ń fara balẹ̀ ṣa àwọn ìdọ̀tí náà.
Lẹ́yìn náà, wọ́n bẹ̀rẹ̀ sí palẹ̀ àwọn ìdọ̀tí náà mọ́, wọ́n ń tún ilẹ̀ náà ṣe ní ìbámu pẹ̀lú bí ilẹ̀ náà ṣe rí, wọ́n wá gbin onírúurú àwọn igi, igbó àtàwọn ewéko.
Bí ilẹ̀ náà ṣe rẹwà lẹ́yìn tí wọ́n tún un ṣe rán wa létí ọ̀rọ̀ tó wà ní Ìsíkíẹ́lì 36:​35, 36 tó sọ pé: ‘Àwọn èèyàn á sì sọ pé: “Ilẹ̀ tó ti di ahoro náà ti dà bí ọgbà Édẹ́nì” . . .
Àwọn orílẹ̀-èdè . . . yóò wá mọ̀ pé, èmi Jèhófà ti kọ́ ohun tó ya lulẹ̀, mo sì ti gbin ohun tó ti di ahoro.’ ”
Ojú ìwé àkọ́kọ́ nínú ìwé ìròyìn tó máa ń sọ nípa iṣẹ́ ìkọ́lé, tí wọ́n pín kiri jù lọ ní ilẹ̀ Gẹ̀ẹ́sì tí wọ́n ń pè ní Construction Manager tó jáde lóṣù March 2019 sọ̀rọ̀ nípa iṣẹ́ ìkọ́lé tó ń lọ lọ́wọ́ ní Chelmsford.
Àpilẹ̀kọ náà sọ̀rọ̀ nípa ìṣọ̀kan tó wà láàárín àwọn tó yọ̀ǹda ara wọn, bó tilẹ̀ jẹ́ pé ibi ọ̀tọ̀ọ̀tọ̀ ni wọ́n ti wá.
Bí àpẹẹrẹ, ìwé ìròyìn náà kíyè sí i pé ọ̀pọ̀ àwọn ọ̀dọ́ àtàwọn obìnrin ló ń ṣiṣẹ́ níbí iṣẹ́ ìkọ́lé náà, èyí sì yàtọ̀ sí bó ṣe máa ń rí láwọn ibi iṣẹ́ ìkọ́lé míì.
Àpilẹ̀kọ náà sọ pé, “Ṣe ni inú gbogbo wọn ń dùn ṣìnkìn níbí,” ó tún sọ síwájú sí i nípa bí àwọn òṣìṣẹ́ ṣe ń kí alábòójútó wọn, àwọn òṣìṣẹ́ kan ń juwọ́, àwọn míì ń bọ̀ wọn lọ́wọ́ nígbà tó jẹ́ pé ṣe làwọn míì ń gbá wọn mọ́ra pàápàá.
Arákùnrin Stephen Morris, tó jẹ́ ọkàn lára àwọn ìgbìmọ̀ ìkọ́lé náà sọ pé:
“Bó tiẹ̀ jẹ́ pé kì í ṣe torí pé káwọn èèyàn lè kan sáárá sí wa la ṣé ń kọ́ ẹ̀ka tuntun náà, ohun táwọn akọ́ṣẹ́mọṣẹ́ sọ nípa iṣẹ́ ìkọ́lé náà jẹ́ ẹ̀rí pé gbogbo àwọn tó kópa nínú iṣẹ́ náà wà létòlétò, wọ́n sì já fáfá.
Jèhófà ni gbogbo ìyìn àti ọpẹ́ tọ́ sí, fún àwọn ìlànà Bíbélì tó fún wa, èyí tó mú ká lè ṣàṣeyọrí lẹ́nu iṣẹ́ ìkọ́lé wa.”​—1 Kọ́ríńtì 14:40."
PDP: A kò mọ nǹkan tí Buhari fẹ́ẹ́ fi bílíọ̀nù dọ́là kan ṣe
Oríṣun àwòrán, STEFAN HEUNIS/GETTY
Ija ileese ọmọogun Naijiria pẹlu Boko Haram ti n sunmọ ọdun mẹjọ bayi
Ẹgbẹ oṣelu PDP lorilẹẹde Naijiria ni ọgbọn alumọkọrọyi ni ẹgbẹ APC fẹ da pẹlu bi Aarẹ Buhari ti ṣe fọwọsi nina owo iya biliọnu dollar kan fun aabo ilu.
Igbakeji alukoro ẹgbẹ PDP, Diran Odeyemi lo lede ọrọ naa nigba ti o'n fesi si ikede Minisita fun eto abo, Mansur Dan Ali lori aṣẹ ti Aarẹ Buhari pa nipa nina owo yii.
O ni ''owo oṣelu ni. Ko si Boko Haram kankan ti wọn fẹ fi ba ja. Sẹbi wọn lawọn ti bori Boko Haram ni? Kini wọn wa fẹ fi aduru owo yii ṣe?''
O tẹsiwaju pe ile igbimọ aṣofin ni lati tọ pinpin bi Aarẹ Buhari ko ṣe gba aṣẹ ko to o buwọ lu nina owo naa.
Onimọ nipa eto inawo kan, Shuaibu Idris, ninu ọrọ ti rẹ ni ki a to le sọ boya ijọba lẹto lati naa owo iya biliọnu kan naa tabi ko lẹto, o yẹ ki a ṣe agbeyẹwo iye ti ijọba ti naa sẹyin lori pipese aabo fun ara ilu.
Oríṣun àwòrán, @MBuhari
Ijọba ni owo naa wa fun kikoju ipẹnija agbesunmọmi Boko Haram
O ni lootọ ni pe ijọba ti ṣe aṣeyọri nipa kikoju Boko Haram ṣugbọn anfaani owo ti wọn naa ko han lara pipese ohun ija tabi iwuri fun awon ọmọ ogun.
Irinajo owo iya biliọnu dọla naa
Lọdun 2014, bi idibo Aarẹ orilẹẹde Naijiria  ti se n sunmo bo ni Aarẹ ana, Goodluck Jonathan, gba iyanda lati ọdọ ile igbimọ asofin lati ya biliọnu dollar.
O ni owo naa wa fun kikoju ipẹnija agbesunmọmi Boko Haram.
Senator Ahmed Makarfi to jẹ alaga igbimọ ọrọ isuna ninu ile nigba naa ni wọn yoo fi owo naa ra ''baalu,ọkọ oju omi ati ohun ija miran''
Asẹyinwa ọrọ naa ni ẹsun ikowoje ti ijọba Buhari fi kan Alamọran fun eto aabo tẹlẹri, Sambo Dasuki ati awọn ọmọ orilẹẹde yi miran.
Àwọn aláboyún f'ẹ̀hónú hàn lórí owó ìgbẹ̀bí ní ìpínlẹ̀ Òǹdó
Oríṣun àwòrán, Aproko Girl
Awon aboyun nfe ki Gomina rotimi Akeredolu yi ofin yi pada
O kere tan, o to ọgọrun aboyun to rọ lọ si Ile-iwosan Alamọja ti ijọba ipinle Ondo nilu Akure ni Ojobo lati fẹhonu han lori awọn idiyele giga fun awọn itọju ati igbẹbi fun alaboyun ni ile iwosan naa.
Awọn obinrin aboyun, ti wọn ti ile-iwosan naa pa ṣe apejuwe awọn owo ti wọn n gba nile iwosan naa bi ohun ibanujẹ ati pe  ojẹ ohun irẹjẹ fun ọpọlọpọ ninu wọn.
Awọn alaboyun naa npe akiyesi Gomina ipinlẹ Ondo, arakunrin Rotimi Akeredolu si ọrọ naa wipe ki o yi ofin naa pada.
Oríṣun àwòrán, Aproko Girl
Awọn alaboyun f'ẹhonu han lori owo igbebi ni Akure
Diẹ ninu awọn alaboyun naa, ti wọn sọrọ pẹlu awọn oniroyin, ṣe akojọ awọn idiyele bi: ẹgbẹrun mẹẹdọgbọn, (N25,000) fun igbẹbi alagboyun, ẹgbẹrun lọna aadọta (N50,000) fun ṣiṣe iṣẹ abẹ (Caesarean Section) ati awọn kẹ aimọye oriṣiriṣi owo ainidi laarin ẹ̀ẹ́dẹ́gbẹ̀ta naira si ẹgbàajì naira.
"Wọn tun fi ẹsun kan awọn aṣoju ile-iwosan naa wipe wọn n gba awọn owo ele yii ""gẹgẹ bi aṣẹ ti ijoba ipinlẹ pa fun wọn."""
Oríṣun àwòrán, Aproko Girl
Wọn ti ilẹkun abawọle si ile iwosan naa pa fun ọpọlọpọ wakati
Pẹlu ibinu, awọn obinrin naa ṣe aridaju wipe wọn gbe ilẹkun iytana igbẹbi ile iwosan naa ti pa lakoko ifẹhonu han yii ati pe wọn tun ti ilẹkun abawọle si ile iwosan naa pa fun ọpọlọpọ wakati.
Komisona fun eto ilera ni ipinle naa, Wahab Adegbenro gbiyanju lati parọwa fun awọn obinrin naa lati dẹkun ifẹhonuhan yii.
Ilé ẹjọ́ Èkìtì d'ájọ́ ikú f’ọ́kùnrin tó jí ọtí méje áti páálí sìgá
Oríṣun àwòrán, Erik S. Lesser/Getty
Ìgò ọtí méje àti sìgá ṣokùnfà ẹjọ́ ikú
Ọkunrin kan ni ipinlẹ Ekiti, lorilẹede Naijiria ti ri idajọ iku he lẹyin to ji ọti ẹlẹrin dodo meje ati paali siga kan.
Ninu idajọ ti wọn gbe kalẹ ni ile ẹjọ giga to wa ni Ekiti, adajọ to pe orukọ ẹni ti wọn f'ẹsun kan naa gẹgẹ bii Babatunde jẹbi ẹsun ole jija ati nini ada ati okọ nigba ti wọn mu u wipe o jale.
Adajọ ni iku ki wọn ye igi fun ni Babatunde yoo ku, nitori wipe o pẹlu awọn adigunjale mẹrin kan ti wọn tun gba foonu alagbeka oniyebiye lọwọ awọn eniyan.
Oríṣun àwòrán, PATRIK STOLLARZ/Getty Images
Ilé ẹjọ́ Èkìtì d'ájọ́ ikú f'ọ́kùnrin tó jí ọtí méje áti páálí sìgá
Amọ, idajọ iku naa ti fa ọpọlọpọ ariyanjiyan laarin awọn ọmọ orilẹede Naijiria, ti awọn miran si n pe fun idajọ iku fun awọn oselu ti wọn n lu owo ilu ni ponpo ati awọn asebajẹ lawujọ.
Kókó ìròyìn t'òní: Ìdájọ́ ikú ní Èkìtì, Aláboyún f'ẹ̀hónú hàn l'Òǹdó
Eyi ni awọn akojọpọ iroyin ti toni.
Àwọn aláboyún f'ẹ̀hónú hàn lórí owó ìgbẹ̀bí ní ìpínlẹ̀ Òǹdó
Oríṣun àwòrán, Aproko Girl
Awọn alaboyun f'ẹhonu han lori owo igbebi ni Akure
O kere tan, o to ọgọrun aboyun to rọ lọ si Ile-iwosan Alamọja ti ijọba ipinle Ondo nilu Akure ni Ojobo lati fẹhonu han lori awọn idiyele giga fun awọn itọju ati igbẹbi fun alaboyun ni ile iwosan naa.
Awọn obinrin aboyun, ti wọn ti ile-iwosan naa pa ṣe apejuwe awọn owo ti wọn n gba nile iwosan naa bi ohun ibanujẹ ati pe  ojẹ ohun irẹjẹ fun ọpọlọpọ ninu wọn.
Ilé ẹjọ́ Èkìtì d'ájọ́ ikú f'ọ́kùnrin tó jí ọtí méje áti páálí sìgá
Oríṣun àwòrán, Erik S. Lesser/Getty
Ìgò ọtí méje àti sìgá ṣokùnfà ẹjọ́ ikú
Ọkunrin kan ni ipinlẹ Ekiti, lorilẹede Naijiria ti ri idajọ iku he lẹyin to ji ọti ẹlẹrin dodo meje ati paali siga kan.
Ninu idajọ ti wọn gbe kalẹ ni ile ẹjọ giga to wa ni Ekiti, adajọ to pe orukọ ẹni ti wọn f'ẹsun kan naa gẹgẹ bii Babatunde jẹbi ẹsun ole jija ati nini ada ati okọ nigba ti wọn mu u wipe o jale. Ẹ ka ẹkunrẹrẹ rẹ ni bii.
Màmá Boko Haram: Leah yóò padà sílé láì s'éwu
Boko Haram yóò dá Leah sílé
Ìkọlù Benue: Ẹ̀mí 24 tún bọ́ sọ́wọ́ darandaran
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ọ̀pọ̀ òkú ló ti sùn láti ọwọ́ darandaran
Àwọn asojú-sòfin láti ìpínlẹ̀ Benue ti ké gbàjarè lórí àkọ̀tun ìkọlù darandaran tó ń wáyé ní ìpínlẹ̀ náà.
Ipe naa waye lọ́jọ́bọ níbi ìjókòó ilé asòfin àpapọ̀ ní ìlu Abuja.
Wọn bèèrè pé káwọn ọmọogun máa wà ní sẹpẹ́ láwọn agbègbè tí ìkọlù ti máa ń wáyé lemọ́lemọ́.
Bákannáà ni wọ́n ń bèèrè pé kí ìjọba àpapọ̀ kéde àwọn darandaran gẹ́gẹ́ bíi adúnkookò mọ́ni nítorí pé ó lé ní ẹ̀mí èèyàn mẹ́rìnlélógún míì tó tún bọ́ sọ́wọ́ àwọn afurasí darandaran naa lásìkò àkọ̀tun ìkọlù míì tó wáyé ní ìpínlẹ̀ Benue lọjọ́ kejì àti ìkẹrin osù kẹrin, bẹẹ si ni ọ̀pọ̀ èèyàn tún ti di àwátì.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ojoojumọ ni ẹmi ọpọ eeyan nbọ ninu ikọlu awọn darandaran lorilẹede Naijiria
Àwọn asojú-sòfin náà tún wá ń kọminú lórí bí wọn se fòpin sí ìgbàródan àwọn ológun nínú isẹ́ Operation Cat Race ni ìpínlẹ̀ Benue, nígbàtí wọ́n fi ọ̀sẹ̀ díẹ̀ kún ìgbàródan àwọn ológun náà ní ìpínlẹ̀ Taraba.
Nígbà tó ń gbarata lórí ìsẹ̀lẹ̀ yìí, Asòfin Dickson Takighir sọ pé agbègbè Ikyon, Semaka, Asom, Babanruwa, Udei, Umenger àti Agasha ni wọ́n kọlù, sùgbọ́n àwọ́n darandaran náà, tí ẹnu kò sìn lára wọn náà, tún ti gẹ̀gùn sí Nzorov, nígbaradì láti kọlu Gbajimba, tó wà níjọba ìbílẹ̀ Guma.
Lọ́wọ́lọ́wọ́ báyìí, àwọ́n agbégbọn darandaran náà ti gbàkóso agbègbè Sengev, Mbakyondo àti Mbapa, a sì ń késí ìjọba àpapọ̀ àti àwùjọ àgbáyé láti dìde sí ọ̀rọ̀ yìí, kó tó bọ́wọ́ sórí.
Bákannáà ni wọ́n ń fẹ́ ètò ìrànwọ́ tó péye fún àwọn èèyàn tí kò nílé lórí mọ́ ní ibùdó ogunléndé tó wà ní ìpínlẹ̀ náà.
Ìṣẹ̀lẹ̀ Èkó: Aáwọ̀ Ọbàkan sọ ilé di áláwọ̀ méjì
Ìṣẹ̀lẹ̀ Èkó: Aáwọ̀ Ọbàkan sọ ilé di áláwọ̀ méjì
Ìyàlẹ́nu ńlá ló jẹ́ fáwọn èèyàn tó ń kọjá ní àdúgbò Bámgbóṣé, lágbègbè Lagos Island nílùú Èkó nítorí ilé alájà méjì yìí tó wà lágbègbè náà, tó jẹ́ abala méjì ọ̀tọ̀ọ̀tọ̀.
Ilé náà, tí kò dín ní àádọ́ta ọdún, la gbọ́ pé ẹni tó nií ti kú.
Àmọ́ṣá ṣe wọ́n ní bí iná bá kú, yóò fi eérú bojú, èyí ló mú àwọn ọmọ rẹ méjì, tí wọn jẹ́ ọkùnrin àti obìnrin, jogún ilé náà.
Lẹ́yìn aáwọ̀ tó wáyé láààrín wọn. kí wọn tó pín ilé náà fún wọn, ó fojú hàn gbangba pé ààrin àwọn ọmọ tó jogún ilé náà kò gún.
Ń ṣe ni wọ́n fi òpó kan pín ilé náà sí méjì níwájú, tí wọ́n tún apákan se, tí wọn sì fi apá kejì sílẹ̀ sí ipò àtijọ́ tó wà tẹ́lẹ̀.
Bí ilé yìí se rí kò se àkóbá fún àwọn ayálégbé ibẹ̀.
Lásìkò àbẹ̀wò BBC Yorùbá sí ilé yìí ládúgbò Bámgbósé, a gbọ́ pé èyí obìnrin ló mú apá òsì ilé náà, nígbàtí ọkùnrin mú apá ọ̀tún.
Àwọn ayálégbé tó bá wa sọ̀rọ̀ ni, ẹnu àwọn ọmọ náà kò ṣọ̀kan lórí ilé yìí, bẹ́ẹ̀ ni ọwọ́ èyí obìnrin rí jájẹ ju ti ọ̀kùnrin lọ̀.
Iṣẹ́ kò ní pẹ̀ bẹ̀rẹ̀ lórí abala kejì ilé náà
Abala tí wọn sì túnṣe yìí jẹ́ ti obìnrin nígbàtí abala tí kò rí àtúnṣe náà jẹ́ ti ọkùnrin.
Àwọn ayálégbé inú ilé náà ní, bí ó tilẹ̀ jẹ́pé ààrin àwọn ọmọ tó jogún ilé náà kò gún, síbẹ̀ èyí kò ní ipa kankan lórí àwọn, pẹ̀lú àfikún pé, isẹ́ kò níí pẹ́ bẹ̀rẹ̀ ní abala kejì ilẹ́ náà.
BBC Yorùbá tiẹ̀ gbọ́ pé ìjọba ìpínlẹ̀ Èkó ti dásí ìsẹ̀lẹ̀ náà.
Aáwọ̀ PDP Ọ̀sun: Igun Omisore dáná sun àṣíá ẹgbẹ́
Oríṣun àwòrán, Toba Adedeji
Àwọn ọmọ ẹgbẹ́ PDP kan nípínlẹ̀ Ọ̀ṣun dáná sun àṣíá ẹgbẹ́ òṣèlú ẹgbẹ́ òṣèlú PDP
Igun ẹgbẹ́ òṣèlú PDP kan nípínlẹ̀ Ọ̀ṣun ti dáná sun àṣíá ẹgbẹ́ òṣèlú náà gẹ́gẹ́bíi ara ọ̀nà láti fi  ẹ̀hónú wọn hàn sí bí nǹkan ṣe ń lọ sí, nínú ẹgbẹ́ òṣèlú náà.
Igun tó dáná sun àṣíá ẹgbẹ́ náà ló jẹ́ tàwọn tó jẹ́ olólùfẹ́ aṣíwájú ẹgbẹ́ òṣèlú PDP, ẹni tó tún ti fìgbàkanrí jẹ igbákejì Gómìnà àti sẹ́nétọ̀ ní ìpínlè Ọ̀ṣun, Iyìọlá Omíṣoore.
Oríṣun àwòrán, Toba Adedeji
Dúkùú abẹ́nú lo ń da omi àláfíà ẹgbẹ́ PDP rú ní Ọ̀sun
Dúkùú lórí bóyá kí ẹgbẹ́ òṣèlú PDP gbé àṣíá olùdíje ipò Gómìnà fún Omíṣoore ti ń wáyé ṣáájú àkókò yíí, kí wọn tó yọ ọwọ́ rẹ̀ láwo nínú àwọn alẹ́núlọ́rọ́ ẹgbẹ́ òṣèlú náà pẹ̀lú ètò ìdìbò láti yan ìgbìmọ̀ ìṣàkóso ẹgbẹ́ òṣèlú náà ní ìpínlẹ̀ Ọ̀ṣun, ni oṣù tó kọjá.
Gbogbo àṣíá ẹgbẹ́ òṣèlú PDP tó wà níwájú iléeṣẹ́ ẹgbẹ́ òṣèlú náà ní agbègbè Ògo Olúwa ní ìlú Òṣogbo ni wọ́n dáná sun, ki sẹnetọ̀ Omíṣoore tó léwájú ìpàdé pèlu àwọn olólùfẹ́ rẹ̀.
Oríṣun àwòrán, Toba Adedeji
Gbogbo àṣíá ẹgbẹ́ òṣèlú PDP tó wà níwájú iléeṣẹ́ ẹgbẹ́ òṣèlú náà ní agbègbè Ògo Olúwa ní ìlú Òṣogbo ni wọ́n dáná sun
Àmọ́ṣá, àwọn aláṣẹ ẹgbẹ́ òṣèlú PDP ní ìpínlè Ọ̀ṣun ti sọ pé, kò yẹ kí Sẹ́nétọ̀ Omíṣore fi ìwàǹwara lábẹ̀ gbígbóná, kó sì tún rántí pé ẹgbẹ́ òṣèlú PDP yí kan náà ló rán an lọ sí ilé aṣòfin àgbà.
"Alága ẹgbẹ́ òṣèlú PDP, Sọjí Adágúnodò, nínú àtẹ̀jáde kan ní, ""kò yẹ kí Omíṣore bọ́ sínú ìkẹkùn ẹgbẹ́ òṣèlú APC"""
Ṣùgbọ́n Omíṣore ti sọ pé, òun kò ní ibií lọ àtipé, digbí lòun ṣì wà lẹ́gbẹ́ òṣèlú PDP.
Ẹ̀sùn ìkówójẹ: Jacob Zuma yóò fojú winá òfin
Oríṣun àwòrán, Reuters
L'oni ni wọn yoo bẹrẹ igbẹjọ Jacob Zuma lori ẹsun iwa ibajẹ
Ààrẹ South Africa tẹ́lẹ̀ri, Jacob Zuma, yóò fojú ba ilé ẹjọ́ lónìí lorí ẹ̀sun ṣiṣé owó ìlú báṣú-bàṣú lori òwo ńǹkan ìjà bílíọ́nù méjì-àbọ̀ dọ́là ni àwọn ọdún 1990.
Lara àwọn ẹ̀sun mẹrìndínlógún ti wọn yóò fi kan an, ni ìwà ìbàjẹ, jìbìtì àti kíkówó jádé lọ́nà àìtọ, èyí tó ń wáyé nile ẹjọ̀ ńlá kan ni ìlú Durban.
O ṣeéṣẹ́ ki ìgbẹ́jọ́ rẹ̀ gba àsìkò gbọ́ọ́rọ́, pàápàá ní báyìí ti àwọn eeyàn fẹ bẹ̀rẹ̀ ìjà lori bóyá ki ìjọ̀ba maá san owó ìgbẹjọ́ Zuma lọ àbí bẹ́ẹ̀ kọ́.
Àwọn olọ́pá ń gbárádì fún ẹgbẹgbẹ̀rún àwọn álátìlẹyìn ààrẹ orílẹ̀èdè náà tẹlẹ̀ri, ti wọn ti ṣé ìlérí pe àwọn yóò ṣe ìwọde lọ si ilé ẹjọ́ náà.
Orin idanimọ South Africa.
Akọ̀ròyìn BBC, Andrew Harding, sọ wipe, kí ààrẹ orilẹ̀ẹde náà tẹ́lẹ̀rí fi ojú ba ilé ẹjọ́ yóò jẹ ńǹkan ńlá fún ìjọba àwá-arawá ní South Africa.
O sọ wipe òpọ̀ yóò ri ìgbesè náà gẹgẹ bi òpin ṣiṣẹ̀ s'ofin lai ni ìjìyà.
Wo ẹ̀sà nínú àwọn àwòran Áfríka tó rẹwà jù l'ọṣẹ̀ yìí.
Ẹ̀ṣà nínú àwọn àwòran to rẹwà jù l'Áfríkà àti tí àwọn èèyán Áfríkàl'ọ́ṣẹ̀ yìí.
Oríṣun àwòrán, AFP
Árákùnrín kán dùbúlẹ̀ nígbá ere órí ìtàge kikán Jésù mọ àgbelébu l'ọjọ́ Jímò rere nígboro Èkó
Oríṣun àwòrán, AFP
Wọn ń pẹ̀tù s'ọmọbìnrín kan nínú nigbà tó ń sunkún nitórí ere órí ìtàge náà...
Oríṣun àwòrán, Reuters
Nigba náà ni ọmọkùnrin yìí ń gbádúrà ní olú ìlú Kenya, Nairobi.
Oríṣun àwòrán, Reuters
Harun Karanja, tó ni ìsò ohún ọ̀wọn lori Facebook , ń lo ẹ̀rọ ìbanisọ̀rọ̀ rẹ̀ lati fi wọ opo Facebook rẹ̀ ni agbẹ̀gbẹ̀ Rift Valley lórílẹ̀ede Kenya.
Oríṣun àwòrán, Reuters
Okùnín kan to n ṣiṣẹ́ nibi ti wọn ti ń kòle kan ni ìlu Goma, olu ìlu kan ni ìlà-óòrun Democratic Republic of Congo...
Oríṣun àwòrán, Reuters
Nígbà tí àwọn ìyókù rẹ̀ ń ṣiṣẹ́ lorí àga pákó
Oríṣun àwòrán, AFP
Ni ìgboro Durban tó wà letí omí ní orílẹ̀ede South Africa l'ọjọ́ Ajé (Monday), wọ́n ṣe àfihán àworán olóògbẹ Winnie Madikizela-Mandela tó jẹ gbajúgbajàá èèyàn to gb'ógún ti ìjọbá ẹlẹ́yàmẹ́yà apatheid tú kú lẹní ọdún mọkàndinlọ́gọ́rín (81)
Oríṣun àwòrán, AFP
Nigbà ti àwọn obìnrin yìí ń korín yin Madikizela-Mandela nilú Soweto
Oríṣun àwòrán, Reuters
Ni olú ìluTunisia, Tunis, ol'gun ka ń lùlù nibi ajọ́ ìlọsíwajú ni ìlànà Islam
Oríṣun àwòrán, Reuters
Ni orílẹ̀edé Australia Salome Nyirarukundo ti ìlẹ Rwanda gbé àsìá orílẹ̀edé rẹ̀ l'ọwọ nigbá ayẹ́yẹ́ sisí ìdijẹ ere ìdaraya Commonwealth Games.
Oríṣun àwòrán, EPA
L'ọjọ́ Ẹ́tì awọṣọ kan ń ṣe àfihan aṣọ kan ni Accra
Oríṣun àwòrán, AFP
L'ọjọ Àbamẹtá (Saturday), obìnrín kan ń dibò nigba ìsòri kejí ìbò ààrẹ orilẹedé Sierra Leone...
Oríṣun àwòrán, AFP
Ìkedé Ọjọ́rú wipe ọmọ ẹgbẹ́ alátákò, Julius Maada Bio, lo jẹ ki àwọn ọlatilẹyin rẹ̀ bẹ̀rẹ̀ si dun nu ni olu ìlú orílẹ̀ede náà, Freetown.
Orisun àwòran: AFP, Reuters, EPA àti Getty Images.
Ilé ìwòsàn Àkúrẹ́ lorí ìfowó kun owó ìbimọ
Oríṣun àwòrán, APROKO GIRL
Olùdarí ilé ìwòsàn ìjọbá Àkúrẹ́, dókítà Moses Adewọle, tí sàlàyé pe òwọn gógó ńǹkan lo faá ti wọn fi fi owó kun owó ìgb'ẹ̀bi.
Olùdarí ilé ìwòsàn náà sọ wipe ìwọdẹ́ ti àwọn aláboyún ṣe ni Ọjọ́bọ̀ (Thursday) ní àpẹrẹ òṣelù nínú.
Díẹ̀ nínù àwọn aláboyún náà, ti wọn sọ̀rọ̀ pẹlu àwọn oníròyìn, ṣe àkojọ́ awọn ìdiyelé náà bií: ẹgbẹ̀rún mẹ́ẹdọ́gbọ̀n, (N25,000) fún ìgbẹ̀bi alábóyún, ẹgbẹ̀rún lọná aádọ́tá (N50,000) fún ṣiṣé iṣẹ́ abẹ́ (Caesarean Section) àti àwọn òkẹ aìmọye oríṣiríṣi owó aìnídí láàárín ẹ̀ẹ́dẹ́gbẹ̀ta naira si ẹgbàajì naira.
Oríṣun àwòrán, Aproko Girl
Awọn alaboyun f'ẹhonu han lori owo igbebi ni Akure
Àwọn alábóyún náà pe àkiyèsí gomìnà ìpinlẹ Ondo, Rótìmi Ákérédolú, sí ọ̀rọ̀ náà wipe ki o yí òfín náà padà.
Dókítà Adewọle sọ wipe wọn fi owó kun owó ìforukọ́ silẹ̀ fun àwọn alábọyún látí N2,500 si N4,000 ni nitori àti dí ònà owó ẹ̀yìn fún àwọn òṣìṣẹ.
Oríṣun àwòrán, Aproko Girl
Wọn ti ilẹkun abawọle si ile iwosan naa pa fun ọpọlọpọ wakati
Sùgbọn nigba ti wọn bi lere iye ti wọn ń gba gẹgẹ bìí owó ìgb'ẹ̀bí tẹlẹ̀, o sọ wipe òwọn gogó  ńǹkan ti wọn lo faá.
L'àpèjúwé, o sọ wipe ilé ìwòsàn náà ma ń lo mímlíọ́nù maárun din ní igba egbèrun (4.8M) lori epó jẹ́nẹ́rétọ̀ l'oṣooṣù.
O tún s'àlàye wipe owó ogun àtí ńǹkan ìṣegun òyinbo ti wọn si.
O sọ wipe gbogbo ẹni to ba ni ìwe tí ìjọba ìpinlẹ̀ náà fí p'àṣẹ́ sisọ owó ìgbẹ̀bi alábóyún dí ẹgbẹ̀rún mẹ́ẹdọ́gbọ̀n (N25,000) ko mú ìwé náà jadé.
Ọlọ́pàá Kwara: À ń wá àwọn adigunjalè tó pa èèyàn méjìlá
Òkú sùn nínú ìṣẹ̀lẹ̀ ìdigunjalè ní Ọ̀ffà
Ile-isẹ ọlọpa lorilẹede Naijiria  sọ wipe awọn n wa awọn adigunjale to yin ibọn pa ọlọpa mẹfa ati awọn ara ilu mẹfa nigba ti wọn ṣe ikọlu si ile ifowopamọ marun ni ilu Ọffa ni ipinlẹ Kwara to wa ni ẹkun iwọ oorun orilẹede Naijiria.
Awọn tọ rọ naa soju rẹ sọwipe awọn adigunjale naa ya bo agọ ọlọpa to wa ni agbegbe naa, ti wọn si pa awọn ọlọpa ati awọn to wa fẹjọ sun ni agọ ọlọpa, ko to di wipe wọn wa bẹrẹ si ni lọ si awọn ile ifowopamọsi lati lọ ja wọn ni ole.
Oríṣun àwòrán, Ayobami Agboola
Ńse ni òkú èèyàn kún ilẹ̀ káàkiri ìlú Ọ̀ffà nítorí Ìsẹ̀lẹ̀ ìdigunjalè náà
Agbẹnusọ fun ile isẹ ọlọpa ni ipinlẹ naa, Ajayi Okasanmi so fun BBC Yoruba wipe awọn ọlọpa n se iwadii atiwipe awọn n sisẹ papọ pẹlu awọn adari awọn ile ifowopamọsi ti wọn se ikọlu si lati le tọ pasẹ awọn adigunjale naa.
Arakunrin Okasanmi sọwipe awọn ti ri lara awọn ọkọ ayọkẹlẹ ti awọn adigunjale naa lo, ti o si sọwipe awọn ọlọpa lo fara kaasa isẹlẹ naa ju nigba ti awọn adigunjale naa da ibọn bo ile.
Oríṣun àwòrán, Ayobami Agboola
Ńse ni òkú èèyàn kún ilẹ̀ káàkiri ìlú Ọ̀ffà nítorí Ìsẹ̀lẹ̀ ìdigunjalè náà
Ile ifowopamọsi igbalode marun ni wọn se ikọlu naa si, ti wọn si lo ado oloro lati fi fọ ibi ifowopamọsi naa, eleyi ti awọn ti ọrọ naa soju rẹ sọwipe o ti di lemọlemọ.
Amọ awọn adari ile ifowopamọsi naa ko ba BBC ni gbolohun pọ.
Ọmọ ilẹ̀ Kenya gbé ‘búrọ́ọ̀ṣì ìfọyín’ mì nígbà tó ǹ fọyín
Oríṣun àwòrán, AFP
Bawo ni burọsi ifọyin se le de ikun eniyan?
Ọpọ awọn eeyan lo n ranti ọjọ lori awọn iṣẹlẹ apanilẹrin to ti ṣẹlẹ si wọn sẹyin.
Okunrin kan to ti gbe burọọṣi ifọyin me sẹyin ni orilẹ-ede Kenya naa n ranti bi o ṣe nilo iṣẹ abẹ nigba naa.
Orisirisi nkan ni awọn ọmọde ati ọdọ koda agbalagba maa n jẹ nigba miran ti wọn ko si mọ bi o ṣe lewu to.
Kini o ti ṣẹlẹ tẹlẹ?
Bo ti lẹ jẹ wipe o ya eniyan lẹnu julọ, awọn dokita lorilẹ-ede Kenya ti yọ burọọsi ifọyin kuro ni ikun arakunrin kan to gbe e mi.
Arakunrin naa ti orukọ rẹ n jẹ, David Charo sọ wi pe oun ṣeeṣi gbe burọọsi ifọyin naa mi nigba t'oun fọ ẹyin rẹ.
Arakunrin naa ti lọ si ile iwosan bii marun un ki o to di wi pe o ri ile iwosan ti yoo ran lọwọ lati yọ ohun eelo ifoyin naa kuro ninu rẹ, lẹyin ti iwadii fihan pe lootọ ni burọọsi naa wa ninu rẹ.
Ile iṣẹ iroyin lorilẹ-ede naa pin aworan burọọsi naa lẹyin ti awọn dokita ṣe iṣẹ abẹ to yọ ohun ifọyin ọhun kuro ninu rẹ.
Awọn eniyan lori ikanni ibaraẹnisọrọ lori opo Twitter fi ero wọn han lori iṣẹlẹ naa.
Kókó ìròyìn t'òní: Ìjọba Òǹdó lórí owó aboyún, Ìdigunjalé l’Ọ́ffà
Eyi ni awọn akojọpọ iroyin ti toni.
Ilé ìwòsàn Àkúrẹ́ ṣ'àlàyé lorí ìfowó kun owó ìbimọ
Oríṣun àwòrán, APROKO GIRL
Olùdarí ilé ìwòsàn ìjọbá Àkúrẹ́, dókítà Moses Adewọle, tí sàlàyé pe òwọn gógó ńǹkan lo faá ti wọn fi fi owó kun owó ìgb'ẹ̀bi.
Olùdarí ilé ìwòsàn náà sọ wipe ìwọdẹ́ ti àwọn aláboyún ṣe ni Ọjọ́bọ̀ (Thursday) ní àpẹrẹ òṣelù nínú.
Dókítà Adewọle sọ wipe wọn fi owó kun owó ìforukọ́ silẹ̀ fun àwọn alábọyún látí N2,500 si N4,000 ni nitori àti dí ònà owó ẹ̀yìn fún àwọn òṣìṣẹ.
Ọlọ́pàá Kwara ń wá àwọn adigunjalè tó pa èèyàn méjìlá
Oríṣun àwòrán, Ayobami Agboola
Ńse ni òkú èèyàn kún ilẹ̀ káàkiri ìlú Ọ̀ffà nítorí Ìsẹ̀lẹ̀ ìdigunjalè náà
Ile-isẹ ọlọpa lorilẹede Naijiria  sọ wipe awọn n wa awọn adigunjale to yin ibọn pa ọlọpa mẹfa ati awọn ara ilu mẹfa nigba ti wọn ṣe ikọlu si ile ifowopamọ marun ni ilu Ọffa ni ipinlẹ Kwara to wa ni ẹkun iwọ oorun orilẹede Naijiria.
Awọn tọ rọ naa soju rẹ sọwipe awọn adigunjale naa ya bo agọ ọlọpa to wa ni agbegbe naa, ti wọn si pa awọn ọlọpa ati awọn to wa fẹjọ sun ni agọ ọlọpa, ko to di wipe wọn wa bẹrẹ si ni lọ si awọn ile ifowopamọsi lati lọ ja wọn ni ole. Ẹ ka ẹkunrẹrẹ rẹ ni bii
Òkú sùn nínú ìṣẹ̀lẹ̀ ìdigunjalè ní Ọ̀ffà
Òkú sùn nínú ìṣẹ̀lẹ̀ ìdigunjalè ní Ọ̀ffà
Alagá PDP ti gbé Lai Mohammed lọ ilé ẹjọ́
Oríṣun àwòrán, Twitter/@uchesecondus
Alaga ẹgbẹ́ òṣèlú PDP, Uche Secondus, ti mú ẹjọ́ minísítà fun ìròyìn atí àṣà Nàìjíríà, Lai Mohammed , lọ silé ẹjọ́ lorí ẹ̀sún ìbánílórúkọ́jẹ́, o sì ń fẹ́ kí mínísítà náà san bílíọ́nù kan àbọ̀ fún òun.
Secondus gbé ìgbesè yìí ni lẹyín ìgbà tí Mohammed fi órúkọ́ rẹ̀ sinú órúkọ́ àwọn ti ìjọba f'ẹ̀sun kíkówó jẹ́ kàn.
Ẹgbẹ́ òṣẹ̀lú PDP ti kọ́kọ́ fún minisita náà ni ọjọ́ mejì ko fi dá ọ̀rọ̀ náà padà.
Ọ̀gbẹ́ní Secondus ń fẹ́ kí Lai Mohammed tọrọ àforijì lẹyín ìgbà tó bá dá ọ̀rọ̀ náà padà gẹ́gẹ́ bi ìwe ìpẹ̀jọ náà fi hàn.
Wo fídíò bí Fẹ́mi Ọ̀tẹdọlá ṣe wọ ọkọ-akér ni London
Oríṣun àwòrán, Instagram/@Femiotedola
Ko si ńǹkan túntún nipa wiwọ okọ̀ akéro ti a mọ̀ si bọ́si, sùgbọ̀n àwọn eeyán ti ń pin fídíò bi Fẹ́mi Ọ̀tẹdọlá ṣe wọ ọkọ̀ akérò nígboro London lórí ẹ̀rọ-ayélujára.
Alága ilé iṣẹ́ Forte Oil to jẹ ọ̀kan lara àwọn ti wọn ni owó jù ni Nàìjíríà sọ wipe òun wọ ọkọ̀ náà ni lati lọ ri olukọ òun tẹlẹ̀ri, Wandsworth.
Sùgbọn àwọn ọmọ Nàìjíríà ti wo fídíò ọ̀hun nigba ẹ́gbẹ̀run l'ọ́ná ogọ́talénígba ( 260,000) lori òpó Instagram láàárin ọjọ́ mẹ́ta ti Ọ̀tẹdọlá fi fídíò ọ̀hun s'ọwọ si ori òpó náà.
Wọn si s'ọ̀rọ̀ nipa fídíò náà nigba ẹgbẹ̀run kan àti àádọ́rùúlénírínwó (1,490).
Saraki bẹ Ọlọ́ffá atí Ọ́ffà wò lori ìkọ̀lú ọlọ́ṣà
Oríṣun àwòrán, Twitter/@bukolasaraki
Ààrẹ ilé ìgbìmọ ásòfin àgbà, Bukọ́lá Sàràkí, bẹ ilu Ọ̀ffà wo lori ìkọ́lú àwọn ọlọ́ṣa l'ọjọ́ Àbámẹ́tá (Saturday).
Sàràki ba Ọlọ́ffá ìlú Ọ́ffà, Ọ́bá Muftau Gbàdámasí, ati àwọn ará ìlú kẹdùn loí òfo ẹ̀mi àti dúkìà tí wọn ṣe nipá ìkọlú àwọn ọlọṣa ti wọn ya wọ ìlú náà.
Oríṣun àwòrán, Twitter/@bukolasaraki
L'Ọjọ́bọ ni àwọn adigunjalè ya wọ ìlú  Ọ̀ffà ti wọn si wọn si jalè ni ilé ìfowópamọ́ marún.
Ọwọ ọlọ́pàá ti tẹ́ afurasí 7 lórí ìdigúnjalẹ́ Ọ́ffà
Oríṣun àwòrán, Ayobami Agboola
Guaranty Trust Bank Offa, Kwara state
Iléeṣé ọlọ́pàá ti ìpinlẹ Kwara ni iyé àwọn ti wọn ku nibi ìdigúnjalé àwọn ilé ìfowó pamọ si ni Ọ́ffà ti di mẹ́tàdínlogun.
Agbennusọ fún ọlọ́pàá ni ìpinlẹ̀ náà, Okasannmi Ajayi, sọ fún BBC  wipe mẹ́san ninú àwọn eeyáy mẹ́san ninu mẹ́tàdínlogun to ku ọ̀hun, ọlọ́pàá ni wọn, nigba ti mẹ́jọ́ jẹ alágbádá.
Botilẹ̀ jẹ́ wipe àwọn iwe ìròyìn kan sọ pe ọgbọ́n èèyán lo ku ninú ìkọlu náà, ọga ọlọ́pàá ọhun sọ wipe àwọn ti wọn ku wọn ku ju ọgbọ lọ
O sọ wipe àwọn ti wọn farapa nibi ìkọlù náà wa ni àwọn ilé ìwosan ìlú Ọ̀ffà ati ti ilè ẹ̀kọ gígá Ìlọ́rín.
O si sọ wipe lẹyín afurasi mẹ́jẹ́ ti wọn mu, ọwọ olọ́pàá ti tẹ ọkọ̀  méjé àti àwọn ẹ̀rọ́ ìbanisọ̀rọ̀ ti àwọn ọlọ́ṣà náà lo nibi ìkọlù ọ̀hun.
O sọ wipe gómináà ìpinlẹ̀ náà Abdulfatah Ahmed, ti kedé ẹ̀bún mílíọ̀nù marú naira fún gbogbo ẹ̀ni to ba le ṣ'àlàyé bi wọn yóò ṣe mu àwọn adigujalè náà.
Oríṣun àwòrán, Facebook/Kwara State Government
Ìlú Ọ̀ffà ní ìpínlẹ̀ Kwara wárìrì lọ́jọ́bọ, tí kowéè ké láì ha, nítorí ìṣẹ̀lẹ̀ ìdigunjalè kan tó wáyé nílé ìfowópamọ́ márùn ún ọ̀tọ̀ọ̀tọ̀ ní ìlú náà.
Àwọn eeṣin kò kọ ikú adigunjalè náà, tí wọ́n tó ọgbọ̀n níye ló ṣe ọṣẹ́ láwọn báńkì náà fún wákàtí méjì àti ààbọ̀ gbáko, èyí tó sọ ọ̀pọ̀ èèyàn di opó àti ọmọ òrukàn.
Kí aráyé baà leè mọ̀ pé eré kọ́ làwọn wá ṣe, àgọ́ ọlọ́pàá tó wà ní Owódé làwọn alọkólóhunkígbe yìí ti kọ́kọ́ kí wọn kú ilé níbẹ̀, tí wọ́n sì rán àwọn ọlọ́pàá tó wà lẹ́nu iṣẹ́, àwọn èèyàn tó ní ẹjọ́ ní tésàn náà àtàwọn èèyàn míì tó wà níbẹ̀ sọ́run ọ̀sángangan.
MMM ti kógbá wọlé
Oríṣun àwòrán, https://nigeria-mmm.net/news/
Níbáyìí, àwọn ti wọ́n lọwọ ninú sogúndogójì MMM wọ́n yóò mọ iyé owó ti wọ́n pàdanù nigbà tí àwọn alákósó rẹ̀ ti fi òpin síi.
Àwọn alákósó opó MMM lórí ẹ̀rọ ayélujara sọ wipe ńǹkan tí ó faà tí àwọn fi tií ni pe àwọn ko le maá bá etò sogúndogójì náà lọ laì sí ọ̀ga wọ́n tó dí olóògbẹ, Sergei Mavrodi.
Àtẹ̀jadé náà sí sọ wipe gbogbo àwọn ti wọn kopa ninú MMM ti mọ nipá ewu to wà nibẹ ki wọ́n ó tó ti ẹsẹ̀ bọọ́.
Wọ́n ni gbogbo ìgbìyanju atí tẹ̀siwaju pẹ̀lú sogúndogójì ọ́hun kò ní ṣeéṣé.
Èèyàn mẹ́fà kú nílé isẹ́ ìwakùsà ní Ghana
Oríṣun àwòrán, Getty Images
ọ̀pọ̀lọpọ̀ ìgbà ni ìjàmbá ti sekú pa àwọn ènìyàn ni àwọn ibi ìwakùsà lóri'lẹ̀èdè Ghana.
Oun tó tó èèyàn mẹ́fà ni a gbọ́ pe wọ́n ti pàdánù ẹ̀mí wọn ninu ìjàmba kan to waye nílé isẹ́ ìwakùsà Newmot lorilẹede Ghana.
Newmot ti ìsẹ̀lẹ̀ ọ̀ún ti sẹlẹ̀ jẹ́ iléese to wa lati ilẹ̀ Gẹ̀ẹ́sì.
Àjà ọ̀kan lara awọn àjaàlẹ̀ ti wọn ti n wa àlùmọ́ọ́nì góóòlù ni wọn ni o já lé awọn eniyan ọun lórí ti ọ̀pọ̀ ninu wọn náà sì farapa.
Awọn alẹ́nulọ́rọ̀ ti sọ pe wọ́n ti dásẹ́ dúró fúngbà díẹ̀ na lati sèwádìí ọ̀rọ̀ naa.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
ọ̀pọ̀ ilé isẹ́ ìwakùsà ti ìjàmbá ti n sẹlẹ̀ ni ọ́ jẹ́ èyí tíkò b'ófin mu
Newmont tó jẹ́ ọ́kan lara àwọn ilé isẹ́ tó n wa oun àlùmọ́ọ́nì góóòlù tó tóbi jù lágbááyé ni ó ní ilé isẹ́ ìwakùsà méjì ọ̀tọ̀ọ̀tọ̀  lórílẹ̀èdè Ghana .
Ìsẹ̀lẹ̀ Èkó: Ọmọge fẹsẹ̀ fẹ nígbàtí ọ̀rẹ́kùnrin rẹ̀ rì sómi nílé ìtura
Oríṣun àwòrán, Reuters
Ọ̀pọ̀ ìgbà láwọn èèyàn máa ń lọ lúwẹ̀ẹ́ nínú adágún odò ní ilé ìtura
Níwọ̀n ìgbà tó jẹ́ pé ọwọ́ epo ni ọmọ aráyé máa ń báni lá, wọn kìí bá ni lá ọwọ́ ẹ̀jẹ̀, ìdí rèé tí ọmọge kan ṣe fẹsẹ̀ fẹ́ẹ nílé ìtura kan ní àdúgbò Ishashi ní ìlú Èkó nígbàtí ọ̀rẹ́kùnrin rẹ̀ tí wọ́n jọ wá rì sínú omi tí wọn fi ń lúwẹ̀ẹ́ nílé ìtura náà.
Ní kété tí wọn sì rí òkú ọkùnrin náà ni wọ́n késí àwọn ọlọ́pàá, tí wọn yọ òkú náà, tí wọ́n sì gbée sílé ìwòsàn ní ọjọ́ kejọ̀, osù kẹrin tí ìsẹ̀lẹ̀ náà wáyé.
Sòwòrẹ́: Èmi kò leè bá jẹgúdújẹrá APC àti PDP se pọ̀
Alukoro iléeṣẹ́ ọlọ́pàá ní ìpínlẹ̀ Èkó, tó fìdí ìsẹ̀lẹ̀ náà múlẹ̀ ní, wọn kò tíì mọ ẹnití ọkùnrin naa jẹ́ àti ibití ó ń gbé, bẹ́ẹ̀ ni wọn kò rí ojú ọgbẹ́ ní ara òkú náà.
Ní kété tí ìṣẹ̀lẹ̀ náà ṣẹlẹ̀ ni obìnrin tí wọn dìjọ wá ti fẹsẹ̀ fẹ́ẹ, tí wọn kò sì rí ẹ̀rọ ìbáraẹnisọ̀rọ̀ alágbèéká ní ara òkú náà láti mọ ẹni tó jẹ́. A sì ti gbé òkú náà sí ibùdó ìgbókùúsí tó wà ní ilé ìwòsàn ìjọba ní ìlú Badagry.
Sàràkí: Orúkọ àwọn tó kówó ìlú mì tíjọba se kò dára tó
Oríṣun àwòrán, Nigeria Senate
Dúkùú láàárín ẹ̀ka ìṣèjọba lórílẹ̀èdè Nàìjíríà ti di ìsẹ̀lẹ̀ ojoojúmọ́
Ààrẹ ilé ìgbìmọ̀ aṣòfin àgbà lórílẹ̀èdè Nàìjíríà, Sẹ́nétọ̀ Bùkọ́lá Sàràkí ti sọ pé, kò sí bí àjọṣepọ̀ tó gún ṣe lè wà láàárín ẹ̀ka ìṣàkóso ìjọba àti aṣòfin nítorí ìwà àìfinipeni, àìfèèyànpèèyàn.
Sẹ́nétọ̀ Bùkọ́lá Sàràkí ní, nìwọ̀n ìgbà tí ẹ̀ka ìṣàkóso bá ń nàka 'olè ni ọ́' sí ẹ̀ka tó kù, àláfíà kò lè ṣí.
Sàràkí sọ ọ̀rọ̀ yìí níbi àpérò kan tó wáyé ní ìlú Jos, lópin ọ̀sẹ̀ tó kọjá.
Oríṣun àwòrán, Nigeria Presidency
Bílíọ̀nù kan dọ́là tí ẹ̀ka aláṣẹ kéde láti ra ohun ìjà ogun ló ṣeéṣe kó tún fa wàhálà míì
Ọ́ ṣàlàyé pé, bí ẹ̀ka ìṣèjọba bá ń nàka àléébù sí ẹ̀ka míràn, kò sí bí nǹkan yóò ṣe dán mọ́rán.
Ààrẹ iléègbìmọ̀ aṣòfin àgbà lórílẹ̀èdè Nàìjíríà wá bu ẹnu àtẹ́ lu ìwé orúkọ àwọn tó kó owó ìlú jẹ, èyí tí ìjọba Buhari ń gbé kiri báyìí gẹ́gẹ́ bíi èyí tó kù díẹ̀ káàtó.
Bákannáà ni, Sàràkí tún yànànà ìhà tí àwọn aṣòfin àgbà kọ sí ìkéde bílíọ̀nù kan dọ́là owó ilẹ̀ Amẹ́ríkà tí ẹ̀ka aláṣẹ ṣe láìpé yìí, láti fi pèèlò ohun ìjà ogun tuntun fún àwọn ọmọ ogun tó ń kojú u ìpèníjà ààbò káàkiri tìbútòró orílẹ̀èdè Nàìjíríà.
Oríṣun àwòrán, Nigeria Presidency
'Dídẹ́yẹsí àwọn ẹ̀ka ìṣèjọba tókù kò leè so èso rere fún ìdàgbàsókè orílẹ̀èdè Nàìjíríà'
Ọ́ ní dídẹ́yẹsí àwọn ẹ̀ka ìṣèjọba tókù kò leè so èso rere fún ìdàgbàsókè orílẹ̀èdè Nàìjíríà.
Ó ní ìwà àìfinipeni, àìfèèyànpèèyàn tí ẹ̀ka aláṣẹ ń hù ló ń fa dúkùú lọ́pọ̀ ìgbà, láàárín ẹ̀ka aláṣẹ àti àwọn aṣòfin lórílẹ̀èdè Nàìjíríà.
CAN: Ẹgbẹ́ àwọn pásítọ̀ náà ṣàjèjì sí ẹgbẹ́ wa
Oríṣun àwòrán, @AsoRock
Ariwo bẹ́ sílẹ̀ láàárín àwọn asáájú ẹ̀sín krìstẹ́nì nítorí àbẹ̀wò àwọn pásítọ̀ kan sí Ààrẹ Mùhámádù Bùhárí
Ẹgbẹ́ àwọn ọmọlẹ́yìn Krístì lórílẹ̀èdè CAN ti sọ èrèdì rẹ̀, tí ẹgbẹ́ náà fi kẹ̀yìn sí àwọn pásítọ̀ kan, láti ẹkùn àríwá orílẹ̀èdè Nàìjíríà, tí wọ́n bẹ Ààrẹ Mùhámádù Bùhárí wò láìpé yìí.
Nínú àtẹ̀jáde tí CAN fi ṣọwọ́ sí BBC Yoruba, ó ní, ìdí àkọ́kọ́ ni pé, ẹgbẹ́ àwọn pásítọ̀ náà ṣàjèjì sí ẹgbẹ́ CAN, àti pé ẹgbẹ́ náà kúkú ti jẹ́wọ́ ara rẹ̀  pé àwọn kìí ṣe ara CAN.
Ìdí kejì ni pé ìyàlẹ́nu ló jẹ́ pé ẹgbẹ́ yìí lọ sí ọ̀dọ̀ Ààrẹ Mùhámádù Bùhárí, láì pè fún ìtúsílẹ̀ Leah Sharibu àtàwọn akẹ́kọ Chibok to kù láhámọ́ àwọn Boko haram.
Sòwòrẹ́: Èmi kò leè bá jẹgúdújẹrá APC àti PDP se pọ̀
Bákannáà ni wọ́n ní kàyééfì ńlá ló jẹ́ pé àwọn pásítọ̀ náà kò sọ̀rọ̀ lórí ìkọlù àti ìpànìyàn tó ń wáyé lórílẹ̀èdè Nàìjíríà.
CAN kò ṣàì kọminu lórí ohun tí àwọn pásítọ̀ náà sọ pé àwọn alátakò ń lo àwọn pásítọ̀ kan láti tako Bùhárí.
Lọ́sẹ̀ tó kọjá làwọn pásítọ̀ kan lábẹ́ àṣíá ẹgbẹ́ àwọn pásítọ̀ lẹ́kùn Arewa tó ń fẹ́ àláfíà, APPIN, bẹ Ààrẹ Mùhámádù Bùhárí wò ní Abúja.
Líìgì obìnrin: Gbèsè táwọn agbábọ́ọ́lù obìnrin jẹ pọ̀
Oríṣun àwòrán, Nigeria women league board
Àjọ NWFL kéde gbèdéke ọjọ́ kẹwàá oṣù kẹrin fún sísan gbèsè
Àjọ tó ń ṣe àmójútó idíje líìgì bọ́ọ̀lù àfẹsẹ̀gbá àwọn obìnrin lórílẹ̀èdè Nàìjíríà, NWFL, ti pariwo síta pé, òun yóò sún idíje líìgì bọ́ọ̀lù àfẹsẹ̀gbá àwọn obìnrin síwájú pátápátá.
Ó ní kò sí ìdí méjì ju bí àwọn ẹgbẹ́ agbábọ́ọ̀lù obìnrin kan tó ń kópa nínú líìgì Nàìjíríà, kò ṣe tíì san owó tí wọ́n jẹ àjọ náà.
Bí ó ti lẹ̀ jẹ́ wí pé wọ́n ti ṣíde líìgì bọ́ọ̀lù àfẹsẹ̀gbá àwọn obìnrin lópin ọ̀sẹ̀ tó kọjá, aláàmójútó àjọ náà, Ayọ̀ Abdulrahaman, ní ohun kan tó lè dènà sísún ìdíje náà síwájú ni kí àwọn ẹgbẹ́ agbábọ́ọ̀lù tó jẹ àjọ náà
ní gbèsè, yára tètè san owó tí wọ́n jẹ.
Àjọ ọ̀hún ní, gbèdéke ọjọ́ kẹwàá oṣù kẹrin ọdún 2018, ni wọ́n fún àwọn ẹgbẹ́ agbábọ́ọ̀lù tó jẹ gbèsè náà láti fi san owó tí wọ́n jẹ.
Irú èèyàn wo ni Akínwùmí Ìṣọ̀lá jẹ́?
Oríṣun àwòrán, @MobilePunch
Oloogbe Ishọla lo kọ iwe Ẹfunsetan Aniwura
Kìí ṣe ìròyìn mọ́ wí pé ògbóǹtagí òǹkọ̀tàn àn nì, Akínwùmí Ìṣọ̀lá ti dágbére  fáyé.
Àmọ́ṣá, lọ́jọ́ ìṣẹ́gun ni ètò ìsìnkú rẹ̀ yóò bẹ̀rẹ̀ kí wọ́n tó gbé e wọ káà ilẹ̀ lọ lọ́jọ́ ẹtì.
Gẹ́gẹ́ ́bíi ọ̀rọ̀ àwọn onímọ̀ nípa iṣẹ́ ọwọ́ àti ìgbé ayé olóògbé Ìṣọ̀lá, ìpapòdà èèkàn ìmọ̀ èdè Yorùbá náà ti ṣílẹ̀kùn ààyè ńlá sílẹ̀ tí yóò ṣòro láti dí.
Wọ́n wòye pé, gẹ́gẹ́ bíi òǹkọ̀wé, agbáṣàga, olùkọ́ ìmọ̀ ìjìnlẹ̀, ẹyẹ tí yóò ṣe bí àdán an Ọ̀jọ̀gbọ́n Akínwùmí Ìṣọ̀lá ṣọ̀wọ́n.
Díẹ̀ nínú ohun tí àwọn ọ̀jọ̀gbọ́n nínú àṣà àti èdè Yorùbá sọ nípa ọ̀jọ̀gbọ́n Ìṣọ̀lá nìyí:
Òǹkọ̀wé tí kò fi àṣà àti ìṣe Yorùbá ṣeré ni. O gbé èdè Yorùbá lárugẹ títí dé òkè òkun.
Ní kíkọ, ó kọọ́; ní ṣíṣe, ó ṣe è. Gbogbo ẹ̀ka èdè ló ti pegedé bíi ìwé kíkọ àti eré ìtàgé.
Tunde Kelani k'ẹdun iku Akinwunmi Ishola
Nǹkan tí èmi mọ̀ ni tó ṣe kókó jù nípa Olóyè Ọ̀jọ̀gbọ́n Akínwùmí Ìṣọ̀lá ni p, ó ṣiṣẹ́ takuntakun láti gbé àṣà Yorùbá lárugẹ. O sì ṣiṣẹ́ yìí pẹ̀lú ọ̀pọ̀lọpọ̀ eré tó kọ sílẹ̀ tí kò lè parun.
Ẹni tó mọ ọ̀rọ̀ ń kójọ ni. Tí wọ́n bá kọ ìwé tàbí eré ìtàgé wọ́n mọ ọ̀rọ̀ ń kó jọ tí yóò níkìmí.
'Honest man' (olóòótọ́ ènìyàn) ni ìnágijẹ bàbá nígbà tí wọ́n wà láyé nítorí èèyàn iyì ni wọ́n.
Ọ̀jọ̀gbọ́n àti onímọ̀ tó yanrantí ni wọ́n, ní ìgbà ayé e wọn. Kò sí akẹ́kọ́ tí kìí sọ ọ̀rọ̀ wọn ní rere.
Wọ́n kọ́ mi ní fásitì, mo mọ̀ wọ́n gẹ́gẹ́ bíi olùkọ́ni tó dáńtọ́ tó sì ṣetán láti ṣe ìrànlọ́wọ́ fún àwọn tó ń bọ̀ lẹ́yìn.
Ìbúgbámù ṣe'kú pa èèyàn kan ní Ilẹ̀ ifẹ̀
Oríṣun àwòrán, Baba oloye
Ìbúgbámù náà wáyé nílú Ilé ifẹ̀ lóru ọjọ́ àbámẹ́ta
Iléeṣẹ́ ọlọ́pàá ti sọ pé àwọn kò tíì leè sọ bóyá àdó olóró ló bú nílééṣẹ́ ìtoògùn  kan  ní ìlú Ilé ifẹ̀.
Ìbúgbámù kan wáyé ni iléeṣẹ́ apoògùn kan níÌlú Ilé ifẹ̀ lóru ọjọ́ àbámẹ́ta sí àìkú.
Iléeṣẹ́ apoògùn náà tí orúkọ rẹ̀ ńjẹ́ Ebenco ni ìròyìn sọ pé àwọn èèyàn tí gbọ́ ìróo ìbúgbàmù eléyìí tó da ilé náà wó lu lẹ̀.
Ìbúgbámù ṣekú pa èèyàn kan ní Ilé ifẹ̀
"Nínú ìfòròwánilénuwò tó ṣe pẹ̀lu BBC Yorùbá, kọmíṣọ́nà ọlọ́pàá nípínlẹ̀ Ọ̀ṣun, Ọláfimíhàn Adéoyè ní ìwaàdí ni yóò sọ ní pàtó, ohun gan tó ṣokùnfà ìbúgbámù náà.""Èèyàn kan tó ṣèṣe nínú ibu ìbúgbámù ọ̀hun padà kú. Ṣùgbọ́n ìwaàdí ni yóò fìdí òkodoro ọ̀rọ̀ múlẹ̀"""
Oríṣun àwòrán, Baba oloye
Ọlọ́pàá ní ìwaàdí ni yóò sọ bóyá àdó olóró ni
Ọ̀gá ọlọ́pàá nípínlẹ̀ Ọ̀ṣun sọ pé irúfẹ́ ìṣẹ̀lẹ̀ náà kò wáyé rí, àwọn yóò sì gbé ìgbésẹ̀ láti dẹ́kun àtúnṣẹ̀ rẹ̀.
Nígbà tí kọmíṣọ́nà ọlọ́pàá, Ọláfimíhàn Adéoyè bẹ ibi tí ìṣẹ̀lẹ̀ ìbúgbàmù náà ti ṣẹ̀lẹ̀ wò lọ́jọ́ ajé, ó ní àwọn agbófìnró yóò máa ṣètò àbò tó gbópọn fún àwọn aráàlú.
Buhari yóò ṣèpàdé pẹ́lú Theresa May lórí ọ̀rọ̀ Nigeria
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Buhari yóò ṣèpàdé pẹ́lú Theresa May lórí ọ̀rọ̀ Nigeria
Ààrẹ Muhammadu Buhari tẹkọ̀ òfurufú létí  lọ sí bẹ ìlu Ọba fún ìbẹ̀wò isẹ́ sáájú ìpàdé àwọn  olórí orílẹ̀èdè Commonwealth èyí tí yóò wáyé ní ọjọ́ kejìdínlógún osù kẹrin ọdún yìí.
Lasiko àbẹ̀wò náà, yóò se ìpàdé pẹ̀lú olórí ìjọba ilẹ̀ Gẹ̀ẹ́sì, Theresa May àti àwọn èèkàn mìíràn lórí àwọn ìpènijà tí orílẹ̀èdè Nigeria ńdojú kọ àti ọ̀nà àbáyọ.
Bákan náà, ààrẹ Buhari yóò pàdé pẹ̀lú Bísọ̀ọ̀bù àgbà ti Canterbury, ẹni ọ̀wọ̀ jùlọ Hon. Justin Welby ẹni tó jẹ́ ọ̀rẹ́ rẹ̀.
Malam Garba Shehu, tó jẹ́ olùrànlọ́wọ́ àgbà fún ààrẹ lórí ìròyìn sọ wípé ààrẹ Buhari  àti olórí ìjọba ilẹ̀ Gẹ̀ẹ́sì, Theresa May yóò tún jíròrò lórí àjọsepọ̀ láàrin orílẹ̀èdè Nigeria àti  ilẹ̀ Gẹ̀ẹ́sì.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ọ̀pọ̀ awuyewuye ló tọ àbẹ̀wò rẹ̀ àkọ́kọ́ sí ilẹ̀ Gẹ̀ẹ́sì
Láfikún, ààrẹ yóò sèpàdé pẹ̀lú ọ̀gá pátátá ilé isẹ́ Royal Dutch Plc, Ben van Beuden lórí àwọn ètò tí ilé isẹ́ Shell àtàwọn alájọsepọ̀ wọn ní láti dókoòwò iye owó bílíọ̀nù dọ́là mẹ́ẹ̀dógún sínú owò epo orílẹ̀èdè Nigeria.
Ní ọdún tó kọjá, ẹ̀ẹ̀mẹ́jì ni ààrẹ Buhari ti lọ si ìlú London lórí ìlera rẹ̀ kó tó padà nínú osù kẹjọ.
Ìpàdé àwọn  olórí orílẹ̀èdè Commonwealth yóò wáyé  láàrin ọjọ́ kejìdínlógún ọdún yìí sí ogúnjọ́ osù kẹrin.
Ẹ̀wẹ̀, kò tíì dájú iye ọjọ́ tí yòó lò.
Buhari: Mo fẹ́ se sáà kejì lórí oyè
Oríṣun àwòrán, Reuters
Àwọn ọmọ Nàíjíríà ti ń fojú sọ́nà láti mọ bóyá Buhari yóò se sáà kejì
Ààrẹ Muhammadu Buhari ti kéde pe òun fẹ́ ṣe ìjọba ni sáà kéjì.
Bashir Ahmad, tíí se òlùrànlọ́wọ́ fún ààrẹ lórí ẹ̀rọ áyélujará, ló fi ọ̀rọ̀ náà sọwọ si orí opó Twitter rẹ̀.
Lẹyín rẹ̀ ni gómìnà ìpinlẹ Kaduna, Nasir El'Rufai náà kéde ìròyìn náà lórí Facebook rẹ̀
A yóò máa mú èrò àwọn aaráàlú wá fún yín lórí ìgbésẹ̀ yìí tó bá yá.
Àgbáríjọpọ̀ àwọn akẹ́kọ̀ọ́ AAUN fẹ̀hónú hàn nípìnlẹ̀ Òndó
Oríṣun àwòrán, AAUA News Forum
Ọlọ́pàá yìnbọn fún akẹ́kọ̀ọ́ AAUA
Àwọn akẹ́kọ̀ọ́ fásitì Adekunle Ajasin, Akungba-Akoko tú síta kẹ̀tí-kẹ̀tí lónì''i láti fẹ̀hónú hàn lórí i àfikún owó iléèwé tí ìjọba ìpínlẹ̀ Òndò paláṣẹ.
BBC Yorùbá ri gbọ́ wípé ìfẹ̀hònúhan náà wáyé ní ìlú Àkùngbá-Àkókó àti ìlú Àkúrẹ́ tí ṣe olú ìlú ìpínlẹ̀ Òndó.
Ààrẹ fún ẹgbẹ́ àwọn ọmọbíbí ìpínlẹ̀ Òndó ní fásitì nàá, Popoọla Morayọ Samson sọ fún BBC pe ìjọba ìpínlẹ̀ Òndó ṣèlérí ètò ẹ̀kọ́ ọ̀fẹ́ fún àwọn akẹ́kọ̀ọ́ nàá láti fi tùwọ́n l'ójú. Ṣùgbọ́n, ó ní àwọn kò fẹ́ ètò ẹ̀kọ́ ọ̀fẹ́ nàá, ẹ̀dínwó owó ilé-ìwé l'àwọ́n fẹ́.
Owó ilé-ìwé tó kéré jù tí àwọn akẹ́kọ̀ọ́ nàá n san tẹ́lẹ́ ni ẹgbẹ̀rún mẹ́tàlélógún lé ọgọ́rùn ún Náírà, ṣùgbọ́n tí ìjọba ti sọ di ààdọ́jọ ẹgbẹ̀rún Náírà.
Oríṣun àwòrán, AAUN News Forum
Akitiyan BBC láti bá iléeṣẹ́ ọlọ́pàá ní ìpínlẹ̀ Òndó jásí pàbó
Ó fi kun pé fásitì nàá ni owó rẹ̀ kéré jùlọ tẹ́lẹ̀rí ní Nàìjíríà.
Lásìkò ìfẹ̀hónúhàn nàá, a gbọ́ wípé àwọn ọlọ́pàá gbìyànjú láti fi afẹ́fẹ́ tajú-tajú tú àwọn akẹ́kọ̀ọ́ nàá ka. Bákanna ni Popoọla Morayọ sọ wípé wọ́n yin ìbọn mọ́ ọ̀kan lára àwọn akẹ́kọ̀ọ́ nàá l'ẹ́sẹ̀.
Akẹ́kọ̀ọ́ ọ̀hún ló ní wọ́n ti gbé lọ sí ilé ìwòsàn fún ìtọ́jú.
Oríṣun àwòrán, AAUN News Forum
Owó ilé-ìwé tó kéré jù tí àwọn akẹ́kọ̀ọ́ nàá n san tẹ́lẹ́ ni ẹgbẹ̀rún mẹ́tàlélógún lé ọgọ́rùn ún Náírà
Ẹ̀wẹ̀, ààrẹ ilé ìgbìmọ̀ aṣòfin fásítì nàá, Awoṣika Ayọdapọ sọ wípé ọ̀pọ̀lọpọ̀ ìpàdé l'àwọn ti ṣe pẹ̀lú ìjọba, ṣùgbọ́n tí wọ̀n kò gbìpẹ̀.
Akitiyan BBC láti bá iléeṣẹ́ ọlọ́pàá ní ìpínlẹ̀ Òndó jásí pàbó.
Sáà kejì Ààrẹ Bùhárí: Àwọn ọmọ Nàíjíríà f'èrò wọn hàn
Ẹ jẹ́ kí Buhari lọ jókòó
Awọn ọmọ orilẹede Naijiria ti fi ero wọn han lori bi Aarẹ Muhammadu Buhari se fi ipinnu rẹ han lati dije fun ipo aarẹ lẹlẹẹkeji ni idibo gbogboogbo ti yoo waye lọdun 2019.
Aarẹ Buhari nigba to n ba awọn igbimọ alaṣẹ ṣe ipade ni ọjọ aje ni Abuja, fi kun un wipe ohun yoo dije si ipo aarẹ labẹ ẹgbẹ oṣelu APC lọdun 2019.
Lara awọn ara ilu nigba ti wọn n ba BBC Yoruba s'ọrọ wipe igba ko lọ dede fun awọn, nitori naa ko yẹ ki aarẹ sọ wi pe oun n lọ fun saa keji.
Ará ìlú f'èrò hàn lórí sáà kejì Bùhárí
Ṣugbọn awọn miran sọ wi pe saa keji yoo fun aarẹ naa laaye lati pari gbogbo iṣẹ to bẹrẹ ni saa kini rẹ.
Ninu ọrọ ti wọn, onimọ nipa eto oṣelu, Gbola Oba ati Kayode Eesuola sọ wi pe Aarẹ Muhammadu Buhari lẹtọ labẹ ofin lati dije gẹgẹbi aarẹ lẹlẹẹ keji.
Oríṣun àwòrán, @BashirAhmaad
Ará ìlú f'èrò hàn lórí sáà kejì Bùhárí
Amọ, wọn fikun un wipe awọn ọmọ Naijiria ni yoo woye gbogbo bi eto oṣelu saa aarẹ Buhari ṣe ri lalakọkọ, ki wọn to pinnu lati d'ibo fun lelekeji.
Kókó ìròyìn t'òní: Sáà kejì Ààrẹ Bùhárí, Ọlọ́pàá yìn'bọn lu akẹ́kọ̀ọ́ l'Óǹdó
Eyi ni awọn akojọpọ iroyin ti toni.
Sáà kejì Ààrẹ Bùhárí: Àwọn ọmọ Nàíjíríà f'èrò wọn hàn
Ẹ jẹ́ kí Buhari lọ jókòó
Awọn ọmọ orilẹede Naijiria ti fi ero wọn han lori bi Aarẹ Muhammadu Buhari se fi ipinnu rẹ han lati dije fun ipo aarẹ lẹlẹẹkeji ni idibo gbogboogbo ti yoo waye lọdun 2019.
Aarẹ Buhari nigba to n ba awọn igbimọ alaṣẹ ṣe ipade ni ọjọ aje ni Abuja, fi kun un wipe ohun yoo dije si ipo aarẹ labẹ ẹgbẹ oṣelu APC lọdun 2019.
Ọlọ́pàá yìn'bọn lu akẹ́kọ̀ọ́ ní ìpínlẹ̀ Òǹdó
Oríṣun àwòrán, AAUN News Forum
Owó ilé-ìwé tó kéré jù tí àwọn akẹ́kọ̀ọ́ nàá n san tẹ́lẹ́ ni ẹgbẹ̀rún mẹ́tàlélógún lé ọgọ́rùn ún Náírà
Àwọn akẹ́kọ̀ọ́ fásitì Adekunle Ajasin, Akungba-Akoko tú síta kẹ̀tí-kẹ̀tí lónì''i láti fẹ̀hónú hàn lórí i àfikún owó iléèwé tí ìjọba ìpínlẹ̀ Òndò paláṣẹ.
Ààrẹ fún ẹgbẹ́ àwọn ọmọbíbí ìpínlẹ̀ Òndó ní fásitì nàá, Popoọla Morayọ Samson sọ fún BBC pe ìjọba ìpínlẹ̀ Òndó ṣèlérí ètò ẹ̀kọ́ ọ̀fẹ́ fún àwọn akẹ́kọ̀ọ́ nàá láti fi tùwọ́n l'ójú. Ṣùgbọ́n, ó ní àwọn kò fẹ́ ètò ẹ̀kọ́ ọ̀fẹ́ nàá, ẹ̀dínwó owó ilé-ìwé l'àwọ́n fẹ́. Ẹ ka ẹkunrẹrẹ ni bii
Gbọ iroyin iṣẹju kan BBC:
Fidio wa fun toni:
Ọmọ́yelé Sòwòrẹ́ tó fẹ́ dupò ààrẹ ní Nàíjíríà ní òun kò leè bá jẹgúdújẹrá ẹgbẹ́ òsèlú APC àti PDP se pọ̀.
Sòwòrẹ́: Èmi kò leè bá jẹgúdújẹrá APC àti PDP se pọ̀
Ìjà jàǹdùkú ní'jẹ̀bú: Ọ̀gá ọlọ́pàá, aráàlú mẹ́rin ku
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Àwọn ọlọ́pàá kìí jáfara láti dá àlàáfíà padà sáwọn ágbègbè tí wàhálà bá ti ń wáyé
Kò dín ní ẹ̀mí márùń, nínú èyí tí a ti rí aráàlú mẹ́rin àti Ìsìpẹ́kítọ̀ ọlọ́pàá kan, tó ku nínú ìpórógan tó wáyé láàrin ẹgbẹ́ kan tí àwọn èèyàn funra sí pé ó ṣeéṣe kó jẹ́ àwọn jàǹdùkú kan láti ẹgbẹ́ OPC àti ẹgbẹ́ òkùnkùn kan ní ìlú Ìjẹ̀bú Igbó lọ.
A gbọ́ pé ìṣẹ̀lẹ̀ náà ṣẹlẹ̀ lẹ́yìn ìpàdé òṣèlú kan tó wáyé láàárín igun óṣèlú méjì kan lágbègbè náà.
Aago márùń ààbọ̀ ìrọ̀lẹ́ lọ́jọ́ àìkú ni ìsẹ̀lẹ̀ náà wáyé ní agbègbè Òkè-Sopen, tó sì sún wọ ìdàjí ọjọ́ ajé, èyí tó tún tàn wọ àwọn àdúgbò míì bíi Òkè Àgbò àti Ojowo.
Àwọn èèyàn tí ìṣẹ̀lẹ̀ náà sojú wọn ní ààrin àwọn ọmọ ẹgbẹ́ OPC kan àti ẹgbẹ́ òkùnkùn Aiyé ni rògbòdìyàn náà ti kọ́kọ́ bẹ̀rẹ̀, kí àwọn ọlọ́pàá tó dá síi, tí ẹ̀mí ọmọ ẹgbẹ OPC kan sì bọ́.
Ileeṣẹ ọlọpaa nipinlẹ Ogun ni awọn ti ko ikọ Olopaa kogberegbe lọ si agbegbe naa lati lọ wawọ́ ọ  rogbodiyan naa bọlẹ.
Alukoro ileeṣẹ ọlọpaa, DSP Abimbọla Oyeyẹmi ni gbogbo awọn ti aje rogbodiyan naa ba ṣi mọ lori ni yoo fi oju wina ofin.
Wàyí ò, iléesẹ́ ọlọ́pàá ìpínlẹ̀ Ògùn ti ń ri dájú pé àlàáfíà ti ń padà jọba lágbègbè náà.
Ìpànìyàn Ìjẹ̀bú Igbó: Ọwọ́ Ọlọ́pàá tẹ afurasí 29
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Àwọn ọlọ́pàá kìí jáfara láti dá àlàáfíà padà sáwọn ágbègbè tí wàhálà bá ti ń wáyé
Iléesẹ́ ọlọ́pàá ìpínlẹ̀ Ògùn ti fìdí rẹ̀ múlẹ̀ pé ọwọ́ òun ti tẹ afurasí mọ́kàndínlọ́gbọ̀n lórí ìpànìyàn tó wáyé ní Ìjẹ̀bú Igbó ní aago márùń ààbọ̀ ìrọ̀lẹ́ ọ́jọ́ àìkú ní agbègbè Òkè-Sopen, tó sì sún wọ ìdàjí ọjọ́ ajé, èyí tó tún tàn wọ àwọn àdúgbò míì bíi Òkè Àgbò àti Ojowo.
A gbọ́ pé kò dín ní ẹ̀mí mẹ́ta, nínú èyí tí a ti rí aráàlú méjì àti Ìsìpẹ́kítọ̀ ọlọ́pàá kan, tó bá ìpórógan tó wáyé láàrin ẹgbẹ́ OPC àti ẹgbẹ́ òkùnkùn kan ní ìlú Ìjẹ̀bú Igbó ọ̀hún lọ.
Gẹ́gẹ́ bíí Alukoro fún iléesẹ́ Ọlọ́pàá ní ìpínlẹ̀ Ògùn, Abimbọla Oyeyẹmi ti wí, ìsẹ̀lẹ̀ náà kò ní ohunkohun se pẹ̀lù ọ̀rọ̀ òsèlú, pẹ̀lú àfikun pé àwọn ọlọ́pàá tún gba ìbọn lọ́wọ́ àwọn afurasi naa.
"Ẹ gbọ́ ẹ̀kúnrẹ́rẹ́ ohun tí Ọ̀gbẹ́ni Abimbọla Oyeyẹmi sọ lórí ìsẹ̀lẹ̀ náà"""
Ìpànìyàn Ìjẹ̀bú Igbó: Ọwọ́ Ọlọ́pàá tẹ afurasí 29
"Nígbà tí òun náà ń sọ̀rọ̀ lórí ìsẹ̀lẹ̀ yìí, Alukoro fún ẹgbẹ́ ọmọ bíbí Oòduà, OPC, Ọ̀gbẹ́ni Sina Akinpẹlu ní ""isẹ̀lẹ̀ náà bani nínújẹ́ púpọ̀ sùgbọ́n OPC kọ̀ ní gbé ìgbẹ́sẹ̀ láti fẹ sẹ̀lẹ̀ náà lójú."
Ó wá rọ iléesẹ́ Ọlọ́pàá láti ri dájú pé àlàáfíà tètè padà jọba lágbègbè náà nítorí ilẹ̀ Yorùbá kò gbọdọ̀ bàjẹ́.
Wàhálà Ìjẹ̀bú Igbó: OPC sọ ohun tó bí ìsẹ̀lẹ̀ náà
Fayose: Nàìjíríà kò nílò Buhari gẹ́gẹ́ bíi ààrẹ rẹ̀ mọ́
Oríṣun àwòrán, Nigeria Presidency
Ààrẹ Bùhárí pẹ̀lú Gómìnà Fáyòṣé kò fìgbàkan ṣọ̀rẹ́ ara wọn
Gómìnà ìpínlẹ̀ Èkìtì, lẹ́kùn ìwọ̀ oòrùn Nàìjíríà, Ayọ̀délé Fáyòṣé ní, orílẹ̀-èdè Nàìjíríà kò nílò Buhari gẹ́gẹ́ bíi ààrẹ rẹ̀ mọ́.
Nínú àtẹ̀jáde kan tó fi síta lórí ìpinnu ààrẹ Bùhárí láti gbé àpótí ìbò lẹ́ẹ̀kejì, ni Fáyóṣé ti sọ èyí di mímọ̀.
Fáyòṣé ní, ' Bùhárí ti kùnà ní gbogbo ọ̀nà títí kan gbígbógun ti ìwà ìbàjẹ́ tó gbé karí.'
Ọ̀kan pàtàkì lára àwọn ènìyàn tó tako Bùhárí ni Fáyòṣé jẹ́, kìí sìí tijú àti kọ lùú nígbà kúgbà tí ààyè rẹ̀ bá yọ.
Oríṣun àwòrán, Nigeria Presidency
Ọ̀pọ̀ àwọn aṣíwájú orílẹ̀èdè Nàìjíríà ni wọ́n ti ṣíwájú láti rọ Ààrẹ Bùhárí pé kó máse gbégbá ìbò ààrẹ lẹ́ẹ́kejì
Fáyòṣé ní ìjọba Buhari kò ṣe àǹfàní fún orílẹ̀-èdè Nàìjíríà mọ àtipé ọ̀rọ̀ ìjọba Bùhárí ti sú ọ̀pọ̀ àwọn ọmọ Nàìjíríà.
A kò fẹ́ bàbá àgbà mọ́ nípò. Kò sí àṣeyọrí kan lẹ́ka ọ̀rọ̀ ààbò bẹ́ẹ̀ ni ẹ̀ka ọ̀rọ̀ ajé pẹ́lú mẹ́hẹ.
Lọ́jọ́ ajé ni ààrẹ Mùhámádù Bùhárí kéde rẹ̀ fáye pé, òun fẹ́ gbégbá ìbò sípò ààrẹ lẹ́ẹ́kejì eléyìí tó ti ń fa àríyànjiyàn láàárín àwọn ọmọ Nàìjíríà.
Fasiti OAU: À wádìí olùkọ́ tó fẹ́ bá akẹ́kọ̀ọ́ lò fún máákì
Oríṣun àwòrán, @OfficialOAU
Fásitì OAU ní ààbò àṣírí wà fún akẹ́kọ̀ọ́ yóówù tó bá ta àwọn aláṣẹ fásitì náà lólobó ìwà ìbàjẹ́
Fásitì Ọbafẹ́mi Awólọ́wọ̀ ní Ìlú Ilé ifẹ̀, OAU, ti gbé ìgbìmọ̀ kan kalẹ̀ lórí ìròyìn aṣemáṣe tó dá lóríi ẹ̀sùn bíbéèrè fún ìbálòpọ̀ láti gba máàkì ìdánwò lọ́wọ́ akẹ́kọ́bìnrin kan, èyítí wọ́n fi kan ọ̀kan lára àwọn olùkọ́ fásitì náà.
Ariwo ta lórí ìtàkùn ayélujára ní ọjọ́ ajé, nípa ọ̀jọ̀gbọ́n Richard Akindele, ti ẹ̀ka ìmọ̀ nípa ìṣirò owó tí wọ́n ní, o ń bèèrè fún ìbálòpọ̀ ìgbà máàrún ọ̀tọ̀ọ̀tọ̀ lọ́wọ́ ọ̀kan lára àwọn akẹ́kọ́bìnrin tó fìdírẹmi nínú ìmọ̀ ẹ̀kọ́ kan tí ọ̀jọ̀gbọ́n náà ń kọ́.
Ohùn àkásílẹ̀ nípa àjọsọ ọ̀rọ̀ láàárín akẹ́kọ́bìnrin ọ̀hún àti ọ̀jọ̀gbọ́n Richard Akindele lórí ẹ̀rọ ìbánisọ̀rọ̀ ti wọ́n ká sílẹ̀ sórí ìkànnì ayélujára, ló tí ń jà ràìn-ràìn káàkiri báyìí.
Alukoro fásitì Ọbafẹ́mi Awólọ́wọ̀ ní Ìlú Ilé ifẹ̀, OAU, Ọ̀gbẹ́ni Abíọ́dún Ọláńrewájú n,i fásitì náà ti bẹ̀rẹ̀ ìwádìí lórí rẹ̀ tí wọ́n sì ti gbé ìgbìmọ̀ kan kalẹ̀ láti tú'ṣu dé ìsàlẹ̀ ìkòkò ọ̀rọ̀ náà.
Oríṣun àwòrán, Facebook/@OfficialOAU
Fasiti OAU: À wádìí olùkọ́ tó fẹ́ bá akẹ́kọ̀ọ́ lò fún máákì
Nínú ìfòròwánilẹ́nuwò rẹ̀  pẹ̀lù BBC Yorùbá, alukoro fásitì OAU ni àwọn aláṣẹ fásitì náà yóò ṣe ohun gbogbo tó bá tọ́ lórí ọ̀rọ̀ náà.
"A fẹ́  gbé ìgbìmọ̀ kan kalẹ̀ láti wòó bóyá nǹkan tí a gbọ́  lórí ìkànnì ayélujára jẹ́ òòtọ́ tàbí irọ́. Tó bá wá jẹ́  òòtọ́, a óò gbé ìgbésẹ tí òfin ilé ìwé yìí là kalẹ̀.Ọ̀gbẹ́ni Abíọ́dún Ọláńrewájú ní fásitì OAU Ife kò fààye gba fífi tìpá tìkúùkù  fẹ́ tàbí bá ọmọbinrin láṣepọ̀, ""yálà látọ̀dọ̀ olùkọ́ sí akẹ́kọ̀ọ́ tàbí akẹ́kọ̀ọ́ sí akẹ́kọ̀ọ́.""Ilé ìwé gíga fásitì OAU ní ààbò àṣírí wà fún akẹ́kọ̀ọ́ yóówù tó bá ta àwọn aláṣẹ fásitì náà lólobó ìwà ìbàjẹ́ lọ́gbà  fásitì náà."
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí:
Buhari: Àì lè ṣe dáradára tó mi wà lọ́wọ́ àwọn aṣòfin àpapọ̀
Oríṣun àwòrán, TWITTER/BASHIR AHMAD
Buhari ní ìṣèjọba òun yóò túbọ̀ gbájúmọ́ ètò àbò, gbígbógun ti ìwà ìjẹkújẹ
Aarẹ Muhammadu Buhari ti di ẹbi bi awọn akanṣe iṣẹ lori ohun amayedẹrun lorilẹede naijiria ṣe n falẹ labẹ iṣejọba rẹ ru sunkẹrẹ-fakẹrẹ awọn aṣofin apapọ lori bibuwọ lu abadofin iṣuna eyi to ni o n ṣe ọpọ akoba.
Ninu ọrọ to sọ lasiko to fi n gbalejo igbimọ awọn eekan ọmọ ipinlẹ Niger kan ni ile aarẹ, Aso rock villa to wa nilu Abuja, aarẹ Buhari ni awọn aṣeyọri iṣejọba oun lẹka ipese ina ọba, opopona ati oju irinna fun ọkọ oju irin waye lai naani awọn ifasẹyin to n waye latọdọ awọn aṣofin apapọ.
WAEC: Ìwé àfihàn pé Ààrẹ Buhari ṣèdánwò la fún un
Ọmọ ìyá mẹ́ta fi oyún ṣe àńkò
NAFDAC: Ẹ ṣọ́ra fún ẹja aṣekúpani Puffer Fish
Ti o ba gba awọn aṣofin apapọ ni oṣu meje lati buwọlu abadofin iṣuna, o yẹ ki aye ko yin wa fun awọn ohun ribiribi ti a ti gbe ṣe. Ko dun mọ mi ninu rara, mo si ti pe awọn adari ile asofin apapọ lori rẹ.
Gẹgẹ bi atẹjade kan lati ọdọ olubadamọran fun aarẹ lori ọrọ iroyin ati ipolongo, Fẹmi Adeṣina ṣe sọ, aarẹ Buhari ni iṣejọba oun yoo tubọ gbajumọ eto abo, gbigbogun ti iwa ijẹkujẹ ati tita eto ọrọ aje ji fun alekun idagbasoke ati ilọsiwaju.
Ki ṣe ohun tuntun mọ pe aarẹ orileede Naijiria Muhammadu Buhari yoo du ipo aarẹ lọdun 2019.
Ikede naa jẹ́ ohun ti eniyan fẹ́ẹ̀ le ni ọpọ ti ń reti fún ìgbà pípẹ́.
Ni bayi tí ààrẹ ti wa ṣiṣo lójú eégún ọ̀rọ̀ náà, ibeere ti awọn oluwoye n beere ni pe: Ta ni yoo koju rẹ?
Ẹjẹ ka tibi pẹlẹbẹ mu ole jẹ ninu APC to jẹ ẹgbẹ to wa lori ijọba.
Awọn Gomina APC fẹ Buhari
Ṣaaju ki Buhari to kede pe ohun yoo du ipo Aarẹ lẹkan si, awọn Gomina labe ẹgbẹ APC  ti ni ki Buhari so ero ọkan re lori ipo aarẹ lọdun 2019.
Igbese yi jo wipe o se afihan isokan laarin awọn Gomina naa.
Ni kete ti Buhari kede pe ohun yoo du ipo Aarẹ, opo lara awọn Gomina naa ti'n kan sara si lori igbese naa.
Ṣugbọn ki se gbogbo ọmọ ẹgbẹ lo tẹlorun wi pẹ ki Buhari nikan du ipo aarẹ labẹ asia ẹgbẹ.
Oríṣun àwòrán, Facebook/Kwankwansiya
Lọdun 2015, Kwankwaso dije nibo abele APC sugbọn o fidiremi lọwo Buhari.
Ẹnu n kun Rabiu Musa Kwankwanso pupọ lori boya yoo du ipo Aarẹ lọdun 2019 .
Ko ti so boya ohun  yoo du ipo aarẹ yala labe asia ẹgbẹ APC tabi ẹgbẹ miran.
Ti a ba woye pelu atimaaṣebọ rẹ̀ tẹlẹ ati awọn ipolongo ti awọn ololufe re nse lori ẹro ayelujara, o ṣe ṣe kí o du ipo Aarẹ pẹlu Buhari.
Oríṣun àwòrán, PIUS UTOMI EKPEI/GETTY
Bukola Saraki ni Aarẹ ile asofin agba
Ninu akoso iṣejọba lorileede Naijiria, Sẹnatọ Bukọla Saraki lo wa ni ipo kẹta.
Ọmọ bibi Ilorin , o ti figba kan jẹ Gomina ni ipinlẹ Kwara o si ni iriri pupọ gẹgẹ bi aṣofin.
Ọpọ lo ti n foju sii lara pe o ṣeeṣe ki o du ipo aarẹ.
Ko tii daju boya yoo jade labẹ aṣia APC lọdun 2019.
Ẹgbẹ alatako
Iye awọn to ti si wi pe awọn fe du Aarẹ to je alatako ti pọ̀ diẹ̀.
Ṣugbọn ninu ẹgbẹ alatako, PDP, Gomina Ayọdele Fayose nikan ni o ti kede ni gbangba pe ohun fẹ di Aare.
Oríṣun àwòrán, TWITTER/AYO FAYOSE
Ninu alatako ijọba Buhari, Gomina Ayo Fayose lo je gbajugbaja ju lọ
Oríṣun àwòrán, TWITTER/ATIKU ABUBAKAR
Atiku Abubakar n na owo ife si awọn olori kakiri orilẹẹde Naijiria.
La i pe yi ni awọn odo oludije miran kan naa yoju sugbọn ko ti daju ẹgbẹ ti won yoo dije labe rẹ.
Oríṣun àwòrán, Twitter Garba/Durotoye/Sowore
Awọn ọdọ ni asiko to lati gba ijọba lọdọ awọn agba oloseelu
Ìjọba Nàìjíríà kìlọ̀ ìṣọ́ra ní ìlú London
Oríṣun àwòrán, @abikedabiri
Abike Dabiri lon kede ikilo fun awọn ọmọ Naijiria ni ilu London
Ijọba orilẹede Naijiria ti kilọ fun awọn ọmọ ilẹ naa to wa ni ilu London lati ma a sọ ara se nitori iṣekupani to n waye lagbeegbe naa.
Oluranlọwọ fun Aarẹ Buhari lori ọrọ ilẹ okeere, Abike Dabiri-Erewa ni oun ibanujẹ lo jẹ fun oun bi awọn alawọdudu, paapaa awọn ọmọ Naijiria se n padanu ẹmi wọn ninu ikọlu ni ilẹ Geesi kọ oun lominu.
Ile isẹ arabinrin naa ni wipe lati ibẹrẹ Osu kini, Ọdun yii, ọdọ to jẹ alawọdudu aadota, 50 ni wọn ti gun lobe tabi ti won yin ibon pa ni ilu london.
O fi kun wipe mẹsan ninu awọn ti wọn sekupa naa jẹ ọmọ Naijiria  to wa ni ilu London ati awọn agbeegbe miran ni ilu Geesi
Arabinrin Dabiri-Erewa naa fikun wipe oun ti kọ lẹta ifẹhọnu han si asoju ilẹ Geesi ni Naijiria, ti oun si bẹrẹ fun iwadii ati idajo otito lori isẹlẹ naa.
Àjọ ajàfẹ́tọ̀ọ́: Ènìyàn 2000 ti kú nínú ìṣẹ̀lẹ̀ darandaran
Oríṣun àwòrán, Getty Images
'Ìkọlù darandaran pa èèyàn 2000'
Ajọ ajafẹtọ kan lorilẹede Naijiria ti sọwipe o le ni ẹgbẹrun meji (2000) eniyan to ti ku ninu rogbodiyan laarin awọn darandaran ati awọn agbẹ lati bi Osu Mejidinlogun lorilẹede Naijiria.
"Ajọ naa ti orukọ wọn n jẹ ""The Coalition on Conflict Resolution and Human Rights in Nigeria"" ninu atejade kan to jade ni Ọjọ Ajẹ, sọ wi pe ọgọọrọ lọ si ti di alairile gbe ni tori isẹlẹ naa."
Gẹgẹbi ọrọ ajọ naa, iye eniyan to ku naa ni wọn fi lede lẹyin iwadii lori iye ẹmi to ti sọnu, dukia, ile ati ọna to ti bajẹ nitori aigbọraeniye laarin awọn agbẹ ati darandaran lẹkun gbungun ariwa orilẹede Naijiria to fi mọ Benue, Taraba, Plateau, Kogi ati ipinle Nasarawa.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Opo eniyan ku ninu ikolu fulani darandaran nipinle Benue
Wọn fikun wipe awọn ọlọsa naa tun kopa ninu isẹlẹ naa, nipa kiko ohun ini awọn eniyan ti ọfọ ba see.
Ti a ko ba gbagbe, awọn ile isẹ ologun Naijiria ti ran ikọ wọn lọ si agbeegbe naa lati da wọ isẹlẹ naa duro, sugbọn ikọlu si n waye lawọn igberiko kookan lagbeegbe naa.
Kókó ìròyìn t'òní: 'Ẹ ṣọ́ra ní London', ‘Ìkọlù darandaran pa èèyàn 2000’
Eyi ni awọn akojọpọ iroyin ti toni.
Ìjọba Nàìjíríà kìlọ̀ ìṣọ́ra ní ìlú London
Oríṣun àwòrán, @abikedabiri
Abike Dabiri lon kede ikilo fun awọn ọmọ Naijiria ni ilu London
Ijọba orilẹede Naijiria ti kilọ fun awọn ọmọ ilẹ naa to wa ni ilu London lati ma a sọ ara se nitori iṣekupani to n waye lagbeegbe naa.
Oluranlọwọ fun Aarẹ Buhari lori ọrọ ilẹ okeere, Abike Dabiri-Erewa ni oun ibanujẹ lo jẹ fun oun bi awọn alawọdudu, paapaa awọn ọmọ Naijiria se n padanu ẹmi wọn ninu ikọlu ni ilẹ Geesi kọ oun lominu.
Àjọ ajàfẹ́tọ̀ọ́ ni ènìyàn 2000 ti kú nínú ìṣẹ̀lẹ̀ darandaran
Ajọ ajafẹtọ kan lorilẹede Naijiria ti sọwipe o le ni ẹgbẹrun meji (2000) eniyan to ti ku ninu rogbodiyan laarin awọn darandaran ati awọn agbẹ lati bi Osu Mejidinlogun lorilẹede Naijiria.
"Ajọ naa ti orukọ wọn n jẹ ""The Coalition on Conflict Resolution and Human Rights in Nigeria"" ninu atejade kan to jade ni Ọjọ Ajẹ, sọ wi pe ọgọọrọ lọ si ti di alairile gbe ni tori isẹlẹ naa. Ẹ ka ẹkunrẹrẹ rẹ ni bii"
Gómìnà ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́ tẹ́lẹ̀rí, Rashidi Ladoja wípé kí àwon ọmọ Nàìjíríà jẹ́ kí Ààre Bùhárí gbé àpótí ìbò wò, bóyá yóò borí.
Rashidi Ladoja: Ẹ jẹ́ kí Bùhárí gbá'pòtí ìbò, bóyá yóò borí
Olórí Asòfin Kwara: Ó ti bọ́ fún Bùhárí láti gbógun tìwà ìjẹkujẹ
Oríṣun àwòrán, Alli/Facebook
Ahmad fi ìka hánu lóríi bí ìjọba àpapọ̀ se kùnà láti tu àwọn èèyàn ìlú Ọ̀ffà nínú
Olórí ilé asòfin ní ìpínlẹ̀ Kwara, Ọ̀mọ̀wé Alli Ahmad ti nàka àlèèbú sí ìjọba àpapọ̀ Nàíjíríà pé ó ti kùnà pátápátá láti se àseyọrí ní ìdí ogun tó ń gbé ti ìwà ìjẹkújẹ, tí kò sì mú ìlérí rẹ̀ sẹ nípa sísẹ́ eegun ẹ̀yìn ìwà jẹgújẹrá.
Ahmad kéde bẹ́ẹ̀ lásìkò tó ń bá àwọn akọròyìn sọ̀rọ̀ ní ìlú Ìlọrin pẹ̀lú àfikún pé àsìse ńlá ni fún Bùhárí láti gbájúmọ́ ètò gbígbé ogun tìwà ìbàjẹ́ nìkan gẹ́gẹ́ bíi àfojúsùn ìjọba rẹ̀ nígbàtí ètò ìdájọ́ wa wọ́lẹ̀ ní Nàíjíríà.
Ẹni tó pegedé jùlọ tí orílẹ̀èdè Nàíjíríà ní láti gbógun ti ìwà jẹgúdújẹrá láti ìgbà tí a ti gba òmìnira ní Bùhárí, sùgbọ́n ó ti pàdánù ànfààní náà, tí èmi kò sì lérò pé ó tún leè rí ọ̀nà míràn láti tún àsìse yìí se.
Bákannáà ni Ahmad tún fi ìka hánu lóríi bí ìjọba àpapọ̀ se kùnà láti tu àwọn èèyàn ìlú Ọ̀ffà àti ìjọba ìpínlẹ̀ Kwara nínú lóríi ìkọlù àwọn adigunjalè àti ìpànìyàn tó wáyé ní Ọ̀ffà ní àìpẹ́ yìí.
Ó ní lẹ́yìn ọjọ́ kẹta tí ìsẹ̀lẹ̀ náà ti wáyé ni ìjọba àpapọ̀ tó sọ̀rọ̀ lórí ìsẹ̀lẹ̀ yìí, èyí tó ní ó da omi tútù sí àwọn lọ́kàn.
Ìsẹ̀lẹ̀ adigunjalè yìí ló fi ìdí iyèméjì àwọn èèyàn kan múlẹ̀ pé Bùhárí kò ní agbára tó láti mú ìrẹ́pọ̀ àti ìdúrósinsin bá orílẹ̀èdè Nàíjíríà .
Ó fikúu pé máákì òdo ni ìjọba àpapọ̀ gbà nínú èyí, tó sì dun àwọn jọjọ́ púpọ̀.
INEC: Ẹgbẹ̀rún márùn ún náírà ni ìbò Òǹdó,Edo àti Anambra
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Láàárín 2015 sí àsìkò yìí, ìdìbò ọ̀rìnlélúgba ó lé mẹ́fà ni àjọ INEC ti ṣe nínú èyí tí wọ́n ti wọ́gilé méjìdínlọ́gbọ̀n
Àjọ elétò ìdìbò ní orílẹ̀èdè Nàìjíríà, INEC, ti fẹ̀sùn kan àwọn olóṣèlú àtàwọn olólùfẹ́ wọn pé, wọ́n ń fi ìbò rírà pa ètò ìdìbò sípò Gómìnà lára ní ìpínlẹ̀ Edo, Ondo àti Anambra.Alága àjọ INEC, Ọ̀jọ̀gbọ́n Mahmood Yakubu, ló sọ èyí di mímọ̀ lásìkò tó ń bá àwọn alẹ́nulọ́rọ̀ sọ̀rọ̀ lórí ìdìbò sípò Gómìnà ìpínlẹ̀ náà, tí yóò wáyé lóṣù keje.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
INEC ní àjọṣepọ̀ tó rinlẹ láàárín àjọ náà àtàwọn agbófinró ni wọ́n yóò fi k'ápá ìbò rírà
"Mahmood Yakubu, ti alákòóso fún ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́, Èkìtì, Ọ̀ṣun àti Òǹdó sojú fún, ṣàlàyé pé àjọṣepọ̀ tó rinlẹ ̀láàárín àjọ náà àtàwọn agbófinró ni wọ́n yóò fi k'ápá rẹ̀.""Gbogbo rẹ̀ ló hàn sí àjọ yìí. Ẹgbẹ̀rún márùn ún náírà ni àwọn olóṣèlú san fún ìbò kọ̀ọ̀kan ní ìpínlè Òǹdó àti Anambra. A tilẹ̀ gba àwọn owó kan lọ́wọ́ àwọn kan nípínlẹ̀ Anambra, ṣùgbọ́n irúfẹ́ èyí kò ní wáyé ní ìbò Èkìtì."""
Oríṣun àwòrán, Getty Images
INEC ní àwọn ràbòràbò r'áyé jẹ lásìkò ìbò ní'pínlẹ̀ Edo, Ondo àti Anambra
Bákannáà ni àjọ INEC  tún pariwo pé, àìkìí fààyè gba ètò ìṣèlú àwarawa abẹ́nú táwọn ẹgbẹ́ òṣèlú lórílẹ̀èdè Nàìjíríà gùnlé, ń ṣe ọ̀pọ̀ àkóbá fún àṣeyọrí ìdìbò.Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí:
INEC yoo sun miliọnu meje kaadi idibo
Láàárín ọdún 2015 sí àsìkò yìí, ìdìbò ọ̀rìnlélúgba ó lé mẹ́fà ni àjọ yìí ti ṣe nínú èyí tí wọ́n ti wọ́gilé méjìdínlọ́gbọ̀n nítorí àìkìí fààyè gba ètò ìṣèlú àwarawa labẹ́nú láàrin áwọn ẹgbẹ́ òṣèlú.Alága àjọ INEC, Ọ̀jọ̀gbọ́n Mahmood Yakubu, wá fi dá àwọn èèyàn ìpínlẹ̀ Èkìtì lójú pé, àjọ náà kò ní ṣègbè lásìkò ìdìbò náà.
Ìkànìyàn: A ti tó igba mílíọ́nù èèyàn ní Nàìjíríá
Oríṣun àwòrán, Reuters
Àádọ́ta ọdún sẹ́yìn ni iye ènìyàn ti pọ̀ gan láì sí ìgbéga tó báa àwọn ohun amáyérọrùn.
Lọ́wọ́lọ́wọ́, òǹkà iye ènìyàn tó wà lórílẹ́èdè Nàìjíríá ti sún mọ́ mílíọ̀nù lọ́nà igba.
Èyí ni àtẹ̀jáde tó wá láti ọ̀dọ̀ àjọ tó ńrísí ìkànìyàn lórílẹ́èdè Nàìjíríá eléyìí tó fi orílẹ̀èdè yìí sí ipò keje nínú àwọn orílẹ̀èdè tó pọ̀ jù lágbayé.
Gẹ́gẹ́ bí akọ̀ròyìn ilé isẹ́ BBC tó wà nílu Abuja, Chris Ewokor se sọọ́, adarí àjọ tó ńrísí ìkànìyàn lórílẹ́èdè Nàìjíríá sọ wípé, péréte mílíọ̀nù mẹ́jì ló kù kó ká ígba mílíọ̀nù.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí:
Olú Fálaè: Orúkọ àwọn jẹgúdújẹrá tí APC tẹ̀ jáde kò tíì pé
Wọ́n se àgbéjáde  òǹkà yìí ní New York lọ́jọ́ ajé níbi ìjókòó ìkọkànléláàdọ́ta ti àjọ náà lórí iye ènìyàn àti ìdàgbàsókè.
Alága àjọ náà, ọ̀gbẹ́ni Eze Duruiheoma ní, wọ́n ńní àfojúsùn wípé ó yẹ kí orílẹ̀èdè Nàìjíríá di ipò kẹta nínú àwọn orílẹ̀èdè tó pọ̀ jù lágbayé ní ọgbọ̀n ọdún sí ìsinsìyìí.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ó ti di igba mílíọ̀nù ènìyàn ó dín díẹ̀ tó wà lórílẹ́èdè Nàìjíríá
Ó Jẹ́ kó di mímọ̀ pé láti àádọ́ta ọdún sẹ́yìn ni iye ènìyàn tó wà ní àwọn ìlú ńlá ti pọ̀ gan láì sí ìgbéga tó báa mu ní ti àwọn ohun amáyérọrùn.
Lọ́sẹ̀ tó kọjá, asojú ilẹ̀ Britain sí orílẹ̀èdè Nàìjíríá, Paul Arlwright fi irú ìjẹlọ́kàn yìí kan náà hàn níbi ìpàdé àpérò kan nílu Abuja.
Ó ní bí wọn ò bá sọ́ra, ìkọlùkọgbà ńrúgbó bọ̀ pàápàá pẹ̀lú ọ̀pọ̀lọpọ̀ ọ̀dọ́ tí kò nísẹ́ lọ́wọ́ tí ètò ẹ̀kọ́, ìlera, àti àmúlò ohun àlùmọ́nì kò sì sí lárọ́wọ́tó wọn.
Àwọn akẹ́ẹ̀kọ́ ni Ọ̀jọ̀gbọ́n tó ń bèèrè ìbálòpọ̀ lọ̀wọ̀ akẹ́ẹ̀kọ́ kò ṣẹ̀ṣẹ̀ máa ṣe bẹ́ẹ̀
Oríṣun àwòrán, @OfficialOAU
Fásitì OAU ní ààbò àṣírí wà fún akẹ́kọ̀ọ́ yóówù tó bá ta àwọn aláṣẹ fásitì náà lólobó ìwà ìbàjẹ́
Ọ̀jọ̀gbọ́n kan nílééwé fásitì OAU Ile-Ife, ni ariwo rẹ̀ ti gbòde kan báyìí pé ó bèèrè àti bà akẹ́ẹ̀kọ́ obìnrin lájọṣepọ̀ fún ìgbà máàrún ọ̀tọ̀ọ̀tọ̀ láti fún ní máàkì.
Ní báyìí, àwọn aláṣẹ fásitì náà ti gbé ìgbìmọ̀ ẹlẹni-márùn ún kalẹ̀ láti ṣèwaàdí  sí ọ̀rọ̀ náà.
Ọ̀sẹ̀ kan ni ìgbìmọ̀ náà ní láti fi jábọ̀ iṣẹ́ rẹ̀.
Àwọn akẹ́ẹ̀kọ́ kan tó ti kọjá ní fásitì náà ní ọ̀jọ̀gbọ́n Akíndélé kò ṣẹ̀ṣẹ̀ máa ṣe e.
Ọ̀kan lara awon akekojade ileewe naa to ti keko jade ni nkan bii ogun ọdún sẹyìn ni igba ti awọn ti wa nileewe naa ni ojogbon yìí ti bẹrẹ.
"Mo rántí ọkan lara àwọn orẹ mi nigba naa to n kaya soke lori pe Ọ̀jọ̀gbọ̀n Akindele dẹ̀nu ibalopọ̀ kọ̀ oun. O ni ki a maa ba oun gbadura.
Lẹyin ọpọlọpọ adura, ọjọgbọn yii ni oun ti yii skan oun pada lori rẹ.
Bakan naa ni iwadi fihan lati ọdọ awọn akẹkọ faisti naa pe ohun ọjọgbọn Richard Akindele lo wa ninu ohun ti wọn gba silẹ naa.
Ikú Alizee: Adájọ́ ju Nielsen s'áhàmọ́ ní Ìkòyí ní ìpínlẹ̀ Èkó
Oríṣun àwòrán, @officializee
Ọgbẹni Nielsen, ọmọkunrin lati orilẹede Denmark nkawọ pọnyin rojọ lori ẹsun wipe o pa eniyan meji
Peter Nielsen, ti ọlọpa fi ẹsun kan pe o pa iyawo rẹ, Zainab ati ọmọ ọdun mẹta rẹ, Petra ti wa ni ẹwọn nilu Ikoyi lẹyin ti ile ẹjọ paṣẹ nibi igbẹjọ rẹ ni Yaba nipinlẹ Eko lọjọru.
Adajọ K.B. Ayeye, ti o fun-un ni idajọ, sọ pe o ki ọdanran naa wa ni ihamọ ẹwọn titi di igba ti awọn ti wọn fi ẹsun ipaniyan kan an lati ileeṣẹ ijọba ti o n risi eto igbẹjọ ara ilu (DPP) yoo fi imọran ranṣẹ nipa idajọ̀ rẹ.
Ọgbẹni Nielsen, ọmọkunrin lati orilẹede Denmark nkawọ pọnyin rojọ lori ẹsun wipe o pa eniyan meji.
Effiong Asuquo, ti o jẹ agbẹjọro, aṣoju ijọba sọ fun ile-ẹjọ pe ọgbẹni Nielsen naa ṣe awọn ẹṣẹ yi ni ọjọ karun oṣu kẹrin ọdun yii ni Block 4, Flat 17, ni Bella Vista Tower, ni agbegbe Banana Island nilu Ikoyi.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
ọlọ́pàá gbé ẹni tó pa ìyàwó àti ọmọ rẹ̀ re'lé ẹjọ́
O ni Nielsen pa iyawo rẹ, Zainab to jẹ ọmọ ọdun mẹ́tàdínlógójì (37) ati ọmọ rẹ obinrin rẹ Petra, ni ile wọn.
Ọdaran yii ti maa n ni ija nigba gbogbo pẹlu aya rẹ, ti o si fọ ori rẹ mọ ogiri laimọye igba, ti o yọrisi iku rẹ, o tun fun ọmọbinrin rẹ ni majele jẹ"", ọlọpaa sọrọ."
Adajọ ti sun igbẹjọ naa si ọjọ kẹjọ oṣu karun ọdun.
Ní Àwòrán: Ètò Ìsìnkú Winnie Madikizela-Mandela
Ẹgbẹẹgbẹrun eniyan peju-pesẹ si ibi akanṣe eto iranti ati ayẹyẹ isnku fun gbajugbaja ọmọ orilẹede South Africa, Winnie Madikizela-Mandela. O figbakan jẹ iyawo aarẹ orilẹede South Africa tẹlẹri,  Nelson Mandela ti o ku ni ọjọ keji oṣu kẹrin ọdun 2018.
Oríṣun àwòrán, AFP
"Igbakeji Aare orile-ede South Africa David Mabuza sọ fun ijọ eniyan pe Ms. Madikizela-Mandela ti ""jagun ti awọn ẹda alawọ kan, iṣiro ile-iwe ati ipalara awọn ọkunrin""."
Oríṣun àwòrán, EPA
Awọn ọmọbinrin Mandela, Zanani ati Zindzi, wa ni pẹsẹ. Oloṣelu alatako, Mangosuthu Buthelezi sọ pe o jẹ oun to lapẹẹrẹ bi wọn ti dagba bi o ti jẹ pe awọn obi wọn ti ja nigba ti wọn wa ni ewe.
Oríṣun àwòrán, AFP
"Awọn to n kẹdun fi ifunni ni ""Agbara dudu"" fun Winnie Madikizela-Mandela."
Oríṣun àwòrán, REUTERS
Ọpọlọpọ awọn eniyan ni wọn ti wọ awọ ẹgbẹ oṣẹlu African National Congress, eyiti o fa ija si apartheid.
Oríṣun àwòrán, AFP
Awọn ọmọ ile-iwe tun wa ninu awọn alafọfọ, ti wn ṣe ayẹyẹ ikẹhin fun obinrin akinkanju ti o ja fun ominira lọwọ apartheid ni 1994.
Oríṣun àwòrán, AFP
"Diẹ ninu awọn ti o ni aṣọ ti o ni aworan ti Ms. Madikizela-Mandela, ti o si ni awọn ọrọ ""hamba kahle"", tabi idagbere, tẹ lori wọn."
Oríṣun àwòrán, EPA
Eto aṣekagba isinku yoo waye ni Ọjọ kẹrinla oṣu kẹrin ọdun yii.
Gbogbo awọn fọto/aworan wọnyi wà labẹ koko aṣẹ fun lilo wọn.
Ọlọ́pàá Èkó gbé ẹni tó pa ìyàwó àti ọmọ rẹ̀ re'lé ẹjọ́
Oríṣun àwòrán, Getty Images
ọlọ́pàá gbé ẹni tó pa ìyàwó àti ọmọ rẹ̀ re'lé ẹjọ́
Ile isẹ ọlọpa ni ipinlẹ Eko sọ wipe ọmọkunrin kan lati orilẹede Denmark, Peter Nielsen ti wọn fẹsun kan wipe o pa iyawo ati ọmọ rẹ ni awọn yoo gbe rele ẹjọ ni Ọjọru.
Agbẹnusọ fun ile isẹ ọlọpa naa, Chike Otti sọ wipe ẹni ti wọn fẹsun kan yoo kawọ pọnyin rojọ ni ile ẹjọ to wa ni Yaba, ni ilu Eko.
Otti wipe Kọmisona fun awọn ọlọpa, Imohimi Edgar ti paṣẹ fun ile iṣẹ ọlọpaa lati gbe ọkunrin naa lọ si ile ẹjọ nitori iwadi ti awọn ọlọpaa ṣe ati ayẹwo ti awọn dokita ṣe fun awọn oloogbe naa.
Gẹgẹbi ọrọ awọn ọlọpaa, iyawo to d'oloogbe naa, Alizee ati ọmọ rẹ to jẹ ọmọ ọdun mẹrin ni wọn ba oku wọn ninu ile wọn to wa ni Banana Island, ni ilu Eko pẹlu amin lilu ni ara wọn.
Kókó ìròyìn t'òní: Ènìyàn 200m ló wà ní Nàíjíríà, Ìsìnkú Winnie Mandela
Eyi ni awọn akojọpọ iroyin ti toni.
Ìkànìyàn: A ti tó igba mílíọ́nù èèyàn ní Nàìjíríá
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ó ti di igba mílíọ̀nù ènìyàn ó dín díẹ̀ tó wà lórílẹ́èdè Nàìjíríá
Lọ́wọ́lọ́wọ́, òǹkà iye ènìyàn tó wà lórílẹ́èdè Nàìjíríá ti sún mọ́ mílíọ̀nù lọ́nà igba.
Èyí ni àtẹ̀jáde tó wá láti ọ̀dọ̀ àjọ tó ńrísí ìkànìyàn lórílẹ́èdè Nàìjíríá eléyìí tó fi orílẹ̀èdè yìí sí ipò keje nínú àwọn orílẹ̀èdè tó pọ̀ jù lágbayé.
Ní Àwòrán: Ètò Ìsìnkú Winnie Madikizela-Mandela
Oríṣun àwòrán, REUTERS
Ọpọlọpọ awọn eniyan ni wọn ti wọ awọ ẹgbẹ oṣẹlu African National Congress, eyiti o fa ija si apartheid.
Ẹgbẹẹgbẹrun eniyan peju-pesẹ si ibi akanṣe eto iranti ati ayẹyẹ isnku fun gbajugbaja ọmọ orilẹede South Africa, Winnie Madikizela-Mandela. O figbakan jẹ iyawo aarẹ orilẹede South Africa tẹlẹri,  Nelson Mandela ti o ku ni ọjọ keji oṣu kẹrin ọdun 2018 . Eka ẹ̀kúnréré ní bíí
Awọn Fidio wa fun toni:
Olú Fálaè: Orúkọ àwọn jẹgúdújẹrá tí APC tẹ̀ jáde kò tíì pé
Olú Fálaè: Orúkọ àwọn jẹgúdújẹrá tí APC tẹ̀ jáde kò tíì pé
Ìsẹ̀lẹ̀ Algeria: Ó tó igba ẹ̀mí tó bá bàálù tó já lọ
More than 250 people have been killed after a military plane crashed in Algeria, local media report.
Àjọ onísirò Nàíjíríà: Àdínkù bá owó ọjà si ìdá mẹ́tàlá
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Àdínkù ti bá owó ọjà lábẹ́lé sí ìdá mẹ́tàlá lósù kẹta ọdún 2018.
Àjọ onísirò ní Nàíjíríà NBS kéde lọ́jọ́bọ pé àdínkù ti bá owó ọjà lábẹ́lé sí ìdá mẹ́tàlá lósù kẹta ọdún 2018.
Gẹ́gẹ́ bíi àlàyé wọn, ìlànà tí wọ́n fi ń se òdiwọ̀n èlé owó orí ọjà fihàn pé, owó ọjà lọ sókè lósù kẹta ọdún 2018.
Ìkéde tí àjọ náà fisíta sọ pé ìgbà kẹrìnÌdí rèé tí BBC Yorùbá se ń bèèrè pé ǹjẹ́ àwọn aráàlú mọ ipa àdínkù owó ọjà náà lára bí?
SERAP fẹ́ pe UI, AAUA lẹ́jọ́ lórí àfikún owó iléẹ̀kọ́
Bùhárí sọ ìdí tó fi ń díje lẹ́ẹ̀kejì
Ìṣẹ̀lẹ̀ Èkó: Aáwọ̀ Ọbàkan sọ ilé di áláwọ̀ méjì
Ìdí rèé tí BBC Yorùbá se ń bèèrè pé ǹjẹ́ àwọn aráàlú mọ ipa àdínkù owó ọjà náà lára bí?
Nígbà tó ń fìdí ọ̀rọ̀ yìí múlẹ̀, ìyálọ́jà kan, arábìnrin Ọmọlọlá Adéoyè ní lọ́ọ̀tọ́ọ́ ni owó àwọn ọjà ń dínwó díẹ̀díẹ̀ láwọn orí ọjà kọ̀ọ̀kan.
Ẹ gbọ́ arábìnrin Adéoyè síwajú síi:
Àjọ onísirò Nàíjíríà: Àdínkù bá owó ọjà si ìdá mẹ́tàlá
Bùhárí: Ariwo ọmọ Nàìjíríà ló mú mi fẹ́ díje lẹ́ẹ̀kejì
Oríṣun àwòrán, Nigeria Presidency
Bùhárí ní òṣèlú ẹ̀tánú ló wà nì ìpìlẹ̀ wàhálà àgbẹ̀ àti darandaran,
Ààrẹ Mùhámádù Bùhárí ti bọ́ síta láti ṣàlàyé ìdí rẹ̀ tòun fi kéde ìpinnu òun láti gbé àpótí ìbò ààrẹ lẹ́ẹ̀kejì.
Nígbà tó ń gbàlejò Bíṣọ́ọ̀bù àgbà ìjọ Anglican ní Canterbury, Ẹniọ̀wọ̀ Justin Welby ní ìlú London. Buhari ní,
Torí awuyewuye tó ń jà láàárín àwọn ọmọ Nàìjíríà lórí bóyá màá díje tàbí n kò ní díje ló jẹ́ kí n kéde kí n tó kúrò ní Nàìjíríà.
Omi ń bẹ láàmù fún wa lórí ètò àbò, ètò ọ̀gbìn, ọrọ̀ ajé, gbígbógun ti ìwà ìbàjẹ́ àti bẹ́ẹ̀bẹ́ẹ̀ lọ. Kò yẹ kí òṣèlú ó jẹ́ ìdààmú fún wa.
Ààrẹ Mùhámádù Bùhárí tún ṣàlàyé àwọn àṣeyọrí ìjọba rẹ̀  fún ẹni ọ̀wọ̀ Welby.
Ó ní lórí wàhálà àgbẹ̀ àti darandaran, òṣèlú ẹ̀tánú ló wà nì ìpìlẹ̀ rẹ̀.
Bákannáà ni ààrẹ Mùhámádù Bùhárí ní àwọn ń mójú tó àtipadà wálé e Leah Sharibu, akẹ́kọ̀ Dapchi tó ṣì wà ní àhámọ́ àwọn Boko haram nítórí pé ó kọ̀  láti yípadà sí ẹ̀sìn Islam.
SERAP: Ọjọ́ méje la fún UI, AAUA lati dá owó iléẹ̀kọ́ padà
Oríṣun àwòrán, AAUN News Forum
Akitiyan BBC láti bá iléeṣẹ́ ọlọ́pàá ní ìpínlẹ̀ Òndó jásí pàbó
Àjọ ajàfẹ́tọ́ ọmọnìyàn kan lórílẹ̀èdè Nàìjíríà, SERAP ti ń lérí léka pé àwọn yóò gbé àwọn aláṣẹ fásitì Ìbàdàn, UI àti fásitì ìpínlẹ̀ Oǹdó lọ sí ilé ẹjọ́ bí wọn kò bá tètè tún èrò wọn pa lórí àfikún owó ilé ìwé
tí wọ́n ṣẹ̀ṣẹ̀ gbé kalẹ̀.
SERAP fún àwọn aláṣẹ fásitì méjèèjì ní gbèdéke ọjọ́ méje làti fi dá owó ilé ìwé náà padà sí iye tó wà tẹ́lẹ̀.
'Ọ̀jọ̀gbọ́n Akindele kò ṣẹ̀ṣẹ̀ máa bèèrè fún ìbálòpọ̀'
Akẹ́kọ̀ọ́ dókítà: Fásitì Ìbàdàn gbọdọ̀ dín owó iléẹ̀kọ́ wa
Àjọ náà ní àwọn yóò lo ìlànà òfin láti fi kàn án nípá fún wọn láti ṣe bẹ́ẹ̀.
Ọ̀pọ̀ akẹ́kọ̀ọ́ ni yóò jókòó sílé nítorí èlé iléèwé
Nínú àtẹ̀jáde kan lọ́jọ́ọ̀bọ tí igbákejì ọ̀gáàgbà àjọ  SERAP, Timothy Adéwálé fi síta, ọgbọ́n àti sé ọ̀nà ìmọ̀ mọ́ àwọn ọ̀dọ́ ni ìgbésẹ̀  àfikún owó iléẹ̀kọ́náà yóò padà jásí.
Àìní leè san àfikún owó ilé ìwé yìí leè mú kí àwọn akẹ́ẹ̀kọ́ ó fi iléẹ̀kọ́ sílẹ̀ tí yóò sì leè ṣílẹ̀kùn ìṣòro ayérayé fún wọn.
Àfikún owó ilé ìwé leè dákún ìsòro Nàíjíríà
Bákannáà ni àjọ SERAP tún ké sáwọn aṣòfin àpapọ̀ lórílẹ̀èdè Nàìjíríà láti gbé òfin kalẹ̀ láti dẹ́kun bí àwọn ilé ẹ̀kọ́ gíga ṣe ń fowó kún owó wọn.
Fásitì  Ìbàdàn, UI  gbé owó àkànṣe ìdánilẹ́ẹ̀kọ́ f'áwọn akẹ́ẹ̀kọ́ rẹ̀ sókè láti ẹgbẹ̀rún márùndínláàdọ́ta, (75, 000) sí ẹgbẹ̀rún lọ́nà ọgọ́rún, (100, 000),  tí owó iléègbé sì kúrò ní ẹgbẹ̀rún mẹ́rìnlá sí ẹgbẹ̀rún lọ́nà ogójì, (40,000)
Fún fásitì ìpínlẹ̀ Oǹdó ní tirẹ̀, ẹgbẹ̀rún márùndínlógójì làwọn akẹ́ẹ̀kọ́ ń san tẹ́lẹ̀ kí wọ́n tó sún un sí ọgọ́fà ẹgbẹ̀rún àti ẹgbẹ̀rún lọ́nà igba.
Fásitì OAU ní ohùn ọ̀jọ̀gbọ́n Richard Akindele ni wọ́n ká sílẹ̀
Fásitì OAU ní ohùn ọ̀jọ̀gbọ́n Richard Akindele ni wọ́n ká sílẹ̀
Àwọn aláṣẹ fásitì Ọbafẹ́mi Awólọ́wọ̀ ní Ìlú Ilé ifẹ̀, OAU ti ìdí rẹ̀ múlẹ̀ pé ohùn un ọ̀jọ̀gbọ́n Richard Akindele, ti ẹ̀ka ìmọ̀ nípa ìṣirò owó tí wọ́n ní, o ń bèèrè fún ìbálòpọ̀ ìgbà máàrún ọ̀tọ̀ọ̀tọ̀ lọ́wọ́ ọ̀kan
lára àwọn akẹ́kọ́bìnrin tó fìdírẹmi nínú ìmọ̀ ẹ̀kọ́ kan ní ó wà nínú  fọ́nrán ohùn àkásílẹ̀ tó ń jà ràìn-ràìn káàkiri báyìí.
Àkásílẹ̀ àjọsọ ọ̀rọ̀ láàárín akẹ́kọ́bìnrin ọ̀hún àti ọ̀jọ̀gbọ́n Richard Akindele pẹ̀lú ẹ̀rọ ìbánisọ̀rọ̀ lori bí ọ̀jọ̀gbọ́n náà ṣe ń bèèrè fún ìbálòpọ̀  lọ́wọ́ akẹ́kọ́bìnrin náà ti di èròyà wá wòó lóríi ìkànnì ayélujára.
Nínú ìfọ̀rọ̀wérọ̀ oríi ẹ̀rọ ìbánisọ̀rọ̀ pẹ̀lú BBC lórí ètò oríi redio  kan nilu London, alukoro fásitì Ọbafẹ́mi Awólọ́wọ̀ ní Ìlú Ilé ifẹ̀, OAU, Ọ̀gbẹ́ni Abíọ́dún Ọláńrewájú ni àwọn aláṣẹ fásitì náà ti fìdí rẹ̀ múlẹ̀ pé ohùn rẹ̀ ni.
Oríṣun àwòrán, @OfficialOAU
Fásitì OAU ní ààbò àṣírí wà fún akẹ́kọ̀ọ́ yóówù tó bá ta àwọn aláṣẹ fásitì náà lólobó ìwà ìbàjẹ́
Bákannáà ló tún ṣàlàyé rẹ̀ pé wọn tí kọ ìwé 'wá wí tẹnu rẹ' sí ọ̀jọ̀gbọ́n Akíndélé lórí ìṣẹ̀lẹ̀ náà.
Ọ̀gbẹ́ni Abíọ́dún Ọláńrewájú ni àwọn aláṣẹ fásitì náà yóò gbé ìgbésẹ tó bá yẹ lẹ́yìn tí ìgbìmọ̀ tí wọ́n gbé kalẹ̀ bá ti jáde pẹ̀lú àbọ̀ ìwádìí rẹ̀.
Ọ̀jọ̀gbọ́n Richard Akindele tilééwé fásitì OAU Ile-Ife, ni ariwo rẹ̀ gbòde kan pé ó bèèrè láti bá akẹ́ẹ̀kọ́ obìnrin lájọṣepọ̀ fún ìgbà máàrún ọ̀tọ̀ọ̀tọ̀ láti fún ní máàkì.
Oríṣun àwòrán, Facebook/@OfficialOAU
Fasiti OAU: À wádìí olùkọ́ tó fẹ́ bá akẹ́kọ̀ọ́ lò fún máákì
Ní báyìí, àwọn aláṣẹ fásitì náà ti gbé ìgbìmọ̀ ẹlẹni-márùn ún kalẹ̀ láti ṣèwaàdí  sí ọ̀rọ̀ náà.
Ọ̀sẹ̀ kan ni ìgbìmọ̀ náà ní láti fi jábọ̀ iṣẹ́ rẹ̀.
Bùhárí: Gaddafi ló kọ́ darandaran ní ìwà ipá
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Gulegule awọn darandaran ti da oniruuru ipaya silẹ kaakiri orilẹede Naijiria
Ààrẹ orílẹ̀èdè Nàìjíríà, Muhammadu Buhari ti dẹ̀bi itankalẹ awọn agbebon darandaran rú Aarẹ̀ àná lorílèèdè Libya, Muammar Gaddafi.
Buhari ṣàlàyé pe, Muammar Gaddafi lo kò awọn darandaran ní ìwà ipá, to sì kó òhun ija fún wọn.
Ọrọ naa jẹyọ nígbà to n ba Biṣoobu àgbà ìjọ Anglican, ẹ̀ni ọwọ Justin Welby, sọrọ ní London lọ̀jo ọjọ́rú.
O ní ìjọba òun n s'apa lati kojú ipenija aawọ darandaran àti àwọn àgbẹ eleyii ti àjọ ajafeto ọmoniyan kan lo ti gb'emi to ju ẹgbẹrun meji ló laipe yii.
Lọdun to kọ̀ja ni ìjọba Naijiria fòfin dè iferanje láwọn agbegbe kan, to sí ni ki awon eniyan maa fi ẹran ọsin sí pápá ijẹ̀ko.
Oríṣun àwòrán, @GovAyoFayose
Ni ibẹrẹ ọdun 2018 Gomina Fayose ipinlẹ Ekiti se ipade pẹlu awọn ọdẹ lori ọrọ ipenija darandaran.
Sugbọ̀n ọpọ èèyàn k'ọti ikùn sí àṣẹ yi.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí:
Black Panther: Ọmọ Nàìjíríà gba àmì ẹ̀yẹ
Oríṣun àwòrán, @sopealuko
Ṣọpẹ́ bẹ̀rẹ̀ iṣẹ́ gẹ́gẹ́ bi òṣèré lẹ́yìn tó k'ẹ́kọ̀ọ́ gboyè nínú ìmọ ẹ̀rọ.
Àwọn aláṣẹ agbègbè Miami-Dade, nílùú Florida, l'órílẹ̀èdè Àmẹ́ríkà ti fi àmì ẹ̀yẹ dá ọmọ orílẹ̀èdè Nàìjíríà, ṣùgbọ́n tí wọ́n bí sí ìlẹ̀ Gẹ̀ẹ́sì, tó sì tún jẹ́ òṣèré, Ṣọpẹ́ Àlùkò lọ́lá.
Wọ́n ṣeya ọjọ́ kẹwà, oṣù kẹrin sọ́tọ̀ gẹ́gẹ́ bi ọjọ́ tí wọn yóò maa mọ rírì rẹ̀ fún ipa tó kó nínú sinimá Black Panthers.
Òṣèrébìnrin nàá t'ínú rẹ̀ dùn fi ìkéde nàá síta lójú òpó Instagram rẹ̀, ó ní ''Èyí ṣẹ̀sẹ̀ ṣẹlẹ̀!!!! Wọ́n fi àmì ẹ̀yẹ dámilọ́lá.
Wọ́n sì ke'de ọjọ́ kéde Àyájọ́ Ọjọ́ Ṣọpẹ́ Àlùkò.
Ìkéde nàá jáse lẹ́yìn oṣù kan tí Ṣọpẹ́ f'ọwọ́ sí ìwé láti kópa nínú sinimá 'Venom' tí yòó jáde l'ọ́jọ́ karùn ún, oṣù Kẹwà, láti iléeṣẹ́ Marvel, nínú èyí tí Tom Hardy nàá ti kópa.
Oríṣun àwòrán, @Sopealuko
Ó tún ti kópa nínú sinimá bí Identity Thief, Pitch Perfect, 96 Minutes àti Grass Stains.
Ṣọpẹ́ bẹ̀rẹ̀ iṣẹ́ gẹ́gẹ́ bi òṣèré lẹ́yìn tó k'ẹ́kọ̀ọ́ gboyè nínú ìmọ ẹ̀rọ.
Èkìtì 2018: Káyòdé Fáyemí f'èròhàn láti dupò gómìnà ìpínlẹ̀
Oríṣun àwòrán, @kfayemi
Kayode Fayemi yoo dupo pelu awon eeniyan mẹẹdọgbọn si ipo
Minisita fun ohun alumọni ilẹ lorilẹede yii, Ọmọwe Kayọde Fayẹmi ti ṣe afihan ipinnu rẹ si awọn olori ẹgbẹ oṣelu All Progressives Congress (APC) ati awọn gomina labẹ ẹgbẹ naa lati dupo gomina ipinlẹ Ekiti ninu idibo ọjọ kẹrinla, oṣu keje 14 ni ipinlẹ naa.
Ọgbẹni Fayemi, ti o jẹ gomina ana ni Ipinle Ekiti, sọ ni ọjọbọ lẹyin abẹwo akanṣe si awọn agbegbe ati ijọba ibilẹ ni Ekiti.
Atẹjade kan lati ọwọ oluranlọwọ̀ ati agbẹnusọ re, Yinka Oyebode, sọ wipe Minisita naa yoo ṣe ikede ipinu lati gbe'gba ibo fun ipo gomina ipinlẹ naa ni ọjọ abamẹta.
Gegebi ọ̀rọ̀ naa, ọgbẹni fayẹmi ti kọ lẹta ranṣẹ si alaga apapọ fun ẹgbẹ oṣelu APC, Oloye John Oyegun; adari apapọ ẹgbẹ APC, Asiwaju Bola Tinubu; Oloye Bisi Akande; gbogbo awọn olori ibilẹ ni Ipinle Ekiti; awọn alabaṣiṣẹpọ rẹ ni ile igbimọ alaṣẹ apapọ (FEC); awọn oludari ati awọn gomina labẹ ẹgbẹ oṣelu APC, ati awọn ọmọ bibi ipinlẹ Ekiti.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ọmọwe Fayẹmi ni ere ọmọde ni igbesẹ ijọba fayose lati fofin de oun
Ọgbẹni Oyebode sọ pe Minisita naa ti ṣe ipade pẹlu awọn ijọba agbegbe ibilẹ ati awọn alagba igbimọ ati awọn alàgba ẹgbẹ lakoko irin ajo rẹ si awọn agbegbe ijọba ibilẹ mẹrindinlogun naa.
Abẹwo naa bẹrẹ ni ọjọ aje ni ijọba ibilẹ Efon, ti o si wa sopin ni ijọba ibilẹ Oye lọjọbọ.
Kókó ìròyìn t'òní: Káyòdé Fáyemí fun Èkìtì 2018, owó iléèwé UI, AAUA
Eyi ni awọn akojọpọ iroyin ti oni.
Oríṣun àwòrán, @kfayemi
Kayode Fayemi yoo dupo pelu awon eeniyan mẹẹdọgbọn si ipo
Minisita fun ohun alumọni ilẹ lorilẹede yii, Ọmọwe Kayọde Fayẹmi ti ṣe afihan ipinnu rẹ si awọn olori ẹgbẹ oṣelu All Progressives Congress (APC) ati awọn gomina labẹ ẹgbẹ naa lati dupo gomina ipinlẹ Ekiti ninu idibo ọjọ kẹrinla, oṣu keje 14 ni ipinlẹ naa.
Ọgbẹni Fayemi, ti o jẹ gomina ana ni Ipinle Ekiti, sọ ni ọjọbọ lẹyin abẹwo akanṣe si awọn agbegbe ati ijọba ibilẹ ni Ekiti.
Àjọ ajàfẹ́tọ́ ọmọnìyàn kan lórílẹ̀èdè Nàìjíríà, SERAP ti ń lérí léka pé àwọn yóò gbé àwọn aláṣẹ fásitì Ìbàdàn, UI àti fásitì ìpínlẹ̀ Oǹdó lọ sí ilé ẹjọ́ bí wọn kò bá tètè tún èrò wọn pa lórí àfikún owó ilé ìwé
tí wọ́n ṣẹ̀ṣẹ̀ gbé kalẹ̀.
SERAP fún àwọn aláṣẹ fásitì méjèèjì ní gbèdéke ọjọ́ méje làti fi dá owó ilé ìwé náà padà sí iye tó wà tẹ́lẹ̀. Ẹ ka ẹkunrẹrẹ ni bii
Awon Fidio wa fun toni
Ǹjẹ́ ìwọ mọ kọ́mú tí wọn ń pè ní foamless, spacer, plunge, strapless, backless àti clap in front?
Àwọ̀tẹ́lẹ̀: Èwo lo ní ìfẹ́ sí nínú orísirísi kọ́mú yìí?
Àwọn akẹ́kọ̀ọ́ fásitì Adekunle Ajasin, Akungba-Akoko fẹ̀hónú hàn ní ìpínlẹ̀ Èkó.
Àgbáríjọpọ̀ àwọn akẹ́kọ̀ọ́ AAUA fẹ̀hónú hàn nípìnlẹ̀ Èkó
Fáyòṣe fèsì lórí bí Buhari se ńdá Gaddafi lẹ́bi wàhálà darandaran
Oríṣun àwòrán, Nigeria presidency
Fayoṣe ni awọn darandaran ti ko pa awọn ọmọ ilẹ̀ Libya ni wọn ń wá pa àwọn èèyàn ní Nàìjíríà.
Gómìnà Ayọ̀délé Fáyóṣe ti ìpínlẹ̀ Èkìtì ti sọ pé ìdójútì ńláǹlà ni Ààrẹ Mùhámádù Bùhárí ń fún orílẹ̀èdè Nàìjíríà pẹ̀lú  bí ó ṣe lọ ń di ẹ̀bi gulegule àwọn darandaran lórílẹ̀èdè Nàìjíríà ru Ààrẹ  Gaddafi ti ilẹ̀
Libya tó ti di olóògbé .
"Nínú àtẹ̀jáde kan tí oludari eto iroyin fun Gómìnà ìpínlẹ̀ Èkìtì náà, ọ̀gbẹ́ni Lere Olayinka fi síta, Fáyóṣé ní "" ìtìjú ń lá ló jẹ́ pé ààrẹ tún gbé àṣà kó máa di ẹ̀bi ru gbogbo èèyàn dé àwùjọ àgbáyé dé ibi pé ó tún ń di"
"ẹ̀bi ru ẹni tó ti jáde láyé."""
Ààrẹ Bùhárí sọ, nínú ìfọ̀rọ̀wérọ̀ rẹ̀ pẹ̀lu Bíṣọ́ọ̀bù àgbà ìjọ Anglican ní Canterbury, Ẹniọ̀wọ̀ Justin Welby ní ìlú London, pé ààrẹ orílẹ̀èdè Libya, Moumah Ghadafi tó kú ní ọdún méje sẹ́yìn ló kó ohun ìjà olóró fún
àwọn ọmọlẹyìn rẹ̀ tí wọ́n ti wá ṣàn wọ orílẹ̀èdè Nàìjíríà.
Ṣùgbọ́n Fáyóṣé ní kí ààrẹ Mùhámádù Bùhárí ó gbájúmọ́  ìpèníjà tó ńkojú ìjọba rẹ̀ láti pèsè ààbò tó péye fún àráàlú dipo didi ẹ̀bi gbogbo ìjákulẹ̀ rẹ̀ ru ẹnikẹni to ba ri lọ̀.
O ni bawo lo ṣe jẹ́ pé awọn darandaran ti ko pa awọn ọmọ ilẹ̀ Libya ni wọn ń wá pa àwọn èèyàn ní Nàìjíríà.
"Awọn ọmọ orilẹede Naijiria n di ẹbi ru aarẹ Buhari ati ijọba rẹ̀ pé wọn lọwọ ikọ̀lu awọn darandaran lorilẹede yii, ṣugbọn ohun ti aarẹ ri lati fi fesi si ẹhonu araalu ni ko di ẹ̀bi ru Ghadaffi to di oku ni ọdun meje
sẹyin.
Ìtìjú agbami agbaye ni eleyii lati ọwọ aarẹ ti ko mọ̀ ju ki o maa di ẹbi gbogbo ijakulẹ rẹ̀ ru ẹlomiran lọ.
Owó tí Àbáchà jí: Wo ohun tí ó lè ṣe fún ará ìlú
Oríṣun àwòrán, AFP
Ijọba orileede Switzerland ti da ẹ̀ẹ́dẹ̀gbẹ̀rin milionu dollar pada ninu owo naa laarin odun mewa seyin.
Ti o ba gbiyanju lati fi ẹrọ iṣiro rẹ tẹ milionu ọ́ọ́dúnrún le méjilelogun dollar ($322.5million dollars) ni iṣiro owo Naijiria elo lo ro wipe yoo je?
Ẹro isiro re'n gbẹko abi?
Ma se wahala jina, a ti ba o te.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Owo tabua ni owo ti ọgagun Abacha fi iye ọdun to wa ni ijọba ko
116,100,000,000.00 to je bilionu mẹ́rìndínlọ́gọ́fà ati ogorun milionu naira lo je.
Eyi ni iye owo ti ijọba apapo kede laipe yi pe awọn ri gba pada lọdun 2017 lati ọdọ ijọba orileede Switzerland ninu owo ti Aarẹ orileede Naijiria nigba kan ri ọgagun Sani Abacha ji pamọ.
Ṣugbọn awuyewuye  po lori owo naa paapa julo lori iye ti awọn agbẹjoro fẹ gba gẹgẹ bi owo ise fun pe wọn se atọna dida owo naa pada.
Bi ẹ ba fi ọkan si iye odo to wa lẹyin biliọnu 116,100,000,000.00  ọrọ na ko le ye yin daada.
Ẹ jẹki a se akawe awọn nnkan ti owo naa le se fun ara ilu.
Se ẹ ranti owo Sukuk ti ijọba apapo ya laipe yi lati fi pari awọn oju ọna kan kakiri orileede Naijiria?
Oríṣun àwòrán, TWITTER/KEMI ADEOSUN
Oju ọna mẹẹdogbọn ni ijọba fẹ fi owo Sukuk se atunse wọn
Ijọba apapọ ni ọgorun billionu (100 billion Naira naira) ni apapọ owo  naa je.
Lara awọn oju ọna ti wọn gbe jade pe awọn  fẹ tun se ninu owo na to kan ilẹ Yoruba lati ri:
Apapọ awọn owona wọnyii (16.6 billion naira ) ko ti ni ipa gbogi lara biliọnu 116,100,000,000.00 owo Abacha ti a gba pada o!
Se ẹ ri wipe owo naa ki se owo die?
Nnkan ti owo naa le se pọ.
Fun apere owo naa le san owo ipin osoosu ti ipinlẹ Osun n ri gba ninu akoto owo ijọba apapọ lati osu yi titi di ipari ọdun 2018.
Oríṣun àwòrán, NBS NIGERIA
Owo ipin osoosu ti ipinle Osun ti ajo to'n risi ounka oun isiro
Sibẹ sibẹ owo naa yoo sẹku.
Ni ẹka eto ẹko, ipese ina ọba, sisan owo osisẹ ati dida abo bo ilu, owo naa le ni ipa ti yoo ko.
Ohun to ku bayi ni ki ijọba se amojuto nina owo naa fun anfaani ara ilu.
Ìpínlẹ̀ Ọ̀sun kéde ọjọ́ ìsinmi lẹ́nu iṣẹ́ láti gba káàdì ìdìbò
Oríṣun àwòrán, Getty Images
ÌJọba ìpínlẹ̀ Ọ̀sun kéde ọjọ́ ajé tó mbọ̀ láti gba káàdì ìdìbò
Ìjọba ìpínlẹ̀ Ọ̀sun ti kéde ọjọ́ ajé ọ̀sẹ̀ tó mbọ̀ ìyẹn ọjọ́ kẹrìndídínlógún, oṣù kẹrin fún àwọn òṣìṣẹ́  ìpínlẹ̀  náà kí wọ́n lèè kópa nínú gbígba káàdì ìdìbò alálòpẹ́ tó ń lọ lọ́wọ́.
Kọmíṣánà fún ọ̀rọ̀ abẹ́nú ní ìpínlẹ̀  náà, ọ̀mọ̀wé Ọbáwálé Adébísí, nínú ọ̀rọ̀ kan tí ó sọ ní ọjọ́bọ̀ ọ̀sẹ̀ nílu Òṣogbo sọ wí pé ìsinmi náà wà láti pèsè ọ̀pọ̀lọpọ̀ ànfàní fún àwọn tó tó dìbò láti kópa nínú ìgbésẹ̀ náà.
Adébísí rọ àwọn tí kò tíì forúkọ sílẹ̀ láti lo àkókò ìsinmi yìí láti se bẹ́ẹ̀ kí àwọn tó sì ti forúkọ sílẹ̀ lo ànfàní náà láti gba káàdì ìdìbò wọn.
APC bori ninu idibo nipinlẹ Ọsun
Ewu n bẹ ninu ki osisẹ oba s'oselu - Gbade Ojo
Ìforúkọsílẹ̀ àwọn olùdìbò àti gbígba káàdì ṣe pàtàkì fún ìlànà ìdìbò bẹ́ẹ̀ sì ni ó ní ipa tí ó ń kó nínú ìsèjọba àwa ara wa, ó ma ń músẹ́ yá nínú ìlànà ìdìbò àti ìsèjọba àwa ara wa.
Nítórí ìdí èyí ni ìjọba se ríì ní pàtàkì láti pèsè ànfàní tó yẹ nípa kíkéde ọjọ́ ajé gẹ́gẹ́ bí ọjọ́ ìsinmi tó sì jẹ́ ọjọ́ àsekágbá fún àwọn tó tó dìbò láti f'orúkọ sílẹ̀.
Fáyóṣé fèsì lórí bí Buhari se ńdá Gaddafi lẹ́bi wàhálà darandaran
Oríṣun àwòrán, Nigeria presidency
Fayoṣe ni awọn darandaran ti ko pa awọn ọmọ ilẹ̀ Libya ni wọn ń wá pa àwọn èèyàn ní Nàìjíríà.
Gómìnà Ayọ̀délé Fáyóṣe ti ìpínlẹ̀ Èkìtì ti sọ pé ìdójútì ńláǹlà ni Ààrẹ Mùhámádù Bùhárí ń fún orílẹ̀èdè Nàìjíríà pẹ̀lú  bí ó ṣe lọ ń di ẹ̀bi gulegule àwọn darandaran lórílẹ̀èdè Nàìjíríà ru Ààrẹ  Gaddafi ti ilẹ̀
Libya tó ti di olóògbé .Nínú àtẹ̀jáde kan tí oludari eto iroyin fun Gómìnà ìpínlẹ̀ Èkìtì náà, ọ̀gbẹ́ni Lere Olayinka fi síta, Fáyóṣé ní  ìtìjú ń lá ló jẹ́ pé ààrẹ tún gbé àṣà kó máa di ẹ̀bi ru gbogbo èèyàn dé àwùjọ àgbáyé dé ibi pé ó tún ń di"
"ẹ̀bi ru ẹni tó ti jáde láyé."""
Ààrẹ Bùhárí sọ, nínú ìfọ̀rọ̀wérọ̀ rẹ̀ pẹ̀lu Bíṣọ́ọ̀bù àgbà ìjọ Anglican ní Canterbury, Ẹniọ̀wọ̀ Justin Welby ní ìlú London, pé ààrẹ orílẹ̀èdè Libya, Moumah Ghadafi tó kú ní ọdún méje sẹ́yìn ló kó ohun ìjà olóró fún
àwọn ọmọlẹyìn rẹ̀ tí wọ́n ti wá ṣàn wọ orílẹ̀èdè Nàìjíríà.
Ṣùgbọ́n Fáyóṣé ní kí ààrẹ Mùhámádù Bùhárí ó gbájúmọ́  ìpèníjà tó ńkojú ìjọba rẹ̀ láti pèsè ààbò tó péye fún àráàlú dipo didi ẹ̀bi gbogbo ìjákulẹ̀ rẹ̀ ru ẹnikẹni to ba ri lọ̀.
O ni bawo lo ṣe jẹ́ pé awọn darandaran ti ko pa awọn ọmọ ilẹ̀ Libya ni wọn ń wá pa àwọn èèyàn ní Nàìjíríà.
"Awọn ọmọ orilẹede Naijiria n di ẹbi ru aarẹ Buhari ati ijọba rẹ̀ pé wọn lọwọ ikọ̀lu awọn darandaran lorilẹede yii, ṣugbọn ohun ti aarẹ ri lati fi fesi si ẹhonu araalu ni ko di ẹ̀bi ru Ghadaffi to di oku ni ọdun meje
sẹyin.
Ìtìjú agbami agbaye ni eleyii lati ọwọ aarẹ ti ko mọ̀ ju ki o maa di ẹbi gbogbo ijakulẹ rẹ̀ ru ẹlomiran lọ.
Òní ni àyàjọ́ ọjọ́ tí àwọn akẹ́kọ̀bìnrin Chibok sọnù
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ẹgbẹ BBOG se àyàjọ́ ọjọ́ tí àwọn akẹ́kọ̀bìnrin Chibok sọnù
Ni ọjọ kẹrinla oṣu kẹrin, ọdun 2014, nileewe girama awọn obinrin ni ilu Chibok, nipinlẹ Borno, awọn akẹkọbinrin kan nṣe idanwo aṣekagba girama wọn lọwọ pẹlu ireti pe esi idanwo ayọ ni adura to ku fun wọn lẹyin eyi.
Boya ni wọn mọ wi pe adura wọn lẹyin ọjọ yii yoo kọja esi ayọ bikoṣe itusilẹ wọn kuro ninu ahamọ nitori ṣa dede ni awọn agbebọn kan lati ikọ boko haram ya wọ ileewe wọn ti wọn si ko awọn akẹkọbinrin ọrinlelugba o din mẹrin lọ.
Okiki kan nigba naa kakiri agbaye lori bi ijọba to wa lode lorilẹede Naijiria lasiko naa ṣe kuna lati daabo bo awọn akẹkọ naa.
Oríṣun àwòrán, @obyezeks
Nilu Abuja, idanilẹkọ yoo waye eleyi ti Pasitọ Tunde bakare yoo ṣe
Ọjọ abamẹta ni yoo pe ọdun kẹrin ti awọn agbebọn Boko Haram ji awọn akẹkọbinrin naa gbe, mejilelọgọfa wọn lo ṣi wa laharamọ awọn agbebọn yii.
Ọkan o jọkan  eto ni ajọ to n lewaju ipe fun itusilẹ awọn akẹkọbinrin yii ti la kalẹ bayii.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ni amẹrika, ipade adura yoo waye fun idapada awọn ọmọ naa
Lati naijiria si ilu ọba titi de orilẹede Amẹrika ni iwọde ati eto yoo ti waye lati tubọ tẹnumọ itusilẹ awọn ọmọ yii.
Ni amẹrika, ipade adura yoo waye ni ijọ Society for Advancement of Judaism lẹyin ti  adura jumaat ti waye lọjọ ẹti ni ibudo ẹsin islam to wa ni ilu New York.
Nilu Abuja, idanilẹkọ yoo waye eleyi ti Pasitọ Tunde bakare yoo ṣe.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Okiki kan nigba naa kakiri agbaye lori bi ijọba to wa lode lorilẹede Naijiria lasiko naa ṣe kuna lati daabo bo awọn akẹkọ naa
Ninu ọrọ to fi sita lori ikanni twitter rẹ, aṣiwaju ikọ to n pe fun itusilẹ awọn akẹkọ naa, BBOG, Ọmọwe Oby Ezekwesili ni  'awọn ti ṣeleri pe ko ni si idaduro ni ipe awọn titi di igba ti ijọba apapọ yoo ko awọn ọmọ naa pada. Eyi lo si mu wa duro ṣinṣin di oni"
"Aisha Yesufu ni tirẹ ni, ""Fun ọdun mẹrin, awọn ọmọbinrin mejilelaadọfa wa ni ahamọ. Itiju nla niyi fun ijọba. Leah Sharibu ti lo ọjọ mejilelaadọta ni ahamọ, ki ni a n beere fun?"""
Kókó ìròyìn t'òní: Wàhálà ìdàmẹ́wàá, Fáyòṣe tako Ààrẹ Bùhárí
Eyi ni awọn akojọpọ iroyin ti toni.
Kí la tún gbọ́ nípa ìdámẹ́wàá?
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Kí la tún gbọ́ nípa ìdámẹ́wàá?
Laipẹ́ yii, olusọ̀aguntan ijọ RCCG, Pasito Adeboye sọ ni gbangba fun awọn ọmọ ijọ rẹ̀ wipe, ẹni ti ko ba san idamẹwa ko ni lọ si ọ̀run.
Ẹ o ranti wipe, ọrọ ti nja rain rain tẹ́lẹ̀ lori pe Daddy Freeze fesi si ọ̀rọ̀ pasitọ̀ Adeboye lori sisan idamẹ́wa leyii ti Freeze fesi pe idamẹ́wo ko pọn dandan.
Fáyóṣé fèsì lórí bí Buhari se ńdá Gaddafi lẹ́bi wàhálà darandaran
Oríṣun àwòrán, Nigeria presidency
Fayoṣe ni awọn darandaran ti ko pa awọn ọmọ ilẹ̀ Libya ni wọn ń wá pa àwọn èèyàn ní Nàìjíríà.
Gómìnà Ayọ̀délé Fáyóṣe ti ìpínlẹ̀ Èkìtì ti sọ pé ìdójútì ńláǹlà ni Ààrẹ Mùhámádù Bùhárí ń fún orílẹ̀èdè Nàìjíríà pẹ̀lú  bí ó ṣe lọ ń di ẹ̀bi gulegule àwọn darandaran lórílẹ̀èdè Nàìjíríà ru Ààrẹ  Gaddafi ti ilẹ̀
Libya tó ti di olóògbé . E ka ekunrere re ni bii
Awọn Fidio wa fun toni
Brọdá Shaggi: Kékeré ni mo ti mọ̀ pé iṣẹ́ apanilẹ́ẹ̀rín l'ọ̀nà mi
'Kékeré ni mo ti mọ̀ pé iṣẹ́ apanilẹ́ẹ̀rín l'ọ̀nà mi'
Ẹ wo àwọn ọmọ tí bàbá wọn fi s'ílẹ̀ sálọ ní Ghana
Ẹwo awọn ọmọ ti baba wọn fi silẹ sa lọ
Ẹ wo àwòrán àti ọ̀rọ̀ ìrántí àwọn akẹ́kọbìrin Chibok
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Òní ni àyàjọ́ ọjọ́ tí àwọn akẹ́kọ̀bìnrin Chibok sọnù
Ọjọ kẹrinla oṣu kẹrin, ọdun 2014, nileewe girama awọn obinrin ni ilu Chibok, nipinlẹ Borno, awọn akẹkọbinrin kan nṣe idanwo aṣekagba girama wọn lọwọ pẹlu ireti idanwo ayọ. Saadede ni awọn ẹgbẹ Boko Haram kọlu ile iwe naa ti wọn si ji awọn akẹkọbinrin naa gbe lọ
Lati igba naa, pabo ni ireti njasi lati rii pe gbogbo wọn pade sile pe. O tan kakiri agbaye lori bi ijọba to wa lode lorilẹede Naijiria lasiko naa ṣe kuna lati daabo bo awọn akẹkọ naa.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Abọde awọn akẹ́kọbinrin Chibok
Oni lo pe ọdun kẹrin ti awọn agbebọn Boko Haram ji awọn akẹkọbinrin naa gbe, mejilelọgọfa wọn lo ṣi wa lahamọ awọn agbebọn yii.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ijọba apapọ orileede se ajoyo awọn akekọbinrin Chibok to kọkọ pada de
Sibẹ́sibẹ́, bi awọn ọ̀dọmọbinrin to ku ko se tii ri itusilẹ gba lọwọ awọn ẹsinokọku Boko Haram, gbogbo igba ni ianti wọn ngba onije loju awọn obi wọn
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Obi awon akekobinrin Chibok ko tii dake riranti awon omo won
Nigba ti isi kinni awọn akẹkọbinrin Chibok pada de, se ni inu ijọba ati gbogbo ara ilu dun bi o tilẹ jẹ wipe ọpọlọpọ aidaa lo ti sẹlẹ̀ si wọn ninu ahamọ Boko Haram
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Igbakeji Aarẹ, Yẹmi Ọsinbajo nigba to nki awọn akẹkọbinrin Chibok to ti de sile ku abọ
Awọn ọdọmọbinrin naa ti wọn ko sai ranti ile nibi ti iko Boko Haram gbe wọn lọ sun ẹkun ayọ
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Iyawo igbakeji Aarẹ, Dolapọ Ọsinbajo yọ̀ pẹlu awọn ọmọ naa
Lati ọdun ,ẹrin sẹyin ti wọn ti ko awọn ọdọmọbinrin yii sigbekun ni ọpọlọpọ ọr ti njẹyọ kaakiri agbaye. Wọ̀nyii ni lara ohun ti awọn eniyan nsọ lori ẹrọ ayelujara
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Awọn obi ati ara ilu Chibok si nreti awọn ọmọ to ku
‘Ara fu mí nígbàtí bàbá gbé Bíbélì ìdílé fúnmi’
Ọwọ́ sìkùn ọba tẹ lára àwọn afurasí tó kọlu ilú Òffà
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ọwọ́ ọlọ́pàá tẹ lára àwọn afurasi tó kọlu ilú Òffà
Látarí ikọ̀lù tó wáyé láìpẹ́ nílu Ọ̀ffa, Iléeṣé ọlọ́pàá ti ìpinlẹ Kwara ti mú àwọn afurasí méjìlá míì tó ní se pẹ̀lú ìkọlù ilú náà láìpẹ́.
Ìròyìn tó ni létí wípé àwọn ikọ̀ ọ̀tẹlẹ̀múyẹ́ ọlọ́pàá alágbára ló kó àwọn afurasí apànìyàn náà.
Ikọ̀ ọlọ́pàá tó ní ǹkan ìjà, ìsọ̀rí mẹ́ta ọlọ́pàá àti àwọn irinsẹ́ amólè ni ọ̀gá àgbà pátápátá  àwọn  ọlọ́pàá kó ráńsẹ́ sí ìpinlẹ Kwara.
Òkú sùn nínú ìṣẹ̀lẹ̀ ìdigunjalè ní Ọ̀ffà
Kí ní ńǹkan tó ṣẹlẹ̀ ní Ọ́ffà
Ìlú Ọ̀ffà ní ìpínlẹ̀ Kwara wárìrì lọ́jọ́bọ, tí kowéè ké láì ha, nítorí ìṣẹ̀lẹ̀ ìdigunjalè kan tó wáyé nílé ìfowópamọ́ márùn ún ọ̀tọ̀ọ̀tọ̀ ní ìlú náà.
Àwọn eeṣin kò kọ ikú adigunjalè náà, tí wọ́n tó ọgbọ̀n níye ló ṣe ọṣẹ́ láwọn báńkì náà fún wákàtí méjì àti ààbọ̀ gbáko, èyí tó sọ ọ̀pọ̀ èèyàn di opó àti ọmọ òrukàn.
Kí aráyé baà leè mọ̀ pé eré kọ́ làwọn wá ṣe, àgọ́ ọlọ́pàá tó wà ní Owódé làwọn alọkólóhunkígbe yìí ti kọ́kọ́ kí wọn kú ilé níbẹ̀, tí wọ́n sì rán àwọn ọlọ́pàá tó wà lẹ́nu iṣẹ́, àwọn èèyàn tó ní ẹjọ́ ní tésàn náà àtàwọn èèyàn míì tó wà níbẹ̀ sọ́run ọ̀sángangan.
Oríṣun àwòrán, Ayobami Agboola
Guaranty Trust Bank Offa, Kwara state
Agbẹnusọ fún  olú iléeṣé ọlọ́pàá, Jimoh Moshood sọ pé wọ́n gba àwọn ǹkan bíi ẹ̀rọ alágbeká, ẹ̀rọ àtẹ́léwọ́ ipad àti káàdì ẹ̀rọ ìbánisọ̀rọ̀ àwọn tí wọ́n fara gbá padà lọ́wọ́ wọn.
Nínú àwọn báǹkì ilú Ọ̀ffa ni àwọn adigunjalè yìí tí sọsẹ́ sùgbọ́n ibi tí ọwọ́ ti tẹ̀ wọ́n ni ilú Èkó, Ìbàdàn, Ìlọrin àti  Ọ̀ffa pẹ́lú àwọn ǹkan ìjà olóró bíi ìbọn gbúntú alágbára àti àwọn ọta ìbọn.
‘Ara fu mí nígbàtí bàbá gbé Bíbélì ìdílé fúnmi’
Amẹ́ríkà UK, France kọlu àwọn ọmọ ogun al-Assad
Oríṣun àwòrán, Getty Images
America,UK, France gbèjà orílẹ̀èdè Syria
Látàrí bí wọ́n se kọlu orílẹ̀èdè Syria láìpẹ́ yìí, orílẹ̀èdè Améríkà, ilẹ̀ Gẹ̀ẹ̀sì ati orílẹ̀èdè Faransé ti koná ogun wọ́n sì ti gbé e ko ibi mẹ́ta kan tí wọ́n fojú sùn wípé àwọn ló kọlu orílẹ̀èdè Syria.
Ìgbésẹ̀ náà wáyé gẹ́gẹ́ bí ọ̀nà àti kojú ìkọlù tó wá sórí orílẹ̀èdè Syria tó sì mú ẹ̀mí ọ̀pọ̀lọpọ̀ lọ.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Olóòtú ìjọba ilẹ̀ Gẹ̀ẹ̀sì, Theresa May sọ pé ó dá òun lójú ọwọ́ àwọn tẹ oun tí wọ́n fẹ́
Látàrí ìkọlù tó wáyé lórí orílẹ̀èdè Syria, olóòtú ìjọba ilẹ̀ Gẹ̀ẹ̀sì, Theresa May sọ pé ìgbésẹ̀  orílẹ̀èdè Amẹ́ríkà àti Faransé tí ilẹ̀ Gẹ̀ẹ́sí dara pọ̀ mọ́ dá òun lójú wípé ti jíjáwé olúborí ni.
May tún sọ wípé nínú ọkàn òun, ohun tí àwọn se yìí gaan ló tọ́.
Ilé isẹ́ tó ńrí sí ọ̀rọ̀ àbò ní  orílẹ̀èdè Amẹ́ríkà sọ pé àwọn ìbúgbàmù  náà ta bá báríkè àwọn ológun kan ní Damascus èyí tíí se olú ìlú orílẹ̀èdè Syria àtàwọn agbègbè méjì míì.
Wọ́n kọlu báríkè ológun ní Damascus àtàwọn agbègbè méjì míì ní Syria
Ẹ̀wẹ̀, asojú orílẹ̀èdè Russia ní àwọn kò ní lajú 'lẹ̀ kí tàlùbọ̀ ó kó wọ̀ ọ́ pẹ̀lú ìgbésẹ̀ tí orílẹ̀èdè Amẹ́ríkà àtàwọn tó kù se.
APC- àjòjì ọkùnrin kan gbàsàkóso iìkànì Twitter rẹ̀
Oríṣun àwòrán, Twitter.com/APC
APC kò tíì sàlàyé oun to sẹlẹ̀
Arakunrin kan, Justin Sun ni o ti gbàsàkóso ìkànì Twitter ẹgbẹ oselu APC lọ́jọ́ ìsinmi.
Oun ti a sàkíyèsí ni pe, níse ni àsíá ẹgbẹ oselu APC to wà lori ikani ọun yípadà si ti ọ̀gbẹ́ni Sun yii, ti ó sì n kọ orisirisi nnkan nipa ijọba orilẹede Naijiria.
Okunrin ọun sọ̀rọ̀ nipa pe ijọba Naijiria n pín owó orí ẹ̀rọ ayélujára ti a mọ̀ sí Bitcoin.
Bákan náà lo tún sọ nipa àjọ INEC. O ni irọ́ pata ni pe INEC n gba awọn eniyan sísé fun ìdìbò 2019.
Oríṣun àwòrán, TWiotter.com/APC
Orisirisi a[rà ni Sun n da lori ìkànì Twitter ẹgbẹ́ oselu APC
Egbẹ APC ko tii fọhùn rárá lori ọ̀rọ̀ naa.
Àwọn olórí orílẹ̀èdè lágbàáyé sọ èrò wọn lori ìkọlù Syria
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Lẹ́yín ti orilẹede Amerika, France ati ilẹ̀ Gẹ̀ẹ́sí pawọ́pọ̀ se ìkọlu si orilẹede Syria, awọn orilẹede àgbàye ti n fi èrò wọn hàn lorisirisi.
Awọn kan sọ pe ìgbésẹ̀ ọ̀ún jẹ́ eyi tó tọ́ tó sì yẹ, nigba ti awọn mìíran ríi gẹgẹ bii oun tí kò tọ̀nà rárá.
Díẹ̀ lara awọn orilẹede ti wọn sọ sí ọ̀rọ̀ naa nìyí:
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Orilẹede Amerika
Aarẹ Donald Trump sọ pe, ìgbésẹ̀ naa jẹ èyí to mu èròngbà awọn wá sí ìmúsẹ. O ni àseyege gbaa ni ni ìkọlù naa jẹ́, ti ó sì tún dúpẹ́ lọ̀wọ̀ awọn orilẹede to fọwọ́sowọ́pọ̀ pẹlu rẹ̀.
Orilẹede China
"China ni tirẹ̀ ni awọn kò faramọ́ ikọlu naa nitori pe ó lòdì si òfin ìbásepọ̀ laarin awọn orilẹede lágbàáyé. China pe fun àtúntò ètò òsèlú lagbaye, ati pe, o ni ó tó ki awọn orilẹede agabye ''maa tẹ̀lé ìlànà to'tọ́""."
Orlẹede Isreal
"Benjamin Netanyahu ti orlẹede Isreal ní tirẹ̀ sọ pe, lati ọdún to kọjá ni oun ti sọọ́ pe, oun faramọ́ ki aarẹ Amerika Donald Trump ""gbé ìgbésẹ̀ to tọ́ lori lílo Kẹ́míkà olóró"" láàárín awn orilẹede lagbaaye."
Orilẹede Russia
"Russia ni gbogbo ara lòún fi lòdì si bi orilẹede Amerika se kọlu orilẹede Syria ""níbití orilẹede Russia ti n se ìrànlọ́wọ́ fun ìjọba to ba òfin mu lorilẹede Syria lati koju awọn ajìjàgbara."""
Ó ní oun n pè fun ìpàdé pàjáwìrì ninu àjọ ìsọ̀kan àgbáyé.
Saudi Arabia
"Saudi Arabia ni awọn faramọ́ bi Amerika, France ati ilẹ̀ Gẹ̀ẹ́sì se kọlu Syria, nitori pe ikọlu ọun |""jẹ́ ìdáhùn si awọn ìwà ọ̀daràn ti ìjọba Bashar al-Assad n hù."""
Turkey
"Orilẹede Turkey ni ""awọn fi ọwọ́ mẹ́wẹ̀ẹ̀wá si ikọlu naa, nitori pe, o mu ẹ̀rì ọkàn fun ìwà ọmọnìyàn kuro, lẹ́yìn ìkọlù to wáyé ni Douma."""
Gold coast 2018: Nàìjíríà ní góòlù mẹ̀sán láti dúró ní ipò kẹsán
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ipo kẹsan lori atẹ igbelewọn ami ẹyẹ ni Nàìjíríà wà nibi idije naa
Bí ìdíje àwọn orílẹ̀èdè tó ti fìgbàkan rí wà lábẹ́ ìmúnisìn ilẹ̀ Gẹ̀ẹ́sì, Commonwealth ṣe ń wá sí ìdádúró lọ́jọ́ àìkú, orílẹ̀èdèNàìjíríà  ti bọ́ sí ipoò kẹsán lórí atẹ ìgbéléwọ̀n àmì ẹ̀yẹ níbi ìdíje náà.
Goolu mẹsan, fadaka mẹsan ati baaba mẹfa ni awọn oludije lati orilẹede Naijiria ti gba bayii.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Naijiria gba àmì ẹ̀yẹ góòlù mẹ̀sán
Ere asafogi ọlọgọrun mita fawọn obinrin, Women's 100m Hurdles, ere asadiju ọlọgọrun mita fun awọn akanda, irin gbigbe ati ijakadi ni orilẹede Naijiria ti gba ami ẹyẹ goolu.
Orilẹede Australia lo n lewaju atẹ igbelewọn naa pẹlu ọgọrin goolu, ilẹ Gẹẹsi tẹlee pẹlu goolu marundinlaadọta ti India si ṣe ipo kẹta pẹlu goolu mẹrindinlọgbọn.
Orilẹede South Africa lo moke julọ laarin awọn orilẹede to wa lati ilẹ Afrika nibi idije naa pẹlu ami goolu mẹtala ti Naijiria si ṣe ipo keji.
Oríṣun àwòrán, Mark Metcalfe
Orilẹede South Africa lo moke julọ laarin awọn orilẹede to wa lati ilẹ Afrika
Orilẹede Kenya lo ṣe ipo kẹta laarin awọn orilẹede Afrika nibẹ pẹlu ami goolu mẹrin.
APC kéde ìkànì ẹ̀rọ ayélujára tuntun
Oríṣun àwòrán, Twitter.com
Ikanni Twitter naa ní àmì ìdánilójú pe APC lo nií
Lẹ́yìn ìsẹ̀lẹ̀ to wáyé lọ́jọ́ abamẹ̀ta, nigba ti ọkunrin àjòjì kan gbàkóso ikani Twitter ẹgbẹ́ oselu APC, ẹgbẹ́ ọun kede pe, oun ti ni awọn ìkànnì ìbáraẹni sọ̀rọ̀ tuntun lori ẹ̀rọ ayélujára.
Bí o tilẹ̀ jẹ́ pe ẹgbẹ́ APC ni ikanni ìbáraẹni sọ̀rọ̀ lori Twitter tẹ́lẹ̀, ẹgbẹ́ ọun sọ pe ikanni ọun kii se tàwọn, ati pe, awọn o ni ounkóhun se pẹlu ikanni ọ̀un ti o ni àdírẹ́ẹ̀sì @APCNigeria.
Ikanni yii ní oun tó tó ẹgbẹ̀rún lọ́na ọgọ́rùún meje olùtẹ̀le, ti wọ̀n si ti síi lati ọdun 2013.
Ikanni Twitter ọun ni àmì ìdánilóju pe ẹgbẹ APC lo nií lọ́ọ̀tọ́, kó tó di pe wọn bẹ̀rẹ̀ si ni fi ikanni naa polówó òwò ẹ̀rọ ayelujara ti a mọ̀ sí Bitcoin lálẹ́ ọjọ́ àbámẹ́ta.
Ikanni Twitter APC n polówó Bitcoin
Ni ọjọ́ ìsinmi ni agbẹnusọ ẹgbẹ APC Bolaji Abdullahi fi àtẹ̀jáde kan síta pe, awọn ti polongo lai mọye ìgbà pe ẹgbẹ APC kò ní ounkóhun se pẹlu ikanni Twitter yii, ati pe awọn rí oun to sẹlẹ̀ yii gẹ́gẹ́ bi iwa ọ̀daràn to lágbára.
Ninu àtẹ̀jáde ọ̀ún ni Abdullahi tun ti sọ pe ẹgbẹ́ APC ti sí awọn ìkanni tuntun ti yoo fun awọn olólùfẹ́ wọn, awọn oníròyìn ati gbogbo eniyan lapapọ̀ ní ooreọ̀fẹ́ lati mọ oun to n lọ ninu ẹgbẹ́ òsèlú ọ̀ún.
Awọn ìkànni ìbáraẹni sọ̀rọ̀ tuntun ti ẹgbẹ́ ọ̀ún fi síta nìyí:
Website:      www.officialapcng.com
Twitter:        https://twitter.com/OfficialAPCNg
Facebook:   https://web.facebook.com/officialapcng/
Instagram: https://www.instagram.com/officialapcng/
YouTube:    Official APC Nigeria
Balarabe Musa: Olè níkan ló leè jẹ ààrẹ Nàíjíríà
Oríṣun àwòrán, Twitter/Onome Igugu
Ẹnikẹ́ni kò leè jẹ ààrẹ Nàíjíríà bí onítọ̀ún kò bá kọ́kọ́ jalè tàbí káwọn olè tìí lẹ́yìn
Gómìnà tẹ́lẹ̀ ní ìpínlẹ̀ Kàdúná, Balarabe Musa ní kò sí ẹnikẹ́ni tó leè jẹ ààrẹ Nàíjíríà bí onítọ̀ún kò bá kọ́kọ́ jalè tàbí kí àwọn olè tìí lẹ́yìn.
Ó ní, kò sí bí ẹnikẹ́ni tó leè kó owó tó pọ̀ bíi èyí jọ fún ìpolongo ìbò ààrẹ lọ́nà tó tọ́ ní orílẹ̀èdè yìí.
Ó wa di ẹ̀bi ètò ọrọ̀ ajé àti ìgbáyé-gbádùn wa tó dagun ru ìlànà ètò òsèlú wa níbi tó ti jẹ́ pé ìdá mọ́kàndínlọ́gọ́rùn ùn nínú ọgọ́rùn ún àwọn asaájú tó wà nípò àsẹ ló jẹ́ olè
Balarabe Musa, ẹni tó kéde bẹ́ẹ̀ nínú fọ́nrán àwòrán kan tó gba ojú òpó ìkànsíraẹni Facebook kan, bó ọ̀rọ̀ náà lójú tòró, nígbà tó ń gbàlejò olùdíje kan fún ipò ààrẹ, Ọmọyẹlé Sòwòrẹ́.
"Musa ni ""Kínni àbùdà rere àwọn asaájú wa? lẹ́yìn sáà ìsèjọba olósèlù kejì, báwo ni yóò ṣe ṣeéṣe fún wa láti ní ìsọ̀rí àwọn aṣaájú tí kò níí jẹ́ olè? Kódà mò ń siyèméjì pé bóyá ni yóò tó ìdá kan nínú wọn tí ọwọ́ wọn mọ́, ọ̀pọ̀ wọn ló jẹ́ ọ̀fọ́n ọ̀n pọ́núnbélé."""
Gẹ́gẹ́ bí Balarabe Musa ti wí, èyí kò rí bẹ́ẹ̀ láyé ìṣèjọba alágbádá ẹlẹ́ẹ̀kejì, tó sì mú u wá sí ìrántí pé Shehu Shagari di ààrẹ Nàíjíríà láì jẹ́ olè.
Aisha Buhari: Torí òtítọ̀ ni mo fi sọ̀rọ̀ tako ọkọ mi
Oríṣun àwòrán, @aishambuhari
Aisha Buhari ní ìfẹ́ ìdájọ́ òdodo ti òun ní ló fàá tí òun fi ṣe bẹ́
Ìyàwó ààrẹ orílẹ̀èdè Nàíjíríà, Aisha Buhari ti sọ ìdí tó fi sọ̀rọ̀ tako ọkọ rẹ, Ààrẹ Mùhámádù Bùhárí̀ lórí ìṣèjọba rẹ̀ láwọn àkókò kan sẹ́yìn.
Aisha Buhari ní ìfẹ́ ìdájọ́ òdodo ti òun ní ló fàá tí òun fi ṣe bẹ́ẹ̀.
Nínú ọ̀rọ̀ tó fi ránṣẹ́ sí ayẹyẹ ìfàmì ẹ̀yẹ dánilọ́lá tí ìwé ìròyìn kan lórílẹ̀èdè Nàìjíríà ṣe nílùú Èkó, ni ìyàwó ààrẹ orílẹ̀èdè Nàíjíríà ti sọ èyí di mímọ̀.
Kìí ṣe àfojúdi rárá. A kọ́ mi láti máa dìde jà fún òtítọ́, nítorí náà ni mo fi se bẹ́ẹ̀
Àmọ́ṣá, Aisha Buhari ní, níwọ̀n ìgbà tí ọmọ ẹni ò ní ṣèdí bẹ̀bẹ̀rẹ̀, ká fi ìlẹ̀kẹ̀ sídí ọmọ ẹlòmíràn, digbí lòun wà lẹyìn ọkọ òun nínú ìpinnu rẹ̀ láti tẹ̀síwájú pẹ̀lú ìṣèjọba rẹ̀ fún sáà kejì.
Bí a ko bani gbagbe, Aisha ti fìgbàkan rí sọọ ́lórí BBC Hausa pé, bí nǹkan ṣe ń lọ nígbà náà kò bá yí padà, òun kò ní polongo ìbò fún ọkọ òun mọ́.
Ọbásanjọ́: Àwọn ọ̀dọ́ kò gbọdọ̀ dìbò fún Bùhárí
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ọ́básanjọ́ tí ké pe Ààrẹ Bùhárí kó jọ̀wọ́ ìpinnu rẹ̀ láti gbe àpótí fún sáà kejì
Ààrẹ Nàìjíría nígbà kan rí, Olúṣẹgun Ọbásanjọ́ àti akọ̀wé ìjọba àpapọ̀ tẹ́lẹ̀, Olóyè Olú Fálaè, ṣe'pàdé bòǹkẹ́lẹ́ lórí ọ̀rò Ààrẹ̀ Muhammadu Buhari ní ọjọ́ Iṣẹ́gun.
Ìpàdé náà wáyé lẹ́hìn ọdún mọ̀kàndínlógún tí Obasanjo àti Falae ti ṣe àtakò ara wọn lórí ìbò ààrẹ l'ọ́dún 1999.
Àwọn èèkàn olósèlú bíi Doyin Okupe tó jẹ́ agbenusọ fún ààrẹ àná, Goodluck Jonathan àti olùdíje fún ipò gómìnà ní ìpínlẹ̀ Ògùn, lábẹ́ asia ẹgbẹ́ PDP, Gboyega Isiaka, wà ní ìpadé náà pẹ̀lú.
A gbọ́ wípé Fálaè, tó jẹ́ alága ẹ́gbẹ́ Social Democratic Party, SDP àti Ọ́básanjọ́ ti pinnu láti mú gbogbo àwọn alátakò sábẹ́ àsía kan ṣoṣo.
Ọ́básanjọ́, tó ti ń gbé ìgbésẹ̀ láti kó àwọn ẹgbẹ́ alátakò bíi ọgbọ̀n mọ́ra, tún ti késí àwọn ọ̀dọ́ pe ki wọ́n maṣe dìbò fun Ààrẹ Buhari nítorí àìṣe dáadáa tó.
Maiduguri: Ènìyàn 380 ní àìsàn onígbàméjì ń bá fíra-Kọ́misọ́nà ilera
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ààrùn onígbá méjì mú ẹmí ènìyàn mẹ́rìnlá
Ìjọba ìpínlẹ̀ Borno tí fìdí ọ̀rọ̀ múlẹ̀ pé ó kéré tán, ènìyàn mẹ́rìnlá ni ààrùn onígbá méjì ti gba ẹmí wọn ní ìpínlẹ̀ náà.
Haruna Mshellia tó jẹ́ kọmisọnà fún ètò ìlera, ló fìdí ọ̀rọ̀ náà múlẹ̀ lásìkò tó ń bá àwọn oníròyìn sọ̀rọ̀ ní ìlú Maiduguri lọ́sàn òní.
O ní àwọn tí tójú àwọn ènìyàn ààdọ́talénígbà tí wọn fòjú hàn ní ilé ìwòsàn, tí àwọn ogúndínirínwó míràn sì wà lórí àkéte àìsàn
Ààrùn yínrùnyínrùn ti gbẹ̀mí ènìyàn méjìlá ní ìlú Katsina
Oríṣun àwòrán, Getty Images
ọ̀pọ̀ awọn tó ṣaláìsí ń kígbe orí fífọ́, àti àìsàn ibà kí wọn tó kú
Ààrùn onígbá méjì (cholera) àti yírùnyírùn (meningitis) ló tún ti súyọ ní ìlú Dan Iyau,  Karaje , Dutsinma nípìnlẹ̀  Katsina tó sì ti gba ẹ̀mí ènìyàn méjìlá,
olórí ìlú Dan Iyau, Suleiman Abdullahi tó jẹ́ẹ̀rí sí ìṣẹ̀lẹ̀ òhún sọ pé  ènìyàn mẹ́wàá ló ti kú láàárín ọ̀sẹ̀ kan
ile ẹ̀kọ́ olùkọ́ni àgbà Isa Kaita ti ìlú Dutsinma ti di títìpa lọ́jọ́ Jímọ̀ tó kọjá
lẹ́yìn tí ọmọ ilé ìwé  méjé gbẹ́mì mì, sùgbọ́n agbẹnusọ ile ẹ̀kọ́ náà Malam Muntari Bala sàlàyé pé wọn ò ti  ile ẹ̀kọ́ pa bíkòṣe pé àwọn lọ fún ìsinmi ráńpẹ́ ni.
Ìjínigbé Nàìjíríà: Agbébọn pa ọlọ́pàá, ó jí ọmọ Germany gbé
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ìgbà àkọ́kọ́ kọ́ rèé tí wọn yóò jí àjèjì gbé ní Nàìjíríà
Àwọn agbébọn ti pa ọlọ́pàá kan, wọ́n sì jí ọmọ orílẹ̀edè Germany kan gbé ní ìpínlẹ̀ Kano ní ìhà àríwá orílẹ̀edè Nàìjíríà.
Ìsẹ̀lẹ̀ yìí wáyé lọ́jọ́ ajé.
Nínú àtẹ̀jáde kan tó wá láti ilé isẹ́ ọlọ́pàá ìpínlẹ̀ Kano, wọ́n fi àìdunnú hàn sí  ìsẹ̀lẹ̀ ọ̀hún gẹ́gẹ́ bí wọ́n se kéde f'árá ìlú.
Ìsẹ̀lẹ̀ abúrú yìí wáyé lọ́jọ́ kẹrìndínlógún osù kẹrin ọdún 2018 ní òpópónà Sabon Titi Madobi, ìlú Kano níbi tí ikọ̀ adigunjalè ẹlẹ́ni márùún nínú ọkọ̀, tú kẹ̀kẹ́ ìbọn sórí ọkọ̀ kan tó ńgbé àwọn òsìsẹ́ ilé isẹ́ agbasẹ́se Dantata & Sawoe lọ sí ibi isẹ́ àgbàse wọn.
Àwọn akọluni náà pa sájẹ̀ntì ọlọ́pàá kan tí ó wà lẹ́nu isẹ́ àkànse ìpèsè ààbò, bẹ́ẹ̀ sì ni wọ́n jí ọ̀gbẹ́ni Michael Cremza, ọmọ ìlú German,y tó ń sisẹ́ darapọ̀ mọ́ ilé isẹ́ náà gbé.
Látìgbà náà, kọmísánà  ọlọ́pàá, Rabiu Yusuf ti rán ikọ̀ òsìsẹ́ àti ọ̀tẹlẹ̀múyẹ́ alágbára lọ síbẹ̀ láti bojú tó agbègbè náà kí ọwọ́ lè tẹ àwọn ọ̀daràn, kí wọ́n sì dá ẹni tó wà nígbèkùn sílẹ̀.
Ilé isẹ́ ọlọ́pàá ìpínlẹ̀ Kano sọ pé, kí ẹnikẹ́ni tó bá ní ìròyìn nípa wọn, kàn sí ilé isẹ́ ọlọ́pàá tó bá wà ní tòsí wọn.
Buhari, Trump yóò ṣèpàdé l'Ámẹ́ríkà
Ohun méje pàtàkì nípa Commonwealth
‘Àwọn olè níkan ló leè jẹ ààrẹ Nàíjíríà
Ikọlu wáyé láàrin àwọn ọmọ ogun Nàìjìríà àti Shiite
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ikọlu wáyé láàrin àwọn ọmọ ogun Nàìjìríà àti Shiite
Fọ́fọ́ ni gbogbo àwọn ìlooro kọ̀ọ̀kan kún fún òkúta àti agolo gáàsì ní ìlú Abuja lẹ́yìn ìkọlù tó wáyé láàrin àwọn ọmọ ogun Nàìjíríà àtàwọn afẹ̀hónú hàn tó n bèèrè fún ìtúsílẹ̀ adarí ẹgbẹ́ Shiite, Sheikh Ibrahim Zakzaky.
Se ni àwọn ọmọ àwùjọ mùsùlùmí yìí ńju òkúta bá àwọn ọlọ́pàá tí àwọn òsìsẹ́ aláàbò sì fín gáàsì padà tí wọ́n fi mú púpọ̀ lára àwọn afẹ̀hónú náà.
Wọ́n ní ìbọn tí àwọn ọlọ́pàá yìn bá lára àwọn afẹ̀hónú ọ̀hún. Kò y'é ni ìhà tó kọ́kọ́ bẹ̀rẹ̀ ìwà ipá náà bẹ́ẹ̀ sì ni àwọn ọlọ́pàá kò tíì fèsì.
ICC pari iwadi lori pipa Shiites, IPOB
Àwọn ọmọ àwùjọ Shia ní orílẹ̀èdè Nàìjíríà máa ń sábà bọ́ sí gbangba ígboro láti bèèrè pé kí wọ́n tú Sheikh Zakzaky, olórí ẹgbẹ́ mùsùlùmí lórílẹ́èdè Nàìjíríà sílẹ̀.
Wọ́n ní kò bá òfin mu bí wọ́n se tì í m'ọ́lẹ́ láti ọdún 2015.
Ìsekúpani darandaran; ọlọ́pàá mẹ́rin forí káásà ní Benue
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Iroyin sọ pe awakọ ọmọ ọdun mẹrinlelọgbọn k'agbako nipinlẹ Ondo
Ọlọọpa mẹrin ti papoda lẹyin ikọlu awọn agbebọn si ibudo awọn ọlọọpa ni ipinlẹ Benue, ti eniyan mọkanla si ti di awati.
Isẹlẹ naa waye nigba ti awọn ọlọọpa n wa ọkọ kaakiri ni agbeegbe Anyibe titi to fi de ijọba ibilẹ Ayilamọ ni ipinlẹ Benue.
Ile isẹ ọlọọpa ipinlẹ naa gba ẹnu agbẹnusọ wọn, ASP Moses Yamu sọwipe lati ibẹrẹ ọdun yii ni ikọlu awọn Fulani darandaran ti n waye lagbeegbe naa, ti ọpọlọpọ ẹmi si ti ba isẹlẹ naa lọ.
Arakunrin yamu sọwipe adari ajọ ọlọọpa, Ibrahim Idris ti ran awọn ikọ ọlọọpa to n wa ọkọ ofurufu si agbeegbe naa lati se iwadi ofintoto nipa isẹlẹ naa
Agbẹnusọ ile isẹ ipinlẹ Benue naa wa fikun wipe ajọ ọlọọpa yoo sa ipa wọn lati ri wipe ọwọ tẹ awọn asekupani naa, ti wọn yoo si foju wina ijọba.
Koko iroyin: ọmọogun Nàìjìríà àti Shiite, ijinigbe Kano
Eyi ni awọn akojọpọ iroyin ti toni.
Ikọlu wáyé láàrin àwọn ọmọ ogun Nàìjìríà àti Shiite
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ikọlu wáyé láàrin àwọn ọmọ ogun Nàìjìríà àti Shiite
Fọ́fọ́ ni gbogbo àwọn ìlooro kọ̀ọ̀kan kún fún òkúta àti agolo gáàsì ní ìlú Abuja lẹ́yìn ìkọlù tó wáyé láàrin àwọn ọmọ ogun Nàìjíríà àtàwọn afẹ̀hónú hàn tó n bèèrè fún ìtúsílẹ̀ adarí ẹgbẹ́ Shiite, Sheikh Ibrahim Zakzaky.
Se ni àwọn ọmọ àwùjọ mùsùlùmí yìí ńju òkúta bá àwọn ọlọ́pàá tí àwọn òsìsẹ́ aláàbò sì fín gáàsì padà tí wọ́n fi mú púpọ̀ lára àwọn afẹ̀hónú náà.
Ìsekúpani darandaran;  ọlọ́pàá mẹ́rin forí káásà ní Benue
Ọlọọpa mẹrin ti papoda lẹyin ikọlu awọn agbebọn si ibudo awọn ọlọọpa ni ipinlẹ Benue, ti eniyan mọkanla si ti di awati.
Isẹlẹ naa waye nigba ti awọn ọlọọpa n wa ọkọ kaakiri ni agbeegbe Anyibe titi to fi de ijọba ibilẹ Ayilamọ ni ipinlẹ Benue. Ẹ ka ẹkunrẹrẹ rẹ ni bii
Sàká: Oun tí orí bá yàn fún ẹ̀dá ni kó ṣe
Sàká: Oun ti orí bá yàn fún ẹ̀dá ni kó ṣe
Iléesẹ̀ Ọlọ́pàá: Ọlọ́pàá 22 farapa nínú ìkọlù Shiite
Oríṣun àwòrán, Getty Images
O ti to ọjọ mejidinlogorun ti awọn ọmọ ẹgbẹ́ Shiite ti'n fẹ̀hónú hàn fún ìtúsílẹ̀ olori wọn Sheikh Ibrahim Zakzaky.
Ile iṣẹ ọlọ́pàá nílu Abuja ni awọn tí mú ọmọ ẹgbẹ́ Shi'ite márùndínlọ́gọ́fà to kópa nínú iwode tó wáyé nílu Abuja lọjo ajé.
Ninu atẹjade kàn ti Anjuguri Manzah fi ṣòwò sí àwọn akọ̀ròyìn, o ní àwọn afurasi naa yóò fojú bá ile ejo ní kété ti àwọn ba parí ìwádìí.
Lọjọ ajé ni ikọlu wáyé láàrin àwọn ọmọ ẹgbẹ́ Shi'ite àti ọlọ́paa, ti ọpọ èèyàn sí farapa nínú ìṣẹlẹ náà.
Ifẹhonu àwọn ọmọ ẹgbẹ́ Shi'ite náà kò sẹyìn bi ìjọba orílẹ̀èdè Nàìjíríà ṣe kọ láti tù olórí wọn, Ibrahim Zakzaky silẹ t'ohun ti bi ile ẹjọ tí pàṣẹ pé kí wọn tú silẹ.
Lọ̀dun 2015 ní wọn mú Zakzaky nínú ikọlu kan ti ọ̀ọ́dúnrún àwọn ọmọ ẹgbẹ́ rẹ ti pàdánù ẹ́mi wọn.
Bàbáńgídá: Àwọn ọmọ Nàíjíríà kò kà mìí kún mọ́
Oríṣun àwòrán, Reuters
Kò sí ẹnití ó yìn mìí láwo pé mo sètò ìdìbò tó pegedé jùlọ nínú ìtàn orílẹ̀èdè yìí.
Olórí ìjọba ológun tẹ́lẹ̀, ajagunfẹ̀yìntì Ibrahim Babangida ti gbarata pé àwọn ọmọ Nàíjíríà ko ka òun sí mọ́ nítorí bí òun se wọ́gilé ìdìbò ààrẹ June 12.
Idìbò Aàrẹ June 12 ìdìbò kan gbógì  tí gbogbo àgbáyé gbà pé òun ló péye jùlọ ninu itan orilẹẹde Nàíjíríà.
Babangida kéde bẹ́ẹ̀ lórí ètò orí móhùnmáwòràn án kan lọ́jọ́ ajé.
Bákan náà ló fikún un pé bí òun bá kọ̀wé nípa ìgbé ayé òun, kò sí ọmọ Nàíjíríà kankan tí yóò fẹ́ kàá.
Ọdalẹ ni Babangida ati Abacha - Ọmọ Abiola
Wọn gbàgbé pé ọ̀rẹ́ ni èmi àti Abíọ́lá
Lọ́ọ̀tọ́ ni mo wọ́gilé ìdìbò ààrẹ June 12, tí gbogbo àgbáyé gbà pé òun ló péye jùlọ, sùgbọ́n kò sí ẹnití ó yìn mìí láwo pé mo sètò ìdìbò tó pegedé jùlọ nínú ìtàn orílẹ̀èdè yìí.
Babangida tún fikun un pé ọ̀pọ̀ èèyàn ni kò mọ̀ pé ọ̀rẹ́ ni òun àti Olóyè MKO Abiọ́lá ká tó di ìbò June 12 àti lẹ́yìn rẹ̀, tí kò sì sẹ́ni tó ròó pé sebí ọ̀rẹ́ làwọn méjèèjì, kín ló wá fa wàhálà yìí.
Ìrànwọ̀ Gẹ̀ẹ́sì: Bùhárí se káre lóríi ìrànwọ́ £1m
Oríṣun àwòrán, Nigeria presidency
Bí ilẹ̀ Gẹ̀ẹ́sì bá jáde kúrò lájọ Yúrópù, àjọṣepọ̀ okòòwò àti ọ̀rọ̀ ajé láàárín orílẹ̀èdè méjèèjì gbópọn síi.
Ààrẹ orílẹ̀èdè Nàíjíríà, Mùhámádù Bùhárí pẹ̀lú olóòtú ìjọba ilẹ̀ Gẹ̀ẹ́sì, Theresa May, ti pinnu láti jùmọ tẹ̀síwájú nínú lìlépa ìfìdímúlẹ̀ ìṣèjọba àwarawa, tó fi mọ́ gbígbógun ti ìwà ìbàjẹ́ àti ṣíṣí ilẹ̀kùn ètò ẹ̀kọ́ sílẹ̀ gbayawu fún aráàlú.
Ilé ìjọba ilẹ̀ Gẹ̀ẹ́s,ì tó wà ni ojúlé kẹwàá, òpópónà Downing ní ìlú London ni ìpàdé náà ti wáyé.
Bùhárí àti Arábìnrin May tún fohùn ṣọ̀kan lórí àjọṣepọ̀ nípa ọ̀rọ̀ iléeṣẹ́ ológun pẹ̀lú ètò ààbò, pàápàá jùlọ lórí ọ̀rọ̀ wíwa ọwọ́ gulegule Boko haram àti ẹgbẹ́ agbésùmọ̀mí Islamic State West Africa bọlẹ̀.
Oríṣun àwòrán, Nigeria presidency
Theresa May kọminú lórí bí àwọn ọmọ obìnrin ṣe ń fara kó ááṣá wàhálà ọ̀rọ̀ ààbò tó mẹ́hẹ lórílẹ̀ èdè Nàìjíríà
Agbẹnusọ fún Ilé ìjọba ilẹ̀ Gẹ̀ẹ́sì tún ṣàlàyé pé, àwọn olórí ìjọba méjèèjì tún jíròrò lórí ètò ìrànlọ́wọ́ owó oní mílíọ̀nù kan pọ́ùn owó ilẹ̀ Gẹ̀ẹ́sì, láti ra àwọn nǹkan ijàgun adójú tàdó olóró, fún ìdáàbòbò àwọn ológun àti aráàlú lórílẹ̀èdè Nàìjíríà.
"Olóòtú ìjọba kò ṣàì fi àìdùnnú rẹ̀ hàn pẹ̀lú bí àwọn ọmọ obìnrin ṣe ń fara kó ááṣá wàhálà ọ̀rọ̀ ààbò tó  mẹ́hẹ lórílẹ̀èdè Nàìjíríà.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí:
Olóòtú ìjọba, Theresa May tún kan sáárá sí Ààrẹ Mùhámmádù Bùhárí, lórí àtúntò okòòwò àti ọ̀rọ̀ ajé lórílẹ̀èdè Nàìjíríà, tó sì tún sọọ́ di mímọ̀ pé, jíjáde tí ilẹ̀ Gẹ̀ẹ́sì fẹ ́jáde kúrò lájọ orílẹ̀èdè Yúrópù, yóò túbọ̀ mú kí okùn àjọṣepọ̀ okòòwò àti ọ̀rọ̀ ajé láàárín orílẹ̀èdè méjèèjì gbópọn síi."
Nínú ọ̀rọ̀ rẹ̀ Ààrẹ Mùhámádù Bùhárí lu olóòtú ìjọba ilẹ̀ Gẹ̀ẹ́sì lọ́gọ ẹnu, fún àtìlẹ́yìn rẹ̀ lóríi gbígbógunti ìdúnkùkùlajà Boko haram.
Awọn ọmọlẹ́yìn El-Zakzaky: Ọlọ́pàá ló ń fa rúkèrúdò lásìkò ìwọ́de wọn
Oríṣun àwòrán, @OfficialPDPNig
Wahala bẹ́ sílẹ̀ nílùú Àbúja lọ́jọ́ ajé láàárín àwọn ọlọ́pàá àti àwọn ọmọ ìjọ ẹ̀sìn shi'ite
Àwọn ọmọ ìjọ ẹ̀sìn  shi'ite ti fi ẹ̀sùn kan iléeṣẹ́ ọlọ́pàá lórílẹ̀èdè Nàìjíríà pé àwọn gan an ló ń ṣokùnfà rúkèrúdò tó máa ń wáyé ní gbogbo ìgbà tí wọ́n bá ṣe ìwọ́de  wọn.
Wahala bẹ́ sílẹ̀ nílùú Àbúja lọ́jọ́ ajé láàárín àwọn ọlọ́pàá àti  àwọn ọmọ ìjọ ẹ̀sìn  Shi'ite.
Àwọn  ọmọ ìjọ ẹ̀sìn  Shi'ite naa ni wọ́n ń pè fún ìtúsílẹ̀  aṣíwájú ìjọ náà, Sheikh Ibrahim Elzakyzaky tí ìjọ ba fi sí àtìmọ́lé láti  bíi  ọdún mẹ́ta sẹ́yìn
Nínú ìfọ̀rọ̀wérọ̀ rẹ̀ pẹ̀lú BBC Yoruba, agbẹnusọ fún ìjọ ẹ̀sìn Islam naa, Ibrahim Musa ní ìwọ́de  alá àláfíà lawọn máa ń ṣe ṣùgbọ́n àwọn ọlọ́pàá ló máa ń fi ipá àti ìbọn kò wọ́n lójú.
Oríṣun àwòrán, @OfficialPDPNig
Àwọn ọmọlẹ́yìn Elzakyzaky ń pè fún ìtúsílẹ̀ aṣíwájú ìjọ náà tí ìjọba fi sí àtìmọ́lé lọ́dún 2015
"Lójú àwọn ọlọ́pàá yìí, tí o bá ti leè sọ fún wọn pé ọmọ ìjọ Shi'ite ni ẹ́, wàhálà ni wọn yóò gbé dìde.
Ìtúsílẹ̀ Sheikh ni a ń béèrè, ṣùgbọ́n ìjọba kò fẹ́ tẹ̀lé ìdájọ́ ilé ẹjọ́ pé kí wọ́n dáa sílẹ̀."
Agbẹnusọ fún ìjọ ẹ̀sìn Islam naa, ni kò sí ẹni tó kú gẹ́gẹ́ bí àwọn èèyàn kan ṣe ń sọ káàkiri.
"Ìbọn ba èèyàn wa kan lórí bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé a ń gbàdúrà pé kó máà kú.
Kò dín ní ogún àwọn obìnrin àti ọmọdé lára mẹ́rìnléláàdọ́fà tí àwọn ọlọ́pàá kó sí àhámọ́ láti ọjọ́ ajé."
Kíni ọlọ́pàá àti ẹgbẹ́ alátakò ń sọ?
Àmọ́ṣá, ileeṣẹ ọlọ́pàá ilu Abuja ní àwọn afurasi ti wọ́n mú yóò fojú bá ile ejo ní kété ti àwọn ba parí ìwádìí.
Ní báyìí, ẹgbẹ́ òṣèlú PDP ti bèèrè fún ìwádìí ìṣẹ̀lẹ̀ náà.
Gẹ́gẹ́ bí àtẹ̀jáde kan tí ẹgbẹ́ òṣèlú PDP fi síta lórí ìṣẹ̀lẹ̀ náà, o ni irufẹ itaporogan bẹ́ẹ̀ láàárín ọlọ́pàá àti àwọn ọmọlẹyìn Elzakyzaky kì bá tí wáyé, kání íjọba tẹ̀lé àṣẹ ilé ẹjọ́ pé kí wọ́n túu sílẹ
Johesu: Òsìsẹ́ ìlera ti bẹrẹ iyanselodi
Oríṣun àwòrán, AFP
Iyansẹlodi lẹka ilera orileede Naijiria ki se ohun tuntun mọ
Àwọn òṣìṣẹ́ elétò ìlera lorilede Naijiria, labẹ àsìá ẹgbẹ apapo awọn oṣiṣẹ ilera Johesu ti bẹrẹ iyansẹlodi loni.
Awọn oṣiṣẹ náà, paapa julo, àwọn tó n ṣiṣe ni awọn ile ìwòsan ìjọba àpapọ, ni yóò kọ̀kọ̀ bẹrẹ iyansẹlodi náà.
Atẹjade kan lati ọdọ igbákejì alága ẹgbẹ́ náà, Ogbonna Chimela ní, ti ìjọba ba je ki iyanselodi náà tẹsiwaju lẹyìn ọsẹ méjì, gbogbo awọn ile iwosan ìjọba ìpínlè àti tìbílẹ̀ ni yóò darapo mo iyanselodi náà.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí:
Eyi kìí ṣe iyanselodi àkọkọ
Losu kẹsán ọdún tó lọ, ní iyanselodi kàn wáyé lórí àfikún owó oṣù, ajemọnu, igbega ati àwọn ẹtọ míràn fún àwọn osíṣe ìlera lorileede Naijiria.
Idasẹsile náà mú ìnira ba opo aláìsàn ṣugbọn lójó keje idasẹsile náà, wọn yanjú òrò ọ̀hún ní tunbi n nubi pẹlu ijọba.
Jack Lampang, to je alamojuto eto iroyin fun Johesu ni, ko si nnkan ti ẹgbẹ naa n beere fun, bi ko se ki ijọba fun awọn ni ẹto awon.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Johesu ni oun mo wi pe ara yoo ni awọn ara ilu lori idasẹsile naa
''Awọn Dokita nikan kọ ni osise ilera to wa ni Naijiria. Lai pe yi ni ijọba sika adehun ti wọn se pẹlu awọn onimo isegun sugbọn ti ọrọ ba kan ti awa osise to ku, awawi ni wọn ma n so''
Jack ni awọn ti fun ijoba ni anfaani lopo igba lati yanju oro naa lai se pe awọn dase sile.
"A mo wi pe ara yoo ni awọn ara ilu lori idasẹsile nitori re ni alaga wa fi ni ki idasesile naa mo ni awọn ile iwosan ijọba apapo nikan bayi. Bi won ba ko lati sika adẹhun ti wọn se pẹlu wa, awọn ile iwosan ìjọba ìpínlè àti ìbílẹ̀ naa yóò darapo mọ iyansẹlodi náà. ''
BBC Yoruba gbiyanju lati ba Minista feto ilera lorileede Naijiria sọrọ sugbọn ẹni to gbe ipe rẹ ni o wa ninu ipade kan.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Awọn Dokita ati awọn osise ilera miran ko gba dede iye owo kannáà.
Losu kẹwa ọdún tó kọjá, awọn Dókítà orileede Naijiria, labẹ àsìá ẹgbẹ onimo isegun sapèjúwe ẹgbẹ àwọn oṣiṣẹ ilera Johesu gẹgẹ bii  ajo ti ko bofinmu""."
Wọn ni ọpọ òun ti Johesu n béèrè fún ko bójú mu.
Ọjọgbọn Mike Ogrima, to jẹ Ààrẹ ẹgbẹ onimo ìṣegun ni '' A lòdì sí kí àwọn Dókítà àti oṣiṣẹ ilera jijo ma gba iye owo kannáà. Johesu n bèèrè fún ìbádọ́gba owo láàrin àwọn oṣiṣẹ ilera to ku ati awon Dókítà.''
Fashola: Omi ń bẹ lámù nídìí ìpèsè ina ọba
Oríṣun àwòrán, Reuters
Inà mọ̀nàmọ̀nà ti wà déédé láti ǹkan bíi osù méjì sẹ́yìn
Ibùdọ Amúnáwá ní Nàìjíríà tún ti kọsẹ́ lẹ́ẹ̀mejì láàrín ọjọ́ márùn ùn, bẹ́ẹ̀ iná ọ́ba ti ń se déédéé láti bíi osù méjì sẹ́yìn ní orílẹ̀èdè Nàìjíríà.
Ìròyìn fihàn pé ó ti sẹlẹ̀ lẹ́ẹ̀mẹfà níbẹ̀rẹ̀ ọdún 2018.
Àkọsílẹ̀ láti ilé isẹ́ ìjọba àpapọ̀ tó ń rísí ọ̀rọ̀ isẹ́ òde, iná mọ̀nàmọ̀nà àti ilégbèé nílu Àbújà fihàn pé, Ibùdọ Amúnáwá da isẹ́ sílẹ̀ láàrín ọjọ́ kejìlá sí ọjọ́ kẹrìnlá, osù kẹrin ọdún yìí, èyí tó sì ń dààmú ìpèsè iná títí di ìsinyìí.
Ọjọ́ kínní osù kejì ló kọ́kọ́ sẹlẹ̀ lọ́dún yìí kó tó tún dákú padà báyìí.
Ilẹ̀ gbígbẹ́ ní Bọ́ùn: Ìpìnlẹ̀ mẹ́fà leè má nìí iná ọba
Ogbẹ́ni Usman Mohammed to je olùdarí ẹ̀ka tó ń pín iná mọ̀nàmọ̀nà ní Nàìjíríà wá pè fún àtúnse sí àwọn ohun eèlò tí wọn ń lò fi n mú iná wá pẹ̀lú àjọsepọ̀ àwọn olókoòwò ńlánlá láti ilẹ̀ òkèèrè.
Fasola gbà pé ìdàgbàsókè iná mọ̀nàmọ̀nà jẹ ìjọba lógún fún ilọsíwájú ètò ọrọ̀ ajé  Nàìjíríà pàápàá lásìkò yìí.
2019: Buhari yan Keyamo ní agbẹnusọ ìpolongo ìbò
Oríṣun àwòrán, Twitter/Keyamo
Ọ̀pọ̀ àwọn to sọ̀rọ̀ l'órí ìyànsípò náà ní ìyànsípò náà kò yà àwọn lẹ́nu.
Ààrẹ Muhammadu Buhari ti yan amòfin àgbà, Festus Keyamo, gégé bíi agbẹnusọ fun ètò ìpolongo ìdìbo sáà kejì rẹ̀ ní ọdún 2019.
Keyamo fúnra rẹ̀ ló kéde bẹ́ẹ̀ lorí ìkànnì Twitter rẹ̀ níbi tó ti ṣe àfihàn lẹ́tà tí wọ́n kọ sii láti fi ìyànsípò rẹ̀ tóo léti.
Ẹ jẹ́ kí Buhari lọ jókòó
Ó tún sọ wípé òun yóò sọ̀rọ̀ lórí ìyànsípò náà ní báyìí tàwọn ọmọ Nàìjíría n fi èrò ọkàn wọn han lórì ọ̀rọ̀ náà.
Ọ̀pọ̀ nínú àwọn tó sọ̀rọ̀ l'órí ìyànsípò náà lorí Twitter sọ wípe, ìyànsípò náà kò yà awọ́n lẹ́nu nítorí wípé Keyamo ti ń gbóríyìn fún ìjọba Buhari láti ọjọ́ tó ti pẹ́.
Kókó ìròyǹ: Ìpàdé Falae àti Ọbasanjọ lórí Buhari, Ìyansẹ́lódì elétò ìlera
Eyi ni awọn akojọpọ iroyin ti toni.
Ọbásanjọ́: Àwọn ọ̀dọ́ kò gbọdọ̀ dìbò fún Bùhárí
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ọ́básanjọ́ tí ké pe Ààrẹ Bùhárí kó jọ̀wọ́ ìpinnu rẹ̀ láti gbe àpótí fún sáà kejì
Ààrẹ Nàìjíría nígbà kan rí, Olúṣẹgun Ọbásanjọ́ àti akọ̀wé ìjọba àpapọ̀ tẹ́lẹ̀, Olóyè Olú Fálaè, ṣe'pàdé bòǹkẹ́lẹ́ lórí ọ̀rò Ààrẹ̀ Muhammadu Buhari ní ọjọ́ Iṣẹ́gun.
Ìpàdé náà wáyé lẹ́hìn ọdún mọ̀kàndínlógún tí Obasanjo àti Falae ti ṣe àtakò ara wọn lórí ìbò ààrẹ l'ọ́dún 1999.
Àwọn òṣìṣẹ́ elétò ìlera lorilede Naijiria, labẹ àsìá ẹgbẹ apapo awọn oṣiṣẹ ilera Johesu yoo bẹrẹ iyansẹlodi ní aago méjìlá òru ọjọ́ ìsẹ́gun.
Awọn oṣiṣẹ náà, paapa julo, àwọn tó n ṣiṣe ni awọn ile ìwòsan ìjọba àpapọ, ni yóò kọ̀kọ̀ bẹrẹ iyansẹlodi náà. Ẹ ka ẹkunrẹrẹ ni bii
Dòdò Ìkirè jẹ́ ohun ìpanu pàtàkì nílẹ̀ Yorùba. Ìlú Ìkirè sì ni wọ́n ti máa ń se Dòdò Ìkirè
Dòdò Ìkirè: Ó dúdú lára sùgbọ́n oyin ni lẹ́nu
Wàhálà ilé aṣòfin àgbà: Ọ̀pá àṣẹ jíjígbé kìí ṣe tuntun
Oríṣun àwòrán, NGR Senate
Ọ̀pá àṣẹ jíjígbé kiìí ṣe tuntun ní Naijria
Wahala bẹ́ sílẹ̀ ní ilé igbìmọ̀ aṣòfin àgbà orílẹ̀èdè Nàìjíríà nígbà tí àwọn jàǹdùkú kan wọ ilé tí wọ́n sì gbé ọ̀pá àṣẹ ilé lọ.
Àmọ́ṣá, ṣaaju asiko yii, ni irufẹ iṣẹlẹ tii n waye.
Diẹ ninu awọn ti a ko jọ pọ fun yin niyi.
Oríṣun àwòrán, NGR Senate
Awọn aṣofin ipinlẹ Nasarawa fi ija pẹẹta lori yiyan awọn alakoso ijọba ibilẹ nipinlẹ naa
Awọn aṣofin ipinlẹ Nasarawa fi ija pẹẹta lori yiyan awọn alakoso ijọba ibilẹ nipinlẹ naa.
Ninu fọnran fidio ti o gbajugbaja lasiko naa lori ẹrọ ayelujara, gbogbo ohun ti awọn aṣofin ipinlẹ Nasarawa nigba naa lee tawọ le ni wọn fi ja, titi kan ọpa aṣẹ ile.
Ni ọjọ kẹsan oṣu keje ọdun 2013, awọn a'sofin ipinlẹ Rivers fi ija pẹẹta ti wọn si lo ọpa aṣẹ ile aṣofin naa fi lu ara wọn.
Awọn aṣofin to fẹ yọ olori ile naa nigba naa, Otelemaba Amachree atawọn to gbe sii lẹyin ni wọn gbe pẹrẹgi kana nigba naa eleyi to di iṣu ata yan an yan an.
Eyi waye lasiko ede aiyede to waye laarin gomina ipinlẹ Rivers nigba naa, Rotimi Amaechi pẹlu ààrẹ nigba naa, Goodluck Jonathan.
Oríṣun àwòrán, Tvc news
Wahala kan bẹ silẹ laarin awọn ọmọ ẹgbẹ oṣelu APC nile aṣofinṣoju lori yiyan ẹni ti yoo jẹ olori ile aṣofinsoju
Wahala kan bẹ silẹ laarin awọn ọmọ ẹgbẹ oṣelu APC nile aṣojuṣofin lori yiyan ẹni ti yoo jẹ olori ile aṣojuṣofin lọdun 2015.
Bi awọn kan ṣe n gbaruku ti Yakubu Dogara, lawọn miran wa lẹyin Gbajabiamila.
Ija to bẹ silẹ laarin igun mejeeji yii lo fa ija nla ninu gbagede ile, eleyi ti awọn kan ti gbiyanju ati gbe ọpa aṣẹ ile naa.
Oríṣun àwòrán, NGR senate
Ni ọjọ kẹsan oṣu keje ọdun 2013, awọn a'sofin ipinlẹ Rivers fi ija pẹẹta ti wọn si lo ọpa aṣẹ ile aṣofin naa fi lu ara wọn
Awọn aṣofin kan gbiyanju lati yọ olori ọmọ ẹgbẹ oṣelu to pọ julọ ni ile, Alhaji Tambaya Dawanu ni ọjọ kẹrinlelogun, Oṣu Keje ọdun 2006.
Ikuuku ati ẹkẹ mimu loriṣiriṣi lo farahan lọjọ naa, ti wọn si tun kan ọpa aṣẹ ile si mẹta. Ki o to di wi pe wọn gbe ọpa aṣẹ onirin miran wa sinu ijoko ile lọjọ naa.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí:
Johesu: Ìjọba ń fọmọ kan kẹ́ ọ̀kan lẹ́ka ìlera
Abdulrafiu Adeniji sọrọ lori isorogun Dokita ati osìsẹ́  ilera
Aarẹ ati Oludari ajọ to'n risi awọn agbẹbi ati olutoju alaisan ni Nàìjíríà, Abdulrafiu Adeniji ti dẹbi aawo to'n fa idasesile lopo igba ru awon eleto ilera lorileede Nàìjíríà.
O ni aisododo awọn eleto ilera ti ọpọ ninu wọn je Dokita lo faa, ti atotonu lati yanju aawo to ba waye kii so eso rere .
Adeniji se alaye pe, oti pẹ ti aisedede ti wa laarin awọn osise to ku ati awọn dokita.
''Iyanselodi wa ki se fun afikun owo nikan bi kii se ki atunto le ba ẹka ilera. A fẹ ki wọn se atunyẹwo ilana ti o'n ri si eto ilera lorileede Nàìjíríà ''
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Awọn Dokita ati awọn osise ilera miran ko gba dede iye owo kannáà.
Iyanselodi lẹka ìlera làgbáyé kii se ohun àjòjì sugbọn awọn amòye ni ti orílẹ̀-èdè Nàìjíríà peleke.
Lọ̀jọ̀ kejindinlogun oṣù kẹrin ọdún yi ni iyanselodi mii tun bẹrẹ ni awọn ile ìwòsàn ìjọba àpapọ̀ káàkiri orílẹ̀èdè Nàìjíríà.
Johesu to je apapọ ẹgbẹ awọn oṣiṣẹ eleto ìlera ni wọn kéde iyanselodi náà eleyi ti ọpọ èèyàn tí n fesi sí.
Oríṣun àwòrán, STEFAN HEUNIS/AFP/GETTY IMAGES
Awọn alaisan lo maa n fara gba iyansẹlodi lọpọ igba lorileede Naijiria
Lara awọn to sọrọ lórí iyanselodi náà ni ẹgbẹ àwọn Dókítà orílẹ̀èdè Nàìjíríà.
Aare ẹgbẹ naa, Dokita Mike Ogrima, ninu ifọrọwanilẹnuwo pẹlu ile isẹ BBC Yoruba ni, iyansẹlodi naa ko tọ nitori pe ẹgbẹ ti ko ba ofin mu ni Johesu.
Ogrima ni, ti ijọba ba tẹti si ohun ti Johesu n beere, o seese ko da ede aiyede sile leka ilera orileede yii.
O ni awọn ara ilu ni yoo faragba iyanselodi yii nitori kii se fun anfaani wọn, bi ko se fun awọn osise ilera nikan.
Kinni Minista ilera sọ si ọrọ yii?
Fun ọpọ igba la gbiyanju lati ba Minista feto ilera lorileede Naijiria sọrọ sugbọn ko gbe ipe wa.
Ona abayo kan ti awọn ọmọ ẹgbẹ Johesu ati ẹgbẹ àwọn Dókítà orílẹ̀èdè Nàìjíríà daba, ni ki ijọba se atunto to peye lẹka ilera.
Ìsẹ̀lẹ̀ Cameroon: Igí wó pa akẹ́kọ̀ọ́ mẹ́ta ọmọ Nàìjíríà
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ọmọ ilé ìwé àádọ́ta àti olùkọ́ mẹ́fà ni o lọ sí ìrìn àjò ẹ̀kọ́ náà.
Igi ti wó pa àwọn akẹ́kọ̀ọ́ mẹ́ta kan, tí wọ́n kúro ní Nàìjíríà láti lọ wo àwọn ẹranko oríṣiríṣi ní ẹkùn àríwá orílẹ̀èdè Cameroon.
Alàkóso agbègbè náà, Jean Abate Edi'i, sọ wípé igi náà wo lu awon àwọn akẹ́kọ̀ọ́ náà lẹ́hin ìji líle tí ó jà.
Àwọn akẹ́kọ̀ọ́ mẹ́rìndínlógún tó ṣèṣe nínú ìṣẹ̀lẹ̀ náà ni wọn gbé lọ sí Garoua, tí ó jẹ́ orí ìlú ẹkùn àríwá Cameroon.
Ilé iṣé ìgbóhùnsáfẹ́fẹ́ agbegbe náà so wípe ọmọ ilé ìwé àádọ́ta àti olùkọ́ mẹ́fà ni o lọ sí ìrìn àjò ẹ̀kọ́ náà.
A gbọ́ wípé àwọn eerin pọ̀ ní agbègbè náà.
Lórílẹ̀èdè Zimbabwe, Ẹgbẹ̀rún mẹ́wá nọ́ọ̀sì pàdánù iṣẹ́
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Àwọn noòsì Zimbabwe kọ̀ láti ṣẹ́wélé ìyanṣẹ́lódì, lẹ́yì tí ìjọba fi mílíọ̀nú mẹ́tàdínlógún
Orílẹ̀èdè Zimbabwe tí fáwọn òṣìṣẹ́ olùtójú aláìsàn tó lé ní ẹgbẹ̀rún mẹ́wá ní ìwé kónílé-ó-gbélé nítorí ìyanṣẹ́lódì tí wọ́n gùnlé láti béèrè fún àfikún owó oṣù wọn.
Nínú àtẹ̀jáde kan láti ọwọ́ igbá-kejì Ààrẹ Constantino Chiwenga lórí ìdí tí wọ́n fi yọ àwọn nọ́ọ̀sì náà níṣẹ́ f'ẹ̀sùn kàn wọ́n pé ìgbésẹ̀ ìyanṣẹ́lódì wọn lọ́wọ́ òṣèlú nínú.
Ọ̀pọ̀ àwọn aláìsàn ni wọ́n dá padà sílé nínú ọ̀sẹ̀ yìí l'áwọn  ilé ìwòsàn ńláńlá tó jẹ́ ti ìjọba.
Ó ti pé ọ̀sẹ̀ kan báyìí t'áwọn dókítà orílẹ̀èdè náà ti ṣẹ́wélé ìyanṣẹ́lódì.
Ìjọba ṣàlàyé pé ìlera ará ìlú lo ṣe pàtàkì sí oùn; nítorínáà gbogbo àwọn òṣìṣẹ́ tó yanṣẹ́lódì ni yóò gba lẹ́tà ìdádúró láti gba àwọn òṣìṣẹ́fẹ̀yìntì lẹ́nu ìṣẹ́ ìtọ́jú aláìsàn.
Chiwenga jẹ́ ọ̀gá ológun tó darí ìdìtẹ̀ gbà'jọba lọ́wọ́ Robert Mugabe ní oṣù kọkànlá ọdún tó kọjá.
Lẹ́yìn tó gbé ọ̀pá àsẹ ilé sálọ, ọwọ́ ọlọ́pàá tẹ Omo-Agege
Oríṣun àwòrán, Ovie Omo-Agege/Twitter
Ile igbimọ asofin kọwe lọ gbe ile rẹ fun Osu mẹta fun Omo-Agege
Ajọ ọlọpaa ti fi panpẹ ọba mu Sẹnatọ Ovie Omo-Agege lẹyin ijoko ile igbimọ asofin.
Ni ọsẹ to kọja ni ile igbimọ aṣofin kọwe lọ-gbe-ile-rẹ fun oṣu mẹta fun Sẹ́netọ̀ Omo-Agege, ṣugbọn o kopa ninu ipade awọn asofin ni Ọjọ Isẹgun ọsẹ yii.
Ileegbimọ aṣofin ti fi ẹsun kan an wipe ohun lo dari awọn janduku to yabo ile igbimọ asofin to si gbe ọpa asẹ ile lọ.
Lẹyin ijoko ile ni iroyin sọ wi pe ni awọn ọlọpaa fi panpẹ ọba mu Sẹnetọ Omo-Agege ti wọn si mu lọ sinu ọkọ to wa ni ita ile igbimọ asofin naa.
Koko iroyin: Ọ̀pá àṣẹ jíjígbé n'ílé aṣòfin, Igí wó pa akẹ́kọ̀ọ́ Nàìjíríà ni Cameroon
Eyi ni awọn akojọpọ iroyin ti toni.
Wàhálà ilé aṣòfin àgbà; Ọ̀pá àṣẹ jíjígbé kiìí ṣe tuntun
Oríṣun àwòrán, @SenateNG
Lásíkò tí ìjókòó ilé ń lọ lọ́wọ́, lawọn jàǹdùkùú ya wọnú ilé, tí wọn sì gbé ọ̀pá àsẹ ilé.
Awọn jàǹdùkú yabo ilé asòfin àgbà ní ìlú Àbújá, lásíkò tí ìjókòó ilé ń lọ lọ́wọ́, lawọn jàǹdùkùú yìí ya wọnú ilé, tí wọn sì gbé ọ̀pá àsẹ ilé.
Àtẹ̀jáde kan tí ilé asòfin àgbà ilẹ̀ fi síta lórí ìsẹ̀lẹ̀ náà sàlàyé pé àwọn jàǹdùkú kan yabo àwọn níbi jókòó ilé, tí asòfin kan tí wọ́n ti ní kó lọ rọọ́kún nílé ná, Ovie Omo-Agege sì ló kó sòdí, tí wọn sì gbé lọ
Ìsẹ̀lẹ̀ Cameroon: Igí wó pa akẹ́kọ̀ọ́ mẹ́ta ọmọ Nàìjíríà
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ọmọ ilé ìwé àádọ́ta àti olùkọ́ mẹ́fà ni o lọ sí ìrìn àjò ẹ̀kọ́ náà.
Igi ti wó pa àwọn akẹ́kọ̀ọ́ Naijiria mẹ́ta, ti mẹ́rìndínlógún si ṣèṣe lorílẹ̀èdè Cameroon nigbatí wọ́n kúro ní Nàìjíríà láti lọ wo àwọn ẹranko oríṣiríṣi lorileede Cameroon.
Alàkóso agbègbè náà wípé igi náà wo lu àwọn akẹ́kọ̀ọ́ náà lẹ́yin ìji líle.  E ka ekunrere re ni bii
Ẹlẹ́wọ̀n: Ẹ̀sùn ìbálòpọ̀ ọmọdé ló gbé dé mi dé ẹ̀wọ̀n
Ẹlẹ́wọ̀n: Ẹ̀sùn ìbálòpọ̀ ọmọdé ló gbé dé mi dé ẹ̀wọ̀n
Wàhálà ilé aṣòfin: Àwọn ọlọ́pàá ti rí ọ̀pá àṣẹ padà
Oríṣun àwòrán, NGR Senate
Àwọn ọlọ́pàá ti rí ọ̀pá àṣẹ ilé aṣòfin padà
Iléeṣẹ́ ọlọ́pàá lórílẹ̀èdè Nàìjíríà ti kéde rẹ̀ pé àwọn ti rí ọ̀pá àṣẹ ilé aṣòfin tí àwọn jàǹdùkú kan wọ ilé gbé lọ ní ọjọ́rú.
Àwọn jàǹdùkú náà gbé ọ̀pá àṣẹ ilé aṣòfin ọ̀hún jù sílẹ̀ lábẹ́ẹ afárá ọkọ̀  tó wà lẹ́nu ìloro ìlú Àbúja.
Nínú àtẹ̀jáde kan tó fi síta, iléeṣẹ́ ọlọ́pàá olú-ìlú orílẹ̀èdè Nàìjíríà, Àbúja ní kété tí ìṣẹ̀lẹ̀ náà ṣẹlẹ̀ ni ikọ̀ kògbérégbè  iléeṣẹ́ ọlọ́pàá kán lu agbami iṣẹ ́láti ṣàwárí ọ̀pá àṣẹ náà.
Ṣáájú rírí ọ̀pá àṣẹ ilé aṣòfin àgbà yìí ni àwọn ọlọ́pàá ti fi panpẹ́ òfin mú Sẹ́nétọ̀ Ovie Omo-Agege tí ọ̀pọ̀ funrasí pé òun ló wà nídìí ìṣẹ̀lẹ̀ náà sùgbọ́n wọ́n ti dá a sílẹ̀ padà. Lẹ́yìn èyí ni àwọn aṣòfin àgbà tí fún wọn ní gbèdéke ọjọ́ kan láti  wá ọ̀pá àṣẹ náà jáde.
Iléeṣẹ́ ọmọogun sáwọn olóṣèlú: Ẹ má t'ọwọ́ òṣèlú b'ọ̀rọ̀ ológun mọ́
Oríṣun àwòrán, Nigeria Army
Ọ̀pọ̀ nǹkan ìjà olóró ati afunrasí ni àwọn ọmọogun ti gbà
Iléeṣẹ́ ọmọogun Nàìjíríà ti ké sáwọn olóṣèlú láti yéé ti owọ́  òṣèlú bọ ọ̀rọ̀ àwọn ọmọ ogun mọ́.
Iléeṣẹ́ ọmọogun ní àwọn ọmọ ogun ń ṣe iṣẹ́ wọn bí iṣẹ́, ṣùgbọ́n adìyẹ rẹ̀ tóń làágùn, ìyẹ́ ara rẹ̀ ni kò jẹ́ kí a mọ̀.
Nínú ìfọ̀rọ̀wérọ̀ kan pẹ̀lú àwọn oníròyìn, ó ní, gẹ́gẹ́ bíi ara ìlàkàkà rẹ̀, àwọn jàǹdukú mẹ́tàlélọ́gọ́sán  ni ọwọ́ ti bà lábẹ́  ètò kògbéégbè operation AYEM AKPATUMA.
Oríṣun àwòrán, Nigeria Army
Ó ṣeéṣe kí ọ̀rọ̀ yìí níí ṣe pẹ̀lú ìpè tí àwọn aṣòfin pè fún ìyọkúrònípò àwọn aṣíwájú ẹ̀ka iléeṣẹ́ ológun
Mẹ́tàdínláàdọ́ta nínú wọn ló jẹ́ afunrasí darandaran Fúlàní,  mẹ́fà jẹ́ ẹlẹ́gbẹ́ òkûnkùn, máàrún jẹ́  ajẹ́rangbé tí mẹ́fà míràn sì jẹ́ agbébọn.
Bákannáà ni o tún ṣàlàyé rẹ̀ pé onírúurú ohun ìjà olóró ni ọwọ́ wọn tún bà.
Iléeṣẹ́ ọmọogun Nàìjíríà ní sísọ̀rọ ̀ òdì sí àwọn ọmọogun yóò domi tútù sí wọn lọ́kaàn ni, yóò sì ṣílẹ̀kùn sílẹ̀ gbayawu fún àwọn ọ̀tá láti   ṣe ọ̀pọ̀ ọṣẹ́ fún ètò àbò orílẹ̀èdè Nàíjíríà.
Ó ṣeéṣe kí ọ̀rọ̀ yìí níí ṣe pẹ̀lú ìpè tí àwọn aṣòfin pè fún ìyọkúrònípò àwọn aṣíwájú ẹ̀ka iléeṣẹ́ ológun gbogbo lórílẹ̀èdè Nàìjíríà nítorí gbọnmọgbọnmọ ìkọlù àti ìpànìyàn tó ń wáyé.
Olùkọ́ OAU: Ẹ̀sùn àdínkù ọjọ́ orí àti ìbéèrè ìbálòpọ̀ lọ́nà àìtọ́ ni wọ́n fi kàn-án
Oríṣun àwòrán, ICPC
Ohùn un ọ̀jọ̀gbọ́n Akindele tí o ń bèèrè fún ìbálòpọ̀ ìgbà márùn ún lọ́wọ́ akẹ́kọ́bìnrin kan bọ́ sójú agbami ayélujára
Àjọ ti o n gbogun ti iwa ibajẹ lorilẹede Naijiria, ICPC ti gbé olukọni fasiti ti wọn fẹsun kan pe o ṣe iduna-dura ibalopọ ati maaki pẹlu akẹẹkọbinrin kan ni fasiti Ọbafẹmi Awolọwọ nilu Ile-Ifẹ, lọ siwaju ile ẹjọ giga kan nilu Oṣogbo,
Nibayii, adajọ ti wa pasẹ pe ki Ọjọgbọn Richard Akindele lọ jọkòó si ọgba ẹ̀wọ̀n báyìí.
Yátọ si ẹ̀sún pe o beere ibalopọ lọwọ akẹkọọ rẹ, wọn tun fi ẹsun kan pe o ṣe magomago ọjọ ori rẹ.
World Toilet Day: Aráàlú ní woléwolé yẹ kó bẹ̀rẹ̀ àyẹ̀wò ojúlé dé ojúlé
Ajọ ICPC ni, ọjọ ori to fi silẹ ninu ọrọ rẹ yatọ si eyi to wa ninu paali rẹ ti wọn ri ni fasiti OAU.
Wọn ni nigba ti wọn fọrọ wa lẹnu wọ, o ni ọdun 1961 ni wọn bi oun, eyi to yatọ si 1959 to wa ninu iwe fasiti rẹ.
Ọjọgbọn Akindele fi oju ba ile ẹjọ ni ọjọ Aje, ọjọ Kọkandinlogun oṣu Kọkanla, lori ẹsun mẹrin to da lori lilo ipo rẹ gẹgẹ bii olukọni ni ẹka imọ nipa akoso ati iṣiro, lati beere fun ibalopọ lọwọ akẹkọ kan ki o lee gba ọna eru fun un ni maaki ninu ọkan lara awọn ẹkọ rẹ.
Akindele to wa sile ẹjọ pẹlu agbẹjọro meji ni, oun ko jẹbi awọn ẹsun naa.
'Oun tí Kunle Afolayan ṣe sí mi, mi ò lè ṣeé sí i'
Ọjọgbọn Richard Iyiola Akindele ni okiki rẹ kan loṣu kẹrin ọdun 2018 pe, o n beere ibalopọ igba marun un ọtọọtọ lọwọ akẹkọbinrin kan, Monica Osagie, ki o to lee yii esi idanwo rẹ kuro ninu awọn to fidirẹmi bọ si awọn to pegede.
Ajọ ICPC ni iwa ti o hu yii tako abala kẹjọ ofin iwa ibajẹ lorilẹede Naijiria ti o si ni ijiya ti o tọ.
Ọjọgbọn Akindele ti beere fun eto ajọro bun mi-n-bun ọ ti oloyinbo n pe ni 'plea bargaining' lẹyin ti o ti gba pe oun jẹbi ẹsun naa.
Bakan naa lo tun tọka si ilera rẹ to ni ko ṣe deede gẹgẹ bii ara oun ti ko ni lee mu oun lagbara ati duro igbe aye ọgba ẹwọn.
O rọ ajọ naa lati boju wo ẹbẹ rẹ fun ajọro bun mi-n-bun ọ niwọn igba ti oun ti bẹrẹ ijiya lori ẹṣẹ naa lẹyin ti awọn alaṣẹ fasiti naa ti yọọ ni iṣẹ.
Oríṣun àwòrán, @OfficialOAU
Ohùn un ọ̀jọ̀gbọ́n Akindele tí o ń bèèrè fún ìbálòpọ̀ ìgbà lọ́wọ́ akẹ́kọ́bìnrin kan bọ́ sójú agbami ayélujára lọ́sẹ̀ tó kọja
Àwọn aláṣẹ fásitì Ọbáfẹ́mi Awólọ́wọ̀, OAU nílu ilé ifẹ̀ ti pàṣẹ lọ rọọ́kún nílé fún ọ̀jọ̀gbọ́n Richard Akindele tí ẹ̀ka ìmọ̀ nípa ìṣirò owó tí wọ́n ní, o ń bèèrè fún ìbálòpọ̀ ìgbà máàrún ọ̀tọ̀ọ̀tọ̀ nítoríi máàkì.
Olùkọ́ náà n bèrè fún ìbálòpọ̀ lọ́wọ́ ọ̀kan lára àwọn akẹ́kọ́bìnrin tó fìdírẹmi nínú ìmọ̀ ẹ̀kọ́ fún ìkẹ́kọ̀ọ́-gboyè ìmọ̀ ìjìnlẹ̀ kejì nínú ìṣàkóso okòòwò.Àṣẹ yìí wáyé lẹ́yìn tí ìgbìmọ̀ olùwádìí tí wọ́n gbe kalẹ̀ lórí ẹ̀sùn aṣemáṣe tó rọ̀ mọ́ ìbáṣepọ̀ tí kò tọ̀nà, èyí tí wọ́n fi kan àgbà ọ̀jọ̀gbọ́n Richard Akíndélé ní fásitì ọ̀hún.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí:
Àwọn aláṣẹ fásitì Ọbáfẹ́mi Awólọ́wọ̀, ní àbájáde ìwádìí ìgbìmọ̀ náà ti fìdí rẹ̀ múlẹ̀ wípé lóòótọ́ ni ọwọ́ ọ̀jọ̀gbọ́n Akíndélé kò mọ́ lórí ẹ̀sùn yii.
Alukoro fásitì náà, ọ̀gbẹ́ni Abíọ́dún Ọláńrewájú ṣàlàyé nínú ìfọ̀rọ̀wérọ̀ rẹ̀ pẹ̀lú BBC Yorùbá pé àwọn méjèèjì yìí ní wọn pè síwájú ìgbìmọ̀ ọ̀hún ṣùgbọ́n arábìnrin tọ́rọ̀ kàn nínú fọ́nràn náà ko farahàn.
Ìgbìmọ̀ yìí sàlàyé nínú àbájáde ìwádìí rẹ̀ pé ìwádìí fìdí rẹ̀ múlẹ̀ pé lóòótọ́ ni ọ̀jọ̀gbọ́n Akíndélé jẹ̀bi  ẹ̀sùn aṣemáṣe tí kò tọ̀nà tí wọ́n fi kàn án.Lẹyìn tí gíwá fásitì yìí sì ti yẹ ọ̀rọ̀ náà wò tó sì fìdí rẹ̀ múlẹ̀ pé ó jẹ̀bi, ó ti pàṣẹ kí ọ̀jọ̀gbọ́n Akíndélé ó lọ rọọ́kún nílé dìgbà tí wọ́n yóò parí ẹ̀kúnrẹ́rẹ́ ìwádìí.Bákanáà ló ní Monica Usetobe Osagie ni orúkọ akẹ́kọ́́bìnrin tí ohùn rẹ̀ hàn nínú ìtàkùrọ̀sọ tó wáyé nínú ohùn tí wọ́n ká sílẹ̀ náà.
Àkókò tó láti gbẹ̀san lára ẹ̀fọ̀n mùjẹ̀mùjẹ̀
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Àwọn eleyinju àánú ń gbèrò láti ṣe àgbékalẹ̀ dollar bilionu mẹta lé díẹ̀
Ọ̀nà àbáyọ tuntun láti gbẹ̀san lára ẹ̀fọn mujemuje tí yọjú.
Àwọn àṣẹwádìí ọmọ orílẹ̀èdè Kenya pẹ̀lú àwọn kan láti ilé ẹ̀kọ́ fún ìsègùn ní ìlú Liverpool lórí àìsàn ibà tí ṣàwárí oògùn tí ó jẹ́ májèlé fáwọn ẹ̀fon tí wọ́n bá ti fẹnu kan ẹ̀jẹ̀ ènìyàn.
Ọ̀jọ̀gbọ́n Olugbenga Mokuolu  to jẹ́ onimo nipa aisan iba ati ọ̀nà láti kojú rẹ̀ wípé májèlé ni ẹ̀jẹ̀ ènìyàn tó bá ti lo ògùn Ivermectin yóò jẹ́ fáwọn yàmùyámú.
Ọ̀nà àbáyọ de láti gbẹ̀san lára Ẹ̀fọ̀n mùjẹ̀mùjẹ̀
Àbẹ̀wò ikọ̀ BBC sì láàbù àwọn àṣèwádìí ọ̀hún ní ìwọ̀-oòrùn Kenya fi hàn pé ẹnití o ba ti lo òògùn Ivermectin, ẹ̀jẹ̀ wọn yóò jẹ májelè fáwọn ẹfon, èyí pẹ̀lú yóò jẹ́ ìrànwọ́ láti jẹ́ kí ẹ̀fọn má máa tàn kalẹ mọ́.
Ìrètí wà pé leyin ti ìwádìí bá kẹ́sẹ járí àìsàn ibà yoo di oun ìgbàgbé lágbaye. Èyí jẹ́ ọ̀nà làti mú ààrùn kúrò, nítorí náà, ó kú ẹ̀fọn nìkan tí kò sì lágbára mọ́ láti fi àìsàn sáwọn ènìyàn lára
Tẹ o bá gbàgbé ọmọ ọba Charles àti àwọn ẹlẹ́yinjú àánú yóò pàdé níbi àjọ Commonwealth láti ṣe àgbélakẹ̀ bílíọ̀nù mẹta lé ọwọ mejo dollar láti ṣe ìwádìí sì ọ̀nà àbáyọ lórí ààrùn ibà.
Ìpínlẹ̀ Kaduna tún ti dá olùkọ́ 4,562 tuntun dúró
Oríṣun àwòrán, Twitter
Gómínà Nasir El-Rufai dá ogunlọ́gọ́ àwọn olùkọ́ ìpínlẹ̀ náà dúro l'ọdún tó kọjá
Ìjọba Ìpínlẹ̀ Kaduna tún ti dá àwọn olùkọ́ ẹgbẹ̀rún mẹ́rin àti ọ̀tàlélẹ́ẹ̀dẹ́gbẹ̀ta lé méjì (4,562) dúró nínú àwọn ti wọ́n ṣẹ̀ṣẹ̀ gbà lẹ́hìn tí wọ́n ní kí olùkọ́ ẹgbẹ̀rún méjìlẹ́lógún (22,000) lọ rọ́kún nílé ní bíi oṣù márùń sẹ́hìn.
Àìpẹ́ yìí ni ìjọba ìpínlẹ̀ náà fún wọn ní ìwé iṣẹ́, ṣùgbọ́n Kọmíṣọ́nà fún ètò Ẹ̀kọ́ ní Ìpínlẹ̀ Kaduna, Ja'afaru Sani, sọ wípé wọ́n pinu láti lé wọn lọ nítorí wípe ọ́gbọ́n àlùmọ̀kọ́rọ́yí ni wọ́n gbà wọlé.
Sani sọ wípé àjọ tí ó ńṣe àkóso ẹ̀kọ́ alákọ́bẹ̀rẹ̀ kọ́kọ́ gba àwọn olùkọ́ tí ó fẹ́ẹ̀ tó ẹgbàájọ sùgbọ́n nígbà tí wọ́n ṣe àwárí nípa ọ̀pọ̀lọ́pọ́ wọn, wọ́n ri wípé wọ́n rá pálá wọlé ni.
Ẹ ó rántí pé àríyànjiyàn bẹ́ sílẹ̀ ní ọdún tó kọjá nígbà tí Gómínà Nasir El-Rufai  dá ogunlọ́gọ́ àwọn olùkọ́ ìpínlẹ̀ náà dúro látàri wípé wọn kò mọ iṣẹ́ to, tí wọ́n sì fìdí rẹmi nínú ìdánwò tí ó yẹ kí ọmọ ilé ẹ̀kọ́ apá kẹrin lè mọ̀.
Sani sọ fún àwọn oníròyin ní Kaduna lọ́jọ́rú ọ̀sẹ̀ pé ọ̀pọ̀lọ́pọ́ àwọn tí wọ́n ṣẹ̀ṣẹ̀ lé dànù náà ni wọ́n kàwé gboyè gíga.
Nípínlẹ̀ Ògùn, Ọ̀gá ọlọpàá yìnbọn jẹ
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Àwọn ìdílé olóògbé náà kò mọ ìdí tí olóògbé Agholor fi gbé ìgbésè náà
Ọ̀gá ọlọpàá kan tó ti fẹ̀yìntì tí orúkọ rẹ ń jẹ́ David Agholor, ti gb'ẹ̀mí ara rẹ̀ ní Ìjokò ní ìpínlẹ̀ Ògùn.
Agbenusọ ilé iṣẹ́ ọlọ́pàá ní ìpínlẹ̀ náà, Abímbọ́lá Oyèyẹmí, sọ fún BBC wípé ọmọ olóògbé Agholor ló fi tó àwọn ọlọ́pàá létí wí pé bàbá òun ti yìn'bọn pa ara rẹ̀ lẹ́yìn tí ó jí tí ó sì wẹ̀ ni ọjọ́ Ọjọ́bọ ní ilé rẹ̀ tó wà lágbègbè Sheraton Estate tí ó wà ní Ìjokò.
"Oyèyẹmí sọ wípé, ""Olóògbé tí ó gbẹ̀mí ara rẹ̀ náà jẹ́ ọ̀gá fún àwọn ọlọpàá pàtàki tí ó ńkọjú ìjà sí àwọn ọlọ́ṣà ní ìpínlẹ̀ Enugu nígbà kan rí. Sùgbọ́n ó ti fẹ̀hìntì. Àwọn oluwádìí láti ilé iṣé ọlọ́pàá ti lọ sí ibi tí ìsẹ̀lẹ̀ náà ti ṣẹlẹ̀ láti lo ya àworán ibẹ."""
A gbọ́ wípé àwọn ará ilé olóògbẹ́ náà funra pé ìkan kò ṣe déédé pẹ̀lú rẹ̀ l'Ọjọ́rú, ṣùgbọ́n ó fi yé wọn wípé kò sí wàhálà rárá.
Ní ọjọ́ kejì, wọ́n sọ wípé bí ó ṣe jí, tí ó wẹ̀ tán ni kó gbogbo kọ́kọ́rọ́ ilé lé ọmọ rè obinrín lọ́wọ́. Àwọn ará ile rẹ̀ sọ wípé lọ bí ó ṣe lọ sí ẹ̀hìnkùle ni wọ́n gbọ́ ìró ìbọn.
Koko iroyin: Awuyewuye Buhari bu awọn ọdọ, Ìpade Commonwealth
Eyi ni awọn akojọpọ iroyin ti toni.
Iléeṣẹ́ ààrẹ: Buhari kò bú ọdọ, àwọn ọ̀bàyéjẹ́ ń pa irọ́
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Iléeṣẹ́ ààrẹ ní ojúṣe ìjọba ni láti pèsè àyè tó tọ̀nà sílẹ̀ fún olúkúlùkù láti mú àlá rere wọn ṣẹ.
Lori ọrọ kan ti o n ja rayin-rayin ti wọn ni aarẹ Buhari sọ nilu London pe ọkundun ti ko fẹ iṣẹ ṣe lawọn ọdọ Naijiria, ileese aarẹ orilẹede Naijiria ti sọ pe, ọrọ ko ri bẹẹ; atipe awọn ọbayejẹ ẹda kan lo fẹ ti ibi ohùn mu aarẹ.
Iroyin sọ pe ilu Lọndon ni A awọn olori orilẹede to wa labẹ ajọ Commonwealth.
Nípínlẹ̀ Ògùn, Ọ̀gá ọlọpàá yìnbọn jẹ
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Àwọn ìdílé olóògbé náà kò mọ ìdí tí olóògbé Agholor fi gbé ìgbésè náà
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ààrẹ Buhari ní awọn eeyan Naijiria gbọdọ di opo iwa ootọ mu ki wọn si gbe igbe aye to duro daadaa
Ọ̀gá ọlọpàá kan tó ti fẹ̀yìntì tí orúkọ rẹ ń jẹ́ David Agholor, ti gb'ẹ̀mí ara rẹ̀ ní Ìjokò ní ìpínlẹ̀ Ògùn.
Agbenusọ ilé iṣẹ́ ọlọ́pàá ní ìpínlẹ̀ náà, Abímbọ́lá Oyèyẹmí, sọ fún BBC wípé ọmọ olóògbé Agholor ló fi tó àwọn ọlọ́pàá létí wí pé bàbá òun ti yìn'bọn pa ara rẹ̀ lẹ́yìn tí ó jí tí ó sì wẹ̀ ni ọjọ́ Ọjọ́bọ ní ilé rẹ̀ tó wà lágbègbè Sheraton Estate tí ó wà ní Ìjokò. E ka ekunrere re ni bii
Àgbà ọ̀jẹ̀ olósèlú tó tún jẹ́ gbajúgbajà ọmọ Yorùbá ni Obáfẹ́mi Awólọ̀wọ́ nígbà ayé rẹ̀.
Igbe àyé Ọbáfẹ́mi Awólọ̀wọ́ nigba aye rẹ̀
Arsene Wenger njọ̀wọ́ ìdarí Arsenal
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Wenger ti lo ọdún mọ́kànlélógún gẹ́gẹ́bíi adarí Arsenal
Arsene Wenger tí ó jẹ́ akọ́nimọ̀ọ́gbá ẹgbé agbábọ́ọ̀lú Arsenal yóò fi àlèéfà sílẹ̀ lẹ́hìn sáà yí.
Wenger tí ó ti lo ọdún mọ́kànlélógún gẹ́gẹ́bí adarí Arsenal nlọ 'lé bí ó tilẹ̀ jẹ́ pẹ́ ó ṣì níi ọdún kan tí àdéhùn iṣé  rẹ̀ yóò parí.
Olukọ̀ni fún ikọ̀ Arsenal náà tí ó jẹ́ ọmọ ọdún méjìdínláàdọ́rin ni òun dúpẹ́ fún iye ọdún to ti lò gẹ́gẹ́bíi olùdari Arsenal.
Kíni àwọn olólùfẹ́Arsenal rí sọ síèyí?
Awọn ilumọ̀ọ́ká ti wọn ba BBC Yoruba sọrọ fi ohun dá meji lori ọrọ naa ni.
ninu ọ̀rọ̀ rẹ̀, Gbenga Adeyinka to jẹ gbajugbaja adẹrinpoṣonu lorilẹ̀ede Naijiria ni lilọ Arsene Wenger kọ̀ ni opin iṣoro ikọ Arsenal nitori, ni iwoye tirẹ, 'Wenger kọ ni i'soro Arsenal.'
Ọrọ gbenga Adeyinka lori Wenger to fẹ fipo silẹ
Bakannaa, ilumọ̀ọ̀ka akọ̀rin takasufe ni, Sound Sultan ṣalaye pe ifẹyinti Arsenal yoo fun ẹgbẹ̀ agbabọ̀ọ̀lu Arsenal lanfani ati yẹ ọ̀na ayò miran wo.
Ọrọ Sound Sultan lori Wenger to fẹ fipo silẹ
Bẹẹ gẹgẹ pẹlu lo fẹẹ̀ jẹ wi pe  ero awọn ololufẹ ikọ naa kaakiri agbaye ko yatọ si ipa meji yii.
G'ẹ́gẹ́bí olùdarí Arsenal, Wenger mú oríṣiríṣi àrínyànjiyàn wá láàrín àwọn olólùfẹ́ ẹgbẹ́ agbábọ́ọ̀lù náà. Púpọ̀ nínú wọn ni ó ti ń gbógun wípé kí ó máa lọ'lé.
Ogunlọ́gọ̀ àwọn tí ó ńwo eré bọ́ọ̀lù ní Nàìjíríà ni wọ́n ti ńfi èrò ọkàn wọn hàn l'órí ọ̀rọ̀ yí ní orí Twitter.
AfricanDrumFestival: Àwọn àwòrán tó làmìlaaka níbi ayẹyẹ
Awọn aworan to lamilaaka nibi ayẹyẹ ajọ̀dún ìlù nílú Abẹ́òkúta.
Aarẹ Muhammadu Buhari ṣe ileri atilẹyin fun idagbasoke aṣa
Ọna abawọle si ori oke olumọ
Oríṣun àwòrán, AfricanDrumFestival
Kani a mọ pataki idagbasoke aṣa si idagbasoke eto ọrọ aje wa, a o tẹpa mọ
Oríṣun àwòrán, AfricanDrumFestival
Ó lé ní ogún ìpínlẹ̀ tí yóò kópa níbi ayẹyẹ àjọ̀dùn ìlù nílẹ̀ Áfíríkà náà
Oríṣun àwòrán, AFRICAN DRUM FESTIVAL
Ijọba ipinlẹ Ogun lo n ṣe agbatẹru ajọdun ilu ilẹ Afirika
Oríṣun àwòrán, AfricanDrumFestival
Awọn ọbalaye kan sara si awọn agbaṣaga
Oríṣun àwòrán, AfricanDrumFestival
Àgba awọn to wa nipo aṣẹ lẹka iṣejọba gbogbo niyanju lati rii wei pe wọn n ṣe koriya fun igbedide aṣa ilẹ Yoruba.
Oríṣun àwòrán, AfricanDrumFestival
Ọkan ojọkan awọn gbajugbaja olosere ni wọn yoo kopa nibi ajọdun naa
Agba osere Nollywood ko gbẹyin nibi ayẹyẹ naa
Awọn onidan naa se bi ọkunrin nibi ayẹyẹ ilu
Awọn aworan yii wa lati ọwọ: BBC ati AfricanDrumFestival
Koko iroyin: Ọdún ìlù l’Abẹ́òkúta, PDP fẹ́ darapọ̀ mọ́ ẹgbẹ́ míì
Eyi ni awọn akojọpọ iroyin ti toni.
AfricanDrumFestival: Àwọn àwòrán tó làmìlaaka níbi ayẹyẹ.
Oríṣun àwòrán, AfricanDrumFestival
Kani a mọ pataki idagbasoke aṣa si idagbasoke eto ọrọ aje wa, a o tẹpa mọ
Aarẹ Muhammadu Buhari ṣe ileri atilẹyin fun idagbasoke aṣa
Ayẹyẹ àjọ̀dùn ìlù nílẹ̀ Áfíríkà to bẹ̀rẹ̀ nílú Abẹ́òkúta ni wọn ti maa n ṣe afihan ọkan o jọkan ilu iṣẹmbaye ati aṣa ilẹ Yoruba ati gbogbo Afirika.
Ninu ọrọ ti wọn sọ nibẹ, awọn eekan ọbalaye meji nilẹ Yoruba, Ọọni ile Ifẹ, Ọba Adeyẹye Ogunwusi Ọjaja II ati Alaafin ti ilu Ọyọ, Ọba Lamidi Adeyemi III gba awọn to wa nipo aṣẹ lẹka iṣejọba gbogbo niyanju lati rii wi pe wọn n ṣe koriya fun igbedide aṣa ilẹ Yoruba.
Ẹgbẹ́ òsèlú PDP ńgbèrò láti dà pọ̀ mọ́ àwọ́n ẹgbẹ́ míì
Oríṣun àwòrán, Kola Ologbondiyan/Facebook
Ẹgbẹ́ òsèlú PDP ńgbèrò láti dà pọ̀ mọ́ àwọ́n ẹgbẹ́ míì
Ẹgbẹ́ òsèlú Peoples Democratic Party ńgbèrò láti yí orúkọ́ wọn padà kó tó di ìgbà ìdìbò gbogbogbò ti ọdún 2019.
Ìfọ̀rọ̀wánilẹ́nuwo ilé isẹ́ BBC pẹ̀lú akọ̀wé ẹgbẹ́ òsèlú PDP, Ọ̀gbẹ́ni Kola Ologbondiyan jẹ́ kó di mímọ̀ pé ẹgbẹ́ òsèlú PDP kàn fẹ́ dàra pọ̀ mọ̀ àwọn ẹgbẹ́ míì fún ìdìbò ọdún 2019. E ka ekunrere re ni bii
Ẹlẹ́wọ̀n kan gba máákì 248 nínú ìdánwò Jamb ní ọgbà ẹ̀wọ̀n Ìkòyí ní ìlú Èkó.
Ẹlẹ́wọ̀n: Ẹ̀sùn ìbálòpọ̀ ọmọdé ló gbé dé mi dé ẹ̀wọ̀n
Àìsàn dá Ààrẹ àná ni Zimbabwe, Robert Mugabe, dùbúlẹ̀
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ara Robert Mugabe ti di ara agba ti pẹ ṣugbọn o kọ lati fi ijọba silẹ
Igba kan ko lọ bi orere. Aarẹ ana lorileede Zimbabwe Robert Mugabe ko le rin mọ.
Aarẹ Emmerson Munagagwa to gba ijọba lọwọ rẹ lo tu keke ọrọ yi nibi iwode oselu kan lagbegbe Murombedzi.
Munagagwa ni o ti to oṣu meji ti Mugabe ti n gba itoju fun ailera ni orileede Singapore ti ko si le rin mọ latari aarẹ naa.
O ti pe ọdun kan ti wọn ni ki Mugabe fi ipo silẹ nitori ailera rẹ.
Munagagwa ko sọ pato iru aarẹ to n ba Mugabe finra sugbọn o ni Aarẹ ana naa ranṣẹ si oun pe ara ohun ti n balẹ ati wi pe ko ni pẹ ti ohun yoo fi pada wale.
Lọwọ ipari ijọba Mugabe, awọn eeyan bẹnu atẹ lu wi pe o ti n lo si ilu okere pupọ ju fun itọju ara rẹ.
Ọmọ ọdun mẹ́tàléláàdọ́rùn ún ni Robert Mugabe nigba ti o fi fi ipo silẹ.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Mnangagwa ni o tu keke ọrọ aarẹ Mugabe silẹ
Lai pẹ yi ni  Ilé ìgbìmọ̀ asòfin orílẹ̀èdè Zimbabwe pe ààrẹ̀ àná, Robert Mugabe láti wá fi àrídájú hàn nípa ohun tí ó sọ lórí jíjí òkúta iyebiye.
Ọ̀gbẹ́ni Mugabe nínú ìfọ̀rọ̀wánilẹ́nuwò kan lórí ẹ̀rọ móhùnmáwòrán ti ìpínlẹ̀ kan fi ẹ̀sùn lílo àlùmọ̀kọ́rọ́yí fi jalè kan ilé isẹ́ tó ńrísí ọ̀rọ̀ ilẹ̀ òkèèrè.
Oríṣun àwòrán, JEKESAI NJIKIZANA/GETTY IMAGES
"Ó ní ""àwọn ilé isẹ́ náà ti kó wa lọ́rọ̀ lọ, àpò ìsúná kàn ti ri owó díẹ̀ ǹka bíi bílíọ̀nù mẹ̀ẹ́dógún dollar tí wọ́n ti ní"
Kò tíì hàn yékéyéké bóyá Robert Mugabe ẹni ọdún mẹ́rinléláàdọ́rùún náà yóò fara hàn níwájú ilé asòfin Zimbabwe
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí:
Àtíkù: Irọ́ ni pé mo fi $1,000,000 fẹ́‘yàwó tuntun
Oríṣun àwòrán, @AtikuOrg
Àtíkù ní òun kò fẹ́ ìyàwó tuntun
Igbákejì ààrẹ tẹ́lẹ̀ ní Nàíjíríà, tó tún jẹ́ olùdíje fún ipò ààrẹ, Àtíkù Abubakar, ti tako fídíò kan tí wọn ń pín kiri lórí ìtàkùn àgbáyé pe, òun fi mílíọ́nù kan dọ́là fẹ́ aya tuntun ní ìlú Dubai.
Àtíkù ní òfo, ọjọ́ kejì ọjà ni ìròyìn náà, tó sì jìnnnà sí òtítọ́.
Àtẹ̀jáde kan tí iléesẹ́ ìròyìn Àtíkù Abubakar fisíta lójú òpó Twitter rẹ̀ ní, àgbẹ́lẹ̀rọ lásán ni ìròyìn náà.
Oríṣun àwòrán, @AtikuOrg
Àtíkù wà níbi ìgbeyàwó Anthony Chuka-Douglas àti Whitney Erin Woods
O ní, Àtíkù Abubakar, àwọn mọ̀lẹ́bí, ọ̀rẹ́ àti Obi tìlú Onitsha, ni wọ́n dìjọ báwọn péjú sí ibi ayẹyẹ ìgbeyàwó Anthony Chuka-Douglas àti Whitney Erin Woods, níbití tí àwòrán náà ti jẹyọ.
Sùgbọ́n fídíò náà ló ti ń fa awuyewuye lórí àwọn òpó ìkànsíraẹni lórí ìtàkùn àgbáyé, tí ọ̀pọ̀ ọmọ Nàíjíríà sì ń yọ sùtì ètè sí igbákejì ààrẹ tẹ́lẹ̀ náà.
Oríṣun àwòrán, 'atikuorg
Àtíkù Abubakar àti Obi tìlú Onitsha ni wọ́n dìjọ báwọn péjú sí ibi ayẹyẹ ìgbeyàwó náà
Àwọn ọmọ Nàíjíríà: Bí Wenger se ń lọ, ni Bùhárí yóò lọ
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Buhari yóò kọ́gbọ́n lára Wenger
Ojú òpó ìkànsíraẹni Twitter ti kún nípa àwọn ọmọ Nàíjíríà tó ń fi bí Arsene Wenger se fẹ́ lọ wé bí Muhammadu Buhari yóò se lọ.
Ọ̀pọ̀ èèyàn tó sọ̀rọ̀ lórí bí Arsene Wenger se ń gbèrò láti yẹ̀bá gẹ́gẹ́ bíi olùkọ́ni fún ẹgbẹ́ agbábọ́ọ́lù Arsenal ní ìparí sáà ìdíje líígì yìí, ní ẹni ọdún méjìdínláàdọ́rin, ni ọ̀pọ̀ ọmọ Nàíjíríà ti gbé sí ẹ̀gbẹ́ ààrẹ Nàíjíríà, Muhammadu Buhari, tó ti pé ọdún mẹ́tàdínlọ́gọ́rin, tí wọ́n ló sì tún ń gbèrò láti gbé igbá ìbò ní ẹ̀ẹ̀kejì.
"Bolanle Victoria @bolaNLee_c ní bí Arsene Wenger se ń yẹ̀bá lẹ́ni ọdún méjìdínláàdọ́rin, tí Bùhárí tó jẹ́ ẹni ọdún mẹ́tàdínlọ́gọ́rin sì fẹ́ gbé igbá ìbò ní lẹ̀ẹ̀kejì, a jẹ́ pé lóòtọ́ làwọn ọmọ Nàíjíríà ya ọ̀lẹ. O wá ń bèèrè pé ""sé Aso Rock jẹ́ ilé ìfẹ̀yìntì ni?'"
"Dare Sunday @Letsmile ní, ""ogún rere tí Wenger ń fi sílẹ̀ ni ọ̀pọ̀ ọ̀dọ́ tí Wenger nígbàgbọ̀ nínú wọn, tó sì mú ìdàgbàsókè báwọn, tó sọ wọ́n di ògo bọ́ọ́lù, bóyá Buhari yóò kọ́gbọ́n lára Wenger."""
Fanklin Eze @frankdoma ń tiẹ̀ gbàdúrà pé Buhari yóò tẹ̀lé ipa ọ̀wọ̀, kó sì kọ̀wé fi isẹ́ sílẹ̀ bíi Wenger.
"Linux @odolinus ní ""tó bá jẹ́ pé Wenger setán láti kúrò lójú agbo lásìkò tí wọn ń yìn ín ni, Buhari náà leè kúrò tọ̀wọ̀tọ̀wọ̀, kó sì di àgba ìlú, dípò kó máa retí ó fìdí rẹmi bíi Wenger."""
Díẹ̀ nínú èrò àwọn ọmọ Nàíjíríà náà rèé
Òbí ọmọ Chibok kú nínú ìjàmbá ọkọ̀
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Awọn ọmọdébìrin yìí ti wà ní àhámọ́ Boko Haram fún ọjọ́ pípẹ́.
Ọkan lára àwọn òbí awọn ọmọ ti ikọ̀ Boko Haram jí gbé ni Chibok ló ti jáláisí nínú ìjàmbá ọkọ̀ kan to wáyé lọ́jọ́ ìsinmi.
Ìjàmbá ọkọ̀ ọ̀ún ni a gbọ́ pé ó wáyé nígbà ti awọn obi náà fẹ́ lọ yọjú sí awọn ọmọ wọn tí wọ́n dá sílẹ̀ ní àhámọ́ Boko Haram tí wọ́n wà ní ile ẹ̀kọ́ gíga ti ilẹ̀ Amerika to wà ní Yola.
Ní ìlú Chibok ni awọn òbí awọn ọmọ òuń ti gbéra lati lọ sí ìlú Yola lọ yọjú sí àwọn ọmọ wọn.
Lágbede méjì ojú ọ̀nà ni ìròyìn sọ pe ọ̀kan lára àwọn awakọ̀ to wa ọkọ̀ oun lọ forísọ ọkọ̀ àjàgbé kan ti wọ́n fi ń sisẹ́ ojú ọ̀nà.
Soyinka: Mo mọ ibití màá dìbò mi sí
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Sóyínká ní òun mọ ibití òun yóò di ìbò òun sí.
Ìlúmọ̀ọ́ká alámì ẹ̀yẹ òǹkọ̀wé nnì, Ọ̀jọ̀gbọ́n Wọlé Sóyínka, ti késí àwọn ọmọ Nàíjíríà láti máa fojú sọ́rí, kí wọn má sì jẹ́ káwọn èèyàn tó ba ilẹ̀ yìí jẹ́, máa gbé wọn mọ́ra, nítorí bí wọn se ń fi ara wọn hàn báyìí gẹ́gẹ́ bíi Olùgbàlà.
Sóyínká gbé ìmọ̀ràn yìí kalẹ̀ lọ́jọ́ àìkú pẹ̀lú gbajúgbajà agbẹjọ́rò àti akétantan kí ọlọ́rọ̀ gbọ́ nnì, Fẹ́mi Fálànà, ní ibi ìdánilẹ́kọ̀ọ́ kan tí wọn fi sọrí ọgọ́rin ọdún tí wọn bí ìlúmọ̀ọ́ká ajàfẹ́tọ̀ọ́ ẹni àti àgbà amòfin nnì, olóògbé Gani Fáwẹ̀hìnmi.
'Aragbe laye'
Sóyínká ní òun ti ní èrò tòun nípa ẹgbẹ́ òsèlú APC tó ń sèjọba lọ́wọ́, tóun sì mọ ibití òun yóò di ìbò òun sí.
Ẹ máse gbàgbé àwọn ìsẹ̀lẹ̀ àti ìwà ibi táwọn olósèlú kan ti hù látẹ̀yìn wàá, sùgbọ́n ń se ni kẹ́ẹ padà lọ rántí àkọsílẹ̀ àwọn ògbólógbòó olósèlú yìí àti ẹgbẹ́ tí wọn ń kó, nítorí ohun táa bá se lónìí, ọ̀rọ̀ ìtaàn ni yóò dà bó dọ̀la.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Èèyàn kan fi ọdún mọ́kànlá àti ààbọ̀ sèjọba láì ní àseyọrí
Bàkan náà ni Fálànà sọ pé orílẹ̀èdè Nàíjíríà ń kojú ìsòro ìsèjọba tó lágbára, tó sì késí àwọn ọmọ orílẹ̀èdè yìí láti máa fojú sọ́rí bíi alákàn, kí wọn má baà gba àwọn èèyàn tó ti ba orílẹ̀èdè yìí jẹ́ tẹ́lẹ̀, láti máa padà yọjú bíi Olùgbàlà wa.
Èèyàn kan fi ọdún mọ́kànlá àti ààbọ̀ sèjọba láì ní àseyọrí
Ẹnìkan wà tó ń gbé ibi tó súnmọ́ ibí yìí, tó ń fi ara rẹ̀ hàn gẹ́gẹ́ bíi Olùgbàlà àwọn ọmọ Nàíjíríà. Ọdún mẹ́ta àti ààbọ̀ ló fi darí Nàíjíríà gẹ́gẹ́ bíi ológun, tó sì tún lo ọdún mẹ́jọ gẹ́gẹ́ bíi ààrẹ alágbádá, tí àpapọ̀ iye ọdún tó fi tu ọkọ̀ Nàíjíríà jẹ́ ọdún mọ́kànlá àti ààbọ̀. Kódà, ó fẹ́ se sáà kẹta lórí oyè, a kò gbà fun ni. Ó tún ti wá ń lọ báyìí, tó sì ń polongo pé òun ní ojútùú sí ìsòro Nàíjíríà. Ó dùn mìí pé kò sí níbí. N kò bá bíí pé kó sọ ohun kan soso tó se fún Nàíjíríà.
Sẹ́nẹ́tọ̀ Shehu Sanni naa ké sáwọn ọmọ Nàíjíríà láti máse fi ẹgbẹ́ òsèlú dìbò àmọ́ kí wọn dìbò wọn fún ẹnìkọ̀ọ̀kan tí wọn ní ìgbẹkẹ̀lé nínú rẹ̀.
PDP: Kínni Bùhárí mú ti Commonwealth bọ̀?
Oríṣun àwòrán, Getty Images
PDP ní èyí kò sẹ̀yìn bí ààrẹ́ Nàíjíríà náà se ń sọ ọ́rọ́ òdì sáwọn ọmọ Nàíjíríà lára
Ẹgbẹ́ òsèlú alátakò ní Nàíjíríà, PDP, ti ń fi ìka hánu pé òfo, ọjọ́ kejì ọjà, ni bí ààrẹ Muhammadu Bùhárí se báwọn péjú sí ìpàdé àwọn olórí orílẹ̀èdè tó wà nínú àjọ Commonwealth, èyí tó wáyé ní ìlú ọba, United Kingdom.
Alukoro fún ẹgbẹ́ òsèlú PDP, Kọ́lá Ọlọ́gbọ́ndiyàn, nínú àtẹ̀jáde kan tó fisíta ní ìlú Àbújá ní, ẹnu kò ya àwọn rárá pé bí Bùhárí ti lọ, náà ló padà bọ̀, láì kó èrè kankan wálé.
Kola Ologbodiyan: Jẹgudu jẹra ni ijọba APC
Ó ní, èyí kò sẹ̀yìn bí ààrẹ́ Nàíjíríà náà se ń sọ ọ́rọ́ òdì sáwọn ọmọ Nàíjíríà lára, tó sì tún pàtẹ irọ́ gẹ́gẹ́ bíi àwọn àseyọrí rẹ̀ fáwọn èèyàn tó gbàá ní àlejò.
Ọlọ́gbọ́ndiyàn ní, nígbà táwọn olórí orílẹ̀èdè míì nínú àjọ Commonwealth lo ànfààní àkókò náà láti se àfihàn ọ̀pọ̀ ànfààní tó wà ní orílẹ̀èdè wọn, ń se ni ààrẹ tiwa yege láti máse ìpolongo ànfààní ọrọ̀ ajé tó wà ní  orílẹ̀èdè yìí, àmọ́ tó ń tàbùkù àwọn ọ̀mọ̀ orílẹ̀èdè yìí, pàápàá àwọn ọ̀dọ́
Dino Melaye: Pápákọ̀ òfurufú ni Ọlọ́pàá ti mú mi
Oríṣun àwòrán, @dino_melaye
O ti pẹ ti awọn ọlọpa ti kede pe awọn n wa melaye
Ọwọ awọn ọlọpaa ti tẹ Sẹnetọ Dino Melaye.
Gẹgẹ bii iroyin naa ṣe sọ, awọn ọlọpaa mu Sẹnetọ Melaye ni papakọ ofurufu Nnamdi Azikiwe nilu Abuja.
Asiko to n lọ si orilẹede Morocco fun isẹ ilu ni wọn mu Melaye.
O ti pẹ ti awọn ọlọpa ti kede pe awọn n wa melaye lori ẹsun didi ihamọra nnkan ija ogun fun awọn janduku kan.
Awọn janduku naa ni wọn darukọ Sẹnetọ Melaye nigba ti ọwọ awọn agbofinro tẹ wọn ni ipinlẹ Kogi.
Onímọ̀ ọrọ̀ ajé: Ẹ mú ìyapa pàsípààrọ̀ Náírà kúrò
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Onímọ̀ nípa ẹ̀tò ọrọ̀ aje sọ pe yoo se ọrọ̀ ajé l'ánfààní ti kò bá sí ìyapa ninu síse pàsípààrọ̀ owó
Àjọ ayánilówó lágbàáyé, IMF, ti gba orilẹede Naijiria níyànjú lati fẹnu pàsípààrọ̀ owó dọ́la sí naira rẹ̀ jóná sí ojú kan soso.
Saájú àsìkò yii, orilẹede Naijiria ni ọ̀nà mẹ́rin ọ̀tọ̀ọ̀ tí wọ́n ń gbà se pààrọ̀ owó dọ́là, ninu èyí ti a ti rí pípààrọ̀ owó fún àwọn ti wọ́n n rìrìnàjò lọ sí Saudi Arabia, awọn tí wọn n sanwó ilé ẹ̀kọ́, ati awọn elépo rọ̀bì, tí ìlànà wọn kò báramu.
Ọmọ Nàíjíríà: Àrímáleèlọ ni àríyá alẹ́ sátidé BB Naija
Olùdarí IMF, lẹ́ka Afrika, ọ̀gbẹ́ni Abebe Aemro Selassie sọ pe, òún faramọ́ bi banki àpapọ̀ Naijiria se n gbe ìgbésẹ̀ lati rii dájú pé kò sí ìyapa nínú síse pàsípààrọ̀ owó.
Nigba tí ó n ba BBC Yoruba sọ̀rọ̀, onímọ̀ kan nipa ètò owónàá ati ọrọ̀ ajé, Ọ̀gbẹ́ni Tunde Olatunji sọ fun BBC Yoruba pe, ìgbésẹ̀ tó dára ni bí ìjọba se fẹ́ ojúnà lati mú ìyapa kúrò nínú pàsípààrọ̀ owó dọ́la yii, ó ní ọ̀nà náà wà láti tuń mú kí ètò ọrọ̀ aje'ru'gọ́gọ́ síi.
Ẹ gbọ́ọ Ọ̀gbẹ́ni Tunde Olatunji siwaju si:
IMF gba Naijiria níyànjú lórí pàsípààrọ̀ owo Dola
Commonwealth: Ànfàní wo ni Nàìjíríà rí?
Oríṣun àwòrán, Twitter/Nigerian Presidency
Orílẹ̀èdè mẹ́rìndínlógún ni Ọbabìnrin Elizabeth keji jẹ́ olórí fún nínú àjọ Commonwealth
Laipẹ yii ni ilẹ Gẹẹsi gba alejo awọn olori ajọ commonwealth ninu ipade kan to waye ni London.
Ọpọ ijiroro waye nibi ipade naa.
Sugbọn oun ti awọn ọmọ Naijiria n bere ni anfaani to mu wa.
Ẹ jẹ ki a se agbeyẹwo diẹ lara anfani to mu wa fun orileede Naijiria.
Oríṣun àwòrán, Twitter /Nigerian Presidency
Ireti wa pe idokowo naa yoo mu idagbasoke ba eto ọrọ aje Naijiria
Ikunpa fun ọrọ aje laarin Naijiria ati ilẹ Gẹẹsi
Awọn onimọ nipa eto ọrọ aje ti tẹnumo pataki ṣiṣe ikunpa fun ọrọ aje laarin Naijiria ati ilẹ Gẹẹsi.
Nibi ipade Commonwealth to pari laipẹ yii,  anfani idokowo ogoje miliọnu poun jẹ yọ fun Naijiria ati orilẹede Pakistan.
Saaju àsìkò yii ni awọn ile iṣẹ  ilẹ Gẹẹsi ti dokowo biliọnu marun poun sí Naijiria ti idokowo laarin Naijiria ati ilẹ Gẹẹsi lọdọọdun si le ni biliọnu mẹta poun.
Oríṣun àwòrán, Twitter/ FMPRng
Ipade laarin Aarẹ Buhari ati Bernadus Van Buerden mu anfaani idokowo to to milionu mẹẹdogun dolla
Nibi ipade naa, ile iṣẹ Royal Dutch Shell ati aarẹ Buhari se ipade eleyii to bi ikede idokowo biliọnu mẹẹdogun dollar ni Naijiria.
Ipenija aarun iba
Ipade Commonwealth naa tun mu anfani ijiroro ati ijẹjẹ ọwọ iranwo lati koju aarun iba nilẹ Afrika.
Oríṣun àwòrán, TWITTER/NIGERIAN PRESIDENCY
Bill Gates ati orileede Naijiria ni asepo lati koju ààrùn rọmọlapa rọmọlẹsẹ ati aironje asaraloge jẹ fun awọn ọmọde.
Bill Gates to je eni to lowo ju lagbaye kesi awọn olori orilẹede Commonwealth lati fi kun iye owo ti won ya soto lati koju aarun iba.
Anfaani nla ni ẹjẹ owo biliọnu meji poun naa jẹ́ ti awọn olori orilẹede fun Naijiria, ọkan lara awọn orilẹede ti o n koju ipenija aarun iba.
Pẹ̀lu gbogbo anfani wọ̀nyii, o si ni awọn kan paapa julọ ninu ẹgbẹ alatako to ni awọn ko ri anfaani kankan ninu irinajo Buhari lọ si ipade naa.
N'ilu Èkó, ọkọ̀ agbépo gbiná
Oríṣun àwòrán, LASEMA
Èèyàn kankan kò fi ara pa
Ọkọ̀ agbépo kan ti gbiná ní Idiroko, ní òpópónà Ikorodu l'Ékòó, ṣugbọ́n bí iná náà ṣe bẹ̀rẹ̀ ni awakọ̀ ọkọ̀ náà fẹsẹ̀ fẹ.
Agbẹnusọ fun àjọ  tí ó ńkojú ìṣẹ̀lẹ̀ pàjáwìri ní ìpínlẹ̀ Ẹ̀kó, sọ fún BBC wípé wọn ko ti mọ ohun tí o fa iná náà lára ọkọ̀ tó gbé kerosínì náà.
Ó sọ wípé èèyàn kankan kò fi ara pa, bẹ́ẹ̀ ni ẹ̀mí kankan kò ṣ'òfò nínú ìṣẹ̀lẹ̀ náà ní ọ̀sán ọjọ́ Ajé.
Iná náà fa ọ̀pọ̀lọpọ̀ súnkẹrẹ-gbàkẹrẹ ọkọ̀ bí àwọn awakọ̀ kò ṣelè kọjá bí iná náà ṣe ńjó.
Kò pẹ́ lẹ́hin tí iná náà bẹ́rẹ̀ ni àwọn panápaná àti àjọ tí ó ńkojú ìṣẹ̀lẹ̀ pàjáwìri d'omi pa iná náà.
Àwọn fọ́tò mìíràn láti ibi ìṣèlè náà rèé:
Oríṣun àwòrán, LASEMA
Àwọn panápaná àti àjọ tí ó ńkojú ìṣẹ̀lẹ̀ pàjáwìri ló d'omi pa iná náà
Ìròyìn tó ni létí wípé ọkọ̀ agbépo náà jó guruguru.
Oríṣun àwòrán, LASEMA
Ọkọ̀ agbépo náà jó guruguru
Ọmọ Nàíjíríà: Àrímáleèlọ ni àríyá alẹ́ sátidé BB Naija
Ọwọ́ ba ọlọ́pàá mẹ́rin tó pa ọmọ Nàíjììrà ní S.Africa
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ìwà ìkórííra n pọ̀si ní orílẹ̀èdè South Africa
Olùrànlọ́wọ́ pàtàkì fún ààrẹ Muhammadu Buhari lórí ọ̀rọ̀ ilẹ̀ òkèrè, Abike Dabiri-Erewa sọ pé ọwọ́ òfin ti ba ọlọ́pàá mẹ́rin tó n fi ẹ̀mí àwọn ọmọ ilẹ̀ Nàíjììrà ṣòfò ní orílẹ̀èdè South Africa.
Ọmọ ilẹ̀ Nàíjììrà kan tí ó fi orílẹ̀èdè náà ṣe ibùgbé, Clement Nwaogu ló ti pàdánù ẹ̀mí rẹ̀ lẹ́yìn tí àwọn ọmọ ilẹ̀ náà jóo níná láàyè.
Alukoro ẹgbẹ́ àwọn ọmọ ilẹ̀ Nàíjììrà tí wọ́n ngbé orílẹ̀èdè South Africa  Habib Miller sọ ọ́ di mímọ̀ pé ọmọkùnrin náà di olóògbé látàrí ìwà àífẹ́rí ẹ̀yà mìíràn tó gbòde kan nílẹ̀ náà.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ìwà pípa àlejò gbòdekan ní orílẹ̀èdè South Africa
Ó sàlàyé pé ọmọkùnrin náà tí ó jẹ́ ọmọbíbí ìlú Njikoka ní ìpínlẹ̀  Anambra lùgbàdì ikú òjijì ní  ìlú Rustenburg.
Miller fikún ọ̀rọ̀ rẹ̀ pé olóògbé náà jẹ́ onísòwó asọ àga ìjókò nígbà tí ó wà láyé.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ìwà ìkórííra n pọ̀si ní orílẹ̀èdè South Africa
Àwọn tí ìsẹ̀lẹ̀ náà sojú wọn sọ pé Nwaogu rawọ́ ẹ̀bẹ̀ s'áwọn ọlọ́pàá sùgbọ́n wọ́n kọ etí ikún síi.
Àkọsílẹ̀ fihàn pé ọgọ́fà dín méjì ọmọ ilẹ̀ Nàíjììrà  ló ti pàdánù ẹ̀mí wọn ní orílẹ̀èdè South Africa láti ọdún 2016 sí àkókó yìí.
Ọlọ́pàá àti Shiites tún fìjà pẹ́ẹ́ta
Oríṣun àwòrán, @OfficialPDPNig
Wahala tún bẹ́ sílẹ̀ nílùú Àbúja láàrin àwọn ọlọ́pàá àti àwọn ọmọ ìjọ ẹ̀sìn shi'ite
Àwọn ọlọ́pàá tún kọlu àwọn ọmọ ìjọ ẹlẹ́sìn shi'ite níwájú olú ilé ẹgbẹ́ tó wà fún ẹ̀tọ́ ọmọnìyàn (National Human Rights Commission) nìlú Abuja, nígbàtí wọ́n ń fi ẹ̀hónú wọn hàn nítorí olórí wọn tó wà ní áhámọ́.
Ìròyìn sọ́ di mímọ̀ pé, àwọn márùndínláàdọ́fà ọmọ egbẹ́ náà ni àwọn ọlọ́pàá mú ní ọjọ́ kérìndínlógún osù kẹrin.
Ọ̀gá ọlọ́pàá kan tí kò dárúkọ ara rẹ̀ sọ pé, àwọn agbófinró fi ipá tú àwọn ọmọ egbẹ́ Shiites náà ká, nígbàtí wọ́n kọ̀ láti kúrò níwájú ilé National Human Rights Commission.
Ìròyìn tó tẹ̀wá lọ́wọ́ láti News Agency of Nigeria sọpé àwọn ọmọ egbẹ́ Shiites ju òkò lu àwọn ọlọ́pàá tí wọ́n sì tún fọ́ gílàsìì àwọn ọkọ̀ tó wà níwájú ilé náà.
Sùgbọ́n agbẹnuso fún àwọn ọlọ́pàá nìlú Abuja Anjuguri Manzah kọ̀ láti sọ̀rọ̀ lórí ìsẹ̀lẹ̀ náà. Ó wípé ẹ̀kúnrẹ́rẹ́ ìṣẹ̀lẹ̀ náà kò tíì té òhun lọ́wọ̀.
Dino: ọlọ́pàá yí ilé mi ká
Oríṣun àwòrán, Twitter/Dino Melaye
Ọrọ kìí sì lẹyìn alábahun Dino Melaye
Lori ọrọ Senatọ Dino Melaye àti ilé iṣẹ ọlọ́pàá labuja ọrọ tun gba ibo míràn yo.
Lẹyin ti ile iṣẹ ọlọ́pàá tu Dino silẹ l'owurọ ọjọ ajé,o gbà ojú òpó Twitter re lati kéde pé àwọn ọlọpaa bi ogbon ti won dirá ogún tí yika ilé rẹ.
Koda o tun fi awọran awọn ọkọ ọlọ́pàá sọwọ pẹlu ikede naa
"Ṣugbọn  Ọ́gá àgbà iléesẹ́ ọlọ́pàá fún ẹkùn keje,Ọ̀gbẹ́ni Istifanus Sunday Bako sọ fun BBC pé kò sí ootọ nínú ọrọ naa.""A ti tú Dino silẹ lataaro. Mi o mo ibi to wa ṣugbọn ọlọ́pàá ko ragba di ile re""L'owurọ ọjọ ajé ni àwọn ọlọpaa mu Sẹnetọ Melaye ni papakọ ofurufu Nnamdi Azikiwe nilu Abuja."
Ìsẹ̀lẹ̀ Ghana: Òògùn ẹ̀fọn pa ìbejì àti ẹ̀gbọ́n wọn
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Awon òbí náà paapaa, fara kasa nínú ìṣẹlẹ ọhun
Awon aláṣẹ ni orílèèdè Ghana ti bẹrẹ iwadi nípa ìṣẹlẹ ikú ọmọ mẹta, lẹyìn tí wọn fa oogún oloro sínú.
A gbọ́ pe awon òbí wọn ní wọn fin òògún náà silẹ, lati fi pa kòkòrò ẹ̀fọn ninu ile wọn.
Awon ìbejì to jẹ obinrin, ti wọn jẹ ọmọ oṣù mẹ́sàn àti ẹgbọn wọn, to jẹ ọmọ ọdún méjì, pàdánù ẹmí wọn ní ilé ìwòsan ologun to wa ni ìlú Accra, ni kété ti wọn gbé wọn dé ibè.
Ìròyìn ta gbọ ni pe, Iya wọn fin ogún oloro náà silẹ̀, lati dẹkùn bi ááyán ṣe n daamu wọn.
Ọmọ Nàíjíríà: Àrímáleèlọ ni àríyá alẹ́ sátidé BB Naija
Awon òbí náà paapaa, fara kasa nínú ìṣẹlẹ ọhun eyi to se akoba fun mimi soke silẹ wọn, bi o tilẹ́ jẹ pe ara wọn pada ya.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Èyí kìí sì se ìgbà àkọ́kọ́ tí irúfẹ́ ìsẹ̀lẹ̀ bẹ́ẹ̀ yóò wáyé
Se ni àwòrán oogún oloro náà gba ori ẹrọ ayelujara kan lẹyìn ìṣẹlẹ náà.
Eyi kii si se igba akọkọ ti irufẹ ìṣẹlẹ bẹẹ yóò wáyé ni orílèèdè Ghana.
Lọdun 2016, àwọn ọmọbìnrin ìbejì, ọmọ ọdún mẹẹdogun ku ni ilu Kumasi, lẹyìn tí wọn sun inu yàrá ti won fin ogún oloro apakokoro si.
Ikọlù Benue: Adaran pa àlùfáà méjì, ọmọ ìjọ 13 ní ilé ìjọsìn
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Bíì ẹgbẹ̀rún kan àbọ̀ ènìyàn ni ó ti kú ní Benue láti 2013
Ìròyìn tí ó ńkàn sí wa fihàn wípé àwọn darandaran agbébọn ti pa àlùfáà méjì àti ọmọ ìjọ mẹ́tàlá ní ilé ìjọsìn kátólíkì kan tí ó wà ní Ayar Mbalom ní ìjọba ìbílẹ̀ ìlà oòrùn Gwer ní ìpínlẹ̀ Benue.
Àwọn darandaran náà ni a gbọ́ pé ó ṣe àkọlù náà sí St. Ignatius Quasi Parish, Ukpor-Mbalom ní bíi aago mẹ́fà àárọ̀ ọjọ́ ìṣẹ́gun nígbà tí àwọn olùjọ́sìn ìjọ náà lọ sí ìjọ́sìn àárọ̀.
Terver Akase ti ó jẹ́ agbẹnusọ fún Gomina Samuel Ortom sọ fún BBC pé awon fada ti o padanu emi won ninu akolu naa ni Fada Joseph Gor ati Fada Felix Tyolaha.
Akase so wípé lẹ́hìn tí àwọn darandaran náà ṣọṣẹ́ tán ní ilé ìjọsìn náà, wọ́n tún sọ'ná sí ilé bíi àádọ́ta ní ìlú náà kí wọn tó sa lọ.
Odumakin sọrọ lori Fulani darandaran
Oṣù kejì ọdún yìí ni kọmíṣọ́nnà fún ìbánisọ̀rọ̀ àti ìlanilọ́yẹ ní Benue, Lawrence Onoja, sọ wí pé bíì ẹgbẹ̀rún kan ààbọ̀ ènìyàn ni ó ti kú ní Benue láti 2013 nínú ìkọlù àwọn darandaran agbébọn, tí ogunlọ́gọ̀ sì pàdánù dúkìá, ohun ọ̀gbìn àti ilé wọn.
Ẹ ó rántí wípé ní oṣù kínní ọdún yìí ni ìjọba ìpínlẹ̀ Benue sin òkú métàléláàdọrin tí àwọn agbébọn pa.
Ìkọlù Benue: Adaran pa àlùfáà méjì, ọmọ ìjọ 13 nílé ìjọsìn
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Bíi ẹgbẹ̀rún kan àbọ̀ ènìyàn ni ó ti kú ní Benue láti 2013
Ìròyìn kàn ní àwọn afurasí darandaran agbébọn ti pa àlùfáà méjì àti ọmọ ìjọ mẹ́tàlá ní ilé ìjọsìn kátólíìkì kan tí ó wà ní Ayar Mbalom ní ìjọba ìbílẹ̀ ìlà oòrùn Gwer ní ìpínlẹ̀ Benue.
Àwọn afurasí darandaran náà ni a gbọ́ pé ó ṣe ikọlù náà sí St. Ignatius Quasi Parish, Ukpor-Mbalom ní bíi aago mẹ́fà àárọ̀ ọjọ́ ìṣẹ́gun nígbà tí àwọn olùjọ́sìn ìjọ náà lọ sí ìjọ́sìn àárọ̀.
Terver Akase ti ó jẹ́ agbẹnusọ fún Gomina Samuel Ortom sọ fún BBC Yorùbá pé, awon fadá ti o padanu ẹ̀mi wọn ninu ikolu naa ni Fadá Joseph Gor ati Fadá Felix Tyolaha.
Akase so wí pé lẹ́hìn tí àwọn darandaran náà ṣọṣẹ́ tán ní ilé ìjọsìn náà, wọ́n tún sọ iná sí ilé bíi àádọ́ta ní ìlú náà, kí wọn tó sa lọ.
Odumakin sọrọ lori Fulani darandaran
Oṣù kejì ọdún yìí ni kọmíṣọ́nnà fún ìbánisọ̀rọ̀ àti ìlanilọ́yẹ ní Benue, Lawrence Onoja,  sọ wí pé bíì ẹgbẹ̀rún kan àbọ̀ ènìyàn ni ó ti kú ní Benue láti 2013 nínú àkọlù àwọn afurasí darandaran agbébọn, tí ogunlọ́gọ̀ sì pàdánù dúkìá, ohun ọ̀gbìn àti ilé wọn.
E ó rántí wípé ní oṣù kínní ọdún yìí ni ìjọba ìpínlẹ̀ Benue sin òkú métàléláàdọrin tí àwọn agbébọn pa.
Ọṣínbàjò: Èmi kìí gbé ilé rárá nítorí iṣẹ́ ìlú
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ipò adarí kò rọrùn rárá
''Iṣẹ́ ń bẹ níwájú igbákejì ààrẹ''
ÈyÍ ni ọ̀rọ̀ to jade lẹnu Ọjọ̀gbọ́n Yẹmí Ọṣínbàjò lásìkò ti o n ka ìwé setigbọ àwọn akẹ́kọ̀ọ́ ilé iwé LEA nilu Àbújá lati fisàmì àyájọ́ ọjọ́ ìwé àti òfin àdáni lágbàyé fún t'ọdún 2018.
Ọrọ yìí jẹyọ ninu atẹjade kan lati ọwọ oluranlọwọ fun igbákejì ààrẹ lori ọrọ iroyin, Laolu Akande.
Ọjọ̀gbọ́n Yẹmí Ọṣínbàjò ni iṣẹ́ adarí yala nípò ààrẹ tàbí nípò igbákejì rẹ̀ ''kìí ṣe kékeré rárá fún ẹni tó bá fẹ́ sin ìlú nítòótọ́.''
Ó ni lọ́pọ̀ igba ni òun máa ń rin ìrìnàjò káàkiri lati le se irawon fun ààrẹ lẹ́nu iṣẹ́ ìlú t'àwọn jìjọ gba.
Ìmọ̀ràn f'áwọn Adarí
Yẹmí Ọṣínbàjò gba àwọn olórí nímọ̀ràn pé, kí wọ́n tẹ̀lé òdiwọ̀n gbèǹdéke iye ọdún tí òfin bá là kalẹ̀ fún wọn, yálà ọdún mẹ́rin ni tàbí ọdún mẹ́jọ.
''Ó yẹ kí olórí lè sinmi, kí ó tún rí ààyè fún ẹbí àtí ará rẹ̀.''
Agbẹnusọ Mélayé: Dino ti lọ yọjú sọ́dọ̀ ọlọ́paa SARS
2019 Election: Olasunkanmi Okeowo ní òun kò díje fun ipo ààrẹ mọ
Oríṣun àwòrán, Okeowo/instagram
Orí àtẹ̀jíṣẹ́ ẹ̀rọ ayélujára rẹ̀ ló ti kéde pé òun yọ ọwọ́ àti ẹsẹ̀ òun lẹ́yìn tó sọ pé àwọn aláwọ dúdú ò lè ronú láti ṣẹ̀dá ohunkohun.
Olasunkanmi Okeowo, tó fẹ́ díje fún ipò ààrẹ orílẹ̀-èdè Nàìjíríà lọ́dún 2019, lábẹ́ àsía African Democratic Congress (ADC) tí sọ pé, òun kò díje fún ipò ààrẹ mọ lẹ́yìn tó sọ̀rọ̀ kan eyi tó bí àwọn ọmọ Nàìjíríà nínú.
Orí àtẹ̀jíṣẹ́ ẹ̀rọ ayélujára rẹ̀ ló ti kéde pé, òun yọ ọwọ́ àti ẹsẹ̀ òun lẹ́yìn tó sọ pé, àwọn aláwọ dúdú kò lèe ronú láti ṣẹ̀dá ohunkohun.
Nínú ìfọrọ̀wánilẹ̀núwò kan tí Folarin Falana (Falz) àti Laila Johnson Salami ṣe fún-un, lóri òhun ti yóò ṣe láti mú ǹkan dáradara se tó bna dé ipò ààrẹ.
Awọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí:
Ayefẹlẹ: Orí ìkúnlẹ̀ ni ìyàwó mi wà, tó ń bẹ gómìnà, láti 11pm si 4am
Nínú èsì rẹ̀, Olasunkanmi ní aláwọ dúdú ni wa, à kó lee da ǹkankan se bí àwọn oyinbo tí máà ń ṣe, bi wọn tilẹ̀ tí wa mọ inu yàrá kan fun odidi ọdun kan.
Lẹ́yìn ti fọran náà dé ìgboro lóri àyélujára ní àkàrà bá tú sepo fún olùdíjè náà, èyí ló mu ṣe ìpinnu pé oun kò díje dupo ààrẹ mọ.
Lẹ́yìn náà ni ọ̀rọ̀ náà bẹ̀rẹ̀ sí ní jà rain-raín lórju opo twitter.
Ó dàbí ẹni pé gbogbo èèbú yìí ló fà idí abajọ ti Ọkẹowo fí sọ pé òun ò ṣe mọ ooo
Atiku Abubakar ní sáà kan ní òun tọrọ lọ́wọ́ ọmọ Nàìjíríà
Oríṣun àwòrán, AFP
Atiku Abubakar ní kò sí tipá nínú kí òun di àarẹ́ Nàíjirìa
Igbákejì ààrẹ àná lórílẹ̀-èdè Nàìjíríà, Atiku Abubakar tí rọ awọn ọmọ orilẹ̀-èdè Nàìjíríà láti gbà òun láàyè, lati lo sáà kan soso gẹ́gẹ́ bíi ààrẹ orílẹ̀-èdè Nàìjíríà.
Abubakar sọrọ ọhún níbi ìfọrọwanilẹnuwo kan táwọn akọ̀ròyìn se fun. O ní láì jẹ́ pé enikẹni bèèrè lọ́wọ́ òun, ohun to bójúmu láti ṣe ni, tori ohun ti ìgbàgbọ òun rọ mọ láti ṣe ni.
"Bí mo ba di ààrẹ ní ọdun 2019, mo ti fi ohùn sílẹ̀ láti ṣe sáà kan ṣoṣo'
Ìyá Darasimi: Ọlọ́run fi ìbejì rẹ̀ mí lẹ́kún, lẹ́yìn ikú Darasimi tó mu sódà
Ó ní bótilẹ̀ jẹ́ pé Buhari náà jẹ́ irú ẹ̀jẹ́ bẹ́ẹ̀ lọdun 2011  tí kò sì tèlée, ọ̀rọ̀ tohun kò ni rí bẹ́ẹ̀ rárá àti pé, òhun ti ṣetán láti tọwọbọ ìwé àdéhun.
Atiku fii kún-un pé, àwọn ọmọ Nàìjíríà le gbé ìwé jáde fún òun lati tọwọ́ bọ̀ọ́ fún ẹ̀ri ọjọ́ iwájú, bí òún bá fẹ́ yẹ̀ kúro lórí àdéhùn.
Atiku: Kò pọn dandan kí ń díje fún ipò àarẹ́ Nàíjirìa
Igbákejì àarẹ́ Nàíjirìa tẹ́lẹ̀rí Atiku Abubakar, ti ní, òun kò sọpé ó pọn dandan fún òun láti jẹ àaré orílẹ́èdè Nàíjirìa ní ọdún 2019.
Atiku sọ pé tí ó bá jẹ́ pé ó pọn dandan ni, òun kò bá má gbà rárá fún M.K.O. Abíọ́lá láti dìje fún ipò àarẹ́ nínú ìdìbò ọdún 1993.
Ó mẹ́núba ìrírí rẹ̀ sẹ́yìn pé tí áwọn ọmọ orílẹ́-èdè Nàíjirìa bá wo ìtàn òun nínú ètò òṣèlù Nàíjirìa, wọn yóò ri pé òun kìí se olóṣèlù bó-báa-o-pá; bó-bàa-o-bùú-lẹ́sẹ̀.
Atiku sọ pé òun wọlé gẹ̀gẹ̀ bí gómìnà ìpínlẹ̀ Adamawa ní ọdún 1999, kí òun tó di igbákejì àarẹ́ Olúsẹ́gun Obásanjọ́ l'ọdún kan náà.
Ó sọ pé òun díje fún ipò àarẹ́ pẹ̀lú olóyè Olúsẹ́gun Obásanjọ́ ní ọdún 2007 láti fihàn wí pé òun lẹ́tọ̀ọ́ láti ṣe bẹ́ẹ̀ ni gẹ́gẹ́ bíi ọmọ Nàíjirìa.
Siasia lè gba iṣẹ́ akọ́nimọ̀ọ́gbá égbẹ́ agbábọ́ọ̀lù Cameroon
Oríṣun àwòrán, Twitter/Siasia
Samson Siasia wà lára àwọn akọ́nimọ̀ọ́gbá tí àjọ tó ń rí sí eré bọ́ọ̀lù àfẹsẹ̀gbá ní orílẹ́èdè Cameroon fẹ́ fọ̀rọ̀ wá lẹ́nu wò
Akọ́nimọ̀ọ́gbá ikọ̀ agbábọ́ọ̀lù Super Eagles tẹ́lẹ̀ rí, Samson Siasia, wà lára àwọn akọ́nimọ̀ọ́gbá mẹ́tàdínlọ́gọ́rin tí àjọ tó ń rí sí eré bọ́ọ̀lù àfẹsẹ̀gbá ní orílẹ́èdè Cameroon fẹ́ fọ̀rọ̀ wá lẹ́nu wò láti tukọ̀  ikọ̀ agbábọ́ọ̀lù ilẹ̀ náà.
Àjọ tó ń rí sí eré bọ́ọ̀lù àfẹsẹ̀gbá ní Cameroon ń wá ẹni tí yóò rọ́pò Hugo Broos látàrí bí orílẹ́-èdè náà ti kùnà láti yege nínú àwọn tí yóò kópa nínú ife ẹ̀yẹ àgbáyé ọdún yìí ní orílẹ́-èdè Russia.
Àwọn míràn tí wọ́n tún yàn fún àyẹ̀wò fún isẹ̀ náà ni: Balógun ikọ̀ agbábọ́ọ̀lù Cameroon tẹ́lẹ̀rí, Rigobert Song; akọ́nimọ̀ọ́gbá ikọ̀ agbábọ́ọ̀lù Super Eagles nígbàkan rí, Philippe Troussier; àti akọ́nimọ̀ọ́gbá égbẹ́ agbábọ́ọ̀lù ilẹ̀ Faransé tẹ́lẹ̀ rí, Raymond Domenech.
Olórí ìgbìmọ̀ tó ń rí sí yíyan akọ́nimọ̀ọ́gbá míràn fún orílẹ́-èdè Cameroon, Djomo Kelvin, sọ pé àwọn yóò se àyẹ̀wò fínífíní kí awọ́n tó yan akọ́nimọ̀ọ́gbá tuntun fun égbẹ́ agbábọ́ọ̀lù ọ̀hún.
Ó dèèwọ̀ láti sọ ilégbèé di iléèjọsìn l'Ékó
Èèyàn mẹ́wàá kú nínú ìkọ̀lù tuntun ni Benue
NAFDAC: Fifi òògùn apakòkòrò 'Sniper' sinu ẹwà leè jásí ewu
Ẹwa jẹ ounjẹ aayo fun ọpọlopọ ni Naijiria
Bi iwọ tabi mọlẹbi rẹ ba fẹran ẹwa ni jijẹ, tete yaa tẹti si ikede pataki yi.
Onimọ nipa ounjẹ jijẹ, Oluwatobi Oyedeji ninu ọ̀rọ̀ to ba BBC News Yoruba sọ, sọ pe ounjẹ ti a ko ti i ṣe to ba ni kokoro ninu tumọ si pe ounjẹ ti wọn ko fi kẹmika kankan gbin ni.
O ṣalaye pe lilo kẹmika bi oogun ẹfọn tabi 'sniper' maa n ba ẹya ara jẹ́ diẹdiẹ ni tabi ko pa eniyan l'oju ẹsẹ. Ẹ gbọ ọ ni ẹkunrẹrẹ.
Lílo òógùn apakòkòrò fún oúnjẹ l'éwu
Ṣaaju ni ajọ to n mojuto ipese ounjẹ ati oogun lilo ni Naijiria, NAFDAC, kilọ fun awọn ọmọ Naijiria lati yago fun awọn ounjẹ ti wọn ba fi kẹmika 'sniper' ṣe lọ́jọ̀.
Kẹmika naa, Dichlorvos dimethyl phosphate, ti gbogbo eniyan mọ si 'sniper' jẹ gbaju-gbaja kẹmika ti ajọ NAFDAC fọwọ si lati maa fi pa kokoro bi ẹfọn.
Laipẹ yii ni iroyin kan jade sita pe awọn kan n lo kẹmika naa lati fi ṣe ounjẹ wọn lọjọ, ko ma ba a bajẹ, ṣugbọn ajọ NAFDAC ti sọ pe o lewu fun ilera ara.
Daniel Ekugo, to jẹ ọga agba fun ileeṣẹ to n daabo bo ẹtọ awọn onraja, fi idi rẹ mulẹ pe lootọ ni awọn oniṣowo kan n lo 'sniper' lati fi tọju ẹwa ti wọn n ta, ati lati fi pa awọn kokoro ro n sapamọ sinu ẹwa.
Ekuko ni oun ko gbagbọ pe awọn ksn le ma a hu iwa buruku bẹ.
Eyi lo wa mu ki ọga agba ajọ NAFDAC, Ọjọgbọn Christiana Mojisọla Adeyẹye, gba awọn ọmọ Naijiria ni imọran pe ki wọn ma ṣe ra tabi jẹ ounjẹ ti wọn fi 'sniper' tabi kẹmika oloro mi i pa.
Ati pe, o ṣe pataki lati fọ ounjẹ wọn daada ki wọn o to se e nitori pe jijẹ ounjẹ ti 'sniper' wa lara rẹ le fa oju fifọ, gìrì, eebi, ìgbẹ́ gbuuru, to fi mọ jẹjẹrẹ tabi ko tilẹ pa ẹni naa.
O gba awọn eeyan niyanju lati ri wi pe wọn fi omi ṣan ẹwa wọn daada ki wọn to daa si ori ina
Ọmọ mẹ́ta láti inú ìyá kan náà kan gbẹ́mì mì nítorí òògùn apakòkòrò tí wọn fà símú.
A gbọ́ pe awon òbí wọn ní wọn fin òògún náà silẹ, lati fi pa kòkòrò ẹ̀fọn ninu ile wọn.
Awon ìbejì to jẹ obinrin, ti wọn jẹ ọmọ oṣù mẹ́sàn àti ẹgbọn wọn, to jẹ ọmọ ọdún méjì, pàdánù ẹmí wọn ní ilé ìwòsan ologun to wa ni ìlú Accra, ní orílẹ-èdè Ghana ni kété ti wọn gbé wọn dé ibè.
Ìròyìn ta gbọ ni pe, Iya wọn fin ogún oloro náà silẹ̀, lati dẹkùn bi ááyán ṣe n daamu wọn.
Níwọ̀n ìgbà tí kò sí ibi tí ìṣe kò sí, ọ̀pọ̀ ènìyàn ló máa ń lo òògùn apakòkòrò ní órílẹ̀-èdè Nàìjíríà bákán náà, èyí ló mú kí BBC Yorùbá ṣe ìwádìí àwọn ewu tí àwọn ènìyàn ti bá pàdé nínú lílo òògùn apakòkòrò.
Ẹ gbọ́ ohun tí wọn sọ.
Àwọn ènìyàn sọ àwọn ewu tí wọn pàdé nínú lílo òògùn ẹ̀fọn
Dókítà Yemisi Adeyeye ní ọ̀pọ̀ ènìyàn ló màa lo òògùn apakòkòrò fún ẹ̀fọn, aáyán àti ìdun, sùgbọn kàkà kó jẹ́ ohun ààbò, ìpalára ni  ó jẹ́ fún elòmíràn.
Ó wá gba àwọn ènìyàn ní ìmọ̀ràn pé, ó ṣe pàtàkì láti yẹ agolo òògùn apakòkòrò wò, kí a sì tèlé ìlànà tó yẹ kí a tó lòó
Dókítà Yemisi Adeyeye sàlàyá lórí àwọn ìpalára tó wà nínú òògùn apakòkòrò
Ọlọ́pàá Kogi: Àwọn tọ́ọ́gì Melaye yìnbọn mọ́ òsìsẹ́ wa, la se ń wa
Oríṣun àwòrán, @dino_melaye
Igba akọkọ kọ ree, ti ileesẹ ọlọpaa ati Dino Melaye yoo maa tutọ si ara wọn loju
N se ni nkan tun n gbona giri-giri fun Sẹnetọ Dino Melaye lọdọ ileesẹ ọlọpaa, kaka ki ewe agbọn aawọ rẹ ati ileesẹ ọlọpaa si dẹ, lile lo tun n le si.
Idi ni pe ileesẹ ọlọpaa nipinlẹ Kogi tun ti fidi rẹ mulẹ pe, ootọ ni ọrọ to n ja rain-rain nilẹ pe awọn ya bo ile Dino Melaye to wa ni ilu abinibi rẹ, Ayetoro Gbẹdẹ, nipinlẹ Kogi, lati ti tun gbe sẹnetọ naa lapan yaka.
Atẹjade kan ti Agbẹnusọ fun ileesẹ ọlọpaa nipinlẹ Kogi, William Aya fisita lọjọ Abamẹta ni, oun fẹ mu Melaye nitori bi awọn janduku rẹ se yinbọn mọ ọlọpaa kan, Sajẹnti Danjuma Salihu losu keje ọdun yii.
Ṣé ẹ rántí orin - Má ṣe jẹ́jẹ́ ma wà mi lọ?
Ọlọpaa ni o di dandan ki awọn tan imọlẹ si ọrọ yii niroti ikede kan ti Melaye fisita loju opo Twitter rẹ lọjọ Ẹti pe Ẹsọ gomina Yahaya Bello lo lewaju awọn eeyan kan lati wa gba ẹmi oun.
A wa fẹ fi to araye leti pe irọ to jinna si ootọ ni ohun ti Melaye sọ yii, ero ọkan rẹ lasan ni. Koda, Kọmisọna ọlọpaa ran wa lọ si ile rẹ lati mu, amọ a ko ri mu."""
Bakan naa ni ileesẹ ọlọpaa Kogi tun n na ika aleebu si Melaye pe o tun lo awọn janduku lati kọlu awọn ọlọpaa to n sisẹ wọn loju ọna Mopa si Ayetoro Gbẹdẹ
Oríṣun àwòrán, @dinomelaye
Ileesẹ ọlọpaa ni oun n sọ fun araye pe irọ to jinna si ootọ ni ohun ti Melaye sọ, ero ọkan rẹ lasan n
Láàrin àná sí oní è je ki a ṣe àgbéyẹ̀wò ohun to ti ṣẹlẹ sí Senato Dino Melaye.
Lọ̀jọ̀ ajé, awọn ilé iṣẹ ọlọpaa mu ní pápáko ofurufu Abuja nígbà tí o fe se irin-ajo lo sí Morocco.
Awon ọlọpaa tú u silẹ, O sí padà sí ilé rẹ̀.
Lẹyìn ìgbà náà, Dino fi ọrọ síta lójú òpó Twitter rẹ̀ pe àwọn ọlọpaa ti rọ̀gbà yíká ile oùn.
Kóda  àwòrán àwọn aṣatipo tí wọn wà bá a kedun lórí ìṣẹlẹ náà tun jẹyọ.
Oríṣun àwòrán, facebook/Mazino Dickson
Awọn asatipo naa ni alanu awọn ni Senato Dino Melaye
Ni òwúrọ̀ ọjọ́ ìṣẹgun, ìròyìn gbálẹ̀ pé Dino ti jọ̀wọ́ ará rẹ̀ fún àwọn ọlọpaa.
Nigba tí ọsán yóò fi tó, ìròyìn bẹ̀rẹ̀ sí ní káàkiri pé àwọn ọlọpaa ti fẹ gbé Dino lo sí ilé ẹjọ́.
Kò pé sí igba naa ni àwọn fídíò bẹrẹ sí ní gba ori ẹrọ ayélujára to ṣe àfihàn Dino níbi tí o joko sí ilé láàrin ojú titi lÁbuja.
Oun ti a ri gbọ ni pe Dino kọ̀ láti tẹlé àwọn ọlọpaa lo sí Lokoja níbi tí àwọn kan ni won yóò ti ṣe àfihàn rẹ pẹlú àwọn adigunjale míràn.
Lọwọ irọlẹ la gbo pé wọn ti gbe e lo sí ilè ìwòsan Zankli, nilu Abuja ti àwòrán rẹ lori ibùsùn aláìsàn sì gbà ojú Twitter kan.
Oríṣun àwòrán, Aminu Omoye
Ọna ti Dino fi farapa ninu ìṣẹlẹ náà ko ti daju
Ni báyìí ìròyìn tó tẹ wá lọwọ ni pé àwọn ọlọpaa ti ragba yíká ilé ìwòsan Zankli láti ri wí pé Dino ko sa kúrò ní bè.
Nwaboshi: Sẹ́nétọ̀ ń lọ ilé ẹjọ́ ní Ọjọ́rú -EFCC
Oríṣun àwòrán, Facebook
EFCC rá sẹ́nétọ̀ náà mú ní òpin ọ̀sẹ̀ tó kọjá yìí lórí ẹ̀sùn pé ó ṣe jìbìti biliọnu mẹfa náírà
Agbẹnusọ fún àjọ tí ó ń kojú ìwà jẹgúdújẹrá (EFCC), Wilson Uwujaren, ti sọ wí pé sẹ́nétọ̀ láti ìpínlẹ̀ Delta,
Peter Nwaboshi, yóò fojú ba ilé ẹjọ́ ní Ọjọ́bọ, lórí ẹ̀sùn pé ó ṣe jìbìtì bílíọ́nù mẹ́fà naira (N6bn).
Uwujaren sọ fún BBC Yorùbá nígbà tí ó ń sọ̀rọ̀ lórí ìdí tí àjọ náà ṣe gbé Nwaboshi tì mọ́lé kọjá ọjọ́ méji (wákàtí méjìdínláàdọ́ta) tí òfin fà lélè, pé, èyi'wáyé nítorí wí pé àjọ náà ń ṣètò ìwé ẹ̀sun rẹ ni.
Agbẹnusọ Mélayé: Dino ti lọ yọjú sọ́dọ̀ ọlọ́paa SARS
EFCC rá sẹ́nétọ̀ náà mú ní òpin ọ̀sẹ̀ tó kọjá, lórí ẹ̀sùn pé, ó ṣe jìbìti biliọnu mefa, àti pé ó fi ilé-iṣẹ́ márùndínlógún gba iṣẹ́ àgbàṣe gẹ́gẹ́ bí olórí ìgbìmọ̀ asòfin àgbà lórí ọ̀rọ̀ Niger-Delta.
Àjọ náà ní pé ó tó ọdún méjì sẹ́hìn tí àwọn kan ti kọ ìwé mọ́ọ tí àwọn sì ti ń dọdẹ Nwaboshi.
Nwaboshi ni ó ń ṣojú ẹkùn àríwá Delta ní ilé ìgbìmọ̀ asòfin àgbà nílu Àbújá.
Ìbálòpọ̀ fún máàkì: Monica fojú hàn níwájú ìgbìmọ̀ OAU
Oríṣun àwòrán, @OfficialOAU
Ohùn un ọ̀jọ̀gbọ́n Akindele tí o ń bèèrè fún ìbálòpọ̀ ìgbà lọ́wọ́ akẹ́kọ́bìnrin kan bọ́ sójú agbami ayélujára lọ́sẹ̀ díẹ̀ sẹ́yìn
Akẹ́kọ̀ọ́ fásitì Ọbáfẹ́mi Awólọ́wọ,̀ OAU tó wà nílùú Ilé ifẹ̀, Monica Osagie, tí ohùn rẹ̀ wà nínú fọ́nrán ohùn  àkásílẹ̀  kan nínú èyí tí  ọ̀jọ̀gbọ́n kan ní ẹ̀ka ìmọ̀ nípa ìṣirò owó ní fásitì náà,  tó ń béèrè fún ìbálòpọ̀ ìgbà máàrún ọ̀tọ̀ọ̀tọ̀ nítoríi máàkì, ti fìdí rẹ̀ múlẹ̀ pé lóòótọ́ ni ọ̀jọ̀gbọ́n Akíndélé béèrè fún ìbálòpọ̀ láti bá fún òun ní máàkì.Arábìnrin Monica Osagie fìdí ọ̀rọ̀ náà múlẹ̀ nígbà tó farahàn níwájú ìgbìmọ̀ tí àwọn aláṣẹ fásitì náà gbé kalẹ̀ fún ìwádìí lórí ìṣẹ̀lẹ̀ náà.Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí:
Amòfin tó ń ṣojú arábìnrin Monica Osagie, Ọ̀mọ̀wé Abíọ́lá Akínyọdé Afọlábí ní, akẹ́kọ̀ọ́ náà jẹ́ kó di mímọ̀ níwájú ìgbìmọ̀ náà pé, òun kò fìdírẹmi nínú ẹ̀kó náà, ṣùgbọ́n ọ̀jọ̀gbọ́n náà ló mọ̀ọ́mọ̀ fìdí òun rẹmi kó leè rọ́nà bá òun lò pọ̀.Monica ni òun mọ̀ọ́mọ̀ ká ìbánisọ̀rọ̀ òun àti ọ̀jọ̀gbọ́n náà sílẹ̀ ni
Àmọ́ o, Ọ̀mọ̀wé Abíọ́lá Akínyọdé Afọlábí ní, akẹ́kọ̀ọ́ náà sọọ́ di mímọ̀ níwájú ìgbìmọ̀ ọ̀hún pé, òun mọ̀ọ́mọ̀ ká ìbánisọ̀rọ̀ tó wáyé láàárín òun àti ọ̀jọ̀gbọ́n Akíndélé sílẹ̀ ni gẹ́gẹ́bíi ẹ̀rí.Wákàtí méje ni Monica lò níwájú ìgbìmọ̀ ọ̀hún pẹ̀lú àwọn agbẹjọ́rò rẹ̀.
Ọ̀ṣun: Iléeṣẹ́ 17 jẹ bílíọ̀nù méjìlá náírà owó orí
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Àwọn iléeṣẹ́ alaladani méje àti iléeṣẹ́ ìjọba àpapọ̀ mẹ́wàá kan ni aje ọ̀rọ̀ yìí ṣí mọ́ lórí.
Ìjọba ìpínlẹ̀ Ọ̀ṣun ti fún àwọn iléeṣẹ́ tí wọ́n ń jẹẹ́ lówó orí ní gbèdéke ọjọ́ méje làti fi san owó orí tí wọ́n jẹ.
Ìjọba ìpínlẹ̀ Ọ̀ṣun ní òun ti parí gbogbo ìgbésẹ̀ láti gbé àwọn iléeṣẹ́ tọ́rọ̀ náà kàn lọ sílé ẹjọ́ ní kété tí gbèdéke náà bá ti parí.
Olùbádámọ̀ràn lórí ọ̀rọ̀ owó orí sísán nípínlẹ̀ Ọ̀ṣun, Amòfin Gbénga Àkànó ló sọ èyí nilú Ọ̀ṣogbo.
Ó ní àwọn iléeṣẹ́ alaladani méje àti iléeṣẹ́ ìjọba àpapọ̀ mẹ́wàá kan ni aje ọ̀rọ̀ yìí ṣí mọ́ lórí.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí:
Amòfin Àkànó dárukọ àwọn iléeṣẹ́ aladani tó jẹ ijọba lówó orí nípìnlẹ́ náà.
Lára wọn la ti rí ileesẹ́ bíì Glo, 9Mobile, OAU, SAMMYA Nigeria Limited, Wetland Construction Nigeria Limited, LAPO Agric Development Initiative, National Centre for Technology Management, Centre for Energy Research and Development, CERD, Obafemi Awolowo Teaching Hospital àti NTA, Ile-Ife.
Ẹ̀wẹ̀, ó ní àwọn iléeṣẹ́ ìjọba àpapọ̀ bíi iléeṣẹ́ aṣọ́bodè, iléeṣẹ́ ààbò ara ẹni lààbò ìlu, NSCDC, iléeṣẹ́ to ń mójútó wọléwọ̀de lórílẹ̀èdè Nàìjíríà, NIS pẹ̀lú iléeṣẹ́ ọgbà ẹ̀wọ̀n lórílẹ̀èdè Nàìjíríà náà ń jẹẹ́ lówó orí àwọn òṣìsẹ́ rẹ̀ gbogbo.
Lápapọ̀, Olùbádámọ̀ràn lórí ọ̀rọ̀ owó orí sísán nípínlẹ̀ Ọ̀ṣun náà ní, owó tó lé ní bílíọ̀nù méjìlá náírà ni àwọn iléeṣẹ́ tó lórúkọ jẹ ìjọba gégébí owó orí nípínlẹ̀ Ọ̀ṣun.
Àyájọ́ Ibà: Ònà àbáyọ sí ikú ọmọdé àt'àgbà lásìkó yìí
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ọ̀pọ̀lọ́pọ̀ àwọn ayédèrú òògùn tí ó wà ní ìta ni ó ń fa ìkùnà tí ó lágbára jù fún ipa láti mú òpin bá àìsàn ibà
Òní tí ń ṣe àyájọ́ ọ́jọ̀ àìsàn ibà, jẹ́ ọjọ́ àkíyèsi.
Akọ́ṣẹ́mọṣẹ́ kan nínú ètò ìlera làti fásitì Obafemi Awolowo, Ile-Ife, Ọjọ̀gbọ́n Adedeji Onayade,  sọ pé a ti ń sún mọ́ òpin àìsàn ibà ní Naijiria, ṣùgbọ́n, a ní láti ṣe àwọn ìṣọ́ra kọ̀ọ̀kan.
Ọ̀jọ̀gbọ́n náà ṣàlàyé pé a gbọ́dọ̀ ri i pé àwọn aláboyún àti ọmọ ọwọ́ sí ọdún márùń un gbọ́dọ̀ máa lo àwọ̀n ẹ̀fọn tí wọ́n fi òògùn tó ń pa kòkòrò sí tí wón bá ti fẹ́ sùn.
Mínísítà fún èto ìlera ní orílẹ́-èdè Naijiria ọ̀jọ̀gbọ́n Isaac Adewole sọ wí pé ọ̀pọ̀lọ́pọ̀ àwọn ayédèrú òògùn tí ó wà ní ìta ni ó ń fa ìkùna tí ó lágbára jù fún ipa láti mú òpin bá àìsàn ibà ní orílẹ̀-èdè yí.
Àjọ àgbáyé tí ó ń rí sí ìlera sọ wí pé àìsàn ibà ń pa ọmọdé kọ̀ọ̀kan ní ìṣẹ́jú méjìméjì. Mẹ́sàń nínú ènìyàn mẹ́wàá tí àìsàn ibà bá pa ni ó jẹ́ ọmọ ilẹ̀ Afrika.
Ní orílẹ̀-èdè Naijiria, ẹ̀ka ilé iṣẹ́ ìjọba tí ó ń rí sí ìlera sọ wí pé mẹ́tàdínlọ́gbọ̀n nínú ọgọ́rùn un ènìyàn ni àìsàn ibà ń bá jà.
Mínísítà Adewole sọ wí pé tí Naijiria bá kápá iba, àìsàn náà yóò fẹ́ẹ̀ tán ní Afrika.
Kí ló dé gan an, tí àìsàn ibà kò tíì lọ pátápátá láti igbà tí a ti ń ba a jà ní orílẹ̀ èdè Naijiria? Ọ̀jọ̀gbọ́n Onayade sọ wí pé àwọn ẹ̀fọn tí ó ń fa ibà ti ní agbára àtakò sí ọ̀pọ̀lọ́pọ̀ àwọn òògùn ibà tó wà níta.
Sùgbọ́n ó gbà pé, ọ̀pọ̀lọ́pọ̀ ǹkan ni a lè ṣe láti ríi pé àìsàn ibà lọ pátápátá.
Àwọn wo ni àìsàn ibà burújù lára wọn?
Ọ̀jọ̀gbọ́n Onayade ní àwọn aláboyún àti àwọn ọmọ ọwọ́ títí dé ọmọ ọdún márùń ni.
Ó ní àwọn wọ̀nyí ni àìsàn ibà máa ń ṣe ikú pa ní ọdọọdún jù.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Àwọn aláboyún àti ọmọ ọwọ́ sí ọdún márùń gbọ́dọ̀ máa lo àpò ẹ̀fọn tí wọ́n fi òògùn tó ń pa kòkòrò sí tí wón bá ti fẹ́ sùn.
Àyájọ́ ọjọ́ àìsàn ibà ló máa ń wáyé ní ọjọ́ karùndínlọ́gbọ̀n oṣù kẹrin ní ọdọọdún.
Ní ti ọdún yìí, bí a ṣe lè dópin àìsàn náà ni ó gbayé kan, tí ọ̀pọ̀lọpọ̀ àwọn ènìyàn ń fi èró ọkan wọn hàn lórí àìsàn náà.
Fani-Kayode: Iwà Dino dójútini gẹ́gẹ́ bí olóṣèlú
Oríṣun àwòrán, Twitter
Fídíò ṣe àfihàn Dino níbi tí o joko sí ilẹ̀ l'ojú títì ní Ábuja
Mínísítà nígbà kan rí, Femi Fani-Kayode, ti bẹnu àtẹ́ lu ìwà Sẹ́nétọ̀ Dino Melaye, nígbà tí àwọn ọlọ́pàá ń gbée látì Abuja lọ sí Kogi tí ó sì fẹsẹ̀ fẹ.
Ẹ ó rantí wí pé ní ọjọ́ ìṣẹgun ni ìròyìn gbálẹ̀ pé Dino ti jọ̀wọ́ ará rẹ̀ fún àwọn ọlọ́paa. Kò pé sí ìgbà náà ni àwọn fídíò bẹrẹ sí ní gba orí ẹ̀rọ ayélujára, to ṣe àfihàn Dino níbi tí o joko sí ilẹ̀ láàrin ojú títì ní Ábuja.
Fani-Kayode sọ lórí Twitter ní Ojoru wí pé bí Melaye ṣe hùwà nínú fídíò ìṣẹ̀lẹ̀ náà kò fi akin àti iyì hàn.
Ó ní, kò yẹ ènìyàn tó jẹ́ Sẹ́nétọ̀ hùwà bẹ́ẹ̀, bí ó ti lẹ̀ jẹ́ pé òun kórira bí Aare Muhammadu Buhari ṣe ń ṣe sí àwọn tí ó gbe sórí oyè.
Àwọn aṣòfin so ìjókòó rọ̀ nítorí Dino Melaye
Oríṣun àwòrán, @dinomelaye
Asofin Melaye ti figba kan korin 'Ajekun Iya' si awọn alatako rẹ ni ọdun 2017.
Ilé ìgbìmọ̀ aṣòfin àgbà l'Abuja ti fún ọ̀gá àgbà ọlọ́pàá ní orílẹ̀-èdè Nàíjìrà Ọgbẹ́ni Ibrahim Idris ní gbèǹdéke ọjọ́ kan láti wá farahàn níwájú ilé.
Wọ́n ní kó wá sàlàyé fún ilé bí àwọn agbófinró tí sètò bí wọ́n ti se mú Sẹ́nẹ́tọ̀ Dino Melaye l'ọ́jọ́ Isẹ́gun.
Kódà wọ́n so ìjókòó fún ọjọ́rùú rọ̀ kí gbogbo ilé lè l'àǹfání láti lọ ṣe àbẹ̀wò sí Dino ní ilé ìwòsaǹ.
Adeoola Soetan bu ẹnu ẹ̀tẹ́ lu àwọn olóṣèlú lórí iṣẹ́ ọwọ́ wọn pé bí àwọn agbófinró ṣe mú Sẹ́nẹ́tọ̀ Dino Melaye yẹn dára.
Kí ó lè jẹ́ àwòkọ́ṣe fún àwọn tó kù
Àwọn aṣòfin so ìjókòó rọ̀ nítorí Dino Melaye
Èwẹ̀, alákóso ẹgbẹ́ tó n rí sí bí ìjọba àwarawa yóo ṣe fẹsẹ̀ múlẹ̀, ọ̀gbẹ́ni Adéọlá Ṣóẹ̀tán, sọ pé, Dino ń se àpèjúwe bí àwọn olóṣèlú orílẹ̀-èdè Nàíjìrà ti rí.
Ilé-ẹjọ́ ìlú Èkó fi Nwaoboshi sátìmọ́le fún ìkówójẹ
Oríṣun àwòrán, Nwaoboshi /twitter
Ilé ẹjọ́ fi Peter Nwaoboshi sátìmọ́lé di òpin ọ̀sẹ̀
Ilé-ẹjọ́ ìjọba àpapọ̀ tí Ìlú Èkó tí sọ Sẹ́nétọ̀ Peter Nwaoboshi tíì ṣe ọmọ ẹgbẹ́ People's Democratic Party tó ń soju fún ẹkùn Delta North sewon.
Muhammed Idris dájọ pé kí Nwaoboshi wà látìmọ́lé di ọjọ́ Jimo tí ilé ẹjọ́ yóò fi ṣe àgbéyèwò gbígba oniduro rè.
Àjọ EFCC ló gbé Sẹ́nétọ̀ náà lọ sile ẹjọ́ lórí ẹ̀sùn ikowo ìlú pamọ́.
Sambisa: Yóò di ibi ìgbàfẹ́ láìpẹ́ ọjọ́
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ìbáṣepọ̀ àjọ ọmọogun pẹ̀lu ìjọba ìpínlẹ̀ Borno yóò ran àtúnṣe sambisa lọ́wọ́
Olórí àwọn ọmọogun orile-ede Naijiria Tukur Buratai sọ pé ibùdó àwọn Boko Haram tẹ́lẹ̀ rí nínú igbó sambisa kò ní pẹ di ibi ìgbàfẹ́.
Tukur sọ̀rọ̀ yìí lásìkò tí àjọ tó ń rí sì ìrìn-àjò ìgbàfẹ́ sabewo sii.
Ó ní Àjọ tó ń mojuto irinajo ìgbàfẹ́, ìjọba Ìpínlẹ̀ Borno àti àjọ ọmọogun tí ń jíròrò lórí kókó náà.
Ó ní sísọ ìbè di ibi ìgbàfẹ́ yóò fi ìgbàgbé sí àwọn tí tí ṣẹlẹ̀ yóò sì tún mú ìlò igbó Sambisa kojú òṣùwọ̀n
Àwọn olólùfẹ́ Bayern Munich ya wọ orí pápá lẹ́yìn ìdíje
Oríṣun àwòrán, AFP
Àwọn olólùfẹ́ Bayern Munich yarí fún ọmọ egbẹ́ agbábọ́ọ̀lù náà
Àjọ tó ń rí sí eré bọ́ọ̀lù nílẹ̀ aláwọ̀ funfun-UEFA ti fi ẹ̀sùn kan ikọ̀ agbábọ́ọ̀lù Bayern Munich lẹ́yìn tí àwọn olólùfẹ́ wọn ya wọ orí pápá.
Eléyìí ṣẹlẹ̀ lẹ́yìn tí Bayern Munich fìdí rẹmi pẹ̀lú ayò kan sí méjì nínú ìfẹsẹwọnsẹ̀ wọn pẹ̀lú ikọ̀ Real Madrid nínú eré bọ́ọ̀lù tó kángun sí àṣekágbá Champions League.
UEFA tún fẹ̀sùn kàn ikọ̀ agbábọ́ọ̀lù náà pé àwọn olólùfẹ́ wọn ṣ'àfihàn àtẹ tí wọ́n kọ ọ̀rọ̀ àlùfàńṣá sí nínú pápá ìṣeré wọn.
Ọkan lára àwọn olólùfẹ́ wọn tilẹ̀ faṣọ mọ́ agbábọ́ọ̀lù wọn, Frank Ribery, lọ́rùn nígbà tí òmíràn ya fọ́tò pẹ̀lú ọmọ agbábọ́ọ̀lù alátakò Real Madrid lẹ́yìn tí ìfẹsẹwọnsẹ̀ náà parí
Ìgbẹ́jọ́ náà yóò wáyé ní ọjọ́kọkànlélọ́gbọ̀n osù karùn ọdún yìí.
ọ̀gọ̀ọ̀rọ̀ èèyàn bẹnu ẹ̀tẹ́ lu ìbẹ̀wò Dino láìṣe iṣẹ́ ìlú
Oríṣun àwòrán, Aminu Omoye
Ọnà tí Dino fi farapa ninu ìṣẹlẹ náà ko ti daju
Òrọ̀ ti bẹ́yìn yọ báyìí
látàrí bí àwọn ọmọ Ilé ìgbìmọ̀ aṣòfin àgbà l'Abuja ti so ìjókòó rọ̀ nítorí Dino Melaye lọ́jọ́rùú láti lọ ṣàbẹ́wò sí Dino Melaye
Àwọn Sẹ́nẹ́tọ̀ náà korò ojú sí bí àwọn ọlọ́ọ̀pá ṣe mú Dino Melaye tí gbogbo wọn sì lọ wòó ní ilé ìwósàn.
Sùgbọ́n ọ̀pọ̀lọpọ̀ èèyàn ló ti bu ẹnu ẹ̀tẹ́ lu ìgbésẹ̀ náà.
Àwọn kàn sọ pé, àwọn aṣòfin àgbà kó ọ̀rọ̀ náà kù, nítorí wọn kò lọ sí ìpínlẹ̀ Benue nígbà tí àwọn darandaran f'ẹ̀mí àwọn aláìṣẹ̀ ṣòfò.
Bẹ́ẹ̀ni wọn kò lọ sí Maiduguri níbi tí Boko Haram tí n fi ẹ̀mí àwọn ènìyàn ṣòfò.
Àbádòfin ogún ni àwọn Sẹ́nẹ́tọ̀ kò bá jíròró lé lórí nígbàtí ti wọ́n so ìjókòó ilé rọ̀ nítorí Dino Melaye lọ́jọ́ rùú.
Àwọn kàn ti ẹ̀ ńretí ìgbàtí àwọn aṣòfin àgbà l'Abuja yóò se àbẹ̀wò sí ìpínlẹ̀ Benue àti Maiduguri lẹ́yìn ìgbà tí wọ́n ti lọ wo Dino Melaye ní ilé ìwósàn.
Oríṣun àwòrán, @dino_melaye
Iléesẹ́ ọlọ́pàá ní, àwọn ti fi orúkọ Mélayé tó iléesẹ́ ọlọ́pàá ọ̀tẹlẹ̀múyẹ́ àgbáyé, Interpol, létí
Ó jẹ́ íyàlẹ́nu pé, nínú gbogbo àwọn Sẹ́nẹ́tọ̀ tó lọ wo Dino Melaye ní ilé ìwósàn, àwọn méjì péré ni àwọn ọlọ́pàá fààyè gbà láti ríi.
Eni tó lójú lojú tì. Èrò àwọn míràn ni pé  àwọn ọmọ Ilé ìgbìmọ̀ aṣòfin àgbà l'Abuja kò lojútì. Ìgbésẹ́ yìí sì lè s'àkóbá fún àwọn ọmọ wọn lẹ́yìnwá ọ̀la.
ọ̀pọ̀lọpọ̀ ló fàáké kọ́rí wípé kí àwọn Sẹ́nẹ́tọ̀ se àbẹ̀wò sí ìpínlẹ̀ Benue
Àìsàn ibà; Àwọn ènìyàn sọ̀rọ̀ nípa lílo ewé áti egbò
Ìfòyà ní Maiduguri bí Boko Haram ṣe ti ya wọ Bárékè
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ọmọ ogun Nàíjírà ń kojú Boko Haram ní àríwá ìlà ooòrùn
Ìròyìn tó ń tẹ̀ wá lọ́wọ́ láti ìlú Maiduguri ní ìpínlè Bornu ló ń sọ pé àwọn afẹ̀míṣòfò Boko Haram, ti ya wọ bárékè Giwa àwọn ológun ní ìlú náà.
Ọ̀rọ̀ ti di bóòlọ-o-yà-mi, báyìí ní agbègbè tí bárékè náà wà lẹ̀yìn tí àwọn Boko Haram dojú ìjà kọ àwọn ọmọ oogun ilẹ̀ Naijiria.
DSP Edet Okon, to jẹ́ agbẹnusọ fún àwọn ọlọ́pàá, tí ó bá ilé isẹ́ BBC Yoruba sọ̀rọ̀ fìdí rẹ̀ múlẹ̀ pé nkàn kò fara rọ báyìí ní ìlú Maiduguri.
Àwọn ará àdugbò bárékè náà sọ lórì Twitter wí pé àwọn ti ń gbọ́ ìró ìbọn látàárọ̀.
Ó dàbí pé àwọn ọmọ ogun ilẹ̀ ti gbé ìgbésè nítorí ọkọ̀ òfurufú ti ń fò kiri, tí ìró ìbọ̀n sì ti ń dínkù
Àwọn ológun kò tíì sọ̀rọ̀ lórí ìsẹ̀lẹ̀ náà.
Àìsàn ibà; Àwọn ènìyàn sọ̀rọ̀ nípa lílo ewé áti egbò
Mnangagwa: Ija Zimbabwe pẹ̀lú ilẹ̀ Gẹ̀ẹ́sì dópin lẹ́yìn ogún ọdún
Oríṣun àwòrán, AFP/Getty Images
Ààrẹ Mnangagwa ilẹ̀ Zimbabwe: ara kìí sá fún ara
Aarẹ orílẹ̀ èdè Zimbabwe, Emmerson Mnangagwa, ní ìjà dópin, ogun sì tán
Ó ní àjọṣepọ̀ orílẹ̀ èdè náà pẹ̀lú ilẹ̀ Gẹ̀ẹ́sì ni àwọn ṣẹ̀ṣẹ̀ bẹ̀rẹ̀ padà lẹ́yìn ọ̀pọ̀lọpọ̀ ọdún tí ààrẹ àná, Robert Mugabe, kò ti jẹ́ kí ọ̀rọ̀ orílẹ̀-èdè méjéèjì kò wọ̀ tẹ́lẹ̀.
Ọ̀rọ̀ orílẹ̀ èdè méjéèjì foriṣọ́npọ́n ní ọdún 1997, nígbà tí olórí ilẹ̀ gẹ̀ẹ́sì nígbà kan rí, Tony Blair, yọwọ́ kùrò nínú ìfọ̀rọ̀wérọ̀ lórí ọ̀rọ̀ àtúntò ilẹ̀ tí Robert Mugabe gbé kalẹ̀.
Nígbà náà, Mugabe fi ẹ̀sùn kan lẹ̀ Gẹ̀ẹ́sì pé ó ń dá sí ọ̀rọ̀ Zimbabwe tí kò kàn wón.
Ṣùgbọ́n ní báyìí, Mnangagwa ní orílẹ̀ èdè náà kò lè máa dá gbé mọ́ o.
Ìjọba san N135m gbàmábínú fun ìdílé àwọn ti wọ́n pa ní Apo
Oríṣun àwòrán, Federal Judicial Service Commission
Malami pín sọ̀wédowó fún àwọn ìdílé àwọn tí ó kú ní Abuja ní Ọjọ́bọ.
Ó pé ọdún márùń tí ikọ̀ ọmọ ogun Naijiria àti àwọn ọ̀tẹlẹ̀múyẹ́ kọlù àwọn kan.
Ikọlù yìí jẹ́ sí ilé àwọn aṣòfin tí wọn kò tíì parí ní Apo/Gudu, Abuja.
Ijọba àpapọ̀ ti san N135m owo gbà-má-bínú fún ídílé àwọn mẹ́jọ tó kú nínú ìkọlú náà.
Nínú ìkọlù náà tí ó ṣẹlẹ̀ ní oṣù kẹsàń odun 2013, yàtọ̀ sí àwọn tó kú, àwọn mọ́kànlá ni ò fara pa.
Mínísítà fún ìdájọ́ àti ọ̀rọ̀ ofin Mr. Abubakar Malami (SAN) ni ó pín sọ̀wédowó fún àwọn ìdílé àwọn tí ó kú náà ní Abuja ní Ọjọ́bọ.
Chidi Odinkalu, tó jẹ́ alága Ìgbìmọ ẹlẹ́ni mẹ́ta tí àjọ ajàfẹ́tọ́ gbé kalẹ̀ salaye nínú àbájáde rẹ̀ ní oṣù kẹrin ọdún 2014 pé ìjọba àpapọ́ ni ó ṣokùnfà ikú àwọn ẹni mẹ́jọ náà.
Àjọ náà ni ó tún sọ pé kí ìjọba san owó náà fún àwọn idílé àwọn tí ó kú.
Àwọn tí wọ́n ṣe 'kú pa nínú ìkọlù náà jẹ́ bíì ọmọ ọdún méjìdínlógún sí márùnlélógún.
Kókó ìròyìn: Òrọ̀ lórí lílo ewé áti egbò fún àìsàn ibà
Èyí ni àwọn àkójọpọ̀ ìròyìn ti tòní.
Àìsàn ibà; Àwọn ènìyàn sọ̀rọ̀ nípa lílo ewé áti egbò
Àìsàn ibà; Àwọn ènìyàn sọ̀rọ̀ nípa lílo ewé áti egbò
Ọjọ́ Karùndínlọ́gbọ̀n, Oṣù Kẹrin ọdọọdún ni Àjọ Àgbáyé yà sọ́tọ̀ láti kọjù ìpèníjà àisan ibà tó wọ́pọ̀ ní ilẹ̀ Afirika, èyí tó ti ṣekúpa ọ̀gọ̀ọ̀rọ̀ ènìyàn.
Ọ̀gọ̀ọ̀rọ̀ èèyàn bẹnu ẹ̀tẹ́ lu ìbẹ̀wò àwọn aṣòfin sí Dino láìṣe iṣẹ́ ìlú
Oríṣun àwòrán, Aminu Omoye
Ọnà tí Dino fi farapa nínú ìṣẹ̀lẹ̀ náà kò tíì dájú
Ọ̀rọ̀ ti bẹ́yìn yọ báyìí bí àwọn ọmọ Ilé ìgbìmọ̀ aṣòfin àgbà l'Abuja ti so ìjókòó rọ̀ nítorí Dino Melaye l'ọ́jọ́rú láti lọ ṣàbẹ́wò sí Dino Melaye
Àwọn Sẹ́nẹ́tọ̀ náà korò ojú sí bí àwọn ọlọ́ọ̀pá ṣe mú Dino Melaye, tí gbogbo wọn sì lọ wòó ní ilé ìwósàn.
Sẹ́nétọ̀ Nàìjíríà tó ń lo ayédérú ìwe ẹ̀rí
NUC: 'Ayédèrú n'ìwé ẹ̀rí sẹ́nétọ̀ Foster'
Sẹ́nétọ̀ Ogola tó ti ń sàfihàn àseyọrí ìwé ẹ̀rí tó sì ti ń lò ó fún pàtàkì òsèlú rẹ̀.
Sùgbọ́n ní báyìí, ìwádìí fi hàn pé àwọn ìwé ẹ̀rí oyè Phd tó gbà nínú ìmọ̀ adarí krìstẹ́nì èyí tó gbà láti fásitì tí àjọ NUC kò fọwọ́ sí jẹ́ ayédèrú.
Àwọn ǹkan míràn tí ẹ ní láti mọ̀ lónìí.
'Kò sí ẹni tí èmi kò lè firun èèyàn yàwòrán rẹ̀'
Irun gígẹ̀ kọjá orí fífá lásán
Arsenal ta ọ̀mì pẹ̀lú Athletico nínú ìdíje Europa
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Gbogbo akitiyan ikọ Arsenal lati tun fi kun ayo ti wọn gba wọle lo ja si pabo
Ọmi ni ẹgbẹ agbabọọlu Arsenal ati Athletico Madrid ta ninu ifẹsẹwọnsẹ akọkọ ipele to kangun si aṣekagba idije Europa to waye ni papa iṣere Emirate lalẹ ọjọbọ.
Bi o tilẹ jẹ wi pe ikọ Arsenal lọwọ rẹ moke ju ninu ifẹsẹwọnsẹ naa lẹyin ti oludari ifẹsẹwọnsẹ naa ti le agbabọọlu Athletico kan jade Sime Vrsaljko laarin iṣẹju mẹwa ti ifẹsẹwọnsẹ naa bẹrẹ, ẹkọ ko ṣoju mimu fun Arsenal.
Lacazette, agbabọọlu Arsenal lo kọkọ fori gbe bọọlu wọle  nigba ti ifẹsẹwọnsẹ naa wọ wakati kan.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Abala keji ifẹsẹwọnsẹ yii yoo waye ni ọjọọbọ ọsẹ to n bọ
Lẹyin eyi gbogbo akitiyan ikọ Arsenal lati tun fi kun ayo ti wọn gba wọle lo ja si pabo.
Amọṣa, nigba ti ifẹsẹwọnsẹ naa ku bii iṣẹju mẹsan ni Anthony Griezmann, agbabọọlu Athletico gba goolu tirẹ wọle lẹyin aṣiṣe kan to waye lọwọ balogun ikọ Arsenal, Laurent Koscielny.
Abala keji ifẹsẹwọnsẹ yii yoo waye ni ọjọọbọ ọsẹ to n bọ lorilẹ€de Spain lati mọ ikọ ti yoo pegede lọ si ipele aṣekagba idije Europa.
Arsenal fẹ́ ṣe bíi Barcelona
Sẹ́nétọ̀ Nàìjíríà tó ń lo ayédérú ìwe ẹ̀rí
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Marseile gbo ewuro si oju Red Bull Salzburg pẹlu ami ayo meji si odo
Eyi ni idije ilẹ Yuroopu ti o kẹyin olukọni ere bọọlu Arsenal bayii, Arsene Wenger pẹlu bi o ti ṣe kede pe oun yoo fipo silẹ ni ipari saa idije bọọẹu to n lọ lọwọ yii.
Ni ifẹsẹwọnsẹ keji to waye, Marseile lati orilẹede France gbo ewuro si oju Red Bull Salzburg lati orilẹede Austria pẹlu ami ayo meji si odo.
Florian Thauvin ati Clinton Njie lo gba ayo meji naa wọle.
Olórí ilé aṣòfin ìpínlẹ Ọyọ, Michael Adeyemo jáde láyé
Oríṣun àwòrán, facebook/Michael Adeyemo
Abẹnugan ilé aṣòfin ipinlẹ Ọyọ, Michael Adeyemo jáde láyé
Olori ile aṣofin ipinlẹ Ọyọ, Aṣofin Michael Adeyemo ni iroyin  sọ pe o ti jade laye.
Ninu ọrọ to ba BBC yoruba sọ, akọwe ipolongo fun ẹgbẹ oṣelu APC ni ipinlẹ Ọyọ, ọgbẹni Mojeed Olaoya, ṣalaye wi pe, ko tii si ẹni tó le sọ pato ohun to ṣokunfa iku rẹ, ṣugbọn o fọwọ rọri ku ni.
Lasiko ti a fi n ko iroyin yii jọ, wọn ti gbe oku aṣofin Michael Adeyemo lo si ile igbokusi.
Ile aṣofin ipinlẹ Ọyọ ko tii fi iroyin sita lori iku rẹ.
Ẹkunrẹrẹ iroyin laipẹ...
Ẹbi yóò sèwádìí ohun tò pa Michael Adéyẹmọ
Oríṣun àwòrán, @Micadeyemo
Kí ó tó kú, ẹkùn ìdìbò ìlà oòrùn Ìbàràpá ni aṣòfin Adeyẹmọ ṣojú fún
Àyẹ̀wò yóò wáyé lórí òkú Olori ile aṣofin ipinlẹ Ọyọ, aṣofin Michael Adeyẹmọ tó dagbere fáyé lówúrọ̀ ọjọ́ ẹtì.
Iléèwòsàn ńlá UCH nílù Ìbàdàn ni àyẹ̀wò yii yoo ti waye.Ọ̀kan lára àwọn mọ̀lẹ́bí olóògbé náà kan tí kò fẹ́ kí wọ́n dárúkọ rẹ̀ ló fi ọ̀rọ̀ yìí tó aṣojúkọ̀ròyìn BBC Yorùbá, Rótìmí Ọ̀kédáre létí nílùú Ìbàdàn.
Ṣáájú iyànsípò rẹ̀ gẹ́gẹ́ bíi olórí ilé aṣòfin ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́, òhun ni igbákejì akójánu ilé náà
Ó ní wọn pinnu ìgbésẹ̀ yìí láti mọ ohun gan an tó ṣokùnfà ikú rẹ̀.Olori ile aṣofin ipinlẹ Ọyọ, Aṣofin Michael Adeyẹmọ kú sí ilé ìwòsàn Jericho nílùú Ìbàdàn tí ìròyìn sì sọ pé àìsàn ọkàn ló paá.
Páropáro ni ile olóògbé náà dá nígbàtí akọ̀ròyìn BBC Yorùbá de ilé rẹ̀
Páropáro ni ile olóògbé náà dá nígbàtí akọ̀ròyìn BBC Yorùbá de ilé rẹ̀ tó wà lágbègbè Agodi GRA nílùú Ìbàdàn.
Bákanáà ní wọ́n ti ṣí ìwé ìbánikẹ́dùn kan síwájú ilé ìgbìmọ̀ aṣòfin àti ilé ìjọba ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́ lórúkọ rẹ̀ .
Oríṣun àwòrán, facebook/Rt Hon Michael Adeyemo
Iléèwòsàn ńlá UCH nílùú Ìbàdàn ni àyẹ̀wò yii yoo sì ti waye
Kí ó tó kú, ẹkùn ìdìbò ìlà oòrùn Ìbàràpá ni aṣòfin Adeyẹmọ ṣojú fún.Ṣáájú iyànsípò rẹ̀ gẹ́gẹ́ bíi olórí ilé aṣòfin ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́, òhun ni igbákejì akójánu ilé náà.
Àwo tuntun tí Simi gbé jáde, 'Simisọ́lá' gbayì fún un láwùjọ́
Oríṣun àwòrán, @The_Headies/iamsimi.com
Simi gba àmì ẹ̀yẹ
"Nínú ìfọ̀rọ̀wánilẹ́nuwò tí akọ̀ròyìn BBC Yorùbá se pẹ̀lú gbajúgbajà olórin ọmọ Nàìjíríà, Simisọla Bolatito Ogunleye, ó ní ""bí èèyàn bá ń se ǹkan, láti ní ìtẹ́wọ́gbà àti ìbò tó pọ̀ jù ni..., èmi kò rí ìpènijà nínú ìdìje fún àmì ẹ̀yẹ̀ yìí, ìsinilọ́kàn lé wà sùgbọ́n ó tún jẹ́ ohun t'ééyàn n'ífẹ sí""."
"Ó fi kún un wípé ""pẹ̀lú ìrétí, gbogbo ìsọ̀rí tó wà fún ìdíje yìí ni òun yóò ti gbégbá orókè""."
Àkókó yìí fẹ́ dà bí ọ̀kan lára èyí tó dára jù nínú isẹ́ orin tí Simi ńse. Àwo tó sẹ̀sẹ̀ gbé jáde, Simisọla ló ti ńwa ọ̀pọ̀lọpọ̀ iyì àti orúkọ fún un láwùjọ.
Ní lọ́ọ́lọ́ yìí ètò àmì ẹ̀yẹ X3M fún àwọn olórin ni Simi ti jáwe olúborí nínú ìdíje t'ọdún yìí fún àmì ẹ̀yẹ Headies èyí tí yóo wáyé nílu Èkó ní Ọjọ́ Kárun Osù Kárun ọdún 2018.
Pẹ̀lú ìpólówó àwọn mẹ́fà tí wọ́n yàn láti figagbága, Simi ló m'ókè jù nínú àwọn olórin náà tí àwọn míì tí wọ́n yàn kò sì ní tó ìbò.
Nínú àwọn àmúyẹ tí wọ́n fi yàn wọ́n ní obìnrin tóhún rẹ̀ jákè jù eléyìí tí wọ́n yan orin rẹ̀, 'Gone for Good' orin rẹ̀ tó gbilẹ̀ jù, Joromi ni wọ́n yàn fún àwo tí àgbéjáde rẹ̀ dára jù nígbàtí orin rẹ̀, 'Sinmisọ̀la' gbégbá orókè nínú ìsọ̀rí orin R&B tó yááyì jù àti àwo tó dára jù.
Bakan náà, orin ẹ̀ tó dá dúró jáde jù 'Smile for me'  ni yóò figbagbága nínú ìdíje ìsọ̀rí orin R&B tó dá dúró jù.
Láfikún, orin t'óùn àti Adekunle jọ kọ, Gold's No Forget wà lára èyí tí wọ́n yàn lára ìsọ̀rí àwọn orin alájọsepọ̀. Bákan náà wọ́n yan ẹni tí wọ́n jọ fí òntẹ̀ lu orin wọn, Praiz nígbà méjì nínú ìdíje àmì ẹ̀yẹ náà. Wọn kò mú Praiz fún ti olórin àdákọ R&B tó dára jù bẹ́ẹ̀ sì ni wọn ò mú u nínú ìsọ̀rí àwọn olórin tí ohùn wọ́n jákè jù.
Oṣó ni mí, àjẹ̀ ni mí - Brymo
Obinrin lo mu mi fẹran orin kikọ - Patoranking
Megabite: Ilé-ìwé ni mo ti bẹ̀rẹ̀ orin kíkọ
NEC fi òfin de dída ẹran ọ̀sìn kiri nìpínlẹ̀ márùn uń
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Darandaran Nàìjíríà gbọ́dọ̀ kọ́ ọgbà fún ẹran ọ̀sìn wọn báyìí
NEC bẹ̀rẹ̀ ìgbésẹ̀ wíwá ojútùú sí ìṣòro àwọn àgbẹ̀ àti àwọn darandaran pẹ̀lú òfin
Àwọn ìgbìmọ̀ alásẹ ìjọba àpapọ̀ orílẹ̀èdè Nàìjíríà, NEC, fọwọ́ sí àbádòfin àwọn ìgbìmọ̀ tí ìjọba yàn láti wá ojútùú sí ìjà ojoojúmọ́ láárín àwọn àgbẹ̀ àti àwọn darandaran gbé wá.
NEC gbé òfin kalẹ̀ pé kí gbogbo darandaran kọ́ ọgbà fún àwọn ẹran ọ̀sìn wọn bẹ̀rẹ̀ láti ìpínlẹ̀ Benue, Taraba, Adamwa, Plateau àti Kaduna kì àláfíà lè jọba ní àwọn ẹkùn wọ̀nyìí.
Òpọ̀lọpọ̀ ìgbà ni ìjà ti wáyé tó já sí ikú àti òfò dúkìá.
Ogbẹ́ni Tever Akase, tó jẹ́ agbẹnusọ ìpínlẹ̀ Benue, ba BBC Yoruba sọ̀rọ̀ pé ohun tó kù ni kí ìjọba àpapọ̀ pàṣẹ fún àwọn òṣìṣẹ́ elétò ààbò pé kí wọ́n fi òfin náà múlẹ̀ bí ó ti yẹ káàkiri.
Báyìí, ẹnu ìpínlẹ̀ Benue ti gba ọ̀rọ̀ lórí òfin darandaran rẹ̀
NEC fi òfin de dída ẹran ọ̀sìn kiri nìpínlẹ̀ márùn uń
NEC gbà pé ìgbẹ́sẹ̀ yìí yóò fòpin sí ìkọ̀lù àwón darandaran láti ilẹ̀ òkèèrè.
Àìsàn ibà; Àwọn ènìyàn sọ̀rọ̀ nípa lílo ewé áti egbò
PDP: A fẹ́ gba odindin Imo padà ni lọdún tó n bọ
Oríṣun àwòrán, Getty Images
PDP kò gbàgbọ́ nínú ètò ìdìbò ìjọba ìbílẹ̀ típínlẹ̀ Imo fẹ́ ṣe lóṣù keje ọdún yìí
Égbẹ́ òṣèlú People's Democratic Party (PDP) nipínlẹ̀ Imo ti ni ó ṣeéṣe kí ó má kópa nínú ètò ìdìbò tó m bọ̀
Ọjọ́ kẹrìnlá, oṣù keje ọdún yìí ni wọ́n ń pinnu kí ìdìbò fún yíyan alága ìjọba ìbílẹ̀ nípínlẹ̀ Imo wáyé.
Ọgbeni Damian Opara, tó jẹ̀ alukoro ẹgbẹ́ náà fún ipínlẹ̀ Imo, fi àtẹ̀jáde síta pé kí àwọn ọmọ ẹgbẹ́ rẹ fà sẹ́yìn nínú ètò ìdìbò náà
O ní ìgbésẹ̀ ìdìbò náà ti ń ni ǹkan míràn nínú, àfi ti àjọ elétò idìbò INEC bá gba àṣẹ ilé ẹjọ́ tó ga jùlọ pé kí wọn sún un síwájú.
PDP: A fẹ́ gba odindin Imo padà ni lọdún tó m bọ
Ogbeni Deji Doherty tọ jẹ́ ọmọ ìgbìmọ̀ amúṣẹ́ṣe ẹkùn ìwọ̀ oòrùn Naijiria ṣalaye ìpinnu ẹgbẹ́ PDP pé ìdìbò àpapọ̀ ló jẹ PDP lógún bayìí, kìí ṣe tìjoba ìbílẹ̀.
A kò tíì rì agbẹnusọ àpapọ̀ ẹgbẹ́ òṣèlú All Progressives Congress bá sọ̀rọ̀ di ìsinyìí.
Àtíkù: Ọbásanjọ́ kìí se Ọlọ́run tó leè ní kí ń má di ààrẹ
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ọjọ́ pẹ́ tí aáwọ̀ ti wà láàárín Ọbásanjọ́ àti Àtíkù
Igbákejì aarẹ tẹ́lẹ̀ ní Nàíjíríà, Àtíkù Abubakar ti kéde pé dandan kọ́ ni kí òun lọ fomí balẹ̀ ní orílẹ̀èdè Amẹ́ríkà, kí òun tó leè di ààrẹ orílẹ̀èdè Nàíjíríà.
Àtíkù kéde bẹ́ẹ̀ lásìkò tó ń bá BBC Hausa sọ̀rọ̀ lọ́jọ́ Sátidé nígbà tí wọn bií pé báwo ló se fẹ́ di ààrẹ orílẹ̀èdè Nàíjíríà láì kọ́kọ́ se ẹ ń lẹ́ ń bẹ̀un sí Amẹ́ríkà.
"Àtíkù wá ń bèèrè pé sé ""òfin kankan wà tó ní dandan ẹni tó bá fẹ́ jẹ ààrẹ orílẹ̀èdè Nàíjíríà gbọdọ̀ kàn sí Amẹ́ríkà ná, kí onítọ̀ún tó leè di ààrẹ?"""
Àmọ́sá, Igbákejì aarẹ tẹ́lẹ̀ náà fi ìdí rẹ̀ múlẹ̀ pé lóòtọ́ọ́ ni orílẹ̀èdè Amẹ́ríkà kọ̀ láti fún òun ní ìwé àsẹ ìwọ̀lú wọn, nígbà tí òun bèèrè fún un.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ọ̀pọ̀ ìgbà ni Àtíkù Abubakar ti ń gbìnyànjú láti di ààrẹ Nàíjíríà
Bákan náà ni Àtíkù tún sọ̀rọ̀ lórí ọ̀rọ̀ kan tí ààrẹ tẹ́lẹ̀, Olóyè Olúsẹ́gun Ọbásanjọ́ sọ pé níwọ̀n ìgbà tí òun Ọbásanjọ́ bá sì wà ní ayé, Àtíkù kò leè di ààrẹ́ orílẹ̀èdè Nàíjíríà. Àtíkù ní sé Ọbásanjọ́ jẹ́ Ọlọ́run ni? kódà òun kò se àìsùn kankan lórí ọ̀rọ̀ yìí.
"'Tó bá jẹ́ ìfẹ́ Ọlọ́run ni kí ń di ààrẹ orílẹ̀èdè Nàíjíríà, kò sí ẹnikẹ́ni, tó fí mọ́ Ọbásanjọ́ tó leè pe Ọlárun ní ìjà."""
Barcelona fàgbà han Deportivo láti gba ife ẹ̀yẹ
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Andres Iniesta gba ife ẹ̀yẹ La liga pẹ̀lú Barcelona fún ìgbà ìkẹyìn kó tó kúrò níbẹ̀
Ikò Barcelona gba ife ẹ̀yẹ La liga lẹ́yìn tí wọ́n f'àgbà han ẹgbẹ́ agbábọ́ọ̀lu Deportivo La Coruna pẹ̀lú àmìn ayò mẹ́rin sí méjì
.Àgbàọ̀jẹ̀ agbábọ́ọ̀lu n nì Lionel Messi ló gbá àmìn ayò mẹ́ta wọle, tí ikọ̀ ẹgbẹ́ agbábọ́ọ̀lu náà fi jáwé olúborí nínú ìdíje náà.
Èyí ni ìgbà karùndínlọ́gbọ̀n tí ikò Barcelona yóò gba ife ẹ̀ye La liga.
Ẹgbẹ́ agbábọ́ọ̀lu alátakò Real Madrid ní wọ́n ti gba àmin ẹ̀yẹ náà lẹ́ẹ̀mẹtàlélọ́gbọ̀n.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Messi fakọyọ pẹ̀lú àmìn ayò mẹ́ta nínú ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ tó wáyé láàrin Barcelona àti Deportivo
Ìgbà kẹrìndínlọ́gbọ̀n nìyí tí Messi yóò gbá àmìn ayò mẹ́ta wọle nínú ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ kan ṣoṣo fún ikọ̀ ẹgbẹ́ agbábọ́ọ̀lu tí o'ń sojú àti orílẹ́-èdè rẹ̀.
Mourinho fẹ́ kojú Wenger nínú ìdíje miràn yàtọ̀ sí EPL
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Mourinho kan sáárá sí Wenger fún isẹ́ tó ṣe nínú eré bọ́ọ̀lù ilẹ̀ Gẹ̀ẹ́sì
Akọ́nimọ̀ọ́gbá ikọ̀ Manchester United Jose Mourinho ǹ gbèrò láti bá alátakò rẹ̀ Arsene Wenger pàdé lọ́jọ́ iwájú.
Wenger tó ti jẹ́ akọ́nimọ̀ọ́gbá fún ẹgbẹ́ agbábọ́ọ̀lu Arsenal fún bí ọdún méjìlélógún ló fìdí rẹmi pẹ̀lú ikọ̀ rẹ̀ pẹ̀lú ayò méjì s'ódo ní Old Trafford lọ́jọ́ àìkú.
Ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ náà ló jẹ́ àgbákẹ́yìn fún Wenger nílé Man U k'ótó fipò rẹ̀ sílẹ̀ ní Arsenal lópin sáà yìí.
Wọ́n se ìmọyì fún Wenger kí ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ náà tó bẹ̀rẹ̀.
Àgbàọ̀jẹ̀ akọ́nimọ̀ọ́gbá Man U tẹ́lẹ́ rí Alex Ferguson l'ógbé ife fàdákà náà fún Wenger láti mọ'yì rẹ̀.
Mourinho wòye pé òun àti Wenger sì lè pàdé nńú ìdíje mìíràn yàtọ̀ sí Premier League nílẹ̀ Gẹ̀ẹ́sì.
Adájọ́ rán agbẹjọ́rò àgbà lọ sẹ́wọ̀n oṣù kan
Oríṣun àwòrán, JNCLAWFIRM
Nwobike ní òótọ́ ni òun fi ìfìwéránṣẹ́ sí àwọn òṣìṣẹ́ náà
Ilé ẹjọ́ kan ní Ìpínlẹ̀ Èkó ti rán agbẹjọ́rò àgbà kan Joseph Nwobike lọ s'ẹ́wọ̀n oṣù kan lorí ẹ̀sùn  pé ó fẹ́ yí da ojú òfin bolẹ̀.
Adájọ́ Raliat Adebiyi tí ó gbọ́ ẹjọ́ Nwobike, so pé àjọ tí ó ń kojú ìwà jẹgúdújẹrá tí a mọ̀ sí EFCC ti fi hàn dájúdájú pé agbẹjọ́rò àgbà náà bá àwọn òṣìṣẹ́ ilé ẹjọ́ kan sọrọ̀ láti jẹ́ kí wọ́n máa gbé àwọn ẹjọ́ rẹ̀  lọ sí iwájú àwọn adájọ́ ti ó fẹ́.
EFCC fi ẹ̀sùn kan Nwobike pé ó fẹ́ fi owó ránṣẹ́ si adájọ́ àgbà méjì, Mohammed Yunusa ati Hyeladzira Nganjiwa, láti rí i pé wọ́n dá ẹjọ́ tí yóò tẹ lọ́rùn. Ṣùgbọ́n ó ní òun kò jẹ̀bi.
Ṣùgbọ́n ilé ẹjọ́ fi àwọn ìfìwéránṣẹ́ rẹ̀ pẹlú àwọn òṣìṣẹ́ ilé ẹjọ́ méjì sọ̀rọ̀ déédé lórí ète yìí.
Nwobike ní òótọ́ ni òun fi ìfìwéránṣẹ́ náà ṣọwọ́ sí àwọn òṣìṣẹ́ náà ṣùgbón kìí ṣe láti fẹ́ yí dà ojú òfin bolẹ̀.
Trump: Bí wọn se ń pa Kristiẹ́ni kò jẹ́ ìtẹ́wọ́gbà
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Aarẹ mejeeji yoo sọrọ nipa eto aabo, ọrọ ajẹ ati idokowo laarin orilẹede mejeeji
Àarẹ ilẹ̀ Amẹrika Donald Trump, ti sọ pé ìṣekúpa àwọn ọmọlẹ́yìn Krístì nílẹ̀ Nàíjírià gbódọ̀ dópin.
Àarẹ Trump sọ̀rọ̀ náà, nígbà tí ó ń gbàlejò akẹgbẹ́ẹ rẹ̀ láti Nàíjíríà, Àarẹ Muhammadu Buhari nílé ìjọba Amẹrika, White House.
Àarẹ ilẹ̀ Amẹrika wá bu ẹnu àtẹ́ lu dídáná sun ṣọ́ọ̀ṣì nílẹ̀ Nàíjírià, o sì rọ ìjọba àpapọ̀ l'áti ṣe ètò ààbò tó múnádóko fún àwọn àwùjọ tọ́rọ̀ kàn.
Ìmọ̀ràn Trump yìí wáyé lẹ́yìn tẹgbẹ́ àwọn ọmọlẹ́yìn Krístì nílẹ̀ Nàíjírià CAN, sọ pé kí àarẹ Buhari kọ̀wé fipò sílẹ̀ lórí ọ̀rọ̀ àwọn darandaran tó ń fẹ̀mí àwọn èèyàn ṣòfò.
Sùgbọ́n Àarẹ Trump sọ́ di mímọ̀ pé, ìjọba ilẹ̀ Amẹrika yóò ṣísẹ́ pẹ̀lú ìjọba Nàíjírià láti fòpin sí àkọlùkọgbà náà.
Ninu ọ̀rọ̀ rẹ̀, Àarẹ Muhammadu Buhari sọ pé, wàhálà àwọn darandaran níí se pẹ̀lú làáṣìgbò tó ṣẹlẹ̀ nílẹ̀ Libya lẹ̀yìn iku ààrẹ Muammar Ghaddafi.
NLC: Ìgbà kẹta rèé tẹ́gbẹ́ òsìsẹ́ yóò wàákò pẹ̀lú ìjọba lábẹ́ Wabba
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Awọn gomina lawọn o le san ọgbọn ẹgbẹrun Naira f'oṣiṣẹ
Ọjọ Kẹrinla, Osu Kẹrin,ọdun 2018 ni ẹgbẹ awọn osisẹ lorilẹede Naijiria yan Comrade Ayuba Wabba gẹgẹbi  aarẹ ẹgbẹ naa.
Lati igba yii ni Ayuba Wabba gẹgẹbi adari ẹgbẹ ti bẹrẹ si ni kopa ninu igbesẹ fun agbelarugẹ awọn osisẹ ati fifi owo kun owo osu wọn lorilẹede Naijiria, eyi to n mu iyansẹlodi lọwọ nigba miran.
Irufẹ igbesẹ  bẹẹ lo fẹ waye ni Ọjọ Kẹfa, Osu Kọkanla, Ọdun 2018, tawọn osisẹ si fẹ faraya pẹlu ijọba lati beere fun ẹkunwo sugbọn Wabba sọ fun awọn osisẹ to n mura lati da isẹ silẹ naa pe, eyi ko lee ri bẹẹ mọ.
Minimum wage: Àwọn ọmọ Nàìjíríà sọ èrò wọn lórí ìyanṣẹ́lódì àwọn òṣìṣẹ́
Lara awọn ohun ti wọn si fi pẹtu sawọn osisẹ lọkan pe iyansẹlodi naa ko wulo mọ ni pe, igbimọ tijọba gbe kalẹ ati ẹgbẹ osisẹ yoo joko sepade, ti wọn yoo si fẹnu ọrọ jona.
Lẹyin ipade naa si ni wọn yoo polongo gbedeke owo osu osisẹ ni irọle Ọjọ Isẹgun, Osu Kọkanla, ọdun 2018.
Ẹgbẹ oṣiṣẹ ti so iyanṣẹlodi to fẹ ẹ gun le l'ọjọ Iṣẹgun lati beere fun afikun owo oṣu rọ bayii.
Ẹgbẹ NLC sọ fun BBC pe wọn so iyanṣẹlodi naa rọ, lẹyin ti ijọba gbe igbimọ ẹlẹni mẹta kalẹ lati jiroro lori owo oṣu tuntun fun awọn oṣiṣẹ.
Lekan Kingkong: Níbikíbi tí mo bá wà, màá gbé àṣà Yorùbá ga
Aarẹ ẹgbẹ naa, Ayuba Wabba to kede ọrọ naa lalẹ ọjọ Aje sọ pe, igbesẹ ti ẹgbẹ oṣiṣẹ gbe waye lẹyin ti awọn ati ijọba fẹnuko, ti wọn si fi ọwọ si iwe adehun.
Bo tilẹ jẹ wipe Wabaa ko sọ iye ti ijọba gba lati san fun oṣiṣẹ, o sọ pe, ikede owo oṣu tuntun yoo waye lọjọ Iṣẹgun lẹyin ti igbimọ ẹlẹni mẹta naa ba gbe abọ iwadi rẹ fun Aarẹ Muhammadu Buhari.
Ẹgbẹ́ NLC n fẹ ki ijọba maa san ẹgbẹrun lọna ọgbọn naira gẹgẹ bi owo oṣiṣẹ to kere ju lọ, ṣugbọn awọn gomina sọ pe awọn ko le san ju ẹgbẹrun mejilelogun.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
NNPC sọ pe awọn to n lo ọkọ ati awọn to tun n lo eporọbi fun awọn nkan mi ko ni ohunkohun lati bẹru
Ileeṣẹ to n mojuto ipese epo rọbi ni Naijiria, National Petroleum Corporation, NNPC ti ni, ko si nkan to jọ pe epo bẹtiro yoo di ọwọn gogo ni orilẹede Naijiria.
Ninu atẹjade kan ti ileeṣẹ naa fi sita lori ẹrọ ayelujara rẹ, Ọga agba ileeṣẹ NNPC lẹka ibaṣepọ araalu, Ọgbẹni Ndu Ughamadu, sọ pe ileeṣẹ naa ni epo rọbi toto lo fun ọjọ mọkandinlogoji, ati pe epo rọbi to wa nilẹ lọwọlọwọ, yoo to lo fun ọjọ mẹẹdọgbọn.
O sọ pe, awọn eeyan to n lo ọkọ ati awọn to tun n lo epo rọbi fun awọn nkan mii, ko ni ohunkohun lati bẹru nitori pe ileesẹ naa ni anito lati fun wọn ni ohun gbogbo ti wọn nilo.
Ireti Yusuf: Ìsòro àti fẹjọ́ sùn ló ń mú kí ìwà ìfipábánilòpọ̀ gbilẹ̀ si
Agbẹnusọ ileeṣẹ NNPC ọhun sọ pe, ikede naa di dandan fun wọn lati ṣe nitori awuyewuye to n lọ kaakiri ilu pe, o sẹeṣe ki awọn eniyan ma ri epo ra jakejado Naijiria, nitori iyanṣẹlodi ti ẹgbẹ oṣiṣẹ fẹ ẹ gun le.
Ughamadu wa gba awọn to n wa ọkọ lati maa ṣe ra epo pamọ, nitori pe, ileeṣẹ naa yoo ṣe gbogbo nkan to ba le ṣe lati ri i daju pe, iyanṣẹlodi naa ko ni ipa buruku lara bi wọn ṣe n pin epo kaakiri Naijiria.
O ni ki gbogbo awọn ọmọ Naijiria maa kuna lati jẹ ki ileeṣẹ to n risi idiyele eporọbi, DPR, tabi awọn agbofinro,  mọ nipa awọn ileepo to ba gbiyanju lati lo anfaani bi nkan ṣe ri l'orilẹede yii lati fi ara ni araalu
Iroyin kan ti sọ tẹlẹ pe, o ṣeéṣe kí adínkù bá epo bẹntiróòlù lọsẹ̀ yìí gẹ́gẹ́ bí ẹgbẹ́ àwọn òṣìṣẹ́ ilé iṣẹ́ epo bẹntiróòlù àti afẹ́fẹ́ gáàsì, NUPENG ṣe fi àtìlẹ́yìn wọn hàn fún ẹgbk àpapọ̀ òṣìṣẹ́, NLC.
Ìjọba àpapọ̀ sì ti gba àṣẹ ilé ẹjọ́ látọ̀dọ̀ ilé ọjọ́ tó ń rí sí ọ̀rọ̀ ilé iṣẹ́ lọ́jọ́ ẹtì láti dẹkun gígùn lé ìyanṣẹ́lódì àwọn òṣìṣẹ́.
Oríṣun àwòrán, Facebook/NLC
NUPENG ti ìyanṣẹ́lódì NLC lẹ́yìn
Ẹ̀wẹ̀, ẹgbẹ́ oṣiṣẹ lapapọ lorilẹede Naijiria ti fi aake kọri wọn ni dandan laa, awọn yoo gun le iyanṣẹlodi miran lọjọ Iṣẹgun ti i ṣe ọjọ kẹfa oṣu kọkanla ti ijọba ba kọ lati maa san ọgbọn ẹgbẹrun naira gẹgẹ owo oṣu oṣiṣẹ to kere julọ.
"Nígbà tí wọ́n bí NUPENG bóyá wọn yóò dara pọ̀, èsì tí ààrẹ NUPENG Prince Akporeha fọ̀ ni pé ""ṣé a ò kí ń ṣe ẹ̀ka àpapọ̀ ẹgbẹ́ òṣìṣẹ́ ni? ṣé NUPENG dá wà ni? Dájú dájú a wà pẹ̀lú NLC."
"Nígbà tí wọ́n rán an létí pé ìjọba àpapọ̀ mà ti gba àṣẹ ilé ẹjọ́ láti dá wọn lẹ́kun, ààrẹ NUPENG ní, ""à ń retí àṣẹ""."
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Awọn gomina lawọn o le san ọgbọn ẹgbẹrun Naira f'oṣiṣẹ
Aarẹ ẹgbẹ oṣisẹ, NLC Ayuba Wabba ni ẹgbẹ naa ko mọ ohun kankan nipa aṣẹ ti ile-ẹjọ pa, bẹẹ ni awọn ko gba iwe kankan lati ile-ẹjọ.
Ọgbẹni Wabba fi kun ọrọ rẹ pe igbesẹ ẹgbẹ oṣiṣẹ lapapọ nibi ipade ti wọn ṣe papọ loni ni lati gun le iyanṣẹlodi miran lọjọ Iṣẹgun.
Awọn gomina lawọn o le san ọgbọn ẹgbẹrun naira
Ẹgbẹ oṣiṣẹ ti fesi si ọ̀rọ̀ ti awọn gomina sọ pe ''awọn ko le san ju ẹgbẹrun mejilelogun ati ẹẹdẹgbẹta Naira gẹgẹ bi owo oṣu oṣiṣẹ to kere ju.''
Oríṣun àwòrán, Facebook/NLC
Ẹgbẹ́ òṣìṣẹ́ sèwọ́de
Nibi ipade oniroyin kan to waye nilu Abuja ni awọn adari ẹgbẹ oṣiṣẹ ti fi ohun ṣọkan pe awọn naa ko le gba owo oṣu to ba din ni ọgbọ̀n ẹgbẹrun gẹgẹ bi owo oṣu to kere ju.''
Wọn fi kun ọrọ wọn pe ki awọn gomina pada si ipinlẹ kaluku wọn, lati lọ duna-dura pẹlu awọn oṣiṣẹ wọn, kiiṣe ipinnu ajumọṣe.''
Ìyanṣẹ́lódì míràn ń kànlẹ̀kùn lẹ́yìn t'áwọn gómìnà sọ pé àwọn kò lè san ju #22,500 lọ fún 'Minimum wage.'
Ati wi pe ẹgbẹ́ awọn gomina ọhun, NGF, kiiṣe ẹgbẹ ti ofin da mọ, bikose ikorajọpọ awọn oloṣelu.''
Aarẹ ẹgbẹ NLC, Ayuba Wabba sọ nibi ipade naa pe ''ti awọn gomina ba fi kọ̀ lati san iye ti awọn n beere fun, ohunkohun ko ni i di iwọde ti awọn fẹ ẹ ṣe jakejado orilẹede Naijiria l'ọjọ kẹfa, oṣu Kọkanla, ọdun 2018.
Ṣaaju ni awọn gomina ipinlẹ mẹrindinlogoji lorilẹ-ede Naijiria kede pe awọn ko le san ju ẹgbẹrun mejilelogun ataabọ naira lọ gẹgẹ bi owo osu oṣiṣẹ to kere julọ lẹyin ipade pajawiri ti wọn ṣe lọjọ Iṣẹgun.
Àwọn gómìnà sọ fun ẹgbẹ́ òṣìṣẹ́ lábẹ́ àbùradà NLC àti TUC pe àwọn kò lágbára láti san ọgbọ̀n ẹgbẹ̀rún tí wọn ń bèèrè fùn, bẹ́ẹ̀ni ìjọba àpapọ̀ náà ti sọ tẹ́lẹ̀ pé ẹgbẹ̀rún mẹ́ẹ̀dọ́gbọ̀n lohun lè san.
NLC: Àwọn olósèlú ń la títì láì sanwó osù torí owó tí wọn yóò rí lórí àkànse isẹ́
Èwẹ̀, alága ẹgbẹ́ àwọn ẹgbẹ́ òṣìṣẹ́ lábẹ́ àbùradà NLC Ayuba Wabba sọ pé ó sàn kí àwọn gómìnà lọ tún ìpàdé wọn ṣe, bíbẹ́ẹ̀kọ́ àwọn yóò gùn lé ìyanṣẹ́lódì míràn ni ọ́jọ́ kẹfà, Oṣù Kọkànlá.
Ẹgbẹ́ òṣìṣẹ́ ṣe ìwọ́de lọ́jọ́ Ìṣégun káàkiri orílẹ́èdè Nàìjírìa pe awọn ko ni gba din ni ọgbọn ẹgbẹrun náírà gẹ́gẹ́ bí owó oṣù òṣìṣẹ́ tó kéré jùlọ.
Omar Victor Diop: Ipa Áfíríkà nínú àkọsílẹ̀ ìwé kọja ògo tí wọ́n ń fún un lágbáyé
Ìwọ́de lórí ẹ̀kúnwó owó oṣù
ẹka ti ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́ ti darapọ̀ mọ́ àwọn ojúgbà wọn káàkiri Nàìjíríà níbi ṣíṣe ìwọ́de láti fẹ̀hónú hàn lórí owó oṣù òṣìṣẹ́ tí ó kéré jù.
Ìwọ́de náà bẹ̀rẹ̀ láti ọ́ọ́fìsì àwọn ẹgbẹ́ ọ̀ṣìṣẹ́ ní agbègbè Yidi, lọ sí Gate àti Mọkọla nílú Ìbàdàn.Wọ́n késí ìjọba àpapọ̀ láti wá ojútùú sí ọ̀rọ̀ owó oṣù òṣìṣẹ́ tí ó kéré jù.
Oríṣun àwòrán, AFP
Owó oṣù tuntun ọ̀hún nìrètí wà pé yóò gbérasọ l'óṣù Kẹjọ, ọdún 2018.
"Wọ́n sì ṣe àlàyé pé ẹgbẹ̀rún lọ́nà ọgbọ̀n naira tí àjọ náà ń béérè fún kò tó láti gbọ́ bùkátà àwọn òṣìṣẹ́.Wọ́n fi kún ọ̀rọ̀ wọn pé ọ̀pọ̀lọpọ̀ ìpèníjà ni àwọn òṣìṣẹ́ ń kojú lórí àtijẹ-àtimu bó tilẹ̀ jẹ́ pé ""àwọn ọmọ ilé ìgbìmọ̀ aṣọ̀fin orílẹ̀-ede Nàìjíríà ló ń gbówó jùlọ l'ágbáyé."
Awa naa n fẹ ẹkunwo owo oṣu
Ìwọdé naáà ń wáyé jákè-jádò àwọn ìpínlẹ̀ tó ń bẹ lórílẹ̀-èdè yìí láti kìlọ̀ fún ìjọba àpapọ̀ lórí ohun tí àwọn òṣìṣẹ́  ń bèèrè fún.Áwọn alákósó ẹgbẹ́ òṣìṣẹ́ náà ṣe àlàyé pé àwọn yóò gùnlé ìyanṣẹ́lódì aláìnígbèdéke láti ọjọ́ kẹfà, oṣù kọkànlá, odún yìí, bí ìjọba bá kọ̀ láti ṣe ohun ti wọ́n fẹ́.
"Kòsí iṣẹ́, kò sí owó ni ìjọba sọ fún àwọn òṣìṣẹ́ tó ń gbèrò láti dá iṣẹ́ sílẹ̀ tẹ́lẹ̀rí, sùgbọ́n níbáyìí, wọ́n ti dá ìjọba lóhùn wípé, ""kò sí owó oṣù, kò sí ìbò""."
Kí ló fàá tí owó oṣù tuntun fi ṣòro?
Ní ọdún 2011 ni wọn ṣe òfin pé ẹgbẹ̀rún méjìdínlógún naira ni yóò máà jẹ́ owó oṣù to kéré jù ní Nàìjíríà.
Ní ìgbà náà, wọ́n ń ra owó dola ní naira 155, sùgbọ́n ní bá yì dola kan ti di naira 363.
Eléyì jẹ́ díẹ̀ lára ìdí tí àwọn òṣìṣẹ fi ń jà fún fífi owó kún owó oṣù.
Àwọn ẹgbẹ́ òṣìṣẹ́ lábẹ́ àbùradà NLC àti TUC ẹ̀ka ti ìpínlẹ̀ Ọyọ ń ṣe ìwọ́de láti fẹ̀hónú hàn lórí owó oṣù òṣìṣẹ́ tí ó kéré jù.
Sùgbọ́n  ìjọ̀ba kọ̀ tíì pinnu lórí iye tí wọn yóò fi kún owó àwọn òṣìṣẹ́.
Láìpẹ́ yìí ni ìgbìmọ̀ àwọn gómìnà lórílẹ̀-èdè Nàìíríà ti sọ wí pé àwọn kò tako fífi owó kún owó àwọn òsìsẹ́, àmọ́ àwọn kò ní owó láti san án ni.
Lẹ́yìn náà ni àwọn ẹgbẹ́ àwọn òṣìṣẹ́ sọ̀ fún ìjọba pé kí owó òṣù tuntun tí ìjọba ṣe ìlẹ́rí má yẹ̀.
Alága ìgbìmọ̀ àwọn gómìnà náà tó jẹ́ gómìnà ìpínlẹ̀ Zamfara, Abdulaziz Yari fi èyí léde lásìkò tó ń bá àwọn oníròyìn sọ̀rọ̀, lẹ́yìn ìpàdé tí wọ́n ṣe ní ìlú Abuja.
Yari ní àwọn gómìnà ṣetán láti ṣe àtìlẹyìn fún fífi owó kún owó osìsẹ́, àmọ́ kò sí owó tàbí ohun àlùmọ́nì tí wọ́n yóò fi san àfikún owó oṣù náà.
Àmọ́sá, ẹgbẹ́ òṣìṣẹ́ ní Nàìjíríà ti f'ewé ọmọ mọ́ ìjọba àpapọ̀ létí láti máse jẹ́ kí ohunkóhun yẹ ṣíṣe ámúsẹ owó oṣù tuntun.
Owó oṣù tuntun ọ̀hún nìrètí wà pé yóò gbérasọ l'óṣù Kẹjọ ọdún 2018.
Ààrẹ ẹgbẹ́ nàá, Ayuba Wabba, fi ìkìlọ̀ nàá síta láìpẹ́  yìí lásìkò ìpàdé ìjíròrò t'ẹ́gbẹ́ nàá ṣe nílùú Abuja ní ìmúrasílẹ̀ fún ayẹyẹ ọjọ́ àwọn òṣìṣẹ́ fún ọdún 2018.
"Wabba ní ""Ẹgbẹ́ òṣìṣẹ́ yóò ri dájú pé ohunkóhun kò pagidínà àsìkò tí ìgbìmọ̀ tó wà fún ètò owó oṣù ní Nàìjíríà ti là kalẹ̀."""
"Ó fi kun pé ""àwọn òṣìṣẹ́, tó n pèsè ọrọ̀, gbọdọ̀ rí ìtọ́jú tó péye gbà, pàápà bí owó ọjà ṣe gbẹ́nu s'ókè."
Ẹgbẹ́ òṣìṣẹ́ nàá wá n bèérè fún sísọ owó oṣù wọn di ẹgbẹ̀rún mẹ́rìndínlọ́gọ́ta Naira.
Lẹ́yìn ìgbà náà ni àwọ̀n òṣìṣẹ́  yan ìṣẹ́ lódì fún ìgbà díè.
Wọ́n sì ń tún sọ wípé àwọn yóò sì padà da iṣẹ́ sílẹ̀ tí ìjọba kọ̀ bá gbé owó oṣù tuntun jáde.
Fídíò codeine: Iléesẹ́ Emzor gba‘sẹ́ lọ́wọ́ òsìsẹ́
Fídíò òògùn ikọ́ Codeine: Àpọ̀jù rẹ̀ ń ya ọ̀dọ́ ní wèrè
Fídíò lórí títà àti rírà oògùn ikọ́ olómi Codeine tí BBC fi síta ti ń bí oríṣíiríṣíi èrò láàrin àwọn ọmọ Nàìjíríà.
Èyí ni wọn fi tún ṣàfihàn èso burúkú tó ń bí láyé àwọn ọ̀dọ́ tó ń muú, pàápàá jùlọ, lẹ́kùn àríwá Nàìjíríà.
Emzor gbọnmú lóríi fídíò codeine
Àwọn aláṣẹ iléeṣẹ́ Emzor, tó jẹ́ ọ̀kan lára àwọn iléeṣẹ́ tó ń se òògùn ikọ́ olómi tó ní èròjà codeine síta, fi sí orí ìkànnì twitter wọn ní @emzornigeria pé, wọ́n ti fòpin sí pínpín oògùn ikọ́ olómi Codeine síta báyìí títí wọn yóò fi parí ìwádìí abẹ́lé tí wọ́n n ṣe.
Bákan náà ni Iléeṣẹ́ Emzor ti dá òsìsẹ́ wọn tó ń pín èròjà náà dúró.
Wọ́n tún ní kí àwọn òṣìṣẹ́ méjì míràn lọ rọọ́kún níle ná.
Aisha Buhari gbarata lórí fídíò Codeine
Aya aàrẹ Nàìjíríà, Aisha Buhari lórí instagram @aishambuhari, ti ké gbàjàrè sí àwọn òṣìṣẹ́ elétò ààbò, àwọn iléeṣẹ́ apoogùn, olùkọ́, alágbàtọ́, òbí, alájọgbélépọ̀ àti àwọn aṣòfin Nàìjíríà láti fọwọ́sowọ́pọ̀ pẹ́lú ìjọba ja ogun yíì lájàyè.
Èrò àwọn ọmọ Nàìjíríà yapa lóríi fídíò codeine
Mairo Mandara, nínú ìkànnì twitter rẹ̀ @Drmairomandara, sọ̀rọ̀ pé, kí ìjọba fòfin de ṣíṣe oògùn ikọ́ olómi Codeine lọ́dọ̀ àwọn iléeṣẹ́ tọ́rọ̀ kàn, bíi Emzor Pharmaceuticals, Bioraj Pharmaceuticals àti Peace Standard Pharmaceuticals
Nínú èrò ti Politbru ni ìkànnì twitter @Politbru, ní, ìsẹ̀lẹ̀ yìí ti ń ní ọwọ́ kan ẹlẹ́yàmẹ̀yà nínú. Ó bèèrè pé, Ìran Ìgbò nìkan ní ojú wà lára rẹ̀ láti ìgbà tí olùkọni kan láti fásitì Bayero ni àríwá Nàìjíríà ti fẹ̀sùn kan àwọn olókowò Igbò pé àwọn ni wọn ń pín Codeine.
Charles the first, ni ìkànnì twitter @9jaBloke ní, kí Codeine to dé ni àwọn ènìyàn kan ti ń fín ṣáláńgá símú bẹ́ẹ̀ iléeṣẹ́ Emzor ni à ń pariwo rẹ̀
NT IPOB AK47 Carrier ni ìkànnì twitter @idmann_mit gbà pé, tí ìjọba kò bá tètè dí àlàfo ti Codeine ti wọn kó nílẹ̀ yìí, ojú awọn tó ń lòó máa ṣí sí lílo ǹkan míràn ni. Ó ní kí ìjọba gbé ìgbésẹ̀ tó yẹ ní kíákíá
Davido: Mo fẹ́ràn Chioma púpọ̀, ọ̀la wa máa dára
Davido fi ọkọ̀ Porsche ṣe ayẹyẹ ọjọ́ ìbí fún Chioma Avril
Davido ṣe ìpinnu láti bá Chioma Avril gbé títí láí.
Gbajugbaja onkọrin nì, Davido Adeleke, ti fìfẹ́ hàn sí olólùfẹ́ rẹ̀, Chioma Avril, lasiko to n ṣe ayẹyẹ ọjọ ìbí ọdún metalelogun laye.
Oríṣun àwòrán, @davidoofficial
ọ̀rọ̀ ìfẹ́ lágbára
Davido fun un ni ọkọ̀ Porsche oní milionu marundinlaadọta naira  pẹlu nọ́mbà Assurance niwaju ati leyin ọkọ̀ ọ̀hún fún ìsàmì ayẹyẹ ọjọ́ ìbí Chioma.
ÀJẸPỌ́NNULÁ
Afénifẹ́re: Oníkálukú ni yóò tẹ̀ka síbi tó wù ú tó bá yá
Oríṣun àwòrán, YOUTUBE
Odumakin àti Adebanjo: Àwọn Ọba kàn ń sọ tẹnu wọn ni o
Ẹgbẹ Afénifẹ́re ṣe lòdì sí ọ̀rọ̀ àwọn Ọba ilẹ Yoruba kan.
Oloye Ayo Adebanjo ati agbẹnusọ fun Afénifẹ́re, Yinka Odumakin, sọ fun BBC pe awọn Ọba ode oni ń beru ijọba ni wọn ṣe n sọrọ atileyin fun Buhari lọdun 2019.
Wón ni ko sẹni tó lè tọ́ka ibi tí awọn Yoruba yoo fì sí ni idibo 2019 nitori pe kò si ìkókó mọ́ nínú oludibo.
Ọ̀rọ̀ yii jẹyọ latari ọ̀rọ̀ Oba Ilu Eko, Ọba Rilwan Akiolu, ni ọjọ Ajé pe, ki awọn Naijiria ti Aarẹ Buhari lẹyin fun saa keji.
Ọ̀sẹ̀ melo kan sẹhin ni Alake ti Ilẹ Ẹgba, Oba Adedotun Gbadebo, naa sọ pe oun fara mọ ki Buhari gbe igba ibo fun saa keji.
"Oloye Ayo Adebanjo so pé, ""Ka to gb'ominira, awọn Ọba kíi lọwọ ninu ọrọ̀ idibo."
Ipo Ọba laye atijọ maa n fi ógbón agba tọni sọna ni, ṣugbón ko ri bẹẹ mọ laye ode oni to jẹ pe, ti wọn ko ba ṣe ti ijọba to wa lode, ijọba le fiya jẹ wọn.
Awọn Ọba to n s'atilẹhin fun Buhari ko fi ohun ti awọn ọmọ ilẹ Yoruba fẹ han. Ọ̀rọ̀ bẹ́ẹ̀ ko mu'na doko l'ọdọ awọn eeyan rara.
O wa rọ awọn ọmọ ilẹ Yoruba ki wọn lọ gba kaadi idibo wọn.  O ni eyi lo maa fun wọn ni agbara lati yan eni ti wọn fẹ sipo to ba wu wọn.
"Ninu ọrọ rẹ, Odumakin ni, ""Ni ọdun 2015, Buhari da bi angeli, t'o n bọ wa yi gbogbo wahala Naijiria pada, ti ẹ ba wo ibo ti wọn di ni ilẹ Yoruba, Buhari ni ida mejilelaadota ibo, nigba ti, aarẹ ana Goodluck Jonathan, ni mejidinlaadota, ká má ṣẹṣẹ wa sọ isinyi. Enikeni ti o ba n sọ pe Buhari n bọ leekeji, ó n tan ara re jẹ pata ni."""
Àyájọ́ òṣìṣẹ́: NURTW gba ẹ̀jẹ̀ lára àwọn òsìsẹ
Awọn oṣisẹ naa ni gbogbo awọn ti wọn ṣe leṣe ni wọn ti gbe lọ sile ìwosan.
Ọ̀rọ̀ di bóòlọ-o-yà fún mi lónìí, ní ibi ayẹyẹ àyájọ́ àwọn òṣìṣẹ́ tó wáyé ní pápá ìṣeré Agége nilú Èkó nígbàtí àwọn ọmọ ẹgbẹ́ ọlọ́kọ̀-èrò NURTW kan bẹ̀rẹ̀ sí ní gún àwọn òṣìṣẹ́ kan lọ́bẹ.
Eléyìí  fa ìdàrúdàpọ̀, nínú èyí tí àwọn òṣìṣẹ́ fi fọ́nká, tí olúkúlùkù sì sá àsálà fún ẹ̀mí rẹ̀.
Àwọn tó bá akọ̀ròyìn BBC Yorùbá, Olu Alebiosu, sọ̀rọ̀ ní, àwọn ọmọ ẹgbẹ́ ọlọ́kọ̀-èrò ọ̀hún ṣà dédé kọlù àwọn ẹgbẹ́ òṣìṣẹ́ tí wọ́n tò kalẹ̀, ní ìgbáradì fún ètò yan-bí-ológun níwájú gómìnà ìpínlẹ̀ Èkó, Akinwunmi Ambode, láti kásẹ̀  ayẹyẹ náà nílẹ̀.
Nígbàtí aféfé wàhálà náà yóò fi rọlẹ̀, ọ̀pọ̀ àwọn òṣìṣẹ́  ni wọ́n ti farapa.
Nígbàtí aféfé wàhálà náà yóò fi rọlẹ̀, ọ̀pọ̀ àwọn òṣìṣẹ́ ni wọ́n ti farapa.
Ọ̀gbẹ́ni Gbénga Olugunna, tó jẹ́ ọ̀kan lára àwọn aṣáájú ẹgbẹ́ òṣìṣẹ́ lawọn ileesẹ tó ń se rọ́bà lórílẹ̀èdè Nàìjíríà, jẹ́ ọ̀kan lára àwọn ọmọ ẹgbẹ́ òṣìṣẹ́ tó fara káásá ìkọlù àwọn ọmọ ẹgbẹ́ ọlọ́kọ̀-èrò ọ̀hún.
Ò ni àwọn n gbaradi fún ètò yiyan-bí-ologun won, ni àwọn ọmọ ẹgbẹ́ ọlọ́kọ̀-èrò náà bá ṣíná ìyà fún àwọn.
 Awọn ọmọ ẹgbẹ wa ti wọn kọlu pọ. Awọn ọmọ ẹgbẹ ọlọkọ ero lo si kọlu wa.
"Gbogbo wa n to lati yan niwaju gomina nigba ti wọn ṣa dede gba ẹburu lai fẹ to. Gbogbo awọ̀n eeyan wa, paapaa julọ awọn to jẹ̀ obinrin ni wọn kọlu."""
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Gómìnà Akinwunmi Ambọ́de gan wà níkàlẹ̀ nígbàtí wàhálà yìí ń wáyé
Awọn oṣisẹ naa ni, gbogbo awọn ti wọn ṣe leṣe ni wọn ti gbe lọ sileewosan.
Nibi ti ikọ BBC Yoruba ti n ya aworan bi rukerudo yii ti n ṣẹlẹ, awọn ọlọpa kan ti ẹka amuṣẹya ileeṣẹ ọlọpaa nipinlẹ Eko gbiyanju, lati ja ohun eelo iyaworan wa gba, ki awọn lọgalọ́ga wọn kan to da sii.
Akitiyan lati kàn si awọn adari ẹgbẹ ọlọkọ ero NURTW nipinlẹ Eko, lo ja si pabo lasiko ti a fi nko iroyin yii jọ.
Òṣiṣẹ́ Emzor tó ta Codeine fun BBC ti bọ́ sọ́wọ́ ọlọ́pàá
Oríṣun àwòrán, Police
Codeine:Ọwọ́ ba òsìṣẹ́ Emzor
Ọwọ́ tí ba òsìṣẹ́ Emzor tẹ́lẹ̀ rí Chukwunonye Madubuike tó ta òògún ikọ́ olómí ọmọdẹ́, codeine fún ìkọ̀ BBC tó ṣe ìwádìí bònkẹ́lẹ́.
Agbẹ́nusọ fún àjọ ọlọ́pàá ìpínlẹ̀ Ekó, Chike Otu tó bá BBC sọ̀rọ̀ sàlàyé pé wọn gbá a mú lásìkò tó ń ta òògùn tí ìjọba ti fòntẹ̀ dè tó sì ti lòdì sófin.
Ó sàlàyé pé òsìṣẹ́ Emzor tẹ́lẹ̀rì ni Madubuike tó sì ń ta òògùn náà lọ́nà àìtọ́ nítori pé ó lẹ́tọ̀ọ́ si láti ilé iṣẹ́.
Fídíò òògùn ikọ́ Codeine: Ó dùn lóòtọ́ àmọ́ ewu ni
O ní bótilẹ̀ jé pé ó yẹ kí o tàá fún àwọn tó tí gba ìwé àṣẹ láti ta irú ǹkan bẹ́ẹ̀ tí wọn sì ní ilé ìtajà òògùn ló yẹ kí ó máà tàá fún, sùgbọn ó bẹ̀rẹ̀ sí ní tàá fún àwọn ti wọn o ma ṣìí òògùn náà lò.
Agbẹ́nusọ fún àjọ ọlọ́pàá ìpínlẹ̀ Ekó ní ọwọ́ àwọn agbófinró bàá ní òsẹ̀ tó kọjá ní Ìdí Ìrókò lásìkò tó ń gbìyànjú láti sá kúrò lórílẹ̀-èdè Nàìjíríà lọ sí orílẹ̀-èdè Benin Republic
Oti sàlaàyé pé àwọn ó ni pẹ́ gbé lọ sí ilé ẹjọ́.
Codeine: Ijọba àpapọ̀, ilé ìgbìmọ̀ aṣofin gbé ìgbésẹ̀ akin
Oríṣun àwòrán, Frankieleon
òpin dé bá lílo oògùn ikọ́ olómi Codeine àti Tramadol
Ijọba àpapọ̀ fòfin de títà àti rírà tramadol àti oògùn ikọ́ olómi to ni codeine
Lẹ́yìn ti BBC gbe fidio jade ti o fi ṣàfihàn ewu ńlá to wa ninu mímu àpọ̀jù iru oògùn ikọ́ báyìí ni òfin jáde lórí rẹ̀.
Minisita fun Ọrọ Ilera, Ọjọgbọn Isaac Adewole, sọ ni Abuja ni ọjọ Ẹtì, wi pe, oun ti fun ajọ ti ó ń gbogun ti ilokulo oògùn, ti a mọ si NAFDAC, ni àṣe lati ri i pe wọn kò fun ẹnikẹni ni iwe aṣẹ lati gbe oògùn naa wọle lati awọn orile-ede miran mọ́.
Oni oun gbe igbesẹ naa latari ilokulo oògùn ikọ́ ti o ni codeine ninu ni orile-ede yii.
"Minisita naa ni, ""A ṣe ipade pàjáwìrì pẹlu ajo ti ó ń ṣakoso oògun pípò ni orilẹ-ede yii ati NAFDAC, lati gba awọn oogun ikọ oni codeine pada kaakiri."
A tun ti pe ẹgbẹ awọn apoògun lati sọ fun wọn pe, a ti gbẹ́sẹ̀ lé awón oògùn naa.
Gbogbo awọn ajọ ti o nii ṣe pelu ọrọ yii ni a ti rọ lati foju sìta lori Codeine,Tramadol ati awọn oogun bẹẹbẹe.
Bakan naa, olori Ile Igbimo Asofin agba, Bukola Saraki, ti gboriyin fun BBC, fun fidio lori codeine naa, ninu agbejade kan ti agbenuso re fi ṣọwọ s'awọn oniroyin.
Saraki ni, ó fihan pe, Naijiria ni lati fọwọ́ líle mu ọrọ aṣilo oògùn bayii.
Saraki ni tori ọrọ yi ni Ile Igbimọ Aṣofin agba ṣe kó awọn ti ọrọ naa kan jọ ni Ipinle Kano ni osu Kejila odun 2017.
"O ni, ""Bi o ti lẹ jẹ pe mo ti n ṣiṣẹ lori ọrọ yii lati bii oṣu melo kan sẹyin, fidio BBC naa jẹ ki ọrọ naa wa ye mi daradara sii."
"Bi a ba ka'wọ gbera, ọrọ yii ko le lójútùú. Gbogbo wa ni ọrọ yi kan."""
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Saraki: Gbogbo wa ni ọ̀rọ̀ yíì kán báyìí
Sẹnetọ naa ni Ile Igbimo Asofin yoo gbe ofin jade lati kápá aṣilo oogun ni orilẹ-ede yi, pẹlu ofin miran ti yoo ṣetò iwosan fun awọn ti aṣilo oogun ti ya ni were sẹyin.
Lori ọrọ Codeine yi, aya aarẹ orile-ede yii ni ọrọ naa ba ni lẹru gan an ni gẹgẹ bi obi.
Oríṣun àwòrán, Aishabuhari
Aisha Buhari: ọ̀rọ̀ yìí kọnilóminú púpọ̀
Aisha Buhari sọ ninu atẹjade kan lori Instagram pe ki awọn agbofinro, aṣofin ati awọn tí o n ṣe oogun sọ ọrọ naa di ija ti awọn funra wọn yoo ja lati dẹkun ilokulo oogun.
Ẹ wo fidio naa nibi:
Fídíò òògùn ikọ́ Codeine: Àpọ̀jù rẹ̀ ń ya ọ̀dọ́ ní wèrè
Koko iroyin: Ìgbésẹ̀ ìjọba l'órí Codeine, ìkọlù NURTW níbi ayẹyẹ ọjọ́ òṣìṣẹ́
Eyi ni awọn akojọpọ iroyin ti toni.
Codeine:  Ijọba àpapọ̀ fòfin de oògùn ikọ́ tó ń dorí àwọn ọ̀dọ́ rú
Oríṣun àwòrán, Frankieleon
òpin dé bá lílo oògùn ikọ́ olómi Codeine àti Tramadol
Ijọba àpapọ̀ f'òfin de títà àti rírà oògùn ikọ́ olómi to ni codeine lẹ́yìn ti BBC gbe fidio jade ti o fi ṣàfihàn ewu ńlá to wa ninu mímu àpọ̀jù iru oògùn ikọ́ báyìí.
Minisita fun Ọrọ Ilera, Ọjọgbọn Isaac Adewole, sọ ni Abuja ni ọjọ Ẹtì, wi pe, oun ti fun ajọ ti ó ń gbogun ti ilokulo oògùn, ti a mọ si NAFDAC, ni àṣe lati ri i pe wọn kò fun ẹnikẹni ni iwe aṣẹ lati gbe oògùn naa wọle lati awọn orile-ede miran mọ́.
Afẹ́nifére: Àwọn Ọba kò lè júwe ìdìbò 2019
Oríṣun àwòrán, YOUTUBE
Odumakin àti Adebanjo: Àwọn Ọba kàn ń sọ tẹnu wọn ni o
Ẹgbẹ Afénifẹ́re ṣe lòdì sí ọ̀rọ̀ àwọn Ọba ilẹ Yoruba kan.
Oloye Ayo Adebanjo ati agbẹnusọ Afénifẹ́re, Yinka Odumakin Adebanjo, sọ fun BBC pe awọn Ọba ode oni ń beru ijọba ni wọn ṣe n sọrọ atileyin fun Buhari lọdun 2019.
Wón ni ko sẹni tó lè tọ́ka ibi tí awọn Yoruba yoo fì sí ni idibo 2019 nitori pe kò si ìkókó mọ́ nínú oludibo.
Ọ̀rọ̀ yii jẹyọ latari ọ̀rọ̀ Oba Ilu Eko, Ọba Rilwan Akiolu, ni ọjọ Ajé pe, ki awọn Naijiria ti Aarẹ Buhari lẹyin fun saa keji.
Àarẹ ilẹ̀ Amẹrika Donald Trump, ti sọ pé ìṣekúpa àwọn ọmọlẹ́yìn Krístì nílẹ̀ Nàíjírià gbódọ̀ dópin.
Trump sọ̀rọ̀ náà nígbà tí ó ń gbàlejò akẹgbẹ́ẹ rẹ̀ láti Nàíjíríà, Àarẹ Muhammadu Buhari nílé ìjọba Amẹ́rika, White House.
NURTW da ayẹyẹ àyájọ́ ọjọ́ òṣìṣẹ́ rú l'Ékó.
Àyájọ́ òṣìṣẹ́: NURTW gba ẹ̀jẹ̀ lára àwọn òsìsẹ
Ìjọba Ọ̀sun: N1.8bn ni OAU jẹ lówó orí òsìsẹ́ rẹ̀
Oríṣun àwòrán, Bose
Bílíọ̀nù kan àti ẹgbẹ̀rin mílíọ̀nù náírà, (1.8 bílíọ̀nù) ni fásitì OAU jẹ ìjọba ìpínlẹ̀ Ọ̀ṣun
Àjọ tó ń pawó wọlé lábẹ́lé, tó tún ń se kòkárí ówó orí nípínlẹ̀ Ọ̀ṣun, OIRS, ti gbé ìloro ọgbà fásitì Ọbáfẹ́mi Awólọ́wọ tó wa nílùú Ilé ifẹ̀ tì pa lórí ẹ̀sùn pé, ó jẹ owó orí to dín díẹ̀ ní bílíọ̀nù méjì náírà.
Owó orí tí fásitì OAU jẹ la gbọ́ wí pé, ó jẹ́ owó orí àwọn òṣìṣẹ́ rẹ, èyí tí kò san sínú aṣuwọ̀n ìjọba ìpínlẹ̀ náà lọ́dún 2015 si 2016.
Oríṣun àwòrán, Bose
Fásitì OAU ṣàlàyé pé àìgbọ́raẹniyé láàárín fásitì àti ìjọba ló fa ìṣẹ̀lẹ̀ náà
Àjọ náà gbé ìloro ọgbà fásitì náà tì pa lẹ́yìn tí gbèdéke ọjọ́ méje tí wọn fún OAU làti san owó orí ọ̀hun forí sánpọ́n.
Kùtùkùtù òwúrò ọjọ́rú làwọn òṣìṣẹ́ ikọ̀ amúṣẹ́yá láti àjọ olówó-orí ípínlẹ̀ Ọ̀ṣun, OIRS, gúnlẹ̀ sí ọgbà fásitì náà, tí wọ́n sì ti gbàgede ìgbìmò alákòóso tó ga jùlọ níléèwé náà ati ọ́fíísì ìṣàkóso níbẹ̀.
Lẹ́yìn  èyí ni wọ́n  mórí lé ìloro ọgbà fásitì náà tí wọ́n sì fi ẹ̀wọn tìí, ṣùgbọ́n wọ́n fi ààyè ìrìnnà ẹsẹ̀ sílẹ̀.
Oríṣun àwòrán, Bose
Gbèdéke ọjọ́ méje ni wọ́n fún fásitì náà làti san owó orí ọ̀hun.
Nígbà tó ń sọ̀rọ̀ lórí ìgbésẹ̀ tí wọ́n gbé náà, ollórí ikọ̀ amúsẹ́yá fọ́rọ̀ owó orí ní ìpínlẹ̀ Ọ̀sun, ọ̀gbẹ́ni Ọládípọ̀ Babátúndé ní, bílíọ̀nù kan àti ẹgbẹ̀rin mílíọ̀nù náírà, (1.8 bílíọ̀nù) ni fásitì náà jẹ ìjọba ìpínlẹ̀ Ọ̀ṣun, tí wọn kò sì  san-án nígbà tí gbèdéke tí wọ́n fún wọn pé.
Oríṣun àwòrán, Bose
Kùtùkùtù òwúrò ọjọ́ ọ̀rú làwọn òṣìṣẹ́ ikọ̀ amúṣẹ́yá láti àjọ olówó-orí nípínlẹ̀ Ọ̀ṣun, OIRS gúnlẹ̀ sí ọgbà fásitì náà
Àmọ́ ṣá, àwọn aláṣẹ fásitì náà ti ṣàlàyé pé, àìgbọ́raẹniyé láàárín fásitì náà àti ìjọba ìpínlẹ̀ Ọ̀ṣun ló fa ìṣẹ̀lẹ̀ náà.
Fásitì yìí ti bẹ̀rẹ̀ sísan àjẹẹ́lẹ̀ gbèsè owó orí náà láti ọdún 2017 ṣùgbọ́n òbítíbitì gbèsè owó orí tàwọn ìṣàkóso tó ti lo ìgbà kọjá jẹ sílẹ, ló ń fa wàhálà yii.
Ìdíje Champions league: Tani yóò tẹ̀síwájú láàárín Roma àti Liverpool?
Oríṣun àwòrán, @ChampionsLeague
Ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ àkọ́kọ́ ìpele yìí ti wáyé lọ́sẹ̀ tó kọjá
Ẹgbẹ́ agbábọ́ọ̀lù Roma àti Liverpool yóò kojú arawọn ni ìlú Róòmù lọ́jọ́rú láti leè mọ ẹni tí yóò tèsíwájú sí ìpele àsekágbá ìdíje Champions league ilẹ̀ Yúrópù.
Ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ àkọ́kọ́ ìpele yìí ti wáyé lọ́sẹ̀ tó kọjá níbití ikọ̀ agbábọ́ọ̀lù Liverpool ti fi àgbà han Roma pẹ̀lú àmì ayò márún sí méjì.
Oríṣun àwòrán, Liverpool FC
Ìlú Romu ni ikọ̀ agbábọ́ọ̀lù Liverpool ti gba ife ẹ̀yẹ yìí
Ohun tí ó ń mú kí àwọn èèyàn ó máa pọ́n ẹnu lá de ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ náà ni bí Roma ṣe yí ojú àwo padà fún Barcelona, lẹ́yìn tí Barcelona ti kọ́kọ́ ní àmì ayò Mẹ́ta sí òdo ni ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ wọn àkọ́kọ́ ni Camp nou.
Ohun míràn tún ní pé, ní ìlú Romu yí ni èèkàn agbábọ́ọ̀lù Liverpool ni, Mohammed Salah ti gba bọ́ọ̀lù gbayì kí ó tó gba ilẹ̀ Gẹ̀ẹ́sì lọ níbi tí ó ti wá di ẹ̀rùjẹ̀jẹ̀  fún àwọn alátakò báyìí.
Ohun mìíràn ni pe, ní ìlú Romu ni ikọ̀ agbábọ́ọ̀lù Liverpool ti gba ife ẹ̀yẹ yìí lọ́dun 1984.
Ṣé yóò bọ́sii tàbí kò ní bọ́ síi ? ni ìbéèrè tó gba ẹnu àwọn olólùfẹ́ ẹ ikọ̀ méjèèjì yí báyìí ṣùgbọ́n ohun kan tó dájú ni pé Real Madrid ni èyí kéyí ikọ̀ tó bá borí nínú àwọn méjèèjì yóò máa pàdé ni àṣekágbá.
Oríṣun àwòrán, Liverpool FC
Real Madrid ni èyí kéyí ikọ̀ tó bá borí nínú Roma ati Liverpool yóò máa pàdé ni àṣekágbá
Lójú olùkọ́ni ìkọ Liverpool, Jorgen Klopp, kò sí èyíkéyìí nínú àwọn ikọ̀ méjèèjì yìí tí kò tọ́ sí láti wọ ìpele àṣekágbá.
Bí a bá leè rí èsì tí a bá fẹ́  níbí, ó tọ́ sí wa láti dé ìpele àṣekágbá. Tó bá sì jẹ́  pé Roma ni, ó tọ́ sí àwọn náà pẹ̀lú.
Oríṣun àwòrán, Roma FC
Olùkọ́ni Roma, Eusebio di Francesco ní ìrètí òun ni pé, ìyanu tó wáyé nínú ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ wọn pẹ̀lú Barcelona yóò tún wáyé
Olùkọ́ni Roma, Eusebio di Francesco ní ìrètí òun ni pé, ìyanu tó wáyé nínú ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ wọn pẹ̀lú Barcelona yóò tún wáyé.
"A kìí  sába ń fún àwọn alátakò láǹfààní àti gbá bọ́ọ̀lù wọ àwọn wa.
A dúpẹ́ lọ́wọ́ àwọn olólùfẹ́ wa, àtìlẹ́yìn wọn ṣe pataki fun wa."
Oríṣun àwòrán, @ChampionsLeague
Agbabọọlu ikọ mejeeji ni wọn ti sese ti ko si ni kopa
Àwọn agbábọ́ọ̀lù márún nínú ìkọ̀ Liverpool ni kò ní kópa nínú ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ tòní.
Àkọ́kọ́ ni Alex Oxlade-Chamberlain tí ó ṣeṣe ní ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ ọ̀sẹ̀ tó kọjá.
Adam Lallana, Emre Can ati Joel Matip pẹ̀lú kò ní kópa.
Roma  pẹ̀lú yóò pàdánù Diego Perotti àti Kevin Strootman nítorí pé wọ́n ṣeṣe.
Iléeṣẹ́ ológun: ilé làbọ̀ ìsinmi oko láìpẹ́ f'Aṣàtìpó
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Iléeṣẹ́ ológun ní ìgbésẹ náà yóò ṣilẹkun fún ìdápadà ọrọ ajé lágbègbè tí ọ̀rọ̀ kàn
Àwọn èèyàn tí làáṣìgbò ìdúnkoòkò-mọ́ni lé kúrò nílé káàkiri àwọn agbègbè kan lórílẹ̀-èdè Nàìjíríà yóò padà sí ìlú àti ilé wọn láìpẹ́.
Iléeṣẹ́ ológun oríilẹ̀ lórílẹ̀èdè Nàìjíríà, ní gbogbo ipá ni wọ́n ti ń sà báyìí láti ríi pé àwọn èèyàn náà padà sí ìgbé ayé wọn, pàápàá jùlọ àwọn tó wá láti agbègbè adágún odò Chad.Iléeṣẹ́ ológun oríilẹ̀ lórílẹ̀-èdè Nàìjíríà ní èyí yoo lè jẹ́ kí ètò káràkátà níbẹ̀ dìde padà.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Iléeṣẹ́ ológun ní gbogbo ipá ni wọ́n ń sà báyìí láti dá àwọn èèyàn náà padà sí ìgbé ayé wọn
Tukur Yusuf Buratai, to jẹ́ ọ̀gágun àgbà iléeṣẹ́ ọmọogun oríilẹ̀, ní òun àti olórí ẹ̀ka àjọṣepọ̀ ará ìlú, Nuhu Angbazo, pẹ̀lú olórí ikọ̀ ọmọogun tó ń rísí ọ̀rọ̀ ààbò ní ẹkùn ìlà oòrùn àríwá Nàìjíríà, 'operation LAFIYA DOLE' ti bẹ̀rẹ̀ ìgbésẹ̀ lílọ sí àwọn agbègbè ni ìpínlè Yobe àti Borno.
Bakan naa ni wọ́n ti pè fún àtìlẹ́yìn àwọn gómìnà ìpínlẹ̀ méjèèjì.Iléeṣẹ́ ológun ní ìgbésẹ̀ tuntun tí wọ́n ṣẹ̀ṣẹ̀ gbékalẹ̀ yìí tí wọ́n dà pè ni 'operation LAST HOLD' yóò yẹ̀ ọ̀nà fún ìdápadà iṣẹ́ ẹja pípa, iṣẹ́ àgbẹ̀ àtàwọn iṣẹ́ ọrọ ajé lágbègbè adágún odò Chad.
Àwón akẹ́kọ̀ọ́ há sínú Ṣáláńgá tó wó nílé ìwé alákọ́bẹ̀rẹ̀
Oríṣun àwòrán, AFP
Ṣáláńgá ibi ìgbọ̀nsẹ̀ tó lè di pósí bí a kò bá ṣọ́ra
Àwọn akẹ́kọ̀ọ́ ṣẹ̀ṣẹ̀ wọlé sáà ètò ẹ̀kọ́ tuntun ni Kenya, ni Ṣáláńgá wó nílé ìwé alákọ́bẹ̀rẹ̀ Kisulisuli, ti ẹkun Nakuru, ni orílẹ̀-èdè Kenya, tí àwon akẹ́kọ̀ọ́ sì há sinu rẹ̀.
Bíi aago mẹ́jọ̀ owuro niroyin gba igboro kàn pe àwọn akẹ́kọ̀ọ́ ti há sínú Ṣáláńgá tó dàwó nílé ìwé alákọ́bẹ̀rẹ̀ Kisulisu náà.
Awọn òbí àti alágbàtọ́ sáre darapọ̀ mọ́ àwón olùránlọ́wọ́ nínú ìṣẹ̀lẹ̀ pàjáwìrì lati dóòlà ẹ̀mí àwón akẹ́kọ̀ọ́ ọ̀hún.
Tẹ́lẹ̀ wón kò mọ̀ iye àwón akẹ́kọ̀ọ́ to rì síbẹ̀, ṣugbón bayii, ọ̀ga àgbà ílé ìwé alákọ́bẹ̀rẹ̀ Kisulisu fìdí ẹ̀ múlẹ̀ pé wọ́n ti ri gbogbo áwọn akẹ́kọ̀ọ́ mefeefa náà yọ tán.
Ṣáláńgá meedogbon ló dàwó nìlé ìwé alákọ́bẹ̀rẹ̀ Kisulisuli yìí lataari àrọ̀ọ̀rọ̀dá òjò tó ń rọ̀ lati ǹkan bii ọ̀sẹ̀ merin seyin ni Kenya, ṣugbon ko si ẹni tó farapa.
Ilé ìwé alákọ́bẹ̀rẹ̀ Kisulisuli, lo tobi ju ni ìwọ̀ oòrùn Kenya ni Bungoma.
Ó tó akẹ́kọ̀ọ́ 3,500 to wà nílé ìwé alákọ́bẹ̀rẹ̀ Kisulisuli.
Òndó: Ọ̀gá àgbà àjọ ẹ̀ṣọ́-aláàbò ojúupópó (FRSC) dolóògbé
Oríṣun àwòrán, @FRSC AKURE/ FACEBOOK
Ọ̀gbẹ́ni Jack jáde láyé lẹ́yìn àìsàn ránpẹ́.
Ọ̀gbẹ́ni Vincent Jack, tó jẹ́ ọ̀gá àgbà àjọ ẹ̀ṣọ́ aláàbò ojúupópó (FRSC) ní ìpínlẹ̀ Òndó ti jáde láyé.
"Ọ̀gbẹ́ni Vincent Jack, ""papòdà lẹ́yìn tó ti wà ní ìdùbúlẹ̀ àìsàn, èyí tó mú kó ma lè ṣiṣẹ́ rẹ̀ daadaa fún ìgbà díẹ̀."""
Oríṣun àwòrán, FRSC/ TWITTER
Ọ̀gá àgbà àjọ ẹ̀ṣọ́ aláàbò ojúpópó (FRSC) ní ìpínlẹ̀ Òndó ti jáde láyé
Adarí ẹ̀ka ìsẹ́ nínú àjọ nàá ní ìpínlẹ̀ Òndó, Ọ̀gbẹ́ni Oluṣẹ́gun Ògúngbémidé sọ fún BBC pé Ọ̀gbẹ́ni Jack jáde láyé lóòrọ̀ kùtù ọjọ́ kejì, oṣù Karùn, lẹ́yìn àìsàn ránpẹ́.
Ó ní ọjọ́ orí olóògbè n bẹ láàrin àádọ́ta ọdún sí ọgọ́ta.
Ìjọba Nàíjíríà leè kógbáwọlé nítorí áíbuwọ́ lu àbà ìṣúná ọdún 2018
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Àìbuwọ́lu àbà ìṣúná ọdún 2018 ti ń kọ àwọn òǹwòye lóminú
O ṣeéṣe kí ìjọba orílẹ̀èdè Nàíjíríà ó paná bí wọn kò bá buwọ́ lu àbà ìṣúná ọdún  2018 kí ó tó di  oṣù kẹfà.
Àwọn onímọ̀ nípa ọrọ̀ ajé tí wọ́n bá BBC Yorùbá sọ̀rọ̀ lóríi pípẹ́ tí ìgbésẹ̀ láti buwọ́ lu àbà ìṣúná ń pẹ́.
Wọ́n ní ìpalára kékeré kọ́ ni èyí ń ṣe fun ètò ọrọ̀ ajé pàápàá ìdókoòwò láti òkè òkun àti ìpèsè iṣẹ́.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ìpalára tí àìbuwọ́lu àbà ìṣúná ń ṣe fún ìpèsè iṣẹ́ kò kéré
Ọ̀gbẹ́ni Túndé Ọlátúnjí ní 'yóò ṣe àkóbá fún àwọn tó fẹ́ dókòwò láti òkè òkun àti ìpèsè iṣẹ́.'
Lóòótọ́ ko ṣẹlẹ̀ rí ṣùgbọ́n bí wọn kò bá buwọ́ lù ú kí oṣù kàrún tó parí, nígbà tí a bá wọ oṣù kẹfà, o ṣeéṣe kí wọ́n tilẹ̀kùn ìjọba.
O ní àwọn ẹ̀ka ọrọ̀ ajé bíi àkànṣe iṣẹ́, ìlàkalẹ̀ ètò ìṣèjọba, àti ìpèsè adùn ìjọba fáráàlú.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ní oṣù kọkànlá ọdún 2017 ni Ààrẹ Mùhámádù Bùhárí̀ gbé àbá ìṣúná ọdún 2018 síwájú ilé ìgbìmọ̀ aṣòfin àpapọ̀
Ní oṣù kọkànlá ọdún 2017 ni Ààrẹ Mùhámádù Bùhárí̀ gbé àbá ìṣúná ọdún 2018 síwájú ilé ìgbìmọ̀ aṣòfin àpapọ̀, sùgbọ́n títí di akoko yìí  kò tíì sí àṣeyọrí kan lórí rẹ̀.
Onírúurú àwáwí àti ẹsùn ni ẹ̀ka ìjọba ń kéde lórí ìdì tí kò fi tíì bọ́  síi.
Dogara: Ohunkóhun kò gbọdọ̀ ṣe Dino Melaye
Oríṣun àwòrán, @HouseNGR
Àwọn aṣojú-ṣòfin gbarata lórí ọ̀rọ̀ Dino
Olórí ilé aṣojú-ṣòfin lórílẹ̀-èdè Nàìjíríà, Yakubu Dogara, ti f'ohùn ránṣẹ́ s'awọn agbófínró pé ohunkóhun kò gbọdọ̀ ṣe Sẹ́nétọ̀ Dino Melaye ti wọ́n gbé lọ sílé ẹjọ́ lórí kẹ̀kẹ́ aláìsàn lọ́jọ́ ọ̀rú àti ọjọ́bọ.
"Níbi ìjòkó ilé ni Dogara ti sọ ọ̀rọ̀ yìí nígbà tí aṣòfin Sunday Karimi, láti ìpínlè Kogi pe àkíyèsí ilé náà sí ìgbésẹ̀ àwọn ọlọ́pàá láti gbé Melaye lọ sí ilé ẹjọ́ lórí kẹ̀kẹ̀ aláìsàn.Dogara ní ""a kò leè torí pé a fẹ́ gbé èèyàn kan lọ síwájú ilé ẹjọ́, ká gba ẹ̀mí lẹ́nu ẹni bẹ́ẹ̀. Bì ohunkóhun bá ṣe Dino, àwọn agbófínró ni yóò forí fá a."""
Mi kò rí orílè-èdè tí wọ́n ti ń gbé aláìsàn tó wà lórí kẹ̀kẹ̀ aláìsàn lọ sí ilé ẹjọ́, ti ẹni bẹ́ẹ̀ kò leè dáhùn ìbéèrè Adájọ́ láti sọ bóyá òun jẹ̀bi tàbí òun kò jẹ̀bi.
Àwọn aṣojú-ṣòfin gbarata lórí ọ̀rọ̀ náà ṣùgbọ́n Dogara rọ̀ wọ́n  láti fí ọkàn balẹ̀ nítorí àwọn aṣòfin àgbà tí ń yẹ ọ̀rọ̀ náà wò. Ní Ọjọ́bọ̀ ni àwọn ọlọ́pàá gbé Sẹ́nétọ̀ Dino Melaye  lọ sí ilé ẹjọ́ lórí kẹ̀kẹ́ tí adájọ́ sì kọ̀  láti gba  onídúró rẹ̀.Aṣòfin Karimi ni àwọn alágbára kan ni ìjọba ló ń dùn mọ̀huru mọ́ Dino nitori iha tó ń kọ sí ìjọba.
Adamu: Olùkọ̀ 2,295 ni Boko Haram pa láàárín ọdún mẹ́sán
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Àwọn olùkọọ́ tí orí kó yọ ti fọ́n káàkiri àwọn ìpínlẹ̀ Yobe, Borno àti Adamawa
Ǹjẹ́ o mọ̀  pé Olùkọ́ tó lé ni ẹgbẹ̀rún  méjì ló ti kú sínú làásìgbò ìkọlù Boko Haram lẹ́kùn ìlà oòrùn àríwá Nàíjíríà?
Mínísítà fétò ẹ̀kọ́ lórílẹ̀-èdè Nàìjíríà, Adamu Adamu, ló ṣàlàyé èyí níbi ìdánilẹ́kọ̀ọ́ lórí ààbò níléèwé tó wáyé nílùú Abuja.Mínísítà Adamu Adamu, tó kọminú lórí bí àwọn agbébọn ṣe ń dojúkọ ètò ẹ̀kọ́, ṣàlàyé pé ẹgbẹ̀rún méjì ó lé márún dín lọ́ọ̀dúnrún olùkọ́ ní àwọn agbébọn Boko haram ti pa, tí ẹgbẹ̀rún mọ́kàndínlógún míràn sì ti fọ́n káàkiri àwọn ìpínlẹ̀ Yobe, Borno àti Adamawa láàárín ọdún mẹ́sán sẹ́yìn.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ìjọba àpapọ̀ ní òun ń sa ipá gbogbo láti wawọ́ ìkọlù iléèwé bọlẹ̀
Mínísítà fétò ẹ̀kọ́ ni yàtọ̀ sí èyí, ẹ̀ẹ́dẹ́gbẹ̀jọ iléèwé làwọn agbébọn Boko Haram ti bà jẹ́ láàrín ọdún 2014 sí àsìkò yìí.O ní orílẹ̀-èdè Nàíjíríà ti làkàkà láti wá nǹkan ṣe sí ìpèníjà yìí bii fífọwọ́sowọ́pọ̀ pẹ̀lú àwọn àjọ aṣèrànwọ àti alátìlẹ́yìn gbogbo láti ríi pé ààbò wà fún àwọn akẹ́kọ̀ọ́, olùkọ́ àti iléèwé lẹ́kùn náà.
Ekiti Election: Èyí ni àwọn olóṣèlú Nàìjíríà tó tí 'fọ́gbọ́n ṣàìsàn'
Oríṣun àwòrán, @ogundamisi
Fayose kọ́ ni olóṣèlú Nàìjíríà tí yóò kọ́kọ́ 'kán l'ọ́rùn'
Oríṣiríṣi awuyewuye ló tí jẹyọ lórí ìṣẹ́lẹ́ tó wáyé ní ìpínlẹ̀ Ekiti l'Ọ́jọ́rú, níbití Gómìnà Ayọdele Fayose ti 'kán l'ọ́rún' nípasẹ̀ afẹ́fẹ́ tajú-tajú.
Fayose fi ẹ̀sùn kan ìjọba àpapọ̀ Nàìjíríà pé ó rán àwọn ọlọ́pàá sí ìpínlẹ̀ Ekiti láti pá òun ṣáàjú ètò ìdìbò gómìnà tí yóò wáyé lọ́jọ́ kẹrìnlá, òṣù Keje.
Èrò àwọn aráàlú kò jọ ara wọn lórí ọ̀rọ̀ Fayosẹ. Bí àwọn kan sẹ gbàgbọ́ pé ọgbọ́n arékérekè ni Fayose n dá, ni àwọn kan ni ìfìyà jẹ ni ìṣẹ̀lẹ̀ nàá.
Ọ̀pọ̀lọpọ̀ gbàgbọ́ pé irọ́ ni Fayose n pa
Joseph Ọlanrewaju sọ lórí Facebook pé ''nkan ti wọ́n ṣe fún Fayose ati ẹgbẹ́ òṣèlú rẹ̀ kò dára rárá.''
Àwọn kan ti lẹ̀ pé è ní aláwàdà
Ṣùgbọ́n Fayose kọ́ ni olóṣèlú Nàìjíríà àkọ́kọ́ tí àwọn ọmọ orílẹ̀-èdè Nàìjíríà fẹ́sùn kàn pé ó parọ́ pé ìlera àwọn kò pé, yálà nítorí pé wọ́n ní ẹjọ́ láti jẹ́ tàbí nínú wàhálà òṣèlú.
Láìpẹ́ yìí ni iléèṣẹ́ ọlọ́pàá Nàìjíríà gbé aṣòfin Dino Melaye lọ sílé ẹjọ́.
Bi ó tilẹ̀ jẹ́ pé orí ibùsùn aláìsàn ló wà lásìkò nàá, èyí kò dáwọn dúró láti gbé aṣòfin nàá, tí wọn fẹ̀sùn ìwà ọ̀daràn kàn lọ síwájú ilé ẹjọ́.
Oríṣun àwòrán, @dinomelaye
Ṣẹnatọ Melaye nàá 'fi ọ̀rùn rọ́' lásìkò tó bẹ́ sílẹ̀ nínú ọkọ̀ ọlọ́pàá
Ṣùgbọ́n Melaye kọ́ ni olóṣèlú Nàìjíríà tí yóò kọ́kọ́  lọ sílé ẹjọ́ lórí àketè àìsàn.
Olisah Metuh, tó ti fìgbàkan jẹ́ akọ̀wé ìpolongo gbogboogbò fún ẹgbẹ́ òṣèlú Peoples Democratic Party, PDP, farahàn nílé ẹjọ́ gíga tìjọba apapọ̀ nílùú Abuja, lọ́jọ́ karùn ún, oṣù Kejì, 2018 lórí kẹ̀kẹ́ aláàrẹ̀, lásìkò tó lọ fún ìgbẹ́jọ́ ẹ̀sùn gbígba irinwó mílíọ́nù Naira láti ọ́ọ̀físì olùgbani nímọ́ràn lóri ètò àábò gbogboogbò lọ́dún 2014, ṣáàjú ètò ìdìbò gbogboogbò tó wáyé lọ́dún 2015.
Èyí mú kí onídàjọ́ Okon Abang, sún ìgbẹ́jọ́ rẹ̀ sí ọjọ́ mì í.
Ẹlòmìí tó tún ti ṣe bẹ̀ ẹ́ ni mínísítà fún ìgbòkè-gbodò ìrìnnà ojú òfurufú, Femi Fani-Kayọde, lásìkò tí agbẹjọ́rò rẹ̀, Norrison Quakers, sọ nílé ẹjọ́ lọ̀jọ́ kọkàndínlọ́gbọ̀n, oṣù Kínní, 2018, pé oníbàárà òun kò lè wá fún ìgbẹ́jọ́ nítorí àìsàn tó ní i ṣe pẹ̀lú ọkàn.
"Norrison ní ""ìyàwó oníbàárà òun ló pe òun lórí ẹ̀rọ ìbánisọ̀rọ̀ pé ìléèwòsàn ti gba ọkọ òun nítẹ̀ẹ́."
Ṣàájú ni wọ́n ti fi ẹ̀sùn lílu owó tó n lọ sí bi i mílíọ́nù máàrùn Naira, tó jẹ́ owó ìlú ní pónpó kàn án àti àwọn méjì mì í.
Nenadi Usman nàá darapọ̀ mọ́ wọn
Mínísítà fún ètò ìnáwó nígbàkan rí, Abílékọ Nenadi Usman, tí wọ́n jọ fi ẹ̀sùn kan òun àti Fẹmi Fani-Kayọde, lọ̀jọ́ karùn ún, oṣù Kejìlá, 2017 nàá bẹ ilé ẹjọ́ gíga tìjọba àpapọ̀ tó wà ní ìlú Èkó láti fún un láàyè kó lọ sí ilẹ̀ Amẹrika fún ètò ìlera rẹ̀.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Nenadi Usman ni mínísítà fún ètò ìnáwó Nàìjíríà láàrin 2006 sí 2007
Sáàjú ló ti sọ fún ilé ẹjọ́ pé àìsàn jẹjẹrẹ n bá òun fínra. Ile ẹjọ́ gba ẹ̀bẹ̀ rẹ̀.
Ẹ̀sùn mẹ́tàdìnlógún ni àjọ EFCC fi kàn án, àti Fani-Kayọde, tó fi mọ́ alága nígbàkan rí fún ẹgbẹ́ àwọn ìjọba ìbẹ́lẹ̀ ní Nàìjíríà, Ọ̀gbẹ́ni Yusuf Danjuma.
Ekiti Election: Ará Èkìtì ń fẹ́ gómìnà tí yòò tù wọ́n lára
Àdéhùn ètò ọrọ̀ ajé ilẹ̀ Afirika le lẹ́yìn
#EkitiDecides: Fayose sùn lórí ibùsùn aláìsàn
Òkùnkùn biribiri bí ilé iṣẹ́ mọ̀nà-mọ́ná ṣe jóná
Ìṣẹ̀lẹ̀ iná n'ìlé iṣẹ́ mọ̀nà-mọ́ná s'ọ̀pọ̀ èèyàn sí òkùnkùn biribiri ni Ìkoyí ní ìlú Èkó
Ìròyìn tó ń tẹ̀wá lọ́wọ́ sọ pé ìjàmbá iná ti ṣẹlẹ̀ ní ilé iṣẹ́ mọ̀nà-mọ́ná t'ówà ní Ìkòyí ní ìlú Èkó.
Ìṣẹ̀lẹ̀ náà ló sì ti sọ àwọn olùbárà ilé iṣẹ́ ọ̀un sí òkùnkùn biribiri.
Gẹ́gẹ́ bí a ti gbọ́, ìjàmbá iná yìí ṣẹ̀lẹ̀ ní bíi agogo mẹ́ta sí aago mẹ́wàá àárọ̀ Ọjọ́bọ tí í ṣe ọjọ́ kẹ̀ta oṣù karùn ún ọdún 2018.
Alukoro fún ilé iṣẹ́ panápaná ti ìlú Èkó, Ògbẹ́ni Shakiru Àmọ́dù, tó bá ilé iṣẹ́ iròyìn wa BBC Yorùbá sọ̀rọ̀ fìdí rẹ̀ múlẹ̀ pé ẹ̀rọ amúnáwá kan ni iná náà jó, kò sì ràn mọ́ ara ilé rárá.
Iná jò ilé iṣẹ́ mọ̀nọ̀-mọ́ná ní Ìkòyí ní ìlú Èkó
Rio Ferdinand kò rí ìwé àṣẹ fún ẹ̀ṣẹ́ kíkàn gbà
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ferdinand fi ìgbàkan rí jẹ́ ad'ẹ̀yìnmú fún ikọ̀ Manchester United
Agbábọ́ọ̀lù tẹ́lẹ̀rí fún ikọ̀ Manchester United, Rio Ferdinand, ni ó ti kùnnà láti rí ìwé àṣẹ fún ẹ̀ṣẹ́ kíkàn gbà
Ferdinand tí ó ti fìgbàkan rí jẹ́ ad'ẹ̀yìnmú fún ikọ̀ Man U, ló bẹ̀rẹ̀ ìgbáradì fún iṣẹ́ ẹ̀ṣẹ́ kíkàn ní oṣù kẹ̀sán an ọdún 2017.
Agbábọ́ọ̀lù náà tí ó jẹ́ ọmọ ọdún méjìdínlógójì fẹ̀yìn tì nínú eré bọ́ọ̀lù ní ọdún 2015.
Lẹ́yìn ìgbà náà ni ó sì ti mú ẹ̀ṣẹ́ kíkàn níbàádà.
Ṣùgbọ́n Ferdinand kò dun nún sí bí àwọn àjọ tó ń rì sí ẹ̀ṣẹ́ kíkàn n'ilẹ̀ Gẹ̀ẹ́sì ṣe kọ̀ láti fún ní ìwé náà àṣẹ fún ẹ̀ṣẹ́ kíkàn.
Ìjẹ́jọ́ Dino; Femi Falana ní ó kù díẹ̀ káàtó fáwọn ọ́lọ̀páá
Oríṣun àwòrán, Salleh Ashaka
Ilé ẹjọ́ Kogi fi Dino Melaye sí àhàmọ́ tí'tí dí ọjọ́ ìgbẹ́jọ́
Ile Igbimọ Asojusofin, àjọ ajafẹtọ ọmọniyan lorilẹede Naijiria, àti amòfin àgbà, Femi Falana lo ti bu ẹnu atẹ lu bii ile-isẹ ọlọpaa lorilẹede Naijiria se fi panpẹ ọba mu sẹnetọ to n soju ẹkun idibo àárin gbungun Kogi, Dino Melaye lori idubulẹ aisan.
Falana ninu atẹjade kan sọ wipe ifiya jẹ ọmọ eniyan ati titẹ oju ofin to de ẹtọ ọmọ eniyan mọlẹ ni ohun ti awọn ọlọpaa se si ọgbẹni Dino Melaye.
Ajafẹtọ ọmọniyan naa ni iwe ofin ilẹ̀ Naijiria ko faaye gba ifiya jẹ ni, ati wipe oun ti Melaye n la kọja ni awọn mẹkunnu to ku n doju kọ lorilẹede Naijiria.
Falana wa ke si ile igbimọ asofin apaapọ lati sa ipa wọn ki ọrọ Dino Melaye o le yọri si rere.
Bakanna, ile igbimọ asofin ti kilọ fun awọn eleto aabo, paapa awọn ọlọpaa wipe nkankan ko gbọdọ se Dino Melaye lasiko to ba fi wa ni ahamọ wọn.
Lọjọ kẹta, Osu Karun ọdun 2018 ni ilé ẹjọ́ tó kalẹ̀ sì Lọkọja fi Sẹnetọ Dino Melaye sí àtìmọ́lé títí di ọjọ́ kọkánlá, Osú Kẹfa, ọdun kan naa.
Aṣọ àti bàtà tọ́ka sáwọn afurasí gbéwiri lábúlé Bugaje
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Owọ́ ọlọ́pàá tẹ afurasí mẹ́ta níbi tí gbéwiri ti ṣọṣẹ́
Àwọn géńdé mẹ́ta d'èrò ilé ẹjọ́ látàri bàta àtí aṣọ ti Sani, ọ̀kan lára àwọn afurasí ọ̀daràn bọ́ sílẹ̀
Owọ́ ọlọ́pàá tẹ afurasí mẹ́ta níbi tí gbéwiri ti ṣọṣẹ́ ni Nassarawa Bugaje nijọba ibilẹ́ Jibia ìpínlẹ̀ Katsina.
Awọn mẹtẹẹta naa ni Aminu Usman to jẹ ọmọ ọdún mẹẹdọgbọn, Ibrahim Iliyasu to jẹ ọgbọ̀n ọdun àti Abdulrahman Umar to jẹ́ ọdún mẹẹdọgbọn.
Sani ni àwọn agbofinro kọ́kọ́ mú latari bata ati aṣọ rẹ̀ ti wọn kó nibi ti olè ti fẹ́ jí alupùpù Ogbẹni Tasiu Bello lọjọ kejilelogun, oṣu kẹrin, labule Nassarawa Bugaje, ki wọn to lọ mu Iliyasu ati Umar lẹyin ti wọ́n fọrọ wa Sani lẹ́nu wò tán.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ṣọ́ra fún ibi tí ò ń bọ́ bàtà rẹ sí
Àwọn ọlọ́pàá ṣàlàyé fún Adajọ n'ile ẹjọ kekere ti Katsina pé ni abule Tsen Kura ni wọn ti gbiyanju lati já ọ̀kadà Bajaj gba lọwọ Tasiu Bello ko tó pariwo s'ita f'araye.
Wọ́n ni nibi ti ó ti ń kigbe ni awọn ara abule ti wa ti àwọn oniṣẹ́ ibi yii sa lọ.
Sani yán aṣọ àti bata sọnù pẹlu ọ̀bẹ nibi to ti ń sá lọ. Èyí ti àwọn agbófinró fi tọpinpin rẹ̀.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Àmì ìdánimọ̀ ni aṣọ àti bàtà rẹ jẹ́
Adajọ Hajiya Fadile Dikko sún ìgbẹ́jọ́ naa siwaju nigba ti ọ́gá ọlọ́pàá Sani Ado beere fun asiko lati ṣe iwadii siwaju síi.
BBC sọ̀rọ̀ lórí òfin tí Burundi fi dè é
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Burundi kò fẹ́ BBC fún ìgbà díẹ̀
Ilé iṣẹ́ BBC ṣe ìwádìí àṣẹ ti Ijọba Burundi pa pé kí wón dẹ́kun iṣẹ́ láti Ọjọ́ Keje oṣù Karùn ún ọdún 2018
Ìjọba orílẹ̀-èdè Burundi kéde òfin pé kí ilé iṣẹ́ BBC lọ rọọ́kún lati ọjọ́ Ajé to ń bọ̀ lataari pé ominú kọ wọ́n lórí ètò kan ti BBC ṣe sita.
"Aláṣẹ ilé iṣẹ́ BBC ni, ""Inú wa kò dùn sí ìpinnu ìjọba orílẹ̀-èdè Burundi, láti f'òfin de Ilé iṣẹ́ BBC bẹ̀rẹ̀ láti ọjọ́ Ajé tó m bọ̀."
Ìjọba orílẹ̀-èdè Burundi ti kàn sí wa lórí ìfọ̀rọ̀wánilẹ́nuwò kan tí ilé iṣẹ́ BBC ṣe ni èdè Faranse lórí rédíò. Ati fi ara balẹ̀ yẹ ìfọ̀rọ̀wánilẹ́nuwò nínú ètò náà wò dáadáa, ní ìbámu pẹ̀lú kókó tó ń kọ wọn lóminu. A má a fún wọn ní èsì ní kíkún.
"Ilé iṣẹ́ BBC ni, ""A máa gbé ìgbesẹ̀ tó bá yẹ fún àtúnṣe tí ètò wa kankan kò bá kún ojú òṣùnwọ̀n gbèǹdéke ìlàna ètò bí ó ti tọ́ àti bí ó ti yẹ. """
Ọlọ́pàá: Ìwádìí ń lọ l'órí agbẹjọ́rò tí afurasí pé ó pa ọkọ
Oríṣun àwòrán, Facebook
Ọlọpaa ba oku Otike ninu agbara ẹjẹ l'ori ibusun.
Ile iṣe ọlọpaa ti Ipinle Eko ní awọn ti bẹrẹ iwadii l'ori agbẹjọro Udeme Odibi, ti wọn fẹ̀sùn kan pe o fi ọ̀bẹ pa ọkọ rẹ ni Diamond Estate, Sangotedo ni Ibeju Lekki ni òwúrọ̀ Ọjọbọ.
Oloogbe Otike Odibi ti o jẹ eni aadọta ọdun ni a gbọ pe wọn ba oku re ninu agbara ẹjẹ ninu ile wọn lẹ́yìn tí awọn aladugbo pe ọlọpaa pe wahala n sẹlẹ ninu ile naa.
Agbẹnusọ ile ise olopaa ni Ipinlẹ Eko Chike Oti ni nigba ti awọn agbofinro maa fi de ile naa, Udeme ti fẹ gbẹ̀mí ara rẹ̀, awọn aladugbo wọn si ti tètè gbe e lọ si ile iwosan.
Fídíò àkàndá ẹ̀dá tó di amòfin
Awọn aladugbo sọ pe agbẹjọro ni oloogbe naa bii ti iyawo rẹ ti ó jẹ́ ẹni ọdun métadinlaadọta. A gbọ pe ọdun mẹta sẹyin ni wọn di tọkọtaya.
"Oti ni, ""Bi agogo meje abọ owuro ni ọga ọlọpaa ti o wà ní Ogombo gbọ ipe pe iyawo oloogbe naa ti pa ni ile won ni Diamond Estate. Nigba ti awọn ọlọpaa si de ile naa, wọn ba oku oloogbe na ninu agbara ẹjẹ l'ori ibusun."
Bi o ti lẹ jẹ pe ẹni afẹsunkan naa ṣi n gba itọju ni ile iwosan, Kọmiṣọna Ọlọpaa ni Ipinlẹ yii, Edgal Imohimi, ti paṣẹ fun awọn olùwádìí ẹka ẹsùn ipaniyan ki wọn lọ ile naa lati lọ kó awọn ẹri jọ.
Bákan naa ni BBC Yorùbá gbiyanju lati wọ ibi ti iṣẹlẹ naa ti ṣẹ ṣugbọn awọn ẹṣọ ti o wa ni ẹnu ọna Diamond Estate ko f'aaye gba awọn oniroyin lati wọle.
Wọn ni ọlọpaa nikan ni o ni agbara lati wọ adugbo naa lati wadi iṣẹlẹ naa.
Ọlọ́pàá gbé N5m silẹ̀ láti ṣàwárí àwọn adigunjalè Offa
Oríṣun àwòrán, NIGERIA POLICE
Awọn afurasí náà gbẹ̀mi ogunlọ́gọ̀ ènìyàn pẹ̀lú ọlọ́pàá mẹsan
Ile ise lọ́pàá ti Ipinlé Kwara ti gbé miliọnu marun naira silẹ fun ẹnikẹni ti ó bá lé fun wọn ni ifitonileti l'ori awọn adigunjale ti ó kópa nínu ìkọlù si Offa ni Ọjo Kerin Oṣun Kẹrin ọdun yii.
Wọn si gbe aworan awọn afurasi naa l'akoko ìkọlu nibi ti wọn ti gbẹmi ogunlọgọ eniyan pelu ọlọpaa mẹsan eniyan jade pẹlu.
Agbẹnusọ fun ile iṣe ọlọpaa ni orile ede Naijiria, Moshood Jimoh, ti ó fi ọrọ naa to awọn oniroyin leti, sọ pe, yatọ si awọn afurasi ti ọwọ awọn ọlọpaa ti tẹ, wọn ti gbe orukọ awọn to ku lọ iwaju INTERPOL ki wọn baa le tete ri wọn mu.
Awọn aworan awọn afurasi yooku ti ọlọpaa gbe jade ree:
Oríṣun àwòrán, NIGERIA POLICE
Ọwọ ti tẹ awọn afurasi kan, sugbọn wọn ṣi n wa awọn miran
NAPTIP tún mú afurasí tó n kó ómódébìnrin lọ ilẹ̀ òkèèrè
Oríṣun àwòrán, NAPTIP/facebook
Ilé ìtura Amazonia ní wọn kó àwọn ọmọ òhun pamọ́ si
Àjọ to ń rí sì fayawọ ọmọniyan lorile-ede Naijiria (NAPTIP) ti gba àwọn ọmọbìnrin mẹ́tàlá kan silẹ.Wọn tú àwọn ọmọbìnrin náà silẹ lásìkò tí wọn ṣèwádìí lọ sí ilé ìgbàfẹ́ kàn to ń jẹ Amazonia Guest House ni agbègbè Gwagwalada n'ilu Abuja.Bákan náà ni ọwọ sinkun àjọ NAPTIP tó ọkùnrin kan, Afeez Abdulsalam, tí wọn ti ń wà fún ẹ̀sùn kíko àwọn ọmọbìnrin lọ sí orile-ede Saudi Arabia, ni bí ti wọn ti ń lò wọn fún onírúurú ìṣe ìdọ̀tí.
Ilé ìtura Amazonia ní wọn kó àwọn ọmọ òhun pamọ́ si
Adarí ẹ̀ka kan nínú àjọ NAPTIP, Ogbẹ́ni Josiah Emerole, salaye pe, o tí pẹ́ tí àwọn tí ń ṣọ́ agbègbè náà kí àwọn tó rí wọn gbà sílẹ̀
Oríṣun àwòrán, NAPTIP/facebook
Ilé ẹjọ ní o fún àjọ NAPTIP láṣẹ láti ti ilé ìtura náà pa
Àjọ NAPTIP gbé ìgbése ọ̀hún pẹlu atileyin àṣẹ ilé ẹjọ́ láti sabewo sì ilé ìgbàfẹ́ náà tí wọn sì ti tíì pa báyìí títí tí ìwádìí yóò fi parí.
Ọmọogun Nàìjírìà: À ó fọwọ́sowọ́pọ̀ pẹ̀lú ẹgbẹ́ obìnrin
Oríṣun àwòrán, Nigeria Army/Twitter
Àjọ ọmọoogun orílẹ̀-èdè ṣe ìpàdé pọ̀ pẹ̀lú ẹgbẹ́ obìnrin
Àjọ ọmọoogun orílẹ̀-èdè Nàìjíríà ti kéde ìpinnu wọn láti fọwọ́si ibaṣepo pẹ̀lú ẹgbẹ́ obìnrin kan nílé Áfíríkà láti túbọ̀ mú igbelárugẹ bá ẹ̀tọ́ ọmọniyan.
Oga àgbà Àjọ ọmọoogun orile-ede Naijiria, Tukur Buratai, ló jẹjẹ òhún lásìkò to gba àwọn Àjọ náà lálejò n'ilu Abuja.Lásìkò to ń bá àwọn ọmọ ẹgbẹ́ ohun sọ̀rọ̀ níbi ìpàdé tí Abileko Doris Joseph ,ti ẹgbẹ́ African Women leadership organizations ṣáájú rẹ ni Buratai ti gbóríyìn fún àwọn ẹgbẹ́ obìnrin ọ̀hún fún títiraka láti ja fún ẹtọ àwọn ènìyàn l'àwùjọ.
Ó rọ wọn láti ṣe atileyin fún àwọn Àjọ ọmọoogun nípa títú àṣírí ohun tí kò bá tọ láyìíká kóówá wọn.Nínú èsì rẹ adarí ẹgbẹ́ ohun Doris Joseph ṣàlàyé pé ìpinnu ẹgbẹ́ náà ni lati gbe awon adarí tuntun dìde fún àwùjọ.
Ékìtì: Obìnrin mẹ́jì, ọkùnrin mọ́kànlélọ́gbọ̀n ń du ipò kan
Oríṣun àwòrán, TWITTER/APC
Papa iṣere Oluyemi Kayode ni idibo naa ti n waye ni Ado Ekiti
Idibo abẹle ti ẹgbẹ́ oṣelu APC n lọ lọwọ ni Ado Ekiti ní ipinlẹ̀ Ekiti
Ọkunrin ọgbọn ati obinrin meta ti jade lati du ipò gomina Ekiti lábẹ́ aṣia ẹgbẹ́ oṣelu APC ti yoo waye ni ọjọ kẹrinla oṣu keje.
Papa iṣere Oluyemi Kayode ni idibo naa ti n waye.
Gomina Ipinle Ekiti, Ayodele Fayose, ni oun kò bá má ti gbà wọn laaye láti lo ibẹ̀ bi ko ba ṣe ẹ̀mí ìfaradà fún alatakò ninu oṣelu ti òun ni.
A gbo pe, awọn olukopa ninu idibo naa ju ẹgbẹrun meji lọ ati pe Gomina Ipinlẹ Nasarawa, Umaru Tanko Al-Makura, lo n ṣe agbatẹru rẹ.
Bẹẹ gẹgẹ ni awọn ọlọpaa yí gbogbo agbegbe naa ká lati pese aabo ni papa iṣere naa.
Oríṣun àwòrán, Abdullahi Garba Birnin Kudu
Awọn olopaa n ṣiṣẹ wón nibi eto idibo ni Ekiti
Oriṣiriṣi iroyin ni o ti n jade lati ibi idibo naa bayii.
Bi idibo naa ṣe n lọ lọwọ ni òjò ṣe bẹrẹ si ni rọ ti awọn olukopa si n bẹru pe ojo naa ko ni jẹ́ ki wọn pari idibo ọhun.
Oríṣun àwòrán, Abdullahi Garba Birnin Kudu
Opolopo omo egbe oselu APC kun ibi idibo
Bi òjò naa ṣe da ni idibo tun tẹ̀ s'iwaju.
Bakan naa ni ifẹnuko ẹgbẹ oṣelu naa ni awọn wọọdu, ijọba ibilẹ ati ipinlẹ ti a mọ si congress n waye bi idibo naa ṣe n lọ.
Buhari ní òun kò ní gbẹ́yìn, Kemi Adeosun gba káàdì APC
Oríṣun àwòrán, TWITTER/Bashir Ahmad
Ifẹnuko wọọdu ẹgbẹ òṣelu APC ṣe n lọ lọwọ kakakiri orilẹ ede Naijiria
Bí ifẹnuko wọọdu ẹgbẹ òṣelu APC ṣe n lọ lọwọ kakakiri orilẹ ede Naijiria ni a gbo pe Aarẹ Muhammadu Buhari naa lọ kopa ni ìlú rẹ̀ ní Daura ní Ipinlẹ Katsina.
Awọn tí wọn jọ k'ọ́wọ̀ọ́ rin lọ sí ibi idibo ifẹnuko naa ti ó wáyé ni ile iwe Bayajidda ti o wà ni Daura ni Gomina Ipinlẹ naa Aminu Masari.
Awọn oludije ipo ninu ẹgbẹ APC, awọn olukopa ati awọn oṣiṣẹ́ ajọ INEC wa ni gbogbo wọọdu kakakiri orilẹ ede Naijiria lati ri pe eto naa lọ b'o ṣe yẹ kó rí.
Ọjogbọn Yemi Osinbajo, ti o je igbakeji aarẹ, wọọdu rẹ ti ó wa ni Agungi ni Eti Osa lo ti lọ ko'pa l'Eko.
Oríṣun àwòrán, TWITTER/LAOLU AKANDE
Igbakeji Aarẹ Osinbajo lọ si wọọdu rẹ ti ó wa ni Agungi ni Eti Osa lo ti lọ ko'pa l'Eko.
Osinbajo rọ awọn ara ilu ti o wa nibẹ pe ẹgbẹ APC yoo ṣe daada o ati pe wọn yoo ri jẹ ninu èrè Naijiria.
Oríṣun àwòrán, TWITTER/LAOLU AKANDE
Osinbajo ba awọn ara ilu sọrọ ni wọọdu rẹ
Bi Gomina Ipinle Kaduna, Nasir El-Rufai ṣe de wọọdu rẹ re:
Oríṣun àwòrán, TWITTER/EL-RUFAI
IIII
Olori ile igbọ asofin agba Bukola Saraki ni inu oun dun lati gbo pe idibo naa lọ ni irọwọrọsẹ ni Ipinlẹ Kwara.
Bakan naa, minisita fun eto ọrọ aje, Kemi Adeosun ni oun ti wa di ọmọ ẹgbẹ APC ni kikun bayi. O gba kaadi ọmọ ẹgbẹ ni wọọdu rẹ ni Abeokuta ni oni.
Gomina Ipinle Eko Akinwunmi Ambode naa ko gbẹyin bi oun naa ṣe lọ wọọdu rẹ lati lọ dibo.
Oríṣun àwòrán, TWITTER/@AKINWUNMIAMBODE
Gomina Ipinle Eko Akinwunmi Ambode naa ko gbẹyin o
Naijiria kò gbàgbé ààrẹ tó d'olóògbé l'ọ́dún mẹ́jọ sẹ́yìn
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Yar'Adua di oloogbe ni oṣu karun ọdun 2010
O pe ọdun  mẹjọ ni oni ti aarẹ ana Umaru Musa Yar'Adua di oloogbe nigba ti o wa l'ori aleefa. Sugbọn awọn ọmọ Naijiria ko gbagbe o.
Wọn ṣe iranti rẹ ni ori Twitter.
Yar'Adua di oloogbe lati ọwọ aisan ọkan ni ọjọ karun oṣu karun ọdun 2010. Igbakeji rẹ Goodluck Jonathan si gori aleefa lẹyin rẹ.
Wọ́n so ìdìbò APC rọ̀ l'Ekiti nitori rògbòdìyàn
Oríṣun àwòrán, Abdullahi Garba Birnin Kudu
Awọn tí o wa nibẹ sọ wipé awọn kan tilẹ̀ ti ji apoti ibo gbe o.
Iroyin to kan wa lọwọ sọ pe wọn ti so idibo abẹle ti ẹgbẹ oṣelu APC ti o waye l'oni ni Ado Ekiti, Ipinlẹ Ekiti rọ latari wahala ti o ṣẹlẹ nibi idibo naa. A pe alukoro ẹgbẹ naa kan ṣugbọn kò jẹ́ ipe wa lati sọ bi o ṣe jẹ́.
Ipinlẹ Nasarawa ti gomina  wọn Tanko Al-Makura n ṣe akoso ibo naa sọ lori Twitter pe ni tootọ ni wahala ṣelẹ ṣugbọn pe gomina naa ti pe awọn oludije si ipade lati dẹkun ọrọ naa.
Ọkan lara awọn oludije nibi idibo naa Femi Bamiṣilẹ ti o ba awọn oniroyin sọrọ lẹyin ipade naa ni, ẹgbẹ APC yoo jiórò lori ọrọ naa ki wọn to mọ oun ti wọn maa ṣe.
A gbọ pe wahala bẹ silẹ nibi idibo abẹle APC ni Ado Ekiti, ti awọn agbofinro si yinbọn soke lati dọwọ iṣele naa.
Ni ori Twitter, awọn tí o wa nibẹ sọ wipé awọn kan tilẹ̀ ti ji apoti ibo gbe, ti awọn olukopa kan si fọ awọn apoti.
Yobo: Ikọ̀ Naijiria gbọ́dọ̀ gbajumọ́ ìdije àkọ́kọ́
Oríṣun àwòrán, Getty Images
"Yobo ni ti ikọ Naijiria ba ja'we olu b'ori ninu idije kini, ọkan wọn yoo balẹ̀ si ni."""
Joseph Yobo ti o jẹ amule fun ikọ agbabọlu orilẹ ede Naijiria nigba kan ri ti rọ ikọ orilẹ ede yii si idije ife ẹyẹ agbaye ki wọn gba'jumọ bi wọn ṣe maa ja'we olu b'ori ninu idije akọkọ wọn pelu Argentina.
Oni ko yẹ ki wọn maa sọrọ aṣekagba lati iwoyi.
"Yobo ni, ""Wọn gbọdọ ja'we olu b'ori ninu idije kini, ki wọn wa mura fun idije keji, lẹyin naa, idije kẹta. Ọkọọkan ni a n yọ ẹse l'eku. Mi o ro pe o dara ki a ja ku'lẹ ninu idije kini. Ti ikọ Naijiria ba ja'we olu b'ori ninu idije kini, ọkan wọn yoo balẹ̀ si ni."""
Ayàwòrán: ọpọlọ, sùúrù àti agbára ni mò ń lò fún iṣẹ́ mi
'Ẹni mọ iyì wúrà ni à ń ta awòrán fún'
Ìgbàkigbà ni ìmísí má a ń wá sí ọkàn mi fún yíya àwòrán
Olọ́tọ̀ ní tòun ọ̀tọ̀, Olumide Orẹṣegun tó ń ya àwòrán ní, kété tí mo ba ti ní ìmísí fún iṣẹ́ àwórán kan, ni màá kọọ silẹ̀ tàbí ki ń tẹ̀ẹ́ si orí fóònù mi.
Maa pe àwọn ọmọ jọ foríkorí wá ǹkan ti mò n fẹ́ lò, ki ó tó di odindin.
'Ẹni mọ iyì wúrà ni à ń ta awòrán fún'
O mẹnuba oriṣii àwòrán to wà, ti wọn kọ́ nile ìwé pé:
Olumide bẹ̀rẹ̀ pẹ̀lú eyi tó n wa lati ókàn rẹ̀ ni yíyà kí ó tó di ọ̀gá àgbà lẹ́nu iṣẹ́ rẹ̀.
O ni òun fi làákàyè ṣagbekalẹ àwón ohun eelo irinṣẹ aworan yiya to wọn ni Naijiria.
Davido, Simi,Omawumi gbégba orókè nínú ìdíje 2018
Oríṣun àwòrán, Simi/Davido/Omawumi/Instagram
Ọ̀kẹ́ àìmọye olórin lo kópa níbi igbami ẹyẹ 'Headies' elekeejila tí ọdún 2018.
Àwọn ọmọ tó jáwé olúborí ní 'Headies' 2018
Ọ̀kẹ́ àìmọye olórin lo kópa níbi igbami ẹyẹ headies elekeejila tí ọdún 2018.Ṣùgbọ́n Simisola Bolatito Ogunleye (Simi), David Adedeji Adeleke (Davido) àti Omawumi Megbele (Omawumi) lọ gbegba oroke níbi ayẹyẹ náà. Láti ọdún 2006 ni 'Headies' tí ń fáwọn to bá pegede nínú ìṣe orin takasufe lami ẹyẹ lorile-ede Naijiria.
Simi gba àmì ẹyẹ to dára ju lọ nínú RnB nínú orin adako rẹ 'Smile For Me' 'Joromi' bákan naa lọ gba Aliboomu tí dára julọ. Davido gba àmì ẹyẹ olórin to gbayii julọ àti orin to gbayii.
Nígbà tí Omawumi gbá àmì ẹyẹ obìnrin tó ní ohun tó dùn julọ ninu orin rẹ 'Butterfly'.
Ọdọ́ Tunisia yóò yan ẹni tó wù wọn sípò nídìbò abẹ́lé
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Àwọn ènìyàn Tunisia ń fẹ́ òmìnìra lẹ́yìn ìdìbò òní
Ẹẹmẹrin ọ̀tọ̀ọ̀tọ̀ ni wọn ti sún ètò ìdìbò abẹ́lẹ́ Tunisia síwájú
Ìdìbò 2011 ni wọn ti dìbò lórí adari Zine El-Abidine Ben Alil.
Oṣù kẹsan an ọdun to kọja ni àwọn ile igbimọ aṣofin foríji àwọn tijọba tó kógbá wọlé fẹ̀sùn jẹgúdújẹrá kàn.
Odún 2010 ni wọn dìbo ijọba ìbìlẹ̀ bayii kẹ́yìn.
Awọn ọ̀dọ̀ Tunisia ń wòye fún ọjọ́ iwájú rere lẹyìn ìdìbò òní.
Ajàfẹ́tọ: Awàkọ̀ mi sùn ẹ̀wọ̀n ọjọ́ márùń t'orí aṣẹ́wó
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Asẹwo di olùpẹ́jọ́ ti wọn fi fa Darlington de agọ ọlọpaa to wa ni Utako, Abuja
Ajafẹtọ ọmọ ènìyàn, Bukky Shonibare, tió ń gbé Abuja ti ṣ'alaye iṣẹlẹ kayefi kan ti o gbe awakọ rẹ ti o n jẹ Darlington lọ ẹwọn ọjọ marun fun ẹṣẹ ti ko m'ọwọ ti ko m'ẹsẹ.
"Shonibare ni, ""Arabinrin aṣẹwo kan ni o pe awọn ọlọpaa pe awakọ mi jọ ọkunrin kan ti o ja oun l'ole ni bii aago meta oru ni ọjọ kerin oṣu keta."
"O fẹ lọ gbe eniyan kan ni ile igbafẹ kan ni Abuja ni aṣẹwo naa ba tọ'ka sii pe o jọ ọkunrin kan ti oun fẹ lọ sun si ọdọ rẹ, sugbọn ti o ja oun l'ole ki wọn to de'le."""
Ajafẹtọ naa ṣ'alaye fun BBC Yoruba lórí wahala ti oun ṣe ki o to di pe Darlington jade ni ahamọ ọlọpaa nigba ti ko si ẹri kankan pe o jẹbi.
Ni orile ede Naijiria, iṣe asẹwo lodi s'ofin. Sugbọn, ni ọjọ Abamẹta, ọjọ kọkanleọgbọn oṣu kerin,  asẹwo di olùpẹ́jọ́ ti wọn fi fa Darlington de agọ ọlọpaa to wa ni Utako, Abuja. Lẹyin naa ni wọn lọ tii m'ọle ni agọ ọlọpaa to wa ni Lugbe.
A gbọ pe aṣẹwo naa sọ fun awọn ọlọpaa pe oun pade ẹni to ja oun l'ole naa nile igbafẹ kan ni Abuja, ti ìná si wọ̀ laarin wọn. Onibaara naa ni oun yoo san ẹgbẹrun mewa naira fun aṣẹwo naa, ni o ba wọ inu ọkọ arakunrin naa.
Sugbọn o sọ fun awọn ọlọpaa pe bi awọn ṣe de agbegbe fasiti Baze ti o wa ni Abuja ni oníbàárà naa duro l'ẹgbẹ ọna ti o si fa ọbẹ yọ ti o gba gbogbo nkan to wa lọwọ oun.
Arabinrin naa tilẹ sọ fun awọn ọlọpaa pe nigba ti onibaara naa n ja oun l'ole, oun gee jẹ. Sugbọn Shonibarẹ ni nigba ti wọn gbe Darlington de agọ ọlọpaa, wọn bọ aṣọ rẹ, wọn ko ri àpá eyin kankan.
"Shonibarẹ ni, ""Wọn fi awakọ mi si ahamọ, lẹyin naa ni awọn ọlọpaa lọ ile re lati lọ wo boya wọn maa ri ẹri kankan, tabi awọn oun ti asẹwo naa ni o gba lọwọ oun. Wọn ko ri nkankan."""
Ajafẹtọ naa ni nitori pe awakọ oun ti lo ju ọjọ meji ni ahamọ, oun sọ fun awọn ọlọpaa naa pe ofin ko gbaa laaye ki wọn ṣi ti mọle. Sugbọn ọlọpaa kan ni ko gbẹnu dakẹ.
Lẹyin ti wọn fa ọrọ naa titi ti wọn ko ri ẹri kankan, ni wọn ba fi Darlington silẹ o lẹyin ọjọ marun ni ahamọ.
Shonibare ni eyi to ya oun lẹnu ju ni pe, awọn ọlọpaa naa ko sọ nkankan nipa pe aṣẹwo naa n ṣe iṣẹ to lodi s'ofin.
Oríṣun àwòrán, TWITTER/BUKKY SHONIBARE
Shonibarẹ ni nigba ti wọn gbe Darlington de agọ ọlọpaa, wọn bọ aṣọ rẹ, wọn ko ri àpá eyin kankan
"O ni, ""Lẹyin ti wọn fi awakọ mi silẹ ni ọga ọlọpaa kan ni agọ naa sọ pe oun ti ri arakunrin kan ti o ni irùgbọ̀n bii ti awakọ mi."
"O ni ki n gbaa ni imoran ko o lọ ge irugbọn rẹ o, ki wọn ma baa ṣìí mu fún ẹsẹ ti ko mọ'di rẹ."""
Ọrọ Darlington ya ọpọ awọn eniyan lẹnu l'ori Twitter, ti wọn si n ba dupẹ pe ori koo yọ.
Kaduna: Ẹ̀mí tó sọ nú nínú àkọlù àwọn agbébọn pọ̀
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Púpọ̀ nínú àwọn tó pàdánù ẹ̀mí wọn ni ìròyìn sọ pé, wọ́n jẹ́ ọmọ ẹgbẹ́ ọdẹ ìbílẹ̀ kan.
Kò dín ní èèyàn mọkànléláàdọ́ta tó j'Ọ́lọ́run nípè ní ìpìnlẹ̀ Kaduna, àwọn t'ọ́rọ̀ ṣojú wọn ló sọ bẹ́ẹ̀.
Èyí wáyé lásìkò tí àwọn agbébọn ya wọ abúlé kan, tí wọ́n sì dáná sun ọ̀pọ̀lọpọ̀ ilé.
Púpọ̀ nínú àwọn tó pàdánù ẹ̀mí wọn ni ìròyìn sọ pé, wọ́n jẹ́ ọmọ ẹgbẹ́ ọdẹ ìbílẹ̀ kan, èyí tí wọ́n dásílẹ̀ láti maa pèsè ààbò fún àwọn abúlé tó wà ní agbègbè nàá, lẹ́yìn ti onírúùrú ìkọlù ti wáyé níbẹ̀. Àwọn ìkọlù ọ̀hún ni wọ́n di ẹ̀bi rẹ̀ ru àwọn olè a-jí-máàlù
Ṣaajú àsìkò yìí, inú fu, àyà fu, l'àwọn olùgbé ní àwọn abúlé tó wà ní tòsí Birnin Gwari wà.
Èyí ló sì mú kí wọ́n dá ikọ̀ aláàbò nàá sílẹ̀, ṣùgbọ́n, ipá wọn kò ká àwọn géndé agbébọn tó yí abúlé Gwaska ká lọ́sàn ań ọjọ́ Àbámẹ́ta, tí wọ́n sì bẹ̀rẹ̀ sí ní yìnbọn, tó fi mọ́ dídáná sun ilé.
Àwọn t'órí kóyọ nínú ìkọlù nàá ti n késí iléèṣẹ́ ológun láti pèsè àwọn ọmọ ogun tí yóò maa dáàbò bo àwọn tó n gbé lẹ́nu àálà ìpínlẹ̀ Kaduna àti Zamfara.
Awọn ọmọ ilẹ̀ Tunisia ń dìbọ ìjọba ìbílẹ̀
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Àwọn ọmọ ilẹ Tunisia n dìbò ìbílẹ̀ lọwọ
Orilẹ-ede Tunisia n dibo abẹle fun igba akọkọ lati ọdun 2011 ti ikólu Aarabu ti sẹlẹ.
Àwọn oludibo to le ni miliọnu marun un ni wọn n kopa ninu eto idibo ti awọn oludije to le ni ẹgbẹrun lọna ogun ti n dije.
Ijoba ilẹ naa ti fun awọn ijọba ibilẹ lagbara sii lẹyin ti wọn fẹ kí wọn maa kopa gidi ninu eto oṣelu ilẹ naa.
Awọn obinrin ko bi ida mẹrindinlaadọta ninu ọgọrun un awọn oludibo nilẹ naa.
Eyi jẹ igbesẹ ijọba ilẹ Tunisia lati rii pe ko ṣegbe lẹyin awọn okunrin ju obinrin lọ.
Cardiff ti gbégbá orókè láti kópa ní Premier League
Ikọ̀ Cardiff yege lati kopa ínú ìdíje Premier League
Ikọ agbabọọlu Cardiff ti gbegba oroke lati kopa ninu idije Premier League ni saa to n bọ.
Ẹgbẹ agbabọọlu naa yege lẹyin igbati ti wọn gba òmì pẹlu ikò Reading ninu ifẹsẹwọnsẹ Championship to waye lọjọ aiku.
Ikọ Cardiff nilo lati jawe olubori tẹlẹ ninu ifẹsẹwọnsẹ naa ki wọn to le yege.
Ṣugbọn wọn gbegba oroke bi ẹgbẹ agbabọọlu Fulham ti fi di rẹmi pẹlu ayo mẹta si ọkan nile Birmingham.
Òmì ti wọn ta naa tun jẹ ko seese fun Reading lati dije ni liigi Championship ni saa to n bọ.
Ìdùnún ṣubú l'ayọ̀ bí Man City ṣe gba ife Premier League
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Manchester City gba ife eye Premier League
Idunu subu l'ayọ bi ikọ Manchester City ti gba ife ẹyẹ Premier League lẹyin gba ti wọn ta ọmin pẹlu Huddersfield l'ọsan ọjọ Aiku.
Ikọ naa ti pegede ninu idije liigi naa lati ọjọ kẹẹdogun oṣu kẹrin.
Ṣugbọn wọ́n ni lati duro di ọjọ Aiku lati gba ife ẹyẹ naa.
Awọn ololufẹ ẹgbẹ agbabọọlu naa ya wọ ori papa lẹyin ti ifẹsẹwọn naa tan.
Akọnimọọgba Manchester City Pep Guadioala lo kọkọ gba amin ẹyẹ olùborí.
Balogun ikọ naa Vincent Kompany lo gba amin ẹyẹ kan in ti wọn si gbe ife naa le lọwọ.
Wenger dágbére fún Arsenal ní pápá ìseré Emirates
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ó dìgbà ó se, Arsene Wenger dágbére fún Arsenal
Ikọ Arsenal fakọyọ pẹlu amín ayo marun un s'odo bi wọn ti se dagbere fun akọnimọọgba wọn Arsene Wenger to n lọ.
Arsenal f'agba han ikọ Burnley ninu ifẹsẹwọnsẹ to jẹ eleyi to kẹyin ti Wenger yoo jẹ oludari ikọ naa ni papa isere Emirates.
Ẹlẹsẹ ayo Pierre-Emerick Aubameyang gba ayo meji wọle ninu ere bọọlu naa.
Ọmọ Nigeria Alex Iwobi, Alexander Lacazette ati Sead Kolasinac naa wa lara awọn to gba bọọlu s'awọn ninu ifẹsẹwọnsẹ naa.
Ikọ alatako Burnley ati awọn agbọọlu Arsenal se ayẹsi fun Wenger ki  ifẹsẹwọnsẹ to bẹrẹ.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Arsenal f'agba han ikọ Burnley ninu ifẹsẹwọnsẹ to jẹ eleyi to kẹyin ti Wenger yoo jẹ oludari ikọ naa ni papa isere Emirates
Wenger to jẹ ẹni ọdun mejidinlaadọrin gba ife ẹyẹ mẹwa to jọju ni ọdun mejilelogun ti o lo gẹgẹ bi akọnimọọgba Arsenal.
Ètò ìdìbò abẹ́lé APC: Ipeníjà fun ẹgbẹ ṣáájú 2019
Oríṣun àwòrán, @APCNigeria
Aáwọ̀ abẹ́nú lóríṣiiríṣìí ló ń ṣẹlẹ̀ ninu ẹgbẹ APC lorilẹ-ede Naijiria
Opin ọse to kọja ní ègbé òsèlú APC ṣe ètò ìdìbò jakejado orílè-èdè Nàìjíríà.
Láwọn agbegbe kàn ètò náà ló ní pèlé kutu ṣugbọn iroyin awuyewuye ati  idarudapọ to fi mọ ẹhonu lo gbalẹ láwọn ìpínlè kàn.
Oríṣun àwòrán, Abdullahi Garba Birnin Kudu
Awọn tí o wa nibẹ sọ wipé awọn kan tilẹ̀ ti ji apoti ibo gbe o.
Nnkan ò sẹnu re nibi ìdìbò abẹ́le to waye nipinle Ekiti.
Ojo lo kókó sebi ẹni da  oju ojo ètò ru.
Lẹyin igba ti ojo dá, ètò náà gba ọna mi yọ ti awọn kan ji apoti ibo gbé ti awọn agbofinro sì bẹrẹ síí yinbọn soke.
Gómìnà ipinle Nasarawa,Tanko Al Makura to je alaga eto ipade idibo si kéde siso adagba eto ìdìbò náà ró titi di ọjọ miran.
Ifehonuhan lo tẹlé  ibo abele APC ìpínlẹ̀ Rivers ti awọn  alatilẹyin Senato Magnus Abe n so wí pé kí ẹgbẹ má ṣe gbà èsì ìbò náà wọle.
Ni Òndó, a gbó pé aiṣedede wáyé níbi idibo náà ti wọn sì sun ọjọ idibo ìpínlẹ̀ Oyo lati ojo abameta s'ojo Aiku lẹyin ti awọn janduku da ètò ru ni ile ẹgbẹ ti o wa ni Oke Ado.
Ipínlẹ̀ Imo ati Abia naa wa lara ìpínlẹ̀ ti eto o ti lo ni irọwọrọsẹ
Awọn eekan ẹgbẹ kàn ko kópa
Bí ìròyìn dàrú dapọ ba koni lominu eyi to je kayefi ni bi awọn eekan ẹgbẹ náà kan ṣe ko lati yoju síbi ìdìbò náà l'agbegbe won.
Lara awon gbajugbaja ti a gbó pé won kọ lati  yoju ni Senato Rabiu Musa Kwankwaso ati igbakeji Gómìnà, Kano,Hafiz Abubakar.
Alatako mu ọrọ APC gbọ
Ni kete ti ìròyìn nípa ìdìbò abẹle bẹrẹ sí tan ka lori afefe ni ẹgbẹ òṣèlú PDP ti fi ọrọ ṣòwò lójú òpó Twitter lati benu àtẹ lu ẹgbẹ APC
Gomina Ayo Fayose ko gbeyin
APC se agbekale ìgbìmò igbẹjo kòtẹmílọrùn
"Ninu atejade kan Akọ̀wé ìpolongo fún ẹgbẹ́ APC, Bọ́lájí Abdullahi ní  ìṣẹlẹ náà je oun to fọwọ kan ni lẹmi sugbọn ""awọn tí yanjú òun tó dà rukerudo silẹ"""
"O ni alaga eto idibo abẹle ti sọrọ ''òun to sí kan ni ki a tẹsíwájú láì jafara.Ọrọ pe ka so eto ro titi di igba tí kò dájú ko ṣẹlẹ rara."""
Ọjọ aje ni ìgbìmònaa yoo bere sini gbo ejo ehonu to wo wa latara eto idbo abela naa.
Bùhárí buwọ́lù ìdásílẹ̀ iléeṣẹ́ ọmọogun tuntun ní Birnin Gwari
Oríṣun àwòrán, NIGERIA PRESIDENCY
Kò dín ní eeyan márùn dín láàdọ́ta tó bá ìṣẹ̀lẹ̀ Birnin Gwari
Ààrẹ Mùhámádù Bùhárí ti buwọ́lù ìdásílẹ̀ ọ̀wọ́ iléeṣẹ́ ọmọogun tuntun àti àwọn iléeṣẹ́ ọlọ́pàá tuntun lágbègbè Birnin Gwari ní ìpínlẹ̀ Kaduna.
Ààrẹ Bùhárí gbé ìgbésẹ̀ náà lẹ́yìn ìkọlù àti ìpànìyàn tó wáyé níbẹ̀.
Lọ́jọ́ àbámẹ́ta làwọn agbébọn kan kọlu agbègbè Birnin Gwari níbi tí wọ́n ti dáná sun àwọn ilé tí wọ́n sì tún  pa àwọn èèyàn tí ọlọ́pàá ní kò dín ní márùn dín láàdọ́ta.
Ilẹ́eṣẹ́ ààrẹ ní ìkọlù náà dun ààrẹ Mùhámádù Bùhárí dé ọ́kàn tí ó sì ti ń gbé ìgbésẹ  láti yànàná ìpèníjà àbò lágbègbè náà àti orílẹ̀èdè Nàíjíríà lápapọ̀.
Ìpínlẹ̀ Kaduna ṣọ̀fọ̀ àwọn tó kú ni Birning Gwari lọ́jọ́ Abamẹta
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Opọ̀ ẹ̀mí ti sọnù ni Birnin Gwari tó fẹ́ sọ ibẹ̀ di ahoro
Opọ̀lọpọ̀ ìgbà ni àwọn oníṣẹ́ ibi yii ti kọlu Birnin Gwari, ti wọn si ti ké gbàjarè sijọba, ki gbogbo ẹ tó di ńlá lọ́jọ́ Abamẹta tó kọja ti wọn pa ènìyàn to le ni aadọta
Àwọn ìkọlù ọ̀hún ni wọ́n di ẹ̀bi rẹ̀ ru àwọn olè a-jí-máàlù kò pẹ àwọn ara abule naa ko fi aaye gba wọn lati fi ibẹ̀ ṣe ibujoko.
Ààrẹ Mùhámádù Bùhárí fi buwọ́lù ìdásílẹ̀ ọ̀wọ́ iléeṣẹ́ ọmọogun tuntun àti àwọn iléeṣẹ́ ọlọ́pàá tuntun lágbègbè Birnin Gwari ní ìpínlẹ̀ Kaduna.
Wọn ti sin òkú àwọn tó doloogbe latari ikọlu to waye gbẹyin lọjọ Abameta to jẹ ọjọ buruku èṣù gbomi mú.
Ijọba ipinlẹ̀ Kaduna ni àwọn òṣìṣẹ́ elétò ààbò yóò máa dáàbò bo àwọn ènìyàn agbegbe yii
Ọmọogun ilẹ̀ ri ẹgbẹ̀rún kan ènìyàn gbà padà lọ́wọ́ B/Haram
Oríṣun àwòrán, @nigeriaarmytwitter
Lafiya Doole ti tún hùwà akọni, wọn dóòlà ẹ̀mí odindi ẹgbẹ̀rún kan ènìyàn
Ikọ̀ àwọn ọmọogun ilẹ̀ Nàìjíríà, Troops of 22 Brigade, ti wọn ń ṣiṣẹ́ àkànṣe Lafiya doole, ti gba ẹgbẹ̀rún kan ènìyàn sílẹ̀ lọ́wọ́ àwọn oníṣẹ́ ibi boko haram.
Wọn ṣe iṣẹ́ àkànṣe náà pẹ́lú àpapọ̀ àwọn ọmọ ogun Multinational Joint Task Force (MNJTF).
Wọn gbà wọ́n kúrò ní abúlé Malamkari, Amchaka, Walasa ati Goranijọba ibilẹ̀ Bama nipinle Borno
Awọn ọmọdé àti obìnrin ló pọ̀jù ninu àwọn èrò naa
Ọkan ninu àwọn ti àwọn ọmọogun ilẹ̀ Nàìjíríà gbà silẹ̀ láti abúlé Amchaka, Alhaji Gambo Gulumba, dúpẹ́ lọ́wọ́ àwọn ọmọogun ilẹ̀  MNJTF fún òminra ti gbogbo wón ri gbà
Bakan naa ni àwọn ọmọogun ilẹ̀ Nàìjíríà tẹpẹlẹ mọ ìlérí wọn làti mójútó aabo dukia ati ẹ̀mí àwọn ènìyàn Nàìjíríà
Wọn n ṣe ìtọ̀jú tó yẹ fún àwọn ènìyàn náà nile ìwòsàn àwọn ọmọogun bayii.
Eyi ni ìgbà kẹta laarin oṣù mẹrin ti àwọn ọmọogun ilẹ̀ Nàìjíríà ni wọn ri àwọn ènìyàn gbà padà lọwọ boko haram.
Ààrẹ Buhari yóò tun tẹko létí lọ London
Oríṣun àwòrán, TWITTER/BASHIR AHMAD
Garba Shehu ni dokita Ààrẹ Buhari lo pe fun àyẹwò náà
Ààrẹ Muhammadu Buhari ti orílèèdè Nàìjíríà yóò ṣe ìrìn àjò lọ́jọ́ ìṣẹ́gun sí ìlú London láti lọ rí Dókítà rẹ̀.
Àtẹ̀jáde láti ọ̀dọ̀ olùrànlọ́wọ́ àgbà sì Ààrẹ lórí ìròyìn sọ pé Ààrẹ yóò lo ọjọ́ mẹ́rin tí yóò sì padà sí Nàìjíríà lọ́jọ́ kejìlá oṣù yìí.
"Garba Sheu ṣàlàyé pé ''ígbà  tí ọkọ̀ bàálù ààrẹ dúró fún àtúnṣe ni London bí ó ti ṣe ń padà láti Washington lààrẹ f'ẹsẹ̀ kan rí Dókítà rẹ. Dókítà rẹ̀ sì ní kó yọjú padà sí òun lẹ́yìn ìgbà náà""."
O tẹsíwájú pe ni kété ti Ààrẹ ba darí yóò ṣe àbẹwò sí ìpínlè Jigawa fún ọjọ méjì.
Laarin ọjọ kaarun oṣù kejì  sí ọjọ kẹwàá ọdún 2016 lo ṣe àbẹwò àkọkọ.
Èyí tó ṣe kẹyìn wáyé lọjo keje oṣù kaarun ọdún 2017 ti o si darí padà ní ọjọ kokandinlogun oṣù kẹjọ
Fásitì Zambia: Asọ ìwọ̀kuwọ̀ ń kóbá àwọn akẹ́kọ̀ọ́-kùnrin
Oríṣun àwòrán, DIKINA MUZEYA
Dikina ní kí awọn akẹkọ ọkùnrin kọjú mọ ẹkọ wọn
Gbajugbaja yunifásítì kan lorílèèdè Zambia tí rọ awọn akẹkọ-bìnrin láti yé máa wọ aṣọ to fara síle nítorí pé kó jẹ kí awọn akẹkọ ọkunrin kọjú mọ́ ìwé.
''University of Zambia'' to wa ni olú ìlú orílẹ̀èdè náà, Lusaka, lẹ ìwé ìkìlọ káàkiri ilé ìkàwé pe, kí àwọn akẹkọ-bìnrin múra ni imúra ọmọluabi.
Oríṣun àwòrán, DIKINA MUZEYA
Ni ṣókí, Ìkìlọ yí ní : è sora pẹlu asọ iwọkuwọ
Awọn akẹkọ obìrin tí wa gbarata lórí ìkìlọ yii.
"Dizina Muzeya sọ fún BBC Yorùbá pe ""Se bi iwe lo fẹ wa ka, ki lo sun ọ dé idi a n yọjú wo ẹsẹ akẹkọ obìrin?"""
Òun tó ba wà ní kò kojú mọ
Ṣugbọn èro akẹkọ ọkùnrin kàn, Killion Phiri, ṣe ọtọọtọ lori ikilọ yii, to si ni òun gbé lẹyìn ìgbésẹ náà.
Ẹ mo wí pé ará àwọn obìnrin máa n fanimọra. Báwo la ṣe fẹ kojú mọ ìwé nígbà tí ẹni tó wọ aṣọ to fara silẹ ba kojú síwá?
Sùgbọ́n Orílèèdè Zambia bọwọ fún àṣà ati iṣẹṣe púpọ̀.
Ó nídìí tí Sẹ́nétọ̀ Melaye fi fo bọ́ọ́lẹ̀ nínú ọkọ̀ ọlọ́pàá
Oríṣun àwòrán, Dino Melaye/Facebook
Ìbẹrù fún ẹ̀mí ara rẹ̀ ló mú kí aṣòfin Melaye bẹ́ sílẹ̀ láti inú ọkọ̀ nígbà tí àwọn ọlọ́pàá fẹ́ gbé e lọ sí ìlú Lokoja.
Njẹ́ ó mọ ìdí tí Sẹ́nétọ̀ Dino Melaye ṣe fò bọ́ sílẹ̀ nínú ọkọ̀ àwọn ọlọ́pàá?
Agbẹjọ́rò rẹ̀, Amòfin àgbà, Mike Ozekhome ní ìbẹrù fún ẹ̀mí ara rẹ̀ ló mú kí aṣòfin Melaye bẹ́ sílẹ̀ láti inú ọkọ̀ nígbà tí àwọn ọlọ́pàá fẹ́ gbé e lọ sí ìlú Lokoja.
Amòfin Ozekhome ní àwọn ọlọ́pàá yín tajútajú si aṣòfin náà ló fi fò bọ́  sílẹ̀ kí ó tó máa sé èmí.
O ní lẹ́yìn  tí àwọn ọlọ́pàá ti fií  lọ́kàn balẹ̀ pé ìlú Àbúja ni wọn yóò ti ṣe ẹjọ́ rẹ̀ ni wọ́n bá tún pẹ̀yìndà fẹ́ máa gba ọ̀nà Lokoja lọ́sẹ̀ tó kọjá.
Síwájú ọ̀rọ̀ Ozekhome ni àwọn amúgbálẹ́gbẹ́ aṣòfin Dino ti ń sọ f'áráyé pé ọlọ́pàá ló tíì jábọ́ láti inú ọ̀kọ̀.
Aṣòfin Dino Melaye wà níléèwòsàn ìjọba nílùú Àbújá lẹ́yìn tí iléẹjọ́  ti pàṣẹ kí wọ́n fún un láàyè láti gba ìtọ́jú níléèwòsàn ńlá tó  wà nílùú Àbújá.
Àbọ̀dé Libya: Èeyàn 218 padà dé sí ìlú Èkó
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ó lé l'ẹ́gbẹ̀rún mẹ́jọ àwọn ọmọ orílẹ̀èdè Nàíjíríà tí wọ́n ti kó padà dé láti orílẹ̀èdè Libya
Okòólénígba ó dín méjì làwọn ọmọ Nàíjíríà tí wọ́n kó padà dé láti orílẹ̀èdè Libya ni ọjọ́ ìṣẹ́gun.
Agogo mẹrin ìdájí kú díẹ̀ ni bàálù tó kó wọn balẹ̀ sí pápákọ̀ òfúrufú ìlú Èkó.
Mẹ́rìndínláàdóta nínú àwọn àbọ̀dé Libya náà ló jẹ́ obìnrin, méjì jẹ́ ọmọdé, tí mẹ́sán sì jẹ́ ọmọ ìkókó.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Òkìkí ìwà ìmúnilẹ́rú lórílẹ̀èdè Libya ti kárí ayé.
Alámójútó àjọ tó ń mójú tó ìṣẹ̀lẹ̀ àjálù lórílẹ̀èdè Nàìjíríà, NEMA lẹ́kùn ìwọ̀ oòrùn gúúsù Nàìjíríà, Alhaji Yakubu Suleiman ló tẹ́wọ́ gba àwọn àbọ̀dé Libya náà, tó sì gba wọ́n níyànjú láti di olùfọnrere wàhálà àti ewu tó wà nínú sísá gba ọ̀nà ẹ̀bùrú r'òkè òkun .
Àwọn àbòdé láti orílẹ̀èdè Libya yìí ni yóò jẹ́ kó di ẹgbẹ̀rún mẹ́jọ àti mọ́kàndínláàádoje àwọn ọmọ orílẹ̀èdè Nàíjíríà, tí wọ́n ti kó padà dé láti orílẹ̀èdè Libya báyìí, láti ìgbà tí òkìkí ìwà ìmúnilẹ́rú lórílẹ̀èdè náà ti kárí ayé.
Wenger: Àìleè kópa ní ife ẹ̀yẹ àgbáyé ba Koscielny nínú jẹ́
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Koscielny fi ẹsẹ̀ ṣèṣe lásìkò tí Arsenal àti Athletico Madrid ń bá arawọn wàákò.
Agbábọ́ọ̀lù ìkọ Arsenal, Laurent Koscielny kò ní leè fi ẹsẹ̀ rẹ̀ gbá bọ́ọ̀lù fún oṣù mẹ́fà gbáko.
Koscielny fi ẹsẹ̀ ṣèṣe níbí ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ ìpele tó kángun si àṣekágbá ìdíje UEFA lọ́jọ́bọ tó kọjá.
Olùkọ́ni ìkọ agbábọ́ọ̀lù Arsenal, Arsene Wenger ṣàlàyé pé, iṣẹ́ abẹ tí wọ́n ṣe sórí iṣan ẹ̀yìn ẹsẹ̀ ti igbákejì Balógun ikọ̀ Arsenal náà fi pa.
Ní báyìí olùkọ́ni fún ìkọ agbábọ́ọ̀lù orílẹèdè France, Didier Deschamps, ti fìdí rẹ̀ múlẹ̀ pé Koscielny kò leè kópa níbi ìdíje ife ẹ̀yẹ àgbáyé tí yóò wáyé loṣù kẹfà.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ó di oṣù Kejìlá ọdún yìí kì ẹ tó leè ríi lórí pápá.
Gẹ́gẹ́bí Arsene Wenger ṣe sọ, ìròyìn yìí ba Koscielny nínú jẹ́ pupọ̀.
Ó di oṣù Kejìlá ọdún yìí kì ẹ tó leè ríi lórí pápá.
Ìṣẹ́jú Kejìlá ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ náà ni Koscielny fi ẹsẹ̀ ṣèṣe lásìkò tí Arsenal àti Athletico Madrid ń bá arawọn wàákò.
Ìbò abẹ́nú PDP Èkìtì: Olújìnmí yẹ̀bá fún Adéyẹyè
Oríṣun àwòrán, facebook/lere olayinka
Ètò ààbò gbópọn níbi tí ẹgbẹ́ òṣèlú PDP ti ń ṣètò ìdìbò abẹ́nú rẹ̀
Ètò ìdìbò ti bẹ̀rẹ̀ nílùú Àdó Èkìtì níbi tí ẹgbẹ́ òṣèlú PDP ti ń ṣètò ìdìbò abẹ́nú láti yan ẹni tí yóò gbé àṣìá ẹgbẹ́ òṣèlú náà, lásìkò ìdìbò sípò gómìnà ìpínlè ọ̀hún lóṣù keje odun yìí.
Ó lé ní ẹgbẹ̀rún méjì àwọn aṣojú tí yóò kópa nínú ètò ìdìbò náà.
Àwọn olùdíje mẹ́ta, igbákejì gómìnà ìpínlẹ̀ Ẹ̀kìtì, Olúṣọlá Eleka, Dayo Adeyeye tó fìgbàkan rí jẹ́ alukoro ẹgbẹ́ òṣèlú PDP pẹ̀lú Sẹ́nétọ̀ Abiodun Olujimo tó ń ṣojú ẹkún gúúsù ìpínlẹ̀ Èkìtì nílé aṣòfin àgbà, ló ń du àsìá náà mọ́ ara wọn lọ́wọ́.
Oríṣun àwòrán, facebook/lere olayinka
Àwọn olùdíje mẹ́ta ló ń du àsìá náà mọ́ arawọn lọ́wọ́.
Sùgbọ́n ìròyìn tó ń tẹ̀ wá lọ́wọ́ báyìí ní, Seneto to n soju ẹkun idibo guusu Ekiti, Abiodun Olujimi, ti yẹ̀bá fun minisita tẹ́lẹ̀rí fun ọ̀rọ̀ isẹ́ lorileede Naijiria, Ọ́mọọba Dayo Adeyeye ninu idije sipo gomina ipinle Ekiiti.
Olujimi sọ wipe oun fi ipo naa silẹ lati gba alaafia laaye, ati fun igbeleke pelu itẹsiwaju ẹgbẹ oselu alaburada, PDP ni ipinle ekiti.
Olujinmi wa parọwa si awọn alatilẹyin rẹ lati fọwọsowọpọ pẹlu Ọ́mọọba Dayo Adeyeye lati lee yege ninu idibo si ipo gomina ti yoo waye ni ọjọ kẹrinla, osu kẹfa ọdun 2018.
Oríṣun àwòrán, facebook/lere olayinka
Ó lé ní ẹgbẹ̀rún méjì àwọn aṣojú tí yóò kópa nínú ètò ìdìbò abẹ́nú PDP
Bí ó tilẹ̀ jẹ́ wí pé igbákejì gómìnà  rẹ ni Fayose ń ṣàtìlẹyìn fún láti gba ipo rẹ̀, èyí ti fa ìkùnsínú láàárín àwọn olùdíje tí wọ́n ti fi ẹ̀họ́nú hàn lórí èyí.
Ìròyìn tó ń tẹ̀ wá lọ́wọ́ láti ibùdó ìdìbò abẹ́nú náà ní, ètò ààbò gbópọn nibẹ̀, eléyìí tó ṣeéṣe kó níí ṣe pẹ̀lú àbájáde irúfẹ́ ìdìbò abẹ́nú tí ẹgbẹ́ òṣèlú APC ṣe lọ́jọ àbámẹ́ta tó kọjá.
Codine: Ọ̀pọ̀ èèyàn tako iléesẹ́ mẹ́ta tíjọba tì pa
Oríṣun àwòrán, Huw Evans picture agency
Ìjọba fi òté lẹ títa oògùn ikọ́ olómi Codeine
Awọn eeyan ti bẹrẹ si sọrọ lori bi ajọ NAFDAC se ti ile iṣẹ apoogun mẹta, ti n se oogun ikọ olomi Coedine pa.
Awọn ile iṣẹ apoogun naa ni Emzor, Peace Standard ati Bioraj.
@pharm_dezzz sọ pe, awọn ile iṣẹ ti wọn n ṣe oogun Codine kọ ni iṣoro, bi koṣe awọn alagbata ti wọn n ko kaakiri
@purrples woye pe, igbesẹ NAFDAC le se okunfa ọwọn gogo oogun nilẹ Naijiria.
Ero ti @ChinnyPillz ni pe, kii se oogun ikọ olomi Codine nikan ni ile iṣẹ Emzor ati awọn ile iṣẹ oogun meji yoku nse. Kilode ti wọn fi di titipa, sebi oogun ikọ nikan lo yẹ kijọba wọgile?
Ori bibẹ kọni oogun ori fifọ. Ohun ti @GbemiDennis sọ si ọrọ naa niyi. O beere pe kin ni yoo sẹlẹ si awọn oogun mii ti wọn n se ati awọn to n siṣẹ nibẹ?
@zhurg_ sọpe igbesẹ ajọ NAFDAC ku diẹ kaato nitori yoo só ọpọlọpọ di alainiṣẹ.
Wenger: Ọ̀pọ̀lọpọ̀ ẹgbẹ́ agbábọ́ọ̀lú ti kàn sí mi fún iṣẹ́
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Bọ́nà kan ò dí, òmíràn ò ní là. Wenger ti fẹ́ ríṣẹ́ míràn
Akọnimọọgba Arsenal to n lọ, Arsene Wenger, ti sọpe ọpọlọpọ ẹgbẹ agbabọọlu ni wọn ti kan si oun lati jẹ akọnimóógba wọn.
Wenger to ti lo ọdun mejilelogun gẹgẹ olukọni pẹlu égbẹ agbagbọọlu Arsenal. O gba idije Premier League lẹẹmẹta, to si gba ife ẹyẹ FA meje.
Ṣugbọn Wenger sọ pe, oun si n kọju mọ iṣẹ oun ni Arsenal, nibayii ti ko ju bi oṣẹ meji lọ mọ ti yoo fi lọ.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ó dì gbà o, Arsene Wenger dágbére fún ikọ Arsenal
Wenger ni, oun ko ti wo ọkánkan ninu awọn ikọ agbabọọlu naa, ti wọn kan si oun.
Akọnimọọgba naa ni, oun yoo ṣiṣẹ wọ igbati akoko oun ni Arsenal yoo fi tan. Lẹyin igba naa ni oun yoo sinmi diẹ, ki oun to gba iṣẹ miran.
Olúbàdàn: Ìgbésẹ̀ Ajimọbi tako ìsèjọba ìsẹ̀ǹbáyé
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Olúbàdàn àti gómìnà Ajimọbi wojù ara wọn lórí oyè jijẹ nilú Ìbàdàn
Osi Olubadan ti ilẹ Ibadan, Rashidi Ladoja lo pe ọkan lara awọn ọba alade tuntun naa lẹjọ.
Ladọja jare n'ilẹ ẹjọ lori bi o ti lodi si awọn ijoye pẹlu awọn baalẹ ti ijọba sọ di ọba.
Osi Olubadan ti ilẹ Ibadan, Rashidi Ladoja lo pe ọkan lara awọn ọba alade tuntun naa lẹjọ.
Ladọja jare n'ilẹ ẹjọ lori bi o ti lodi si awọn ijoye pẹlu awọn baalẹ ti ijọba sọ di ọba.
Ṣugbọn Gomina ipinlẹ Ọyọ Abiola Ajimobi lọ sile ẹjọ ko tẹmilọrun lori ọrọ naa.
Ijọba só di mimọ pe igbesẹ naa tọna lẹyin ipade pẹlu awọn lọbalọba ni ipinlẹ Ọyọ.
Ṣugbọn agbẹjọro fun Olubadan, Adeniyi Adewọle,sọ pe gomina ko lágbara lati s'epade pẹlu awọn ọba alaye.
Ìbò abẹ́nú PDP Èkìtì: 421 ni Ẹlẹ́ka fi borí alátakò rẹ̀
Oríṣun àwòrán, Facebook/Kolapo Eleka
Òjọ̀gbọ́n Kọ́lápọ̀ Olúsọlá Ẹlẹka gbégbá orókè ínú ìdìbò abẹ́lé PDP fún ipò gómìnà l'Ekiti
Ọjọgbọn Kọlapọ Olusọla Ẹlẹka ni yoo dije fun ipo gomina labẹ ẹgbẹ oṣelu PDP ni ipinlẹ Ekiti ninu idibo ti yoo waye ni ọjọ kẹrinla osu keje.
Ọjọgbọn Ẹlẹka jawe olubori ninu ibo abẹle fun ipo gomina to waye l'ọjọ iṣégun l'Ekiti pẹlu ibo ẹgbẹ́run kan ati igba din kan.
Alatako rẹ ọmọọba Adebayọ Adeyẹyẹ ri ibo ọta le lẹẹdẹgbẹrin o le mẹwa.
Ibo mọkanlelogun o le nirinwo ni ọjọgbọn Ẹlẹka fi fagba han alatako rẹ.
APC: Ìdìbò abẹ́lé Èkìtì yóò wáyé lọ́jọ́ kọkànlá oṣù Karùn-ùn
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ẹgbẹ́ òsèlú APC ṣèlérí láti ṣe àtúngbéyẹ̀wò ááwọ̀ tó wáyé ní Èkìtì
Ẹgbẹ́ òṣèlú All Progressives Congress, APC, ti dá ọjọ́ mìi fún ètò ìdìbò abẹ́lé sí ipò gómìnà tó foríṣánpọ́n ní ìpínlẹ̀ Èkìtì.
Ètò ìdìbò nàá yóò wáyé báyìí lọ́jọ́ kọkànlá, oṣù Karùn ún ọdún 2018.
Akọ̀wé ìpolongo fún ẹgbẹ́ nàá, Bolaji Abdullahi, fi ìkéde nàá síta nígbà tó n bá àwọn akọ̀ròyìn sọ̀rọ̀ lólú ilé ẹgbẹ́ APC tó wà ní ìlú Abuja.
Ìgbìmọ̀ tó ń se agbátẹrù ètò ìdìbò nàá, gbé àbọ̀ ìwádìí tó ṣe lórí ètò ìdìbò tó forísánpọ́n lọ́jọ́ Àbámẹ́ta nítorí rògbòdìyàn, kalẹ̀ lọ́jọ́ Ajé.
Ẹgbẹ́ nàá ti ṣèlérí láti ṣe àtúngbéyẹ̀wò ìṣẹ̀lẹ̀ nàá.
Àwọn olùdíje mẹ́tàlélọ́gbọ̀n, ló n jà fita-fita láti gba tíkẹ́ẹ̀tì ẹgbẹ́ APC. Lára wọn la ti rí àwọn gómìnà nígbà kan rí, àti àwọn aṣòfin àgbà mẹ́ta nígbàkan rí.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Tinubu àti Ọ̀sọbà n ṣe ìpàdé ìdákọ́nkọ́ lọ́wọ́ nílé ìjọba ìpínlẹ̀ Èkó tó wà ní Abuja.
Àmọ́, ìròyìn tó n tó wa lọ́wọ́ sọ pé, asaájú kan fẹgbẹ́ òṣèlú APC, Aṣíwájú Bọla Tinubu, gómínà tẹ́lẹ̀ ní ìpínlẹ̀ Ògùn, Àrẹ̀mọ Ṣẹgun Ọ̀ṣọbà, àti àwọn àṣàyàn èèyàn nínú ẹgbẹ́ nàá n ṣe ìpàdé ìdákọ́nkọ́ lọ́wọ́ nílé ìjọba ìpínlẹ̀ Èkó tó wà ní Abuja.
Ìpàdé nàá ni, ìwé ìròyìn Punch sọ pé ó dá lórii àti fẹnukò lórí ọ̀nà àbáyọ sí ètò ìdìbò tó dàrú l'Ékìtì.
Ọ̀ọ̀ni Ifẹ̀: Ìbọ̀wọ̀ fún àṣà ni yóò mú Nàìjíríà gòké
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ọba Enitan Ogunwusi, Ojaja kejì ké pe àwọn ọmọ orileede Nàìjíríà láti ṣe igbelárugẹ àti apọnle àṣà
Ọ̀ọ̀ni tí Ìlú Ilé Ifẹ̀, Ọba Enitan Ogunwusi, Ojaja kejì, tí ké pe àwọn ọmọ orileede Nàìjíríà láti ṣe igbelárugẹ àti aponle àṣà wá.Ó ní láìsí èyí, ìdàgbàsókè àti igbega kò ní de ba orileede wa.
Ọọ̀ni sọ̀rọ̀ ọ̀hún lásìkò to ṣe abẹwo sí Olú tí Ìlú Warri, Ogiame Ikenwoli ni ààfin rẹ n'ilu Warri nipinle Delta.
Ó ní Eleduwa lo yàn Olú ti ìlú Warri, Ogiame Ikenwoli, fún àwọn ènìyàn Itsekiri àti ìran Yorùbá.Arole Oodua wa kan saara si Olú tí Ìlú Warri fún ọgbọ́n atinuda, ìrẹlẹ ati ojú àánú tó sáfihan bí elédùmarè ṣe ṣeé lọ́jọ tó, gẹ́gẹ́ bí Ọba.Nínú ọ̀rọ̀ rẹ, Olú tí Ìlú Warri tọ́ka sí pé, abewo àkọ́bí Òoduà yóò mú àlàáfíà àti Itesiwaju bá onírúurú ẹ̀yà ni Ìpínlẹ̀ Delta nílé at lẹ́yìn odi.
Benue: Ọwọ́ ọlọ́pàá tẹ àwọn afurasí olókoòwò nkan ìjagun
Oríṣun àwòrán, Nigerian Police
Àwọ́n afurasí ló n ta ìbọn AK47, àtàwọn nkan olóró miì fàwọn jàndùkú, ajìjàgbara àti daran-daran ní Benue àti Taraba.
Ilé iṣẹ́ ọlọ́pàá Nàìjíríà ti tẹ àwọn afurasí tó n fi kátà-kárà nkan ìjagun, tí òfin kò fàáyè gbà ṣiṣẹ́ ṣe ní ìpínlẹ̀ Benue àti Taraba.
Àwọn afurasí ọ̀hún ni wọ́n fi ẹ̀sùn kàn pé, wọ́n n ta ìbọn AK47, àtàwọn nkan olóró miì fún àwọn jàndùkú, ajìjàgbara, tó fi mọ́ àwọn daran-daran àti àwọn àgbẹ̀ tó jẹ́ ọ̀daràn, ní ìpínlẹ̀ Benue àti Taraba.
Wọ́n fi wọ́n hàn lólú iléèṣẹ́ ọlọ́pà tó wà ní ìlú Abuja lọ́jọ́ kẹjọ, oṣù Karùn ún, ọdún 2018.
Lára àwọn tọ́wọ́ bà nàá ni Morris Ashwe, Kabiru Idris, Miracle Emmanuel àti Husseini Safiyanu, tí gbogbo wọn jẹ́ olókoòwò nkan ìjagun.
Àwọn obìnrin Ìkòròdú: Ọdún orò kò ni wá lára rara
Bákan nàá ni ọwọ́ tẹ Emmanuel Ushehemba Kwembe, Sekad Uver, Ordure Fada,  Stephen Jirgba, Peter Lorham, Achir Gabriel, àti Lorhemen Akwambe. Ẹ̀sùn tí wọ́n fi kàn wọ́n ni ijínigbé àti olè jíjà.
Oríṣun àwòrán, Nigerian Police
Àwọn afurasí nàá ló n ta nkan ìjagun fún àwọn adàlúrú ní Benue
Lára àwọn nkan ìjagun tí wọ́n gbà lọ́wọ́ wọn ni òjìlérúgba dín méjì ìbọn AK47 máàrùn ún, àti òjìlérúgba dín méjì ọta ìbọn.
Alukoro fún iléeṣẹ́ ọlọ́pà, Jimoh Moshood sọ nínú àtẹ̀jáde kan pé ìwádìí ṣì n tẹ̀síwájú, kawọ́ le tẹ àwọn afurasí yóòkù tó ti sálọ.
Oríṣun àwòrán, Nigerian Police
Ilé iṣẹ́ ọlọ́pàá fi dá àwọn olùgbé ìpínlẹ̀ Benue àti àwọn tó múlé tì wọn lójú pé òun yóò ri dájú pé àláàfíà tó ti n jọba fi ẹsẹ̀ múlẹ̀.
Ẹ̀wẹ̀, Moshood sọ wí pé,''gbogbo àwọn tọ́wọ́ tẹ̀ nàá ni wọn yóò gbé lọ sí ilé ẹjọ́ níkété tí ìwádìí bá parí.
Ilé iṣẹ́ ọlọ́pàá ti wá fi dá àwọn olùgbé ìpínlẹ̀ Benue àti àwọn tó múlé tìí lójú pé òun yóò ri dájú pé àláàfíà tó ti n jọba fi ẹsẹ̀ múlẹ̀.
Ebola - DR Congo kéde ìtànkálẹ̀ ní ìhà àríwá orílèèdè
Oríṣun àwòrán, AFP
Ìtànkálẹ̀ ààrùn Ebola tó wáyé kẹyìn lọdun 2017 pá èèyàn mẹ́rin.
Ìtànkálẹ̀ ààrùn Ebola ti ṣẹlẹ ní iwọ oórún àríwá orílèèdè DR Congo.
Ile iṣẹ ìlera fìdí ìṣẹlẹ méjì múlẹ wọ́n sì sọ wí pé ènìyàn mẹ́tàdínlógún ti pàdánù ẹ̀mí wọn.
Ìṣẹ̀lẹ̀ náà tó wáyé nílu Bikoro tún ṣẹlẹ̀ lẹ́yìn ọdún kàn tí  Ebola pa ènìyàn mẹ́rin lórílẹ̀èdè náà.
L'ọ́dun 2014,  ó lè ní  ẹ̀ẹ́dẹ́gbẹ̀fà ènìyàn tí ó bá ààrùn náà lọ ní Guinea, Sierra Leone àti Liberia.
Eléyìí ní ìgbà kẹẹ̀sán tí ààrùn Ebola yóò ṣẹlẹ ní DR Congo.
Ọdún 1976 ni wọ́n kọ́kọ́ ṣe àwárí kòkòrò afàìsàn náà nígbà tí orúkọ orílèèdè náà shì n jẹ Zaire.
Orúkọ odo ti wọn ti ṣe àwárí rẹ ni wọn fi perí ààrùn náà.
Ẹgbẹ APC ti kéde ọjọ́ tuntun fún ìdìbò abẹ́nú ní Ekiti
Oríṣun àwòrán, APC NIGERIA
Ìdìbò abẹ́nú ti sáájú wáyé l'ekiti èyí tí wọn kò rójútùú rẹ.
Ẹgbẹ òṣèlú APC ti kéde ọjọ fún ìdìbò abẹ́nú láti yan eni ti yóò gbé àsìá gẹgẹ bí oludije ipò Gómìnà nipinle Èkìtì.
Ọgbẹni Bolaji Abdullahi, akòwé ìpolongo ẹgbẹ, ló lédè ọrọ náà fún àwọn akoroyin nílu Abuja.
Ìgbìmò eleto ìdìbò ẹgbẹ náà ti sáájú fí èsì ìwádìí  lórí òun tó fà ikọlu nibi ìdìbò abẹnu nipinle naa ṣòwò si alága ẹgbẹ lójó ìṣẹgun.
Ẹgbẹ pinnu láti ṣe ìwádìí ìṣẹlẹ náà.
Olùdíje mẹ́tàlélọ́gbọ̀n ni o n kópa nínú ìdìbò náà ti a ti ri Gómìnà nígbà kàn ri méjì àti Senato nígbà kan rí mẹta nínú wọn.
Pàṣípàrọ̀ Yuan si Naira: Èròngbà aráàlú ṣe ọ̀tọ̀ọ̀tọ̀
Oríṣun àwòrán, PBC
Ọjọ tí pé tí awọn orílẹèdè méjèjì tí n peroja àdéhùn paṣi paarọ owo náà
Èrò ṣe ọtọtọ lórí ìgbésẹ orílè-èdè Nàìjíríà láti yan ọwọ yuan orílèèdè China fun idokowo láàrin àwọn méjèjì.
Ìgbésẹ náà tó wáyé lẹyìn ìgbà tí àwọn méjèjì tọwọ bo iwe adehun paṣi paarọ Yuan pẹlu Naira, ni a gbọ wí pé, yóò mú adinku ba lílò dola fún idokowo láàrin àwọn orílèèdè méjèjì.
Ọ̀nà láti mọ anfaani tabi alebu to wa ninu igbesẹ yii lo mu ka kan sawọn eeyan ti eto pasi-paarọ owo ilẹ wa si ti ilẹ okeere gberu.
Lero ti Ken Ukaoha, to jẹ ààrẹ ẹgbẹ oníṣòwò lorílèèdè Nàìjíríà (NANTS) sọ wí pé, ìgbésẹ náà bójú mu.
O ni ''Ọjọ ti pẹ ti a ti n jẹ aràn irú ìgbésẹ báyìí nítorí bí káràkátà ti ṣe pọ láàrin orílèèdè Nàìjíríà àti China''
''Ṣẹ mo wí pé nnkan ko gùn régé láàrin Amerika ati China, fún ìdí èyí, a gbọdọ lo anfààní yii lati mu itẹsiwaju ba eto orò ajé wá.''
Oríṣun àwòrán, Getty Images
China ni orílèèdè ti káràkátà re pọju lọ pẹlu Nàìjíríà
Bákan náà ni ọjọgbọn Uche Uwaleke, to je Olùdarí ẹka imọ nipa eto ifowopamọ ati eto ìṣúná ni yunifásítì Nassarawa ní, ìgbésẹ náà ''yóò mú irọrun ba paṣi paarọ Náírà l'oja àgbáyé.''
''Ko ní sí wàhálà piparo Naira sí dollar ṣáájú ka to lee rà ojà lati China. Yóò sì jẹ kí Naira ni òkun sí ''
Ìpalára ni igbesẹ́ naa fún awon ilé iṣẹ Nàìjíríà
Sugbọn ohun to kọju si ẹnikan, ẹyin lo kọ̀ si ẹlomiran bii ilu gangan. Tóun ti bi ìgbésẹ yii ti ṣe dun to létí, ero awọn onimọ kan tako igbesẹ́ naa. Gẹ́gẹ́ bi wọn ti wi, o ṣeese ko mú ìpalára bá àwọn ilé iṣẹ to n pese ọja ni lorílèèdè Nàìjíríà.
Ninu ọrọ rẹ Uche Uwaleke ni ''oṣuwọn káràkátà fi sọdọ China ju Naijiria lo.''
Ìyè ọja tí Naijiria n ta fún China kéré sí èyí tó n wa lati ọdọ wọn. Fun ìdí èyí, a gbọdọ fi ofin rinlẹ pe kí àwọn olokoowo lati China wà dá ileese silẹ ni Nàìjíríà
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ọdún mẹta ni wọn yóò fí ṣe àdéhùn paṣi paarọ náà
Awọn orilẹede ti China ṣe pàṣípàrọ̀ pẹlú rẹ
Ebola: Nàìjíríà ń ṣọ́ pápákọ̀ òfurufú tórí Ebola
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Àjọ tí ó ń rí sí ìwọlé-wọ̀de ní àwọn kó tún ní gba Ebola láàye o.
Àjọ tí ó ń rí sí ìwọlé wọ̀de ní àwọn yóò bẹ̀rẹ̀ sí ní ṣa ipa ju ti ẹ̀hìn wá lọ láti ríi pe Ebola tí ó ṣẹ̀ṣẹ̀ ṣẹ́ yọ ni DR Congo kò wọ 'nú orílẹ̀ èdè Naijiria.
Agbẹnusọ àjọ náà, Sunday James sọ fún BBC pé gbogbo ọmọ orílẹ̀èdè yìí ní láti sapá wọn kí àìsàn búburú náà ti àwọn eléto ilera DR Congo ni ó ti pa eniyan mẹ́tàdínlógún báyìí, kó má ri 'bi jòkó ni ilẹ̀ẹ wa.
"Ó ní, ""A ó ránṣẹ́ si gbogbo àwọn òṣìṣẹ́ àjọ wa tí o wà ní gbogbo pápákọ̀ òfurufú pe kí wọn fojú sita, kí wọn tún máa lo ẹ́rọ tàmómítà tí wọ́n fi ń wo bí ǹkan ṣe ngbóná sí láti ṣ'àyẹ̀wò fun àwọn èrò."
Bí a bá rí ẹni kankan tí ó dà bíi pé ó ní àìsàn kankan, a ó fa ẹni náà lé àwọn òṣìṣẹ́ ìlera tó wà ní pápákọ̀ òfurufú lọ́wọ́ lẹ́sẹ̀kẹsẹ̀.
Ẹ ó rántí wípé ní ọdún 2014 ni Ebola wọ orílẹ̀èdè Nàìjíríà láti ọwọ́ arákùnrin ọmọ Sierra Leone kan, Patrick Sawyer tí ó gbe àìsàn náà wá láti orílẹ̀èdè rẹ̀. Enìyàn mẹ́jọ ni àìsàn náà pa lákòókò náà.
Ní báyìí, ilú Bikoro ni orílẹ̀èdè DR Congo ni a gbọ́ pé àìsàn náà tún ti bẹ́ jáde.
NYSC: ìdí tí a fí gba Davido láàyè láti jade
Oríṣun àwòrán, Instagram/Davido official
Davido ti di asoju fun ile-isẹ ẹrọ ibaraẹnisọrọ, Infinix
Ilé iṣẹ́ agùnbánirọ tí ìpínlẹ̀ Eko sàlàyé pé àwọn fún Davido láàyè láti kúrò ní àagọ agùnbánirọ nítorí pé ó gbààyé pé ààbo àti aláfíà ẹmi oun kò gbópọn tó.
Òkìkí kan nígboro lẹ́yìn tí Davido fí fotò síta pé oun bẹ̀rẹ̀ ètò agúnbánirọ lẹ́yìn ọdun mẹ́ta tó parei ẹkọ rẹ̀ ní fasiti.
Ilé[-iṣẹ́ agunbanirọ sàlàyé péọdun lati sìnrú ilú baba ẹni ṣe pàtàki àti pé ọdun kan gbáko ló wà fún lójúnààti mú ìrẹ́pọ̀ wà láàrín gbogbo ẹku orílẹ̀-èdè yìí.
Bótill jẹ́ pé Davido fí fotò bó ṣe ń ṣe ìforukọsíll ní àgọ agunbanirọ ní Abulé Ẹgbá nínú oṣu tó kọja síbẹ̀ kò dúro lati parí ètò náà bó ṣe tún fi fótò míràn síta pé òun ní òde orin ní ilẹ̀ Amẹríkà.
Èyí ló fa ìdí abájọ oo tí gbogbo àwọn ènìyàn ṣe ń bèrè lóri ẹ̀rọ àyélujara pé ọ̀nà wọ ní Davido gba kú ní àgọ́ agùnbánirọ̀
Lẹyin 'Assurance'; Davido ra ọkọ ofurufu  kekere
Oríṣun àwòrán, Instagram/Davido official
Davido ti di asoju fun ile-isẹ ẹrọ ibaraẹnisọrọ, Infinix
Olorin taka-sufe nnì,David Adeleke, ti gbogbo eniyan mọ si Davido, ti di ọdọmọde akọkọ lati orilẹede Naijiria ti yoo ra ọkọ baalu kekere fun ara rẹ.
Davido, to pe orukọ ara rẹ ni ‘peace of mind’, ti sọ lori itakun ibaraẹnisọrọ Twitter rẹ pe, oun ti ra ọkọ baalu lẹyin ọkọ̀ ‘assurance’, iyen ọkọ ayọkẹlẹ to ra fun ọrẹbinrin rẹ, Chioma.
Iroyin naa waye lẹyin wakati diẹ ti ọrẹbinrin rẹ, ti wọn tun mọ si ‘personal assurance‘, Chioma Avril Rowland, bu ọwọ lu iwe ibasepọ lori isẹ́ ìdáná rẹ, ti Davido si di asoju fun ile-isẹ ẹrọ ibaraẹnisọrọ, Infinix.
Wayii o, èrò ọmọ Naijiria kan ree ninu ọpọ eeyan to ti fesi si igbesẹ tuntun Davido naa.
Shiite: Bí Buhari kò bá tú ZakZaky silẹ̀, apa APC kò níí káa mọ́
Ìgbà àkọ́kọ́ kọ́ nìyí tí àwọn ọmọ ẹgbẹ́ Shiite yóò fẹ̀hónú hàn fún ìtúsílẹ̀ olori wọn
Ẹgbẹ́ ẹlẹ́sìn Islamic Movement kan ni Nàìjíríà, Shiite, ti ṣe ìfẹ̀hónú han lọ sí ilé ọ̀kan ninu aṣíwájú ẹgbẹ́ òṣèlù All Progressives Congress, APC, Aṣíwájú Bola Tinubu, tó wà ní ìlú Èkó.
Ìfẹ̀hònú hàn nàá tó wáyé lọ́jọ́ kẹsàn án, oṣù Karùn ún, ni wọ́n ṣe, láti fi rawọ́ ẹ̀bẹ̀ sí Tinubu, kó le bá Ààrẹ Muhammadu Buhari sọ̀rọ̀, láti tú olórí wọn, Ibrahim Zakzaky, sílẹ̀.
Zakzaky ti wà láhàmọ́ àwọn ẹ̀ṣọ́ aláàbò ọ̀tẹlẹ̀múyẹ́ DSS, láti ọdún 2015.
Shiite ní ó yẹ kí Tinubu lee bá Buhari sọ̀rọ̀ nípa Zakzaky.
Wọ́n ní, níwọ̀n ìgbà tó jẹ́ pé Tinubu jẹ́ ọ̀kan gbòógì, lára àwọn tó dá ẹgbẹ́ òṣèlú APC tó gbé Buhari wọlé sí ipò ààrẹ sílẹ̀, ó yẹ kó le bá a sọ̀rọ̀ nípa Zakzaky.
"Muftau Zakariyau, tó jẹ́ Olùdarí ẹgbẹ́ Shiite ní ẹkùn Gúúsù ìwọ̀ oorùn Nàìjíríà, sọ fún BBC Yorùba pé, ''àwọn wá láti sọ fún Tinubu pé Buhari tó gbé wọlé sípò ti gbàbọ̀dè fún Nàìjíríà""."
Apá APC le má ká ohun tó le tẹ̀yìn rẹ̀ yọ tí Buhari bá kọ̀ láti tú Zakzaky sílẹ̀.
"Àti pé apá APC le máà ká ohun tó le tẹ̀yìn rẹ̀ yọ tí Buhari bá kọ̀ láti tú Zakzaky sílẹ̀."""
"Ó ní ''àwọn kò ní sinmi ìfẹ̀hónú hàn títí tí ọ̀gá àwọn yóò fi gba òmìnira."""
Sàràkí: Ọ̀gá ọlọ́pàá Nàíjíríà kò yẹ láti dipò òsèlú mú
Oríṣun àwòrán, @PoliceNG
Àwọn aṣòfin bojú wo ọ̀rọ̀ náà gẹ́gẹ́ bíi ìwà àìlákàsí àti àfojúdi.
Ilé aṣòfin àgbà ti kéde ọ̀gá ọlọ́pàá lórílẹ̀èdè Nàìjíríà, Ibrahim Idris gẹ́gẹ́ bíi ọ̀tá ìjọba tiwa-n-tiwa ti kò sì yẹ láti di ipò ìṣèjọba mú yálà lórílẹ̀èdè Nàìjíríà tàbí lókè òkun.
Èyí ni ọ̀rọ̀ tí ààrẹ ilé aṣòfin àgbà fi kásẹ̀ ọ̀rọ̀ rẹ̀ nílẹ̀, níbi ìjòkó ilé lọ́jọ́ọ̀rú lẹ́yìn tí  Ibrahim Idris tún kùnà láti farahàn níwájú ilé.Ìgbà kẹ́ta nìyí tí ọ̀ga olọ́pàá Idris yóò máa kọ etí  ikún sí ìpè àwọn aṣòfin àgbà láti wá wí tẹnu rẹ̀ lórí àwọn ìhùwàsí olọ́pàá lórílẹ̀ede Nàíjíríà.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí:
Sẹ́nétọ̀ Sàràkí ní, lẹ́yìn ìpàdé ìdákọ́ńkọ́ tí wọ́n ṣe, àwọn aṣòfin bojú wo ọ̀rọ̀ náà gẹ́gẹ́ bíi ìwà àìlákàsí àti àfojúdi.
BBC: Ìhùwàsí iléẹ̀kọ́ IMT àti ọlọpàá kò jẹ́ ìtẹ́wọ́gbá
Akọ̀ròyìn BBC, Ebere Ekeopara, ni wọ́n gbámú, tí wọn sì tì mọ́lé fún wákàtí mẹ́rin lọ́jọ́ Ajé
Iléesẹ́ BBC ti se àpèjúwe ìhùwàsí àwọn ọlọ́pàá àtàwọn òsìsẹ́ iléẹ̀kọ́ gbogbo-ǹse Poly ti Enugu, lẹ́kùn ìlà òòrùn gúúsù Nàíjíríà, tí wọn yájú sí akọ̀ròyìn wa, Ebere Ekeopara, ti BBC Ìgbò, tí wọn sì tìí mọ́lé, gẹ́gẹ́ bíi èyítí kò jẹ́ ìtẹ́wọ́gbà.
Ekeopara ló lọ se àkójọpọ̀ ìròyìn kan ní iléẹ̀kọ́ ìmọ̀ ẹ̀rọ̀ IMT ní Enugu lọ́jọ́ ajé, nígbàtí àwọn òsìsẹ́ kan ya bòó, tí wọn sì fàá lé ọlọ́pàá lọ́wọ́.
"Agbẹnusọ fún BBC ní ""Ìhùwàsí iléẹ̀kọ́ náà àti àwọn ọlọpàá kò lẹ́tọ̀ọ́ rárá, tí kò sì jẹ́ ìtẹ́wọ́gbá."""
Wọ́n ba ọkọ̀ Ebere jẹ́ lásìkò wàhálà náà
Ọpẹ́lọpẹ́ kọmísánà ọlọ́pàá ní ìpínlẹ̀ náà, Mohammed Danmallam, tó ní kí wọn tú Ekeopara sílẹ̀.
Nígbà tí BBC kàn sí ọ̀gá àgbà iléẹ̀kọ́ Poly náà, ó ní ó yẹ kí akọ̀ròyìn náà gba àsẹ lọ́wọ́ iléẹ̀kọ́ náà, kó tó lọ kó ìròyìn jọ nínú iléẹ̀kọ́ náà.
Ó ń fọ̀rọ̀ wá àwọn èèyàn lẹ́nu wò láì gba àsẹ. Mo ti ní káwọn ọlọpàá wọ́gilé ẹjọ́ náà.
Adájọ́ fi amòfin tó pá ọkọ rẹ̀ satìmọ́lé títí yoo fi gbàmọ̀ràn
Oríṣun àwòrán, Facebook
Adájọ fi aya olóògbé Otike sátìmọ́lé lẹ́yìn tó gbádùn nilé ìwòsàn
Udeme Odibi yóò wà látìmọ́lé tìtì Adájọ́ Kikẹlọmọ Ayeye yóò fi gba ìmọ́ran tó yẹ fún ìdájọ́ rẹ̀.
Adajọ Kikẹlọmọ tile ẹjọ Abẹ́lé ni Yaba ni ipinlẹ Eko ti ni ki Udeme Odibi, ti wọn fẹ̀sùn kàn pé ó pa ọkọ rẹ̀ Otike Odibi l'ọjọ Bọ to kója ṣi wà látìmọ́lé ná.
O sọ èyi lọjọ Ru nigba ti wọn gbe ẹjọ agbejọrò abilekọ ti wọn tún ni o gé ǹkan ọmọkunrin ọkọ rẹ̀ lẹ́yìn tó pa á, wà si ilé ẹjọ́.
Ẹsùn ìpànìyàn ni wọn fi kan agbẹjọrò ọmọ ọdun mejidinlaadọta ọhún, ni eyi to ṣe lodi si ofin ilẹ yii.
Oluṣẹyẹ Bamijoko, to jẹ agbẹjọrò olùjẹ́jọ́, bẹbẹ pe ki wón ti  olùjẹ́jọ́ òun si ọgba ẹwọn ikoyi dipo ti kirikiri pèlú igbagbọ pe àwón onisegun oyinbo yóò le yẹ Udeme wo bi o ti yẹ.
O ni àwón dokita tó ń tọju agbẹjọrọ naa wa ni agbegbe Ikoyi si Victoria Island ni Eko.
Adajọ Ayeye ni ki wọn maa gbe Udeme lọ si ọgba éwón Kirikiri nitori pe kò si aaye fún obìnrin ni ọgba ẹwọn ikoyi bayii,  ṣugbọn, ó ni ki wọn fún olujẹjọ naa laaye lati maa ri ẹbí àti agbẹjọrọ rẹ̀ nidakóńkọ́.
Bakan naa ló ni ki wọn má tíì sin òkú Otike, gẹgẹ bi wọn ṣe pinnu lọjọ Bọ tẹlẹ, ṣugbọn ki wọn duro ki iwadii fi parí ki wọn to sin in.
Adajọ sún ìgbẹ́jọ́ naa siwaju di ọjọ kẹẹdọgbọn, oṣu kẹfa ọdun.
Ọdún méta ni àwọn agbẹjọro mejeeji fi jọ gbé ni lọ́kọláya ti wọn kò si bímọ fún ara wọn ki Otike tó doloogbe nile wón ni Daimond Estate ni Ajah nipinẹ Eko.
PDP: Ọ̀tẹ̀ tó pa wọ́n pọ̀ náà ló ń tu wọ́n ka
Oríṣun àwòrán, @AbekeOlamide
Mo sa ipá mi ni NIMC gẹ́gẹ́ bii ọmọ Nàìjíríà rere ṣùgbọ́n mo fẹ́ tẹ̀siwaju ninu ìran míràn
Omọba Olagunsoye Oyinlola ti kọ̀wé fi ipò rẹ̀ silẹ̀ gẹ́gẹ́ bii alaga àjọ NIMC to ń ṣè káàdì ìdánimọ̀ ni Nàìjíríà, tó sì tún kúrò nínú ẹgbẹ́ òsèlú APC
Oyinlọla kọwe ìfipòsílẹ̀ náà ránṣẹ́ sí Aarẹ Buhari lọjọ kẹsan an osù karùn-ún.
"Ó ní ""Aarẹ, mo dúpẹ́ pé mo ni oore ọ̀fẹ́ láti sin ilẹ̀ baba mi gẹ́gẹ́ bi ipò ti mo dìmú. Mo ṣiṣẹ́ bi mo ṣe ni agbára to láti ṣee, ṣùgbọ́n o di dandan fún mi láti fipò yìi sílẹ̀, ki n lè gbájúmọ́ iṣẹ́ òṣèlù ti mo fẹ́ tọrun bọ̀"
"bayii. Emi kò jẹ́ dalẹ̀ ọga mi lẹ́nu iṣẹ́, ṣùgbọn mo fẹ́ tọ ipa ti ọkàn mi fẹ́ lásìkò yii ninu òṣèlu. Idí niyii ti mo ṣe gbọ́dọ̀ fi ipò mi silẹ̀ ni NIMC.  Inú mi dùn fún bi ẹ ṣe gbàmi laaye láti sin ilẹ baba mi. Ní bayii, àsìkò ti tó fún mi láti sin àwọn ènìyàn mi lọna miran""."
Wàyí ò, ẹgbẹ́ òsèlú PDP, tó jẹ́ ẹgbẹ́ òsèlú alátakò gbòógì ní ilẹ̀ Nàíjíríà, ti fèsì lórí ìsẹ̀lẹ̀ yìí.
Ọ̀gbẹ́ni Diran Odẹyẹmi, to jẹ́ oluranlọwọ alukoro ẹgbẹ́ òṣèlú PDP sàlàyé pé, ìgbésẹ́ Oyinlola yìí kò ya ẹgbẹ òṣèlú PDP lẹ́nu nitori pe kìí se ara wọn tẹ́lẹ̀-tẹ́lẹ̀.
Ó fi kún pé ọ̀tẹ̀ tó pa wọ́n pọ̀ náà ló ń tu wọ́n ka.
Oyinlọla kọ̀wé fipò rẹ̀ sílẹ̀ ni NIMC
Odẹyẹmi sọ̀rọ̀ lori àìsí agbára òfin lòdì sí ki àwọn ènìyàn maa ṣe aṣẹ́wó òṣèlú lati égbẹ́ òṣèlú kan si ìkejì.
O yẹ ki wọn maa padanu ipò wọn ti wọn ba ti kuro lati inu ẹgbẹ òṣelu kan si omiran ni.
Idá-omi ya pa ènìyan 27 ní Kenya
Oríṣun àwòrán, AFP/Getty Images
Ọ̀pọ̀lọ́pọ̀ dúkìá àti ẹ̀mí ló ti ṣ'òfò nínú ìṣẹ̀lẹ̀ náà
Kò dín ní ènìyàn mẹtadinlọgbọn tí ó ti kú báyìí ní Kenya bí ìdá-omi kan ṣe ya ní ìlú Solai, ní apá àríwá Nairobi.
"Gomina ẹkùn Nakuru, Lee Kinyajui, ní, ""Omi tó ya láti Patel Dam ti ba ọ̀pọ̀lọ́pọ̀ dúkìá jẹ́ tí ó si ti f'ẹ̀mí púpọ̀ ṣ'òfò. A kò tilẹ̀ tíì mọ bí òfò náà ṣe burú tó baáyìí."""
Ẹgbẹ́ alaanu Red Cross ní orilẹ̀ èdè Kenya ni bí eniyan mọ́kàndínlógójì ni àwọn ti dóòlà ẹ̀mí wọn báyìí ti wọn ti kó lọ sile ìwòsàn fún ìtójú.
Àwọn tí ó n ṣe ìrànlọ́wọ́ fún àwọn tí ó fara kááṣa ìṣẹ̀lẹ̀ náà ṣàlàyé pé ọ̀pọ̀lọ́pọ̀ ènìyàn ni ó rì sínú ẹrọ̀fọ̀ tí wọ́n ṣì ń wá.
Oríṣun àwòrán, AFP/Getty Images
Wọ́n ṣì ń wá ọ̀pọ̀lọ́pọ̀ ènìyàn tí ó rì sínú ẹrọ̀fọ̀
A gbọ́ pé ìró ńlá dún nígbà tí ìdá omi náà ya ni oru. Bí omi náà ṣe ya ni ó kó àwọn ogunlọ́gọ̀ ilé tí ó wà ní ìsàlẹ̀ odò lọ.
Bíi ẹgbẹ̀rún méjì ènìyàn ni ó ti di aláìnílelórí báyìí.
Àwọn onímọ̀ nipa ojú ọjọ́ ni àrọ̀ọ̀rọ̀dá òjò to ń rọ̀ ni gbogbo ìlà oòrùn Afrika ló jẹ́ ki Omi ya pa ni Kenya ni èyí to n fa ikú ọ̀pọ̀ ènìyàn púpọ̀.
EFCC: Ààrẹ Buhari ní gbogbo àwọn aṣèbàjẹ́ ni wọn yóò fojú winá òfin
Oríṣun àwòrán, Reuters
Aarẹ orilẹede Naijiria, Muhammadu Buhari ti ni lọọtọ ni iwa ibajẹ ati jẹgudujẹra gbinlẹ ni orilẹede Naijiria.
Buhari sọ ọrọ yii lasiko ti oun fesi fun igba akọkọ lori bi wọn ṣe yọ Ibrahim Magu kuro ni ipo gẹgẹ bi adari Ajọ to n gbogun ti iwa ibajẹ lorilẹede Niajiria, EFCC.
Aarẹ ni gbogbo ọmọ Naijiria gbọdọ mọ wi pe wọn yoo jiyin ohun gbogbo ti wọn ba ṣe, paapaa awọn to di ipo mu lorilẹede Naijiria.
O ni bi ọwọ sinku awọn agbofinro ṣe mu Magu fihan pe ko si ẹni to kọja ofin ni Naijiria.
Aarẹ Buhari lasiko idibo sipo aarẹ ni ọdun 2015 ati 2019 sọ wi pe ọkan googi ninu ohun ti iṣejọba oun yoo ṣe ni gbigbogun ti iwa ibajẹ.
Amọ, awọn alatako ati onwoye ọrọ ilu n sọ wi pe aarẹ Buhari ko ṣiṣẹ takuntakun nipa gbigbogun ti iwa ibajẹ, nitori wọn fi ẹsun kan awọn to wa ni iṣejoba rẹ fun iwa ibajẹ.
Igbakeji aarẹ Yemi Osinbajo ti sẹ lori ahesọ iroyin kan to ni Ibrahim Magu, alaga ajọ EFCC tẹlẹ, ti jẹwọ pe, oun tẹwọ gba miliọnu mẹrin naira lọwọ rẹ.
Atẹjade kan ti akọwe iroyin si igbakeji aarẹ, Laolu Akande fisita ni irọ to jinna sootọ ni awọn iroyin nipa isẹlẹ naa, to wa lawọn oju opo iroyin kan.
Oríṣun àwòrán, @YemiOsinbajo
Awọn iwe iroyin kan lo gbe iroyin naa jade pe, wọn fi ẹsun kan Ibrahim Magu pe, o ko owo to to biliọnu mọkandinlogoji naira jọ, to si fun Osinbajo ni biliọnu mẹrin naira ninu rẹ.
Ẹsun miran ti wọn tun fi kan igbakeji aarẹ ninu awọn iroyin naa ni pe, o pasẹ fun ajọ EFCC lati wọgile awọn ipinnu rẹ kan lai tẹle ofin to yẹ.
Amọ igbakeji aarẹ ti wa ni ofuutu fẹẹtẹ, aasa ti ko ni kaun ni awọn ẹsun naa, to si se apejuwe wọn bii ara ọna lati ta epo si asọ aala oun loju araye ni.
Oríṣun àwòrán, Facebook/Ibrahi Magu
Laolu Akande wa salaye pe, igbakeji aarẹ ni oun ko ni faaye gba irufẹ awọn iroyin eke yii lati si i oun lọna nidi sise isẹ ilu bo se yẹ.
Atẹjade kan to fi sita ni Osinbajo kede pe oun ti fa ọrọ yii le awọn agbofinro lọwọ fun iwadi ati igbẹjọ to yẹ.
Bẹẹ ba gbagbe, Ibrahim Magu tii adele alaga fun ajọ EFCC fun ọdun marun, ni igbimọ kan ti aarẹ gbe kalẹ n tanna wadi rẹ lọwọ lori ẹsun iwa ajẹbanu ati aigbọran si awọn alasẹ.
Oríṣun àwòrán, Getty Images/others
Ọdun 2002 ni ijọba da ajọ to n gbogun ti iwa ibajẹ l'orilẹ-ede Naijiria, EFCC, silẹ.
Eyi si waye labẹ iṣakoso Aarẹ Olusegun Obasanjo.
Gẹgẹ bi ofin to da ajọ naa silẹ ṣe sọ, EFCC ni oju'se lati dena tabi wadii iwa ibajẹ.
O si tun ni ẹtọ lati gbe awọn afurasi lọ sile ẹjọ.
Lati ọdun 2003 ti ajọ EFCC ti bẹrẹ, Alaga mẹrin lo ti ni.
Awọn mẹrẹẹrin ni Mallam Nuhu Ribadu, Arabinrin Farida Waziri, Ọgbẹni Ibrahim Lamorde, ati Ibrahim Magu.
Sugbọn nkan ti a ṣakiyesi ni pe, gbogbo awọn alaga ajọ EFCC to ti jẹ, lo maa n koju awuyewuye kan, tabi omiran.
O le jẹ nigba ti eto iyansipo wọn bẹrẹ, ti wọn ba bẹrẹ isẹ, tabi ti wọn ba ti n ṣiṣẹ lọ.
Ẹsun to si wọpọ ti wọn fi ma n kan wọn ni aṣilo ipo, ati iwa ibajẹ.
Bi ọkọọkan wọn, isẹ ti wọn se ati bi wọn se ba itiju kuro lori aleefa se lọ ree:
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Lara awọn aṣeyọri rẹ ni bo ṣe mu Gomina ipinlẹ Delta nigba kan, James Ibori, to ji obitibiti owo ipinlẹ rẹ ko.
Aarẹ Oluṣegun Obasanjo lo yan Ribadu sipo gẹgẹ bi alaga akọkọ fun ajọ EFCC.
"Obasanjo da a pada sipo lẹyin saa rẹ akọkọ, 'fun pe o ṣe daada""."
Iṣejọba Aarẹ Umar Musa Yar'Adua lo yọ ọ nipo lẹyin ọsẹ diẹ to bẹrẹ saa keji gẹgẹ bi alaga EFCC.
Awọn ẹsun ti wọn fi kan Ribadu nigba naa ni pe, o lọwọ si fifi iya jẹ awọn afurasi ti ọwọ ajọ naa ba tẹ lọna to tako ẹtọ ọmọniyan.
Wọn tun fi ẹsun kan an pe, awọn 'ọta' aarẹ Obasanjo nikan lo n doju 'ija igbogun ti iwa ibajẹ kọ.
Lara ẹṣẹ ti ọpọ tun sọ pe Ribadu ṣẹ ni pe, ko sọ otitọ nipa iye dukia rẹ to kede.
Niṣe ni wọn rọ Ribadu loye kuro ni ipo Igbakeji Ọga agba ọlọpaa, si ipo kọmisana, ni kete ti wọn gba iṣẹ alaga ajọ EFCC lọwọ rẹ.
Ileeṣẹ ọlọpaa sọ pe iyansipo rẹ ko ba ofin mu.
Lara awọn aṣeyọri rẹ ni bo ṣe mu Gomina ipinlẹ Delta nigba kan, James Ibori, to ji obitibiti owo ipinlẹ rẹ ko.
Ọrọ Ibori naa si ni ọpọ gbagbọ pe o fa yiyọ ti wọn yọ nipo alaga EFCC.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ọdun 2011 ni Aarẹ Goodluck Jonathan, to yan Farida Waziri sipo alaga ajọ EFCC, gba iṣẹ lọwọ rẹ.
Lati ibẹrẹ iṣẹ rẹ ninu ajọ EFCC si ni awuyewuye ti n waye nipa rẹ.
Wọn fi ẹsun kan an pe, o ṣe oniduro fun gomina ipinlẹ Benue tẹlẹ, Gerorge Akume, ti EFCC fi ẹsun iwa ibajẹ kan labẹ iṣakoso Nuhu Ribadu.
Lara ẹsun ti wọn tun ka si Waziri l'ẹsẹ ni pe, o yọnda awọn gomina tẹlẹ ti ajọ naa fi ẹsun ibajẹ kan.
"Jonathan sọ nigba naa pe oun yọ Waziri nipo ""lati le mu atunṣe ba gbigbogun ti iwa ibajẹ ni Naijiria""."
O ni oun pinnu lati gba iṣẹ naa lọwọ rẹ nitori ẹsun ati awuyewuye to n waye lori rẹ, lati ọdọ awọn ọmọ orilẹ-ede Naijiria, ati awujọ agbaye.
Ajọ keji to n gbogbun ti iwa ibajẹ ni Naijiria, ICPC, sọ nigba naa pe oun n wadii Waziri fun iwa ibajẹ.
Igbakeji rẹ, Ibrahim Lamorde lo si gba ipo rẹ.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ọpọ ọmọ Naijiria lo sọ nigba naa pe ile aṣofin n fi oro ya oro lara Lamorde ni, fun bo ṣe n wadii awọn aṣofin kan.
Lara awọn ẹsun ti wọn fi kan Lamorde ni pe, o kọ lati ko owo to to triliọnu meji aabọ, ti ajọ naa gba lọwọ awọn olori to ji i ko, si apo ijọba.
Ṣugbọn Lamorde sọ fun BBC nigba naa pe, nitori pe ajọ EFCC n ṣe iwadii ọkunrin to fi ẹsun naa kan oun, lo ṣe ṣe bẹ ẹ.
Koda, ọpọ ọmọ Naijiria lo sọ nigba naa pe, ile aṣofin n fi oro ya oro lara Lamorde ni, fun bo ṣe n wadii awọn aṣofin kan.
Bakan naa ni wọn tun fi ẹsun kan an pe o dari owo ti ajọ naa pa lara tita awọn dukia ti ijọba gba lọwọ Ọga Agba ọlọpaa nigba kan, Tafa Balogun, ati gomina ipinlẹ Bayelsa, Alamieyesiegha.
Ṣugbọn, Lamorde sọ pe oun ko jẹbi awọn ẹsun naa.
Oríṣun àwòrán, Others
Laarin awọn alaga mẹrin to ti dari ajọ EFCC, Ibrahim Magu lo koju awuyewuye julọ.
Ẹẹmeji ni ile aṣofin agba kọ lati buwọlu iyansipo rẹ, nitori iwe 'ẹ fura' ti awọn ọlọpaa ọtẹlẹmuyẹ DSS kọ nipa rẹ.
Ipo adele alaga lo wa titi iyọnipo rẹ lọjọ Keje, oṣu Keje, ọdun 2020.
Pupọ ninu awọn ẹsun naa niroyin sọ pe, o wa lati ọdọ Agbẹjọro Agba fun Naijiria, Abubakar Malami, ati aabọ iwadii ti ajọ DSS fun ile aṣofin laarin ọdun 2016 si 2017.
Wọn tun fi ẹsun kan Magu pe, oun naa n dari owo ti EFCC gba lọwọ awọn ọdaran si ibomii, o n ba awọn oniwa ibajẹ ṣe pọ, ati afojudi si ọfiisi Agbẹjọro agba.
Oladapo Adu: Nàíjíríà já mi kulẹ̀ torí wọn kò wá gbé mi
O farahan niwaju igbimọ tileeṣẹ aarẹ gbekalẹ lati ṣewadi ẹsun mẹrinlelogun ti wọn fi kan larin ọdun maarun to fi jẹ adele alaga ajọ EFCC.
Ṣugbọn ajọ EFCC tako iroyin to kọkọ jade sori ayelujara pe, Ibrahim Ibrahim Magu ti wa ni gbaga ajọ ọtẹlẹmuyẹ DSS.
Ajọ EFCC ṣalaye loju opo Facebook rẹ lọjọ Aje wi pe, lootọọ ni Magu lọ farahan niwaju igbimọ ijọba to ṣayẹwo iṣẹ EFCC lọjọ Aje niluu Abuja.
Ajọ naa fikun ọrọ rẹ pe, Ọgbẹni Magu gba ifiwepe lati ọdọ igbimọ naa nigba ti o n lọ si olu ileeṣẹ ajọ ọtẹlẹmuyẹ fun ipade kan.
EFCC ni ajọ DSS ko fi panpẹ ofin mu Magu, bẹẹ si ni igbimọ ijọba to lọ farahan niwaju rẹ ko fi tipa mu un pe ki o wa farahan.
Ẹwẹ, ajọ ọtẹlẹmuyẹ DSS naa ti sọ tẹlẹ irọ ni iroyin to tan kalẹ kaakiri pe, ajọ naa ti fi ọwọ ofin adele alaga ajọ EFCC, Ibrahim Magu.
Ninu atẹjade ti alukoro fun ajọ DSS, Ọmọwe Peter Afunanya fi sita lọjọ Aje, o ṣalaye pe iroyin ofege lawọn ileeṣẹ iroyin kan n gbe kiri lori ọrọ Magu
Oríṣun àwòrán, Facebook/Ibrahim Magu
Ọmọwe Afunanya sọ pe ajọ DSS fi atẹjade sita nitori ọpọ lo n pe wọn, lati mọ bo ya lootọọ ni wọn ti fi panpẹ ofin mu Magu.
Ọpọ iwe iroyin papaa julọ lori ayelujara lo sọ pe, Magu ti wa ni gbaga DSS lori ẹsun pe o kojẹ ninu owo ti ajọ EFCC gba lọwọ awọn jẹgudujẹra ti wọn kowo Naijiria jẹ.
Koda awọn iwe iroyin kan tiẹ sọ pe awọn ẹṣọ Ọgbẹni Magu atawọn DSS fija pẹta nigba ti wọn fẹ mu un.
Ṣugbọn alukoro DSS ti sọ pe ayederu iroyin ni gbogbo ẹ.
N24bn pọ̀ jù láti kọ́ ọ́fíìsì EFCC
Ẹnu kò tí i sìn lára àjọ EFCC lórí iye tó lò láti kọ́ olú iléeṣẹ́ tuntun fún àjọ nàá.
Ilé tuntun ọ̀hún, ni alága àjọ nàá, tó n gbógun ti ìwà ìbàjẹ́ àti ìjẹkújẹ l'órílẹ̀èdè Nàìjíríà, Ibrahim Magu ní '' ó yẹ kí àwọn ọmọ Nàìjíríà yin òun ni fún lílo bílíọ́nù mẹ́rìnlélógún Naira fi kọ́ ilé tó yẹ kí àwọn kọ́ pẹ̀lú ọgọ́rùn bílíọ́nù Naira.
Ilé alájà mẹ́wàá ọ̀hún tó wà ní ìlú Abuja, ni ìrètí wà pé Ààrẹ Muhammadu Buhari yóò ṣí lọ́jọ́ kẹẹ̀dógún, oṣù Karùn ún.
Oríṣun àwòrán, @officialEFCC
Magu fi ìdí rẹ̀ múlẹ̀ pé olú iléeṣẹ́ tuntun nàá kò le gba gbogbo àwọn òṣìṣẹ́ àjọ nàá tó wà ní ìlú Abuja.
"Àmọ́, Onímọ̀ kan nípa ìdíyelé ilẹ̀ àti ilé, tó bá BBC Yoruba sọ̀rọ̀ sọ pé ""owó nàá pọ̀ kọjá bó ṣeyẹ láti fi kọ́ ìlé alájà mẹ́wàá nàá, tó fi mọ́ àwọn tó wà lẹ́gbẹ̀ẹ́ rẹ̀."
"Ó ní, ó ṣeéṣe kí àwọn irinṣẹ́ ètò ààbò tó jẹ́ ojúlówó wà níbẹ̀, tó fi mọ́ àwọn nkan mìi tí wọ́n kó síbẹ̀, ṣùgbọ́n kò yẹ kí iye tí wọ́n nàá láti fi kọ́ ìlé nàá tó bẹ́ẹ̀."""
Láìpẹ́ yii, ni àjọ EFCC ké gbàjarè pé àìsí owó tótó n ṣe ìdíwọ́ fún iṣẹ́ òhun. Ìbéèrè tó ti wá gba orí ẹ̀rọ ayélujára ni pé, ṣé àjọ tí kò rówó ṣiṣẹ́ yẹ kó ná mílíọ́nù mẹ́rìndínlógún láti fi kọ́lè.
Oríṣun àwòrán, @officialEFCC
Magu ni olú iléeṣẹ́ tuntun nàá kò le gba àwọn òṣìṣẹ́ tó wà ní ìlú Abuja.
Ìwé ìròyìn Premium Times jábọ̀ pé ''Magu fi ìdí rẹ̀ múlẹ̀ pé olú iléeṣẹ́ tuntun nàá kò le gba gbogbo àwọn òṣìṣẹ́ àjọ nàá tó wà ní ìlú Abuja. Àti pé, wọn yóò ṣi maa lo olú iléeṣẹ́ àtijọ́ tó wà ní agbègbè Adetokunbọ Ademọla, ní ìlú Abuja.
"Bákan náà, ó ni, ""àwọn òṣìṣẹ́ àjọ nàá tó fi àwọn ilé tí wọn yá ṣe ọ́fíìsì nílùú Abuja, yóò ṣì maa lo àwọn ilé nàá."""
Iléẹjọ́: Ọjọ́ mérìnlá ló yẹ kí Omo-Agege fi jókòó sílé
Oríṣun àwòrán, @OvieOmoAgege
Ileegbimọ aṣofin fi ẹsun kan an wipe oun lo dari awọn janduku to gbe ọpa asẹ ile lọ.
Ilé ẹjọ́ gíga ìjọba àpapọ̀ tó wà ní ìlú Abuj,a ti wọ́gi lé àṣẹ lọ gbélé rẹ, tí ilé ìgbìmọ̀ aṣòfin àgbà pa fún Aṣòfin Ovie Omo-Agege.
Onídàjọ́ Nnamdi Dimgba, tó gbé ìdájọ́ nàá kalẹ̀ l'Ọ́jọ́bọ̀ sọ pé, ìgbésẹ̀ àwọn aṣòfin nàá kò bá òfin mu.
Ìwé ìròyìn The Punch jábọ̀ pé, Onídàjọ́ Dimgba ní ''bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé ìlé aṣòfin ní agbára láti bá ọmọ ilé tó bá ṣìwà hù wí, ó ní, ọ̀nà tí wọ́n gbé ọ̀rọ̀ Omo-Agege gbà lòdì s'ófin, tó sì tún jẹ́ ìwà àrínfín sí ilé ẹjọ́.
Iléẹjọ́ fi kun pé àkọsílẹ̀ ìgbìmọ̀ ilé aṣòfin tó wà fún ìhùwàsí, tó gba àwọn aṣòfin nímọ̀ràn láti lé Omo-Agege lọ sílé, jẹ́ kó di mímọ̀ pé, wọ́n bá a wí nítorí pé ó pe ẹ̀jọ́ tako ilé aṣòfin lẹ́yìn tó tọrọ àforíjì lọ́wọ́ ilé fún ẹ̀sùn tí wọ́n fi kàn án.
Adájọ́ ní ilé ṣègbè pé ó gba Dino Melaye láàyè láti kópa níbi ìjókòó ilé
"Ó fi kun pé, kò yẹ kí wọ́n da a dúró ju ọjọ́ mẹ́rìnlá lọ gẹ́gẹ́ bí òfin ilé ṣe là á kalẹ̀, '''ká ti ẹ̀ ní wọ́n gbe e gba ọ̀nà tó tọ́."""
Ẹ̀wẹ̀, nínú ìdájọ́ náà, adájọ́ ní ilé ṣègbè fún bí ó ṣe fàáyè gba Aṣòfin Dino Melaye, tó pe ẹjọ́ tako Omo-Agege láti ma kópa níbi ìjókòó ilé.
Dimgba ti wá pa á láṣẹ pé, kí wọ́n gba Omo-Agege padà sílé lọ́gán, kí wọ́n sì san gbogbo àjẹmọ́nú, tó fi mọ́ owó oṣù tó tọ́ si lásìkò tó fi lọ rọ́ọ̀kún nílé.
Oríṣun àwòrán, @NigeriaSenate
Adájọ́ ní kí wọ́n sì san gbogbo àjẹmọ́nú, tó fi mọ́ owó oṣù tó tọ́ si lásìkò tó fi lọ rọ́ọ̀kún nílé.
Lọ́jọ́ kẹtàlá, oṣù Kẹrin ni ilé aṣòfin ní kó lọ rọ́ọ̀kún nílé fún àádọ́rùn ún ọjọ́ nítorí ọ̀rọ̀ tó sọ lórí àtúnṣe sí òfin ètò ìdìbò ọdún 2010, èyí tí wọ́n fi n pè fún àtuntò ìbò gbogbo-gbòò, pé Ààrẹ Muhammadu Buhari ni ìgbésẹ̀ nàá dojú kọ.
Ọjọ́ kejìdínlógún, oṣù Kẹrin nínú àtẹ̀jáde kan lórí ìsẹ̀lẹ̀ jíjí ọ̀pá àṣẹ ilé gbé, ni ilé asòfin àgbà fi ẹ̀sùn kan Ovie Omo-Agege pé òun ló kó àwọn jàndùkú sòdí láti gbé ọ̀pá àṣẹ nàá.
Tẹlifísàn Sudan: Ó dàbí pé wọn fi ọ̀bẹ gún asojú Nàíjíríà pa ni
Wọn ní o ṣeeṣe kó jẹ́ pé wọ́n ṣeku pa á ni
Wọ́n ti rí òkú aṣojú orílẹ̀èdè Nàìjíríà kan ní Sudan. Ìwádìí sì ti bẹ̀rẹ̀ lọ́gán ki ọ̀rọ̀ nàá tó lu síta.
Nínú ilé kan tó wà ní Khartoun, tíi ṣe olú ìlú fún Sudan, ni wọ́n ti rí òkú nàá. Kò tí i sí ẹnikẹ́ni tó mọ́ òhun tó ṣekú pa a.
Àmọ́, iléeṣẹ́ amóhùn-máwòrán Al-Arabiya, ti ṣàpéjúwe ikú tó paa gẹ́gẹ́ bí ''ìṣekúpani'', táwọn kan sì n sọ pé, wọ́n fi ọ̀bẹ gun un pa ni.
Shiite: Tinúbú, bá Buhari sọ̀rọ̀ kó tú ZakZaky sílẹ̀ kó tó pẹ́ jù
Aó maa fún yín ní ẹ̀kúnrẹ́rẹ́ ìròyìn nàá, bí ó bá ṣe n tẹ̀wá lọ́wọ́.
Oyinlọlá: A di ẹgbẹ́ òsèlú láti já ìjọba gbà lọ́wọ́ APC
Ọ̀nà láti jẹ́ kí àlá nípa ìdásílẹ̀ orílẹ̀èdè Nàíjíríà tuntun jọ, ló mú ká dara pọ̀ mọ́ ẹgbẹ́ òsèlú ADC.
Asaájú ẹgbẹ́ alájùmọ̀se tí Olóyè Olúsẹ́gun Ọbásanjọ́ dá silẹ̀, Ọmọọba Ọlọ́gúnsóyè Oyinlọlá kéde pé, ẹgbẹ́ náà ti dara pọ̀ mọ́ ẹgbẹ́ òsèlú African Democratic Congress ( ADC).
Oyinlọlá, níbi ìpàdé àwọn akọ̀ròyìn tó se ní àárọ̀ ọjọ́bọ, o ní, òun ti kọ́wé fi ẹgbẹ́ òsèlú APC sílẹ̀, láti bọ́ sí ADC, lọ́nà àti pa ègún àìní asaájú rere jẹ́ nílẹ̀ Nàíjíríà ni.
Ẹgbẹ́ alájùmọ̀se gbé ìgbésẹ̀ náà láti se ara àwọn ní òsùsù ọwọ̀, fi já ìjọba gbà lọ́wọ́ ẹgbẹ́ òsèlú APC, nínú ìbò ọdún 2017.
Ó fi kun pé àwọn gbé ìgbésẹ̀ náà láti se ara àwọn ní òsùsù ọwọ̀, fi já ìjọba gbà lọ́wọ́ ẹgbẹ́ òsèlú APC, nínú ìbò ọdún 2017.
Láti ìgbà tí a ti dá ẹgbẹ́ alájùmọ̀se sílẹ̀, làwọn ẹlẹ́gbẹ́-jẹgbẹ́ òsèlú ti ń kàn sí wa pé ka jọ fọwọ́-sowọ́pọ̀ di ọ̀kan. Àmọ́ lẹ́yìn ìjíròrò tó kún, làwọn adarí ẹgbẹ́ alájùmọ̀se wá pinnu láti dara pọ̀ mọ́ ẹgbẹ́ òsèlú ADC.
Nínú ọ̀rọ̀ rẹ̀ níbi ìpàdé akọ̀ròyìn náà, Olóyè Olúsẹ́gun Ọbásanjọ́ ní ọ̀nà láti jẹ́ kí àlá nípa ìdásílẹ̀ orílẹ̀èdè Nàíjíríà tuntun jọ, ló mú kí ẹgbẹ́ alájùmọ̀se náà dara pọ̀ mọ́ ẹgbẹ́ òsèlú ADC.
OSIEC: A kò fi epo b‘ọyọ̀ lórí ìbò káńsù l'Ọ́yọ́
Oríṣun àwòrán, Oyo state government
Eto idibo si ijọba ibilẹ yoo waye ni ipinlẹ Ọyọ ni ọjọ Satide
Eto idibo si ijọba ibilẹ yoo waye ni ipinlẹ Ọyọ ni ọjọ Satide, ọjọ́ kejìlá, osù karùn-ún, sugbọn oniruuru ede aiyede lo ti n waye lori rẹ.
Amọ ṣa, ajọ eleto idibo ipinlẹ Ọyọ ti sọ wi pe ko si ohun ti yoo yẹ idibo naa.
"Ẹni to jẹ alaga fun ajọ eleto idibo ipinlẹ Ọyọ, Ọgbẹni Jide Ajeigbe ṣalaye fun BBC Yoruba pe, ""Gbogbo eto lo ti to ati pe ilana ati igbesẹ gbogbo to yẹ ni gbigbe la ti gbe, lati rii pe awọn igun gbogbo ti ọrọ idibo naa kan fi ẹdọ lori oronro lori ato idibo naa."
Oríṣun àwòrán, oyo state government
Eyi ni igba akọkọ ti eto idibo si ijọba ibilẹ yoo maa waye ni ipinlẹ Ọyọ laarin ọdun mẹjọ
Ọgbẹni Ajeigbe ni, ẹru iwa idibajẹ atẹyinwa lo n ba awọn eeyan to n fapa janu lori eto idibo naa.
O ni ko si idi fun awọn oloṣelu tabi oludibo lati ko aya soke lori iddibo naa nitoripe didun lọsan yoo so lori rẹ.
Ibẹru iwa idibajẹ atẹyinwa lo faa ti awọn kan fi n kun. Bi ẹ ba woo, o ti to ọdun mẹjọ ti a ti dibo gbẹyin ni ipinlẹ Ọyọ; boya ẹru bi wọn ṣe maa n ṣe tẹlẹ lo n ba awọn eeyan naa. Ko si ẹni to lee tọka aleebu kan si eto idibo ti a fẹ ṣe yii o.
Amọ o, bi eto idibo naa ṣe fẹ waye, adiyẹ ti ba lokun laarin ẹgbẹ oṣelu APC to n ṣejọba nipinlẹ Ọ̀yọ́, pẹlu bi awọn igun kan lagbo oṣelu naa se gba ile ẹjọ lọ lati ka ẹgbẹ oṣelu naa lọwọ ko ninu titẹsiwaju pẹlu lílo orukọ awọn to fi ṣọwọ gẹgẹ bii oludije labẹ aṣia ẹgbẹ oṣelu naa.
Ọmọwe Wasiu Ọlatunbọsun, to jẹ Ọkan lara awọn igun to n fẹhonu han ni, bi awọn agba ẹgbẹ kan pẹlu gomina Abiola Ajimọbi ṣe parapọ maa fi tipa gbe awọn oludije kan le awọn ọmọ ẹgbẹ lori, lo faa ti awọn fi n pariwo sita.
Wọn ko tẹle ofin ẹgbẹ. Ohun ti ofin ẹgbẹ sọ ni pe, ẹni ti yoo dije fun ipo labẹ aṣia ẹgbẹ oṣelu gbọdọ jẹ awọn ti ọmọ ẹgbẹ mu funra wọn. Awọn ti ẹgbẹ fa kalẹ fun idibo yii, gomina atawọn eeyan kan ni wọn joko sile igbafẹ lati mu wọn.
O ni, awọn ti gba ileẹjọ lọ lori ọrọ naa ti ileẹjọ si ti kọkọ da wọn lọwọ kọ, ki o to tun di pe wọn ni ki wọn tẹ siwaju ṣugbọn igbẹjọ yoo maa lọ. Bi ile ẹjọ ba wa rii pe ilana to dari si idibo naa ko ba ofin mu, gbogbo rẹ ni wọn yoo da nu tiketike.
Alaga ajọ eleto idibo ipinlẹ Ọyọ wa fi da awọn eeyan ipinlẹ naa loju pe didun lọsan yoo so lori eto naa.
Oríṣun àwòrán, Oyo state government
Awọn kan n fapa janu lori idibo naa
Bakanaa lo ni, ki eto naa lee so eso rere, ajọ ọhun ke si ajọ kan to n ri si ẹkọ nipa aṣeyori ibo lagbaye, International foundation for electoral System, IFES, fun idanilẹkọ ati igbani niyanju lori idibo naa.
Awa o fi si igun kankan gẹgẹ bii ahesọ ọrọ ti awọn eeyan kan n sọ kaakiri. Gbogbo ilana ti a n ṣe la n ṣe ni gbangba.
Eyi ni igba akọkọ ti eto idibo si ijọba ibilẹ yoo maa waye ni ipinlẹ Ọyọ laarin ọdun mẹjọ.
Adéyẹyè: Òkùnkùn ni Fáyóṣé, ìmọ́lẹ̀ ni èmi
Oríṣun àwòrán, @Adedayo_Adeyeye
Adéyẹyè ni irọ lasan ni ohun ti awọn kan n sọ kiiri pe oun ti ṣe adehun pẹlu ẹgbẹ oṣelu APC
Adedayo Adeyeye, to ba igbakeji Fayose du asia oludije gomina lẹgbẹ oselu PDP l'Ékiti, ti fi ẹgbẹ oṣelu naa silẹ.
Adeyẹye kede igbesẹ lati fi ẹgbẹ oṣelu PDP silẹ, lẹyin to kuna ibo lati bori ibo abẹnu f'awọn oludije fun ipo gomina ninu ẹgbẹ naa.
Ọjọgbọn. Ẹlẹka ni ẹgbẹ PDP fa sita gẹgẹ bii oludije nibi eto idibo si ipo gomina ipinlẹ Ekiti, ti yoo waye ni ọjọ kẹrinla oṣu keje ọdun yii.
Bi o tilẹ jẹ pe, ko tii sọ ni pato ẹgbẹ oṣelu ti o n kọri si, amọ, Ọmọọba Adeyeye fi ẹsun kan Ayọdele Fayoṣe, to jẹ gomina ipinlẹ Ekiti lọwọ-lọwọ yii pe, ijọba fami-lete n tutọ lo n ṣe nipinlẹ naa ati laarin ẹgbẹ oṣelu PDP nibẹ.
Ninu ọrọ to ba awọn akọroyin sọ nilu Ado Ekiti lọjọbọ, o ni, adehun wa laarin oun ati gomina fayose lori ọrọ oludije fun ẹgbẹ oṣelu naa, eleyi to ni gomina Fayoṣe ti tako bayii.
"Ko si ibarẹpọ to lee waye laarin okunkun ati imọlẹ,. Fayose duro fun okunkun ni eto oṣelu ipinlẹ Ekiti, eleyi ti ko see maa fẹnu sọ fawọn eeyan ipinlẹ yii.
Ko si bi mo ṣe lee maa tesiwaju pẹlu eeyan ti ko lee mu ileri ati adehun rẹ ṣẹ."
Oríṣun àwòrán, facebook/Lere olayinka
Adéyẹyè kò tíì sọ ẹgbẹ́ òṣèlú tí yóò darapọ̀ mọ́ láti díje fún ipò gómìnà ìpínlẹ̀ Èkìtì
Amọ sa, Adeyẹye ni ohun ko lọ si ẹgbẹ oṣelu APC bi awọn kan ṣe sọ.
O ni irọ lasan ni ohun ti awọn kan n sọ kiiri pe, ohun ti ṣe adehun pẹlu ẹgbẹ oṣelu APC lati di igbakeji oludije fun ipo gomina nibẹ.
 Kii ṣe ti igberaga, mo ti kọja ẹni ti yoo maa le igbakeji gomina kiri. Nitori awọn eto ti mo ni lati ṣe fun irapada ipinlẹ Ekiti ni.
Amọ sa, o ni ọyẹ yoo la lori ẹgbẹ oṣelu ti oun yoo darapọ mọ lati dije fun ipo gomina ipinlẹ naa laarin wakati diẹ laipẹ.
Íyanṣẹ́lòdì Johesu: ǹkan ń bàjẹ́ síi ni fún àwọn ará ìlú
Àwọn aláìsàn n dúró dé àwọn òṣìṣẹ́ ìlera lati wa tọjú wọn
Ọrọ iyanṣelodi láwọn ilé ìwòsan káàkiri orílè-èdè Nàìjíríà ti mu ki ìnira túbọ̀ peléke síi fún àwọn ará ìlú-ati awọn Dókítà.
Láwọn ilé ìwòsàn ti ìkọ BBC ṣe àbẹwò sí, awọn akẹkọọ dókítà ni wọn n gbé ìgbá, gbé àwo láti ríi pé àwọn aláìsàn ri itọju.
"Dokita kan to bá BBC sọrọ ní ""iṣẹ yìí tojú súmi. Ẹ wo bi awọn aláìsàn ṣe kun le lọrùn èmí nikan"""
Awọn akẹ́kọ̀ọ́ dókítà la ri tí wọn n tọjú àwọn aláìsàn ni LASUTH
Nile ìwòsan ikọni ti fafiti ìpínlè Eko, LASU, ni Ikeja, àwọn akẹ́kọ̀ọ́ dókítà la ri tí wọn n tọjú àwọn aláìsàn.
Won ní iṣẹ wàhálà ni ṣugbọn ''o di dandan láti ṣe.''
"Ọkan nínú wọn ni ""a  ko gba aláìsàn tuntun mọ. Àwọn tó tí wà nílé tẹlé nikan ní a ń tọjú"""
Awọn akẹ́kọ̀ọ́ dókítà LASUTH
Bákan náà ni ọrọ ṣe rí ní ilé ìwòsan ìjọba tí o wà ní Ifako Ijaiye.
N'isẹ ní àwọn aláìsàn àti awọn dókítà n ke ìnira lori bi ko ṣe sí àwọn òṣìṣẹ́ ìlera nílẹ̀.
Àwọn òṣìṣẹ́ ìlera ní ilé ìwòsan ìjọba ìpínlè àti ìjọba ìbílẹ jakejado Naijirià darapọ̀ mọ́ iyanṣẹlodi labẹ àsìá ẹgbẹ oṣiṣẹ Johesu lojooru.
Ninu atejade ti awọn olórí ẹgbẹ náà fi sita, wọn ni igbésẹ náà wáyé láti mú kí ìjọba gbarata lórí iyanṣelodi ti àwọn ti kọ́kọ́ bẹ̀rẹ̀ láti nnkan bíi ọsẹ mẹta sẹyìn
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí:
Èrò ṣe ọ̀tọ̀ọ̀tọ̀ bi Ilé ṣe takò ìdájọ lori Omo-Agege
Oríṣun àwòrán, Facebook/Nigerian Senate
Iléẹjọ́ ni Ọjọ́ mérìnlá ló yẹ kí Omo-Agege fi jókòó sílé
Ilé aṣòfin àgbà Nàìjíríà tí lọ ilé ẹjọ kòtẹmílọrùn láti yí ìdájọ Ilé ẹjọ́ gíga ìjọba àpapọ̀ tó dá aṣòfin Omo-Agege padà sílé.
Kété ti adájọ Nnamdi Dimgba tí ilé ẹjọ gíga apapọ ni Abuja wọgi le àṣẹ lọ gbélé rẹ ti ilé aṣòfin pa fún Omo-Agege ni Ilé ti kọ iwe ẹjọ láti takò ìdájọ náà.
Bákan náà ní won fi ìkéde ìgbésè yi sójú òpó Twitter ilé aṣòfin agba.
Àríwísí ọtọọtọ ni  ìkéde yìí ti mú wà lójú òpó ayelujara pàápàá jùlọ ní Facebook ati Twitter
Oríṣun àwòrán, FACEBOOK/SAMUEL OLAKANLA
Samuel Olakanla gba pe, bi kò ba ni ǹkan miran ninu, kò yẹ ki ilẹ ló sile ẹjọ kotẹmilọrun lori ọrọ naa.
Adesomo Ifedayo ni tirẹ gba Omo-Agege nimọran lati gbọ́ àṣẹ ile-ẹjọ pe
Oríṣun àwòrán, facebook/Adesomoju Ifedayo
Àwọn kàn kúkú bu ẹnu àtẹ lù Omo Agege pé kii ṣe aṣojú dáadáa.
Oríṣun àwòrán, facebook/Prince Joseph Edemenya
Kódà, ọrọ yà lọ bá ìṣúná ọdún 2018, Dino Melaye àti ọgá ọlọ́pàá tí kọ̀ láti yọjú sí ilé aṣòfin.
Oríṣun àwòrán, facebook/olusola ogundeko
Ojú wo ni APC fẹ yàn fi kojú PDP l'Ekiti
Oríṣun àwòrán, Facebook/Ekiti APC
Wọn kéde pé ìyípadà dé bá ibi ti ìdìbò náà yóò ti wáyé ni Ado Ekiti
Wákàtí diẹ loku ti ìdìbò abẹ́nú ẹgbẹ́ òṣèlú APC n'ipinle Èkìtì yóò fi wáyé.
Ọpọ èèyàn sí ti n woye ẹni tí yóò jáwé olúborí .
Olùdíje mẹ̀talèlọgbọ̀n ní o kọ́kọ́ kópa nínú ìdìbò náà lọ́sẹ̀ to kọja ṣùgbọ́n Babafemi Ojudu tó jẹ́ olùrànlọwọ fún Ààrẹ Buhari lórí ọrọ òṣèlú ni òun ko ní kópa mọ.
O ni òun fẹ dúró gẹ́gẹ́ bíi ''apẹ̀tù sááwọ̀ ni ipinlẹ̀ Ekiti.''
Àwọn wo ló kù bayi
Mínísítà fún alumọọni lorílè-èdè Nàìjíríà lọwọlọwọ, Kayode Fayemi wa nínú wọn.
O ti ṣe Gómìnà rí nipinle Ekiti ki Ayo Fayose to wa lórí aleefa bayii to gbà yọ kúrò.
Oríṣun àwòrán, @kfayemi
Kayode Fayemi yoo dupò pelu awon eniyan mẹẹdọgbọn si ipo
Ṣugbọn oun nìkan kọ ló ti ṣe gómìnà ríi tó  tún n du ipò naa.
Segun Oni  tó ṣe gómìnà láàrin ọdún 2007 sí 2010 náà n gbìyànjú ati ṣe lẹkan síí.
Ìdíje náà kò yọ àwọn míràn silè tọ fi mọ Senato Gbenga Àlùkò, Ogbeni Debo Àjàyí, Ọgbẹni Kayode Ọjọ ati Christanah Mojisola Kayode.
Oríṣun àwòrán, Facebook/Taal Cirlce
Ìpeníjà aabo to peye wa lara awọn nkan ti ẹgbẹ naa gbọdọ mojuto
Pẹlú bi dàrú-dapọ ti ṣe wáyé níbi ìbò abẹnu ti wọn kọkọ ṣe l'ose to kọjá, òpó tí n béèrè pé ṣé kò ní sí wàhálà leekeji.
Gómìnà Tanko Al Makura ti ìpínlè Nassarawa tí de si Èkìtì pẹlú àwọn ọmọ ìgbìmò eleto ìdìbò ẹgbẹ APC.
Lára àwọn àtúnṣe tí wọn kéde fún ìbò abẹ́nú ipinle Ekiti ni:
Bákan náà la gbó pé ìgbìmò náà yóò ṣe ọpọlọpọ ìpàdé pẹlu àwọn ọmọ ẹgbẹ ati awọn olùdíje láti ríi pé òun gbogbo lọ bi o ti yẹ.
Ọmọ Yahoo Plus: Wọn ní kí ń pa ìyá mi, kí ń lè lówó si ni
Oríṣun àwòrán, Lagos state police command
Ileesẹ ọlọpaa ni Ipinlẹ Eko ti mu ọmọkunrin ẹni ọdun mọkandinlọgbọn kan ti orukọ rẹ njẹ Taiwo Akinola, ti o gbiyanju lati fi igi fọ ori iya rẹ ni adugbo Raji Ajanaku, ni Ayọbọ.
Ọjọ Aiku ni iṣẹlẹ naa ṣẹlẹ ninu ile ti Akinola n gbe pẹlu iya rẹ naa, Alice Akinola, ati ọmọdekunrin miiran kan.
Nigba ti awọn ọlọpaa mu Akinola, o jẹwọ wipe ọmọ ẹgbẹ okunkun Aiye ni oun.
Sunday Adelaja: Tẹ́tẹ́ làwọn pásítọ̀ tó ń gba owó ‘ìserere’ ń ta
Agbẹnusọ ọlọpaa ni Ipinlẹ Eko, Chike Oti ni, Akinola lọ sinu ṣọọbu ti iya rẹ naa ti n ta ọja niwaju ile wọn. O pee pe oun ni ọrọ pataki ti awọn dijọ fẹ jiroro ninu ile, asiko yii naa lo si ran ọmọ ẹgbọn rẹ kekere, Farouk, ti wọn jọ n gbe inu ile nisẹ, lati lọ ra asọ pelebe inuju (handkerchief) funfun, wa fun oun.
Bi iya Taiwo se wọle wa, lati da ọmọ rẹ lohun, ni Taiwo yii fi igi nla, ẹrọ ilọsọ (iron) ati ẹrọ to n tan ina si idi Kọmputa, (UPS) gbaa lori lọna ati ri daju pe iya rẹ ko ye isẹlẹ naa.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Amọ nigba ti Farouk to ran nisẹ de, lo ri iya wọn ninu agbara ẹjẹ, to si fi igbe ta pe kawọn ara adugbo wa gba iya oun. Awọn aladugbo to de sibẹ lo ransẹ pe awọn ọlọpaa to gbe iya Taiwo lọ sile iwosan, amọ ko tii yaju titi di akoko yii.
Nigba to n salaye fawọn ọlọpaa lori ohun to ri lọbẹ, to fi waru sọwọ, Taiwo ni wọn ni ki oun lọ pa iya oun ki oun lee ni owo sii ni.
Lasiko tawọn ọlọpaa sayẹwo ile rẹ, wọn ba igba meji, ti ọkan ni ori oku ninu, nigba ti igba keji kun fun agbo dudu.
Oríṣun àwòrán, @PoliceNGLagos
Bakan naa ni wọn ri igi kan ti wọn fi iso gun kaakiri eyi ti ẹjẹ wa lara rẹ, ẹrọ ilọsọ to ni ẹjẹ lara, asọ inuju funfun kan to fẹ fi nu ẹjẹ iya rẹ ati igo to kun fun ororo ti wọn kọ ‘back to sender’ si lara.
Ileesẹ ọlọpaa ti wa kesi awọn olugbe ipinlẹ Eko lati dide tako iwakiwa to nii se pẹlu iwa ọdaran nitori iwa gbigba kamu si ohun to lewu kọ ni ọna abayọ sawọn iwa ọdaran bii iru eyi.
Oríṣun àwòrán, Twitter/EFCC
Ọrọ dii bo o lọ, oya a mi ni ile igbafẹ Club 57, ni Ikoyi, Lagos
Ninu iroyin miran ẹwẹ, ajọ to n gbogun ti iwa ibajẹ lorilẹede Naijiria, EFCC, sọ wi pe, oun ti fi panpẹ ọba mu awọn afurasi ọmọ yahoo yahoo mejila, ni ile igbafẹ Club 57 ni Ikoyi ni ipinlẹ Eko.
Ajọ EFCC ni, wọn gbe igbesẹ naa lowurọ kutu ọjọ Ẹtì, ọjọ́ kọkanla, Osu Karun, ọdun 2018, lẹyin ti awọn eeyan kan gbe si wọn leti pe, awọn afunrasi onijibiti naa n sọsẹ ni agbeegbe naa.
Ajọ naa, tó sisọ loju ọrọ naa loju opo Twitter rẹ fi kun pe, ọrọ dii bo o lọ, oya a mi, sugbọn awọn ri ọkọ ayọkẹlẹ mẹwa gba silẹ, ti awọn si fi panpẹ ọba mu awọn mejila miran ni bi ile igbafẹ naa.
Bakan naa lo ni awọn ọmọ 419 yii kan sa mọ awọn lọwọ, ti wọn si fi ọkọ ayọkẹlẹ, olowo iyebiye wọn silẹ, fẹsẹ fẹẹ.
CAN: Ìbànújẹ́ ńlá ni iku ọ̀mọ̀wé Musa Asake jẹ
Oríṣun àwòrán, Dailypost
Owurọ ọjọ ẹti ni akọwe ẹgbẹ CAN naa jade laye nilu Abuja lẹyin aisan ranpẹ
Akọwe ẹgbẹ ọmọlẹyin kristi ni orilẹede Naijiria, CAN, Ọmọwe Musa Asake, ni iroyin sọ wi pe o ti jade laye bayii.
Atẹjade kan, ti ẹgbẹ naa fi ṣọwọ si BBC Yoruba, tun fi kun pe oloogbe naa silẹ bora lẹyin aisan ranpẹ.
Iku oloogbe naa n waye ni nkan bii ọsẹ meji to lewaju iwọde jakejado orilẹede Naijiria, eyiti wọn fẹ fi dide tako bi awọn darandaran Fulani ṣe n pa awọn eeyan kaakiri.
Ni ọdun 1976, ni iranṣẹ Ọlọrun Musa Asake bẹrẹ iṣẹ iranṣẹ rẹ ni ijọ ECWA to wa ni ilu rẹ ni Unguwar Rimi, Bajju nijọba ibilẹ Zangon Kataf, nipinlẹ Kaduna.
Aborisade: Mẹ̀kúnù gbọ́dọ̀ funra sí Obasanjo
Iranṣẹ Ọlọrun naa kun ara awọn ohun to n fọn tan-tan-tan lori wahala ọrọ aabo lorilẹede Naijiria, paapaa julọ, ni idi didaabo bo awọn ọmọlẹyin Kristi.
Nibayii, Aarẹ Muhammadu Buhari ti ranṣẹ ibanikẹdun si awọn ọmọlẹyin Kristi lori iku iranṣẹ Ọlọrun naa.
Ninu atẹjade kan ti agbẹnusọ fun aarẹ, Fẹmi Adeṣina fi sita, Aarẹ Buhari gba a ladura pe, ki Ọlọrun tu awọn ẹbi rẹ ninu.
Ajimọbi: Ààbò wà nílẹ̀ láti kojú mọ̀dàrú lásìkò ìbò
Oríṣun àwòrán, oyo state government
Ijọba ipinlẹ Ọyọ ti ranṣẹ ikilọ sawọn eeyan tabi ẹlẹgbẹjẹgbẹ to lee fẹ da wahala silẹ lasiko idibo sijọba ibilẹ ti yoo waye nipinlẹ naa lọjọ abamẹta.
O ni Awọn agbofinro ti wa nikalẹ lati fi irufẹ awọn eeyan bẹẹ jofin.
Atẹjade kan ti oluranwọ fun gomina ipinlẹ Ọyọ lori ọrọ oṣelu, Ọmọwe Morounkọla Thomas fi sita ṣalaye pe, ikilọ yii ṣe pataki pẹlu iroyin ti o n jade pe, awọn ẹgbẹ onikọlọransi kan laarin ẹgbẹ oṣelu APC, n gbero lati da họwuhọwu silẹ lọjọ abamẹta.
Oríṣun àwòrán, oyo state government
Ijọ̀ba ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́ ní ètò ti tò lórí ìpèsè ààbò lásìkò ìbò náà
Ijọba ipinlẹ ipinlẹ Ọyọ ni, gbogbo eto to yẹ fun idaabo bo ẹmi ati dukia ṣaaju, lasiko ati lẹyin idibo naa, ni wọn ti gbe kalẹ.
Gẹgẹ bii atẹjade naa ṣe sọ, iroyin kan ti tẹ ijọba lọwọ pe, awọn ọmọ ẹgbẹ kan ti wọn n pe ni Unity Forum, ti n gbero lati lo awọn janduku fi kọlu awọn oludibo lasiko idibo naa.
BBC Yoruba gbiyanju lati gbọ tẹnu ẹgbẹ Unity Forum lori ẹsun naa, ṣugbọn olotu ẹgbẹ naa, Ọmọwe Wasiu Ọlatunbọsun ko gbe ẹrọ ibanisọrọ rẹ, nigba ti a pee, ki a to ko iroyin yii jọ.
Buhari padà sí Naijiria lẹ́yìn tó lọ tọ́jú ara rẹ̀
Oríṣun àwòrán, @BashirAhmaad
Ni ọjọ iṣẹgun ni Aarẹ Buhari fi orilẹede Naijiria silẹ
Aarẹ Muhammadu ti pada si ilu Abuja, lẹyin to lọ si ilu ọba lati gba itọju lọdọ dokita rẹ.
Ni nkan bii agogo meje ku diẹ lalẹ ọjọ ẹti, ni baalu to gbe aarẹ gunlẹ si papakọ ofurufu Nnamdi Azikwe nilu Abuja.
Ni ọjọ iṣẹgun ni Aarẹ Buhari fi orilẹede Naijiria silẹ lọ si ilu Lọndọn, lẹnu irinajo ati tọju ara rẹ.
Etò ààbò ìdìbò abẹ́lé APC Ekiti kúrò ní kèrémí lòní
Oríṣun àwòrán, @apcnigeria
Lálá yóò lù loni, APC Ekiti yóò yan olùdíje gómìnà wọn
Gomina Al Makura, tó ń ṣètò ìdìbò Ekiti ni kélé a gbé ẹni tó bá fẹ́ da ìdìbò tòní rú
Àwọn ọmọ ìgbìmọ̀ tó ń ṣeto idibo abẹle fun ẹgbẹ oṣelu APC ni ipinlẹ̀ Ekiti ti fi àwọn ènìyàn lókàn balẹ pé yoo yọri si rere loni.
Gomina ipinlẹ Nassarawa to jẹ alaga igbimọ, Gomina Al Makura, naa ni ki gbogbo àwọn oludibo wa pẹlu àmì ìdánimọ̀ tó ba òfin mu ki wọn tó le wọle.
Igbimọ naa ni wọn ti fi òfin de àwọn to da idibo rú lọsẹ to kọja àti pe ìjìyà to tọ́ ń duro de àwọn ti adé òfin ba ṣimọ lori ninu wọn.
Aborisade: Mẹ̀kúnù gbọ́dọ̀ funra sí Obasanjo
Wón ni ẹnikẹni kò gbọdò wọ aṣọ to ń polongo oludije kankan loni.
Awọn kan gba pe ti idibo abẹle yii kò bá ti waye, o di dandan ki ẹgbẹ fa oludije kan kalẹ̀ ni eyi ti àwọn kò fẹ́.
Bayii, ọpọlọpọ àwọn agbofinro lo ti wa ni Ekiti lati rii pé ohun gbogbo lọ ni irọworọsẹ.
Tinubu: kò sí àṣàdànù nínú gbogbo olùdíje APC Ekiti
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Gbogbo olùdíje APC Ekiti ló tó gbangba sùn lọ́yẹ́
Bola Tinubu ni òun kò ni ààyò kankan nínú àwọn olùdíje APC Ekiti
Èèkàn nínú ẹgbẹ́ òṣèlú All Progressives Congress (APC), Bola Ahmed Tinubu, ti ni kò si ẹni ti kò tó o ṣe gomina nínu gbogbo àwọn olùdíje APC Ekiti loni.
O ni àtilẹyin kan naa ni òun ń ṣe fún gbogbo wọn papọ.
Ati pé oun ko ni ayanfẹ ọ̀tọ̀ ninu gbogbo wọn.
Awọn agbófinró kún ibùdó ìdìbò APC Ekiti fọ́fọ́
Oríṣun àwòrán, olasunkanmi Ogunmoko
Àwọn agbófinró pọ̀ ni Ado Ekiti láti rii pé ìdìbò toni kógojá
Àyẹ̀wò orúkọ ń lọ lọ́wọ́ ni Damlek Event Centre ni Ado Ekiti to jẹ olú ìlú ipinlẹ Ekiti
Àwọn oludibo ti n dé si Damlek Event Centre, to wa ni òpópónà Afao, nibi ti wọn yoo ti dibo yan ẹni tó wù wọn gẹ́gẹ́ bii oludije fun ipò gomina ipinlẹ Ekiti labẹ asia ẹgbẹ́ òṣèlú All Progressives Party (APC).
Oríṣun àwòrán, Olasunkanmi Ogunmuko
Awon oludibo n tò fún àyẹ̀wò
Gomina ipinle Nassarawa, Al Makura, ni alaga igbimọ to ń ṣeto ìdìbò náà, eyi to daru lọsẹ to kọja.
Oríṣun àwòrán, Olasunkanmi Ogunmuko
Gbongan Damlek Event Center ni Ado Ekiti ti idibo APC ti n waye
Ati oludije ati oludibo ni àwọn agbofinro n farabalẹ yẹ ara wọn ati apamọwọ wọn wò ki wọn to wọle.
Oríṣun àwòrán, Olasunkanmi Ogunmuko
Awọn olukopa ti gbaradi fún idibo
Ọpọ̀ àwọn olùdije ti wa ni ibùdó ìdìbò bayii
Akọ́nimọ̀ọ́gbá ikọ̀ DC United fẹ́ ra Rooney lọ sí MLS
Oríṣun àwòrán, Getty Images
ọ̀pọ̀ ikọ̀ agbábọ́ọ̀lù MLS ní orílẹ̀-èdè Amẹ́ríkà l'óbá aṣojú Rooney, Paul Stretford, sọ̀rọ̀ bíi ọdún kan sẹ́yìn
Akọọnimọgba ikọ DC United ń ṣẹ́jú sí Wayne Rooney, tó jẹ́ ọ̀kan lára agba-ọjẹ agbabọọlu àgbáyé
Ṣugbọn DC United fidi rẹ mulẹ pe ikọ naa ko tii ra Rooney lati ẹgbẹ agbabọọlu ilẹ Gẹẹsi, Everton ti ó ń ṣoju lọwọ.
Iroyin kan laarin ọṣẹ yii ni ifẹnuko ti wa lori bi Rooney yoo ṣe di ọmọ ẹgbẹ agbọọlu DC United fun owo tó tó £12m.
Ọpọ ikọ agbabọọlu MLS ni orilẹ-ede Amẹrika loba aṣoju Rooney, Paul Stretford, sọrọ bii ọdun kan séyin, ki o to lọ darapọ mọ Everton lati Manchester United.
Rooney to jẹ ọmọ ọdun mejilelọgbọn ni agbabọọlu to gba bọọlu s'awọn julọ fun ilẹ Gẹẹsi.
Ọ̀yọ́: PDP àti Accord kò ní kó pa nínú ìdìbò káńsù
Àwọn òṣìṣẹ́ elétò ìdìbò kò tí ì dé sáwọn ibùdó ìdìbò kọọkan
Gbogbo ètò ti tò fún ìdìbò alága ìjọba ìbílẹ̀, tó fi mọ́ t'àwọn kánsélọ̀ wọ́ọ̀dù, jákèjádò ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́.
Àwọn èròjà ìdìbò ti gúnlẹ̀ s'áwọn ibùdó ìdìbò kan, ṣùgbọ́n táwọn kan ṣì n retí àwọn òṣìṣẹ̀ àjọ elétò ìdìbò.
Aborisade: Mẹ̀kúnù gbọ́dọ̀ funra sí Obasanjo
Ìrètì wà pé ìdìbò yóò wáyé láàrin agogo mẹ́jọ àárọ̀ sí mẹ́ta ọ̀sán. Bákan nàá ni kò ní sí lílọ-bíbọ̀ fún àwọn ọkọ̀ tí kò gbàṣẹ.
Ẹ̀wẹ̀, akọ̀ròyìn BBC Yorùba, Adedayọ Okedare, jábọ̀ pé àwọn kan n fẹsẹ̀ palẹ̀ ní ibùdò ìdìbò kan, tí wọ́n sì n sọ pé àwọn kò ní dìbò táwọn kò bá rí ẹnì kankan fún àwọn lówó.
Ìforúkọ sílẹ̀ ti n lọ lọ́wọ́ fún ètò ìdìbo kánsù ní ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́
Ẹgbẹ́ òṣèlú méjìlá ni yóò kópa nínú ìdìbò nàá tó n wáyé ní ìjọba ìbílẹ̀ mẹ́tàlélọ́gbọ̀n, tó fi mọ́ àwọn ìjọba ìbílẹ̀ ẹlẹ́kùn kéèkè márùndínlógójì.
Ìdìbò yóò wáyé ní ẹgbẹ̀rún máàrùn ún àti ọ̀tàlérúgba (5260) wọ́ọ̀dù
Lára àwọn ẹgbẹ́ tí yòó kó pa ni ANRP, NRM, YPP, PDC, Kowa, UDP, PPA, TÓ FI MỌ́ APC tó n tukọ̀ ìṣàkóso lọ́wọ́.
"Alága àjọ tó n ṣe ètò ìdìbò ní ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́, OSIEC, ọ̀gbẹ́ni John Ajeigbe sọ fún àwọn oníròyìn pé ""ẹgbẹ́ òṣèlú Peoples Democratic Party, PDP àti Accord kò ní kó pa."""
NAFDAC gbẹ́sẹ̀ kúrò lórí òfin tó fi de àwọn iléeṣẹ́ apòògùn
Àṣìlò òògùn ikọ́ olómi tó ní èròjà codeine nínú máa ń fa ki kíndìrín bàjẹ́, gìri, ọpọlọ dídàrú àti orí yíyí.
Àjọ tó n mójútó ìpèsè oúnjẹ àti òògùn lílò ní Nàìjíríà, NAFDAC, ti gbẹ́sẹ̀ kúrò lórí òfin tó fi de àwọn ilé iṣẹ́ apòògùn kan látàrí ìwádìí BBC lórí codeine.
Ṣáàjú ni àjọ nàá tí gbé ilẹ̀kùn àwọn iléeṣẹ́ nàá, Peace Standard, Emzor àti Bioraj, táwọn méjéèjì wà ní ìpínlẹ̀ Èkó àti Kwara tì pa fún ipa tí wọ́n kó lórí ìtànkálẹ̀ ògùn ikọ́ olómi tó ní èròjà codeine nínú, èyí tí àwọn ọ̀dọ́ Nàìjíríà ti sọ di egbòogi, tí wọ́n n lò ní ìlòkulò.
Iléeṣẹ́ Bioraj, Emzor àti Peace Standard ni ìwádìí fihàn pé wọn jẹ́bi bí òògùn codeine ṣe tàn kálẹ̀
Àbọ̀ ìwádìí àjọ NAFDAC, tó ṣe lẹ́yìn fídíò ìṣẹ́ ìwádìí BBC tú àṣírí ìlòkulò òògùn nàá, fihàn pé lóòtọ́ ni iléeṣẹ́ Bioraj jẹ́bi
Àjọ NAFDAC nínú àtẹ̀jáde kan tí olùdarí rẹ̀, Ọ̀jọ̀gbọ́n Mojisọla Christianah Adeyẹye, fi ọ̀wọ́ sí, ti ní kí àwọn iléeṣẹ́ apòògùn mẹ́tẹ̀ẹ́ta dáwọ́ ṣíṣe òògùn ikọ́ olómi tó ní èròjà codeine dúró lọ́gán, kí wọ́n ó sì gba gbogbo èyí tí wan ti tà síta padà fún àyẹ̀wò lọ́dọ̀ NAFDAC.
Oríṣun àwòrán, Frankieleon
Àṣìlò codeine wọ́pọ̀ láàrin àwọn ọ̀dọ́
Ẹ̀wẹ̀, wọ́n ní kò ní i sí ààyè láti kọ̀wé tuntun bèérè fún àṣẹ láti kó codeine wọ́lé láti ilẹ̀ òkèérè gẹ́gẹ́ bi èròjà gbòógì fún ṣíṣe òògùn ikọ́ olómi, tàbí sọ èyì tó ti wà nílẹ̀ tẹ́lẹ̀ dọ̀tun.
Àtẹ̀jáde ọ̀hún tun sọ pé wọ́n ti ní kí àwọn iléeṣẹ́ tọ́rọ̀ kàn san owó ìtanràn tó bá ìkọ̀ọ́kan àwọn ẹ̀sùn tí wọ́n fi kàn wọ́n.
Ọmọ orílẹ́èdè Gẹ̀ẹ́sì méjì sọnù nínú ọgbà ẹranko
Oríṣun àwòrán, Getty Images
ọ̀pọ̀lọpọ̀ èèyàn pẹ̀lú àwọn obìnrin àti ọmọdé ni wọ́n ti jí gbé nÍ agbègbè náà láti ọdún 2016.
Ọfiisi to n ri si ọrọ ilẹ-okeere ti kàn si awọn ẹbí wọn ati awọn alaṣẹ ijọba
Iṣẹlẹ naa waye lapa ariwa ilu Goma ni ila-oorun orilẹ-ede D.R. Congo ninu ọgba ẹranko ti Virunga National Park.
Akọroyin fun BBC, Louise Dewast, t'owa ni olu-ilu orilẹ-ede naa, ni Kinshasa ni awọn to d'ira pẹlu ohun ija olóró maa n ṣọṣẹ l'agbegbe naa.
Ṣugbọn o fi kun ọrọ pe awọn ọmọ ogun orilẹ-ede D.R Congo ma n wa nibẹ nigba gbogbo lati gbogun ti wọn.
Ọpọlọpọ eeyan pẹlu awọn obinrin ati ọmọde ni wọn ti ji gbe ni agbegbe naa lati ọdun 2016.
Gómìnà ìpínlẹ̀ Ọyọ àti ìyàwó rẹ̀ kò gbẹ́yìn nínú ìdìbò tó ń lọ
Gómìnà Abiola Ajimọbi àti ìyàwó rẹ̀ níbi ìdìbò yan alága kánsù
Gómìnà ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́ Abiọla Ajimọbi àti ìyàwó rẹ̀ ló kọ́wọ̀ọ́rìn lọ sí ibi àpótí ìdìbò ti wọn.
Wọ́ọ̀dù kẹsàn-án nínú ọgbà ilé ìwé Girama ní Olúyọ̀lé, ìlú Ìbadan ní àpótí ìdìbò wọn wà gẹ́gẹ́ bí akọ̀ròyìn wa tó ń mójú tó ètò ìdìbò náà ní ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́ sọ
wọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí:
Burundi: Ìbẹ̀rù bojo gbilẹ̀ bí ẹ̀mí se sòfò sáájú ìdìbò
Oríṣun àwòrán, AFP
Ètò àbò ti gbépọn si sáájú ìdìbò gbogbogbò l'ọ́ṣẹ̀ tó ń bọ̀
O kere tan eeyan mẹrindinlọgbọn lo padanu ẹmi wọn lẹyin ti awọn agbebọn kọlu abule kan ni apa iwo oorun ariwa orilẹede Burundi.
Eleyi ṣẹlẹ bi ibẹru-boju ṣe gbalẹ saaju idibo gbogbogbo nilẹ naa.
A gbọ pe awọn agbebọn naa wa lati orilẹede DR Congo tan wọn si ya bo ẹkun  Cibitoke.
Awọn akọroyin sọpe o ṣeeṣe ki ipaniyan naa ni i se pẹlu eto idibo oṣẹ to n bọ.
Wọn ni eto idibo naa le jẹ ki aarẹ orilẹede naa wa lori aleefa di ọdun 2034.
Aarẹ Pierre Nkurunza ti n ṣe 'jọba  orilẹede naa lati ọdun 2005 ti ogun abẹlẹ ti pari n'ilẹ naa.
Fayoṣe: Iná tí kò ní pẹ̀ ẹ́ kú ni àṣeyọrí Fayẹmi
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Fayoṣe fa igákejì rẹ̀ kalẹ̀ gẹ́gẹ́ bi olùdíje PDP nínú ètò ìdìbó gónínà tó n bọ̀ l'Ékítì
Gómìnà ìpìnlẹ̀ Èkìtì,ti ní kí Kayọde Fayẹmi maa tì i dun nú fún bó ṣe borí nínú ìdìbò abẹ́lé APC.
Ayọdele Fayoṣe, tó sọ̀rọ̀ nàá nínú ìkéde kan tó fi síta lójú òpó Twitter rẹ̀ ní ''iná tí yòó kú lọ́ja kẹrìnlá, oṣù Keje ní àṣeyọrí Fayẹmi.
"Ó ní ''kí Fayẹmi ní ìrètí wí pé ìjákulẹ̀ rẹ̀ nínú ètò ìdìbò tó n bọ̀ yóò burú fun un ju ti 2014."""
Fayẹmi tó jẹ́ mínísítà fún ìdàgbàsókè ìwakùsà àti ìrìn rírọ́ ló gbégbá orókè nínú ètò ìdìbò abẹ́lé ẹgbẹ́ All Progressives Congress, tó wáyé lọ́jọ́ Àbámẹ́ta láti yan ẹni tí yóò ṣojú ẹgbẹ́ nàá nínú ètò ìdìbò sí ipò gómínà tí yòó wáyé lọ́jọ́ kẹ̀rìnlá, oṣù Keje, 2018.
Fáyẹmí pè fún àjọṣepọ̀ àwọn olùdíje fún àṣeyọrí APC l'Ékìtì
Oríṣun àwòrán, Tunji Ariyomo
Àwọn olùdíje ti ń fikùlukù lórí ọ̀nà àti mú àṣeyọrí bá ìlàkàkà ẹgbẹ́ òṣèlú APC
Eto idibo lati yan oludije fun ipo gomina ipinlẹ Ekiti labẹ aṣia ẹgbẹ oṣelu APC ti pari, o si ṣeeṣe ki eyi fi opin si aawọ to waye laarin awọn eekan ẹgbẹ oṣelu naa nibẹ nitori bi a ti ṣe n sọrọ yii igbesẹ ti nlọ lati dẹkun dukuu abẹnu nibẹ.
Ọmọwe Kayọde Fayẹmi ti na ọwọ ifẹ si gbogbo awọn oludije yooku pẹlu arọwa pe ki wọn jẹ ki gbogbo ohun to waye lasiko idije fun aṣia ẹgbẹ naa rodo igbagbe lọ ree mumi.
Ninu atẹjade kan ti Fayẹmi fi sita lẹyin ti wọn kede rẹ gẹgẹ bii olubori fun awọn oludije fun ipo gomina labẹ aṣia ẹgbẹ oṣelu APC.
"O ni ""igbesẹ akọkọ ni lati gbe igbimọ olubadamọran kalẹ lẹyẹ o ṣọka eleyi ti yoo ko gbogbo awọn oludije mọra""."
"O sọ síi wi pe ""a gbọdọ parapọ ja ija bibọ ajaga aimọkan kuro lọrun awọn eeyan wa, ki a si gba wọn kuro lọwọ aisan ati awọn ohun idena to n de wọn lọna ati de ipo ti o yẹ ki a wa."""
Oríṣun àwòrán, Olasunkanmi ogunmuko
Marundinlọgbọn ninu awọn oludije to dije naa ni awọn to dibo fun wọn ko wọn marun
Fayẹmi ni ohun ti ẹgbẹ oṣelu APC nilo ni iṣọkan awọn eeyan rẹ gbogbo fun aṣeyọri ẹgbẹ oṣelu naa nibi eto idibo sipo gomina nipinlẹ Ekiti, eleyi ti yoo waye lọjọ kẹrinla oṣu keje ọdun yii.
"O ni ""mo gbara le atilẹyin awọn eeyan mi ti a jumọ dije fun iriri, imọ ati ọgbọn inu wọn lọna ati lee gbe ipinlẹ Ekiti soke tente lẹẹkan sii."""
Bakannaa la gbọ wi pe ọkan ninu awọn oludije naa, Bimbọ Daramọla, ti ṣeto apejẹ binukonu kan leyi ti yoo fun awọn oludije naa lanfani ati fikuluku lori ẹhonu ati ọna abayọ fun aṣeyọri ẹgbẹ oṣelu naa nibi idibo sipo gomina to n bọ.
Olópàá Nàíjíríà: A ti rí owó NNPC tí wọ́n kó sílé ìfowópamọ́
Oríṣun àwòrán, NNPC
Mallam Kyari ni ọ̀gá àgbà fún ẹ̀ka tó ń rí sí káràkátà epo rọ̀bì ní àjọ NNPC
Ajọ ọlọpaa ni orilẹ-ede Naijira ni awọn ti ri owó to le ni aadọrinlenirinwo billiọnu dọla to jẹ ti Ajọ Eleto Bẹntirol Lorile-ede Naijiria, NNPC.
Ajọ ọlọpaa ni awọn ile ifowopamọ to wa ní Naijiria ti wọn ko owo naa pamọsi ni awọn ti ṣawari owo naa.
Agbẹnusọ ajọ ọlọpaa, Jimoh Moshood, to fi ọrọ naa lede ni Olu-Ilu Naijria, Abuja fikun un pe awọn tun ti ri owo miran to le ni biliọnu mẹjọ Naira to jẹ ti NNPC/LNG ti wọn ko fi si apo asuwọn ijọba to yẹ ko wa.
Osun Election 2018: A ti gbaradì de ìdìbò Ọṣun bí ó ti yẹ- Adeoye
Bakan naa, Jimoh Moshood fikun wi pe awọn tun ri owo to le ni erinlelaadọfa milliọnu Naira lati ọwọ awọn osisẹ eleto idibo mejila lasiko idibo to waye ni Osu Kejila, ọdun 2016 ni ipinlẹ Rivers.
Ajọ elepo rọbi lorilẹ-ede Naijiria, NNPC ti kede yiyan Mallam Mele Kyari gẹgẹ bii aṣoju tuntun fun orilẹ-ede Naijiria ni ajọ awọn orilẹede to n wa epo rọbi lagbaye, OPEC.
Ninu atẹjade kan ti ajọ NNPC fi sita lọjọ Aiku ni wọn ti kede rẹ pe Ọmọwe Ibe Kachickwu lo yan Kyari si ipo tuntun yii.
Atẹjade naa tun fi kun un pe, Mallam Mele Kyari to jẹ akọṣẹmọṣẹ imọ nipa epo rọbi wiwa yoo maa ti Minisita kekere fun epo rọbi, Ibe Kachukwu lẹyin ninu iṣẹ rẹ.
OsunDecides: Adeleke kò jáwọn olólùfẹ́ tó fẹ́ wòran ijó rẹ̀ kulẹ̀
Ṣaaju ipo tuntun yii, Mallam Kyari ni ọga agba fun ẹka to n ri si karakata epo rọbi ni ajọ NNPC.
Lara awọn iṣẹ ti yoo maa ṣe lẹnu ipo tuntun yii ni lilewaju ikọ orilẹede Naijiria lọ si igbimọ ọrọ aje lajọ OPEC.
Ọṣun Decides: ADC, ADP, APC àti SDP soju abẹ níkòó lórí ìwà ìbàjẹ́
Wenger: Ohun méje tí àwọn olólùfẹ́ Arsenal yóò rántí nípa rẹ̀
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ọdún 1996 ni wọ́n gba Arsene Wenger sí ipò olùkọ́ni ẹgbẹ́ agbábọ́ọ̀lù Arsenal
Loni ni Arsene Wenger, olukọni ikọ agbabọọlu Arsenal yoo gba ifẹsẹwọnsẹ rẹ to kẹyin gẹgẹ bii olukọni ẹgbẹ agbabọọlu naa.
Ni oṣu kẹrin ni Wenger kede pe oun yoo kuro nipo gẹgẹ bii olukọni ikọ agbabọọlu Arsenal lẹyin to ti lo ọdun mejilelogun nibẹ.
Laarin ọdun mejilelogun yii, oniruuru ni iṣẹlẹ to ṣẹlẹ eyi ti o sọ Wenger di olukọni to pẹ julọ ni ẹgbẹ agbabọọlu naa.
Ẹ jẹ ki a wo awọn ohun ti awọn ololufẹ ẹgbẹ agbabọọlu Arsenal atawọn ololufẹ ere bọọlu lagbaye yoo maa ranti Wenger fun lẹyin ti o ba lọ tan.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ọdún méjìlélógún ló lò ní Arsenal
Ni ọdun 1996 ti wọn kede Arsene Wenger  gẹgẹ bii olukọni tuntun fun ẹgbẹ agbabọọlu Arsenal, pupọ nínú awọn ololufẹ ikọ naa ni kò mọ ohunkohun nipa rẹ.
Nigba naa, orukọ rẹ ko tii di ilumọọka nitori ẹgbẹ agbabọọlu Monaco lorilẹ-ede france ni a lee pe ni ikọ to lorukọ julọ to ba ṣiṣẹ. Ni asiko ti a si n wi yii, iwọnba perete lawọn ti n wo liigi orilẹ-ede France lagbaye, paapaa julọ lorilẹ-ede Gẹẹsi.
"Wenger kini? Wenger ewo?"" ni ibeere to gba ẹnu pupọ awọn ti awọn oniroyin bi leere ọrọ nipa rẹ n sọ."
Arsenal di ẹgbẹ agbabọọlu ti n lepa ife ẹyẹ lọdọọdun
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Fun igba akọkọ ninu itan liigi ilẹ Gẹẹsi, ikọ Arsenal gba ife ẹyẹ liigi lai fidirẹmi ninu ifẹsẹwọnsẹ kankan
Nigba ti Wenger gba akoso iṣẹ ni Arsenal, ni Arsenal di ikọ ti o n lepa ife ẹyẹ lọdọọdun.
Ni ọdun 1998 ati 2002, ife ẹyẹ meji-meji ni arsenal gba-ife ẹyẹ liigi ati FA.
Laaarin ọdun to fi wa ni Arsenal, ife ẹyẹ liigi ni mẹta ati FA meje ni Wenger gba.
Ikọ 'The Invincibles'Arsenal to gba liigi lọdun 2004 lai padanu ifẹsẹwọnsẹ kankan
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ni ọdun 1998 ati 2002, ife ẹyẹ meji-meji ni arsenal gba-ife ẹyẹ liigi ati FA
Fun igba akọkọ ninu itan liigi ilẹ Gẹẹsi, ikọ Arsenal labẹ akoso Arsene Wenger gba ife ẹyẹ liigi ilẹ Gẹẹsi lai fidirẹmi ninu ifẹsẹwọnsẹ kankan.
Eyi lo faa ti wọn fi fun ikọ Arsenal igba naa ni orukọ 'The Invisibles'eyi to tumọ si ikọ ti ko ṣee ba ta kangbọn.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ọpọlọpọ ololufẹ ẹgbẹ agbabọọlu Arsenal ni wọn ri Wenger gẹgẹ bii 'Baba ijẹbu' ti ko fẹ na owo
Ọpọ lo ni igbagbọ pe kikọ papa iṣire igbalode Emirate fun Arsenal lati lo dipo Highbury ti wọn n lo tẹlẹ ri ni ibẹrẹ idamu Arsene Wenger gẹgẹ bii olukọni.
Arsene Wenger ṣe atọna ikọ naa ninu eyi ti wọn ko lee ra awọn gbajugbaja agbabọọlu nitori ọda owo pẹlu inawo papa iṣire tuntun wọn naa.
Ni ilẹ to mọ loni ikọ Arsenal lo fẹrẹ ni gbagede ere idaraya to yaayi julọ ni ilẹ Gẹẹsi, eyi ti ko ṣẹyin Arsene Wenger.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Laarin ọdun to fi wa ni Arsenal, ife ẹyẹ liigi ni mẹta ati FA meje ni Wenger gba
Titi di asiko ti Wenger fi n kuro ni ipo olukọni ẹgbẹ agbabọọẹu Arsenal, ko si olukọni to tii gba ife ẹyẹ FA tóo lorilẹ-ede gẹẹsi.
Igba meje ọtọọtọ ni Wenger ti gba ife ẹyẹ FA ko si si olukọni miran to tii gbaa.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ọpọ lo gbagbọ pe kikọ papa iṣire igbalode Emirate ni ibẹrẹ idamu Arsene Wenger
Ni gbogbo ọdun mejilelogun to lo nipo, Wenger ati alex Ferguson to jẹ olukọni fun ikọ manchester United nigba naa kii wọn ọn laabọ funra wọn. Pupọ igba ti ẹgbẹ agbabọọlu Arsenal ati Manchester United ba ti fẹ waako ni awọn ololufẹ ikọ naa maa n reti ki awọn meji yii o gbe ina woju ara wọn.
Amọṣa, lẹyin ti Ferguson fẹyinti, Wenger ati olukọni ikọ Chelsea nigba naa Mourinho lo tun bẹrẹ itaporogan.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ni ilẹ to mọ loni ikọ Arsenal lo fẹrẹ ni gbagede ere idaraya to yaayi julọ ni ilẹ Gẹẹsi
Ọpọlọpọ ololufẹ ẹgbẹ agbabọọlu Arsenal ni wọn ri Wenger gẹgẹ bii 'Baba ijẹbu' ti ko fẹ na owo lati ra awọn agbabọọẹu to lorukọ. Eyi si ti mu ki ọpọ ololufẹ ikọ agbabọọlu Arsenal o maa fi oju laabi wo o.
Sugbọn ọpọ igba pẹlu ni Wenger naa ti sọrọ sita pe, 'owo ti igbimọ adari ba fun mi ni mo n na
World Cup 2018: Orílẹ̀-èdè mẹ́sàn-àn ló ti gba ife sẹ́yìn
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ohun ti gbogbo agbabọọlu agbaye n ja si ree!!!!!
Àjọ eléré bọ́ọ́lù lágbàáyé, FIFA, ló ń ṣe agbátẹrù ife ẹ̀yẹ àgbáyé, Ọdún mẹ́rin-mẹ́rin sì ni ìdíje naa máa ń wáyé.
Ìdíje ife ẹ̀yẹ àgbáyé jẹ́ ìdíje láàrin àwọn ikọ̀ agbábọ́ọ̀lù ọkùnrin láwọn orílẹ̀-èdè káàkiri àgbáyé.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Uruguay àti Argentina kojú ara wọn lọ́dún 1930 amọ́ Uruguay ni orílẹ̀èdè àkọ́kọ́ tó kọ́kọ́ gba ife ẹ̀yẹ
Orílẹ̀-èdè Uruguay ló kọ́kọ́ gba àlejò ìdíje ife ẹ̀yẹ àgbáyé lọ́dún 1930, orílẹ̀-èdè mẹ́tàlá sì ló kópa nínú rẹ̀.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Orílẹ̀-èdè West Germany ló gba ife ẹ̀yẹ lọ́dún 1954, 1974 ati 1990
Ọdún 1942 si 1946 nìkan sì ni ìdíje náà kò leè wáyé nítorí ogun àgbáyé tó ń lọ lọ́wọ́ nígbà náà.
Fídíò BBC yọ àwọn èèyàn FIFA níṣẹ́ ṣááju Russia 2018
Ìgbà ogún ni ìdíje ife ẹ̀yẹ àgbáyé ti wáyé sẹ́yìn. Ìdíje ti ọdún 2018 sì ni yóò sọ ọ di mọ́kànlélógún, èyí tó ń wáyé lọwọ ní orílẹ̀-èdè Russia loṣù kẹfà si oṣù keje, ọdún 2018 bayii, nibi tí àwọn orílẹ̀-èdè bíi mẹ́tàlélógún sì ti n kópa nínú rẹ̀, ó kéré tán, ní ẹ̀ẹ̀kan soso.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Brazil gba ife ẹ̀yẹ lọ́dún 1958, 1962, 1970, 1994 ati ni 2002 fún ìgbà karun-un
Táa bá sì ní ká kàá ní ení, èjì, ọdún kejìdínláàádọ́rùn-ún rèé tí wọn bẹ̀rẹ̀ ìdíje ife ẹ̀yẹ àgbáyé.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Lọ́dún 1966, England àti West Germany ló díje, England ni ife já mọ́ lọ́wọ́
Ikọ̀ agbábọ́ọ́lù láti orílẹ̀-èdè méjìlá ló ti dé ìpele àsekágbá ìdíje náà láti ìgbà tó ti bẹ̀rẹ̀, àmọ́ ikọ̀ agbábọ́ọ́lù méjọ péré ló tii gba ife ẹ̀yẹ àgbáyé náà.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Orílẹ̀-èdè Argentina sì ló gba ife ẹ̀yẹ àgbáyé lọ́dún 1978 ati 1986 fún ìgbà keji
Orílẹ̀-èdè Brazil ló tíì se àseyọrí nínú ìdíje ife ẹ̀yẹ àgbáyé jùlọ, tó sì jẹ pé òun náà sì ló tíì farahàn jùlọ nínú gbogbo ìdíje ife ẹ̀yẹ àgbáyé tó ti ń wáyé.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Lọ́dún 1998, France àti Brazil ni wọ́n figa-gbága àmọ́ France ló gba ife ẹ̀yẹ
Ọjọ́ Àìkú, ni àsekágbá àwọn ìdíje ife ẹ̀yẹ àgbáyé máa ń wáyé àyàfi ọdún 1930 àti 1966 nìkan tí ìdíje ife ẹ̀yẹ àgbáyé wáyé ní ọjọ́rú àti ọjọ́ àbámẹ́ta.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Lọ́dún 2010, Spain àti Netherland dije fún àsekágbá, Spain ló gba ife ẹ̀yẹ
Titi di ọdún 2014, àwọn orílẹ̀-èdè láti ilẹ̀ Europe àti South Amẹrika ni wọ́n ń figa-gbága nínú àsekágbá ìdíje ife ẹ̀yẹ àgbáyé.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ní 2014, Germany àti Argentina ni wọ́n tún náa tán bíi owó ní àsekágbá, tí Germany sì gbé ife ẹ̀yẹ lọ
Ẹlẹẹkọkanlelogun ni eyi to n waye lọwọ ni RUSSIA.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Idije ife ẹyẹ agbaye ti di ajanaku kọja mo ri nkan fìrí bayii
Àwọn Alex Iwobi kékèké
Ọrọ ìfẹ́: Tunrayọ Adeoye kú lọ́sẹ̀ karun ti a sin ọkọ rẹ̀
Àbẹ̀wò Buhari: Gómìnà márùn-ún ki káábọ̀
Oríṣun àwòrán, @BashirAhmaad
Ṣaaju abẹwo yii, aarẹ ti kọkọ ṣabẹwo si ipinlẹ Taraba, Plateau, Benue ati Zamfara
Aarẹ Muhammadu Buhari ti gunlẹ si ipinlẹ Jigawa fun abẹwo ọlọjọ meji.
Gomina Abubakar Badaru ti ipinlẹ Jigawa, Abdullahi Ganduje tipinlẹ  Kano, Ibrahim Geidam ti ipinlẹ Yobe, Abdullahi Abubakar ti ipinlẹ Bauchi, pẹlu Aminu Masari lati ipinlẹ Katsina, ni wọn wa nikalẹ lati gba Aarẹ Buhari lalejo ni papakọ ofurufu ilu Dutse.
Ireti wa wi pe, Aarẹ Buhari yoo ṣe abẹwo sawọn iṣẹ akanṣe kan ni agbegbe Hadejia, Auyo ati Dutse ni ipinlẹ Jigawa lasiko abẹwo ọhun.
Oríṣun àwòrán, @ImamShams
Ọ̀gọ̀rọ̀ àwọn èèyàn ló jáde wá pàdé Ààrẹ Buhari nígbà tó gúnlẹ̀ sí pápákọ̀ òfúrufú ní Dutse
Nibayii, Aarẹ Buhari ti wa ni Auyo lati ṣi ibudo ipese omi to wa ni Hadejia.
Iroyin sọ wi pe, ọgọọrọ awọn olugbe ipinlẹ naa ni wọn tu sita lati ki Aarẹ buhari kaabọ sibẹ.
Ṣaaju abẹwo yii, aarẹ ti kọkọ ṣabẹwo si ipinlẹ Taraba, Plateau, Benue ati Zamfara lori wahala ọrọ abo to gbode kan lawọn agbegbe kan lorilẹede Naijiria.
Iléẹjọ́ Kenya: Owó tí aya ná ni yóó gbà tí wọn bá túká
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ẹgbẹ awọn obinrin agbẹjọro nilẹ Kenya fẹ ki wọn maa pin nkan ini wọn ni dọgba dọgba
Ile ẹjọ kan ni orilẹede Kenya ti dajọ pe, ofin igbeyawo ilẹ naa, eyi  to fun ọkọ ati aya l'anfani lati ko nkan ini onikaluku wọn lọ, lẹyin ti wọn ba ti kọ ara wọn silẹ, ko lee mulẹ.
Ẹgbẹ awọn obinrin agbẹjọro nilẹ Kenya fẹ ki ofin naa yi pada,
Wọn fe ki lọkọ-laya ti wọn ba ti kọ ra wọn silẹ, maa pin nkan ini wọn ni dọgba dọgba.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Adajọ ni ẹnikẹni ko le wọnu igbeyawo ko si kuro pẹlu ohun to ju iṣẹ ọwọ rẹ lọ.
Ṣugbọn adajọ naa sọ pe, ẹnikẹni ko le wọnu igbeyawo ko si kuro pẹlu ohun to ju iṣẹ ọwọ rẹ lọ.
Ni oṣẹ to kọja, ile ẹjọ to ga julọ l'orilẹede naa sọ pe, ohun ko lagbara lati gbẹjọ laarin awọn ọkọ ati iyawo kan ti wọn ti kọ'ra wọn silẹ.
Iyawo naa beere fun owo itọju lati ọwọ ọkọ rẹ ana. Ṣugbọn ile-ẹjọ naa sọ pe ọrọ mọlẹbi ni.
Yahoo Yahoo: Ọ̀pọ̀ olórin ti kọ́rin ìwúrí fún àgbéga rẹ̀
'Yahoo-yahoo' tàbí 419, kìí ṣe tuntun ní Nàìjíríà, bí ó tilẹ̀ jẹ́ wí pé ìwà ọ̀daràn ni.
Ìwà ìlu-ni ní jìbìtì lórí ìtàkùn àgbáyé, tí àwọn kan tún n pè ní 'yahoo-yahoo' tàbí 419, kìí ṣe tuntun ní Nàìjíríà, bí ó tilẹ̀ jẹ́ wí pé ìwà ọ̀daràn ni.
Àwọn kan tilẹ̀ gbàgbọ́ pé, ara ọ̀nà àtijẹ ni, kìí ṣe ìwà ọ̀daran.
Kódà, kò yọ àwọn tó n kọrin sílẹ̀, nítorí pé àwọn kan lára wọn ti kọrin tó mú kó dà bí ẹni pé, wọ́n n kan sáàrá sí àwọn tó n ṣe é.
Wọ́n fi orin wọn ṣe ìgbélárugẹ fún iṣẹ́ ìlu-ni ní jìbìtì yìí, táwọn ọmọ Nàìjíríà nàá a sì maa jó sí àwọn orin nàá, bí ẹni pé jíjẹ́ 'ọmọ yahoo-yahoo' jẹ nkan tó dára.
Díẹ̀ lára àwọn orin tó tí gbóríyìn fún àwọn ọmọ yahoo, àti okòwò wọn ni yìí:
Oríṣun àwòrán, Olu Maintain/Instagram
Orin Yahoozee gbaju-gbaja púpọ̀ láàárín àwọn ọ̀dọ́
Ọdún 2008 ni Olu Maintain gbé orin ọhun, tó pè ní 'Yahoozee' jáde. Orin nàá gbajúmọ̀ púpọ̀ lásìkò nàá, débi pé, ó gba àmì ẹ̀yẹ Nigeria Entertainment Award, gẹ́gẹ́ bi orin tó tayọ jù lọ ní 2008.
Oríṣun àwòrán, Kelly Hansome/Instagram
Kò fẹ́ẹ̀ sí orin tó gbajúmọ̀ tó 'Maga don pay' tó jáde lọ́dún 2008
Ọdún 2008 nàá ni Kelechi Orji, tí ìnagijẹ rẹ̀ n jẹ́ Kelly Handsome, gbé orin 'Maga don pay' jáde. Ó tilẹ̀ máà fẹ̀ ẹ́ sí orin tó gbajúmọ̀ tó orin yìí lásìkò nàá. Nínú orin nàá ló ti sọ nípa bí 'maga', èyí tó túmọ̀ sí 'mumu' tàbí 'ọ̀dẹ́', tó bọ́ sọ́wọ́ àwọn ọmọ yahoo ṣe ń se.
Oríṣun àwòrán, 9ice/Instagram
Àjọ NBC f'òfin de orin 9ice tó fọnrere iṣẹ́ 'Yahoo'
Gbajú-gbajà olórin tàka-súfèé, Abọlọrẹ Akande, tí gbogbo ènìyàn tún mọ̀ sí 9ice, nàá gbé orin ọ̀hún tó polongo iṣẹ́ yahoo bí ọ̀nà ìwá n kan jẹ.
Orin náà tilẹ̀ tọ̀ka sí oríṣiríṣi ọ̀nà tí àwọn apani-lẹ́kún ọ̀hún n gbà ṣiṣẹ́ wọn. Bi i ká díbọ́n bí olólùfẹ́ lórí ẹ̀rọ ayélújára, ká fi lu ni ní jìbìtì, tàbí ká ṣe bí olókoòwò láti lu ẹni tí kò bá fura ní jíbìtì.
Àwọn orin tí à n gbọ́ ní ipalórí ìrònú àti ìgbé ayé wa
Àjọ tó n mójútó àwọ̀n iléeṣẹ́ ìgbóhùn sáfẹ́fẹ́ ní Nàìjíríà, NBC, tilẹ̀ f'òfin de àwọn iléeṣẹ́ agbóhùn sáfẹ́fẹ́ láti má lo orin nàá.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Àwọn olórin gbọdọ̀ kó ara wọn ní ìjánu nípa orin tí wọn ń kọ lórí ìwà lílu jìbìtì.
Bí ó tilẹ̀ jẹ́ wí pé, púpọ̀ nínú àwọn olórin yìí ló maa n sọ pé àwọn kò ṣe ìgbé lárugẹ fún 'yahoo' ṣíṣe, ohun tó dájí ni pé, àwọn orin tí à n gbọ́, tàbi ere tí à n wò, ní ipa tó n kó lórí ìrònú àti ìgbé ayé wa.
Tí a bá sì fẹ́ mú àdínkù bá àsà lílu èèyàn ní jìbìtì, àwọn olórin gbọdọ̀ kó ara wọn ní ìjánu nípa orin tí wọn ń kọ lórí ìwà lílu jìbìtì.
Ààwẹ Ramandan: Àwọn ouńjẹ tí a fi ń sínu àwẹ̀
Àwẹ Ramandan ń bẹ̀rẹ̀, irú ouńjẹ wo la lè jẹ?
Awọn ẹlẹsin Musulumi ni agbaye yoo bẹrẹ aawẹ Ramadan ni ọsẹ yii, eleyii ti yoo mu ki wọn yẹra fun jijẹ ati mimu lati owurọ titi di asalẹ.
Idi ti wọn fi n gba aawẹ yii ni lati bu ẹwa kun aye igbagbọ wọn ati ihuwa bi Ọlọrun, eleyii ti yoo mu wọn sun mọ Ọlọrun ati gbigbe igbe aye to wuyi, ti o si bu ọla fun Ọlọrun.
Ounjẹ jijẹ lasiko yii le jọ ohun ti ko lera, sugbọn eniyan gbọdọ sọra nipa ounjẹ ji jẹ lasiko aawẹ.
ẹ̀fọ́ rírò jẹ́ alábárìn iyán, fùfú, ẹ̀bà, àmàlà àti ìrẹsi funfun
Eniyan gbọdọ sọra nigba ti eniyan ba n ja aawẹ ni asalẹ, ki eniyan ma baa da awọn eto to n jẹ ki ounjẹ walẹ lagọ ara rú.
Amọ, ounjẹ ajẹju o dara lasiko aawẹ Ramadan, ati wi pe sise ohun gbogbo ni iwon tuwon si lasiko Ramadan yoo jẹ ki ara ati ọkan eniyan o ji pepe.
Ìjọba: Zakzaky ń kó èrò jọ lọ́nà tó lòdì sófin
Oríṣun àwòrán, @ELBINAWI
Ọjọ́ Ajé ni wọ́n ti gbé asaájú ẹgbẹ́ Shiite naa wá sí ìlú Kaduna,
Asáájú ẹgbẹ́ ẹlẹ́sìn Shiite, Sheik Ibrahim Zakzaky yọjú sílé ẹjọ́ giga ti Kaduna  lọ́jọ́ ìsẹ́gun.
Déédé aago mẹ́jọ ààbọ̀ ni wọ́n gbé Zakzaky àti ìyàwó rẹ̀ wá sílé ẹjọ́, tí ètò ààbò sì gbópọn gidi.
A gbọ pé alẹ́ ọjọ́ Ajé ni wọ́n ti gbé asaájú ẹgbẹ́ Shiite naa wá sí ìlú Kaduna, tí wọn sì fi pamọ́ sí ibití ẹnikẹ́ni kò mọ̀.
Oríṣun àwòrán, @aayola81
Àwọn alátìlẹyìn Zakzaky kò fi ijọba àpapọ̀ lọ́rùn sílẹ̀ lórí bó se fi asaájú wọn sí àhámọ́ ọlọ́jọ́ gbọọrọ
Nígbà tó ń bá àwọn akọ̀ròyìn sọ̀rọ̀ lẹ́yìn ìgbẹ́jọ́ náà, ọ̀kan lára agbẹjọ́rò rẹ̀, Amòfin Maxwell Kyom ni lára àwọn ẹ̀sùn tí wọn fi kan Zakzaky ni pé ó ń kó àwọn èèyàn jọ, lọ́nà tó lòdì sófin, ìdìtẹ̀ hùwà ọ̀daràn àti ìwà pípa ọ̀pọ̀ èèyàn, èyí tí ikú jẹ́ èrè ẹ̀sẹ̀ rẹ̀.
Oríṣun àwòrán, @ELBINAWI
Ìjọba fi ẹ̀sùn kan Zakzaky pé ó ń kó àwọn èèyàn jọ, lọ́nà tó lòdì sófin
Amòfin kyon fi kun pé wọn kò leè tẹ̀síwájú lórí ẹjọ́ náà nítorí méjì nínú àwọn olùjẹ̀jọ́ ni kò yọjú sílé ẹjọ́.
Ó ní wọ́n bèèrè fún gbígba onídúró tọkọ-taya náà, àmọ́ adájọ́ tó ń gbọ́ ẹjọ́ náà, Gideon Kurada ní kí òun kọ̀ ìbèèrè náà sínú ìwé.
Ilé aṣòfin Ọ̀yọ́: Ọlágúnjú Òjó di olórí ilé tuntun
Oríṣun àwòrán, NAtional Insight
Igbakeji olori ile, Abdulwasil Musa Ojo lo ṣe akoso eto iyansipo lori ile tuntun
Joshua Olagunju Ojo ti di olori tuntun fun ile aṣofin ipinlẹ Ọyọ.
Ojó gun akasọ ipo olori ile aṣofin naa lẹyin ti Michael Adeyemọ, to jẹ olori ile naa tẹlẹ ti jade laye ni ọjọ kẹtadinlọgbọn oṣu kẹrin ọdun 2018.
Gba-gba-gba lawọn agbofinro raga bo gbagede ile aṣofin ipinlẹ Ọyọ lasiko ti eto ati yan olori ile naa fi n waye.
Wọ́n yan olórí tuntun lẹ́yìn tí olórí ilé tẹ́lẹ̀, Micheal Adéyẹmọ jáde láyé.
Yatọ si awọn aṣofin ati iwọnba perete oniroyin, ko si ẹnikẹni ti awọn agbofinro jẹ ko wọ gbagede naa.
Igbakeji olori ile, Abdulwasil Musa lo ṣe akoso eto iyansipo lori ile tuntun naa.
Oríṣun àwòrán, facebook/oyo state house of assembly
Ojó gun akasọ ipo olori ile aṣofin naa lẹyin ti Michael Adeyemọ, to jẹ olori ile naa tẹlẹ jade laye
Joshua Ọlágúnjú Òjó ni olori awọ̀n ọmọ ẹgbẹ́ òṣèlù tó kéré jùlọ ní ilé, náà kí ó tó di olórí ilé.
Bakannaa ni wọn tun yan Akeem Ademola, gẹgẹ bii olori awọn ọmọ ẹgbẹ oṣelu to kere julọ nile aṣofin naa.
Buhari: N kò fi ìgbógun ti ìwà ìjẹkújẹ halẹ̀ mọ́ ẹnikẹ́ni
Oríṣun àwòrán, EFCC
Ààrẹ Buhari ní kò sí ohun to leè yẹ ìpinnu òun láti gbógun ti ìwà ìjẹkújẹ
Aarẹ Muhammadu Buhari ti ṣi olu ileeṣẹ tuntun fun ajọ to n gbogun ti iwa ijẹkujẹ to rọ mọ iṣuna lorilẹede Naijiria, EFCC nilu Abuja.
Ninu ọrọ rẹ lasiko to fi n ṣe ifilọlẹ olu ileeṣẹ naa, Aarẹ Buhari ni, iṣejọba oun ko fi eto gbigbo-gun ti iwa ijẹkujẹ toun gunle, dunkoko mọ ẹnikẹni.
Aarẹ Buhari ni, ko si ani-ani lori ipinnu oun lati tubọ tẹra mọ gbigbo-gun ti iwa ijẹkujẹ.
Oríṣun àwòrán, EFCC
Olori ile aṣoju-ṣofin, Yakubu Dogara pe fun amojuto igbayegbadun awọn oṣisẹ ajọ EFCC
Afojusun mi ni lati doju ija kọ iwa ijẹkujẹ lai wẹyin wo. Ohun ti iṣejọba mi n lepa ni lati daabo bo igbẹkẹle araalu. A ko wa lati fi eto igbogun ti iwa ibajẹ dun mọhuru-mọhuru mọ ẹnikẹni.
Oríṣun àwòrán, EFCC
Ọpọ ọmọ orilẹede Naijiria lo bu ẹnu atẹ lu obitibiti owo ti wọn fi kọ olu ileeṣẹ ajọ EFCC
Ninu ọrọ tirẹ nibi ayẹyẹ ifilọlẹ olu ileeṣẹ ajọ EFCC naa, olori ile aṣoju-ṣofin, Yakubu Dogara ni, asiko to lati mojuto igbayegbadun awọn oṣisẹ ajọ EFCC, a si gbọdọ mu ayipada ba gule-gule iwa ijẹkujẹ lorilẹede Naijiria.
Ọpọlọpọ awọn ọmọ orilẹede Naijiria lo ti bu ẹnu atẹ lu awọn alaṣẹ EFCC, fun obitibiti owo to to biliọnu mẹrinlelogun naira, ti wọn fi kọ olu ileeṣẹ naa.
Ìsúná 2018: N410bn ni àwọn asòfin fi lé ìsúná Buhari
Oríṣun àwòrán, @bukolasaraki
Tírílíọ̀nù mẹ́sán náírà ni àwọn aṣòfin buwọ́lù
Igbimọ ile asofin agba to wa feto isuna gbe abọ ayẹwo iṣuna ọdun 2018 siwaju ile aṣofin agba lorilẹede Naijiria.
Ni ọjọ aje ni Sẹnetọ Danjuma Goje, to jẹ alaga igbimọ naa, gbe ayẹwo iṣuna naa si iwaju ile.
Ni ọjọ kẹrinlelogun oṣu kẹrin ni awọn aṣofin agba kọkọ ti pinnu lati buwọlu aba naa, ṣugbọn to kuna lati ṣe bẹ́ẹ̀.
Ọpọ awuyewuye lo ti waye lori bi bibuwọlu aba iṣuna ṣe n falẹ niwaju igbimọ aṣofin apapọ, lati ọdun to kọja ti Aarẹ Buhari ti gbe e kalẹ niwaju ijoko apapọ awọn aṣofin agba ati awọn aṣoju-ṣofin orilẹede Naijiria.
Awọn aṣoju-ṣofin ni tiwọn ti kede pe, ọjọọru ni awọn yoo buwọlu abadofin eto iṣuna oni tiriliọnu mẹsan-an o le diẹ naa.
Oríṣun àwòrán, @AsoRock
Tiriliọnu mẹjọ ati ẹgbẹta biliọnu, N8.61 trilion, ni aba iṣuna ti aarẹ Buhari ṣeto siwaju awọn aṣofin apapọ
Aba eto iṣuna ti ile aṣofin agba ati aṣoju-ṣofin panupọ le lori, fi irinwo o le mẹwa biliọnu naira ga ju eyi ti aarẹ gbe ka iwaju awọn aṣofin apapọ.
Tiriliọnu mẹjọ ati ẹgbẹta bilisnu, N8.61 trilion, ni aba iṣuna ti aarẹ ṣeto siwaju awọn aṣofin apapọ, ṣugbọn lẹyin ijiroro gbogbo ẹka ile mejeeji fẹnuko si tiriliọnu mẹsan o le ọgọfa biliọnu naira, N9.12 trilion.
Osinbajo: Buhari kò gbàgbé àwọn agbègbè tí ikọlù tú ká
Oríṣun àwòrán, @ProfOsinbajo
Gomina Ortom ni abẹwo Osibajo yoo fun awọn eeyan ipinlẹ Benue ni ireti
Aarẹ Muhammadu Buhari ti buwọlu biliọnu mẹwa naira fun atunṣe awọn ileto ti ikọlu awọn agbebọn bajẹ kaakiri tibu-toro orilẹede Naijiria.
Igbakeji aarẹ, Ọjọgbọn Yẹmi Ọsibajọ lo sọ eyi lasiko to fi ṣe abẹwo sawọn ibudo ogunlende kan nipinlẹ Benue ni irọlẹ ọjọ iṣẹgun.
Igbakeji aarẹ Oṣibajọ ṣalaye fun awọn olugbe ibudo ogunlende ni Abagena nibi ti awọn eeyan to le ni ẹgbẹ mẹrinlelọgbọn wa, pe ijọba apapọ n sa ipa lati ṣe atunto awọn agbegbe ti ikọlu ti waye lọna ati rii pe aabo ati irọrun pada sibẹ ki awọn olugbe ibẹ lee pada si ilẹ abinibi wọn laifoya.
Oríṣun àwòrán, @akandeoj
Osibajo gúnlẹ̀ sí Benue láti ṣe àyẹ̀wò si àwọn ibùdó ogunléndé
Ninu ọrọ rẹ, gomina Ortom ti ipinlẹ Benue dupẹ lọwọ aarẹ Buhari ati igbakeji rẹ fun aigbagbe awọn eeyan ipinlẹ naa ati ipenija wọn.
Gomina Ortom ni abẹwo igbakeji aarẹ Osibajo yoo tubọ fun awọn eeyan ipinlẹ Benue, paapaajulọ awọn ti rogbodiyan le kuro ni ileto wọn ni ireti irapada.
Ni asiko ti a fi n ko iroyin yii jọ, igbakeji aarẹ ati awọn alẹnulọrọ nipinlẹ Benue n ṣe ipade apero lọwọ nibi ti wọn ti n sọ ẹdun ọkan wọn fun un ti oun pẹlu si n tẹti lori ọna ati gba da alaafia to tọjọ pada si ipinlẹ na.
Irinṣẹ́ òǹkà ọdún ti wà láti ka iye ọdún tó leè lò láyé
Njẹ́ o mọ̀ pé, iye ọdún tó ṣeé ṣe kí gbogbo ènìyàn lò láyé, ti fi ọdún méje pọ̀ si láti ọdún 1990?
Irinṣẹ́ òǹkà ọdún yìí, yóò ràn ọ́ lọ́wọ́ láti ṣe ìṣìrò tìrẹ̀, ní ìbámu pẹ̀lú orílẹ̀èdè to ti wá.
Jọwọ yẹ ẹrọ ayelujara rẹ wo, ki o si tẹ 'show results' lati gbiyanju lẹẹkan si.
Ọdun mejilelaadọrin nireti wa pe o jẹ ọdun to kere ju ti ẹda yoo lo laye  - aadọrin ọdun fun ọkunrin, marundinlọgọrin fun obinrin. Ṣugbọn, eyi n yipada pẹlu ọjọ ori. Fun apẹẹrẹ,ireti wa pe ẹni ti o ti pe ọdun mọkandinlaadọrin yoo lo ọdun mẹtadinlogun si.
Ilé ẹjọ́ gba béèlì Dino Melaye
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ilé ẹjọ́ gba béèlì Dino Melaye
Adájọ́ tó ń dá ẹ́jọ́ ẹ̀sùn tí wọ́n fi kan Sẹ́netọ̀ tó ń sojú ẹkùn ìdìbò Ìwọ̀-oòrùn ìpínlẹ̀ Kogi, Dino Melaye ti gba onídùró rẹ̀.
Adájọ́ Nasir Ajana tó dárí bíbojú wo ìwe onídùró náà tí wọ́n fi ránsẹ́ níwájú ilé ẹjọ́ gíga ti ìlú Lokoja dá ẹjọ́ rẹ̀ lórí àrídájú tó wà nínù onídùró náà gẹ́gẹ́ bí agbẹjọ́rò rẹ̀, Agbẹjọ́rò àgbà Olóyè Mike Ozekhome se fi sọwọ́ sí ilé ẹjọ́.
Ìwé onídùró náà sọ wí pé ó ní se pẹ̀lú bí wọ́n se ti Dino mọ́le láti ọjọ́ yìí, lèyí tó ní ó le sàkóbá fún ìlera rẹ̀.
Ó ní wọn ò rí àrísá pé bí wọ́n bá gba onídùró rẹ̀, yíò sá lọ. Nítorí náà, Ajana gba onídùró Melaye pẹ̀lú mílíọ̀nù mẹ́wàá Náírà.
Ṣáájú, ilé ẹjọ gíga tíó kalẹ̀ sí Lokoja ti kọ́kọ́ sún ìdájọ́ lórí gbígba onídùró fún Dino èyí tí agbẹjọ́rò rẹ Amofin àgbà Mike Ozekhome gbé wà.
Ìdájọ tó wáyé lónìí ṣẹlẹ láì sí Dino ní ilé ẹjọ́. Ìròyìn tó tẹ̀ wá lọwọ ni pé ó ń gba ìtọ́jú ní ile Ìwòsàn National Hospital Abuja.
Ọ̀nà àbáyọ sí àìrọ́mọbí tọkùnrin tobìnrin
Saraki ni ọ̀gá ọlọ́pàá, Ibrahim Idris fẹ́ lo àwọn ọ̀daràn láti parọ́ mọ́ òun
Oríṣun àwòrán, Bukola Saraki
Sẹnetọ Bukọla Saraki ni ọga agba ọlọpa lorilẹede Naijiria, Ibrahim Idris n gbero lati hun panpẹ akoba kan fun oun
Aarẹ ile aṣofin agba, Sẹnetọ Bukọla Saraki ti ke gbajare sita pe ọga agba ọlọpa lorilẹede Naijiria, Ibrahim Idris n gbero lati hun panpẹ akoba kan fun oun.
Nigba to n sọrọ nibi ijoko ile lọjọọru, Sẹnetọ Saraki ni Ọga ọlọpa n gbero lati lo awọn afunrasi ẹlẹgbẹ okunkun kan ti ọwọ ọlọpa ba ni ilu ilọrin ti wọn si ti bẹrẹ eto ati ṣe ẹjọ wọn lati parọ mọ ohun ati awọn eekan oloṣelu kan ni ipinlẹ Kwara pe awọn ni baba isalẹ wọn.
"Iwadi ti pari, eto si ti nto lati gbe wọn lọ siwaju ile ẹjọ ni ibamu pẹlu amọran olupẹjọ agba nipinlẹ Kwara. Ṣa dede ni wọn ni ọga agba ọlọpa ni ki wọn ko wọn wa si ilu Abuja.
Iroyin ti mo si n gb ni pe wọn fẹ wa ọna ti wọn yoo fi yii akọsilẹ ti wọn kọ nilu Ilọrin pada lati fi ẹsun kan ijọba ipinlẹ Kwara, paapaajulọ emi."
Oríṣun àwòrán, Nigeria Senate
Ọ̀gá ọlọ́pàá, Ibrahim Idris àti àwọn aṣòfin ti ń gbéná wojú ara wọn fún ìgbà pípẹ́
Ile aṣofin agba kọminu lori igbesẹ yii ti wọn si ṣe apejuwe rẹ gẹgẹ bii 'iwa idunkokomọni ati ibanilorukọ jẹ.'
Ninu ọrọ to sọ, Sẹnetọ Mishau ni oun ti pe akiyesi ile si 'iwa ijẹgaba ati idunmọhuru mọni lati ileeṣẹ ọlọpaa ni nkan bii ọdun kan sẹyin pe gbogbo wa ni ọga ọlọpaa yii yoo ṣi fi oju rẹ ri rẹdẹrẹdẹ.'
Amọṣa, gbogbo awọn aṣofin agba naa lo fẹnuko pe ki ile aṣofin agba o gbe igbimọ kalẹ ti yoo lọ ṣepade pẹlu Aarẹ Buhari lori ọrọ naa.
Koko iroyin: Ọmọge Campus d'olóògbé, Ilé Aṣòfin fòǹtẹ̀ lù àbá ìsúná 2018
Eyi ni awọn akojọpọ iroyin ti toni.
Lara tiata ti Aisha se ni Omoge Campus
Gbájú-gbajà òsèré tíátà obìnrin, Aisha Abimbọla, tí ọ̀pọ̀ èèyàn mọ̀ sí ‘Ọmọge Campus’ tí jáde láyé ní orílẹ̀èdè Canada.
Aisha ni ìròyìn gbalẹ̀ kan ní ààrọ̀ ọjọ́rú lórí ìtàkùn àgbáyé pé ó ti mí kanlẹ̀ lásìkò àìsàn ọlọ́jọ́ gbọọrọ.
Ọ̀pọ̀ àwọn òsèré tíátà, tí wọn jẹ́ akẹẹgbẹ́ rẹ̀ ni wọ́n ń se ìdárò ikú ìlúmọ̀ọ́ká òsèrè tíátá obìnrin náà láwọn ojú òpó ìkànsíra ẹni wọn lórí ìtàkùn àgbáyé Facebook àti Instagram.
Ilé Aṣòfin buwọ́ lu àbá ìsúná 2018
Oríṣun àwòrán, @NGRSenate
Ile aṣofin mejeeji gbe aba naa lọ si triliọnu mẹsan o le diẹ.
Ile igbimo Aṣofin agba orilẹede Naijiria l'Abuja ti f'ọwọ si  abadofin eto isuna fun ọdun 2018 .
Tiriliọnu mẹjọ ati ẹgbẹta biliọnu, N8.61 trilion, ni aba iṣuna ti aarẹ ṣeto siwaju awọn aṣofin apapọ, ṣugbọn lẹyin ijiroro, gbogbo ẹka ile mejeeji fẹnuko si tiriliọnu mẹsan o le ọgọfa biliọnu naira, N9.12 trilion. E ka ekunrere re ni bii
IVF: Bí ẹyin àti àtọ̀ ṣe ṣe sí la fi ń mọ̀ irú ọmọ tí yóò jáde
Ọ̀nà àbáyọ sí àìrọ́mọbí tọkùnrin tobìnrin
Ìsekú pani lọ́jọ́ ìbò: Mọ̀lẹ́bí aláìsí ń bẹ Ajimọbi
Oríṣun àwòrán, @oyostategovt
Àwọn òbí ọmọ tó sàìsí ti ń késí gómìnà Abiọla Ajimọbi láti se ìdájọ́ òdodo
Ọjọ́ burúkú, èsù gbomimu ni ọjọ́ Sátidé, ọjọ́ kejìlá osù Karùn-ún, ọdún 2018 jẹ́ fún ìdílé Lateefat Abubakar, tíí se ọmọde-bìnrin ẹni ọdún méjìdínlógún tí wọn yìnbọn mọ́ ní ọjọ́ tí ìdìbò ìjọba ìbílẹ̀ ń wáyé ní ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́.
Àdúgbò Ìdí Òro ní ìlú Ìbàdàn la gbọ́ pé àwọn òsìsẹ́ ààbò ara ẹni, ni ààbò ìlú, táa mọ̀ sí Civil Defence, ti yìnbọ mọ́ ọmọdébìnrin náà lásìkò tó lọ ra òògòn fún àìlera ara rẹ̀.
Ní báyìí, ìwé ìròyìn Punch ní, àwọn òbí ọmọ náà ti ń késí gómìnà Abiọla Ajimọbi àti àwọn àjọ ajàfẹ́tọ̀ọ́ ẹni láti sèrànwọ gba ìdájọ́ òdodo lórí ikú ọmọ wọn.
Bàbá Aláìsí náà, Kọlawọle Abubakar ni gómìnà Ajimọbi gan kò tíì wá se àbẹ̀wò ìbánikẹ́dùn sí ìdílé òun.
"Àbúrò ológbèé, Gbemisọla ní ""ìdájọ́ òdodo ni à ń bèèrè. Irọ́ ńlá sì ni pé ìbọn òsìsẹ́ Civil Defence náà sèèsì yìn lásìkò tó ń bọ́ sílẹ̀ nínú ọkọ̀ rẹ̀."""
Ramadan 2018: Sultan rọ Mùsùlùmí láti gba àlààfía lááyè
Àwẹ Ramandan; Àwọn ouńjẹ tí a fi ń já àwẹ̀
Sultan ti Sokoto, Alhaji Muhammad Sa'ad Abubakar, tí ó jẹ́ adarí àjọ tí ó ń ṣàkósó ọ̀rọ̀ àwọn Musulumi jákèjádò orilẹ́ èdè Naijiria (NSCIA), ti kéde pe, Ramadan bẹ̀rẹ̀ ní Ọjọ́bọ, lẹ̀yin tí wọn rí oṣù.
Sultan náà bá àwọn akọ̀ròyin sọrọ ni ààfin rẹ̀ ni Ọjọ́rú, nibi tí ó ti rọ àwọn Musulumí jákèjádò agbaye pé, kí wọn lo àǹfàní ààwẹ̀ ọgbọn'jọ́ náà, láti fi ọkàn wọn jì fún àlàáfía.
Àlaga ajọ Musulumi naa ní agbara láti sọ ọjọ tí àwọn Mùsùlùmí Naijria lèe bẹ̀rẹ̀ ààwẹ̀, ti àwọn ti orilẹ̀ èdè míran ba tilẹ kéde ọjọ́ mìíràn.
Bákanaa ni Aarẹ Muhammadu Buhari rọ gbogbo Musulumí pe kí wọn ránti láti ran àwọn tí kò rí jẹ tó lọ́wọ́.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ààwẹ̀ náà kìí ṣe fún jíjẹ àti mímu nìkan
Ó ní ààwẹ̀ náà kìí ṣe fún jíjẹ àti mímu nìkan o.
Ẹ ó rántí wípé Saudi Arabia ló kọ́kọ́ kéde pé Ọjọ́bọ ni ààwẹ̀ ń bẹ̀rẹ̀.
Nigerian Muslims will join their counterparts across the world to commence the Ramadan fast on Thursday.
This was confirmed by the Nigeria Supreme Council for Islamic Affairs which announced the sighting of the crescent moon marking the start of the Islamic month.
PREMIUM TIMES earlier reported how Saudi Arabia had announced that the Ramadan should commence on Thursday.
During Ramadan, Muslims are expected to fast from dawn to sunset, abstaining from food and water.
Already, President Muhammadu Buhari has sent his greetings and best wishes to Muslims in Nigeria and across the world as they commence the 30-day Ramadan fast.
In his message to the nation on the beginning of the Ramadan, the president says fasting is not just merely meant to stay hungry or thirsty, but an opportunity to strive for inner purification and self-accountability.
It is meant to inculcate righteousness and discipline, he said.
He enjoined fasting Muslims to increase their love for humanity, acts of charity, kindness, generosity and gratitude. He said the Holy Prophet Muhammad used to spend very generously on the poor and the needy during this period, and urged Muslims in the country and all over the world to copy the good example.
He called on Muslims and all Nigerians to always remember men and women who are less fortunate than themselves and to help the government in confronting the challenges facing the nation.
The president prays Allah to grant all Muslims the strength to successfully complete the fasting period.
Ẹ̀bùn ọ́kọ N303m: Fún ààbò ẹ̀mí ni àbí àbẹ̀tẹ́lẹ̀?
Oríṣun àwòrán, @NigerianSenate
Ẹnu ko sin lara Ile igbimọ aṣọfin apapọ paapa julo lori iye owo ajemonu ti wọn n gba
Ẹ gbọ́ ná, iru ẹ́mi wo la lee fi  mílíọ́nù mẹ́tàlélọ́ọ̀dúnrún náírà dáàbò bo lorílè-èdè Nàìjíríà?
Ìbéèrè yìí ló ń tawọ́-tasẹ̀ nínú awọn ọmọ orilẹede Naijirià nígbà tí iroyin gbalẹ pe, Senato kan, Bassey Akpan, gbà ọkọ ayọkẹlẹ ti owo rẹ le ni ọ́ọ̀dúnrún mílíọ̀nù Náírà lọwọ oníṣòwò elépo robi kan, Babajide Ọmọkore, lati fí dáàbò bo ẹmi re.
Ọrọ naa ya yin lẹnu bii?
Loju opo itakun agbaye, awọn eeyan ti  bẹrẹ si ni so èrò ọkan wọn lai fepo-bọyọ.
Lọwọ bi a se n ko ìròyìn yìí, Senato Akpan wa ni àhámọ́ lọdọ ile iṣẹ to n gbogun ti jegudujera lorílè-èdè Nàìjíríà, EFCC.
Iwé ìròyìn Punch so pé, EFCC gbe iwadi jade pe Akpan gbé iṣẹ agbaṣe fún Omokore nigba ti ọ jẹ Komisana ètò ìṣúná n'ipinle Akwa Ibom.
Oríṣun àwòrán, FACEBOOK/Senator Oba
Senato Akpan ni oun ati Omokore tin se ọrẹ bọ ọjọ ti pẹ
"EFCC ni, abẹtẹlẹ ni àwọn ọkọ naa jẹ sugbon Senato Akpan fèsì pé, ẹbun ní àwọn ọkọ náà ti ''ọre òun Omokore"" fi  ta oun lọrẹ gẹgẹ bí ọrẹ sí ọrẹ ''."
''O ni ki n fi dáàbò èmí mi, kín sí lò wọn fún ìpolongo ìdìbò mi lodun 2014 ni ''
'Ìyapa láàrin àwa araalu àti awọn oloselu ti pọju''
Adetokunbo Mumuni, to je Olùdarí àjọ ajàfètọ́ ọmọnìyàn kàn lorílè-èdè Nàìjíríà, SERAP ní, òun ko ro wí pé lóòótọ́ ni Senato náà fe fi àwọn ọkọ naa doola ẹmi re.
O ni lópin igba ti awon alasẹ ko ba ka ààbò èmí ara ilu lapapọ kún, iru ìṣẹlẹ bayi ko ni ye máa wá yẹ.
Ọ tèsíwájú pé, inú ará ìlú kò dùn sí bí àwọn tó di ipò mu ti ṣe n gba owo tabua, ti àwọn ará ìlú mi kò sí ri oúnjẹ jẹ.
Oríṣun àwòrán, @ShehuSani
Shehu Sani tu kẹkẹ ọrọ silẹ lori iye owo ti awọn asofin Naijiria n gba
Laipe yi ni Sẹnatọ kan, Shehu Sani tu asiri awọn asofin nipa miliọnu mẹtala ati aabọ naira ti wọn gba lososu.
Eyi naa kun idi ti awon omo Naijiria fi n kominu lori ohun to mu Senato Akpan gba ọkọ ayokele lati fi daabo bo ẹmi re
''A ní ki wọn wà jẹun ní ṣùgbọ́n n'isẹ ni wọn mú wà lọwọ sí lẹ. Mo mọ wí pé àwọn ọmọ orílèèdè yii n kẹ ìrora ṣugbọn ariwo won ko ti lagbara dé ibi kí wọn mu iyipada wa.''
O wa parọwa si ara ilu pe ki wọn má kaare ọkan nipa ijiroro eleyi ti yóò ''pé àkíyèsí sí bí wọn ti ṣe lè mú ìyípadà wa.''
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí:
Olósèlú: Àpótí Sobàtà bíi èèlò ìróni-lágbára sàn ju ebi lọ
Oríṣun àwòrán, Babawo
Babawo se siọ̀ awọn eeyan to n bu ẹnu atẹ lu igbesẹ rẹ naa lori itakun agbaye
Ọ̀pọ ọmọ Naijiria la ẹnu silẹ lai lee pa de nigbati Kọmisana feto ẹkọ giga ni ipinlẹ Borno,Usman Jaha Babawo, pin awọn ohun eelo ironi lagbara fawọn ọdọ to wa lẹkun idibo rẹ.
Kii kuku se awọn ohun eelo to pin lo n se awọn araalu ni haa-hin, bi ko se irufẹ awọn ohun eelo naa, eyi to n kọ wọn lominu.
Lara awọn ohun eelo naa lati ri apoti sobata, burọọṣi inubata, ori inubata, taa mọ si pọliiṣi ati fukẹ́-fukẹ́ inubata, taa mọ̀ si foam, asọ, mọto ati ẹrọ iransọ.
Oríṣun àwòrán, Facebook
Oniruuru awọn eroja apanilẹrin lawọn oloselu maa n pin bii ohun eelo aroni lagbara
Taa ba si wo daada, kii se Babawo ni yoo kọ̀kọ̀ pin awọn ẹbun ironi laagbara ti yoo kọ awọn ọmọ Naijiria ni ominu bayii, nitori a ti gbọ nipa awọn oloselu ati awọn gomina kan ti wọn ti kọkọ pin awọn ohun eelo ironi lagbara bii tii alagbada, taa mọ si Lipton tea, eroja Noodles, ẹyin adiẹ, garawa ipọnmi ati ọmọ-lanke ti wọn n pe ni wheel barrow.
Bẹẹ ba si gbagbe, gomina ipinlẹ Benue, Samuel Ortom naa ti pin ọmọlanke ri fawọn eeyan ipinlẹ rẹ bii ohun eelo ironi-lagbara, eyiti okiki rẹ gbalẹ kan nigba naa.
Eyi lo wa mu ki BBC Yoruba kan si araalu kan lati beere pe oju wo lo fi wo igbesẹ yii ? N jẹ iwa ipese idẹrun fun araalu ni eyi abi iwa tita abuku wọn.
Lero ti Alagba Olu Israel, apa oke ọya ni iwa pinpin awọn ohun eelo ironi lagbara to jẹ kayeefi yii wa, ọna lati jẹ gaba lori awọn araalu si ni.
Ẹ gbọ Alagba israel siwaju sii.
Èèlò ìróni-lágbára, fún ìdẹ́rùn ni àbí àbùkù
Niwọn igba to jẹ pe a gbọ́ ẹjọ ẹnikan da, agba osika ni. Ọna lati mase role apakan, da apakan si, lo mu ki BBC Yoruba kan si Kọmisana to pin apoti sobata naa ni ipinlẹ Borno, Hon Babawo.
Oríṣun àwòrán, Babawo
Babawo ni ko si ohun to buru ninu apoti sobata ti ohun pin
Lero tiẹ́, o ni ko si ohun to buru ninu apoti sobata ti ohun pin yii, nitori ohun ti awọn ọdọ naa n fẹ ni eyi, wọn si mọọmọ beere lọwọ ohun ni.
Babawo ni miliọnu mẹta naira ni oun na lori ipese awọn eroja sobata naa, fawọn ọdọ yii, ti wọn jẹ ọmọ orukan, ti ogun Boko Haram ti pa awọn obi wọn.
Oríṣun àwòrán, Babawo
Babawo ni miliọnu mẹta naira ni oun na lori ipese awọn eroja sobata
Ko sai wa se siọ̀ awọn eeyan to n bu ẹnu atẹ lu igbesẹ rẹ naa lori itakun agbaye, to si ni ailaju lo n da irufẹ awọn eeyan yii laamu nitori awọn eeyan to n so bata gan wa lawọn orilẹede to ti goke agba bii Amerika, canada, ati Gẹẹsi.
L'Ógùn, Ọlọ́pàá mú olùkọ́ mẹ́ta fún síso akẹ́kọ̀ọ́ mọ́gi
Oríṣun àwòrán, Naija parrot
Awọn olukọ ọhun tun kọlu awọn ọlọpaa meji ti wọn gbiyanju ati dawọn lẹkun iwa ọhun.
Ileeṣẹ ọlọpaa nipinlẹ Ogun ti mu awọn alaṣẹ ileekọ kan si ahamọ bayii, lori ẹsun pe wọn gbe awọn akẹkọ kan kọ sori igi, nitori pe wọn pẹ de ileewe.
Okiki kan loju opo ikansira ẹni lori itakun agbaye ni ọjọ iṣẹgun, nigbati iroyin nipa awọn alaṣẹ ileewe aladani kan ni agbegbe kan nipinlẹ Ogun, ti wọn gbe awọn akẹkọ kan to pẹ de ileewe kọ igi, gẹgẹ bii ijiya fun iwa apẹlẹyin wọn.
Haa-hin ni ọrọ ọhun n ṣe ọpọ eeyan ṣugbọn ileeṣẹ ọlọpa nipinlẹ Ogun sọ wi pe, awọn olukọ ti ọrọ kan titi de ori ẹni to ni ileewe naa, ni wọn ti ko, ti wọn si ti n wi tẹnu wọn niwaju awọn ọlọpa ẹka ọtẹlẹmuyẹ ni ilu Abẹokuta.
Ọmọge Campus: Lọla Alao ní ẹbí Aisha kò tọrọ owó
Alukoro fun ileeṣẹ Ọlọpaa nipinlẹ Ogun, DSP Abimbọla Oyeyẹmi ṣalaye fun BBC Yoruba pe, eeyan mẹta lo wa ni ahamọ Ọlọpaa lori ọrọ naa.
Lootọ ni iṣẹlẹ yii waye. Ẹni to ni ileewe aladani yii, Ọga agba ileewe naa pẹlu olukọ kan ti wa lahamọ bayii. Wọn si maa foju ba ile ẹjọ laipẹ.
Kíni ohun tí Kọmíṣọ́nà fétò ẹ̀kọ́ nípínlẹ̀ Ògùn sọ?
Amọṣa ijọba ipinlẹ Ogun ko tii sọ ohunkohun si ọrọ ọhun.
Nigba ti BBC Yoruba kan si Kọmisọna feto ẹkọ nipinlẹ Ogun, Arabinrin Modupẹ Mojota, o ni ọrọ ọhun ṣajeji si ileeṣẹ eto ẹkọ, paapaa julọ pẹlu igbesẹ gbogbo ti ijọba n gbe lati rii pe, amojuto to peye wa fawọn ileẹkọ.
Awọn oṣiṣẹ wa ti bẹrẹ iwadi lori rẹ nitori laarọ yii lawa naa gbọ nipa rẹ. Mo fẹ kẹẹ mọ pe awọn nkan to yẹ lo n lọ labẹnu, lati mu eto ẹkọ nipinlẹ Ogun wu oju ri. Bi o ti lẹ jẹ wi pe ileewe aladani leyi ti ṣẹlẹ, sibẹ igbesẹ to tọ yoo waye, ni kete ti mo ba ti gba ẹkunrẹrẹ abajade iwadi lori ọrọ naa.
Bakannaa ni alukoro ileeṣẹ ọlọpa nipinlẹ Ogun, Abimbọla Oyeyẹmi, tun fi idi rẹ mulẹ pe, awọn eeyan ọhun tun kọlu awọn ọlọpaa meji ti wọn gbiyanju ati dawọn lẹkun lori iwa ọhun.
O ni, awọn ọlọpa mejeeji wa lalafia lẹyin ti ọga ọlọpaa fun agọ ọlọpa to wa ni agbegbe naa atawọn ọlọpaa abẹ rẹ, sare kan si ileewe naa lati gba wọn silẹ.
Awọn ọlọpa mejeeji gbiyanju lati tu awọn akẹkọ naa silẹ nibi ti wọn so wọn kọ, ṣugbọn awọn alaṣẹ ileewe naa rii igbesẹ wọn gẹgẹ bii eyi ti ko tọna, ni wọn ba tun kọ oju si awọn ọlọpaa, ti wọn si lu wọn bi ẹni lu bara, ki o to di wi pe ọga ọlọpaa agbegbe naa de ibẹ lati gbawọn silẹ.
FIFA: Super Eagles bọ́ sí ipò kẹrin ní Afrika
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Orílẹ̀èdè Germany ló ń léwájú lórí atẹ ìgbéléwọ̀n FIFA
Ipo kẹtadinlaadọta ni orilẹede ẹgbẹ agbabọọlu Super eagles Naijiria  ṣi wa, lori atẹ igbelewọn awọn orilẹede to n gba bọọlu lagbaye fun oṣu karun eleyii to jade lọjọbọ.
Amọ ni ilẹ Afirika, ipo kẹrin ni Super Eagles sun si bayii lati ipo kẹfa ti wọn wa tẹlẹ.
Awọn ikọ agbabọọlu orilẹede Argentina, Croastia ati Iceland ti Super Eagles yoo koju, ni idije ife ẹyẹ agbaye wa ni ipo karun-un, ikejidinlogun ati ikejilelogun ni ṣisẹ n tẹle, lori atẹ igbelewọn awọn orilẹede to n gba bọọlu lagbaye.
Orilẹede Germany lo ṣi n gbe ipo kinni, ti brazil si n tẹle e.
NDLEA: A kò tíì mọ àwọn tó ni Tramadol náà
Oríṣun àwòrán, NDLEA/Twitter
Àjọ NDLEA ti gbésèlé tọ́ọ̀nù mẹ́rin Tramadol
Àjọ NDLEA ti gbésèlé tọ́ọ̀nù mẹ́rin Tramadol ní pápákọ̀ òfurufú Muritala Mohammed ìlú Èkó, bẹẹ ni ìjọba ṣẹ̀ṣẹ̀ pàṣẹ pé kò gbọdọ̀ sí lórí àtẹ mọ́,
Ọ̀gá àgbà àjọ NDLEA, Ahmadu Garba ló sàlàyé ọ̀rọ̀ ọ̀hún, fún àwọn akọròyìn pé ọ̀nà méjì ni wọ́n gbé tramadol òhún gbà wọ inú ìlú láti orílẹ̀-èdè India, tí àwọn sì ríi gbà ní ibùdó ìkẹ̀rùsí ilé iṣẹ́ náà tó wà ní pápákọ̀ òfurufú ìlú Èkó.
Gẹ́gẹ́ bó ṣe sọ, àjọ NDLEA kò ní oore ọ̀fẹ́ láti mọ àwọn tó fi òògun òhún ráńṣẹ́, bákan náà kò sí ẹnikẹ́ni tó wá láti gba a kúrò ní pápákọ̀ òfurufú.
Garba ní àjọ ọ̀tẹlẹ̀múyẹ́ tí àwọn jọ ń ṣiṣẹ́ pọ̀, ló ta àjọ òun lólobó nípà òògùn Tramadol tó fẹ́ wọlé pèlú ọkọ̀ òfurufú United Arab Emirate.
Oríṣun àwòrán, NDLEA/Twitter
Garba ní àjọ ọ̀tẹlẹ̀mú tí àwọn jọ ń ṣiṣẹ́ pọ̀ ló ta àjọ òhun lólobó nípà òògùn Tramadol tó fẹ́ wọlé
Ó sàlàyé pé, àjọ NDLEA ti gbésẹ̀lé kílò òògùn olóró mẹ́tàdínláàdọ́rún-ún láàárín oṣù kínní ọdún sí oṣù kẹrin ọdún yìí.
Ìgbéyàwó Ọmọọba: Ọjọ́ márùn-ún ni wọn fi se àkàrà òyìnbó
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ìgbéyàwó Ọmọọba Ìlẹ̀ Gẹ̀ẹ́sì Harry àti ìyàwó rẹ̀ yóò wáyé lọ́la
Ìrọ́-kẹ̀kẹ̀ ti gbode kan ní ilẹ̀ Gẹ̀ẹ́sì ní báyìí tí ìgbaradì ti dé ojú ọ̀gbagadè fún ìgbeyàwó Ọmọọba ilẹ̀ Gẹ̀ẹ́sì, Harry àti ìyàwó rẹ̀, Meghan Markle.
Bí ìmúrasílẹ̀ ìgbéyàwó náà ṣe n kásẹ̀ nlẹ̀ di ọjọ́ Àbámẹ́ta báyìí, kò tíì sí ẹni tí yóò dúró gẹ́gẹ́bíi bàbá ìyàwó ni ibi àyẹyẹ náà, tí yóò wáyé ni ilé ìjọsìn St. George.
Ìyawó ọ̀la, Meghan Markl,e gbé àtẹ̀jáde kan síta ní Ọjọ́bọ pe bàbá òun, Thomas Markle, kò ní lè wá sí ibi ìgbéyàwó náà, kó bàá lè tọ́jú ara reẹ̀.
A gbọ́ pé ìyá ìyàwó Doria Ragland, yóò lọ kí Ọbabìnrin Elizabeth fún ìgbá kínní lónìí.
Ní báyìí ná, wọ́n ti gbé fọ́tò àkàrà òyìnbó tí ọgọ́rùń mẹ́fà àwọn àlejò Ọmọọba ilẹ̀ Gẹ̀ẹ́sì, Harry àti ìyàwó rẹ̀, Meghan Markle yóò jẹ, ní ibi ìgbéyàwó wọn ti yóò wáyé lọ́la jáde báyìí.
Oríṣun àwòrán, PA
Claire Ptak ń ṣiṣẹ́ lórí àkàrà òyìnbó náà
Fọ́tò náà ṣe àfihan Claire Ptak, tó ń ṣiṣẹ́ lórí àkàrà òyìnbó náà nínú ilé ìdáná ààfin Ọbabìnrin Elizabeth, ti a mọ̀ sí Buckingham Palace ni ọjọ́ Ọjọ́bọ.
Ọjọ́ márùń ni la gbọ́ pe Ptak àti àwọn òṣìṣẹ́ rẹ̀ mẹ́fà ti ń ṣiṣẹ́ lórí àkàrà òyìnbó náà.
Oríṣun àwòrán, PA
The cake is being decorated with a white, elderflower Swiss meringue buttercream
Amofin: Owó ni ìjọba ìpínlẹ̀ ń jà fún nídi ètò ìgbeyàwó
Awuyewuye wà lórí ṣiṣe igbéyàwó ni kọ́ọ́tù Ìkòyi
Ìpinlẹ̀ Èkó ti gba idájọ kan, tí ó ká ọwọ ìjọba àpapọ̀ kò láti so àwọn tọkọtaya pọ ní kọ́ọ́tù magisireti Ìkòyi, ni ilu Eko.
Adájọ́ Chuka Austine Obiozor, tí ó dá ẹjọ́ náà ni, ṣíṣe igbéyàwó ní kọ́ọ́tù Ìkòyi lódì sófin o, nítori pé, ìjọba ìbílẹ̀ àti ìjọba ìpínlẹ̀ nikan ni ó ní agbára láti ṣe irú ojúṣe bẹ́ẹ̀.
O fikun pe, kiki da igbeyawo ti awọn lọkọ-laya ba se ni awọn kootu to wa labẹ ijọba ipinlẹ ati ijọba ibilẹ nikan lo duro labẹ ofin, amọ igbeyawo ti kootu ijọba apapọ ba so pọ, ofuutu-fẹẹtẹ, aasa ti ko ni kaun ni.
Nigba to wa n ba awọn akọroyin sọrọ lẹyin iodajọ naa, Kọmíṣọnà fún ọrọ ìjọba ìbílẹ̀ ní Ìpinlẹ̀ Èkó, Muslim Folami ẹni to sọ igun ti ijọba ipinlẹ Eko kọ si idajọ yii ní, ìjọba yóò kéde ìdájọ tuntun náà fun gbogbo àwọn ilé iṣẹ́ asoju orílẹ̀ èdè okeere tó wà ní Naijria.
Kọ́ọ́tù majisireti Ìkòyi ní okìkí púpọ nitori ibẹ̀ ni àwọn tí o fẹ́ gbéyàwó nlò julọ, ìwé ẹrí tí wọ́n bá fun àwọn lọ́kọláya nibẹ lo jẹ ìtẹ́wọgbà ni àwọn ilé iṣẹ́ asoju orílẹ̀ èdè lagbaye nigbá tí àwọn ènìyàn bá fẹ́ lọ sòkè òkun.
Kín ní ìdájọ náà tumọ sí fún àwọn to ti segbeyawo sẹyin nibẹ?
Eyí tí ó wá mu awuyewuye wá lórí ìdájọ́ yìí ni pé, o dabi ẹni pe awọn ileẹjọ ti n tako ara wọn, nitori ìlé ẹjọ́ kan ní Ìpínlẹ̀ Èkó ti kọ́kọ́ dájọ́ pé, àwọn  ìjọba ìbílẹ̀ àti ìjọba ìpínlẹ̀ kò ní agbára láti fún àwọn ènìyàn ní ìwé ẹ̀rí ìgbéyàwó.
Idi ree ti ikọ BBC Yoruba se kan si amofin kan lati mọ ẹka isejọba ti ofin gbe isẹ idapọ lọkọ-laya le lọwọ. Se ijọba apapọ ni, abi tipinlẹ abi awọn ijọba ipinlẹ.
Amòfin Alfred Akinjo, tí ó jẹ onímọ̀ ofin ìgbéyawó ní Ìpinlẹ̀ Èkó ń jà fún owó tí ó yẹ kí ó wọ àpo rẹ ni, nitori lọwọ-lọwọ ba yii, ẹ́gbẹrun mẹẹdọgbọn naira ni lọ́kọ-laya kan n san lati se igbeyawo nibẹ.
Ni ojoojumọ, ogunlọgọ àwọn tọkọtaya si lọ máa ń wá fún igbéyàwó ní ibẹ̀.
Ile ejo kan ti so ni odun to koja pe ijoba ipinle ati ibile ko le se igbeyawo
Gómìnà rè sodò nì Kenya nígbà tó ń ya fọ́tò ara rẹ̀
Oríṣun àwòrán, @BarakaFmKe
Gómìnà Mutua, igbakeji rẹ àti àwọn akoroyin lára àwọn tó já sodo nígbà tí afárá náà já
Ọrọ burúkú tòun ẹrín. Afárá já Gómìnà já sodo.
Ṣókí ìròyìn kayefi yíi ree láti orileede Kenya níbi tí Gómìnà Alfred Mutua ti agbegbe Machakos àti àwọn akoroyin méjì, tí wọn já sodo nigba ti afárá tí Gómìnà wa se ìfilọ́lẹ̀ rẹ já.
Ṣugbọn Gómìnà Mutua ní ọrọ̀ kò ri bẹẹ.
Bákannáà lójú òpó Twitter rẹ, Gomina Mutua fi ìkìlọ sita pe, oun yóò pé ẹnikẹ́ni to bá gbé ìròyìn eleje nipa ìṣẹlẹ náà lẹjọ.
Ẹfẹ tóun yèyé ní àwọn ọmọ Kenya tun fí da esi pada fún-un lórí Twitter .
Àwọn kan ni, kàkà kí o kọjú mọ awọn tó ṣe iṣẹ ajambaku lórí afárá to já, n sẹ ní ọ n dùn kọkọ mọ àwọn akoroyin.
Èyí kìí ṣe àkọkọ ikọlu láàrin àwọn ará ìlú àti Gómìnà Mutua.
Lai pẹ yi ni ile isẹ iròyìn kan kọ si oju opo Twitter rẹ pe,  Mutua sọ pe ''àwọn ilé ìwòsan ti mo kọ, lo mọ jùlọ lorílè-èdè  Kenya.''
Ka ṣáà dúpẹ pé, kò sí èmí to ba isẹlẹ naa rin.
Ìgbéyàwó Ọmọọba Harry àti Meghan Sparkle yóò wáyé ní Windsor
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ẹgbẹlẹgbẹ awọn eeyan kaakiri agbaye ni yoo wo igbeyawo naa
Ẹgbẹlẹgbẹ awọn eeyan kaakiri agbaye ni yoo wo igbeyawo laarin ọmọọba ilẹ Gẹẹsi, Harry ati omidan meghan Sparkle ni ilu Windsor.
Ọkẹ aimoye awọn eeyan lo da orun mọju lawọn opopona ilu Windsor lọna ati lee duro si ọgangan ibi ti iran yoo ti dun un wo lasiko ti igbeyawo naa baa n waye lọjọ abamẹta.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ọsan gangan ni igbeyawo naa yoo waye ni ileejọsin St George's Chapel
Ọsan gangan ni igbeyawo naa yoo waye ni ileejọsin St George's Chapel to wa ni Windsor ki wọn to gunle irinajo ẹyẹ lori kẹkẹ ẹ'sin kaakiri ilu naa ni nkan bii aago kan ssan.
Ọmọọba Charles to jẹ baba ọkọ iyawo, Harry ni yoo tẹwọ gba iyawo lọ siwaju awọn alufaa lẹyin ti baba iyawo, arakunrin Thomas Markle ko lee farahan nibi igbeyawo naa nitori ailera rẹ.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ọmọọba Harry àti omidan Sparkle yóò ṣe ìgbéyàwó
Ni oojọ, igbeyawo ku ọla, Ọmọọba Harry sọ f'awọn  ero to peju si Windsor pe ko si ifoya fun oun lori igbeyawo naa, bakanna si ni omidan Markle pẹlu ni ṣẹṣẹ ni inu oun n dun.
Ìgbéyàwó Harry àti Markle: Ẹni ńlá ní ń ṣe ohun ńlá
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ẹgbẹfa awọn araalu ni yoo kopa nibi eto igbeyawo naa
Kaakiri agbaye ni okiki yoo ti kan ni ọjọ abamẹta ti Ọmọọba Harry ati Omidan Meghan Markle ba ṣe'gbeyawo wọn ni ilu Windsor nilẹ Gẹẹsi.
Lootọ ilu mọọka ni igbeyawo naa yoo jẹ, ṣugbọn awọn ohun kan wa ti o yẹ ki o mọ nipa igbeyawo yii.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ọgbẹni Thomas to jẹ baba Meghan Markle ko lee farahan nibi igbeyawo naa nitori ailera ara rẹ
Nigba ti asiko ati fi aya fun ọkọ ba to, ma ṣe foya nigba ti o ba gbọ, 'mo gbe iwọ Rachel niyawo' nitori Meghan ni ọpọ mọ orukọ iyawo si.
Orukọ akọkọ ti omidan Meghan n jẹ ni Rachel ṣugbọn ni ẹnu iṣẹ rẹ gẹgẹ bii gbajugbaja oṣiṣẹ mohunmaworan ni orilẹede Amẹrika, orukọ rẹ keji lo mu lọkunkundun ni jijẹ, ohun si ni ọpọ eniyan mọọ mọ.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Kaakiri agbaye ni okiki ti kan de nípa igbeyawo Ọmọọba Harry ati Omidan Meghan
Henry boo? Ni ibeere to ṣeese ko gba ẹnu awọn eeyan pupọ nitori Harry ni wọn mọ orukọ ọkọ iyawo ọjọ abamẹta si.
Ẹ maa foya, apeja orukọ ọmọọba Harry ni Henry Charles Albert David ti ilu Wales, ṣugbọn orukọ ti gbogbo wa mọọ si ni Ọmọọba Harry.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
"Orukọ oye tuntun, ""Duke of Sussex"" ni o ṣeeṣe ki wọn fun Ọmọọba Harry lẹyin igbeyawo yii"
Gẹgẹ bii aṣa ilẹ Gẹẹsi, o ṣeeṣe ki orukọ ọkọ iyawo ati iyawo rẹ o yi pada lẹyin igbeyawo wọn.
"Orukọ oye tuntun, ""Duke of Sussex"" ni o ṣeeṣe ki wọn fun Ọmọọba Harry nigbati iyawo rẹ, Meghan yoo di ""Duchess of Sussex""."
Oríṣun àwòrán, OLI SCARFF
baba ọkọ ni yoo fi iyawo fun ọmọ rẹ dipo baba iyawo
Lara awọn wọnyii ni Ọmọọbakunrin Goerge ati Ọmọọbabinrin Chalotte yoo wa.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
O ṣeeṣe ki orukọ ọkọ iyawo ati iyawo rẹ o yi pada lẹyin igbeyawo yii
Bẹẹni, ẹ maa jẹ ko ya yin lẹnu pe baba ọkọ ni yoo fi iyawo fun ọmọ rẹ dipo baba iyawo.
Ọgbẹni Thomas to jẹ baba Meghan Markle ko lee farahan nibi igbeyawo naa nitori ailera ara rẹ. Lootọ awọn eeyan kan daaro pe boya ki iya rẹ o gba ipo yii, ṣugbọn lẹyin ọpọlọpọ ijiroro ni wọn ni ki Ọbalọla, iyẹn ọmọọba Charles to jẹ baba ọkọ iyawo o mu iyawo wọ ileejọsin lati faa le awọn alufaa lọwọ.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ìrọ́-kẹ̀kẹ̀ ìgbeyàwó Ọmọọba ilẹ̀ Gẹ̀ẹ́sì, Harry àti ìyàwó rẹ̀, Meghan Markle ti gbalé kan ní ilẹ̀ Gẹ̀ẹ́sì
Ẹgbẹfa awọn araalu ni yoo kopa nibi eto igbeyawo naa. Eyi si yatọ si awọn ọtọkulu kaakiri agbaye ti awọn pẹlu yoo peju sibi eto igbeyawo naa.
Ìran Ọba ilẹ̀ Gẹ̀ẹ́sì dúpẹ́ lọ́wọ́ gbogbo ènìyàn
Oríṣun àwòrán, Elvis
Ìdílé Ọba dúpẹ́ lọ́wọ́ gbogbo ènìyàn
Ìdílé òyè ilẹ̀ Gẹ̀ẹ́sì ti fi ọ̀rọ̀ ọpẹ́ ránsẹ́ sí gbogbo àwọn tó rìnrìnàjò lọ sí Windsor fún ìgbéyàwó ọmọọba Harry pẹ̀lú Meghan Markle.
Ẹgbẹgbẹ̀rún ènìyàn ló tò sójú ọ̀nà tí wọ́n tún sun ojú pópó mọ́jú fún ìgbéyàwó náà láti rí tọkọtaya lọ́jọ́ ẹ̀yẹ wọn tí ọ̀pọ̀lọpọ̀ sì ń wò ó lórí ẹ̀rọ móhùnmáwòrán káàkiri àgbáyé.
Wọn se àsekágbá ìgbéyàwó náà pẹ̀lú àsálẹ́ wẹ̀jẹwẹ̀mu ní ilé Frogmore lẹ́bá Windsor Castle níbí tí  ìdùnú àti ayọ̀ ti búyọ lójú gbogbo ènìyàn.
Àwọn ọ̀rẹ́ Meghan àti Harry tó wá síbi àpèjẹ náà jẹ́ igba pẹ̀lú àwọn mọ̀lẹ́bí wọn.
Oríṣun àwòrán, ELVIS/FACUNDO ARRIZABALAGA
Ọmọọba Harry àti Meghan lọ́nà gbọ̀ngàn àpèjẹ
Ìròyín tó ni léti wí pé ọkọ àti aya kò tíì ní rìnrìnàjò alárédè ní kíákíá sùgbọ́n wọ́n yàn láti ṣì wà ní ilẹ̀ United Kingdom kí wọ́n tó lọ fún ìsinmi.
Ọmọọba Harry fún aya rẹ̀ ní òrùka gẹ́gẹ́ bí ẹ̀bùn èyí tó se pé ìyá rẹ̀ olóògbé Ọmọọ̀babìnrin Wales, Diana ló ni í.
Ìdílé ọba nílẹ̀ Gẹ̀ẹ́sì fi ọ̀rọ̀ jáde lórí ìtàkùn Twitter wọn wípé àwọn dúpẹ́ lọ́wọ́ gbogbo àwọn tó kópa nínú ìgbéyàwó náà láti ilẹ̀ UK, àjọ ìsskan àgbáyé Commonwealth àti láti káàkiri àgbáyé.
Ìdìbò 2019: Fani-Kayode ní kí Buhari gbáradì fún ìfẹ̀yìntì
ọ̀rọ̀ ń bọ́ mokó morò bọ̀ lórí ìdìbò ààrẹ ọdún 2019
Minisita tẹlẹ ri fun ile iṣẹ ọkọ ofurufu lorilẹede Naijiria Femi Fani-Kayode ti sọ fun Aarẹ Muhammadu Buhari pe ko mura silẹ fun ifẹyinti lọdun 2019.
Fani-kayode sọrọ naa loju opo Twitter rẹ nigba ti o n ki Atiku Abubakar ku oriire lẹyin ti o jawe olubori gẹgẹ oludije fun ipo Aarẹ labẹ asia ẹgbẹ oselu PDP lọjọ Aiku.
O fi kun ọrọ rẹ pe ki ẹgbẹ oselu APC mu ra silẹ fun ogun ninu idibo Aarẹ ọdun 2019.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí:
Ẹwẹ, Aarẹ Muhammadu Buhari ti kí àwọn olùdíje ẹgbẹ APC ni kakakiri orilẹede Naijiria ku oriire, bẹẹ ni o tun rọ wọn ki wọn ma ṣe binu si ara wọn.
Atẹjade kan lati ọwọ agbẹnusọ rẹ Garba Shehu rọ awọn ọmọ ẹgbẹ lati ma sa kuro ninu ẹgbẹ nitori pe wọn ko wọle ninu idibo abẹle ẹgbẹ APC.
Aarẹ Buhari ni oun ṣetan lati ṣe ijọba lai fi ti ẹ̀yà kankan ṣe
Àárọ ọjọ Aiku ni iyawo aarẹ Aisha Buhari fi ẹhonu han nitori pe o ni awọn idibo abẹle ẹgbẹ oṣelu APC ko lọ deede. O sọ ninu ọrọ rẹ wipe, o to ki eeyan yéra fun ẹgbẹ oṣelu naa.
'Ẹ wo àwokọṣe Ambode'
"Atẹjade aarẹ ni,""Ninu idije, eniyan kan a bori, ẹlomiran a ja kulẹ. Ṣugbọn awọn to ja kule ko gbọdọ sa kuro ninu ẹgbẹ taki ki inu wọn ma dun si ẹgbẹ mọ. Awọn oloṣelu gbọdọ fi ti Gomina Akinwunmi Ambode ti Ipinlẹ Eko kọgbọn. Bo tilẹ jẹ pe o ja kulẹ, ko fi ibinu sa kuro ninu ẹgbẹ."""
Ṣaaju, Aarẹ Buhari ni ina ijọba ti gbooro si, awọn ti sẹgun Boko Haram de ibi to lamilaaka ati pe eto isuna fun awọn onisowo n ran ọpọlọpọ eniyan lọwọ.
Aarẹ naa wa fikun pe awọn ko ni kawọ gbera ti awọn ba wọle ẹlẹẹkeji, ati pe oju rere ti awọn ara oke fi n wo orilẹ-ede Naijiria bayiii yoo tẹsiwaju.
Ẹgbẹ̀rún méje aṣojú ti yan Buhari lẹyin ti awọn ọmọ ẹgbẹ ti kọkọ dibo to ti ni 14, 842, 072 ìbò ki wọn to wa kéde rẹ̀ bayii ni Eagle Square.
Aare Buhari yoo ni anfani lati dije lẹẹkansii gégé bii aarẹ Naijiria
Buhari ni yoo dije dupò pẹlu ẹnikẹni ti ẹgbẹ oṣelu PDP bá fa kalẹ atawọn ẹgbẹ oṣelu to ba kù ninu ẹgbe mokanlelọgọrun ti ajọ eleto idibo INEC kede.
Awọn ẹgbẹrun meje aṣoju ni yoo yan Aarẹ Buhari
Àago mọ́kànlá alẹ́ ni ìdìbò abẹ́lé ti ẹgbẹ oṣelu APC ti o n waye ni Eagle Square, ni ilu Abuja yoo bẹ̀rẹ̀ nibi ti fi ontẹ lu Aarẹ Muhammadu Buhari gẹgẹbii ẹni ti yoo dije du'po aarẹ labẹ aṣia ẹgbẹ oselu naa ni ọdun 2019.
Buhari nikan ni ẹgbẹ oṣelu naa fa kalẹ lati dije.
Bẹẹ ni nilu Eko, Sẹ́nétọ̀ Gbenga Ashafa ti já kulẹ̀ nínú ìdíje abẹ́le ti ẹgbẹ oṣelu APC fun ipo aṣoju ẹkùn ilà oorùn Eko (Lagos East) ni Ilé Ìgbìmọ̀ Aṣòfin Àgbà.
Bayo Oshinowo ní ìbò 247,743 nigba t Gbenga Ashafa ní ìbò 20,385
Alatako rẹ Bayo Oshinowo ní ìbò 247,743 nigba ti Ashafa ni ibo 20,385.
Bakan naa, Olamilekan Solomon (Iwọ oorun) jawe olu bori pẹlu ibo 378,906 nigba ti alatako rẹ Kayode Opeifa ni ibo 1,179.
Nitori naa, àwọn sẹnetọ ti yóò díje ni APC Eko ni Rẹmi Tinubu (Aarin gbungbun) Olalekan Yayi (Iwọ oorun) àti Bayo Oṣinọwọ (Ila oorun).
Remi Tinubu yoo jade laini alatako kankan ninu idibo abẹle ẹgbẹ APC naa.
Bakan naa, ẹgbẹ oselu APC ti sun ipade gbogboogbo rẹ si iwaju di irọlẹ Ọjọ Kẹfa, Ọsu Kẹwa, ọdun 2018.
Ninu atẹjade ti ẹgbẹ APC fi sita ni ọjọ ipade naa sọ pe wọn gbe igbese naa ki awọn eniyan to n bọ lati awọn ipinlẹ le de ibi ti ipade naa yoo ti waye lasiko.
Atejade naa ni awọn asoju lati ipinlẹ kọọkan yoo se ayẹwo kaadi ẹgbẹ wọn ni papa isere Old Parade Ground labuja ki wọn to wa peju si Eagles Square nibi ti ipade naa yoo ti waye.
Eto idibo abẹle ni ẹgbẹ APC ipinlẹ Jigawa:
Gomina Badaru ti ipinlẹ Jigawa lo jawe olubori gẹgẹ bi oludije sipo gomina labẹ asia ẹgbẹ oṣelu APC ni ipinlẹ Jigawa.
Oríṣun àwòrán, @Saifullahi_Abas
Gomina Badaru Abubakar
Apapọ ibo ẹgbẹrun mẹta le mẹtalelọgọfa, 3123 lati fẹyin Ubale Hashin to ni ibo mẹrinlelaadọta, 54. Kiiṣe ilana tuntun ti ẹgbẹ APC gbekalẹ ni wọn lo fun eto idibo naa.
APC primary: Nkan kò tìí ṣẹnu ire fún àná Gómìnà Rochas ní Imo
Ọkọ ọmọ Rochas Okorocha to jẹ gomina ipinlẹ Imo, Uche Nwosu, ti padanu ni wọọdu kan ninu idibo abẹlẹ APC fun oludije si ipo gomina.
Iroyin to tẹ wa lọwọ sọ wi pe ko si ẹni to dibo fun Nwosu ni wọọdu naa.
Oludije keji Hope Uzodinma to jẹ ọmọ wọọdu kan naa pẹlu Nwodu lo gba gbogbo ibo aadọrun naa.
Oludije keji, Hope Uzodinm, a to jẹ ọmọ wọọdu kan naa pẹlu Nwodu lo gba gbogbo ibo aadọrun naa.
Idibo naa waye ni ile ẹkọ alakọbẹrẹ Unity Primary School, Umuchoke Amaigbo ni ipinlẹ Imo.
Awọn oludibo ṣi n duro lati dibo ni wọọdu Okorocha to jẹ gomina ipinlẹ Imo.
Ètò ìdìbò abẹ́lé ẹgbẹ́ òṣèlú All Progressives Congress n lọ jákè-jádò àwọn ìpínlẹ̀ ní Nàìjíríà yàtò si Eko, àti Imo.
Wan ni kí alága APC ní Ìpínlẹ̀ Kwara lọ rọ́ kún ńlé
Bósẹnlọ l'áwọn ìpínlẹ̀:
Rivers:
Awọn ẹka ti Abe ti n dibo lọ nipa lilo ìbò gboogbo ti yoo fun gbogbo awọn ọmọ ẹgbẹ laaye lati dibo nigba ti awọn ẹka ti Rotimi Amaechi n péjọ si olu ilé ẹgbẹ APC ni Porthacourt lati dibo nipa lilo ibo awọn aṣoju.
Ile iya egbe APC ni Rivers nibiti awon eka Amaechi ti n pejo fun idibo won
Iroyin to tẹ wa lọwọ sọ pe ẹgbẹ oṣelu APC ti sọ pe ki igbimọ alaṣẹ ẹgbẹ naa ni ipinlẹ Kwara labẹ alaga Ishola Balogun-Fulani lọ rọ kun nile.
Alukoro fun ẹgbẹ oṣelu APC, Yekini Nabena, lo fi ọrọ naa lede nibi idibo abẹle ẹgbẹ ọhun lọjọ Aiku.
Bakan naa ni ọgbẹni Nabena kede pe ẹgbẹ APC ti sun idibo abẹle to yẹ ko waye ni ipinlẹ Ogun, Zamfara, Bauchi ati Abia si ọjọ Aje.
Adebayọ Adelabu ni wọn dibo yan lati dije fun ipo gomina ipinlẹ Ọyọ l'ọdun 2019.
Adelabu to ti figba kan jẹ igbakeji gomina banki apapọ Nigeria, CBN, gbegba oroke nibi eto idibo abẹle ẹgbẹ APC nipinlẹ Ọyọ to waye l'ọjọ Aiku, ni papa iṣere Adamasingba, niluu Ibadan.
Oríṣun àwòrán, Adebayo Adelabu/Facebook
Adelabu ti figba kan jẹ igbakeji gomina banki apapọ Nigeria, CBN.
Eyi waye lẹyin ti awọn alatako rẹ bi i Joseph Tegbe, ti awọn kan gbagbọ pe oun ni ẹni ami ororo Gomina Abiọla Ajimọbi, ati awọn oludije mi i finu-findọ jawọ ninu eto idibo naa, ayafi Amofin Adeniyi Akintọla to ni dandan ni ki wọn jẹ ki eto idibo waye fun gbogbo oludije.
Ṣugbọn, o ku diẹ ki eto idibo bẹrẹ ni Akintọla naa sọ pe oun yọnda fun Adelabu.
Ero pọ to ti jade lati wa yan oludije APC nipinlẹ Ọyọ nibiti oludije meje ti n dije
Adebayọ Adelabu jẹ ọkan lara awọn ọmọọmọ gbaju-gbaja oloṣelu niluu Ibadan, Adegoke Adelabu, ti gbogbo eniyan mọ si Pẹnkẹlẹmẹẹsi.
Kwara:
Hon. AbdulWahab Omotose Kayode ti jawe olubori nínu idibo abẹlẹ ipinlẹ Kwara gẹgẹ bi oludije.
Akọroyin nigba kan ri ni yoo ṣoju APC dupò gomina Kwara
O ti ṣiṣẹ pẹlu ileeṣe iwe iroyin THISDAY ri, ko to wọle di olori awọn ọmọ ile igbimo asofin to kere ju nipinlẹ Kwara.
Alhaji Kayọde tó jáwé olúborí ní Kwara ti di oludije dupò gomina
Seriki Yahaya ní ìbò 6, Abdulrahaman Abdulrazaq, ní ìbò 3, Garba Gobir ní ìbò 2, Akeem Oladimeji Lawal ní ìbò 27, Lukman Mustapha ní ìbò 11, Mashood Mustapha ní ìbò 5, Modibo Kawu ní ìbò 2, Mohammed Belgore, SAN ní ìbò 6, Professor ShuaibAbdulraheem ní ìbò 5, Mallam Saliu Mustapha ní ìbò 12, Yaman Abdullahi ní ìbò 7 ati Alh Tajudeen Makama ní ìbò 4, nigba ti Kayọde ni 891.Ibo mejila ni wọn wọgile. Laaarin ariwo ayò ati idunnu ni Hon. Christopher Ayẹni ṣe ikede èsi idibo yii. O ni idibo ẹka ti wọn ni ajọ INEC yoo gba wọle fun idibo gangan.
Oludije yii fidunnu rẹ han pẹlu ileri pe oun yoo saipa oun ki ẹgbẹ APC wọle lọdun to m bọ̀.
Ki lo ṣẹlẹ ni idibo abẹlé Kwara tẹlẹ?
Hon. Christopher Ayeni, to jẹ akọwe ẹgbẹ APC ti ipinlẹ Kwara ni àwọn oludije mẹtala naa ni wọn ti pegede gba ami o yege lati dije dupò gomina ni Kwara.
Onikaluku ni eka Filani n dibo yan eni to fe
Bakan naa lo ṣalaye pé awọn oludibo 1007 to jẹ aṣoju lo n kopa ninu idibo naa nibiti ko ti si wahala kankan ti gbogbo rẹ n lọ bi o ti yẹ.
APC pin si meji ni Kwara, awon kan n dibo loni
Hon Ishola Balogun-Filani to jẹ alaga ẹgbẹ APC ni Kwara ba BBC Yoruba sọrọ lori idibo naa pe ẹka ti wọn to n dibo loni ni ajọ INEC yoo gba wọle nitori pe aṣẹ wa lati òkè pé ki awòn ṣeto idibo naa loni ni.
O ni àwọn alatilẹyin Ogara George Tabugbo to jẹ ọkan lara awọn oludije sipo gomina ni Enugu ya bo ibudo idibo naa ni eyi to di wahala ti awọn to fẹ ṣeto idibo ọhun tẹlẹ si kuro.
O ni ko pẹ lẹyin eyi ni àwọn agbofinro fi ẹsẹ fẹẹ lẹyin ti awon alatilẹyin awọn oludije tutọ soke.
Koda ọkan ninu awọn oniwahala naa kọlu akọroyin ti wọn si ba ẹrọ ibanisọrọ rẹ jẹ.
Awọn akọroyin BBC ṣi n duro wòye boya idibo naa a tẹsiwaju tabi bẹẹ kọ́.
Akọroyin BBC to wa nipinlẹ Enugu ni oriṣii ẹ̀ka meji ni awọn oludibo pin si ni awọn ibudo idibo abẹlẹ to n lọ lọwọ.
Awon oludije to ni àmì yii ni won n je ki won wole dibo fun oludije to wu won ni Enugu
Awọn agbatẹru ibo ni Enugu ti ya awọn oludibo si ọtọọtọ nipa wiwo iru ààwọ̀ kaadi idbo ti won ba muwa sibudo idibo.
W#on ko faaye gba awon oludibo to niru kaadi yii lati wo ibudo idibo ki won dibo yan oludije ti won fẹ́ ni Enugu
Awọn agbofinro NSCDC  ati ọlọpaa ti n de si àwọn ibudo idibo l'Enugu bi ti UNEC ni aarin gbungbun Enugu
Eto Idibo abẹlẹ yii n mu ọwọ agbofinro dani fun aabo ni Enugu
Ogun: Kò tìí dábì pé ètò ìdìbò abẹ́lé yóò wáyé ní ìpínlẹ̀ Ogun. Àwọn ìròyìn kan sọ pé wọ́n ti sún ọjọ́ ìdìbò nàá síwájú nígbà tí àwọn kan tún sọ pé irọ́ ni.
Alága ẹgbẹ́ APC ní ìpínlẹ̀ Ogun, Olóyè Derin Adebiyi tó bá BBC sọ̀rọ̀ ní nkan bii aago mọ́kànlá òwúrọ̀ ọjọ́ Àìkú tó yẹ kí ìdìbò nàá wáyé, sọ pé àwọn kò tìí rí àwọn èròjà ìdìbò gbà láti olú ilé ẹgbẹ́ nàá tó wà ní ìlú Abuja.
Ó ní bíbá tí òun bá olórí ìgbìmọ̀ tó n mójútó ìdìbò abẹ́lé ní ìpínlẹ̀ Ogun, Alhaji Muhammed Idabawa, kò so èsò kankan, nítorí pé Idabawa nàá sọ pé omiinú n kọ òun nàá lórí bí èròjà ìdìbò kò ṣe tíì gúnlẹ̀ sí ìpínlẹ̀ Ogun.
Bayii, Alaga APC ipinlẹ Ogun ti fidi ẹ mulẹ fun BBC pe ipinlẹ Ogun ti sun idibo abẹlẹ wọn siwaju nitori pe ilé ìyá ẹgbẹ ko gbe ohun elo ranṣẹ. O ni wọn yoo kede ọjọ tuntun to ba ya.
Idibo ti bẹrẹ nibudo kọọkan nipinlẹ Kano bayii. Nigba ti awọn eeyan ti jade sibudo idibo mii ti  wọn si n duro de awọn ohun eelo idibo kaakiri.
Ganduje ko ni alatako kankan lati APC Kano
Gomina Ganduje Abdullahi Umar nikan lo jade lati tun dije tẹsiwaju lẹẹkan sii gẹgẹ bii gomina Kano.
Ibo abẹlẹ APC ti bẹrẹ ni Kano
Bayii ibudo idibo bii Hotoro North, Unguwa Uku Cikin Gari àti Gyadi Gyadi ti n mu esi idibo wọn wa si Kano.
Àwọn obinrin Kano naa jade wa dibo abẹlẹ APC
Akọroyin BBC to wa ni Adamasingba ni ọpọ awọn oludibo lo ṣi wa nita abawọle papa iṣere naa ti wọn koi tii raaye wọle, bẹẹ, ko tii si oludije kankan to tii de.
Buhari borí ìdìbò abẹ́lẹ́ fun ìdíje ààrẹ̀ lẹgbe APC
Ìgbésẹ̀ ìdìbò abẹ́lẹ́ ti bẹ̀rẹ̀ nínú ẹgbẹ́ òṣelu All Progressives Congress ki wọn fi yan awọn oludije ọmọ ẹgbẹ fun ipo gomina àti aarẹ fun idibo 2019.
Ọjọ Abamẹta, ọjọ kọkandinlọgbọn, oṣu kẹsan an ni ẹgbẹ APC dìbò yan Mohammadu Buhari gẹgẹ bi oludije kan ṣoṣo fun ipo aarẹ lọdun 2019.
Nipinlẹ Kano nikan ni Buhari ti ni o lé diẹ ni ọ̀rùn-dín-ni-miliọnu-mẹta ibo pe kó tésiwaju lẹẹkeji. Gomina Abdullahi Ganduje to ṣalakoso ibo naa ni Buhari ni 2,931,235 ìbò.
Bakan naa ni ọmọ ṣori nipinlẹ Katsina nibi ti Buhari ti ni ìbò 802, 819 ninu gbogbo awọn 813, 877 to forukọ silẹ.
Ẹrin kò yatọ nipinlẹ Rivers nibi ti Buhari ti ni ibo 388, 653 àti nipinlẹ Imo to ti ni 697, 532 ìbò ninu àwọn 944, 843 to forukọ silẹ titi lọ ba àwọn ipinlẹ bii Bauchi, Borno, Bayelsa. Sokoto àti Zamfara.
Eyi fihan pe Mohammadu Buhari ni gbogbo wọn ninu ẹgbẹ oṣelu APC ti faramọ pe ko tun dije lorukọ ẹgbẹ sipo aarẹ ninu idibo Naijiria to m bọ lọdun 2019.
Idibo abẹle lati yan oludije fun ipo gomina labẹ asia ẹgbẹ oṣelu APC yoo waye lawọn ipinlẹ to ku ni Naijiria loni ọgbọn ọjọ, oṣu kẹsan an yatọ si ti ipinlẹ Imo ati ti Eko ti wọn sun si ọjọ kini, oṣu kẹwaa, ọdun yii.
NLC: Àwọn olósèlú ń la títì láì sanwó osù torí owó tí wọn yóò rí lórí àkànse isẹ́
Igbimọ amusẹya fẹgbẹ oselu APC jake-jado Naijiria, ti gbe orukọ awọn oludije fun ipo gomina, ti wọn ti wẹ yan kain-kain lẹyin ayẹwo kinni-kinni labẹ  ẹgbẹ oselu naa jade.
Atẹjade kan ti adele akọwe ipolongo fẹgbẹ oselu APC, Yekini Nabena fisita, lo sisọ loju ọrọ yii.
Ni ẹkun iwọ oorun Guusu orilẹ-ede yii ati ilẹ Kaarọ Oojiire lapapọ, ipinlẹ mẹta ni pere ni ẹgbẹ oselu APC ti gbe orukọ awọn oludije gomina to pegede sita.
Ọlọ́jọ́ festival 2018: Láwàní (ọ̀já) ni máa kọ́ka wé kí n tó jẹ Ọọni nítórí Oodua ló nií
Idi ni pe ninu awọn ipinlẹ mẹfa to wa lẹkun iwọ oorun guusu Naijiria, ipinlẹ mẹta pere lo ku ti yoo seto idibo gomina lọdun 2019. Awọn ipinlẹ naa ni ipinlẹ Ọyọ, Ogun ati Eko.
Ẹwẹ, nipinlẹ Kwara, to jẹ ara ilẹ Oodua, ẹgbẹ oselu APC ṣẹṣẹ kede orukọ awọn eeyan to yege lati dije fun ipo gomina nibẹ.
1.H.E. Akinwunmi Ambode     - O yege2.Dr. Kadir Obafemi Hamzat     - O yege (Bayii, o ti ju awà silẹ fun Jide Sanya-Olu, pe oun yọ̀ǹda ipinlẹ Eko fun Sanya-Olu lasiko yii)3.Jide Sanwo-OluCleared       - O yege
1.Niyi Akintola, SAN      - O yege
2.H.E. Christopher Alao Akala       - O yege3.Joseph Olasunkanmi Tegbe       - O yege4.Dr. Olusola Ayandele, PhD        - O yege5.Dr. Owolabi Babalola        - O yege6.Dr. Azeez Popoola Adeduntun    - O yege7.Adebayo Adekola Adelabu         - O yege8.Hon. Barr. Adebayo Shittu, Esq     -Ko yege  (ko ni iwe ẹri isinru ilu NYSC ni èyí to ti ni òun kò kọ̀ lati ṣẹṣẹ lọ sin ilẹ̀ baba oun lasiko yii)
Ipinlẹ Ogun:1.Jimi Lawall                                      - O yege2.Dapo Abiodun                          - O yege3.Hon. Bimbo Abiodun                      - O yege4.H.E. Sen. Adegbenga Kaka              - O yege5.Hon. Kunle Akinlade            - O yege6.Abayomi Semako Koroto Hunye      -O yege
Ipinlẹ Kwara1) Mal. Saliu Mustapha       -Kò yege
2) Abdulfatai Yahaya Seriki    -Kò yege
3) AbdulRaham AbdulRasak  - Ò yege
4) Ọjọgbọn Ọba AbdulRaheem -Ò yege.
5) Mal. Ishaq Modibbo Kawu  -Ò yege.
6) Hon. Kayode Omotoshe  - Kò yege.
7) Yakub Gobir - Ò yege.
8) Mal. Lukman Olayiwola Mustapha  -Ò yege
9) Shuaib Yahman Abdullahi -Ò yege
10) Moshood Mustapha   -Ò yege
11) Dele Mohammed Belgore (SAN) - ó yọwọ́ pé òun kò ṣe mọ́.
12) Tajudeen Audu     -ó yọwọ́ pé òun kò ṣe mọ́.
13) Hakeem Lawal -Ò yege
Awọn eeyan to yege yii, ti yoo kopa ninu idibo abẹnu ẹgbẹ oselu APC, to n bọ lọjọ Aiku ni yoo maa figa gbaga, ẹni ti odu rẹ ba si kun ju ninu wọn, ni yoo soju ipinlẹ rẹ pẹlu awọn oludije yoku latinu awọn ẹgbẹ oselu alatako lọdun 2019.
APC sún ìdìbò abẹ́lé fún ìpò gómìnà síwájú nipinlẹ Imo ati Eko
Ẹgbẹ oṣelu APC ti sun idibo abẹle fun ipo gomina ni Ipinlẹ Eko to yẹ ko waye lọjọ Aiku tẹlẹ si ọjọ Aje bayii.
Alaga gbogbo fun ẹgbẹ oṣelu naa Adam Oshiomole lo fi ọrọ lede lọjọ Abamẹta.
Ẹwẹ, ọkan lara awọn oludije gomina labẹ ẹgbẹ oselu APC nipinlẹ Eko tẹlẹ, Ọbafẹmi Hamzat ti yẹba fun Babajide Sanwo-Olu, saaju idibo naa.
Dokita Kadri Ọbafemi Hamza, to kede igbesẹ rẹ yii fawọn Akọroyin ni pe oun ko ni dije mọ lati dupo gomina ipinlẹ Eko.
O wa rọ awọn alatilẹyin rẹ lati fọwọsowọpọ ri i pe Sanwo-Olu lo jawe olubori, ninu idibo abẹle naa ti yoo waye lọjọ Aje, ọjọ kinni, oṣu kẹwaa.
Ninu ọrọ rẹ, Femi Hamzat ni oun gbagbọ pe Sanwo-Olu ni okun ati agbara lati mu itẹsiwaju ba ipinlẹ Eko.
Oríṣun àwòrán, APC
Iroyin fi idi rẹ mulẹ pe awọn eekan oloṣelu lẹgbẹ oṣelu naa kaakiri awọn ipinlẹ ni wọn pin eto idibo naa mọ ara wọn lọwọ
Hamzat fikun pe, itẹsiwaju ipinlẹ Eko pọn dandan ju ẹnikẹni lọ, nitorina ni oun se yẹba fun ẹnikeji oun ti awọn ti wa tipẹtipẹ.
Femi Hamzat wa parọwa si awọn ọmọ ẹgbẹ APC lati fọwọsowọpọ, ki itẹsiwaju le ba ẹgbẹ naa.
Awọn ipinlẹ yoku bii ipinlẹ Ekiti, Ondo ati Ọsun ti seto idibo gomina tiwọn, ti wọn ko si ni kopa ninu eto idibo gomina ti yoo waye lawọn ipionlẹ yoku lọ̀dun 2019.
Oríṣun àwòrán, Twitter
Adebayo Shittu wà lára awọn to fẹ́ díje fun ipò gómìnà ìpínlẹ̀ Ọyọ
A gbọ pe ẹgbẹ oselu APC ni Shittu ko wẹ yan kain-kain lati kopa ninu idibo abẹle fawọn oludije fun ipo gomina naa, nitori pe ko seto isinru ilu lẹyin to jade nile ẹkọ fasiti, gẹgẹ bi ofin ilẹ wa se laa kalẹ.
Bẹẹ ba si gbagbe, Adebayọ Shittu gan ti sọ loju-taye pe, oun ko kopa ninu eto sinru ilu, nitori bi oun se jade fasiti, ni wọn dibo yan oun sile asofin ipinlẹ Ọyọ.
Ètò ìdìbò abẹ́lé kò tìí dábì pé yóò wáyé ní ìpínlẹ̀ Ogun. Àwọn ìròyìn kan sọ pé wọ́n ti sún ọjọ́ ìdìbò nàá síwájú nígbà tí àwọn kan tún sọ pé irọ́ ni. Alága ẹgbẹ́ APC ní ìpínlẹ̀ Ogun, Olóyè Derin Adebiyi tó bá BBC sọ̀rọ̀ ní nkan bi i aago mọ́kànlá òwúrọ̀ ọjọ́ Àìkú tó yẹ kí ìdìbò nàá wáyé, sọ pé àwọn kò tìí rí àwọn èròjà ìdìbò gbà láti olú ilé ẹgbẹ́ nàá tó wà ní ìlú Abuja.
Ó ní bíbá tí òun bá olórí ìgbìmọ̀ tó n mójútó ìdìbò abẹ́lé ní ìpínlẹ̀ Ogun, Alhaji Muhammed Idabawa, kò so èsò kankan, nítorí pé Idabawa nàá sọ pé omiinú n kọ òun nàá lórí bí èròjà ìdìbò kò ṣe tíì gúnlẹ̀ sí ìpínlẹ̀ Ogun.
APC supporters from all the 33 Local government arears of Oyo state are already gathered at Adamasingba Stadium, Ibadan, Oyo state capital for the governorship primaries. The supporters are standing in groups according to their LGAs, waiting for the accreditation to begin.
Omiṣore: Ọlọ́run mọ̀ sí bí mo ṣe fi PDP sílẹ̀
Oríṣun àwòrán, Iyiola Omisore/Facebook
Omiṣore ti kọ́kọ́ dupò gómìnà lábẹ́ àsìá PDP lọ́dún 2014
Igbákejì  gómìnà ìpílẹ̀ Ọ̀ṣun nígbà kan rí, Sẹnatọ Iyiọla Omisore ti fi ẹgbẹ́ òṣèlú Peoples Democratic Party, PDP sílẹ̀.
Omisore fi PDP sílẹ̀. O ni òun yóò lọ si íbi tó ti ní ìrètí láti díje dupò gómìnà nínú ètò ìdìbò gómìnà tí yòó wáyé lọ́jọ́ kejìlélógún, oṣù Kẹsàn án.
Omiṣore kéde ìgbésẹ̀ nàá nínú àtẹ̀jáde kan tó fi síta fún àwọn àkọ̀ròyìn ní ìlú Oṣogbo, tí ṣe òlú ìlú fún ìpínlẹ̀ Ọ̀ṣun. ni iwo oorun guusu Nàìjíríà.
"Ó ní ''nínú ẹgbẹ́ tuntun tí maa fẹ́ darapọ̀ mọ́ ni àfojúsùn mi yóò ti wá sí ìmúṣẹ, àti pé mo ti ṣetán láti dóòlà ìpínlẹ̀ nàá kúrò lọ́wọ́ ìṣàkóso APC."""
Ó ní èyí ló fà á tí òun fi ń wá ẹgbẹ́ mì í tí yóò fàáyè gba òtítọ́ àti àwọn tó tọ́ láti dòólà ìpínlẹ̀ Ọ̀ṣun kúrò ní abẹ́ ìṣèjọba tó n ṣe é bí kò ṣe tọ́, tí yòó sí mú kí ó ṣeéṣe fún àwọn ara ìlú láti jèrè ìjọ́ba tó n kó àkóyawọ́.
Ẹ̀wẹ̀, Omisore ní ''mo ti kúrò ní PDP, láì fi ti akitiyan mi láti kọ́ ẹgbẹ́ nàá se, lẹ́yìn tí mo ti fi ọ̀rọ̀ nàá lọ Ọlọ́run mi, ìdìlé mi, tó fi mọ́ àwọn alátìlẹyìn mi ní tilé-toko, ki n to bọ́ sí ẹgbẹ́ tó ní ìgbàgbọ́ nínú ìbára ẹni dọ́gba, tó fi mọ́ ifẹ̀ orílẹ̀-èdè Nàìjíríà tó múná dóko hàn.
Koko iroyin: Iyiọla Omisore darapọ̀ mọ́ SDP, Ọwọ́ tẹ agbésùnmọ̀mì ní yobe
Eyi ni awọn akojọpọ iroyin ti toni.
Omiṣore ní Ọlọ́run mọ̀ sí bí òun ṣe fi PDP sílẹ̀.
Oríṣun àwòrán, Iyiola Omisore/Facebook
Omiṣore ti kọ́kọ́ dupò gómìnà lábẹ́ àsìá PDP lọ́dún 2014
Igbákejì  gómìnà ìpílẹ̀ Ọ̀ṣun nígbà kan rí, Sẹnatọ Iyiọla Omisore ti fi ẹgbẹ́ òṣèlú Peoples Democratic Party, PDP sílẹ̀.
Omisore fi PDP sílẹ̀ lọ sínú ẹgbẹ́ òṣèlú Soc, níbi tó ti ní ìrètí láti díje dupò gómìnà nínú ètò ìdìbò gómìnà tí yòó wáyé lọ́jọ́ kejìlélógún, oṣù Kẹsàn án.
Ilé-isẹ́ olóogun Nigeria: Ará ìlú dá ìkọlù dúró ní Yobe
Oríṣun àwòrán, Twitter/Nigerian Army
Lilo awọn agbesunmọmi to jẹ ọmọde tabi obinrin jẹ ọna kan gboogi ti ikọ Boko Haram ma n lo lati se ikọlu.
Ile-isẹ ologun lorilẹede Naijiria sọ pe awọn ọmọ Naijiria rere ti dawọ ikọlu obinrin agbesunmọmi to fẹ se si mọsalasi kan ni abule Gashua, ni ijọba ibilẹ Gubja ni ipinlẹ Yobe.
"Adari ikọ ipolongo fun ikọ ọmọogun ‘Operation Lafia Dole’,Onyema Nwachukwu ni ""ti ko ba si ti awọn ara ilu ati awọn ọlọdẹ ibilẹ to ba igbimọ awọn agbesunmọmi naa jẹ, ibugbamu na o ba ba nkan jẹ. E ka ekunrere re ni bii"
James Ó ta lẹ́nu: Ìwọ tó o bá ń tijú, o ò le dé 'bi gíga
Akàwégboyè alákàrà
Ilé-isẹ́ olóogun Nigeria; Ará ìlú dá ìkọlù dúró ní Yobe
Oríṣun àwòrán, Twitter/Nigerian Army
Lilo awọn agbesunmọmi to jẹ ọmọde tabi obinrin jẹ ọna kan gboogi ti ikọ Boko Haram ma n lo lati se ikọlu.
Ile-isẹ oloogun lorilẹede Naijiria sọ wi pe awọn ọmọ Naijiria rere ti dawọ ikọlu obinrin agbesunmọmi to fẹ se si mọsalasi kan ni abule Gashua, ni ijọba ibilẹ Gubja ni ipinlẹ Yobe.
Adari ikọ ipolongo fun ikọ ọmọogun ‘Operation Lafia Dole’,Onyema Nwachukwu fi ikede naa sita ninu atẹjade ti wọn fi sita ni ilu Maiduguri.
"Ninu atẹjade naa, Nwachukwu ni ""ti ko ba si ti awọn ara ilu ati awọn ọlọdẹ ibilẹ to ba igbimọ awọn agbesunmọmi naa jẹ, ibugbamu na o ba ba nkan jẹ."
Ọmọọba Harry ati Meghan Markle ti di tọkọtaya
Wọn fikun wipe, awọn eniyan to ba obinrin agbesunmọmi naa nibi to ti n tiraka lati tu ado oloro to wa lara rẹ, ni wọn ko fun laaye lati sọsẹ, ti wọn si bọ asọ ado oloro naa kuro l'ọ́rùn rẹ̀.
Lilo awọn agbesunmọmi to jẹ ọmọde tabi obinrin jẹ ọna kan gboogi ti ikọ Boko Haram ma n lo lati se ikọlu si agbeegbe ariwa orilẹede Naijiria.
Bàbá olówó Chelsea, Abramovich rí ìdíwọ́ lórí ìwé ìgbéèlú ilẹ́ Gẹ̀ẹ́sì
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Iroyin sọ wi pe asẹ iwe igbelu rẹ dọpin ni bii ọsẹ mẹta sẹyin
Ẹni to ni ẹgbẹ agbabọọlu Chelsea, Roman Abramovich ti koju idiwọ lori a ti gba iwe igbelu fun ilẹ Gẹẹsi.
Abramovich to jẹ ọmọ orilẹede Russia ni ko si nibi asekagba idije FA to waye lọjọ Abamẹta, nibi ti Chelsea ti gba ife naa lẹyin ti wọn naa Manchester United pẹlu àmìn ayo kan si òdo.
Ọmọ ọdun mọkanlelaadọta naa ni wọn sọ wi pe ati gba iwe igbelu rẹ n gba ọjọ gbọọrọ ju bi oti yẹ lọ.
Bi o ti lẹ jẹ wi pe ile isẹ arakunrin naa ko ti fesi si isẹlẹ naa, iroyin sọ wi pe àṣẹ iwe igbelu re dopin ni bii ọsẹ mẹta sẹyin.
Grenfell Tower: Ìwádìí yóò bẹ̀rẹ̀ lórí ilé alájà tó jóná ní London
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ìfọ̀rọ̀wánilẹ́nuwò yóò bẹ̀rẹ̀ láìpẹ́ yìí láti fún wọn lánfàní láti jẹ́rìí sí ohun tí wọn mọ
Ẹlẹ́dẹ̀ yóò dé Ọ̀yọ́, ariwo rẹ̀ ní yóò pọ̀. Láìpẹ́, ìwádìí yóò bẹ̀rẹ̀ lórí ilé alájà tó jóná ní London.
Àwọn ìdílé tó pàdánù àwọn ènìyàn wọn níbi ilé alájà mẹ́rìlélógún ti Grenfell Tower tó jóná ní Keshinton, west London yóò rí ìdájọ́ fún àwọn ẹni wọn to pàdánu ẹ̀mí níbẹ̀.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Òsẹ̀ méjì ní o yẹ kí ètò ìwádìí òhún lò tí ẹnìkọ̀ọ̀kan yóò sì sọ̀rọ̀ bó ṣe wùú láì fi gbèdéke síi ibi tí wọn le sọ̀rọ̀ mọ
Ìfọ̀rọ̀wánilẹ́nuwò yóò bẹ̀rẹ̀ láìpẹ́ yìí láti fún wọn lánfàní láti jẹ́rìí sí ohun tí wọn mọ
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ọ̀pọ̀ àwọn tí yóò kópa ní wọn nírètí pé yóò ka ọ̀rọ̀ tàbí sàfihàn fọ́rán-án àwọn olólùfẹ́ wọn tó ti kú.
Òsẹ̀ méjì ní o yẹ kí ètò ìwádìí òhún lò tí ẹnìkọ̀ọ̀kan yóò sì sọ̀rọ̀ bó ṣe wùú láì fi gbèdéke síi ibi tí wọn le sọ̀rọ̀ mọ
Ìwádìí ọ̀hún yóò sàyẹ̀wò sí ikú ènìyàn méjìléláàdọ́rin, tó fi mọ́ ọ́kan lára wọn tó wà ní ilé ìwòsàn láti inú oṣù kẹfà ọdún 2017, to ṣẹ̀ṣẹ̀ saláìsí nínú oṣu kíní ọdún yìí.
Ọlọ́pàá mú èèyan mẹ́ta pé wọ́n so akẹ́kọ̀ọ́ mọ́gi
NDLEA gbéṣèlé tọ́ọ̀nù mẹ́rìn oogun Tramadol
Ọmọọba Harry ati Meghan Markle ti di tọkọtaya
Àjọ ọlọ́pàá: kọ́kọ́ sàyẹ̀wò ọlọ́pàá kó tó yẹ̀ ọ́ wò
Ọ̀pọ̀ àwọn tí yóò kópa ní wọn nírètí pé yóò ka ọ̀rọ̀ tàbí sàfihàn fọ́rán-án àwọn olólùfẹ́ wọn tó ti kú.
Orúkọ gbogbo àwọn tó ti saláìsí ní wọn ò kà síta nibi ìgbẹ́jọ́ tí yóò wáyé ní ilé ìgbáfẹ́ Millennium Gloucester, ní Gúúsù Kensington, west London, sùgbọ́n kìí ṣe gbogbo ebí ní yóò lánfàní láti sọ̀rọ̀ níbẹ̀
Sir Martin Moore-Bick tó jẹ́ adájọ́ fẹ̀yìntí ni yóò jẹ́ alága ìwádìí, tí yóò sì máa gba ẹ̀rí láti ọ̀dọ̀ àwọn ọlọ́dani, àwọn ilé-iṣẹ́ àti àwọn akọ́ṣẹ́mọṣẹ́.
Àṣírí fàyàwọ́ ọmọnìyàn tú nílé ẹ̀kọ́ kan nípìlẹ́ Edo
Oríṣun àwòrán, @solomon
Okoduwa wá kìlọ̀ fáwọn ọmọ ilé ẹ̀kọ́ òhún láti kíyèsára kí wọn máà bọ́ sọ́wọ́ ìtànjẹ àwọn fàyàwọ̀ ọmọnìyàn
Ó tí tó ọmọ ọgọ́rùn ún tí àwọn fàyàwọ̀ ọmọnìyàn ti kó lọ sí orílẹ̀-èdè Libya láti ilé ìwé kan ní ìlú Benin, ní ìpínlẹ̀ Edo, orílẹ̀-èdè Nàìjíárìà láti bíi oṣù mẹ́rin sẹ́yìn.
Olùrànlọ́wọ́ pàtàkì fún Gómìnà ìpínlẹ̀ Edo, Godwin Obaseki lórí ìfàyàwọ́ ọmọnìyàn àti ìrìnàjò kúrò nílùú lọ́nà àìtọ́, Solomon Okoduwa, sọ pé, ọ̀gá kan nílé ẹ̀kọ́ náà ló sọ bẹ́ẹ̀ fún òun.
O ní àwọn fàyàwọ́ ọmọnìyàn ti kojú bọ ilé ìwé òhún láti máa kó àwọn ọmọ lọ sí ilẹ̀ òkèèrè.
Ọ̀gbẹ́ni Okoduwa sọ̀rọ̀ òhún ní ìlú Benin lásìkò tí wọn ń ṣe ìpolongo ìta gbangba kan
Àṣírí ìfàyàwọ́ ọmọnìyàn tú nílé ẹ̀ka kan nípìlẹ́ Edo
Ó ní ìjọba ìpínlẹ̀ Edo kò ní fààyè gba irú ìwà búburú báyìí láti tèsíwájú nípìnlẹ̀ náà
O ni ìjọba yóò fí irú nkan báyìí kún àwọn ìpolongo ìta gbangba tí wọn ń ṣe kí àwọn ará ìlú leè dẹ́kún fàyàwọ́ ọmọnìyàn, àti pé àjọ ìjọba tó ń rí sí gbígbígun ti fàyàwọ́ yóo máa tọ pinpin àwọn ọ̀bàyéjẹ́ ọ̀hún.
Okoduwa wá kìlọ̀ fáwọn ọmọ ilé ẹ̀kọ́ òhún láti kíyèsára kí wọn máà bọ́ sọ́wọ́ ìtànjẹ àwọn fàyàwọ̀ ọmọnìyàn láti rínrin àjò to léwu nínú lilọ sí orílẹ̀-èdè Libya
Àwẹ̀ Ramadan wákàtí 22 lóòjọ́, ṣé ẹ̀mí rẹ gbà á?
Wákàtí a má jó bi pé kò sáré rárá nínú àwẹ̀.
Lootọ  ní pé láàrin ìgbà tí oòrùn bá yọ sì ìgbà tí o bá wọ ní jíjẹ àti  mímú dì èèwò fún àwọn Mùsùlùmí nínú oṣù Ramadan.
Ṣùgbọ́n bí ojú ọjọ ti ṣe rí a má ṣe òkùnfà ìyè wákàtí ti awọn èèyàn fi n gba àwẹ ní àwọn orílẹ̀èdè àgbáyé.
Láwọn orílèèdè kàn, ìyè wákàtí àwẹ̀ ko kọjá àfaradà ṣugbọn láwọn ibòmìíràn,a máa dàbí pé àwẹ̀ ò ní tán.
Ní ìgbà wọ̀nyí, àwẹ̀ gbígbà a máa dàbí àdánwò àti ìpèníjà  fún àwọn mùsùlùmí tí wọ́n gba àwẹ̀ fún wákàtí pípẹ́.
Wákàtí àwẹ̀ káàkiri àgbáyé
Àgbègbè àwẹ̀ ọlọjọgbòòrò
Ki a kọkọ fi ìbéèrè ṣọwọ́ pe ṣe ẹ mọ ìbí ti wọn n pé ní Greenland?
Greenland ni erékùsù  ti o tobi jù lọ lágbayé.
Bi Ọlọ́run bá kọ ọ́ pé  èèyàn ba wọn gba awẹ níbẹ̀, wákàtí méjìlelogun gbáko ní èèyàn o fí mẹnu mọ fún jíjẹ àti mímú.
Ìtumọ̀ eléyìí ni pé wákàtí meji péré ni yóò fi ṣínú, kí irun Maghrib ati Ishai ti yóò sì tún jẹ saari nínú rè!
Oríṣun àwòrán, Reuters
T'ọmọdé tí agbà ló má n ṣé isẹ́ ibadah oríṣiríṣi nínú oṣù Ramadan
Oṣiṣẹ ilera nílu Abuja ni Ọgbẹni Jimoh Jeleel Anjọrin.
Ìṣẹ rẹ̀ a sì máà gbà àgbàrá láti ṣe.
O sọ pé  àwẹ̀ gbígbà fún wákàtí méjìlelogun kìí ṣe òun tó rọrùn ṣùgbọ́n tó bá jẹ pé àgbègbè náà ní Ọlọrun dá èèyàn sí, ''o di dandan láti gbà àwẹ̀ náà''
Lọdọ ti rẹ, Lateefat aya Ahmad ni t'oba se agbègbè bi Greenland loun ba wa,òun yóò gba àwẹ̀ náà lai bikita.
''Ati ẹni tó gba wákàtí meji ati ẹ́ni to gba wákàtí méjìlelogun kò sí eyi tó rọrùn láti gbà. A fí kí ọlọrun fún wà ní òkun àti agbára láti gbà níí''
Nàìjíríà àti àwọn orílè-èdè bi Kenya n gbádùn lafiwe pẹlú àwọn tá ká ṣáájú.
Wákàtí mẹ́rìnlá làwẹ̀ gbígbà ni Nàìjíríà,Kenya wákàtí mẹ́tàlá, Egypt  si jẹ́ wákàtí mẹẹdogun.
Ṣùgbọ́n awọn tí  ìyè wákàtí àwẹ̀ wọn kéré diẹ ni Australia ati Chile níbi tí wọn ti n gbà àwẹ̀ wákàtí mọkanla ati mẹwàá.
Abikẹ Dabiri: irọ́ ni wọ́n ń pa f'awọn ọ̀dọ́ pé wọn a ríṣẹ́ ṣe
Abikẹ Dabiri: Iṣẹ́ pọ̀ lọ́wọ́ Naptin àti àwọn aṣọ́bodè Nàìjíríà
Ọmọ Nàìjíríà mẹrindínlógún ni wọn ti fẹ̀sùn kàn ni Paris pé wọn ń f'awọn ènìyàn ṣiṣẹ́ aṣẹwo ni France, Italy ati Spain.
Ọkùnrin marun un àti obìnrin mọkanla ni àjọ arannilọwọ ti kìí ṣe tijọba, Bus De Femme, ti gbe lọ sile ẹjọ ni France.
Àjọ yii gba agbẹjọ́rò fún àwón ọmọ Naìjíríà ti wọn fi tipá mu fi ṣe iṣẹ́ aṣẹwó nilẹ̀ Yuroopu.
Igbẹjọ fihan pé àwọn oniṣẹ ibi yii maa n parọ fun awọn ènìyàn pe wọn ń kó wọn lọ ṣiṣẹ́ ọmọ ọ̀dọ̀, iṣẹ́ agbálẹ̀, iṣẹ́ iná dida ati bẹẹ bẹẹ lọ.
Abikẹ Dabiri, to jẹ oluranlọwọ pàtàkì fún Aarẹ lori àjọṣepọ̀ ilẹ̀ òkèèrè ati ọrọ àwọn ènìyàn Nàìjíríà loke òkun, gba àwọn òbí àti alagbatọ nimọran láti mojuto àwọn ọmọ wọn.
O ni ki wọn má jẹ ki ẹnikẹni fi iṣẹ́ ilẹ̀ òkèèrè tàn wọ́n jẹ́ mọ́ nitori pe irọ ni.
O rọ àjọ NAPTIN àti àwọn aṣọ́bodè láti tẹra mọ́ iṣẹ takuntakun ti wọn ń ṣe, ki àwọn àjọ arannilọwọ gbogbo fọwọsowọpọ pẹlu ijọba lati fi gbogun ti àwọn oníṣẹ ibi to ń ta ènìyàn sóko ẹrú kaakiri agbaye.
Abikẹ Dabiri fidunnu hàn pe bi ọwọ́ ṣe ń tẹ̀ àwọn ìka yii nile naa ni wọn ń mú wọn loke okun fun ìjìyà to tọ́.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Iṣẹ́ aṣẹ́wó àti gbígbé oògùn olóró ni wọn ń fi ọ̀dọ́ Nàìjíríà ṣe lókè òkun
Ọjọ kẹrinla oṣu karun un ni wọn kọkọ gbọ́ ẹjọ́ náà nile ẹjọ giga ti Paris ki adajọ to sọ àwọn mẹrin ninu wọn sẹwọn.
Awọn mokandinlaadọta ni wọn padà jẹri lodi si àwọn Authentic Sisters ti wọn fẹsun kàn pé wọn parọ fún àwọn pe iṣẹ ń duro de wọn ni Paris.
Awọn olùpẹ̀jọ́ mẹjọ akọ́kọ́ ti àjọ Bus De Femme, gba agbẹjọro fun náà ṣalaye pé àwọn ọbayejẹ ọ̀hún mu àwọn lọ sile babalawo lati búra pé àwọn kò ni dà wọn tabi ki wọn kóbá wọn ti wọn ba de ilẹ̀ Yuroopu tán.
Wọn ni àwọn ìkà ènìyàn yii a tún gba owó ti àwọn ba pa lẹ́nu iṣẹ́ aṣẹwo ọ̀hun lọwọ wọn.
Ajọ arannilọwọ yii tún n ṣeto itọju fun àwọn ènìyaǹ naa nile iwosan bayii.
Asa Trokosi nibi ti ọmọde ti n jiyan ẹsẹ mọlẹbi rẹ , wọpọ  ni Ghana, Togo ati Benin.
Oríṣun àwòrán, @abikedabiri
Ki gbogbo òbí àti alágbàtọ́ máa ṣọ àwọn ọmọ wọn
Offa robbery: Saraki, NOPRIN ní ọlọ́pàá gbọ́dọ̀ ṣàlàyé bí Adikwu ṣe kú
Oríṣun àwòrán, NIGERIAP POLICE FORCE
Awọn marun un ni awọn afurasi ti o farahan ni iwaju ile ẹjọ nilu Ilọrin ni ọjọru.
Aarẹ Ile Igbimọ Aṣofin Agba Bukola Saraki ati àjọ ti o n pè fun atunṣe ileeṣẹ ọlọpaa (NOPRIN) ti pe fun iwadi si bi Michael Adikwu, to jẹ olori awọn afunrasi ọlọṣa ti wọn ja ọpọ banki lole ni ilu Ọffa ni oṣu kẹrin, ọdun 2018, ṣe ku si ihamọ.
Ninu atẹjade kan ti agbẹnusọ rẹ Yusuph Olaniyonu fọwọ si, Saraki ke pe ileeṣẹ aarẹ lati gbe igbimọ dide lati ṣe iwadii na. NOPRIN naa sọ ninu atẹjade adari ajọ naa pe o fi han pe ootọ ni pe awọn ọlọpaa ti pa Adikwu si ihamọ bo tilẹ jẹ pe o ni oriṣiriṣi ọrọ lati sọ fun ile ẹjọ.
Gẹgẹ bi ọrọ ti agbẹjẹro agba ni ipinlẹ Kwara, Kamaldeen Ajibade, sọ niwaju ile ẹjọ lọjọru ni ilu Ilọrin, ọga ọlọpaa ikọ to ṣe iwaadi idigunjale naa, Abba Kyari lo fi to oun leti pe Adikwu ti ku.
Adikwu, to figba kan jẹ ọlọpaa ri ki iṣẹ to bọ lọwọ rẹ lo ko awọn adigunjale to ṣọṣẹ ni ilu Ọffa sodi.
Oríṣun àwòrán, Nigeria police force
Olórí ikọ̀ adigunjalè tó ṣ'ọṣẹ́ ní Ọ̀ffà ti kú
Banki marun un ni awọn adigunjale naa kọlu nigba naa ti wọn si pa eeyan ti ko din ni ọgbọn ninu eyi ti awọn ọlọpaa wa.
Awọn afurasi marun un ti wọn farahan niwaju ile ọjọ loni ni Ayoade Akinnibosun, Ibikunle Ogunleye, Adeola Abraham, Salaudeen Azeez ati Niyi Ogundiran.
Amọṣa adajọ ti o n gbọ ẹjọ naa, Halima Salman, ti sun igbẹjọ di ọgbọn ọjọ, oṣu kọkanla, ọdun 2018 lati fun olupẹjọ lanfani ati ṣe awọn atunṣe to yẹ lori iwe ipẹjọ wọn.
Nigba ti BBC kan si ileeṣẹ ọlọpaa lati bere bi o ṣe kú ni agbẹnusọ wọn ni ile ẹjọ nikan lo le ṣalaye.
Oríṣun àwòrán, PRNigeria
Ojú olè rèé!!!!!!
Awọn ọlọ́pàá ti mu àwọn ole ti won ja ni Ọffa ti wọn ṣe ikú pa ọpọlọpọ ènìyàn.
Awọn ọlọ́pàá fi aworan àwọn olè naa sita ninu ẹrọ ayelujara pẹlu ileri owo miliọnu marun un naira fun ẹnikẹni to ba kẹfin wọn nigboro tẹlẹ.
Alukoro ọlọ́pàá ni àwọn oninure eniyan ti ń pe wọn fun itọni si awọn ole naa kaakiri ni eyi to ti ń bi èso rere bayii.
Bayii, ikọ̀ IRT ti ọga ọlọ́pàá gbe lọ si ipinle Ekiti, Kwara, Oṣun, Oyọ àti Ondo ti mu meji ninu àwon ìgárá ọlọ́ṣà náà.
Parental Guidance: Ọdún méjì ni kí ẹ ti bẹ̀rẹ̀ kíkọ́ ọmọ nípa ìbálòpọ̀
Atẹjade ti awon ọlọpaa fi sita ni pe Adikwu di ọlọ́ṣà ni kete to jade kuro ni ẹwọn. Osẹ meji sẹyin ni awọn agbofinro IRT tun mu u ni ipinle Kwara.
Gbogbo àwọn afurasi ati awọn ti ọwọ agbofinro ti tẹ̀ ni wọn ti n ran àwon ọlọpaa lọwọ lati mu àwọn to kù wọn.
Oríṣun àwòrán, NIGERIA POLICE
Awọn afurasí náà gbẹ̀mi ogunlọ́gọ̀ ènìyàn pẹ̀lú ọlọ́pàá mẹsan
Alukoro ọlọpaa ni iwadii ṣi n lọ lọwọ lori idigunjale Ọffa.
Awọn adigunjalè míràn ti ọwọ́ tún tẹ̀
Èèmọ̀, alukoro PDP tẹ́lẹ̀, Olisah Metuh dákú ní ilé ẹjọ́
Oríṣun àwòrán, Pdp
Metuh ń jẹ́jọ́ fún ẹ̀sùn ṣíse owó ìlú báṣu-bàṣu
Alukoro nigba kan ri fun ẹgbẹ oṣelu PDP lorilẹ-ede Naijiria, Olisa Metuh, daku ni nu ile ẹjọ giga apapọ nilu Abuja loni.
Ọgbẹni Metuh ati ileeṣẹ rẹ kan n kawọ pọnyin rojọ fun ẹsun gbigba irinwo miliọnu Naira lọna àìtọ́ lati ọfiisi olootu aabo lorilẹ-ede yii lọdun 2014.
Metuh ṣubu lulẹ nigba ti wọn pe ẹjọ rẹ ni ọjọ Aje.
Ni kia ni adajọ to n gbọ ẹjọ naa pe awọn oṣiṣẹ ilera wọle lati wa moju to o ti o si gbe ẹjọ naa ti sẹgbẹ kan ki wọn fi mojuto o.
Nigba ti adajọ tun fẹ pe ẹjọ naa lẹyin ti wọn da Metuh pada saye, agbẹjọro rẹ faake kọri pe ko le ṣeeṣe nitori ẹmi onibara oun lo ṣe iyebiye ju fun oun.
Ẹjọ rẹ ni onidajọ Okon Abang, kọkọ pe lati tẹsiwaju ninu igbẹjọ ẹsun ṣiṣowo ilu baṣubaṣu ti wọn fi n kan an.
Onidajọ Abang ti wa sun igbẹjọ si ọjọ Iṣẹgun, ọjọ kejileogun, oṣu karun un ọdun yii.
Ramadan, wakati ṣọ̀tọ̀ọ̀tọ̀, kini ẹ mọ̀ nipa àwọn Yollywood?
Eyi ni awọn akojọpọ iroyin ti toni.
Ọwọ́ ṣìnkú ọlọ́pàá tẹ àwọn adigunjalè apanìyàn Ọfa míràn.
Ojú olè rèé!!!!!!
Awọn ọlọ́pàá ti mu àwọn ole ti won jalè ni Ọfa ti wọn ṣe ikú pa ọpọlọpọ ènìyàn.
Awọn ọlọ́pàá fi aworan àwọn olè naa sita ninu ẹrọ ayelujara pẹlu ileri owo miliọnu marun un naira fun ẹnikẹni to ba kẹfin wọn nigboro tẹlẹ.
Bayii, ikọ̀ IRT ti ọga ọlọ́pàá gbe lọ si ipinle Ekiti, Kwara, Oṣun, Oyọ àti Ondo ti mu meji ninu àwon ìgárá ọlọ́ṣà náà.
Abikẹ Dabiri: irọ́ ni wọ́n ń pa f'awọn ọ̀dọ́ pé wọn a ríṣẹ́ ṣe
Abikẹ Dabiri: Iṣẹ́ pọ̀ lọ́wọ́ Naptin àti àwọn aṣọ́bodè Nàìjíríà
Ọmọ Nàìjíríà mẹrindínlógún ni wọn ti fẹ̀sùn kàn ni Paris pé wọn ń f'awọn ènìyàn ṣiṣẹ́ aṣẹwo ni France, Italy ati Spain.
Ọkùnrin marun un àti obìnrin mọkanla ni àjọ arannilọwọ ti kìí ṣe tijọba, Bus De Femme, ti gbe lọ sile ẹjọ ni France.
Àjọ yii gba agbẹjọ́rò fún àwón ọmọ Naìjíríà ti wọn fi tipá mu fi ṣe iṣẹ́ aṣẹwó nilẹ̀ Yuroopu. E ka ekunrere re ni bii
Àsá Trokosi tó ń fi ọmo jìyà ẹ̀sẹ̀ mọ̀lẹ́bi rẹ̀, wọ́pọ̀ ní Ghana, Togo àti Benin.
Asa Trokosi nibi ti ọmọde ti n jiyan ẹsẹ mọlẹbi rẹ , wọpọ  ni Ghana, Togo ati Benin.
Boss Mustapha: A na 64 mílìònù náírà fun àtúntò ójú òpó ayélujára
O ní àṣeyọrí tó ṣe pàtàkì jùlọ ní pé àwọn ará ìlú yóò ní ore-ọ̀fẹ́ láti dásí ìṣèjọba níbikibi tí wọn bá wà
Ìjọba àpapọ̀ orílẹ̀-èdè Nàìjíríà  ni awọn  tí mú àtúntò bá ojú òpó ayélujára ilé iṣẹ́ akọwé àgbà ìjọba pẹ̀lú mílìònù mẹ́rìnlélọ́gọ́ta Náìrà.
Akọ̀wé àgbà fún ìjọba Boss Mustapha, ló kédé ọ̀rọ̀ ọ̀hún lánàá lásìkò tí wọn ń ṣe ìfilọ́lẹ̀ rẹ̀.
Boss sàlàyé pé ìgbésẹ̀ yíì ṣe pàtàkì lójúnà àti mú kí gbogbo ènìyàn dá sí ètò ìjọba pàápàá lórí ayélujára.
O ní àṣeyọrí tó ṣe pàtàkì jù lọ ní pé àwọn ará ìlú yóò ní ore-ọ̀fẹ́ láti dásí ìṣèjọba níbikibi tí wọn bá wà.
Sugbon ọro naa ti mu iriwisi orisirisi dani lodo awọn ara ilu lori Twitter.
Lati odun 2017 ni won ti gbe  ise atunto ojo opo naa fun agbasese.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Mustapha ní mílìònù mẹ́rìnlélọ́gọ́ta ọ̀hun yóò mójútó ètò ikọ́ni awọn oṣìṣẹ́ àti pípesè àwọn ẹ́rọ Kọ̀mpútà.
Mustapha sàlàyé pé lára àwọn ohun amóríwú tó wà lóri ojú òpó ayélujára náà ni gbogbo àwọn ìwé ìjábọ̀ àwọn ìgbìmọ aláṣẹ láti ọdún 2015 yóò wà lórí rẹ̀, àwọn ìwé àdéhùn pẹ̀lú àwọn ilé-iṣẹ́ ìlúòkèrè
O ni mílìònù mẹ́rìlélọ́gọ́ta òhun yóò mójútó ètò ikọ́ni àwọn oṣìṣẹ́ àti pípìsè àwọn ẹ́rọ Kọ̀mpútà.
Afẹ́nifẹ́re: A kò tíì ní ẹnìkankan táá gbè lẹ́yìn rẹ̀ fún ipò Ààrẹ
Oríṣun àwòrán, @SenatorAdesanya
Lẹyin ipade naa Afẹ́nifére kọ lati sọ ẹni ti wọn yoo mu laarin Buhari ati Atiku
Ori la fi n  mẹran lawo sugbọn to ba kan ọrọ yiyan ẹni ti awọn Yoruba yoo gbe lẹyin rẹ́  fun ipo Aarẹ Naijiria lọdun 2019, ọrọ naa yoo gba isiro ati apero daadaa.
Eyi lo mu ki ẹgbẹ́ Afẹnifẹre maa ti sọ pato ẹni ti wọn yoo gbe lẹyin rẹ fun idibo Aarẹ ọdun 2019.
Laipẹ yi ni ẹgbẹ naa se abẹwo si Ààrẹ àná lórílẹ̀-èdè Nàìjíríà Oluṣegun Obasanjọ lati fọrọ jomitooro ọrọ lori odo ti awọn Yoruba yoo dọra si.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ọbasanjọ lo fa Ya'Adua àti Jonathan Kalẹ, o yan Buhari pẹlú
Abajade ipade naa ko ti tọka boya wọn fẹ se ti Buhari tabi ti Atiku sugbọn ipade naa tubọ fi ifarajin ẹgbẹ afẹnifẹre lori ọrọ aato isejọba ti ọpọ mọ si ''Restructuring.''
Afẹnifẹrẹ ko sẹsẹ maa tẹnu mọ atunto isejọba gẹgẹ bi ohun to le dẹkun wahala to n koju orilẹede Naijiria .
Atunto lo le yanju ọrọ Naijiria
Sugbọn loju opo ayelujara awọn eeyan ti dari ọrọ ipade naa si ibo miran.
Ohun ti wọn n sọ bayi ni pe se Afẹnifere lasẹ lati sọ ibi ti awọn Yoruba yoo lọ lọdun 2019.
Adebambo Olugbemigun n se kayefi lori bi o ti se jẹ Obasanjọ ni Afẹnifẹre lo ba ki wọn to le sọ ẹni ti wọ́n yoo gbaruku ti fun ipo Aarẹ lọ́dun 2019
Ero ọkan Adebambo se rẹgi pẹlu ti Abiodun Bamiduro
Ko jẹ tuntun mọ pe Atiku Abubakar ati Muhammadu Buhari ni wọn jẹ oludije to lewaju lati du ipo Aarẹ lọdun 2019.
Lati igba ti Atiku ti pegede si ni iriwisi ọtọọtọ ti n waye lori ẹrongba rẹ ati boya awọn ọmọ Naijiria yoo gba lati fi Atiku rọpo Buhari ni ile ijọba.
Ti a ko ba gbagbe ,Ààrẹ àná lórílẹ̀-èdè Nàìjíríà Oluṣegun Obasanjọ ti saaju sàbẹ̀wò sí adarí ẹgbẹ́ Afenifere, Pa. Reuben Fasoranti ní ìlú Akure, tíí ṣe olú ìlú ìpínlẹ̀ Ondo.
Nibi ipade naa Obasanjo sọ pé òhún gùn lé ìrìnàjò ọ̀hún láti gba orílẹ̀-èdè Nàìjíríà kúrò lọ́wọ́ ẹgbẹ́ òṣèlú All Progress Congress (APC) lọdún 2019.
Ìbẹ̀wò ọ̀hún jẹ́ ìgbà àkọ́kọ̀ sí adarí Afẹnifẹre láti ogun ọdún sẹ́yìn.
Kíni àwọn ọmọ orílẹ̀-èdè yìí ń sọ lórí àwọn tí Obasanjọ ti yàn tẹ́lẹ̀
Kínì ìdí tí Obasanjọ fí sàbẹ̀wò sí adarí Afẹ́nifére
Kínì ìdí tí Obasanjọ fí sàbẹ̀wò sí adarí Afẹ́nifére
Ó gbóríyìn fún Afẹnifẹre fún àdúrótì, ìgbàgbọ́ nínú Yorùbá àtí ìlọsíwájú orílẹ̀-èdè Nàìjíríà
Bákannáà, ni Fasoranti dúpẹ́ lọ́wọ́ Obasanjọ fún ìgbìyánjú rẹ̀ láti mú orílẹ̀-èdè Nàìjíríà dé èbúté ogo, o fi ẹ̀dùn ọkan rẹ hàn sí bí wọn ṣe ń darí rẹ̀.
Fasoranti ní àwọn wà lẹ́yìn PDP, SDP àti ADC.
Otunba Oyewole Fasawe àti Ayọ Osuntokun ni wọn jọ kọ́wọ̀ọ́ rìn lọ síbẹ̀
Wọ́n ti yọ igbákejì olórí ilé aṣòfin ìpínlẹ̀ Òǹdò
Oríṣun àwòrán, Ondo state government
Àwọn aṣòfin ìpínlẹ̀ náà tún dìbò yan ẹlòmíràn sí ipò rẹ̀
Wọn ti yọ igbakeji olori ile aṣofin ipinlẹ Ondo, Ogundeji Iroju kuro nipo.
Nibi ijoko ile naa ni ọjọ iṣẹgun ni awọn ọmọ ileegbimọ aṣofin ipinlẹ naa ti dibo yọ Ogundeji Iroju.
Bakannaa ni wọn si ti tun fi Aṣofin Bimbo Fadoju rọpo rẹ.
Ẹkunrẹrẹ iroyin n bọ laipẹ.
Buhari: Níbo ni iná ọba tí Ọbasanjọ́ ya $16bn lé lórí wà ?
Oríṣun àwòrán, @NGRPresident
Ọbasanjọ ti kọ lẹta si Buhari eleyi to di gbajugbaja kaakiri agbaye
Aarẹ orilẹede Naijiria, Muhammadu Buhari ti sọ wi pe Aarẹ tẹlẹri, Olusegun Ọbasanjọ ni ẹjọ lati ro, lori bi ijọba rẹ se na owo to le ni trilionu marun naira ($16 billion) lori ina mọnamọna lasiko rẹ.
Aarẹ Buhari sọ eleyii ni Ọjọ Isẹgun, ni Aso Rock ni Abuja, nigba to n gbalejo awọn ẹgbẹ to n satilẹyin fun Aarẹ Buhari, ti Ọga Agba Ileẹsẹ asọbode orilẹede Naijira, Hameed Ali, se adari fun.
Bi o ti le se wipe, aarẹ naa ko darukọ Ọbasanjọ, Amọ Aare Buhari so wi pe ‘ni bo ni ipese ina mọnamọna ti aarẹ tẹlẹri naa sọ wi pe oun na iye owo to to biliọnu mẹrindinlogun dọla naa wa?’
Ti a ko ba gbagbe, isẹ ipese ina mọnamọna ni isejọba Aarẹ Ọbasanjọ lọdun (1999-2006) da owo le lasiko, sugbọn ti awọn ajafẹto omoniyan, Serap sọ wi pe, wọn se basubasu.
Serap si kan si olootu eto idajọ lorilẹede Naijiria, Walter Onnoghen, lati se ofin toto bi wọn se naa owo naa.
Koko iroyin: Àyẹ̀wò di ọ̀ranyàn ni sọọsi, Ẹ̀mí èṣù ni okunfa ipààyàn Benue
Eyi ni awọn akojọpọ iroyin ti toni.
Ìjọ Redeem: Àyẹ̀wò ojú ara wà láti dènà ìjà nínú ìgbeyàwó
Oríṣun àwòrán, @PastorFOdesola
Ìgbésẹ̀ náà ló wà láti dènà ọ̀pọ̀ lààsígbò ló ń mi ìgbeyàwó lògbò-lògbò
Ìjọ Ìràpadà ti ẹ̀mi, táa mọ̀ sí The Redeemed Chriatian Church of God (RCCG) ti fi àtẹ̀jáde tuntun kan síta.
Atẹjade naa wi pé, láti àkókò yìí lọ, àwọn àfẹ́sọ́nà tó bá fẹ́ se ìgbeyàwó nínú ìjọ náà, ni wọn yóó máa se àyẹ̀wò fúń ṣáájú ìgbeyàwó lórí àwọn ohun to so rọ̀ mọ́ ìbálòpọ̀ àti ìbímọ wọn.
Buhari: Ìwà èṣù pátápátá ni ìkọlù àti ìpànìyàn nípínlẹ̀ Benue
Oríṣun àwòrán, Benue state government
Ẹni to ba n pa eeyan ti sọ alaafia rẹ nu, o si ti di ẹni itanu ati ẹni ifib
Aarẹ Muhammadu Buhari ni ẹmi esu lo n gbe inu awọn to n pa eeyan ni ipinlẹ Benue.
Aarẹ woye ọrọ yii ninu ọrọ ibanikẹdun to fi ranṣẹ si ibi isinku awọn fada meji atawọn ọmọ ijọ mẹtadinlogun, ti awọn afunrasi apaniyan kan ṣekupa nipinlẹ Benue.
Igbakeji aarẹ, Ọjọgbọn Yẹmi Oṣinbajo, lo ṣoju fun aarẹ Muhammadu Buhari nibi eto isinku naa.E ka ekunrere re ni bii
Ìtakurọ̀sọ máa ń jẹ́ kí ìsọ̀ ìwé ìròyìn dùn
Ìsọ̀ oníwe ìròyìn àtàwọn tó ń kà a lọ́fẹ̀ẹ́
NASS: San 2 Mílíọ́nù tàbí lọ ẹ̀wọ̀n ọdún méjì fún ìlòkulò Codeine
Àbádòfin òhún ń wá ojúùtú sí òfin ìjọba Nàíjíríà (2004) tó de Oúnjẹ, àti àwọn ǹkan tó jọ mọ́ òògùn,
Ilé ìgbìmọ Aṣòfin Nàíjíríà tí buwọ́ lu àtúnṣe àbádòfin lorí ìlòkulò Tramadol tàbí òògùn ikọ́ olómi codeine pẹ̀lú àbá pé ẹni tí igbá ọ̀rọ̀ náà bá ṣí mọ́ lórí yóò fi ẹ̀wọn ọdún méjì jura tàbí kó san mílíónù méjì náìrà.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí:
Àbádòfin ọ̀hún ń wá ojúùtú sí òfin ìjọba Nàíjíríà ti ọdún 2004 tó de oúnjẹ, àti àwọn ǹkan tó jọ mọ́ òògùn,
Òfin náà tí Betty Apiafi ( PDP Rivers) ṣe onígbọ̀wọ́ fún tún ń wá àtúnṣe sí ìjìyà tí yóò ṣe é gbọ́ nílé ẹjọ́ gíga àpapọ̀ àti ti ìpínlẹ̀
Àbádòfin òhun ṣe àlàkalẹ̀ ìjìyà ẹnìkọ̀ọ̀kan láti orí ẹ̀ẹ́dẹ́gbẹ̀ta náírà, ẹ́wọ̀n ọdún méjì tàbí owó ìtanran àti ẹ̀wọ̀n papọ, tí ilé-iṣẹ́ àti gbogbo àwọn lọ́ọ̀gálọ́ọ̀gá ibẹ̀ yóò jẹbi ẹ̀sùn gẹgẹ bíi pé àwọn gan ló ṣẹ̀.
Ọbasanjọ tako ìnáwó Ààrẹ Buhari fún ìpèsè inà ọba
Ọbasanjọ tako ìnáwó Ààrẹ Buhari fún ìpèsè inà ọba
Awuyewuye kò tí ì tán lórí ọ̀rọ̀ ṣíṣe bílíọ́nù mẹ́rìndínlógún Naira tó n fa àríyànjiyàn láàrin Ààrẹ Muhammadu Buhari àti Oluṣẹgun Ọbasanjọ.
Ìgbà àkọ́kọ́ kọ́ nìyíì tí ìrú ẹ̀sùn bẹ̀ yóò jẹjáde lórí bí àwọn ìṣ'[akóso tó kọjá ṣe ná owó lórí ìná ọba, tí àwọn owó nàá kò sí mú àyípadà tó dára bá ẹ̀ka tó n pèsè ìná ní Nàìjíríà.
Àjọ tó n jàfún àkóyawọ́ lẹ́ka ètò ọrọ̀ ajé ní Nàìjíríà, (SERAP), lọ́dún 2017 nínú àbọ̀ ìwádìí kan fi ẹ̀sùn kan ìṣèjọba Olusẹgun Ọbasanjọ, olóògbé Umar Yaradua, tó fi mọ́ Goodluck Jonathan, pé wọ́n ná bílíọ́nù mọ́kànlá Naira básu-bàṣù lórí iná ọba.
'Ọ̀lọ́wọ́ òsì kọ́ndọ́rọ́'
Ṣùgbọ́n, Ààrẹ àná, Goodluck Jonathan nínú ìkède kan lójú òpó Facebook rẹ̀ ní kò ṣeéṣe fún òun sláti ná irú owó bẹ̀ ní ìnákúnàá nítorí wí pé òun làárẹ Nàìjíríà tó sọ ẹ̀ka iná mọ̀nàmọ́ná di ti aládàáni, bẹ̀rẹ̀ láti ọdún 2010, lásìkò tó se ìfilọ́lẹ̀ ètò àtúnṣe sí ẹ̀ka ìná ọba, títí di oṣù Kẹwàá, 2012, nígbà tó kéde títà àwọ̀n iléèsẹ́ tó n pèsè tó sì n pín iná. Àti pé níṣe lòún fi ìgbésẹ̀ nàá pawó wọlé fún orílẹ̀èdè Nàìjíríà.
Lọ́dún 2008 ni ilé ìgbìmọ̀ aṣojúsòfin ṣàpéjúwe bílíọ́nù mẹ́rìndínlógún tí ìṣàkóso Ọbasanjọ ná lórí iná ọba gẹ́gẹ́ bí ànádánù, tí wọ́n sì di ẹ̀bi ru àìsètò tó yẹ́ nínú àgbékalẹ̀ òwó ìṣúná, tó fí mọ́ àìní àfojúsùn ọjọ́ iwájú látọ̀dọ̀ àwọn iléèṣẹ́ tó yẹ.
Oríṣun àwòrán, @NGRPresident
Ọbasanjọ ti kọkọ kọ lẹta si Buhari eleyi to di gbajugbaja kaakiri agbaye
Ẹ̀wẹ̀, àjọ tó n jàfún àkóyawọ́ lẹ́ka ètò ọrọ̀ ajé, (SERAP), lọ́dún 2016 késí adájọ́ àgbà ní Nàìjíríà, Onídàjọ́ Walter Onnoghen, láti yan agbẹjọ́rò tí kìí sẹ tìjọba láti ṣe ìwádìí àwọn ẹ̀sùn ìwà ìbàjẹ́ tó jẹyọ nínú bí ìṣàkóso Oluṣẹgun Ọbasanjọ ṣe ná mílíọ́nù mẹ́rìndínlógún lórí iná ọba.
Bí ó ti lẹ̀ jẹ́ wí pé Ààrẹ Buhari sọ pé Ọbasanjọ ní ẹjọ́ láti jẹ́ lóri òbítíbitì owó tó ná lásìkò ìṣàkósò ọlọ́dún mẹ́jọ rẹ̀, Ọbasanjọ ti ní ẹ̀sùn nàá kò ní ẹsẹ̀ nílẹ̀, tó sì ti ní kí ìṣàkóso Buhari tẹ̀síwájú láti tanná wá ìdí òun.
Ọbasanjọ ní òun ti fèsì sí gbogbo ẹ̀sùn tí wọ́n ti fi kan òun lọ́pọ̀lọpọ̀ ìgbà lórí iná ọba, tó fi mọ́ ìwé ''My Watch'' tí òun kọ. Ó ní ''nínú ìwé nàá lòun ti ṣàlàyé ní ẹ̀kúnrẹ́rẹ́ tí òun sì tun ṣàfihàn àbọ̀ ìwádìí tí àjọ EFCC, àti ìgbìmọ̀ ilé aṣòfin tó wádìí àwn ẹ̀sùn tí bí wọ́n ṣe ná owó bàntà-banta nàá sórí ìpèsè àti pípín ìná ọba láàrin oṣù Kẹfà, 1999 sí oṣù Karùn ún, 2007, láì so èso rere.
Ìrẹsì, Jéró, Ẹ̀gẹ́ àti Ewébẹ̀ nínú ewu kòkòrò Fall armyworm
Ekòló oko ajokorun tuntun ti to n jẹ fall armyworm (FAW) ti wọ orílẹ̀-èdè ìwọ̀orùn
Ekòló oko ajokorun tuntun ti to n jẹ fall armyworm (FAW) ti wọ orílẹ̀-èdè ìwọ̀orùn àti àrin gbùngùn ilẹ̀ Àfíríkà.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí:
Èyí jẹ́ kòkòrò ajokorun ẹlẹ́ẹ̀kejì tó wọlé láti ilẹ̀ Àmẹ́ríkà tí wọn rí nínú ẹ̀gẹ́ lagbègbè gúúsù-ìlàorùn orílẹ̀-èdè Nàìjíríà nínú oṣù kejìlá ọdún 2016.
Ìdídé kòkòrò tuntun yìí sí ilẹ̀ adúláwọ̀ tí dá ìpòrúùru sí ọkan àwọn àgbẹ̀ ní orílẹ̀-èdè mẹ́rìnlélógójì tí kòkòrò náà ti wọ̀, pẹ̀lú ìsòro tí yóò kojú Jéró, ìrẹsì  àti ewébẹ̀.
Àwọn àgbẹ̀ ti kọ́kọ́ ri bíbẹ́ sílẹ̀ ọmọ kòkòrò tata èyí tó fa ọ̀pọ̀lọpọ̀ ìbàjẹ́ sí ara ẹ̀gẹ́ ní oko onílẹ̀ irínwó àbọ̀ saarè lẹ́bàá ìlú Ubiaja ní ìhà Gúúsù-ìlà Oòrùn Nàìjíríà ní ọdún 2016.
Láti ìgbà náà, kòkòrò yìí ti gbilẹ̀ gan tó sì ń jẹ ọ̀pọ̀lọpọ̀ erè oko. Irú ìwòye yìí kan náà wáyé ní ọdún 2017 ní àwọn oko kọ̀ọ̀kan yíkáa agbègbè Dasso ní apá Gúúsù orílẹ̀èdè Benin Republic.
Èyí jẹ́ kòkòrò ajokorun ẹlẹ́kejì tó wolé láti ilẹ̀ Àmẹ́ríkà
Látàrí gbogbo eléyìí, àwọn onímọ̀ sáyẹ̀nsì se ọ̀pọ̀lọpọ̀ ìwádìí àti ìgbsẹ̀ láti kojú àwọn kòkòrò yìí nípa kíkó ọmọ àti àgbà wọn ránsẹ́ sí olú ilé isẹ́ ibùdó tó wà ní ìlú Ibadan tí wọ́n ti ń se ìwádìí nípa àwọn ǹkan ọ̀gbìn nilẹ̀ olóoru, Àbájade àyẹ̀wò sì jẹ́ kó di mímọ̀ pe òótọ́ ní àwọn kòkòrò ajokorun yìí ṣẹ́ jáde.
Ilé asòfin Ondo: Olórí di méjì láàrin ọjọ́ kan soso
Oríṣun àwòrán, @jollofricejim
Igba akọkọ kọ ree tawọn asofin yoo yọ ọwọ ẹsẹ si ara wọn
Awọn asofin ipinlẹ Ondo ti fi ija pẹẹta ni Ile Igbimo Asofin ipinlẹ naa, lẹyin ti awọn asofin di ibo lati yọ Igbakeji olori Ile Asofin, Iroju Ogundeji.
Awọn asofin ti wọn pade lati jiroro ni ile asofin, ki ijoko ile to bẹrẹ, ni iroyin sọ wi pe wọn bẹrẹ ija, lẹyin awuyewuye laarin ara wọn.
Iroyin sọ wi pe, ọkan lara wọn ju ẹsẹ lu igbakeji abẹnugan ti wọn yo ọ nipo naa.
'Ọ̀lọ́wọ́ òsì kọ́ndọ́rọ́'
Ni Ọjọ Aje ni wọn yo Igbakeji Agbẹnugan ile asofin kuro ni ipo rẹ nitori aawọ to wa laarin oun ati abẹnugan ile.
Wayi o, iroyin kan tun tẹ wa lọwọ pe awọn asofin Ondo tun ti dibo pada, ti wọn si da igbakeji Olori ile tẹlẹ, ti wọn yọ ni ipo, pada si ipo rẹ.
Àwọn òṣèré tíátà dágbére fún Ọmọge campus pé ò dìgbóṣe!
Kò sí ẹni ti kò ni kú lọ́jọ́ kan
N'ise ní ìlú Èkó dákẹ́ rọ́rọ́ nígbà tí àwọn òṣeré tíátà pejọ láti ṣé ìrántí gbajugbaja òṣèré tíátà Yoruba, Aisha Abímbọ́lá to ku laipẹ́ yìí.
Awọn osere ori itage lọkunrin ati ni obinrin ni wọn si to ni ọwọọwọ pẹlu àbẹ́là lọwọ wọn lati se ẹyẹ ikẹyin fun oloogbe naa.
Ọmọge Campus, ó dàárọ̀ o
Òpó àwọn òṣeré ati ololufẹ oloogbe to wa nibẹ wọ aṣọ dudu ti wọn ya àwòrán Aisha si lati kẹdun oloogbe náà ti àrùn jẹjẹrẹ ọyàn pa lọjọ kẹrindinlogun osu karun-un ọdun 2018.
Awon osere tan ọ̀pọ̀ àbẹ́là ni iranti Aisha Abimbola
Ọgba Ile iṣẹ amóhunmáwòrán LTV ni Ikẹja ni ilú Èkó si ni ẹyẹ ikẹyin naa ti bẹrẹ.
Lara awọn osere ori itage to peju sibi ẹyẹ ikẹyin naa ni Saheed Balogun ati ilumọọka ajafẹtọ ẹni nni, Okei Odumakin.
Joe Odumakin ati Saheed Balogun wa lara awon ilumooka to pejo sibi ale iranti naa
Aisha ni ìròyìn gbalẹ̀ kan ní ààrọ̀ Ọjọ́rú, ọjọ́ kẹ́rindinlogun, osu karun-un, ọ̀dun 2018 lórí ìtàkùn àgbáyé pé, ó ti mí kanlẹ̀ lẹyin àìsàn ọlọ́jọ́ gbọọrọ.
A gbọ́ pé àìsàn jẹjẹrẹ ọyàn tó ń bá Aisha fínra, láti ọjọ́ díẹ̀ ló gba ẹ̀mi rẹ̀.
Ọ̀pọ̀ àwọn òsèré tíátà, tí wọn jẹ́ akẹẹgbẹ́ rẹ̀ ni wọ́n ń se ìdárò iku Aisha Abimbọla
Ọ̀pọ̀ àwọn òsèré tíátà, tí wọn jẹ́ akẹẹgbẹ́ rẹ̀ ni wọ́n ń se ìdárò ikú ìlúmọ̀ọ́ká òsèrè tíátá obìnrin náà láwọn ojú òpó ìkànsíra ẹni wọn lórí ìtàkùn àgbáyé Facebook àti Instagram.
Aago mẹ́jọ alẹ́ ọjọ́bọ, ọjọ kẹ́tadinlogun osu karun-un ni wọn sìnkú olóògbé Aisha Abimbọla ní orílẹ̀èdè Canada.
Koko iroyin: Ìjọ Àgùdà ni ẹ̀jẹ̀ pọ̀ ní Nàíjíríà, Àwọn asòfin gbára wọn lẹ̀sẹ́ l‘Ondo
Eyi ni awọn akojọpọ iroyin ti toni.
Ìjọ Àgùdà ni kò dára ká máa ké gbàmí-gbàmí kiri lójoojúmọ́
Ìjọ Àgùdà: Kò dára ká máa ké gbàmí-gbàmí kiri lójoojúmọ́
Àwọn ọmọ ìjọ Àgùdà ní ìlú Èkó se ìwọ́de ní ọjọ́ ìsẹ́gun pé kí ìjọba tètè fòpin sí ìwà ìsekúpani tó ń wáyé ní ojoojúmọ́.
Wọn wá rọ ìjọba àpapọ̀ láti tètè fòpin sí ìtàjẹ̀sílẹ̀ ojoojúmọ́ yìí.
Ilé asòfin Ondo: Olórí di méjì láàrin ọjọ́ kan soso
Oríṣun àwòrán, @jollofricejim
Igba akọkọ kọ ree tawọn asofin yoo yọ ọwọ ẹsẹ si ara wọn
Awọn asofin ipinlẹ Ondo ti fi ija pẹẹta ni Ile Igbimo Asofin ipinlẹ naa, lẹyin ti awọn asofin di ibo lati yọ Igbakeji olori Ile Asofin, Iroju Ogundeji.
Iroyin sọ wi pe, ọkan lara wọn ju ẹsẹ lu igbakeji abẹnugan ti wọn yo ọ nipo naa. Ẹ ka ẹkunrẹrẹ nibi
'Kò sí ǹkan tí ọwọ́ ọ̀tún ń se tí ọwọ́ òsì kò lè se'
'Ọ̀lọ́wọ́ òsì kọ́ndọ́rọ́'
Ileesẹ ọmọogun Nàìjìríà: A ò fipá bá ẹnikẹ́ni lò ní ìpàgọ́
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Sùgbọn agbẹnusọ fún àjọ ọmọogun sọ pé irọ́ pátápátá ni ọrọ náà pé àwọn ń fi tipátipá báwọn aṣàtìpó lájọṣepọ̀
Ìròyìn tuntun tún jáde pé àwọn ọmọogun orílẹ̀-èdè Nàìjìríà ń ṣe àwọn ọ̀dọ́mọbìnrin àti àwọn abilékọ to sá fún ìkọlù Boko Haram báṣubàṣu.
Àjọ ajàfẹ́tọ̀ọ́ Amnesty International ni àwọn aṣàtìpó ń ṣe èyí ní àwọn aṣatipo ń fi ṣe pàṣípààrọ̀ pèlú ounjẹ̀ àti àti àwọn ohun èlò mííràn tókù ni ibùdó ní.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí:
Ìròyìn tó tẹ BBC Yorùbá lọ́wọ́ sọ pé ẹ̀rí Amnesty International dá lórí ìfọ̀rọ̀wánilẹ́nùwò ti wọn ṣe fún àwọn àádọ́talénígba eniyan ní budo àwọn tó sá fun ìkolù Boko Haram tí wọn ṣe láàárin ọdún 2016 sí 2018.
Wọn ní àwọn ọmọogun máa ń fipá bá àwọn obìnrin sùn ti wọn sì ń fiwọn fọ́kọ pẹ̀lúu túlàsì, Amnesty ni wọn rí èyí ṣe ní ìdápadà fún oúnjẹ àti ààbò.
Obìnrin mẹ́sà-án ní wọn ti fi tipá bálòpọ tí wọn sì fi ìyàwó àwọn Boko Haram séwọ̀n lọ́nà àìtọ́, pẹ̀lú ẹ̀rí pé àwọn márùn-ún àti ọmó wẹ́wẹ́ méjìlélọ́gbọ̀n ló ti kú.
Sùgbọn agbẹnusọ fún àjọ ọmọogun sọ pé irọ́ pátápátá ni ọrọ náà pé àwọn ń fi tipátipá báwọn aṣatipo lájọṣepọ̀ ni ipagọ.
Kin lo de ti ọ̀rọ̀ ajínigbé ni Kaduna ń peléke síi?
Oríṣun àwòrán, Getty Images
T'obìnrin àti t'ọmọde ni wọn ń jigbe kaakiri bayii
Ọrọ ti di ojú ni alákàn fi ń ṣọ́rí nipinlẹ Kaduna báyìí lọ́wọ́ àwọn ajínigbé
Ọpọ̀ ìgbà ni àwọn oníṣẹ́ ibi ti foju àwọn ènìyàn Brinin Gwari nipinlẹ Kaduna ri èèmọ̀ láti ìgbà díẹ̀ sẹyin.
Lẹyin ti wọn pa ọ̀pọ̀lọpọ̀ laípẹ nigbe wọn de etí ijọba apapọ Nàìjíríà, ti Aare Buhari si ni ki ikọ̀ àwọn ọmọ ogun ati agbofinro kan kó lọ sibẹ.
Awọn awakọ ni agbegbe Birnin Gwari lo tun kigbe pe àwọn ajinigbe ji àwọn èrò to to marundinlaadọta to n lọ lati àríwá si gúúsù Nàìjíríà gbé.
Àwọn ajinigbe ń ṣọṣẹ́ ni Birnin Gwari
Wọn ni àwọn agbebọn fipa ń da ọkọ duro ti wọn si n ko èrò wọ inu igbó lọ.
Ọpọ ẹbí lo ń wa owó ìtanràn bayii bii ti oloselu Zamfara ti àwọn ọlọpaa ṣì ń wa iyawo rẹ ati ọmọ mẹfa ti àwọn ajinigbe ji bayii.
Awon to n gbe agbegbe yii ni ijọba ko tii mu ìlérí to ṣe fún wọn lori ìpèsè ààbò ṣẹ́ rara
Ebola: Àwọn aláìsàn mẹ́ta sá kúrò níléwòsàn ní DR Congo
Oríṣun àwòrán, AFP
Ó lé ní ẹgbẹ̀rún mọ́kànlá ènìyàn tí àìsàn Ebola pa ní ẹkùn Ìwọ̀ Oòrùn Afrika láàrin 2014 sí 2016
Àwọn aláìsàn Ebola mẹ́ta sá kúrò ní ibùdó ìtọ́jú gba ṣọ́ọ̀sì lọ ní orílẹ̀-èdè Democratic Republic of Congo.
Àjọ tó n mójútó ètò ìlera ní àgbáyé, WHO, ní wọ́n fi ilé ìwòsàn ti wọn ti n gba itọju sílẹ̀ lẹ́yìn tí àwọn mọ̀lẹ́bí wọn ní àwọn gbọdọ̀ gbé wọn lọ sí ṣọ́ọ̀ṣì.
Méjì nínú àwọn aláìsàn nàá padà jẹ́ Ọlọ́run nípè, tí ẹnì kẹta padà sí ibùdó ìtọ́jú nàá ní ìlú Mbandaka.
Èyí ti wá mú kí ẹ̀rù ma ba àwọn aláṣẹ pé ó ṣeéṣe kí àìsàn nàá tàn yíká ìlú Mbandaka. Àti pé sísá tí àwọn èèyàn naa sá nílé ìwòsàn jẹ́ ìpèníjà ńlá fún àwọn òṣìṣẹ́ ètò ìlera tó n là kàkà láti fòpin sí ìtànkálẹ̀ Ebola ní orílẹ̀-èdè DR Congo.
Ìgbà kẹsàn án nìyí tí àìsàn Ebola yóò bú jáde ní orílẹ̀èdè DR Congo.
WHO ní àwọn ẹbí àwọn aláìsàn nà wá sí ibùdó ìtọ́jú ọ̀hún, tó jẹ́ ti àjọ aláànú, Medecins Sans Frontieres, tí wọ́n sì ní kí wọ́n yọ̀ǹda àwọn ènìyàn wọn fún wọn, kí àwọn le gbé wọn lọ fún ètò àdúrà, tí wọ́n sì gbé wọn lọ lórí ọkàdà.
Ilé ìwòsàn MSF ní gbogbo akitiyan àwọn òṣìṣẹ́ ilé ìwòsàn nà láti káwọn lọ́wọ́ kò, ló já sí pàbó.
Ní báyìí, wọ́n tí n ṣọ́ àwọn ẹbí àwọn aláìsàn mẹ́tẹ̀ẹ́ta, tí díẹ̀ lára wọn sì ti gba abẹ́rẹ́ àjẹsára nítorí Ebola.
Àjọ WHO ní ''ìtànkálẹ̀ àìsàn náà ní agbára láti pọ̀ ju ti tẹ́lẹ̀ lọ.''
Ọjọ́ kọkànlélógún, oṣù Kárùn, ni àwọn òṣìṣẹ́ ètò ìlera bẹ̀rẹ̀ sí ní fún àwọn ará ìlú ní abẹ́rẹ́ àjẹsára, láti dá ìtànkálẹ̀ àìsàn náà dúró.
Ìgbà kẹsàn-án nìyí tí àìsàn Ebola yóò bú jáde ní orílẹ̀-èdè DR Congo.
Keyamo: Cocaine tí ò ń fà ní o da orí rẹ rú
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Bi ó tilẹ̀ jé pé Ààrẹ Muhammadu Buhari kò dárúkọ Ààrẹ kankan nínú ọrọ rẹ̀
Lórí awuyewuye tó ń tàn ká lórí ẹ̀sùn tí Ààrẹ Muhammadu Buhari fí kàn ààrẹ àná, Oloye Oluṣẹgun Ọbasanjọ
Esun naa kò ṣẹyin owó bilìọ̀nù dọ́là mẹrindinlogun to yẹ fún iṣẹ́ mọ̀namọ́na lórílẹ̀-èdè Nàìjíríà tí kò ní ipa lo tí dì ohun ti à ń gbà bí ẹní gba igbá ọtí láàárín àwọn èèkàn orílẹ̀-èdè yìí.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí:
Ẹ jẹ́ kí Buhari lọ jókòó
Ààrẹ Muhammadu Buhari kò dárúkọ Ààrẹ kankan, sùgbọn ní báyìí àwọn olólùfẹ́ Ààrẹ Buhari àti Ààrẹ Ọbasanjọ tí bẹ̀rẹ̀ sí ní tahùn sí ara wọn bayii.
Fún àpẹrẹ, Femi Fani Kayode ni aṣiṣe nla ni Ọbasanjọ ṣe ti kò sọ Buhari sẹwọn lori kiko owo PTF jẹ. O ni ko yẹ ki Ọbasanjọ gba ẹbẹ Buhari nigba to ń sunkun bi ìkókó pe
Bẹẹ, Dada kò le ja ni ọrọ Buhari, o ni aburo to gboju nitori pe Festus Keyamo naa fun Femi Fani-kayode lesi pe, aṣiṣe Ọbasanjọ ni yiyan àwọn to n mu oogun oloro sipo olori bii Fani-kayode
Àjọ tó n jà fún àkóyawọ́ lẹ́ka ètò ọrọ̀ Ajé ní Nàìjíríà, (SERAP), lọ́dún 2017 nínú àbọ̀ ìwádìí kan fi ẹ̀sùn kan ìṣèjọba Olusẹgun Ọbasanjọ, olóògbé Umar Yaradua, tó fi mọ́ Goodluck Jonathan, pé wọ́n ná bílíọ́nù mọ́kànlá Naira básu-bàṣù lórí ọrọ iná ọba.
Trump: ojú agan tí Kim gbé ni mo se wọ́gilé ìpàdé wa
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Aarẹ Trump kesi Kim lati pe oun lori ẹrọ ayelujara to ba ti yi ọkan rẹ pada
Aarẹ Ilẹ Amẹrika, Donlad Trump ti fagile ipade po pẹlu Aarẹ Ilẹ North- Korea, Kim Jong-Un.
Aarẹ Trump wi pe, oun gbe igbesẹ naa nitori oju agan ati ọrọ ibinu ti o tẹnu aarẹ ilẹ North Korea naa jade ninu atẹjade rẹ.
Trump ninu atẹjade rẹ fikun wi pe, oun ti o tọ ni lati takete si ipade naa nitori North Korea sọ wi pe, oun ni ohun ija asekupani ọlọgọọrọ nuclear.
Amọ, aarẹ ilẹ Amẹrika naa ni, ohun ija ilẹ Amẹrika ju ti North Korea lọ, sugbọn awọn lero wi pe, awọn ko ni nilo rẹ rara.
Ọmọge Campus jẹ́ ẹni tó kó ẹbí mọ́ra
Nipari atẹjade naa, Aarẹ Trump kesi Kim lati pe oun lori ẹrọ ayelujara oun, to ba ti yi ọkan rẹ pada.
Ti a ko ba gbagbe, ọkan lara awọn asoju fun ilẹ North-Korea, Choe Son-hui ni ọrọ asan ni ọrọ Aarẹ Trump to wi pe North Korea yoo dabi Libya.
Koko iroyin: awon elere tiata sedaro aisha abimbola, ‘Fani-Kayode n fa Cocaine’
Eyi ni awọn akojọpọ iroyin ti toni.
Àwọn òsèré: Ìgbé ayé Ọmọge Campus jẹ́ ẹ̀kọ́ fún wa
+
Àwọn òsèré: Ìgbé ayé Ọmọge Campus jẹ́ ẹ̀kọ́ fún wa
Ìkẹ̀jà pa lọ́lọ́ lálẹ́ ọjọ́rú nígbàtí àwọn òsèré tíátà tò lọ́wọ̀ọ̀wọ́ pẹ̀lú àbẹ́là lọ́wọ́ wọn èyí tí wọn fi ń se ẹ̀yẹ ìkẹyìn fún Aisha Abimbọla.
Àwọn gbajúmọ̀ òsèré bíi Saheed Balogun, Sọla Kosọkọ, Sunkanmi Ọmọbọlanle ati ajàfẹ́tọ̀ọ́ ẹni, Okei Odumakin ni wọ́n se ìdárò olóògbé náà.
Wọ́n fi kún-un pé Obìnrin dúndùn abi ìwà dúndùn ni Aisha.
Festus Keyamo ni cocaine tí Femi Fani-Kayode ń fà ní o da orí rẹ rú
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Bi ó tilẹ̀ jé pé Ààrẹ Muhammadu Buhari kò dárúkọ Ààrẹ kankan nínú ọrọ rẹ̀
Àwọn olólùfẹ́ ààrẹ méjèèjì sọ̀rọ̀ òdì sí ara wọn nítorí ẹ̀sùn bílìọ̀nù mẹ́rìndínlógún dọ́là tí Ààrẹ Muhammadu Buhari fí kàn ààrẹ àná, Oloye Oluṣẹgun Ọbasanjọ
Esun naa kò ṣẹyin owó bilìọ̀nù dọ́là mẹrindinlogun to yẹ fún iṣẹ́ mọ̀namọ́na lórílẹ̀-èdè Nàìjíríà tí kò ní ipa lo tí dì ohun ti à ń gbà bí ẹní gba igbá ọtí láàárín àwọn èèkàn orílẹ̀-èdè yìí. E ka ekunrere re ni bii
Ọmọge Campus jẹ́ ẹni tó kó ẹbí mọ́ra
Ọmọge Campus jẹ́ ẹni tó kó ẹbí mọ́ra
Kí ló n dá iṣẹ dúró lórí afárá ọya kejì?
Oríṣun àwòrán, @BashirAhmaad
Wọn kọkọ bẹrẹ iṣẹ ipile afárá náà labẹ ìjọba Goodluck Jonathan lọdun 2014
Ẹnikẹ́ni to bá ti ni anfààní ati rin irinajo kọja lorí afárá odo ọya to so Onitsha ni ila oòrùn gúsù àti Asaba ni apá gúúsù yóò mọ ìnira ti ojú àwọn arinrin-ajo máà n rí l'agbegbe òun.
Mímú idẹkùn bá ará ìlú wá lara idi ti awọn ijọba to ti kojá sẹyìn ni Naijiria fi ni, awon yóò kọ afárá keji ti yóò gbà orí odo ọya kọjá.
Ala náà kò ti di mimuṣe bi a ti ṣe n ko ìròyìn yìí jọ, ṣugbọn ó yẹ ká mọ nkàn díẹ̀ nípa afárá náà.
Ọdún tí wọn kọ afárá odo ọya àkọkọ
Ọdún kàn ní wọn fí ko afárá odo ọya àkọkọ láàrin 1964-1965.
Olori ijoba nigba naa, Tafawa lo ṣé ìfilọ́lẹ̀ rẹ lọdun 1966.
Oríṣun àwòrán, @BashirAhmaad
Àwọn ìṣe ìpìlẹ afárá náà nìkàn ní wọn ṣì ṣé
A gbọ pe mílíọ̀nù mẹfa pọ́un o le diẹ, ni wón fún agbàṣẹ́se tó kọ afárá ọhun nigba náà.
Nígbà ogun abẹ́lé Nàìjíríà to waye laarin ọdun 1967-1970, wọn já apa kan afárá náà.
Ọpọ ìjọba àná lorílè-èdè Naijirià lo ti tẹpele mo pàtàkì kíkọ afárá keji, ti yóò gbà orí odò ọya kọjá lati mú adinku ba sùnkẹrẹ fakẹrẹ ti o pọ lórí afárá àkọkọ.
L'ọdun 2007, Aare àná Olusẹgun Obasanjo ṣe ayẹyẹ ìfilọ́lẹ̀ iṣẹ lórí afárá náà, eyi t'owo rẹ to biliọnu mejidinlogoji naira le díè.
Ọdún mẹrin ni wọn ní àwọn yóò fi parí afárá náà.
Eto idokowo pọ láàrin ìjọba àti aladani sí ni won láwọn yóò fí ṣe e.
Jonathan náà ṣe ìfilọ́lẹ̀ tiẹ
Nígbà ti ìdìbò ọdún 2015 n sunmọ, ìjọba Ààrẹ Goodluck Jonathan kéde pé oun yóò bẹrẹ iṣẹ lórí afárá keji.
Tayọ ti ìdùnnú láwọn ará agbègbè náà fi gba ìròyìn náà.
Biliọnu metadinlọgofa naira ni wọn láwọn yóò fi kọ afárá náà àti ojú ọnà tó so pọ.
Wọn  bẹrẹ iṣẹ níbi afárá náà ti wọn sì  bẹrẹ sí ní rí opo ti yóò di afárá náà mú.
Ọdún mẹrin láwọn náà láwọn yóò fi kọ.
Ìjọba Jonathan lo kọkọ san owó fún ile iṣẹ Julius Berger, láti bẹrẹ iṣẹ ipile afárá náà.
Owó tí wọn sàn ló jẹ kí wọn lè ṣíṣe lórí ipele kinni, ìkejì àti lára ìpele kẹta iṣẹ ipile afárá náà.
Ìbí ti wọn bá iṣẹ dé ní ìjọba Buhari tí gbà a.
Àlàyé pàtàkì àkọkọ nipa afara odo ọya ní pé, àjọṣepọ pẹlú aladani ni awọn ijoba orisirisi n gbèrò láti lo fi kọ afárá elèkejì yii.
Labẹ ijoba Buhari, awọn naa kò ti f'owo bọ ìwé lórí iye owó pato tí wọn yóò fi parí gbogbo iṣẹ pátápátá lórí afárá keji.
Oríṣun àwòrán, @Laurestar
Wọn ti fẹ mú ọrọ̀ òṣèlú wọnú kikọ afárá náà
Mínísítà fún ètò òhun amusagbara, iṣẹ ode ati ilegbe, Ọgbẹni Babatunde Fashola, ko ye maa tẹnumọ ifarajin ìjọba ode oni láti kọ afárá náà.
Lai pé yí ni awuyewuye wáyé lórí dédé ìbí ti won ba iṣẹ dé lórí afárá náà.
Nigba to n ṣe àyẹwò sí afárá náà, Fashola ni iṣẹ ibẹrẹ pẹpẹ riri òpó tí yóò mú afara náà dúró ni awọn sí n ṣé lọwọ, ti ọ sí ti dé idà àádọta nínú ìdá ọgọrun dédé iṣẹ naa.
Olóri aṣòfin Ekiti: Igbákejì mi ń hùwà kòtọ́ la se yọ́ nípò
Oríṣun àwòrán, Ekiti State Government
Ile asofin Ekiti nigba ti Gomina Fayose gbe aba isuna odun 2017 wa si iwaju won
Yorùbá ní ohun tó ń se Lébánjé kò se ọmọ rẹ̀, Lébánjé ń sunkú owó, ọmọ rẹ̀ ń sunkún ọkọ.
Bẹ́ẹ̀ ni ọ̀rọ̀ rí ní ìpínlẹ̀ Èkìtì nítorí lọ́jọ́ ti Gómìnà Ayodele Fayose, tií se gómìnà ìpínlẹ̀ náà n ṣé ìfilọ́lẹ̀ ilé ẹjọ gíga ìpínlè Èkìtì, ni àwọn aṣòfin gbimọrán láti yọ igbákejì olórí ilé àti akojanu ilé asòfin ìpínlẹ̀ náà.
Ọgbẹni Adesegun Adewumi àti Ọgbẹni Akinniyi Sunday ni won yọ bi ẹni yọ jìgá ní ọjọ́rú ní ipò ìkọ̀ọ̀kan kóówá wọn.
Kété ní àwọn ọmọ ile sí ti yan Ọgbẹni Onigiobi Olawale, láti rọpo Akinniyi gẹgẹ bí akojanu ilé.
Ìròyìn tó tẹwa lọwọ sọ pé, olórí ilé, Akinyẹle Olátúnjí fẹ̀sùn kan igbákejì rẹ̀ pé o ń kópa nínú àwọn ìwà kan tó lè ṣe àkóbá fún ìdúró-sìnsìn ilé.
Àwọn asòfin méjìdínlógún ni wọ́n lò tọwọ bọ ìwé iyọni nípò òhun, ni ìbámu pẹlú òfin orílèèdè Nàìjíríà.
Àmọ́ Gómìnà Ayodele Fayose kò ti sọrọ kánkan lórí ìṣẹlẹ náà, yálà lójú òpó Twitter rẹ tàbí láti ẹnu àwọn oluranlọwọ rẹ.
Bẹ́ẹ̀ bá sì gbàgbé, wákàtí mẹ́rìnlélógún sẹ́yìn ni irúfẹ́ ìsẹ̀lẹ̀ yìí wáyé ní ìpínlẹ̀ Ondo, níbití wọn ti yọ igbákejì ilé asòfin ìpínlẹ̀ náà, kí wọn tó dáa padà ní ọjọ́ kejì sí ipò rẹ̀.
Kwesi gbòmìnira lọ́wọ́ ọlọ́pàá lẹ́yìn ìfọ̀rọ̀wánilẹ́nùwò
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ohun tó ṣẹlẹ̀ ní Ghana yíì tí kóbá ẹgbẹ́ àgbábọ́ọ̀lù ibẹ̀ láti rí onígbọ̀wọ̀ fún eré bọ́ọ̀lú
Wọ́n ti kìlọ̀ ìṣọ́ra fún ààrẹ ẹgbẹ́ agbábọ́ọ̀lù orílẹ̀-èdè Ghana àti igbákejì àjọ CAF,  Kwesi Nyantekyi
Bákan náà ní wọn ti gba ìdúró rẹ̀ lẹ́yìn tí wọn ṣe ìfọ̀rọ̀wánilẹ́nùwò fún un tán lóri lílo ọ̀nà àlùmọ̀kọrọ́yí lu jìbìtì.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí:
Àwọn ọlọ́pàá sọ fún ikọ̀ ìròyìn BBC pé wọn ó pèé lẹ́jọ́ ní ìlànà òfín ní kété tí ìwádìí bá ti parí.
Nyantekyi ní wọn kámọ́ nínú fọnrán kan tó tí ń ṣe ìpàdé ìdákankọ́ olówó ńlá kan lórúkọ ààrẹ orílẹ̀-èdè Ghana, Nana Akufo-Addo, àti igbákejì rẹ̀.
Lẹ́yìn ìfọ̀rọ̀wáni-lẹ́nùwò bíi wákàtí márùn-ún pẹlu ọ̀ga ọlọ́pàá, tí wọn sì yẹ ẹ̀rọ kọ̀mpútà àti ilé rẹ̀ wò, kò sí ohun kan tó ṣe àkóbá fún.
Ohun tó ṣẹlẹ̀ ní Ghana yíì tí koba ẹgbẹ́ àgbábọ́ọ̀lù ibẹ̀ láti rí onígbọ̀wọ̀ fún eré bọ́ọ̀lú ní orílẹ̀-èdè náà.
Gani Adams: 'Ìdàgbàsokè nínú ìmọ̀ ló jẹmí lógún'
Oríṣun àwòrán, Aare ona/Instagram
Ọ̀pọ̀ àwọn ololúfẹ́ ààrẹ lo tí ń kíi kú oríre
Ààrẹ ọ̀nà kakanfò ilẹ̀ Yorùbá, Gani Abiodun Adams, gbá ìwé ẹ̀rí nínú ìmọ̀ ètò òṣelú, (political Science) nile ìwé gíga fáfitì ti ipinlẹ Eko.
Ààrẹ sọ èyí di mímọ̀ lóri ojú òpó ìkànsíraẹni Instagram rẹ.
Ó ní òún ṣe èyí fún ìdàgbàsókè ara òun nítorí pe òún fẹ́ran ìwé kíkà púpọ.
Bákan náà ló gba ọdọ níyànjú láti múrawọn dàgbàsókè nínú ẹ̀kọ́ ohun gbogbo ti wọn ba yàn láàyò.
Ọ̀pọ̀ àwọn ololúfẹ́ rẹ̀ lo sì tí ń kíi kú oríre
Kò si ohun to ni ibẹrẹ ti kii ni òpin
Oloye Gani Adams ni aarẹ ọna kakanfo tuntun fun gbogbo ilẹ Yoruba.
Bàbá kan fipá bá ọmọbìnrin rẹ̀ mẹ́rin lòpọ̀ ní Pọtá
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ifipábanilòpọ̀ máa ń fa ẹ̀rù, ìbànújẹ́ àti ìrònú ni
Ilé ẹjọ́ Magistrate kan tó wà ní ìlú Port Harcourt ní ìpínlẹ̀ Rivers ti ju ọkùnrin kan sẹ́wọ̀n lẹ́yìn tí wọ́n fi ẹ̀sùn kàń án pé ó ń fipá bá àwọn ọmọ rẹ̀ obìnrin mẹ́rin lajọṣepọ̀.
Michael Akpan Isaiah, to jẹ aṣọ́gbà ni wọ́n fi ẹ̀sùn kàn pé ó fi ipá bá àwọn ọmọ nàá tí ọjọ́ orí wọn jẹ́ ọdún méjì, méje, mọ́kàńlá àti mẹ́tàdínlógún, ló ń kojú ẹ̀sùn mẹ́ta tó ní i ṣe pẹ̀lú ìfipá-báni-lòpọ̀.
"Bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé kò sí agbẹjọ́rò kankan tó ṣojú rẹ̀ ní ilé ẹjọ́, ó faramọ́ èrò ilé ẹjọ́, ṣùgbọ́n ó ní ''èṣù ló ti òun'' láti ṣe bẹ́ẹ̀ nítori pé ""òun n bẹ lábẹ́ ìdarí àwọn ẹ̀mí burukú ni."""
Adájọ́ ilé ẹjọ́ nàá, Onídàjọ́ Zinna O. Alikor ní, nkan èèwọ̀, ìṣẹ́ ibi, tó fi mọ́ ìwà ìkà ni ohun tí ọkùnrin nàá ṣe.
Abikẹ Dabiri: Iṣẹ́ pọ̀ lọ́wọ́ Naptin àti àwọn aṣọ́bodè Nàìjíríà
Adájọ́ ní, ilé ẹjọ nàá kò ní agbára láti gbọ́ ẹjọ nàá, ṣùgbọ́n ó pa á láṣẹ pé kí wọ́n gbé ìwé ẹjọ́ nàá lọ síwájú Olùdarí iléesẹ́ tó wà fún ìgbẹ́jọ́ fún ìmọ̀ràn tó yẹ.
Ẹ̀wẹ̀, ó ní kí wọ́n fi ọ̀kùnrin nàá sí ọgbà ẹ̀wọ̀n nàá títí di ìgbà tí ìgbẹ́jọ́ yóò maa tẹ̀síwájú.
Nínú ẹ̀rí tó jẹ́ nílé ẹjọ́, aṣojú ẹgbẹ́ àwọn agbẹjọ́rò obìnrin ní  Nàìjíríà, (FIDA), Fortune Ada Ndah, sọ fún ilé ẹjọ pé ó ti lé ní ọdún mẹ́ta tí olùjẹ́jọ́ ọ̀hún tí n fi tipá-tipá ṣe kòtọ́ pẹ̀lú àwọn ọmọ rẹ̀. Àti pé, àwọn ní èsì àyẹ̀wò ilé ìwòsàn tó fi ìdí ọ̀rọ̀ náà múlẹ̀.
Ndah ní, níṣe ni Alikor maa ń na àwọn ọmọbìnrin nàá bíi bàrà lásìkò tó bá ti fẹ́ bá wọn lòpọ̀.
Ṣùgbọn, àṣírí tú lásìkò tí ọmọ rẹ̀ ọkùnrin ka a mọ́ ìdí ìwà burúkú náà. Lẹyìn èyí ni wọ́n fi ọ̀rọ̀ ọhun tó iléèṣẹ́ tó n ṣe ìwádìí ìwà ọ̀daràn ní ìpínlẹ̀ Rivers létí.
Ẹ̀wẹ̀, ó di ẹ̀bi ọ̀rọ̀ nàá ru ìyá àwọn ọmọ rẹ̀ nítorí pé kò súnmọ́ àwọn ọmọbìnrin nàá bó ṣe tọ́, bíbẹ̀kọ̀ọ́, ì bá ti mọ̀ pé irú nkan bẹ̀ n wáyé.
Ṣùgbọ́n, ìyá àwọn ọmọ náà ní ''òun fí ẹjọ́ ọkọ òun sun àwọn ẹbí rẹ̀ nígbà tí òun ṣe àkíyésí àrà tó n fi àwọn ọmọbìnrin náà dà, àmọ́ tí wọn kò gbé ìgbésẹ̀ kankan. Àti pé, níṣe ni ọkùnrin nàá n dún kookò mọ́ ẹnikẹ́ni tó bá takòó.
Ṣé ó ṣeéṣe kí ìtàn tún ara rẹ̀ sọ nínú ìdìbò gómìnà l'Ekiti?
Oríṣun àwòrán, JFK/ELEKA/TWITTER
Ẹlẹka àti Fayẹmi ni yoo ṣoju ẹgbẹ PDP ati APC ninu eto idibo gomina to m bọ ni Ekiti
Ta ni yóò kó lọ sílé ìjọba ni Adó Ekiti?
Ọjọ́ kẹrìnlá, oṣù keje ni ètò ìdìbò sípò gómìnà ní ìpínlẹ̀ Ekiti yọò wáyé.
Oríṣiríṣi ìgbáradì ló sì ti n wáyé nínú àwọn ẹgbẹ́ òṣèlú tó n kópa, pàápàá ni All Progressives Congress, (APC) àti Peoples Democratic Party, (PDP).
Lẹ́nu lọ́ọ́lọ́ yìí ni ẹgbẹ́ APC ṣe ìfilọ́lẹ̀ ìgbìmọ̀ ẹlẹ́ni mẹ́tàdínlọ́gọ́rin láti polongo fún olùdíje ẹgbẹ́ nàá, Kayọde Fayẹmi. Àwọn gómìnà mẹ́rìndínlógún ni yóò darí ikọ̀ ìpolongo náà.
Èyí wáyé lẹ́yìn tí fídíò kan ṣe àfihàn àwọn ọ̀dọ́ kan tó n ba pátákó ìpolongo ìbò Fayẹmi jẹ́.
Bákan náà ni gómìnà ìpínlẹ̀ Ekiti lọwọlọwọ, Ayọdele Fayoṣe, naa léwájú ètò àdúrà kan, níbi tó ti sọ pé ''kò sí bí igbákejì òun yóò ṣe kùnà nínú ètò ìdìbò náà''.
Ìròyìn kan tilẹ̀ tún sọ pé Ààrẹ Muhammadu Buhari sọ pé ''òun mọ̀ pé àwọn ènìyàn ìpínlẹ̀ Ekiti kò ní ṣe àṣìse láti díbó yan PDP lẹ́ẹ̀kan si i.
'Oúnjẹ ibìkan jẹ́ èèwọ̀ ibòmíì ni ọ̀rọ̀ ọmú ńlá'
Àwọn ìṣẹ̀lẹ̀ má-ni-gbàgbé nípa ìdìbò gómìnà Ekiti ní 2014
Bi ọmọ kò bá bá ìtàn, ó di dandan kó bá àrọ́bá.
Nínú ètò ìdìbò gómìnà tó wáyé ní ìpínlẹ̀ nàá l'óṣù Kẹfà, 2014, oríṣiríṣi awuyewuye ló wáyé ṣaajú àti lẹ́yìn ètò ìdìbò nàá.
Àwọn òṣiṣẹ́ elétò ààbò dá àwọn gómìnà kan láti inú ẹgbẹ́ All Progressives Congress pada. Wọn kọ̀ láti jẹ ki wọn wọ ìpínlẹ̀ Ekiti lọ́jọ́ tí ètò ìdìbò naa ku ọjọ́ méjì.
Èròngbà àwọn gómìnà ọhun, tó fi bá àwọn olóyè ẹgbẹ́ APC, ni láti darapọ̀ mọ́ àṣekágbá ipolongo ìbó fún aṣojú ẹgbẹ́ rẹ, tó tún jẹ́ gómìnà ìpínlẹ̀ Ekiti lásìkò idibo náà, Kayọde Fayẹmi.
Lara àwọn gómìnà ọ̀hún ni Rotimi Amaechi, tó ti di mínísítà fún ètò ìrìnnà báyìí, àti Adams Oshiomole, tó jẹ́ gómìnà ìpínlẹ̀ Edo lásìkò náà.
Ẹgbẹ́ APC, ní abajade ìṣẹ̀lẹ̀ ọ̀hún ní, dídá tí àwọn òṣìṣẹ́ elétò ààbò dá àwọn ọmọ ẹgbẹ́ àwọ̀n dúró.
Ati pe igbesẹ yii kò ṣẹ̀yìn àṣẹ tó wá láti òkè ki àwọn má lè ri ọwọ mu ni.
Ni idakeji ẹ̀wẹ̀, awọn tí PDP ní ọ̀nà láti mú kí ìdìbò náà lọ láì sí rúdurùdu kankan ni ijọba PDP to wa lori aleefa lasiko yii ṣe gbe igbesẹ naa.
Oríṣun àwòrán, @APCNigeria/@PDP
Ẹgbẹ́ PDP àti APC tí n lérí pé ọwọ́ àwọn ni ipò gómìnà yóò bọ́ sí l'Ekiti
Ẹ̀wẹ̀, lẹ́yìn ètò ìdìbò náà ni ọmọ iléesẹ́ ológun kan, Ọ̀gágun Sagir Koli, fi fọ́nrán kan síta, èyí 'tó ṣe àfihàn ohùn àwọn èèkàn nínú ẹgbẹ́ òṣèlú PDP, nínú èyí tí a ti rí mínísítà fún ọ̀rọ̀ iléeṣẹ́ ọlọ́pàá, Jelili Adesiyan, Musiliu Ọbanikoro, Iyiola Omisore, Ayọdele Fayose, ti oun náà jẹ́ olùdíje lasiko yii, tó tun wa padà jáwé olúborí.
Nínú fọ́nrán ọ̀hún ni wọ́n ti n jíròrò lórí ọ̀nà tí wọn yóò gbà 'ṣe màgòmágó' ìbò nà, ṣùgbọ́n tí ẹgbẹ́ PDP ní kò rí bẹ́ẹ̀.
Jelili Adeṣiyan ní òótọ́ ni fọ́nrán ọhun, àmọ́ kíì ṣe ọ̀rọ̀ àti dabarú ìbó rara. Ó ní níṣe ni Fayose n fẹ̀sùn kan Ọ̀gágun Aliyu Momoh, tó tukọ̀ ìdìbò náà pé ó gba owó ẹ̀yìn lọ́wọ́ Kayode Fayẹmi àtẹgbẹ́ APC.
Bákan nàá, ni Fayose ní àdọ́gbọ́nsí ni fọ́nràn náà.
"Lẹ́yìn tí ètò ìdìbò nàá wáyé ni akọ̀wé gbogbogbò fún PDP lásìkò ọhun, Temitope Aluko, lásìkò ìfọ̀rọ̀ wáni lẹ́nu wò tó ṣe lórí ẹ̀rọ́ amóhùnmáwòrán TVC, ní ''ẹgbẹ́ PDP lo agbára ìjọba apàpọ̀ láti yẹ̀yẹ́ àwọn olórí ẹgbẹ́ APC, táwọn sì tún fi àwọn kan sí àhámọ́."""
Ṣùgbọ́n ní bàyíì tó jẹ́ pé ẹgbẹ́ APC ló wà n dari Naijiria nipò ààrẹ, ta ni ìjọba apàpọ̀ yóò sẹ àtìlẹyìn fún nínu ètò ìdìbò gómìnà tí yóò wáyé ní ìpínlẹ̀ Ekiti ní oṣù Keje 2018?
Njẹ́ ó ṣeéṣe kí APC náà lo 'agbára òkè láti yẹ̀yẹ́ tàbí fi ìyà jẹ' àwọn ọmọ ẹgbẹ́ PDP lásìkò ètò ìdìbò náà?
Ipa wo ni Musiliu Ọbanikoro tó jẹ́ ògúnná gbòǹgbò nínú ìgbìmọ̀ tó ṣe ètò bí PDP sẹ 'ṣe mọ̀dàrú ìbò tó gbé Fayoṣe wọlé ní 2014', (gẹ́gẹ́ bí fọ́nrán tó jáde ọ̀hún ṣe sọ), yóò kò nínú ìdìbò tó n bọ̀ pẹ̀lú bí ó ṣe tún wà nínú igbimọ ìpolongo APC báyìí?
SDP: A kò tíì fún Omiṣore ní àṣíà olùdíje gómínà
Oríṣun àwòrán, @DrIyiolaOmisore
Ẹgbẹ oṣelu SDP ní gbogbo ọ̀nà tó yẹ kí Omiṣore rìn gẹ́gẹ́ bíi ọmọ ẹgbẹ́ ló ti rìn
Ẹgbẹ oṣelu SDP ti ṣalaye wi pe, lootọ ni igbakeji gomina nigbakan nipinlẹ Ọṣun, Ọtunba Iyiọla Omiṣore ti darapọ mọ ẹgbẹ oṣelu naa.
Ẹgbẹ oṣelu SDP ni, yatọ si oloye Omiṣore, gbaragada ni ilẹkun ẹgbẹ oṣelu naa ṣi silẹ fun awọn oloṣelu to ba fẹ darapọ.
Alaga ẹgbẹ oselu SDP nipinlẹ Ọṣun, Ọgbẹni Ishọla Ademọla, ni alaye naa ṣe pataki nitori ọrọ kan to gba ori opo iroyin lorilẹede Naijiria kan laipẹ yii , nipa ọkan pataki lara awọn ọmọ ẹgbẹ oṣelu naa kan to ni Omiṣore kii ṣe ọmọ ẹgbẹ oṣelu SDP.
"Ọmọ ẹgbẹ oṣelu SDP ni Omisoore, gbogbo igbesẹ to yẹ ki ẹnikẹni to ba fẹ darapọ mọ ẹgbẹ wa gbe, naa lo ti gbe.
Oríṣun àwòrán, @DrIyiolaOmisore
Ẹgbẹ oṣelu SDP ko tii fa aṣia oludije fun ipo gomina Ọṣun le Omiṣore, tabi ẹnikẹni lọwọ
O fẹ dupo gomina labẹ ẹgbẹ SDP gẹgẹbii awọn oludije miran. Aaye wa fun ẹnikẹni to ba darapọ mọ wa lati ṣe bẹẹ nitori ojo ni wa, a ko ba ẹnikẹni ṣọta."
Amọ ṣa, awọn adari ẹgbẹ oṣelu naa yanana rẹ pe, ẹgbẹ oṣelu SDP ko tii fa aṣia oludije fun ipo gomina Ọṣun le Omiṣore, tabi ẹnikẹni lọwọ ati pe, awọn ọmọ ẹgbẹ ni yoo si yan ẹni ti wọn ba fẹ.
UN gbé mílíọ́nù méjì dọ́là kalẹ̀ fún ìtọ́jú onígbáméjì
Oríṣun àwòrán, @UN_Nigeria
Àjàkálẹ̀ ààrùn onígbáméjì ti di kálé n káko láwọn ìpínlẹ̀ bíi Borno, Yobe àti Adamawa
Ajọ iṣọkan agbaye ti ya miliọnu meji dọla owo ilẹ Amẹrika sọtọ lati ṣe agbatẹru igbesẹ lati koju arun onigbameji to bẹ silẹ lagbegbe ila oorun ariwa orilẹede Naijiria.
Ko din ni aadọta eeyan ti arun onigbameji yii ti ran lọ sọrun lati ibẹrẹ ajakalẹ aarun ọhun ni opin oṣu kẹta.
Owo ti ajọ iṣọkan agbaye gbe kalẹ naa yoo wa fun ipese omi to mọ gaara fun awọn eeyan to ju miliọnu kan ati ẹgbẹta lọ, ko si tun ṣeto ayika to peye fun awọn agbegbe ti ọrọ kan.
Ìjọ Àgùdà: Kò dára ká máa ké gbàmí-gbàmí kiri lójoojúmọ́
Gẹgẹ bii ajọ to n gbogun ti ajakalẹ arun lorilẹede Naijiria, CDC ṣe sọ, ko din ni ẹgbẹrun mẹta iṣẹlẹ arun onigbameji to ti waye, ti o si tun ti gba ẹmi awọn eeyan kaakiri orilẹede Naijiria, paapaa lawọn ipinlẹ kan lẹkun ila oorun ariwa bii Borno, Adamawa ati Yobe.
Alamojuto eto iranwọ labẹ ajọ iṣọkan agbaye lorilẹede Naijiria ti sọ wi pe, ajakalẹ arun onigbameji lee pa ẹgbẹlẹgbẹ awọn eeyan, paapaa julọ awọn obinrin ati awọn ọmọde ti wọn n gbe lawọn iagbegbe bii ibudo awọn ti wahala Boko Haram le kuro nile.
Oríṣun àwòrán, @UN_Nigeria
Awọn omi ati ounjẹ ti ko mọ pẹlu ayika ti o kun fun ẹgbin kun ara awọn ohun ti wọn ni o n ṣokunfa aarun onigbameji
Amọ ṣa, ajọ iṣọkan agbaye ti ni, wọn ṣi nilo alekun owo, paapaa lasiko ojo, nigba ti aisan to rọ mọ omi yoo pọ.
Awọn omi ati ounjẹ ti ko mọ, pẹlu ayika ti o kun fun ẹgbin kun ara awọn ohun ti wọn ni o n ṣokunfa ọwọja aarun onigbameji.
Iparí UCL: Pápá ìṣiré Kiev gbàlejò Madrid àti Liverpool
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ẹgbẹ agbabọọlu Liverpool ni ẹgbẹ agbabọọlu akọkọ ni ilẹ Gẹẹsi akọkọ ti yoo de ipele aṣekagba
Wo bi gbagede papa iṣire Kiev, ti ifẹsẹwọnsẹ aṣekagba idije Champions league yoo ti waye lọjọ Abamẹta.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Real madrid àti Liverpool yóò gbéná kojú ara wọn ní Pápá ìṣiré Kiev láti mọ ọba bọ́ọ̀lú àfẹsẹ̀gbá láàárín àwọn ẹgbẹ́ agbábọ́ọ̀lú ní ilẹ̀ Yúróòpú
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Real madrid àti Liverpool yóò mọ ọba bọ́ọ̀lú àfẹsẹ̀gbá láàárín àwọn ẹgbẹ́ agbábọ́ọ̀lú ní ilẹ̀ Yúróòpú lọjọ abamẹta
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Real Madrid ati Liverpool ti kọkọ pade ni ipele aṣekagba ni ọdun 1981
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Real Madrid vs Liverpool: Pápá ìṣiré Kiev ree
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Igba marundinlogun ni Real Madrid ti wọ ipele aṣekagba idije yii
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Igba meje ni Liverpool ti wọ ipele aṣekagba idije naa
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Real Madrid lo tii gba ife ẹyẹ Champions league ju
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Eyi ni igba kẹta laarin ọdun mẹta ti Real madrid yoo maa wọ aṣekagba idije Champions league
Kòkòrò ajokorun da ìpòruru sí ọkan àwọn àgbẹ̀ Nàìjíríà
Kòkòrò ajokorun le sọ àgbẹ̀ di ẹdun arinle toba ya wọ oko.
''Mo ti ṣe àbẹwò sí àwọn oko kan láwọn ìletò kaaakiri ile kaarọ ojiire ti ohun ti a sì rí ní bẹ kọnilominu nitori ijamba ti kòkòrò ajokorun n ṣe. Bi a ko ba wa wọrọkọ fi ṣada ni kíá, o lè ṣe àkóbá fún ìpèsè oúnjẹ lọdun yìí''.
Ọrọ ree láti ẹnu ọmọwe Olugbenga Egbetokun nigba ti o n ba ìkọ BBC Yoruba sọrọ lórí ìpeníjà kòkòrò ajokorun to n dá ìpòruru sí ọkan àwọn àgbẹ̀ Nàìjíríà.
Ọmowé Olugbenga wà lára àwọn tó n ṣíṣe nípa ọgbin àgbàdo ní ilé iṣẹ  iwadi ijinlẹ IAR and T to wa ni agbegbe Àpáta Ibadan.
Àwọn onimọ nípa isẹ agbẹ sapejuwe kokoro ajokorun to sẹ̀sẹ̀ sẹ́ wọlu gẹ́gẹ́ bi Arun Ebola fun àwọn agbẹ́.
O ni, ọdún 2016 láwọn kọkọ kojú ìpeníjà kòkòrò ajekorun náà.
''Ogbẹle to sẹlẹ lọdun yẹn lo ran itankalẹ awọn kòkòrò naa lowo''
Nípasẹ ṣíṣe àkóso ètò nnkan ọgbin, Olugbenga sọ wi pé awọn kòkòrò wọnyi ti n jẹ ọ̀pọ̀ oúnjẹ tó yẹ ki àgbẹ̀ kò lérè.
Ẹ gbọ ohun to sọ nipa kòkòrò náà.
Kòkòrò ajokorun n ṣé ọsẹ fún ọpọ àgbẹ lorílè-èdè Naijirià
Tope Amujo n ṣíṣe pẹlú àwọn àgbẹ̀ ní ìpínlè Kwara Osun ati Oyo.
O ni àwọn àgbẹ̀ náà kò rí eré tó yẹ kí wọn rí latari ìpeníjà kòkòrò ajokorun yìí.
''Ọpọ nínú wọn ló yá  owó ìrànwọ́ láti ọdọ àwọn àjọ àlàjẹ́sẹku ṣugbọn tí wọn kò lè rí sàn padà mọ nítorí pé kòkòrò yii tí ṣé àkóbá fún nnkan oko won.''
Amujo ní ìgbìyànjú láti ṣe idanilẹkọ fún àwọn àgbẹ̀ n lọ káàkiri lórí kòkòrò ajokorun yii ṣùgbọ́n tí kòkòrò náà bá tí wọ inú okò tán, afi kí èèyàn máà gbà ádùrá.
Idanilẹkọ fún àwọn àgbẹ̀ lórí kòkòrò ajokorun
Àwọn onímọ̀ nípa ètò nnkan ọgbin ṣàlàyé pé òun tí àwọn àgbẹ̀ lè ṣe láti dẹ́kun ìpeníjà kòkòrò yii kò jù wí pé kí wọn tètè yà owó kikoju rẹ bọ inu ìṣirò.
Ọmowé Olugbenga  ni ''bi èèyàn bá ní pé òun yóò dúró títí tí kòkòrò náà bá wọ inú okò tán kí òun tó ná owó sí ìtànkálẹ̀ rẹ̀, ẹpa kò ní boro mọ.''
''Ki o tó di pé kòkòrò náà wọ inú okò, a gbọ́dọ̀ tí rà àwọn òògùn apá kòkòrò kì a sì máà fin wọn lóòrèkóòrè sí nnkan ọ̀gbìn wà. Bi a bá ṣè eléyìí tán, kí a gbàdúrà pé kí kòkòrò náà má yà inú okò wà''.
Ebola: ìjọba Gẹ̀ẹ́sì fún DR Congo lówó láti fi gbógunti i
DR Congo ń ja ogun Ebola lójú méjèèjì lásìkò yìí
Ìjọba ilẹ̀ Gẹ̀ẹ́si fẹ́ pèsè miliọnu marun un pọun fún gbígbógunti Ebola ni Democratic Republic of Congo
Wọn kede pé Ebola tún ṣẹyọ ni Bikoro tó jẹ ileto ni ariwa Kinshasa to jẹ olu ilu DR Congo ni èyí to ti ń mu ẹ̀rù ba àwọn ènìyàn kaakiri ilẹ̀ Adulawọ bayii.
Ikú ènìyàn 11,308 lorilẹ-ede Guinea, Liberia, Sierra Leone, laarin ọdun 2014 si ọdun 2016
Ikú ènìyàn 280 lorilẹ-ede DR Congo, l'ọdun 1976
Ikú ènìyàn 254 lorilẹ-ede DR Congo, l'ọdun 1995
Ikú ènìyàn 224 lorilẹ-ede Uganda, l'ọdun 2000
Ikú ènìyàn 187 lorilẹ-ede DR Congo, l'ọdun 2007
(Orisun: WHO)
Bayii, Ebola ti pa eniyan mẹtadinlọgbọn ni DR Congo ni eyi to dẹ tun ń tàn kalẹ lati ileto lọ si àwọn ilu nla bii Mbandaka, ti wọn ti ri iṣẹlẹ Ebola tuntun lọjọ kẹtadinlogun oṣu karun un.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ebola ti di ohun ti gbogbo àgbáyé ń mójútó báyìí
Iranlọwọ ilẹ United Kingdom yii yoo jẹ ki iṣẹ tubọ rọrun fún àjọ WHO to n mojuto ìlera agbaye lati ri si ìtànkálẹ̀ Ebola.
Ajọ WHO n mojuto pe ki Ebola má tankalẹ sii, wọn ń ṣayẹwo fun iṣẹlẹ Ebola tuntun, wọn tun n pese iranwọ lori ipolongo abẹrẹ ajẹsara Ebola to n lọ lọwọ.
Ipolongo imọtoto lori fifọ ọwọ́ nigba gbogbo ati idanilékọọ lori ṣiṣe ayẹwo Ebola n lọ ni DR Congo sii.
Awọn ajọ aranilọwọ loriṣiriṣii náà ti wa ni Congo bayii ti wón n pese iranlọwọ fún wọn.
Jonathan ṣí afárá ọkọ̀ tuntun ní Adó Èkìtì
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ọrọ aarẹ Jonathan ko ṣẹyin gbogbo pọpọṣinṣin idibo gomina nipinlẹ Ekiti
Aarẹ ana lorilẹede Naijiria, Goodluck Jonathan lo sọ ọrọ yii nilu Ado Ekiti.
Awọn eeyan ipinlẹ Ekiti ti n ṣe ajọyọ afara ọkọ akọkọ iru ẹ ni ipinlẹ naa eleyi ti wọn ṣẹṣẹ ṣi ni ilu Ado Ekiti ni ala ọjọ ẹti.
Aarẹ ana lorilẹede Naijiria, Goodluck Jonathan lo ṣi afara tuntun naa eleyi ti gomina ipinlẹ ọhun, Ayọdele Fayoṣe kọ si olu ilu ipinlẹ naa.
Oríṣun àwòrán, facebook/lere olayinka
Ààrẹ Jonathan ní bí àwọn orílẹ̀èdè àgbáyé ṣe wá ń wẹnu sí Nàìjíríà lára kò dára
Ninu ọrọ rẹ, aarẹ Jonathan ni asiko to fun awọn adari lorilẹede Naijiria lati mu idagbasoke ijọba tiwantiwa lskunkundun ninu ohun gbogbo ti wọn ba n ṣe.
Ọrọ aarẹ Jonathan ko ṣẹyin gbogbo pọpọṣinṣin idibo gomina nipinlẹ Ekiti eleyi to n bọ laipẹ.
Oríṣun àwòrán, facebook/lere olayinka
Jonathan ní Nàìjíríà ti di àríwísí láwùjọ àgbáyé
O ni ohun to da oun loju ni pe 'pẹlu awọn akanṣe iṣẹ ti gomina Fayoṣe ti gbe ṣe ni ipinlẹ Ekiti, yoo ṣoro fun ẹgbẹ oṣelu miran lati gba akoso'nibẹ
O ni iwa awọn aṣiwaju lorilẹede naijiria ti sọ ọ di ariwisi ti ko tọna lawujs agbaye.
Oríṣun àwòrán, facebook/lere olayinka
Jonathan ṣí afárá ọkọ̀ tuntun ní Adó Èkìtì
Afara ọkọ naa ni akọkọ ni ipinlẹ Ekiti latigba ti wsn ti daa silẹ lsdun 1996.
Gomina Fayoṣe ninu ọrọ tirẹ ṣalaye pe awọn iṣẹ ti iṣejsba oun gbe ṣe ko lee jẹ ko ṣeeṣe fun ẹgbẹ oṣelu kankan lati gba ijọba nibẹ.
Lagos; Àwọn ará ìlú ló ni ohun amáyédẹrùn tó wà ní Eko
Oríṣun àwòrán, AFP
Gomina se ileri lati se awọn akanse isẹ tuntun mii
Ijọba ipinlẹ Eko ti sọ wi pe awọn ara ilu lo ni gbogbo awọn ohun amayedẹru ati dukia to wa ni ilu Eko.
Gomina ipinlẹ Eko, Akinwunmi Ambode sọ eleyii nibi igbaradi fun ayẹyẹ ọdun mọkanlelaadọta ti wọn da ipinlẹ Eko silẹ.
Ambode ninu ọrọ rẹ sọ wi pe ilu Eko ti rẹwa si ju ti ọdun to kọja lọ, nitori awọn isẹ akanse ti wọn sẹsẹ se si awọn agbeegbe ilu Eko.
Ijọba naa wa fikun wipe awọn ko ni dawọ isẹ duro ni ipinlẹ naa, ki igbe aye awọn eniyan ipinlẹ naa le rọrun ju ti atẹyin wa lọ.
Jiganbabaoja: Àwa Yorùbá ò fi ọ̀rọ̀ ọjọ́ orí ṣeré
Oríṣun àwòrán, Instagram/jiganbabaoja
Abimbola Kazeem mẹnu ba ọr moju ẹ lọ o ju mi lọ ti ọpọ ni Naijiria ko fi sere rara
Bí eré ló bẹrẹ ṣùgbọ́n báyìí o tí gbà ilẹ̀
Kí o to bẹrẹ sí ní ká ìròyìn yi,  jẹ kín kọkọ béèrè lọwọ ẹ pé ''ShoMoAgeMiNi?''
O mó age mí àbí?
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí:
Mohammed Salah: A ó pàdé ní Russia
Àláìsàn Ebola sá kúrò níléwòsàn lọ sí ṣọ́ọ̀ṣì
Òjò owó N6m fẹ́ rọ̀ fún ìyá ìbarùn-ún l‘Èkó
Ajẹwipe o kò tí já sí àṣà tuntun tó gbà ìgboro ni yen.
Abímbólá Kazeem òṣeré tíátà Yorùbá lo dá àṣà náà lè.
Nigba ti o n ba BBC Yoruba sọrọ, o ni ko ye oun bi àṣà #ShoMoAgeMiNi ti ṣé gbálè káàkiri.
''Mi o lérò wí pé àwọn èèyàn má tẹwọ gba àṣà náà bí wón ti ṣé gba báyìí. Mo kan ni kín da lasa ní  láì ro wí pé yóò dá ìgboro rú to báyìí''
Ko fe sí ẹni tí kò má dá àṣà #ShoMoAgeMiNi pàápàá jù lọ láàrin àwọn òṣeré eré tíátà Yorùbá ati awọn olorin takasufe
Ni ilẹ kaaro ojiire, ipò ọwọ ní ẹni tí o ba dàgbà má n wá.
Fún ìdí èyí òpó a má fẹ fìdí ọrọ múlẹ  pé àwọn kìí ṣé ẹgbẹ́ ẹní tí kò tó wọn.
"Jiganbabaoja salaye pe ""Yoruba fẹràn ipo.Bi wọn bá bi ọmọ méjì nínú agbolé  kannáà wọn a má sọ ara wọn nípasẹ ọjọ orí wọn láti má ṣe jẹ kí ẹnìkejì rí wọn fin.''"
Abímbólá Kazeem  dúpẹ lọdọ àwọn ololufẹ rẹ bí wọn ṣe tẹwọgbà àṣà 'ShoMoAgeMiNi?''
''Mo n gbìyànjú àti gbé fídíò orin jáde.Ẹ tẹti leko''
JOHESU - Saraki yóò ríi pe ìyansẹ́lódì wọn parí
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Saraki yóò ríi pe ìyansẹ́lódì JOHESU parí
Adarí ilé ìgbìmọ̀ asòfin àgbà, Sẹ́nétọ̀ Bukola Saraki yóò sèpàdé pẹ̀lú àwọn adarí ẹgbẹ́ àwọn òṣìṣẹ́ elétò ìlera JOHESU lónìí ọjọ́ ajé.
Ilé ìgbìmọ̀ asòfin ń gbìyànjú láti fópin sí ìyansẹ́lódì ọlọ́jọ́ pípẹ́ tí àwọn òṣìṣẹ́ elétò ìlera gùn le.
Ọ́fììsì tó ń rí sí ọ̀rọ̀ ìròyìn níle isẹ́ adarí ilé ìgbìmọ̀ asòfin ló sọ wí pé ìpàdé náà yóò wáyé lọ́san òní.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí:
Mẹkunnu loun jiya idasẹ silẹ Johesu - Ajafẹtọ ọmọniyan
Sẹ́nétọ̀ Saraki sọ pé ìpàdé náà yóò wáyé gẹ́gẹ́ bí àtẹ̀lé èyí tó se pẹ̀lú Mínísítà fún ètò ìlera àti Mínísítà fún ọ̀rọ̀ òsìṣẹ́ lọ́jọ́ ẹtì.
Látinú osù kẹrin ni àwọn òṣìṣẹ́ elétò ìlera ti gùn lé ìyanṣẹ́lódì náà pẹ̀lú ẹ̀sùn tí wọ́n fi kan ìjọ̀ba àpapọ̀ pé wọn kò se gẹ́gẹ́ bí àdéhùn tí wọ́n jọ se.
Ẹ̀sùn náà dá lórí àdéhùn wọn láti ọdún 2009 pàápàá èyí tí wọ́n se ní ọgbọ̀njọ́ osù kẹsan ọdún 2017 tó sì ní gbèdéke ọ̀sẹ̀ márùn-ún sùgbọ́n tí ìjọba kò dáwọ́ lé.
Fayose ní òun yóó di ààrẹ tábí igbákejì ààrẹ ni 2019
Oríṣun àwòrán, LARU0004
Fayose yoo fi ipò sílẹ̀ ní ọdun 2019
Ileéṣẹ́ ààrẹ orílẹ̀èdè Naijiria ti ní Gomina Ìpínlẹ̀ Ekiti, Ayodele Fayoṣe kò já mọ́ ẹni tí àwọn ń fún lésì látàrí ọ̀rọ̀ rẹ̀ pé ó ní bí òun bá ti kúrò lórí àlèéfa ní ọdún tó ń bọ̀, òun yóó gba ipò Ààrẹ Muhammadu Buhari tábí igbákejì rẹ̀, Yemi Osinbajo.
Àwa kìí fesì sí Fayose ni ohun tí agbẹnusọ ààrẹ, Femi Adesina, fi d'áhùn nígbà tí BBC kàn síi lórí ọ̀rọ̀ gómínà náà.
"Fayose sọ níbi tí ó ti ń ṣi ọ́fíìsì gómínà tuntun ní Ado-Ekiti ní ọjọ́ ẹtì tó kọjá, ""Oluwa Olorun ọ̀run ti sọ fún òun pé oun yóó di ààrẹ tábí igbákejì ààrẹ. Òótọ́ ọ̀rọ̀ ni o. Ẹ lè gbagbọ́, ẹ lé má gbàgbọ́"""
Bí ó ṣe sọ́ ọ̀ tán ni àwọn ará ìlú tó wà níbẹ̀ bú sẹ́rìń.
'Obìnrin tí kó ba fẹ́ òṣìṣẹ́ Mọ́ṣúárì, ìpinu rẹ̀ mẹ́hẹ'
Onímọ̀ ní Nàìjíríà kò jàǹfàní ìdàgbàsókè ọrọ̀ ajé l'ábẹ́ Buhari
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Lai Mohammed ní ètò ọrọ̀ ajé ti padà sí ojú ọ̀nà ìdàgbàsókè, lẹ́yìn tó dagun láàrin ọdún 2016 sí 2017.
Ọjọ́ Kọkàndínlọ́gbọ̀n, oṣù Karùn ún ni àyájọ́ ọjọ́ ètò ìṣèjọba àwaará ní Nàìjíríà, tó sì tún jẹ́ ọdún kẹta tí Ààrẹ Muhammadu Buhari ti wà ní orí àga ìṣàkóso.
Láti ìgbà tí ètò ìṣakóso nàá ti bẹ̀rẹ̀ ní oríṣiríṣi awuyewuye ti n wáyé lórí àwọn ẹ̀jẹ́ tí Buahri jẹ́ lásìkò ìpolongo ìbò tó ṣe ṣáàjú ètò ìdìbò gbogboogbo tó wáyé lọ́dún 2015, pàápàá lórí ètò ààbò àti ọrọ̀ ajé, pẹ̀lú bí ọ̀pọ̀lọpọ̀ ọmọ Nàìjíríà ṣe n sọ pé ìjọba Buhari kò ṣe tó.
Èyí n wáyé nítorí ìkọlù tí àwọn darandaran Fulani n ṣe jákèjádò orílẹ̀-èdè yìí, àti ní pàtàkì, ìpínlẹ̀ Benue. Bákan nàá ni tí àwọn ìkọlù tí ikọ̀ Boko Haram n ṣe.
Fayose sọrọ lori lẹta oloye Ọbasanjọ.
Ṣùgbọ́n, mínísítà fún ètò ìròyìn àti àṣà, Lai Mohammed, tako àríwísí àwọn tó ni ìṣàkóso Muhammadu Buhari, kò ní àṣeyọrí kankan láti fi hàn fún ọdún mẹta tó ti wà ní ipò.
O ni ètò ìṣàkóso nàá ti ṣe ju ohun tí àwọn ènìyàn lérò lọ, pàápàá mímú àyípadà bá ọ̀rọ̀ ètò ààbò, àgbénde ọrọ̀ ajé àti ìgbógun ti ìwà ìbàjẹ́, tó jẹ́ àwọn ohun tó ṣe kókó nínú ẹ̀jẹ́ tí Buhari jẹ́ lásìkò ìpolongo ìbò.
"Ẹ̀wẹ̀, ó ní ''ètò ọrọ̀ ajé ti padà sí ojú ọ̀nà ìdàgbàsókè, lẹ́yìn tó dagun láàrin ọdún 2016 sí 2017."""
Ṣùgbọ́n onímọ̀ nípa ètò ọrọ̀ ajé, Kunle Olomofe, tó bá BBC Yoruba sọ̀rọ̀ ní, ''lóòtọ́ ni ọrọ̀ ajé Nàìjíríà ti yípadà, ṣùgbọ́n, kò dé ọ̀dọ̀ àwọn ará ìlú. Bí i ti báwọ̀? Àlàyé n bẹ nínú fọ́nrán yìí:
Onímọ̀ nípa ètò ọrọ̀ ajé sọ̀rọ̀ lórí ipò tí ọrọ̀ ajé Nàìjíríà wà.
"Ẹ̀wẹ̀, onímọ̀ kan nípa ètò ààbò, Ọ̀gbẹ́ni Richard Amuwa, sọ fún BBC Yoruba pé, ""ohun tí àwọn ará ìlú n sọ ló yẹ kí ìjọba Buhari fi ṣe òdinwọ̀n àṣeyọrí ìṣàkóso rẹ̀, nítorí pé àwọn ló mọ bí ààbò ṣe wà fún ẹ̀mí àti dúkìá wọn."""
Àti pé, ó yẹ kí Buhari ti pàárọ̀ àwọn olórí láwọn iléesẹ́ ètò ààbò Nàìjíríà.
Osuntokun: Ó sàn kí ilé iṣẹ́ ààrẹ ka àwọn àṣeyorí rẹ̀
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Osuntokun ní, ó yẹ kí ilé-iṣẹ́ ààrẹ sàlàyé ohun tí wọn ti ṣe kí wọn le wọlé fún sáà ẹlẹ́keejì ni
Iná tí jó dé orí kókó lópin ọ̀sẹ̀ yìí nígbàtí Ilé iṣé Ààrẹ Muhammadu Buhari tú rúná sí àwọn ìṣesí Ààrẹ àná Olusegun Obasanjọ látẹ̀yìn wá gẹ́gẹ́ bíi agbẹ́nilẹ́sẹ̀.
Iná ọ̀rọ̀ ọ̀hún ti ń rú láti bíi ọ̀sẹ̀ méjì sẹ́yìn nígbà tí Ọbasanjọ sọ pe Ààrẹ Muhammadu Buhari kò kún ojú òsùwọn gẹ́gẹ́ bí ààrẹ orílẹ̀-èdè Nàìjíríà.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí:
#ShoMoAgeMiNi# Àṣà tó ń dá ìgboro rú
'Oró ejò ń sọ ènìyàn di aláàbọ̀ ara'
Olúwòó ti Iwo fakọ yọ nínú asọ ẹ̀yà Igbo
Ní báyìí, ilé iṣẹ́ ààrẹ ní kìí ṣe ìgbà àkọ́kọ́ níyìí tí Obasanjọ tí ń tẹ ojú òfin mọ́lẹ̀ láti lé Gómìnà márùn-ún kúrò níjọba láti ọdún 1999-2007.
Garba Shehu tó jẹ́ agbẹnusọ fún ilé iṣẹ́ ààrẹ sọ pé àsìkò Ọbásanjọ láààrin 1999-2007 jẹ àsìkò okùnkùn fún ìjọba àwa-ara wa nípa bí Ọbásanjọ ṣe ń tẹ ojú òfin mọlẹ̀.
Ó ní Ọbásanjọ máa ń lo irinṣẹ ìjọba láti fi bá àwọn Gómìna bíi Joshua Dariye, Rashidi Ladoja, Peter Obi, Chris Ngige àti Ayo Fayose jà látẹ̀yìn wá, àwọn olóṣèlú ọ̀hún jẹ́ Gómìnà ìpínlẹ̀ Plateau, Oyo, Anambra, Anambra àti Ekiti.
Lásìkò tí BBC Yorùbá bá agbẹnusọ fún ẹgbẹ́ òṣèlú ADC Akin Osuntokun sọ̀rọ̀ lórí ọ̀rọ̀ tí agbẹnusọ fún ilé ààrẹ sọ yìí,
Osuntokun: Ó sàn kí ilé iṣẹ́ ààrẹ ka àwọn àṣeyorí rẹ̀.
Ó ní ọ̀rọ̀ tí kò mú ọgbọn dání ni, nítorí pé Ọbasanjọ ko dupo pẹlú Buhari bíkòṣe pe, ohún ṣe ìṣe àgbà kìí wà lọ́ja korí ọmọ tuntun wọ́.
Osuntokun ní, ó yẹ kí ilé-iṣẹ́ ààrẹ sàlàyé ohun tí wọn ti ṣe kí wọn le wọlé fún sáà ẹlẹ́keejì ni, kìí ṣe láti máa sọ ohun tí Ọbasanjọ ti ṣe lati ọdún tó ti pẹ́ sẹyìn.
Bi ẹ ko ba gbagbe, isẹ ipese ina mọnamọna ni isejọba Aarẹ Ọbasanjọ lọdun (1999-2006) da owo le lasiko, sugbọn ti awọn ajafẹto omoniyan, Serap sọ wi pe, wọn se owó rẹ̀ basubasu.
Serap si kan si olootu eto idajọ lorilẹede Naijiria, Walter Onnoghen, lati se ọ̀fin toto bi wọn se naa owo naa.
Ben Murray-Bruce: ilé aṣòfin ń ṣàárò Dino Melaye
Oríṣun àwòrán, Instagram/dinomelaye
Senatọ Dino Melaye farapa nigba ti àwọn agbófinró ń gbé e lọ sí Lọkọja
''Bó ṣe pé kí o tẹ pọ̀pá wa sí ijoko ilé aṣòfin, ri i wí pé o yọjú sílé lọjọ rú!''BEN
Senato Ben Murray-Bruce lo ke gbajare yii sí akẹgbẹ rẹ, Senato Dino Melaye, to n gba ìtọjú lọwọ nile ìwòsan.
Ojú òpó Twitter rẹ lo fi ọrọ náà lédè sí.
Ben Bruce ni lootọ lòún mò pé Senato Dino n tẹ pọpa ṣùgbọ́n ìtara àìsí ní ilé rẹ lo mu òun ke pè é.
''A n jarán rẹ ninu ilé. Ilé aṣòfin kò dùn pẹlú bí Dino kò ti ṣe sí níbẹ''
Loju òpó Twitter rẹ, Senato Dino Melaye ko fèsì bóyá òun yoo wa tàbí òun ko ni wá sugbọn o fi àwòrán ìwé àṣẹ ifi-muni ti awọn ọlọpaa mú wà láti wá fí tú ilé rẹ hàn fun ayẹwo ẹrù òfin.
O ni won ko ri nnkankan to lodi sofin ninu ile oun lẹyin ayẹwo wọn
Bí a kò bá gbàgbé, ilé Senato Dino àti ilé iṣẹ ọlópàá Nàìjíríà ti jọ n wọ ṣòkòtò kannáà lórí ẹsùn oríṣiríṣi tí wọn fí kàn an.
Láti ìgbà ti adájọ tí gbà oniduro rẹ ni Senato Dino Melaye ti wo ile ìsinmi.
O kàn ń fí ọ̀rọ̀ iṣiti ṣòwọ lórí Twitter ni, o dàbi pé, kò fẹ dá sí ọrọ ìṣèlú bí a ti ṣe mọ ọ sí tẹlẹ
Aárò Dino ń sọ àwọn aṣòfin; Mammadou dọmọ onilu ni France
Eyi ni awọn akojọpọ iroyin ti toni.
Attahiru Jega pe àwọn Asòfin ní olè
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Àwọn Asòfin Naijiria fẹ́ràn gbígba owó ẹ̀bùrú
Alaga ajọ to ń rísí ètò ìdìbò Nàìjíríà (INEC) tẹlẹri, Ọjọgbọn Attahiru Jega, ni ọ̀nà àbáyọ ni ki a dẹ́kun rìbá gbígbà ni Naijiria.
Attahiru Jega ti fi ẹsun kan awọn Ile Igbimọ Asofin lorilẹ-ede Naijiria pe wọn fẹran lati ma a gba owo ni ọna ẹburu lati le se isẹ wọn.
Jega sọ ọrọ yii nibi to ti n se idanilẹkọọ lori ayajọ Ọjọ Iṣejọba Tiwantiwa (Democracy Day) t'ọdun yii ni Abuja lorilẹ-ede Naijiria.
Nigeria vs DR Congo: Eagles gbá ọ̀mì pẹ̀lú Leopard ní Pọtá
Orilẹ-ede Naijiria wa lara orilẹ-ede marun un lati ile Afrika ti yoo kopa ni Russia 2018
Ìkọ agbaboolu Super Eagles orílè-èdè Nàìjíríà ati akẹgbẹ wọn láti orílè-èdè DR Congo ti gba àmì ayò kọọkan nínú ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ ọlọrẹsọrẹ
Ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ náà wà lára ipalemo ìkọ Super Eagles ṣaaju ìdíje ife ẹyẹ àgbáyé to n bò lónà ní Russia. E ka ekunrere re ni bii
Aliu Sodiq mú ìbẹ̀rù kúrò lọ́kàn àwọn ènìyàn nípà ìrírí mọ́ṣúàrì.
'Obìnrin tí kó ba fẹ́ òṣìṣẹ́ Mọ́ṣúárì, ìpinu rẹ̀ mẹ́hẹ'
Èrò àwọn ọmọ Nàìjíríà lórí 'Democracy Day'
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Nàìjíríà n ṣe àjọyọ̀ ọdún kejìdínlógún tí wọ́n ti n lo ètò ìṣèjọba àwaarawa.
Lọ́jọ́ kọkàndínlọ́gbọ̀n ni àwọn ọmọ orílẹ̀èdè Nàìjíríà n ṣe àjọyọ̀ ọdún kọkàndínlógún tí wọ́n ti n lo ètò ìṣèjọba àwa ara wa.
Àyájọ́ ọjọ́ nàá jẹyọ lọ́dún 1999, lẹ́yìn tí Nàìjíríà ti wà lábẹ́ ìṣàkóso ológun fún ọdún mẹ́ẹ̀dógún.
Bákan nàá ni ti ọdún 2018 n ṣe àmì ọdún mẹ́ta tí ẹgbẹ́ òṣèlú All Progressives Congress, APC, ti wà lórí àga ìṣàkóso Nàìjíríà, lẹ́yìn ọdún mẹ́rìndínlógún tí Peoples Democratic Party, PDP, fi ṣèjọba.
Ṣíṣe àjọyọ̀ ètò ìṣèjọba àwa ara wa lọ́jọ́ kọkàndínlọ́gbọ̀n, oṣù Karùn ún ṣábà maa n fa àríyànjiyàn, pẹ̀lú bí èrò kálukú ṣe maa n ṣọ̀tọ̀ọ́tọ̀ lórí pàtàkì ọjọ́ nà.
Bí àwọn kan ṣe n rí ọjọ́ nàá bí ànfàání láti ṣàjọyọ̀ àwọ̀n nkan rere tó n jẹyọ lára irú ìṣèjọba bẹ̀ ẹ́, láwọn kan n takò ó pẹ̀lú àríyànjiyàn pé kò sí nkankan tó wú ni lórí, tó n pé fùn àjọyọ̀ ní Nàìjíríà, pàápàá nípa ìjọba rẹ̀.
Àwọn kan tilẹ̀ ní àkóba ni ètò ìṣèjọba àwaarawa ju ti tẹ́lẹ̀ lọ.
Bákan nàá, ni àwọn mì í tilẹ̀ di ẹ̀bi àwọn ìṣòro tí Nàìjíríà ní ru àwọn ọmọ orílẹ̀èdè ọ̀hún fún ra wọn, tí kií sì i ṣe ètò ìṣèjọba ọ̀hún tó ti mú ìdàgbàsókè bá àwọn orílẹ̀èdè mi í ní àgbáyé, tó sì ti gbá wọ́n kúrò lóko ẹrú, àti ìyà.
Ẹ̀wẹ̀, àwọn kan ní ìjọba Muhammadu Buahri kó tì ṣe àsẹyọrí kankan láti ọdún mẹ́ta tó ti wà lórí àga ìṣàkóso, pàápàá lórí ètò ọrọ̀ ajé àti ààbò.
Láti ìgbà tí ètò ìṣakóso nàá ti bẹ̀rẹ̀ ní oríṣiríṣi awuyewuye ti n wáyé lórí àwọn ẹ̀jẹ́ tí Buahri jẹ́ lásìkò ìpolongo ìbò tó ṣe ṣáàjú ètò ìdìbò gbogboogbo tó wáyé lọ́dún 2015, pàápàá lórí ètò ààbò àti ọrọ̀ ajé, pẹ̀lú bí ọ̀pọ̀lọpọ̀ ọmọ Nàìjíríà ṣe n sọ pé ìjọba Buhari kò ṣe tó.
Èyí n wáyé nítorí ìkọlù tí àwọn darandaran Fulani n ṣe jákèjádò orílẹ̀-èdè yìí, àti ní pàtàkì, ìpínlẹ̀ Benue. Bákan nàá ni tí àwọn ìkọlù tí ikọ̀ Boko Haram n ṣe.
Onímọ̀ nípa ètò ọrọ̀ ajé sọ̀rọ̀ lórí ipò tí ọrọ̀ ajé Nàìjíríà wà.
"Ẹ̀wẹ̀, onímọ̀ kan nípa ètò ààbò, Ọ̀gbẹ́ni Richard Amuwa, sọ fún BBC Yoruba pé, ""ohun tí àwọn ará ìlú n sọ ló yẹ kí ìjọba Buhari fi ṣe òdinwọ̀n àṣeyọrí ìṣàkóso rẹ̀, nítorí pé àwọn ló mọ bí ààbò ṣe wà fún ẹ̀mí àti dúkìá wọn."""
Àti pé, ó yẹ kí Buhari ti pàárọ̀ àwọn olórí láwọn iléesẹ́ ètò ààbò Nàìjíríà.
Attahiru Jega pe àwọn Asòfin ní olè
Ààrùn Ebola ti 'wá ni kòkòrò ajokorun
Mozambique: Àwọn alákatakítí ẹlẹ́sìn bẹ́ orí ènìyàn mẹ́wàá
Oríṣun àwòrán, AFP
Ìgbàgbọ́ ọ̀pọ̀lọpọ̀ ni pé ẹgbẹ́ nàá n pá òbítí-bitì Dọla látara igi igbó àti òkúta olówó iyebíye.
Kò dín ní ènìyàn mẹ́wàá tí wọ́n bẹ́ lórí lórílẹ̀èdè Mozambique.
Òṣìṣẹ́ ìjọba kan lẹ́kùn Palma, tó wà ní àgbègbè Cabo Delgado, fi ìdí ìṣẹ̀lẹ̀ nàá múlẹ̀, ṣùgbọ́n kò sọ̀rọ̀ ní ẹ̀kúnrẹ́rẹ́.
Ẹgbẹ́ kan tí wọ́n mọ̀ lábẹ́lé sí  al-Shabab tàbí al-Sunna, bẹ̀rẹ̀ gẹ́gẹ́ bí ẹgbẹ́ ẹlẹ́sìn lọ́dún 2015, ṣùgbọ́n tó ti ṣe ọ̀pọ̀lọpọ̀ ìkọlù láàrin ọdún kan péré.
"Ìjọba tiwa n' tiwa ; Ṣé ó yẹ láti ṣàjọyọ̀?
Àyájọ́ ọjọ́ ìjọba Tiwa n' tiwa, kí la ti se?
Ìgbàgbọ́ ọ̀pọ̀lọpọ̀ ni pé ẹgbẹ́ nàá n pá òbítí-bitì Dọla látara igi igbó àti òkúta olówó iyebíye.
Ọ̀pọ̀lọpọ̀ mọ́ṣáláàṣí ni àwọn aláṣẹ orílẹ̀èdè Mozambique ti tì pa báyìí.
Iléẹjọ́: Buhari gbọdọ̀ dènà N40bn táwọn asòfin fẹ́ mú nínú ìsúná
Oríṣun àwòrán, @NGRSenate
Buhari gbọdọ̀ pàsẹ fáwọn iléisẹ́ tó ń gbọ́ ẹ̀sùn ìwà àjẹbánu, láti tanná wadìí ẹ̀sùn síse àfikún ètò ìsúná náà,
Iléẹ́jọ gíga ìjọba àpapọ̀ tó kalẹ̀ sí ìlú Èkó ti pàsẹ pé, kí wọn tètè fi ojú àwọn asaájú ilé asòfin, tí wọn fẹ̀sùn kàn pé, wọn de ìdí fún ètò ìsúná ọdún 2016, tó fi fò sókè pẹ̀lú owó tótó mílíọ́nù lọ́nà ọ̀rìnlénírinwó ó lé ẹyọ kan naira, ba iléẹjọ́ lẹ́yẹ ò sọkà.
Adájọ́ Mohammed Idris tó gbé ìdájọ́ náà kalẹ̀ tún ní ààrẹ Muhammadu Buhari gbọdọ̀ pàsẹ fáwọn iléisẹ́ tó ń gbọ́ ẹ̀sùn ìwà àjẹbánu, tí wọn tanná wadìí ẹ̀sùn síse àfikún ètò ìsúná náà, láti gbé àbọ̀ wọn kalẹ̀ sí iwájú òun.
Odùoyè: Àwọn àgbààgbà tó ti sèjọba kọjá yẹ kó lọ sinmi
Adájọ́ Idris gbé ìdájọ́ náà kalẹ̀ ní ìbámu pẹ̀lú ẹjọ́ tí àjọ tó ń rísí ètò ìjíyìn isẹ́ ìríjú ẹni, SERAP pè láti jẹ́kí ìjọba àpapọ̀ fojú àwọn asòfin tó gbé owó ìsúná 2016 sókè, balé ẹjọ́.
Adájọ́ náà tún pàsẹ pé kí ààrẹ Buhari tètè dènà ète àwọn asaájú ilé asòfin àpapọ̀ kan láti jí ogójì bílíọ́nù naira nínú ọgọ́rùn-ún bílíọ́nù tí ìjọba rẹ̀ gbé kalẹ̀ fún àwọn asòfin náà láti fi pèsè ohun èèlò amáyédẹrùn fún ẹkùn ìdìbò wọn lọ́dún 2017."""
Oríṣun àwòrán, @NGRSenate
SERAP ni ìwà àjẹbánu gogò ní ìdí ètò ìsúná Naijiria
"Nígbà tó ń fèsì lórí ìdájọ́ náà, igbákejì olùdarí fájọ SERAP, Timothy Adewale ni ""ìdájọ́ náà ló fi ìdí rẹ̀ múlẹ̀ pé ìwà àjẹbánu gogò ní ìdí ètò ìsúná wa, tí àsà ‘taa ni yóò mú mi’ sì di tọ́rọ́ fọ́n kálé láàrin àwọn asòfin wa, tó fi mọ́ ìkùnà àwọn alásẹ láti máse fi igbá kan bo ọ̀kan nínú, nínú ìlànà ètò ìsúná wa àti ìmúsẹ rẹ̀."""
CAN: Ó pọn dandan kí wọn fágile ìdánwò ọlọ́pàá
Oríṣun àwòrán, Dan Kitwood
Ẹ́ fágile ìdánwò ọlọ́pàá
Agbarijpọ ẹgbẹ awọn onígbàgbọ́ ni orílẹ̀-èdè Nàìjíríà (CAN),  tí ké gbànjarè pé, kí àjọ ọlọ́pàá fagilé ìdánwò gbogbo-gboo fún ìgbanisíṣẹ́ to wayé láìpẹ́ yìí jakèjádò Nàìjíría.
Àjọ CAN gùnlé ọ̀rọ̀ òhún nítorí awuyewuye tó súyọ lẹyìn tí ìdánwò náà parí, wípé, wọn fi èdè Arabic sínú ìbéèrè tí wọn ṣe fún awọn olùkọpa náà
Awọn òṣìṣẹ́ tí o ń gbá títì olọ́da ní Ékó fẹ̀hónú hán ní ọ́fìsì Visionscape
'Isẹ́ Tíátà tí mò ń se ti tó mi jẹun'
"Agbenusọ fún ààrẹ àjọ CAN ní Nàìjíría, Adebayo Oladeji sọ fún BBC Yorùbá pé, '' fífi Arabic sínú ìdanwò ìgbaniwọlé sí iṣẹ́ ọlọ́pàá jẹ́ ọnà láti dín ànfààní àwọn kristẹni kú fún ìgbanisíṣẹ́ náà"""
Ó pọndandan kí àjọ ọlọ́pàá fagilé ìdánwò ọ̀hún
CAN: ó pọn dandan kí wọn fágile ìdánwò ọlọ́pàá
Bákan náà ní Ọ̀jọ̀gbọn Charles Adisa, to bá BBC Yoruba sọrọ sàlàyé pé, lẹyìn tí òun gbọ ìṣẹ̀lẹ̀ náà, ní òun fi ìpè síta láti wádìí ohun tó ṣẹlẹ̀.
Ó ní òun se iwadii oun laarin  àwọn tó ṣe ìdánwò ní Port Harcourt, Gombe, Osun àti Umuahia, tí wọn sì jẹ́rìí pé, Arabic wà nínú ìdáwò náà.
CAN: ó pọn dandan kí wọn fágile ìdánwò ọlọ́pàá
Kíní ìhà tí Àjọ JAMB kọ sí ọ̀rọ̀ náà:
Fabian Benjamin, tó jẹ agbẹnusọ fún àjọ JAMB, nínú àtẹjáde kan sàlàyé pé, ìyàlẹnu ló jẹ láti máa gbọ pé àjọ JAMB ló èdè Arabic láti fí dán àwọn olùkópa wò.
Irú ọ̀rọ̀ bẹ́ẹ̀ kò ní òtítọ́ nínú, tò sì jé ohun ìṣìnà pátápátá. Igbọra ẹni ye wà pé èdè gẹ̀ẹ́sì nìkan ní kí wọn dahun sí
Ìgbìyànjú wa láti bá ileesẹ ọlọ́pàá sọ̀rọ̀ ló já sí pàbó nitori agbẹnusọ fun ileesẹ ọlọ́pàá, Moshood Jimoh,  kò gbé ẹrọ ibara ẹni sọrọ ti a fi pee.
Koko ìròyìn: Democracy Day lorilẹede Naijiria, Kewu ati Idanwo ọlọ́pàá
Eyi ni akójọpọ̀ àwọn ìròyìn ti toni.
Àyájọ́ ọjọ́ ìjọba Tiwa n' tiwa: Kókó mẹ́wàá nínú ọ̀rọ̀ Buhari
Àyájọ́ ọjọ́ ìjọba tiwa n' tiwa: Kókó 10 nínú ọ̀rọ̀ Buhari
Lọ́jọ́ kọkàndínlọ́gbọ̀n ni àwọn ọmọ orílẹ̀èdè Nàìjíríà n ṣe àjọyọ̀ ọdún kọkàndínlógún tí wọ́n ti n lo ètò ìṣèjọba àwa ara wa.
Àyájọ́ ọjọ́ nàá jẹyọ lọ́dún 1999, lẹ́yìn tí Nàìjíríà ti wà lábẹ́ ìṣàkóso ológun fún ọdún mẹ́ẹ̀dógún.
Bákan nàá ni ti ọdún 2018 n ṣe àmì ọdún mẹ́ta tí ẹgbẹ́ òṣèlú All Progressives Congress, APC, ti wà lórí àga ìṣàkóso Nàìjíríà, lẹ́yìn ọdún mẹ́rìndínlógún tí Peoples Democratic Party, PDP, fi ṣèjọba.
CAN: Ó pọn dandan kí wọn fágile ìdánwò ọlọ́pàá
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ọ̀jọ̀gbọn Charles Adisa to bá BBC sọrọ sàlàyé pé lẹyìn tí òun gbọ ìṣẹ̀lẹ̀ náà ní òun fi ìpè síta
Agbarijopọ ẹgbẹ awọn onígbàgbọ́ ni orílẹ̀-èdè Nàìjíríà (CAN), tí ké gbànjarè pé kí àjọ ọlọ́pàá fagilé ìdánwò gbogbo-gboo fún ìgbanisíṣẹ́ to wayé láìpẹ́ yìí jakèjádò Nàìjíría.
Àjọ CAN gùnlé ọ̀rọ̀ òhún nítorí awuyewuye tó súyọ lẹyìn tí ìdánwò náà parí, wí pé, wọn fi èdè Arabic sínú ìbéèrè tí wọn ṣe fún awọn olùkọpa náà. E ka ekunrere re ni bii
Kayọde Oduoye: Àwọn àgbààgbà tó ti sèjọba kọjá yẹ kó lọ sinmi
Odùoyè: Àwọn àgbààgbà tó ti sèjọba kọjá yẹ kó lọ sinmi
Àwọn ọmọ ilé aṣòfin Nàìjíríà fèsì lórí ẹ̀sùn gbígba rìbá tí Jega fi kàn wọ́n
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Àwọn Asòfin nà ní kí Jega gbé orúkọ àwọn tó n gbowó ẹ̀yìn síta
Ilé ìgbìmọ̀ aṣofin ti fèsì sí ẹ̀sùn tí alága àjọ INEC nígbà kan rí, Attahiru Jega, fi kan àwọn aṣòfin.
Láìpẹ́ yìí ni Jega, níbi ìdánilẹ́kọ̀ọ́ kan tó ṣe láti ṣààmì àyájọ́ ọjọ ìṣèjọba àwa ara wa ní ìlú Abuja, ní àwọ̀n ọmọ ilé aṣòfin Nàìjíríà fẹ́ràn láti maa gba owó ní ọ̀nà ẹ̀bùrú, kí wọ́n ó tó ṣe iṣẹ́ wọn.
Ṣùgbọ́n, ní ọjọ́ kọkàndínlọ́gbọ̀n ni àwọ̀n aṣòfin fún Jega ní èsì ọ̀rọ̀ rẹ̀.
Odùoyè: Àwọn àgbààgbà tó ti sèjọba kọjá yẹ kó lọ sinmi
CAN faraya lórí fífi kéwú kọ ìdánwò ọlọ́pàá
Àwọn asòfin tó de ìdí fún ìsúná 2016 wọ gàù
Ìwé ìròyìn Vanguard jábọ̀ pé àwọn aṣòfin láti ilé aṣofin méjèéjì panu pọ̀ láti sọ pé, kí Attahiru Jega fi orúkọ àwọn aṣòfin tó jẹ̀bi ẹ̀sùn nàá sí ta láti lè gbe ẹ̀sùn tó fi kàn wọ́n lẹ́sẹ̀.
Àti pé, ọ̀rọ̀ nàá dàbíì ẹni tó n yọ èrúnrún igi lójú ẹlòmíì, láì yọ ìtí igi tó n bẹ lójú ara rẹ̀. Ìròyìn nàá sọ pé, akójàánu fún ilé aṣòfin àgbà, Sẹnetọ Olusọla Adeyẹye ní '' kìí ṣe ìgbà àkọ́kọ́ tí irú ẹ̀sùn bẹ́ẹ̀ yóò jẹyọ, àti pé ẹni tó fún ni ní owó ẹ̀yìn, tó fi mọ́ ẹni tó gbà á, ló jọ jẹ̀bi ìwà ìbàjẹ́ náà.
Èyí ni bí àwọn ọmọ̀dé 20 ṣe kú sínú kànga ní Kano
Kànga ni orísun omi fún ọ̀pọ̀lọpọ̀ ìdílé ní ìpínlẹ̀ Kano
Máni gbàgbé ni ọjọ́ kọkàndínlógún, oṣù Kẹrin ọdún 2018 jẹ́ fún ìdílé Bashir Hotoro. Lọ́jọ́ nàá, ọmọ wọn obìnrin, tó jẹ́ ọmọ ọdún mẹ́jọ, Zulaiha Bashir, lọ pọn omi ní inú kànga kan tó wà nítòsí ilé wọn, láti fi wẹ̀, ṣùgbọ́n tí kò padà sílé nítorí pé ó jábọ́ sínú kànga.
Gẹ́gẹ́ bí ilé iṣẹ́ paná-paná ní ìpínlẹ̀ Kano ṣe sọ, ọmọdébìnrin ọ̀hún ni ẹnì kẹrìnlélọ́gbọ́n tí ìròyìn rẹ̀ tẹ àwọn lọ́wọ́ pé ó kú nípa kíkó sí kànga tàbí inú odò.
Ṣùgbọ́n, ohun tó n kọ ọ̀pọ̀lọpọ̀ lóminú ni pé, ọdún yìí kò ti dé ìlàjì, tí nkan tó tó bẹ̀ ti ṣẹlẹ̀.
Ìyá ọmọ náà, Mallama Haddaniya Bashir, tó bá BBC Pidgin sọ̀rọ̀ ní , òun kò le gbàgbé ìṣẹ̀lẹ̀ na títí láí.
"Èmi àti Zulaiha la jọ wà lábẹ́ igi tó wà nínú ọgbà ilé wa lọ́jọ́ nà, ló bá sọ pé ooru n mú òun, ni mo bá ní kó lọ pọn omi kó fi wẹ̀. Bẹ̀ ẹ́ ló bá gbé ike omi tó sì lọ
Omi àkọ́kọ́ ló n  fà jáde nínú kànga, nígbà tí ìfami fa òun fúnra rẹ̀ sínú kànga nà. Kó sì tó dí pé àwọn ènìyàn dóòlà rẹ̀, ó ti kú.
Inú kànga yìí ni Zulaiha kú sí ní agbègbè Hotoro ní ìpínlẹ̀ Kano.
Bíó tilẹ̀ jẹ́ wí pé a gbà pè àsìkò rẹ̀ ló tó gẹ́gẹ́ bíi musulumi, ṣùgbọ́n ìrú èyí kò bá má ṣẹlẹ̀ kání a ní omi ẹ̀rọ̀ nínú ilé wa tàbí nítòsí. Ìjọba maa n gbé omi wá fún wa tẹ́lẹ̀, ṣùgbọ́n, wọ́n ti dáwọ́ rẹ̀ dúró."""
Abílékọ Bashir tún sọ pé kí ìjọba wá nkan ṣe sí bí àwọn ènìyàn ṣe n gbẹ́ kànga lọ́nà tó wù wọ́n.
Ilé aṣòfin fèsì sí ẹ̀sùn tí Jega fi kàn án
'Obìnrin tí kó ba fẹ́ òṣìṣẹ́ Mọ́ṣúárì, ìpinu rẹ̀ mẹ́hẹ'
Alhaji Aminu Kura tún ni òbí míì tó pàdánù ọmọ rẹ̀ Farook, tó jẹ́ ọmọ ọdún mẹ́ta lọ́dún márùn ún sẹ́yìn.
Ó sọ fún BBC pé ìjọba pẹ̀lú ìfọwọ́sowọ́pọ̀ àwọn olórí agbègbè, gbọdọ̀ maa mójútó bí àwọ̀n ènìyàn ṣe n gbẹ́ kànga ní ìbámu pẹ̀lú àwọn ìlànà ètò ààbò.
Àwọn olóye ní báyìí ló ṣe yẹ kí kànga maa wà ní dídé
"Àmọ́ nínú ọ̀rọ̀ rẹ̀, agbẹnusọ fún gómìnà ìpínlẹ̀ Kano, Dókítà Abdullahi Ganduje, Aminu Yassar, sọ pé ""ohun tó ṣẹlẹ̀ kò ní nkankan ṣe pẹ̀lú pé ìyà omi n jẹ ìpínlẹ̀ naa."
Ó ní kànga ti wà fún ọ̀pọ̀lọpọ̀ ọdún, ó sì ní bí wọ́n ṣe n gbẹ́ ẹ, tí wọ́n sì ti lo ọ̀pọ̀ ọdún tí ẹnikẹ́ni kò sì kú sínú wọn.
"Àti pé títẹ̀lé ìlànà ètò ààbò ni ọ̀nà àbáyọ̀."""
Dino Melaye pa àga dà, ó jókòó ságbo PDP
Oríṣun àwòrán, @dino_melaye
Òwúrọ̀ Ọjọ́rú ni Melaye padà sí ilé aṣòfin lẹ́yìn rògbòdìyàn tó wáyé láàrin òun àti àwọn ọlọ́pà
Ipinnu Sinetọ Dino Melaye lati lọ joko sẹba aga ti Sinetọ David Mark maa n joko si, ti n mu ki ọpọ ọmọ Naijiria maa beere pe, se sinetọ naa ti fi ẹgbẹ oselu APC silẹ ni, to si ti ba ẹgbẹ oselu PDP lọ ?
Awọn onwoye ni, boya igbesẹ yii ni Melaye fi n pasamọ fawọn ọmọ ilẹ yii pe, oun ti ba ẹgbẹ oselu PDP lọ.
Ohun to dabi ere ori itage naa bẹrẹ, nigba ti Dino Melaye rọ aarẹ ile asofin agba, Bukọla Saraki pe, ko pasẹ fun agbọpa ile pe, ko wa aaye fun oun ni agbo tawọn ọmọ ẹgbẹ oselu PDP maa n joko sii, to si ni oun fẹ jokoo si ẹba aarẹ ile tẹlẹ, Sinetọ David Mark.
Kia si ni awọn ọmọ ẹgbẹ oselu PDP tete faa mọra, ti wọn si wa aaye fun laarin wọn, paapa lẹba aga David Mark bi o til jẹ pe Mark ko si lori ijokoo.
Oríṣun àwòrán, @dino_melaye
Àṣòfin Dino Melaye fi ẹgbẹ́ òṣèlú APC sílẹ̀
Amọ sa, Saraki pasẹ pe, ko si idi fun Melaye lati paarọ ijoko.
Bẹẹ ba si gbagbe, Òwúrọ̀ Ọjọ́rú ni Melaye padà sí ilé aṣòfin lẹ́yìn rògbòdìyàn tó wáyé láàrin rẹ àti àwọn ọlọ́pà, lórí ẹ̀sùn tí wọ́n fi kàn án pé, ó pa irọ́ pé àwọn kan fẹ́ gba ẹ̀mí òun, tó fi mọ̀ bí àwọn ọ̀daràn kan tí ọwọ́ tẹ̀ ṣe sọ pé, Melaye ni baba ìsàlẹ̀ àwọn.
Ọ̀ọ̀ni Ilẹ̀ ifẹ̀ ké s'áwọn adarí láti mójútó àwọn ọ̀dọ́
Ọọni Ogunwusi Adeyẹye pe fun itọju awọn ọdọ
Bi aarẹ Buhari ṣe n leri leka pe oun yoo buwọlu abadofin to ro awọn ọdọ lagbara lati du ipo oṣelu lorilẹede yii, Ọọni ilẹ ifẹ, kọrọbọtọ bi ọka, jigbini bi akun Ọba Adeyẹye ogunwusi ti ke sawọn adari lati tubọ faaye gba awọn ọdọ ninu eto iṣelu.
Ọọni Ogunwusi pe ipe yii ninu ọrọ to sọ ni aafin ile oodua ni ilẹ ifẹ.
O ni bi awọn onwoye ṣe n sọ ọ wi pe orilẹede Naijiria ti pọ to, awọn ọdọ lo ko ida mẹfa ninu mẹwaa rẹ ti o si jẹ wi pe aifun wọn ni amojuto to peye lee fa ipenija nla fun ọjọ ọla orilẹede Naijiria.
"Awọn ọdọ ni Eledunmare gbe ọjọ iwaju orilẹede Naijiria le lọwọ. Asiko si to fun awọn oloṣelu lati wa wọrọkọ fi ṣada lori ọrọ naa.
Bi a fẹ bi a kọ, ida mẹfa ninu mẹwa awọn ọmọ orilẹede yii ni wọn jẹ ọdọ. Awọn ọdọ lo si ni ilu."
Ọọni Ogunwusi ni awọn ọdọ lo ko ida mẹfa ninu mẹwa iye eeyan to wa lorilẹede Naijiria
Bakanna ni Ọọni ilẹ ifẹ tun kọminu lori aisi ipolongo to lori eto ifeto sọmọbibi lorilẹede Naijiria.
O ni awọn to wa nipo gbọdọ sapa lati rii pe wọn gbe ipolongo naa de awọn aye gbogbo to yẹ fun awọn eeyan lati ṣe amulo rẹ.
Iléẹjọ́: Nyame jẹ̀bi ẹ̀sùn lílu owó Taraba ní póńpó
Oríṣun àwòrán, @abati1990
Ilé ẹjọ ní Nyame jẹbi ẹsùn mẹ́tàdínlọ́gbọ̀n nínú ẹsùn mọ́kànlélọ́gbọ̀n ti won fi kan.
Ilé ẹjọ gíga kan nílu Abuja ti dajọ ẹwọn ọdun mẹ́rìnlá fún Gómìnà àná ní ìpínlẹ̀ Taraba, Ogbeni Jolly Nyame.
Ilé ẹjọ ní Nyame jẹbi ẹsùn mẹ́tàdínlọ́gbọ̀n nínú ẹsùn mọ́kànlélọ́gbọ̀n ti won fi kan.
Awọn ẹsun naa nii sẹ pẹlu lilu ọwọ ijoba ní pónpó nígbà ti o je Gómìnà ni ìpínlè Taraba.
Adájọ Adebukola Banjoko dajọ ẹwọn mẹrin otooto fún-un, lẹyìn tí wọn fìdí ọrọ múlẹ pé o gba ribà, tọ sí se owo ilu ti wọn fi si ikawọ rẹ basu-basu.
Oríṣun àwòrán, EFCC Facebook
Nyame yóò ṣe ẹwọn ọdun mẹrinla náà àyàfi tí ilé ẹjọ gíga mii ba yí ìdájọ náà padà
Nyame yóò ṣe ẹwọn ọdun mẹrinla náà àyàfi tí ilé ẹjọ gíga mii ba yí ìdájọ náà padà.
Àjọ tí ó ń kojú ìwà jẹgúdújẹrá lo fẹsun kàn Nyame  pé o lu owo 1.64 biliọnu náírà ní pónpó.
Mnangagwa: Oníkálukú yóò yàn ẹni tó fẹ́ sípò tó wù ú
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Zimbabwe yóò dìbò lọjọ Aje, ọgbon ọjọ́, osù keje, ọdun 2018
Ìdìbò yìí ni àkọkọ iru rẹ lẹyin ti Robert Mugabe kúrò lori àlééfà ni Zimbabwe
Aare Emmerson Mnangagwa to ń tukọ orilẹ-ede Zimbabwe lọwọ lo kede ètò idibo naa.
Awọn ènìyàn ilẹ̀ Zimbabwe yóò ni anfani lati dibo yan aarẹ, awọn ọmọ ile igbimọ aṣofin ati àwọn kansilọ wọ́ọ̀dù kọọkan to ba wu wọn si ipo ti wọn fẹ.
Oṣù kọkanla ọdun to kọja ni Aarẹ Mnangagwa gori aleefa pẹlu iranlọwọ àwọn ológun nigba ti wón gba ijọba lọwọ Robert Mugabe.
Ọpọ àwọn ènìyàn ilẹ Zimbabwe ri ikede yii gẹgẹ bi igbesẹ si iṣejọba to munadoko ni èyí ti yoo bi idagbasoke to yẹ ti idibo naa ba waye láìsí wahala kankan.
Aarẹ Emmerson Mnangagwa jẹ ọmọ ọdun marundinlọgọrin bayii.
O ti ṣeleri pe eto idibo naa ko ni ni kọ́núunkọ́ọ kankan ninu.
Ọmọ ogoji ọdun, Nelson Chamisa, to n dije labẹ asia ẹgbẹ oṣelu 'The Movement for Democratic Changes' ni o jẹ olori alatako fun Emmerson Mnangagwa.
Morgan Tsvangirai to doloogbe loṣu keji ọdun yii lo ti jẹ olori ẹgbẹ oṣelu 'The Movement for Democratic Change' fun ọdun pipẹ.
Abimbọla Kazeem: Hábà! Ṣé ìwọ ti sáré pé ọmọ ọdún 40 ni?
INEC: Ẹgbẹ́ òṣèlú méje ni yóò kópa ní ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Àtúndì ìbò yó wáyé láti lé dí àlàfò tó ṣí sílẹ̀ nínú ilé ìgbìmọ̀ aṣòfin ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ
Ọjọ́ Abamẹta ni Ìbàràpá yóò yan ẹlòmíì ti wọ́n fẹ́ fi rọ́pò Oloogbe Micheal Adeyẹmọ nílé ìgbìmọ̀ aṣòfin
Àjọ olómìnira tó n ṣètò ìdìbò ní Nàìjíríà, INEC, ti kéde pé ẹgbẹ́ òṣèlú méje ni yóò kópa nínú àtúndì ìbò tí yóò wáyé ní ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́.
Ètò ìdìbò náà yóò wáyé láti lé dí àlàfò tó ṣí sílẹ̀ nínú ilé ìgbìmọ̀ aṣòfin ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́, látààrí ikú aṣojú ẹkùn náà, tó tún jẹ́ olórí ilé ìgbìmọ̀ aṣòfin ọ̀hun, Michael Adeyẹmọ tó papòda lọ́jọ́ kẹtàdínlọ́gbọ̀n, oṣù Kẹrin. ọdun 2018.
Oríṣun àwòrán, facebook/Michael Adeyemo
Abẹnugan ilé aṣòfin ipinlẹ Ọ̀yọ́, Michael Adeyemo jáde láyé lọ́jọ́ kẹtàdínlọ́gbọ̀n, oṣù Kẹrin, ọdún 2018.
Abimbọla Kazeem: Hábà! Ṣé ìwọ ti sáré pé ọmọ ọdún 40 ni?
Alága àjọ náà ní ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́, Ọ̀gbẹ́ni Mutiu Agboke, ló fi ìkéde ọhun síta níbí ìpàdé kan tó wáyé ní ìlú Eruwa l'Ọ́jọ́rú, lori ìmúrasílẹ̀ fún ètò ìdìbò náà.
O ni àwọn ẹgbẹ́ òṣèlú ọ̀hún ni, Accord, Peoples Democratic Party, All Progressives Congress, tó fi mọ́ Fresh Democratic Party atawọn miran.
Ẹ̀wẹ̀, ó fi kun un pé, ogóje ibùdó ìdìbò ni ètò ìdìbò náà yó ti wáyé jákèjádò ẹ̀kùn ìdìbò Ibarapa. Àti pé, ẹgbẹ̀ta lé mẹ́wàá òṣìṣẹ́ ní yóò tukọ̀ ìdìbò óhun.
Ètò ìdìbò náà ni ìrètí wà pé yó wáyé láàrin agogo mẹ́jọ òwúrọ̀ sí aago méjì ọ̀sán.
'Isẹ́ Tíátà tí mò ń se ti tó mi jẹun'
Oluwo: Ọpọ̀ àṣà àdáyébá tó ti dogbó, ló yẹ kí Aláàfin yípadà
Oríṣun àwòrán, Facebook/Alaafin
Ade yoo pẹ lori fun Alaafin Ọyọ
Oluwo ti ilu Iwo, Ọba AbdulRasheed Adewale Akanbi, Telu Kinni, ti ransẹ ikini si Alaafin Ọyọ, Ọba Lamidi Ọlayiwọla Adeyẹmi Kẹta, lori ayẹyẹ ọjọ ibi ọgọrin ọdun rẹ.
Bakan naa ni Oluwo tun gba Alaafin nimọran pe, ni bayii to ti pẹ lori oye, o yẹ ko ri daju pe awọn asa adayeba kan ti ọjọ ti lọ lori wọn nilẹ Yoruba, ni atunse ba, paaà ipo tawn olori ọba wa.
Oluwo ti Iwo Ọba AbdulRasheed Akanbi kí Aláàfin Ọyọ kú ọjọ́ ìbí
Oluwo wa fi awọn olori laafin se apẹrẹ, awọn to ni olori obinrin ni wọn jẹ, o si yẹ ka gba wọn laaye lati maa dade bii Ọbabinrin nilẹ Yoruba.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí:
Ìjọba Ọ̀yọ́: Kò sí ilé kan tí wọn kò tíì bí ìbejì ní Igbó Ọrà
Nigba to n ba BBC Yoruba sọrọ, Oluwo sọ pe, o wa ninu itan iṣẹdalẹ Yoruba pe, Olokun to jẹ iyawo Oduduwa de ade.
Oluwo ni bi a ti n fi ade mọ ọba nilẹ Yoruba, bẹẹ gẹgẹ lo yẹ ki a maa fi ade mọ awọn olori naa.
Oluwo wa gbadura pe Ọba Lamidi Adeyẹmi yoo lo aadọta ọdun laye si ati lori itẹ baba rẹ.
Oríṣun àwòrán, FunmiSodiq
Ọba Àkànbí ní iìjọba leè dá àjọ kan sílẹ̀ láti gbógun ti ìwà ẹgbẹ́ òkùnkùn
Oluwo tako ẹgbẹ́ òkùnkùn
Ijọba gbọdọ da ajọ kan silẹ ti yoo koju iwa ẹgbẹ okunkun lawujọ.
Oluwo ti ilu Iwo, Ọba Abdulrasheed Akanbi lo sọ bẹ nilu iwo.
Olúwòó ní  àwọn Ọba ń se ẹgbẹ́ òkùnkùn
Ọba Akanbi ni gulegule ẹgbẹ okunkun lawujọ n fẹ amojuto to jọju bayii.
O ni didẹkun iwa ibajẹ naa lawujọ, yoo nilo ki awọn Ọbalaye, oloṣelu ati aṣiwaju awujọ gbogbo pẹlu paramọ kuro ninu ẹgbẹ okunkun ṣiṣe.
Oríṣun àwòrán, FunmiSodiq
Ọba Àkànbí ní iìjọba leè dá àjọ kan sílẹ̀ láti gbógun ti ìwà ẹgbẹ́ òkùnkùn
Olúwo ni pupọ awọn Ọbalaye ati oloṣelu ni wọn wa lẹgbẹ okunkun, ti wọn ko si lee ko awọn ọdọ to n ṣe ẹgbẹ buruku naa nijanu.
"Nigba ti a ba n bu awọn ọdọ pe wọn n dara pọ mọ ẹgbẹ okunkun, ti awọn agba pẹlu, paapaa awọn lọbalọba pẹlu tun n ṣe ẹgbẹ okunkun.
Gbogbo awọn lọbalọba ati oloṣelu gbọdọ kuro lẹgbẹ okunkun ki wọn lee ba awọn ọdọ to n ṣe ẹgbẹ naa wi."
Bakan naa ni Ọba Akanbi tun pe fun idasilẹ ajọ kan ti ojuṣe rẹ yoo wa lati maa gbogunti iwa ẹgbẹ okunkun lawujọ laarin awọn ọdọ ati awọn agbablagba.
"Gbogbo awọn ofin to de iwa ẹgbẹ okunkun lawọn ọgba ileẹkọ, lawọn agbofinro ni lati gbe ko awọn agbaagba, awọn oloṣelu atawọn lọbalọba to n ṣe ẹgbẹ okunkun yii, loju.
Ijọba si gbọdọ da ajọ kan silẹ lati gbogun ti ẹgbẹ okunkun ṣiṣe."
Ilé ẹjọ́ ju gómínà àná ní Kaduna, Ramalan Yero s'átìmọlé
Oríṣun àwòrán, @MobilePunch
Yero jẹ́ gómìnà ní ìpínlẹ̀ Kaduna láàrin 2012 sí 2015
Ramalan Yero àti àwọn mẹ́ta míì ni adájọ́ pàṣẹ kí wọ́n fi sẹ́wọ̀n nítorí ẹ̀sùn tí àjọ tó ń gbógun ti ìwà ìbàjẹ́, EFCC, fi kàn wọ́n.
Ilé ẹjọ́ gíga ìjọba àpapọ̀ kan ní ìpínlẹ̀ Kaduna tí ju gómìnà nígbà kan rí s'atimọle títi ìgbẹjọ yoo fi pari.
Àwọn mẹ́ta ọ̀hún ni mínísítà fún ọ̀rọ̀ ilẹ̀ òkèérè nígbà kan rí, Nuhu Way, tó fi mọ́ ẹni tó ti fígbà kan jẹ́ akọ̀wé fún ìjọba ìpínlẹ̀ Kaduna, Hamza Ishaq, àti alága ẹgbẹ́ òṣèlú Peoples Democratic Party fún ìpínlẹ̀ Kaduna nígbà kan, Abubakar Gaya Haruna.
Yero tó jẹ́ gómìnà ní ìpínlẹ̀ Kaduna láàrin 2012 sí 2015 ni àjọ EFCC fi ẹ̀sùn lílú owó tó lé ní ẹ̀ẹ́dẹ́gbẹ̀rin mílíọ́nù Naira, 700 Million Naira ní pónpó.
Ṣáàjú àsìkò yí ni EFCC tí n wádìí gómínà ọ̀hún fún ipa tó kó nínú níná àti pínpín owó náà tó jẹ́ owó ìpolongo fún ẹgbẹ́ òṣèlú PDP lásìkò tí ìdìbò gbogboogbo ọdún 2015 kù díẹ̀.
Oríṣun àwòrán, @EFCC
Ẹsun ṣiṣe owọ ilu kumọkumọ ni wọn fi kan Yero
Adájọ́ àgbà ní ilé ẹjọ́ náà, Onídàjọ́ Mohammed Shuaibu, ní kí àwọn olùjẹ́jọ́ náà wà ní atimọle títí di ọjọ́ kẹfà, oṣù Kẹfà.
Èyí wáyé lọjọ́ keji tí ilé ẹjọ́ jú gómìnà àná fún ìpínlẹ̀ Taraba, Jolly Nyame sí ẹ̀wọ̀n ọdún mẹ́rìnlá, fún ipa tó kó nínú bí N1.64billion ṣe di àwátì lásìkò tó fi jẹ́ gómìnà láàrin ọdún 1999 sí 2007.
Abimbọla Kazeem: Hábà! Ṣé ìwọ ti sáré pé ọmọ ọdún 40 ni?
Gbadebọwale Abọdẹrin kú lásìkò isẹ́ abẹ ọkàn
Oríṣun àwòrán, @MobilePunch
Abọdẹrin lọ sí ilé ìwé Government College, Ibadan, ó sì tún kẹ́kọ̀ ní orílẹ̀èdè Amẹrika, gẹ́gẹ́ bi awakọ̀ òfurufú
Alága ìwé ìròyìn Punch, Gbadebọwale Abọdẹrin ti dágbére fáyé ní Ọjọ́rú lẹ́ni ọgọ́ta ọdún.
Ìwé ìròyìn Punch jábọ̀ pé, ó kú ní nkan bi agògò mẹ́fà kọjá ìṣẹ́jú màrun ùn òwúrọ̀ Ọjọ́rú, tí ṣe ọgbọ̀njọ́, oṣù Karùn ún, 2018.
Gbadebọwale Abọdẹrin jẹ́ ìpè Ọlọ́run lẹ́yìn iṣẹ́ abẹ ọkàn tí wọ́n ṣe fun un ní ilé ìwòsàn First Cardiology Consultants, Ikoyi, ní ìpínlẹ̀ Eko.
Abimbọla Kazeem: Hábà! Ṣé ìwọ ti sáré pé ọmọ ọdún 40 ni?
Nígbà ayé rẹ̀, òun nà ni Alága ilé iṣẹ́ ìtẹ̀wé Punch.
Ó lọ sí ilé ìwé Government College, Ibadan, ó sì tún kẹ́kọ̀ ní orílẹ̀èdè Amẹrika, gẹ́gẹ́ bi awakọ̀ òfurufú.
Ìyàwó kan, Titilayọ, àti ọmọbìnrin méjì, Nicole àti Cherelle ló ń gbẹ̀yìn tẹ́yìnse fún Ológbèé Gbadebọwale Abọdẹrin.
Dino: Kò tọ́ bi Buhari se tàbùkù ilé aṣòfin
Oríṣun àwòrán, Voice TV
Senato Dino Melaye ni oun fẹ kí Ààrẹ Buhari tọrọ aforijin lọwọ ilé
Senato Dino Melaye tutọ soke fojú gbàá, tó sì bẹnu àtẹ lù ààrẹ orílèèdè Nàìjíríà, Muhammadu Buhari.
O ní ọrọ tí ààrẹ sọ pé àwọn aṣòfin kan joko sile fún ọpọ ọdún, láì fi aba kánkan ṣòwò ku diẹ kaato.
Melaye ni, òkun ọrun ko ye adiẹ, nítorí náà kò tọ́ bi Aare Buhari ṣé sọ iru ọrọ bẹẹ sì àwọn aṣòfin.
Gẹ́gẹ́ bí Dino ti ṣe sọ, ọ ni Ààrẹ sọ ọrọ náà nígbà tí o gba àlejò awọn ọmọ ẹgbẹ tó n ṣé  ìpolongo fún ùn Buhari (Buhari Campaign Organisation), ti olórí ilé iṣé aṣobode, Ọgagun Hameed Ali ko sódì.
''Ipò ni Ọgá ile iṣẹ asobode. O lòdì s'ofin ki oga ile iṣẹ aṣobode máa polongo fún Ààrẹ.''
''Mo ti wa ni ilé fún nnkán bi ọdún mọkanla sẹyìn. Se Aare Donald Trump yóò sọ iru ọrọ yi sile asofin ile Amerika?''
Oríṣun àwòrán, @dino_melaye
Òwúrọ̀ Ọjọ́rú ni Melaye padà sí ilé aṣòfin lẹ́yìn rògbòdìyàn tó wáyé láàrin òun àti àwọn ọlọ́pà
Senato Dino ni, kò yá òun lẹnu pé àwọn tí Ààrẹ je oga fún kọ láti yọjú sí ilé
''Fèré ti olówó wọn n fọn sinu wọn, ni wọn n fọn sita.''
Fidio ọrọ rẹ ree loju opo Twitter.
Ko tan sibẹ. Dino kin ọrọ re lẹyin pẹlu abadofin tuntun ti Aare Buhari buwolu.
''Èmí ni mo se atona abadofin ti o faaye gbà àwọn ọdọ láti du ipò tí o bá wù wọ́n èyí tí ààrẹ buwọ́lù.''
''Bí Ààrẹ  bá fẹ mo òun ti a n  ṣe, ara rẹ ni abadofin náà''
Oríṣun àwòrán, facebook/Dino Melaye
Senato Dino Melaye ni oun fẹ kí Ààrẹ Buhari tọrọ aforijin lọwọ ilé
Lẹnu ọjọ mẹta yìí, Senato Dino Melaye àti ilé iṣé ọlọ́pàá, to fi mọ Gómìnà ipinle rẹ Kogi, ti n bá ará wọn fà wàhálà.
Ọrọ rẹ pada de ilé ẹjọ ṣugbọn lẹyìn ọpọ atotonu, adájọ gba oniduro rẹ̀.
Àwọn onwòye ní, inú Senato Dino kò dùn sí bí ẹgbẹ oselu APC pàápàá jùlọ Ààrẹ Buhari, kò ṣé kò ọgá ọlọ́pàá ni ijanu lórí ọrọ rẹ.
Òfin tuntun: Ọmọ ọgbọ̀n ọdún lè dupò ààrẹ báyìí
Oríṣun àwòrán, NIGERIA PRESIDENCY
Muhammadu Buhari ti bu ọwọ́ lu àbádòfin tì ó fààyè gba àwọn ọdọ́ láti du ipò kípò
Ààrẹ Muhammadu Buhari ti bu ọwọ́ lu àbádòfin tì ó fààyè gba àwọn ọdọ́ láti du ipò kípò tí ó bá wù wọ́n.
A gbọ́ pé ààrẹ bu ọwọ́ lu àbádòfin náà, ninu gbọ̀ngàn ìpàdé ìgbìmọ́ aláṣe tí ó wà ní ilé ààre, Aso Rock, ní Abuja ní Ọjọ́rú.
Ẹ ó rántí pé ààrẹ ti sọ ní àyájọ́ ọjọ́ ìjọba tiwantiwa ni ọjọ́ Ẹtì pé, oun yóò buwọ́ lu àbádòfin náà ní láìpẹ́ yìí.
Ọdún tó kọjá ni Ìgbìmo Aṣòfin Àpapọ̀ gba àbádòfin náà wọlé, láti ṣe àyípadà sí àwọn abala ìwé òfin orílẹ̀-èdè Naijiria, èyítí yóò gé ọjọ orí ati du ipò ààrẹ láti ogójì ọdún sí ọgbọ̀n ọdún.
Òfin náà yóò gé ọjọ orí ati du ipò gómìnà àti sẹ́nétọ̀ láti ọdún márùnlélọ́gbọ̀n sí ọgbọ̀n, ọjọ́ orí àwọn tí o lè dupò aṣojú-ṣòfin láti ọgbọ̀n ọdún sí mẹ́ẹ̀dọ́gbọ̀n.
Oríṣun àwòrán, NIGERIA PRESIDENCY
Muhammadu Buhari ti bu ọwọ́ lu àbádòfin tì ó fààyè gba àwọn ọdọ́ láti du ipò kípò
Uganda: Á lo owọ́ orí náà láti san gbèsè táa jẹ
Oríṣun àwòrán, AFP
Igba ṣílẹ̀, eyiun dọ́là márùn-ún àbí pọ́ùn mẹ́rin, làwọn èèyàn tó bá ń lo Whatsapp àti Facebook yóò máa san
Ilé asòfin lórílẹ̀-èdè Uganda ti buwọ́lu òfin kan tó ń fa awuye-wuye èyí tó ní káwọn èèyàn tó ń lo ojú òpò ìkànsíraẹ́ni lórí ìtàkùn àgbáyé bíi Whatsapp àti Facebook máa san owó orí.
Igba ṣílè, eyiun dọ́là márùn-ún àbí pọ́ùn mẹ́rin, làwọn èèyàn tó bá ń lo àwọn ojú òpó wọ̀nyí lórí ìtàkùn àgbáyé yóò máa san lójoojúmọ́, tí wọn bá sí Facebook, Whatsapp, Viber àti Twitter.
Àarẹ̀ Yoweri Museveni ti orílẹ̀èdè Uganda ló se agbátẹrù òfin náà pẹ̀lú àwíjàre pé àwọn ojú òpó ìkànsíraẹ́ni náà máa ń se kóríyá fún ìwà gbéborùn àbí ọ̀rọ̀ ẹ̀yìn.
Oríṣun àwòrán, AFP
Uganda nílò owó orí náà láti fi san díẹ̀ lára gbèsè tó jẹ
Ọjọ́ kìnní osù keje ọdún 2018 ni òfin náà yóò fẹsl múlẹ̀ sùgbọ́n iyèméjì wà lórí ọ̀nà tí wọn yóò gbà se àmúsẹ rẹ̀.
Mínísítà abẹ́lé fétò ìsúná ní Uganda, David Bahati sọ fáwọn asòfin náà pé ìjọba nílò owó orí náà, láti fi san díẹ̀ lára gbèsè tí orílẹ̀èdè náà jẹ, èyí tó ń rú gọ́gọ́ síi.
Iléesẹ́ ológun: 300,000 ọta ìbọn la gbà ní ìpínlẹ̀ Ògùn
Oríṣun àwòrán, @HQNigerianArmy
Àwọn èèyàn kan ló sín àwọn agbófinró ní gbẹ́rẹ́ ìpàkọ́ nípa àwọn onísẹ́ ibi náà,
Ọ̀wọ́ kọkànlélagọ́rin iléesẹ́ ológun ní Nàíjíríà kéde lọ́jọbọ pé òun ti sẹ́bùrú ọkọ̀ akẹ́rù mẹ́ta tó kún fún ẹgbẹ̀rún lọ́nà ọ̀ọ́dúnrún ọta ìbọn ní agbègbè Ìgbógílà-Ìlárá ní ìpínlẹ̀ Ògùn.
Olùdarí ọ̀wọ́ kọkànlélọ́gọ́rin iléesẹ́ ológun náà, Ọ̀gágun Enobong Udoh, ẹ́ni tí Ọ̀gágun Olusẹgun Ọlatunde sojú fún, ló sísọ lójú ọ̀rọ̀ yìí fáwọn akọ̀ròyìn ní ìlú Èkó.
Ọ̀wọ́ kọkànlélagọ́rin iléesẹ́ ológun pẹ̀lú àjọ́sepọ̀ àwọn agbófinró la jọ sẹ́bùrú àwọn ọkọ àkẹ́rù tó kó ọ̀pọ̀ ọta ìbọn ní déédé aago mẹ́ta ku ìsẹ́jú méjì òru Ọgbọ̀jọ́ osù karùn-ún, ọdún 2018. Abúlé Balógun ní òpópónà Ìgbógílà-Ìlárá ní ìpínlẹ̀ Ògùn, lọwọ́ ti tẹ àwọn ọkọ̀ náà tí nọ́nbà wọn jẹ́ Anambra, AAH 409 ZV, Lagos, BDG 782 XU àti Lagos, GGF 88 XU.
Sé Dino Melaye ti bọ́ sẹ́gbẹ́ PDP ni ?
Buhari buwọ́ lu òfin ọ̀dọ́ leè dupò
Abimbọla Kazeem: Hábà! Ṣé ìwọ ti sáré pé ọmọ ọdún 40 ni?
Ọ̀gágun Ọlatunde fi kun pé ní kété táwọn awakọ̀ àtàwọn ìsọmọgbè wọn kófírìí ikọ̀ agbófin náà, ni wọn bá ẹsẹ̀ wọn sọ̀rọ̀, tí àwọn sì ti ń tanná wádìí wọn àti àwọn èèyàn tó leè jẹ́ onígbọ̀wọ́ wọn.
Ò sàlàyé pé àwọn èèyàn kan ló sín àwọn ní gbẹ́rẹ́ ìpàkọ́ nípa àwọn onísẹ́ ibi náà, tó sì gbósùbà fáwọn olùgbé ìpínlẹ̀ Ògùn àti Èkó fún ìfọwọ́sowọ́pọ̀ wọn pẹ̀lú àwọn agbófinró.
Johesu: A so ìyansẹ́lódì rọ̀ kí ìjíròrò leè já gaara
Oríṣun àwòrán, AFP
Iyansẹlodi lẹka ilera orileede Naijiria ki se ohun tuntun mọ
Àwọn òṣìṣẹ́ elétò ìlera lórílẹ̀èdè Naijiria, labẹ àsìá ẹgbẹ́ àpapọ̀ àwọn òṣiṣẹ́ ìlera JOHESU fòpin sí iyansẹlodi wọn lónìí.
Adarí ẹgbẹ́ JOHESU, Josiah Biobelemoye, sọ ní Abuja lọ́jọ́bọ́ pé, àwọn so yanṣẹ́lódì náà rọ̀, láti lè jẹ́ kí ìfọ̀rọ̀wérọ̀ lọ déédé lórí àwọn oun tí wọ́n n béérè.
Biobelemoye ní kí àwọn ọmọ ẹgbẹ́ JOHESU padà sí ẹnu íṣẹ́ ní ọjọ́ Ajé tó ń bọ̀.
Àwọn aláìsàn rawọ́ ẹ̀bẹ̀ sí ẹgbẹ́ JOHESU
"Iyanṣẹ́lódì Johesu ti pé ọ̀sẹ̀ mẹ́ta lbáyìí, bẹ́ẹ̀ bá sì gbàgbé, osu kẹwa ọdún tó kọjá ni awọn dókítà orileede Naijiria, sapèjúwe ẹgbẹ àwọn oṣiṣẹ ilera Johesu gẹgẹ bii  ""ajo ti ko bofinmu""."
Wọn ni ọpọ òun ti Johesu n béèrè fún ko bójú mu.
Iyanṣẹ́lódì lẹ́ka ìlera Naijiria kìi ṣe ohun tuntun mọ́, ọ̀pọ̀lọ́pọ̀ àwọn ilé ìwòsan ni ó ti ní àwọn yóò lé àwọn ọmọ ẹgbẹ́ Johesu lẹ́nu iṣẹ́, tí wọn ko bá padà fòpin sí ìyanṣẹ́lódì náà.
Buhari: Ẹ̀yin ọ̀dọ́, ẹ padà wa díje lẹ́yìn mi ní 2019
Oríṣun àwòrán, NIGERIA PRESIDENCY
Muhammadu Buhari ti bu ọwọ́ lu àbádòfin tì ó fààyè gba àwọn ọdọ́ láti du ipò kípò tó wù wọ́n ni Nàìjíríà
Èrò àwọn ọmọ Nàìjíríà ṣọ̀tọ̀ọ́tọ̀ lórí àbá òfin tì ó fààyè gba àwọn ọdọ́ láti du ipò kípò tí ó bá wù wọ́n, #NotTooYoungToRun, èyí tí Ààrẹ Muhammadu Buhari ṣẹ̀ṣẹ̀ bu ọwọ́ lu.
Lọ́jọ́ Ajé ni Ààrẹ Buhari bu ọwọ́ lu àbá ọ̀hún, lẹ́yìn tó ti kọ́kọ́ ṣèlérí lọjọ kọkàndínlọ́gbọ̀n, oṣù Karùn ún, nínú ọ̀rọ̀ tó bá àwọn ọmọ orílẹ̀-èdè Nàìjíríà sọ lásìkò àjọ̀dún ètò ìṣèlú àwaarawa láti bu ọwọ́ lù ú.
Ṣùgbọ́n, ojú ti kálùkù ọmọ orílẹ̀-èdè Nàìjíríà fi wò ó yàtọ̀ síra wọn. Bí àwọn kan ṣe gbóríyìn fún Ààrẹ Buhari fún ìgbésẹ̀ nà, ni àwọn kan n sọ ìdàkejì lọ́rọ̀.
Kíni àbájáde òfin tuntun yìí fún àwọn ọdọ Naijiria?
Adúrà wa ni pé ki òfin yii ru àwọn ọdọ soke lati ṣe rere.
Kíni àbájáde òfin tuntun yìí fún àwọn ọdọ Naijiria?
Nínú ọ̀rọ̀ ti rẹ̀, Ààrẹ ilé aṣòfin àgbá, Bukọla Saraki, ní òfin tuntun náà ni ìpìlẹ̀ kíkó àwọn ọ̀dọ́ mọ́ra nínú ètò ìṣèlú, àti pé Nàìjíríà nílò agbára àwọn ọ̀dọ́ fún ìdàgbàsókè rẹ̀.
Ṣe kò sí ti òfin yìí kò fi kan ọjọ orí àwọn sẹnetọ ati gomina? Bẹẹ, kò yẹ ki ìbí ju ìbí lọ
Àwọn kan gbà pe, o tumọ si pe ki àwọn arúgbó lọ rọ ọ kún sile ni.
Oríṣun àwòrán, Twitter
Àwọn ọ̀dọ́ Nàìjíríà ti n késí ara wọn láti gbégbá ìbò
Kódà, olú ilé iṣẹ́ ilẹ̀ Amẹrika tó wà ní ìlú Abuja nínú ọ̀rọ̀ tí wọn, kí àwọn ọ̀dọ́ Nàìjíríà kú oríire fún òfin tuntun náà.
Ẹ̀wẹ́, àwọn kan ní ó yẹ́ kí Buhari bu ọwọ́ lu òfin míì tí ó fi òfin de àwọn tó ti 'dàgbà jù' láti má díje fún ipò ìṣèlú, tí wọ́n sì ti n lo àmì #TooOldToRun láti gbe ìpolongo wọn lẹ́yìn.
Oríṣun àwòrán, Twitter
Àwọn ọ̀dọ́ kan n fẹ́ kí Buhari fi òfin de àwọn tó ti 'dàgbà jù' láti maa dupò ìṣèlú
Abimbọla Kazeem: Hábà! Ṣé ìwọ ti sáré pé ọmọ ọdún 40 ni?
Amòfin: Nínà ojoojúmọ́ lé mu kí ìyàwó pa ọkọ rẹ̀
Oríṣun àwòrán, CC
Ara ìwà ipá ni sísọ ọ̀rọ̀ kòbákùngbé síra ẹni, tàbí fífi ọ̀rọ̀ èébú ránṣẹ́ sí òbí ọkọ tàbí ìyàwò ẹni.
Kìí ṣe tuntun fún tọkọ-taya láti ní gbólóhùn asọ̀ láàrin ara wọn, ṣùgbọ́n kàyéèfì tó wà níbẹ̀ ni pe, kí irú àáwọ́ bẹ̀ maa yọrí sí ikú tàbí ìfarapa.
Láyé ìgbà kan, ọkùnrin ni a ṣábà maa n gbọ́ pé, ó lu ìyàwó rẹ̀, ṣùgbọ́n lóde òní, ìròyìn nípa àwọn òbìnrin tó n lu ọkọ wọn nàá tí n jáde.
Láti bi i ọdún mélòó sẹ́yìn, ni ìròyìn ń gbalẹ̀ kan nípa bi ọkọ tàbí ìyàwó ṣe n pàdánù ẹ̀yà ara wọn lásìkò tí ìjà bá n wáyé láàrin tọkọ-taya, tí àwọn mìí tilẹ̀ n pàdánù ẹ̀mí wọn.
Amòfin kan tó tún jẹ́ ajàfẹ́tọ̀ àwọn obìnrin, Abiade Abiala, nígbà tó n bá BBC Yoruba sọ̀rọ̀, ṣàlàyé oríṣiríṣi ìwà ipá tó wà.
Oríṣun àwòrán, Facebook/Abiade Abiola
Ìmọ̀ràn rẹ̀ ni pé níṣe ló yẹ kí ọkọ àti ìyàwó tó bá n la ìwà ipá kọjá wá ọ̀nà láti ṣàtúnṣe.
Kí ló lé mú kí obìnrin pa ọkọ rẹ̀?
Ó wá gba tọkọtaya ní ìmọ̀ràn pé, n ṣe ló yẹ kí ọkọ àti ìyàwó tó bá n la irú nkan bẹ́ẹ̀ kọjá wá ọ̀nà láti ṣàtúnṣe.
Àti pé, kí gbogbo ènìyàn àwùjọ mọ̀ pé, bí àwọn obìnrin nàá ti ṣe n gba ara wọn sílẹ̀, tí àwọn mì í tilẹ̀ n ṣekú pa ọkọ wọn, n fihàn pé, àsìkò ti tó láti fi òpin sí irú àwọn ìṣẹ̀lẹ̀ bẹ́ẹ̀, àti láti wá ọ̀nà tí nkan kò fi ní bàjẹ́ ju bóṣe wà lọ.
'A ń sa ipá wa láti dẹ́kun ìwà ìjẹkújẹ lórílẹ̀-èdè Nàìjíríà'
Oríṣun àwòrán, @officialEFCC
Àjọ EFCC ní òun leè fọwọ́ sọ̀yà pé iṣẹ́ ń lọ ní pẹrẹu
Ajọ to n gbogun ti iwa jẹgudujẹra lorilẹ-ede Naijiria, EFCC, sọ  pe eeyan mẹtadinlaadọta o le ni ẹgbẹta l'awọn ti ran lọ sẹwọn laarin oṣu kọkanla si asiko ti a wa yii lori ẹsun ṣiṣowo baṣubaṣu.
Ọgbẹni Samin Amadin, to jẹ olori ẹka ilanilọyẹ ati itaniji fun ajọ EFCC, ṣalaye nilu Abuja pe nipasẹ ilakaka ajọ ọhun, ọkan o jọkan awọn agbaagba lẹnu iṣẹ ologun, agbẹjọro, adajọ atawọn oloṣelu gbogbo ni wọn n kawọ pọnyin rojọ l'awọn ile ẹjọ kaakiri fun ẹsun jẹgudujẹra.
Laarin ọdun mẹta, ko din ni ẹẹdẹgbẹta biliọnu naira ti ajọ naa ti gba pada lọwọ awọn to ko owo ilu jẹ
Ọgbẹni Amadin ni ohun to dara ni bi awọn ọdọ lorilẹ-ede Naijiria pẹlu ti ṣe bẹrẹ si ni da si igbesẹ ati ijiroro pẹlu ijọba lori gbigbogun ti iwa jẹgudujẹra.
O ni ajọ EFCC yoo tẹsiwaju lati maa fọwọsowọpọ pẹlu awọn ẹgbẹ ọdọ lori riro igbesẹ gbigbọgun ti iwa ibajẹ lagbara.
Dangote ni ìdàgbàsókè ẹ̀ka ọ̀gbìn ti mú àwọn agbẹ gòkè àgbà
Oríṣun àwòrán, @NGRPresident
Bí Nàìjíríà bá tẹra mọ́ ìdàgbàsókè ẹ̀ka ọ̀gbìn, yóò leè bọ́ ẹkùn ìwọ̀ oòrùn Áfíríkà lapapọ
Olokoowo to lowo ju ni Afirika, Aliko Dangote, ti fi ọrọ ẹri lelẹ pe nnkan ti n sẹnuure fawọn agbẹ lorilẹ-ede naijiria.
Dangote ni awọn agbekalẹ  ilana ati eto iṣejọba ti Aarẹ Buhari gbe kalẹ ti ro awọn agbẹ lagbara ti awọn pẹlu si lee fi ọwọ sọya lawujọ pe iṣẹ ọwọ wọn n to wọn jẹ ti wọn si fi n pa owó sapo.
Dangote mẹnu le ọrọ lasiko to fi kọwọrin pẹlu awọn oniṣowo jankanjankan lorilẹ-ede Naijiria lọ sibi apejẹ iṣinu awẹ eleyi ti aarẹ Buhari ṣeto ni lu Abuja.
"Eto ọrọ aje ti n pada bọ sipo, owo wa si ti i burẹkẹ sii lojoojumọ; nnkan yoo tubọ maa se rẹgi lorilẹ-ede yii.
Iṣoro ati idamu ti awọn ileeṣẹ la kọja lọdun 2016 si 2017 ti di ohun igbagbe bayii."
Oríṣun àwòrán, @NGRPresident
Iṣoro ati idamu ti awọn ileeṣẹ la kọja lọdun 2016 si 2017 ti di ohun igbagbe
O ni yoo dara pupọ bi ijọba ba n tẹsiwaju lati yẹ awọn ẹka miran yatọ si epo rọbi wo fun idagbasoke eto ọrọ aje.
Bakan naa lo tun ni awọn agbẹ ti di ọba bayii ti apo wọn gan ti wu soke ju ti awọn oṣiṣẹ ijọba gan an lọ.
O ni orilẹ-ede Naijiria lee bọ gbogbo ẹkun iwọ oorun Afirika bi awọn adari rẹ ba gbajumọ idagbasoke eto ọgbin.
Tramadol: Orísun ikú, àìní-rètí àti Boko Haram
Ìlú Maiduguri ló ń forí sọta làásìgbò Boko Haram fún ọ̀pọ̀lọpọ̀ ọdún - bákan náà ló tún ń ja ìjà abẹ́nú pẹ̀lú àsìlò òògùn
Òògùn Codeine nìkan kọ́ ni òògùn táwọn èèyàn sọ di bárakú jákè-jádò ẹkùn ìwọ̀ òòrùn Afrika. Òògùn araríro míì, Tramadol, náà sì ń tàn kálẹ̀, bíi òògùn táwọn èèyàn ń sì lò - gẹ́gẹ́ bi akọ̀ròyìn BBC, Stephanie Hegarty se sàwárí rẹ̀, èyí tún leè ta epo pẹtiroolu sí ina ìgbésúnmọ̀mí tó ń jó ní ìlú Maiduguri.
Nígbà tí Mustapha Kolo, ẹni ọdún mẹ́tàdínlógún mu òògùn pupa tó dùn wò lójú náà, ó dà bíi pé ó leè hú igi. Bíí ìgbà tí ara rẹ̀ kìí se tiẹ̀. Ó sì ń mú èrò burúkú jáde.
Tí mo bá ti múú, mo máa ń gbàgbé gbogbo nkan ni.
Fídíò òògùn ikọ́ Codeine: Ó dùn lóòtọ́ àmọ́ ewu ni
Ojú Kolo dúdú, tó sì pọ́n bíi ẹ̀yẹ iná, ohùn rẹ̀ ń lọ́ pọ̀, tí kò sì já gaaraga bó se ń sọ̀rọ̀. Ọ̀rẹ́ rẹ̀, Modu Mustapha ni kò mọ ohun tó ń se mọ́, tí orí rl sì ń mì dirọ̀-dirọ̀ ní ààrin èjìká rẹ̀ tó jk kìkì eegun.
Ó fojú hàn gbangba pé irọ̀ ni wọ́n ń pa, tí olórí wọn, tí wọn wà lọ́dọ̀ rẹ̀ gẹ́gẹ́ bíi fijilante tó ń sọ́ ìlú Maiduguri, sì rọ̀ wọn láti sọ tòótọ́.
Tẹ́lẹ̀-tẹ́lẹ̀, mo máa ń mu tó mẹ́ta tàbí mẹ́rin nígbà tí mo bẹ̀rẹ̀ sí ní muú. Sùgbọ́n ní báyìí, mo ti dínkù sí ẹyọ kan tabi ààbọ̀, tí Kolo kò sì setán láti sọ̀rọ̀ síwájú.
Mustapha Kolo ní òògùn oníhóró náà máa sèrànwọ́ tóun bá wà nínú igbó láti bá Boko Haram ja
Ní ìlú tí kò fararọ yìí, ẹgbẹ̀lẹ́gbẹ̀ èèyàn ni òògùn olóró Tramadol ti di bárakú fún - àwọn ẹ̀sọ́ fijilante, àwọn tí ogun le nílé àti àwọn adúnkookò gan fún ra wọn.
Òògùn aporó tí kò wọ́n rara yìí wà láti wo ara ríro níwọ̀n ba. Sùgbọ́n, gẹ́gẹ́ bó se máa ń rí pẹ̀lú àwọn òògùn olóró, èèyàn leè kúndùn rẹ̀, kó sì di bárakú sí onítọ̀ún lára - sùgbọ́n àríyàn-jiyàn sì ń wáyé lórí bí èèyàn se leè kúndùn rẹ̀ sí.
"Àjọ elétò ìlera lágbàáyé (WHO) ní Tramadol làwọn èèyàn lérò pé ó ""èèyàn leè má tètè kúndùn rẹ̀ táa fi wé Morphine"""
Àmọ́ bí ọwọ́jà òògùn náà se ń jà rànìn-rànìn káàkiri ẹkùn ìwọ̀ òòrùn Afrika tako èrò yìí.
Bí àwọn ọmọ Nàíjíríà se kúndùn òògùn lílò ti di ìràwọ̀ ọ̀sán, tó ń ba àgbà lẹ́rùn báyìí - àjọ ìsọ̀kan àgbáyé sì fẹ́ se ìwádìí lópin ọdún yìí
Àwọn olórí àtàwọn ológun ni wọ́n se Tramadol fún, àmọ́ bí àwọn àdúnkookò-mọ́ni se wá kúndùn rẹ̀ láti máa gbẹ̀mí ẹni, wá di àpérò àwọn ọmọ eríwo báyìí, èyi tí wọn ló ń dákún bí ọwọ́jà wọn se ń le koko síi.
Ọ̀kan lára àwọn agbébọn tẹ̀lẹ̀, tíí se ẹni ọdún mọ́kànlélógún, tó wà ní àgọ́ àwọn ológun ilẹ̀ Nàíjíríà, lẹ́yìn tó ti sá ní àgọ́ Boko Haram lósù kínní 2018, sàlàyé pé ọdún mẹ́rin ni òun fi gbé inú igbó níbi tí kò sí omi tó tó tàbí oúnjẹ - sùgbọ́n Tramadol wà.
Tá a bá ń lọ se ìkọlù wa, wọn yóò fún wa ní òògùn náà láti lò, bí bẹ́ẹ̀ kọ́, tó o bá mu ú, wọ́n leè pa ọ́. Wọ́n sọ fún wa pé tí o bá ti mu òògùn náà, ẹ̀rù kò ní bà ọ́ ma, ó ní agbára àti okun síi. Òògùn áà pọ̀ ní àpsjù.
Àwọn olórí àtàwọn ológun ni wọ́n se Tramadol fún
"Gẹ́gẹ́ bí Ọ̀gbẹ́ni Àyúbà ti wí, ""kò sẹ́ni tó leè pa èèyàn lójú lásán, sùgbọ́n òògùn Tramadol wà níbẹ̀ láti tìẹ́ sisẹ́ ibi."""
"Àwọn obìnrin kan wà tí wọn ti sá kúrò ní ibùba Boko Haram, àmọ́ tí òògùn olóró ti di bárakú fún nítorí ń se làwọn àdúnkookò-mọ́ni náà máa ń lo òògùn fáwọn ọmọdebìnrin náà tí wọn bá ti ń sunkún."""
Àjọ ìsọ̀kan àgbáyé ní, àwọn ikọ̀ ọ̀daràn lágbàáyé ló ń kó Tramadol wọ ilẹ̀ Afrika láti ẹkùn gúúsù ilẹ̀ Asia. tí àwọn agbófinró sì ń gbẹ́sẹ̀ lé ìwọ́n kílò tó tó ọ̀ọ̀dúnrún ní ọdọọdún.
Àjọ ìsọ̀kan àgbáyé ní, àwọn ikọ̀ ọ̀daràn lágbàáyé ló ń kó Tramadol wọ ilẹ̀ Afrika láti ẹkùn gúúsù ilẹ̀ Asia
Ní báyìí tí ìlòkulò Tramadol ń wáyé ní Nàíjíríà, ó nira púpọ̀ láti mọ ìdí tí wọ́n se gbé Tramadol sí abẹ́ àwọn òògùn olóró bíi oxycontin, morphineàtàwọn òògùn olóró míì bíi Cocaine ní orílẹ̀èdè Amẹ́ríkà.
Jẹẹsí Eagles: Bí wọ́n ṣe ṣíi ní London náà ló tán lórí igbá
Oríṣun àwòrán, @conroy_bumpus/Twitter
Ní wákàtí péréte lẹ́yìntí wọn ṣí jẹsí náà ni wọn ra gbogbo rẹ̀ tan
Àwọn ọmọ orílẹ̀-ede Naijiria ati àwọn aláwọ̀ funfun, ti ya bo iléeṣẹ́ Nike tí ó ṣe aṣọ egbẹ́ agbáọ́ọ̀lù Naijria, ní kété tí wọn ṣí aṣọ náà ní iléeṣẹ́ wọn tí ó wà ní London.
Jẹẹsi náà dùn lati wo lójú
A tí lẹ̀ gbọ́ pé, èrò tí ó wá sí ṣọ́ọ́bù Nike náà láti ra jẹẹ́sí ní ìgbaradì fun ìdíje ife àgbáyé pọ̀ tó bẹ̀ẹ̀, tí wọ́n tò láti àdúgbò kan sí òmíran.
Iléesẹ́ Nike sọ lójú òpó ìkànsíraẹni Twitter wọn pé lóótọ́ ni ajé bu igbá jẹ.
A gbọ́ pé, aago mẹ́jọ àárọ̀ ni wọn ṣí jẹẹsí náà, ní wákàtí péréte lẹ́yìn náà, ni Nike ba sọ pé wọn ti ra gbogbo jẹẹsí tí ó wà nílẹ̀ tán.
'Obìnrin tí kó ba fẹ́ òṣìṣẹ́ Mọ́ṣúárì, ìpinu rẹ̀ mẹ́hẹ'
Opeyemi Bamidele fara gbọgbẹ́ níbi ìwọ́de fún Fayẹmi
Oríṣun àwòrán, @repbamidele
Ikun ati ẹsẹ ni ọta ibọn naa ti ba Opeyemi Bamidele
Eniyan kan ti ku ti ọpọ eniyan si fara pa ninu isẹlẹ iyinbọn to waye ni ibi igbalejo tí wọ́n se fún Kayọde Fayemi,oludije ipo Gomina ni ipinle Ekiti.
Olu ile ẹgbé oselu APC to wà ní Ado-Ekiti ni isẹlẹ naa ti waye.
Lara awon to farapa ni ibi isele naa ni Opeyemi Bamidele, to jẹ ọmọ asoju ile asofin orileede Naijiria ana ni ipinle Ekiti.
Ọkan lara awọn amugbalẹgbe Bamidele fun eto iroyin, Ahmed Salami, sọ fun BBC Yoruba pe, ni ibi igbalejo ti wọn n se fun Kayode Fayemi, ẹni to jawe olubori ninu idibo abẹle ẹgbẹ oselu APC to kọja ni Ipinlẹ Ekit,i ni ìṣẹlẹ náà ti ṣẹlẹ.
Salami ni, Bamidele ti n gba itọju bayii ni ile iwosan ijọba ipinlẹ to wa ni Ado-Ekiti ati pe ikun ati ẹsẹ ni ọta ibọn naa ti baa
Oríṣun àwòrán, @repbamidele
Bamidele jẹ ọkan lara awọn oludije fun ipo gomina labẹ ẹgbẹ oselu APC
Bẹẹ ba gbagbe, Bamidele jẹ ọkan lara awọn oludije fun ipo gomina labẹ ẹgbẹ oselu APC ti Kayọde Fayemi bori wọn, ninu idibo abẹle APC to kọja naa.
Iroyin to tẹ wa lọwọ ni, wahala kan bẹ silẹ ni ibi igbalejo Fayemi, nigba ti janduku kan bẹrẹ si ni lọ ibọn mọ ọlọpaa kan lọwọ, ni ibọn naa ba ro kùù, ti ọta si fọn jade,eyi to lọ ba Bamidele.
John Oyegun kò ní dije Alága APC
Oríṣun àwòrán, @APCNigeria
Awọn aawọ abẹ́nu ninu ẹgbẹ oselu APC jẹ ìpèníjà fun Odigie ni saa rẹ gẹgẹ bi Alaga ẹgbẹ
Alága ẹgbẹ́ òṣèlú APC lorílè-èdè Nàìjíríà Ọgbẹni John Odigie-Oyegun ní òun ko ni du ipò Alága ẹgbẹ́ nínú ìpàdé gbogboògbò ẹgbẹ́ tó n bò lónà.
O kéde ọrọ̀ náà nígbà tí o n ba àwọn akoroyin sọrọ l'Abuja.
Oyegun ni òun o fe je ìṣòro tí ẹgbẹ́ yóò máa wa ona abayọ si.
Fún ìdí èyí ni mo fi jáwọ kúrò nínú ìdíje fún ipò Alága ẹgbẹ́
Odigie-Oyegun ní eléyìí ko ni jẹ idiwọ fún titẹsi waju ṣíṣe iṣẹ òun gẹ́gẹ́ bíi Alága ẹgbẹ́ títí di ọjọ keedogbon, osu kefa ti sáà òun yóò wá sí òpin.
Kò tíì dájú òun tó mú gbé ìgbésẹ yi lẹyìn alaye tó ṣe ṣùgbọ́n àwọn kan ní ọ gbe ìgbésẹ náà lẹyìn tó ṣe ìpàdé pẹlú Ààrẹ Buhari lọjọ kerindinlogbon, oṣù  kẹrin.
Shina Peller: Afojúsùn mi ni kí gbogbo ènìyàn jẹ mùdùn-múdùn ìjọba
Oríṣun àwòrán, @ShinaPeller
Ọmọ Prof. Peller gbé 'gbá ìbò fún 2019
Alága ilé isẹ́ Aquilla Group, Olóyè Shina Peller ti kéde pé òun yóò du ìpò asojú ní ilé ìgbìmọ̀ asojúsòfin nínú ètò ìdìbò tó m bọ̀ lọ́dún 2019.
Shina Peller to jẹ́ ọmọ bíbí inú gbajúgbajà onídán tí gbogbo ènìyàn mọ̀ sí Professor Peller ní òun yóò díje láti sojú kùn ìdìbò  Iseyin, Itesiwaju, Kajola àti Iwajowa ti ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́.
Àwọn tó ní dandan àfi kí Shina Peller rawọ́lé òsèlú sọ pé àksìkò tó kí àwọn ará Ọ̀yọ́ wá ọ̀dọ́ tó sì ní òye sínú ìjọba fún ìdàgbàsókè ìpínlẹ̀ náà.
Ó sọ ọ́ di mímọ̀ pé ní ọ̀pọ̀lọpọ̀ ìgbà ni wọ́n ti rọ òun láti lo ànfàní pé ó jẹ́ gbajúgbajà mí ìpínlẹ̀ náà fún òsèlú sùgbọ́n tí kò tíì pinnu lọ́kàn rẹ̀.
"Shina ti fi ìgbà kan f'èsì wí pé ""ní báyìí, òwò mí ló jẹ́ àkọ́kọ́ lọ́kàn mi, bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé àwọn ènìyàn mi ń fàmi n''ihìín lọ́hùún láti dara pọ̀ mọ́ òsèlú, sùgbọ́n mi ò tíì pinnu ọkàn mi"""
Ọmọ bíbí ìsẹ́yìn náà sọ pé láti ìgbà tí 'ti wà nílé ìwé gíga fásitì Ladoke Akintola ní Ogbomosho lòun ti ń sèrànwọ́ àti ìgbaniníyànjú fún àwọn ènìyàn, èyi ni bí ó se di gbajúgbajà.
Oríṣun àwòrán, @ShinaPeller
Àworan Shina Peller
Shina Peller tún mẹ́nu ba ọrọ̀ ajé orílẹ̀èdè Nàìjíríà, ó tẹnu mọ ọ wí pé ìgbafẹ́ ní ọ̀pọ̀lọpọ̀ ànfàní tó le è mú ọrọ̀ ajé Nàìjíríà gbòòrò síi.
Ó rọ ìjọba láti yé se ojú ayé lórí ọ̀rọ̀ à ń sọ ọrọ̀ ajé di ọ̀pọ̀ yanturu sùgbọ́n kí wọ́n dojú kọ ọ́ bó ti tọ́.
Ìṣẹlẹ iyinbon APC Ekiti : Ki gaan lo ṣẹlẹ?
Justice Mustapha Akanbi f'ayé sílẹ̀ lẹ́ni ọdún 85
Oríṣun àwòrán, Abdul Momoh
Justice Mustapha Akanbi f'ayé sílẹ̀
Adájọ́ Àgbà Mustapha Akanbi ti re 'bi àgbà ń rè. Òsìsẹ́fẹ̀yìntì ilé ẹjọ́ kòtẹ́milọ́rùn tó tún jẹ́ alága àkọ́kọ́ àjọ tó ń gbógun ti ìwà jẹgúdújẹrá ICPC papòdà ní àfẹ̀mójúmọ́ òní, ọjọ́ àìkú, ọjọ́ kẹta osù kẹ́fà ọdún 2018 lẹ́yìn àìsàn ráńpẹ́.
Olóògbé Wàkílì ti ilú Ilọrin f'ayé sílẹ̀ ní ẹni ọdún márùndínláàdọ́rin.
Ìsìnkú yóò wáyé lọsan ọjọ́ àìkú.
Àwọn abáni kẹdun sí ti n ṣe àbẹwò sí ilé olóògbé náà ni ìlú Ilorin.
Wọnyi ni akojopo àwòrán bi ètò ṣe n ló níbẹ.
Oríṣun àwòrán, Abdul Momoh
Adari Ajọ to n risi eto idanwo aṣewọle s'ile ẹkọ giga, JAMB Ojogbon Oloyede ati agba oje agbejoro Olaolu Alli
Oríṣun àwòrán, Abdul Momoh
Won gbe iwe ibanikedun kale ti awọn eeyan si n fọwọ si
Oríṣun àwòrán, Abdul Momoh
Ọpọ eniyan lo'n jaran Ologbee Akanbi
England na Nigeria pẹ̀lú àmi ayó 2- 1
Motunrayo Adeoye: Ọgbẹ́ inú mú òṣèré  lọ
Ìṣẹlẹ iyinbon APC Ekiti : Ki gaan lo ṣẹlẹ?
Ẹgbé òsèlú APC ní Ekiti dáwọ́ ìpolongo ìdìbò Gómìnà dúró
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Alaga Ẹgbẹ́ òsèlú APC ní Èkìtì ni àwọn kò ní ṣé ipolongo ti ko ba sì ààbò tó péye
Ẹgbẹ òṣèlú APC ti fi adagba ètò ìpolongo ìdìbò fún ipò Gómìnà wọn ni ìpínlè Ekiti rọ̀ ná.
Ìpolongo náà tó yẹ kí ọ wáyé ni ọjọ ajé ni wọ́n ni sun sí iwájú títí di ìgbà tí àwọn ọlọ́pàá yóò lè pèsè ààbò tó péye fún wọn.
Ìròyìn ti ile iṣẹ ìròyìn News Agency of Nigeria gbé sọ wí pé alága ẹgbẹ APC ni ipinle Ekiti, Jide Awe sọ pé isunsiwaju náà ní ṣe pẹlú ìsẹ̀lẹ̀ ìyìnbọn to wáyé láìpẹ́ yìí ní ìpínlẹ̀ náà.
Ìṣẹlẹ iyinbon APC Ekiti : Ki gaan lo ṣẹlẹ?
Olùdìbo 2327 ló péjú fún yíyàn Asoju APC Gómìnà Ekìtì
Ọ tẹnumọ ọ pe ìsẹ̀lẹ̀ ìyìnbọn to wáyé kìí se àṣìṣe bi kíì ṣe pé wọn fẹ pa Kayode Fayemi tó jẹ Oludije ẹgbẹ́ awọn ni.
Oríṣun àwòrán, Facebook/APC Ekiti
Eniyan kan ti ku ti ọpọ eniyan si fara pa ninu isẹlẹ iyinbọn to waye ni ibi igbalejo tí wọ́n se fún Kayọde Fayemi.
Ṣugbọn ile iṣé ọlọ́pàá nínú esi ìwádìí ti wọn gbe jade lọ́jọ́ àbámẹ́ta sọ pé àṣìṣe ni ìsẹ̀lẹ̀ ìyìnbọn náà .
Alukoro ile iṣé ọlọ́pàá , DSP Caleb Chukwuemeka sọ pe ''a ti mú ọlọ́pàá to yin ìbon náà.''
''Ìlú Eko ní ayé iṣẹ́ re wa ṣugbọn ọ wá ṣé ìṣe àlùmọ̀kọ́rọ́yí ni Ekiti pẹlú olóṣèlú kàn ní.''
O fi kun un pe àwọn tó f'arapa nínú ìṣẹlẹ náà n gba ìtọjú ni ile ìwòsan nígbà tí ọlopaa ọ̀ún wa ni ìtọ́jú lábẹ́lé.
Ayédèrú agbẹjọ́rò tó ṣiṣẹ́ fún ọdún mẹ́ta láì ní'wé ẹ̀rí
Oríṣun àwòrán, LAGOS STATE POLICE COMMAND
Uche Julian Nwajiakwu bẹ̀rẹ̀ iṣẹ́ agbẹjọ́rò ni 2015
Ọwọ́ ọlọ́pàá ti tẹ arákùnrín kan ní ilé ẹjọ́ ìbílẹ̀ tí ó wà ní Ọ̀jọ́ ni Ìpínlẹ̀ Eko lórí ẹ̀sùn pé ayédèrú agbẹjarò ni.Agbẹnusọ fún àjọ ọlọ́pàá Ìpínlẹ̀ Eko, Chike Oti, sọ wipé àwọn ikọ̀ ọ̀tẹlẹ̀múyẹ́ àjọ náà ni ó mu u, ti ó sì jẹ́wọ́ wípé òun ti ń ṣiṣẹ́ agbẹjọ́rò fún ọdún mẹ́ta láà ní ìwé ẹ̀rí kankan.
Ilé ẹjọ́ kan náà ni Ọ̀jọ́ tí wọn ti mú arákùnrín náà ni awọn ọlọ́pàá gbé e lọ láti lọ jẹ́jọ́.
Ajọ ọlọ́pàá nínú ìfọ̀rọ̀wánilẹ́nuwò rẹ̀, ayédèrú agbẹjarò náà ní òun nífẹ̀ sí ìṣẹ́ agbẹjọ́rò nígbà tí ọ̀rẹ́ rẹ̀ kan ran kí ó ṣe bí amòfin láti lọ jáwè fún ayálégbé kan.
A gbọ́ pé ọwọ́ tẹ̀ ẹ́ nígbà tí àwọn ojúlówó agbẹjọ́rò tó wà nínu ilé ẹjọ́ nígbà tí ó ń sọrọ níwájú adájọ funra pé kò kàwé.
Àjọ ọlọ́pàá fìwépe Bukola Saraki lórí ìdigunjalè Offa
Oríṣun àwòrán, @bukolasaraki/Twitter
Ọlọ́pàá fẹ́ fi ọrọ wá Bukola Saraki lẹ́nu wo nítori oun tí adigunjalè márùń sọ
Àjọ ọlọ́pàá orílẹ̀eèdè Naijiria ní àwọn ti fìwé pe Olórí Ilé Aṣòfin Àgbà, Bukola Saraki, láti wá sọ oun tí ó mọ̀ nípa ìdigunjálè Offa, ní Ìpínlẹ̀ Kwara nínú èyí tí àwọn ọlọ́ṣà pa ènìyàn mẹ́tàlélọ́gbọ̀n ní Oṣù Kẹrin.
Agbẹnusọ àjọ ọlọ̀paa, Jimoh Moshood, ní ó ṣe pàtàki láti fi ọrọ wá Saraki lẹ́nu wo nítori ọ̀rọ̀ tí márùń nínú àwọn adigunjalè tí ọwọ́ ti tẹ̀ sọ tí ó ta bá olóṣélú nàá.
Agbẹnusọ fun Saraki, Yusuf Olaniyonu, ní olori ile aṣòfin náà yóó fèsì lórí ẹ̀sùn tí wọn fi kàń tí àkókò bá tó.
Moshood ní àwọn márùń náà ni Ayoade Akinnibosun, Ibukunle Ogunleye, Adeola Abraham, Salawudeen Azeez ati Niyi Ogundiran.
A gbọ̀ pé ọwọ́ tẹ gbogbo àwọn afrunrasí tí ó wà ní àhámọ báyìí lẹ́hìn tí ọlọ́pàá kọ́kọ́ mú afunrasí méjì - Kunle Ogunleye àti Michael Adikwu tí fídíò ilé ìfowópamọ́sí rí ojú wọn nígbà ìsẹ̀lẹ̀ náà.
Oríṣun àwòrán, PRNigeria
Afrunrasí méjì - Kunle Ogunleye àti Michael Adikwu tí fídíò ilé ìfowópamọ́sí rí ojú wọn ni ọwọ́ kọ́kọ́ tẹ̀
Moshood sọ nígbà tí òun bá àwọn oníròyìn sọ̀rọ̀ lórí bí ìwádìí ṣe ń lọ lórí ọrọ nàà, pe afunrasí méjìlélógún ni ọwọ ti tẹ̀ báyìí o.
Bẹ́ẹ̀ náà ni ó ṣe àfihàn àwọn ìbọn, ọkọ̀ àti owo tí wọn rí gbà lọ́wọ́ àwọn arunrasí náà.
Gomina Ipinlẹ̀ Kwara, Abdulfatah Ahmed, wà lára àwọn tí ọ̀rọ̀ ti ta bá lórí ìdigunjalè náà. Méjì lára àwọn olùranlọ́wọ́ gómínà náà, Alabi Olalekan àti Yusuf Abdulwahab ni ọ wà ní àhámọ́ báyìí.
Saraki: Mo ti ní kí olùrànlọ́wọ́ mi gba ìwé ìpeni àwọn Ọlọ́pàá
Oríṣun àwòrán, @bukolasaraki
Adarí ilé ìgbìmọ̀ asòfin àgbà se tán láti yọjú s'áwọn Ọlọ́pàá'
Adarí ilé ìgbìmọ̀ asòfin àgbà, Bukola Saraki ní òun ti ni kí olùrànlọ́wọ́ pàtàkì òun tẹ́wọ́ gba ìwé ìpeni látọ̀dọ̀ ilé isẹ́ Ọlọ́pàá látàrí ẹ̀sùn tí wọ́n fi kàn án lánàá wí pe ó lọ́wọ́ nínú ìsẹ̀lẹ̀ ìdigunjalè Ọffa tó wáyé nínú osù kẹrin ọdún yìí níbí tí wọ́n ti pa ọ̀pọ̀lọpọ̀ ènìyàn.
'Èmi ò kí ń lu ìyàwó mi'
"Saraki sọ pe ""mo sẹ̀sẹ̀ sọ fún olùrànlọ́wọ́ mi pé kó gba ìwé ìpeni látọ̀dọ̀ ilé isẹ̀ Ọlọ́pàá èyí tó ní se pẹ̀lú ẹ̀sùn tí wọ́n gbé jáde lánàá kí n lè tètè jẹ́ wọn ní òo""."
Sáájú, adarí ilé ìgbìmọ̀ asòfin àgbà, Bukola Saraki ti kọ ìwé jáde lórí ẹ̀rọ ayélujára wí pé ó ń fẹ́ kí gbogbo ará ìlú kọ etí ikún sí ẹ̀sùn tí kò lẹ́sẹ̀ ńlẹ̀ tó tún jẹ́ ọàdọ́gbọ́n kó bá ni ní gbogbo ọ̀nà èyí tí ilé isẹ́ ọlọ́pàá rawọ́lé.
Oríṣun àwòrán, ALHAJI ABDULFATAH AHMED
Saraki àti Gòmínà Fattah fèsì lórí ìdigunjalè Offa
"Ẹ jẹ́ kó di mímọ̀ wí pé kò sí ọ̀nà tí mo fẹ́ gbà lọ́wọ́ nínú kí wọ́n digun ja àwọn ènìyàn mi. Nígbà tí ìdigunjalè Ọffa sẹlẹ̀, èmi ní àgbà òsìsẹ́ Ọba tó kọ́kọ́ se ìbẹ̀wò síbẹ̀ bẹ́ẹ̀ si ni ní ààfin Ọba ìlú náà, mo fi ẹ̀rọ alágbéká pe Ọ̀gá àgbà àwọn Ọlọ́pàá, Ọ̀gbẹ́ni Ibrahim Idris pé kó se àlàkalẹ̀ fún àbò tí àwọn ènìyàn nílò.
Bóo jẹun lásìkò tó wù ọ́ wàhálà, bí ò tó, ìsoro
Ọkọ̀ Lexus kan tí wọ́n lẹ orúkọ Olórí Ilé Aṣòfin Àgbà, Bukola Saraki, sí wà nínú nkan tí ó dá wàhálà sílẹ̀ tí ó fi di pé ọlọ́pàá orílẹ̀èdè Naijiria yóò máa fa Gómínà Ìpínlẹ̀ Kwara, Abdulfatah Ahmed, létí aṣọ lórí ìdigunjalè Offa.
Agbẹnusọ àjọ ọlọ̀paa, Jimoh Moshood, ní ọ̀gbẹ́ni Alabi Olalekan, tí ó jẹ́ olùrànlọ́wọ́ pàtàki fun gómínà náà rán arákùnrin kan tí orúkọ rẹ̀ njẹ́ Adeola Omiyale láti lọ fi ọkọ̀ náà pamọ́ sí Ilé Gomina ní Ilorin nígbà tí ó gbọ́ pé ọlọ̀paa ń wá ọkọ̀ náà nítorí ìdigunjalè Offa.
Oríṣun àwòrán, NIGERIA POLICE
Ọkọ̀ náà ni wọn ní àwọn jandùkú fi ṣọsẹ́ ní Offa
Olalekan tí wọ́n tún bá ìbọn ìléwọ́ kan lọ́wọ́ rẹ̀ wà ní panpẹ́ ọlọ́pàá bayìí.
Ṣùgbọ́n gomina Kwara ní kò sí ọwọ́ oun nínú ọ̀rọ̀ náà,
Bákan náà, adarí àwọn òṣìṣẹ́ gómínà, Yusuf Abdulwahab, ni wọ́n fẹ̀sùn kan pé ó tún yọ nọ́mbà ìdánimọ̀ tí wọ́n kọ orúkọ Sarakí sí lára ọkọ̀ náà kí ó ṣẹ̀ tó wá lo ṣe ìfórúkọsílẹ̀ ọkọ̀ náà. Oun náà ti wà ní àhámọ báyìí.
Oríṣun àwòrán, NIGERIA POLICE
Wọ́n fẹ̀sùn kan adarí àwọn òṣìṣẹ́ gómínà Kwara pé ó yọ nọ́mbà ìdánimọ̀ tí wọ́n kọ orúkọ Sarakí sí lára ọkọ̀ náà kí ó ṣẹ̀ tó wá lo ṣe ìfórúkọsílẹ̀ ọkọ̀ náà.
Ninú ìdáhùn rẹ̀ sí ẹ̀sùn tí ọlọ́pàá fi kàń, Ahmed, sọ wí pé òun kò ṣàtìlẹ́yìn fún àwọn jàǹdùkú kankan o.
Àtẹ̀jáde kan tí olùrànlọ́wọ́ pàtàki rẹ̀ lórí ọ̀rọ̀ ìròyin, Muyideen Akorede ní òun ṣe ìrànlọ́wọ́ oríṣiríṣi fún àwọn ọ̀dọ́, ṣùgbọ́n kò mọ àwọn agbeébọn ti ọ ṣọsẹ́ ní Offa rí.
Ilé-Iṣẹ́ Ọlọ́páà: Ọlọ́kadà ẹ sọ́ra nílùú Èkó
Oríṣun àwòrán, Police forcee/twitter
Ọlọ́pàá kò ní mú ọlọ́kadà níkan bíkòṣe pé kí kojú ìjìyà tó tọ lábẹ́ òfin.
Ilé iṣẹ́ ọlapàá ìpínlẹ̀ Èkó ti kéde pé, ètò ti wà ni ṣẹpẹ́ báyìí láti bẹ̀rẹ̀ sí ní mú àwọn ọlọ́kada tí kò bá rìn ní ìlànà òfin láti ọjọ́ kẹẹ̀dógun oṣù yìí.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí:
'Isẹ́ Tíátà tí mò ń se ti tó mi jẹun'
Saraki àti Gòmínà Kwara dáhùn sí ẹ̀sùn ìdigunjalè Offa
Ìpinu ọ̀hún wáyé lẹ́yìn ìpàdé pẹ̀lúu kọmísọ́nà ọlapàá fún ìpínlẹ̀ Èkó, Imohimi Edgal pẹ̀lú onírúuru ẹgbẹ́ ọlọ́kadà.
Ilé-iṣẹ́ ọlọ́pàá ní òun yóò gùnlé ìpinu rẹ nítorí ìṣẹ̀lẹ̀ aburú tó wáyé ní Ọgbọ̀n ọjọ́ oṣù tó kọjá nígbà tí àwọn ọlọ́kada yabo ilé-iṣẹ́ ọlọ́pàá ní Ìbeṣhe tí wọn sì sun ọkọ̀ ọlọ́pàá kan délẹ̀.
Àtèjáde tí àgbẹnusọ ọlọ́pàá Chike Oti fọwọ́sí sàlàyé pé, àgbékalẹ̀ ìpádé ọ̀hún wáyétí wọn sì bu ẹnu àtẹ́ lu ìwà tí àwọn ọlọ́kàdà náà hù.
Ó ní ọlọ́pàá kò ní mú ọlọ́kadà níkan bíkòṣe pé kí kojú ìjìyà tó tọ lábẹ́ òfin.
Ohun tó sọ Okorocha di olóròróó ọ̀sán gangan
Oríṣun àwòrán, IGBERE TV
Àwọn mìíràn ní bóyá Rochas Okorocha ti sọ ara rẹ̀ di wòlíì ni
Gómínà ìpínlẹ̀ Imo, Rochas Okorocha, di ẹni tí ń ṣe ìfàmi-òróró-yàn fún àwọn ará ijọ nínú ilé ijọ́sìn?
Ìbéèè yìí ló gba ayé kan nígba tí àwọn fọ́to ṣàfihàn rẹ ninu ìsìn tó wáyé nílé ìjọsìn tó wà nínú ilé ijọba ìpínlẹ̀ náà ní Owerri l'ọ́jọ́ Aiku.
Awọn kan gbà pé agbára òṣèlú ni
Àwọn mìíràn ní bóyá ó ti sọ ara rẹ̀ di wòlíì ni o.
Sùgbọ́n nígbà tí BBC kan sí gómínà náà láti mọ ǹkan tí ó ń ṣẹlẹ̀,  olùrànlọ́wọ́ pàtàki rẹ̀ lórí ọ̀rọ̀ ìfitónilétí, Ebere Nzewuji, ni kò rí bẹ́ẹ̀.
Ó ṣalayé pé, wón ní kí ọmọ ìjọ kọọkan fi oróró sí iwájú orí ẹni tí ó wà ní sàkání rẹ̀ ní.
Sùgbọ́n àwọn ayàwòrán ni wọ́n ya gómínà náà nígba tó ṣe bẹ́ẹ̀, tí wọ́n sí gbẹ́e síta tí ó fi dà bí ẹni pé ó ń ṣe bí wòlíì.
Èèyàn ọgọ́ta ni Pásítọ̀ se ìrìbọmi fún kí ọ̀nì tó bù ú jẹ
Oríṣun àwòrán, AFP
Pásítọ̀ Docho Eshete náà ti se ìrìbọ́mi fún èèyàn tó lé ní ọgọ́ta ní àárọ̀ ọja àìkú nínú adágún odò náà
Pásítọ̀ ajíhìnrere kan ní orílẹ̀èdè Ethiopia, ẹni tó ń se ìrìbọmi fún àwọn ọmọ ìjọ rẹ̀ létí adágún odò Arba Minch, lágbègbè Merkeb Tabya, ní àríwá Ethiopia, ni ọ̀nì kan ti rán sọ́run.
Gẹ́gẹ́ bí àwọn olùgbé àdúgbò náà àti àwọn ọlọ́pàá ti sọ fún ikọ̀ BBC, Pásítọ̀ Docho Eshete náà ti se ìrìbọ́mi fún èèyàn tó lé ní ọgọ́ta ní àárọ̀ ọja àìkú nínú adágún odò náà, kí ọ̀nì náà tó sàdédé jáde wá.
Olùgbé àdúgbò náà kan, Ketema kairo sọ fún BBC pé, Ó se ìtẹ̀bọmi fún ẹnì kínní, ìkejì títí lọ bẹ́ẹ̀. Lójijì ni ọ̀nì kan fò jáde láti inú odò náà, tó sì gbá Pásítọ̀ náà mú, tó tún ti ẹni tó ń se ìtẹ̀bọmi fún sẹ́yìn."""
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Awọn apẹja kàn tiraka láti wá òkú rẹ̀ àmọ́ wọ́n kùnà láti ra ẹ̀mí rẹ̀ padà.
"Ọlọ́pàá kan, Eiwnetu Kanko sọ fún BBC pé, ""Bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé àwọn apẹja àtàwọn olùgbé agbègbè náà sa ipá wọn láti dóòlà ẹ̀mí Pásítọ̀ Docho, àmọ́ pàbó ni aáyan wọn já sí."""
Eiwnetu fi kún-un pé,  wọ́n kàn tiraka láti rí òkú rẹ̀ ni. Wọ́n kùnà láti ra ẹ̀mí rẹ̀ padà.
Agbẹjọro àgbà: Ara Melaye ti ya láti bẹ̀rẹ̀ ìgbẹ́jọ́ padà
Oríṣun àwòrán, @dino_melaye
Òwúrọ̀ Ọjọ́rú ógbón ọjọ oṣù kàrún ni Melaye padà sí ilé aṣòfin lẹ́yìn rògbòdìyàn tó wáyé láàrin òun àti àwọn ọlọ́pà
Agbẹjọro àgbà fún orílèèdè Nàìjíríà tí fí ìwé ránṣẹ sí ilé ẹjọ gíga tó wà ní Maitama nilu Abuja, láti bèèrè pé kí wọn bẹrẹ ìgbẹjọ padà lórí ẹsùn tí wọn fí kàn Senato Dino Melaye.
Won fi ìwé náà ranṣẹ ní ọjọ́ kẹrin oṣù kẹfà lẹyìn tí Senato Dino padà sí ilé aṣòfin àgbà lọgbọjọ oṣù kàrún-un.
Ṣáájú ni ilé ẹjọ gíga náà dáwọ ìgbẹjọ Senato Dino dúró, títí di igba ti ara rẹ yóò fi yà.
Ṣùgbọ́n bayi ti ọ ti bẹrẹ iṣẹ padà, ìwé náà to wa láti ọdọ agbẹjọro àgbà nfẹ kí adájọ fún àwọn ni ''ọjọ ti awọn yóò bẹrẹ ẹjọ náà padà ni ìbámu pẹlú àṣẹ tí ilé ẹjọ pá ṣáájú''
Amọ nigba to n ba BBC Yoruba sọrọ, agbẹnusọ fún Senato Dino Melaye, Gideon Oladele ní, lootọ láwọn ti gbọ nípa ìwé tí agbẹjọro àgbà fi ṣòwò sí adájọ ṣugbọn ''awọn kò ti fojú kan iwe kánkan láti ọdọ adájọ.''
Bí a kò bá gbàgbé, adájọ Olasunbo Goodluck, lọjọ ketadinlogun osu kàrún-un ọdún 2018 dajọ pe, ki wọn sun ẹjọ Senato Dino Melaye siwaju títí di ìgbà tí ará rẹ yóò fi yà.
Agbẹjọro àgbà wa n pé Senato Dino Melaye lẹjọ, lori ẹsùn méjì ọtọọtọ, eyi tó níi ṣé pẹlú pé, ọ paro fún àwọn agbofinro láti lè ṣe àkóbá fún Olori àwọn oṣiṣẹ ní ilé ìjọba ní ọfisi Gómìnà ipinle Kogi, ọgbẹni  Edward Onoja wí pé o rán àwọn èèyàn láti pá òun.
Ekiti2018: Fayẹmi ni ìkérora àwọn èèyàn Èkìtì ló mu òun díje
Oríṣun àwòrán, Kayode Fayemi
Fayẹmi ni igbe awọn eeyan ipinlẹ Ekiti lo mu oun fi pinnu lati gbegba ibo fun gomina
Fayẹmi ìpínlẹ̀ Ekiti di ẹni Ọlọrun kò pa lọ́wọ́ ìbọn
Oludije fun ipo gomina ipinlẹ Ekiti labẹ aṣia ẹgbẹ oṣelu APC, Ọmọwe Kayọde Fayẹmi, ti sọ pe, ori lo ko oun ati awọn aṣaaju ẹgbẹ oṣelu APC yọ lọwọ iku ibọn lọjọ Ẹti to kọja.
Fayẹmi ni bi kii ba ṣe ti Ọlọrun ni, o ṣeeṣe ki oun, gomina ipinlẹ Ondo, Rotimi Akeredolu ati aṣofin apapọ tẹlẹri, Ọpẹyẹmi Bamidele ti di oku lasiko ti iṣẹlẹ naa ṣẹ.
Fayẹmi ni igbe awọn eeyan ipinlẹ Ekiti lo ta si oun leti ni oun fi pinnu lati gbegba ibo fun gomina.
APC Ekiti so ìpolongo rọ̀
nPDP jáwọ́ nínú ìjíròrò pẹ̀lú APC
Ìṣẹlẹ iyinbon APC Ekiti : Ki gaan lo ṣẹlẹ?
O ni o da oun loju bi àdá pe awọn eeyan ipinlẹ Ekiti ti ṣetan lati bọ lọwọ ohun to pe ni 'isinru' labẹ gomina Ayọdele Fayoṣe.
Ni ọsẹ to kọja ni iro ibọn sọ lálá lati ọwọ ọlọpaa kogberegbe kan, nibi ipade ikinikaabọ ti wọn ṣe fun Fayẹmi ni olu ile iya ẹgbẹ oṣelu APC nilu Ado Ekiti.
Nigba ti ariwo ọhun si rọlẹ ni o di mimọ pe ọta ibọn ti ba aṣofin apapọ tẹlẹri, Ọpẹyẹmi Bamidele, atawọn eeyan marun un miran ti wọn ti di ero ileewosan bayii.
Òsìsẹ́ ìjọba: Ọmọ títọ́ kò rọrùn rárá, ọdún kan kò pọ̀jù!
Oríṣun àwòrán, Getty Images
'Igbesẹ̀ to dara ni ijọba gbe, amọ pe obinrin nilo ọdun kan lati faramọ ọmọ ti wọn sẹsẹ bi’
Awọn ọmọ Naijiria ti fesi lori igbese ijọba apapọ lati fi osu kan kun ọjọ isinmi awọn osisẹ'binrin to ba sẹsẹ bimọ, eleyii to sun un lati osu mẹta si mẹrin.
Minisita fọrọ oṣiṣẹ ati igbanisisẹ lorilẹ-ede Naijiria, Sẹnatọ Chris Ngige, lo sọ ọrọ yii nibi ipade ‘International Labour Confedence’ to n lọ lọwọ ni Geneva, lorilẹ-ede Swtizerland.
Ngige fikun pe ijọba apapọ ti f'ofin de isẹ awọn abiyamọ, ati pe wọn ko gbọdọ yọ ẹnikẹni ni isẹ nitori o lọ fun isinmi lẹyin ibimọ.
Abilekọ Adeọla Akọgun to jẹ osisẹ ijọba ba BBC Yorùbá sọrọ lori igbese naa sọ pe ‘igbesẹ̀ to dara ni ijọba gbe, amọ obinrin nilo ọdun kan lati faramọ ọmọ ti wọn sẹsẹ bi naa ki ibasepo to dan mọran le wa laarin wọn'.
Bakan naa, Abilekọ Funke Olutuyi, ba BBC Yorùbá sọrọ gẹgẹbi onisẹ ọwọ, pe, o pọn dandan lati fi osu mẹfa silẹ lati fun ọmọ ni ọyan lai fi ounjẹ la a, ki ara ọmọ o ba le ji pepe
‘A nílò ọdún kan láti sinmi lẹ́yìn ìbímọ’ - Òsìsẹ́ ìjọba
Laipe yii ni ijọba fagile erongba awọn ọkunrin lati máa gba isinmi osu kan lẹyin ti iyawo wọn ba bimọ, ki wọn ba le se itọju wọn bo ṣe to ati bo ti yẹ.
Amọ, Ọmọwe Micheal Afolayan nigba to n ba BBC Yorùbá sọrọ lori koko yii pe, ọkunrin kò nilo isinmi lasiko ti iyawo wọn ba sẹsẹ bimọ, nitori obinrin lo máa n se isẹ inu ile.
Dokita Afolayan wa kan sara si ijọba apapọ fun igbese naa, o si rọ awọn ọkunrin lati tẹpa mọ isẹ nitori ọwọ to ba dilẹ ni esu máa n lo.
Njẹ ọkunrin nilo isinmi nigba ti iyawọ wọn ba sẹsẹ bi ọmọ?
Ajafẹtọ ọmọ eniyan lori ọrọ igbanisisẹ ati agbẹjọro, Babatunde Ogala, nigba to n fi ero rẹ han lori igbese ijọba apapọ naa sọ pe, isinmi osu mẹrin fun awọn osisẹ obinrin lẹyin ibimọ yoo mu ibugbooro ba eto ọrọ aje orilẹ-ede Naijiria nitori awọn obinrin yoo pa ọkan wọn papọ si ọna kan nigba ti wọn ba n tọ ọmọ lọwọ.
Ipa ti isinmi osu mẹrin yoo ko lori eto ọrọ aje
Bakan naa o fikun wi pe, ọjọ iwaju awọn ọmọ ti wọ̀n sẹsẹ bi naa se koko, nitori itọju ti wọn ba fun wọn ni kekere ni yoo mu wọn dagba bo se ye, ati lati gbe orilẹ-ede wọn ga.
Malawi: Igbákéjì ààrẹ fẹgbẹ́ sílẹ̀ torí àjẹbánu ààrẹ̀
Oríṣun àwòrán, BBC Sport
Ọ̀pọ̀ èèyàn ti ń rọ̀ Chilima láti díje dupò Ààrẹ pẹ̀lú Ààrẹ́ Peter Mutharika tí ó jẹ́ ẹni ọdún mọ́kàndínlọ́gọ́rín
Igbakeji Aarẹ orilẹede Malaw,i Saulos Chilima, ti fi ẹgbẹ oṣelu to n ṣe 'jọba nilẹ naa silẹ, lẹyin igbati o tako Aarẹ orilẹede naa, Peter Mutharika ni gbangba.
Ọgbẹni Chilima ti o tako iwa ajẹbanu labẹ ijọba Aarẹ  Mutharika l'ọjọ Iṣẹgun, lo ti kuro ninu ẹgbẹ oṣelu naa.
O ṣeeṣe ki ọgbẹni Chilima dije ninu ibo Aarẹ to n bọ lọna ni orilẹede naa.
Nàìjíríà àti Ghana léwájú nínú wíwá òògun ìsẹ́yún
Falz: MURIC ní ọ̀rọ yí kọjá orin, wọ́n ni ó dilé ẹjọ́
Fídíò ṣàfihàn àwọn ọlọ́pàá nibi tí wọ́n ti ta tẹ́tẹ́
Aarẹ Mutharika yan Chilima gẹgẹ bi igbakeji rẹ, ti wọn si jọ dije ninu ibo gbogbo-gboo labẹ ẹgbẹ oṣelu Democratic People's Party ni ọdun 2014.
Ọgbẹni Chilima kede igbesẹ rẹ nitori bi ọpọ eeyan ninu ẹgbẹ oṣelu DPP se ti n rọọ lati dije dupo Aarẹ pẹlu Aarẹ Mutharika, ti o jẹ ọmọ ọdun mọkandinlọgọrin.
Idibo Aarẹ ni orilẹede Malawi yoo waye ni ọdun 2019.
June 12: Awọn ọmọ Abiọla sọrọ lori idanilọla fun MKO
‘Mo fẹ́ mọ ẹni tó jáwé olúborí nínú ìdìbò June 1993’ - Abdulmumini Abiola
Àwọn ọmọ Abiọla fi ìdùnnú hàn sí ìkéde Aarẹ Buhari lórí June 12
Bí àarẹ orilẹ-ede Naijiria, Muhammadu Buhari, ṣe kede ọjọ kejila, oṣu kẹfa gẹgẹ bii ayajọ tuntun fun iṣejọba awa-ara-wa l'awọn eeyan ti kọ oniruuru iha sii
Yorùbá bọ wọn ni onikangun-n-kangun, aṣọ to ba kangun si eegun ni wọn n pe ni jẹ̀pẹ̀, awọn ọmọ oloogbe MKO Abiola fimoore hàn fun ikede aarẹ Buhari yii.
Awọn naa ni gbogbo agbaye ri gẹgẹ bii àmì idanimọ fun baba wọn ati opo ijijagbara to waye nipasẹ idibo ọjọ kejila, oṣu kẹfa ọdun 1993.
Oríṣun àwòrán, @wura_abiola
Lẹ́yìn ogún ọdún tí ó jáde láyé, ìjọba àpapọ̀ ṣe ẹ̀yẹ fún olóògbé MKO Abíọ́lá
Ọdun 1993 ni ijọba fagile idibo ọhun.
Hafsat Abiola-Costello, ọmọ ti Alhaja Kudirat Abiola, ọkan lara awọn to ba ijijagbara fun idapada ijọba alagbada lẹyin iwọgile esi idibo June 12 lọ, bi fun Oloye Abiola ni idunnu nla gbaa ni ikede ọhun jẹ fun oun ati gbogbo ẹbi MKO Abiọla.
Oríṣun àwòrán, Paul Morigi
Inú mi dùn gidi pé ijóba pọ́n baba mi lé lásìkò yìí
Ko si ọrọ kan pato to lee sọ ọkan imoore mi ati ayọ to n bẹ ninu mi. Mo dupẹ lọwọ Ọlọrun to mu ki o ṣoju mi
Hafsat Abiola-Costello ni oun ti n reti igbesẹ̀ naa ti pẹ́, ki o to waye bayii.
"Ireti mi ni pe nigba ti ologun da ijọba pada falagbada, yoo ṣe bẹẹ ni ọjọ kejila, oṣu kẹfa, eleyii ti yoo saami aṣepari igbesẹ to bẹrẹ pẹlu ala rere ti awọn kan danu ṣugbọn asan ni ireti mi, ọjọ kọkandinlọgbọn, oṣu karun un ni wọn fi si nigba naa.
Mo ro pe ẹni akọkọ to janfanii rẹ yoo tilẹ ni ki orilẹ-ede yii dakẹ iranti iṣẹju kan fun un sibẹ, asan ni ireti mi jasi."
Lẹyin ti Aarẹ Muhammadu Buhari kẹdẹ June 12 gẹgẹ bii 'Ayajọ Ọjọ Isejọba tiwantiwa', ọmọ M.K.O. Abiola, Abdulmumini Abiola, ni inu oun dun lọpọlọpọ.
Abiola to fi ìdìnnú rẹ hàn sikede Aarẹ Buhari naa ni pe ẹbun Ramadan pataki ni eyi jẹ fun oun.
Bakan naa lo ke si ijọba lati se ofintoto ẹni tó jáwé olúborí nínú ìdìbò June 1993 lati le mu inu awọn mọlẹbi awọn ti ẹmi wọn lọ si idibo naa lodun ọhun.
Wura Abiola ni tirẹ ni ọjọ ayọ leyi lati pe ara oun ni ọmọ Naijiria tọkantọkan.
Ninu ọkan-o-jọkan atẹjade to fi si oju opo twitter rẹ, Wura Abiola ni idunnu nla ni ọrs naa jẹ fun oun.
Baba mi ọwọn Baṣọrun Moshood Kashimawo Olawale Abiola GCFR. Inu mi dun gidigidi pe lẹyin o rẹyin mo lee kọ ọrọ yii lẹyin ogun ọdun. Mo dupẹ lọwọ yin o Aarẹ Buhari.
Ni ọjọru ni aarẹ Buhari kede ọjọ kejila, oṣu kẹfa, gẹgẹ bii ọjọ ti orilẹ-ede Naijiria yoo maa ṣe ayajọ iṣejọba tiwantiwa.
Bakan naa ni aarẹ kede oye to ga julọ lorilẹede Naijiria, GCFR fun oloogbe Oloye MKO Abiọla.
Aarẹ Buhari tun fi oye to ga julọ ṣekeji, GCON da ogbontagi ajafẹtọ ọmọ-niyan to ti doloogbe, Amofin agba Gani Fawehinmi, ati Alhaji Baba Gana Kingibe naa lola
June 12: Ribadu ni Fawẹhinmi ni akin tí a gbọ́dọ̀ yẹ́ sí
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Gani Fawẹinmi kó ipa to kúrò ni kèrémí fún ìfẹsẹ̀múlẹ̀ iṣejọba alágbádá ni Naijiria
Nuhu Ribadu ti kan sárá si bi aarẹ Muhammadu Buhari ṣe da ogbontagi ajafẹtọ araalu ni, Oloogbe Gani Fawehinmi lọla.
Nuhu Ribadu ti figba kan jẹ alaga ajọ to n gbogunti iwa ibajẹ gbogbo to rọ mọ iṣuna lorilẹ-ede Naijiria, EFCC.
Ni ọjọru ni Aarẹ Muhammadu Buhari kede ami ẹyẹ to ga julọ ṣekeji lorilẹ-ede Naijiria, GCON fun Oloogbe amofin agba Gani Fawehinmi, SAN.
Ninu ọrọ rẹ, Mallam Nuhu Ribadu ṣe apejuwe Gani gẹgẹ bi 'ọkan ṣoṣo araba'ajafẹtọ to fi gbogbo aye rẹ jin fun orilẹ-ede Naijiria.
Lai simi ati lai kaarẹ ni Gani ja fun ja fun ẹtọ ọmọniyan ati ibọwọ fun ofin. Akinkanju tootọ ni Gani ti o si yẹ ki a maa ṣe afẹri rẹ nigba gbogbo.
Nuhu Ribadu ni yatọ si ọrọ iṣejọba tiwantiwa  ajọyọ nla ni igbesẹ naa jẹ fun ijijagbara ati ifaraẹnijin fun igbayegbadun gbogbo eniyan lorilẹede Naijiria.
Afẹ́nifẹ́re: Buhari rò pé òun gbọń lójú ara òun ni pẹ̀lú ìkéde yìí
Afẹ́nifẹ́re: Ọgbọ́n ìbò ni Buhari ń dá
Ẹgbẹ Afẹnifẹre ṣapejuwe ikede Aarẹ Buhari gẹgẹ bii ọgbọn alumọkọrọyii lati fi ṣi oju awọn ọmọ Naijiria kuro ninu gbogbo aṣiṣe rẹ
Aarẹ Buhari kede ọjọ kejila, oṣu kẹfa gẹgẹ bii ayajọ tuntun fun iṣejọba tiwantiwa lorilẹ-ede Naijiria.
Bakna naa lo foye to ga julọ da oloogbe MKO  Abiọla lọla (GCFR) pẹlu oloogbe Gani Fawẹinmi (GCON).
Ẹgbẹ Afẹnifẹ ni, bi o tilẹ jẹ pe awọn faramọ ikede naa, inu awọn si dun si, sibẹ ohun ti ọjọ kejila, oṣu kẹfa duro fun ninu itan orilẹ-ede Naijiria ju kikede ọjọ naa gẹgẹ bii ayajọ ijọba tiwantiwa nikan.
June 12: Lai Mohammed ni Buhari ti wo ọgbẹ́ June 12 sàn
Ninu ọrọ to ba BBC Yoruba sọ, agbẹnusọ fun ẹgbẹ Afẹnifẹre, Ọmọwe Yinka odumakin ni ohun ti June 12 duro fun ni iṣọkan orilẹede Naijiria lai si idẹyẹsi ẹsin, ede tabi ẹya eleyi ti wọn ni o ti sọnu lorilẹede Naijiria lọwọ yii.
Bakan naa ni ẹgbẹ naa tun sọ pe, idibo sipo gomina nipinlẹ Ekiti ni yoo sọ boya ootọ inu ni Aarẹ Buhari fi ṣe ikede naa ati idanilọla to ṣe fun Oloogbe MKO Abiọla.
Muhammed Fawẹ̀hinmi: Bàbà mi yóò dunú níbi tó bá wà báyìí
Muhammed Fawẹ̀hinmi: Bàbà mi yóò dunú níbi tó bá wà báyìí
Kání Gani wa laye ni, yoo tẹwọ gba ami idanilọla yii
Akọbi oloogbe amofin agba Gani Fawẹhinmi, (SAN) Ọgbẹni Mohammed Fawẹhinmi, sọ fun BBC Yoruba pe oyẹ yii ko ba dun mọ baba oun ninu pupọ ka ni ko tii filẹ bora bi aṣọ ni.
Oye GCON ni oye keji to tobi julọ ni Naijiria.
Mohammed ni ohun idunnu patapata lo jẹ fun ẹbi oloogbe Gani Fawẹhinmi pe awọn ohun to jẹ ẹdun ọkan fun ajafẹtọ naa tẹlẹ, ti ó ja fun titi di ọjọ iku ni Aarẹ Buhari fọwọ si bayii.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Àrólé Gani Fawẹhinmi, Mohammed ní inú bàbà òun yóò dùn lórí àmì ìdánilọ́lá GCON
O ni ohun to jinna si ootọ ni ọrọ ti awọn kan n sọ pe ka ni Amofin agba, Gani fawẹhinmi wa loke erupẹ ni, ko ni gba ami idanilọla naa, paapaa bi o ti jẹ pe o ti figbakan ri kọ awọn irufẹ ami idanilọla bẹẹ nigba ti o wa laye.
Muhammed fawẹhinmi ni Gani Fawẹhinmi yoo gba ami idanilọla naa, bi o tilẹ jẹ pe, o lee gba tan, ko kọ oju oro si Buhari lori bi nkan ṣe dagun lorilẹ-ede Naijiria bayii.
‘Ajìjà-gbara fun ijọba tiwantiwa ni Gani’
MKO Abiọla gba oyè GCFR tó ga jùlọ ní Nàìjíríà
Bàálù Ọsinbajo: Kété tó gbéra tán ló ń yọ̀ èèfín
Baalu kekere naa lo ni isoro ranpẹ laarin isẹju perete to gbera nilẹ.
Ọlọrun kó Naijiria yọ lọwọ ijamba ojiji ti ko bà fa ọ̀fọ̀ l'Ọjọbọ
Ijamba ojiji kan ni Ọlọrun koore rẹ ni orilẹ-ede Naijiria nigba ti baalu kekere to gbe igbakeji aarẹ, Ọjọgbọn Yẹmi Ọsinbajo, deede bà silẹ pada ni kete to gbera tan.
Bi wọn ṣe gbéra ni ileẹkọ awọn osisẹ asọbode to wa ni Gwagwalada nilu Abuja niṣẹlẹ naa ṣẹlẹ.
A gbọ pe baalu kekere naa lo ni isoro ranpẹ laarin isẹju perete to gbera nilẹ.
Ọjọgbọn Yẹmi Ọsinbajo lo bawọn peju si ibi ayẹyẹ ikẹkọjade fawọn lọga-lọga osisẹ asọbode.
Ni kete ti ayẹyẹ naa wa sopin ti igbakeji aarẹ si wọ baalu alawọ tinu ẹyin (YELLOW) ati olomi aro (BLUE) naa, to si gbera, ni ko lee fo kọja awọn igi to wa nile ẹkọ̀ naa, to si tun n yọ eefin.
Ni kete ti isẹlẹ́ yii waye, ti ori si ko Yẹmi Ọsinbajo yọ, lo ba wọ inu ọ̀kọ lati kuro nibẹ.
June 12: Ilé Aṣòfin rọ INEC ko kéde èsì ìbo àarẹ 1993
Oríṣun àwòrán, Getty Images
'Ẹ kede esi ibo'
Ilé Ìgbìmọ Aṣòfin Àgbà ti ké pe àjọ elétò ìdìbo Naijiria (INEC) láti kéde èsì ìbo ti àarẹ 1993 ti gbogbo eniyan gba pe olóògbé MKO Abiola ti jáwé olú borì.
Àwọn aṣòfin náà,  sọ̀rọ̀ yí ní Ọjọ́bọ lákókò ìjókòó lẹ́yìn ọjọ́ tí Aare Muhammadu Buhari kéde pé òun ti yí àyájọ́ ọjọ́ ìjọba tiwantiwa padà láti May 29 sí June 12 láti fi buyì kún Abiola.
‘Mo fẹ́ mọ ẹni tó jáwé olúborí nínú ìdìbò June 1993’ - Abdulmumini Abiola
'Ààrẹ Buhari, a dúpẹ́ ìdùnnú ńlá ni fún wa'
Ghana f'ofin de gbogbo ọ̀rọ̀ eré bọ́ọ̀lù torí rìbá lásìko yìí
Ogunlọ́gọ̀ àwọn adarí ni àwọn akọ̀róyin fún ní owó láti ṣe màgòmágó ṣùgbọ́n wọ́n ya àwòrán wón laí mọ̀.
Lẹ́yin ìwádìí iléesẹ́ BBC pẹ̀lú àjọṣepọ̀ Anas Arameyaw Anas, akọ̀ròyìn ọmọ Ghana kan, nijọba Ghana ṣe ìkéde tuntun yìí
Eyi tumọ si pe yoo pa idije Liigi Abẹ́lé àti ti  àwọn agbbọọlu agba lára.
Wọn gbé fídíò ìwádìí ọhun jáde lórí bí àwọn adarí eré bọ́ọ̀lù ṣe ń gba rìbá láti ṣe màgàmágó.
Ìjọba orílẹ̀-èdè náà ati awọn aṣofin rẹ̀ ti ní kí ọlọ́pàá bẹ́rẹ̀ iṣẹ́ láti ṣe ìwádìí àwọn èèyàn tí ọ̀rọ̀ náà ta bá kiakia.
Nínú fídíò náà tí wọn pè ní Number 12, tí wọ́n ṣe àfihàn rẹ̀ ní Ọjọ́bọ, ni a ti gbọ́ pé, ogunlọ́gọ̀ àwọn adarí eré bọ́ọ̀lù ni àwọn akọ̀róyin fún ní owó, láti ṣe màgòmágó ṣùgbọ́n wọ́n ya àwòrán wón laí mọ̀.
Anas tí ó jẹ́ akọ̀ròyin ọ̀tẹlẹ̀múyẹ́ tó máa ń da agọ̀ bojú kí wọn má bàá lé rí ojú rẹ̀, sọ pé, màgòmágó àti rìba ti ba ere bọ́ọ̀lù jẹ́ ní Ghana.
Ọ̀gá àgbà fún àjọ eleré bọ́ọ̀lù ni Ghana (GFA) Kwesi Nyantakyi gba ẹgbẹ̀rún lọ́nà márunléọgọ́ta dọ́là gẹ́gẹ́bíi rìbá.
Èyí tó ga jù nibẹ ni ti ọ̀gá agba àjọ tí ó ń rí sí eré bọ́ọ̀lù ni Ghana (GFA), Kwesi Nyantakyi, tí ó gba ẹgbẹ̀rún lọ́nà márunléọgọ́ta dọ́là gẹ́gẹ́ bíi rìbá.
Àwọn aláṣẹ orílẹ̀-èdè Ghana ti ní Nyantakyi àti àwọn mìíràn tí wọn gba rìbá naa ni yóò wọ wàhálà.
Fidiò náà ṣe àfihàn Kwesi Nyantakyi bí ó ṣe gba ẹgbẹ̀rún lọ́nà márunléọgọ́ta dọ́là gẹ́gẹ́bíi rìbá
Àtẹ̀jáde orílẹ̀-èdè Ghana rèé lórí ọ̀rọ̀ náà:
Oríṣun àwòrán, GHANA PRESIDENCY
Ẹtàn ni àwọn ọ̀rẹ́ fi ń tan èèyàn lọ si Libya pé iṣẹ́ gidi wà níbẹ̀
Awọn ènìyàn ìpínlẹ̀ Anambra ti ń jànfàni #5000
Ìjọba Nàìjíríà ń san ẹgbẹ̀rún márùn-ún márùn-ún fún awọn ènìyàn to tálákà jùlọ ní orílẹ̀-èdè yìí
Láìpẹ́ yìí ní ìjọba àpapọ̀ kéde láti máà san ẹgbẹ̀rún márùn-ún gba fún àwọn tálaákà lórìlẹ̀-èdè Nàìjíríà.
Owó yìí ni yóò jẹ́ atọ́nà sáájú pínpín owó Abacha ti wọ́n rí gbà fún àwọn ènìyàn.
Sùgbọ́n ọ̀rọ̀ náà ti wa dí òòtọ́ọ́ báyìí bí ètò náà ṣe ti bẹ̀rẹ̀ ni pẹrẹwu, àwọn ènìyàn kan ní abúlé Ifitedunu, ni ìjọba ìbílẹ̀ Dunukofia nípinlẹ̀ Anambra ló jẹ́ri si ọ̀rọ̀ yìí nígbà ti wọn ń bá BBC Pidgin sọ̀rọ̀.
Ìjọba Nàìjíríà ń san ẹgbẹ̀rún márùn-ún márùn-ún fún awọn ènìyàn to tálákà jùlọ ní orílẹ̀-èdè yìí.
Àjọ̀ tó ń rí sí pínpín owó nílè ìjọba àpapọ ló ń ri kí  ìlú náà, wọn ni àwọn ṣe ìforúkọ sílẹ̀ nítorí pé ìpele àkọ́kọ́ kò kan àwọn míràn.
Abacha Loot: Awọn ìpínlẹ̀ Anambra ti ń jànfàni #5000
Awọn to gba owó náà sàlàyé fún BBC Pidgin pé àwọn ti gba owó náà bí ẹ̀mẹ́fà báyìí àti pé oṣooṣù ni wọn máà ń fun àwọn ni ẹgbẹ̀rún mẹ́wàá-mẹ́wàá.
Wọn ni ẹgbẹ́run márùn ọ̀hún kò tó ǹkankan sùgbọ́n ogún ẹgbẹrun náírà yóò wúlò fun gbogbo ǹkan ti àwọn bá fẹ́ fi ṣe.
Bó tilè jẹ́ pe àwọn ẹgbẹ́ òṣèlú alátakò PDP ti sọ pé àrékereke òṣèlú lásán ni ọ̀rọ̀ owó náà.
Kìí ṣe gbogbo ìpínll ni owó náà ti de báyìí
Kìí ṣe gbogbo ìpínlẹ ni owó náà ti de báyìí sùgbọn àwọn àjọ to ń ri sí àmúludùn àti ààbo àrá-ìlú (NASSCO) ti ń lọ káàkiri láti gba orúkọ sílẹ̀ nígbà ti àjọ tó ń ri sí pínpín owó náà yóò máa san owó.
Ìjọba Nàìjíríà ń san ẹgbẹ̀rún márùn-ún márùn-ún fú awọn ènìyàn to tálákà jùlọ ní orílẹ̀-èdè yìí.
Èto ọ̀hún jẹ́ ti Banki àgbáyé láti ran àwọn orilẹ̀-èdè lọ́wọ́ kí ìpín àwọn aláìní ènìyàn baà lè dínkù, sùgbọn wọn ni àwọn ń fi ojú sí owó náà láti rii dájú pé magòmágó ò wáyé.
Àwọn ènìyàn sọ̀rọ̀ lẹ́yìn ọdún 20 tí Abacha kú
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ọ̀pọ̀ ènìyàn kò gba ọ̀rọ tí Dokita íjọba sọ pé àìsàn ọkàn ló pa á
Ogun ọdun ti kọja lẹyin ti Ọgagun Sani Abacha to jẹ adari orilẹ-ede Naijiria lọdun 1993 si 1998 ku iku ojiji.
Sani Abacha to jẹ ọmọ bibi ilu Kanuri lati ipinlẹ Borno. O lọ si ile iwe ọlogun ti Kaduna ko to gba oye ọgagun lọdun 1963.
Titi di oni to jẹ ayajọ ọjọ ti oloogbe naa papoda, ọ̀pọ̀ awọn ọmọ Naijiria ko sọ nkan rere nipa rẹ lori ẹrọ ayelujara
Ọrọ ìfẹ́: Tunrayọ Adeoye kú lọ́sẹ̀ karun ti a sin ọkọ rẹ̀
Awọn miran sọ pe ọwọ lile ni Abacha fi se ijọba nigba aye rẹ, ti ọpọlọpọ ajafẹtọ ọmọ eniyan sọ pe o ru ofin to de ihuwa si ara ilu.
Awọn miran fẹsun kan an pe, o lu ọpọlọpọ owo ilu ni ponpo nigba aye rẹ, ati pe awọn eniyan gbagbọ pe obinrin lo se iku pa a.
Amọ, Aarẹ Naijiria, Muhammadu Buhari ati awọn ọmọ Naijiria miran gbagbọ pe asiko rẹ tu eniyan lara nitori ipese ohun amayedẹrun bii ina ijọba, ọna to gbooro, ẹkọ ọfẹ ati eto ilera fun awọn eniyan.
Zuma: Èmi kò jẹ̀bi ẹ̀sùn ìwà ìbàjẹ́
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Jacob Zuma ń jẹ́jọ́ lórí ẹ̀sùn ìwà ìbàjẹ́
Ọgọọrọ awọn alatilẹyin lo peju si ile ejọ giga nilu Durban l'orilẹ-ede South Africa, nibi ti Aarẹ tẹlẹ ri Jacob Zuma ti farahan lori ẹsun iwa ibajẹ
Ọgbẹni Zuma n jẹjọ lori ẹsun iwa ibajẹ onikoko mẹrindinlogun, ẹsun iwa ajẹbanu ati ṣiṣe owo ilu bii bílíọ́nù méjì àti ààbọ̀ dọ́là ($2.5 bn), ti wọn fẹ fi ra ohun ija oloro, kumọkumọ.
Ifarahan Zuma ni ile-ẹjọ l'ọjọ Ẹti, lo tumọ si pe igbẹjọ naa n tẹsiwaju.
Ninu ọrọ rẹ, Aarẹ ana, Zuma, to ba awọn alatilẹyin rẹ sọrọ ni ede Zulu, sọ pe, oun ko jẹbi ẹsun ti wọn fi kan òun.
Ọpọ abẹnugan ninu ẹgbẹ oṣelu ANC, ni wọn duro ti Zuma nibi to ti n bawọn eniyan sọrọ.
Atilẹyin ti awọn kan fun Zuma lati inu ẹgbẹ naa, lo ti jẹ ki ahesọ ọrọ wa pe, ko si isọkan ninu ẹgbẹ naa saaju idibo gbogbo-gboo to n bọ.
Sugbọn Zuma ni, ko si otitọ ninu ọrọ naa.
Àyájọ́ June 12: Ìsinmi di ọdún tó ń bọ̀
Oríṣun àwòrán, PIUS UTOMI EKPEI/AFP/Getty
Ọmodekunrin kan ko asia orileede Naijiria lọwọ lọjọ ayajọ òṣèlú tiwá n tiwá
Bí o ba n f'ọkan sí pe ìsinmi yoo wa ni ayajọ ọjọ ijọba tiwá n tiwá lọjọ kejìlá oṣù kẹfà, yara tètè mú ọkàn kúrò níbẹ. nitori kò sí òhun tó jọ rárá.
Ìjọba àpapọ̀ orílèèdè Nàìjíríà ló ṣàlàyé ọrọ yíi lójú òpó Twitter ilé iṣẹ Ààrẹ.
Atẹjade náà ní, àlàyé yii ṣé pàtàkì pẹlú bí àwọn èèyàn ṣé n béèrè pé, ṣé ìsinmi yóò wá tàbí kó ní sí.
Ìkéde náà tèsíwájú pé, ni ìbámu pẹlú òun tó wà nínú atẹjade to tí wáyé ṣáájú, ìsinmi yóò maa waye lọjọ Kejìlá oṣù Kẹfà ọdọọdun, gẹgẹ bíi ayajọ ọjọ ijọba tiwá n tiwá dipo ọjọ kokandinlogbon osu karun ti a mọọ̀ si tẹlẹ.
Laipe yii ni Ìjọba àpapọ orílẹ̀-èdè Nàíjíríà kéde ọjọ́ kejìlá, oṣù Kẹfa (June 12) gẹ́gẹ́ bíi àyájọ ọjọ́ iṣèjọba awa-ara-wa dipo ọjọ́ kọkandinlọgbọn, osu karun-un (May 29) to maa ń wáyé l'ọdọọdun.
Ààrẹ Muhammadu Buhari ni awọn  kéde ọjọ yii, lẹ́yin ìjíròrò pẹ̀lú àwọn èèkan lórílẹ̀-èdè Nàíjíríà, to si tun fi ami ẹyẹ to ga julọ ni orilẹede yii da MKO Abiọla, ti gbogbo agbaye gba pe o moke ninu ibo naa, lọla.
Ọbasanjọ: Buhari ń pète láti ka ẹ̀sùn èké si mi lọrùn
Oríṣun àwòrán, @NGRPresident
Ọbasanjọ ti kọ lẹta tó fẹ̀sùn kan Buhari eleyi to di gbajugbaja kaakiri agbaye
Ààrẹ àná orílèèdè Nàìjíríà, Olusegun Obasanjo, ti ke gbajare pe ìjọba Buhari n pète láti ka ẹsùn sí òun lọrùn.
Obasanjọ ní, ìjọba Buhari fẹ lo ayédèrú ìwé láti ṣe ìṣe aburú yìí.
Nínú atẹjade kàn láti ọwọ olùrànlọwọ rè lórí ọrọ ìròyìn, Kehinde Akinyemi, Obasanjọ ní, ọnà méjì ní wọn fẹ gba fí panpe mu òun.
''Àkọkọ ni pé, wọn fẹ ló àjọ to n gbogun ti iwa jegudu-jera, EFCC, láti bẹrẹ Ìwádìí padà lórí òhun tó ṣẹlẹ lasiko ìjọba mi''
''Ẹlekeji ni pé, wọn fẹ ló awọn ayédèrú ìwé kan láti ṣe àkóbá fún òun gẹgẹ bí wọn ti ṣe ṣe ní àsìkò ìjọba ológun Abacha.''
Kíni àwọn ọmọ Nàìjírìà ń sọ lórí ọ̀rọ̀ tí Obasanjọ lóri ìkànsíraẹni twitter:
Ọrọ yí láwọn kan ti ṣe àpèjúwe rè gẹgẹ bí èsì Obasanjo sí ìgbésẹ ìjọba Buhari, láti fi ọjọ ayajọ òṣèlú tiwá n tiwá da olóògbé Moshood Kasimawo Abiola lọla.
Buhari fún Ẹ̀ka ìdájọ́, ilé àsòfin ìpínlẹ̀ l'òmìnira owóòná
Oríṣun àwòrán, Buhari/ Twitter
Ààrẹ Muhammadu Buhari tí fún ilé-iṣẹ́ adájọ ìpinlẹ̀ àtí àwọn ilé ìgbìmọ aṣofin ìpínlẹ̀ mẹ́rìndínlọ́gbọ̀n ni òmìnira owóòná,
Ààrẹ Buhari tí f'ofin de igbákejì gómìnà àti ti àarẹ láti lo sáà meji gẹ́gẹ́ bii olórí tuntun
Aarẹ buwọ́lu abadofin mẹrin, ọ̀kan níbẹ̀ ní o ti fún ilé-iṣẹ́ adájọ ìpinlẹ̀ àtí àwọn ilé ìgbìmọ aṣofin ìpínlẹ̀ mẹ́rìndínlọ́gbọ̀n ni òmìnira owóòná.
Èyí jẹ́ àbájáde àtúnṣe òfin tí ilé ìgbìmọ̀ asojú-sofin gùnlé, láti ṣẹ àtúnṣe sí àwọn òfin kan nínú ìwé òfin orílẹ̀-èdè Nàìjíríà tọdún 1999.
Bákan náà, ààrẹ tún buwọ́lu àbádòfin mẹ́rin gẹ́gẹ́ bíi àtúnṣe iwé òfin ọdún 1999.
Ọ̀kan nínú àwọn òfin ọ̀hún tún ni fífún àjọ eletò ìdìbò (INEC) ní àsìkò tó péye láti se àtúndì ìbò.
Kò tán síbẹ̀, lára òfin náà ló tún ní, igbákejì ààrẹ tó bá parí sáà pẹ̀lú ọ̀gá rẹ̀, tó tún fẹ́ lọ se ààrẹ, yóò lo sáà kan soso péré.
Bákan náà ni òfin yìí tún kan àwọn ìgbákejì gómìnà ìpínlẹ̀ tó bá parí sáà pẹ̀lú ọ̀gá rẹ̀.
Olùrànlọ́wọ́ fún ààrẹ lórí ọ̀rọ̀ ilé asòfin àgbà, Ita Enang, ló sísọ̀ lójú ọ̀rọ̀ yìí fún àwọn akọ̀ròyìn ní ilé ìjọba ní Àbújá.
Fídíò BBC yọ àwọn èèyàn FIFA níṣẹ́ ṣááju Russia 2018
Lai Mohammed: Ọbasanjọ, bí ìwo bá ṣé réré, Ara kì yóò yà ọ?
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ọbasanjọ ti ṣe nnkan ìtùfù sẹyin lo ṣe n kíyèsí ẹninkule rẹ̀
Ẹní jẹ fufu lára n fu lọrọ Ọbasanjọ
Èsì ọrọ ree láti ọdọ ìjọba Buhari sí Obasanjo to so pe Buhari n pète láti ka ẹsùn sí òun lọrùn lasiko yii.
Mínísítà fun ètò ìròyìn, Oloye Láì Muhammed, lo fèsì naa pada pe ''aheso ọrọ ni Obasanjo n sọ ati pé ìjọba Buhari ko ráàyè a n diran moni lẹsẹ''
Ọrọ náà jẹyọ nínú atẹjade kàn ti o fí ṣòwò s'awọn akoroyin lọjọ Ẹtì nílu Èkó.
Lai Mohammed so pé àwọn kò ní jẹ kí ''ọrọ ti kò fidimule kánkan yí ìpinnu awọn pada, pàápàá jùlọ lẹyìn ìgbà tí àwọn ṣẹṣẹ kéde ìyípadà ti gbogbo ara ìlú tẹwọgbà.''
O tèsíwájú nínú atẹjade náà :''o ti fojú hàn pé ìgbésẹ tí a gbé láti kéde ìyípadà àṣìṣe ti awọn kan ṣé ló n biwon nínú nipasẹ ètò ìdìbò ti ará ìlú gba pé òhun lo yanranti julọ.''
''Èyí  lo mú kí wọn má sare gbogbo ona láti fẹ pajá lọ́bọ fún ara ìlú''
Ogundamisi: Ọbasanjọ ni ko jẹ k'awọn ọdọ de'po
Ifọrọwanilẹnuwo pẹlu Ọjogbọn Wọle Soyinka
Lai Mohammed ni aseyori ìjọba Buhari lo n ko Obasanjo lominu pàápàá jùlọ pẹlu bi ọ ṣe l'ànfààní ati mú ìyípadà bá ètò ilu ṣugbọn tí o kò láti ṣe òhun tó yẹ.
Ṣáájú ni ọjọ Ẹtì kàn náà ni Ààrẹ àná orílè-èdè Nàìjíríà, Olusegun Obasanjo, ti figbe ta pé ìjọba Buhari n pète láti ka ẹsùn sí òun lọrùn.
Lẹnu ọjọ mẹta yí, itako ọrọ láàrin Obasanjo àti Buhari ti peleke sí i lẹyìn tí Obasanjo kọ leta sí Buhari lórí bí o tí ṣe n ṣètò ìlú.
Koko iroyin: Lai Mohammed fèsì sí ọrọ Obasanjo, Ìjọ́ba ìpínlẹ̀ Ògùn kéde ìsinmi ní June 12
Èyí ni àkójọpọ̀ àwọn ìròyìn tí tòní
Lai Mohammed: Ọbasanjọ, bí ìwo bá ṣé réré, Ara kì yóò yà ọ?
+
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ọbasanjọ ti ṣe nnkan ìtùfù sẹyin lo ṣe n kíyèsí ẹninkule rẹ̀
Ẹní jẹ fufu lára n fu lọ̀rọ̀ Ọbasanjọ.
Èsì ọrọ ree láti ọdọ ìjọba Buhari sí Obasanjo to so pe Buhari n pète láti ka ẹsùn sí òun lọrùn lasiko yii.
Mínísítà fún ètò ìròyìn,Alhaji Lai Muhammed, lo fèsì naa pada pé ''àhesọ ọ̀rọ̀ ni Ọbasanjọ n sọ, àti pé ìjọba Buhari kò ráàyè a n dìràn mọ́ni lẹ́sẹ̀''
Ọrọ náà jẹyọ nínú aàtẹ̀jáde kàn tó fí ṣọwọ́ s'awọn akọ̀ròyìn lọ́jọ́ Ẹtì nílùú Èkó. Ẹ ka ẹ̀kúnrẹ́rẹ́ níbí
June 12: Ògùn, Ọ̀yọ́ kéde ìsinmi lẹ́nu iṣẹ́
Oríṣun àwòrán, http://ogunstate.gov.ng
Wọ́n ni ọjọ́ nàá yó le fún àwọn aráàlú ní ànfàání láti ṣe àjọyọ̀ ọjọ́ ìṣèjọba àwaarawa.
Ìjọba ìpínlẹ̀ Ògùn ti kéde ọjọ́ kejìlá, oṣù Kẹfà, gkgẹ́ bí ọjọ́ ìsinmi lẹ́nu iṣẹ́.
Èyí jẹyọ nínú àtẹ̀jáde kan tí akọ̀wé fún ìjọba ìpínlẹ̀ nàá, Taiwo Adeoluwa fọwọ́ sí.
Nínú àtẹ̀jáde nàá tó tẹ ìwé ìròyìn Punch lọ́wọ́, wọ́n ni ọjọ́ nàá yó le fún àwọn aráàlú ní ànfàání láti ṣe àjọyọ̀ ọjọ́ ìṣèjọba àwaarawa. E ka ekunrere re ni bii
'Bóo rántí ikú Gáà kóo ṣòótọ́ ni ọ̀rọ̀ Abacha'
'Ọpọ̀ ẹ̀mí èèyàn ló bọ́ lọ́wọ́ Abacha láàrín 1993 sí 1998'
Òpópónà Mokwa sí Jebba; Afáárá fún àwọn awakọ̀ wó lulẹ̀
Oríṣun àwòrán, Facebook/Lara Wise
FRSC gba awọn awakọ niyanju lati gba popona Lokoja ti wọn ba n lo si olu ilu Naijiria, Abuja.
Afaara to wa ni oju opopona Mokwa si Jebaa ti wo lulẹ, lẹyin ti ojo arọọrọda sọsẹ lagbeegbe naa.
Agbẹnusọ fun ajọ to n risi ọrọ oju popo, Bisi Kazeem nigba to n ba BBC Yoruba sọrọ fikun un wi pe ki awọn awakọ o sọra lati gba ọna naa.
Ninu ọrọ rẹ, Kazeem ni looto ni isẹlẹ naa waye ni ipinlẹ Niger, lẹyin ti ojo rọ.
Ọ̀rọ̀ fún àwọn tó ń lo ike rọ́bà
O gba awọn awakọ niyanju lati gba opopona Lokoja ti wọn ba n lo si olu ilu Naijiria, Abuja.
Iroyin fi lede wi pe ọna Mokwa si Jebba ni ọpọlọpọ eniyan ma n gba lọ si Ilorin ati si Abuja.
Ṣina Peters bú sẹ́kún lórí ikú Ras Kimono, pé ẹni rere lọ
Oríṣun àwòrán, OFFICIALRASKIMONO/INSTAGRAM
Ẹni ọgọ́ta ọdún ni olóògbé Ras Kimono
Gbajúgbajà olórin Reggae ni, Ras Kimono, tí órúkọ rẹ̀ gangan ń jẹ́ Ekeleke Elumelu ti papòdà ní ẹni ọgọ́ta ọdun
Ààrẹ ẹgbẹ́ àwọn olórin ti orílẹ̀-èdè Naijiria (PMAN), Pretty Okafor, ní ikú nàá jẹ́ ìbànújẹ́ ńlá fún àwọn àwùjọ olórin.
A gbọ́ pé ilé ìwòsàn kan ní Ìkòyí ni olórin náà kú sí lẹ́yìn tí ó dákú ní ọjọ́ Àbámẹ́ta.
Ọrọ ìfẹ́: Tunrayọ Adeoye kú lọ́sẹ̀ karun ti a sin ọkọ rẹ̀
Ìròyin sọ fún wa pé Ras Kimono ń lọ orílẹ̀-èdè Amẹ́rika kí ó tó dipé ó dá kú, tí wọ́n sì gbée lọ sí ilé ìwòsàn.
Nígbà tí BBC kàn sí olórin Afro-Juju ni, Sir Shina Peters, tí ó jẹ́ ọ̀rẹ́ rẹ̀ tímọ́tímọ́, ṣe ni ó bú sẹ́kún tí kò sì lè sọ̀rọ̀.
Oríṣun àwòrán, OFFICIALRASKIMONO/INSTAGRAM
Ras Kimono dágbére f'aye pé o dìgbóṣe lọjọ Aiku
Ras Kimono tí ó jẹ́ ọmo Ìpínlẹ̀ Delta ṣe àwo orin rẹ̀ àkọ̀kọ̀ 'Under Pressure' ní ọdún 1989.
"A gbọ́ pé Ras Kimono jẹ́ ènìyàn tí kíì mu ọtí. Ó máa ń sọ nínú àwọn ìfọ̀rọ̀wánilẹ́nuwò pẹ̀lú àwọn akọ̀ròyin pé, ""Èmi kìí mu ọtí, sìgá tabi igbó, bẹ́ẹ̀ ni mi kìí ṣe àlágbèrè."""
Ìkú rẹ̀ di kókó ọ̀rọ̀ tí àwọn ọmọ òrílẹ̀-èdè Naijiria sọ̀ nípa rẹ̀ jù lórí Twitter bi ọ̀pọ̀ ènìyàn ṣe ń ṣe'rántí olóògbé náà pe:
Ọ̀rọ̀ fún àwọn tó ń lo ike rọ́bà
Iléeṣẹ́ ọlọ́pàá tún ti ṣèlérí àtúntò ikọ̀ ọlọ́pàá kògbérégbè FSARS
Oríṣun àwòrán, @OfficialSARS
Àwọn aláṣẹ Iléeṣẹ́ ọlọ́pàá ní ìlànà iṣẹ́ ikọ̀ ọlọ́pàá kògbérégbè FSARS kò fi ààyè ìrégbè sílẹ̀ fún wọn
Ileeṣẹ ọlọpa ti ni ko si ofin kan to fun awọn oṣiṣẹ ọlọpa FSARS lati da ọkọ duro fun ayẹwo loju popo.
Kọmiṣọna ọlọpaa ni ipinlẹ Edo, Haliru Gwandu lo ṣalaye ọrọ yii lasiko ifọrọwerọ lori ikanni ayelujara twitter kan to waye lori ọrọ awọn ọlọpa SARS.
Ifọrọwerọ ori ikanni ayelujara Twitter naa ti wọn  pe ni #AskThePolice #ReformSARS ni wọn gbe kalẹ lati fun araalu ni anfani lati fi ẹhonu wọn han  lori ise awọn ọlọpa FSARS lorilẹede Naijiria.
Gwandu to jẹ kọmisọna ọlọpaa ni Edo ni lootọ ojuṣe ọlọpa labẹ ofin ni lati daabo bo araalu, ṣugbọn eredi idasilẹ ikọ kogberegbe FSARS ni lati da si ipe 'gbami-gbami' araalu.
"Iṣẹ pọ lọrun ikọ ọlọpa FSARS, lati koju iwa idigunjale, ijinigbe, jiji ẹran ọsin gbe atawọn iwa ipa gbogbo
Ko si ẹni to ran awọn ọlọpa ikọ naa lati maa da ọkọ duro tabi ṣe ayẹwo ọkọ"
Gẹgẹ bii ọga ọlọpa naa tun ṣe tẹẹ si oju ikanni Twitter, o ni ''ko si ilana iṣẹ awọn ọlọpa ikọ FSARS to fun wọn lagbara tabi aṣẹ lati mu alaiṣẹ''.
Gwandu ni gbogbo ẹhonu araalu ni awọn alaṣẹ ileeṣẹ ọlọpa yoo mojuto ni ibamu pẹlu ipinnu ọga agba awọn ọlọpa lati mu atunto ati atunṣe ba ikọ ọlọpaa kogberegbe FSARS lati lee bẹrẹ si ni ṣe iṣẹ wọn bi o ti tọ ati bi o ti yẹ.
World Cup 2026: Canada, US àti Mexico ni yóò gbàlejò ife ẹ̀yẹ àgbáyé 2026
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Canada, US àti Mexico ni yóò gbàlejò ife ẹ̀yẹ àgbáyé 2026
Ìpàdé àpérò ìkejìdínláàdọ́rin tó ń wáyé ní orílẹ̀èdè Mexico ti yan Amerika, Canada àti Mexico láti gbàlejò ife ẹ̀yẹ àgbáyé ti ọdún 2026.
Orílẹ̀èdè Morocco ti ń fàá pẹ̀lú àpapọ̀ Amerika, Canada àti Mexico èyí tí wọ́n jùmọ̀ pè ní 'United 2026' láti gbàlejò ìdíje ti ọdún 2026.
Ànfàní tí ilẹ̀ àríwá Áfíríkà ní tún gòkè síi lọ́sẹ̀ yìí láti jẹ́ olùgbàlejò ìdíje ńlá náà lágbàyé lẹ́yìn tí orílẹ̀èdè mẹ́rin ní erékúsù ilẹ̀ Amẹ́ríkà gbà wípé àwọn fọ ọwọ́ kúrò nínú ìdìbò àsekágbá.
Sùgbọ́n ti àpapọ̀ orílẹ̀èdè mẹ́ta 'United 2026' ló dùn un gbọ́ jù nítorí pápá bọ́ọ̀lù àwòmáleèlọ́ wọn, àwọn yàrá ìgbàlejò àti ọ̀nà tó tẹ́ lọ bí ẹní tó fi mọ́ èrè owó tí yòó mú wá.
APC: Ọ̀rọ̀ àbùkù látẹnu Okorocha ń ta ẹrẹ̀ bá ẹgbẹ́ wa
Oríṣun àwòrán, @ImoGovernor
Okorocha ni alága ìgbìmọ̀ àwọn gómínà APC tẹ́lẹ̀
Nkan kò lọ déédé láàrín ìgbìmọ̀ aláṣẹ ẹgbẹ́ òṣèlú APC àti Gomina Ìpínlẹ̀ Imo, Rochas Okorocha, lórí àwọn ọ̀rọ̀ kan tí wọ́n ní ó ń tẹnu rẹ̀ jáde.
Atẹ̀jáde kan láti ọwọ́ alukoro ẹgbẹ́ òsèlú APC, Bolaji Abdullahi, sọ pé, lẹ́nu ọjọ́ mẹ́ta yìí ni Okorocha ń sọrọ àbùkù sí ẹgbẹ́ nàá, àwọn àgbààgbà ẹgbẹ́ àti alaga wọn, Olóyè John Odigie-Oyegun lórí ìdìbò abẹ́le tí ó wáyé ní oṣù karùń-un ní ìpínlẹ̀ Imo.
Okorocha, tó jẹ́ alága ìgbìmọ̀ àwọn gómínà APC ni wọ́n ní ó lo ọmọ ẹ̀yìn rẹ̀ kan tí orúkọ rẹ̀ ńjẹ́ Ireagwu Obioma láti gbé àtẹ̀jáde kan jáde tí ó fẹ̀sùn oríṣiríṣi kan ẹgbẹ́ APC.
Àwọn òǹwòye ní, ọ̀rọ̀ náà jẹ àbùkù fún ìṣọkan APC nítori ipò tí Okorocha wà nínú ẹgbẹ́ nàá láti ilẹ̀ wá.
Oríṣun àwòrán, @ImoGovernor
APC ní àwọn kò ní gba ọ̀rọ̀-kọ́rọ̀ láàyè nínú ẹgbẹ́ náà
Atẹ̀jáde ẹgbẹ́ náà tilẹ̀ fi ẹ̀sùn kán pé, o gbé ìwé kan jáde nínú èyí tí wọ́n lo ayédèru orúkọ àwọn olọ́yè ẹgbẹ́ nàá méjì - Edwin Ikhinmwin àti amòfin agbà Muiz Banire.
Ẹgbẹ́ APC ní, àwọn kò ní gba ọ̀rọ̀-kọ́rọ̀ láàyè nínú ẹgbẹ́ náà o. Wọ́n wa rọ Okorocha láti kó ara rẹ̀ ní ìjánu, kí ó sì wá ọ̀nà àlàáfíà pẹ̀lú àwọn àgbààgbà ẹgbẹ́ náà.
Ọlọ́pàá Ethiopia: $185,000 ni àwọn ọlọ́ṣa fi sílẹ̀ sá lọ
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Bí àwọn ọlọ́ṣà náà ṣe ń sá lọ ní ọkọ́ wọn kọ lu ọkọ̀ tó wà ní iwájú tí ó sì ta kú
Àwọn ọlọ́ṣà méjì tí wọ́n lọ jálè ní ilé ìfowópoamọ́ kan ní Ethiopia, há sínú súnkẹ̀rẹ̀-fàkẹrẹ ọkọ̀ ní ọjọ́ Ìṣẹ́gun ní olú ìlú orílẹ̀èdè náà, Addis Ababa.
Àwọn olè náà se ìkọlù sí ilé ìfowópamọ́ tí orúkọ rẹ̀ ń jẹ́ Abyssinia, ṣùgbọ́n ọwọ́ òfo ni wọ́n mú lọ o, nítórí pé wọ́n sá lọ kí àwọn ọlọ́pàá má bàá mú wọn.
Síbẹ̀síbẹ̀, ọwọ́ tẹ àwọn afunrasí méjì míràn.
Oríṣun àwòrán, AFP
Awọn ọlọpaa ni ẹgbẹ̀rún márùndínlàádọ́wàá dọ́là ni àwọn ọlọ́ṣa nàá fi sílẹ̀ sá lọ
Arákunrin kan tó wà nibi ìṣẹ̀lẹ̀ náà ní, bí àwọn ọlọ́ṣà náà ṣe ń sá lọ ní ọkọ́ wọn kọ lu ọkọ̀ tó wà ní iwájú, tí ó sì ta kú. ni wọ́n ba f'ẹsẹ̀ fẹ.
Ó ní àwọn ará ìlú fẹ́ mú àwọn ọlọ́ṣà náà, ṣùgbọ̀n ẹ̀rù ń bà wọ́n nítorí pè ọkan lára wọn mú ọ̀bẹ dání.
Agbẹnusọ fun àjọ ọlọ́pàá ìlú nàá ní, bíẹgbẹ̀rún márùndínlàádọ́wàá dọ́là ni àwọn ọlọ́ṣa nàá fi sílẹ̀ sá lọ.
Iléesẹ̀ ọlọ́pàá: NHRC fẹ́ mọ bàwọn afurasí se dé túbú
Oríṣun àwòrán, RCCG
Bí wọ́n ṣe ń ti àwọn ènìyàn mọ'lé ní Naijiria jẹ kókó ọ̀rọ̀
Àjọ tí ó ń rí sí ẹ̀tọ́ ọmọ ènìyàn (NHRC) yóò ṣe àyẹ̀wò gbogbo túbú àwọn ọlọ́pàá tó wà ní orílẹ̀èdè Naijiríà.
Nínú àtẹ̀jáde kan tí igbákejì agbẹnusọ iléeṣẹ́ ọlọ́pàá, Abayomi Shogunle, gbé jáde lórukọ ọ̀gá ọlọ́pàá ní orílẹ̀èdè Naijiria, Ibrahim Idris ni Ọjọ́rú, ó ní NHRC yóò lọ wo ọ̀nà bí wọ́n ṣe ń ti àwọn ènìyàn mọ́'lé.
A gbọ́ pé, àwọn túbú àwọn ọlọ́pàá tó ń gbógun ti àwọn adigunjalè (SARS) wà lára àwọn tí wọn yóò wò.
Bí wọ́n ṣe ń ti àwọn ènìyàn mọ'lé ní Naijiria tí jẹ́ ọ̀rọ̀ àfẹnubà fún ọjọ́ tó ti pẹ́. Àwọn kan tilẹ̀ ń kú sínú túbú ọlọ́pàá.
Oríṣun àwòrán, @PoliceNG
Tubu (SARS) wà lára àwọn ọgbà ẹ̀wọ̀n tí wọn yóò wò.
Àwọn ọmọ Naijiria ti wá n fi èrò wọn hàn lórí ọ̀rọ̀ nàá lórí ìkànni Twitter.
Ọlọ́pàá: Agúnbẹ náà kò ju ọ̀bẹ sílẹ̀ la fi yìnbọn páá
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Awọn ọlọpaa ni Agúnbẹ náà kò ju ọ̀bẹ sílẹ̀ ni wọn se fi yìnbọn páá
Eeyan mẹta lo padanu ẹmi wọn lẹyin ikọlu mọsalaasi miran l'orilẹede South Africa.
Ikọlu naa ṣẹlẹ ni deedee agogo mẹta oru nigbati awọn musulumi n mura fun adura owurọ ni Malmesbury lagbegbe ilu Cape Town.
Iroyin sọ di mimọ pe, ọkunrin kan lo wọ mosalaasi, to si beere ọna, ko to f'ọbẹ gun eeyan meji pa lojiji ti eeyan mẹta si f'arapa.
Gbolahan Kabiawu: Fífi ẹ̀jẹ̀ sílẹ̀ dára fún ẹ̀yà ara
Awọn agbofinro fidi rẹ mulẹ pe okunrin naa, to to ẹni ọgbọn ọdun kọ lati fi ọbẹ to mu dani silẹ, to si doju kọ ọlọpaa to wa nibẹ ki ọlọpaa naa to yinbọn paa.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ìkọlù mọ́sáláásí ní ìlú Cape Town mú ẹ̀mí okùnrin tó gún èèyàn méjì pa náà lọ
Awọn ti iṣẹlẹ naa ṣoju wọn se apejuwe ọbẹ ti okunrin naa lo bi ọbẹ Rambo.
Ikọlu yii ṣẹlẹ lẹyin osu kan ti iru rẹ ṣẹlẹ ni mọsalaasi kan ni apa ariwa ilu Durban, l'orilẹede South Africa.
Keyamo: N kò nígbàgbọ́ nínú àwọn tó ń sisẹ́ pẹ̀lú Buhari
Oríṣun àwòrán, @fkeyamo
Keyamo ni kìí ṣe ààrẹ ní yóò kó orúkọ àwọn tí yóò ṣiṣẹ́ jọ, àwọn òsìsẹ́ ni
Olùdarí féka ètò ìbánísọ̀rọ̀ lábẹ àjọ ìpolongo ìbò fún Muhammadu Buhari, Festus Keyamo ( SAN) sọ pé, ààrẹ Muhammadu Buhari nìkan ní òún le fọwọ́sọ̀yà fún, gẹ́gẹ́ bí olóòtọ́ọ́ nínú gbogbo àwọn tó ń báa ṣiṣẹ́.
Keyamo sọ̀rọ̀ ọ̀hún nínú ìfọ̀rọ̀wánilẹ́nu wò kan ní ìlú Abuja.
Keyamo sọ̀rọ̀ yìí ní ìdáhùn sí ẹ́sùn kan pé, ìjọba Buhari fárí apá kan, dá apá kan si, àti pé, àwọn òsìsẹ́ ń gba ọ̀nà ẹ̀yìn wọ Bánkì orilẹ̀-èdè Nàìjíríà (CBN).
"O ní ""mo ránti pé nígbà kan, àwọn ènìyàn ń pariwo pé wọ́n fún àwọn ènìyàn ẹkùn ibì kan níṣẹ ju àwọn ẹkùn míràn lọ, sùgbọn ọ̀pọ̀ àwọn ǹkan wọ̀nyìí tí ó bá dé détigbọ́ ààrẹ, Buhari kò lè káwọ́ gbera lórí rẹ̀."
Oríṣun àwòrán, @AsoRock
Kìí ṣe ààrẹ Buhari ní yóò kó orúkọ àwọn tí yóò ṣiṣẹ́ jọ, àwọn òsìsẹ́ ni, ẹnikẹ́ni kò sì lée gba ẹ̀rí wọn jẹ.
Kìí ṣe ààrẹ ní yóò kó orúkọ àwọn tí yóò ṣiṣẹ́ jọ, àwọn òsìsẹ́ ni, ẹnikẹ́ni kò sì lée gba ẹ̀rí wọn jẹ.
Nígbà ti ọ̀rọ̀ ọ̀un jẹyọ, ààrẹ Buhari dáwọ́ ìgbanisísẹ́ ọ̀hún dúro
Keyamo bẹ́nu àtẹ́ lu àwọn tí wọn sọ pé, ààrẹ ń fárí apa kan, dá apákan sí láti máa yan àwón èèyàn apá Aréwa nìkan sí ipò to ga jù.
Keyamo wa rọ àwọn Nàìjíríà láti mase fi ẹ̀tẹ̀ sílẹ̀, kí wọ́n maa pa làpálàpá kiri.
Buhari ní àìmú ẹ̀kọ́ ẹ̀sìn lò ló ń fa ìwà ìbàjẹ́ láwùjọ
Oríṣun àwòrán, Nigeria Presidency
Ààrẹ Buhari rọ àwọn Mùsùlùmí láti tẹsiwaju ninu iṣẹ rere ṣiṣe lẹyin Ramadan
Aarẹ Muhammadu Buhari ti rọ awọn musulumi Naijiria lati maṣe gbagbe ẹkọ ti wọn kọ lasiko aawẹ oṣu Ramadan to pari.
Ninu ọrọ ikinni ku ọdun itunu aawẹ to fi ranṣẹ sawọn musulumi lorilẹ-ede Naijiria ni Aarẹ ti sọ ọrọ yii.
Aarẹ Buhari ni ọpagun lo yẹ ki ẹsin jẹ fun iwa awọn to ba gbagbọ lati ṣe atọna fun igbe aye wọn ni gbangba ati ni kọọrọ.
Bi awọn eeyan ba gba ẹkọ ẹsin wọn laaye lati maa ṣe atọna fun ihuwasi wọn, awọn iṣoro bii iwa ijẹkujẹ eleyii to n ko owo ilu lọ si apo awọn eeyan kan yoo ti di itan lawujọ.
Aarẹ Buhari ni lẹyin ti wọn ti pari 'oṣu to ni ipa pataki nipa ti ẹmi lori ifara ẹni jin' yii, ki awọn musulumi o ronu lori pataki oṣu Ramadan ki wọn le di aṣoju rere fun ẹsin Islam ni gbogbo igba.
Gbolahan Kabiawu: Fífi ẹ̀jẹ̀ sílẹ̀ dára fún ẹ̀yà ara
2000 ọ̀dọ́ ìpínlẹ̀ Oṣun jàǹfàní ìkọ́ṣẹ́ lọwọ́ ìjọba àpapọ̀
Oríṣun àwòrán, Bosẹ Sodiq
Iṣẹ́ ọnà, àsè gbígbà, ilé ṣíṣe lọ́ṣọ́ àti kẹ́míkà ṣíṣe kún ara iṣẹ́ ọwọ tí wọ́n kọ́ àwọn ọ̀dọ́ náà
Gẹgẹ bii ara eto lati le airiṣẹ wọlẹ lorilẹ-ede Naijiria, ijọba apapọ ti ṣeto ikọṣẹ ọwọ fun ẹgbẹrun meji awọn ọdọ nipinlẹ Ọṣun.
Awọn ẹgbẹrun meji naa ni wọn ṣa kaakiri awọn ijọba ibilẹ mẹwaa lẹkun idibo aringbungbun Ọṣun ati ijọba ibilẹ Ede South nipinlẹ naa.
Awọn alakoso eto ọhun, Liberty Olawale Badmus ati Ọmọwe Saka Ominiwe, ni afojusun eto ikọṣẹ ọfẹ naa ni lati fun awọn ọdọ ni anfani igbagbọ ninu ara wọn bi o ti ṣe wa lawọn orilẹ-ede kaakiri agbaye.
O tẹnumọ pataki ṣiṣamulo awọn ẹkọ ti wọn kọ lati mu ayipada rere ba ara wọn ati orilẹ-ede Naijiria lapapọ.
Ọmọwe Saka Ominiwe ni bi igbesẹ naa ba n tẹsiwaju, yoo mu iṣoro airiṣẹ di ohun igbagbe lorilẹ-ede Naijiria.
Wọn ni eto ọhun ti kọkọ waye ni ipinlẹ Eko lati gbe igbesẹ fun riro awọn ọdọ lagbara lati da duro pẹlu bi iṣẹ ọba ati aladani ṣe di wahala nitori bi ọrọ aje ṣe ri.
Gbogbo awọn ọdọ naa ni wọn kọ ni ẹkọ iṣẹ ọna, ṣiṣe ile lọṣọ, fọtọ yiya ati ṣiṣe eroja kẹmika ati bẹẹbẹẹ lọ.
Russia 2018:Super Eagles ti kẹ́kọ̀ọ́ nínú ìdíje tó kọjá
M.K.O Abiola: Eyi ni àwọn ńkan tó yẹ kí ẹ mọ̀ nípa rẹ̀
Abiọla ti jẹ́ olùdárí iwe ìròyìn Trumpeter rí ti Obasanjọ sì jẹ́ igbákejì rẹ̀
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí:
Ìsẹ̀lẹ̀ Èkó: Àwòrán bí èèyàn mẹ́ta se bá ìjàmbá lọ
Ajọ to n risi ìsẹ̀lẹ̀ pajawiri ni ipinlẹ Eko, Lasema, to fi idi isẹlẹ naa mulẹ, fi kun un p, eniyan mẹta naa ku loju ẹsẹ, ti ọpọ si farapa.
Awọn igi to da wo labẹ afara naa
Ọkọ̀ akérò kan tí igi náà wó lù mọ́lẹ̀ ló rún jégé-jégé.
Ìjàmbá kò nílé, àfi kí Ọba òkè máa kó wa yọ
Èrò kò gbẹsẹ̀ ní ibití ìsẹ̀lẹ̀ náà ti wáyé.
Ń se ni ọ̀pọ̀ èèyàn ń bèèrè pé sé kò yẹ ká leè máa dènà irúfẹ́ ìjàmbá bíi èyí?
Kò sí ibi tó kù mọ́ lára ọ̀kọ̀ tí igi wó lù yìí
Àwọn agbófinró ti ta okùn dí agbègbè ibití ìsẹ̀lẹ̀ náà ti wáyé
Àlààfíà ti ń padà sí àdúgbò Ojúẹlẹ́gba, tí àwọn òsìsẹ́ ìjọba sì ti ń tún àyíká ibití ìsẹ̀ll náà ti wáyé se
Àwọn òsìsẹ́ tó ń gbá ilẹ̀ kò jáfara láti se ìtọ̀jú àyíká náà
Kátà-kárà ti bẹ̀rẹ̀ padà ní agbègbè tí ìjàmbá náà ti wáyé.
Ohun gbogbo ti padà bọ̀ sípò ní Ojuẹlẹgba ni ilu Eko
Gbàgede òkè àti ìsàlẹ̀ ibití ìsẹ̀lẹ̀ ìjàmbá náà ti wáyé
Isẹ́ ńla ló wà níwájú àwọn òsílẹ̀ tó ń gbálẹ̀ ní Ojúẹlẹ́gba
Àwòrán ọ̀kọ̀ tó ní ìjàmbá gbẹnu tán ní Ojúẹlẹ́gba.
Àwọn èrò ya ẹnu lórí ìsẹ̀lẹ̀ náà, wọn kò leè pádé mọ́
Haa, irú kín ni èyí ni ọ̀pọ̀ èèyàn n sọ lórí ìsẹ̀lẹ̀ náà.
Àwọn èèyàn tó ń ya ẹnu, lórí ìsẹ̀ll náà
Ìsẹ̀lẹ̀ ìjàmbá tó mú ẹ̀mí èèyàn mẹ́ta lọ nigba ti igi nla rebọ lati ori ọkọ agbegi to n sọkalẹ lori afara Ojuẹlẹgba ni ilu Eko gba ẹ̀nu tán.
Oríṣun àwòrán, Alamy
Bí èèyàn bá jẹ orí ahun. yóò kẹ́dùn ní Ojúẹlẹ́gba
Fẹmi Adebayọ: Òsèré tíátà Yorùbá kò leè gba owó ju òsèré olóyìnbó lọ
Oríṣun àwòrán, @realfemiadebayo
Ọmọ to ba mọ́ iya abi baba rẹ loju osi ni yoo ta ọmọ naa pa ni Yoruba maa n sọ. Eyi to ba tiẹ wa na obi rẹ, o ti jẹ eewọ. Sugbọn eyi ko rii bẹẹ rara taa ba n sọrọ awọn osere ori itage.
Ilumọọka osere tiata kan, Fẹmi Adebayọ ti ni ohun to buru julọ ti oun tii se ninu ere ori itage ni ere kan ti wọn ti ni ki oun gba baba oun, Adebayọ Salami, ti gbogbo eeyan mọ si Ọga Bello leti.
Fẹmi ni ti kii ba se ere, kin ni oun ko ba jẹ yo, debi ti oun yoo maa gba baba oun leti pẹlu afikun pe gẹgẹ bii osere tiata to dantọ, ojuse ti wọn gbe le oun lọwọ ninu ere ni eyi, oun si gbọdọ see ni.
Femi Adebayo: Ẹyin ọ̀dọ́, ẹ káàbọ̀ ságbo ilé Tíátà
Nigba to n ba akọroyin Punch sọrọ, Fẹmi Adebayọ ni, oun ko ri baba oun bii baba oun rara to ba di ẹnu isẹ tiata, o ti di akẹẹgbẹ oun ti awọn dijọ n sisẹ, tawọn si gbọdọ se ojuse awọn daadaa.
O fikun pe baba oun lo kọ oun ni isẹ tiata, ọga oun si lo tun jẹ, to si ti kọ oun pe nigb-kuugba ti oun ba pade awọn agba osere lẹnu isẹ, oun ko gbọdọ bẹru rara .
"Fẹmi ko sai fi kun pe ""ni kete ti oludari ere ni o to, ni mo yara dọbalẹ lati tọrọ aforijin lọwọ mi pe ko ma binu pe mo fọ oun leti."""
Oríṣun àwòrán, @realfemiadebayo
Fẹmi Adebayọ tun fi kun pe ko seese ki osere tiata lede Yoruba maa gba owo ju awọn akẹ́ẹgbẹ́ rẹ to n sọ oyinbo lọ.
O ni idi ni pe awọn ẹya Yoruba nikan lo n ra fiimu lede Yoruba, nigba ti fiimu oloyinbo jẹ itẹwọgba kari aye.
xxxxxxxxxxxxxxxxxxxxxxxxxxxxxxxxxxxxxxxxxxxxxxxxxxxxxxxxxxxxx
Oríṣun àwòrán, realmercyaigbe
Ilé náà tó kùn ní àwọ̀ búlùù ojú sánmọ̀ àti ti ọtí wáìnì ló ní gbàgede ìgbafẹ́ ní òkè àti ìsàlẹ̀
Gbajú-gbajà òsèré tíátà ni óbìnrin, Mercy Aigbe ti ra ilé alájà kan tó jẹ́ àwòsí-fìlá.
Ilé náà, tó jẹ́ àwọ̀ búlùù ti ojú sánmọ̀ àti ti ọtí wáìnì, ló ní gbàgede ìgbafẹ́ ní òkè àti ìsàlẹ̀, bẹ́ẹ̀ ló tún ní ilẹ̀ tó tẹ́jú nínú àgbàlá rẹ̀ láti yan fanda,
Mercy Aigbe, tó ti se eré tíàtà ní èdè Yorùbá àti òyìnbó, ló kéde pé òun ti di ìyá onílé tuntun, ní ojú òpó Twitter rẹ̀ ní ọjọ́ ìsẹ́gun.
Bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé Aigbe kò sọ agbègbè tí ilé náà wà, síbẹ̀ ọ̀pọ̀ àwọ̀n akẹgbẹ́ rẹ̀ ló ti ń ki kú oríire ní ojú òpó Twitter wọn.
Mide Martins, tóun náà jẹ́ òsèré tíátà míì, ní ojú òpó twitter rẹ̀@mydemartins ní, inú òun dùn pé Mercy gbé ohun rere se, tó sì ń bèèrè pé ìgbà wo ni àwọn yóò sí ilé náà.
Nigba to n jẹ́ri lori ile naa, Mercy Aigbe ni ọ̀kan lara awọn eeyan oun kan, tyo pe orukọ rẹ ni Luminee, lo fi akara oyinbo ti wọn mọ bii ile alaja kan ta oun lọrẹ lasiko ayẹyẹ ọjọ ibi ogoji ọdun oun ti oun se ni ibẹrẹ̀ ọdun tii.
Mercy ni Luminee gba adura fun oun pe ki ọdun yii to pari, oun naa yoo ni ile ti ara oun, ti oun si fesi pada pe ko fi oun silẹ, nitori ile ti oun n kọ lọwọ, oun ko tii pari rẹ.
O ni Luminee ni oun ko sọ nipa ile naa, amọoun n sọ̀ nipa ile to rwea, ti oun yoo ra si agbegbe to jẹ oju ni gbese ni ilu Eko, ti oun si jaa niyan pe nibo ni oun ti fẹ́ ri owo banta-banta lati iru ile bẹẹ.
Luminee wa sọ fun oun pe ki oun mase se aniyan lori rẹ rara nitori Ọlọrun yoo bu kun oun, ti yoo si ro oun ni agbara.
Oríṣun àwòrán, realmercyaigbe
A see ẹbun akara oyinbo lasan lee pa owe nla fun ẹda kan
Mercy Aigbe ni n se ni oun rẹrin iyangi, to si lọra lati se amin.
Emi ko mọ pe Ọlọrun n lo ohun asiwere lati da Ọlọgbọn mi laamu ni, lati ẹnu Luminee si ni Ọlọrun ti fun mi ni ẹri ile tuntun.
Mercy ni lẹyin osu diẹ ti oun gba ẹbun akara oyinbo naa, ni oun ra ile tuntun fun ara oun ni adugbo to rẹwa ni ilu Eko,
Ẹ dakun, ẹ ki iya onile tuntun ni Mercy sọ, pẹlu afikun pe oun ti ri oore ọfẹ Ọlọrun, ti iyanu rẹ si ti wa oun ri. O ni ibẹrẹ oun ọtun ree ninu aye oun, Ogo si ni fun Ọlọrun.
Buhari: N kò dunnú sí àyípadà táwọn asòfin se sí ìsúná
Oríṣun àwòrán, @BashirAhmaad
Ààrẹ Buhari buwọ́ lu ìsúná 2018
Ààrẹ buwọ́ lu ìwé ètò ìsúná Nàìjíríà lẹ́yìn osù kẹfà tí wọ́n se àgbéjáde rẹ̀ níwájú ilé ìgbìmọ̀ asòfin.
Lára ohun tí Ààrẹ mẹ́nu bà gẹ́gẹ́ bí àkùdé nínú ètò ìsúná ọ̀hún ni pípèsè fún àwọn isẹ àkànse ohun amáyérọrùn kọ̀ọ̀kan bíi ibùdó ìpèsè iná ti Mambilla, afára tó fi mọ́ òpópónà Niger, àwọn ọ̀nà apá Ílà Oòrùn-Ìwọ̀ Oòrùn, òpópónà Bonny sí Bodo, òpópónà Eko sí Ibadan tó fi mọ́ ojú ọ̀na irin Itakpe sí Ajaokuta.
Ẹ̀wẹ̀, Ààrẹ Buhari ní inú òhun kò dùn sí àwọn àyípadà tí ilé ìgbìmọ̀ aṣòfin se sí ìwé ètò ìsúná tí òun fi ṣọwọ́ sí wọn. Ó ní bó ṣe yẹ kó jẹ́ ni wí pé ẹ̀ka aláṣẹ ló yẹ kó dábàá ètò ìsúná, nítorí òun ló mọ̀ tó sì lè sàlàyé àwọn àlàkalẹ̀ àti iṣẹ́ àkànṣe.
"Sùgbọ́n ó ní wọn kò kọbi ara sí èyí tó nínú ohun tí wọ́n fi ṣọwọ́ sí òun. ""Ilé ìgbìmọ̀ aṣòfin gé owó tó tó bílíọ̀nù N347 nínú N4,700 tó yẹ kó wà fún iṣẹ́ àkànṣe èyí tó fi ṣọwọ́ sí wọn fún àgbéyẹ̀wò, ó sì dábàá iṣẹ́ àkànṣe 6,403 tó tó bílíọ́nù N578."
Sáájú, báyìí ni ó se wà nínú àbá ètò ìsúná Nàìjíríà:
Iye owó =N=9,120,334,988,225 ni ó wà nínú ìwé ètò ìsúná náà lára èyí tí =N=530,421368,624 ni wọ́n yà sọ́tọ̀ fún owó tí wọ́n gbudọ̀ fi ṣọwọ́ èyí tó di dandan.
=N=2,203,835,365,699 ló wà fún gbèsè sísan; =N=3,512,677,902,077 wà fún owónàá àtìgbàdégbà èyí tí kìí se gbèsè nígbàtí =N=2,873,400,351,825 jẹ́ owó fún ìdàgbàsókè àkànṣe iṣẹ́ ńlá ńlá.
Owó fún ìdàgbàsókè àkànṣe iṣẹ́ ńlá ńlá ọ̀hún fún ọdún yìí máa parí ní ọjọ́ kọkànlélọ́gbọ̀n oṣù kéjìlá ọdún 2018.
(i) Wọn yóò kó iye owó tó wà nínú àlàkalẹ̀ pínpín lókè yìí fún àwọn adarí àkànse iṣẹ́ kọ̀ọ̀kan bó ṣe wà lákọsílẹ̀ àbá ètò ìsúná.
(ii) Kò ní sí àgbéjádé iye owó kankan nínú èyí tó ń wọlé fún ìjọba lẹ́yìn ọdún tí wọ́n darukọ nínú àlàkalẹ̀ pínpín.
(iii) Fún èrèdí ohun tó wà fún gangan gẹ́gẹ́ bí àlàkalẹ̀ [pínpín nìkan ni wọn yóò fi gbé àwọn owó kalẹ̀.
A n se akojọpọ ẹkunrẹrẹ iroyin yajoyajo lọwọ, a o maa gbe ẹkunrẹrẹ iroyin naa sori atẹ iroyin wa laipẹ. Ẹ jọwọ, ẹ tun oju opo iroyin yi yẹwo, ki ẹ lee ri ẹkunrẹrẹ iroyin ọtun laipẹ.
Ìsúná 2018: Òwó osù àwọn òsìsẹ́ ló pọ̀ jùlọ
Eto iṣuna fun ọdun 2018
Iléesẹ́ ọlọ́pàá Zambia: A rí òkú 10 àti èèyàn 7 tó farapa
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Charity Katanga sàlàyé pe àwọn ti rí òkú ènìyàn mẹ́wàá àtí àwọn méje míìràn kó farapa jáde lábé kùsà
Ó kéré tán ènìyàn mẹ́wàá ló ti pàdé ọlọ́jọ́ wọn, lẹ́yìn tí èròjà ìbúgbàmù tí wọn ń lò fún ìwakùsà tí wọn kójọ, wó lu àwọn òṣìṣẹ́ mọ́lẹ̀.
Èyí wáyé ní Kitwe, ìlú tó tóbi sìkejì ní orílẹ̀-èdè Zambia, tó tún jẹ́ olú ìlú fún ibudo ìwakùsà, gẹ́gẹ́ bí àwọn ọlọ́pàá ṣe sọ.
Charity Katanga, to jẹ́ ọgá ọlọ́pàá tó bá ilé iṣẹ́ ìròyìn AFP sọ̀rọ̀ sàlàyé pe àwọn ti rí òkú ènìyàn mẹ́wàá àtí àwọn méje míìràn kó farapa jáde lábé kùsà náà.
Ìjàmbá Ojúẹlẹ́gbá: Ọ̀pọ̀ ìgbà ni irúfẹ́ àjálù bẹ́ẹ̀ ti wáyé
Ènìyan tó lé ní ogún lo tí kú gẹ́gẹ́ bí ile iṣẹ ìròyìn Zambian Watchdog se sọ, ó tún ní ọ̀pọ̀ àwọn awakùsà ló lú àwọn ènìyàn tó gbìyànjú láti yá ìṣẹ̀lẹ̀ náà ní fọ́tọ̀
Northern Youths in Lagos: Iléeṣẹ́ ọlọ́pàá pàṣẹ fún ikọ̀ fijilańté láti wá àwọn ọ̀dọ́ àríwá tó dìhámọ́ra jáde
Oríṣun àwòrán, Others
Jinni-jinni ti da wo awọn olugbe ipinlẹ Eko bayii nitori aworan awọn ọdọ kan ẹkun ariwa ilẹ yii, ti wọn dihamọra pẹlu ibọn.
Aworan naa, to gba ori ayelujara kan, to n kọ ọpọ eeyan lominu, lo mu ki ileesẹ ọlọpaa ipinlẹ Eko kede ayẹwo ikọ naa.
Ibẹrubojo yii lo n waye lẹyin ọsẹ diẹ ti ọkunrin fi aworan soju opo ayelujara nipa awọn ọdọ ariwa Naijiria to n ya wọlu Eko, ti wọn si ni ibuba ti wsn fori pamọ si.
Ọkunrin naa ninu alaye rẹ lori ayelujara ni oun gun ọkada lọ si adugbo ELF lọna Ajah ni Lagos Island, ti awọn si pade ọdọ apa oke ọya miran marun, tawọn naa gun ọkada.
Oríṣun àwòrán, Others
O ni ọlọkada toun si apo rẹ, to si ko asọ 'vest' ti wọn kọ 'Gallante Vigilante, Makoko Division‘ si lara, eyi to n sọ pe filante adugbo makoko ni wọn.
Awọn ọdọ naa wọ asọ yii, ti ọlọkada oun si ja oun silẹ nibi toun n lọ, to si sẹri pada.
Ọkunrin naa ni ara fu oun, ti oun si mu ọkada miran lati tọpasẹ rẹ lọ sinu ile akọpati kan ti banki Zenith n kọ lọwọ ni ilegbe ELF, ti oun si ri pe awọn ọdọ lati oke ọya to wa ninu ile naa le ni aadọta.
African Eye: Ìwádìí BBC lórí ikú tó pa ọmọ ogun 26 ní Libya láti ipasẹ̀ Díróònù àìmọ̀dí
O ni oun ri Asọna abawọle ilegbe ELF naa ati ọlọkada oun akọkọ ti wọn n takurọsọ, nibẹ si ni oun ti kọkọ ya aworan ti oun ju sori ayelujara.
O dabi ẹni pe ọlọkada akọkọ naa fi iwe idanimọ kan han Asọna ọhun, ti onitọun si gba pe ko wọle sinu ọgba awọn ilegbe Elf yii.
O wa n beere pe ki lo de ti ẹnikan yoo fi wọ asọ vijilante adugbo Makoko, ti yoo si wa ni adugbo Lekki, nitori Makoko jinna si Lekki?
Bakan naa lo ni ọlọkada oun akọkọ ni ẹrọ afẹfẹ tajutaju kekere ati ọbẹ lara, nigba ti ọlọkada miran ni ibọn ilewọ.
Mistura Oseni Akintunde: Ara múmú kìí ṣe oríṣun ìfipábánilòpọ̀, ìran àwòjù ló ń fà á
O ni o da oun loju pe ipade ni awọn ọdọ apa oke ọya naa n se ninu ile akọpati naa, eyi to tumọ si pe se ni wọn fọn kaakiri ipinlẹ Eko, o si yẹ ka fura.
Ọrọ ọkunrin yii ti wa de setigbọ ileesẹ ọlọpaa ipinlẹ Eko, to si ti pasẹ fun awọn ẹsọ to n gbogun tiwa ibajẹ lati sawari awọn ọdọ naa.
Oríṣun àwòrán, @AsoRock
Ọwọ tun tẹ diẹ́ lara àwọn afurasi agbesunmọ̀mi naa ni ipinlẹ Edo, Benue ati Cross River.
Ọjọ gbogbo ni ti ole, amọ̀ ọjọ kan soso pere ni ti olohun. Bẹ́ẹ́ lọ̀rọ̀ rí fún àwọn ọmọ ẹgbẹ́ adúnkookò-mọ́ni ISIS méjì, tí ọwọ́ pálábá wọn ségi nílu Abuja.
Ìròyìn náà ní, òkété bórù mọ́ Bashiru Adams ati Rufai Sajo lọwọ̀ nigbati àwọn òsìsẹ́ àjọ ọ̀tẹlẹ̀múyẹ́ DSS gba wọn mu ni abule Kukuntu, lagbegbe Gwagwalada nilu Abuja.
Gẹgẹ bi atẹjade kan ti osisẹ́ kan fun ajọ DSS, Tony Opuiyo fisita ti wi, awọn afurasi ọhun ni wọn kẹ́ẹ́fin pe wọn ti n dete lati tun se isẹ ọwọ wọn, nifọwọ sowọpọ pẹlu ikọ agbesunmọmi Boko Haram, ti wọn si tun fẹ pa awọn alaisẹ ọmọ orilẹede yii lẹkun.
Atẹjade naa fi kun pe, ọwọ tun tẹ diẹ́ lara àwọn afurasi agbesunmọ̀mi naa ni ipinlẹ Edo, Benue ati Cross River.
Lara awọn ohun ija oloro ti wọn ri gba lọwọ awọn afurasi naa ni ibọn AK 47, ọ̀ta ibọn ibọn ilewọ atawọn eroja oloro mii loniran-nran.
Oshodi-Oke: Kò dára báwọn òsèré se ń fi dúkìá sakọ
Oríṣun àwòrán, Ronkẹ Oshodi-Oke
Ronkẹ́ Oshodi-Oke ní ohun tí kò dara, kò dára ni, bí àwọn akẹẹgbẹ́ rẹ̀ tó jẹ́ òsèré tíátà se máa ń fi dúkìá tí wọn bá sẹ̀sẹ̀ rà, bíi ilé àti mọ́tò, se bùgá lórí òpó ìkànsíra-ẹni.
Ó ní ilé làá wò, ká tó sọ ọmọ ní orúkọ̀, nítorí náà, ó yẹ káwọn òsèré náà máa kọ́kọ́ se àkíyèsí inú ilé tí wọn ti jáde wá, kí wọn tóo máa se yàǹga lórí ìtàkùn àgbáyé.
Sé wọn rí òsìsẹ́ ilé ìfowó-pamọ́ (Banker) kankan, kó máa se àfihàn mọ́tò àbí ilé wọn lórí afẹ́fẹ́?, sùgbọ́n àwọn akẹẹgbẹ́ mi yóò ra mọ́tò lásán, wọn yóò máa gbé wá sórí ayélujára, kódà, ẹnití kò tíì tó ogójì ọdún náà yóò máa polongo pé òun ń se ọ̀jọ́ ìbí ogójì ọdún. Bí wọn sì tún ra ilé náà, wọn yóò máa gbe wa sórí afẹ́fẹ́, Kín ló dé ?
"Ronkẹ Oshodi-Oke wá ń bèèrè pé kín ni wọ́n ń se èyí fún? ""Ọdúnladé Adékọ́lá ra ọkọ̀ Range Rover, kò sẹ́ni tó gbọ́ síi, nítorí pé ó gbọ́n, ó sì ní ọpọlọ ni. Bí Lámọ́ín bá ra mọ́tò, ó di orí ayélujára, bí làkásègbè bá ra ilé, ó di orí ìtàkùn àgbáyé, se orí afẹ́fẹ́ ni èèyàn ti ń se ilé ayé ni ?"""
Bẹ́ẹ̀ bá sì gbàgbé, ọ̀pọ̀ àwọn òsèré orí ìtàgé ni wọ́n fi dúkìá tí wọn sẹ̀sẹ̀ rà se yàǹnga lórí ayélujára. Lára wọn ni Mercy Aigbe tó ra ilé, tó gbe sí orí ìtàkùn àgbáyé àti Nkechi Blessing, tó sẹ̀sẹ̀ ra ọkọ̀ Toyota Venza pẹ̀lú Ọlátáyọ̀ Amọkade, tí gbogbo èèyàn mọ̀ sí Ìjẹ̀bú, tóun náà ra ọkọ̀ kan.
Oríṣun àwòrán, Ronkẹ Oshodi-Oke
Ronkẹ Oshodi-Oke wá ń bèèrè pé kín ni àwọ́n òsèré tíátà ń se èyí fún?
AFCON 2019: Nàìjírìa àti Uganda fi ijó bẹ́ẹ ni ìlú Asaba
Super eagles fi ijó bẹ́ẹ lẹ́yìn tí wọ́n ta òmì pẹ̀lú Uganda
Inu ẹni kii dun ka pa mọra.
Bẹẹ gẹgẹ lọrọ ri pẹlu ikọ Super Eagles ati Uganda lẹyin ti wọn gba ọọmi 0-0 ninu ifẹsẹwọnsẹ ọlọọrẹsọọrẹ lọjọ Iṣẹgun nilu Asaba.
Fidio ti ẹgbẹ agbabọọlu Super Eagles fi lede lori opo Twitter wọn fihan bi ẹlẹsẹ ayo, Ahmed Musa, adilemun, Ikechukwu Ezenwa ati awọn agbabọọlu miran ti kijo mọlẹ.
Oríṣun àwòrán, Facebook/Nigeria Super Eagles
Ikọ Super Eagles n yọ muda
Koda akọnimọọgba ẹgbẹ agbabọọlu Naijiria Gernot Rohr ati awọn igbakeji aarẹ ajọ to n ri si ere bọọlu ni Naijiria Shehu Dikko naa ko gbẹyin ninu ijo ọhun.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí:
AFCON 2019: Nàìjírìa àti Uganda ta òmì 0-0 ní ìlú Asaba
Ikọ Super Eagles ta omi 0-0 ninu ifẹsẹwọnsẹ ọlọrẹẹsọrẹẹ ti wọn gba lọjọ Iṣẹgun pẹlu ẹgbẹ agbabọọlu orilẹede Uganda.
Ni papa iṣere Stephen Keshi nilu Asaba ni ifẹsẹwọnsẹ naa ti waye lẹyin ọjọ mẹta ti wọn pegede lati kopa ninu idije ere bọọlu ilẹ Afirika AFCON 2019 ti yoo waye lorilẹede Cameroon.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Super Eagles ti pegede fun AFCON 2019
Akọnimọọgba ẹgbẹ agbabọọlu Naijiria Gernot Rohr lo awọn agbaọjẹ agbabọọlu bi Alex Iwobi, Ahmed Musa, Oghenekaro Etebo ninu ifẹsẹwọnsẹ naa.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí:
Ṣugbọn bi wọn ti gbiyanju to, wọn kuna lati gbayo sawọn nile Uganda.
Uganda naa ti pegede lati kopa ninu idije AFCON 2019 lẹyin ti wọn fiya jẹ Cape Verde pẹlu ami ayo kan sodo.
Super Eagles yege láti kópa nínú ìdíje AFCON 2019
Agbábọ̀ọ̀lù nígbàkan rí fun Super Eagles,Mutiu  Adepoju ti gba ikọ Super Eagles niyanju lati bẹrẹ imura ni perewu lẹyin ti wọn pegede fun AFCON 2019.
Adepoju fi ọrọ iyanju yi lede nigba ti o n ba ikọ BBC Yoruba sọrọ ni kete ti ifẹsẹwọnsẹ laarin Naijiria ati South Africa wa si opin lọjọ abamẹta.
Agbabọọlu agba ọjẹ Mutiu Adepoju ni aaya bẹ silẹ o bẹ́ sare lọrọ to de ilẹ
O ni ohun idunnu ni pe Super Eagles yoo kopa ni idije naa lẹyin ọdun maarun ti wọn kopa kẹyin sugbọn wọn ni lati san bantẹ wọn daada nitori pe ibẹrẹ ko ni oniṣẹ.
Mutiu Adepoju ni ki akọnimọọgba wọn yi ma lo awọn to kopa titi ti wọn fi pegede ṣugbọn ti o ba di dandan wọn le mu atunto ba awọn aye kan ti o ba di dandan
Ni bayi awọn ikọSuper Eagles ti n fi ijo ati ayo dupe fun aseyọri yi ninu fọnran fidio ti wọn fi sita  loju opo Twitter wọn.
Ikọ agbabọọlu Super Eagles  Naijiria pegede, wọn si  fi gbọọrọ jẹka lati kopa ninu idije AFCON 2019.
Ọmi ayo kọọkan ti wọn gba pẹlu South Africa lo mu wọn ṣe aṣeyọri yii.
'Oun tí Kunle Afolayan ṣe sí mi, mi ò lè ṣeé sí i'
Loju opo Twitter  Super Eagles, gbagada ni wọn gbe ikede ikini ku orire aseyori yi sibẹ.
Eyi ni igba akọkọ ti ẹgbẹ́ agbábọ́ọ̀lù Nàìjírìa yoo kopa ninu AFCON lati 2013 ti wọn ti kopa kẹyin.
Ni bayi, Naijiria ti ni ami ayo mẹwa, ti South Africa to ṣe ipo keji si ni ami ayo mẹsan.
Awọn mejeeji ti pegede lati kopa ninu idije AFCON lati isọri kaarun.
Oríṣun àwòrán, ng_supereagles/Instagram
Ikọ̀ Super Eagles pegedé nínú ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ wọn pẹ̀lú Libya
Saaju ni ẹlẹsẹ ayo fun ikọ Super Eagles, Ahmed Musa, ti fọwọ sọya pe Naijiria yoo na South Africa mọle ninu ifẹsẹwọnsẹ komẹsẹoyọ AFCON 2019 lọjọ Abamẹta.
Ikọ Super Eagles balẹ si ilu Johannesburg laarọ kutu ọjọ Ẹti lati ilu Asaba nipinlẹ Delta.
Ni papa iṣere Stephen Keshi to wa nilu Asaba ni ikọ naa ti ṣe igbaradi fun ọjọ mẹrin gbako ṣaaju ere bọọlu ọhun.
'Mo máa ń fi orin ìbílẹ̀ tiwa n tiwa gbá ti òkè òkun lẹ́gbẹ̀ẹ́'
Ìgbé ayé Instagram fún ọ́sẹ̀ kan
Musa ni gbogbo agbabọọlu ikọ Super Eagles lo ti wa ni igbaradi fun Bafana Bafana, bẹẹ ni awọn yoo si rẹrin ni ipari ifẹsẹwọnsẹ naa.
Ẹwẹ, South Africa na Naijiria mọle ninu ipele akọkọ ifẹsẹwọnsẹ yii, eleyi lo jẹ ki ẹlẹsẹ ayo Musa sọ pe awọn ṣetan lati gbẹsan.
Agogo mẹta ọsan lọjọ Abamẹta ni ere bọọlu ọhun yoobẹrẹ ni papa iṣere FNB nilu Johannesburg.
Rohr gb'óṣùbà káré fún Super Eagles
Akọnimọọgba ẹgbẹ agbabọọlu Naijiria Gernot Rohr ti gb'oṣuba kare fun ikọ̀ Super Eagles lẹyin ti jáwẹ olúborí ninu ifẹsẹwọnṣe wọn pẹlu Libya lọjọ Iṣẹgun.
Oríṣun àwòrán, ng_supereagles/Instagram
Ikọ̀ Super Eagles ti saaju pegedé nínú ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ wọn pẹ̀lú Libya
Ami ayo mẹta si méjì ni Naijiria fi fagba han Libya ninu ere bọọlu ti wọn yoo fi pegede fun idije ilẹ Afirika AFCON 2019.
Ẹlẹsẹ-ayo Odion Ighalo lo kọkọ gba ayo wọle fun Naijiria ki Ahmed Musa to sọ ọ di meji fun ikọ Super Eagles.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí:
Libya gbiyanju lati gba ayo meji wọle, ṣugbọn Igbalo tún gba ayo kan wọle si lati ri i pe Naijiria jawe olubori ninu ifẹsẹwọnsẹ naa.
Oríṣun àwòrán, Ighalojude/Instagram
Odion Ighalo tún fakọyọ fún Nàìjírìa
Naijiria lo n siwaju bayi ni isọri karun un fun idije ilẹ Afirika lọdun to n bọ lorilẹede Cameroon, AFCON 2019.
Ahmed Musa dábírà ní apá keji ifẹsẹ̀wọnsẹ̀ náà bí ó ṣe sọ àmi ayò méjèèjì tí Naijiria fi bori wọlé.
Ṣe ni agbabọọlù Iceland Gylfi Þór Sigurðsson tí kò bá tún fún wọn ní ayò kan pẹlu wòmí-n-gba-sí-ọ, gbáa sígbó.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ahmed Musa dábírà ní apá keji ifẹsẹ̀wọnsẹ̀ náà
Ifẹsẹ̀wọnsẹ̀ náà ló jẹ́ kó ṣeéṣe fún Naijiria láti tẹ̀síwájú nínú idíje ife ẹ̀yẹ àgbáyé ní Russia.
World Cup 2018: Àwọn ọmọ Nàíjíríà kún fáyọ̀ lóri Super Eagles
Bí ayò náà ṣe parí ni Twitter gbiná pẹ̀lú ìdùnú tí àwọn ọmọ Naijiria nilé àti lókèère fi ays wọn hàn.
Aarẹ Muhammadu Buhari ní inú òun dún gan ni.
Igbákejì Aarẹ Naijiria, Ọjọ̀gbọn Yemi Osinbajo ko gbẹ́yìn.
Àwọn ọmọ Naijiria ni ayọ̀ wọn kò lópin.
World Cup 2018: Saba sọ àsọtẹ́lẹ̀ tó ṣẹ nípa ìdíje ní Russia
Oríṣun àwòrán, @Tolusaba/Twitter
Tolulope alásọtẹ́lẹ̀
Wákàtí méjìlá kí ìfẹsẹ̀wónsẹ̀ Naijiria àti Iceland tó wáyé ni arákunrin kan, Tolulope Saba tí ó ń jẹ́ @tolusaba ní Twitter tí kọọ̀ pé Super Eagles yóò borí pẹ̀lú ayò méjì sí òdo.
Nígba tí ìfẹsẹ̀wónsẹ̀ náà parí tí ó sì rí bó ṣe sọ́ ní ó bá d'olókìkí. Ní bí ìṣẹ́jú mélòó kan tí ayò náà parí, àsọtẹ́lẹ̀ náà lórí Twitter ti ní ẹda bíi ẹgbẹ̀rún mẹ́sàń.
Ìyàlẹ́nu ló jẹ́ fún àwọn tó rí àsọtẹ́lẹ̀ náà.
Àwọn kan tó fèsì sí àsọtẹ́lẹ̀ náà tilẹ̀ ní kó padà sùn kó wá fún àwọn ní nọmba tí àwọm fi lè ta tẹ́tẹ́ kí wọ́n sì jẹ.
Tolulope ni oríṣiríṣi ibéérè tí ọmọ Naijiria ń bééè látàrí àsọtélẹ̀ náà tí wá peléke báyìí.
Àjọ̀dún APC lónìí, E wo ẹnu ilẹ̀, ẹ wo ẹnu ọkọ́ ni báyìí
Oríṣun àwòrán, @gloria-adagbon
Gbogbo ètò ń tò fún àjọ APC loni nilu Abuja
Ẹgbẹ́ òṣèlú APC tó ń tukọ̀ Nàìjíríà báyìí fẹ́ yan àwọn olóyè míràn.
Àwọn igba din lẹgbẹrun meje aṣoju ọmọ ẹgbẹ́ òṣèlú All Progressives Congress kaakiri Naijiria ni wọn yoo dibo loni.
Ọpọlọpọ ọmọ ẹgbẹ lati ipinlẹ mẹrindinlogoji Naijiria ni wọn ti jade lati dije du ipo mejilelogoji to ṣi silẹ loriṣirisi.
Ipo fún ogun eniyan ni wọn ko ni alatako rara nigba ti wọn yoo yan ẹni to wu wọn si awon ipo to ku.
Eto idibo naa yẹ ko waye loni lasiko ajọdun ẹgbẹ oṣelu APC nilu Abuja ni eyi ti o han pe gbogbo eto ti to ko le bẹrẹ lasiko.
Lori lẹta Obasanjọ
O ti hande pe Adams Oshiomole lati ipinlẹ Edo ni yoo rọpo John Oyegun gẹgẹ bii alaga gbogboogbo.
Ìran ni ounjẹ ojú lonii, ki a maa wo ibi ti adé idibo àwọn ipò to ṣi silẹ fún idibo naa yoo ṣi si.
Kola Ologbodiyan: Jẹgudu jẹra ni ijọba APC
SARS ti bẹ̀rẹ̀ ìgbésẹ̀ láti yọ àwọn ọ̀bàyéjẹ́ kúro
Onímọ̀ ọrọ̀ ajé: Àfíkún ìsúná táwọn asòfin se b‘ófin mu
Ilé ìwòsàn- Ololufẹ́ nọ́ọ́sì ni dókítà tó lùú kí tírélà tó yà wọn
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Dokita to lu Nọọsi nile iwosan, o lagbara ni
Èti tó bá gbọ́ àlọ di dandan kò gbọ́ àbọ̀, ọ̀rọ̀ àwọn mejeeji kọja bẹ́ẹ̀.
Ilé ìwòsàn ìgbẹ̀bí kan ní Awóyaya (Awoyaya Hospital and Merternity Centre) tó wà ní Ibeju Lekki ni Ìpinlẹ Eko sọ pé olólùfẹ́ ni dókítà tó lu nọ́ọ́sì kan bolẹ̀ jẹ́ sí arábìnrin náà.
Nọ́ọ́sì náà Dorcas Adeyẹra fẹsun kan Dokita Okolo Emmanuel pé ó fi ìbínú wọ òun wọ inú ọ́fíísì rẹ̀, tó sì tún gbá òun létí nígbà tí òun kọ̀ láti kúnlẹ̀ gẹ́gẹ́ bó ṣe pàṣẹ.
Àwọn aláṣẹ ilé ìwòsàn náà sọ fún ìwé ìròyìn Punch wípé àwọn ti kọ lẹ́tà wá-wí-tẹnu-rẹ sí àwọn méjééjì , ṣùgbọ́n wọ́n kọ́ láti lọ gba lẹ́tà náà.
À gbọ́ pé ilé ìwòsàn nàá ṣe ìwádìí tiwọn lẹ́yìn tí Adeyera lọ fi ọ̀rọ̀ náà lọ àwọn ọlọ́pàá.
Ẹ ó rántí pe agbẹnusọ àjọ ọlọ́pàá Ipinlẹ Eko, Chike Oti ṣalaye fun BBC Yoruba lánàá pe, iwadii awọn ọlọpaa n lọ lọwọ lori iṣẹlẹ naa.
APC Convention: Àwọn èèkàn ẹgbẹ́ kò gbẹ́yìn níbẹ̀
Ààrẹ Muhammadu Buhari àti igbákejì rẹ̀ ọjọ̀gbọ́n Yemi Osinbajo balẹ̀ sí gbọ̀gàn Eagle Square fún ìpàdé Ẹgbẹ́ All Progressives Congress (APC) .
Oríṣun àwòrán, APC/tritter
Ààrẹ Buhari àti igabkeji rẹ̀ níbi ìpade ẹgbk òṣelú APC
Aarẹ ile asofin apapọ, Bukọla Saraki naa ko gbẹyin nibi ipade apapọ ẹgbẹ oselu APC.
Oni nkan laa jẹ ko see. Alaga apapọ tuntun fẹgbẹ oselu APC, Adams Oshiomọlẹ ati Iyawo rẹ, Lara, ree nibi ipade apapọ APC, to ti wọle bii alaga tuntun.
Gomina ipinlẹ Kwara, Abdulfatai Hammed naa wa lara awọn eekan ilu to yọju sibi ipade apapọ APC naa.
Oríṣun àwòrán, APC/twitter
Gonina ìpínlẹ̀ Kwara Abdulfatah Ahmed lásìkò ìforúkaọsílẹ̀
Ankara yẹbẹ-yẹbẹ ni, nibi ti awọn asoju ipinlẹ Abia joko si.
Àwọn asoju lati ipinlẹ Jigawa se bẹbẹ, koda wọn duro re o
Àwọn asoju lati ipinlẹ Kano gan se bẹbẹ lọhun.
Awọn asoju lati ipinlẹ Ọsun ree o, oju wọn gun rege, ankara wọn to jẹ asọ ẹgbẹjọda gan fa ni mọra.
Awọn eeyan wa lati ipinlẹ Ondo naa ni awọn wa o, Gomina Rotimi Akeredolu ree, to nki awọn eeyan.
N se ni asia ami idamọ̀ ẹgbẹ oselu APC n fẹ lẹlẹ lasiko ipade apapọ ẹgbẹ oselu naa.
Hajia Salamatu to ń dupò olorí obinrin fún ẹgbẹ́ ti yẹ̀ba fun akẹgbẹ́ rẹ̀, Ramatu Tijani Aliyu, bákan náà ló jẹ́jẹ̀ẹ́ ìfọwọ́sowọ́pọ̀ pẹ̀lú rẹ̀.
Oríṣun àwòrán, APc twitter
Awọn asojú ìpínlẹ̀ kọ̀ọ̀kan níbi ìpàde APC
Gbogbo àwọn èèkan nínú ẹgbẹ́ òṣèlú APC ló péju níbi ìpàdé ìdìbò yan olóyè ẹgbẹ́ tuntun, to fi mọ Bọla Tinubu ati Yakubu Dogara.
Oríṣun àwòrán, APC/ twitter
Gbogbo àwọn èèkan nínú ẹgbẹ́ òṣèlú APC ló péju níbi ìpàdé ìdìbò yan olóyè ẹgbẹ́ tuntun
Ẹsẹ ko gbero ni ilu Abuja nitori iupade apapọ ẹgbẹ oselu APC.
Oríṣun àwòrán, APC/twitter
Ohun gbogbo ló ń lọ létòletò níbi ètò ìdìbò tó ń lọ L'abuja
APC: Gbogbo ìpínẹ̀ lẹ́tọ lati yan àsoju lọ́nà to wù wọn
Oríṣun àwòrán, APC/twitter
APC: Gbogbo ìpínẹ̀ lẹ́tọ lati yan àsoju lọ́nà to wù wọn
Ẹgbẹ́ òṣèlú All Progressives Congress (APC) nínú àbájáde ìpàdé tó wáyé lónìí tí ni àwọn o ní fá ori apá kan dá pakan sí  láti yan àsọju ẹgbẹ́ òṣèlú náà fún ààrẹ níbi ìdìbò gbogboogbo ọdun 2019.
Nínú ìpàdé àpérò ti wọn ṣe lọ́nìí ni wọn ti sàlàyé pé gbogbo ọmọ ẹgbk ni yóò ní ànfàní láti yan ẹni tó bá wù wọn pẹ̀lú ìdìbò ti yóò fààyè gba gbogbo ọmọ ẹgbẹ́, nígbà ti àwọn ìpínlẹ̀ yóò yan ọ̀nà tó ba wù wọn láti yan ẹni ti wọn ń fẹ́
Oríṣun àwòrán, APC/twitter
APC: Gbogbo ìpínẹ̀ lẹ́tọ lati yan àsoju lọ́nà to wù wọn
Wọn fi kún-ún pé ]ipínlẹ̀ to bá pinu lati tọ ìlana ti ile ẹgbẹ ti gbogboogbo lò yóò nílati kọ̀wé ráńṣẹ́ àkọwé ẹgbk àpapọ̀.
APC Convention: Adams Oshiomole, di alága àpapọ̀ láì látakò
Oríṣun àwòrán, APc/twitter
Adam Oshiolmolẹ̀ ló jáwé olúborí
Ẹgbẹ oṣelu APC ti kede Adams Aliyu Oshiomole gẹgẹ bii alaga tuntun fun ẹgbẹ oṣelu naa.
Níbi ìpàdé ìdìbò ẹgbẹ́ òṣèlú APC tó ń lọ lọ́wọ́ nílu Abuja ni wọn ti kede Adams Aliyu Oshiomole gẹgẹ bii alaga tuntun fun ẹgbẹ oṣelu ọhun.
Oshiomole, ti o ti figba kan ri jẹ aarẹ ẹgbẹ oṣiṣẹ NLC ati gomina ipinlẹ Edo fun ọdun mẹjọ, lo n bọ si ipo alaga ẹgbẹ oṣelu APC lẹyin ti gbogbo awọn to kọkọ ti fi ifẹ han lati dije fun ipo naa ju awa silẹ pe, awọn ko ṣe mọ.
Ẹgbẹ oṣelu APC kede alaga apapọ wọn, lẹyin ti wọn ti ṣe idibo 'ẹ gbohun soke fun ẹni ti ẹ fẹ' laarin awọn ọmọ ẹgbẹ oṣelu naa.
Ipo mejidinlogun miran ti ko si alatako fun, ni wọn tun kede lọjọ abamẹta.
Oríṣun àwòrán, APc/twitter
Adam Oshiolmolẹ̀ ló jáwé olúborí
Kọlawọle Oluwajana, lati ìpínlẹ̀ Ondo, ni alaga fun ẹkun iwọ-oorun guusu orilẹede yii ninu ẹgbẹ oselu APC.
Lara awọn to kọkọ fi ifẹ han si ati dije ipo naa, lo gbégbá olokè nitori kò sé sí olùdíje míìràn tó ń báa dupo,
Ọjọgbọn Osunbor ati alaga to n fipo silẹ John Oyegun, sì ni wọn ti fi ìfẹ́ hàn sááju sí ipò nàá àmọ́ wọn yẹ́bá lẹ́yìn-ò-rẹyìn.
Tí ẹ ò bá gbàgbé, APC tí pín ipò alága ẹgbẹ́ fẹ́kùn ààrin gbùn-gbùn Gúúsù orílẹ̀èdè yìí, tí Oshiomolè sì dìde láì ni alátakò
Zimbabwe àti Ethopia: Adó olóró méjì ní gbàngàn ìpolongo
Ààrẹ orílẹ̀-èdè Zimbabwe ní bi ìpolongo ìbò
Ori lo ko Ààrẹ orilẹ́-èdè Zimbabwe, Emmerson Mnangagwa yọ lónìí lọ́wọ́ àdó olóró tó bú ní gbàngàn ìpolongo ìdìbò ẹgbẹ́ oṣelu Zanu PF sájúu ìdìbò gbogbogbò tí yóò wáyé ní òpin osù yìí.
Ìṣẹ̀lẹ̀ ọ̀hún tó wáyé ní pápá ìṣeré white city ní ilú Bulawayo jọ bí  ẹni pé wọn dojú rẹ̀ kọ ààrẹ gan ni sugbọn ori kò padà lẹ́yìn rẹ̀, nítorí kété tí Mnangagwa bá àwọn olólùfẹ́ rẹ̀ sọ̀rọ̀ tan ni àdó olóró náà dáhùn.
Bi ó tilẹ jẹ́ pé ààrẹ kò farapa rárá gẹ́gẹ́ bí ile iṣẹ́ móhùmáwòran orilẹede náà ṣe sọ, sùgbọ́n ọ̀rọ̀ ò rí bẹ́ẹ̀ fún àgbákejì ààrẹ Kembo Mohadi àtí ìyàwó igbákejì ààrẹ àkọ́kọ́ Constantino Chiwenga bí o ṣe fí ara pa yánayàna
Mnangagwa gorí oyè nínú oṣù kọkànlá ọdún to kọja lẹ́yìn tí wọ́n lé Robert Mugabe kúrò ní ìjọba.
Ẹ̀wẹ̀, lórilẹ̀-èdè Ethopia bákan náà, atúlúto tuntun tó jẹ́ olóòtú ìjọba Abiy Ahmed ku díẹ̀ kó fara káásá níbi adó olóró tú dún níbí ìwóde tó wáyé ní Meskel Square nílu Addis Ababa tí ènìyàn kan pàdánù ẹ̀mi rẹ̀ súgbọ́n tí ọ̀pọ̀lọpọ̀ farapa tí o fí mọ́ àwọm mẹ́wàá kan ti wọn ò jẹ́ ará ayé tí wọn ò sì jẹ́ èrò ọ̀run.
Oríṣun àwòrán, Fitsum Arega/twitter
Awọn olólùfẹ́ olóòtú ìjọba Abiy Ahmed lásìkò tí tó ń báwọn sọ̀rọ̀
Kété ti Abiy parí ọ̀rọ̀ ìṣítí rẹ̀ níbi ti ogúnlọ́gọ̀ àwọn ènìyàn tí péjọ sí ní wọn ju àdó olóró náà sí apá ibití èrò pọ̀ sí lórí ìtàgé ní wọn sáré gbe olóòtú ìjọba sá lọ.
Lẹ̀yìn iṣẹ̀lẹ̀ òhún ní olóòtú ìjọba Abiy sọ̀rọ̀ lórí móhùnmáwòrán pé ọ̀pọ̀lọpọ̀ ènìyàn ló kú, sùgbọ́n lẹ́yìn náà ní mínísítà fún ètò ìlera ní ènìyàn kan péré ló bá ìṣẹ̀lẹ̀ náà rin, ènìyàn métàlééládọ́ọ́jọ ló farapa tí ènìyàn mẹ́wàá sì wà ní ipò tó bani lẹ́rù.
PDP: kò sí àpẹẹrẹ ìṣèjọba àwa-ara-wa ninu ìdìbo APC
Oríṣun àwòrán, APC/twitter
Àwọn ọ̀dọ́ APC rọọ́ lati máa fárí apákan dá apá kan síAdams Oshiomole
Ẹgbẹ́ òṣèlú People's Democratic Peolpe (PDP) ní ìbànújẹ́ ló jẹ́ láti rí bí àwọn olùkópa dupò níbi ìpádé APC se ń jáde pé àwọn juwọ́ sílẹ̀ fún elòmíran.
PDP sọ èyí dí mímọ̀ lọ́rí àtẹ̀jíṣẹ́ twitter rẹ̀ pé ẹgbẹ́ òṣèlú APC kò fààyè gbá ìjọba àwa-ara-wa.
Kíní àwọn ọmọ Nàìjíríà ń sọ lóri ọ̀rọ̀ tí PDP sọ yìí lórí twitter
Wọn ní ohun tó ṣelẹ̀ sàfihan bí àwọn ọmọ ẹgbẹ́ ṣ ń gbé nínú ibẹ̀rù bojo.
Ẹ̀wẹ̀ àwọn ọ̀dọ́ ẹgbẹ́ oṣèlú All Progressives Congress (APC) tí kí alága tuntun fún ẹgbẹ́ Adams Aliyu Oshiomole kú oríre ìyàn sípò rẹ̀.
Àwọn  ọ̀dọ́ APC ọ̀hún sọ ọ̀rọ̀ náà dí mímọ̀ nínú àtẹ̀jáde kan láti ọwọ́ akowe rẹ̀ Collins Edwin, pé o se pàtàkì láti ríi dájú pé kò fí ara rẹ̀ ji fún àwọn ẹgbẹ́ alátakò.
APC Convention: Àwọn aṣojú láti Warri yọ igi sí ara wọn
Gẹ́gẹ́ bí wọn ṣe sọ ìpèníjà ọjọ́ iwájú kò ní onka nítorí náà kí alága kó gbogbo ọmọ ẹgbẹ́ mọ́ra fún ànàfáni ìdìbò gbogboogbò tó ń bọ̀ lọ́dun 2019.
APC: Convention: Ọ̀wàrà òjò balẹ̀ ní gbàgede Eagles Square
Ọwara ojo to bẹ silẹ nilu Abuja sé ọpọ awọn olugbe ilu naa mọle
Ọwara ojo to bọ lulẹ lowurọ ọjọ Abamẹta lo ni kò tíì jẹ́ ki ìpade idibo apapọ ẹgbẹ oṣelu APC nilu Abuja bẹ̀rẹ̀.
Ipade idibo apapọ ẹgbẹ oṣelu naa ti wọn fi si agogo mẹwa owurọ ni ko tii bẹrẹ titi di asiko ti a fi n ko iroyin yii jọ.
Ọwara ojo to bẹ silẹ nilu Abuja se ọpọ awọn olugbe ilu naa mọle.
Awọn aṣoju lati gbogbo ipinlẹ mẹrindinlogoji orilẹ-ede Naijiria ati olu ilu rẹ nilu Abuja ni yoo kopa nibi ipade apapọ naa
Amọṣa, ẹgbẹrun meje o din igba aṣoju ni yoo kopa ninu ipade apapọ naa nibi ti wọn yoo ti dibo yan awọn adari ẹgbẹ oṣelu naa fun sdun mẹrin miran.
Lara awọn eekan to ti gunlẹ si gbagede Eagles square nibi ti ipade naa yoo ti waye ni gomina Yahaya Bello ti ipinlẹ Gomina, minisita fọrọ abẹle, Abdulrahman Dambazau pẹlu Gomina ana nipinlẹ Sokoto, Aliyu Wamako.
Awọn aṣoju lati gbogbo ipinlẹ mẹrindinlogoji orilẹede Naijiria ati olu ilu rẹ nilu Abuja ni yoo kopa nibi ipade apapọ naa.
SARS ti bẹ̀rẹ̀ ìgbésẹ̀ láti yọ àwọn ọ̀bàyéjẹ́ kúro
Ìyìn, ati ìmọ̀ràn fún Super Eagles
Ìpàdé àpapọ̀ APC: 5000 ọlọ́pàà wà níkàlẹ̀ fún ààbò
Ẹgbẹrun marun ọlọpaa ni yoo mojuto eto abo nibi ipade apapọ ẹgbẹ oṣelu APC ti o n waye lọjọ abamẹta nilu Abuja.
Bakanna ni awọn alaṣẹ ileeṣẹ ọlọpaa tun  ṣalaye pe baluu kekeeke meji pẹlu ọkọ ayẹta mẹfa lo wa nikalẹ lati da awọn to ba fẹ dómi alaafia ru nibẹ lọwọ kọ.
Oríṣun àwòrán, #APCNationalConvention
Ẹgbẹ oṣelu APC n yan awọn adari rẹ fun ọdun mẹrin miran
Awọn ikọ ọlọpaa kogberegbe PMF, ikọ agbogun ti iwa igbesunmọmi, CTU atawọn ikọ akọṣẹmọṣẹ nipa ado oloro, EOD ati bẹẹbẹ lọ.
Ni bayii, ẹgbẹ oṣelu PDP ti fi ẹsun kan APC pe owo ilu ti wọn ji ko ni wọn fi ṣeto ipade awọn wọn.
Alukoro fun ẹgbẹ oṣelu PDP, Kola Ologbondiyan salaye ninu atẹjade kan pe ipolongo iwa aiṣootọ ati iwa ijẹkujẹ ni APC n fi ipade apapọ wọn ṣe.
Oshiomole: Asaajú, àtẹ̀lé yẹ kó fìmọ̀ sọ̀kan nínú APC
Oríṣun àwòrán, Jubril A. Gawat
Ọpọ onwoye gbagbọ pe omi n bẹ lamu fun Oshiomole lori iṣọkan ẹgbẹ oṣelu naa
Alaga tuntun fun ẹgbẹ oṣelu APC, Adams Oshiomhole, ti kede pe aisi ifẹnuko to kuna laarin awọn adari ẹgbẹ ati awọn ọmọ ẹgbẹ lo n da wahala silẹ lẹgbẹ oṣelu naa.
Adams Oshiomole ni, oun yoo rii daju pe eto oṣelu tiwantiwa fẹsẹ rinlẹ laarin ẹgbẹ oṣelu naa, eleyii ti yoo fun awọn ọmọ ẹgbẹ lẹnu ọrọ ninu bi nnkan ṣe n lọ si laarin ẹgbẹ oṣelu naa.
Ninu ọrọ to ba awọn akọ̀royin sọ nibi ipade apapọ ẹgbẹ oṣelu APC to n lọ l'Abuja, lẹyin ti wọn ti kede rẹ gẹgẹ bii alaga tuntun fẹgbẹ oṣelu naa, Adams Oshiomole ni, nibi ti ọrọ de duro bayii laarin ẹgbẹ oṣelu  APC, ati adari, ati ọmọlẹyin lo gbọdọ lẹnu lori bi idagbasoke yoo ṣe de ba ẹgbẹ oṣelu naa.
Oríṣun àwòrán, Jubril A. Gawat
Oshiomole ni akọkọ ojuṣe oun ni lati pari aawọ lẹkajẹka ẹgbẹ oṣelu naa
Lori dukuu to n waye lawọn ipinlẹ kan ninu ẹgbẹ oṣelu naa, Oshiomole ni, igbagbọ oun ni pe bi ọpọlọpọ awọn ọmọ ẹgbẹ ṣe gbimọ pọ̀ gbe oun wọle, n fun oun ni idaniloju pe afẹfẹ ifẹ yii ni oun yoo gun lati fi wa ojuutu si awọn aawọ naa.
Bakan naa lo tun ni awọn aṣiwaju feto oṣelu ati eto karakata lagbo ẹgbẹ oṣelu APC , yẹ ko jumọ joko pọ lati gbe ilana ọtun kalẹ, eleyii ti yoo ṣe akawe ohun gan to n damu orilẹede yii to bẹẹ gẹẹ, ti awọn ọmọ Naijiria ko ni lee maa fi oju idẹyẹsi ẹsin, ẹya tabi ipo lawujọ, wo ara wọn mọ.
APC Convention: Buhari dúpẹ́ fún ìpàdé àpapọ̀ ẹgbẹ́ náà
Buhari ki awọn asoju to moke nibi ipade abẹle ẹgbẹ APC lati awọn wọọdu ati ipinlẹ ku oriire
Aarẹ Muhammadu Buhari, ninu ọrọ apilẹkọ to ka nibi ipade apapọ ẹgbẹ oselu rẹ, All Progressive Congress, APC, dupẹ pupọ lọwọ awọn ọmọ ẹgbẹ oselu naa fun aseyọri ipade apapọ fẹgbẹ oselu ọhun, eyi tii se akọkọ iru rẹ lẹyin idibo ọdun 2015.
Buhari tun wa ki awọn asoju to moke nibi ipade abẹle ẹgbẹ APC lati awọn wọọdu ati ipinlẹ ku oriire, ti wọn wa sibi ipade apapọ naa lati yan awọn oloye apapọ ẹgbẹ tuntun.
Bakan naa lo tun ki awọn olori ẹgbẹ tẹlẹ fun akitiyan wọn lati ri daju pe ẹgbẹ oselu APC moke ninu eto idibo to kọja naa.
Buhari wa rọ awọn ọmọ ẹ́gbẹ to n fapa janu lati tubọ nigbagbọ ninu ẹgbẹ oselu naa.
Mo fẹ fi da gbogbo yin loju pe lai naani awọn awuye-wuye kọọkan to suyọ lasiko eto idibo abẹ́nu lawọn wọọdu ati ipinlẹ, sibẹ́, ẹ́gbẹ oselu naa yoo tubọ maa ni okun si ni.
O wa rọ awọn ọmọ ẹ́gbẹ to n fapa janu lati tubọ nigbagbọ ninu ẹgbẹ oselu naa.
Ethiopia: Bíi ti Zimbabwe, àdó olóró mìíràn bú ní Ethiopia
Ikọ̀ BBC tó wà ní'bi ìwọ́de naa rí bó ṣe ṣẹlẹ̀
Àwọn alaṣẹ orilẹede Ethiopia ni eniyan meji ni o ku ti awọn ogunlọgọ si f'ara pa lẹyin ti ado oloro kan bu gbamu nibi iwọde fun olori orilẹede naa tuntun, Abiy Ahmed.
Abiy ṣẹṣẹ ba awọn ero sọrọ tan nibi iwọde naa, ni ado oloro ọhun dun. O ṣe apejuwe iṣẹlẹ naa bii iṣe ọwọ awọn ti ko fẹ ki Ethiopa ṣ'ọkan.
Wọn tete gbe e sa lọ lẹyin ti eniyan kan ju ado oloro naa si aarin awọn ẹgbẹgbẹrun awọn oluwọde to wa ni orita Meskel to wa ni olu ilu orilẹede Ethiopa, Addis Ababa.
Oríṣun àwòrán, Reuters
Olori orilẹede naa tuntun, Abiy Ahmed ṣẹṣẹ ba awọn ero sọrọ tan nibi iwọde naa, ni ado oloro naa dun
Ko ju bii wakati melo kan lọ ti ori ko aarẹ orilẹede Zimbabwe Emmerson Mnangagwa yọ lọwọ ado oloro ti ti Ethiopa naa ṣẹlẹ.
Ni kete ti iṣẹlẹ naa waye ni wọn fi olori ile iṣẹ olopa ti Addis Ababa si atimọle pe ko ṣe iṣẹ rẹ to.
Wọn tilẹ tun fi ọlọpàá mẹjọ si atimọle pẹlu rẹ. Wọn ni wọn o yẹ ki wọn ṣọ ibi iwọde naa daadaa.
Oríṣun àwòrán, Reuters
Egbẹgbẹrun lo lọ ibi iwode naa fun Abiy
Minisita fun Eto Ilera ni Ethiopia sọ pe eniya bii mẹrinlelogoji ni o wa ni ile iwosan bayi ti eniyan marun si wa ni ẹsẹ-kan-aye-ẹsẹ-kan-orun.
Abiy di olori orilẹede naa lẹyin ti olori ti tẹlẹ Hailemariam Desalegn, kọ'we f'iṣe silẹ ni oṣu keji ọdun yii.
'Ẹlẹ́dẹ̀ wa ti tó kó jáde síta'
CPC: Irẹsì oloro ti wọ́pọ̀ ní àwọn ṣọ́ọ́bù Akwa Ibom
Oríṣun àwòrán, CPC
Irukera n wo irẹ̀sì ti wọ́n sá s'òòrùn
Awọn ikọ ajọ to n ri si ẹtọ àwọn onibàára ni orilẹede Naijiria (CPC) pẹlu iranlọwọ ajọ aṣọbode, ati awọn ọlọpàá ti ya bo awọn ṣọ́ọ́bù kan ni Uyo, olu ilu Ipinlẹ Akwa Ibom, ni bi ti wọn ti ja awọn irẹsi oloro kan gba.
Olori ajọ CPC, Babatunde Irukera ni o sáájú ikọ to lọ Uyo, ni bi ti wọn ti ri bi wọn ṣe n ta àwọn irẹsi naa.
Irukeruka ni awọn ri irẹsi oriṣiriṣi ti o n rùn, ti wọn tun fọ̀ lẹ́yin eyi ti wọn wa sa wọn sinu òòrun nibi ti eku ti n yagbẹ sori rẹ. O ni lẹyin ti wọn ba sa irẹsi naa tan ni wọn yoo wa ko pada sinu apo, ti wọn yoo si wa taa fun awọn ara ilu.
Oríṣun àwòrán, CPCNig/Twitter
Ọ̀ga CPC Babatunde Irukera ni o sáájú ikọ to lọ Uyo
Irukera ni bo ti lẹ jẹ pe awọn irẹsi naa ko dara, ti wọn ba ti fọ̀ọ́ tan, ṣe ni awọn onibara yoo ro pe irẹsi daradara ni.
O tun sọ pe nigba ti awọn wo awọn iresi ti wọn ti di sinu apo lati ta, ṣe ni wọn ri pe irẹsi alawọ̀ oriṣiriṣi lo wa ninu wọn, eyi to fi han pe, oniruuru irẹsi ni wọn n da pọ soju kan.
Olori ajọ CPC naa ni oun ti oju wọn ri ni awọn ṣọ́ọ́bù Uyo ba'ni l'ẹru jọjọ.
Oríṣun àwòrán, CPCNig/Twitter
Irukera n wo irẹ̀sì ti wọ́n sá s'òòrùn
Ẹ ó ranti pe ni ọjọ́ Ajé tó kọjá ni Mínísítà fún Ètò Ọ̀gbin, Audu Ogbeh ké gbàjarè pé orílẹ̀èdè kan ń pèsè ìrẹsì olóró.
Ijọba Apapọ sọ ni igba naa pe awọn yoo ti ibode orilẹede Naijiria pẹlu orilẹede naa lati dẹkun kiko irẹsi oloro naa wọle lati ibẹ.
Ṣugbọn bawo ni irẹsi buruku wọnyii ṣe wọ Naijiria ti o si di tita lori igba?
Olori ajọ CPC ni, o dabi ẹni pe awọn kan ko ṣiṣẹ wọn to ni o.
Plateau: Ẹ̀mí 86 ṣ'òfò ni ìkọlù tuntun
Oríṣun àwòrán, Chuwang Dalyop
Ọ̀pọ̀ ẹ̀mí sòfò ní ìpínlẹ̀ Plateau
Eniyan bii aadọrin ni àwọn alaṣẹ Ipinlẹ̀ Plateau sọ pe wọn ti ku ninu ikọlu awọn darandaran ati awọn agbẹ ni agbegbe Gashish ati Ropp ni Ipinlẹ Plateau.
Ṣugbọn awọn ile iṣẹ iroyin kan ni àwọn to ku to igba eeyan.
Iroyin to n tẹ̀ wa lọwọ fi han pe Ọjọbọ ni ija naa bẹrẹ nibi ti ikọlu kan ti gbẹ̀mi darandaran marun. Sugbọn nigba ti awọn darandaran naa lọ ṣi'gun pada wa ni ọjọ Abamẹta, oku sun lọ ni.
Ijọba Ipinlẹ Plateau ti f'ofin gbele-ẹ lọ́lẹ̀ ni àwọn agbegbe ti ikọlu náà ti waye.
Àgbegbe to yi ibi ikọlu naa po bii Barkin Ladi ti n gbona fun bii ọdun mẹwaa bayii nitori ija laarin awọn agbẹ ati darandaran.
Bii oṣu kẹrin ọdun yii ni ija tun bẹ lẹ l'akọtun.
Ìpànìyàn Plateau: Buhari, Lalong gbanájẹ lórí wàhàlà tó mú ẹ̀mí 86 lọ
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Atẹjade kan latọdọ awọn ọlọpa nipinlẹ naa ni eeyan mẹrindinlaadọrun lo ku ninu iṣẹlẹ Plateau
Aarẹ Muhammadu Buhari ti sọ pe ibanujẹ nlanla ni ikọlu to waye lawọn ileto kan nipinlẹ  Plateau.
Aarẹ Buhari ni o di dandan ki awọn to wa nidi ikọlu naa o jẹ iyan wọn niṣu.
Ni Ọjọ Aiku ni okiki kan pe awọn ija laarin awọn darandaran ati agbẹ ti ran ọpọ eeyan lọ sọrun.
Atẹjade kan latọdọ awọn ọlọpa nipinlẹ naa ni eeyan mẹrindinlaadọrun lo ku ninu iṣẹlẹ naa.
Oríṣun àwòrán, @SimonLalong
Iléeṣẹ́ ọlọ́pàá ní ọ̀pọ̀ dúkìá bíi alùpùpù, ilé àti ọkọ̀ ló parẹ́ sínú ìjà náà
Bakan naa ni wọn tun ṣalaye pe eeyan mẹfa farapa, wọn dana sun aadọta ile, alupupu marundinlogun ati ọkọ meji ninu ikọlu naa.
Aarẹ Buhari ni gba-gba-gba bayii nijọba apapọ duro ti ijọba ati awọn eeyan ipinlẹ naa ninu irora wọn.
Ibanujẹ ọkan nla ni adanu ẹmi ati dukia to waye ninu ikọlu ipinlẹ Plateau.
SARS ti bẹ̀rẹ̀ ìgbésẹ̀ láti yọ àwọn ọ̀bàyéjẹ́ kúro
"Mo ba awọn eeyan ileto ti ọrọ kan kẹdun, mo si n fi da wọn loju pe mi o ni sun, mi o si ni wo titi ti awọn apaniyan ati amokunṣika ẹda to wa nidi rẹ yoo fi fi im u ko ata ofin."""
Bakan naa, Gomina Simon Bako Lalong ti kede ofin konile o gbele alaago mẹfa irọlẹ si agogo mẹfa idaji lati yanju wahala miran to lee fẹ ṣẹyọ lori ikọlu naa.
Gomina Lalong ni ijọba ipinlẹ Plateau atawọn agbofinro n ṣiṣẹ laisinmi ati lai kaarẹ lati rii pe gbogbo awọn ti wọn wa nidi wahala naa ni wọn yọ sita bi ẹni yọ jiga.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Awọn ile iṣẹ iroyin kan ni àwọn to ku to igba ènìyàn
Igbesẹ ti bẹrẹ lori wiwa ọna ati daabo bo awọn ileto ti ọrọ kan. Ofin Konile o gble naa yoo wa ni ijọba ibilẹ gusu Jos, Riyom ati barkin ladi titi di igba ti a ba kede pe ko duro.
Ileeṣẹ ọlọpaa ni awọn ti gbe oku awọn to ku fun awọn ẹbi wọn lati ṣeto ikẹyin to tọ fun wọn.
Ikọlu laarin awọn darandaran ati agbẹ olohun ọsin nipinlẹ Plateau atawọn ipinlẹ kan lagbegbe aringbungbun ariwa ati ila oorun ariwa orilẹede Naijiria ti n di lemọlemọ ti ọpọlọpọ ẹmi si ti baa lọ.
Ikú ọmọ Dbanj: Ohun ti awọn òṣeré n sọ
Oríṣun àwòrán, @iambangalee
Oṣù tó kọjá ní Daniel pé ọmọ ọdún kàn
Ọ̀fọ̀ ti ṣẹ̀ ní ìdílé gbajúgbajà akọrin tàkasúfèé ọmọ orílèèdè Nàìjíríà, Daniel Oyebanjo tí gbogbo ènìyàn mọ̀ sí Dbanj.
Dbanj, pàdánù ọmọ rẹ tí orúkọ rẹ n jẹ Daniel ẹni tó pé ọmọ ọdún kan láìpẹ́ yìí.
Oríṣun àwòrán, Instagram/iambangalee
Oṣù tó kọjá ní Daniel pé ọmọ ọdún kàn
A gbọ́ pé inú adágún omi ti won se lọ́jò sínú ilé wọn ni ọmọ náà já sí ti ó sí kù sí inú rẹ̀.
Ìròyìn ikú ọmọ Dbanj jẹ́ nnkan tí o kò òpó ọmọ orílèèdè Nàìjíríà nínú.
Ikú, bo je t'ọmọdé tàbí àgbà jẹ nnkan tí ó máa ń ba ni nínú jẹ.
Kété ti ìròyìn jáde ní àwọn èèyàn tí n ki Oladapo Daniel Oyebanjo ku ara feraku ọmọ rẹ.
Ruggedy Baba to je ilumoka olorin takasufe wa lara awọn to fi ikini ransẹ.
Banky W naa sọ pe iroyin ọ̀hún fọwọ ba oun lẹmi tohun ti iroyin isẹlẹ ipaniyan to waye ni ipinlẹ Plateau
Olamide ati Davido ko gbẹyin
Ajé kò gbà, ẹ rìn síwájú
Awọn ololufe Dbanj ti n bá a kẹ́dùn láwọn ojú òpó ayélujára tó ní.
Wọn ti gbé òkú ọmọ náà lọ sì ilé ìgbókùúsí kan tó wà ni GRA Ikeja nílu Èkó.
Dbanj wa ni orileede Amerika nibi ayeye idanilola BET.
Banky W: ojoojúmọ́ ayé mi ni mo ti fi lá àlá kó lè wá sí ìmúṣẹ
Oríṣun àwòrán, @bankyw
Mo mọ pe àwọn eniyan n fẹ aṣoju ọkan wọn
Olorin Takasufe Bankọle Wellington ti kéde loju opo twitter rẹ pe òun ti fẹ mu ìran oṣelu ṣẹ laye oun ni 2019.
Oríṣun àwòrán, @bankyw
Ifẹ ara agbegbe ti mo n lọ ṣoju fun ló jẹ mi logun
O ni oun mọ pe oun kò ni baba isalẹ ti ọpọ gbà pé o ṣe pataki sí oṣelu Naijiria ṣugbọn oun gbagbọ ninu Ọlọrun.
Oríṣun àwòrán, @bankyw
Mo ti ṣetan láti ṣoju àwọn eniyan Eti ọsa lAbuja
O sọrọ nipa àwọn nkan bii ọgbọn inú ati ootọ inu ti oun fẹ lo fi dupo aṣojuṣofin fun àwọn eniyan Eti Ọsa nilu Abuja to jẹ olu ilu Naijiria.
Tony Elemelu Foundation: Gbogbo okòwò ló ní ìdojúkọ
Banky W. ṣalaye pé oun nigbagbọ ninu agbara oludibo ati ireti awọn eniyan Naijiria lati ni ọjọ iwaju rere ti ko ṣẹyin awọn adari to bẹru Ọlọrun.
O ni o tẹ́ oun lọrun lati gbiyanju wo boya oun a wọle tabi bẹẹ kọ ju ki oun kan fọwọ lẹran lasan lọ lasiko yii.
Banky W. ni Modern Democratic Party ni ẹgbẹ oṣelu to fẹ dije ninu rẹ, bi o tilẹ jẹ pe ọpọ ẹgbẹ oṣelu ti pari idibo abẹle wọn lati yan oludije ninu idibo 2019 ṣugbọn ajọ eleto idibo INEC ti kede pe aaye ṣi wà fáwọn ẹgbẹ oṣelu lati paarọ àwọn oludije wọn.
O tó ìdá méjì àwọn ènìyàn àgbáyé to wà nínú ewu àìsàn ibà
Banky W padanu ọmọ
Oríṣun àwòrán, Instagram/iambangalee
Ọmọ ọdún kan ní Daniel ọmọ Dbanj tó kù s'omi
Ìròyìn ikú ọmọ Dbanj jẹ́ nnkan tí o kò òpó ọmọ orílèèdè Nàìjíríà nínú.
Ikú, bo je t'ọmọdé tàbí àgbà jẹ nnkan tí ó máa ń ba ni nínú jẹ.
Kété ti ìròyìn jáde ní àwọn èèyàn tí n ki Oladapo Daniel Oyebanjo ku ara feraku ọmọ rẹ.
Ruggedy Baba to je ilumoka olorin takasufe wa lara awọn to fi ikini ransẹ.
Banky W naa sọ pe iroyin ọ̀hún fọwọ ba oun lẹmi tohun ti iroyin isẹlẹ ipaniyan to waye ni ipinlẹ Plateau
Olamide ati Davido ko gbẹyin
APC Primaries: 'Kò sí 'Faction' ni Kwara APC rárá, NWC ti sọ̀rọ̀'
#Oshimole: Àwọn aṣáájú APC kò mọ ohun ti wọ́n n ṣe lásìkò yí
Plateau: Ọ̀gá ọlọ́pàá ní ọlọ́pàá yóò ṣàwárí àwọn amòkùnṣìkà
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Awọn agbebọn ti awọn eeyan funrasi pe wọn jẹ darandaran kọlu ileto meje kan ni agbegbe Barkinladi
Ọga agba ọlọpaa lorilẹede Naijiria ti ran ikọ kogberegbe kan lọ si ipinlẹ Plateau lati lọ gbin eso alafia sawọn agbegbe ti rogbodiyan ti waye laarin awọn darandaran fulani ati agbẹ olohunọsin.
Awọn agbebọn ti awọn eeyan funrasi pe wọn jẹ darandaran kọlu ileto meje kan ni agbegbe Barkinladi
Okiki ikọlu laarin awọn darandaran ati agbẹ olohun ọsin kan eleyi ti o ti ṣe okunfa iku  eeyan ti ko din ni mẹrindinlaadọrun.
Bakan naa ni ọga agba ọlọpaa lorilẹede Naijiria tun ṣi ọkan lara awọn igbakeji rẹ to n mojuto ọrọ iṣẹ gbogbo nileeṣẹ ọlọpa lorilẹede Naijiria lọ si ilu Jos.
Baluu kekeeke meji, ọkọ ayẹta APC marun, ikọ ọlọpaa kogberegbe mẹta, ikọ agbogun ti iwa igbesunmọmi, CTU meji pẹlu awọn ọlọpaa ọtẹlẹmuyẹ ni wọn ko lọ si ipinlẹ naa bayii.
Igbagbọ ọpọ ni pe igbesẹ ọga ọlọpaa yii ko ṣẹyin ọrọ Aarẹ Muhammadu Buhari, ninu eyi to ti ṣeleri fun awọn eeyan ipinlẹ Plateau pe igbesẹ abo ati iwadi to tọ yoo waye lori ikọlu naa.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ikọlu yii ti n fa ibẹru bojo lori idasilẹ wahala ẹlẹsin jẹsin ati ẹlẹyamẹya ni Plateau.
Awọn agbebọn ti awọn eeyan funrasi pe wọn jẹ darandaran kọlu ileto meje kan ni agbegbe Barkinladi nibi ti wọn ti pa ọpọlọpọ eeyan ti wọn si jo ọpọlọpọ ile ati dukia miran nibẹ.
Iroyin sọ pe ikọlu yii ko ṣẹyin ikọlu kan to ṣiwaju ti wọn ni awọn eeyan kan lọ ṣigun lu awọn darandaran ati ẹran ọsin wọn.
Ikọlu yii ti n fa ibẹru bojo lori idasilẹ wahala ẹlẹsin jẹsin ati ẹlẹyamẹya pẹlu bi pupọ awọn darandaran ti wọn funra ọrọ yii si ṣe jẹ lati ẹya Fulani ati ẹsin musulumi.
Ikú ọmọ D'banj: Àwọn mọ̀lẹ́bí sọ̀rọ̀ lórí ikú ọmọ rẹ̀
Ẹbí D'banj kò fẹ́ sọ̀rọ̀ lórí ọ̀rọ̀ náà
Àwọn ẹbí gbajúgbajà akọrin tàkasúfèé ọmọ orílèèdè Nàìjíríà, Daniel Oyebanjo tí gbogbo ènìyàn mọ̀ sí Dbanj sọ̀ pé àwọn banujẹ́ gidi gan lórí ikú ọmọ náà.
Ènìyàn kan nínú ẹbí wọn tí kò fẹ́ ká a dárukọ rẹ, sọ pé àwọn kò fẹ́ sọ̀rọ̀ nítorí ọ̀rọ̀ tó kan mọ̀lẹ́bí ni.
Ìròyìn fihàn wí pé ìṣẹ̀lẹ̀ náà lu síta ni nítorí ẹbí sọ wí pé àwọn fẹ́ kí ohun gbogbo wà ní bòńkẹ́lẹ́.
Bákan náà, wọn ní àwọn kò ní dáhùn ìfọ̀rọ̀wánilẹ́nuwò kankan lórí ọ̀rọ̀ náà.
Ní àkókó tí akọ̀ròyìn BBC bẹ agbolé àwọn D'banj wò, kò sí olórin náà nílé bẹ́ẹ̀ sì ni kò sí ohun tó jọ pé ìyàwó rẹ̀ náà wà níbl.
Wọ́n ní ògiri ló la ẹnu tí ọ̀rọ̀ náà ṣe lu síta
Kódà bí ẹ bá ṣe ń súnmọ́ agbo ilé gbajúgbajà náà, ìdàkejì gbáà ni afẹ́fẹ́ ibẹ̀ jẹ́ sí bó ṣe ń gbóná níta káàkiri àwọn ẹ̀rọ ayélujára láti ìgbà tí ìṣẹ̀lẹ̀ náà ti ṣẹlẹ̀.
Ṣe ni gbogbo àdúgbò dákẹ́ rọ́ọ́rọ́ báyìí, bóyá títí di ìgbà tí D'banj náà bá dé.
Ju gbogbo rẹ̀ lọ, ẹbí náà ń gbìyànjú láti má fèsì sí àtẹ̀jáde kankan èyí tó ti ń jà kálẹ̀ láti ìgbà tí ọmọ ọdún kan ọmọ D'banj, Daniel Oyebanji kẹta ti dákẹ́.
SARS: Awọn ará ìlú fi ẹ̀rí síta nípa ìrírí wọn
Oríṣun àwòrán, Police/twitter
Àwọn tó bá ikọ ìròyìn BBC sọ̀rọ̀ láti ìlú Èkó, Ibadan àti Oshogbo sàlàyé ìrírí wọn lọwọ́ SARS
Láìpẹ́ yìí ní Fídíò kan tó gbilẹ̀ lórí ẹ̀rọ ayélujára láti fòpin sí àjọ ọlọ́pàá tó wà fún gbígbógun ti ìwà olè (SARS).
SARS: Awọn ará ìlú fi ẹ̀rí síta nípa ìrírí wọn
Èyí wáyé nípa ìwà ìjẹkujẹ àti ìwà ọ̀daran tí àwọn kọ̀rọ̀wọ̀sí tó wà láàárín wọn ń wù fún ará ìlú.
Nígbàti BBC Yorùbá fí ọ̀rọ̀ wá àwọn ọmọ Nàìjíríà tó tí sẹ alábápàdé ẹ̀ka ọlọ́pàá SARS tẹ́lẹ̀ rí ní wọn sàlàyé ǹkan ti ojú wọn ti ri .
Àwọn tó bá ikọ ìròyìn BBC sọ̀rọ̀ láti ìlú Èkó, Ibadan àti Oshogbo sàlàyé ìdojúkọ wọn.
Èyí ní ẹ̀rí tí ẹnìkan fi sọwọ́ sí ilé iṣẹ́ BBC
Oríṣun àwòrán, BBC Sport
Eri owó ti Lekan Fashakin san fún ọlọpàá
Bótilẹ̀ jẹ́ pé àwọn míran gbà pé kìí ṣe gbogbo SARS ní ó ń hùwà ìbàjẹ́ bíkò ṣe àwọn àsáwọ kan tó wà lára wọn, nítorí pé láti ìgbà ti wọn ti bẹ̀rẹ̀ ní àwọn ìwà ọ̀daràn tí ń díkù láwùjọ, sùgbọn síbẹ àjọ ọlọ́pàá gbọdọ̀ wá wọ̀rọ̀kọ̀ fi sàdá kí àwọn ọ̀bàyéjẹ́ láàárin àwọn ọlọ́páà yìí leè tọwọ́ ọmọ wọn bọsọ.
Ìpànìyàn Plateau: Buhari kẹ́dùn pẹ̀lú àwọn ará Plateau
Ààrẹ Buhari ti fi ìlú Calabar sílẹ̀ lọ sí ìpínlẹ̀ Plateau láti mọ ibi tí ǹkan dé dúró àti fún ìbẹ̀wò ìbánikẹ́dún.
Láti ilé ìjọba, ìròyìn tó ni létí wí pé ààrẹ tí ó lọ ṣí iṣẹ́ àkanṣe kan ní Calabar ní ìpínlẹ̀ Cross River ló ti fi ìlú náà sílẹ̀ báyìí.
Lẹ́yìn tí àwọn ọlọ́pàá sọ pé ènìyàn mẹ́rìndínláàdọ́run ló bá ìṣẹ̀lẹ̀ Barkin Ladi ní ìpínlẹ̀ Plateau rìn, ọ̀kan lára àwọn tó fara gbá níbi ìṣẹ̀lẹ̀ náà, Ezekiel Danbwarang ti sọ ìtàn bí àwọn darandaran ṣe pa ènìyàn mẹ́jọ nínú ẹbí rẹ̀.
Ìṣẹ̀lẹ̀ aburú yìí bẹ̀rẹ̀ lọ́jọ́bọ̀ ọ̀sẹ̀ nígbà tí ìkọlù bá àwọn darandaran kan tó sì la ẹ̀mí márùún lọ, èyí ló wá koná ìkọlù lsan lọ́sàan ọjọ́ àbámẹ́ta tó tún wá gba ẹ̀mí ọ̀pọ̀lọpọ̀.
Ọ̀gbẹ́ni Danbwarang sọ fún BBC pé wọ́n pa ìyá, àti bàbá,ìyàwó rẹ̀ àti ọmọ mẹ́rin, wọ́n sì tún jó ilé wọn pẹ̀lú.
Ẹ̀mí 86 ṣ'òfò ni ìkọlù Plateau
Ọ̀gá ọlọ́pàá kó ikọ̀ kògbéregbè lọ sí Plateau
Ìgbà wo ni Buhari yóò simi àwáwí?
Plateau state dey north-central Nigeria
"Wọ́n já ilẹ̀kùn ibodè ilé mi wọ́n sì wọ 'yàrá mi wá, níbẹ̀ ni wọ́n ti sọ iná sílé.
Ó ṣì le láti sọ wí pé ìṣẹ̀lẹ̀ ìkọlù tó lé ní wákàtí mẹ́rin mú kí àwọn darandaran pa ènìyàn tó lé nígba lágbègbè náà.
Oríṣun àwòrán, Chuwang Dalyop
bí àwọn darandaran ṣe pa ènìyàn mẹ́jọ nínú ẹbí rẹ̀
CAN, àwọn ajàfẹ́tọ̀ pè fún ìdájọ́ lórí ìpànìyàn Plateau
Oríṣun àwòrán, Getty Images
CAN ni ikọlu ọhun ṣe afihan ijakulẹ to n waye lori ọrọ abo lorilẹede Naijiria
Ẹgbẹ ọmọlẹyin Kristi lorilẹede Naijiria, CAN pẹlu ajọ fun idaabo bo ẹtọ ọmọniyan lorilẹede Naijiria, NHRC ti pe fun fifi awọn to wa nidi iṣẹlẹ ipaniyan to waye nipinlẹ Plateau jofin.
Gẹgẹ bii ọlọpaa ṣe sọ, eeyan mẹrindinlaadọrun lo ku ninu ikọlu naa to waye ni Barkin Ladi nipinlẹ Plateau.
Bi o tilẹ jẹ pe awọn aṣiwaju ẹgbẹ darandaran lorilẹede Naijiria, Miyetti Allah, ti sọ pe ikọlu ẹsan ni ikọlu naa, ẹgbẹ CAN ti ke si ijọba lati tete wa ọna fi mu awọn to wa nidi ikọlu naa.
CAN ni ikọlu ọhun ṣe afihan ijakulẹ to n waye lori ọrọ abo lorilẹede Naijiria.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ijọba àpapọ̀ ní ìgbésẹ̀ àwọn agbófinró ti bẹ̀rẹ̀ láti ṣàwárí gbogbo àwọn tó wà nídí ìkọlù náà
 A mọ pe awọn ileto ti ọrọ kan ko tii lee sọ ni pato iye awọn eeyan wọn ti wọn pa, ṣugbọn ibanujẹ nla lo jẹ wi pe eeyan mẹrindinlaadọrun lo ku ninu ikọlu ọhun gẹgẹ bii awọn ọlọpaa ṣe sọ titi kan awọn obinrin ati ọmọde."""
Ẹgbẹ awọn ọmọlẹyin Kristi ni ko si iwulo fun iṣẹ ọtẹlẹmuyẹ awọn ajọ alaabo gbogbo bi o ba lee ṣeeṣe fun awọn amokunṣika lati pa ọpọlọpọ eeyan lawọn ileto laisi si pe awọn ileeṣẹ alaabo n doola wọn.
Bakan naa ni akọwe ajọ fun idaabo bo ẹtọ ọmọniyan lorilẹede Naijiria, NHRC Anthony Ojukwu ati ajọ ajafẹtọ kan ti orukọ rẹ njẹ CACOL ni afihan aikun oju iwọn ijọba lati kapa iwa igbesunmọmi  lorilẹede Naijiria.
Awọn ajọ mejeji yii ni wọnke si aarẹ pe idaniloju ẹnu ni gbogbo igba ko lee tan ọrọ to wa nilẹ yii ju ki ijọba san ṣokoto rẹ ko le lati koju awọn ikọlu ati ipaniyan gbogbo to n ko ẹmi lọ kaakiri orilẹede Naijiria.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
CAN ni ko si iwulo fun iṣẹ ọtẹlẹmuyẹ awọn ajọ alaabo bi o ba lee ṣeeṣe fun awọn amokunṣika lati pa ọpọlọpọ eeyan
Amọṣa, igbakeji aarẹ Yẹmi Oṣinbajọ ti ṣapejuwe ikọlu naa gẹgẹbii eyi to buru jọjọ pẹlu idaniloju pe iṣẹ ti n lọ labẹnu lati ko awọn to wa nidi iṣẹlẹ naa.
Ileeṣẹ ọmọogun pẹlu ni awọn ti ko alekun akọṣẹmọṣẹ ọmọ ogun lọ si ipinlẹ Plateau.
Ìpànìyàn Plateau: Ọwọ́ ọlọ́pàá tẹ afurasí ènìyàn 13
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ọmọ ìpínlẹ̀ Plateau ní ènìyàn 8 nínú ẹbí òun wà nínú awọn 86 to pàdánù ẹmí wọn níbí ìkọlù sí ìlú wọn.
Ọwọ́ sìnkún ọlápàá ti tẹ ènìyàn mẹ́tàlá ní ìpínlẹ̀ Plateau nítorí ìpànìyàn tó gbẹ̀mí ènìyàn mẹ́rìndíláàdọ́rùn ni Ọjọ Aiku
Agbẹnusọ ikọ ọlọpaa fun ‘Operation Safe Haven’, Major Umar Adam tó fìdí ọ̀rọ̀ náà múlẹ̀ fún BBC, wi pe àwọn kọ ni ní pẹ́ gbé awọn afurasi naa lọ sí ilé ẹjọ́.
Adam fíi kúu pé àwọn afurasi ti wọn ko jẹ lara àwọn to kópa nínú ìṣẹ̀lẹ̀ náà ní ìhà méjééjì.
Laipẹ yii ni ilé isẹ Ààrẹ Buhari sọ wi pe Buhari yóò sè abẹ̀wò sí ìpínlẹ̀ Plateau láti mọ ibi tí ǹkan dé dúró àti fún ìbẹ̀wò ìbánikẹ́dún.
Ìkọlù Plateau: Ẹyìn aṣáájú ìlú gbọdọ mojuto àlàfíà
Oríṣun àwòrán, @NGRPresident
Aarẹ Buhari ti saaju pase ki awọn osise alabo pẹtu si aawọ naa
Ààrẹ Mùhámádù Buhari ti orílẹ̀èdè Naijirià ti ke si àwọn olórí ìlú nipinle Plateau láti mú  ibasepọ àlàfíà láàrin àwọn èèyàn wọn n'isẹ.
Aarẹ Buhari parowa yìí nigba to n ṣe ìpàdé pẹlú awọn alenuloro ni ìpínlè náà lọjo ìṣẹgun.
Buhari ni ipaniyan to gbérí padà ní Plateau jẹ́ òun tó n kọni lominu ati pé ìjọba òun yóò wá wọ̀rọ̀kọ̀ fí ṣada láti dẹkùn rẹ
Ọpọ èèyàn ló ti pàdánù ẹmí wọn nínú ikọlù láàrin àgbẹ àti darandaran.
Ìṣẹlẹ yìí sí ti mu kí ọpọ bẹnu àtẹ lú ètò ààbò lorílẹ̀-èdè eleyii ti wọn ní ko gbámúsé.
Ṣáájú ní igbákejì ààrẹ Yemi Osinbajo ti ṣe àbẹwò sí ìpínlè náà.
Dogara: Buhari yóò tún àwọn adarí ẹ́ka ètò àbò tò láìpẹ́
Oríṣun àwòrán, Nigeria presidency
Ile aṣofin apapọ pẹlu ẹka iṣakoso ti tahun sira wọn lọpọlọpọ igba lori eto abo
Olori ile aṣoju-ṣofin lorilẹede Naijiria, Yakubu Dogara ti ṣalaye pe, aarẹ orilẹede Naijiria, Muhammadu Buhari ti n gbaradi lati ṣe atunto eto abo rẹ laipẹ.
Dogara ni atunto ọhun wà lati wa ojuutu si rukerudo to n waye lori ọrọ abo lawọn agbegbe kan lorilẹede Naijiria.
Oríṣun àwòrán, Nigeria Presidency
Aarẹ ile aṣofin agba, Bukọla Saraki ti gunlẹ si ipinlẹ Plateau bayii lẹnu abẹwo lori iṣẹlẹ ikọlu naa
Olori ile aṣoju-ṣofin ṣalaye ọrọ yii lẹyin ipade ti awọn olori ile aṣofin apapọ mejeeji, iyẹn Sẹnetọ Bukọla Saraki to jẹ aarẹ ile aṣofin agba ati olori ile aṣoju-ṣofin, Yakubu Dogara ṣe pẹlu Aarẹ Muhammadu Buhari lori ikọlu to waye ni ipinlẹ plateau lopin ọsẹ to kọja.
 Aarẹ ti gbe awọn igbesẹ to yẹ, ọrọ abo la n sọrọ nipa rẹ yii, kii ṣe awọn ọrọ ti a lee ma tu sita fun araye, ṣugbọn ṣa o ti sọ awọn ohun ti o n ṣe fun wa, atunto to n gbero lati ṣe lati rii daju pe iru rẹ ko ṣẹlẹ mọ.
Awọn adari lo pe ipade yii lori ọgọrọ ẹmi to ku sinu ikọlu to waye nipinlẹ Plateau ninu eyi ti awọn ọlọpaa ti sọ pe ẹmi to ku ko din ni mẹrindinlaadọrun.
Ẹwẹ, aarẹ ile aṣofin agba orilẹede Naijiria, Bukọla Saraki ti gunlẹ si ipinlẹ Plateau bayii lẹnu abẹwo lori iṣẹlẹ ikọlu naa.
Joe Jackson, bàbá Micheal Jackson jáde láyé
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Owurọ ọjọọru ni alagba Joe Jackson jade laye
Joe Jackson to jẹ baba gbajugbaja olorin ni Micheal Jackson ti ku ni ẹni ọdun mọkandinlaadọrun.
Eeyan kan to sun mọ ẹbi awọn onkọrin naa lo fi iroyin nipa iku rẹ to BBC leti.
Owurọ ọjọọru ni alagba Joe Jackson jade laye lẹyin ti o ti wa ni ileewosan fun itọju aisan jẹjẹrẹ inu oronro.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ẹni ọdún mọ́kàndínláàdọ́rùn ni Joe Jackson, bàbá Micheal Jackson kí ó tó jáde láyé
Iku rẹ waye lẹyin ọjọ meji ti wọn ṣe ayẹyẹ iranti iku ọmọ rẹ Micheal Jackson ti o jade laye ni ọdun mẹsan sẹyin.
Bakan naa, ọmọ-ọmọ rẹ, Taj Jackson ti fi idi iroyin naa mulẹ lori ikanni twitter rẹ.
Oríṣun àwòrán, @tajjackson3
Iroyin sọ pe ipa diẹ kọ ni alagba Joe Jackson ko ninu idagbasoke iṣẹ orin kikọ awọn ọmọ rẹ nigba ti wọn bẹrẹ gẹgẹ bii 'The Jackson 5'
Ọmọ mẹsan ninu mọkanla ti alagba Joe Jackson bi lo gbẹyin rẹ.
Plateau Crisis: Àafa f'àwọn Krìstìẹ́nì pamọ́ sínú mọ́ṣáláṣí
Ìmáámù Muhammed Ali
Nígba tí aafa alaanu yii rii tí ogunlọ́gọ̀ àwọn ènìyàn ń sá wọ abúle rẹ̀ ní Nghar Yelwa ní Ìpínlẹ̀ Plateau l'ọjọ́ Aikú, kò ròó lẹ́ẹ̀méjì to fi ṣílẹ̀kùn láti gbà wọ́n wọlé.
Àwọn tó ń sá àsálà fún ẹ̀mí wọn náà wá láti abúlé kan ní Ìjọba Ìbílẹ̀ Barkin Ladi níbi tí àwọn darandaran agbébọn wọ̀ láti pa àwọn ènìyàn.
Lẹ́yìn ò rẹyìn, ènìyàn mẹ́rìndínláàdọ́rin ni àwọn ọlọ́pàá ní ó kú, ṣùgbọ́n àwọn ará ìlú ní wọ́n ju igba lọ.
"Ali sọ fún BBC pe, ""Mo kọ́kọ́ mú àwọn obìnrin wọ ilée mi láti fi wọ́n pamọ́. Lẹ́yìn náà ni mo wá mú àwọn ọkùnrin wọ inú mọ́ṣáláṣí láti fi wọ́n pamọ́."" Ó lé ní'gba ènìyàn tí ààfá náà dóólà ẹ̀mí wọn."
Ọ̀pọ̀lọ́pọ̀ àwọn ènìyàn Berom àti àwọn Mùsùlùmí to sá kúrò níbi ìkọlù náà ló sá lọ sà wọ Abule Nghar Yelwa fún ààbò.
Awọn ará ilu n sá lọ ní agbègbè náà
Èyí tó ba ni lérù ju ni pé, àwọn agbébọn náà lọ bá Imam Ali, wọn ní kó fa àwọn Krìstìẹ́nì tọ wà lọ́dọ̀ rẹ̀ sílẹ̀ kí wọ́n pa wọ́n ṣùgbọ́n ó sọ fún wọn pé Mùsùlùmí ni gbogbo àwọn tó wà lọ́dọ̀ òun.
Bẹ́ẹ̀ ló ṣe parọ́ tó fi bẹ àwọn agbébọn náà láti máa lọ.
Bẹ́ẹ̀ ni orí ṣe yọ àwọn Berom to wà ni abúlé ọhun. Ṣùgbọ́n bí wọn kò ṣe nilé báyìí, mọ́ṣáláṣí náà ni ibi tí wọ́n ń gbé.
BBC gbọ́ pé ọdun mélòó kan sẹ́yìn tí àwọn Mùsùlùmí ìlú náà ń wá ilẹ̀ láti kọ́ mọ́ṣáláṣí sí, àwọn Berom ló fún wón nílẹ̀ lọ́fẹ̀ẹ́.
Gbogbo abúlé ti di aworo
Wàhálà Bódìjà: Ẹ̀mí bọ́ nígbàtí alápatà àti ọlọ́pàá wọ̀já ìjà
Àwọn alápatà takú láti tẹ̀lé àsẹ ìjọba pé kí wọn kó lọ sí ọjà ẹran tuntun, àmọ́ tí wọn yarí
Àwọn alápatà ti takú láti tẹ̀lé àsẹ ìjọba ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́ pé kí wọn kó lọ sí ọjà ẹran tuntun, àmọ́ tí wọn yarí.
Ìdí nìyí tí ìjọba se kó àwọn ọlọ́pàá lọ sí ọjà Bódìjà láti pé wọn tẹ̀lé àsẹ ìjọba, sùgbọ́n tí ọ̀rọ̀ náà bọ́wọ́ sórí.
A gbọ́ pé ẹ̀mi méjì ló bọ́ lásìkò táwọn alápatà àti ọlọ́pàá wọ̀já ìjà, tí rògbò-dìyàn sì gbòde ní ọjà náà.
A gbọ́ pé ẹ̀mi méjì ló bọ́ lásìkò táwọn alápatà àti ọlọ́pàá wọ̀já ìjà, tí rògbò-dìyàn sì gbòde ní ọjà náà.
Níbáyìí, ìjọba ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́ ti ti ọjà Bódìjà pa.
Nigba ti akọroyin BBC Yoruba de sibi isẹlẹ naa, a ri pe awọn eeyan kan ti dana sun aloku taya ọkọ loju popo, ti ọpọ eeyan si duro go go go niwaju ẹnu ọna abawọle ọja naa.
Ọ̀kan lara àwọn ontaja ni ọja Bodija to ba ileesẹ wa BBC sọrọ salaye bi isẹlẹ naa se waye.
Wàhálà Bódìjà: Àwọn alápatà àti ọlọ́pàá wọ̀yá ìjà
Koda, a gbọ pe diẹ ninu awọn alapata naa ti lọ si ibudo tuntun ti ijọba si fun wọn, ti awọn to fi aake kọri, lati lọ si ọja tuntun naa, si n fi apa janu.
Nigba to n salaye idi ti ijọba fi gbe ilẹkun ọja naa ti, alaga agbegbe idagbasoke ti A Aarẹ Latoosa, ti ọja Bodija wa labẹ rẹ, Adekunle Ọladeji, salaye pe ijọba fẹ dena ofo ẹmi ati dukia lo mu ko gbe ilẹkun ọja naa ti pa.
Ọladeji ni alaafia ti n pada jọba ni agbegbe Bodija bayii.
O ni ijọba ko tun fẹ ki ọwọja rogbodiyan naa tan ka awọn agbegbe miran ni ipinlẹ Ọyọ, ni wọn se ti ọja Bodija.
Ọladeji ni alaafia ti n pada jọba ni agbegbe Bodija bayii.
Akọroyin wa ri pe n se ni awọn alapata naa fi awọn ẹran wọn silẹ, ti wọn si salọ.
Ìjàmbá iná: Ọkọ̀ epo ló gbiná, tó ran ogún ọkọ̀ míì
Oríṣun àwòrán, Ọllabọ̀dé Akamọ
Àwọn èèyàn àti ọkọ̀ tó há sínú súnkẹrẹ-fàkẹrẹ tó ń wáyé lásìkò tí ọkọ̀ epo náà gbinná, ló forí sọta àjálù náà
Ọkọ̀ epo kan ti sàdédé gbiná, tí ọ̀pọ̀ ọkọ̀ ayọ́kẹ́lẹ́ tó lé ní ogún sì gbinná tẹle.
Ìròyìn náà ní ọ̀pọ̀ ẹ̀mí ló ti bá ìsẹ̀lẹ̀ náà rìn, àmọ́ kò sẹ́ni tó leè sọ iye àwọn tó kú nínú ìsẹ̀lẹ̀ náà lọ.
Agbègbè Ìkóríta Ọ̀tẹ́dọla ní opópónà márosẹ̀ Ìbàdàn sí ìlú Èkó ni ìsẹ̀lẹ̀ náà ti wáyé.
Agbègbè Ìkóríta Ọ̀tẹ́dọla ní opópónà márosẹ̀ Ìbàdàn sí ìlú Èkó ni ìsẹ̀lẹ̀ náà ti wáyé.
Àwọn èèyàn àti ọkọ̀ tó há sínú súnkẹrẹ-fàkẹrẹ tó ń wáyé lásìkò tí ọkọ̀ epo náà gbinná, ló forí sọta àjálù náà.
A gbọ́ pé gbogbo àwọn èèyàn àti ọkọ̀ náà ló jóná di eérú.
A n se akojọpọ ẹkunrẹrẹ iroyin yajoyajo lọwọ, a o maa gbe ẹkunrẹrẹ iroyin naa sori atẹ iroyin wa laipẹ. Ẹ jọwọ, ẹ tun oju opo iroyin yi yẹwo, ki ẹ lee ri ẹkunrẹrẹ iroyin ọtun laipẹ.
Iná Edo: Àwọn ọmọ ni àdájọ́ lọ wò ní fásitì, tí ina fi mú wọn
Oríṣun àwòrán, @wololo_co_ke
Bi eeyan ba jẹ ori ahun, yoo sunkun ni ọjọ ẹti nigba ti ijamba ina kan waye ni ilu Ekpoma ni ipinlẹ Edo lasiko ti ọkọ adajọ kan se agbako tanka epo to fọn epo silẹ, to si gbinna.
Adajọ ileẹjọ majisireti Okiti-pupa nipinlẹ Ondo, Banji Ayeomoni pẹlu ọmọkunrin rẹ, Dara ati ibatan wọn kan to fi mọ awakọ la gbọ pe wọn se agbako iku ojiji naa.
Iroyin naa ni isẹlẹ ọhun waye ni agbegbe ti ko jinna si ileekọ fasiti Ambrose Ali ni ilu Ekpoma.
Sunday Adelaja: Tẹ́tẹ́ làwọn pásítọ̀ tó ń gba owó ‘ìserere’ ń ta
Adajọ Ayeomọni la gbọ pe o lọ wo awọn ọmọ rẹ to wa ni fasiti naa, nigba to si n pada bọ ni isẹlẹ naa waye.
A gbọ pe ipele karun-un eto ẹkọ imọ isegun oyinbo ni fasiti Ambrose Ali to wa ni Ekpoma, ni Dara, ọmọkunrin adajọ to ku naa wa.
Oríṣun àwòrán, @SeimenBurum
Ti gbogbo wọn si jẹ Ọlọrun nipe ni ile iwosan kan ti wọn gbe wọn lọ.
Bẹẹ ba gbagbe, igba akọkọ kọ ree ti isẹlẹ tanka epo yoo maa gbẹmi awọn eeyan.
Bakan naa ni irufẹ isl yii waye ni ilu Eko laipẹ yii, eyi to mu ẹmi eeyan mẹsan lọ.
Èèrù ina tó jó ọ̀pọ̀ ọkọ tó sì mú ẹmi lo nilu Eko tí n tútù ṣugbọn àrà àwọn ọmọ Nàìjíríà sí n gbóná lórí ìṣẹlẹ náà.
Lójú òpó Twitter, iriwisi loriṣiiriṣii ní wọn tí n sọ ti ọpọ sí dá lórí pe ki ọkọ epo ma rìn lójú ọsán mọ.
Ìṣẹlẹ náà to waye lagbègbè Ìkóríta Ọ̀tẹ́dọla, Berger, ní opópónà márosẹ̀ Ìbàdàn sí ìlú Èkó lọjobo ní ọpọ èèyàn tí ṣé àpèjúwe rè gẹgẹ bí ìṣẹlẹ tó gbenilọkan soke
Àwọn kàn ní ìjọba kò gbọdọ̀ fí ọwọ yẹpẹrẹ mú ọrọ̀ yí nítorí  ìpalára tí àwọn ọkọ èpo àti àjàgbé n ṣé fún ará ìlú kọjá afẹnuso.
Ninu iriwisi tire, Dokita Dipo Awojide ni adura pe ki irufe isẹle bayi ma waye mọ ko le tan ọrọ to wa nile yi bi kò ṣe pe ki ijọba wa wọrokọ fi ṣada lori ipenija ijmaba ina ọkọ agbepo.
Opeyemi Babalola bẹnu ẹtẹ lu bi awọn ohun amaye dẹrun gege bi ọkọ ojurin ati ile ise ipọnpo ko se sisẹ to ni Naijiria.
O ni bi wọn ba n sisẹ ni,ijamba bi ti teko to sẹlẹ ko ba ma waye.
JJ Omojuwa ni asiko ti to bayi ki awọn olori orileede Naijiria se ojuse wọn bo ti se to ati bo ti se ye.
Ìjàmbá iná Èkó: Èèyàn méjì wa lẹ́sẹ̀ kan ayé ẹsẹ kan ọrùn
Ile iwosan isele pajawiri ilu Eko gbalejo eeyan mefa lara awọn to farapa ninu isele naa
Awọn osisẹ pajawiri tí gbè àwọn tó f'arapa nínú ìjàmbá iná ọkọ agbepo Èkó kuro ní Ilé ìwòsan ìṣẹlẹ pajawiri lọ sí ile-iwosan to wa fun awọn to ni ijamba ina to wa ni Gbagada, ni ipinle Eko.
Akoroyin BBC News Yoruba, Kunle Falayi to ṣe àbẹwò sí ilé ìwòsan náà ní àwọn dókítà gbe ìgbésẹ náà kí wọn ba le ri ìtọjú tó péye gbà.
Iroyin ni eniyàn mẹfa ni wọn kọkọ gbé wá sí ilé ìwòsan náà kété ti ìjàmbá naa ṣẹlẹ.
Akọroyin wa jabọ pe, lẹyin ayẹwo, awọn osise ilera gbé èèyàn méjì ti ifarapa wọn pọ pupo ló sì ilé ìwòsan ìjọba to wà ní Gbagada.
Ireti si ni pe awọn mẹrin to ku yoo gba itoju ni  ilé ìwòsan ìṣẹlẹ pajawiri titi ti ara wọn yoo fi ya lati pada sile wọn.
Bakan naa,  oniroyin wa ri àwọn mọlẹbi bi wọ́n se joko síta ti wọn sì n dúró dé àwọn dókítà mú ìró nípa ìtọjú awọn eeyan wọn wà.
Àwọn mọlẹbi n dúró dé kí àwọn Dókítà mú ìró wa nípa èèyàn wọn
Amọ, sadede ni wọn ko awọn mẹrin to ku si inu ọkọ ti wọn si wa wọn lo si lọ sí ẹka ti o n tọjú àwọn tí iná jó ni ile iwosan ijoba ni Gbagada.
Akoroyin wá jabo pé oun ko ti i ni aanfaani lati mo boya iye eeyan to ku ninu isẹlẹ naa ti le ni mẹsan.
Èèyàn mẹsan ní ìròyìn kókó sọ pé ọ pàdánù ẹmi wọn nínú ìjàmbá náà tí èèyàn mẹrin sí f'arapa.
Ekiti 2018: Igbákejì Gómìnà ṣèlérí ìtẹ̀síwájú kébi-má-pàlú
Oríṣun àwòrán, @matsecooks
"Fayose gbe ètò olóògùn ebi ""Stomach infrastructure"" kalẹ ni ibẹrẹ saa keji iṣejọba rẹ"
È gbọ àlàyé lẹnu àwọn ti ójúẹlẹgba leko irú iṣẹ ti oògùn olóró má n ṣé lara.
Eto oloogun ebi yoo tẹsiwaju lẹyin iṣejọba Gomina Ayodele Fayose.Oludije fun ipo gomina ipinlẹ Ekiti labẹ aṣia ẹgbẹ oṣelu Peoples Democratic Party, PDP, Ọjọgbọn Kọlapọ Oluṣọla Eleka, lo ṣeleri yii, lasiko ti o n ba awọn oṣiṣẹ kan sọrọ nilu Ado Ekiti.
"Eto ""oloogun ebi"" eleyi ti adape rẹ lede Gẹẹsi jẹ ""stomach infrastructure"" ni gomina Fayose gbe kalẹ ni ibẹrẹ saa keji iṣejọba rẹ, eyi to si da ọpọlọpọ họwu-họwu silẹ nigba naa."
Eleka ni ko si ohun to buru ninu ka bu irẹsi igba Naira, ati ẹwa diẹ fun araalu lati fi gbenuro
Iṣọla Eleka to tun jẹ igbakeji ijọba to n kogba wọle lọwọ nipinlẹ Ekiti sọ pe atunṣe ranpẹ yoo ba eto naa eleyi ti yoo gbee kuro ni anfani ipinlẹ nikan lọ si awọn ẹka ijọba ibilẹ gbogbo to wa l'Ekiti.
Plateau: Àsìkó tó láti fi káádì ìdìbò yanjú ọ̀rọ̀ Buhari
Ijamba ina Eko; Awakọ ni omi gọta lo yọ oun ninu ijamba ina
Èèmọ̀! Pósí ìyá tó kú ṣekú pa ọmọ rẹ
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Àwọn kan ni àwọn aláṣẹ agbègbè nàá ló ni ẹ̀bi ìṣẹ̀lẹ̀ kàyéèfì nàá.
Arakunrin kan ti kagbako iku ojiji lasiko to n ṣe eto isinku iya rẹ to doloogbe.
Samen Kondarura, ẹni ogoji dun, ni ajalu naa de ba lasiko to n gbe posi oku iya rẹ, Berta, ni igbe ẹyẹ ìkẹyìn.
Eto isinku naa waye ni Parinding Valley, ni ẹkun North Toraja, l'orilẹ-ede Indonesia.
Wọn ni lasiko ti awọn agbokujo n gbiyanju lati gbe posi naa si ori pepele kan ti wọn ti yasọtọ lati ṣe awọn eto ikẹyin si oku lara ni ibamu pẹlu aṣa agbegbe naa, ni ẹsẹ ọkan lara awọn agbokujo naa yẹ gẹrẹ lori akasọ, ti posi naa si jabọ lu Kondorura to n bẹ nisalẹ.
Loju ẹsẹ ti iṣẹlẹ naa waye ni wọn sare gbe Kandorura lọ si ileewosan nibi to ti papa gbẹmi mi.
Ileeṣẹ iroyin kan labẹle, Khaleej Times, sọ pe awọn alaṣẹ agbegbe naa to kuna lati gbe akasọ naa duro daada lo ni ẹbi iṣẹlẹ kaayefi ọhun.
Ṣugbọn, awọn ẹbi Kondorura pinnu lati maa ba awọn alaṣẹ naa ṣ'ẹjọ.
Nibayii, wọn ti sin oku Kandorura si ẹgbẹ iya rẹ.
SARS ti bẹ̀rẹ̀ ìgbésẹ̀ láti yọ àwọn ọ̀bàyéjẹ́ kúro
Alagbalúgbú jẹ́ ọ̀rọ̀ Yorùba tí a fi ń ṣàpèjúwe agbára òkun
Wọ́n rí alààyè obìnrin tó ti kú tẹ́lẹ̀ nínú mọ́ṣúárì
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ko sẹni to le kede oku eeyan ti ọlọjọ kò ba tii dé
Obinrin kan ti n gbadun diẹ̀-diẹ̀ nile ìwosan lẹ̀yin ti wọn ba laaye ninu firiiji ti wọn n ko oku pamọ si ni mọṣuari.
Obinrin naa ni wọn gbe lọ si ile igboku-pamọ-si to wa ni Carletonville, ni ẹkùn Gauteng, l'orile-ede South Africa lẹyin ti awọn oṣiṣẹ adoola ẹmi sọ pe o ti ku ninu ijamba ọkọ to waye.
Ṣugbọn, ori ko o yọ nigba ti oṣiṣẹ mọṣuari kan pada lọ yẹ ẹ wo nibi ti wọn gbe e si.
Èèyàn 12 ló ti kú báyìí nínú ìjàmbá iná Eko
'Obìnrin tí kó ba fẹ́ òṣìṣẹ́ Mọ́ṣúárì, ìpinu rẹ̀ mẹ́hẹ'
Ọkan lara awọn oṣiṣẹ sọ fun BBC pe obinrin naa ti wọn ko darukọ ti n gba itọju ni ile Iwosan kan to wa ni ilu Johannesburg, lẹyin ti awọn onimọ nipa ẹya ara fi ti ọwọ si i.
Bakan naa ni iwadii ti n lọ lori iṣẹlẹ naa, ti awọn ẹbi rẹ si n fẹ mọ ohun to faa ti wọn fi kọkọ kede oku rẹ.
Ọkan lara awọn ẹbi obinrin naa, to fi orukọ bo ara rẹ laṣiri sọ fun BBC pe,''gẹgẹ bi ẹbi, a o ni ohunkohun lati sọ, ayaafi ti gbogbo awọn ọlọpaa, ati oṣiṣẹ adoola ẹmi, to fi mọ awọn oṣiṣẹ mọṣuari ba wa nijoko o.
A n fẹ idahun.
South Africa niṣẹ lati ṣe
Bakan naa ni arakunrin naa sọ pe ohun to janilaya ni iṣẹlẹ naa.
Ṣugbọn, olori fun ileeṣẹ adoola ẹmi, Gerrit Branick, ni ko si ẹri kankan to fi idi rẹ mulẹ pe ẹ̀bi awọn oṣiṣẹ awọn ni, nitori gbogbo wọn lo mọṣẹ.
Igba akọkọ kọ niyi ti iru iṣẹlẹ bẹẹ yoo waye ni South Africa. Ọkan ti waye bẹ ri ni 2011, nigba ti ọkunrin aadọta ọdun kan ji ninu mọṣuari kan to wa ni Cape Town, to si bẹrẹ si ni pariwo.
Bakan ni omiran ṣẹlẹ si ẹnikan to ni ijamba ọkọ, ti wọn si sọ pe o ti ku, ko to di pe wọn rii to n mi l'ọjọ keji.
Ṣugbọn o pada ku lẹyin wakati marun un lẹyin ti wọn ri.
Àyàn: Ti mo bá ti gbọ́ ohùn ìlù ni àárẹ́ mi ma ń lọ!
Fredrick Fasheun jáde láyé lẹ́yìn àìsàn ráńpẹ́
Oríṣun àwòrán, Facebook/Frederick Faseun
Frederick Faseun di oloogbe
Aarẹ Muhammadu Buhari ti ba gbogbo ẹya Yoruba kẹdun lori iku Dokita Fredrick Fasheun.
Ibanikẹdun naa jẹ yọ ninu atẹjade kan ti oluranlọwọ pataki si aarẹ lori ori iroyin Femi Adeshina fi sita lọjọ Abamẹta.
Aarẹ Buhari to ki gbogbo ẹbi oloogbe naa, ṣe iranti ipa ribiribi ti Dokita Fasheun ko ninu ẹgbẹ NADECO , o si gbaa ladura pe ki Edumare dẹlẹ fun.
Ọọni ti ilẹ Ifẹ Oba Adeyeye Ogunwusi ti ranṣẹ ibanikẹdun si gbogbo ọmọ Yorùbá lori iku Dokita Fredrick Fasheun , ẹni ti o jade laye ni owurọ ọjọ Abamẹta.
Ọba Ogunwusi ninu atẹjade kan ti oludari eto iroyin rẹ, Moses Olafare fi sita , ṣe apejuwe iku oloogbe naa bi ajalu nla fun gbogbo ọmọ ilẹ kaaarọ oojiire.
O ṣapejuwe Dokita Fasheun bi ọkan gboogi ninun ọmọ Yorubá to fẹran orilẹede Naijiria , to si fi gbogbo ọjọ aye e rẹ ja fun ilọsiwaju ilẹ Yoruba.
Gẹgẹ bi Ọọni Ifẹ ṣe wi, gbogbo ọmọ Yoruba patapata ni yoo ṣe afẹri bàbá Fasheun.
Oríṣun àwòrán, Faseun
Ẹwẹ, Aarẹ ọna Kakanfo, Oloye Gani Adams naa ti dara pọ mọ gbogbo ọmọ Yoruba lati kẹdun iku Dokita Fasheun to lọ ibi agba a rẹ.
Oloye Adams , to tun jẹ alamojuto apapọ fun OPC, ṣalaye pe ẹni apọle ni baba Fasheun, ẹni ti o ni o jẹ adari rere, to kun fun ọgbọn, imọ ati oye.
Aarẹ ọna kakanfo tun ṣe apejuwe oloogbe naa bi olotiitọ eniyan ati ẹni to jẹ awokọṣe fun gbogbo eniyan.
Oríṣun àwòrán, Fasheun
Ọmọ bíbí ìpínlẹ̀ Ondo ni Dokita Fasheun
Bakan naa, ẹgbẹ ọdọ Yoruba 'Yoruba Youth Socio-cultural Association' ti ba ẹbi, ara, ojulumọ ati gbogbo ọdọ ilẹ Yoruba da aaro agba yoruba to ku.
Aarẹ ẹgbẹ naa, Olalekan Hammed,sọ ọ di mimọ pe gbogbo akitiyan Oloogbe Fasheun si idagbasoke ọmọniyan jẹ ohun manigbagbe.
Olori ẹgbẹ ẹya ọmọ Oodua, Oodua Peopls Congress, OPC Dokita Frederick Fasheun ti jade laye.
Iroyin sọ pe alagba Faṣeun Jade laye ni owurọ ọjọ abamẹta ni ileewosan nla fasiti ipinlẹ Eko, LASUTH ni Ikẹja.
WORLD AIDS DAY 2018: HIV/ AIDS kìí ṣe ìdájọ́ ikú mọ́
Ni ọjọ iṣẹgun ni wọn gbe e lọ si ileewosan naa fun itọju ki o to jade laye.
Ni ọdun 1938 ni wọn bii ni ilu Ondo, ni ipinlẹ Ondo.
Nigba ti o n fidi iroyin naa mulẹ fun BBC News Yoruba, alamojuto apapọ fun OPC to tun jẹ Aarẹ Ọna Kakanfo ilẹ Yoruba, Otunba Gani Adams ṣalaye pe lootọ ni Dokita Fasehun ti papoda.
Àwọn agbébọn pa àwọn ọlọ́pàá tó wà lẹ́nu iṣẹ́ l'Abuja
Oríṣun àwòrán, AFP
Ìgbà àkọ́kọ́ kọ́ nìyí tí irú ìṣẹ̀lẹ̀ bẹ̀ yòó wáyé
Àwọn agbébọn ṣekupa àwọn ọlọ́pàá ní ìlú Abuja.
Awọn agbebọn naa ni iroyin ni wọn deede yabo awọn ọlọpa naa ni ikorita Galadimawa, loju ọna to lọ si papakọ ọkọ ofurufu to wa ni ilu Abuja.
Agbẹnusọ fun ileeṣẹ ọlọpa, ẹka ti ilu Abuja, Anjuguri Manzah fi idi iṣẹlẹ naa mulẹ.
Àwọn ti iṣẹlẹ naa ṣ'oju wọn ni ẹnu iṣẹ́ ni àwọn ọlọpaa naa wa lasiko ti awọn agbebọn naa dáná ìbọn fun wọn.
Ati pe ni nkan bi aàgo mẹsan alẹ́ ọjọ Ajé ni wọn bẹrẹ si ni yinbọn, to si tẹ́siwaju fun ọpọlọpọ iṣẹju.
Ọ̀gá ọlọ́pàá kó ikọ̀ kògbéregbè lọ sí Plateau
'Àwọn SARS ló yìnbọn pa ìyá mi'
ọ̀gá ọlọ́pàá sọ̀rọ̀ lórí SARS
Ara adugbo naa kan to sọrọ ni bo n kẹlẹ ni 'asiko ti awọn ọlọpa da awọn agbebọn naa duro lati ṣe ayẹwo ọkọ wọn, ni wọn bẹrẹ si ni yinbọn mọ awọn ọlọpa ọhun.
Eyi si ni igba keji laarin wakati mẹrinlelogun ti awọn agbebọn yoo doju ibọn kọ ọlọpaa.
Ilà kíkọ: Adetutu ní ilà tóun kọ̀ ni kò jẹ́ kí òun lọ ilé-ẹ̀kọ́ fásitì
Oríṣun àwòrán, @adetutuoj8811
Ni igba atijọ, asa ila kikọ jẹ ohun amuyangan ati ara oge sise fun tọkunrin-tobinrin ni ilẹ Yoruba.
Sugbọn o se ni laanu pe asa ila kikọ yii ti wa di ohun itiju nitori ọlaju to de ba wa. Adetutu Alabi jẹ ọkan ninu awọn obinrin ti asa ila kikọ ti ko ba lati ka iwe, pẹlu ọpọ ipa ti ko see sọ miran to tun ni lori rẹ.
Nigba to n salaye loju opo twitter rẹ, @adetutuoj8811, lori ohun ti oju rẹ n ri lawujọ nitori pe o kọ ila, Adetutu ni yẹyẹ, ẹsin ati itiju naa pọ debi gẹẹ, ti oun ko fi lee tẹsiwaju lẹnu ẹkọ oun.
Damilọla pàdánù ọ̀rẹ́kùnrin rẹ̀ nítorí ilà kíkọ
Iwọnba eeyan lo maa ni oye iru irora ti mo n jẹ ati ohun ti mo n la kọja. N jẹ mo sọ fun yin bi wọn se n yẹyẹ mi si titi debi pe mo taku lati lọ sile ẹkọ Yunifasiti? Mo jija gbara, ti mo si ja fita-fita ni ki n to lee ni ominira funra ara mi. Iru eeyan ti mo jẹ ree, ohun ti mo ba foju sun, o gbọdọ tẹ mi lọwọ
Adetutu ni ẹkọ imọ ofin (law) lo wu oun lati lọ ka ni fasiti, amọ oun ko tilẹ sopo gba fọọmu lati joko se idanwo Jamb, nitori ẹsin ti wọn fi oun se nile ẹkọ alakọbẹrẹ ati girama ti to gẹẹ, idi si ree ti oun fi lọ kọ isẹ ọwọ.
Ẹru n ba mi lati lọ si fasiti nitori yẹyẹ ti wọn maa fi mi se, koda, mo lee pa ara mi ti ẹsin yii ba tun pọ si, idi si ree ti n ko se ba wọn ya fọto nile ẹkọ girama nitori ila ti mo kọ.
Oríṣun àwòrán, @adetutuoj8811
Adetutu fi kun pe, o de asiko kan, ti oun lọ ba awọn obi oun lati mọ idi ti wọn se kọ oun ni ila, amọ alaye wọn ni pe ara asa ilẹ Yoruba ni ila kikọ, eyi ti yoo bu kun ẹwa oun.
O tun sọ siwaju pe ọpọ awọn alejo to ba ri oun ni wọn maa n sọ pe oun burẹwa, toun ba si n rin lọ loju popo nigba miran, awọn eeyan maa n fa oun sẹyin pe oun burẹwa, amọ ti awọn eeyan miran maa n gbeja oun.
Oríṣun àwòrán, @adetutuoj8811
Koda, ila kikọ yii ni Adetutu sọ pe o tun mu ki baba ọmọ oun kọ oun silẹ, nitori pe oju maa n tii lati ba oun rin loju popo.
Ara idi ti baba ọmọ mi fi kọ mi silẹ ni pe ko fẹ maa fi mi han loju taye. O si ni alẹ ni ki a maa pade. A pade ni ikọkọ fun osu diẹ lọdun 2008, ti mo si loyun lọdun 2009. Obinrin ni mo bi fun-un, ti yoo si pe ọdun mẹsan laipẹ.
Adetutu ni oun ro pe oun ni oun burẹwa julọ ni gbogbo agbaye, toun ko si fẹ ni ajọsepọ pẹlu ọkunrin kankan mọ tori alẹ nikan ni wọn fẹ maa ba oun jade.
Oríṣun àwòrán, @adetutuoj8811
Koda o ni ọkan tiẹ wa, ti oun ba jade fun ọdun meji, gbedeke to si fi lelẹ ni pe alẹ ni awọn yoo maa pade, ti oun si fara daa, toripe ọmọ ọdun mẹrin ni oun wa, ti iya oun fi ku, ajọ alaanu kan si lo wo oun dagba.
Lọwọ-lọwọ bayii, oriire ti gbe alawo re ko Adetutu, ti gbaju-gbaja olorin kan ni ilẹ Amẹrika, Rihanna si ti n fesi pada fun Adetutu lori ibeere rẹ lati ba Rihanna sisẹ pọ.
Ohun to kọju s'ẹnikan, ẹyin lo kọ s'ẹlomii ni ọrọ ila kikọ jẹ laaarin awọn ọmọ Yoruba, paapa lode oni.
Bi awọn kan ṣe gbagbọ pe ko si ohun to buru ninu ki obi kọ ila sọmọ loju, ni awọn kan gbagbọ pe aye ti laju kọja ki a maa kọ ọmọ nila.
Àmì ìdánimọ̀ àti oge ṣíṣe ni ilà jẹ́ nílẹ̀ Yorùbá
Arabinrin Sekinat Adekoge ni 'ohun amuyangan ni ila oju oun jẹ fun oun, lai fi ti eebu ti awọn eniyan maa n bu oun ṣe.
Ni ti Balkiss Yusuph, ila ti wọn kọ sii loju jẹ ki o padanu anfaani lati jẹ akẹkọ to jafafa, nitori pe oju maa n ti i lati dide soke dahun ibeere olukọ, debi wi pe o fẹ rẹ pa ileewe ti.
Damilọla pàdánù ọ̀rẹ́kùnrin rẹ̀ nítorí pé ó kọlà
O ni 'awọn ẹlẹgbẹ mi fi aye su mi, nigba ti mo wa ni kekere.'
Damilọla pàdánù ọ̀rẹ́kùnrin rẹ̀ nítorí ilà kíkọ
Ni ero ti @iamtito lori Instagram BBC Yoruba, 'a ko gbọdọ titori pe awọn to kọla n dojukọ idẹyẹsi, ka pa aṣa wa run.'
O ni 'orilẹede Indian ati China ṣi n ṣe amulo awọn aṣa wọn, lai fi ohunkohun ti ẹnikẹni ba sọ ṣe.'
Kàyéèfì ni ilá maa n jẹ́ fún àwọn tí kì í sẹ ọmọ Yorùbá
Ile aṣofin agba Naijiria ti gbe igbesẹ ri lati fi ofin de ila kikọ lode oni l'orilẹede Naijiria. Ọdun 2017 ni Sẹnetọ Dino Melaye to wa lati ipinlẹ Kogi kọkọ gbe aba ofin naa kalẹ niwaju ile igbimọ aṣofin.
Aba ofin naa n fẹ ki wọn o fi oju ọdaran wo ẹnikẹni to ba kọ ila tabi lọwọ si ila kikọ si oju ọmọde.
Amọṣa, aba naa ko ti i di ofin titi di asiko yii.
Ekiti2018: Ilé ẹjọ́ ni Fayoṣe kò láṣẹ láti f'òfin de Fayẹmi láti dupò òṣèlú
Oríṣun àwòrán, Ekiti state government
Fayose lo fi aṣẹ ijọba de Fayẹmi la ti maa dije fun ipo oṣelu
Ile ẹjọ giga kan nilu nilu Abuja ti wọgile abajade igbimọ iwadi kan ti ipinlẹ Ekiti gbe kalẹ, eleyi to fi ofin de gomina ipinlẹ naa tẹlẹ, Ọmọwe Kayọde Fayẹmi pe ko lẹtọ lati di ipo ilu mu mọ nipinlẹ naa.
Ẹgbẹ oṣelu Action Peoples Party, APP lo pe Kayọde Fayẹmi lẹjọ pe ko lẹtọ lati dije nibi idibo sipo gomina ipìnlẹ Ekiti ti yoo waye loṣu yii, nitori iwe aṣẹ ti ijọba ipinlẹ Ekiti gbe jade pe Fayẹmi ko lẹtọ l'abẹ ofin lati di ipo iṣejọba kankan mu nipinlẹ naa.
Ninu idajọ to gbe kalẹ ni ọjọ Iṣẹgun, Onidajọ O.A. Musa ni ipẹjọ ẹgbẹ oṣelu APP ko lẹsẹ nlẹ.
Oludasilẹ Alibaba, Jack Ma, gbé ìgbésè lórí PVC
'Òṣìṣẹ́ àgbà ọgbà ẹ̀wọ̀n di adigunjalè'
Onidajọ Musa ṣalaye pe Fayẹmi lẹtọ lati dije lasiko ibo gomina ipinlẹ Ekiti to n bọ lọna, nitori idajọ ile ẹjọ to ga julọ l'orilẹede Naijiria lori awọn ẹjọ to jọ iru eyi latẹyin wa ni pe, idajọ igbimọ oluwadi ko lee da ọmọ orilẹede Naijiria kankan duro lati maa lee dije fun idibo.
ọ̀gá ọlọ́pàá sọ̀rọ̀ lórí SARS
Ninu ọrọ to ba BBC Yoruba sọ, oludari ẹka iroyin nileeṣẹ ipolongo Kayọde Fayẹmi, Ọgbẹni Wọle Olujọbi ni idajọ naa kii ṣe kayefi fun awọn nitori awọn gbagbọ pe gbogbo igbesẹ ti ijọba Gomina Ayọ Fayoṣe gbe lori igbimọ iwadi naa lo ni ọwọ oṣelu ninu, ti ko si fara mọ eto idajọ ododo.
Akitiyan lati kan si igun ijọba ipinlẹ Ekiti lori ọrọ naa ko so eso.
D'Banj: A dúpẹ́ fún ìfẹ́ yín
Oríṣun àwòrán, Instagram/iambangalee
Oṣù tó kárùún ọdún ní Daniel pé ọmọ ọdún kàn
Ìlúmọ̀ọ́ká olórin tàkasúfèé ọmọ Nàìjíríà, Ọladapọ Oyebanjọ tí gbogbo ènìyàn mọ̀ sí D'Banj ti pàpà fọhùn síta nípa ikú ọmọkùnrin rẹ̀.
Bí ẹ bá rántí, D'banj pàdánù ọmọ ọdún kan rẹ̀ ní ọjọ́ kẹrìnlélógún oṣù kẹfà ni ọmọ náà fayé sílẹ̀ tí àwọn ènìyàn sì ń tàn án kálẹ̀ pé inú adágún omi ìgbafẹ́ tó wà nínú ilé D'Banj ni ọmọ náà kú sí.
Àwọn olórin Nàìjíríà kẹ́dùn ikú ọmọ DBanj
Ẹbí D'banj sọ̀rọ̀ lórí ikú ọmọ ọdún kan rẹ̀
Láti ìgbà náà, ìdílé D'Banj kọ̀ láti bá àwọn oníṣẹ́ ìròyìn sọ̀rọ̀ tábi tẹ ohunkóhun jáde sórí ẹ̀rọ ayélujára.
Nígbàtí akọ̀ròyìn BBC sèbẹ̀wò sí agbo ilé wọn, àti D'Banj, àti ìyàwó rẹ̀, wọn kò kó fìrí ẹnikẹ́ni nínú wọn.
Ẹ̀wẹ̀ lónìí, D'Banj ti fi okun kún okun láti sọ̀rọ̀ jáde sí gbogbo ará ìlú.
D'Banj fọhùn lẹ́yìn ọjọ́ mẹ́wàá tí ó pàdánù ọmọ
Macron: Èróńgbà láti se àtìpó ní Yúróòpù kò leè jọ àyàfi...
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ko tii si eyikeyi ninu awọn orilẹede Afirika ti o tii gba ki ibudo naa wa ni ilẹ wọn
Aarẹ orilẹede France, ti fi to BBC leti pe, erongba ajọ awọn orilẹede Yuroopu lati gbe ibudo ayẹwo kan si agbegbe ariwa ilẹ Afirika, fun awọn ọmọ Afirika to fẹ lọ ṣe atipo nibẹ ko lee duro.
O ni ayafi bi awọn orilẹede tọrọ kan ba lewaju irufẹ igbesẹ bẹẹ  lo to lee di ohun.
Lasiko abẹwo rẹ si ilu Eko, Emmanuel Macron tẹnumọ ipinnu orilẹede France lati ran awọn orilẹede Afirika lọ́wọ́ ni idi sise amojuto ipenija to rọ̀ mọ́ ọrọ ati lọ ṣatipo loke okun.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Macron ni awọn Afirika lo lee damọran lori bi iyanju yoo ṣe ba ipenija atipo
Amọṣa, o ni ilẹ Afirika lo lee wa ojuutu si iṣoro naa nitori a kii mọ ọṣọ ju iya ọṣọ lọ.
Aarẹ Macron ṣalaye pe ọrọ ipenija to rọ̀ mọ́ lilọ ṣatipo awọn ọmọ Afirika nilẹ Yuroopu, ko sẹṣẹ maa waye ati pe ajọṣepọ laarin awọn orilẹede Yuroopu ati Afirika yoo ṣe pataki lati wa ojutu si iṣoro naa.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Macron wa lẹnu abẹwo si orilẹede Naijiria lọwọ yii
Ni oṣu kẹfa lawọn orilẹede Yuroopu fẹnuko lati gbe awọn ibudo ayẹwo kalẹ fun awọn atipo lẹkun ila oorun ilẹ Afirika.
Bi o ba ti ọwọ awọn ijọba ilẹ Afrika jade wa, yoo ṣe daadaa. O dun un ṣe lati maa gbe igbesẹ fun elomiran.  Awa orilẹede Yuroopu ni lati kọkọ gbe igbesẹ fun ara wa. Lori ọrọ yii, fun emi, ohun to ja ju kọ ni ki awọn eeyan maa fori la iku lati darapọ mọ orilẹede Yuroopu, idi gan si niyi ti mo fi n fẹ ki a ṣiṣẹ pẹlu awọn orilẹede to ba ilẹ Yuroopu pa aala lori okun Mediterranean ati iha gusu rẹ.
Amọṣa, ko tii si eyikeyi ninu awọnorilẹede Afirika ti o tii gba ki ibudo naa wa ni ilẹ wọn.
Lai Muhammed: Ó dìgbà tí a bá rí ìwé ìdájọ́ kí a tó sọ̀rọ̀
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ileẹjọ giga apapọ nilu Oṣogbo gbe idajọ kalẹ pe ki awọn aṣofin apapọ o bẹrẹ igbesẹ lati yọ aarẹ loye
Ijọba apapọ ti fesi lori idajọ ileẹjọ giga apapọ kan loni eleyi to paṣẹ pe ki awọn aṣofin apapọ bẹrẹ igbesẹ irọloye lori aarẹ Muhammadu Buhari.
Minisita feto iroyin, Alhaji Lai Muhammed ni ileeṣẹ aarẹ ko tii tẹwọ gba iwe idajọ naa ati pe iroyin ọhun ṣajeji si ijọba apapọ.
Mohammed fesi ọrọ yii lasiko to fi n ba awọn oniroyin sọrọ lẹyin ipade apapọ ọlọsọọsẹ igbimọ iṣakoso orilẹede Naijiria to waye ni ilu Abuja.
Iléẹjọ́ pàṣẹ f'áwọn asòfin láti yọ Buhari nípò
Àwọn Bísọ̀ọ̀bù Aguda figbeta lóri ìtàjẹ̀ sílẹ̀
 Mo ṣẹṣẹ n gbọ iroyin yii ni, o si di igba ti iwe idajọ naa ba tẹ wa lọwọ ki a to lee ṣe ohun kohun lorii rẹ.
Bi ẹ ko ba ni gbagbe, ni owurọ Ọjọọru ni ileẹjọ giga apapọ kan nilu Oṣogbo gbe idajọ kalẹ pe ki awọn aṣofin apapọ o bẹrẹ igbesẹ lati yọ aarẹ loye pẹlu bi amofin Kanmi Ajibọla ati ajafẹtọ araalu kan, Sulaiman Adeniyi ṣe pe ẹjọ pe ki ileẹjọ kan an nipa fun awọn aṣofin apapọ lati rọ Buhari loye lori ẹsun aini iwe ẹri ati ṣiṣe owo ilu baṣubaṣu.
rAPC: Àwọn èèkàn olóṣèlú APC kéde ẹgbẹ́ tuntun
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ni ọjọọru ni wọn kede ẹgbẹ yii ti wọn si yan Onimọẹrọ Buba Galadima gẹgẹ bii alaga rẹ
Igun kan ni ẹgbẹ oṣelu APC ti ya sọtọ pẹlu orukọ tuntun ti wọn pe ni Reformed All Progressive Congress, rAPC.
Ni Ọjọọru ni wọn kede ẹgbẹ yii ti wọn si yan Onimọẹrọ Buba Galadima gẹgẹ bii alaga rẹ.
Ninu ọrọ ti alaga tuntun na a ba awọn oniroyin sọ nilu Abuja, Galadima ṣalaye pe gbogbo akitiyan lati ba awọn alaṣẹ ẹgbẹ oṣelu APC sọrọ lo ja si pabo.
Onimọ ẹrọ Galadima woye pe ẹgbẹ oṣelu APC ti ja awọn eeyan orilẹede Naijiria kulẹ ni ọdun mẹta to fi wa lori oye.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Awọn onwoye n sọ pe awọn igun nPDP to darapọ mọ APC ṣaaju idibo 2015 ni wọn n ṣe agbatẹru igun tuntun yii
Alaga rAPC ni idojuti nla gbaa ni APC mu ba awọn eeyan to bẹẹ to fi jẹ wi pe ọpọ lo n tọka sii pe o buru ju iṣejọba to le kuro nipo lọ.
Awọn smọ Naijiria gbe ijọba le APC lọwọ pẹlu ireti pe yoo mu ileri rẹ gbogbo ṣẹ. O bani ninu jẹ lati sọ eyi pe lẹyin iṣejọba ọdun mẹta, ofo ọjọ keji ọja ni ireti wa ja si.
Ohun ti awọn eeyan n sọ ni pe awọn igun nPDP to darapọ mọ ẹgbẹ oṣelu APC lati ẹgbẹ oṣelu PDP ṣaaju idibo 2015 ni wọn n ṣe agbatẹru igun rAPC yii.
Bi ako ba ni gbagbe bi awọn eekan kan lẹgbẹ oṣelu PDP pẹlu ṣe bẹrẹ ẹhonu tiwọn niyi, eyi to mu wọn kuro ni ẹgbẹ oṣelu naa.
Ekiti Votes: Adó Èkìtì sọkutu-wọ̀wọ̀ fún ìpolongo ìbò PDP
Awọn alatilẹyin ẹgbẹ oselu PDP nipinlẹ Ekiti ati yika ilẹ wa Naijiria, ni ireti wa pe wọn yoo peju sibi ipolongo ibo naa,
Ilu Ado Ekiti ti n sọ̀kutu-wọ̀wọ̀ fun iwọde ita gbangba fun ipolongo ibo fun oludije fun ipo gomina ninu ẹgbẹ oselu PDP, Ọmọwe Kọlapọ Olusọla.
Se ni gbogbo àwọn oju popo to wọ ilu naa kun pitimu fun ero, ti ibudo ipolongo ibo naa, ikorita Ojumose,  ko si gba ẹsẹ.
Gbogbo awọn alatilẹyin ẹgbẹ oselu PDP nipinlẹ Ekiti ati yika ilẹ wa Naijiria, ni ireti wa pe wọn yoo peju sibi ipolongo ibo naa, koda, awọn kan ti fi ikalẹ si ibudo naa.
Bi o ti lẹ jẹ pe eto ipolongo ibo naa ko tii bẹrẹ, sibẹ, n se ara awọn ero to wa nibẹ n wa gale-gale pe ki ayẹyẹ naa bẹrẹ, ti aọn kan ninu wọn si ti n kọrin oselu.
Lara awọn eekan ẹgbẹ ti wọn n reti nibi ipolongo ibo naa ni alaga ẹgbẹ oselu PDP ni Naijiria, Uche Secondus
Aago mẹwa aarọ̀ọ ni wọn kede pe ipolongo ibo naa yoo bẹrẹ, amọ o dabi ẹni pe yoo lọ jai diẹ ko to waye.
Lara awọn eekan ẹgbẹ ti wọn n reti nibi ipolongo ibo naa ni alaga ẹgbẹ oselu PDP ni Naijiria, Uche Secondus, awọn gomina PDP, atawọn asaaju ẹgbẹ jakejado Naijiria.
Buhari: Aó wá àwọn olóṣèlú tó n fa rògbòdìyàn ní àwárí
Oríṣun àwòrán, @BashirAhmaad
Ọ̀pọ̀lọpọ ẹ̀mí àti dúkìá ló ti bá rògbòdìyàn lọ ní Nàìjíríà
Aarẹ Naijiria, Muhammadu Buhari ti di ẹbi awọn rogbodiyan to n ṣẹlẹ ni Naijiria ru awọn oloṣelu tinu n bi.
Buhari sọrọ naa lasiko to n kopa nibi ayẹyẹ ayajọ ileesẹ ologun, to waye ni ipinlẹ Borno.
Ninu atẹjade kan ti oluranlọwọ pataki fun un lori eto iroyin, Bashir ahmad fi sita lori Twitter, Buhari, bo tilẹ jẹ wipe ko tọka si rogbodiyan tawọn oloṣelu tinu n bi fa, O ni:
Ọpọlọpọ rogbodiyan lo ti waye ni awọn ipinlẹ kan, eleyi ti awọn oloṣelu tinu n bi, to si ti kuna ni gbogbo ọna, mọọ-mọ ṣe agbatẹru rẹ, pẹlu bi wọn ṣe n wa gbogbo ọna lati da wahala silẹ gẹgẹ bi ọna lati polongo ara wọn
A o wa wọn ri, a o si fi iya jẹ wọn gẹgẹ bi ofin ṣe la a kalẹ.'
Bẹ́ẹ̀ bá sì gbàgbé, onírúurú rògbòdìyàn ló ti wáyé ní orílẹ̀-èdè Nàíjíríà, èyí tó ti mú ẹ̀mí ọ̀pọ̀ èèyàn lọ.
Ìsẹ̀lẹ̀ Ghana: Fífi nkàn ọkùnrin Olùkọ́ seré ni ìbáwí ẹ̀sẹ̀ fáwọn akẹ́kọ̀ọ́bìnrin
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ẹsun ifipabanilopọ ni wọn yoo fi kan ẹnikẹni to ba ni ibalopọ pẹlu ọmọ ti ko tii to ẹni ọdun mẹrindinlogun ni Ghana
Ajọ to n mojuto eto ẹkọ l'orilẹede Ghana ti da awọn olukọ mẹrin, to n ṣiṣẹ nileewe kan ni ẹkùn Ashanti duro lẹnu isẹ, lẹyin ti wọn fi ipa mu awọn akẹkọbinrin lati fi nkan ọmọkunrin wọn ṣere gẹgẹ bi ibawi.
Dida ti wọn da wọn duro waye lẹyin abọ iwadi igbimọ olubaniwi nileeṣẹ eto ẹkọ ni ẹkùn Ashanti. Igbimọ naa lo ṣe iwadi gbogbo ẹsun hihu iwa ti ko t,ọ ti awọn akẹkọọ fi kan awọn olukọ wọn.
Ni ibẹrẹ ọdun yii, awọn akẹkọbinrin mẹwa  nileewe naa, fi ẹsun kan pe awọn kan lara awọn olukọ awọ, n fipa mu awọn lati maa fi nkan ọmọkunrin wọn ṣere titi ti wọn o fi da.
Bọ̀dé George: Ìpànìyàn ló yẹ ká dẹ́kun, ká tó máa du ààrẹ
Olukọ mẹsan lo farahan niwaju igbimọ naa, ṣugbọn wọn da ọ̀kan silẹ ninu wọn. Diẹ lara awọn akẹkọọ naa tu aṣiri bi ọkan lara awọn olukọ naa ṣe ni ki akẹkọbinrin kan fi ọwọ pa nkan ọmọkunrin rẹ titi to fi da lẹẹmeji ọtọọtọ.
Iléeṣẹ́ ọlọ́pàá ti gbé ọlọ́pàá tó pa kọ́pà l'Abuja lọ sílé ẹjọ́
Oríṣun àwòrán, @PoliceNG
Ripẹtọ peters yinbọn pa Angela Igwetu ni ọjọru ọsẹ yii, lalẹ o ku ọla ti yoo pari agunbanirọ rẹ
Iṣẹ ti bọ lọwọ ọlọpaa to yinbọn pa agunbanirọ kan, Angela Igweatu, lọjọru nilu Abuja.
Bakan naa ni ileeṣẹ ọlọpaa ni Ripẹtọ Bẹnjamin Peters yoo tun fi oju ba ile ẹjọ.
Kọmiṣọna ọlọpaa nilu Abuja, Sadiq Bello lo ṣalaye ọrọ yii nilu Abuja.
Kọmiṣọna ọlọpaa Sadiq Bello ni 'atimọle ni o wa bayii ni ireti ibẹrẹ igbẹjọ rẹ'.
O ni ko si idi fun Ripẹtọ naa lati yinbọn ati pe awawi ti ọlọpaa naa n ṣe pe agunbanirọ ọhun n pariwo fun iranlọwọ kii ṣe idi fun ibọn yinyin.
O ni awọn ọkunrin meji to wa ninu ọkọ naa sọ pe ile igbafẹ ni awọn ti n bọ pẹlu agunbanirọ to di oloogbe naa ki o to yọ ori sita lati inu ọkọ ati pe ko si ewu kankan to wu ki ọlọpaa naa to yinbọn.
Oríṣun àwòrán, IGWETU LINDA NKECHI/FACEBOOK
Linda Igwetu ti ọlọpàá yinbọn pa ni Abuja
"Ileeṣẹ ọlọpaa ti gbe igbesẹ gbogbo to yẹ, ọlọpaa ti yinbọn ti wa lahamọ, igbesẹ gbogbo fun ibaniwi ni a si ti pari.
Iṣẹ ti bọ lọwọ rẹ, o si ti farahan niwaju ile ẹjọ. O ti wa latimọle ni ireti igbẹjọ rẹ."
Kọmiṣọna ọlọpaa nilu Abuja ni ileeṣẹ ọlọpaa ko jẹ fi ọwọ pa oṣiṣẹ rẹ to ba tapa si ofin lori nitori gbogbo igba ni wọn n tẹẹ mọ wọn leti pe iwa ọmọluabi ṣe pataki lẹnu iṣẹ.
LASTMA: Ẹ̀rí la nílò láti fi òsìsẹ́ tó ń gba rìbá jófin
Ìjà ọlọ́pàá àti alápatà ni Bodija gbẹ̀mí Sulia aláìṣẹ̀ ni UCH
MKO Abiọla: Ilẹ̀ ń jèèyàn, kò sẹni ti kò ni kú, ọ̀run nìkan làrèmabọ̀!
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ohun kan lo so ọpọ awọn eeyan pọ ninu ero wọn nipa Abiọla, iyẹn ni idibo June 12, 1993
Ni ọjọ keje, oṣu keje, ọdun 1998 ni Oloye MKO Abiola jade laye.
Ọpọ lo mọ Abiola fun oniruuru ohun nigba aye rẹ: fun awọn kan oniṣowo nla ni; fun awọn miran alatilẹyin fun idagbasoke ere idaraya nilẹ Afirika ni bẹẹni fun àwọn miran, olowo ti n fi owo ṣaanu ni.
Amọṣa, ohun kan lo so ọpọ awọn eeyan wọnyii pọ ninu ero wọn nipa Abiọla, iyẹn ni idibo June 12, 1993 eleyi ti gbogbo onwoye gba pe oun lo jawe olubori, ṣugbọn ijọba ologun nigba naa ko gbe ijọba fun un.
Oríṣun àwòrán, @wura_abiola
Ọpọ lo mọ Abiola fun oniruuru ohun nigba aye rẹ
Àwọn ará ìlú Abiola ní Abẹokuta bá BBC sọ̀rọ̀
Igbesẹ ati kan an nipa fun ijọba ologun labẹ Ọgagun Sani Abacha lo mu ki Abiọla kede ara rẹ gẹgẹ bii aarẹ orilẹ-ede Naijiria lagbegbe Ẹ̀pẹ nilu Ibadan eleyi ti o di gbajugbaja gẹgẹ bii ikede ilu Ẹpẹ iyẹn 'Ẹpẹ Declaration'
Eyi lo mu ki wọn gbe e sọ si ahamọ fun ẹsun gbigbimọ ati ditẹ gbajọba ati gbigbe igbesẹ lati da hilahilo silẹ lorilẹ-ede Naijiria.
Oríṣun àwòrán, @mko_abiola
Kani MKO Abiola ko tii ku ni, ọdun yii ni ko ba pe ọdun mọkanlelọgọrin
Lẹyin ti Ọgagun Abacha ku ni oṣu kẹfa, ọdun 1998 pẹlu ireti pe Abiọla yoo gba itusilẹ ni iroyin kan seti araye ni ọjọ keje, oṣu keje, ọdun 1998 pe Oloye Moshood Kashimaawo Olawale Abiola ti jade laye.
Nigba naa, ohun ti awọn eeyan n sọ ni pe ohun mimu tii oyinbo ni oloogbe Abiola mu ti o fi dagbere faye, ṣugbọn ko tii si ẹni to tii fi idi eyi mulẹ.
Ka ni MKO Abiola ko tii ku ni, ọdun yii ni ko ba pe ọdun mọkanlelọgọrin.
Iku Abiọla yii bi ijọngban ati idarudapọ kaakiri ilẹ Yoruba ti ọpọ eniyan n fẹhonu han kaakiri, ti ọpọ ẹmi si ba iṣẹlẹ naa rin.
Ekiti Election: Pọpọ sinsin idibo n lọ lori lawọn wọọdi
'Aláàbọ̀ ara tó ń dari ọkọ̀ ojú pópó ní àìlera kìí ṣàrùn'
LASTMA: Ẹ̀rí la nílò láti fi òsìsẹ́ tó ń gba rìbá jófin
Ìjà ọlọ́pàá àti alápatà ni Bodija gbẹ̀mí Sulia aláìṣẹ̀ ni UCH
Buhari: Ohunkóhun kò le yẹ ìdájọ́ tílé ẹjọ́ dá fún Saraki
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Wọ́n fi ẹ̀sùn kan Saraki pé ṣe màgò-mágó nígbà tó n kéde dúkìá rẹ̀
Aarẹ Muhammadu Buhari ti fesi lori idajọ̀ ile ti ile jọ to ga julọ ni Nàìjíríà gbe kalẹ lori ẹsun ti wọn fi kan Bukọla Saraki.
Buhari ninu atẹjade kan to fisita loju opo ikansiraẹni Twitter rẹ ni, Aarẹ ile aṣofin agba Naijiria, Bukọla Saraki farada ìgbẹ́jọ́ to nira. Ṣugbọn nigbẹhin, o fi idi òdodo ara rẹ mulẹ.
Aarẹ Buhari ṣapejuwe ohun ti Saraki la kọja gẹgẹ bi ohun ti oun fun ra rẹ la kọja nigba mẹta ọtọọtọ to dije fun ipo aarẹ ṣaaju ọdun 2015.
O ni ''wọn yan oun jẹ, oun si lọ sile ẹjọ lẹẹmẹtẹẹta, nitori pe oun ni igbagbọ ninu agbekalẹ ofin. Ati pe ọpẹlọpẹ Ọlọrun ni nkan fi bọ si fun oun ni igba kẹrin.
Buhari ni ohunkohun ko le e yẹ idajọ ti ile ẹjọ naa gbe kalẹ lori ọ̀rọ̀ Saraki, nitori ko si bi ipenija ṣe le pọ to fun ẹka idajọ Naijiria, o jẹ ọkan pataki lara ohun to gbe eto iṣejọba tiwa-n-tiwa ro, ti ẹnikẹni ko si gbọdọ ki ọwọ́ bọ ọ l'oju.
FFK: Buhari ló ń fún àwọn Fulani láàyè láti máa pa ènìyàn'
Ajọ to n risi ihuwasi ọmọniyan, CCT, lo fi ẹsun kan Saraki lọdun 2015 pe o parọ́ lasiko to kede dukia rẹ ko to o di aarẹ ile aṣofin agba.
Ọjọ́ Ẹti ni ilé ẹjọ́ to ga julọ ni orilede Naijiria dajọ pe ki Bukọla Saraki maa lọ sile rẹ lalaafia, nitori pe awn ajẹri takoni to wa fun ẹsun ti wọn fi kan ko ni awọn ẹri to pojuowo.
#KẹmiAdeọṣunNYSC: Ìwádìí yóò bẹ̀rẹ̀ lóri ayédèrú iwé
Oríṣun àwòrán, NYSC/twitter
Wọn ni ìwádìí yóò bẹ̀rẹ̀ ní perewu láti mọ bi omi ṣe tẹ̀yìn wọgbín lẹ́nu lóri ọ̀rọ̀ náà.
Ajọ tó n ri si ètò àgunbaniro lórílẹ̀-èdè Nàìjíríà (NYSC) ti fèsì lórí awuywuye tó gbòde lóri ìwé ẹ̀rí ìsinlẹ̀ rú baba ẹni nípa Minisità fún ètò ìsúná Kemi Adeosun.
Wọn ni ìwádìí yóò bẹ̀rẹ̀ ní perewu láti mọ bi omi ṣe tẹ̀yìn wọgbín lẹ́nu lóri ọ̀rọ̀ náà.
CUPP: JJ Ọmọjuwa sọ ohun tí ìdàpọ̀ àwọn ẹgbẹ́ yìí yóò jẹ́
Ajọ náà ní ẹni tó ba ti pe ọmọ ọgbọn ọdun kò lè ni ànfààní láti sìnrú ìlú bàbá rẹ̀.
NYCS sọ èyí di mímọ nínú àtẹjáde kan tí adari èto ìfọ̀rọ̀léde Adeyemi Adenike fí síta, sàla[yé pé nínú akọsílẹ̀ àwọn, o fi han pe Adeosun kọ̀wé ránṣẹ́ láti gbààyè, sugbọn ìwádìí yóò wáyé lóri ọ̀rọ̀ náà.
Asiko ko dẹrun fun minisita fun eto iṣuna lorilẹede Naijiria, Kẹmi Adeoṣun lọwọlọwọ pẹlu iroyin kan to n ja kaakiri bayii pe ó lo ayederu iwe ẹri iyọnda kikopa gẹgẹ bi agunbanirọ.
Ileesẹ iroyin ori ayelujara kan, 'Premium times' lo gbee sita pe minisita naa ko ṣe isinruulu lẹyin to pari ẹkọ giga rẹ ni fasiti  Polytechnic of East London ni ilẹ Gẹẹsi, gẹgẹ bi ofin ṣe laa silẹ fun gbogbo awọn ọdọ ti ọjọ ori wọn ko tii to ọgbọn ọdun lorilẹede Naijiria.
Iwe iroyin naa ni lasiko ti minisita pari ẹkọ rẹ ko tii pe ọmọ ọgbọn ọdun ati pe lẹyin ọpọlọpọ ọdun ni arabinrin Adeọṣun to lọ gba iwe ẹri to wa fun awọn ti wọn yọọ lẹ kuro leto isinruulu nitori ọjọ ori wọn eleyi ti iwe iroyin naa ni iwadi awọn fihan pe ayederu ni.
"Ẹ̀wẹ̀, ọ̀rọ̀ náà ti ńtàn kálẹ̀ débi pé lorí ẹ̀rọ ayélujára, àti Kẹ́mi Adeọsun, àti ìjọba àpapọ̀ ni àwọn ọmọ Nàìjíríà ti ń nàka sí. Fún àpẹẹrẹ lójú òpò Twitter, ènìyàn kan sọ pé ""bí ó bá jẹ́ lóòótọ́ ni Mínísítà fún ètò ìsúná kò ṣìnrú ìlú tí ó sì mú ayédèrú ìwé ẹ̀rí jáde, kò tọ́ sí ipò tí ó wà bẹ́ẹ̀ sì ni wọ́n gbúdọ̀ rọ̀ọ́ lóyè."""
"Bákan náà, JJ Ọmọjuwà tẹ̀ẹ́ síta wípé ""dídákẹ́ Kẹ́mi Adéọ̀ṣun ti bábá pariwo ara rẹ̀. àwọn ẹ̀sùn tí wọ́n fi kàn án ti lóòrìn tó sùgbọ́n bí ó ṣe kan àwọn aṣòfin lórí ẹ̀sùn tí wọ́n ń fi kàn án, o tí wá sọ ọ di ọ̀rọ̀ tó le tí ǹkan gbúdọ̀ tibẹ̀ jáde"""
Gbogbo akitiyan BBC Yoruba lati kan si arabinrin Kẹmi Adeọṣun lati wi ti ẹnu rẹ lo jasi pabo nitori pe ipe si ori number ibanisọrọ rẹ gbogbo ti akọrọyin BBC ṣe ni o dun ṣugbọn ti ẹnikẹni ko gbe.
Bakanaa ni ileeṣẹ aarẹ pẹlu ko tii sọ ohunkohun lori ọrọ naa.
nigba ti BBC pe olubadamọran pataki fun aarẹ lori ọrọ iroyin, Ọgbẹni Fẹmi Adesina, o ni oun yoo sọrọ lori rẹ bi o ba ya.
Nibayii, ẹgbẹ oṣelu PDP pẹlu ti da si ọrọ naa ti wọn si ti n ke si aarẹ Buhari pe ko rọ Adeọṣun loye; ko si ṣe iwadi rẹ pẹlu ijiya to tọ bi aje iwa ibajẹ naa ba ṣi mọọ lori.
Ninu atẹjade kan ti ẹgbẹ oṣelu PDP fi sita, o ni asiko to fun aarẹ lati jẹwọ smọluwabi ti o n pe ara rẹ nipa fifaaye gba iwadi ti ko lọwọ ijọba ninu lori ẹsun iwa ibajẹ laarin awọn ọmọ igbimọ rẹ.
 A rọ aarẹ Buhari lati maṣe daabo bo Adesṣun gẹgẹ bii iṣe rẹ nigbakugba ti awsn eeyan to sun mọọ tabi jẹ oṣiṣẹ rẹ ba ti ko sinu ọgbun ẹsun iwa kotọ
Oríṣun àwòrán, @HMKemiAdeosun
PDP ni pupọ awọn ọmọ igbimọ iṣejọba Buhari lo ni ẹsun iwa ibajẹ lọrun wọn
Ẹgbẹ oṣelu PDP ni ọọyẹ to la lori ọrọ yii ti fihan pe ootọ n bẹ ninu awọn ọrọ ti ẹgbẹ oṣelu naa ti sọ ṣaaju pe, ibuba awọn agbalọwọ meri ati ọlọṣa to fi mọ awọn ti iṣẹ ọwọ wọn ko mọ ni iṣejọba aarẹ Buhari.
Bi a ko ba ni gbagbe, laipẹ yii pẹlu ni ileẹjọ giga kan nilu Oṣogbo gbe idajọ kalẹ pe lati faaye gba ile aṣofin apapọ pe ko bẹrẹ igbesẹ irọloye fun aarẹ lori awọn ẹsun kan ninu eyi ti a ti ri ẹsun to nii ṣe pẹlu iwe ẹri pẹlu.
Ìhà wo ní àwọn ọmọ orilẹ̀-èdè Nàìjíríà kọ si ọ̀rọ̀ yìí
Ọ̀pọ̀ àwọn ọmọ orílẹ̀-èdè Naàìjíríà ló ti ń nàka àlébù sí ilé iṣẹ́ ààrẹ pé kò wá wọ̀rọ̀kọ̀ fi sàdá lóri ọ̀rọ̀ Kẹ́mi Adeosun
Eyi ni ohun ti Femi Fani Kayode àti àwọn ọmọ Nàìjíríà míìràn sọ lori ọ̀rọ̀ náà
Oríṣun àwòrán, ogundamisi/twitter
Àwọn ọmọ Nàìjíríà ti gbé onírúurú àwòrán Kẹmi Adeọṣun nínú ẹ̀wù àgùnbánirọ̀ jáde lórí ẹ̀rọ ayélujára
Àwọn míràn tilẹ̀ ń nàka àlébù sí àwọn ọmọ ilé ìgbìmọ asòfin pe wọn mọ àṣírí ọ̀rọ̀ náà lásìkò ti wọn ń ṣe ìfọ̀rọwanilẹ́nu wo fún Kemi Adeosun, sùgbọ́n wọn bo ọ̀rọ̀ náà mọ abẹ́ aṣọ
Ọlọ́pàá Ondo: A ó ṣe àfihàn ọ̀rẹ́kùnrin Khadijat l'Ọjọ́rú
Àwọn ilé iṣẹ́ ọlọ́pàá Ìpínlẹ̀ Ondo sọ pé àwọn yóò ṣe àfihàn ọ̀rẹ́kùnrin Khadijat l'Ọjọ́rú.
Agbẹnusọ fun ile iṣẹ ọlọpaa Ipinlé Ondo Femi Joseph sọ pe o ṣeeṣe ki Adeyemi Alao to jẹ ọrẹkunrun khadijat  ọmọ Igbakeji Gomina Ipinle Ondo tẹlẹri, Alhaji Lasisi Olubọyọ fẹ lo fun oogun owo.
Alukoro fun ile iṣẹ ọlọpaa naa to ba BBC Yoruba sọrọ wipe ṣe gbe oku Khadijat sinu ile fun ọjọ mẹfa pe fun ifurasi.
Ṣugbọn o fidi rẹ mulẹ pe awọn ọlọpaa yoo duro de ayẹwo awọn dokita ki awọn to le sọ pato ohun to ṣẹlẹ.
FFK: Buhari ló ń fún àwọn Fulani láàyè láti máa pa ènìyàn'
Ìtúsílẹ̀ dé f'áwọn ọmọ tó jìn sí kòtò!
Ilé MKO Abiọlá di ibùgbé àwọ̀n asínwín
Àwọn ṣajẹ tó gbayì jù láwùjọ
O fi kun ọrọ rẹ pe awọn ọlọpaa yoo ṣe afihan afurasi naa l'Ọjọbọ.
Joseph ni o ti to ọsẹ mẹta ti awọn obi ọmọbinrin naa ti n wa lẹyin to kuro ni ile iwe giga fasiti Adekunle Ajasin University (AAUA) ti o n ti n lo si ile iwe lati lo ki ọrẹkunrin rẹ.
Kí lo kàn ìlànà iyansipo àti ìwé ẹrí NYSC lorílè-èdè Nàìjíríà?
Oríṣun àwòrán, @NGRSenate
Ile Asofin agba lagbara lati buwọlu tabi tapa si ẹnikẹni ti Aarẹ ba fi orukọ re sowo si wọn
Kí èèyàn tó gbà isẹ gẹgẹ bí Mínísítà lorílè-èdè Nàìjíríà, o ní àwọn ìlànà kàn tó gbọdọ tẹle.
Lẹ́nu ìgbà tí Nàìjíríà padà sí ìjọba alágbádá, àwọn èèyàn oríṣiríṣi ní àwọn aláṣẹ tí yan láti ṣíṣe pẹlú wọn.
Ṣùgbọ́n kíní òfin sọ nípa ṣíṣe àyẹwò fínífíní fún àwọn tí wọn bá yan sí  ipò àti wí pé kí ni ìlànà tí wọn là kalẹ kí èèyàn tó lè di ipò mú ní Nàìjíríà?
CUPP: JJ Ọmọjuwa sọ ohun tí ìdàpọ̀ àwọn ẹgbẹ́ yìí yóò jẹ́
Abala kéjìlélógóje òfin orílèèdè Naijirià fún Ààrẹ lágbára láti yan èèyàn sípo yálà gẹgẹ bí Mínísítà tàbí fún ipò míràn.
Ṣáájú kí o tó fí orúkọ ẹni náà ránṣẹ, àyẹwò fínífíní yóò tí wáyé lọdọ àwọn ilé ìṣẹ́ ọ̀tẹlẹ̀múyẹ́ láti mọ irú ẹni tíì ṣe.
Àyẹwò yìí, gẹgẹ bí nnkán tí agbẹjọro Kayode Ajulo sọ fún BBC Yoruba nínú ìfòròwánilénuwò, yóò kàn ''ìwé ẹ̀rí tí ẹni náà n gbé ká àti àyẹwò nnkán ìní rẹ.''
Oríṣun àwòrán, FACEBOOK/KAYODE AJULO
Labe ofin ko to ki eeyan sise lai ni iwe eri pe ko pari agunbaniro
''Bí oun gbogbo bá dúró ní ṣẹpẹ́, Ààrẹ yóò fí orúkọ ẹni náà ránṣẹ sí ilé aṣòfin àgbà.''
Agbẹjọro Ajulọ ní '' Ìdí tí a fí n ṣé àyẹwò yí ní kí iyansipo yí maba mú àbuku bá Ààrẹ tó yan ẹni náà sìpo.''
Lára àwọn ìlànà àyẹwò kí èèyàn tó lè di ipò mú ní Nàìjíríà pàápàá jùlọ ipò Mínísítà ni pé o gbọdọ ní ìwé èrí tó péye.
Labẹ òfin Naijiria, o ní oṣuwọn ìwé ẹ̀rí tí èèyàn lè fí di ipò yìí mú.
Oríṣun àwòrán, @ngrpresidency
Aare a ma yan awọn Minisita lati ba ṣíṣe
Fún ipò Mínísítà, abala mẹ́tàdínláàdọ́jọ sọ pé ẹni bá fẹ di ipò Mínísítà mú ''gbọdọ ní ìwé ẹrí eléyìí tó ṣé dédé òun tí wọn fí n gbà aṣojú ilé aṣòfin àgbà wọlè.''
Nínú ìwé òfin bákan náà, òfin sọ pé èèyàn lè ṣe aṣojú nílé aṣòfin àgbà tó bá tí ní ò kéré tán ìwé ẹrí ileewe gírámà.
Kò sí ìbi tí òfin náà tí sọ wípé èèyàn gbọdọ ní ìwé ikẹkọjáde yunifásítì tàbí ìwé erí pé o sìnrú ìlú labẹ ètò àgùnbánirọ̀ kí o tó lè jẹ aṣojú ilé aṣòfin àgbà.
Ti a bá fí eleyii ṣe oṣuwọn ipò Mínísítà, a jẹ wí pé ìwé erí yunifásítì tàbí ìwé ẹrí kikopa nínú ètò àgùnbánirọ̀ kò ṣe dandan.
Àlàyé akọkọ  ti Kayode Ajulo ṣé ní pé ''ẹnikẹni tó bá fẹ ṣé iṣẹ ní Nàìjíríà tí o sí parí ilé ẹkọ gíga yunifásítì tàbí ilé ìwé gbogbo n'isẹ (poly) gbọdọ sìn ìlú fún ọdún kàn. ''
''O se dandan kí o fí ìwé ẹrí isinlu hàn kí o tó lè gbà iṣẹ.''
Oríṣun àwòrán, @nysc_ng
Ajọ NYSC ko fi ojuure wo awọn to ba n ko lati kopa ninu eto isinlu ọlọdunkan
O tesiwaju pe ''fún iṣẹ aladani àti iṣẹ ìjọba ní òfin yìí wà fún labẹ́ ètò àgùnbánirọ̀. Ko sí sí ẹni ti yóò gbà èèyàn ṣíṣẹ́ tí kò ní bèèrè ìwé ẹrí yìí''.
Alaye ti agbejoro naa se fi han ni ṣoki pe ''bí èèyàn bá sì fẹ ṣiṣẹ́ fún ìjọba yálà gẹgẹ bí Mínísítà ní tàbí ní ipò míràn, bi o bá ti sọ wí pé òun parí ilé ẹkọ gíga yunifásítì, o di dandan kí o fí ìwé ẹrí pé o parí ètò àgùnbánirọ̀ han.''
Èèyàn kò lè di ipò mú ní Nàìjíríà tí o bá fi ìwé ẹrí gbarọgudu ṣọ́wọ́
Àyẹwò fún ẹni tó bá fẹ jẹ Mínísítà ni iwájú ilé aṣòfin àgbà má n n'ise pẹlú àyẹwò ìwé ẹrí ti ẹni náà fi ṣọwọ́ sí ilé.
Ilé a sì máa ṣe àyẹwò ìwé náà pẹ̀lú ìbéèrè lọwọ ẹni to bá fẹ jẹ́ ipò Mínísítà láti mo bóyá o kún ojú oṣuwọn.
Ti o bá dá ilé lójú wí pé ẹni náà kún ojú oṣuwọn ti kò sí ní àlébù kánkan yálà nípa ìwé ẹrí rẹ tàbí ìlera rẹ, ilé yóò buwọ́lù iyansipo rẹ tí yóò sì ní anfààní láti ṣíṣe pẹlú Ààrẹ.
Theresa May: A dúpé lọ́wọ́ Minisita fún isẹ́ tó se lásìkò rẹ̀
Oríṣun àwòrán, PA
Ìròyìn sọ pé ìkọ̀wéfipọ̀sílẹ̀ Boris Johnson tó jẹ́ Minisita fórọ̀ ilẹ̀ òkèèrè, ní Ilẹ̀ Gẹ̀ẹ́sì nííse pẹ̀lú 'Brexit'.
Minisita fọrọ ilẹ okeere ni Ilẹ Gẹẹsi, Boris Johnson ti kọ iwe fi ipo rẹ silẹ.
Iroyin so pe ikọwe fi ipo silẹ Boris Johnson to jẹ Minisita fọrọ Ilẹ Okeere ni Ilẹ Gẹẹsi niise pẹlu igbaradi orilẹede Britain lati kuro ninu Ajọ Isọkan Ilẹ Europe ( European Union) , eleyi ti wọn n pe ni  'Brexit'.
Boris Johnson ni ẹnikeji ti ipo rẹ gaju lẹyin olootu ijọba Ilẹ Gẹẹsi naa, Theresa May.
Ninu atẹjade kan,  Ile-isẹ Olotu Ijọba IlẹGẹẹsi (No 10 ) , dupẹ lọwọ Arakunrin Johnson fun isẹ ribiribi to se nigba to wa ni ipo, atiwipe wọn ko ni pẹ kede ẹni ti yoo gba ipo rẹ.
Iroyin fikun wipe ikọwefiposilẹ rẹ waye nigba to ku ọgbọn isẹju ti olotu naa yoo se ipade pẹlu awọn asofin ni Ile Igbimo Asofin Orilẹede naa nipa afihan ero rẹ tuntun lori ati kuro ninu Ajo Isọkan Europe ( European Union) naa.
Thailand: Gbogbo àwọn agbábọ́ọ́lù náà láti yọ kúrò nínú ihò
Ìtúsílẹ̀ dé f'áwọn ọmọ tó jìn sí kòtò!
Gbogbo awọn ogo wẹẹrẹ mejila to jẹ agbabọọlu ni orilẹede Thailand ni wọn ti doola ẹmi wọn lẹyin ti wọn ha si inu iwo lati bi ọsẹ meji sẹhin.
Ile isẹ ọmọogun ilẹ Thailand to fi ọrọ naa lede sọ wi pe omuwe kọọkan lo gbe awọn ọmọ naa jade ni ẹyọ kọọkan.
Ìtúsílẹ̀ dé f'áwọn ọmọ tó jìn sí kòtò!
Awọn omuwẹ ti ilẹ Thailand to bẹrẹ ni Ọjọ Isinmi lati doola ẹmi wọn, yọ mẹ́rin miran pẹlu awọn mẹrin ti wọn yọ tẹlẹ ni ọjọ keji igbiyanju lati yọ awọn ọmọ naa.
Oríṣun àwòrán, Alamy
Lẹyin ti wọn yọ mẹrin ninu awọn ọmọ naa ni ọjọ Isinmi, àwọn ẹlẹ́yinjú àànú ti yọ àwọn to ku kúrò nínú íhò.
‘Ki lo buru ninu keeyan wẹwu agbọta?'
Nibayii, iroyin sọ wi pe wọn gbogbo awọn omuwẹ mẹrin ati dokita to tọju awọn ọmọ naa ni inu iho ti wọn ha si ti jade si ita kuro ni inu iho ohun.
Ekiti decides: Oshiomole fẹ̀sùn kan Fayose
Ààrẹ Muhammadu Buhari, Bola Tinubu àti àwọn adarí ẹgbẹ́ òsèlú APC wà ní àsekágbá ìpolongo ìdìbò gómìnà lábẹ́ òsèlú APC ní ìpínlẹ̀ Ekiti.
Alaga gbogbo-gboo fun ẹgbẹ oselu APC, Adam Oshiomole, ti fẹsun kan Gomina Ipinlẹ Ekiti, Ayọ̀délé Fayose pe, o n lo owo osu to yẹ ko san fun awọn osisẹ fun apo ara rẹ.
Oshiomọlẹ fi ẹsun naa kan Fayose ni ibi asekagba ipolongo idibo gomina fún Kayode Fayemi, tó n dije du ipo gomina labẹ ẹgbẹ oselu APC ni ipinlẹ Ekiti.
Adams Oshiomọle ni Gomina Ayo Fayose ń lo owó osù àwọn òsìsẹ́ fún ara rẹ̀
Aarẹ Muhammadu Buhari, Bola Tinubu ati awọn adari ẹgbẹ oselu APC pẹlu ọgọọrọ awọn ololufẹ wọn wa ni asekagba ipolongo idibo naa.
CUPP: JJ Ọmọjuwa sọ ohun tí ìdàpọ̀ àwọn ẹgbẹ́ yìí yóò jẹ́
Amọ, iroyin ni wipe bi o tilẹ jẹ pe gomina Fayose kéde ìséde ni ìpínlẹ̀ Èkìtì,  sugbọn awọn eniyan si jade lọ si ibi ipolongo idibo naa.
Joseph Hanlon: Ogójì tọ́ọ́nù heroin ló ń gba Mozambique kọjá
Oríṣun àwòrán, iStock
Pupọ lara ogun oloro to n wọ ilẹ Europe n wa lati Mozambique.
Apo oogun oloro to to ogoji n gba orilẹede Mozambique ni ọdọọdun, Onimọ Joseph Hanlon lo sọ bẹẹ.
Iwadi ti Hanlon lati Mozambique se fihan wipe, orilẹede Mozambique ni orilẹede kẹta ni agbaye, ti wọn ti n gbe oogun oloro kuro lorilẹede naa lo si omiran pẹlu iranwo oju opo ikansiraẹni Whatsapp.
Hanlon ni awọn onifayawọ naa n gbe oogun oloro lati Afghanistan lọ si guusu-iwọ oorun Pakistan, lati ibẹ lọ si ariwa Mozambigue nibi ti wọn ti n gba ọna ẹburu gbe wọ ilẹ Europe.
#EkitiDecides: Fayose sùn lórí ibùsùn aláìsàn
Iwadii fihan wipe awọn to n se isẹ fayawọ naa maa n ko o pamọ si inu paali, ti wọn si n lo atẹjisẹ lori ẹrọ ikansiraẹni Whatsapp lati ba ara wọn sọrọ pẹlu orukọ bii 555, Tokapi ati Africa Demand.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Orilẹede Afghanistan ni wọn ti n gbin ogun oloro, ti wọn a si gbe gba Mozambique lọ si Europe
Onimọ naa fi kun wipe, awọn onibara ma n ra oogun oloro heroin naa ni ọgọọrọ, ti wọn yoo si gbiyanju lati gba a ni orilẹede Mozambique, lẹyin ti wọn ba ti lo Whatsapp lati seto gbogbo nkan ti wọn nilo. Lẹyin naa ni won yoo pin heroin naa ka lo si Olu-ilu South Africa tii Johanesburg.
Ekiti Decides: Buhari ni òun kọ́ ló rán àwọn darandaran nisẹ
Nibi asekagba ipolongo ibo to waye ni Ọjọ Isẹgun ni ilu Ado Ekiti, ni Chris Ngige ti sìsọ pe kí wọn dá Fayose padà sípò lọ́jọ́ Satide .
Aarẹ Muhammadu Buhari ti ni, kii ṣe wi pe oun ko gbe igbese to lami-laaka lori isekupani awọn Fulani Darandaran nitori pe oun jẹ Fulani ni orilẹede Naijiria.
Buhari sọ eyi nibi asekagba ipolongo ibo to waye ni ọjọ isẹgun ni ilu Ado Ekiti fun Dokita Kayode Fayemi, to n dije dupo gomina ninu idibo ti yoo waye ni Ọjọ Satide, ọsẹ yii.
Nibi asekagba ipolongo ibo to waye ni Ọjọ Isẹgun ni ilu Ado Ekiti, ni Chris Ngige ti sìsọ pe kí wọn dá Fayose padà sípò lọ́jọ́ Satide .
Awọn leekan-leekan to wa nibi ipolongo ibo naa ni Gomina ipinlẹ Ogun, Ibikunle Amosun, Gomina Ipinlẹ Ọyọ, Abiola Ajimobi, Gomina ipinlẹ Osun, Rauf Aregbesola, Gomina ipinlẹ Ondo, Rotimi Akeredolu ati Yahaya Bello ti ipinlẹ Kogi.
Papa isere Oluyemi Kayode ni olu olu- ilu ipinle Ekiti,  Ado-Ekiti ni ipolongo ibo naa ti waye.
‘Ki lo buru ninu keeyan wẹwu agbọta?'
Iṣẹ́ ju iṣẹ́ lọ: Wọ́n ra Ronaldo ọmọ ọdún 33 ni £99m
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Cristiano Ronaldo ni agbábọ́ọ̀lù tó dàgbà jùlọ tí wọn yóò ra ní owó tó tó £99m
Agbabọọlu iwaju fun ikọ Real Madrid, Cristiano Ronaldo darapọ mọ ẹgbẹ agbabọọlu Juventus lẹyin ti Juve san £99m fun Real Madrid to ti wa.
Ṣugbọn ọpọlọpọ ololufẹ ere bọọlu lo ti n sọ pe owo naa pọ lati na lori agbabọọlu to ti pe ọmọ ọdun mẹtalelọgbọn.
Awọn kan ro pe ọjọ ori Ronaldo le ma gba laye lati fakọyọ fun ikọ Juventus fun igba pipẹ.
Ronaldo gba ayo 450 sawọn ninu ifẹsẹwọnsẹ 438 nigbati o wa pẹlu Real Madrid
O si gba ami ẹyẹ Idije Champions League pẹlu Real Madrid ni igba mẹrin.
Àdéhùn ètò ọrọ̀ ajé ilẹ̀ Afirika le lẹ́yìn
Ekiti Election: Ará Èkìtì ń fẹ́ gómìnà tí yòò tù wọ́n lára
Stella Akinsọ: Àwọn Ìwé Mímọ́ fi àsẹ sí ìfètòsọ́mọbíbí
Buhari: Mo gbọdọ̀ lọ́ra kàwé, kí ń tó buwọ́ lùú
Oríṣun àwòrán, Muhammadu Buhari/Facebook
lBuhari ní òun lọ́ra láti buwọ́ lu ìwe kankan nítorí èèyàn kìí kánjú lá ọbẹ̀ gbóná.
Ààrẹ Muhammadu Buhari ti gbá àwọn èèyàn tó ń pèé ní bàbá go slow pe òun ń lọ́ra láti buwọ́ lu ìwe kankan nítorí èèyàn kìí kánjú lá ọbẹ̀ gbóná.
Buhari ní òun kò tètè fọwọ́sí ìwé àdéhùn lóríi ètò ìdókówó ọ̀fẹ́ jádè-jádò àgbáyé, nítorí pé òun lọ́ra láti kàwé.
Buhari kéde ọ̀rọ̀ yìí lásìkò tó ń gbàlejò ààrẹ orílẹ̀-èdè South Africa, Cyril Ramaphosa.
Okunrounmu: Ijọba Buhari jẹ ijiya Ọlọrun fun Naijiria
A gbọ́dọ̀ sọra nípa bíbu ọwọ́ lu àwọn ìwé àdéhùn tí yóò bá figa-gbága pẹ̀lú ètò ìgbani-sísẹ àti kárà-kárà ọjà ní orílẹ̀-èdè yìí, tó sì tún leè se àkóbá fún àseyọrí àwọn iléesẹ̀ ńlá-ńlá gbogbo nílẹ̀ yìí.
Mo lọ́ra láti kàwé, bóyá nítorí pé mo jẹ́ ajagun-fẹ̀yìntì ni. Èmi kìí tètè kàwé lásìkò, màá sì kàá dáa-dáa kí ń tó buwọ́ lùú.
Ekiti Election: Oludije PDP ní ìdigunjalè ọ̀sán gangan tí kò ṣẹlẹ̀ rí ni ìdìbò Ekiti
Oríṣun àwòrán, @Eleka
Emi kọ èsì ìdìbò INEC-Eleka
Elẹka yarí pé irọ́ ni èsì ìdìbò INEC.
Oludije si ipo gomina ni abe ẹgbẹ oselu PDP, Olusọla Eleka ni oun n gba ileẹjọ to n dajọ ọrọ eto idibo ni Naijiria lọ lati koju esi idibo to gbe Kayde Fayemi wọle.
Oríṣun àwòrán, @PDP
PDP: Gbogbo ènìyàn mọ̀ pé ipá àti agídí ni APC fi gbà káàdì àwọn oludibo Ekiti
Ẹlẹka ninu atẹjade to fi lede so pe oun ti fi ọwọ osi da esi idibo naa nu nitori pe oun gbagbọ pe oun lo jawe olubori gẹgẹ bi gomina ni ipinlẹ Ekiti.
Bakan naa ni ẹgbẹ oselu PDP ti gbogbogbo fi àtẹ̀jáde síta pé APC ṣe màgòmágó nínú ìdìbò Ekiti.
Ekiti Election: Kọmísánà fétò ìdìbò ní jàǹdùkú já àpótí gbà ní wọ́ọ́dù mẹ́fà
Kola Ologbodiyan to jẹ akọwe apapọ ẹgbẹ oṣelu Peoples Democratic People to fọwọ si atẹjade naa ni akọ okuta ni PDP ti ibo Ekiti ko lee fọ rara.
O ni PDP kọ esi idibo to gbe Fayẹmi wọle patapata nitori pe àjọmọ̀ INEC ati APC atawọn oṣiṣẹ eleto aabo lo bi madaru to ṣẹlẹ l'Ekiti.
Kola ni esi idibo to jẹ ògidì to wa lọwọ PDP lori idibo Ekiti fihan pe Eleka Olusola to dije labẹ PDP lo wọle gegẹ bii gomina ipinlẹ Ekiti ni eyi to yatọ si ti ajọ INEC.
O ni iwa ipá ni awọn APC atawọn oṣiṣẹ eleto aabo lo fawọn eniyan PDP atawọn ara Ekiti.
Kola Ologbodiyan lorukọ ẹgbẹ oṣelu PDP ni àwọn ti n to gbogbo ẹ̀rí wọn jọ pẹlu gbogbo esi ti awọn oṣiṣẹ PDP ni l'Ekiti papọ .
O ni laipẹ ni wọn yoo fi ẹ̀rí yii gba ipo PDP pada fun Olusola Eleka to yẹ ko wọle idibo naa l'Ekiti.
Kola ni PDP yoo kede igbesẹ ti wọn fẹ gbe lẹyin ti wọn ba pari àtòjọ ẹ̀rí wọn.
Ẹgbẹ alatako gboogi lorilẹ-ede yii, PDP, ti n pọnju kẹkẹ si rogbodiyan to waye ni ipinlẹ Ekiti ni ọjọbọ, ti wọn si n kede pe eto iselu wa ni Naijiria n mi lẹsẹ.
Awọn asaaju ẹgbẹ oselu naa, to fi mọ alaga wọn, Uche Secondus to siwaju ifẹhonu han naa, lo lọ si olu ileesẹ ajọ eleto idibo, INEC ati ile asofin apapọ ilẹ wa lati gbe iwe ẹsun wọn kalẹ siwaju awọn asofin naa lori bi ileesẹ ọlọpaa ilẹ wa se kọlu gomina ipinlẹ Ekiti, Ayọdele Fayose ni ilu Ado-Ekiti.
Oríṣun àwòrán, @PDPOfficialNIG
Kiko ọpọ ọmọ ogun lọ si tibu-tooro ipinlẹ Ekiti ko ba PDP lara mu
PDP ni aimọye igba ni ijọba aarẹ́ Muhammadu Buhari ti n dun kooko mọ eto isejọba awa ara wa, to si n tubọ̀ fẹju si ni ojoojumọ, paapa ni bayii ti eto idibo gomina ni ipinlẹ Ekiti n sunmọle.
Wọn ni ajọ eleto idibo ilẹ wa ati awọn ileesẹ agbofinro ti yẹsẹ kuro loju opo ofin isẹ wọn, to si ti foju han pe ijọba apapọ ilẹ wa fẹ́ se mago-mago ninu eto idibo naa.
Oríṣun àwòrán, @OfficialPDPNig
PDP ni ajọ eleto idibo ilẹ wa ati awọn ileesẹ agbofinro ti yẹsẹ kuro loju opo ofin isẹ wọn,
#EkitiDecides: 'Ìjà ẹgbẹ́ òkùnkùn ló ń ṣẹlẹ̀ kìí ṣe ti òṣèlú'
Oríṣun àwòrán, @PDPOfficialNIG
Ẹsun bi ajọ eleto idibo Inec se n segbe si ibikan ko tẹ PDP lọrun
1. Ikọlu ati ọyaju si gomina ipinlẹ Ekiti, Ayọ Fayose lati ọwọ awọn ọlọpaa, osisẹ ọtẹlẹmuyẹ, awọn ologun ati ẹgbẹlẹgbẹ ọlọpaa kogberegbe.
2. Kiko awọn ẹsọ alaabo kuro lẹyin gomina Fayose saaju ki awọn agbofinro to taku si ẹnu ọna ile ijọba eyi to fidi rẹ mulẹ pe wọn n dete lati gbẹmi Fayose, ti wọn too si ni ibọn seesi baa ni.
3. Kiko ọpọ ọmọ ogun lọ si tibu-tooro ipinlẹ Ekiti pẹlu akọsilẹ to fi han pe ẹgbẹrun lọna ọgbọn ọlọpaa, ẹgbẹrun marun ọmọ ogun ati ẹgbẹrun mẹrin ati aabọ osisẹ ọtẹlẹmuyẹ ti wọn fi sọwọ si ipinlẹ Ekiti.
4> Bi ajọ eleto idibo INEC se n segbe si ibikan- Wọn ni awọn ti hu gbọ pe wọn ti pasẹ fun awọn osisẹ ajọ eleto idibo kọọkan lati ri daju pe oludije fun ipo gomina labẹ asia ẹgbẹ oselu APC lo jawe olubori ninu eto idibo naa.
5. Kiko janduku wọ ipinlẹ Ekiti - PDP ni ẹgbẹ-lẹgbẹ awọn janduku lo ti wọ ipinlẹ Ekiti lati awọn ipinlẹ to mule ti wọn bii Ọsun, Ondo ati Kogi, ti wọn yoo si lo wọn  lati maa dunkoko mọ awọn eeyan ipinlẹ Ekiti.
6. PDP wa n kesi awujọ agbaye ati awọn ololufẹ ijọba tiwa n tiwa lati gba aarẹ Muhammadu Buahri ni imọran pẹlu ọga agba ọlọpaa, ọtẹlẹmuyẹ, olori ile isẹ ọmọ ogun atawọn ile isẹ agbofinro yoku, ti yoo kopa ninu eto idibo ni ipinlẹ Ekiti, lati ri pe wọn ka ojulowo ibo tawọn eeyan ba di ni ọjọ Satide.
Ilé ìwòsàn UNN: Lóòótọ́ ọjọ́ ti lọ lórí omi náà, ẹ ma bínú
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Chidozie ni ọ̀rá omi mẹ́jọ ni wọ́n fún òun láàrin wákàtí méjìdínlógójì nígbà tí èsì àyẹ̀wò kò tí ì jáde
Akẹkọọ kan to wa ni ipele kẹta ni fasiti Nsukka (UNN), Chidozie Okonkwo ti fẹsun kan ileewe naa pe wọn fa omi t'ọjọ ti lọ lori rẹ si òun lara.
Chidozie to jẹ akẹkọọ imọ ede Gẹẹsi sọ fun BBC pe, iba diẹ lo mu oun toun fi lọ si ileewosan fasiti naa lọjọ karun, oṣu Keje 2018.
O ni ''nise ni wọn tun gba ẹgbẹrun kan aabọ Naira lọwọ oun fun ayẹwo ẹjẹ, lai fi ti pe oun ti san owo eto ilera mọ owo ileewe ṣe.
Igba ti yoo si fi di alẹ ọjọ keji, wọn ti fun Chidozie ni ọpọlọpọ abẹrẹ pẹlu omi mẹjọ, ki esi ayẹwo to ṣe to o jade.
Oríṣun àwòrán, @emmyskillful
Arabinrin Chidozie sare ya fọto omi naa nigba to ri i pe ọjọ ti lọ lori rẹ
Igba ti ikeji rẹ, Chiamaka wa bẹ ẹ wo nileewosan naa lo ṣakiyesi pe ọjọ ti lọ lori omi ti wọn n fa si ara ikeji rẹ lara.
Oṣu kinni, 2018 ni ọjọ omi naa ti pe. Eyi lo mu ko sare yẹ gbogbo ọra omi ti wọn ti fun tẹlẹ wo, to si jẹ pe bakan naa ni gbogbo wọn ri.
Idi si ree ti aburo Chidozie, Emmanuel se fi awọn aworan omi naa, to fi mọ ile iyagbẹ ileewosan ọhun soju opo Twitter.
Igbakeji ọ̀gá fasiti UNN, Ọjọgbọn Charles Arizechukwu Igwe ti wa ṣẹ kan lẹ pe ko s'ohun to jọ iru iṣẹlẹ bẹ ẹ ni fasiti naa.
"O ni ""mi o gbọ pe nkan bẹ sẹlẹ, ẹnikẹni ko si wa fi iru ẹjọ bẹ sun wa."""
Lootọ ni Chidozie ti n gba itọju nileewosan miran, sugbọn dokita to n tọju rẹ nileewosan tuntun ti wọn gbe e lọ, sọ fun pe akọ iba ati iba jẹdọ-jẹdọ lo n ṣe e. Ati pe omi t'ọjọ ti lọ lori rẹ ti wọn fa si lara ti mu ki kokoro kan, to n ba ile ìtọ̀ jẹ wọ agọ ara rẹ
Titi di asiko yii, ileewosan fasiti UNN ko ti i fun Chidozie ni esi ayẹwo to ṣe. Ṣugbọn wọn ti bẹ Chidozie ati arabinrin rẹ lati maa binu lẹyin ti wọn jẹwọ pe lootọ ni ọjọ ti lọ lori awọn omi ti awọn fa si lara.
Ekiti Election: Ará Èkìtì ń fẹ́ gómìnà tí yòò tù wọ́n lára
#EkitiDecides: 'Ìjà ẹgbẹ́ òkùnkùn ló ń ṣẹlẹ̀ kìí ṣe ti òṣèlú'
Ekiti Election: Pọpọ sinsin idibo n lọ lori lawọn wọọdi
Boko Haram: ile ejọ dá ẹ̀wọn ọdún 20 fún Banzana Yusuf
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ile Ẹkọ Chibok níbi ti ìjínigbé ti wáyé ní ọdún 2014
Ilé ẹjọ́ tí dájọ́ ẹwọn ogún ọdún fún ọdaran míran tó kópa nínú ìjínigbé àwọn ọmọbinrin Chibok.
Banzana Yusuf tó wá láti ìpínlẹ̀ Kano ní wọn sọ sẹwọn nitori pe, ó lọ́wọ́ nínú ìjínigbé àwọn akẹ́kọ̀ọ́ Chibok.
Ọdún merin sẹyín ní àwọn oniṣẹ ibi Boko Haram ji àwọn ọmọdebinrin gbe ni Chibok ni ìpínlẹ̀ Borno.
Wọn ti ri ninu awọn ọmọdebinrin naa ṣugbọn wọn ko tii pé.
Òun ní ẹnìkejì tí wọn ti se idajọ fún lẹ́yìn Haruna Yahaya ti wọn dájọ́ ẹwọn ọdún mẹ́ẹ̀dógún fún nínú oṣù kejì ọdún yìí ní ìpínlẹ̀ Niger lẹ́yìn ti wọn jẹ́wọ pe àwọn lọ́wọ́ nínú ìjínigbe náà.
Àwọn ọdaràn méjèèjì yìí wà lára ẹgbẹ́rún kan le ọkandínláàdọ́rinlélẹgbẹta àwọn ọmọ ikọ Boko Haram.
Ó ti di ènìyàn ogójìlénígba ti ìjọba tí sèdájọ fún láti oṣù kẹ̀wá ọdún tó kọjá lóri ìwà ìgbésùmọ̀mí.
Stella Akinsọ: Àwọn Ìwé Mímọ́ fi àsẹ sí ìfètòsọ́mọbíbí
Ekiti Election: Ìjọba ìbílẹ̀ làwọn òsìsẹ́ Inec yóó sùn mọ́jú ọjọ́ ìbò
#EkitiDecides: Sẹgun Adewale ní ìpèsè ohun ìdẹ̀rùn yóò bá ìfẹ́ aráàlú mu
Ekiti Election: Àwọn ohun èèlò ìdìbò ń dé síjọba ìbílẹ̀
Ekiti Election: Ẹ́gbẹ̀rún mẹ́rin nàirà ni ẹnikọ̀ọ̀kan ń gbà
Ekiti Election: Ẹ́gbẹ̀rún  mẹ́rin nàirà ni ẹnikọ̀ọ̀kan ń gbà
Fidio to wa loke yii lo n salaye bi awọn eeyan iluEkiti se n gba ẹgbẹrun mẹrin naira saaju ididbo gomina.
Ni bayii to ku wakati mẹrinlelogun pere ki eto idibo gomina ni ipinlẹ Ekiti bẹrẹ, BBC ri arigbamu pe awọn oloselu kan ti n pin owo fawọn oludibo ni ipinlẹ Ekiti.
Iyalẹnusi  lo jẹ ni ọsan oni nigba ti ikọ iroyin BBC se awari awọn eeyan kan ti wọn n rọ kẹti-kẹti lọ si ile ijọba atijọ to wa ladugbo Okesha ni ilu Ado Ekiti, tii se olu ilu ipinlẹ Ekiti.
Bi o tilẹ́ jẹ́ pe a tiraka lati mọ ẹgbẹ oselu to n pin owo naa fawọn oludibo, sugbọn idahun ikọọkan wọn yatọ sira.
Ninu iwadi ikọ iroyin BBC, a se awari rẹ pe kaadi idibo ni awọn eeyan naa mu dani, ti wọn fi n lọ gba ẹgbẹrun mẹrin naira ẹni kọọkan.
Bi o tilẹ́ jẹ́ pe a tiraka lati mọ ẹgbẹ oselu to n pin owo naa fawọn oludibo, sugbọn idahun ikọọkan wọn yatọ sira.
Ekiti Election: Àwọn ará Èkìtì ń fẹ́ gómìnà tí kò ní f‘ebi pa wọ́n
Bi ẹnikan se ni Fayẹmi ni, ni ẹlomin ni PDP ni, eyi ti ko jẹ ka ri arigbamu gidi.
Ori ẹrọ ibaraẹni sọrọ alagbeka ni wọn ti n pe ara wọn lati wa gba owo, ni ibamu pẹlu wọọdu ti ẹni kọọkan wọn ti wa.
Tọkọ-tayà Osinbajo kò gbẹ́yìn níbi ayẹyẹ ọjọ́ ìbi Folu Adeboye
Oríṣun àwòrán, Rccg/twitter
O ni àwọn ise ìrànwọ ti ó ń wọn se fawọn ọ̀dọ́ àti àwọn alaini kò lẹ́gbẹ́
Ìyá Adeboye jẹ́ àwòkọ̀ṣe rere fàwọn obínrin ìwòyí
Igbakeji ààrẹ orílẹ̀-èdè Nàìjíríà, Ọjọgbọn Yemi Osinbajo, tí dáwọ̀ọ́ ìdùnnú pẹ̀lú ìyàwó adari ìjọ ìràpada (Redeemed Christian Church of God), Olusọaguntan Folu Adeboye.
Oríṣun àwòrán, Osinbajo/twitter
Osinbajo dúpẹ́ lọ́wọ́ Mummy G.O, Folu Adeboye bí ó ṣe jẹ àwokọṣe fún àwọn obinrin
Oríṣun àwòrán, Osinbajo/twitter
O ni àwọn ise ìrànwọ ti ó ń wọn se fawọn ọ̀dọ́ àti àwọn alaini kò lẹ́gbẹ́.
Osinbajo ní ó jẹ́ ohun ìdunnu lati ni iru arabinrin Folu Adeboye lawujọ àwọn obínrin gẹgẹ bíi oniwàásù àti àwokose fawọn obinrin.
Ó rọ awọn obinrin lati ni suuru pẹ̀lú ẹbí wọn lai faaye gba iwa ipá ninu ile ati lawujọ pẹlu afiwe Iya Adeboye.
O ni àwọn ise ìrànwọ ti Iya Adeboye ń se fawọn ọ̀dọ́ àti àwọn alaini kò lẹ́gbẹ́.
Wo imọran Fọlọrunṣọ Alakija fun awọn ọdọ adulawọ
'Obinrin jẹ amuludun'
Igbákeji ààrẹ, Ọjọgbọ́n Yemi Osinbajo gbadura kí Ọlọrun túbọ̀ lọ́ra ẹ̀mí wọn
Oríṣun àwòrán, Osibajo/twitter
O ni àwọn iṣẹ́ ìrànwọ́ ti ó ń se fawọn ọ̀dọ́ àti àwọn alaini kò lẹ́gbẹ́.
Arabìnrin Folukẹ Adeboye pe ọmọ ààdọrun ọdún lori oke eèpẹ̀ lánàá.
Opọlọpọ eto ni awọn eniyan ṣe lati fi sami ayẹyẹ ọdun rẹ ti awọn èrò pupọ si n ki olukọ ati oniwaasu naa lori ayelujara kaakiri agbaye.
Ekiti Election: Awọn oludibo ko mọ idi ti wọn fi n yin tajutaju ni Okesha
Ọbẹ Ẹgusi sise ati jijẹ
Femi Adebayo: Ẹyin ọ̀dọ́, ẹ káàbọ̀ ságbo ilé Tíátà
Russia 2018: Ọjọ́ 11 ní à ò fí jẹun tí kò rí ibi sùn - Ọmọ Naijiria
Oríṣun àwòrán, Yulia Siluyanova
O ní nígbà ti ọ̀rọ̀ náà sẹlẹ̀ obinrin kan tó ń mójú to àwọn ti irú ìṣẹ̀lẹ̀ bẹ́ẹ̀ bá sẹlẹ̀ sí Yulia Siluyanova ló ti kọ̀kọ̀ bẹ̀rẹ̀ ìtọ́jú wọn kí ó tó pe òhun.
Ọ̀pọ̀ ọmọ Nàìjíríà tó ló ṣe àtìlẹyìn fún àwọn ikọ agbábọ̀ọ̀lù Naijiria ní orílẹ̀-èdè Russia ní wọn kò le padà wále mọ, lẹ́yìn ìdíje ti orílẹ̀-èdè Nàìjíríà ti fìdí rẹmi.
Igbà ènìyàn ló wà ní ilé iṣẹ asojú Nàìjíríà ní Russia nítorípé wọn o rí owó ọkọ̀ léyìn ìdíje ife ẹ̀yẹ àgbáyé 2018.
Nígba ti BBC Yoruba ba ọ̀kan lára àwọn ti ọ̀rọ̀ náà ṣẹlẹ̀ sí sọ̀rọ̀ sàlàyé pé, ìlé ìṣe àrìrinajó sí ilẹ̀ òkèrè kan to se ìforúkọsílẹ̀ fún àwọn ní kò ṣe ètò tó péye, tí pápákọ̀ òfurufú sì sọ pé kò sí ǹkan tí àwọn le ṣe síi.
Ẹtàn ni àwọn ọ̀rẹ́ fi ń tan èèyàn lọ si Libya pé iṣẹ́ gidi wà níbẹ̀
Ọ́ sàlàyé pé nígbà ti àwọn kọ́kọ́ dé bẹ̀, odidi ọja máàrun ni kò fi sí ounjẹ́ tàbí ibùsùn kí aṣójú Naijíríà lórílẹ̀-èdè Russia tó yojú.
World Cup: Ambode sanwo ènìyàn 50 ní Russia
O fi kún un pé, ọpẹ́lọpẹ́ Gomina ìpínlẹ̀ Eko Akinwumi Ambode tó wá sí Russia fún àṣekágbà ìdíje ifé ẹ̀yẹ àgbáyé ti 2018 ló síjú àànú wo àwọn ènìyàn lórúkọ ara rẹ̀.
Bákan náà ní BBC Yorùbá tún bá ọmọ Nàìjíríà kan tó fi orílẹ̀-èdè Russia ṣe ibùgbé Kehinde Oluremi sọ̀rọ̀, ó sàlàyé pé Akinwumi Ambode ló sanwó ìrìnà àwọn ènìyàn ààdọ́ta láti pada sílé láàná.
Russia 2018: Awọn alátilẹyin àgbabọọlu kò le pada sílé
O ní nígbà ti ọ̀rọ̀ náà sẹlẹ̀ obinrin kan tó ń mójú to àwọn ti irú ìṣẹ̀lẹ̀ bẹ́ẹ̀ bá sẹlẹ̀ sí, Yulia Siluyanova ló ti kọ̀kọ̀ bẹ̀rẹ̀ ìtọ́jú wọn kí ó tó pe òhun.
O ní ilé iṣẹ́ ilè òkèrè kan tí a ò fé dárúkọ ló sètò ìrìnà àlọ àtí ààbọ̀ wọn, sùgbọ́n ti wọ́n yọ owó náà pada kí àwọn tó dé pápákọ̀ òfurufú.
Oríṣun àwòrán, AFP
Russia 2018: Awọn alátilẹyin àgbabọọlu kò le pada sílé
Oluremi ní pé ‘Fan IDs’ wọn ló yẹ kí wọn lò, sùgbọ́n ó jẹ́ ohun tó yani lẹ́nu pé kò sí ọnà láti rìn irìnààjò, bótilẹ̀ jẹ́ pé ọ̀ọ̀fẹ́ ní Fan IDs jé láti orílẹ́-èdè Russia.
Olúrẹ̀mi sàlàyé pé àwọn yóò sa gbogbo ipá àwọn látí ríi dájú pé àwọn ènìyàn yìí padà sílé kí Fan ID wọn to parí iṣẹ́ ní Russia
O rọ gbogbo àwọn ẹ́lẹ́yinju àànú ní Nàìjíríà láti ran àwọn ènìyàn yìí lọ́wọ́, nítorí ìtìjú ló jẹ́ kí ìyà máa jẹ àwọn ọmọ Nàìjíríà ní ìlú onílùú.
Nígbà ti BBC Yorùbá kàn sí ilé iṣẹ́ Turkish Airline ti àwọn ènìyàn ọ̀hún fẹ̀sún kan, aṣojú wọn sàlàyé pé lọ́ọ̀tọ́ ní àwọn èrí to wà níwájú àwọn fí han pé ọks òfurufú àwọn ní wọn bá rin ìrìn àjò, sùgbọ́n àwọn kò tí le fídí ọ̀rọ̀ múlẹ̀ òṣíṣẹ́ tó wà ní ìdí ọ̀rọ̀ náa.
Ó ní ìwádìí tí ń lọ lọ́wọ́ lórí ẹ̀sùn tí wọn fi kan, pélú ìdánilójú pé àwọn yóò kan sí BBC padà lẹ́yìn ìwádìí.
Russia 2018: Belgium ti gba ípò kẹ̀ta Ife Ẹyẹ Agbaye
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Bí England se jà fitafita tó síbẹ̀ wọn ri ipò kẹ́ta mú
England ti fidi rẹmi nínú ife ẹ̀yẹ àgbáyé tó ń lọ lọ́wọ́ nígbati wọn wàákò pẹ̀lú Belgium ní ìrọ̀lẹ́ ọjọ Satide, ní St Petersburg.
Balogun ẹgbẹ́ agbábọ̀ọ̀lù Belgium Eden Harzard lo ran ikọ̀ rẹ̀ lọ́wọ́ látim gbégbá orókè, pẹlu bi ìfẹsẹ̀wọ́sẹ̀ náà se parí pẹ̀lú àmi àyò méjì si òdò
Bí England se jà fitafita tó síbẹ̀ wọn ri ipò kẹ́ta mú.
Ọjọ̀ Isinmi ni asekagba Ife Ẹyẹ Agbaye ti Russia 2018 naa yoo waye nigba ti ikọ ilẹ Faransẹ yoo ma a waako pẹlu ikọ orilẹede Croatia.
Ọbasanjọ: PDP bẹ̀bẹ̀ lórí ìwà àìda wọn sí mi
Oríṣun àwòrán, Getty Images
"Ọbasanjọ ti foriji PDP ni ibamu pẹlu ohun ti Bibeli sọ.''
Ẹgbẹ oselu Peoples Democratic Party, PDP, ti tọrọ aforiji lọwọ aarẹ ana, Oloye Oluṣẹgun Ọbasanjọ lori iwa 'buruku ti wọn hu si.'
Oluranlọwọ fun Ọbasanjọ, Kehinde Akinyẹmi lo fi ikede naa sita fun awọn akọroyin.
O ni alaga apapọ fun ẹgbẹ oselu PDP, Uche Secondus lo ko igbimọ ẹlẹni mọkanlelogun sodi, lati se abẹwo ikinni si ọdọ Ọbasanjọ.
Lara ohun ti Secondus tun gbekalẹ nibi ipade naa ni ti iwe adehun ti awọn ẹgbẹ kan fọwọ si, lati da ẹgbẹ oṣelu Coalition of United Political Party, CUPP, silẹ.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Alaga apapọ fun ẹgbẹ oselu PDP, Uche Secondus lo ko igbimọ ẹlẹni mọkanlelogun sodi, lati se abẹwo ikinni si ọdọ Ọbasanjọ.
Ẹwẹ, o ni alaga PDP ọhun tun rawọ ẹbẹ si Ọbasanjọ lati tẹsiwaju ninu wiwa ojuutu si awọn iṣoro to n dojukọ eto ọrọ aje orileede Naijiria.
Akinyẹmi ni, lootọ ni Ọbasanjọ ti foriji wọn ni ibamu pẹlu ohun ti Bibeli sọ, sugbọn ẹgbẹ alajumọṣe African Democratic Congress, ADC, ṣi ni yoo gbe e leke.
Secondus, to ba awọn akọroyin sọrọ lẹyin ipade naa fidi rẹ mul pe 'lootọ lawọn oloye ẹgbẹ PDP lọ si Abẹokuta lati ni ijiroro pẹlu ọbasanjọ lori eto idibo ọdun 2019.
O ni ṣiṣe ipade pẹlu ọbasanjọ se koko fun awọn lati gba imọran ati itọni lori imurasilẹ PDP fun idibo 2019.
Ekiti Election: NBC ní EKBC ń gbé ayédèrú èsì ìbò síta
Oríṣun àwòrán, @nbcgovng
NBC ni ileesẹ igbohun-safẹfẹ Ekiti n hu awọn iwa to tako ofin isẹ igbohunsafẹfẹ.
Àjọ tó ń se àkóso ètò ìgbóhùnsáfẹ́fẹ́ nílẹ̀ yì, NBC, ti sọ kọ́kọ́rọ́ sẹ́nu ọ̀nà iléesẹ́ ìgbóhùnsáfẹ́fẹ́ Èkìtì .
Ikọ iroyin BBC to wa ni ipinlẹ́ Ekiti ni, ajọ NBC pasẹ pe ki wọn ti ileesẹ igbohun-safẹfẹ naa pa nitori pe o n hu awọn iwa to tako ofin isẹ igbohunsafẹfẹ.
Ninu atẹjade kan ti ajọ naa fi sita ni alẹ ọjọ abamẹta ni eyi ti jẹyọ.
Ajọ̀ to n ri si eto igbohunsafẹfẹ lorilẹ-ede Naijiria ni,  bi gomina ipinlẹ Ekiti, Ayọdele Fayose se n kede awọn esi ibo ti ajọ eleto idibo ko fọwọ si, lo mu ki oun gbe igbesẹ naa.
Oríṣun àwòrán, @nbcgovng
Ajọ̀ NBC ni ileesẹ igbohunsafẹf Ekiti yoo si wa ni titi pa fun igba diẹ na.
Bakan naa ni NBC salaye pe, Fayose tun bọ sori afẹfẹ ileesẹ agbohunsafẹfẹ ipinlẹ Ekiti lati maa sọrọ abuku nipa ajọ eleto idibo ilẹ wa, Inec, ileesẹ ọlọpaa ati awọn osisẹ ọtẹlẹmuyẹ.
Ajọ̀ NBC ni ileesẹ igbohunsafẹfẹ Ekiti yoo si wa ni titi pa fun igba diẹ na.
Ekiti Election: Ẹgbẹ́ awakọ̀ Ekiti pa ìjọba dà lẹ́yìn tí wọ́n kéde Fayẹmi
Ekiti Election: Ẹgbẹ́ awakọ̀ Ekiti pa ìjọba dà lẹ́yìn tí wọ́n kéde Fayẹmi
Ẹgbẹ́ awakọ̀ Ado-Ekiti yọ àwọn alaga ẹgbẹ́ tó sé ti ìjọba Fayoṣe
Afi bi ere ori itage ni nilu Ado Ekiti to jẹ olu ilu fun ipinlẹ Ekiti lọjọ Aje, nigba ti ẹgbẹ awọn ọlọkọ èrò yan awọn alásẹ tuntun, eyi to ṣeese ko jẹ ni ibamu pẹlu ayipada to ba eto iṣejọba oloṣelu nipinlẹ naa.
Ekiti Election: Kọmisana feto idibo ni ibo kika si n lọ lọwọ
Loorọ kutukutu ni igun kan ninu ẹgbẹ awọn ọlọkada to n ṣatilẹyin fun ẹgbẹ oṣelu All Progressives Congress, APC, yabo ọpọlọpọ ẹka ile ẹgbẹ wọn lati le awọn alaga ẹgbẹ to wa ni iṣakoso.
Fayẹmi ti kọkọ jẹ gomina ipinlẹ Ekiti laarin ọdun 2000 si 2014
Kódà wọn yọ àwọn alatilẹyin wọn, ti wọn fi ẹsun kan pe wọn n ṣe ti iṣakoso Fayose, kuro.
Bakan naa ni ọrọ ri lọdọ ẹgbẹ awọn awakọ naa.
Awọn ọlọ́pà dìgbòlùjà ti lọ sí àwọn agbègbè tí ọ̀rọ̀ kàn
Abẹwo BBC Yoruba si adugbo Old Garage nilu Ado-Ekiti fihan pe ẹgbẹ tuntun to n ṣatilẹyin fun APC ti gbakoso ibudokọ naa, ti awọn ọmọ ẹgbẹ ti oniroyin BBC ri si n fi pankẹrẹ, waya ina ati orisirisi igi nakan-nakan loju opopona.
Ṣugbọn, wọn ti so okun aabo le lawọn agbegbe ti ọrọ kan, ti awọn ọlọpa digboluja ati awọn ọmọ ologun si wa ni ṣẹpẹ lati pa ina wahala to ba ṣeeṣe ko ṣuyọ.
Ààrẹ ilé ìgbìmọ̀ aṣòfin àgbà, Bukola Saraki ti fi àtẹ̀jáde síta lójú òpó Twitter láti kí Kayọde Fayẹmi kú oríire ìdìbò ìpínlẹ̀ Ekiti.
Saraki sọ pé O kú oríire Dókítà Kayode Fayemi, Gómìnà tí ìpínlẹ̀ Ekiti ṣẹ̀ yàn lórí àṣeyọrí rẹ nínú ìdìbò gómìnà lánàá. Ọlọrun alágbára yóò tọ́ ọ sọ́nà gẹ́gẹ́ bí o ṣe ń múra láti bẹ̀rẹ̀ iṣẹ́, bẹ́ẹ̀ sì ni àkòkò rẹ yóò mú ìdàgbàsókè wá síi fún ìpínlẹ̀ náà àti àgbéga bá ìgbé ayé àwọn ènìyàn""."
Àwọn Gómínà ẹgbẹ́ òṣèlú Peoples Democratic Party, PDP náà ti bẹ̀rẹ̀ sí kí olùdíje ẹgbẹ́ alátakò, Kayode Fayemi kú àṣeyọrí àbájáde ìdìbò ìpínlẹ̀ Ekiti gẹ́gẹ́ bíi gómìnà.
"Ẹgbẹ́ PDP sọ wí pé ""a fún ẹgbẹ́ wa àti olùdíje wa, Ọ̀jọ̀gbọ́n Kọlapọ Oluṣọla Ẹlẹka ní gbogbo àtìlẹ́yìn tó yẹ láti jáwé olúborí nínú ìdìbò Ekiti sùgbọ́n ó ṣe ni láànú pé a fìdí rẹmi. Nínú ayé, o lè borí, o sì lè kùnà nínú àwọn kan. A kí ajáwé olúborí, Dókítà John Kayode Fayemi kú oríire""."
Ẹgbẹ́ òṣelú All Progressive Congress ti kí Dókítà Kayode Fayemi tó jẹ́ olùdíje ẹgbẹ́ òṣèlú wọn fún àṣeyọrí rẹ̀ gẹ́gẹ́ bíi Gómìnà ìpínlẹ̀ Ekiti.
Ẹgbẹ́ òṣèlú náà jẹ́ kó di mímọ̀ pé Dókítà Fayẹmi ṣe ìpolongo ìbò tó dá lórí àlàkalẹ̀ rẹ̀ láti ṣe àtúntò ọrọ̀ ajé ìpínlẹ̀ náà àti dídá iyì, ìṣedéédé àtìwà ire rẹ̀.
A dúpẹ́ lọ́wọ́ ẹ̀yin ènìyàn ìpínlẹ̀ Ekiti pé ẹ tú yáyá láti dìbò fún olùdije ẹgbẹ́ wa''.
Ó jẹ́ àfihàn ìgbàgbọ́ àti ìgboyà tí wọ́n ní nínu ipá tí wọ́n ríi pé Kayode Fayemi ni láti ṣe gẹ́gẹ́ bí ó ṣe ṣèlérí nínú ìpolongo rẹ̀ àti bí ó ṣe kọ irú òṣèlú tí PDP ń ṣe.
Wọ́n ní ẹ́gbẹ́ àwọn wà ní ipò tó dára láti mú orílẹ̀èdè Nàìjíríà tẹ̀ síwájú.
Oríṣun àwòrán, Kayode Fayemi/Facebook
Ààrẹ Buhari kí Fayẹmi kú oríire
Ààrẹ Muhammadu Buhari naa ti kí Ọmọwé Kayọde Fayẹmi kú oríire fún àṣeyọrí rẹ̀ gẹ́gẹ́ bíi gómìnà tí ìpínlẹ̀ Ekiti yàn nínú ìdìbò tó ṣẹ̀ṣẹ̀ wáyé.
Lẹ́yìn ìpolongo ìdìbò ẹgbẹ́ APC, ààrẹ gbóríyìn fún olùdíje ẹgbẹ́ òṣèlú APC àtàwọn alátìlẹ́yìn ẹgbẹ́ fún iṣẹ́ takun takun tí wọ́n ṣe láti ja àjàyè.
Bákan náà, ààrẹ tún gbóríyìn fún àwọn àwọn ará ìpínlẹ̀ Ekiti pé ìhùwàsí wọn àti àláfíà gẹ́gẹ́ bí wọ́n ṣe fi àgbara ìtẹ̀ka wọn láti yan ẹni tí wọ́n fẹ́.
Sáájú, ajọ eleto idibo ti kede Kayode Fayẹmi to jẹ oludije fun ipo gomina ni ẹgbẹ oṣelu APC gẹgẹ bi oludije to jawe olubori ninu idibo gomina ipinlẹ Ekiti.
Alaga ajọ eleto idibo ni ipinlẹ Ekiti, Ọjọgbọn Idowu Ọlayinka to ṣe ikede naa sọ wi pe Kayode Fayemi bori pẹlu ibo 197,459.
O fidi oludije fun ẹgbẹ oṣelu PDP, Oluṣọla Ẹlẹka to ni ibo 178,121 janlẹ.
Eyi ni igba keji ti Kayode Fayemi yoo jẹ gomina ipinlẹ Ekiti.
Ẹlẹka jẹ igbakeji gomina to wa lori alefa lọwọlọwọ, Peter Ayodele Fayoṣe ẹni to fidi Kayode Fayemi rẹmi ninu idibo ọdun 2014 ni ipinlẹ naa.
06:37am At'agba at'ọmọde ni ijọba ibilẹ Ọyẹ ti oludije fun ipo gomina ni ẹgbẹ oṣelu APC, Kayọde Fayẹmi ti wa tu sita lowurọ kutu hai fun ajọyọ pe Fayẹmi n jawe olubori ninu idibo naa.
Awọn ọdọ ijọba ibilẹ Ọyẹ
06:46am Ni afẹmọju kaakiri oniruuru ijọba ibilẹ ati awọn ilu to wa ni ipinlẹ Ekiti, kedere ni oju awọn eniyan da ti wọn si n reti ki ajọ eleto idibo kede abajade esi ibo gomina lati mọ gomina wọn tuntun.
Awọn eniyan ipinlẹ Ekiti nreti esi idibo
'INEC, APC yi ibo'
05:34am Ẹwẹ, awọn alatilẹyin ati aṣoju ẹgbẹ oṣelu PDP to wa ni ile iṣẹ INEC nibi ti wọn ti n ka ibo sọ pe ajọ eleto idibo ti yi ibo da fun ẹgb oṣelu APC. Wọn ni ẹgbẹ oṣelu awọn lo gbe 'gba oroke, ko si ootọ ninu iye ibo ti wọn kede. Nitori naa, wọn n fẹ ki wọn so ikede esi naa rọ titi wọn yoo fi koju iṣẹlẹ to waye ni ijọba ibilẹ Ilejemeje.
Oludije fun ipo gomina nipinlẹ́ Ekiti labẹ asia ẹgbẹ oselu APC, Ọmọwe Kayọde Fayẹmi, lo gbegba oroke ninu idibo naa, to si fi ẹyin oludije latinu ẹgbẹ oselu alatako, to sun mọ pẹki-pẹki, Ọjọgbọn Olusọla Ẹlẹka janlẹ̀, ẹni to n soju fun ẹgbẹ́ oselu to n sejọba lọwọ ni ipinlẹ naa, PDP.
Ẹgbẹ oselu APC ni apapọ ibo to jẹ 197,459 nigbati PDP ni  178,115.
Ìbò 19,344 ni APC fi f'àgbà han PDP. Ijọba ibilẹ marun-un ni ẹgbẹ oselu PDP ti jawe olubori nigbati APC moke ninu ijọba ibilẹ mọkanla.
Bi o tilẹ jẹ pe eto idibo naa lọ ni wọọrọ wọ, sibẹ Kọmisana feto idibo nipinlẹ Ekiti fidi rẹ mulẹ pe awọn janduku kan si ja apoti ibo gba ni awọn agọ idibo bii marun si mẹfa lasiko eto idibo naa.
APC - 4,153, PDP- 3,937
APC - 12,342, PDP - 11,145
APC- 13,869, PDP- 11,456
4) Ijọba ibilẹ Ọyẹ́:
APC - 14,995, PDP - 11,271
APC - 5,028, PDP - 5,192
APC - 11,837, PDP - 8,520
APC - 14,192, PDP - 11,077
APC - 11,498, PDP - 8,027
APC - 7,048, PDP - 7,121
APC - 11,515, PDP - 17,183
APC - 12,648, PDP - 10,137
APC - 14,522, PDP - 13,961
APC - 11,908, PDP - 6,297
APC - 12,778, PDP - 11,564
APC - 11,015, PDP 8,423
APC - 28,111, PDP - 32,810
Oríṣun àwòrán, @APCNigeria
Ekiti Election: Fayẹmi bá BBC sọ̀rọ̀ gẹ́gẹ́ bíi gómìnà tí Ekiti yàn
Fayẹmi bá BBC sọ̀rọ̀ ní kété tó di gómìnà Ekiti
Ní kété ti àjọ elétò ìdìbò ìpínlẹ̀ Ekiti kéde Kayọde Fayẹmi gẹ́gẹ́ bíi gómìnà ìpínlẹ̀ Ekiti, Fayẹmi ti fi ọrọ ìdúpẹ̀ ránṣẹ́ síta sí gbogbo àwọn tó jẹ́ kí ìdìbò náà lọní ìrọwọ́rọsẹ̀.
Kayọde Fayẹmi jẹ́ kó dí mímọ̀ wí pé bí wọn ṣe lérò rẹ̀ náà ni ó ṣe rí.
Ìdùnú ṣubú l'ayọ̀ ní Ishan Ekiti, ìlú olùdíje fún ẹgbẹ́ òṣèlú APC John Kayode Fayemi nínú ìbò Gómìnà ipínlẹ̀ Ekiti.
Kété tí àjọ elétò  ìdìbò INEC kéde iròyìn àṣeyọrí rẹ̀ nínú ìdíje ọ̀hún ni àwọn olólùfẹ́ rẹ̀ bẹ̀rẹ̀ sí ní jó tí wọ́n sì ń kọrin.
‘Ko si ìdí fun 30, 000 ọlọpaa ni Ekiti’
Ekiti Election: Pọpọ sinsin idibo n lọ lori lawọn wọọdi
Nínú ilé rẹ̀ níbi tí òun àti àwọn gómìnà ẹgbẹ́ òṣèlú APC ti jọ wo ìkéde náà lórí ẹ̀rọ asọ̀rọ̀mágbèsì, n'íṣe ni àyọ̀ wọn kún.
"Nígbàtí ó  n bá àwọn olólùfẹ́ rẹ̀ sọ̀rọ̀, Fáyẹmí ní gbogbo ìpínlẹ̀ Ekiti ló ní àṣeyọrí yìí.""Mo fẹ́ fi dá a yín lójú pé gbogbo ohun tí a mọ̀ ìpínlẹ̀ Ekiti fún gẹ́gẹ́ bíi ìwà ìrẹ̀lẹ̀ àti àláfáà ni a ṣe tán láti mú padà wá."""
Fáyẹmí dúpẹ́ lọ́wọ́ gbogbo àwọn ará ìlú, àgbààgbà ẹgbẹ APC àti mọ̀lẹ́bí rẹ̀.
Fayemi saaju ikede
Nínú ọrọ tirẹ, gómìnà Ibikunle Amosun ti ìpínlẹ̀ Ògùn ní ìdìbò yìí ṣe àfihàn ìgbàgbọ́ tí àwọn ará ìlú ní nínú ẹgbẹ́ APC. Ó ní pẹ̀lú ìjáwé olúborí yìí, ẹgbẹ́ náà ti wá fi ẹsẹ̀ múlẹ̀ ní àwon ìpínlẹ̀ tó wà ní Gúúsù ìwọ̀ Oòrùn Nàìjíríà.
Gómìnà ìpínlẹ̀ Kebbi náà bá Kayode Fayemi yọ̀ lórí àbájáde èsì ìdìbò ìpínlẹ̀ Ekiti.
Ekiti Election: Àwòrán bí ètò ìdìbò gómìnà ṣe lọ ní Ekiti
Ẹ wo akojọpọ aworan bi eto idibo gomina ṣe lọ ni ipinlẹ Ekiti.
Ní kété tí àjọ elétò ìdìbò Nàìjíríà kédé ọ̀jsgban Kayode Fayemi gẹ́gẹ́ bí eni tó jáwé olú borí ni àwọn ará ìlú ti bó sí ìgborláti dáwọ̀ọ́ ìdùnú.
Aago mẹjọ̀ owurọ ni awọn oludibo ti jade lati yẹ orukọ wo ati iforukọsilẹ.
Awọn arugbo to lọwọọwọ lati yan eni ti wọn fẹ ko jẹ gomina wọn ni Ekiti.
Ẹgbẹ oselu marundinlogoji lo dije du ipo fun gomina ipinlẹ Ekiti ni ọdun 2018.
Ajo INEC leyin idibo naa sọ wi pe idibo naa lọ ni irọwọrọsẹ laisi si ifarapa.
PDP sọ wi pẹ idibo naa ko lọ ni irọwọrọsẹ atiwipe wọn ji ibo gbe ni awọn agbeegbe kan.
Witi witi ni awọn eniyan pe jọ lati gbọ esi idibo ni wọọdu ati ekun idibo wọn.
John ọmọ Fayẹmi sin ilẹ Naijiria ilẹ baba rẹ̀ gẹgẹ bii olukọni ni Police College to wa ni Ṣokoto lapa ariwa Naijiria.
Ile ti mọ, ta lo jawe olubori ni ibeere awọn eniyan ni owurọ kuto ọjọ keji idibo.
Ilú àdó Ekìtì ní àwọn ará ìlú ti gbòdé láti fi ìdúnú wọn han lóri èsì ìbò.
Kayode Fayemi ti ṣe gomina ipinlẹ Ekiti ri laarin Ọjọ kẹrindinlogun, osu kẹwaa, ọdun 2010 si ọjọ kẹẹdogun, osu kẹwaa, ọdun 2014.
Ní kété tí àjọ elétò ìdìbò Nàìjíríà kédé ọ̀jsgban Kayode Fayemi gẹ́gẹ́ bí eni tó jáwé olú borí ni àwọn ará ìlú ti bó sí ìgborláti dáwọ̀ọ́ ìdùnú.
Awọn eekan ninu ẹgbẹ oselu APC ni wọn ki Fayemi ku orire.
Awọn aworan naa wa lati ileesẹ BBC.
Ẹgbẹ́ awakọ̀ Ekiti fẹ́ pa ìjọba dà lẹ́yìn tí Fayẹmi di gómìnà
Oríṣun àwòrán, Lere Olayinka/Facebook
'Níṣe ni wọ́n fọ́n sí àárin ìlú, tí wọ́n sì bẹ̀rẹ̀ sí ni fi oríṣiríṣi nkan ìjà olóró bá ara wọn jà.'
Ìròyìn tó tẹ̀wá lọ́wọ́ sọ pé àwọn ọmọ ẹgbẹ́ awakọ̀, NURTW, ní ìpínlẹ̀ Ekiti, n da ìgboro ru.
A gbọ́ pe níṣe ni wọ́n fọ́n sí àárin ìlú, tí wọ́n sì bẹ̀rẹ̀ sí ni fi oríṣiríṣi nkan ìjà olóró bá ara wọn jà.
Ẹnìkan tí ìṣẹ̀lẹ̀ nàá ṣojú rẹ̀, Adeyẹye Ishọla, sọ fún BBC Yoruba pé àwọn kan lára ọmọ ẹgbẹ́ NURTW ọ̀hún ló fẹ́ yọ alága ẹgbẹ́ wọn tó ti wà nípò láti àsìkò ìṣàkóso gómìnà Ayọdele Fayose, tí àwọn alátìlẹyìn ti ẹ̀ nàá sì gbáná wojú wọn.
''Níṣe ni wọn kún gbogbo àárin ojú ọ̀nà, tí ẹnikẹ́ni kò si le kọjá. Ọ̀rọ̀ di ẹni orí yọ, ó dilé.''
 Mo ri i tí wọ́n n dáná sun àwọn ṣọ́ọ̀bù kékèéké tó wà ní ẹ̀gbẹ́ ojú pópó. Bákan nàá ni ipá àwọn ọlọ́pàá kò ká wọn, àyàfi ìgbà tí wọ́n tó ò kó àwọn ọlọ́pàá adìgbòlùjà, MOPOL, wá ni nkan ṣẹ̀ṣẹ̀ n rọlẹ̀.
"Ní bàyíì, wọ́n ti n dá àwọn ọ̀kọ̀ tó n wọ inú ìlú Ado-Ekiti, láti àwọn ìlú mi i  padà, kí wọ́n máà bà fi ara gbọta."""
Àwọn ọlọ́pàá mú ẹnìkan níṣojú mi, mí ò si le sọ bóyá ẹnikẹ́ni fi ara pa.
Oríṣun àwòrán, Lere Olayinka/Facebook
Ẹgbẹ́ NURTW n ja l'Ekiti
Nígbà tí a kàn sí iléèṣẹ́ ọlọ́pàá, alukoro iléèṣẹ́ ní ìpínlẹ̀ Ekiti, Caleb Ikechukwu, sọ pé lóòtọ́ ni òun gbọ́ pé rògbòdìyàn wáyé láàrin àwọn ọmọ ẹgbẹ́ awakọ̀, ṣùgbọ́n òun kò ní ẹ̀kúnrẹ́rẹ́ ìròyìn nípa rẹ̀.
Ṣùgbọ́n nínú ọ̀rọ̀ ti ẹ̀, akọ̀wé ìkéde fún ìjọba ìpínlẹ̀ Ekiti, Yinka Oyebọde, sọ fún BBC Yoruba pé, lóòtọ́ ni wàhálà nàá wáyé láàrin àwọn tó fẹ́ yọ alága ẹgbẹ́ NURTW.
Àmọ́, ìjọba ti dási i, tí àwọn aláṣẹ sì ti n bá igun méjèéjì ṣèpàdé láti yanjú àáwọ̀ nàá.
Ṣùgbọ́n, ìjà nàá ṣì n lọ lọ́wọ́ ní àsìkò tí a kó ìròyìn yíì jọ.
Afi bi ere ori itage ni nilu Ado ekiti to jẹ olu ilu fun ipinlẹ Ekiti lọjọ Aje, nigba ti ẹgbẹ awọn ọlọkọ eero yan awọn alásẹ tuntun, eyi to ṣeese ko jẹ ni ibamu pẹlu ayipada to ba eto iṣejọba oloṣelu nipinlẹ naa.
Loorọ kutukutu ni igun kan ninu ẹgbẹ awọn ọlọkada to n ṣatilẹyin fun ẹgbẹ oṣelu All Progressives Congress, APC, yabo ọpọlọpọ ẹka ile ẹgbẹ wọn lati le awọn alaga ẹgbẹ to wa ni iṣakoso, to fi mọ awọn alatilẹyin wọn, ti wọn fi ẹsun kan pe wọn n ṣe ti iṣakoso Fayose, kuro.
Bakan naa ni ọrọ ri lọdọ ẹgbẹ awọn awakọ naa.
Awọn ọlọ́pà dìgbòlùjà ti lọ sí àwọn agbègbè tí ọ̀rọ̀ kàn
Abẹwo BBC Yoruba si adugbo Old Garage nilu Ado-Ekiti fihan pe ẹgbẹ tuntun to n ṣatilẹyin fun APC ti gbakoso ibudokọ naa, ti awọn ọmọ ẹgbẹ ti oniroyin BBC ri si n fi pankẹrẹ, waya ina ati orisirisi igi nakan-nakan loju opopona.
Ṣugbọn, wọn ti so okun aabo le lawọn agbegbe ti ọrọ kan, ti awọn ọlọpa digboluja ati awọn ọmọ ologun si wa ni ṣẹpẹ lati pa ina wahala to ba ṣeeṣe ko ṣuyọ.
Operation Velvet: Ilé ẹjọ́ alágbéèká bẹ̀rẹ̀ láti fìyà jẹ́ awakọ̀ tó bá r'úfin
#Adetutu Alabi OJ: Mo ti gba kámú lórí ilà ojú mi
Iléesẹ́ ológun: Àwọn ọmọ-ogun ṣi wá gbọ́ lórí ìsípò-rọpò wọn ni
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Boko Haram: Awọn ọmọogun ò sọnu, enikan péré ló farapa
Àláfíà ti gbàjọba ní pápákọ̀ òfurufú táwọn ọmọogun orílẹ̀ gbà lánàá, láti fẹhonu han lóri bí wọn se pín wọn sí ibùdó tuntun fún iṣẹ́ wọn.
Igbákejì adarí alukoro fún àjọ ọmọogun ilẹ̀ 'Operation Lafiya Dole', Onyema Nwachukwu, ló fi ìdí ọ̀rọ̀ náà múlẹ̀ nínú àtẹjade kan pé, àwọn ọmọogun wọde ìfẹ̀honú hàn, sí bí ileesẹ ologun ṣe pín wọn fun iṣẹ́ ní Maoduguri, èyí dàbí ohun ti kò tẹ́ wọn lọ́rùn tó tó sì fa awuyewuye.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí:
Ìyá Darasimi: Ọlọ́run fi ìbejì rẹ̀ mí lẹ́kún, lẹ́yìn ikú Darasimi tó mu sódà
O ní àtúnpín àwọn ọmọogun yìí ṣe pàtàkì látàrí àbájáde ìwádìí ètò ààbò ní Maiduguri, sùgbọn o ṣe ni láànú pé, àwọn ọmọogun kan ṣi ọ̀rọ̀ náà gbọ́ ti wọn si bọ́ síta láti fẹ̀hónú hàn nípa yinyin ìbọn ní pápákọ̀ òfurufu nítorí wọn si ọ̀rọ̀ náà gbọ́.
Ẹ̀wẹ̀, o ní àláífìà ti jọba báyìí  sùgbọn àjọ ọmọogun kábàmọ pé irú ǹkan bẹẹ waye bí o ṣe kó ìpayà bá àwọn ará ìlú ní pápákọ̀ òfurufú.
Oríṣun àwòrán, @HQNigerianArmy
sẹlẹ yii lo mu ki awọn arinrin ajo Hajj to wa ni papakọ ofurufu naa, to fẹ wọ baalu lọ si Saudi Arabia, tete sa asala fun ẹmi wọn.
Boko Haram: Awọn ọmọogun ò sọnu, enikan péré ló farapa
Ilé iṣẹ́ ọmọogun orílẹ̀ tí kédé pé ìròyìn tó gbòde kan pé àwọn ọmọogun orílẹ̀-èdè Nàìjíríà pòórá ní ìjọba ìbìlẹ̀ Bama ní ìpínlẹ̀ Borno.
Ọmọogun orí ilẹ̀  sọ fun gbogbo ayé pé òtu bántẹ́ ní ìròyìn náà, òtítọ́ kan kò sí níbẹ̀, nítorí náà kí gbogbo èniyàn lọ fi ọkan balẹ̀ pàápàá júlọ àwọn to wà ní ìhà ìlà-oorùn - àríwá láti ketí ọ̀gbọin sí àhesọ ọ̀rọ̀ náà nítori pe ètò ààbò tó wà nílẹ̀ kò ni kọ́nukọ́họ nínú.
Nínú àtẹ̀jáde tó tọwọ́, tó jẹ́  adari alukoro fún ilé iṣẹ́ ọmọogun orílẹ̀, Texas Chukwu jáde sàlàyé pé lóòtọ́ ní àwọn ọmọogun ní ìdojúkọ Haram ní ìlú Chingori ní àgbègbè Bámá nípìnlẹ̀ Borno, tí wọn sì gbìyanjú láti gba mọ́tò sùgbọ́n àwọn ọmọogun ṣì dóju ìjà kọ wọn pẹ̀lú àṣeyọrí àti ìrànlọ́wọ́ àwọn ọmọogun ojú ofurufu Nàìjíríà.
Ó lé ní méjìlélógun nínú àwọn ìkọ̀ Boko-Haram ti wọn sọ di aláìlágbára nígbà ti ọ̀pọ̀ wọn sá lọ pẹ̀lú àpá ọta ìbọn, tí àwọn ọmọogun sì ń sapá láti rí àwọn ọmọ Boko Haram, bó tilẹ̀ jẹ́ pé ọmọogun kan sì ní àpá ìbọn sùgbọn ó ti wà ní ilé ìwòsàn ọmọogun tó ti ń gba ìtójú.
Ìlérí Fayemi lati san owó oṣù oṣìṣẹ́ l'Ekiti: ẹnu lásán kò lè ṣe é
Oríṣun àwòrán, @nbs
Odu ni Kayode Fayemi jẹ nidi iṣejoba ṣugbọn nnkan yato lasiko to pada wa yi
Àáyá bẹ sílẹ̀, ó bẹ́ sí aré ní Kayode Fayemi fẹ fí ipadabọ rẹ sì orí aleefa gẹgẹ bí Gómìnà ìpínlẹ̀ Èkìtì ṣé.
Láì tíì ṣe ibura wolẹ́ sí ilé ìjọba, o ti n pinnu láti sàn owó oṣù oṣiṣẹ láàrín oṣù mẹfa.
Ọ ni bi ìṣẹ́ òun òṣì ti peleke láàrin àwọn ará ìlú ko ṣẹyin bí ìjọba Fayoṣe tí kùnà láti san owó oṣù àwọn oṣiṣẹ.
Ìkéde yí jé òun ti o mú àriwisi otooto wà láàrin àwọn ará ìlú àti àwọn amòye.
Nínú èsì tí rè, Ọgbẹni Kola Bankole to je onimo nipa eto inawo so pe òun tó dáa ní kí ìjọba san owó ní kété ti oṣù bá parí fún àwọn oṣiṣẹ ṣugbọn ọ ti ya ju bi Fáyẹmí ti ṣe n ṣé ìlérí yí.
''Ko ti mò ipò tí akoto owó ijoba ipinle wa, bawo lo ti se fe san owo nigba ti ko ti mo awọn gbese to wa ni ile ati iye owo ti o''n wole fun ijoba ipinle ohun?''
Oríṣun àwòrán, Kola Bankole
Àwọn olóṣèlú a má ṣé ìlérí tí wọn kò ní lè mú ṣẹ fún ará ìlú lọpọ ìgbà
Ọgbẹni Kola ní lootọ ni pé Fáyẹmí tí je Gómìnà nígbà kan rí ṣugbọn bí nnkan ti ṣe n ló lẹnu ọjọ mẹta yí tí owó tó yẹ kí ìjọba àpapọ pin fun àwọn ìjọba ìpínlẹ̀ kò ti ni iyanju, yóò ṣòro kí Fáyẹmí le mú irú ìlérí bẹẹ ṣé.
''O kàn n sọ ọrọ òṣèlú ní. Sisan owo oṣù kọja afẹnuso. O gbọdọ ṣe àyẹwò dáadáa kí ọ sí mó irú owó tí ìjọba ti tẹlẹ fi sinu akoto ìjọba bi bee kọ, oun ati awọn osise yoo pada gbena wo oju ara wọn''.
Suleiman Akingbolu tó jẹ́ oṣiṣẹ ìjọba ìpínlẹ̀ ní ìlú Ekiti ni kò bá dá ti Fáyẹmí ba le mú ìlérí yí ṣé nítorí ará n ní àwọn oṣiṣẹ.
O ni ''ko yẹ ki awọn olosẹlu maa ka sisan owo osu gẹgẹ bi aseyori nitori ẹ̀tọ́ ni ki wọn gba owo lẹyin isẹ.''
Nígbà tí BBC béèrè pé báwo ní ìgbé ayé tí ṣe rọrùn laigba owó oṣù, Suleiman ní ìpeníjà nlá ní eyi jẹ fun awọn oṣiṣẹ.
Oríṣun àwòrán, @sgyemikale
Ìpínlè Èkìtì wà lára àwọn ìpínlẹ̀ tí o n gba owó tó kéré jù láti ọdọ ìjọba àpapọ̀
''Nnkán rọrùn díẹ fún àwa ti a n ṣé iṣẹ àgbẹ diẹdiẹ ṣugbọn fún àwọn tí kò ní ọnà míràn ìnira nlá ní àìrí owó oṣù gbà je''
Ìwádìí ilé iṣé BBC ṣé àfihàn pé oṣù kẹwa ọdún tó kọjá ní Gómìnà Fayoṣe san owó oṣù oṣiṣẹ ijoba ibile àti àwọn olùkọ kẹyìn.
Ni ti awọn oṣiṣẹ ìjọba ìpínlè àti olùkọ ilé ẹkọ gírámà, Oṣù kíni ọdún yi ni wọn gbà owó oṣù kẹyìn.
Khadijat Oluboyo: Ilé ẹjọ́ sọ ọ̀rẹ́kùnrin rẹ̀ sí gbaga
Khadijat Oluboyo: Ilé ẹjọ́ sọ ọ̀rẹ́kùnrin rẹ̀ sí gbaga
Olólùfẹ́ ti wọ́n ló pa ọ̀rẹ́bìnrin rẹ̀ fi ṣòògùn ní Akurẹ fojú ba ilé ẹjọ́.
Ilẹ ẹjọ kan nilu Akure ti paṣẹ ki arakunrin Adeyemi Alao ti wọn fẹsun kan pe o pa Khadijat ọmọ igbakeji gomina Ipinlẹ Ondo nigba kan ri, Alhaji Lasisi Oluboyo, lọ rọọkun naa lẹwọn.
Ọjọ Aje ni wọn gbe Adeyemi lọ ile ẹjọ kekere to wa ni Oke Eda, Akure, lori ẹsun pe o gbèrò lati pa Khadijat pẹlu awọn afurasi miran ti wọn ti fẹsẹ fẹ.Adajọ Victoria Bob-Manuel to gbọ ẹjọ naa sọ pe ile ẹjọ oun kò lagbara lati gbọ ẹjọ naa.
Ọlọ́pàá Ondo bá òkú ọmọ igbákeji gómínà tẹ́lẹ̀rí nílé Adeyemi Alao
Fun idi eyi, o ni ki Adeyemi lọ rọọkun lẹwon titi ti ẹka to n ri si ipẹjo (DPP) yoo fi gba ile ẹjọ ni imọran lori ọrọ naa.
Adajo ni ki wọn gbe Adeyemi pada siwaju ile ẹjọ ni ọjọ kẹrinlelogun oṣu to m bọ.Nigba ti awọn ọlọpaa gbe Adeyemi de ile ẹjọ, ṣe ni ero ya bo yara igbẹjọ lati wo afurasi naa.Sugbon ko si awọn ẹbi Khadijat kankan nibi igbẹjọ naa.
Bi a ko ba gbagbe Lẹ́yìn ọ̀sẹ̀ kan tí wọ́n ti ń wá Khadijat tó jẹ́ ọmọ igbákeji gómínà tẹ́lẹ̀rí ní ìpínlẹ̀ Ondo,ni wọ́n bá òkú rẹ̀ ní ilé àfẹ́sọ́nà rẹ̀, Adeyemi Alao.
Agbẹnusọ ileeṣẹ ọlọpaa Ipinlẹ Ondo ni awọn ṣi n wa awọn afunrasi to ku.
Ekiti Decides: Abiọdun Aluko ní báwọn se kàwé tó l‘Ekiti, ìyà sì ń jẹ àwọn
Ẹ̀kùn omi Katsina: Omi gbé òpó àti ọmọ mẹ́ta lọ
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ìṣẹ̀lẹ̀ omíyalé wọ́pọ̀ l'órílẹ̀èdè Nàìjíríà lásìkò òjò. Ó tí wáye ní ìpínlẹ̀ Ọyọ, Ogun ati Eko nàá.
Awọn olugbe ilu Jabiya nipinlẹ̀ Katsina, ṣi n ka ofo wọn lori iṣẹlẹ omiyale to waye nibẹ.
Ọpọlọpọ ile lo ṣi wa ninu ibanujẹ ti iṣẹlẹ ojo arọọrọda naa mu ba ẹbi wọn.
Bakan naa ni isẹlẹ ẹkun omi yii tun mu ẹmi ọmọ osu mẹta lọ.
Baba Khadijat Oluboyo jẹ́rìí ọmọ rẹ̀
Baba ọmọ naa, to ba BBC sọrọ salaye pe, idunnu ṣubu lu ayọ fun oun nigba ti iyawo oun bimọ yii, nitori pe oun ni akọbi wọn, ṣugbọn o jẹ nkan ibanujẹ pe omi gbe e lọ.
Ohun to tun ba ni lọkan jẹ nipe ko ni aworan ọmọ naa, nitori aworan kan ṣoṣo to ya wa lori ẹrọ ibanisọrọ t'omi gbe lọ.
Ohun kan to n tu u ninu nipe, iyawo rẹ wa laye, awọn mejeeji si nireti pe wọn yoo bimọ mii.
Obinrin opo kan ku pẹlu ọmọ mẹta
Isẹlẹ ẹkun omi yii tun da họu-họu silẹ ninu ile kan nigba to gbe opo kan ati ọmọ rẹ mẹta lọ.
Awọn aladugbo obinrin naa sọ fun BBC pe ọdun to kọja ni ọkọ obinrin naa ku, oun atawọn ọmọ rẹ mẹta lo si n gbe ninu ile naa.
Wọn ni lasiko ti ẹ̀kun omi naa n pọ si, ni awọn ara adugbo to ti raaye gun ibi to ga n gbọ igbe ẹ gbami lẹnu obinrin naa atawọn ọmọ rẹ.
Eyi lo mu ki wọn so okun mọ igi kan, ti wọn si ju okun naa si lati lo fi gun igi, sugbọn agbara omi naa mu ki o ṣoro fun lati fa ogun naa.
Bi omi ṣe gbe lọ ọ pẹlu ọmọ mẹrin ni yii.
Ẹyin ọ rẹyin ni wọn ri oku wọn, ti wọn si ti sin wọn.
Àwòrán atọ́ka àwọn ìlú tó wà ní Katsina
Ọjọ Ẹti to kọja ni awọn ara adugbo sọ pe ọmọbinrin naa ṣe igbeyawo, ko to dipe wọn gbe e wa sile ọkọ rẹ lọjọ Abamẹta.
Ọjọ Aiku, ti i ṣe ọjọ keji ni ojo naa bẹrẹ.
Oun naa wa lara awọn ti omi gbe lọ, to si gba ibẹ di ero ọrun.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ìgbà àkọ́kọ́ kọ́ nìyíì tí omíyalé yòó ṣọṣẹ́ ní Nàìjíríà
Awọn eniyan ṣi pọ babi ni ile iwe alakọbẹrẹ ilu Jibiya, ti wọn lo gẹgẹ bi ibudo ifiniwọ si, sugbọn awọn eniyan naa n kun pe awọn ko ri ounjẹ ati awọn nkan amaye dẹrun mi i gba.
Aarẹ Muhammadu Buhari sọ pe, iṣẹlẹ omiyale naa to waye ni ipinlẹ Katsina dun oun pupọ.
Bakan naa ni gomina ipinlẹ naa, Aminu Masari sọ fun awọn oniroyin pe o to eniyan mẹrinlelogoji to padanu ẹmi wọn sinu iṣẹlẹ naa.
Ẹ̀ẹ́dẹ́gbẹ̀ta ile lo ti lugbadi iṣẹlẹ omiyale to ṣẹlẹ ni ipinlẹ Katsina.
Aarẹ Muhammadu Buhari ni ìsẹlẹ omiyale to waye ni Katsina yii ba oun lọkan jẹ pupọ.
Gomina ipinlẹ naa, Aminu Masari to fi idi iṣẹlẹ naa mulẹ f'awọn oniroyin ni ko din ni eniyan mẹrinlelogoji to padanu ẹmi wọn sinu i'sẹlẹ yii, ti ogun eniyan o si tii jẹ rírí ni ìlú Jibia, ti iṣẹlẹ naa ti waye.
Ogunlọgọ eniyan lo ti di alainile lori l'awọn ilu bi Tundun Takari, Dan Tudu, Unguwar kwakwa, Unguwar Mai Kwari, atawọn mii ni ipinlẹ Katsina.
Oluranlọwọ pataki fun Buhari lori eto iroyin ati ipolongo, Garba Shehu sọ pe ààrẹ ti pasẹ fun awọn alaṣẹ lati pese iranlọwọ fun awọn ti ọrọ kan.
Ojo arọọrọ da naa bẹrẹ ni alẹ ọjọ Aiku, to si rọ titi di ọjọ keji.
Ọ̀nà ọ̀fun lọ̀nà ọ̀run - omi ò jẹ́ ká ta ọjà
Olórí ìlú Jibia, Alhaji Rabe Rabi'u, ni ohun ko ti i ri iru ojo bẹ ẹ ri laye oun, ati pe o da a loju pe ọtalerugba maalu lo ku nitori iṣẹlẹ naa, ti ọpọlọpọ oko si di bibajẹ.
Akọwe agba fun ajọ to n mojuto iṣẹlẹ pajawiri nipinlẹ Katsina, Dokita Aminu Waziri, ni awọn ti bẹrẹ si ni san gbogbo ọna lati ṣawari awọn to di awati.
Bakan naa lo ni, awsn ti n wa ile ifiniwọ si fun awọn ti omiyale naa ti ss di alainile lori.
Àgbàrá omíyalé Katsina ru ìyàwó mi lọ si orílẹ̀-èdè Niger
È gbọ òun ti ojú  awọn ara ipinle Ogun rí  lọwọ ìṣẹlẹ omiyale
Nǹkan kò rọgbọ fún àwọn tí ọ farakaaṣa omíyalé to sẹlẹ laipẹ yi láwọn ìpínlè mẹta lorílè-èdè Nàìjíríà.
Ọpọ ile àti nnkán ìní ló ṣofo nínú ìjàmbá omí yalé naa tó wáyé ní Katsina,Ogun ati Ondo.
Nígbà tí BBC Yoruba ṣe àbẹwò sí àwọn agbègbè tí ìṣẹlẹ náà kàn ni ipinle Ogun ati Katsina n'isẹ ní àwọn ará àdúgbò n bá ará wọn kẹdun.
Ládugbó Oke Sokori, alàgbà  James Oluyinka Okebujola di ẹbí ìṣẹlẹ náà rú ìjọba.
''Wọn ko la ojú ọnà tí omi le gbà lo se okunfa ìjàmbá yí''
Ṣugbọn Gómìnà ìpínlẹ̀ Ogun Ibikunle Amosun ní aitele ìlànà tó dé ilé kíkọ lo ṣokunfa ìṣẹlẹ náà.
Oríṣun àwòrán, Facebook/SenatorIbikunleAmosun
Gomina Ibikunle Amosun ko awọn alase ijoba sodi lo si awọn agbegbe ti isẹle naa kan.
Nigba tí o ṣé àbẹwò sí àgbègbè tí ìṣẹlẹ náà kàn Gomina Amosun ro àwọn ará ìlú láti ye ma ko ilé sójú ònà ti omi n gbà.
Sugbọn  awọn ara ipinle Ogun nikan ko ni ìṣẹlẹ náà kàn.
Ogunlọgọ eniyan lo ti di alainile lori ni agbegbe  Jibiya nipinle Katsina  latari ìṣẹlẹ omíyalé ọjọ Aiku
Oun ti oju wọn ri o kọja afẹnusọ.
Wọn ti sin oku iyawo Sani ti omiyale gbe lo
Sani Yahaya to padanu ẹmi iyawo rẹ so fun BBC pe orileede Niger lawọn ti ri oku rẹ nibi ti omi gbe lọ.
Ilu Sani sun mo Madarumfa ti o wa ni orileede Niger .
"Ori ibusun ni iyawo mi wa nigba ti omiyale naa bẹrẹ laago mọkanla alẹ''
Bi mo ti se n sapa lati di nnkan mu ni  omi naa gbe lo.Leyin ti mo ribi bọ labere si ni wa.Ọjọ keji la to ri oku rẹni Madarumfa nibi ti ẹrọfọ ti bo mọle.''"
O kere tan eeyan ogoji la gbo pe o ku ninu isele naa ni ipinle Katsina.
Ọpọ ile àti nnkán ìní ló ṣòfò nínú ìjàmbá omíyalé naa
Bakannaa ni ọpọlọpọ ilé ìgbé to wa lagbegbe Totoro ni Ipinle Ogun ní o farakasa ìṣẹlẹ náà ti omi sí gbé òpó ọkọ ayọkẹlẹ  lọ.
Ìkọ BBC Yoruba rí àwọn oṣiṣẹ pajawiri ipinle Ogun ti wọn n tiraka lati kò àwọn nnkán to bajẹ kúrò nínú omí.
Ládugbó Amolaso, òpó ilé ìgbé lo wọ omí nígbà tí afárá kan ti wọn ṣẹṣẹ parí láì pé yí na já lulẹ̀.
Yíyan olùdíje gómìnà ń dá wàhálà sílẹ̀ lẹ́gbẹ́ òṣèlú APC l'Ọ́ṣun
Olubadamọran fun ẹgbẹ oṣelu APC lo kede rẹ fun awọn oniroyin pe awọn ọmọ igbimọ amuṣẹya ẹgbẹ oṣelu yọ alaga ati akọwe ẹgbẹ ọhun
Oniruuru awuyewuye lo ti n wọ tọ eto ati dibo yan oludije fun ipo gomina labẹ aṣia ẹgbẹ oṣelu APC nipinlẹ Ọṣun.
Ohun to n da awuyewuye silẹ naa ni ipinnu awọn aṣiwaju ẹgbẹ oṣelu APC lati lo eto idibo oju koro ninu eyi ti gbogbo ọmọ ẹgbẹ kaakiri wọọdu idibo nipinlẹ naa yoo ti dibo fun yiyan oludije ẹgbẹ oṣelu  naa dipo ti aṣoju ti wọn n lo tẹlẹ.
Yatọ si pupọ awọn ọmọ ẹgbẹ ati awọn oludije ti wọn koro oju si eyi,  awọn eeyan kan laarin igbimọ iṣakoso ẹgbẹ oṣelu naa yọ alaga ẹgbẹ oṣelu naa, ọgbẹni Gboyega Famodun ati akọwe ẹgbẹ, Rasak Salinsile.
Olubadamọran fun ẹgbẹ oṣelu APC nipinlẹ Ọṣun lori ọrọ ofin, amofin Goke Ogunsọla lo kede rẹ fun awọn oniroyin pe awọn ọmọ igbimọ amuṣẹya ẹgbẹ oṣelu naa lo yọ alaga ati akọwe ẹgbẹ ọhun.
A ti dibo inu wa ko dun si ọ ranṣẹ si alaga ati akọwe ẹgbẹ yii. Ẹsun wọn si ni pe wọn lẹdi apo pọ pẹlu awọn kan ninu ẹgbẹ oṣelu naa lati kan eto idibo ojukoro ni didan fawọn ọmọ ẹgbẹ oṣelu naa eleyi ti awọn ọmọ ẹgbẹ ko dunu si.
Ninu ọrọ to ba BBC Yoruba sọ, akọwe ẹgbẹ oṣelu APC nipinlẹ Ọṣun, Rasak Salinsile ṣalaye pe ere'mọde lasan ni igbesẹ naa.
Bakan naa lo tun ṣalaye pe ọna ati dena lilo owo fi ra ibo ni igbesẹ ti awọn adari ẹgbẹ gbe lati lo eto idibo oju koro ninu eyi ti gbogbo ọmọ ẹgbẹ yoo ti funra wọn yan ẹni ti wọn fẹ.
Awọn ọmọ ẹgbẹ la fẹ ko funrawọn yan ẹni ti wọn fẹ. Lọtẹ yii a ko fẹ ki awọn baba olowo o lo owo fi ra iwọnba perete aṣoju tẹlẹ. Ko si wahala laarin ẹgbẹ ṣugbọn awọn kọlọransi lo n pariwo lori rẹ.
APC fẹ lo eto idibo oju koro ninu eyi ti gbogbo ọmọ ẹgbẹ kọọkan yoo dibo yan oludije dipo ti aṣoju ti wọn n lo tẹlẹ
Ohun ti pupọ awọn ọmọ ẹgbẹ n beere fun naa ni eto idibo awọn aṣoju (Delegate system)
Bi eyi ti n lọ lọwọ lawọn igbimọ iṣakoso ẹgbẹ oṣelu naa tun pariwo 'ko si giri'
Amọṣa bayii, ọrọ tun ti ba ibomiran yọ pẹlu bi awọn oludije mejila to wa lati ẹkun iwọ oorun ipinlẹ Ọṣun ti pariwo pe ohun ti awọn n fẹ naa ni eto idibo aṣoju ti o wa nilẹ tẹlẹ.
Ohun ti wọn n sọ ni pe awọn eeyan kan ngbero fi eto naa ṣe arumọjẹ ni wọn fi n pe fun eto idibo gbogbo ọmọ ẹgbẹ dipo ti aṣoju.
Nigeria Air: Ilé iṣẹ́ ọkọ̀ òfúrufú tuntun ṣí'wọ́ iṣẹ́
Oríṣun àwòrán, @Bashir Ahmad
Ijọba Naijiria sọ nigba ti wọn kede idasilẹ ileeṣẹ naa pe ojú ọnà mọ́kànlélọ́gọ́rin ni ọkọ òfurufú náà yóò ma rin
Mínístà fún ètò ìrìnàjò ọkọ̀ òfurufú Hadi Sirika ti kẹde pe wọn ti so ileesẹ ọkọ ofurufu Naijiria tuntun, Nigeria Air rọ bayi.
O sọ lori Twitter ni Ọjọru pe igbimọ apapọ orilẹede Naijiria lo ṣe ipinnu naa lati so ileeṣẹ naa rọ. Ko sọ igba ti wọn yoo yi ipinnu naa pada.
Ẹ o ranti wipe nigba ti wọn ṣe ikede idasile ileeṣẹ naa, ẹgbẹ awọn oṣiṣẹ fẹhinti, ẹka ti Nigeria Airways sọ fun BBC pee awọn ko ni jẹ ko ṣiṣẹ ti wọn ko ba san owo ajẹsilẹ awọn
Alaga ẹgbẹ naa, Sam Ezene ni iyalẹnu lo jẹ fun oun ati awọn ọmọ ẹgbẹ nigba ti wọn gbọ pe ijọba kede ileeṣẹ ọkọ ofurufu tuntun, pe ko yẹ ki ijọba Naijiria da ileeṣẹ mi i silẹ nigba ti wọn ṣi n jẹ awọn oṣiṣẹ fẹhinti ni owo ọdun mẹrinla
O ni  'O yẹ ki wọn yanju owo ajẹmọnu awọn oṣiṣẹ to n ba ileeṣẹ ọkọ ofurufu akọkọ, Nigeria Airways, to kogba wọle naa ṣiṣẹ.''
O ni itiju lo jẹ fun Naijiria, bi ijọba ṣe lọ sẹ ikojade ileeṣẹ tuntun naa ni orilẹede England.
Bakan naa ni Ọgbẹni Ezene ni, awọn ti kọ lẹta si minisita fun igbokegbodo ọkọ ofurufu ni Naijiria, Hadi Sirika, pe ileeṣẹ tuntun Nigeria Air ko ni bẹrẹ iṣẹ, ayafi ti wọn ba san owo awọn to to biliọnu mejidinlọgọrin Naira.
O ni eyi yoo ṣeeṣe fun awọn nitori pe 'akọṣẹmọṣẹ ninu imọ nipa igbokegbodo ọkọ ofurufu ni gbogbo awọn.''
Ijọba ti kọ kede pe wọn yoo san owo ajẹmọnu awọn oṣiṣẹ fẹhinti naa ninu ọdun yii, amọ ti wọn ko ti i ri i gba titi di asiko yii.
Ijọba ti kọ kede pe wọn yoo san owo ajẹmọnu awọn oṣiṣẹ fẹhinti naa ninu ọdun yii, amọ ti wọn ko ti i ri i gba titi di asiko yii
Ṣaaju ni ijọba Naijiria ṣe ikojade ileeṣẹ ọkọ ofurufu tuntun l'Ọjsru l'orilẹede England, lati fi rọpo meji to ti wa nigba kan ri, Nigeria Airways ati Air Nigeria .
Eero awọn ọmọ Naijiria ṣọtọọtọ lori orukọ ti wọn fun ileeṣẹ tuntun naa. Bi awọn kan ṣe n dunnu pe iru rẹ waye, ni awọn kan n yọ ṣuti ete si i.
"Babatunde E. Aideloje sọ loju opo Facebook BBC Yoruba pe ''Kilode ti won o fi pada tunsọ ni ""Nigeria Airways"" eyi ti n se orukọ ti wọn n jẹ tẹlẹ tẹlẹ?"
Igbesẹ naa i ba dara pupọ. Sugbọn sa orukọ titun wọn yii ko fi bẹ yẹn dara.''
"Ṣugbọn ni eero Bello Taoheed Ọlawale ""Orukọ tuntun yii naa rẹwa. O da gẹgẹ bii Egyptian air. Mo fẹran amin tuntun ti wọn fun un bayii."""
'Nigeria Air' ni orúkọ ti wọn yan fún un.
Ojú òpó Twitter ilé iṣẹ ìjọba Naijirià ní wọn fí ìkéde náà sì lọ́jọ́rú ọ̀sẹ̀.
Mínístà fún ètò ìrìnà òfurufú Naijiria, ọgbẹni Hadi Sirika ti sáájú fí ọrọ síta láti kí àwọn èèyàn Naijirià ku ojú lọnà àjínde ọkọ̀ òfurufú orílè-èdè Nàìjíríà.
Nigba ti o n sọrọ níbi ayẹyẹ igboruko tuntun ọkọ òfurufú náà jáde níbi ayẹyẹ àfihàn ọkọ òfurufú to n wáyé ni Farnborough, Hadi sọ pé ìṣẹlẹ manigbagbe ni igboruko jade náà jẹ.
O tẹ̀síwájú pé ìdá marun-un nínú ọgọrùn ní ìjọba yóò ní nínú ilé iṣẹ ọkọ òfurufú náà àti pé ìjọba yóò yọwọ kúrò nínú iṣẹ àkóso ọkọ òfurufú náà.
Oríṣun àwòrán, @FAAN_Official
Hadi so pé ìṣẹlẹ manigbagbe ni igboruko jade náà jẹ.
Ọdún 1958 ni wọn dá ọkọ̀ òfurufú Nigeria Airways silẹ̀ ṣugbọn o ko 'gba si ile lọdun 2013.
Ọpọ ọmọ Naijirià lo ti n jaran àjínde ọkọ òfurufú ti orílẹ̀èdè Naijiria.
Boko Haram: Ọlọ́pàá ní aràrá wà láàárín àwọn afurasí
Oríṣun àwòrán, AUDU MARTE
Ilé iṣé ọlọ́pàá Nàìjíríà ti ṣe àfihàn àwọn afurasi méjo ọmọ ẹgbẹ Boko Haram to jí àwọn akẹkọ Chibok gbé.
Àfihàn àwọn afurasi ọmọ ẹgbẹ Boko Haram náà wáyé ni Maiduguri ní ìpínlẹ̀ Borno.
Ọgá ọlọ́pàá, Damian Chukwu, nínú atẹjade kàn sọ pé àwọn afurasi náà jẹwo pe awọn láwọn wa nìdí ikọlù oríṣiríṣi to waye ní ìpínlẹ̀ Borno ati Adamawa.
Chukwu ni àwọn afurasi náà tun so fun àwọn pe ijinigbe awọn akẹkòó  Chibok kò sẹyìn àwọn.
Ọgá olópàá náà ní awọn ajinigbe yii nikan kọ ni ọwọ awọn tẹ.
Lara awọn ti wọn se afihan wọn ni awọn ọmọ ogun Boko Haram mẹrinla miran, ti ọlọpaa ni wọn ko ipa orisirisi ninu ikọlu, ijinigbe ati ilo eeyan gẹgẹ bi ado oloro.
Ekiti Election: Gómìnà tí wọn sẹ̀sẹ̀ dìbò yàn gbàwé ẹ̀rí
Oriko INEC to wa ni popona Iyin tuntun to wa ni ilu Ado-Ekiti ni o ti tgba iwe ẹri naa pẹlu igbakeji rẹ, Oloye Bisi Egbeyemi,
Kayode Fayemi to jawe olubori ninu idibo gomina Ipinlẹ Ekiti ti wọn ṣẹṣẹ ṣe tan, ti gba iwe ẹri iyansipo rẹ lati ọwọ ajọ INEC.
Ilesẹ ajọ INEC to wa ni popona Iyin tuntun ni ilu Ado-Ekiti ni o ti gba iwe ẹri naa pẹlu igbakeji rẹ, Oloye Bisi Egbeyemi,
Fayemi to dije labẹ aṣia ẹgbẹ oṣelu APC, lo jawe olu bori ninu idibo gomina naa to waye ni ọjọ Abamẹta to kọja, ti oludije labẹ asia ẹgbẹ oṣelu PDP, Ọjọgbọ́n Kolapo Olusola-Eleka si gbe ipo keji.
Ilé ìwé tuntun kò wúlò mọ́ fáwọn akẹ́kọ̀ọ́ ìpínlẹ̀ Kogi
Oríṣun àwòrán, @Dino
Awọn janduku ba ẹ̀tọ́ àwọn akẹkọọ ipinlẹ Kogi jẹ́
Àwọn kan ti dáná sun iṣẹ́ àkànṣe Dino nilé ìwé Government Girls Secondary School ni Lokoja.
Lọjọ Ru ni àwọn afurasi Janduku kan lọ dana sun awọn iṣẹ akanṣe ti Senetọ Dino Melaye lati iwọ oorun ipinlẹ Kogi fẹ ṣí laipẹ.
Ile iwe awọn akẹkọbinrin ti agbegbe Sarkin-Noma ni Lokoja atile iwe alakọbẹrẹ ti LGEA ni Lokogoma ni wọn ti bajẹ.
Oríṣun àwòrán, @Dino
ọjọ ọla awọn akekoo kan ni janduku ti dana sun ni Kogi
Awọn eniyan ipinle Kogi ati gomina ipinlẹ Kogi ti benu ẹ̀tẹ́ lu iwa bàsèjẹ́ yii pé dié lara èrè iṣejọba awa-ara-wa to yẹ ki awọn akẹkọọ jẹ ni awọn janduku yii ti bajẹ.
Inu Senetọ Dino Melaye to n ṣoju ijọba ibilẹ meje ni iwọ oorun Kogi ko dùn rara si ohun to ṣẹlẹ yii.
Iṣẹlẹ náà ni àwọn kan gba pe kò ṣẹ̀yìn gomina Yaya Bello to n tukọ ipinlẹ Kogi pe
Ọpọlọpọ gba pe iṣẹlẹ yii jẹ́ ẹ̀rù ohun ti oṣelu Naijiria ti di bayii pẹlu ifoya ọkan lori ọjọ iwaju ijọba tiwantiwa ni Naijiria
Russia 2018: Awọn alátilẹyin àgbabọọlu kò le pada sílé
Khadijat Oluboyo: Ilé ẹjọ́ sọ ọ̀rẹ́kùnrin rẹ̀ sí gbaga
Osun Election: Èrò àwọn olùdíje yapa lórí ìbò abẹ́nú APC
Awọ̀n oludije fun ipo gomina ninu ẹgbẹ APC nipinlẹ Ọ̀sun ko lee fẹnu ọrọ jona lori awọn ilana kan to nii se pẹlu eto idibo ọ̀hun.
Ẹ̀kọ ko soju mimu nilu Osogbo lọjọbọ nibi ipade awọn alẹnu-lọrọ̀ fẹgbẹ APC ni ipinlẹ Ọ̀sun to waye lana eyiti igbimọ to n se kokari ibo abẹnu naa se kokari rẹ.
Idi ni pe awọ̀n oludije fun ipo gomina ninu ẹgbẹ APC nipinlẹ Ọ̀sun ati igbimọ to n se kokari eto idibo abẹnu naa, ko lee fẹnu ọrọ jona lori awọn ilana kan to nii se pẹlu eto idibo ọ̀hun.
Àwọn ẹgbẹ́ òṣèlú APC nipinlẹ Osun n ṣe ìpàdé
Alaga igbimọ to n se kokari eto idibo abẹnu naa, tii tun se gomina ipinlẹ Zamfara, Abdulaziz Yari, ẹ́niti Sẹnetọ Ọmọ Agege soju fun, pe ipade naa lati fi eegun otolo to awọn gbọn mi si-omi o to kan to n waye ninu ẹgbẹ oselu naa ni.
Akọroyin BBC Yoruba to wa nilu Osogbo nibi ti ipade naa ti waye ni, o dabi ẹni pe gbun-gbun-gbun naa ko lee niyanju nitori pe o ti foju han lati ibẹrẹ ipade naa pe, iyapa lee ba awọn ọmọ ẹgbẹ oselu naa nitori bi awọn alatilẹyin awọn oludije se n kọrin eebu, ti wọn si n yẹyẹ ara wọn, lati sọ ibi ti wọn fi si.
O dabi ẹni pe gbun-gbun-gbun naa ko lee niyanju nitori pe o ti foju han lati ibẹrẹ ipade naa pe, iyapa lee wa
Wahala lo gba inu ẹgbẹ oselu APC Ọsun kan nitori ilana idibo lawọn ijọba ibilẹ ti ẹgbẹ naa fẹ lo lati yan ẹniti yoo soju APC nipinlẹ Ọsun ninu idibo gomina to n bọ.
Ti a kò bá gbàgbé, ẹgbẹ òṣèlú APC ti sáájú kéde isunsiwaju ọjọ ìdìbò lati yan olùdíje ẹgbẹ fún ìbò Gómìnà nipinle Osun, lati Ọjọbọ si ọjọ Ẹti.
Èèyàn mẹtadinlogun ló n dije láti gbé àsìá ẹgbẹ APC sókè bíi olùdíje gómìnà ní ìpínlẹ̀ Osun.
Èèyàn mẹtadinlogun ló n dije láti gbé àsìá ẹgbẹ APC sókè bíi olùdíje gómìnà ní ìpínlẹ̀ Osun.
Nigba ti ipade alaafia ti wọn pe lana wa fori sanpọn, n jẹ bawo ni eto abẹnu lati yan oludije fun ipo gomina ti yoo waye loni yoo se lọ ?
Ẹ maa ba wa bọ lori ikanni yii lati maa fi ohun gbogbo to n waye nibi idibo ọhun to yin leti
Ẹ ká díẹ nínú ìmọràn tí ará ìlú Èkìtì n gba Fáyẹmí
Kayode Fayemi fi iwe eri moyege han Aare Buhari
Awọn èèyèn ìpílẹ̀ Èkìtì ti dibo yan Ọmọwe Kayode Fayemi gẹgẹ bí Gómìnà wọn túntún ṣugbọn wọn kò fẹ dá iṣẹ ìṣèjọba dá òun nìkan.
Lójú òpó ayélujára Facebook wa, a béèrè ohun ti ará ìlú fẹ kí ọmọwe Fayemi gbajumọ ni kété t'oba bẹrẹ ìṣèjọba.
Díẹ rèé lára ohun ti wọn sọ ni yii
Sugbon kii se gbogbo eeyan lo dunu si bi Kayode Fayemi ti se jawe olubori
'Ẹnu lásán kò lè sàn owó oṣu oṣiṣẹ l'Ekiti'
Fayẹmi bá BBC sọ̀rọ̀ ní kété tó di gómìnà Ekiti
Kayode Fayemi fun ara rẹ mọ pe ipenija ti o wa nilẹ kii se kekere.
Lọpọ aaye ti o ti n sọrọ leyin idibo,nise ni o tenu mo dida ogo ilẹ Ekiti pada.
Sugbọn awọn amoye ni ẹnu lasan ko le mu iyipada wa si ipinlẹ Ekiti bi kii se ki Fayemi de okun sokoto re ko le daada.
Alagemo rẹ bayi ti bimo silẹ,afaimojo di ọwọ Fayemi ati bi o ba ti se dari eto ipinle Ekiti.
Ekiti Election: Ìhà wo ni aráàlú kọ sí àsà ‘See and Buy’
Ekiti Election: Àwọn aráàlú ń tahùn síra wọn lórí ìbò rírà
‘See and Buy’ ni aṣa tuntun to jẹ jade lasiko eto idibo sipo gomina to waye lọjọ kẹrinla, oṣu Keje ọ́dun 2018 ni ipinlẹ Ekiti.
Awọn oludibo ṣalaye pe, igbesẹ naa nii ṣe pẹlu gbigba owo gẹgẹ bi oludibo, lẹyin ti ẹgbẹ́ oselu ti o dibo fun ba ri i daju pe ẹgbẹ wọn lo di ibo rẹ fun.
Saaju ki oludibo to lọ tẹka sori iwe pelebe ti yoo fi dibo, ni awọn asoju ẹgbẹ oselu to n 'mojuto bi nkan se n lọ nibi eto idibo to n lọ lọwọ', yoo ba oludibo naa sọrọ lori iye ti wọ̀n yoo fun to ba fi dibo fun ẹgbẹ wọn.
Baba Khadijat Oluboyo jẹ́rìí ọmọ rẹ̀
Nigba miran ẹwẹ, awọn to ti kọkọ dibo, to si ṣe 'See and Buy' ni yoo ṣalaye fun awọn akẹgbẹ wọn, bi igbesẹ naa ṣe n lọ.
Iriri awọn akọroyin BBC lori bi ‘See and Buy’ ṣe n ṣiṣẹ
Oludibo yoo gba iwe pelebe ti yoo fi dibo, yoo lọ si ibi ti yoo ti tẹka.
To ba ti tẹka si iwaju ami ẹgbẹ to fẹ ẹ dibo rẹ fun, ni yoo na iwe pelebe naa soke lati fi han aṣoju ẹgbẹ oṣelu ti wọn yan, to si duro si ọkan, nitosi ibi ti wọn ti n tẹka, lati fihan wọn pe ẹgbẹ wọn ni oun dibo fun.
Aṣoju ẹgbẹ naa yoo mi ori si i lọọkan, lati fihan pe oun ti ri ibi ti o dibo rẹ si.
Alaga ajọ INEC nipinlẹ Ekiti ni ko si ohunkohun ti ajọ INEC lee ṣe si ọrọ naa.
Lẹyin eyi ni oludibo naa yoo to lọ ju iwe pelebe naa sinu apoti ti ajọ INEC ti pese, ti yoo si kuro nibudo idibo lọ si ibi pataki ti wọn ti pese silẹ lati lọ gba owo ibo to di.
Asoju ẹgbẹ oṣelu naa, ti oludibo fi iwe idibo rẹ han, yoo mi ori lati ọọkan to wa, lati sọ fun ẹni to n sanwo pe oludibo to de ọdọ rẹ dibo fun ẹgbẹ wọn.
Kin ni ajọ INEC n ṣe lori asa 'See and Buy'?
Akọroyin BBC to ba Ọjọgbọn Abdulganiyu Raji, tii ṣe alaga ajọ INEC nipinlẹ Ekiti, to si tun dari eto idibo naa sọrọ, jábọ̀ pé, o ni ko si ohunkohun ti ajọ INEC lee ṣe si ọrọ naa.
O ni 'ojuse ti ofin la kalẹ fun ajọ eleto idibo ni lati se kokari bi eto idibo yoo ṣe waye, kii ṣe lati tọpinpin ihuwasi awọn oludibo lasiko ti wọn n dibo. O ni ojuṣe awọn agbofinro ni lati mu ẹnikẹni to ba ṣe bẹẹ.
See and Buy nii ṣe pẹlu gbigba owo gẹgẹ bi oludibo, lẹyin ti ẹgbẹ́ oselu ti o dibo fun ba rii daju pe ẹgbẹ wọn lo di ibo rẹ fun.
Ṣugbọn awọn agbofinro naa ti faake kọ̀ri lori eyi, ti wọn si ni ojuṣe awọn ni lati pese aabo nibudo idibo, ki i ṣe lati mojuto iwa bii 'See and Buy.'
Kin ni awọn araalu wa n sọ lori asa ‘see and Buy’ ?
World Cup: Bàálù tíjọba fi ránsẹ́ ló kó wọn wálé
Oríṣun àwòrán, Yulia Siluyanova
Àwọn ọmọ Nàíjíríà tó lé ní igba ló há sí Russia láì ní owó ọkọ̀ lẹ́yìn tí ife ẹ̀yẹ àgbáyé parí tán.
Orire ti gbe alawo rere pade awọn ọmọ Naijiria to ha si orilẹ-ede Russia lẹyin ife ẹyẹ agbaye to sẹsẹ pari losu keje ọdun 2018.
BBC Yoruba gbọ pe o le ni igba awọn ọmọ Naijiria ti ọna pin mọ lati pada sile lẹyin ti ẹgbẹ agbabọọlu ilẹ wa, Super Eagles fidi rẹmi ninu idije naa, ti ko si si ọna abayọ fun wọn lati pada si ilẹ baba wọn.
Small Doctor: Mo kórira igbó, ọtí àti sìgá nítorí màmá mi lòdì si
Amọ ijọba apapọ ilẹ wa ti fi baalu kan ransẹ si Russia lati lọ ko awọn ‘Atipo’ ojiji yii pada sile.
Oríṣun àwòrán, Yulia Siluyanova
Amọ ijọba apapọ ilẹ wa ti fi baalu kan ransẹ si Russia lati lọ ko awọn 'Atipo' ojiji yii pada sile.
Ni alẹ ọjọbọ, ni baalu naa gunlẹ́ si orilẹ-ede Russia, to si gbera ni aago mẹfa aarọ ọjọ Ẹti lati kọkọ ko aadọta ninu awọn ololufẹ ere bọọlu naa pada sile.
Gẹgẹ biirofin kan ti ọkan lara ọmọ Naijiria to fi orilẹ-ede Russia se ibujoko, to n se iranwọ fawọn arinrin ajo naa lati rọna abayọ, ti fi to BBC leti,  irinajo lati orilẹ-ede Russia si Naijiria to wakati mẹjọ, ti ireti si wa pe nigba ti yoo ba fi di aago meji ọsan ọjọ Ẹti, awọn arinrinajo ọhun yoo gunlẹ si papakọ ofurufu Muritala Muhammed nilu Eko.
Adeoti: àwọn ọmọ ẹgbẹ́ míran tún ti kòwé fipò sílẹ̀ l'Ọsun
Oríṣun àwòrán, Adeoti/facebook
Awọn oludije to yẹba ni Moshood Adeoti, tii se akọwe ijọba ipinlẹ Ọsun, Peter Babalọla ati Senatọ Babajide Ọmọworarẹ.
Ọmọ ẹgbẹ́ APC mẹ́sàn-án ní ìpínlẹ̀ Ọ̀ṣun ló ti kòwé fipò sílẹ̀ báyìí tí wọn sí ti lọ sí ẹgbẹ́ oṣèlú Action Democratic Party (ADP).
lOhun to n ṣẹlẹ yii lo ti di àǹkóò fawẹli kaakiri ipìnlẹ ni Naijiria bẹrẹ lati ile igbimọ aṣofin agba de tipinlẹ lasiko yii.
Awọn eniyan n soro pe ohun tó ń ṣẹ́lẹ̀ nínú ẹgbẹ́ òṣèlú All progressives progress (APC) nípìnlẹ̀ Ọsún láìpẹ́ yìí kò bójúmú.
Fadele: Dán an wò, lóbí ìyá ọ̀kẹ́rẹ́ ni a fi ọ̀rọ̀ ọ̀kadà náà ṣe
Gẹ́gẹ́ bí ìwé ti wọn jo kọ láti fi ipo sílẹ̀ ṣe sọ, tí o sì tẹ BBC lọ́wọ́ ní pé ìfẹ́nukò àwọn ará ìlú àti àwọn tọ́rọ̀kàn ní ẹkùn mẹ́tẹẹ̀ta ní ìpínlẹ̀ Ọsun ló fa ìdí abájọ tàwọn ṣe lọ sí ẹgbẹ́ òṣèlú ADP.
Wọn ní àwọn ìṣẹ̀lẹ̀ tó ń ṣẹ́lẹ̀ nínú ẹgbẹ́ òṣèlú APC nípìnlẹ̀ Ọsún láìpẹ́ yìí jẹ́ ohun tó lòdì sí ẹ̀kọ́ tó bá ojú mú ninu iṣejọba awa-ara-wa.
Awọn tó fi ipò sílẹ̀ ní
Kunle Oyatomi, to jẹ  olúdari ìbánisọ̀rọ̀ nínú ẹgbẹ́ òṣèlú All progressives Congress ba ṣalaye pe  kò sí ohun tuntun labẹ ọrun mọ.
Nínú ọ̀rọ̀ rẹ̀, nínú ìwé tó fi sọwọ́ si BBC Yorùbá o ṣàlàyé pé, gbogbo ènìyàn ló ní ẹ̀tọ́ láti fí ẹgbẹ́ sílẹ̀ sùgbọ́n èrèdí ti wọn fi fi égbẹ́ sílẹ̀ kò tẹ̀wọ̀n tó.
'wọn rò pé pipariwo pé àwọn ń lọ pẹ̀lú ọmọ ẹ̀yìn ẹgbẹ̀rún mẹ́fà ní yóò mú wọn jáwé olúbori fun ìdìbò gomínà tó ń bọ̀, wọn ń gbéra wọn gẹṣin aáyán lásán ni.'Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí:
Awọn oludije ti wọn jade ninu idibo abẹle ni Moshood Adeoti, tii se akọwe ijọba ipinlẹ Ọsun, Peter Babalọla ati Senatọ Babajide Ọmọworarẹ.
"Atẹjade kan ti Sẹnetọ Ọmọworarẹ́ fisita, eyi ti oludari feto iroyin rẹ, Tunde Dairo fọwọsi ni aarọ ọjọ Ẹti ni ilu Osogbo ni ""nitori ọ̀pọawọn isẹlẹ oselu to n waye, eyi to kọja akoso, ni oun ko se ni fi awọn asoju oun si wọọdu kọọkan tabi se iwuri fawọn alatilẹyin oun lati lọ, bẹẹ si ni oun ko ni lo ohun alumọọni oun feto idibo abẹnu naa."""
O ni igbesẹ naa lo wa lati ri daju pe isọkan wa ninu ẹgbẹ oselu naa ko lee bori idibo gomina ti yoo waye lọjọ kejilelogun osu kẹsan ọdun yii.
Awọn oludije to yẹba ni Moshood Adeoti, tii se akọwe ijọba ipinlẹ Ọsun, Peter Babalọla ati Senatọ Babajide Ọmọworarẹ.
Bakan naa, akọwe ijọba ipinlẹ Ọsun, Moshood Adeoti, ninu atẹjade toun naa fisita fawọn akọroyin, lo ti sisọ loju ọrọ yii, pẹlu awijare pe oun fẹ fara mọ ipinnu ẹkun idibo oun, tii se ẹkun idibo iwọ oorun guusu Ọsun, eyi to ni oun to nii kopa ninu eto idibo abẹnu naa.
O wa parọwa sawọn ololufẹ rẹ pe oun si n dije fun ipo gomina ipinlẹ Ọsun o, bi o tilẹ jẹ pe oun ko ni kopa ninu eto idibo abẹnu APC. Eyi si lo n mu kawọn eeyan maa fura pe o seese ko fẹ lọ sinu ẹgbẹ oselu miran.
Oludije kẹta, Peter Babalọla ni tiẹ kede pe oun ti yẹba ninu idije naa lati ori ẹrọ ibaraẹni sọrọ.
LASG: LASTMA, àtàwọn àjọ míràn ti bẹ̀rẹ̀ ìgbésẹ̀ dídẹ́kun súnkẹrẹ ọkọ̀ lásìkò ọdún
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ijọba ipinlẹ Eko ti ṣeleri pe ko lee si wọlu-kọlu ọkọ ni ipinlẹ Eko lasiko ayẹyẹ opin ọdun
Ijọba ipinlẹ Eko ti ṣeleri pe ko lee si wọlu-kọlu ọkọ ni ipinlẹ Eko lasiko ayẹyẹ opin ọdun.
Kọmiṣọna feto irinna ọkọ nipinlẹ Eko, Ladi Lawson lo ṣalaye yii lẹyin ipade idakọnkọ kan to waye laarin awọn ajọ ati ileeṣẹ eto irinna nipinlẹ Eko ni ọjọbọ.
Ọba Olutayọ: ìgbésẹ̀ Ọọni àti Alaafin ti ń mú ìṣọ̀kàn dé sáàrin àwọn Ọba Yorùbá
Ọgbẹni Lawson ni ijọba ti gbe eto kalẹ eleyii ti yoo rii daju pe igbokegbodo ọkọ n lọ bi o ti tọ lai si idiwọ ni bi ayẹyẹ opin ọdun ṣe n sunmọ.
O ni idi ti gomina Akinwumi Ambọde fi pe ipade idakọnkọ naa ni lati ṣe eto ati ilana ti yoo wa iyanju si wahala sunkẹrẹ-fakẹrẹ ọkọ pẹlu abo fun ẹmi ati dukia lasiko ọdun.
Bakan naa ni ọga agba ajọ LASTMA, Chris Olakpe pẹlu ṣalaye pe wọn yoo tete ṣe eto ẹkọṣẹ fun awọn ẹgbẹrun kan oṣiṣẹ ti ajọ naa ṣẹṣẹ gba laipẹ yii ki wọn lee bs si ẹnu iṣẹ ki asiko ọdun to wọle.
Oríṣun àwòrán, LASTMA
Bọọsi kan to duro soju irin reluwe lo fa sababi ijamba naa
Eeyan mẹjọ ti di ero ọrun ni aarọ ọjọ Ẹti, nigba ti ọkọ reluwe kan kọ lu ọkọ akero kan ni adugbo Agege.
Ijamba ọhun, to see dena lo waye nigba ti ọkọ akero kan duro si oju ọna reluwe.
Oríṣun àwòrán, LASTMA
An osi panpana ti wa nibi i naa lati palẹ ajoku ọkọ mọ
Nigba ti reluwe fọn pe ko kuro nibẹ́, wadu-wadu to n se lo mu ki awakọ naa fi ọkọ rẹ si rifaasi lai mọ, to si mu ki reluwe naa kọlu.
Small Doctor: Mo kórira igbó, ọtí àti sìgá nítorí màmá mi lòdì si
Ijamba naa si lo mu ki ọkọ akero naa gbina, amọ ori ko awọn ero to wa ninu rẹ yọ.
Nigba to n fi idi isẹlẹ ọhun mulẹ fun BBC Yoruba, ọga agba fun ajọ to n se akoso oju popo nipinlẹ Eko, LASTMA, Ọgbẹni Ọla Musa salaye pe lootọ ni isẹlẹ naa waye.
Ẹni kan to sọ nipa isẹlẹ naa loju opo twitter rẹ @Oshofaze, to ni isẹlẹ naa soju oun,lo kede pe eeyan mẹjọ lo ku.
Igba akọkọ kọ ree ti irufẹ ijamba ọkọ oju irin yoo maa waye ni agege. Bẹẹ ba si gbagbe, bakan naa ni irufẹ isẹlẹ yii waye lọdun 2017 nigba ti ọ̀kọ oju irin naa ya kuro loju opo rẹ.
Oríṣun àwòrán, LASTMA
Igba akọkọ kọ ree ti irufẹ ijamba ọkọ oju irin yoo maa waye ni agege
Amọ o ni oun ko tii lee sọ ni pato, iye eeyan to ba isẹlẹ naa rin.
Nibayii na, ajọ Lastma tisisẹ lati mu ki ohun gbogbo pada bọ sipo lagbegbe naa.
Ìran kan si ìkejì ló n gbèrò láti ṣe ìrú ìgbéyàwo àjùmọ̀ṣe 'Shao' fọ́mọ wọn
Ekiti Election: Fayẹmi ní òun kò ní se àsìse bíi ìjọba tó ń lọ
Oríṣun àwòrán, @KBStGovt
Fayẹmi tun lo asiko naa lati fi iwe ẹri ti INEC fun han Aarẹ Muhammadu Buhari
Gomina ti wọn sẹsẹ dibo yan nipinlẹ Ekiti, Kayọde Fayẹmi ti sọ pe oun yoo ṣewadi gbogbo ohun to waye ninu iṣejọba Ekiti lati bi ọdun mẹrin sẹyin.
Fayẹmi sọrọ naa lẹyin to ṣe abẹwo si Aarẹ Muhammadu Buhari nile aarẹ to wa nilu Abuja.
Fayẹmi ni 'oun yoo 'se iwadi eto iṣakoso ipinlẹ Ekiti labẹ iṣakoso Gomina Ayọdele Fayoṣe to n kogba wọle, fun anfaani eto iṣejọba to mọyan lori.
Oríṣun àwòrán, Fayemi/Fayose/Facebook/Twiter
O ni 'oun yoo wadi iye to wọle si apo ijọba ati idi ti owo awọn oṣiṣẹ ko fi jẹ sisan.
Fayẹmi, to ti figba kan jẹ minisita fun idagbasoke iwa kusa ati irin tutu, tun lo asiko naa lati fi iwe ẹri moyege ti ajọ eleto idibo Naijiria, INEC fun lẹyin eto idibo to ti jawe olubori han aarẹ Muhammadu Buhari.
Ile Igbimo Asofin Ekiti: ìjòkó jẹ́? A ko fẹ́ kú o
Bi o tilẹ jẹ pe o sọ pe oun yoo yẹ awọn iwe akọsilẹ ijọba, Fayẹmi ni afojusun oun ki i sẹ lati tanna wadi Fayose tabi igbakeji rẹ, Olusọla Ẹlẹka.
O ni afojusun igbesẹ naa ni lati ri i daju pe awọn ko ṣe aṣiṣe t'awọn to kọja sẹ. Ati lati fun awọn eniyan ipinlẹ Ekiti ni eto iṣejọba to dara.
Bakan naa ni Fayẹmi ni oun ti bẹrẹ si ṣe awọn to yẹ ni imurasilẹ fun eto igbajọba.
Oríṣun àwòrán, @VoteFayemi
Fayẹmi ni oun ti bẹrẹ si ṣe awọn to yẹ ni imurasilẹ fun eto igbajọba.
Ati pe ohun yoo ṣe igbelewọn awọn dukia ti Ekiti ni, to fi mọ awọn ohun to n nawo le lori.
Igbakeji niyi ti ikede yoo jade lẹyin eto idibo gomina to waye nipinlẹ Ekiti lọjọ kẹrinla, oṣu Keje, ọdun 2018, nipa ṣiṣe iwadi eto iṣakoko Gomina Fayose. Ajọ to n gbogun ti iwa ijẹkujẹ ni Naijiria, EFCC, ti kọkọ fi ikede kan sita loju opo Twitter lati wadi mago-mago to waye lori idasilẹ ile adiyẹ kan ti ijọba ipinlẹ ekiti ṣe lasiko ti Fayose fi kọkọ ṣe gomina laarin ọdun 2003 si 2006. Ṣugbọn ajọ EFCC pada pa ikede naa rẹ.
Dino fàgilè ìfilọ́lẹ̀ àti ìsìn idupẹ
Oríṣun àwòrán, @dino_melaye
Ọrọ kìí sì lẹyìn alábahun Dino Melaye
Sẹ́nètọ̀ tó ń sojú ẹkùn ìdìbò ìlà oórùn Kogí, Dino Mélayé  ti fàgilè ìfilọ́lẹ̀ akanse ise àti ìsìn idupe to ye ki o se fun awọn eeyan ẹkun idibo rẹ.
Agbẹnusọ fun Sẹ́nẹ́tọ̀ DIno Mélayé, Gideon Ayọ̀délé  lo lede oro yi fún BBC Yorùbá ninu iforowanilenuwo kan lori ẹro ibanisọrọ.
Gideon sọ wipe ìgbésẹ náà wáyé nítorí ìpeníjà ààbò ẹmi Seneto Dino.
Gẹgẹ bi oun ti Gideon sọ, o ní pẹlu bi àwọn kan ṣe sọnà sí ileewe méjì ti Dino fe se ìfilọ́lẹ̀ wọn, àwọn ṣì tẹsíwájú pẹlú eto náà lọjọ kejidinlogun osu yii.
Ṣugbọn bi idunkoko mọni lati odo àwọn ọlọpa ti ṣe peleke ló mú kí Seneto Dino yí èrò pada láti fagile eto ìsìn idupẹ ati apejẹ to yẹ ko waye ni Aiyetoro Gbede
Nígbà tí BBC bẹrẹ lọwọ Gideon boya Seneto Dino ṣì wà ní ipinle Kogi,o kọ láti fèsì.
O ni ọrọ náà nise pẹlú ààbò ẹmi Seneto Dino.
Lọjọru ni àwọn afurasi Janduku kan lọ dana sun awọn iṣẹ akanṣe ti Senetọ Dino Melaye fẹ ṣí.
Ile iwe awọn akẹkọbinrin ti agbegbe Sarkin-Noma ni Lokoja atile iwe alakọbẹrẹ ti LGEA ni Lokogoma ni wọn bajẹ.
Idibo Ọsun : Adeleke,Ogunbiyi, Adejare ati Nathaniel lo n dije
Idibo Ọsun : Adeleke,Ogunbiyi, Adejare ati Nathaniel lo n dije
Iroyin to n tẹwa lọwọ sọ pe nkan o rọgbọ nibi eto idibo abẹlẹ ti ẹgbẹ oselu PDP, lẹyin ti awọn ọdọ kan gbe igi lati fi se ikọlu si Alaga ẹgbẹ oselu PDP ni ipinlẹ naa, Sola Adagunodo.
Awọn ọdọ to n se agbatẹru fun oludije, Sẹnatọ Nurudeen Adeleke fi ẹsun kan Adagunodo wi pe o wa lẹyin Akin Ogunbiyi to jẹ ọkan ninu awọn oludije si ipo gomina naa.
Amọ, awọn ẹsọ eleto aabo ti mu ohun gbogbo pada bo sipo, lẹyin ti awọn ọdọ naa ba ọkọ Ajọ INEC to wa nibe jẹ.
Awọn amoye ni idije naa wa laarin Akin Ogunbiyi, Fatai Akinbade ati Ademola Adeleke
Awọn ẹlẹto idibo ni ipinlẹ Ọsun ti bẹrẹ si ni ka ibo awọn oludije ninu eto idibo abẹnu lati mọ ẹni ti yoo soju ẹgbẹ oselu PDP nipinlẹ Ọsun ni idibo si ipo gomina ti yoo waye ni Osu Kẹsan, ọdun yii.
Tani yóò pegedé nínú ìbò abẹ́lé PDP l‘Ọ́sun?
Ọpọ awọn ọmọ ẹgbẹ oselu PDP lo ti pe jọpọ si ile itura GMT ni ilu Osogbo, ti eto idibo abẹnu naa ti n waye.
Ni owurọ Ọjọ Satide ni awọn oludibo di ibo lati yan ẹni ti yoo gbẹ asiya ẹgbẹ oselu PDP, atiwipe awọn oloye ẹgbẹ ati awọn agbofinro ti peju sibi aye idibo naa.
Ènìyàn kan láàáarín àwọn olúdíje mẹ́rin yìí ni yóò láǹfààní àti kópa nínú ìdìbò Gomina ìpínlẹ̀ Osun.
O le ni ẹgberun mẹta ọmọ ẹgbẹ lati ijoba ibile ogbọn ti yoo kopa ninu yiyan oludije fun ẹgbẹ ninu idibo naa
Wayi o, awon oludije kan ninu awọn to n dije fun ipo gomina labẹ asia ẹgbẹ oselu PDP ti kede pe awọn ko ni kopa ninu idibo naa mọ.
Òsìsẹ́-fẹ̀yìntì Èkìtì: À ń bẹ̀bẹ̀ fún gómìnà tí yóò sàánú wa
Lara awọn oludije naa ni ati ri Ojogbọn Durotoye Adeolu,Lere Oyewumi,Ayoade Adewopo ati olori ile asofin ipinle Osun nigba kan ri Adejare Bello.
Awọn amoye ni idije naa wa laarin Akin Ogunbiyi, Fatai Akinbade ati Ademola Adeleke.
Iroyin fikun wipe yàtọ̀ sí Akogun Lere Oyewumi tó yẹba fún Ademola Adeleke, àwọn Olùdíjé tó kù yẹba fún Akin Ogunbiyi.
Osun Election: Ìbò méje péré ni Adeleke fi fẹ̀yìn Adebiyi janlẹ̀
Oríṣun àwòrán, Ademola Adeleke/Facebook
Adeleke ni yóò kojú ọgbẹni Gboyega Oyetola ti ẹgbẹ òṣèlú APC nínú ìdìbò Gómìnà ìpínlẹ̀ Osun
Sẹ́nétọ̀ Ademola Adeleke ni yóò máa ṣojú ẹgbẹ́ òṣèlú PDP nínú ìdìbò sípò Gomina tí yóò wáyé ní Ìpínlẹ̀ Osun.Adeleke ni ìbò 1569 ṣáájú Akin Ogunbiyi tó ní ìbò 1562.
Ìbò méje péré ni Adeleke fi fẹ̀yìn Adebiyi janlẹ̀
Alaga eto ìdìbò náà, tó tún jẹ́ Gomina Ipinle Bayelsa Seriake Dickson ló kéde Adeleke gẹ́gẹ́ bí ẹni tó jáwé olú borí, lẹ́yìn tí wọ́n ka ìbò náà ní ẹ̀ẹ̀meji ọ̀tọ̀ọ̀tọ̀.
Adeleke ni yóò kojú ọgbẹni Gboyega Oyetola ti ẹgbẹ òṣèlú APC nínú ìdìbò Gómìnà ìpínlẹ̀ Osun tí yóò wáyé ní ọjọ kejilelogun oṣù kẹsán ọdún 2018.
Adeleke ni Sẹ́nétọ̀  tó n sójú ẹkùn ìdìbò  iwọ òrun ìpínlẹ̀ Osun ní ilé aṣòfin àgbà.
Osun Election: Babatunde Loye, Bunmi Ibiloye ati Pade Okunọla lo dije fun ibo abẹnu Accord
Sugbọn eto idibo abẹnu ẹgbẹ oselu Accord naa ko lọ lai jẹ pe o ni awọn isẹlẹ kan ninu
Saa idibo abẹnu lati yan awọn oludije ti yoo soju awọn ẹgbẹ oselu to gbode kan nipinlẹ Ọsun, ko yọ ẹgbẹ oselu Accord naa silẹ.
O le ni awọn asoju to wa lati awọn ijọba ibilẹ toto ọgbọn ati ijọba ibilẹ onidagbasoke kan, ti wọn peju silu Osogbo ni ọjọ abamẹta lati wa yan ẹniti yoo soju ẹgbẹ naa bi oludije gomina.
Awọn oludije mẹta lo fa ipo naa mọ ara wọn lọwọ ninu ẹgbẹ oselu Accord. Awọn oludije fun ipo gomina naa ni Babatunde Loye, Bunmi Ibiloye ati Pade Okunọla.
Segun Ọdẹgbami: Mo kọ̀ láti lọ sí APC àti PDP nítorí ń kò fẹ́ ní ‘Bàbá ìsàlẹ̀’
Lẹyin ọ rẹyin ti ibo naa pari, Pade Okunọla lo bori awọn eeyan meji ti wọn dijọ dije pẹlu ibo mọkanlelogoje.
Sugbọn eto idibo abẹnu ẹgbẹ oselu Accord naa ko lọ lai jẹ pe o ni awọn isẹlẹ kan ninu, gẹgẹ bo se wa pẹlu awọn ẹgbẹ oselu yoku.
N se si ni awọn ọlọpa duro wa wa wa sibẹ lati ri daju pe ọfọn kankan ko firu na igba nibi idibo abẹnu Accord naa.
Lẹyin ikede esi ibo yii, ni wọn rọ gbogbo awọn asoju lati maa lọ sile koowa wọn.
Bi alaga ẹgbẹ osleu Accord nipinlẹ Ọsun, Hon Fanibẹ si sen kede esi ibo naa, ni iroyin gbalẹ kan pe awọn gende agbebọn kan ti wa layika ibẹ, lati da rugudu silẹ́ lẹyin ikede esi ibo naa.
Lẹyin ikede esi ibo yii, ni wọn rọ gbogbo awọn asoju lati maa lọ sile koowa wọn.
Bẹẹ ba si gbagbe, ni ọjọ abamẹta ti ẹgbẹ oselu PDP n se eto idibo abẹnu tiẹ ni ilu Osogbo, naa ni ẹgbẹ oselu Accord n se tiẹ ni ẹgbẹ kan lati yan ẹni ti yoo soju rẹ gẹgẹ bii gomina.
Lẹyin ọ rẹyin ti ibo naa pari, Pade Okunọla lo bori awọn eeyan meji ti wọn dijọ dije pẹlu ibo mọkanlelogoje.
Sẹnatọ Ademọla Adeleke lo fi ibo meje fẹyin alatako rẹ, Akin Ogunbiyi janlẹ lati di oludije fun ipo gomina fẹgbẹ oselu PDP>
ẸBakan naa ni ẹgbẹ oselu APC ti se eto idibo abẹnu lati yan ẹniti yoo soju rẹ gẹgẹ bii gomina ninu idibo to n bọ losun kẹsan ọdun yii lọjọ Ẹti.
Gboyega Oyetola, tii se olori awọn osisẹ ni ọọfisi gomina nipinlẹ Ọsun si lo pegede ninu ìdìbò abẹ́nú APC naa.
Ikú alaga PDP: Niyi Aborisade ni alága PDP ní ìjọba ìbílẹ̀ Apápá
Wọn gbe Niyi Aborisade lọ ile iwosan kan ni Obalende, sugbọn ẹ̀pa kò bóró mọ́
Àlaga ẹgbẹ oṣelu PDP ni ijọba ibilẹ Apapa ni Ipinlẹ Eko, Niyi Aborisade, ti gbẹmii mi bayi, lẹyin ti awọn janduku ti yinbọn pa nibi ipade kan to waye ni ọjọ Abamẹta ni Eti Osa.
Ileesẹ ọlọpaa Ipinlẹ Eko sọ wipe, ipade awọn alaga ijọba ibilẹ ẹgbẹ PDP nilu Eko waye ni adugbo Igbosuku lopopona marosẹ Lekki si Ẹpẹ to wa ni ijọba ibilẹ Eti Osa, nibi ti ija ti bẹ silẹ laarin igun (faction) meji ẹgbẹ naa.
Inu ija naa ni wọn ti yinbọn si ẹsẹ Aborisade to jẹ ọkan gboogi ninu awọn alaga ijọba ibilẹ PDP n'Ipinlẹ naa.
Agbẹnusọ fun ileesẹ ọlọpaa Ipinlẹ Eko, Chike Oti, ni wọn gbe Aborisade digbadigba lọ ile iwosan First Consultant to wa ni Obalende, sugbọn wọn ko le doola ẹmi rẹ.
O ni awọn meji miiran lo fara pa nibi iṣẹlẹ naa, ti wọn si n gba itọju ni awọn ni ile iwosan kan ni Ajah.
Oti ni kete ti ọga ọlọpaa ni Ipinlẹ Eko, Edgal Imohimi gbọ nipa iṣẹlẹ naa, lo paṣẹ fun ọga ọlọpaa agbegbe Area 'J' Elemoro, lati gbe awọn to lọwọ ninu ọrọ naa ti mọle.
Awọn ti wọn ti wa ni ahamọ ọlọpaa bayii ni awọn alaga PDP fun ijọba ibile Eti Osa, Surulere, Amuwo Odofin, Mushin ati Lagos Island.
Imohimi ti ni ki wọn gbe ọrọ naa lọ ẹka ileeṣẹ ọlọpaa ọtẹlẹmuyẹ to wa ni Panti, Yaba.
#EndSARS: Lẹ́yin àṣẹ́ adelé Ààrẹ Osinbajo, ọgá ọlọ́pàá yan orúkọ tuntun fun SARS
Oríṣun àwòrán, @NG_Police
Idris ko ba awọn oniroyin s'ọrọ lẹyin ipade rẹ pẹlu aarẹ
Ọga agba ileeṣẹ ọlọpàá Ibrahim Idris ti kede ayipada orukọ, SARS, lẹyin ti adele Ààrẹ orílè-èdè Naijiria,Yemi Osinbajo  pàṣẹ ko ṣe àtúnto ẹka naa.
Ni bayi, o ni Federal Special Anti Robbery Squad(FSARS) ni SARS yoo maa jẹ.
Bakanna lo ni gbogbo ẹka SARS teleri ri to wa labẹ ti bọ si abe FSARS pẹlu iyipada tuntun yi.
Eyi nikan kọ, Kọmiṣọna ọlọpàá kan ni yoo maa dari ajọ naa bayii, yoo si maa jẹ abọ fun ẹka ileeṣẹ olopaa ni Abuja to n ri si iwa ọdaran.
Sugbọn awọn ọmọ Naijiria ti n se eemọ lori igbese yi.
Ni oju opo Twitter ibeere ti awọn eeyan n bere ni pe kini iyato to wa laarin SARS ati FSARS ati wipe ṣebi FSARS lorukọ ti wọn ti n jẹ latilẹ tẹlẹ ri?
Lọjọ isẹgun ni  agbẹnusọ fún adele Ààrẹ, Laolu Akande, fi  ọrọ síta loju opo Twitter  pé Adele Aarẹ Yemi Osinbajo ti pasẹ fun ọgá ọlọpaa lati se atunto SARS.
Osinbajo so wí pé ọmọ tuntun ti atunto SARS yoo bí gbọdọ máa ṣíṣe lọnà to tọ ati eyi to yẹ.
gbọdọ kojú mọ iṣẹ ti wọn gbe kale fun un ti ṣe didẹkun iwa adigunjale àti ìwà ajinigbe tó fí mọ mímú àwọn tí wọn hù ìwà tó jẹ mọ àwọn ẹṣẹ wọn yí.
Adele Ààrẹ Osinbajo tẹsíwájú pé  o di dandan ki àwọn oṣiṣẹ SARS ni àmì idanimo lara wọn ní gbogbo ìgbà tí wọn bá n ṣíṣe wọn.
Ti a kò bá gbàgbé oríṣiríṣi iriri lo tí n waye lati ọdọ ara ìlú nípa ìhùwàsí àwọn oṣiṣẹ SARS
Ẹsun iseku pa awọn ọmọ Naijiria nipakupa jẹ ọrọ ti awọn ọmọ Naijiria ko le mẹnu kuro nibẹ lati bii oṣu meloo kan.
Tóun tí bí ẹnu ti ṣe n kun wọn,ilé iṣẹ ọlọpa lorílè-èdè Nàìjíríà ni awon kò ri ìdí tí wọn yóò fi kagba Sars wọlé Bo tilẹ jẹ pe awọn yoo gbe igbeṣẹ lati ri pe wọn ṣe atunto ẹka SARS naa.
ọ̀gá ọlọ́pàá sọ̀rọ̀ lórí SARS
SARS ti bẹ̀rẹ̀ ìgbésẹ̀ láti yọ àwọn ọ̀bàyéjẹ́ kúro
Abuja-Kaduna: Àwọn arìnrìn àjò ní àwọn ọlọ́pàá kò leè ta pútú
Oríṣun àwòrán, @Omojuwa
Àwọn ajínigbé ti sekú pa ológun kan, wọ́n tún jí ọ̀pọ̀ arìnrìniajò lọ lójú ọ́na marosẹ̀ Abuja sí Kaduna lọ́jọ́ Àìkú.
Awọn ajinigbe mẹwa ni wọn ṣọsẹ loju ọna mọrosẹ Abuja si Kaduna lọjọ Aiku nibi ti wọn ṣeku pa ọmọ ologun kan ti wọn si ji ọpọ arinrinajo gbe.
Iṣẹlẹ naa lo ṣẹlẹ lẹba abule Gidan Busa to wa laarin Jere ati Kateri lopopona ọhun.
Arinrinajo kan tori kọyọ Mohammed Sheriff fidi rẹ mulẹ pe, awọn ọdaran naa ṣọsẹ fun bii wakati kan loju ọna naa.
Bọlanle Aliyu: N kò nílò bàbá ìsàlẹ̀ láti di gómìnà
Arinrinajo miran jẹri wipe, ọlọpa kan naa wa lara awọn ti wọn padanu ẹmi wọn ninu iṣẹlẹ ọhun.
Awọn ti iṣẹlẹ naa tun ṣoju wọn sọ pe, awọn oṣisẹ eleto aabo ko le doju jọ awọn janduku ọhun.
Wọn ni awọn ọlọpaa naa sọ pe awọn nilo iranwọ si lati le koju awọn ajinigbe naa.
Ọ̀sun Election: Akin Ogunbiyi àti Moshood Adeoti kọ èsì ìbò
Oríṣun àwòrán, @akmediaonline
Akin Ogunbiyi àti Moshood Adeoti kọ èsì ìbò abẹnu ẹgbẹ koowa wọn
Ọmwe Akin Ogunbiyi, ti oun ati Senatọ Ademọla Adeleke dijọ dije ninu ibo abẹnu fun ipo gomina labẹ ẹgbẹ oselu PDP nipinlẹ Ọsun, ti fariga lati faramọ esi ibo abẹnu ti wọn kede naa lọjọ Abamẹta, to si leri leka pe oun yoo gbe igbesẹ lati wa iyipada lori ọrọ yii ninu ẹgbẹ naa.
Lasiko to n bawọn akọroyin sọrọ lori abajade ibo abẹnu PDP nipinlẹ Ọsun, eyi to se ni ilu Ile-Ogbo, tii se ilu abinibi rẹ, Ogunbiyi ni bi wọ́n se se ayẹwo orukọ awọn asoju to dibo, eto idibo ati kika esi ibo ni wọn se lati gbe lẹyin alatako oun, Senatọ Ademọla Adeleke.
Bọlanle Aliyu: N kò nílò bàbá ìsàlẹ̀ láti di gómìnà
O ni nigba ti wọn tun ibo naa ka ni ẹẹkeji, sebi ibo oun tun lowura ju ti akọkọ lọ, eyi to fihan pe eto idibo naa lọwọ magomago ninu, ti ko si tẹ oun ati awọn alatilẹyin oun lọrun.
"Mo n fi da yin loju pe awọn dibo fun mi pupọ, ọpọ̀ awọn asoju to dibo lo n se temi, lagbara Ọlọrun, maa gba ipo mi pada bii oludije fun ipo gomina fẹgbẹ oselu PDP nipinlẹ Ọsun.
Bakan naa, akọwe ijọba ipinlẹ Ọsun, Alhaji Moshood Adeoti, toun naa kopa ninu ibo abẹnu APC lati yan ẹniti yoo soju ẹgbẹ oselu naa, ninu eto idibo gomina to n bọ losu kẹsan ọdun 2018 nipinlẹ Ọsun, amọ to fidi rẹmi, ti kọwe pe oun ko se ẹgbẹ oselu APC mọ.
Oríṣun àwòrán, @Akinogunbiyi48
Ogunbiyi ni bi wọ́n se se ayẹwo orukọ awọn asoju to dibo, eto idibo ati kika esi ibo ni wọn se lati gbe lẹyin alatako oun, Senatọ Ademọla Adeleke.
Adeoti, kede igbesẹ rẹ naa lẹyin ti ọkan lara awọn ti wọn dijọ dije, tii tun se olori osisẹ lọọfisi gomina nipinlẹ Ọsun, Alhaji Gboyega Oyetọla, jawe olubori ninu ibo naa.
Nigba to n bawọn akọrioyin sọ̀rọ nilu Osogbo, Adeoti, ẹni ti amugbalẹgbẹ rẹ feto iroyin, Kayọde Agbaje soju fun ni awada kẹri-kẹri lasan ni eto idibo abẹnu to waye lọjọ ẹti naa, eyi ti ko se afihan ifẹ ọkan awọn asoju to wa nibẹ.
Amugbalẹgbẹ rẹ feto iroyin naa ni  Akọwe ijba yoo papa du ipo gomina sugbọn emi ko lee sọ abẹ asia ẹgbẹ ti yoo ti dije fun ipo naa."""
Oríṣun àwòrán, @MoshoodAdeoti
Atẹjade kan ti Adeoti fi ransẹ si wọọdu idibo rẹ, tii se Wọọdu kejila, nijọba ibilẹ Iwo, fihan pe o ti fi ẹgbẹ oselu APC silẹ.
Wayi o, atẹjade kan ti Adeoti fi ransẹ si wọọdu idibo rẹ, tii se Wọọdu kejila, nijọba ibilẹ Iwo, fihan pe o ti fi ẹgbẹ oselu APC silẹ.
Ninu atẹjade naa si lo ti n dupẹ lọwọ gbogbo awọn alatilẹyin rẹ, to dibo fun, to si tun n jẹjẹ pe oun setan lati sisẹ fun ilọsiwaju ipinlẹ Ọsun ni ipokipo ti oun ba ba ara oun.
Ìsẹ̀lẹ̀ Boko Haram: Mọ́sálásí ni aso àdó ikú mọ́ra ti sọsẹ́
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Awọn eeyan ti isẹlẹ naa soju wọn ni ko din ni eeyan mẹjọ to se agbako iku ojiji naa nigbati awọn marun miran farapa.
Eeyan mẹjọ mii tun ti tẹri gbasọ lati ipasẹ ado iku Boko Haramni abule Konduga nipinlẹ Borno.
Idaji ọjọ Aje, ni deede aago marun kọja isẹju mẹẹdogun aarọ ni isẹlẹ naa waye nigbati aso ado iku mọra gbẹmi ẹni kan rin wọ inu mọsalasi lasiko irun idaji, to si yin ado oloro to wa lara rẹ.
Awọn eeyan ti isẹlẹ naa soju wọn ni ko din ni eeyan mẹjọ to se agbako iku ojiji naa nigbati awọn marun miran farapa.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Mọ́sálásí ni aso àdó ikú mọ́ra náà ti sọsẹ́
Meje ninu awọn eeyan yii lo gbẹmi mi ninu mọsalasi nigbati ẹni kan yoku ku loju ọna ile iwosan ti wọn n gbe lọ fun itọju.
Ọsun Decides: Charlie Boy ni ọ̀pọ̀ àìda ló wáyé lásìkò ìbò Ọ̀sun
Oríṣun àwòrán, Funmi Sodiq
Gbajugbaja onkọrin takasufe nni, Charles Oputa ti ọpọ mọ si  Charly Boy ti pe fun iwadii to jinlẹ lori bi eto idibo gomina ipinlẹ Ọsun to kọja ṣe lọ.
Charlie boy sọrọ yii nigba to darapọ mọ awọn ajafẹtọ ẹni miiran nibi apero kan ni ilu Osogbo.
O ni bi orileede Naijiria ko ba fẹ fi awokọṣe buruku lori ibo rira, didun mọhuru mọ oludibo ati magomago lasiko idibo lelẹ, afi ki awọn alasẹ ti ọrọ kan o yara tete ṣe iwadii to kunna lori bi isu ṣe ku, ti ọbẹ sí bẹẹ lasiko idibo naa.Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí:
Jide Kosọkọ: Isẹ́ tíátà yóò gòkè tíjọba bá gbówó kalẹ̀ láti seré
Ni ọjọ Isẹgun ni ẹni ti ajọ INEC Kede pe o bori ninu idibo sipo gomina ni ipinlẹ Ọsun, eyi to waye ni osu kẹsan ọdun 2018, iyẹn Ọgbẹni Gboyega Oyetọla yoo máa tẹwọ gba ọpa aṣẹ gomina lọwọ Rauf Aregbesola, to ti di ipo naa mu fún ọdun mẹjọ.
Lara awọn ohun ti awọn ajafẹtọ naa salaye gẹgẹ bii aleebu ara idibo naa ni, ṣiṣe segesege awọn ẹrọ ti n yẹ kaadi oludibo wo, didun mọhuru mọ awọn akọroyin, pẹlu ohun ti wọn pe ni àìsí ootọ awọn oṣiṣẹ eleto idibo lasiko ti ibo naa waye.
Oríṣun àwòrán, Funmi Sodiq
Charlie Boy ni ojuse awọn ọmọ orilẹede yìí ni lati fi eto rere lelẹ fawọn iran ti o n bọ nipa eto idibo ti yoo ṣafihan ifẹ araalu ni tootọ.
Bẹẹ lo ni asiko idakẹ jẹẹ fún àwọn ọmọ orilẹede Naijiria ti to gẹẹ, yoo si dara kí wọn dìde láti tako eru lasiko idibo.
O wá rọ awọn ọdọ lati dide ja fun agbekalẹ eto iṣejọba tiwantiwa ti ko lẹjanbakan ninu, eto idari to see fi ọkan tan ati idajọ ododo fun mutumuwa, ki Naijiria lee tẹ siwaju.
Oríṣun àwòrán, @Oyetọla_Gboyega
Awọn ajafẹtọ miiran to sọrọ nibi eto naa ni Dare Ariyo lati ajọ Democracy and Good governance ati Festus Ojewumi lati ibudo to wa fun eto idajọ ododo ati ipẹtu saawọ.
Awọn yoku ni Festus Ojewunmi ati Wole Oladapo lati Virtues Restorative Justice Initiative.
Awọn ajafẹtọ naa ni, eto idibo gomina to waye ni ipinlẹ Ọsun jìnnà sí ìlànà aatẹle fún idibo lagbaye ti won sì ke sí ẹka isedajo lati fi oju tó tọ wo awọn ẹhonu to ba tipasẹ idibo naa jade sí ọdọ wọn.
Awọn ẹgbẹ oṣelu to wa nibi apero naa pẹlu ko sai rọ àwọn orileede agbaye lati mase kọpakọ si bi eto idibo àpapọ ọdun 2019 yóò ṣe lọ lorileede Naijiria.
Ìwọ́de, ìkọ̀wéfipò sílẹ̀, gbode lori ìdìbò abẹ́lé l‘Ọsun
Ìdìbò abẹnu ipinle Osun to waye lopin ọse, kángun kángun kángun,o kọ, ko ríbi kángun sí
Bi àwọn alatilẹyin ọgbẹni Akin Ogunbiyi tó fidi rẹmi nínú ìdìbò abẹnu ẹgbẹ òṣèlú PDP nipinlẹ Osun ṣé n wọde ni Olú ilé ẹgbẹ wọn nílu Òṣogbo lakowe osise ijọba ipinle Osun,Moshood  Adeoti kowe fi APC sile.
Koda, Ọgbẹni Adeoti ti yan ẹgbẹ oselu ADP lẹbi tuntun ti o si ti kede idarapọmọ ẹgbẹ naa.
Adeoti ní aiṣedeede nínú ìdìbò abẹnu APC ló sún òun débi a n kowefiposilẹ àti wí pé òun ṣetan láti dije ipò Gómìnà nínú ìdìbò tó n bọ lónà lábé àsìá ẹgbẹ ADP.
Toun ti ijakule idibo abẹnu APC,Moshood Adeoti tẹsiwaju ipinu rẹ lati di Gomina ipinlẹ Osun
Bákannáà lọmọ ṣori lọdọ awọn alatilẹyin ọgbẹni Akin Ogunbiyi ti wọn ṣe iwode lọ sí ilé ẹgbẹ PDP losogbo.
Wọn ní àwọn n ṣé iwọde náà láti fi ehonu hàn lórí àbájáde èsì ìdìbò abẹnu ẹgbẹ òṣèlú PDP to waye lopin ọsẹ to kọjá.
Wọn ní àwọn lòdì sí àbájáde ìdìbò náà èyí tí Seneto Ademola Adeleke jáwé olú bori.
Oríṣun àwòrán, Yemi Akintunde
Nisẹ ni awọn alatileyin Ogunbiyi fariga pẹ oun lo jawe olubori ninu idibo abẹnu to waye lopin ọsẹ
Àwọn alatilẹyin Akin Ogunbiyi ní, ti ẹgbẹ ba tẹsiwaju láti fà Ademola Adeleke kalẹ gẹgẹ bí Oludije ẹgbẹ PDP nínú ìdìbò Gómìnà ti yoo waye loṣù kẹsán, o ṣé ṣé kí ẹgbẹ náà padanu ipò Gómìnà.
Ṣáájú ní Akin Ogunbiyi ti tapa sí àbájáde ìdìbò abẹnu naa eyi to wáyé lópin ọsẹ nílu Òṣogbo.
PDP Ogun: Ilé ẹjọ́ dájọ́ àre fún Buruji Kashamu àti Adebayo Dayo
Oríṣun àwòrán, Sen_Kashamu
Sẹneto Buruji Kashamu
Ile ẹjọ giga kan nilu Abuja ti fagile aṣẹ ẹgbẹ oselu Peoples Democratic Party, PDP to le Sẹnẹto Buruji Kashamu ati alaga ẹgbẹ nipinlẹ Ogun kuro ninu ẹgbẹ.
Ninu idajọ to waye lọjọru ti se ọjọ kẹ́wa osu kẹwa,adajọ Vanlentine Ashi ni igbese ẹgbẹ naa lati le Kashamu ati Dayo kuro ninu ẹgbẹ lodi sofin ti o si jẹ iwa aibikita fun aṣẹ ti ile ẹjọ ti saaju paa ki wọn ma se nnkankan lori ọr naa to wa ni iwaju ile ẹjọ.
Oríṣun àwòrán, FACEBOOK/Senator-Buruji-Kashamu
Aworan Seneto Buruji Kashamu
Lọjọ kẹtalelogun oṣu keje ni ẹgbẹ òṣèlú PDP ni kí  Senetọ Buruji Kashamu kẹru rẹ kuro ninu ẹgbẹ awọn.
Asẹ yi waye lẹyin ipade gbogbogbòò ẹgbẹ PDP nibi ti  ìgbìmò alákòóso ẹgbẹ ti  pàṣẹ kí Seneto Kashamu Buruji  àti àwọn mẹrin mí kuro ninu ẹgbẹ oselu PDP nipinlẹ Ogun.
Akọ̀wé ẹgbẹ́ òsèlú PDP, Ọ̀gbẹ́ni Kola Ologbondiyan lo lede oro yi loju opo Twitter ẹgbẹ naa.
Awọn mẹrin ti ọrọ naa kan ni Ogbẹni  Samiu Sodipo,Bayo Adebayo aati asoju Segun Seriki.
Bakanna ni o so wi pe ẹgbẹ  fasẹ si ki ẹka ẹgbẹ́ PDP ni ipinlẹ Ekiti tako ẹsi idibo Gomina ipinlẹ Ekiti to waye laarin asiko yi ni ile ẹjọ
Ìgbìmò alákòóso ẹgbẹ PDP tun fọwọ si adehun ti ẹgbẹ naa se pẹlu awọn ẹgbẹ oselu mii.
Wọn ni awọn yoo sapa lati ri wi pe gbogbo  ẹgbẹ  to jijo towo bọ adehun se aseyọri.
Sugbọn aṣẹ kuro ninu ẹgbẹ yi ko tẹ Sẹnẹtọ Buruiji Kashamu  ati Alaga ẹgbẹ Adebayo Dayo lọrun ti wọn si pe ẹgbẹ sẹjọ ninu iwe ipẹjọ M/8696/2018, ti agbẹjọro wọn Charles Ndukwe fi tapa si aṣẹ kuro ninu ẹgbẹ wa yii.
Awijare wọn ni pe ẹgbẹ gbe igbesẹ naa nigba ti ọrọ naa si wa ni iwaju ile ẹjọ
Iná sọ ní Ilééṣẹ́ ijọba Ipinlẹ Osun
Ìròyìn ti fi han pe ina ti mu apa kan ọfiisi Gomina Ipinlẹ Osun, Rauf Aregbeṣọla, ni Oṣogbo.
Akọroyin wa to lọ s'ibi iṣẹlẹ naa wipe ni kete ti ina naa bẹrẹ ni awọn panapana b'omi pa ina naa. A gbọ pe ina naa bẹrẹ ni bii agogo marun.
Kọmiṣọna fun Eto Iroyin Adelani Baderinwa ni ina ijọba to sọ lojiji lati ara ẹrọ amule tutu lo fa iṣẹlẹ naa, ṣugbọn Aregbesọla ko si nile ni akoko naa.
Àwọn ti iṣẹ̀lẹ̀ naa ṣoju wọn ni ilẹkun ofiisi gomina ko ṣee ṣi nigba ti ina naa n jo lọwọ.
Baderinwa wipe ko si iwe kankan tabi irin iṣẹ ti ina naa bajẹ.
"O ni, ""Ọfiisi gomina nikan ni ina naa mu. Ko de awọn ofiisi to ku."""
Oyedepo: Ẹni tó bá ń sàánú àwọn apànìyàn, kò ní mú 2018 jẹ
Oyedepo ni ọdun yii ko ni lọ lai jẹ pe Ọlọrun bẹ awọn eeyan to n gbẹmi awọn ọmọ orilẹ-ede yii wo
Olori ijọ Living Faith, ti wọn n pe ni Winners Chapel, Bisọọ́bu David Oyedepo ti fewe ọmọ mọ gbogbo awọn to n gbẹmi alaisẹ ni orilẹ-ede yii leti pe, ọjọ ẹsan wọn sunmọ etile, ti ilẹ yoo mọ ba osika wọn.
Oyedepo kede ọrọ yii lasiko iwaasu to se nibi isin ọjọ isinmi to waye ninu olu ijọ Winners to wa ni Ọta, nipinlẹ Ogun.
Gẹgẹ bo ti wi, ọdun yii ko ni lọ lai jẹ pe Ọlọrun bẹ awọn eeyan to n gbẹmi awọn ọmọ orilẹ-ede yii wo, to fi mọ awọn eeyan to n se atilẹyin fun wọn, tabi awọn to n saanu fun awọn apaniyan.
Ọrẹ Falọmọ: Buhari yóò rí ìbò Yorùbá gbà ju Atiku, Ọbasanjọ lọ
Nigba to n gbarata lori isẹlẹ ipaniyan to waye ni ipinlẹ Benue laipẹ yii, nibi ti ọpọ ẹmi awọn araalu ti bọ, olori ijọ Winners lagbaye ni, o dabi ẹni pe ẹmi eeyan ko tiẹ wa jọ awọn apaniyan yii loju mọ, ti wọn ko si bikita mọ rara lati da ẹmi awọn eeyan legbodo.
Emi ko ri iru isẹlẹ ipaniyan bi eyi ri, ti awọn eeyan n sare kiri, ti ọpọ wọn si n subu lulẹ, ti wọn n ku. O si yẹ ko ye wa pe gbogbo ẹmi lo jẹ ti Ọlọrun, to fi mọ ẹmi awn ẹranko, ti Ọlọrun si ti setan lati gba ẹsan lara ẹnikẹni to ba da ẹmi alaisẹ legbodo, ki ọdun yii to pari.
Oyedepo, ẹni ti iwaasu rẹ kun fun ire fawọn olujọsin rẹ, ati egun lori awọn ẹni apaniyan ni Naijiria, tun gegun pe ẹnikẹni to ba ni oun yoo pa eniyan ko to de ipo oselu, ko ni de ori ipo naa laelae.
Oyedepo ni o dabi ẹni pe ẹmi eeyan ko tiẹ wa jọ awọn apaniyan yii loju mọ, ti wọn ko si bikita mọ rara lati da ẹmi awọn eeyan legbodo.
Nigba to n tako iroyin kan to ni o n gba owo lọwọ awọn oloselu, Oyedepo ni oun ko gba kọbọ ri lọwọ oludije kankan ko to de ipo, ti oun ko si setan lati gba owo lọwọ oloselu kankan.
O fikun pe alaafia orilẹ-ede yii lo jẹ oun logun, eyi ti oun n tiraka fun ni gbogbo igba, bẹẹ si ni wolii Ọlọrun alaaye ni oun bi o tilẹ pe awọn woli eke wa, to fara jọ woli Ọlọrun.
Oyedepo tun rọ ojo epe sori awọn eeyan to n ti awọn apaniyan lẹyin pe, egun ati ibi to n bẹ lori awọn apaniyan naa ni yoo jẹ ipin tiwọn naa.
Oyedepo ni oun ko gba kọbọ ri lọwọ oludije kankan ko to de ipo, ti oun ko si setan lati gba owo lọwọ oloselu kankan.
O da mi loju pe awọn alasẹ Naijiria ko lee sọ pe awọn ko ti awọn apaniyan lẹyin nitori gbogbo awọn eeyan tawọn agbofinro mu pe wọn n pa eniyan, ni ijọba ti tu silẹ patapata.
Bawo ni wọn se lee maa gba ẹmi awọn ọmọ ilẹ yii ni gbogbo igba, ti a ko si tii ri ẹnikẹni mu lati fi jofin. Koda, ẹni tawọn agbofinro mu pe o pa iyawo oniwaasu kan ni ijọ Deeper Life, lo ti gba idande kuro lahamọ, ti wọn si tun dana sun ọpọ sọọsi lorilẹ-ede yii.
Oyedepo wa leri leka pe, laipẹ ni oun yoo kede iye sọọsi ti wọn ti sọ ina si ni orilẹ-ede yii.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ìkọlù àwọn Fulani Darandaran ti mún ọ̀ps ẹ̀mí lọ
Bakan naa, Olori ijọ Living Faith, ti wọn n pe ni Winners Chapel, Bisọọ́bu David Oyedepo ti kepe Aarẹ orilẹede Naijiria, Muhammadu Buhari, lati kọwe fipo silẹ lori ọrọ awọn Fulani darandaran ti wọn n fẹmi awọn eeyan ṣofo.
Bisọbu Oyedepo lo jẹ ojiṣẹ Ọlọrun kẹta, ti yoo rọ Aarẹ Buhari lati kọwe fipo silẹ lẹyin ti bisọọbu agba fun Ijọ Aguda l'Abuja, John Cardinal Onaiyekan, ati akẹẹgbẹ rẹ tẹlẹ nipinlẹ Eko, Cardinal Anthony Olubunmi Okogi, sọ fun Aarẹ Buhari lati fipo silẹ lẹyin to kuna lati daabo bo awọn ọmọ Naijiria.
Oyedepo sọ pe fifi ẹmi awọn alaiṣẹ Kristẹni ṣofo,  papa julọ laarin gbungbun orilẹede Naijiria  ti to gẹẹ.
O fi kun ọrọ rẹ pe, kin lode ti awọn Fulani darandaran fi n kọlu awujọ awọn ọmọlẹyin Kristi nikan, ti ọwọ sinkin ofin ko si mu wọn.
Ojiṣẹ Ọlọrun naa woye pe, awọn alaṣẹ ijọba lo n tiwọn lẹyin, bibẹẹkọ wọn o ba ti dẹkun ipaniyan.
Saraki: Ète láti fi ipá mú mi dúró ní APC yóò já s'ásán
Ọlọpaa di ẹnu ọna ile Saraki pa
Aarẹ ile aṣofin agba Naijiria, Bukọla Saraki ti fesi si bi ileeṣẹ ọlọpa ṣe ni ko wa sọ nkan to mọ lori idigunjale kan to waye nilu Ọffa laipẹ yii.
Saraki ninu ọrọ kan to fi si oju opo Twitter rẹ ni, ileeṣẹ ọlọpa ti fi ọwọ́ oṣelu mu ọrọ idigunjale naa.
Ati pe, ''gbogbo igbesẹ naa dalori ati fi tipa-tipa mu oun ati awọn alatilẹyin oun duro ninu ẹgbẹ to n fi ẹsun ọdaran kan ni lọna ti ko bofin mu.''
Ṣaaju ni ileesẹ ọlọpaa ni Naijiria kọ lẹta si Saraki pe ko wa si olu ileeṣẹ wọn laago mẹjọ aarọ ọjọ Iṣẹgun, ko too di pe wọn fi ọkọ wọn dí oju ọna mọ ọ,  ni deede aago mẹjọ aarọ oni.
Fidio bawọn ọlọpaa se sẹburu Saraki lati mase kọja lo wa loke yii.
Bẹẹ ba gbagbe, igba keji ree ti ileesẹ ọlọpaa pe Saraki lati yọju si awọn lori ọrọ idigunjale ilu Ọffa to waye laipẹ yii, amọ iwe ni Saraki kọ si wọn lati fesi pada, ki wọn to tun ransẹ pee lẹẹkeji.
Oríṣun àwòrán, @Gidi_Traffic
Ọpọ eeyan si lo ti n fi ikede naa soju opo ikansira ẹni wọn lori ayelujara.
Àsìkò tó ń lọ síléesẹ́ ọlọ́pàá lati lọ jẹ ipe ọga agba ọlọpaa to ransẹ pee lori ọrọ idigunjale Ọfaa, ni wọ́n sẹ́bùrú rẹ̀.
Oríṣun àwòrán, @MrBanksOmisore
Àsìkò tó ń lọ síléesẹ́ ọlọ́pàá ni wọ́n sẹ́bùrú rẹ̀.
Oríṣun àwòrán, @Gidi_Traffic
Ikorita Lake Chad nilu Abuja ni awọn ọlọpa ti sena mọ aarẹ ile asofin agba naa.
Ikede kan ti amugbalẹgbẹ aarẹ ile asofin agba, Senator bukọla Saraki fọrọ ibasepọ ilẹ okeere, ati isẹ nla-nla, Bamikọle Banks Omisore, fisita loju opo twitter rẹ ni ikorita Lake Chad nilu Abuja ni awọn ọlọpa ti sena mọ aarẹ ile asofin agba naa.
Ọpọ eeyan si lo ti n fi ikede naa soju opo ikansira ẹni wọn lori ayelujara, bẹẹ ni wọn n sọ ero wọn nipa isẹlẹ naa.
Lero ti @ogundamisi, o ni ko ba dara ki ileesẹ ọlọpaa faaye gba Saraki ko yọju si wọn na, ki wọn to maa lọ dena dee.
Rosanwo, @rosanwo naa ni iwa ọjaju si eto isejọba alagbada ni lati lo iwa ipa maa fi di ẹka isejọba lọwọ lati se is wọn.
Buhari: Mo gbiyanju láti ma jẹ kí àwọn aṣòfin fi APC silẹ́
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Buhari sni oun yoo ṣiṣẹ pẹlu gbogbo awọn ọmọ ile igbimọ aṣofin eyi o wu ti ẹgbẹ ọṣelu wọn jẹ
Aarẹ orileede Naijiria,Muhammadu Buhari ni oun ti sapa ti oun lati dẹkun bi awọn aṣòfin marundilogun to jẹ ọmọ ẹgbẹ oṣelu APC tẹle ṣe paarọ aye lọ si ẹgbẹ PDP.
Igbesẹ naa ya ọpọlọpọ lẹnu ni ọjọ Isẹgun.
Aarẹ sọ lori oju opo Twitter re  pe, oun mọ daju wipe, kii ṣe oun ni awọn sẹ́nétọ naa ni ija pẹlu.
O parowa si awọn ọmọ ẹgbẹ APC to ku ki wọn ma banujẹ, nitori igbesẹ awọn aṣòfin naa ko le ba nkan jẹ fun ẹgbẹ wọn bi idibo gbogbogbo 2019 ṣe n sunmọle.
Buhari sọ wipe oun yoo tẹsiwaju ninu iṣẹ oun pẹlu gbogbo awọn ọmọ ile igbimọ aṣòfin lalai fi ti ẹgbẹ ọṣelu wọn ṣé.
APC Convention: Ààrẹ Muhammadu Buhari ti dé sí Gbọ̀gàn ìdìbò
Okunrounmu: Ijọba Buhari jẹ ijiya Ọlọrun fun Naijiria
Afárá 3rd Mainland: Ìjọba ṣí afárá lẹ́yìn àtúnṣe
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Iṣẹ́ àtúnṣe ti parí lórí afárá 3rd Mainland ní ìlú Eko
Ijọba ipinlẹ Eko ti kede pe afárá 3rd Mainland si erekusu ile Eko ti wọn ti pa lalẹ Ọjọbọ ti di ṣiṣi bayii.
Agogo marun-un irọlẹ ọjọ Aiku  ni afara naa di ṣiṣi pada fun lilo.
Afárá 3rd Mainland: Ìjọba ṣí afárá lẹ́yìn àtúnṣe
Kọmisọna fun igbokegbodo ọkọ nipinlẹ Eko, Ọmọwe Taiwo Salaam fidi rẹ mulẹ pe igbesẹ lati ṣi afara naa saaju igba ti wọn fẹẹ ṣi waye lẹyin ti wọn ti pari iṣẹ atunṣe ti wọn se lori afara naa.
Ọdún kan lẹ́yìn ogun musulumi Rohingya, ìbànújẹ̀ dorí àgbà kodò
'Mi o fẹẹkan ni mo fẹ dupo aarẹ'
Ẹ̀wẹ̀, akọ̀ròyìn wa tó ṣe abẹwo kaakiri erekusu ilu Eko jabọ pe wámúwámú ni àwon òṣìṣẹ́ agbófinró dúró láti mójútó ìgbòkègbodò ọkọ̀ nigba ti afara naa wa ni titi pa.
àwon òṣìṣẹ́ agbófinró
Owó ọkọ̀ di gọbọi nígbà tí wọ́nti afara 3rd Mainland
Awakọ ni oju ọna afara third mainland ni ilu Eko, Ọlamilekan Rafiu ti sọ wi pe gbogbo eniyan to wa ni ilu Eko ni yoo faragba ninu igbese ijọba ipinlẹ Eko ati ijọba apapọ lati ti afara kẹta to wa ni ilu Eko.
Rafiu nigba to n ba BBC Yoruba sọrọ wi pe igbese naa ku die kaato nitori ijọba ko gbe igbese to yege lati yanju isoro ọna apapa ti awọn ọkọ nlanla ma n pejọ pọ si ni oju ọna.
Ninu ọrọ rẹ, o fi kun un wi pe o di dandan ki awọn gbe owo le owo ọkọ nitori inira sunkẹrẹ fakẹrẹ ọkọ yoo kọja agbara wọn.
Awakọ̀ 3rd Mainland Bridge:  Ìjọba ko yanjú súnkẹrẹ fàkẹrẹ ọ̀nà Apapa
Wọn ti kọkọ dájọ titi 3rd mainland tẹ́lẹ̀
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Idi ti wọn fi sun ọjọ ti wọn yoo ti afara naa si iwaju niise pẹlu igbiyanju ijọba ipinlẹ Eko lati mu idiwọ ati ipara ti yoo jẹ fun awọn ara ilu kuro lasiko naa
"Ijọba apapọ ti sun ọjọ mẹta ti wọn fẹ fi se atunse afara ""Third mainland bridge"" lati ọjọ kẹtadinlọgbọn si ọgbọnjọ Osu yii, si ọjọ kẹrinlelogun si ọjọ kẹrindinlọgbọn, Osu kẹjọ ọdun 2018."
Minisita fun ọrọ isẹ ode, ọrọ ilẹ ati ilegbe, Arakunrin Babatunde Fashola lo se ikede iyipada ọjọ atunse afara naa ninu atẹjade kan to fun awọn oniroyin.
Fashola ni, idi ti wọn fi sun ọjọ ti wọn yoo ti afara naa si iwaju, nii se pẹlu igbiyanju ijọba ipinlẹ Eko lati mu idiwọ ati ipalara ti yoo jẹ fun awọn ara ilu kuro lasiko naa.
Minisita naa fikun wipe, Ijọba apapọ tun pasẹ fun awọn ọkọ nla nla lati dari si papakọ to gba ọọdunrun ọkọ, ti wọn se lati dẹkun sunkẹrẹ ọkọ ni oju ọna marọse Oshodi si Apapa.
PDP: Kashamu ti gba ìwé nílé ẹjọ́ láti gbé àwọn asaájú wa
Oríṣun àwòrán, @Sen_Kashamu
PDP ni ijọba apapọ ati Kashamu ti n dete lati fi iwe asẹ ile ẹjọ gbe awọn asaaju ẹgbẹ oselu naa.
Wahala to n waye laarin ẹgbẹ oselu PDP ati sẹnatọ kan lati ipinlẹ Ogun, Buruji Kashamu, ko tii jẹ rodo, lọ ree mu omi o, lẹyin ti awọn alasẹ ẹgbẹ PDP le Kashamu kuro ninu ẹgbẹ wọn.
Idi ni pe awọn asaaju ẹgbẹ oselu PDP ti fi igbe bọnu lana pe ijọba apapọ ati Kashamu ti n dete lati fi iwe asẹ ile ẹjọ gbe awọn asaaju ẹgbẹ oselu naa.
Akọwe ipolongo fẹgbẹ oselu PDP, Kọla Ọlọgbọndiyan lo fi ikede naa sita lasiko to n bawọn akọroyin sọrọ nilu Abuja, pẹlu afikun pe Kashamu n gbe igbesẹ naa nitori igbesẹ ti PDP gbe lati juwe ọna ile fun.
Wùnmí Toríọlá: Toyin Abraham kìí se ọ̀gá mi nínú tíátà
"Ọ́lọgbọndiyan ni ""Awa la ni ẹgbẹ wa, ti wọn si yan wa lati maa se akoso rẹ nibamu pẹlu ofin orilẹ-ede Naijiria. Bi a si se n tukọ ẹgbẹ oselu PDP wa nibamu pẹlu ofin naa, to fi mọ awọn igbesẹ taa n gbe ati ipinnu ti a n se. Nitori naa, gbogbo igbesẹ kigbesẹ ti ẹnikẹni ba gbe lati ba ẹgbẹ naa laa tako pata-pata."""
Oríṣun àwòrán, @PDP
PDP wa rọ awọn ọmọ ẹgbẹ oselu PDP lati mase foya
Ọlọgbọndiyan, ẹni to se apejuwe igbesẹ bi ijọba apapọ lati dena de Saraki ati Ekweremadu, ti wọn jẹ asaaju ile asofin apapọ, bii iwa ọyaju ati idunkoko mọni lati ọdọ ijọba ẹgbẹ oselu APC ati aarẹ Muhammadu Buhari.
O wa rọ awọn ọmọ ẹgbẹ oselu PDP lati mase foya nitori iwa idunkoko mọni naa, to si tun n rọ awọn ololufẹ eto iselu ijọba tiwa n tiwa kaakiri agbaye lati dide tako iru iwa aidaa yii.
Red Cross: Irọ́ ni pé á ń duna-dura pẹ̀lú Boko Haram
Oríṣun àwòrán, @nrc_ng
Iduna-dura lu Boko Haram yoo pagidina ohun ti ẹgbẹ Red Cross duro fun
Agbarijọpọ ẹgbẹ alagbelebu pupa l'agbaye (Red Cross) ti kede pe, oun kii duna-dura pẹlu ikọ adunkooko mọni kankan lori awọn ti ikọ naa ji gbe.
Agbẹnusọ fun ẹgbẹ naa, Alexsandra Matijevic Mosimann, to fi ikede naa sita ni, ko sootọ kankan ninu awọn iroyin kan to n jade pe, oun ba ikọ Boko Haram sọrọ lati da awọn to mu si ahamọ silẹ.
O ni ṣiṣe bẹẹ yoo pagidina ohun ti ẹgbẹ Red Cross duro fun, eyi ti i ṣe aiṣègbè tabi fifi ara ti ẹnikẹni.
Báwo lo se gbọ́ èdè Yorùbá sí ?
Ọpọlọpọ eniyan ni ikọ agbesunmọmi Boko Haram ti ji gbe lapa Iwọ-Oorun Ariwa orilẹ-ede Naijiria, ti eyi si n mu ki orisirisi ajọ alaanu nilẹ okeere ati l'abẹle, to fi mọ awọn ẹlẹyinju aanu, maa pese iranlọwọ fun awọn ti ikọlu Boko Haram ti sọ di alainile lori.
Oríṣun àwòrán, AFP
Red Cross ni ko sootọ kankan ninu awọn iroyin kan to n jade pe, oun ba ikọ Boko Haram sọrọ
ICRC ti wa ni ohun kan ti oun le ṣe gẹgẹ bi iranlọwọ ni lati pese eto irinna fun awọn ti wọn ji gbe pada si ile wọn.
Ortom: APC ko ṣe bi ẹni pe ọrọ awọn ara Benue jẹ wọn logun
Oríṣun àwòrán, @OrtomSamuel/Twitter
Agbẹnusọ Ortom ni APC ko ṣe gomina naa daadaa
Ẹ̀gbẹ́ òṣèlú All Progressive Congress, APC ti fèsì pé bí Gómìnà Samuel Ortom ṣe fi ẹgbẹ́ òṣèlú wọn sílẹ̀ jẹ́ èyí tó ya ni lẹ́nu.
APC ṣèránti akitiyan alága ẹgbẹ́ Adams Oshiomolẹ láti kojú àwọn ìkùnsínú kọ̀ọ̀kan tí Gómìnà ìpínlẹ̀ Benue mẹ́nu bà èyí tó ní ṣe pẹ̀lú òṣèlú abẹ́nú ní ìpínlẹ̀ Benue.
Lẹyin ọsẹ kan ti iroyin kọkọ kede pe, Gomina Ipinlẹ Benue, Samuel Ortom ti fẹ fi ẹgbẹ oṣelu APC silé lọ PDP, iroyin fi han pe o ti fẹgbẹ APC silẹ bayii.
Kọmisọna fun Iroyin ana ni ipinlẹ naa, Laurence Onoja lo kọkọ fi han fun BBC pe, ootọ ni iroyin naa. Lẹyin naa ni agbẹnusọ gomina naa, Terver Akase gbe atẹjade lori ipinnu naa sita.
A gbọ pe, Ortom funra rẹ sọ bẹẹ fun awọn alaga ijọba ibilẹ niipinlẹ naa ninu ipade kan to waye nile ijọba ni Markurdi.
Ìwádìí Anas: $1000 ni rìbá tí akọ́ni-mọ̀ọ́gbá Super Eagles gba
"Akase ni, ""Ẹgbẹ oṣelu APC ko ṣe daadaa si gomina (Ortom). APC ko ṣe bi ẹni pe ọrọ awọn ara Benue jẹ wọn logun, nitori naa ni awọn ọdọ ilu ṣe di ọna mọ gomina ni aarọ yii, ti wọn ni ko gbọdọ lọ ipade  ipẹtu saawọ APC kan ti wọn gbe kalẹ ni Abuja. Wọn ni awọn ko fẹ ko duro si ẹgbẹ APC."""
Nigba ti BBC beere boya gomina naa sa kuro ni APC nitori ẹsun pe ko le daabo bo ẹmi ati dukia awọn eniyan Benue ni, o ni ko ri bẹ, ati pe awọn oloṣelu ti ko fẹran rẹ ni wọn n parọ mọ.
Ipinnu na waye lẹyin ti a gbọ pe awọn ọdọ kan ni Makurdi di ọna mọ ọkọ rẹ nigba ti o fẹ rinrin ajo lati lọ ipade kan ni Abuja. Àwọn ọdọ naa tun yọ asia ẹgbẹ APC to wa lara ọkọ rẹ.
Oríṣun àwòrán, @OrtomSamuel/Twitter
Awọn ọdọ ni Ortom ko gbọdọ lọ ipade Abuja
O ya ni lẹnu pe ni ọsẹ to kọja nigba ti gomina naa kọkọ fi han pe, oun fẹ fi ẹgbẹ APC silẹ, sugbọn to tun yi oju pada lati sọ pe ko ri bẹẹ.
Oun ni gomina akọkọ ti o maa tẹle awọn aṣofin mẹ́tàléláàdọ́ta to fi ẹgbẹ APC silẹ lọ PDP lanaa.
Ortom ti ni ija pẹlu ijọba apapọ fun igba diẹ lori iku awọn ara ilu lọwọ awọn darandaran. Oṣu kinni ọdun yii ni awọn darandaran pa eniyan bii mẹtalelaadorin ni ipinlẹ naa. Ọpọlọpọ ni wọn ti pa pẹlu lati igba naa.
Ààrẹ Buhari: Ó ṣeéṣe kí o lè wọ reluwé lọ orílẹ̀èdè Benin láìpẹ́
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Aarẹ Buhari ni laarin igba ti oun gba ọpa aṣẹ iṣejọba lọdun 2015 si asiko yii, fayawọ irẹsi ti dinku pẹlu ida aadọrun lorilẹede Naijiria
Aarẹ Buhari ati aarẹ Patrice Talon ti orilẹede Benin Republic ni oju opo irinna ọkọ reluwe laarin orilẹede Naijiria, Benin republic ati Niger Republic jẹ ohun ti ko yẹ ko pẹ pupọ ki o to di ohun.
Lasiko ti aarẹ Patrice Talon ti orilẹede Benin republic ṣe abẹwo si aarẹ orilẹede Naijiria, Muhammadu Buhari nilu Abuja.
"Aarẹ Buhari ni "" igbesẹ to dara ni eyi ti o si ṣe pataki fun idagbasoke ọrọ aje"" ti wọn yoo si tubọ gbe yẹwo daradara."
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Orilẹede Naijiria pẹlu orilẹede Benin Republic ni fayawọ n ṣe akoba fun eto ọrọ aje ati eto abo
Bakan naa ni orilẹede Naijiria pẹlu orilẹede Benin Republic tu n gbe igbesẹ lati dẹkun fayawọ irẹsi ṣiṣe laarin aala orilẹede mejeeji.
Lara igbesẹ yii naa ni afẹnuko laarin orilẹede mejeeji lori agbekalẹ igbimọ kan ti yoo maa gbogun ti iwa fayawọ.
Lasiko abẹwo Aarẹ Patrice Talon si aarẹ Muhammadu Buhari naa ni wọn fi ẹnu ọrọ ọhun jo sibikan.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Buhari ni lara awọn akoba ti owo fayawọ n ṣe ni ti awọn ohun ija oloro ti wọn n ko wọ orilẹede Naijiria, to si n ṣe igbọwọ fun eto abo to mẹhẹ
Aarẹ Buhari ni laarin igba ti oun gba ọpa aṣẹ iṣejọba lọdun 2015 si asiko yii,  fayawọ irẹsi ti dinku pẹlu ida aadọrun lorilẹede Naijiria.
Aarẹ fi kun un pe akoba ti gulegule awọn fayawọ n ṣe fun ilakaaka orilẹede Naijiria lati lee daa ẹnu ara rẹ bọ ni ti ounjẹ abẹle ko kere rara.
O ni lara awọn akoba ti owo fayawọ n ṣe ni ti awọn ohun ija oloro ti wọn n ko wọ orilẹede Naijiria, to si n ṣe igbọwọ fun eto abo to mẹhẹ.
Ninu ọrọ tirẹ, Aarẹ Patrice Talon ṣalaye pe aarun ti n ṣogoji nii ṣ'ọọdunrun ni ọrọ akoba fayawọ nitori bo ṣe n koba ọrọ aje Naijiria naa lo n koba ọrọ aje orilẹede Benin republic.
Àárẹ̀ wo ló mú kí Dino má yọjú sile ẹjọ́?
Oríṣun àwòrán, Dino Melaye/Facebook
Ọrọ gbogbo kìí sé lórí alábahun Dino Melaye
Dino tún kọ̀ láti yọjú sílé ẹjọ́ nígbà kejì
Fún ìgbà ìkejì, Seneto to n sójú ẹkùn ìdìbò ila oòrùn Kogi, Dino Melaye, ti kùnà láti yọjú sile ẹjọ to n gbọ ẹjọ rẹ eleyi to da lè ẹsùn ṣisowo ìbon lọnà tí kò bá òfin mu.
Òun àti àwọn afẹsunkan méjì ní wọn fẹsun náà kan níwájú Adájọ.
Ṣáájú ní agbẹjọro Melaye ti beere fún isunsiwaju ẹjọ náà nítorí pé Dino ní àwọn kan fẹ ji òun gbe lójú ọnà Abuja si Lokoja.
Nígbà tí wọn pè fún igbejọ rẹ lójóóru n'isẹ ní agbẹjọro rẹ, Yemi Mohammed, ní ará Dino kò yá ni kò fi le yọjú sile ẹjọ.
Láti kín ọrọ rẹ lẹyìn, Mohammed fi ìwé nípa ìlera rẹ ṣòwò eleyi ti agbẹjọro fún ilé iṣẹ ọlọpaa ipinle Kogi kò lòdì sí.
Àwọn afẹsunkan méjì tó kù, Kabir Seidu àti Nuhu Salihu bẹbẹ fún ilé ẹjọ pé ki wọn gbà beeli awọn pẹlu awijare pe awon ko mo nipa ẹsùn tí wọn fi kan àwọn.
Adájọ Sulyman Abdallah dajọ isunsiwaju ẹjọ náà titi di ọjọ kokanlelogun níbi tí wọn yóò ti gbọ ẹjọ àwọn afẹsunkan méjì tó kù.
Ogunjọ, oṣù kẹsán ní wọn sun ẹjọ Seneto Dino Melaye sí.
Ohun ti awọn eeyan sọ nipaijinigbe Dino tẹlẹ
Oríṣun àwòrán, @dino_melaye
Ọjọ́ Kẹtadinlọgbọn, Osu Keje, ọdun yii ni Oluranlọwọ Dino Melaye sọ wi pe wọn jii gbe ni Gwagalada, Abuja.
Ọrọ ijinigbe Seneto Dino Melaye gbà ònà míràn yọ pẹlú bí o tí ṣé bẹnu àtẹ́ lù ilé iṣẹ ọlọ́pàá pe wọn parọ pé àbúrò òun kò fẹjo sun lagọ ọlọ́pàá.
Èsì yí to fí ṣọwọ lójú òpó Twitter rẹ jáde lẹyìn ìgbà tí o fi esi ọpẹ sita lori bí orí ṣé ko oun yọ lọwọ àwọn ajinigbe.
Dino faake kọri o ni aburo oun fẹjọ sun awọn ọlọ́pàá laarọ Ọjọbọ
Ti a ko ba gbagbe,Sẹnetọ Dino Melaye  to n soju ẹkun idibo Iwọ- oorun Kogi, ti  saaju kede pe oun ti jajabọ ni ọwọ awọn to ji oun gbe.
Oro naa to fi lede ni oju opo Twitter rẹ ni, ori lo ko oun yọ, lẹyin ti oun lo wakati mọkanla ninu aginju lẹyin ti wọn ji oun gbe.
Oluranlọwọ fun sẹnetọ Dino Melaye, Gideon Ayọdele nigba to n ba BBC sọrọ so pe ni  ikorita Gwagwalada, ni ilu Abuja ni awọn agbebọn ti fẹ ji Dino gbe.
Awọ̀n ọmọ Naijiria fesi si oun ti Sẹnẹtọ Dino Melaye fi si oju opo rẹ wipe ori lo yọ oun ninu isẹlẹ ajinigbe ti oun ti lo wakati mọkanla ni inu igbo ki oun to rapala jade pada si ilu.
Wọn ni irọ lasan ni Dino n pa, ati wi pe ko si otitọ kankan ninu ọrọ rẹ, ti awọn miran si n fi se ẹlẹya.
Ọjọbọ ọsẹ yii ni Oluranlọwọ fun sẹnetọ Dino Melaye, Gideon Ayọdele ni ikorita Gwagwalada, ni ilu Abuja ni awọn agbebọn pẹlu ọkọ ijọba ipinlẹ Kogi lo ji Dino gbe.
Amọ olulufẹ rẹ kan dupe pe o wa ni alaafia, ti o si rọ ọ lati gbe fidio jade ti yoo fihan wipe alaafia ni o wa.
Ọ̀ṣọ́ Aṣọ Òkè ti kọjá lílo ìlẹ̀kẹ̀ níkan
SMS alert: Wo ọ̀nà láti dẹ́kun jìbìtì lórí àṣùwọ̀n báǹkì rẹ
Afẹnifere: Omisore kò jẹ́ ká mọ ìgbésẹ̀ rẹ̀ nínú ìdìbò Oṣun
Ẹgbẹ́ ọmọ Yoruba lápaapò, Afenifere tí kòwé lọ gbé ilé rẹ fún Sẹnetọ Omisore fún ọdún kan lórí ipa tó kó lásìkò ìdìbò gomina ni Ọsun.
Ẹgbẹ Afẹnifẹre to n soju ọmọ Yoruba lapapọ ti ni awọn le oludije sipo gomina labẹ ẹgbẹ oselu SDP, Sẹnetọ Iyiola Omisore fun ọdun kan nitori ko fi inu han wọn lasiko idibo sipo gomina to waye ni ipinle Osun.
Ọkan lara awọn adari ẹgbẹ Afẹnifẹre, Oloye Korede Duyile, ṣalaye fún BC Yoruba ni kikun lori bi wọn se kọwe lọ gbe ile rẹ fun Sẹnetọ Omisore fun ọdun kan.
Duyile sọ pe asa ati ise ti ẹgbẹ Afenifere dirọ mọ fayegba ki ọmọ ẹgbẹ o bere imọran lọwọ awọn adari ẹgbẹ lori ọrọ to ba niise pẹlu gbogbo ọmọ Yoruba.
Adetoun Ogunṣẹyẹ: ìrìnàjò ẹ̀kọ́ mi títí dé òkè kò rọrùn rárá
Ẹsun ti wọn fi kan Omisore ni pe ẹgbẹ Afenifere ye ki wọn mọ gbogbo igbesẹ to gbe lasiko idibo ni ipinlẹ Osun , ṣugbon Omisore kọ lati se bi o ti yẹ ki o se e.
O fikun wi pe ahesọ ni gbogbo ohun ti awọn eniyan n sọ wi pe nitori Omisore se iranwọ fun ẹgbẹ Oselu APC ni ẹkun idibo Guusu Ile-Ife ati ijọba ibilẹ Ariwa ipinlẹ Ọsun.
Ẹgbẹ Afẹnifẹre naa wa fikun wi pe awọn ko i ti i sọ ẹni ti awọn yoo basẹ ninu idibo gbogboogbo ti yoo waye ni ọdun 2019, ati wi pe ahesọ ni iroyin pe ẹgbẹ oselu APC ni awọn fẹ dibo fun ni idibo gbogboogbo ti ọdun to n bọ.
Amọ gbogbo igbiyanju BBC Yoruba lati ba Sẹneto Iyiola Omisore sọrọ lati fesi si ẹsun naa lo jasi pabo.
#Adetutu Alabi OJ: Mo ti gba kámú lórí ilà ojú mi
Oludije si ipo gomina ipinlẹ Ọṣun labẹ ẹgbẹ oṣelu PDP ti o n siwaju ninu idibo naa Ademola Adeleke ti sọ pe ata ika ti ko ran ikọ ni ọrọ ti oludije si ipo gomina labẹ asia ẹgbẹ oṣelu SDP Iyiọla Omiṣore sọ pe ẹgbẹ APC l'oun yoo satilẹyin fun ninu atundi ibo Gomina ipinlẹ Osun ti yoo waye l'Ọjọbọ.
Adeleke sọ pe Omisore kosi pẹlu PDP nigba ti awọn jawe olubori ninu idibo ọjọ Abamẹta to lọ, o fi kun ọrọ rẹ pe ẹgbẹ PDP ko ba ni bi ibo ẹgbẹrun marun un si ṣugbọn mọgomọgo ni ko jẹ.
Lẹnu ọjọ mẹta yi ni iroyin orisirisi ti n ja ranyin lori ẹgbẹ ti yoo gbe lẹyin ninu atundi ibo Gomina Osun .
Ọpọ eeyan lo ti n reti ibi ti Omisore yoo fi adagba atilẹyin rẹ rọ si ninu atundi ibo Gomina ipinlẹ Osun
Alaye to se fun igbesẹ naa ni wi pe ẹgbẹ oselu APC ni erongba rẹ papọ mọ ti ẹgbẹ SDP ti wọn si ti fi da oun loju  wi pe awọn yoo tele adehun lati mu awn adisokan won yi sẹ.
Ní ọ̀sán Ọjọ́rú ni akọ̀wé ìjọba àpapọ̀, Boss Mustapha náà bẹ Omisore wo nile rẹ lẹyin ikede rẹ pe APC ni oun n ba lọ. Akọ̀ròyin BBC to wa nibi abẹwo gbiyanju lati wadii boya Mustapha wa jiṣẹ Aarẹ Muhammadu Buhari ni, ṣugbọn ko si aridaju ni asiko ti iroyin yi wọle.
Mustapha sọ fun awọn oniroyin wipe abẹwo naa ni lati fidi rẹ mulẹ pe aṣiwaju ni Omisore jẹ ni Osun ati orilẹede Nigeria.
Omisore naa dahun wipe oun ṣe ipinnu lati wa ilọsiwaju ni awujọ ṣugbọn pe kii ṣe pe oun fi SDP silẹ lọ APC.
Ohun tí ọ n tẹ BBC Yoruba leti n'ipe yatọ si iwe adehun ajumose ti ẹgbẹ oṣelu SDP gbe ka iwaju  APC, ẹgbẹ oṣelu naa tun se ileri ipo Sẹnetọ kan,  ipo ile aṣoju aṣofin meji, komisona meji bi oyetola ba Wọle ati ipo ile aṣofin mẹrin fún un.Nigba ti BBC Yoruba béèrè ọrọ yìí lọwọ Omisore, ọgbọn tí Ọga ẹdà fi n sa fún ẹlẹwọn to ba buru lo fi yẹba fún ìbéèrè náà.Ni bi a ṣe n sọrọ yii, ileesẹ ipolongo ibo fún Sẹnetọ Adeleke tabi ẹgbẹ oṣelu PDP ko tii sọ ohunkohun lori rẹ.
Fayẹmi ko sọ ohunkohun to jọ mọ atundi ibo gomina Osun
"Lọwọ yii, ikede yii ti dabi ẹni pin ìpinnu awọn ọmọlẹyin rẹ àti ọmọ ẹgbẹ oṣelu SDP sí ọtọọtọ nitori bi awọn kan ṣe n kọrin""ibi ọ bá lọ lá n lọ"" fún un l'awọn miran n royin ohun oju ti ri ti ko lee mu ki awọn fara mọ irufẹ ètò bẹẹ.""Àpá àdá ṣi ǹ bẹ lara mi. Awọn APC ni wọn dá ogbe simi lara ti wọn sì tún ba mọto mi jẹ, APC ọhun ni wọn tun ni ki a ti lẹyin emi ọ ṣe ọ!"" ni ariwo ti ọkan lára àwọn ọmọlẹyìn agba oṣelu naa n pa ni gbagede ile oloṣelu naa lẹyin to gbọ iroyin ọhun."
Ti a ko ba gbagbe,laip e yi ni Gomina ti wọn dibo yan ni ipinlẹ Ekiti,Ogbẹni Kayode Fayemi se abẹwo si Iyiola Omisore  lai tii pe wakati mẹrinlelogun ti aare ile igbimọ aṣofin agba, Bukọla Saraki ba Omiṣore lalejo lori atundi ibo ti yoo waye lọjọbọ ni awọn ibudo idibo bii meje otọọtọ nipinlẹ Ọsun.
Ninu ọrọ rẹ pẹlu awọn oniroyin lẹhin ipade bonkẹlẹ ti wọn ṣe, Fayemi ni ipade naa ko ni ohunkohun ṣe pẹlu ọrọ oṣelu, bikoṣe abẹwo lasan.
Fayẹmi bá BBC sọ̀rọ̀ ní kété tó di gómìnà Ekiti
Minisita tẹlẹri ọhun fi kun ọrọ rẹ wipe ana oun ni Omisore, bẹẹ sini ko si ohun to buru ninu ki a ṣe abẹwo si ana ẹni.
Njẹ ẹyin ko mọ wipe ana mi ni Omiṣore? Igba ti o ba si wu mi ni mo le ṣe abẹwo si ana mi
Fayẹmi ko sọ ohunkohun ti o jọ mọ atundi ibo gomina ipinlẹ lasiko to n dahun ibeere awọn oniroyin nibi abẹwo naa.
Ẹwẹ, oludije si ipo gomina ninu ẹgbẹ oṣelu SDP, Iyiọla Omiṣore ṣi yẹnu mọ ọrọ rẹ wipe ijọba ti yoo ṣe anfani fun awọn eeyan ipinlẹ Ọṣun ni yoo ri ojurere oun gba ninu atundi ibo si ipo gomina ipinlẹ Ọṣun.
Omiṣore fi kun ọrọ rẹ wipe ẹgbẹ ti o ba ni ifojusun iṣejọba rere gẹgẹ bii ti ẹgbẹ oun(SDP) ni yoo ri atilẹhin gba ninu atundi ibo si ipo gomina ti yoo waye lọjọbọ.
Fayẹmi ko dahun ibeere awọn oniroyin nibi abẹwo naa.
Ọjọ Aje ni Aarẹ ile igbimọ aṣofin agba Bukola Saraki ṣe abẹwo tirẹ si Omisore nile rẹ ni Ile-Ife ni ọjọ Aje, eyi to fi han pe ootọ wa ninu ahesọ pe ẹgbẹ oṣelu PDP n wa iranlọwọ rẹ fun atundi ibo ti yoo waye ni ọjọ Ojọbọ.
Kí ipade naa to waye ni ni Omisore sọrọ lori esi idibo to waye ni Osun ni Satide to kọja.
Ninu atẹjade kan to fi sita ni ọjọ Aje, Omisore, ti o ṣe ipo kẹta ninu esi idibo ti ajọ INEC kede ni owurọ ọjọ Aiku, ni ipolongo ibo oun lo mu ki awọn ijọba Ipinlẹ Osun tete san lara owo oṣu ti wọn jẹ.
Omisore ni oun mọ wipe wọn tun ti fi owo ra ibo awọn ara ilu ti wọn si lo ebi to n pa awọn eniyan lati ra ibo.
"O ni, ""Mo dupe lọwọ gbogbo eniyan to fẹ ijọba to dara fun iṣẹ takuntakun wọn. Bó tilẹ̀ jẹ́ pe ó dàbí ẹni pé òun já kulẹ̀ nínu ìdìbò naa, a gbé igbá orókẹ̀ nínú ìpè fún ìjọba tó tọ́."
"A tun gbe igba oroke ninu ijakadi yii lọna ti eti ko gbọ ri ni ipinlẹ yii.
Mo dupẹ lọwọ Ooni ti Ife, awọn lọbalọba, ijoye ilu ati awọn ara Ife. A o tẹra mọ iṣẹ fun idagbasoke ara ilu. O ni ẹgbẹ oun, SDP, ko ni fi Ipinlẹ Osun silẹ fun awọn jẹgudujẹra."
Ko si ẹni to gbọ iroyin naa ti ko yanu  lati gbọ pe ẹgbẹ mẹta gboogi ninu awọn ẹgbẹ ninu awọn mejidinlaadọta ti yoo kopa ninu idibo sipo gomina ti yoo waye nipinlẹ Ọsun lọjọ satide ṣe ipade bonkẹlẹ loru ọjọru nilu Osogbo.
Oniruru ahesọ ọrọ lo waye lori ohun ti Fatai Akinbade ti ẹgbẹ oṣelu ADC, Moshood Adeoti ti ẹgbẹ oṣelu ADP ati Iyiọla Omiṣore ti ẹgbẹ oṣelu SDP fẹ sọ ni ko ye awon eeyan.
Ibeere ti o n gba ẹnu ọpọ ni pe abi meji ninu awon oludije yii fẹ tẹ fun ni ọkan ninu wọn ni?
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí:
Omiyalé Àkútè: N50 si N100 làwọn èèyàn fi ń kọjá lórí ẹ̀kún omi l‘Ákútè
Koda, ki a to wi, ka to fọ, iroyin ti kan de ile ipolongo ibo ọkan ninu wọn pe, wọn ti gba lati ṣiṣẹ fún ọkan ninu wọn.
Amọṣa ninu ọrọ to ba BBC Yoruba sọ, agbẹnusọ fun ikọ ipolongo Moshood Adeoti ti ẹgbẹ oṣelu ADP, salaye pe, ohun to fa ìpàdé naa ko ṣeyin bi wọn yoo ṣe fopin si iwa janduku ati madaru lasiko idibo naa.
Ko si eyikeyi ninu awọn Oludije mẹtẹẹta to tẹ fun ọkan. Ohun to waye ni ifowosowopo ati ifohunsokan laarin wọn, lọna ati lee gbogun ti iwa ibo rira ati eru sise eleyi ti awọn oludije kan pẹlu ti n pete rẹ.
Bakan naa ni ileesẹ ipolongo oludije fún ẹgbẹ oṣelu SDP, Iyiọla Omiṣore pẹlu fidi ọrọ naa múlẹ.
Ọkan pataki lara awọn ọmọ ẹgbẹ oṣelu PDP nipinlẹ Ọṣun ni oloye Fatai Akinbade koda o wa lara awọn oludije mẹrin to kopa ninu idibo abẹnu lati yan oludije fun ipo gomina labẹ aṣia ẹgbẹ oṣelu PDP.
Fatai Akinbade ninu iwe to kọ lati fi ẹgbẹ oṣelu PDP silẹ ṣalaye pe abajade esi idibo abẹnu naa ninu eyi ti o ti ni ibo mejilelaadọta lo fa oun si irin lati fi ẹgbẹ oṣelu naa silẹ.
Lẹyin ti mo ti rii pe o dabi ẹni pe awọn adari ẹgbẹ oṣelu yii ko fẹ mi mọ tabi pe wiwa ti mo wa lẹgbẹ yii n dooru mu wọn ni mo fi gbe igbesẹ yii. Ero mi lori awọn nnkan wọnyii wa fidi mulẹ lasiko idibo lati yan oludije fun ipo gomina eleyi ti o waye laipẹ yii.
Fatai Akinbade kọ ni oloṣelu akọkọ ti yoo fi ẹgbẹ oṣelu rẹ silẹ lẹyin eto idibo lati yan awọn oludije fun ipo gomina l'Ọṣun.
Moshood Adeoti naa ti kọwe fi ẹgbẹ oṣelu APC silẹ lori ẹsun to fi ara jọ ti Akinbade, to si gba ẹgbẹ oṣelu APD lọ
Ṣaaju ni akọwe ijọba ipinlẹ naa tẹlẹ, Moshood Adeoti naa ti kọwe fi ẹgbẹ oṣelu APC silẹ lori ẹsun to fi ara jọ ti Akinbade, to si gba ẹgbẹ oṣelu APD lọ.
Awuyewuye n lọ lọwọ lori esi idibo abẹnu PDP pẹlu bi Akin Ogunbiyi to ṣe ipo keji ninu idibo ọhun ṣe ti n f'apa janu bayii pe ohun lo bori ninu idibo naa.
Àwòrán àwọn tó kù pẹ̀lú Buhari láàárín àwọn sẹ́nétọ̀ Nàìjíríà nìyí
Oríṣun àwòrán, Nigeria presidency
Buhari ti ki awọn to ya kuro lẹgbẹ oṣelu APC pe iwaju ti wọn doju kọ yoo dara.
Ṣe awọn agba bọ, wọn ni, kii buru titi ko maa ku ẹni kan mọ ni; ẹni ti yoo ku ni a ko mọ.
Asiko yii kii ṣe igba to dun fun ẹgbẹ oṣelu APC, paapaa julọ Aarẹ Muhammadu Buhari to jẹ olori ẹgbẹ oṣelu naa bayii.
Ko din ni sẹnetọ mejila to fi ẹgbẹ oṣelu APC silẹ pẹlu ọgọọrs awọn akẹgbẹ wọn nile aṣoju ṣofin pẹlu aṣofin ipinlẹ kaakiri.
Amọṣa ninu iji yii, awọn wọn ni wọn ṣẹku pẹlu Aarẹ Buhari bayii.
Oríṣun àwòrán, Bashir ahmad
Aarẹ orileede Naijiria,Muhammadu Buhari ni oun ti sapa ti oun lati dẹkun bi awọn aṣòfin marundilogun to jẹ ọmọ ẹgbẹ oṣelu APC tẹle ṣe paarọ aye lọ si ẹgbẹ PDP
Oríṣun àwòrán, Nigeria Presidency
Oríṣun àwòrán, Nigeria presidency
Igbesẹ awọn aṣofin to fi ẹgbẹ oṣelu APC silẹ ya ọpọlọpọ lẹnu
Oríṣun àwòrán, Nigeria presidency
Aarẹ Buhari parowa si awọn ọmọ ẹgbẹ APC to ku ki wọn ma banujẹ lori iṣẹlẹ ọhun
Oríṣun àwòrán, Bashir ahmad
Aarẹ ni igbesẹ awọn aṣòfin naa ko le ba nkan jẹ fun ẹgbẹ wọn bi idibo gbogbogbo 2019 ṣe n sunmọle
Oríṣun àwòrán, Bashir Ahmad
Buhari sọ wipe oun yoo tẹsiwaju ninu iṣẹ oun pẹlu gbogbo awọn ọmọ ile igbimọ aṣòfin lalai fi ti ẹgbẹ ọṣelu wọn ṣe
Oríṣun àwòrán, Bashir ahmad
Awọn aṣofin naa ya lọsi ẹgbẹ oṣelu PDP, ADC ati ẹgbẹ oṣelu miran
Oríṣun àwòrán, Bashir Ahmad
Iyalẹnu ni ọrọ naa jẹ fun ọpọlọpọ onwoye ni Naijiria ati loke okun
Oríṣun àwòrán, Bashir ahmad
Ẹgbẹ oṣelu APC ni awọn to ya kuro ninu ẹgbẹ oṣelu naa ko lee ṣe akoba fun ifẹsẹmulẹ ipinnu ẹgbẹ naa.
Àwọn òṣìṣẹ́ ilé iṣẹ́ ìròyìn NAN wọ́de lórí ìlànà iṣẹ́ tó mẹ́hẹ
Oríṣun àwòrán, Abdulwahab
Awọn oṣiṣẹ NAN ke si'jọba apapọ lati tete wa wọrọkọ fi ṣada lori amojuto igbayegbadun awọn oṣiṣẹ.
Awọn oṣiṣẹ ileeṣẹ akoroyinjọ apapọ Naijiria, NAN gunle iyanṣẹlodi niwaaju olu ileeṣẹ naa nilu Abuja.
Kutukutu owurọ ọjọbọ lawọn oṣiṣẹ naa ti ya bo olu ileeṣẹ ọhun pẹlu awọn patako alakọle ti wọn kọ awọn ẹhonu wọn si.
Lara awọn ẹhonu ti awọn oṣiṣẹ naa n beere fun ni atunyẹwo ilana iṣẹ ni ileeṣẹ naa eleyi ti wọn ni wọn ni o ti di ogbo.
Àwọn oṣiṣẹ feyinti ni Osun ṣé iwọde
Bakannaa ni wọn tun beere fun sisan ẹgbẹrun marun owo irinsẹ fun awọn oṣiṣẹ, sisan ajẹẹlẹ owo ajẹmọnu igbega laarin ọdun 2012 si 2017 pẹlu adinku to waye lori ajẹẹlẹ owo ajẹmọnu igbega laarin ọdun 2014, 2015 ati 2016 atawọn nnkan miran.
Atẹjade kan ti awọn adari ẹgbẹ oṣiṣẹ iroyin, NUJ, ẹgbẹ oṣiṣẹ radio ati tiata, RATTAWU fi sita ṣalaye rẹ pegbogbo ilakaka awọn oṣiṣẹ nileeṣẹ naa lati ri pe irawọ rẹ ko wọmi ni aisi amojuto fawọn oṣiṣẹ nibẹ n bu omi pa.
Wọn wa ke si ijọba apapọ lati tete wa wọrọkọ fi ṣada lori amojuto igbayegbadun awọn oṣiṣẹ, alekun owo oṣu, ati ilana iṣẹ to tọna fun awọn oṣiṣẹ nibẹ.
Jiti Ogunye: Ọ̀jẹ̀lú ni àwọn tó ń fi APC sílẹ̀ fún PDP
Oríṣun àwòrán, APC
Ajafẹtọ ọmọniyan, Jiti Ogunye ni ọna abayọ si eto oselu Naijiria ni ki awọn eniyan yan ẹgbẹ oselu tuntun.
Ajafẹtọ ọmọniyan, Jiti Ogunye ti ni awọn oloselu ti wọn n kuro ni ẹgbẹ oselu kan lọ̀ si ẹgbẹ oselu miran ko fẹran awọn ọmọ Naijiria, ati wi pe ikun wọn ni wọn n ja fun.
Jiti Ogunye nigba to n ba BBC sọrọ lori bii awọn asofin se sigun kuro ni ẹgbẹ oselu APC losi PDP saaju idibo gbogboogbo ni ọdun 2019.
O ni Ojẹlu ni gbogbo awọn oloselu ti wọn n fi ẹgbẹ oselu APC silẹ fun ẹgbẹ oselu PDP, ati wipe oju wọ̀n kan wa ni APC ni sugbọn kan wa ni PDP ki wọn to darapọ mọ ẹgbẹ oselu PDP.
Ṣé ẹ rántí orin - Má ṣe jẹ́jẹ́ ma wà mi lọ?
Oríṣun àwòrán, Jiti Ogunye
O parọwa si awọn alawọdudu lati fẹran ara wọn nitori awọn ara ilu ni o le yan eniyan ti yoo tukọ wọn lo si ilẹ ileri si ipo.
Ajafẹtọ ọmọniyan naa fi awọn oloselu naa we onisowo ti o seese ki o fi okoowo kan silẹ fun omiran nitori ko pe wọn mọ.
"Jiti Ogunye wa kesi ""awọn ara ilu lati wa wọrọkọ fi se ada nitori wọn ko le gbẹkẹle awọn oloselu to n kaakiri naa nitori wọn kii se eniyan gidi""."
"O parọwa si ""awọn alawọdudu lati fẹran ara wọn nitori awọn ara ilu ni o le yan eniyan ti yoo tukọ wọn lo si ilẹ ileri si ipo""."
Lunar Eclipse: Babalawo lo le sọ bí ire ni yóò já sí ní tàbí ibi
Oloye Ìdòwú Olukunle so pe babalawo lo le mo òun ti ọ̀sándòru yóò já sí fun ara ilu.
Ikéde ti awọn onímọ̀ sáyẹ́nsì fi síta pé ìṣẹlẹ ọ̀sándòru kàn yóò waye ti mu iriwisi wa lati ọdọ awọn onimo nipa Asa Yoruba.
Lasiko to ba n sẹlẹ, ojú òrun yoo pawọ dá ti awọ òṣùpá yóò sì ṣadede di pupa bí awọ ẹjẹ.
Ìṣẹlẹ yí tí awon oloyinbo n pe ni 'blood moon' yóò wáyé fún nnkán bi wakati kan ati ogójì iṣẹju le diẹ.
Àlàyé tí awọn onimo sayensi ṣe nipa iṣele naa ni wipe òṣùpá yóò gbà arin ojiji orilẹ ayé ta wa yi ati òrun koja,ojiji ti orun ba tàn sara òṣùpá ni yóò mú kí awọ rẹ pupa bí ẹjẹ.
'Irú ìṣẹlẹ bayi ki ṣéé túntún nilẹ Yoruba, kò ṣèṣe má wáyé.''
Ọrọ rẹ láti ẹnu Oloye Ìdòwú Olukunle ti ọ jẹ akoda awo ti ìjọba ibilẹ ọnà ará nílu Ibadan nigba ti wọn se alaye fún ilé iṣẹ BBC nipa ìṣẹlẹ òṣùpádeje tí yóò wáyé loní.
Oríṣun àwòrán, SPL
Ọ̀ṣùpádẹ̀jẹ̀
O ni awọn onimo sayẹnsi le mọ nípa ọjọ ti iru ìṣẹlẹ yí yóò wáyé ṣugbọn ''Babalawo lo le mo òun ti yóò gbẹyin rẹ.'
Fun ìdí èyí o so pe ''o yẹ kí àwọn aláṣẹ kesi Babalawo lati sọ 'boya ire ni yóò já sí ní tàbí ibi  fun ara ilu'
Bakanaa ni alagba Ìdòwú ṣàlàyé pé ètùtù ní í gbẹyin irú ìṣẹlẹ bayii sugbọn pẹlu bi nnkan ti se ri lode oni, awọn eeyan ko ka ọrọ etutu sise kun mọ
Anfani de fun ọ lati lo internet lọfẹ
'Ọ̀jẹ̀lú ni àwọn tó ń fi APC sílẹ̀ fún PDP'
Àwọn ibi tí ọ̀sándòru yìí yóò ti wáye ni Europe, ààrin gbùngbùn Ìlà Oòrùn, Africa, Australia Asia, South America àti ní UK láti nkan bíi agogo mẹ́sàán sí mẹ́wàá kọjá ìṣẹ́jú mẹ́ẹ̀dógún alẹ́ káàkiri.
Lálẹ́ yii kan náà àt'àwọn ọjọ́ tó tẹ̀lé e ni yóò jẹ́ ìgbà tí Mars yóò sún mọ́ ayé jù láti ọdún 2003 tí yóò sì mọ́lẹ̀ bí ìràwọ̀ pupa níbi tí ojú ọ̀run ti mọ́.
Àwòrán bí Ọ̀ṣùpádẹ̀jẹ̀ yóò ṣe wáyé
Òṣùpá yóò la àárin òjiji ayé kọjá lọ́gángán ibi tí òjiji náà ti fẹ̀ jù.
Òṣùpá yóò fara hàn pẹ̀lú àwọ̀ pupa nínú ọ̀ṣùpádẹ̀jẹ̀ náà gẹ́gẹ́ bí ìtànsán oòrùn yóò ṣe gba inú ayé kọjá fẹ́ẹ́rẹ́fẹ́.
Ọ̀jọ̀gbọ́n Tim O'Brien ti ilé ìwé gíga fásitì Manchester sàlàyé pé eléyìí ni yóò jẹ́ ìṣẹ̀lẹ̀ ọ̀ṣùpádẹ̀jẹ̀ tó gùn jù ní ọ̀ọ̀rùndúnrún yìí.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ìṣẹ́lẹ̀ ọ̀sándòru ní Montevideo, Uruguay, ọdún 2014
Bákan náà, kò kàn ṣe kòńgẹ́ bí Mars yóò ṣe súnmọ́ ayé nìkan sùgbọ́n yóò jẹ́ pẹ̀lúu ohun tí ọ̀jọ̀gbọ́n ṣàpèjúwe gẹ́gẹ́ bí títòjáde àwọ́n òfurufú òkè tí wọ́n jẹ́ amúgbálẹ́gbẹ̀ẹ́ òde ayé.
Èyí ni yóò jẹ́ ànfàni fún àwọ́n awòràwọ̀ láti rí Venus, Jupiter, Saturn àti Mars dáadáa.
Nàìjíríà kéde orúkọ àwọn agbábọ́ọ̀lù Falconets fún ìdíje àgbáyé
Oríṣun àwòrán, FIFA.com
Ikọ Falconets kii ṣe ajeji si idije ife ẹyẹ agbaye, ṣugbọn ikọ yii ko tii fi igba kan pa idije yii jẹ lati igba ti o ti bẹrẹ
Olukọni fun ikọ agbabọọlu ọdọbinrin orilẹede Naijiria ti ọjọ ori wọn ko ju ogun ọdun lọ, Christopher Danjuma ti kede orukọ awọn agbabọọlu mọkanlelogun ti yoo ṣoju naijiria nibi idije ife ẹyẹ agbaye awọn ọdọbinrin ti ọjọ ori wọn ko ju ogun ọdun lọ, FIFA U20.
Ikọ Falconets kii ṣe ajeji si idije ife ẹyẹ agbaye, ṣugbọn ikọ yii ko tii fi igba kan pa idije yii jẹ lati igba ti o ti bẹrẹ.
Idije naa yoo waye laarin ọjọ karun si ikẹrinlelogun oṣu kẹjọ ni orilẹede france.
Orilẹede Naijiria, Brazil, Germany ati Amẹrika nikan ni orilẹede mẹrin ti ko tii figbakan ri jẹ awati nibi ọdọbinrin ti ọjọ ori wọn ko ju ogun ọdun lọ.
‘Wọn ti ji Dino Melaye gbe’
Ìpinu Gómìnà Ortom ya ni lẹ́nu - APC
Ìwádìí Anas: $1000 ni rìbá tí akọ́ni-mọ̀ọ́gbá Super Eagles gba
Igba meji ni orilẹede naijiria ti de ipele aṣekagba; orilẹede Germany lo si na wọn ni igba mejeeji ni ọdun 2010 ati 2014.
Ireti ọpọ si ni pe ikọ Falconets yoo lee gba ife naa lọdun yii lẹyin ti awọn agbabọọlu ọkunrin, Super eagles ti ja ireti ọpọ ọmọ Naijiria kulẹ lorilẹede Russia nibi idije ife ẹyẹ agbaye Russia 2018.
Iléeṣẹ́ google gbé àǹfàní internet ọ̀fẹ́ wọ Eko
Oríṣun àwòrán, Punchng
Ileeṣẹ ikanni ayelujara, google ti gbe awọn ibudo lilo ayelujara lọfẹ wa si agbegbe marun nipinlẹ Eko
Anfani ti wa fun awọn ọmọ orilẹede Naijiria lati maa lo ikanni ayelujara, internet lọfẹ bayii nipinlẹ Eko.
Awọn ibudo mẹfa ni anfani yii sọkalẹ si nipinlẹ Eko, eleyi ti ko ni na ọ lowo ti ko si si gbede fun; iye to ba wu ọ, tabi ohun to ba wu ọ lo si lee fi gba lori ikanni ayelujara.
Ileeṣẹ ikanni ayelujara, google ti gbe awọn ibudo lilo ayelujara lọfẹ wa si agbegbe marun nipinlẹ Eko.
Osisẹ Fidelity Bank: Lati Osu Kẹwa, ọdun to kọja lati gba owo osu kẹhin.
Gẹgẹ bii awọn alaṣẹ ileeṣẹ naa ṣe sọ, awọn ibudo ti ifa yii gunlẹ si naa ni
Oríṣun àwòrán, @googleafrica
Igbakeji aarẹ Yẹmi Osibajọ ni ara igbesẹ ti ijọba apapọ n gbe niyi lati darapọ mọ awọn orilẹede ti o n fi imọ ẹrọ ṣọrọ
Ninu ọrọ rẹ nibẹ, igbakeji aarẹ orilẹede Naijiria, Ọjọgbọn Yẹmi Osibajọ to ṣi eto ọhun ni ara ohun to lee mu eto ẹkọ ati mọọkọ-mọọka gbẹrẹgẹjigẹ sii lagbaye ni amulo ẹrọ ayelujara.
"''Loni, ida ọgọta ninu ọgọrun awọn eeyan ilẹ Afirika lo jẹ ọdọ. A ko lee tọ awọn ọdọ orilẹede yii ti iye wọn yoo ti wọ igba miliọnu ti a o ba fi de ọdun 2045 ni yara ikẹkọ kilaasi nikan"""
Oríṣun àwòrán, @googleafrica
Ko si ohun ti o ko lee fi wo, kii tan bẹẹni anfani yii yoo kan awọn agbegbe miran laipẹ
O ni ara igbesẹ ti ijọba apapọ n gbe niyi lati darapọ mọ awọn orilẹede ti o n fi imọ ẹrọ ṣọrọ.
 Ko si ohun ti o ko lee fi wo, kii tan bẹẹni anfani yii yoo kan awọn agbegbe miran laipẹ. Ni arabinrin Juliet Ehimuan-Chiazor ti o jẹ adari ileeṣẹ Google Nigeria ṣalaye fun ikọ BBC.
Ìjàmbá iná l'Eko: Ọkọ̀ aképo gbiná ní òpópónà Eko sí Badagry
Oríṣun àwòrán, lagos state police command
Aago marun aarọ ni ọkọ naa gbina ni opopona Eko si Badagry
Ọkọ̀ aképo kan ti bú gbàmù ní òpópónà Eko sí ìlú Badagry lówurọ̀ ọjọ́ ìṣẹ́gun.
Ìròyìn tó ń tẹ̀ wá lọ́wọ́ ni wí pé ó mú ẹ̀mí ènìyàn lọ tí ọ̀pọ̀lọpọ̀ sì jóná.
A kò tíì rí àrídájú tó tó sùgbọ́n a ó máa mú ìròyìn bó ṣe ń lọ níbi ìṣẹ̀lẹ̀ yìí wá fún un yín.
Agbẹnusọ fún àjọ tó ń kojú ìṣẹ̀lẹẹ̀ pàjáwírì ní Ipinlẹ Eko (LASEMA) Ọgbẹni Adebayo Kehinde, ni ọkọ̀ akérò mẹ́ta, àti àjàgbé mẹ́fa ni ó jóná nínú ìṣẹ̀lẹ̀ náà.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ sí:
Ambode àti Sanwoolu, ta lẹ ó gbádé fún?
Àwọn amọkòkò kò fẹ́ fi iṣẹ lé ọmọ lọ́wọ́ mọ́
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ilu Kano ni wọn ti mu arakunrin to ni ọkọ ajagbe akepo naa
Ni ǹkan bí oṣù díẹ̀ sẹ́yìn ni irú ìṣẹ̀lẹ̀ aburú yìí ṣẹlẹ̀ ní orí afárá Ọtẹdọla ní ìpínlẹ̀ Eko.
Ileeṣẹ ọlọpaa ni ọwọ awọn ti tẹ arakunrin ti o ni ọkọ agbepo to ṣokunfa ijamba ina to waye lori afara Ọtẹdọla nilu Eko.
Ninu atẹjade kan ti alukoro ileeṣẹ ọlọpaa ni ipinlẹ Eko fi sita, ọwọ awọn ọtọlẹmuyẹ tẹ ọgbẹni Hassan Maiwake ni ilu Kano ṣugbọn awakọ ajagbe elepo naa ṣi na papa bora.
Lunar Eclipse: Ifá letùtù wa lẹyìn Òṣùpádẹ̀jẹ̀
Aworan ìṣẹlẹ òṣùpádeje káàkiri àgbáyé
Passport Nàìjírìa: ìjọba ti sọ gbèdéke ori ìwé ìrìnnà di ọdun mẹ́wàá
Ni ọjọ kejidinlọgbọn oṣu kẹfa ni ọkọ ajagbe elepo kan to  gbe jala epo ẹgbẹrun mẹtalelọgbọn gbina lẹyin ti o ṣubu ti o si da epo silẹ kaakiri ori afara naa.
Ki ato wi, ki a to fọ, eeyan mẹsan ati ọkọ mẹrinlelaadọta lo ti jona ninu ijamba naa.
Oríṣun àwòrán, ỌLLABỌ̀DÉ AKAMỌ
Lọjọ kejidinlọgbọn oṣu kẹfa lọkọ elepo kan da ijamba ina silẹ lori afara Ọ̀tẹdọla nilu Eko to si gba ẹmi ati dukia
Gẹgẹ bii ọgbẹni Chike Oti to jẹ alukoro ileeṣẹ Ọlọpaa ipinlẹ Eko ṣe sọ, 'oju kẹrindinlogun, opopona Hitoro Limawa ni wọn ti mu arakunrin Hassan Maiwake ni ipinlẹ Kano, o si ti n ran awọn ọlọpaa lọwọ ninu iwadi wọn lati ṣawari awakọ to wa ọkọ ajagbe yii lọjọ ti iṣẹlẹ  naa ṣẹ.'
O ni Ẹka ileeṣẹ ọlọpaa nipinlẹ Eko yoo sa gbogbo ipa rẹ lati rii daju pe awọn to padanu ẹbi ati dukia wọn sinu iṣẹlẹ naa gba idajọ ododo.
Iléeṣẹ́ aṣọ́bodè gba àgbá ọjà tó kún fún ẹrù ogun
Oríṣun àwòrán, Nigeria Customs service
opopona marosẹ Aba si Port Harcourt ni wọn ti gba ẹru ofin naa
Ileeṣẹ aṣọbode orilẹede Naijiria ti gba awọn ohun elo ologun kan ti awọn eeyan kan fẹ ko wọ orilẹede Naijiria lọna aitọ.
Ninu atẹjade kan ti alukoro ileeṣẹ naa, Joseph Attah fi sita, ileeṣẹ aṣọbode ni ọwọ awọn oṣiṣẹ ikọ ojulalakan fi nṣọri rẹ lo tẹ agba ikọja si kan ti nọmba rẹ jẹ MRSU 3040288 ti wọn fi nko ẹru nnkan ijagun naa lopopona marosẹ Aba si Port Harcourt.
Ọga agba to n ṣakoso ẹka iṣẹ apapọ gbogbo fun Ẹkun kẹta, Zone C ileeṣẹ aṣọbode orilẹede Naijiria, Ahmed Azarema ni wọn ti fi aṣoju ẹni to ni awọn ọja naa si ahamọ, ti iwaadi si n tẹsiwaju lori rẹ.
#EndSARS: Oṣinbajo ní Ìjọba àpapọ̀ ti ń wáàdí àṣemáṣe ikọ̀ SARS
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Oṣinbajo ni ohun to kan awọn ikọ ọlọpaa kogberegbe SARS ni gbigbogun ti iwa idigunjale ati ijinigbe pẹlu awọn iwa ipa gbogbo miran
Ijọba apapọ ti n boju wo gulegule wahala awọn ọlọpaa kogberegbe SARS lori oniruru ẹsun aṣemaṣe ti wọn n fi kan awọn ọlọpaa ikọ naa.
Igbakeji aarẹ orilẹede Naijiria, Ọjọgbọn Yẹmi Oṣinbajo lo fi eyi to BBC leti.
Igbakeji aarẹ Oṣinbajo ni iwa awọn oṣiṣẹ ikọ naa tabi ẹnikẹni to ba n hu iwa aitọ si araalu kii ṣe ohun ti ijọba to wa lode bayii yoo fi ọwọ awẹwa mu.
O ni ohun to kan awọn ikọ ọlọpaa kogberegbe SARS ni gbigbogun ti iwa idigunjale ati ijinigbe pẹlu awọn iwa ipa gbogbo miiran sugbọn ẹsun ti awọn eeyan fi n kan wọn bayii fihan pe ibi ti wọn fi ẹlẹmọṣọ wọn ṣọ kọ lo n ṣọ bayii.
Oríṣun àwòrán, POLICENG_PCRRU/TWITTER
Iwa aṣemaṣe awọn oṣiṣẹ ikọ SARS ti di ohun ti gbogbo eeyan lorilẹede Naijiria n bu ẹnu atẹ lu bayii
Ọgọọrọ awọn ọmọ orilẹede Naijiria lo si tun ti tọwọ bọ iwe ẹhonu kan ti wọn gbe ka iwaju ile aṣofin apapọ orilẹede naijiria lati pe fun wiwọgile ikọ naa, amọṣa lẹyin ọpọlọpọ oṣu, ikerora lori ikọ SARS ati aṣemaṣe wọn ko tii kuro lẹnu awọn ọmọ orilẹede Naijiria.
Mo ti ba ọga agba ileeṣẹ ọlọpaa sọrọ lori rẹ, aarẹ pẹlu nreti ẹkunrẹrẹ abọ lori awọn ohun to ti ṣẹlẹ, awọn ohun ti a ti ri nitori fidio ti o ti jade lori wọn ko kere rara.
Oṣinbajo ni bi ijọba ṣe n tiraka lati rii pe iwa ọdaran dẹkun lawujọ, o tun yẹ ka ba awọn oṣiṣẹ SARS naa sọrọ lati mọ ẹtọ awọn araalu ninu iṣẹ yoowu ti wọn ba n ṣe.
L'Ondo, àwọn agbébọn jí alága káńsù tẹ́lẹ̀ gbé
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Iṣẹlẹ ijinigbe ti n di gbọnmọgbọnmọ bayi nipinlẹ Ondo
Awọn agbebọn ti ji alaga tẹlẹ fun ijọba ibilẹ ariwa Akurẹ nipinlẹ Ondo, ọgbẹni Dele Fagoriọla gbe.
Ni ọsan ọjọ abamẹta ni wọn ji i gbe lasiko to wa ninu oko rẹ lopopona akurẹ si Ikẹrẹ Ekiti lati mojuto awọn alagbaro ti wọn n baa ṣiṣe.
Ọgbẹni Busuyi Fagoriọla to jẹ ẹgbọn rẹ ṣalaye pe awọn agbebọn ọhun ti wọn to meje niye wọ iboju lasiko ti wọn ji ọgbẹni Dele fagoriọla gbe.
Ileeṣẹ ọlọpaa nipinlẹ Ondo ni awọn ti bẹrẹ iwaadi lori iṣẹlẹ naa.
Iṣẹlẹ ijinigbe, paapaa jiji awọn oloṣelu ati ọbalaye gbe ti n di gbọnmọgbọnmọ bayi nipinlẹ Ondo.
Simi: Èmi kò mọ ohunkóhun nípa ‘owó Buhari’ o
Oríṣun àwòrán, @SympLySimi
Iwe iroyin ayelujara kan gbe iroyin pe awọn kan gbe, N200 Million fun Simi, BankyW lati polongo fun Aarẹ Buhari
Gbajugbaja olorin takasufe ni, Simi ti ke gbajare sita pe ohun ko lọwọ ninu eto awọn ọdọ kan ti wọn ni wọn n fi igba miliọnu fun oun atawọn olorin miiran lati polongo idibo lẹẹkeji fun aarẹ Buhari.
Ninu ọrọ to fi si oju opo twitter rẹ, @SympLySimi, o ni ohun ko jẹ pẹlu ọbọ j'awura.
Lẹ́yín ọpọ̀lọpọ̀ ọdún, Lagbaja da  ìlù bolẹ̀ nílú Abuja
Ileeṣẹ iroyin ayelujara kan ti orukọ rẹ n jẹ LeadersNG lo gbe iroyin ọhun sita pe ẹgbẹ ọdọ kan to n ja fun idapada si ipo lẹẹkeji fun aarẹ Muhammadu Buhari, ti wọn pe orukọ wọn ni #67MillionYouth ti san igba miliọnu naira, N200 Million fun Simi, BankyW atawọn olorin miiran lati polongo ibo fun Buhari.
"Ẹnikẹni to ba gba ọrọ yii gbọ lai ni ẹri, oun gan an paapaa wa lara iṣoro wa!
Mi o tilẹ gbọ nipa ẹgbẹ yii ri! Inu n bimi gidigi pe mo tilẹ n sọrọ lori iroyin to duro lori irọ yii. "
Akọringbayi naa to ṣẹṣẹ pari ode orin kan pẹlu agba ọjẹ olorin ni, Lagbaja nilu Abuja ṣalaye pe ọrọ naa dun oun gidigidi.
"Bi ẹ ba mọ mi daradara, ẹ o mọ iru ohun ti mo n ja fun mi o si lee dibọn lori rẹ.
Lẹyin ti mo ti pariwo pe n ko mọ ohunkohun nipa ọrọ yii, iwe iroyin yii ṣi papa gbe iroyin irọ naa jade, oju yoo ti yin ni!"
Simi fesi si ọrọ yii nigba ti awọn ololufẹ rẹ kan sọrọ sita lori iroyin naa ti pupọ wọn si n fi aidunnu wọn han lori rẹ.
Ẹwẹ, gbajugbaja olorin takasufe miran, bankyW ti orukọ rẹ wa lara awọn ti iwe iroyin ayelujara naa da pe wọn gba owo pẹlu ko dakẹ.
"Ninu atẹjade to fi sita lori ikanni ayelujara tirẹ, BankyW ni, ""Ọlọrun ma jẹ. Gbogbo yin lẹ mọ bi mo ṣe n pariwo awọn ohun ti ko tọ ninu ijọba yii ati igbesẹ mi gbogbo lorii jija fun idagbasoke awọn ọdọ lorilẹede Naijiria. Ẹgbẹ yii kii ṣe ti ijọba, ko si ni ohunkohun nṣe pẹlu ijọba, bẹẹni ko si owo kankan lori rẹ, ilakaka ifẹ lasan ni."""
BankyW ni ohun ko figba kankan kede atilẹyin fun oludije ipo aarẹ kankan.
Ọmọ Nàíjíríà: Ó yẹ kíjọba gbé ìgbẹ́sẹ̀ akin lásti dẹ́kun ìpànìyàn
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ọ̀pọ̀lọpọ̀ ènìyàn ló ti pàdánù ẹ̀mí wọn ní Zamfara l'ọ́dún 2018.
Awọn ọmọ Naijiria ko ti i dakẹ lori ipe wọn si ijọba apapọ lati wa atunṣe ti yoo wa lailai si iṣẹlẹ iṣekupani to n waye nipinlẹ Zamfara.
"Ọpọlọpọ lo ti fi ohun wọn sita loju opo Twitter lọjọ isinmi lati fi aidunnu wọn han si bi ""ọpọlọpọ eniyan ṣe ti padanu ẹmi wọn ni ipinlẹ Zamfara lati igba ti ọdun 2018 ti bẹrẹ."""
Awọn kan ni ki ijọba apapọ ṣe iru akitiyan to ṣe si ipaniyan to n waye l'awọn ibomi i ni Zamfara naa.
Awọn kan bu ẹnu ẹtẹ lu Aarẹ Muhammadu Buhari pe 'ko ni ko awọn ọlọpa ati ọmọ ogun lọ si ipinlẹ Zamfara bo ṣe ko wọn lọ si Ekiti lasiko eto idibo gomina to waye nibẹ.
Wahala eyi to waye kẹhin lọsẹ to kọja mu ki awọn eniyan kan padanu ẹmi wọn, t'ọpọlọpọ si di alainilelori nitori bi awọn onikupani naa ṣe dana sun awọn ile wọn l'awọn abule kan mejidinlogun nijọba ibilẹ Zurmi.
Ẹwẹ, ìṣẹlẹ iṣekupani naa ti mu ki ogunlọgọ eniyan maa fi ibugbe wọn silẹ ki wọn o maa ba tun sẹ kongẹ iru iṣẹlẹ bẹ mọ.
Minisita: Ileeṣẹ apòògùn 20 lo jẹbi síse òògùn ikọ́ Codeine
Oríṣun àwòrán, Frankieleon
Àṣìlò èròjà codeine àti awọn òògùn mi i maa n ṣe àkóbá fún ara
Ọwọ ileeṣẹ eto ilera ni Naijiria ti tẹ igo oogun ikọ olomi to n lọ si bi i miliọnu mẹta (2, 405,724) to ni eroja codeine ninu.
Eyi waye lẹyin ayẹwo atigbadegba kan ti ajọ to n mojuto ipese ounjẹ ati oogun lilo ni Naijiria, NAFDAC, ṣe.
Igbesẹ naa gẹgẹ bi minisita fun eto ilera, Ọjọgbọn Isaac Adewọle ṣe sọ, jẹ ọna lati ti tubọ fi ipinnu ijọba apapọ lati f'opin si aṣilo oogun ikọ olomi to ni codeine ninu, ati awọn oogun mi i l'orilẹede Naijiria han.
Fídíò òògùn ikọ́ Codeine: Àpọ̀jù rẹ̀ ń ya ọ̀dọ́ ní wèrè
Iwe iroyin Nigerian Tribune jabọ pe, Ọjọgbọn Adewọle sọ eyi di mimọ nilu Abuja lasiko to n tẹwọ gba abọ iwadi igbimọ ti ileeṣẹ eto ilera gbe kalẹ lati mojuto aṣilo oogun ikọ olomi to ni eroja codeine ninu.
Abọ iwadi naa fihan pe ogún ninu mẹtalelogun awọn ileeṣẹ to n ṣe oogun oyinbo ti wọn ṣe ayẹwo si lo jẹbi ọrọ naa.
Ati pe ibudo ti awọn ileeṣẹ naa n ko awọn ọja wọn si ni ọwọ ti tẹ awọn oogun ikọ naa.
Ìjọba Èkó: À fẹ́ kí asaajú ẹ̀sìn yí èrò aráàlú padà lórí ìwà àìtọ́, ìjẹkújẹ
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ipinlẹ Eko yoo tubọ maa fara kinra pẹlu awọn asaaju ẹsin
Ijọba ipinlẹ Eko ti kede ipinnu rẹ lati gbe isẹ le awọn asaaju ẹsin, to fi mọ awọn pasitọ ati imaamu lọwọ, ti yoo si maa san owo osu fun wọn.
Igbesẹ yii lo ni yoo mu ki wọn lee seto itaniji fawọn araalu lati kẹyin si iwa ijẹkujẹ ati awọn iwa aitọ mii to kun awujọ wa dẹnu.
Kọmisana fọrọ mọlẹbi ni ipinlẹ Eko, Abdulhakeem Abdulateef lo sisọ loju ọrọ yii lasiko eto ilanilọyẹ kan fawọn imaamu atawọn ọmọwe jake-jado ipinlẹ Eko.
Ṣé ẹ rántí orin - Má ṣe jẹ́jẹ́ ma wà mi lọ?
Kọmisana naa tun fikun pe ijọba ipinlẹ Eko yoo tubọ maa fara kinra pẹlu awọn asaaju ẹsin naa, to si tun rọ wọn lati jẹ awokọse rere, ki wọn si tun maa sewuri fawọn ọmọlẹyin wọn lati takete si iwa ijẹkujẹ.
A setan lati gbe isẹ le ọpọ wọn lọwọ nipa pipese owo osu fun wọn, ki wọn lee maa se atilẹyin fun ijọba lati fun awọn araalu ni ilanilọyẹ si iwa rere. A gbagbọ pe eeyan Ọlọrun ni awọn Imaamu ati Pasitọ, Nitori naa la se nilo iranlọwọ yin lati sewuri fun iwa ọ́mọluabi lawujọ, paapa nidi iwa ijiyin isẹ iriju ẹni ati titako iwa ibajẹ.
Abdulahateef fikun pe Ọlọrun yoo beere lọwọ gbogbo wa lati jiyin isẹ wa taa gbe ile aye se ni ọjọ idajọ. Nitori naa lo se yẹ ki awọn asaaju ẹsin yii lewaju wa si ọna to tọ nitori pe awokọse wa ni wọn.
Oríṣun àwòrán, @Governor Ambode
Sugbọn ọpọ eeyan lo ti n fi ero wọn han, bi awọn eeyan kan se tako igbesẹ yii si lawọn mii fara mọ.
Sugbọn ọpọ eeyan lo ti n fi ero wọn han oju awọn opo ikansira ẹni lori itakun agbaye, bi awọn eeyan kan se tako igbesẹ yii si lawọn mii fara mọ.
Loju opo Twitter, @AASCHE_KAATZE, o ni iroyin to dara ni eyi, ti oun si lero pe wọn yoo maa san owo osu fawọn Onisango naa, ti gbogbo ẹni ti ko nisẹ lọwọ yoo si maa di ojisẹ Ọlọrun.
Àwọn ọmọ Iyabọ Ojo rí bàbá wọn fún ìgbà àkọ́kọ́ ní ọdún mẹ́fà
Oríṣun àwòrán, Priscilla Ojo
Awọn mejeeji naa, ti wọn lọ lo isinmi wọn ni orilẹ-ede Amẹrika lo se alabapin awọn aworan ti wọn ya pẹlu baba wọn nibẹ.
Awọn ọmọ mejeeji ti gbaju gbaja osere tiata lobinrin, Iyabọ Ojo bi, eyiun Priscilla ati Festus ti bẹrẹ si ni sọ bi inu wọn ti dun to lati fi oju kan baba wọ̀n lẹyin ọdun mẹfa ti wọn ti foju-rinju kẹyin.
Awọn mejeeji naa, ti wọn lọ lo isinmi wọn ni orilẹ-ede Amẹrika lo se alabapin awọn aworan ti wọn ya pẹlu baba wọn nibẹ.
Oríṣun àwòrán, Festus Ojo
Inu awọn ọmọ Iyabọ Ojo dun lati fi oju kan baba wọ̀n lẹyin ọdun mẹfa ti wọn ti foju-rinju kẹyin.
Bẹẹ ba gbagbe, ipinya ti wa ninu igbeyawo iyawo Iyabọ Ojo lati ọjọ pipẹ, to si jẹ pe oun lo n da awọn ọmọ mejeeji naa tọ ni Naijiria.
'Mo ni baba isalẹ'
"Loju opo ikansira ẹni Instagram, Festus Oladunjoye Ojo, fedel x, to jẹ ọmọkunrin Iyabọ Ojo ni ""Baba mi ree, fun ẹyin ti ẹ fẹ mọ bi baba ti ri. Bi o tilẹ jẹ pe emi ko tii foju kan-an lati ọ̀dun mẹfa sẹyin, n se lo dabi ẹni pe ọsẹ diẹ sẹyin ni mo ti ri gbẹyin, nigba ti a foju kanra loni. Itan naa pọ̀ sugbọn mo gbadun ara mi loni."""
"Bakan naa ni eyi obinrin ni, Priscilla Ajọkẹ Ojo sọ loju opo Instagram rẹ, its priscy pe ""Ẹyin eeyan, ẹ wo baba mi, a ko fi oju ri ara wa fun ọdun mẹfa, amọ inu mi dun lati jade pẹlu rẹ loni, lati dara pọ di ẹbi kan soso."
"Iyabọ Ojo gan funra rẹ, to jẹ mama awọn ọmọ mejeeji yii, loju opo Instagram rẹ, iyaboojofespris, ni ""Ẹ́ wo awọn ẹbi Ojo, awọn ọmọ baba wọn"". Sugbọn Iyabọ ko ba wọn ya ninu fọto ti awọn mọ naa ba baba wọn ya."
Nàíjíríà: ‘Civil Defence’ yóò kún ológun lọ́wọ́ ní Zamfara
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Awọn ọmọ ogun setan lati jẹwọ ara wọn nipinlẹ Zamfara
Ìjọba orílẹ̀-èdè Nàìjíríà tí kéde pé àwọn yóò ràn ikọ ọmọ ẹgbẹrun kan lọ sí ipinlẹ Zamfara láti kojú ìpeníjà awọn janduku agbebon.
Ìkéde ìgbésẹ náà jáde láti ilé iṣẹ Ààrẹ fikun pé àwọn ọmọ ogun orilẹ, ti òfurufú, ọlọpàá àti àjọ ojú lalakà fí n sọri yóò k'ọwọ rìn láti kojú awọn agbebon lagbegbe òun.
Garba Shehu to je agbẹnusọ fún Ààrẹ Buhari ṣàlàyé pé papakó òfurufú Katsina to súnmọ́ Zamfara ni  àwọn ọmọ ogun òfurufú yóò ti má gbéra lọ si Zamfara.
Ìpeníjà àwọn agbebon nipinlẹ Zamfara jẹ òun ipaya fún àwọn èèyàn ibẹ pẹlú bí wọn ti ṣe n pá èèyàn tí wọn sì n ji dukia ati èèyàn gbe.
Lójó ẹtì ni awọn janduku agbebon òhun yà lù awọn abúlé kan ni ìpínlẹ̀ Zamfara, ti wọn sì pa èèyàn mejilelogoji nigba tí wọn kọlù abúlé méjìdínlógún láwọn ìjọba ìbílẹ̀ kan nipinlẹ naa.
Ìkọlù Zamfara: Awọn kan ni 1000 agbófinró kéré, àwọn mii ni ó pọ̀jù
Oríṣun àwòrán, STR/AFP/GETTY
Ọpọ ẹmi lo ti ba isẹlẹ ipaniyan Zamfara lọ
Agbẹnusọ fún ilé iṣẹ Ààrẹ orílèèdè Naijiria Garba Sheu, tí fèsì sí ariwisi àwọn ará ìlú lórí iye agbofinro ti ìjọba fi ranṣẹ sí ipinle Zamfara, láti dẹkùn ìpeníjà àwọn jaguda agbebon.
Nínú ìfọ̀rọ̀wánilẹ́nuwò pẹlú akoroyin BBC, Garba Shehu ní iye agbofinro tó yẹ ni ìjọba fi ranṣẹ, lẹyìn tí wọn ṣe àyẹwò ìṣẹlẹ tó n wáyé lagbegbe náà.
"Ìjọba ìbílẹ̀ kan perei ọrọ yí kan, ti a bá sì wò dáadáa a ri wí pé àwọn ọmọ ogun wá kunju oṣuwọn, láti lèe dẹkùn awọn agbebon wọn yí''
Shomolu gbajúmọ̀ fún ìwé títẹ̀
Ṣùgbọ́n awọn ọmọ Naijirià kan ko le ro wí pé iye àwọn agbofinro yi tó lati dẹkun ipaniyan ni ipinlẹ Zamfara.
Lójú òpó Twitter àwọn kan n ṣé àfiwé iye agbofinro ti wọn ran lo sí Zamfara, pẹlú ìyè agbofinro tó lò sí ipinle Ekiti nigba ìdìbò Gómìnà ibẹ.
Onímọ̀ nípa ètò ààbò kàn lorileede Naijiria, Tony Ofoyetan nínu ero tirẹ ni, iye ọmọ ogun tí wón rán lo sí Zamfara, paapa ti pọju.
''O dami lójú wí pé, áwọn agbegbon wọnyi ko lee to ẹgbẹrun kan ti awn ọlọpaa yii jẹ́, ẹja wọn to si n daamu ibu ko to nkan. Nitori nà, egberun kan agbofinro tó fún iṣẹ tó wà nílé yí.''
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Àarẹ Muhamadu Buhari ti se àbẹ̀wò sí ágbèègbè náà laipe yii
Tony so wi pe, bi àwọn agbofinro naa bá ṣe iṣẹ wọn bí o ti yẹ, ''kò yẹ ki o gbawọn lásìkò láti kojú awọn jaguda wọn yi''
''Ti wọn ba gbajumo isẹ otẹlẹmuye daada, ti ko si si ija laarin awọn agbofinro ti wọn ran lọ si Zamfara, o ye ki wahala yii dopin laipe.''
Oríṣun àwòrán, ABDULRAZAQ BELLO SHARMA
A gbo wi pe o to eeyan àádọ́jọ to padanu ẹmi wọn ninu ikolu yi laarin ọsẹ meji
Ninu ikọlu to waye laipe yi, awọn janduku agbebon yà lù awọn abúlé kan ni ìpínlẹ̀ Zamfara, ti wọn sì pa èèyàn mejilelogoji nigba tí wọn kọlù abúlé méjìdínlógún láwọn ìjọba ìbílẹ̀ kan nipinlẹ naa.
N se ni aworan awọn ara ilu ti wọn sa asala fun ẹmi wọn latari ikọlu naa gba ori ẹrọ ayelujara kan.
Oríṣun àwòrán, ABDULRAZAQ BELLO SHARMA
O ti to ọdun mẹjo ti awọn ara ilu Zamfara ti n koju ipenija ikọlu awọn agbebon
Lara wọn la ti ri eleyi ti awọn ara ilu to di eru wọn mọri, ti wọn si  n rin pẹlu.
Lọdun yi nikan, ọgọ̀ọ̀rọ̀ ènìyàn ni wọn ti fara káásà ninu ìkọlù aimoye to n waye nipinlẹ Zamfara.
Oníkẹ̀kẹ̀ NAPEP: Àwọn ọlọ́pàá ń gba owó kòtọ́ lọ́wọ́ wa
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ọpọ awọn olugbe ilu Maiduguri ni wọn ni lati fi ẹsẹ rin lọ si ibi iṣẹ wọn
Awọn onikẹkẹ NAPEP ni ilu Maiduguri, tii ṣe olu ilu ipinlẹ Borno, ya bo awọn opopona marosẹ to wa nilu naa ni owurọ ọjọ aje lati fi ẹhonu han lori ohun ti wọn pe ni bi ọlọpa ṣe n fi awọn jẹun"""
Awọn opopona to lorukọ bii opopona Baga, opopona Maiduguri si Damaturu, ati agbegbe Lagos street, ni wọn fi kẹkẹ wọn di pa lagbegbe ileeṣẹ awọn ọlọpaa nibẹ.
O to gẹẹ, gbogbo igba lawọn ọlọpaa fi n gba owo lọwọ wa lai ni idi kan pato. Nigba miran, wọn a gba owo to to N1,500 tabi N2,500 lọwọ wa.
Àwọn oṣiṣẹ feyinti ni Osun ṣé iwọde
Ọpọ awọn olugbe ilu Maiduguri ni wọn ni lati fi ẹsẹ rin lọ si ibi iṣẹ wọn.
Awọn eeyan miran ti wọn ni ọkọ ara wọn ni wọn ni lati yago fun awọn opopona ti awọn onikẹkẹ NAPEP naa ti gbajọba.
Awọn ọlọpaa ko tii sọrọ lori iṣẹlẹ ọhun.
Omiyale Ile Ife: Dukia sọfọ, awọn eniyan si tun farapa
Omiyale Ile Ife: Dukia sọfọ, awọn eniyan si tun farapa
Awọn eniyan ti agbara ojo ni ilu Ile Ife sọ oun ti oju wọn ri lasiko omiyale to sẹlẹ laipẹ yii.
Ninu ọrọ wọn, wọn ni arọrọda ojo ni asiko ojo yii ti fa ijamba ọkọ ati wipe ọpọlọpọ eniyan lo farapa ninu isẹlẹ omiyale naa.
Awọn ara agbeegbe naa wa rọ ijọba lati ba wọn wa atunsẹ si isẹlẹ omiyale to n sẹlẹ lati igba de igba ni ile Ile-Ifẹ.
Oríṣun àwòrán, @ojedeletemitayo
Awọn akẹkọ ileewe giga fasiti Ọbafẹmi Awolowo ni ilu Ile ifẹ naa ko ṣai fara gba ajalu naa
Awọn akẹkọ ileewe giga fasiti Ọbafẹmi Awolowo ni ilu Ile ifẹ, naa ko ṣai fara gba ajalu naa.
Ni ọdun 2017 ni irufẹ ajalu yii waye eleyi ti o sọ ọpọ di alainile.
Irú ẹ̀dá wo ni Fẹla Jẹ́?
Bi o tilẹ jẹ wi pe ijọba ti gbiyanju fifẹ oju agbara kaakiri ipinlẹ Ọṣun, ko dabi ẹni pe eyi ran wahala ikun omi ni ilu ile ifẹ.
Saraki, Dogara: Buhari gbọdọ̀ kìlọ̀ fún àwọn ọlọ́pàá lórí ọ̀rọ̀ Benue
Oríṣun àwòrán, @nassnigeria
Saraki ati Dogara ni awọn lọpaa ti n toju bọ ọrọ oṣelu
"Aarẹ Ile Aṣofin Agba, Sẹnetọ Bukọla Saraki ati  Olori Ile Aṣoju Aṣofin, Yakubu Dogara ti koro oju si igbesẹ to n waye ni ile aṣofin ipinlẹ Benue, eleyi ti wọn ṣe akawe rẹ gẹgẹ bii "" dida ẹgbin si ibi mimọ eto iṣofin"""
Awọn aṣofin mẹjọ ninu ọgbọn aṣofin to wa nile igbimọ aṣofin ipinlẹ Benue bẹrẹ igbesẹ ati yọ gomina ipinlẹ, Samuel Ortom nipo lẹyin ti wọn se awọn aṣofin mejilelogun yoku mọ ode gbagede ile aṣofin ipinlẹ naa.
Ninu atẹjade kan ti Saraki ati Dogara jumọ fọwọ si, wọn ke si aarẹ Mohammadu Buhari lati ke si ileeṣẹ ọlọpaa pe ko tọwọ ọmọ rẹ bọ aṣọ, ki wọn si yee sọ ara wọn di ohun elo fun dida ilana iṣejọba tiwantiwa ru.
Oríṣun àwòrán, Benue News
Olori ile naa tẹlẹ ti wọn ti rọ loye, Terkimbir Ikyange ko awọn aṣofin meje miran sodi lati fi iwe iyọninipo ranṣẹ si Gomina Samuel Ortom
A ti boju wo ohun to n lọ nipinlẹ Benue daradara nibi ti olori ile naa tẹlẹ ti wọn ti rọ loye, Terkimbir Ikyange ko awọn aṣofin meje miran sodi lati fi iwe iyọninipo ranṣẹ si Gomina Samuel Ortom, nigba ti ti wọn ko faaye gba awọn aṣofin mejilelogun ti wọn pọ julọ ninu ile naa lanfani ati wọ gbagede ile aṣofin ipinlẹ ọhun. A gbagbọ pe iwa arufin patapata ni eyi ko si ba ilana ti ofin la kalẹ fun awọn aṣofin lati gunle fun yiyọ gomina mu.
"Bakan naa ni o tun jẹ iyalẹnu pẹlu ipa ti awọn ọlọpaa n ko ninu ilana arufin yii. Igbagbọ wa ni pe, ẹka aṣofin ni wọn n ta ẹrẹ ba lori ọrọ yii.
Eyi si tun ṣe akawe bi wọn ṣe n lo ọlọpaa lọna aitọ lati fun ọrọ oṣelu lorilẹede yii."
Fẹ́mi Kútì: Ó ku ogún ìsẹ́jú táa fẹ́ seré, ni atagìtá mi pòórá
Oríṣun àwòrán, @ Femi Anikulapo-Kuti
Ó ku ogún ìsẹ́jú ki ere bẹr, ni Aghedo Andrew poora bi iso, ni atagìtá mi pòórá
Ilu mọọka akọrin Afro beat, Fẹmi Anikulapo-Kuti, ti n kerora pe atagita oun, Aghedo Andrew, ku diẹ ko ba isẹ oojọ oun jẹ ni orilẹ-ede Amẹrika, nibiti awọn ti lọ kọrin.
Fẹmi Kuti, tii se ọmọkunrin Fẹla Anikulapo Kuti, lo n tara poro ni ilu New York pe, o ku ogun isẹju ki ere orin ti oun gba bẹrẹ, ni oun ri pe atagita oun naa ti di awati, eyi ti oun kọ̀kọ bẹru pe yoo se ipalara fun orin ti oun fẹ kọ.
Sugbọn, Fẹmi, ẹni to n dupẹ lọwọ awọn ọmọ ẹgbẹ akọrin rẹ yoku, fun bi wọn se duro ti oun, ti wọn si ti oun lẹyin bii igba ẹkẹ ti n fi ọwọ ti ile, tun fi kun pe, awọn ko fi bẹẹ mọ ipa atagita to poora ni Amẹrika naa lara, nitori pe orin ti awọn kọ dun, to si tun ni arinrin.
Shomolu gbajúmọ̀ fún ìwé títẹ̀
Fẹmi, ẹni to kede isẹlẹ yii loju opo Twitter rẹ @Femi Anikulapo-Kuti, fi kun pe, obinrin ni atagita oun ba lọ nitori oun ti se awọn iwadi to yẹ, ti oun si ri pe Andrew ko si ninu ewu rara.
O salaye pe, awọn pe ni ori aago pe ko gbe ọkọ lati wa tete dara pọ mọ awọn, amọ to kọ lati se bẹẹ.
Amọ o wa n fọwọ sọya pe, ẹru ko bodo fun oun rara, nitori oun si ni awọn ọmọ ẹgbẹ ti muse-muse wọn da muse-muse, lati se ere to wu ni lori, ti wọn si tun setan lati gbe orukọ rere ẹgbẹ akọrin oun soke lala.
"Fẹmi ko sai yan pe ""A ko ri iru eyi ri, a fi n dẹru ba ọlọrọ ni, iru awọn isẹlẹ bayi maa n waye lati jẹ ki eeyan ni agbara ati ọgbọn si ni."""
Oríṣun àwòrán, @ Femi Anikulapo-Kuti
"Fẹmi Anikulapo Kuti ko sai yan pe ""A ko ri iru eyi ri, a fi n dẹru ba ọlọrọ ni"
Fẹmi, ẹni to n kọminu lori idi ti atagita ti oun fọkan tan se lee hu iru iwa bayii fun oun, wa n salaye pe, kii kuku se pe oun n fi iya owo jẹ awọn ọmọ ẹgbẹ oun.
O ni isẹ gidi lọwọ, mo si n san owo ribi-ribi fun wọn. Koda o ni owo to jọju lọwọ lati kọwe fi isẹ silẹ lọna to tọ,, bẹẹ ni awọn iwe asẹ iwọlu lorisi-risi nilẹ okeere (VISA), lo wa lori paali iwe asẹ irinna rẹ, eyi to lee fi wọ ibikibi lagbaye. Nitori naa, ko lee wi awijare pe oun ko ri itọju, loun se wu iru iwa bayii.
Nigba ti ọpọ eeyan n beere pe, kin lo de ti oun naa ko se ti gba iwe asẹ irinna rẹ, Passport, ni kete ti wọn wọ̀ ilẹ Amẹrika, Fẹmi dahun pe, eyi lodi pata-pata si ihuwasi oun, nitori iwa ifiyajẹni ni oun ka igbesẹ naa si, bẹẹ ni oun ni igbagbọ ninu gbogbo awọn to n ba oun sisẹ, ọna ti oun si maa n gba sisẹ niyi.
Ìjọ Hàkíkà: O leè sùn ti ìyàwó mi, kí ń sùn ti tìrẹ
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Asaaju ẹgbẹ Tijjaniyya ti ta kete si ẹgbẹ Hakika yii, ti wọn si ni awọn ko ba wọn se rara.
Bi orilẹ-ede Naijiria se n jẹ ekuru ọran ko tan lori ọrọ ikọ Boko Haram, tun ni ẹgbẹ ẹlẹsin miran tun dide ni awọn ipinlẹ bii Adamawa, Nasarawa ati Kano. Orukọ ẹgbẹ ẹlẹsin naa ni Hakika.
Bi o tilẹ jẹ pe ẹgbẹ yii ni ara ẹka ẹgbẹ ẹlẹsin musulumi Tijjaniyya ni oun wa, amọ awọn asaaju ẹgbẹ Tijjaniyya ti ta kete si ẹgbẹ Hakika yii, ti wọn si ni awọn ko ba wọn se rara.
Eyi ri bẹẹ nitori awọn iwa kan to se ajeji ti awọn ẹlẹsin Hakika maa n hu bii pi paarọ iyawo laarin ara wọn ti wọn ba ti de ipo giga kan ninu ẹsin, kikọ irun kiki silẹ ati kikọ ẹyin si aawẹ gbigba lasiko Ramadan, eyi to jẹ ara opo ẹsin Islam.
Èkó: Àwọn akínkánjú obìnrín tó ń wa Márúwá
Ọkan lara ẹlẹsin Hakika to ba BBC sọrọ labẹ asọ ni oun n foju sọna lati de ipo giga ninu ẹsin naa, nibi ti oun yoo ti ni anfaani lati paarọ iyawo oun pẹlu ẹlomiran..
Ti mo ba fi lee de ipo giga yii ninu ẹsin, maa gba ẹlomiran ni aaye lati maa sun ti iyawo mi, amọ emi ko ti de ipo naa bayii. Ti o ko ba jẹ ara ikọ ẹlẹsin Hakika, oye imọ yii ko lee ye ọ.
Bakan naa lo ni ti eeyan ba de ipo naa, ti wọn n pe ni ‘Tarbiyatul Askaru’, wọn yoo ya wọn sọtọ lati mase da ẹsẹ, ti wọn si leehu iwa to ba wu wọn lai ro pe ẹsẹ ni wọn n da.
Iha wo ni awọn asaaju ẹsin ati awujọ kọ si Hakika ?
Awọn ọba alaye ati awọn asaaju ẹsin ti wa rọ awọn araalu lati mase dara pọ mọ ijọ Hakika nitori ẹkọ ati ilana wọn yatọ si ti Islam.
Onimọ ẹlẹsin Islam kan ni ilu Numan nipinlẹ Adamawa, Malam Aminu Yakubu, sọ fun BBC pe iwa aimọkan nipa ẹkọ ẹsin Islam lo n da awọn ẹlẹsin Hakika laamu. O fikun pe, igbe aye ‘taa ni yoo mu mi’ ti awọn ẹlẹsin Hakika n hu lo n se iwuri fawọn ọdọ lati tete dara pọ mọ wọn.
Oríṣun àwòrán, @ABBAYOLA447
Awọn agbofinro ti wa sọ fun BBC pe awọn ti n finmu-finlẹ nipa ikọ ẹ́lẹsin tuntun naa, tawọn si ti n dọdẹ wọn.
Awọn agbofinro ti wa sọ fun BBC pe awọn ti n finmu-finlẹ nipa ikọ ẹ́lẹsin tuntun naa, tawọn si ti n dọdẹ wọn.
Atẹjade kan ti ileesẹ ologun ilẹ wa fisita ni ẹkọ wọn se ajeji, ti awọn si ti n sọ wọn tọwọ-tẹsẹ, ki iwa wọn to bọwọ sori.
Oríṣun àwòrán, @ABBAYOLA447
Ọranyan kọ ni gbigba aawẹ Ramadan fun awọn ọmọ ẹgbẹ Hakika
Wọn ni kekere ni awọn ti fẹ pa eekan ikọ ẹlsin Hakika, tori ti wọn ba dagba tan, wọn lee maa gba ẹbọ lọwọ awọn ọmọ ilẹ Naijiria bii Boko Haram. Wọn ni idasilẹ ẹgbẹ Hakika yii gan ti n da ẹru ba awọn eeyan Naijiria, eyi to n ran wọn leti bi ikọ mujẹ-mujẹ Boko Haram se bẹrẹ ni ọdun mẹwa sẹyin.
Kin lo de ti ikọ ẹlẹsin Hakika fi yatọ ?
Osun Election: Secondus sèpàdé pẹ̀lú Adeleke àtàwọn tó ń fapá-jánú
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Awọn oludije kan n fapa janu lori ètò ìdìbò abẹnu PDP típínlẹ̀ Osun
Alaga apapọ̀ fẹgbẹ òṣèlú People's Democratic Party, PDP, Ọgbẹni Uche Secondus, ti dasi aawọ tó n wáyé láàrin àwọn ọmọ ẹgbẹ PDP, lori Ìdìbò abẹnu fun ipò Gómìnà to waye laipe yi nipinlẹ Osun.
Níbi ìpàdé kan tó wáyé lolu ilé ẹgbẹ náà labuja, Secondus àti àwọn ọmọ ìgbìmò amusẹya ẹgbẹ fikún-lukun pẹlú Oludije ẹgbẹ náà fún ipò Gómìnà l‘Ọ̀sun, Seneto Ademola Adeleke ati àwọn ọmọ ẹgbẹ míi ti wọn n fapa janu.
Adeleke lo jáwé olúborí nínú ìdìbò abẹnu ẹgbẹ náà, eyi tó waye losu keje odun yii, pẹlú ìbò 1,569, nigbati Akin Ogunbiyi n pọn lẹyin rẹ pẹlu ìbò 1,562.
Ṣugbọn Ogunbiyi táko èsì ìbò náà niwájú ìgbìmò apẹtu-saawọ ẹgbẹ.
Lion Chaser: Richard, ọmọ ọdún mẹ́ẹ̀dógún se iná tó ń lé kìnìún
Ìròyìn tó tẹwa lọwọ sọ̀ pé, ọtọtọ ní Uche Secondus se ìpàdé pẹlú àwọn ọmọ ẹgbẹ náà àti wí pé, o ṣeéṣe kí ìgbìmò alabe-sekele kan tun ṣepàdé láti tunbo wà woroko fi ṣada lórí ọrọ náà.
Èèyàn mẹrin láti ọdọ Adeleke ati Ogunbiyi ni ìrètí wa wipe wọn yóò yan láti jo fọrọ jomitoro ọrọ lórí aawọ òhun.
Ìkọlù Plateau: Ortom ní inú òun dùn pé Buhari ń fi àmì ẹ̀yẹ dá Abdullahi lọ́lá
Ìmáámù Abubakar fi awọn okunrin ati obirin pamo sinu Mosalasi rẹ
Atoore ati ika, ọkan kii gbe.
Ọrọ yi se rẹgi nipa Imam ti BBC gbé ìròyìn rẹ sita lori bọ se doola ẹmi àwọn èèyàn ọ̀tàlénígba lé meji lọwọ àwọn agbebon-paniyan nipinle Plateau.
Lọ́jọ́ Ajé ni Aare Muhammadu Buhari ránṣẹ sí Imam Abubakar pé, oun fẹ ko wa bọ óun lọwọ, kí òun sì fi òye dà lọla lórí bo ti se doola ẹmi àwọn èèyàn tó sa asalà d'ọdọ rẹ, lọwọ àwọn asekupani agbebon ní àdúgbò Barkin Ladi ní ìpínlẹ̀ Plateau.
Inú mosalasi ní Abdullahi Abubakar, tó jẹ ẹni ọdún mẹtalelogun, fí àwon èèyàn naa pamọ sí lójó kẹrinlelogun osu kẹfa ọdún 2018.
Lion Chaser: Richard, ọmọ ọdún mẹ́ẹ̀dógún se iná tó ń lé kìnìún
Àwọn tí Abubakar doola ẹmi wọn sọ fún BBC pé, inú àwọn dùn gán bi Aare ṣe fẹ dá Abdullahi lọla.
Wọn ní bí ki ba se pe o gbe ìgbésẹ tó gbé, àwọn ki bá má wa l'ayé lóni.
Ewé, aṣojú ilé Amerika sí orílèèdè Naijirià náà ti gba lalejo.
Gómìnà ipinle Plateau Simon Lalong, lo fi ikede si'ta pé Ààrẹ Buhari fe fojú kan Abdullahi, níbi àpérò kan tí yóò wáyé lórí ètò alafia ati aabo.
Gómìnà Lalong ni, gbogbo ìlú ní Abdullahi dóóla ẹmi wọn pẹlú èèyàn oodunrun tí o gbà lá.
Yakubu Datti, to je agbẹnusọ fún Gómìnà Lalong ní, àìsí nílé Ààrẹ Buhari lo faa, ti àwọn kò ti le fi sọ àsìkò àti ààyè ti idanilọla náà yóò to wáyé.
Gómìnà Lalong ní, ayọ òun kún pe àsìkò ti òun jẹ Gómìnà ni irú nnkán bayii wáyé.
Awọn ọlọ́pàá àti àwọn òṣiṣẹ́ ààbò ti ṣí afárá 3rd mainland padà
ọkọ̀ wagon kan ló sàdédé gbina lori irin lórí afárá
Òpópónà afárá Third Mainland tó dí lówùrọ̀ òní kò sẹ̀yìn ìná to sẹ́yọ lára ọ̀kan lára àwọn ọkọ̀ tó ń rin lójú pópó.
Èyí ló fàá tí àwọn ọlọ́pàá fí tí apákan ọ̀nà náà, tí ìgbòkègbodò ọkọ̀ sì fi lọ́ jáí.
Gẹ́gẹ́ bí ìròyìn ṣe fi tó wa léti súnkẹrẹ-fàkẹrẹ ọkọ̀ láti Owonronshoki sí inú Ekó báyìí kò ṣee fẹ́nu sọ bó tile jẹ́ pé àwọn tọ́rọ̀kan ti ń sisẹ́ lée lórí.
Oríṣun àwòrán, Empics
Ọkọ̀ wagon kan ló ṣààdédé gbina lori irin lórí afárá
Ọkọ̀ epó gbina ní Banki ECO
Ìṣẹlẹ iná ọkọ agbepo kan tun ti ṣẹlẹ̀ nipinle Eko, eyi to sọ irufẹ isẹlẹ yii di kaka kewe agbọn dẹ, lile lo nle si.
Ilé epo to wa ni olu ilé iṣẹ ilé ifowopamọ Ecobank ni Victoria Island, ní ìṣẹlẹ náà ti wáyé.
Oríṣun àwòrán, Lasema
Ṣugbọn awọn panapana ti dẹkùn ina náà
Ìṣẹlẹ náà wáyé ni aaro ọjọ Isẹgun nigbati ọkọ náà n já èpo sínú akoto èpo ile ifowopamọ sí òun.
Ṣugbọn awọn panapana ti dẹkùn ina náà.
Lion Chaser: Richard, ọmọ ọdún mẹ́ẹ̀dógún se iná tó ń lé kìnìún
Akọroyin BBC to lọ sibi isẹlẹ naa ni, kò sí ẹni tó kù nínú ìṣẹlẹ náà ṣùgbọ́n kò ti dájú iye èèyàn to f'arapa nínú ìjàmbá ọhun.
Bákan náà ló ní, wọn ti dawọ iṣẹ dúró ní ilé ifowopamọ Eco to wa ni Victoria Island, ti wọn sì sáré ko àwọn onibara wọn jáde nínú ọọfisi wọn
Èyí ni igbákejì ti ọkọ agbepo yóò gbina nílu Èkó, lẹyìn ìṣẹlẹ tí Otedola to mú òpó ẹmi ati dukia ló.
Nigba to n sọrọ lori isẹlẹ yii ninu atẹjade kan to fi sita, ọga agba fun ajọ to n ri si akoso isẹlẹ pajawiri ni ipinl;ẹ Eko, Lasema, Adesina Tiamiyu niaago mẹjọ aabọ aarọ ọjọ isẹgun ni awn gba ipe nipa isẹlẹ naa, tawọn si dide lọgan lati lọdoola rẹ.
O ni awọn ko ti mọ ohun to fa isẹlẹ ina naa sugbọn awọn tete dide pẹ́lu ileesẹ pana-pana lati pa ina ọhun.
Adegoke: APC kò tẹ̀lé ìlànà ìdìbò tó yẹ l'Ọ́ṣun
Adegoke n rọ ile ẹjọ lati kede pe idibo naa ko ba ilana ti igbimọ amuṣẹya APC fọwọ si mu
Amofin Kunle Adegoke to jẹ ọkan lara awọn oludije fun gomina labẹ asia ẹgbẹ oṣelu APC ni ipinlẹ Ọṣun ninu idibo abẹnu APC,  to kọja ti gba ile ẹjọ giga apapọ̀ ni ilu Abuja lọ, pẹlu ẹbẹ pe ki ile ẹjọ o wọgile esi idibo abẹnu ẹgbẹ oselu naa to waye.
Ẹgbẹ oṣelu APC, ati ajọ eleto idibo INEC ni amofin naa gbe lọ siwaju ileẹjọ lori ọrọ naa.
Ninu iwe ipẹjọ rẹ, Adegoke n rọ ile ẹjọ lati kede rẹ pe idibo naa ko ba ilana ti igbimọ amuṣẹya APC la kalẹ, ti igbimọ alakoso rẹ si tun fọwọ si mu.
Onídájọ́ Fọlahanmi Oloyede léwájú ìwọ́de òṣìṣẹ́fẹ̀yìntì fún ọjọ́ mẹ́ta l'Ọ́ṣun
Ibo to le dẹ ni ẹgbẹrun mẹtadinlaadoje (127,017) ni Oyetọla ni, nigba ti Amofin Kunle Adegoke ni ibo ọtalelugba o din mẹjọ, 252.
Ọgbẹni Gboyega Oyetọla lo gbegba oroke nibi idibo abẹle ẹgbẹ oṣelu APC to waye ni ogunjọ Oṣu Keje.
Ẹgbẹ oṣelu APC, ati ajọ eleto idibo INEC ni amofin naa gbe lọ siwaju ileẹjọ lori ọrọ naa
O ni ki ile ẹjọ wọgile idibo naa nitori ko gbe ilana ati eto to yẹ ni titẹle kalẹ fun idibo naa.
Adegoke wa beere fun aṣẹ ile ẹjọ eleyi ti yoo ka ẹgbẹ oṣelu APC lapako lati maṣe lo esi idibo abẹnu naa lati fi kopa ninu eto idibo sipo gomina ti yoo waye nipinlẹ Ọṣun,  lọjọ kejilelogun Oṣu Kẹsan.
Bukola Saraki: Irọ́ ni pé sẹ́nétọ̀ kan yóò má gba ₦15m owó àjẹmọ́nú
Oríṣun àwòrán, Nigeria Senate
Àjọ tó ń jà fún ẹ̀tọ́ àwọn ará ìlú, SERAP kéde pé Bukola Saraki ń gbìyànjú láti sọ owó àjẹmọ́nú sẹ́nétọ̀ kan da N15m.
Aarẹ Ile Igbimọ Asofin Agba, Bukọla Saraki ti ni, ko si otitọ kankan ninu ẹsun ti Ajọ to ja fun ẹtọ awọn ara ilu, SERAP kede lori afikun owo ajẹmọnu awọn sẹnetọ lorilẹede Naijiria.
Ọjọ Kẹfa, Osu Kọkanla ọdun 2018 ni Ajọ SERAP fi si ori ẹrọ ikansiraẹni Twitter rẹ pe, igbesẹ Bukola Saraki lati fikun owo ajẹmọnu awọn asofin, ti ẹni kọọkan yoo si maa gba milliọnu mẹẹdogun Naira losoosu, ko ba ofin to rọ mọ owo osu lorilẹede Naijiria mu.
Grandma Maruwa: Ó yẹ kí obìnrin sisẹ́ láì wojú ọkọ kó tó jẹun
Amọ, Agbẹnusọ fun Bukola Saraki, Olu Onemola fi si ori itakun ibaraẹnisọrọ Twitter pe ẹsun ti ko lẹsẹ nlẹ ni SERAP fikan Saraki.
Onemola fikun wi pe, Ajọ SERAP to n soju awọn ọmọ Naijiria ni ko yẹ ko maa gbe iroyin ẹlẹjẹ ti gbogbo ọmọ Naijiria yoo ri sita.
Ọmọ ilé ìgbìmọ aṣòfin àgbà tó díje dupò gómìnà ìpínlẹ̀ Osun lósù tó kọja, Ademola Adeleke ní pípada síle aṣòfin lẹ́yìn tí àwọn ọmọ ile ṣe ìfọ̀rọ̀wérọ̀ ránpẹ́, kò ṣeyìn kíkẹ́dùn ọkan lára ọmọ ile igbìmọ̀ aṣojúṣofin tó papoda l'óṣù Kẹsàn án.
O fi kún ọ̀rọ̀ rẹ̀, lásìkò tó ń ba BBC sọ̀rọ̀ nílé ìgbìmọ aṣofin l'Abuja lónìí pé kò sí nínú ìpinu ọmọ ilé láti dìbò yọ ààrẹ ilé ìgbìmọ aṣofin.
Ademọla Adeleke: 'Àwa ò fí ti ẹgbẹ́ òṣelú ṣe nílé ìgbìmọ aṣòfin àgbà
O ní ìtẹ́síwájú orílẹ̀-èdè  ló ṣe pàtàkì lásìkò yìí, àwọn kò sì fi tí ẹgbẹ́ òṣèlú ṣe rárá bíkò ṣe ọ̀nà láti wá ojúútu sí ìṣòrò tó ń ko orílẹ̀-èdè yìí lọ́wọ.
Sẹ́nàtọ́ Omo Agege: Kò tọ́ sí Saraki láti darí Ilé Asofin Agba
Oríṣun àwòrán, FACEBOOK
Aarẹ Ile Igbimọ Asofin lorilẹede Naijiria, Bukola Saraki ni o dari ijoko ile loni, lẹyin ti wọn lọ fun idibo abẹlẹ ẹgbẹ oselu wọn saaju idibo gbogboogbo ti ọdun 2019.
Saraki to dari ile lo saaju awọn adari Ile Igbimọ nigba ti wọn n to lọ wọọwọ wọle pẹlu adura ni agogo mọkanla owurọ ooni lati bẹre isẹ.
Lasiko ti wọn n jiroro, Sẹnetọ Bukola Saraki ni ipade awọn toni da le lori bi Ile Igbimọ Asofin yoo se gbooro si, eyi ti yoo mu ilosiwaju ba orilẹede Naijiria lapaapọ.
'Ìlù Bàtá ló yàn mi, èmi kọ́ ni mo yàn an'
Ile Igbimo Asofin naa lọ fun isinmi lati Ọjọ Kẹrinlelogun, Ọsu Kẹjọ pada si ẹnu isẹ loni, nigbati Ile Igbimo Asojusofin yoo pejọ lati se ọfọ ọkan lara wn to papoda, Arabinrin Funke Adedoyin.
Bakan naa, Sẹnetọ to n soju ẹkun gbungun ipinlẹ Delta, Sẹnetọ Omo Agege ti kesi Bukola Saraki lati kọwe fi ipo silẹ gẹgẹbi Aarẹ Ile Igbimọ Asofin Agba.
Sẹnetọ Omo Agege ni ki alaafia o le e jọba, pe ko to si Saraki  lati dari Ile Asofin Agba pẹlu bo se fi ẹgbẹ oselu APC silẹ fun PDP.
Ẹwẹ, awọn oluranlọwọ fun awọn asofin ti se ifẹhọnu han lori bi Ile Igbimọ Asofin se kọ lati san owo osu wn ati ajẹmọnu wọn.
Awọn osisẹ naa se ifẹhọnu han naa ni ayika Ile Igbimọ Asofin ni Olu-ilu orilẹede Naijiria, Abuja.
Ijọba apapọ ko tii gbọ nipa ikọwe fipo silẹ aarẹ ile aṣofin agba.
Minisita feto iroyin, Lai Muhammed lo sọ bẹẹ ninu ifọrọwerọ pẹlu BBC Yoruba lẹyin ti aarẹ ile aṣofin agba, Bukọla Saraki kọwe fi ipo silẹ.
Lai Mohammed: Saraki ko tíì fi ìgbésẹ̀ rẹ̀ tó wa létí
Lai Mohammed ni Sẹnetọ Saraki kii ṣe ara ijọba APC nitori naa ijọba apapọ ko lee sọ boya fifi ẹgbẹ silẹ to fi ẹgbẹ silẹ lee ni ipa kan tabi omiran.
"Awa o tii gbọ gẹgẹ bi ilana to tọ.
Inu ẹgbẹ lo ti kuro, ko kuro ni ijọba nitori kii ṣe ọmọ igbimọ ijọba wa. Ẹgbẹ ni yoo sọrọ lori boya yoo ni ipa ninu ẹgbẹ tabi rara."
Oríṣun àwòrán, Presidency Nigeria
Aarẹ ile aṣofin agba, Bukọla Saraki kede pe oun ti kuro lẹgbẹ oṣelu APC ṣugbọn ko tii sọ ibi gan ti o n doju ni pato.
Bukola Saraki - Lẹyin ọpọlọpọ ijiroro mo ti fi ẹgbẹ APC silẹ lọ PDP
Oríṣun àwòrán, Twitter/Bukola Saraki
Àwọn ènìyàn ti fẹ̀sì lórí ẹ̀rọ ayélujára lori iròyìn wí pé Aare ile igbimọ Asofin, Bukola Saraki ti kuro ninu ẹgbẹ oselu APC.
Aare ile igbimọ Asofin Agba, Bukola Saraki ti kuro ninu ẹgbẹ oselu APC, o si ti  fi lede wipe ẹgbẹ oselu PDP ni ohun nlọ darapọ mọ.
Saraki to fi ero rẹ han lori ikanni Twitter rẹ ni wakati diẹ sẹyin, fi atẹjade sita nibi to ti fihan wi pe ẹgbẹ oselu APC ti da oun afisẹyin ti egun fi sọ, ati wipe oun ti pada si ẹgbẹ oselu PDP ti oun ti bẹrẹ irinajo oselu.
Bakannaa, Gomina ipinlẹ Kwara, Alhaji Abdulfatah Ahmed lori ikanni Twitter rẹ naa fi ipinnu rẹ han lati kuro ninu ẹgbẹ oselu APC lọ si PDP nitori ẹgbẹ oselu APC ko fun ohun laaye lati koju isoro to n koju ni ipinlẹ Kwara.
Lion Chaser: Richard, ọmọ ọdún mẹ́ẹ̀dógún se iná tó ń lé kìnìún
Ẹgbẹ oselu PDP, Atiku sọrọ lori ifẹgbẹsilẹ Saraki
Ọkan lara awọn sẹnẹto ni ile igbimo asofin agba, Ben Murray Bruce labẹ ẹgbẹ oselu PDP fi idunnu rẹ han wipe lati Saraki n bọ wa si ẹgbẹ oselu PDP, bi o tilẹ jẹ pe Saraki ko i ti fi ero rẹ han lasiko ti Bruce sọ eyi.
Lori ikannni Twitter wọn, ẹgbẹ oselu PDP ni  ayo ati idunnu lo jẹ fun awọn lati ri wi pe aarẹ ile igbimọ Asofin pada si ẹgbẹ osẹlu won, ti wọn si ki ku nabo ati awọn miran bii Gomina Kwara, Ahmed Abdulfatah ati Asoju ilẹ Naijiria si South- Africa ALhaji Ahmed Ibeto pada si ẹgbẹ oselu alaburada.
Bakan naa, ninu ọrọ tirẹ, Igbakeji aarẹ tẹlẹri lorilẹede Naijiria, Atiku Abubakar sọ wi pe oun pẹlu ẹni to parwa si Saraki lati darapọ mọ PDP nitori iru iwa ti APC wusi Saraki naa ni wọn n hu si awọn ọmọ Naijiria.
Laipẹ yii ni Sẹnatọ mẹ́ẹ̀dógún fi ẹgbẹ́ òṣelú APC sílẹ̀ lọ sí PDP.
Saraki: Mo kọ́ ẹ̀kọ́ ńlá lọ́dún mẹ́ta tí mo lò ní APC
Oríṣun àwòrán, BUKOLA SARAKI
Saraki ni ohun ti oun fẹ ja fun labẹ aburada ẹgbẹ oṣelu PDP ni iṣọkan orilẹede Naijiria
Sẹnetọ Saraki ni ileri ayipada ọtun lo mu ki oun atawọn akẹgbẹ oun to fi PDP silẹ o darapọ ms APC.
 A kuro ni ilepa fun idajọ ododo, aisi irẹjẹ ati ibaṣepọ to dan mọran eleyi to jẹ ipinlẹ ẹgbẹ oṣelu PDP gan lati ipilẹ ki o to fi oju opo naa silẹ.
Lẹyin to darapọ mọ ẹgbẹ oṣelu APC to si di aarẹ ile aṣofin agba labẹ ẹgbẹ oṣelu naa ni Saraki n pada si ẹgbẹ oṣelu PDP bayii, ṣugbọn ko ṣai sọ idi to n muu pada si ẹgbẹ oṣelu naa.
Saraki ni idi ti oun fi n pada ni pe ẹgbẹ oṣelu APC ti ṣe atunto ati atunṣe gbogbo to tọ ni ṣise.
Gẹgẹ bii Sẹnetọ Saraki ṣe sọ ninu ọrọ rẹ, lẹyin ijakulẹ rẹ ninu eto idibo apapọ to kọja nipataki julọ idibo aarẹ eleyi ti o ti fidirẹmi, o ni ẹgbẹ oṣelu PDP ti kọ ẹkọ lara ijakulẹ rẹ pẹlu agbekalẹ awọn atunṣe to yẹ.
"PDP ti a n pada si ti di ẹgbẹ oṣelu to ti kọ ẹkọ rẹ lọna to le ti wọn si ti wa mọ daju bayi pe ko si ọmọ ẹgbẹ kankan ti wọn lee yan ni pọṣin. O ti di ẹgbẹ oṣelu to ti mọ pe, koṣemani ni idajọ ododo, aisi irẹjẹ ati ibaṣepọ to dan mọran fun alaafia.
Oríṣun àwòrán, BUKOLA SARAKI
Saraki ni idi ti oun fi n pada ni pe ẹgbẹ oṣelu APC ti ṣe atunto ati atunṣe gbogbo to tọ ni ṣise
Saraki tun tẹnu mọọ pe ẹkọ ti oun kọ laarin ọdun mẹta ti oun lo pẹlu ẹgbẹ oṣelu APC ni pe pataki julọ ojuṣe to n koju orilẹede yii ni ọna lati mu awọn eeyan orilẹede yii ṣọkan. Ko tii si igba kan ninu itan ilẹyii ti awọn ọmọ orilẹede yii tii ta kete si orilẹede yii bii ti asiko yii."""
O ni ohun ti oun fẹ ja fun labẹ aburada ẹgbẹ oṣelu PDP ni iṣọkan orilẹede Naijiria.
Buhari: Màá sisẹ́ fún ààbò àti àgbéga ẹkùn wa
Oríṣun àwòrán, @BashirAhmad
Kete ti awọn olori orilẹ-ede lẹkun iwọ oorun Afrika pari ipade ajọ Ecowas naa, ni wọn kede Buhari gẹgẹ bii alaga wọn tuntun.
Aarẹ Muhammadu Buhari ti ilẹ wa Naijiria ni ajọ to n se asepọ ni idi okoowo lẹkun iwọ oorun Afrika, ECOWAS, dibo yan gẹgẹ bii alaga rẹ nibi ipade ajọ naa to waye ni ilu Lome, tii se olu ilu orilẹ-ede Togo ni ọjọ isẹgun.
Ikede kan ti agbẹnusọ fun aarẹ Buhari, Bashir Ahmad fisita loju opo Twitter rẹ lo sisọ loju eleyii.
Oríṣun àwòrán, @BashirAhmad
Muhammadu Buhari ni inu oun dun si bi wọn se yan oun ni alaga ajọ Ecowas
O ni ni kete ti awọn olori orilẹ-ede lẹkun iwọ oorun Afrika pari ipade ajọ Ecowas naa, ni wọn kede Buhari gẹgẹ bii alaga wọn tuntun.
Nigba to n sọ ero kan rẹ lori isẹlẹ yii, Aarẹ Muhammadu Buhari ni inu oun dun si bi wọn se yan oun ni alaga ajọ Ecowas.
Ìbaàrún pe ọdún kan
O wa jẹjẹ lati sisẹ tọkan-tara pẹlu awọn olori orilẹ-ede yoku fun ipese eto aabo to duro re, alaafia , isejọba rere ati igbaye-gbadun araalu pẹlu eto ọrọ aje to mu yan-yan, ki ẹkun iwọ oorun Afrika lee ni idagbasoke to yẹ.
Buhari wa fi ẹmi imoore rẹ han si awọn akẹẹgbẹ rẹ ninu ajọ Ecowas, ti wọn kọ lati faramọ bi oun se faake kọri lati gba ipo naa nigba ti wọn kọkọ fi ipinnu wọn ọhun to oun leti.
Mo mọọmọ fẹ dupẹ pupọ lọwọ aarẹ orilẹ-ede Togo, Faure Gnassingbe, fun isẹ takun-takun to gbe se lasiko to n ko ajọ Ecowas sodi. mo si n fi oju sọna fun igbesẹ gbigba alejoipade ajọ Ecowas miran ni ilu Abuja losu kejila ọdun 2018.
Sokoto bandits: Buhari bá ìpínlẹ̀ Sokoto kẹ́dùn lẹ́yìn tí àwọn agbégbọn f'ọ̀pọ̀ ẹ̀mí ṣòfò níbẹ̀
Oríṣun àwòrán, Garba Shehu
Aarẹ Muhammadu Buhari ti ba awọn eeyan ipinlẹ Sokoto kẹdun lẹyin ti awọn agbebọn ṣekupa ọpọ eeyan ni ijọba ibilẹ Sabon Birni ni pinlẹ naa.
Ninu atẹjade kan ti agbẹnusọ aarẹ, Garba Shehu fi lede ni aarẹ Buhari ti gbadura pe ki Ọlọrun tu awọn ẹbi to padanu awọn eeyan wọn ninu.
Buhari ni o ṣeni laanu pe awọn agbebọn ọhun n gbẹmi awọn eeyan lasiko ti ajakalẹ arun Coronavirus n ba gbogbo aye finra yii.
Oríṣun àwòrán, Garba Shehu
Aarẹ ti wa ṣeleri fun awọn ọmọ Naijiria pe ijọba rẹ yoo sa gbogbo akitiyan rẹ lati dabo bo awọn eeyan lọwọ awọn afẹmiṣofo.
Lẹyin naa lo ni awọn ọmọ ogun Naijiria yoo tẹsiwaju lati ma kọju ija si awọn agbebọn ọhun ki alaafi le wa lagbegbe naa atawọn agbegbe mii ti wọn ti n ṣoṣẹ.
Iroyin ni awọn agbebọn ọhun ya bo ijọba ibilẹ naa lẹyin nnkan bii wakati mẹrinlelogun ti gomina ipinlẹ ọhun, Aminu Tambuwal ṣabẹwo sibẹ.
Oríṣun àwòrán, Tambuwal/twitter
Tambuwal: Olùrànlọ́wọ́ 252 kọ̀wé fipò sílẹ̀
Ó kéré tán ààdọ́talénígbà lé méjì olùbádámọ̀ràn àti olùrànlọ́wọ́ fún Gómìnà ìpínlẹ̀ Sokoto Aminu Waziri Tambuwal ló ti kòwé fipò sílẹ̀.
Àwọn òṣìṣẹ́ tó kọ̀wé fipò sílẹ̀ ọhún sàlàyé pé ìgbésẹ̀ àwọn kò ṣẹ̀yìn ìpinu Gómìnà láti fi ẹgbẹ́ òṣèlú APC sílẹ̀, àti pé àwọn ò ṣetán lati fi ẹgbẹ́ oṣèlú APC sílẹ̀ èyí kò sì ni ṣeṣe ṣe lati tẹ̀síwáju bi alábaṣiṣẹ́ pọ̀ pẹ̀lú gómìnà.
Lásìkò tí wọn ń fi ọ̀rọ̀ náà to àwọn oníròyìn léti lọ́jọ́ àìkú ní ìpínlẹ̀ Sokoto àgbẹnusọ fun àwọn olùbádámọ̀ràn Dasuki Haske, sàlàyé pé ìgbéṣẹ̀ àwọn kò sẹ̀yìn ìnú kan tí àwọn fi bá ẹgbẹ́ lò.
'A ń fi gbogbo ẹnu sọọ́ pé a ò lé tẹ̀lé gómìnà Tambuwal ló sí ẹgbẹ́ òṣèlú tuntun rẹ̀., a ti ṣeán láti dúró si ẹgbẹ́ APC'
Aminu Tambuwal darapo mọ ẹgbẹ́ òṣèlú PDP
Lẹyin ti aarẹ ile asofin agba l'Abuja Bukola Saraki fi ẹgbẹ oṣelu APC silẹ lọ si PDP lọjọ Iṣegun, Gomina Ipinlẹ Sokoto Aminu Tambuwal naa ti kede loju opo Twitter pe, oun ti ba gbẹ oselu PDP lọ.
Tambuwal ni oun fi ọrọ naa lọ ọpọ eeyan nipinlẹ Sokoto, ti wọn si gba pe ki oun to gbe igbesẹ naa.
Oríṣun àwòrán, @SokotoGovtHouse
Ọgọọrọ awọn ololufẹ rẹ ni wọn pejọ siwaju Ile Ijọba Ipinlẹ Sokoto ni Ọjọru saaju ikede naa
Ọgọọrọ awọn ololufẹ rẹ ni wọn pejọ siwaju Ile Ijọba Ipinlẹ Sokoto ni Ọjọru saaju ikede naa.
Ọgọọrọ awọn ololufẹ rẹ ni wọn pejọ siwaju Ile Ijọba Ipinlẹ Sokoto loni Ọjọru saaju ikede naa.
Oríṣun àwòrán, Abdullahi/facebook
Abdullahi fìdí ọ̀rọ̀ ọ̀hún múlẹ̀ ní ilé ẹgbẹ́ APC l'Abuja wípe ìròyìn ẹlẹ́jẹ̀ ní, kí ẹnikẹ́ni máa ṣe gbàágbọ.
Ẹwẹ, akowe ìpolongo ẹgbẹ́ òṣèlù APC, Bolaji Abdullahi, lokọkọ kọwe fi ipo rẹ silẹ ninu ẹgbẹ oselu naa l'Ọjọru.
Abdullahi ninu atẹjade to fi sita sọ wi pe nitori rogbodiyan to su jade ninu ẹgbẹ oselu naa lo mu oun pinnu lati fi ẹgbẹ oselu APC silẹ.
Ti a ko ba gbagbe, owurọ Ọjọ Isegun ni akowe ẹgbẹ APC tẹlẹri naa ké gbàjarè pé, òtítọ kan kò sí nínú ìròyin kan to ni òún ti kọ̀wé fipò silẹ gẹ́gẹ́ bi ọmọ ẹgbẹ́ APC, láti darapọ̀ mọ́ ẹgbẹ́ òṣẹ́lú People's Democratic Party (PDP).
Ìbaàrún pe ọdún kan
Abdullahi fìdí ọ̀rọ̀ ọ̀hún múlẹ̀, ní ilé ẹgbẹ́ APC l'Abuja wípe ìròyìn ẹlẹ́jẹ̀ ní, kí ẹnikẹ́ni máa ṣe gbàágbọ.
Ó ní àìsí nílé mínísítà fún eré ìdárayá tẹ́lẹ̀ rí, ló dákún àhesọ ọrọ tó gbòde kan, nítorí ìpàdé àwọn ọmọ igbimọ amusẹya ẹgbẹ́ APC kò wáyé l'ọ́jọ́ ajé, èyí sì mú kí ó ma ṣeeṣe láti ṣe ìpàdé lórí bọyá òùn yóò fi ẹgbẹ́ sílẹ̀.
Nígbà tó ń fesì lóri èrò rẹ̀ nípa ààrẹ ilé ìgbimọ̀ aṣofin tó kúrò nínú ẹgbẹ́, o ní èyí kò tọ́ka sí pe, òun yóò fí ẹgbẹ́ APC sílẹ̀.
"'' Iwáju ilé ní mo gbà wọlẹ́ sinu APC, tí ń o bá sì lọ, mí ò ní gba ẹ̀yìnkùlé lọ."""
Oríṣun àwòrán, Abdullahi/facebook
Abdullahi fìdí ọ̀rọ̀ ọ̀hún múlẹ̀ ní ilé ẹgbẹ́ APC l'Abuja wípe ìròyìn ẹlẹ́jẹ̀ ní, kí ẹnikẹ́ni máa ṣe gbàágbọ.
Iyiola Oyedepo: Ọgọrọ ọmọ ẹgbẹ PDP ni yoo dárapọ mọ APC ní Kwara
Oríṣun àwòrán, @akoguniyiola
Oyedepo ni oun ko le ba Saraki sepọ ninu ẹgbẹ PDP
Awọn eekan ẹgbẹ oselu Peoples Democratic Party PDP ni ipinlẹ Kwara ti fi ẹgbẹ silẹ lati darapomo ẹgbẹ oselu All Progressives Congress,APC.
Igbesẹ yi n waye gẹgẹ bi awọn ọmọ ẹgbẹ APC naa se n kọwọrin kuro ninu ẹgbẹ wọn lo si PDP.
Iroyin to tẹwa lọwọ so pe Alaga ẹgbẹ PDP ni ipinlẹ Kwara Ogbẹni  Iyiola Oyedepo wa lara awọn to kọkọ kede pe awọn yoo kuro ninu ẹgbẹ PDP lọ si APC.
Nigba ti o n soro lori eto ori redio kan ni ilu Ilorin, Iyiola ni oun ko le ba Aarẹ ile asofin agba Bukola Saraki sisẹ papọ.
''O tẹmi lọrun kin darapomọ APC ju kin ba Saraki sisẹ. Ni kete ti mo ba ti pari lori eto yi ni mo ma gba ọna Abuja lọ lati kowe fẹgbẹ silẹ''
Oun nikan kọ ni o kuro ninu PDP lọ si APC.
Ni Ọjọru ni awọn ọmọ ẹgbẹ PDP kan se iwọde nilu Ilorin lati fi ẹhonu han pẹ awọn ko si ninu ẹgbẹ mo.
Ọjọgbọn Shuaib Oba Adulraheem to fi igba kan jẹ ọga agba ile ẹko fasiti Ilorin, toun naa si n gbero lati jẹ Gomina ipinle Kwara kuro ninu ẹgbẹ PDP.
Oríṣun àwòrán, Talba Offa Chapter
Awọn to n mu ara ilu Kwara sin lo fe pada si PDP, a ko le bawọn se pọ
Ninu ifọrọwanilẹnuwọ pẹlu ile isẹ BBC, o ni PDP ti 'fori sanpọn ni ipinlẹ Kwara'
Egbẹ naa ti di atan bayi. Imotara ẹni nikan lo ku ninu ẹgbẹ naa loni.
O ni awọn duro sinu ẹgbe naa nitori pẹ awọn amunisin kuro nibẹ la ti lo si APC, sugbọn ni bayi ti wọn ti pada de, ko si sise ko si aise ju pe ki a fi ẹgbẹ silẹ fun wọn.
Loni oloni naa ni agbo pe awọn asofin mẹtalelogun ni ile asofin ipinlẹ Kwara kọwọrin pẹlu olori ile asofin kuro ninu APC lọ si PDP.
Eeeyan kan soso ninu awọn ọmọ ẹgbẹ ni ko kuro.
Ali Ahmad to jẹ olori ile so ni oju opo Twitter re pẹ ni ọdun 2014 ti oun fi PDP silẹ lo si APC, nise ni inu oun bajẹ sugbọn loni ti oun pada,ayo oun kun.
Aarẹ Buhari n lọ sinmi ni London fun ọjọ mẹwa
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ààrẹ Muhammadu Buhari ti sọ wí pé ní àìsí nílé òun, igbákejì rẹ̀ ni yó máa delé dè é.
Agbẹnusọ aarẹ ti sọ ọ́ lójú òpó Twitter pé igbakeji aarẹ, ọ̀jọ̀gbọ́n Yẹmi Oṣinbajo ni yóò máa sisẹ́ ààrẹ fún àsìkò tí ààrẹ fi lọ sinmi ni Ilẹ Gẹẹsi.
Aarẹ orilẹede Naijiria, Muhammadu Buhari lo ti lọ si Ilẹ Gẹẹsi ni London lati lọ lo isinmi ọlọjọ mẹwaa, eleyi ti yoo bẹrẹ ni Ọjọ Kẹta, Osu Kẹjọ ti a wa yii.
Agbẹnusọ aarẹ Muhammadu Buhari, Garba Shehu to fi eyi lede ni ori ẹrọ ikansiraẹni Twitter rẹ, sọ wi pe ọjọ mẹwa ni Buhari yoo lo lati lọ se ayẹwo ara rẹ.
Shehu ni aarẹ Buhari ni asẹ ati ẹtọ ni abẹ ofin ilẹ Naijiria ti ọdun 1999, labẹ ẹka 145 (1), lati lọ fun isinmi ati ayẹwo ara rẹ, atiwipe awọn ti fi iwe ransẹ si Aarẹ Ile Igbimọ Asofin Agba, Agbẹnusọ Ile ati Ile Asojusofin.
Agbẹnusọ aarẹ ti sọ ọ́ lójú òpó Twitter pé igbakeji aarẹ, ọ̀jọ̀gbọ́n Yẹmi Oṣinbajo ni yóò máa sisẹ́ ààrẹ fún àsìkò tí ààrẹ fi lọ sinmi ni Ilẹ Gẹẹsi.
Olóṣelú máa ń wá ẹgbẹ́ ti wọn lè lò láti mu ìpinu wọn ṣẹ
Ti a ko ba gbagbe, Osu Kẹsan, ọdun to kọja ni Aarẹ Buhari lọ irinajo si ilẹ Gẹẹsi lati lọ se ayẹwo ara rẹ.
FEC: ìjọba buwọlu pàsípàrọ̀ ẹlẹ́wọn láti China
Oríṣun àwòrán, Government of Nig/twitter
gbìmọ̀ aláṣẹ nínú ìpàdé kan náà tí búwọlu ìgbésẹ̀ amúṣẹ́ṣe lóri dídẹ́kun kíkówó ìlú lọ sí ilẹ̀ òkèrè
Ìgbìmọ̀ aláṣẹ ìjọba ti fàṣẹ sí ìpààrọ̀ àwọn ẹlẹ́wọn pẹ̀lú ìjọba China láti dá awọn ẹlẹ́wọn pade lati wá parí ẹ̀wọ̀n wọn ní Nàìjíríà.
Irú ẹ̀dá wo ni Bukọla Saraki jẹ́ ?
Irú ẹ̀dá wo ni Fẹla Jẹ́?
Olóṣelú máa ń wá ẹgbẹ́ ti wọn lè lò láti mu ìpinu wọn ṣẹ
Awọn Obinrin Dahomey:  Awọn obinrin ilẹ Afirika ti wọn yii itan pada re e
Mínísítà fún ìdájọ́, Abubakar Malami ló ṣíṣọ lójú ọ̀rọ̀ ọ̀hún léyìn ìpàdé ọlọ́sọ̀ọ̀sẹ̀ ìgbìmọ̀ àláṣẹ èyí ti ààrẹ Muhammadu Buhari nílùú Abuja.
Ó sàlàyé pé lára àwọn ọmọ Nàìjíríà tọ́rọ̀ náà kan níbàyìí ní àwọn ti wọn wà ní ọgbà ẹwọn Macau, ẹkun ìwọ̀orun kan ní orílẹ̀èdè China.
Mínísítà sọ pé kí ètò náà tó fìdí múlẹ̀, ó nílò láti gba ìfọwọ́sí láti ọ̀dọ̀ ìjọba China bí ìjọba náà ṣe tún ń pinu irú àdéhùn bẹ́ẹ̀ pẹ̀lú àwọn orílẹ̀èdè mìíran.
Ìgbìmọ̀ aláṣẹ nínú ìpàdé kan náà, tí búwọlu ìgbésẹ̀ amúṣẹ́ṣe lóri dídẹ́kun kíkówó ìlú lọ sí ilẹ̀ òkèrè àti gbígbogun ti lílu owó ìlú ní póńpó.
Bukola Saraki: Kí ló dé tí Adams Oshiomole n fẹ́ kó gbé adé APC sílẹ̀?
Oríṣun àwòrán, APC/twitter
Alága ẹgbẹ́ APC, Adams Oshiomole ní kí Saraki ṣe ohun tó yẹ́ nípa fífí ipò sílẹ
"Ko yẹ ki o gbe ade ti wọn fi de ọ lori ninu ile kan lọ sí ilé ẹlomiran.''
Alaga apapọ f'ẹgbẹ oṣelu All Progressives Congress, APC, Adams Oshiomole lo sọ bẹẹ lati fi sapejuwe kikuro ti Aarẹ ile aṣofin agba, Bukọla Saraki kuro ninu ẹgbẹ oṣelu APC lọ si Peoples Democratic Party, PDP.
Oríṣun àwòrán, @NGRSenate
Osu kẹrin lẹyin ti Aarẹ Buhari gbe aba eto isuna ọdun 2018 kalẹ, ko tii lojuutu niwaju awọn asofin apapọ
O sọ ọ̀rọ̀ naa lẹyin ti Aarẹ Muhammadu Buhari ṣe ipade l'Ọ́jọ́rú, pẹlu awọn gomina to kù sinu ẹgbẹ oṣelu APC.
Oshiomole ni ohun to kan fun Saraki lẹyin to fi ẹgbẹ awọn silẹ ni lati fi ipo rẹ silẹ gẹgẹ bi Aarẹ ile aṣofin.
Irú ẹ̀dá wo ni Bukọla Saraki jẹ́ ?
Ọjọ Iṣẹgun, ọjọ kọkanlelọgbọn, oṣu Keje, ni Saraki kede pe oun ti kuro ni APC lọ si ẹgbẹ oṣelu alatako, PDP.
Oríṣun àwòrán, Presidency
Lẹyin to ṣe bẹ ẹ ni awọn eniyan nlanla lagbo oṣelu naa fi ẹgbẹ naa silẹ - Lara wọn ni akọwe ikede fun APC, Bolaji Abdullahi, ati gomina ipinlẹ Sokoto, Aminu Tambuwal, ati awọn mi i.
Oshiomole ni kikuro ti awọn eniyan naa kuro ninu ẹgbẹ awọn ko ba awọn ni ojiji, nitori pe awọn ti n foju sọna fun un.
Amọ o ni, o yẹ ki Saraki ṣe ohun to yẹ, nipa fi fi ipo rẹ silẹ gẹgẹ bi aarẹ ile aṣofin.
Oshiomole nkan ko le fi bẹ ẹ r'ọrun fun APC nitori awọn to fi ẹgbẹ silẹ, o ni sṣugbọn, ẹni kan, ibo kan ni yoo bori lọjọ idibo.
Zimbabwe Election: Ẹgbẹ́ alátakò kọ èsì ìdìbò
Ìdá ààdọta o lé ní Mnangagwa fí tayo alátakò rẹ̀ níbí ìdìbo náà
Ààrẹ Emmerson Mnangagwa ti jáwé olúborí níbí ìdìbò sípò ààrẹ orílẹ̀èdè Zimbabwe.
Àjọ elétò ìdìbò Zimbabwe sàlàyé pé nínú àwọn ẹkùn mẹ́wàá, Mnangagwa jáwé olúborí nínú ìdá ààdọ́ta ó lé tí adarí ẹgbẹ́ alátakò rẹ̀ Nelson Chamisa  sí ní ìdá ogójì àti díẹ̀.
Olùdíje gbé APC lọ sílé ẹjọ́ nítorí èsì ìbò
Ìbaàrún pe ọdún kan
Irú ẹ̀dá wo ni Fẹla Jẹ́?
Mnangagwa tó wá láti inú ẹgbẹ́ òṣèluú Zanu-PF, gbàjọba gẹ́gẹ́ bí ààrẹ nínú oṣù kọkànlá ọdún tó kọjá lọ́wọ́ Robert Mugabe.
Nínú ọ̀rọ̀ Mnangagwa tó fí ṣọwọ lórí àtẹ̀jíṣẹ́ twitter rẹ̀, o ní ìjáwé olúborí òhun jẹ́ kí òhun tí ní ìrẹ̀lẹ̀ síì
Alága ẹgbẹ́ òṣèlú MDC sọ pé kò sí àrídájú ìbò ti wọn kà nítorí ọlọ́pàá ló wá gbé ọ̀pọ̀ ọmọ ẹgbẹ́ alátakò kúro níbi tí àwọn elétò ìdìbò tí ń ka ìbò
léyìn èyí ní àwọn ọmọ ẹgbẹ́ alátakò gba ìgboro Harare lati fẹ̀honú han pé màgòmágò wáyé nínú ìdìbò náà, tí ènìyàn mẹ́fà sì ti gbé ẹ̀mi mì.
Ìdìbò yíì ní orílẹ̀-èdè Zimbabwe lò láti mú àláfìà padà bọ̀ sípò ní orílẹ̀-èdè náà
Ìdìbò yìí ní àkọ́kọ́ lẹ́yìntí wọn yọ Mugabe ẹni ọmọ ọdún márùn-ùn lé láàdọ́rùn kúrò nípò ààrẹ lọ́dún tó kọjá.
Oríṣun àwòrán, Reuters
Ìdìbò yìí ní alákọ̀ọ́kọ́ láti ìgbà tí Ààrẹ tẹ́lẹ̀rí, Robert Mugabe ti kúrò lórí oyè ní ọdún tó kójá.
Ijọba ilẹ Zimbabwe ti ti awọn ilẹ itaja gbogbo to wa ni olu-ilu orilẹede Zimbabwe, Harare lẹyin ti ija bẹ ẹ lẹ nigba ti awọn eniyan n reti esi idibo si ipo aarẹ lorilẹede naa.
Awọn oloogun pẹlu ibọn wọn ni wọn n kaakiri agbeegbe naa pẹlu ikilọ pe ki olukaluku so ewe agbejẹ mọ ọwọ titi esi idibo yoo fi jade.
Eniyan mẹta ni o padanu ẹmi wọn ni Ọjọru lasiko ti ija bẹẹẹ laarin awọn ẹsọ alaabo ati awọn alatilẹyin fun adari ẹgbẹ alatako, Nelson Chamisa.
Irú ẹ̀dá wo ni Fẹla Jẹ́?
Awọn ẹgbẹ alatako sọ wi pe wọn se magomago ninu idibo to waye ni Ọjọ Aje lati ri wi pe Aarẹ Emmerson Mnangagwa wọle gẹgẹbi aarẹ ti wọn di ibo yan.
Idibo ti wọn reti esi rẹ yii ni alakọkọ lati igba ti Aarẹ tẹlẹri, Robert Mugabe ti kuro lori oye ni ọdun to kọja.
Zimbabwe Election: Ẹgbẹ́ alátakò kọ èsì ìdìbò
Ìdá ààdọta o lé ní Mnangagwa fí tayo alátakò rẹ̀ níbí ìdìbo náà
Ààrẹ Emmerson Mnangagwa ti jáwé olúborí níbí ìdìbò sípò ààrẹ orílẹ̀èdè Zimbabwe.
Àjọ elétò ìdìbò Zimbabwe sàlàyé pé nínú àwọn ẹkùn mẹ́wàá, Mnangagwa jáwé olúborí nínú ìdá ààdọ́ta ó lé tí adarí ẹgbẹ́ alátakò rẹ̀ Nelson Chamisa  sí ní ìdá ogójì àti díẹ̀.
Olùdíje gbé APC lọ sílé ẹjọ́ nítorí èsì ìbò
Ìbaàrún pe ọdún kan
Irú ẹ̀dá wo ni Fẹla Jẹ́?
Mnangagwa tó wá láti inú ẹgbẹ́ òṣèluú Zanu-PF, gbàjọba gẹ́gẹ́ bí ààrẹ nínú oṣù kọkànlá ọdún tó kọjá lọ́wọ́ Robert Mugabe.
Nínú ọ̀rọ̀ Mnangagwa tó fí ṣọwọ lórí àtẹ̀jíṣẹ́ twitter rẹ̀, o ní ìjáwé olúborí òhun jẹ́ kí òhun tí ní ìrẹ̀lẹ̀ síì
Alága ẹgbẹ́ òṣèlú MDC sọ pé kò sí àrídájú ìbò ti wọn kà nítorí ọlọ́pàá ló wá gbé ọ̀pọ̀ ọmọ ẹgbẹ́ alátakò kúro níbi tí àwọn elétò ìdìbò tí ń ka ìbò
léyìn èyí ní àwọn ọmọ ẹgbẹ́ alátakò gba ìgboro Harare lati fẹ̀honú han pé màgòmágò wáyé nínú ìdìbò náà, tí ènìyàn mẹ́fà sì ti gbé ẹ̀mi mì.
Ìdìbò yíì ní orílẹ̀-èdè Zimbabwe lò láti mú àláfìà padà bọ̀ sípò ní orílẹ̀-èdè náà
Ìdìbò yìí ní àkọ́kọ́ lẹ́yìntí wọn yọ Mugabe ẹni ọmọ ọdún márùn-ùn lé láàdọ́rùn kúrò nípò ààrẹ lọ́dún tó kọjá.
Àwọn òṣìṣẹ́ ilé ẹ̀kọ́ olùkọ́ni gùnlé ìyanṣẹ́lódì l'Ọ́ṣun
Oríṣun àwòrán, Bosefunmi
Ijọba ipinlẹ Ọṣun ni aisi owo lo ṣokunfa aile san owo oṣu awọn loṣiṣẹ lẹkunrẹrẹ
Gbogbo iṣẹ ikẹkọ nileẹkọṣẹ olukọni ipinlẹ Ọṣun to wa nilu Ileṣa ti wa si idaduro pẹlu bi awọn olukọni nileẹkọ naa ṣe gunle iyanṣẹlodi.
Ẹgbẹ awọn olukọni ileewe giga kaakiri ipinlẹ Ọṣun, COEASU gunle iyanṣẹlodi naa lẹyin ti wọn ni ijọba ipinlẹ Ọṣun ti kuna lati mu gbogbo awọn adehun ti ijọba ati awọn olukọ naa ṣe ṣaaju.
Awọn olukọ naa gbe patako alakọle kaakiri ileewe naa ni ilu ileṣa tawọn ti orin ẹhonu lẹnu wọn.
Ninu ọrọ rẹ, alaga ẹgbẹ awọn olukọ nileẹkọṣẹ olukọni naa, Oluṣẹgun Lana ṣalaye pe ijọba ipinlẹ Ọṣun kuna didẹkun sisan aabọ owo oṣu fun wọn gẹgẹ bi o ṣe ṣeleri.
Oríṣun àwòrán, Bosefunmi
Awọn olukọ naa ni ijọba ipinlẹ Ọṣun kuna didẹkun sisan aabọ owo oṣu fun wọn gẹgẹ bi o ṣe ṣeleri
O ni aisan ẹkunrẹrẹ owo oṣu wọn fawọn olukọ naa ti fa ọpọlọpọ inira fun awọn ati idile wọn.
Bakan naa, ni wọn tun n bere fun sisan awọn owo ti wọn yọ ninu owo oṣu wọn ṣaaju fun oṣu mẹrindinlogoji ati dida awọn oṣiṣẹ mejilogoji ti wọn ni wọn da duro lẹnu iṣẹ ni ọdun 2016.
Oríṣun àwòrán, Bosefunmi
Awọn olukọ naa tun n bere fun sisan awọn owo ti wọn yọ ninu owo oṣu wọn ṣaaju fun oṣu mẹrindinlogoji.
Amọṣa o, ninu ọrọ rẹ, ijọba ipinlẹ Ọṣun ni aisi owo lo ṣokunfa aile san owo oṣu wọn lẹkunrẹrẹ.
Komiṣọna feto iroyin, Adelani Baderinwa ni ijọba ipinlẹ Ọṣun ko fi ọrọ awọn oṣiṣẹ jafara yi o si san an ni kete ti nnkan ba ti yipada si rere.
Babatunde Fashola: Iná mọ̀nàmọ́ná ní Nàìjíríà ti wọ 7000 Megawaati
Oríṣun àwòrán, @FMPWH
Babatunde Fashola
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ọ̀kan lára ìpènijà tó ń kójú orílẹ̀èdè Naijiria ní ìpèsè iná mọ̀nàmọ́ná tó gbòrò fún àwọ̀n ọmọ Naijiria.
Minisita fun ọrọ ipese ina, isẹ ode ati ile gbigbe, Babatunde Fashola ni ipese ina mọnamọna ti wọ ẹgbẹrun meje mẹgawaati lorilẹede Naijiria.
Fashola sọ eyi nigba to n se ipade pẹlu awọn adari ẹka to wa ni abẹ ile isẹ to n risi ipese ina, isẹ ati ile gbigbe ni ilu Calabar.
Ninu ọrọ rẹ, O ni ipese ina mọnamọna  ni Naijiria ti gboro si bayii, amọ ise pupọ si wa lati se.
Ọ̀ṣọ́ Aṣọ Òkè ti kọjá lílo ìlẹ̀kẹ̀ níkan
Ọkan lara ipenija to n koju orilẹede Naijiria ni ipese ina mọnamọna to gboro fun awọn ọmọ Naijiria.
Ladọja: PDP dalẹ́ àdéhùn ni mo fi gbé ẹrù mi kúrò níbẹ̀
Oríṣun àwòrán, facebook/Rashidi Adewolu Ladoja
Ẹsun ti o fi kan ẹgbẹ oṣelu PDP ni pe ẹgbẹ oṣelu naa dalẹ adehun to wa laarin oun ti wọn
Gomina ipinlẹ Ọyọ, to tun figbakan ri jẹ aṣiwaju ẹgbẹ oṣelu Accord, Sẹnetọ Raṣidi ladọja ti kuro lẹgbẹ oṣelu PDP lọ si ẹgbẹ oṣelu ADC.
Ẹsun ti o fi kan ẹgbẹ oṣelu PDP ni pe ẹgbẹ oṣelu naa dalẹ adehun to wa laarin oun ti wọn paapaa lori igbimọ alakoso ẹgbẹ oṣelu naa ti wọn gba gẹgẹ bii  eyi gan an to jẹ ootọ ni ipinlẹ Ọyọ.
Raṣidi Ladọja ṣalaye ọrọ yii lasiko to fi n fikunluku pẹlu awọn ololufẹ rẹ kaakiri ijọba ibilẹ mẹtalelọgbọn to wa nipinlẹ Ọyọ ni ile rẹ to wa lagbegbe Bodija nilu Ibadan.
Ladọja ni gbogbo awọn to lorukọ ninu igbimọ adari ẹgbẹẹ oṣelu PDP titi kan alaga apapọ ẹgbẹ oṣelu naa loun ba sọrọ ti wọn si fi da ohun loju pe igbimọ iṣakoso ẹgbẹ oṣelu naa eleyi ti Lyel Imoke fi lọlẹ ni wọn yoo gba wọle gẹgẹ bii adari ẹgbẹ oṣelu PDP nipinlẹ Ọyọ, ki wọn to tun gbẹyin lọ tẹwọ gba igbimọ ti Onimọẹrọ Ṣeyi Makinde gbe kalẹ.
O ni ẹgbẹ oṣelu ADC ti oun wa bayii ti gbe akanṣe iṣẹ nla le oun lọwọ lati rii daju pe awọn gomina kan darapọ mọ ẹgbẹ oṣelu naa kaakiri tibu toro orilẹede Naijiria, eleyi to ni yoo bẹrẹ pẹlu agbekalẹ idibo abẹnu ẹgbẹ oṣelu naa lati wọọdu titi de ẹka ti ipinlẹ laipẹ.
2019 Election: Ilé Asófin késí INEC láti fi N143bn sọwọ́ sí wọn lẹ́ẹ̀kan si
Oríṣun àwòrán, Senate Nigeria
Ọjọ karundinlọgbọn Oṣu Kẹsan ni awọn aṣofin agba yoo pada si ẹnu iṣẹ
Ariyanjiyan su yọ laarin ajọ eleto idibo lorilẹede Naijiria ati Igbimo to n bojuto ọrọ eto idibo ni Ile Igbimo Asofin.
Igbimọ naa faake kọri wi pe awọn ko ni bu owo lu eto isuna toto biliọnu mọkandinlaadọwa ti wọn gbe wa si waju wọn, ayafi ti wọn ba gbe iye eyi ti Aarẹ Muhammadu Buhari koko gbe ka iwaju wọn ni alakọkọ.
Ile Igbimọ Asofin Agba ti kesi ajọ INEC lati pada gbe aba iṣuna oni billiọnu mẹtalelogoje (N143bn ) to wọn nilo fun eto idibo gbogboogbo ni ọdun 2019 wa siwaju oun.
Igbimọ apapọ ti Ile Igbimọ Asofin lori ajọ INEC ti Sẹnetọ Suleiman Nazif jẹ adari fun, lo paṣẹ bẹ lẹyin ipade to ṣe l'ọjọ Aje ọ̀ṣẹ̀ yii, ti wọn si fi ikede rẹ sita lori ẹrọ ikansiraẹni Twitter.
Igbimọ naa f'ẹnuko pe Inec gbọdọ tun àbá owo isuna ti Aarẹ Muhammadu Buhari fi sọ wọ si wọn pada wa ni ẹẹkan si, ki awọn le wo o finifini.
Wọ́n rò pé mo ya wèrè ni Saudi lẹ́yìn ikú ọkọ mi
Ọjọ keje, Oṣu Kẹjọ, 2018, lo yẹ ki awọn aṣofin naa kọkọ ṣe ipade pajawiri ti Aarẹ ile aṣofin agba, Bukọla Saraki pe, lori owo eto iṣuna ajọ INEC ati 'ilọsiwaju Naijiria'.
Sugbọn, ipade naa ko le waye nitori 'wahala kan' to waye nile aṣofin naa ni ọjọ ipade.
Oríṣun àwòrán, @NGRSenate
Lẹ́yìn wàhálà tó wáyé nílé aṣòfin ni Bukọla Saraki ṣe ìpàdé pẹ̀lú àwọn oníròyìn àgbáye
Eyi ri bẹẹ nitori wahala to waye nile aṣofin naa ni owurọ kutu-kutu ọjọ ipade, pẹlu bi awọn aṣofin kan ti ko ṣe ti Aarẹ Muhammadu Buhari ṣe fẹsun kan pe awọn oṣiṣẹ eleto aabo DSS di ọna mọ wọn lati wọn ile aṣofin.
Oríṣun àwòrán, kwange
Asòfin yóò ṣe ìpàdé pàjáwìrì l'Abuja
Eyi si ti mu ki awọn onimọ nipa ohun to n lọ ni Naijiria, sọ pe eyi le ṣe akoba fun eto idibo gbogboogbo naa.
Iléèṣẹ́ Ààrẹ bẹ àwọn aṣòfin láti bẹ̀rẹ̀ ìjókò padà
Ṣaaju ki Saraki to pe ipade pajawiri naa ni ileeṣẹ aarẹ bẹ àwọn aṣofin pe ki wọ́n bẹrẹ ijoko ilé ìgbìmọ̀ padà laipẹ nitori ọ̀rọ̀ Nàìjíríà.
Sẹnetọ Ita Enang, to jẹ olubadamọran fun aarẹ Buhari lori ọrọ ile aṣofin apapọ, lo fi ẹ̀bẹ̀ naa sita.
Oriṣii nkan ni àwọn eeyan gba pe o n jẹ kile iṣẹ aarẹ maa parọwa fun àwọn ọmọ ilé igbimọ lasiko yii bíi.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Adelé Ààrẹ, Yẹmi Ọṣinbajo gba ìṣẹ́ lọ́wọ́ ọ̀gá àjọ DSS, Lawal Daura nítorí wàhálà tó wáyé nílé aṣòfin
Ẹwẹ, ohun kan ti isinmi wọn yii tun ṣeeṣe ko ṣe akoba fun ni eto ọrọ aje orilẹ-ede Naijiria, nitori pe igbesẹ pinpin owo lati ẹka ijọba kan si mi i ko ni ṣeeṣe lai si aṣẹ awọn aṣofin, eyi ti yoo ran awọn ẹka eto ọrọ aje yooku lọwọ.
Adele akọwe ipolongo ẹgbẹ oṣelu APC, Ọgbẹni  Yekini Nabena, ninu ikede kan to fi sita ni irọ patapata ni pe alaga apapọ fun ẹgbẹ APC, Adams Oshiomole lo wa ni idi rogbodiyan to waye naa.
O ni aarin awọn aṣofin naa ni ki wọn o ti wadi bi wahala naa ṣe waye. Ati pe ẹgbẹ APC naa ṣi n woye bi nkan ṣe nlọ nile aṣofin.
Awọn sẹnetọ kan ninu ẹgbẹ oṣelu alatako, PDP, ni gbogbo iṣẹlẹ to waye nile igbimọ aṣofin jẹ ọna lati mu ki awọn ọgbọn sẹnetọ to jẹ ti ẹgbẹ oṣelu APC yọ aarẹ ile asọfin agba.
Ṣugbọn oluranlọwọ fun Aarẹ Muhammadu Buhari lori ọrọ ile aṣofin, Ita Enang, sọ pe 'Aarẹ Buhari ko mọ nkankan nipa iṣẹlẹ naa.'
Díẹ̀ lára àwọn nkan tí àwọn aṣòfin fi síta lójú òpó Twitter nìyíì:
Ọkan nínú àwọn sẹ́natọ Rafiu Ibrahim ní 'wọn dí òun l'ọ́nà láti wọ ilé ìgbìmọ̀.'
Àwọn míran ní ìdìtẹ̀ láti yọ ààrẹ ilé ìgbìmọ̀ Bukola Saraki àti Ike Ìkweremadu ìgbákejì rẹ̀ nípò.
Ọjọ kẹrinlelogun, oṣu Keje ni ile aṣofin agba gunle isinmi ẹnu iṣẹ, lẹyin ti awọn aṣofin kan fi ẹgbẹ oṣelu Peoples Democratic Party, PDP, silẹ lati darapọ mọ APC.
Ọjọ karundinlọgbọn, oṣu kẹsan an, ni awọn aṣofin agba pinnu lati pada si ẹnu iṣẹ.
Ohun tí ojú opó ń rí láwùjọ kò kéré"""
Ọ̀gá Bello: Àìgbọ́n ló ń da àwọn òsèré tíátà tó ń jà lórí ayélujára láàmú
Ọbìnrin tó fẹ́ ṣojú àwọn ẹ̀yà Sheedi
Aisha Buhari, ìyàwó ààrẹ Gambia Fatoumatta Bah-Barrow ṣe ọjọ ìbí níléèwòsàn l'Ábújá
Oríṣun àwòrán, @Laurestar
Ni ọjọ karun oṣu kẹjọ ọdun 1974 ni wọn bi Fatoumatta Bah-Barrow ni ilu Banjul
Iyawo aarẹ orilẹede Naijiria, Aisha Buhari ti darapọ mọ iyawo aarẹ orilẹede Gambia, Fatoumatta Bah-Barrow lasiko ayẹyẹ ọjọ ibi ọdun kẹrinlelogoji rẹ nilu Abuja.
Gẹgẹ bii iroyin kan lori ikanni twitter oluranlọwọ aarẹ lori ọrọ iroyin ayelujara, Lauretta Onoche, Aisha buhari ati Fatoumatta Bah-Barrow ṣe pọpọsinsin ọjọ ibi naa pẹlu abẹwo si ileewosan Maitama nilu Abuja.
Oríṣun àwòrán, @Laurestar
Nileewosan naa ni iyawo aarẹ orilẹede Gambia, Fatoumatta Bah-Barrow ti ba awsn obinrin ati ọmọde dawọọ idunnu
Nileewosan naa ni iyawo aarẹ orilẹede Gambia, Fatoumatta Bah-Barrow ti ba awọn obinrin ati ọmọde dawọọ idunnu ti wọn si tun ge akara oyinbo rẹ ni ile aarẹ, Aso Rock nilu Abuja kan naa.
Ni ọjọ karun oṣu kẹjọ ọdun 1974 ni wọn bi Fatoumatta Bah-Barrow ni ilu Banjul tii ṣe olu ilu orilẹede Gambia.
Oríṣun àwòrán, @Laurestar
Aisha buhari ati Fatoumatta Bah-Barrow ṣe pọpọsinsin ọjọ ibi naa pẹlu abẹwo si ileewosan Maitama nilu Abuja
Ni oju opo twitter tirẹ, iyawo aarẹ orilẹede Naijiria, Aisha Buhari ni idi ti Fatoumatta Bah-Barrow fi sami ayajọ ibi rẹ lorilẹede Naijiria ko se lori bi ọjọ ibi rẹ ṣe ṣe kongẹ abẹwo iyawo aarẹ  Gambia naa si Naijiria lati bẹ awọn akẹkọ orilẹede naa marun kan wo nileewe girama aladani kan lorilẹede Naijiria.
Fayose: Dídarapọ̀ mọ́ APC dàbí bíbá adigunjàlè ṣ'ọ̀rẹ́ ni
Oríṣun àwòrán, @GovAyoFayose
Fayose jẹ alatako ẹgbẹ oṣelu All Progressives Congress
'Irọ́ ni pé èmi àti Oluṣọla Ẹlẹka wa Tinubu lọ'
Gomina ipinlẹ Ekiti, Ayodele Fayose ti ni ko si ootọ kankan ninu iroyin to gba igboro pe, oun ni nkan 'ṣe pẹlu Asiwaju ẹgbẹ oṣelu All Progressives Congress, APC, Asiwaju Bola Tinubu.
Saaju ni aworan kan gba ori ẹrọ ayelujara, pe Gomina Fayose ati igbakeji rẹ, to tun jẹ oludije sipo gomina ninu eto idibo to waye ninu oṣu Keje, 2018 ni ipinlẹ Ekiti, Ọjọgbọn Oluṣọla Ẹlẹka, ṣe abẹwo si ile Bola Tinubu to wa ni ilu Eko.
Fayose ni fifi iru ẹsun bẹẹ kan oun ko yatọ si ki oun maa ba awọn adigunjale ṣe ọrẹ.
Fayose fi ikede naa sita l'oju opo ikansiraẹni Twitter rẹ pe...
O ni 'mo si wa ninu ẹgbẹ PDP, gbogbo awọn to ba n so mi pọ mọ APC le tẹsiwaju lati maa ṣe ajọyọ titan ara wọn jẹ ninu oṣelu.
Ati pe 'bo ku ọkunrin kan ṣoṣo ti yoo tako ijọba apaṣẹ wa a Buhari ati ẹgbẹ oṣelu APC, Ayọdele Fayoṣe ni yoo jẹ ọkunrin naa'.
NYSC: Àwọn àgùnbánirọ̀ gbọ́dọ̀ gba àṣẹ kí wọ́n tó ṣètò ìgbafẹ́
Oríṣun àwòrán, Nysc/twitter
Ibi ìgbáfẹ́ já sí ibi ikú fún àwọn agànbánirọ̀ mẹ́san an
Ọga agba ajọ agunbanirọ, Ọgagun Suleiman Kazaure kilọ fawọn agunbanirọ lati ṣọra fun irede oru.
O sọrọ yii lẹyin ọkan-o-jọkan iṣẹlẹ aburu lori awọn agunbanirọ lẹnu ọjọ mẹta yii
Kazaure ni ko saye wẹjẹ-wẹmu tabi igbafẹ mọ fawọn agunbanirọ afeyi ti awon alaṣẹ ajọ naa ba fọwọsi.
O ni ibanujẹ lo jẹ fun ajọ naa pe awọn agunbanirọ mẹsan tun ku nipinlẹ Taraba.
Bi ẹ ba fẹ ṣeto wẹjẹ-wẹmu tabi igbafẹ kankan, ẹ gbọdọ gba aṣẹ lọwọ awọn oṣiṣẹ ajọ agunbanirọ, yala lẹkun ijọba ibilẹ tabi oludari nipinlẹ; aṣẹ mi niyẹn.
Laipẹ yii ni awọn agunbanirọ mẹsan padanu iku aitọjọ nigba ti ẹkun omi gbe wọn lọ lasiko ti wọn lọ wẹ lodo Moyo Salva fun igbafẹ ní ìjọ̀ba ìbílẹ̀ Gashaka ìpínlẹ̀ Taraba.
Agùnbánirọ̀ mẹ́sàn-án ló ti ṣe pẹ̀kí ọlọ́jọ́ wọn lẹ́yìn tí wọn lo si odo Moyo Salva fún ìgbáfẹ́ ní ìjọ̀ba ìbílẹ̀ Gashaka ìpínlẹ̀ Taraba.
Fadele: Dán an wò, lóbí ìyá ọ̀kẹ́rẹ́ ni a fi ọ̀rọ̀ ọ̀kadà náà ṣe
Gẹ́gẹ́ bí agbẹnusọ ọlọ́pàá ní ìpílẹ̀ Taraba, David Missal, ṣe sọ, ọ̀pọ̀ àwọn agùnbánirọ̀ ló lọ́ fún ìrìnàjò ìgbáfẹ́ ọ̀hún sí odò náà ti omi ọhun si déédé ru kójá bèbè rẹ̀ tí ó si gbé àwọn agùnbánirọ̀ náá lọ
O ní ènìyàn méjìlélógún ló lọ sùgbọ́n méje nínú àwọn tí omi náà gbé lọ ni ó kú ti àwọn méjì sì di àwátì, sùgbọn ìwádìí sì ń lọ lọ́wọ́ lati wa wọn. Nínú ọ̀rọ̀ Florence Yaakugh, tó jẹ́ alákoso àwọn agùnbánirọ̀ ní ìpínlẹ̀ náà jẹ́rìsí ìṣẹ̀lẹ̀ náà, o ní ìwádìí ṣì ń lọ lọ́wọ́ pẹ̀lú àwọn àgbófinro àti àwọn òmùwẹ̀ ìlú nàá.
Odò Mayo Selbe ninu aworan yii lo gbe awọn agunbanirọ lọ.
Yaakugh sàlàyé pé kò sí ẹ̀ni tó tii mọ àwọn agùbánirọ̀ tí ìṣẹ̀lẹ̀ náà ṣẹ̀lẹ̀ sí tan tí àsìkò yìí sí jẹ́ àsìkò ọ̀fọ̀ fún ilé iṣẹ́ agùnbánirọ̀ ní ìpínlẹ̀ Taraba.
Ọmọ Yoruba ni mi
Ṣé ẹ rántí orin - Má ṣe jẹ́jẹ́ ma wà mi lọ?
Wọn dóòlà ẹ̀mí ọ̀pọ̀ èrò níbi ìṣẹlẹ̀ ilẹ̀ rírì erékúṣù Lombok
Oríṣun àwòrán, AFP
Àwọn olutọju alaisan n gbe alaisan kuro nile iwosan Mataram
Irinajo afẹ́ to di irinajo to n gbẹ̀mí àwọn ènìyàn ni Indonesia.
Odiwọn iye awọn to ti ku nibi iṣẹlẹ ilẹ riri nla to ṣẹlẹ ni Lombok ti di mejidinlọgọrun bayii.
Awọn ti wọn farapa ti le ni igba.
Awọn agbegbe to bajẹ julọ ni bii abule Lading-Lading, ilu Mataram, ati àwọn agbegbe miran ni ariwa Lombok.
Bayii wọn ti ko ọpọlọpọ àwọn èrò lọ kuro ni Gili nibi ti wọn ṣi ti n ko àwọn arinrinajo kuro pẹlu ọkọ oju omi.
Oríṣun àwòrán, @lauramilne
Àwọn arinrinajo to wa ni Gili Trawangan
Ọpọ àwọn to wa ni erekuṣu naa ni ebi n pa wọn nitori ko si omi to ṣee mu ati ohun jijẹ ni eyi ti awọn eniyan ti n fẹ huwa ipá.
Erekuṣu Lambok ni Indonesia
Ọdunlade Adekọla gbóṣùbà fáwọn ọkùnrin tó ń ran ìyàwó wọn lọ́wọ́
Fẹla Durotoye: ọ̀rọ̀ ìṣọ̀kan Nàìjíríà tó àpérò ọmọ eríwo
Ṣé ẹ rántí orin - Má ṣe jẹ́jẹ́ ma wà mi lọ?
Iléèṣẹ́ ọlọ́pàá: ìwádìí bẹ́rẹ́ lórí ikú ọdaran tó tojú orun dójú ikú'
Oríṣun àwòrán, @sahara
Àsùnjí o fún olóorun ajínigbé oní Tramadol
Láti ojú oorun de ojú ikú, ṣe àwọn ọlọpaa ṣe ohun to yẹ?
Ọrọ Yoruba kan lo ni ‘asun fọn-fọn n tifọn, asun-maparada ni ti igi aja’, bẹẹ́ ni ọrọ ri fun ọkunrin ajinigbe naa, ti ẹnikẹni ko tii mọ orukọ rẹ.
Ṣugbọn, bawo ni iṣẹlẹ naa gan an ṣe waye? Agbẹnusọ fun ileeṣẹ ọlọpaa ti Ipinlẹ Ondo, Ọgbẹni Femi Joseph ṣalaye fun BBC Yoruba pe:
Ileesẹ ọlọpa fi ẹsun idigunjale ati ijinigbe kan an. Ati pe wọn sakiyesi pe oogun oloro Tramadol ni o lo nigba ti wọn mu nitori wọn ba saṣẹẹti oogun naa ni apo rẹ.
Ìgbẹ́sẹ̀ àwọn ọlọpaa kí o tó kú
Igba ti wọn si ṣakiyesi pe ko le gbe apa, ko le gbe ẹsẹ, lasiko ti wọn safihan rẹ fun awọn oniroyin ni wọn gbe e lọ sileewosan.
O ni ọjọ ti awọn mu naa ni wọn gbe e lọ sile ìwosan, to si wa nibẹ fun ọjọ mẹsan.
Ati pe, awọn dokita n fa omi si i lara ni gbogbo igba to fi wa nileewosan.
Sugbọn o pada ku ni ọjọ Aje, ọjọ kẹtala, oṣu Kẹjọ, lẹyin ọjọ mẹsan.
Iléèṣẹ́ ọlọ́pàá: ìwádìí bẹ́rẹ́ lórí ikú ọdaran tó tojú orun dójú ikú'
Joseph ni 'ikọ ẹlẹni mẹta naa wọ ile itaja oogun kan ni ìlú Ọ̀wọ̀, nipinlẹ Ondo, pẹlu ibọn lọwọ wọn, sugbọn ti onile itaja oogun naa ti wọn fẹ ẹ jigbe tete pariwo ẹ gbami, to si gba ẹnu ọna mi i sa jade.'
Àṣìlò òògùn Tramadol ati àwọn mi i bi codeine le ṣe àkóbá fún ara
Awọn akẹgbẹ rẹ meji ti wọn jọ lọ fun iṣẹ buruka naa ja ọkada ẹnikan to wa ra oogun nile itaja oogun naa, ti wọn si gbe e salọ.
Nibi ti oun ti n gbiyanju lati gun ọkada ti wọn ti wọn gbe wa, ni awọn ara adugbo sare le e mu. Bi o se n gbiyanju lati wa ọkada naa kuro nibẹ, ni ko le lọ mọ, to si subu lati ori ọkada.
Ati igba naa ni oogun Tramadol ti n se isẹ ki sẹ lara rẹ.
O ni ayẹwo awọn dokita ni ileewosan General Hospital to wa ni ilu Ọwọ ti wọn gbe e lọ jẹ ki awọn mọ pe oogun naa ti se isẹ buruku lara rẹ.'
Joseph ni oku rẹ si wa nileewosan, ti ileeṣẹ ọlọpaa si n duro de ayẹwo lati mọ ohun to ṣekupa, ki wọn to yọnda rẹ fun awọn eniyan rẹ.
Sugbọn nigba ti a bii pe ṣe wọn ti mọ awọn eniyan rẹ, Joseph ni wọn ko ti i mọ wọn.
O ni ọ̀rọ̀ ọkunrin naa da bi ọrọ̀ Yoruba kan to sọ pe 'ko si ẹni to fẹ ẹ fi ọbẹ to nu j'ẹsu.'
Awọn mọlẹbi rẹ kankan ko ti i yọju. O ni ẹẹkan ṣoṣo to laju, 'Iṣẹ́ Olúwa' nikan ni ọrọ to sọ lẹyin ti wọn mu. O ni awọn gbọ pe awọn ara ilu rẹ ko sọrọ rẹ daada.
O ni iku ọkunrin naa dun ileesẹ ọlọpa, nitori pe ko ba ran wọn lọwọ lati jẹ ji ọwọ tẹ awọn akẹgbẹ rẹ to salọ.
Kin lo yẹ ko mọ nipa apọju oogun Tramadol ninu ara ?
Onisegun oyinbo kan, Dokita Kunle Obilade, tile iwosan ijọba ipinlẹ Ọyọ salaye fun BBC wi pe ewu n bẹ loko longẹ ni oogun oloro Tramadol ninu agọ ara.
Oríṣun àwòrán, @kojonyed
Èrò àwọn ọmọ Naijiria ṣọ̀tọ̀ọ́tọ̀ lórí ohun tó n wáyé l'ágbo òṣèlú
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Tinubu ni 'ki awọn to n gbimọ ìkà jawọ, nitori pe 'ko ni ṣeeṣe fun alangba lati ba igala ja; mo ki ara mi kú iṣẹ́ ni Eko'
Tinubu: kí ló dé ti Ọbasanjọ kò ṣe fi ìpìlẹ̀ rere lélẹ̀ lásìkò rẹ̀?
Oloye Bola Tinubu to jẹ àgbà egbẹ fun APC ti fun Oloye Oluṣegun Obasanjọ to jẹ aarẹ Naijiria nigba kan ri ni esi lẹta to kọ si Buhari to n tukọ Naijiria.
Tinubu fi ẹsun kan Obasanjọ pe ka ni o ti ṣe ipilẹ to dara silẹ fun iṣelu awa-ara-wa lasiko to n ṣe aarẹ ni, gbogbo wahala oṣelu yii ko ni si nibẹ.
O ṣiṣọ loju ọ̀rọ̀ naa nile ẹgbẹ APC nilu Eko lasiko ipade awọn ọmọ ẹgbẹ nibi to ti fi ara rẹ ṣe apẹrẹ pe ipilẹ rere ti oun fi silẹ gege bi gomina nipinlẹ Eko lo di òpó oṣelu mu bayii nipinlẹ Eko.
O ni wọn maa dibo abẹle yan ẹni to wu wọn gẹgẹ bii gomina ipinlẹ Eko ni ti asiko ba tó pẹlu ileri pe àwọn to se daadaa ninu oloye ẹgbẹ yoo ni anfani lati lọ leekeji.
'Kò ṣéèṣe fún aláǹgbá láti bá ẹtu jà' ni ọrọ idagbere Bola Tinuba fun àwọn to n ya kuro ni ẹgbe oselu APC ni eyi to tun fi n ki awon to ṣẹṣẹ n darapọ mọ ẹgbẹ kaabọ sile.
Tinubu gbà pé ó ṣoro láti ko ìwo ẹkùn lé ajá lọ́wọ́
Adari ẹgbẹ oṣelu All Progressives Congress, APC, Bola Tinubu, ti fẹsun kan awọn kan lara awọn ọmọ ile aṣofin, pe wọn n gbero lati yọ Aarẹ Muhammadu Buhari l'oye.
Tinubu sọrọ naa ni Ọjọru nibi ayẹyẹ igbaniwọle fun olori ọmọ ile to kere ju nile aṣofin agba Naijiria, Sẹnetọ Godswill Akpabio, to waye ni papa iṣere Ikot Ekpene, nipinlẹ Akwa Ibom.
Tinubu ni 'ki awọn to n gbimọ ika jawọ, nitori pe 'ko ni ṣeeṣe fun alangba lati ba ẹtu ja.'
Oríṣun àwòrán, @SenGbengaAshafa
Akpabio ni ọmọ ẹgbẹ PDP to nipo julo to fi ẹgbẹ silẹ lọ si APC Lẹnu ọjọ mẹta yi
O ṣapejuwe ohun to n ṣẹlẹ lọwọlọwọ ni Naijiria gẹgẹ bi 'ogun laarin awọn onilọsiwaju ati awọn to wa l'oju kan.
O ni 'a gbagbọ ninu ijọba awaarawa, sugbọn awọn to wa l'oju kan ni igbagbọ nilu iṣejọba pipin owo ilu laarin awọn kan, to fi mọ jiji owo orilẹede Naijiria ko sapo ara wọn.
Saaju ni Akpabio to jẹ Olori ọmọ ẹgbẹ oṣelu to kere ju nile igbimọ aṣofin agba Naijiria, ti kọwe fipo rẹ silẹ, ko to di pe o kuro ninu ẹgbẹ PDP lọ darapọ mọ ẹgbẹ oṣelu APC ni Ọjọru, ọjọ kẹjọ, oṣu Kẹjọ, 2018.
Ni papa isere Ikot Ekpene ni wọn ti n ṣe ayẹyẹ ikini kaabo sinu ẹgbẹ fun un ni ipinle Akwa Ibom.
Ọgọrọ ọmọ ẹgbẹ oselu APC ati awọn eekan ẹgbẹ ni wọn pejo sibi ayẹyẹ naa
Lọjọ Aje ni awọn aworan kan ti kọkọ jade sita, eyi to ṣafihan Godswill Akpabio pẹlu Asiwaju ẹgbẹ oṣelu All Progressives Congress, APC, Bola Tinubu.
Oríṣun àwòrán, @SenGbengaAshafa
Awọn Sẹnẹtọ ọmọ ẹgbẹ APC kọwọ rin pẹlu Akpabio
Kíni awọn ọmọ Naijiria n sọ?
Awọn ọmọ Naijiria ko tilẹ jẹki ayẹyẹ naa pari ki wọn to bẹrẹ iriwisi loju opo Twitter.
E gbọ naa, ẹgbẹ wo ni Akpabio fi silẹ lati lọ darapọ mọ omiran? Ọrọ naa polukurumusu mọ awọn kan loju debi wi pe wọn n gbe ẹgbẹ si ara wọn.
Ni kiakia lawọn oloju kogberegbe ti sare tọka si asikọ yii.
Awọn eeyan kan kan saara fun un bi ero ti se pọ nibi ayẹyẹ ọhun ti wọn si ni ifasẹyin ni kikuro ninu ẹgbẹ Akpabio yoo jẹ fun PDP.
Bi ẹrin ni awọn kan fi ọrọ naa ṣe.
Fadele: Dán an wò, lóbí ìyá ọ̀kẹ́rẹ́ ni a fi ọ̀rọ̀ ọ̀kadà náà ṣe
Ṣaaju eyi ni Akpabio lọ si ilu London lati lọ ki Aarẹ Muhammadu Buhari to wa lẹnu isinmi.
Eyi si ti mu ki awọn kan maa sọ pe boya o fẹ fi ẹgbẹ oṣelu rẹ, PDP, silẹ lati darapọ mọ APC.
Izeowayi gb'ẹ̀bùn ẹ̀kọ́ ọ̀fẹ́ lórí ìdíje àròkọ BBC Pidgin:
Ìdíje àròkọ̀ ni BBC Pidgin
Ọgbẹni Izeowayi Victor lo jawe olubori ninu idije arokọ ni ede Pidgin.
Ìdíje yii wà fún àwọn akẹ́kọ̀ọ́ ti wọn ti pé tàbí ju ọmọ ọdún mejidinlogun lọ.
BBC, erin nla to n ṣeun nla lawujọ
Izeowayi lo gba ami ẹyẹ naa ninu awọn akẹẹkọ mejidinlogun to kopa ninu idije naa.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí:
Akori arokọ naa ni: Ṣé Ọ̀dọ́ Afrika ti ṣetán fun ipò adarí nínú òṣèlú?
Akẹẹkọ Victor gba ẹbun ẹ̀kọ́ ọ̀fẹ́ fun ọdun kan pẹlu owó iwe ti yoo lo pata lẹyin to jawe olubori ninu idije naa.
Eyi ni igba akọkọ ti iru idije yii yoo waye lati igba ti BBC Pidgin ti bẹrẹ.
Adari ile isẹ BBC lapa iwọ-oorun Afirika, Toyọsi Ogunṣẹyẹ, rọ awọn ọdọ lati maa kopa ninu ṣiṣe ipinnu l'orilẹede Naijiria nipa lilọwọ si ohun to n ṣẹlẹ layika wọn.
Ebun nla n duro de ẹni to ba bori
Bawo ni idije naa ṣe lọ?
Kọ arokọ ọ̀rọ̀ to to ẹẹdẹgbẹrin si ẹgbẹrun kan (800-1000 words) ranṣe lede Pidgin si bbcpidgin.essay.bbc.co.uk
Rii pe ko si ọrọ ija, ọ̀rọ̀ aworan iwokuwo/iṣekuṣe (Pornography), igbesunmọmi, ohunkohun to le ba awujọ jẹ tabi rogbodiyan ninu arokọ rẹ.
Kọ orukọ rẹ, nọmba rẹ, adirẹsi ilé rẹ, koko arokọ ti o n kọ, àti gbolohun diẹ nipa ara rẹ ni eyi ti BBC yoo lo fun idije yii nikan ṣoṣo.
Idije yii bẹrẹ lojo Aje, ọjọ kẹfa, oṣu kẹjọ yoo si pari ni ọjọ  Aiku, ọjọ keji, oṣu kẹsan, ọdun 2018 ni agogo 23:59 GMT.
BBC Pidgin yoo kan si ẹni to ba gbegba oroke laarin ọjọ kẹwaa si ọjọ kejila, oṣu kẹsan an, ọdun 2018.
Igba akọkọ ti a maa ṣe eyi niyi
Ko arokọ rẹ daadaa ni ede PIDGIN.
Mo itan sọ daadaa.
Mọ ilana bi a ṣe n kọ arokọ ni kikun.
Tẹle ilana ofin girama ede Pidgin bi o ti yẹ.
Idije yii ko si fun oṣiṣẹ BBC kankan ati awọn ẹbi wọn rara.
Oríṣun àwòrán, @istock
Ẹni ba láyà
Yusuf Magaji Bichi di Olùdarí àgbà tuntun
Oríṣun àwòrán, @BysShuwaki
Yusuf Bichi
Àjọ Ọ̀tẹlẹ̀múyẹ́ DSS ti ní Olùdarí àgbà tuntun.
Ọjọ́bọ̀, ọjọ́ kẹrìnlá, oṣù Kẹsàn án ni Àárẹ Muhammmadu Buhari buwọ́lu ìyànsípò Yusuf Magaji Bichi, gẹ́gẹ́ bi Olùdarí Àgbà fún àjọ Ọ̀tẹlẹ̀múyẹ́ DSS.
Nínú àtẹ̀jáde kan tí iléèṣẹ́ Ààrẹ fi síta lójú òpó Twitter ni wọ́n ti kéde ìyànsípò Magaji Bichi.
Ìyànsípò Bichi wáyé lẹ́yìn tí wọ́n yọ Olùdarí Àgbà fún àjọ Ọ̀tẹlẹ̀múyẹ́ DSS tó wà nípò tẹ́lẹ̀, Lawal Daura kúrò nípò rẹ̀.
Kò yá wà lẹ́nu pé Dogara lọ sí PDP
Ambọde: Kò sí ìjà láàrin èmi àti Tinubu
Igbákejì Àárẹ Nàìjíríà, Ọ̀jọ̀gbọ́n Yẹmi Ọṣinbajo ló gba iṣẹ́ lọ́wọ́ Daura l'ọ́jọ́ keje, oṣù Kẹjọ, 2018, lásìkò tó fi delé fún Ààrẹ Buhari tó lọ fún ìsìnmi ẹnu iṣẹ́ nílẹ̀ Gẹ̀ẹ́sì.
Ìgbésẹ̀ yíyọ Daura níṣẹ́ wáyé lẹ́yìn tí àwọn òṣìṣẹ́ àjọ DSS kan yabo ilé ìgbìmọ̀ asọfin Nàìjíríà, tí wọ́n sì dí ọ̀nà mọ́ àwọn aṣòfin.
Oríṣun àwòrán, dss
Ọ̀gá àgbà tuntun nàá gba oyè ìmọ̀ ìjìnlẹ̀ nípa ètò òṣèlú nílé ẹ̀kọ́ gíga fásìtì Ahmadu Bello tó wà nílùú Zaria.
Lẹ́yìn awuyewuye yìí ni Ààrẹ ilé aṣòfin àgbà, Bukọla Saraki, àti àwọn aṣòfin mìíràn fi ẹgbẹ́ òṣèlú All Progressives Congress sílẹ̀ tí wọ́n sì darapọ̀ mọ́ ẹgbẹ́ òṣèlú alátakò, Peoples Democratic Party, PDP.
Àwọn àmúyẹ wo ni Ọ̀gá DSS tuntun, Yusuf Magaji Bichi ní ?
Ọ̀gá àgbà tuntun nàá gba oyè ìmọ̀ ìjìnlẹ̀ nípa ètò òṣèlú nílé ẹ̀kọ́ gíga fásìtì Ahmadu Bello tó wà nílùú Zaria.
Ó bẹ̀rẹ̀ iṣẹ́ ní ẹ̀ka ètò àábò ní ìlú Kano, lẹ́yìn èyí ló sì darapọ̀ mọ́ àjọ elétò àábò Nigerian Security Organization (NSO), tó ti kógbá sílé báyìí.
Àjọ NSO ni a mọ̀ sí àjọ Director of State Service (DSS).
Ọ̀gbẹ́ni Bichi ti kẹ́kọ̀ọ́ nípa ṣíṣe àtúpalẹ̀ àbọ̀ ìwádìí iṣẹ́ ọ̀tẹlẹ̀múyẹ́, tó fi ma nípa ètò ìgbanisíṣẹ́ ọ̀tẹlẹ̀múyẹ́ ní ilẹ̀ Gẹ̀ẹ́sì.
'Ilé ìwòsàn ṣi abẹ́rẹ́ Formalin gún mí; n kò lè dá ìgbẹ́ àti ìtọ̀ dúró mọ́'
Ọ̀gá àgbà DSS tuntun ọ̀hún ni iléèṣẹ́ Ààrẹ́ ní yóò ṣe àmúlò àwọn ìrírí tó ti ní nínú iṣẹ́ ìwádìí, àtúpalẹ̀ iṣẹ́ ìwádìí, ìpẹ̀tù sí àáwọ̀, ìpèsè àábò,tó fi mọ́ kíkópa nínú àwọn ìṣẹ́ tó léwu àti èyí tó jẹ́ ẹlẹgẹ́.
Bichi ti ṣiṣẹ́ gẹ́gẹ́ bi Olùdarí àjọ DSS ní ìpínlẹ̀ Jigawa, Niger, Sokoto àti Abia.
Bákan nàá lo ti ṣiṣẹ́ gẹ́gẹ́ bi Olúdarí Ilé ẹ̀kọ́ tí wọ́n ti n kọ́ nípa ogun jíjà (National War College), tó fi mọ́ iléèwé tí àwọn òṣìṣẹ́ àjọ DSS, àti àwọn ẹ̀ka mì í tó wà nínú àjọ DSS.
Iyansipo Lawal Daura gẹgẹ bi ọga agba ajọ ọtẹlẹmuyẹ DSS lọdun 2015, mu awuyewuye dani.
Ọpọlọpọ ọmọ Naijiria lo fi oju aitọ wo o, nitori pe ipinlẹ Katsina l'oun ati Aarẹ Muhammadu Buhari ti jọ wa, ati lori 'aikoju oṣuwọn rẹ fun iṣẹ naa'.
Bakan naa lo jẹ wi pe Daura ti fẹhinti kuro lẹnu iṣẹ nileeṣẹ ajọ DSS, ko to di pe Buhari tun pe e pada. O tun jẹ ọkan lara ọmọ igbimọ fun eto aabo ati ọtẹlẹmuyẹ fun ẹgbẹ oṣelu APC lasiko eto idibo ọdun 2015.
Lati igba to si ti bẹrẹ iṣẹ ni awuyewuye loriṣiriṣi ti n jẹyọ lori ihuwasi rẹ.
Daura tun kọ iwe ẹsun si ile aṣofin nipa ọga agba ajọ EFCC, Ibrahim Magu, eyi to mu ki awọn 'koju oro si iyansipo rẹ.'
Ta ló wà nidi wàhálà ílé aṣòfin Nàíjíríà?
Irú ẹ̀dá wo ni aṣòfin Bukola Saraki jẹ́?
Awuyewuye jẹyọ lori eto igbanisiṣẹ awọn oṣiṣẹ ọrinlenirinwo din ẹyọkan, 479, tuntun fun ajọ DSS.
Ninu 479 ni ipinlẹ Katsina ti ni eniyan mọkanlelaadọta, 51, eyi to ju ida mẹwa gbogbo awọn ti wọn gba siṣẹ jake-jado Naijiria lọ.
Ọpọlọpọ lo bu ẹnu ẹtẹ lu Daura nigba naa pe bawo ni ipinlẹ Katsina, to jẹ ipinlẹ rẹ yoo ṣe ni to bẹ ju awọn ipinlẹ yooku lọ.
Wọn fi ẹsun kan iṣakoso rẹ fun obitibiti biliọnu Naira ti wọn fi kọ ile ẹkọ DSS ni ipinlẹ Katsina; kikuna lati jẹ ki olubadamọran lori eto aabo Naijiria nigba kan, Sambo Dasuki, wa sile ẹjọ lati jẹri lori awọn ẹsun to ni i ṣe pẹlu iwabajẹ.
Ni ọjọ kọkanlelogun, oṣu Kọkanla, ajọ DSS da awọn oṣiṣẹ ajọ EFFC duro lati maa fi ofin gbe Ita Ekpeyong, to jẹ Ọga agba ajọ DSS tẹlẹ, lai fi ti pe wọn ni aṣẹ lati mu u ṣe.
Oríṣun àwòrán, Twitter
Ọjọ́ keje, oṣù Kẹjọ ni Adele Aarẹ, Yẹmi Ọsinbajo gba iṣẹ́ lọ́wọ́ rẹ̀
Bakan naa ni wọn ko jẹ ki wọn o fi ofin gbe Ọga agba ajọ ọtẹlẹmuyẹ National Intelligence Agency, NIA, Ayodele Oke, ti Aarẹ Buhari da duro lẹnu iṣẹ.
Ẹsun kikowo ilu jẹ ni ajọ EFCC nwa ọga agba DSS ọhun fun.
Ademọla Adeleke: Àwọn akẹẹgbẹ́ mi ní iléẹ̀kọ́ girama mọ̀ mi bíi ìsáná ẹlẹ́ẹ́ta
Oríṣun àwòrán, @IsiakaAdeleke
Adeleke ni oun lọ si fasiti kan ni ilẹ Amẹrika lai lo iwe ẹri oniwe mẹwa Waec ti oun ni
Ademọla Adeleke, tii se oludije fun ipo gomina labẹ́ẹ ẹgbẹ oselu PDP ni ipinlẹ Ọsun sọrọ lẹyin idajọ ile ẹjọ nipa iwe ẹri rẹ.
Adeleke ni oun lọ si fasiti kan ni ilẹ Amẹrika lai lo iwe ẹri oniwe mẹwaa WAEC ti oun ni.
Ilu Ẹdẹ ni Adeleke ti sọrọ yii lasiko to n fesi nipa iwe ẹri rẹ, ti meji ninu awọn akẹẹgbẹ rẹ ni ile ẹkọ girama Ẹdẹ Muslim Grammar School, si rọgba yii ka.
O ni awọn ọkẹẹgbẹ oun ni ile ẹkọ girama naa da oun mọ, bii isana ẹlẹẹta, nitori odu ni oun nile ẹkọ naa, kii se aimọ fun oloko, taa ba n sọrọ ọrọ idaraya.
Oludije fun ipo gomina nipinlẹ Ọsun naa wa sisọ loju rẹ pe, bi oun yoo se lọ si ile ẹkọ giga ni ilẹ Amẹrika lo mumu laya oun nigba naa, ti oun ko si duro ki esi idanwo waec oun jade, ti oun fi lọ
O wa foju laifi wo igbesẹ bi wọn se n beere iwe ẹri oun, to si se apejuwe igbesẹ naa gẹgẹ bii ‘iwa agabagebe ati ẹtan
Bẹẹ ba gbagbe, Ileẹjọ ti fun Sẹnetọ Adeleke to n dije fun ipo gomina ipinlẹ Ọṣun labẹ aṣia ẹgbẹ oṣelu PDP ni aṣẹ maa niṣo ko sewu lori ẹsun ayederu iwe ẹri ti wọn fi kan an.
Onidajọ David Oladimeji, ti ile ẹjọ giga ipinlẹ Ọṣun, ninu idajọ to gbekaẹ lọjọọru ile ẹjọ naa ko lee kaa lọwọ ko lori erongba rẹ lati dije fun ipo gomina nitoripe olupẹjọ kuna lati fi idi ẹsun ayederu iwe ẹri to fi kan an mulẹ.
Onídájọ́ Fọlahanmi Oloyede léwájú ìwọ́de òṣìṣẹ́fẹ̀yìntì fún ọjọ́ mẹ́ta l'Ọ́ṣun
"Onidajọ Ọladimeji ni lootọ iwe ti olupẹjọ gbe kalẹ niwaju ile ẹjọ naa ni ""ọpọlọpọ kotọ to lagbara gidigidi"" sibẹ ile ẹjọ ko lee doju rẹ kọ oorun alẹ lori didije fun ipo gomina."
Awọn ọmọ ẹgbẹ oṣelu PDP meji kan, rasheed Ọlabayọ ati Idowu Oluwaseun, ni wọn gba ile ẹjọ lọ pẹlu ẹbẹ pe ki ileẹjọ paṣẹ lati da Adeleke lọwọkọ gẹgẹ bii oludije PDP ninu idibo sipo gomina nipinlẹ Ọṣun eleyi ti yoo waye lọjọ kejilelogun oṣu kẹsan, ọdun 2018.
Oríṣun àwòrán, @IsiakaAdeleke1
Awọn ọmọ ẹgbẹ oṣelu PDP meji kan, rasheed Ọlabayọ ati Idowu Oluwaseun, ni wọn gba ile ẹjọ lọ pẹlu ẹbẹ pe ki ileẹjọ paṣẹ lati da Adeleke lọwọkọ gẹgẹ bii oludije PDP
Adajọ ni oun rii pe olujẹjọ naa, iyẹn sẹnetọ Ademọla Adeleke, ka iwe de ipele girama eleyi to ni o fi han ninu iwe ibura to fi ran'sẹ si ile ẹjọ naa.
O ni olupẹjọ ko gbe ẹsun dide lori ayederu iwe ẹri ninu ẹjọ to kọkọ pe; o si kuna lati fi idi rẹ mulẹ pe ayederu ni iwe ẹri to fihan.
Saraki: Àwọn kan n hùwà tani-ó-múmi ni Aso Rock lábẹ́ Buhari
Oríṣun àwòrán, @NGRSenate
Bakan naa lo dupẹ lọwọ awọn aṣofin apapọ fun iwa akin ti wọn hu.
Saraki ní ijọba miran wà nínú ijọba Buhari
Aarẹ ile aṣofin apapọ orilẹ-ede Naijiria, Sẹnetọ Bukọla Saraki ni awọn eeyan kan ti gbe ijọba ara wọn kalẹ laarin ijọba ti Aarẹ Muhammadu Buhari eyi ti araalu mọ.
Saraki sọrọ yii lasiko to n ba awọn akọroyin sọrọ nibi ipade to pe nilu Abuja.
O ni APC ló wà nídí ilé aṣòfin àpapọ̀ t'áwọn agbófinro dí pa.
Saraki ni pẹlu bi awọn ọmọ orilẹ-ede Naijiria, awọn aṣofin apapọ atawọn oṣiṣẹ ile aṣofin ṣe dide tako awọn ohun to pe ni iwa familete-n-tutọ, lo tubọ mu ki igbẹkẹle oun ninu awọn eeyan orilẹ-ede yii gbopọn sii.
Oríṣun àwòrán, @NGRSenate
'APC ló wà nídí ilé aṣòfin àpapọ̀ t'áwọn agbófinro dí pa'
"Bi ẹ ba ranti pe ni ọdun meji sẹyin mo pariwo sita pe awọn eeyan kan ti gbe ijọba kalẹ laarin ijọba aarẹ Buhari atipe iṣẹ ati iṣe wọn lo ti wa n farahan bayii.
O jẹ iyalẹnu nla pe olori ajọ kan yoo kan dede dide lati paṣẹ pe ki wọn ṣigun lu ile aṣofin apapọ gẹgẹbi a ti ṣe rii lana."
Sẹnetọ Saraki ko ṣai kan sara si adele-aarẹ Yẹmi Oṣinbajọ fun igbesẹ akin to gbe lati daabo bo iṣejọba tiwantiwa eleyi to ni o mu ọpọ ifọkanbalẹ wa; ṣugbọn ko tii 'dahun ibeere lori bi iwa kotọ yii ṣe waye gan.'
O wa pe fun iwadii kikun lori iṣẹlẹ naa pẹlu afikun ipe fun fifi gbogbo awọn ti wọn ba mu jofin.
Aarẹ ile aṣofin agba, Sẹnetọ Bukọla Saraki ti fẹsun kan ẹgbẹ oṣelu APC pe o n gbiyanju lati da oju iṣejọba tiwantiwa bolẹ pẹlu bi o ṣe ṣigun bo ile aṣofin agba pẹlu awọn agbofinro ọtẹlẹmuyẹ ni ọjọ iṣẹgun.
Saraki, ninu ọrọ to sọ lasiko ipade iroyin agbaye to ṣe nilu Abuja ṣalaye wi pe awọn sẹnetọ kan labẹ ẹgbẹ oṣelu APC lo fẹ gbiyanju ati yọ oun nipo ni wọn lo ile-eṣẹ ọtẹlẹmuyẹ apapọ lati fi dukuku mọ awọn aṣofin ti wọn si se ọna to wọ ile aṣofin apapọ.
Bakan naa lo dupẹ lọwọ awọn aṣofin apapọ fun iwa akin ti wọn hu eleyi to ni wọn fi daabo bo eto ijọba tiwantiwa lorilẹ-ede Naijiria
Kí lẹ ò mọ̀ nípa àwọn obinrin Yollywood yìí?
Ogundiya: Àṣìṣe Dókítà ló sọ mi di aláàbọ̀ ara lórí kẹ̀kẹ́
Ìgbésí ayé àwọn ọmọdébìnrin wọ̀nyìí di ọ̀tun láti 2008
DBanj: Ikú ọmọ mi kò leè paná ìfẹ́ láàrín èmi àti ìyàwó mi
Oríṣun àwòrán, @Dbanj
DBanj ni lootọ ni nnkan ko rọgbọ latigba ti ọmọ oun ọkunrin ti ku
D Banj: àdánwò kò lè ṣalai má de ba ẹ̀dá láyé
Gbajugbaja olorin takasufe ni, Dapo Daniel Oyebanjo ti ọpọ mọ si DBanj ti sọ pe iku ọmọ ohun to waye laipẹ yii ko lee ya ifẹ oun ati iyawo oun, Lineo.
Ninu awo orin tuntun to gbe jade, diẹ ninu eyi to fi sori oju opo Instagram ati twitter rẹ, DBanj ni gbogbo ipenija yoowu ti o lee koju oun tabi ẹbi oun, iyawo oun ni iyawo oun yoo ma jẹ o.
'Mímu ọyàn àyà ìyàwó rẹ̀ ní àǹfàní tó pọ̀'
Kò sáyè ìgbafẹ́ mọ́ fáwọn àgùnbánirọ̀
Sunday Ayẹni: Damilọla, aya ọmọ mi fìgbónára sọ mi sókùnkùn alẹ́
"Olorin takasufe naa tun jẹ ko di mimọ ninu ọrọ pelebe to kọ sori ikanni Instagram rẹ pe, "" A o jumọ la gbogbo idanwo ti a ba n koju kọja ni. Eyi ni fun iwọ iyawo mi #WhatYouWant #LetterToMyWife #Everything #MamaDaniel 8/8/18.''"
Oríṣun àwòrán, Dbanj
Oṣu kẹfa, ọdun 2018 ni Daniel, ọmọ ọkunrin DBanj ku lẹyin oṣu diẹ to ṣe ọjọ ibi ọdun kan rẹ.
Orin yii n wọle lẹyin ọjọ diẹ to ṣe akọsilẹ ohun ti oju ẹbi rẹ ri ati ọna ti o n gba wẹ ọgbẹ ajalu iku ọmọ rẹ ninu atẹjade kan to fi sita lori ikanni instagram rẹ.
Gẹgẹ bi o ṣe sọ, nnkan ko fi bẹẹ rọgbọ latigba ti ọmọ rẹ ọkunrin ti ku.
Oríṣun àwòrán, Dbanj
Dbanj ni gbogbo ipenija yoowu ti o lee koju oun tabi ẹbi oun, iyawo oun ni iyawo oun yoo ma jẹ o
Lati igbayi wa, DBanj yẹra fun ikanni ayelujara gbogbo titi di ibẹrẹ oṣu keje to gbe atẹjade kan jade ninu eyi to ti dupẹ fun atilẹyin gbogbo eeyan to ṣugbaa rẹ.
'Ọṣinbajo jọmí lójú pẹ̀lú ìwà akin tó hù'
Ọ̀ṣọ́ Aṣọ Òkè ti kọjá lílo ìlẹ̀kẹ̀ níkan
Ogundiya: Àṣìṣe Dókítà ló sọ mi di aláàbọ̀ ara lórí kẹ̀kẹ́
Ìgbẹ̀yìn Joe, akínkanjú to dóòlà ẹ̀mí èèyàn 13 ni P/Harcourt
Oríṣun àwòrán, FACEBOOK/JOE BLANKSON
Ọdun maarun sẹyin ni Blankson ati Mercy sẹgbeyawo, ti wọn si bi ọmọ mẹta,
Àwọn ti akọni orí omi Blankson dóòlà ẹ̀mí wọn fẹ́ bẹ̀rẹ̀ ètò ìpèsè ààbò lórí omi fáwọn èrò.
Idasefiema Ibimina, Chinonso Cecelia Ndukwe ati Odelusi Bunmi Joy jẹ mẹta lara àwọn ti Blankson to doloogbe lẹyin to gba awọn ero ori omi là kọ̀ lati jẹ ki ikú rẹ̀ ja si asan.
Awọn mẹtẹẹta wa lara awọn ero ti wọn ri sodo Bakana lọjọ kejidinlọgbọn, oṣu keje lasiko ti Blankson gba awọn mẹtala là.
Agbaagba mẹta to wà nidi ẹẹta pe ki iku Blankson lodo Bakana ma ja si asán
Wọn ni ẹ̀rù omi ti ń ba àwọn lati igba ti ọrọ yii ti ṣẹlẹ, ṣugbọn bayii, wọn fe bẹrẹ ajọ aranilọwọ ti kii ṣe tijọba 'Boat Safety Minders Foundation' ti wọn yoo fi ṣeto iwe akọsilẹ awon arinrin ajo ọkọ oju omi tori iṣẹlẹ idagiri bayii.
Wọn yoo tun maa ṣeto ilanilọyẹ nipa eto aabo fun ẹmi loju omi ni Pọtá pẹlu iranlọwọ awọn ara ìlú.
Ọbìnrin tó fẹ́ ṣojú àwọn ẹ̀yà Sheedi
SMS alert: Wo ọ̀nà láti dẹ́kun jìbìtì lórí àṣùwọ̀n báǹkì rẹ
'Ikú ọkọ mi kò gbọdọ̀ já si asàn ni Nàìjíírà'
Mercy, opó arakunrin Joe Blankson ni bi ala lo ṣi n ri l'oju oun.
Ọgbẹni Blankson, ni ọpọlọpọ ti gboriyin fun gẹgẹ bi akọni to ṣubu loju ija lasiko to n doola awọn eniyan ti ọkọ oju omi ti wọn wọ doju de sinu odo nilu Port Harcourt.
Blankson nikan l'oku ninu ijamba ọkọ oju omi naa to waye l'ọjọ Abamẹta naa.
Mercy, sọ fun BBC pe oun ti ọkọ oun ṣe ko ya oun lẹnu, nitori ọkọ oun maa n fi gbogbo igba ran ọmọnikeji lọwọ ni.
Ọdun marun sẹyin ni Blankson ati Mercy sẹgbeyawo, ti wọn si bi ọmọ mẹta, sugbọn akọbi wọn obinrin di oloogbe l'oṣu Kejila, 2016.
Ògidì ọmọ Yorùbá gbọ́dọ̀ kọ́ ọmọ rẹ̀ ni àṣà àti ìṣe Yorùbá
Mercy ni 'oun ko ti i fi tara-tara gbagbọ pe ọkọ oun ti ku , nitori nigba mi i, o maa n ṣe oun bi pe yoo rin wọle wa ba oun.
"O ni ile awọn ṣofo lai si ọkọ oun. ati pe "" l'ọjọ kan ni ọmọ mi ọkunrin, Owen, gbe baagi rẹ pe oun n wa baba oun lọ si Bakana."""
Bawo l'oṣe gbọ pe ọkọ rẹ ku?
Ni ọjọ buruku, eṣu gbomi mu ọhun, Mercy ni ọkọ oun sọ fun oun pe oun yoo gba ibi iṣẹ lọ si Bakana fun eto isinku.
Ṣugbọn, nigba ti ilẹ ṣu ti Joe ko pe gẹgẹ bi iṣe rẹ ni wọn to bẹrẹ si ni bẹru pe boya nkan ti ṣẹlẹ si. Wọn pe ẹrọ ibanisọrọ rẹ, sugbọn ko lọ.
Oríṣun àwòrán, Mercy Blankson/Facebook
Mercy, aya oloogbe Blankson ni o da bi ẹni pe awọn ri awọn apẹẹrẹ ki iṣẹlẹ buruku naa to waye.
Koda, awọn ọrẹ rẹ ti Mercy pe, ko ri nkankan sọ lori ibi ti o wa.
Laipẹ ni iya Joe wa sọ fun un pe ọkọ oju omi kan danu sinu odo ni Bakana, ti ọkọ rẹ si wa lara awọn ti o wa ninu rẹ, sugbọn wọn ṣi n wa.
Eyi mu ki o nireti pe wọn yoo si ri ọkọ rẹ laaye.
Igba to lọ sile iya ọkọ rẹ, o ri ọpọ eniyan to ko rajọ, ti wọn si n sunkun. Sibẹ, wọn sọ fun un pe wọn ko ti i ri ọkọ rẹ.
Ọjọ Aje, ọgbọnjọ, oṣu Keje, ni iyawo ẹgbọn ọkọ rẹ kan ṣẹṣẹ sọ fun un pe ọkọ rẹ ti ku lẹyin ti awọn pẹja-pẹja ri oku rẹ to lefo soju odo.
O sare lọ si ibudokọ omi Abonnema, ṣugbọn wọn ko jẹ ko ri oku rẹ nitori pe o n t'ọmọ lọwọ.
Bakan naa ni aṣa sọ pe ki wọn o sin oku ẹnikẹni to ba ku sinu odo si eti odo naa. Nitori eyi, ko mọ ibi ti wọn sin ọkọ rẹ si.
Mercy ni awọn ti ri awọn apẹẹrẹ ki iṣẹlẹ buruku naa to waye.
Odo Abonnema ni Bakana to di oju oori Blankson
O ni awọn lọ sibi ayẹyẹ ọjọ ibi ni ọsẹ ti Joe ku. O si sọ fun ọkọ rẹ pe o da bi ẹni pe nkan buruku kan yoo ṣẹlẹ laipẹ, nitori pe igba ti awọn lọ si agbegbe naa kẹyin, ijamba ina kan waye to mu ẹmi akọbi wọn obinrin lọ.
Kii si akọsilẹ odiwọn iye ero to n wọnu ọkọ oju omi ni Bakana
Ṣugbọn, ọkọ rẹ ni ko fi ọkan balẹ, pe nkankan ko ni i ṣẹlẹ. Ọjọ Abamẹta to tẹle ni Joe ku.
Mercy ni igbagbọ pe iku ọkọ rẹ, Joe, yoo mu ki ijọba wa nkan ṣe si ibudokọ omi Abonnema, lati sọọ di ibi to pojuowo, ti yoo si ni awọn adoola ẹmi, iwe akọsilẹ orukọ awọn arinrinajo, ati awọn eroja mi i.
O ni o yẹ ki awọn ọlọpaa oju omi wa ti yoo ma tọpinpin bi nkan ṣe n lọ, ati pe ki awọn alaṣẹ maa ko idọti oju omi naa, ko maa ba maa kọ ẹnjinni ọkọ oju omi, eyi to maa n fa ijamba.
Abilekọ Blankson ni, gomina ipinlẹ Rivers, Nyesom Wike, ti ṣeleri lati pese iranlọwọ fun eto ẹkọ awọn ọmọ oun, ati lati fun oun ni iṣẹ nileeṣẹ ijọba.
Ẹwẹ, o ni yoo dara ti ilu Bakana ba ṣe nkan iranti kan si ibi ti ọkọ oun ku si, nitori ti awọn ọmọ rẹ ba n beere ibi ti wọn sin baba wọn si l'ọjọ iwaju.
Ogundiya: Àṣìṣe Dókítà ló sọ mi di aláàbọ̀ ara lórí kẹ̀kẹ́
Bimpe: Èèyàn bíi tiyín ni àfín, ẹ dẹ́kun dídẹ́yẹsí àfín
Akintọla Williams: Àwọn nkan tó ṣe pàtàkì tó yẹ kí o mọ̀ nípa Olùṣirò owó Àgbà àkọ́kọ́ ní Afrika
Oríṣun àwòrán, Facebook /Lagos State Government
Akintọla Williams ni Aarẹ akọkọ fun Institute of Chartered Accountants, ICAN
Olóyè Akintọla Williams ni Oluṣiro owo Agba akọkọ ni ilẹ Afrika, Chartered Accountant. O pe ẹni ọdun mọkandinlọgọrun bayii.
Irú ẹ̀dá wo ni Fẹla Jẹ́?
Oríṣun àwòrán, @followlasg
Akintọla Williams pe ẹni ọdun mọkandinlọgọrun bayii.
Oríṣun àwòrán, @followlasg
Àwọn ènìyàn nlanla ló péjú sí ibi ayẹyẹ ọdún mọ́kàndínlọ́gọ́rùn Akintọla Williams
Òsìsẹ́ ilé-wòsàn Ondo: Gbogbo ìgbà ni alárùn ọpọlọ ń kọlù wàá
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ọkunrin alarun ọpọlọ kan lu awọn oṣiṣẹ ileewosan ti wọn ti n tọju awọn alarun ọpọlọ ni alubami.
Iṣẹlẹ naa waye ni ilu Akurẹ, ti i ṣe olu ilu ipinlẹ Ondo.
Ileeṣẹ ọlọpa ipinlẹ naa la gbọ pe, o gbe ọkunrin alarun ọpọlọ naa lọ sileewosan nitori pe ọrọ rẹ ko baramu lasiko to jẹwọ fun awọn ọlọpa pe, oun wa lara awọn to pa Khadijat, ọmọ igbakeji gomina ipinlẹ Ondo nigba kan, Lasisi Olubọyọ.'
Ọkunrin ọhun, Fọlọrunsọ Olawale, ni iroyin naa sọ pe 'aisan rẹ le si’ nigba to de ileewosan naa, to si bẹrẹ si ni ba awọn irinṣẹ ileewosan jẹ.
Ọ̀gá Bello: Àìgbọ́n ló ń da àwọn òsèré tíátà tó ń jà lórí ayélujára láàmú
Ati pe o lu awọn nọọsi, to fi mọ Ọga Agba nileewosan naa, Dokita Akinwumi Akinloye, ni alaubami.''
Eyi lo mu ki awọn oṣiṣẹ ileewosan naa ṣe ifẹhonu han ni Ọjọbọ, lati fi ẹdun ọkan wọn han si ohun ti wọn ṣapejuwe gẹgẹ bi 'aibikita ijọba ipinlẹ naa si alaafia wọn.'
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Awọn olufẹhonu han naa fi ẹsun kan pe, ijọba n fi ẹmi wọn wewu lọwọ awọn alarun ọpọlọ ti wọn ba gbe wa sileewosan naa, nitori pe gbogbo igba ni wọn maa n kọlu wọn.
Nigba to n sọrọ lorukọ awọn olutọju alaisan, Alaga Igbimọ to n duna-dura fun alekun owo osu nipinlẹ Ondo, to tun jẹ Alaga ẹgbẹ awọn Nọọsi nipinlẹ Ondo, Ọpẹyẹmi Oloniyo sọ fun BBC Yoruba pe, awọn oṣiṣẹ ileewosan naa ti pada sẹnu iṣẹ wọn, ati pe ijiroro ṣi n lọ lọwọ lori awọn ẹsun ti wọn fi kan ijọba.
Nigba to n sọrọ lori aisi ipese awọn ohun eelo fun aabo lọwọ ikọlu, tawọn osisẹ ile-wosan naa n fẹhonu han le lori, Oloniyọ fi kun pe, diẹ-diẹ ni ijọba yoo maa pese awọn ohun eelo aabo nile iwosan nitori ilu Romu ko se kọ ni ọjọ kan soso.
Ijọba Ondo fesi si isẹlẹ yii.
Ẹwẹ, akòwé àgbà fún ìgbìmọ̀ ìlé ìwòsàn ní ìpínlẹ̀ Ondo Dr Niran Ikumọla ti bu ẹnu atẹ lu bi awọn ẹgbẹ awọn nọọsi nipinlẹ Ondo ti ṣe 'wọde lẹyin ti alarun ọpọlọ kan lu nọọsi ati dokita to n tọju rẹ nilu Akure.
O fidi rẹ mulẹ nigba to ba BBC Yoruba sọrọ pe ijọba ko lẹbi kankan ninu iṣẹlẹ to ṣẹlẹ.
O rọ awọn nọọsi lati ba ijọba sọ ohunkohun ti o ba n dun wọn ni itubi-inubi.
Akọ̀wé àgbà ìgbìmọ̀ ilé ìwòsàn ìpínlẹ̀ Ondo sọ̀rọ̀ lórí ìkọlù ilé ìwòsàn àwọn alárùn ọpọlọ
CAN: Ìjọ tó bá bá àwọn èèyàn láramu ni kí wọ́n lọ̀
Oríṣun àwòrán, Getty Images
CAN ni ọrọ ọhun ku sọwọ awọn eeyan to ba n lọ sawọn ile ijọsin kọọkan
Ni ẹnu lọọ-lọọ yii, ariwo gee ti gba ori ikanni ayelujara lori bi awọn iranṣẹ Ọlọrun kan ṣe n pe fun 'eso owo' lati ọdọ awọn ọmọ ijọ wọn.
Ariwo iranṣẹ Ọlọrun kan lo kọkọ gba ori afẹfẹ kan, ninu fidio kan ti o ti npe fun awọn ọmọ ijọ ti yoo fi owo dọla ilẹ Amẹrika silẹ, gẹgẹ bii eso fun Ọlọrun.
Ogundiya: Àṣìṣe Dókítà ló sọ mi di aláàbọ̀ ara lórí kẹ̀kẹ́
Lati ilẹ yii titi de oke okun ni ariwo ti lori isẹlẹ yii - bi awọn kan ṣe n ti wọn lẹyin pe ko si ohun to buru ninu rẹ, ni ọgọọrọ miran ti n pariwo pe Ọlọrun ko roro to bẹẹ.
Eruku ọrọ naa ko ti lọ silẹ, ti fidio kan tun jade bayii ninu eyi ti iranṣẹ Ọlọrun miran, ti n beere fun ilaji miliọnu kan naira lọwọ awọn akẹkọ gẹgẹ bii eso fun Ọlọrun.
eyi lo wa mu kawọn araalu maa beere pe se ilana gbigba eso owo nla-nla yii baa ofin Ọlọrun mu ?
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Amọ ṣa, ẹgbẹ CAN ni ọrọ ọhun ku sọwọ awọn eeyan to ba n lọ sawọn ile ijọsin kọọkan. Eyi ti o ba wu wọn ni wọn lee ṣe gẹgẹ bi o ba ṣe dara ninu ọkan wọn.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ẹgbẹ CAN ni awọn ko laṣẹ lati ba ẹnikẹni wi nitori Ajọṣepọ laarin awọn onigbagbọ ati ijọba lo jẹ awọn logun
Ninu ọrọ rẹ pẹlu BBC Yoruba, olubadamọran fọrọ iroyin fun aarẹ apapọ ẹgbẹ CAN lorilẹede Naijiria, Ẹni-ọwọ Bayọ Oladeji ṣalaye pe, ko si ni ikawọ CAN lati sọ boya ijọ kan lẹtọ lati beere fun owo lọwọ ọmọ ijọ tabi rara.
"Ijọ ti ẹ ba ti n lọ to ba baa yin lara mu naa ni ki ẹ maa lọ. CAN ko lee sọ pe ẹ gbe owo eleyi kalẹ tabi ki ẹ maa gbe tọhun kalẹ.
Ẹgbẹ CAN ko laṣẹ lati ba ẹnikẹni wi tabi gbee soke. Ajọṣepọ laarin awọn onigbagbọ ati ijọba lo jẹ wa logun."
NLC: Ìjọba ti gbà láti san owó oṣù mẹ́rin fáwọn òṣìṣẹ́ l'Ọ́ṣun
Oríṣun àwòrán, Nigeria Labour Congress
Ijọba ni lootọ ni wọn yoo san owo oṣu mẹrin ninu mẹtalelọgbọn ti ijọba jẹ awọn oṣiṣẹ ati oṣiṣẹfẹyinti nipinlẹ naa
Ẹgbẹ oṣiṣẹ nipinlẹ Ọṣun ni ijọba ipinlẹ naa ti gba lati san ajẹẹlẹ owo oṣu mẹrin ninu owo oṣu mẹtalelọgbọn ti wọn jẹ awọn oṣiṣẹ.
Alaga ẹgbẹ oṣiṣẹ NLC nipinlẹ Ọṣun, Jacob Adekomi lo sọ eleyi ninu ifọrọwerọ rẹ pẹlu BBC Yoruba.
Ọpọlọpọ ariwo ni o ti n wọ tọ iye ajẹẹlẹ owo oṣu ti ijọba jẹ awọn oṣiṣẹ ni pinlẹ Ọṣun papaa bi eto idibo sipo gomina ni ipinlẹ naa.
Oríṣun àwòrán, Olu Alebiosu
Abajade ipade naa si ni pe ijọba yoo san ajẹẹlẹ owo oṣu mẹrin to ku ninu ọdun 2015 fawọn oṣiṣẹ
Awọn adari ẹgbẹ oṣiṣẹ nipinlẹ Ọṣun ti fi iwe ikede gbedeke ọlọjọ meje sita lopin ọsẹ fun ijọba lati san ajẹẹlẹ owo oṣu fawọn oṣiṣẹ abi ki wọn maa reti iyanṣẹlodi awọn oṣiṣẹ laipẹ.
Jacob Adekomi ni alẹ ọjọ aje ni awọn aṣoju ẹgbẹ oṣiṣẹ ati ijọba ṣepade nibi ti wọn ti fẹnu ọrọ jona lori rẹ.
Abajade ipade naa si ni pe ijọba yoo san ajẹẹlẹ owo oṣu mẹrin to ku ninu ọdun  2015 fawọn oṣiṣẹ, pẹlu ajẹẹlẹ ajẹmọnu owo isinmi ọdọọdun (leave bonus) fawọn oṣiṣẹ ijọba ipinlẹ ati ibilẹ nipinlẹ naa.
Bakan naa ni wọn yoo tun san ẹkunrẹrẹ owo oṣu kẹjọ fawọn oṣiṣẹ pẹlu.
Àwọn oṣiṣẹ feyinti ni Osun ṣé iwọde
"Bi wọn ba kọ lati san owo naa laarin asiko yii si ọjọ ẹti, o ṣeeṣe ki a pada si ẹnu gbedeke ọlọjọ meje ti a fẹ gunle o.
Gomina ti buwọlu aṣẹ fun sisan owo na wọn si ti jẹ ko di mimọ pe nigba ti a o ba fi ri ọla (ọjọbọ) awọn oṣiṣẹ yoo bẹrẹ si ni gba owo naa lori aṣuwọn ifowopamọ si wọn."
Nigba ti BBC Yoruba beere pe ṣe awọn eeyan ko ni maa fi oju ọgbọn oṣelu wo sisan owo naa lasiko yii ti ibo gomina ipinlẹ naa ku ọsẹ meji, alaga ẹgbẹ oṣiṣẹ NLC nipinlẹ Ọṣun naa ni ohun yoo wu ti awọn eeyan ba tumọ rẹ si, eyi to jaju fun oun ni ki awọn oṣiṣẹ ti oun n ṣoju o gba ẹtọ wọn.
"Bakan naa lo ni idi ti o fi jẹ pe owo oṣu mẹrin ninu mẹtalelọgbọn ti ijọba jẹ ni ẹgbẹ oṣiṣẹ ati ijọba f'ẹnuko si fun sisan ko ju pe 'lẹyin ọpọ ijiroro, a wo aṣuwọn ijọba, a ko si lee maa beere ohun ti wọn ko ni la fi ni ki a gba si oṣu mẹrin ọhun."""
Oríṣun àwòrán, @raufaregbesola
Salinṣile ni bi oju ọrọ ti ṣe ri bayii, ko si idi fun ijọba ipinlẹ Ọṣun lati san aabọ owo oṣu mọ
Ẹwẹ, ijọba ipinlẹ Ọṣun ti fi idi ọrọ naa mulẹ.
Olori awọn oṣiṣẹ gomina nipinlẹ Ọṣun, Họnọrebu Rasaq Salinṣile ṣalaye fun BBC Yoruba pe lootọ ni ijọba ti gba lati san owo oṣu mẹrin ninu mẹtalelọgbọn ti ijọba jẹ awọn oṣiṣẹ ati oṣiṣẹfẹyinti nipinlẹ naa lẹyin ifikuluku pẹlu awọn adari ẹgbẹ oṣiṣẹ.
Salinṣile ni bi oju ọrọ ti ṣe ri bayii, ko si idi fun ijọba ipinlẹ Ọṣun lati san aabọ owo oṣu mọ lẹyin eyi nitori ayipada rere to de ba eto iṣuna orilẹede Naijiria lapapọ ati paapaa julọ ipinlẹ Ọṣun.
Iyanṣẹlodi awọn olukọ nileẹkọ giga yii n waye lẹyin bi ọsẹ kan lẹyin ti awọn olukọ nileẹkọṣẹ olukọni ni ilu Ileṣa naa ti gun le iyanṣẹlodi
Ile ẹkọ giga mẹta nipinlẹ Ọṣun ni wọn ti gbe ti pa bayii nitori iyanṣẹlodi awọn olukọ nibẹ.
Awọn olukọ labẹ aṣia ẹgbẹ olukọni ileẹkọ giga gbogbonise lorilẹede Naijiria, ASUP lawọn ileẹkọ giga gbogboniṣe nipinlẹ Ọṣun gunle iyanṣẹlodi naa lati fi ẹhonu han lori aisan owo oṣu mejidinlogun ti ijọba jẹ wọn.
Ọ̀gá Bello: Àìgbọ́n ló ń da àwọn òsèré tíátà tó ń jà lórí ayélujára láàmú
Awọn ileẹkọ giga ti ọrọ kan ni ile ẹkọ giga gbogbonse Poly ipinlẹ Ọṣun ni ilu Iree, ileẹkọ giga imọ ẹrọ ni ilu Ẹsa oke ati ile ẹkọṣẹ olukọni to wa nilu Ila Ọrangun.
Iyanṣẹlodi awọn olukọ nileẹkọ giga yii n waye lẹyin bi ọsẹ kan ti awọn olukọ nileẹkọṣẹ olukọni ni ilu Ileṣa naa ti gu le iyanṣẹlodi.
Amọ, ijọba ipinlẹ Ọṣun ti ni awọn ko tii gbọ nipa iyanṣẹlodi kankan.
Lẹyin ipade gbogbogbo ti wọn ṣe lọgba ile ẹkọ giga gbogboun'se ipinlẹ Ọṣun ni ilu Iree, agbẹnusọ fun ẹgbẹ awọn olukọni ile ẹkọ giga gbogboun'se lorilẹede naijiria, ASUP lawọn ileewe naa, Ọmọwe Jacob Adegbite ni igbesẹ awọn olukọni ọhunda lori ẹhonu wọn.
Awọn olukọni ile ẹkọ giga gbogbo-nse Poly naa n beere fun sisan ẹkunrẹrẹ ajẹẹlẹ owo oṣu wọn fun oṣu mejidinlogun ati gbogbo adehun to wa laarin awọn ati ijọba.
Amọ, ijọba ipinlẹ Ọṣun ti ni awọn ko tii gbọ nipa iyanṣẹlodi kankan.
Kọmiṣọna feto iroyin nipinlẹ Ọṣun, Lani Baderinwa ni 'ijọba gomina Aregbeṣọla ko lee yẹ ipinnu rẹ lori alaafia awọn oṣiṣẹ'
Bunmi Ojo: Ó ń wòran bọ́ọ́lù lọ́wọ́ ni àgbébọn sekú pàá
Oríṣun àwòrán, Facebook/Bunmi.ojo.
Ilumọka oloseelu ni Bunmi Ojo jẹ nipinlẹ Ekiti
Àwọn agbebon kan tí ṣeku pá  arákùnrin Bunmi Ojo nílu Ado Ekiti, níbi tí ọ ti n wò bọọlu lójó ẹtì.
Ọgbẹni Bunmi Ojo, tó ti figba kàn jẹ olùrànlọwọ fun Gómìnà ìpínlẹ̀ Èkìtì tẹlẹri, Segun Ọni pàdé ikú rè nibudo igbafẹ to wa ni Ajitadundun ladugbo Adebayo nilu Ado Ekiti nibi  ti  o ti n wò ifẹsẹwọnsẹ Premiership láàrin Manchester United ati Leicester City.
Ninu igbinyanju BBC Yoruba lati fi idi isẹlẹ yii mulẹ lo mu ka pe alukoro fun ileesẹ ọlọpa nípinlẹ Ekiti, DSP Caleb Ikechukwu, ẹni to sọ pé àwọn kò tí gbọ nipa iṣẹlẹ òhun.
Ṣugbọn awọn kan ti ọrọ náà sójú wọn sọ fún BBC Yoruba pe, looto ni isẹlẹ naa waye.
Sunday Adelaja: Tẹ́tẹ́ làwọn pásítọ̀ tó ń gba owó ‘ìserere’ ń ta
Adekunle Omega, to je olugbe ilu Ado sọ pe ẹni mimọ si oun ni Bunmi Ojo, ti iroyin iku rẹ si jẹ ohun ti o ba ni lọkan jẹ.
''Gbogbo igba ti wọn ba wa sile lati Abuja ni wọn ma n sere pẹlu awọn onisẹ ọwọ mẹkaniki wọn, ni aaye igbafe to wa ladugbo Ajitadundun. Eeeyan daada ni wọn''
Adekunle sọ fun ile isẹ BBC Yoruba wi pe, gbogbo eeyan to mọ Bunmi Ojo, to jẹ Komisana to n soju ipinlẹ Ekiti ninu ajo to n risi igbesẹ aparo kan ko gbọdo ga ju ọkan lọ lorileede Naijiria, (Federal Character Commission) ni iroyin iku rẹ dun.
Bakan naa ni BBC Yoruba kan si Oloye Sẹgun Oni, lati  fidi isẹlẹ yii mulẹ, o ni lootọ ni amugbalẹgbẹ oun nigba kanri naa ti jalaisi, ti iku rẹ si ka oun lara pupọ, amọ oun ko tii lee sọrọ kankan lori isẹlẹ yii.
Loju opo Facebook Ogbeni Bunmi Ojo, isẹ ibanikẹdun orisirisi lawọn eeyan ko sibẹ.
Oríṣun àwòrán, Facebook/Adenitan Akinola
Ikini ikẹdun loju opo Facebook Bunmi Ojo
Oríṣun àwòrán, FACEBOOK/AKOLAWOLE GBENGA
Ikini ikẹdun loju opo Facebook Bunmi Ojo
Ko ti daju idi ti awọn agbebon naa fi pa Bunmi Ojo.
Ni kete ti a ba gborọ lẹnu agbenuso ile isẹ ọlọpa nipinle Ekiti, ni a o jabọ fun yin.
Technovation 2018: Àwọn akẹ́kọ̀ọ́-binrin Naijiria gba ipò kínní
Oríṣun àwòrán, @technovation
Áwọn akẹkọ obìnrin Nàìjíríà naa gbogbo Naijiria ga nínú ìdíje ìmọ ẹrọ l'amerika
Ikọ àwọn akẹ́kọ̀ọ́ obìnrin kan to soju orileede Nàìjíríà ti ṣe bẹ fagba han orílèèdè Amerika, Spain,Turkey, Uzbekistan ati China lati gba ami ẹyẹ ipele àwọn ojẹ-wẹwẹ, nínú ìdíje ìmọ ẹrọ ''Technovation World pitch'' tọdun 2018, to waye nilu San Francisco, ni orilẹ-ede Amerika.
Ikọ naa, ti orukọ rẹ n jẹ ''Save-A-Soul'', se agbekalẹ imọ ẹrọ ayelujara kan, ‘app’ lori ẹrọ̀ alagbeka, ti wọn pe orukọ rẹ ni ''FD Detector''.
'App' naa n sisẹ lati dẹkun itankalẹ ayederu oogun oloro lorileede wọn.
Sunday Adelaja: Tẹ́tẹ́ làwọn pásítọ̀ tó ń gba owó ‘ìserere’ ń ta
Wọn ni ọmọ ti yoo ba jẹ asamu, kekere ni yoo ti maa jẹnu samu-samu. Àwọn akẹ́kọ̀ọ́-binrin Naijiria òhun, lo gba ipò kínní láàrin ẹgbàá oludije tó ṣe àfihàn iṣẹ ọwọ wọn níbi ìdíje náà.
Awọn akẹkọ obinrin naa, yoo gbinyanju lati ta ‘app’ wọn fun awọn oludokowo ni Silicon Valley  nilu California.
Yooba ni bi eegun ẹni ba jo ree, ori a maa ya atọkun rẹ. Aseyori awọn ọmọ obirin naa, ti mu ikinni ku orire wa lati ọdọ awọn ọmọ Naijiria atawọn asaaju wa.
Koda Adele Aarẹ, Yemi Osinbajo ati Aarẹ ile asofin agba, Bukola Saraki naa kan saara si wọn.
Wọn se agbekalẹ idije ''Technovation'', lati gba awọn ọmọ obinrin ni iyanju ki wọn baa le se oun eelo to le mu igbayegbadun ba awujọ wọn.
Oríṣun àwòrán, edufuntechniknig
Eyi ni igba akọkọ ti ikọ oludije ọjẹwẹwẹ Naijiria kankan yoo di abala asekagba idije naa .
Gegẹ bi ohun ti ikọ Save-A-Soul sọ, orileede Naijiria laaye ti gba tita oogun ayederu ju lọ.
Awọn akẹkọ naa to wa lati ipinlẹ Anambra, ni ila oorun guusu orileede Naijiria sọ pe, awọn fẹ pawọpọ pẹlu ajo to n moju to isakoso ounje ati ogun lorileede Naijiria NAFDAC,  ki wọn ba le koju ipenija ayederu ogun.
Lalẹ ọjọbọ ni wọn gba ami ẹyẹ naa lẹyin ti awọn adajọ eto kaakiri agbanlaaye se ayẹwo isẹ wọn.
Àtundi ìbò Katsina: APC ri Sẹnẹtọ túntún kúnrá nílé Asojú-sòfin
Oríṣun àwòrán, Facebook/Ahmad Babba Kaita
Ahmad Babba Kaita yoo jọwọ ipo rẹ nile asojusofin lati di ọmọ ile asofin agba
Ọrọ náà jọ bí eré ṣugbọn kii se ere. Abúrò kan ree ti ko mọ agba lẹgbọn nínú atundi ìdìbò to waye nipinlẹ Katsina.
Ahmad Babba Kaita, ti ẹgbẹ òṣèlú APC lo pegede nínú ìdìbò náà eleyi ti oun ati ẹgbọn rẹ, Kabir Babba Kaita ti ẹgbẹ òṣèlú PDP jijo kojú.
Nínú Iransẹ ìkínni lójú òpó Twitter rẹ, ẹgbẹ òṣèlú APC ki Kabir ku oriire àṣeyọrí rẹ nínú ìdìbò òhun.
Ọ̀gá Bello: Àìgbọ́n ló ń da àwọn òsèré tíátà tó ń jà lórí ayélujára láàmú
Gẹgẹ bí òhun tí wọn fi síta, Ahmad fi ìbò 224,607 tayọ ẹgbọn rẹ, Kabir, tó ní ìbò 59,724.
Ni báyìí, Ahmad Babba ní yóò jẹ Seneto ti yóò maa sójú  ẹkùn àríwá Katsina nile aṣòfin àgbà lorílè-èdè Nàìjíríà.
Anfààní nla ní iyansipo rẹ yóò jẹ fún ẹgbẹ òṣèlú APC pẹlú bí àwọn Seneto kan ṣé fi egbe náà silẹ lọ darapọ̀ mọ́ ẹgbẹ́ òṣèlú PDP laipẹ yìí.
Ọlọ́pàá: À ó wá agbẹ́bọn tó pa ọmọ ikọ IRT mẹ́rin
Oríṣun àwòrán, NIGERIA POLICE/IRT
Mẹ́ta ninu awọn ọlọpaa mẹrin to padanu ẹmi wọn
Kowee ke ko ha ni abule Jankasa, nijọba ibilẹ Rigasa nipinlẹ Kaduna, ni aago mẹfa abọ irọlẹ ọjọ abamẹta, nigba ti awọn gende agbebn dena de awọn ọlọpaa kan to wa lẹnu isẹ wọn ni abule naa.
Lẹyin ija ajaku akata pẹlu ibọn ti wọn fi sere ọwọ, mẹrin ninu awọn ọlọpaa naa dero ọrun, ti wọn ko si tii ri ọkankan ninu awọn janduku ẹda naa mu.
Nigba to n salaye bi isẹlẹ naa ti waye fawọn akọroyin, Alukoro fun ileesẹ ọlọpaa ipinlẹ Kaduna, Sabo Yakubu ni, laipẹ-laijinna ni ọwọ yoo tẹ awọn agbegbọn to da iwa naa ni asa, ti wọn yoo si fi imu wọn ko ata ofin.
Adari ikọ IRT ti ileeṣe ọlọpaa, Abba Kyari, ṣalaye pe bi ikọ̀ òun ṣe ń jáde láti inú igbó ni àwọn akẹgbẹ́ awọn ajínigbé ti awọn ti mú dà'bọn bò wọ́n.
Awọn ọlọpàá tó kú ninu iṣẹlẹ naa ni Benard Odibo, Mamman Abubakar, Haruna Ibrahim ati Emmanuel Istifanus.
Kyari sọ pe wọn ti gbe oku wọn lọ mọṣuari kan ni Ipinlẹ Kaduna, ati pe iṣẹ n lọ lati wa awọn agbebọn naa ri
'Ọ̀lọ́wọ́ òsì kọ́ndọ́rọ́'
Sabo wa n kesi awọn araalu, to ba ni iroyin lọwọ, lori bi wọn se lee ri awọn afurasi ọdaran to sisẹ laabi naa mu, lati tete fi iroyin ọhun sọwọ si ileesẹ ọlọpaa.
Ọọ̀ni: Gbogbo ẹni tó rí tajé se ló yẹ kó tọ́jú ọmọ òrukàn
Ọọni Ile-Ifẹ Ọba Enitan Adeyeye Ogunwusi, Ọjaja keji ti dẹrin pa ẹkẹ awọn ọmọ orukan atawọn ọmọ to ku diẹ kaato fun nilu Ibadan lọjọ aiku, nibi iṣile tuntun fawọn ọmọ orukan.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí:
"Ajo ẹlẹyinju aanu ti Ọba Alayeluwa naa da silẹ, Hopes Alive Innitiatives (HAI)"" wa lati ri daju wipe gbogbo ọmọ orukan ati awọn to kudiẹ  kaato fun lo bẹrẹ sini gbayegbadun, eyi lo mu ki ajọ naa maa lọ lati ipinlẹ de ipinlẹ ninu igbiyanju ati wa ojutu si iṣoro irufẹ awọn eeyan bẹẹ."""
Lasiko to n sọrọ nibi ajọyọ isile naa ni agbegbe Ọmí nilu Ibadan, Ọba Enitan, eni ti Agbolu ti Ilu Agbaje Ọba Adekunle Adebọwale soju fun fi idunnu rẹ han fun aṣeyọri akanṣe iṣẹ naa.
Ìyá Darasimi: Ọlọ́run fi ìbejì rẹ̀ mí lẹ́kún, lẹ́yìn ikú Darasimi tó mu sódà
"O ṣe alaye wipe gbogbo ẹni ti Eleduwa ṣẹgi ọla fun lo ni ojuṣe ati se iranlọwọ fun awọn eeyan to kudiẹ kaato fun.O ni, ""gbogbo ẹni to ri taje ṣe lo yẹ ki o ṣe awokọṣe ajọ ẹleyinju aanu yi,  ki aye le dẹrun fun gbogbo eyan ti ara n ni."""
Ọba Adekunle Adebọwale lo ṣoju Ọọni
Ninu ọrọ tiẹ, igbakeji oludasile ajọ ẹlẹyinju aanu naa, arabinrin Temitọpẹ Morẹnikẹ Adeṣẹgun ṣe alaye wipe Ọọni Ile-Ife Ọba Ogunwusi ṣe agbekale ajo naa pẹlu ajọṣepọ awọn lajọlajọ mii ti kiiṣe tijọba fun anfani awọn ọmọ orukan ati awọn to kudiẹ kaato fun lojunna ati le fun igbe aye wọn ni itumọ ati ibẹrẹ ọtun.
"O tẹsiwaju wipe akanṣe iṣẹ naa ko se e da ṣe fun Ọọni Ile-Ife ni kan, labẹẹ bẹẹ lofi keesi gbogbo ẹni ti nnkan rọrun fun lati fi ifẹ han nipa fifọwọ sọwọpọ pẹlu ajọ naa.O ni, ""Ati ẹni to lowo, ati ẹni ti o toṣi, Ọlọrun lo da gbogbo wa. Ti Ọlọrun ba si fẹ ṣe ni loore, eeyan naa ni yoo lo. Nitori idi eyi ni a fi n keesi gbogbo ẹlẹyinju aanu lati fi ifẹ han si awọn to kudiẹ kaato fun."""
Alamojuto ile awọn ọmọ orukan naa, arabinrin Victoria Adeleke dupe lọwọ Ọba Ogunwusi fun idasilẹ ajo ẹlẹyinju aanu naa, gẹgẹ bi o ṣe parọwa si ọgọrọ awọn eeyan to lowo lọwọ lati se awokọṣe Ọọni Ile-Ife.
Church of Satan: ọ̀rọ̀ Femi Fani-kayode fàbínú àwọn ọmọ ìjọ yọ
Oríṣun àwòrán, Church of Satan archive
Awọn ọmọ ìjọ sàtánì ń bínú sí Nàìjíríà
'Satani wa kọ́ ló ń yọ Nàìjíríà lẹ́nu o'.
Awọn ọmọ ìjọ Sàtánì tí bẹ̀rẹ̀ sí ni bínu sí orílẹ̀-èdè Nàìjíríà lóri ọ̀rọ̀ kan ti Femi Fani-Kayode sọ tó si ń dà èbi ru Sàtánì nínú ọ̀rọ̀ rẹ̀, láwọn ọmọ ìjọ̀ Sàtánì bá fárígá.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí:
Ọdún 1940 ni wọ́n ti ń sin ọ̀ọ̀nì ilé Delesolu ní Ìbàdàn
Wọn ni gbgobo ọ̀rọ̀ tó bá tó ba ti jọ  mọ́ ǹkan ti kò dára ní wọn máa ń da ẹ̀bi rẹ̀ ru Sàtánì; bẹẹ Satani ti àwọn n sìn kìí ṣe buruku.
Mínísítà, fún ètò ìrìnnà orí afẹ́fẹ́ tẹ́lẹ̀ ri, Femi Fani-Kayode, ló fa ìbínú wọn yọ nígbà tó ń bú adelé ààrẹ ọjọgbọn Yemi Osinbajo pé ọmọ iṣẹ́ Sàtánì ni.
Oríṣun àwòrán, Church of Satan archive
Awọn ọmọ ìjọ sàtánì ń bínú sí Nàìjíríà
Femi Fani-Kayode tó jẹ́ ọmọ ẹgbẹ alátakò People's Democratic Party (PDP), sọ pé Ọ̀jọ̀gbọ́n Osínbajo ò yẹ lẹ́ni to lè bẹnu àtẹ́ lu àwọn olùṣọ́ àgùntàn tó hùwà àjẹbánu ni orílẹ̀-èdè yìí nítorí òun gan-an tí dalẹ̀ àwọn àwọn ọmọlẹ́yìn Kírístì
Ọ̀rọ̀ ti Fani Kayode so lórí òpó twitter rẹ̀ tó fa ìbínú tí ìjọ Sàtáni tó ti bẹ̀rẹ̀ láti ọdún 1966 nìyìí:
Ó sọ̀rọ̀ náà nígbà tó ń fèsì sí ọ̀rọ̀ ti Osinbajo sọ láti tako àwọn olùsọ àgùntan tí wọn ni àwọn tako ìgbógun ti ìwà àjẹbanu ti ìjọba àpapọ̀ ń jà àti pé àwọn kìí wàásù lòdì síi.
Ohun tó tún dá kún ìsòro yìí pàápàá ní orílẹ̀-èdè Nàìjíríà ni pé wọn ti dá ààrẹ Buhari lóhùn nígbà kan ri lórí àtẹ̀jíṣẹ́ twitter rẹ lẹ́yìn tó dárukọ Sàtánì.
SMS alert: Wo ọ̀nà láti dẹ́kun jìbìtì lórí àṣùwọ̀n báǹkì rẹ
Ààrẹ Kenyatta: mi ò kọ̀ láti pàdánù ọ̀rẹ́ tó bá lọ́wọ́ nínú ìwà àjẹbánu
Oríṣun àwòrán, EPA
Ọpọ àwọn ọmọ orílèèdè Kenya ni inú wọn dùn sí ìgbésẹ náà
Olóri àjọ ojurin lorileede Kenya àti àjọ tó ń ri sí ọ̀rọ̀ ilẹ títà ti wọ gau lori pé wọn san owó tó lé ní mílíọ̀nù méjì dọ́là gẹgẹ bí owó gbà mábìnú fún ilẹ̀ tó jẹ ti ìjọba.
Mohammed Abdalla Swazurri alaga àjọ ojurin lorileede Kenya ati Ogbeni Atanas Kariuki Maina wa lara awọn ti iwadi kan so pe nise ni wọn san owo gba mabinu oun lọna eru.
Gbogbo àwọn ti igbá ọ̀rọ̀ náà sí mọ lórí  to fi mọ awọn to gba owo naa ní wọn ti pè lẹ́jọ́ pẹ̀lú.
Gbogbo wọn sọ pe àwọn ko jẹ̀bi ẹsun naa.
Ilẹ ti wọn ta ọhun jẹ eleyi ti ijọba Kenya ra ni biliọnu mẹ́ta dọ́là pẹ̀lú ìrànwọ́  China láti ṣe ojú irin tí yóò sọ oluulu Nairobi pẹ̀lú ilu ìdíkọ̀ oju omi Mombasa pọ.
Awọn alatako ijọba bẹnu atẹ lu bi ijọba ti se n na owo lori oju irin naa tohun ti bi ọrọ aje ko ti se gun rege fun orileede naa.
Bakaana lawọn ajafẹtọ ẹranko ni oju ọna ti oju irin naa gba yoo se akoba fun ibudo iko ẹranko si Tsavo ati ti Nairobi.
Lẹnu ọjọ mẹta yii, iroyin orisirisi to ni se pẹlu bi awọn osise ijọba ti se n wuwa jẹgudujẹra tan kalẹ lorileede Kenya .
Amọ Ààrẹ Uhuru Kenyata ti kede pe òún o ni kọ láti pàdánù awọn ọ̀rẹ́ oun toba lọwọ ninu ìwà àjẹbánu.
Ijọba Nàìjíríà pinnu láti dá àwọn èèyàn lókowò N10,000
Oríṣun àwòrán, Getty Images
iṣẹ́ lòògùn ìṣẹ́
Ọṣinbajo ni káàdì ìdìbò kọ́ ni wan a fi san ẹgbẹrun mẹwaa náà fáwọn ènìyàn.
Ijọba Naijiria ti kede pe wọn yoo pese ẹgbẹrun mẹwaa owo iranwọ fawọn oniṣowo keekeeke jakejado Naijiria.
Lẹyin tijọba ṣe ìkede yii ni BBC jade lọ ṣe iwadii oriṣii irufẹ ọja tabi okòwò ti èèyàn le fi ẹgbẹrun mẹwaa naira ṣe lasiko yii pẹlu bi ìta ṣe rí.
Ọpọlọpọ lara awọn ti BBC ba sọrọ ni àwọn ti sẹ okowo loriṣii pẹlu owo ti kò to ẹgbẹrun mewaa naira sẹyin.
Ọ̀ṣọ́ Aṣọ Òkè ti kọjá lílo ìlẹ̀kẹ̀ níkan
Iwadii BBC fihan pe eniyan le maa ta aṣọ àlòkù oyinbo ti àwọn kan n pe ni òkìrìkà ni ẹyọ.
Awọn mii gba pe ẹni ti kò ba ni itiju iṣẹ le maa ta èso bii ọsan, ibẹpẹ, ọ̀pẹ̀ oyinbo àti bẹẹ bẹẹ lọ.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ibi gbogbo lo gba alagbara
Àwọn oniṣowo kan sọro lori tita ohun mimu tutu bii ẹlẹrindodo ati omi tutu ninu ọ̀rá àti nínú ike.
Ero awọn miran ni síse ounjẹ ta nitori wi pe, ojumọ kan kò ni mọ́ ki ẹnu má gba ẹbọ ounjẹ.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
olounjẹ ni oloogun ebi
Imọran àwọn oniṣowo mii ni pe ki wọn maa ta àwọtẹlẹ obinrin bii kọ́mú àti pátá àti tọkunrin naa ni èrè lórí ti ko si nilo owó okowo to pọ ju.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ọ̀lẹ nìkan lààyè kó gbà.
Igbagbọ awọn mii nipe àtẹlẹwọ́ ẹni kìí tan ni jẹ. Pe iṣẹ́ ọwọ́ ni o yẹ ki èèyàn fi ẹgbẹrun mẹwaa naa dá silẹ̀ ki o le maa mu owó wole sii.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Àtẹlẹwọ ẹni kò le tan ni jẹ
Oriṣi iṣẹ ọwọ bii aránṣọ, irun gigẹ, irun dídì, kafinta àti bẹẹ bẹẹ lọ.
Omiran tun ni iṣẹ alagbafọ aṣọ fifọ ni eyi to dabi apọnmita ti ko le kuna loju awọn kan.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Alagbafọ ko le ṣai ṣere eti odo
Bimpe: Èèyàn bíi tiyín ni àfín, ẹ dẹ́kun dídẹ́yẹsí àfín
SMS alert: Wo ọ̀nà láti dẹ́kun jìbìtì lórí àṣùwọ̀n báǹkì rẹ
FEC: Ìgbìmọ tuntun dìde láti sàtúntò ọlọ̀pàá
Oríṣun àwòrán, Federal Govt/twitter
Ìjọba bẹ̀rẹ̀ ìgbésẹ̀ àtúntò ọlọ̀pàá
Ìgbmọ tó ń moju to ètò ọrọ̀ ajé ti sàgbé dìde ìgìmọ tẹ̀ẹ́kótó lati mu ojuṣe ilé iṣẹ́ ọlọpàá pín sí ipele.
Olúbádámọran lórí ètò ààbò Babangida Munguno ló sísọ lójú ọ̀rọ̀ náà lẹ́yìn ìpàdé àwọn aláṣẹ ìjọba, èyí ti adele ààrẹ ọjọ̀gbọ́n Yemi Osinbanjo ní ile ààrẹ l'Abuja lónìí.
Mungono sàlàyé pé Ìbrahim Idris tó jẹ́ ọgá àgbà ọlọ́pàá, ní yóò jẹ́ alága ìgbìmọ tí àwọn asojú ẹkùn mẹfẹ̀fà yóò wà níbẹ̀.
Ó tọ́ka síi pé Nàìjíríà ń koju àwọn ǹkan to lòdí pàápàá jùlọ lórí ètò ààbọ.
Olùbádàmọ̀ràn pàtàkì fún ààrẹ tún fi kún pé ìjọba àpapọ̀ ń mójú to àwọn ìpèníjà míràn tó ń jẹyọ láti ẹ̀yìn odi orílẹ̀-èdè yìí.
Gẹ́gẹ́ bó ṣe sọ, àwọn ìdojúkọ ètò ààbò yìí ní gbogbo ilé iṣẹ́ elétò ààbò ń ṣe àtòpọ̀ rẹ̀, o fi kún pé àwọn ìgbìmọ míràn yòó tún dìde láti máa ṣe àbẹwò láti rẹyin gbpogbo ìdojukọ lori ààbo
Ìdìbò 2019: INEC fẹ́ ná N6bn lórí ounjẹ fún àwọn ọlọ́pàá
Àjọ́ eleto idibo INEC ni awọn yoo na N6bn sori ounjẹ ti awọn ọlọpàá ti yoo kopa ninu eto idibo gbogboogbo 2019 a jẹ.
Alaga INEC, ọjọgbọn Mahmoud Yakubu ni o sọ bẹẹ nigba ti o gbe eto iṣuna idibo 2019 ti ajọ naa gbé siwaju ile igbimo aṣojuṣofin ni Abuja l'Ọjọru.
Awọn aṣofin naa ti iye owo ọhun ko ba lara mu ti ni ajọ naa gbọdọ ṣalaye bi yoo ṣe na owo naa.
Bakan naa, igbimọ awọn gomina Naijiria ti ni awọn gomina ipinlẹ mẹrindinlogoji orilẹ-ede yii na N2trn ni aarin ọdun mẹwaa lati ṣe iranlọwọ for ileeṣẹ ọlọpaa.
Oríṣun àwòrán, Fedral Govt/ Twitter
Eto idibo 2019 ti n kan ilẹkun
Agbẹnusọ igbimọ naa, Abdulrazaque Barkindo, lo sọ bẹẹ ni Abuja ni ọjọ Iṣẹgun, nibi to ti ṣalaye pe iwadii ẹka igbimọ naa lo fi ọju iye owo naa lede.
"O ni, ""Ni ọdun 2015, Ipinlẹ Eko nikan, labẹ iṣakoso Gomina Akinwunmi Ambode, na N4.765bn lati ran ileeṣẹ ọlọpaa lọwọ."""
'Ọ̀lọ́wọ́ òsì kọ́ndọ́rọ́'
INEC yoo sun miliọnu meje kaadi idibo
River Nile: Ọmọ ilé-ìwé Kenba 24 ló kú s'ómi ní Sudan
Afi ki ọlọrun ma jẹ ki abiyamọ fojú sunkun ọmọ.
Afi ki ọlọrun ma jẹ ki abiyamọ fojú sunkun ọmọ.
Sùgbọn ni ti àwọn obí ọmọ mẹrinlélógun ile -iwe Kenba High School to padanu ẹmi wọn ni orilẹ-èdè Sudan ni ko ri bẹẹ fun.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí:
Ìṣẹlẹ ọ̀hún ló waye ní ìhà ariwa Sudan lasiko ti awọn ọmọ náà ń lọ si ile ẹkọ wọn, wọn ni ojiji ni ẹnjini bajẹ ti ọkọ oju omi náà si bẹ̀rẹ̀ si ni ri.
Yatọ si àwọn ọmọ wọnyìí ninu ọkọ àwọn oṣiṣẹ eto ilera náà wa nínú ọkọ ti wọn si bomilọ
Oríṣun àwòrán, BBC
Oku ọmọ meji pere ni wọn
Wọn ni ogoji ọmọ lo wa ninu ọkọ oju omi to rì náà sugbọn ti ori ko àwọn to ku yọ lágbegbe odo Nile.
Ọmọ ọdun meje si mẹrindinlogun ní àwọn ọmọ to wa ninu ọkọ náà gẹgẹ bii ọga agba ile-iwe náá, Ab el-Khayr Adam Yunis, ṣe sọ fun BBC àti pe ẹru lo ba awọn ọmọ náà nigba ti ẹngini sọsẹ silẹ ti gbogbo wọn si wọ jọ soju kan èyi to faa ti ọkọ oju omi náà fi doju de.
Oku ọmọ meji pere ni wọn ṣi rí.
Ẹni ti ko riran to nlọ'ta ni Mushin
Wùnmí Toríọlá: Toyin Abraham kìí se ọ̀gá mi nínú tíátà
'Ilé orin wa tí Ajimobi tun kọ́ dára púpọ̀, ṣùgbọ́n a kò ní dẹ́kun òtítọ́'
Oríṣun àwòrán, @yinkaayefele
Ayefele
Lẹyin oṣu mẹta ti Ijọba Ipinlẹ Oyo wo ileeṣẹ orin Yinka Ayefele to wa ni agbegbe Challenge, Ibadan, o ti dupẹ lọ́wọ́ Gomina Ipinlẹ naa, Abiola Ajimọbi, bo tilẹ jẹ pe o ni oun ko ni dẹkun lati maa sọ ootọ ọrọ to maa ṣe ara ilu lanfani.
O sọ fun BBC Yoruba pe eyi ti ijọba kọ wayi tilẹ̀ dara ju ti eyi ti wọn wo lọ.
Ilé orin wa tí Ajimobi tun kọ́ dára púpọ̀, ṣùgbọ́n a kò ní dẹ́kun òtítọ́
Ẹ o ranti wi pe oṣu kẹjọ ni Ipinlẹ Oyo wo ileeṣẹ orin naa latari pe ko gba iwe to tọ. Igbesẹ naa bi awọn ara ilu ninu gidi.
Ṣugbọn Ayefele ni oun ko ba ijọba ja, bẹẹ ni oun ki i ṣe ọta Ajimọbi.
Oríṣun àwòrán, David Ajiboye
Ijọba ipinlẹ Ọyọ ni 'aigbọran Yinka Ayefẹlẹ lo mu ki awọn wo ileeṣẹ rẹ.'
Látàrí ìlérí tí gómìnà ìpínlẹ̀ Ọyọ, Abiọla Ajimọbi ti ṣe láti wá ǹkan ṣe sí ilé iṣẹ́ rẹ́díoò Yinka Ayefẹlẹ tí wọ́n wó, ó ti ṣèpàdé pẹ̀lú olórin náà.
Níbi ìpàdé àtilẹ̀kùnmọ́rí ṣe ọ̀hún, àwọn lọ́ba lọ́ba wà níbẹ̀ tó fi mọ́ olùgbani nímọ̀ràn àgbà fún gómìnà lórí ìṣe dára dára, ọ̀mọ̀wé Isaac Ayandele.
Àwọn lọ́ba lọ́ba náà bá wọ́n pé níbi ìpàdé náà
Ẹ̀wẹ̀, ní àkókò tí ikọ̀ oníròyìn wa kó ìròyìn yìí jọ, a kò tíì mọ àbájáde ìpàdé náà.
Ajimọbi: Pé Ayefẹlẹ jẹ́ àkàndá kò fún láṣẹ láti rú òfin
Ṣáájú àkókò yìí, gomina ipinlẹ Ọyọ Abiọla Ajimọbi ti sọ ninu fọnran awọran tó wà loke yii pe oun yoo wa nnkan ṣe si ọrọ ileeṣẹ Fresh Fm, to jẹ ti gbaju-gbaja onkọrin Yinka Ayefẹlẹ, eleyi to ti di orisun awuyewuye bayii lẹyin ti ijọba wo ile naa ni owurọ ọjọ aiku.
Ninu ọrọ kan to ba awọn akọroyin sọ lẹyin to kirun ọdun ileya tan ni yidi Agodi nilu Ibadan, ni gomina Ajimọbi ti sọ ọrọ yii.
O ni ko si ẹni to tayọ ofin bi o ti wu ki ipo ti ẹni bẹẹ ba wa ṣe lee ri lawujọ.
Ìgbé ayé Instagram fún ọ́sẹ̀ kan
Gomina Ajimọbi ni, ni iwoye ti oun, ibi ti ileeṣẹ Ayefẹlẹ wa ko ba ofin mu ati pe, awawi ni ohun ti awọn kan n sọ kiri pe akanda ẹda ni, to si n gba ọpọlọpọ eeyan siṣẹ.
Ṣe awọn adigunjale naa ko gba eeyan siṣẹ ni ? Abi ka sọ pe tori pe wọn gba awọn eeyan si ẹnu iṣẹ, ka fi wọn silẹ.
Ayefẹlẹ: Orí ìkúnlẹ̀ ni ìyàwó mi wà, tó ń bẹ gómìnà, láti 11pm si 4am
Fidio oke yii lo n salaye ipade akọroyin ọtọọtọ, ti ijọba ipinlẹ Ọyọ ati Yinka Ayefẹlẹ se lori ileesẹ Fresh FM ti ijọba wo lulẹ lọjọ Aiku, amọ ti alaye igun kọọkan lori isẹlẹ naa tako ara wọn
Ohun tó wà lórí ilẹ̀ Ayefẹlẹ́ ju àsẹ tó gbà lọ - Ìjọba Ọ̀yọ́ .
Wayi o, Ijọba ipinlẹ Ọyọ ti ṣe alaye wipe, eti ikun ti gbaju-gbaja akọrin juju, Yinka Ayefẹlẹ kọ si aṣe ajọ to n risi aato ati idagbasoke ilu, lo mu ki ijọba wo apa kan ile iṣẹ redio rẹ.
Akọroyin BBC Yoruba to wa nibi ipade akọroyin naa, Adedayọ Okedare jábọ̀ pe, adari ajọ to n risi aato ati idagbasoke ilu nipinlẹ Ọyọ, Waheed Gbadamọsi lo ṣe alaye ọrọ ọhun, nibi ipade awọn akọroyin to waye nile iṣẹ ijọba ipinlẹ Ọyo l'ọjọ Aje.
"Gbadamọsi ni ""awọn ile iṣẹ igbohun safẹfẹ mejilelogun ọtọọtọ ni ijọba kesi, lati ṣe afihan iwe aṣẹ ti wọn fi kọ ile iṣẹ wọn ninu osu Kaarun ọdun 2017."
Ijọba ni ile iṣẹ naa ko lẹtọ lati kọ apa ibi ti ijọba wo, lai ṣe ohun ti ijọba fẹ.
"Ati pe iṣẹ iwadi ati abẹwo ti awọn asoju ijọba ṣe si ile iṣẹ redio Ayefẹlẹ, lo fi idi ọrọ mulẹ wipe gbajugbaja olorin naa ti tayọ aṣẹ ti ijọba fun un."""
Ijọba fi ẹsun kan pe, yatọ si ojupopo ti ile iṣẹ naa bọsi, to si n ṣe fa ijamba ọkọ ni agbegbe naa, ile igbọnsẹ, yara idana, gbọngan igbalejo ati pẹtẹsi to n bẹ lẹyin ile naa, tako aṣẹ ti ijọba buwọlu.
O fikun ọrọ rẹ wipe, lati inu osu kẹfa ọdun 2017 niwọn ti kọwe si Ayefele lati wa se atunṣe, sugbọn o kọ eti ọgboin sijọba.O ni ile iṣẹ naa ko lẹtọ lati kọ apa ibi ti ijọba wo, lai ṣe ohun ti ijọba fẹ.
Ohun elo igbohun safẹfẹ ti owo rẹ ko din ni milliọnu mejidinlọgbọn naira lo da wo lasiko ti ijọba ipinlẹ Ọyọ fi katakata wo ile iṣe redio Fresh Fm ti o jẹ ti gbajugbaja akorin juju, Yinka Ayefẹlẹ lojo Aiku.
Adari ipolongo fun ile iṣe redio naa, David Ajiboye lo sọ ọrọ ọhun di mimọ lasiko to n ba awọn oniroyin sọrọ ninu ọgba ile iṣẹ naa to wa ni opopona Challenge, Ibadan.
Ajiboye bẹnu atẹ lu ijọba ipinlẹ Ọyọ pẹlu ẹsun wipe igbese naa lọwọ oṣelu ninu.O ni ọjọ Aje, ogunjọ osu Kẹjọ lo yẹ ki awọn aṣoju ile iṣẹ redio naa ati ijọba ipinlẹ Ọyọ jọ pade nile ẹjọ giga kan nilu Ibadan lori ọrọ ọhun, sugbọn ìjọba ipinlẹ Ọyọ ko duro de asiko ti ile ẹjọ da ki o to ṣe ifẹ inu rẹ.
Ajiboye bẹnu atẹ lu ijọba ipinlẹ Ọyọ pẹlu ẹsun wipe igbese naa lọwọ oṣelu ninu.
Ọrọ yi ni ọwọ oṣelu ninu, a si mọ wipe kọmiṣọna fun eto iroyin ati aṣa nipinlẹ Ọyọ, Toye Arulogun lo wa nidi ẹ nitori lọpọlọpọ igba lo ti pe wa wipe ki a paarọ awọn eto wa kan nitori wọn n tako ijọba.A si sọ fun-un wipe ile iṣẹ olominira le yi.
"Awọn ile iṣẹ igbohun safẹfẹ ti o jẹ ti ijọba ni wọn le paṣẹ fun.""Ajiboye tẹsiwaju wipe aifi aye silẹ fun ijọba ipinlẹ Ọyọ lati tọwọ bọ eto ile iṣẹ redio naa loṣokunfa igbeṣe ati lo ọwọ agbara.O se afikun ọrọ wipe ile iṣẹ redio naa yoo duro de idajo ile ẹjọ lori ọrọ ọhun."
Ìdí ti gómìnà Ajimobi fi wo ilé mi- Ayefelẹ
Oludasilẹ ileesẹ Fresh Fm, Yinka Ayefẹlẹ ti fesi si bi ijọba ipinlẹ Ọyọ se wo ileesẹ redio naa ni kutu hai aarọ ọjọ Aiku.
Yinka Ayefẹlẹ, lasiko to n sọrọ lori redio ọhun, Fresh FM, to bẹrẹ isẹ pada lẹyin wakatai meji ti ijọba wo ile naa, rọ awọn araalu to n se atilẹyin fun-un, lati mase da rogbodiyan kankan silẹ lori isẹlẹ naa.
O tun dupẹ lọwọ gbogbo agbaye fun atilẹyin wọn pẹlu afikun pe ibi to ba le, la n ba ọmọkunrin.
"Ẹ ni suuru, ẹma fa rogbodiyan, to ba jẹ pe lootọ lẹ́ ni ifẹ́ mi, mo bẹ yin ni, ẹ mase jo ọkọ ijọba to wa nilẹ.
Bi ijọba tilẹ wo ileesẹ, redio Fresh FM ko lee wo lailai, tori araalu lo nii."
"Bakan naa ni Ayefẹlẹ tun dupẹ́ pupọ lọwọ ijọba ipinlẹ Ọyọ fun ibi ti wọn sin oun de, o si tun dupẹ lọwọ kọmisana f'eto iroyin, Toye Arulogun, pe oun lo pilẹ ọrọ bi wọn yoo se wo ile oun, oun si ki pe o ku aseyọri lori isẹ naa.
Igbimọ awọn ọdọ nilẹ Yoruba ti koro oju si igbesẹ ijọba ipinlẹ Ọyọ lori ileesẹ redio Yinka Ayefẹlẹ, Fresh FM.
Ninu atẹjade kan ti Aarẹ ẹgbẹ naa, Arẹmọ Ọladọtun Hazzan fi ọwọsi lọjọ Aiku, ẹgbẹ naa ni, isẹlẹ naa jẹ iwa aṣilo agbara, ọtẹ oselu ati titẹ ẹtọ ẹni loju, nitori pe o yẹ ki ijọba duro de idajọ ileejọ na, ko to lọ wo ileesẹ redio naa.
Awa ọdọ nilẹ Yoruba n bu ẹnu atẹ lu igbesẹ ti ijọba gomina Abiọla Ajimọbi tipinlẹ Ọyọ gbe lati wo ileesẹ redio Fresh Fm, eyi to si lewu fun alaafia orilẹ-ede yii."
A wa n kesi ileesẹ aarẹ, ile asofin apapọ, adajọ agba lorilẹ-ede yii ati gbogbo ọmọ Yoruba pata-pata, pe ki wọn tete yọ suti ete si iwa bayii ko to bọwọ sori.
Awọn eeyan ya kẹti-kẹti lọ si ileesẹ redio Fresh FM lẹyin ti ijọba wo ile naa.
Lara wọn ni ọkan ninu awọn oludije fun ipo gomina ipinlẹ Ọyọ l'abẹ ẹgbẹ oselu PDP, Onimọ-ẹrọ Seyi Makinde.
Oríṣun àwòrán, David Ajiboye
Ijọba ipinlẹ Ọyọ ni 'aigbọran Yinka Ayefẹlẹ lo mu ki awọn wo ileeṣẹ rẹ.'
"O ni ""Ni aye ọlaju ati ijọba tiwa-n-tiwa ta n se yii, iru igbesẹ wiwo ile bayii ko bojumu rara."""
Ṣaaju iṣẹlẹ naa ni gomina tẹlẹ nipinlẹ Ọyọ, Sẹnetọ Rasheed Ladọja ati Engr Seyi Makinde parọwa sijọba ipinlẹ Ọyọ ninu atẹjade ọtọọtọ, lati mase wo ileesẹ redio naa,  .
Bakan naa niasọfin lati nipinlẹ Ọyọ, to jẹ ọmọ ẹgbẹ oselu APC to n tukọ ijọba ipinlẹ Ọyọ lọwọ, Dapọ Lam-Adesina, naa wa sibi iṣẹlẹ naa, to si ni 'iwa ika bẹ ẹ ko dara rara.'
Dapọ Lam Adesina ni, o yẹ ki ijọba ipinlẹ Ọyọ duro de idajọ ileẹjọ ko to lọ̀ da ileesẹ redio naa wo niwọn igba ti ọrọ naa ti wa niwaju ileẹjọ.
Oríṣun àwòrán, Olusina Olabode
Lẹyin ọpọlọpọ awuye-wuye to ti waye lori iwe kan ti ijọba ipinlẹ Ọyọ fi sita pe, oun yoo wo ileesẹ redio Fresh Fm, ti gbaju-gbaja olorin juju n ni, Yinka Ayefẹlẹ da silẹ, ijọba ipinlẹ Ọyọ ti mu ipinnu rẹ sẹ, to si ti bi ile naa wo.
Akọroyin BBC Yoruba to wa nibi isẹlẹ naa ni, deede aago mẹrin aarọ ọjọ Aiku ni awọn ẹrọ kata-kata ijọba ipinlẹ Ọyọ de si adugbo Challenge, nilu Ibadan ti ileesẹ naa wa, ti wọn si wo lulẹ.
Ọpọ eeyan ti ara aje n ta, lo n gbarata lori igbesẹ ijọba naa, tawọn eeyan miran si n bu sẹkun nibẹ.
A gbọ pe lasiko ti wọn fẹ bẹrẹ si gbe eto safẹfẹ lori redio Fresh FM ni isẹlẹ naa waye, ti wọn si tete ti ileesẹ redio naa pa.
Oríṣun àwòrán, @yinkaayefele/@tolanialli
Yinka Ayefẹlẹ ní àwọn olóṣèlú ló ní kí Gómìnà Ajimọbi wó iléèṣẹ́ rédíò òun
Gbajugbaja olorin ni, Yinka Ayefẹlẹ ni kọmisana fun eto iroyin ati aṣa nipinlẹ Ọyọ, Toye Arulogun lo wa nidi bi ijọba ṣe fẹ ẹ wo ileeṣẹ igbohun s'afẹfẹ oun, Fresh FM, to wa nilu Ibadan.
Ninu ọrọ to ba BBC Yoruba sọ, Ayefẹlẹ ni oun gba awọn iwe to yẹ ki oun to kọ ile naa. Ati pe ara ijọba ipinlẹ Ọyọ kọ otitọ ọrọ ni wọn ṣe fẹ gbe igbesẹ naa.
O fi ẹsun kan kọmisana naa pe o sọ̀ fun ileeṣẹ redio naa lati da awọn eto kan 'to n tọka si awọn nkan ti ko dara ninu eto iṣakoso ijọba Gomina Abiola Ajimọbi.
Yinka Ayefẹlẹ ni awọn ololufẹ ileeṣẹ igbohun s'afẹfẹ Fresh FM, to jẹ agbẹjọro ti gbe ijọba ipinlẹ Ọyọ lọ s'ile ẹjọ.
Ẹkunrẹrẹ ọ̀rọ̀ rẹ n bẹ ninu fọnran yii:
Ayefẹlẹ - Ara ìjọba ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́ kọ òtítọ́ ní wọ́n ṣe fẹ́ wó iléèṣẹ́ rédíò mi
Ọjọ kẹtala, oṣu Kẹjọ ni ijọba kọ lẹta si ileeṣẹ redio Fresh FM pe ko 'gbe ile naa kuro nibi to wa laarin ọjọ mẹta, bi bẹ ẹ kọ, wọn yoo wo ni.
Ọjọ mẹta naa ti tẹnubodo lọjọ kẹẹdogun.
Sugbọn nigba ti a kan si kọmisana fun eto iroyin ati aṣa nipinlẹ Ọyọ, Ọgbẹni Toye Arulogun, ti Yinka Ayefẹlẹ fi ẹsun kan pe oun lo wa nidi iṣẹlẹ naa, Arulogun ni 'ti wọn ba sọ pe oun ni, oun naa ni.'
Oríṣun àwòrán, Toye Arulogun Snr/Facebook
Ayefẹlẹ ko sọ fun ijọba ipinlẹ Ọyọ̀ pe oun yoo lo 'Music House' fun ileeṣẹ redio nigba to fẹ gba iwe aṣẹ lati kọ ọ
Ati pe ki i se nkan ti Yinka Ayefẹlẹ sọ pe oun fẹ fi ile naa ṣe nigba to fẹ ẹ gba iwe aṣẹ lo fi ṣe. O ni ko si adehun redio ninu adehun to ba ijọba ṣe.
Ẹwẹ, Kọmisọna fun ọrọ ayika nipinlẹ Ọyọ, Oloye Isaac Ishọla ni ko ni nkankan ṣe pẹlu Yinka Ayefẹlẹ, bi ko ṣe ofin ijọba to sọpe ẹni to ba fẹ ẹ k'ọle gbọdọ fi alafo amita marunlelogoji silẹ si oju popo.  Ahesọ nipe tori wọn n sọrọ sijọba ni. Ibi ti wọn kọ ile naa si ko ba ofin mu.
O ni 'bi ẹẹmẹta nijọba ti kọ lẹta si i, sugbọn ti wọn ko dahun. Ati pe ile naa n fa ijamba.
Eniyan to ti padanu ẹmi wọn lati bi oṣu mẹsan nitori ibi ti ile naa wa , koda osisẹ wọn kan naa jana mọ mọto lẹnu.'
Kofi Annan: Ọbasanjọ àti Saraki nàá bá wọn péjú síbi ìsìnkú
Kofi Annan
O darinako, odi oju ala.
Lẹyin ayẹyẹ isinku to waye lorileede Ghana l'Ọjọbọ,wọn ti sin oku akọwe ajọ isọkan agbaye nigba kan ri, Kofi Annan.
Awọn to wa nibi isinku naa ni titi lai , awọn ko ni gbagbe ipa ti Kofi Annan ko.
Jakejado agbalaaye lawọn àalejo ti wa lati ba ẹbi Annan kẹdun ipapoda rẹ.
Oríṣun àwòrán, PIUS UTOMI EKPEI/AFP/Getty Images
Nínú wọn là ti ri Ààrẹ orílèèdè Naijiria nigba kan ri Olusegun Obasanjo,Aarẹ ologun Naijiria tẹlẹ ri Ajagunfẹyinti Abdulsalam Abubakar àti akọwe apapọ àjọ iṣọkan orílèèdè  àgbáyé  Antonio Gutierrez.
Oríṣun àwòrán, Facebook/bukola.saraki
Senatọ Bukọla Saraki to jẹ Aarẹ ile asofin agba Naijiria naa pẹlu iyawo rẹ, Toyin Saraki naa pejọ sibi ẹyẹ ikẹyin fun Kofi Annan.
Oríṣun àwòrán, FACEBOOK/bukola.saraki
Oríṣun àwòrán, Other
Fọ́fọ́ ni gbọ̀ngàn Accra International Conference Center kún fún èèrò láti dágbere fún Kofi annan
Oríṣun àwòrán, AFP
Orin ìyìn àti ọrọ àyọkà lorisirisi ni o wáyé níbi ètò ìsìnkú náà nibi ti ìbátan Akọwe àgbà nígbà kan rí náà, Kojo Amoo Gottfried ka ọrọ ìrántí nipa Kofi Annan.
Awọn lọbalọba ni ilu Ghana naa jade wa lati wa se ẹyẹ ikẹyin fun Annan
Nínú rẹ lọ ti ṣe àpèjúwe bí Annan ti ṣe darí ifehonuhan kàn lati tako bi wọn ti ṣe n fún àwọn akẹkòó ni oúnjẹ tí kò sunwọ̀n nigba ti ọ wá ni ilé ẹkọ gírámà Mfantsinin ni ilu Accra.
Oríṣun àwòrán, EPA
Tìlù-tìfọn ni wọ́n fi sin Annan lọ s'ọ́run
Nínú awọn míràn to sọ ọrọ ìwúrí ni ìyàwó Annan,Nane Maria Annan ati awọn mọlebi rẹ míràn.
Oríṣun àwòrán, AFP
Wọ́n ti kọ́kọ́ tẹ́ Annan ní ìtẹ́ ẹ̀yẹ lẹ́yìn tí òkú rẹ̀ gúnlẹ̀ sí orílẹ̀èdè Ghana láti Switzerland
Iyawo rẹ ni kò si ìgbà tí Annan ba n pada wá sí ilẹ tí inú rẹ kìí dùn.
Oríṣun àwòrán, AFP
Iyawo Koffi Annan, Nane wa lẹgbẹ rẹ̀ nigba to dagbere faye
Awọn oju opo ikan sira ẹni kun pitimu fun oniruuru idaro lati ẹnu awọn eekan ilu lagbaye.
Ninu atẹjade kan to fi sita loju opo Twitter, Aarẹ Muhammadu Buhari daro pẹlu awọn ẹbi Kofi Annan lorukọ awọn ọmọ Naijiria.
Buhari ni iwa irẹlẹ ati ifẹ fun agbega ọmọniyan lo mu ki Kofi Annan tayọ lagbaye.
Ninu idaro tiẹ, olootu ijọba ilẹ Gẹẹsi, Theresa May, ni iku Annan ka oun lara pupọ, asaaju to dantọ, ati olurapada ajọ isọkan orilẹ-ede agbaye, ẹni to ko ipa ribi-ribi lati mu ki aye dun gbe ju bo se baa lọ.
Tun wẹ, aarẹ orilẹ-ede Faranse, Emmanuel Macron naa daro ẹni re to lọ. O ni lojiji ni Annan faye silẹ lai dagbere.
Macron ni gbogbo agbaye ko ni gbagbe iwa pẹlẹ ati oju akin to ni.
Ninu atẹjade kan, Aarẹ orilẹede Ghana, Aarẹ Akufo-Addo fọwọsi, o ni iku oloogbe naa ba oun ati iyawo oun, Rebecca ni ojiji.
O se apejuwe Annan gẹgẹ bii ẹni to jẹ asoju rere fun orilẹ-ede Ghana lawujọ agbaye.
Oríṣun àwòrán, AFP
"Gẹgẹ bi ajọ alaanu kan to da sile ti wi, ""wọọrọ-wọ ni iku mu Kofi Annan lọ lasiko aisan ranpẹ to see àti pe ilumọka ni lagbaye, nitori o ja fita-fita ni gbogbo ọjọ aye rẹ fun ipese alaafia jake-jado agbaye."
"Ajọ naa ni ""Ti aini kan ba wa, o maa n na ọwọ sita lai tii kan sawọn eeyan pẹlu oju aanu ati iyọnu nla. O maa n fi awọn eeyan miran siwaju ara rẹ,o ni ikonimọra ati ọpọlọ pipe ninu ohunkohun to ba dawọle."""
Kofi Annan, tii se ọmọ bibi ilẹ Ghana, lo n gbe orilẹ-ede Geneva fun ọjọ pipẹ, nibi ti ọlọjọ ti de baa.
Annan ti gba ami ẹyẹ olufẹ alaafia lọdun 2001 lori awọn akanse isẹ aanu to ti gbe se nigba aye rẹ ati bo se ta ajọ United Nations ji pada.
Oríṣun àwòrán, @theresa_may
Annan ni adúláwọ̀ àkọ́kọ́ tí yóò jẹ àkọ̀wé àpapọ̀ fájọ isọkan orilẹ-ede agbaye, United Nations, to si wa ni ipo naa fun saa meji ọtọọtyọ̀, eyiun ni aarin ọdun 1997 si 2006.
Lẹyin naa lo sisẹ gẹgẹ bii asoju ajọ isọkan agbaye si orilẹ-ede Syria, to si siwaju ikọ apẹtu-saawọ to lọ yanju ija ni Syria.
Asiko ti Annan wa lori oye bii akọwe agba ajọ isọkan agbaye ni ogun bẹ silẹ ni orilẹ-ede Iraq, to fi mọ bi akoko ti ajakalẹ́ arun asekupani HIV/Aids gbalẹ kan
Ẹ̀kún omi India: Ìsẹ̀lẹ̀ náà ló tíì burú julọ́ làti ọgọ́rùn-ún ọdún sẹ́yìn
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Awọn eniyan ni Cochin n lo gbogbo ọkọ ti wọn le ri lati sa kuro nibi ti omiyale wa
Eniyan to ju ọọdurun lọ ti padanu ẹmi wọn ninu isẹlẹ́ ẹkun omi to fa ilẹ riri ni ipinlẹ Kerala to wa ẹkun Guusu India. Iroyin sọ wipe, awọn to tun to ẹgbẹrun lọna ọọdurun miran lo ti di alainile lori bayii lẹyin ojo arọọrọda ni orilẹede naa.
Minisita agba fun Kerala ni omiyale yii lo tii buruju lati bi ọgọrun ọdun ni orilẹede India.
Awọn oṣiṣẹ pajawiri naa sọ pe, lati igba ti ojo ti bẹrẹ ni India ni oṣu kẹf ọdun 2018, eniyan bii ẹgbẹrun kan lo ti ku.
Oríṣun àwòrán, AFP
Awọn oṣiṣẹ pajawiri ni ẹkun Kozhikode fun awọn ara ilu lounjẹ
Akoroyin BBC to wa nibẹ sọ pe, awọn ara ilu ni Cochin ta okun si awọn adugbo ki awọn ti o ba fẹ sa asala fun ẹmi wọn baa ri nkan di mu.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ọpọlọpọ awọn agbalagba ti ko le rin daadaa lo ha sinu omiyale naa.
Awọn ologun naa wa lara awọn to n dola ẹmi awọn ara ilu. Pẹlu ọkọ oju omi ati ọkọ ofurufu ni awọn ologun bọ si igboro lati ran awọn eniyan lọwọ.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
A gbọ pe Kerala ni odo mọkanlelogoji to n domi sinu okun Arabia, ọgọrin adagun odo to wa leti awọn odo naa lo ti ṣi bayii, nitori pe agbara wọn ko ka awọn odo naa mọ.
Adí-àgbọn: Ọ̀jọ̀gbọ́n Fasiti Harvard ní kẹ má mu àdí-àgbọn mọ́
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Májèlé ni àdín àgbọn
Ọ̀jọ̀gbọ̀n kan ní Fasiti Harvard, Karen Michels ní, májelé pọnbélé ni òróró àgbọn ti à mọ sí àdínagbọn.
Ọ̀jọ̀gbọ́n náà, nígba tó ń fèsì sí fọ́rán ìdínilẹ́kọ̀ọ́ kan tó ń sọ àwọn àǹfàní tó wà lára òróró àgbọn lórí Youtube.
Àwọn èèyàn àti awakọ̀ ké igbe ìrora bí àwọn ọkọ̀ ńlá ṣe dí ọ̀nà mọ́rosẹ̀ Apapa-Oshodi pa
Bákan náà ni àwọn ẹgbẹ́ àwọn tó ń rí sí ìlera ọkan l'Amerika, rọ̀ àwọn ènìyàn láti yàgò fún àdín àgbọn nínú ìwé ìròyìn Business Insider ti Deutschland.
Ọ̀jọ̀gbọ́n Karen ni adarí dídènà iṣan wíwú lọ́nà ti kò dára ní Fasiti Freiburg àti Ọ̀jọ̀gbọ́n Harvard TH Chan nílé ẹ̀kọ́ ilera.
Nínu ìkọ́ni rẹ̀, Michel sàlàyé ìrú òunjẹ tó yẹ kí ènìyàn máà jẹ, tó sì fí kún-un pé àdín àgbọn kò dára rárá fún mimu tabi jijẹ.
Saraki: Tinubu fẹ́ di ààrẹ ní 2023, ló se ń tẹ̀lé Buhari
Oríṣun àwòrán, @bukolasaraki
Saraki ni bi oun atawọn eekan ẹgbẹ oṣelu APC kan ṣe tako erongba Tinubu lati di igba keji aarẹ Buhari lọdun 2014 lo fa bi o ṣe n tako oun
Aarẹ ile aṣofin agba, Bukọla Saraki ti ṣalaye wi pe irọ ni ọrọ ti kan ti wọn ni aṣiwaju ẹgbẹ oṣelu APC, Bọla Ahmed Tinubu sọ lori idi ti oun fi fi ẹgbẹ oṣelu naa silẹ.
Saraki, ninu atẹjade kan to fi sita gẹgẹ bii esi si ọrọ naa ni bi ''Aarẹ Buhari ati awọn isọmọgbe rẹ ṣe n fi ọwọ idẹyẹsi mu ẹka aṣofin kun ara ohun to mu ki oun ati awọn eekan ẹgbẹ naa kan fi ẹgbẹ silẹ.
Bakan naa ni Saraki ṣalaye pe Tinubu ti ṣalaye fun oun ati awọn eekan ẹgbẹ naa ri pe inu oun ko dun si iṣejọba Aarẹ Muhammadu Buhari nitori ẹgbin ti ijọba Buhari ti awọn jọ ṣiṣẹ gbe si ipo fi n kan oun.
Obìnrin akunlé ìgbàlódé
"Saraki ni Tinubu ṣọ ọrọ naa l'asiko to fi dari eto ipẹtusaawọ laarin ẹgbẹ oṣelu naa pe ""bi aarẹ Buhari di alailera lori kẹkẹ alaisan oun ni oun yoo ti lẹyin nitori ki ipo aarẹ lee tọ si ẹkun Iwọ oorun -Guusu l'ọdun 2023."""
Oríṣun àwòrán, @bukolasaraki
Sẹnetọ Bukọla Saraki rọ ẹgbẹ oṣelu APC lati faramọ ipinnu oun lati fi ẹgbẹ oṣelu naa silẹ
Saraki tun sọọ siwaju wi pe, ko si idi meji ti Tinubu fi n sọ ọrọ ti ko tọ nipa oun ju wi pe oun atawọn eekan ẹgbẹ oṣelu APC kan tako erongba rẹ lati di igba keji fun Aarẹ Buhari l'ọdun 2014 lori bi awọn mejeeji ṣe jẹ ẹlẹsin musulumi kan naa.
Amọṣa aarẹ ile aṣofin agba l'orilẹede Naijiria naa ko ṣai rọ awọn agbagba ẹgbẹ oṣelu APC lati faramọ ipinnu oun lati fi ẹgbẹ oṣelu naa silẹ, niwọn igba ti o jẹ pe ori opo ipinnu ara ẹni ni eto iṣejọba tiwantiwa duro le.
NECO: Ẹ̀kọ́ Ìsírò, Gẹ̀ẹ́sì làwọn akẹ́kọ̀ọ́ ti fọ́mọyọ
Oríṣun àwòrán, AFP
Ajọ to n se kokari idanwo NECO  ni orilẹede Naijiria, ti fi esi idanwo ti Neco June/July 2018 fun awọn akẹẹkọ ti girama.
Adele adari fun Ajọ NECO, Alhaji Abubakar Gana to kede eyi ni Minna, sọ wi pe awọn akẹẹkọ to fi orukọ silẹ fun idanwo naa to 1,041,536, ti awọn akẹẹkọ to to 1,032,729 si joko fun idanwo naa.
Ninu ọrọ rẹ, Gana ni ida aadọrun o le diẹ ni awọn akẹẹkọ to ni ‘Credit’ maarun ni Ẹkọ Isiro ati Ede Gẹẹsi ninu esi idanwo naa.
Awọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí:
Ileya: Àgbò wọ́n torí ọjà ẹran mẹ́ta ni wọ́n tìpa lókè ọya torí Boko Haram
Amọ, nigba to n ke gbajare wipe awọn akẹẹkọ ti ko joko se idanwo ni iwe idanwo, fikun wipe, awọn akẹẹkọ to to 20, 181 se magomago ninu idanwo naa, paapaa ninu Ẹkọ Isiro ati Ede Gẹẹsi.
Ọdún iléyá 2018: Àwòrán tó jẹ arimaleelọ ni Yidi
Òní ní ọdún Eid il Adha eleyi tí ọpọ èèyàn mọ sí ọdún iléyá.
Jakejado agbàyè ni awọn Musulumi ti kirun lasiko ọdún
Awọn ara Ijebu n se ajọyọ ọdun ileya ni Eid Prayer Arena, Igbeba - Ijebu-Ode
Àwọn ọmọ ọlọdun ń yẹra wo l'Osogbo
Lọjọ ọdún yí àwọn mùsùlùmí yóò ki Irun rakaah méjì leyin tí Imam yoo pa eran tirẹ.
Ọdun Ileya yii dun ni Ijẹbu, ẹsin ni ọmọde yii fi n jaye.
Leyin ti Imam ba pa eran tan ni awon janmọ to ku le pa ti wọn náà
Ní àwọn Aaye ìkìrun ati ọkunrin ati obirin ló peju
Ọdun ba wa ni aye ati ni alaafia, o ye ka jo, ka si tun yọ pẹlu.
Awọn olorin ati oni ilu fi ilu se idaraya fun awọn eniyan lasiko ayeye ileya ti ọdun yii.
Awọn agbagba ni ilu Ibadan naa o gbeyin nibi ọdun ileya ni yidi Agodi, ilu Ibadan.
Ọ̀pọ awọn olutaja lasiko odun yii lo n pariwo ko sowo nita rara lọdun Ileya yii.
Ẹ ri ẹgbẹ wa bi, o yẹ wa n ti wa
Oríṣun àwòrán, @BashirAhmaad
Eegun nla lo n kẹyin igbalẹ́, aarẹ Muhammadu Buhari naa du ẹran ọdun
Ọṣun; Àwọn aláìsàn ojú ké sí ìjọba láti ràn wọ́n lọ́wọ́
Ohun to tọna bayii ni ki awọn ti Ọlọrun ṣẹgi ọla fun lawujọ o dide fun ipese owo lati seto itọju fun awọn ti oju n dun lawujọ
Lootọ ni oju n dunmi; ṣugbọn airi itọju ni o koba oju mi.
Ọrọ yii lo ti ẹnu alagba Ahmed Lamidi, ẹni ọgọrin ọdun jade ninu ifọrọwerọ rẹ pẹlu BBC Yoruba ni aafin ọba ilu Ifọn orolu nipinlẹ Ọṣun.
Alagba Lamidi wa lara awọn eeyan ilu Ifọn-Orolu nipinlẹ Ọṣun to wa fun iwosan ọfẹ fun aisan oju wọn.
Alagba Lamidi ni aisi owo ti fọ oju ọpọlọpọ oju awọn eeyan ni ẹsẹ pupu.
Ọdun mejila ni alagba ẹni ọgọrin ọdun naa ni oju oun ti kọkọ bẹrẹ ki o to di pe o fọ nitori aisi owo lọwọ rẹ pẹlu ọwọngogo itọju aisan oju.
O dara ki ijọba maa gbe eto ilera ati iwosan oju wa si ẹsẹ pupu nitori aisi owo ati bi itọju aisan oju ṣe di ọwọngogo lo n fa ọpọ oju to n fọ laarin awọn ọmọ orilẹede Naijiria.
Dokita iwosan oju, ṣalaye pe aimọkan, aisi iroyin to to ati ọwọngogo itọju aisan oju n ṣe akoba fun awọn ti oju n yọ lẹnu lorilẹede Naijiria
Bakan naa lawọn to laisan oju ti wọn wa sibi eto iwosan ọfẹ lori aisan oju naa ni wọn pariwo sita pe asiko to fun ijọba lati ṣe iranwọ ti yoo mu adinku ba iye owo ti wọn n san fun itọju aisan oju lorilẹ-ede Naijiria.
Arabinrin Ọlayiwọla Abọsẹde sọ fun BBC Yoruba pe ''oju popo ni oun ti n ta ọja lati fi bọ ẹbi ki o to di pe oun ṣakiyesi pe oju oun n wo bayi-bayi.
O ti n lọ bii ọdun kan abọ ti oju yii ti wa bayii, o si ṣeeṣe ki oju mi maa ri bayii kani agbara mi gbe inawo rẹ ni.
Aisi owo nṣakoba fun itọju aisan owo lorilẹede Naijiria
Ninu ọrọ tirẹ, Dokita iwosan oju, Echetta Ugonna ṣalaye pe aimọkan, aisi iroyin to to ati ọwọngogo itọju aisan oju n ṣe akoba fun awọn ti oju n yọ lẹnu lorilẹ-ede Naijiria, paapaa lẹsẹ pupu.
Dokita Ugonna ni lootọ omi lee ṣebi ẹni pọ ju ọka lọ fun ijọba lori eto iwosan ati ilera oju, ṣugbọn ohun to tọna bayii ni ki awọn ti Ọlọrun ṣẹgi ọla fun lawujọ o dide fun ipese owo lati seto itọju fun awọn ti oju n dun lawujọ.
Ìjẹ̀bú: Àgbàlàgbà ni mo máa ń ṣe nínú eré tẹ́lẹ̀
Bimpe: Èèyàn bíi tiyín ni àfín, ẹ dẹ́kun dídẹ́yẹsí àfín
'O yé kí ìbáṣepọ̀ Nàìjíríà àti UK dán mọ́rán síi lẹ́yìn àbẹ̀wò May'
Iku Fẹ́lẹ́: MC Oluọmọ, àwọn èèkàn ìlú sọ̀rọ̀ lórí ikú alága NURTW, Fẹ́lẹ́
MC Oluọmọ, àtàwọn èèkàn ìlú míràn sọ̀rọ̀ lórí ikú alága NURTW, Fẹ́lẹ́
Ọpọ awọn eekan ẹgbẹ awakọ ero lorilẹede Naijiria ni wọn peju sibi isinku oloogbe Taofeek Oyerinde ti pupọ eeyan mọ si Fẹlẹ.
Isinku rẹ waye nilu Ibadan ni ibamu pẹlu ilana ẹsin musulumi.
Lara awọn eekan to peju sibẹ naa ni MC Oluọmọ, ẹni to jẹ ilumọọka aṣiwaju ẹgbẹ ọlọkọ ero NURTW nipinlẹ Eko.
Ẹ wo bí ìsìnkú Fẹ́lẹ́ se lọ
Saraki, yára kọ̀wé fipò sílẹ̀ tàbí ká lé o - Miyetti Allah
Àwọn èèyàn àti awakọ̀ ké igbe ìrora bí àwọn ọkọ̀ ńlá ṣe dí ọ̀nà mọ́rosẹ̀ Apapa-Oshodi pa
MC Oluọmọ ni obitibiti ero to peju kii ṣe iyalẹnu nitori irufẹ eeyan ti oloogbe Fẹlẹ jẹ nigba aye rẹ.
Lara awọn miran to peju sibẹ ni aṣoju ijọba ipinlẹ Ọyọ, Kọmiṣọna ọlọpaa nipinlẹ Ọyọ, awọn agba ẹgbẹ awakọ ero nipinlẹ ati ni apapọ orilẹede Naijiria.
Obitibiti ero kora jọpọ lati kẹdun nile alaga NURTW  ẹkun gúúsù -ìwọ̀-oorunTọtun tosi ni igbe ẹkun ati idaro ti n sọ lasiko ti ẹbi, ara, ọrẹ, ojulumọ ati awọn alabaṣiṣẹ pọ kora jọpọ, lati kẹdun nile alaga ẹgbẹ awọn awakọ NURTW ipinlẹ Ọyọ, Alhaji Taofeek Oyerinde Fẹlẹ, to padanu ẹmi rẹ sọwọ aisan kidinrin lọjọ isẹgun.
Awọn oloselu, asoju ẹgbẹ awakọ jakejado ẹkun iwọ orun-guusu, to fimọ awọn amuludun naa ko gbẹyin nile oloogbe.Lara awọn eeyan to ba ikọ BBC Yoruba sọrọ nile oloogbe ni agbegbe ẹlẹbu nilu Ibadan, ṣe apejuwe ipapoda Alhaji Fẹlẹ gẹgẹ bii adanu nla fun ẹgbẹ NURTW ati ipinlẹ Ọyọ lapapọ.
Bọlanle Ninalowo: Ọ̀rẹ́ lásán àti olóore mi ni Mercy Aigbe
Wọn fi kun ọrọ wọn wipe, oloogbe naa to dagbere faye lẹni ọdun mejidinlọgọta ni ko duro jẹ ere ise rẹ, gẹgẹ bi wọn se rawọ ẹbẹ si Ọlọrun lati tu aya, ọmọ ati awọn mọlẹbi to fi silẹ ninu.Alhaji Taofeek Oyerinde Fẹ́lẹ́, ti o jẹ alaga ẹgbẹ awọn awako NURTW ipinlẹ Ọyọ jade laye lọjọ isegun, nile iwosan to n risi itọju kindinrin nilu Abuja nipasẹ aisan kindinrin to baa finra.
Ìṣẹ́ kọ̀ndọ́ ní Fẹ́lẹ́ fí bẹ̀rẹ̀ iṣẹ́ níbẹ̀rẹ̀ ayé rẹ̀
Alága àwọn awakọ̀ ní ìhà gúúsù-ìwọ̀-oòrùn (NURTW) Alhaji Taofeek Oyerinde tí gbogbo ènìyàn mọ̀ sí Fẹ́lẹ́ tún jẹ́ alága ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́.
Ó kú ní ọ̀san àná ọjọ́ kẹ́jọ oṣù kẹjọ, ọdún 2018, ní ilé ìwòsàn Zenith Medical Kidney Hospital Abuja lẹ́yìn àìsàn kídìrín.
Wọn ó sin ni Elebu, Ibadan láàrọ òní nílànà ẹ̀sìn Musulumi, Oyerinde dí alága ẹgbẹ́ awakọ ní 2011, ó bẹ̀rẹ̀ iṣẹ́ kọ̀ndọ́ bọ́ọ̀sì ní ọdún 1975, ó gba ìwé ọkọ ìrìnà ní 1979 nígbà to dí ọmọ ẹgbk tó fẹsẹ̀ rinlẹ̀ láti 'ọdun 1983 titi tó fi kú.
Oríṣun àwòrán, facebook\Alhaji Taofeek Oyerinde
Alhaji Fẹlẹ dagbere faye lẹyin aisan kindinrin to baa finra
Lẹ́yìn ìkú rẹ̀ ní  Gómìnà Ọyọ́ Abiola Isiaka Ajimobi tí gbà pẹ̀lú olórí NURTW tí àpàpọ̀ láti fi Abideen Olajide tí gbogbo ènìyàn mọ sí Ejìogbè bọ́ sípò rẹ̀ gẹ́gẹ́ bí adelé alága.
Lójó òpó twitter àwọn ọmọ Nàìjírtíà ń ṣelédè lẹ́yìn rẹ̀.
Àìsàn kíndìnrín tó dasẹ́ sílẹ̀ ló pa Fẹ́lẹ́ - Ààrẹ NURTW
Loni, Ọjọru ni wọn yoo fi iyoku ara alaga ẹgbẹ ọlọkọ ero (NURTW) nipinlẹ Ọyọ, Alhaji Taofeek Oyerinde, ti gbogbo eeyan mọ si Fẹlẹ, fun ilẹ.
Atẹjade kan ti aarẹ ẹgbẹ Nurtw nilẹ wa, Alhaji Najim Yasin fisita ni aisan to nii se pẹlu kindinrin Fẹlẹ to da isẹ silẹ, lo se okunfa iku rẹ.
A gbọ pe aisan naa ti n se Fẹlẹ, to tun jẹ alaga ẹgbẹ ọlọkọ ero lẹkun iwọ oorun ilẹ yii, lati bii ọjọ melo kan, ti wọn si ni ni ode lọsẹ mẹfa sẹyin lasiko ipade igbimọ alasẹ ẹgbẹ naa nipinlẹ Ọyọ, eyi to waye ni olu ileesẹ Nurtw tuntun ni adugbo Ọjọọ, nilu Ibadan.
Adebisi Idikan: Òun ló gba Ìbàdàn sílẹ̀ lọ́wọ́ ìyà owó orí sísan
Atẹjade naa ni ile Fẹlẹ to wa ni adugbo Ẹlẹbu nilu Ibadan ni wọn yoo sin oloogbe naa si ni aago mẹsan si mẹwa oorọ yii.
Najim Yasin, ẹni to ni orilẹ-ede Saudi Arabia ni oun wa fun haji, wa se apejuwe oloogbe Oyerinde Fẹlẹ bii ololufẹ alaafia, to si gbadura pe ki Ọlọrun gba abọ rẹ.
Iku Fẹlẹ ti wọn kede lojiji yii lo mu ki ayẹyẹ ọdun ileya tete di wẹlo ninu ile rẹ, ti awọn ẹbi rẹ si bẹrẹ si se ọfọ rẹ.
Bakan naa ni wọn tete palẹ awọn tẹnti ati aga ọdun mọ nilẹ.
Ni ọsan ọjọ Iṣẹgun ni Alhaji Fẹlẹ jade laye nileewosan Zenith Kidney Hospital nilu Abuja.
Ninu ọrọ to ba BBC Yoruba sọ lati orilẹede Saudi Arabia, Aarẹ ẹgbẹ awakọ ero l'orilẹede Naijiria, Alhaji Najeem Yasin ni ''dokita to n tọju oloogbe Taofeek Oyerinde lo pe oun lati tufọ rẹ ati pe ohun ti ṣe eto bi oku oloogbe naa yoo ṣe de ilu Ibadan lati ilu Abuja ni.
Oríṣun àwòrán, Facebook\Alhaji Taofeek Oyerinde
Ni ọsan ọjọ iṣẹgun ni Alhaji Fẹlẹ jade laye nileewosan Zenith Kidney Hospital nilu Abuja
Alhaji Fẹlẹ, gẹgẹbi aarẹ ẹgbẹ NURTW lorilẹede Naijiria ṣe sọ, ti wa ni ile iwosan lati nnkan bii ọsẹ mẹta sẹyin, nibi ti o ti n gba iwosan fun aisan kidinrin to ba n finra.
"Ọsẹ mẹta lo ti wa ni ileewosan Zenith Kidney hospital nibi ti o ti n gba itọju.
Aisan kidinrin lo n yọọ lẹnu, aisan naa lo si ṣokunfa iku rẹ lọsan oni."
Ki oto dagbere faye, Alhaji Oyerinde Fẹlẹ ni alaga ẹgbẹ awakọero NURTW lẹkun iwọ oorun gusu orilẹede Naijiria.
Buhari: ó wù mí láti kí àwọn èèyàn mi ni Daura lójúkojú.
Oríṣun àwòrán, @BashirAhmaad
Nibayii gan aworan igbakeji aarẹ̀ Yẹmi Ọṣinbajo gan ti wa lori ayelujara
Aarẹ Muhammadu Buhari salaye idi ti o fi rin irin ẹgbẹrin mita lẹyin to kirun Yidi tan nilu rẹ Daura nipinlẹ Katsina.
Aarẹ sọ loju opo Twitter pe oun ko rin lati fihan awọn eeyan pe ara oun le.
Aarẹ Buhari sọ pe oun gbe igbesẹ lati rin nitori awọn ara ilu oun tu yaaya jade lati ri oun, ṣugbọn wọn ko ni anfani lati ṣe bẹẹ nitori gilaasi ilẹkun ọkọ ti oun wa ninu rẹ ṣe dudu.
Aarẹ ni eleyi gan-an lo ṣe okunfa bi oun ṣe bọ silẹ ninu ọkọ ti oun si bẹrẹ si lọ.
Aarẹ Buhari sọ pe awọn ti wọn mọ oun daadaa mọ pe oun ko rin nitori oṣelu.
O fi kun ọrọ rẹ pe oun ko ni lati rin ki o to di pe awọn eeyan gbagbọ pe ara oun da muṣe lati dije dupo Aarẹ lẹlẹẹkeji.
Oríṣun àwòrán, Omoleye Sowore/Facebook
Sowore
Ẹwẹ, olùdíje fún ipò ààrẹ lẹ́gbẹ́ òṣèlú AAC, Ọmọyẹle Soworẹ, náà ti fi àwòrán sórí ìtàkùn Facebook rẹ̀ níbi tó ti sáré yípo ilẹ̀ New York ká láàrin wákàtí mẹ́rin.
Ó ní ààrẹ rìn ìrìn ẹgbẹ̀rin mítà láti jẹ́ káyé mọ̀ pé òun dángájíá nígbà tí olùdíje míì, Abubakar Atiku náà tún gbé ara rẹ̀ sáyé lórí ìdárayá.
Ni ọjọ́ ìṣẹ́gun ni àwòrán Ààrẹ Muhammadu Buhari tó ń fi ẹsẹ̀ rìm láti yídì ìlú Daura lọ sí ilé rẹ̀ gbòdekan; ṣugbọn Abubakar Atiku to figbakanri jẹ igbakeji aarẹ lorilede Naijiria ti tako aarẹ Muhammadu Buhari lórí òṣèlú 'onírìnsẹ̀' àti 'eré sísá' yii.
Oríṣun àwòrán, Twitter\BashirAhmaad\@tiku
"Ibeere ti awọn eeyan wa n beere bayi ni pe igbawo ni ipolongo oṣelu lorilẹede Naijiria wa di ti ""mole rin ju ọ lọ"""
Igbakeji aarẹ orilẹ-ede Naijiria nigbakanri, Atiku Abubakar, ti koro oju si irin ẹlẹgbẹrin mita ti aarẹ Muhammadu Buhari rin nilu Daura ni ọjọ Iṣẹgun pẹlu ọrọ pe ere idaraya kii ṣe ọpakutẹlẹ fun ati ṣe odinwọn bi eeyan ṣe jafafa si  lati fi ẹsẹ orilẹede Naijiria le pepele to tọ.
Ninu ọrọ to gbe jade lori ikanni ayelujara Twitter rẹ, Atiku ni oun gan a maa sare ju ibusọ kọn lojoojumọ atipe yoo jẹ ohun idojuti nla gbaa fun oun lati wa maa fi eyi yangan tabi fi  ke sawọn ọmọ orilẹede Naijiria lati dibo fun oun.
Igbagbogbo ni mo maa n sare to le ni maili kan ti mo si n ṣere idaraya, ṣugbọn yoo jẹ ohun ti ko bojumu fun mi lati wa maa fi eyi pe awọn ọmọ naijiria lati dibo fun mi.
Ni ọjọ iṣẹgun ni aworan Aarẹ Muhammadu Buhari to n fi ẹsẹ rin lati yidi ilu Daura lọ si ile rẹ gbodekan lori ayelujara ti awọn amugbalẹgbẹ rẹ si ni irin ẹgbẹrin mita ni Baba rin.
Atiku ni ohun to ṣe pataki ni ohun ti oloṣelu lee ṣe fun idagbasoke awujọ
"Ibeere ti awọn eeyan wa n beere bayi ni pe igbawo ni ipolongo oṣelu lorilẹede Naijiria wa di ti ""mole rin ju ọ lọ"" tabi ""mole goke mo le sọ"""
"Awọn eeyan kan lori ikanni ayelujara ni owe kokoko lara ọta n le ni aarẹ pa ranṣẹ si awọn alatako rẹ ni igbaradi fun idibo ọdun 2019; ṣugbọn igbakeji aarẹ tẹlẹ, Atiku Abubakar ni ""Ohun ti mo fẹ ni ẹgbẹ oṣelu mi-PDP, atawọn ọmọ orilẹede Naijiri o dibo fun mi nitori iṣẹ ti mo lee ṣe, kii ṣe nitori irin ti mo lee rin."""
Oríṣun àwòrán, @BashirAhmaad
Ni ọjọ iṣẹgun ni aworan Aarẹ Muhammadu Buhari to n fi ẹsẹ rin lati yidi ilu Daura lọ si ile rẹ gbodekan
Nibayii gan aworan igbakeji aarẹ̀ Yẹmi Ọṣinbajo gan ti wa lori ayelujara.
Aworan naa ninu eyi ti igbakeji aarẹ Yẹmi Oṣinbajo ti n juwọ ti ọpọ ero si n wọ tọọ lẹyin naa ti n gbera sọ bayi lori ikanni ayelujara twitter!
Sáájú ni Aarẹ Muhammadu Buhari ti ṣalaye pe pẹlu bi o ṣe jẹ pe awọn kan n bu ẹnu atẹ lu orilẹede Naijiria, orilẹede Naijiria ti wa ni oju ọna irapada isọdọtun.
Ninu atẹjade kan ti agbẹnusọ fun aarẹ lori ọrọ iroyin, Fẹmi Adeṣina fi sita ni ọjọru ni aarẹ ti sọ di mimọ lasiko to fi n kan sara sawọn agbofinro meji kan ti wọn da apo to kun fun ohun alumọni eyi ti arinrinajo kan lati ilẹ Amẹrika sọnu ni papakọ ofurufu Murtala Muhammed nilu Eko.
Aarẹ Buhari rọ awọn ọmọ orilẹede Naijiria lati wawokọṣe awọn agbofinro meji naa nitori iwa wọn naa ṣe afinhan Naijiria tuntun ti gbogbo eeyan n fẹ.
"O ṣeeṣe fawọn agbofinro mejeeji lati ṣe ohun miran to yatọ si eyi ti w ọn ṣe pẹlu iwa ibajẹ didarapọ mọ awọn iwa kotọ gbogbo lawujọ.
Orilẹede Naijiria kii ṣe adape orukọ iwa ibajẹ ati iṣowo ilu baṣubaṣu mọ bayii nitori ọna tuntun ti a ti yan lati maa tọ niyi ti ko si si ẹni ti yoo so wa mọlẹ sinu iwa ibajẹ atẹyinwa mọ."
Oríṣun àwòrán, @MBuhari
Buhari kan sara sawọn agbofinro ti wọn da apo to kun fun ohun alumọni pada fun arinrinajo lati ilẹ Amẹrika
Iroyin sọ pe dokita iṣegun oyinbo kan to filu Eko ṣe ibujoko ni o lọ pade awọn mọlẹbi rẹ kan ti wọn tajode lati orilẹede Amẹrika ni papakọ ofurufu naa ni ọjọ kejidinlogun oṣu kẹjọ ọdun 2018.
Ni idunnu ipade ojutunrari wọn ni wọn ti gbagbe ẹru iyawo arakunrin to t'ajo de naa laimọ.
Ni nkan bi wakati kan abọ lẹyin eyi ni awọn oṣiṣẹ ileeṣẹ alaabo aladani Halogen Securities kan rii he to si pe wọn lati wa gba apo wọn.
Awọn eeyan naa mu ẹbun to jọju fi ta awọn agbofinro naa lọrẹ ṣugbọn ti wọn kọ; ti wọn si ni iṣẹ awọn lawọn nṣe.
IlorinDurbar: Emir Sulu-Gambari léwájú àwọn èèkàn ẹlẹ́ṣin níbi àjọ̀dún Dubar nílú Ilọrin
Oríṣun àwòrán, @onile050
Ajọdun Dubar nilu Ilọrin
Ayẹyẹ durba ilu Ilọrin waye loni pẹlu oniruru ilu, ijo ati ifọn.
Oríṣun àwòrán, @Mr__Calox
Ajọdun Dubar nilu Ilọrin
Oríṣun àwòrán, @bukolasaraki
Ajọdun Dubar nilu Ilọrin
Gẹgẹ bi ẹ ti ṣe mọ pe ohun kan ti kii gbẹyin nibi ajọdun durba ni ẹṣin gigun; eyi naa ko si gbẹyin nibi ajọdun Dubar ilu Ilọrin.
Oríṣun àwòrán, @bukolasaraki
Ajọdun Dubar nilu Ilọrin
Lara awọn to peju sibi ajọdun naa ni Waziri ilu Ilọrin to tun jẹ aarẹ ile aṣofin agba lorilẹede Naijiria, Sẹnetọ Bukọla Saraki.
Oríṣun àwòrán, @MR_LanreHabeeb
Ajọdun Dubar nilu Ilọrin
Oríṣun àwòrán, @MR_LanreHabeeb
Ajọdun Dubar nilu Ilọrin
Oríṣun àwòrán, @onile050
Ajọdun Dubar nilu Ilọrin
Bakan naa ni olori ile aṣofin ipinlẹ Kwara, họnọrebu Ali Ahmad pẹlu wa nibẹ.
Lasiko ajọdun Dubar ilu Ilọrin ti ọdun yii, Emir ti ilu Ilọrin, Alhaji Ibrahim Sulu-Gambari lo lewaju awọn ẹlẹṣin ti ko din ni ẹẹdẹgbẹta pẹlu ṣin ti wọn ṣe lọṣọ ati lọjọ loriṣiriṣi lati ṣe ajọyọ ajọdun naa.
Èrò ọmọ Nàìjíríà ṣọ̀tọ̀ọ̀tọ̀ lóri ohun to ṣẹlẹ̀ si Saraki lojude Ọba
Ọba Sikiru Adetọna ti korò ojú sí bí àwọn èèyàn kan ṣe tàbùkù ààrẹ ilé ìgbìmọ̀ aṣòfin àgbà l'Abuja Sẹ́nétọ̀ Bukola lọ́jọ́ ayẹyẹ ojúde-ọba
Lọjọ keji ọdun ileya ni ojude Ọba maa n waye lọdọọdun ni Ijẹbu-òde nipinlẹ Ogun.
Aarẹ ile igbimo aṣofin agba l'Abuja, Bukola Saraki ni alejo pataki fun ọdun naa ni ọdun 2018 ni eyi ti àwọn kan tabuku lasiko to n sọrọ.
Awọn eniyan ti bu ẹnu atẹ lu ihuwasi ati iṣesi awọn ololufẹ ẹgbẹ oselu APC lasiko ayẹyẹ ọdun Ojude Ọba ni ilu Ijẹbu Ode.
Awùjalẹ̀ ti ilẹ̀ Ìjẹ̀bú, Ọba Sikiru Adetọna lo kọkọ bu ẹnu atẹ lu bi awọn eniyan ṣe n pariwo APC! APC! lasiko ti Aarẹ Ile Igbimọ Asofin Agba, Bukola Saraki darapọ mọ ayẹyẹ naa.
Ọba Adetọna fikun un pe ọgọrun ọdun niyi ti awọn ti n se ọdun Ojude Ọba lai fi ti ẹgbẹ oselu kankan se.
O ni ohun to buru jai ni ki ẹgbẹ oselu kan ma a polongo lasiko ọdun ọmọ Yoruba to jẹ ọdun Ojude Ọba.
Bí ìlù ṣe ń pe ìlù ránṣẹ́ ní Ojúde Ọba 2018
Awọn eniyan ni oju opo ikansiraẹni Twitter naa fi aidunnu wọn han si bi awọn eniyan se sọ gbagede Ojude Ọba di ibi ti wọn ti n se ipolongo ẹgbẹ oselu.
Iroyin fi lede wi pe ọgọọrọ awọn ọmọ ẹgbẹ oselu APC  to wa ni ibi ayẹyẹ Ojude Ọba naa mu igbalẹ dani ti wọn si bẹrẹ si ni pe Bukola Saraki ni ole.
Ọkan lara awọn ọmọ Ijebu to wa nibi isẹlẹ naa, sọ wi pe oun ko ni kopa ninu ọdun Ojude Ọba mọ nitori isẹlẹ naa, lẹyin ọgbọn ọdun ti ohun ti n wa si ibi ayẹyẹ naa.
Irun gígẹ̀ kọjá orí fífá lásán
Ìjọba Nàìjíríà: Ọ̀rọ̀ ẹ̀yìn ni ọ̀rọ̀ Trump nípa Ààrẹ Buhari
Ìjọba Nàìjíríà: Ọ̀rọ̀ ẹ̀yìn ni ọ̀rọ̀ Trump nípa Ààrẹ Buhari
Ijọba apapọ orilẹede Naijiria ti sọ pe ko daju pe aarẹ Donald trump lee sọ ọrọ ti iwe iroyin Financial times kede pe o sọ lẹyin ipade oun ati aarẹ Muhammadu Buhari lorilẹede Amẹrika.
Ijọba apapọ orilẹede Naijiria ni pẹlu gulegule iroyin ayederu to n waye bayii lorilẹede Naijiria ati kaakiri agbaye, o yẹ ki eniyan ṣọra fun irufẹ iroyin bayi paapaa julọ lati ẹnu aarẹ orilẹede bii ti Amẹrika.
Minisita feto iroyin lorilẹede Naijiria, Alhaji Lai Muhammed to gbẹnusọ fun ijọba apapọ orilẹede Naijiria ṣalaye fun BBC Yoruba pe to ba jẹ pe lootọ ni Aarẹ Donald Trump sọ ọrọ yii jade, o ku diẹ kaato; paapaajulọ bi o ṣe jẹ pe niwaju gbogbo agbaye ni aarẹ Trump ti sọrọ to si gboṣuba fun aarẹ Buhari pe o kun oju iwọn lati kogoja gẹgẹ bii adari orilẹede Naijiria.
Ọ̀rọ̀ Trump àti Russia kò yàtọ̀ pé àhesọ lásán ni èyí jẹ́
Ni owurọ ọjọ aje ni okiki kan nipa iroyin kan ti iwe iroyin Financial times gbe jade nipa ohun ti wọn ni aarẹ Trump sọ pe Buhari ko dun un ba rin pọ atipe oun ko gbadura ki oun pade irufẹ eeyan bii rẹ mọ laye oun.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Lẹyin ipade naa ni aarẹ orilẹ-ede Amẹrika, Trump ṣalaye pe oun ko fẹ pade 'ẹni ti ko dun-un ba ṣe pọ' bii Buhari mọ laye oun
Aarẹ orilẹ-ede Amẹrika, Donald Trump, ṣe apejuwe aarẹ orilẹ-ede Naijiria, Muhammadu Buhari, gẹgẹ bii 'ẹni ti ko dun-un ba ṣe pọ' ni kete ti wọn ṣe ipade tan ni ọgbọn ọjọ, oṣu kẹrin, ọdun 2018.
Ninu agbejade rẹ ninu iwe iroyin Financial Times ti ọjọ́ Aje ló ti sọ eyi di mimọ.
Buhari ni Aarẹ akọkọ lati ilẹ Afirika ti yoo ba Trump joko ṣepade pọ lẹyin ti wọn bura fun un gẹgẹ bii aarẹ karundinlaadọta fun orilẹ-ede Amẹrika.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Lẹyin ipade ni aarẹ orilẹede Amẹrika,Trump ṣalaye pe oun ko fẹ pade 'ẹni ti ko dun-un ba ṣe pọ' bii Buhari mọ laye oun
O ba Trump sọrọ lasiko ipade naa lori ajọṣepọ okoowo laarin orilẹ-ede mejeeji.
Lẹyin ipade naa ni aarẹ orilẹ-ede Amẹrika, Trump ṣalaye pe oun ko fẹ pade 'ẹni ti ko dun-un ba ṣe pọ' bii Buhari mọ laye oun.
Lọwọ yii, ijọba Amẹrika ati Naijiria ko tii fesi lori iroyin yii paapaa bi o ṣe jẹ ọjọ́ kan naa ti aarẹ orilẹ-ede Kenya, Uhuru Kenyatta yoo ma ṣepade pẹlu aarẹ Donald Trump ni ile funfun balau White house.
Eyi yatọ gedegbe si ohun ti Aarẹ Trump sọ sita faraye gbọ lasiko ti ipade naa waye.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Buhari ati Trump ṣe ipade lori ajọṣepọ owo ni oṣu kẹrin ọdun 2018
"Trump ni oun ni igbagbọ to kuna ninu Buharai lati gbogun ti ""obitibiti iwa ijẹkujẹ"" to wa lorilẹ-ede Naijiria."
"Gẹgẹ bii ọrọ kan ti eeyan kan ti iwe iroyin Financial Times fi orukọ bo laṣiri sugbọn to n ṣe alarinna laarin orilẹ-ede Amẹrika ati Kenya sọ, ""Afirika ko figba kan ri wa ni ara ohun to ṣe koko fun aarẹ Trump ṣugbọn bi o ba fẹran rẹ yoo wa ọna lati rii pe nnkan rere waye laarin ẹyin mejeeji."""
Wọ́n rò pé mo ya wèrè ni Saudi lẹ́yìn ikú ọkọ mi
Ìjà Anglophone àti Francophone ti ń gba ẹbọ lọ́wọ́ tonílé-tàlejò
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ogun kìí bimọ re, ọmọ bíi iku, ọ̀fọ̀, ibanujẹ àti ìpayínkeke ló ń bí.
Ogunlọgọ eniyan lo padanu ẹmi wọn l'opin ọsẹ to kọja ni ẹkùn Iwọ̀-oorun Ariwa, orilẹ-ede Cameroon.
Iroyin fi idi rẹ mulẹ pe awọn ọmọ ogun Ambazonia mọkanlelogun, ati awọn ọmọ ogun meji nileeṣẹ ẹka ileeṣẹ ologun to wa ni Menchum, lo dagbere f'aye lasiko idoju ibọn kọra ẹni to waye ni abule Wum ati Bafmen, to wa ni ẹkùn Iwọ̀-oorun Ariwa.
Agbẹnusọ fun ileeṣẹ ologun Cameroon, Didier Badjeck sọ fun BBC pe àwọn tó kú ọhun padanu ẹmi wọn lasiko ti awọn ọmọ ogun Ambazonia wọ̀yá ìjà pẹlu àwọn ọmọ ogun Cameroon ni Wum l'ọjọ Abamẹta to kọja.
Wọ́n rò pé mo ya wèrè ni Saudi lẹ́yìn ikú ọkọ mi
Ṣaaju ni iroyin kan jade lori ẹrọ ayelujara pe àwọn isọmọgbe awọn ológun mẹsan ati oludari wọn, ni wọn ṣekupa nigba ti ọta ìbọn wọn tan, ti ko si si awọn ọmọ ogun to to lati ranwọn lọwọ.
Ṣugbọn Ọgagun Badjeck sọ fun BBC pe ''lootọ ni ọpọlọpọ awọn ọmọ ogun Ambazonia yabo ẹka ileeṣẹ ologun naa, ti wọn si pa akọni ọmọ ogun meji. Amọ, ileeṣẹ ologun naa pa mejila lara wọn, ti awọn to ku si salọ pẹlu ọta ibọn lara wọn.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
ọjọ a ku laa dere
O fi kun un pe bi ileeṣẹ ologun ṣe n gbiyanju lati pese aabo fun agbegbe naa, ni wọn tun ṣekupa awọn 'agbesunmọmi' mẹsan ni Bafmen.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Awọn agbebọn tun kọlu awọn oṣiṣẹ ajọ Cameroon Development Cooperation ni ẹkùn Iwọ Oorun Guusu, ti wọn pa eniyan mẹrinlelogoji lara ninu wọn
O ti le ni ọdun kan ti awọn ẹya to n sọ èdè Gẹẹsi ti ni ifọkanbalẹ kẹhin, eyi si ti mu ki awọn Biṣọbu ijọ Aguda kesi ijọba ati awọn ọmọ ogun Ambazonia lati dawọ ipaniyan naa duro.
Ọdún kan lẹ́yìn ogun musulumi Rohingya, ìbànújẹ̀ dorí àgbà kodò
Àyẹ̀wò DNA ti fẹ́ bẹ̀rẹ̀ fún àwọn àlùfá Kátólíìkì tó bímọ
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ọpọlọpọ igba ni ẹsun ti jade pe awọn alufa ijọ katoliiki n dalẹ ẹjẹ ti wọn jẹ lati ma ni ibalopọ pẹlu obinrin.
Ajọ aladani kan ti ṣe ifilọlẹ eto ipolongo ni orilẹede Kenya lati kesi awọn obinrin to fi ẹsun kan awọn alufa ijọ Katoliki pe awọn bi ọmọ fun wọn, lati wa sẹ ayẹwo DNA.
Ajọ naa yoo ran ajọ kan to jẹ ti ijọ Katoliiki ni agbaye, ti ẹnikan ko mọ, lọwọ lati ṣe ayẹwo ẹjẹ lati le mọ boya lootọ awọn alufa naa lo fun awọn obinrin to fẹsun kan wọn loyun, ti wọn si fi bimọ.
Inec gbọ̀dọ̀ tún owó ìsúná ìdìbò 2019 gbéwá síwajú wa
Agbára ju agbára lọ: Wo bàbá Godwin to pe òjò
Wọ́n rò pé mo ya wèrè ni Saudi lẹ́yìn ikú ọkọ mi
Lẹyin ti ayẹwo ọhun ba waye ni ajọ naa yoo fi aabọ ayẹwo naa ranṣẹ si awọn alaṣẹ ijọ Katoliiki ni bonkẹlẹ, fun igbesẹ ti o ba tọ ni oju wọn.
Awọn to ba lọ fun eto ayẹwo naa yoo san owo perete.
Ọpọlọpọ igba ni ẹsun ti jade ni orilẹede Kenya pe awọn alufa ijọ katoliiki n dalẹ ẹjẹ ti wọn jẹ lati ma ni ibalopọ pẹlu obinrin, ṣugbọn ti wọn n bimọ, ti wọn si n pa awọn ọmọ naa ti .
Diẹ lara awọn ẹsun naa de ile ẹjọ, ti wọn si fi ọwọ bo awọn kan mọlẹ.
NJC: Ẹ̀sùn kíkéde ìyanṣẹ́lódì tí kò bófinmu ló mú kí a fòfinde adarí òṣìṣẹ́ méjì
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Agbarijọpọ ẹgbẹ awọn oṣiṣẹ, JNC ti buwọlu awọn mejeeji gẹgẹ bii aṣiwaju ẹgbẹ oṣiṣẹ.
Agbarijọpọ ẹgbẹ awọn oṣiṣẹ, JNC nipinlẹ Ekiti ti fofin de awọn meji kan ti wọn ti figbakanri jẹ adari fun ẹgbẹ oṣiṣẹ nipinlẹ naa.
Agbarijọpọ ẹgbẹ awọn oṣiṣẹ, JNC nipinlẹ Ekiti ṣalaye pe idi ti wọn fi fofin de Ayọdeji Aluko ati Kọlawọle Ọlaiya ni pe wọn kede iyanṣẹlodi ti ko bofinmu pẹlu titu igbimọ iṣakoso ẹgbẹ oṣiṣẹ TUC ati NLC nipinlẹ Ekiti ka.
Ọdun mẹwa ni awọn mejeeji yii ko fi ni lee kopa ninu eto ẹgbẹ oṣiṣẹ nipinlẹ Ekiti.
"Lọsẹ to kọja ni awọn mejeeji yii lewaju ifẹhonu han kan labẹ eyi ti wọn pe ni ""Rescue team"" ti wọn si bẹrẹ si nii le awọn oṣiṣẹ kuro ni ọfiisi wọn; ti wọn si tun kede iyanṣẹlodi ọlọjọ gbọọrọ pẹlu ituka igbimọ iṣakoso ẹgbẹ oṣiṣẹ mejeeji to wa nipinlẹ naa."
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ọdun mẹwa ni awọn mejeeji yii ko fi ni lee kopa ninu eto ẹgbẹ oṣiṣẹ.
Nigba to n ba awọn oniroyin sọrọ lẹyin ipade agbarijọpọ ẹgbẹ awọn oṣiṣẹ, JNC nilu Ado Ekiti, alaga ẹgbẹ oṣiṣẹ NLC nibẹ, Ade Adesanmi pẹlu akẹgbẹ rẹ fun ẹgbẹ oṣiṣẹ TUC Ọdun Adesoye ṣalaye pe Agbarijọpọ ẹgbẹ awọn oṣiṣẹ, JNC ti buwọlu awọn mejeeji gẹgẹ bii aṣiwaju ẹgbẹ oṣiṣẹ nibẹ atipe ofutufẹtẹ lawọn igbesẹ ti awọn mejeeji yii gbe.
'Ògidì ọmọ Yorùbá ni mí, kò sí ọ̀rọ̀ tí n kò lè túmọ̀'
Theresa May: A ó fún Nàìjíríà ní £70-million láti pèsè isẹ́
'O yé kí ìbáṣepọ̀ Nàìjíríà àti UK dán mọ́rán síi lẹ́yìn àbẹ̀wò May'
Ijọba Ilẹ Gẹẹsi ti kede pe awọn yoo fun orilẹ-ede Naijiria ni aadọrin miliọnu owo ilẹ okeere Euros lati fi pese ọkẹ marun isẹ fun awọn ọdọ Naijiria.
Minisita fun ọrọ Ilẹ Afirika ni Ilẹ Gẹẹsi, Harriet Baldwin lo sọ eyi lasiko ti Olootu Ilẹ Gẹẹsi, Theresa May n se abẹwo si orilẹ-ede Naijiria, gẹgẹ bi ara eto lati se abẹwo si Afirika.
Baldwin sọ pe eniyan miliọnu mẹta lati awọn agbegbe ti iya ati isẹ wa ni orilẹ-ede Naijiria ni wọn yoo mu ibugboro ba igbe aye wọn nipa pi pese ohun amayedẹrun fun awọn eniyan.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Theresa May ni ijọba oun yoo fún Nàìjíríà ní £70-million láti pèsè isẹ́
Ìjẹ̀bú: Àgbàlàgbà ni mo máa ń ṣe nínú eré tẹ́lẹ̀
Laipe yii, ni Olootu Ilẹ Gẹẹsi naa sọ ni orilẹ-ede South Africa wi pe Naijiria lo ni awọn talaka julọ ni agbaye.
Olóòtú ìjọba ilé Gẹẹsi,Theresa May,ti seleri lati da owo Nàìjíríà pada sugbọn o le má ya ni kiakia.
Olùrànlọwọ pataki fun Aarẹ Muhammadu Buhari, Femi Adeshina, lo lede ọrọ yi ninu atẹjade kan to fi sita lori abẹwo May si Aarẹ Muhammadu Buhari ni ile ijọba l'Abuja.
''A ko fẹ wa ọwọ mọ nnkan ìní awọn ọmọ orile-ede Naijiria kankan sugbọn a o ri wi pe a tele ilana to tọ sugbọn o seese ki o pẹ diẹ''
Bakan naa ni Theresa May mẹnu ba pataki kikoju ipenija aabo ati ìfọwọ́sowọ́pọ̀ láti kojú ìpeníjà Boko Haram.
Ninu ọrọ ti rẹ, Aare Muhammadu Buhari so pe oun yoo sa ipa lati ri pe ijọba tarawa fẹsẹ mulẹ lorile-ede Naijiria.
'Digbi ni mo wa lẹyin ki a se idibo to yanranti, inu mi dun pe ẹgbẹ oselu mi n se daadaa''
O tẹsiwaju pe ''Idibo to waye lai pẹ yi ni Katsina Bauchi ati Kogi je oun iwuri fun wa''
Oríṣun àwòrán, @NGRPresident
Orilẹ-ede South Africa, Nigeria ati Kenya ni olootu ijọba ilẹ Gẹẹsi n bẹwo pẹlu ireti ati tubọ fi idi iṣakoso rẹ mulẹ gẹgẹ bii olootu ijọba
Buhari tun dupẹ lọwọ Thersesa fun ìfọwọ́sowọ́pọ̀ láti kojú ìpeníjà Boko Haram.
Lori ọrọ Brexit, Buhari ni anfaani nla ni eleyi jẹ fun awọn mejeji lati tun tẹsiwaju ninu ajosepo wọn.
Awọn mejeeji tun jiroro lori ọrọ to nii se pẹlu eto ọrọ aje ati eto abo to kan awọn orile-ede mejeeji.
Saaju ni May ti se abẹwo si orile-ede South Africa nibi ti o ti so pe orile-ede Naijiria ni awọn to tosi julo lagbaye.
Theresa May ti tẹsiwaju pẹlu irinajo rẹ lo si orile-ede Kenya.
Minisita fun ọrọ ilẹ okeere ni orilẹ-ede Naijiria tẹlẹri, Bolaji Akinyemi ti sọ pe awọn ọmọ Naijiria kii sọ otitọ nigba gbogbo nipa ọrọ aje Naijiria.
Akinyemi sọ ọrọ yii nigba ti o n fesi si ọrọ ti Olootu Ilẹ Gẹẹsi, Theresa May sọ lasiko to n se abẹwo si South Africa gẹgẹ bi ara abẹwo rẹ si ilẹ Afrika, pe orilẹ-ede Naijiria lo gba awọn to tosi julọ ni agbaye.
Minisita fun ọrọ ilẹ okeere naa ni awọn ọmọ ilẹ Naijiria kii sọ otitọ nipa iye owo ti wọn n pa nibi isẹ wọn, nitori naa akọsilẹ ti awọn ilu okeere ni nipa Naijiria ko jẹ otitọ lọpọlọpọ igba.
Oriọla: ó yẹ kí a jẹ́ káwọn ọmọ ìsinyi mọ pàtàkì ṣíṣe eré ìdárayá papọ̀
Minisita naa sọ pe igbese to dara ni pe Theresa May n bọ ni Naijiria lati wa se ipade bọ pẹlu Aarẹ Muhammadu Buhari.
O fikun ọrọ rẹ pe nitori Naijiria jẹ ilẹ ọlọra to ni ohun alumọni ni Ilẹ Gẹẹsi fi n wa ibasepo to dan mọran pẹlu orilẹ-ede Naijiria lẹyin ti wọn ba kuro ninu Ajọ Isọkan Europe, European Union(EU).
Ààrẹ Muhammadu Buhari yóò gba Theresa May tó jẹ́ olóòtú ìjọba ilẹ̀ Gẹ̀ẹ́sì níle ìjọba l'Abùja lónìí.
Èrèdí àbẹ̀wò Theresa May sí orílẹ̀-èdè Nàìjíríà ní láti ṣe àdéhùn lórí ètò kátàkárà tí yóò nípa láàrín Afíríkà àti Brexit.
Bákàn náà ni May yóò jíròrò nípa ètò ààbò, fífí ènìyàn ṣòwò, lẹ́yìn náà ní yóò lọ si Èkó láti sàbẹ̀wò sí àwọn to ti bọ́ sọ́wọ́ ìmúnisìnru lọ́nà ìgbàlódé.
Olóòtú ìjọba náà ti kéde bílíọnu mẹ́rin Pọun láti ran ọrọ̀ àjé ilẹ̀ Afíríka lọ́wọ́
Sùgbọn, bí Nàìjíríà ṣe ń múra sílẹ láti gba Theresa May lálejò ní àwọn ọmọ Nàìjíríà ti ké pe ààrẹ Muhammadu Buhari lati ríi dáju pé ó sọ ohun tó tọ àti ọ̀nà ti ìbaṣepọ̀ ilẹ̀ Gẹ̀ẹ̀sí yóò fí ṣe Nàìjíríà láànfàní.
Lóri àtẹ̀jíṣẹ́ twitter, àwọn ọmọ Nàìjíríà sọ èrò ọkàn wọn fún ilé iṣẹ́ ààrẹ .
Theresa May ti gúnlẹ̀ sí South Africa
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Orilẹ-ede South Africa, Nigeria ati Kenya ni olootu ijọba ilẹ Gẹẹsi naa yoo maa bẹwo pẹlu ireti ati tubọ fi idi iṣakoso rẹ mulẹ gẹgẹ bii olootu ijọba
Olootu ijọba ilẹ Gẹẹsi, Theresa May ti gunlẹ si ilu Cape Town bi o ṣe n bẹrẹ abẹwo rẹ si orilẹede South Africa.
Eyi ni yoo jẹ ibẹẹrẹ abẹwo rẹ akọkọ si ilẹ Afirika nibi ti o ti n reti ati fi idi ajọṣepọ okoowo mulẹ lẹyin ti ilẹ Gẹẹsi ja ara rẹ kuro ninu ajọ ilẹ Yuroopu eleyi ti wọn n pe ni BREXIT.
Orilẹ-ede South Africa, Nigeria ati Kenya ni olootu ijọba ilẹ Gẹẹsi naa yoo maa bẹwo pẹlu ireti ati tubọ fi idi iṣakoso rẹ mulẹ gẹgẹ bii olootu ijọba.
"Ninu atẹjade kan, Theresa May ṣalaye pe, ""Bi a ṣe n gbaradi lati fi ajọ ilẹ Yuroopu silẹ, asiko niyi fun ilẹ Gẹẹsi lati tubọ mu ajọṣepọ rẹ pẹlu awọn orilẹede jakejado agbaye gbopọn sii."""
Ilẹ Afirika duro daadaa lati ko ipa to jọju ninu irapada eto ọrọ aje gbogbo agbaye.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
May yoo ṣ'abẹwo si erekuṣu Robben Island nibi ti wọn fi Aarẹ Nelson Mandela si fun ọpọlọpọ ọdun
Lara awọn ibi ti olootu ijọba ilẹ Gẹẹsi, Theresa May yoo ṣe abẹwo si lorilẹede South Africa ni erekuṣu Robben Island nibi ti wọn fi Aarẹ Nelson Mandela si fun ọpọlọpọ ọdun lati fi ṣami ọgọrun ọdun ti wọn bi Mandela.
Lẹyin eyi ni May yoo tẹkọ leti lọ si orilẹ-ede Naijiria.
Ọ̀ọ̀ni bá Buhari sọ̀rọ̀ lórí dídá iṣẹ́ sílẹ̀ fáwọn ọ̀dọ́
Oríṣun àwòrán, @BashirAhmaad
Ọ̀ọ̀ni bá Buhari sọ̀rọ̀ lórí dídá iṣẹ́ sílẹ̀ fáwọn ọ̀dọ́
Ọọni ti ilẹ ifẹ, Ọba Adeyẹye Ogunwusi Ọjaja II ṣepade pẹlu Aarẹ Muhammadu Buhari ni ọjọ Iṣẹgun.
Nipade ọhun to waye nile aarẹ, Aso rock nilu Abuja ni Ọọni ti mu agba oludokoowo kan, Sharif Ahmad Bin Zuhir Bin Mohammad Bin Jaber Al Natour sodi lati jiroro lori idokoowo.
Ni ọjọ Aje ni Ọọni Adeyẹye Ogunwusi tọwọ bọ iwe adehun pẹ̀lú àjọ kan láti ilẹ̀ Arab ti Sharif Ahmad Bin Zuhir Bin Mohammad Bin Jaber Al Natour n dari láti dá Iléesẹ́ ohun ọ̀gbín àti ọ̀sìn nílẹ̀ Ìfẹ́.
Gẹgẹ bii atẹjade kan lati aafin Oodua ṣe sọ, ipade naa yoo da lori ajọṣepọ to lee waye laarin ileeṣẹ naa ati ijọba apapọ fun idaṣẹsilẹ fun awọn ọdọ, idagbasoke ati ironilagbara.
Bọde George: Àwọn èèyàn mọ ẹni to yìnbọn pa Adeniyi Aboriṣade
Wọ́n rò pé mo ya wèrè ni Saudi lẹ́yìn ikú ọkọ mi
'Mi o fẹẹkan ni mo fẹ dupo aarẹ'
Àwọn ọ̀dọ́ lu 'Ẹja' tó fi mọ́tò pa ọ̀dọ́kùnrin kan pa
Oríṣun àwòrán, florbabs
Wọn ni o ti kọkọ fi ọkọ rẹ kọlu obinrin ẹlẹha kan lagbegbe Olowo-Bida nilu Ẹdẹ kan naa
Awọn eeyan ilu Ẹdẹ nipinlẹ Ọṣun tu lu ọmọ ileewe onipele kẹrin ileewe giga gbogbońṣe apapọ to wa ni ilu naa pa.
Eyi ṣẹlẹ lẹyin to fi mọto pa akẹkọọ kan ti o n wa ọna ati wọ ileewe naa.
Akẹkọọ naa ti inagijẹ rẹ̀ ń jẹ 'Ẹja' ni wọn sọ pe o n kẹkọọ imọ nipa ile kikọ nileewe gbogboniṣe Polytechnic to wa nilu Ẹdẹ.
Bi o tilẹ jẹ pe ko si ẹni to lee sọ ni pato iye ẹmi to lọ sii, awọn olugbe adugbo Ita Oloki nilu Ẹdẹ ni eeyan mẹrin lo tun ku yatọ si akẹkọọ to n wa ọna ati wọle si ileewe naa.
Ileeṣẹ ọlọpaa ni eeyan kan ṣoṣo ni ọkọ̀ arakunrin naa gba.
Gẹgẹ bi iroyin ti sọ, awọn ọdọ ilu Ẹdẹ ti inu n bi ni wọn lu arakunrin naa pa lẹyin ti wọn ni ere aṣapajude to n fi ọkọ rẹ sa nigba to n gbiyanju ati sa bọ mọ agbofinro lọwọ.
Wọn ni o ti kọkọ fi ọkọ rẹ kọlu obinrin ẹlẹha kan lagbegbe Olowo-Bida nilu Ẹdẹ kan naa.
Irọlẹ ọjọ Aje ni iṣẹlẹ naa ṣẹlẹ eleyi to ti sọ ilu iṣẹmbaye naa sinu ọfọ nla.
Bọde George: Àwọn èèyàn mọ ẹni to yìnbọn pa Adeniyi Aboriṣade
Wọ́n rò pé mo ya wèrè ni Saudi lẹ́yìn ikú ọkọ mi
'Mi o fẹẹkan ni mo fẹ dupo aarẹ'
Agbófinró mú ọ̀dọ́mọkùnrin 57 níbi ètò ìgbaniwọlé fún ìbálòpọ̀ akọ-sí-akọ
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ofin Naijiria ko tako ibalopọ laarin ọkunrin s'ọkunrin
Ẹgbọn ọkan lara awọn ọdọmọkunrin ti awọn ọlọpaa ko ni ọjọ Aiku nipinlẹ Eko, ti wọn fẹsun kan pe wọn n si ibalopọ akọ-si-akọ, ni irọ ni wọn pa mọ aburo oun.
Ọjọ Aiku to kọja ni awọn ọlọpaa mu awọn ọdọmọkunrin mẹtadinlọgọta nilu Eko, ti wọn si fi ẹsun kan wọn pe wọn n ni ibalopọ ọkunrin s'ọkunrin.
Ọkan lara awọn ọdọmọkunrin naa ni Wọle, to jẹ ẹni ọdun mẹtalelogun.
Ẹgbọn rẹ, Ojo Ọladele sọ fun BBC pe  'ibi ariya ni aburo oun(Wọle) dagbere pe oun n lọ ni alẹ ọjọ Abamẹta, ko to di wi pe awọn ọlọpaa mu u.
'Àwọn ọ̀tẹlẹ̀múyẹ́ tí n ṣèwádí ohùn Leah Sharibu'
Ìgbẹ́ ọmọdé ń dènà ààrun jẹjẹrẹ, àìsàn ìtọ̀ súgà
Ọwọ́ ba òsìsẹ́ SARS tó pà akẹ́ẹ̀kọ́ ní Iwo
Ọladele ni ''aburo oun ati awọn ọrẹ rẹ kan ni wọn jọ lọ si ibi ariya kan to waye nile itura kan ni agbegbe Ẹgbẹda.
"O ni ""ko pẹ to de ile itura naa, ni nkan bi aago kan oru, to si n wa awọn ọrẹ rẹ, ni awọn ọlọpaa wọle."
Bi awọn ọlọpaa sẹ wọle ni awọn eniyan to wa nibẹ bẹrẹ si ni salọ.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ofin Naijiria ko tako ibalopọ laarin ọkunrin s'ọkunrin
Ibi ti oun ti n gbiyanju lati ṣalaye ara rẹ fun awọn ọlọpa ni wọn ti gbe gbogbo wọn ju sinu ọkọ ọlọpaa.''
Ọladele ni ' O damiloju pupọ pe aburo mi ki i ni ibalopọ ọkunrin s'ọkunrin rara, o kan ṣirin ni.''
Wọn o jẹ ki a sun mọ ibi to wa, wọn o jẹ ka fun un ni ounjẹ, koda inu iporuru ọkan lo wa bayi, ti a ko si mọ nkan ti wọn n ṣe fun wọn ni agọ ọlọpaa.
"Wọn ko ri ẹsun kankan fi lọ wọn, ṣugbọn ile ẹjọ ti gba beeli wọn bayii.''
Agbẹjọro ọkan lara awọn ọdọmọkunrin naa, Ṣẹgun Awosanya, ti awọn eniyan tun mọ si Segalink, sọ fun BBC pe, ọrọ ọhun ko ye awọn ọlọpaa gan nitori sẹ ni awọn agbẹjọro wọn n jasi ẹni ti ẹjọ naa yoo ja mọ lọwọ ninu wọn.
Awosanya ni 'awọn ni awọn ti gba beeli wọn, titi di igba ti ileeṣẹ ọlọpaa yoo mọ ẹsun ti wọn fẹ ẹ fi kan wọn."
A si gbọ pe awọn kan ni wọn ko ni i fi ẹsun ibalopọ ọkunrin s'ọkunrin kan wọn mọ, pe ki wọn ko wọn pada lọ si ẹka ileeṣẹ ọlọpa to n gbogun ti ẹgbẹ okunkun ṣiṣe.
Ẹgbẹ́ àwọn agbẹjọro kan ti kede pe wọn ti gba beeli awọn ọdọmọkunrin naa.
Ẹwẹ, Awosanya ni bi wọn ṣe f'oju wọn han sita fun gbogbo eniyan lori ẹsun pe wọn fura siwọn ko b'ojumu.
Ileeṣẹ ọlọpaa nipinlẹ Eko ni ko din ni awọn ọdọmọkunrin mẹtadinlọgọta ti awọn ọlọpaa nipinlẹ Eko fi ofin mu 'lasiko ti wọn n ṣe eto igbaniwọle fun awọn to fẹ maa sẹ ibalopọ ọkunrin s'ọkunrin.'
Eto igbaniwọle ọhun ni iroyin ni pe o waye ni aago kan oru ọjọ Aiku, ni ile itura kan l'agbegbe Ẹgbẹda nipinlẹ Eko.
Kọmiṣọna fun ileeṣẹ ọlọpaa ipinlẹ Eko, Edgal Imohimi, ni mimu ti awọn mu wọn ko ṣẹyin awọn oṣiṣẹ alaabo abẹle to sin ileesẹ ọlọpa ni gbẹrẹ ipakọ.
O ni eyi lo mu ki awọn ọga ọlọpaa ni agbegbe Shasha ati Idimu nipa asẹ kọmisọna, yabo ile igbafẹ naa lati ṣe iwadii lori eto igbaniwọle naa.
Bọde George: Àwọn èèyàn mọ ẹni to yìnbọn pa Adeniyi Aboriṣade
Edgal ni awọn ọdọmọkunrin to le ni ọgọrin ni awọn ọlọpaa ba nibẹ ni nkan bi aago meji oru ti wọn n mu oriṣiriṣi ọti lile, to fi mọ Tramadol ati Shisha ti wọn po igbo mọ.
Wọn ni ni kete ti awọn ọmọkunrin naa ri awọn ọlọpaa ni wọn sa gba ọna ọtọọtọ, amọ ọwọ ọlọpaa tẹ mẹtadinlọgọta lara wọn.
Ṣugbọn awọn ọmọkunrin ti ọwọ ọlọpaa tẹ ọhun ni irọ ni wọn pa mọ wọn, pe awọn ki i ṣe ibalopọ ọkunrin s'ọkunrin.
Ati pe awọn ọlọpaa ko fun awọn ni anfaani lati sọ ọrọ gbe ara wọn lẹsẹ.
Ilu Ubang, jẹ ilu kan nibiti ede ti awọn ọkunrin wọn n sọ yatọ si ti awọn obinrin wọn.
2019 Election: Ẹgbẹ́ ọmọ Nàìjíríà ra fọ́ọ̀mù fún ààrẹ Buhari
Oríṣun àwòrán, Muhammadu Buhari/twitter
2019 Election: Ẹgbẹ́ ọmọ Nàìjíríà ra fọ́ọ́smu fún ààrẹ Buhari
Lánà òde yìí ní ẹgbẹ òṣèlú All Progressive Congress (APC) gbé owó tí àwọn tó bá nífẹ láti dupò níbi ìdìbò gbogboogbo ọdún 2019 yóò san jade.
Lẹ́yìn eyí ní ọ̀pọ̀ àwọn ènìyàn ti ń sọ pé ìgbéṣẹ̀ ẹgbẹ òṣèlú APC kò fí ti mẹ̀kúnù àti t'àwọn ọ̀dọ́ ṣe.
Owó fọ́ọ̀mù APC fún ipò Ààrẹ gọbọi- olùdíje
Lósàn òní ní àwọn ẹgbẹ́ kan tí wọn pé ara wọn ní ọmọ Nàìjíríà dáradára rá fọ́ọ̀mù fún ààrẹ láti díje lọ́dún 2019 gẹ́gẹ́ bi ààrẹ Nàìjíríà.
Oríṣun àwòrán, Ahmed Bashir/twitter
Buhar tí gbà fọ́ọ̀mù fún ìdupò ààrẹ ọdún 2019
Gẹ́gẹ́ bí àgbénúsọ fún ààrẹ lóri ìbánisọ̀rọ̀ ìgbàlódé Bashir Ahmad ṣe sọ lóri àtẹ̀jíṣẹ́ twitter rẹ pé àwọn ẹgbẹ́ rere ọmọ Nàìjíríà kan ló ra fọ́ọ̀mù náà fún ààrẹ Buhari
Ààrẹ ẹgbẹ́ òṣèlú APC Adams Oshiomole ló gba àwọn ẹgbé ọ̀hún sí ilé ẹgbẹ́ lásìkò tí wọn wá ra fọ́ọ̀mù náà lórúkọ ààrẹ
Àwọn ọmọ Nàíjíríà tí bẹ̀rẹ̀ sí fẹ̀sì báyìí lóri ríra fọ́ọ̀mu ọ̀hún
Buhari bá àwọn aṣíwáju APC sọ̀rọ̀ lórí ìdìbò 2019
Oríṣun àwòrán, @BashirAhmaad
Buhari lo lewaju ipade naa
Ipade Igbimọ APC waye l'Abuja.
Aarẹ Buhari lo ṣe alaga ipade igbimọ ẹgbẹ oṣelu APC to waye loru ọjọ Iṣẹgun ni ile ijọba nilu Abuja.
Awọn eekan ẹgbẹ oṣelu APC bii gomina ipinlẹ awọn ọmọ ile aṣofin apapọ, awọn minisita atawọn ọtọkulu ẹgbẹ naa lo wa nibẹ.
Oríṣun àwòrán, @BashirAhmaad
Gomina ana nipinlẹ Eko, Babatunde Faṣọla ati Ambọde n fi ẹrin atayọ ki ara wọn ni gbogbo igba ti ipade naa fi waye.
Pẹlu gbogbo iroyin nnkan o rọgbọ laarin gomina ana nipinlẹ Eko, Babatunde Faṣọla ati gomina ipinlẹ naa lọwọlọwọ to ti n lọ kaakiri fun igba diẹ ẹrin atayọ ni awọn mejeeji fi n ki ara wọn ni gbogbo igba ti ipade naa fi waye.
Oríṣun àwòrán, NAN
Awọn eekan ẹgbẹ oṣelu APC lo wa nibẹ
Senator Godswill Akpabio ati gomina ana nipinlẹ Delta, Emmanuel Uduaghan ti wọn ṣẹṣẹ fi Ẹgbẹ oṣelu PDP silẹ lati darapọ mọ APC naa wa nibi ipade naa fun igba akọkọ.
Oríṣun àwòrán, @BashirAhmaad
Senator Godswill Akpabio ati gomina ana nipinlẹ Delta, Emmanuel Uduaghan ti wọn ṣẹṣẹ fi Ẹgbẹ oṣelu PDP silẹ naa wa nibẹ
Eyi si ni irufẹ ipade yii akọkọ ti aarẹ ile aṣofin agba, Sẹnetọ Bukọla Saraki ko ni si pẹlu bi oun pẹlu ti ṣe darapọ mọ ẹgbẹ oṣelu PDP laipẹ yii.
Oríṣun àwòrán, NAN
Ọrọ idibo 2019 ko gbẹyin ninu ijiroro wọn
Ẹgbẹ́ àpapọ̀ àwọn òṣìṣẹ́ ṣì dúró lórí ọ̀rọ̀ wọn
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Awọn gomina lawọn o le san ọgbọn ẹgbẹrun Naira f'oṣiṣẹ
Àpapọ̀ ẹgbẹ́ àwọn òṣìṣẹ́ àti ẹgbẹ́ àwọn òṣìṣẹ́fẹ̀yìntì ní Nàìjíríà ti gba Ààrẹ Muhammadu Buhari nímọ̀ràn láti ṣọ̀ra fún ẹgbẹ́ àwọn Gómìnà Nàìjíríà tí wọ́n ṣàpèjúwe gẹ́gẹ́ bí aṣòdì sí òṣìṣẹ́.
Wọ́n fẹ̀sùn kàn pé irú àwọn gómìnà yìí ń ṣiṣẹ́ láti da àdéhùn ẹgbẹ́ NLC àti ìjọba àpapọ̀ rú ni lórí 30,000 owó oṣù òṣìṣẹ́ tó kéré jù.
Nínú àtẹ̀jáde kan tí Ààrẹ ẹgbẹ́ NLC Ayuba Wabba fọwọ́ sí, wọ́n ní ẹgbẹ́ àwọn gomínà Nàìjíríà kò lẹ́tọ̀ọ́ láti sọ̀rọ̀ lórúkọ ìpínlẹ̀ kọ̀ọ̀kan wọ́n sì lọ́ èyí mọ́ alága wọn lẹ́sẹ̀.
Oríṣun àwòrán, Others
Ngige àti àwọ́n òṣìṣẹ́
Awọn gomina l'orilẹede Naijiria ti sọ pe awọn ko ni le san ọgbọn ẹgbẹrun Naira ti ẹgbẹ oṣiṣẹ n beere fun bi bẹẹẹ kọ, ki wọn maa reti idaduro awọn oṣiṣẹ kan lẹnu iṣẹ.
Alaga fẹgbẹ awọn gomina, to tun jẹ gomina ipinlẹ Zamfara, Abdulaziz Yari, to ka abọ ipade pajawiri ti awọn gomina naa ṣe l'Ọjọru nilu Abuja, sọ pe ''wọn yoo gbe igbimọ kan dide lati ṣepade pẹlu Aarẹ Muhammadu Buhari lori ọrọ naa.''
Igbimọ naa ni yoo jiroro lati mọ ọna ti awọn gomina le gbe ọrọ owo oṣu oṣiṣẹ gba, paapa ọgbọn ẹgbẹrun Naira ti wọn n beere fun gẹgẹ bi owo oṣu oṣiṣẹ to kere ju.
Awọn gomina ọhun sọ pe 'owo oṣu tuntun naa ko le rọrun lati san, ayafi ti wọn ba da awọn oṣiṣẹ kan duro.''
Wọn yan gomina ipinlẹ Eko, Kebbi, Bauchi, Plateau, Akwa-Ibom, Ebonyi, Enugu ati Kaduna gẹgẹ bi ọmọ igbimọ tuntun ọhun.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Awọn gomina lawọn o le san ọgbọn ẹgbẹrun Naira f'oṣiṣẹ
Igbimọ awọn gomina lorilẹede Naijria ti sọ wi pe awọn ko tako fifi owo kun owo awọn osisẹ, amọ awọn ko ni owo lati san an ni.
Alaga igbimọ awọn gomina naa to jẹ gomina ipinlẹ Zamfara, Abdulaziz Yari  fi eyi lede lasiko to n ba awọn oniroyin sọrọ, lẹyin ipade ti wọn se ni ilu Abuja.
Yari ni awọn gomina setan lati se atilẹyin fun fifi owo kun owo osisẹ, amọ ko si owo tabi ohun alumọni ti wọn yoo fi san afikun owo osu naa.
Gomina ipinlẹ Zamfara naa fikun wi pe agbara kaka ni awọn fi n san owo osu awọn osisẹ bayii, ti o si jẹ wi pe iranwọ ijọba apapọ lawọn fi n tiraka lati san owo osu ati ajẹmọnu awọn osisẹ.
Ìgbìmọ̀ ẹlẹ́ni mẹ́ta lórí ọ̀rọ̀ owó oṣù àwọn òṣíṣẹ́ ní àwọn ti fi àdàgbá lórí ọ̀rọ̀ owó oṣù òṣìṣẹ́ rọ̀ lòdì sí ohun tí Mínísítà Chris Ngige sọ pé ìjọba ò fọwọ́ sí i.
Ìgbìmọ̀ sọ èyí nínú àtẹ̀jáde kan tí àwọn adarí ìgbìmọ̀ ẹlẹ́ni mẹ́ta ọ̀hún, Comrade Ayuba Wabba, Comrade BAla Bobboi Kaigama àti Comrade Joe Ajaero fọ́wọ́ sí.
Oríṣun àwòrán, Chris Ngige/Facebook, NLC
Ngige àti àwọ́n òṣìṣẹ́
Wọ́n ní bí Mínísítà ṣe sọ pé ìjọba ṣí ń dúnàá dúrà ọ̀rọ̀ náà pẹ̀lú ẹgbẹ́ àwọn òṣìṣẹ́ kìí ṣe òtítọ́.Ẹ̀wẹ̀, ìgbìmọ̀ tí ẹgbẹ́ kó jọ yìí sọ pé yéké yéké ni àwọn párí iṣẹ́ àwọn, gbogbo ìgbìmọ̀ fọ́wọ́ sí i láì sí àtakò kànkàn.
Wọ́n ní eléyìí wáyé lẹ́yìn ìfọ̀rọ̀jomitoro ọ̀rọ̀ pẹ̀lú ẹ̀ka ìgbìmọ̀ tí Sẹ́nétọ̀ Chris Ngige funra rẹ̀ darí tí wọ́n sì gbé ọ̀rọ̀ mẹ́rin yẹ̀wò.
Ijọba apapọ ti sọ pe oun ko fọwọ si ẹgbẹrun lọna ọgbọn Naira gẹgẹ bi owo oṣiṣẹ to kere julọ lorilẹede Naijiria eyi ti ẹgbẹ oṣiṣẹ n beere fun.
Minisita fun ọrọ oṣiṣẹ ati iṣẹ ṣiṣẹ, Chris Ngige lo fọrọ naa lede ni Ọjọru lẹyin ipade igbimọ alaṣẹ ijọba apapọ ti Aarẹ Muhammadu Buhari dari rẹ ni Abuja.
Ngige salaye pe ijọba n gbero lati maa san ẹgbẹrun mẹrinlelogun gẹgẹ bi owo oṣiṣẹ to kere julọ, nigba ti awọn ile iṣẹ aladani n gbero mẹrindinlọgbọn.
'Mo kẹ́kọ̀ọ́ fásitì sùgbọ́n aṣọ òké ló ń jáwó báyìí'
Minisita fi kun ọrọ rẹ pe ifọrọwerọ si n lọ lọwọ, ṣugbọn o fidi rẹ mulẹ pe ohun ti o ṣe pataki ju nipe maa fọwọ si owo oṣu ti o ba lagbara lati san.
O ni eyi wa ni ilana pẹlu ofin ti ajọ to n ri si ọrọ oṣiṣẹ lagbaye fi le lelẹ.
Ẹ o ranti pe ẹgbẹ oṣiṣẹ gunle iyanṣẹlodi ninu oṣu kẹsan lati fi ẹhonu han lori owo oṣu oṣiṣẹ to kere julọ lorilẹede Naijiria.
'Aisan owo osu ki se nnkan ti oju ko ri ri'
Gbagbaagba ni wọn ti abawọle ile isẹ ijọba nipinlẹ Ọṣun pẹlu bi awọ́n osise ti ṣe bẹrẹ iyansẹlodi ikilọ ọlọjọ mẹta.
Iyansẹlodi naa wa ni ibamu pẹlu asẹ ti awọn olori ẹgbẹ osisẹ pa ki awọn osisẹ bẹrẹ iyansẹlodi ọlọjọ meta ọhun.
Iroyin to tẹwa lọwọ so pe ko si osisẹ to lo si ibisẹ bi ki sẹ awọn osisẹ alaabo.
Arẹgbẹṣọla: Kò sí ìjọba tí kìí jẹ gbèsè
Bakan naa ni ọmọ sori ni ile isẹ osisẹ ijọba ibilẹ ni Olorunda ati Oṣogbo.
Ọjọ Iṣẹgun ni awọn olori ẹgbẹ oṣiṣẹ kede ninu atẹjadẹ kan ki awọn osisẹ yan isẹlodi lataari bi ijọba ti ṣe kuna lati san owó oṣù to le ni osu mẹrinlelọgbọn ati owo oṣu awọn oṣisẹ fẹyinti nipinle naa.
Oríṣun àwòrán, Facebook/Famuyantan Razak Olawale
Aworan iwe ikede Iyansẹlodi ọlọjọ mẹta losun
Ni igba to ń ba ile isẹ BBC Yoruba sọrọ, Komiṣọna fun eto iroyin, Adelani Baderinwa, ni ijọba Gomina Aregbẹsọla n gbiyanju lati yanju aawọ to rọmọ iyanṣelodi naa.
''Bi owo ti se n wa la se n san fun awọn osisẹ.Ki ijọba ati osisẹ jọ joko lati soro lo se pataki.Lati igbati Gomina Aregbesọla ti n se ijọba lati ma'n fi ọrọ jomitoro ọrọ lati yanju ọrọ laarin ara wa.''
Àwọn oṣiṣẹ feyinti ni Osun ṣé iwọde
O salaye pe '' Gomina Arẹgbẹsọla ni erongba lati san gbese ti a jẹ silẹ sugbọn ti a ko ba le san,adehun wa laarin ijọba lati san owo fun awọn osisẹ''
Laipẹ yi ni Ìgboro ìlú Oṣogbo kún fọfọ pẹlú bí awọn oṣiṣẹ feyinti ni ìpínlẹ̀ Osun ti ṣe wọde láti fí ehonu hàn sí bí wọn ti ṣe ní Gómìnà Aregbesola kò sàn owó oṣu awọn.
Kayode Fayemi: Mi ò níi lọ́kàn láti wádìí Fayoṣe
Oríṣun àwòrán, Kayode fayemi
Iṣẹ EFCC ni lati wadii Fayoṣe, kii ṣe iṣẹ mi
Gomina ipinlẹ Ekiti, Kayọde Fayẹmi ti ni ko si igba tabi akoko kan ti oun sọ fun ẹnikẹni pe ijọba oun yoo ṣewadii Ayọ Fayoṣe.
Ni ọjọ aje ni gomina Fayẹmi sọ ọrọ yii lẹyin to pade ipade idakọnkọ kan pẹlu Aarẹ Buhari ni ile aarẹ nilu Abuja.
Fayẹmi ni ojuṣe awọn ileeṣẹ to n gbogunti iwa ijẹkujẹ niyi ti o si ti wa niwaju wọn.
137 obìnrin ni ikú ń pa lójúmọ́ lágbàáyé
Kò sí ohun tó yípadà pẹ̀lú ìwọṣọ akẹ́kọ̀ọ́ ISI
"Ohun ti mo sọ ni pe maa ṣe ayẹwo awọn iwe iṣẹ ijọba lati mọ ibi ti iṣẹ de duro nibẹ.
Ojuṣe gomina yoowu to ba ṣẹọ de ipo ni lati yẹ awọn iwe wo. O ni lati mọ awọn ohun to wa nilẹ, gẹgẹ bi mo ṣe ṣẹṣẹ sọrọ nipa agbekalẹ igbimọ olubẹwo si ẹka eto ẹkọ ni ipinlẹ yii."
Adedoyin: Tí mo bá rí Buhari, màá sọ fun kó rántí pé Ọlọ́run wà
O ni kii ṣe iwadii ni oun fẹ ṣe bi ko ṣe lati mọ ibi ti ijọba to lọ ba iṣẹ de ati ibi ti o ku si.
"Kii ṣe ẹjọ mi. Mo fa Fayose le Ọlọrun lọwọ. Mo ti sọ eyi tẹlẹ."""
Lọwọ yii, Fayose n jẹjọ ẹsun ikowojẹ ti ajọ EFCC n fi kan an.
Oríṣun àwòrán, Google
Gómìnà tẹ́lẹ̀rí, Ayodele Fayọse ló kọ́ ọjà náà lásìkò tó wà nípò, tó sì ti ta lára àwọn sọ́ọ̀bù fún àwọn ènìyàn.
Gomina ipinlẹ Ekiti sọ pe oun ti ọja tuntun ti wọn kọ si Ado-Ekiti pa nitori wọn kò kọ́ọ daadaa tó.
Fayẹmi sọ eyi ninu atẹjade to fi lede gba ọwọ agbẹnusọ rẹ, Olayinka Oyebọde pe awọn gbe igbesẹ naa lẹyin ti awọn se ayẹwọ Ọja- Ọba naa.
Atẹjade naa fikun un pe awọn ti setan lati da owo pada fun awọn to ti san owo sọọbu ọja naa ko to di wi pe awọn tii pa.
Ògidì ọmọ Yorùbá gbọ́dọ̀ mọ 'áayan ògbufọ̀' dáadàa
Gomina tẹlẹri, Ayodele Fayose lo kọ ọja naa lasiko to wa nipo, to si ti ta lara awọn sọọbu fun awọn eniyan.
Amọ, Agbenuṣọ fun gomina tẹlẹri naa, Ọlalere Ọlayinka lasiko to n fesi si igbese naa, ni awọn faramọ igbese naa sugbọn ijọba gbọdọ ranti adehun ti wọn se pẹlu awọn to ra sọọbu naa, ki wọn to bere igbese lori rẹ.
Ati wi pe awọn ti ọrọ naa kan ṣalaye pe ijọba ipinlẹ Ekiti ko i tii fi iwe ransẹ si wọn wi pe wọn ti gba sọọbu lọwọ wọn nitori atunse ti wọn fẹ se lori rẹ.
Anfaani maarun un to wa ninu itẹsiwaju isejọba
Orilẹ-ede Naijria lọpọ igba ti koju aisi-itẹsiwaju ninu isejọba kan si omiran, eyi to maa n mu sisan owo osu ati didawọle ohun amayedẹrun lawujọ di ohun pipati.
Awọn gomina ni awọn ipinlẹ kọọkan ni Guusu-Iwọ oorun orilẹ-ede Naijria ko san owo osu ti ijọba to wa nilẹ jẹ silẹ, nitori wọn gbagbọ pe awọn kọ ni wọn jẹ owo osu wọn yii.
Nitori naa ni a ko le koyan isejọba to gbooro kere fun itẹsiwaju agbegbe kan si omiran to fi mọ orilẹ-ede Naijiria.
Ti àwọn to ba gba ipò kò ba tẹsiwaju ninu iṣẹ àkànṣe ìlú, ifasẹyin nla lo maa n jẹ fun ara ìlú.
O yẹ ki itẹsiwaju de ba awọn iṣẹ akanṣe ti ijọba kò ba pari lain nii fi ṣe bo ya ẹgbẹ oṣelu kan naa ló wọle lẹẹkeji tabi bẹẹ kọ.
Fayẹmi: Ọ̀pọ̀lọpọ̀ iṣẹ́ àkànṣe tó jẹ́ àsepatì ní màá ṣe yọrí
Gomina tuntun nipinlẹ Ekiti, ọmọwe Kayode Fayẹmi ti ni ipadabọ oun gẹgẹ bii gomina ipinlẹ naa kii ṣe lati gbẹsan, tabi dẹyẹ si ijọba to kogba wọlẹ.
Fayẹmi ni oun pada wa fun imubọsipo ati itẹsiwaju gbogbo awọn eeyan ipinlẹ Ekiti lapapọ.
Fayẹmi fi ọrọ naa lede lọjọ Iṣẹgun lẹyin ti adajọ agba nipinlẹ Ekiti, Ayodeji Daramọla bura fun un, gẹgẹ bii gomina tuntun ni gbagede Ekiti Parapọ, nilu Ado-Ekiti tii ṣe olu ilu ipinlẹ Ekiti.
Fayẹmi: Ọ̀pọ̀ èèkàn ìlú ló bá se ayẹyẹ ìbúra
Minisita tẹlẹri ọhun ṣe alaye pe, gbogbo awọn iwe akosilẹ nipa eto ijọba to koja lọ ni oun yoo ṣe afihan rẹ, bẹẹ sini iṣakoso oun yoo rii daju wipe, ipinlẹ naa sun kuro ni ipo to wa lọwọlọwọ bayii.
Ọpẹmipọ Bamgbọpa: Obìnrin gbọdọ̀ kó ara rẹ̀ níjànu lórí ọ̀rọ̀ ìfẹ́ nínú tíátà
"Loni, a gba ilẹ wa pada lọwọ awọn to fi wa sinu igbekun. A o ṣe ofintoto, bẹẹ sini a o ṣe afihan akọsile awọn iṣẹlẹ to waye nipinlẹ wa lasiko ijọba to kọja lọ.""Ninu iṣejọba to kọja lọ ni ipinlẹ yii ti jẹ gbese owo oṣu mẹjọ. A ko nifẹ si idajọ lori itakun ayelujara tabi idẹyẹ sini sugbọn o di dandan ki a sọ otitọ ọrọ."
A ko gbọdo ṣi ilẹkun anfani silẹ fun ẹnikẹni ti ko ni oye iṣejọba lati tọwọ bọ eto oṣelu nipinlẹ Ekiti. Bẹẹ sini a ko gbọdọ ta iyi ti a ni nitori ohun ti a fẹ jẹ.Fayẹmi ṣe alaye wipe lara awọn ifojusun iṣejọba oun ni idagbasoke eto ọgbin, idokowo to muna doko, ipese awọn ohun elo amayedẹrun, idagbasoke eto ọrọ aje ati bẹẹbẹẹ lọ.O tẹsiwaju wi pe, ọpọlọpọ awọn iṣẹ akanṣe to jẹ pipati nipinlẹ naa, ni oun yoo ṣe yọri. Bẹrẹ lati ibi oju ọna ti o ṣee rin, titi ti o fi de ori ibudo igbafẹ Ikọgọsi.
Bakan naa ni o ṣe ileri itọju ti o peye fun awọn arugbo ati ọgọrọ awọn ọdọ ti ko ri'ṣẹ ṣe.O fi kun ọrọ rẹ wipe oun ko ni sinmi titi t'awọn oṣiṣẹ yoo fi ri owo oṣu wọn gba.Fayẹmi dupẹ lọwọ gbọgbọ awọn eeyan ipinlẹ Ekiti nile-loko pẹlu alaye wipe nipasẹ wọn ni anfani lati pada s'ori apere ijọba fi waye.
Dokita Kayode Fayemi ti sebura gẹgẹbi gomina tuntun ni ipinlẹ Ekiti.
Fayemi lo jawe olubori ninu idibo si ipo gomina to waye ni Ọjọ Kẹrinla, Osu Kẹjọ labẹ asia ẹgbẹ oselu APC.
Fidio bi ayẹyẹ ibura naa se lọ lo wa ni isalẹ yii.
Ilu Ado-Ekiti to jẹ Olu-Ilu ipinlẹ Ekiti, ni ayẹyẹ ibura naa ti waye, tawọn gomina ipinlẹ Eko, Akinwunmi Ambọde, Gomina ipinlẹ Kaduna, Nasir El-Rufai, Gomina ipinlẹ Ọyo, Abiola Ajimobi ati ti ipinlẹ Kebbi, Atiku Bagudu, si pejọ si ibi ayẹyẹ naa.
IVF: Ìyá ìbejì se IVF mẹ́ta lókè òkun, ìkẹrin tó se ní Nàíjíríà, ló fi bímọ
Akọwe ijọba apapọ orilẹ-ede yii, Boss Mustapha, lo soju fun aarẹ ilẹ wa, Muhammadu Buhari nibi ayẹyẹ naa.
Igbakeji ni yii ti Kayode Fayemi yoo ma tukọ ipinlẹ Ekiti gẹgẹbi gomina. Ọdun 2010 si 2014 ni o ti se saa akọkọ labẹ ẹgbẹ oselu tẹlẹri, Action Congress of Nigeria(ACN).
Lẹyin ti wọn bura tan fun Fayẹmi, lo wa se ayẹwo awọn ọlọpaa to to lọwọọwọ lati yẹ si.
Fayemi ṣe tán láti na tán bí owó pẹ̀lú Eleka n'ílé ẹjọ́
Gomina ti wọn dibo yan ni ipinlẹ Ekiti, Ogbẹni Kayode Fayemi ti bẹrẹ igbesẹ lati koju oludije ẹgbẹ oselu PDP, Kolapo Olusola Eleka niwaju ile ẹjọ.
Oríṣun àwòrán, Fayemi /twitter
Kayode Fayemi ni oludije ẹgbẹ oselu APC to jawe olubori ninu idibo Gomina ipinlẹ Ekiti.
Ninu awijare to fi ẹri to le ni ẹgbẹrun meta segbe re,Fayemi ni oun loun gbegba oroke ninu idibo ọjọ kẹrinla osu keje ọdun 2018 ti o si rọ ile ẹjọ lati ma se ka ẹjọ ti Eleka gbewasiwaju rẹ kun.
Agbẹjọro agba mẹta ati awọn agbejọro miran lo ko sodi lati koju Eleka ti a si gbọ wi pe Hakeem AfoIabi (SAN),Yomi Aliyu (SAN) ati Kayode Olatoke (SAN) wa lara wọn.
Kayode Olatoke (SAN),  to gbẹnu sọ fun awọn agbẹjọro to ku ni ofutufẹtẹ ni iwe ehonu ti Eleka gbe wa si iwaju ile ẹjọ ti ko si le so eso rere kankan.
O salaye pe  Fayemi fidire janlẹ ni ijọba ibilẹ mejila ninu mẹrindinlogun ti idibo ti waye nipinlẹ Ekiti .
Nigba ti o n fẹsi si ẹsun pẹ iye ibo ti wọn ka ni awn aye idibo kan koja iye awọn to dibo,Olatoke ni aheso ọrọ lasan ni.
Ile ẹjọ ko ti ya ọjọ sọtọ fun igbẹjọ naa
CBN pàṣẹ kí MTN àti àwọn ilé ìfowópamọ́ da $8bn pada
Oríṣun àwòrán, Central Bank of Nigeria
Banki apapọ orilẹede Naijiria lo n se isakoso eto ọrọ owo Naijiria
Ile ifowopamọ apapọ l'orileede Naijiria (CBN) ti paṣẹ ki awọn ile ifowopamo mẹrin kan san owo itanra to le ni biliọnu marun naira.
Standard Chartered Bank, Stanbic-IBTC, Citibank, ati Diamond Bank wa lara awọn banki ti CBN lo padi apopọ pẹlu ile isẹ MTN lati tapa sofin idunadura to de pasiparọ owo lorileede Naijiria.
Bakannaa ni CBN ni ki wọn da owo to to biliọnu mẹjọ dọla pada si akoto ijọba fun pe MTN n fi ọna eru da owo pada si orileede South Africa.
Ile ifowopamọsi agba naa fi ikede naa sita loju opo Twitter re lojo aje.
Ikede naa se atupalẹ owo itanran ti awọn Banki naa yoo san bayi pe:
Ìjọba ìpínlẹ̀ Òndó àti Zamfara ya ọjọ́ sọtọ fún gbígba PVC
Oríṣun àwòrán, @inecnigeria
Iye kaadi idbo ti awọn eeyan ko tii gba n kan ọpọ lominu
Iroyin to n te wa lọwọ ni pe ọgọọrọ eniyan lo tu jade lati lọ gba kaadi idibo PVC won, leyin ti Ajo eleto idibo kede ojo kokanlelogbon, osu kejo gege bi ojo ti won yoo pari gbigba kaadi naa.
Ọgọọrọ awon eniyan to tu jade ko ṣẹyin bi ipinlẹ Ondo ati Zamfara se gbe igbesẹ lati rii pe awọn ara ilu wọn gba kaadi idibo PVC wọn pẹlu yiya ọjọ isinmi sọtọ lati lọ gba.
Ọjọbọ tìi se ọgbọn ọjọ, osu kẹjọ ni Ipinlẹ Ondo kede gẹgẹ bi ọjọ isinmi nigba ti ipinlẹ Zamfara si kede Ọjọ Ẹti ti i se ọjọ kọkanlelọgbọn, Oṣù Kẹjọ.
Ọjọ́ kọkanlelọgbọn, oṣù kẹjọ ní Àjọ eleto ìdìbò INEC kéde gẹgẹ bí gbendeke fún gbígba káàdì ìdìbò PVC.
Lai pe yi ni iroyin kan gbode pe o to kaadi idibo 315,000 ti awọn oludibo ko ti ri gba nipinle Kwara.
Ọjọ kẹtadinlọgbọn,Osu Kẹrin, ọdun 2017 ni ajọ eleto idibo INEC bẹrẹ eto iforukọsilẹ fun eto idibo ni orile-ede Naijiria.
Lẹyin ti wọn ri wi pe kaadi idibo ti awọn oludibo to f'orukọ silẹ ko tii wa gba pọ kaakiri awọn ileeṣẹ ajọ naa lorilẹ-ede Naijiria ni ti wọn kede isunsiwaju ọjọ gbedeke fún gbígba PVC.
Loju ọpo Twitter INEC, wọn fi ikede iye awọn to ti gba kaadi wọn ati iye awọn kaadi ti wọn ko ti wa gba pe...
Ni awọn aye iforukọsile ti ile isẹ BBC se abẹ́wo si, nise ni awọn oludibo kun ibẹ̀ rẹpẹtẹ.
Ọpọ awọn to ba BBC sọrọ si salaye pe iye awọn osise ajo eleto idibo to wa ni ilẹ̀ kere si iye awn eeyan to wa gba kaadi.
Folayemi Busoye to je adari ni aaye kan ti BBC kan si ni agbegbe Ikoyi nilu Eko so pe kii se kaadi tuntun nikan lawọn n fun awọn oludibo ni aaye naa.
''Awọn to sọ kaadi nu to fe gba kaadi tuntun miran naa n wa si ibi.''
Awọn eeyan kan ti forukọsilẹ tipẹ ti wọn ko si ti ri kaadi idibo wọn gba
Lai pe yi ni iroyin kan gbode pe o to kaadi idibo 315,000 ti awọn oludibo ko ti ri gba nipinle Kwara.
Garba Madami to jẹ alamojuto eto idibo nipinlẹ naa lo salaye ọrọ yi fun awọn oniroyin .
O ni eeyan 1.2 milionu ni wọn letọ lati kopa ninu idibo gbogbogbo ọdun 2019 lati ipinlẹ naa sugbọn eeyan 160,000 tutun lo sẹsẹ fi orukọ silẹ ninu eto iforukọsilẹ to n lọ lọwọ.
Gẹgẹ bi nnkan ti ajọ INEC sọ,gbigba kaadi idibo yoo tẹsiwaju titi di igba ti idibo ọdun 2019 ba sun mọ sugbọn etọ iforukọsilẹ yoo wa si ọpin ni Ọjọ́ kọkanlelọgbọn oṣù kẹjọ
Ìjẹ̀bú: Àgbàlàgbà ni mo máa ń ṣe nínú eré tẹ́lẹ̀
'O yé kí ìbáṣepọ̀ Nàìjíríà àti UK dán mọ́rán síi lẹ́yìn àbẹ̀wò May'
Ekiti: Awọn ọ̀dọ́ 2000 yóò gba iṣẹ́ lọ́wọ́ àwọn àgbàlagbà tó fẹ̀yìntì
Oríṣun àwòrán, @ekitistategov
Awọ̀n to ba fẹ gba iṣẹ agbalẹ, ọlọdẹ ati aṣọgba ko nilo lati ṣe idanwo ni tiwọn
Ko din ni awọn ọdọ ẹgbẹrun mejidinlaadọta (48,000) ti wọn ti gba fọọmu igbanisiṣẹ ti wọn si tun ti joko ṣe idanwo igbanisiṣẹ to n lọ lọwọ bayii nipinlẹ Ekiti.
Pabambari ibẹ ni pe aaye iṣẹ fun ẹgbẹrun meji eeyan lo wa nilẹ nipinlẹ naa.
Bi a o ti wa ṣee ti ọdọ ẹgbẹrun mejidinlaadọta (48,000) yoo ṣe gba iṣẹ ẹgbẹrun meji (2000) ni idamu to ba awọn alaṣẹ igbanisiẹ naa bayii nipinlẹ Ekiti.
Ìjẹ̀bú: Àgbàlàgbà ni mo máa ń ṣe nínú eré tẹ́lẹ̀
Atẹjade kan lati ọdọ olori ẹka oṣiṣẹ ọba nipinlẹ Ekiti, Ọmọwe Olugbenga Faṣeluka fi sita ṣalaye pe eredi eto igbanisiṣẹ naa ni lati di awọn aaye to ṣi silẹ lẹka iṣẹ ijọba nipinlẹ naa.
O ni alafo ti o waye lẹyin ti awọn oṣiṣẹ ti ijọba ipinlẹ Ondo atijọ labẹ Oloye Adekunle Ajaṣin laarin ọdun 1881 si 1982 gba sisẹ fi silẹ lẹyin ti wọn fẹyinti lọgọọrọ lo faa.bi o tilẹ jẹ pe awọn ẹgbẹ oṣelu alatako ti n pariwo pe ofutufẹtẹ lasan ni eto ọhun, ṣugbọn olori ẹka oṣiṣẹ ọba nipinlẹ ọhun ni awọn ẹka ti o ṣe koko ni wọn fẹ gba awọn eeyan naa si.
Idris Ibrahim, kéde ìdí tó fi kó ọlọ́pàá 30,000 lọ si Ekiti
Idris tun paroko ikilọ ranṣẹ sawọn oloṣelu lati yago fun iwa tabi ọrọ to lee fa wahala ṣaaju idibo gomina nipinlẹ Ọṣun.
Ọga agba ọlọpaa lorilẹ-ede Naijiria, Ibrahim Idris, ti ṣalaye idi ti o fi ko ọgbọn ẹgbẹrun awọn ọlọpaa lọ si ibi idibo nipinlẹ Ekiti.
Ninu ọrọ to sọ nibi ipade idanilẹkọọ kan nilu Oṣogbo lọjọbọ, ọga ọlọpaa Idris ni bi ọrọ oṣelu ṣe ri ni ipinlẹ Ekiti loun ṣe ko iye ọlọpaa to to bẹẹ jade lọ sibẹ.
Ọga Ọlọpaa Idris ni lootọ awọn eeyan pariwo ibosi lasiko naa, ṣugbọn ohun to ṣẹlẹ lasiko ibo agbegbe kan nipinlẹ Rivers, eleyi ti oun fi ọlọpaa ẹgbẹrun mẹwa ranṣẹ fun ti jẹ ko di mimọ pe oun ko j'ayopa pẹlu ẹgbẹrun lọna ọgbọn ọlọpaa ti oun fi ranṣẹ si ipinlẹ Ekiti.
Bakan naa lo tun pa aroko ikilọ ranṣẹ sawọn oloṣelu lati yago fun awọn iwa tabi ọrọ to lee fa wahala silẹ ṣaaju idibo gomina nipinlẹ Ọṣun ati idibo apapọ ti ọdun 2019.
Mo fẹ fi asiko yii gba awọn oloṣelu ni amọran atawọn ọmọlẹyin wọn gbogbo eyi keyi ninu wọn to ba ṣaigbọran si awọn ọlọpaa lọjọ ibo tabi tako ofin gbele ẹ ti yoo wa lọjọ idibo ti tapa si ofin kele yoo si gbe.
'Mi o fẹẹkan ni mo fẹ dupo aarẹ'
#NotTooYoungtoRun: Gbájú-ẹ̀ ni Saraki lò fún wa
Oríṣun àwòrán, @bukolasaraki
Sẹnẹtọ Bukola Saraki wa lara awọn ọmọ ẹgbẹ PDP to kede lati du ipo Aarẹ orileede Naijiria
Ẹgbẹ ọdọ tó pé ará wọn ni ''Not Too Young to Run Movement'' ti bẹnu àtẹ lù bí Ààrẹ ile aṣòfin àgbà Nàìjíríà Bukola Saraki ti ṣe fi ayẹyẹ wọn kéde pé òun fẹ dupo ààrẹ.
Won ni ọtọ ní nnkán tí àwọn pé Saraki wá ṣé kí o tó ṣadede fi ayẹyẹ àwọn kéde èrò rẹ láti dije ipò Ààrẹ Nàìjíríà.
Lọjọbọ ni ẹgbẹ náà fi ọrọ yí síta lójú òpó Twitter wọn lẹyìn tí fónrán fídíò kan se àfihàn àwọn ọdọ tó n dunu níbi ayẹyẹ wọn ti Saraki ti kéde pé òun yóò dije ipò Ààrẹ Nàìjíríà
Ninu atejade naa, ẹgbẹ náà ni ojú gbà awon tí fún Saraki pẹlú bí ọ ti ṣe wù iru wa bẹẹ.
Oríṣun àwòrán, @YIAGA
Sadede ni Saraki fi ayẹyẹ wa kéde èro rẹ láti dije ipò Ààrẹ Nàìjíríà.
Bakan naa ni wọn tẹsíwájú pé àwọn kò gbé lẹyìn Saraki tàbí ni ero lati kopa gẹgẹ bi ẹgbẹ oselu.
Nínú èsì rẹ sí ọrọ àwọn ẹgbẹ ọdọ náà,Senator Bukola Saraki ti agbẹnusọ rẹ Yusuph Olaniyonu fi atẹjade síta lórúkọ rẹ sọ pé òun ṣe ìkéde náà láti ṣe ìwúrí fún àwọn ọdọ ẹgbẹ òṣèlú PDP ton n gbero láti du ipò ní.
''Lootọ ni pé àwọn ọdọ  ẹgbẹ náà kò mọ sí èrò mí ṣùgbọ́n mi o gbèrò láti ṣe àkóbá fún wọn.
O ni ''mo mọ riri ipa ti awọn ọdọ nkọ lorílè-èdè yí, má sì má tẹsiwaju láti má b'awọn ṣíṣe pọ''
Europa: Arsenal yóò kojú Sporting, Chelsea yóò kojú PAOK Salonika
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ipele to kangun si aṣekagba ni Arsenal ti kuna ninu idije naa ni saa to kọja
Ẹgbẹ agbabọọlu Arsenal yoo maa koju ẹgbẹ agbabọọlu Sporting Lisbon ti Portugal ni ipin E ipele akọkọ idije Europa League ti ọdun yii.
Ninu eto ipin isọri ti ajọ ere bọọlu Yuroopu, UEFA ṣe ni ọjọ ẹti ni eyi ti farahan.
Awọn ẹgbẹ agbabọọlu miran ti Arsenal yoo tun maa waa ko pẹlu ni Arabag ti orilẹede Azerbaijan pẹlu Vorskla lati orilẹede Ukraine.
Ẹgbẹ agbabọọlu Chelsea ni tirẹ yoo maa waa ko pẹlu PAOK Salonika lati orilẹede Greece,  BATE Borisov lati orilẹede Belarus ati ẹgbẹ agbabọọlu Vidi lati orilẹede Hungary
Ipele to kangun si aṣekagba ni Arsenal ti kuna ninu idije naa ni saa to kọja lẹyin ti wọn fidirẹmi ninu ifẹsẹwọnsẹ wọn pẹlu Athletico Madrid.
SON: Aṣọ ọmọ iléèwé tó n fa jẹjẹrẹ n bẹ l'ọ́jà ní Nàìjíríà
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Àwọn iléèṣẹ́ tó n lo èròjà nàá ní china ni Sing Shun Fat School-Clothier Company àti Zenith Uniform Company.
Àjọ tó n ṣe àyẹ̀wò bí àwọn nkan èlò tí wọ́n nko wọ Nàìjíríà láti ilẹ̀ òkèérè, tó fi mọ́ èyí tí wọ́n n ṣe l'ábẹ́lé, ṣe pójú owó sí, SON, ní àwọn aṣọ ọmọ iléèwé kan tó le fa àìsàn jẹjẹrẹ ti wọlé sí Nàìjíríà.
Ajọ Standard Organisation of Nigeria, SON, sọ pé àwọn aṣọ ọmọ ileewe kan tí àwọn òntàjà n kó wọ orílẹ̀-èdè Nàìjíríà láti China, ní àpọ̀jù aró kan tí wọ́n n pè ní ''azo''. Aró azo ni àwọn iléèṣẹ́ tó n ṣe aṣọ l'órílẹ̀-èdè China àti àwọn mi i nlò.
Arsenal, Chelsea gba 'ìdájọ́' lórí ìdíje Europa
Buhari, Merkel fọwọ́ sí àdéhùn lórí ìrìnàjò ọmọ Nàìjíríà sí Germany
PVC: Ṣé a ṣẹ̀ 'jọba la ṣe ń jìyà lóri káádì ìdìbò ni?
Àjọ nàá lójú òpó ayélujára rẹ̀ sọ pé àwọn èròjà kan maa n jáde lára ''azo'', tó sì le fa jẹjẹrẹ, tó bá fi dàpọ̀ mọ́ òógùn ara ènìyàn.
SON ṣàlàyé pé wọ́n ti fi òfin de azo ní ọ̀pọ̀lọpọ̀ orílẹ̀-èdè, ṣùgban àwọn iléèṣẹ́ méjì kan l'órílẹ̀-èdè China ṣi n lò ó.
Àwọn iléèṣẹ́ nàá ni Sing Shun Fat School-Clothier Company àti Zenith Uniform Company.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ẹ̀wẹ̀, àjọ SON ní kí gbogbo àwọn tó bá fẹ́ kó aṣọ àwọn ọmọ iléèwé wọlé sí Nàìjíríà kọ́kọ́ sọ fún àwọn, kí àwọn le ṣe ìwádíì rẹ̀ kí wọ́n tó ò ko wọ Nàìjíríà.
Ọ̀pọ̀lọpọ̀ iléèwé ìjọba àti aládàáni ló n ra aṣọ̀ tí àwọn ọmọ iléèwé wọn n wọ̀ láti orílẹ̀-èdè China.
Olùkọ́ lu akẹ́kọ̀ọ́ pa nítorí ẹ̀sùn olè jíjà ní Tanzania
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Lóòtọ́ ni òfin orílẹ̀-èdè Tanzania fi àáyè gba fífi ẹgba na àwọn ọmọdé
Sperius Eradius, ọmọ ọdún mẹ́tàlá dágbére fáye l'ọ́jọ́ Ajé lẹ́yìn ọja díẹ̀ tí olùka kan nà á níléèwé fún ẹ̀sùn pé ó jí báàgì òun.
Nínú ìṣẹ̀lẹ̀ ọ̀hún tó wáyé ní orílẹ̀-èdè Tanzania, ní ìròyìn ti fìdí rẹ̀ múlẹ̀ pé ẹ̀sùn olè jíjà ni olùkọ́ ọmọ nàá fi kàn án, tó sì ''bá a wí.' Ṣùgbọ́n, ìbáwí nàá ní wọ́n ní ó yọrí sí ikú ọmọkùnrin nàá.
Ẹ fura o! Awọn kan n kó aṣọ ọmọ iléèwé tó n fa jẹjẹrẹ wọ Nàìjíríà
Kíló fa ìpànìyàn tó tún ń wáyé ní South Africa
Se ẹ mọ pe pẹlu Google Maps, ọmọ to ba sọnu lee di riri?
Àwọn mọ̀lẹ́bí ọmọ nàá ti yarí pé àwọn kò ní sin òkú ọmọ nàá títí tí àwọn aláṣẹ yóò fí fìyà jẹ olùkọ́ ọ̀hún.
Bakan naa ni iléèṣẹ́ ètò ìlera orílẹ̀-èdè naa ti bú ẹnu ẹ̀tẹ́ lu ìṣẹ̀lẹ̀ nàá, pẹ̀lú àlàyé pé ó tako òfin tó n dábò bò ẹ̀ta àwọn ọmọdé l'órílẹ̀-èdè Tanzania.
Mínísítà ètò ìlera, Ummy Mwalimu, sọ fún àwọn oníròyìn pé àwọn ti rán onímọ̀ ìjìnlẹ̀ nípa ẹ̀yà ara, tó jẹ́ aládáàni lọ sí ìlú Bukoba, tó wà ní ẹkùn Ìwọ̀ oorùn Àríwá Tanzania, níbi tí ìṣẹ̀lẹ̀ nàá ti wáye, fún ìwádìí.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Àwọn mọ̀lẹ́bí ọmọ nàá ti yarí pé àwọn kò ní sin òkú ọmọ nàá títí tí àwọn aláṣẹ yóò fí fìyà jẹ olùkọ́ ọ̀hún.
Ẹ̀wẹ̀, ẹgbẹ́ àwọn obìnrin tó jẹ́ oníṣẹ́ ìròyìn ti ṣàpéjúwe ìṣẹ̀lẹ̀ nàá gẹ́gẹ́ bi ìwà ''ìkà'', wọ́n sí tún n polomgo pé kí ''ìpànìyàn àti nína ọmọ d'ópin''.
Iléèṣẹ́ ìròyìn AFP jábọ̀ pé lóòtọ́ ni òfin orílẹ̀-èdè Tanzania fi àáyè gba fífi ẹgba na àwọn ọmọdé, àmọ́, ó ní irú ìjìyà bẹ̀ gbọdọ́ wáyé ní ọ̀nà tó b'ójúmu. Àti pé ọwọ́ àti ìbàdí bi kí wọ́n o ti na irú ọmọ bẹ̀ ẹ́.
Boko Haram: Ejò lọwọ nínú lórí ikọlù àwọn ọmọ ogun Nàìjíríà
Oríṣun àwòrán, BBC/Boko Haram
Awọn Adunkoko mọni Boko Haram sefilọlẹ idunkuku laja wọn lọdun 2009
''Boya o jẹ ootọ tabi irọ, emi ko mọ sugbọn ti o ba jẹ wi pe ikọ Boko Haram n da awọn omoogun Naijiria lọna ti wọn si n seku pawọn,ọrọ yi  fe amojuto ni kiakia''
Esi ọrọ ti ajagunfẹyinti nigba kan,ọgagun Ayo Olaniyan sọ fun ileesẹ BBC Yoruba rẹ ninu ifọrọwanilẹnuwo kan nipa ọrọ ikọlu awọn omoogun orileede Naijiria ti Boko Haram pa to aadọta ninu  wọn.
Ile ise ologun Naijiria ti ni ko si ootọ ninu iroyin naa sugbọn ọpọ ile ise iroyin lo gbe iroyin naa jade pe awọn ikọ Boko Haram lo sigun ba awọn ọmọ ogun Naijiria ni agbegbe Sari ni  ipinlẹ Borno.
Ayo Olaniyan to fi igba kan jẹ oludari ni ẹka to n risi ọrọ iroyin ni ileese ologun Naijiria so pe oun to bani lọkan jẹ ni ki a ma gbo iroyin pe awọn Boko Haram n sigun ba awọn ọmọ ogun Naijiria
'''Ti iru nnkan bayi ba n selẹ, ko si nnkan to tọka si to  ju wi pe awọn kan n fun awọn agbesunmọmi yi ni iroyin nipa isesi awọn ọlogun wa ni.''
Olaniyan tẹsiwaju pe ''aibikita si iwadi to gunrege ati otẹlẹmuyẹ lo sokunfa bi awọn Boko Haram ti se n le koju awọn ọmọ ogun Naijiria''
''Awa lo yẹ ki a ni iroyin ati ọtẹlẹmuyẹ nipa Boko Haram,kii se awọn''
Bi ikọ Boko Haram se n se ikọlu rẹ losoosu
Iléèṣẹ́ ológun Nàìjíríà ní irọ́ ni ìròyìn tó jáde síta l'ọ́jọ́ kíní oṣù Kẹsàn án, pé ikọ̀ Boko Haram pa ọgbọ̀n ọmọ ogun.
Agbẹnusọ fún ikọ̀ Operation Lafiya Dole, Ọ̀gágun Onyeama Nwachukwu ní lóòtọ́ ní àwọn ọmọ ogun àti ikọ̀ Boko Haram d'ojú ìjà kọ ara wọn, tí àwọn ọmọ ogun Nàìjíríà sì pa ọ̀pọ̀lọpọ̀ nínú àwọn ọmọ ogun Boko Haram, tí wọ́n sì tún rí àwọn nkan ìjagun wọn kó.
Nwachukwu ni òun kò tí rí i gbọ́ pé ọmọ ogun Nàìjíríà kankan kú níbi ìjà nàá. Àti pé kò tọ́ fún ẹnikẹ́ni láti maa sọ pé àwọn ọmọ ogun tó pọ̀ tó bẹ̀ẹ̀ ni àwọn pàdánù.
Ṣáàjú ni ìròyìn kan látí iléèṣẹ́ ìròyìn AFP gbé e pé àwọn ọmọ ikọ̀ Boko Haram ṣekú pa ọgbọ̀n ọmọ ogun Nàìjíríà ní ìpínlẹ̀ Borno.
Ikọlu Boko Haram lọdun 2016
Gẹ́gẹ́ bí ìròyìn tó tẹ̀ wá lọ́wọ́ láti ọ̀dọ̀ AFP, alẹ́ Ọjọ́bọ̀ ni àwọn ọmọ ogun Boko Haram ya bo ibùdó àwọn ọmọ ogun Nàìjíríà ní abúlé Sari, ìpílẹ̀ Borno, tí wọ́n sì gba ìṣàkóso agbègbè nàá fún ìgbà díẹ̀.
Ọmọ ogun kan tó bá ikọ̀ ìròyìn AFP sọ̀rọ̀, ní ''wọ́n ya bo ibùdó iléèṣẹ́ ọmọ ogun nàá, tí wọ́n sì jọ kojú ara wọn fún bi i wákàtí kan.''
''Ó ní wọ́n borí àwọn ọmọ ogun Nàìjíríà, wọ́n sì tún kó àwọn nkan ìjà kó.''
Àti pé àwọn ọmọ ogun Nàìjíríà nàá ṣe bi i akọni pẹ̀lú bí wan ṣe fi bàálù kojú Boko Haram, kí wan tó na pápá bora.''
Ṣùgbọ́n, iléèṣẹ́ ológun kò sọ ẹ̀kúnrẹ́rẹ́ bí ìjà nàá ṣe wáyé. Wọ́n kàn kéde rẹ̀ lójú òpó Twitter wọn ni pé ''àwọn ọmọ ogun dojú ìjà kọ Boko Haram ní Sari.''
Ko si alaye kankan lori iye ọmọ ogun to ku ninu isẹlẹ naa. Wọn kò sí ṣàlàyé kankan lórí iye ọmọ ogun tó kú níbi ìṣẹ̀lẹ̀ nàá.
Ìwádìí atọpinpin BBC fihàn pé iks agbésùnmọ̀mí Boko Haram,rán ènìyàn tó lé ní ẹ̀ẹ́dẹ́gbẹ̀wá s'ọ́run ní ọdún 2017. Èyí ló tí ì pọ̀jù láti ìgbà tí wan ti n ṣọṣẹ́.
Oríṣun àwòrán, AFP
Ilu Maiduguri lorilẹede Nigeria ni ibudo afojusun Boko Haram julọ
Ikọ adunkoko mọni ni Boko Haram, to si kọlu ijọba orilẹede Naijiria lọdun 2009 pẹlu erongba lati se agbekalẹ isejọba ẹlẹsin Islam lagbegbe iwọ oorun Afrika.
Ikọ naa, to dojukọ ẹkun ila oorun ariwa orilẹede Naijiria, lo ti ran eeyan bii ọkẹ kan (20,000) sọrun ọsangangan, to si tun ti sọ awọn eeyan bii miliọnu meji  di alaini ile lori.
Boko Haram, ti Abubakar Shekau n dari rẹ, lo ti jẹjẹ atilẹyin rẹ fun ikọ tamọ ntiye ISIS losu kẹta ọdun 2015. Amọ nigba to di osu kẹjọ ọdun 2016, ni ikọ Boko Haram fọ si wẹwẹ, lẹyin ti ikọ IS kede pe wọn ti rọ Shekau loye.
Iroyin ni, apapọ ikọlu ti Boko Haram se jẹ aadọjọ (150) lọdun 2017, eyi si fihan pe ọwọ ikọ adunkoko mọni naa mulẹ pupọ lọdun 2017 ju tọdun 2016 lọ, nitori ikọlu mẹtadinlaadoje (127)  lo se lọdun 2016.
Ni ọdun mejeeji yi, osu kinni ọdun ni ikọlu Boko Haram peleke julọ, ti ọwọja wọn si rinlẹ pupọ eyiun lẹyin ti aarẹ Muhammadu Buhari ti ni oun ti ri opin ikọ naa.
Bi ikọ Boko Haram se n se ikọlu rẹ losoosu
Orilẹede Naijiria si lo faragba ọpọ ikọlu naa julọ lọdun 2016 ati 2017, ti ipinlẹ Borno si jẹ ilu abinibi awọn adunkoko mọni  ọhun,  ti wọn n dojukọ julọ.
Bakanaa ni ikọ Boko Haram fidi rẹ mulẹ pe oun lee tun gba ilẹ kan si lọdun 2017 pẹlu bo se tun kọlu ẹknu ariwa orilẹede Cameroon, agbegbe Niger Diffa ati Lake Chad, ti gbogbo wọn wa leti aala ilẹ ila oorun ariwa Naijiria.
Aworan yi se afihan awọn ibudo ti Boko Haram yan mu lati kọlu lọdun 2016, amọ iyatọ diẹdiẹ wa laarin ọdun meejeeji, ti orilẹede Naijiria si ni iriri ikọlu to pọ julọ lọdun 2017, ti orilẹede Niger si ni ikọlu Boko Haram to kere julọ lọdun naa.
Aworan agbegbe ti Boko Haram kọ̀lu julọ̀ lọ̀dun 2016
Awọn agbegbe ti Boko Haram kọlu Lọdun 2017
Iroyin ni, ikọlu aadọrun (90) ni awọn gende agbebọn se  nigbati  ikọlu awọn aso ado iku mọra jẹ mọkandinlọgọta (59).
Orilẹede Naijiria naa si ni ori ikọlu wọnyi ta julọ, ti ikọlu Boko Haram to buru julọ si jẹ tawọn agbebọn.
Ni aala ilẹ Naijiria si Cameroon, ikọ naa nsamulo ilana to yatọ, ti wọn si nlo awọn aso ado iku mọra ju awọn agbebọn lọ.
Bakanaa ni wọn lo ilana yi lawọn orilẹede mejeeji lọdun 2016.
OsunDecides: Saraki ní kò sí ìpínlẹ̀ tó jẹ òsìsẹ́ lówó tó Ọ̀sun
Saraki ni inira ati awọn ipenija to n ba awọn eeyan ipinlẹ Ọṣun finra ko lẹgbẹ lorilẹede Naijiria
Aarẹ ile igbimọ aṣofin Bukọla Saraki ni ko yẹ ki itẹsiwaju de ba ẹgbẹ tabi ijọba ti ko ṣe anfani fun awọn eeyan ilu.
Saraki sọ ọrọ ọhun l'Ọjọru nibi aṣekagba ipolongo ibo to waye ni gbagede 'Freedom Park' ilu Oṣogbo fun oludije si ipo gomina lati inu ẹgbẹ oṣelu PDP, Sẹnatọ Ademọla Adeleke.
O tẹsiwaju wipe bi orilẹede Naijiria ba nilo atunṣe lootọ, lati ipinlẹ Ọṣun gan lo ti yẹ ki awọn oludibo fi apẹrẹ rẹ han lọjọ kejilelogun oṣu kẹẹsan ọdun yii.
Saraki fi kun ọrọ rẹ wipe, inira ati awọn ipenija to n ba awọn eeyan ipinlẹ Ọṣun finra ko lẹgbẹ lorilẹede Naijiria, pẹlu alaye wipe ko si ipinlẹ to jẹ awọn oṣiṣẹ lowo to ipinlẹ Ọṣun lati igba ti iṣejọba awarawa ti bẹrẹ lọdun 1999.
OsunDecides: Omisore ní ẹni tó bá fẹ́ ra ìbò, àwọn yóò lọ lásọ mú ni
"Igba to ku bii ọsẹ kan si idibo ni wọn wa san diẹ lara owo yin. Ẹyin eeyan mi l'Ọsun, wọn ko fẹran yin o. Ẹ jẹ ki wọn mọ wipe iru ẹ ko gbọdọ ṣẹlẹ mọ l'Ọṣun
Mo ti ṣe gomina ri fun ọdun mẹjọ, bakan naa sini mo ti jẹ alaga igbimọ awọn gomina. Lati igba ti. ti bẹrẹ iṣejọba awarawa lọdun 1999, mi o mọ ipinlẹ kankan ti wọn ti jẹ gbese owo oṣu fun ọdun mẹta gbako yatọ si ti ipinlẹ Ọṣun.
Wọn si ni ki ẹ dibo yin fun itẹsiwaju.
Njẹ a le pe ijọba to n jẹ gbese ni onitẹsiwaju?"
Saraki tẹsiwaju wipe jakejado orilẹede Naijiria ni awọn gomina ti n wa ojutu si ọrọ owo oṣu awọn oṣiṣẹ, titi to fi de awọn apa ibi ti Boko Haram ti n ṣoro bi agbọn, sugbọn bakan naa kọ lọmọ ṣori nipinlẹ Ọṣun.
O rọ awọn eeyan ipinlẹ Ọṣun lati tuyaya jade lọjọ kejilelogun oṣu kẹẹsan ọdun yii, ki wọn si fi ibo wọn le ijọba ajigbese kuro ni ipinlẹ Ọṣun.
Ogunlọgọ awọn eeyan to ti de sibi ipolongo ibo naa ni wọn wọ asọ ẹgbẹjọda ti wọn tẹ́ẹ ami idamọ ẹgbẹ oselu PDP si lara.
Lara awọn eekan to bawọn peju-pesẹ sibi aṣekagba ipolongo ibo naa ni igbakeji aare orilẹese yi tẹlẹri, Atiku Abubakar, aare ile igbimọ asofin tẹlẹri, David Mark.
Awọn yoku ni, alaga apapọ fẹgbẹ oṣelu PDP, ọmọọba Uche Secondus, gomina ipinlẹ Kwara, Abdulfatah Ahmed, gomina ipinlẹ Ogun tẹlẹri, Ọtunba Gbenga Daniel ati bẹẹbẹẹ lọ.
Gbajugbaja olorin takasufe, David Adeleke ti gbogbo eeyan mọ si 'Davido' naa ko gbẹyin nibi ipolongo ibo fun aburo baba rẹ, Ademọla Adeleke ti o jẹ oludije si ipo gomina lati inu ẹgbẹ oṣelu PDP.
Eto idibo si ipo gomina ipinlẹ Ọṣun yoo waye lọjọ kejilelogun oṣu kẹẹsan ọdun yii, Ademọla Adeleke yoo si maa takangbọn pẹlu awọn oludije mẹtadinlaadọta mii.
Bi o tile jẹ wipe aago mejila ni wọn sọ wipe eto naa yoo gbinaya, titi di aago meji ọsani, nnkan ko tii fi bẹẹ ṣarajọ nitori awọn alejo pataki ti wọn n reti ko tii gunlẹ si papa ipolongo.
Ogunlọgọ awọn eeyan to ti de sibi ipolongo ibo naa ni wọn wọ asọ ẹgbẹjọda ti wọn tẹ́ẹ ami idamọ ẹgbẹ oselu PDP si lara.
Oorun mu, ti oju ọjọ si dara laisi ifarahan ojo wẹli-wẹli kankan to lee ba eto ipolongo ibo naa jẹ.
Oorun mu, ti oju ọjọ si dara laisi ifarahan ojo wẹli-wẹli kankan to lee ba eto ipolongo ibo naa jẹ.
Ninu iroyin miran ẹwẹ, Pẹlu gbogbo gbọnmọgbọnmọ iroyin nipa awọn oloṣelu to n fi ẹgbẹ oṣelu APC silẹ nipinlẹ Ọsun, kaka ki ewe agbọn ọ dẹ fun ẹgbẹ oṣelu naa,  lile lo n le ṣii o.Nibayii, ọmọ ile asofin ipinlẹ Ọṣun miran tun ti fi ẹgbẹ oṣelu APC silẹ.
Dokita Olaolu Oyeniran to n ṣoju fun ẹkun idibo Odo-ọtin nipinlẹ Ọsun ti gbera sọ lọ si ẹgbẹ oṣelu ADC.Ọmọlẹyin gomina ana nipinlẹ Ọsun, Ọmọọba Ọlagunsoye Oyinlọla to tun jẹ agba ọjẹ lẹgbẹ oṣelu ADC ni ọpọ eeyan mọ aṣofin Oyeniran si.Ilu Okuku ni aṣofin Oyeniran ti kede pe ohun ti darapọ mọ ẹgbẹ oṣelu ADC eyi ti ko tii pe wakati merinlelogun ti awọn aṣofin mẹta kan ti kọkọ kede awọn n fi ẹgbẹ oṣelu APC silẹ nipinlẹ ọhún.
Nnkan ko fẹ ṣe deede fún ẹgbẹ oṣelu APC nipinlẹ Ọsun lọwọ yii pẹlu bi awọn ọmọ ileegbimo aṣofin ipinlẹ naa mẹta tun ti ṣe yẹba lọ darapọ mọ ẹgbẹ oṣelu ADP ni ọjọ abameta.Bi ẹ ko bá kúkú ní gbàgbé, ẹgbẹ ADP yii kan naa ni Alaaji Moshood Adeoti tó jẹ akọwe ijọba labẹ ijọba gomina Rauf Aregbesola to jẹ ti ẹgbẹ APC darapọ mọ lẹyin to kuro laipẹ yìí.Ẹni tó n baa dije gẹgẹ bii igbakeji, iyẹn ọjọgbọn Durotoye Adeolu gan an lo tẹwọ gbà awọn aṣofin mẹta yii.
"Ninu ọrọ to ba awọn ololufẹ rẹ sọ nibẹ, Họnọrebu Debọ Akanbi ṣalaye wí pé, "" A mọ ipilẹṣẹ APC nipinlẹ Ọsun, a si ni adehun pẹlu gomina Arẹgbẹṣọla lati lo ọdun mẹjọ rẹ nipo, kii ṣe lati wa yan eeyan kan le wa  lọwọ nigba ti o ba ṣetan ati lọ."
A ko faramọ jijoye baba isalẹ le ẹgbẹ lori, mi ṣi n fi daa yin loju pe púpọ ọmọ ẹgbẹ oṣelu APC lo ṣi n bọ
Oríṣun àwòrán, @MoshoodAdeoti
Adeoti wa lara awọn ọmọ ẹgbẹto kọkọ fi ẹgbẹ oselu APC silẹ nipinlẹ Osun .
Bi ẹ ko ba ní gbagbe kò tíì pé ọsẹ meji ti aṣofin Clement Akanni to n ṣoju ẹkun idibo Ila to jẹ agbegbe ọkan lara awọn àgba ẹgbẹ oṣelu APC lorilẹ ede Naijiria, oloye Bisi Akande, pẹlu ti dagbere fun ẹgbẹ oṣelu naa to sì gba ẹgbẹ oṣelu PDP lọ.Amọṣa o, ẹgbẹ oṣelu APC ti ni igbesẹ awọn aṣofin mẹta yii ko tu irun kan lara oun o.Alukoro fun ẹgbẹ oṣelu naa ni ipinlẹ Ọṣun, Amofin Oyatomi sọọ ninu atẹjade kan to fi sita lori ikanni WhatsApp awọn oniroyin nipinlẹ Ọsun pe arọwa ọmọluabi ti ẹgbẹ APC fẹ gba awọn aṣofin naa ni pe ki wọn kọwe fi ipo ti wọn wa gẹgẹ bíi aṣofin silẹ nitori aya ọlẹ laa gba, ẹni kan kii gba ọmọ ọlẹ.
Ìbúgbàmù Somalia: Àwọn ọmọ ilé ìwé farapa nínú ìbúgbàmù
Oríṣun àwòrán, Reuters
Obinrin kan n sa kuro nibi ti ibugbamu ti waye ni Mogadishu
Eeyan kan to wa ọkọ ti o ko ado oloro si inu rẹ ti se okunfa ibugbamu kan to se akoba fun ile isẹ ijọba kan ni olu ilu Somalia, Mogadishu ti o si tun ko ipalara ba ile iwe kan to sunmọ ibi iṣẹlẹ naa.
Ado oloro to bu gbamu ni agbegbe Howladag ni awọn osisẹ ijọba lagbegbe naa sọ fun BBC  pe o se iku pa ọmọ ogun mẹta ti eeyan mẹrinla si farapa.
Ọmọde mẹfa wa ninu awọn to farapa ọhun.
Awọn ile to wa ni tosi isẹlẹ naa to fi mọ mọsalasi kan la gbọ pe ibugbamu naa ko ba.
Ikọ ọmọ ogun Al Shabab ti o wa nidi igbesunmọmi lagbegbe yii ti ni isẹ ọwọ awọn ni.
Oríṣun àwòrán, Twitter/@abdi_adaani
Agbesunmọmi to wa nidi ibugbamu naa wa ọkọ to gbe ado oloro wọ inu ọgba oun ni
Salah Hassan Omar to jẹ osisẹ ijọba lagbegbe naa sọ pe awọn ọmọ ogun mẹta to ku ko agbako nigba ti wọn dina mọ ki agbesunmọ naa ma gbe ọkọ to fẹ fi se isẹ ibi naa wọnu ọgba ile isẹ ijoba kan.
Raqiya Mahamed Ali,  ti oun naa wa ninu ọgba naa nigba isẹlẹ oun ni ''ẹnu isẹ wa la wa ki a to saa dede gbọ ibugbamu naa''
O sọ fun ile isẹ iroyin Reuters pe ''Mo sa asala fun ẹmi mi si abẹ tabili. Ni se ni iro ibọn gbalẹ... nigba ti ngo fi jade sita,se ni mo ri ọpọ eeyan to farapa nilẹ ti awọn miran si ti ku''
Lai ọdun 1991 ni orileede Somalia ti n koju ipenija rukerudo ati iwa janduku lati igba ti awọn kan gba ij ba lọwọ awọn ologun.
Ìjọba àpapọ̀ buwọ́lu $1.3b fún àkanṣe iṣẹ́ márùn ún
Oríṣun àwòrán, Getty Images
'Buhari yoo si tẹsiwaju lati pari awọn apati akanṣe iṣẹ gbogbo dipo bibẹrẹ awọn miran'
Ijọba apapọ ti buwọlu owo to le ni biliọnu kan dọla owo ilẹ Amẹrika fun nina lori awọn akanṣe iṣẹ to loorin kan.
Gẹgẹ bi minisita feto iroyin, Alaaji Lai Mohammed ṣe sọ ọ lasiko to fi n kopa lori eto ileeṣẹ Mohunmaworan apapọ Naijiria, NTA, inu òṣuwọn ajọni fun idokoowo, Sovereign Investment Fund ni wọn ti fa owo naa yọ lati fi yanju akanṣe iṣẹ marun kan kaakiri ibu ati oro orilẹede Naijiria.
Awọn akanṣe iṣẹ ti ọrọ kan ni opopona marosẹ Eko si Ibadan, afara keji ori odo Niger pẹlu opopo alasopọ ẹkun ila oorun si iwọ oorun orilẹede Naijiria.
Awọn akanṣe iṣẹ miran ti ọrọ kan tun ni opopona marosẹ Abuja si Kano pẹlu akanṣe iṣẹ lori ipese ina ọba lati Mambilla.
Minisita Lai Mohammed ni iṣejọba aarẹ Muhammadu Buhari ti fara rẹ jin fun idagbasoke ohun amayedẹrun gbogbo jakejado orilẹede Naijiria; yoo si tẹsiwaju lati pari awọn apati akanṣe iṣẹ gbogbo dipo bibẹrẹ awọn miran.
'Wiwa ọkọ Baalu da bi ki ẹ lọ da duro sori apata'
Ìdìbò 2019: Ọmọ ẹgbẹ́ APC àti PDP fìja pẹ́ẹ́tà l'Ábuja
Oríṣun àwòrán, Atiku/twitter
Ijà bẹ́sílẹ̀ nílé 'ẹgbẹ́ PDP
Ija bẹ silẹ lolu ile iṣẹ ẹgbẹ oṣelu PDP l'Abuja loni Ọjọbọ lẹyin ti igbakekeji Aarẹ orilẹede Naijiria tẹlẹ ri Atiku Abubakar lọ fi fọọmi idije fun 'po ààrẹ sọwọ sile ẹgbẹ pada.
Àwọn ọmọ ẹgbẹ́ òṣèlú All Progressive  Congress àti àwọn ọmọ ẹgbk òṣèlú People's Democractic Party PDP ló fìjà pẹ́ẹta ní kété ti ààrẹ àná Atiku Abubakar ṣe àdá pada fọọmù ìfèróngbà rẹ̀ hàn láti du ipò ààrẹ lọ́dún 2019
Oríṣun àwòrán, Atiku/twitter
Ọmọ ẹgbẹ́ òṣèlú APC àti PDP fìja pẹ́ẹ́tà nílé ẹgbẹ PDP l'Ábuja
Rúkèrúdò òhún tó wáyé fún ǹkan bi ọgbọn iṣéjú tí fi àpá málagbàgbé sí àwọn obìnrin méjì kan nígbà ti wọn ń gbìyànjú láti wọ olú ilé ẹgbẹ́ PDP.
Bí elòmíràn ṣé ń lèkò ní àwọn míràn ń yọwọ́ ẹ̀ṣẹ́ gẹ́gẹ́ bí ìròyìn Vanguard ṣe sọ pé ìjà bk sílẹ̀ nígbà ti àwọn ọmọ ẹgbẹ́ APC dà ps mọ àwọn PDP pẹ̀lú àsìá ẹgbk wọn lọ́wọ́.
Ìròyìn fí kúu pé àwọn ọmọ ẹgbẹ́ òṣèlú PDP pe ọ̀kan níja pé kí ló wá ṣe ní àgbo àwọn, èyí ló dí ariwo tí wọn sì fìjà pẹ́ẹ́ta tí ẹníkan sí lu alátìlẹ́yìn Atiku lálùbami.
Tajutaju l'awọn ọlọpaa fi pẹtu saawọ naa nibi ti awọn eeyan kan ti farapa
Oríṣun àwòrán, Dele Momodu
Ọrọ atunto eto iṣejọba jẹ ohun ti o ti gba iwaju ọrọ oṣelu lorilẹede Naijiria
Ọkan lara awọn oludije fun ipo aarẹ orilẹede Naijiria labẹ aṣia ẹgbẹ oṣelu PDP ni Alhaji Abubakar Atiku; o si ti bẹrẹ ifikuluku kaakiri orilẹede Naijiria lori ilepa rẹ.
Lopin ọsẹ to kọja ni Alhaji Atiku gbe ifikuluku rẹ de ọdọ olori ẹgbẹ Afẹnifẹre to jẹ ẹgbẹ awọn ọmọ Yoruba, Oloye Ayọ Adebanjọ nibiti iroyin ti sọ pe Oloye Adebanjọ kan sara sii pe eeyan ti awọn lee fi ọwọ rẹ sọya pe yoo ṣe ifẹ awọn Yoruba nitori ipe rẹ fun atunto eto iṣejọba lorilẹede Naijiria.
Ọrọ atunto eto iṣejọba jẹ ohun ti o ti gba iwaju ọrọ oṣelu lorilẹede Naijiria, amọṣa ọpọ ni ko mọ boya Alhaji Atiku ti lewaju ipe yii tabi rara.
Alhaji Abubakar Atiku ti wa lara awọn to lewaju ipe fun atunto ilana iṣejọba lorilẹede naijiria lati igba ti iṣejọba to wa lode bayii ti gun ori aleefa.
Oríṣun àwòrán, Dele Momodu
Awọn ọmọ Naijiria ti n sọrọ lori abẹwo yii ati boya Atiku lee ṣika adehun rẹ lori atunto ilana iṣejọba
Amọṣa awọn ọmọ orilẹede Naijiria ti n sọrọ lori abẹwo yii ati boya Atiku lee ṣika adehun rẹ lori atunto ilana iṣejọba bi o ba ni anfani lati de ori aga aarẹ.
Sẹnẹtọ David Mark ṣèlérí láti yí Nàìjíríà padà láàrin ọdún méjì
Oríṣun àwòrán, Getty Images
David Mark fìfẹ́ hàn láti dupò ààrẹ
Ààrẹ ilé ìgbìmọ àṣofin tẹ́lẹ̀ rí David Alechenu Bonaventure Mark so pe  ọdun meji loun yoo fi se atunto orileede Naijiria ti wọn ba yan oun sipo Aarẹ.
O lede ọrọ yi nigba ti o lọ gba  ìwé ìfèrongbà han lolu ile ise ẹgbẹ oselu PDP labuja ní ìgbáradì  lati du ipo Aarẹ ninu ìdìbò gbogboogbo ti ọdún 2019.
Gẹgẹ bi oun ti a ri gbọ lati ọdọ ile isẹ iroyin Sahara Reporters,Mark ni iwe ilana oun to n jẹ '730' da lori atunto Naijiria.
O si ni  laarin ọdun meji loun yoo se atunto yi.
''Mo ti n se oselu bọ ọjọ ti pẹ,O da mi loju pe mo le mu iyipada to munadoko ba Naijiria ti gbogbo ọmọ orileede yi yoo si jẹri si''
Saaju ni Mark ti kede erongba rẹ lati du ipo Aarẹ labẹ́ àsía ẹgbẹ́ òṣèlú People's Democratic Party (PDP) .
Àtẹjáde to gba ọwọ́ olúdari ètò ojule dé ojúlé fun David Mark James Oche sọ pé ọ̀gá òun lẹ́yin tó fi ọ̀rọ̀ náà lọ àwọn àgbààgba jákèjádò Nàìjíríà  ló gbé ero rẹ̀ sita láti díje.
David Mark ní òun fẹ́ díje lati gba orílẹ̀-èdè yìí sílẹ̀ lọ́wọ́ ìṣùbú ni.
Ní báyìí Bukola Saraki, Rabiu Musa Kwankwaso, Atiku Abubakar, Ahmed Markarfi, Aminu Tambuwal àti David Mark ló ti fi èrongba wọn han lati dí ààrẹ labẹ àsìá ẹgbẹ́ òṣèlú PDP.
INEC 2019: Kí ló leè mú INEC fẹ́ sún ìdìbò síwájú?
Aarẹ Muhammadu Buhari kọ lati buwọlu atunyẹwo abadofin ọdún 2018 fun eto idibo to mbọ nitori awọn ohun to pe ni 'kudiẹ kudiẹ' kan to wa ninu rẹ
Iroyin ti bọ sigboro pe o ṣeeṣe ki ajọ INEC o sun idibo ọdun 2019 siwaju nitori awọn ohun to n ṣẹlẹ lagbo eto abo.
Iroyin yii ba ọpọlọpọ ni àbo nitori pupọ awọn onwoye eto oṣelu ni wọn ni ko yẹ ko ri bẹẹ.
Awọn ẹgbẹ oṣelu alatako bii PDP ni wọn ti koro oju si iroyin ọhun.
Amọṣa o, ajọ eleto idibo, INEC ti bọ sigboro lati pariwo sita pe ko si ohun to jọ bẹẹ ninu eto wọn.
Ajọ naa ni erongba awọn kan ti wọn fẹran lati maa ko imi ẹṣin da sile ẹran niyii.
Ṣe idi wa fun awọn onwoye lati bẹẹru?
Ṣe awọn agba bọ wọn ni o nbọ, o mbọ, awọn laa dẹ dee; eyi gan an lo fa ti ọpọ fi n ko aya soke lori iroyin yii.
Arẹgbẹṣọla: Kò sí ìjọba tí kìí jẹ gbèsè
Bi a ko ba si ni gbagbe, bayii naa ni ọrọ ṣe bẹrẹ ni ọdun 2015 lasiko ti iroyin fi kọkọ jade pe ajọ INEC nigba naa yoo sun idibo aarẹ siwaju eleyii ti alaga ajọ shun nigba naa, Ọjọgbọn Atahiru Jega ti sọ pe ko si oun ti o jọ
Ẹyin-o-rẹyin ni ajọ naa pada wa kede ayipada ọjọ idibo naa.
Abala kẹrindinlọgbọn ti ajọ naa sa di lọdun 2015 ni ọfiisi  alaga ajọ naa bayii, ọjọgbọn Mahmood Yakubu sọ pe  o mẹnu ba lasiko ipade pẹlu awọn adari ẹka eto abo fun eto idibo ni Naijiria.
Ṣugbọn ninu ọrọ kan to ba BBC Yoruba sọ, kọmiṣọna agba fun eto ipolongo ati idanilẹkọ faraalu, Ọmọọba Deji Ṣoyebi ni gbogbo nnkan lo ti to fun idibo lajọ naa.
Ajọ INEC ni ko si idi fun ayipada idibo
Ohun miran to tun n kọ ọpọ lominu ni awuyewuye to n waye lori bibu ọwọ lu aba eto idibo tuntun eleyi ti aarẹ kọ lati buwọlu.
Iwoye ọpọ ni pe ṣe eyi naa ko ni fi aaye awawi silẹ fun sisun idibo siwaju?
Amọṣa kọmiṣọna agba fajọ INEC, Deji Ṣoyebi tun jẹ ko di mimọ pe gẹgẹ bii ajọ to n tẹle ilana ofin, iwe ofin idibo to wa nilẹ tẹlẹ to jẹ ti ọdun 2010 eleyi ti wọn n lo titi di asiko yii naa ni ajọ naa yoo maa lo titi digba ti ọrọ ba yanju lori abadofin eto idibo tuntun naa.
Niwọn igba ti ajọ yii ti fi da araalu loju, ireti awọn oludibo orilẹede Naijiria ninu ileri ati idaniloju rẹ pe ko ni si ayipada ninu ọjọ idibo apapọ 2019 ṣi duro lai yẹ.
Oríṣun àwòrán, INEC
Ṣé ó ṣeéṣe kí INEC sún ìdìbò 2019 síwájú?
Ajọ eleto idibo Naijiria, INEC ti ni ko si idi fun oun lati sun idibo 2019 siwaju o.
Ajọ INEC ṣalaye ọrọ yii ninu atẹjade kan ti o jade lati ọfiisi alaga ajọ naa, ọjọgbọn Mahmood Yakubu
INEC ni awọn eeyan kan lo gba ọrọ lẹnu alaga ajọ naa sọ pe o salaye nibi ipade awọn ẹṣọ alaabo lori idibo Naijiria,  ati pe ami to n foju han bayi lee mu ki ajọ naa sun idibo siwaju
Ajọ INEC ti ni irọ patpata ni iroyin naa.
O ni oun ti alaga ajọ naa ṣe lalaye fawọn adari ileeṣẹ alaabo gbogbo nibi ipade atigbadegba ti wọn maa nṣe lori eto abo fun idibo ni pe o yẹ ki igbims naa tubọ tẹmpẹlẹ mọ ipade rẹ nitori eto idibo apapọ ọdun 2019 ti n sunmọ'le.
Oríṣun àwòrán, InEC
INEC ni awọn eeyan kan lo gba ọrọ lẹnu alaga ajọ naa sọ pe o n gbaa lero lati sun idibo ọdun 2019 siwaju
"Alaga ajọ INEC ṣalaye fun igbimọ aabo naa pe, ""ko si bi idibo ṣe lee waye laarin rukerudo. O si tọka si abala kẹrindinlọgbọn iwe ofin idibo lorilẹede Naijiria to fun ajọ naa laṣẹ lati sun idibo siwaju 'bi idi ba wa fun un lati gbagbọ pe o ṣeeṣe ki wahala waye bi wọn ba tẹ siwaju pẹlu idibo naa ni ọjs ti wọn da fun un tabi nitori ajalu kan tabi pajawiri."""
Bakan naa lo ni alaga ajọ INEC tun lo anfani ipade naa lati pe akiyesi awọn ileeṣẹ alaabo naa si awọn fidio kan to n kaakiri ninu eyi ti awọn oloṣelu kan ti n sọrọ to le dabu eto abo ṣaaju, lasiko tabi lẹyin idibo lọdun 2019.
O ni nitori naa ko si ibi ti alaga ajọ naa tabi ajọ INEC lapapọ ti gbaa lero lati sun idibo ọdun 2019 siwaju.
Aarẹ Muhammadu Buhari kọ lati buwọlu atunyẹwo abadofin ọdún 2018 fun eto idibo to mbọ nitori awọn ohun to pe ni 'kudiẹ kudiẹ' kan to wa ninu rẹ
Ajọ eleto idibo lorilẹede Naijiria, INEC ti sọ pe kikuna ti aarẹ kuna lati buwọlu iwe aba atunyẹwo ofin eto idibo orilẹede Naijiria ti ọdun 2018 ko lee di igbesẹ ati igbaradi ajọ naa fun awọn idibo ọjọ iwaju, paapaa eto idibo gomina nipinlẹ Ọṣun ati eto idibo apapọ lọwọ.
Ninu ọrọ to ba BBC Yoruba sọ, Ọmọọba Deji Shonubi to jẹ ọga agba fun eto ipolongo ati ilanilọyẹ fawọn oludibo lajọ INEC lorilẹede Naijiria ni ofin to ba wa nilẹ ni ajọ INEC ma n tẹlẹ fun ilana iṣẹ rẹ gbogbo ati pe ko lee si idiwọ bi o ti wulẹ ko mọ fun ajọ naa lati gbaradi fun awọn idibo to n bọ lọnakaakiri orilẹede Naijiria.
Ajọ INEC ni ko si idi fun ayipada idibo
Ọmọọba Shonubi ni ki agbado to daye kini kan ladiyẹ n jẹ lawọn n fi ọrọ naa ṣe nitori naa ofin eto idibo kan wa nilẹ tẹlẹtẹlẹ eleyi ti ajọ naa n lo ṣaaju agbekalẹ iwe aba atunyẹwo ofin eto idibo orilẹede Naijiria ti ọdun 2018 ti a n sọrọ rẹ yii.
Laarin aarẹ ati awọn aṣofin ni ọrọ yii wa ti ko si fi bẹẹ fi gbogbo ara kan ajọ INEC eleyi ko si lee di igbaradi fun idibo ipinlẹ Ọṣun atawọn igbesẹ eto idibo fun ọdun 2019 lọwọ rara nitori sẹpẹ la wa lakọ bi ibọn.
Ajọ INEC sọ pe kikuna aarẹ lati buwọlu iwe aba atunyẹwo ofin eto idibo ọdun 2018 ko lee di igbesẹ ati igbaradi ajọ naa lọwọ
Lori ọrọ igbaradi fun idibo sipo gomina nipinlẹ Ọṣun, Ọmọọba Shonubi to tun jẹ Kọmiṣọna agba ajọ INEC to n ṣe amojuto ẹkun iwọ oorun orilẹede Naijiria ni eto idibo sipo gomina nipinlẹ Ọṣun yoo tun dara ju ti ipinlẹ Ekiti to waye loṣu keje ọdun yii lọ nitori ajọ naa ti ṣe awọn atunṣe to yẹ sawọn kudiẹ0-kudiẹ to fi oju han nipinlẹ Ekiti.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
PDP ni awọn awawi ti aarẹ n tọka si ko lee fi ohunkohun tayọ pataki atunṣe aba idibo naa
Aarẹ Muhammadu Buhari kọ lati buwọlu atunyẹwo abadofin ọdún 2018 fun eto idibo to mbọ nitori awọn ohun to pe ni 'kudiẹ kudiẹ' kan to wa ninu rẹ.
Olubadamọran fun aarẹ Buhari lori awọn ọrọ gbogbo to jẹ mọ ile aṣofin apapọ, Sẹnetọ Ita Enang ni aiṣe atunṣe gbogbo to yẹ lori abadofin naa nitori awọn agbeyẹwo ati atunṣe iṣaaju to ti waye lori rẹ lo fa awọn 'kudiẹ kudiẹ' ọhun.
Gbèsè Nàìjíríà ti di N23 Trillion
David Mark fìfẹ́ hàn láti dupò ààrẹ
Ìjọba àpapọ̀ buwọ́lu $1.3b fún àkanṣe iṣẹ́
Sẹnetọ Enang ni aarẹ ti fi ọrọ naa to awọn aṣofin ile mejeeji nile aṣofin apapọ leti ṣaaju.
"Aarẹ ti ke sawọn aṣofin apapọ lati tete wa nnkan ṣe si 'kudiẹ kudiẹ to farahan naa ki oun lee tete buwọlu lu u.''
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Sẹnetọ Enang ni aarẹ ti fi ọrọ naa to awọn aṣofin ile mejeeji nile aṣofin apapọ leti ṣaaju
O ni lara awọn kudiẹ kudiẹ ti a n sọrọ rẹ ọhun ni ti wahala aito ọjọ fun ajọ INEC lati ko orukọ awọn oludije pọ ati paapaa julọ ṣe akoso idibo abẹnu awọn ẹgbẹ oṣelu mọkanlelaadọrun to wa nilẹ bayii.
O ṣalaye pe atunyẹwo abadofin naa ko gbe abala kọkanlelọgbọn, ikẹrinlelọgbọn ati ikarundinlaadọrun to mojuto akoko fifi orukọ awọn to nifẹ lati dije ṣọwọ si ajọ naa, gbigbe orukọ awọn oludije sita to fi mọ ipolongo akoko idibo ẹgbẹ ati fifi orukọ awọn oludije ti wọn mu han yẹwo.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Aarẹ Muhammadu Buhari ni oun ko lee buwọlu iwe atunyẹwo abadofin eto idibo ọdun 2018 nitori awọn ohun to pe ni 'kudiẹ kudiẹ' to wa ninu rẹ
Amọṣa, ẹgbẹ oṣelu PDP ti ke sawọn aṣofin apapọ lati wọgile igbesẹ aarẹ Buhari naa nipa agbara ti ofin gbe le wọn lọwọ.
Ninu atẹjade kan eleyi ti alukoro fun ẹgbẹ oṣelu PDP lorilẹede Naijiria, Kọla Ologbondiyan fi sita, ohun ti aarẹ ṣe lori abadofin naa ko jẹ iyalẹnu nitori gẹgẹ bii ọrọ rẹ, aarẹ ko figbakan tẹlẹ naa fi ara rẹ jin fun eto idibo ti ko ni ẹja n bakan ninu."""
O ni awọn awawi bi wọn ṣe tẹẹ ati awọn aṣiṣẹ ti aarẹ n tọka si ko lee fi ohunkohun tayọ pataki atunṣe aba idibo naa fun igbeleke idibo to tọna, to jọju ti o si jẹ ojulowo ni ọdun 2019.
Ìdìbò 2019: kò s'ọ̀dọ́ tó lè ra fọ́ọ̀mù ipò Ààrẹ ní #45m
Owó fọ́ọ̀mù APC fún ipò Ààrẹ gọbọi- olùdíje
Olùdíje fún ipò aṣojú-ṣòfin àgbà l'Abuja Kolawole Temitope to fẹ soju ẹka idibo Okitipupa-Irele nipinlẹ Ondo sọ pé #45m owo rira fọọmu fun awọn oludije fun ipo rẹ ninu ẹgbẹ oṣelu APC ti pọju.
Temitope to ba BBC Yoruba sọrọ fidi rẹ mulẹ pe ọgbọn a ti dena awọn ọdọ lati dije ninu idibo aarẹ ọdun 2019 ni ẹgbẹ APC n da lo jẹ ki wọn gbowo gọbọi le fọọmu naa.
Temitope sọ pe o ṣeeṣe ki ẹgbẹ naa ti ni awọn ti wọn fẹ ki wọn dije lọkan ki wọn to kede owo naa.
O ni kosi ọdọ kankan to le ri iru bayii lati ra fọọmu idije fun ipo kan tabi omiran.
Ninu atẹjade kan ti igbimọ amusese ẹgbẹ naa fi sọwọ si awọn oniroyin,wọn kede ilana ti ẹgbẹ yoo lu lati sk idibo abẹnu fun idibo gbogbogbo ọdun 2019.
Oríṣun àwòrán, @APC Nigeria
Oríṣun àwòrán, @APC Nigeria
Lọjọ kaarun osu kẹsan ti se ọjọru ni wọn yoo bẹrẹ sini ta ìwé ìfèrongbà han ti ipade gbogbogbo  ẹgbẹ yoo waye ni ọjọ kejila osu kẹsan.
Gbogbo awọn oludije fun ipo Aarẹ,Gomina asoju ile asofin agba ati ile asoju sofin yoo gba fọọmu wọn ni olu ile ise ẹgbẹ to wa ni Abuja.
Osun Election 2018: Wọ́n ṣe ìbúra fún Oyetọla gẹ́gẹ́ bí gómìnà tuntun
Oríṣun àwòrán, Gboyega Oyetola/Facebook
Oyetola je olori awọn osisẹ ni ọfisi Gomina Aregbesọla.
Tonile talejo lo peju sibi ibura-wọle fun gomina tuntun Ipinlẹ Ọṣun, Adegboyega Oyetọla ni papa iṣere ni Ilu Oshogbo.
Oyetola ni ajọ INEC kede gẹgẹ bi ẹni to jawe olubori ninu atundi ibo gomina to waye losu to lọ.
O dupo gomina labẹ asia ẹgbẹ oṣelu APC nibi to ti fẹyin alatako rẹ, Ademola Adeleke ti o ṣoju ẹgbẹ PDP ninu ibo naa janlẹ.
Oríṣun àwòrán, Gbemi Jesuleke
Gómìnà tuntun Ìpínlẹ̀ Osun Adegboyega Oyetola gbàwé ẹ̀rí
Ademọla Adeleke to jẹ oludije fun ipo gomina labẹ asia ẹgbẹ PDP to se ikeji ninu idibo naa ni eeru wa ninu esi idibo ọhun, ṣugbọn ajọ INEC Oyetọla lo jawe olubori.
Buhari buwọ́lu owó oṣù tuntun fáwọn ọlọ́pàá
Wo ìdí tí Boko Haram fi ń pa ọmọogun Nàìjíríà
Osun 2018: Àwọn olùdíje ADC, ADP, APC, SDP bá aráàlú sọ̀rọ̀ lórí èròǹgbà wọn
Isiaka Adegboyega ti wọn bi ni ilu Iragbiji, ni ijọba ibilẹ Boripe ni ipinlẹ Ọsun lo si ile iwe girama ti Ifeoluwa Grammar School ni ilu Osogbo ni ọdun 1972. Lati ibẹ̀, O lọ si ile iwe giga ti Fasiti Ilu Eko nibi ti o ti gba iwe ẹri ikẹkọgboye imọ ijinlẹ Bachelor of Science (Honours) ni imọ ẹkọ idojutofo ni ọdun 1978.
Oríṣun àwòrán, Gboyega Oyetola/Facebook
Ààrẹ Muhammadu Buhari kò gbẹ́yìn lásìkò tí Oyetọla n polongo ìbò
Bawo ni ìṣèlú Oyetọla Adegboyega ṣe bẹ̀rẹ̀?
Tọkọtaya láti Najiria wọ wahálà torí ààwẹ̀ p'ọmọ wọn ní Amẹrika
Oríṣun àwòrán, Sauk County Sheriff's Office
Tọkọtaya kan lati orilẹede Naijira, Kehinde Omosebi ati iyawo rẹ Titilayo Omosebi ti foju ba ile ẹjọ kan ni Ipinlẹ Wisconsin, orilẹede Amẹrika nitori ọmọ wọn ẹni ọdun marundinlogun gbẹmi mi nigba ti wọn n gba aawẹ.
Ileeṣẹ ọlọpàá ilu Reedsburg ni ọkọ to jẹ ẹni ọdun mọkandinlaadọta ati iyawo ẹni ọdun mejidinlaadọta naa ni awọn fi ẹsun aitọju ọmọ ati aikọbi ara si ọmọ ara ẹni to fa iku kan.
Ọga ọlọpàá Reedsburg Timothy Becker ni Kehinde funra rẹ lo wa si ileeṣẹ ọlọpàá lati wa funra rẹ jẹwọ pe ọmọ wọn ti gbẹmi mi ninu ile. O sọ fun awọn ọlọpaàá pe awọn ti n gbàwẹ̀ nàá fun ọjọ mẹ́rìnlelogoji ki ọmọ wọn to gbẹ́mìí mi.
Nigba ti awọn ọlọpàá tẹ le Kehinde dele, wọn ni lati ja lẹkun wọle ni. Wọn ṣakiyesi wipe, ko si ounjẹ kankan ninu ile naa ti wọn si ri oku ọmọdekunrin naa ti ko ni omi kankan lara.
Bẹẹ naa ni wọn ri aburo rẹ ọmọ ọdun mọkanla, ti ebi ti fẹ luu pa.  Ipo kan naa ni wọn ba Titilayo, ko si omi kankan lara rẹ. Awọn ọlọpàá gbe ọmọ ọdun mọkanla naa ati iya rẹ lọ ile iwosan ṣugbọn iya rẹ kọ itọju; o sọ pe igbagbọ oun ko gba. Lẹyin naa ni wọn gbee lọ ẹwọn.
Ọlọpaaa ni awọn ti fa ọmọdekunrin naa le ẹka ijọba to n ri si itọju ọmọde lọwọ.
Kehinde sọ fun awọn ọlọpaa pe adari ijọ ni oun ni ile ijọsin Cornerstone Reformation Ministries, ṣugbọn awọn ọlọpaa ni o jọ pe ofege ni ọrọ rẹ.
OsunDecides: Ohun mẹ́wàá tó yẹ kó o mọ̀ nípa Akinbade
Oríṣun àwòrán, Akinbade
OsunDecides: Adeleke kò jáwọn olólùfẹ́ tó fẹ́ wòran ijó rẹ̀ kulẹ̀
Oríṣun àwòrán, Akinbade
Ọdun 2003 ni Olagunsoye Oyinlọla yan gẹgẹ bii akọwe Ipinlẹ Osun
2019 Election: Reuben Abati ni igbakeji gomina fún Kashamu
Oríṣun àwòrán, Wikipedia
Ìròyìn ní Adeleke Shittu tò borí ní ìdìbò abẹ́lẹ́ fipò sílẹ̀ fún Sẹ̀nétọ̀ Kashamu to n soju ẹkún ìdìbò Ìlá-Oorun ìpínlẹ̀ Ogun.
Ẹgbẹ oselu PDP ti fa ọwọ sẹnetọ Buruji Kashamu soke gẹgẹ bi ẹni ti yoo dije dupo gomina ni ipinlẹ Ogun ni idibo gbogboogbo ọdun 2019.
Oluranlọwọ fun Kashamu lori ọrọ to jẹ mọ iroyin, Austin Oniyokor sọ wi pe awọn adari ẹgbẹ lo parọwa si Kashamu lati dije dupo naa lẹyin Adeleke Shittu jọwọ ipo rẹ lẹyin idibo abẹle.
Adeleke Shittu to jawe olubori ninu idibo abẹlẹ ẹgbẹ oselu PDP ni iroyin fi lede wi pe o fi ipo rẹ silẹ fun sẹnetọ naa.
World Toilet Day: Aráàlú ní woléwolé yẹ kó bẹ̀rẹ̀ àyẹ̀wò ojúlé dé ojúlé
Amọ, iroyin fikun wi pe agbẹnusọ tẹlẹri fun Aarẹ, Reuben Abati naa ni yoo ma dije dupo gẹgẹbi igbakeji gomina labẹ ẹgbẹ oselu PDP naa ni ipinlẹ Ogun.
Àṣẹ̀yìn wá àṣẹ̀yìn bọ̀ Dapọ Abiọdun ní ẹgbẹ́ òsèlú APC kéde gẹ́gẹ́ bíi olùjáwé ilúbori níbi ìdìbò abélé fún ẹni ti yóò dupò gómìnà lábẹ́ àsíà APC ní ìpínlẹ̀ Ogun.
Saáájú ní àwọn ọmọ égbẹ́ APC ẹka ti ìpínlẹ̀ Ogun ti kéde Adekunle Akinlade ní yóò dupò gómìnà lái fi ariweo ará ìlú àti àwọn olùkopa tókù ṣe.
Ogun 2019: APC fà Dapọ Abiọdun silẹ loludije ipò Gómìnà ajumọyan
APC Primaries: A ṣi n lọ sílé ẹjọ́ lóṣù tó m bọ̀ lórí ọ̀rọ̀ yìí
Akinlade to jẹ́ ọmọ ilé ìgbàmọ aṣofin l'Abuja ní wọn ti fà kalẹ̀ tẹ́lẹ̀, sùgbọn lẹ́yìn ti àwọn ọmọ ìgbìmọ̀ amúṣẹ́ṣe tí Adams Oshiomhole ń dari dé láti wá tun ìbò dí làwọn ọmọ ẹgbẹ́ APC ipínlẹ̀ Ogun bẹ̀rẹ̀ sí ni ké gbàjarè pé ilé ẹgbẹ́ àpaps frẹ́ yàn lé àwọn lọ́wọ́. Ẹ̀yìn ò rẹyìn Dapọ̀ Abiodun ló wolé níbí àtúndi ìbò tí ìgbìmọ amúṣẹ́ṣe àpapọ̀ darí.
APC Primaries: 'Kò sí 'Faction' ni Kwara APC rárá, NWC ti sọ̀rọ̀'
Dapọ Abiọdun jáwé olúbori pẹ̀lú ìbò ẹgbẹ̀rún lónà ọgọ́rùn o lé méjì àti márùnlélọ́ọ̀dúrúǹ, nígbà ti Jimi Lawal to pọwa lée ní ẹgbẹ̀rún  mọ́kànléní ààdọ́ta àti ẹ̀tàléláàdọ́jọ, Bimbo Ashiru tó ní ìbò ẹgbẹ̀rún makàndínlọ́gbọ̀n  àti ẹ̀rìnlélọ́gọ́talélẹ́ẹ̀dẹ̀gbẹ̀rin.
Ẹni tó tún tòlé èyí ní  Adekunle ti wọn kakọ́ yàn ní ìbò ẹgbẹ̀rún mẹ́tàlélógún àti ẹ̀tàlélógójìlénírinwó, Sẹnatọ Adegbenga Kaka ní ẹgbẹ̀rún mẹ́tàd'inlógún àti ọ̀kanléláàdọ́rinlélẹ́ẹ̀dẹ́gẹ̀rin àti Abayomi Semako0 Koroto tó ní ẹgbẹ̀rún mẹ́sàn àti mẹ́wàálélẹ́gbẹ̀ta
Ogun 2019: APC fà Adekunle Akínlàdé silẹ loludije ipò Gómìnà ajumọyan
Oríṣun àwòrán, Facebook/Adekunle Abdulkabir Akinlade
Asoju fun ẹkun idibo guusu Egbado ati Ipokia ni Adekunle Abdulkabir Akinlade
Awọn agbagba ẹgbẹ oselu APC nipinlẹ Ogun ti kede orukọ ẹni ti yoo jẹ oludije fun ipo Gomina labẹ asia ẹgbẹ wọn .
Adekunle Akínlàdé Abdulkabir lorukọ rẹ.
Eyi jẹyo lẹyin ti awọn eekan ẹgbẹ APC nipinlẹ Ogun se ipade  nile akọwe ijọba ipinlẹ Ogun nigba kan ri Oloogbe Poju Adeyemi lori ọna ti wọn yoo fi yan oludije ẹgbẹ fun ipo Gomina.
Bakanna la gbo wi pe Gomina Ibikunle Amosun  naa  ti kede pe oun yoo du ipo asofin agba labe asia APC fun ẹkun arin gbungbun ipinlẹ Ogun.
Ìdìbò Ọṣun: Omisore, Akinbade ni ìjọba àpapọ̀ fẹ fi N10,000 rà'bò ni
Adekunle to jawe olubọri gẹgẹ bi oludije ayanfẹ ẹgbẹ jẹ asoju sofin nile asofin orileede Naijiria.
A gbo pe oun lo pegede laarin awọn oludije  ti wn le ni mewa to n du ipọ naa.
Oríṣun àwòrán, Facebook/Adekunle Abdulkabir Akinlade
Gomina Ibikunle Amosun n gbero lati pada si ile asofin gẹgẹ bi Seneto lọdun 2019
Ẹwẹ,Gomina ipinlẹ Oyo, Abiola Ajimọbi naa ti ni oun ati awn eekan ẹgbẹ yo pa'mọranpọ lati yan ẹni ti yoo soju ẹgbẹ ninu idije Gomina lọdun 2019.
Ikede yi la gbo pe o waye lọjọru nibi ipade awọn alẹnulọrọ ẹkun arin gbungbun ipinlẹ Oyo ni papa isere Durbar ni Oyo.
Ijọba ibilẹ mọkanla lo wa labẹ ẹkun idibo yii.
Rinsola Abiola: ADP fi ayé gba obìnrin ati ọdọ ni mo ṣe darapọ̀ mọ́ wọn.
Oríṣun àwòrán, Facebook/Rinsola Abiola
ADP ni adisokan lati fi aaye gba ọdọ ati obinrin ninu eto oselu
Ọmọ oloogbe MKO Abiola, Rinsola Abiola, ti yan ẹgbẹ oselu ADP laayo lẹyin igba to fi ẹgbẹ oselu APC sillẹ.
Ikede to se atọna igbese rẹ yii jẹyọ loju opo Twitter rẹ .
Ninu ọrọ to fi sita, o sọ wipe oun ''darapọ mọ awọn obinrin ati ọdọ ninu ẹgbẹ oselu ADP nibi ifilọlẹ awọn ọmọ igbimọ alasẹ ẹgbẹ́ naa ni ijọba ibilẹ ariwa Abeokuta''
Josh Posh: Inú mi máa ń dùn láti kọrin fún àbúrò mi ní kékeré
Ninu alaye to se nipa igbese toun gbe yii, Rinsola so pe fifun awọn obinrin ati ọdọ lanfaani lati kopa ninu oselu jẹ nnkan gbogi ti oun yan ladi-sọkan.
''ipinnu mi lati yan ADP ko sin lẹyin pe wọn ni ifarajin fun ọrọ obinrin ati ọdọ''
Bakanna lo tẹsiwaju ninu alaye rẹ pe, iye owo ti ẹgbẹ oselu ADP n gba fun fọọmu fifi erongba han lati dije fun ipo oselu, ko gunpa rara.
Oríṣun àwòrán, Facebook/Rinsola Abiola
''Fun awọn to n dije ipo ile asofin nipinlẹ, ₦330,000.00 ni wọn n san, nigba ti awọn to n du ipo ile asoju sofin si n san N1,100,000''
O ni awọn oludije obinrin laanfani pe wọn ko ni san owo fọọmu.
Bi APC ṣe pàdánù ọmọ MKO Abiọla
Ọmọ ẹgbẹ oselu APC ni Rinsola jẹ tẹlẹ ti o si n ba olori ile asoju sofin agba labuja, Yakubu Dogara, sisẹ gẹgẹ bi oluranlọwọ pataki.
Nigba ti afẹfẹ iyiẹgbẹ pada n fẹ loun naa kede pẹ oun ko se ẹgbẹ APC mọ.
Ninu lẹta kan to kọ ranṣẹ si alaga wọọdu idibo rẹ, eyi to tẹ fi sọwọn si oju opo Twitter rẹ ni Rinsọla ti salaye pe igbesẹ ohun lati fi ẹgbẹ  APC silẹ ko ṣẹyin ofin tuntun ti awọn oludari ẹgbẹ All Progressives Congress, APC, fi sita.
O ni irinajo ọdun maarun pẹlu ẹgbẹ osẹlu naa jẹ eyi to kun fun ẹ̀ka ti ko ṣe e gbagbe.
Bi o tilẹ jẹ wipe awọn kan n sọ lori ayelujara Twitter pe ẹgbẹ oṣelu Peoples Democratic Party, PDP, ni Rinsọla darapọ mọ, arabinrin naa ni oun ko ti darapọ mọ ẹgbẹ́ oṣelu kankan.
Ati pe awọn nkan bi fifi aaye gba awọn obinrin ati ọ̀dọ́, to fi mọ iṣejọba awa-arawa l'abẹle, ni yoo sọ ẹgbẹ oṣelu ti oun yoo pada darapọ mọ.
O ni ki awọn alaṣẹ ẹgbẹ oṣelu PDP ṣi fi ara balẹ naa.
Awọn iroyin ti ẹ lee nifẹ si:
Ọdalẹ ni Babangida ati Abacha - Ọmọ Abiola
'IBB da Abiola lẹ́yìn tó búra pẹ̀lú Quran'
Òjò àrọ̀rọ̀dá: Iṣẹ́ òòjọ́ dẹnu kọlẹ̀ l'Ékòó
Ojo arọrọda Eko ṣe idiwọ fún káràkátà
Lati owurọ kutukutu ọjọ Ẹtì, bii deede aago mẹfa, ni ojo arọrọda ti bẹrẹ, to si se idiwọ feto karakata nipinlẹ Eko.
Ọpọlọpọ òpópónà ló kún fún omi, ti awọn awakọ mi i si duro diẹ ki ojo naa wawọ, ki wọn to tẹsiwaju lẹnu irinajo wọn.
Àsìkò yi ni ojo máa n pọ ní orílèèdè Naijirià, tí àwọn àjọ tó n mójú tó ojú ọjọ sí ti fi ìkìlọ síta pé, o ṣeéṣe kí ọjọ po lẹnu ọjọ mẹta yí.
NISE NI OJO TO RO LEKO KUN OJU TITI
Gẹgẹ bi akọroyin BBC Yoruba, to tọpinpin ojo arọrọda naa ti wi, ọpọ isẹlẹ sunkẹrẹ-fakẹrẹ ọkọ lo waye lawọn ọpọ oju popo nilu Eko, ti aimọye osisẹ si pẹ pupọ, ki wọn to de sẹnu isẹ wọn.
Koda, ọpọ awọn ọja nla-nla gbogbo lo da paro-paro nitori bawọn ontaja ati onibara ko se ri ọna de awọn inu ọja yii, ti agadagodo si wa lẹnu awọn sọọbu ile itaja gbogbo.
Ladugbo Ikoyi nibi ti ofisi Ile isẹ BBC wa, awọn opopona bi Lugard, Alfred Rewane ati Glover kun fọfọ fun omi.
Tremor: Awọn olùgbé Mpape sọ ìrìrì wọn
Ojú kan la fí ń sùn, lẹ́yìn ilẹ̀ mímì tó wáyé
Ọ̀pọ̀ àwọn olùgbé Mpape ní wọn sọ pé orùlé ilé àwọn ti lọ lẹ̀yìn ilẹ̀ mímì tó wáyé ní ni Abuja tí gbogbo ile àwọn sì ti ń dàwó.
Ọpọ wọn sàlàyé pé ilé ọ̀rẹ́ àti ẹbí ní àwọn ńgbé báyìí nígbà ti àwọn kán kó ẹ̀rù wọn sí ẹgbẹ́ kan ilé àwókù.
Bótilẹ̀ jẹ́ pé sps ilé ti wàhálà yìí ṣẹ̀lẹ̀ sí jẹ́ ilé alábara ti àwọn míràn máà ń pè ní ilé alámọ̀ tí wọn sì ńka ohun tí wọn pàdánù báyìí.
Abdullahi sàlàyé pé ọdún mẹ́ẹ̀dógún séyìn ní òun ka ilé òhun tí  oun kò sí mọ pé bí gbogbo rẹ̀ yóò ṣe dàyà déll rèé.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ojú kan la fí ń sùn, lẹ́yìn ilẹ̀ mímì tó wáyé
O fi kún ọ̀rọ̀ rẹ̀ pé nígbà ti ilẹ̀ mú àrìwo ńlá ka jáde ní ìpìlẹ̀ ilé náà bẹ̀rẹ̀ sí ni mì títí ti àpá kan ilé náà fi ya lulẹ̀.
Abdullahi ní kọ́tìnì ni oun fí bo apá kan ile tó yapa tí oun àti ebí oun ń sùn.
Abuja Tremor: Adarí àjọ DGNG rọ àwọn ará Abuja láti fọkan balẹ
Ní ti Hafusatu Haruna, ó sàlàyé pé nígbà tí òun gbọ́ àriwo nla náà ẹru ba oun àti pe oun rò pé àyé ti parẹ́ ni, kíá ni oun ti sáré lọ sápamọ nínú yàrá kí ọkan oun to balẹ̀
O ní  ẹ̀ru sì ń ba oun pé ti irú ǹkan bayìí bá tẹ̀siwajú, ọ̀pọ̀ ènìyàn yóò dàmú pùpọ̀
Oluwafẹmi Samuel sọ pé lati ìgbà tí dé àdúgbò náà oun ò rí ńkan tó jọ bẹ́ẹ̀ rí, ati pé ní bayìí oun kìí fi ọkan balẹ̀ sùn mọ.
Abuja Tremor: Adarí àjọ DGNG rọ àwọn ará Abuja láti fọkan balẹ
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Kò sí ewu ló ilè mímì ìlú Abuja
Olùdarí àgbà fàjọ tó ń rí sí ìwádìí imọ ijinlẹ nipa ọ̀rọ̀ ilẹ ní orílẹ́-èdè Nàìjíríà, Alex Nwegbu tí rọ àwọn olúgbé ìlú Abuja pé, kò si ewu nínú ohun tó ṣẹlẹ̀ nípa ilẹ mímì.
Ó fi ìdí ọ̀rọ̀ yìí múlẹ̀ lásìkò tó ń bá àwọn oníròyín sọrọ nílù Abuja, pẹlu afikun pé Nàìjíríà kò pààlà pọ pẹ̀lú àwọn orílẹ̀ èdè tó le koju ilẹ̀ rírì.
'Fún ìdí èyí, ó ṣeeṣé kí rí ilẹ mì díẹ̀. Fún àwọn tó ń gbé àgbègbè Mpape, níwọn ìgbà tí ilé ò bá ti wó, kò sí wàhálà, wọn lee padà sí ilé wọn.
"Lẹ́yìn tí ìṣèlẹ̀ yẹ sẹlẹ̀ ní ijẹ́ta 05-09-2018, à ti rán àwọn òṣìṣẹ́ lati lọ wo ìdí abájọ rẹ, sùgbọ́n àkíyèsi ní pé, kò sí pé ogiri ile to lanu tabí pé ile wo, èyí sì túmọ sí pé ilẹ mímì náà kò lágbára.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Tremor: Adarí àjọ DGNG tí rọ àwọn ènìyàn Abuja láti fọkan balẹ
Tí ẹ ò bá gbàgbé, ní ààrọ kùtùkùtù ọjọru ní ìlẹ̀ bẹ̀rẹ̀ sí ní mí, ilé mímì yìí, gẹ́gẹ́ bí àwọn olùgbé àdúgbò kan ṣe fidi rẹ mulẹ.
Níbà yìí àjọ tó ń ri sí ọ̀rọ̀ pàjáwìrì l'Abuja FEMA tí gbé àwọn ìtọ̀nà tí àwọn ará ìlú yóò máa tọ tí ilẹ̀ rírì bá ṣẹlẹ̀.
Oríṣun àwòrán, FEMA
Tremor: Adarí àjọ DGNG tí rọ àwọn ènìyàn Abuja láti fọkan balẹ
NEMA, NHISA ní ó ṣeéṣe kí ẹ̀kun omi wáyé ní ìpínlẹ̀ méjìlá
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ki awọn eeyan orilẹede yii, paapaa awọn olugbe ipinlẹ ti ọrọ kan atawọn alẹnulọrọ lee gbaradi ni awọn ajọ tọrọkan yii fi ke ibosi sita
Ajọ to n mojuto iṣẹlẹ pajawiri lorilẹede Naijiria, NEMA pẹlu ajọ to n ṣe iwadi nipa ọrọ omi lorilẹede Naijiria ti ṣekilọ pe awọn ipinlẹ mejila kan lorilẹede Naijiria ko ni pẹ foju wina ẹkunomi eleyi ti yoo waye nipasẹ arọọrọda ojo.
Awọn ajọ mejeeji yii tọka si awọn ipinlẹ ti ọrọ shun yoo kan gẹgẹ bii ipinlẹ Kogi, Kebbi, Niger, Kwara, Edo, Anambra, Rivers, Bayelsa ati Delta.
Ojú kan la fí ń sùn, lẹ́yìn ilẹ̀ mímì tó wáyé
Òjò òwúrọ̀ ṣèdíwọ́ fún ọ̀pọ̀ olùgbé ìlú Èkó
Bakan naa ni wọn tun darukọ Taraba, Benue ati Adamawa gẹgẹ bii ara awọn ipinlẹ ọhun.
Awọn ajọ naa ni, iṣẹlẹ ẹkun omi naa ti n kankun ni lọwọlọwọ bayii nitori gbogbo awọn ohun atọka to ṣe atọna fun iṣẹlẹ ẹkun omi lọdun 2012 ti farahan bayii.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ṣiṣi awọn adagun omi Shinroro, Kainji ati Jebba nitori arọọrọda ojo ti n mu ki iṣẹlẹ ẹkun omi o maa kan ilẹkun ni Naijiria
Awọn ajọ mejeeji yii ni idi ti awọn fi ke ibosi sita lori rẹ naa ni lati fun awọn eeyan orilẹede yii, paapaa awọn olugbe ipinlẹ ti ọrọ kan atawọn alẹnulọrọ laaye lati gbaradi.
Ọkan lara awọn ọgaagba ajọ to n ṣe iwadi nipa ọrọ omi lorilẹede Naijiria, Clem Eze ṣalaye wi pe bi ati n sọrọ yii, kikun omi odo ọya, iyẹn River Niger ti le ni mita mẹwa eleyii to pọ ju mita mẹwa o din diẹ to wa lasiko iṣẹlẹ ẹkun omi ọdun 2012 to si n pọ sii ni wakati, wakati.
Fayoṣe fẹ́ kí EFCC sàn owó Ìtanràn N20 biliọnu fún òun
Oríṣun àwòrán, EFCC/Fayose/Twitter
Ẹ̀nu kun EFCC lórí ìkéde tó fi síta nípa Fayose níkété tí wọ́n kéde èsì ìbò gómìnà Ekiti
Gomina Ayodele Fayose ti ipinlẹ Ekiti ti kowe si ile isẹ EFCC, Ajọ to n gbogun ti iwa ijẹkujẹ lorilẹ-ede yii, lori ẹsun pe won ba oun loruko je ti wọn si kowe majade nilu si awọn ile isẹ alaabo.
Iyẹn nikan kọ, Fayose ni ki ọrọ naa to le tan nilẹ afi ki wọn san ogún biliọnu Naira ki wọn si kowe mabinu soun.
Ninu atẹjade kan ti agbẹnusọ fún gomina Fayose, Lere Olayinka, fi sita loju opo ayelujara,o ni wakati méjíléláàdọ́rin ni oun fun ajọ EFCC lati se atunse bi bẹẹ kọ, awọn agbejọro yoo pe wọn lẹjọ.
Ọjọbọ ni atejade naa jade nibi ti  agbẹjọro Fayose, Obafemi Adewale ti bẹnu atẹ lu igbese ajọ EFCC ninu iwe kan ti wọn fi sita lọjọ kejila, Osu kẹsan pe ki ''awọn ile isẹ alaabo ma sọ Fayose tọwọ tẹsẹ ni awọn ibode Naijiria ki o ba ma sa mọ wọn lọwọ.''
Obafẹ́mi ni ''Ọrọ yi mu abuku ba ẹni ti a n soju fun paapa julọ pe o tilẹ jẹ Gomina ti ofin daabo bo. Looto ni pe wọn n se iwadi ẹsun ti wọn fi kan Fayose sugbọn eyi ko tumọ si wi pe yoo wa fẹsẹ fẹ. Fun idi eyi, a fẹ ki ẹ se agbeyewo ki ẹ si yọ orukọ Fayose kuro ninu awọn ti wọn le sa kuro nilu tori pe awọn agbofinro n se iwadi wọn''
APC Primaries: 'Kò sí 'Faction' ni Kwara APC rárá, NWC ti sọ̀rọ̀'
Obafemi pari ọrọ rẹ́ pe wọn gbodo ko iwe lati fi tọrọ aforijin lọdọ Fayose ti wọn si gbọdo san bilionu ogun Naira lowo itanran bi bẹ kọ,ile ẹjọ ni yoo pari ọrọ fun awọn.
APC Primaries: A ṣi n lọ sílé ẹjọ́ lóṣù tó m bọ̀ lórí ọ̀rọ̀ yìí
Oríṣun àwòrán, Ayodele Fayose/Facebook
Ayọdele Fayoṣe ti máa ń tako ìjọba Ààrẹ Muhammadu Buhari
Ni ọdun 2016 ni àjọ EFCC gbẹ́sẹ̀ lé àṣùwọ̀n ìfówópamọ́sí Gómìnà ìpínlẹ̀ Èkìtì, Ayọ̀délé Fáyóṣe.
Ni kete ti igbakeji Fayose,Olusọla Eleka ti fidirẹmi ninu idibo Gomina ipinlẹ Ekiti  ajọ EFCC kede pe 'awọn ti gbọn awọn iwe to wa lọwọ awọn lori magomago to waye lori awọn ile adiyẹ ti wọn dá sílẹ̀ l'Ekiti.'
Ko pẹ si igba naa ni EFCC kowe ransẹ ki Fayose yọ́ju si ile isẹ ajọ naa ti o si kọ lati yọju.
Lati igba naa ni ọrọ laarin ajọ naa ati Fayose ti di ikun n dẹ dẹdẹ,dẹdẹ n dẹ ikun.
Laipẹ yi ni Ijọba ipinlẹ Ekiti labẹ akoso Gomina Ayodele Fayose fẹsi si ẹsun ti  Gomina ti wọn sẹsẹ dibo yan ni ipinlẹ Ekiti, Kayọde Fayẹmi fi kan lori jijẹ gbese ₦117bn kalẹ de Fayemi.
'Awa ko tọwọ bọ iwe adehun ẹyawo kankan ko si si bi a ti ṣe le ya owo ti ile iṣe to n risi ọrọ gbese ati ile ise fun eto isuna ko nimọ nipa rẹ'
Atejade lati ọdọ Lere Olayinka to jẹ agbenusọ fun Gomina Fayose ni niṣe ni Fayemi n ''wa awawi kale de bi ijọba rẹ yoo ba fori sanpọn.
O tẹsiwaju pe ijọba Fayose ko da bi Fayẹmi ti eru n ba lati koju igbimọ iwadi lẹyin to pari saa rẹ gẹgẹ bi Gomina.
''ẹru o ba odo wa. Bi won ba fe ṣe iwadi baa ti ṣe ṣe ijọba kiba jẹ ijọba ipinlẹ tabi lati ọdọ ijọba apapọ.''
Lere ni gbese tiijọba ipinlẹ Ekiti jẹ kalẹ jẹ N59.5bn eyi ti awọn jogun lati ọdọ ijọba Fayemi ati awọn eyawo miran to ti ati ọwọ ijọba apapọ wa latari bi wọn ti ṣe ṣe atunto awọn eyawo ohun.
Bi a ko ba gbagbe  laipe yi ni Gomina ti wọn sẹsẹ dibo yan ni ipinlẹ Ekiti, Ọmọwe Kayọde Fayẹmi kede pe, oun ti fa gomina to n kogba wọle nipinlẹ naa, Ayọdele Fayọṣe si kootu Ọlọrun lori awọn obitibiti gbese to jẹ lasiko to wa nijọba.
Fayẹmi ni, gbogbo gbese yoowu ti ijọba to n palẹmọ bayii lati kogba wọle nipinlẹ naa ba jẹ, ni oun yoo tẹwọ gba nitori igbagbọ oun ni pe, ijọba n tẹsiwaju ni, ko duro si oju kan.
Lasiko ti o fi n tẹwọgba abajade iṣẹ igbimọ to gbe kalẹ fun iyipada iṣejọba nipinlẹ Ekiti ni Ọmọwe Fayẹmi kede eyi.
Adebisi Idikan: Òun ló gba Ìbàdàn sílẹ̀ lọ́wọ́ ìyà owó orí sísan
O ni iyalẹnu lo jẹ bi gbese ipinlẹ naa ṣe gbera lati biliọnu mejidinlogun lasiko ti oun fi ipo silẹ di biliọnu mẹtadinlọgọfa labẹ iṣejọba Fayose, gẹgẹ bii ileeṣẹ to n mojuto ọrọ gbese lorilẹede Naijiria, DMO ṣe sọ.
Ohun ti igbimọ naa sọ fun Fayẹmi ni pe, gbese ti a n sọrọ rẹ yii ko mọ owo oṣu ti ijọba jẹ awọn oṣisẹ ati oṣiṣẹ fẹyinti atawọn owo to yẹ ni sisan fawọn Agbasẹṣe to n ṣiṣẹ fun ijọba nibẹ.
Bakan naa ni Fayẹmi tun pe fun agbekalẹ ofin, ti yoo kan nipa fun ijọba to ba n fipo silẹ lati fun eyi to fẹ wọle lanfani, si gbogbo iroyin nipa eto ati iṣẹ ijọba gbogbo nitori gẹgẹ bi ọrọ rẹ, ijọba Fayoṣe kuna lati fi anfani silẹ fun igbimọ rẹ lati mọ ibi ti nnkan de duro nidi isejọba rẹ.
Agbófinró mú afurasí to ṣekú pa Collins Esiabor
Oríṣun àwòrán, Lagos State Police Command
Malik Onebiri ni wọn fi ẹsun kan pe o yinbọn to pa sajẹnti naa
Ifakọ Ijaye ni Ọgba ni wọn ti yinbọn pa agbofinro naa.
Ọwọ ileeṣẹ ọlọpaa ni Ipinlẹ Eko ti tẹ arakunrin kan ti orukọ rẹ n jẹ Malik Onebiri ti wọn fura si pe o pa sajẹnti ọlọpaa kan.
Collins Esiabor ni wọn yinbọn pa ni Ifako Ijaiye, Ogba ni ọjọ kọkandinlọgbọn, oṣu  kẹjọ, ọdun yii.
Agbẹnusọ fun ileeṣẹ ọlọpaa ni Ipinlẹ Eko, Chike Oti ni ilu Gboko ni Ipinlẹ Benue ni awọn ọtẹlẹmuyẹ ti mu Onebiri ti inagijẹ rẹ n jẹ Kobad Baron.
Àjọ Ọlọ́pàa Naijiria: A ó fi òsìsẹ́ SARS tó se isẹ́ ibi náà jófin
Onebiri ni wọn fi ẹsun kan pe o yinbọn to pa sajẹnti naa.
Ara ikọ ọlọpaa kan to wa ni Haruna Bus Stop ni Ijako Ijaiye ni Esiabor wa nigba ti awọn ọmọ ẹgbẹ okunkun ti wọn n pe ni Eiye ṣe ikọlu si wọn ọlọpaa naa. Wọn tun ba ọkọ ọlọpaa jẹ ninu akọlu naa.
Ẹyin iṣẹlẹ naa ni kọmiṣọna fun ọlọpaa ni Ipinlẹ Eko, Imohimi Edgal leri pe, ibikibi ti Onebiri to yinbọn to pa sajẹnti naa ba wọ, ọwọ yoo tẹ.
Lẹyin naa ni awọn ikọ ọtẹlẹmuyẹ lati Area 'G' Ogba gbe awọn mọkandinlogun ti mọle, ti wọn si tun wa Onebiri lọ.
Ọlọpaa ni awọn ọmọ ẹgbẹ okunkun naaa pa ọlọpaa naaa lati gbẹsan ọkan lara wọn ti wọn ni o gbẹmi mi nigba to fara pa nibi to ti n sa lọ nigba to ri awọn ọlọpaa ni Ifakọ Ijaiye.
Bọla Tinubu: Ìpínlẹ̀ Ọ̀ṣun kò ní owó mi lọ́wọ́
Àarẹ Tanzania: Ẹ má lo òògùn ìfètò sọ́mọ bíbí mọ́
Oríṣun àwòrán, AFP
Awọn obinrin Tanzania maa n bi to ọmọ marun ni ọjọ aye wọn
Ààrẹ orilẹede Tanzania John Magufuli ti rọ awọn obinrin orilẹede naa ki wọn ye lo oogun ìfètò sọ́mọ bibi nitori awọn eniyan orilẹede naa ko pọ to.
Ṣugbọn olori alatako ni ile igbimọ aṣofin orilẹede naa Cecil Mwambe ti bẹnu atẹ lu ọrọ naa. O ni ọrọ ọun lodi si ilana eto ilera orilẹede Tanzania.
Miliọnu mẹtalelaadọta eniyan lo wa ni Tanzania, ti ida mọkandinlaadota ninu ọgọrun wọn n gbe igbe aye wọn pẹlu dọla meji lọjumọ.
Bi ida mẹta ninu ọgọrun ni awọn ero orilẹede naa fi n pọ si, eyi to fi  wa lara orilẹede to tete n pọ si ju lagbaye.
Its population is growing by more than 3% a year, among the highest rates in the world.
Oríṣun àwòrán, AFP
Àarẹ Magufuli ni ọlẹ ni awọn ti ko fẹ ọmọ si.
Magufuli sọ nibi ipade ita gbangba kan ni ọjọ Aiku pe awọn to n lo oogun ifeto sọmọ bibi, ọle ni wọn.
O ni, Wọn ko fẹ ṣiṣẹ lati bọ idile to tobi ni. Wọn fẹ maa lo oogun ifeto sọmọ bibi ki wọn baa le bi ọmọ kan tabi meji. Ẹ lọ si oke okun ki ẹ lọ ri ijamba ti oogun ifeto sọmọ bibi n ṣe lara."""
Oríṣun àwòrán, AFP
Ọjọ kan lẹyin ti Magufuli sọ ọrọ yi, olori ile igbimọ aṣofin Job Ndugai fi ofin de awọn aṣofin to jẹ obinrin lati maa lẹ ike mọ eekan ọwọ wọn ti wọn ba wa ni gbọngan aṣofin.
Ndugai sọ fun BBC Focus on Africa pe nitori ilera ni oun ṣe gbe igbesẹ naa, ṣugbọn ko ṣalaye.
Ofin naa tun de awọn obinrin aṣofin lati maa wọ aṣọ penpe tabi jinsi.
Se ẹ mọ pe pẹlu Google Maps, ọmọ to ba sọnu lee di riri?
David Bamigboye: Ọjọ́ Ẹtì ló mí kanlẹ̀ lẹ́yìn àìsàn ráńpẹ́
Oríṣun àwòrán, @IlọrinInfo
Igi da, erin wo, Ajanaku ti sun bi oke, iku ti mu akọni lọ.
Gomina ologun akọkọ ni ipinlẹ Kwara, Ajagunfẹyinti David Bamigboye, ti ki aye pe o digbose ni ọjọ ẹti.
Aburo oloogbe, Ajagunfẹyinti Theophilus Bamigboye lo tufọ iku rẹ, pẹlu afikun pe aisan ranpẹ lo mu ẹmi rẹ lọ.
Osun Election 2018: Aráàlú ní àwọn kò fẹ́ ìjọba elébi mọ́
Oloogbe David Bamigboye ni wọn bi lọjọ keje, osu kejila ọdun 1940. Oun si ni lo se agbekalẹ ile ẹkọ gbogbo n se Poly tijọba ipinlẹ Kwara lọdun 1972,
Niwọn igba to si jẹ pe baa ba ku laa dere, eeyan kii sunwọn laaye, awọn ẹni bii ẹni, eeyan bii eeyan ti n sedaro iku akọni oloogbe to faye silẹ naa.
Aarẹ orilẹ-ede Naijiria, Muhammadu Buhari ti ransẹ ibanikẹdun sawọn ọmọ ilẹ yii lori iku David Bamigboye.
Oríṣun àwòrán, @IlọrinInfo
Atẹjade kan ti amugbalẹgbẹ Buhari feto iroyin, Shehu Garba fisita ni, titi aye ni awọn ọmọ orilẹ-ede yii yoo maa seranti oloogbe naa fun ifaraẹnijin rẹ, isẹ takuntakun ati iwa asaaju rẹ, to fi mu idagbasoke ba ilẹ Naijiria.
Bakan naa, loju opo Twitter,@bukọlasaraki, aarẹ ile asofin agba ilẹ wa, Bukọla Saraki ti n para poro lori iku David Bamigboye, to si ni isẹ takuntakun to se si ipinlẹ Kwara, lawọn ko ni gbagbe laelae.
Bakan naa ni gomina ipinlẹ Kwara, Alhaji Abdul Fatai Ahmed ni ọkan oun gbọgbẹ lori iku Bamigboye, ti iku rẹ si jẹ adanu nla fun ipinlẹ Kwara amọ igbe aye rere to gbe ati idagbasoke to mu ba ipinlẹ́ Kwara lawọn yoo fi rẹ ara awọn lẹkun.
A wa gbadura pe ki Ọlọrun dẹ ilẹ fun ẹni re to lọ.
Okú àgba ọ̀jẹ ọmọ Ghana, Kofi Annan to jẹ akọwe agba fun àjọ ìṣọ̀kan àgbáyé nígba kan rí ti de Accra ni orilẹede Ghan ni ọjọ Aje.
Baalu ajọ ìṣọ̀kan agbaye (United Nations) lo gbe lati Geneva ni orilẹede Switzerland wa si Ghana.
Iyawo oloogbe naa, Nane Maria ati awọn ọmọ wọn (Ama, Kojo and Nina) darapọ mọ awọn oṣiṣẹ ajọ agbaye to tẹle oku naa wa si Ghan fun isinku. Ijọba orilẹede Ghana ni yoo ṣe isinku naa ni ọjọ  Ojobo,  ọjọ́ kẹtàlá oṣù kẹsàn, ọdun 2018.
Ààrẹ Nana Akufo-Addo ati awọn ẹẹkan ilu ati ileeṣé oloogun orilẹede naa ni wọn lọ pade oku naa ni ibudo ọkọ ofurufu ti Kotoka.
Lati ibudokọ naa, wọn gbera lọ oriko apejọro to wa ni Accra nibi ti wọn yoo ti tẹ safẹfẹ ti awọn eniyan yoo lanfani lati wa wo ni ọjọ Iṣẹgun.
Ijọba orilẹede Ghana kede ni osẹ to kọja wipe ilẹ isinku ti awọn oloogun to wa ni Accra, ni wọn yoo Annan si.
Ilẹ isinku tuntun naa ni Ghana ma n sin awọn ẹẹkan ni ileeṣẹ oloogun, awọn aarẹ to ba di oloogbe ati awọn eekan ilu si.
Oríṣun àwòrán, Kofi Annan/Twitter
Kofi Annan ati awọn ẹbi rẹ
Ọjọ kejidinlogun oṣu kẹjọ ni Anna ku ni Bern, ni orilẹede Switzerland lẹyin aisan ranpẹ.
Ìjọba ìpínlẹ̀ Ọ̀ṣun ní N16 bílíọ̀nù, owó Paris fund ti tẹ àwọn lọ́wọ́
Oríṣun àwòrán, Rauf Aregbesola
'Ko si idi fun ijọba ipinlẹ Ọṣun lati san abọ owo oṣu mọ bayii'
Ariwo ta ni ọjọ diẹ sẹyin nipa iroyin kan to kan nigboro pe ijọba apapọ ti gbẹyin san adapada owooya Paris fund fun ijọba ipinlẹ Ọṣun.
Bi awọn eeyan kaakiri ibu ati oro orilẹede Naijiria ni wọn sọ si ọrọ naa; koda ẹgbẹ oṣelu PDP gan ko gbẹyin pẹlu ẹhonu pe ti iroyin naa ba jẹ lootọ, o ku diẹ kaato fun ijọba apapọ labẹ aarẹ Buhari.
APC pàdánù aṣòfin míràn ní'pínlẹ̀ Osun
APC àti PDP takora wọn lórí Olùsirò owó àgba Ọsun tó fisẹ́ sílẹ̀
Bọla Tinubu: Ìpínlẹ̀ Ọ̀ṣun kò ní owó mi lọ́wọ́
Nibayii, ijọba ipinlẹ Ọṣun ti sọọ wi pe lootọ lawọn gba biliọnu mẹrindinlogun naira lọwọ ijọba apapọ.
Olori awọn oṣiṣẹ gomina ipinlẹ Ọṣun, Họnọrebu Rasaq Salinṣile lo fidi ọrọ yii mulẹ fun BBC Yoruba ninu ifọrọwerọ ori ẹrọ Ibanisọrọ kan pe ijọba ipinlẹ Ọṣun ti tẹwọ gba owo naa lọwọ ijọba apapọ.
Owo naa wa lara owo ti a o mu lara rẹ fi san lara ajẹẹlẹ owo oṣu awọn oṣiṣẹ nipinlẹ Ọṣun
Talàwọn ọmọlẹ́yìn Saraki tó ń du ipò Gómìnà ní Kwara?
Ali Ahmad,BolajjiAbdullahi,Zakari Mohammed ati Aliyu Ahman Pategi wa lara awọn oludije fun ipo Gomina labẹ ẹgbẹ PDP
Ọrọ oselu ipinlẹ Kwara n polukuu musu ni lọọlọ yii  paapa julọ nipa ẹni ti yoo jawe olubori  lati soju ẹgbẹ PDP ninu idibo Gomina ni ipinlẹ naa.
Ti a ba ni ki a ma ka wo o ni eni eji,o kere tan oludije maarun to jẹ ọmọlẹyin Aarẹ ile asofin agba Bukola Saraki lo ti fi erongba silẹ lati soju ẹgbẹ PDP.
Bolaji Abdullahi to jẹ agbẹnusọ fun ẹgbẹ oselu APC teleri wa lara awọn to sẹsọẹ kede erongba lati du ipo naa.
Oríṣun àwòrán, Facebook/Bolaji Abdullahi
Bolaji Abdullahi nibi ikede iferongba lati dije Gomina
Ni ọjọru ni o kede erongba rẹ ni Ilu Ilorin niwaju awọn alatilẹyin rẹ.
Bakan naa la gbo pe Zakari Mohammed to jẹ asoju fun Baruten Kaima ni ẹkun ariwa ipinlẹ Kwara naa fi iwe iferongba rẹ sowo si ile ẹgbẹ PDP, iyẹn Wadata House, labuja lọjọru.
Oríṣun àwòrán, @HonZakari
Zakari Mohammed naa ti fi iwe ferongba sowo si oul ile ẹgbẹ PDP labuja
Bi a ko ba gbagbe, olori ile asofin ipinlẹ Kwara Ali Ahmad naa ti saaju kede erongba rẹ lati du ipo Gomina ipinlẹ Kwara labẹ asia PDP.
Gbogbo awọn ti a ka sile yii to fi mọ Ahmad Pategi to jẹ ọmọ ile asojusofin agba fun Edu/ Moro/Patigi ni ẹkun ariwa Kwara naa ko gbeyin .
Oríṣun àwòrán, @fatimah_jiyah
Aliyu Ahman Bahago Pategi naa ko gbẹyin ninu idije to wa nilẹ yi
Ti a ba fi bi nnkan ti se ma n sẹlẹ lateyin wa wo,Bukola Saraki to jẹ Baba Isale fun awọn oloselu ipinlẹ Kwara a ma yan oludijk kan laayo leni ti awn oludije to ku yoo si  gbaruku ti ninu idibo.
Sugbọn bayi ti o j wi pe Bukola Saraki naa n du ipo Aarẹ orileede Naijiria o le ma rọrun lati mu eeyan kan.
Oríṣun àwòrán, @bukolasaraki
Temi to mi lẹru.Bukola Saraki naa n dije ipo Aarẹ Naijiria
Ti a ba tun wo wi pe gbogbo awọn to n du ipo yi naa ni wọn ti n ba Bukola Sraki se po ti pe.yoo soro ki o to le so wi pe ohun mu eeyan kan ti o j aayo rẹ.
Lafikun,awọn amoye kan ni sisi ipo pada lati inu ẹgbẹ APC lo si PDP le fe se idiwọ fun awọn oludije yi nitori o ni awọn kan to wa ninu gbẹ PDP tele ti awn naa f du ip Gomina nipinlẹ Kwara.
Lara wọn lati ri ojọgbọn Shuaib Oba Abdulraheem to o fi igba kan jẹ Alakoso Yunifasiti ilu Ilorin.
Awọn oloselu Kwara a ma saba seto pipin ipo oselu laarin awn ẹkun idibo to wa ni ipinlẹ naa.
Nigba ti nnkan to di dojuru to bayi,ẹkun kan ni yoo fa Gomina kale ti awọn ẹkun miran naa yoo si di ipo miran mu gẹg biigbakeji tabi Minisita ninu ijọba apapọ.
Abdulfatai Ahmed to jẹ Gomina kẹyin nipinlẹ Kwara wa lati ẹkun idibo Guusu Kwara.
Oríṣun àwòrán, @AbdulfataAhmed
Gomina Fatai Ahmed n gbero lati lo ile asofin agba lẹyin saa rẹ gẹgẹ bi Gomina
Bukola Saraki to jẹ Gomina saaju ri wa lati ẹkun gbungbun Kwara.
Awọn kan n sọ wi pe ni bayi, ẹkun idibo ariwa Kwara lo kan lati yan Gomina sugbọn ko si ẹni to le so pato boya adehun yi le di mimusẹ.
Idibo abẹnu ẹgbẹ PDP ni yoo yanju ọrọ yi sugbọn kko to di igba naa o seese ki awọn oludije ma se idunadura lori ni ti yoo jọwọ ipo naa ati ẹni ti  wn yoo gbaruku ti lati jawe olubori ninu idibo to n b lọna.
Yakubu Dogara tẹ́wọ́ gba fọ́ọ̀mù láti dupò ààrẹ
Oríṣun àwòrán, @YakubDogara
Yakubu Dogara tẹ́wọ́ gba fọ́ọ̀mù láti dupò ààrẹ
Ẹgbẹ òṣèlú APC ti fèsì sí ìròyìn tó n já ranyin pe olórí ilé aṣojú ṣofin àgbà Yakubu Dogara tí dára pọ mọ ẹgbẹ òṣèlú PDP.
Egbe náà ni 'Ìgbésẹ rẹ ko  jẹ iyalẹnu fún àwọn.'
Nínú atẹjade kàn ti akowe ìpolongo ẹgbẹ APC Yekini Nabena fi ṣòwò sí àwọn akoroyin,APC ni wọlé wode Yakubu Dogara pẹlú PDP ti wa fojú hàn gbangba báyìí.
Oríṣun àwòrán, @YakubDogara
Ohun ti awọn iwe iroyin abẹle n sọ ni pe bonkẹlẹ ni olori ile naa lọ gba fọọmu rẹ lẹgbẹ oṣelu PDP
Nabena ni Dogara kò ''ṣèṣe bẹrẹ ìrìn kurukere pẹlú PDP.''
Bakanna lo ni  ní ìgbésẹ ti awọn ti n reti ti pẹ ni ati wi pe  kò tú irun kánkan lára àwọn.
O tun tẹsiwaju pe ẹgbẹ awon gba Dogara ni imoran pe ki o ya tete du ipo rẹ labe asia ẹgbẹ tuntun to yan ni nitori pe ijakulẹ  nla n duro de.
Oríṣun àwòrán, @YakubDogara
Awọn alatilẹyin Dogara ni oun lawọn fẹ ko soju awọn ni 2019
Dogara ko ti sọ boya looto loun fi ẹgbẹ APC silẹ tabi ko ri bẹẹ.
Iroyin oloṣelu kan n fi ẹgbẹ oṣelu kan silẹ lọ darapọ mọ ẹgbẹ oṣelu miiran lo n gbode bayii.
Oríṣun àwòrán, @YakubDogara
Yakubu Dogaraso fun awọn alatilẹyin rẹ laipe wi pe ko si ẹni to le kọdi iyansipo oun lọdun 2019
Atiku, Saraki, Akpabio, Tanbuwal, Ortom, koda akọwe ẹgbẹ  oṣelu APC , Bọlaji Abdullahi ati bẹẹ bẹẹ lọ.
Nibayii iroyin tun ti n kan ka igboro pe olori ile aṣoju-ṣofin Yakubu Dogara pẹlu ti fẹ darapọ mọ iwe orukọ awọn oloṣelu to ti n fi ẹgbẹ oṣelu wọn silẹ.
"Ninu ifọrọwerọ kan pẹlu BBC Yoruba, ọkan lara awọn eekan ẹgbẹ oṣelu PDP lorilẹede Naijiria ti ko fẹ ka darukọ rẹ ni ""lootọ ni Họnọrebu Dogara ti darapọ mọ ẹgbẹ oṣelu PDP."
"Lalẹ ana lo wa gba fọọmu rẹ ṣugbọn nigba ti ko tii sọrọ ni gbangba lori rẹ awa naa pẹlu ṣi fẹ baa dakẹ gẹgẹ bi ẹgbẹ oṣelu."""
Gbogbo awọn iwe iroyin orilẹede Naijiria ni wọn gbe iroyin jade pe olori ile aṣoju-ṣofin Yakubu Dogara ti gba fọọmu erongba ati dije sile aṣoju-ṣofin lẹẹkan si lọdun 2019.
Ohun ti awọn iwe iroyin ọhun ni wọn n sọ ọ pe bonkẹlẹ ni olori ile naa lọ gba fọọmu rẹ lẹgbẹ oṣelu PDP.
Oríṣun àwòrán, @YakubDogara
Awọn ọmọ orilẹede Naijiria ṣi dẹ oju silẹ lati mọ ibi ti ọrọ naa yoo jasi
Ọkan lara awọn aṣaaju ẹgbẹ oṣelu naa to ba BBC Yoruba sọrọ ni lootọ ni eyi ati pe bi nnkan ṣe n lọ bayii omi ti n ṣe bi ẹni gbẹ lẹyin ẹja ẹgbẹ oṣelu APC paapaa nile aṣofin apapọ.
Gbogbo akitiyan BBC Yoruba lati wadi ootọ ọrọ yii lati ọdọ igun Họnọrebu Dogara ni ko tii so eso rere pẹlu bi awọn amugbalẹgbẹ rẹ ṣe n fi bi ọgbọn-bi ọgbọn yẹ ibeere yii.
Oríṣun àwòrán, @YakubDogara
Nibayii ẹgbẹ oṣelu APC ko tii sọ ohunkohun lori iroyin yii; bakan naa ni PDP pẹlu mẹnumọ lori ọrọ naa
Nibayii ẹgbẹ oṣelu APC ko tii sọ ohunkohun lori iroyin yii; bakan naa ni PDP pẹlu mẹnumọ lori ọrọ naa.
Lootọ, iroyin yiya kuro lẹgbẹ oṣelu APC ko lee jẹ kayefi fun ọpọ onwoye oṣelu lorilẹede Naijiria nitori lati igba ti iṣejọba to wa lode yii ti bẹrẹ ni oniruuru awuyewuye ti bẹrẹ lori bi Dogara ati aarẹ ile aṣofin agba, Sẹnetọ Saraki ṣe de ipo.
Amọṣa nibayii, awọn ọmọ orilẹede Naijiria ṣi dẹ oju silẹ lati mọ ibi ti ọrọ naa yoo jasi.
Mimiko: Mo ti jáwọ́ lórí ìdíje ààrẹ, Sẹ́nétọ̀ ni mo fẹ́ báyìí
Oríṣun àwòrán, @Segunmimiko
Gboye Adegbenro to n dije fun ipo sẹnetọ ni ẹkun idibo Ondo Central tẹlẹ, ni oun pẹlu ti yọ ọwọ lati fun Mimiko laaye lati dije.
Oludije ipo aarẹ labẹ aṣia ẹgbẹ oṣelu Zenith Labour Party , Olusẹgun Mimiko ti dagbere fun idije ipo aarẹ lọdun 2019.
Lasiko ti o fi ṣepade pẹlu awọn ọmọ ẹgbẹ oṣelu naa ni ọjọbọ ni Dokita Mimiko kede ọrọ yii.
O ni 'fun anfani ẹgbẹ oṣelu Zenith Labour Party ni mo ṣe gbe igbesẹ yii.'
Amọṣa, Mimiko ti ni oun ko ni lọ lọwo ofo o nitori naa ipo sẹnetọ ni oun yoo maa lọ fun bayii ni abẹ aṣia ẹgbẹ oṣelu kan naa.
Oríṣun àwòrán, @Segunmimiko
Mimiko ni fun anfani ẹgbẹ oṣelu Zenith Labour Party ni igbesẹ ti oun gbe
Ni bayii, oludije fun ipo sẹnetọ ni ẹkun idibo ile aṣofin apapọ Ondo Central tẹlẹ, Onimọ ẹrọ Gboye Adegbenro ni oun pẹlu ti yọ ọwọ kuro ninu idije fun ipo sẹnetọ lọdun 2019 lati fun gomina ana nipinlẹ Ondo, Dokita Oluṣẹgun Mimiko laaye lati dije.
Amọṣa Mimiko ko sọ ọrọ lori boya yiyọ ti ẹgbẹ oṣelu rẹ yọ ọwọ ninu idije aarẹ tumọ si pe wọn yoo gbaruku ti ẹgbẹ oṣelu miran fun idije ipo arẹ lasiko idibo apapọ lọdun 2019.
Mimiko ti kọkọ ṣalaye ninu ifọrọwerọ pẹlu BBC Yoruba laipẹ yii pe ohun ti ṣeto igbaradi gbogbo to yẹ lati di aarẹ.
Bakan naa lo sọ pe Ọlọrun sọ fun oun pe awọn ipo ti oun ti de ṣaaju wa lati mu oun dide fun ipo aarẹ lọdun 2019, ohun ti o wa n fa ibeere bayii ni boya ohun Ọlọrun naa ti yipada?
'Lọ́gán tí mo bá di ààrẹ, mo máa bẹ̀rẹ̀ iṣẹ́'
Mimiko kéde láti dupò Ààrẹ ni 2019
Wọn ko fẹ ọ nilu o ń da orin,toba da tan tani yoo ba o gbe?
Apejuwe to fẹẹ se rẹgi rẹ lori ọrọ  to n sẹlẹ laarin ẹgbẹ osise orileede Naijiria ati Gomina ana fun ipinlẹ Ondo Olusegun Mimiko to ni oun fẹ du ipo Aarẹ Naijiria labẹ asia ẹgbẹ oselu osisẹ,LP.
Mimiko fẹ du ipo sugbọn ẹgbẹ ni awọn ko fọwọsi erongba rẹ.
Oríṣun àwòrán, Labour Party Facebook
Ẹgbe oselu awon osisẹ Naijiria ni Labour Party
Ayuba Waba to jẹ Aarẹ ẹgbẹ osise lo sọ fun BBC Yoruba ninu ifọrọwanilẹnuwo kan pe adisọkan Mimiko ati tawọn ko papọ fun idi eyi,awọn ko le gba gẹgẹ bi oludije Aarẹ awọn.
''Ẹiyele Mimiko ba onile wa jẹ o ba wa mu,sugbọn nigba ti o di ọjọ iku nise ni o yẹri. Nigba ti wọn kọọ nibi to salọ,o wa fẹ pada si ẹgbẹ wa, Ko jọ rara''
Lọ́jọ́bọ̀ ni Mimiko kede pé òun yóò gbé àpótí ìbò láti di Ààrẹ orílẹ̀èdè Nàìjíríà lọ́dún 2019 labẹ asia ẹgbẹ Labour Party.
Oríṣun àwòrán, @Segunmimiko
Mimiko ni Gomina akọkọ to wole labẹ asia ẹgbẹ Labour Party lorileede Naijiria
Mimiko tó kúrò lẹ́gbẹ́ òṣèlú alátakò, PDP nínú oṣù kẹ́fà ọdún yìí láti dara pọ̀ mọ̀ ẹgbẹ́ òṣèlú Labour Party kéde ní ìlú Abuja.
Ó ní ìpinu òun láti padà sí ẹgbẹ́ oṣèlú LP jẹyọ látàrí èrèdí láti ṣe àgbéǹde àfojúsùn ńla fún gbàgede òṣèlú Nàìjíríà.
Ọmọdé tó ń fi ọpọ́n àyò gba ipò
DSS: Àwọn ọ̀gá àgbà wo ló ti lo sáà rí lájọ ọ̀tẹlẹ̀múyẹ́ Nàìjíríà
Oríṣun àwòrán, dss
Ọ̀gá àgbà tuntun nàá gba oyè ìmọ̀ ìjìnlẹ̀ nípa ètò òṣèlú nílé ẹ̀kọ́ gíga fásìtì Ahmadu Bello tó wà nílùú Zaria.
Ọ̀pọ̀lọ̀pọ̀ awuyewuye ló ti n jẹyọ lorí bí Ààrẹ Muhammadu Buhari ṣe yan Yusuf Magaji Bichi sí ipò gẹ́gẹ́ bí Olùdarí àjọ ọ̀tẹlẹ̀múyẹ́ DSS.
Àwọn kan fi ẹ̀sùn kan Buhari pé óun ṣe ẹlẹ́yàmẹ̀yà nínú àwọn ìyànsípò rẹ̀, èyí tí kò yọ Bichi sílẹ̀.
Ṣùgbọ́n àwọn mì í gbóríyìn fún ìyànsípò nàá.
Àkọsílẹ̀ àwọn tó ti jẹ Olùdarí àjọ SSS láti ìgbà tí wan ti da a sílẹ̀.
Ọ̀gágun Abdullahi Mohammed ni Olùdarí àkọ́kọ́ fún àjọ ẹ̀sọ́ aláàbò Nigeria Security Organisation tó ti di State Security Service (SSS) bàyíì.  Ó ṣiṣẹ́ láàrin ọdún 1976 sí 1979.
Alhaji Umaru Shinkafi ni Olùdarí kejì. Òun nàá ṣiṣẹ́ gẹ́gẹ́ bi Olùdarí fún àjọ NSO láàrin oṣù Kẹwàá, ọdún 1979 sí oṣù Kọkànlá, ọdún 1983. Ọmọ ìpínlẹ̀ Sokoto ni.
Mohammed Lawal Rafindadi ni Olùdarí kẹta, òun nàá ló sì kẹ́hìn lásìkò tí àjọ nàá n jẹ́ National Security Organisation, kó tó di pé wọ́n pa orúkọ rẹ̀ dà sí State Security Service. Ọmọ ìpínlẹ̀ Katsina ni.
Alhaji Ismaila Gwarzo : Ọmọ ìpínlẹ̀ Kano Aliyu Ismaila Gwarzo.  Nínú oṣù Kẹfà, ọdún 1986 ni Ọ̀gágun Ibrahim Babangida yàn án sípò gẹ́gẹ́ bi Olùdarí àgbà fún àjọ Ọ̀tẹlẹ̀múyẹ́ State Security Service tuntun. Ó sì ṣiṣẹ́ láàrin ọdún 1986 sí oṣù Kẹ́sàn án, ọdún 1990.
Kọntínúítì gbèsè, fásitì Lautech àti àwọn ìbéèrè mìíràn ní ìpàdé ìtagbangba Ọṣun
Àwọn ohun tó yẹ́ kí o mọ̀ nípa Ọ̀gá DSS tuntun
Ọmọdé tó ń fi ọpọ́n àyò gba ipò
Albert Korubo ni Olùdarí àjọ State Security Service (SSS) karùn ún. Ọmọ ìpínlẹ̀ Rivers ni.  Ó ṣiṣẹ́ láàrin oṣù Kẹsàn án, ọdún 1990 sí oṣù Kẹwà, ọdún 1992.
Chief Peter Nwaoduah: Abẹ́ ètò ìṣàkóso Ọ̀gágun Sani Abacha ló ti jẹ ọ̀gá àgbà SSS láàrin ọdún 1992 sí 1998.
Lateef Kayọde Arẹ ni Olùdarí àjọ SSS láàrin ọdún 1999 sí 2007. Ààrẹ Oluṣẹgun Ọbasanjọ ló yàn án sipò. Ó wà ní ipò nàá láti ìbẹ̀rẹ̀ títí dé òpin ètò ìṣàkóso Ọbasanjọ.
Afakriya Gadzamaló gba ipò lọ́wọ́ Kayọde Arẹ. Nínú oṣù Kẹjọ, ọdún 2007 ni olóògbé Umaru Yar'Adua yàn án sípò. Ọmọ bíbí ìpínlẹ̀ Borno ni. Ọjọ keje, oṣù Kẹsàn án ni,Alhaji Umaru Shinkafi ọdún 2010 ni Ààrẹ àná, Goodluck Jonathan gba iṣẹ́ lọ́wọ́ rẹ̀.
N11.1 Mílíọ̀nù ni Ọlọ́pàá ti gbà lọ́wọ́ àwọn ọmọ Nàìjíríà
Arẹgbẹṣọla: Kò sí ìjọba tí kìí jẹ gbèsè
Ita Ekpeyong: Oṣù Kẹsàn án, ọdún 2010. Níkété tí wọ́n gba iṣẹ́ lọ́wọ́ rẹ̀ ni Goodluck Jonathan yàn án sípò lẹ́yìn tó gba iṣẹ́ lọ́wọ́ Afakriya Gadzama. Ó ṣiṣẹ́ láàrin ọdún 2010 sí 2015. Ọmọ ìpínlẹ̀ Cross River ni.  Níkété tí Ààrẹ Muhammadu Buhari dé ipò ló yọ ọ́ nípò.
Lawal Musa Daura: Òun ló rọ́pò Ekpeyong nínú oṣù Kẹsàn án, ọdún 2015. Ó di ipò nàá mú títí di ọjọ́ Kẹjọ, oṣù Keje, ọdún 2018, tí Adelé Ààrẹ, Ọ̀jọ̀gbọ́n Yẹmi Ọṣinbajo dáà dúró lẹ́yìn wàhálà tó wáyé nílé aṣòfin. Ọmọ bíbí ìpínlẹ̀ Katsina ni.
Matthew Seiyefa: Lẹ́yìn ìyọnípò Daura ní Ọṣinbajo yàn án gẹ́gẹ́ bi adelé Olúdarí Àgbà fún àjọ SSS. Ó ṣiṣẹ́ títí di ọjọ́ kẹtàlá, oṣù Kẹsàn án, ọdún 2018 tí Ààrẹ Buhari yan Yusuf Magaji Bichi sípò nàá. Ọmọ bíbí ìpínlẹ̀ Bayelsa níì ṣe.
Yusuf Magaji Bichi: Ààrẹ Muhammadu Buhari yàn án sípò nàá lọ́jọ́ kẹtàlá, oṣù Kẹsàn án, ọdún 2018.
Davido: Bí ọjọ́ ìbí mi se ń súnmọ́lé, lẹ̀bùn olówó ńlá ń wọlé fún mi
Oríṣun àwòrán, davidoofficial
Bi o tilẹ́ jẹ pe ayẹyẹ ọjọ ibi ilu mọọka olorin taka-sufe ni, Davido si ku ranpẹ ko wọle de, sibẹ awọn ọrẹ, ẹbi, ara ati ojulumọ ti n fi ẹbun olowo iyebiye ransẹ si.
David Adeleke, taa mọ si Davido, kede ni oju opo ikansira ẹni Twitter rẹ pe ojo awọn ẹbun olowo nla lo n rọ le oun lori, ninu eyi taa ti ri aago ọwọ ati ẹgba ọrun lorisirisi.
Davido ni aago ọwọ, ti awọ rẹ jẹ alawọ funfun lo kọkọ wọle de, tawọn goolu ọrun naa si bẹrẹ si ni tẹle.
Ọjọ Kọkanlelogun Osu Kọkanla ni Davido maa n sami ayẹyẹ ọjọ ibi rẹ, to si seese ki awọn ẹbun naa ti pọ ju eyi lọ, ti yoo ba fi di ọjọ naa.
Davido wọ́gilé òde eré rẹ̀ l'Ámẹ́ríkà nítorí NYSC
Gbajugbaja olorin takasufee nni, Davido ti wọgile ode ere rẹ lorilẹede Amẹrika lati lee wa pari eto ifinimọle agunbanirọ rẹ.
Ọwọ keji eto agunbanirọ orilẹede Naijiria fun ọdun 2018 yoo maa pari eto ifinimọle ni ọjọ aje, ọjọ kẹtadinlogun oṣu kẹsan eleyi ti Davido si ti gbọdọ kopa nilu Eko.
Oríṣun àwòrán, @iam_Davido
Ile ya
Dandan lowo ori ni eto isinrulu fun awọn akẹkọ jade faisiti lorilẹede Naijiria.
Àwọn èèyàn mi ló gba fọ́ọ̀mù PDP fún mi ṣùgbọ́n ...
APC àti PDP takora wọn lórí Olùsirò owó àgba Ọsun tó fisẹ́ sílẹ̀
Lẹyin to pari eto iforukọsilẹ rẹ ni ọjọ kọkandinlọgbọn oṣu kẹjọ ni Davido ti fi ibudo ifinimọle wọn silẹ lati lọ gbaradi fun ode ere ti o ni lorilẹede Amẹrika.
Ni ọjọ ẹti ni Davido kede funrarẹ pe oun ti wọgile ode ere gbogbo ti oun ni nilẹ Amẹrika lati lee pada wale fun eto isinruulu naa.
Oríṣun àwòrán, @iam_Davido
"Nitori bi ọjọ eto agunbanirọ mi ati awọn ọjọ ode ere ni mo ni ti ṣe forigbari, mo ti wọgile awọn ode ere to ku funmi ni Amẹrika.
Oríṣun àwòrán, @iam_Davido
Lẹyin to pari eto iforukọsilẹ rẹ ni ọjọ kọkandinlọgbọn oṣu kẹjọ ni Davido ti fi ibudo ifinimọle wọn silẹ
Gbogbo awọn to ti san owo iwọle ni a o da owo pada fun ni ibi gbogbo ti wọn ti sanwo."
Mo tọrọ aforiji lọwọ gbogbo awọn ololufẹ mi patapata; ṣugbọn mo ṣeleri ati kede awọn ọjọ tuntun fun Houston Dallas, Lọs Angeles ati San Fransisco.
Ìjọba Buhari: Orúkọ Adeọsun tún wà lórí òpó ayélujára lẹ́yìn tó fipò sílẹ̀
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Iwe ofin ko sọ pe ki wọn maa lẹ orukọ eeyan kan mọ ipo kan ni pato
Lẹyin ọjọ merindinlaadọta ti minisita eto inawo tẹlẹ ri, Kemi Adeọṣun kọwe f'ipo silẹ, orukọ rẹ si tun wa lori oju-opo ayelujara ijọba apapọ.
Koda, orukọ minisita ọrọ obinrin tẹlẹ ri, Aisha Alhassan, to kuro ninu ẹgbẹ APC ati gomina tuntun ipinlẹ Ekiti, Kayode Fayemi, to jẹ minisita fun idagbasoke ohun alumọọni naa wa nibẹ.
Adeọsun kọwe f'ipo silẹ lọjọ kẹrinla, oṣu kẹsan an, ọdun 2018 lori ẹsun pe o lo ayederu iwe-ẹri agunbanirọ.
O si fori le Ilẹ Gẹẹsi lọjọ keji to kọwe fipo silẹ gẹgẹ bii minisita fun eto inanwo lorilẹ-ede Naijiria.
#Adetutu Alabi OJ: Mo ti gba kámú lórí ilà ojú mi
Ewu wo lo wa ninu ki iroyin to wa lori oju-opo ayelujara ti pẹ?
Onimọ nipa oju-opo ayelujara kan, Zainab Sule, sọ pe ''iroyin to ti pẹ maa n saaba wa lori oju-opo ayelujara ijọba nitori ''kii saaba ni ẹnikan gbogi ti o maa n bojuto o.''
Bẹẹ lo fi kun ọrọ rẹ pe ninu ewu to wa nibẹ nipe ''awọn ti wọn ba bẹ lati ṣiṣẹ lori oju-opo naa le parọ ohun to wa nibẹ nigba kuugba.''
Gbogbo akitiyan wa lati ba minisita eto iroyin ati aṣa, Oloye Lai Mohammed sọrọ lo jasi pabo.
Ta ló lẹ̀bi ọ̀rọ̀ lórí awuyewuye ayédèrú ìwé ẹ̀rí NYSC Adeosun?
Ni aipẹ yii ni okiki kan pe ayederu iwe ẹri agunbanirọ ni minisita feto iṣuna fi wọ iṣẹ minisita; lẹyin o rẹyin ni arabinrin naa kọwe fipo silẹ lẹyin to kọ lẹta si aarẹ pe 'aimọ lo ṣe oun nipa ọrsọiwe ẹri naa nitori awọn ti oun fẹyinti lati ba oun gba iwe ẹri naa ni wọn gbẹyin b'ẹbọ jẹ.
Eyi lo mu ki ọpọ awọn ọmọ orilẹede Naijiria o maa beere ohun ti o ba eyi wa nitori kii ṣe ohun ikọkọ pe ki eeyan to de ipo ilu giga bẹẹ yoo la ọpọlọpọ iwadi ati ifọrọwanilẹnuwo kọja.
Fun eeyan bii Kẹmi Adeọṣun to ti fi igba kan ri ṣe kọmiṣọna ni ipinlẹ abinibi rẹ, iyẹn ipinlẹ Ogun ki o to wa di minisita, o fihan pe igba meji ọtọọtọ lo ti la irufẹ awọn igbesẹ iwadi bẹẹ kọja.
Idi niyi ti BBC Yoruba fi kanlu agbami itọpinpin lori ohun gan ti awọn aṣofin maa n wo ki wọn to gba eniyan kan sipo ilu.
Aṣofin Babatunde Ọlatunji to jẹ ọmọ ileegbimọ aṣofin ni ipinlẹ Ọṣun, to si tun jẹ alaga igbimọ to n mojuto karakata nile aṣofin naa ṣalaye pe ohun marun lo ṣe koko.
Oríṣun àwòrán, @nassnigeria
Ọpọ ọmọ Naijiria lo ti n pariwo lori ohun to faa ti aṣiri ayederu iwe ẹri agunbanirọ minisita feto iṣuna tẹlẹ ṣẹṣẹ n foju han.
Iwe ofin ko sọ pe ki wọn maa lẹ orukọ eeyan kan mọ ipo kan ni pato. Nitorinaa, ohun akọkọ ti a maa n wo ni pe ṣe irufẹ ẹni bẹẹ nikun oju iwọn ati di eyikeyi ninu ipo ilu mu lorilẹede Naijiria.
Ifẹ orilẹede tabi ipinlẹ ti o fẹ yan an: O ni ohun keji ti awọn aṣofin maa n wo ni ṣe ẹni ti wọn fi orukọ rẹ ranṣẹ ni ifẹ ilẹ rẹ denudenu. Ṣe kii ṣe ẹni ti yoo joko si ipo eku maa huwa ẹyẹ.
Ohun miran ti awọn aṣofin tun maa n wo ni boya ẹmi adari wa lara ẹni ti wọn fẹ yan sipo naa.
Oríṣun àwòrán, @nassnigeria
Ẹrẹ naa kanawọn aṣofin apapọ ti wọn ṣe ayẹwo fun
Lara awọn ohun ti a n wo ni ayẹwo ti awọn agbofinro ba ṣe lori ẹni bẹẹ. Awọn ileeṣẹ agbofinro bii DSS ni o maa n saba ṣe eleyii.
Idi eyi ni lati rii pe awọn eeyan ti wọn jẹ ọdaran ko bọ si ipo ọṣelu.
Ayẹwo iwe ẹri: o ni ohun ti o tun ṣe pataki ni lati mọ boya lootọ ni awọn eeyan yii ni iwe ẹri ti o fi ṣọwọ si wọn.
Oríṣun àwòrán, @NGRSenate
Ayẹwo wa lati rii pe awọn eeyan ti wọn jẹ ọdaran ko bọ si ipo ọṣelu.
"Ṣugbọn Aṣofin Babatunde Ọlatunji ṣai m'ẹnu ba awọn ipenija ti o maa n waye lori awọn igbesẹ wọnyii paapaa gbedeke asiko ti o maa n wa fun eto naa eleyi ti kii ba iwadi iwe ẹri d'ọrẹ nitori gẹgẹ bii ọrọ rẹ, "" ọpọ igba lo jẹ pe bi ẹ ba kọ iwe si awọn ileewe ti awọn eeyan wọnyii lawọn ti gba iwe ẹri, ko ni si idahun lasiko, eleyi si maa n ṣe ipenija tirẹ pẹlu."""
O ni sibẹ eyi ko wẹ ile aṣofin mọ bi irufẹ ohun to ṣẹlẹ si Minisita yii ba ṣẹlẹ.
Oríṣun àwòrán, @nassnigeria
Ojuṣe awọ̀n agbofinro ni lati ṣe iwadi ipilẹ ẹni to fẹ di ipo ilu mu
O ni lootọ ọpọ igba lawọn aṣofin maa n nii lskan pe ko si bi ẹni ti wọn pe fun ipo to gaa lawujọ lee wa lai ni awọn iwe ẹri to yẹ, ṣugbọn nitori ki ọrọ o ma baa ba ẹyin yọ ni eyi ṣe pọn dandan.
Amọṣa, o ni ohun to ṣẹlẹ lori ọrọ minisita tẹlẹ Kẹmi Adeọṣun jẹ ohun to ku diẹ kaa to ṣugbọn to jẹ pe laifọta pe abawọn nla lo jẹ fun ile aṣofin apapọ orilẹede Naijiria.
Oríṣun àwòrán, @HMKemiAdeosun
Kemi Adeosun
Lórí ọ̀pọ̀lọpọ̀ ìwé ìròyìn abẹ́lé ní orílẹ̀èdè Nàìjíríà ni ó ti jáde wí pé mínísítà àná fún ètò ìsúná, Kemi Adeosun ti rìnrìnàjò jáde kúrò lórílẹ̀èdè Nàìjíríà.
Onírúurú ilé iṣẹ́ ìròyìn ló jábọ̀ láti pápákọ̀ òfurufú wí pé o ti tẹkọ̀ òfurufú létílọ sí London.
Wọ́n ni gbogbo akitiyan láti bá olùgbaninímọ̀ràn rẹ̀ lórí ọ̀rọ̀ tó kan ìròyìn, Oluyinka Akintunde sọ̀rọ̀ lórí èyí, pàbó ló já sí.
"Bákan náà ni  agbẹnusọ fún ilé iṣẹ́ ọkọ̀ òfurufú British Airways tí àwọn akọ̀ròyìn abẹ́lé ni Nàìjíríà sọ pé ó bá rìnrìnàjò, Yinka Kola sọ pé òun kò ní lè pèsè ìròyìn kankan fún wọn ''nítorí àṣírí ni ohunkóhun tí gbogbo oníbarà wọn bá ṣe jẹ́ sí oníbarà tìkárarẹ̀""."
Lọjọ ẹti ni okiki kan pe Kẹmi Adeọṣun kọwe fipo minisita feto iṣuna silẹ lori ẹsun ayederu iwe ẹri ti wọn fi kan an.
Lẹyin ti minisita feto iṣuna, Kẹmi Adeọṣun kọwe fipo silẹ lọjọ ẹti lori ẹsun ayederu iwe ẹri agunbanirọ rẹ, ẹgbẹ oṣelu PDP to jẹ aṣaaju ẹgbẹ oṣelu alatako lorilẹede Naijiria ti beere fun fifi minisita naa jofin lori ẹsun ko ṣe eto isinruulu NYSC rẹ ti o si tun lọ lo ayederu iwe ẹri fun.
Ninu atẹjade kan ti ẹgbẹ oṣelu PDP fi sita ni ọjọ abamẹta, ẹgbẹ oṣelu naa ni o ti lu si awọn lọwọ pe ijọba apapọ ti n gbero ati fi oru boju gbe Kẹmi Adeọṣun kuro lorilẹede Naijiria lọ si oke okun.
PDP ni ọrun aarẹ Buhari ni ẹbi ẹsun gbogbo ti wọn fi kan Adeọṣun wa nitori, gẹgẹ bii ẹgbẹ oṣelu naa ṣe sọ, Buhari ni anfani si gbogbo awọn iwadi lori iwe ẹri rẹ lai ṣe ohun to tọ sii.
Ẹgbẹ oṣelu PDP wa pe fun iwadi iṣẹ ileeṣẹ eto iṣuna apapọ orilẹede Naijiria lasiko ti Kẹmi Adeọṣun fi jẹ minisita nibẹ lati lee ṣawari awọn iwa kots ti awọn agbẹyinbẹbọjẹ to wa ni iṣejọba aarẹ Buhari n ṣe titi to fi kan kiko owo epo rọbi sapo ara wọn pẹlu adinku owo to wa ninu aṣuwọn apapọ orilẹede yii nilẹ okeere
Oríṣun àwòrán, @FinMinNigeria
Adeọṣun pada sọrọ lori ẹsun ayederu iwe ẹri isinruulu NYSC ti wọn fi kan
Lẹyin nnkan bi osu meji ti awuyewuye lori ẹsun ayederu iwe ẹri isinruulu NYSC ti wọn fi kan an ti n ja ranyin ranyin,Minisita fun feto iṣuna lorilẹede Naijiria,Kemi Adeosun  ti kọwe fi ipo silẹ.
Awọn ileeṣẹ iroyin abẹle gbogbo lorilẹede Naijiria ni wọn ti  saaju gbe e sita lọsan ọjọ ẹti pe minisita Adeosun ti kowe fipo sile.
Sugbọn nigba ti yoo fi di asalẹ ọjọ ẹti ni o fi ikede soju opo Twitter ti ile ise Aarẹ Naijiria naa si kede ifiposilẹ rẹ
Adeosun ninu iwe ifiposilẹ rẹ loun dupe lọwọ Aarẹ Buhari fun anfaani ti o fun oun l;ati di ipo mu ninu ijọba rẹ.
O salaye pe iyalẹnu lo jẹ fun oun pe iwe ẹri ayederu ni oun gbe ka ati wi pe oun ko mọ wi pe ọna eru ni wọn fi ba oun gba.
Ikowefiposile rẹ ko ya ọpọ eeyan lẹnu nitori awọn ara ilu ti n farata lati igba ti iroyin lu jade pe iwe ẹri ayederu ni o n lo.
Ohun ti awọn ileeṣẹ iroyin abẹle lorilẹede Naijiria kan n gbe kaakiri bayii ni pe, minisita Adeọṣun kọwe fi ipo silẹ ki ọrọ ẹsun ayederu iwe ẹri isinruulu NYSC ti wọn fi kan an ma baa pagi dina erongba ati pada sipo aarẹ lẹẹkeji eleyi ti aarẹ Buhari n gba fun ọdun 2019.
Awọn kan pẹlu ni boya o fẹ lọ du ipo gomina ni ipinlẹ rẹ, iyẹn ipinlẹ Ogun lati gba ọpa aṣẹ lọwọ Gomina Amosun ti yoo pari saa keji rẹ ni ọdun to n bọ ni.
Oju opo ayelujara gbana jẹ pẹlu ikede yi ti awọn ọmọ Naijiria si n sọ iriwisi ọtọọtọ.
Awon kan kaanu rẹ pẹlu isẹlẹ naa ti wọn si ni ki ijọba forijin fun ẹsẹ pe o lo ayederu iwe.
Sugbọn lọdọ awọn kan, ohun to jẹ lo yoo ti wọn si ni ijiya tọ si
Oríṣun àwòrán, @HMKemiAdeosun
Awọn kan ni boya o fẹ lọ du ipo gomina ni ipinlẹ rẹ ipinlẹ Ogun ni
Bi a ko ba ni gbagbe, ileeṣẹ iroyin Premium Times lo kọkọ gbee sita pe lẹyin ti awọn ṣe iwadi lori iwe ẹri ti Adeọṣun n gbe kiri fun eto isinruulu rẹ lawọn kẹẹfin pe ayederu gbaa ni.
Titi di igba to wa kowe fipo silẹ, Adeọṣun ko sọrọ lori rẹ.
Gbogbo akitiyan BBC Yoruba lati fi idi ọrọ ọhun mulẹ nigba ti o sẹlẹ  lo n ja si pabo pẹlu bi ko ṣe si ẹnikẹni ni ijọba ti a kan si, tabi minisita naa fun ara rẹ to fẹ sọrọ lori rẹ.
Ṣugbọn iroyin kan pẹlu tun n sọ ọ pe eeyan kan lati ileeṣẹ aarẹ ni kii ṣe ootọ.
Ileeṣẹ aarẹ ko tii sọ ohunkohun lori ọrọ yii bẹẹ ni igbimọ alaṣẹ orilẹede Naijiria pẹlu.
Buhari: Àìsí ìtọ́jú tó péye ló mú ṣọ́jà gba iṣẹ́ ọlọ́pàá ṣe láwùjọ
Oríṣun àwòrán, Bashir Ahmad
Ọga ọlọpaa lorilẹede Naijiria ni awọn ọlọpaa yoo tubọ tẹpa mọ iṣẹ wọn
Idunnu ti ṣubu lu ayọ fun awọn ọlọpaa lorilẹede Naijiria lẹyin ti iroyin kan sita ni ọjọ aje pe Aarẹ Buhari ti buwọlu  owo oṣu tuntun fun awọn ọlọpaa.
O ti to ọjọ mẹta ti ọrọ naa ti n ja ranyin ṣugbọn ẹnikankan ko ti lẹ́ sọ pato boya ootọ ni.
Amọ ṣa abẹwo awọn igbimọ alakoso ajọ to  n ṣe amojuto ileeṣẹ ọlọpaa lorilẹede Naijiria to lọ ki aarẹ lati dupẹ lọwọ rẹ fun igbesẹ naa lo jẹ ki awo ọrọ yii lu sita.
Labẹ eto ẹkunwo oṣu tuntun ti Buhari fọwọ si yii, owo oṣu, ajẹmọnu ati owo ifẹyinti awọn ọlọpaa ni yoo gbẹnusoke.
Lasiko abẹwo naa, Aarẹ Buhari ṣalaye pe aisi amojuto to peye fun awọn ọlọpaa lo fa aijafafa wọn lẹnu iṣẹ wọn eyi ti o ni o mu ki awọn ologun maa ti oju bọ iṣẹ amojuto ofin ati abo laarin ilu jakejado orilẹede Naijiria.
Oríṣun àwòrán, Bashir Ahmad
Ààrẹ Buhari ní ìjáfáfá ọlọ́pàá yóò fún ìjọba àti aráàlú ní ìfọ̀kànbalẹ̀ tó kúnná
"'lati Taraba de Sokoto, de ẹkun aringbungbun gusu orilẹede yii, ọkan ọpọlọpọ araalu kii balẹ ayafi ti wọn ba ri awọn ologun. Inu mi dun lati buwọlu ẹkunwo oṣu naa pẹlu ireti pe yoo mu ki ijafafa awọn ọlọpaa o lọ siwaju sii."""
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Alhaji Smith ni ai kii ṣe ere idaraya deede lo faa ti awọn ọlọpaa fi n yọkun ayọju
Ni aye atijọ gẹgẹ awọn agba ilẹ yii ṣe sọ, o ṣoro lati ri agbofin to yọ ikun ni igboro.
Amọṣa ni bayii awọn ọyọkun agbofinro ti di tọrọ-fọnkale, eleyi to si da bi ẹnipe o n kọ awọn adari ẹka ileeṣẹ ọlọpaa lominu.
Nibayii, ajọ to n mojuto akoso ileeṣẹ ọlọpaa lorilẹede Naijiria, ti ke gbajare sita pe 'ọyọkun ọlọpaa ti pọju nigbeoro.
Ajọ naa ti wa fi ikilọ sita pe ki awọn adari ileeṣẹ ọlọpaa lati tete lọ wa nnkan ṣe si ọrọ awọn ọgọrọ ọlọpaa to yọkun nigboro Naijiria bayii.
Alaga ajọ naa, Alhaji Musiliu Smith lo paṣẹ yii.
Kini awọn ohun miran ti ajọ to n mojuto akoso ileeṣẹ ọlọpaa lorilẹede Naijiria  tun yọ sita fun amojuto?
Gbogbo ọlọpaa lo gbọdọ le wa ọkọ pẹlu iwe aṣẹ iwakọ to pe.
Titun gbogbo ileegbe awọn ọlọpaa kọ ni ibamu pẹlu ilana igbalode.
Ṣiṣe aṣọ iṣẹ awọn ọlọpaa ni oju kan naa.
Alhaji Smith ni ai kii ṣe ere idaraya deede lo faa ti awọn ọlọpaa fi n yọkun ayọju.
Bakanna ni ajọ naa ninu atẹjade rẹ tun  kọminu lori bi awọn ọlọpaa ṣe n ko awọn to wa lẹka akanṣe iṣẹ si ẹnu iṣẹ ọlọpaa igboro laiko fi ti eto ati ilana gbogbo to yẹ ṣe?
Bakan naa ni Alhaji Smith, ti oun pẹlu ti fi igbakan ri jẹ ọga agba ọlọpaa lorilẹede Naijiria tun ni ko si aaye fun ọlọpaa lati gba igbega lẹnu iṣẹ lai jẹ pe o ṣe awọn idanwo gbogbo to ba yẹ.
Ọwọ́ Ọlọ́pàá tẹ́ àwọn ajókùúgbé mọ́túárì
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ọwọ́ Ọlọ́pàá tẹ́ àwọn ajókùúgbé mọ́túárì
Àwọn Ọlọ́pàá ti mú ọkùnrin méjì kan ti ń bèèrè owó ìtanràn mílíọ̀nù mẹ́rin náírà kí wọ́n tó dá òkú tí wọ́n jí gbé ní mọ́ṣúárì padà.
Àwọn ẹbí olókùú ti ń múra láti sin òkú wọ́n nígbà tí àwọn ajínigbé yìí ṣe ọṣẹ́.
Òkú Kofi Annan balẹ̀ sí Ghana
Àyẹ̀wò DNA bẹ̀rẹ̀ lẹ́yìn ìjàmbá iná Eko
Sallah vs Kane, tani yóò pegedé?
Ni ọjọ́ ẹtì ni àwọn Ọlọ́pàá ìpínlẹ̀ Imo sọ wí pé lóòtọ́ ni ọwọ́ ti tẹ àwọn ọ̀daràn náà tó lọ jí òkú arábìnrin kan gbé ní mọ́ṣúárì nílùú Owerri.
Wọ́n ni ṣe ni àwọn ajínigbé ọ̀hún gbé òkú arábìnrin yìí wọ inú igbó lọ tí wọ́n sì blrl sí ní da àwọn ẹbí olóku àti ilé ìwòsàn tó ni mọ́ṣúárì láàmú pé kí wọ́n san mílíọ̀nù mẹ́rin náírà kí àwọn tó gbé òkú náà sílẹ̀.
Andrew Enwerem tó jẹ́ alukoro ilé iṣẹ́ Ọlọ́pàá ìpínlẹ̀ Imo sọ fún ile iṣẹ́ BBC Igbo pé nígbà tí wàhálà wọn pọ̀ ni àwọn bí olóku wá fi ẹjọ́ sun Ọlọ́pàá lẹ́yìn náà ni ọwọ́ sì tẹ̀ wọ́n.
Ó ní àwọn afurasí méjèèjì ti jẹ́ èrò ọgbà ẹ̀wọ̀n rí tí wọ́n ṣẹ̀ṣẹ̀ dá sílẹ̀ lẹ́yìn ọdún mẹ́fà àti mẹ́rìnlá lẹ́wọ̀n lórí ẹ̀sùn ìjínigbé.
Ọ̀gbẹ́ni Andrew ní Ọlọ́pàá ti dá òkú padà fún ẹbí rẹ̀ láti tẹ̀síwájú pẹ̀lú ètò ìsìnkú tí wọ́n ti dájọ́ sí tẹ́lẹ̀.
Ìròyìn tó tẹ̀ wa lọ́wọ́ ni pé arábìnrin tí wọ́n jí òkú rẹ̀ gbé yìí kò fíbẹ́ẹ̀ jẹ́ ọlọ́rọ̀ bẹ́ẹ̀ sì ni àwọn mọ̀lẹ́bí rẹ̀.
'Obìnrin tí kó ba fẹ́ òṣìṣẹ́ Mọ́ṣúárì, ìpinu rẹ̀ mẹ́hẹ'
ICPC: Ìwádìí ti pari lóri iwe ẹ̀ri ayéderú Kemi Adeosun
Oríṣun àwòrán, @HMKemiAdeosun
Kemi Adeọṣun kọwe fipo rẹ silẹ
Àjọ tó ń ri sí ìwá ajẹbanu àti jẹgúdújẹrá lórílẹ̀-èdè Nàìjiríà (ICPC) ní òun kò ṣe ìwadìí mọ lóri ọ̀rọ̀ ìwé ẹ̀rí NYSC ayédèrú tí ó fa awuyewuye fun mínísítà owó àti ìsuná Kemi Adeosun.
Àjọ ICPC sọ èyí di mímọ̀ ní kété tí àjọ tó ń ri sí ètò ìsinrú ìlú baba ẹni sọ pé òun ti pari ìwádìí lórí ọ̀rọ̀ náà tí ó si ti fi àbájáde rẹ̀ sọwọ́ sí ilé iṣẹ́ tó ń ri sí ìdàgbàsokè ọ̀dọ́ àti eré ìdárayá.
Osun Decides: Adegoke ni òun kò ni lo kọngilá n
Mínísítà tẹ́lẹ̀rí kòwé fipò sílẹ̀ lọ́jọ Etì lẹ̀yìn tó gbà pé ayédèrú ní ìwé ẹ̀rí àgùnbánirọ̀ ti òun ní.
ICPC: Ìwádìí ti pari lóri iwe ẹ̀ri ayéderun Kemi Adeosun
Agbẹnusọ fún ICPC, Rasheedat Okoduwa sọ̀rọ̀ sàlàyé pé àwọn dáwọ́ ìwádìí náà dúro kó máa dí ọ̀nà méjì.
Tẹ́ ò bá gbàgbé àjọ agùnbánirọ̀ sọ nínú oṣù keje pé àwọn ti bẹ̀rẹ̀ ìwádìí tí adarí ẹka igbọ́rọ̀ sáfẹ́fẹ́ àjọ náà Adenike Adeyemi si sọ pé abájade ìwádìí náà ti wa ní ile iṣk ọ̀dọ́.
PDP: Kẹmi Adeosun gbọ́dọ̀ fojú winá lórí ẹ̀sùn ayédèrú ìwé ẹ̀rí NYSC rẹ̀
Oríṣun àwòrán, @HMKemiAdeosun
Kẹmi Adeọṣun kọwe fipo minisita feto iṣuna silẹ lori ẹsun ayederu iwe ẹri ti wọn fi kan an
Lẹyin ti minisita feto iṣuna, Kẹmi Adeọṣun kọwe fipo silẹ lọjọ ẹti lori ẹsun ayederu iwe ẹri agunbanirọ rẹ, ẹgbẹ oṣelu PDP to jẹ aṣaaju ẹgbẹ oṣelu alatako lorilẹede Naijiria ti beere fun fifi minisita naa jofin lori ẹsun ko ṣe eto isinruulu NYSC rẹ ti o si tun lọ lo ayederu iwe ẹri fun.
Ninu atẹjade kan ti ẹgbẹ oṣelu PDP fi sita ni ọjọ abamẹta, ẹgbẹ oṣelu naa ni o ti lu si awọn lọwọ pe ijọba apapọ ti n gbero ati fi oru boju gbe Kẹmi Adeọṣun kuro lorilẹede Naijiria lọ si oke okun.
PDP ni ọrun aarẹ Buhari ni ẹbi ẹsun gbogbo ti wọn fi kan Adeọṣun wa nitori, gẹgẹ bii ẹgbẹ oṣelu naa ṣe sọ, Buhari ni anfani si gbogbo awọn iwadi lori iwe ẹri rẹ lai ṣe ohun to tọ sii.
Ẹgbẹ oṣelu PDP wa pe fun iwadi iṣẹ ileeṣẹ eto iṣuna apapọ orilẹede Naijiria lasiko ti Kẹmi Adeọṣun fi jẹ minisita nibẹ lati lee ṣawari awọn iwa kots ti awọn agbẹyinbẹbọjẹ to wa ni iṣejọba aarẹ Buhari n ṣe titi to fi kan kiko owo epo rọbi sapo ara wọn pẹlu adinku owo to wa ninu aṣuwọn apapọ orilẹ-ede yii nilẹ okeere
'A máa ń bẹ́ orí ẹni tó bá gbé imọlẹ̀ ọdún ìjẹṣu tó bá ṣubú ni'
Bọla Tinubu: Ìpínlẹ̀ Ọ̀ṣun kò ní owó mi lọ́wọ́
BBC OSUN DEBATE: Àwọn olùdíje sípò gomina sọ̀rọ̀ lórí ètò Èkọ́
Awọn oludije si ipo gomina ni ipinlẹ Ọsun fi erongba wọn han lori ọna abayọ siṣoro eto ẹkọ ni ipinlẹ Ọsun.
Awọn oludije lati ẹgbẹ oselu APC, ADP, ADC ati SDP fi ero wọn han lasiko ipade itagbangba ti Ile-Ise Iroyin BBC News Yoruba gbe kalẹ saaju ọjọ idibo si ipo goimna ti yoo waye ni Ọjọ Kejilelogun, Osu yii.
Osun 2018: Àwọn olùdíje ADC, ADP, APC, SDP bá aráàlú sọ̀rọ̀ lórí èròǹgbà wọn
Eto ipade itagbangba naa waye ni gbongan Olagunsoye Oyinlọla ni fasiti ipinlẹ Ọṣun lọjọ Ẹti, ọjọ kẹrinla, oṣu kẹsan an.
Alhaji Gboyega Oyetola ni gbese daa, ti a ba mọ nkan ti a fi ṣe
Oludije si ipo gomina labẹ ẹgbẹ oselu APC, Alhaji Gboyega Oyetola lasiko to n fesi si ibeere nipa eto ẹko to da ẹnu kọlẹ ni ipinlẹ Osun, ni wi pe ijọba to wa ni ipo lọwọlọwọ n gbiyanju lati mu ibugbooro ba eto ẹkọ ati pe o ti dara si i ju ti atẹyinwa lọ. O ni ijọba ṣẹṣẹ san owo fun ile iwe giga Ladoke Akintola University ni Ogbomosọ laipẹ ni.
Bọla Tinubu: Ìpínlẹ̀ Ọ̀ṣun kò ní owó mi lọ́wọ́
Ninu ọrọ ti rẹ, oludije si ipo gomina labẹ ẹgbẹ oselu ADC, Fatai Akinbade ni awọn yoo da ogo ipinlẹ Osun pada nipa mimu eto ẹkọ lọkunkundun. O mẹnuba ohun tó ni lọkan lati ṣe fun itẹsiwaju LAUTECH ki eto ẹkọ le dara sii ni Ọṣun.
Akinbade: ''Due Process'' ni awa yoo fi se ijọba
Akinbade ni Ile-iwe giga fasiti LAUTECH ti awọn olukọ ko ki n ye da isẹ silẹ nitori ijọba kò san owo oṣu wọn, sọ pe òun yoo rii daju pe wọn da eto ẹkọ pada si ipo to yẹ ki o wa.
Bakan naa, Oludije si ipo gomina labẹ ẹgbẹ oṣelu ADP, Moshood Adeoti ninu ọrọ tirẹ fikun wi pe eto ẹkọ se pataki o ṣe koko si ìjọba òun, ati pe ọna abayọ si isoro eto ẹkọ ni ipinlẹ Osun ni gbigba awọn olukọ to dangajia lati bu iyi kun eto ẹkọ lọna to yẹ. O ni ọrọ LAUTECH yoo jẹ afẹnuko ijọba ipinlẹ Ọyọ ati Ọṣun ni.
Alhaji Adeoti
Ti a ko ba gbagbe, ni esi idanwo asekagba ile iwe girama WAEC ti wọn fi lede laipe yii, ipinlẹ Osun lo se ipo kọkandinlọgbọn ninu ipinlẹ mẹrindinlogoji.
Awọn ohun miran ti awọn oludije naa sọrọ le lori ni itẹsiwaju ijọba, iyẹn Kọntínúítì, gbèsè ti ijoba ipinle osun jẹ ile ifowopamọsi banki agbaye, eto ẹkọ fásitì LAUTECH to dẹnu kole, eto ilera alabọde àti àwọn ìbéèrè mìíràn lo jẹyọ ní ìpàdé ìtagbangba Ọṣun.
Olúdíje ẹgbẹ òṣèlú PDP nikan ni kò yọjú síbi ìpàde ìta gbángba ninu gbogbo awọn oludije ti wọn kọwe pe.
Ọ̀rọ̀ Imam yìí ṣe kòńgẹ́ bó ti ń rí láàrin lọ́kọ láya
UNICEF: Ẹ̀rọ ìbánisọ̀rọ̀ pọ̀ ju ilé ìgbọ̀nsẹ̀ lọ l'órílẹ̀-èdè Nàìjíríà
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ida mọkandinlogoji ninu ọgọrun awọn ọmọ orilẹede Naijiria ni wọn lanfani si ile igbọnsẹ to jẹ pe idile kan nikan lo n lo o
Ẹ gbọ na, ninu ẹrọ ibanisọrọ ati ile igbọnsẹ ewo gan lo ṣe pataki ju?
Ibeere yii lo n gba ẹnu ọpọ kan bayii lẹyin ti Ajọ to n risi idagbasoke ọmọ wẹwẹ lagbaye, UNICEF sọ pe awọn ọmọ orilẹ-ede Naijiria to ni ẹrọ ibanisọrọ pọ ju awọn to lanfani ile igbọnsẹ lọ.
Ko si ani-ani pe iṣoro igbọnsẹ pọ lorilẹ-ede Naijiria, paapaa julọ lawọn ẹsẹ pupu.
Ọṣun Decides:'Màá san gbogbo owó oṣù òṣìṣẹ́ lékunréré'-Akinbade
Amọṣa awọn onka ti ajọ UNICEF wa fi sita nibi idanilẹkọọ kan lo tun da bi ẹni pe o kọ ọpọ onwoye nibi idanilẹkọọ naa ni ominú.
Gẹgẹ bii ọga agba fun imọtoto ati omi to mọ gaara lajọ UNICEF, Zaid Jurji ṣe sọ, ogoje miliọnu lawọn ọmọ orilẹ-ede Naijiria to ni ẹrọ ibanisọrọ, ṣugbọn miliọnu mẹtadinlọgọrun lawọn to ni anfani ile igbọnsẹ.
O ni ida mẹtadinlogoji ninu ọgọrun awọn ile eto ilera lorilẹ-ede Naijiria lo ni ile igbọnsẹ fawọn alaisan.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ko si aniani pe iṣoro igbọnsẹ pọ lorilẹede Naijiria, papaa julọ lawọn ẹsẹ pupu
Bakan naa lo ni ida mọkandinlogoji ninu ọgọrun awọn ọmọ orilẹ-ede Naijiria ni wọn lanfani si ile igbọnsẹ to jẹ pe idile kan nikan lo n lo o.
Lai si ile igbọnsẹ, ọranyan ni fun awọn eeyan lati wa ibi ti wọn yoo tura si; ita gbangba si ni ọna abayọ niru ipenija bẹẹ, eleyi si lee fa ọpọ arun bii igbẹ gbuuru, ọnigbameji tabi iba pọnju-pọntọ
"Ọga agba UNICEF naa ṣalaye pe, ""ẹgbẹrun mejilelọgọfa awọn ọmọ orilẹ-ede Naijiria, ninu eyi ti ẹgbẹ mẹtadinlaadọrun ti jẹ ọmọ wẹwẹ, ni aisan igbẹ gbuuru n ran lọ sọrun lọdọọdun; bẹẹ ni biliọnu marundinlẹẹdẹgbẹta naira ni orilẹ-ede Naijiria n padanu lọdun nitori aisi imọtoto to yẹ""."
Ìkọ BBC Yorùbá ṣe àbápade ọkùnrin tó ní òún le darí òjò síbi tó wù òun
EMMY Awards 2018: Game of thrones gba àmì ẹ̀yẹ mẹ́jọ
Oríṣun àwòrán, Getty Images
"Ere ọlọsọọsẹ to gbayi ju (OUTSTANDING DRAMA SERIES) : ""Game of Thrones"""
Ni ọjọ Aje ni eto ifami-ẹyẹ-da awọn oniṣẹ ọpọlọ lẹka amuludun, orin ati ere sinima lọla (EMMY awards) waye ni ilu Los Angeles lorilẹ-ede Amẹrika.
Ere ọlọsọọsẹ 'Game of Thrones' lo gbayi julọ nibi ayẹyẹ naa pẹlu ami ẹyẹ mẹsan.
"'Saturday live' pẹlu ""The Marvelous Mrs Maisel"" lo tun tẹlee pẹlu ami ẹyẹ mẹjọ."
Ọṣun Decides:'Màá san gbogbo owó oṣù òṣìṣẹ́ lékunréré'-Akinbade
Eyi si ni orukọ awọn to gba ami ẹyẹ nibẹ ati ami ẹyẹ ti wọn gba
"Ere ọlọsọọsẹ to gbayi ju (OUTSTANDING DRAMA SERIES) : ""Game of Thrones"""
Oríṣun àwòrán, Getty Images
"Oṣere akọkọ l'ọkunrin to pegede ju ninu ere apanilẹrin (BEST LEAD ACTOR, COMEDY): Bill Hader, ""Barry"""
"Ere apanilẹẹrin ọlọsọọsẹ (OUTSTANDING COMEDY SERIES) : ""The Marvelous Mrs Maisel"""
"Oṣere akọkọ l'ọkunrin to pegede ju (BEST LEAD ACTOR, DRAMA): Matthew Rhys, ""The Americans"""
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ere ọlọsọọsẹ 'Game of thrones lo gbayi julọ nibi ayẹyẹ naa pẹlu ami aẹyẹ mẹsan.
"Oṣere akọkọ l'obinrin to pegede ju (BEST LEAD ACTRESS, DRAMA) : Claire Foy, ""The Crown"""
"Oṣere akọkọ l'ọkunrin to pegede ju ninu ere apanilẹrin  (BEST LEAD ACTOR, COMEDY): Bill Hader, ""Barry"""
Oríṣun àwòrán, Getty Images
"Oṣere akọkọ l'obinrin to pegede ju ninu ere apanilẹrin (BEST LEAD ACTRESS, COMEDY) : Rachel Brosnahan, ""The Marvelous Mrs Maisel"""
"Oṣere akọkọ l'obinrin to pegede ju ninu ere apanilẹrin  (BEST LEAD ACTRESS, COMEDY) : Rachel Brosnahan, ""The Marvelous Mrs Maisel"""
"Oṣere keji l'ọkunrin to pegede ju (BEST SUPPORTING ACTOR, DRAMA): Peter Dinklage, ""Game of Thrones"""
Oríṣun àwòrán, Getty Images
"Oṣere akọkọ l'obinrin to pegede ju (BEST LEAD ACTRESS, DRAMA) : Claire Foy, ""The Crown"""
"Oṣere keji l'obinrin to pegede ju (BEST SUPPORTING ACTRESS, DRAMA): Thandie Newton, ""Westworld"""
"Oṣere keji l'ọkunrin to pegede ju ninu ere apanilẹrin (BEST SUPPORTING ACTOR, COMEDY): Henry Winkler, ""Barry"""
Oṣere keji l'obinrin to pegede ju ninu ere apanilẹrin.
Osun Decides: Adegoke ni òun kò ni lo kọngilá n
Ọṣun Decides:'Màá san gbogbo owó oṣù òṣìṣẹ́ lékunréré'-Akinbade
Tìlù tìfọn ní Ọṣun fi kí Buhari káàbọ̀ l'Óṣogbo
Eyi ni yoo jẹ aṣekagba ipolongo idibo gomina fun ẹgbẹ oṣelu APC
Alaga apapọ ẹgbẹ oṣelu APC, Adams Oshiomole ti fọrọ lede wipe mimu itesiwaju ba awọn iṣẹ rere ti ẹgbẹ naa ti fi lọlẹ nipinlẹ Ọṣun da lori ẹni ti yoo gba iṣakoso lọwọ gomina Rauf Arẹgbẹṣọla.
Oshiomole ṣe alaye ọrọ naa nibi asekagba ipolongo idibo ẹgbẹ oselu APC to waye lọjọ iṣẹgun, nilu Oṣogbo .
Adari ẹgbẹ osisẹ tẹlẹri ọhun fi kun ọrọ rẹ wipe ''ipinlẹ Ọṣun nilo ẹni to ni oye kikun ati ọgbọn atinuda nipa eto iṣejọba, yatọ si ẹni ti wọn ṣẹṣẹ n kọ.''
'Ẹni ti a fa kalẹ yi ko kundun ode owanbẹ. Ko le ma a jo skelewu'
O tẹsiwaju wipe idi ti aare Muhammadu Buhari fi ba wọn peju-pesẹ sibi eto naa kii se fun itẹsiwaju isakoso ẹgbẹ oselu APC nikan, sugbọn lati fi da gbogbo eeyan ipinlẹ Ọṣun loju wipe ise rere ti egbe naa ti bẹrẹ yoo yọri.
O ni anfani ti Gboyega Oyetọla fi tayọ awọn oludije ti o ku ni oye ati iriri rẹ nipa eto iṣejọba.
Oríṣun àwòrán, Empics
Eyi ni yoo jẹ aṣekagba ipolongo idibo gomina fun ẹgbẹ oṣelu APC
Oshiomole tẹsiwaju wipe awọn eeyan ipinlẹ Ọṣun ko nilo gomina to kundun ode owanbẹ, tabi ẹni to fẹran ile ijo.
"Ẹni ti a fa kalẹ yi ko kundun ode owanbẹ. Ko le ma a jo skelewu.''
''Mo ranti wipe lọjọ diẹ sẹyin, wọn pe ipade itagbangba fun ifọrọwanilẹnu wo laarin awọn oludije si ipo gomina ipinlẹ Ọṣun, sugbọn ara ibi kọ lati yọọ ju sibẹ,nitori wipe o ti gba ijo lọ.''
Oríṣun àwòrán, @NajeemFSalaam
Awọn Gomina ẹgbẹ APC naa wa gbaruku ti akẹgbẹ wọn Rauf Aregbesola nibi ipolongo ohun
O rọ awọn eeyan ipinlẹ Ọṣun lati jade dibo wọn fun ẹgbẹ oṣelu APC lọjọ kejilelogun oṣu kẹẹsan ọdun yi, ki oṣẹ rere ẹgbẹ naa le tẹsiwaju.Ipolongo eto idibo naa ni aṣejagba iruẹ fun ẹgbẹ oṣelu APC saaju eto idibo si ipo gomina ti yoo waye ni ipinlẹ naa.
Ni ipari ipolongo naa wọn gbe asia ẹgbẹ fun Gboyega Oyetọla
Lara awọn eekan to ba wọn peju-lesẹ nibi akanṣe eto naa ni aare Muhammadu Buhari, adari ẹgbẹ oṣelu naa, Bola Ahmed Tinubu, Minisita fun ikansira ẹni, Adebayọ Shittu, minisita fun eto ilera Isaac Adewole,  ati bẹẹbẹẹ lọ
Bola Tinubu,Adams Osiomole ati awon eekan ẹgbẹ wa lara awọn to peju sibẹ .
Fadeyi Oloro Aliasi Sukee wa nibẹ
Osun Decides: Adegoke ni òun kò ni lo kọngilá n
'A máa ń bẹ́ orí ẹni tó bá gbé imọlẹ̀ ọdún ìjẹṣu tó bá ṣubú ni'
Ìdí tí Obìnrin fi lé saǹ ìdajì owó láti ra fọ́ọ̀mù ìfèróngbà hàn
Oríṣun àwòrán, @Apcofficials
Ìdí tí Obìnrin fi lé saǹ ìdajì owó láti ra fọ́ọ̀mù ìfèróngbà han
Owó gọọbọi ní olóṣelú tó bá ń gbìyanjú láti gba fọ́ọ̀mù ìfèróngbà han lórílẹ̀-èdè Nàìjíríà nílò.
Fọ́kùnrin tó ba fẹ́ dupò lọdún 2019 nínú ẹgbẹ́ òṣelú All Progressives Congress (APC) àti Peoples Democractic Party (PDP).
Èyí yàtọ̀ sí owó ìpolongo, tí ènìkẹ́ni bá fẹ́ fèróńgbà hàn láti dupò ààrẹ, ó di dandan kí ó kọkọ náwó kí ẹgbẹ́ to díbò yan an lati mọ̀ bóyá òun ní yóò sojú ẹgbẹ́ náà tabí bẹ́ẹ̀ kọ́.
Ní ọdún yìí, owó ìfèróngbà hàn nínú ẹgbẹ́ òṣèlú APC kò dín ní mílíọ̀nù márùndínláàdọ́ta nígbà ti ẹgbẹ́ òṣèlú PDP tún rọjú díẹ̀ pẹ̀lú mílíọ̀nù méjìlá náìrà.
Ní ti obìnrin àǹfání wà láti san ìdajì owó nínú ẹgbẹ́ òṣèlú APC nígbà ti ó jẹ́ ọ̀fẹ́ pátápátá nínú ẹgbẹ òṣèlú PDP fún obìnrin tó ba dá ara rẹ̀ lójú tó sì ṣetan láti díje, sùgbọn ohun tó yani lẹ́nu ní pe kò sí ẹgbẹ́ kankan tó ti fa obinrin sílẹ̀ gẹ́gẹ́ bíi aṣojú ẹgbẹ́ òṣèlú wọn láti ìgbà ti ìjọba awa ara wa ti bẹ̀rẹ̀ lọ́dún 1999 àti pé obìnrin kan ṣoṣo Sarah Jibril nìkan ló kópa nínú ìbò kòmẹ́sẹ̀ yọ.
Ìbò kan ṣoṣo ló Serah Jibril ní nínú ìbò ọdun 2011.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ìdí tí Obìnrin fi lé saǹ ìdajì owó láti ra fọ́ọ̀mù ìfèróngbà han
Sùgbọ́n ní báyìí ọ̀rọ̀ náà ti di ẹni bá láyà ka wá wọ̀ọ́ bí àwọn ọkunrin náà ṣe ń gbin láti dupò ààrẹ, nítori olówó nìkan ni ipò náà wà fún bayíì.
Osun Decides: Adegoke ni òun kò ni lo kọngilá n
Ọṣun Decides: ADC, ADP, APC àti SDP soju abẹ níkòó lórí ìwà ìbàjẹ́
Adeleke: 'Èmi ò kú o, koko lara mi le'
Èmi ò kú o
Ademọla Adeleke ti kede pe oun ko ku o lẹyin tim ọrọ kan ti tan kaakiri pe o ti jade laye.
Adeleke ni oludije ti 'Jackson' wa ninu inagijẹ rẹ, ti o si jẹ oludijẹ ti iwọle rẹ taara sinu agbami oselu orileede Naijiria waye lẹyin igba ti ẹgbọn rẹ papoda.
Senetọ Nurudeen Ademola Adeleke, ni oludije ipo Gomina labe asia ẹgbẹ oselu Peoples Democratic Party, PDP, ninu idibo Gomina ipinlẹ Osun .
Oríṣun àwòrán, Ademola Adeleke/Facebook
Adeleke ni oludije ẹgbẹ òṣèlú PDP nínú ìdìbò Gómìnà ìpínlẹ̀ Osun
Ọdun ti orileede Naijiria gba ominira, 1960 ni wọn bi i ni ilu Enugu.
OsunDecides: Omisore ní ẹni tó bá fẹ́ ra ìbò, àwọn yóò lọ lásọ mú ni
Raji Ayoola baba rẹ jẹ Musulumi, ọmọ bibi ilu Ede nipinlẹ Osun, sugbọn mama rẹ Nnena Esther Adeleke jẹ ẹya Igbo, ti o si jẹ Kristẹni .
Koda Isiaka di ipo asofin agba to n soju ẹkun idibo iwọ oorun ipinlẹ Osun mu leemeji, ki ọlọjọ to de ni odun 2017.
Oríṣun àwòrán, @IsiakaAdeleke1
Awọn amoye kan ni orukọ ẹgbọn Ademola, Isiaka Adeleke ko ipa ribibi bi o ti se di Sẹnẹtọ
Idile Oloselu ni Ademọla ti wa
Ti a ba so wi pe oselu jẹ nkan ti o n tọ iran Sẹnẹtọ Adeleke lẹyin, a ko j'ayopa.
Bẹrẹ lati ori baba rẹ, Ayoola Adeleke, to jẹ Sẹnẹtọ ni saa isejọba oselu ẹlẹkeji, ẹgbọn rẹ naa, Isiaka Adetunji Adeleke, ti ọpọ eeyan mọ si ''Sẹrubawọn'' jẹ Gomina akọkọ lẹyin ti wọn da ipinlẹ Osun silẹ.
Oríṣun àwòrán, Osun Defenders
Abi ẹ n ro wi pe Jacksonville ni inagijẹ Jackson rẹ ti waye ni?
Lọdun 2017 ti ẹgbọn rẹ, Isiaka Adetunji ku, anfaani si silẹ fun Nurudeen Ademọla lati wọ agbami oselu taara.
O dije fun ipo asoju labe asia ẹgbẹ oselu PDP, lẹyin to kuro ninu ẹgbẹ APC.
Oríṣun àwòrán, @IsiakaAdeleke1
Ọmọ igbimọ ile asofin agba lori ọrọ idasẹsilẹ ati isẹ ilu ni Sẹnẹtọ Adeleke
Adeleke gbe igba oroke, ti o si jẹ asofin agba to n soju ni ile asofin agba labuja lọwọ-lọwọ yii.
Adeleke pegede gẹgẹ bi oludije fun ẹgbẹ oselu PDP ninu idije Gomina nipinlẹ Osun, lẹyin to fẹyin Akin Ogunbiyi janlẹ pẹlu ibo meje.
‘Dancing Senatọ’ni baba olorin Takasufe meji
Ti a ba ni ki a sọrọ nipa iriri rẹ nipa oselu, ko fẹ si ọrọ pupo ju wi pe, o bẹrẹ irinajo oselu pẹlu ẹgbọn rẹ, Isiaka Adeleke ni ọdun 2001.
Koda awọn to mọ ọ daada ni, Ademọla a maa saba tele ẹgbọn rẹ lo si ibi ipolongo oselu, ni ibi ti awọn to mọ ọ daada ni a ma fi ijo da ara.
Oríṣun àwòrán, @IAM_DAVIDO, @ISIAKAADELEKE1
Adeleke ni aburo baba gbajugbaja olorin Davido
O seese ko jẹ wi pe ibi ti inagijẹ rẹ ‘Dancing Sẹnẹtọ’ ti wa ye ree.
Adeleke jẹ aburo Baba gbajugbaja olorin takasufe, ti gbogbo aye mọ si Davido sugbọn se  ẹ  mọ wi pe, awọn ọmọ rẹ okunrin meji naa a ma kọ orin takasufe?
Sina Rambo ati B red lorukọ awọn ọmọ Ademọla mejeeji tawọn naa n kọ orin.
Oríṣun àwòrán, @iam_Davido
Ọmọ Adeleke T red jẹ olorin takasufe
Oríṣun àwòrán, @SINARAMBO
Orin kikọ jẹ atewọgba laarin awọn ọmọ okunrin mọlẹbi Adeleke
Ki a to gbagbe, onisowo ni Adeleke, ti o si ti fi igba kan jẹ oga ni ile ise Pacific Hoildings to jẹ́ ti ẹgbọn rẹ, laarin odun 2001 si 2016.
Saaju igba naa lo ti  ba ile ise Quicksilver Courier Company lorileede America sisẹ gẹgẹ bi osisẹ́ fun igba ranpẹ.
Sẹ́nétọ̀ Ademọla Adeleke ń jẹ́jọ́ aṣemáṣe lásìkò ìdánwò
Oríṣun àwòrán, @IsiakaAdeleke1
Ṣaaju idibo ọṣun ni wọn ti fi ẹsun yii kan sẹnetọ Adeleke
Lẹyin ti awọn ọlọpaa ti gbe e lọ siwaju ile ẹjọ ni ọjọru fun ẹsun iwa aitọ lasiko idanwo, ile ẹjọ giga apapọ kan nilu Abuja ti gba oniduro Sẹnetọ Ademọla Adeleke, oludije fun ipo gomina ipinlẹ Ọṣun labẹ ẹgbẹ oṣelu PDP.
Awọn ọlọpaa gbe Sẹnetọ Adeleke atawọn mẹrin miran lọ siwaju Onidajọ I.E. Ekwo nibi ti awọn mẹrẹẹrin ti ni awọn ko jẹbi ẹsun mẹrẹẹrin ti wọn fi kan awọn.
Sikiru Adeleke,  Alhaji Aregbesola Muftau to jẹ Ọga agba ile ẹkọ girama Ojo-aro Community grammar school, Gbadamosi Ojo to jẹ akọwe agba ileewe naa, pẹlu Dare Samuel Olutọpẹ to jẹ olukọ nibẹ ni wọn pe lẹjọ pe wọn lọwọ ninu iwa aṣemaṣe lasiko idanwo fun aṣekagba ileewe girama NECO June/July 2017.
Ni kete ti wọn ti sọ niwaju ileẹjọ naa pe awọn ko jẹbi ẹsun ni adajọ ti gba oniduro awọn mẹta pẹlu Sẹnetọ Adeleke.
Agba agbẹjọrọ, Alex Izinyon SAN, lo n ṣoju fun sẹnetọ Adeleke, nigba ti Nathaniel Oke SAN, ati Abdusalami Abdufatai n gbẹjọro fun awọn olujẹjọ keji ati ikẹta.
Meji ninu awọn ti wọn n jẹjọ naa ni wọn fi pamọ si ahamọ ọgba ẹwọn nitori aisi nile agbẹjọro wọn lati beere fun gbigba oniduro.
Ile ẹjọ ni oun fun Sẹnetọ Adeleke ni anfani oniduro nitori ipo rẹ lawujọ, amọṣa o gbọdọ fi iwe irinna rẹ soke okun ṣọwọ si akọwe agba ileẹjọ naa, ko si gbọdọ rinrin ajo lọ si oke okun lai gba aṣẹ lọwọ lọdọ ile ẹjọ.
Oríṣun àwòrán, @IsiakaAdeleke1
Ile ẹjọ fi aaye gbigba oniduro rẹ silẹ nitori ipo rẹ lawujọ
Nibayii, ile ẹjọ ti wa sun igbẹjọ si ọjọ kẹtadinlogun, ikejidinlogun ati ikọkandinlogun oṣu kejila.
Awọn ọlọpaa gbe Sẹnetọ Adeleke atawọn mẹrin miran lọ siwaju Onidajọ I.E. Ekwo nibiti awọn mẹrẹẹrin ti ni awọn ko jẹbi ẹsun mẹrẹẹrin ti wọn fi kan awọn.
Sikiru Adeleke,  Alhaji Aregbesola Muftau to jẹ Ọga agba ile ẹkọ girama Ojo-aro Community grammar school, Gbadamosi Ojo to jẹ akọwe agba ileewe naa, pẹlu Dare Samuel Olutọpẹ to jẹ olukọ nibẹ ni wọn pe lẹjọ pe wọn lọwọ ninu iwa aṣemaṣe lasiko idanwo fun aṣekagba ileewe girama NECO June/July 2017.
Ni kete ti wọn ti sọ niwaju ileẹjọ naa pe awọn ko jẹbi ẹsun ni adajọ ti gba oniduro awọn mẹta pẹlu Sẹnetọ Adeleke.
Oríṣun àwòrán, @IsiakaAdeleke1
Meji ninu awọn ti wọn n jẹjọ naa ni wọn fi pamọ si ahamọ ọgba ẹwọn
Oríṣun àwòrán, @IsiakaAdeleke1
Senator Isiaka Ademola Adeleke
Aarẹ Muhammadu Buhari ti pasẹ fun Ọga Agba Ọlopaa, lati ti ọwọ ọmọ rẹ bọ asọ lori iwe ipẹ̀jọ ti wọn fi n pe oludije si ipo gomina labẹ ẹgbẹ oselu PDP ni ipinlẹ Osun.
Ẹni ti ọrọ naa soju rẹ, amọ ti ko fẹ ka darukọ rẹ sọ fun awọn akọrọyin ni ile Aarẹ wi pe, Aarẹ Buhari ti fi asẹ si pe, o di ẹyin idibo ki wọn to le fi iwe ipẹjo ransẹ si Sẹnetọ Adeleke.
Saaju ni ileesẹ ọlọọpa ti fi iwe pe Sẹnetọ Adeleke lati wa kawọ pọnyin ro ẹjọ lori ẹsun sise magomago lasiko idanwo, iwa ọdanran, lilo oruko ti ki n se ti ẹ, ati sise onigbọwọ fun ọdaran.
Omiyalé Àkútè: N50 si N100 làwọn èèyàn fi ń kọjá lórí ẹ̀kún omi l‘Ákútè
Alukoro ile ise ọlọọpa, Jimoh Moshood fi iwe pe sẹneto Adeleke ati awọn mẹrin miran lori ẹsun yi kan naa.
Lẹ́yin oṣu mẹrinla ti awọn ọlọpaa gbọ pe Sẹnetọ Ademọla Adeleke to jẹ oludije ipo gomina labe asia ẹgbẹ oselu PDP ninu idibo ipinlẹ Osun ṣe magomago ninu idanwo NECO ti 2017, ti o si gba ayederu iwe ẹri idanwo naa, wọn ti fẹ gbe lọ ile ẹjọ ni Abuja.
Ọlọpaa ni Sẹneto Adeleke ati awọn mẹta ti wọn fi ofin mu lori ẹsun naa ni awọn ti ṣetan lati gbe lọ si iwaju adajọ ni Ile Ejọ Giga ti ilu Abuja ni ọjọ kọkanlelogun oṣu kẹsan, ọdun 2018. O wa nibi aṣekagba ipologo idibo ti ẹgbẹ rẹ PDP ni Osogbo. Sẹnetọ naa ti awọn eniyan ti mọ fun bi o ṣe maa n fi ijo dabira, fi ẹsẹ rajo ranpẹ nibi ipolongo naa.
OsunDecides: Adeleke kò jáwọn olólùfẹ́ tó fẹ́ wòran ijó rẹ̀ kulẹ̀
Agbẹnusọ ọlọpaa ni orilẹede Naijiria Jimoh Moshood Wọn ti wa rọọ bayi lati farahan niwaju ọlọpaa fun anfani ara rẹ.
Moshood  sọ ninu atẹjade kan ni ọjọ Ọjọru pe, Adeleke forukọ sile lati ṣe idanwo NECO ni ọdun 2017, ṣugbọn ko yọju lati kọ idanwo naa botilẹ jẹ pe o gba iwe ẹri idanwo naa."
"Moshood ni, ""Ni ọjọ kọkanlelogun oṣu keje, ọdun 2017, ẹka ọtẹlẹmuyẹ ti ọlọpaa ni Ipinle Ọṣun gbọ wipe Sẹnetọ Ademola Adeleke ati Sikiru Adeleke n ṣe magomago idanwo ni ile iwe  girama Ojo/Aro ni Osun."
Nigba ti wọn de ile iwe naa, Sikiru Adeleke nikan ni wọn ri lori ijoko, ṣugbọn ko si Sẹnetọ Ademola Adeleke nibẹ. O jọ bi ẹni pe, o ti sa lọ ki awọn ọlọpaa o to de. Iwadi fi han wipe Sẹnetọ Ademola Adeleke forukọ silẹ lati ṣe idanwo NECO ti ọduin 2017. Oga agba ile iwe naa ati awọn olukọ meji lo ṣe elegbe lẹyin rẹ fun aṣemaṣe yii.
A gbọ pe, ọlọpaa fi panpẹ mu ọga agba ile iwe naa, Alhaji Aregbeṣọla Mufutau, olukọ to forukọ Adeleke silẹ, Ogbẹni Gbadamosi Ojo, ati olukan keji kan, Dare Olutope.
Moshood ni ọjọ mẹfa lẹyin rẹ - ọjọ kẹtadinlọgbọn oṣu keje, ọdun 2017 ni awọn ọlọpaa mu ṣẹnetọ, ti wọn  si mu Sikiru Adeleke ni ọjọ kẹjọ oṣu kẹjọ, ọdun 2017.
O tun fi kun wipe ṣẹnetọ naa fi ọrọ silẹ wipe ni tootọ ni oun fi orukọ silẹ fun idanwo naa, ṣugbọn pe oun ko kọ ọ. Ṣugbọn o ni iwe ẹri idanwo naa to fi han pe o gba kirẹditi meje ati paasi kan.
Ìtàn Mánigbàgbé: Kuti ni akọni Obìnrin Ẹ̀gbá tó di àwòkọ́ṣe rere f'áwọn ọ̀dọ́bìnrin ìwòyí
Oríṣun àwòrán, @NzekweGerald
Ọmọ ju ọmọ lọ, agbára ju agbára lọ ni ọrọ Funmilayọ Kuti tí Ilééṣẹ́ Google ń ṣe ìrántí rẹ̀.
Ọmọ ju ọmọ lọ, agbára ju agbára lọ ni ọrọ Funmilayọ Kuti tí Ilééṣẹ́ Google ń ṣe ìrántí rẹ̀.
A bi Olufunmilayọ Frances Abigail Thomas ni ilu Abeokuta, ni ipinlẹ Ogun, Naijiria ni ọjọ Kẹẹdọgbọn, oṣu kẹwaa, ọdun 1900.
Funmilayọ Ransome Kuti jẹ ọmọ iya aranṣọ àti agbẹ ti baba rẹ ti oko ẹru de ni ilẹ Saro.
Oríṣun àwòrán, @Ransome-Kuti
Akọni obìnrin Olufunmilayọ Ransome-Kuti
Ọjọ kẹta, oṣù kinni, ọdún 1949 jẹ́ ọjọ́ málegbàgbé ni Abẹokuta nipinlẹ Ogun.
Ọjọ yii ni pẹpẹyẹ pọnmọ, ti Oba Samuel Ladapọ Ademọla kejì kọwe fipo rẹ silẹ ni Ẹ̀gbá.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Funmilayọ gba agbára lọ́wọ́ Ọba Ladapọ Ademọla keji
Olufunmilayọ ni olori ẹgbe ìṣọ̀kan àwọn obinrin Ẹ̀gbá nigba naa. Oun lo ṣaaju ìwọ́de ti wọn ṣe lati fẹhonu han lori owo orí gọbọi àti ìyà ti wọn n jẹ lọwọ awọn Oyinbo Ajẹ́lẹ̀.
'Èmi gan máa ń béèrè lọ́wọ́ ara mi pé ta ni Wole Soyinka gangan'
Ọjọ kẹẹdọgbọn, oṣu kẹwaa, ọdun 1900 ni a bi Frances Abigail Olufunmilayọ Thomas sinu idile ti wọn fẹran ẹ̀kọ́ iwe.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Àwọn Ajẹ́lẹ̀ miran huwa kòtọ́ nilẹ alawọ dúdú.
Nigba ti o lọ sile iwe ni England, ni oju rẹ ṣi si bi àwọn oyinbo kan ṣe n huwa ìdẹ́yẹsí si àwọn alawọ dudu.
Eyi ni àwọn kan fi ro pe o jẹ ki o yọ orukọ oyinbo kuro lara orukọ rẹ, to fi n jẹ Olufunmilayọ nikan.
Wo imọran Fọlọrunṣọ Alakija fun awọn ọdọ adulawọ
Nigba ti Funmilayọ pada sile ni Naijiria, o rii pe, awọn oyinbo Ajẹlẹ ti n ṣiṣe ibi nipa gbigbe owó orí gọbọi le awọn eniyan lori.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Orí ń ta àwọn olokowo ni Naijiria
Ijọba ibilẹ ti Alake ti Ẹ̀gba n bojuto ni wọn n gba bu owó orí naa fawọn ọlọ́jà. Owó orí gọbọi lori ọjà yii pẹlu iwa ipá ti awọn agbofinro n lò lati fagidi mu awọn ọlọja, di ẹru nla lori awọn obinrin.
Bẹẹ, wọn ko fi aaye gba awọn obinrin lati da si ọrọ oṣelu, ko si ọna fun awọn obinrin lati gbe ọrọ wọn jade.
Eyi lo mu wọn forikori lati ṣe iwọde, eyi ti ẹgbẹ Iṣokan awọn obinrin  Abẹokuta ṣaaju rẹ̀.
Oríṣun àwòrán, @Ransome Kuti
Agbara obinrin pọ̀
Funmilayọ Ransome-Kuti ati àbúrò ọkọ rẹ̀, Ẹniọla Ṣoyinka ( Iya Wọle Ṣoyinka), ni wọn jọ dá ẹgbẹ iṣọkan yii silẹ lati fi ja ija ominira awọn abo kuro lọwọ awọn Ajẹlẹ.
Ọkan Funmilayọ poruru nigba ti o gbọ ohun to n ṣelẹ sawọn obinrin Egba lọwọ awọn oṣiṣẹ Alake ati Ajẹlẹ ati pe, wọn n tún irẹsi ti wọn fagídí gbà lọwọ awọn obinrin tà, ti wọn n kowo rẹ sapo ara wọn.
Ìgbésí ayé àwọn ọmọdébìnrin wọ̀nyìí di ọ̀tun láti 2008
Eyi lo fi bẹrẹ iwọde ojoojumọ ṣe lodi si iwa Alake ati Ajẹlẹ yii. Ijọba n yin tajútajú fi tú wọn ka pẹlu kóńdó àti kùmọ̀ ni.
Gbogbo rẹ dé òtéńté nigba ti Funmilayọ kò san owó orí ara rẹ, ti wọn fi gbee lọ sile ẹjọ́ ti ọpọlọpọ awọn obinrin sì tẹle lọ lọdun 1947.
Yoruba Culture: ọjọ́ méje ni wọ́n fí n rẹ ẹ̀kú Danafojura kó tó jáde
Kete tijọba ti mu Funmilayọ lori ẹsun pe kò san owó orí ara rẹ, ni awọn obinrin ti pe bo ilé ẹjọ naa.
Wọn kò gbé igi tabi kùmọ̀ rara. Wọn ṣe gẹgẹ bi awọn obinrin ilu Aba ṣe ṣe lọdun 1929, nigba ti wọn n ja pe owọ orí ti áwọn n san ti pọ̀ ju. Eyi kò jẹ ki o ṣeeṣe fawọn agbofinro lati kọlu wọn.
Oríṣun àwòrán, @Ransome-Kuti
Awon obinrin Ẹ̀gbá fariga
Ọba Alake igba naa, Ọba Samuel Ladapọ Ademọla ati awọn Oyinbo Ajẹ́lẹ̀ gbogun ti aya Ransome-Kuti.
Wọn fi ofin dee pe kò gbọdọ wọ àfin mọ, wọn gbiyanju lati da aarin awọn oloye ẹgbẹ rú, ki wọn le rọ Kuti loye, ṣugbọn pàbó ló já sí.
Awọn obinrin naa fi aake kọri pe, a fi ti Alake ba kọwe fipo rẹ silẹ ni awọn yoo to dẹkun iwọde.
Ilu Ubang, jẹ ilu kan nibiti ede ti awọn ọkunrin wọn n sọ yatọ si ti awọn obinrin wọn.
Lẹyin ọpọlọpọ ọdun ifẹhonuhan, ni oṣu keje, ọdun 1948, ni awọn Oloye Ẹ̀gbá atawọn agbaagba ninu iṣelu gbe ofin sita, to fẹsun kan Alake pe o n huwa aitọ, to tun n ṣi agbara Ọba lò.
Wọn yọ Alake kuro nipo, wọn si lu ilu iyọkuro nipo fun un leyin ikede.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ti ọmọ ko ba jọ iya, aa jọ baba; Fẹla Anikulapo Kuti ba awọn iwa kan nile ni.
Alake fi orí oye rẹ silẹ, o tun fi Ẹ̀gbá silẹ. Awọn obinrin mẹrin pẹlu Olufunmilayọ Ransome-Kuti ni wọn yan si ara igbimọ ijọba ibilẹ, ti wọn si fi ofin de ki obinrin maa san owọ orí.
Funmilayọ tun tesiwaju lori ijajagbara fun ẹtọ awọn obinrin kaakiri ilẹ Adulawọ lọ si Ghana, Sierra-Leone ati bẹẹ bẹẹ lọ.
Loṣu keji, ọdun 1978 ni wọn ju Funmilayọ Kuti lati oju ferese nile ọmọ rẹ Fela Anikulapo Kuti ni eyi to ja si aarẹ fun un.
'Èmi gan máa ń béèrè lọ́wọ́ ara mi pé ta ni Wole Soyinka gangan'
Oṣu kẹrin, ọdun 1978 ni Funmilayọ jade laye.
Bi aladi ko ba si nile, ọmọ wọn nii jogun ẹbu ni Funmilayọ fi ọrọ ijajagbara rẹ ṣe, Awọn ọmọ rẹ bii Bẹkọ Ransome - Kuti ati Fẹla naa tẹsiwaju lori eyi ni, sé ọmọ ti ẹya ba bi, ẹya nii jọ.
Obinrin lo mu mi fẹran orin kikọ - Patoranking
Sunny Ade: Ebenezer Obey sọ pé onírẹ̀lẹ̀ ènìyàn ni
Oríṣun àwòrán, @KingSunnyAde70
Yoruba ni ọdọọdun la n ri orogbo, ọdọọdun la n ri awusa, ọdọọdun la n ri ọmọ obi lori atẹ.
Ọdun miran tun ti ko fun ilumọọka olorin juju nni, Oloye Sunday Adeniyi Adegẹye, ti gbogbo eniyan mọ si King Sunny Ade.
Oríṣun àwòrán, @KingSunnyAde
Ọjọ Satide, ọjọ kejilelogun osu kẹsan ọdun 2018 ni Sunny Ade pe ẹni ọ̀dun mejilelaadọrin loke eepẹ, ti ọpọ eeyan si ti n ki ku oriire, eyi ti ko yọ BBC Yoruba silẹ.
Ọ̀ṣun Oṣogbo 2018: Ulrich Salazar wálé ọdún láti New York
Oríṣun àwòrán, @KingSunnyAde
Ebenezer Fabiyi Obey, ti gbogbo eeyan mọ si Obey, ti wa ransẹ ikinni ku oriire ọdun tuntun miran si akẹẹgbẹ rẹ nidi orin kikọ, Sunny Ade.
"Lasiko to n ba BBC Yoruba sọrọ, Obey ni ""Oniwa irẹlẹ, ọlọpọlọ pipe ẹda ati ẹni iyi kaakiri agbaye ni King Sunny Ade, mo si gbadura pe Ọlọrun yoo fun ni ẹmi gigun ati alaafia lati se ọpọ ọdun laye."""
Ibura Gomina: Akọ̀wé ìjọba àpapọ̀ ló sojú Buhari
Oríṣun àwòrán, Gbemi Jesuleke
Gboyega Oyetọla búra
Alhaji Gboyega Oyetọla ni wọn ti bura fun gẹgẹ bii gomina tuntun ni ipinlẹ Ọsun.
Adajọ agba nipinlẹ naa, Oyebọla Adepele lo dari eto ibura fun gomina Oyetọla ati igbakeji rẹ ni deede aago mejila aabọ ọsan.
Nigba to n sọrọ nibi ayẹyẹ naa, Asaaju fun ẹgbẹ APC ni Naijiria , Bola Ahmed Tinubu kọrin re ki Gomina to n fipo silẹ ni ipinlẹ Ọsun, Rauf Arẹgbẹsọla
Jide Kosọkọ: Isẹ́ tíátà yóò gòkè tíjọba bá gbówó kalẹ̀ láti seré
Orin ibilẹ ilẹ wa si ni wn fi side ayẹyẹ naa
Lara awọn eeyan pataki ti o tun darapọ mọ ipejọpọ naa ni Ọọni Ile Ifẹ, Ọba Enitan Ogunwusi, Ọjaja keji, Alaafin Ọyọ, Ọba Lamidi Adeyẹmi .
Oríṣun àwòrán, @Oyetola_Gboyega
Awọn ọba alaye yoku ni Ataọja ilu Ọṣogbo, adari ẹgbẹ oṣelu APC, Bọla Tinubu ati aya rẹ, Senatọ Olurẹmi Tinubu ati gomina ipinlẹ Ọṣun tẹlẹri, Oloye Adebisi Akande ati bẹẹbẹẹ lọ.
Awọn gomina ipinlẹ Ekiti, Ọndo, Ọyọ, Eko, Kogi ati Kano naa ko gbẹyin nibi ayẹyẹ ibura naa.
Adajọ agba ipinlẹ Ọṣun, arabinrin Adepele Ojo naa ti wa ni kalẹ lati ṣe akoso iburawọle ọhun.
Akọwe ijọba apapọ orilẹede yii, Boss Mustapha lo ṣoju aarẹ Muhammadu Buhari nibi ipejọpọ naa.
Oríṣun àwòrán, Omonijo Sunday
Bakan naa, ọgọọrọ awọn oṣiṣẹ ijọba, ọniṣe ọwọ, ọniṣowo, agunbanirọ ati awọn aṣoju ijọba ipinlẹ Ọṣun lo pejupesẹ si papa iṣere gbilu Ọṣogbo fun ayẹyẹ naa.
Awọn ladelade-loyeloye naa ko gbẹyin ninu awọn to wa ba gomina tuntun yọ. Lara awọn Ọba alade to ti wa nikalẹ ni Ọrangun Ile Ila ati Oluwo ti Ilu Iwo.
Oríṣun àwòrán, Omonijo Sunday
Lati aago mẹwa owurọ lo ti yẹ ki eto naa gbinaya, sugbọn titi di asiko yii, a ṣi n reti gomina tuntun, igbimọ alakoso ẹgbẹ oṣelu APC ati awọn alejo pataki mii nibi ayẹyẹ naa.
Alẹ ana ni awọn alejo pataki ti n wọle si ilu Osogbo fun ayẹyẹ ibura naa, lara awọn to kọkọ de ni asaaju ẹgbẹ oselu APC ni Naijiria, Bọla Ahmed Tinubu.
Ajọ eleto idibo lorilẹede Naijiria ti bẹrẹ kika esi idibo si ipo gomina ni ipinlẹ Osun.
Adari INEC ni ẹkun Guusu-Iwọ Oorun orilẹede Naijiria, Ọmọọba Deji Soyebi ati awọn adari Ajo INEC ni ipinlẹ Osun, Rivers, Ebonyi, Cross Rivers, Nasarawa, Gombe, Sokoto, Kano, Edo, Benue lo peju pese si ibẹ.
Adari Ajọ Inec ni Osun, Olusegun Agbaje dupẹ lọwọ gbogbo awọn to jẹ ki eto idibo naa lọ ni irọwọrọsẹ lai si rogbodiyan ninu.
Àbájáde èsì ìbò gómìnà ìpínlẹ̀ Ọ̀sun
Osun Election 2018: Aráàlú ní àwọn kò fẹ́ ìjọba elébi mọ́
O fi kun un wi pe ẹgbẹ oselu mejidinlaadọta lo dije dupo gomina ni ipinlẹ naa.
Ni bayii, awon egbe oselu ti bere si ni ka esi idibo fun woodu ati unit won.
Ọjọ kejìlélógún, oṣù kẹsan an, ọdún 2018 ni àwọn èèyàn ìpínlẹ Ọṣun dìbò yan ẹni tó wù wọ́n sìpó gomina fún saa ọdún mẹrin tó m bọ.
Ṣùgbọn abajade náà kò ṣẹnu 're fún awọn ara Ọṣun gẹ́gẹ́ bí àjọ INEC ṣe kéde wí pé
Bi o tilẹ jẹ pe eto idibo gomina nipinlẹ Ọsun naa lọ ni irọwọ-rọsẹ, sibẹ a gbọ lati ẹnu oludari eto idibo ni ijọba ibilẹ Orolu pe, agọ idibo mẹta ni wọn ti ja apoti idibo gba, ti wọn ko si wọgile ibo lawọn agọ idibo mẹtẹtẹta naa.
Ni bayii, awon egbe oselu ti bere si ni ka esi idibo fun woodu ati unit won.
Esi idibo lati awọn ijọba ibilẹ ni ipinlẹ Osun
Boluwaduro APC 3,843PDP 3779
APC 5019PDP 5401
APC 3182PDP 3374
APC 4512PDP 16693
APC 5442PDP 7776
APC 7229PDP  10859
IleṣaEast
APC 9790PDP 8244
APC 11655PDP 6892
Ilesa West
APC 7251PDP 8286
APC 9778PDP 10109
APC 6517PDP 8058
APC 8403PDP 8241
APC 7297PDP 9048
APC 9996PDP 9879
APC 10861PDP 9836
APC 7073PDP 5218
APC 7025PDP 18745
APC 9882PDP 12269
APC 5474PDP 5133
APC 6527PDP 5486
APC 14779PDP 11116
APC 7354PDP 7231
APC 6957PDP 3200
APC 10049PDP 13848
APC 16254PDP 9850
APC 5025PDP 4026
APC 7223PDP 4872
APC 8925PDP 6608
APC - 7644PDP - 6122
APC - 23379PDP - 14499
Osun Election Results 2018: Adeleke sọ pé PDP yóò gba ipò gómìnà rẹ̀ padà nílé ẹjọ́
Osun Election Results 2018: Adeleke sọ pé PDP yóò gba ipò gómìnà rẹ̀ padà nílé ẹjọ́
Oludije fun ipo gomina labẹ ẹgbẹ oselu PDP nipinlẹ Ọsun, Ademọla Adeleke, ti se apejuwe bo se fidi rẹmi ninu eto idibo gomina to sẹsẹ kọja naa gẹgẹ bii ifasẹyin ranpẹ, eyi ti yoo ni atunse laipẹ.
Ademọla Adeleke, lasiko to n bawọn akọroyin sọrọ ni ile rẹ to wa ni Ẹdẹ, tun fikun pe, ẹgbẹ oselu oun, PDP, yoo lo gbogbo agbara ofin to ba wa nikawọ rẹ lati gba ipo rẹ ti wọn ‘ji gbe’ pada.
"O fikun pe ""Ẹgbẹ oselu to n se ijọba lọwọ mọọmọ fi tipa-tipa gbe ifẹ ọkan wọn le awọn araalu lori ni, pẹlu bo se ko awọn janduku lati awọn ipinlẹ miran wa dunkoko mọ awọn araalu atawọn akọroyin."""
Dele Adeleke: Ǹkan tó tọ́sí Ọsun kó ni Ọsun rígbà
Adeleke wa rọ̀ awọn araalu lati bomi suuru mu, to si tun n fẹsun kan pe awọn janduku, to dibọn bii ologun pẹlu asọ sọja ati ọlọpaa, si wa yika ipinlẹ naa, ti wọn si lee lo anfaani ifẹhonu han lati pa awọn alaisẹ, ki wọn si tun se wọn lese pẹlu.
O wa fọwọ gbaya pe idagbasoke ipinlẹ Ọsun ati ti ẹgbẹ oselu PDP lo mumu laya oun.
Olùdíje tó jáwé olúborí ṣùgbọ́n tí wọn kò kéde rẹ̀ nínú ìdìbò ìpínlẹ̀ Ọṣun, Sẹ́nétọ̀ Ademola Adeleke ti fi ẹ̀mí ìmore hàn sí àwọn ará ìpínlẹ̀ Ọṣun fún àtilẹ́yìn wọn.
Nínú àtẹ̀jáde kan tí ó buwọ́lù lọ́jọ́ kẹtàlélógún oṣù kẹ́sàn án, Sẹ́nétọ̀ Adeleke ní àtìlẹ́yìn púpọ̀ tí òun rí jákèjádò ìpínlẹ̀ Ọ̀sun tún fún òun ní ẹ̀mí ìrẹ̀lẹ̀ síi.
Ó tún jẹ́ kó di mímọ̀ pé àwọn ará Ọṣun bu iyì kún òun ni tó fi jẹ́ pé òun ló jáwé olùborí nínú èsì ìdìbò ìpínlẹ̀ Ọṣun káàkiri àwọn ìjọba ìbílẹ̀.
"Mo fi ànfàní yìí dúpẹ́ lọ́wọ́ àwọn olùdìbò ìpínlẹ̀ Ọ̀ṣun tó rí mi gẹ́gẹ́ bí ẹni tó yẹ láti ní ìbò wọn. Bí ẹ ṣe dìbò yàn mí túnbọ̀ fún mi ní ẹ̀mí írẹ̀lẹ̀ síi ó sì tún fún mi ní ìgboyà láti sin àwọn aráàlú.
Pẹ̀lú gbogbo ẹ̀sùn irọ́ tí wọ́n lọ́ mọ mi lẹ́sẹ̀, ẹ ṣì dúró tì mí, ẹ dìbò fún mi bẹ́ẹ̀ sì ni ẹ dúró gbọingbọin lórí ìpinu yín. Ẹ gbà mí gẹ́gẹ́ bí ni tó leè ṣe ìràpadà. Mi ò leè sọ bí ọpẹ́ mi ṣe pọ̀ tóo, ni Adeleke wí."
"Ó ní ""a ó dé ilẹ ìlérí. Ó bẹ̀rẹ̀ dáradára, ìyìn sí Ọlọrun wa sì ni yóò gbẹ̀yìn rẹ̀. Ẹ jhẹ́ ká fi ara wa jín fún ìlàkàkà nítorí ẹ ti fi hàn pllú ìpinu yín. À lée fi tipátipá mú alágbára láti ṣe ifẹ́ aráàlú."
"Mo dúpẹ́ lọ́wọ́ gbogbo yín"", Ló bá parí ọ̀rọ̀."
Ibùdó ìdìbò 7 ni yóò tún ìbò dì l'Ọṣun
Ẹ̀wẹ̀ gẹ́gẹ́ bí àjọ elétò ìdìbò ṣe sọ ọ́, wọ̀nyìí ni àwọn apa ibi tí wọn yóò ti tún ìbò dì ní ìpínlẹ̀ Ọṣun:
Ibùdó mẹ́ta ní ìjọba ìbílẹ̀ Orolu
Ibùdó méjì ní ìjọba ìbílẹ̀ Ifẹ South
Ibùdó kan ní ìjọba ìbílẹ̀ Ifẹ North
Ibùdó kan ní ìjọba ìbílẹ̀ Oṣogbo
Osun Election Results: Lai muhammed fẹ̀sí sí ìdìbò Ọsun
Minisita fun ifitonileti ati Asa ni orilẹ-ede Naijiria, Lai Muhammed ni APC fi ọwọ yẹpẹrẹ mu PDP lori idibo Ọṣun ni won ko ṣe jawe olubori.
Lai Muhammed ṣalaye fun BBC Yoruba pe awọn maa lọ gbaradi fun awọn agbegbe ti wọn yoo ti lọ tun ibo naa di.
Eyi ni èsì idibo Ọṣun fawọn oludije to ṣaaju
'Lọ́gán tí mo bá di ààrẹ, mo máa bẹ̀rẹ̀ iṣẹ́'
Amọ, Minisita naa fikun pe ẹru ko ba awọn latari idibo gbogboogbo ti yoo waye ni ọdun 2019Link.
Lai Mohammed ni àwọn faramọ igbẹ́sẹ̀ INEC ṣugbọn APC a tun ara mú láti rọ àwọn èèyàn Ọṣun sii.
O mẹnuba ẹ̀rí ti APC naa ni lori ìdìbò Ọṣun.
Osun Election 2018: Aráàlú ní àwọn kò fẹ́ ìjọba elébi mọ́
Nínú ìkéde àjọ INEC, ẹgbẹ́ òṣèlú PDP fi ìbò 254,698 gbà a mọ́ ẹgbẹ́ òṣèlú APC tó wà lórí aléfà lọ́wọ́ tí wọ́n ní ìbò 254,345.
Ìyàtọ̀ tó wà láàrin ìbò méjèèjì ni 353. Gbogbo ìbò tí INEC fagilé ni 3,498.
Ọ̀jọ̀gbọ́n Adeola Fiwapẹ tó jẹ adarí ètò ìdìbò náà kéde lórukọ INEC pé wọ́n yóò ṣe àtúndì ìbò àwọn agbègbè kọ̀ọ̀kan.
O ṣalaye ìdí ti èyí fi ri bẹẹ pe odiwọn ìbò ti awọn oludije mejeeji to ṣaaju ninu idije naa fi ju ara wọn lọ ko pọ to odiwọn iye ìbò ti wọn fagilé.
Fun idi èyi atundi ìbò ni yóò foju gomina tuntun fun ipìnlẹ Ọṣun hande.
Osun Election 2018: 'Ojú ọ̀dọ́ nipinlẹ̀ Ọṣun ti la'
Osun Election Results: Wọ́n ti ka ìbò Ọṣun tan, ìkéde INEC lo kù
Abajade èsì ìdìbò Ọṣun bí INEC ṣe kàá sita
Onikaluku n dúró de ìkéde ajọ INEC lórí idibo Ọṣun.
Awọn oludije mejidinlaadọta ni wọn figa gbaga jọ du ipo gomina nipinlẹ Ọṣun lọjọ Abamẹta, ọjọ kejilelogun, oṣu kẹsan an, ọdun 2018.
Ibudo idibo 3,010 ni wọn fi sita fun ètò idibo naa nipinlẹ Osun pẹlu ọlọpaa 18, 426 gẹgẹ bi ọga agba ọlọpaa, Idris Ibrahim ṣe fi sita.
Bayii, ajọ eleto idibo ti ka awọn ibo ti wọn gbe wa ni eyi ti ọpọlọpọ Link ti ṣe iṣiro le lori.
Ile iṣe BBC Yorùbá naa n duro pẹlu awọn eniyan Naijiria de ikede INEC lori ijọba ibilẹ ọgbọn tidibo naa ti waye ni ipinlẹ Ọṣun.
Osun Election 2018: Aráàlú ní àwọn kò fẹ́ ìjọba elébi mọ́
Osun Election Results 2018: oníkaluku fi èrò rẹ̀ hàn lórí ayélujára
Eyi ni apapọ èsi idibo Ọṣun ni àròpọ̀
Ìdìbò Ọṣun di àpèrò àwọn olóṣèlù
Ọjọgbọn Afuwape to ṣe alakoso eto idibo to waye lọjọ kejilelogun, oṣu kẹsa an kaakiri ipinlẹ Ọṣun lo kede pe atundi ìbò yoo waye ni ki INEC to le kede ẹni to ba wọle gẹgẹ bii gomina tuntun ti yoo rọpo Ogbẹni Arẹgbẹṣọla.
O ni ibo ti wọn wọgile jẹ 3, 498 nigba tio iyatọ ìbò APC ati PDP to gbegba oroke jẹ 353Link.
Osun Election 2018: Aráàlú ní àwọn kò fẹ́ ìjọba elébi mọ́
Isọkusọ ní INEC sọ lórí ìdìbò Osun
Oludije ẹgbẹ oṣelu APC, Adegboyega Oyetọla ni asiko ọ̀rọ̀ kòí tó fun òun nigba ti BBC kan sii ni Ọṣogbo.
Oludije APC
Bakan naa ni Iyola Omiṣore ko tii ba BBc sọrọ ṣugbọn awọn agbẹnusọ rẹ ni àwọn ti n ṣe ipade lori ohun tó kàn lati ṣe.
Ikede Atundi ìbò yii lo ti n bi Ìgè ati Àdùbí kaakiri ayelujara bayii. Ṣaaju ki wọn to kede ni àwọn kan ti gba pe ikede naa ṣeeṣe ko ni ọwọ kan ninu.
Loju Al-Gombawi, ka ni APC lo wọle, INEC yoo ti tete kede ẹni to jawe olubori.
Awọn ẹgbẹ oṣelu PDP ni àwọn ti pariwo sita tẹlẹ ki ọrọ ma le di ohun to di yii nitori pe ati okeere ni oloju jinjin àwọn ti n kigbe.
Bẹẹ, ero ọkan Davido ni pe àwọn ènìyan Ọṣun ti yan ololufẹ wọn fun igba ọtun sipo pẹlu abajade esi ti INEC fi sita lai nilo atundi ibo rara.
Ọpọlọpọ ló gbàgbọ́ pé afurasi ọkunrin ti wọn mu pe o fa èsì ìdìbò Ayedaade ya lo ṣokunfa atundi yii. PDP fi léde ní ìkanni twitter wọn pé
Loju àwọn mii, ohun ti INEc ṣe dára, àṣiṣe ni ki ẹgbẹ PDP gbagbọ pe àwọn ti bori ìbò Ọṣun. Ọgbẹni Ayọ ni:
Loju Oloye Lai Mohammed to jẹ minista fun ifitonileti ati àṣa ni Naijiria, to tun jẹ eekan lẹgbẹ oṣelu APC APC fojú di PDP ni èsì ìdìbò ṣe wọ́ l’Ọsun àràbà APC gbọdọ lọ tun ara mú ni.
Àwọn mii da ẹ̀bi náà ru Ọgbẹni Arẹgbeṣọla pe àìsan owó oṣù lo jẹ ki àwọn ara Ọṣun dibo bẹ́ẹ̀. Tunde lori ikanni rẹ ni @gbosa ni:
Ọpọ gba pé ẹ̀kọ́ nla nidibo Ọṣun yii jẹ fún àwọn èèyàn Naijiria, eyi to fihan pe, idagbasoke ti n ba ètò ìdìbò wa. Amos Cole ni @amosiano ni
Ohun to kọju si ẹnikan kọ ẹyin si ẹlomii bi ìlù gángan, awọn miran gbagbọ pe èsi yii fi òótọ́ inú Buhari hàn pé ọwọ PDP kò mọ́. Amedo lori @amedoreports ni
Ohun to wa ninu iwe ofin Naijiria ni pé, ẹni to ba jawe olubori ninu idibo gbọdọ ni ida kan ninu mẹrin ninu ibo naa ati ida meji ninu mẹta apapọ ijọba ibilẹ ti wọn ti dibo na ninu ipinlẹ, iyẹn, ó kere tán.
Awọn mii gba pe èsì yii fihan pe kò si ẹni ti wọn kò le bori ninu idibo. Omowe Chima ni @amadichima pe akiyesi aarẹ Buhari si koko yii
A gbọ́ ti ẹran ejò, se ẹ ti mu ọtí wáìnì ejò rí?
INEC ni idibo mii yoo wa ni ibudo idibo meje ti wọn wọgile ibo wọn laarin àwọn oludije mejeeji to sunmọ ara wọn julọ.
Ọlọ́jọ́ Festival 2018: Ayẹyẹ ọdún Ọlọ́jọ́ ti Ilẹ Ifẹ̀ á parí pẹ̀lú àyájọ́ òmìnira Nàìjíríà
Oríṣun àwòrán, AFP
Kabiesi, ki ade pẹ lori O
Ọjọ́ Iṣegun, ọjọ́ kejidinlogun, oṣu kẹsan an ni ayẹyẹ ọdun Ọlọ́jọ́ ti 2018 bẹ̀rẹ̀ pẹ̀lú ayẹyẹ àṣà Gbajure.
Ọdun Ọlọ́jọ́ ṣe pataki si gbogbo ọmọ Yorùbá paapaa àwọn to wa lati Ile Ifẹ to jẹ orisun.
Arole Oodua to jẹ Ọọni ti Ifẹ iyẹn Oba Adeyeye Ẹnitan Ogunwusi, Ọjaja II nipaseẹ ile iṣẹ aranilọwọ rẹ̀ ti kii ṣe tijọba, iyẹn, Hopes Alive Initiatives (HAI) ti nawọ iranlọwọ si awọn Aṣatipo ti ogun Boko Haram le nile ni agbegbe Wasa nilu Abuja.
Oríṣun àwòrán, @Olafaremoses
Inu àwọn ọdọ dun nibudo Aṣatipo Wasa
Wọn pin ounjẹ loriṣiiriṣi, egbogi oyinbo, awọn irinṣẹ fun ọgbin ati awọn ohun eelo eré idalaraya bii àwọ̀n bọọlu alafẹsẹgba, aṣọ wiwọ fun ere idaraya fawọn aṣatipo nibudo naa.
Arabinrin Temitọpẹ Adeṣegun to jẹ igbakeji oludari ajọ HAI lo sọrọ fun Ọọnirisa to wọ ìléèdí ọlọjọ meje fun tọdun 2018.
O ni Ọba Ogunwusi nifẹ awọn aṣatipo naa ni ko ṣe ṣalai ranti wọn ninu ileedi to wa fun ayẹyẹ ọdun ọlọjọ lasiko yii. Bakan naa ni Asoya ti Ile Isoya, Oba Muraina Adedini mẹnuba awọn iṣe akanṣe ti Ọọni n ṣe fawon to ku diẹ kaato fun lawujọ.
Oríṣun àwòrán, @Olafaremoses
Ere idaraya ko yọ agba silẹ nibudo awọn Aṣatipo
Awọn ajọ aranilowo miran bii  Development Support International(DSI)  to jẹ awọn oniṣegun oyinbo naa wa si ibudo aṣatipo Wasa lati wa ṣeto ilera fawọn to wa ni ibudo naa.
Eto n lọ ni pẹruwu bẹẹni imurasilẹ ti lọ loriṣii fun ọdun Ọlọjọ eleyi ti Ọọ̀ni ti ilé Ifẹ, Ọba Adeyẹye Ogunwusi, Ọjájá kejì yoo ṣe agbatẹru rẹ.
Ẹwẹ, Ọọ̀ni ti wọ 'léédì ọlọ́jọ́ méje láti ṣíde ayẹyẹ ọdún Ọlọ́jọ́ ti ọdun 2018.
Ọọ̀ni ti Ifẹ déjú mọ́lé fún ọjọ́ méje
Ìsélé yìí bẹ̀rẹ̀ ní alẹ́ ọjọ́ àìkú lẹ́yìn tí ìrètí wà pé Ọọ̀ni tó jẹ́ àrólé Oduduwa yóò fara hàn ní gbangba pẹ̀lú adé ìṣẹ̀mbáyé tó jẹ́ wí pé ẹ̀ẹ̀kan lọ́dún ló máa ń dé e.
Ìtàgé ti tò fún ọdún ọlọ́jọ́ 2018
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ sí:
Iriwisi àwọn ará ìlú ṣe ọtọtọ lórí èsì ìdìbò Osun
Kó tó bẹ̀rẹ̀ ìsélé, Ọọ̀ni ti ṣe àbẹ̀wò sí ojúbọ 'Ilemọle' ní ìlú Moore láti ṣìpẹ̀ kò tó lọ ṣe 'ra rl mọ́lé níbi tí ojú òun àti ẹ̀dá alàyè kankan kò ní gáání ara wọn títí dí ọjọ́ ẹtì.
Ọba aládé yìí sọ pé òun yóò lo ọjọ́ méje yìí gẹ́gẹ́ bí ànfàní láti bá elédùmarè, àwọn irúmọlẹ̀ àtàwọn igba irúmọlẹ̀ sọ̀rọ̀ fún ìlú, ìpínlẹ̀ àti orílẹ̀èdè Nàìjíríà lápapọ̀ fún ìgbà ọ̀tun.
Oríṣun àwòrán, @Ọọniadimulaifẹ
Ọọ̀ni ti Ifẹ déjú mọ́lé fún ọjọ́ méje
Ọba Ogunwusi kí àwọn ará ìpínlẹ̀ Ọṣun kú oríire bí wọ́n ṣe hùwà dáradára sáájú, lákòókò àti lẹ́yìn ìdìbò tí wọ́n sì dúró lórí ṣíṣe ohun tó tọ́.
Ó kan sárá sí àwọn olùdìbò pàápàá àwọn ọ̀dọ́ pé wọn kò gbà kí wọ́n fi wọ́n ṣe jàndùkú sùgbọ́n tí wọ́n gba àláfíà láàyè lásìkò ìdìbò gómìnà tó kọjá.
'Lọ́gán tí mo bá di ààrẹ, mo máa bẹ̀rẹ̀ iṣẹ́'
FIBA World Cup: D'Tigress tún fakọyọ lẹ́yìn tí wọ́n na Argentina
Oríṣun àwòrán, @DTigressNG
Ikọ̀ D'Tigress fàgbà han Argentina
Ikọ agbabọọlu afọwọgba ti obirin Niajiria ti orukọ wọn njẹ D'Tigress tun ti fakọyọ ninu ife ẹyẹ agbaye to n lọ lọwọ lorilẹede Spain lẹyin ti wọn fagba han ikọ Argentina ayo marundinlọgọrin si aadọrin(75-70) ninu ifẹṣẹwọnsẹ keji wọn ninu idije naa.
Ẹ o ranti pe D'Tigress jẹwọ ara wọn nigba ti wọn lu ikọ orilẹede Turkey ni alubami ninu ifẹsẹwọnsẹ akọkọ wọn.
Ifẹsẹwọnsẹ naa koko bi oju ẹja bi awọn ikọ Naijiria ati Argentina ti n yi ara wọn sọtun sosi.
Àwọn ìròyìn mìíràn tí ẹ lè nífẹ̀ sí:
Adeleke fọhùn, 'èmi ni gómìnà tí wọ́n dìbò yàn'
Ikọ D'Tigress ni agbabọọlu afọwọgba akọkọ bayii ti wọn yoo jawe olubori ninu ifẹsẹwọnsẹ meji ti wọn kọ gba ninu idije ife ẹyẹ agbaye.
Ẹwẹ, D'Tigress ti sọ Argentina dero ile lẹyin iya ti wọn fi jẹwọn.
Ikọ D'Tigress yoo koju orilẹede Greece bayii ni iplele kọmẹsẹọyọ ẹlẹni mẹjọ(quarter finals).
Ọpọlọpọ lo ti n ranṣẹ ikini ku oririre si awọn ọmọbinrin Naijiria yii ti wọn fakọyọ, koda ajọ to n ri si ere bọọlu afẹsẹgba lorilẹede Naijiria gan NFF ko gbẹyin.
Bakannaa ni ọgọrọ eeyan fi idunu wọn han loju opo twitter nibi ti wọn ti n ki D'Tigress ni mẹsan mẹwaa.
Ṣugbọn ọpọ ọmọ Naijria ni ko mọ nipa aṣeyọri awọn aramọda obinrin wọn yii.
Orukọ awọn mejila ti wọn ko lọ idije naa ni: Jasmine Nwajei,  Adaora Elonu, Sarah Imovbioh, Sarah Ogoke, Elo Edema, Nkechi Akashili, Evelyn Akhator, Aisha Mohammed, Ezinne Kalu, Atonye Nyingifa, Cecilia Okoye ati Promise Amukamara
Oríṣun àwòrán, @phatill
Fun anfani awọn ti ko mọ bii idije naa ṣe waye, awọn oun to ṣẹlẹ nigba idije naa ree.
Akọnimọọgba D'Tigress Otis Hughley ree nibi to ti n ṣe aṣepari iṣẹ lori igbaradi awọn ikọ obinrin naa fun idije naa.
Oríṣun àwòrán, @nbbfonline.com
Otis Hugbley sọ fun awọn agbabọọlu naa pe, dandan ni, wọn gbudọ fagba han
OsunElectionResult2018: Báwọn kan se faramọ́ ìlànà ìdìbò náà, làwọn míì takòó
Eto idibo gomina nipinlẹ Ọsun ti waye, to si ti lọ bayii pẹlu atundi ibo to tẹle, eyi to wa sopin lọjọbọ.
Ninu esi ibo naa ni oludije fun ipo gomina labẹ ẹgbẹ oselu APC, Alahaji Adegboyega Oyetọla ti fi ẹyin alatako rẹ latinu ẹgbẹ oselu PDP, Sẹnetọ Ademọla Adeleke janlẹ pẹlu atundi ibo to waye naa.
Amọ onirruuru ero awọn ọmọ ilẹ yii lo se ọtọọtọ lori eto idibo naa, paapa nitori awọn ẹsun iwa jagidi-jagan, ọyaju, idunkooko mọni ati itabuku ẹni ti wọn lo waye lasiko atundi ibo naa.
Ọlọ́jọ́ festival 2018: Láwàní (ọ̀já) ni máa kọ́ka wé kí n tó jẹ Ọọni nítórí Oodua ló nií
Lawọn oju opo ikansira ẹni bii Twitter ati Facebook, bawọn eeyan kan se n ki ajọ Inec atawọn agbofinro pe wọn fakọyọ, naa ni awọn eeyan kan n yọ suti ete si wọn.
Loju opo Twitter, @fkeyamo, to jẹ ti Festus Keyamo ni to ba jẹ pe lootọ ni eru ibo waye, esi ibo ti oludije APC ati PDP ni ko ni sunmọ ara wọn pẹki-pẹki, nse ni ẹni to ba fẹ se mago-mago ibo yoo yi ibo to pọ sọdọ ara rẹ.
Njoku Machi @MachiNjoku ni esi ibo gomina nipinlẹ Ọsun yii ni yoo sọ fun awujọ agbaye nipa eto iselu ijọba alagbada taa n se ni Nigeria.
Kayọde Ogundamisi, @ogundamisi, lero tiẹ ni, to ba di igba miran, ẹlo ọpọ akoko si lati polongo ibo, se aato, dipo kẹ maa tan iroyin ti ko jẹ ojulowo kiri.
Ben Murray Bruce, @benmurraybruce sọ ntiẹ wipe ole ojuaye lo waye nipinlẹ Ọsun.
Ajọ eleto idibo ilẹ wa, Inec wa n kọminu n tiẹ lori abajade eto itọpinpin atundi ibo Ọsun.
@inecnigeria, Inec ni o ya wọn lẹnu pe wọn mu awọn olutọpinpin ibo kan lawọn agọ idibo, tawọn yoo si sewadi rẹ.
Wayi o, ileesẹ ọlọpa orilẹede Naijiria ti ṣe alaye ọrọ wipe ko ni si anfani fun ẹnikẹni lati tasẹ agẹrẹ si ofin ninu atundi ibo si ipo gomina ti yoo waye l'Ọjọbọ.Igbakeji ọga agba ajọ ọlọpa, Habila Joshak lo fi ọrọ naa lede l'Ọjọru nibi ipade awọn oniroyin to waye ni olu ile iṣẹ ajọ ọlọpa tokalẹ si ilu Ọṣogbo.O ni iroyin ti o n to ajọ naa lọwọ ni wipe awọn janduku kan ti n gbero lati da atundi ibo naa iru, sugbọn ẹnikẹni ti o ba da iru aṣọ bẹẹ ṣoro yoo jẹ iyan rẹ niṣu.
APC ni Omiṣore bá lọ fún àtúndì ìbò Ọṣun
Fatai Diekola wa niílé ìwòsàn báyìí
Iriwisi àwọn ará ìlú ṣe ọtọtọ lórí èsì ìdìbò Osun
"Joshak fi kun ọrọ rẹ wipe ajọ naa yoo gbena woju ẹnikẹni ti o ba n fi ẹsẹ gbalẹ kiri lai ni ohunkohun ṣe ni awọn ibudo ti idibo yoo ti waye.""Gẹgẹ bii ile iṣẹ agbofinro, ajọ ọlọpa ko ni fi aye gba ẹnikẹni lati tapa si ofin.  Ao jọ gbena woju ara wa ni pẹlu ẹnikẹni ti o ba gbero lati da eto iṣejọba awara ru. Ajọ ọlọpa ko ni tẹti ninu ojuṣe rẹ lati ṣe afihan gbogbo awọn ọta ilọsiwaju. A keesi awọn oludibo lati pa ofin mọ, ki wọn si ṣe ojuṣe wọn lai si ibẹru.""Igbakeji ọga gba ajọ ọlọpa fi kun ọrọ rẹ wipe aabo to peye wa fun gbogbo ẹni ti o ba pa ofin mọ ninu atundi ibo ti yoo waye lọjọbọ, pẹlu alaye wipe ajọ ọlọpa ati awọn ẹṣọ aabo to ku ni yoo jọ ṣiṣẹ pọ fun eto aabo to fi ẹsẹ mulẹ."
O tẹsiwaju wipe awọn oludibo to ni kaadi wọn lọwọ ati awọn oṣiṣẹ to n ṣe akoso eto idibo nikan ni yoo lanfani si awọn idubo ti atundi ibo yoo ti waye.
Oríṣun àwòrán, CDD
Joshak parọwa si awọn eeyan ipinlẹ Ọṣun lati ma daṣọ ro ẹnikẹni ti o ba gbero lati ṣe ohun aito, boya nipa rira ibo ni, tabi ihuwa ipanle.
Dipo bẹẹ, o ni ki wọn kesi awọn agbofinro lọgan ti wọn ba ti kẹẹfin awọn aṣebaje. Atundi ibo si ipo gomina ipinlẹ Ọṣun yoo waye lọjọbọ ni awọn ibudo idibo meje to wa ni ijọba ibilẹ mẹrin ọtọọtọ ti awọn kudiẹkudiẹ ti waye lẹhin ibo ọjọ kejilelogun oṣu kẹẹsan ọdun yi.
Ijọba Ilẹ Gẹẹsi, orilẹede Amerika ati European Union ti rọ awọn oludibo Oṣun lati ri pe ko si jagidijagan, ẹru ati ibo rira ni atundi ibo ti yoo waye ni Ọjọbọ ọsẹ yii ni ibudo idibo meje ni Ipinlẹ Osun.
Awọn ileeṣẹ to n ṣoju ijọba Ilẹ Gẹẹsi, orilẹede Amerika ati European Union lo jumọ gbe atẹjade kan sita ni ọjọ Iṣẹgun ninu eyi ti wọn ti gboriyin fun awọn ara Osun fun didi ibo ni alaafia.
Wọn si tun gb'oṣuba fun ajọ INEC ati awọn oṣiṣẹ aabo, nitori pe idagbasoke ti ba bi wọn ṣe n ṣeto idibo.
"Atẹjade naa sọ pe, ""A n rọ gbogbo eniyan lati rii pe eto idibo naa pari ni irọwọ-rọsẹ, bi INEC ṣe n ṣeto lati ṣe atundi ni awọn ibudo idibo meje, nibi ti awọn kan ko ti raye dibo ni Satide to lọ bo tilẹ jẹ pe ki i ṣe ẹbi wọn."
Ẹnikẹni to ba jawe olubori ni Ọjọbo gbọdọ ṣe oun to tọ, bẹẹ naa ni ẹni to ba fidi rẹ mi gbọdọ ṣe bi o ti tọ.
Ọṣun Decides: ADC, ADP, APC àti SDP soju abẹ níkòó lórí ìwà ìbàjẹ́
BBC World News Komla Dumor award 2018: Waihiga Mwaura ló fakọyọ
Waihiga Mwaura ti Kenya gba àmì ẹ̀yẹ Komlar Dumor
Akọ̀ròyìn tó tún jẹ́ atọ́kùn ètò lórí ẹ̀rọ móhùnmáwòrán ní orílẹ̀èdè Kenya Waihiga Mwaura ti gbégbá orókè nínú ìfigagbága láti gba àmì ẹ̀yẹ̀ BBC World News Komla Dumor award ti ọdún 2018.
Arákùnrin náà ló ń ṣe atọ́kùn ìròyìn ìrọ̀lẹ́ èyí tó gbayì jù lórí ẹ̀rọ̀ móhùmáwòrán Kenya, Citizen TV.
Lára àwọn mùdùǹmúdùn àmì ẹ̀yẹ náà, yóò lo oṣù mẹ́ta ní ilé iṣẹ́ BBC London yóò sì tún pada sí ilẹ̀ Áfíríkà láti gbé ìròyìǹ kan síta níbẹ̀.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ sí:
Omiṣore gba Fayẹmi l'álejò ṣáájú àtúndì ìbò Ọṣun
‘Wọ́n fẹ́ yí ìbò mi bíi ti June 12'
Wọ́n ṣe àgbékalẹ̀ àmì ẹ̀yẹ yìí láti yẹ́ Komlar Dumor tó jẹ́ atọ́kùn pẹ̀lú ilé iṣẹ́ BBC World News sí sùgbọ́n ṣàà dédé ló kú lọ́dún 2014 lọ́mọ ọdún mọ́kànlélógójì.
Ajáwé olúborí yìí ni ẹni ìkẹẹ̀rin tí yóò gba àmì ẹ̀yẹ́ náà lẹ́yìn tí Nancy Kacungira ọmọ oríllèdè Uganda gbà a ní ọdún 2015 lẹ́yìn náà ni àwọn ọmọ Nàìjíríà méjì Didi Akinyulere àti Amina Yuguda gba àmì ẹ̀yẹ náà.
Ajáwé olúborí náà jẹ́ mọ̀lúmọ̀ọ́ka oníròyìn tí wọ́n sí máà ń ṣí fílà fún ojú rẹ̀ lórí afẹ́fẹ́ jákèjádò Kenya pẹ̀lú àwọn ìròyìn rẹ̀ nípa eré ìdárayá títí dóri òṣèlú.
"Ọ̀pọ̀lọpọ̀ ǹkan ni Komlar Dumor jẹ́ sí mi gẹ́gẹ́ bí oníròyìn àti bí ọlọ́dani. Ó tún sọ wí pé "" bí mo bá le ṣe ìdá mẹ́wàá tàbí ogún ohun tó ṣe nígbà ayé rẹ̀, n gó ti ṣe ipa tèmi nínú iṣẹ́ ìròyìn."
Gẹ́gẹ́ bí ọmọ ilẹ̀ adúláwọ̀, mó ní ìyangàn ànfàní tí mo ní láti lè sọ ìtan Áfíríkà fún àwọn ènìyàn káàkiri àgbáyé.
Arákùnrin yìí mú orí àwọn adájọ́ ìdíje wú pẹ̀lú bí ó ṣe máa ń sọ ìròyìn rẹ̀ àti bí ó ṣe máa ń fi ara rẹ̀ hàn lórí afẹ́fẹ́.
Àwọn adájọ́ ìdíje ní ìjẹlọ́kàn rẹ̀ láti gbé ohùn Áfíríkà àti ọ̀nà ìṣèwádìí rẹ̀ ló mú u tayọ àwọn olùdíje tó kù.
Wòlíì Àgbà ní àwàdà òun, ọwọ ọlọ́run ló ti ń wà
NLC: Ẹgbẹ́ òṣìṣẹ́ so ìyanṣẹ́lódì rọ̀
Ẹgbẹ́ òṣìṣẹ́ so ìyanṣẹ́lódì rọ̀
Ẹgbẹ́ òṣìṣẹ́ orílè-èdè Nàìjíríà ti so Ìyanṣẹ́lódì ti wọn gùn le rọ lọjọ Aiku.
Iroyin to tẹ wa lọwọ sọ pe ẹgbẹ́ òṣìṣẹ́ gba lati so iyanṣẹ́lódì naa rọ lẹyin ti ijọba apapọ kọ iwe ranṣẹ si wọn pe ohun ṣetan lati bẹrẹ ijiroro pẹlu ẹgbẹ naa lori ẹkun owo to kere julọ fun oṣiṣẹ.
Ijiroro naa yoo waye lọjọ kẹrin ati ọjọ karun un oṣu kẹwa.
Ṣáàjú ni ẹgbẹ́ òṣìṣẹ́ l'órílẹ̀-èdè Nàìjíríà lawọ́n yóò gùnlé ìyànṣẹ́lódì tí kò ní gbèdéke ìgbà tí yóò parí pẹ̀lú bí wọ́n ti ṣe ti ẹsẹ̀ bọ ṣòkòtò kan nàá pẹ̀lú ìjọba àpapọ̀ lórí àfikún owó oṣù wọn.
Igun kejì ẹgbẹ́ òṣìṣẹ́, Trade Union Congress lo kọkọ kéde pé òwúrọ̀ ọjọ́ kẹtàdínlọ́gbọ̀n, oṣù Kẹsàn án ni ìyanṣẹ́lódì nàá yóò bẹ̀rẹ̀ lẹ́yìn tí ìjọba apápọ̀ kùnà láti tún ìpáde ìjíròrò lórí ẹ̀kúnwó nàá ṣe ṣáàjú gbèdéke tí wọ́n fun un.
Àwọn òsìsẹ́ gbélé wọn
Ẹwẹ, akoroyin wa to wa ni ipinlẹ Rivers jabọ wi pe digbi ni wọn ti ile isẹ ijọba ati ile ise idajọ to fi mọ awọn ile ifowopamọ nilu naa.
Nilu Ilorin nise ni awọn ọmọ ẹgbẹ osise duro wamuwamu lati ri wi pe ko si ẹni to sisẹ lawọn ile isẹ ijọba ti wọn si rọ awọn osisẹ lati tele asẹ iyansẹlodi naa.
Ìsinmi bẹ̀ẹ̀rẹ̀
Akọ̀wé ẹgbẹ́ TUC, Musa-Lawal Ozigi, sọ fún BBC pé ọ̀sẹ̀ méjì ni àwọn fún ìjọba láti ṣe ìpàdé tí wọ́n dádúró.
Ó sọ pé ọdún 2017 ni ìjọba gbé ìgbìmọ̀ kan kalẹ̀ láti jíròrò lórí owó oṣù tuntun tí àwọn òṣìṣẹ́ n bèérè fún. Ṣùgbọ́n, ó ku díẹ̀ kí iṣẹ́ parí ni Mínísítà fún ọ̀rọ̀ àwọn òṣìṣẹ́, Chris Ngige, dá gbogbo ètò dúró.
Ó ní ''ìrètí gbogbo òṣìṣẹ́ ni pé oṣù Kẹsàn án, ọdún 2018 ni wọn yóò bẹ̀rẹ̀ sí ì gba owó oṣù tuntun, ṣùgbọ́n tí ìjọba kọ̀ láti ṣe àsẹparí iṣẹ́ lórí ọ̀rọ̀ nàá. Èyí ló sì mú kí á pinnu láti bẹ̀rẹ̀ ìyanṣẹ́lódì.
Oríṣun àwòrán, NLC
Ozigi ní ìgbà tí ìjọba bá tó ṣe ohun tó yẹ kó ṣe ni àwọn yóò tó fi òpin sí ìyanṣẹ́lódì nàá.
Bákan nàá ló késí gbogbo aráàlú pé ''kí wọ́n ra oúnjẹ púpọ̀ sílé, àti pé kí ó yé wọn pé ìrọ̀rùn gbogbo ènìyàn ni ẹgbẹ́ TUC n jà fún.
Ọṣọba ké gbàjarè lórí ẹ̀rọ ayàwòrán òfúrufú ?
Agbẹnisọ Osoba ni oun mọ daju pe oun to n ṣẹlẹ ninu ile Osoba ni wọn fi ẹrọ naa wo.
Gomina Ipinlẹ Ogun nigba kan ri, Oloye Olusegun Osoba ti ke gbajare lori bi ẹrọ ayaworan oju ofurufu kan ṣe wọnu ile rẹ ni Abeokuta. Eniyan meji ni ọwọ ti tẹ lori iṣẹlẹ naa.
Atẹjade kan lati ọwọ oluranlọwọ rẹ, Adekunle Adeyemi, ni Osoba ti pe fun iwadi lori iṣẹlẹ naa lẹyin ti wọn fa awọn afurasi meji naa le awọn agbofinro lọwọ.
Atẹjade naa fi han pe Oṣoba gbagbọ pe iṣẹlẹ naa ni ṣe pẹlu oṣẹlu. Ṣugbọn agbẹnusọ fun ileeṣẹ ọlọpaa Ipinlẹ Ogun Abimbola Oyeyemi ni oun ko tii nipa iṣẹlẹ naa. O ni oṣeeṣe ko ma jẹ ọlọpaa ni wọn fa awọn afẹsunkan naa le lọwọ.
Iroyin sọ pe awọn oṣiṣẹ aabo to wa nile Osoba lo ja ẹrọ ayaworan naa bọlẹ loju ofurufu. Adeyemi sọ pe nigba ti wọn mu awọn afurasi meji naa, wọn ko le ṣalaye ara wọn. Ṣugbọn o ni oun mọ daju pe oun to n ṣẹlẹ ninu ile Osoba ni wọn fi ẹrọ naa wo.
O fi kun wipe ipenija nla ni iṣẹlẹ naa jẹ fun aabo oloṣelu naa.
Ni orilẹede Naijiria, lilo ẹrọ ayaworan oju ofurufu (drone) ni agbegbe ti awọn eniyan n gbe lodi so fin ati pe. Ajo to n ṣe akoso ọkọ oju ofurufu (NCAA) naa ni o n ṣe akoso ẹrọ ti wọn fi n ya awọran ofurufu. Ajọ naa ti ṣofin wipe, ẹnikẹni to ba fẹ lo ẹrọ naa gbọdọ gba iyonda.
Osun Election Results 2018: Àwọn olùdìbò tú jáde fún àtúndì ìbò
Sẹgun Agbaje: Àwọn agbófinrò yóò dá sẹ̀ríà fún ẹni tó bá ṣèṣèkuṣe
Àtúndì ìbò Ọṣun gbérasọ
Ní ǹkan bí agogo mẹ́jọ kọjá ìṣẹ́jú márùn ún òwúrọ̀ yìí ni àtùndì ìbò ìpínlẹ̀ Ọṣun bẹ̀rẹ̀ ní wọ́ọ̀dù káàrún, ibìdó ìdìbò kẹ́tàdínlógún ti ìjọba ìbílẹ̀ Oṣogbo.
Àtúndì ìbò Ọṣun gbérasọ
Àjímúna ni àwọn ará ìpínlẹ̀ Ọṣun fi ọ̀rọ̀ àtúndi ìbò fún ìpò gómìnà ṣe.
Awọn oludibo ti tu jade ni ward 5, unit 17 ijọba ibilẹ Ọṣogbo. Awọn to ni kaadi idibo lọwọ n ṣe ayẹwo orukọ wọn, bẹẹ sini awọn agbofinro duro wamuwamu lati ṣe amojuto atundi ibo naa.
Ní ìjọba ìbílẹ̀ Oṣogbo ìye àwọ́n olùdìbò tó forúkọ sílẹ̀ ni 884 sùgbọ́n iyé káàdì tí àwọn olùdìbò gbà ni 677.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ sí:
Adeleke fọhùn, 'èmi ni gómìnà tí wọ́n dìbò yàn'
Òṣìṣẹ́ INEC
Ṣáájú, àwọn ará ìpínlẹ̀ Ọṣun ti ní ìbò àwọn dá àwọn lójú.
Awọn alatilẹyin ẹgbẹ oṣelu PDP korajọpọ si iwaju olu ile iṣẹ ajọ eleto idibo nilu Oṣogbo lati fi ẹhonu han tako abajade eto idibo si ipo gomina to waye lọjọ Satide.
Niṣe ni ariwo n sọ lọtunlosi wi pe awọn ko fẹ atundi ibo. Ọkan o jọkan patako ajuwe si ni wọn ko lọwọ lati fi ẹhonu tako ikede ajo INEC.
Àwọn olùdìbò
Iriwisi àwọn ará ìlú ṣe ọtọtọ lórí èsì ìdìbò Osun
Osun rerun election: ''Olè jíjà tó tìí lágbara ni àtúndì ìbò tòní-PDP
Ohun gbogbo ti ṣetan, onikaluku n duro de èsì ìdìbò O'sun
Alága ẹgbẹ́ òṣèlú Peoples Democratic Party, PDP ní ìpínlẹ̀ Ọṣun, Sọji Adagunodo, ti ṣàpéjúwe àtúndì ìbò gómìnà tó wáyé l'Ọṣun gẹ́gẹ́ bi àjálù nla fún ètò ìṣèjọba àwa-ara-wa àti olè jíjà tó tìí lágbara jù ní ẹ̀kun Ìwọ̀ oòrùn Gúùsù Nàìjíríà.
Eyi ni ibudo ti wọn ti n ka ibo Ọṣun lọwọ
Adagunodo fi ẹ̀sùn kan ẹgbẹ́ òṣèlú All Progressives Congress, APC, pé wọ́n ṣe màgò-mágó nínú àtúndì ìbò tó wáyé ọ̀hún.
Ó sọ pé ''àwọn jàndùkú ẹgbẹ́ APC kò jẹ́ kí àwọn ènìyàn ìjọba ìbílẹ̀ Ọrọlu, Ifẹ North ati Ifẹ South, dìbò.
Lára àwọn ẹ̀sùn tó tọ̀ka sí ni:
Àwọn èékàn nínú ẹgbẹ́ PDP bí Sẹ́nétọ̀ Ben Murray-Bruce àti alukoro ẹgbẹ́ PDP, Kọla Ọlọgbọndiyan nàá ti bú ẹnu ẹ̀tẹ́ lu àtúndì ìbò nàá.
Adagunodo sọ pé ó dun òun bí àtúndì ìbò tí INEC gbékalẹ̀ ní àwọn ibùdó ìdìbò méje ní màgò-mágó nínú.
Nítorí èyí ló ṣe sọ pé òun kò ní gba èsì 'ìdìbò awúrúju nàá, tó sì gba àwọn aláṣẹ INEC ní ìmọ̀ràn láti dáwọ́ kíka ìbò nàá dúró.
Iriwisi àwọn ará ìlú ṣe ọtọtọ lórí èsì ìdìbò Osun
NEMA: Ǹkan méje ló ń fa omíyale ní orílẹ̀-èdè Nàìjíríà
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ipinle Niger, Kogi, Anambra ati Delta lo faragba julo.
Ọdọọdun ni òjò arọọda maa n waye ni orilẹ-ede Naijiria, ti ọpọlọpọ ile to wa leti omi si ma n faragba ninu isẹlẹ omiyale.
Ni ọdun 2019 yii, awọn eniyan to ti papoda ninu isẹlẹ omiyale to igba eniyan, ti ọgọọrọ si ti di alairile gbe.
Ajọ to n risi ọrọ ìsẹlẹ pajawiri ni Naijiria, NEMA, ni o ṣeeṣe ki iye awọn to faragba ninu isẹlẹ naa ti peleke sii pẹlu bi wọn ṣe kede ipinlẹ Niger, Kogi, Anambra ati Delta gẹgẹ bi ipinlẹ to faragba julo.
Orilẹ-ede Naijiria lo ni odo meji to tobi julọ ni agbaye. River Niger to wa ni Iwọ-oorun ariwa ati River Benue tó n ṣan wa lati Ila oorun Cameroon.
Ajọ to n risi wiwo oju ọjọ, NIMET sọ pe ojo arọọrọda ọdọọdun maa n fa omiyale, agbara ya sọọbu.
Nkan miran to tun n fa omiyale ni isoro awọn adagun odo dáàmù pẹlu bi ojo arọọrọda se n jẹki awọn adagun odo to n mu ina ijọba wa fun awọn eniyan bii Kainji, Jebba ati Shiroro ru soke.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Kainji dam
Bi awọn eniyan ṣe n kọ ile si oju omi naa jẹ ọkan lara awọn ohun to n fa ijamba omiyale nitori oju omi ko fẹ to lati jẹ ki omi raye kọja.
Ilu Lokoja jẹ ọkan lara awọn agbegbe to n lugbadi omiyale nitori aarin gbungun ọdọ River Benue ati Niger lo wa.
Bakan naa ni kikọ ile si awọn agbegbe ti ọdọ wa naa le fa ijamba omiyale ati agbara ya sọọbu.
Awọn elomiran a tun ma a da idoti si oju omi ati panti si oju odo, eyi ti o fa ki odo máa dagun ati ẹkun omi.
Osisẹ Ajọ to n risi ọrọ pajawiri naa, Hussaini Ibrahim, ni bi awọn eniyan se n bẹ igi ni igbo naa n se okunfa omiyale nitori igi maa n gba omi sara, sugbon awọn olugbe orilẹ-ede Naijria ma n bẹ igi ni igbo lati fi dana tabi ta a lati fi ko ile.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Awọn elomiran a tun ma a da idoti si oju omi ati panti si odu odo, eyi ti o fa ki odo o ma dagun ati ẹkun omi.
Ọna abayọ to jẹ gboogi si ọrọ omiyale lorilẹ-ede Naijria ni ki ajo to n risi ile kikọ máa bojuto ọna igbalode ti awọn eniyan n gba fi kọ ile, ki wọn dawọ lati maa ko ile si oju agbara tabi eti odo.
Oríṣun àwòrán, AFP
NEMA: Ǹkan méje ló ń fa omíyale ní orílẹ̀-èdè Nàìjíríà
Bakan naa, ijọba Naijria gbọdọ fọwọsowọpọ pẹlu awọn orilẹ-ede to wa layika wọn, lati le fi aye gba ki omi o lo bi o se yẹ, ki awọn adagunodo maṣe ru soke ju bi o ti yẹ lọ.
Amọ, awọn onimọ nipa oju ọjọ ti wi pe ojo arọọrọda ni se pẹlu bi oju ọjọ se n yipada (climate change).
Painter: Samuel ni ìdàgbàsókè Nàìjíríà ló jẹ òun lógún!
Ìjàmbá Bàálù: Àjọ̀dún òmìnira ilẹ̀ wa ni wọn ń se lọ́wọ́, ni bàálù méjì já
Oríṣun àwòrán, @NigAirForce
Ileesẹ ologun ilẹ wa tun ti fi iroyin miran sita loju opo Twitter rẹ pe, tẹdun-tẹdun ọkan ni oun tun  fi n kede iku ọkan lara awọn awakọ baalu kekere meji tileesẹ ọmọ ogun ofurufu ilẹ wa, to ja laarọ ọjọ Ẹti  nilu Abuja.
Alukoro fun ileesẹ ologun ofurufu ilẹ wa, Ibikunle Daramọla, loju opo Twitter rẹ ni awakọ baalu naa, ti wọn ti saseyọri lati fa yọ ninu ọbaalu to ni ijamba naa, F-7Ni, lo papa jalaisi.
O wa gbadura pe ki Ọlọrun tẹ si afẹfẹ rere.
A ti kọkọ mu iroyin wa fun yin saaju pe, baalu kekere tileesẹ ọmọ ogun ofurufu ilẹ wa naa lo ja ni ilu Abuja, lasiko ti wọn n sàmì ayẹyẹ ominira ọdun kejidinlọgọta ti orilẹ-ede yii.
Akọroyin BBC to wa nibi isẹlẹ naa ni oke Katampe ni Abuja, ni isẹlẹ naa ti waye,
Oríṣun àwòrán, @Artii_M
Ni kete ti baalu kekere naa si ja, lo gba ina, lasiko isẹlẹ naa to waye ni deede aago mọkanla aarọ ọjọ Ẹti.
Ọlọ́jọ́ festival 2018: Láwàní (ọ̀já) ni máa kọ́ka wé kí n tó jẹ Ọọni nítórí Oodua ló nií
Ọkọ ofurufu kekere naa, to n fo pẹlu awọn mẹta miran lo sadede ja lulẹ.
Iroyin naa ni ọkan ninu awọn ologun ọhun, ẹni to lo ohun idaabo loju ofurufu tawọn oloyinbo n pe ni Parachute, lo papa jẹ Ọlọrun nipe.
Awọn ọkọ ofurufu bii mẹta miran la gbọ pe wọn n ra baba loju ọrun nibi ti isẹlẹ naa ti waye.
Oríṣun àwòrán, @Artii_M
Alukoro fun ileesẹ ologun ilẹ wa, Ibikunle Daramọla, to fi idi isẹlẹ naa mulẹ ni, ọkọ ofurufu meji lo ba ijamba naa rin.
Daramọla, ẹni to fidi isẹlẹ naa mulẹ loju opo Twitter ileesẹ ologun ofurufu ilẹ wa ni.
Bẹẹ ba si gbagbe, ileesẹ ologun ofurufu Naijiria lo ti kede saaju pe oun yoo se idanrawo loju ofurufu gẹgẹ bii ara eto to n sami ayẹyẹ ọdun kejidinlọgọta tilẹ wa gba ominira.
Jos crisis: Àwọn òbí n kó ọmọ wọn kúrò ní Unijos
Oríṣun àwòrán, unijos.edu.ng
Akẹ́kọ̀ọ́ kan ti pàdánù ẹ̀mí rẹ̀, wọ́n ṣì ń wá ọ̀kan tí àwọn míì sì fara pa nínú rògbòdìyàn tó wáyé ní fásitì ìjọba tó wà ní ìlú Jos.
Ààrẹ Muhammadu Buhari ti korò ojú sí wàhálà tó wáyé nílùú Jos, olú ìlú ìpínlẹ̀ Plateau.
Nínú ọ̀rọ̀ rẹ̀, Buhari sọ pé ''ó n kọmí lómínuu pé àwọn kan ti fàáyè gba iṣẹ́ ibi láti jọba l'ọ́kàn wọn.
Nínú ikèdé kan tí agbẹnusọ fún Ààrẹ Buhari, Garba Sheu fi síta lórí Twitter ni Buhari ti sọ pé òun mọ̀ pé kò rọrùn láti fi ìdí àláàfíà múlẹ̀, ṣùgbọ́n kò yẹ kí àwọn kan tún da omi àláàfíà ti ìjọba ìpínlẹ̀ nàá ti ṣiṣẹ́ fún rú.
Bákan nàá ló sọ pé ẹ̀tọ́ gbogbo ọmọ Nàìjíríà ni ìdàgbàsókè àti ìgbéayé tó f'ẹsẹ̀ múlẹ̀. Ó wá rawọ́ ẹ̀bẹ̀ sí gbogbo àwọn ìlú tó wà ní olú ìlú ìpínlẹ̀ Plateau, láti gba àláàfíà l'áyè pẹ̀lú àlàyé pé ìbọ̀n tàbí wàhálà kò le yanjú ìkùnsínú kankan, bí kò ṣe títẹ̀lé òfin.
Ní ìtẹ̀síwájú ọ̀rọ̀ rẹ̀, Ààrẹ Buhari ní o ṣeni láànú pé àwọn olóṣèlú kan n gbé ẹlẹ́yàmẹ̀yà àti ọ̀tẹ̀ ẹ̀sìn l'árugẹ fún òkìkí ara wọn.
O ní ìṣàkóso òun yóò tẹ̀síwájú láti maa ṣiṣẹ́ pẹ̀lú àwọn tí ọ̀rọ̀ kàn láti le wá àtúnṣe sí orísun rògbòdìyàn tó n wáyé ní gbogbo ìgbà ní ìpínlẹ̀ Plateau àti àwọn ìbòmìí tí wàhálà ti n wáyé ní Nàìjíríà.
Ní ọjọ́ àìkú tí ìṣẹ̀lẹ̀ náà ṣẹ̀, ọ̀kan lára àwọn akẹ́kọ̀ọ́ fásitì ọ̀hún sọ fún BBC pé àwọn ṣì n gbọ́ ìró ìbọn kíkan-kíkan ní ìwájú ẹnu ọ̀nà tó wọ iléèwè nàá, tí ọ̀pọ̀lọpọ̀ òbí sì ti n yawọ ọgbà iléèwé láti mú ọmọ wọn.
Oríṣun àwòrán, Unijos
Ọ̀pọ̀lọpọ̀ òbí sì ti n yawọ ọgbà iléèwé láti mú ọmọ wọn lọ sílé.
Akẹ́kọ̀ọ́ nàá sọ pé l'ọ́jọ́ Àìkú ni àwọn kan tó wọ aṣọ ológun wọ inú ọgbà iléèwé ọ̀hún, tí wọ́n sì bẹ̀rẹ̀ sí yìnbọn mọ́ àwọn akẹ́kọ̀ọ́, èyí tó padà yọ́rí sí ikú akẹ́kọ̀ọ́ kan tó wà ní ìpele kẹta.
Kí ló kan AS Roma àti ìrẹsì jọ̀lọ́fù?
NLC: Àwọn olósèlú ń la títì láì sanwó osù torí owó tí wọn yóò rí lórí àkànse isẹ́
Akẹ́kọ̀ọ́ nàá tó ní kí BBC fi orúkọ bo òun ní àṣírí sọ pé àwọn aláṣẹ fásitì nàá kò tí pàṣẹ́ kankan fún àwọn akẹ́kọ̀ọ́ lórí ìṣẹ̀lẹ̀ nàá, ṣùgbọ́n àwọn tó kù síléèwè farapamọ́ sí ilégbèé wọn.
Ìṣẹ̀lẹ̀ nàá ti mú kí ọ̀pọ̀ ọmọ Nàìjíríà maa késí ìjọba àti àwọn òṣìṣẹ́ aláàbò lórí ẹ̀rọ ayélujára láti tètè dásí ọ̀rọ̀ nàá.
Nígbà tí BBC kàn sí alukoro iléèṣẹ́ ọlọ́pàá ní ìpínlẹ̀ Plateau, Terna Tyopev, lórí ọ̀rọ̀ nàá, ó sọ pé òun kò ní ohunkóhun láti sọ lórí rẹ.
Ìgbà àkọ́kọ́ kọ́ nìyí tí rògbòdìyàn yóò wáyé ní ìpínlẹ̀ Plateau, nítorí pé ó jẹ́ ọ̀kan lára àwọn ibi tí wàhálà ti n wáyé láàrin àwọn àgbẹ̀ àti daran-daran ní Nàìjíríà.
Wàhálà yìí pọ̀ débi pé Gómìnà ìpínlẹ̀ nàá, Samuel Lalong, p'àṣẹ kónílé ó gbélé láti ìrọ̀lẹ́ di òwúrọ̀ l'ọ́jọ́ kejìdínlọ́gbọ̀n, oṣù Kẹsàn án, ní olú ìlú ìpínlẹ̀ nàá, Jos, lẹ́yìn tí rògbòdìyàn kan mú ẹ̀mí ọ̀pọ̀lọpọ̀ ènìyàn lọ.
Lagos APC Primaries: Gómìnà Ambode gbà pé òun fìdí rẹmi
Oríṣun àwòrán, Ambode
Gómìnà Akinwumi Ambode
Gómìnà Akinwumi Ambode ti ìpínlẹ̀ Eko ti dúpẹ́ lọ́wọ́ àwọn ọmọ ẹgbẹ́ òṣèlú APC fún ìrẹ́pọ̀ wọn láti yan olùdíje wọn.
Ninú ọ̀rọ̀ rẹ̀ tí ó bá gbogbo aráàlú sọ lọ́jọ́rú ọjọ́ kẹta oṣù kẹ́wàá ọdún 2018 ló ti wí fún àwọn ará ìpínlẹ̀ Eko wí pé àkókò ti tó fún ìpínlẹ̀ Eko láti tẹ̀ síwájú.
Ó ní èyí ṣe pàtàkì kí àwọn mùdùnmúdùn àtọdún mẹ́ta àbọ̀ má baà forí ṣánpọ́n.
Oríṣun àwòrán, @jide_sanwoolu
Sanwo-Olu
Ìgbìmọ̀ p'ohùn dà, wọ́n kéde Sanwo-Olu ní APC EkoAlága ìgbìmọ̀ amúṣẹ́yá nínú ẹgbẹ́ òṣèlú APC, Clement Ebris ti kéde Babajide Sanwo-Olu gẹ́gẹ́ bí ẹni tó jáwé olúborí láti dupò gómìnà nínú ẹgbẹ́ òṣèlú APC lọ́dún tó mbọ̀.
Gẹ́gẹ́ bí ọ̀gbẹ́ni Ebris ṣe sọ ọ́, iye ìbò tí Babajide Sanwo-Olu ní ni 970,851 nígbà tí gómìnà Akinwumi Ambode ní ìbò 72,901.
ìdìbò abẹ́lé APC nípinlẹ̀ Eko
Oríṣun àwòrán, @Ambode
Ìgbìmọ̀ amúsẹ́yá fún ẹgbẹ́ APC fagilé ìdìbò abẹ́lé APC
Saaju eyi, igbimọ amusẹya fun ẹgbẹ oselu APC ti fagile idibo abẹle to waye ni ipinlẹ Eko lati yan ẹni ti yoo soju ẹgbẹ APC.
Alaga Ẹgbẹ Igbimo Amuseya (NWC), Ọgbẹni  Clement Ebri nigba to n ba awọn akọroyin sọrọ wi pe awọn sẹsẹ n gbaradi fun idibo abẹlẹ naa ni.
Ebri fikun wi pe awọn fẹ duro de gbogbo awọn ti ọrọ naa kan lati le tẹsiwaju ninu idibo naa.
Alaga naa wa rọ awọn eniyan lati gba alaafia laaye ki idibo ti awọn fẹ se le lọ ni irọwọrọsẹ.
Lagos APC Primaries: Ambode kò dìbò, ìgbákejì rẹ̀ Adebule dìbò fún Sanwoolu
Oríṣun àwòrán, Ambode
Omowe Idiat Adebule to jẹ igbakeji Gómìnà Akinwumi Ambode ti fi atilẹyin han fun alatakò ọga rẹ̀  nínú ìdìbò abẹ́nú ẹgbẹ́ òṣèlú APC, Babatunde Sanwoolu.
Adebulẹ to ba awọn oniroyin sọrọ nibi idibo ni Ward A ati D ni ijọba ibilẹ Iba ni ẹgbẹ ti yan oludije ti wọn fẹ ati wipe oun ni oun yoo ti lẹyin.
Iroyin lati ọwọ ikọ BBC to wa ni Epe Ward A5 ati A6 nibi ti Ambode ti yẹ ko dibo fi han pe kó wá díbò títí tí ibò fi parí.
Nigba ti akọroyin BBC kan si agbẹnusọ Ambode, Lanre Olagunju, o ni gomina ko fẹ sọrọ bayii ṣugbọn yoo gbe atẹjade sita ni wakati ranpẹ.
Awọn olùdìbò ń woye boya gomina Ambode yoo yọju
Ṣáájú, alátakò gómínà náà Babajide Sanwoolu ti dúpẹ́ lọ́wọ́ gbogbo àwọn tó tú jáde láti dìbò fún un.
Ó sọ èyì nínú ìfọ̀rọ̀wánilẹ́nuwò pẹ̀lú akọ̀ròyìn BBC Yorùbá tó wà ní ibùdó ìdìbò rẹ̀ lẹ́yìn tí òun fúnra rẹ̀ dìbò tan.
Ni wọ́ọ́dù ti Sanwoolu ti dibo ni E3, oludije naa ni ibo 4,530 ninu 4,920, ṣugbọn Ambode ko ni ẹyọkan.
Gbágbá ni àwọn ti Sanwoolu wà lẹ́yìn rẹ̀
Òni lònìí ń jẹ́ ẹni a bẹ̀ lọwẹ̀ ló gbòde gẹ́gẹ́ bí ọjọ́ tí wọ́n sún ìdìbò abẹ́nú ẹgbẹ́ òṣèlú APC ìpínlẹ̀ Eko síwájú sí ṣe ti pé.
Láàrin gómìnà tó wà lórí àléfà báyìí, Akinwumi Ambode àti olùdíje fún ìgbà àkọ́kọ́, Babajide Sanwoolu ni ìfigagbága yóò ti wáyé.
Àwọn ti Ambode ń kọrin ìyìn rẹ̀
Báyìí ni ìlànà ìdìbò abẹ́nú ẹgbẹ́ òṣèlú APC l'Eko yóò ṣe lọ
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ sí:
Ambode àti Sanwoolu, ta lẹ ó gbádé fún?
Ọkọ̀ aképo gbiná ní òpópónà Eko sí Badagry
Àjọ́ elétò ìdìbò tí yóò mójútó bí gbogbo ètò náà yóò ṣe lọ ti wà níkàlẹ̀.
Àjọ elétì ìdìbò
Ní ibùdó ìdìbò àwọn méjèèjì yìí, àwọn ọmọ ẹgbẹ́ ti wà níkàlẹ̀ láti dìbò yan ẹni tí wọ́n fẹ́.
Ibùdó tó wà ní St. Stephens Primary School, Adeniji Adele ni Babajide Olusola Sanwoolu yóò ti dìbò.
Ìdìbò abẹ́nú APC bẹ̀rẹ̀ nípinlẹ̀ Eko
Akinwumi Ambode yóò sì dìbò ní Epe Wọ́ọ̀dù A5 àti A6.
Wọ́ọ̀dù Ambode
Ẹ̀wẹ̀, ní Ikeja Wọ́ọ̀dù C, ibùdó ìdìbò kẹta ní Bola Ahmed Tinubu tó jẹ́ Baba ìsàlẹ̀ fún ẹgbẹ́ yóò ti dìbò.
Wọ́ọ̀dù Tinubu
Àwọn amọkòkò kò fẹ́ fi iṣẹ lé ọmọ lọ́wọ́ mọ́
Ìkọlù Plateau: Àwọn agbébọn tún pa ènìyàn mẹ́tàlá ní Plateau
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Eniyan mẹtala lo ti padanu ẹmi wọn lẹyin ti awọn agbebọn kọlu ilu kan ni ijọba ibilẹ Riyom, nipinlẹ Plateau.
Emmanuel Danboyi Jugu, to jẹ alaga igbimọ oludari nijọba ibilẹ naa sọ wi pe eniyan mẹwa ni wọn ti sin, eyi ti ko yọ awọn ọmọde ati obinrin silẹ.
Ikọlu naa waye lẹyin ọjọ diẹ ti ọkan waye ninu ọgba fasiti ilu Jos, nibiti akẹkọ kan ti padanu ẹmi rẹ, ti awọn mi i si farapa.
Ẹ wo àrà tí ẹ le fi gèlè dá láàrín ìṣẹ́jú mẹ́ta
Bakan naa lo jẹ pe ana ni wọn ṣẹṣẹ ri akẹkọ kan ti wọn n wa lati igba ti ikọlu to waye ni ọgbọnjọ, oṣu Kẹsan an ti waye.
Ko ti i ye ẹnikẹni igba ti awọn ikọlu to n waye nipinlẹ Plateau yoo dawọ duro, o si dabi ẹni pe ẹnu awọn alaṣẹ, eleto aabo ati awọn araalu ko kọ lati wa atunse si ohun to n fa awọn ikọluraẹni naa.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ọ̀pọ̀lọpọ̀ ènìyàn ló ti fi ìlú nàá sílẹ̀ nítorí ìkọlù tó n wáyé nígbà gbogbo
Ọgagun Augustine Agundu to ṣoju Ọga agba patapata fun ileeṣẹ ologun Naijiria, Tukur Buratai nibi eto isinku awọn ọmọ ogun mẹta kan ti wọn ṣekupa ni Barkin Ladi, sọ pe o da bi ẹni pe awọn agbaagba niluu naa n lọwọ si bi wahala naa ṣe n pọ si.
Ẹwẹ, agbẹnusọ fun ileeṣẹ ọlọpa nipinlẹ naa, Mathias Terna Tyopev, sọ pe oun ko ti i ni ẹkunrẹrẹ iroyin nipa ikọlu to ṣẹṣẹ waye ni Riyom.
Bakan naa ni Giwa fasiti ilu Jos, Ọjọgbọn Sebastian Maimako sọ pe akata ikọ ọmọ ogun amuṣẹya kan ni wọn ti ri akẹkọ ti wọn n wa ọhun, ti wsn si ti fa a le mọlẹbi rẹ lọwọ.
Obìnrin míràn gbẹ́mi mi torí pé o fẹ́ ki ìdí òun tóbi síi
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ìdí ti kò tẹ́ àwọn obìnrin lọ́rùn ń jẹ́ ki iṣẹ́ abẹ rán wọn sọrun.
Ìdí ti kò tẹ́ àwọn obìnrin lọ́rùn ń jẹ́ ki iṣẹ́ abẹ rán wọn sọrun.
Àjọ àwọn oniṣegun fun iṣẹ abẹ atunṣe agọ ara nilẹ Gẹẹsi, British Association of Aesthetic Plastic Surgeons (Baaps) ti fi ikede sita pẹ ki awọn obinrin ṣọra fun iṣẹ abẹ ikebe nla nitori pe o léwu pupọ.
Wọn ke gbajare yii lẹyin iku ọmọbinrin ilẹ Gẹẹsi kan to lọ ṣe iṣe abẹ naa to si gabẹ re ọrun aremabọ.
'Oúnjẹ ibìkan jẹ́ èèwọ̀ ibòmíì ni ọ̀rọ̀ ọmú ńlá'
Awọn gbajugbaja ilumọọka adanilaraya ni wọn saaba n ṣee ti o fi n di itẹwọgba kaakiri agbaye bayii.
Losu kẹjọ ni Leah Cambridge to jẹ ọmọ Turkey doloogbe lataari iṣẹ abẹ idi ni eyi to dẹmi ọmọ ọdun mọkandinlọgbọn naa legbodo.
Àwa obìnrin tó ń lépa afòjúsùn máa n ba ọkùnrin lẹ́rù ni -Toyin Lawani
Orilẹ-ede Brazil lo ti lọ ṣe iṣe abẹ naa ni eyi ti àwọn dokita gba imọran pe ki wọn ṣọra fún iṣẹ abẹ lọwọ awọn ti kò koju oṣuwọn tó.
Ìṣẹ abẹ ikebe nla ti Brazil (BBL) jẹ ọkan lara awọn ọna ti awọn  obinrin fi n ṣafikun ẹwa ẹya ara  paapaa idi wọn ko lè tobi sii.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ọmọ ilẹ̀ Gẹẹsi gbẹ́mi mi torí pé o fẹ́ ki ìdí òun tóbi síi
Baaps ṣalaye fun Victoria Derbyshire ti BBC pe o keere tan, ẹni kan ninu ẹgbẹrun mẹta lo n ku lagbaye lataari nkan to n tẹyin iṣẹ abẹ naa jade.
Iwadii BBC fihan pé ọmọbinrin Gẹẹsi mii ku latari iṣẹ abẹ naa.
Victoria Derbyshire tún ṣe ìwàdìí pé obìnrin ilẹ̀ gẹ̀ẹ́sì mii tó ku díẹ̀ kó tó ọmọ ọgbọ̀n ọdún naa tun ku ni eyi ti ìwádìí sì ń lọ lọ́wọ́ lórí ohun tó ṣokùnfà ikú rẹ̀.
'Obinrin jẹ amuludun'
Gerard Lambe. to jẹ oniṣegun oyinbo lori atunṣe ẹwà sọ pe ohun ni iṣẹ abẹ to lewu jú, nítorí àwọn àbẹ́rẹ́ tí wọn máà ń lò lati fa ọ̀rá sí inú iṣan tó wà nínú ìkébè a máa rìnrìn àjò lọ sí inú ọkàn tàbí inú ọpọlọ.
Obinrin ilẹ Gẹẹsi kan ni oun ṣe iṣẹ abẹ toun ni Turkey lọdun meji sẹyin nitori pe, o dinwo ni Turkey daadaa.
O ni iṣẹju mẹwaa ṣaaju iṣẹ abẹ naa loun to foju kan dokita to fẹ ṣee fun oun ati pe, oun ṣaisan lẹyin ti oun ṣee tan ki oun to pada lọ si UK fun itọju to peye.
Ms Palmer-Hughes ni o le ni idaji awọn onibara oun ti wọn ti ṣe iṣẹ abẹ ikebe nla yii ni orilẹ-ede bii Turkey, Hungary, Belgium ati Spain.
Gbenga Daniel: Onímọ̀ ọrọ̀ ajé tó dáńtọ́ àti ọ̀dọ́ ni Peter Obi ló se kájúẹ̀
Oríṣun àwòrán, @Demolalanrewaju
Oludari agba feto ipolongo ibo aarẹ fun Atiku Abubakar, Ọtunba Gbenga Daniel, ti salaye ọpọ ohun amuyẹ ti wọn ri lara gomina ipinlẹ Anambra tẹlẹri, Peter Obi, ki wọn to ni oun lo kajuẹ lati ba Atiku dije gẹgẹ bii igbakeji aarẹ ninu eto idibo to n bọ ni 2019.
Gẹgẹ bi Daniel ti wi ninu atẹjade kan to fi sita, ika to ba tọ simu, la fi n re imu, Obi ti jẹ gomina ri, to si tun jẹ́ alaga tẹlẹ fun banki fidelity. Koda, ọdọ to jẹ ọlọpọlọ pipe ni, to si tun ni imọ pipe nipa eto ọrọ aje labẹle ati lagbaye.
O fikun pe, awọn iriri Peter Obi yii ko se fi owo ra, iriri si se agba ohunkohun, irufẹ ọlọpọlọ pipe bayii si ni orilẹ-ede Naijiria nilo niru asiko taa wa yii.
Ìyá àkàndá ẹ̀dá: Àwọn ẹbí mi fẹ́ kí n pa ọmọ mi torí ó jẹ́ àkàndá ẹ̀dá
Atẹjade naa fi kun pe, iyansipo Peter Obi ati ajọsepọ rẹ Atiku Abubakar ti wọn ba de ipo aarẹ, yoo seranwọ lati mu agbega ba eto ọrọ aje wa, irẹpọ ati agbega ba Naijiria lapapọ.
Olùdíje fún ipò aarẹ l'ábẹ́ àsìá ẹgbẹ́ òṣèlú Peoples Democratic Party, PDP, ti yan Peter Obi gẹ̀gẹ̀ bi igbakejì rẹ̀ tí wọn yóò jọ síje dú ipò l'ọ́dún 2019.
Igbákejì alukoro ẹgbẹ́ PDP, Diran Ọdẹyẹmi sọ fun BBC Yoruba pé wọ́n yan Obi tó ti jẹ́ gómìnà rí ní ìpínlẹ̀ Anambra, nítorí pé ọmọ Nàìjíríà tòótọ́ ni, tí kò sí tún dàgbà tàbí kéré jù.
Bákan nàá ni ẹgbẹ́ wo àwọn àṣeyọrí tó ṣe nígbà tó wa ní ipò gómínà, àti láti ìgbà tó ti fi ipò sílẹ̀.
Yíyàn tí a yan Obi kíì ṣe láti fa ojú ẹ̀yà ìgbò mọ́ra, ṣùgbọ́n nítorí pé ẹgbẹ́ wa gbà pé ẹ̀yà kan kò ju òmíràn lọ ní Nàìjíríà.''
Ìyànsípò Peter Obi ti n fa àríyànjiyàn lórí ẹ̀rọ̀ ayélujára.
Bí àwọn kan ṣe n gbóríyìn fún ìgbésẹ̀ tí ẹgbẹ́ òṣèlú PDP gbe, ní àwọn kan ti sọ ọ̀rọ̀ nàá di ẹní bá láyà láàrin ìgbákejì aarẹ Nàìjíríà, Yemi Ọṣinbajo àti Peter Obi, ti olùdíjé fún ipò aarẹ nínú ẹgbẹ́ PDP, Atiku Abubakar, ṣẹ̀ṣẹ̀ yàn.
Àáyáa Atiku Abubakar oludije fún ipò Ààrẹ labẹ àsìá ẹgbẹ́ òṣèlú PDP tí bẹ́ sílẹ̀ ó bẹ́ ááré báyìí.
Lẹyìn ìkéde rẹ gẹ́gẹ́ bí ẹni tí yóò sójú ẹgbẹ́ náà, n'isẹ ní àwọn ọmọ orílèèdè Nàìjíríà n dá aba oríṣi lórí ẹni tí yóò kọwọrin pẹlu rẹ gẹ́gẹ́ bí igbákejì.
Ọrọ náà gbà ìṣirò diẹ nítorípé o lè ṣe atọna tàbí kó jẹ ijakulẹ fún.
Oríṣun àwòrán, FACEBOOK
Ẹgbẹ́ òsèlú onígbaàálẹ̀, APC ti kí Igbákejì Ààrẹ Tẹ́lẹ̀rí, Atiku Abubakar kú oríire pẹ̀lú bí ó se jáwé olùborí nínù ìdìbò sípò Ààrẹ lẹ́gbẹ́ PDP.
Àwọn orúkọ kọọkan ti n jẹ yọ lójú òpó ayelujara ṣùgbọ́n kò tí sí ìkéde kánkan pàtó lórí ìgbésẹ yí.
Ṣáájú kí a tó mọ irú ẹni tí Atiku yóò yan, a ni kí a jijọ ṣe àgbéyẹ̀wò àwọn kókó pàtàkì tí o gbọdọ fi sọkan ki o to le yan ẹ́nikẹni ni  igbákejì rẹ.
Òṣèlú Nàìjíríà ní àwọn ohun tó ya sọto pẹlú tí ibòmíràn.
Nínú àwọn nnkán ti o sí le se atọna tàbí àkóbá fún Atiku Abubakar nípasẹ igbákejì to bá yan ni ẹsin ti ẹni náà bá n tẹlé.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ipa ti ko se fọwọ rọ sẹyin ni ẹsin nko ninu oselu Naijiria
Kò fẹ sí oludije ààrẹ tabi ipo miran ti kí yan igbákejì to bá n ṣẹsin to yàtọ sí ti rẹ ki o ba ma da bí wipe o n gbé lẹyìn ẹsìn kàn.
Fún ìdí èyí,o ṣeéṣe kí atiku mu ẹlẹsin Kristẹni ní igbákejì ààrẹ.
Ọmọ ọdún méjìlelaadọrin ní Atiku Abubakar .
Tí a bá sì wò bí ìpolongo fífún àwọn ọdọ ni ààyè nínú òṣèlú ti ṣe n lọ, òhun tó fẹ dájú ni wí pé,Atiku yóò yan ọdọ gẹgẹ bí igbákejì.
Owó fọ́ọ̀mù APC fún ipò Ààrẹ gọbọi- olùdíje
Pẹlú bí òun náà ti ṣe tẹnu mọ wí pé òun yóò faye gba awon odo ninu ìṣèjọba rẹ, kí ba da ti ọ bá bẹrẹ lórí yíyan igbákejì ọdọ
Nínú ìwé òfin orílèèdè Nàìjíríà, kò sí àkọsílẹ wí pé èèyàn gbọdọ yan igbákejì láti ẹyà kan tabi òmíràn ṣugbọn kò sí olóṣèlú ti yóò yan igbákejì lalai woye ẹyà ti ẹni náà ti wa.
Lọwọlọwọ lorílè-èdè Nàìjíríà, ẹyà Igbo kò fi taratara gba ti ìjọba Buhari pàápàá jùlọ lórí ọrọ atunto ti ọ bi ẹgbẹ bi Massob àti ipe fún ìdásílẹ̀ orílèèdè Biafra.
Idibo ko ni waye ti wọn ko ba mu ọkọ mi jade
Afọjusun òpó èèyàn ni pé Atiku yóò yan igbákejì láti ẹyà Igbo kí o bá lè rí ìyọnu wọn ati ìbò wọn lọdun 2019.
Nínú àwọn tí orúko wọn ti n lédè bayi, o adabi ẹ́ni wi pe púpọ jẹ ẹyà Igbo.
Kí ọkùnrin rí ejò kì obinrin rí ejò... òwe yí gbà ọgbọn láti tù nípa yíyan ẹni tí yóò jẹ igbákejì Atiku.
Tí o bá yan obìnrin gẹgẹ bí igbákejì oun ni yóò jẹ oludije akọkọ to lórúkọ ti yóò ṣe bẹ lagbo òṣèlú Nàìjíríà.
Tí kò bá ṣe bẹ àwọn tó n já fún fífún àwọn obìnrin àti ọdọ ní ayé láti kópa nínú òṣèlú Nàìjíríà yóò bẹnu àtẹ lù.
Ọrọ ba di ọba ran ni niṣẹ,odo ọba ya, iṣẹ ọba ko ṣe kọ, bẹẹ si ni odo ko ṣe kan lu.
Botilewukori, ohun kan tó ṣe kókó ni pé tí yóò bá yan obìnrin,o gbọdọ jẹ obinrin tó jẹ ògúnná gbòngbò nínú òṣèlú tí òun náà sí le wọ èro fún Atiku.
Ẹgbẹ òṣèlú Atiku Abubakar ní ipá nlá láti kó nínú ìgbésẹ yiyan igbákejì fún un.
Ní ọpọ ìgbà,ẹgbẹ a má yan igbákejì lẹyìn àgbéyẹ̀wò àwọn ìṣirò kọọkan gẹgẹ bí ẹni tí ẹgbẹ bá fẹ àti irú anfààní ti ẹni náà yóò mú bá àṣeyọrí nínú ìdìbò.
Nígbà tí ìkọ BBC Yorùbá n ba akọwe ìpolongo fún ẹgbẹ PDP Ọgbẹni Kola Ologbondiyan lori boya ẹgbẹ yóò yan igbákejì fún Atiku,o ni ''àwọn yóò jọ pa imọran pọ ni ti àsìkò ba to.''
Oríṣun àwòrán, Twitter
Aarẹ ana Olusegun Obasanjọ ti sọ tẹlẹ pe oun ko ni ṣatilẹyin fun Atiku Abubakar
Nígbà tí Atiku náà du ipò Ààrẹ pẹlu Ààrẹ Olusegun Obasanjo lọdun 1999, ẹgbẹ òṣèlú PDP lo yan fún Obasanjo láti tẹ apá kan orílèèdè Nàìjíríà lọrùn.
Lori ọrọ Aarẹ Obasanjo, ti a ba fi bi o ti ṣe n bẹnu atẹ lu Atiku,ko daju wi pe Atiku yoo yan ni igbakeji rẹ tabi ki Obasanjo tilẹ gbaruku ti Atiku ninu idijẹ fun ipo Aarẹ ni 2019.
Ẹgbẹ Oselu APC ti ni Igbakeji Aarẹ tẹlẹri, Abubakar Atiku ko ni akọsilẹ rere lati le tukọ orilẹede Naijiria.
APC fi eyi lede ninu atẹjade ti wọn fi sọwọ si awọn oniroyin lati fi ki Atiku ku orire bi o se jawe olubori ninu idibo abẹle ẹgbẹ oselu PDP lati fi yan oludije sipo aarẹ lọdun 2019.
Ninu atẹjade naa, APC sọ wi pe iwa ibajẹ ti Atiku hu lọ jẹ ki oun ati Aarẹ orilẹede Naijiria tẹlẹri, Olusegun Obasanjo tako ara won.
Wọn tun fi kun un wi pe orilẹede Amerika di eewọ fun igbakeji aarẹ tẹlẹri naa nitori iwa jẹgudujẹra ti o hu, eyi to fa a ti ilẹ Amerika fi n wadii rẹ lati fi jofin ijọba.
Ẹgbẹ oselu APC wa fi kun un wi pe, gbogbo igba ti Atiku ba pinnu lati dije dupo ni o ma n ra ibo awọn eniyan ki o baa le bori.
Oríṣun àwòrán, @Toyin Saraki/Twitter
Aarẹ Ile Igbimọ Aṣofin Agba, Bukola Saraki ti ki Atiku ku oriirẹ, o si tun fi atilẹyin rẹ han fun un lati jẹ ko ṣe aṣeyọri ni 2019.
Saraki ni aṣeyọri naa yẹ Atiku ati wipe awọn ọmọ ẹgbẹ PDP ṣe daradara.
Ninu ọrọ idupe rẹ, Saraki ni o jọ bi ẹni pe Naijiria ko ti i ṣetan fun oun o.
Saraki dúpẹ́ lọ́wọ́ àwọn alátìlẹ́yìn rẹ̀
Bẹẹ naa ni Ibrahim Dankwambo to jẹ Gomina Ipinlẹ Gombe ṣe ileri wipe oun yoo ba Atiku ṣiṣẹ lati jẹ ko ṣe aṣeyọri.
Lẹyin ti ẹgbẹ oṣelu PDP kede igbakeji aarẹ nigba kan ri, Atiku  gẹgẹ bii ẹni to jawe olubori ninu idibo abẹle ẹgbẹ naa ni Port Harcourt, Atiku gboṣuba fun Aarẹ nigba kan ri, Oluṣẹgun Obasanjọ gẹgẹ bii ẹni to jẹ ki oun de ibi to de lonii.
Atiku ni ti kii ba ṣe pe Obasanjọ yan oun gẹgẹ bii igbakeji rẹ laarin 1999 si 2007, oun ko ni wa nipo ti oun wa lonii.
Oríṣun àwòrán, Twitter
Aarẹ ana Olusegun Obasanjọ ti sọ tẹlẹ pe oun ko ni ṣatilẹyin fun Atiku Abubakar
Eyi ni ọkan lara awọn oun ti Atiku sọ nigba ti oun dupẹ lọwọ awọn aṣoju ẹgbẹ naa to yan gẹgẹbii oludije.
O tun sọ wipe lati igba ti oun ti n dije, oun ti kopa ninu idibo abẹle marun ọtọtọ.
Atiku ni oludije fun PDP ni idibo 2019
Ọsan ọjọ Aiku ni ẹgbẹ́ oṣelu PDP kéde pé Atiku ló tó gbangba sùn lọ́yẹ́ láti kojú Buhari ni 2019.
Atiku Abubakar ni PDP fa kalẹ̀ pé oun ati Buhari a jọ na an tan dupo aarẹ ni 2019
Awọn aṣoju 3, 274 ni wọn dibo ninu awọn ẹgbẹrun mẹrin (4, 000) to forukọsilẹ nigba ti wọn fagile ìbò 68. Eto idibo naa pari ni aago mẹfa kọja iṣẹju mẹrindinlogun.
Ibo 1, 532 ni Atiku fi jawe olubori di oludije fun ẹgbẹ PDP lati dije dupo aarẹ Naijiria ni 2019.
Ero awọn eniyan lori esi idibo to gbe Atiku wọle
Awọn eniyan ti bẹrẹ si ni fesi si idibo to gbe Igbakeji aarẹ tẹlẹri, Abubakar Atiku lẹyin ti idibo abẹle ẹgbẹ PDP gbe wọle pẹlu ibo 1, 532 ni ipade gbogboogbo wọn.
Lara awọn to fesi si idibo naa ni oju opo Twitter ba Atiku yọ pe owó ṣe pàtàkì pẹlu adura pé ko lè bori ninu idibo to n bọ.
Awọn ọmọ Naijiria gbàá nimọran pe ki o fi gbogbo ipa rẹ sin orilẹ-ede Naijiria nitori awọn setan lati se atilẹyin si.
Amọ, awọn ẹlomiran sọ pe magomago ko ni jẹ ki Atiku bori ni idibo to n bọ lọdun 2019, ti wọn si fi idibo ọdun 2019 we idibo Ọṣun to waye ni oṣu to kọja.
Awọn elomiran bi Femi Fani-Kayode ti inu wọn dun si esi idibo abẹle PDP naa ni ki APC mura silẹ fun ogun.
Jonah Jang ni ìbò 19.; Datti Babà Ahmed ni ibo 05; David Mark ni ibo 35; Kabiru Turaki ni ibo 65; Sule Lamido ni ibo 96; Bafarawa Attahiru 48; Ibrahim Dankwanbo ni ibo 111; Makarfi Ahmed ni ibo 74; Kwakwanso Rabiu ni ibo 158; Bukọla Saraki ni ibo 317;  Aminu Tambuwal ni ibo 693 àti Atiku Abubakar ni ibo 1,532.
Abia 106; Adamawa 76; Akwa Ibom 153 ṣugbọn 151 lo dibo; Anambra 54; Bauchi 76; Bayelsa 74; Benue 121; Borno 57; Cross River 95; Delta 150; Ebonyi 101; Edo 79; Enugu 126; Ekiti 109; Gombe 89; Kaduna 103; Kano 129; Imo 117;  Jigawa 84; Katsina 102 ṣugbọn 101 lo dìbò; Kebbi 68 ṣugbọn 66 lo dìbò; Kogi 94 ṣugbọn 93 lo dibo; Kwara 102; Lagos 62; Nasarawa 52; Niger 83; Ogun 21; Ondo 64; Osun 89; Oyo 88; Plateau 76; Rivers 131; Sokoto 95; Taraba 93; Yobe 59; Zamfara 48 àti FCT 36.
Odiwọn iye awọn aṣoju to dibo lati ipinlẹ kọọkan ni yii:
Awọn aṣoju ti bẹrẹ idibo lati yan ẹni ti yoo koju Buhari (APC) lọdun 2019.
Awọn aṣoju 3274 ni yoo dibo naa lati ipinlẹ mẹrindinlogoji ati FCT Abuja.
Awọn oludije mejila lo dije dupo ẹni ti ẹgbẹ PDP yoo fa kalẹ láti kojú Buhari ti ẹgbẹ AOC ti fa kalẹ bayii ni nu idibo sipo aarẹ Naijiria lọdun 2019.
Oríṣun àwòrán, @empic
Awọn aṣoju ti n dibo yan ẹni ti wọn fẹ bi aarẹ ni PDP
Ayẹwo awọn oludije ti pari
Oríṣun àwòrán, BC
Gbogbo àwọn oludije náà niroyin ni wọ́n kọ̀ láti yẹ̀ba fún ara wọ́n nítorí kálukú gbà pé òun lè ṣe é dáadáa
Awọn mejila to n dije dupo asoju ẹgbẹ oselu APC ati awọn asoju wọn ti pari ayẹwo ki idibo to bẹrẹ si ipo oludije aarẹ ni abẹ ẹgbẹ oselu PDP.
Lẹsẹẹsẹ ni awọn asoju naa joko lati bẹrẹ si ni di ibo yan ẹni ti  wọn fẹ ko koju Aarẹ Muhammadu Buhari ninu idibo gbogbooogbo ti yoo waye ni ọdun to n bọ.
Bakanaa, olorin takasufe ti igbalode to tun jẹ aburo oludije sipo gomina labẹ egbẹ oselu PDP ni ipinlẹ Ọsun, David Adeleke ti gbogbo eniyan mọ si ‘Davido’ naa ko gbẹyin nibi ipade gbogboogbo to n lọ lọwọ naa.
PDP Convention 2018: Wọ́n ti parí àyẹ̀wò àwọn olùdíje fún ààrẹ ní PDP
Papa isere Amaesimaka nilu Port Harcourt ni ipade gbogboogbo naa ti n waye ti n waye
Eto ti to nibi ibudo ìdibo abẹle PDP ni Port Harcourt
Oun gbogbo ti wa ni sẹpẹ fun ipade apapọ ẹgbẹ oselu PDP  ni papa isere Amaesimaka nilu Port Harcourt.
Oniroyin wa to jabọ lati ibi ti ipade naa yoo ti waye so pe nise ni awọn agbofinro duro digbi lati ri wi pe ohun gbogbo lọ leto leto.
Awọn to n wọ agbegbe idibo naa ni a gbo wi pe awọn ọlọpaa n se ayẹwo finifini fun pẹlu irinsẹ ayẹwo igbalode.
Ejò Sebe, Ọká, òjòlá àti àkeèké jẹ́ alábagbé Phillipe
Oludije mejila ni yoo kopa ninu ibo abẹnu ẹgbẹ lati yan ẹni ti yoo koju Aarẹ Muhammadu Buhari ninu idibo Aarẹ ọdun 2019.
Awọn onisọwo naa ko gbehin nibẹ
Karakata naa si nlọ ni agbegbe naa paapa julọ fun awọn to ba fẹ ra asia ẹgbẹ tabi awọn ohun isaraloge miran lati fi se afihan pe ọmọ ẹgbẹ ni wọn.
Jakejado Naijiria ni awọn asoju ẹgbẹ ti wa lati kopa ninu idpade apapọ yi
Bi wakati naa ti se n sunmọ bọ ni awọn amoye ati ara ilu ti n bere ibeere pé: Tani yoo koju Buhari lati PDP?
Awa naa ko le dahun ibere yi bi ki ba se wi pe a gbo abajade ibo abẹnu naa sugbọn oun ti a le se ni ki a se agbeyewo awọn oludije to lewaju larin awọn to n du ipo yi.
Die ninu wọn re ati ohun to yẹ ki ẹ mọ nipa wọn.
Oríṣun àwòrán, PIUS UTOMI EKPEI/GETTY
Bukola Saraki ni Aarẹ ile asofin agba
Ninu akoso iṣejọba lorile-ede Naijiria, Sẹnatọ Bukọla Saraki lo wa ni ipo kẹta.
Ọmọ bibi Ilorin to ti figba kan jẹ gomina ni ipinlẹ Kwara ni pẹlu iriri pupọ gẹgẹ bi aṣofin.
Ọpọ lo ti n foju sii lara pe o ṣeeṣe ki o du ipo aarẹ, ko si jẹ iyalẹnu nigba ti o kede erongba rẹ lati du ipo Aarẹ nibi ipade ẹgbẹ awọn ọdọ ni Abuja.
Awọn amoye n fi oju sii lara gẹgẹ bi ọkan lara awọn to le ri tikẹti ẹgbẹ gba ti ireti si wa wi pe ó le koju Buhari ninu idibo ọdun 2019.
Oríṣun àwòrán, TWITTER/ATIKU ABUBAKAR
Atiku Abubakar ko fi igba kan sinmi nina ọwọ ife si awọn olori kakiri orilẹẹde Naijiria.
Atiku ni ti wọn ba yan oun sipo Aarẹ Naijiria, atunto isejọba ni oun yoo gbajumọ.
APC Primaries: A ṣi n lọ sílé ẹjọ́ lóṣù tó m bọ̀ lórí ọ̀rọ̀ yìí
Oríṣun àwòrán, @AWTambuwal
Tambuwal fi igba kan sa kuro ninu ẹgbẹ PDP lo si APC
Aminu Waziri Tambuwal jẹ olori ile asojusofin nigba kan ri.
Lẹyin to sipo kuro ninu ẹgbẹ oselu PDP lo si APC, o du ipo Gomina nipinlẹ Sokoto ti o si wole gẹgẹ bi Gomina.
Lẹyinwa igba naa ni o tun fi ẹgbẹ APC silẹ pada si PDP nibi ti o ti ferongba silẹ lati du ipo Aarẹ.
APC Primaries: 'Kò sí 'Faction' ni Kwara APC rárá, NWC ti sọ̀rọ̀'
Tambuwal ni ọpọlọpọ iriri gẹgẹ bi asofin ti awọn kan si ri gẹgẹ bi irawo ọjọ iwaju ẹgbẹ PDP.
Nàíjíríà pé ọmọ ọdún 58 lónìí, ǹjẹ́ o mọ ìtàn ìbẹ̀rẹ̀ oílẹ̀-èdè rẹ?
Oríṣun àwòrán, Facebook/Kwankwansiya
Lọdun 2015, Kwankwaso dije nibo abele APC sugbọn o fidiremi lọwo Buhari.
O pe die ki Rabiu Musa Kwankwanso to sọ boya ohun  yoo du ipo aarẹ  labe asia ẹgbẹ PDP tabi ẹgbẹ miran.
Sugbọn pẹlu atimaaṣebọ rẹ tẹlẹ ati awọn ipolongo ti awọn ololufe re n se lori ẹro ayelujara, ko ru ẹnikẹni loju pe o fẹ du ipo  Aarẹ pẹlu Muhammadu Buhari.
Ọmọ bibi ipinlẹ Kano ni Kwankwanso, o si jẹ ilumọọka oloṣelu ti o ti fi igba kan jẹ Minista ati Gomina ipinlẹ Kano ri.
Kwankwaso kii se ajoji si ka ma du ipo Aarẹ sugbọn idije ọtẹ yi yoo fẹ le die fun un pẹlu bi ọrọ ko ti se wọ laarin oun ati Gomina ipinlẹ rẹ lọwọlọwọ, Abdullahi Ganduje.
Ti Kwankwaso ba ribi ja tikẹti ẹgbẹ PDP gba fun ipo Aarẹ, o seese ki o ba Buhari fa ibo pupo to ma n saba wa lati ipinlẹ Kano.
Oríṣun àwòrán, @bukolasaraki
Ko daju wi pe Mark yoo fẹ jọwọ ipo Aarẹ fun Saraki lọtẹ yi
Ajagunfẹyinti ni David Mark sugbọn iriri rẹ ninu oselu Naijiria jẹ oun to lami laka.
O ti saaju jẹ  Aarẹ ile asofin agba Naijiria laarin ọdun 2007-2015.
Mark wa lara awọn ogunna gbongbo ẹgbẹ oselu PDP lati ibere pẹpẹ ti ko si sipo kuro ninu ẹgbẹ titi di bi a ti se n sọrọ yi.
Mark ni ti wọn ba yan oun gẹgẹ bi Aarẹ, ọdun meji loun yoo fi se atunto orile-ede Naijiria.
Isoro rẹ bayi ni ki o ri tikẹti ẹgbẹ gba. Ọmọ àádọ́rin ọdun nii se.
Oríṣun àwòrán, @AWTambuwal
Sule Lamido ati Aminu Waziri Tambuwal
Sule Lamido ni o fẹ da bi wi pe ipolongo rẹ fun ipo Aarẹ ko gbode sugbọn kii se ẹni a a foju di.
Ipinlẹ Jigawa lo ti wa nibi ti o ti jẹ gomina labẹ asia ẹgbẹ oselu PDP lọdun 2007.
Ninu awọn to duro ti ẹgbẹ PDP nigba isoro lo jẹ ti awọn to mọ nipa oselu ko si ko iyan rẹ kere rara.
Aarẹ orile-ede Naijiria nigba kan ri, Olusegun Obasanjo, nigba ti o n gba a ni alejo ni Ota so pe ''Lamido kun oju osunwọn lati dari Naijiria.''
Ti awọn ọmọ ẹgbẹ ba wo ti wi pe o duro gbagba ti awọn, o yẹ ki wọn dibo yan an gẹgẹ bi oludijẹ ẹgbẹ fun ipo Aarẹ.
Àwọn tó n bọ Ṣàngó n jẹ iná níni ọdún Ọlọ́jọ́
Àwa obìnrin tó ń lépa afòjúsùn máa n ba ọkùnrin lẹ́rù ni -Toyin Lawani
Osun Election 2018: Àwọn ọlọ́pàá fi tajútajú tú àwọn ọmọ ẹgbẹ́ PDP tó fẹ̀hónú hàn nítorí ìbò Ọṣun
Oríṣun àwòrán, Dele Momodu
Sẹnetọ Dino Melaye wọ̀yá ìjà pẹ̀lú àwọn ọlọ́pàá níbi ìfẹ̀hònú hàn tí ẹgbẹ́ PDP ṣe
Wahala nla bẹ silẹ l'ọjọ Ẹti lasiko ti ẹgbẹ́ alatako googi ni Naijiria, PDP, ṣe iwọde niluu Abuja.
Iroyin fi idi rẹ mulẹ pe awọn ọmọ ẹgbẹ oṣelu PDP fi ẹhonu han niluu Abuja, ti wọn si fi ẹsun kan iṣakoso Aarẹ Muhammadu Buhari pe o fẹ ẹ ba eto oṣelu awaarawa jẹ ni Naijiria nitori eto idibo sipo gomina to waye nipinlẹ Ọṣun, nibiti ẹgbẹ oṣelu APC ti jawe olubori.
Ṣugbọn ko pẹ ti iwọde naa bẹrẹ ni awọn ọlọpaa bẹrẹ si ni wọ iya ija pẹlu àwọn to n ṣe iwọde ọhun, ti wọn si da afẹfẹ tajutaju si agbegbe ti iwọde naa ti n waye.
Olori ile igbimọ asofin agba ati asoju-sofin l'Abuja Bukola Saraki ati Yakubu Dogara wa lara awọn eekan ẹgbẹ oṣelu PDP to wa nibi ifẹhonu han naa.
Ẹgbẹ́ òṣèlú PDP f'ẹ̀sùn kan Ààrẹ Muhammadu Buhari pé wọ́n fẹ́ ba ètò ìṣèjọba àwaarawa jẹ́ ní Nàìjíríà.
Alukoro ẹgbẹ́ nàá, Kọla Ologbondiyan, sọ pé àwọn yóò gbé ìwé ẹ̀sùn nàá lọ sí ọ̀dọ̀ àjọ INEC àti iléèṣẹ́ ọlọ́pàá.
Ologbondiyan sọ fún BBC pé àwọn n fi ẹ̀hónú hàn nítorí ìhùwàsí àjọ INEC lórí ọ̀nà tó gbà ṣètò ìdìbò gómìnà tó wáyé ní ìpínlẹ̀ Ọṣun.
Oríṣun àwòrán, Bukola Saraki/Facebook
Saraki léwájú ẹgbẹ́ PDP láti fẹ̀hónú hàn nítorí ìbò Ọṣun
Asọjú ẹgbẹ́ APC, Gboyega Oyetọla ni wọ́n kéde lẹ́yìn tí àtúndì ìbò wáyé. Olùdíje lábẹ́ ẹgbẹ́ PDP, Ademọla Adeleke ló jáwé olúborí nínú ètò ìdìbò tó kọ́kọ́ wáyé.
Ologbondiyan ní ìjọba apápọ̀ àti ẹgbẹ́ APC fẹ́ ẹ̀ mọ̀ọ́mọ̀ da ètò ìṣèjọba àwaarawa Nàìjíríà jẹ́ ni. Àti pé ó yẹ kí àjọ INEC dá dúró láì gba àṣẹ lọ́wọ́ ẹnikẹ́ni.
Ó ní ṣùgbọ́n àjọ INEC n ṣiṣẹ́ gẹ́gẹ́ bi ẹ̀ka kan nínú ẹgbẹ́ òṣèlú tó wà ní ìṣàkóso.
Ṣugbọn, ajọ INEC sọ fun BBC l'ọjọ Ẹti pe awọn ko jẹbi ẹsun ṣiṣe mago-mago lasiko eto idibo gomina to waye ni ipinlẹ Ọṣun ti ẹgbẹ oṣelu PDP fi kan awọn.
Akọwe ikede fun alaga ajọ INEC, Rotimi Oyekanmi sọ pe ajọ naa ko fọwọsowọpọ pẹlu ẹgbẹ osṣelu kankan lati jale ibo ni Ọṣun.
Ọgbẹni Oyekanmi sọ pe awọn seto idibo gomina l'Ọṣun ni ibamu pẹlu bi awọn ṣe maa n ṣe eto idibo lọdọọdun, paapa ọdun 2015.
Kọla Ologbondiyan sọ pé èsì ìbò tí INEC kéde ní ìpínlẹ̀ Ọṣun kò bá òfin mu, tó sì yẹ kí ọ̀gá àgbà fún INEC, Mahmood Yakubu kọ̀wé fi ipò rẹ̀ sílẹ̀
Oríṣun àwòrán, PDP
Saraki léwájú ẹgbẹ́ PDP láti fẹ̀hónú hàn nítorí ìbò Ọṣun
Oyekanmi sọ pe 'eto idibo to waye l'Ọṣun gan an lo ti i daraju ninu gbogbo idibo gomina ti ajọ naa ti ṣe, nitori bi awọn eroja idibo ṣe tete de si awọn ibudo idibo, ati pe ni nkan bi i aago mẹjọ aarọ ni ida mejidinlọgọrun awọn ibudo naa ti wa ni ṣiṣi.
Àwọn kọmisana ajọ INEC meji to ba àwọn to sẹ iwọde ọhun sọrọ, May Agbamuche-Mbu ati Mohammed Haruna, sọ pe ajọ INEC ti pinnu lati ṣe eto idibo ti ko ni i ni ikunsinu ninu l'ọdun 2019.
"Oyekanmi sọ pe ""irọ ni PDP pa pe ajọ INEC n ṣiṣẹ fun ẹgbẹ oṣelu APC."
"Nigba ti ẹgbẹ PDP wa ni iṣakoso, ẹsun kan naa ni ẹgbẹ oṣelu APC fi kan INEC pé a n ṣe atilẹyin fun wọn, ṣugbọn ni bayii ti APC naa ti wa nipo, PDP naa tun n sọ ẹsun kan naa.
INEC sọ pé ki ẹgbẹ́ PDP fi ọkan balẹ, pe wọ́rọ́wọ́ ni eto idibo 2019 yoo lọ, ti ko si ni i si mago-mago kankan.
Ọlọ́pàá Ìpínlẹ Ondo: Egúngún tó pa ọ̀dọ́kùnrin yóò fojú ba Ilé- Ẹjọ́
Femi Joseph: Egungun to pa ọdọkunrin yoo foju ba Ile- Ẹjọ
Ile-Isẹ Ọlọ́pàá Ìpínlẹ Ondo ti fi panpẹ ọba mu eleegun kan ti wọn pe orukọ rẹ ni Olu Olowokere lori ẹsun pe o gun arakunrin kan to sẹsẹ ri isẹ pa.
Agbẹnusọ ile isẹ ọlọpaa ni ipinlẹ Ondo, Femi Joseph to sọ pe lootọ ni isẹlẹ naa waye, ni iwadii nlọ lọwọ lori isẹlẹ naa.
Alukoro Ọlọpaa naa fikun wi pe awọn ti fi panpẹ ọlọpaa mu olori awọn eleegun naa ni ipinlẹ Ondo.
Oríṣun àwòrán, NAiraland
Ilé-Isẹ́ Ọlọ́pàá Ìpínlẹ Ondo ti fi pańpẹ́ ọlọ́pàá mú arákùnrin eléégún tó sekúpa ọmọkùnrin kan ní ìlú Akure.
'Bí aya bá kọ ọkọ rẹ̀ silẹ̀, kó wà láì lọ́kọ̀'
Awọn ti ọrọ naa se oju rẹ ni Ọkunrin ti wọn sekupaa naa, Femi Makanjuọla lọ ra ounjẹ lasiko ti awọn eleegun naa bere owo lọwọ rẹ, ti o si kọ lati fun wọn.
Wọn ni Makanjuọla sẹsẹ ri isẹ pẹlu Ile-Isẹ Dangote Cement Company , ti o si yẹ ko lọ bẹrẹ isẹ ni Ọjọ Aje, ọsẹ yii.
Amọ eleegun ti wọn fẹsun kan naa wi pe o pa ọmọkunrin naa, Olu Olowokere sọ wi pe oun ko lo pa arakunrin naa.
Oríṣun àwòrán, FACEBOOK
Gomina Ìpínlẹ̀ Ondo tí kẹ́dùn pẹ̀lú ẹbí arábìnrin tí àwọn agbẹ́nipa fibá ba lopọ̀ tí wọ́n sí pa á ní ìlú Akure.
Gomina Ipinlẹ Ondo, Oluwarotimi Akeredolu ti pasẹ fun ile-isẹ ọlọpaa ni ipinlẹ Ondo latiri wi pe wọn wa awọn ẹni to pa ọmbinrin ogun ọdun ni ipinlẹ Ondo.
Ọmọbinrin ti orukọ rẹ n jẹ Motunrayọ Seun Ajila ni o ṣetan lati Ile-Iwe Giga, Adeyemi College of Education, Ondo ti awọn kan si fi ipa baa lopọ ni adugbo Sunday Bus Stop, Akure.
Ninu atẹjade ti Gomina Akeredolu fi lede lati ọwọ akowe eto iroyin rẹ, Arakunrin Segun Ajiboye to sọ pe gbogbo agbegbe to wa ni ipinlẹ Ondo ni awọn yoo ri daju pe awọn ṣe idaabobo to peye fun.
Ẹ wo àrà tí ẹ le fi gèlè dá láàrín ìṣẹ́jú mẹ́ta
Akeredolu to kẹdun pẹlu ẹbi ati ara ọmọbinrin to doloogbe naa ni oun yoo ri daju wi pe awọn to sekupa ọmọbinrin naa ko lọ lai fi oju wina ofin.
Gomina Ipinlẹ Ondo naa wa parọwa si awọn ọdọ lati ri wi pe wọn se isẹ takuntakun lati jẹ eniyan nla lai gba ọna ẹburu, ki ọjọ iwaju wọn le dara.
È gbọ àlàyé lẹnu àwọn ti ójúẹlẹgba leko irú iṣẹ ti oògùn olóró má n ṣé lara.
Àwa obìnrin tó ń lépa afòjúsùn máa n ba ọkùnrin lẹ́rù ni -Toyin Lawani
Tọkọtaya méjì, ọmọ ìyá mẹ́rin bá ìjàmbá ọkọ̀ ayọ́kẹ́lẹ́ lọ l'Amerika
Èèyàn ogun ti padanu ẹmi wọn ninu ijamba ọkọ kan to waye nilu New York lorilẹede Amerika.
Ile isẹ ọlọpaa sọ pe ijamba naa sẹlẹ nigba ti ọkọ ayokẹlẹ to n gbe wọn lọ si ode ariya sadeede kọlu ọkọ miran ti o si ya lọ ba awọn eeyan ni iwaju ile itaja kan.
Ijamba ina Eko; Awakọ ni omi gọta lo yọ oun ninu ijamba ina
Gbogbo awọn eeyan mejidinlogun ati awọn eeyan meji kan to n lọ ti wọn jẹjẹ lẹgbẹ titi ba isẹlẹ naa lọ.
Ko ti si alaye nipa ohun ti o fa ijamba naa.
Bakanna ni wọn ko ti mọ awọn to farakasa ninu isẹlẹ ọhun sugbọn iwe iroyin New York Times sọ pe awọn ọmọ iya mẹrin kan wa lara awọn to ko ijamba yi ati awọn tokotaya meji kan naa.
Agbalagba ni gbogbo awọn to ku ninu ijamba ọkọ ohun.
Awako to wa ọkọ naa ba iselẹ ohun lọ.
Nigba ti o n ba awọn akoroyin sọrọ, alaga ajọ to n mojuto abo loju popo Robert Sumwalt ni ''iselẹ ọhun jẹ eyi to buru ju lọ nipa iye ẹmi to ku ati wi pe awọn ko ti ri iru ijamba ọkọ bee lati ọdun 2009.''
Disability in Africa: 'Ojú kò tì mí mọ́ pé ọmọ mi ní ìpènéjà ara'
Agnes Nditi ati ọmọ rẹ, Nambia
Nígbà tí Agnes Mutemi kọ́kọ́ gbọ́ pé àkọ́bí rẹ̀ obìnrin, Nambia, ní ààrùn ọpọlọ l'ọ́mọ ọdún méjì, ìtìjú nla ló jẹ́ fun un.
Bẹ̀ ẹ́ ni kò sì fẹ́ ẹ̀ gbàgbọ́ fún ọ̀pọ̀lọpọ̀ ọdún, kó tó ò di pé ó ṣàwárí iléèwé kan tó n tọ́jú àwọn ọmọdé tó ní ìpèníjà ara.
Ìyá ọlọ́mọ mẹ́ta ọ̀hún sọ pé ìbànújẹ́ òun maa n wáyé látara bí àwọn ènìyàn ṣe maa n wo òun, àti ìhùwàsí wọn si i lójoojúmọ́.
Fídíò mánigbàgbé nípa ìgbà ayé Bàbá Sala
Ní ìbẹ̀rẹ̀ pẹ̀pẹ̀, mó maa n bi ara mi lérè pé kí lódé tí Ọlọrun fún mi nírú ọmọ bẹ́ẹ̀.''"
Abílékọ Mutemi, tó n gbé l'ábúlé Katoloni ní ẹkùn ìlà oorùn Kenya sọ pé ''Ó ṣòro fún mi láti rìn láàrin ìlú pẹ̀lú ọmọ mi, nítorí ojú burúkú tí àwọn ènìyàn fí n wò mí.
Agnes sọ pé àìsàn tí wọ́n n pè ní Asphyxia ni ọmọ òun ní. Àìsàn nàá maa n jẹyọ tí ọmọ tuntun kò bá rí atẹ́gùn gbà sára lásìkò tí ìyá rẹ̀ bá n rọbí.
Èyí ló fà á tí ẹsẹ̀ rẹ̀ kò ṣe ní àláàfíà, tí wàhálà sí bá ọpọlọ rẹ̀ nàá.
Lẹ́yìn ọ̀pọ̀lọpọ̀ àbẹ̀wò sí iléèwòsàn, Agnes lọ fi orúkọ ọmọ rẹ̀ sílẹ̀ ní ìléèwé kan tó n kọ́ àwọn ọmọdé nígbà tó wà l'ọ́mọ ọdún mẹ́ta.
''Ìgbà tí Nambia lo ọdún mẹ́fà ní kíláàsì kan, tí kò sí le ṣe àwọn nkankan tó jẹ́ dandan, ni mo tó ò mọ̀ pé nkan kò lọ déèdé.
Ó fi kun un pé owó ìtọ́jú ẹni tó bá ní ààrùn ọpọlọ ti pọ̀jù ní Kenya.
''Ohun tó wù mí ni pé kí ọmọ mi di dókítà tàbí ọ̀jọ̀gbọ́n, tàbí olùkọ́. Ṣùgbọ́n, ó ṣe ni láànú pé èyí kò ní ṣeeṣe.
Nambia àti olùkọ́ rẹ̀, Margaret Mbithi
Ní ìkóríta kan, Agnes tilẹ̀ pinnu láti maa jókòó sílé pẹ̀lú Nambia, nítorí pé àwọn iléèwé tó wà fú àwọn ọmọ tó dápé kò gbà á.
Ṣùgbọ́n, ohun tó mú àyípadà bá ayé Agnes ni àsìkò tó pàdé ọ̀rẹ́ rẹ̀ àtijọ́ kan, tó gbà á nímọ̀ràn pé kó mú ọmọ rẹ̀ lọ sí àkànṣe íléèwé.
"Lẹ́yìn tí miò rí àyípadà lára ọmọ mi ní mo tó gba kádàrá.
Mi o tan ara mi mọ́.''"
Lóòtọ́ ni Nambia ní ìpèníjà ara, ṣùgbọ́n èyí kò di i lọ́wọ́ láti má gbé ìgbé ayé rẹ̀ pẹ̀lú ìdùnnú.
Nambia jẹ́ ọ̀kan lára àwọn ènìyàn tó lé ní bílíọ́nù kan tó n gbá pẹ̀lú ìpèníjà ara l'ágbàyé.
Oríṣun àwòrán, AFP
Àwọn ènìyàn yí n fẹ́ kí Aarẹ Joseph Kabila fi àwọn aláàbọ̀ ara sí ipò ìṣàkóso
Àjọ tó n mójútó ètò ìlera l'ágbàyé, WHO sọ pé ìdá mẹ́ẹ̀dógún àwọn ènìyàn tó wà l'áyé ni yóò ní ìpèníjà ara kan, pàápà ní àwọn orílẹ̀èdè tó ṣẹ̀ṣẹ̀ n dàgbà.
Gẹ́gẹ́ bi àkọsílẹ̀ àjọ Unesco, ìdá àádọ́rùn nínú àwọn ọmọ tó ní ìpèníjà ara l'áwọn orílẹ̀èdè tó ṣẹ̀ṣẹ̀ n gòkè, ni kìí lọ sí iléèwé.
Ní Kenya, ibùdó ẹgbẹ̀rún kan lé ọ̀ọ́dúnrún ni wọ́n ti n tọ́jú àwọn tó ní ìpèníjà ara, àti iléèwé ọgọ́fà dín mẹ́fà, gẹ́gẹ́ bi àkọsílẹ̀ ilé iṣẹ́ tó n mójútó ètò ẹ̀kọ́ l'ọ́dún 2009.
Ṣùgbọ́n, kò tó, kìí sì ṣe gbogbo ọmọ tó ní ìpèníjà ara ló n rí ìtọ́jú bi Nambia.
Atiku ń wá igbákejì, ta ni yóò jẹ́?
BBC Yorùbá kópa nínú Àpérò èdè Yorùbá ti ẹgbẹ́ YSAN
Àbọ̀ ìwádì ọ̀hún fihàn pé ìdá àádọ́rùn nínú àwọn ọmọ tó ní ìpèníjà ara ní Kenya, ló n jókò sílé tàbí lọ sí iléèwé tí kìí ṣe fún àwọn tó ní ìpèníjà ara, tí wọn kìí sì rí ìtọ́jú tó péye gbà níbẹ̀.
Ìgbá ayé kò rọrùn fún àwọn òbí tó ní ìpèníjà ara, tó sì tún n pèsè fún àwọn ọmọ wọn.
Kevin Momanyi, ọmọ ọdún mẹ́wàá, maa n ti ìyá rẹ̀ pẹ̀lú kẹ̀ẹ̀kẹ́ lọ sí ilé ìtajà rẹ̀ ní òwúrọ̀ ojoojúmọ́ kó tó lọ sí iléèwé.
Irene Kerubo, ẹni ọdún méjìlélọ́gbọ̀n, gbẹ́kẹ́lé ọmọ rẹ̀ tó jẹ́ ọmọ ọdún mẹ́wàá, láti tìí pẹ̀lú kẹ̀ẹ̀kẹ́ lọ sí ilé ìtajà rẹ̀ ní òwúrọ̀ ojoojúmọ́ kó tó lọ sí iléèwé ní agbègbè Nakuru ní Kenya.
Èyí ni bí Kevin Momanyi ṣe n lo ayé rẹ̀, nítorí pé ìyá rẹ̀ ní àárùn rọmọlápá, rọmọlẹ́sẹ̀ nígbà tó wà ní ọmọ ọdún mẹ́rin, èyí tó mú kó yarọ láti ìbàdí dé ẹsẹ̀ rẹ̀.
Irene ati ọmọ rẹ, Kevin, tó maa n ti i lọ sí ilé ìtajà rẹ̀ l'ójoojúmọ́
Ọmọ mi, ọmọ ọdún mẹ́wàá ni ohun gbogbo fún mi.
Ìyá ọlọ́mọ mẹ́rin ọ̀hún sọ pé ''òun ló n ṣe gbogbo iṣẹ́ ilé, tó sì tún n pèsè oúnjẹ́ fún wa nítorí pé óun tì mí pẹ̀lú kẹ̀ẹ̀kẹ́ lọ sí ilé ìtajà mi.''
Ipò tó wà ti jẹ́ kó wà nínú ìṣẹ́ àti òṣì.
Ìyansẹ́lódì MMA2: Alẹ́ Ọjọ́bọ ni ìyansẹ́lódì náà wá sópin
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Àwọn arìnrìàjò ní pápákọ̀ òfúrufú MMA2
Àwọn òṣìṣẹ́ pápápọ̀ òfurufú ní Ìpínlẹ̀ Eko fi ẹ̀honú wọn hàn
Àwọn ẹgbẹ́ òṣìṣẹ́ lẹ́kàa ètò ìrìnà òfúrufú ti fagile iyanṣẹlodi ti wọn gun le.
Iroyin to tẹ wa lọwọ ṣọ pe, ẹgbẹ oṣiṣẹ naa ṣe ipade pẹlu awọn alaṣẹ ile iṣẹ naa lalẹ Ọjọbọ nibi ti wọn ti gba lati fagi le iyanṣẹlodi naa.
Abioye sọ pe bi adari awọn ti le oṣiṣẹ bi aadọrin lọ, ko ba ofin mu.
Àwọn òṣìṣẹ́ MMA2
Ẹ o ranti pe awọn ẹgbẹ́ òṣìṣẹ́ naa da ẹ̀rù bolẹ̀ wí pé àwọn yóò ti pápákọ̀ òfurufú Murtala Muhammed international Airport 2 (MMA) tó wà ní ìlú Eko pa.
Lọ́jọ́rú ọjọ́ kẹ́wàá oṣù kẹ́wàá ni èyí wáyé lórí ẹ̀sùn pé wọ́n dá òṣìṣẹ́ ogún dúró lẹ́nu iṣẹ́.
'Nígbà tí kò ṣeéṣe fún wa láti fò, a ó lọ́ wọkọ̀'
Ṣáájú, ẹgbẹ́ náà nínú ìkìlọ̀ tí wọ́n ṣe lọ́jọ́ ìṣẹ́gun ti sọ wí pé àwọn yóò dí iṣẹ́ lọ́wọ́ ní ibùdókọ̀ eléyìí tí ilé iṣẹ́ Bi-Courtney Aviation Services Limited (BASL) ń ṣe àkóso rẹ̀.
Àwọn òṣìṣẹ́ MMA2
Gẹ́gẹ́ bí wọ́n ṣe sọ ọ́ lọ́jọ́ ìṣẹ́gun, bẹ́ẹ̀ gẹ́lẹ́ náà ló rí lọ́jọ́rú tí wọ́n tú síta lówùrọ̀ kùtù hàì sí ẹnu ọ̀nà pápákọ̀ òfúrufú náà láì jẹ́ kí ẹnikẹ́ni wọlé.
Àwọ́n ẹgbẹ́ tó dá a sílẹ̀ ni The National Union of Air Transport Employees (NUATE) and Air Transport Services Senior Staff Association of Nigeria (ATSSSAN) àti the National Association of Aircraft Pilots and Engineers (NAAPE)
Ẹnu ibodè MMA2
Akọ̀ròyìn BBC Yorùbá tó bá àwọn òṣìṣẹ́ àti arìnrìnàjò sọ̀rọ̀ jábọ̀ wí pé lóòtọ́ ni wọ́n ti ẹnu ibodè pápákọ̀ òfúrufú pa tí wọn kò sì jẹ́ kí àwọn tó ti forúkọ sílẹ̀ láti rìnrìnàjò wọlé.
Kódà, àwọn tí kò lérò wí pé ìgbẹ́sẹ̀ tí àwọn òṣìṣẹ́ yìí gbè leè pa àwọn lára, ṣe ni wọ́n ń dì ẹrù wọn padà sílé.
Àwọn ẹgbẹ́ náà ní gbogbo iṣẹ́ tó ń wáyé ní MMA2 ní àwọn yóò bẹ́gi dínà rẹ̀ láti ọjọ́ kẹ́wàá oṣù kẹ́wàá àyàfi bí wọ́n bá dá gbogbo àwọn òṣìṣẹ́ tí dá dúró padà láì pàdánù owó oṣù tàbí ipò gíga wọn.
Oríṣun àwòrán, AP
Àwọn arìnrìàjò ní pápákọ̀ òfúrufú MMA2
Páropáro ni gbogbo ìnú ọgbà àti ibi ìgbàléjò pápákọ̀ òfúrufú náà dá.
Inú ọgbà MMA2
Pẹ̀lú ìròyìn tó ń tẹ̀ wá lọ́wọ́, kò sọ́nà fún àwọ́n arìnrìn àjò káàkiri oríllèdè Nàìjíríà láti wọ ọkọ̀ bàálù lọ ibikíbi.
A ó máa mú ẹ̀kúnrẹ́rẹ́ ìròyìn wá fún un yín bó ṣe ń lọ látẹnu àwọn akọ̀ròyìn wá.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Murtala Muhammed international Airport 2
'Bí aya bá kọ ọkọ rẹ̀ silẹ̀, kó wà láì lọ́kọ̀'
Ibikunle Amosun: Ǹ ó fi ẹgbẹ́ òsṣèlú APC sílẹ̀'
Oríṣun àwòrán, Senator Ibikunle Amosun Facebook
Gómìnà Ibikunle Amosun
Gómìnà Ibikunle Amosun ti ìpínlẹ̀ Ogun, Sẹ́nétọ̀ Ibikunle Amosun ti dẹ́rù bolẹ̀ lọ́jọ́rú ọjọ́ kẹwàá oṣù kẹwàá pé oun yóò fi ẹgbẹ́ òṣèlú APC sílẹ̀.
Ó ní òun yóò ṣe èyí bí ìgbìmọ̀ amúṣẹ́yá ẹgbẹ́ náà bá kọ̀ láti kéde olùdíje tí òun fà sílẹ̀, Abdul-Kabir Adekunle Akinlade.
Èyí wáyé lẹ́yìn wákàtí díẹ̀ tí Gómìnà Akinwumi Ambode ti ìpínlẹ̀ Eko, Rochas Okorocha ti Imo, Umar Ganduje ti Kano, Mohammed Abubakar ti Bauchi and Kashim Shettima ti Borno ṣèpàdé pẹ̀lú ààrẹ Muhammadu Buhari láti mú u kí ó dá sí ọ̀rọ̀ ìdìbò abẹ́lé ìpínlẹ̀ wọn.
Gẹ́gẹ́ bí ọkan lára àwwọn tó kópa níbi ìpàdé náà ṣe sọ ọ́, gómìnà ọ̀hún tó jábọ̀ àbábọ̀ ìpàdé rẹ̀ pẹ̀lú ààrẹ Buhari kò ta ẹnikẹ́ni lólobó ẹgbẹ́ t íyóò ṣẹ̀ṣẹ̀ dara pọ̀ mọ́.
Ó sọ fún àwọn oníròyìn pé dípò kí ìgbìmọ̀ amúṣẹ́ yá yanjú ọ̀rọ̀ náà, ṣe ni wọ́n ní kí òun pín tíkẹ̀ẹ̀tí ilé àṣòfin àpapọ̀ àti ti ìpínlẹ̀ pẹ̀lú àwọn kan tó ní wọn ò bá wọn kópa nínú ìdìbò abẹ́lé ti gómìnà àti ti aṣòfin ìpínlẹ̀.
Tanzania: Lẹ́yìn ọjọ́ mẹ́wàá, ajínigbé dá Dewji olówó sílẹ̀
Oríṣun àwòrán, AFP
Iwe iroyin nipa ọrọ aje iyẹn Forbes Magazine ni biliọnu dola kan le diẹ ni ọrọ Mohammed
Ọ̀dọ́mọdekùnrin olówó ilẹ̀ Áfíríkà Mohammed Dewji tí wọ́n jí gbé ní ọjọ́ mẹ́wàá sẹ́yìn ti di rírí báyìí.
Olówó ọmọ orílẹ̀èdè Tanzania náaà sọ ọ́ di mímọ̀ lójú òpó Twitter rẹ̀ fún ra rẹ̀ wí pé òun ti padà sílé lálàáfíà.
Lẹ́yìn ọdún kan, wọ́n rí Nnamdi Kanu ni Israel
Ọọni Adeyẹye; Olorì tuntun ṣe gbogbo nkan tó yẹ́ kó tó wọlé tọ kábíèsí
Mínísítà fún ọ̀rọ̀ àyíká lóríllèdè Tanzania, January Makamba tó tún jẹ́ ọ̀rẹ́ tímọ́tímọ́ rẹ̀ fi hànde wí pé òun bá Dewji àti bàbá rẹ̀ sọ̀rọ̀.
Makamba sọ pé àwọn tó jí Mo gbé pa á tì sórí pápá kan lẹ́bàá ilé ijó Gymkana ni Dar es Salam èyí tíí ṣe olú ìlú kátàkárà Tanzania.
Ìròyìn tó ń tẹ̀ wá lọ́wọ́ ni wí pé ìlera pípé ni olówó oníṣòwò náà wà súgbọ́n ó fara pa lọ́wọ́ àti ẹsẹ̀ nítorí ẹ̀wọ̀n irin tí wọ́n kò síì lọ́wọ́.
Kò sí àrídájú bóyá ẹnikẹ́ni san owó ìtanràn kí wọ́n tó dá a sílẹ̀.
Nínú sọ́ọ̀sì, wọ́n ń sáré lọ síwájú fún ìwòsàn sùgbọ́n lẹ́yìnkùlé,...
Ọdọmọkunrin tó lówó jùlọ ní Afrika ti di awati ni olu ilu orileede Tanzania, Dar es Salaam. nigba ti awọn aijinigbe ji gbe.
Awọn ọlọpaa to kede ijinigbe naa ni Mohammed Dewji  n lọ fún ifaralokun  to ma n se laarọ ní àwọn ajinigbe ṣadede gbé sálọ.
Wọn ni ọwọ ti tẹ eeyan mẹta kan ti wọn si ni meji ninu wọn kii  ṣe ọmọ orileede Tanzania.
Pato idi ti wọn fi ji ọgbẹni Dewji gbe ko ti jẹyọ.
Ta ni Mohammed Dewji?
Financial magazine Forbes says Mohammed Dewji is worth $1.5bn (£980m)
Iwe iroyin nipa ọrọ aje, iyẹn Forbes Magazine so pe biliọnu dola kan le diẹ ni ọrọ Mohammed ti o si jẹ wi pe oun nikan lo ni owo to to bẹ ni Tanzania.
Ninu iwadi kan to jadi ni ọdun 20117, wọn ni ọgbẹni Dewji ni ọdọmọkunrin tó lówó jùlọ ní Afrika.
Ogbẹni Dewji si tun jẹ alatilẹyin fun ọkan lara awọn ilumọka ẹgbẹ agbabọọlu ni Tanzania ti orukọ rẹ njẹ Simba
Iwe iroyin Forbes so pe ni ọdun 2016, o fi idaji owo rẹ se itọrẹ.
Inagijẹ  ti ọpọ eeyan mọ si ni Mo.
Ile iṣẹ rẹ METL pẹka ni orileede Afrika mẹfa ti wọn si  n ṣe aṣọ,ounjẹ ati ororo.
Lati ọwọ  Athuman Mtulya,Akoroyin  BBC Africa, Dar es Salaam
Lati inu ede larubawa ni wọn ti ya orukọ ilu Dar es Salaam ti o tunmọ si ''Agọ Alafia'' city's name comes from Arabic, and literally means Abode of Peace.
Ti a ba se akawe laarin ilu bi Eko tabi Johannesburg ti wọn jẹ olu ilu Nigeria ati South Africa,ko fẹ si wahala pupọni Dar es Salaam.
Lootọ awọn ikọlu kọọkan ti waye ti ijinigbe awọn oloselu kan si waye laipe yi,eyi ni igba akọkọ ti wọn yoo ji onisowo gbe ni Tanzania paapa julọeleyi ti o lorukọ bi ọgbẹni Dewji.
Ko si ifoya fun awọn onisowo ti ọpọ ninu wọ́n a si ma rin lalai ni ẹsọ.
Fun idi ẹyi, ijinigbe ọgbẹni Dewji jẹ oun iyalẹnu.
Ibe Kachikwu ,Mínísítà fún epò rọ̀bì sọ pé òun kò parọ́ ìwé ẹ̀rí
Oríṣun àwòrán, @IbeKachikwu
Àṣìwí kò tó àṣìsọ l'ọ̀rọ̀ tó wà nílẹ̀ nípa mínísítà kejì fún epo rọ̀bì Nàìjíríà, Ibe Kachukwu, tí ìwé ìròyìn kan sọ wí pé ó parọ́ nípa irú ìwé ẹ̀rí tó gbà jáde ni yunifásitì.
Ibe Kachikwu ti fèsì wí pé òun kò parọ́ ìwé ẹrí, bí kò ṣe wi pé àwọn akọ̀ròyìn ṣi òun gbọ́ ní.
Nínú àtẹ̀jáde kan tó fi síta l'ọ́jọ́bọ̀ lójú òpó Twitter, Kachikwu ṣàlàyé pé ohun tí òun sọ ni òun wà lára àwọn akẹ́kọ̀ọ́ tó lákè nígbà tí òun parí ẹ̀kọ́ ìmọ̀  nípa òfin ná yunifásitì Nigeria, Nsukka.
 Ìwé ẹrí tó tẹ̀lé èyí tó tayọ jù ni mo gbà, tí òun ṣì wà lára àwọn akẹ́kọ̀ọ́ tó ṣe dáadáa jùlọ
''Níbi ọrọ ti mo n bá àwọn ọ̀dọ́ sọ níbi ayẹyẹ ilé ìjọsìn Commonwealth of Zion,ohun ti mo sọ ni wí pé mo wà lára àwọn tó l'eke.Ìdí tí mo ṣì fi sọ bẹẹ ni lati ṣe ìwúrí fún àwọn ọ́dọ́, ki wọ́n baa le ṣe dáadáa níbi ẹ̀kọ́ wọn''
Ó tèsíwájú pé nigba ti òun wa ni ilé ẹ̀kọ́ ìmọ̀ òfin l'ọ́dún 1979 ''èmi ni mo tayọ láàrin àwọn tí a jọ wà ní kíláàsì kan na.''
Oríṣun àwòrán, @IbeKachikwu
Kachukwu kawe gboye orisirisi sugbọn iroyin to jade nipa rẹ yi fẹ tapo si aṣọ ala rẹ
''L'ọ́dún ta n wí yí, àmì ẹyẹ márùn ni mo gbà nínú méje tí ilé ẹ̀kọ́ náà fún àwọn akẹ́kọ̀ọ́.''
Ó sọ pé ''kò sí ohun tó jọ ìwé ẹ̀rí tó tayọ jù lọ l'ọ́dún náà, ṣùgbọ́n ìwé ẹ̀rí tí mo gbà ṣe déédéé kí èèyàn gba ìwé ẹ̀rí tó tayọ l'óde òní.''
Tí a kò bá gbàgbé, mínísítà méjì nínú ìjọba Ààrẹ Muhammadu Buhari ni wọ́n ti fi ẹ̀sùn kàn nípa ìwé ẹ̀rí ìsìnrú ìlú ètò àgùnbánirọ̀, NYSC.
Atiku: Ọ̀dọ́ yóò gba isẹ́ 40%, obìnrin yóò mú 30%
Oríṣun àwòrán, @Atiku
Mo ti ṣetan lati sin Naijiria
Oludije si ipo aarẹ lẹgbẹ oselu PDP ni Naijiria fun idibo 2019, Atiku Abubakar ti ni ida aadọrin ninu awọn ti awọn yoo jọ se ijọba yoo jẹ ọdọ ati obinrin.
Abubakar sọ eyi lasiko to n se ipolongo ni ipinlẹ Yola.
Ninu ọrọ rẹ, o ni ida ogoji yoo jẹ fun awọn ọdọ, nigbati ida ọgbọn yoo lọ si ọdọ awọn obinrin ati wi pe awọn agbalagba ni yoo wa ni ida ọgbọn to ku.
Ọba Olutayọ: ìgbésẹ̀ Ọọni àti Alaafin ti ń mú ìṣọ̀kàn dé sáàrin àwọn Ọba Yorùbá
Ìwé ìlànà ìṣèjọba ọlọdún méje tí Atiku gbé jáde lọjọ Àìkú tún sọ wí pé, àwọn eeyan to padanu isẹ wọn lati 2014 ti to miliọnu meje bayii.
Oludije ipo Aarẹ fun ẹgbẹ oselu PDP lorileede Naijiria Atiku Abubakar, ti sefilọlẹ eto ipolongo ibo rẹ ni ọsan ọjọ Aje, to si ni oun ti fa ara oun kalẹ lati ba ireti ati ilakaka awọn ọmọ Naijiria pade.
Nigba to n bawọn omilẹgbẹ ololufẹ rẹ sọrọ loju opo ikansiraẹni Twitter ati Facebook rẹ lori itakun agbaye, Atiku ni, ibeere to se pataki to wa niwaju awọn ọmọ Naijiria ni pe ‘N jẹ igbe aye wọn ru gọgọ si lati ọdun mẹrin sẹyin ti ijọba to wa lode ni orilede yii ti gba ijọba’?
World Toilet Day: Aráàlú ní woléwolé yẹ kó bẹ̀rẹ̀ àyẹ̀wò ojúlé dé ojúlé
Bakan naa lo woye pe ọpọ eeyan ni ko ni isẹ lọwọ, ti ẹka awọn ileesẹ to n pese asọ sita si ti dẹnu kọlẹ patapata.
"Atiku ni "" Orilẹede wa ko tii pinya bii eyi ri, ohun gbogbo lo ti dẹnu kọlẹ, ọpọ eeyan lo ti padanu is wọn, eyi to n sọ awọn ọmọ orilede yii sinu agbami isẹ ati osi. Amọ mo si jẹjẹ lati jẹ́ ki Naijiria gberasọ pada."""
Oríṣun àwòrán, @Atiku
Atiku fi kun pe gbogbo ileri ti oun n se yii kii se afẹnuse lasan, amọ oun setan lati mu ki awn ileri yii wa si imusẹ laipẹ ti oun ba wọle sipo aarẹ.
Oludije ipọ Aarẹ fun ẹgbẹ oselu PDP lorileede Naijiria Atiku Abubakar ti seleri lati pese miliọnu mẹta iṣe lọdọọdun, ti ohun ba jẹ Aarẹ Naijiria.
Ileri yi jẹ ọkan gboogi ninu awọn eto ti o la kalẹ ninu iwe ilana iṣejọba to gbe jade lọjọ Aiku.
Atiku sọ pe ''o sunmọ miliọnu merindinlogun eeyan ni ko nisẹ ni Naijira, ti eyi si fi miliọnu mesan ju iye awọn ti ko nise lọwọ lodun 2014 lọ.''
Oríṣun àwòrán, @atiku
Atiku ni iṣẹ nla lo wa niwaju ohun
''Pipese isẹ ṣe pataki lati maṣe jẹ ki awọn ọdọ darapọ mọ ẹgbẹ kẹgbe ati ti a ba fẹ mu adinku ba awọn ikunsinu to n fa gbọnmisi omi o too lawujọ''
Fun idi eyi,o sọ wi pe oun yoo ṣe ''agbekalẹ eto idanilokowo eleyi ti o muna doko ti yoo si pese pese miliọnu mẹta iṣe ati ọna ise lẹka aladani lọdọọdun''
Yatọ si ọrọ iṣe ti iwe naa mẹnuba,Atiku sọ pe ọun yoo mu idagbasoke ba ipese awọn ohun amayederun ati wi pe ohun yoo mu adinku ba iṣẹ oun oṣi lawujọ.
Oríṣun àwòrán, Atiku.org
Lati ilẹ ni Atiku ti tẹnumọ ipese iṣẹ ni adisọkan rẹ
Bakannaa ni iwe eto iṣejọba naa ni ti awọn ọmọ Naijiria ba dibọ fun Atiku,yoo sọ ajọ to wa nidi ọrọ epo rọbi lorilẹede Naijiria, NNPC di aladani ti yoo si ta awọn ile iṣe ifọpo epo mẹrẹrin to wa ni Naijiria.
Lọjọ aje ni ayeye agbekale ẹto ipolongo Atiku Buhari yoo waye.
Atiku Abubakar ti fi igba kan jẹ igbakeji Aarẹ lorileede Naijiria ti o si wa lara awọn ti o ṣetan lati gba agbara lọwọ Aarẹ Muhammadu Buhari.
Oríṣun àwòrán, Atiku.org
Odu ni Atiku lagbo oselu Naijiria
Lai pẹ yi ni ijọba Naijiria fesi si ẹsun ti Oludije sipo Aarẹ, Atiku Abubakar fi kan awọn oṣiṣẹ papakọ ofurufu to wa ni ilu Abuja pe wọn fi abuku kan oun lasiko ti ọkọ ofurufu oun balẹ si papakọ naa.
Atiku ninu atẹjade to fi si oju opo Twitter rẹ sọ pe awọn oṣiṣẹ fi ipa wọ oun ati oṣiṣẹ oun.
Minisita fọrọ ofurufu, Hadi Sirika lasiko to n fesi ṣalaye pe ẹsun naa ko ni idi nlẹ nitori pe ohun to pọn dandan ni ki wọn ṣe ayẹwo ọkọ ofufuru ati awọn eniyan to ba balẹ si papakọ ofurufu lorilẹ-ede Naijiria.
Sirika fikun un wi pe gbogbo ọ̀wọ̀ tó tọ́ si Atiku ni awọn fi fun un, ati pe ko si ohun to jọ bii arifin ninu iṣẹlẹ naa.
Parental Guidance: Ọdún méjì ni kí ẹ ti bẹ̀rẹ̀ kíkọ́ ọmọ nípa ìbálòpọ̀
Bakan naa, awọn ọmọ Naijiria ti bẹrẹ si ni fun Atiku lesi lori ẹrọ ikansiraẹni Twitter rẹ lẹyin ti o fi ẹsun naa lede.
Lara awọn to fun un lesi bu ẹnu atẹ lu u pe ohun to pọn dandan ni lati ṣe ayẹwo ni papakọ ofurufu ati wi pe ko nii ṣe pẹlu ipo ti eniyan di mu lawujọ.
"Ẹlomiran ninu ọrọ tirẹ ni ""ati minisita, ati ọba ilu o, ko sẹni ti kii ṣe ayẹwo ni papakọ ofurufu""."
Somalia: 'Wọ́n pàṣẹ fún mi láti dá Ramla dúró ká tò lè ṣe igbeyàwó'
Amọ, awọn ẹlomiran dáhùn pe kani bi wọn ṣe n ṣe ayẹwo lojoojumọ fun Atiku ni yii, ko ni ke gbajari si ta wi pe wọn ṣe oun baṣubaṣu ni papakọ ofurufu Abuja.
Ẹgbẹ́ oṣèlú PDP ti ṣeé níkìlọ̀ fún adarí àgbà ẹgbẹ́ oṣèlú All Progressive Congress (APC), Aṣíwájú Bola Ahmed Tinubu lórí pé ó ní ẹ̀rù ò bodò kódà bí Atiku bá lọ ṣèpàdé ní Dubai tàbí nínú igbó.
Wọ́n ní kí Aṣíwájú má kò ara rẹ̀ síta nípa sísọ ọ̀rọ̀ kòbákùngbé sí olùdíje ẹgbẹ́ PDP, Atiku Abubakar.
"''Kò yẹ kí Aṣíwájú gẹ́gẹ́ bí àgbàlagbà fi ọ̀wọ̀ rẹ̀ wọ́lẹ̀ nípa dídarapọ̀ mọ́ ọ̀rọ̀ àlùfànsá sísọ eléyìí tó ti di bárakú ẹgbẹ́ oṣèlú rẹ̀ aláìríṣẹ́ṣe""."
Oríṣun àwòrán, Getty Images
PDP kóTinubu ní ìjánu
"Ẹgbẹ́ oṣèlú PDP nínú àtẹ̀jáde rẹ̀ tí akọ̀wé ẹgbẹ́, Kọla Ọlọgbọ́ndíyàn fọwọ́ sí sọ wí pé ""èèyàn bíi Tinubu leè ṣe òṣèlú rẹ̀ láì dá sí lílo ọ̀rọ̀ òdì èyí tí kò bọ̀wọ̀ fún ènìyàn bíi Atiku ẹni tí gbogbo Nàìjíríà káàkírí ti gbà láti jẹ́ Ààrẹ wọn tó mbọ̀."""
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí:
Ọgọrọ eeyan lo ti fesi lori ẹrọ ayelujara sọrọ ti abẹnugan ẹgbẹ oṣelu APC Asiwaju Bola Tinubu sọ lori ipade oludije fun ipo Aarẹ labé asia ẹgbẹ oṣelu PDP Atiku Abubakar ati awọn alatilẹyin rẹ ṣe ni ilu Dubai.
Adaba tiwa ko nọnni a n kungbẹ, ina n jo ẹyẹ oko n lọ...lowe ti Tinubu fi bọnu lori bi Atiku Abubakar ti lọ ṣepade nilu Dubai.
Òkò ọ̀rọ̀ ṣáájú ìdìbò 2019
Tinubu sọrọ yii lẹyin to ṣepade idakọnkọ pẹlu Aarẹ Muhammadu Buhari nilu Abuja.
Asiwaju sọrọ, o fa kumookun rẹ yọ, o ni ''to ba wu Atiku o le lọ ṣepade ninu aginju igbo tabi ni Abu Dhabi, ohun to wa nibẹ nipe awọn eeyan lanfani lati pade nibi kibi to ba wu wọn. Ṣugbọn o daju pe awọn ọmọ Naijiria ko ni pada s'ijọba PDP mọ.''
@_MrAwaji ati @ayanbaba1 tako ara wọn lori ọrọ Tinubu, @_MrAwaji lo kọkọ sọ pe ẹru lo n ba Tinubu lo jẹ ko sọrọ bẹẹ ṣugbọn @ayanbaba1 ni irọ nio wipe ko si ẹru kankan fun Tinubu ati ẹgbẹ APC.
@CaptainGabby100 ni awọn oriroyin ni wọn n gbe ọrọ yii gẹgẹ, o ni kosi nkankan nibẹ. Amọ o sọ pe Atiku lanfani lati gbegba oroke ninu idibo Aarẹ ọdun 2019 ju Aarẹ Muhammadu Buhari lọ.
Ọrọ lori alaga ẹgbẹ oṣelu APC Adams Oshiomole lo jẹ @KabirAbdulazee6 logun ni tirẹ, o ni wọn yan an sipo wipe ko sẹni to dipo fun gẹgẹ alaga ẹgbẹ APC.
@shittuisiakao tiẹ binu tan, o ni ọpọlọpọ eeyan ko mọ pe ko boju mu rara fun oludije fun ipo aarẹ lati ni ofisi rẹ si ilu okere. Bẹẹ naa lo sọ pe Aarẹ Muhammadu gbọdọ jara mọṣẹ lori iṣejọba rẹ.
Tinubu tun sọrọ lori bi awọn kan ninu ẹgbẹ oṣelu APC ṣe n sọ pe ki wọn yọ alaga ẹgbẹ oṣelu naa Adams Oshiomole nipo, o ni kosi ohun to jọ bẹ rara.
Asiwaju Tinubu ni iku wa ajọku, awẹ wa ajọgba ni ọrọ Oshiomole nitori ẹgbẹ lo yan an sipo to wa.
Obasanjo ṣatilẹyin fun Atiku
Awọn ajagunfẹ́yinti kan ni ilẹ Yoruba ti se atilẹyin fun aarẹ orilẹ-ede yii tẹlẹ, Oloye Olusẹgun Ọbasanjọ lori bo se n se atilẹyin fun igbakeji rẹ, Atiku Abubakar lati lọ dije fun ipo aarẹ orilẹ-ede yii.
Awọn ajagunfẹyinti naa, ti wọn jẹ ẹya Yoruba, ninu eyi ti a ti ri David Medayese Jẹmibẹwọn ati Ajibọla Togun ni, ko si ohun to buru ninu ohun ti Ọbasanjọ se yii, gẹgẹ bo se n sugba Atiku lati di aarẹ Naijiria lọdun 2019.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
"Gẹgẹ bi awọn mejeeji ti wi,"" Bi o tilẹ jẹ pe lọpọ igba ni Ọbasanjọ maa n tako Atiku, sugbọn ko si ohun to buru to ba pinnu lati yi ero rẹ pada nipa Atiku, a sa n pa ọna oko da, anbọsin ọna ẹnu."""
Ìyá àkàndá ẹ̀dá: Àwọn ẹbí mi fẹ́ kí n pa ọmọ mi torí ó jẹ́ àkàndá ẹ̀dá
Awọn ajagunfẹyinti naa ni Ọbasanjọ ko ti s si ofin lori igbesẹ rẹ yii, o si ni ẹtọ labẹ ofin lati sọ tabi se ohun to ba ba ero ọkan rẹ lọ.
Bakan naa, awọn agbagbagba ilẹ Yoruba ti kede pe, igbakeji Aarẹ tẹlẹ ri Atiku Abubakar ni awọn yoo satilẹyin fun ninu ibo Aarẹ lọdun 2019, lẹyin ti Aarẹ ana Oluṣẹgun Obasanjọ kede atilẹyin rẹ fun Atiku.
Akọwe ẹgbẹ ọmọ Yoruba, Yoruba Council of Elders (YCE), Kunle Olajide to ba BBC Yoruba sọrọ salaye pe, o ṣeeṣe ki ẹgbẹ agbaagba ilẹ Yoruba tẹle Atiku nitori oun fara mọ atunto Naijiria, ti ẹgbẹ naa ti n sọ fun igba pipẹ.
Ètò Atiku ló bá èròngbà Yorùbá mu
Sẹ́nẹ́tọ̀ Femi Okunronmu sọ pé Atiku ló le tún Nàìjírìa ṣe
Bakannaa Sẹnẹtọ Femi Okunronmu naa sọrọ, to si fa komookun rẹ yọ pe, ibi ti Obasanjọ lọ gan an l'oun n lọ lori ọrọ ibo Aarẹ lọdun 2019.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí:
Ṣọla Allyson: Obìnrin tí kò bá rẹwà ni yóò máa ṣí ara sílẹ̀
Okunronmu sọ pe, Atiku lo to gbangba sun lọyẹ lati gba awọn ọmọ orilẹede Naijiria lọwọ iṣẹ ti o n ba wọn finra, ati pe Atiku lo le ṣe eto aabo to peye lorilẹede Naijiria.
Ẹwẹ, ile iṣẹ Aarẹ ti fesi tẹlẹ pe Aarẹ orilẹede Naijiria ana, Olusẹgun Obasanjọ ati igbakeji rẹ Atiku Abubakar, yoo jọ padanu ninu idibo Aarẹ ọdun 2019 nigbati Aarẹ Muhammadu Buhari ba jawe olubori.
Oluranlọwọ pataki fun Aarẹ Buhari Garba Shehu, lo fọrọ naa lede lẹyin ti Obasanjo kede pe oun ti dariji Atiku, ati pe oun ṣetan lati ṣatilẹyin fun-un lati di aarẹ Naijiria.
Shehu salaye pe, igbesẹ Obasanjo ko ya Aarẹ Buhari lẹnu, nitori o fi han gbangba pe, oye nipa eto oṣelu ode oni ko ye e.
Oríṣun àwòrán, Usman Okai Austin
Kódà, ìpàdé nàá kò yọ àwọn olórí ẹ̀sìn sílẹ̀
O fi kun ọrọ pe, Aarẹ Buhari ti kọ eti ikun si ọrọ Obasanjo ati Atiku nitotri o n tẹsiwaju ninu eto igbogun ti iwa ibajẹ ati ṣiṣe owo ilu kumọkumọ
Ẹyin l'ohùn,tó bá ti jabọ kìí ṣe ko mọ
Rẹgi ni ọrọ yi ṣe ti a ba wo ọrọ ti Aarẹ ana l'orileede Naijiria, Olusẹgun
Oríṣun àwòrán, @atiku
Ṣaaju ni Ọbasanjọ sọ pe Ọlọrun ko ni dari ji oun ti oun ba gbe lẹyin Atiku Abubakar.
Ṣugbọn, bi Ọbasanjọ ṣe ti wa a yi ero rẹ pada pẹlu bi o ti se fori jin Atiku, to si tun sọ pe  oun ''ṣetan lati ṣatilẹyin fun lati di aarẹ Naijiria'' ti n mu iriwisi ọtọọtọ wa lori ayelujara.
Tẹ o ba gbagbe, abi ko dayin loju wi pe o sọ ọrọ yi, ẹ wo fọnran fidio yi nibi ti Obasanjọ ti n sọrọ nipa Atiku ninu iwe rẹ to fi sita,''My Watch''.
Ninu ifọrọwanilẹnuwo ninu fọnran naa to wa loju opo YouTube,Ọbasanjọ sọ pe pẹlu ''ohun ti oun mọ nipa Atiku, Ọlọrun ko ni forijin oun ti oun ba segbe lẹyin Atiku''
Ṣe Ọlọrun yoo fori ji Ọbasanjọ?
Ibeere re ti awọn ọmọ Naijiria n gba ni agba tungba loju opo Twitter niyii lẹyin ti Obasanjọ fori jin Atiku.
Sugbọn kii ṣe ọrọ Obasanjọ nikan lo gboju opo ayelujara.
Awọn kan mẹnu ba bi awọn adari ẹsin kan bi David Oyedepo,Sheikh Ahmad Gumi ati Bisọọbu Mathew Kuka ti ṣe kọwọrin lọ ọ ba Atiku pari aawọ laarin oun ati Obasanjọ
L'ọjọbọ ni Atiku Abubakar tii ṣe oludije fun ipo aarẹ labẹ asia ẹgbẹ oṣelu Peoples Democratic Party, PDP, Atiku Abubakar, gunlẹ si ile aarẹ ana l'orilẹede yii, Oloye Oluṣẹgun Ọbasanjọ ni nkan bi aago kan ọsan.
Lẹyin ipade naa, Atiku Abubakar sọ pe idunnu lojẹ fun oun lati ṣepade pẹlu ọ̀ga oun nigba kan, tawọn si tun jọ jẹ ounjẹ ọsan.
Abubakar to jawe olubori laipẹ yii gẹgẹ bi aṣoju ẹgbẹ PDP fun idibo aarẹ ti yoo waye ni Naijiria l'ọdun 2019, lo ṣeeṣe ko bẹ Ọbasanjọ wo pẹlu ireti pe yoo ṣe atilẹyin fun erongba rẹ lati di aarẹ orilẹede Naijiria.
Atiku Abubakar jẹ igbakeji aarẹ lasiko ti Ọbasanjọ fi jẹ aarẹ Naijiria laarin ọdun 1999 si 2007. Ṣugbọn, aarin awọn mejeeji pada daru, ti Ọbasanjọ si jẹẹjẹ pe oun ko ni ṣatilẹyin fun ipinnu Atiku lati aarẹ Naijiria lailai.
Oríṣun àwòrán, Usman Okai Austin
Atiku bẹ Ọbasanjọ wo pẹlu ireti pe yoo ṣe atilẹyin fun erongba rẹ lati di aarẹ orilẹede Naijiria.
Bakan naa ni alaga gbogboogbo fun ẹgbẹ oṣélu PDP, Uche Secondus, ati oludari eto ipolongo ibo fun Atiku, Gbenga Daniel, naa kọwọrin pẹlu rẹ.
Awọn olori ẹ̀sìn bi olùdásílẹ̀ ìjọ Living Faith Church, Bíṣọ́ọ̀pù David Oyedepo, tó fi mọ Bíṣọ́ọ́pù ijọ Aguda ni ipinlẹ Saokoto, Matthew Kukah, ati Oniwaasu ẹsin Islam, Ahmed Gumi. Sẹnetọ Ben Murray-Bruce ati Alagba Ayọ Adebanjọ to jẹ eekan ninu ẹgbẹ Afẹnifẹre.
'Mo kẹ́kọ̀ọ́ fásitì sùgbọ́n aṣọ òké ló ń jáwó báyìí'
Celestine ẹlẹ́wọ̀n: Òun àti ọmọ rẹ̀ ló wà lọ́gbà ẹ̀wọ̀n
Oríṣun àwòrán, GLOBAL SOCIETY FOR ANTI-CORRUPTION
Paul àti Celestine Egbuchune ti lo ọdún méjìdínlógún ní ọgbà ẹ̀wọ̀n
Celestine Egbunuche ti pé ọgọ́rùn ún ọdún, tí àwọn kan si gbàgbọ́ pé òun ni ẹlẹ́wọ̀n tó dàgbà jù ní Nàìjíríà, èyí sì tí mú kí àwọn ènìyàn maa bẹ ìjọba láti tu u sílẹ̀.
Ó ti lo ọdún méjìdínlógún ní ọgbà ẹwọn lẹ́yìn tí wọ́n ní ó kó àwọn kan jọ láti ṣekúpa ẹnìkan.
Celestine àti ọmọ rẹ̀ ọkùnrin, Paul Egbunuche, tó jẹ́ ẹni ọdún mọ́kànlélógójì, ni wọ́n jọ wà nínú ọgbà ẹ̀wọ̀n Enugu Maximum Security Prison, ní ẹkùn Ìlà Oorùn Gúsù, fún ẹ̀sùn kan nàá.
Ṣọla Allyson: Obìnrin tí kò bá rẹwà ni yóò máa ṣí ara sílẹ̀
Wọ́n fi ẹ̀sùn kan wọ́n pé wọ́n gba àwọn ènìyàn kan láti jí ọkùnrin kan gbé, tí wọ́n sì tún pa á nítorí ilẹ̀ ní ìpínlẹ̀ Imo.
Bàbá àgbàlagbà ọ̀hún kò le sọ̀rọ̀ mọ́, ó sì n ṣe bi ẹni tó ní àìsàn, débi pé ọmọ rẹ̀ ló n gba ẹnu rẹ̀ sọ̀rọ̀.
Nínú oṣù Kẹfà, ọdún 2000, ni ọwọ́ ọlọ́pàá tẹ̀ wọ́n, kó tó di pé wọ́n dájọ́ ikú fún bàbá àti ọmọ ní ọdún 2014. Paul sọ pé àwọn kò jẹ̀bi ẹ̀sùn tí wọ́n fi kan àwọn.
Ó sọ pé bàbá òun kò tilẹ̀ mọ nkankan tó n lọ ní agbègbè rẹ̀ mọ́.
''Tí ẹ bá bi i ní ìbéèrè kan, ọ̀tọ̀ ni ìdáhùn tí yóò fún yín. Àwọn dókítà sọ fún mi pé ọjọ́ orí rẹ̀ lójẹ́ kí ó maa ṣe bi ọmọdé.''
''Nígbà míràn, ó maa n bi mí pé kíni àwọn ènìyàn yìí (àwọn ẹlẹ́wọ̀n) n ṣe níbí?''
Ọ̀pọ̀lọpọ̀ àwọn ẹlọ́wọ̀n ló n retí ìdájọ́ ikú láti ọjọ́ pípẹ́.
Paul sọ pé òun ni ó n tọ́jú bàbá òun nínú ẹ̀wọ̀n láti ìgbà tí ìlera rẹ̀ ti mẹ́hẹ̀. Ó ní àìsàn ìtọ̀ ṣúgà, ojú rẹ̀ kò sì ríran dáàda mọ́.
''Ọ̀gẹ̀dẹ̀ tí kò pọ́n ni mo maa n fun un jẹ́, àwọn olùṣọ́ ọgbà ẹ̀wọ̀n naa si maa n fun ní òògùn.''
Inú yàrá kan naa ni Paul àti bàbá rẹ̀ jọ wà l'ọ́gbà ẹ̀wọ̀n, pẹ̀lú àwọn ẹlẹ́wọ̀n mi i  tó n retí ìdájọ́ ikú.
"Tí mo bá jí ní òwúrọ̀, màá gbé omi kaná láti fi wẹ̀ fun un.''
Wo fidio 'ẹwọn idẹra'
''Màá pàárọ̀ aṣọ rẹ̀, màá sì ṣe oúnjẹ rẹ̀ fun un. Tí wọ́n bá ṣí ìlẹ̀kùn yàrá tí a wà, máà gbe jáde síta kí òòrùn le pá díẹ̀.''
Paul sọ pé àwọn ẹlẹ́wọ̀n yóòkù maa n ran òun lọ́wọ́ láti tọ́jú bàbá rẹ̀ nígbà mi i.
Lẹ́yìn tí Bàbá àgbà Celestine ṣe ọjọ́ ìbí ọgọ́rùn ún ọdún l'ọ́gbà ẹ̀wọ̀n ni àwọn akọ̀ròyìn kọ nípa rẹ̀.
Àwọn ènìyàn sì bẹ̀rẹ̀ sí bèérè pé ọdún mélòó gan ló yẹ́ kí ẹni tó bá ti gba ìdájọ́ ikú lò l'ẹ́wọ̀n.
Àkọsilẹ̀ láti iléèṣẹ́ ọgbà ẹ̀wọ̀n Nàìjíríà fihàn pé àwọn ẹlẹ́wọ̀n tó lé ní ẹgbẹ̀rún méjì ló n retí ikú ní àwọn ọgbà ẹ̀wọ̀n ní Nàìjíríà.
Oríṣun àwòrán, AFP
Ó ṣeesẹ kí Gómìnà ìpínlẹ̀ Imo, Rochas Okorocha buwọ́ lùú pé kí wọ́n tú Alàgbà Egbuchune sílẹ̀.
Pamela Okoroigwe tó jẹ́ agbẹjọ́rò fún ètò ìrànwọ́ Legal Defence and Assistance Project (LEDAP) sọ pé ''ó wọ́pọ́ láti bá ẹni tó ti gba ìdájọ́ ikú láti bi ọgbọ̀n ọdún.''
Àwọn gómìnà kìí ṣábà buwọ́ lu àṣẹ láti pa ẹlẹ́wọ̀n, bákan nàá ni wọ́n kìí fún wọn ní òmìnira, ló fàá tí àwọn ẹlẹ́wọ̀n tó n retí ikù pọ̀.''"
Franklin tó jẹ́ ààrẹ ẹgbẹ́ tó n gbógun ti ìwà ìbàjẹ́, Global Society for Anti-Corruption (GSAC) sọ pé àwọn ti fi ọ̀rọ̀ Alàgbà Egbuchune tó ìjọba àti agbẹjọ́rò àgbà fún ìpínlẹ̀ Imo, Miletus Nlemedim létí, pé kí ìjọba f'oríji bàbá nàá, ṣùgbọ́n gómìnà Rochas Okorocha kò tìí buwọ́ lùú.
Ọmọ rẹ̀, Paul sọ pé ''yóò dára tí wọ́n bá fun ní òmìnira, kó le bà á ní ànfàání láti kú ní ìrọ̀rùn ní ilé rẹ̀ ju pé kó kú sínú ọgbà ẹ̀wọ̀n.
Ìtàn Mánigbàgbé: D.O Fágúnwà máa ń sùn sí ibojì, aginjù tàbí ti ara rẹ̀ mọ́lé láti kọ̀wé
Ẹmi kan lo maa n dari Fagunwa, to si maa n ba ẹmi airi sọrọ
Ọpọ ọdọ lode oni ni ko mọ ohunkohun nipa gbaju-gbaja Onkọwe nni, to kọkọ kọ iwe ni ede abinibi nilẹ adulawọ, eyiun Daniel Ọlọrunfẹmi Fagunwa.
D.O Fagunwa, gẹgẹ bi ọpọ eeyan se mọ si, lo kọ iwe Ogboju ọdẹ ninu igbo Irunmọlẹ̀ lọdun 1938, Igbo Olodumare lọdun 1945, Ireke Onibudo lọdun 1949, Irinkerindo ninu igbo Elegbeje lọdun 1954, Adiitu Olodumare ni 1961, to si n kọ apa keji rẹ, to pe ni Ireọla Olodumare ati Igbo Adimula lọwọ nigba ti Ọlọjọ de.
Ohun to yẹ ko mọ nipa D.O Fagunwa
'Èmi gan máa ń béèrè lọ́wọ́ ara mi pé ta ni Wole Soyinka gangan'
Mo fi iṣẹ́ Banki silẹ̀ lọ bẹ̀rẹ̀ alápatà - Derin
Sogidi Lake: Kòṣẹja-kòṣèèyàn lá bá nínú adágún odò náà -Ojedele
BBC Yoruba gbọ pe lati igba ti D.O Fagunwa ti dara ilẹ, Ijọba ko fi bẹẹ se ohunkohun lati maa se iranti rẹ, tawọn ẹbi rẹ ko si ri ọwọ ijọba rara.
Sugbọn bi onirese Daniel Ọlọrunfẹmi Fagunwa ko ba fingba mọ, awọn eyi to ti fin silẹ, ko lee parun.
Illegal Rehab Centre: A le ni ogójì tí wan n kó 'sinú ìyará kékeré kan níle Ọlọrẹ
BBC: Ìrọ́ ní, a kò ṣètò owó ẹ̀kọ́ òfẹ fún akẹ́kọ̀ọ́ gboyè fásítì
BBC: Ìrọ́ ní a kò ṣé ètò owó ẹ̀kọ́ òfẹ fún akẹ́kọ̀ọ́ gboyè fásítì
Àtẹ̀jíṣẹ́ kan ti ń jà ràin-ràin ká orí ẹ̀rọ ayélujara bayii pé, BBC ń ṣètò owó ẹ̀kọ́ ọ̀fẹ́ fún àwọn akẹ̀kọ̀ọ́ gboyé àkọ́kọ̀ ní fásítì lórílẹ̀-èdè Nàìjíríà atawọn to nílò ẹ̀yáwó láti tẹ̀síwájú nílùú òyìnbó.
Àtẹ̀jíṣẹ́ náà tun fi kun pe, BBC ń fẹ́ láti ran ọ̀gọ̀run lọ́nà ẹgbẹ̀rùn àkẹ́kọ̀ọ́ jáde fásitì lọ́wọ́ láti tẹ̀síwáju nínú ẹ̀kọ́ wọn ní Fásítì tó wù wọn lágbàyé.
Nibayii, ileesẹ BBC lagbaye ati ni orilẹ-ede Naijiria ti wa n kede bayii pe, irọ to jinna sootọ ni ahesọ ọrọ yii, oun ko gbero lati seto iranwọ iranwọ owo eto ẹ́kọ fun akẹkọọ kankan ni Naijiria tabi loke okun.
Ṣọla Allyson: Obìnrin tí kò bá rẹwà ni yóò máa ṣí ara sílẹ̀
Ilé iṣẹ́ BBC kò ṣe ètò owó ẹ̀kọ́ ọ̀fẹ́
Gẹgẹ bi ileesẹ BBC lagbaye ti wi, yoo dara kawọn araalu yẹra fun awọn iroyin ti ko lẹsẹ nilẹ bii iru eyi.
BBC tun gba wọn nimọran lati yẹra fawọn onijibiti ẹda to lee fẹ maa gbe wọn mọra lati gba owo iforukọsilẹ lọwọ wọn.
Jemimah: Wàhálà àwọn òbí mi pọ̀ ló jẹ́ kí n gbé ara mi níyàwó
Oríṣun àwòrán, Lulu Jemimah
Arábìnrin kan tó ti sú láti maa dáhùn ìbéèrè lori ìdí tí kò fi tì i l'ọ́kọ, ti gbé ara rẹ̀ níyàwó.
O ti su Lulu Jemimah láti maa gba ìdánilẹ́kọ̀ọ́ lórí ìdì tó fi gbọdọ̀ l'ọ́kọ.
Ṣùgbọ́n, ìgbéyàwó kò ti lee sí ní ọkàn rẹ̀ rárá, nítorí pé óun kẹ́kọ̀ọ́ láti gba oyè ìmọ̀ ìjìnlẹ̀ kejì nínú iṣẹ́ tó yàn láàyò ní fásitì Oxford, tó wà ní ilẹ̀ Gẹ̀ẹ́sì.
Ṣọla Allyson: Obìnrin tí kò bá rẹwà ni yóò máa ṣí ara sílẹ̀
Ṣùgbọ́n, ìgbéyàwó kò ti lee sí ní ọkàn rẹ̀ rárá, nítorí pé ó n kẹ́kọ̀ọ́ láti gba oyè ìmọ̀ ìjìnlẹ̀ kejì nínú iṣẹ́ tó yàn láàyò ní fásitì Oxford, tó wà ní ilẹ̀ Gẹ̀ẹ́sì.
Níṣe ni Lulu dájọ́ ayédèrú ìgbéyàwó, àmọ́ ó fún àwọn ọ̀rẹ́ rẹ̀ ní ojúlówó ìwé ìpè.
Ó yá aṣọ ìyàwó, ó sì lọ síbi tí ayẹyẹ ìgbéyàwó nàá yóò ti wáyé. Ìgbà tí ayẹyẹ bẹ̀rẹ̀ ni ó tó sọ fún àwọn àlejò rẹ̀ pé kò sí ọkọ kankan.
Lulu jẹ́wọ́ pé, òun gbé ìgbésẹ̀ ọ̀hún láti lé fi rú bàbá àti màmá rẹ̀, tó wà ní ìlú wọn ní Uganda, l'ójú ní, ṣùgbọ́n ó sọ pé, ayẹyẹ nàá ni ọ̀nà pàtàkì láti so òun àti ètò ẹ̀kọ́ rẹ̀ papọ̀.
Gbogbo owó tó ná fún ayẹyẹ nàá kò sì ju ẹgbẹ̀rún kan àti àádọ́ta Naira tàbí Dọ́là mẹ́ta lọ̀, eyi si jẹ owó ọkọ̀ tó gbe de ibùdó ayẹyẹ nàá, nítorí pé àwọn ọ̀rẹ́ rẹ̀ dá nkan ìpanu, owó àti ẹ̀bùn jọ fun un.
Oríṣun àwòrán, Lulu Jemimah
Lulu sọ pé ''ara n yá mi láti mú àfojúsùn mi láti jẹ́ ọ̀mọ̀wé ṣẹ.''
''Ṣùgbọ́n nkan ẹyọkan tí ẹbí mi n bá mi sọ ni ìgbà tí màá ṣe ìgbéyàwó - òhun ló ṣe pàtàkì jù ní ìlú tí mo ti wá ní Uganda - ìgbà tí màá bímọ ló sì tẹ le.''
"Ìgbà tí mo pé ọmọ ọdún mẹ́rìndínlógún ni bàbá mi ti kọ ọ̀rọ̀ tí yóò sọ níbi ayẹyẹ ìgbéyàwó mi''
''Àdúrà kan ṣoṣo tí màmá mi sì maa n gbà fún mi láti ìgbà tí mo ti di obìnrin, kò ju ọkọ níní lọ
Bó tilẹ̀ jẹ́ pé Lulu ti ṣe àṣeyọrí lẹ́nu ẹ̀kọ́ rẹ̀ lẹ́yìn tó gba ẹ̀bùn ẹ̀kọ́ ọ̀fẹ́ láti gba oyè ìmọ̀ ìjìnlẹ̀ àkọ́kọ́ l'órílẹ̀-èdè Australia, tó sì tún ti ṣiṣẹ́ pẹ̀lú iléèṣẹ́ kan nínú àjọ ìṣọ̀kan àgbáyé, ohun kan tó kan ẹbí rẹ̀ ni ìgbà tí yóò mú ọ̀rẹ́kùnrin rẹ̀ wá sílé, tí yóò sì ṣe ìgbéyáwó.
Oríṣun àwòrán, Lulu Jemimah
Lulu Jemimah
Ìgbà tó ṣe àbẹ̀wò sí Uganda l'óṣù Kẹjọ fún ayẹyẹ ọjọ́ ìbí ọdún kéjìlélọ́gbọ̀n rẹ̀, ní eròngbà nàá wọ́ ọ́ l'ọ́pọlọ.
Lulu sọ pé ''ní kété tí mo fi ìwé ìpè ránṣẹ́, ni àwọn ènìyàn bẹ̀rẹ̀ sí pè mí pé taa ni ọkọ ìyàwó, ṣùgbọ́n mo sọ pé ìyàlẹ́nu ni mó fẹ́ fi ṣe fún wọn.''
Bó tilẹ̀ jẹ́ pé ìyá àti bàbá Lulu kò wá fún ayẹyẹ nàá, Lulu padà sọ fún wọn.
Lulu sọ pé, bàbá òun kò tì sọ ohunkóhun nípa ìṣẹ̀lẹ̀ nàá, ọ̀rọ̀ nàá jẹ́ kàyéèfì fun un, ó sì tún dùn ún.
Lulu padà ṣàlàyé fún màmá rẹ̀ pé, aṣọ ìgbéyàwó jẹ́ àpẹrẹ pé òun ti ṣetan láti l'ọ́kọ.
Ìjámbá ọkọ̀: Ẹ̀mí mẹ́rin sọnù sínú ìjámbá ọkọ̀ n'Íbàdàn
Oríṣun àwòrán,  BBC
Ẹni kẹrin dúró jẹ́ẹ̀jẹ́ rẹ̀ ni, ṣùgbọ́n ọkọ̀ epo nàá kan an ẹsẹ̀ rẹ̀ méjèéjì, ó sì tún kú kí wọ́n tó ò gbe dé ilé ìwòsàn.
Omijé ló gba ojú àwọn ènìyàn ní agbègbè Ring Road nílùú Ibadan lẹ́yìn tí ìjàmbá ọkọ kan gba ẹ̀mí ènìyàn mẹ́rin lọ.
Akọ̀ròyìn BBC tó bẹ ibi tí ìjàmbá nàá ti wáyé wò jábọ̀ pé ìjàmbá nàá wáyé láàrin ọkọ̀ agbépo iléèṣẹ́ Total kan, àti ọkọ̀ takisí Micra kan tó fi mọ ọ̀kadà kan ní ọjọ́ Ẹtì ní òpópónà tó lọ láti Challenge sí Ring Road.
Ènìyàn mẹ́rin; lára wọn ni obìnrin kan àti ọmọ ti kò tí ì le pé ọdún kan tó pọ̀n sẹ́yìn rẹ̀, ló pàdánù ẹ̀mí wọn sínú ìjàmbá ọkọ nàá.
Ijamba ọkọ le m'ẹmi lọ
Àwọn ti ìṣẹ̀lẹ̀ nàá ṣojú wọn sọ fún akọ̀ròyìn BBC Yoruba pé ọkọ̀ agbépo ọ̀hún tó kún bámú fún epo ni bíréèkì ọkọ̀ rẹ̀ déède kọ̀ láti ṣiṣẹ́ ní apá ibi tí ọ̀nà naa ti da gẹ̀gẹ́-gẹ̀rẹ́, èyí tó mú kí o fara ti takisí Micra nàá 'láti ràn án lọ́wọ́.'
ṣùgbọ́n ti Micra naa ya ara rẹ̀ kúrò, èyí tó mú kí ọkọ̀ agbépo nàá lọ kọ lu alùpùpù (ọ̀kadà) kan tó fẹ́ já àwọn èèrò tó gbé; obìnrìn nàá àti ọmọ rẹ̀.
Ṣùgbọ́n, orí kò kó ọlọ́kadà nàá àti àwọn èérò rẹ̀ yọ nítorí pé l'ójú ẹsẹ̀ ni gbogbo wọ́n kú.
Ṣọla Allyson: Obìnrin tí kò bá rẹwà ni yóò máa ṣí ara sílẹ̀
Ẹni kẹrin dúró jẹ́ẹ̀jẹ́ rẹ̀ ni, ṣùgbọ́n ọkọ̀ epo nàá kan an ẹsẹ̀ rẹ̀ méjèéjì, ó sì tún kú kí wọ́n tó ò gbe dé ilé ìwòsàn.
Ọwọ́ àwọn òṣìṣẹ́ aláàbò tó wà ni ìbi tí ìjàmbá nàá ti wáyé ti tẹ awakọ̀ ọkọ̀ epo nàá, tí wọn kò sì jẹ́ kí àwọn aráàlú pá, tàbí dáná sun ọkọ̀ epo rẹ̀.
Bákan nàá ni àwọn òṣìṣẹ́ àjọ ẹ̀ṣọ́ ojúpópó, FRSC, ti kó àgékù ara àwọn tó kú lọ sí ilé ìgbókùú sí.
Agneroh: Ohun gbogbo tí ẹ bá rí lórí ẹ̀rọ ayélujára kọ́ ni òtítọ́
Oríṣun àwòrán, CHRISTIAN SHABANTU MPENGA
Arábìnrin Arlène Agneroh sọ ìrírí rẹ̀ lórí ẹ̀rọ ayélujáre lẹ́yín tò fi àwòrán ọ̀hún àti ọ̀rẹ́ rẹ̀ ọkùnrin tí wọ́n ti wọ asọ kan náà sórí afẹ́fẹ́.
Arabinrin to jẹ ọmọwe ati gbajumọ lawujọ, Arlène Agneroh sọ iriri rẹ lori bi awọn eniyan se ma n fi agbara mu awọn ọmọbinrin to ti to oju bọ, lati lọ fẹ ọkọ, nitori abamọ nla ni loju wọn ti obinrin to ba balaga, ko ba fẹ ọkọ lasiko.
Ọrẹ Arlẹ̀ne kan lo fi iwe ipe ransẹ si i wi pe, oun se igbeyawo ni Kinshaha, to jẹ olu-ilu Democratic Republic of Congo, ti oun ati ọrẹ ọkunrin rẹ si jọ wọ asọ kan naa gẹgẹ bo se wọpọ laarin awọn ẹya ilẹ naa, lati  ma a da asọ ẹbi lasiko igbeyawo.
Arlene ni, oun ati ọrẹ oun ọkunrin ti wọn jọ joko papọ ni wọn wọ asọ kan naa, ti wọn si ya aworan lati fi si ori ẹrọ ikansiraẹni Facebook.
Ṣọla Allyson: Obìnrin tí kò bá rẹwà ni yóò máa ṣí ara sílẹ̀
Ọrẹ wọn miran to wa si ibi igbeyawo naa, to ya awọn aworan lorisirisi lo fi si ori itakun rẹ ni Facebook.
Arlene ni, ka to wi ka to fọ ni ipe bẹrẹ si ni ja lu ipe lori ẹrọ ilewọ oun ati gbogbo oju opo ikansiraẹni, ti awọn eniyan si n ki oun ku orire igbeyawo ati wi pe ọjọ wo gangan ni igbeyawo ọhun, ki awọn ba le wa yẹsi.
N se ni ẹnu ya Arlene, to si pinnu pe oun ati ọrẹ oun naa yoo ya aworan miran ni aaye ọtọ, lori aga ti wọn ma n pese fun awọn ọkọ ati iyawo lọjọ igbeyawo wọn, lati fi kọ awọn eniyan ni ọgbọn wi pe, ohun gbogbo to dan kọ ni wura.
Ninu ọrọ rẹ, Arlene ni ọrọ ọhun ju ti tẹlẹ lọ, ti awọn miran ti ẹ n beere fun gbagede ti wọn ti fẹ se igbeyawo naa, ati wi pe, awọn mọlẹbi ati ibatan ti oun ko gburo lati bii ogun ọdun sẹyin bẹrẹ si ni pe oun.
Oríṣun àwòrán, LARISSA DIAKANUA
Kii se gbogbo aworan ti eniyan ba fi si oju opo ikansiraẹni ni o jẹ otitọ tabi ki awọn eniyan ma a sọ oun ti oju wọn kori
Ìyá àkàndá ẹ̀dá: Àwọn ẹbí mi fẹ́ kí n pa ọmọ mi torí ó jẹ́ àkàndá ẹ̀dá
Lẹyin eyi ni Arlene wa gbe igbese lati kilọ fun awọn eniyan lori ẹrọ ayelujara wi pe, gbogbo ohun to dan ko ni wura, nitori ọrẹ lasan ni awọn mejeeji, ti ko si si ohun to jọ igbeyawo ninu aye oun bayii.
Ati wi pe, kii se gbogbo aworan ti eniyan ba fi si oju opo ikansiraẹni, ni o jẹ otitọ tabi ki awọn eniyan ma a sọ ohun ti oju wọn ko ri.
Igbésẹ̀ Buhari láti yọ orúkọ Omisore àti Obanikoro kò bójú mú
Oríṣun àwòrán, @MBuhari
Àwọn ẹgbẹ́ ọ̀dọ́ Yorùbá kan tí korò ojú sí ìgbésẹ̀ ààrẹ Muhammadu Buhari fún yíyọ oríkọ Sẹnátọ Iyiola Omisore àti Musiliu Obanikoro kúrò nínú àwọn orúkọ ti wọn fi síta pé wọn ò gbọdọ̀ rìnrìn àjò lọ sí òkè òkún.
Àwọn ẹgbẹ́ ọ̀dọ́ ọ̀hún sọ èyí di mímọ̀ nínú àtèjáde kan tí ààrẹ ẹgbẹ́ náà Olalekan Hammed àti akọ̀wé ẹgbẹ́ Olawale Ajao fọwọ́sí nílùú Osogbo lójọ́ Ìsinmi.
Wọn ní yíyọ orúkọ̀ àwọn olóṣèlú méjèèjì ọ̀hún túbọ̀ ń fi lọ́lẹ̀ pé gbígbogun tí ìwà jẹgúdújẹrá tí ìjọba Buhari ń jà ń fári apá kan dápákan sí ni.
Awọn ọ̀dọ́ Yorùbá ọ̀hún sọ pé ìyàlẹ́nu ló jẹ́ láti ríi pé ìjọba yọ orúkọ àwọn olóṣèlú méjèjì tí wọn ni ẹsun ìkówójẹ lọ́rùn
PDP: Buhari ni kẹ mú tí ibi bá se ọmọ ẹgbẹ́ alátakò
Oríṣun àwòrán, BayoOmoboriowo
Ẹgbẹ oṣelu alatako gboogi ni Naijiria, PDP ni, oun kọ igbesẹ iṣakoso aarẹ Muhammadu Buhari lati maa lo aṣẹ onikumọ tabi dẹyẹ si ẹgbẹ tabi ẹya kankan ni orilẹ-ede naa.
PDP ni, oun tako aṣẹ ti Buhari pa lati fi ofin de awọn ọmọ Naijiria kan lati ma se rinrinajo lọ silẹ okeere.
Akọwe ipolongo ẹgbẹ PDP, Kọla Ọlọgbọndiyan, ninu ikede kan to fi sita sọ pe, ọna lati gbogun ti awọn ọmọ ẹgbẹ oṣelu alatako, to fi mọ awọn ti Buhari n foju wo gẹgẹ bi ọta rẹ, awọn olori ẹsin ati awọn oniṣowo, ti wọn n foju wo pe, o tako idibo yan Buhari gẹgẹ bi aarẹ fun saa keji, ni asẹ naa wa fun.
PDP ti wa kesi awujọ agbaye, lati di ẹbi ru eto iṣakoso Buhari ti iṣẹlẹ buruku kankan ba ṣẹlẹ si olori ẹgbẹ oṣelu alatako kankan, to fi mọ awọn oniṣowo pataki tabi olori oṣelu jakejado Naijiria, lasiko ti imurasilẹ lọ lọwọ fun eto idibo ọdun 2019.
Ṣé ẹ rántí orin - Má ṣe jẹ́jẹ́ ma wà mi lọ?
Bẹẹ ba gbagbe, ọjọ Abamẹta ni ileeṣẹ Aarẹ Naijiria kede pe, oun fi ofin de awọn aadọta awọn ọmọ Naijiria to jẹ eekan ilu, lati mase rinrinajo lọ si ilẹ okeere.
Bo tilẹ jẹ wi pe wọn ko gbe orukọ awọn aadọta eniyan naa sita, sibẹ, agbẹnusọ fun aarẹ, Garba Shehu to fi ikede naa sita sọ pe, awọn ti ọrọ̀ kan jẹ awọn eeyan to ni dukia ti owo rẹ to aadọta miliọnu Naira, ti wọn si ti fi ẹsun iwa ibajẹ kan wọn.
Ọrẹ Falọmọ: Buhari yóò rí ìbò Yorùbá gbà ju Atiku, Ọbasanjọ lọ
Shehu salaye pe, aṣẹ ti aarẹ Buhari pa ọhun jẹ ọkan lara ọna lati ri daju pe, ofin ti wọn n pe ni 'Executive Order Number 6' fidimulẹ, eyi ti ko faaye gba ẹnikẹni ti o ba ni iru dukia bẹẹ, ti ijọba si n wadi rẹ fun ẹsun iwa ibajẹ, lati raaye fi orilẹ-ede Naijiria silẹ, titi ti wọn yoo fi gbe igbesẹ to tọ lori ọrọ wọn.
Bakan naa ni shehu sọ pe, 'ijọba n sọ bi awọn ti ọrọ ọhun kan ṣe n nawo lati le ri daju pe wọn ko ta iru dukia bẹẹ, tabi dọwọ bo iṣẹ iwadi loju.
Ati pe, aarẹ Muhammadu Buhari ti paṣẹ fun Agbẹjọro agba to tun jẹ minisita fun eto idajọ̀ ni Naijiria, lati ri daju pe ofin naa ṣe iṣẹ rẹ.
O si rọ gbogbo ọmọ Naijiria rere pe, ki wọn fi ọwọ sowọpọ pẹlu eto iṣakoso aarẹ Buhari ninu igbogun ti iwa ibajẹ ni ibamu pẹlu ofin ọdun 1999.
Ìlú Igbo-Ọra: Ijọba ipinlẹ Ọyọ ṣe ayẹyẹ ọdun ibeji fún ìgbà àkọ́kọ́
Awọn akọṣẹmọṣẹ nipa onka awọn eeyan ilu fidirẹ mulẹ wi pe ilu Igbo Ọra lo ni onka awọn ibeji to pọ julọ l'agbaye.
Tilu, torin ati oniruuru asọ alarambara ni awọn ibeji, ibẹta, awọn obi, aṣoju ijọba ati awọn eeyan ilu peju pesẹ silu Igboọra nipinlẹ Ọyọ lọjọ Abamẹta fun ayẹyẹ ọdun awọn ibeji.
Ayẹyẹ naa to jẹ akọkọ iru rẹ lo waye nipasẹ ajọsepọ laarin ẹka ile iṣẹ iroyin, aṣa ati irinajo igbafẹ nipinlẹ Ọyọ, ijọba ibilẹ Ibarapa, ẹgbẹ awọn ọmọ bibi ilu IgboỌra ati ajọ to n risi idagbasoke awọn ibeji l'agbaye.
Lara awọn eniyan pataki to ba wọn pejọ pọ sibi ayẹyẹ naa ni alakoso fun iroyin, asa ati irinajo igbafẹ nipinlẹ Ọyọ, Oloye Toye Arulogun, alaga ijọba ibilẹ Ibarapa, Họnọrebu Ibrahim Habib Adegoke ati bẹẹbẹẹ lọ.
Kí lo fẹ́ mọ̀ nípa D.O Fágúnwà?
Àwọn ìbejì yabo Igbó Ọrà fọ́dún ìbejì lágbàáyé
‘‘Àwọn egúngún ń mu òògún olóró ló ń jẹ́ kí wọ́n sì ìwà hù’
'Mo kẹ́kọ̀ọ́ fásitì sùgbọ́n aṣọ òké ló ń jáwó báyìí'
Ọba Jamiu Adedamọla Badmus, JP, Ayelẹsọ III, Olu Aso ti Iberekodo naa ko gbẹyin ninu awọn ọba ati ijoye to darapọ mọ ọdun naa.
Ninu ọrọ rẹ nibi ipejọpọ naa, alakoso fun iroyin, aṣa ati irinajo igbafẹ nipinlẹ Ọyọ, Toye Arulogun ṣalaye wi pe ẹbun lati ọrun wa ni ilu IgboỌra jẹ fun ipinlẹ Ọyọ ati orilẹede Naijiria l'apapọ, gẹgẹ bi ilu ti ibeji ati awọn ọmọ to ju meji lọ ti pọ julọ ni agbaye.
Arulogun sọ wi pe akanṣe eto naa duro gẹgẹ bi ipilẹ fun ilepa lati ṣe akojọpọ awọn ibẹji l'agbaye.
Arulogun fi kun ọrọ rẹ wipe akanṣe eto naa duro gẹgẹ bi ipilẹ fun ilepa lati ṣe akojọpọ awọn ibẹji l'agbaye, pẹlu afojusun akọsilẹ ninu iwe to n ṣe onka awọn iṣẹlẹ ayanilẹnu l'agbaye, 'Guiness Book of Record'.
O tẹsiwaju wipe ajọdun ibeji tọdun yii jẹ ọkan lara awọn alakalẹ eto fun ayajọ ọjọ irinajo igbafẹ ni agbaye fun ọdun 2018, lati ọwọ ijọba ipinlẹ Ọyọ, pẹlu alaye wipe gbogbo ọna ni ijọba ipinlẹ naa n gbaa lati rii daju wi pe idagbasoke de ba eto ọrọ aje, aṣa ati ẹka irinajo igbafẹ.
Ẹ wo àrà tí ẹ le fi gèlè dá láàrín ìṣẹ́jú mẹ́ta
Ọdun awọn ibeji yoo fun wa ni anfani lati ṣe afihan ilu Igbo-Ọra gẹgẹ bi ilu ti o tayọ ninu onka ibeji ati ọmọ to ju mẹji lọ lagbaye."
"A fẹ rii daju wipe ipejọpọ naa n waye ni ọdọọdun, ki a le fi aye gba awọn eto l'oriṣiriṣi ti yoo sọ Igbo-Ọra di ibudo igbafẹ fun awọn arinrinajo lati ilẹ okeere."""
Ẹṣẹ ko gba eero nibi ayẹyẹ ọdun ibeji niluu Igbo-Ọra
Arulogun ni lẹyin ajọdun tọdun yii, ijọba ipinlẹ Ọyọ yoo gbiyanju lati ṣe ọdun ibeji ni ẹkun iwọ-oorun guusu ki o to di wipe yoo kari orilẹede Naijiria ati gbogbo agbaye.
Lara awọn eto to waye nibi ayẹyẹ naa ni orin idaraya, idije lọlọkanojọkan laarin awọn ibeji, yiyanfanda bi ologun, ifamiẹyẹdanilọla ati bẹẹbẹẹ lọ.
Awọn akọṣẹmọṣẹ nipa onka awọn eeyan ilu fidirẹ mulẹ wi pe ilu Igbo Ọra lo ni onka awọn ibeji to pọ julọ l'agbaye, pẹlu alaye wipe okere tan, ibeji mejidinlọgọjọ lo ma a n wa ninu awọn ọmọ ẹgbẹrun kan ti wọn ba bi nilu Igbo-Ọra.
Eleyi si tayọ ibeji marun un pere to ma a n wa ninu awọn ọmọ ẹgbẹrun kan ti wọn ba bi ni gbogbo ilẹ Yuroopu.
Ọpọlọpọ awọn eeyan gbagbọ wipe Amala ati ọbe Ilasa ti awọn eeyan ilu naa kundun lo n ṣokunfa ibeji ati ọmọ to ju meji lọ, bẹẹ sini awọn ẹlomii ri iṣẹlẹ naa gẹgẹ bi ohun ti o ti ọwọ Ọlọrun wa.
Ẹ lọ mú ẹ̀rí ibi tí a ti gba owó wá- NLC/TUC
'Àwa ò gba owó lọ́wọ́ Fayose ooo'
Àìtó eyín ká làá dọwọ́ bòó, àwọn olórí òṣìṣẹ̀ méjèjì tí wọn fi ẹsùn owó rìbá kan Nigeria Labour Congress (NLC) àti Trade Union Congress (TUC) ti fèsì.
Wọn ni irọ́ pátápátá ní àwọn to fi ẹ̀sùn kan ń pa bíkò ṣe pé èdè aiyedè tó ṣẹlẹ̀ nínú ẹgbẹ́ ló faa àhesọ.
Lásìkò tí BBC Yoruba ń ba àwọn alága ẹgbẹ́ òṣèlú méjèèjì sọ̀rọ̀ Ade Adesanmi ti NLC àti Odunayo Adesoye ti TUC sàlàyé pé gbogbo ẹni to bá ni ẹ̀rí lórí ọ̀rọ̀ náà kó jáde wa.
Alága NLC ati TUC sọ́ òhun tó fa ìdì abájọ ìbani lórúkọ jẹ́
Ẹ lọ mú ẹ̀rí ibi tí a ti gba owó wá- NLC/TUC
Ekiti Workers: Ìbásepọ̀ àìtọ́ láàárín Fayose àtàwọn olórí wa ló fìyà jẹ wá
‘Ẹ wádìí ₦264m táwọn asaájú òsìsẹ́ gba lásìkò Fayose’
Àwọn òṣìṣẹ̀ ìpínlẹ̀ Ekiti tí kọ̀wé ẹ̀hónú sí ilé ìgbìmọ̀ aṣofin ìpínlẹ̀ Ekìtì, láti ṣe ìwádìí lórí mílíọ̀nù mẹ́fà tí gomina ana nipinlẹ naa, Ayọdele Fayose ń san fáwọn olórí òṣìṣẹ́ lósoosù, tó fi di mílíọ̀nù lọna ọtalerugba o le mẹfa náírà ( ₦264m).
Onigbajamọ: Báwo lẹ se gbọ́ èdè Yorùbá sí?
Nínú ìwé ẹ̀hónú náà tó jáde ní ọjọ́ Kẹ́tàlélógún osù Kọkanla, àwọn òsìṣẹ́ lábẹ́ àsíá Ekiti Workers Rescue Team, sàlaàyé pé, ninu mílíọ̀nú mẹ́fà náírà ti wọn n yọ losoosu, mílíọ̀nù márun ń lọ sọ́dọ̀ ẹgbẹ osisẹ NLC nígbà ti mílíọ̀nù kan ń lọ sọ́dọ̀ ẹgbẹ osisẹ TUC, eyi tí kò fojú hàn nínú ìwé owó ẹgbẹ́.
Ìwé ẹ̀hónú náà, tí alága ẹgbẹ́, Ojo Ayodeji àti akọ̀wé ẹgbẹ́, W.A Ajayi fọ́wọsi fi kún un pé, ìbáṣepọ̀ tí kò tọ́ tó wà láàrín àwọn olórí òṣìṣẹ́ àti gómìnà àná ní kò jẹ́ kí àwọn lè rí ẹ̀tọ́ àwọn òṣìṣẹ́ gbà nínú ìṣèjọba. Fayose.
Oríṣun àwòrán, @FAYOSE/TWITTER
Nínú èsì ìwádìí ayẹ̀wé owó wò fún ti ọdún 2017, ó hàn gbangba pé ,TUC gba mílíọ̀nù kàn Naira lósoosù tí NLC sì ń gbà mílíọ̀nù márùn-ún náírà lábẹ́ ìjọba Fayose.
Sùgbọ́n alága ẹgbẹ́ òṣìṣẹ́ Ade Adesanmi tako ọ̀rọ̀ yìí, ó ní àwọn kò gba owó lásìkò ìsèjọba Fayose àti pé ọ̀rọ̀ ẹgbẹ́ òṣìṣẹ́ kò sí lábẹ́ àkóso ilé ìgbìmọ̀ aṣòfin.
Fayoṣe vs EFCC: Agbẹnusọ Fayoṣe ní àwọn ti pèsè ohun gbogbo tó yẹ
Oríṣun àwòrán, Lere Olayinka
Ọ̀sán ọjọ́ Aje ni Fayoṣe kérò l'ọ́gbà ẹ̀wọ̀n Ikoyi, ní ìpínlẹ̀ Eko.
Ile ejọ́ gíga ìjọba àpapọ̀ tó wà ní ìpínlẹ̀ pàṣẹ ìtúsílẹ̀ rẹ̀ lẹ́yìn tó ti san gbogbo nkan tí ilé ẹjọ́ bèérè fún láti gba onídúró rẹ̀.
Ọ̀sán ọjọ́ Aje ni Fayoṣe kérò l'ọ́gbà ẹ̀wọ̀n Ikoyi, ní ìpínlẹ̀ Eko.
Mike Ifabunmi: Òrìṣà ló gbè wà jù ni Brazil
Agbẹnusọ fún Fayoṣe, Lere Ọlayinka ló fìdí èyí múlẹ̀ fún BBC Yoruba.
Bákan nàá ló kéde lójú òpó Twitter rẹ̀ pé ọjọ́ kọkàndínlógún, oṣù Kọkànlá ni ìgbẹ́jọ́ yóò maa tẹ̀síwájú.
Ọ̀sẹ̀ tó kọjá ni Fayoṣe ti wà l'ọ́gbà ẹ̀wọ̀n Ikoyi nípìnlẹ̀ Eko, lẹ́yìn tí ilé ẹjọ́ gba onídúró rẹ̀ lórí ẹ̀sùn ṣíṣe owó ìlú báṣu-bàṣu lásìkò tó fi jẹ́ gómìnà ìpínlẹ̀ Ekiti.
A ti ṣe ohun gbogbo tí òfin ní ká ṣe, kí wọ́n dá Fayoṣe sílẹ̀ ló kù.
Lere Ọlayinka tó jẹ́ agbẹnusọ fún Gómìnà ìpínlẹ̀ Ekiti tẹ́lẹ̀ rí, Peter Ayodele Fayoṣe ti sọ wí pé gbogbo ìwé àti ẹ̀rí ni àwọn ti kó lọ síwájú ilé ẹjọ́ tí ilé ẹjọ́ sì ti rí àrídájú rẹ̀.
"Ó sọ ọ́ síwájú pé ""ìrètí wà pé títí ọjọ́ Ajé, Fayoṣe yóò jáde látìmọ́lé, a dúpẹ́ lọ́wọ́ gbogbo ọmọ Nàìjíríà fún àtìlẹ́yìn wọn""."
Ile ẹjọ giga apapọ to wa ni Ikoyi ni ilu Eko ti fun gomina ana nipinlẹ Ekiti, Ayọdele Fayoṣe ni anfani oniduro lori igbẹjọ ẹsun ṣiṣowo ilu baṣubaṣu ati gbigba owo kotọ ti ajọ to n gbogun ti iwa ijẹkujẹ lorilẹede Naijiria, EFCC n fi kan an.
'Ta ló dà bíi Ọlọ́run Fayoṣe' lorin tó ń jáde nílé ẹjọ́
Ọjọru ni ileẹjọ naa kede fun gbigbọ ẹjọ lori ẹbẹ fun gbigba oniduro Ayọdele Fayoṣe, babi si ni yara igbẹjọ kun fun awọn agbẹjọro atawọn ololufẹ gomina ana ni ipinlẹ Ekiti ọhun to bẹẹ gẹẹ ti Onidajọ Olatoregun to n gbọ ẹjọ naa ni lati paṣẹ fun gbogbo awọn eeyan ti ko ba tii ṣe agbẹjọro ti wọn ko si ri aaye joko si lati jade sita.
Ikọ agbẹjọro Fayose rọ ile ẹjọ naa lati fi ojuure wo ẹbẹ rẹ fun gbigba oniduro rẹ. O ni olorukọ nla lawujọ ni gomina ana naa ti ko si lee sa mọ ofin lọwọ paapaa julọ pẹlu bi o ṣe jẹ wi pe ko si akọsilẹ pe irufẹ igbesẹ bẹẹ ṣẹlẹ ri sii.
Onidajọ to n gbọ ẹjọ naa ni ọgba ẹwọn ikoyi ni Fayoṣe yoo wa titi ti yoo fi mu awọn ilana beeli rẹ ọhun ṣẹ
Onidajọ Ọlatoregun to n gbọ ẹjọ naa ninu idajọ to gbe kalẹ lori boya ki wọn gba beeli rẹ tabi rara, ni ile ẹjọ naa yoo faye silẹ fun un gbigba oniduro rẹ bi  o ba ti lee mu awọn ilana ti ile ẹjọ la kalẹ fun beeli rẹ ṣẹ.
Ninu idajọ rẹ, adajọ to n gbọ ẹjọ naa ni ki Fayose san owo iduro aadọta miliọnu naira ki o si jọwọ iwe irinna rẹ soke okun si akoso ile ẹjọ naa.
Bakan naa ni ile ẹjọ tun bere fun oniduro meji ti wọn gbọdọ ni dukia bi ile tabi ilẹ ni ilu Eko ti wọn si gbọdọ ni ẹri owo ori sisan fun ọdun mẹta sẹyin.
Onidajọ to n gbọ ẹjọ naa ni ọgba ẹwọn ikoyi ni Fayoṣe yoo wa titi ti yoo fi mu awọn ilana beeli rẹ ọhun ṣẹ.
Idunnu nla, Ijo ati ariwo ayọ ni wọn n pa ni ayika ile ẹjọ naa to bẹẹ gẹ ti gomina ana naa ni lati ke si wọn ki wọn dakẹ ariwo nitori gbagede ile ẹjọ ni wọn wa.
Ninu ọrọ to ba BBC Yoruba sọ, agbẹnusọ fun Ayọ Fayose, Lere layinka, ni idunu nla lo jẹ fun wọn pe ile ẹjọ fi aye silẹ fun gbigba oniduro gomina ana naa.
'EFCC ti wá dà bíi ara ẹgbẹ́ òṣèlú APC'
O ni ipenija nla ni igbẹjọ Fayoṣe jẹ fun APC ati gbogbo awọn ti wọn ti fi ẹsun ikowojẹ kan labẹ aarẹ Buhari ati iṣejọba rẹ.
"Bakan naa lawọn obinrin kan ti wọn ni awọn wa lati ilu Ado ekiti si ilu Eko nitori igbẹjọ naa ṣalaye pe ""ajọyọ nla lo jẹ, o si da wa loju pe ọga wa yoo bọ ninu idamu yii."""
Lasiko ti a fi n kọ iroyin yii, awọn agbẹjọro rẹ ko tii ri ilana beeli rẹ muṣẹ.
Bakan naa si ni awọn oṣiṣẹ ajọ EFCC ti gbe e pada si ọgba ẹwọn ikoyi titi di igba ti yoo fi lee pari eto gbogbo lori beeli ọhun.
Ile ẹjọ ti gba oniduro Gomina tẹlẹ, Ayọdele Fayoṣe.
Wọn si ti sun igbẹjọ si ọjọ kọkandinlogun, oṣu Kọkanla, ọdun 2018
Lẹ́yìn tí ilé ẹjọ́ ti gba onídùúró gómìnà ìpínlẹ̀ Ekiti tẹ́lẹ̀ rí, Ayodele fayoṣe lórí ẹ̀sùn tí wọ́n fi kàn an, wọ́n ti gbé e lọ sí ọgbà ẹ̀wọ̀n tó wà ní Ikoyi, ìpínlẹ̀ Eko.
Ọjọru ni ajọ to n gbogunti ijẹkujẹ  lorilẹede Naijiria, EFCC, pada gbe Fayoṣe lọ sile ẹjọ giga ti ijọba apapọ to wa ni adugbo Ikoyi nipinlẹ Eko.
Ninu idajọ to gbe kalẹ, adajọ to n gbọ ẹjọ awọn ẹ̀sun ti wọn fi kan Fayoṣe, Onidajọ Ọlatoregun, sọ pe ki wọn gba oniduro Fayose pẹlu aadọta miliọnu Naira, ati wi pe ko fi iwe idanimọ irinna silẹ okeere rẹ sile ẹjọ.
Bakan naa ni adajọ sọ pe o gbọdọ mu awọn meji ti yoo ṣe oniduro rẹ wa. Wọn si gbọdọ ni iwe ẹri owo ori ti wọn san fun ọdun mẹta, ati ilẹ̀ tabi ile to j'oju nigbese.
Àwọn alátìlẹyìn Fayoṣe tẹ̀lè lọ sílé ẹjọ́
Wọn si ti sun igbẹjọ si ọjọ kọkandinlogun, oṣu Kọkanla, ọdun 2018.
Ni ọjọ Aje ni ajọ to n gbogun ti iwa ijẹkujẹ lorilẹede Naijiria, EFCC, gbe Fayoṣe lọ si ile ẹjọ giga apapọ to wa ni Ikoyi nilu Eko lori ẹsun ikowojẹ ati ṣiṣe owo ilu baṣubaṣu ati gbigbowo rin lọna ti ko bofinmu, eleyi ti gomina ana ọhun dahun si pe oun ko jẹbi.
Fayoṣe gunlẹ si ile ẹjọ naa ni nkan bi aago mẹjọ owurọ Ọjọru, ni awọn alatilẹyin rẹ duro wamu-wamu lati ṣe koriya fun.
Eero kun ile ẹjọ debi wi pe awọn kan ko raaye joko, ti adajọ to n gbọ ẹjọ naa de awọn ti ko raaye joko, eyi ti ko yọ awọn akọroyin silẹ.
Awọn agbẹjọro rẹ beere fun ore ọfẹ ile ẹjọ naa lati lee gba oniduro rẹ ẹyin ti wọn ni awọn ti kọwe ẹbẹ fun gbigba oniduro rẹ ranṣẹ siwaju ile ẹjọ naa ṣaaju ni ọjọ ẹti.
Ni ọjọru ni ile ẹjọ naa sun igbẹjọ rẹ si lati sọrọ lori boya ki wọn fun un laye lati gba oniduro tabi ki wọn ṣi fi si ahamọ.
Oríṣun àwòrán, EPA
Ilé ẹjọ́ sún ìgbẹ́jọ́ Fayoṣe síwájú di Ọjọ́rú
Wọ́n ti gbé ẹjọ́ gómìnà ìpínlẹ̀ Ekiti tẹ́lẹ̀, Ayodele Fayose sí iwájú adájọ́ àgbà Ọlatoregun ní ilé ẹjọ́ gíga tó wà ní Ikoyi, ìpínlẹ̀ Eko.
Wọ́n mú Fayose wọ inu kòtò ìjẹ́jọ́ gẹ́gẹ́ bí àwọn agbẹjọ́rò ṣe bẹ̀rẹ̀ lórí àwn ẹ̀sùn tí wọ́n fi kàn án.
Bí wọ́n ṣe ń ka gbogbo àwọn ẹ̀sùn náà ni Ayo fayose ń dáhùn wí pé òun kò jẹ̀bi ẹ̀sùn kankan;
Agbẹjọ́rò: Ẹsun pe Ọgbẹni Ayọ Fayoṣe ati Ọgbẹni Abiọdun Agbele ti ajọ naa sọ pe o ti na papa bora gba N1.219 biliọnu  ni ọjọ kẹtadinlogun oṣu kẹfa ọdun 2014, lati fi ṣeto ipolongo ibo gomina rẹ lọdun 2014 nipinlẹ Ekiti.
Fayoṣe: Mi ò jẹ̀bi ẹ̀sùn kankan
Agbẹjọ́rò: Ẹsun pe Ọgbẹni Ayọ Fayoṣe ni ọjọ kẹtadinlogun oṣu kẹfa ọdun 2014, tẹwọ gba owo ti iye rẹ jẹ miliọnu marun dọla owo ilẹ amẹrika lọwọ Sẹnetọ Musiliu Obanikoro, ẹni to jẹ minisita abẹle feto abo nigba naa. Owo yii ju iye ti ofin la kalẹ fun ẹnikẹni lati gba lorilede Naijiria.
Fayoṣe: Mi ò jẹ̀bi ẹ̀sùn kankan
Fayoṣe ní ilé ẹjọ́ gíga ìpínlẹ̀ Eko
Agbẹjọ́rò: Ẹsun pe Fayoṣe gbe owo to jẹ ọọdunrun miliọnu naira, N300 miliọnu, ti ajọ EFCC ni o jẹ ara owo ti ko bofinmu, si aṣuwọn ifowopamọsi rẹ to wa pẹlu banki Zenith ni ọjọ keje oṣu kẹrin ọdun 2015.
Fayoṣe: Mi ò jẹ̀bi ẹ̀sùn kankan
Agbẹjọ́rò: Pe Ayọdele Fayose ati ileeṣẹ kan ti orukọ rẹ n jẹ spotless limited jumọ gba owo kan ti apapọ rẹ jẹ N317 miliọnu laarin ọjọ kẹtadinlogun osu kẹfa si ọjọ kẹrin oṣu kẹjọ ọdun 2014.
Owo yii ni ajọ EFCC ni o wa lara owo kan ti ko bofinmu.
Fayoṣe: Mi ò jẹ̀bi ẹ̀sùn kankan
Agbẹjọ́rò: Pe Fayose tun gba owo kan laarin ọjọ kẹrindinlọgbọn oṣu kẹfa si ọjọ kẹtadinlọgbọn oṣu kẹjọ ti owo naa ko si  bofinmu. Iye owo ọhun jẹ N305.760 miliọnu.
Fayoṣe: Mi ò jẹ̀bi ẹ̀sùn kankan
Fayoṣe àti Fani Kayode ní ilé ẹjọ́ gíga ìpínlẹ̀ Eko
Lẹ́yìn ẹ̀sùn ìkarùn ún, ni agbẹjọ́rò Fayoṣe bá bèrè lórúkọ rẹ̀ pe ki wọn gba oníduró fún òun. Ó ní ọjọ́ ẹtì tó kọjá ni wọ́n ṣẹ̀ṣẹ̀ fi tó àwọn létí tí àwọn sì ti kọ̀wé láti gba oníduró.
Ẹ̀wẹ̀, agbẹjọ́rò Oyedepo tó ń ṣojú àjọ EFCC sọ pé òun tẹ́wọ́ gbà á. Adájọ́ ní Fayoṣe lẹ́tọ̀ọ́ láti ṣe bẹ́ẹ̀ súgbọ́n nígbẹ̀yìngbẹ́yìn, ilé ẹjọ́ sún ìgbẹ́jọ́ náà síwájú di Ọjọ́rú ọ̀sẹ̀ (ọjọ́kẹ́ẹ̀rǹlélógún ọṣù kẹẹ̀wá).
Fayoṣe ní ilé ẹjọ́ gíga ìpínlẹ̀ Eko
Ní òwúrọ̀ ọjọ́ ajé, ọgbà ilé ẹjọ́ gíga ìpínlẹ̀ Eko níbi tí ìjẹ́jọ́ Fayose yóò ti wáyé ti ń kórajọ́ fún iṣẹ́ òòjọ́.
Àwọn agbẹjọ́rò sì ti ń wọ'ṣẹ́ ní ìgbáradì fún ẹjọ́ náà.
Ni owurọ ọjọ aje ni gomina ana nipinlẹ Ekiti, Ayọdele Fayose yoo foju ba ile ẹjọ.
Ilé ẹjọ́ gíga ti ìlú Eko
Ni ọjọ iṣẹgun ni Fayoṣe farahan ni ileeṣẹ ajọ to n gbogun ti iwa ijẹkujẹ lorilẹede Naijiria, EFCC gẹgẹ bii ileri rẹ to ṣe ninu lẹta kan to ti kọ lasiko ti o ṣi fi wa lori ipo gomina.
Lati igba naa ni o si ti wa ni ahamọ ajọ naa ni ilu Abuja.
Ni irọlẹ ọjọ aiku ni ajọ EFCC gbe Fayoṣe lọ silu Eko lati lọ jẹjọ lori ẹsun mọkanla ti wọn fi kan an eleyi to nii ṣe pẹlu ṣiṣe owo ilu baṣubaṣu.
Awọn ẹsun ti wọn fi kan Fayoṣe ni gbigba oniruuru owo lọna ti ko bofinmu, gbigba owo ẹyin lọwọ awọn ileeṣẹ kan ati fifi owo ilu ra ile kaakiri awọn agbegbe kan lorilẹede Naijiria.
SERAP si Buhari: Pàṣẹ fún amòfin àgbà, EFCC láti ṣèwáàdí Ganduje
Oríṣun àwòrán, @GovUmarGanduje
Ajọ kan to n ja fun ẹtọ araalu ati ijọba rere, SERAP ti ke si aarẹ Muhammadu Buhari pe ko tete wa n kan ṣekan lori ẹsun gbigba owo riba ti wọn fi kan gomina ganduje tipinlẹ Kano.
Ninu lẹta kan ti o kọ si aarẹ Buhari, ajọ SERAP ni pẹlu fidio to n lọ kaakiri ninu eyi to ṣafihan gomina Ganduje nibi ti o ti n gbowo ẹyin yii, O di dandan ki aarẹ tete dari amofin agba orilẹede yii atawọn ajọ to n gbogun ti iwa ijẹkujẹ lati tete bẹrẹ iwaadi lori ẹsun naa.
"Gbedeke ọjọ mẹrinla ni wọn fun aarẹ lati bẹẹrẹ iwaadi gomina Ganduje nitori, ""ẹsun riba gbigba tabi ṣiṣi ipo iṣejọba lo ti wọn ba fi kan ẹnikẹni nipinlẹ yoowu lorilẹede Naijiria kan gbogbo ọmọ Naijiria, nitori naa o si yẹ ko kọ iṣejọba rẹ lominu pẹlu."""
Oríṣun àwòrán, @GovUmarGanduje
Lai pẹ yii ni awọn fidio kan bọ si ori ẹrọ ayelujara eyi ti o ṣafihan gomina ipinlẹ Kano ti o n gba owo dọla ilẹ Amẹrika lọpọ yanturu lọwọ ẹnikan ti wọn funra pe o jẹ Kọngila.
Bi o tilẹ jẹ pe Gomina Ganduje ti ṣalaye pe oun ko gba owo ẹyin lọwọ ẹnikẹ ri, sibẹ olori ileeṣẹ iroyin to gbe fidio naa sita, Jafar Jafar farahan niwaju ile aṣofin ipinlẹ Kano nibi ti o ti sọ pe ootọ ni gbogbo ohun to wa ninu fidio naa, o si fi ẹsun kan gomina naa pe lootọ lo gba owo ẹyin lọwọ awọn kọngila ti wọn gbe iṣẹ ijọba fun nipinlẹ ọhun.
SERAP wa ke si aarẹ Buhari pe o nilati ṣeto abo to peye fun oniroyin naa lọwọ ewu ti o lee fẹ wu u nitori aṣiri awọn alagbara ti o tu sita naa.
Omar Victor Diop: Ipa Áfíríkà nínú àkọsílẹ̀ ìwé kọja ògo tí wọ́n ń fún un lágbáyé
Oríṣun àwòrán, GANDUJE HALLACCI
Ja'afar Ja'afar tí ò ń jẹ́jọ́ lórí fídìo tó s'àfihàn bí gomina ipinlẹ Kano ti ń gba rìbá dúró lórí ẹsẹ̀ rẹ̀ pé òtítọ́ ni.
Gomina ipinlẹ Kano, Abdullahi Ganduje ti kọ lati yọju si Ile Igbimọ Asofin ipinlẹ Kano lori ẹsun ajẹbanu ti wọn fi kan an.
Awọn igbimọ ti wọn yan lati Ile Igbimọ Asofin ipinlẹ naa n sewadii lori fidio ti akọrọyin kan fi lede to fi han pe  gomina naa n gba riba.
Gomina Ganduje ran kọmisọna fun ọrọ to jẹ mọ iroyin ni ipinlẹ naa, Muhammad Garba lati lọ soju rẹ pẹlu lẹta ti ọga rẹ Ganduje kọ.
'Òṣìṣẹ́ Bánkì ni mí l'Amẹ́ríkà kí n tó bẹ̀rẹ̀ Tíátà'
Lẹta naa sọ wi pe Gomina ipinlẹ Kano naa ko gba riba ri lati igba ti wọn ti bii, ati wi pe iruẹsun ajẹbanu pẹlu fidio yii ti sẹlẹ si Gomina Ipinle naa tẹlẹri, Ibrahima Shekarau ati Emir ti Kano.
Oludasilẹ iwe iroyin ori ayelujara kan, Daily Nigeria, Ja'afar Ja'afar to gbe fidio ibi ti Gomina Ipinlẹ Kano, Abdullahi Ganduje ti n gba owo jade si duro lori ẹsẹ rẹ pe fidio naa ko lẹja nbakan rara.
O fidi ọrọ naa mulẹ niwaju Ile Igbimọ Aṣofin Ipinlẹ kano to n se iwadi nipa fidio ọhun.
Jafar Jafar niwaju igbimo ile asofin ipinle Kano
Igbimọ ile naa ti saaju fi iwe pe Ja'afar Ja'afar lati wa wi tẹnu rẹ nipa fidio naa ti o n ja rain-rain.
Ninu fidio, nise ni Gomina Ganduje n ri owo dolla  to gba lọdọ ẹnikan bọ inu apo rẹ.
Ìjọba Kano sọ pé Gómìnà kọ́ ló wà nínú fídíò rìbá gbígbà naa.
Oríṣun àwòrán, @GovUmarGanduje
Iroyin to tẹwa lọwọ so pe Oludasilẹ iwe Iroyin Daily Nigeria ọhun kọ lati jẹwọ ẹni to fi fidio owo gbigba naa sọwọ si i.
Amọ ṣa, o jọwọ ẹri to fi mọ ohun iko nkan elo ẹrọ ayarabiaṣa komputa pamọ si (hard disk) ati awọn nkan miiran.
Ninu ọrọ apilẹkọ rẹ niwaju igbimọ iwadi, Jaafar Jaafar ni ile ise iroyin Daily Nigeria se iwadi ofintoto saaju ki wọn to gbe fidio ibi ti Ganduje ti n gba owo abẹtẹlẹ jade.
Ẹwẹ awọn akẹkọ kan ti fi atilẹyin wọn han si Gomina Ganduje pẹlu bi wọn ti ṣe gbe iwe ifẹhonuhan niwaju ile asofin Kano.
Loju opo Twitter awọn eyan ti n bẹnu atẹ lu igbese yi.
Ọjọ Aiku to kọja ni fidio kan gba ori ẹrọ ayelujara, eyi to ṣafihan gomina Abdullahi Umar Ganduje to n gba 'riba lọwọ agbaṣẹṣe kan.'
Ja'afar Ja'afar sọ pe, awọn oṣiṣẹ ijọba kan fi to oun leti pe, awọn akẹẹgbẹ wọn kan, lai ni ọwọ gomina Ganduje ninu, n gbeero lati kọlu oun.
Oniweeroyin ọhun ni, o da oun loju pe owo ti gomina gba ninu fidio naa jẹ ọkan lara awọn owo ti ko tọ, ti gomina maa n gba lọwọ oriṣiriṣi awọn kọngila to n ṣe awọn akansẹ iṣẹ ni ipinlẹ naa.
Ja'afar sọ pe ''ẹ̀rù ile ẹjọ́ ti ijọba ipinlẹ naa ni oun yoo gbe mi lọ ko ba mi, nitori mo mọ pe otitọ ni iroyin ti mo gbe jade.''
''Iwe iroyin mi kii gbe ayederu iroyin tabi eyi to le ba orukọ ẹnikẹni jẹ, jade . Gbogbo iroyin wa ni a maa n wadii daada ki a to gbe jade. A si ni ẹ̀rí to daju lori iroyin yii.''
Fidio naa kii ṣe ẹyọkan, ko da, o to mẹẹdogun tabi ko ju bẹ ẹ lọ. A kan da ọwọ duro lori gbigbe awọn fidio to ku jade ni, nitori aabo ẹmi mi ati ti ẹbi mi.
Oríṣun àwòrán, @GovUmarGanduje
Ṣe irọ ni fidio to ṣafihan Gomina Ganduje?
Aṣofin agba kan ni ile aṣofin apapọ ilẹ wa, Sẹ́netọ́ Ben Murray Bruce ti kede pe ẹ́bu lasan ni fidio kan to n ja rain-rain pe Gomina ipinlẹ́ Kano, Abdullahi Ganduje gba owo abẹtẹlẹ to to miliọnu marun dọla.
Murray Bruce ni iwadi oun nipa ọrọ naa ti fi han pe, owo idana ni gomina Ganduje n gba lori ọmọ rẹ obinrin, kii se owo abẹtẹlẹ lori isẹ agbase.
Loju opo Twitter rẹ, @BenMurrayBruce, ni Murray Bruce ti ṣiṣọ loju ọrọ yii faraye.
Bẹẹ ba gbagbe, ọjọ aiku ní fọ́nrán kan gbòde níbi ti gómìnà ìpínlẹ̀ Kano, Abdulllai Ganduje, tí ń kó owó dọ́là sínú àpò agbádá rẹ̀ eyi tí Daily Nigerian gbé síta.
Ìjọba Ọ̀yọ́: Kò sí ilé kan tí wọn kò tíì bí ìbejì ní Igbó Ọrà
Ọ̀pọ̀ ọmọ Nàìjíríà si ló tí ń gbarata lórí ọ̀rọ̀ náà pé, owó àbẹ̀tẹ́lẹ̀ ní Ganduje ń gbà lọ́wọ́ àwọn kọngila.
Oríṣun àwòrán, @GovUmarGanduje
Ṣugbọn ijọba ìpínlẹ̀ Kano ti fi àtẹ̀jáde kan síta lálẹ́ ọjọ aiku pé, àwọn yóò gbe ile iṣẹ́ ìròyìn náà àti akọ̀ròyìn Jafar Jafar lọ sílé ẹjọ́, ní tori pé wọn ń gbìyànjú àti ba gómìnà lórúkọ jẹ́ ni.
Agbẹnusọ fun Gomina Kano,Muhammad Garba salaye pe ayederu ni fọnran fidio naa a ti wi pe ẹni to gbe fidio naa jade ko ṣẹṣẹ ma wu iri iwa bẹ.
Lálẹ́ ọjọ Aiku ní wọn gbé fọ́nrán tí ẹnikan yọ́lẹ̀ ya, níbi ti gómìnà ń kó dọ́là tó tó mílíọ̀nù márùn sínú àpò agbádá rẹ̀, èyí ti wọn ni owó àbẹ̀tẹ́lẹ̀ tó ń gbà lọ́wọ́ kọngilá tó fẹ gba iṣẹ́ lọ́wọ́ rẹ̀ ní.
Ọrọ yi ti mu iriwisi ọtọọtọ wa ti o si ti  bi hastag kan to n ja rain rain loju opo Twitter-#BabanrigaMobileBanking .
Nise ni  ọ̀pọ̀ àwọn ọmọ Nàìjírìa tí n sọ èrò wọn lórí fọnrán náà, tí wọn sì bẹnu àtẹ́ lu ìgbèsẹ̀ gómìnà Kano.
rẹ̀,  ni, tòun, èrò, tiyín, ìgbésẹ̀, yìí
Travel Ban: Nnkán marun tó yẹ kí o mọ nípa àṣẹ wàá
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ofin oriuleede Naijiria faye gba ki Aarẹ pa àṣẹ wàá
Ni oṣu kinni ọdun 1868,Aarẹ orileede Amerika Abraham Lincoln, pasẹ waa kan lati mu iyipada ba ipo awọn ẹru alawọ-dudu to le ni miliọnu mẹta, labẹ ofin ni awọn ipinlẹ mẹwa lamẹrika.
Asẹ itusilẹ rẹ ọhun ko jẹ ofin alagbada tabi ofin ologun, sugbọn aṣẹ waa ni wọn pee, ti itunmọ rẹ lede Gẹẹsi a si maa jẹ Executive Order.
Lamerika ati ni orileede Naijiria ti isejọba awa ara wa nipase lilo Aarẹ gẹgẹ bi olori ijọb, aye wa fun Aarẹ lati lo agbara aṣẹ waa.
Ayọrinde: Ohun tó burú ni ‘Dìbò ko sebẹ̀’, ìyà ló bá de
Ọrẹ Falọmọ: Buhari yóò rí ìbò Yorùbá gbà ju Atiku, Ọbasanjọ lọ
Bakan naa, lai pẹ yii ni Aarẹ Muhammadu Buhari gbe aṣẹ waa, ẹlẹkẹfa jade eleyi ti ko faaye gba ẹnikẹni ti o ba ni dukia to le ni aadọta miliọnu Naira, ti ijọba si n wadi rẹ fun ẹsun iwa ibajẹ, lati raaye fi orilẹ-ede Naijiria silẹ, titi ti wọn yoo fi gbe igbesẹ to tọ lori ọrọ wọn.
N ṣe ni awuyewuye n waye lori igbese naa, eyi kii si se igba akọkọ ti Aarẹ Buhari yoo pa iru aṣe yii ṣugbọn o da bi ẹni wi pe, oun ti àṣẹ wàá je gan, ko yẹ ọpọ eeyan.
E jẹ ki a jọ salaye rẹ ko ye wa yegeyege.
Ki a to lee ṣofin kankan, a gbodo tele awọn ilana ti ofin la kalẹ.
Ilana wọnyi a maa gba asiko ti o seese ki o ma le jẹ ki ofin naa ba nnkan ti wọn fẹ lo fun.
Fun idi ẹy,i ni wọn fii fun Aarẹ ni agbara lati pasẹ wa lai beere iyọnda lọdọ awọn asofin.
Ti Aarẹ ba gbe igbese yi, aṣẹ naa ti di ofin, to si di dandan ki awọn ara ilu tele.
Oríṣun àwòrán, @Mbuhari
Aarẹ Buhari ti pa awọn Àṣẹ wàá kan lẹ́nu igba to de ori alefa
Àṣẹ wàá  gbọdọ wa ni ibamu pẹlu ofin ilu
Ohun pataki to yẹ ki a mọ nipa asẹ waa ni pe, awọn ile ẹjọ a ma se agbeyẹwo aṣẹ wa ti Aarẹ ba pa loorekoore.
Koda awọn asofin le tapa si tabi fagile aṣẹ wa ti Aarẹ ba pa, ti wọn ba ri wi pe Aarẹ fẹ lo ofin ọhun nilokulo tabi ti ofin naa ko le ṣe anfaani fun ara ilu.
Sugbọn Aarẹ gbodo buwọlu ofin tuntun naa ki o to le parọ àṣẹ wàá,  to wa nilẹ tele.
Oríṣun àwòrán, @MBuhari
Àṣẹ wàá le jẹ lilo fun ọdun kan, ọdun mẹwa tabi titi lailai, lopin igba ti Aarẹ mii ko ba ti fagile
Fun idi eyi, aṣẹ wa a ma wo ibi ti kudie kudie ba wa ninu isejọba,lọna ati mu agbega ba agbọn yii.
Ti àṣẹ wàá  ko ba tẹ Aarẹ tuntun miran lọrun, o le paarẹ
Àṣẹ wàá le jẹ lilo fun ọdun kan, ọdun mẹwa tabi titi lailai, lopin igba ti Aarẹ mii ko ba ti fagile.
Gẹgẹ bi agbekalẹ ati ilana lilo agbara yii labẹ iwe ofin Naijiria, Aarẹ tuntun le ni oun fẹ yi àṣẹ wàá pada ti yoo si fi omiran rọpo rẹ tabi ko tilẹ ma lo mọ rara.
Apẹrẹ iru rẹ kan to waye ni Naijiria ni ti aṣẹ waa ti Aarẹ Obasanjọ pa, lati sọ ọjọ kọkandilọgbọn osu kaarun di ayajọ ọjọ oselu tiwantiwa ni Naijiria.
Lai pe yi ni Aarẹ Buhari yi aṣẹ yi pada, si ọjọ Kejila osu Kefa, June 12, di ọjọ ayajọ ijọ oselu awa ara wa ni Naijiria.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Èrò kálukú maa n ṣọ̀tọ̀ọ́tọ̀ lórí pàtàkì ọjọ́ nà.
Àṣẹ wàá melo ni aarẹ le pa?
Iye àṣẹ wàá ti Aarẹ le pa ko niye.
Lorileede Amerika, a ti ri Aarẹ to pa àṣẹ wàá  to to ẹgbẹrun meta, ti awọn miran ko si buwọlu àṣẹ wàá  kankan ti saa wọn fi pari saa wọn.
Ni Naijiria Aarẹ Muhammadu Buhari lo tii pasẹ waa to poju, tii se mẹfa.
Nigba Aarẹ Obasanjọ ati Aarẹ Goodluck Jonathan, awọn naa pa awọn asẹ waa kan sugbọn ko to ti iye Aarẹ Buhari.
Oríṣun àwòrán, @MBuhari
Aarẹ a ma lo àṣẹ wàá lati fi se ẹkunrẹrẹ alaye nipa ofin
Nigba miran alaye nipa ofin le ma ye awọn eeyan daada tabi ko se wi pe o sokunkun si awọn eeyan.
Lati le mu alaye to ye kooro wa nipa ofin bẹ, Aarẹ le pase wa ti yoo mu ekunrẹrẹ alaye wa nipa irufẹ ona ti wn le lo ofin naa tabi  alaye nnkan pato ti wọn tori rẹ sofin naa.
Ìjọba Ọ̀yọ́: Kò sí ilé kan tí wọn kò tíì bí ìbejì ní Igbó Ọrà
Alaafin Ọyọ: Asiri agbara bibi ibeji lọpọ igba
Boko Haram: Ẹgbẹ́ BBOG sèwọ́le l‘Abuja tako ìkú Hauwa Leman
Ẹgbẹlẹgbẹ awọn ọmọ ẹgbẹ ajafẹtọ, labẹ ẹgbẹ to n pe fun idapada awọn ọmọdebinrin wa ti Boko Haram ji gbe, Bring Back our Girls (BBOG), lo peju si gbagede Unity Fountain ni aarọ oni nilu Abuja, lati wa fi ẹhonu wọn han lori bi ikọ Boko Haram se gbẹmi osisẹ kan, to n sisẹ pẹlu ẹgbẹ alaanu Red Cross.
Arabinrin naa, Hauwa Leman ati awọn akẹgbẹ́ rẹ ni awọn alakatakiti ẹsin ọhun ji gbe, lẹyin ti wọn ṣe ikọlu si ibudo ológun kan to wa ni Rann, ni ipinlẹ Borno.
Gbogbo awọn ajafẹtọ ẹni to peju sibi iwọde naa ni oju wọn kọrẹ lọwọ, ti wọn si n kesi ijọba apapọ lati tete wọna ti yoo fi doola ẹmi awọn eeyan to wa ni igbekun Boko Haram, ki wọn to da ẹmi wọn legbodo.
Koda, adari ikọ BBOG, Oby Ezekwesili gan ko lee pa ọ̀rọ mọra, to si bu sẹkun gbaragada nibi iwọde naa.
Awọn ajafẹtọ ilu to ba BBC sọrọ ni, o se ni laanu pe Boko Haram si n pa awọn ọmọdebinrin wa lai naani oniruuru iwọde tawọn ti se tako iwa isekupani bayii.
Oríṣun àwòrán, Other
Hauwa Liman
Wọn wa foju laifi wo iwa kawọn adunkoko mọni maa mu awọn eeyan lẹru nibi ti aye laju de yii, ti wn si n kesiawujọ agbaye lati sugba ijọba apapọ, ko lee rẹyin iwa aidaa naa, nitori ẹru ọran Boko Haram yii wuwo fun ijọba Naijiria nikan lati gbe.
Gbogbo akoko ti iwọde naa fi waye si lawọn agbofinro fi duro wawawa, aibaamọ, iwọde naa lee la jagidi-jagan lọ.
Loju opo ayelujara ati loju awọn iwe iroyin lorileede Naijiria, orukọ ọdọmọbirin kan, Hauwa Leman to n sisẹ pẹ́lu awọn ajọ alaanu Red Cross n ja rain-rain.
Ọrọ naa ko sẹyin pe ikọ alakatakiti agbesunmọmi Boko Haram dẹmi rẹ legbodo.
Toun ti ẹbẹ ti awọn ara ilu ati ijọba bẹ wọn, pe ki wọn ma se pa Hauwa Leman, sibẹ Boko Haram kọ jalẹ, wọn sẹmi rẹ lofo.
Boko Haram yóò dá Leah sílé
Iwa laabi yi dori agba ati ọmọde kodo, ti awọn eeyan si n fi itara wọn han loju opo ayelujara.
Lero ọkan awọn ara ilu kan, ijọba lo kuna lati doola ẹmi Hauwa.
Ijọba apapọ Naijiria ti saaju fi ibanujẹ ọkan rẹ̀ han lori bi ikọ̀ agbesunmọmi Boko Haram se pa Hauwa.
Ninu atẹjade kan ti Minisita fun eto iroyin ati ibanisọ́rọ Lai Muhammed fi sita,awọn sa gbogbo apa wn lati ri wi pe Hauwa pada wa sile layo ati alafia
Ọjọ Aje ni awọn ọmọ ikọ naa sẹkupa Hauwa Leman, lẹyin ọpọlọpọ ojọ ti wọn ti mu u si ahamọ wọn.
Hauwa jẹ́ ọ̀kan lara awọn oṣiṣẹ àjọ ICRC, to n pese iranlọwọ fun awọn to ti lugbadi ikọlu ikọ Boko Haram.
Hauwa ati awọn akẹgbẹ́ rẹ, Saifura to jẹ agbẹ̀bí, to fi mọ Alice, ti oun jẹ oṣiṣẹ nọọsi ni awọn alakatakiti ẹsin ọhun ji gbe, lẹyin ti wọn ṣe ikọlu si ibudo ológun kan to wa ni Rann, ni ipinlẹ Borno.
Ninu oṣu Kẹsan an ni wọn ṣekupa Saifura Ahmed ni tiẹ, ti wọn si dunkooko pe, awọn yoo tun pa ẹlomii ti ijọba ko ba fi ṣe ohun ti awọn n fẹ fun awọn.
Oríṣun àwòrán, @Twitter/ICRC
Wọn ṣekupa Saifura Ahmed ni tiẹ, ti wọn si dunkooko pe awọn yoo tun pa ẹlomii ti ijba ko ba fi ṣe ohun ti awọn n fẹ fun awọn.
Ṣaaju ni ajọ alagbelebu pupa ti wọn n ṣiṣẹ fun,  ICRC, rawọ ẹbẹ pe, ki wọn da ẹmi wọn si latari bi gbedeke ti ikọ Boko Haram fun ijba ṣe ku diẹ ko pari.
Ninu atẹjade kan to fi sita ni ilu London, Minisita fun eto iroyin ati aṣa, Lai Mohammed, ṣapejuwe iṣekupani ọhun gẹgẹ bi aibikita fun ẹmi ọmọnikeji, ati aini ibẹru Ọlọrun, nitori ko si ohunkohun to sọ gbigba ẹmi ẹlomii di ohun to tọ.
Lai Muhammed to ba mọlẹbi oloogbe kẹ́dùn sọ pe, ''o ṣe ni laanu pe wọn paapa gba ẹmi ọdọmọbinrin naa lai fi ti gbogbo ariwo, ikede, ẹ̀bẹ̀, ati iduna-dura ti ijọba ṣe pe ki wọn tu u silẹ.''
Oríṣun àwòrán, AFP
Ìgbà àkọ́kọ́ kọ́ nìyíì ti Boko Haram yóò ṣekú pa òṣìṣẹ́ tó n pèsè ìrànlọ́wọ́
Lai sọ pe ''lootọ ni iku ọmọbinrin naa dun ijọba, ṣugbọn wọn ko ni jẹ ki eyi mu irẹwẹsi ba wọn lati dẹ́kun iduna-dura fun idande awọn obinrin tó kù sí ahamọ.''
O wa a dupẹ lọwọ ''gbogbo awọn ọ̀rẹ́ orilẹ-ede Naijiria, to fi mọ awọn olórí ẹ̀sìn, to n ṣiṣẹ pẹlu orileẹde naa lati le ri itusilẹ gba fun gbogbo awọn obinrin ti Boko Haram fi si ahamọ rẹ.
Iya Rainbow: Olùtọ̀jú aláìsàn ni kó tó di òsèré
Oríṣun àwòrán, @mamarainbowofficial
Gbaju-gbaja oṣere tiata, Idowu Philips, ti gbogbo eniyan mọ si Mama Rainbow wa lati ilu Ijẹbu Ode, nipinlẹ Ogun.
Mama Rainbow lọ si ileewe alakọbẹrẹ ni ipinlẹ Ogun, lẹyin naa lo kẹkọ gboye ni ileewe ẹkọṣẹ awọn nọọsi. O si ṣiṣẹ nọọsi fun ogún ọdun.
Ọjọ kẹrindinlogun, oṣu Kẹwaa, ọdun 1942 ni wọn bi Iya Rainbow.
IVF: Ìyá ìbejì se IVF mẹ́ta lókè òkun, ìkẹrin tó se ní Nàíjíríà, ló fi bímọ
A gbọ pe lati igba ti Iya Rainbow ti n ṣiṣẹ nọọsi lo ti nifẹ si ere ori itage ṣiṣe, o si bẹrẹ rẹ diẹdiẹ ninu ẹgbẹ oṣere Oṣumare ti ọkọ rẹ, Ayanfẹmi Oroniyi Phillips da silẹ.
Ọdun 1984 si ni Ayanfẹmi, ti gbogbo eeyan mọ si ‘Baba Rainbow’ jade laye. Osere ori itage ni Baba Rainbow naa, ko to di olukọ ni fasiti Eko, UNILAG.
'Mí ò ya wèrè, mí ò burú, ọ̀nà àtijẹ là ń wá'
Ẹyin iku ọkọ rẹ, si ni Mama Rainbow bẹrẹ ere siṣe ni ẹkunrẹrẹ.
Oríṣun àwòrán, @mamarainbowofficial
Orukọ rẹ 'Iya Rainbow' jẹyọ lati ara orukọ ẹgbẹ oṣere ọkọ rẹ, Oṣumare
Orukọ rẹ 'Iya Rainbow' jẹyọ lati ara orukọ ẹgbẹ oṣere ọkọ rẹ, Oṣumare, eyi to tumọ si 'Rainbow' ni ede oyinbo.
Iya Rainbow ti kopa ninu ọpọlọpọ sinima lati igba to ti bẹrẹ si ni ṣere. Lara wọn ni ere:
Ọ̀gá Bello: Àìgbọ́n ló ń da àwọn òsèré tíátà tó ń jà lórí ayélujára láàmú
'Èmi ò kí ń lu ìyàwó mi'
Ibori: Ọlọ́pàá òyìnbó tó wádìí mi jẹ́ oníjẹkújẹ
Oríṣun àwòrán, @ogbetakome
Gọ́mìnà ana nìpínlẹ̀ Delta, James Ibori, to lọ sọgba ẹwọn ni ilẹ̀ Gẹ̀ẹ́sì lẹ́yìn tó jẹ̀bi ẹ̀sùn kíkó aimọye mílíọ̀nù naira owó ìjoba lọ̀sí òkè òkun lọ́nà àìtọ́, ti fìdí rẹmi níbi ẹjọ́ kò-tẹ́mi-lọ́rùn to pe ni London.
Ẹjọ́ tí ilé ejọ́ kò-tẹ́mi-lọ́rùn dá fún James Ibori jẹ́ ílọsiwájú fún ìjọba ilẹ̀ Gẹ̀ẹ́sì, pàá-pàá nígbà tí wọ́n gbìyànjú láti dẹkun kíkó owó ìdọ̀tí wọ orílẹ̀edè náà.
Ibori, tó jẹ́ ọ̀kan lára àwọn tí wọ́n lágbára jù ni Nàìjíríà, gbà pé òun jẹ̀bi níwájú ilé ẹjọ́ London kan ni ọdún 2012 lórí ẹ̀ṣùn mẹwaa, to nii se pẹlu iwa ajẹbanu àti gbígbé ààdọ́ta miílíọ̀nù poun (N 23,918,750,000) jáde lọ́nà àìtọ́ .
Ezekwesili: Mo fẹ́ sọ Nàíjíríà di ilẹ̀ tí àǹfàní ọgbọọgba wà
Wọ́n rán Ibori ní ẹ̀wọ̀n ọdún mẹ́tàlá (13), ó sì ṣe ìdajì rẹ̀, gẹ́gẹ́ bí wọ́n ṣe ń ṣe ní ilẹ̀ Gẹ̀ẹ́sì.
Bi o tilẹ jẹpé o gbà pé oún jẹ̀bi, Ibori, tó wà ní Nàìjíríà báyìí, pe ẹjọ́ kò-tẹ́mi-lọ́rùn lọ́rí ẹjọ́ tí wọ́n dá fún un , tó sì sọ wípé, ọ̀kan lára àwọn ọlọ́pàá tọ́ ṣe ìwádí nípa oun jẹ́ oníjẹkujẹ, àti wípé, àwọn olùpẹ̀jọ́ bo o lá sírí ni.
Àwọn adájọ́ ilé ẹjọ́ kò-tẹ́mi-lọ́rùn mẹ́ta sọ wípé, kọ̀ sí àrídájú pé ọlọ́pàá nàá jẹ́ oníwà ìbàjẹ, ti ọrọ rẹ ko si ní ńǹkan ṣe pẹ̀lu ẹjọ́ Ibori.
Ilé aṣòfin àgbà Nàìjíríà dàbí ọjà bí Saraki ṣe pa Akpabio lẹ́nu mọ́
Niṣe ni ile aṣofin agba Naijiria ri bi ọja Oyingbo l'Ọjọru lẹyin ti Aarẹ ile aṣofin naa, Sẹnetọ Bukọla Saraki, ko gba ki Sẹnetọ Godswill Akpabio o joko si aaye to tọ si i.
Ile aṣofin naa daru lẹyin ti Sẹnetọ Bassey Akpan to n ṣoju ẹgbẹ oṣelu PDP, lati ipinlẹ Akwa Ibom, tọka si awọn kudiẹ-kudiẹ kan to waye nibi eto idibo abẹle ẹgbẹ APC to waye ni ipinlẹ Akwa Ibom.
Akpan wa kesi ile aṣofin pe ko gbe igbesẹ nitori pe 'eto idibo naa dunkooko mọ alaafia ipinlẹ Akwa Ibom’.
Ki lo sọ eyi si, ni Sẹnetọ Akpabio, to ti fi igba kan jẹ olori ọmọ ẹgbẹ oṣelu to kere julọ nile aṣofin naa, ba na ọwọ lati fesi lori ọrọ ọhun, ṣugbọn Bukọla Saraki ni ko gbọdọ sọrọ, ayafi to ba pada si ibi aaye ijoko rẹ.
Oríṣun àwòrán, @NGRSenate
Laipẹ yii ni Godswill Akpabio kuro ninu ẹgbẹ oṣelu PDP, to si lọ darapọ mọ ẹgbẹ oṣelu All Progressives Congress, APC.
Ki leyii waye si, a fi bi olori ọmọ ẹgbẹ oṣelu to pọju lọ, Sẹnetọ Ahmad Lawan ati awọn sẹnetọ mi i to jẹ ọmọ ẹgbẹ oṣelu APC, ṣe sọ pe ko si nkan to jọ bẹ, pe ko si ibi ti Akpabio joko si ti ko ti le sọrọ ninu ile aṣofin naa.
Ṣugbọn awọn iroyin kan tun sọ pe, ẹrọ gbohungbohun ti Akpabio n lo lati sọrọ ko ṣiṣẹ daada lo mu ki Saraki sọ fun un pe ko lo omiran - ti Sẹnetọ Alli Ndume.
Lootọ ni Akpabio pada si ibi aaye ijoko rẹ, ṣugbọn o sọ pe, Saraki gbọdọ tọrọ aforiji lọwọ oun fun iwa ifini se ẹlẹya to hu si oun. Amọ, Saraki sọ pe rara, ọ̀rọ̀ ko ri bẹ.
Awọn kan sọ pe nitori pe Akpabio ti fi ẹgbẹ PDP silẹ Saraki ṣe huwa bẹ si
Laipẹ yii ni Godswill Akpabio kuro ninu ẹgbẹ oṣelu Peoples Democratic Party, PDP, to si lọ darapọ mọ ẹgbẹ oṣelu All Progressives Congress, APC.
Ka nípa ọ̀nà tí agogo inú ara rẹ ń gbà ṣiṣẹ́
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Gbéra kí o tàn - ọjọ́ tuntun wà ní iwájú re
Ǹjẹ́ o mọ̀ pẹ́ gbogbo ńǹkan abẹ̀mí lo ní agogo ara, láti orí kòkòrò àf'ojúrí (fungi) sí ènìyàn?
Ó dà bí ẹní pẹ́ gbogbo ńǹkan abẹ̀mí - àti kòkòrò àìf'ojúrí (bacteria) - ní agogo ara (circadian cycle): tó tó bíi wàkàtí mẹ́rìnlélógún tó sì ń ṣẹ atọ́kùn fún ìṣẹ̀mí wa.
Sùgbọ́n báwo ní ìwọ yóò ṣe mọ̀  bí agogo yìí ṣe  ń ṣiṣẹ́?
1. Ọjọ́ ti pẹ́ tí agogo ara ti wà
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ọbẹ̀ ayé àtijọ́ yìí ní láti wá ọ̀nà àti tú ara rẹ̀ tò
Àwọn onímọ̀ sáyẹ́ǹsì rò wí pé òòrun ba àwọn sẹ́ẹ́lì àkọ́kọ́ jẹ́. Nítorí ìdí ẹ̀yí ni wọ́n fi má ń tún ara wọ́n ṣe ní alẹ́.
2. Ìwọ nìkan kọ́ ló ní wọn
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Igi mimosa kọ̀ nílo òrùn láti mọ̀ àsìkọ̀ tí yóò fẹ àwọn ewé rẹ̀
Wọ́n lérò wí pé gbogbo irú ńkan abẹ̀mí tó máa ń gba agbára láti inú òòrùn ló ní agogo ara (circadian rhythm), látí lè lo iná àti òkùnkùn .
Àyẹ̀wò ti fi hàn pé ewé igi mimosa yóò ṣí sílẹ̀ tàbí kó padé nínú òkùnkùn, nípasẹ̀ agogo ara rẹ̀, yàtọ̀ sí oòrun.
3. Wọ́n máa ń fún ìṣẹ̀mí lágbárá
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Olú (mushroom) gáa ní agogo nínú ara rẹ
Agogo ínú ara (Circadian rhythms) máa ń fún àwọn àsìkọ̀ bíi alẹ́ àti ọ̀sán, àsìkọ̀ ooru àti òtútú ànfàní àti mọ̀ ìgbà tí ǹkan yóò ṣẹlẹ̀, nítorí náà wọ́n máa ń gbaradì fún wọn.
4. O ní agogo láraà rẹ
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Gbàgbé nípa agogo GMT, agogo to jà jù fún ara rẹ ni igun ọpọlọ rẹ tí wọ́n pe ní hypothalamus
Ó wà ní igun tí hypothalamus nínú ọpọlọ rẹ, gẹ́gẹ́ bíi atọ̀nà, tó ń fi ojú sí bí àlàyé ṣe ń lọ sí gbogbo ara ní àsìkò ọ̀tọ̀tọ̀.
5. O ní agogo ẹ̀gbẹ̀ẹ̀gbẹ́ náà
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ara 'ọmọ ènìyàn máa ń gbìnyànjú láti dúró dédé ni gbogbo ìgbà...
Gbogbo àwọn ríkèé ríkèé ara rẹ ní àlẹékún agogo tí agogo ńlá inú ọpọlọ máa ń mójú tó.
6.Ò sì ní agogo nínú gbogbo sẹ́ẹ́lì rẹ
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Gbogbo sẹ́ẹ́lì lọ́ mọ̀ àsìkò
Gbogbo sẹ́ẹ́lì ni ara rẹ ní agbára  àti máa jí à ti máa jí l'àáàrín wákàtí 24.
7. Agogo ara
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Àsìkò oúńjẹ àárọ̀, ní ìlànà ẹranko esi (bear)
Ní àsìkò tí alẹ́ ń gùn sií ti àsìkò orun sì ń gùn sií, ọpọlọ máa ń gbẹ́ èròjà melatonin jáde-  èròjà tó máa ń mójútọ́ orun àtí títají.
Ọpọlọpọ eranko, bíi àgbọ̀rín, máa ń lo àsìkò yìí látí ṣe ìbálópọ̀ tá bí kí wọ́n fí ara pamí (hibernate).
Àwọn olùmọ̀  rò wípé ara èèyàn máa ń pèsè èròjà tó máa ń gbógun tí àìsàn nígbà ọ̀tútù.
8.Ọ̀sán máa ń mú ara dá ní gbogbo ìgbà
Oríṣun àwòrán, EPA
O ní láti rí ọ̀pọ̀lọpọ̀ òye ọ̀sán l'ojojúmọ́ fún ìlẹra
Tí o bá [wa nínú òkùnkùn, agogo ara rẹ yóò tàsé agogo wákàtí mẹ́rìnlélogún (24).
Àwọn wọ́n yìí ni àwọn isan tó máa ń fi iná ránsé sí igun ọpọlọ tó máa ń jẹ́  kí agogo ara ṣe dédé.
9. Kín l'àsìkò orun?
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Báwo ló ṣe mo àsìkò orun?
Láti àsìkò tí o bá jí ní òwúrọ̀, ni wàhálà orun ti ń máa kójọ pọ.
Súgbọ́n o kọ́kín sùn títí tí agogo ara rẹ yóò fi sọ fún o wípé àsìkò tí to láti sùn.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
It can take time to catch up on your sleep after crossing time zones
You feel jet lagged when your body's master clock is at one time and other parts of your body such as your liver, gut, brain and muscles are at slightly different times.
It takes about one day for each time zone crossed for them to synchronise.
11. Wàhálà orun
Oríṣun àwòrán, Getty Images
"Nígbà tí agogo rẹ sọ fún o wípé kí o lọ sùn sùgbọ́ ara rẹ sọ wípé ""rara"""
Àwọn tí wọ́n ṣe isé àsìkò ọ̀tọ̀tọ̀ àti àwọn èlọ̀míràn ti wọ́n ní kọ́núńkọ́họ láàárín àsìkò ara wọn àti àsìkò ìbagbépọ̀  le ní ńǹkan tí wọ̀n pè ní 'social jet lag'.
E lé yìí ni ìyàtọ̀  láàárín àsikò tí ara wọn fẹ́ jí àti àsìkò tí agogo ara wọn sùn.
Àwọn ìwádí fi hàn pé ìabáṣepọ̀ wà láàárín elé yìí àti ọpọ ìrọ̀nú, sísanra jù, àìsan sug àìsàn ọkàn  àti àìsàn jejere .
12. E jẹ́ kí àwọn ọdọ́mọdé tó ti rẹ̀ símí
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Àìsùn àti àìgbọràn láàárń àwọn ọdọ́ wọ́n jọ ń rìn ni
Àwọn èròjà ara (hormone) máa ń pọ̀ síi nígbà t'ọmọ dé bá fẹ́ bàlàgà eléyìí tó ń máa ń dá owọ́ agogo dúró fún bíi wákàtí méjì.
Pípàsẹ fún ọ̀dọ́mọdé kó jí ní agogo 7 òwúrọ̀ dà bíi kí èèyàn jí ẹni àádọ́ta ọdún ní aago 5 òwúrọ̀.
Nígbà tí aba dàgbà aó padà sí bí à ń tí ń sùn tí à ń jí ń gbà tí a wà ní ọ̀dọ́ .
Agbègbè Somolu f'ojú winá ìjà ní ìpínlẹ̀ Èkó
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ìjà ìgboro bẹ́ sílẹ̀ ní agbègbè Ṣomolu, ní ìpínlẹ̀ Èkó lásìkò tí ìwọ́de ẹgbẹ́ òṣèlú ń lọ lọ́wọ́.
Ìròyìn fi ìdí rẹ̀ múlẹ̀ fún wa pé l'Ọjọru tó kọjá ni ẹgbẹ́ òkùnkùn méjì ló kọlu ara wọn lásìkò tí ẹgbẹ́ òṣèlú kan tí iléeṣẹ́ ọlọ́páà fi orúkọ bò láṣírí, ń ṣe ìwọ́de òṣèlú nú agbègbè náà.
Ìjà tó wáyé ọ̀hún sì mú kí àwọn olùgbé ní agbègbè Somolu, Bariga, Onipanu àti àwọn àdúgbò míràn tó súnmọ́ wọn sá àsálà fún ẹ̀mí wọn.
Shomolu gbajúmọ̀ fún ìwé títẹ̀
Ẹka ileeṣẹ ọlọpa ipinlẹ Eko to n gbogun ti iwa ọdaran, Rapid Response Squad, RRS, sọ loju opo Twitter rẹ pe ọwọ tẹ eniyan mọkanlelogun lori iṣẹlẹ naa, ti iṣẹ iwadii si n tẹsiwaju.
Ṣugbọn alukoro ileeṣẹ ọlọpa ipinlẹ Eko, Chike Oti, kọ̀ lati fi idi eyi mulẹ fun akọroyin BBC, tabi sọ bi iṣẹlẹ naa ṣewaye ati ibi ti nkan de duro.
Vaginismus: Nígbà tí ara rẹ bá kọ ìbálòpọ̀, kí ló ṣẹlẹ̀?
Oríṣun àwòrán, The Other Richard
"Kìí ṣe ìwọ lò ń ṣàkóso bí ara rẹ ṣe ń se. yálà o lọ́wọ́ sí i tàbí o kò lọ́wọ́ sí i. Àwọn olóyìnbó ń pe ọ̀rọ̀ kan ní vaginismus.
Nígbà tí Isley Lynn rántí ìgbà àkọ́kọ́ tó ní ìbálòpọ̀ gẹ́gẹ́ bí amúgbálẹ́gbẹ̀ẹ́ ọ̀dọ́, ó ṣàpèjúwe rẹ̀ gẹ́gẹ́ bí èyì tí kò jọ ìgbà àkọ́kọ́.
Ó bà mí lọ́kàn jẹ́ púpọ̀. Ó dà bí ẹni pé wọ́n fọ́ mi tútú. Mo dá ẹ̀bi lé ara mi lórí ohun tí kì''i ṣe ẹ̀bi mi."
Nígbà tí ọ̀pọ̀lọpọ̀ wa lè rántí bí ìbálòpọ̀ àkọ́kọ́ ṣe fún tó tàbí rí bákan bákan, ó jẹ́ ohun tí ènìyàn ò kí ń fẹ́ sọ nípa ti Isley.
Isley ti pe ọgbọ̀n ọdún báyìí sùgbọ́n ara rẹ̀ kò fẹ́ gáánní ǹkan ọmọ ọkùnrin rárá, ìrírí yìí ń fa ọkàn rẹ̀ ya pẹ́rẹpẹ̀rẹ. Ó dà bí ẹni tó fẹ́ bò awọ olóógbò ni.
Oríṣun àwòrán, The Other Richard
Bí o bá le bò awọ olóógbò, òó mọ bó ṣe rí fún ẹni tí kò fẹ́ kí ǹkan ọmọkùnrin wọ ara rẹ̀.
The NHS sọ ìtumọ̀ vaginismus gẹ́gẹ́ bí ìdáhùn àgọ́ ara kánmọ́ kánmọ́ sí ìbẹ̀rù ohunkúhun tàbí ohun gbogbo tó fẹ́ wọ ojú ara obìnrin.
Ṣe ni gbogbo iṣan yóò dì pọnpọn tí obìnrin kò sì ní lágbára lórí rẹ̀.
'Ìgbésí ayé tí kò pariwo ló dára'
Fún ènìyàn tó bá ń ní irú ìrírí yìí, yóò nira láti ki òwú tí wọ́n fi ń dá ìsun ẹ̀jẹ̀ dúró bọ ojú ara rẹ̀, yóò jàa fita fita láti ní ìbálòpọ̀ tàbí kí abẹ́ máà ta á.
"Isley ní: ""mo gbìyànjú láti lo owù fún dídá ìsun ljẹ̀ dúró nígbà tí mo wà láàrin ọdún kan sí mẹ́wàá, ó kan mí lára gaan bí ẹni pé kò sí ihò lójú ara mi tàbí ògiri dí i pa."
Mo mọ̀ dájú pé ǹkankan ń ṣẹlẹ̀ lẹ́yìn tí mo ní ọ̀rẹ́kùnrin àkọ́kọ́.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Yóò nira láti lo òwú tí wọ́n fi ń dá ìsun ẹ̀jẹ̀ dúró
"Ọ̀rọ̀ náà ń fa ìpalára gan lórí àwọn ìbáṣepọ̀ Isley. ""Mo rántí pé lrù máa ń bà mi pé àwọn ọkùnrin máa ń rò pé mi ò nífẹ̀ẹ́ wọ́n tàbí ọkàn mi kò fà sí wọn."
Ònkọ̀wé yìí ní ìdàmú vaginismus nígbà tó ń súnmọ́ ogún ọdún tí àwọn onímọ̀ nípa ojú ara obìnrin èyí tó mú u tóbi díẹ̀ síi kára lè balẹ̀.
Isley sọ pé lẹ́yìn tí òun gba ìtọ́jú náà ló ríi pé wọ́n ò ṣe iṣẹ́ pé èyí kò sì lè tán ìṣòro àìnídùnú rẹ̀ ọlọ́jọ́ pípẹ́.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Treatment for vaginismus includes psychosexual therapy and relaxation techniques
Onímọ̀ nípa ara míìràn ló bi mí wí pé kí ni mo fẹ́ gaan láti dá lára.
Ọ̀rọ̀ náà ló wà ní ìparí ìwé tó kọ níbi tí wọ́n ti ní kí òṣèré náà sàlàyé ohun tó fẹ́ nípa ti ìbálòpọ̀.
Ìgbà náà ló mọ̀ wí pé òun kò nílò láti ní ìrírí ìbálòpọ̀ bíi gbogbo ènìyàn.
Wí pé, kọ ìtan tìrẹ láyé kí o sì ṣe ohun tó le mú inú ara rẹ̀ dùn.
Oríṣun àwòrán, Science Photo Library
Bí ohunkóhun nínú ọ̀rọ̀ yìí bá ń bí ọ nínú, o leè rí ìmọ̀ràn tó wúlò lójú èwèBBC Advice fún ìmọ̀ràn.
Ó nira láti lè sọ iye obìnrin nílẹ̀ Gẹ̀ẹ́sì tó ń jìyà vaginismus bí ó tilẹ̀ jẹ́ wí pé ìwádìí kan fihàn wí pé ọ̀kan nínú mẹ́wàá obìnrin wọn ni kìí gbádùn ìbálòpọ̀. Ọ̀pọ̀lọpọ̀ ìdí ló ń fa èyí, vaginismus kàn jẹ́ ọ̀kan lára wọn ni.
"Vaginismus yàtọ̀ sí kí ìbálòpọ̀ máa dun èèyàn nítorí ìdáhùn ara ló fà a gẹ́gk bí Dókítà Vanessa Mackay tó jẹ́ oníṣègùn òyìnbó nípa obìnrin ní ilé ìwòsàn ọm ọbabìnrin Elizabeth ní Glasgow.
Shehu Sani: Màá kéde ẹgbẹ́ òṣèlú tí mo máa darapọ̀ pẹ̀lú láìpẹ́
Oríṣun àwòrán, Shehu Sani
Sẹ́nétọ̀ Shehu Sani rọ awọn ololufẹ rẹ lati ṣe suuru ki wọn si farabalẹ lati mọ ohun to kan.
Shehu sani ti kede pe oun ko tii darapọ mọ ẹgbẹ oṣelu kankan lẹyin ti oun fi ẹgbẹ oṣelu APC silẹ ni ọjọ abamẹta.
Sẹnetọ Sani kede lori ikanni Twitter rẹ lọjọ aiku pe laarin ọjọ meji si asiko yii ni oun yoo sọ ni pato, ibi ti oun yoo ko ẹru oṣelu oun gba lọ.
Bakan naa lo fi da awọn ololufẹ rẹ loju pe oun yoo dije lasiko idibo apapọ to n bọ
Sani fi ẹ̀sùn ìwà tí kò tọ́ kan àwọn aláṣẹ́ ẹgbẹ́ òṣèlú APC.
Sẹnetọ to n ṣoju ẹkun idibo aarin gbungbun Kaduna nile aṣofin agba Naijiria, Shehu Sani ti fi ẹgbẹ All Progressives Congress, APC, silẹ.
Ninu lẹta kan to kọ si alaga apapọ ẹgbẹ APC, Sani sọ pe ẹgbẹ APC ko faaye gba awọn afojusun ati iran rere toun ni fun eto isṣejọba awaarawa Naijiria lati wa si imuṣẹ, nitori awọn iwa oṣelu abẹle.
Sani sọ pe oun fi ẹgbẹ APC silẹ nitori pe awọn to wa ninu ẹgbẹ naa kundun lati maa tapa si ofin ẹgbẹ, ti awọn gomina si n ṣe boṣe wu wọn, ti wọn si tun lagbara ju Aarẹ Muhammadu Buhari lọ.
Nnamdi Kanu yóò tó ṣàlàyé bí ó ṣe rìn ín
Ǹjẹ́ ara rẹ ń kọ ìbálòpọ̀ bí?
Chelsea àti Man U ta òmì ní Stamford Bridge
Botilẹ jẹ pe mi o ri tikẹẹti ẹgbẹ APC gba lati tun dije fun ipo Sẹnetọ lẹẹkan si, eyi ko di mi lọwọ lati dije fun ipo naa l'ọdun 2019 nitori pe ọpọlọpọ ẹgbẹ oṣelu lo ti n ṣẹju si mi."
O ni oun ti kọkọ gbiyanju lati fi ẹgbẹ silẹ lasiko ti awọn akẹgbẹ oun kan ṣe bẹ, sugbọn ileri ti awọn adari ẹgbẹ naa ṣe fun un pe wọn yoo yanju awọn nkan to yẹ lati yanju, lo jẹ ki oun duro. Sugbọn ẹtan ni gbogbo rẹ jasi.
Ajimajasan; Àwọn ọmọ olóògbé gbóríyìn fún bàbá wọn
Ọrọ Sẹnetọ Sani ati gomina ipinlẹ Kaduna, Mallam Nasir El-Rufai dabi eku ati oloogbo lati ọdun 2015 ti wọn ti dibo yan wọn.
Paapa lati igba ti gomina naa ti ṣe atilẹyin fun Mallam Baba Sani lati di oludije fun ipo sẹnetọ ti Sani n fẹ.
Oríṣun àwòrán, Ijọba ipinlẹ Kaduna/Twitter
Gomina El-Rufai ati Sẹnetọ Shehu Sani kii ri imí ara wọn laatan
Sani ni olu ile ẹgbẹ APC nilu Abuja fọwọ si ṣaaju eto idibo abẹle, sugbọn ti gomina El-Rufai ati awọn olori ẹgbẹ naa ni ipinlẹ Kaduna kọ ọ.
Sugbọn ko sọ ẹgbẹ ti yoo darapọ mọ. O sọ pe ti asiko ba to, oun yoo kede rẹ.
Arábìnrin kan rè é tó n ṣa ìdọ̀tí l'étí òkun láti dóòlà ìjàpá inú omi ní Nàìjírià
Oríṣun àwòrán, Ijeoma Ndukwe
Doyin Ogunye ati awọn ogún ọmọde to n finufindọ ba a ṣiṣẹ, maa n fi gbogbo igba ṣa ike ati panti ni bebe odo, eyi to le ṣe akoba fun ijapa inu omi ni ilu Eko.
Ogunye to jẹ olupolongo fun ayika to mọ,ti akọroyin BBC, Ijeoma Ndukwe ba pade ni Elegushi beach sọ pe pipalẹ idọti mọ nigba mi maa n kọja agbara.
L'ọsọọsẹ ni oun ati awọn ọmọde kan maa n ko idọti ti yoo kun aadọta apo nla.
Iṣẹ to l'agbara ni, amọ o fi ara rẹ jin lati dena ijamba to le sẹ awujọ.
Oríṣun àwòrán, Ijeoma Ndukwe
Awọn ọmọde yii nkẹkọọ nipa lilo idọti lati pese nkan mi i
Yatọ si pe o maa n ko iti kuro ni bebe òkun naa, o tun maa n gbin igi, o si tun maa n doola awọn ijapa to wa ninu òkun.
Bakan naa ni Ogunye da ibudo kan to to eeka ilẹ mẹtadinlogun silẹ, nibi ti awọn ọmọde maa n lọ lati kọ́ nipa ayika.
Oríṣun àwòrán, Ijeoma Ndukwe
Kò yẹ ki a máa pa àwọn ẹranko inu omi nipakúpa
Arabinrin Ogunye gbagbọ pe lati ọdọ awọn ọmọde ni ayipada ti n bẹrẹ.
Bi o tilẹ jẹ pe iṣẹ amofin ni arabinrin Ogunyẹ kọ nileewe, o gba pe oun to wu u ṣe ni lati jẹ ki ìran to n bọ jogun ifẹ ati ẹmi ifọkansin to ni fun ayika.
O pinnu lati da àjọ kan silẹ l'ọdun meje sẹyin lasiko to fi wa nileewe. Ara rẹ si ni ọgbà 'Kids' Beach Garden' ti dide.
Oríṣun àwòrán, Ijeoma Ndukwe
Diẹ lara awọn ike omi ti wọn ko jade ninu Òkun Elegushi lati fi ṣe awọn nkan mi i
Gbogbo igba ti mo ba fẹ gba atẹgun alaafia, bebe òkun ni mo maa n wa lati sinmi.
"Mo si ṣakiyesi pe òkun naa dọti. Ko tilẹ si bi ara mi yoo ṣe balẹ niru ibẹ.
Eyi lo mu ki arabinrin Ogunye gbe igbesẹ. O lo akọsilẹ rẹ lati ṣawari awọn ti yoo maa tun òkun naa ṣe laigbowo, lẹyin naa niyoo sa awọn nkan to ṣe fi ṣe nkan mi i lara wọn.
Ko pẹ to fi ye e pe oun gbọdọ maa doola awọn ijapa inu okun, bi oun ba se n tun òkun ṣe.
Ọpọlọpọ awọn ẹranko naa lo ri ti omi ti gba si eti òkun.
Oríṣun àwòrán, Ijeoma Ndukwe
Apẹja kan lo doola ijapa yii ninu omi, sugbọn o ku ki wọn to o le tju rẹ
O ṣalaye pe nkan to n pa ọpọlọpọ ẹranko naa ni ike jijẹ.
Awọn ọmọ ti wọn ba bi si maa n ku nitori pe ayika eti òkun ko fararọ fun wọn."""
Oríṣun àwòrán, Ijeoma Ndukwe
Yatọ si pe oun tun ayika òkun ṣe, arabinrin Ogunyẹ ti gbin ẹgbẹta igi agbọn seti òkun
O sọ pe o ṣe pataki fun awọn to n gbe ni ayika omi lati ni imọ nipa titọju awọn nkan inu omi.
O ni o pọn dadan lati laa ye awọn agbegbe to n fi ẹja pipa ṣe iṣẹ́ pe ewu nla ni fun wọn ti ko ba fi si ijapa inu omi mọ.
NYSC: àgùnbánirọ̀ márùn ún gb'òmìnira lọ́wọ́ ajínigbé
Oríṣun àwòrán, NYSC
NYSC
Ile iṣẹ ọlọpaa ti gba awọn agunbanirọ marun ati awọn eeyan meji miran silẹ lọwọ awọn ajinigbe ninu igbo kan nipinlẹ Imo.
Awọn agunbanirọ naa n rinrin ajo lati ilu Ibadan lọ si Ipinlẹ Rivers ati Akwa Ibom l'Ọjọru ki wọn to ji wọn gbe loju ọna mọrosẹ ilu Owerri si Port Harcourt.
Ọga ọlọpaa nipinlẹ Imo Dasuki Galadanchi ni orukọ awọn agunbanirọ ni Abiola Temitope, Olubisi Adekanmi, Jose Temitayo, Folarin Opeyemi and Shonibare Ademola.
'Ọlọ́run kò ní jẹ́ kí àwa dìbò fún Buhari'
O salaye pe awọn ajinigbe ọhun fẹsẹ fẹ nigba ti wọn ri awọn agbofinro ninu igbo ti wọn wa pẹlu akẹẹkọ gboye naa, ṣugbọn o ni wọn ko awọn ohun ti wọn gba lọwọ awọn agunbanirọ ọhun lọ.
Ọga ọlọpaa Galadanchi fi kun ọrọ rẹ pe miliọnu marun naira lawọn ajinigbe ọhun kọkọ beere lọwọ ẹbi awọn agunbanirọ naa ki awọn to fi wọn silẹ.
'Kaduna ni àjọ NYSC pín mi sí sùgbọ́n...'
'Kaduna ni àjọ NYSC pín mi sí sùgbọ́n...'
Josephine Olawa jẹ́ àgùnbánirọ̀ tó yẹ kó lọ sìnrú ìlú ní ìlú Kaduna. Ó ti ra ohun gbogbo bẹ̀ẹ́ sì ni ó ti ṣe gbogbo ètò tó yẹ. Bẹ́ẹ̀ gẹ́gẹ́ náà ni àwọn akẹgbẹ́ rẹ̀ tó yẹ̀ kí wọ́n jọ lọ sùgbọ́n tí ìsẹ̀lẹ̀ Kaduna ti dí wọ́n lọ́wọ́. Àtàwọn àgùnbánirọ̀ àtàwọn òbí wọn ni ìbẹ̀rù bojo ti gba ọkàn wọn.
Ẹ̀wẹ̀, ìgbìmọ aláṣẹ ìjọba ìpínlẹ̀ Kaduna ti n wá ojúùtú si rògbòdìyàn tó mú ẹ̀mí ènìyàn márùnléláàdọ́ta lọ lọ́jọ́ àìkú.
Lówùrọ̀ ọjọ aje ni wọn ṣe ìpàdé kan ti  igbimọ aláṣe si fẹnukò pé kí wọn mú àdínkù bá iye wákàti tí ètò kóníléógbélé yóò fi wà.
Abájáde ìpàdé èètò ààbò naa ti Samuel Aruwan oluranlọwọ fun Gomina Kaduna lori ọrọ ibanisọrọ fi sita ṣe àlàkalẹ  ètò kóníléógbélé naa.
Lawọn àdúgbò  bi Kasuwan Magani àti Kujama wọn  yóò máa wà lábẹ́ kóníléógbélé fún wákàti méjìlá.
Èyí túmọ̀ sí pé láàrín ààgo mẹ́fà ààrọ̀ sí ààgo márùn-ún ìrọ̀lẹ́ dípò wákàti mẹ́rìnlélógun tí wọn gbé lée tẹ́lẹ̀  ni kóníléógbélé yoo fi wa  kí àwọn ènìyàn lè ní àànfàní láti lọ sẹ́nu iṣẹ́ wọn.
Oríṣun àwòrán, NASir El-Rufai/Facebook
Iṣẹlẹ naa lo mu ki ijọba ipinlẹ Kaduna kede aṣẹ ko nile o gbele fun wakati mẹrinlelogun.
O sàlàyé pé àgbègbè Kabala West, Kabala Doki, Sabo-Tasha, Narayi àti Maraban Rido tó wà ní ìgboro Kaduna kò ti fararọ nítori àwọn alákatakítí ọ̀hún sí ń  gbiyanju lati kógùn já àwọn ènìyàn ní inú sọọsì lásìkò ìṣọ́-òru.
Wọn fi kún-un pé àwọn agbègbè tó kù kò tíì fararọ to nítori náà wọn fi ààyè díẹ̀ sílẹ̀ farailu láti ní àǹfàní fún ríra àwọn ǹkan ti wọn ba nílò nínú ilé.
Ìpàdé náà tún fẹ́nukò pé àwọn agbófinro yóò yí àwọn àdúgbò àti ọja ká láti mójú tó kùdìẹ́-kúdíẹ̀ tó ba wà nílẹ̀.
Lójú òpó twitter gomina ìpínlẹ̀ Kaduna Nasir El-Rufai kabamọ lóri gbogbo ìṣẹ̀lẹ̀ náà.
Gomina ipinlẹ Kaduna, Mallam Nasir El-Rufai ti fi ẹdun ọkan rẹ han si ija ẹsin to waye nipinlẹ naa lọsẹ to kọja, ninu eyi ti ọpọlọpọ eniyan ti padanu ẹmi wọn.
Iṣẹlẹ yìí lo mu ki ijọba ipinlẹ Kaduna kede aṣẹ ko nile o gbele fun wakati mẹrinlelogun.
El Rufai ni ki awọn ti ọrọ naa kan fi ọkan balẹ nitori pe ijọba yoo ri i daju pe idajọ ododo fẹsẹ mulẹ, ati pe awọn ọdaran to ṣe iṣẹ naa ko ni lọ lai jiya to tọ labẹ ofin.
Ninu ọrọ to sọ lasiko to ba awọn olugbe ni ipinlẹ naa sọrọ lalẹ ọjọ Aje, El-Rufai ba awọn to padanu eniyan wọn tabi dukia sinu iṣẹlẹ naa kẹdun.
Ní Kaduna, Ẹ̀mí 55 sọnù sínú ìjà ẹ̀sìn
Ìdájọ́ ikú ń dínkù, àmọ́ orílẹ̀-èdè mélòó ló sì ń pa ẹlẹ́sẹ̀?
Ẹmi marun sọnu ninu ija Kaduna
O ni ohun to ba ijọba lọkan jẹ pupọ ninu wahala ọhun to waye ni pe ayederu iroyin kan to tan kaakiri gbogbo agbegbe ti iṣẹlẹ naa ti waye, ni awọn janduku lo anfaani rẹ lati ṣe iṣẹ ibi.
O wa rọ gbogbo awọn olugbe nipinlẹ naa lati faaye gba ara wọn, nitori pe ofin orilẹede Naijiria fi aaye silẹ fun gbogbo eniyan lati gbe ni ibi to ba wu wọn.
Ati pe ọna kan ṣoṣo to le mu ki alaafia jọba lawujọ ni ki awọn to n gbe ninu rẹ ni ọkan lati gbe pọ ni alaafia, isọkan, ati yiyanju aawọ ni ilana ofin.
Oríṣun àwòrán, NASir El-Rufai/Facebook
Lati wa ri i daju pe ẹtọ awọn ọmọ Naijiria lati gbe tabi ṣiṣẹ ni ibi to ba wu wọn, Gomina El-Rufai sọ pe ijọba oun yoo tete ṣiṣẹ lati fi oju eniyan mẹẹdọgbọn ti ọwọ awọn agbofinro tẹ lori iṣẹlẹ to ṣẹṣẹ waye yii, ati awọn mẹtalelọgọta ti wọn mu lasiko eyi to waye ninu oṣu Keji, ọdun 2018 ni agbegbe Kasuwan Magani.
Ọjọ Iṣẹgun, ti i ṣe ọjọ kẹtalelogun, oṣu Kẹwaa ni igbimọ to n mojuto eto aabo ipinlẹ naa yo tun ṣe ipade lati lati jiroro lori ohun to kan lati ṣe si aṣẹ konile o gbele to wa nita.
Bakan naa lo sọ pe awọn oṣiṣẹ alaabo ti wa nilẹ lati mojuto awọn to n rinrinajo gba ipinlẹ Kaduna lati awọn ipinlẹ bi Eko, ati ilu bi i Abuja, Zaria, Kachia ati Jos.
Látàrí ìṣẹ̀lẹ̀ ìpànìyàn tó wáyé ní Kaduna, àjọ àgùnbánirọ̀ (NYSC) tí kéde sísun ètò ìgbaniwọlé àgùnbánirọ̀ ní ìpínlẹ̀ náà.
Ọjọ Ajé ni àjọ náà ṣe ìkéde yìí lórí ìtàkùn ayélujára Facebook.
Eyi ṣẹlẹ̀ lẹ́yìn tí ìpínlẹ̀ Kaduna pàṣẹ kónílé ó gbélé wákàtí mẹ́rìnlélógún ní ìlú náà àti agbègbè rẹ̀ nítorí ìdàrúdàpọ̀ titun tó ń jà rọ̀ìn rọ̀ìn ní ìhà àríwá náà lórí kíkásẹ̀ rògbòdìyàn nílẹ̀ ní agbègbè Kasuwan Magani n'ípinlẹ̀ náà l'ọ́jọ́ ẹtì.
'Ó ṣojú mi kòró, ẹ wọ bí ìgbà ayé Bàbá Fagunwa ṣe rí'
Ó ti di ènìyàn márùnléláàdọ́ta tí wọ́n pàdánù ẹ̀mí wọn nínú ìṣẹ̀lẹ̀ náà báyìí.Ninu àtẹ̀jáde kékeré kan lórí ẹrọ ayélujára twitter ni gómìnà Nasir El-Rufai ti kéde àṣẹ kónílé ó gbélé yìí.
Ọgá ọlọpa Ibrahim Idris ti da ẹ̀ka ọlọ́pàá tó ń ṣe ìwádìí sí'ta, ìgbákejì ọ̀gá ọlọ́pàá tó n mójú tó zone 7 sì ló darí ẹgbẹ́ náà.
Idris, tí o ṣe lòdì sí ìpànìyàn ní ìpínlẹ̀ náà wí pé àwọn ọlọ́pàá ti jáde si'ta láti bẹrẹ ìwádìí fínífíní sí ìṣẹ̀lẹ̀ tí o là ẹ̀mí ọ̀pọ̀ èèyàn lọ yìí.
Oríṣun àwòrán, Twitter/@elrufai
Gómǹà Elrufai sọ wípé ìgbésẹ̀ náà lótọ́ fún ìpínlẹ̀ náà
Gómínà ìpínlẹ̀  Kaduna, Nasir El-Rufai, ti kéde kónílé ó gbélé ní ìgboro Kaduna àti àwọn agbègbè rẹ̀ nítorí ìjà tó bẹ́ sílẹ̀  ní ìlú náà.
Nínú ọ̀rọ̀ tó tẹ̀ jáde lórí òpó Twitter rẹ̀, El-Rufaí sọ wípé òhun gbé ìgbésẹ̀ náà ni nítorí ìlọsíwájú ìpílẹ̀ náà.
Ìjà tó ròpọ̀ mọ́n ẹ̀sìn náà kọ́kọ́ bẹ̀rẹ̀ ní ìlú Kasuwar Magani tó wà ní ìjọba ìbílẹ̀  Kajuru n' Ọjọ́bọ.
Ìjọba ìpílẹ̀ Kaduna ti kọ́kọ́ séde ní ìlú tí ìjà náà ti kọ́kọ́ bẹ̀rẹ̀.
Oríṣun àwòrán, Twitter/@elrufai
Ní Ọjọ́bọ́ ní ìjá kọ́kọ́ bẹ́ sílẹ̀ ní ìlú Kasuwar Magani ní ìjọba ìbílẹ̀ Kajuru
Sùgbọ́n ìjà náà padà tàn dé olú ìlú ìpílẹ̀ náà l'ọjọ́ Àìkú.
El Rufai: A ti mú àdínkù ba kóníléógbélé
Ìdìbò Cameroon: Paul Biya wọlé ipò àarẹ lẹ́ẹ̀keje
Oríṣun àwòrán, Anadolu Agency/Getty Images
Ààrẹ Biya, ẹni ọdún márùndínlọ́gọ́rùn ti wà ní ipò láti ọdún 1982
Ààrẹ orílẹ̀èdè Cameroon, Paul Biya, ti jáwé olúborí sí ipò àarẹ fún ìgbá keje.
Ó jáwé olúborí nínú ètò ìdìbò nàá tí àwọn aráàlú kò ti jáde láti dìbò, bàkan nàá ni wọn dẹ́rù ba àwọn olùdìbò.
'Ó ṣojú mi kòró, ẹ wọ bí ìgbà ayé Bàbá Fagunwa ṣe rí'
Ọ̀gbẹ́ni Biya, tó jẹ́ ẹni ọdún márùndínláàdọ́rùn, ni olórí orílẹ̀èdè tó dàgbà jù ní ilẹ Afrika, ló tún borí pẹ̀lú ìbò ìdá mọ́kànlélàádọ́rin gẹ́gẹ́ bi èsì ìbò tí wọ́n kéde.
Ẹgbẹ́ alátakò tí n polongo fún àtúndì ìbò àarẹ tó wáyé ọ̀hún, ṣùgbọ́n ìgbìmọ̀ olùṣàkóso kọ̀ ọ́.
L'ọ́jọ́ Àìkú sì ni wọ́n ti kó àwọn ọlọ́pàá dìgbòlùjà lọ sí àwọn ìlú nla tó wà ní orílẹ̀èdè nàá; Yaounde àti Douala, nítorí tí àwọn alátakò bá fẹ́ ṣe ìfẹ̀hónúhàn.
Agbègbè méjì tí wọ́n ti n sọ èdè Gẹ̀ẹ́sì ní orílẹ̀èdè nàá ti n kojú rògbòdìyàn àti ìkọlù láti ọwọ́ àwọn ikọ̀ ọlọ̀tẹ̀, nínú èyí tí ọ̀pọ̀lọ̀pọ̀ ènìyàn ti pàdánù ẹ̀mí wọn.
Àjọ tó n pẹ̀tù sáàwọ̀ ní àgbáyé sọ pé àwọn olùdìbò kò jáde tó l'áwọn agbègbè méjéèjì tí wọ́n ti n sọ èdè Gẹ̀ẹ́sì
Ọjọ́ méjì ṣáàjú kí wọ́n tó kéde èsì ìbò ni Ààrẹ tó ti pẹ́ lórí oyè julọ̀ ní Afrika, Teodoro Obiang Nguema, tí orílẹ̀èdè Equatorial Guinea kí Ọ̀gbẹ́ni Biya kú oríìre.
Alátakò gbòógì tí Biya ní, Maurice Kamto, ti ẹgbẹ́ òṣèlú MRC/CRM, ní ìdá mẹ́rìnlá péré nínú ìbò tí wọ́n dì.
Ìlàjì àwọn tó tó ìbò dì ní Cameroon ló jáde dìbò, Tí ẹgbẹẹgbẹ̀rún ènìyàn kò sì ráàyè dìbò nítorí ètò àábò tó mẹ́hẹ.
Ìdúnkookò tí àwọn ọlọ̀tẹ̀ ti fi síta láti kọlu àwọn olùdìbò tó wà ní agbègbè tí wọ́n ti n sọ èdè Gẹ̀ẹ́sì ní ìrìyìn sọ pé ó jẹ́ kí ọ̀pọ̀lọpọ̀ jókòó sílé wọn.
Fayoṣe: Mi ò jẹ̀bi ẹ̀sùn kankan
Íjọba ìpínlẹ̀ Kaduna ti kéde kónílé ó gbélé
Oshiomole pajúdà sí àwọn olóyè ẹgbẹ́ APC
Àwọn kan tilẹ̀ sọ fún ilé iṣẹ́ ìròyìn AFP pé àwọn gbọ́ ìró ìbọn ní òwúrọ̀ kùtù ọjọ́ Ajé ní Buea, tíì ṣe olú ìlú agbègbè tí wọ́n ti n sọ èdè Gẹ̀ẹ́sì.
Bákan nàá ni àjọ elétò ìdìbò Cameroon, Elecam, nàá dín ibùdó ìdìbò kù jákèjádò àwọn agbègbè tí wọ́n ti n sọ èdè Gẹ̀ẹ́sì.
Ṣáàjú kí wọ́n tó kéde èsì ìbò ni àwọn ọmọ ẹgbẹ́ alátakò ti kọ ìwé ẹ̀sùn pé kí àtúndì ìbò wáyé, nítorí 'màgò-mágó, ní ilé ẹjọ́ tó wà fún òfin orílẹ̀èdè Cameroon, èyí tí yóò kéde èsì ìbò nàá.
Ọ̀gbẹ́ni Kamto tilẹ̀ kéde ara rẹ̀ gẹ́gẹ́ bi ẹni tó gbégbá orókè nínú ètò ìdìbò nàá láì ní ẹ̀rí kankan láti fi ìdí èyí múlẹ̀.
Oríṣun àwòrán, Anadolu Agency/Getty Images
Díẹ̀ l'àwọn tó dìbò fi ju ìdá àádọ́ta lọ
"Àwọn ònwòye ètò ìdìbò nàá tó ṣojú àjọ ìṣọ̀kan ilẹ̀ Afrika, sọ pé ètò ìdìbò nàá lọ dáàda, ṣùgbọ́n wọ́n fi kun un pé ''ọ̀pọ̀lọpọ̀ ẹgbẹ́ òṣèlú ni kò ní aṣojú ní ibùdó ìdìbò.but added that ""most parties were not represented amongst the polling personnel""."
Ọjọ́ kan nàá tí ṣe ọjọ́ keje, oṣù Kẹwàá, tí ìdìbò àarẹ wáyé nàá l'óyẹ kí ti ilé aṣòfin wáyé, ṣùgbọ́n wọ́n ti sun un sí ọdún 2019.
NHIS: Ìjọba àpapọ̀ gbé ìgbìmọ̀ ẹlẹ́ni méje kalẹ̀ lórí wàhálà iléeṣẹ́ adójútòfò ìlera
Oríṣun àwòrán, NHIS Nigeria
Inu awọn oṣiṣẹ NHIS ko dun si bi ọga agba ajọ naa ko ṣe tẹle aṣẹ lọ rọọ kun nile ti wọn fun un
Lẹyin ọpọlọpọ awuyewuye, ijọba apapọ ti ran akọwe agba ajọ adojutofo ilera lorilẹede Naijiria, NHIS, Ọjọgbọn Usman Yusuf lọ si isimi ni kiakia bayii.
Ijọba apapọ tun gbe igbimọ ẹlẹni meje kalẹ lati wadi awọn ẹsun ti wọn fi kan an.
Igbimọ iṣakoso ileeṣẹ naa ti fi ẹsun aṣemaṣe lẹnu iṣẹ kan ọjọgbọn Yusuf, eleyi to mu ki wọn ni ko lọ rọọ kun nile laipẹ yii ṣugbọn ti akọwe agba naa kuna lati tẹle.
Àìsan N30,000 owó oṣu f'óṣìṣẹ́ kò ní rọgbọ o- NLC
Iléèṣẹ́ ológun ti ri òkú Ọ̀gágun Alkali tí wọ́n n wá nínú kànga
Eyi fa ọpọlọpọ ikunsinu ni ileeṣẹ NHIS, debi pe awọn oṣiṣẹ ileeṣẹ naa ṣe iwọde.
Ṣaaju asiko naa ni Ọjọgbọn Yusuf sọ pe awọn ti o fẹ maa ṣe owo araalu to wa labẹ eto adojutofo ilera baṣubaṣu ni wọn n ko ina wahala mọ oun ni idi, ṣugbọn awọn ọmọ igbimọ naa sọ pe o di igba ti abọ iwadi ba jade ki awọn eeyan to ri idi okodoro ọrọ naa.
Minisita feto ilera naa ti f'gbakan ri paṣẹ lọ rọọkun nile fun Ọjọgbọn Yusuf ṣugbọn ti aarẹ Buhari daa pada
Ina ru ni ileeṣẹ adojutofo ilera lorilẹede Naijiria, NHIS, ina ọhun kii sii ṣẹ kekere.
Awọn igbimọ alakoso ileeṣẹ naa ni wọn pe birikoto paṣẹ lọ rọọkun nile naa fun ẹni to jẹ ọga agba ileeṣẹ naa, Ọjọgbọn Usman Yusuf lori ẹsun iwa ko-tọ ti wọn fi kan an.
Wọn ni ko yẹra fun igba diẹ ki wọn fi ṣe iwadii lori awọn ẹsun ọhun, ṣugbọn Ọjọgbọn Yusuf kọ jalẹ ko tẹle aṣẹ yii lo ba tun gba ileeṣẹ naa lọ ni ọjọ aje.
Amọṣa ọrọ kọ sisọ nitori nṣe lawọn oṣiṣẹ ajọ naa dabu rẹ ti wọn pẹlu iwọde ti wọn ko si fun un lanfani lati wọ ileeṣẹ naa.
Ni afẹmọjumọ lawọn oṣiṣẹ naa ti lọ ti abawọle ileeṣẹ naa pa, ti wọn si ni Ọjọgbọn Yusuf ko lẹtọ lati wa si ibi iṣẹ nitori wọn ti ni ko lọ rọọkun nile naa.
Igbimọ alakoso NHIS ni ki ọga agba ileeṣẹ naa, Ọjọgbọn Usman Yusuf lọ rọọkun nile naa
Amọṣa, eyi kọ ni igba akọkọ ti ọga agba ajọ adojutofo ilera lorilẹede Naijiria yoo maa ko sinu ọgbun wahala bayii.
Ni oṣu diẹ sẹyin ni minisita fun eto ilera lorilẹede Naijiria, Ọjọgbọn Isaac Adewọle pẹlu ti paṣẹ lọ rọọkun nile fun lori oniruuru ẹsun iwa ijẹkujẹ ṣugbọn ti aarẹ Buhari daa pada pe ko lọ bẹrẹ iṣẹ.
Eyi mu ki ọpọ eeyan maa bere pe ki gan an lo wa laarin aarẹ ati ọjọgbọn Usman Yusuf?
Oríṣun àwòrán, @IsaacFAdewole
Inu awọn oṣiṣẹ NHIS ko dun si bi ọga agba ajọ naa ko ṣe tẹle aṣẹ lọ rọọ kun nile ti wọn fun un
Ọjọgbọn Usman Yusuf ni ko si ohun ikọkọ kan laarin ohun ati aarẹ ati pe ilana ofin ni aarẹ n tẹlẹ eleyi to fidi rẹ mulẹ wi pe igbimọ tabi minisita ko lee yọ oun bi ko ṣe aarẹ.
Ọjọgbọn Usman Yusuf ni awọn eeyan ti wọn n lo owo ara ilu lati lu jibiti lẹka naa ni wọn n fin ina mọ oun nidi.
O ni awọn alakoso eto adojutofo ilera ti amọ si HMO ko ri owo ọfẹ na mọ; wọn ko si gbadun  awọn ilana atunto gbogbo ti oun n gbe kalẹ lo faa; eyi lo si n fa wahala lọ rọọ kun nile ti wọn n fun oun.
Ìjàmbá ọkọ̀: Ènìyàn mẹ́ta péré ló ye ìjàmbá ọkọ̀ l'Eko
Oríṣun àwòrán, Ogun State Traffic Enforcement Agency
Ìjàmbá ọkọ̀
Ìkọlù láàrin ọkọ̀ akẹ́rù kan àti ọkọ̀ akérò ti fa ìjàmbá ńla ní agbègbè Aṣeeṣe, òpópónà Eko sí Ibadan.
Ìsẹ̀lẹ̀ náà ti fa súnkẹrẹ-fàkẹrẹ lójú pópó báyìí.
Àwọn ẹ̀ṣọ́ ojú pópó ti sọ pé ki àwọn tó ń gba ọ̀nà náà kọjá láti wá ọ̀nà mìíràn gbà fún àkókò tí wọ́n yóò fi bójú tó ìṣẹ̀lẹ̀ náà.
A ó máa mú ẹ̀kúnrẹ́rẹ́ ìròyìn yìí wá fún un yín.
Ijamba ina Eko; Awakọ ni omi gọta lo yọ oun ninu ijamba ina
Fani-Kayọde: Ìjọba Buhari ń gbógun ti Fayoṣe ni
Shonekan -Mọ̀lẹ́bí Olórí Nàìjíríà nígbà kan rí ní kokoko lara rẹ̀ ẹ́ le
Oríṣun àwòrán, @BashirAhmaad
Agba ti de si alagba Ernest Ṣhonekan ṣugbọn o ṣi wa laye ati laaye
'Ìròyìn ẹlẹjẹ gba ni pe Aarẹ Naijiria nigba kan ri alagba Ernest Shonekan ti papoda.'
Ninu ifọrọwanilẹnuwo pẹlu ile isẹ iroyin BBC, akowe ijọba ipinlẹ Ogun, Taiwo Adeoluwa so pe ''kokoko lara alagba Shonekan le.''
''Gomina Ibikunle Amosun ṣẹṣẹ ba olori Ìjọba fìdíẹẹ́ lorileede Naijiria nigba kan ri sọrọ ni''
Yomi Fabiyi ló ni ki òun àti ìyàwó rẹ̀ yàgò fún ra wọn
Bakanna ni awọn kan naa ti fi ikede soju opo Twitter pe ko si ootọ kankan ninu iroyin pe Shonekan wa ja
Iroyin iku rẹ yi tunbọ ṣe afihan aburu ti iroyin ẹlẹjẹ ma n ṣe lawujọ.
Ni kete ti ọrọ na lu si ayelujara ni awọn kan ti n kede iku rẹ lalai ṣe iwadi ẹkunrẹrẹ
Alagba Ṣhonekan  to jẹ agbẹ́jọro ati oloseelu ti fi igba kan jẹ Aarẹ ijọba fidihẹ ri ni Naijiria lọjọ kerindinlọgbọn Oṣu kẹjọ ọdun 1993.
Oṣu mẹta pere lo lori aleefa ki ọgagun Sani Abacha to fipa gba ijọba lọwọ rẹ.
Family Planning: Ìjọba Nàìjíríà n fẹ́ kí àtúnṣe wà sí bí àwọn obìnrin ṣe n bímọ
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ijọba sọ pe igbesẹ naa jẹ ọkan lara ọna lati mu idagbasoke ati irapada ba ọrọ aje Naijiria.
Minisita fun eto isuna orilẹede Naijiria, Zainab Ahmed, ti salaye pe kii ṣe pe ijọba fẹ fi gbedeke si iye ọmọ ti obinrin gbọdọ bi.
O fi ikede naa sita loju opo Twitter rẹ, gẹgẹ bi alaye loti ọ̀rọ̀ kan to sọ nibi ipade apero kan to waye nilu Abuja l'ọjọ Iṣẹgun.
O ni kii ṣe pe ijọba orilẹede fẹ ẹ maa fi gbedeke sita lori iye ọmọ ti obinrin kọọkan gbọdọ bi.
Amọ, ijọba Naijiria n wa gbogbo ọna lati ri i daju pe awọn obinrin n fi alaafo si aarin awọn ọmọ ti wọn ba n bi.
Nibi eto apero ọrọ aje, ikẹrinlelogun iru rẹ to waye nilu Abuja ni ọ̀rọ̀ naa ti jẹyọ.
Ahmed sọ pe ijọba ti fi ọrọ naa lọ awọn ọba alaye ati awọn olori mi i jakejado orilẹede Naijiria.
O ṣalaye pe igbesẹ naa jẹ ọkan lara ọna lati mu idagbasoke ati irapada ba ọrọ aje Naijiria.
Ileewosan gba ọmọ silẹ nitori airowo san
Tọkọtaya lu ọmọ ni gbanjo fun 400k
Ìyá àkàndá ẹ̀dá: Àwọn ẹbí mi fẹ́ kí n pa ọmọ mi torí ó jẹ́ àkàndá ẹ̀dá
O sọ pe 'bi awọn eniyan ṣe pọ to ni Naijiria ni wọn ti tọka si gẹgẹ bi ọkan lara awọn ipenija ti ko jẹ ki igbiyanju ijọba o yọ lori eto ọrọ aje.
Ahmed sọ pe ifọwọsowọpọ awọn lọbalọba ni ireti wa pe yoo jẹ ki o rọrun lati gbe eto kan kalẹ ti yoo jẹ ki awọn obinrin maa fi aaye silẹ lẹyin ti wọn ba bi ọmọ kan, ki wọn tun to o bi omiran, nitori pe o sẹ pataki fun idagbasoke awujọ.
Igba akọkọ kọ niyii ti ijọba yoo fi gbedeke si iye ọmọ ti obinrin gbọdọ bi. Ijọba orilẹede China ti gbe ofin kalẹ pe ọmọ kan ṣoṣo ni ẹnikọọkan gbọdọ bi, ko to o di pe wọn tun sọ ọ di meji.
Stella Akinsọ: Àwọn Ìwé Mímọ́ fi àsẹ sí ìfètòsọ́mọbíbí
Ọna ti ijọba Naijiria fẹ ẹ gbe e gba ko ti i fojuhan, nitori igbagbọ ọpọ eniyan ni pe Ọlọrun lo n ṣọmọ, ẹnikẹni ko si gbọdọ ka ọmọ f'ọlọmọ.
Yorùbá dùn lẹ́nu àwọn ọmọ yìí níbi ìdíje ẹgbẹ́ Àtúnbí Yorùbá
Aláàfin Ọyọ: Pọ́ńbélé Yorùbá ni mí, n ò sì ní tijú rẹ níbikíbi
Ẹgbẹ Atunbi èdè Yorùbá bẹ̀rẹ̀ látàrí àwọn ohun tí kò tọ́ ti a n fojú rí láwùjọ.
Àwọn lọ́ba lọ́ba kò gbẹ́yìn níbi ìdíje náà nítórí wọ́n lòdì sí ìparun èdè Yorùbá.
Ọba Lamidi Adeyemi sọ pé kò sí bí ènìyàn ṣe leè gbọ́ ede Gẹ̀ẹ́sì dáadáa tó,  tí kò bá peregede nínú ede abínibí rẹ, kò já mọ́ ǹkankan.
Iku babayeye Alaafin of Oyo
Kábíyèsí ni ede Yorùbá dára púpọ̀, ''Pọ́ńbélé Yorùbá ni mí, n ò sì ní tijú rẹ níbikíbi''. Ó tẹ̀síwájú pé 'ẹ jẹ́ ká ko àwọn ọmọ wa lédè Yoruba to dan mọ́ran'.
'A gbudọ rán BBC Yoruba lọ́wọ́ láti gbé Yorùbá ga'. Kábíyèsí gbé osuba káre fún Iléesẹ́ BBC
Aṣojú ilé iṣẹ́ BBC Yorùbá
Aṣojú ilé iṣẹ́ BBC Yorùbá, Jelilat Opẹyẹmi Ọlawale tó jẹ́ alámójúto ìtàkùn ìkànsíra ẹni lójú òpó BBC Yorùbá tẹnu mọ́ pàtàkì ìfọwọ́sowọ́pọ̀ àwọn ojogbon ninu èdè ati asa Yoruba pelu BBC Yoruba. ''BBC Yoruba ti dé fún ògo Yorùbá àti igbe lárugẹ èdè àti àṣà Yoruba pelu awon eto mii tí a ní lọ́jọ́ iwájú bíi idije, ààyè àti ojúlówó ìròyìn ti o je òótọ́''.
Àwọn ìhùwàsí tí kò bójúmu bii ìwà ibaje tí gbilẹ̀ nílé ẹ̀kọ́, ilé ẹ̀sìn, ádúgbò, laarin ìlú, lariwa, gusu, ìlà oòrùn àti ìwọ oòrùn, ọ̀nà láti wá ojútùú sì, ló bí ẹgbẹ́ Atunbi Yorùbá.
Àwọn àlejò níbi ìdíje
"Alága ẹgbẹ́ Àtúnbí, Ọ̀jọ̀gbọ́n Kayọde Oyediran, sọ pé ""lẹ́yìn àròjinlẹ̀ ni a rí pèé ogúnlọ́gọ́ ọmọ Yorùbá, lọ́mọdé àti lágbà lo ti kọ àṣà àti ìṣe Yorùbá sílẹ̀, tí kò sì ìwà ọmọlúàbí l'áwùjọ mọ́."""
Àwọn ọmọ kò lè sọ èdè abínibí wọn mọ́.
Ó ṣàlàyé pé ẹgbẹ́ Atunbi dá dúró gedegbe, ó sì ń ṣe igbe lárugẹ àṣà, kò fi ti òṣèlú àti ẹ̀sìn ṣe.
Àwọn iléèwé láti ìjọba ìpínlẹ̀ mọ́kànlá tó wà ní Ibadan ló kópa níbi ìdíje nàá tó wáyé lọ́gbà Fáṣitì Ìbàdàn.
Ẹgbẹ́ yìí ń gbìyànjú láti gbé ìlànà tí ọmọ Yorùbá yóò fi ní ìrírí àṣà, ìgbéga fún sísọ àti kíka èdè Yorùbá, wọ́n sì fẹ́ ṣe àwárí ìmúpadàbọ̀sípò àti tí tẹ́wọ́ gba ìwà ọmọlúàbí l'áwùjọ.
Ọjọ́ ọ̀la èdè Yorùbá ti ń kùnà, nítorí nàá ni a ṣe gbé ìdíje kalẹ̀ fún àwọn ọmọ iléèwé l'édè Yorùbá.
Obìnrin àkọ́kọ́ tó gboyè ọ̀jọ̀gb an nílẹ̀ Afrika, Adetoun Ogunsẹyẹ nàá wà níkàlẹ̀
Àwọn iléèwé láti ìjọba ìpínlẹ̀ mọ́kànlá tó wà ní Ibadan ló kópa níbi ìdíje nàá tó wáyé lọ́gbà Fáṣitì Ìbàdàn.
"Alága ètò nàá, Ọ̀jọ̀gbọ́n Ayọ Bámgbóṣé nínú ọ̀rọ̀ rẹ̀ sọ pé ó ṣe pàtàkì láti náàní ""nkan tí a ná, ṣùgbọ́n nítorí pé ó jẹ́ èdè wa, a kó kọbi ara sii."
Alága ètò nàá, Ọ̀jọ̀gbọ́n Ayọ Bámgbóṣé
"Ó sọ pé ""ọ̀nà kínní ona tí èyí fi ń jẹyọ ni pé ọ̀pọ̀ òbí kìí sọ èdè Yorùbá sí àwọn ọmọ wọn, bíkò ṣe èdè Gẹ̀ẹ́sì."
Bamgboṣe rọ àwọn ilé ẹ̀kọ́ àti Yorùbá láti jẹ́ kí èdè Yorùbá mú igbà orókè láwùjọ wa.
Ẹgbẹ́ Atunbi dá dúró gedegbe, ó sì ń ṣe igbe lárugẹ àṣà, kò fi ti òṣèlú àti ẹ̀sìn ṣe.
Ọ̀pọ̀lọpọ̀ ijó àti eré ìdárayá ni àwọn èwe fi dá àwọn akópa lára yá.
Ere ori itage
YSAN 2018: llú Ondo gbàlejò Àpérò Ẹgbẹ́ Onímọ̀ èdè Yorùbá Nàìjírìa
Fashọla sọ pé ìṣàkóso Awolọwọ nìkan ló ṣee fi wé ti Buhari'
Faṣọla sọ pe ki awọn eniyan ẹkun Iwọ oorun Gusu ṣe atilẹyin fun aarẹ Muhammadu Buhari ninu eto idibo ọdun 2019.
Minisita fun akanṣe iṣẹ, ina ọba, ati ilegbee, Babatunde Raji Faṣọla sọ pe ẹkun Iwọ oorun Guusu ni yoo gba ipo aarẹ lẹyin saa keji Buhari.
Fasọla sọ ọrọ naa nibi ipade apero ita gbangba kan to waye ni gbọngan Emeritus Professor Theophilus Ogunlesi, to wa ni adojukọ ileewosan UCH, ilu Ibadan.
'EFCC ti wá dà bíi ara ẹgbẹ́ òṣèlú APC'
Afojusun ipade naa jẹ ọna lati mu idagbasoke ati atunṣe ba oju ọna irin, oju ọna ọkọ, awọn ileesẹ nlanla, ina ọba ati bẹẹbẹ lọ,
Lara awọn to kopa nibi ipade naa ni Minisita fun eto iroyin ati asa, Lai Mohammed ati akẹgbẹ rẹ, minisita fun akanṣe iṣẹ, ina ọba, ati ilegbee, Babatunde Raji Faṣọla, ati minisita fun irinna, Rotimi Amaechi, Minisita fun nkan alumọni inu omi, Suleiman Adamu, ati gomina ipinlẹ Ọyọ, Abiọla Ajimọbi ati awọn mi i.
Bakan naa ni awọn ọba alaye, oniṣẹ ọwọ, ẹgbẹ awọn ọlọja, ati awọn to wa ni iṣakoso ninu ijọba ipinlẹ Ọyọ.
Bakan naa ni awọn ọba alaye, oniṣẹ ọwọ, ẹgbẹ awọn ọlọja, ati awọn to wa ni iṣakoso ninu ijọba ipinlẹ Ọyọ.
Ipade apero naa ni wọn ni yoo fi aaye gba awọn aṣoju ijọba apapọ lati ṣalaye awọn eto ati ilana ti ijọba n gba ṣiṣẹ, ati lati gbọ erongba awọn araalu lori idagbasoke awọn nkan amayedẹrun.
Faṣọla sọ pe ki awọn eniyan ẹkun Iwọ oorun Gusu ṣe atilẹyin fun aarẹ Muhammadu Buhari ninu eto idibo ọdun 2019.
'Taló dà bí Ọlọ́run Fayose?
Akọ̀ròyìn tó fí fídío Ganduje síta tí fojú hàn nílé aṣòfin
O ni iṣakoso kan to o ṣe fi we ti aarẹ Buhari taa ba ni ka sọ nipa minu adehun ipolongo ibo ṣẹ, ni ti Ọbafẹmi Awolọwọ.
O sọ pe awọn ijọba to ti kọja ṣakoso orilẹede Naijiria fun ọdun mẹrindinlogun, wọn si fi ipo naa silẹ lai ni aṣeyọri kankan to pojuowo, ayafi awọn ileri ti wọn ṣe ki wọn to bọ si ipo.
Nkan mẹta ni ẹgbẹ wa, APC, ṣeleri fun yin; eto aabo, ọrọ aje ati lati gbogun ti iwa ijẹkujẹ. Iyatọ akọkọ to wa laarin wa niyii.
Kí ló dé tí ẹ kò fi kọ́ mi lédè Yoruba?
O ni ki awọn ẹya Yoruba dibo fun Buhari lati ṣe saa keji, nitori wi pe Iwọ Oorun Gusu ni yoo gbe ijọba fun lẹyin saa keji rẹ.
"Ẹ maa ti jẹ ki ẹnikẹni gbọ. Wọn ti sọ fun wa pe ẹkun Iwọ oorun Gusu lo kan lati bọ si ipo aarẹ lẹyin saa keji Buhari.
O tumọ si pe nkan kan ti ẹ gbọdọ fi sọkan niyẹn lasiko ti ẹ ba fẹ sibo yan adari yin. Ẹ nilo lati tẹle aarẹ Buhari, ka ma ba a padanu anfaani naa."
2019 Election: INEC ya ọ̀sẹ̀ kan sílẹ̀ fún àyẹ̀wò orúkọ oludibo
Oríṣun àwòrán, @inecnigeria
Aworan alaye ayẹwo orukọ awọn oludibo
Ajọ eleto idibo lorile-ede Naijiria, INEC ti bẹrẹ afihan iwe orukọ awọn oludibọ jakejado orileede Naijiria.
INEC ni igbesẹ yi wa ni ibamu pẹlu ofin idibo orileede Naijiria.
Laarin agogo mẹsan owurọ titi di aago mẹta ọsan ni ayẹwo orukọ naa yoo ma waye lojumọ.
Lekan Kingkong: Níbikíbi tí mo bá wà, màá gbé àṣà Yorùbá ga
Oju opo Twitter INEC ni ikede nipa ibẹrẹ ayẹwo orukọ yii ti waye.
Laipẹ yii ni Alaga ajọ eleto idibo, INEC, ọgbẹni Mahmood Yakubu ba awọn akọroyin sọrọ lori awọn alaye to ni se pẹlu idibo to n bọ lọna.
Pataki lara awọn ohun ti wọn sọ nibi ipade naa ni pe, awọn yoo fun awọn ara ilu lanfani lati gba ile ẹjọ lọ, ti alaye kankan nipa oludije ipo Aarẹ ati awọn to n du ipo ile asọfin agba ti wọn ba fi sita ninu iwe 'Form CF001' ko ba tẹ wọn lọrun.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Awon oludibo
Mahmood salaye pe, igbese yii yoo fun awọn ara ilu laanfani lati tọpinpin awọn to fẹ soju wọn saaju ọjọ idibo.
Ninu alaye rẹ, o ni wọn le gba ile ẹjọ giga lọ ti wọn ba ri aisedede kankan ninu ohun ti oludije naa ba fi sọwọ.
Yakubu fikun pe, awọn yoo fi ọsẹ kan se afihan orukọ awọn oludibo, bẹrẹ lati ọjọ kẹfa Oṣu kọkanla ọdun yi titi di ọjọ kejila Oṣu kọkanla
Oríṣun àwòrán, @inecnigeria
Ireti INEC ni pe, ayẹwọ orukọ yi yoo fun awọn ara ilu lanfaani lati mọ boya aisedede kankan wa ninu orukọ wọn.
Ọjọ méjìléláàdọ́fà lo ku ki idibo ọdun 2019 fi  waye, awọn oludije mọ́kàndínlọ́gọ́rin ( 79) si ni yoo du ipo Aarẹ.
INEC sọ wi pe, ẹgbẹ oselu mọ́kàndínláàdọ́rùn ún lo ti fi orukọ oludije bii ẹgbẹrun kan ati mẹtalelẹgbẹrin (1,803) sọwọ fun ipo asofin agba, nigba ti wọn si ti fọwọ si orukọ awọn 4,548 fun ipo asoju-sofin.
Aṣòfin ìpínlẹ̀ Èkìtì tí wọ́n yìnbọn fún ti kú nílé ìwòsàn
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Kò tí ìdájú ìdí tí àwọn agbébọn náà ṣe ṣíná fún ọkọ̀ Adedeji
Iléese ọlọ́pàá ìpínlẹ̀ Ekiti ti fi ìdí ẹ̀ múlẹ̀ pé aṣòfin Micheal Adedeji tí agbébọ́n yìnbọ́n fún l'ọ́jọ́ Etì ti rẹ̀ walẹ̀ àsà.
Ní ọjọ́ Ajé ni agbenusọ fún ilé iṣé ọlọ́pàá ìpínlẹ̀ náà, Caleb Ikechukwu, sọ pé ìwádìí ti fi hàn pé asòfin náà ti pá'pò dà.
Lọ́jọ́ Etì ní àwọn agbébọn kan yìnbọn fún Micheal Adedeji.
Nígbà náà, orí bá Micheal ṣeé pẹ̀lu bí í ti ṣe ríbi jàjàbọ́ lọ́wọ́ àwọn agbégbon ọ̀hún nígbà tí ó ń lọ sí ìlú Akurẹ.
Igbákejì olórí ilé asòfin Ekiti, Segun Adewumi fìdí ọ̀rọ̀ náà múlẹ̀ fún àwọn oníròyìn l'ọ́jọ́ Ẹtì.
Ìṣẹlẹ iyinbon APC Ekiti : Ki gaan lo ṣẹlẹ?
Ó ní  wọ́n sáré gbé Adedeji tó ń sojú agbègbè  iwọ̀ oòrùn guusu kejì ní ilé asòfin Ekiti lọ sí ilé ìwòsàn kan ní Ado Ekiti lẹ́yìn ìgbà tí wọ́n sì tún gbée lọ sí ilé ìwòsàn olùkọ́ni  ìjọba àpapọ̀ ní Ido Ekiti.
Ọ̀gbẹ́ni Adedeji wà lára àwọn asojú tí wọ́n yọ olórí ilé asòfin ìpínlẹ̀ Ekiti tẹ́lẹ̀ , Kola Oluwawọle tí wọ́n sì fi Adeniran Alagbada rọ́pò rẹ̀.
Ẹ̀wẹ̀, olórí ilé asòfin ìpínlẹ̀ Ekiti, Adeniran Alagbada ti ké sí àwọn ọlọ́pàá latí ríi wí pé wọ́n se ìwádìi lórí ìṣẹ̀lẹ̀ ìyìnbọn mọ́ Adedeji.
Nínú àtèjáde kan láti ọwọ́ agbenusọ fún olórí ilé ,Oluwatoyin Babablola, ó ní èyí kìí se ''ìgba àkọ́kọ́ tí àwọn kan yóò máa dún kùkùlàjà mọ́ àwọn ọmọ ilé asòfin tófi mọ́ oun náà''
''Ejò ọ̀rọ̀ yíì lọ́wọ́ nínú, fún ìdí èyí mo rọ̀ àwọn ọlọ́pàá láti tọ pinpin rẹ̀''
Mike Ifabunmi: Òrìṣà ló gbè wà jù ni Brazil
#67yearoldmother:ọ̀pọ̀ gbà pé àdúrà ló gbà lóri tọkọtaya Otubusin
Google ati awọn ọmọ Naijiria ṣe ìrántí ọjọ ibi Dokita Stella Adadevoh pẹlu àwòrán
''Eeehya! Iku ma d'oro o!
"Emi na ri ""doodle"" naa ni owuro oni, ni igba ti mo si oju-iwe google lori ayelujara itakun agbaye."
Mi o kọkọ mọ itumọ rẹ fun igba diẹ, sugbọn lẹhin ti mo ri aworan kokoro aarun Ebola , o ye mi kedere wi pe Arabinrin Dokita Stella Folashade Adadevoh ni wọn n se iranti rẹ.
Ki Ọlọrun Olodumare o fi ọrun kẹ wọn.''
Ọrọ ree lati ọdọ ọkan lara awọn ololufẹ oju opo BBC Yoruba, arakunrin Olayemi Patrick Edema nigba ti o ri aworan Dokita Stella Adadevoh ti Google se iranti ọjọ ibi méjílélọ́gọ́ta ti ko ba ṣe kani pe o wa laye.
Oríṣun àwòrán, Google
Oun nikan kọ ni o n ranti Dokita Stella Adadevoh ati ipa ribi ribi to kọ nigba ti itankalẹ aarun Ebola  ṣẹlẹ ni Naijiria.
Loju opo ayelujara ni kete ti aworan Google yii lu jade ni awọn ọmọ Naijiria ti n fi ọrọ iranti ati adura ranse loju opo Twitter lori ọjọ ibi Dokita Adadevoh.
Sugbọn ṣe ẹyin tilẹ ranti itan Dokita Adadevoh ati oun ti o ṣe ti gbogbo eeyan  fi n jaran iku rẹ?
Ẹ jẹ ki a ranyin leti.
Ogunjọ osu kẹjọ odun 2014 ni Dokita Stella Ameyoh Adadevoh se alabapade arakunrin ọmọ orileede Sierra Leone kan ti orukọ rẹ n jẹ Patrick Sawyer nigba ti arakunrin  naa ti o ni aarun Ebola  fẹ fi tipa kuro ni ile iwosan  aladani kan ti Dokita Stella  ti n sisẹ ni ilu Eko.
Oríṣun àwòrán, PIUS UTOMI EKPEI/Getty
Ipade wọn yii jẹ eleyi to lamilaka nitori oun lo se okunfa bi Dokita Adadevoh ti se di ilumọka gẹgẹ bi ẹni to kọdi itankalẹ aarun ebola ni orileede Naijiria.
Oye ati ifarajin Dokita Stella lo mu u sọ wi pe oun ko ni jẹ ki wọn tu arakunrin na silẹ kuro nile iwosan naa nitori pe o fura si i pe o ni aarun Ebola.
Oríṣun àwòrán, Reuters
Ilakaka rẹ ati tawọn osise ilera miiran sokunfa bi Naijiria ti se ribi koju aarun yi ti ajọ eleto ilera lagbaye si sọ wi pe Naijiria ti jajabọ lọwọ ajakalẹ aarun naa logunjọ Osu kẹwa ọdun 2014.
Àtọ̀ ọmọkùnrin ti rógo o!
Oríṣun àwòrán, Reuters
Ipinlẹ Eko ti isẹlẹ yi ti waye ko ni agbara tabi ipalẹmọ kankan ti wọn se kalẹ de aarun Ebola sugbọn igbiyanju Dokita Stella ko ipa ribiribi lati le dena aarun naa.
Lẹyin orẹyin, arakunrin Patrick Sawyer to gbe aarun naa wọ Naijiria ku ti osisẹ ilera mẹfa si padanu ẹmi wọn bakanna.
Ninu awọn mẹfa naa ni a ti ri Dokita Stella Adadevoh.
Olóòtú ìjọba Abiy ni awọn obìnrin kìí hùwà jẹgúdújẹrá tó àwọn ọkùnrin
Oríṣun àwòrán, Alamy
Okunrin mẹfa,Obinrin mẹfa ni wọn bura wọle fun sipo bi minisita lorileede Ethiopia
Njẹ ijọba orile-ede Naijiria le fun awọn obinrin ni ida kan ida meji ipo minisita ninu ijọ́ba?
Ibeere yi gba aronusi ṣugbọn ki ẹ to wa esi fun, a fẹ fi to yin leti wi pe awọn orile-ede kan l'Afrika ti n ṣe bẹẹ.
Olootu ijọba orile-ede Ethiopia Abiy Ahmed ti se oun ti ẹnikan o ṣe ri nijọba  ilẹ naa pẹlu bi o ti ṣe fun awọn obinrin ni ida kan ninu ida meji awọn  ipo minisita ninu ijọba rẹ.
Koda a gbọ pe minisita to n risi eto abo lorile-ede naa jẹ́ obinrin.
Nigba ti o n ṣalaye ohun to fa igbese yi, Abiy ni awọn obinrin kii ṣe onijẹgudujẹra bi awọn ọ́kunrin ati wi pe wọn leè mu alaafia ati iduro ṣiniṣin ba ijọba.
Oríṣun àwòrán, EDUARDO SOTERAS/AFP/GETTY
wọn obinrin ti kun inu ijọba Ethiopia
Ni bayi, orile-ede Ethiopia ti kun Rwanda gẹgẹ bi orile-ede ti won ni ida to se deede laarin okunrin ati obinrin ninu ipo igbimọ alaṣẹ  ijọba.
Bakan naa ni ọgbẹni Abiy mu adinku ba iye awọn to di ipo minisita mu ku lati mejidinlgbn si oogun.
Oríṣun àwòrán, Reuters
Abiy ti ṣe awọn iyipada to lamilaka laarin oṣu mẹfa to de ori aleefa
Lati igba ti ọgbẹni Abiy ti de ori ijọba losu kẹrin, orisirisi ayipada lo ti mu ba isejọba.
O ti mu opin ba ija ogun ọdun ton waye laarin Ethiopia ati Eritrea, o si tun ti tu awọn oloselu ti wọn sọ sẹwọn silẹ.
O tun dẹkun bi ijọba ti se wawọ mọ eto ọrọ aje lorileede naa.
Aisha Mohammed ni o kọkọ kede orukọ rẹ gẹgẹ bi minisita fun eto abo.
Lati agbegbe Afar lo ti wa ni ariwa ila oorun Ethiopia ti o si ti saaju jẹ minisita fun eto ile kikọ
Muferiat Kamil, to jẹ olori ile asofin tele di Minisita fun eto alaafia akọkọ.
Oun ni yoo ma dari awọnile iṣe otẹlmuyẹ ati ọlọpaa ijọba apapọ orile-ede naa.
Mahlet Hailu, to jẹ igbakeji asoju Ethiopia si ajọ isọkan agbaye ṣe afihan iye awọn minisita tuntun ohun sójú opo Twitter pé
Ogbeni Abiy ni eto ayipada ọhun ni lati se agebyẹwo awọn aiṣedede to koba orile-ede awọn tele.
O ni awọn obinrin ko ipa ribiribi nipase mimu alaafia wa ti wọn ko si ki n mu igba kan bọ ọkan ninu.
Oríṣun àwòrán, AFP
Aisha Mohammed ti saaju jẹ Minisita eto ikọle saaju ki o to jẹminisita fun eto abo
Ọmọ ọdun mejilelogoji naa di olootu ijọba leyin igba ti Hailemariam Desalegn ṣaadede fipo silẹ.
Eyi waye lẹyin ọpọ ọdun ti awọn ẹya Oromo ti n fi ehonu han lori bi wọn ti ṣe ko iyan wọn kere ninu isejọba orileede Ethiopia
Oromo ni ọgbẹni Abiy ṣugbọn bi o ti ṣe n pe fun isọkan ati ibaranisepo ti mu ki awọn ara ilu fẹ maa tẹwọ gba a.
Owó ounjẹ El-Zakzaky lósù kan nijọba lè fi bọ́ ẹlẹ́wọ̀n 208
Oríṣun àwòrán, Islamic movement
Agbẹnusọ fun ijọ ẹsin Shiite ni El-Zakzaky n kerora lori ohun ti oju rẹ n ri nipa ounjẹ
Miliọnu mẹta ati aabọ ti ijọba apapọ ni awọn fi n bọ olori ijọ Shiite Ibrahim El-Zakzaky to wa ni atimọle ni oṣooṣu ni iye ti ijọba apapọ fi n bọ ẹlẹwọn mẹjọlenigba ni Naijiria.
Eyi ni iwadii BBC Yoruba latari rogbodiyan to jade lẹyin ti Minisita fun Iroyin ati Aṣa ni Naijiria, Lai Mohammed sọrọ lori iye owo ounjẹ El-Zakzaky.
Isuna owo 2018 ti ileeṣẹ ijọba fun ọrọ abẹle eyi ti o n ṣe akoso awọn ọgba ẹwọn Naijiria ṣe fihan pe N15.34 biliọnu ni ijọba fi n bọ awọn ẹlẹwọn 75,789 to wa ni orilẹ-ede yii.
Eyi tumọ si pe, ẹlẹwọn kookan yoo fi N202,404 jẹun fun ọdun kan tabi N16,867 fun oṣu kan, eyi to ja si N562 lojoojumọ.
Miliọnu mẹta ati aabọ ti Lai Mohammed ni El-Zakzaki fi n jẹun ja si N117,000 lojoojumọ.
Ki ni ounjẹ ti ẹ ro pe N117,000 le ra ni ojoojumọ?
Ki ni ounjẹ ti ẹ ro pe N117,000 na le ra ni ojoojumọ?
Agbẹjọro fun Ibrahim El-Zakzaky ti sọ fun BBC pe irọ ni Alhaji Lai Mohammed pa lori iye ti El-Zakzaky fi n jẹun lojoojumọ.
Haruna Magashi sọ ọrọ naa gẹgẹ bi esi si ohun ti Minisita fun eto iroyin ati aṣa ni Naijiria, Lai Mohammed sọ ninu fidio kan, pe miliọnu mẹta ataabọ ni ijọba apapọ fi n bọ olori ẹlẹsin Shia loṣooṣu.
"Ọrọ yii ki ṣ'oun to pamọ fun mi, mo mọ nipa ohun ti mo ri ati nkan ti  El-Zakzaky sọ fun mi, fun ra rẹ lo n ra ounjẹ to n jẹ lati igba to ti wa ni ahamọ
ẹ̀fọ́ rírò jẹ́ alábárìn iyán, fùfú, ẹ̀bà, àmàlà àti ìrẹsi funfun
O si yẹ k'oju ko ti ijọba pe iru eniyan bi Lai Mohammed n parọ.''"
Irọlẹ Ọjọbọ ni iroyin kan jade pr Minisita ọhun, Lai Mohammed sọ pe miliọnu mẹta ataabọ Naira ni ijọba fi n fun El-Zakzaky l'ounjẹ loṣooṣu lati igba to ti wa lakata wọn.
Ileeṣẹ amohunmaworan Oaks lo fi fidio ipade oniroyin ti Mohammed ṣe pẹlu awọn akọroyin lẹyin ti ipade igbimọ alaṣẹ orilẹede Naijiria waye l'Ọjọru.
Bakan naa ni agbẹnusọ fun ijọ ẹsin Shia lorilẹ-ede Naijiria, Ibrahim Musa sọ fun BBC News Yoruba pe ẹni ti wọn ba n na obitibiti owo bẹ fun ounjẹ rẹ yẹ ki o mọọ li ara.
Ẹwẹ, ọkan lara awọn oloye ẹgbẹ ẹlẹsin Shia, ta a tun mọ si Islamic Movement of Nigeria, IMN, Mohammed Ibrahim Gamawa, ṣalaye pe awọn ọmọ ijọ El-Zakzaky paapa maa n da owo lati fi ra awọn nkan ti olori wọn nilo lahamọ.
Ẹwa Agọnyin jẹ aayo ounjẹ Badagry
"'Koda, ẹrọ amunawa t'oun lo lahamọ ti wọn fi si, awa la ra a."""
Ìwà olè, jìbìtì àti ìjẹkújẹ ló n jé káwọn mii yí ọjọ́ orí wọn padà
IMN fidirẹmulẹ pe lootọ ni ileeṣẹ ọtẹlẹmuyẹ DSS, ti gbe El-Zakzaky kuro ni ilu Abuja lọ si ipinlẹ Kaduna, ṣugbọn wọn ko ti i gba beeli rẹ.
Amọṣa awọn ọmọlẹyin ijọ Shiite lorilẹ-ede Naijiria, IMN ni o ṣeeṣe ki o jẹ pe awọn eeyan kan ni ijọba aarẹ Buhari n fi orukọ aṣiwaju ẹsin Shiite naa, El-Zakyzaky gba owo si apo ara wọn.
Gẹgẹ bi ẹ ṣe mọ bi iwa ijẹkujẹ ṣe gbilẹ ninu iṣejọba yii, eyi fihan pe nṣe ni wọn n gbọn owo kuro ninu apo araalu lorukọ Sheikh El-Zakyzaky nitori, lai fọta pe, irọ nla ni wọn n pa.
Ọrọ yii ti wa di alatagba laarin awọn Ọmọ orilẹede Naijiria bayii. Ti ọpọlọpọ si n bu ẹnu ẹtẹ lu minisita naa pe irọ pipa rẹ ẹ ti pọju, ati pe ijọba to n ri owo fun ẹni kan ṣoṣo l'ounjẹ pẹlu miliọnu mẹta ataabọ Naira gbọdọ le ri ọgbọ̀n ẹgbẹrun Naira san gẹgẹ bi owo oṣu oṣiṣẹ to kere ju.
Awọn kan tilẹ n ṣe atupalẹ iru ounjẹ ti ẹnikan le jẹ loṣu.
Oríṣun àwòrán, @i_batoula
Ile-ẹjọ giga to n joko si ipinlẹ Kaduna ti kọ lati gba oniduro adari ẹgbẹ musulumi Shitte, El-Zakzaky ati iyawo rẹ.
Iroyin to to wa leti sọ pe, ko to yọju si ile ejo ni Ọjọru, ile isẹ ọlọpa nipinlẹ Kaduna ti fofin de eto irinna awọn eniyan lagbeegbe ilu Kaduna.
Bẹẹ si awọn ọmọ ẹgbẹ́ Shitte ti n se iwọde lọpọ igba láti bèérè fún ìtúsílẹ̀ olórí wọn, Ibrahim El-Zakzaky, tó ti wà ní àhámọ́ àwọn ológun láti bi i ọdún méjì.
Ìròyìn tó tẹ̀wá lọ́wọ́ sọ pé iléèṣẹ́ ológun Nàìjíríà àti àwọn ọmọ ẹgbẹ́ ẹlẹ́sìn Shiite tún ti n kọlu ara wọn ní agbègbè Maraba nílùú Abuja.
Ìkọlu tuntun yìí wáyé lẹ́yìn ọjọ́ díẹ̀ tí ọ̀kan wáyé. Tí iléèṣẹ́ ológun Nàìjíríà sì sọ̀ pé l'óòtọ́ ni àwọn ọmọ ogun yìnbọn pa ọmọ̀ ẹgbẹ́ Shiite mẹ́ta ní agbègbè Zuba, tó wà ní ìlú Abuja.
"Ẹnìkan tí ìṣẹ̀lẹ̀ nàá ṣojú rẹ̀ sọ fún BBC pé ìjà ọ̀hún bẹ̀rẹ̀ lásìkò tí àwọn ọmọ ẹgbẹ́ Shiite n rìnrìn àjò láti Nasarawa lọ sí ìlú Abuja, tí àwọn ọmọ ogun sì ''dí ọ̀nà mọ́ wọn, pé kí wọ́n padà sí ibi tí wọ́n ti n bọ̀."""
Ṣùgbọ́n, àwọn ọmọ ẹgbẹ́ Shiite kò dá wọn lóhùn. Èyí ló mú kí wọ́n wojú ara wọn.
Akọ̀ròyìn BBC, Ahmed Wakili tí ìṣẹ̀lẹ̀ nàá ṣojú rẹ̀ jábọ̀ pé níṣe ni àwọn ọmọ ogun n yìnbọn sí afẹ́fẹ́, kí ìbọn nàá tó bá àwọn ọmọ ẹgbẹ́ Shiite lásìkò tí wọ́n kọ̀ láti mú àṣẹ tí àwọn ọmọ ogun pa fún wọn ṣẹ.
Oríṣun àwòrán, Nigeria Army
Aworan awọn ọmọ ogun naa farapa nibi iṣẹlẹ naa
O sọ pé ''àwọn ọmọ ẹgbẹ́ Shiite péjọ sí agbègbè Maraba, wọ́n n gbìyànjú láti wọ ìlú Abuja.''
Òkú ènìyàn mọ́kànlá ni mo rí níbi tí ìṣẹ̀lẹ̀ nàá ti wáyé, tó fi mọ́ òkú obìnrin kan tó n tọ́mọ lọ́wọ́.
Agbẹnusọ fún ẹgbẹ́ Shiite sọ fún BBC pé ẹgbẹ́ nàá n ṣe ìwọ́de ẹ̀sìn tó l'ápẹrẹ ní ọ̀sán ọjọ́ Aje, ni àwọn ọmọ ogun yabò wọ́n.
Àwọn ọmọ ẹgbẹ́ nàá n ṣe ìwọ́de láti bèérè fún ìtúsílẹ̀ olórí wọn, Ibrahim El-Zakzaky, tó ti wà ní àhámọ́ àwọn ológun láti bi i ọdún méjì.
Oríṣun àwòrán, Manzo Ezekiel
Nísẹ ni àwọn tó n lọ, àti àwọn to n bọ̀ kòrí àáye kọjá nítorí bí ojú ọ̀nà ṣe dí.
Ní báyìí, páro-páro ni agbègbè nàá dá, tí àwọn onílé ìtajà sì ti gbé ilẹ̀kùn wọn tì pa.
Ẹ̀wẹ̀, àwọn òṣìṣẹ́ aláàbò ti gbégi dínà gbogbo ọ̀nà tó wọ ìlú Abuja látu agbègbè ọ̀hún.
Iléèṣẹ́ ológun kò tíì sọ nkankan lórí ọ̀rọ̀ yìí, bẹ́ẹ̀ni a kò sí tí ì rí wọn bá sọ̀rọ̀ títí di àsìkò tí a kó ìròyìn yíì jọ.
Iléeṣẹ́ ológun Nàìjíríà ti fidi ọrọ mulẹ pe awọn ọmọ ẹgbẹ́ ẹlẹ́sìn Shiite mẹta lo ku ninu ikọlu to wáyé láàrin àwọn ọmọ ogun Nàìjìríà àti ẹgbẹ Shiite l'Abuja.
Wọn ni awọn ọmọ ogun meji kan naa farapa ninu ikọlu ohun púpọ̀.
Ogagun James Myam ninu atẹjade kan ti o fi sita loju opo Twitter, Iléeṣẹ́ ológun Nàìjíríà  so pe ikọlu naa waye nigba ti awọn ọmọ ẹgbẹ ẹlẹsin naa gbegi dina awọn ọmọ ogun ti wọn n gbe ọta ati ohun ija lati Abuja lo si Kaduna.
Oríṣun àwòrán, Ibrahim Musa
Òkú ènìyàn mọ́kànlá ni mo rí níbi tí ìṣẹ̀lẹ̀ nàá ti wáyé, tó fi mọ́ òkú obìnrin kan tó n tọ́mọ lọ́wọ́.
O ni o ''ṣe ni laanu pe awọn ọmọ ẹgbẹ naa mẹta padanu ẹmi wọn ninu ikọlu ohun ṣugbọn awọn ọmọ ogun meji naa farapa.''
''Iwọde lo yẹ ki wọn ma ṣe ṣugbọn niṣe ni wọn gbegi dina ti wọn ko jẹ ki awọn eeyan kọja.
Nigba ti awọn ọmọ ogun wa gbiyanju lati kọja,niṣe ni wọn kagidi bori ti wọn si bẹrẹ si ni sọ oko ati awọn nkan ija oloro lu wa.Wọn ba ọkọ wa ati tawọn ara ilu ti wọn koja ninu iṣẹle naa.''
Oríṣun àwòrán, @Nigerian Army
Aworan awọn ọmọ ogun naa farapa nibi iṣẹlẹ naa
Eyi kii se igba akọkọ ti ikọlu yoo ma waye laarin awọn ọmọ ogun Naijiria ati ọmọ ẹgbẹ Shiite papajulọ lati igba ti awọn ologun ti sọ olori wọn Ibrahim El-Zakzakky si ahamọ.
Shiite: Tinúbú, bá Buhari sọ̀rọ̀ kó tú ZakZaky sílẹ̀ kó tó pẹ́ jù
Àwọn obi ọmọ Obìnrin Chibok ni wọn tí lọkọ ní Cameroon
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Inu ibanujẹ lọpọ awọn obi ọmọ Obìnrin Chibok wa
Àwọn òbí àwọn ọmọ akẹkọ obìnrin Chibok ti boko-haram ji gbé ti figbe síta pé àwọn ní ìròyìn tó dájú wí pé metadinlogota nínú àwọn ọmọ obinrin Chibok lo wà ní àríwá orílèèdè Cameroon.
Wọn ni Obìnrin  kàn láran awọn tí boko-haram ji gbé to ribi sá mọ wọn lọwọ l'agbegbe ibẹ ló jẹri sí wí pé lootọ ní àwọn ọmọ obinrin náà wà lahamọ níbẹ.
Wọn ṣàlàyé pé  o sọfun awọn pe abúlé Garin Magaji ati Garin Mallam ní Marwa lariwa Cameroon ní àwọn ọmọ náà wà.
Obinrin ohun ní ọpọ nínú wọn ló tí lọkọ ti wọn sì ti bímọ.
Boko Haram yóò dá Leah sílé
Alága ẹgbẹ́  àwọn òbí ọmọbinrin Chibok tí wọn jigbe ṣàlàyé fún BBC pé àwọn gbà obinrin náà gbọ nitoripe o juwe àwọn ọmọ àwọn yékéyéké.
Yakubu Nkekeso ni obinrin naa sọ wi pe nnkan ko rọgbọ lawọn abule ti awọn ọmọ naa wa ti wọn si fẹ le ma ri ounjẹ jẹ nibẹ.
Méjìléláàdọ́fà ninu ọ̀rìnlénígba din mẹrin awọn ọmọbinrin naa ti wọn jigbe ni wọn ko mọ ibi ti wọn wa bayi.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Boko Haram ta taba cewa ta musuluntar da 'yan matan wadanda mafi yawansu Kiristoci ne
Ijinigbe wọn lọdun 2014 mu ki awọn eeyan jankanjankan kaakiri agbaye pe fun itusilẹ wọn.
Ninu wọn la ti ri iyawo Aarẹ  Amerika ana Michelle Obama.
Buhari, Saraki, PDP, Obaseki àti àwọn èèkàn ṣelédè lẹ́yìn Anenih
Oríṣun àwòrán, @PDPOFFICIAL
Anenih rèwàlẹ̀ àsà lẹ́ni ọdún 85
Alága ìgbìmọ̀ aláṣẹ ẹgbẹ́ òṣèlú Peoples Democratic Party (PDP) nígbà kan rí, Olóyè Tony Anenih tó rèwàlẹ̀ àsà lẹ́ni ọdún márùndínláàdọ́rùn ní àwọn èèkan lórílẹ̀-èdè Nàìjíríà tí ń ṣelédè lẹ́yìn rẹ̀.
Anenih, ti wọn ló ṣàìsàn fún ìgbà díẹ̀ ló kú sí ilé ìwòsàn Cedar Crest l'Abuja.
Ààrẹ Muhammadu Buhari fí ọ̀rọ̀ ìbánikédùn rẹ̀ ránṣẹ́ sí àwọn ẹbí Anenih pẹ̀lú ìjẹ́rìí pé Anenih ló ayé rẹ̀ láti sin Nàìjìríà.
Buhari to fí ìwé ìkíni sọ́wọ́ nínú àtèjáde kan ti olùbádàmọ̀ràn rẹ̀ lóri ìròyìn, Femi Adesina fọ́wọ́sí ní adarí tòótọ́ ní Anenih tó sì ti kó àwọn ipa ribiribi nínú ètò òṣelú orílẹ̀-èdè Nàìjiríà
Mike Ifabunmi: Òrìṣà ló gbè wà jù ni Brazil
Ààrẹ ìlé-ìgbìmọ̀ àṣòfin Bukola Saraki, ìgbákejì rẹ̀, Ike Ekweremadu náà bá àwọn ìdílé Anenih kẹ́dùn lásìkò tí Saraki ń sọ̀rọ̀ lórí ikú Anenih láti ori ìfọ̀rọ̀ ránṣẹ́ rẹ̀ lórí ayélujára rẹ̀.
O sàlàyé pé àwọn yóò sàfẹ́rí Anenih púpọ̀ nírú àsìkò yìí.
Nínú  ìkíni tirẹ̀ ìgbákejì ààrẹ ilé ìgbìmọ aṣòfin gbóríyìn fún Anenih to sì bá àwọn ẹbí rẹ̀ kẹ́dùn ẹni ire tó ti lọ, ó sàlàyé pé Anenih ṣe ìwọn to lè ṣe lórí ètò òṣèlú orílẹ̀-èdè yìí.
A bí Anenih ní inú oṣù kẹjọ ọdún 1933, ní Uzenema-Arue, Uromi, ó wọ iṣẹ́ ọlọpàá Nàìjíríà ní ọdún 1951 ní ìpínlẹ̀ Benin.
Ó lọ kọ́lẹ̀jì ọlọpàá ní Ikẹja níbí ti wọn ti yàn-án fún ìtẹ̀síwajú ẹkọ rẹ̀ ní Bramshilll Police College ní Basingstoke, England ní 1966 àti International Police Academy, Washionton DC ní 1970.
Ó ṣiṣẹ́ gẹ́gẹ bíi ẹṣọ̀ Gómìnà àkọkọ lórílẹ̀-èdè Nàìjíríà fún Dokita Nnamdi Azikiwe.
Ó jẹ́ àlága ìpínlẹ̀ National Party of Nigeria láàrín 1981 sí 1983.
Oun ní alága ẹgbẹ́ òṣèlú Social Democratic Party láti ọdún 1992 sí ọdún 1993 àti ọmọ ìgbìmọ tó rí si ètò òfin lọdún 1994
Anenih darapọ̀ mọ́ ẹgbẹ́ òṣèlú Peoples Democratic Movement èyí ti ọgágun Musa Yar'Adua dá sílẹ̀
Lẹ́yìn náà ló darapọ̀ mọ Peoples Democratic Party tó tún jẹ mínísítà lásìkò ààrẹ Olusegun Obasanjọ.
Túnbọ̀sún Ọládàpọ̀: Òǹkọrin ni etí Ọba láti sọ  òdodo
PDP: Lọgan ní a máa fún Ambode ni tíkẹ̀ẹ̀tì Gómìnà to ba dárapọmọ́ wà
Oríṣun àwòrán, Idowu-Sowunmi
O jọ bi igba pe aawọ laarin Gomina Ambode ati Asiwaju Tinubu ti pari
'Iwọ sáà tí sọ pé o fẹ tikẹẹti gómìnà labẹ ẹgbẹ́ òṣèlú wà, kíá làá fí fún ọ.'
Ọrọ ìdánilójú rè láti ọdọ ẹgbẹ́ òṣèlú PDP sí gómìnà ìpínlẹ̀ Èkó Akinwunmi Ambode.
Agbẹnusọ ẹgbẹ PDP nílu Èkó Taofiq Gani ló lédè ọrọ yí nígbà tí o n ba BBC sọrọ nínú ìfọ̀rọ̀wánilẹ́nuwò kàn lọ́jọ́ Ajé.
Taofiq ní òṣèlú lọrọ to wa nilẹ yí ati wí pé ẹgbẹ́ àwọn n na ọwọ sí gbogbo àwọn tí ẹgbẹ òṣèlú APC dojú tí nílu Èkó.
''Ti Ambode ba wa bawa lóni ti a sì ṣẹ àgbéyẹ̀wò ti a ri wí pé tọ́kàn tókàn ló fi fẹ dárapọ mọ́ wà, a lè gbà wọlé. Awa kò ní Oludije bíi o ba o pa kánkan. Ìlọsíwájú ẹgbẹ́ ló jẹ wá lógún''
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Gomina Ambode ko ti ṣọrọ lori nnkan ti PDP sọ
Labẹ òfin ètò ìdìbò, anfààní ṣì wà fún ẹgbẹ́ òṣèlú láti parọ orúkọ oludije kí gbedeke ọjọ ti INEC fi sílẹ tó pé
Ohùn tá gbọ ní pé Gómìnà Ambode ti n palẹmo  láti kẹrú rẹ  kúrò ní Alausa lẹyìn tí ọ pàdánù tikẹti ẹgbẹ́  APC lati du ipo Gomina lọdun 2019.
Ko sọna ni APC ati PDP
Kola Ologbodiyan: Jẹgudu jẹra ni ijọba APC
Gani ṣo pe àwọn yóò gba ìlú ati ijo tí Ambode ba fí lè dára pọ mọ PDP nitori o ṣíṣe ríbi ríbi nílu Èkó gẹgẹ bí Gómìnà
Alága ẹgbẹ PDP náà tún sọ fún BBC pé àwọn olóṣèlú ẹgbẹ́ APC tí ọ n fapajanu kan  tí n ṣé ìpàdé bonkẹlẹ pẹlú àwọn.
Gómìnà Ambode ti ọrọ náà kan ko tí fèsì sí ọrọ yí.
Oríṣun àwòrán, Idowu-Sowunmi
Opo igba ni Gomina Ambode ti so pe itẹsiwaju ẹgbẹ APC lo jọ oun loju
Iwode fun Ochanya  ti won ba lopo waye nilu Eko
#Fake News: Irọ́ ni! Ọmọ ọdọ̀ Ọpẹ Bademosi kò kú
Oríṣun àwòrán, Ope bademosi/facebook.com
Àwọn ọlọpàá sọ wípé ọmọ̀ ọ̀dọ̀ Sunday Adefonou Anani ti jẹ́wọ́ pé òun ló pa ọ̀ga rẹ̀, Ọpẹ Bademọsi, tó wà nínú àwọran yìí
Ọgbà ẹ̀wọ̀n ti ilu Eko sọ pé irọ gbáà ni pe Sunday Anani tó jẹ́ ọmọ ọ̀dọ̀ tó ń dáná fún Oloye Ọpẹ Bademọsi ti gbẹ́mìí mì.
Nigbà tó bá BBC Yorùbá sọ̀rọ̀, agbẹnusọ fún ọgbà ẹ̀wọ̀n ìpínlẹ̀ Eko, Rotimi Oladokun ni kò sí ẹyọ òótọ́ kankan nínú ìròyìn òfégè tí àwọn ilé iṣẹ́ ìròyìn kan ń gbé jáde pé  ọmọ ọ̀dọ̀ náà ti kú.
Oloye Ọpẹ Bademọsi tí wọn sọ pe ọmọ ọdọ rẹ ẹ gun pa lagbegbe Ikoyi ni ipinlẹ Eko laipẹ yii ti wọ kaa ilẹ lọ bayii.
Ọjọ Ẹti , ọjọ kẹtalelogun, osu Belu ni ẹbi, ara ati ojulumọ pejọ pọ ti wọn si sin oku oloye naa ni Ipinlẹ Ondo, tii ṣe ilu oloogbe naa.
Oríṣun àwòrán, LIB
Ọmọ bíbí ìpínlẹ̀ Ondo ni olóògbé Bademosi
Ile ẹjọ Majisireti to wa ni agbegbe Igbosere nipinlẹ Eko ti paṣẹ pe ki Sunday Anani, wa ni ẹ̀wọ̀n fun ọgbọnjọ.
Wọn fi ẹsun kan Sunday pe ogun ọga rẹ, Ọpẹ Bademọsi pa lasiko to fẹ ja oloogbe l'ole nile rẹ to wa ni Ikoyi nipinlẹ Eko.
Wọ́n rò pé mo ya wèrè ni Saudi lẹ́yìn ikú ọkọ mi
Iwe iroyin Punch jabọ pe ẹni to n rojọ tako Sunday, J.I. Eboseremene, bẹbẹ pe ki Onidajọ O.O Ọshin gba ki ẹni ti wọn fi ẹsun kan an wa ni ọgba ẹwọn fun bi oṣu kan, lati le faaye gba iwadi to munadoko.
Wọn ti wa sun igbẹjọ si ọjọ kejidinlogun, oṣu Kejila, ọdun 2018.
Ọmọ ọdọ to n da ina ounjẹ fun Oloye Ọpe Bademosi ti jẹwọ wi pe oun lo pa ọga rẹ lẹyin to jaa lo le.
Ile isẹ ọlọpaa ni ipinlẹ Eko lo fi eyi lede ninu atẹjade kan pe afurasi naa ti orukọ rẹ n jẹ Sunday Adefonou Anani jẹwọ lẹyin ti ẹrọ ayaworan ikọkọ(CCTV) fihan wi pe oun lo pa ọga rẹ.
Oríṣun àwòrán, LIB
Ọmọ ọ̀dọ̀ ni wọ́n fi ẹ̀sùn kàn pé ó pa Oloye Bademosi
Gẹgẹbi ọrọ afurasi naa, lẹyin ọjọ kẹta ti wọn gba a si ibisẹ ni o pinu lati ja ọga re lole, ti o si wo ibusun ti ọga rẹ lati bere owo lọwọ rẹ, lẹyin ti iyawo rẹ jade kuro ni ile laarọ kutu, amọ ti o sọ wi pe oun koni owo nile lati fun ọmọ ọdọ naa.
'Ẹ má pè mí ní Kupe; DJ Copy l'orúkọ mi'
Oríṣun àwòrán, Facebook
Ilé isẹ́ ọlọ́pàá ní ìpínlẹ̀ Èkó ní Sunday Adefonou Anani jẹ́wọ́ lẹ́yìn tí ẹ̀rọ ìgbàlódé fihàn wí pé òun ló pa ọ̀gá rẹ̀.
'Wọ́n ní a kò lówó tó láti díje dupò ní Nàìjíríà'
Somalia: 'Wọ́n pàṣẹ fún mi láti dá Ramla dúró ká tò lè ṣe igbeyàwó'
Lẹyin naa ni ọmọ̀ ọdọ naa sọ ọga rẹ mọ igi ibusun, ko to di wi pe ọga naa gbiyanju lati gba ara rẹ silẹ, eleyi ti o jasi iku, lẹyin ti o gun ọga rẹ lọna mẹta.
Kọmisọnna Ọlọpaa ni ipinlẹ Eko, Edgal Imohimi, dupẹ lọwọ awọn ara ilu fun suuru wọn ati wi pe wọn yoo gbe ọmọ ọdọ naa lo si ile ẹjọ laipẹ.Ondo: 'Kò sẹlẹ̀rí ní ìtàn Ondo ká fagilé ọdún Ekimogun'
Ajọ to n risi idagbasoke ilu Ondo ni ipinlẹ Ondo, ODC ti kede wi pe ọdun Ekimogun ko ni waye ni ọdun yii.
Alaga ipolongo fun ọdun Ekimoogun ti 2018, Alhaji Yemi Adewetan, labẹ asẹ Osemawe ti ilu Ondo, ti ba BBC Yoruba sọrọ lori igbese ti ko i tii waye naa lati ọdun mọkanlelọgbọn ti ọdun Ekimogun ti bẹrẹ.
Yemi Adewetan sọ pe iku Lotin ti ilu Ondo, Oloye Ope Bademosi lo fa a ti awọn fi fagile ọdun Ekimogun ti ọdun yii.
Ọdun Ekimogun jẹ ayẹyẹ asa ati igbelaruge ilu Ondo, ti tọmọde ati agba lati ilu okeere si ma n pejọ lati se ayẹyẹ yii.
Ìnú mi kìí dùn nígbà trí mo ń ṣiṣẹ́ ni bánkì tó ìgbà ti mo bẹ̀rẹ̀ mẹkáníìkì
Adewetan fikun wi pe ibanujẹ ọkan lo jẹ fun awọn lẹyin isekupani Oloye Bademosi ni inu ile rẹ ni ilu Eko , ati wi pe ọna lati daa lọla ni awọn ṣe fagile ọdun naa.
Ninu ọrọ rẹ, Oloye Bademosi jẹ ọkan googi lara awọn to kọkọ bẹrẹ ọdun naa ni ọgbọn ọdun sẹyin.
Yemi Adewetan wa parọwa si awọn ọmọ bibi ilu Ondo lati fọwọwọnu lori bi wọn se fagile ọdun Ekimogun ti ọdun yii.
Bakan naa lo gbadura fawọn eniyan ilu Ondo loke okun pe, wọn a ko ire oko dele layọ ati pe Olodumare ko ni jẹ kiru eyi ṣẹlẹ mọ ni Ondo.
Oríṣun àwòrán, Femi Joseph
Afurasí alásè gún ọ̀gá rẹ̀ pa
Ọgbẹni Joseph sọ pe awọn ọlọpaa ti fi afurasi naa ranṣẹ si ilẹ iṣẹ ọlọpaa Ipinlẹ Eko nibi ti iṣẹlẹ naa ti ṣẹ.
Ibanujẹ nile Oloye Ọpẹ Bademọsi
Ibanujẹ nla gbaa ni iku Oloye Ọpẹ Bademọsi jẹ fun ẹbi ati ara bi wọn ṣe peju-pesẹ si ile olóògbé naa. Ikọ̀ BBC Yoruba ṣe àbẹ̀wò sí ilé Olóyè ìlú Ondo tí wọ́n furasí pé ọmọọ̀dọ̀ gún pa, fọ́fọ́ si ni ó kún fún àwọn abánikẹ́dùn.
Bi àwọn mọ̀lẹ́bí ṣe ń rẹ ìyàwò olóògbé lẹ́kún, bẹ́ẹ̀ ni awọn ọmọ olóògbé ń ṣe ìdárò rẹ̀.Awakọ oloogbe sọ fun BBC Yoruba pe ọjọ Aiku ni oun ati ọga oun mu afurasi alase naa to jẹ ọmọ orilẹede Togo,wa lati Ondo, ti wọn si fura si pe o gun ọga rẹ pa lọjọ kẹrin.
Ìjà ọlọ́pàá àti alápatà ni Bodija gbẹ̀mí Sulia aláìṣẹ̀ ni UCH
"''A gbaa ko maa dana ounjẹ fun ẹbi, amọ oṣeni laanu pe a ko ṣayẹwo rẹ, ka to gbaa s'iṣẹ nitori pe a niloo rẹ ni kiakia."""
Gẹgẹ bi awakọ naa ṣe sọ, Iyawo oloogbe lọ si ile ifowopamọ laarọ Ọjọru ti iṣẹlẹ yii ṣẹlẹ, lo fi jẹ wipe Oloye ati alase ti wọn furasi pe o pa oloogbe nikan ni o wa ninu ile.
Oríṣun àwòrán, Ope bademosi/facebook.com
Àwọn ọlọpàá sọ wípé ọmọ̀ ọ̀dọ̀ Sunday Adefonou Anani ti jẹ́wọ́ pé òun ló pa ọ̀ga rẹ̀, Ọpẹ Bademọsi, tó wà nínú àwọran yìí
Nigba ti iyawo oloogbe dele ti ori Oloye ninu agbara ẹjẹ ti wọn ti gun pa, ni o kigbe sita. Awakọ naa sọ ọ di mimọ wipe kete ti iṣẹlẹ naa ṣẹlẹ ni oun ti pe awọn ọlọpa ni ẹka ti Yaba ni Ondo.
Ọwọ wọn si ti tẹ awọn ọmọkunrin to mu alase naa wa fun oloogbe Bademusi.
Àwọn èèyàn ń lọ ṣàbẹ̀wò sí àwọn mọlẹ́bí olóògbé náà
Bakan naa, awọn agbofinro si ti mu ẹgbọn-kunrin afurasi ọhun. Awọn abanikẹdun si ti n bọwọlu iwe iforukọsilẹ ikẹdun nile Oloogbe to wa ni agbegbe Park view, Ikoyi niluu Eko.
Nigba aye rẹ, oun ni Alaga ileesẹ CreditSwitch Technology, to wa nilu Eko.
Awọn abanikẹdun si ti n bọwọlu iwe iforukọsilẹ ikẹdun nile Oloogbe to wa ni agbegbe Park view, Ikoyi niluu Eko.
Nigba t'oun naa fidi iṣẹlẹ naa mulẹ fun BBC, Akọwe agba fun ẹgbẹ Ondo Development Committee, Alufa Damilọla Akinwale, sọ pe awakọ Oloye Bademọsi lo pe ọọfisi ileeṣẹ naa ni owurọ Ọjọru pe ọga oun ti ku. Ati pe alase to ṣẹṣẹ gba sile lo ṣeku paa.
Ohun ti a tun gbọ ni pe alase ti o n ba oloogbe naa ṣiṣẹ tẹlẹ lo ṣe eto bi alase tuntun naa ṣe darapọ mọ awọn oṣiṣẹ abẹle fun oloogbe Ọpẹ Bademọsi.
Ipe wa si alukoro ileeṣẹ ọlọpa nipinlẹ Eko, Chike Oti, lati fidi iṣẹẹ naa mulẹ, ko ti i so eso rere, pẹlu bi o ṣe ṣeleri lati kan si akọroyin wa to pe e.
Sugbọn a gbọ pe oṣiṣẹ alaabo to n sọ ile naa, to jẹ pe ọjọ kan naa l'oun ati alase ọhun jọ bẹrẹ iṣẹ lọjọ kan naa, ti wa lagọ ọlọpa lori ọrọ naa.
Bakan naa la gbọ pe wọn ko mọ ile tabi ọna alase ọhun to ti salọ bayii.
Taa ni Haleemat Busari tí yóò ṣe igbákejì Jimi Agbaje?
Oríṣun àwòrán, @Jimi
Haleemat Busari ti ṣiṣẹ pẹlu awọn ileeṣẹ aladani gẹgẹ bi amofin ati onimọ nipa okoowo.
Wọn bi Haleemat Yemisi Busari l'ọdun 1964 sinu idile Oloogbe Ahmed Giwa ati Oloogbe Mujibat Giwa, to jẹ ọmọọbabinrin Kosọkọ ti Isalẹ Eko.
O lọ sileewe alakọbẹẹrẹ nipinlẹ Eko, o si kẹkọ gboye imọ ijinlẹ ninu ede Gẹẹsi ni fasiti Ilọrin l'ọdun 1986. Lẹyin naa lo gboye ninu imọ ofin ni fasiti ilu Eko 1990.
O bẹrẹ iṣẹ amofin l'ọdun 1992.
Bọlanle Aliyu: N kò nílò bàbá ìsàlẹ̀ láti di gómìnà
Yatọ si wi pe o jẹ amofin, o tun kẹkọ gboye nipa òwò ṣiṣe lati ileewe ikọsẹ nipa okoowo, Lagos Business School, ni nkan bi ọdun 2005.
O ti ṣiṣẹ pẹlu awọn ileeṣẹ aladani gẹgẹ bi amofin ati onimọ nipa okoowo.
Lọwọlọwọ, o jẹ oludari ni ẹka banki nla kan ni Naijiria, to wa ni orilẹede Sierra Leone.
Lẹyin ti Jimi Agbaje kede rẹ gẹgẹ bi igbakeji rẹ ti wọn yoo jọ dije fun ipo gomina ipinlẹ Eko l'ọdun 2019, ni Busari fesi si yiyan ti wọn yan an.
Ninu ikede kan to fi sita loju opo Twitter rẹ o sọ pe ''ko si ohun to to ipe lati ṣiṣe iṣẹ sin Ọlọrun, ati orilẹede. Ati wi pe oun ko ṣaimọ riri anfaani ti wọn fun un.
Adetoun Ogunṣẹyẹ: ìrìnàjò ẹ̀kọ́ mi títí dé òkè kò rọrùn rárá
Àwọn ìgbà tí àwọn ọmọ Ọbasanjọ ti takò ó ní gbangba
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Gbenga Ọbasanjọ fi ẹsun kan pe o n ba iyawo oun ni ibalopọ
O jẹ ohun ti ko wọpọ ki ọmọ tako baba tabi iya rẹ nilẹ Yoruba, nitori pe aṣa ati iṣe Yoruba gbagbọ pe obi ẹni jẹ ọlọrun kekere fun ni, ati pe ọmọ to ba gboju soke wo awọn obi rẹ n tapa si ọrun ara rẹ ni.
Sugbọn ninu idile aarẹ tẹlẹ fun Naijiria, Olusẹgun Ọbasanjọ, kiiṣe ẹẹkan tabi ẹẹmeji ni awọn ọmọ rẹ ti tako o tabi gbena woju rẹ ni gbangba.
Gbenga Ọbasanjọ fi ẹsun kan an pe o n ba iyawo oun lopọ
Igba akọkọ ni ti ọkan lara awọn ọmọ Ọbasanjọ gbena woju rẹ ni gbangba ni ọdun 2008.
Ọkan lara awọn ọmọ rẹ ọkunrin, Olugbenga Ọbasanjọ fi ẹsun kan baba rẹ ni gbangba pe o n ni ibalopọ pẹlu iyawo oun.
Gbenga fi ẹsun kan iyawo rẹ, Mojisola Olayemisi Amope, to jẹ ọmọ gbajugbaja oloselu, Ọtunba Alex Ọnabanjọ, pe oun ni ibalopọ pẹlu Ọbasanjọ lati le ri iṣẹ agbaṣe gba lọwọ ijọba.
Oríṣun àwòrán, Olugbenga O. Obasanjo/Facebook
Nile ẹjọ nibi ti Gbenga ati iyawo rẹ ti fẹ ẹ tu ara wọn ka lo ti fi ẹsun naa kan baba rẹ gẹgẹ bi ẹri l'ọdun 2008.
Ati pe baba oun san 'owo iṣẹ agbere'' fun iyawo oun nipa gbigbe ọpọlọpọ iṣẹ akanṣe fun ileeṣẹ rẹ, Bowen and Brown, nileeṣẹ to n mojuto ipese epo rọbi ni Naijiria, NNPC.
Nile ẹjọ nibi ti Gbenga ati iyawo rẹ ti fẹ tu ara wọn ka lo ti fi ẹsun naa kan baba rẹ gẹgẹ bi ẹri l'ọdun 2008.
Sáájú àbẹ̀wò Gbenga sí oko Olóyè Ọbasanjọ to n jẹ Otta Farm, ọfiisi Aarẹ ti y ara wọn kuro ninu oun ti Gbenga sọ eleyi to jẹ ki ọplọp ro wi pe lati ile iṣẹ Aarẹ lawn ọrọ rẹ ti ṣẹ wá.
Ninu atẹjade ile iṣẹ Aarẹ, wọn tẹnu mọ ọ pe itiju nla gbaa ni ọrọ ti Gbenga sọ o si buru jai.
Dokita Iyabọ Ọbasanjọ naa gbena woju rẹ
Igba keji ni ti akọbi rẹ, Iyabọ Ọbasanjọ to ti figba kan jẹ kọmisana fun eto ilere ni ipinlẹ Ogun.
Iyabọ kọ lẹta gbọọrọ kan to pe ni 'Lẹta gbangba si baba mi.''
'Òṣìṣẹ́ Bánkì ni mí l'Amẹ́ríkà kí n tó bẹ̀rẹ̀ Tíátà'
Ninu lẹta ọhun to kọ, to si di kika ninu awọn iwe iroyin jakejado Naijiria, Iyabọ fi ẹsun wiwu iwa atobi ma ṣe e bawi, ti ki i gbọ imọran ẹlomii lori ohunkohun to ba fẹ ẹ ṣe.
Lẹta rẹ naa waye lẹyin ti Oloye Ọbasanjọ kọ lẹta kan si aarẹ tẹlẹ ni Naijiria, Goodluck Jonathan, lati bu ẹnu ẹtẹ lu iṣakoso rẹ.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
O kọ lẹta naa lẹyin ti Ọbasanjọ kọ lẹta kan si aarẹ tẹlẹ ni Naijiria, Goodluck Jonathan, lati bu ẹnu ẹtẹ lu iṣakoso rẹ.
Iyabọ sapejuwe baba rẹ ninu lẹta naa to kọ l'ọjọ kẹrindinlogun, oṣu Kejila, ọdun 2013, sọ pe opurọ, ọlọgbọn ẹwẹ, ati alagabangebe, to fẹ wa ni iṣakoso titi lai.
Ati pe kii ṣe baba daada, nitori awọn ko jẹ anfaani rẹ gẹgẹ bi baba.
Lẹta Iyabọ ọhun fa awuyewuye ni asiko naa, ti ọpọlọpọ si n sọ pe 'lẹta ti iyabọ kọ ṣeeṣe ko jẹ apejuwe itẹlẹ idi ẹni, kii ri ni ti.''
Ẹwẹ, nkan bi ọdun kan lẹyin ti Iyabo kọ lẹta atẹjade rẹ si Ọbasanjọ, Aarẹ tẹlẹ ri, Olusgun Ọbasanjọ da esi pada si i to si fi ẹsun kan an pe ijọba Aarẹ Goodluck Jonathan lo kọ ọ si oun lati kọ lẹta naa.
Ninu awọn ọrọ t sọ lori iroyin kan, Ọbasanjọ ni wọn ti kilọ fun oun tẹlẹ pe ijọba Jonathan yoo kọ ọmọ oun obinrin meji lati ṣe iṣẹ idọti, oun si kilọ fun wọn.
Oríṣun àwòrán, @BashirAhmaad
Eyi to tun n waye laipẹ yii ni ọmọ rẹ ọkunrin mii, Juwọn Ọbasanjọ, to n ṣatilẹyin fun Aarẹ Muhammadu Buhari lati dije fun saa keji.
Koda o ṣabẹwo si Aarẹ Buhari nile aarẹ to wa niluu Abuja lọjọ kinni, oṣu Kọkanla, ọdun 2018, lati jẹjẹ atilẹyin rẹ.
Saaju ni baba rẹ, Ọbasanjọ, ti bu ẹnu atẹ lu iṣakoso Buhari, to si  gba a nimọran lati ma dije fun ipo fun igba keji.
Bakan naa ni Ọbasanjọ bu ọwọ lu oludije fun ipo aarẹ labẹ ẹgbẹ oṣelu Peoples Democratic Party, PDP, Atiku Abubakar.
Vibrator -Ǹkan ìṣeré ìbálòpọ̀ mi ńpaná iṣẹ́ mọ́ mi lára'
Oríṣun àwòrán, Eve Lloyd Knight
Ǹkan ìṣeré ìbálòpọ̀ ti gbòde kan
Ọmọ ọdún mọ́kànlélógún ni Leanne nígbà tó kọ́kọ́ ra ǹkan ìṣeré ìbálòpọ̀ rẹ̀ àkọ́kọ́.
O jẹ ohun didan gbiinrinn ti a ṣe latara kẹmika silikọọnu. O ni awọ okuta pẹlu bọtiini olododo goolu gẹgẹ bi o ṣe ṣalaye. Ko jọ nkan ọmọkunrin, o da yatọ, o dara gan ni.
O dagba ni abule lẹyin odi Birmingham, nilẹ England o ti da nikan wa fun ọdun meji nigba to wọ ọkọ oju irin lọ sinu igboro lọsan ọjọ abamẹta kan.
Lẹni ọdun mọkanlelogun, Leanne ko tii ṣe Leanne bi ẹni to fẹ ni ibalopọ ri rara.
"Ṣugbọn ọjọ lọjọ naa. Mo ti pinnu. Mo n lọ ra ǹkan ìṣeré ìbálòpọ̀ ti mo ti n la ala rẹ tipẹ.
Wọn ti ja ibale rẹ lati ọdun kẹtadinlogun nigba ti yoo si fi pe ọdun mọkanlelogun, o ti ni ibalopọ pẹlu ọkunrin ti ko lonka sugbọn ajọṣepọ oun pẹlu gbogbo wn ko pẹ rara.
O ti gbadun ibalopọ, sugbọn oriṣiriṣi ni iriri igbadun rẹ. Mo gbadun bi mo ṣe maa n pade eniyan, bi mo ṣe maa n mu ara wọn wa lọna tabi ko jẹ awọn lo mu ara temi wa lọna."
Bó ṣe ń lọ ń dùn mọ mi ṣùgbọ́n mi ò kànlẹ̀ ní ìmọ̀lára ìtẹ́lọ̀rùn ìbálòpọ̀.
Ó máa ń jẹ́ kí eré tó ṣáájú ìbálòpọ̀ ni mí lára, ó mí kanlẹ̀.
Bí ọdún ṣe ń gorí ọdún ni ìpòruru ọkàn m bá Leanne nítorí àìlè jí pépé imọ̀lára rẹ̀ fún ìbálòpọ̀.
"Gbogbo ìgbà tí mo bá ni ìbálòpọ̀ ni ọkàn mi máa ń bàjẹ́, mo máa ń dá ara mi lẹ́bi dípò ni ti mo bá lájọṣepọ̀. Mi ò fẹ́ sọ fún ẹnikẹ́ni nítorí àwọn ọ̀rẹ́ mi ma ń sọ̀rọ̀ rẹ̀ bíi pé gbogbo ìgbà làwọn ma ń gbádùn ìbálòpọ̀.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Leanne kò gbádùn ìbálòpọ̀
Ìgbẹ̀yìn gbẹ́yín, ó lahun sí ọ̀rẹ́ rẹ̀.
Ohun tó ṣẹlẹ̀ ni wí pé, nígbà náà mi ò tíì máa fi ojú ara ṣe bíi ẹni tó nílò ìbálòpọ̀"". Inú ọ̀rẹ́ mi dùn pé, "" lóòtọ́, oò tíì lè mọ níní ìmọ̀lára ìgbádùn ìbálòpọ̀ bí o kò bá tíì fi ojú ara ṣe bíi ẹni tó nílò ìbálòpọ̀ rí tí wàá ṣe bí ẹni ń bá ara rẹ̀ lájọṣepọ̀""."
"Ìwọ́ ni wàá kọ́ ara rẹ láti dá a mọ̀ àti láti rẹra mọ́ ọ. bí o kò bá mọ bó ṣe ńrí, òó kàn máa tiraka lásán ni.
Lọ́jọ́ àbámẹ́ta náà lọ́hun nílé, ó ṣí ǹkan ìṣeré ìbálòpọ̀ rẹ̀ tuntun ló bá bẹ̀rl iṣẹ́.
Ó gbà mí ní wakàtí kan ó lé kí n tó pàpà ní ìmọ̀lára kiní yìí... Ǹkan tí ara mi ma ń ṣe fúnra rẹ̀ láì nílò kí n rò ó tàbí mú u ṣiṣẹ́""."
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ọ̀rẹ́ Léanne ní kó máa dá a ṣe pẹ̀lú ara rẹ̀.
Lákọ̀kọ́, ó run mí nínú kí afẹ́fẹ́ ìgbádùn tó fẹ́, ara mi wá ṣẹ̀'sẹ̀ balẹ̀, ọkàn mí wá tutù wẹ̀ẹ̀. Mo wá wò ó wí pé, ṣé èmi náà ni mò ń gbádùn eré ìbálòpọ̀ báyìí? Ó jẹ́ ìrírí ńlá.
Ǹkan ìṣeré ìbálòpọ̀ ti ma ń ró kì lọ́kàn wa láti ìgbà ayé ọbabìnrin Victoria tí àwọn dókítà ṣe àgbéjáde rẹ̀ fún ìrànwọ́ àwọn obìnrin tí kò lè mára dúró.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
ìgbà ayé ọbabìnrin Victoria tí àwọn dókítà ṣe àgbéjáde rẹ̀ fún ìrànwọ́ àwọn obìnrin tí kò lè mára dúró
Ẹ̀rọ̀ fún fífẹ́ ìbálòpọ̀ ní gbogbo ìgbà
Ní ìgbà tí wọ́n rò wí pé béèyàn bá dé ìpele gbígbádùn ìbálòpọ̀ léè wò àìlèmáradúró.
"Ó jẹ́ ohun ti Leanne ṣèrántí dáadáa: ""Dájú dájú, inú mi kò dùn sùgbọ́n ọpẹ́ fún ìgbádùn ìbálòpọ̀."
Ìfilọ́ọ́lẹ̀ rẹ̀ lọ́dún 1980s ló sọ ǹkan ìṣeré ìbálòpọ̀ di gbajúgbajà - ìrísí rẹ̀ jọ ti èkúte.
Fún ọ̀pọ̀lọpọ̀ ìgbà, fẹ́lẹ́ fẹ́lẹ́ ni àwọn ǹkan ìseré ìbálòpọ̀ ma ń rí tojú ò sì leè rí i dáadáa Stuart Nugent tó jẹ́ alámojútó àgbáyé ilé iṣẹ́ tó ń ṣe ǹkan ìṣeré ìbálòpọ̀ ní orílẹ̀èdè Sweden, LELO sọ pé,
"Kò jẹ́ kí ọ̀pọ̀lọpọ̀ máa ra ǹkan ìṣeré yìí. 'Sùgbọ́n bí ìrísí rẹ̀ ṣe wá rí bíi èkúte, ó fa ni mọ́ra ju àwọn ìṣeré ti ìṣájú lọ. Kódà lọ́dún 1998, ètò àgbéléwò 'Sex and the City' ya abala kan sọ́tọ̀ fún un láti kéde pé ó ti kúrò ní ǹkan ìṣeré lásán. Nìgbà bá bẹ̀rẹ̀ sí ní yípadà fún àwọn ènìyàn.
Oríṣun àwòrán, Eve Lloyd Knight
Ó jẹ́ èèwọ̀ tẹ́lẹ̀ láti sọ̀rọ̀ ìgbádùn ìbálòpọ̀
Láàrin ọdún 2000 sí 2009, àwọn tó ń ṣe é bá bẹ̀rẹ̀ sí ní ṣe ẹ̀dà àti àwọ̀ oríṣiríṣi jáde. Ó ti wá sáre di ǹkan ìṣeré fún àgbàlagbà lọ́jà, ìrètí sì wà wí pé iye owó rẹ̀ yóò ju £22 billion ($29 billion) lọ títí ọdún 2020. Stuart s èyí nítorí wí pé wọn ti ń ṣe é jáde gkgẹ́ bí ohun èlò ìgbádùn. Ó ní láàrin ọdún márùn-ún sí mẹ́wàá, a ti di oníbarà tó ń fẹ́ ọjà ní mẹ́sàn-án mẹ́wàá.
A ti wá mọ̀ nípa ǹkan ìgbàlódé à sì ń fẹ́ ohun tí yóò bá ìní wa pàdé gẹ́lẹ́ bó ti yẹ tó fi mọ̀ èyí tí à ń mú wọ inú yàrá."
Mímọ̀ ohun tó jọjú yìí ti wá dá oríṣiríṣi àti iye owó ọ̀tọ̀tọ̀ kalẹ̀. Ǹkan ìṣeré ìbálòpọ̀ ń ṣiṣẹ́ bákan náa lára ni tẹ́lẹ̀ ṣùgbọ́n àwọn ilé iṣẹ́ ti ń wo onírúurú ìpele tí ara fi ń wà lọ́nà báyìí láti ṣe ọ̀tọ̀tọ̀.
Àwọn ojúlówó ǹkan ìṣeré ìbálòpọ̀, bí o bá ti gbé e lé ojú ara, yóò máamú ara rẹ wà lọ́nà láì kan ojú ara torí afẹ́fẹ́ ló ń lò kò si ni kanra.
"Leanne sọ pé ""ẹ̀gbẹ́ ibùsùn mi ni mo ma ń fi ǹkan ìṣeré ìbálòpọ̀ mi sí ojoojúmọ́ sì ni mò ń lò ó"". Ṣe ló dà bí ìgbésẹ̀ tó dára fún ìgbé ayé ìbálòpọ̀ mi""."
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Àwọn tí wọ́n ń ṣe jáde nísisìyìí yàtọ̀ sí ojúlówó
Lẹ́yìn ọdún méje, ó ṣì ń lo ǹkan ìṣeré ìbálòpọ̀ kan náà fún ìgbà díẹ̀ lọ́sẹ̀. Ṣùgbọ́n níwọ̀n ìgbà tí ìfẹ́ bá ṣì wà níbẹ̀, ó ti bẹ̀rẹ̀ sí ni rò ó bóyá ó ń ṣèrànwọ́ fún ìgbádùn ìbálòpọ̀ rẹ̀ ní ọ̀nà mìíràn.
Ó ti pẹ́ ti mo ti mọ̀ wí pé mi ò lé gbádùn ìbálòpọ̀ tí mi ò bá lo ǹkan ìṣeré ìbálòpọ̀ tó tọ́, kí n sì sun ìhà tí mo ti kọ́kọ́ wà.
Leanne ti wá pé ọmọ ọdún méjìdínlọ́gbọ̀n báyìí pẹ̀lú ọ̀rẹ́ ìbálòpọ̀ rẹ̀ ọlọ́dún márùn-ún
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Oríṣiríṣi ọ̀nà ni obìnrin fi lè gbádùn ìbálòpọ̀
Inú wọn máa ń dùn wọ́n sì ń gbádùn ìbálòpọ̀. Olólùfẹ́ mi kò bínú sí ǹkan ìṣeré ìbálòpọ̀ mi, a ma ń lò ó nínú eré tó ṣáájú ìbálòpọ̀.
Lákọ̀kọ́, mo rò pé kò ni fẹ́ ẹ ni ṣùgbọ́n kò bínú sí i àyàfi ti pé mo máa fẹ́ gbádùn ìbálòpọ̀ lọ́nà mìíràn.
Pẹ̀lú gbogbo bí mo ṣe dán an wò nígbà tí a bá ń lájọṣepọ̀ tó wà níwájú mi, tí mo wà lórí rẹ̀ pẹ̀lú oríṣiríṣi ǹkan ìṣeré ìbálòpọ̀, mo ma ń sábà fẹ́ padà sí ọ̀rẹ́ mi àtijọ́.
Ó ń kọ mi lóminú pé mi ò lè ṣe láì lo ǹkan ìṣeré ìbálòpọ̀ mi. Ó ti kó sí mi lórí.
Oríṣun àwòrán, iStock
Àwọn ẹlòmíràn ò kí ń gbádùn ìbálòpọ̀ bí wọ́n ṣe fẹ́ pllú olólùfẹ́ wọn.
Pasuma: Mọ dúpẹ́ lọ́wọ́ Ọlórun fún oríire ọjọ́ ìbí òní
Oríṣun àwòrán, Instagram
Pasuma ní nínú gbogbo ìlú àgbáyé, òun kò lè lọ kọrin ní Saudi Arabia ko si iye owo tí wọ́n lè gbé sílẹ̀.
"Gbajugbaja olorin Fuji ati osere tiata, Wasiu Alabi Pasuma ti ọpọ eniyan mọ si ""Ọ̀gáńlá"" ti dupẹ lọwọ Ọlọrun fun oriire ọjọ ibi ọdun mọkanlelaadọta loke eepẹ."
Ọjọ kẹtadinlọgbọn, Osu kọkanla, ọdun 1967 ni wọn bi Pasuma ni agbeegbe Mushin, ni Ipinlẹ Eko, ti o si dagba si ipinlẹ Kwara, lorilẹede Naijiria.
Ni oju opo ikansiraẹni Instagram rẹ ni Pasuma ti fi ero rẹ han wi pe gbogbo ilọsiwaju ati ibugbooro ti oun ti la kọja, Ọlọrun lo gbe oun leke.
Jide Kosọkọ: Isẹ́ tíátà yóò gòkè tíjọba bá gbówó kalẹ̀ láti seré
Gbajugbaja olorin Fuji naa fikun ọrọ rẹ pe ijakunlẹ nigba miran maa n fihan wi pe, eniyan ẹlẹran ara ni oun, ati wi pe Ọlọrun nikan lo ju gbogbo ẹda lọ.
Ọkan lara awọn gbajugbaja elere tiata Yoruba, Dayo Amusa naa ba Pasuma yọ ayọ ọjọ ibi rẹ lori ẹrọ ikansiraẹni Instagram.
Ti a o ba gbagbe, lasiko to n ba BBC sọrọ lori Facebook Live, Pasuma sọ pe orilẹede Canada ni oun yoo ti se ayẹyẹ ọjọ ibi oun ti ọdun 2018.
Bakan naa, ni ọdun 2018 ni ilu Georgia, lorilẹede Amẹrika fun Pasuma ni iwe igbelu ọmọ onilẹ ati asoju ilẹ naa.
Gbajugbaja olorin Fuji, Alhaji Wasiu Alabi ti ọpọ eeyan mọ si Pasuma ti ni ko si ohunkohun ti o lee mu ki oun gbe ode ere orin lọ si orilẹ-ede Saudi Arabia.
Ninu ọrọ rẹ pẹlu BBC news Yoruba ni ileeṣẹ rẹ nilu Eko ni Pasuma ti sọ ọrọ yii.
Oríṣun àwòrán, @NigeriaNewsWeb
Amọṣa, Pasuma ni ko si iye owo to lee mu oun lọ si Saudi Arabia lọ kọrin nitori 'ile adura ni'
Ọkan lara awọn ololufẹ Pasuma lo fi ibeere ṣọwọ si i lórí ètò Facebook Live pẹ̀lu Pasuma ni wi pe awọn n reti rẹ ni orilẹ-ede naa lati wa fi orin da awọn laraya nitori awọn n ri bira ti aṣiwaju elere fuji naa n da lara kaakiri awọn orilẹ-ede agbaye ati pe igba wo gan an lo n bọ wa kọrin ni Saudi.
Lábẹ́ odò! Ìgbéyawó yìí lárinrin
Amọṣa, Pasuma ni ko si iye owo to lee mu oun lọ si Saudi Arabia lọ kọrin nitori 'ile adura ni'
A maa n wa gba adura ni Saudi Arabia ni. Ti a ba ti wá sí Saudi, a wa sin Ọlọrun ni. Ẹyin ti Saudi, ẹyin ti Jedah ẹ gbagba nnkan to n jẹ pe a wa kọrin o. Bi ẹgbẹ ba ti ri wà ni Saudi, mo wa ki anọbi Muhammad ni, mo wa rọgba yi Kaaba lati wa dupẹ ore ti Ọlọrun ṣe kí n si tun beere omiiran ni. Ilẹ mimọ ni
Lori ajọṣepọ to wa laarin oun ati Gbajugbaja Olorin fuji miran, Saheed Oṣupa, Pasuma ni iṣẹ ti pọ lọwọ awọn bayii ju ki awọn mejeeji máa ta'hun orin sira.
Ko si nnkan kan laarin wa. Emi le maa ro o bayii pe ko si wahala, mi o le gba ẹnu rẹ sọrọ pe ko si wahala. Sugbọn nitori pe o ti pẹ ti mo ti gbọ pe o sọrọ nipa Pasuma, iṣẹ ti pọ lọwọ rẹ bayii, ko s'aye. O  ti to bi ọdun kan bayii ti a ti gbọ pe Saheed kọrin ba Pasuma tabi Pasuma kọrin ba Saheed. Iṣẹ ti pọ lọwọ awa mejeeji, ko si aye.O fi kun un pe igbaradi ti wa fun ṣiṣe ayẹyẹ ọjọ ibi ọdun mokanlelaadọta oun ni orilẹ-ede Canada.
Ọjọ kẹtadinlọgbọn oṣu kọkanla tii ṣe ọjọ ibi rẹ ni ayẹyẹ alujo náà yóò sì waye.
Dora Akunyili, Ngozi Okonjo-Iwealla, Oby Ezekwesili: Òbìnrin mánigbàgbé mẹ́ta nínú ìjọba tiwantiwa láti odún 1999
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Lati igba ti orilẹede Naijiria ti pada si iṣejọba tiwantiwa, oniruru awọn obinrin lo ti sa ipa ti wọn
Lati ọdun 1999 ti orilẹ-ede Naijiria ti pada si iṣejọba tiwantiwa, oniruru awọn obinrin lo ti ṣa ipa ti wọn ninu idagbasoke iṣejọba tiwantiwa ti gbogbo agbaye si mọ kale-kako.
Mẹta ninu wọn ree.
Awọn obinrin ti ina orukọ wọn ko fi igba kan ku lati igba ti iṣejọba tiwantiwa ti bẹrẹ.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Akunyili ku ni ọjọ keje oṣu kẹfa ọdun 2014 lẹyin to ba aisan jẹjẹrẹ finra fun ọpọlọpọ igba
Oloogbe Ọjọgbọn Dora Akunyili
Ọjọgbọn Dora Akunyili jẹ ọmọ ipinlẹ Anambra, ṣugbọn ilu Markurdi ni ipinlẹ Benue ni wọn bii si ni ọjọ kẹrinla, oṣu keje, ọdun 1954.
Igba ti o di ilumọọka fun awọn ọmọ orrilẹ-ede yii ni asiko ti aarẹ orilẹ-ede nigba naa, Oluṣẹgun Ọbasanjọ yan an gẹgẹ bii oludari agba fun ajọ to n gbogun ti ilokulo ounjẹ, ohun mimu ati ogun ni Nijiria, NAFDAC laarin ọdun 2001 si 2008.
Femi Falana, Endsars: Awolowo kò fáààyè gba kí èèyàn máa yàgò fún Màálù nígboro
Aṣeyọri ti Ọjọgbọn Dora Akunyili ṣe lasiko naa kuro ni kekere nitori oun lo mu igba ọtun wọ eto gbigbogun ti ayederu oogun oloro lorilẹ-ede Naijiria nigba naa.
Koda, awọn awujọ agbaye gbogbo ni wọn kan sara si fun iṣẹ takuntakun ti o ṣe nigba naa.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Dora Akunyili lo gbe eto Nigeria...good people, great nation jade fun atunṣe orukọ Naijiria
Labẹ iṣejọba aarẹ Naijiria ti o di oloogbe, Musa Yaradua ni wọn ti yan an gẹgẹ bii minisita fun eto iroyin ati ibanisọrọ lọdun 2008 si 2010.
Lasiko ti aarẹ Yaradua di oloogbe, ti igbakeji rẹ, Goodluck Jonathan si rọpo rẹ, yii gan an ni Dora Akunyili gbe akanṣe eto kan kalẹ to pe ni 'Re-branding Nigeria Project' fun atunṣe orukọ ati iyi orilẹ-ede Naijiria.
Oladele Ogbeyemi Albert: Irin tí mò ń lò máa ń bá mi sọ̀rọ̀ nínú ẹ̀mí kí ń tó gbẹ́ wọn sóh
Nigba naa ni o gbe akori,  Nigeria...good people, great nation jade.
O dije dupo senetọ ni Anambra Central lọdun 2011 ṣugbọn Chris Ngige lo gbegba oroke.
Dora Akunyili jade laye lọdun lọjọ keje, oṣu kẹfa, ọdun 2014 lẹyin to kopa ninu apero itesiwaju Naijiria CONFAB.
wọn sin in ni ọjọ ketadinlogun ati ikejidinlogun, oṣu kẹjọ, ọdun 2014.
Ninu idanilẹkọ kan ti o ṣe ni ilu Eko ni ibẹrẹ ọdun 2018, aarẹ ana Oluṣẹgun Ọbasanjọ ni, eeyan kan to gburo iwa olootọ Dora lasiko to fi wa ni ileewe kan ni ilẹ Gẹẹsi lo fi ọrọ rẹ to oun leti ti oun fi yan an.
Lẹyin ti o kuro ni ijọba, Ọjọgbọn Dora Akunyili wa lara awọn ti wọn yan fun igbimọ apero ti ijọba apaps gbe kalẹ fun agbeyẹwo ẹhonu awọn ẹya lorilẹede Naijiria.
Akunyili ku ni ọjọ keje oṣu kẹfa ọdun 2014 lẹyin to ba aisan jẹjẹrẹ finra fun ọpọlọpọ igba.
Oríṣun àwòrán, @NOIweala
Ọkan lara awọn eekan to lagbara labẹ iṣejọba aarẹ Ọbasanjọ laarin ọdun 2003 si 2006 ni Okonjo-Iweala
Ọjọgbọn Ngozi Okonjo-Iweala jẹ minisita ijọba meji lorilẹede Naijiria-2003 si 2006 labẹ aarẹ Oluṣẹgun Ọbasanjọ, 2011 si 2015 labẹ iṣejọba aarẹ Goddluck Jonathan.
Banki agbaye ni Ọjọgbọn Ngozi Okonjo-Iweala ti n ṣiṣẹ ki aarẹ Oluṣẹgun Ọbasanjọ to pe e wa sile.
O ni ko wa ṣe minisita fun eto iṣuna lorilẹ-ede Naijiria oun ni obinrin akọkọ ti yoo ṣe minisita fun eto iṣuna ati minisita fun ọrọ ilẹ okeere lorilẹ-ede Naijiria.
Oríṣun àwòrán, @NOIweala
Pupọ ọmọ orilede Naijiria ni ko ni gbagbe minisita 'alaṣọ ankara' yii pẹlu gele 'ipakọ o gbọ ṣuti' rẹ
Ọkan lara awọn eekan to lagbara labẹ iṣejọba aarẹ Ọbasanjọ laarin ọdun 2003 si 2006 ni Okonjo-Iweala.
O si ko ipa ribiribi ninu bi awọn igbimọ orilẹ-ede agba kan lagbaye ṣe wọgile gbese biliọnu mejidinlogun dọla, $18bn ti orilẹ-ede Naijiria jẹ ṣaaju igba naa.
Pupọ ọmọ orile-ede Naijiria ni ko ni gbagbe minisita 'alaṣọ ankara' yii pẹlu gele 'ipakọ o gbọ ṣuti' rẹ.
Bayii, Ngozi Okonjo-Iwealla ti di oludari ajọ olokowo agbaye.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ohun ti ọpọ awọn ọdọ mọ Obiageli Ezekwesili fun ni ipa rẹ gẹgẹ bii aṣiwaju ẹgbẹ #BringBackourGirls
Ohun ti ọpọ awọn ọdọ mọ Obiageli Ezekwesili fun ni ipa rẹ gẹgẹ bii aṣiwaju ẹgbẹ to n ja fun itusilẹ awọn akẹkọọ ileewe girama kan ni Chibok ipinlẹ Borno.
Awọn ni awọn ọmọ-ogun Boko haram ji gbe ni ọdun 2014, #BringBackourGirls.
Bakan naa lo tun lewaju ẹgbẹ kan to n ja fun ilana iṣejọba rere, 'Red Card'
Lara awọn ipo ti o ti di mu ninu iṣejọba orilẹ-ede Naijiria lati igba ti saa iṣejọba tiwantiwa yii ti bẹrẹ ni amugbalẹgbẹ pataki fun aarẹ Ọbasanjọ lori amojuto iwe eto iṣuna, minisita fun ohun alumọni ati minisita feto ẹkọ.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Oniruuru awọn aarẹ orilẹede Afirika ni o ti ṣiṣẹ fun gẹgẹ bii olubadamọran ptataki
Lasiko to fi jẹ minisita feto ẹkọ ni Oby, gẹgẹ bi ọpọ ṣe maa n pe e, ṣe eto atunto ẹka eto ẹkọ lorilẹ-ede Naijiria ninu eyi ti spọ awọn orilẹede Afirika mira ti ya lo bayii.
Oniruuru awọn aarẹ orilẹ-ede Afirika ni o ti ṣiṣẹ fun gẹgẹ bii olubadamọran ptataki.
Ni bayii, Ọmọwe Oby Ezekwesili ni oludije ipo arẹ fun ẹgbẹ oṣelu Allied Congress Party of Nigeria, ACPN fun idibo apapọ ọdun 2019 lorilẹ-ede Naijiria.
Lori iro: Ká ni àwọn Òbí mi gbà fún mí, èmi àti Sunny Ade  á jọ máa 'Compete- Baba Lórí ir
Ìtàn Mánigbàgbé: Kí lo fẹ́ mọ̀ nípa ‘Ajala Travels’?
Oríṣun àwòrán, Keystone-France
• Asọ iran Yoruba, taa mọ si Agbada ati Sokoto ni Ajala wọ lori kẹkẹ to fi rin yika agbaye
N jẹ ẹyin ti gbọ nipa ‘Ajala the Traveller’ tabi Ajala Travels’ ri?
Ọpọ eeyan lo maa n da asa nipa ẹnikan to rin irinajo afẹ yika gbogbo agbaye pẹlu alupupu lasan, taa mọ si Ọkada, ti wọn si maa n pe ẹni to ba n ti ilu kan si ekeji ni orukọ onitọun.
Ọmọ ilẹ kaarọ oojire ni ọkunrin to da ara yii, orukọ rẹ a si maa jẹ Moshood Ọlabisi Adisa Ajala, ti gbogbo eeyan mọ si Ajala Travels.
Bi o tilẹ jẹ pe Ọlabisi Ajala ti fi ilẹ bora bii asọ, sibẹ o yẹ ki iran iwoyi mọ ohun kan tabi meji nipa rẹ nitori bi ọmọ ko ba ba itan, yoo ba arọba.
Oríṣun àwòrán, @AfricaFactsZone
Bi o tilẹ jẹ pe Onirese Ọlabisi ọmọ Ajala ko fin igba mọ, amọ eyi to ti fin silẹ ko lee parun, nitori a ko tii ri eeyan miran to fi Ọkada rin yika agbaye mọ bii Ajala.
Ẹ jẹ ki awa naa sa ipa wa, lati fi ipa tiwa han lawujọ agbaye nitori arise ni arika, ohun ta ba si se ni oni, ọrọ itan ni yoo da, bo ba di ọla.
Minimum wage: Ọ̀pọ̀ ẹ̀ka isẹ́ ajé tó se kókó ló fẹ́ dara pọ̀ mọ́ ìyansẹ́lódì náà
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ọlọjọ gbọọrọ ni iyanṣẹlodi yii, gẹgẹ bii awọn adari ẹgbẹ oṣiṣẹ ti ṣe sọ, a gbọdọ mura silẹ fun un.
Bi iroyin ṣe n kaakiri lori iyanṣẹlodi awọn oṣiṣẹ, eleyii ti o ṣeeṣe ki o bẹrẹ ni ọjọ kẹfa oṣu kọkanla ọdun 2018, ọpọ lo ti wa ninu ipaya ati iwariri bayii lori ipa ti irufẹ iyanṣẹlodi bẹẹ lee ko ba eto ọrọ aje orilẹede Naijiria.
Ni lọwọlọwọ ti a n sọrọ yii, awọn ẹgbẹ oṣiṣẹ ni ẹka ọrọ aje ti o ṣe koko gbogbo, ni wọn ti n faramọ gigun le iyanṣẹlodi yii.
Amọṣa, bi ọrọ ti ṣe ri yii, o yẹ ki awọn ọmọ orilẹede yii gbaradi fun ohun yowu to lee waye pẹlu iyanṣẹlodi.
Ireti Yusuf: Ìsòro àti fẹjọ́ sùn ló ń mú kí ìwà ìfipábánilòpọ̀ gbilẹ̀ si
Ni iwọn igba ti o jẹ wi pe, ọlọjọ gbọọrọ ni iyanṣẹlodi yii, gẹgẹ bii awọn adari ẹgbẹ oṣiṣẹ ti ṣe sọ.
Eyii ni awọn ohun marun ti o gbọdọ ṣe ni igbaradi fun iyanṣẹlodi yii:
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ni lọwọlọwọ ti a n sọrọ yii awọn ẹgbẹ oṣiṣẹ ni ẹka ọrọ aje ti o ṣe koko gbogbo ni wọn ti n fara mọ gigun le iyanṣẹlodi yii
Ko si idaniloju pe ipese epo bẹntiroolu ko ni fi ara gba ninu iyanṣẹlodi yii, to ba n pẹ ju boṣe lọ. Ohun ti iroyin n sọ ni pe, o ṣeeṣe ki awọn ẹgbẹ oṣiṣẹ agbepo rọbi lorilẹede Naijiria, NUPENG pẹlu darapọ mọ iyanṣẹlodi yii.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ọpọ lo ti wa ninu ipaya ati iwariri bayii lori ipa ti irufẹ iyanṣẹlodi bẹẹ lee ko ba eto ọrọ aje
Lootọ awọn ẹka ipese ina ọba ti di aladani bayii, ọrọ idasilẹ ẹgbẹ oṣiṣẹ nibẹ ko si tii duro daadaa nitorinaa o ṣeeṣe ki awọn oṣiṣẹ nibẹ ma gunle iyanṣẹlodi.
Amọṣa, ko yẹ ki a gbagbe pe afẹfẹ gaasi ni awọn ileeṣẹ ti o n pese ina ọba n lo, bi awọn ẹgbẹ oṣiṣẹ lẹka afẹfẹ gaasi yii ba yanṣẹ lodi, o di dandan ki ipese ina o fara gba.
Bi o ba ri bẹẹ, ki a gbaradi fun ọna ipese ina miran, yala ti ohun elo amu oorun ṣ'agbara ina solar, tabi ẹrọ amunawa generator, abi atupa.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ju gbogbo rẹ lọ, ẹ mojuto ọrọ abo ẹyin ati ẹbi yin nitori lasiko iyanṣẹlodi yi
Nitori iṣoro irinkerindo ọkọ ti o lee waye, eleyi ti o lee ṣe idiwọ lilọ si ọja lọ ra awọn ohun jijẹ ati idana gbogbo, yoo dara ki a ra awọn ohun elo jijẹ ati ile gbogbo bii elo ọbẹ, ati bẹẹbẹẹ lọ.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Lootọ awọn ẹka ipese ina ọba ti di aladani bayii, ọrọ idasilẹ ẹgbẹ oṣiṣẹ nibẹ ko si tii duro daadaa nitorinaa o ṣeeṣe ki awọn oṣiṣẹ nibẹ o maa gunle iyanṣẹlodi
Afẹfẹ idana gaasi ni ọpọlọpọ ile fi nṣe idana bayii, bi awọn ẹgbẹ oṣiṣẹ afẹfẹ gaasi ba si darapọ mọ iyanṣẹlodi yii, afaimọ ki afẹfẹ idana gaasi o maa di afẹti.
Mojuto ọrọ aabo iwọ ati idile rẹ
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Amọṣa, bi ọrọ ti ṣe ri yii, o yẹ ki awọn ọmọ orilẹede yii gbaradi fun ohun yoo wu ti o lee waye pẹlu iyanṣẹlodi
Ju gbogbo rẹ lọ, ẹ mojuto ọrọ aabo ẹyin ati ẹbi yin nitori lasiko iyanṣẹlodi yii, o ṣeeṣe ki iwọde waye, asiko yii si ni oniruuru awọn eeyan n farahan ti erongba wọn yatọ si ti awọn adari ẹgbẹ oṣiṣẹ to n ṣe aayan iwọde naa.
Paul Biya: Kìí ṣèpàdé pẹ̀lú àwọn mínísítà rẹ̀, ilé ìtura ní Switzerland ló ń gbé
Oríṣun àwòrán, AFP
Aarẹ orilẹede Cameroon, Paul Biya, yoo ṣe ibura wọle fun igba keje ni ọjọ Iṣẹgun, ọjọ kẹfa, oṣu Kọkanla.
Ọdun 1982 ni aarẹ Paul Biya gba ọpa asẹ lati maa dari orilẹ-ede Cameroon, o si jẹ ọkan lara awọn aarẹ to dagba julọ lori oye ni ilẹ Afrika.
Nigba to si jẹ pe saa keje lo fẹ se bayii lori aleefa, o yẹ kẹ mọ awọn ohun meje nipa aarẹ Biya, ti orilẹ-ede Cameroon naa.
1. O jẹ́ ọ̀kan lara awọn olórí ni Afrika to n gba owó ju lọ
Oríṣun àwòrán, NIC BOTHMA
Abọ iwadi kan sọ pe ìlọpo igba le mọkandinlọgbọn owo oṣu ti oṣiṣẹ n gba ni Cameroon, ni owo oṣu Aarẹ Biya
Aarẹ Biya wa lara awọn aarẹ to n gbowo ju lọ ni Afrika. O ti ẹ ṣeeṣe ko jẹ oun lowo oṣu rẹ pọ ju. Iwe iroyin African Review sọ pe, Biya n gba ọtalelọọdunrun o din ẹyọkan miliọnu CFA francs, owo orilẹede Cameroon, ti afiwe rẹ jẹ ẹgbẹrun lọna ẹgbẹta o le mẹwa Dọla ($610,000) lọdọọdun.
2. Baba onile to n sun ita ni Biya
Oríṣun àwòrán, Intercontinental Hotel
Ile itura to gbayi ni Switzerland ni Biya n gbe ju
Awọn kan maa n ṣapejuwe Aarẹ Biya gẹgẹ bi baba onile, ṣugbọn ti kan-in-kan-in ile rẹ kii ta nidi, nitori pe ọpọlọpọ akoko lo maa n wa ni awọn ile itura to gbayi, to si wọ́n pupọ ni orilẹede Switzerland.
O si maa n ko to ogoji eniyan dani lọ fun irinajo kọọkan to ba n lọ, wọn si le na to ẹgbẹrun mejidinlaadọta le ni ẹẹdẹgbẹta Dọla l'ọjọ kan.
Ajọ aladani kan tilẹ sọ pe o ti na to aadọrun biliọnu FCFA laarin ọdun 1982 si 2017.
3. Aarẹ Biya jẹ ọkan lara awọn aarẹ to dagba ju ni Afrika
Oríṣun àwòrán, Lintao Zhang
Biya yoo pe ẹni ọdun mejidinlaarun nigba ti yoo ba fi pari saa keje rẹ
Aarẹ Biya bọ si ori aga iṣakoso l'ọjọ kẹfa, oṣu Kọkanla, ọdun 1982, lasiko ti Aarẹ Amadou Ahidjo gbe agbara iṣakoso le e lọwọ. Yoo si tun bura wọle fun saa ọlọdun meje mi i, eyi ti yoo mu ko pe ọdun marundinlogoji to ti wa nipo.
Biya ti pe ẹni ọdun marundinlaadọrun. Ilaji awọn ọmọ orilẹede Cameroon tilẹ sọ pe Biya lo ti wa ni ipo lati igba ti wọn ti bi wọn.
4.  Igba meji lo ti ṣegbeyawo
Oríṣun àwòrán, CHRISTOPHE SIMON
Chantal Biya
Aarẹ Biya ti fi igba kan jẹ́ ọmọ ile ẹkọṣẹ alufaa Katoliiki, ko to di pe o fẹ iyawo rẹ akọkọ, ti ko bimọ fun un. Aṣa wọn si ni pe o le bimọ lati ara arabinrin iyawo rẹ.
Lẹyin ti Jean Irene Biya ku, ni aarẹ Biya fẹ Chantal, wọn si bi ọmọ meji. Chantel ti kọkọ bi ibeji fun ọkunrin kan.
5. Biya ko kuna ri ninu eto idibo aarẹ
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ọjọ keje, oṣu Kẹwaa ni wọn ṣe eto idibo to gbe Biya wọle fun igba keje
Aarẹ Biya kọkọ fi ẹyin Amadou Ahidjo janlẹ l'ọdun 1982. Lẹyin ọdun mẹwaa, o tun bori ni 1992, 1997, 2004 ati 2011. Bakan naa ni 2018, o bori pẹlu ibo ìdá mọkanlelaadọrin, botilẹ jẹ pe eniyan miliọnu meji ataabọ pere lo dibo ninu miliọnu mejilelogun to yẹ ko dibo.
6.  Iwa jẹgudu-jẹra gbayi l'orilẹede naa
Oríṣun àwòrán, MARCO LONGARI
Cameroon ti gba ami ẹ̀yẹ fun iwa ibajẹ lẹẹmeji, kekere kọ si ni kiko owo ìlú jẹ lati igba ti Aarẹ Biya ti wa nipo fun ọdun marundinlogoji bayii. Cameroon lo wa ni ipo mẹrindinlaadọjọ ninu orilẹede mẹrindinlaadọsan to n hu iwa ijẹkujẹ.
7. Aarẹ Biya kii ṣe ipade pẹlu awọn minisita rẹ
Oríṣun àwòrán, ALEXIS HUGUET
Orilẹede Isreal ni awọn oṣiṣẹ alaabo Biya ti n kẹ́ẹ̀kọ̀ọ́
Aarẹ Biya kii ṣe ipade pẹlu awọn ọmọ igbimọ iṣakoso ati minisita rẹ ni gbogbo igba, ayafi asiko to ba fẹ ẹ yan minisita sipo nikan.
Eyi si mu ki kaluku wọn maa ṣe boṣe wu wọn lẹnu iṣẹ. Ọdun 2015 ni Biya ti se ipade igbimọ alaṣẹ kẹhin, ko to o tun ṣe ni 2018. O tilẹ maa n gba iṣẹ́ lọwọ minisita ti ko ti ẹ ri soju ri.
Èéfín gẹnẹratọ: Iléẹjọ́ ní kí ayálégbé san ₦2m owó ìtanràn
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Kii ṣe ẹẹkan tabi ẹẹmeji, ni iroyin ti gbe e pe eefin ẹrọ amunawa ṣekupa mọlẹẹbi ni Naijiria.
Ile ẹjọ kan ni agbegbe Ikẹja nipinlẹ Eko ti ni ki ayalegbe kan san miliọnu meji owo gba mabinu fun ayale ẹgbẹ rẹ nitori eefin ẹrọ amunawa.
Ọjọ Aje ni ile ẹjọ gbe idajọ kalẹ pe, ki ayalegbe naa san owo ọhun fun ayalegbe ẹgbẹ rẹ, Bunmi Ọdẹniyi, nitori pe eefin ẹrọ amunawa rẹ n wọ ile Ọdẹniyi, nile ti awọn mejeeji n gbe ni Gbagada, nilu Eko.
Lekan Kingkong: Níbikíbi tí mo bá wà, màá gbé àṣà Yorùbá ga
Ile ẹjọ sọ pe ẹsun naa n bẹ labẹ abala ti wọn pe ni 'aikọbi ara si nkan' labẹ ofin orilẹede Naijiria. Ofin naa fihan pe, ojuṣe aigbọdọ ma se ni ki o maa ro eto idẹrun alajọgbepọ rẹ mọ ti ẹ.
Ẹjọ naa to ti wa nile ẹjọ lati ọdun 2015, ni wọn gbe idajọ rẹ kalẹ lọjọ kẹfa, oṣu Kọkanla,.
Oríṣun àwòrán, @HeyLagos
Ile ẹjọ sọ pe ki alajọgbelepọ Ọdẹniyi san miliọnu meji Naira fun ipalara, aisan, idinilọwọ pẹlu ariwo, ti ẹrọ amunawa rẹ ọhun fa fun ẹnikeji, to jẹ alabagbele rẹ.
Ko jẹ tuntun mọ pe ọpọlọpọ ọmọ Naijiria lo gbọkan le ẹrọ amunawa fun ipese ina ẹlẹtiriiki ninu ile ati ibi iṣẹ wọn
Bẹẹni kii si ṣe ẹẹkan tabi ẹẹmeji, ni iroyin ti gbe e pe, eefin ẹrọ amunawa ṣekupa mọlẹbi ni Naijiria
Minimum Wage: Buhari gbọdọ̀ fi àbá owó osù tuntun sọwọ́ sáwọn asòfin
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Awọn gomina lawọn o le san ọgbọn ẹgbẹrun Naira f'oṣiṣẹ
Sẹnetọ Rafiu Ibrahim, to n ṣoju ẹkun idibo Guusu ipinlẹ Kwara salaye pe, ileeṣẹ aarẹ gbọdọ kọkọ fi aba ofin ranṣẹ sile aṣofin fun ayẹwo.
O sọ eyi lasiko ti BBC Yoruba kan si lori ilana ti owo oṣu tuntun naa yoo gba, ko to o di sisan.
Sẹnetọ Rafiu salaye pe, igba ti aba ofin naa ba de iwaju awọn asofin, ni wọn yoo ṣe ayẹwo rẹ finifini, lẹyin eyi ni wọn yoo ṣe atunse si ofin to nii ṣe pẹlu owo oṣu oṣiṣẹ ni Naijiria.
Grandma Maruwa: Ó yẹ kí obìnrin sisẹ́ láì wojú ọkọ kó tó jẹun
O sọ pe, bi aarẹ Muhammadu Buhari ba ṣe tete gbe aba ofin naa wa siwaju wọn, ni yoo sọ igba ti yoo di ofin, ti owo oṣu naa yoo si bẹrẹ si ni jẹ sisan. Amọ ko sọ ni pato iye ọjọ, ọsẹ tabi oṣu ti ilana ọhun yoo gba wọn.
Sugbọn ṣa, pe ile aṣofin buwọlu aba owo osu naa, ko ti i tumọ si pe yoo di sisan, nitori pe ile asofin mejeeji gbọdọ fi ohun ṣọkan lori rẹ, ki wọn to o gbe pada si ọdọ aarẹ.
Oríṣun àwòrán, Garba Shehu
Aarẹ Buhari nigba ti o n gba abọ iwadi igbimọ to ṣiṣẹ lori ẹkunwo owo oṣu oṣiṣẹ
Bakan naa ni o tun ṣe pataki, ki awọn ijọba ipinlẹ gba lati mu ofin naa lo.
Idi ni pe ọpọlọpọ awọn ipinlẹ lo ti sọrọ sita lasiko ti awọn oṣiṣẹ n ja fun owo oṣu tuntun, pe awọn ko ni le san ẹgbẹrun lọna ọgbọn Naira ti ẹgbẹ oṣiṣẹ n beere fun, bi ko ṣe ẹgbẹrun mejilelogun ataabọ Naira ti agbara awọn ka.
Awọn ọmọ Naijiria ti fesi si igbesẹ Aarẹ Muhammadu Buhari lati gbe aba owo osu tuntun naa lọ si Ile Igbimọ Asofin lẹyin to tẹwọgba àbá ẹkunwo owó oṣù òṣìṣẹ́ ti igbimo naa gbe kalẹ.
Aarẹ Buhari sọ nipa igbese naa lẹyin ti ẹgbẹ́ òṣìṣẹ́ NLC fagile ìyansẹ́lódì ti wọn fẹ gunle ní Ọjọ́ Ìṣẹ́gun láti bèèrè fún àfikún owo oṣù òsìsẹ́ ní Naijiria.
Lara awọn ọmọ Naijiria to fesi si igbesẹ aarẹ naa gboriyin fun aarẹ Buhari nigbati awọn miran bu ẹnu atẹ lu pe ọna miran lati fa ẹkunwo owo osu sisan naa gun ni Aarẹ Buhari dawọ le.
Grandma Maruwa: Ó yẹ kí obìnrin sisẹ́ láì wojú ọkọ kó tó jẹun
John Agbaja sọ wi pe oun ni gbagbọ ninu Aarẹ Buhari lati sa ipa rẹ ki irọrun o le de ba  awọn osisẹ lorilẹede Naijiria.
Amọ awọn miran parọwa si ẹgbẹ osisẹ lorilẹede Naijiria lati mọkanle nitori ọna ni yii lati ri wi pe won ko se ekunwo owo osu awọn osisẹ naa lasiko to tọ ati eyi to yẹ.
Àwọn ọmọ Naijiria fèsì sí gbèǹdéke owó osú tí Ààrẹ buwọ́lù
Abubakar Musa nigba to n fesi si igbesẹ naa rọ awọn ọmọ Naijiria lati ri wi pe wọn fọwọsowọpọ pẹlu Aarẹ Buhari lati mu idagbasoke ba orilẹede Naijria.
Ìròyìn tó ń tẹ̀ wa lọ́wọ́ sọ pé Ààrẹ orileede Naijiria Muhammadu Buhari ti tẹwọgba àbá ẹkunwo owó oṣù òṣìṣẹ́ ti igbimọ to ṣiṣe lori rẹ jabọ fun un l'Abuja.
Nigba ti o n gba abọ iwadi naa ti olori igbimọ ọhun Amal Pepple gbe fun un, Aarẹ Buhari ni oun yoo ṣa agbara oun lati ri wi pe ilé aṣòfin mú ayípadà bá owó oṣù ti àwọn òṣìṣẹ́ n gba.
Agbẹnusọ ile iṣẹ Aarẹ Garba Shehu fi ẹkunrẹrẹ alaye ohun ti Aarẹ Buhari sọ nibi to ti tẹwọgba aba naa lede loju opo Twitter rẹ.
ASUU Strike: Bí àwọn kan se dunnú, làwọn kan fajúro
Ninu atẹjade naa Aarẹ Buhari ko sọ pato boya oun yoo buwọlu ẹgbẹrun lọna ọgbọn Naira ti awọn oṣiṣẹ n bere fun.
Sugbọn o fi ifarajin rẹ han lati fi abadofin lori ẹkunwo oṣiṣẹ rinlẹ lọjọ waju.
Oríṣun àwòrán, @GarShehu
O ni bi ijọba ti n ṣe agbeyẹwo aba yi, oun rọ awọn oṣisẹ ati awọn asaaju wọn lati ṣe suuru di ọṣẹ to n bọ.
Oríṣun àwòrán, @GarShehu
Ero ọkan ọpọ ọmọ Naijiria ni wi pe Aarẹ Buhari yoo buwọlu ẹkunwo owo oṣu tuntun
Ondo police: Ìwádìí ń tẹ̀síwájú lórí ìjínigbé náà
Agbẹ́nusọ́ fún ilé isẹ́ ọlọ́ọ̀pàá ní ìpínlẹ̀ Ondo ní lóòtọ́ ni ìsẹ̀lẹ̀ náà wáyé ní ọ́ná Ọ̀bà Àkókó àti pé ìjínigbé wọ́pọ̀ lágbèègbè náà.
Ile iṣẹ ọlọpaa ni ipinlẹ Ondo ti fi idi ẹ mulẹ pe lootọ ni awọn ajinigbe ti ji Alaga Ẹgbe Oselu ADC ni ipinlẹ Ondo, Bisi Ogungbemi ati awọn mẹrin miran lọ.
Awọn mẹrin miran ti awọn ajinigbe naa jigbe lọ ni Oludije sipo sẹnetọ lẹkun idibo ariwa ni ipinlẹ Ondo lẹgbe oṣelu ADC, Jide Ipinsagba, Ọmọọbabinrin Funmilayo Abdulraman to jẹ aṣaju awọn obinrin ni Guusu Ondo, Abẹsinkawọ Alaga, Arakunrin Idowu ati awakọ wọn.
Agbenusọ fun ile iṣẹ ọlọpaa, Femi Joseph to ba BBC Yoruba sọrọ ni irọlẹ ana ni isẹlẹ naa waye ati wi pe awọn adigunjale ti maa n ṣọṣẹ ni agbegbe Ọba-Akoko to wa lọna Ọwọ si Akungba-Akoko.
Ìnú mi kìí dùn nígbà trí mo ń ṣiṣẹ́ ni bánkì tó ìgbà ti mo bẹ̀rẹ̀ mẹkáníìkì
Joseph ni iwadii ti n lọ lọwọ lati ri awọn ajinigbe naa ati lati doola ẹmi awọn ti wọn jigbe naa.
El-Zakzaky: Ṣé lóòtọ́ ni ìjọba ń ná N3.5 mílíọ̀nù lórí aṣíwájú ẹ̀sìn Shiite lóṣù?
Oríṣun àwòrán, @FMICNigeria
Lai ni aye ọba ni adari ijọ ẹsin Shiite lorilẹede Naijiria, Ibrahim El-Zakzaky n jẹ lahamọ
Ni ọjọru ni iroyin kan jade pé minisita fun eto iroyin ati aṣa lorilẹ-ede Naijiria, Lai Mohammed ṣalaye fun awọn oniroyin pe miliọnu mẹta abọ naira ni ijọba apapọ fi n yanju ọrọ ounjẹ fun adari ijọ ẹsin Shiite lorilẹ-ede Naijiria, Ibrahim El-Zakzaky loṣu.
Minisita Lai Mohammed to n laa ye awọn akọroyin pe ijọba ko ṣa deede fi Ibrahim El-Zakzaky si ahamọ bikoṣe nitori pe ile ẹjọ ti o n gbọ ẹjọ rẹ ni ki wọn fi si ahamọ eyi to mu ki ileeṣẹ ọtẹlẹmuyẹ orilẹ-ede Naijiria o fi pamọ sinu ile kan ni ilu Abuja nibiti o ni ijọba ti n na owo to to miliọnu mẹta abọ ni ijọba apapọ lati fi gbọ bukata rẹ.
Ìnú mi kìí dùn nígbà trí mo ń ṣiṣẹ́ ni bánkì tó ìgbà ti mo bẹ̀rẹ̀ mẹkáníìkì
Ọrọ yii ti wa di alatagba laarin awọn Ọmọ orilẹ-ede Naijiria bayii.
Ọgbẹni Reno Omokri to figbakan ri jẹ amugbalẹgbẹ fun aarẹ ana, Goodluck Jonathan ninu ọrọ tirẹ ni irọ nla ni minisita lai Mohammed pa.
"Ninu ọrọ kan to kọ lori ikanni twitter rẹ, Omokri ni: ""N3.5 miliọnu loṣu lati bọ Ibrahim El-Zakzaky tumọ si ẹgbẹrun lọna mẹrindinlọgọfa (N116,000) lojumọ. Nibo ni @Mbuhari ti ri onirọ nla bayii?"
"Ni tirẹ, ọmọ ile igbimọ aṣofin agba, Ben Murray Bruce ni, ""Bi aarẹ @Mbuhari ba lee na N3.5 miliọnu lati bọ Ibrahim El-Zakzaky loṣu, ko si idi ti ko yẹ ko ri ọgbọn ẹgbẹrun naira, N30, 000 lati san owo oṣu oṣi'\sẹ to kere ju lọ. Abi ki gbogbo oṣiṣẹ darapọ mọ Ibrahim El-Zakzaky lahamọ ni ki wọn lee maa gba ẹgbẹrun lọna mẹrindinlọgọfa (N116,000) lojumọ."""
Ọkan o jọkan awọn ọmọ orilẹede Naijiria nile ati loke okun ni wọn ti n sọrọ lori ọrọ yii.
Ibadan: Ìdàrúdàpọ̀ wáyé láàrin ọlọ́jà Yoruba àti Igbo nítorí ipò lọ́jà Ògùnpa
Ibadan: Ìdàrúdàpọ̀ wáyé láàárín ọlọ́jà Yoruba àti Igbo nítorí ipò lọ́jà Ògùnpa
Ede-aiyede bẹ silẹ ni Ọjọbọ ni isọ awọn ti o n ta nnkan iranṣọ ni gbajugbaja Ogunpa ni ilu Ibadan.
Ohun ti o si fa ede-aiyede yii gẹgẹ bi BBC News Yoruba ti ṣe gbọ ko ju ija tani yoo jẹ alaga ọja naa eleyi ti o bẹ silẹ laarin awọn ontaja to jẹ ọmọ ilẹ Yoruba ati awọn to jẹ ẹya Igbo nibẹ.
Ohun ti BBC News Yoruba gbọ ni pe awọn ontaja to wa ni ọja naa to jẹ ẹya Igbo ni wọn sọọ nibi ipade kan ti alaga  ẹgbẹ awọn ọlọja ohun elo iranṣọ ni ọja ogunpa pe ni imura silẹ fun ajọdun ẹgbẹ naa ti yoo waye ni opin oṣu yii, pe asiko to fun awọn pẹlu lati jẹ alaga ni ọja naa.
Ògidì ọmọ Yorùbá gbọ́dọ̀ mọ 'áayan ògbufọ̀' dáadàa
"Iroyin ti a gbọ tun tẹsiwaju pe eyi lo bi awọn ọlọja to jẹ ọmọ Yoruba nibẹ ninu ti wọn fi fi aake kọri pe ""niwọn igba ti ko si ọmọ Yoruba ti o lee da iru aṣọ bẹẹ ṣoro ni ilu Onitsha ati aba nibiti irufẹ ọja ohun elo iranṣọ bayii wa, ko si nnkan to jọọ ni ilu Ibadan."""
Titi pa ni ọja naa wa di nnkan bi agogo kan ọsan ki wọn to ṣi ọja naa ni ọjọbọ.
Ìwà olè, jìbìtì àti ìjẹkújẹ ló n jé káwọn mii yí ọjọ́ orí wọn padà
Ninu ọrọ to ba ikọ BBC News Yoruba sọ, alaga ẹgbẹ naa, Ọgbẹni Kunle Olowu ṣalaye pe lootọ ni edeaiyede bẹ silẹ laarin ọja naa, ṣugbọn laarin awọn eeyan meji ti wọn jẹ ẹya Yoruba ati Igbo nibẹ ni.
Amọ ohun ti Ọgbẹni olowu kuna lati yannana rẹ ni bi edeaiyede laarin ọlọja meji ṣe mu ki wọn gbe ọja naa tipa di nnkan bi agogo kan si meji ọsan.
Ede aiyede kan waye lootọ kiiṣe ọrọ ati ṣe olori ni wọn n jaasi ṣugbọn a ti yanju ẹ.
"Amọṣa awọn eeyan kan to wa ra ọja ti iṣẹlẹ naa ṣe oju wọn fidi rẹ mulẹ fun BBC News Yoruba pe ""Ọrọ naa n fẹ amojuto nitori lootọ ni wahala naa waye ṣugbọn gẹgẹ bi ohun ti wọn sọ, koda wọn lọ pin pankẹrẹ laarin ọja lati fi na awọn eeyan nibẹ."""
Ọrọ naa tun fẹ ba ibo miran yọ nigba ti awọn ọmọ ita ati janduku kan ti ọpọ mọ si awon omo oju ina tun ya bo ọja naa ni nnkan bi agogo mẹrin si marun ti wọn si paṣẹ fun gbogbo awọn ontaja to jẹ ẹya igbo nibẹ lati ti ṣọọbu itaja wọn ki wọn si kuro ni ọja naa lẹyẹ-o-ṣọka.
Àwọn aṣofin Nàìjíríà fẹ̀sùn kan Ọṣinbajo lórí ọ̀rọ̀ NEMA
Oríṣun àwòrán, @profosinbajo
Àjọ NEMA to n dide siṣẹlẹ pajawiri ni Naijiria ni àwọn eẹ̀ yan kainkain
NEMA sọ pe ọwọ wọn mọ, bi awọn aṣoju-ṣofin ṣe fẹsun kan Yẹmi Ọṣinbajo lori jibiti biliọnu mẹfa din diẹ.
Àjọ tó n rí sí ìsẹ̀lẹ̀ pàjáwìrì lorilẹ-ede Naijiria, NEMA ti sọ pe ọwọ wọn mọ lẹyin igba ti ile igbimọ-aṣofin kekere naa sọ pe ọga agba ajọ ọhun lọwọ ninu jibiti ti o to biliọnu mẹtalelọgbọn naira.
Ninu atẹjade ti wọn fi sita ni NEMA ti ṣalaye ohun ti igbimọ naa gbe jade pé wọn kò ni nkan ṣe pẹlu awọn iwe aṣẹ ati aridaju ti awọn fi silẹ.
Ni ọjọbọ, igbimọ naa tun sọ pe igbakeji aare Naijiriya Yẹmi Ọṣinbajo naa fi ọwọ si milionu naira mẹfa-din (N5.8bn) ti ariwa owo-ifilọlẹ idasi, ti ile-igbinmọ sọ pe olodi s'ofin.
Ile-Igbinmọ naa sọ pe Yẹmi Ọṣinbajo ṣiṣe gẹgẹ bi aare nigba naa ni o fi tẹ ontẹ ki wọn na ọwọ naa in oṣu kẹfa, ọdun 2017.
Wọn ni o na ninu owo-ifilọlẹ apapọ nigba ti ko ri aṣe gba ni ile-igbinmo aṣofin lasiko naa.
Laolu Akande ti o je agbẹnusọ fun Ọṣinbajo jeri rẹ fun BBC pe awọn mọ si ẹsun naa ati pe awọn yoo fesi si iroyin naa láipẹ̀.
Mike Ifabunmi: Òrìṣà ló gbè wà jù ni Brazil
NEMA ṣalaye pẹlu apẹẹrẹ bi owo ti o le ni bilonu meji naira (N2.25 Billion) ni iye owo irẹsi ti ijọba China fi ranṣẹ si ilẹ Niajiria fun awọn aṣatipo ni ariwa, wọn si sọọ di mimọ pe bii milionu aadọtalenirinwo naira ni wọn na lati gbaa ati lati tọju awọn irẹsi naa, kii ṣe ẹgbẹrin milionu naira bi igbimọ naa ṣe sọ.
Ile-igbinmọ aṣoju naa ti gba Aare Muhammadu Buhari nimọran pé ki o da ọga NEMA, Maihaja duro lẹnu iṣẹ, pé ki o fun awọn agbofinro to n gbogun ti iwa ibajẹ n'ilu laṣẹ lati foju wọn ba ilé ẹjọ bi o ti yẹ.
Ìnú mi kìí dùn nígbà trí mo ń ṣiṣẹ́ ni bánkì tó ìgbà ti mo bẹ̀rẹ̀ mẹkáníìkì
Ọ̀pọ̀lọpọ̀ ǹkan ni àwọn ènìyan ń bèèrè lọ́wọ́ Buhari lásìkò yí
Oríṣun àwòrán, @MBuhari/Twitter
Awọn kan n fẹ ki Aarẹ Buhari din iye ti wọ̀n n ta jaala epo bẹtiro ku.
Ọpọlọpọ awọn ọmọ orilẹ-ede Naijiria ti fi èrò ọkan wọn han lori ohun ti wọn yoo ba Aarẹ Muhammadu Buhari sọ ti wọn ba ni anfaani iṣẹju meje pere lati ba a sọrọ.
Awọn ọmọ Naijiria ọhun fesi si ibeere kan ti BBC News Yoruba fi sita loju opo Facebook rẹ pe 'Ti ẹ ba ni anfaani iṣẹju meje pẹlu Aarẹ Buhari, ki lẹ o ba a sọ?''
A si ṣe akojọpọ diẹ lara awọn nkan ti wọn sọ.
"Ọ̀kan lara wọn, Adeniji Jacobson Gbenga sọ pe oun yoo ni ''ki Aarẹ Buhari o fi kurani bura fun mi pe ìwé ẹri ti ajọ WAEC fun òun kii se ayederu""."
Laipẹ yii ni awuyewuye waye lori esi idanwo WAEC ti Buhari ṣe nigba to pari ileewe girama. Ọpọlọpọ eniyan lo n sọ pe Buhari ko joko sẹ idanwo naa.
Lati ọdun 2015 to si ni awuyewuye naa ti di gbajugbaja, nitori pe Buhari ko fun ajọ eleto idibo Naijiria, INEC, ni iwe ẹri rẹ gẹgẹ bi ara ohun ti wọn n gba lọwọ ẹnikẹni to ba fẹ ẹ dupo oṣelu ni Naijiria.
Oríṣun àwòrán, @BashirAhmaad
Àjọ WAEC ṣàfihàn ìwé ẹ̀rí girama Ààrẹ Muhammadu Buhari
Ohun ti Buhari sọ nigba naa ni pe ọwọ ileeṣẹ ologun ni iwe ẹri oun wa, ti awọn eniyan si n sọ pe to ba jẹ lootọ ni, ki ileeṣẹ ologun fi sita.
Awuyewuye naa lọ silẹ diẹ ko tun to di ọdun 2018 ti Buhari tun kọ lati fun ajọ INEC ni iwe ẹri naa nitori pe o fẹ tun dije fun ipo aarẹ l'ọdun 2019. Lẹyin ti ariwo pọ ni Buhari mu iwe ẹri kan lọ fun ajọ naa, eyi to tun bẹrẹ awuyewuye mi i.
Minisita meji ninu eto iṣakoso Muhammadu Buhari ni wọn fi ẹsun ayederu iwe ẹri agunbanirọ kan; Kẹmi Adeọṣun ati Adebayọ Shittu.
Diẹ lara awọn to dahun ibeere ọhun n fẹ ki Aarẹ Buhari sọ owo oṣu awọn oloṣelu dọgba pẹlu t'awọn oṣiṣẹ ijọba ni Naijiria.
O ṣeeṣe ki esi wọn yi jẹyọ nitori ẹkunwo oṣu ti ẹgbẹ́ oṣiṣẹ ni Naijiria, NLC, n beere fun. Ẹgbẹ́ naa n fẹ ki ijọba maa san ọgbọ̀n ẹgbẹrun Naira gẹgẹ bi owo oṣu fun oṣiṣẹ to kere ju.
Oríṣun àwòrán, @MBuhari/Twitter
Buhari tẹwọgba abọ ipade igbimọ to jiroro lori owo oṣu tuntun fun oṣiṣẹ lọjọ kẹfa, oṣu Kọkanla, ọdun 208
Bo tilẹ jẹ pe Aarẹ Buhari ko ti i le sọ owo oṣu tuntun naa di ofin, lai jẹ pe ile aṣofin buwọlu, ọpọlọpọ awọn gomina Nairia ti sọ pe awọn ko le san ju ẹgbẹrun mejilelogun atẹẹdẹgbẹta Naira.
Awọn kan to tun kopa ninu ibeere naa ni awọn yoo gba aarẹ Buhari ni iyanju tabi sọ fun pe ko fẹhinti ninu oṣelu, ko si pada si ilu rẹ, Daura nipinlẹ Katsina.
Lara wọn gbagbọ pe Buhari ti dagba kọja ẹni to yẹ ko wa lori aga iṣakoso. Igba akọkọ kọ niyi ti imọran yii jade si Buhari.
Awọn kan si gba pe iṣakoso rẹ ko so eso rere fun orilẹede Naijiria. Sugbọn eyi ko di Buhari lọwọ lati ma polongo ibo fun ọdun 2019.
Ṣaaju ọdun 2015 to ti bọ si ipo aarẹ Naijiria ni ọpọ ọmọ orilẹede yii ti n pariwo pe ọjọ ori rẹ ko ni i jẹ ko ṣaṣeyọri nipo. Awọn kan si ti n sọ pe ọrọ wọn ọhun ti wa si imuṣẹ nitori bi Buhari ṣe ti lọ si ilẹ okeere lati gba itọju ni awọn asiko kan.
O ti pẹ ti ija ẹsin ati ẹ̀yà ti n waye ni orilẹede Naijiria, paapa ni ẹkùn Ariwa. Ṣugbọn awọn kan gbagbọ pe ipaniyan ati ija ẹsin peleke si ni asiko eto iṣakoso Buhari.
Awọn daran daran fi ọbẹ ge baba mi lori - ọmọ ọdun mọkanla
Ipaniyan wọpọ l'awọn ipinlẹ bi i Kaduna, Plateau ati Benue. Bakan naa ni ẹgbẹ agbesunmọmi Boko Haram naa n ṣọsẹ l'awọn ipinlẹ kan.
Ọpọ gbagbọ pe Buhari kọ lati koju awọn Fulani ti awọ̀n eeyan n fi ẹsun ipaniyan jakejado Naijiria kan, nitori pe o jẹ ẹ̀yà kan naa pẹlu wọn.
Awọn kan n fẹ ki Aarẹ Buhari din iye ti wọ̀n n ta jaala epo bẹtiro ku.
Ọdun 2016 ni ijọba Buhari kede alekun owo epo, to si yi i pada kuro ni naira mẹtadinlaadọrun to wa tẹlẹ si naira marundinlaadọjọ.
Alaye ti minisita keji fun ọ̀rọ̀ epo rọ̀bi, Ibe Kachikwu, ṣe nipe ijọba gbe igbesẹ naa lati fopin si ọwọn gogo epo bẹtiro to maa n waye.
Oríṣun àwòrán, AFP
Ọwọn epo bẹtiro wọpọ ni orilẹede Naijiria, eyi si maa n waye latari ẹkunwo epo tabi ikunsinu latọdọ awọn oṣiṣẹ elepo rọ̀bì
Owo epo to le si ni awọn kan gbagbọ pe o n mu inira ba awọn to n gbe ni orilẹede Naijiria, nitori bi owo ounjẹ, ile, owo ọkọ, ati awọn nkan mi i ṣe lewo si.
Awọn kan gbagbọ pe Aarẹ Buhari kuna ninu ẹ̀jẹ́ to jẹ lasiko ipolongo ibo pe iṣejọba oun yoo gbogun ti iwa ibajẹ ni Naijiria, ti oun yoo si fi ofin fiyajẹ awọn to ti ko owo ilu jẹ.
Lootọ ni ọwọ ajọ to n gbogun ti iwa ibajẹ ni Naijiria, EFCC, ti tẹ awọn oloṣelu kan to hu iwa ibajẹ, ṣugbọn awọn kan n koro oju si Buhari pe awọn ọmọ 'to jẹ ọ̀tá iṣakoso rẹ' nikan lo n fi igbesẹ rẹ gbogun ti.
Ẹgbẹ oṣelu alatako gboogi, Peoples Democratic Party, PDP, tilẹ n sọ pe awọn ọmọ ẹgbẹ́ awọn nikan ni Buhari doju ogun kọ, ti ko si gbe igbesẹ kan naa si ẹsun ti wọn fi kan awọn ọmọ ẹgbẹ́ All Progressives Congress to jẹ ti ẹ.
Ni ipari, ọ̀kan lara awọn olukopa, Mercy Mercy, n fẹ ki Buhari fi opin si eto isinru ilu, NYSC. O gba a nimọran pe ki ijọba maa ko owo to yẹ ki ọ̀dọ́ kọọkan o gba ninu eto isinru ilu fun un to ba ti n kẹkọ jade nileewe giga.
Oríṣun àwòrán, @NGRPresident
Awọn agunbanirọ padanu ẹmi wọn lasiko awọ̀n eto idibo kan to ti waye ni Naijiria, ati ninu awọn iṣẹlẹ mi i.
O ni wọn yoo le lo o lati fi da iṣẹ́ silẹ fun ara wọn, lati le koju iṣoro airi iṣẹ́ ṣe.
Igba akọkọ kọ niyii ti ipe lọ si ọ̀dọ̀ ijọba lati f'opin si eto isinru ilu, paapa nitori bi awọn agunbanirọ sẹ maa n padanu ẹmi wọn nibi ti wọn ti n sinru ilu.
Awọn agunbanirọ padanu ẹmi wọn lasiko awọ̀n eto idibo kan to ti waye ni Naijiria, ati ninu awọn iṣẹlẹ mi i.
Yemi Osinbajo: Ìpínlẹ̀ Ondo lè bọ́ Naijiria pẹ̀lú ohun àlùmóọ́nì rẹ̀
Oríṣun àwòrán, @RotimiAkeredolu
Kọmisọnna fún ètò ìsúná nípínlẹ̀ Ondo ní pé òkun tó jìn jùlọ ní ilẹ̀ Afirika àti bitumen wà nì ìpínlẹ̀ Ondo.
Ipinlẹ Ondo ni ohun alumọni to le bọ awọn ara orilẹede Naijiria ti wọn ba lo awọn ohun alumọni yii fun imugboro ọrọ ajẹ lorilẹede Naijria.
Kọmisọnna fun eto isuna ni ipinlẹ Ondo, Emmanuel Igbasan fi idi ọrọ yii mulẹ, lẹyin ti igbakeji aarẹ orilẹede Naijiria, Yemi Osinbajo sọ pe ipinlẹ Ondo ni ọpọlọpọ ohun alumọni kaakiri ipinlẹ naa.
Kọnisọnna Igbasan fikun ọrọ rẹ wi pe ipinlẹ Ondo ni ibudokọ okun to jin julọ ni ilẹ Afirika(largest sea port) to le gba awọn ọkọ nla nla , eyi ti o le pese ibudokọ fun awọn oko oju omi ti wọn ba n kẹru bọ lati oke okun wa si Naijiria.
Ọba Olutayọ: ìgbésẹ̀ Ọọni àti Alaafin ti ń mú ìṣọ̀kàn dé sáàrin àwọn Ọba Yorùbá
Kọmisọnna fun eto isuna ni ipinlẹ Ondo ninu ọrọ rẹ sọ wi pe aibikita lo mu ki awọn ohun alumọni to wa ni ipinlẹ Ondo ni ifasẹyin.
Ninu ọrọ rẹ, Emmanuel Igbasan fikun wi pe epo bẹntiroolu ti ijọba gbe ọkan le lo mu ki wọn fi ọwọ yẹpẹrẹ mu awọn ohun alumọni ti Ọlọrun ti fi fun ipinle naa.
O fikun wi pe nitori epo bẹntiroolu ti lọ silẹ lagbaye bayii, ijọba ti pada si ohun alumọni ati agbẹ to lere gẹgẹbi ọna lati mu ki ibugboro ba ọrọ aje Naijiria.
"Kọmisọnna naa fikun wi pe laipe si isinyii ipinlẹ Ondo yoo ma a pese ""sweet"" ati ohun ipanu awọn ọmọ ile iwe bii ""sunshine chocolate"" lati ara cocoa."
Awọn aṣofin mejidinlogun ti wọn yọ olori ile aṣofin ipinlẹ Ondo ati igbakeji rẹ, ti sa fi ipinlẹ naa silẹ.
Ohun ti awọn aṣofin naa ni o faa ti wọn fi sa kuro ni ilu Akurẹ ko ṣẹyin  bi wọn ṣe ni abo to peye ko si fun ẹmi awọn lati igba ti wọn ti yọ olori ile naa tẹtẹ nipo.
Oríṣun àwòrán, Ondostate house of assembly
Olori tuntun ti wọn ṣẹṣẹ yan fun ile naa, Ọlamide George ni ilu Ibadan ni awọn sare wa fi ara pamọ si nitori abo ẹmi wọn
Lẹyin ti awọn aṣofin naa yọ Bamidele Ọlẹyẹloogun ati igbakeji rẹ Ogundeji Iroju nipo ni awọn janduku ti iroyin sọ pe wọn jẹ ọmọ ẹgbẹ awakọ ero NURTW nilu Akurẹ ya bo ile aṣofin naa ti wọn si lu awọn aṣofin ati oṣiṣẹ ti ọwọ wọn ba.
Ninu ọrọ to ba BBC News Yoruba sọ, olori tuntun ti wọn ṣẹṣẹ yan fun ile naa, Ọlamide George ni ilu Ibadan ni awọn sare wa fi ara sinko si nitori abo ẹmi wọn.
Oríṣun àwòrán, @RotimiAkeredolu
Kọmisọnna fún ètò ìsúná nípínlẹ̀ Ondo ní pé òkun tó jìn jùlọ ní ilẹ̀ Afirika àti bitumen wà nì ìpínlẹ̀ Ondo.
A ni lati sa kuro nilu nitori ko si abo fun ẹmi wa mọ. Ẹmi mi, ẹbi mi ati awọn aṣofin ẹgbẹ mi lo wa ninu ewu, idi si niyii ti a fi fi  ilu silẹ wa fi ara pamọ si ilu Ibadan.
A si ti fi asiko yii kigbe iranwọ si aarẹ Buhari ati ọga ọlọpa lorilẹede yii lati wa gba wa silẹ.Ni ọjọ ẹti ti o kọja ni awọn aṣofin mejidinlogun ninu mẹrindinlọgbọn to wa ni ile naa dibo yọ olori ile naa ati igbakeji rẹ lori ẹsun iwa aitọ, ṣiṣe owo baṣubaṣu, ṣiṣi agbara lo ati aikun oju iwọn lẹnu iṣẹ.
Olamide George lori olori tuntun ile asofin Ondo
Aṣofin Olamide George ti wọn yan sipo lẹyin ti awọn aṣofin kan panupọ yọ olori ile aṣofin ipinlẹ Ondo nipo ti fi ẹsun kan gomina ipinlẹ naa, Rotimi Akeredolu pe o lọwọ ninu wahala ti o n waye laarin aṣofin ipinlẹ naa.
Ninu ifọrọwerọ rẹ pẹlu BBC News Yoruba, aṣofin George ni idi ti awọn aṣofin mejidinlogun fi gbe igbesẹ ati yi adari ile naa pada ko ju wi pe awọn aṣofin ipinlẹ naa ko lanfani lati ṣe ojuṣe wọn gẹgẹ bii iṣẹ ti awọn araalu fi ran wọn.
''Oúnjẹ òkèlè àti òróró le fa ẹ̀jẹ̀ rúru àti àrùn rọpárọsẹ̀''
O ni gomina Akeredolu lo ko awọn agbofinro fun olori ile ti wọn yọ, Bamidele Ọlẹyẹlogun lati pada lọ ṣi ijoko ile lẹyin ti wọn ti yọọ.
"Gomina lọwọ sii ni. Nitori a gbọ pe lẹyin ti a yọ awọn adari ile tẹlẹ kuro, a gbọ pe awọn mẹfa ko ara wọn jọ lati pada lọ joko yi ohun ti awa mejidinlogun fi ẹnu ko le lori. Ti gomina si ko agbofinro tẹle wọn. Eyi ko yẹ ko ri bẹẹ rara.
Nigba to n sọrọ siwaju, o ni irọ ni pe awọn ti ko ni anfani ati pada ni wọn n da wahala silẹ.
 Emi ti mo n sọrọ yii, mi o ra fọọmu pe mo fẹ dibo, nitorinaa ko si ẹni to lee sọ pe aini anfani ati pada si ile aṣofin lẹẹkan sii lo n faa."""
Bakan naa lo fi kun un pe bi ọrọ ṣe ri yii, ẹsẹ ofin ni awọn yoo tọ lori ọrọ naa.
Ondo Assembly: Gómìnà Akeredolu ń ti àwọn tó ń da ilé aṣòfin ìpínlẹ̀ Ondo rú-
Amọṣa, olori ile naa ti wọn yọ nipo, Bamidele Ọlọyẹloogun ni mimi kan ko mi ohun kuro lori aga olori ile naa.
Ninu ọrọ ti oun pẹlu ba BBC News Yoruba sọ, awọn aṣofin ti ọrọ kan fẹ yọ oun ati gomina ipinlẹ naa nipo ni.
"Wọn ya mi laṣọ, wọn na gbogbo awọn amugbalẹgbẹ mi. Mo si bi wọn pe ko si ijoko loni, emi nikan gẹgẹ bii olori ile nikan lo lee pe ipade ijoko ile."""
Aṣofin Ọlẹyẹloogun ni ko si ohun to jọ janduku ni ile aṣofin naa ati pe awọn agbofinro wa nikalẹ. O ni o ṣeeṣe ko jẹ ẹhonu lori awọn ẹtọ to yẹ ati bi awọn kan ko ṣe ni anfani ati dije fun ijoko ile naa ni ibo ọdun 2019 wa lara ohun ti o n fa ikunsinu wọn.
O fi kun un pe igbesẹ alaafia yoo bẹrẹ ni ọsẹ ti o nbọ lati pa ina aawọ laarin wọn.
Oríṣun àwòrán, APC Ondo
Ẹsun ti wọn fi kan awọn mejeeji ti wọn yọ nipo naa ni iwa ibajẹ lẹnu iṣẹ
Ọrọ di iṣu ata yan-an-yan-an ni ile aṣofin ipinlẹ ondo lọjọ ẹti pẹlu bi awọn aṣofin meji ṣe n pe ara wọn ni olori ile naa.
Gẹgẹ bi BBC News Yoruba ṣe gbọ, ọrọ naa bẹrẹ ni owurọ ọjọ ẹti nigba ti awọn aṣofin  mejidinlogun ninu mẹrindinlọgbọn to wa ni ile naa dibo yọ  ni ile olori ile aṣofin ipinlẹ Ondo, Bamidele Oloyelogun ati  igbakeji rẹ, Iroju Ogundeji kuro nipo.
Oloyelogun ti wọn yọ nipo wa lori ijoko ni gbogbo asiko ti ariwo ati ys loye fi n waye.
Iroyin ọhun tun fi kun un pe idarudapọ waye ninu gbọngan ile aṣofin ọhun lẹyin ti igbesẹ ati yọ olori ile naa ati igbakeji rẹ ti waye tan pẹlu bi awọn janduku kan, ti awọn ti iṣẹlẹ naa ṣoju wọn sọ pe wọn jẹ ọmọ ẹgbẹ ọlọkọ ero, NURTW ti ṣe ya wọ ile aṣofin naa ti wọn si le gbogbo awọn aṣofin atawọn oniroyin to fi mọ awọn oṣiṣẹ nile aṣofin naa da sigbo.
Koda iroyin naa fidi rẹ mulẹ pe awọn janduku naa tun ya aṣọ mọ olori ile naa tẹlẹ, Jumọkẹ Akindele lọrun lasiko ti gbogbo rukerudo yii fi waye.
Ògidì ọmọ Yorùbá gbọ́dọ̀ mọ 'áayan ògbufọ̀' dáadàa
Lẹyin eyi ni olori ile naa ti wọn ys nipo, Bamidele Oloyelogun atawọn to jẹ tirẹ ni ile aṣofin naa lọ ko ara jọ pọ ni ile rẹ nibi to ti ba awọn oniroyin sọrọ pe oun ṣi ni olori ile naa ati pe ohun ti ko lẹsẹ nlẹ ni igbesẹ naa.
Ni kete ti o pari ipade pẹlu awọn oniroyin yii ni o pada laarin ọpọ ọkọ, awọn janduku ọmọ ẹgbẹ ọlọkọ ero NURTW ati awọn oṣiṣẹ alaabo lọ si ile aṣofin naa nibi ti oun ati awọn aṣofin mẹwa ti wọn fẹ tirẹ ni ile naa tun ti gbe ijoko mira kalẹ ti wọn si yọ paṣẹ lọ rọkun nile fun awọn aṣofin marundinlogun ti wọn ni wọn fi gbogbo ara kopa ninu igbesẹ lati yọọ nipo.
Kii ṣe aṣiri to bo rara laarin agbami oṣelu nipinlẹ Ondo ati laarin awọn onwoye oṣelu nibẹ pe ọdọ gomina Rotimi Akeredolu ni olori ile aṣofin ipinlẹ Ondo, Bamidele Oloyelogun ti wọn yọ kuro nipo fi ara ti si
Eyi ni ọrọ ọpọ awọn onwoye to ba BBC News Yoruba sọrọ sọ.
Ìnú mi kìí dùn nígbà trí mo ń ṣiṣẹ́ ni bánkì tó ìgbà ti mo bẹ̀rẹ̀ mẹkáníìkì
Ni oṣu diẹ sẹyin ni wọn ti kọkọ yọ Bamidele Oloyelogun kuro ni ipo gẹgẹ bii olori ile naa ṣugbọn ti wọn ni gomina ipinlẹ naa, Rotimi Akeredolu paṣẹ ki wọn daa pada sipo.
Amọṣa ohun ti wọn ni o ṣeeṣe ko fa ti ọtẹ yii ko fẹẹ ṣẹyin bi pupọ awọn aṣofin ile naa ko ṣe ni anfani ati oreọfẹ pipada dije fun ijoko ile ni ọdun 2019 naa lasiko idibo abẹle ti ẹgbẹ oṣelu APC ṣe kọja.
Ni bayii, olori ile aṣofin ipinlẹ Ondo, Bamidele Oloyelogun ati  igbakeji rẹ, ti wọn yọ kuro nipo atawọn aṣofin mẹwa to jẹ tirẹ ti so ijoko ile aṣofin naa rọ di ọjọ miran ọjọ ire.
"Nigba ti awọn akọroyin bere idi ti o fi ti ile pa, aṣofin Oloyelogun ni ""ofin ilana ile fun oun laṣẹ lati ṣe bẹẹ."""
Oríṣun àwòrán, DailypostNigeria
"Nigba ti awọn akọroyin bere idi ti o fi ti ile pa, aṣofin Oloyelogun ni ""ofin ilana ile fun oun laṣẹ lati ṣe bẹẹ."""
Iroyin to tẹ BBC news Yoruba lọwọ ṣalaye pe nibi ijoko ile naa to waye ni ọjọ ẹti lawọn aṣofin mejidinlogun to wa nile aṣofin naa.
Nibayii, wọn ti yan Ọlamide George lati ẹkun ididbo ipinlẹ ti Akurẹ North gẹgẹ bii olori ile aṣofin naa nigba ti Abimbọla Fajolu lati ẹkun idibo Oluji/Okeigbo si bs si ipo igba keji.
Ẹsun ti wọn fi kan awọn mejeeji ti wọn yọ nipo naa ni iwa ibajẹ lẹnu iṣẹ.
Alaga igbimọ ile lori eto iroyin, aṣofin Fatai olotu ṣalaye fun awọn oniroyin lẹyin ijoko ile pe ẹsun ṣise owo baṣubaṣu, aikun oju iwsn lẹnu iṣẹ ati ẹsun miran ni wọn tun fi kan Bamidele Oloyelogun ati  igbakeji rẹ, Iroju Ogundeji ki wọn to yọọ
Tenancy: Njẹ́ o mọ ẹ̀tọ́ rẹ̀ gẹ́gẹ́ bi ayálégbé?
Wọn ti yọ olori ile aṣofin ipinlẹ Ondo, Bamidele Oloyelogun ati  igbakeji rẹ, Iroju Ogundeji kuro nipo.
Iroyin to tẹ BBC news Yoruba lọwọ ṣalaye pe nibi ijoko ile naa to waye ni ọjọ ẹti lawọn aṣofin mejidinlogun to wa nile aṣofin naa.
Iroyin ọhun tun fi kun un pe idarudapọ waye ninu gbọngan ile aṣofin ọhun lasiko ti igbesẹ ati yọ olori ile naa ati igbakeji rẹ fẹ waye.
Ni bayii, wọn ti yan Ọlamide George lati ẹkun idibo ti ariwa Akurẹ North gẹgẹ bii olori ile aṣofin naa nigba ti Abimbọla Fajolu lati ẹkun idibo Oluji / Okeigbo si ipo igba keji.
Ẹsun ti wọn fi kan awọn mejeeji ti wọn yọ nipo naa ni iwa ibajẹ lẹnu iṣẹ.
Alaga igbimọ ile lori eto iroyin, aṣofin Fatai olotu ṣalaye fun awọn oniroyin lẹyin ijoko ile pe ẹsun ṣise owo baṣubaṣu, aikun oju iwsn lẹnu iṣẹ ati ẹsun miran ni wọn tun fi kan Bamidele Oloyelogun ati  igbakeji rẹ, Iroju Ogundeji ki wọn to yọọ.
'Ó ṣojú mi kòró, ẹ wọ bí ìgbà ayé Bàbá Fagunwa ṣe rí'
Ogoni: Ṣé nǹkan ti yàtọ̀ lẹ́yìn tí Ken Saro-Wiwa fi ẹ̀mí rẹ̀ lélẹ̀?
Oríṣun àwòrán, TIM LAMBON / GREENPEACE
Awọn ogoni ko le gbagbe Ken Saro Wiwa, akoni tootọ
Ni ọjọ kọkanlelọgbọn, oṣu kẹwaa, lọdun 1995 ni ile ẹjọ ologun kan dajọ iku fun Ken Saro Wiwa atawọn akẹgbẹ rẹ mẹjọ ti wọn n ja fun irapada ayika agbegbe Ogoni lorilẹ-ede Naijiria.
Ẹsun ipaniyan ni wọn fi kan wọn, ijọba ologun nigba naa labẹ ọgagun Sani Abacha fi ẹsun kan wọn pe wọn lọwọ ninu iku awọn agba ilẹ Ogoni mẹrin kan.
Ọjọ kẹwaa, oṣu kọkanla, ọdun 1995 ni wọn pa wọn.
Ni igba aye rẹ, Ken Saro Wiwa ko jẹ ki awọn ileeṣẹ ìwapo rọ̀bì lẹkun naa o sinmi nitori awọn idibajẹ ti aibikita iṣẹ wọn n ko ba ayika nigba naa.
Titu epo si oju agbami, eleyi to n ṣe ọpọ akoba fun awọn ohun abẹmi ninu omi agbegbe naa. n mu inira nla ba awọn eeyan ibẹ nitori iṣẹ ẹja pipa ni gbajugbaja iṣẹ nibẹ.
Tony Elemelu Foundation: Gbogbo okòwò ló ní ìdojúkọ
O si da ẹgbẹ ajijagbara MOSOP lati ja fun ẹtọ ayika agbegbe Ogoni.
Bakan naa ni eyi n fa arun fun awọn eeyan agbegbe Ogoni ti wọn n mu omi bẹẹ tabi lò fún ọ̀gbìn wọn.
Ileeṣẹ ìpọnpo Shell ni Ken atawọn ajafẹtọ ilẹ Ogoni yooku na ika aleebu si julọ nigba naa.
Ni ọdun 1941 ni wọn bi Ken Saro-Wiwa, itara idagbasoke fun agbegbe Ogoni ti o mu'mu ni aya rẹ lo si faa ti wọn fi lee kuro lẹnu iṣẹ ni ipinlẹ Rivers lọdun 1973.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Saro-Wiwa da ẹgbẹ ajijagbara MOSOP lati ja fun ẹtọ ayika agbegbe Ogoni.
Lai naani oniruuru ipe ati ẹbẹ ti o waye latọdọ awọn ọmọ ilẹ Naijiria ati ni oke okun, ijọba ologun Sani Abacha pa Saro Wiwa.
Koda, alaga igbimọ awọn Oludari agba ni ileeṣẹ ipọnpo rọbi Shell nigba naa, Cor Herkstroter pẹlu fi lẹta ẹbẹ ranṣẹ si Ọgagun Sani Abacha nigba naa pẹlu.
"Ninu ọrọ kan to ba ileeṣẹ iroyin BBC kan sọ ni BBC's Newsday ni ọdun 2015, Suzanne Dhaliwato, to jẹ ọmọ ẹgbẹ ajafẹtọ kan ti a mọ si, Action Saro-Wiwa ni, ""Iwa kan naa ti ijọba hu si ẹtọ ati wi tẹnu ẹni ni ogun ọdun sẹyin ni a ṣi n ri bayii."""
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ileeṣẹ ipọnpo Shell ni Ken atawọn ajafẹtọ ilẹ Ogoni yooku na ika alebu idibajẹ ayika agbegbe Ogoni si julọ
Lẹyin iku rẹ iyatọ diẹ lo tii de ba agbegbe Ogoni lori atunṣe ati irapada ayika ibẹ. Eyi lo fa oniruuru ijijagbara to dide lẹyin rẹ bi MEND ati awọn ọdọ agbebọn ti wọn dide ki o to di pe ijọba apapọ laye aarẹ Musa Yaradua ṣeto idariji eleyi ti o mu alaafia pada si agbegbe aaringbungbun guusu orilẹ-ede Naijiria, (South-south)
Abajade iwadii kan ti ajọ iṣọkan agbaye gbe jade ni ọdun 2011 ṣalaye pe yoo fẹrẹ to ọgbọn ọdun ki agbegbe Ogoni to lee bọ lọwọ ọṣẹ ti epo rọbi ti wọn tu si ayika rẹ ṣe nibẹ.
"Ajọ UN ni ""eyi yoo nilo eto afọmọ to jinlẹ nibẹ"""
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ni ọdun 1941 ni wọn bi Ken Saro-Wiwa, itara idagbasoke fun agbegbe Ogoni lo faa ti wọn fi lee kuro lẹnu iṣẹ ni ipinlẹ Rivers lọdun 1973
Aarẹ Muhammadu Buhari ni ibẹrẹ saa iṣejọba rẹ ṣeleri eto atunṣe agbegbe naa ti igbakeji rẹ, Yẹmi Oṣinbajọ si ṣe ifilọlẹ eto naa ni oṣu kẹfa, ọdun 2016 ṣugbọn titi di bi a ṣe n sọrọ yii, ko tii si ohun kan pato ti eniyan lee ri dimu lori eto naa nibẹ.
Kii ṣe ijijagbara nikan ni Ken Saro wiwa ṣe nigba aye rẹ. Onkọwe ti gbogbo agbaye mọ ni.
Ninu ọpọ iwe rẹ, a maa gbiyanju ati ṣe afihan ohun ti oju awọn eeyan rẹ n ri nitori agbegbe wọn ti awọn to n wa epo rọbi n fi igba gbogbo bajẹ.
Lara awọn iwe ti o kọ ni: Forest of Flowers (1986).
Ìwà olè, jìbìtì àti ìjẹkújẹ ló n jé káwọn mii yí ọjọ́ orí wọn padà
DJ Cuppy: Kíni àwọn èèyàn ń sọ nípa orin rẹ̀ tuntun 'Charge Up'?
Oríṣun àwòrán, @Cuppymusic
Pẹlu ayọ ni DJ Cuppy fi n sọrọ orin rẹ tuntun lai naani èrò awọn eniyan
Gbajugbaja olorin ni DJ Cuppy, ẹni ti ọpọlọpọ n royin owó baba rẹ pe o to ọmọ naa dárà to ba wùú.
Yatọ si pe o jẹ ọmọ baba olowo, Fẹmi Ọtẹdọla, Florence Ifẹoluwa Ọtẹdọla, ti ọpọ mọ si DJ Cuppy ti lami-laaka lagbo ariya lorilẹ-ede Naijiria, ilẹ Afirika ati kaakiri agbaye.
Ni kete to gbe awo orin 'Charge Up' yii sita ti àwọn eniyan sì bẹrẹ si ni sọrọ nipa rẹ kaakiri ẹrọ ayelujara ni o ti fun orukọ ara rẹ lorukọ tuntun lataari pe awọn eniyan n ṣi orukọ rẹ pe.
Iṣẹ aforindanilaraya nibi ariya ti oyinbo n pe ni Disc Jockey (DJ) ni DJ cuppy yan laayo lẹyin to kẹkọ gboye imọ ijinlẹ Akọkọ ni ọdun 2014.
Oríṣun àwòrán, DJCUPPY
Orin naa ti pin awọn olufẹ DJ Cuppy si oniruuru ero ati esi lori boya orin naa dun tabi ko dun
Amọṣa kii ṣe tori eyi ni ẹnu ṣe n kun DJ Cuppy bayii, bikoṣe nitori awo orin tuntun to gbe jade ni ọjọ ẹti, eyi to pe akọle rẹ ni, Charged UP.
Tony Elemelu Foundation: Gbogbo okòwò ló ní ìdojúkọ
Ọrọ ti awọn eeyan n sọ nipa rẹ kọja ohun ti gbajugbaju aforindanilaraya nibi ariya naa n reti nitori pupọ awọn eeyan ni wọn ti tabuku orin naa.
Oríṣun àwòrán, @cuppymusic
Ohun ti o ba wù ni lo lè gbiyanju ẹ nigba to ba wu eeyan
Amọṣa, awọn kan pẹlu luu l'ọgọ ẹnu fun iṣẹ ọpọlọ naa.
Oríṣun àwòrán, DJ Cuppy
Ọmọ baba olowo, Fẹmi Ọtẹdọla ni DJ Cuppy
#Oshimole: Àwọn aṣáájú APC kò mọ ohun ti wọ́n n ṣe lásìkò yí
Man City lékè tábílì Premier League, Liverpool na Fulham
Oríṣun àwòrán, Getty Images
David Silva ti gbá Manchester City jẹ bọ́ọ́lù mẹ́rin nínú ìfesẹ̀wọnsẹ̀ máárùn tó kojá.
Ẹgbẹ́ agbábọ́ọ́lù Manchester ti padà sí òkè tábìlì ìdíje líígi ilẹ̀ Gẹ̀ẹ́sì lẹ́yìn ìgbà tí wọ́n na Manchester United pẹ̀lú àmì ayò mẹ́ta sí ọ̀kan.
Ẹ̀sì ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ náà sọ àmì ayò Manchester City di mẹ́jìlélọ́gbọ̀n (32) lóríi tábílì.
Liverpool, tó na Fulham pẹ̀lú àmì ayò mẹ́jì sí òdo, sì ń tẹ̀lé City lóríi tábìlì pẹ̀lú ọgbọ̀ (30) àmì ayò.
Chelsea tó gbá ọ̀mì ọ̀dọ sọ́dọ pẹ̀lú Everton sì ń gba tẹ̀lé Liverpool lóríi yábìlì pẹ̀lú àmì ayò mẹ́jìdínlọ́gbọ̀n (28).
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Bọ́ọ́lù àkọ́kọ́ tí Mohamed Salah jẹ Fulham ni ẹ̀kẹẹ̀fà tó jẹ nínú ìdíjẹ líígì ọdún yìí
David Silva lọ́ kọ́kọ́ bá City jẹ bọ́ọ́lú ní ìṣẹ́jú mẹ́jìlá sí ìgbà tí wọ́n bẹ̀rẹ̀ eré.
Nígbà tí eré di ìṣẹ́jú mẹ́jìdínláàádọta ni Sergio Aguero bá tún gba bọ́ọ́lù sínú àwọ̀n Manchester United.
Sùgbọ́n ìyànjú United láti gbẹ̀san jẹ́kí Anthony Martial gbá bọ́ọ́lù sínú àwọ̀n City lẹ́yìn ìṣẹ́jú mẹ́jìdínlọ́gọ́ta tí wọ́n bẹ̀rẹ̀ eré.
Àmọ́sá Gündogan tún fi kúnun fún Man United nígbà tí eré kuu ìṣẹ́jú mẹ́jì.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Chelsea kò tíì pàdánù ìfẹ́sẹ̀wọsẹ̀ kankan nínú ìdíjẹ líígì ọdún yìí
Ìròyìn òfégè: ìwádìí lórí ayédèrú ìròyìn l'Afirika fún ọdún kan
Àwòrán ayé
Titan kalẹ iroyin ayederu nilẹ Afirika ni awọn kan ti sọ pe o n fa ija ẹlẹyamẹya ati rukerudo laarin awọn oludibo, bẹẹni o n ṣe akoba fun bi owo ṣe lọ soke ti o nlọ silẹ
Ile iṣẹ iroyin BBC ṣe iwadi lori iroyin ayederu marun un to ni ipa nla nilẹ Afirika ni ọdun kan ṣeyin.
1. Ẹgbẹ ololufẹ ọkunrin s'ọkunrin fọwọ si oludije ipo aarẹ
Kinni iroyin naa?
Lẹyin ti wọn kede Atiku Abubakar gẹgẹ bi oludije fun ipo aarẹ ninu idibo ọdun 2019, ayederu opo Twitter kan lorukọ olori ẹgbẹ alatako fi ọrọ kan lede ti o fi ki ẹgbẹ awọn ololufẹ ọkunrin s'ọkunrin fun atilẹyin wọn.
Ninu iroyin naa, ''Ọgbẹni Abubakar'' sọ pe ohun akọkọ ti oun yoo ṣe nigba t'oun ba di aarẹ ni pe oun yoo wọgi le ofin ti ko gba ki ọkunrin ati ọkunrin ẹgbẹ rẹ fẹ ara wọn eyi ti aarẹ ana, Goodluck Jonathan bọwọ lu lọdun 2014.
Fifi ifẹ han laarin ọkunrin kan si omiran lodi sofin orilẹede Naijiria, koda ẹwọn ọdun mẹrinla ni ẹni ti ọwọ ba tẹ yoo fi gbara, bẹẹni igbeyawo ọkunrin s'ọkunrin naa lodi si ofin.
Iru ipa wo ni iroyin yii ni?
Oríṣun àwòrán, The Nation
Aworan iroyin ayederu lori opo ayelujara kan
Lẹyin ti awọn eeyan ti pin iroyin yii loju opo Twitter lọjọ kẹrinla osun Kẹwaa, awọn iwe iroyin ayelujara meji ba gbe iroyin ọhun. Lẹyin bi ọjọ mejila, gbajugbaja iwe iroyin meji The Nation ati Vanguard naa fi iroyin ti akori rẹ jọ iroyin yii sita.
Wọn sọ ninu iroyin naa pe ẹgbẹ awọn ololufẹ ọkunrin s'ọkunrin kan ti orukọ rẹ n jẹ ''Diverse'' n ṣatilẹyin fun Atiku Abubakar fun ipo aarẹ. Wọn ni ti gbogbo eeyan lo n ṣe.
Iroyin ofege nipa oludije fun ipo aarẹ to n ṣatilẹyin fun ololufẹ ọkunrin s'ọkunrin le fa wọn ṣeyin.  Bakan naa, awọn olori ẹsin kristẹni ati musulumi le sọ fun awọn ọmọ lẹyin wọn lati maa dibo fun iru oludije bẹẹ.
Bawo ni a ṣe le mọ iroyin ayederu?
Orisun iroyin yii kii ṣe lati oju opo oloṣelu Atiku Abubakar fun ra rẹ. Oju opo rẹ 'his real account' to ni ami idamọ alawọ buluu.
Fake news is often published on legitimate-looking websites
Ko si ẹri lati fihan pe ọrọ awọn ẹgbẹ ololufẹ  ọkunrin s'ọkunrin wa iroyin to tan kalẹ kaakiri ayelujara. Bẹẹ ni ko si akọsilẹ fun ẹgbẹ ololufẹ  ọkunrin s'ọkunrin.
Ati pe at'awọn ati agbẹnusọ fun wọn (Spinky Victor Lee), ko si ẹni to ri wọn ri lori ayelujara ko to digba ti iroyin ọhun jade lori Twitter ninu oṣu kẹwaa gẹgẹ bi iwaadi ile isẹ iroyin AFP
2. Awọn ilumọka oniroyin lorilẹede Kenya meji pin iroyin ayederu
Kinni iroyin naa?
Oniroyin ọrọ aje fun ile iṣẹ iroyin CNN Richard Quest lọ si olu ilu Kenya, Nairobi ninu oṣu kẹwaa fun eto rẹ lori ẹrọ amohunmaworan.
Akaroyin tẹlẹ ri Julie Gichuru fi iroyin kan lede lori opo Twitter rẹ lọjọ karundinlọgbọn oṣu kẹwa ki awọn eeyan jiroro lori bi Ọgbẹni Quest ṣe n gbadun ara rẹ ni Kenya.
Wọnyi ni awọn iroyin to fi lede, to si sọ pe lati ọdọ Ọgbẹni Quest lo ti wa:
''Kosi ohun to dabi ile iṣẹ itura ni Kenya..awọn agunfọn yi mi ka nibi ti mo ti jẹun aarọ mi bayii! Ni orilẹede ti banki agbaye sọ pe ibẹ ni o dara lati dokowo nilẹ Afirika. ki lotun ku ti mo n fẹ? Ajẹ bi idan ni orilẹede Kenya!''
Oríṣun àwòrán, Twitter
Iru ipa wo ni iroyin yii ni?
Awọn eeyan bi miliọnu kan ni wọn n tẹle Julie lori Twitter , bẹẹ ni awọn bi ẹgbẹta lo n tẹle e lori Instagram, laarin iṣẹju akan ẹgbẹgbẹrun eeyan lo ti ri iroyin naa ti wọn si gbagbọ ọtitọ ni.
Ọpọ tiẹ fi ṣe yẹyẹ fun aṣiṣe rẹ papaa julọ pẹlu iriri rẹ ninu iṣẹ iriyin.
Djibouti and Somalia.
Oniroyin CNN fesi si iroyin ti Julie fi lede lori Twitter pe oun o sọ ohun to jọ bẹẹ.
Gichuru ni lati lọ tọrọ aforiji lori Twitter lọwọ awọn alatẹle rẹ, bẹẹ lo yọ iroyin naa kuro.
3. Wọn 'ti awọn ọmọ orilẹede Somalia inu iboji' ni Ethiopia
Kinni iroyin naa?
Ninu oṣu Keje, ile iṣẹ amohunmaworan kan to wa ni orilẹede Amẹrika(ESAT) gbe fidio kan jade to ṣafihan bi wọn ti n ti awọn Oromos ni Ethiopia sinu iboji ti ko jin.
Ile iṣẹ iroyin naa ni ẹkun Oromia ni orilẹede Ethiopia ni wọn ti ya fidio naa nibi ti ikolu lile ti n waye laarin ẹgbẹ meji ninu ọdun yii.
Iru ipa wo ni iroyin yii ni?
Oríṣun àwòrán, YouTube
Fidio yii fihan bi wọn ti n ti oku eeyan sinu koto
BBC Afaan Oromo gbe iroyin kan jade pe itankalẹ fidio naa ṣe okunfa ikọlu awọn ẹya Oromo ti wọn n gbe ni orilẹede Djibouti ati Somalia.
Awọn atipo ẹya Oromo ti wọn wa ni Djibouti sọ fun BBC pe wọn na awọn, bẹẹni wọn ja awọn lole nitori fidio ọhun.
Bawo ni a ṣe le mọ iroyin ayederu?
Ayederu fidio yii kan naa ni wọn pin ninu oṣu kẹfa lori ayelujara ti wọn ni pe o nii ṣe pẹlu aawọ to n lọ lwọ laarin apa orilẹede Cameroon to n sọ ede oyinbo ati ijọba nibi maili to din diẹ ni ẹgbẹrun meji lapa iwọ oorun Ethiopia.
Ẹda fidio naa ti ileeṣẹ mohunmaworan ESAT TV fi han lai ṣe ayẹwo boya otitọ ni tabi ayederu, jẹ eyi ti wọn ti tọwọ bọ ti wọn si gbe agbasilẹ ohun awọn eeyan kan ti wọn pe ni awọn ọdọ ẹya Oromo ti wọn n pariwo le ori ohun tootọ to ba fidio naa jade.
Ni kete ti ESAT rii pe ayederu ni fidio naa ni wọn ti yọọ kuro lori afẹfẹ wọn ti wọn si tọrọ aforiji ni ori ikanni Youtube wọn.
Ko si ẹni n sọ pe mohunmaworan ESAT TV dọgbọn si fidio yii tabi pe wọn mọọmọ gbe e sori afẹfẹ pẹlupẹlu pe wn mọ pe ayederu ni.
Atunṣe ọjọ kẹtalelogun oṣu kọkanla: A ti ṣe atunṣe lori akọsil iroyin yii lati lee jẹki o di mim pe ESAT TV ko mọ nipa didọgbọn si fidio naa, tabi wọn mọọmọ gbe ayederu rẹ si ori afẹfẹ.
4.'Ikọwe-fiposilẹ' Aarẹ South Africa acob Zuma
Kinni iroyin naa?
Lọjọ kejila oṣu keji, akọroyin fun ile iṣẹ iroyin SABC lorilẹede South Africa sọ pe Aarẹ igba na Jacob Zuma ti gba lati kọwe fipo silẹ.
Tshepo Ikaneng lo firoyin naa lede nigba ti o n jabọ iroyin yajoyajo nibi ti ko jina si bi ti awọn ọmọ African National Congress ti n ṣepade ọjọ iwaju Aarẹ Zuma.
Oniroyin ọmọ orilẹede South Africa miran firoyin ọhun lede lori opo Twitter
Wọn ti onirururu ẹsun iwa ibajẹ kan Ọgbẹni Zuma ti awọn ti ẹ ti n ṣo fun pe ko kọwe fipo silẹ.
Orilelẹede South Africa ti n reti ikọwe fiposilẹ rẹ.
Iru ipa wo ni iroyin yii ni?
Owo orilẹede naa Rand to ti gberu si lẹyin tawọn eeyan gbọ pe Aarẹ Zuma yoo kọwe fipo silẹ lọjọ kejila oṣu keji ja walẹ nigba ti agbẹnusọ ijọba sọ pe irọ ni iroyin SABC.
Ṣe a mọ pe ayederu iroyin ni?
Agbénusọ fun Aarẹ Zuma naa sọrọ pe ayederu iroyin ni.
Ṣugbọn lẹyin ọjọ mẹta, Zuma pada kọwe fipo sile ni tootọ.
5. Olori orilẹede Tanzania faramọ nini ju'yawo kan lọ lati fopin agbere
Oríṣun àwòrán, Zambian Observer
Kinni iroyin naa?
Iroyin kan to sọ pe Aarẹ orilẹede Tanzania John Magufuli sọ fun awọn ọkunrin lati fẹ ju iyawo kan lọ lati dena iwa agbere lu ayelujara pa.
Iroyin naa sọ pe aarẹ sọrọ niwaju awọn ọkunrin bi ẹgbẹrun mẹrinla, nibi to ti sọ fun pe obinrin bi aadọrin miliọnu lo wa lorilẹede naa ti awọn ọkunrin kosi ju ọgbọn miliọnu lọ.
Ọwọn ọkunrin yii lo n fa agbere papa laarin awọn obinrin, iroyin naa ni Aarẹ lo sọ bẹẹ.
Iru ipa wo ni iroyin yii ni?
Iroyin ti wọn kọkọ gbe sita ni ede oyinbo loṣu keji ọdun kọ lo da wahala silẹ.
Ṣugbọn nigba ti wọn wa gbe sita ni ede Swahili to jẹ ede apapọ Tanzania lori opo ayelujara nipasheonline.com ni ọpọ eeyan bẹrẹ si ni maa kaa.
Lati bẹ ni o ti de ori gbajugbaja opo ayelujara JamiiForums nibi ti o ti wa gbona fẹlifẹli ti o si tan ka de Kenya, South Africa, ati Ghana.
Bawo ni a ṣe mọ pe ayederu iroyin ni?
Agbẹnusọ fun ijọba orilẹede Tanzania sọrọ lori opo Twitter pe Aarẹ ko sọ ohun to jọ bẹ rara.
Bakan naa, iṣẹ iwadii BBC Swahili tun fi han pe kosi otitọ ninu iroyin ọhun.
Ninu iroyin ayederu naa, ''Aarẹ Magufuli'' sọ nipa aadọrin eeyan to wa ni orilẹede Tanzania ti awọn obinrin si miliọnu mẹwa ju awọn ọkunrin lọ
Ṣugbọn ajọ iṣọkan sọ pe eeyan to wa lorilẹede Tanzania ko ju ọgọta miliọnu lọ, bẹẹ kosi iyatọ to pọ ninu iye ọkunrin ati obinrin
Oju ayelujara ti iroyin ayederu naa ti jade le dabi gbajugbaja iwe iroyin Nipashe ni Tanzania.
Ṣugbọn ko ni nkankan ṣe pẹlu opo ayelujara fun iwe iroyin naa ti oju opo gangan jẹ https://www.ippmedia.com/sw/nipashe.
Iroyin yii jẹ ọkan lara awọn ofege ti BBC n la awọn eeyan lọyẹ lori rẹ- iṣoro lagbaye ti o doju kọ bi a ti n pin iroyin, ti a ṣe n gbọ layika wa.
Lati ka si nipa iṣẹ iwadi yii , lọ si opo ayelujara yii www.bbc.co.uk/fakenews
Ìwádìí ilé aṣòfin foríṣánpọ́n lórí ẹ̀sùn Gómìnà Ganduje
Oríṣun àwòrán, DWasiu
Alaga igbimọ ẹlẹni meje nile aṣofin ipinlẹ Kano to n ṣewadi Gomina Abdullahi Ganduje sọ pe awọn ti dawọ iṣẹ duro na lori ọrọ rẹ.
Aṣofin Baffa Dan Agundi sọ fun BBC pe ko tọ si awọn lati ṣaigbọran si aṣẹ ti ile ẹjọ pa pe ki wọn jawọ ninu iwadi naa patapata.
"O ṣalaye pe ""a ko le ṣe ohunkohun lori ẹsun owo ẹyin gbigba ti 'wọn fi kan gomina Ganduje' mọ ayafi ti ile ẹjọ ba pada gba wa laaye""."
Awọn eniyan kan ni ipinlẹ Kano n fura pe o ṣeeṣe ki ẹgbẹ to gbe ọrọ lọ sile ẹjọ lati da awọn aṣofin lọwọ kọ, jẹ awọn oloṣelu lo n fun wọn ni owo lati le da iṣẹ iwadi naa ru.
'Kò si ẹ̀ri fún ìbò ọmọ kékèké ni Kano'
Buhari gbọ́dọ̀ bẹ̀rẹ̀ ìwádìí Ganduje láàrín ọjọ́ mẹ́rìnlá-SERAP
Ọsẹ yii lo yẹ ki iṣẹ iwadii ti igbimọ naa n ṣe wa s'opin, ki ile aṣofin to wa sọ eero rẹ lorii boya Gomina Ganduje jẹbi tabi ko jẹbi.
Ṣaaju asiko yii ni ọkunrin kan, Muhammad Zubair ati ẹgbẹ kan ti wọn pe ni Lawyers for Sustainable Democratization of Nigeria, gbe ọrọ lọ sile ẹjọ pe awọn aṣofin ọhun ko gbọdọ ṣewadi Ganduje.
Ọjọ kẹẹdogun, oṣu Kẹwa, ni ile aṣofin ipinlẹ naa gbe igbimọ ẹlẹni meje kalẹ lati ṣewadii awọn fidio kan to fihan pe Gomina Ganduje n gba owo ẹyin lọwọ awọn kọngila.
Akeredolu: Àwọn akọ̀ròyìn tó fẹ́ sọ ilé ìjọba di ilé ọtí àti tẹ́tẹ́ ni mo lé dànù
Oríṣun àwòrán, @RotimiAkeredolu
Ni ọjọ Aje ni ijọba ipinlẹ Ondo kede pe wọn ti le awọn akọroyin ileeṣẹ meji kan kuro ni ọfiisi gomina ipinlẹ naa
Lẹyin ti iroyin tan kalẹ pe o le awọn akọroyin ileeṣẹ iroyin kan kuro ni ile ijọba ni ilu Akurẹ, gomina ipinlẹ Ondo, Rotimi Akeredolu ti ṣalaye pe awọn akọroyin to fẹ sọ ile ijọba di ile ọti ati tẹtẹ ni oun gbọn yọ kuro ni ibudo awọn akọroyin ijọba to wa ni sẹkitariati ijọba ipinlẹ naa ni ilu Akurẹ.
"Ninu atẹjade kan ti Kọmiṣọna fun eto iroyin, Yẹmi Owolabi fi sita ni ọjọ Iṣẹgun, igbesẹ ti ijọba gbe wa ""lati le awọn alatẹnujẹ ati awọn ti ko tọ ti wọn n pe ara wọn ni oniroyin kuro ni ile ijọba ni."""
"Ninu atẹjade naa, o ni awọn oniroyin ti wọn le ni awọn ti o fẹ sọ ""yara iroyin to wa ni ofiisi gomina di ile ọti ati ile tẹtẹ pẹlu ibuba awọn abanilorukọ jẹ gbogbo."""
O ni lootọ iroyin ti n lọ kaakiri ori ayelujara pe ijọba ipinlẹ naa ti di ọna mọ awọn akọroyin kan lati maa le ṣe iṣẹ wọn, ṣugbọn ohun to ṣẹlẹ ni pe awọn oniroyin ti ko mọ iṣẹ wọn ni iṣẹ ni awọn le kuro ni ile.
'Olórí ìjọ wa kò fẹ́ràn Daddy Freeze'
Amọṣa iwadi ti BBC News Yoruba ṣe pẹlu awọn akọroyin kan to n ṣiṣẹ ni ipinlẹ ondo fidi rẹ mulẹ pe awọn akọroyin yii ko tilẹ ki n mu ọti de ibi ti wọn yoo tilẹ maa mu amupara.
Awọn ileeṣẹ akọroyin ti ọrọ kan, Channels Television ati AIT, ko tii sọ ohunkohun lori ẹsun naa.
Diabetes - Kí ló ń fa àìsàn ìtọ̀ súgà?
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Aisan itọ ṣuga jẹ odu lawujọ ọmọniyan lagbaye
Aisan itọ ṣuga jẹ odu lawujọ ọmọniyan lagbaye; yala laaarin mẹkunu tabi ọtọkulu, olowo tabi talaka.
Aisan itọ ṣuga eyi ti oloyinbo mọ si Diabetes jẹ aisan ti o lagbara pupọ ti o si jẹ aisan ọlọjọ pipẹ eleyi ti o nii ṣe pẹlu iye eroja adun ṣuga ti o wa ninu ẹjẹ eniyan nipasẹ eroja gulukoosi ninu agọ ara.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ida aadọrun ninu ọgọrun awọn to ni aisan itọ ṣuga ni wọn wa ni aarin ọmọ ogoji si ọgọta ọdun
Irufẹ aisan itọ ṣuga mẹrin lo wa; ṣugbọn Ninu ọrọ to ba BBC News Yoruba sọ, oniṣegun oyinbo kan, Dokita Ọlamoyegun ṣalaye pe meji ninu wọn ni o jẹ ilu mọọka.
'Olórí ìjọ wa kò fẹ́ràn Daddy Freeze'
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Awọn ohun ti eniyan njẹ tabi mu pẹlu lee fa aisan itọ ṣuga
Oniruru ni ohun to lee fa itọ ṣuga. Lara ohun ti awọn onimọ bii Dokita Ọlamoyegun ati ajọ eto ilera agbaye fi sita ni ajogunba eleyi ti o lee waye bi ẹnikẹni ninu ẹbi eniyan bẹẹ ba ni.
Njẹ ọ mọ̀ pé mímí afẹ́fẹ́ tí kò dára lè fa àìsàn?
Kí ni àìsàn ìtọ̀ ṣúgà àti ọ̀nà tí o leè gbà dènà rẹ̀?
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Aisan itọ ṣuga lee fa aisan ọkan, rọpa-rọsẹ, ifọju, idakureku kidirin tabi gige ẹsẹ
Aisan bẹmi dije to lagbara ni itọ ṣuga jẹ ti o si n gba ẹmi awọn eeyan to le ni miliọnu kan ni ọdọọdun- ko si ẹni ti ko lee ni aisan yii.
Aisan yii maa n waye nigba ti agọ ara ko ba lee ṣe atupalẹ ati amulo awọn aadun ṣuga ninu ẹjẹ; o lee fa aisan ọkan, rọpa-rọsẹ, ifọju, idakureku kidirin tabi gige ẹsẹ.
Aisan yii n fi ojojumọ gbilẹ sii ni- Nnkan bii okooleni irinwo o le meji ni awọn ọdọ to ni aisan itọ ṣuga lagbaye, gẹgẹ bi ajọ ilera lagbaye, WHO ṣe sọ ọ.
Pẹlu bi ọrọ ṣe ri yii, ilaji awọn eeyan to ni aisan yii gan ni wọn mọ wi pe awọn nii.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Aisan yii n fi ojojumọ gbilẹ sii ni
Bi a ba jẹun, agọ ara wa yoo ṣe atupalẹ rẹ si elo ṣuga fun ara. Eroja ara kan ti o n jẹ insulin eleyi ti o njade lati inu oronro ni yoo ṣeto bi agọ ara wa yoo ṣe loo fun alekun agbara.
Aworan bi arun itọ suga ṣe gbilẹ nilẹ Afirika
Amọṣa bi eroja ara ti a n pe ni insulin yii ba kuna tabi ko ṣiṣẹ bi o ti tọ, eyi yoo maa fa akojọpọ aadun ṣuga ni inu ẹjẹ.
Awọn obinrin miiran to loyun pẹlu a maa ni aisan yii. Itọ ṣuga alaboyun, gestational diabetes ni a n pe eyi. A maa waye nigba ti ara alaboyun ko ba lee se eroja insulin ti o to fun alaboyun ati ọmọ inu rẹ.
Awọn miiran wa ti wọn lee ni aisan ti o n tọka si itọ ṣuga. Ko tii di itọ ṣuga o, ṣugbọn o ṣi n tọka si i ni, o si lee sun kẹẹrẹ di itọ ṣuga to ba ya.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Aisan itọ ṣuga nii ṣe pẹlu ajogunba ati awọn ohun ti o n ṣẹlẹ ni ayika ṣugbọn o lee mojuto iye aadun ṣuga ti n bẹ ninu ẹjẹ rẹ nipa ṣiṣọ jijẹ ati mimu rẹ
Pupọ awọn ami ti o n fi  aisan ṣuga han naa ni:
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Aadun ṣuga a maa fa alekun ṣuga ni agọ ara
Aisan itọ ṣuga nii ṣe pẹlu ajogunba ati awọn ohun ti o n ṣẹlẹ ni ayika ṣugbọn o lee mojuto iye aadun ṣuga ti n bẹ ninu ẹjẹ rẹ nipa ṣiṣọ jijẹ ati mimu rẹ pẹlu irufẹ igbe aye ti o n gbe.
Yiyẹra fun awọn ounjẹ ati ohun mimu aladun ṣuga.
Apẹẹrẹ bii iyẹfun funfun, burẹdi funfun, irẹsi funfun, ounjẹ aladun ṣuga.
Ayajọ fifi opin si arun atọgbẹ
Awọn ounjẹ bii ẹfọ, eso, ẹwa dara fun jijẹ
Ere idaraya lasiko pẹlu a maa ṣe ọpọ iṣẹ lati din iye adun ṣuga ninu ẹjẹ ku.
Bakan naa ni o dara lati yẹra fun siga mimu ati awọn ounjẹ ọlọra nitori aisan ọkan.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ilaaji awọn eeyan to ni aisan yii gan ni wọn mọ wi pe awọn nii
Gẹgẹ bii ajọ ilera agbaye , WHO ṣe sọ, iye awọn eeyan to ni aisan itọ ṣuga ti goke lati ọgọrun miliọnu o le mẹjọ (108milion) ni ọdun 1980, iyẹn ọdun mejidinlogoji sẹyin si okooleni irinwo o le meji mílíọ̀nu ni ọdun mẹrin sẹyin, (2014)
Ni ọdun 1980, o din ni ida marun un ninu ọgọrun awọn ọdọ ti ọjọ ori wọn le ni mejidinlogun ti wọn ni aisan itọ ṣuga lagbaye, eyi ti goke si ida mẹjọ abọ ninu ọgọrun (8.5%)
Ilaaji awọn eeyan to ni aisan yii gan ni wọn mọ wi pe awọn nii
Ajọ to mbojuto ọrọ itọ ṣuga lagbaye, The International Diabetes Federation, ni nnkan bi ida ọgọrin ninu ọgọrun, (80%) awọn ọdọ ti o ni aisan yii ni wọn jẹ ọdọ langba ti wọn si wa lati awọn orilẹede ti ko ri ọwọ họ ori lagbaye nibi ti atijẹ ati mu ko tii dan mọran to.
Àtúndì ìbò Kwara: Raheem Ọlawuyi ní èsì ìbò náà jẹ́ àseyọrí ire tó ń bọ̀
Oríṣun àwòrán, Olawuyi Facebook
Raheem Ọlawuyi, to jawe olubori ninu atundi ibo si Ile Asojusofin lẹkun idibo Ekiti/Irepodun/Isin/Oke-Ero ni ipinlẹ Kwar, ti kede pe awọn eeyan ipinlẹ Kwara ti se oriire nitori bi wọn se dibo yan oun.
Ọlawuyi sọ eyi lasiko to n fesi si abajade idibo ti Ajọ INEC ti kede rẹ gẹgẹbi ẹni to jawe olubori ninu atundi ibo naa.
Ìfipábánilòpọ̀: Abiamọ bú sẹ́kún nígbà tí ọkùnrin kan fi tipá bá ọmọ méjì lòpọ̀
O ni, bi oun se moke ninu atundi ibo naa jẹ aseyori to n bọ lọpọ fawọn eeyan ipinlẹ naa.
Ẹgbẹ oselu PDP ti ni, oun ko gba esi idibo ti Ajọ Eleto idibo lorilẹede Naijiria, INEC gbe jade, lẹyin ti wọn kede Raheem Olawuyi ti ẹgbẹ oselu APC, gẹgẹbi ẹni to jawe olubori ninu atundi ibo si ile asojusofin lẹkun idibo Ekiti/Irepodun/Isin/Oke-Ero ni ipinlẹ Kwara.
Alaga ẹgbẹ oselu PDP ni ipinlẹ Kwara, Kola Shittu, lasiko to n ba BBC Yoruba sọrọ ni, ẹgbẹ PDP ti setan lati kọ esi idibo naa, amọ awọn si n duro ki INEC fi akọọlẹ akojọpọ esi ibo naa ransẹ si awọn.
Shittu ni, gbogbo ohun ti ko yẹ ko sẹlẹ lo waye lasiko idibo naa, ati wi pe, awọn ọlọpaa fi panpẹ ọba mu awọn ẹgbẹ oselu PDP ki idibo to bẹrẹ rara, tawọn ọlọpaa si n sa wọn kaakiri.
Ko si ọmọ ẹgbẹ APC kankan ti ọlọpa gbe lasiko ibo naa, amọ se ni wọn n dunkoko mọ awọn asaaaju ẹgbẹ PDP lasaiko atundi ibo naa.
Shittu ni nigba ti ilẹ ọjọ Aiku yoo ba fi su, ẹgbẹ oselu PDP yoo kede erongba rẹ fun araye gbọ nipa esi ibo naa.
O tun fẹsun kan ẹgbẹ oselu APC wi pe, wọn lo ọkọ baalu lati fi dẹruba awọn eniyan lasiko ti wọn n dibo, eleyii ti wọn ni pe, ko fun wọn laaye lati dibo pẹlu irọrun.
Amọ, igbiyanju lati kan si ẹgbẹ oselu APC lati fesi si ẹsun naa jasi pabo.
Ajọ Eleto idibo lorilẹede Naijiria, INEC ti kede Raheem Olawuyi ti ẹgbẹ oselu APC, gẹgẹbi ẹni to jawe olubori ninu atundi ibo si ipo asojusofin lẹkun idibo Ekiti/Irepodun/Isin/Oke-Ero ni ipinlẹ Kwara.
Asoju Ajọ INEC ninu eto idibo ni ipinlẹ Kwara, Ọjọgbọn Abimbola Adesoji, lasiko to n kede esi ibo naa ni, Olawuyi jawe olubori pẹlu ibo ẹgbẹrun lọna mọkanlelelogun ati ojilerugbadinmẹrin(21,236), nigba ti oludije fun ẹgbẹ oselu PDP ni ibo ẹgbẹrun lọna mejidinlogun ati marundinlọgọrun(18,095).
Ẹgbẹ Oselu Labour Party ni ibo aadọjọ( 150), ti ẹgbe oselu Peoples Party of Nigeria (PPN) ni ibo mẹrindinlọgọrin(76) ti UPN si ni ibo mejilelogoji(42).
Ọjọgbọn Adesoji ni, ninu gbogbo ibo ẹgbẹrun lọna ogoji ati ojilelẹẹdẹgbẹrun o din mẹwa (40, 930) ti wọn di, ẹgbẹrun lọna mọkandinlogoji ati ẹgbẹta din ẹyọ kan (39,599) lo jẹ ibo to yanju ninu rẹ, nigbati ibo ojilelẹẹdegbeje o din mẹsan (1,331) si jẹ asadanu.
Atúndì ibo bere ni láwọn ìjọba ìbílẹ̀ Kwara
Iroyin to n tẹ wa lọwọ ti fidi rẹ mulẹ pe ibo kika ti bẹrẹ lawọn agọ idibo gbogbo to wa ni ẹkun idibo Irẹpọdun, Isin Ekiti àti Oke Ẹrọ, nibi ti atundi ti n waye lọjọ Satide.
Aago meji ọsan ni eto idibo naa pari, ti ohun gbogbo si lọ leto-leto bi o tilẹ jẹpe iroyin kan ti a ko lee fidi rẹ mulẹ sọ pe, awọn janduku oloselu kan si ja apoti idibo gba lawọn agọ idibo kan lẹkun idibo ọhun.
Ayàwòrán Obama: Ọ̀pọ̀ ìgbà ni èmi àti ìyá mi pa èbi mọ́nú kí n tó jẹ́ èèyàn
Wayi o, ẹgbẹ oselu APC ni ipinlẹ Kwara ti kede pe, ko si ootọ kankan ninu iroyin kan to gbode wi pe, ọmọ ẹgbẹ awọn kan n ṣe fakinfa pẹlu awọn ọ̀dọ́ nílùú Ekan meje ní ìjọba ìbílẹ̀ Oke-Ero, lasiko ti idibo atundi n waye nibẹ lọjọ Satide.
Charles Folayan, to jẹ ọkan lara awọn ọmọ ẹgbẹ APC lo salaye ọrọ yi fun BBC ninu ifọrọwanilẹnuwọ kan.
Folayan ni, lootọ ni wi pe Abdulfatah Yahaya Seriki Gambari, lo wa ninu awọran naa ṣugbọn wọn ko ya aworan naa ni ibudo idibo to wa ni ilu Ẹkan meje.
Oríṣun àwòrán, Kwara APC Information Center
Aṣọ ti Fatai Seriki wọ ninu awọ́rna yi ti Charles Folayan fi ṣọwọ si BBC yato si eyi to wa ninu aworan ti tẹlẹ
''Ni Ẹkan ni mo ti dibo mi, mi o si gburo nkankan nibẹ. Aworan igba ti Abdulfatah Yahaya Seriki Gambari, n ṣe ipolongo gẹgẹ bi oludije fun ipo Gomina labẹ asia ẹgbẹ APC, ni awọn ọbayejẹ eeyan fi sita''
O ni ọtọ ni aṣọ ti Abdulfatah Yahaya Seriki Gambari w,ọ ko si wa lati ṣe madaru kankan nibi idibo toni.
Ẹwẹ, ẹka to n risi ọrọ Iroyin nipa ẹgbẹ APC loju opo Facebook wọn ti fi ikede sita wi pe, ko si ootọ ninu iroyin kan to ni pe awọn ọdọ koju oro si Yahaya Seriki.
Oríṣun àwòrán, Kwara APC Information Center
APC ni ayederu aworan ni awọn alatako fi sita nipa Yahaya Seriki
Saaju ni iroyin ti gbode lori ẹrọ ayelujara wi pe awọn ọ̀dọ́ nílùú Ekan meje ní ìjọba ìbílẹ̀ Oke-Ero, tí kọjú ìjà sí ọkan nínú àwọn oludije tẹlẹ tó feròngba han láti díje dupò gómìnà ninu ẹgbẹ APC nipinlẹ Kwara, Abdulfatah Yahaya Seriki Gambari, tí ìjọba ìbílẹ ìlà-oòrùn Ilorin.
Wọn fẹ̀sùn kàn pé o ń fí owó ra ìbò àwọn ará ìlú.
Nigba to n fidi isẹlẹ yii mulẹ, Oludamọran agba feto iroyin si gomina ipinlẹ Kwara, Muideen Akorede ni, se ni awọn ọ̀dọ̀ náà ń pariwo Gambari pé kó fi ìlú àwọn sílẹ̀ nítori kò sí ìdí tó fi yẹ kó wà nínú ìlú náà.
Oríṣun àwòrán, @Bashir Ahmaad
Akorede sọ siwaju pe, awọn ọdọ naa ni Gambari pẹ̀lú àwọn ọ̀tẹlẹ̀múyẹ́ tó lé ní ogun, tó fí mọ àgba ẹgbẹ́ òṣèlú APC kan, Cook Gani Olododo, ní wọn ri níbi ti wọn ti ń fún àwọn ènìyàn lówó, kí wọn báa lè dìbò fún ẹgbẹ́ wọn.
Wọn fi kún ọ̀rọ wọn pé, ilé olùdíje ẹgbẹ PDP ninu atundi ibo naa, onímọ-ẹrọ Dare Bankole, ni Seriki Gambari ko awọn tẹlẹmuyẹ lọ lati mu si ahamọ̀, sùgbọn àwọn ọmọ ìlú kò gbà kí èyí wáyé.
Bí àtúndì ìbò ṣé ń lọ lọ́wọ́ ní ìpínlẹ̀ Kwara, ìròyìn tó ń dé sí etí ìgbọ́ BBC Yorùbá ní, àwọn jandùkú ti jí àpótí ìdìbò gbé ní ibùdó ìdìbò Olupodo ní wọ́ọ̀dù 1 Omù-Aran àti Federal Girls College Omu-Aran Woodu 2, sùgbọn àwọn ọlọ́ọpàá ti ríi gbà padà.
Bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé à kò lè fì ìdí rẹ̀ múlẹ̀ irúfẹ́ ẹgbẹ òṣèlú tí àwọn janduku náà ń ṣiṣẹ́ fún, sibẹ ẹgbẹ́ òsèlú PDP àti APC ń nàka àlébù si ara wọn lori isẹlẹ naa.
House of Rep: Atúndi ilé ìgbìmọ Aṣofin tí gbérasọ ní Kwara
Bakan náà ní ìròyín tún tẹ̀wá lọ́wọ́ pé, ẹ̀rọ̀ tó máà yẹ orúkọ àwọn olùdibò wo ti daṣẹ́ sílẹ̀ láwọn ibìkan, tàwọn ọmọ ẹgbẹ òṣèlú PDP si ní INEC mọ̀ọ́mọ̀ ṣe èyí ni nítòrí ibi tí ẹgbẹ àwọn ti láanfàní láti jáwé olúbori ni.
Isẹlẹ ‘dìbò kòo sebẹ̀’ náà kò gbẹ́yìn níbi ìdìbò tòní lágbègbè ile Bale nílù Òró sùgbọn ọkàn nínú èèkan ẹgbẹ́ òṣèlú APC tó bá BBC sọ̀rọ̀, Lattef Oloyin sàlàyé pé ọwọ́ àwọn agbofínro ti tẹ ènìyàn márùn báyìí lori isẹlẹ naa.
Àtúndì Ìbò Kwara: APC àti PDP ń sọ òkò ọ̀rọ̀ síra wọn
Oríṣun àwòrán, @SKSolaKuti
Iran yoo dun wo ni ipinlẹ́ Kwara loni ọjọ Abamẹta nigba ti ẹgbẹ oselu PDP ati APC yoo maa ti ẹsẹ bọ sokoto kan naa lati yan asoju-sofin tuntun ti yoo maa soju ẹkun idibo Irẹpọdun, Isin Ekiti ati Oke ẹrọ.
Bẹẹ ba gbagbe, asoju-sofin to n soju ẹkun idibo naa tẹlẹ, Funkẹ Adedoyin lo dagbere faye lọjọ kejidinlọgbọn osu kẹsan ọdun 2018, lasiko aisan kan to mu, eyi to mu ki aga ẹkun idibo naa sofo nile asofin apapọ ilẹ wa.
Ọpọ eeyan si lo n fi oju wo eto atundi ibo naa gẹgẹ bii ija agba meji laarin aarẹ ile asofin agba ilẹ wa, Bukọla Saraki, tii se ọmọ bibi ipinlẹ Kwara ati aarẹ orilẹ́-ede yii, Mohammadu Buhari.
Oríṣun àwòrán, Greatkay
Ọwọ́ tẹ àwọn olóṣèlú tó ń fowó ràbò ní Kwara
Niba yii na, awọn ẹgbẹ oselu meji to gbaju gbja julọ nipinlẹ Kwara, eyiun ẹgbẹ oselu PDP ati APC ti n sọ oko ọrọ si ara wọn nibayi ti eto atundi ibo naa wọle de.
Ẹgbẹ oselu APC, ninu igbe to fi bọnu faraye ni ẹgbẹ oselu PDP to n se ijọba lọwọ ni ipinlẹ Kwara ti fọn awọn janduku soke lati maa dunkoko mọ awọn alatako rẹ ninu atundi ibo ọhun.
Atúndì ibo bere ni láwọn ìjọba ìbílẹ̀ Kwara
Oludije fẹgbẹ oselu APC ninu atundi ibo naa, Raheem Ọlawuyi ninu atẹjade kan ti amugbalẹgbẹ rẹ fisita fawọn akọroyin nilu Omu Aran ni PDP da awọn janduku sita lati maa dun mahuru mahuru mọ awọn oludibo keto idibo naa to waye ni.
Sugbọn gomina ipinlẹ Kwara, AbdulFatai Ahmed, ti wa fesi pada pe ọ̀rọ naa ko ri bẹẹ rara nitori aabo to peye si n bẹ fun awọn oludibo.
Oríṣun àwòrán, @Bashir Ahmaad
Atẹjade kan ti Oludamọran agba rẹ feto iroyin, Muyideen AKorede fisita ni, ijọba ti ko awọn agbofinro sita lati fi ẹsẹ eto aabo mulẹ dain-dain, eyi ti yoo fun awọn oludibo lanfaani lati wa se ojuse wọn.
Gomina Ahmed wa rọ awọn olugbe ẹkun idibo naa lati tu jade sita wa kopa ninu atundi ibo ọhun, ki wọn si fi ibo wọn yan oludije ti ọkan wọn n fẹ.
Bi awọn ẹgbẹ oṣelu ṣe n gbaradi fun atundi ibo sile aṣoju-ṣofin lẹkun ijọba ibilẹ Ekiti, Oke Ero, Isin ati Irẹpọdun ni ipinlẹ Kwara, eleyi ti yoo waye ni ọjọ abamẹta, awọn agbebọn kan lo ṣaa dede kọlu awọn ọkọ ti o ko oludije fun ẹgbẹ oṣelu APC, Tunji Ajulo Opin ati ikọ ipolongo rẹ pẹlu ibọn.
Iroyin to tẹ BBC News Yoruba lọwọ ṣalaye pe nnkan bii aago kan oru ni ikọlu naa waye ni agbegbe ijọba ibilẹ Oke Ero nipinlẹ Kwara.
Iroyin naa tun ṣalaye pe ibi ipolongo idibo kan ni Tunji Ajulo Opin ati ikọ rẹ ti n bọ ki awọn agbebọn naa to kọlu wọn.
BBC News Yoruba fi idi rẹ mulẹ pe oludije fun ipo gomina ipinlẹ Kwara labẹ aṣia ẹgbẹ oṣelu APC, Abdulrazaq Abdulrahman ko si ninu eyikeyi ninu awọn ọkọ ti wọn kọlu lasiko naa gẹgẹ bii awọn iroyin kan ti n gbe e kiri.
#Oshimole: Àwọn aṣáájú APC kò mọ ohun ti wọ́n n ṣe lásìkò yí
"Ninu ọrọ ti ọkan ninu awọn amugbalẹgbẹ oludije ẹgbẹ oṣelu APC naa ba BBC news Yoruba sọ, ""ko si Alhaji Abdulraham pẹlu ikọ ipolongo naa lasiko ti ikọlu naa waye; ṣugbọn a lee sọ wi pe, Tunji Ajulo Opin to jẹ oludije fun aga ile aṣoju-ṣofin lẹkun Ekiti, Oke Ẹro, Isin ati Irẹpọdun ni ipinlẹ Kwara lẹgbẹ oṣelu APC ni wọn n lepa."
Ninu ifọrọwerọ pẹlu alukoro ileeṣẹ ọlọpaa nipinlẹ Kwara, Ajayi Ọkasanmi, ileeṣẹ ọlọpaa ṣi n ṣe akojọpọ iroyin ti ati iwadi lori iṣẹlẹ naa.
Tani yoo rẹyin ara wọn?
Gbangba fẹ dẹkun ti kedere yoo si bẹwo nipinlẹ Kwara pẹlu ibo atundi ti yoo waye nibẹ lọjọ abamẹta.
Ibo naa ti yoo waye ni awọn ijọba ibilẹ kan ni guusu ipinlẹ naa jẹ eleyi ti wọn yoo fi yan asoju tuntun fun ẹkun idibo Irepodun/Oke-Ero/Isin/Ekiti .
Asofin to n soju agbegbe naa tẹlẹ Funke Adedoyin papoda laipẹ, eleyii to mu ki INEC seto idibo miiran.
APC Primaries: A ṣi n lọ sílé ẹjọ́ lóṣù tó m bọ̀ lórí ọ̀rọ̀ yìí
#Oshimole: Àwọn aṣáájú APC kò mọ ohun ti wọ́n n ṣe lásìkò yí
Lootọ ni pe idibo ko ni waye ni gbogbo ipinlẹ naa sugbọn awọn amoye ni esi rẹ yoo sẹ atọna ibi ti ọpa ẹbiti idibo 2019 yoo re si.
Idibo yi le jẹ laarin awọn oludibo ẹgbẹ APC ati PDP ṣugbọn ọrọ naa tan de ori Aarẹ ile asofin agba Bukola Saraki ati Aarẹ orileede Naijiria iyẹn Muhammadu Buhari.
Idi ni wi pe  idibo yii tunbọ fagbara fun fa kin faa laarin wọn lori ẹni ti o lagbara ju lori oselu Kwara.
Saaju asiko yii, ẹgbẹ oselu APC lo n dari akoso ipinlẹ naa ti gbogbo awọn asoju to fi mọ awọn to di ipo mu wa lati inu ẹgbẹ APC.
Sugbọn bi Aarẹ ile asofin Bukola Saraki ti se kede wi pe oun ti kuro ninu ẹgbẹ apc lọ si PDP, nise ni gbogbo awọn asoju to fi mọ Funke Adedoyin to salaisi naa sun tele.
Ti PDP ba mu oke ninu idibo yii, a jẹ wi pe gbogbo awọn asofin Kwara yoo jẹ ti wọn ni sugbọn tio APC ba fi le ri aaye rẹ gba,ohun iwuri ni yoo jẹ fun wọn.
Ifidirẹmi fun eyikeyi ẹgbẹ le se akoba fun wọn ninu idibo gbogbogbo to n ba lọdun 2019.
Awọn wo lon du ipo rẹ
Labẹ asia ẹgbẹ APC ni Funke Adedoyin to di ipo naa mu tẹlẹ wa ki o to lọ si ẹgbẹ PDP.
Ọgbẹni Raheem Olawuyi ni awọn ọmọ ẹgbẹ gbimọpọ yan gẹgẹ bi oludije ẹgbẹ oselu APC.
Oríṣun àwòrán, FACEBOOK/Saheed Alatise/Raheem Olawuyi
Awọn oludije mejeeji
A gbo wi pe ẹgbẹ oselu mẹwa lo fi oludije sile lati du ipo naa ṣugbọn nigba ti yoo fi di ọjọ iṣẹgun nise ni iroyin gbode wi pe awọn ẹgbẹ oṣelu meje ti pa imọran pọ  lati yan Raheem Olawuyi gẹgẹ bi oludije wọn.
Bi ọrọ yi ba ri bẹ, ajẹ wi pe ẹgbẹ meje to fi mọ APC ni PDP yoo ma ba wọ iya ija lọjọ idibo.
Ọgbẹni Saheed Alatishe ni oludije ẹgbẹ PDP.
Ajumọyan ni awọn ọmọ ẹgbẹ PDP fi yan ohun naa si ipo gẹgẹ bi oludije ẹgbẹ.
Donkey ban: Nàìjíríà bẹ̀rẹ̀ ìgbésẹ̀ òfin láti dẹ́kun kíkó kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ lọ sí China
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Lagbaye, miliọnu mẹrinlelogoji ni iye kẹtẹkẹtẹ ti o wa
Ile aṣoju-ṣofin lorilẹede Naijiria ti n gbe igbesẹ lati dẹkun ọwọja tita kẹtẹkẹtẹ tabi ẹya ara kẹtẹkẹtẹ si oke okun.
Ẹranko to gbajugbaja ni apa oke ọya orilẹede Naijiria ni kẹtẹkẹtẹ jẹ ṣugbọn iwadi ijinlẹ ti fi idi rẹ mulẹ pe iye awọn ẹranko yii ti n dinku gidigidi lorilẹede Naijiria.
Aṣofin Garba Datti Muhammad lo gbe aba kan lori fifi ofin de tita tabi rira kẹtẹkẹtẹ lọ si oke okun kalẹ siwaju ile aṣoju-ṣofin fun agbẹyẹwo ati ifọwọsi wọn.
Ẹ̀sùn tí ẹbí fi kan bábá t'ọmọ méjì rẹ̀ kú sínú ẹ̀rọ amómítutù rèé
Ohun to ṣokunfa aba naa ni bi kẹtẹkẹtẹ ati ẹya ara rẹ ti ṣe wa di ohun ti awọn eeyan kan fi n ṣowo ọrọ aje si orilẹede China.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Iye Kẹtẹkẹtẹ ti o wa lorilẹede Naijiria ti din ni miliọnu kan
"Ninu ifọrọwanilẹnuwo kan ti o ṣe pẹlu BBC News, aṣofin Datti Muhammad ni ""ni ọdun mẹwa sẹyin, iwadii fi idi rẹ mulẹ pe miliọnu mẹta tabi ju bẹẹ lọ ni iye awọn kẹtẹkẹtẹ ti o wa lorilẹede Naijiria; bayii o ti din ni miliọnu kan. Idi niyii ti a fi gbọdọ gbe igbesẹ ki ọrọ naa to bọ s'ori."""
Ohun to kọ ni lominu julọ, aṣofin Datti Muhammad ṣalaye fun BBC news, ni pe gbogbo agbaye lo ti ji si wahala ti o n de ba ẹranko yii ayafi orilẹede Naijiria ati Kenya.
Ohun elo fun irinna, ẹru kiko ati ọpọlọpọ iwulo ni kẹtẹkẹtẹ jẹ fawọn eeyan lẹkun apa oke ọya lorilẹede Naijiria, ṣugbọn o dabi ẹni pe, iṣoro owo ati iṣẹ ti n mu ki awọn eeyan maa pa kẹtẹkẹtẹ ki wọn si maa taa ni owo gọbọi si  orilẹede China.
Yatọ si irina ati ẹru kiko, ṣe kẹtẹkẹtẹ tun ni iwulo kan eyi ti o n koba ẹmi rẹ bayii?
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Aṣofin Datti Muhammad ṣalaye fun BBC news, ni pe gbogbo agbaye lo ti ji si wahala ti o n de ba ẹranko yii ayafi orilẹede Naijiria ati Kenya
Aṣofin Datti Muhammad salaye fun BBC News pe, yatọ si iwulo ẹru kiko ati irina ti ọpọ mọ mọ kẹtẹkẹtẹ lorilẹede Naijiria, ọrọ ju bẹẹ lọ lorilẹede China. O ni wọn a maa lo ẹya ara kẹtẹkẹtẹ fun ogun ati awọn ohun elo alekun ounjẹ lẹyin ti wọn ba fi awọn eroja kan ati omiran sii.
"Eyi lo n mu ki awọn oniṣowo orilẹede China o doju kọ orilẹede awọn orilẹede ti kẹtẹkẹtẹ wọpọ si lagbaye. ""Amọṣa, awọn orilẹede yoku ti gbọn wọn si ti fi ofin de tita kẹtẹkẹtẹ tabi ẹya ara rẹ si oke okun."
"Ṣugbọn orilẹede Naijiria ati Kenya nikan ni ko tii ṣe ohun ti o tọ. Bi ofin yii ba lee gba ifọwọsi ile aṣofin apapọ, ẹwọn ọdun mẹwa ni ẹnikẹni to ba tẹ ofin yii loju mọlẹ yoo fi gbara."""
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Awọn aṣofin Naijiria ni wọn a maa lo ẹya ara kẹtẹkẹtẹ fun ogun ati awọn ohun elo alekun ounjẹ lorilẹede China
Lagbaye, miliọnu mẹrinlelogoji ni iye kẹtẹkẹtẹ ti o wa, ṣugbọn, gẹgẹ bi aṣofin Muhammad ṣe sọ ọ, iye awọn ẹranko yii to wa lorilẹede Naijiria din ni miliọnu kan.
Surety - Àwọn kan n ṣe onídùró gẹ́gẹ́ bi okòówò
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Iwọ ti o ba fẹ gba oniduro gbọdọ mọ ki o si ni oye irufẹ ẹsun ti wọn fi kan ẹni to fẹ ṣe oniduro fun.
O lewu fun ọ ti o ko ba mọ ẹsun ti wọn fi kan ẹni to n jẹjọ.
Ti ẹni naa ba sa lọ, ori rẹ ni gbogbo atunbọtan ẹjọ yoo da le lori.
Ẹni ti o fẹ ṣoniduro fun gbọdọ jẹ ẹni ti o mọ daadaa, dele dele, too mọ ọna rẹ. To da ọ loju pe yoo wa sile ẹjọ lọjọkọjọ ti ile ẹjọ ba sọ pe ko wa, ti ko ni salọ.
Idibo ko ni waye ti wọn ko ba mu ọkọ mi jade
Ẹsun ti wọn ba si fi kan ẹni naa ni yoo sọ iru oniduro ti adajọ yoo sọ pe ko mu wa.
Owo ti ile ẹjọ ba sọ pe ki ẹ fi gba oniduro, kii se fun ile ẹjọ, o tumọ si pe iye owo ti o o san fun ile ẹjọ niyẹn ti ẹni to duro fun ba salọ.
Bakan naa ni dukia ti ile ẹjọ ba beere lọwọ rẹ, ile ẹjọ kọ lo ni i, ile ẹjọ yoo gba a ni ti ẹni naa ba sa lọ.
Awọn kan ti wa to n fi jijẹ oniduro ṣe iṣẹ ṣe. Awọn gan an lo n ba ẹka ofin jẹ ni Naijiria. Awọn lo mn jẹ ki ẹni to n jẹjọ salọ.  Wọn ko ni iṣẹ meji ti wọn n ṣe ju iyẹn lọ.
Ko si si bi adajọ ṣe fẹ ẹ mọ. Ti adajọ ko ba si ṣe iwadi daada ko n i mọ. Ti ẹni to n jẹjọ ba salọ, awọn naa yoo salọ.
Koda wọn maa n ṣe atọwọda iwe ilẹ, iwe ile, iwe ileesẹ ati bẹẹbẹ lọ lati fi tan ile ẹjọ.
Kí ni Yorùbá ń pe ọmọ tí wọ́n bí lẹ́yìn Àlàbá?
Iṣẹlẹ kan to ṣẹlẹ sẹyin ni ile ẹjọ giga ti ijọba apapọ nilu Abuja sọ pe ki awọn to ṣe oniduro fun olori  ẹgbẹ́ to n polongo fun idasilẹ orilẹ-ede Biafra, Nnamdi Kanu, san ọgọrun un miliọnu ẹni kọọkan wọn sile ẹjọ.
Eyi ko ṣẹyin bi Kanu ti wọn duro fun ko ṣe yọju sile ẹjọ l'ọjọ kẹtala, oṣu Kọkanla ti igbẹjọ rẹ yẹ ko waye.
Awọn mẹtẹẹta, Sẹnetọ Enyinnaya Abaribe; alufa ijọ Juu kan, Immanuel Shalom, ati oluṣiro owo, Tochukwu Uchendu, ni onidajọ Binta Nyako paṣẹ fun lati san owo gọbọi naa si apo asunwọn ile ẹjọ.
Eyi lo mu BBC News Yoruba ba Amofin Sadiku Ibitayọ sọrọ lori awọn nkan to rọ mọ ṣiṣe oniduro fun ẹni to n j'ẹjọ.
Nnamdi Kanu ti ṣàlàyé bí ó ṣe rìn lẹ́yìn ọdún kan tó dàwátì
Amofin ṣalaye pe oriṣi oniduro meji lo wa. Akọkọ ni eyi ti ileeṣẹ ọlọpa beere fun ati ti ile ẹjọ.
"Oniduro ti ileeṣẹ ọlọpa maa waye lasiko ti awọn ọlọpa ko ti i pari iwadi wọn lati mu ki ẹni naa duro fun afurasi ọdaran.
Wọn yoo  kan sọ pe ki ẹni naa buwọlu iwe tabi fi iwe idanimọ rẹ silẹ. Awọn ọlọpa yoo pada ranṣẹ pe e ti o ba paa dandan."
Èyí ni àwọn nkan tí o gbọ́dọ̀ mọ̀ kó ò tó ṣe onídúùró ẹnikẹ́ni
Ni ti ile ẹjọ, awọn ti ẹsun ti wọn fi kan wọn ba fi aaye silẹ pe wọn le maa gba ile wọn wa jẹjọ ni adajọ maa n gba oniduro fun.
Àwọn ìgbà tí jándùkú òṣèlú tí wáyé ní Nàìjíríà
Oríṣun àwòrán, Atiku Abubakar/Facebook
Oludije fun ipo aarẹ labẹ aburada ẹgbẹ oṣelu Peoples Democratic Party l'ọdun 2019, Atiku Abubakar, ti sọ pe oun mọ orisun ẹgbẹ agbesunmọmi Boko Haram.
Atiku, ninu ifọrọwanilẹnuwo kan pẹlu iwe iroyin ori ayelujara, African Reports, eyi ti oun paapa fidirẹ mulẹ l'oju òpó Twitter rẹ, sọ pe oun mọ bi Boko Haram ṣe bẹrẹ. O sọ pe 'awọn oloṣelu lo ni ẹbi rẹ.'
Ati wi pe jagidijagan oṣelu lo bẹrẹ Boko Haram. O ṣalaye pe awọn oloṣelu kan lo lo awọn ọmọ ẹgbẹ Boko Haram lati jawe olubori ninu eto idibo, ṣugbọn ti wọn ko ri ti wọn ro mọ lẹyin idibo, ti ko si si iṣẹ fun wọn mọ. O sọ pe bẹẹ na ni ọrọ ri fun ẹkùn Niger Delta pẹ̀lú wàhálà àwọn ajìjagbara tí wọ́n ń kojú lónìí.
Kwara - Àwọn agbébọn kọlu olùdíje APC
Aṣòfin 18 sá àsálà kúrò nípínlẹ̀ Ondo
Laipẹ yii naa ni Aarẹ Naijiria nigba kan, Oluṣẹgun Ọbasanjọ parọwa fun awọn oloṣelu lati maa lo awọn ọmọ bibi inu wọn fun jagidijagan oṣelu. O sọ ọrọ naa nibi eto kan kan to waye nilu London.
Eyi waye latari ibẹru ati ifoya pe o ṣeeṣe ki wahala ṣẹlẹ ni awọn agbegbe kan ni Naijiria lasiko eto idibo 2019.
Ṣe a le sọ pe eyi n fidi rẹ mulẹ pe lootọ ni awọn oloṣelu n lo janduku ṣaaju, lasiko ati lẹyin eto idibo?
Kiiṣe ohun tuntun pe awọn oloṣelu maa n lo awọn janduku ti eto idibo ba n bọ lọna, lasiko eto idibo ati ti idibo ba waye tan.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Awọn janduku yii lọpọ igba maa n da eto ipolongo ibo tabi iwọde oṣelu ẹgbẹ tabi ẹni to jẹ alatako fun ẹni to bẹ wọn niṣẹ ru.
Awọn janduku yii lọpọ igba maa n da eto ipolongo ibo tabi iwọde oṣelu ẹgbẹ tabi ẹni to jẹ alatako fun ẹni to bẹ wọn niṣẹ ru. Igba miran, wọn a ba awọn dukia ẹgbẹ bẹ jẹ.
Lọjọ idibo waye, ọpọ igba ni iroyin ti jade nipa bi awọn janduku oloṣelu ṣe yabo ibudo, ti wọn yoo si ji apoti ibo salọ. Bakan naa ni wọn a maa dẹru ba awọn oludibo tabi tilẹ ṣe wọn ni ijamba.
Eyi si maa n mu ki ọpọlọpọ eniyan ma a kopa ninu eto idibo nitori ibẹru pe nkan buruku le ṣẹlẹ si wọn.
Ọpọlọpọ awọn janduku naa ni ko ni iṣẹ ọwọ, okoowo tabi iṣẹ to n mu owo wọle fun wọn. Orisun atijẹ atimu wsn ko ṣẹyin ṣiṣe janduku. Ti eto idibo, oṣelu ba kasẹ nilẹ, wọn a di 'alainiṣẹ lọwọ.'
Eyi si le mu ki ọpọlọpọ wọn sọ ole jija, tabi awọn ọna alumọkọrọyi mi i di orisun ọrọ aje wọn.
Lọdun 2018 ni iṣẹlẹ idigunjale kan waye nilu Ọffa, ni ipinlẹ Kwara. Iṣẹlẹ naa mu ẹmi awọn eniyan to niye lọ.
Lẹyin iṣẹlẹ naa, ni ọwọ awọn ọlọpa tẹ awọn afurasi kan to sọ pe Aarẹ ile aṣofin àgbà Naijiria, Bukọla Saraki ni awọn n ṣiṣẹ fun, botilẹ jẹ wi pe iwadi kankan ko ti i fi mulẹ pe lootọ Saraki ni wọn n ṣiṣẹ fun.
Ìdigunjale Offa: Ọlọ́pàá gbé N5m sílẹ̀
Saraki lọ́rọ̀ láti dáhùn lórí ìdigunjalè Offa
Ṣugbọn ohun kan to han sita faye ri ni pe janduku oloṣelu ni awọn afurasi ole ọhun.
O si ṣeeṣe ko jẹ wi pe nigba ti owo oloṣelu ko wọle fun wọn mọ, ni wọn gba oko olè lọ nitori atijẹ, ati atimu.
Eto idibo ọdun 2011 yọri si wahala ni ẹkùn Ariwa Naijiria. Awọn kan gbagbọ pe iyanjẹ ati mago-mago lo gbe Aarẹ nigba kan, Goodluck  Jonathan wọle sipo aarẹ, ti wọn si bẹrẹ si ni fa wahala.
Ajọ to n woye nipa ẹtọ ọmọniyan ni Naijiria, National Human Rights Watch jabọ pe lọjọ keji ọjọ ti wọn kede esi ibo, ọjọ kẹtadinlogun, oṣu Kẹrin ni awọn ololufẹ Muhammadu Buhari bẹrẹ iwọde ni Ariwa Naijiria.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Awọn ọdọ to n fa wahala lẹyin eto idibo ọdun 2011 ni Naijiria
Iwọde naa pada yọri si rogbodiyan ni ẹkùn naa, ti ọpọlọpọ ile, ile ijọsin, ile itaja ati awọn dukia mi si ti di bibajẹ tabi jijo ni ina.
Awọn eniyan kan si padanu ẹmi wọn.
Ipaniyan naa ko yọ awọn ọdọ to n sinru ilu silẹ. Ni ipinlẹ Bauchi, awọn agunbanirọ to le ni maarun ni iroyin gbe e pe awọn onijagidija gan ọhun pa. Awọn agunbanirọ naa ba ajọ INEC ṣiṣẹ ninu eto idibo naa.
Bakan naa ni ipinlẹ Kaduna. Janduku oṣelu yọri si ija ẹsin laarin awọn kristẹni ati musulumi. Ọpọ eniyan lo si tun padanu ẹmi ati dukia wọn.
Ṣaaju eto idibo naa ni iroyin gbe e pe awọn janduku oloṣelu yabo iwọde oṣelu ẹgbẹ APC ninu oṣu Kẹfa. Ọkan gboogi lara ọmọ ẹgbẹ, Ọpẹyẹmi Bamidele atawọn mi i fara gba ọta ibọn.
Ìṣẹlẹ iyinbon APC Ekiti : Ki gaan lo ṣẹlẹ?
Bakan naa ni eto idibo gomina to waye ni ipinlẹ Ọṣun, rogbodiyan waye, paapa lẹyin ti eto idibo naa waye ati lasiko atundi ibo.
Awọn janduku oṣelu ji apoti ibo lawọn ibi kan, awọn eniyan kan si farapa.
Pẹlu bi eto idibo gbogboogbo ọdun 2019 ṣe n bọ lọna ni Naijiria, ṣe kii ṣe pe asiko tun ti to fun awọn janduku oloṣelu lati tun ri iṣẹ sẹ?
Ṣe awọn agbegbe to ti n ni iriri alaafia ko tun ni bọ si inu ibẹru ohun ti awọn onijagidijagan naa le ṣe lati de ipo, tabi fun oludije wọn lati de ipo?
Food Poison - Májèlé inú Àmàlà ṣekúpa ènìyàn mẹ́rin ní Ilorin
Oríṣun àwòrán, @Bamshaq_Potato
Àmàlà
Énìyàn mẹ́rin nínú ìdílé kan ní ìlú Ilorin ti gbkmìí mì lkyìn tí wọ́n jẹ àmàlà tí wọ́n fura sí pé ó ní májèlè nínú.
A gbọ́ pé àwọn mẹ́rin mìí tó jẹ nínú àmàlà náà ti wà nílé ìwòsàn ti ìjọba tó wà ní ìlú Ilorin.
Lílo òógùn apakòkòrò fún oúnjẹ l'éwu
Ìṣẹ̀lẹ̀ yìí wáyé ní agbègbè Magaji - Ogo lẹ́yìn ilé ìwé Kwara State Collefe of Arabic and Islamic Legal Studies nílùí Ilorin.
Ìròyìn sọ pé alẹ́ ọjọ́ àìkú ni wọ́n jẹ àmàlà, nígbà tó ma fi di òwúrọ̀ ọjọ kejì, wọ́n ti rékọjá sí ọ̀run alákeji.
Lọ́jọ́rú sì ni a gbọ́ pé olórí ilé náà gbẹ́mìí mì. Àwọn tí wọ́n ní wọ́n ti gbẹ́mìí mì ni bàbá, àbúrò rẹ̀ àti ọmọ méjì nígbà tí ìyá àti ọmọ mẹ́tàá ń gbìyànjú láti yè é nílé ìwòsàn.
Wọ́n ti sin òkú àwọn tó ti bá ìṣllẹ̀ náà rìn ní ìlànà ẹ̀sìn Islam.
Ọbẹ Ẹgusi sise ati jijẹ
Dapchi: Àwọn akẹgbẹ́ Leah Sharibu padà sí ilé ìwé, ṣùgbọ́n Leah kò bá wọn wọlé
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ni ọjọ kọkandinlogun oṣu keji ọdun 2018 lawọn Boko haram ji aadọfa akẹkọ gbe n'ile iwe kan ni ilu Dapchi, ipinlẹ Yobe
Oṣu mẹsan lẹyin ti awọn agbebọn Boko haram ji aadọfa akẹkọbinrin gbe ni ile iwe kan ni ilu Dapchi ipinlẹ Yobe, ileewe naa ti pada bẹrẹ iṣẹ ẹkọ kikọ bayii.
Ni ọjọ kọkandinlogun oṣu keji ọdun 2018, gẹgẹ bi awọn akẹgbẹ wọn kaakiri orilẹede Naijiria, awọn akẹkọ nileewe girama Government Girls'Science and Technical College, Dapchi pẹlu ji lọ si ileewe wọn pẹlu ireti ati gba imọ kun imọ wọn.
Amọṣa, ọrọ yii pada lọjọ naa eleyi ti o yi itan igbe aye awọn akẹkọ, awọn olugbe ilu Dapchi ati orilẹede Naijiria lapapọ pada nigba ti awọn igara agbebọn kan ti wọn jẹ ọmọ  ikọ Boko haram ya bo ileewe naa ti wọn si ko awọn akẹkọ naa lọ.
Lẹyin igba diẹ wọn da awọn kan pada laaye ninu wọn ni oṣu  kẹta ṣugbọn wọn ko tii da Leah Sharibu pada.
#Oshimole: Àwọn aṣáájú APC kò mọ ohun ti wọ́n n ṣe lásìkò yí
Ọga agba ileewe girama naa, Hajiya Adama Abdulkarim ṣalaye fun awọn oniroyin pe ida ọgọrin ninu ọgọrun awọn akẹkọ ati olukọ ileewe naa ni wọn ti pada si ẹnu ẹkọ ati iṣẹ wọn.
O ni awọn ti gbe igbesẹ lati pẹtu si awọn akẹkọ ati olukọ naa ninu pẹlu igbesẹ iranwọ gbogbo lati ọdọ ijọba ibilẹ, ipinlẹ lati rii daju pe ẹru ko ba awọn akẹkọ naa ju bi o ti yẹ lọ.
Amọṣa, bi awọn akẹkọ yii ṣe n pada si ẹnu ẹkọ wọn o daju pe Leah Sharibu ti wọn ji gbe pẹlu awọn akẹgbẹ ṣi wa lahamọ awọn agbebọn naa.
Igba ti yoo darapọ mọ awọn akẹgbẹ rẹ ni ko tii han si araye.
Nigeria Elections 2019: Wọ́n yàn-án ní gómìnà, àmọ́ orí gbé e dé ipò igbákejì ààrẹ
Oríṣun àwòrán, @AtikuOrg
Atiku Abubakar
Ọjọ Kẹẹdọgbọn Osu Kọkanla ọdun 1946, eyi tii se ọdun mejilelaadọrin sẹyin, ni Garba Atiku ati Aisha Kande Abubakar se ọlọkọ ọmọ tuntun jojolo kan de ile aye.
Ilu Jada nipinlẹ Adamawa si ni ẹjẹ ọrun naa fi ori sọlẹ si, eyi ti wọn pe suna rẹ ni Atiku Abubakar.
O se ni laanu pe ọmọde yii ko ju ọdun mọkanla lọ, to fi di ọmọ alaini baba, ti iya rẹ si jade laye ldun 1984.
Ètò Atiku ló bá èròngbà Yorùbá mu
Fun awọn eeyan miran, wọn bi wọn sile ọla ni, wọn ba ọla nile tabi de ba ọla, sugbọn ni ti Atiku Abubakar, ọmọ atapata dide ni, to si sisẹ pẹlu ọwọ rẹ mejeeji ko to de ipo ọla.
Oríṣun àwòrán, @Atiku
Gẹgẹ Atiku ti se akọsilẹ rẹ, o ni oju oun ri to nigba ti oun wa ni kekere, tori ọmọ ti ko ni baba lo dun fi iya jẹ. Ọdọ baba baba oun si ni oun gbe dagba, bẹẹ si ni isẹ ati osi ko jẹ ko lee setọju oun bo se yẹ, ọjọ tawọn si fi ebi sun lo pọ, nigba ti ounjẹ ẹẹkan lojumọ mọ awọn lara.
Bi o tilẹ́ jẹ pe baba rẹ ko fẹ ko ka iwe oyinbo, sibẹ o lọ sile ẹkọ alakọbẹrẹ Jada lọmọ ọdun mẹjọ, to si lọ sile ẹkọ Adamawa Provincial Secondary School, Yola lọdun 1960.
Lẹyin eyi ni Atiku jẹ anfaani ẹkọ ọfẹ lọdun 1967 lati tun lọ kẹkọ siwaju nile ẹkọ fasiti Ahmadu Bello nilu Zaria, to si gba iwe ẹri Diploma ninu imọ ofin.
Oríṣun àwòrán, @Atiku
Atiku Abubakar ti sisẹ gẹgẹ bii osisẹ asọbode ri, to si lo ogun ọdun nibẹ. Koda o di igbakeji oludari agba fun ileesẹ naa, eyi to jẹ ipo to ga sikeji.
Osu Kẹrin ọdun 1989 lo fẹyin ti lẹnu isẹ, to si di olokoowo ati oloselu paraku.
Atiku pade omidan Titilayọ Albert lasiko ti isẹ gbe lọ si Idi Iroko bii asọbode, ti wọn si se igbeyawo bonkẹlẹ losu kejila ọdun 1971 nilu Eko, nitori mọlẹbi Titilayọ tako igbeyawo wọn.
Ọjọ kẹrindinlọgbọn osu kẹwaa ọdun 1972 ni wọn bi ọmọbinrin kan ti wọn pe orukọ rẹ ni Fatima, ti wọn si tun bi Adamu, Halima ati Aminu tẹle.
Lọdun 1979 ni Atiku tun fẹ Ladi Yakubu bii iyawo keji pẹ́lu alaye pe, oun fẹ di alagbo nla nigba to jẹ pe oun nikan poloro lawọn obi oun bi. - Abba, Atiku, Zainab, Ummi-Hauwa, Maryam ati Rukaiyatu.
Oríṣun àwòrán, @Atiku
Awọn iyawo ati awọn ọmọ mi ni ara, oludamọran ati ọrẹ ti mo ni. Ọmọ mẹfa si ni Ladi bi fun - Abba, Atiku, Zainab, Ummi-Hauwa, Maryam ati Rukaiyatu.
Rukaiyatu ni iyawo kẹta, o si bi Aisha, Hadiza ati Aliyu, nigba ti Fatima Shettima si jẹ iyawo kẹrin, ẹni to bi Amina, Mohammed ati Ibeji - Ahmed ati Shehu, Zainab ati Hafzat.
Aarin oun ati Ladi daru, ti wọn si kọ ara wọn silẹ, lẹyin eyi lo wa fẹ Jẹnnifer.
Atiku ti kopa ninu ibo abẹnu fun ipo gomina lọdun 1991 nipinlẹ Gongola ijọun ( tii se ipinlẹ Adamawa ati Taraba bayii ), to si tun kopa ninu ibo abẹnu fun ipo aarẹ ilẹ wa lọdun 1993 ninu ẹgbẹ oselu SDP tijọba ti fofin de, to si se ipo kẹta lẹyin oloye MKO Abiọla ati Babagana Kingibe.
Amọ lọdun 1998 ni Abubakar Atiku jawe olubori lati di gomina ti ilu dibo yan labẹ asia ẹgbẹ oselu PDP. Sugbọn ko to gba ọpa asẹ ni aarẹ tilu dibo yan nigba naa, Oloye Olusẹgun Ọbasanjọ ba yan-an gẹgẹ bii igbakeji rẹ.
Oríṣun àwòrán, @Atiku
Ni saa keji isejọba awọn asaaju mejeeji naa, ni esu tapo si aarin wọn, ti ikunsinu ati aawọ si bẹ silẹ, eyi to se akoba nla fun igbiyanju Atiku lati dije fun ipo aarẹ orilẹede yii.
Lọwọ lọwọ bayii, Atiku Abubakar ni oludije fun ẹgbẹ oselu PDP, ti yoo si gbe asia ẹgbẹ oselu naa ninu idibo ti yoo waye losu keji ọdun 2019
Ẹlẹyinju aanu ni Atiku, to si maa n fi owo saanu fun awọn eeyan to nilo rẹ. Idi ree ti wọn se fi jẹ oye Turaki ati Waziri ti Adamawa.
Atiku ni aya mẹrin, to si bi ọmọ mejidinlọgbọn.
Oríṣun àwòrán, @Atiku
#BBCNigeria2019
Nigeria Elections 2019: Bàbá rẹ̀ àgbà ni Adegoke Adelabu Pẹnkẹlẹmẹ́sì
Oríṣun àwòrán, Adebayo_adelabu
Agbo ile Oke Oluokun ni adugbo Kudẹti nilu Ibadan ni wọn ti bi Adebayọ Adelabu lọjọ kejidinlọgbọn osu Kẹsan ọdun 1970.
Aderibigbe Adelabu ni orukọ baba rẹ, ti baba rẹ agba, Adegoke Adelabu, ti gbogbo eeyan mọ si ‘Pẹnkẹlẹmẹsi’ nigba aye rẹ, si jẹ gbaju-gbaja agba oselu nilẹ Ibadan.
Igba ọtun de fawọn afọju ninu eto idibo
Grandma Maruwa: Ó yẹ kí obìnrin sisẹ́ láì wojú ọkọ kó tó jẹun
Adebayọ lọ si ileẹkọ alakọbẹrẹ Ibadan Municipal Government (IMG), to wa ni adugbo Agodi nilu Ibadan, laarin ọdun 1976 si 1982, ko to morile ile ẹkọ girama Lagelu Grammar School lọdun 1982 nibi to ti jade iwe mẹwa lọdun 1987.
Adebayọ gba oye imọ ijinlẹ akọkọ, Isọri kinni (First Class) ninu imọ nipa isiro owo (Accountancy), nile ẹkọ fasiti Ọbafẹmi Awolọwọ nilu Ile Ifẹ, to si jẹ ọmọ ẹgbẹ awọn akọsẹmọsẹ oluṣiro owo lorilẹede Naijiria, ICAN.
Oríṣun àwòrán, Adebayo_Adelabu
Awọn ileeṣẹ ti Adebayọ Adelabu ti ṣisẹ bii oluṣiro owo
Ileeṣẹ oluṣiro owo kan to jẹ tilẹ okeere amọ ti ẹka rẹ fidi kalẹ si orilẹede Naijiria, ti wọn pe ni PriceWaterhouseCoopers ni Adebayọ ti kọkọ ṣisẹ ni kete to jade nile ẹkọ fasiti.
Ọdun meje gbako lo lo nile isẹ naa, to si dari oniruuru ẹka lab ileesẹ ọhun nilẹ yii ati loke okun.
Lọdun 1999 lo gba aye lati lọ ṣare sisẹ pẹlu banki apapọ ilẹ wa (CBN), fun ọdun kan pere, nibẹ lo si ti ko ikọ kan sodi eyi to ṣe atunto banki agba naa, eyi ti wọn pe akori rẹ ni akanse isẹ  ‘Project Eagles’.
Oríṣun àwòrán, @BayoAdelabu
Ọdun 2009 lo fi ileesẹ PriceWater silẹ gẹgẹ bii Alakoso eto ayẹwo iwe owo, to si lọ dara pọ mọ banki olokoowo First Atlantic.
Lẹyin eyi lo tun lọ ṣiṣẹ ni Standard Chartered Bank, to si di ipo Oludari fun ẹka isuna ati aato banki naa fun ẹkun iwọ oorun Afrika mu, ti ọọfisi rẹ si wa nilu Eko ati Abuja.
Banki yii lo wa titi to fi di Oludari agba fun First Bank of Nigeria lọdun 2009, ẹni ọdun mọkandinlọgbọn si ni nigba to de ipo giga ọhun.
Oríṣun àwòrán, @Adebayo_Adelabu
Aarẹ ana, Goodluck Jonathan lo yan Adebayọ bii igbakeji Gomina fun banki agba ilẹ wa loṣu keji ọdun 2014, ipo yii si lo wa to fi fẹyin ti.
Irinajo oṣelu Adebayọ Adelabu
Yatọ si pe gbaju-gbaja olokoowo ni Adebayọ, to si ni ileesẹ aje kaakiri ilu Ibadan, o tun jẹ eekan ti ko ṣe fi ọwọ rọ sẹyin lagbo oṣelu nipinlẹ Ọyọ.
Ogunjọ oṣu Kẹfa ọdun 2018 lo si yọju sita bii oloselu lasiko to fi erongba rẹ han nileesẹ gbe oṣelu APC lati dije ninu ibo abẹle ẹgbẹ naa fun ipo gomina ipinlẹ Ọyọ.
Oríṣun àwòrán, @BayoAdelabu
Adebayọ lo jawe olubori ninu ibo abẹnu ẹgbẹ oṣelu APC nipinlẹ Ọyọ ninu ibo abẹnu to waye lọgbọjọ oṣu Kẹsan-an ọdun 2018 gẹgẹ bii oludije fun ipo gomina labẹ ẹgbẹ oṣelu naa.
Rice Subsidy: Ìjọba àpapọ̀ gbé ₦60bn kalẹ̀ bíi owó ìrànwọ́
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Rice Subsidy: Ìjọba àpapọ ṣétàn láti yá àwọn àgbẹ̀ ìrẹ̀sì lówó
Mínísítà feto ọ̀gbìn, Audu Ogbeh ní ìjọba àpapọ̀ tí buwọ́lu ọgọ́ta bílíọ̀nù náírà gẹ́gẹ́ bíi owó iranwọ fún ìpèsè ìrẹsì ní orílẹ́-èdè Nàìjíríà.
Ó sọ èyí di mímọ̀ lẹ̀yìn ìpàdé pẹ̀lú àjọ tó ń mójú tó ààbò oúnjẹ tó wáyé ní ilé ìjọba nílù Abuja.
Ayàwòrán Obama: Ọ̀pọ̀ ìgbà ni èmi àti ìyá mi pa èbi mọ́nú kí n tó jẹ́ èèyàn
Nínú ìpádé ọ̀hún, eyi ti ààrẹ Muhammadu Buhari darí, ní mínísítà ti sàlàyé pé owó ìrànwọ ọhún ni láti mú àdínkù bá owó ìrẹ̀sì tó gbówó lórí gọbọi.
Ó ní ọ̀nà ọ̀tọ̀ ní àwọn yóò gbé owó ìrànwa eléyìí gba lójuna àti mase kó sínú wàhálà tí wọn kojú, lásìkò owó ìrànwọ́ epo bẹtiro, nítori náà ìgbìmọ tẹ̀ẹ́kótó yóò dìdé, tí mínísítà fún ìsúna yóò wà nínú rẹ̀ pẹ̀lú, láti sètò tó bá yẹ.
Oríṣun àwòrán, @Auduofficial
Rice Subsidy: Ìjọba àpapọ ṣétàn láti yá àwọn àgbẹ̀ ìrẹ̀sì lówó
Ogbeh fí kún-un pé, ó sàn láti yá àwọn àgbẹ́ ìrẹ̀sì, àwọn tó n bó ìrẹ̀sì àtí àwọn alágbàtà lówó pẹ̀lú èlé tí kò guni lápá.
Osun: Aregbesola ń kó'gbá sílé, Gboyega ń gbàjọba l'Ọ́ṣun
Oríṣun àwòrán, Aregbesola
Gboyega Oyetọla ni olori awọn oṣiṣẹ to n ba gomina Arẹgbẹṣọla ṣiṣẹ fun ọdun mẹjọ
Ipinlẹ Ọṣun ti n gbaradi fun ayipada iṣejọba ni ipinlẹ naa.
Ni ọjọ iṣẹgun ni Alhaji Gboyega Oyetọla yoo gba ijọba lọwọ gomina Rauf Arẹgbẹṣọla gẹgẹ bii gomina tuntun ni ipinlẹ ọhun.
Ni asiko idibo sipo gomina eyi to waye ni oṣu kẹsan ọdun 2018 ni awọn oludibo nipinlẹ Ọṣun yan gboyega Oyetọla gẹgẹ bii gomina tuntun lẹyin atundi ibo to waye laarin oun pẹlu Sẹnetọ Ademọla Adeleke ti ẹgbẹ oṣelu PDP.
Ni ọjọ kẹtadinlogun oṣu kọkanla ọdun 2010 ni gomina to n fipo silẹ nipinlẹ Ọṣun, Rauf Arẹgbẹṣọla gun ori oye lẹyin idajọ ile ẹjọ kan to kede rẹ gẹgẹ bii ẹni ti ara ilu dibo yan ni tootọ lẹyin ti Ọmọọba Ọlagunsoye Oyinlọla ti wa ni ipo naa fun ọdun mẹta.
Oríṣun àwòrán, Omonijo Sunday
Ni ọjọ kẹtadinlogun oṣu kọkanla ọdun 2010 ni gomina to n fipo silẹ nipinlẹ Ọṣun, Rauf Arẹgbẹṣọla gun ori oye
Gboyega Oyetọla ni olori awọn oṣiṣẹ to n ba gomina Arẹgbẹṣọla ṣiṣẹ fun ọdun mẹjọ ti o fi wa nipo ki wọn to dibo yan an gẹgẹ bii gomina ipinlẹ naa.
Ọkan o jọkan awọn alejo ni wọn ti wọ ilu Oṣogbo ni igbaradi fun ayẹyẹ ijẹjẹ fun ipo gomina ti wọn yoo ṣe fun gomina tuntun Gboyega Oyetsla ni ọjọ iṣẹgun, ọjọ kẹtadinlọgbọn oṣu kọkanla ọdun 2018.
Oríṣun àwòrán, Rauf Aregbesola, Facebook
Nipari Osu kọkanla ni ọgbẹni Aregbesola yoo fi ijọba silẹ
Gomina ipinlẹ Ọṣun to n palẹmọ lati kuro lori oye, Rauf Aregbesola,ti ju ọrọ gbankọgbi kan kalẹ pẹlu bi o ti ṣe ni oun ko gba owo osu lọdun mẹjọ to fi jẹ gomina.
Lori eto kan nibi ti o tin ba ara ilu sọrọ lo ti lede ọrọ yi to si ni ọun ko nilo owo nitori ijọba lo n bọ́ ohun, to n san owo ọkọ ti wọn si tun fun oun ni ile igbe.
O ni ''pẹlu gbogbo nnkan wọn yi, mi o nilo owo''
Àwọn oṣiṣẹ feyinti ni Osun ṣé iwọde
Arẹgbẹṣọla: Kò sí ìjọba tí kìí jẹ gbèsè
Ṣugbọn ọrọ yi ti mu iriwisi orisirisi wa ti awọn kan sin yinmu si pẹlu oun to sọ.
Lẹnu ọjọ mẹta yi ọrọ nipa owo oṣu ti awọn ti wọn dibo yan si ijọba n gba ti n kọ ọpọ lominu paapa julọ pẹlu bi ara ilu ti ṣe mọ wi pe awọn sẹnẹto n gba owo ajẹmọnu to ju owo osu wọn lọ nilọpo mẹtala.
Koda gomina kan tẹlẹ ri sọ wi pe ti awọn ara ilu ba mọ iye ti awọn gomina n gba , niṣe wọn yoo yari patapata.
Eeyan kan lori ẹrọ ayelujara woye pe ṣe ọmọde ni ogbẹni Aregbesola ro wi pe oun n ba sọrọ ni ti ẹlomiran si bere wi pe 'bawo ni ai gba owo osu Aregbesola ti ṣe mu adinku ba inira to n ba ara ilu?'
Losu to n bọ ni ọgbẹni Aregbesola yoo fi ipo silẹ gẹgẹ bii gomina.
Gboyega Oyetola ni yoo gba ipo lọwọ rẹ lẹyin to jawe olu bori ninu ibo to waye losu kẹsan.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí:
Grandma Maruwa: Ó yẹ kí obìnrin sisẹ́ láì wojú ọkọ kó tó jẹun
Ìtàn Mánigbàgbé: Hubert Ogunde jẹ́ kọ́sítébù ọlọ́pàá àti olùkọ́, kó to bẹ̀rẹ̀ eré síse
Oríṣun àwòrán, @hubertogunde
Ere tiata ti di gbajugbaja ti ọpọ n fi le ọmọ lọwọ bayii
Yoruba ni odo kii gun, ko ma ni orirun.
Bẹẹ naa ni isẹ ere itage sise jẹ, tori Hubert Adedeji Ogunde ni ọpọ eeyan gba pe o bẹrẹ ere tiata lede Yoruba, eyi to wa di itẹwọgba lode oni.
Oniruuru ere itage to n kọni lọgbọn, pani lẹrin, to si tun n kọ ni lẹkọ ni Ogunde ti ṣe jade nigba aye rẹ, bẹẹ si ni awọn awo orin rẹ lo maa n gbe jade lati fi kilọ fun iwa ibajẹ lawujọ wa, paapa laye awọn oyinbo amunisin.
Oríṣun àwòrán, @hubertogunde
Ọpọ igba lawọn obinrin n pagbo yi awọn oṣere ka
Bi Hubert Ogunde tilẹ ṣilẹ bora, sibẹ ko yẹ ka gbagbe awọn iṣẹ takun-takun to ti gbe ṣe lati ṣeranwọ fun aṣa, iṣe ati ede Yoruba ko ma baa parun, idi si ree taa fi gbọdọ mọ ohun kan tabi meji nipa irufẹ eeyan ti Ogunde jẹ.
Oríṣun àwòrán, @hubertogunde
Iná PHCN tó dé lójijì ṣàkóbá ńlá ní Ibadan
Ikogosi-Ekiti: Ilu ti omi tutu ti dapọ mọ gbigbona
Sogidi Lake: Kòṣẹja-kòṣèèyàn lá bá nínú adágún odò náà -Ojedele
Cancer: Àṣe ara mi ni iso ti n run gbogbo bí mo ṣe n ṣèrànwọ́ lórí jẹjẹrẹ
Mike Ifabunmi: Òrìṣà ló gbè wà jù ni Brazil
Yoruba ni ati oore, ati ika, ọkan kii gbe, nitori naa lo se yẹ ka se aye re.
Bi o tilẹ jẹ pe Hubert Adedeji Ogunde ti waye, o ti se iwọn to lee se, ti ipa to fi lelẹ ninu idagbasoke igbe aye ọmọniyan ko si lee parẹ;
O yẹ ki awa ta jẹ abẹmi loke eepẹ loni fi eyi se awokọse rere, ka si se aye re.
Bakan naa lo yẹ ka maa bi ara wa leere pe ti mo ba lọ tan, ki ni aye yoo maa wi nipa temi?
'500 level'' ni mo wà nígbà tí mo di adélé Ọba'
Tani Kingsley Moghalu, ọ̀dọ́ tó fẹ́ jẹ ààrẹ?
Oríṣun àwòrán, Facebook/KingsleyMoghalu
ọpọ ọdọ Naijiria lo jade lati dupo arẹ lasiko yii
Kingsley Moghalu ni olùdíje fún ipò ààrẹ Nàìjíríà lábẹ́ àsìà ẹgbẹ oṣelu Young Progressives Party (YPP) ní ìbò ọdún 2019.
Ó jẹ́ ọ̀kan lára àwọn olùdíje fún ipò ààrẹ Nàìjíríà tó ṣe ìlérí pé òun yóò ṣe àtúntò (restructuring) orilẹ̀-èdè tó ní ènìyàn pò ní ilẹ̀ adúláwọ̀ tó bá di ààrẹ.
'Obìnrin ló ni ilé àti àdúgbò fún ìdí èyí wọ́n lè ṣe ìlú dáadáa'
Ìtàn ìgbésíayé Kingsley:
Wọ́n bí Kingsley Moghalu ní ọdún 1963.
Moghalu àti àwọn òbi rẹ̀ gbé ìgboro Geneva ní orílẹ̀-èdè Switzerland àti ìgboro Washington ní orílẹ̀-èdè Amẹ́ríkà fun igba pipẹ.
Láàrín ọdún 1970 sí 1980 Moghalu kàwé ní ilé ìwé girama ìjọba àpapọ̀ tó wà ní Umuahia, ìyen Federal Government College Umuahia.
Oríṣun àwòrán, Facebook/KingsleyMoghalu
Kingsley Moghalu ń ti ń káakiri gbogbo orílẹ̀-èdè Nàìjíríà fún ìpòlongo
Osinbajo: Ikẹnnẹ yẹ kó jẹ́ Mẹ́kà òṣèlú ni
Ní ọdún 1986 ni Moghalu gba oyè ìmọ̀ ìjìnlẹ̀ àkọ́kọ́ LLB lóríi òfin ní fásitì Nììjíríà, (UNN), tó sì lọ́ sí ilé ẹ̀kọ́ agbẹjọ́rò tó wà l'Ékó, Nigerian Law School.
Moghalu gba oyè ìjìnlẹ̀ ẹlẹ́ẹ̀kẹjì ní ilé ìwé ìmọ̀ òfin Fletcher ní Fáṣitì Tufts l'Ámẹ́ríkà níbi tó ti jẹ́ akẹ́kọ̀ọ́ lá bẹ́ ètò ẹ̀kọ́ Gillespie àti olùrànlọ́wọ́ lórí ìwádìí nípa ètò ìṣúná àti ìṣèlú orilẹ̀-èdè sí orílẹ̀-èdè ní ọdún 1992.
Lẹ́yìn ìgbà náà ni Moghalu gbà oyè ìjìnlẹ̀ elẹ́ẹ̀kẹẹ̀ta (Ph.D) lórí ìṣèlú orílẹ̀-èdè sí orílẹ̀-èdè ní London School of Economics tó wà ní fásitì London.
ìpàdé ìtagbangba ìfọ̀rọ̀wánilẹ́nuwò pẹ̀lú àwọn olùdíje sípò gomina ní ìpínlẹ̀ Eko.
Bákan náà ó gbà oyè olọ́kanòjọ̀kan ní fásitì Havard àti ti Pennsylvania.
Moghalu ṣe igbákejì gómìnà bánkì àpapọ̀ Nàìjíríà (CBN) láti ọdún 2009 sí 2014.
Láti ìgbà náà a kò gbọ́ nǹkan púpọ̀ nípa Moghalu mọ́ títí tó fi gbé àpótí ìbò.
2019 Elections: Èrò àwọn ọmọ Nàíjíríà se ọ̀tọ̀ọ̀tọ̀ lóri ètó àlùfáà tàbí ìmámù lásìkò ìbò
Oríṣun àwòrán, Facebook/KingsleyMoghalu
Awọn mẹkunnu naijria ṣetan lati dibo lọdun 2019
Ó ní ìgbàgbó pé ètò ẹ̀kọ́ tó pé ye àti ètò ìsúná fún àwọn onísòwò ló lè tán ìṣẹ́.
Kingsley fẹ́  kí àwọn dókítà Naìjíríà má lọ ṣiṣẹ́ lókè òkun mọ́n.
Murphy Elégungun Rọba: Mo fẹ́ di ẹnití egungun rẹ rọ jùlọ ní àgbáyé
Ẹ̀tò àtúntò (restructuring) tí Kingsley gbà lérò
Ó ń fẹ́ kí wọ́n pín Nàìjíríà sí ọ̀nà mẹ́fà gẹ́gẹ́ lábẹ́ ìsàkóso ìjọba àpapọ̀.
Ó fẹ́ kí wọ́n pa gbogbo ìpínlẹ̀ mẹ́rìndínlógójì tó wà ní Nàìjíríà rẹ́.
Ó fẹ́ kí gbogbo ìpínlẹ̀ kọ̀ọ̀kan nínú mẹ́fà máa bọ́ 'rarà.
Oríṣun àwòrán, Facebook/KingsleyMoghalu
Ọ̀tọ̀ ni nkan tí wọ́n sọ fún ẹbí rẹ̀, iṣẹ́ aṣẹ́wó ni wọ́n fi n ṣe
Moghalu Kingsley fẹ́ kí gbogbo ìpínlẹ̀ l'ágbára lórí nǹkan àlùmọ́nì tó wà lábẹ́ wọn.
Ó fẹ́ fi òpin sí títa nǹkan àlùmọ́ọnì láì yí wọ́n padà sí nǹkan tó lówó lórí.
Ó fẹ́ kí wọ́n ya ẹ̀sìn kúrò lára ìṣẹ̀lú
Obasanjo: Atiku kìí se Áńgẹ́lì, àmọ́ yóò se dáadáa ní ìlọ́po méjì ju Buhari lọ
Sowore: olùdíje Ààrẹ tó loun fẹ gbà Nàìjíríà padà fún àwọn ọdọ
Sòwòrẹ́: Èmi kò leè bá jẹgúdújẹrá APC àti PDP se pọ̀
Ṣaṣa ni ọmọ Naijiria ti on fi ọkan tele awọn isẹlẹ lori ẹrọ ayelujara ti ko ti gbọ nipa Sahara Reporters.
Ile isẹ iroyin naa ti wọn da silẹ ninu iyara kolobo kan ni ilu Manhattan lọdun 2006 wa lati koju awọn iwa ibaje ni eto isejọba Naijiria.
Omoyele Sowore, ọmọ ọdun mẹ́tàdínláàdọ́ta to n du ipo Aarẹ lorileede Naijiria labẹ asia ẹgbẹ oselu African Action Congress (AAC) ni oludasilẹ ile iṣẹ iroyin naa.
Oríṣun àwòrán, omoyele
Ọjọ kẹẹdọgbọn, Oṣu keji, 2018 ni o kede erongba rẹ lati du ipo Aarẹ orileede Naijiria ṣugbọn saaju igba naa ni o ti n dasi oselu Naijiria.
Lati kekere ni aisedede ti o n waye lawujọ ti jẹ nnkan to n kan ni ominu.
Nitori pe o wa lati idile olorogun,titiraka lati pese ijẹ imu jẹ ohun ti o ti n ba finra tipe ti eyi si mu ki o pinu lati ri wi pe ohun lo gbogbo ọna lati mu iyipada ba awujọ.
Oríṣun àwòrán, Omoyele Sowore
'A ni òfin púpọ̀ ní Naijiria ṣùgbọ́n a kò bọ́wọ́ fún un ni'
Oríṣun àwòrán, AFP
Awọn ọdọ Naijiria a ma gbaruku ti Sowore lọpọ ibi to ba ti n ṣe ipolongo
Lọdun 1989 o kopa ninu iwọde awọn akẹkọ fasiti ilu Eko(Unilag) eleyi ti awọn akẹkọ ṣe lati tako awọn gbedeke to rọmọ owo iya ọgọfa miliọnu ti ijọba fẹ gba lọwọ ile ifowopamọ agbaye nii IMF.
Lara ohun to rọ mọ owo iya yi ni ki ijọba mu adinku ba iye ile ẹko fasiti to wa ni Naijiria lati mejidinlọgbọ si maarun.
Awọn to mọ Soworẹ ni bi ọrọ ba niiṣe pẹlu jija fun ẹtọ omoniyan,Sowore kii gbeyin.
BBC Gov Debates: Ètò ẹ̀kọ́ ọ̀fẹ́ ni àwọn olùdíje yóò ṣe
Oríṣun àwòrán, Omoyele Sowore
Odu ni Omoyele Sowore fun awọn ologun ki ṣe aimọ
Awọn to wa lori alefa nigba ti Naijiria wa labẹ Ijọba ologun  mọ Sowore bi ẹ ni mọ owo fun bi o ti ṣe ma n le iwaju ninu awọn iwọde to n tako isejọba ologun.
Oríṣun àwòrán, Alamy
Sowore nibi ti o ti n se ere idaraya
Bo je ni ọdun 1992 ti wọn fi si ahamọ fun pe o kopa ninu iwọde ti awọn ọlọpa ti yinbọn pa eeyan meje tabi lodun 1993 to lewaju nigba iwode idibo June 12,Sowore kii ṣe ẹran rirọ ti awọn alaṣẹ le fọwọrọ sẹgbẹ.
Ademọla Ogunbanjo: A nílò bàbá ìsàlẹ̀ nínú òsèlú
Ilakaka rẹ ninu jija fun ẹtọ ọmọniyan wa lara awọn ohun to mu ki awọn eeyan Naijiria lero wi pe yoo jẹ Aare ti o le ni aanu mẹkunu loju.
Agbẹjọro Gani Fawehinmi ati Fela Anikulapo Kuti jẹ awọn to ti saaju gbe iru igbese ti Sowore n gbe yi sugbọn ti wọn ko ribi ruu ja.
Ọrọ naa le koro leti ṣugbọn ootọ ibẹ ni wi pe: oselu Naijiria ko dẹrun lati kopa  fun ẹni ti ko ba ni Baba isalẹ lẹyin tabi ti ko ni owo ti yoo fi du ipo.
Koda a ti ri awọn to lowo ti gbogbo aye si gba ti wọn bi MKO Abiola ti ko ri bi de ipo Aarẹ.
Oríṣun àwòrán, Omoyele Sowore
Falana: Awọn to n dije dupo ìdìbò 2019 fẹ́ fa ogun si Naijiria
Ọpọ nnkan ti Sowore n sọ ninu awọn ifọrowanilẹnuwọ jọ bi ẹ ni wi pe ti oba de ori alefa,yoo gba gbogbo awọn agbagba oloselu si ẹgbẹ kan ti yoo si fi isejọba ọdọ rinlẹ.
Ohun ti awọn kan fẹ ni iru erongba yi sugbọn gẹgẹ bi a ti ṣe sọ saaju, ẹnu lasan ko ni le ṣe ni orileede Naijiria nibi ti awọn ẹgbẹ oselu bi PDP ati APC ti fẹsẹ rinlẹ gidigba.
Oríṣun àwòrán, Omoyele Sowore
Ninu ojo
Sowore ati awọn alatilẹyin rẹ ko sọ ireti nuu ti wọ́n si gbagbo wi pe ọ́dun 2019 yoo jẹ ọdun ti awọn ọdọ Naijiria yoo kopa ribiribi ni isejọba.
-O ti sa ere ọlọgbọnrangandan (Marathon) mẹjọ lẹnu igba ti o daye
-Sowore gbagbo wi pe ẹtọ  gbogbo obinrin ni ki wọn di ipo oselu mu.
-O ni ohun yoo sapa bi Naijiria yoo ti ṣe ma ta igbo lọ si ilẹ okere lati le mu ọrọ aje Naijiria gboro si.
-Ẹgberun lọna ọgorun Naira lo ni ohun yoo ma san fun awọn agunbanirọ ti wọn ba yan ohun gẹgẹ bi Aarẹ
World Toilet Day: Onímọ̀ kan ní ìpèsè ilé ìgbọ̀nsẹ̀ nìkan kò lè tàn ipenija yí
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Orisisrisi aisan lawọn eeyan ma n ko latara yiyagbe sita
Ati oṣisẹ ilera ati ara ilu, ko si ẹni to ko fẹ ẹ mọ ipalara ti ṣiṣe igbọnse si ita gbangba n ṣe lawujọ.
Yala ni awọn ilu kekeeke tabi lawọn ilu nla bi Abuja, Eko tabi Port-Harcourt, ipenija yii jẹ ohun to n kọ awọn eeyan lominu.
Ninu iwadi kan ti Ajọ to n risi idagbasoke ọmọ wẹwẹ lagbaye, UNICEF gbe jade lọdun 2017, Naijiria wa ni ipo kẹji ninu awọn orileede ti ṣisẹ igbọnsẹ ni ita gbangba ti peleke.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Orileede India naa n ba ipenija igbẹ yiya ni ita gbangba finra
Pẹlu bi iṣesi yii ti ṣe gbale, ki ni awọn aburu to wa ninu ki eeyan ma yagbẹ si ita gbangba lalai bikita.
A na ọwọ ibeere yi si onimo isegun ilera ayika ẹni, Dokita Olajire Olanrewaju, to si salaye fun ileese BBC Yoruba wi pe, ewu nla lo wa ninu ki awọn ara ilu ma yagbẹ sita gbangba.
'Yato si wi pe o fun Naijiria lorukọ buruku laarin awọn orileede to ku,iwa yi a ma ṣe ipalara fun ilera ati alafia ara ilu.'
Èwo ló pàtàkì jùlọ nínú ẹ̀rọ ìbánisọ̀rọ̀ àti ilé ìgbọ̀nsẹ̀?
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Iwa ṣiṣe gaa yi ko yọ agba naa silẹ
O salaye pe, pupo ninu awọn aisan ti o ma n ba ẹdọ inu ara jẹ, bii Hepatitis A ati Typhoid, maa n wọwa latara bi igbọnse ṣe ma n dapọ mọ omi mumu.
Dokita Olanrewaju ni, lawọn ipinlẹ bii Kebbi, Sokoto ati Zamfara nibi ti awọn ijọba wọn ko ti kọ ibi ara si kikọ ile igbọnse, orisirisi aisan a ma ba awọn ara ilu finra.
Dokita Olanrewaju ni, pelu bi nnkan ti ṣe ri lawujọ loni, o di dandan ki ijọba ṣe agbedide awọn oṣiṣe ilera ti yoo maa tọpinpin ibi ti awọn eeyan n ṣe ibẹrẹ si.
'Bi eeyan ba tapa si ofin, ọlọpa yoo mu iru ẹni bẹẹ, bi ara ilu ba wuwa aitọ nipa ayika, nibo lawọn wolewole wa ti yoo mu iru ẹni bẹẹ?'
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Awọn wole wole kii mojuto ibi ti awọn eeyan ti n se ounjẹ lopọ awọn agegbe ni Naijiria
Dokita Olanrewaju ni, o di dandan ki ijọba pese ohun eelo to yẹ fun awọn oṣise ilera yii lati ṣe iṣẹ wọn.
"Ẹyin e woo nnkan ti ijọba Eko ṣe pẹlu ile ise to n ṣe ọṣẹ kan nipa bi wọn ti ṣe kọ ile iyagbe si awọn arin ọja kaakiri.
Iru igbese yi daa pupọ ti a ba fẹ dẹkun iwa ibaje ka ma yagbẹ sita gbangba."
O rọ awọn ara ilu naa ki wọn ri wi pe wọn mu imọtoto wọn lokunkundun.
Okeho Robbery: Ó tó 60 mílíọ̀nù tí àwọn olè jí ṣùgbọ́n a kò rí kọ́bọ̀ gbà padà- Òṣìṣẹ́ banki
Oríṣun àwòrán, Others
Ileeṣẹ ọlọpaa ni ipinlẹ Oyo ti ni iwadii ti bẹrẹ ni pẹrẹwu lori ibi ti ọwọ ti awọn adigunjale gbe ni banki to wa ni ilu Okeho wọlẹ si.
Agbẹnusọ awọn ọlọpaa ni ipinlẹ Oyo, Olugbenga Fadeyi lo fi idi ọrọ naa mulẹ fun BBC.
Eyi ko ṣẹyin ẹsun ti ileeṣẹ banki naa ṣe ni awọn araalu gan an lo gba owo ti awọn adigunjale naa jigbe lọ, ti wọn si pin laarin ara wọn.
Amọ, Fadeyii ni awọn ko i tii le fi idi ọrọ naa mulẹ, amọ awọn n fi ọrọ wa awọn adigunjale marun un to wa ni panpẹ awọn lẹnu wo lori bi owo naa ṣe rin.
O ni: ''Gbogbo awọn olè naa kọ ni awọn araalu Okeho sun ni ina, marun un si wa ni agọ ọlọpaa wa
A n ṣewadii lori ibi ti awọn adigunjale naa ti wa, ki lo de ti wọn se fọ banki naa ati owo ti wọn jigbe nibo lo wa?''
Bakan naa ni agbẹnusọ awọn ọlọpaa naa ni awọn yoo ṣe afihan awọn adigunjale naa laipẹ ti awọn yoo si fi abajade iwadii awọn fihan awọn ọlọpaa.
Wọn ti fẹsun kan awọn olugbe ilu Okeho, to wa ni ijọba ibilẹ Kajola ni ipinlẹ Oyo pe wọn kò obitibiti owo ti wọn gba lọwọ awọn adigunjale to ṣakọlu si banki kan lagbegbe ọhun.
Nigba to n fidi iṣẹlẹ naa mulẹ fun ileeṣẹ iroyin abẹle kan, Baalẹ ilu naa, Rafiu Mustapha sọ pe iwadii ti bẹrẹ lati fi panpẹ ofin mu awọn ọdaran naa.
Oríṣun àwòrán, others
Bakan naa ni ọkan lara awọn adari banki ti awọn adigunjale ọhun ṣakọlu si, ti ko fẹ ki wọn darukọ oun ṣalaye pe awọn ọlọdẹ ati ọmọ ẹgbẹ OPC ilu naa ṣe ọkan akin lati dojukọ awọn adigunjale ọhun nigba ti wọn n ṣọṣẹ.
O ni awọn eeyan naa kọlu awọn adigunjale ọhun, wọn mu mẹrin lara wọn, wọn si lu wọn ni ilu bara.
Ṣugbọn o ni ọkọ ti awọn adigunjale naa ko owo ti wọn ji si ṣagbako ijamba nigba ti wọn n gbiyaju ati salọ, awọn ara ilu kan si kọlu awọn adigunjale naa ti wọn si ji owo ti awọn ole ọhun ko.
"Gẹgẹ bo ṣe sọ pe: ""O ṣeni laanu pe iṣẹ akin ti awọn ọlọde ati ọmọ ẹgbẹ OPC ṣe ja sofo nitori iwa ọkanjua ti awọn eeyan ilu naa wu lẹyin iṣẹlẹ naa."""
BBC Africa Eye: ìwádìí ìkọ̀ks BBC fihàn pé àwọn kan ń jí ohun èèlò ìdáàbòbò ìjọba tà nígbo
Owo ti awọn adigunjale naa ji ko din ni ọgọta miliọnu naira, ṣugbọn a ko ri kọbọ gba pada nitori awọn ara ilu to ko gbogbo rẹ tan.
O ṣalaye pe ibanujẹ nla ni pe ko si iyatọ laarin awọn adijale to kọlu ile ifowopamọsi naa atawọn ara ilu to tun ji owo ọhun gba lọwọ wọn.
O ni awọn ara ilu ọhun ni lati ṣatunṣẹ orukọ wọn, bi bẹẹ kọ, o ṣeeṣe ko jẹ pe wọn mọ nipa idigunjale naa.
Teach your children Yoruba: Wo àwọn òyìnbó tó ń kẹ́kọ̀ọ́ èdè Yorùbá ní Michigan, America
Ki lo ti ṣẹlẹ sẹyin?
Oríṣun àwòrán, @SaifRikiji
Ọlọpaa kan ati araalu miran lo tun farapa ni Ọjọbọ, lẹyin ti ado oloro dynamite tun bu gbamu ni ile ifowopamọ First Bank to wa ni agbegbe Okeho, nipinlẹ Oyo.
Agbegbe yii ni awọn adigunjale ti sọṣẹ ni Ọjọọru, ti ẹmi awọn eniyan kan si lọ si iṣẹlẹ naa.
Awọn araalu naa pejọ pọ, ti wọn si dana sun mẹrin ninu awọn adigunjale naa, ti awọn meji si wa ni panpẹ ọlọpaa.
Ni Ọjọbọ ni iroyin gbe e pe, awọn eniyan tun pejọ pọ si banki naa lasiko ti awọn ọlọpaa wa ṣe ayẹwo sibẹ, lati mọ iru ijamba to waye nibẹ.
Oríṣun àwòrán, @SaifRikiji
Iroyin ni ṣe ni awọn eniyan bẹrẹ si ni fariga, ti wọn si n rọ awọn ọlọpaa lati fun awọn ni adigunjale meji to wa ni panpẹ wọn, ki awọn ba le dana sun wọn.
Lasiko naa ni ado oloro dynamite miran tun bu gbamu nibẹ, to si fa ipalara fun ọlọpaa kan ati ọkan lara awọn afẹhonu han naa.
Kọmisana ọlọpaa ipinlẹ Oyo,  Nwachukwu Enwonwu ni awọn eniyan naa wa kọju ija si awọn ọlọpaa lasiko yii.
Oríṣun àwòrán, @SaifRikiji
Enwonwu ni oun paṣẹ fun awọn ọlọpaa lati kuro ni agbegbe naa, ki ifẹhonu han ma ba a da rogbodiyan silẹ.
O fikun pe awọn ọlọpaa naa lọ ibomiran, amọ awọn afẹhọnu han naa tun tẹlẹ wọn.
Nitori naa ni wọn ṣe wa kuku kuro ni agbegbe naa patapata, ki ifẹhọnu han ma ba a mu ẹmi ẹnikẹni lọ.
Oríṣun àwòrán, Others
Bakan naa lo ni ileeṣẹ ọlọpaa ti mu awọn adigunjale meji to wa ni panpẹ wọn naa wa si ilu Ibadan fun iwadii ijinlẹ to munadoko.
Ọga ọlọpaa ni ipinlẹ Ọyọ, Joe Nwachukwu Ewonwu ti ṣalaye pe, awon agbebọn kan wa digun ja banki First Bank to wa niluu Okeho lole, ni nnkan bii agogo mẹfa abọ Ọjọru.
Ìdílé tí ọkọ da ọmọ síta tóríi ojú Búlùú tí wọ́n ní bá BBC sọ̀rọ̀
Ninu atẹjade kan eyi ti ileeṣẹ ọlọpaa ni ipinlẹ Ọyọ fi sita, eleyii ti alukoro rẹ, SP Fadeyi Oluugbenga fi fọwọsi ni alaye naa ti jẹyọ.
Gẹgẹ bi o ṣe sọ, awọn eroja ado oloro pẹlu awọn ibọn atamatase AK47 ni wọn fi fọ ẹnu ọna banki naa wọle.
Amọṣa o fi kun un pe, awọn olopaa kogberegbe atawọn fijilante pẹlu ọdẹ jumọ kọ oju oro s'awọn Adigunjale naa ti wọn si ṣe aṣeyọri.
"Lẹyin o rẹyin ""ọwọ tẹ mẹta ninu awọn ọlọṣa naa nigba ti ọkọ bọọsi ti wọn n gbe salọ gb'okiti taraalu si da ina sii nigba ti wọn fẹ salọ."
Oríṣun àwòrán, @comrade_ahmad
Kọmiṣọna ọlọpaa n'ipinlẹ Ọyọ si tete gbe ikọ ọlọpaa SARS, ọlọpaa kogberegbe MOPOL at'awọn ọlọpaa lagbegbe naa dide lati lọ koju wọn Ki wọn si tọ ipasẹ awọn iyoku wọn lọ.
Ọga ọlọpaa Ewonwu ko ṣai jẹ ko di mimọ faraalu, paapaa àwọn eeyan ipinlẹ Ọyọ pe awọn ọlọpaa yoo maa sa ipa gbogbo nigbakugba lati daabo bo ẹmi ati dukia araalu.
Oríṣun àwòrán, @mosobaky
Saaju la ti kọkọ mu iroyin wa fun yin nipa isẹlẹ kan to n ja rainrain lori ayelujara, eyi to ni awọn adigunjale mẹrin ni ọwọ palaba wọn segi ni Ọjọru nilu Okeho nipinlẹ Oyo.
Idi ni pe ode ko daa fun wọn nigba ti awọn ọdẹ ibilẹ to wa nilu naa bawọn fija pẹẹta pẹlu ibọn, lasiko ti wọn n digun jale.
Iroyin naa ni isẹlẹ naa buru to bẹẹ ti ẹmi osisẹ ọlọpa kan gan bọ ninu isẹlẹ naa.
Gẹgẹ baa se gbọ, awọn adigunjale naa ni wọn ya lọ sile ifowopamọ ati agọ ọlọpa to wa niwaju ile ifowopamọ naa.
Awọn adigunjale ọhun, ti wọn to meje niye la gbọ pe wọn sisẹ idigunjale ọhun, ti wsn si lo ohun eelo ibugbamu lati ri aaye wọle sinu ile ifowopamọ naa.
Oronpoto Animation: Akin Alabi ní kò dára bí eré aláwòrán fáwọn ọmọdé ṣe jẹ́ aláwọ̀ funfun
Sugbọn ilẹ pooyi fun wọn lọjọ naa, nigba ti awọn ọdẹ ibilẹ to wa nilu naa gba ya wọn, ti mẹta ninu wọn si juba ehoro.
Koda, a gbọ pe awọn araalu ti inu wọn dun si bi awọn ọdẹ naa se mu mẹrin balẹ ninu awọn adigunjale ọhun, tun dana sun oku wọn.
Bakan naa ni wọn n kan saara si awọn ọdẹ atamatase ọhun fun isẹ takuntakun ti wọn se lati fi oju awọn ole naa ri mabo.
BBC Yoruba yoo kan sileesẹ ọlọpaa laipẹ lati mu ẹkunrẹrẹ iroyin wa fun yin nipa isẹlẹ naa.
Ẹ ku oju lọna.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Adígunjalè kùnà láti fọ́ báǹkì l'Ọsun
Ọwọ́ pálábá àwọn afurasi adigunjale ti ṣegi lọ́jọ́ Ajé nígbà tí wọn gbìyànjú lati kọlu ilé ìfòwópamọ kan ní agbègbè Lagere ílùú Ilé-Ifẹ ní ìpínlẹ̀ Ọsun, nígbà táwọn ará adúgbo to ri wọn dìde láti jà.
Ìfipábánilòpọ̀: Abiamọ bú sẹ́kún nígbà tí ọkùnrin kan fi tipá bá ọmọ méjì lòpọ̀
Ilé ìfowópamọ méje ló ni ẹ̀ka ní àdúgbò Lagere yii tàwọn adìgunjalè gúnlẹ̀ sí ní dédé aago mẹ́wàá òwúrọ.
Gẹ́gẹ́ bí ọ̀kan nínú àwọn tí ọ̀rọ̀ náà ṣe ojú ẹ ṣe sọ, pé àwọn adigunjalè náà wọ àdúgbò nínú ọkọ̀ ayọ́kẹ́lẹ́ Toyota Camry àti bọọsi kan ti wọn gbé sí ẹgbẹ́ báǹkì náà, tí wọn sì bẹ̀rẹ̀ sí ní yìbọn sí inú afẹ́fẹ́ láti dẹ́rù ba àwọn ènìyàn.
Ẹ̀wẹ̀, àwọn agbófinró tí wọn fi sí ilé ìfowópaamọ àti àwọn ọlọ́dẹ àdúgbò ni wọn fìjà pẹ́ẹ́ta pẹ́lú wọn, èyí sì ló mú kí àwọn olè náà pẹ̀yìnda.
Agbẹ̀nusọ fún Ajọ ọlọpàá ní ìpínlẹ̀ Osun (SP) Folashade Odoro, náà fìdí ọ̀rọ̀ náà múlẹ̀ àtí pé iṣẹ́ sì ń lọ lọ́wọ́ láti mú àwọn afunrasí adigùnjalè náà.
Ìwádìí bẹ̀rẹ̀ lórí iná tó sọ nileeṣẹ EFCC
Oríṣun àwòrán, @officialEFCC
Lai pẹ yi ni wọn kọ olú iléeṣẹ́ tuntun fun EFCC kò le gba gbogbo àwọn òṣìṣẹ́ àjọ nàá tó wà ní ìlú Abuja.
Ajọ to n gbogun ti iwa jẹgudujẹra lorilẹ-ede Naijiria, EFCC, ni awọn yoo bẹrẹ iwadii ohun to fa ina to sọ ni ọọfisi wọn kan lAbuja.
Ina naa to sọ lẹka ajọ naa to wa ladugbo Wuse 2,  lAbuja la gbọ pe o bẹrẹ lalẹ ọjọ Aje.
Atejade kan ti ajọ naa fi sita lati ẹka to n ri si ọrọ iroyin sọ pe ọpẹlọpẹ awọn panapana to yara pa ina naa, ọtọ ni nnkan ti a ko ba máa sọ.
Bakan naa ni wọn ni ori ko awọn oṣiṣẹ meji kan yọ lọwọ ijamba ina ọhun
Ajẹ ké lana ọmọ ku loni
O jọ gáté kò jọ gàté lọrọ to wa nilẹ yi pẹlu pe ko tii ju ọjọ mẹrin lọ ti Aarẹ Buhari paṣẹ pé kajọ EFCC ṣe iṣiro gbogbo owo ti o ti ri gba ti ina fi sọ ni ile ti wọn n ko ifitonileti si.
Irufẹ iṣẹlẹ ina bayi ko jẹ tuntun ni Naijiria paapa julọ ti ọrọ ba ti niiṣe pẹlu ki awọn eeyan wa ṣe iṣiro owo tabi ti iwadii kan ba n lọ lọwọ.
Bi a ko ba gbagbe iru ina bayi sọ ni ọọfisi ajọ to n mojuto ere bọọlu lorile-ede Naijiria,  NFF lọdun 2014.
Ina jo ọja binukonu lọjọta
Iwadii kan n lọ lọwọ nigbana naa lori ẹsun jẹgudujẹrati wọn fi kan awọn alaṣẹ ajọ naa.
Ko tii  daju boya ejo lọwọ ninu pẹlu iṣẹlẹ ti EFCC yi ṣugbọn ireti wa wi pe ti iwadii ẹkunrẹrẹ ba waye, ohun to sokunkun nipa ijamba ina yi yoo di mimọ.
Car Race: Elizade àti Akeredolu kópa nínú ìdíje eré sísá ni Ondo
Ọlọpaa ni Abdullahi tó fipá bá ọmọdékùnrin méjì lò yoo foju ba ilẹ ẹjọ́
Ìfipábánilòpọ̀: Abiamọ bú sẹ́kún nígbà tí ọkùnrin kan fi tipá bá ọmọ méjì lòpọ̀
Arakunrin kan Abdullahi Garuba ti wọn fẹsun kan pe o fipa ba awọn ọmọdekunrin meji lopọ ni Ipinlẹ Eko ni awọn ọlọpaa ti foju rẹ han fun awọn oniroyin bayii.
Abdullahi to jẹ ni ọdun mejidinlọgọta ni awọn ọlọpàá ni o tan awọn ọmọdekunrin naa wọ inu ile rẹ ni ọjọ kẹwaa, osu kọkanla, ọdun yii.
Oríṣun àwòrán, Lagos State Police Command
Atẹjade kan lati ọwọ agbẹnusọ fun ileeṣẹ ọlọpaa ni Ipinlẹ Eko, Chike Oti ni ọga ọlọpaa ni Ipinlẹ Eko Edgal Imohimi ti gba awọn ọbi ni imọran wipe ki wọn ma ṣọ awọn ọmọ wọn.
Ọlọpaa ni Abdullahi yoo foju ba ilẹ ẹjọ́ laipẹ.
Awọn iya awọn ọmọ mejeeji ba BBC Yoruba sọrọ ni ibanujẹ, ti wọn si sọ ẹdun ọkan wọn pelu omije l'oju.
Wọn ni ọkunrin to fi tipa ba awọn ọmọ awọn lo pọ, tun si oju wọn si ibalopọ akọ si akọ taa mọ si ‘Homosexuality’ tabi ‘Gay’, eyi to se ajoji si awọn gan-gan.
Wọn salaye pe kẹkẹ ti Abdullahi naa, tii se ẹni ọdun marundinlọgọta ni, lo n mu kawọn ọmọde nifẹ lati maa rọgba yii ka, to si maa n lo eyi lati bawọn se asepọ akọ si akọ.
A gbọ pe lẹyin ti Abdullahi tan awọn ọmọ yii wọle tan, ti ọjọ ori wọn jẹ ọdun mọkanla, lo fi tipa ti wọn lu ibusun, to si fi tipa jẹ dodo ifẹ lara wọn.
Wọn ni o tun dunkoko mọ awọn ọmọde naa pe wọn ko gbọdọ sọ fun awọn obi wọn, tori ọjọ ti wọn ba sọ, ni wọn yoo ku.
Iwode fun Ochanya  ti won ba lopo waye nilu Eko
Awọn obi mejeeji ni Abdullahi ti wa ni ahamọ awọn ẹsọ aabo ara ẹni ni aabo ilu, taa mọ si ‘Civil Defence’. Ajọ alaabo naa ti fi Abdullahi ṣọwọ si awọn ọlọpaa.
Parental Guidance: Ọdún méjì ni kí ẹ ti bẹ̀rẹ̀ kíkọ́ ọmọ nípa ìbálòpọ̀
Ọọnìrìsà ṣe ìfilọ́lè àpérò ọlọdọodun àwọn lóbalọba láti pẹ̀tù sááwọ̀ wọn
Ọọni ti Ifẹ pe apero awọn lọbalọba
Awọn ladelade-loyeloye to le ni ọgọrun un lo kora jọ pọ silu Ile-Ifẹ fun akanṣẹ eto apero to da lorii imubọsipo ogo awọn lọbalọba ilẹ Yoruba. Lọjọ Iṣẹgun ni Ọọni Ile Ifẹ, Ọba Ẹnitan Ogunwusi, Ọjaja Keji gbalejo awọn Ọba alade naa ni gbagede igbalejo Ife Grand Resort to wà nilu Ile-Ifẹ.
Ọrọ àwọn lọbalọba ilẹ Yoruba gba apero
Ipade naa lo da lorii fifi opin si aawọ laarin awọn Ọba ilẹ Yoruba pẹlu ifojusun lati bomirin iṣọkan laarin wọn.
Ọọni Ogunwusi Adeyẹye pe fun itọju awọn ọdọ
"Ninu ọrọ rẹ, alaga igbimọ to ṣeto ipejọpọ naa, Ẹlẹ́rìnmọ̀ ti Ẹ̀rìnmọ̀, Oba Michael Odunayo Ajayi ṣe alaye fún BBC Yoruba pe lati aye atijọ ni awọn lọbalọba ti n kora jọpọ fun ipade, sugbọn ko ri bẹẹ mọ laye ode oni nitori ija ""emi ju ọ, iwọ ko ju mi"" to n waye laarin awọn ọba alade."
ọọni Ifẹ pe apero idagbasoke asa Yoruba
O fi kun ọrọ rẹ pe eyi lo mu ki Ọba Ẹnitan Ogunwusi ṣe agbekale apero naa fun itẹsiwaju gbogbo ilẹ Yoruba. Lara Ọba alade to kora jọpọ sibi apero naa ni, Ọọni Ile Ifẹ, Ọba Ẹnitan Ogunwusi, Ọjaja keji, Elerinmo of Erinmo, Oba Michael Odunayo Ajayi, Olupe ti Ipe Akoko, Oba Oludo Ido Ijesha, Oba Jegun Okitipupa ati bẹẹbẹẹ lọ.
Aṣa ati iṣe Yoruba kuro ni keremi
Awọn lọbalọba yii gbagbọ pe lẹyin apero yii, orí adé kọọkan a tun mọ iwa to yẹ ni hihu lawujọ ti ko ni maa tabuku ba ipo ọba ilẹ̀ Yoruba.
Wọn tun gbagbọ pe, gbogbo ija to n ṣẹlẹ laarin awọn lọbalọba yoo dinku lẹyin ti gbogbo wọn ba ti fọrọ jomitooro ọrọ tan.
Opolopo awọn ogidi ọmọ Yoruba lo ti n gabgbe ipo pataki to yẹ ki ori ade wà lawujọ.
Parental Guidance: Ọdún méjì ni kí ẹ ti bẹ̀rẹ̀ kíkọ́ ọmọ nípa ìbálòpọ̀
Ìran kan si ìkejì ló n gbèrò láti ṣe ìrú ìgbéyàwo àjùmọ̀ṣe 'Shao' fọ́mọ wọn
Ilé isẹ́ ológun nílò onímọ nípa kíkọjú Boko Haram -Temitope Olodo
Oríṣun àwòrán, Getty Images
'Ọmọogun Nàìjíríà
Orilẹede Naijiria nilo ile isẹ ologun to gbamuse fun idibo ọdun 2019 ki awọn agbeegbe ti Boko Haram ti sọsẹ le dibo ni irọwọrọsẹ.
Onimọ nipa eto abo lagbaye, Temitope Olodo lo salaye pe ile isẹ ologun nilo lati gba awọn onimọ nipa kikoju ikọ adunkokomọni lọna igbalode.
Temitọpe ninu ọrọ rẹ sọ wi pe Naijiria ko ni awọn onimọ to le sọ gbogbo bi awọn Boko Haram se n rin, ati ibi ti wọn ba n rin si, ki wọn ba le maa fi iroyin to yẹ lede fun awọn ọmogun to n koju Boko Haram.
Beautiful Nubia: Kò sí wàhálà tó ń ṣẹlẹ̀ láàgbáyé tí kò ní ọwọ́ ẹ̀sìn lábẹ́nú
Lori ọrọ ti adari awọn osisẹ ologun Naijiria sọ pe Boko Haram ti n lo ohun ija drone, onimọ nipa eto abo naa fi kun un  wi pe ile isẹ ologun ofurufu Naijria nilo lati gba awọn eniyan si isẹ ti yoo ran wọn lọwọ lati lo awọn ohun ija igbalode ati imọ ẹrọ fun ibanisọrọ.
"Tẹmitọpe Olodo ni ""awọn ọmọ ikọ Boko Haram ko koju awọn ọmọogun Naijiria pẹlu ohun ija igbalode, sugbọn wọn lo ""armour tank"" pẹlu ibọn lati wọ inu baraaki wọn lati koju ija si wọn""."
Wọn nilo agbada satalite ti yoo ma sọ igba ati akoko bi awọn Boko Haram se n gbero lati koju wọn.
Ati wi pe wọn nilo ‘anti-drone’ lati jagun naa lai si iru isẹlẹ to pa ọgọọrọ awọn ologun Naijiria mọ.
Ti a ko ba gbagbe, ọdun to koja ni ijọba apapọ lorilẹede Naijiria, sọ wi pe awọn yọ biliọnu Dọla kan kuro ninu apo ijọba apapọ lati lẹ ra ohun ija igbalode fun awọn ọmọogun.
Ile isẹ ologun lorilẹede Naijria ti sọ wi pe eniyan mẹtalelogun lo ku ninu ikọlu ti awọn ikọ Boko Haram ṣe si ibudo ọmọ ogun kan lagbeegbe Metele ni ipinlẹ Borno, ti mọkanlelọgbọn si farapa.
Ikọlu to waye ni Ọjọ Kejidinlogun, Osu Kọkanla, ọdun 2018 ni ọpọlọpọ iroyin sọ wi pe o mu ẹmi ọmọọgun to to ọgọrun lọ, ti ọpọlọpọ si di awati, ṣugbọn ile iṣẹ ologun sọ wi pe ko si otitọ ninu iroyin naa.
Abdulfatah Ahmed: PDP kò fi tíkẹ́ẹ̀tì mi fa ojú ẹnìkejì mọ́ra
Ninu atẹjade ti ọga awọn ọmọọgun ilẹ Naijiria, Ọgagun Tukur Buratai fi lede gba ọwọ Ọgagun Sani Usman ni lootọ ni ikọ Boko Haram se ikọlu si awọn ọmoọgun ni Ọjọ Keji ati Ọjọ Kẹtadinlogun, Osu Kọkanla, ọdun 2018 ni agbeegbe Kukawa, Ngoshe, Kareto ati Gajiram.
Beautiful Nubia: Kò sí wàhálà tó ń ṣẹlẹ̀ láàgbáyé tí kò ní ọwọ́ ẹ̀sìn lábẹ́nú
Usman ni awọn ọmọogun Naijiria bori ikọ Boko Haram,sugbọn ọmọogun mẹrinlelogun ni ẹmi wọn lọ si ikọlu naa, ti mejila si farapa ninu ikọlu naa.
Iku ọwọọwọ awọn ologun Naijiria ti o n koju ikọ agbebọn Boko Haram ti n kọ ọpọ lominu.
Oniruuru ikọlu ti Boko Haram ti gbe kọlu awọn ọmọogun Naijiria ni o jasi iku ọpọ ọmọogun lọpọ igba.
Iroyin awọn ọmọogun ti wọn ku laipẹ yii lẹyin ti awọn agbebọn Boko Haram ya bo ibudo wọn ni ilu Metele ni ipinlẹ Borno, ti fa ọpọ ẹhonu lorilẹede Naijiria ati agbaye.
Adedoyin: Tí mo bá rí Buhari, màá sọ fun kó rántí pé Ọlọ́run wà
Amọṣa, ẹni to ti fi igba kan ri jẹ ọgagun agba ileeṣẹ ologun lorilẹede Naijiria, Ajagunfẹyinti Marthin Luther Agwai ni, bi awọn ologun ṣe n ku iku ọwọọwọ naa ko le ṣai ri bẹẹ nitori irufẹ ogun ti wọn gba ikọni fun yatọ si eyi ti wọn n koju lọwọ.
Ajagunfẹyinti Marthin Luther Agwai ṣalaye pe, ogun kọju simi ki n kọju si ọ ni awọn ọmọogun Naijiria kọ nipa rẹ, kii ṣe eyi ti wọn n ba awọn Boko Haram ja lọwọ.
Oríṣun àwòrán, Nigeria army
Iku ọwọọwọ awọn ologun Naijiria ti o n koju ikọ agbebọn Boko Haram ti n kọ ọpọ lominu
Ṣe ki n maa parọ  fun yin, ọfọ nla ni pe a padanu iye awọn ọmọogun to pọ to bayii
Amọ o ni ko yẹ kawọn ọmọ orilẹede Naijiria sọ ireti nu ninu ijafafa awọn ologun orilẹede yii, pẹlu afikun pe bi yoo ṣe ri niyi nitori irufẹ ogun ti wọn n ja lọwọ.
Bi aja ba bu eniyan jẹ, kii ṣe iroyin ṣugbọn ni ọjọ ti eniyan ba yi oju pada lati bu aja jẹ ni ariwo yoo ta. Iroyin kii pọ lori iye awọn agbebọn Boko Haram ti awọn ologun ti pa tabi mu si ahamọ?
Idi ni pe aja lo n bu eniyan jẹ nigba yẹn. Ojuṣe ti a n reti lọwọ awọn ologun niyi.
Oríṣun àwòrán, Nigeria army
Agwai ni ko si ologun ṣe lee ja iru ija yii ti wọn ko ni fara gba ọta.
O ni ko si bi awọn ọmọogun yoo ṣe maa ja ogun bayii lai ni fara kaaṣa ikọlu awọn agbebọn yii.
Ni ibẹẹrẹ ọdun 2018 ni aarẹ Buhari buwọlu biliọnu kan dọla owo ilẹ Amẹrika fun rira awọn nnkan ija ogun fun awọn ologun lati koju Boko Haram.
Ni gba naa, kii ṣe ede aiyede kekere lo waye laarin ẹka aṣofin, ẹka iṣakoso ati awọn alatako, paapaa julọ ẹgbẹ oṣelu PDP, to fi mọ igun kan laarin awọn ọmọ orilẹede yii.
Nibayii ti ọrọ ikọlu ati pipa awọn ọmọogun ti wa n di lemọlemọ bayii, ọpọ lo ti n ṣe ibeere pe nibo ni owo naa wọlẹ si ati pe kini wọn n fi awsn ohun ija ogun ti wọn ra ṣe ti o fi di pe awọn agbebọn yii n gbẹyẹ mọ awọn ọmọogun lọwọ lẹnu ọjọ mẹta yii.
Oríṣun àwòrán, Nigeria army
Oniruuru iroyin lo ti jade ni pa iye awọn ọmọogun ti wọn ku ni pato ninu ikọlu naa
Lẹnu oṣu diẹ bayii lemọlemọ ni ikọlu awọn ologun lorilẹede Naijiria lati ọdọ awọn agbebọn Boko Haram yii.
Awọn ibudo ologun lawọn ilu bii, Metele (November 18), Kekeno (September 23), Mainok, Gajiram, Gashigar (September 25), Damsak (September 12), Zari (August 30), Garunda (August 8) ni awọn agbebọn yii ti kọlu.
Bi awọn onwoye kan si ti n sọ, ikọlu wọnyii ni batani bi o ti n lọ eleyii ti o mu ki wọn maa beere pe nibo lo tun kan bayii?
Akọroyin kan, Ahmad Salkida ṣalaye lori ikanni twitter rẹ pe ọwọ ti awọn ikọ agbebọn yii fi n gba awọn eeyan tuntun si agbo wọn n fẹ amojuto.
O ni lọwọ yii ipo akọkọ ni ikọ agbebọn Boko Haram ti wọn n pe orukọ rẹ ni ISWAP laarin awọn ẹgbẹ agbesunmọmi ati agbebọn lagbaye.
Oríṣun àwòrán, Nigeria army
Buhari ni ijọba yoo pese oun ija to peye fun awọn ọmọ ogun Naijiria
Iṣẹlẹ bi awọn Boko Haram ṣe kọlu ikọ ọmọogun Naijiria laipẹ yii ti wọn si pa pupọ ninu wọn ti di eyi ti eeyan lee sọ pe gbogbo agbaye ti gbọ.
Oniruuru gbọyisọyi lo si ti ti ara rẹ jade lagbo oṣelu, awujọ orilẹede agbaye ati laarin awọn sms orilẹede Naijiria funrawọn.
Ni ọjọ abamẹta ni aarẹ Buhari funrarẹ pẹlu bu ẹnu atẹ lu iṣẹlẹ naa ti o si tẹnumọ ipinnu ijọba rẹ lati rii pe aabo wa fun tẹrutọmọ lorilẹede Naijiria.
Èmi kì í ṣe olórí tí kò bìkítà nípa ọmọlẹ́yìn rè-Ààrẹ Buhari
Pín fídíò 'ayédèrú' kó o ríjà ológun Nàìjíríà
Amọṣa, ẹgbẹ ajafẹtọ ọmọniyan kan ti o fi orilẹede Naijiria ṣe ibugbe ti ke gbajare sita pe ko yẹ ki ọrọ naa ms bẹẹ, ayaafi ki aarẹ tete gbe iwadi kalẹ lati tan ina wadi bi wọn ṣe n na gbogbo owo ti wọn n ya sọtọ fun nina lẹka abo ati ileeṣẹ ologun ninu eto iṣuna orilẹede Naijiria bẹrẹ lati ọdun 1999 si 2018.
Oríṣun àwòrán, Nigeria army
Ikẹdun Ààrẹ Buhari yí n wáyé lẹyìn bí ọjọ máàrún tí ìròyìn ìṣẹlẹ ikọlù àwọn ọmọ ogún pẹlú ìkọ Boko Haram wà ye
SERAP ni ni ibi ti ọrs de duro bayii ti awọn ọmọ ogun orilẹede Naijiria wa n ku iku ọwọọwọ loju ija, o to ki aarẹ dari gbogbo ẹsun iwa ijẹkukjẹ to niiṣe pẹlu nina owo to yẹ fun rira nnkan ijagun fun awọn ologun lorilẹede Naijiria si iwaju kootu agbaye, ICC.
"Ninu lẹta kan ti o kọ ṣọwọ si aarẹ Buhari, ajọ naa ni, ""ẹgbẹlẹgbẹ biliọnu naira ni a ti ya sọtọ fun ileeṣẹ ologun lati daabo bo orilẹede yii ṣugbsn ko jọ bi ẹni pe eyi ti ni ipa kankan ninu ipa awọn ọmọogun Naijiria lati dojukọ awọn agbebọn BokoHaram atawọn iks agbebọn miran lorilẹede Naijiria."""
Oríṣun àwòrán, Nigeria Army
SERAP ní kí Ààrẹ Buhari darí gbogbo àwọn ìwé ẹ̀sùn ìkówójẹ tí ó bá rọ̀ mọ̀ ríra ohun èlò ológun ránṣẹ́ sí kóòtù àgbáyé
Ajọ naa woye pe bi ọrs ṣe ri bayii, ti awọn ologun ko lee wawọ kilanko awọn agbebọn naa bọlẹ, o fihan pe ejo lọwọ ninu pẹlu bi wọn ṣe n ṣe awọn owo ti wọn ya sọtọ labẹ iṣuna orilẹede Naijiria fun ẹka aabo.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Eyi kii ṣe igba akọkọ ti Buhari yoo ma kẹdun pẹlu awọn ọmọ Naijiria lori ipaniyan
Lẹyin nnkan bi ọjọ maarun ti iroyin pe ikọ Boko Haram ṣe iku pa awọn ọmọ ogun Naijiria,Aarẹ Muahmmadu Buihari ti ba awọn ọmọ Naijiria kẹdun lori iṣẹlẹ naa.
Ikẹdun rẹ ti o wa ninu atejade kan ti agbẹnusọ ileeṣẹ Aarẹ Garba Sheu fi sita lọjọ Aiku so pe ''inu Aarẹ Buhari bajẹ pupọ lori iṣẹlẹ iku awọn ọmọ ogun ni abule Metele lọwọ Boko Haram''
Aarẹ Buhari  so ninu atejade naa pe ''ko si olori kankan ti yoo kawo pọnyin ti yoo si ma wo bi awọn agbesunmọmi yoo ṣe ma ṣeku pa awọn ọmọogun rẹ''
O ni ohun n ṣe ipade pẹlu awọn olori ọmọogun lati ri wi pe awọn koju Boko Haram.
Buhari ni ijọba yoo pese oun ija to peye fun awọn ọmọ ogun Naijiria.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ija laarin awọn ologun Naijiria ati ikọ Boko Haram ti n lọ ti pẹ
O tẹsiwaju wi pe oun  'ṣetan lati fun awọn ọmọ ogun wa ni gbogbo iranwọ ti yoo mu wọn ṣe iṣẹ wọn bo ti ṣe yẹ'
Lai pe yi ni iroyin gbode nipa iku awọn ọmọogun Naijiria lọwọ ikọ Boko Haram ni abule Metele ni ipinlẹ Borno.
Iṣẹlẹ naa mu ki ara ilu bẹnu atẹ lu ijọba Buhari ti o ni oun ti dẹkun agbara ikọ Boko Haram.
Ile ise ologun ko sọ pato iye ọmọogunto ku ninu ikọlu naa sugbọn awọn iroyin kan ni wọn le ni ọgọrun.
Fidio orisirisi ni o si ti gba ori ayelujara nibi ti awọn ọmọ ogun ti n ke gbajare si Aarẹ Buhari lati wa wọrọkọ fi sada lori bi awọn olori wn ko ti ṣe ra nnkan ija fun wọn lati koju Boko Haram.
Ilé iṣẹ́ ológun orílẹ̀èdè Nàìjíríà ti ní lóòtọ́ ni ikọ̀ Boko Haram kọ lu àwọn ológun tí wọ́n sì pa lára wọn ní Metele, ìjọba ìbílẹ̀ Abadam, ìpínlẹ̀ Borno.
Ọ̀rọ̀ tó jáde láti olú ilé iṣẹ́ ológun Nàìjíríà sọ pé ìkọlù tí àwọn ẹsin ò kọ'kú Boko Haram ṣe sí ọ̀wọ́ ogun 157 Task Force Battalion wáyé ní ọjọ́ kejìdínlogún oṣù kọ́kànlá ṣùgbọ́n kò sọ iyé ọmọ ogun tó kú.
Àwọn oníròyìn sì ti bábá gbé e síta wí péó lé ni ààdọ́rin ọmọ ogun tí wọ́n ti pa tó fi mọ́ olórí ọ̀wọ́ ogun náà, fídíò rẹ̀ sì ti gba gbogbo orí ẹ̀rọ ayélujára.
Ibi ìpamọ̀ ohun ìjagun púpọ̀, ta ìbọn àti ohun èlò àwọn ológun ni ikọ̀ Boko Haram kó lọ lákokò ìkọlù yìí tó wáyé ni Metele, ìjọba ìbílẹ̀ Abadam ní ìpínlẹ̀ Borno.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Iléeṣẹ́ ológun Nàìjíríà kò tíi fo hùn lórí ìròyìn náà
Ọga ileeṣe ọtẹlẹmuyẹ DSS tẹlẹ lorilẹede Naijira Mike Ejiofor ti sọ pe ibo to n bọ lọna lo jẹ ki ikọlu Boko Haram pẹlu awọn ọmọ ogun Naijiria pọ si lẹnu lọọlọ yii.
Ejofor to ba BBC sọrọ yii lẹyin ti ara awọn ẹgbẹ agbesumọmi Boko Haram, Islamic State West Africa Province(ISWAP) pa ọpọ ọmọ ologun ti wọn si tun ko nnkan ija wọn lọ.
O fikun ọrọ rẹ pe Boko Haram ko ni gbagbọ ninu eto ijọba awa-ara-wa, eleyi lo jẹ ki wọn maa da rukerudo silẹ ki ẹru le maa ba awọn eeyan ṣaaju idibo ọdun 2019.
Ejiofor tilẹ tun sọ pe o ṣeeṣe ki awọn ọmọ ologun ti Boko Haram pa ju iye ti ile iṣẹ ọmọ ogun Naijiria fi lede lọ, nitori wọn o ni fẹ ki awọn ọmọ ologun ti wọn si n ja kaya soke.
Awọn ile iṣẹ ologun Naijiria kọ lati sọrọ nigba ti BBC kan si wọn lori ọrọ yii.
Boko Haram ti fi ẹmi ọpọ ọmọ ogun orilẹede Naijiria ṣofo lati bi ọdun meji wa sẹyin, bo tilẹ jẹ pe ijọba ni ohun ṣẹgun agbesumọmi Boko Haram
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Iléeṣẹ́ ológun Nàìjíríà kò tíi fo hùn lórí ìròyìn náà
Ìròyin tó tẹ̀ wá lọ́wọ́ láti ìpínlẹ̀ Borno tó wà ní àríwá Nàìjíríà ń sọ wí pé Boko Haram ti pa ọmọ ogun Nàìjíríà àti àwọn àgbẹ̀ mẹ́tàléláàádọ́ta' láàrin ọjọ́ mẹ́ta.
Súgbọ́n iléeṣẹ́ ologun orílẹ̀-èdè Nàìjíríà kò tíì sọ ǹkankan nípa ìròyìn náà.
Ilé iṣẹ́ ìròyìn AFP fidi ẹ mulẹ lati ọdọ àwọn ológun kan tí wọ́n sọ wí pé ìkọ̀ Boko Haram pa, ó kéréjù, sọ́jà mẹ́tàlélógójì ( 43) ní oko Metele tí kò jìnǹa sí ẹnu aàlà orílẹ̀-èdè náà àti orílẹ̀-èdè Nìjẹ́r ní ọjọ́  Àìkú.
"Ológun náà sọ pé: ""Wọn pa àwọn ọmọ ogun wa, lẹ́yìn náà ni wọn gba bárékè wa nígba tí a dáná fún rawa yá."
Sọ́jà náà ṣe àfikún pé àwọn ológun ti wo inú igbó láti wá àwọn sọ́jà tí wọn sọnú lẹ́yìn ìkọlù náà.
"Àwọn ọmọogun aráìlú fi tó iléeṣe AFP létí pé ikọ̀ Boko Haram náà wa ọkọ̀  bíi ogún (20), wọn kò sì rí ìrànlọ́wọ́ àwọn ọmọ ogun míràn títí tí àwọn ikọ̀ Bko Haram náà fi dòyì ká bárékè náà tí wọn sì kó nǹkan ìjagun lọ́ ."""
Ní ọjọ́ náà ni Boko Haram kọlu oko Gajiram láàárọ̀ kùtù-kùtù. Oko náà tó máìlì mọ́kàndínláàádọ́ta (49 miles) sí Maiduguri, olú ìlú ìpínlẹ̀ náà.
Ará oko náà sọ fún iléese AFP pé àwọn Boko Haram àti ológun náà jà fún wákàtí díẹ̀.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Boko Haram n gbẹbo laarin awọn orilẹ ede ilẹ Adulawọ
Blac Chyna fẹ́ wá ta ìpara bórabóra Whitenicious ni Eko
Ipara yii yoo fun obinrin ni à[wọ to pọn daadaa.
Àjọ NAFDAC ni àwọn n fojú si ìpara bórabóra ti Blac Chyna ọmọ ilẹ̀ America n kó bọ̀.
Ajọ yii lo n mojuto ọrọ ounjẹ àti oogun lilo ni Naijiria.
Monica Eimunjeze to jẹ oludari ẹka to n ri si àṣìlọ nkan ni NAFDAC ṣalaye fun BBC pé ileeṣẹ naa ko ni ọrọ lati sọ lasiko yii ṣugbọn NAFDAC wa lati daabo bo àwọn eniyan Naijiria ni.
Arábirin olókiki ọmọ Amẹrika kan, Angela White, ti gbogbo eniyan mọ si Blac Chyna n bọ nilu Eko ni ọjọ isinmi, ọjọ karundinlọgbọn, oṣu yii, ṣugbọn oun to n gbee bọ ni orilẹ-ede Naijiria ni o ya ọpọlọpọ eniyan lẹnu.
Owo to tó aadọrun ẹgbẹrun naira ni ikan iru ipara yii yoo jẹ ni owo Naira.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Blac Chyna ṣe ipara tuntun
O fẹ wa ta ipara borabora rẹ ti o pe ni Whitenicious ni.
Lori ikanni rẹ lori Instagram, lo ti ṣalaye pe oun n ṣe agbajọwọ pẹlu awọn ti n ṣe ipara Whitenicious ni.
Blac Chyna to j'ẹ ẹni ọgbọn ọdun naa n pe awọn alatilẹyin rẹ ni orilẹ-ede Naijiria lati wa si ibi ayẹyẹ ti wọn yoo ti ṣi aṣọ loju ipara naa nilu Eko.
Oríṣun àwòrán, @Blac Chyna/Instagram
"O kọ sori Instagram pe, ""Ẹyin ara Eko, ẹ wa pade mi nibi ti a o ti ṣi aṣọ loju ipara mi Whitenicious ni ọjọ Aiku ni ile itaja. Gbogbo eniyan ni a pe."""
Inu agolo kekere kan ti awọn onibara yoo ra ni iye owo bii ẹgbẹrun lọna aadọrun naira.
Ṣugbọn eebu ni awọn ọmọ Naijiria fi n ki kaabọ o.
Parental Guidance: Ọdún méjì ni kí ẹ ti bẹ̀rẹ̀ kíkọ́ ọmọ nípa ìbálòpọ̀
'Wọ́n ní kí n máa jẹ ewébẹ̀ láti dín ìtọ̀ súgà kù'
John Mahama: Kò sí àní-àní pé Ilẹ̀ Ifẹ̀ ni orírun àgbáyé
Oríṣun àwòrán, Ile oodua
Ọọni ile ifẹ ni iṣọkan Afirika ṣe pataki
Ọọni ile ifẹ ,Adeyẹye Ogunwusi ti ṣalaye pe aala ilẹ to wa laarin awọn orilẹ-ede kaakiri ilẹ Afirika ko lee pa ina iṣọkan ti o wa laarin awọn eeyan rẹ.
Ni ọjọbọ ni Ọọni sọ ọrọ yii lasiko ti o n gbalejo aarẹ ana Orilẹ-ede Ghana, John Mahama ni ile Oodua ni ilu Ile Ifẹ.
Ọba Olutayọ: ìgbésẹ̀ Ọọni àti Alaafin ti ń mú ìṣọ̀kàn dé sáàrin àwọn Ọba Yorùbá
"Ọọni Ogunwusi ni ki ọlaju awọn alawọ funfun to dé, ko si aala ilẹ orilẹ-ede si orilẹ-ede ni ilẹ Afirika, ""ẹbi kan ṣoṣo ni gbogbo eeyan ilẹ yii."""
"Inu mi si dun pe awọn eeyan kan loni ko sinmi tabi kaarẹ lati rii pe ilẹ Afirika ṣi duro gẹgẹ bii ẹbi kan naa.
Oríṣun àwòrán, Ile oodua
Aarẹ Mahama ni lati igba ti oun ti jẹ akẹkọ ni oun ti gba pe, pataki ni ọrọ Ilẹ ifẹ laarin itan agbaye
Ninu ọrọ rẹ, aarẹ orilẹ-ede Ghana tẹlẹ, John Mahama ni oun gba pe ilẹ ifẹ ni orirun aṣa ilẹ Afirika.
Aarẹ Mahama ni lati igba ti oun ti jẹ akẹkọọ ni ohun ti gba pe, ẹni maa pẹgan ajanaku laa sọ pe oun ri kini kan firi lori ọrọ Ilẹ ifẹ ati itan agbaye.
Oríṣun àwòrán, Ile oodua
Mahama kan sara si Ọọni fun ipa rẹ lori iṣọkan Afirika
Gẹgẹ bii akẹkọ nipa itan, mo ti kọ ẹkọ, mo si tii kaa ninu iwe pe Ifẹ ni ni orirun eniyan, ipo ti o si wa laarin itan agbaye ko kere rara."""
Ìran kan si ìkejì ló n gbèrò láti ṣe ìrú ìgbéyàwo àjùmọ̀ṣe 'Shao' fọ́mọ wọn
Black Friday 2018: Afẹ́fẹ́ káràkátà tuntun tó fẹ́ wọ Nàìjíríà
Black friday
Ọpọ ọmọ Naijiria ni wọn ji ni ọjọ Ẹti si pọpọ-ṣinṣin ẹdinwo gọbọi lori awọn ọja kaakiri awọn gbajugbaja ile itaja lorilẹ-ede Naijiria.
"Koda ọrọ naa kan gbogbo agbaye pẹlu eleyi ti wọn n pe ni ""Black Friday"""
"Ọpọ ni o si maa n lo anfani eto ayajọ ẹdinwo 'Black Friday"" naa lati fi ra awọn ọja opin ọdun sile."
Ẹdinwo ọja yii a maa fa wọlu-kọlu ni ọpọ awọn ile itaja nitori ọpọ ero ti o fẹ ra ọja lowo pọọku.
Bi o tilẹ jẹ pe pupọ awọn ọmọ orilẹ-ede yii ni wọn kopa, ọpọ ni ko lee sọ ni pato, bi eto Black Friday yii ṣe bẹrẹ.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
"Ọpọ ni o si maa n lo anfani eto ayajọ ẹdinwo 'Black Friday"" naa lati fi ra awọn ọja opin ọdun sile"
Lai deena pẹnu, bi eto ẹdinwo ọja, black Friday ṣe bẹrẹ ṣi ṣokunkun pẹlu oniruuru itan lori bi o ṣe bẹrẹ ṣe n gba aye kan.
Ọkan lara awọn itan black Friday ti o gba igboro kan ju ni pe pupọ awọn ọlọja ti wọn kii ri ọja ta pupọ ni wọn maa n ri ọja ta ni ọjọ ti o ba tẹlẹ ọjọ idupẹ ni orilẹede Amẹrika. Awọ dudu si ni awọ ti wọn maa fi n ṣe apẹrẹ pe aje n bu igba jẹ nigba ti awọn pupa fihan pe ọja ko ta to bi wọn ti fẹ.
Awọn miran ṣalaye pe ilu Philadephia ni orukọ yii ti bẹrẹ laarin ọdun 1950 si 1960.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
"Ọpọ ni o si maa n lo anfani eto ayajọ ẹdinwo 'Black Friday"" naa lati fi ra awọn ọja opin ọdun sile"
Ohun ti itan yii sọ ni pe awọn ọlọpaa atawọn awakọ ni wọn maa n lo o Black Friday lati fi ṣe apejuwesunkẹrẹ-fakẹrẹ ọkọ ti o maa n waye lasiko ti awọn to wa raja ba fọn si oju popo ni ọjọ ẹti, (Friday) ṣaaju ifẹsẹwọnsẹ bọọlu laaarin ikọ ọmọogun oriilẹ ati ọmọogun oju omi eleyii ti o maa n waye ni ọjọ abamẹta nigba naa.
Bi o tilẹ jẹ pe a ko lee sọ ni pato bi o ṣe bẹrẹ, ṣugbọn ohun kan ti a lee fi ọwọ rẹ sọya ni pe ogunlọgọ awọn ọmọ orilẹede Naijiria ni wọn ti n dara pọ mọ eto yii bayii.
Ni ilu Ibadan n ṣe ni awọn ero wọ ni kẹtikẹti lọ sawọn ile itaja ti o ṣe eto naa.
Ni ibudo itaja igbalode Shoprite, ẹsẹ o gbero pẹlu bi awọn eeyan ṣe bo ibẹ lati ra awọn ohun elo ti awọn alaṣẹ ibudo itaja naa ti kede ni ẹdinwo.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Bakan naa ni awọn ọja bii ẹrọ ibanisọrọ, ororo, ohun elo iṣura ara obinrin pẹlu maa n ta pupọ
Ọkan lara awọn eeyan to lọ ra ọja nibẹ, Adeọla Ọdọle to ba BBC News Yoruba sọrọ ṣalaye pe igba keji niyi ti oun n kopa ninu ayajọ ẹdinwo ọja Black Friday nibẹ.
Ko si ẹni ti ko fẹran ẹdinwo nitori ko si owo nilu, ṣugbọn nigba ti wọn kede rẹ ni mo fi wa. Fun apẹrẹ, oro ti a n ra ni ẹgbẹrun meji naira ni wọn ta ni ẹgbẹrun meji o din igba naira. Bakan naa ni ohun mimu milo ti wọn n ta ni ẹgbẹrun kan ni wọn ta ni ẹgbẹrin naira. Ara ohun ti o faa ti awọn eeyan fi pọ yanturu niyi.
Ajyajọ yii ko mọ pẹlu awọn ibudo itaja nikan. Awọn ileeṣẹ itaja ori ayelujara bii Konga, Jumia ati bẹẹbẹẹ lọ pẹlu ti dara pọ mọ ayaju yii pẹlu oniruuru eto ẹdinwo ọja bii ọja kolọ-n-lẹ ko dowo Flash sales ni Jumia ati Konga yakata.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ni ilu Ibadan n ṣe ni awọn ero wọ ni kẹtikẹti lọ sawọn ile itaja ti o ṣe eto naa
"Oṣiṣẹ ileeṣẹ Jumia kan ti o ba BBC Yoruba sọrọ ṣalaye pe""asiko yii ni iye awọn ti o n ra ọja maa n pọ nitori ẹdinwo ori ọja."" O ni awọn ohun elo ile bii ẹrọ ifọṣọ (washin machine) ati mohunmaworan ni o maa n ta julọ lasiko yii."
Bakan naa ni awọn ọja bii ẹrọ ibanisọrọ, ororo, ohun elo iṣura ara obinrin pẹlu maa n ta pupọ.
Chef Adefunkẹ: Òórùn ewé tí wọ́n n pọ́n ìrẹsì ọ̀fadà si jẹ́ adùn lọ́tọ̀
Fanny gbà kádàrá lórí àwọn orin rẹ̀ kí wọn to ṣe alakọkọ lọdun 2012
FGM: Obìnrin igba mílíọ̀nù(200m) ló ti farakásá abẹ́ dídá
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Abẹ́ dídá fún obìnrin sì tún wọ́pọ̀ l'Afirika
Awọn kan si tun n dabẹ fun ọmọbinrin nilẹ Afirika bi ilanilọyẹ lori ewu to wa ninu rẹ ṣe ti tan kalẹ to.
Ajajagbara fun obinrin kan, Ketcha Pertulla Enzigha sọ pe abẹ dida fun ọmọbinrin si tun wọpọ ni apa ariwa orilẹede Cameroon bo tilẹ jẹ pe ajọ iṣọkan agbaye n ke fawọn eeyan lati dẹkun rẹ.
Eleyi lo mu ki ijọba ilẹ Gẹẹsi gbe ọgọta miliọnu o le mẹrin owo dọla silẹ lati fi dẹkun abẹ dida fun ọmọbinrin kaakiri ilẹ adulawọ.
Ṣe wahala wá ti ọkọ bá kọ̀ láti fún aya tó ti kọ̀ silẹ lára ogún rẹ?
Orilẹede Naijiria naa wa lara awọn orilẹede ti yoo jẹ anfani owo iranwọ yii.
Ijọba ilẹ Gẹẹsi fẹ ki abẹ dida ko di ohun igbagbe nilẹ Afirika laarin ọdun mejila si asiko yii.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Abẹ́ dídá fún obìnrin sì tún wọ́pọ̀ l'Afirika
Owo naa tun wa fun didena abẹ dida fun  awọn ọmọ ilẹ Gẹẹsi ti wọn ba lọ silẹ okere.
Ajọ iṣọkan agbaye sọ pe abẹ dida fun ọmọbinrin le ṣakoba fun oju-ara rẹ, koda o le yi pada.
Iwadi ajọ iṣọkan agbaye sọ pe awọn ọmọbinrin to to igba miliọnu ti wọn si wa laaye bayi ni wọn ti dabẹ fun.
Gẹgẹ bi Iwadi naa tun ṣe sọ, aṣa abẹ dida yii wọpọ ni bi ọgbọn lorilẹede, ṣugbọn kii ṣe ilẹ adulawọ ni gbogbo wọn wa.
Nigeria Elections 2019: Ezekwesili ti jẹ́ mínísítà ní Nàìjíríà lẹ́ẹ̀ mejì ọ̀tọ̀ọ̀tọ̀
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ezekwesili ti fi ìgbà kan jẹ́ igbakeji ààrẹ Banki Agbaye éka ilẹ̀ Afrika
Ti a ba n darukọ àwọn eekan obinrin lorilẹede Nàìjíríà, a o le tii ka mẹta ka to darukọ Ọmọwe Obiageli Ezekwesili to n dupo aarẹ Naijiria.
Ilumọọka ni Ọmọwe Ezekwesili, ẹni ti o ti di oniruuru ipo mu ni Naijiria ati agbaye .
Yatọ si pe o jẹ ọkan pataki lara oludasilẹ ẹgbẹ ajafẹtọ ọmọniyan #BBOG to n ja fun ominira awọn ọmọbinrin to wa ni ahamọ ikọ Boko Haram, Ezekwesili jẹ ọkan lara awọn ọmọ Naijiria to n fi ojoojumọ ke tantan lori eto iṣakoso orilẹede naa.
Ipinlẹ Anambra la ti bi Oby, ni ọjọ́ kejidinlọgbọn, osu igbe ọdun 1963. O si kẹkọọ gboye gẹgẹ bi akọṣẹmọṣẹ iṣiro owo.
Igba meji ọtoọtọ lo ti ṣe minista ni Naijiria, to si tun ti figba kan jẹ igbakeji aarẹ Banki agbaye, ẹka ilẹ adulawọ.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ọ̀kan lára olùdásílẹ̀ ẹgbẹ́ #BBOG ni Oby Ezekwesili
Minisita Ohun Alumọni láàrin ọdun 2005 si 2006
Ni ọdun 2005 ni Aarẹ Olusegun Obasanjo yan Ọmoọwe Ezekwesili gẹgẹ bi minisita ohun alumọni inu ilẹ, lẹyin to ti jẹ adari ẹka to n ri si amojuto eto isuna , nibi to ti gba inagijẹ 'Mama Due Process'.
Gẹgẹ bi minisita ohun alumọni, o ṣe agbatẹru abadofin to ni ṣe pẹlu alumọni ati iwakusa 'Minerals and Mining Act', idasilẹ ileeṣe iwakusa orilẹede Naijiria, o si tun rii daju pe ẹka naa rọrun lati wọ fun awọn aladaani.
Minisita Eto Ẹkọláàrin ọdun 2006 si 2007
Ipo minista ohun alumọni inu ilẹ, ni ọmọwe Ezekwesili wa, ti aarẹ nigba naa, Oloye Obasanjo tun ti sọ ọ di minista eto ẹkọ labẹ iṣakoso rẹ̀.
Gẹgẹ bi minisita eto ẹkọ, Ezekwesili ṣe atunto ẹka etò ẹkọ orilẹede Naijiria. Oun lo tun ṣe agbatẹru ibaṣepọ laarin ijọba ati aladaani fun eto ẹkọ to yanranti.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ezekwesili ti fi ìgbà kan jẹ́ igbakeji ààrẹ Banki Agbaye éka ilẹ̀ Afrika
Ni ọdun 2007 ni arabinrin Ezekwesili di igbakeji aarẹ Banki agbaye, ni kete to fi ipo minisita eto ẹkọ silẹ ni Naijiria, ipo to dimu di ọdun 2012.
Gẹgẹ bi igbakeji-aarẹ Banki agbaye ẹka ilẹ Adulawọ yii, oun lo jẹ alamojuto gbogbo ohun to n lọ kaakiri awọn orilẹede mejidinlaadọta to wa ni 'Sub Saharan Afirika', o si tun jẹ adari owoyaa to le ni ogoji biliọnu dọla.
Oríṣun àwòrán, @obyezeks
Ezekwesili sọ pé àsìkò ti tó láti gba agbára lọ́wọ́ ẹgbẹ́ òṣèlú PDP àti APC
Abẹ ẹgbẹ oṣelu ACPN ni o ti n dije sipo aarẹ orilẹede Naijiria
Ọmọwe Ezekwesili kede ipinnu rẹ lati dupo aarẹ orilẹede Niajiria ninu ọdun 2018 pẹlu alaye pe awọn ẹgbẹ oṣelu mejeeji to ti ṣe ijọba ri jẹ ọbayejẹ, ti ko si yẹ ki wọn wa ni ijọba mọ lorilẹede eyi.
Ọgbẹni Ganiyu Galadima ni wọn yoo jọ maa dije gẹgẹ bi igbakeji.
#BBCNigeria2019
Ilé iṣẹ́ ológun Nàìjíríà korò ojú lórí fídíò ayédèrú
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ileesẹ ologun lorileede Naijiria ti faraya lori bi awọn eeyan ṣe n pin fidio ati aworan ti wọn pe ni ayederu kaakiri lori iku awọn ọmọogun ti Boko Haram pa ni Borno.
Ninu atẹjade kan ti wọn fi ṣọwọ lori Facebook,wọn ni awọn ko kọ lati wọ ẹni ti o ba n pin iru iroyin ayederu bẹẹ lọ si ile ẹjọ.
Atẹjade naa salaye pe awọn iroyin bẹẹ ''a ma mu irẹwẹsi ọkan ba awọn ọmo ogun ti o si le ko ipalara ba akitiyan lati koju awọn ọmọ ikọ Boko Haram.''
Laipẹ yi ni awọn ọmọ ikọ Boko Haram ṣigun lọ ba awọn ọmọ ogun Naijiria labule kan ti wọn n pe ni Metele nipinlẹ Borno.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Awọn ọmọogun Naijiria ati ikọ Boko Haram ti n gbena wo ju ara wọn ti pẹ
Kete ti iroyin iṣẹlẹ naa lu si ẹrọ ayelujara ni awọn eeyan bẹrẹ si ni ko iriwisi orisirisi, lẹyin naa ni fọnran fidio kan lati ọdọ awọn ọmọ ikọ Boko Haram naa runa si ọrọ naa.
Aarẹ Buhari lara ipinu rẹ nigba to gba ijọba, sọ wi pe ohun yoo koju Boko Haram sugbọn lẹyin ọdun mẹta ti o de ori alefa,kaka ki ewe agbọn Boko Haram de,niṣe ni o n le koko si.
Ẹgbẹ oselu PDP to jẹ alatako APC ko tile jẹ ki ọrọ naa pẹ nilẹ ki wọn to gbe aworan kan ti o ruju sita.
Aworan yi jade si oju opo Twitter wọn lati bẹnu atẹ lu Aarẹ Buhari lori iku awọn ọmọ ogun ṣugbọn iwadi fi han wi pe aworan naa ki ṣe ti awọn ọmọ ogun to ku ni Metele.
Ọjọgbọn kan ni fasiti lorileede Amerika ti o tun jẹ akoroyin naa fara kasa ninu a n gbe iroyin ayederu yi ka.
Loju opo rẹ o fi aworan kan sita  ti o ro wi pe o jẹ  aworan awọn ọmọ ogun to n ke irora lori iku awọn akegbe wọn ni.
Ko pe pupo ti awọn eeyan pe akiyesi rẹ si aworan naa wi pe aworan awọn osere Kannywood lofi sita to pe ni aworan awọn ọmọ ogun Naijiria.
Beebẹ lorisirisi awọn aworan ati fọnran fidio ti awọn eeyan se alabapin wọn lasiko ti isẹlẹ ikọlu awọn ọmọogun Naijiria yi waye.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí:
Àwọn agbébọn kan tí wọ́n funrasí pé  Boko Haram ní wọ́n ti jí ọmọbìnrin mẹ́ẹ̀dógún gbé ní agbègbè Diffa tó wà ni ilà oòrùn Gúsù orílẹ̀èdè Niger.
Wọ́n jí àwọn ọmọbìnrin náà ní ìlú Toumour tó wà ní ẹnu ààlà orílẹ̀èdè náà àti Nàìjíríà ní ọjọ́ Àbámẹ́ta, gẹ́gẹ́ bí alákóso ilú Toumour náà ṣe fìdí ọ̀rọ̀ ọ̀hún múlẹ̀ fún iléeṣẹ́ ìròyìn Reuters.
Boukar Mani Orthe sọ pé àwọn agbébọn bíi àádọ́ta ni wọ́n kọlu ìlú náà, tí wọ̀n sì gbé àwọn ọmọbìnrin náà lọ.
Ní Ọjọ́bọ, àwọn agbébọn kan kolu ìlú Toumour ọ̀hún tí wọ́n sì pa èèyàn mẹ́jọ nínu àwọn òṣìṣẹ́ ará ilẹ̀ Faransé kan tí wọ́n ṣe ẹ̀rọ omi ọlọ́wọ́ fún àwọn àtìpọ́ tó sá àsálà kúrò níbi ìjà Boko Haram ní agbègbè náà.
Agbègbè Diffa ní orílẹ̀èdè Niger ti ń rí ìkọlù Boko Haram, láti osù kejì ọdún 2015 ti wọ́n ti bẹ̀rẹ̀ sí kolu agbègbè náà.
Nínú oṣù kínní ni wọ́n pa àwọn ológun Niger méje nígbà tí Boko Haram kolu ìlú Toumour.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Àwọn ibúdó àtìpó pọ̀ ní ẹnu ààlà Nàìjíríà àti Niger
AFRIMA: Davido, Falz, Ambọde gba àmì ẹ̀yẹ olórin Afíríkà
Oríṣun àwòrán, Davido
Agba olorin takasufe, 2Baba lo gba ami ẹyẹ orin takasufe to gbayi julọ ni ilẹ Afirika
Awọn gbajugbaja akọrin smọ orilẹede Naijiria Fakọyọ nibi eto ami ẹyẹ fawọn olorin nilẹ Afirika, AFRIMA to waye ni ilu Accra, orilẹede Ghana.
Davido ni wọn fun ni ami ẹyẹ akọrin to gbayi julẹ pẹlu awo orin rẹ FIA. Bakan naa lo tun gba ami ẹyẹ akọrin ti ko lẹlẹgbẹ lẹkun iwọ oorun Afirika.
Tiwa Savage gba akọrin obirin ti ko lẹlẹgbẹ lẹkun iwọ oorun Afirika pẹlu.
Ilumọọka asọrọdorin, Rapper Falz ni wọn fun ni ami ẹyẹ olorin Rap ti o pegede julọ ni Afirika.
Oríṣun àwòrán, @falzthebahdguy
Orilẹ̀èdè Ghana ni àmì ẹ̀yẹ náà ti wáyé
Ko tan sori awọn olorin nikan, gomina ipinlẹ Eko, Akinwunmi  Ambode pẹlugba ami ẹyẹ fun ipa ti o n ko lori idagbasoke aṣa ati irinajo afẹ, paapaa julọ gẹgẹ bii olugbalejo eto ami ẹyẹ ọhun laarin ọdun 2014 si 2017.
Agba olorin takasufe, Innocent Idibia ti gbogbo eniyan mọ sí 2Baba lo gba ami ẹyẹ orin takasufe to gbayi julọ ni ilẹ Afirika.
Oríṣun àwòrán, tufaceidibia1
Ọ̀pọ̀ àmì ẹ̀yẹ ni 2Baba ti gbà
Amọsa, gbogbo awọn olorin Naijiria to gba ami ẹyẹ yii ni ko sí nibi ti eto naa ti waye lorilẹede Ghana, to jẹ ẹlẹkaarun iru rẹ.
Ìtàn Mánigbàgbé: Samuel Ladoke Akintọla jẹ́ olóṣèlú pàtàkì tó tako Awolọwọ
Oríṣun àwòrán, @abati1990
Samuel Ladoke Akintọla jẹ ojulowo ọmọ Yoruba to ko ipa manigbagbe ni saa isejọba alagbada akọkọ ni orilẹede Naijiria.
Agba ọjẹ oloselu ni Akintọla, to si tun jẹ agbẹjọro to moye, bakan naa lo tun jẹ ẹni ti yoo sọrọ, ti yoo dabi ki a pọn ni ete la, tori ọrọ da saka lẹnu rẹ, boya ni ede Yoruba ni, abi Gẹẹsi.
Oríṣun àwòrán, @TLA4_6
Bi o tilẹ jẹ pe lọdun 1966, eyiun ọdun mejilelaadọta (52) sẹyin, ni wọn gbẹmi Oloye Akintọla lojiji, ti ọpọ̀ ọdọ atawọn agbagba kan ko si baa laye, sibẹ o yẹ ka lee mọ iru isẹ́ ribiribi ti akikanju ọmọ Oodua yii se.
Malabu Deal: Ìgbẹ́jọ́ bẹ̀rẹ̀ lóri rìbá tí Eni, Mobil san fún Nàíjíríà
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ọrọ lori owo epo rọbi
Ile ẹjọ kan ni ilu Milan lorilẹede Italy ti bẹrẹ si gbọ ẹsun iwa ajẹbanu ti wọn fi kan ile iṣẹ epo rọbi meji, Eni ati Shell lori owo epo to jẹ ki Naijiria padanu biliọnu mẹfa naira.
Ajọ kan to n jẹ The Campaign Global Witness ṣalaye pe, owo epo yii ti wọn ṣe ni ọdun 2011, ti jẹ ki Naijiria kuna ni ilọpo meji owo isuna ọdun kan fun eto ẹkọ ati ilera.
Wọn fi ẹsun kan ile iṣe epo Eni ati Shell pe wọn mọ pe owo riba ni owo ti wọn san fun orilẹede Naijiria.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí:
Adedoyin: Tí mo bá rí Buhari, màá sọ fun kó rántí pé Ọlọ́run wà
Ṣugbọn awọn ile iṣẹ mejeeji lawọn ko jẹbi ẹsun ti wọn fi kan wọn.
Ẹjọ naa kan awọn oṣiṣẹ ajọ ọtẹlẹmuyẹ M16 ati FBI nilẹ Amẹrika, bẹẹ naa ni o kan aarẹ ilẹ Naijiria kan tẹlẹ, pẹlu awọn oṣiṣẹ kan ile iṣẹ epo mejeeji.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ọrọ lori owo epo rọbi
Ile ẹjọ kan lorilẹede Faranse ti sọ tẹlẹ pe, minisita tẹlẹ fun epo rọbi Dan Etete jẹbi ẹsun pe o kowo lọ silẹ okere, ati pe o fi owo ra ọkọ oju omi ayara bi aṣa lọna aitọ.
Ilẹ naa tun sọ pe Etete ni ẹgbẹlẹgbẹ owo bi ọgọrun biliọnu owo dọla ti o ko pamọ.
Ajọ Global Witness ti n ṣe iwadi fun ọpọlọpọ ọdun, lati mọ ẹni to fun ile iṣẹ epo Eni ati Shell lasẹ, lati maa wa epo ti wọn pe ni OPL 245 lagbegbe Niger Delta.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ọrọ lori epo rọbi ni Naijiria
Iwadi naa si gbe jade pe, mọkaruru wa ninu adehun ti wọn ṣe lati gbe lẹyin awọn ile isẹ epo mejeeji, ati pe orilẹede Naijiria le padanu owo to din diẹ ni biliọnu mẹfa($5.86bn).
Ṣe adehun wa abi ko si?
Ajọ campaigners ni wọn gbọdọ fagi le adehun kankan to ba tiẹ wa laarin orilẹede Naijiria ati ile iṣẹ epo mejeeji.
Ava Lee to n ba ajọ Global Witness ṣiṣẹ sọ pe, ilẹ iṣẹ Shell ṣe adehun lọna to jẹ pe Naijiria yoo kuna ere to yẹ ko ri latara owo epo naa.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ọrọ lori owo epo rọbi
Orilẹede Naijiria lo ni ọrọ aje to lowo lori ju nilẹ Afirika, ṣugbọn ọpọ ọmọ orilẹede naa si n ba osi ati iṣẹ finra.
Hijab Crisis: Fásitì Ibadan ní kò sí ohun tó yípadà pẹ̀lú ìwọṣọ akẹ́kọ̀ọ́ ISI
Wamuwamu ni awọn ẹṣọ aabo duro lẹnu ọna abawọle ẹkọ naa, ti wọn ko si fi aye gba ikọ iroyin BBC Yoruba lati wọle.
Eto ẹkọ ti bẹrẹ ni pẹrẹwu nile ẹkọ 'The International School' to n bẹ ninu ọgba fasiti ilẹ Ibadan, lẹhin ọṣẹ kan ti wọn ti gbe ilẹkun ile ẹkọ naa ti lori awuyewuye to waye nipasẹ awọn akẹkọ kan to wọ Hijab lọ sinu kilaasi wọn.
Awọn alakoso ile ẹkọ naa koro oju si awọn akẹkọ ti o hu iru iwa yii, ti wọn si tẹnumọ pe, ofin ile ẹkọ naa ko fi aye gba iru rẹ.
Eyi lo mu ki awọn obi to jẹ ẹlẹsin Islam gbena woju awọn alakoso ile ẹkọ naa pẹlu alaye wi pe, awọn akẹkọ lẹtọ lati mura nilana ẹsin ti o ba wu ọkan wọn.
Adedoyin: Tí mo bá rí Buhari, màá sọ fun kó rántí pé Ọlọ́run wà
Ede-aiyede naa lo fa bi wọn ṣe gbe ilẹkun ilẹ ẹkọ naa ti lati le dena ija ẹsin ti o ṣeeṣe ko waye, bi eefin ọrọ ọhun ba ru ju bo tiyẹ lọ.
Sugbọn lẹhin ọkanojọkan ifẹhonu han lati ọdọ awọn alẹnulọrọ ati awọn ipade to waye laarin awọn obi ati alakoso ile ẹkọ naa, eto ẹkọ ti bẹrẹ pada lowurọ Ọjọ Aje.
Awọn obi ati alagbatọ ṣi n mu awọn ọmọ wọn wọle lọkọọkan-ejeeji, bẹẹ si ni ko si ẹni to wọ Hijab wọle ninu awọn akẹkọ naa.
Ede-aiyede lo se atiwaye bi wọn ṣe gbe ilẹkun ilẹ ẹkọ naa ti lati le dena ija ẹsin
Ninu iwe ti aṣoju igbimọ alakoso ile ẹkọ naa, Ọjọgbọn A.A Aderinto kọ ranṣẹ si awọn obi saaju iwọlẹ naa, o dupẹ lọwọ wọn fun ọgbọn, oye ati suuru ti wọn mu lo lasiko ti aawọ naa waye.
Botilẹ jẹ wi pe ko sọ boya ile ẹkọ naa ti fi aye gba lilo Hijab tabi bẹẹkọ, ọrọ rẹ kun fun arọwa si awọn obi lati mase fi aye gba ohunkohun ti o le da omi alafia ile ẹkọ naa ru, pẹlu alaye pek, ohun ti o tọ ni ifọwọsọwọpọ ti o le mu itẹsiwaju ba ile ẹkọ naa.
Ile ẹkọ 'The International School, UI' ti wọle pada lẹhin rogbodiyan ọlọsẹ kan gbako lori ọrọ Hijab
Wamu-wamu ni awọn ẹṣọ aabo duro lẹnu ọna abawọle ileẹkọ naa, ti wọn ko si fi aye gba ikọ iroyin BBC Yoruba naa lati wọle.
Bakan naa si ni gbogbo igbiyanju lati ba awọn obi ati alakoso ile ẹkọ naa sọrọ ja si pabo lasiko ti a ṣe akojọpọ iroyin yii.
Aregbesola: Ó se bẹbẹ ní ọdún mẹ́jọ tó fi sèjọba l‘Ọ́sun
Oríṣun àwòrán, @raufaregbesola
Ariṣe la ri ka, arika si ni baba iregun, Yoruba ni ohun taa ba se loni, ọrọ itan ni yoo da bo dọla.
Loni ọjọ Kẹtadinlọgbọn osu Kọkanla ọdun 2018 ni irinajo ijọba ọdun mẹjọ Gomina Rauf Arẹgbẹsọla dopin, ti ijọba tuntun ti Gboyega Oyetọla yoo si gberasọ.
Lasiko igba ti Gomina Rauf Aregbesola ṣe ijọba, ọpọ nnkan lo mu ba isejoba ipinlẹ Ọsun, ṣugbọn ohun to kọju si ẹnikan gẹgẹ bi Yoruba ti ṣe n sọ, ẹyin lo kọ si ẹlomiran.
Jide Kosọkọ: Isẹ́ tíátà yóò gòkè tíjọba bá gbówó kalẹ̀ láti seré
Bi awọn kan ṣe n kan saara si Arẹgbẹsọla fun iṣẹ ribiribi to ṣe nigba to jẹ Gomina, lawọn miran n bẹnu atẹ lu ijọba rẹ pe ki lo se gan?
Oríṣun àwòrán, @raufaregbesola
Agbeyẹwo awọnohun ti Arẹgbẹsọla gbe ori aleefa se lọọkọkan.
1) Eto pipese ounjẹ fun ọmọ ileewe:
Fun awọn obi ti o ni ọmọ nileewe alakọbẹrẹ nipinlẹ Osun, yoo ṣoro diẹ ki wọn to le gbagbe Aregbesola fun eto ipese ounjẹ lọfẹ fun awọn akẹẹkọ ileẹkọ alakọbẹrẹ to wa ni ipele kilaasi kinni si ikẹrin, ti oloyinbo n pe ni basic 1-4
Oríṣun àwòrán, @raufaregbesola
Bi o tilẹ jẹpe awọn eeyan kan ko fara mọ iru igbesẹ yii, ti wọn si ni owo to n tako ipese ounjẹ yii pọ ju, paapa lasiko ti ọrọ aje Naijiria ko fara rọ, sibẹ awọn akẹkọ to n jẹun ko ni gbagbe Arẹgbẹsọla.
Eto ipese ounjẹ naa gbajumọ debi wi pe, ijọba apapọ Naijiria ya lo, to si di eto ti ijọba apapọ naa n ṣe lati pese ounjẹ fun awọn akẹkọ lawọn ipinlẹ jakejado Naijiria.
Oríṣun àwòrán, @raufaregbesola
Ọpọ eeyan ati awọn ọmọ ẹgbẹ oselu alatako, to fi mọ awọn osisẹ ijọba ipinlẹ Ọsun lo n mu igbe bọnu lọpọ igba pe Rauf Arẹgbẹsọla jẹ gbese to pọ.
Koda, eyi ni wọn lo se akoba fun ijọba rẹ lati ri owo osu awọn osisẹ san fun ọpọlọpọ osu, ti awọn osisẹ ni Ọsun si n ba idaji owo osu wọn.
Sugbọn lero ti Ọgbẹni, gbese ayọ ni oun jẹ si wọn lọrun ni ipinlẹ Ọsun, tori awọn akanse isẹ ribiribi ti oun fi gbese naa se wa nilẹ bii ẹri maa jẹ mi niso.
Ẹ́ wo fidio ohun ti Gomina Arẹgbẹsọla sọ lori gbese to jẹ ni ipinlẹ Ọsun:
Arẹgbẹṣọla: Kò sí ìjọba tí kìí jẹ gbèsè
3) Ipese oju Ọna:
Bi wọn ba beere wi pe, bawo ni ijọba Aregbesola ti ṣe jẹ gbese to pọ kalẹ, lara ohun ti ‘Ogbẹni’ maa n tọka si ni wi pe, ohun pese oju ọna ati awọn ohun amayedẹrun fun ara ilu.
Ẹni to ba si rin yika tibu-tooro ipinlẹ Ọsun, yoo foju ganni ọpọ isẹ atunse awọn oju popo ati lila opopona tuntun to waye nibẹ.
Oríṣun àwòrán, @raufaregbesola
Lara awọn oju ọna to jẹ manigbagbe ti Arẹgbẹsọla pese ni ti awọn oṣiṣẹ, oju ọna Gbongan ati bẹbẹ lọ.
Oríṣun àwòrán, @raufaregbesola
Awọn Oṣiṣẹ́ fẹyinti ti ko dunnu si Aregbesola:
Ara ko rọ̀ okun, bẹẹ ni ko rọ adiẹ fawọn osisẹ fẹyinti lawọn akoko kan lasiko isejọba Rauf Arẹgbẹsọla, to si jẹ pe ija loni, asọ̀ lọla ni ijọba atawọn osisẹfẹyinti n se titi ti ijọba naa fi wa sopin.
Lọpọ igba ni iporogan maa n waye, tawọn osisẹfẹyinti yoo si gba oju popo kan lati se iwọde pe ki ijọba Arẹgbẹsọla san owo osu awọn.
Lasiko ọkan ninu awọn iwọde yii, awọn osisẹfẹyinti kan ba BBC Yoruba sọrọ nipa ohun ti wọn n la kọja, ẹ gbọ wọn:
Àwọn oṣiṣẹ feyinti ni Osun ṣé iwọde
Atunse Ile Ekọ:
Lọpọ igba ni ijọba ipinlẹ Ọsun labẹ Arẹgbẹsọla ati ẹgbẹ oselu rẹ, APC, maa n tọkasi ọpọ iyipada rere to de ba awọn ile ẹkọ nigba ti Aregbesola ṣe ijọba.
Won ni saaju ki Aregbesola to de ori aleefa, ipinlẹ Osun ko ni awọn ileewe igbalode to se fi yangan.
Yoruba ni iroyin ko to afojuba, ọkan lara awọn ile iwe ti ijọba Aregbesola pese, ti wọn si maa n tọka si ree:
Oríṣun àwòrán, @raufaregbesola
Osogbo High School
Lara awọn aseyọri to tun wa ni akọsilẹ fun ijọba Arẹgbẹsọla lẹka ipese eto ẹkọ ni ipese ọpọn imọ (IPAD) fawọn akẹkọ ile ẹkọ girama.
O si daju pe awọn akẹkọ ileewe Girama nipinlẹ Osun ko ni gbagbe Gomina Aregbesola laelae lori ipese ọpọn imọ.
Ipese ọpọn imọ yii ni wọn ni yoo mu ki eto ẹkọ wọn tubọ ja gaara sii, bi o tilẹ jẹ pe iroyin kan n ja ranin-ranin nigba kan pe awọn eeyan kan n fi apa janu pe owo ti wọn fi ra ọpọn imọ yii kọja sisọ, ti ko si tun sisẹ pẹ, ti wọn fi kọsẹ silẹ.
Oríṣun àwòrán, @raufaregbesola
Sugbọn bi o tilẹ jẹ pe ijọba Arẹgbẹsọla sa ipa rẹ lati mu ki eto ẹkọ muyanyan lasiko rẹ, sibẹ akọsilẹ fihan pe ajorẹyin si ni ina eto ẹkọ jo nipinlẹ Ọsun.
Fun apẹẹrẹ, laarin awọn ipinlẹ mẹrindinlogoji tawọn kẹkọ ti kọ idanwo Waec lọdun 2018, ipinlẹ Ọsun ṣe ipo kọkandinlọgbọn .
Bi onirese Ọgbẹni Rauf Adesọji Arẹgbẹsọla ko ba si wa fingba mọ nipinlẹ Ọsun, awọn eyi to ti fin silẹ ko lee parun, tawọn eeyan ipinlẹ naa yoo si maa ranti rẹ fun awọn ohun to gbe se laarin ọdun mẹjọ to fi se ijọba.
Premature Ovarian Failure: 'Ǹkan oṣù mi sọnù mo bá rò pé ó ti doyún'
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ǹkan oṣù mi sọnù mo bá rò pé ó ti doyún
Ẹni ọgbọ̀n ọdún ni ọ̀nà ti dí pa fún Evans. Ó kọ àkọsíll fún ètò BBC 100 Women nípa ìṣòro àìrọ́mọbí tó dé báa lójijì àti bó ṣe gba ìròyìǹ náà.
"Ǹkan oṣù mi ò fíbẹ́ẹ̀ ki mọ́, ó ti ń ri fẹ́lẹ́ fẹ́lẹ́ fún ǹkan bíi ọdún méjì, ṣùgbọ́n nígbà tí mo fi tó àwọn òṣìṣẹ́ elétò ìlera ní ìlú mi New Zealand wọn kàn sọ̀rọ̀ lórí rẹ̀ léréfèé bíi pé ògùn tí mò ń lò ló kàn fà á.
Nígbà tó pé oṣù kan géérégé tí mi ò rí ǹkan oṣù mi, mo bá ìdùnú lọ sọ́dọ̀ dókítà pé bóyá mo ti lóyún. Ó ti pé ọdún kan tí mo ṣègbéyàwó a sì ṣẹ̀ṣẹ̀ ń sọ̀rọ̀ ọmọ bíbí ni.
IVF: Ìyá ìbejì se IVF mẹ́ta lókè òkun, ìkẹrin tó se ní Nàíjíríà, ló fi bímọ
Ṣùgbọ́n nínú ẹja nbákàn, ẹja ni àyẹ̀wo oyún bí; kìí ṣe oyún. Dókítà mi ṣe àyẹ̀wò ẹ̀jẹ̀ ó sí wá ṣalàyé fún mi pé ibi tó yẹ kí hòmóònì mi wà kọ́ ló wà. Ló bá kọ̀wé gbé mi lọ sí ọ̀dọ̀ dókítà akọ́ṣẹ́mọṣẹ́ nípa hòmóònì ni wọ́n bá sọ fún mi pé àìlèbímọ ló ti yáa dé sí mi lára. Mi ò ms pé ẹyin ìbímọ lè tètè dáwọ́ iṣẹ́ dúró ní ọjọ́ orí yìí - ó jẹ́ ìyàlẹ́nu òjijì.
Láyé òde òní, ìgbàgbọ́ nínú obìnrin sọ fún wa pé a lè ní ohun gbogbo tí a fẹ́ bí a ṣe fẹ́ ẹ àti àkókò tí a fẹ́ ẹ. Ṣùgbọ́n irọ́ yìí kó bá wa lọ́pọ̀lọpọ̀ nígbà tí ìṣẹ̀lẹ̀ ohun tí a kò rò bá bọ́ sọ́nà èyì tí a rò.
Oríṣun àwòrán, Nicole Evans
Nicole àti ọkọ rẹ̀ lọ́jọ́ ìgbéyàwó
Mo mọ̀ pé tó bá jẹ́ ní ti mọ̀lúmọ̀ọ́ká ni, bí àìlèbímọ mọ́ obìrin tó yẹ kó bẹ̀rẹ̀ ní ààdọ́ta ọdún ó lé bá fí àwọn ìṣòro kọ̀ọ̀kan hàn, ó ṣeé fojú fò dá. Mi ò fìgbà kan mọ̀ rárá pé oreọ̀fẹ́ àtibímọ obìrin leè bẹ̀rẹ̀ sí ní dínkù láti ọgbọ̀n ọdún.
A pinu láti fi ẹyin ìbímọ ẹlòmííràn tí wọ́n ń pè ní IVF èyí tí ọ̀rẹ́ dáadáa kan pèsè mo sì rò ó pé yóò jẹ́ ìdáhùn sí gbogbo ìṣòro wa. Ṣùgbọ́n pàbó ló já sí. Eléyìí dun gbogbo àwọn tó kópa gaan ni.
67 year old mother: Mo kojú ọ̀pọ̀lọpọ̀ àìsàn fún ọdún 35 lẹ̀yín ìgbéyàwò
Lẹ́yìn ọdún kan, ọ̀rẹ́ mìíràn yọ̀nda láti ràn wá lọ́wọ́ ṣùgbọ́n lákokò yìí mi ò fẹ́ kọ́kọ́ gbà. Mo ní èyí ni yóò jẹ́ IVF ìkẹyìn tí ìjọba yuóò kówó lé lórí fún mi, ọkàn mi wá balẹ̀.
Ni a bá gbìyànjú IVF ẹlẹ́ẹ̀kejì nítorí mo ti wá pé ọdún méjìlélọ́gbọ̀n. Àkókò kò dúró.
Orísun: NHS UK
Ó ba ni nínú jẹ́ pé ìgbìyànjú lẹ́ẹ̀méjì tí a ṣe láti bímọ kò doyún a ò sì ní owó àti ohun tí a nílò fún ìkẹta.
Mí ò lè dojú kọ kí n lọ gba ọmọ aláìlóbìí. Lẹ́yìn tí wọ́n ti tì mí láti se é. Màa ṣẹ̀ṣẹ̀ tún wá bẹ̀rẹ̀ omíì nípa ìbáṣepọ̀ wa, iṣẹ́, ìdílé, ìsúná. Lótitọ́ mo mọ̀ pé ó ṣe pàtàkì ṣùgbán mi ò lè dojú kọ ọ́ pẹ̀lú gbogbo ìka àlébù tí ojú mi ti rí.
Ọkàn mi dàrú. Ìdàmú ọkàn ti àwọn ọmọ tó yẹ kó jẹ́ tiwa ṣì wà níbẹ̀ kò sí bí a ṣe fẹ́ gbé e kúrò lọ́kàn tó. Ìdàmú ọkàn yìí sì wà lára mi títí di ìrọ̀lẹ́ ọjọ́ kan. Mo lò ó pẹ̀lú ọ̀rẹ́ mi kan tó ṣẹ̀ṣẹ̀ bímọ, nígbà tó lọ tán, mo rí i pé èrò láti bí ọmọ tèmi ti lọ. Ó ti parẹ́.
Oríṣun àwòrán, Nicole Evans
Nicole tó ti lé lógójì ọdún báyìí
Mi ò lè ṣàlàyé ju pé mo gbàgbọ́ pé Ọlọ́run ló mú ìrònú ọjọ́ pípẹ́ kúrò lọ́kàn mi. Mo sì wá bojú wẹ̀yìn mo rí i pé ó ní èrò tó dára míì fún mi - mo súnmọ ọ síi.
Ọ̀pọ̀lọpọ̀ dókítà ni kò mọ pé àìlèbímọ mọ́ máa ń yá. Mo ti bá ọ̀pọ̀lọpọ̀ obìnrin sọ̀rọ̀ nínú ẹgbk onírànwọ́ tí mò ń darí, nígbà tí wọ́n sọ fún dókítà wọn pé ǹkan oṣù wọn ń ṣe ṣégeṣège, wọn kàn máa ń kọ̀wé gbé wọn lọ sọ́dọ̀ àwọn akọ́ṣẹ́mọṣẹ́ ni.
'Àṣírí ọkọ mi tú sími lọ́wọ́, ṣé mo le dáríjì í?'
Ó jẹ́ ǹkan ìdùnú láti má náwó àti ṣíṣe wàhálà ǹkan oṣù lóṣooṣù. Ṣùgbọ́n kò tíì mọ́ra láti wà nínú ipò yìí.
Àìlèbímọ tó tètè dé ṣeéṣe kó fún mi ní ẹ̀fọ́rí, ṣùgbọ́n ó túnbọ̀ tú àṣírí pé ètò ìlera léè pèsè ìdáhùn sí ohun gbogbo.
Àwọn jàndùkú dáná sún ọkọ̀ níwájú ilé aṣòfin Akwa Ibom
Oríṣun àwòrán, @OfficialPDPNig
Ẹgbẹ́ òṣèlú People's Democratic Party (PDP) ti tọka si Senẹtọ Godswill Akpabio gẹgẹ bi igi wọrọkọ ti dana ru ni ile asofin ipinlẹ Akwa Ibom.
Wọn ni aawọ to n waye nibi ti awọn kan ti sọna si ọkọ niwaju ile asofin ipinlẹ naa ko sẹyin rẹ.
Oju opo Twitter ẹgbẹ naa ni wọn fi ọrọ yii si lọjọ Iṣẹgun.
Iroyin to tẹwa lọwọ sọ wi pe wahala to n waye ni ile asofin naa ko sẹyin bi awọn asofin kan lati inu ẹgbẹ oṣelu APC ti ṣe fẹ yọ olori ile asofin naa to jẹ ọmọ ẹgbẹ PDP.
Saaju ni olori ile to jẹ ọmọ ẹgbẹ PDP, Nofiok Luke, ti kede wi pe aga awọn asoju marun to fi ẹgbẹ PDP silẹ lọ si APC ti sofo.
Ọrọ yi ko dun mọ awọn asoju yi ninu ti o si da wahala sil nile asofin ohun.
Oríṣun àwòrán, @OfficialPDPNig
Nse Etuen to jẹ ọmọ ẹgbẹ APC ko awọn asofin sọdi lati yọ olori ile to jẹ ọmọ ẹgbẹ PDP
Lọwọ lọwọ  bayi olori ile asofin meji lo wa ti awọn alatilẹyin wọn sin jijọ woya ija lori ẹni ti o jẹ ojulowo  olori ile .
Bi olori ile kan ṣe n  pe ijoko lati fi yọ ikẹji rẹ naa ni awọn ti ẹgbẹ kan yoku naa n ṣe bẹ.
Nse Ntuen ni olori ile ti o wa lati inu ẹgbẹ APC,Nofiok Luke ni olori ile to wa lati inu ẹgbẹ PDP.
Godswill Akpabio to fi igba kan jẹ Gomina ipinlẹ Akwa Ibom to si  jẹ Seneto to n soju agbegbe iwọorun ariwa ipinlẹ naa kuro ninu ẹgbẹ PDP lai pe yi lọ si APC.
Igbese rẹ yi lo fa ti awọn ọmọ ile asofin to ri gẹgẹ bi olori wọn naa ti ṣe tele kuro ninu ẹgbẹ PDP lo si APC.
A ko ri aridaju wi pe oun lo wa nidi rukerudo to waye sugbọn olori ile asofin naa to jẹ ọmọ ẹgbẹ PDP n naka abuku si ẹgbẹ oselu APC pe awọn ni wọn fẹ da ile ru
A gbo pe Gomina ipinlẹ Akwa Ibom Emmanuel Udomm yọju si ile asofin lọjọ iṣẹgun nigba ti awọn asofin ọmọ ẹgbẹ APC ati olori wọn asofin Nse Ntuen  n ṣe ijoko lati yọ olori ile to jẹ ọmọ ẹgbẹ PDP.
A pe alukoro ile ise ọlọpaa nipinlẹ naa Odiko Macdon lati fidi iṣẹlẹ naa mulẹ sugbọn ko gbe ẹrọ alagbeka rẹ
Gómìnà ìpínlẹ̀ Ọṣun ṣèlérí láti gba Ọṣun fún Buhari
Gómìnà ìpínlẹ̀ Ọṣun
Gomina tuntun nipinlẹ Ọṣun, Gboyega Oyetọla ti ṣe ileri lati mu itẹsiwaju de ba awọn aṣeyọri ẹgbẹ oṣelu APC nipinlẹ naa.Ọyetọla se alaye ọrọ ọhun lẹhin to bura gẹgẹ bii gomina tuntun nipinlẹ Ọṣun ni papa iṣere ilu Ọṣogbo lọjọ Iṣẹgun.
O kede ipinnu rẹ lati bomirin itẹsiwaju ipinlẹ Ọṣun lati ileto de ileto, ile iṣẹ si ile iṣẹ, ile ẹkọọ si ile ẹkọọ, titi t'anfani iṣejọba rere yoo fi de ori eeyan kọọkan to n bẹ nipinlẹ naa.Gomina tuntun naa tẹsiwaju wipe awọn eeyan ipinlẹ Ọṣun yoo ni iriri iṣejọba to ni eto rere fun tẹrutọmọ, nipase awokọṣe awọn adari to ni ifojusun ati ọgbọn atinuda bii Oloye Ọbafẹmi Awolọwọ, Oloye Bisi Akande, Oloye Bọla Tinubu ati Ọgbẹni Rauf Arẹgbẹṣọla.
O fi da awọn oṣiṣẹ ati oṣiṣẹ fẹhinti loju wi pe owo oṣu wọn yoo maa jẹ gbigba lasiko, gẹgẹ bo ṣe fi kun ọrọ rẹ wi pe ijọba tuntun yoo mu ọrọ itọju awọn oṣiṣẹ lọkunkundun.Lati le ṣe atunṣe ọrọ aje ipinlẹ Ọṣun, a o ṣe akanṣe apero lori eto ọrọ aje ki o to di opin oṣu mẹrin akọkọ ninu ọdun kinni iṣejọba wa.A o rii daju wipe owo oṣu awọn oṣiṣẹ n jẹ sisan lasiko, bẹẹ sini a o maa ṣe itoju awọn oṣiṣẹ ati oṣiṣẹfẹhinti botitọ ati botiyẹ."
Ẹgbẹ́ oṣelu PDP ti ní ìjọba fìdí-hẹẹ́ ni Gómínà tuntun tí wọ́n ṣẹ̀ṣẹ̀ búra fún ní Ìpínlẹ̀ Ọṣun, Gboyega Oyetola fẹ́ gùn lé nítorí kò tọ́ lójú àwọn ará ìlú.
Alága ẹgbẹ́ náà ní Ọṣun Soji Adagunodo sọ nínú àtẹjáde kan lórí gbígba ọpá àṣẹ Oyetola, wípé olè jíjà ìbò tó gbé Oyetola wọlé ní o fẹ̀ẹ́ burú jù láti ìgba tí Naijiria ti padà sí ìjọba tiwantiwan ni 1999.
"O sọ wípé, ""Àjọ àwọn agbẹjọ́rò Naijiria (NBA), ìjọba Amẹrika, Ilẹ̀ Gẹ̀ẹ́sì ati EU ni wọ́n rí bí ìbò náà ṣe wáye. Àwọn ará ìlú pàápàá ti dájọ́ fun ìjọọba tuntun yì."
A lérò wípé ilé ẹjọ́ yóò ṣe ẹ̀tọ́ lórí ọ̀rọ̀ náà láti gbé ipò náà fún Sẹ́nétọ̀ Ademola Adeleke tí ó yẹ fún.
Osun Election Results 2018: Adeleke sọ pé PDP yóò gba ipò gómìnà rẹ̀ padà nílé ẹjọ́
Òṣìṣẹ́ ìjọba ẹ̀ni ọdún mọ́kàndínláàdọ́ta pokùn so ní Ekiti
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Aworan okun ti awọn eeyan fi n pokun so
Ọrọ di boo lọ o yaa mi ni ileese oṣisẹ nipinlẹ Ekiti nigba ti oṣisẹ ijọba kan, ọgbẹni Abolarinwa Olaoye pokun so.
Oku arakunrin naa to lọmọ maarun ti o si n ṣiṣẹ ọlọdẹ pẹlu ijọba ipinlẹ Ekiti lawọn eeyan sadede ri nirọlẹ ọjọ iṣẹgun.
Ohun taa gbọ ni pe o fi aṣọ kan ṣe okun ti o si so o mọ ọrun rẹ eleyi to sokunfa iku rẹ.
Ọpọ awọn oṣiṣe ijọba to rọ yika oku rẹ ni kayefi ni iṣẹlẹ naa ti wọn si ṣe apejuwe ẹni ọdun mọkandinlaadọta yii gẹgẹ bi oniwa tutu.
Alupupu rẹ ti o gbe wa si ibiṣẹ ni ọjọ naa wa ni ẹgbẹ kan ti o gbe e kalẹ si.
Elizabeth Babalola to jẹ ana oloogbe naa ṣọ wi pe ogbẹni Olaoye a ma ṣiṣẹ oko dida ati ọkada lati le fi kun iye owo to n gba nibi iṣẹ ijọba to n ṣe.
Oríṣun àwòrán, Toba Babalola
Oun to mu ki arakunrin Olaoye pokunso ko ye ẹnikankan
Babalola salaye pe ni nnkan bi aago merin abọ ọjọ iṣẹgun ni Olaoye to jẹ ọmọ bibi ilu Igogo Ekiti, ni ijọba ibilẹ Moba,wa si ile oun ti o si n bọkan jẹ nipa ipenija aisiowo lọwọ ti o n ba finra.
Babalola ni ''ọrọ owo ile ati awọn gbese ti o jẹ lo n ran lẹnu nigba ti o wa si ọdọ mi ni ago mẹrin ọjọ iṣẹgun. O ni oun tun jẹ gbese ẹyawo owo ile ati ọkọ''
Nigba ti BBC Yoruba ba alukoro ọlọpa ni ipinlẹ Ekiti Caleb Ikechukwu sọrọ, o fidi ọrọ naa mulẹ pe lootọ ni wọn si ti gbe oku rẹ lọ si ile igbokupamọ si.
Caleb Ikechukwu ni lori ọrọ náà, iwadii ṣi n lọ lọwọ.
Ọlọ́pàá Abuja: Deji Adeyanju àtàwọn méjì míràn fẹ́ dá ìlú rú
Oríṣun àwòrán, Nigeria police force
Ileeṣẹ Ọlọpaa mu Adeyanji atawọn meji miran ṣaaju iwọde wọn
Ileeṣẹ ọlọpaa lorilẹede Naijiria ti ṣalaye idi ti wọn fi mu gbajugbaja ajafẹtọ ọmọniyan kan, Deji Adeyanju ati awọn meji miran ni ọjọru.
Ninu alaye kan ti o ṣe ninu atẹjade kan to fi sita, ileeṣẹ ọlọpaa ni igbimọ pọ huwa ọdaran, ibanilorukọ jẹ kikọ eti ikun si ofin ati dida alaafia ilu laamu wa lara idi ti wọn fi mu ajafẹtọ naa.
Awọn ọlọpaa mu Deji Adeyanju, Daniel Abobama ati Boma Williams ṣaaju iwọde kan ti wọn gbero lati ṣe ni ọjọru, ọjọ kejidinlọgbọn oṣu kọkanla ọdun 2018.
"Ileeṣẹ Ọlọpaa ko ṣai mọ pe gbogbo awọn ọmọ orilẹede Naijiria lo ni ẹtọ lati sọ ero ọkan wọn, ẹtọ lati korajọpọ ati ẹtọ lati rin bi o ti wu wọn gẹgẹ bii ọpakutẹlẹ fun iṣejọba tiwantiwa gẹgẹ bii iwe ofin ọdun 1999 ti ṣe laa kalẹ labẹ ipele kẹtadinlogoji, ikọkandinlogoji, ogoji ati ọkanlelogoji, amọṣa awọn ẹtọ wọnyii gbọdọ waye lai ni tako ẹtọ awọn ẹgbẹlẹgbẹ ọmọ Naijiria to ku pẹlu.
Iroyin nipa mimu ti ọlọpaa mu awọn ajafẹtọ mẹta yii ti n da ọpọ ariyanjiyan silẹ bi o tilẹ jẹ pe ileeṣẹ ọlọpaa ni mimu ti wọn mu wọn ko lodi si ofin.
Ọgbẹni Adeyanju wa lara awọn ajafẹtọ lorilẹede Naijiria ti wọn ṣiwaju ipe fun aiṣegbe ileeṣẹ Ọlọpaa, paapaa julọ bi eto idibo apapọ ọdun 2019 ṣe n kan ilẹkun ni orilẹede Naijiria.
Ni nnkan bi agogo mẹwa ana ni Ọgbẹni Adeyanju ṣi kọọ si ori ikanni Twitter rẹ pe awọn ti wa lọna olu ileeṣẹ ọẹọpaa nilu Abuja lati lọ ṣe iwọde #PoliceNotPoliticians"" to tumọ si pe #ọlọpaa kii ṣe oloṣelu, ki iroyin to jade pe ọlọpaa ti muu."
Oríṣun àwòrán, Nigeria police force
Ọgbà ẹ̀wọ̀n ìlúu Keffi ni àwọn mẹ́tẹ̀ẹ̀ta wà báyìí nítorí àìmú ìlànà béèlì tí ilé ẹjọ́ fún wọn ṣẹ.
Nibayii ileeṣẹ ọlọpaa ti gbe lọ si ile ẹjọ ni Ọjọru kan naa ni ile ẹjọ Karshi Court ni olu ilu orilẹede Naijiria, Abuja.
Adajọ fi aye silẹ fun gbigba oniduro rẹ ṣugbọn wọn ti fi wọn si  ahamọ lọgba ẹwọn ilu Keffi ni ipinlẹ Nasarawa nitori aile mu ilana beeli rẹ ṣẹ.
LUTH: Nítorí àìsan owó oṣù, àwọn dókítà ARD da iṣẹ́ sílẹ̀ ní ilé ìwòsàn LUTH nílùú Èkó
Oríṣun àwòrán, LUTH
Gẹ́gẹ́ bí ìròyìn tí ó ń tẹ̀wálọ́wọ́ ṣe sọ, àìsan owó oṣù ló ṣokùnfà iyanṣẹ́lódì náà.
Awọn dokita ni ile iwosan nla ti fasiti ilu Eko, LUTH ti gunle iyanṣẹlodi.
Ni aago mẹjọ owurọ ọjọbọ ni awọn dokita ni ileewosan nla naa, labẹ aṣia ARD bẹrẹ iyanṣẹlodi ọhun.
Ninu ọrọ to ba BBC News Yoruba sọ, aarẹ ẹgbẹ awọn dokita ni ileewosan nla fasiti ilu Eko, LUTH, Dokita Ọlawale Ọba ni ọrọ lori owo oṣu awọn dokita ti awọn alaṣẹ kuna lati san lo ṣokunfa iyanṣẹlodi naa.
Dokita Ọba ni oṣu kẹjọ ọdun 2018 ni awọn dokita ileewosan naa, titi to fi kan awọn dokita agba nibẹ gba owo oṣu kẹyin eyi to tumọ si pe owo oṣu mẹta ni wọn jẹ awọn Dokita nibẹ.
A ti ṣe ipade ṣaaju iyanṣelodi yii ti a si ti fun awọn alaṣẹ ni gbedeke ọsẹ meji eyi to pari ni ọjọru, ọjọ kejidinlọgbọn oṣu kọkanla lai si ayipada. Idi niyi ti a fi gunle iyanṣẹlodi yii.
Awọn dokita iṣegun oyinbo ni ileewosan nla fasiti LUTH nilu Eko ni kudiẹkudiẹ ti o waye lori owo iṣuna ileewosan naa ninu eto iṣuna ti awọn alaṣẹ ileewosan naa fi ranṣẹ si ileeṣẹ eto iṣuna ijọba apapọ lo ṣokunfa aisan owo oṣu wọn.
Beautiful Nubia: Kò sí wàhálà tó ń ṣẹlẹ̀ láàgbáyé tí kò ní ọwọ́ ẹ̀sìn lábẹ́nú
Dokita Ọba to jẹ aarẹ ẹgbẹ awọn dokita nileewosan nla LUTH ṣalaye pe ninu biliọnu mẹjọ o din igba ẹgbẹrun naira, N7.8biliọnu ti wọn kọ fun owo awọn oṣiṣẹ, ileeṣẹ eto iṣuna buwọlu lu iwọnba biliọnu mẹrin abọ, N4.5 biliọnu ninu rẹ leyii ni o si ti n mu inira ba eto sisan owo oṣu awọn oṣiṣẹ nibẹ.
Nibayii, ko tii si ẹni lee sọ ohun ti yoo ṣẹlẹ sawọn alaisan ti wọn wa labẹ itọju ni ileewosan naa ṣaaju iyanṣẹlodi ọhun.
Titi di asiko ti a fi n  ko iroyin yii jọ awọn alaṣẹ ileewosan naa ko tii fi ọrọ sita lori rẹ.
Ọlọ́pàá: Ọmọ ìyá méjì gé orí ọmọ ọdún mẹ́wàá nítorí N200,000
Oríṣun àwòrán, Lagos State Police Command
Ayodeji ati Saheed salaye fun awọn ọlọpaa pe ọgbẹni kan ti orukọ rẹ njẹ Sodiq Abefe ni o ni ki awọn lọ wa ori eniyan kan wa
Ọwọ ileṣẹ ọlọpaa ti tẹ ọmọ iya meji kan pẹlu ori ọmọdekunrin ti wọn ṣẹṣẹ ge nilu Eko.
Aago mẹjọ aabọ alẹ ọjọ Iṣẹgun ni awọn ọlọpaa to n gbogun ti ijinigbe ni Ipinlẹ Eko da Ayodeji Obadimeji to jẹ ọmọ ọdun mejidinlogun ati ẹgbọn rẹ Saheed Obadimeji duro ni opopona Ajah si Ẹpẹ nilu Eko. Nigba ti wọn maa wo inu ọkọ ti wọn wa, ori ọmọdekunrin naa ti wọn pe ni ọmọ ọdun mẹwaa ni wọn ba ninu rẹ
Agbẹnusọ fun ileeṣẹ ọlọpaa Ipinlẹ Eko, Chike Oti ni awọn afunrasi naa ti wọn n gbe agbegbe Shapati ni Ibẹju-Lekki, ṣalaye fun awọn ọlọpaa pe ọgbẹni kan ti orukọ rẹ njẹ Sodiq Abẹfẹ ni o ni ki awọn lọ wa ori eniyan kan wa ti oun yoo si nfun wọn ni ẹgbẹrun lọna igba naira (N200,000).
Wọn tun sọ siwaju pe awọn tan ọmọdekunrin naa ki o lọ ba awọn ra elerindodo Coca-Cola wa, nigba ti o mu elerindodo naa de, wọn dee mọlẹ, wọn si fi ọbẹ ge ori rẹ.
Jide Kosọkọ: Isẹ́ tíátà yóò gòkè tíjọba bá gbówó kalẹ̀ láti seré
Ọlọpaa ti kan si awọn obi ọmọ naa ti wọn ni orukọ rẹ n jẹ Joseph Makinde.
Lẹyin ti ọlọpaa mu awọn afẹsunkan naa, ni wọn mu awọn oluwadii lọ ibi ti wọn sọ iyoku ara ọmọdekunrin naa si ninu ile kan ti wọn ko ti i kọ tan ni Sapati.
Kọmiṣọna fun ileeṣẹ ọlọpaa ní Ipinlẹ Eko Edgal Imohimi ti paṣẹ fun ẹka ọtẹlẹmuyẹ lati bẹrẹ iwadi kikun lori ọrọ naa. Bẹẹ ni o si tun kilọ fun awọn ara ilu lati maa ṣọ awọn janduku aṣẹkupani to le wa ni ayika wọn.
Sunday Ayẹni: Damilọla, aya ọmọ mi fìgbónára sọ mi sókùnkùn alẹ́
CAF Awards: Ahmed Musa, Alex Iwobi, Asisat Oshoala wà lára olùdíje àmì ẹ̀yẹ CAF
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Àwọn agbábọ́ọ̀lù Nàìjíríà farahàn lára àwọn tí yóò díje fún àmì ẹ̀yẹ̀ agbábọ́ọ̀lù tó pegedé lọ́kùnrin àti lóbìnrin
Ajọ elere bọọlu ni ilẹ Afirika, CAF ti gbe orukọ awọn agbabọọlu mẹrinlelọgbọn jade lati dije fun ami ẹyẹ agbabọọlu to pegede julọ lori papa ni saa ere bọọlu ni ọdun 2017 si 2018.
Ajọ CAF gbe iwe orukọ awọn agbabọọlu naa jade ni ọjọ ẹti ninu eyiti ti wọn yoo ti mu mẹta ti yoo figagbaga fun ami ẹyẹ naa lẹyin o rẹyin.
Balogun ikọ Super eagles, Ahmed Musa ti o n gba bọọlu fun ẹgbẹ agbabọọlu Al-Nassr ni Saudi Arabia pẹlu Alex Iwobi ti ẹgbẹ agbabọọlu Arsenal ni agbabọọlu to wa ninu ipele ti ọkunrin.
Ni abala awọn agbabọọlu obinrin, Asisat Oshoala, agbabọọẹu Super Falcons Naijiria ati ikọ Dilian Quanjian ti orilẹede China, Desire Oparanozia ti falcons ati ẹgbẹ agbabọọli Guingamp, Francisca Ordega lati ikọ agbabọọlu Washington Spirit, ati Onome Ebi lati ikọ Hekan Huisanhang ni wọn wa lori orukọ ti ajọ CAF fi sita.
Bakan naa, orukọ Wilfred Ndidi to n gba bọọlu jẹun ni iks Leicester city ni ilẹ gẹẹsi pẹlu wa ni orukọ awọn agbabọọẹu ti wọn la kalẹ fun ami ẹyẹ agbabọọlu ọdọ ti o pegede.
Ni abala awọn olukọni agbabọọlu, gernert Rohr to jẹ olukọni fun ikọ Super Eagles ati Thomas Dernnerby ti ikọ Super falcons pẹlu wa lara awọn ti wọn fa kalẹ fun olukọni to pegede julọ ni ipele awọn ọkunrin ati obinrin.
Ìjọba Naijiria: À ń se ìwádìí lórí àwọn oníwàásù Sokoto tó ń gbé ìbọ̀n
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ẹgbẹ́ agbébọ̀n náà wọ ìpínlẹ̀ Sokoto láti orílẹ̀èdè Niger tí wọ́n sì ń gbé ìjọba ara wọn kalẹ̀ lórí àwọn èèyàn agbègbè ọ̀hún
Agbẹnusọ fun Aarẹ Muhammadu Buhari, Garba Shehu ti sọ wi pe ijọba apapọ yoo bẹrẹ iwadii lori awọn oniwaasu ti wọn lo n gbe oun ija kaakiri lagbeegbe kan ni Sokoto.
Iroyin kan ti o n da ẹru ba ọpọ lẹkun ariwa orilẹede Naijiria, paapaa julọ ni ipinlẹ Sokoto ni ti ẹgbẹ agbebọn tuntun kan ti wọn ni wọn n waasu ẹsin Islam tawọn tibọn lọwọ.
Iroyin sọpe orilẹede Niger ni awọn ẹgbẹ alakatakiti yii ti ṣẹ wọ ẹkun iwọ oorun ariwa orilẹede Naijiria.
garba shehu fikun wipe ijoba naijiria ko ni fi isele yii jafara, amo won yoo kesi awon elebo aabo lati wo bi o se n lo lawon agbeegbe yii.
Goodluck Jonathan ní òun nìkan kọ́ ló l'ẹ̀bi ìjínigbé akẹ́kọ̀ọ́ Chibok àti Boko Haram
Ẹgbẹ́ alákatakítí agbébọ̀n tuntun wọ Nàìjíríà!
Olugbe ijọba ibilẹ Tangaza kan nipinlẹ Sokoto ti o ba BBC Hausa sọrọ ṣalaye pe nnkan bi oṣu meji sẹyin ni awọn ẹgbẹ naa wọn awọn ileto kan ni ijọba ibilẹ naa.
Arakunrin naa ti o bẹbẹ pe ki BBC o fi orukọ bo oun laṣiri fi kun un pe awọn ẹgbẹ agbebọn naa tilẹ n rin lati ileto si ileto lati gba owo ori ti wọn si n yọ ẹgba si awọn eeyan ti wọn ba wo pe wọn ṣẹ tako ofin ẹsin Islam.
Bakan naa ni o ṣalaye pe awọn ọmọ ẹgbẹ alakatakiti naa ti wọn to igba ni iye kii ṣe alawọ dudu, wọn fara jọ awọn larubawa ti wọn fi lawani bo ori pẹlu awọn ibọn atamatase ni ọwọ wọn.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ijọba ko tii sọ ohunkohun lori rẹ
O ni awọn ọmọ ẹgbẹ yii a tun maa gbe awọn ọmọde wọ inu igbo lọ lati kọ wọn ni oriṣiriṣi ẹkọ nigba ti wọn pada de. Wọn si tun fun wọn ni alupupu ọfẹ.
Ijọba ibilẹ Tangaza ni ipinlẹ Sokoto sun mọ orilẹede Niger, nibẹ ni wọn ṣi wa bayii.
Orilẹede Naijiria ṣi n ba wahala ati ipenija ikọ agbebọn Boko Haram finra bayii eleyii to ti mu ọpọlọpọ ẹmi lọ ti pupọ si ti di alainilelori.
Algeria: Ààrẹ Abdelaziz Bouteflika re 'bi àgbà ń rè
Oríṣun àwòrán, AFP
Abdelaziz Bouteflika
Abdelaziz Bouteflika fẹrẹẹ lo ogun ọdun ninu aginju oṣelu ki wọn to dibo yan an gẹg bi Aarẹ orilẹede Algeria lọdun 1999.
Ipa ti o ko ninu ija fun ominira Ageria fun un ni iyi nla lagbaye bi o tilẹ jẹ wi pe ero tirẹ ati aato maa n tako ohun ti awọn alawọ funfun n fẹ.
Kii ṣe bii tawọn adari mii lẹkun naa, isejọba tirẹ ggẹ bi aarẹ bori ifẹhonu han awọn ara Arab lodi si ijọba.
Wọn bi Abdelaziz Bouteflika ni Morocco ni ọjọ keji oṣu kẹta ọdun 1937; ara orilẹede Algeria lawọn obi rẹ.
Ọpọlọpọ igbe aye rẹ lo gbe ni Algeria ti o si dara pọ mọ ẹgbẹ oṣelu National Liberation Front (FLN) nigba to wa ni ọdọ langba.
Lẹyin ominira lọdun 1962, Aarẹ Ahmed Ben Bella fi Bouteflika jẹ minisita fun ọrọ awọn ọdọ ati ere idaraya. Lọdun to tẹle e, o di minisita fun ọrọ ilẹ okere.
Oríṣun àwòrán, Reuters
Bouteflika, ẹni ikeji lati apa ọtun pade Saddam Hussein
Ṣugbọn nigba to maa fi di ọdun 1965, ẹgbẹ oṣelu FLN ti wa ninu idamu. gba gba lo yiyọ Ben Bella loye ti wọn fi Houari Boumedienne sibẹ.
Ṣugbọn awọn alatako rẹ pada fẹsun kan an pe o lọwọ ninu iku ọmọ gb oṣelu FLN marun un.
Ọpọ lo ri i gẹgẹ bi opomulero iṣejọba, Bouteflika ni agbatẹru bi Algeria ṣe goke ninu ẹgbẹ to n jẹ Non-Aligned Movement.
Pẹlu iku Boumedienne ni 1978, orisun agara Bouteflika tan. O ti ro pe oun yoo di aarẹ lẹyin Boumedienne ṣugbọn awọn ẹgbẹ kan laarin awọn ologun yan Chadli Bendjedid dipo rẹ.
Ati adun ati ipenija oṣelu ni Bouteflika yago fun lẹyin gbogbo ẹsun ti wọn fi kan an nigba to n dari ile iṣẹ to n ri si ọrọ ilẹ okere lo ba na papa bora kuro ni Algeria ldun 1983 ti ibi to wa si ru ni loju.
Oríṣun àwòrán, AP
Wahala mu ki awọn ologun maa ṣọna gbogbo iloro ni gbogbo igba
Ẹgbẹ oṣelu FLN to ti jọba ni orilẹede ẹlẹgb oṣelu kan lati igba ominira rẹ wa pin si ẹgbẹ modernisers ati conservatives; igba yẹn ni Bouteflika to jẹ ti conservative ba pada lati ibi to ṣako lọ.
Bouteflika pada sori itage oṣelu lọdun 1999 nigba to dupo aar plu atilẹyin awọn ologun. O jẹ ọkan lara awọn oludije meje ṣugbọn ṣe lawọn mẹfa to ku ni awọn o dupo aarẹ mọ ti wọn si fi ẹhonu han pe wọn ti da ibo ru fun anfani Bouteflika.
Ọpọlọpọ ri i gẹgẹ bi adari to lee yanju aawọ awọn araalu eyi to bẹ silẹ lẹyin ti awn ologun da si i lati dena ki ẹgbẹ ẹlẹsin Islam kan bori ninu idibo gbogbo gbo ti ọdun 1992.
Laarin oṣu marun un pere to gori oye, wọn tẹwọ gboriyin fun un lori aato rẹ fun iyanju aawọ eyi to fun ọpọlọpọ ẹgbẹ Islam.
Oríṣun àwòrán, Reuters
Ọpọ ara Algeria n sọ pe ko ṣe nkankan lati mu ọrọ aje gberu sii
Bakan naa, o ṣe iṣẹ lati dọrẹ pẹlu orilẹede aladugbo wọn, Morocco. Orilẹ̀ede mejeeji ti wa ninu aigbọraẹni ye lori ọjọ iwaju apa Ila Oorun Sahara.
Wọn tun yan Bouteflika gẹgẹ bi aarẹ lọdun 2004 ti o si fi ẹyin oludije marun un janlẹ lati gba ibo to pọ ju.
Awọn alatako rẹ fi ẹsun ole ibo kan an bi o tilẹ jẹ pe ko ni aridaju awọn onwoye lati ilẹ okere to mojuto idibo naa.
Ọpọlọpọ ara Algeria lo kan sara si i pe o da alafia pada si orilẹede naa wọn si ro o wi pe o nilo saa kan sii ni ijọba.
Ni ọdun 2008, o ri aridaju ayipada ninu ofin Algeria eyi to yọ gbedeke saa meji ti aarẹ le lo, igbesẹ yii si ni ile igbimọ aṣofin wọn ṣe atunṣe rẹ lọdun 2008.
Oríṣun àwòrán, AFP
O ni oun ko lọwọ ninu ẹsun iwa ole ninu ibo
Lọdun to tẹle e, Bouteflika gbe apoti ibo fun saa kẹta o si ni ida aadọrun ninu ọgọrun ibo eyi si tun mu ki ẹgbẹ oṣelu alatako tun ri wi nipa iwa ole idibo.
Gbogbo igba lo maa n doju kọ ifẹhonu han lasiko to wa lori alefa ṣugbọn nigba to ku diẹ ki oṣu kejila ọdun 2010 pari, atako nla yọju si aato rẹ ti awọn afhonu han si tu sigboro lati fi ibinu wọn han si ọrọ ọbayejẹ, ọwọngogo ounjẹ ati airilegbe.
Fifi ẹhonu han yi di rangbọndọn kete ni osu ti owo ounjẹ wẹwẹwẹ goke sii ti wọn si fipa mu ki ijọba din i ku.
Lọjọ kẹẹẹdogun oṣu kẹrin, Bouteflika fara han lori ẹrọ mohunmaworan to ti n ṣeleri lati ṣatunṣe iwe ofin ati itẹsiwaju ijọba awa ara wa ni Algeria.
Oríṣun àwòrán, Reuters
Wọn fi ẹsun kan an pe o n tẹ awọn alatako ri mọlẹ lati ṣi wa lori alefa
Abdelaziz gbiyanju lati rii pe alafia jọba ni orilẹede Algeria bi o tilẹ jẹ pe awọn onija ẹsin Islam ṣi tẹsiwaju ti wọn si yan orukọ tuntun Al-Qaeda lọdun 2007, wọn n ṣe ikọlu kaakiri awọn orilẹede agbegbe.
Bakan naa Bouteflika ko ribi koju awọn ẹsun iwa ajẹbanu ti wọn fi kan an eyi to tapo si aṣọ ala rẹ pupọ lori alefa.
Wọn wa ri aato atunṣe rẹ bi eyi ti ko to nkan to si pẹ, awọn ara Algeria paapaa ọdọ ko wa ni suuru mọ pẹlu ohun ti wọn ri gẹgẹ bii ipinu rẹ lati lo ilana to lodi si ijọba awa ara wa lati tẹ ẹ pa sori alefa gẹgẹ bi aarẹ lai kuro nibẹ mọ.
Ǹǹkan márùn ún nínú ilé tó lè ṣe ikú pa ni
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Efin to n jade latara ẹrọ amunawa ti ran ọpọ lọ si ọrun
Yoruba bọ wọ ni a kii joko sile ka fi ọrun yin. Amọ ṣa ti ọrọ ba kan awọn nnkan elo kan ninu ile, ọpọ lo ti fi nnkan to ju ọrun yin lọ.
Koda ẹmi ti bọ latara lilo awọn nnkan wọnyii.
Losu kẹjọ ọdun yii ni a gbọ iroyin awọn ẹbi kan nilu Port Harcourt ti wọn dero ọrun latara bi eefin ẹrọ amunawa ṣe ṣeku pa wọn.
Wọn ṣe aajo ki wọn ri ina tan lẹyin igba ti ina ọba lọ, lọrọ ba di mo ha mọ.
Ajalu kanna tun waye nipinlẹ Osogbo lọjọ kọkandinlọgbọn Osu kọkanla nibi ti eniyan mẹta ninu idile kan to n gbe ni agbole Olorisaoko ni Osogbo ni Ipinlẹ Osun gbẹmii mi.
Eefin ẹrọ amunawa lo pa sajẹnti ọlọpaa to jẹ́ olori ẹbi naa ati awọn ẹbi rẹ.
Lọdun 2014, ajọ aladani  kan ti orukọ rẹ n jẹ 'Good Governance Initiative' so pe o to ẹgbẹrun lọna ọgọrun eeyan to salabapade iku ojiji lọwọ eefin.
Ṣugbọn kii ṣe eefin ẹrọ amunawa nikan lo n ṣe ijamba fun ẹmi ninu ile.
Akọṣemọṣẹ oniṣegun kan to mọ nipa iṣẹlẹ pajawiri Dokita Anthony Mgbolu sọ pe ti afẹfẹ buruki ba file wọ inu ọna ọfun lọ ,yoo sẹ akoba fun ọpọlọ ti eleyii yoo si mu ki ẹni naa ma le mi mọ.
O salaye awọn nnkan maarun to yẹ ki asọra pẹlu bi a ti ṣe n lo wọn ninu ile.
Ogun apakokoro  (Insecticide)
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Fifin oorun awọn ogun apakoro paapa ju ti ẹfọn ninu ile le sakoba fun ara
Lai pẹ yii la gbọ iroyin bi awọn ọmọ mẹta kan ṣe di ero ọrun lẹyin ti iya wọn fin ogun apẹfọn sile.
Eefin ti awọn  ọmọ naa fin si imu lo ṣeku pa wọn.
"Dokita Anthony ṣalaye pe kẹmika to wa ninu ogun apẹfọn ti orukọ rẹ n njẹ ""Organophosphate""  buru pupọ ti o si ma n ṣe akoba fun ẹni to ba ba ṣe alabapade."
"O sọ pe ""Ọpọlọpọ awọn ogun apakokoro ti wọn n ta ni ọja kọ lo yẹ ki a maa lo ninu ile. Wọn ṣe awọn miiran fun lilo ninu oko ni''"
Eefin ẹrọ amunawa
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ọpọ mọlẹbi ni efin ẹrọ amunawa ti to si inu ibanujẹ
Carbon monoxide lorukọ ti awọn oloyinbo n pe eefin ti o ma n jade lati inu ẹrọ amunawa.
''Bi ẹni wi pe ara ran bọmbu lọwọ ni ti eeyan ba fin in si imu''
Dokita Anthony tun sọ wi pe ''ti eeyan ba mi afẹfẹ yi to yẹ ki a ma mi sita sinu, a maa ṣokunfa iku''
Afẹfẹ Idana gaasi
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Afẹfẹ gaasi idana le mu ina dida ya amọ o le yara pa eeyan
O ṣeeṣe ki eefin rẹ naa ṣe iku paniyan ninu ile.
Ona ti o le gba se eleyi kii sẹ ki o gbana ṣugbọn ti eeyan ba fin in si imu, Dokita Anthony wi pe ''o le fa iku ti eeyan ko ba tete ri atẹgun aafin simu lasiko.''
Oda ikunle(Paint)
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Bi eeyan ba wọ inu iyara ti wọn ṣẹṣẹ kun lọda lewu
Igbiyanju eeyan lati fi ọda pa oju ile naa a maa ṣokunfa ijamba ninu ille gẹgẹ bi alaye Dokita Anthony.
''Eyi a maa je aburu ti a ba joko sinu ile ti wọn ṣẹṣẹ kun tan ti a si n fin eefin rẹ simu''
Kemika kan wa ninu oda tuntun to jẹ wi pe o le fa iku ti eeyan ba fa si imu.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Epo pupa
Iru efin epo ti a ba gba lori ina ni aye idana ti efin rẹ si gbalẹ kan le ṣe akoba fun ẹmi.
''Iru awọn to ba ni aisan ''asthma'' ko gbọdọ fin eefin yii simu bi bẹẹ kọ, o le ṣe akoba fun wọn''
HIV AIDS: Ìdí tí o kò fi lè kó àa[rùn HIV nínú itọ́
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ọrọ lori aarun Hiv
Koko HIV wa lara awọn arun to jẹ ipenija nla lagbaye ninu eto ilera lẹyin ti o ti gbẹmi eeyan bii marundinlogoji.
Ajọ to to n ri si eto ilera lagbaye(WHO) ṣalaye pe eeyan miliọnu kan to ni aarun HIV lo padanu ẹmi wọn lọdun to lọ lasan.
Iwadi fihan pe eeyan miliọnu mẹtadinlogoji lo larun HIV lagbaye ti ida aadọrin ninu ọgọrun si wa lati ilẹ Afirika- bẹẹ eeyan to din diẹ ni miliọnu meji ṣẹṣẹ lugbadi aarun ọhun ni ọdun 2017 nikan.
WORLD AIDS DAY 2018: HIV/ AIDS kìí ṣe ìdájọ́ ikú mọ́
Ẹni to ba ni kokoro HIV nikan lo le ni aarun AIDS.
Ọpọ nnkan lawọn eeyan ti n sọ nipa aarun AIDS lati igba ti o ti kọkọ jade ni bi ogoji ọdun o din dẹ ṣẹyin.
Ṣugbọn ko si otitọ ninu ọpọlọpọ ọrọ naa.
Irọ: Mi o le ni kokoro HIV ti mo ba n bawọn to ni kokoro HIV gbe
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ninu ẹjẹ ni aarun HIV wa
Ero yii ti ṣe okunfa ki ọpọ eeyan maa ba awọn ti wọn ni kokoro HIV ṣe papọ fun ọjọ pipẹ.
Lẹyin inalilọyẹ ati ipolongo lori aarun HIV AIDS, ida ogun ninu ida ọgọrun awọn eeyan Ilẹ Gẹẹsi si gbagbọ pe eeyan le lugbadi aarun naa nipa fifi ara kan ara tabi ninu itọ.
Ṣugbọn eeyan ko le karun HIV AIDS nipa fifi ara kan ara, tabi omi oju, oogun, itọ tabi itọ.
O ko le ko aarun HIV AIDS nipa:
Oríṣun àwòrán, PA
Oloogbe ọmọbabinrin Diana pẹlu ẹni to ni aarun HIV
Kokoro HIV maa n ran nigba ti omi ara ẹnikan ba dapọ mọ ti tẹni to ba ni aarun naa, fun apẹrẹ, ẹjẹ, atọ, omi oju ara obinrin ati omi ọyan.
Irọ: Oogun ibilẹ le wo aarun HIV san
Irọ funfun balau ni. Oogun ibilẹ, iwẹ lẹyin ibalopọ tabi ibalopọ misconception  ko le wo aarun HIV AIDS.
Wiwẹ pẹlu ọmọbinrin tii ko mọ ọkunrin to le wo aarun HIV AIDS san.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Itọ ko le fa aarun HIV
Irọ nla ni pe o le tara ẹfọn ni aarun HIV
Irọ ni pe o le ko aarun HIV lati ibasun ẹnu.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Rọba idaabobo wulo fun idena aarun HIV
Wiwọ rọba idaabobo(condom) ko sọ pe ki eeyan maa lugbadi aarun HIV.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Aarun HIV
Irọ nla ni pe awọn to ba larun HIV maa n ku ni kekere
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ọmọ ikoko
Alaboyun to ba ni aarun HIV, ọmọ rẹ le maa ni aarun ọhun
Fisa Atiku: Ọ̀pọ̀ aráàlú dunú, àwọn míràn yẹ̀gẹ̀ rẹ̀
Oríṣun àwòrán, @atiku
Ọjọ Abamẹta ni iroyin kan gbalẹ pe, Oludije fun ipo aarẹ labẹ asia ẹgbẹ oselu PDP, Atiku Abubakar, ti ni anfaani bayii lati se abẹwo si orilẹede Amẹrika pẹ̀lu bi ọwọ rẹ se ba iwe asẹ irinna silẹ Amẹrika.
Iroyin naa ni ọdun kẹtala ree ti Atiku ti ni anfaani kẹyin lati se abẹwo si orilẹede Amẹrika nitori ẹsun ajẹbanu ti wọn fi kan lori ọrọ epo rọbi lasiko to jẹ igbakeji aarẹ fun Oloye Olusẹgun Ọbasanjọ.
A gbọ pe ilu Abuja ni Atiku ti lọ gba iew asẹ irinna si Amẹrika naa, ti inu rẹ si dun dẹyin pe ọwọ oun tẹ ‘Fisa’ naa.
Ọkọ ìyàwó ẹlẹ́kún: N kò bá tí ba ẹnu jẹ́ lọ́jọ́ ìgbeyàwó, àwàdà ni mo se
Ni kete ti iroyin ọhun gbalẹ kan lawọn Naijiria ti n fi ero wọn nipa iroyin naa han lawọn oju opo ikansiraẹni lori ayelujara, paapa loju opo Twitter.
@G_Abdulazeez, o yọ suti ete si iroyin yii, to si ni nibayii ti Atiku ti gba, aseyọri nla ni eyi fawọneeyan to pe ‘onijẹkujẹ’ati ẹgbẹ oselu PDP pẹlu afikun pe ara oun n wa galegale lati dibo.
@OtunbaSula, o ni inu oun dun lati gbọ pe Atiku ti ri fisa Amẹrika gba, to si n ki awọn ololufẹ Atiku yoku ku oriire.
@WazirinBuhari n tiẹ ni to ba jẹ lootọ ni Atiku gba fisa, eyi pa ni lẹrin, amọ se o lee lọ si Amẹrika bi?
"@Noelema2, o n beere pe ""ki ni igbesẹ gbigba fisa Amẹrika nii se pẹlu akoso ijọba Naijiria? Koda bi Atiku gan jẹ ọdaran to buru julọ lagbaye, o si san ju Buhari lọ. ""A ko nilo fisa Amẹrika kankan, akoso to yanranti la nilo. N jẹ Trump gan ti wa si Naijiria ri, se Obama de Naijiria ri?"""
Jonathan: Mó ń sàtilẹyìn fún Atiku kí ìsoro Nàíjíríà má baà fọ́n wa ká
Oríṣun àwòrán, @GEJonathan
Aarẹ orilẹ ede Naijiria ana, Goodluck Jonathan ti salaye pe irọ nla ni pe ẹgbẹ oselu PDP ko se daadaa to fun ọdun mẹrindinlogun to fi tukọ orilẹede yii.
Ninu fidio kan ti BBC Pidgin gbe sita ni Jonathan ti kede ọrọ yii pẹlu afikun pe, to ba jẹ pe ẹgbẹ oselu PDP ko pegede lori aleefa ni, ebi ati iyan ni ko ba ti lu gbogbo ọmọ Naijiria pa tan.
Jonathan wa n beere pe, eelo ni wọn ta apo irẹsi kan nigba ti PDP gba akoso orilẹede yii ati iye ti wọn n ta bayii?
Ọkọ ìyàwó ẹlẹ́kún: N kò bá tí ba ẹnu jẹ́ lọ́jọ́ ìgbeyàwó, àwàdà ni mo se
O tun fikun pe ẹgbẹ oselu PDP ti se iwọn to lee se fun ọdun mẹrindinlogun, ẹgbẹ oselu to wa lori aleefa lọwọlọwọ ni ko mura lati sa ipa tiẹ naa.
Jonathan, ẹni to sọ idi ti oun fi n se atilẹyin fun Atiku Abubakar lati di aarẹ orilẹede yii ni, isoro to n ba Naijiria finra, taa ba tete mojuto, o lee tu orilẹede yii ka, ti ọpọ eeyan yoo si fọn ka lọ sawọn orilẹede miran.
O ni oun nigbagbọ ninu Atiku pe, oun nikan lo lee mu ki irẹpọ ati isọkan pada si orilẹede Naijiria, ti yoo si mu ki gbogbo ẹya ati ede pada wa nisọkan.
Oríṣun àwòrán, @GEJonathan
Jonathan ni orilẹede yii ti yapa to bẹẹ gẹ, debi pe taa ba tete pana rẹ, ọpọ ẹmi ni yoo ba rin, to si seese ki ọpọ eeyan sa kuro nilẹ yii.
Nigba to n salaye lori ohun to faa, ti oun fi tẹ iwe kan sita, Jonathan ni ọpọ eeyan ni ko mọ ohun to n sẹlẹ́= nijọba, paapa awọn ọmọ, ti oun si fẹ ki ọpọ wọn mọ nipa isejọba ti oun se kọja,
O fi kun pe awọn ọdọ nilo iwe itan lati ka, ki wọn lee mọ awọn aseyọri ti oun se lori oye, ti wọn yoo si maa fi tọ awọn adari sọna lọjọ iwaju, paapa bo se kan eto idibo ọdun 2015.
New Era OPC: Ọshinbọtẹ kìí se ọmọ ẹgbẹ́ OPC, alárinà lásán ni
Oríṣun àwòrán, @OPC
Igun ẹgbẹ ajijagbara fun iran Yoruba, Oodua people‘s Congress (OPC) kan, New Era OPC, ti kede pe oun ko fara mọ Ọshinbọtẹ OOdua, tawọn eeyan kan kede gẹgẹ bii aarẹ apapọ fun gbogbo ọmọ ẹgbẹ OPC.
Nigba to n ba BBC Yoruba sọrọ lori isẹlẹ yii, Alukoro fun igun New Era OPC, Sina Akinpẹlu salaye pe awọn kan hu gbọ pe wọn yan olori tuntun ni, awọn ko mọ rara nipa igbesẹ naa.
Gẹgẹ bi Akinpẹlu ti wi, Ọshinbọtẹ ti wọn yan naa kii se ọmọ ẹgbẹ ajijagbara OPC nitori ko ni kaadi idamọ ọmọ ẹgbẹ, bẹẹ naa ni kii se ojuse rẹ gẹgẹ bii ọmọ ẹgbẹ OPC.
Ọkọ ìyàwó ẹlẹ́kún: N kò bá tí ba ẹnu jẹ́ lọ́jọ́ ìgbeyàwó, àwàdà ni mo se
New Era OPC ni alarina lasan ni Ọshinbọtẹ ninu ẹgbẹ OPC, to si maa n sanna alaafia laarin ijọba ati ẹgbẹ OPC>
O fikun pe bonkẹlẹ tabi inu okunkun ti wọn yan Ọshinbọtẹ lai jẹ pe wọn ti sin oludasilẹ ẹgbẹ OPC to jẹ ipe Ọlọrun lọjọ Satide,  Frederick Faseun, jẹ eyi to mu ifura lọwọ.
Akinpẹlu ni Adele asaaju ẹgbẹ lo si yẹ ki wọn yan to ba jẹ pe omi alaafiaigun OPC Faseun ko toro.
O ni ẹgbẹ ajijagbara OPC ti pin si mẹrin, eyiun ni igun Faseun, igun Gani Adams, igun Reformed OPC ati igun New Era OPC.
Alukoro ẹgbẹ New Era OPC tẹ siwaju pe Ọni tilu Ile Ifẹ, Ọba Ẹnitan Adeyẹye Ogunwusi, Ọjaja keji, ti n gbe igbesẹ lasti ri daju pe ẹgbẹ OPC pada si ọkan soso lai pin si yẹlẹ-yẹlẹ mọ, eyi si ni awọn n se lọwọ.
O fikun pe igba ti allafia ba jọba pada ninu OPC lawọn yoo yan aarẹ apapọfun ẹgbẹ ajijagbara naa.
Oríṣun àwòrán, @Faseun
Bẹẹ ba gbagbe, ẹgbẹ ajijagbara fun iran Yoruba, Oodua people‘s Congress (OPC), ti kede lọjọ abamẹta pe, oun ti yan aarẹ apapọ miran lati rọpo oludasilẹ ẹgbẹ OPC to di oloogbe, Frederick Faseun.
Ọjọ ti Faseun papoda naa ni wọn si kede olori tuntun, eyi tii se Osinbọtẹ Oodua.
Sanwo-Olu: Kò ní sí súnkẹrẹ-fàkẹrẹ ọkọ mọ́ l‘Eko tí mo bá dé ipò
Oríṣun àwòrán, Jide Sanwo-Olu Campaign
Olùdíje fún ipò Gómínà Ipinlẹ Eko  lábẹ́ àṣíá ẹgbẹ́ oṣèlú APC, Jide Sanwo-Olu gbé ìgbésẹ̀ láti dáhùn ọ̀pọ̀lọpọ̀ àwọn ibéérè tí awọn ará ìlu Eko ni fún loju opo Twitter rẹ lọ́jọ́ Àìkú.
Sanwo-Olu, nigba to n sọrọ lórí bó ṣe di olùdíje ati awọn ọ̀rọ̀ míràn tí ayé ti ń mẹ́nu bà láti ìgba tí ìdìbò abẹ́lé APC ti waye, O ni awọn isẹlẹ to n waye lo safihàn pé àwọn ọmọ ẹgbẹ́ náà kò fẹ́ Gomina Akinwúnmí Ambode fun sáà kejì.
Tọkọ-taya Aràrá: Àwọn èèyàn máa ń wò wá, ta bá fa ọwọ́ ara wa ní títì
Àwọn kókó mẹ́wàátí Sanwo-Olu sọ:
Oríṣun àwòrán, PIUS UTOMI EKPEI
Oríṣun àwòrán, Sanwo Olu Campaign
Oríṣun àwòrán, PIUS UTOMI EKPEI
Oríṣun àwòrán, Lago State Government
Femi Hamzat yẹ̀bá fún Sanwo-Olu ní ìdìbò abẹ̀lẹ̀ APC
NLC: Ìjọba àpapọ̀ ń tán wa ní sùúrù pẹ̀lú bó se dákẹ́ lórí owó osù tuntun
Oríṣun àwòrán, @NLCHQ_ABUJA
Agbarijọpọ ẹgbẹ osisẹ NLC ti fi igbe ta pe ara awọn ọmọ ẹgbẹ naa ko balẹ mọ, ti ijọba si n tan awọn ni suuru lori ọrọ sisan ẹgbẹrun lọna ọgbọn naira gẹgẹ bii owo osu to kere julọ lorilẹ ede Naijiria.
Nigba to n bawọn akọroyin sọrọ, akọwe apapọ fẹgbẹ NLC, Peter Ozon Eson ni, ọwọ yẹpẹrẹ tijọba apapọ fi mu ọrọ sisan owo osu to kere ju naa ko bawọn osisẹ lara mu.
O ni ayafi tijọba ba gbe igbesẹ to lowura ni kia-kia, nikan lẹgbẹ naa ko fi ni sepade lẹẹkan si, ti yoo si gbe igbesẹ to yẹ lati beere fun ẹtọ rẹ.
Tọkọ-taya Aràrá: Àwọn èèyàn máa ń wò wá, ta bá fa ọwọ́ ara wa ní títì
Ẹgbẹ osisẹ NLC ni o yẹ ki aarẹ Muhammadu Buhari ti fi aba sisan owo osu to kere julọ naa ransẹ si ile asofin apapọ fun agbeyẹwo ati ibuwọlu to yẹ lati igba ti wọn ti gbe abọ igbimọ to n dunadura ka iwaju rẹ.
"Ti idaduro yii ba si tẹsiwaju, a o kede igbesẹ to kan tẹgbẹ NLC yoo gbe lẹyin ta ba sepade lati se agbeyẹwo ibi ti ọrọ naa de duro.
Coronavirus Cases in Africa:Ẹ wo bí ìpínlẹ̀ Eko, Ondo àti Oyo yóò ṣe dá ilé ìjọ̀sìn padà
Oríṣun àwòrán, Twitter
Ní Ọ̀jọ́ Ajé ni ìjọba orilẹ-ede Naijiria ti kede pe isede yoo tẹsiwaju fun ọsẹ meji miran lórílẹ̀èdè Naijiria.
Awọn alaṣẹ ni ipinlẹ Eko, Ondo ati Oyo ti fi lede ọna ti wọn yoo gba lati sin awọn ile ijọsin pada ni ipinlẹ wọn.
Eyi jadẹ ninu atẹjade ti awn Gomina ipinlẹ mẹtẹẹta naa fi si oju opo ikansiraẹni Twitter wọn.
Amọ Aarẹ orilẹede Naijiria, Muhammadu Buhari ti fi lede lati ọdọ ajọ amuṣẹya lorilẹede Niajiria pe iṣede yoo tẹsiwaju fun ọsẹ meji miran lorilẹede Naijiria lati kapa arun Coronavirus.
Nibayii iye awọn to ti ni arun naa lorilẹede Naijiria ti le ni ẹgbẹẹta bayii.
Gomina ipinlẹ Eko, Babajide Sanwo-Olu lasiko to n ṣe ipade lori igbesẹ ti wọn n gbe lati koju arun Coronavirus sọ wi pe awọn ti ṣe ipade pẹlu awọn adari ile ijọsin ati awọn imaamu ni ipinlẹ Eko.
Abajade ipade naa si ni pe ile ijọsin ko i tii le ṣi lasiko yii, amọ awọn yoo tẹsiwaju lati ma a gba awn adari ile ijọsin ni imọran lori arun Coronavirus ati bi o ṣe lẹwu si ni ibi ti awọn eniyan ba parapọ si.
Awọn adari ile ijọsin ati imaamu naa si sọ wi pe awọn ni igbagbọ ninu aṣẹ ijọba ati wi pe wiwa ni alaafia awọn eniyan jọ wọn loju.
Gomina ipinlẹ Oyo, Seyi Makinde kede wi pe ijinasiraẹni gbọdọ tẹsiwaju ni ipinlẹ naa nitori iye awọn to n ni arun naa n peleke si ni ipinlẹ naa.
Makinde ni nitori naa ni oun ṣe bẹrẹ si ni gbe e yẹwọ asiko ti ile ijọsin le pada bẹrẹ ijọsin nitori awọn ile ijọsin ti kọwe si oun, ti wọn si n bere aṣẹ lati ma a ṣe ẹsin pada ninu ijọ wọn.
Gomina  naa ni oun yoo ṣe ipade pẹlu awọn adari ile ijọsin ni ipinlẹ naa ki ọsẹ yii to pari lati fi igbesẹ oun han si awọn eniyan.
Bẹẹ lo fikun pe iwadii fihan pe arun Coronavirus ni agbara lati tankalẹ ju bo ṣe lọ nibi ti awọn eniyan ba fun pọ si.
Nitori naa ni oun gbogbọ ṣe iwadii daradara lati mọ ewu to wa ninu ṣiṣi awọn ile ijọsin pada.
Gomina ipinlẹ Ondo, Oluwarotimi Akeredolu ti fi da awọn asaaju ile ijọsin loju wi pe oun yoo ṣe ipade pẹlu wọn lati jiroro lori bi awọn ile ijọsin naa yoo ṣe bẹrẹ pada.
Akeredolu ni oun yoo si tete ṣe agbeyẹwo ọna abayọ ti ijiroro naa ba la kalẹ lati ri wi pe lilọ si ile ijọsin  pada si awujọ wọn.
Bẹẹ ni Gomina naa dupẹ lọwọ awọn eniyan pẹlu bi wn ṣẹ tẹlẹ ofin ijọba lori ijinasiraẹni, nitori ilera ara wn ṣe pataki lati bori itankalẹ arun Coronavirus.
Ijọba orilẹ-ede Naijiria ti kede pe isede yoo tẹsiwaju fun ọsẹ meji miran.
Alaga igbimọ amuṣẹya ti ijọba gbe kalẹ, Boss Mustapha lo kede aṣẹ yii lasiko to n ba awọn akọroyin sọrọ nilu Abuja lọjọ Aje.
Mustapha sọ pe bi nkan ṣe wa ni asiko yii naa ni yoo ṣi wa titi di ọjọ kinni, oṣu Kẹfa, ọdun 2020.
Oríṣun àwòrán, @BashirAhmaad
Ṣugbọn fun ipinlẹ Kano, isede tọsan-toru ni yoo ṣi wa nibẹ.Ijọba apapọ ti sọ pe Aarẹ Muhammadu Buhari ko ni ba awọn ọmọ Naijiria sọrọ lọni lori ibi ti iṣẹ de duro lori ajakalẹ arun Covid-19.
Ṣaaju ni olubadamọran agba fun aarẹ lori ọrọ to n lọ, Femi Adesina kede loju opo Twitter rẹ pe Aarẹ Buhari ko ni ba awọn ọmọ Naijiria sọrọ lọjọ Aje.
Adesina sọ pe aarẹ ko pinnu lati ba awọn ọmọ Naijiria sọrọ, ati pe ohun yowu to ba yẹ ki awọn eeyan mọ nipa ibi iṣẹ de duro lori arun Coronavirus ni igbimọ amuṣẹya ti aarẹ gbe kalẹ yoo fi to awọn eeyan leti.
Ṣaaju ni iroyin kan kan ti gbode pe aarẹ yoo ba awọn ọmọ Naijiria sọrọ lalẹ ọjọ Aje, papa julọ lori igbesẹ to kan lori igbele to n lọ lọwọ lawọn ipinlẹ kan nitori arun Coronavirus.
Oríṣun àwòrán, Twitter
Ọpọlọpọ ọmọ Naijiria ti fi ẹro wọn han lori ẹrọ ayelujara lori ohun ti wọn lero pe Aarẹ Buhari yoo sọ lori arun Coronavirus.
Awọn to n fi ẹrọ wọn lede lara awọn ololufẹ ile iṣẹ BBC lori ẹrọ ibanisọrọ Facebook sọ wi pe ki Aarẹ Muhammadu Buhari fi opin si ofin konile-o-gbele lorilẹẹde naa.
Bakan naa ni wọn n bere fun ki aarẹ gbekile ofin to de irinna lati ipinlẹ kan si omiran lorilẹede Naijiria.
Lara wọn sọ wi pe iya ati iṣẹ lorilẹede Naijiria kọja bo ṣe yẹ lasiko ofin konile o gbele lorilẹede Naijiria.
Wọn kesi aarẹ Buhari lati bojuwo awọn mẹkunu nitori ibi n pa mọ.
Amọ, awọn miran n gba awọn eniyan ni imọran lati ni igbagbọ ninu Aarẹ Buhari wi pe yoo ṣe ohun to tọ fun awọn ọmọ Naijiria.
Bakan naa ni awọn miran sọ wi pe oun ti aarẹ Buhari yoo ṣe ni lati fi ọsẹ meji kun ọjọ ti ofin konile-o-gbele yoo dopin ni Naijiria.
Nibayii, Orilẹede Naijiria ti ni eniyan mejidinlogojilelẹlọọdurun(5,959) lo ti ni arun Coronavirus ni Naijiria.
Bẹẹ ni iye awọn to ti ri iwosan gba ti da mẹfadinlẹgbẹjọ, ti eniyan mejilelọgọsan si ti ri iwosan gba.
AjọAmuṣẹya ti Aarẹ Buhari gbekalẹ lori arun Coronavirus,PTF yoo ṣe ipade lọni lati ṣe agbeyẹwo ofin konile-o gbele ni Naijiria.
Ajọ amuṣẹya naa yoo ma a woye igbesẹ ti wọn yoo gbe lori ofin konile-o-gbele to n lọ lọwọ ni ipinlẹ Eko, Ogun ati ilu Abuja.
Oríṣun àwòrán, Twitter
Ijọba ìpínlẹ̀ Eko ti ní ó ṣeeṣe kí òfín kónílé-ó-gbélé ó tẹ̀síwájú nítórí iye àwọn tó ní àrùn náà ń peléke si.
Lorilẹede Naijiria bayii, iye awọn eniyan to ti ni arun Coronavirus naa ti da ẹgbẹrun marun ati mọkanlelogunlelẹgbẹta (5,621).
Eniyan mejilelaadọrinlenirinwo( 1742) lo ti ri iwosan gba, nigba ti eniyan mẹrindinlọgọsan to ti papoda nitori arun Coronavirus.
Ilumọọka oniroyin orileede Naijiria, Ayinde Soaga ti moribọ lọwọ arun Covid-19.
Lẹyin ayẹwo , o sọ pe awọn to n tọju ohun ni ko sewu ki oun maa lọ sile laayọ ati alaafia.
Oríṣun àwòrán, Others
Bí a kò bá gbàgbé, ní ǹkán bí ọ̀sẹ̀ méjì ṣẹ́yìn ni ìròyìn gba òde kan pé ó ti kó àrùn Coronavirus.
Nigba ti akọroyin BBC kan si lori ago, o fidi ọrọ yii mulẹ to si ni alẹ ọjọ Eti ni wọn ni ki oun maa pada sile.
Bi a ko ba gbagbe ni nkan bi ọsẹ meji sẹyin ni iroyin gbode pe o ti ko arun Covid-19.
Ko pẹ si igba ti iroyin jade lo ni lootọ ni to si bẹrẹ si ni gba itọju ni ibudo iyasọtọ ni ipinlẹ Katsina.
AjọAmuṣẹya ti Aarẹ Buhari gbekalẹ lori arun Coronavirus,PTF yoo ṣe ipade lọni lati ṣe agbeyẹwo ofin konile-o gbele ni Naijiria.
Ajọ amuṣẹya naa yoo ma a woye igbesẹ ti wọn yoo gbe lori ofin konile-o-gbele to n lọ lọwọ ni ipinlẹ Eko, Ogun ati ilu Abuja.
Oríṣun àwòrán, Twitter
Ijọba ìpínlẹ̀ Eko ti ní ó ṣeeṣe kí òfín kónílé-ó-gbélé ó tẹ̀síwájú nítórí iye àwọn tó ní àrùn náà ń peléke si.
Amọ ni ipinlẹ Ogun, Gomina Dapo Abiodun ti fi ọsẹ kan kun ofin konile-o-gbele naa nitori awọn eniyan ko bọwọ fun ofin yiyagofunraẹni, eleyii to n mu ki iye eniyan to ni arun naa ni ipinlẹ ohun peleke si.
Ni ipinlẹ Eko, Gomina Babajide Sanwo Olu ti kede wi pe ti awọn eniyan ba kọ lati tẹlẹ asẹ konile-o-gbele, yiyagofunraẹni ati fifọwọ ni gbogbo igba, oun yoo paṣẹ ki konile-o-gbele ọlọjọyipo pada.
Lorilẹede Naijiria bayii, iye awọn eniyan to ti ni arun Coronavirus naa ti da ẹgbẹrun marun ati mọkanlelogunlelẹgbẹta (5,621).
Eniyan mejilelaadọrinlenirinwo( 1742) lo ti ri iwosan gba, nigba ti eniyan mẹrindinlọgọsan to ti papoda nitori arun Coronavirus.
Ilumọọka oniroyin orileede Naijiria, Ayinde Soaga ti moribọ lọwọ arun Covid-19.
Lẹyin ayẹwo , o sọ pe awọn to n tọju ohun ni ko sewu ki oun maa lọ sile laayọ ati alaafia.
Oríṣun àwòrán, Others
Bí a kò bá gbàgbé, ní ǹkán bí ọ̀sẹ̀ méjì ṣẹ́yìn ni ìròyìn gba òde kan pé ó ti kó àrùn Coronavirus.
Nigba ti akọroyin BBC kan si lori ago, o fidi ọrọ yii mulẹ to si ni alẹ ọjọ Eti ni wọn ni ki oun maa pada sile.
Bi a ko ba gbagbe ni nkan bi ọsẹ meji sẹyin ni iroyin gbode pe o ti ko arun Covid-19.
Ko pẹ si igba ti iroyin jade lo ni lootọ ni to si bẹrẹ si ni gba itọju ni ibudo iyasọtọ ni ipinlẹ Katsina.
‘Emi kọ o,awọn ọmọ yahoo yahoo ti  gbakoso oju opo mi’
Amọ sa akọroyin naa ti fi ikilọ sita pe ki awọn ara ilu sọra fawọn alaburu ori ẹrọ ayelujara ti wọn ti gbakoso ikanni ibaraẹnisọrọ rẹ ni Facebook.
Ninu ọrọ rẹ pẹlu akọroyin  BBC  Ayinde Soaga ni lati ọjọ Kẹsan osu Kẹrin ni awọn gbajuẹ ti gbakoso oju opo oun ti o si ni gbogbo ohun ti awọn eeyan ba ri nibẹ ko ti a ti ọwọ ohun wa.
''Mi o fi ọrọ  idupẹ lọwọ awọn ọmọ Naijiria kankan si oju opo naa bẹ si ni mi o kan si ẹnikẹni lati wa sowo sogundogoji kankan.
Mo rọ yin lati yago fun iru ọrọ bẹ''
Egbẹ akọroyin orile-ede Naijiria ẹka ipinlẹ Katsina tibanujẹ lori bi ọkan lara wọn, gbajugbaja akọroyin ni, Ayinde Soaga, ti se lugbadi arun Coronavirus.
Soaga to tun jẹ ọga agba ile isẹ amounmaworan Naijiria, NTA Katsina ni ẹgbẹ naa sọ ninu atẹjade pe ayẹwo fihan pe o ni Covid-19.
Oríṣun àwòrán, Facebook/Atinde Soaga
Pupọ awọn akọroyin ni o wa ninu ewu arun yi ni Naijiria nipasẹ lilọ bibọ lati le se akojọpọ iroyin faraye gbọ.
Alaga ẹgbẹ naa, Tukur Dan Alli, sọ pe asiko yi lawọn akọroyin nilo iranwọ ijọba ati awọn aladani lati le daabo to peye bo wọn.
O kesi ijọba ati awọn ti o lẹnu lọrọ lẹka iroyin lati pese irinsẹ idaabobo ẹni  ati awọn nkan miran to le ko awọn akọroyin yọ́ lọwọ arun Covid 19.
Ọmọ bibi  Ẹgba Gbagura ni Ayinde Soaga  jẹ nipinlẹ Ogun.
Eeyan meje lo ti dero ọrun nipasẹ Covid 19  nipinlẹ Katsina to jẹ ipinlẹ ti aarẹ Naijiria,  Muhammadu Buhari ti wa.
Losu kẹta ọdun yi ni wọn kede ẹni akọkọ to safihan arun yi.
Lati igba naa disin,awọn mẹtalelọgbọn lo n gba itọju ni ileewosan lori arun yi  ti iroyin si sọ pe mẹfa lara wọn ti ya lẹyin tayẹwo ni ko si arun naa lara wọn mọ.
Asa Trokosi nibi ti ọmọde ti n jiyan ẹsẹ mọlẹbi rẹ , wọpọ  ni Ghana, Togo ati Benin.
Ọkọ̀ ojú omi dànù ní Kwara, ọmọ́dé 9 ba rìn
Ìjàmbá Kwara: Isẹ́ ìdárò ń wọlé sọ́dọ̀ ìjọba Kwara
Ilu Lafiagi, nijọba ibilẹ Edu nipinlẹ Kwara ni ọkọ oju omi to ko ero mejilelogun naa ti danu lagbami.
Oríṣun àwòrán, @thisislagos1
Kowee ke, ko ha nilu Lafiagi nipinlẹ Kwara lopin ọsẹ nigba ti ọkọ oju omi kan, to ko ero mejilelogun, ti ọpọ wọn jẹ ọmọde, danu ni agbami odo Niger, lasiko ti wọn bọ lati ibi ayẹyẹ igbeyawo kan.
A gbọ pe bi o tilẹ jẹ pe awọn eeyan tiraka lati doola ẹmi awọn ero omi naa, amọ aayan wọn ko fi bẹẹ ni ipa, tori ọmọde mọkandinlogun lo si papa ba isẹlẹ naa rin, ti wọn si gba ẹmi eeyan meji la.
Titi di irọlẹ ọjọ Satide si ni wọn n yọ oku awọn eeyan to ba isẹlẹ naa rin, tawọn ọlọpaa atawọn osisẹ panapana naa si n tiraka lati sisẹ wọn.
Tọkọ-taya Aràrá: Àwọn èèyàn máa ń wò wá, ta bá fa ọwọ́ ara wa ní títì
Wayi o, Gomina ipinlẹ Kwara, Abdulfatah Ahmed ti ba Emir tilu Lafiagi, Alhaji Saadu Kawu Haliru kẹdun,lori iku awọn eeyan to ba ijamba omi naa lọ.
Atẹjade kan ti akọwe eto iroyin gomina Ahmed, Abdulwahab Ọba fisita wa se apejuwe iku awọn eeyan naa bii adanu ati ofo nla fawọn ẹbi wọn, ati ipinlẹ Kwara lapapọ.
Oríṣun àwòrán, @thisislagos1
Bakan naa, aarẹ ile asofin agba, to jẹ ọmọ bibi ipinlẹ Kwara, Dokita Bukọla Saraki, naa ti daro lori iku awọn eeyan naa.
Nigba to n kẹdun loju opo Twitter rẹ, Saraki ni lasiko yii tawọn eeyan ilu Lafiagi n se ọfọ awọn eeyan wọn yii, oun wa gbadura pe ki Ọlọrun fun wọn ni ẹmi lati gba adanu naa mọra, ki ara awọn eeyan tori ko tọ ninu ijamba naa si tete mokun pada.
Sebótimọ Ẹlẹ́wà Sàpọ́n - Ó ń rọ̀ wá láti má se kọjá agbára wa
Oríṣun àwòrán, AFP
Òwe Sebótimọ Ẹlẹ́wà Sàpọ́n ló bẹ̀rẹ̀ lọ́dọ̀ obìnrin kan tó ń ta ẹ̀wà ní ìlú Abẹokuta.
Oniruuru owe ati asamọ lo wa nilẹ Yoruba.
Wọn maa n fi eyi parọwa fun wa, kọ wa lọgbọn, fun wa loye, to si tun maa n tọ wa sọna ninu igbe aye wa lojoojumọ.
Ọkan lara awọn owe to n parọwa fun wa ni Ṣebotimọ Ẹlẹwa Sapọn"", awọn ohun to si yẹ ka mọ nipa owe naa ree:"
Itan nipa owe ‘Sebótimọ Ẹlẹwa Ṣàpọ́n
Obinrin kan wa nilu Abẹokuta to n ta ẹwa sise ni adugbo Sàpọ́n nilu Abẹokuta, tii se olu ilu nipinlẹ Ogun bayii.
Obinrin ẹlẹwa yii mọ ounjẹ naa se debi pe awọn eeyan maa n pe biba sọdọ rẹ lati du ẹwa rẹ ra ni.
Kí ló máa ń wú ìyá Nike Davies lori láti wé gèlè ràbàtá?
Tọkọ-taya Aràrá: Àwọn èèyàn máa ń wò wá, ta bá fa ọwọ́ ara wa ní títì
Agbada ikoko nla kan lo maa fi n se ẹwa fun tita, to si n jẹ ere rẹpẹtẹ nibẹ lojoojumọ.
Koda, nibi ti ẹwa rẹ dun, to si tun jẹ itẹwọgba de, awọn onibara rẹ maa n ra ounjẹ naa ni awin, lai sanwo ti owo ba sa fẹrẹ lapo wọn.
Nigba to ya, oju aanu n pa obinrin ẹlẹwa yii ku lọ, tori ọpọ gbese tawọn eeyan jẹ ẹ, ko jẹ ko ri owo ta ọja mọ, ti odiwọn ikoko ẹwa to n se si n din ku lojoojumọ.
Niwọn igba to si jẹ pe alatise ni yoo mọ atise ara rẹ, eyi lo mu ki ẹlẹwa Ṣapọn da ọgbọn ti awọn onibara rẹ ko fi ni gba igba lori rẹ, nipa rira ọja rẹ lawin.
Ti onibara kan ba si tọ obinrin naa wa pe oun fẹ ra ẹwa sise rẹ ni awin, iya ẹlẹwa yii yoo sọ fun pe ko ma ra ẹwa lawin, se ni ko ra iye ẹwa ti owo rẹ ka lai jẹ gbese.
Ondo: Dejí sun ọmọ méje àtagbalagba meji mọ́lé nítorí pé ó ń bínú
Oríṣun àwòrán, @irdafrika
Agbada ikoko nla kan lo maa fi n se ẹwa fun tita, to si n jẹ ere rẹpẹtẹ nibẹ lojoojumọ.
"Esi to si saaba maa n fọ jade fun wọn, lati rọ wọn ki mase ra ẹwa lawin ni pe ""Ṣe bo ti mọ"", eyi to tumọ si pe mase ra kọja iye owo too ni lapo bayii."
Bi ọjọ se n gori ọjọ, ti oṣu si n gori oṣu, lawọn eeyan ba sọ di owe ati aṣa obinrin ẹlẹwa naa.
Ki wọn si to beere ọja awin lọwọ rẹ, ni wọn ti mọ esi ti yoo fi da wọn lohun.
"Ọrọ yii si ni wọn fi maa n sa obinrin naa pe ""Ṣe bo ti mọ, Ẹlẹwa Ṣapọn"". Diẹ-diẹ si ni owe naa gbilẹ, to si di itẹwọgba titi di oni."
Itumọ owe yii lo si n parọwa si ẹni kọọkan wa pe ka ma se kọja agbara wa, ka maa se ohun gbogbo ni iwọntun wọnsi, iwọn eku ni iwọn itẹ, ka maa baa maa jẹ gbese kiri, eyi to lee mu itiju ati ipaya de ba ni.
Ta ni Ẹlẹwa Ṣapọn?
BOWEN: Àwọn adarí ti fásitì Bowen pa lẹ́yìn wàhálà àwọn akẹ́kọ̀ọ́
Oríṣun àwòrán, @Bowen University
Fasiti Bowen ti ajọ nla onitẹbọmi da silẹ mu ẹsin ati eto ẹkọ nilana Kristeni ni pataki.
Wọn ti gbe fasiti Bowen nipinlẹ Ọṣun ti pa.
Awọn alaṣẹ fasiti naa ni wọn kede titi pa ileewe naa ni ọsan ọjọ aje lẹyin wahala to waye lori bi wọn ṣe le awọn akẹkọ kan nileewe naa lọ sile lori lilo ogun oloro.
Akọwe agba ile ẹkọ fasiti naa, Kayode Ogunleye  ni wọn fun awọn akẹkọọ naa di aago mẹrin ọsan ọjọ Aje lati kuro ninu ọgba ile iwe naa, bi bẹẹ kọọ, wọn o da ṣeria fun ẹni tọwọ ba tẹ.
Iroyin to n tan kalẹ loju opo ayelujara ni pe, ile ẹkọ fasiti Bowen le awọn akẹkọ to to igba lọ sile lori ẹsun pe wọn kọ lati kopa ninu ayewo ti yoo safihan boya wọn n lo ogun oloro.
Akọwe agba fun ile ẹkọ fasiti Bowen nipinlẹ Ọsun, Ọmọwe Kayode Ogunleye ni ko si ootọ ninu ọrọ to n ja rain rain wi pe wọn ti ti ile ẹkọ na pa.
Ninu ifọrọwanilẹnuwo kan pẹlu ile isẹ iroyin BBC Yoruba lọjọ Aje, ọmọwe Ogunleye sọ pe, lootọ lawọn akẹkọ kan ṣi iwa hu ṣugbọn eto ẹkọ si n lọ lọwọlọwọ ni ile ẹkọ naa.
O salaye pe ''ninu ogba ile iwe ni mo wa bayi. Ko si iyọnu kankan. Ohun gbogbo n lọ leto leto.''
Tọkọ-taya Aràrá: Àwọn èèyàn máa ń wò wá, ta bá fa ọwọ́ ara wa ní títì
''Ni ijẹta la sọ fun awọn to siwahu pe ki wọn ma lọ sile lati lọ rọkun nile. A si ti fi to awọn obi wọn leti ''
Iroyin to n tan kalẹ loju opo ayelujara ni pe, ile ẹkọ fasiti Bowen le awọn akẹkọ to to igba lọ sile lori ẹsun pe wọn kọ lati kopa ninu ayewo ti yoo safihan boya wọn n lo ogun oloro.
Ṣugbọn nigba ti a beere lọwọ Ogunleye iye awọn akẹkọ ti wọn le, o ni ''wọn ko ju aadọta lọ''
Awọn Oludari ile ẹkọ giga fasiti Modibbo gbe agadangodo s'ilẹkun ile ẹkọ naa
''Mi o fẹ sọ iye ti yoo wa yatọ si eleyi ti o le jade lẹyin wa ṣugbọn mo mọ daju wi pe wọn ko to aadọta.''
''Awọn perete lo ṣi iwa hu lara awọn akẹkọ wa, ti a si gbe igbesẹ gẹgẹ bi ile iwe ti kii gba iwa kiwa laaye lati ba wọn wi.''
Lori aworan ile ibusun ti awọn kan n pin lori ẹrọ ayelujara wi pe awọn akẹkọ kan dana sun, Ogunleye so pe oun ko mọ nipa rẹ.
Eyi kii ṣe igba akọkọ ti gbọnmisi omi ooto yoo ma waye laarin awọn akẹkọ Bowen ati awọn alasẹ ile ẹkọ naa ti ajọ nla onitẹbọmi da silẹ.
Lọdun 2014 lawọn alaṣe ti ile iwe naa pa nitori bi awọn akẹkọ ti ṣe fariga lori akoko ti ile ẹkọ naa la kalẹ fun wọn lati ma jeun.
Ninu wahala to bẹ silẹ nigba naa, awọn akẹkọ ba awọn ọkọ kan ti wọn gbe kalẹ sinu ile ẹkọ naa jẹ.
A beere lọwọ ọmọwe Ogunleye wi pe ki lo le mu ki awọn akẹkọ ma wu iru iwa janduku bayi.
Alaye to ṣe ni pe ''awọn ọmọ ode oni ko fẹ ibawi mọ. Awa nikan si kọ ni ọrọ naa kan gẹgẹ bi ile ẹkọ. Ọrọ to gbode nii.''
Nigeria 2019 Elections: Kíni o mọ̀ nípa Jimi Agbaje tó ń díje fún gómìnà ìpínlẹ̀ Eko
Kini o mọ nipa Jimi Agbaje to n dije fun Gomina ipinle Eko
Olujimi Joseph Kolawole Agbaje ti gbogbo ènìyàn mọ̀ sí jẹ  ní a bí ní ọjọ́ kejì, oṣù kẹta ọdún 1957 sí ìdílé olóyè Julius Kosebinu tó jẹ òsíṣẹ́ ilé ìfowópamọ àti abilekọ Magret Olabisi to jẹ́ olùkọ́, àbíkejì nínú ọmọ márùn ni ọmọ bàbá rẹ̀ sì ni Segun Agbajé tó jẹ́ aláṣẹ àti olùdárí ilé ìfowópamọ́ GTbank.
Ilé ẹkọ́ ti Jimi Agbaje ti lọ
Ó lọ sí ilé-ìwé St Mary's Private School, ilú Eko àti Corona School ní Apapa fún ilé ẹkọ́ alákọbẹ̀rẹ̀, Gregory's College ní ìpínlẹ̀ Eko fún ilé ẹkọ girama, ó tún lọ sí ilé-ìwé fásìtì ilé Ifẹ tó ti di Awololwo University Ile-Ifẹ níbi tó ti kọ ẹkọ́ ìmọ̀ ìpoogùn (Pharmacist).
Yatọ sí pé Jimi Agbaje jẹ́ ìlúmọọká olóṣèlú síbẹ̀ ó ti fi àmì hàn nínú ìṣẹ́ tó yàn láàyò gẹ́gẹ́ bii apòògùn ó ṣì tún  jẹ́ olùdássílẹ̀ JayKay Pharmaceutical àti Chemical ti ó sì jk olùdari titi di ọdún 2005 nígbà ti ó rárí wọn agbo òṣèlú. Oun ní olùdarí Vigeo Holding, akọweé gbogbogbò fún ẹgbẹ́ apòògùn lórílẹ̀-èdè Naijíríà 1989-1993, alága ẹgbẹ olóògùn Nàìjíríà ní ìpínlẹ̀ Eko 1994-1997.
Oríṣun àwòrán, Jimi Agbaje@official
Kini o mọ nipa Jimi Agbaje to n dije fun Gomina ipinle Eko
Jimi Agbaje lágbo òṣèlú
Olujimim Agbaje bẹ̀rẹ̀ Oselú pẹ́lú jíjàjàgbara nígbà ìdìbò Mohood Abiola ti wọn yí dànù pẹ̀lú àwọn Pat Utomi, Asue Ighodalo, Oby Ezekwesili sì ṣe ṣẹ́ ìjagbara Lẹ̀yìn tó bẹ̀rẹ̀ òṣèlú lọ́dún 2007 ní ó kọ̀kọ́ wọ ẹgbẹ́ òṣèlú Action Congress, lẹ̀yìn náà ló lọ sí ẹgbẹ́ òṣèlú Democratic Peolple Alliance(DPA), nínú ẹgbẹ́ yìí ní Agbaje tí kọ́kọ́ gbégbá ìdìbò gómìnà ìpínlẹ̀ Eko èyí tó pada jámọ Babatunde Fashola lọ́wọ́.
Ó wà lára àwọn olùdíje gomínà mọ́kànlá tó pẹ̀yìda kúrò nínú ẹgbẹ́ òsèlú Action Congress lọdún 2007, lásìkò tí wọn fẹ̀sùn kan pé gómìnà tẹ́lẹ̀rí Bola Tinubu tí ni ẹni ami òróró tó yàn láti gbajọba lẹ́yìn rẹ̀ kí wọn to ṣe ìdìbò abẹ́lé
Oríṣun àwòrán, Jomo@official
Kini o mọ nipa Jimi Agbaje to n dije fun Gomina ipinle Eko
Ó kúrò nínú ẹgbẹ́ DPA lọ́dún 2011 láti darapọ̀ mọ Peoples Democratic Party (PDP) lẹ́yìn ti INEC yọ orukọ ẹgbẹ́ náà kúrò nínú ẹgbẹ́ òṣelú.
Ní ọjọ keje oṣu kejila ọdun 2014 ó jáwé olúborí gẹ́gẹ́ bíi olúdije gómínà lábẹ́ àsíá ẹgbẹ́ oṣèlú PDP fún ọdún 2015 lẹ́yín to fẹ́yìn Musiliu Obanikoro jánlẹ̀ níbi idibo kòmẹsẹyọ.
Oríṣun àwòrán, Jimi@offical
Kini o mọ nipa Jimi Agbaje to n dije fun Gomina ipinle Eko
Ó jẹ́ ọmọ ẹgbẹ́ alábojuto lórí gbàrọgudù òògùn oyìnbo (1989-1993)
Olùdarí ilé iṣẹ́ apòògùn Jaykay Pharmaceutical & Society Ltd
Olúdari Viego Holdings Ltd
Bakán náà Olujimi Agbaje tí gba ami ẹyẹ nínú ẹgbẹ́ Pharmaceutical Society of Nigeria.
Ó fẹ́ ìyàwó Abiola Agbaje ( nee Bankole), agéjórò ni. Ọlọ́rún fíọmọ mẹ́ta tawọn lọ́rẹ
APC: A kò ní ìjìyà kankan fún Amosun lórí ìgbésẹ̀ rẹ̀
Oríṣun àwòrán, @Govsia
Ẹgbẹ oṣelu APC ti fesi lori ikede kan ti Gomina ipinlẹ Ogun, Ibikunle Amosun se laipẹ yii pe, oun yoo gbe lẹyin oludije fẹgbẹ oselu APM, Adekunle Akinlade lati di gomina ipinlẹ Ogun lọdun 2019.
Ọjọ Aje ni Gomina Amosun fọwọ idaniloju sọya bẹẹ, to si tun se adura aseyọri fun oludije naa.
Ninu ọrọ ẹgbẹ, APC ni Gomina Ibikunle Amosun ko ti  kọja aaye rẹ pẹlu bo ṣe ni oun ko ni gbè lẹyin oludije ẹgbẹ APC, fun ipo Gomina nipinlẹ Ogun.
Ọdẹrinde Oníjaàálá: Ìjálá mi máa ń mú káwọn onísẹ́ ibi gbàgbé láti sebi
Akọwe ipolongo fẹgbẹ APC, Mallam Lanre Issa Onilu ni, Amosun lẹtọ labẹ ofin ẹgbẹ APC, lati ṣọ ero ọkan rẹ laisi idiwọ kankan.
Issa kede ọrọ yi ninu ifọrọwanilẹnuwo pẹlu ile iṣẹ BBC Yoruba.
"A ko le ni ki ọmọ ẹgbe ma sọ ero ọkan rẹ amọ to ba jẹ wi pe o sọ nnkan to ba tako ẹgbẹ nigba yẹn lẹgbẹ to le gbe igbesẹ lati fi iya to tọ jẹ''
Onilu ni boya igbonara lo mu ki Amosun ṣọ oun to ṣọ ati wi pe ko ti ṣọ ọrọ na di mimuṣẹ.
Oríṣun àwòrán, @APCNigeria
Aáwọ̀ abẹ́nú lóríṣiiríṣìí ló ń ṣẹlẹ̀ ninu ẹgbẹ APC lorilẹ-ede Naijiria
O tẹsiwaju wi pe awọn ti  ''gbe igbimọ ti yoo pẹtu saawọ  laarin awọn ọmọ ẹgbẹ kalẹ.O ṣi ṣeeṣe ki wọn  yanju ohun ti o'n mu ki Gomina Amosun ṣọ wi pe oun ko ni gbe lẹyin oludije ẹgbẹ''
Bi a ko ba gbagbe,Gomina Ibikunle Amosun fi  saaju fi àtẹ̀jáde kan síta nínú ìpàdé tó ṣe pẹ̀lú àwọn adarí ẹgbẹ́ káàkiri ìjọba ìbílẹ̀ pe oun yoo fi ẹgbẹ oselu APC silẹ.
Lẹyin wa igba naa ni o ri tikẹti gba lati du ipo asofin labẹ asia ẹgbẹ APC ṣugbọn ti aayo rẹ fun ipo Gomina Adekunle  Akinlade ko ri tikẹti ẹgbẹ gba.
Eyi lo mu ki Gomina Amosun leri wi pe ohun yoo gbe lẹyin Adekunle Akinlade to ti gba tikẹti ẹgbẹ oselu miiran ti ṣe Alliied People's Movement, APM.
Gómìnà ìpínlẹ̀ Ogun Ibikunle Amosun sọ pé òun ti sàdúrà fún olùdíje Gomina nínú ẹgbẹ́ òṣèlú Alliied People's Movement APM ní ìpínlẹ̀ Ogun Adekunle Akinlade láti lépa ohun ti ọkan rẹ̀ ń fẹ́ nínú ẹgbẹ́ náà.
Amosun ni ohun kìí ṣe ẹni ti yóò máà farapamọ sábẹ́ ìka kan, Ó sàlayé lónìí ọjọ́ ajé níbi ìpadé àwọn ọmọ lẹ́yìn rẹ̀, tó wáyé nío ilé igbé ààrẹ tó wà ní Ibara Housing Estate Abeokuta.
Gómìnà tẹnu mọ́ọ pé ifarajì rẹ̀ láti ríi dájú pé Akinlade yóò górí àléfà lẹ́yìn ohun nínú oṣù kárún ọdún 2019 àti pé kò sí ọ̀nà abáyọ fún Dapọ Abiodun nítori pé ó jí nkan tó tọ́ sí Akinlade ninú ẹgbẹ́ APC ní.
Àwọn aṣòfin 26 fi ẹgbẹ́ òṣèlú APC 26 sílẹ̀ lọ sí APM
Oríṣun àwòrán, APc
Èyí ni ara àwọn ìgbésẹ̀ tí ó ń ṣàfihàn èdèaìyedè nínú agbo ẹgbẹ́ òṣèlù APC ní ìpínlẹ̀ Ògùn.
Ó kéré tán ọmọ ilé ìgbìmọ̀ aṣòfin mẹ́rìndínlọ́gbọ̀n nínu ẹgbẹ́ òṣèlú All Progressives Congress (APC) ló ti kúrò lọ sí ẹgbẹ́ òṣèlú Allied Peoples Movement APM
Jíjá ẹgbẹ́ òṣèlú APC sílẹ̀ yìí wáyé lẹ́yìn òṣẹ̀ kan tí eni àmì òróró Gominà Ibikunle Amosun fún ipò gómìnà ní ìpínlẹ̀ Ogun lọ sí inú ẹgbẹ́ APM.
Agbẹnusọ fún àwọn ọmọ ilé ìgbìmọ̀ asofin Lamidi Olatunji pé àwọnti fi ìmọ sọkan láti lọ mú èróngbà wọn ṣẹ ní nínú ẹgbk òṣèlú APM.
Olatunji added that: We also wish to acknowledge the fatherly role of President Muhammadu Buhari in seeking to sustain the tenets of democracy, fairness and equity in the resolution of the crisis in Ogun APC."
"Olatunji fí kún-un pé '' a ṣe àkíyèsí akitikyan àtí ipò bàbá ti ààrẹ Muhammadu Buhari láti ríi dájú pé ìṣèjọba awà-arawa tún gbilẹ̀ sí, àìfárí apákan dá apákan si àti ìwà aparò kàn o ga jú ìkan lọ ti ó fi kọ àwọn ọmọ ẹgbẹ́""."
"Ó ṣe ni láànú pé gbogbo akitikyan ààrẹ ní àwọn kan yí dànù tí wọn sì kọ̀ jálẹ̀ láti gba ẹkùn ìwọ̀-òòrún- guusu pada sí àyé ìmunísìn ní bi tí àwọn àìkúkú joyè ó sàn ju ẹnu mi ò kálùú.
Kọmísọnà fún ìgbóhùn sáfẹ́fẹ́  Dayo Adeneyhe àti Modupe Mujota kọmisọnà fún ètò ẹkọ wà lárá àwọn tó kọ́wọ̀ọ̀ rí lọsí inú ẹgbẹ́ APM
Election 2019: Atiku Abubakar bẹ̀rẹ̀ ìgbésẹ̀ àti di ààrẹ Nàìjíríà pẹ̀lú ìpolongo ní Sokoto
Oríṣun àwòrán, Atiku Abubakar
Ọ̀pọ̀ èèkàn ẹgbẹ́ òṣèlú PDP ló péjú pésẹ̀ síbi ìpolongo ìbò náà nílúù Sokoto.
Oludije fun ipo aarẹ lorilẹede Naijiria ni ẹgbẹ oṣelu PDP, Atiku Abubakar ti tu kẹkẹ ipolongo idibo rẹ silẹ bayii nibi ipolongo idibo to waye ni ilu Sokoto ni ọjọ aje.
Atiku Abubakar ni ọpọ n fi oju wo gẹgẹ bi ẹni ti yoo ba aarẹ Buhari ta kangbọn julọ lasiko idibo apapọ ọdun 2019.
Ìtàn tó wà nídi òwe ‘Sebótimọ Ẹlẹ́wà Sàpọ́n’
Fásitì Bowen nílùú Ìwó di títìpa
Tọkọ-taya Aràrá: Àwọn èèyàn máa ń wò wá, ta bá fa ọwọ́ ara wa ní títì
Ọpọ ero ni wọn peju si ibi ipolongo naa, bẹẹni awọn eekan ẹgbẹ oṣelu PDP bii aarẹ ana lorilẹede Naijiria, Goodluck Jonathan, aarẹ ile aṣofin agba, Sẹnetọ Bukọla Saraki, olori ile aṣoju-ṣofin Yakubu Dogara, gomina Aminu Tambuwal wa nibi ipolongo naa pẹlu.
Ninu ọrọ rẹ, aarẹ ana lorilẹede Naijiria, Goodluck Jonathan ni ẹgbẹ oṣelu PDP ni ẹgbẹ oṣelu akọkọ lorilẹede Naijiria ati pe Atiku Abubakar ni ẹni naa ti o lee yọ orilẹede Naijiria ni ọdun 2019.
2019 Election: APC ní ẹ̀ka asòfin ló leè tún Nàíjíríà tò, kìí se ààrẹ
Oríṣun àwòrán, @atiku
Awọn ọmọ orilẹede yii ti n sọ ero ọkan wọn lori ikede kan tawọn agbaagba ilẹ Yoruba ati ẹgbẹ Afẹnifẹre se laipẹ yii pe oludije fun ipo aarẹ, labẹ asia ẹgbẹ oselu PDP< Atiku Abubakar, nilẹ Yoruba yoo pọn lẹyin rẹ ninu ibo ọdun 2019.
Nigba to n fesi lori ikede yii, onimọ kan nipa ọrọ oselu, to tun jẹ eekan kan ninu ẹgbẹ oselu APC ati olori osisẹ ni ọọfisi gomina ipinlẹ Ọyọ, Ọmọwe Gbade Ojo ni, awọn agbaagba Yoruba ati ẹgbẹ Afẹnifẹre kii se ẹgbẹ oselu rara.
Ọdẹrinde Oníjaàálá: Ìjálá mi máa ń mú káwọn onísẹ́ ibi gbàgbé láti sebi
Ojo salaye pe awọn eeyan yii ko lasẹ lati sọrọ nipa ẹni ti Yoruba yoo dibo fun lọdun 2019 nitori ko si gomina ipinlẹ kankan nilẹ Yoruba, ti wọn lee da fi ibo gbe wọle, ka ma sẹsẹ sọ ti aarẹ Naijiria.
Olori osisẹ ni ọọfisi gomina Ọyọ naa ni, ẹru ko bodo ni ọrọ ẹgbẹ oselu APC, ẹni ti yoo wọdo ni ominu n kọ, bẹẹ ni ẹru ko ba APC rara lori ikede awọn agbaagba Yoruba yii.
Oríṣun àwòrán, @Atiku
O sọ igi kansoso Atiku ko lee da igbo se nidi atunto Naijiria, ileri asan lo si n se fawọn ọmọ ilẹ yii pe oun yoo tun Naijiria to. Sugbọn ko si ohun ti ẹni to ba n wa ibo ko lee sọ, ileri asan ni."""
Gbade Ojo fikun pe, lootọ ni ẹya Yoruba n poungbẹ atunto, amọ ojuse awọn asofin ni lati gbe ofin tuntun kalẹ, ti yoo se atunto ẹka gbogbo nilẹ Naijiria, eyi to kọja agbara aarẹ kankan.
Ilu Eko gbalejo lọjọ Aje nigba ti awọn agbaagba Yoruba, to fi mọ ẹgbẹ Afẹnifẹre korajọpọ lati sepade apero lori eto iselu il wa.
Atẹjade onikoko mejila kan ti wọn fisita lopin ipade wọn ọhun salaye pe, awọn agbaagba Yoruba naa ti fẹnu ọrọ jona lati fontẹ lu oludije fun ipo aarẹ labẹ asia ẹgbẹ oselu PDP, Atiku Abubakar gẹgẹ bii oludije ti iran Yoruba yoo to lẹyin rẹ ninu eto idibo to n bọ lọdun 2019.
Tọkọ-taya Aràrá: Àwọn èèyàn máa ń wò wá, ta bá fa ọwọ́ ara wa ní títì
Atẹjade naa ni ẹya Yoruba n fohun kan soso sọrọ, ti wọn ko si pin yẹlẹ-yẹlẹ, ti igbagbọ wọn si wa ninu igbesẹ atunto orilẹede naijiria lọna ati jẹ ki ibaradọgba ati iwa aparo kan ko ga ju ọkan lọ fidi mulẹ, pẹlu idajọ ododo.
Nigba ti wọn n fidi ipe fun atunto Naijiria mulẹ, atẹjade naa salaye pe ijọba apapọ ti gbooro ju, ti ko si tun ni afojusun to yẹ, ti atunto ba wa ni yoo si rọrun lati pin ọrọ aje ajumọni wa bo se yẹ, eyi ti yoo mu ki irẹpọ, ibaradọgba ati idajọ ododo wa.
Oríṣun àwòrán, @Afenifere_ARG
"Atẹjade naa salaye pe "" Awa Yoruba n se atilẹyin fun Atiku Abubakar lati di aarẹ orileede yii lọdun 2019 nitori bo se faramọ eto atunto Naijiria eyi ti yoo peses anfaani ọgbọọgba, aisegbe sibikan ati idajọ ododo fun gbogbo awọn eeyan ti ọrọ orilẹede yii kan."""
Nass: A ó tí ilé aṣòfin pa fún ọjọ́ méjì
Awọn oṣìṣẹ́ fẹ̀hónú hàn níle ìgbìmọ̀ Aṣofin
Àwọn òṣìṣẹ́ ilé ìgbìmọ́ Aṣòfin l'Abuja tí bẹ̀rẹ̀ sí ní fẹ̀hónú hàn nínú ọgba ilé iṣẹ́ náà lórí àìsan owó oṣù.
Òṣìṣẹ́ lábẹ́ àsìá Paliamentary Staff Association of Nigeria (PASAN) lógún lọ́gọ̀ wọn ti pé jọ̀ sí ààrín yàrá ìgbàlejo ilé ìgbìmọ̀ àsofin, wọn lérí pé awọn yóò ti ilé asofin pa tí wọn ò bá san owó osù àti àwọn ajẹmọnu mìíràn to yẹ ki wọn san.
Awọn oṣìṣẹ́ fẹ̀hónú hàn níle ìgbìmọ̀ Aṣofin
Nínú àtẹ̀jáde ti akọwé PASAN fọ́wọ́ sí Comrade Suleiman Haruna, ní àwọn òṣìṣẹ́ náà tí sàlayé pé ìgbésẹ̀ àkọ́kọ́ ní pé àwọn yóò wọ́de ìfẹ̀hónú hàn láti dí ìgbòkègbòdò ilé ìgbìmọ̀ àsṣòfin lọ́wọ́ lónìí tíí ṣe ọjọ́ kerin àti ọjọ́ kẹjọ oṣù yìí, ọdún 2018.
Harun sàlàyé pé ìgbéṣẹ̀ yìí pọn dandan nítori pé àwọn fẹ́ jẹ́ kí wọ́n mọ̀ pé ọ̀rọ̀ àwọn kìí ṣe àwadà rárá bí kò ṣe pé ki àwọn aláṣẹ́ sàn àwọn owó oṣù àti àwọn owó ìgbéga ti wọn jẹ òṣìṣẹ́ ní wàrà-ń-sesà.
Awọn oṣìṣẹ́ fẹ̀hónú hàn níle ìgbìmọ̀ Aṣofin
Ọkan lára àwọn oṣìṣẹ́ ọ̀hún sọ pé ìwọ́dé náà yóò máà wáyé láàrin aago mẹ́jọ ààrọ sí aago méjì ọsàn àwọn ọjọ́ tí àwọn fi léde.
Nínú ọ̀rọ̀ tirẹ̀ olùdarí ọ̀rọ̀ tó ń lọ àti ìgbóhùn sáfẹ́fẹ́ nílé ìgbìmọ̀ aṣòfin Rawlings Agada sàlàyé pé sísàn àwọn owó àjẹmọnu kàn kọ́já àgbàra àwọn aláṣẹ ilé ìgbìmọ aṣòfin, ó fi kún-un pé sísàn CONLESS ti ju agbára àwọn ìgbìmọ alákoso lọ nítorí kò sí nínú ètò ìṣúná owó fún ọdún 2018.
2019 Elections: Ilọrin ń gbàlejò Atiku lónìí fún ìpolongo ìbò
Ireti wa wi pe awọn eekan ẹgbẹ yoo kọwọrin pẹlu Atiku lọ si Ilorin
Oludije fun ipo Aarẹ labẹ asia ẹgbẹ oselu PDP, Atiku Abubakar, yoo balẹ silu Ilorin, tii se olu ilu ipinlẹ Kwara fun ipolongo idibo Aarẹ.
Atejade kan lati owo ẹgbẹ oselu PDP ti wọn fi sita loju opo Twitter wọn so pe, ipolongo naa jẹ ti ẹkun aarin gbungbun ariwa.
Tọkọ-taya Aràrá: Àwọn èèyàn máa ń wò wá, ta bá fa ọwọ́ ara wa ní títì
Ninu awọn ti ikede naa ni yoo kọwọrin pẹlu Atiku, la ti ri awọn Gomina ẹgbẹ naa, awọn eekan ẹgbẹ to fi mọ ọmọ ẹgbẹ PDP jakejado.
Saaju ni Atiku Abubakar ti gbe ipolongo rẹ lọ si ipinlẹ Sokoto, ti wọn fi sọri iwọ oorun ariwa, ti a si gbo wi pe ipolongo naa yoo kari gbogbo awọn ẹkun idibo orileede Naijiria.
Lẹyin ipolongo ẹkun idibo ni ẹgbẹ naa yoo bẹrẹ ipolongo idibo lo si awọn ipinlẹ lọọkọkan.
Oríṣun àwòrán, @OfficialPDPNig
Atilẹyin Bukola Saraki wa lara nnkan ti Atiku n gboju le lati fikoju Aarẹ Buhari ninu idibo 2019
Ipinlẹ Kwara ni ipinlẹ ti Aarẹ ile asofin agba Bukola Saraki ti wa.
Oselu ipinlẹ naa si ṣe pataki fun oludije yala fun ipo Aarẹ ni tabi Gomina.
Ireti wa wi pe awọn eekan ẹgbẹ yoo kọwọrin pẹlu Atiku lọ si Ilorin
Idi ni wi pe, isakoso ijọba nipinlẹ naa jẹ fa-ki-n-fa laarin ẹgbẹ oselu APC ati PDP.
Lafikun, ni bi nnkan ti ṣe n lọ lenu ọjọ mẹta yi ti ẹgbẹ oselu APC ti ṣe fẹyin ẹgbẹ PDP gbolẹ ninu atundi ibo fun asoju ile asofin to waye eleyi ti wọn fi yan asoju miran  rọpọ Funke Adedoyin to salaisi.
Diezani: Iléẹjọ́ ní Diezani yẹ kó sọ tẹnu rẹ̀ lórí ẹ̀sùn àjẹbánu lẹ́ka èpò rọ̀bì
Oríṣun àwòrán, @diezanimadueke
Ileeẹjọ giga tilu Abuja ti pasẹ lọjọ isẹgun pe ki ajọ EFCC lọ gbe minisita fọrọ epo rọbi ni isejọba to kọja, Diezani Allison Madueke, ẹni ti wọn n tanna wadi rẹ lọwọ ni ilu Ọba.
Adele Agbẹnusọ fun ajọ EFCC, Tony Orilade lo sisọ loju ọrọ yii fawọn akọroyin.
Iroyin naa ni adajọ to n gbọ ẹjọ ti EFCC gbe wa nipa ẹsun ajẹbanu ti wọn fi kan Diezani, Valentine Ashi, pasẹ fun EFCC, ileesẹ ọlọpaa, ileesẹ ọtẹlẹmuyẹ atawọn ileesẹ agbofinro yoku lati wa Diezani lawari ti obinrin n wa nkan ọbẹ.
Ọdẹrinde Oníjaàálá: Ìjálá mi máa ń mú káwọn onísẹ́ ibi gbàgbé láti sebi
Adajọ Ashi fikun pe awọn ileesẹ naa gbọdọ di Diezani lapa n yaka wa siwaju oun laarin ọjọ mẹta pere ti oun gbe asẹ naa kalẹ.
CAMA 2020: Falana, SERAP ní CAMA ni òfin tó tíì burú jùlọ nínú ìtàn Nàíjíríà
Oríṣun àwòrán, Others
Ọrọ ko tii tan lori ofin ti yoo maa se akoso awọn ileesẹ atawọn ajọ to rọ mọ ti ijọba sẹsẹ gbe jade.
Ofin naa ti adape rẹ n jẹ CAMA, si lo fun awọn asoju ijọba lagbara lati gba akoso awọn ile ijọsin, ki wọn si yọ igbimọ oludari ibẹ lai lọwọ ile ẹjọ ninu.
Akọtun awuyewuye to tun waye lori ọrọ naa ni bi agba amofin Femi Falana se se atupalẹ ofin ọhun, to si ni wọn ko kọ ofin naa daada rara.
Mo ti ka ofin naa, wọn ko gbe kalẹ lọna to dara nitori ijọba to ba n san na bi eto idalesẹ silẹ yoo se rọrun, ko ni gbe ofin mẹrinlelẹgbẹta kalẹ lori agbekalẹ ileesẹ aje.
Oríṣun àwòrán, Others
Falana fikun pe awọn ofin ti ijọba gbe sita naa kii se tuntun, amọ ohun to yẹ ka tako ninu ofin ọhun ni bi ijọba se fun ajọ rẹ kan lagbara lati gba akoso awọn ileesẹ ti kii ba se tijọba, ti wọn ba kẹẹfin iwa sise magomago nibẹ.
Nigba toun naa n sọ ero rẹ lori ofin yii, ajọ to n dena iwa kotọ ni Naijiria, SERAP ni abala ogoji ninu ofin naa lo n tako ẹtọ ọmọniyan nipa ominira ibakẹgbẹpọ.
Sunday Igboho: Ẹ fi Ògún búra fún wa láti jà fún ilẹ̀ Yorùbá láì gbé Amotekun sábẹ́ ìjọba
"SERAP ni ""Abala ti ko tọ rara ninu ofin naa ni agbara ti ijọba gbe fun ajọ CAMA lati maa dari awọn ileesẹ ti kii se tijọba naa."""
SERAP ni ofin CAMA ni ofin ijẹgaba le ni lori to tii buru julọ ninu itan orilẹede Naijiria, eyi ti wọn yoo tun lo lati tẹ ẹtọ araalu loju mọlẹ.
Bẹẹ ba gbagbe, asaaju ijọ Living Spring, David Oyedepo ti kọkọ koro oju si ofin CAMA naa, ti ijọba si fesi pada fun pe o gbọdọ tẹle ofin Naijiria dandan ni.
Adari ijọ Living Faith Church Worldwide ti ọ̀pọ̀ n pe ni Winners' Chapel, Bisọ̀ọ̀bù agba David Oyedepo ti fun awọn to n bu u lesi pe ko kan oun.
O ni ipakọ ko gbọ́ suti nitori ori ẹ̀lẹ́gan lo ba jẹ.
O ni ninu ariwo ni ijọ Olorun ti n dagba sii nitori pe ariwo ọja ni gbogbo ohun to n sẹlẹ yii.
Bisọ́ọbu ni koda laipe ni ijọ Winners tun da ẹ̀ka okoo le ni ẹẹdẹgbẹta silẹ̀.
Saaju ni Aare Buhari ti buwọlu ofin tuntun lọjọ keje, osu yii nipa abadofin Companines and Allied Matters 2020 ni eyi ti ijọba fi paarọ 1990 CAMA.
Ninu iwaasu ti Bisọọbu Oyedepo se nile ijọsin re lọjọ Isẹgun to pe ni: Titayọ kọja gbedeke ni eyi ti wọn gbe sita lori ayelujara ijọ naa lo ti fesi.
Oyedepo ni ẹ̀rín ni toun lọ́jọ́ gbogbo ati pe ti oun ba waasu ti ko mu ayọ̀ ati ẹ̀rin da ni pe ki awọn eeyan ma gbọ́ oun.
Bisoobu ni lati odun 1976 ni oun ti n rẹrin lati igba ti oun ti sawari ẹ̀sẹ̀ Bibeli Mathew 6: 33 ni eyi to si oju oun si fifi satani se yẹ̀yẹ̀ ki oun si maa rẹrin bi oun se n sin Olorun.
O ni koda, ti o ba bu mi, inu mi maa n dun sii ni nitori n ko ni dẹkun lilọ si ibi isẹ nitori pe o bu mi, gbogbo ẹya ara mi ti awọn eeyan le fi se yẹ̀yẹ̀ lo tẹ́ mi lọ́rùn ni mo si n dupẹ́ fun.
Akomolede ati asa Yoruba: Ẹ wá kọ́ nípa àpòtí ìṣura èdè wa lórí BBC Yorùbá
Ki lo kọkọ sẹlẹ?
Oyedepo àti ìjọba ń tahùn síra lórí bí ìjọba ṣe ń gba àkóso àwọn ilé ìjọsìn
Ìjọba àpapọ̀ ní kó lọ dá orilẹ̀èdè tiẹ̀ sílẹ̀, bí kò bá ní tẹ̀ lé òfin
Oríṣun àwòrán, @DavidOyedepoMin
Ọkan lara awọn amugbalẹgbẹ aarẹ Muhammadu Buhari Lauretta Onchie ti bẹnu atẹ lu ọrọ kan ti oludasilẹ ati adari ijọ Winners Chapel, Bisọọbu David Oyedepo sọ, lori ofin tuntun ti ijọba gbe kalẹ fun awọn ijọ.
Ofin CAMA naa to ti wa nilẹ tẹlẹ, sugbọn ti wọn ṣẹṣẹ ṣe afikun rẹ, ti o si kan awọn ijọ nlanla lo fa gbọnmisi omi o to laarin adari ijọ ọhun ati agbẹnusọ aarẹ Buhari.
Ofin naa sọ pe, awọn ile ijọsin lẹyin iforukọ silẹ pẹlu CAC ati ile isẹ to wa fun amojuto rẹ, ni ijọba maa ṣe akoso wọn.
Bakan naa, ile iṣẹ ijọba to n ṣe amojuto yii naa le yọ alaga igbimọ ijọ to ba se aṣemaṣe, to si tun ni agbara lati yan ẹlomiran dipo.
Afikun ofin yin lo fa ibinu yọ, ti Bisọọbu fi fesi pe:
"Oyedepo ni: ""Ohun ini Ọlọrun ni ijọ jẹ lorilẹ aye. Bi ẹnikẹni ba si ṣe aṣemaṣe pẹlu iyawo eniyan, igba naa ni yoo ri ibinu ọkọ rẹ. Iyawo ni ijọ jẹ si Jesu."
Alaafin: Olori Aanu Adeyemi ṣàlàyé ìdí tó ṣe gẹ́ Oba Lamidi Adeyemi ti ìlú Oyo
"Aṣẹ ti Ọlọrun fun wa ni ki a maa ṣe ikilọ fun awọn olori to n hu iwa buburu, ki ẹjẹ wọn maa ba si lori wa."""
Sugbọn nigba ti amugbalẹgbẹ aarẹ Onochie yoo fesi lori ọrọ yii loju opo Twitter rẹ, o fa ibinu yọ.
"Mo nigbagbọ pe ootọ kọ ni ọrọ yii, Oyedepo yoo nilo lati da orilẹ-ede tirẹ silẹ ti yoo si ma da ibẹ gbe pẹlu awọn ofin tirẹ.
Niwọn igba ti o ba ti jẹ pe orilẹ-ede Naijiria naa lo wa, o di dandan ki o tẹle ilana ati ofin ibẹ. Yoo se gẹgẹ bi ofin ṣe sọ ni.
Aibọwọ fun ofin ti to gẹẹ"
Onochie fi kun un pe, Oyedepo n ti iwa aitẹle ofin lẹyin ni Naijiria, o ni ati ilu Ọba ni wọn ti n fi owo iranwọ ranṣẹ si Oyedepo, sugbọn o n dunkoko mọ ijọba ni Naijiria.
Aarẹ apapọ fun ijọ Winners, Bishọọbu David Oyedepo, ti sọ asọtẹlẹ pe gbogbo agbara okunkun to n jọba lori ilẹ Naijiria ati ni Afrika ni yoo kan abuku ki ọdun yii to pari
Bishọọbu Oyedepo kede bẹẹ lasiko iwaasu rẹ nibi ipade ajọ nla Shiloh, Ogun iru rẹ, to side rẹ ninu gbọngan nla ijọ naa to wa nilu Ọta, nipinlẹ Ogun.
"Oyedepo ni ""akoko ọtun lo de yii, ti Ọlọrun yoo si gbe agbara asẹ fun awọn ijọ lati dẹkun awọn ilana ofin to mẹhẹ atawọn oloselu ti ko pegede to ni Naijiria."""
Ìbejì Oníbẹ̀mbẹ́ Òru: Owó, ọmọ àbí aya kò leè yà wá
O fikun pe orilede Naijiria ati il Afrika lapapọ, ni Ọlọrun setan lati gba lọwọ awọn aninilara ati ọrọ aje to mẹhẹ.
"Olori ijọ Winners naa ni ""ọpọ ẹtan lo wa ninu aye loni, amọ emi duro fun otitọ, agbara nla ti Ọlọrun yoo si gbe wọ ijọ rẹ lọrun yoo pọ to bẹẹ gẹ, ti yoo mu owu jijẹ dani."""
O ni akoko ti to, to jẹ pe asọtẹlẹ latinu ijọ Ọlọrun yoo maa sẹ, ẹniti wọn ba ni ko ku, yoo ku, ẹni ti wọn ba si ni ko ye, yoo ye.
Ijọ Ọlọrun yoo maa kọ awọn eeyan ni ẹka kọọkan lọna to pegede lati se amusẹ awn afojusun wọn, ti yoo si mu esi nla jade.
Eko: Wale Oluwo ní ìdìbò abẹ́nú APC tó mẹ́hẹ l‘Eko ló fa sábàmí
Oríṣun àwòrán, @Epiczone
Ẹgbẹ oṣelu Peoples Democratic Party, PDP ti sọ wi pe lootọ ni Wale Oluwo to jẹ Kọmisọna eto ohun amusagbara nipinlẹ Eko ti kuro lẹgbẹ oṣelu APC dara pọ mọ PDP.
Wale Oluwo fun ra rẹ s fun BBC pe oun kọwe fi Ambode sil tori bi ẹgbẹ oṣelu wọn, All Progressives Congress ṣe ṣe mọndaru ninu idibo abẹnu wọn nipinlẹ Eko.
O tun sọ pe ''maa dara pọ mọ PDP, maa si ṣiṣẹ fun oludije wọn Jimi Agbaje lati di gomina''.
Kọmisọna feto ohun amusagbara ati ohun alumọọni ilẹ, nipinlẹ Eko, Wale Oluwo ti kọwe fẹgbẹ oselu APC silẹ, to si tun juwọ si ipo rẹ ninu igbimọ alasẹ gomina Akinwunmi Ambọde pe o digbose.
Bakan naa ni Oluwo wa fọwọ gbaya pe oludije fun ipo gomina ninu ẹgbẹ oselu PDP, Jimi Agbaje, ni oun yoo se atilẹyin fun lati moke ninu eto idibo gomina nipinlẹ Eko.
Oríṣun àwòrán, Adedayo Owolabi
Oluwo kede ọrọ yii ninu iwe to kọ pe oun ko sisẹ mọ, to si n naka aleebu si awọn asaaju ẹgbẹ oselu APC pe wọn n tẹ ilana eto isel ijọba awa ara wa loju, eyi to sanna fun Babajide Sanwo Olu lati moke ninu ibo abẹnu ẹgbẹ naa l‘Eko.
Ìbejì Oníbẹ̀mbẹ́ Òru: Owó, ọmọ àbí aya kò leè yà wá
Oluwo fi kun pe idibo abẹnu ẹgb APC to lọw mọkaruru ninu nipinlẹ Eko lo ti ta ẹrẹ nla si ara ẹgbẹ ọhun pẹlu afikun pe, awọn ikọ alagbara kan wa ninu ẹgbẹ naa, ti wọn jẹ igi wọrọkọ to n da ina alafia ẹgbẹ ru nipinlẹ Eko.
Cardi B ti pín yà pẹ̀lú ọkọ rẹ̀ Offset lẹ́yìn ọdún kan
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Cardi B àti Offset ṣeré pọ̀ lọ́jọ́ Àìkú tó jẹ́ ọgbọ̀n ọjọ́ oṣù kọọ̀kànlá.
Akọrin takasufe Amerika Cardi B ti kede ipinya pẹlu ọkọ rẹ, Offset, ọdun kan lẹyin igba ti wọn ṣe igbeyawo.
Obirin naa to jẹ iya ọmọ kan sọ pe yoo pẹ diẹ ki wọn to pin ya pata-pata nitori pe wọn jọ bimọ pọ.
Lọjọru ni Cardi B sọ eleyi di mimọ lori  Instagram to si sọ wi pe oun yoo maa nifẹ olorin Migos oun lailai.
Awọn akọrin mejeeji naa jọ kọrin pọ lọjọ Aiku ni ode kan.
Ọrọ naa ka awọn eeyan lara lagbaye titi ti orukọ awọn mejeji naa si jẹ eyi ti awọn eeyan n sọ niparẹ ju lori ero ayelujara.
Ladi Àdebutu ni olùdíje gómìnà wa l'Ogun —PDP
Oríṣun àwòrán, Facebook/LadiAdebutu
Ladi Adebutu
Ẹgbẹ́ òṣèlú PDP ti ké gbàjarè pé Ladi Adebutu ni oludíje ipò gómìnà ní ìpílẹ̀ Ogun fún ẹgbẹ́ náà.
Àtẹ̀jáde kan tí agbẹnusọ ẹgbẹ́ náà,  Kola Ologbodiyan, fi léde sọ wí pé iyè-méjì nípa olùdíje gómìnà ẹgbẹ́ náà ní ìpìnlẹ̀ Ogun.
Ìkéde náà wáyé lásìkò tí àwọn ìròyìn kan sọ wí pé Sẹ́nétọ̀ Buruji Kashamu ni olùdíje fún ìpò náà nínú ẹgbẹ́ PDP.
Ologbodiyan sọ wí pé Ladi Adebutu ni ẹni tí wọn dìbò yàn níbi ìbò abẹ́lé tí wọ́n dì lábẹ́ ìgbìmọ̀ amúṣẹ́ṣe PDP .
Agbẹnusọ PDP náà bá kéde pé kí àwọn ọmọ ẹgbẹ́ kọ̀yìn sí gbogbo ẹni tó bá ń dábàá pé òun ni yóò du ipò náà lábé àsìá PDP.
Oríṣun àwòrán, Facebook
Ìkéde náà wáyé lásìkò tí àwọn ìròyìn kan sọ wí pé Sínátọ̀ Buruji Kashamu ni olùdíje fún ìpò náà nínú ẹgbẹ́ PDP
Sẹ́nétọ̀ Buruji Kashamu kò tíì sọ sí ọ̀rọ̀ náà lásìkò tí à ń ko ìròyìn yìí jọ.
Èmi kò mọ obìrin tí DSS mú rí —Aisha Buhari
Oríṣun àwòrán, Twitter/@AishaBuhari
Ìyàwó ààrẹ Nàìjíríà, Aisha Buhari ti sọ wí pé òun kò mọ ọbìrin tí ilé iṣẹ́ ọ̀telẹ̀múyé orílẹ̀èdè Nàìjíríà, DSS, fi ẹ̀sùn jìbìti kan rí.
Àtẹ̀jáde kan tí agbenusọ ìyàwó ààre náà, Suleiman Haruna, fi síta sọ pé arábìrin Aisha Muhammadu Buhari ń bá àwọn ìṣẹ̀lẹ̀ tó rọ̀ mọ́ ìwádìí tí ilé iṣẹ́ ọ̀tẹlẹ̀múyẹ́ (DSS) ń ṣe nípa ìwà jìbìtì kan.
Aisha Buhari sọ wí pé òun kò ní ǹkankan ṣe pẹ̀lú ìwà jìbìtì tí ilé iṣẹ́ DSS ń ṣe ìwádí rẹ̀ lọ́wọ́.
Lọ́jọ́rú ni ilé iṣẹ́ DSS ṣe àfihàn obìnrin kan tí wọ́n fi ẹ̀sùn lílo ilé ààrẹ láti lu àwọn èèyàn ní jìbìtì.
Ṣùgbọ́n nínú àtẹ̀jáde tó fi síta lọ́jọ́bọ, Asiha Buhari sọ pé obìnrin tó ń jẹ́ Mariyatu tí wọ́n sì ń pè ní Amina Mohammed kìí ṣe ọmọ ìya òun.
Ìyàwó ààrẹ Nàìjíríà náà sọ pé gbogbo òṣìṣẹ́ tí wọ́n bá ká àìṣe dédé mọ́ lọ́wọ́ yó fojú winá òfin.
Oríṣun àwòrán, .
Obìnrin tí DSS fi ẹ̀sùn kan pé ó ń ọ̀nà alùmọkọ́rọ́yín wọ ilé ààrẹ l'Abuja láti lo gbájúẹ náà rèé
Ìròyìn sọ pé obìnrin yìí máà ń lo onírúurú ọ̀nà alùmọkọ́rọ́yín wọ ilé ààrẹ l'Abuja láti lo gbájúẹ pẹ̀lú àwọn ayédèrú òwò ṣíṣe ṣùgbọ́n ó ti kábamọ̀ ìwà rẹ̀ báyìí.
Ilé iṣẹ́ ọ̀tẹlẹ̀múyẹ́ sọ pé Amina Muhammed tí kọ́kọ́ sọ pé oun ní aya gómìnà ìpínlẹ̀ Kogi lójúnà àti rí ààyè wọ Aso Rock ní ìlú Abuja.
Atiku Abubakar bẹ̀rẹ̀ ìpolongo ìdìbò rẹ̀ fún 2019
Ìlérí àsan ni Atiku ń se lórí àtúntò Nàíjíríà - APC
Ilé iṣẹ́ ọ̀tẹlẹ̀múyẹ́ sọ pé Amina Muhammed tí kọ́kọ́ sọ pé oun ní aya gómìnà Kogi lójúnà àti rí ààyè wọ Aso Rock ní ìlú Abuja.
Lẹ́yìn èyí ló bẹ̀rẹ̀ sí ní ráńṣẹ́ sí àwọn ènìyàn lórúkọ ayá ààrẹ Muhammadu Buhari.
"Níbi ìpàdé àwọn oníròyìn tí wọn ti sàlàyé ọ̀nà tí wọn gba mú arábìnrin Mohammed ṣe ló kígbe pé ""irọ́ ní''"
Electoral bill 2018: Buhari àtàwọn aṣòfin àpapọ̀ leè gbéná wojú ara wọn láìpẹ́
Oríṣun àwòrán, Bukola Saraki
Ìgbà mẹ́ta ọ̀tọ̀ọ̀tọ̀ ni ìwé òfin yìí ti lọ sí ọ̀dọ̀ ààrẹ ṣùgbọ́n tí kò buwọ́lùú òfin ìdìbò tuntun naa
Afaimọ ki ẹka aṣofin ati ẹka iiṣakoso o maa gbe ina woju ara wọn ni awọn ọjọ ti o n ṣaaju idibo apapọ bayii o.
Ko si idi meji ti eyi lee fi waye ju lori ọrọ bi aarẹ ṣe n fi ẹsẹ falẹ lori ọrọ bibu ọwọ lu abadofin tuntun lori ọrọ ilana idibo lorilẹede Naijiria.
Aarẹ ile aṣofin agba lorilẹede Naijiria, Sẹnetọ Bukọla Saraki lo tun mu ọrọ naa wa si iranti ninu atẹjade kan to fi sita pe ki aarẹ Buhari o kọ eti ikun si ọrs awọn kan ti wọn n ke sii pe ko maa buwọlu abadofin naa.
Èmi kò mọ obìrin tí DSS mú rí —Aisha Buhari
'Màá dara pọ̀ mọ́ PDP, màá sì ṣiṣẹ́ fún Jimi Agbaje'
Àwọn ará Kwara tú jáde pàdé Atiku n'Ilorin
Saraki ni ohun ti o tọna ni ki aarẹ pa ọrọ oṣelu ti ki o si gbe igbesẹ lori ohun to pe ni 'anfani orilẹede Naijiria' ki o si buwọlu ofin naa.
Ọrọ nipa bibuwọlu ofin ilana idibo tuntun yii ti wa nilẹ fun ọjọ pipọ. Akọkọ rẹ ti ile aṣofin fi ṣọwọ si aarẹ ko gba igbọwọle aarẹ nitopri ohun ti aarẹ pe ni aidọgba awọn abala kan ninu abadofin naa.
Awọn aṣofin apapọ ṣe atunṣe si abadofin naa lẹyin ti aarẹ daa pada fun wọn ki ọrọ to de ipele ti o wa bayii.
Goodluck Jonathan ní òun nìkan kọ́ ló l'ẹ̀bi ìjínigbé akẹ́kọ̀ọ́ Chibok àti Boko Haram
Saraki ni awọn aṣofin gbogbo ni wọn ti n da oun laamu lati fi aidunu wọn han lori bi aarẹ ṣe n fi ẹsẹ falẹ lori rẹ paapaajulọ bi oṣu kan ti ofin la kalẹ fun abadoofin naa ti ṣe fẹ pari ni ọjọ diẹ si asiko yii.
"Saraki woye pe ""bi ọrọ ṣe bẹrẹ niyi lasiko ti awọn ẹgbẹ kan bii ABN ko ara js lọ si ile ẹjọ lati dena kikede esi idibo June 12, ọgbọn yii kan naa lawọn ẹgbẹ ati eeyan kan tun fẹ maa lo bayii lati dena bibuwọlu ofin ilana idibo tuntun yii."""
Electoral bill 2018: Èrèèdí wàhálà láàárín Buhari àtàwọn aṣòfin àpapọ̀ lórí òfin ìdìbò 2018
Oríṣun àwòrán, Getty Images
 Lara awọn ohun ti o n fa gbonmisii laarin ẹka ijọba mejeeji ni ọrọ lilo ẹrọ idibo fun idibo labẹ ofin
Ni ọjọ Ẹti, ọjọ keje oṣu kejila ọdun 2018 ni gbedeke ti ofin la silẹ fun ẹmi abadofin fun igbọwọle aarẹ yoo wa sopin.
Eyi tumọ si pe bi aarẹ Buhari ko ba buwọlu abadofin naa ki ọjọ ẹti to lọ, abadofin naa fori ṣanpọn niyii.
Pẹlu bi orilẹede Naijiria ṣe n gbaradi fun idibo apapọ ni ọdun 2019, ọpọ onwoye lo ti n woo bi eyi yoo ṣe ri pẹlu ilana ati igbaradi fun idibo naa.
Ninu iwe atẹjade kan eyi ti o fi sita, aarẹ ile aṣofin apapọ orilẹede Naijiria, Sẹnetọ Bukọla Saraki ni kii ṣe araalu atawọn onwoye nikan ni ọrọ naa n kọ lominu, o ni awọn aṣofin pẹlu ti n ranṣẹ si oun lati mọ idi ti aarẹ fi n wọsẹ nilẹ lori bibuwọlu abadofin naa. O ni bi aarẹ ko ba buwọlu abadofin yii, ko si bi awọn aṣofin ko ṣe ni gbe igbesẹ naa.
Oríṣun àwòrán, @BashirAhmaad
Àwọn aṣòfin tí wọ́n sọ̀rọ̀ lórí èdèàìyedè láàárín Buhari àtàwọn aṣòfin àpapọ̀ ní àwọn kan nínú ìjọba ló n gbè lẹ́yìn àwọn tó ń ké sí ààrẹ pé kò gbọdọ̀ buwọ́lù àbá náà.
Ninu ọrọ ti wọn ba BBC News Yoruba sọ awọn aṣofin ajafẹtọ araalu meji kan, Malachi Ugumadu ati Iniebe Effiong pẹlu kọminu lori rẹ, ṣugbọn wọn ni iwe ofin orilẹede Naijiria ti ọdun 1999 ti la ọna kalẹ fun abayọ.
Ọna abayọ ọhun, gẹgẹ bi wọn ṣe sọ ni pe awọn aṣofin lee pa aṣẹ waa lori abadofin naa ti yoo si di ofin.
Aṣofin Malachi Ugumadu ti o jẹ alaga ajọ ti o n ja fun ẹtọ araalu, CDHR lorilẹede Naijiria ṣalaye pe irufẹ iṣẹlẹ bayii ti waye ri ni ọdun 2006 ṣugbọn ti awọn aṣofin apapọ lo agbara aṣẹ waa lati buwọlu iwe abadofin naa funra wọn.
Oríṣun àwòrán, @BashirAhmaad
Bi aarẹ ba kuna lati buwọlu abadofin naa, awọn aṣofin lee pa aṣẹ waa lori abadofin naa ti yoo si di ofin
Amofin Effiong ni aifi ọwọ si iwe ofin eto idibo yii yoo mu ọpọlọpọ  ibeere jade lori iduro ṣinṣin eto idibo naa nitori iwe ofin ti o yẹ ko mu ọpọlọpọ atunto ba eto naa ni eyi.
Gẹgẹ bi o ṣe sọ awọn ilana tuntun bii lilo ẹrọ idibo ti o wa ninu abadofin yii jẹ itẹsiwaju fun eto idibo ti ko ni ẹja-n-bakan ninu lorilẹede Naijiria, nitori naa ko si idi fun aarẹ lati ma buwọlu u.
Amofin Malachi Ugumadu ni bi aarẹ ba kuna lati ṣe ohun ti o tọ, ki awọn asofin tẹ siwaju lati fi aṣẹ waa wọn gbe ofin naa wọle.
Oríṣun àwòrán, @BashirAhmaad
Bi aarẹ Buhari ko ba buwọlu abadofin naa ki ọjọ ẹti to lọ, abadofin naa yoo fori ṣanpọn
Eyi kọ ni igba akọkọ ti edeaiyede yoo maa waye lori abadofin yii. Koda eyi to kẹyin ni aarẹ ti beere fun atunṣe awọn abala kan ninu ofin naa eleyi ti awọn aṣofin ti ṣe atunṣe si ki wọn to tun daa pada.
Ninu ọrọ rẹ, amofin Malachi Ugumadu ni lara awọn ohun ti o n fa gbonmisii laarin ẹka ijọba mejeeji ni ọrọ lilo ẹrọ idibo fun idibo labẹ ofin.
O ni ṣaaju asiko yii ko si ẹni to lee lo akude lori ẹrọ idibo yii lati fi gbe ẹjọ kalẹ niwaju ile ẹjọ, eleyii ti o ni abadofin yii mu atunṣe ba.
Jimi Agbaje: Kò sí òfin tói n['i a gbọ́dọ̀ gbàyè láti lẹ ìwé ìpolongo
Ohun keji ti o wa ninu abadofin yii eyi ti awọn aṣofin fi  kun un ni fifun ajọ INEC ni agbara labẹ ofin lati lee gbe igbesẹ to tọ lori awọn idibo abẹle ẹgbẹ oṣelu yoowu ti wọn ba ri pe ko lọ ni ilana ti ofinla kalẹ.
Tẹlẹtẹlẹ, bi INEC ba lọ si awọn ipade abẹle awọn ẹgbẹ oṣelu kaakiri, oluworan ni wsn maa n ṣe nibẹ, wọn ko lẹtọ lati gbe igbesẹ lori iwa aitọ yoowu ti wọn ba kẹẹfin nibẹ
"Ni tirẹ, amofin Effiong ni 'Ko si awawi kan fun aarẹ lati maṣe buwọlu abadofin yii. Ayafi ti o ba jẹ pe aarẹ kan nlo iwa iṣegbe fun ẹgbẹ oṣelu abi oun ti yoo boo lẹsẹ nikan ni o ku."""
Ọ̀ọ̀ni Ilé Ifẹ̀: Ọ̀rúnmìlà ni ó kọ́kọ́ lo 'Google' láàgbáyé
Kabiyesi ni Yoruba gbọdọ ranti mọ ipo wọn gẹgẹ bii ẹya ti ko ṣee fi ọwọ rọ sẹyin ni agbaye
Ọọni ile ifẹ, Adeyẹye Ogunwusi ti ṣalaye pe ilẹ Yoruba ni ipa nla ti o ko lori idagbasoke imọ ẹrọ ati imọ sayẹnsi lagbaye.
Ọọni Ogunwusi ni Orunmila ni o kọkọ gbe imọ eroja iṣẹ lori ayelujara ti a mọ si 'Google' kalẹ lati ọpọ ọdun sẹyin ki o to di wi pe oyinbo gbee kalẹ.
Ninu ọrọ to ba BBC News Yoruba sọ lasiko eto facebook live lori ikanni ayelujara facebook ni o sọrọ yii.
Ọọni Ifẹ ni ko si ẹsin kan ti o ju ẹsin kan lọ nitori ninu ifẹ ati iṣọkan ni gbogbo ẹsin ti waye.
O ni iṣẹ ti awọn alalẹ gbe le oun lọwọ ni lati lọ igi alaafia ni alọye laaarin awọn lọbalọba ati ọmọ bibi ilẹ Yoruba lagbaye.
O ni ko si ija tabi ikunsinu laarin awọn Ọbalaye ni ilẹ Yoruba mọ nitori alaafia ti jọba.
Aifagba fun ẹnikan ni o n fa wahala laaarin awọn ọbalaye ilẹ Yoruba. Loootọ emi ni olori gbogbo Ọbalaye ni ilẹ Yoruba, sibẹ awọn agba ọba n bẹ ti mo ba lori itẹ ti mo si ni lati fi ọwọ fun gẹgẹ bi agba lori ilẹ. Ki Ọlọrun ki o bawa lọọra ẹmi wọn ki wọn tubọ pẹ fun wa.
2019 Elections: Saraki, Dino ní kí Yorùbá dìbò ààrẹ fún Atiku
'Ẹ dìbò fún Atiku nílẹ̀ Yorùbá'
Aare igbimọ aṣofin agba l'Abuja, Bukọla Saraki kesi gbogbo ọmọ Yoruba lati gbaruku ti Atiku Abubakar ninu idibo aarẹ ọdun 2019 nitori awọ rẹ nikan lo ka oju inu iṣakoso orilẹede Naijiria.
O fi idaniloju han wi le ijọba Atiku yoo tu tolori-tẹlẹmu lara nitori saaju asiko lo ti n lese iṣẹ lọpọ yanturu fun ọpọlọpọ awọn ọdọ ti ko riṣẹ ṣe nipasẹ awọn ile iṣẹ aladani ti o ṣe agbekalẹ rẹ.
Ipolongo Atiku Abubakar
Ninu ọrọ tiẹ, Gomina ipinlẹ Ogun tẹlẹri, Ọtunba Gbenga daniel ti o tun jẹ aṣoju ipolongo ibo fun ẹgbẹ oṣelu PDP, Ọtunba Gbenga Daniel ti ṣe alaye wipe ibo alajọbi ni ibo ti awọn ọmọ bibi ilẹ Yoruba yoo di fun Atiku Abubakar ninu eto idibo si ipo aarẹ lọdun 2019.
Gomina tẹlẹri ọhun sọ ọrọ naa di mimọ nibi akanṣe eto ipolongo ibo fun oludije si ipo aarẹ ninu ẹgbẹ oṣelu PDP ti o waye l'Ọjọbọ ni gbagede Mapo nilu Ibadan.
Awọn aworan oriṣiriṣi nibi ipolongo Atiku n'Ibadan
Ipolongo Atiku
Ipolongo Atiku
Ipolongo Atiku
Ipolongo Atiku
Ipolongo Atiku
Ọgọrọ awọn alatilẹyin ẹgbẹ oṣelu PDP lo pejupesẹ sibi ipolongo naa. Lati awọn ipinlẹ to n bẹ lẹkun Iwọ Oorun ni awọn ọmọ ẹgbẹ oṣelu PDP ti kora jọpọ fun akanṣe eto naa.
Ipolongo Atiku
lara awọn eeyan pataki ti wọn n reti nibẹ ni awọn alẹnulọrọ ninu ẹgbẹ oṣelu PDP, igbimọ alakoso, awọn oludije ninu ẹgbẹ oṣelu naa ati Atiku Abubakar to jẹ ọmọ oye fun ẹgbẹ oṣelu PDP ninu idije si ipo aarẹ lọdun 2019.
Ipolongo Atiku
Lati aago mejila lo ti yẹ ki eto naa bẹrẹ, ṣugbọn awọn alẹnulọrọ ti wọn n reti ko tii de si ibi eto naa.
Àwọn olórin níbi ìpolongo Atiku
Lara awọn oṣere to darapọ mọ ipolongo naa ni Sanyẹri Afọnja, Murphy Afọlabi, Kunle Afod, Kamilu Kampo, Saheed Oṣupa ati Taiye Currency.
Ǹjẹ́ o mọ pàtàkì igi tó wà ní àyíká rẹ bí?
Fayoṣe gba ibi ìjàmbá ọkọ̀ dé ìpolongo ìbò Atiku
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Lọjọru ni iroyin kàn pé gomina tẹlẹ ni ipinlẹ Ekiti, Ayọdele Fayoṣe ní ijamba ọkọ loju ọna marosẹ afara Third Mainland ni ipinlẹ Eko.
Ninu ikede kan ti oluranlọwọ pataki fun un lori eto iroyin, Lere Ọlayinka ni ọrọ naa ti fojuhan. Botilẹ jẹ wi pe ile iwosan lo gba Fayoṣe lalejo lẹyin ijamba naa, eyi ko di i lọwọ lati ma kopa nibi eto ipolongo ibo oludije fun ipo aarẹ labẹ asia ẹgbẹ́ oṣelu Peoples Democratic Party, PDP, Atiku Abubakar, to waye ni ilu Ibadan, ti i ṣe olu ilu ipinlẹ Ọyọ.
Orí yọ Fayose nínú ìjàmbá ọkọ̀
Buhari àtàwọn aṣòfin àpapọ̀ leè gbéná wojú ara wọn láìpẹ́
Ọ̀rúnmìlà ni ó kọ́kọ́ lo 'Google' láàgbáyé-Ọ̀ọ̀ni Ìlẹ̀ ifẹ̀
Amọ ṣe ẹnu ki i sin lara Fayoṣe, niṣe ni awọn eniyan ti n bu ẹnu ẹ̀tẹ́ lu u fun ọrọ kan to sọ pe aṣeyọri meji ti iṣakoso Aarẹ Muhammadu Buhari labẹ ẹgbẹ́ All Progressives Congress, APC, ko ju pe Naijiria ti di olu ileeṣẹ fun òṣì l'agbaye, ati orilẹede kẹta ti igbesunmọmi ti wọpọ julọ lagbaye.
Ọrọ to sọ yi si tun mu ki ọpọ eniyan sọ oko eebu si ẹgbẹ́ oṣelu PDP, pe ibi ti wọn ba orilẹede Naijiria de naa lo wa bayii.
Ati wi pe Fayoṣe fun ra rẹ ṣe akoba nla fun ipinlẹ Ekiti to dari, to si fi awọn olugbe inu ipinlẹ naa sinu ebi, ìṣẹ́ ati òṣì, nitori iwa ijẹkujẹ rẹ.
Shiite: Ẹgbẹ́ Shiite fẹ́ wọ́de ní ìrántì àwọn ọmọ ẹgbẹ́ wọn ti iléèṣẹ́ ológun Nàìjíríà pa
Oríṣun àwòrán, @imnig_org
Shiite tún fẹ́ fi ẹ̀hónú hàn lórí 'ọ̀pọ̀' ọmọ ẹgbẹ́ wọn ti iléèṣẹ́ ológun Nàìjíríà pa.
Ọkan pataki ninu ẹgbẹ ẹlẹ́sìn Shiite, Abdullahi Mohammed Musa sọ pe wọn ti kọwe pe awọn ajafẹtọ ọmọniyan, to fi mọ awọn kristẹni ati pasitọ, lati darapọ mọ iwọde ti ẹgbẹ naa fẹ ẹ ṣe.
Igbesẹ eyi ni Abdullahi sọ pe oun ni igbagbọ pe yoo yọri, nitori pe awọn pasitọ gan an n ṣe awuyewuye pe eto aabo ko fararọ ni Naijiria.
Lọjọ Ẹti ni awọn ọmọ ẹgbẹ ẹlẹsin Islam Movement of Nigeria, ti awọn eniyan tun mọ si awọn ọmọ ẹgbẹ Shiite, tun fẹ ẹ ṣe iwọde ifẹhonu han miran niluu Abuja, nitori ẹsun ti wọn fi kan an pe awọn ọmọ ogun pa awọn ọmọ ẹgbẹ naa l'oṣu Kẹwa, ọdun 2018.
Akọwe ẹka ikẹkọọ ninu ẹgbẹ naa, Abdullahi Mohammed Musa, sọ fun akọroyin BBC, Onyinye Chime, pe ara ohun ti yoo waye nibi ifẹhonuhan naa ni gbigbe aworan awọn ọmọ ẹgbẹ ti awọn ọmọ ogun Naijiria pa, kaakiri gẹgẹ bi ẹri, nitori ileeṣẹ ogun sọ pe mẹta pere l'awọn pa.
Awọn ọmọ ẹgbẹ Shiite n sọ pe o pe ogoji ọjọ bayii ti awọn ọmọ ileeṣẹ ológun Naijiria ṣekupa àwọn ọmọ ẹgbẹ àwọn to le ni aadọta lasiko ti n fi ẹhonu han lọjọ kẹtadinlọgbọn, to fi mọ ọjọ kọkandinlọgbọn si ọgbọnjọ, oṣu Kẹwa, lori olórí wọn, Ibrahim El Zakzaky ti ijọba fi sahamọ lati ọdun 2015.
Papalolo ní ìlépa owó ni ìyàtọ̀ tó wà láàárín àwọn òṣèré tíátà àtijọ́ àti ìsisìnyí
Igba akọkọ kọ niyii ti awọn ọmọ gbẹ́ naa yoo fẹhonuhan lori bi ijba apapọ ṣe fi olori wn si ahamọ lati ọdun 2015, lẹyin ti ija waye laarin wọn ati awọn ọmọ ologun Naijiria.
Ifẹhonuhan to waye l'oṣu Kẹwaa, ti awọn ọmọ ologun si pa lara wọn.
ICC pari iwadi lori pipa Shiites, IPOB
Ọ̀pọ̀ èèyàn farapa nínú ìwọ́de Shiite
Gbogbo igbesẹ lati ba agbẹnusọ ileesẹ ologun, Ọgagun Kukasheka Usman, sọrọ ni ko so eso rere. O kọ lati gbe ìpè rẹ lẹyin ti oun ati akọroyin BBC kọkọ fi atẹjisẹ ba ara wọn sọrọ lori oun ti o fẹ ba a sọ.
Aisha Buhari: Àwọn alágbára ti já ìjọba gbà mọ́ ọkọ mi lọ́wọ́
Oríṣun àwòrán, @aishambuhari
Aisha Buhari ní ìfẹ́ ìdájọ́ òdodo ti òun ní ló fàá tí òun fi n sọ̀rọ̀ tako ọkọ òun
Aya Aarẹ orilẹede Naijiria, Aisha Buhari, ti gbaju-gbaja ni ọpọ igba, paapa fun sisọ ọrọ to tako ọkọ rẹ, Muhammadu Buhari, iṣakoso rẹ, ati ẹgbẹ oṣelu to gbe e wọle, All Progressives Congress, APC.
Eyi si ti mu ki ọpọlọpọ ọmọ Naijiria maa beere nipa iru ibaṣepọ to wa laarin tọkọ-taya ọhun, tabi iru ọkọ ti Aarẹ Buhari jẹ ninu ile.
Ẹ jẹ ka bojuwo awọn iye igba ti Aisha ti sọrọ nipa ijọba ọkọ rẹ ni sisẹ n tẹle:
Ìfipálówó: Bàbá ọmọ tí wọn gé lórí ní òun rán an láti l gbowó lẹ́nu ATM ni
Igba akọkọ ti Aisha Buhari kọkọ sọrọ to tako iṣakoso ọkọ rẹ, o sọ pe awọn alagbara ti gba iṣakoso mọ ọkọ oun lọwọ.
O sọrọ naa lasiko ifọrọwanilẹnuwo kan to ṣe pẹlu BBC loṣu Kẹwa, 2016.
"O ni pe ""Aarẹ Buhari ko mọ eniyan marundinlogoji ninu aadọta to yan sipo nigba naa, ati pe emi paapa ti mo ti jẹ iyawo rẹ fun ọdun mẹtadinlọgbọn ko mọ wọn."""
Oríṣun àwòrán, @aishambuhari
"Awọn kan joko sinu ile wọn jẹjẹ ni lasiko ta n se wahala eto idibo, ṣugbọn niṣe ni wọn ransẹ pe wọn lati wa jẹ olori ileeṣẹ ijọba tabi di minisita."""
Ṣaaju ki Aisha to sọrọ ni ita gbangba, ni ọpọlọpọ eniyan ti n fi ẹsun kan Aarẹ Muhammadu Buhari pe, ọwọ awọn ìbátan rẹ kan, bi i Mamman Daura, ni iṣakoso orilẹede Naijiria wà.
Ọrọ ti Aisha sọ yii ya ọpọlọpọ eniyan lẹnu pe, o le sọ iru nkan bẹ ẹ tabi bu ẹnu ẹtẹ lu iṣakoso ọkọ rẹ ni gbangba.
"Buhari ni ifesi si ọrọ yii, lasiko to wa ni orilẹede Germany nigba ti iyawo rẹ sọrọ naa, sọ pe ""mi o mọ ẹgbẹ oṣelu ti iyawo mi n ṣe, ṣugbọn ibujoko rẹ n bẹ nile idana mi, to fi mọ iyara igbalejo mi, ati inu yara miran.''"
Igba keji ti Aisha Buhari tun sọrọ lodi si iṣakoso ọkọ rẹ ni ọdun 2017 nigba to sọ pe oun ko ni ṣatilẹyin fun ọkọ oun to ba dije fun saa keji gẹgẹ bi aarẹ l'ọdun 2019.
Ninu ifọrọwanilẹnuwo pẹlu BBC, Aisha sọ pe oun bi oun ṣe n 'fọ aṣọ idọti ọkọ oun ni gbangba' kii ṣe nitori afojudi, ṣugbọn nitori o jẹ otitọ ti oun gbọdọ sọ.
Oríṣun àwòrán, @aishambuhari
Bakan naa lo fi kun un pe ihuwasi oun ko ṣẹyin bi oun ṣe ri wi pe awọn awọn to sun mọ ọkọ oun n lo agbara ti ara ilu gbe e wọ ni ilokulo.
Aisha sọ pe 'ti ọkọ mi ko ba wa atunṣe si awọn kudiẹ-kudiẹ to wa ninu iṣakoso rẹ titi di ọdun 2019, mi o ni jade lọ ba a polongo ibo tabi kesi obinrin kankan lati dibo fun un.
Igba miran tun ni asiko to fi awọn fidio kan sita. Awọn fidio naa safihan awọn sẹnetọ meji kan ti ko gba t'ọkọ rẹ sita loju opo Twitter rẹ.
Awọn sẹnetọ meji naa ni Isah Misau ati Ben Murray-Bruce.
Ninu ọkan ninu awọn fidio naa, Sẹnetọ Misau sọ pe oun ko faramọ bi Aarẹ Muhammadu Buhari ṣe yan ẹni ti m'ọṣẹ si ipo Oludari Agba fun ajọ Ọtẹlẹmuyẹ Naijiria.
Ekeji ti Aisha tun fisita ṣafihanbi Sẹnetọ Ben Bruce ṣe n sọ pe orilẹede Naijiria jẹ ilu ti ko ni ofin ati ilana.
Awọn fidio naa ti Aisha Buhari fi sita fa awuyewuye lori ẹrọ ayelujara, ti ọpọ eniyan si bẹrẹ si ni foju wo o gẹgẹ bi alatako gboogi fun Aarẹ.
Igba miran ti Aisah Buhari tun mi ori ẹrọ ayelujara ni asiko ti o sọrọ tako eto idibo abẹle ẹgbẹ oṣelu APC labẹ iṣakoso Adams Oshiomole.
Ninu atẹjade kan to fi sita, Aisha sọ pe eto idibo naa kun fun fifi ẹtọ ẹni dun ni, pẹlu alaye pe ẹgbẹ yọ orukọ awọn oludije kan to ti ra fọọmu lati dije kuro l'ọjọ idibo.
O sọ pe ẹgbẹ oṣelu APC to n polongo ayipada yẹ ko le fi apẹrẹ rere han.
Sugbọn awọn kan sọ pe o ṣeeṣe ko jẹ pe ara lo n ta Aisha Buhari, nitori pe aburo rẹ kan, Halilu Mahmud kuna ninu idibo abẹle sipo gomina nipinlẹ Adamawa.
Laipẹ yii ni fidio kan tun jade to ṣafihan Aisha Buhari to sọ pe awọn ọkunrin alagbara meji kan lo n dari iṣakoso ọkọ oun.
Aisha sọrọ naa nibi ipade apero kan to waye nilu Abuja pe awọn mejeeji ọhun, to kọ̀ lati darukọ, lo jẹ idiwọ ati idena fun idagbasoke orilẹede Naijiria.
Oríṣun àwòrán, @aishambuhari
Aisha Buhari ní ìfẹ́ ìdájọ́ òdodo ti òun ní ló fàá tí òun fi ṣe bẹ́
Aisha ṣalaye ninu fidio naa pe ''aṣeyọri iṣakoso ọkọ oun ko ba pọ ju boṣe wa lọ, ṣugbọn awọn alagbara mejeeji yii ni igi wọ́rọ́kọ́ to n da ina a ru.''
Ọrọ to sọ yi n fa ariyanjiyan, pẹlu bi awọn kan ṣe n sọ pe o ṣeeṣe ki aarẹ Muhammadu Buhari ma a koju igbelewọn ninu ile gẹgẹ bi ọkọ, bi ko ṣe koju oṣuwọn gẹgẹ bi aarẹ.
Bakan naa ni awọn kan n sọ pe, kii ṣe gbogbo aṣọ lo yẹ ka maa ṣa l'oorun nipa iṣakoso ọkọ gẹgẹ bi aya arẹ.
Ooni Ile Ife: Àwọn ohun tó yẹ kí o mọ̀ nípa Ọ̀ọ̀ni Ilẹ̀ ifẹ̀ to pe Ọdún mẹ́ta lórí ìtẹ́ Òdùduwà
Oríṣun àwòrán, Ooni ile ife
gomina ipin#sun nigba naa, Rauf Arẹgbẹṣọla gbe ọpa aṣẹ funi tuntun nibi ayẹyẹ nla to waye ni gbagede Ẹnuwa ni aafin Oodua ni ilu ile Ifẹ
Ṣaaju ọjọ kejidinlogun oṣu keje ọdun 2015, ko si ẹni to leero pe Adeyẹye Ogunwusi lee gun ori itẹ Oodua gẹgẹ bii Ọọni ile ifẹ nitori bi ọba kan ko ba ku, omiran kii jẹ.
Ọjọ yii gan an ni Ọọni ana, Okunade Ṣijuwade Olubuṣe keji waja ti igbesẹ ati yan Ọọni tuntun bẹrẹ.
Ni ọjọ kẹrindinlọgbọn oṣu kẹwa ọdun 2015 ni awọn afọbajẹ ni Ilẹ Ifẹ kede orukọ Adeyẹye Ẹnitan Ogunwusi gẹgẹ bii Ọmọ oye ti yoo jẹ Ọọni.
Lẹyin ti eto gbogbo to, ọjọ keje oṣu kejila ọdun 2015 ni gomina ipinlẹ Ọṣun nigba naa, Rauf Arẹgbẹṣọla gbe ọpa aṣẹ fun un nibi ayẹyẹ nla to waye ni gbagede Ẹnuwa ni aafin Oodua ni ilu ile Ifẹ.
Lati igba yii wa ni Ọọni Ogunwusi ti bẹrẹ iṣẹ ti gbogbo ọmọ Yoruba ni ilẹ yii ati oke okun si ti n kan saara si.
Oríṣun àwòrán, Ooni ile ife
Ní ọjọ́ kẹrìndínlọ́gbọ̀n oṣù kẹwàá ọdún 2015 ni wọ́n kéde orúkọ rẹ̀ gẹ́gẹ́ bíi ọmọ oyè tí ifá mú
Ohun mẹta ni o farahan ninu awọn ohun ti Ọọni Adeyẹye Ogunwusi Ọjaja II gbajumọ julọ ni
i.Idagbasoke awọn ọdọ
ii.Igbesoke alaafia laaarin awọn lọbalọba ati gbogbo Yoruba lapapọ
iii.Ironilagbara ati idagbasoke ọmọniyan.
Kaakiri agbaye si ni Ọọni ti lọ lati lọ igi ifẹ, iṣọkan ati idagbasoke Yoruba ati gbogbo ọmọniyan ni alọye.
Oríṣun àwòrán, Ooni ife
Ọjọ́ kéje oṣù kéjìlá ọdún 2015 ni Adeyeye Enitan Ogunwusi gba ọ̀pá àṣẹ gẹ́gẹ́ bíi Ọ̀ọ̀ni Ilẹ̀ Ifẹ̀
Awọn orilẹede bii Amẹrika, Gẹẹsi, Brazil, Cuba , Ghana ati bẹẹbẹẹ lọ ni Ọọni Ogunwusi ti de lati kan si awọn ọmọ Yoruba ti wọn gbilẹ kaakiri agbaye.
Adeyẹye ni Ọọni kọkanlelaadọta ti yoo jẹ; bẹẹni onimọ nipa iṣiro owo ti o dantọ si ni.
Ki o to de ori itẹ, o jẹ gbajugbaja oludaṣẹsilẹ ti itan tilẹ fi idi rẹ mulẹ pe ati ilu ẹkọ ni o ti bẹrẹ si ra ọwọ le okoowo ati idaṣẹsilẹ.
Oríṣun àwòrán, Ooni ife
Adeyẹye ni Ọọni kọkanlelaadọta ti yoo jẹ
Ni ọjọ kẹtadinlogun, oṣu kẹwa, ọdun 1974 ni wọn bi Ọọni Ogunwusi ni idile Ọba Giesi ni ile ifẹ. Gbajugbaja agbohunsafẹfẹ ni baba rẹ, Olurọpo.
Gẹgẹ bi itan ṣe sọ, asọtẹlẹ ti wa nipa ibi rẹ ni wọn fi sọọ ni Ẹnitan, baba baba rẹ ni o si sọọ ni Adeyẹye.
Ileewe alakọbẹrẹ Subuola Memorial Nursery and Primary School ati ileewe girama Loyola College ni ilu Ibadan ni o lọ ki o to lọ gba oye ijinlẹ HND ninu imọ iṣiro owo nile ẹkọ gbogbounṣe, the Polytechnic, Ibadan.
Oríṣun àwòrán, Ooni ogunwusi
Orukọ oye ọjaja keji ni Ọọni nlo
Ọọni Derinọla Ọlọgbẹnla ni Ọọni to jẹ kẹyin ni idile Ọba Giesi ni aarin ọdun 1880 si 1894.
Ọọni wa lara awọn ọba ti  aarẹ orilẹede Naijiria ko fi ọrọ rẹ ṣawada rara.
Ko si si ẹni ri ariwisi si iwa ati iṣesi rẹ lawujọ lati igba ti o ti gun ori oye.
Baba Sala: Ẹbí, ọ̀rẹ́, ojúlùmọ̀ péjú láti ṣ'ẹ̀yẹ ìkẹyìn fún Baba Sala nílùú Ilesa
Ayẹyẹ ikẹyin fun Baba Sala
Awọn ebi, ara, ọrẹ ati ojulumọ lo korajọpọ nilu Ileṣa lati ṣe ẹyẹ ikẹhin fun alagba Moses Ọlaiya Adejumọ ti ọpọlọpọ awọn eeyan mọ si Baba Sala.
Ayẹyẹ ikẹyin fun Baba Sala
Ọjọ keje ọṣu kẹẹwa ọdun 2018 ni Baba Sala jade laye lẹni ọdunmọkanlelọgọrin.
Ayẹyẹ ikẹyin fun Baba Sala
Isin idagbere ikẹhin n lọ lọwọ nile ijọsin ti Baba Sala ti jẹ oluṣọ aguntan, 'The Sacred Cherubim & Seraphim Church of Nigeria and Overseas Inc.' to wa nilu Ileṣa.
Ayẹyẹ ikẹyin fun Baba Sala
Ayẹyẹ ikẹyin fun Baba Sala
Lẹhin isin idagbere ni wọn yoo gbe baba Salah wọ kaa ilẹ lọni ilẹ rẹ to n bẹ ni agbegbe Abiọla Avenue nilu Ileṣa.
Ayẹyẹ ikẹyin fun Baba Sala
Daniel Arap Moi: Ọdun 2002 ló yẹ̀bá lórí àlééfà bíi ààrẹ Kenya, tí wọ́n sì ní kò gbọdọ̀ díde mọ́
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Daniel arap Moi jẹ gaba lori eto oṣelu orilẹede Kenya fun bi ọdun mẹẹdọgbọn.
Koda o gbajumọ gẹgẹ bi oloṣelu ju ọga rẹ Jomo Kenyatta gan an lọ, bẹẹ lo si ni awọn alatilẹyin kaakiri orilẹede Kenya.
Ṣugbọn o kuna lati fopin si ijọba amunisin nilẹ naa, koda oun gan an fimu awọn alatako rẹ danrin.
Moi tiẹ gba orukọ inankijẹ ''Ọjọgbọn eto oṣelu'' ṣugbọn ẹsun iwa ajẹbanu ati ọrọ aje to dẹnu kọlẹ ba ijọba rẹ jẹ.
''Eto oṣelu niiṣe pẹlu bibori ati fifidi rẹmi'' - Daniel Arap Moi.
Wọn bi Daniel Arap Moi lọjọ keji oṣu kẹsan an ọdun 1942 si idile agbẹ kan lagbegbe Balingo, lapa iwọ oorun orilẹede Kenya.
Orukọ abisọ rẹ Torotich Arap, ṣugbọn o bẹrẹ sii jẹ Daniel nigba ti o ṣe iribọmi.
Aṣoju
Moi jẹ ọkan lara awọn oloṣelu ti ko wa lati inu ẹya meji to tobi ju- ẹya Kikuyu ati Luo. Ẹya Tugen ni.
O di olukọ ni ile iwe ile ijọba ilẹ Afirika(Government African School) lọdun 1945, ki o to di ọga olukọ lọdun 1946 ni ẹni ọdun mejilelogun.
O pada si Kapsabet ni ọdun 1954 gẹgẹ bi ọga ile iwe, ibẹ lo si wa di ọdun 1957.
Moi ko kopa ninu idojukọ Mau Mau ṣugbọn kaanu awọn ajijagbara ominira lati ilẹ Gẹeṣi
O jẹ ọkan lara awọn eeyan dudu mẹjọ ti wọn dibo yan si ile aṣofin lọdun 1957.
Ni ibẹrẹ ọdun1960, o wa lara awọn aṣoju ilẹ adulawọ ti wọn kọ iwe ofin ilẹ Kenya nibi apero nilu London lọdun 1960
''Ti wọn ba fiya jẹ wọn, ki lode ti wọn ṣe lọ sile ẹjọ?'' Daniel Arap Moi lo sọrọ yii fun BBC lẹyin ẹsun pe ijọba n fiya jẹ awọn ẹgbẹ alatako.
Moi di minisita fun eto ẹkọ lọdun 1961, o si tun jẹ minisita fun ijọba ibilẹ.
Eto aabo orilẹede
Nigba tirẹ, Moi kopa ninu oriṣiiriṣii apẹro ti wọn fi ṣe igaradi fun ominira orilẹede Kenya. Bẹẹ wọn si rii pe ijọba apapọ ti yoo fun awọn eeyan lagbara ati aabo fun ẹya kekeke.
Kenyatta jẹ Olootu ijọba nigba ti Kenya gbominira lọdun 1963, ti Moi si jẹ minisita fun eto ọgbin.
Alabaṣiṣẹ pọ pẹlu ni Moi pẹlu Jomo Kenyatta
Lọdun keji, Kenyatta di aarẹ, bẹẹ ni wọn bura fun Moi gẹgẹ bi minisita fun ọrọ abẹle.
Lọdun 1867 ninu oṣu kinni, Moi di igakeji aarẹ orilẹede kenya ati igbakeji ẹgbẹ ajajagbara aṣofin Kanu.
''Nilẹ alawọdudu gbogbo eeyan la fẹran to fi mọ awọn otosi.''- Daniel Arap Moi
Awọn ẹka tuntun
Nigba ti Kenyatta ku lọdun 1978, Moi di aarẹ fidihẹ.
Ninu oṣu kẹwaa, wọn dibo yan an gẹgẹ bi olori ẹgbẹ oṣelu kan ṣoṣo to wa lorilẹede Kenya, bẹẹ lo si di aarẹ keji ilẹ Kenya.
Loṣu kọkanla, o ṣe atunto ijọba rẹ ati awọn to yab si po gbogbo.
Oríṣun àwòrán, PA
Ọmọbabinrin Ilẹ Gẹẹsi nigba to ṣabẹwo si Kenya lọdun 1983
Awọn ẹka ijọba tuntun bi ẹka alumọni ati ayika bẹrẹ, ti ẹka eto ọgbin ṣi di pinpin.
Awọn ologun fẹ gbajọba lọdun 1982, ṣugbọn ko ṣeeṣe fun wọn.
''Awọn ara ilẹ Kenya ti fihan pe Afirika le sẹto ijọba ara wọn laisi idiwọ.''- Daniel atap Moi.
Ninu oṣu kan naa, aarẹ tu awọn ologun ti wọn gbimọ lati gbajọba rẹ ka.
Iṣẹlẹ iditẹ gbajọba lo fun Moi lanfani lati jẹ ki agbara rẹ pọ si nipa lile awọn to fẹ gbajọba danu. Bakan naa, lo ṣe ayipada iwe ofin ilẹ Kenya lati faye gba ẹgbẹ oṣelu kan ṣoṣo
Gbogbo awọn alatako rẹ papa lo bori
Iye awọn to ṣẹwọn mitori oṣelu pọ si, bẹẹ ni Moi gbe igbesẹ lati din ominira awọn oniroyin ku.
Laarin ọdun 1990 ati 1999, ọpọlọpọ lati apa Rift Valley lo le danu, bakan ọpọ eeyan niroyin sọ pe wọn padanu ẹmi wọn ninu ija ẹlẹyamọnya.
''Mi o ṣetan lati dari orilẹede ọmuti.''- Daniel arap Moi
Moi gbe osẹlu ẹlẹgbẹjẹgbẹ pada, o si tun wọle lọdun 1992 ati 1997.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ẹsun nla kan ti wọn kan an ṣẹlẹ lọdun 1992.
Ẹsun ijale igba meji owo ti ijọba rẹ san bi owo ajẹmọnu fun ile isẹ Goldenberg lati polowo goolu ati okuta iyebiye orilẹede Kenya.
Lẹyin ọdun mẹrinla ni wọn fi ẹsun jibiti kan alakoso ile iṣẹ ọhun, akọwe agba ile ifowopamọ ati igbakeji oludari banki itẹwo.
Iwadi sọ pe aarẹ Moi mọ nipa iwa jibiti naa, ṣugbọn o ni ko si ohun to jọ bẹ, wọn o si gbe lọ sile ẹjọ.
Ninu idibo gbogbogbo lọdun 2002 ti wọn fofin de Moi, ọpọ lo fi ṣẹlẹya ti wọn si lẹ amọ mọ ọkọ rẹ.
Ẹgbẹ osẹlu rẹ Kanu fidi rẹmi. Koda ninu ayẹyẹ to fi gbejọba fun Mwai Kibaki, awọn eeyan yẹyẹ rẹ.
Lọdun 2007, Aarẹ Kibaki yab an aṣoju si orilẹede Sudan nitori iriri rẹ ati imọ rẹ nipa ọrọ ilẹ Afirika
Moi gbe igb aye rẹ to ku ninu ifẹyin ti, ti ko si dasi eto oṣelu kankan mọ.
MMA: ilé Epo Forte oil gbiná súkẹ́rẹ́-fàkẹrẹ ọkọ̀ ti bẹ̀rẹ̀
Oríṣun àwòrán, LASEMA
Ilé epo gbaná ní pápákọ̀ òfurufú MMA
Ilé epo Forte Oil tó wà ní abáwole pápákọ̀ òfurufú Muritala Muhammed tó wà ní Ikẹ̀ja ló dédé gbaná lọ́sàn òní.
Lásìkò tí ìròyìn yìí tẹ̀ wá lọ́wọ́ ohun tó fa iná ọ̀hún kò sí ẹni tó lè sọ, bótilẹ̀ jẹ́ pé àwọn panápaná tí ṣe akìtiyan bí wọn o ṣe paá.
'Ologun ko lee koju Boko Haram'
Wọn nwa awọn ọmọde ninu isẹlẹ ina Russia
Ina jo ọja binukonu lọjọta
Agbenusọ ilé iṣẹ́ panápaná ìpínlẹ̀ Eko Amodu Shaikiru tó bá BBC sọ̀rọ̀ sàlàyé pé àwọn ò ti le fídi ohun to fa ina náà múlẹ̀ sùgbọn àwọn sì ń gbìyànjú láti pána báyìí.
Oríṣun àwòrán, LASEMA
MMA: ilé Epo Forte oil gbiná súkẹ́rẹ́-fàkẹrẹ ọkọ̀ ti bẹ̀rẹ̀
Ọ̀kan nínú àwọn òṣìṣẹ́ pápákọ̀ òfurufú náà sàlàyé pé ìjàmbá náà kò bá burú jáì bíkò ṣe ìgbéṣẹ̀ àwọn pánápána tó wà ní pápákọ̀ òfurufú.
'' Àwọn òṣìṣẹ́ FAAN ló kọ́kọ́ jígìrì sí iṣẹ́ náà láàrín ìṣẹ́jú mẹ́jọ tó bẹ̀rẹ̀ tí wọn sì gbìyànjú láti ma jẹ kí ó ràn mọ àwọn ilé míràn tó wà ní àyíká.
ìròyìn tó tẹ BBC lọ́wọ́ fi yé ni pé súkẹrẹ fàkẹrẹ ọkọ̀ tí gbàlú kan láwọn agbègbè tó gba ọ̀nà náà kọjá
Ijora-Wharf bridge: Ìjọba àpapọ̀ ṣí afárá Ijora-Wharf lẹ́yìn àtúnṣe
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ìjọba àpapọ̀ ti afárá náà ní oṣù díẹ̀ sẹ́yìn fún àtúnṣe lórí àwọn kọnkéré orí afárá ọ̀hún
Lẹyin ọpọlọpọ oṣu ti o ti wa ni titi pa, Ijọba apapọ ti ṣi afara ọkọ Ijora-Wharf ni apapọ fun lilọ bibọ ọkọ.
Ijọba ti afara naa pa fun atunṣe lati fi awọn kọnkere miran rọpọ awọn ti o ti dibajẹ lori afara naa.
Nigba ti wọn ti afara naa pa fun atunṣe, minisita funina ọba, iṣẹ ode ati ipese ile lorilẹede Naijiria, babatunde Faṣola ni igbesẹ to le pupọ lati gbe ni igbesẹ naa, ṣugbọn ko ṣee ma gbe ni nitori ati daabo bo ọpọ ẹmi.
Minisita Faṣọla ni ko tii si atunṣe kan ti o waye lori afara naa lati ogoji ọdun sẹyin ti wọn ti kọọ.
Ǹjẹ́ o mọ pàtàkì igi tó wà ní àyíká rẹ bí?
Pẹlu ṣiṣi afara naa, adinku yoo ba sunkẹrẹ-fakẹrẹ ọkọ ti o rin ni ilu Eko.
Bakan naa lo ṣalaye pe pupọ awọn afara kaakiri orilẹede Naijiria naa ni wọn ṣi nile irufẹ amojuto bayii nitori ailakasi awọn ijọba ti o ti jẹ kọja lorilẹede Naijiria.
Electoral bill 2018: Ní ìgbà wo gan an ni àbádòfin ìdìbò tuntun yóò di òfin?
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Fún ìgbà kẹta, Ààrẹ Buhari tún ti dá àbádòfin ìdìbò tuntun padà f'áwọn aṣòfin àpapọ̀
Aarẹ Muhammadu Buhari ti da abadofin ilana idibo 2018 pada fawọn aṣofin apapọ pẹlu idi pe idibo apapọ ti wọle de, bibuwọlu abadofin naa si lee da nnkan ru
Igba kẹta niyi ti aarẹ yoo maa da abadofin yii pada nitori idi kan tabi omiran.
Aarẹ Buhari fi iwe naa ranṣẹ pada sawọn aṣofin pẹlu lẹta kan eyi to kọ siwọn, ninu rẹ ni o si ti mẹnu ba, bi abadofin naa ṣe lee da edeaiyede silẹ lori ilana fun titẹle lori idibo apapọ ti yoo waye lọdun 2019.
Aarẹ ni ki awọn aṣofin wulẹ sinmi naa di igba ti eto idibo apapọ ba pari ati pe abadofin ilana idibo tuntun naa ki wọn jẹ ki o jẹ eyi ti yoo bẹrẹ iṣẹ lẹyin idibo apapọ ọdun 2019.
Buhari tun tọka si awọn-abala mẹrin miran ninu abadofin naa ti o fẹ ki awọn aṣofin apapọ o tun ṣe.
Amọṣa, awọn eekan ilu ati ẹgbẹ alatako gbogbo ti n bu ẹnu atẹ lu igbesẹ arẹ yii eleyi ti awọn kan ni o ku diẹ fun idagbasoke eto iṣejọba awarawa lorilẹede Naijiria.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Kikuna Buhari lati buwọlu abadofin ilana eto idibo naa ti n da awuyewuye silẹ lagbo oṣelu ni Naijiria
Ajọ Agbarijọpọ  ẹgbẹ oṣelu lorilẹede Naijiria, CNPP ni aibuwọlu abadofin naa ṣaaju eto idibo apaps ọdun 2019 yoo ni ipa.
Akọwe agba fun ajs naa, Willy Ezugwu ni 'awọn alagbara kan ti wọn ko fẹran iṣejọba tiwantiwa ni wọn fẹ fi tipa tikuuku bu omi pa ina bibuwọlu abadofin ilana eto idibo naa.'
"Bakan naa, ọkan pataki lara awọn sẹnetọ ọmọ ẹgbẹ oṣelu APC tẹlẹ ki o to lọ darapọ mọ ẹgbẹ oṣelu miran, Sẹnetọ Sani Shehu ni 'awọn alatako ijọba awarawa lawọn ti o n tako abadofin naa"""
Bawo ni awọn ti a gbe agbara fun ṣe lee pẹyinda lati ta kẹkẹ to gbe wọn de ipo ni ipa?
"Ninu atẹjade kan ti alukoro rẹ fi sita, ẹgbẹ oṣelu PDP ni ""ẹru abajade idibo 2019 to n ba aarẹ Buhari ni ko jẹ ki o fẹ buwọlu abadofin yii nitori yoo wa ọwọ igbimọ ati ṣe eru ibo wọlẹ."""
Ṣugbọn pẹlu bi ọrs ti ṣe ri yii, awọn onimọ ti n pe fun awọn aṣofin apapọ lati lo agbara aṣẹ waa ti ofin orilẹede yii fun wọn lati fi gbọwọle abadofin naa.
Bakan naa ni ẹgbẹ oṣelu PDP gan ti fọwọ si igbesẹ bẹẹ.
Aṣofin Malachi Ugumadu ti o jẹ alaga ajọ ti o n ja fun ẹtọ araalu, CDHR lorilẹede Naijiria ṣalaye pe irufẹ iṣẹlẹ bayii ti waye ri ni ọdun 2006 ṣugbọn ti awọn aṣofin apapọ lo agbara aṣẹ waa lati buwọlu iwe abadofin naa funra wọn.
Amofin Malachi Ugumadu ni bi aarẹ ba kuna lati ṣe ohun ti o tọ, ki awọn asofin tẹ siwaju lati fi aṣẹ waa wọn gbe ofin naa wọle.
Ogun PDP; Wàhálà tó n wáyé lórí ẹni tí yóò dúpò gómìnà kò tí ì d'ópin
Oríṣun àwòrán, FACEBOOK/Senator-Buruji-Kashamu
Lẹyin eto idibo abẹle PDP, ni Adeleke Shittu gba lati jẹ ki Buruji Kashamu di oludije ẹgbẹ.
Ede aiyede to n waye lori ẹni ti yoo dije fun ipo gomina labẹ asia ẹgbẹ oṣelu Peoples Democratic Party, PDP, ni ipinlẹ Ogun ko ti i dabi ẹni pe yoo dopin laipẹ.
Eyi ribẹ nitori bi Alaga ẹgbẹ naa, Ọmọọba Uche Secondus, ṣe gbe asia ẹgbẹ naa fun Họnọrebu Ọladipupọ Ọlatunde Adebutu gẹgẹ bi oludije ẹgbẹ naa, l'olu ile ẹgbẹ PDP to wa ni Abuja.
Lati igba ti eto idibo abẹle ẹgbẹ naa ti waye l'oṣu Kẹsan an, nitori idibo abẹle ọna meji to waye.
Igun akọkọ to jẹ ti Sikirullahi Ogundele, eyi ti awọn adari ẹgbẹ faramọ dibo yan Ladi Adebutu gẹgẹ bi oludije, nigba ti igun ti Adebayọ Dayọ n dari yan Adeleke Shittu ni oludije ti wọn.
Oríṣun àwòrán, Facebook/LadiAdebutu
Igun akọkọ to jẹ ti Sikirullahi Ogundele, eyi ti awọn adari ẹgbẹ faramọ dibo yan Ladi Adebutu gẹgẹ bi oludije
Lẹyin eto idibo naa ni Adeleke Shittu gba lati jẹ ki Sẹnetọ to n ṣoju ẹkùn idibo Ila Oorun Ogun, Buruji Kashamu di oludije ẹgbẹ.
Lori igbesẹ ti Secondus gbe yii, amugbalẹgbẹ fun Kashamu lori eto iroyin, Austin Oniyokor sọ fun akọroyin BBC Yoruba, Yẹmisi Oyedepo, pe Buruji Kashamu ni ajọ eleto idibo INEC da mọ gẹgẹ bi oludije fun ipo gomina ẹgbẹ PDP nipinlẹ Ogun.
Oríṣun àwòrán, Facebook
Igun to daramọ Buruji Kashamu naa ti mu ọjọ ti wọn yoo gbe asia ẹgbẹ́ fun un.
"Ati wi pe ""wọn gbe asia ẹgbẹ fun ko sọ pe oun ni oludije. Asọ lasan ni wọn gbe fun, tori ofin ko da a mọ."
"To ba wa a ṣeeṣe fun lati mu asọ naa lọ si ọdọ INEC lati sọ ọ di oludije tabi ile ẹjọ, ki wọn sọ ọ di tikẹẹti oludije fun."""
Kíni ìdí tí Ààrẹ Buhari kò fi buwọ́lu àbádòfin ìdìbò tuntun?
Saheed Oṣupa, Taye Currency sọ ibùdó ìpolongo ìdìbò Atiku di ibi àríyá
Nigba ta a bi boya ede aiyede wa ninu ẹgbẹ PDP l'Ogun, o sọ pe awọn kan ninu ẹgbẹ  l'Abuja lo to ro pe awọn tobi ju ofin lọ, ohun lo mu wọn ti wọn fi n gbe igbesẹ to tako ofin.
"Ajọ INEC paapa ti sọ pe asẹ ti ile ẹjọ pa pe ipade ita gbangba ti Onimọ Ẹrọ Adebayọ Dayọ ṣe ni awọn faramọ. Wọn ko gba tikẹẹti lọwọ ẹni kan fun ẹnikan.
Pe awọn eniyan n dibo fun ẹgbẹ, eyi ko tumọ si pe ẹgbẹ gbọdọ maa ṣe nkan ti ko tọ ọ. Ẹgbẹ PDP l'Ogun lodi sofin lo fa gbogbo wahala yii, lẹyin idajọ ile ẹjọ.
Aminat Abiodun: Òun ni Iyalode kẹtàlá, tó sì ń gun àkàsọ̀ láti ọdun 1971
Oríṣun àwòrán, Kola Carew
Oloye Aminat Abiọdun ti wa saye, to si ti di ero ọrun bayii, amọ o yẹ ka mọ iru eeyan ti obinrin takun-takun yii jẹ nigba aye rẹ.
Akọkọ, odun ni iyalode taa ba n sọrọ eto oselu, kii se aimọ fun oloko awọn oloselu, tori pe o jẹ ọkan gboogi lara awọn to lẹnu lori bi eto oṣelu ṣe n lọ nipinlẹ Ọyọ.
Gẹgẹ bi iyalode, oun ni oloye Obinrin ti o ga julọ ni igbimọ lọbalọba ilẹ Ibadan ni igba aye rẹ.
Adebisi Idikan: Òun ló gba Ìbàdàn sílẹ̀ lọ́wọ́ ìyà owó orí sísan
Awọn kan ti ẹ maa n pe Iyalode Aminat Abiọdun ni Ọbabinrin ilẹ Ibadan.
Ati owo, ọrọ ati agbara ni Iyalode ilẹ Ibadan fi ṣ'ọla., to si ri aye gbe ko to jẹ Ọlọrun nipe lọjọ ogbo rẹ.
Gẹgẹ bi Iyalode, o jẹ aṣoju awọn obinrin ninu igbimọ Olubadan.
Aminat Abiọdun ni iyalode kẹtala ti o jẹ ni ilẹ Ibadan. O si bẹrẹ si ni i gun akasọ oye l'ọdun 1971.
Oríṣun àwòrán, Olatunji Babatunde
Gẹgẹ bi iyalode, ohun ni oloye Obinrin ti o ga julọ ni igbimọ lọbalọba ilẹ Ibadan
O bẹrẹ lati ori oye Jagun Iyalode, ko to o di pe o jẹ oye Iyalode lọdun kẹrindinnlọgbọn to bẹrẹ ọrọ oye ìlú.
Ni ọdun 2007 ni Alhaja Aminat Abiọdun gun ori oye iyalode ilẹ Ibadan, lẹyin iku Iyalode to gbesẹ, Oloye Wuraọla Akintọla.
Gbajugbaja oniṣowo pataki ni Iyalode Abiodun nigba aye yẹ.
Alagbara ati ajafẹtọ araalu ni gẹgẹ bii awọn aṣiwaju rẹ bi Iyalode Ẹfunṣetan Aniwura ati Humani Alaga.
Ko si si ibi ti o lọ ti kiiṣe ari-ma-lee-lọ awo pada sẹyin ni wọn n woo nitori ẹwa rẹ.
Ọjọ Abamẹta, ọjọ kẹjọ, oṣu Kejila, ọdun 2018 ni Iyalode ilu Ibadan, Oloye Aminat Abiọdun jade laye.
Iroyin ti o tẹ BBC News Yoruba lọwọ ṣalaye pe ni owurọ ọjọ naa ni Iyalode Abiọdun ju awa silẹ.
Gẹgẹ bii iroyin ti o tẹ BBC News Yoruba lọwọ ṣe sọ, ni ọjọ aiku ni wọn yoo sin oku Iyalode Ilẹ Ibadan, Aminat Abiọdun ni ilana ẹsin Musulumi
Papalolo ní ìlépa owó ni ìyàtọ̀ tó wà láàárín àwọn òṣèré tíátà àtijọ́ àti ìsisìnyí
Iléesẹ́ ológun: Amẹrika, Italy ń tìwá lẹ́yìn láti sẹ́gun Boko Haram
Oríṣun àwòrán, @NigeriaAirforce
Olori ileesẹ ologun ofurufu nilẹ Naijiria, Ọgagun Sadique Abubakar ti kede pe oun ti digba dagbọn lọ fi ijoko si ẹkun ila oorun ati iwọ oorun ariwa Naijiria, gẹgẹ bi asẹ ti aarẹ orilẹede yii, Muhammadu Buhari pa.
Ilu Kano ni Abubakar ti sisọ loju ọrọ yii pẹlu afikun pe ileesọ ologun ofurufu ilẹ yii tun n reti baalu mejila miran lati orilẹede Amẹrika yatọ si baalu mejidinlogun ti ijọba apapọ ra fun ileesẹ naa.
Abubakar ni orilẹede Italy ati Amẹrika ko da awọn da ogun ti awọn n gbe ti Boko Haram, ti wọn si n se atilẹyin alailẹgbẹ fun wọn loore koore.
'Kékeré ni mo ti mọ̀ pé iṣẹ́ apanilẹ́ẹ̀rín l'ọ̀nà mi'
Ijọba apapọ naa ko kawọ gbera lori ọsẹ ti Boko Haram n se, tori o ti se atunto ileesẹ ologun ofurufu, ti ko si si idi kankan fawọn ọmọ ogun ofurufu lati mase run tapa titan wọn si ogun Boko Haram."""
Olori ilees ọmọ ogun ofurufu tun fikun pe orilẹede Italy naa yoo fi baalu ijagun kekere mẹfa ransẹ sawọn laipẹ.
Oríṣun àwòrán, @NigeriaAirforce
Ko sai waa rọ awọn eeyan to ri jajẹ sẹku lawujọ, lati dide se atilẹyin tiwọn naa fun awọn ẹka ileesẹ ologun ilẹ wa, ki ogun Boko Haram lee di afiẹyin, ti eegun n fi asọ.
PDP: Bí ìjọba Buhari se gbẹ́sẹ̀ lé owó Peter Obi, aya àti ẹ̀bí rẹ̀ kò bójúmu
Oríṣun àwòrán, @PeterObi
Ẹgbẹ oselu alatako nilẹ Naijiria, PDP, ti n naka aleebu si ijọba apapọ orilẹede yii labẹ aarẹ Muhammadu Buhari pe , o ti gbẹsẹ le apo asunwọn owo oludije fun ipo igbakeji aarẹ ninu ẹgbẹ oselu naa, Peter Obi.
PDP ni igbesẹ yii lo tẹle oniruuru iwa idunkoko mọ ni ati tita abuku ẹni loju aye, eyi ti wọn n se sawọn ẹbi, ọmọ ati Peter Obi gan funra rẹ, to fi mọ awọn alatilẹyin ẹgbẹ oselu PDP.
Atẹjade kan ti agbẹnusọ fẹgbẹ oselu PDP, Kọla Ọlọgbọndiyan fisita lo naka aleebu yii, pẹlu afikun pe gbogbo okoowo awọn ẹbi ati iyawo Peter Obi lawọn ileesẹ to n gbogun tiwa ajbanu ti gbẹsẹ le.
'Kékeré ni mo ti mọ̀ pé iṣẹ́ apanilẹ́ẹ̀rín l'ọ̀nà mi'
Sugbọn ileesẹ ICPC ati EFCC ti wọn gbogun tiwa ajẹbanu nilẹ yii, ti sẹ lori ẹsun naa, ti wọn si na ọwọ wọn soke pe, funfun nẹnẹ ni.
Olori ẹka to wa fun eto iroyin ati ipolongo labẹ ajọ EFCC, Tony Orilade ni ki ẹnikẹni mase lọgun ọran nibi ti ko si.
lootọ ni ẹsun naa fẹ jọ mọ wa niwọn igba to jẹ pe ojuse wa ni lati tanna wadi ẹsun iwa ijẹkujẹ, amọ lori isẹlẹ gbigbe ẹsẹ le apo asunwọn owo Peter Obi, a ko mọ ohunkohun nipa rẹ, bẹẹ ni PDP gan ko darukọ ileesẹ wa nidi isẹlẹ yii.
Oríṣun àwòrán, @PeterObi
EFCC ni ileesẹ to n bọwọ fun ofin ni oun, to si n tẹle ilana ti ofin la kalẹ lati sisẹ rẹ, bẹẹ ni a ko ni tẹti nidi fifọ ilẹ Naijiria mọ lọwọ iwa ijẹkujẹ.
Rasheedat Okoduwa, toun naa jẹ agbẹnusọ fun ICPC ni ileesẹ naa ko mọwọ mẹsẹ nidi fifi ofin de apo asunwọn owo Peter Obi ati tawọn mọlẹbi rẹ.
Saaju ni agbẹnusọ fun Peter Obi, Valentine Obinyem ti fidi rẹ mulẹ pe, lootọ ni awọn ajọ to n gbogun ti iwa ijẹkujẹ ni Naijiria gbẹsẹ le awọn apo asunwọn owo Peter Obi, sugbọn ọrọ naa ko mi oludije fun ipo igbakeji aarẹ ninu ẹgbẹ oselu PDP lọkan nitori pe ko lẹb lẹru rara.
Adeboye: Màá fi ọlọ́pàá gbé ẹni tó bá lo fọ́tò mí sára kàlẹ́ńdà
Oríṣun àwòrán, @rcgchristchurch
Olusọagutan Adejare Adeboye ti n fi ewe ọmọ mọ awọn ọmọlẹyin ijọ Redeem lagbaye pe ki wọn pinwọ iwa fifi aworan oun ati aya oun sara awọn ẹbun ti wọn ba n pin.
Adeboye ni eniyan lasan ni oun, oun kii si se Ọlọrun rara.
Lasiko to n kasẹ isin ipagọ ẹmi mimọ ọlọdọọdun ijọ Redeem nilẹ, ni Adeboye sisọ loju ọrọ yii pẹlu afikun pe awọn ọmọ ijọ naa kan tun maa n lo aworan iyawo oun sara ẹbun pẹlu.
'Kékeré ni mo ti mọ̀ pé iṣẹ́ apanilẹ́ẹ̀rín l'ọ̀nà mi'
Emi kii se Ọlọrun. Ẹ ye ri mi tabi fi mi we Oluwa rara nitori eniyan ẹlẹran ara ni mi, ẹ ye fi aworan mi ati ti aya mi sara awọn eroja kankan.
Adeboye fikun pe oun ko f ri ibinu Ọlọrun, yoo si dara kawọn eeyan naa ma mu oun kọsẹ niwaju Ọlọrun pẹlu aworan oun ti wọn fi n pe Ọlọrun yii.
Oríṣun àwòrán, @rcgchristchurch
O ti de si etigbọ̀ mi bayii pe awọn eeyan kan n lo fọto mi lara kalẹnda, iwe, ẹbun tẹ n pin ati ‘keyholder’. Eyi ko tọna rara, ma si fi ọlọpaa mu ẹnikẹni ti ọwọ ba tẹ pe o n se bẹẹ.
Eniyan Ọlọrun lasan ni mi, emi kii se Ọlọrun, Ọlọrun ko ni ba eniyan kankan pin ninu ogo rẹ, emi ko si setan lati ku, Esu, emi ko setan lati ku o
Aminat Abiọdun: Ọjọ́ Satide ni Iyalode kí ayé pé ó dìgbóṣe
Òní ní ìṣìnkú ìyálódé Ibadan
Eto ti n lọ lọwọ ni igbaradi fun isinku Iyalode ilẹ Ibadan, Alhaja Aminat Abiodun ẹni to jade laye lọwurọ ọjọ ẹti l'ẹni ọdun mẹtalelaadọrun.
'Kékeré ni mo ti mọ̀ pé iṣẹ́ apanilẹ́ẹ̀rín l'ọ̀nà mi'
Akanṣe adura yoo waye fun oloogbe ni aago mẹrin irọlẹ oni tii ṣe ọjọ Aiku, ninu ọgba ile iṣẹ tẹlifisan ipinlẹ Ọyọ, (BCOS) to n bẹ ni agbegbe Baṣọrun nilu Ibadan.
Akanse adura naa yoo waye saaju eto isinku nile oloogbe to kalẹ si Oluwo Nla ni agbegbe Baṣọrun nilu Ibadan.
Ìyálóde Ìbàdán: Ètò tí bẹ̀rẹ̀ ní perewu fún ìsìnkú
Awọn asiwaju ẹsin, aṣoju ijọba, oniṣe ọwọ, oniṣowo ati awọn ẹgbẹ awujọ ni ireti wa wipe wọn yoo peju pesẹ lati ṣe ẹyẹ ikẹhin fun Iyalode ilẹ Ibadan.
Òní ní ìṣìnkú ìyálódé Ibadan
Saraki: PDP yóò mókè ní Kwara, yóò tún gba ipò ààrẹ
Oríṣun àwòrán, @bukolasaraki
Aarẹ ile asofin agba, Dokita Bukọla Saraki ti fọwọ gbaya pe fawọn alatilẹyin ẹgbẹ oselu PDP pe didun lọsan yoo so fun ẹgbẹ oselu naa ninu idibo ọdun 2019.
Bakan naa lo rọ wọn lati mase naani agbara ijọba apapọ to wa labẹ ẹgbẹ oselu to n se ijọba orilẹede yii lọwọ.
Bukọla Saraki fọwọ idaniloju yii sọya lasiko to n sefilọlẹ igbimọ eleto ipolongo fẹgbẹ PDP, ẹlẹni mejilelogoji, eyi to waye nilu Ilọrin.
Ìfipálówó: Bàbá ọmọ tí wọn gé lórí ní òun rán an láti l gbowó lẹ́nu ATM ni
Saraki fi kun pe ẹgb oselu PDP ni awọn amuy to y lati ẹyin ẹgbẹ APC to n sejọba lọwọ janl ninu ibo to n bọ.
Ẹyin ololufẹ PDP, ẹ ko gbọdọ bẹru nipa agbara ijọba apapọ ninu ibo to n bọ, mo ti koju wọn agbara ijba apapọ ni ẹẹmeji ọtọọtọ ri, ti mo si fẹyin wọn janlẹ.
Oríṣun àwòrán, @bukolasaraki
Aarẹ ile asofin agba tun tọkasi pe, ibo 2019 ni awọn ipenija tiẹ lootọ, gẹgẹ bii awọn eto idibo yoku, amọ o ni iriri atẹyinwa ti fi han pe, tawọn ba gbe igbesẹ to tọ, tawọn si rin bo se yẹ, kedere lẹgbẹ oselu PDP yoo moke lọdun 2019.
O tẹsiwaju pe, yatọ si pe PDP yoo bori ni ipinlẹ Kwara, yoo tun moke ninu ibo aarẹ pẹlu.
Obasanjo: Ìdùnnú ọmọ Nàìjíríà ló jẹ́ mí lógún ní 2019
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ọ̀pọ̀ igbà ni Olúsẹ́gun Ọbásanjọ́ ti sọ̀rọ̀ àbùkù sí ìjọba Muhammadu Bùhárí
Aarẹ nigba kan fun Naijiria, Oloye Oluṣẹgun Ọbasanjọ ti sọ pe, ko si ọrọ ko gbona ko tutu lori ibi ti oun fi si lori eto idibo ọdun 2019.
Ọbasanjọ, ninu atẹjade kan ti oluranlọwọ rẹ lori eto iroyin, Kẹhinde Akinyẹmi fi sita sọ pe, Ọbasanjọ sọ ọrọ naa nibi ipatẹ ọja ilẹ Afrika to waye fun igba akọkọ nilu Cairo l'orilẹede Egypt,.
Ọbasanjọ ṣalaye pe oun tako ohun ti awọn ileeṣẹ iroyin kan fi sita nipa ọrọ ti oun sọ nibi ipade awọn ọmọ bibi ilẹ Owu, to waye nilu Iwo nipinlẹ Ọṣun laipẹ yii.
Ìfipálówó: Bàbá ọmọ tí wọn gé lórí ní òun rán an láti l gbowó lẹ́nu ATM ni
"O ni pe 'botilẹ jẹ wi pe oun ko ni gbe oludije kan le wọn lori, imọran ti oun yoo gba awọn ọmọ Naijiria ni pe, ẹni ti yoo mu idagbasoke ati ayipada ba igbe aye wọn ju boṣe wa bayii lọ, ni ki wọn dibo fun."""
Kẹhinde sọ pe, ọrọ ti Ọbasanjọ sọ yii ko tumọ si pe ko mọ iha ẹni to wa, bi ko ṣe pe 'ọdẹ tabi omugọ eniyan nikan ni ko ni mọ ibi to n lọ lasiko ti aijafafa, iwa ibajẹ, ailafojusun, aibọwọ f'ofin ati ṣiṣe ègbè n ba orilẹede rẹ jẹ.''
Ọbasanjọ, to ti fi atilẹyin rẹ han fun oludije fẹgbẹ́ oṣelu Peoples Democratic Party, PDP, Atiku Abubakar sọ pe, ohun ti yoo ṣe awọn ọmọ Naijiria ni anfaani ni oun faramọ.
"O si daju wi pe bi iṣakoso Naijiria ṣe n lọ bayii kii ṣe oun to ṣanfaani fun awọn ọmọ Naijiria.''
Oríṣun àwòrán, @Atiku
Ọbasanjọ ti sọ tẹlẹ pe oun le fi Atiku yangan pe yoo sisẹ pẹlu ọ̀wọ̀ àti ìrẹ̀lẹ̀
Aarẹ nigba kan ri ọhun sọ pe, oun rọ awọn ọmọ Naijiria to ti ṣe sababi ohun to n bẹ nita lasiko yii, lati bọ sita, ki wọn si wa ayipada ti yoo ṣe wọn loore.
''Ṣugbọn ayipada yii ko le waye bi wọn ko ba ṣe n kankan, ti wọn si gba ki awọn ọta Naijiria maa tan wọn.
Ati pe bi wọn ko ba wa ayipada si iṣakoso to wa lasiko yii, ohun ti yoo ṣẹlẹ si Naijiria si lẹyin rẹ yoo buru ju boṣe wa lọ."
Ilé asòfin àpàpọ̀: Owó osù amúgbálẹ́gbẹ̀ẹ́ aṣòfin kan dín ní ₦150k sí ₦250k
Oríṣun àwòrán, NGRSenate
Awọn amugbalẹgbẹ naa ni awọn akọsilẹ kan fihan pe wọn jẹ ẹgbẹrun meji ati ẹẹdẹgbẹta le aadọrin niye.
Laipẹ yii ni awọn amugbalẹgbẹ fun awọn aṣofin agba lorilẹede Naijiria fi ẹhonu han, ti wọn si ṣe iwọde pe awọn aṣofin naa ko san owo oṣu ati ajẹmọnu fun awọn.
Igba akọkọ si kọ niyii ti awọn amugbalẹgbẹ f'awọn aṣofin apapọ to wa niṣakoso lọwọlọwọ, yoo fẹhonu han lori airowo oṣu gba.
Awọn aṣofin naa ti sọrọ pe, awọn ko mọ nkankan nipa rẹ, nitori pe igbimọ to wa fun amojuto ile aṣofin mejeeji lo wa nidi owo oṣu sisan.
Amọ alaye yii ko da awọn amugbalẹgbẹ naa duro lati fi ẹsun kàn pe, aarẹ ile aṣofin agba, abẹnugan ile aṣofin kekere, atawọn mi n dari owó awọn gba ibomi i lọ.
Ìfipálówó: Bàbá ọmọ tí wọn gé lórí ní òun rán an láti l gbowó lẹ́nu ATM ni
Awọn amugbalẹgbẹ naa si kọwe ẹbẹ si ajọ EFCC, ICPC, to fi mọ Aarẹ Muhammadu Buhari ati igbakeji rẹ.
Awọn amugbalẹgbẹ naa ni awọn akọsilẹ kan fihan pe, iye awọn jẹ ẹgbẹrun meji ati ẹẹdẹgbẹta le aadọrin niye.
Bakan naa ni iwadi fihan wi pe, ẹnikọọkan awọn amugbalẹgbẹ ọhun n gba owo oṣu ti apapọ rẹ n bẹ laarin ẹgbẹrun lọna aadọjọ naira ( ₦150,000) si ẹgbẹrun lọna ọtalerugba o din mẹwa naira (₦250,000).
Koda, awọn kan tun wa ti owo wọn ju bẹ ẹ lọ. Eyi nii ṣe pẹlu ipele tabi ipo ti iru amugbalẹgbẹ bẹ ẹ ba wa.
Oríṣun àwòrán, NASSNIGERIA
Abẹnugan ile ni ẹtọ si amugbalẹgbẹ marundinlogoji, igbakeji rẹ, mẹẹdogun, ti ọkọọkan awọn olóyè ile si lẹtọ si mẹwa.
Ofin ile aṣofin naa faaye gba aṣofin kọọkan lati ni amugbalẹgbẹ maarun, nigba ti aarẹ ile aṣofin agba lanfaani si amugbalẹgbẹ marundinlaadọta.
Bakan naa ni igbakeji rẹ ni anfaani si ọgbọn, ti awọn olóyè ile si ni anfaani si ogún ẹnikọọkan wọn.
Bakan naa ni ọrọ ri lọdọ awọn ọmọ ile aṣofin kekere.
Abẹnugan ile ni ẹtọ si amugbalẹgbẹ marundinlogoji, igbakeji rẹ, mẹẹdogun, ti ọkọọkan awọn olóyè ile si lẹtọ si mẹwa.
Oríṣun àwòrán, NGRSenate
Gbogbo awọn amugbalẹgbẹ yii ni apapọ wọn ko din ni ẹgbẹrun meji le ni ẹẹdẹgbẹta. Gbogbo wọn lo si n gba owo oṣu latinu apo aṣuwọn ile aṣofin.
Ilé ẹjọ́ gba onídúró Sẹ́nétọ̀ Ademọla Adeleke
‘A nfẹ adinku agbara ijọba apapọ’
Apapọ awọn ọmọ ile aṣofin apapọ jẹ irinwo ati mọkandinlaadọrin. Awọn sẹnetọ mọkandinlaadọrin, ati ọtalelọọdunrun aṣoju-ṣofin.
Akojọpọ owo oṣu wọn niyii ti ọkọọkan wọn ba n gba ẹẹdẹgbẹta ẹgbẹrun Naira l'oṣu:
Ti ọkọọkan awọn amugbalẹgbẹ naa ba n gba ẹgbẹrun lọna aadọjọ (₦150,000) Naira l'oṣu, apapọ owo wọn yoo jẹ biliọnu mẹrin ati miliọnu lọna okoolelẹgbẹta ati mẹfa Naira (₦4,626,000,000bn) l'ọdun.
Fela Durotoye: ọmọ̀ ọ̀jọ̀gbọ́n tó di olóṣèlú Nàìjíríà
Oríṣun àwòrán, @feladurotoye
Ni ọjọ kejilelogun, oṣu keji, ọdun 2018 ni Fẹla Durotoye kede erongba rẹ lati dije fun ipo aarẹ orilẹ-ede Naijiria
Ta ni Fẹla ọmọ Durotoye?
Fun ẹni ti o ba mọ itan oṣelu orilẹ-ede Naijiria fun igba diẹ sẹyin,, orukọ Fẹla Durotoye ko lee jẹyọ gẹgẹ bii ara awọn oloṣelu atigbadegba lorilẹ-ede Naijiria.
Ọjọ kejila, oṣu karun, ọdun 1971 ni wọn bi Fẹla Durotoye gẹgẹ bii Adetokunbọ Oluwafẹọlami Durotoye.
Ọjọgbọn ninu imọ ijinlẹ ni baba ati iya rẹ, Layiwọla ati Adeline Durotoye ni fasiti Ibadan ki wọn to lọ si fasiti ilu Ifẹ eyi ti o ti di Obafemi Awolowo University, OAU bayii.
'Obìnrin ló ni ilé àti àdúgbò fún ìdí èyí wọ́n lè ṣe ìlú dáadáa'
Ohun to yẹ ki o mọ nipa Fẹla Durotoye:
Ọrọ Fẹla Durotoye yatọ si ọpọ awọn oloṣelu nitori pupọ awọn oloṣelu lorilẹ-ede Naijiria lode oni, papa julọ awọn ti wọn n dupo aarẹ ni awọn tabi baba ati iya wọn ti wa lẹnu owo oṣelu fun ọpọlọpọ ọdun.
2019 Elections: Èrò àwọn ọmọ Nàíjíríà se ọ̀tọ̀ọ̀tọ̀ lóri ètó àlùfáà tàbí ìmámù lásìkò ìbò
Ni fasiti Obafemi Awolowo yii ni Fela Durotoye ti kẹkọ gboye imọ ẹrọ Kọmputa pẹlu eto ọrọ aje ki o to tun kawe gba imọ kun imọ pẹlu ẹkọ imọ ijinlẹ keji, MBA ni fasiti OAU yii kan naa ki o to tun wa imọ lọ si gbajugbaja fasiti ni, Havard University ni orilẹ-ede Amẹrika.
Oríṣun àwòrán, @feladurotoye
Ni ọjọ kọkandinlọgbọn, oṣu kẹsan, ọdun 2018 ni wọn yan an gẹgẹ bii oludije ẹgbẹ oṣelu naa
Ogunna gbongbo onimọ nipa iṣuna ni Fẹla Durotoye.
O ti ṣiṣẹ pẹlu ọpọ ileeṣẹ ja-n-kan-ja-n-kan kaakiri agbaye bii Ventures and Trust Limited, Phillips consulting limited ki o to lọ da ileeṣẹ V.I.P Consulting limited silẹ ni ọdun 2000.
Oríṣun àwòrán, @Fela2019
Ọjọ kejila, oṣu karun, ọdun 1971 ni wọn bi Fẹla Durotoye gẹgẹ bii Adetokunbọ Oluwafẹọlami Durotoye
Gbajugbaja onimọ ati olukọni nipa ọrọ akoso ati idari ni Fẹla Durotoye ti o si ti ṣe idanilẹkọ fun ọpọ ni ilẹ yii ati ni oke okun.
Ni bayii, Fẹla ni aarẹ ileeṣẹ GEMSTONE Nation Builders Foundation, ileeṣẹ ti ko gbara le ijọba ti ko si le ere ninu iṣẹ rẹ.
Festus keyamo: Ọ̀rọ̀ Obasanjọ sí Buhari ti di ìrégbè
"Ni oṣu kejila, ọdun 2009 ni o lewaju awọn eekan ilumọọka lagbo amuludun lorilẹ-ede Naijiria bii,  Banky W, Alibaba, Kate Henshaw, Omoni Oboli, Teju Babyface, Sound Sultan, TY Bello, Dj Jimmy Jatt, Omawunmi, Denrele, Dele Momodu, Tosin Bucknor, Stella Damascus, Tee A, Segun Dangote, Ebuka Obi ati bẹẹbẹẹ lọ  fun eto kan ti o pe ni ""Mushin Makeover"" eyi ti wọn fi tu ọpọ ile ni agbegbe Mushin nipinlẹ Eko kun fun ayika to gbayii."
Oríṣun àwòrán, @feladurotoye
Ni ọjọ kejilelogun, oṣu keji, ọdun 2018 ni Fẹla Durotoye kede erongba rẹ lati dije fun ipo aarẹ orilẹ-ede Naijiria
Ko din ni ẹgbẹrun meji awọn eeyan ti wọn korajọ fun eto yii.
Obasanjo: Atiku kìí se Áńgẹ́lì, àmọ́ yóò se dáadáa ní ìlọ́po méjì ju Buhari lọ
O tó bií ile mẹrindinlaadọọrun ti wọn kun. Lẹyin o rẹyin, ọgọrun un awọn ọdọ ni wọn ni ileeṣẹ apọda Berger Paints PLC kọ ni iṣẹ ile kikun lọna igbalode ti awọn pẹlu si di ẹni ti o n fi iṣẹ naa jẹun bayii.
Oríṣun àwòrán, @feladurotoye
"Ni oṣu kejila, ọdun 2009 ni o lewaju awọn eekan ilumọọka lagbo amuludun fun eto kan ti o pe ni ""Mushin Makeover"" eyi ti wọn fi tu ọpọ ile ni agbegbe Mushin nipinlẹ Eko kun fun ayika to gbayii"
Ni ọjọ kejilelogun, oṣu keji, ọdun 2018 ni Fẹla Durotoye kede erongba rẹ lati dije fun ipo aarẹ orilẹ-ede Naijiria lasiko idibo apapọ ọdun 2019 labẹ aṣia ẹgbẹ oṣelu Alliance for New Nigeria, ANN.
ìpàdé ìtagbangba ìfọ̀rọ̀wánilẹ́nuwò pẹ̀lú àwọn olùdíje sípò gomina ní ìpínlẹ̀ Eko.
Ni ọjọ kọkandinlọgbọn, oṣu kẹsan an, ọdun 2018 ni wọn yan an gẹgẹ bii oludije ẹgbẹ oṣelu naa.
Oríṣun àwòrán, @feladurotoye
Ọjọ kejila oṣu karun ọdun 1971 ni wọn bi Fẹla Durotoye gẹgẹ bii Adetokunbọ Oluwafẹọlami Durotoye
Ṣe wọn ni eeyan bi ahun naa nii ri ahun he, gbajugbaja agbanisiṣẹ bii tirẹ, Tara Fẹla-Durotoye ni Fẹla fẹ ni iyawo.
Osinbajo: Ikẹnnẹ yẹ kó jẹ́ Mẹ́kà òṣèlú ni
Tara jẹ amofin ati aṣaraloge. Oun si ni oludasilẹ ileeṣẹ aṣaraloge House of Tara.
Ọmọ ọkunrin mẹta ni wọn bi ti orukọ wọn a si maa jẹ Mobolurin, Demilade & Morolaoluwa.
Ọ̀tọ̀ ni nkan tí wọ́n sọ fún ẹbí rẹ̀, iṣẹ́ aṣẹ́wó ni wọ́n fi n ṣe
2019 elections: Saraki, Dogara ṣèkìlọ̀ lórí ewu ìbò rírà fún ìdìbò ọ́dún 2019
Oríṣun àwòrán, @NGRSenate
Ipenija ibo rira wa si gbangba lasiko idibo Ekiti ati Ọṣun
Awọn aṣofin apapọ orilẹede Naijiria ti pariwo sita pe ibo tita ati rira jẹ penija kan ti yoo koju aṣeyọri eto idibo apapọ lọdun 2019.
Nibi ipade itagbangba kan to waye lori gbigbogun ti ipenija ibo tita ati rira ni ilu Abuja lawọn aṣofin apapọ ti sọrọ yii.
Ibo rira ati tita farahan gẹgẹ bii ipenija tuntun ti awọn alakoso eto idibo lorilẹede Naijiria gbọdọ mojuto pẹlu bi o ṣe wọpọ lasiko idibo sipo gomina ni ipinlẹ Ekiti ati Ọṣun.
Olori ile aṣojuṣofin, Yakubu Dogara ni ohun kan to lee mu ki eto idibo o jẹ itẹwọgba labẹ ilana iṣejọba awarawa naa ni ki irufẹ eto idibo bẹẹ o lọ lai si wahala, ki o wa lai labawọn, ki o si duro lori ifẹ awọn oludibo.
Oríṣun àwòrán, @NGRSenate
Ìpèníjà ìbò rírà ló mú àwọn aṣòfin àpapọ̀ láti pe ìpàdé ìta gbangba lóríi ìpèníjà rẹ̀ fún ìdìbò àpapọ̀ ọ́dún 2019
Ipenija isisinyi ni ibo rira ti o si bani ninu jẹ gidigidi. Gẹgẹ bii ọmọ orilẹede yii, a ko ni lati sọ ara wa di ọdaran, nitori iwa ibo rira tabi tita atawọn  iwa aitọ miran lasiko idibo ti da wahala silẹ si ọrun awọn ọmọ orilẹede yii nitori ibẹru bojo lọrọ naa da si aya wọn dipo ki o fun wọn ni igboya lati koju awọn iwa aitọ leto idibo wa.
Ninu ọrọ tirẹ, aarẹ ile aṣofin agba, Sẹnetọ Bukọla Saraki ni gẹgẹ bii ipenija kan ti o n ba eto idibo lorilẹede Naijiria finra, awọn alẹnulọrọ atawọn alaṣẹ gbọdọ dide gbogun tii ni wara-n-ṣeṣa  ki o to bọ aṣọ iyi ati ẹyẹ lara eto idibo apapọ ọdun 2019.
"Gbogbo awọn ti ọrọ idibo lorilẹede yii kangbọdọ fihan pe eto idibo ti ko lẹja-n-bakan ninu san ju ẹni to bori idibo lọ.
Ko ni dara ki a maa fi apẹẹrẹ ti ko dara ṣọwọ si awujọ agbaye nipa ailakiyesi ati aikọbiara wa. Gbogbo agbaye gbọdọ rii pe a ṣetan lati gbe igbesẹ itẹsi."
Nigeria Elections 2019: Dapo Abiodun, ǹkan márùn ún tó yẹ kẹ́ẹ mọ̀ nípa rẹ̀
Oríṣun àwòrán, Twitter/Dapo Abiodun
Ìgbìmọ̀ amúsẹ́yé ẹgbẹ́ òsèlú APC ti polongo Dapo Abiodun gẹ́gẹ́ bí olùdíje sípò gómìnà lẹ́gbẹ́ òsèlú APC ní ìpínlẹ Ogun.
Ẹgbẹ oselu APC ni ipinlẹ Ogun ti polongo Dapo Abiodun gẹgẹ bi ẹni ti yoo gbe asia oludije sipo gomina ni idibo gbogboogbo ti 2019.
Bi Dapo Abiodun ba jawe olubori ni idbo gbogboogbo ti ọdun 2019, oun ni yoo gba ijọba lọwọ gomina Ibikunle Amosun ti ipinlẹ Ogun.
Ọjọ kọkandinlọgbọn, Osu Karun, ọdun 1960 ni wọn bi ọmọọba Dapo Abiodun lati ijọba ibilẹ Iperu-Remo ni ipinlẹ Ogun.
Awọn ohun marun nipa oludije sipo gomina ni ipinlẹ Ogun fun idibo ọdun 2019.
ìpàdé ìtagbangba ìfọ̀rọ̀wánilẹ́nuwò pẹ̀lú àwọn olùdíje sípò gomina ní ìpínlẹ̀ Eko.
2019 Election: Ta ni olùdíje gómìnà l‘Ogun, Kashamu àbí Adebutu?
Oríṣun àwòrán, @Sen_Kashamu
Omi alaafia ẹgbẹ oselu PDP ni ipinlẹ Ogun lo ti n daru logbologbo bayii, ti awọn ọmọ ẹgbẹ oselu naa si ti pin si meji.
Awọn ọmọ ẹgbẹ PDP kan ti to sẹyin Ọladipupọ Adebutu, ti olu ile ẹgbẹ ni Abuja fi ontẹ lu pe oun ni oludije ẹgbẹ to kajuẹ, bẹẹni wọn ti gbe asia ẹgbẹ le lọwọ.
Amọ lọwọ-lọwọ bayii, ajọ eleto idibo nilẹ wa, INEC, ti kede pe, Adebutu kọ ni oun mọ bii ojulowo oludije fun ipo gomina ni ipinlẹ Ogun labẹ ẹgbẹ oselu PDP bikose Sẹnetọ Buruji Kashamu.
Igun OPC: OPC ti sọnù, àwọn èèyàn ń sá fún wa láì fẹ́ darapọ̀ mọ́ wa
Lẹyin ọjọ mẹta ti alaga ẹgbẹ PDP ni Naijiria, Uche Secondus si ti gbe asia ẹgbẹ le Adebutu lọwọ, igun ti Kashamu ti se ifilọlẹ eto ipolongo ibo rẹ nilu Ijẹbu Igbo.
Nibi ayẹyẹ ifillẹ eto ipolongo ibo naa, alaga ẹgbẹ PDP to ko igun Kashamu sodi, Bayọ Dayọ ni igun tawọn ni ojulowo PDP ti ofin ti lẹyin , ti ajọ eleto idibo si damọ.
Nigba to n ba ipejọpọ ero sọrọ ipolongo ibo naa, ti wọn gbe sori mohun-maworan bo se n lọ lọwọ, Buruji Kashamu seleri pe ijọba to nifẹ mẹkunnu ni oun yoo se.
Oríṣun àwòrán, @Sen_Kashamu
O ni oun ti n ran mẹkunnu lọwọ tẹlẹ, amọ ti oun ba di gomina, anfaani yoo tubọ wa fun oun lati ran awọn eeyan ti ori n ta lẹru.
Nigba to n gbe asia ẹgbẹ fun Kashamu, Bayọ Dayọ ni Buruji ni Awolọwọ asiko yii, ti ajọ Inec si ti tẹwọ gbaa.
Amọ nigba to n fesi si isẹlẹ yii, agbẹnusọ fun ẹgbẹ PDP lapapọ, Kọla Ọlọgbọndiyan ninu atẹjade kan ni , ipolongo ibo arumọjẹ ni Kashamu se, o ya ero lo ni, ayederu asia ẹgbẹ si ni wọn gbe fun.
Ìtàn Mánigbàgbé: Ẹfunsetan Aniwura lọ́lá, ó lówó, ó sì tún gbajúmọ̀
Oríṣun àwòrán,  @ibadaninsider
Eledua fi awọn obinrin takuntakun jinki ilẹ adulawọ, ti ọpọ wọn ko si se fi ọwọ rọ sẹyin rara.
Lara awọn obinrin takuntakun to gbe ounjẹ fẹgbẹ, to si tun gba awo bọ nilẹ Yoruba ni obinrin bi ọkunrin kan nilẹ Ibadan, Ẹfunsetan Aniwura, tii se Iyalode ilẹ Ibadan.
Niwọn igba to jẹ pe ọjọ ti pẹ, Iyalode Ẹfunsetan ti wa, to si ti pada sọdọ Eledua, oniruuru itan ni a gbọ nipa rẹ. Idi ni pe ko si akọsilẹ to daju nipa igbe aye akọni obinrin naa.
Itan igbesi aye Ẹfunsetan ko lọ gaara ga bo se yẹ, nitori oniruuru ọna lo pin si. Amọ wọn ni bi ọmọ ko ba ba itan, yoo ba arọba, tii se baba itan.
Akọsilẹ oju opo Wikipedia ni a lo, lati se akojọpọ itan nipa igbe aye Ẹfunsetan Aniwura yii.
Itan igbe aye Ẹfunsetan Aniwura:
'Èmi gan máa ń béèrè lọ́wọ́ ara mi pé ta ni Wole Soyinka gangan'
Florida: Ọ̀ọ̀nì àléègbà dé ba Mary lálejò lọ́gànjọ́ òru
Sugbọn ta ba n sọrọ awọn obinrin takuntakun nilẹ Ibadan ati nilẹ Yoruba, itan ko lee gbagbe Ẹfunsetan Aniwura, tori o se iwọn to lee se lasiko tiẹ.
Abayọmi Aranmọlatẹ, Dr Laser: Vagino Plasty àti iṣẹ́ abẹ ẹwà Obìnrin ló jẹ mí lógún
Painter: Samuel ni ìdàgbàsókè Nàìjíríà ló jẹ òun lógún!
PDP: Buhari fẹ́ pa ohùn mọ́ àwọn alátakò lẹ́nu
Oríṣun àwòrán, @doyinokupe
Awọn asaaju ẹgbẹ oselu PDP ti fi igbe bọnu pe ki ajọ EFCC yara tete fi Doyin Okupe silẹ ni ahamọ wọn lai ni gbedeke kankan.
Atẹjade kan ti akọwe ipolongo fẹgbẹ PDP, Kọla Ọlọgbọndiyan fisita wa se apejuwe bi EFCC se gbe Okupe si ahamọ gẹgẹ bii iwa idunkoko mọni ati itabuku ẹni ti ijọba Muhammadu Buhari n se lati tẹ ori awọn ọmọ ẹgbẹ alatako ba.
A n kesi awọn ọmọ Naijiria pe ajọ EFCC ti n foju Doyin Okupe ri mabo pẹ́lu awọn irọ to buru jai nitori bo se kesi ajọ eleto idibo lati wọgile orukọ aarẹ Muhammadu Buhari ninu iwe idibo nitori ọna ti wọn gba fa kalẹ lati dije ko tọna.
Igun OPC: OPC ti sọnù, àwọn èèyàn ń sá fún wa láì fẹ́ darapọ̀ mọ́ wa
Lati akoko yii wa ni wọn ti n halẹ mọ Okupe, tawọn osisẹ EFCC si ya bo ile rẹ lọjọ abamẹta lori ẹsun pe o n lo itakun agbaye, lati fi ọna eru gba owo, eyi ti wọn ko lee fi idi rẹ mulẹ, amọ ti wọn pada wa gbe si ahamọ lọjọ Satide.
PDP wa n beere pe to ba jẹ pe EFCC ko tii gba abọde lọwọ Buhari, ki lo de ti wọn ko se kesi awọn osisẹ nileesẹ aarẹ ti wọn fi ẹsun iwa ijẹkujẹ kan saaju.
Wọn ni eyi gan kan alaga ẹgbẹ APC, Adams Oshiomole, ti wọn lo gba owo lọna aitọ lọwọ awọn ọmọ ẹgbẹ APC< to si tun rin irin ajo jadejkuro ni orilẹede yii.
Orji Uzor Kalu: Ilé ẹjọ́ tó ga jùlọ ní Nàìjíríà wọ́gilé ẹ̀wọ̀n Orji Uzor Kalu, pàṣẹ ìgbẹ́jọ́ tuntun
Ile ẹjọ to ga julọ lorilẹede Naijiria ti wọgile idajọ ẹwọn ọdun mejila ati gbigbẹsẹle dukia ti ile ẹjọ gbe le gomina ipinlẹ Abia tẹlẹ Orji Uzor Kalu.
Gbogbo adajọ mejeeje to joko lori igbẹjọ naa ni wọn fohun ṣọkan pe ile ẹjs giga apapọ ilu Eko to gbe idajọ kalẹ pe Kalu, ileeṣẹ rẹ Slok Nigeria Limited ati oludari eto iṣuna tẹlẹ nipinlẹ Abia, Jones Udeogu jẹbi ẹsun kiko ipinlẹ Abia owo to le ni biliọnu meje naira jẹ.
Ile ẹjọ to ga julọ lorilẹede Naijiria woye pe Onidajọ Mohammed Liman to dajọ naa kii ṣe adajọ mọ nigba to gbe idajọ kalẹ lori ẹjọ naa.
O ni niwọn igba to jẹ pe wọn ti gbe Onidajọ Liman ga lọ si ile ẹjọ kotẹmilọrun ṣaaju igba naa, ko lẹtọ mọ lati pada lọ gbọ ẹjọ naa tabi gbe idajọ kalẹ lori rẹ. Ile ẹjọ to ga julọ lorilẹede Naijiria woye pe aṣẹ ti aarẹ ile ẹjọ kotẹmilọrun fun un pe ko lọ gbs ẹjọ naa labẹ ofin iṣedajọ lorilẹede Naijiria ko ba ofin mu.
Ile ẹjọ to ga julọ lorilẹede Naijiria wa wọgile idajọ naa pẹlu aṣẹ pe ki wọn lọ tun ẹjọ naa gbọ lati ibẹrẹ
Oríṣun àwòrán, @officialEFCC
àjọ EFCC ní òun leè fọwọ́ sọ̀yà pé iṣẹ́ ń lọ ní pẹrẹu
Ajọ to n gbogun ti iwa ibajẹ ni Naijiria, EFCC, ti kegbare sita pe, awọn ko fi panpẹ ofin gbe awọn ọmọkunrin oludije fun ipo aarẹ ninu ẹgbẹ Peoples Democratic Party, PDP, Atiku Abubakar.
Ṣaaju ni ẹgbẹ oṣelu PDP fi ikede kan sita pe, ajọ naa lọ tu ile awọn ọmọ Atiku wo, lati mọ boya wọn ko owo ilẹ okeere pamọ sile.
Igun OPC: OPC ti sọnù, àwọn èèyàn ń sá fún wa láì fẹ́ darapọ̀ mọ́ wa
Sugbọn EFCC, ninu atẹkade kan loju opo ikansiraẹni Twitter rẹ ṣalaye pe, ahesọ ọrọ ati irọ to jina sootọ ni ẹsun naa.
EFCC ṣalaye wi pe, ọmọ gomina tẹlẹ nipinlẹ Abia, Theodore Orji Kalu, ati ọrẹ rẹ kan ni awọn mu.
Ajọ naa to ti n ṣe iwadi gomina naa tẹlẹ fun ẹsun kiko biliọnu mẹtadinlogun Naira pamọ lọna aitọ, ti 'iṣẹ iwadi wọn si fihan pe, Orji ko diẹ lara owo naa pamọ nipasẹ awọn ọmọ rẹ ọkunrin.
Ajọ EFCC to ni, igbesẹ awọn ko ni nkankan ṣe pẹlu Atiku Abubakar tabi awọn ọmọ rẹ, wa tako awọn iroyin to wa nita.
Wọn fikun pe awọn ko mọ ohunkohun nipa bi wọn ṣe gbẹsẹ le apo aṣuwọn oludije fun igbakeji rẹ, Peter Obi, eyi to tako ohun ti ẹgbẹ oṣelu PDP sọ.
Bakan naa ni agbẹnusọ fun Aarẹ Muhammadu Buhari, Garba Shehu sọ pe, ayederu iroyin ni ẹgbẹ oṣelu PDP n fi sita lori ọrọ naa.
Sheu loju opo Twitter sọ pe, irọ ni pe ijọba apapọ Naijiria lo paṣẹ pe ki EFCC ṣayẹwo ile awọn ọmọ Atiku Abubakar.
EFCC tẹsiwaju ninu alaye rẹ pe, idaji ọjọ Abamẹta to kọja ni ọwọ wọn tẹ ọkan lara awọn ọmọ naa, Ogbonna Orji ati ọrẹ rẹ kan, lasiko ti wọn lọ fun igbadun opin ọsẹ nile igbafẹ kan l'Abuja.
Eyi mu ki EFCC tẹle awọn ọmọkunrin mejeeji lọ sile ti wọn n gbe, ti ayẹwo wọn si fihan pe, ọgọrun miliọnu Naira ni ọmọkunrin Orji ra ọkọ ayọkẹlẹ to n lo, ti ti ọrẹ rẹ, Kelvin Ilonah si jẹ miliọnu marundinlogoji Naira.
Bakan naa ni EFCC sọ pe, miliọnu mẹtala Naira l'ọdun ni ile ti ọkọọkan wọn n gbe.
Ogun PDP:Buruji Kashamu kìí ṣe ọmọ ẹgbẹ́ wa- Ọlọgbọndiyan
Oríṣun àwòrán, Kashamuofficial
Ẹgbẹ́ PDP kò pín sí méjì nípìnlẹ̀ Ogun
Bí ọjọ́ ṣe ń gori ọjọ́ ní àrídájú hàn pé èdè àìyedè  ń pọ si nínú ẹgbẹ́ òṣèlú People's Democratic Party (PDP) ní ìpínlẹ̀ Ogun nígbà tí àwọn olùdíje méjèèjì lábẹ ẹgbẹ́ kan náà Buruji Kashamu àti Oladipupo Adebutu síde ìpolongo ìdìbò ní lọ́tọ̀ọ̀tọ̀ fún ìdíjè gómínà fún ọdún 2019.
Àlàyé Buruji Kashamu nígbà tó bá BBC yorùba sọ̀rọ̀ ní pé òun ní àjọ elétò ìdìbò (INEC) mọ tí orúkọ oun sì wà nínú ìwé wọn gẹ́gẹ́ bí ẹni tó yẹ kó díje dupò gómìnà ọdún 2019 ní ìpínlẹ̀ Ogun.
Njẹ́ ìgbésẹ̀ People's Democratic Party (PDP) yìí kò ni pín ẹgbẹ́ sí meji?
Nínú ọ̀rọ̀ rẹ̀ agbẹnusọ apapọ ẹgbẹ́ òṣèlú PDP Kola Ọlọgbọndiyan sàlàyé pé kò sí ǹkan tó ń jẹ èdè àìyedè nínú ẹgbẹ́ PDP ní ìpínlẹ̀ Ogun.
Kola Ọlọgbọdiyan sàlàyé pé sẹnatọ Buruji Kashamu kò fí ìgbà kankan gbé igbá ìdíje gómìnà nínú ẹgbẹ́ PDP ní ìpínlẹ̀ Ogun àti pé Ọladipupọ Adebutu ní wọn dìbò abẹlé yàn. Orúkọ rẹ̀ sí ni wọn lọ fí sílẹ̀ nílé àjọ elétò ìdìbò (INEC) sùgbọn ní ti Buruji Kashamu, kì ra fọọmu nínú ẹgbẹ́, kò díje dupò kankan, bẹ́ẹ̀ si ní ẹgbẹ́ ò gbé àsíá fún láti díje lórukọ ẹgbẹ́, èyí fi hàn pé kò sí pé ènìyàn méji ló ń du ipò kan náà.
Agbẹnúsọ PDP ní kò sí òfin ilẹ̀ Nàìjíríà tó fi ààyè gbàá pé ènìyàn le lọ sí kọọtu láti lọ gba àṣẹ kó sì mú orúkọ ara rẹ lọ si àjọ INEC pé òhun ní ojúlowó olùdíje gómínà ní ìpínlẹ̀ Ogun, sùgbọn orúkọ Adebutu ní ẹgbẹ́ mú lọ si ọ̀dọ̀ INEC.
'' Sẹnatọ Buruji Kashamu ò tẹ̀lé ìlànà ẹgbẹ́, Uche Secodus sì ní alága ẹgbẹ́ PDP lórílẹ̀-èdè Nàìjíríà gbogbo ẹni tí kò bá si tí tẹ̀lẹ́ ìlànà adarí ẹgbẹ́ kìí ṣe ọmọ ẹgbẹ́ PDP''.
Sáájú ní PDP ti yọ Sẹnatọ Kashamu àti Dayo Bayo ti wọn jẹ adarí PDP nípinlẹ̀ Ogun. Sùgbọn wọn lọ sí ilé ẹjọ ti wọn si gba ìdáláre bọ
Ìdìbò ọdún 2019: Atiku Abubakar kò yóju síbi ìpàdé àjùmọse àláfíà
Oríṣun àwòrán, FGofficial
Ààrẹ Buhari tọ́wọ́bọ̀wé àláfìà
Ààrẹ Muhammadu Buhari, ti balẹ̀ sí International Conference Centre (ICC) Abuja ní bi ti ètò ìgbìmọ àpàpọ̀ lórí àlàfíà lórí ìdìbò àpapọ̀ ọdún 2019.
Ètò àpérò ọ̀hún ló mu àkójọpọ̀ gbogbo ẹgbẹ òṣèlú pàdé lójú kan náà níbi ti àwọn olùdíje ipò ààrẹ yóò ti ìfọwọ́sí ìwé àdéhùn àláfíà.
Ètò Atiku ló bá èròngbà Yorùbá mu
Oríṣun àwòrán, FGofficial
Ààrẹ Buhari tọ́wọ́bọ̀wé àláfìà
Olùdíjé lábẹ́ ẹgbẹ́ òṣèlú PDP Atiku Abubakar kò yọjú níbi ìfọwọ́wọ́sí àjùmọ̀se àláfíà náà bákan náàni olóri égbé òṣèlú PDP Uche Secondus.
Ọ̀rọ̀ náà kò yé, idí ti Atiku àti àwọn ọmọ ẹgbẹ́ PDP ṣe kọ̀ láti yọjú níbí ayẹyẹ náà
Ìfọwọ́sí ìwé àjùmọse àláfíà yìí jẹ ohu ti ààrẹ orílẹ̀-èdè Nàìjíríà nígbà kan rí Abdulsalami Abubakar gbé kalẹ̀ láti ríi dájú pé olùdíje àti ẹgbẹ́ òṣèlú wọn kò sọ̀rọ̀ tako ẹ̀sìn, àti ẹya tò fi mọ lílo èdè tó le dá rògbòdiyàn sílẹ̀.
Bákan náà, ìwé àdéhùn alafíà yìí yóò  tun mú ìrẹ́pọ̀ wáyé láàrin àwọn olùdíje sípò ààrẹ orílẹ̀-èdè Nàìjíríà láti ríi dájú pé kò sí ìwà ipá tàbí jàgídíjàgan lásìkò ìpolongo, lásìkò ìdìbò àtí tí ìdìbò ọdún 2019 bá kẹ́sẹjári tan.
Oríṣun àwòrán, FGofficial
Ìdìbò dún 2019: Àwọn ààrẹ tọwọ́bọ̀wé àdéhùn àláfíà
Lọ́dun 2015, irú ìwé àdehun yìí náà wáye tí spọ̀ sì gbàgba pé ó kún ìdí ti ohun gbogbo ṣe lọ ní ìrọwọ́rọsẹ̀ lẹ́yín ìdìbò tí ààrẹ ìgbà náà tí Goodluck Jonathan gbà pé òun fìdi rẹmi.
Oríṣun àwòrán, FGofficial
Ìdìbò dún 2019: Àwọn ààrẹ tọwọ́bọ̀wé àdéhùn àláfíà
Ẹ̀wẹ̀, ààrẹ Nàìjíríà nígbà kan rí Abdusalami Abubakar sọ pé àìwá ọ̀kan gbòógì nínú àwọn olúdíje sí ipò ààrẹ kò mú ìdíwọ́ kankan dáni sí fún àjùmọse àláfíà.
Ìjọba Eko: Ìwàkuwà àwọn awakọ̀ ló ń fa ojú súnkẹrẹ ọkọ̀
Oríṣun àwòrán, AFP
Yoruba ni ilu ti ko si ofin, ẹsẹ ko si nibẹ,  eyi lo mu kijọba ipinlẹ Eko fi n kede bayii pe awakọ to ba tapa sawọn ofin to de eto irinna loju popo, yoo ri ẹwọn ọdun mẹta he.
Adajọ agba nipinlẹ Eko, to tun jẹ Kọmisana feto idajọ, Adeniji Kazeem lo kede ọrọ yii fawọn kọlọransi awakọ pẹlu afikun pe gbogbo agbara ofin ni ijọba yoo lo lati da wọn lẹkun iwa ibajẹ loju popo.
Adeniji sọ siwaju pe ijiya ẹṣẹ awọn awakọ to ba sẹ si ofin irinna fun igba akọkọ, ni wọn yoo fi ẹwọn ọdun kan soso pere fa leti.
Igun OPC: OPC ti sọnù, àwọn èèyàn ń sá fún wa láì fẹ́ darapọ̀ mọ́ wa
Ijọba Eko ko fi ọwọ yẹpẹrẹ mu ifẹsẹmulẹ awọn ofin to de eto irinna loju popo, to si tun n lakaka lati mu ki ọkọ wiwa ni Eko ma mu wahala kankan lọwọ.
Adajọ agba naa ni ofin eto irinna loju popo tọdun 2015 lo laa kalẹ pe ijiya n bẹ fun awakọ to ba sẹ sawọn ofin yii:
Oríṣun àwòrán, AFP
Adajọ Adeniji wa mẹnuba awọn ijiya ẹsẹ to wa fun kọlọransi awakọ ti ọwọ ofin ba gba mu:
Kọmisana feto idajọ naa wa rọ awọn ara ilu lati maa bọwọ fun ofin, ki wọn si maa fi ọwọ sowọpọ pẹlu awọn osisẹ to n se akoso eto irinna loju popo, ki alaafia lee jọba lawọn oju popo gbogbo ni ipinlẹ Eko.
Ìbálópọ̀ nínú ọkọ̀: Ọlọ́pàá ìpínlẹ̀ Eko tako ìsesí yìí
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ijọba ipinlẹ Eko ti tako ọrọ ile isẹ ọlọpa apapọ wi pe kii se ẹsẹ lati ni ibalopo ninu ọkọ ayọkẹlẹ ni ita gbangba.
Kọmisọnna ọlọpaa ni ipinlẹ Eko, Imohimi Edgal to fi eyi lede ninu atẹjade bu ẹnu atẹ lu ọrọ ti Ọga ọlọpaa Abayọmi Shogunlẹ sọ ni Ọjọ Isẹgun pe awọn ọmọ Naijiria lẹtọ labẹ ofin lati ofin lati ni ibalopọ ninu ọkọ ni ojutaye.
Edgal ni ile isẹ eto idajọ ni ipinlẹ Eko ti gba ile isẹ ọlọpaa ni imọran wi pe ohun itiju ati ohun to ba ni loju jẹ ni ki akọ ati abo ma a ba ara wọn ni ibalopo ni ita gbangba.
O fikun wi pe iwe ofin ipinlẹ Eko to nii se pẹlu iwa aito lawujọ sọ wi pe ẹni to ba wu iru iwa bẹẹ lawujọ yoo fi ẹwọn ọdun meji si mẹta jura gẹgẹbi iwe ofin to niise pẹlu iwuwasi lawujọ to wa ni Section 134 (a) ati section 136 ti iwe ofin ipinlẹ Eko.
Kọmisọnna ọlọpaa ipinlẹ Eko naa wa parọwa si awọn araalu ni ipinlẹ Eko lati se akiyesi ofin wọnyii, ki wọn ma ba A lu ofin ibalopo ni gbangba ni ọjọ iwaju.
Igbakeji Kọmisana Ọlọpaa (ACP), Abayọmi Shogunlẹ lo kede loju opo ikansira ẹni Twitter rẹ pe kii se ẹsẹ rara fun awọn akọ ati abo lati ni ibalopọ ninu ọkọ nita gbangba.
Òkè Ìdànrè: Òkè tó kéré jùlọ jẹ́ ẹsẹ̀ bàtà 3000
Shogunlẹ, ẹni to bo ọrọ yii loju boro, lasiko to n dahun ibeere kan ti ẹnikan ju si loju opo naa, fi kun pe, bi o tilẹ jẹ pe iwa ibalopọ ninu ọkọ ko sẹ si ofin Naijiria, sibẹ, awọn gbedeke kan rọ mọ isẹlẹ yii.
Gẹgẹ bo se wi, lara awọn gbedede naa ni iwọnyii:
Shogunlẹ ko sai fi kun pe ti ẹnikẹni ba dun ikoko m ọmọ Naijiria kankan lori igbesẹ naa lẹyin ti wọn ba ti tle awọn ilana ofin to rọ mọ sise bẹẹ, ki wọn yara kan si ohun kia-kia.
Sugbọn lati igba ti Shogunlẹ ti n sọrọ yii, ni awn ọmọ Naijiria ti n gba ọrọ naa mọ ara wọn lọwọ, ti wn si n fi ero wọn han nipa rẹ loju opo Twitter wọn bẹẹ naa ni wn n fesi si ohun ti Shogunl sọ loju opo Twitter rẹ.
Bi awọn eeyan kan si se faramọ abala ofin naa ni awọn kan ta ko ofin yii
@Ibukun_olu, o ni bi o tilẹ jẹ pe ko si ofin kankan to tako ibalopọ ninu ọkọ loju taye, sibẹ, wọn lee gbe awọn eeyan to ba da asa yii wo pẹlu ẹsun aini iwa ọmọluabi.
O ni abala ojilerugba o din mẹsan ofin iwa ọdaran ilẹ wa lo sọrọ nipa awọn iwa kotọ lawujọ. O si wa lọwọ ileẹjọ lati sọ boya nini ibalopọ ninu ọkọnita gbangba jẹ iwa kotọ , paapa, taa ba wo wo ọkọ ti wọn lo jẹ dukia adani.
@OsaAOsula, o dup pupọ lọwọ Shogunlẹ fun alaye to se lori ọrọ yii, amọ o wa n beere pe ki wa ni itumọ sisi ara silẹ lọna aitọ?
@PatrickOkouzi, iwa nini ibalopọ ninu ọkọ ni ita gbangba lee sokunfa ijamba ọkọ tabi iwa ajẹbanu, ko si yẹ ka gbaa laaye.
Ìwé àdéhùn: Àwa olùdíje jẹ́ẹ̀jẹ́ láti se ìpolongo ìbò láì lọ́wọ́ ẹ̀sìn àti ẹ̀yà nínú
Oríṣun àwòrán, @MBuhari
Ajọ eleto alaafia nilẹ wa (National Peace Commission) NPC, ti gbe iwe adehun kalẹ fun awọn oludije ipo aarẹ ninu idibo ọdun 2019 lati fọwọsi.
Aarẹ Muhammadu Buhari ati awọn oludije kan fun ipo aarẹ  ni wọn ti tọwọbọ iwe adehun naa bayii eyi to wa lati gba alaafia laye lasiko ibo.
Ninu iwe adehun naa lo ti foju han pe, igbimọ eleto alaafia nilẹ wa ti se ipade apero pẹlu awọn oludije fun ipo aarẹ naa, ti yoo waye losu keji ọdun yii.
Ilé Asòfin: Buhari kò fi asojú South-South, South-East sínú olùdarí EFCC
Oríṣun àwòrán, Twitter/The Seante
Awọn sẹnẹtọ woju ara wọn
Ede-aiyede bẹ silẹ nile aṣofin agba l'Abuja lọjọ Iṣẹgun lori orukọ awọn eeyan mẹrin ti Aarẹ Muhammadu Buhari fi sọwọ fun igbimọ oludari ajọ EFCC.
Awọn sẹnẹtọ to n ṣoju apa ila oorun guusu (South East) ati awọn to ṣoju apa aarin gbungbun guusu ( South South) yari, wọn ni ko si ẹnikan lati agbegbe awọn ninu awọn ti aarẹ yan sipo.
Ṣugbọn awọn sẹnẹtọ lati apa ariwa orileẹde Naijiria, ti wọn tun jẹ ọmọ ẹgbẹ oṣelu APC ni ki ile tẹsiwaju lati buwọlu orukọ awọn ti Aarẹ Buhari fi ranṣẹ sile.
Ẹ wo àwọn ọmọ orílẹ̀-èdè Brazil tó wá síilẹ̀ Yorùbá láti mọ orisun wọn
Orukọ awọn mẹrin naa ni Ndasule Moses lati aarin gbungbun ariwa, Lawan Mamman lati ila oorun ariwa, Gladanci Imam Najip lati iwọ oorun ariwa ati Adeleke Adebayo lati iwọ oorun guusu.
Lai beṣu bẹgba, ni igbimọ ile to wa fun igbogun tiwa ajẹbanu ati siṣe owo ilu kumọkumọ labẹ alaga Chukwuka Utazi ti sọ pe, ki ile ṣe apero lori iyansipo naa lati ọdọ aarẹ.
Ṣugbọn ariyanjiyan bẹ silẹ, ti awọn sẹnẹtọ kan si dide si ara wọn. Akitiyan aarẹ ile, Bukọla Saraki lati dawọn lẹkun si lo ja si pabo.
Eleyi lo mu ki awọn aṣofin ṣe ipade idakọnkọ, lẹyin ipade yii ni wọn jọ gba lati so apero rọ lori ọrọ naa.
ASUP: Ìjọba kò sàmúsẹ àdéhùn 2009 àti 2017 la se ń wosẹ́ níran
ASUP Strike: Gbogbo ilé ìwé gbogbonìsẹ di títì pa
Àwọn ẹgbẹ́ òṣìṣẹ́ nílé ìlé ẹ̀kọ́ gbogboniṣe ìjọba tí a mọ sí (ASUP) lọjọ́ Kejìlá oṣù Kejìlá ti gùnlé ìyanṣẹ́lódi jákèjádò Nàìjíríà títí dí ọ̀jọ́ ti ìbéèrè wọn bá tó ni ìdáhùn.
Olóri ẹgbẹ́ ASUP, Usman Dutse tó bá BBC sọ̀rọ̀ sàlàyé pé, ìyàṣẹ́lódì yìí wáye nitori etí ọ̀gbọin tí ìjọba àpapọ̀ kọ sí ṣíṣe àmúlò àdéhùn ọdún 2009 àti 2017 tí wọ́n bá àwọn ọmọ ẹgbẹ́ ṣe.
ASUU Strike: Bí àwọn kan se dunnú, làwọn kan fajúro
Àwọn ọmọ ẹgbẹ́ ASUU fẹnukò láti gùnlé ìyanṣẹ́lódì yìí, léyìn ìpàdé àwọn ìgbìmọ aláṣẹ ẹlẹ́kẹtàléláàdọ́rún rẹ̀ tó wáyé ní ọjọ́ kọkàndílọ́gbọ̀n oṣù kọkànlá ọdún yìí.
Dutse sàlàyé pé, ẹgbẹ́ nírètí pé gbogbo ọmọ ẹgbẹ́ pátápátá láwọn ilé ẹkọ́ ìjọba jákèjádò orilẹede yii ni yóò kópa nínú ìyanṣẹ́lódì náà.
Tẹ ò bá gbàgbé, ìyáṣẹ́lódì yìí tún ti kún àwọn ẹgbẹ olùkọ́ ti Fasiti tó gùnlé ìyanṣẹ́lódi láti ọjọ́ kíní oṣù kọkànla.
2019 Election: Èmi kìí se alárùn ọpọlọ, n kò lọ tọ́jú ara ní Gbagada
Oríṣun àwòrán, Babajide Sanwo-Olu
Babajide Sanwo-Olu ni ṣaka lara oun dá
Olùdíje fún ipò gómìnà fẹ́gbẹ́ òṣèlú APC ní Ìpínlẹ̀ Eko Babajide Sanwo-Olu ti ṣojú abẹ ní kòó lórí ọ̀rọ̀ pé ó ti lọ fún ìtọ́jú ààrun ọpọlọ ni ilé ìwòsàn Ìpínlẹ̀ Eki tó wà ní Gbagada.
Sanwo-Olu ṣàlàyé pé, òun lọ sí ilé ìwòsàn ní Gbagada láti ran àwọn aláìní lọ́wọ́ ni, kìí ṣe wí pé òun lọ tọ́jú ara òun níbẹ̀.
O fìdí ọ̀rọ̀ yìí múlẹ̀ lórí ètò kan láàrọ́ọ̀ Ọjọ́rú lórí ẹ̀rọ amóhùnmáwòrán ní ìlú Eko.
Ẹ rántí pé, Gómìnà Ìpínlẹ̀ Eko Akinwunmi Ambode nígbà tó bá àwọn oníròyìn sọ̀rọ̀ nínú oṣù kẹsàn án sọ pé, Sanwo-Olu ti lọ ṣètọ́jú ara rẹ̀ rí ní ilé ìwòsàn náà nítorí ó láárùn ọpọlọ rí.
Olùdíje ẹgbẹ́ òsèlú APC àti PDP ń sòkò ọ̀rọ̀ síra wọn
Ojú rèé ìran rèé nílù Èkó bí àwọn olùdíje gbòógì fún gómìnà méjèèjì ṣe ń sòkò ọ̀rọ̀ sí àrà wọn lórí àtẹ̀jíṣẹ́ twitter.
Femi Hamzat yẹ̀bá fún Sanwo-Olu ní ìdìbò abẹ̀lẹ̀ APC
Nínú ọ̀rọ̀ Jìmí Agbaje, ó ní nínú gbogbo ìfọ̀rọ̀wánilẹnuwò tí ó tí ṣe láti ọjọ́ yìí, Babajide Sanwo-Olu kìí gbórí yìn fú àwọn ènìyàn ìpínlẹ̀ Eko bíkòse kíí ò máá dúpẹ́ lọ́wọ́ ẹni tó ń pe ni asujú ẹgbẹ́ tó ó sì máa ń dúpẹ́ fún àànfaní ti wọn fún òun. O fí kún ọ̀rọ̀ rẹ̀ pé Sanwo-Olu ò tó bẹ́ẹ̀ láti jade dupò gómìnà ìpínlẹ̀ Eko tíì baa ṣe pe wọn gbe lé àwọn ènìyàn ìpínlẹ̀ Eko lórí.
Oríṣun àwòrán, Babjide Sanwo-Olu
Olùdíje ẹgbẹ́ òsèlú APC àti PDP ń sòkò ọ̀rọ̀
Lẹ́yọọ ò sọka náà ní Babajíde ti dálohun , ó ké gbàjare sí àwọn ènìyàn ìpínlẹ̀ Eko pe alátako òhún Jimi Agbaje ń gbìyanjú láti dóju ọ̀rọ̀ rú tí ó sì ń gbìyànjú láti fa ọ̀rọ̀ ti kò ní ìtumọ pẹ̀lú lóri ìfọ̀rọ̀wánilẹ́nuwo ti òun ṣe níle iṣẹ́ amóhùnmáwòrán kan láàrọ̀ ànàá.
Ọlọ́páà Ghana ń wa pásítọ̀ tó fẹsẹ̀ fẹ lẹ́yìn tọ́mọ ijọ rì sọ́mi
Oríṣun àwòrán, DONAT SOROKIN
Pásítọ̀ fẹsẹ̀ fẹ lẹ́yìn tọ́mọ ijọ rì sọ́mi
Ẹni ọmọ ogún ọdún kan kú ikú oró ní orílẹ̀-èdè Ghana, lẹ́yìn tó rì sínú omi lásìkò tó lọ se ìrìbọmi ní odò Densu, ní Accra.
Akoroyin BBC ní Ghana Favour Nunoo tó ba agbenusọ ọlọpàá ní Accra DSP Afia Tenge tó fìdí ọ̀rọ̀ náà múlẹ̀ sàlàyé pé ní gẹ́rẹ́ ti àwọn gbọ́ ìṣẹ́lẹ̀ náà ní àwọn lọ sí ibi tó ti sẹlẹ̀ ti ọ̀kan nínú àwọn olùsọ́àgùntàn ìjọ náà ti wà ní gbaga ọlọ́pàá báyìí.
Nínú fọ́nrán tó ń jà ràìnràìn lọ́ri ayélujárá ní Accra, ọdámọkunrin tó dórú sétí odò àti olùsọ́àgùntàn tó ń rìí bọ inú odò  ní àkọ́kọ́, ìrìbọmi elékejì ní okùnrin náà bẹ̀rẹ̀ sí ni rì.
Ẹ wo fọrán ìrìbọmi náà ní àtagbà Ghana in Africa Facebook
Ìṣẹ̀lẹ̀ náà wáye lọ́jọ́ àìkú, ọjọ́ kẹsán, Oṣù kejìlá, 2018, èyí tó fàá kí àwọn ìbérè máà jẹ̀yọ lórí ẹ̀rọ ayélujára pé kíló dé tí ènìyàn yóò ṣe máa sọ ẹmi rẹ̀nù nítorí ètò ẹ̀sín
Àwọn ebí eni tó kú náà sàlàyé pé kò sí ǹkan tí àwọn fẹ́ bá ọlọ́run fà àwọn kò sì da ẹbi ru ẹníkẹ́ni nínú ìṣẹlẹ̀ náà, wọ́n ní ohun tó ṣe pàtàkì ọ̀nà tí wọn ó gba sin òkú rẹ̀ ló  jẹwọn lógún jùlọ.
Àjọ ọlọ́pàá tún sàlàyé fún àkọròyìn BBC pé àwọn ti rí òkú ọkùnrin nàà tí ó sì ti wà ní mọ́ṣúàrí ọlọ́pàá àti pé àwọn ó tún ṣe àyèwò okú náà kí wọn to le gbée fún àwọn ẹbi rẹ̀
Ẹ̀wẹ̀, pásítọ̀ kan tí ọwọ́ to wà ní àgọ́ wọn, nígbà ti wọn sì ń wá olórí ìjọ tó ṣe ìtẹ̀bọmi náà fún ẹni tó di olóògbé.
Ìjọba Naijiria: Ọ̀rọ Olusẹgun Ọbasanjọ kò jọ wá lójú mọ́
Oríṣun àwòrán, @Atiku
Ọbasanjọ ti sọ tẹlẹ pe oun le fi Atiku yangan pe yoo sisẹ pẹlu ọ̀wọ̀ àti ìrẹ̀lẹ̀
Ijọba orilẹede Naijiria ti bu ẹnu atẹ lu ọrọ ti Olusẹgun Ọbasanjo sọ laipe yii pe ki se ọrọ ti awọn le fi esi si.
Aarẹ orilẹede Naijiria tẹlẹri, Olusegun Obasanjo laipe yii sọ wi pe oun ko sẹnurọ ninu idibo 2019 ati wi pe Aarẹ Muhammadu Buhari gbọdọ fi ipo silẹ ni idibo ọdun 2019.
Agbẹnusọ fun Aarẹ Buhari, Garba Shehu lasiko to n ba awọn oniroyin sọrọ ni Abuja, sọ pe ko nii se pẹlu awọn ẹnikeni ti Ọbasanjọ ba dibo fun lọdun 2019.
Shehu ni igba akọkọ ko ni yii ti Olusegun Ọbasanjo yoo ma se segesege lati sọ ẹni ti yoo se alatilẹyin fun ninu idibo ọdun 2019.
Nigeria swearing in 2019: Babajide Sanwoolu gba ọpa àṣẹ láti tukọ̀ Eko
Ọjọ́ kẹẹdọgbọn, oṣù kẹfà, ọdún 1965 la bí Babajide Olusola Sanwoolu tó ti jawe olubori ninu idibo ipinlẹ Eko.
O jẹ́ olùdíje fún ipò gómínà Ìpínlẹ̀ Eko lábẹ́ ẹgbẹ́ òṣèlú APC, eyí tó jẹ́ pé ẹni ọdún mẹ́rìnléláàdọ́ta ni.
Ẹ̀kọ́
Fásitì Eko (UNILAG) ló ti kọ́kọ́ kẹ́kọ̀ọ́ gboyè wọnlẹ̀wọnlẹ̀ (Surveying) nígba tó wà ní ẹni ọdún mẹ́tàlélógún ní ọdún 1988.
Láìpẹ́ rẹ̀ ni ó tún kẹ́kọ̀ọ́ gboyè àgbà ìmọ̀ okòwò ni fásìtì kan náà.
Ó tún tẹ̀ síwájú láti kẹ́kọ̀ọ́ ìmọ̀ okòwò àti ìṣèjọba ní àwọn ilé ẹ̀kọ́ gígá wọ̀nyìí:
Àwọn ibi tó ti ṣiṣẹ́
Sanwo Olu bẹ̀rẹ̀ iṣẹ́ ṣíṣe ní ilé ìfowópamọ́ Lead Merchant Bank láàrin ọdún 1994 sí 1997 gẹ́gẹ́ bíì akápò.
Lẹ́yin náà ni ó tún gbéra lọ ilé ìfowópamọ́ UBA gẹ́gẹ́ bí adarí owó lati òkèèrè.
Lẹ́yìn èyí ni ó lọ ilé ìfowópamọ́ First Inland Bank, èyí tí a mọ̀ sí First City Monument Bank báyìí.
Oríṣun àwòrán, Babajide Sanwoolu
Àwọn iléeṣẹ́ àdáni tí Sanwoolu ti ṣe adarí
Gomina tuntun ti ajọ INEC kede náà jẹ́ alága iléeṣẹ́ Baywatch Group Limited àti First Class Group Limited nígbà kan rí.
Ó tún jẹ́ ọ̀kan lára àwọn ọmọ ìgbìmọ̀ ayẹ̀wé owó wò fún Caverton Offshore Services Group Plc.
Àgbà ni Obasanjo, oun tó ń sọ yé e, ìjọba ni kó tají - Wale oke
Àwọn ipò òṣèlú tó ti dì mú rí:
Ọdun 2003 ni Sanwo Olu bẹ̀rẹ̀ òṣèlú nígba tí igbákejì gomina Ipinlẹ Eko nígbà kan rí Femi Pedro yàn án gẹ́gẹ́ bíi olùdámọ̀ràn pàtàkì lórí ọ̀rọ̀ àwọn iléeṣẹ́ àdáni.
Lẹyìn náà ni Gomina Ipinlẹ Eko lákòókò náà, BolaTinubu yàn án gẹ́gẹ́ bíi olùdámọ̀ràn pàtàkì lórí ọ̀rọ̀ àwọn iléeṣẹ́ àdáni lẹ́yìn tí wàhálà bẹ́ sílẹ̀ láàrin Pedro àti Tinubu.
Òun ni alága àkọ́kọ́ ìgbìmọ̀ tó ń ṣe àkóso Security Trust Fund Ipinlẹ Eko.
Murphy Elégungun Rọba: Mo fẹ́ di ẹnití egungun rẹ rọ jùlọ ní àgbáyé
Àwọn ipò òṣèlú mìíràn tó dìmú lẹ́yìn èyí rèé:
Oríṣun àwòrán, Lagos State Government
Ní ọdún 2016, Gomina Akinwunmiu Ambode yàn án gẹ́gẹ́ bíi adarí iléeṣẹ́ ìjọba Ìpínlẹ̀ Eko tó ń ṣàkóso àwọn ilé kíkọ́.
Oluṣọla Sanwo olu lo gba aṣẹ lati bẹrẹ si ni tukọ ipinlẹ Eko ni ọjọ kọkandinlọgbọn, oṣu karun un, ọdun 2019.
Ìbádọ́gba nínú ìsèlú àti iṣẹ́ láwùjọ ṣe pàtàkì fún ìdàgbàsóké
Climate Change: Àwọn ọmọ Nàìjíríà mẹ́ta gba owó ìrànwọ́ iwádìí ìjìnlẹ̀
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ko si ẹka iṣẹ ati iṣe ti ọmọ Naijiria ko tii maa moke tabi ko ipa ribiribi lagbaye
Awọn olukọ fasiti mẹta lorilẹ-ede Naijiria ni wọn ti gba owo iranwọ bayii fun iwadii imọ ijinlẹ lori ayipada ayika ati ojuọjọ.
Arunma Oteh ni igbakeji aarẹ banki agbaye, World Bank. Oun si tun ni akapo banki naa bayii.
Orukọ rẹ wa ninu iwe itan gẹgẹ bii ẹni ti o ṣe afọmọ ọja idokoowo lorilẹ-ede Naijiria lasiko ti o fi jẹ oludari agba fun ajọ ọja idokoowo Naijiria, SEC.
Fasiti orilẹ-ede Naijiria, to wa ni ilu Nsukka ni o ti kẹkọ jade. Oun naa pẹlu ṣiṣẹ diẹ pẹlu Banki idagbasoke ilẹ Afirika atawọn ajọ miran lagbaye ki wọn to yan an gẹgẹ bii oludari agba ajọ ọja idokoowo ní Naijiria ni asiko iṣejọba Aarẹ Umaru Musa Yaradua.
Oríṣun àwòrán, Alamy
Ajọ iwadi ijinlẹ African Institute for Mathematical Sciences (AIMS) fun awọn ọmọwe naa ni owo iranwa iwaadi
Ajọ iwadi ijinlẹ African Institute for Mathematical Sciences (AIMS) fun awọn olukọ fasiti naa, Ọmọwe Daniel Akinyele, Ọmọwe Ayanṣina Ayanlade ati Ọmọwe Adanna Henri-Ukoha ni owo iranwọ naa pẹlu awọn Ọmọwe miran jakejado ilẹ Afirika bii Ọmọwe Lindani Ncube lati South Africa, Ọmọwe Timothy Dube lati Zimbabwe pẹlu Ọmọwe Muhire Innocent lati Rwanda.
Lẹyin ayẹwo to jina to si gbona girigiri ni wọn yan awọn mẹfa yii eyi ti ọpọ sọ pe o ṣafihan pe kii ṣe ninu iwa ibajẹ nikan ni awọn ọmọ orilẹede Naijiria ti n tayọ bikoṣe ninu awọn ohun amuyangan pẹlu.
Kii kuku ṣe awọn mẹta yii nikan ni ọmọ Naijiria ti o n da bi ẹdun, rọ bi owe lawujọ agbaye, ọpọ lo n tayọ lawọn ẹka bii imọ ẹrọ ati sayẹnsi, irinajo afẹ, karakata ati idokoowo lai yọ idaleeṣẹ silẹ ati bẹẹbẹẹ lọ sẹyin.
Diẹ lara wọn niyi:
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Owo iranwọ iwaadi ijinlẹ ti wọn gba naa yoo tubọ mu idagbasoke ba imọ nipa ayipada oju ọjọ ati iṣesi ayika
Akinwumi ni aarẹ banki idagbasaoke Afirika, African Development Bank, ADB bayii. O de ipo yii pẹlu iṣẹ takuntakun ti o gbe ṣe lasiko ti o fi wa nipo akoso lorilẹede Naijiria. Fasiti Ile Ifẹ ti o ti di fasiti Ọbafẹmi Awolọwọ , OAU bayii ni o ti kẹkọ jade. Ipo minisita fun eto ọgbin labẹ iṣejọba aarẹ Goodluck Jonathan ni o wa ti wọn fi dibo yan an fun ipo aarẹ banki afirika naa.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Awọn ìròyìn ìwà ìbàjẹ́ ni ó ń s'aba máa jáde nípa àwọn ọmọ Nàìjíríà káàkiri àgbáyé
Laipẹ yii ni wọn yan an gẹgẹ bii akọwe ẹgbe ajọ awọn orilẹede to n wa epo rọbi lagbaye, OPEC yatọ si iriri rẹ lẹka epo rọbi, o ni iriri pupọ pẹlu ni ẹka ifowopamọ ati awọn ileeṣẹ idokoowo agbaye. Ni ọdun 2009 ni wọn yan an gẹgẹ bii Ọga agba ajọ epo rọbi lorilẹ-ede Naijiria, NNPC ki aarẹ Goodluck Jonathan to yọ ọ nipo lọdun 2010 ti o si pada si ajọ OPEC.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ọ̀pọ̀ ló ṣì ń dá bí ẹdun rọ̀ bí òwè nínú iṣẹ́ tí wọ́n yàn láàyò.
John jẹ ara awọn elere itage ti irawọ rẹ ṣẹṣẹ  n yọ ni agbo ere fidio agbelewo ni orilẹ-ede Amẹrika. Ilẹ Gẹẹsi ni o gbe nibẹ ni o si ti bẹrẹ ere itage ṣiṣe ni ileewe lati nnkan bi ọdun mẹjọ. Ki o to lu aluyọ pẹlu ipa ti o ko ninu ere gbajugbaja ni the Star Wars.
O kopa ninu fidio agbelewo ti wọn ṣe ninu iwe ilumọọka Half of a Yellow Sun ti gbajugba akọwe nni, Ngozi Adichie kọ. Ọrẹ lo si jẹ Damilọla Taylor, ọmọ Naijiria ti awọn eeyan kan yinbọn pa ni ilẹ Gẹẹsi ni ọdun 2000.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
ẹẸka bii imọ ẹrọ ati sayẹnsi, irinajo afẹ, karakata ati idokoowo lai yọ idaleeṣẹ silẹ ati bẹẹbẹẹ lọ ni awọn ọmọ Naijiria ti n tan bi oorun
Ilu Eko ni Hakeem gbe ni igba ewe rẹ ki o to lọ si ilu London fun ẹkọ nileewe ere itage Briston Old Vic Theater Shool. Lẹyin eyi lo si kopa ni awọn fidio agbelewo to gbajumọ lagbaye bii Hotel Rwanda, Pirates of the Carribean: At World's End ati X-Men Origins: Wolverine pẹlu 24 hours.
Oríṣun àwòrán, Texas Children's Hospital
Dokita iṣegun ti o ṣe ohun ti ẹni kan ko ṣe ri ni Dokita Oluyinka Olutoye. Ohun ni dokita ti o ṣe iṣẹ abẹ fun oyun inu, ti o si tun gbe e pada si inu iya rẹ pada ki wọn to bii.
Bi o tilẹ jẹ pe awọn dokita iṣegun kan ni ki arabinrin naa o ṣẹ oyun naa, Dokita Olutoye atawọn ẹmẹwa rẹ ni ileewosan Texas Children's Hospital ni ko si iṣoro bi obinrin naa ko ba dẹyẹsi ki wọn ṣe iṣẹ abẹ fun un ki wọn gbe oyun inu rẹ jade ki wọn si ṣe iṣẹ abẹ fun oyun naa lati yọ jẹjẹrẹ ti o n daa lamu.
Lẹyin wakati marun un, Dokita Olutoye atawọn ikọ dokita ti o ko sodi pari iṣẹ abẹ naa wọn si da oyun yii pada si inu iya rẹ ki wọn to wa bii ni nnkan bi ọsẹ mejila lẹyin iṣẹ abẹ naa.
'Mo ti gba kádàrá lórí bí Ọlọrun ṣe dá mi'
Gbogbo agbaye ni okiki iṣẹ abẹ aramọnda yii kan de ti wọn si n pe ọmọ ti wọn bi naa ni ọmọ ti wọn bi ni igba meji ọtọọtọ.
Fasiti Ọbafẹmi Awolọwọ ni Oluyinka Olutoye ti kọkọ gba oye imọ ijinlẹ akọkọ ninu imọ iṣegun ati iṣẹ abẹ ki o to gba oke ọkun lọ lati lọ gba imọ kun imọ.
Nibayii oun ni Oludari agba ileewosan awọn ọmọ wẹwẹ ti Texas Children's Hospital lorilẹede Amẹrika.
CJ Gold: ẹ̀rù kọ́ka ba ìyá mi nígbà ti mo fẹ́ bẹ̀rẹ̀ iṣẹ́ ìjà jíjà
Omi titun ti rú nínú oríṣii ètò ìgbéyàwó Yorùbá lásìkò yí
Europa: Arsenal, Chelsea gbáradì fún ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ ìpele ìsọ̀rì tó kẹ́yìn
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Arsenal ati Chelsea ti kógojá fún ìpele tí ó kàn nínú ìdíje Europa ti sáà bọ́ọ̀lù 2018/2019
Awọn ẹgbẹ agbabọọlu kaakiri ilẹ Yuroopu yoo tun kan lu papa ni ọjọbọ ninu ifẹsẹwọnsẹ ti o gbẹyin ninu abala isọri-isọri idije Europa ti saa ọdun 2018/2019.
Lara wọn ni awọn ikọ agbabọọlu ilẹ Gẹẹsi bii Arsenal ati Chelsea.
Lootọ Arsenal ati Chelsea ti pegede fun ipele to kan, ṣugbọn awọn mejeeji ṣi n ja fun pipegede lati jawe olubori ninu isọri wọn.
Ẹgbẹ́ agbábọ́ọ̀lù parọ́ ikú mọ́ agbábọ́ọ̀lù rẹ̀ láti wọ́gilé ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀
Arsenal yoo maa koju ikọ agbabọọlu FK Qarabag ni papa iṣire Emirates; nigba ti Chelsea yoo lọ ba MOL Vidi lalejo .
"Olukọ ẹgbẹ agbabọọlu Chelsea, Maurizio Sarri ni ifẹsẹwọnsẹ naa ""le pupọ lati gbaradi fun""."
Amọṣa, o ni oun yoo gbe ikọ ti ko fi bẹẹ le pupọ kalẹ fun ifẹsẹwọnsẹ naa nitori ọna ti la fun wọn pe awọn yoo bori isọri naa.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Lootọ Arsenal ati Chelsea ti pegede fun ipele to kan, ṣugbọn awọn mejeeji ṣi n ja fun pipegede lati jawe olubori ninu isọri wọn
Ifẹsẹwọnsẹ naa yoo le pupọ nitori pe ko si afojusun tabi ilepa to yanranti kan lori rẹ
"O fi kun un pe""Ifẹsẹwọnsẹ ti a gba ṣaaju eyi pẹlu ikọ agbabọọlu Vidi ti a bori pẹlu ami ayo kan si odo le pupọ nitori wọn di oju ile wọn daradara, o nira fun wa pupọ lati gba ayo wọ ile wọn."""
Fun ẹgbẹ agbabọọlu Arsenal, olukọni ẹgbẹ agbabọọlu naa, Unai Umery ni oun ko tii lee sọ boyaMesut Ozil yoo kopa ninu ifẹsẹwọnsẹ naa nitori ẹyin ti o n dun un.
Amọṣa o ni Laurent Koscielny yoo kopa lẹyin ti o ti gbọn ara nu kuru ninu iṣoro iṣan ẹsẹ ti o n yọọ lẹnu.
Bakan naa lo ni Aaron Ramsey yoo kopa n inu ifẹsẹwọnsẹ naa.
Ẹ̀rù ló n bà NEDG ni kò jẹ́ kí wọ́n pè mí sí ìfọ̀rọ̀wérọ̀ f'áwọn olùdíje
Oríṣun àwòrán, @yelesho
Ṣoworẹ sọ pe oun yoo sọ tita ati lilo igbó di ohun to ba ofin mu ni Naijiria ti oun ba fi di aarẹ
Oludije fun ipo aarẹ ninu ẹgbẹ oṣelu African Action Congress, (AAC) ninu eto idibo aarẹ Naijiria l'ọdun 2019, Ọmọyẹle Ṣoworẹ sọ pe ẹrù ni ko jẹ ki ẹgbẹ to n ṣeto ifọrọwerọ lasiko eto idibo ni Naijria, Election Debate Group (NEDG) pe oun si ibi ifọrọwerọ laarin awọn oludije fun ipo aarẹ.
Ṣoworẹ sọ ọrọ yii ninu ọrọ to ba BBC Pidgin sọ lati fesi si bi NEDG ko ṣe fun l'anfaani lati kopa ninu ifọrọwerọ na
Sòwòrẹ́: Èmi kò leè bá jẹgúdújẹrá APC àti PDP se pọ̀
Oludije maarun pere ninu eyi ti Aarẹ Muhammadu Buhari ati alatako rẹ̀ gboogi, Atiku Abubakar, ni ẹgbẹ NEDG ati Ẹgbẹ agbohunsafẹfẹ, Broadcasting Organization, pe fun ifọrọwerọ laarin awọn oludije fun ipo aarẹ.
Oṣu Kinni, ọdun 2019 ni eto naa yoo waye.
Awọn nkan mẹta ti awọn ọmọ Naijiria yoo ṣafẹri ninu ohun ti oludasilẹ ileeṣẹ iroyin Sahara Reporters Òun i ba sọ nibi ifọrọwerọ naa.
1.Ominira lati lo tabi ta igbó - Ṣoworẹ ti sọ tẹlẹ pe ọpọlọpọ orilẹede l'agbaye ti mọ anfaani to wa ninu igbo lilo ninu eto iwosan ati ọrọ aje, nitopi pe o le p'awo wọle. Eyi lo mu ki Ṣoworẹ sọ pe oun yoo sọ tita ati lilo igbó di ohun to ba ofin mu. Nibi ifọrọwerọ yii ni ko ba ti l'anfaani lati ṣalaye ọna to fẹ ẹ gbe gba.
2.Ọgọrun ẹgbẹrun Naira owo oṣu oṣiṣẹ to kere ju - Awọn gomina ipinlẹ ati ẹgbẹ oṣiṣẹ ṣi n jiyan lori ọgbọn ẹgbẹrun Naira ti awọn oṣiṣẹ n fẹ gẹgẹ bi owo oṣu to kere ju. Ṣugbọn, Ṣoworẹ sọ pe ọgọrun ẹgbẹrun Naira l'oun yoo san ti oun ba di aarẹ, nitori pe Naijiria ni owo lati san an. Nibi ifọrọwanilẹnuwo naa ni ko ba ti raaye sọ bi yoo ṣe ṣe e.
3.Ẹgbẹrun mọkanlelogun agbara ina (Megawatts) laarin ọdun kan - Oludije naa ko ba lo anfaani lati ṣariyan-jiyan lori ohun to fa a ti orilẹede Naijiria ṣi fi n lo ẹgbẹrun mẹta agbara ina mọna-mọna, nigba to yẹ ko ti tayọ ọ rẹ. Oludije naa sọ pe erongba oun ni lati fi ẹgbẹrun mọkanlelogun kun, ti yoo si jẹ ẹgbẹrun mẹrinlelogun laarin ọdun kan ti oun ba di aarẹ.
Faṣọla: Kìí ṣe ẹ̀bi ìjọba àpapọ̀ tí o kò bá rí iná ọba lò
Oríṣun àwòrán, @fasola
Faṣọla ni ki ẹnikẹni má ṣe da ẹ̀bi ru ijọba mọ
Oriṣiriṣi nkan lawọn ọmọ Naijiria ti n sọ lori ohun ti Faṣọla sọ nipa ina mọnamọna Naijiria lasiko yii.
Tó ò bá ri ina mọnamọna lo, kii ṣe ẹbi ijọba apapọ ni ọrọ ti awọn ọmọ Naijiria n ba minisita fun nkan amuṣagbara, ile gbigbe ati iṣẹ ode, Babatunde Fashọla, fà.
Fashọla ni iroyin sọ pe o sọ ọrọ yii nibi ipade ijiroro kan to waye lori ọrọ ina mọnamọna, Nextier Power Dialogue, lalẹ Ọjọru, nilu Abuja.
Fashola sọ fun awọn to wa nibi eto naa pe lootọ ni iṣoro wa lẹka nkan amuṣagbara, ṣugbọn o ni ki wọn o ranti pe kii ṣe iṣoro ijọba apapọ ti awọn araalu ko ba ri ina mọnamọna lo, paapa niwọn igba ti wọn ti sọ ẹka naa di ti aladani.
'Gbogbo dukia ileesẹ to wa fun nkan amuṣagbara ti wọn n lo fun amojuto ina mọnamọna ni iṣakoso to kọja ta ki n to de ipo. Nitori eyi, ka ma parọ fun'ra wa, kii ṣe ẹbi ijọba ni ti ẹ ko ba ri ina lo.''
"Fashọla ṣalaye pe ""ojuṣe kan ṣoṣo ti oun ni ni lati pese awọn ilana ti wọn yoo mu lo ati amojuto, bo tilẹ jẹ wi pe mi o le ri iṣoro ki n ṣe bi alairi i.''"
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ina mọnamọna jẹ koṣee-mani fawọn eniyan lawujọ ọlaju. Yoruba ni ti ẹyin lohùn, to ba ti bọ, ko ṣee kó mọ́.
Awọn kan ran Faṣọla leti pe ina ọba wa lara awọn koko ti ijọba yii fi ṣe ipolongo idibo lọdun 2015. Lara wọn ni Senetọ Shehu Sanni to pe Faṣọla ni opurọ ni ikanni twitter rẹ pe:
Babatunde Fashọla sọ pe awọn olokoowo to ra ileeṣẹ ina mọnamọna ni ki awọn eniyan d'oju ibeere tabi ẹdun ọkan wọn lori airi ina lo kọ, kiiṣe oun gẹgẹ bi minisita tabi ijọba apapọ.
Awọn bii Banusọ n beere fun alaye lori ona ti ijọba ti gba ta ina ọba ati ọna pinpin ina mọnamọna.
Pupọ ninu awọn to n fesi si ohun ti Fashọla sọ loju opo Twitter sọ pe ki Fashọla ranti ọrọ to sọ l'ọ̀dun 2014 pe ''ijọba to ba mọ nkan to n ṣe yoo yanju wahala to n koju ina mọnamọna ni Naijiria laarin oṣu mẹfa pere.''
Awọn miran gbà pe kii ṣe Faṣola ti awọn mọ to tun ipinlẹ Eko ṣe lo n sọrọ bayii sawọn eniyan Naijiria.
Bakan naa lawọn miran ni:
Aimọ iye igba ni ijọba to wa ni iṣakoso ti sọ ni gbangba pe ipese ina mọnamọna ti dara si ju bi awọn ṣe ba a lọ, ṣugbọn ohun ti awọn araalu n sọ tako eyi.
Bi awọn kan ṣe n pariwo airi ina lo daada, ni awọn miran n polongo pe owo ti awọn ileeṣẹ amunawa n gba lọwọ awọn oniibara pọju boṣeyẹ lọ.
'Mo ti gba kádàrá lórí bí Ọlọrun ṣe dá mi'
Nigeria Swearing in 2019: Seyi Makinde di gómìnà tuntun
Ọjọ kẹẹdọgbọn oṣu kejila ọdun 1967 ni wọn bi Oluwaseyi Abiodun Makinde si idile oloogbe Pa Olatunbosun Makinde ati iyaafin Abigael Makinde ni agbo ile Aigbọfa Oja'aba, ilu Ibadan.
Seyi Makinde bẹrẹ ile iwe alakọbẹrẹ ni St. Paul Primary School, ko to re si ile iwe alakọbẹrẹ St. Michael Yemetu, mejeeji ni ilu Ibadan.
Ile iwe Girama ti Bishop Phillips Academy ni Monatan, Ibadan lo lọ.
Oludije ipò Gómìnà labẹ asia PDP ní Oyo sọrọ nípa Ladoja
Ni ọdun 1985, o wọ ile iwe giga fasiti ilu Eko, nibi to ti gba oye Bachelor's degree ninu imọ ẹrọ, Electrical Engineering.
Makinde ṣe agunbanirọ ni ile iṣẹ epo Shell lọdun 1990, lati ibẹ lo ti bẹrẹ iṣẹ nipa biboju to oniruuru ẹka ile iṣẹ epo naa.
Oríṣun àwòrán, @SupportSeyi
Oniṣowo ni Ṣeyi Makinde, oloṣelu si ni pẹlu. O jẹ akọṣẹmọṣẹ ninu imọ ẹrọ. O ti ṣiṣẹ ni ọpọlọpọ ẹka imọ ẹrọ ati awọn ile iṣẹ epo bẹntiroo ati afẹfẹ gaasi lorileede Naijiria ati loke okun. Bẹẹ naa si lo ka iwe kun iwe sii loke okun.
Ẹ́ni ọdun mọkandilọgbọn ni Seyi Makinde nigba to kọkọ da ile iṣẹ epo ati afẹfẹ gaasi aladani tirẹ silẹ lọdun 1997, lẹyin to ti ṣiṣẹ fun ọdun marun un nile ati lẹyin odi.
Gẹgẹ bi oludari ati alakoso ile iṣẹ epo, Makinde ti darapọ mọ ọpọlọpọ ẹgbẹ awọn akọṣẹmọṣẹ ninu iṣẹ epo bẹntiroolù ati afẹfẹ gaasi lorilẹede Naijiria ati loke okun.
Oríṣun àwòrán, @seyimakinde
Oluwaseyi Makinde
Ni ti Oṣelu, Seyi Makinde ti du ipo aṣoju nile aṣofin fun ẹkun idibo Guusu ipinlẹ Oyo labẹ asia ẹgbẹ oṣelu All Nigeria Peoples Party, ṣugbọn o bọ mọ ọ lọwọ si ọwọ oludije ẹgbẹ oṣelu PDP nigba naa lọhun, Kamoru Adedibu.
Makinde ko jẹ ki ijakulẹ rẹ fun igba akọkọ da omi tutu si i lọkan, o tun gbe apoti ibo lati ṣoju ẹkun idibo kan naa lọdun 2011 ṣugbọn nibi idibo abẹle lo ti fidi re'mi.
Lọdun 2014, Seyi Makinde kara bọ didu ipo gomina labẹ asia ẹgbẹ oṣelu Peoples Democratic Party.
Oríṣun àwòrán, Oluwaseyi Makinde
Day 20: Ìgbà mélòó ni Ṣeyi Makinde ti dupò rí? #BBCNigeria2019
Ni kete ti wọn pari idibo abẹle ni wọn ko fun un ni tikẹẹti 'a yan ọ gẹgẹ bi oludije ẹgbẹ', sugbọn o bọ lọwọ rẹ si ọwọ oludije miran.
Ẹwẹ, Makinde o mikan, o tẹra mọ ipinu rẹ o si kuro ni ẹgbẹ oṣelu PDP lọ si ẹgbẹ oṣelu Social Democratic Party, SDP nibi tó ti dije gẹgẹ bii gomina ipinle Oyo lodun 2015 ṣugbọn nigbẹyin, ko bọ sii fun un.
Oríṣun àwòrán, @seyimakinde
Oluwaseyi Makinde
Lọdun 2017, amoju ẹrọ Makinde pada si ẹgbẹ oṣelu rẹ tẹlẹ, PDP; o ni kii ṣe tori anfani ti oun yoo jẹ loun ṣe dara pọ mo egbe PDP, bi ko se fun idagbasoke ipinle Oyo nipa wiwa ojutu si opolopo isoro to n doju ko ipinle naa.
Ni ojo kokandinlogbon osu kesan, odun 2018, Makinde jawe olubori gege bi eni ti yoo dije fun ipo gomina legbe oselu Peoples Democratic Party, ninu idibo gbogbo gbo ti odun 2019 nipinle Oyo.
Ibo 2,772 lo ni ninu idibo abele eyi to waye ni ilu Ibadan.
Mọ̀ síi nípa Yakubu tó wọ bàtà tí Jẹ́gà bọ́ sílẹ̀ ni INEC
Oríṣun àwòrán, @inec
Ẹni to ba dantọ lo le ṣeto idibo Naijiria ko kógo já
Oṣu karun un, ọdún 1962 ni wọn bi Mahmood Yakubu nipinlẹ Bauchi ni ariwa iwọ oorun Naijiria.
O lọ sile iwe alakọbẹrẹ Kobi ko to lọ si ile ẹkọ ikọni-niṣẹ olukọ laarin ọdun 1975 si ọdun 1980 nibi to ti gbegba oroke ni kilaasi rẹ ko to lọ si fasiti Ṣokoto to ti di ti Usman Danfodio bayii.
INEC yoo sun miliọnu meje kaadi idibo
Mahmood gbami ẹyẹ Waziri ti Ṣokoto lọdun 1985 nigba ti o jẹ akẹkọọ to dara julọ ninu ẹko nipa ìtàn oṣelu to ti ṣetan pẹlu ipele akọkọ. Oun ni o jẹ ọmọ ilẹ Hausa akọkọ ti yoo gbami ẹyẹ ipele kinni yii.
Oríṣun àwòrán, @inec
Ibeere ọpọlọpọ ni pe ṣe Mahmood to lati wọ bata Jẹga?
Ati ranmu gangan, kọ ṣeyin eekanna ni ọrọ aṣeyọri Mahmood.
O ri anfani owó iranwọ gbà loriṣiiriṣii lati fi kawe bii ti owo ẹkọ ọ̀fẹ́ tipinlẹ Bauchi ati Cambridge Commonwealth Trust Scholarship ni eyi to fi kẹkọọ gboye ikeji lori ọna ibaraẹniṣepọ lagbaye lọdun 1987 ati iranwọ to fi gba oye ọmọwe ni Oxford lọdun 1991 lọmọ ọdun mọkandinlọgbọn.
Opọlọpọ ami ẹyẹ bii ti Beit Fund Research Grant lo gba lasiko to n kawe nilu Ọba.
Yakubu Mahmood bẹrẹ iṣe olukọni ni fasiti Jos lọdun 1986 ko to lọ si Defence Academy ni Kaduna nibi to ti goke agba gba oye ọjọgbọn lọdun 1998.
Oríṣun àwòrán, @inec
Mahmood ti fawon eeyan Naijiria lokan bale pe, didun losan a so ninu idibo 2019 nitori INEC a ṣiṣẹ bo ti yẹ
O ṣe adari ati alakoso ẹka eto ẹkọ lorisiirisii ni eyi to ti ni iwe apilẹkọ to le ni aadọta.
Mahmood ṣiṣe kaakiri bii nio ajọ TETFund, ETF, PRESID ati bẹẹ bẹẹ lọ.
Ohun to jẹ ọjọgbọn Mahmood logun ni ayipada rere si awọn ẹka eto ẹkọ ni Naijiria ni eyi to n sọrọ le lori lasiko to n kopa ninu apero CONFAB tọdun 2014 ti aarẹ Goodluck Jonathan pè.
Oríṣun àwòrán, @inec
Abajade iṣẹ ti ajọ INEC ba ṣe ninu idibo 2019 yii lo maa sọ ibi ti Naijiria n lọ
Oṣu kẹwaa, ọdun 2015 ni Buhari yan Ọjọgbọn Mahmood Yakubu to gba iṣẹ lọwọ Amina Zakari ti aarẹ Buhari yàn gẹgẹ bii adelé alaga ajọ eleto idibo INEC leyin ti Ọjọgbọn Attahiru Jega lọ lẹyin idibo 2015.
Obasanjo: Buhari ní àìlera lẹ́mìí, lára, àti lọ́kàn.
Wọn yan Amina Zakari gẹgẹ bi adele lọgbọn ọjọ, oṣu keje, ọdun 2015 lẹyin ti Jẹga pari ọdun marun un rẹ gẹgẹ bii alaga ajọ INEC.
Ọjọgbọn Mahmood Yakubu gbe iyawo, o si bi ọmọkunrin meji ati ọmọbinrin meji.
Kinni wọn n pè ni oṣupa déjé ní kíkún?
'Obinrin jẹ amuludun'
Minimum Wage: Apá àwọn gómìnà ò ká ọgbọ̀n ẹgbẹ̀rún Naira owó oṣù-Yari
Oríṣun àwòrán, @BashirAhmad
Buhari wa fi ẹmi imoore rẹ han si awọn akẹẹgbẹ rẹ ninu ajọ Ecowas
Aarẹ Buhari sọ fun wa pe eto ọrọ aje orilẹede Naijiria ko dara lasiko yii.
Eyi ni ọrọ ti iroyin sọ pe alaga ẹgbẹ awọn gomina, to tun jẹ gomina ipinlẹ Zamfara, Abdulaziz Yari, sọ fun awọn oniroyin lẹyin ipade ti awọn gomina mẹrindinlogoji to wa ni Naijiria ṣe pẹlu Aarẹ Muhammadu Buhari l'ọjọ Ẹti.
Gẹgẹ bi o ṣe sọ, 'Aarẹ Buhari fi to wa l'eti wi pe ipo ti ọrọ aje Naijiria wa bayii ko dara. Nitorina, a gbọdọ pejọ, ki a ronu, ki a si sẹ atungbeyẹwo ọna abayọ.''
Ipade naa waye lati jiroro lori aigbọra ẹni ye to n waye laarin awọn gomina ati ẹgbẹ osisẹ lori ọgbọn ẹgbẹrun gẹgẹ bi owow oṣiṣẹ to kere ju.
Aarẹ Buhari ti ṣe iru ipade bẹ ẹ ri pẹlu awọn gomina l'ọjọ kọkandinlogun, oṣu Kọkanla, lẹyin ti igbimọ ẹlẹni mẹta gbe aabọ iwadi rẹ kalẹ fun Aarẹ Buhari. Ninu aabọ iwadi naa ni wọn ti gbero pe ki owo oṣu oṣiṣẹ to kere ju jẹ ọgbọn ẹgbẹrun Naira.
Minimum wage: Àwọn ọmọ Nàìjíríà sọ èrò wọn lórí ìyanṣẹ́lódì àwọn òṣìṣẹ́
Ṣugbọn, awọn gomina sọ pe ẹgbẹrun mejilelogun Naira ni awọn le san, nitori agbara awọn ko gbe ọgbọn ẹgbẹrun Naira.
Ọwọ́ ọ̀lọ́pàá tẹ́ àwọn afurasí ayédèrú apòógùn l'Eko
Oríṣun àwòrán, Abba Kyari
Ileeṣẹ ti wọn ti n ṣe oogun naa to wa ni adugbo Ikọtun-Egbe, nipinlẹ Eko, ni ileeṣẹ ọlọpa tu aṣiri rẹ lọjọru.
Ileeṣẹ ọlọpa ti ṣe awari ayederu ileeṣẹ kan nibi ti awọn kan ti n ṣe ayederu oogun oyinbo ni ilu Eko.
Ileeṣẹ ti wọn ti n ṣe oogun naa to wa ni adugbo Ikọtun-Egbe, nipinlẹ Eko, ni ileeṣẹ ọlọpa tu aṣiri rẹ lọjọru.
È gbọ àlàyé lẹnu àwọn ti ójúẹlẹgba leko irú iṣẹ ti oògùn olóró má n ṣé lara.
Ninu ikede to fi sita, Ọga Agba fun ẹka Ọtẹlẹmuyẹ kan nileeṣẹ ọlọpa, Abba Kyari fi sita l'oju opo Facebook rẹ, ọwọ tẹ afurasi mẹrin nibi ti wọn ti n ṣe ayederu oogun .
Oríṣun àwòrán, Abba Kyari
Lara ohun ti wọn ka mọ awọn afurasi naa lọwọ ni awọn Garawa to kun fun oriṣiriṣi ayederu oogun to fi mọ awọn kẹmika loriṣiriṣi ti wọn fi n ṣe awọn oogun naa.
Awọn afurasi naa, Emeka Madu to jẹ oludasilẹ ileeṣẹ naa, ati oṣiṣẹ mẹta; Eze Young, Chijoke Umunna ati Kingsley Obilo.
Lara ohun ti wọn ka mọ awọn afurasi naa lọwọ ni awọn Garawa to kun fun oriṣiriṣi ayederu oogun, awọn paali ayederu oogun ti wọn fẹ ẹ lọ ta, to fi mọ awọn kẹmika loriṣiriṣi ti wọn fi n ṣe awọn oogun naa.
Bakan naa ni wọn ba awọn ẹrọ agbelẹrọ ati ayederu iwe ẹri apoogun oyinbo ninu ile ti wọn n lo fun ṣiṣe awọn oogun naa.
Àwọn nkan tó jẹyọ níbi ìfọ̀rọ̀wánilẹ́nuwò f'áwọn tó fẹ́ di igbákejì àárẹ
Àwọn marun un ti wọn figagbaga sọ ohun ti wọn ni lọkan fun Naijiria ni 2019
Ipá kò rajà; ipá kò tàá ni ọ̀rọ̀ ijiroro awọn oludije igbakeji aarẹ bá de
Eruku sọ lasiko ti awọn oludije fun ipo igbakeji aarẹ marun un pejọ sibi ifọrọwerọ ti ajọ Nigeria Election Debate Group (NEDG) ati Broadcasting Organizations of Nigeria ṣagbatẹru rẹ l'Abuja lọjọ Eti
Yẹmi Osinbajo - All Progressives Congress (APC)
Peter Obi - People's Democratic Party (PDP)
Umma Getso - Youth Progressives Party (YPP)
Alhaji Abdulganiyu Galadima - All Congress Party of Nigeria (ACPN)
Khadijah Abdullahi-Iya - Alliance for New Nigeria (ANN)
Diẹ lara awọn nkan ti wọn sọrọ le lori niyii:
Bi awọn kan ṣe n binu pe wọn ko pe gbogbo oludije, ni wọn n ri ariwisi sawọn ti wọn kopa, loju Ọmọyẹle Ṣoworẹ:
Loju àwọn kan bii Omoba Abodunrin Siwoniku lori ikanni BBC Yoruba, wọn gbà pé ibi gbogbo la ti n kadiyẹ alẹ ni ọrọ iwa ibajẹ yii jẹ.
Obi n ṣafiwe ọrọ, Ọṣinbajo naa n fesi, lori ona abayọ siṣoro Naijiria
Loju Fayoṣe to jẹ gomina àná ipinlẹ Ekiti, Peter Obi ti PDP lo fakọyọ julọ pẹlu ọgbọn siṣoro eto ọrọ aje Naijiria lasiko yii ni eyi ti awọn miran fun un lesi pe irọ ló ba de.
Koko ti ọpọlọpọ n jiyan lé lori lẹyin ijiroro naa ni ọrọ Obi pe, o ko le tilẹkun ṣọọbu maa fojoojumọ le olè kiri ni eyi ti Ọṣinbajo fun un lesi pe, ko ni si ọja kankan mọ ni ṣọọbu to ba gba olè laaye lati maa jale lọ
Bi àwọn bii Balogun Adewunmi ṣe n gboriyin fun Obi fun akaye rẹ lori ikanni BBc Yoruba naa ni àwọn bii Adeyanju Wadudu Olaoluwa n ki Ọṣinabjo pe o mọ esi ọrọ
Awon eeyan kan n kigbe pe ebi n pa ara ilu laisko yii
Loju ọpọ eniyan Obi ati Oṣinbajo lo fakọyọ ju ti wọn si gba awọn oludije igbakeji to ku lati tun ero wọn pa bi o ti yẹ ko le han pe wọn kun oju oṣuwọn.
Ero àwọn mii bii Sotunde Olasile ati Shogbola Temmy Tayo lori ikanni BBC Yoruba naa ṣotọọtọ lori ohun to n ṣẹlẹ ni Naijiria pe:
Ebi kii wọnu ki ọrọ mii wọo lero ọpọlọpọ
Tambuwal ati awọn ẹgbẹ PDP gboriyin fun eeyan wọn pe omọ to to ran niṣẹ ni Peter Obi nigba ti APC naa yombo Ọṣinbajo pe akọni to to gbangba sun lọye ni
Awọn mii n gba imọran pe iwọnba ni ki awọn ọmọ Naijiria ba ara wọn ja lori ayelujara mọ nitori ẹni aàmọ̀rí
Ni ipari ijiroro naa, bi awọn kan ṣe sọ pe Obi n parọ ninu awọn odiwọn to mẹnuba naa ni awọn miran gboriyin fun ọrọ ikadii Obi ti PDP nigba ti awọn mii tabuku bi oludije ẹgbẹ YPP ṣe n polongo Ojọgbọn Moghalu dipo ko sọ ohun to ni fun ilu. Bakan naa lawọn mii n sọrọ lodi si ọrọ Ọṣinbajo ti APC pe o ṣaa n tako iṣejọba PDP fun ọdun mẹrindinlogun ni dipo ko mẹnuba aṣeyọri ti wọn ba ni.
Omi titun ti rú nínú oríṣii ètò ìgbéyàwó Yorùbá lásìkò yí
a) Ti ede aiyede ba waye laarin yin ati aarẹ ti ẹ n ṣe igbakeji fun, ki lẹ o ṣe?
Lori eyi, Ọṣinbajo sọ pe ipo igbakeji aarẹ jẹ olugbaninimọran agba fun aarẹ.
Bakan naa lo jẹ ẹni ti aarẹ le fun ni oriṣiriṣi ojuṣe lati ṣe, ṣugbọn eyi ni i ṣe pẹlu bi aarin wọn ba ṣe ri, ati ifinutan ara ẹni.
Ẹwẹ, Ọṣinbajo sọ pe ipo igbakeji aarẹ gba ọpọlọpọ suuru, nitori pe oriṣiriṣi ilana ni aarẹ yoo gbe jade, iwọ si le ma faramọ wọn.
Lori ibeere yii, aṣoju PDP, Peter Obi sọ pe oun ko ni wahala tabi ikunsinu pẹlu ẹnikẹni ri ninu iṣejọba, nitorina ieu nkan bẹ ko le aye laarin oun ati Atiku Abubakar.
Àwọn nkan tó jẹyọ níbi ìfọ̀rọ̀wánilẹ́nuwò f'áwọn tó fẹ́ di igbákejì àárẹ
Bakan naa lo sọ pe ojuṣe igbakeji aarẹ ni lati mu ajinde ba eto ọrọ aje orilẹede.O gbọdọ le da iṣẹ́ silẹ
Igbákejì ààrẹ orilẹ̀-èdè Nàìjíríà ọjọgbọ́n Yemi Osinbajo tún dẹbi ru ẹgbẹ́ òṣèlú People's Democratic Party lóri ètò ọ̀rọ̀ ajé tó dẹnukọlẹ̀.
Lẹ́yìn ti wọn bií lóri ìdí tí gbogbo ìdóko-òwò Nàìjíríà ò ṣe kọjá ìdá mẹ́rìndínlógun láti ọdún mẹwàá sẹ́yìn yàtọ́ sí bí South Africa àti China ṣe ni ìdàgbàsókè
"Osinbajo ní"" mo rò pé ohun tó jọ ara wọn láàrin orílẹ̀-èdè méjèèji ti ẹ dárúkọ ni pé wọn ni ohun etò amúlùdùn tó gbópọn. Orílẹ̀-èdè Nàìjírìà ní ọdún mẹ́rìndílogún sẹ́yìn ní pé ìyà ohun amúludùn ti jẹ wa sẹ́yìn."
b) Njẹ o yẹ lati maa san owo iranwọ lori epo bẹtiro?
Isoro kan to n fa idiwọ fun ẹka dida iṣẹ silẹ ni aisi awọn akanṣe iṣẹ. A nilo akanṣe iṣẹ.
Nkan gboogi to n fa iṣẹ ati oṣi l'orilẹede Naijiria ni iwa ibajẹ gẹ̀gẹ̀ bi ile ifowopamọ̀ agbaye ṣe sọ. Ti a ko ba pa iwa ibajẹ run, a ko ni le ṣe ohunkohun.
Àwọn nkan tó jẹyọ níbi ìfọ̀rọ̀wánilẹ́nuwò f'áwọn tó fẹ́ di igbákejì àárẹ
Àwọn nkan tó jẹyọ níbi ìfọ̀rọ̀wánilẹ́nuwò f'áwọn tó fẹ́ di igbákejì àárẹ
Lori ọrọ owo iranwọ epo, Ọṣinbajo sọ pe kiiṣe ohun to buru ni lati san an, sugbọn iwa jibiti laarin awọn alagbata epo lo ba eto naa jẹ.
''Ni kete ti a ba yọ owo ori iranwọ epo, nkan yoo wọn. A gbọdọ faramọ sisan owo iranwọ epo fun igba diẹ, to ba ya, ao dawọ rẹ duro.
Ti a ba fẹ ẹ yọ, a gbọdọ kọkọ bi awọn ọmọ Naijiria pe ''eelo ni wọn le ra epo bẹtiro?''
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Lori eyi, oludije fun igbakeji aarẹ fun ẹgbẹ oṣelu PDP, Peter Obi, sọ pe Naijiria gbọdọ fi opin si sisan owo iranwọ epo fun awọn alagbata. Ẹwẹ, Obi sọ wipe gbigbogun ti iwa ibajẹ kiiṣe ara ilana iṣejọba.
Bakan naa ni awọn oludije yoo ku bi Umma Getso ti ẹgbẹ oṣelu Young Progressives Party, eto naa gbọdọ wa sopin nitori a ko gbọdọ tẹsiwaju lati maa san owo fun aikoju oṣuwọn.
------------------------------------------------------------------------------------------
Lori boya ki orilẹede Naijiria bu ọwọ lu iwe ajumọṣe fun eto ibudo idokowo kan ṣoṣo fun awọn orilẹ-ede ilẹ Afrika, Continental Free Trade Zone agreement, Ọṣinbajo sọ wipe ojuṣe ijọba to mọ nkan to n ṣe ni ko ṣe agbeyẹwo awọn nkan to yẹ, ki o to buwọlu iru adehun bẹ.
Ohun to sọ yii na lo wọpọ ninu ohun ti awọn oludije to ku sọ. Gbogbo wọn gbagbọ pe iru igbesẹ bẹ n fẹ ikiyesara ati agbeyẹwo anfaani ti yoo ṣe orilẹede Naijria.
Ni tiẹ, aṣoju ẹgbẹ oṣelu Youth Progressives Party, YPP, Umma Getso, o sọ pe iru eto naa kiiṣe igbesẹ to yẹ fun Naijiria lati gbe.
-----------------------------------------------------------------------------------------------
Girma Wolde Giorgis: Ààrẹ Ethiopia tẹ́lẹ̀ jáde láyé lẹ́ni ọdún 94
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Iku mu Aarẹ Girma Wolde Giorgis lọ
Aarẹ orilẹ-ede Ethiopia tẹlẹ Girma Wolde Giorgis ti papoda ni ẹni ọdun mẹrinlelaadọrun.
Giorgis jẹ Aarẹ ilẹ Ethiopia laarin ọdun 2001 si ọdun 2013.
Ẹwẹ, Olootu ijọba orilẹ-ede naa, Abiy Ahmed ti ranṣẹ ibani kẹdun si ẹbi oloogbe ọhun.
Olootu ijọba ilẹ Ethiopia ṣapejuwe Giorgis bi ẹni ti ọpọ n wo bi awokọsẹ nigba aye rẹ, bakan naa lo kede pe ijọba yoo ṣe oku rẹ gẹgẹ olori orilẹ-ede naa tẹlẹ ri.
Nigba ti Giorgis wa lori laeefa, o gbiyanju lati fopin ija ilẹ to wa laarin orilẹ-ede Ethiopia ati Eritrea to wa lẹgbẹ rẹ.
Giorgis to jẹ oniṣowo ati oṣiṣẹ ile ifowopamọ fi iyawo rẹ ati ọmọ marun un saye silẹ lọ.
Omi titun ti rú nínú oríṣii ètò ìgbéyàwó Yorùbá lásìkò yí
CJ Gold: ẹ̀rù kọ́ka ba ìyá mi nígbà ti mo fẹ́ bẹ̀rẹ̀ iṣẹ́ ìjà jíjà
Ondo Kidnapping: Egbìnrìn ọ̀tẹ̀ ni ọ̀rọ̀ àwọn ajínigbé ní ìpínlẹ̀ Ondo
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ọ̀pọ̀lọ̀pọ̀ ìgbà ni ìjínigbé ti wáyé ní ojú ọ̀nà ìlú Ọ̀wọ̀ sí Ìkàrẹ́-Àkókó.
Laiti pe ọsẹ kan ti awọn ajinigbe ji eniyan mẹẹrin ni ipinlẹ Ondo, wọn tun ti ji eniyan mẹta miran gbe lọjọ Abamẹta to kọja.
Alukoro fun ileeṣẹ ọlọpa nipinlẹ Ondo, Fẹmi Joseph sọ fun akọroyin BBC Yoruba, pe eniyan mẹta ni awọn ti wọn ji gbe lootọ, ṣugbọn ''ileeṣẹ ọlọpaa ko ti i le sọ boya Fulani lo ji wọn gbe nitori pe a ko ti i ri wọn'' tako iroyin to jade pe awọn fulani daran-daran lo ji wọn gbe.
Bakan naa lo sọ ijinigbe ati iwa ọdaran gbogbo kiiṣe ọrọ ẹya tabi ẹsin.
Ile isẹ ọlọpaa n gbe Ọrẹkunrin Khadijat rẹlẹ ẹjọ ni Ọjọ Aje
Ọwọ wa tẹ awọn afurasi ajinigbe mẹjọ ni bi ọsẹ meji sẹyin, ko si si ẹya Fulani kankan lara wọn. Awọn mẹjọ naa si ti wa ni ihamọ nitori ọrọ wọn ti de ile ẹjọ.
Gẹgẹ bi ohun ti Joseph sọ, ọkan lara awọn mẹta ti wọn ji gbe jẹ olukọ ni ileewe gbogbonise Rufus Giwa to wa ni ilu Ọwọ nipinlẹ Ondo.
Ọna to lọ si ilu Ipele nitosi Ọwọ ni wọn ti ji olukọ naa gbe.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Laipẹ yii ni awọn ọlọpa tu awọn inu igbo kan ti igbagbọ wa pe awọn ajinigbe naa fi ṣe ibuba wọn ni oju ọna ti ọrọ kan
Awọn meji to ku ni wọn ji gbe ni ilu Ọsẹ loju ọna to lọ Ọwọ si Ikarẹ-Akoko, nipinlẹ Ondo bakan naa lasiko ti wọn n rinrinajo.
Ṣugbọn ohun to daju nipe ileeṣẹ ọlọpa ko ni duro tabi fọwọ lẹran ti ọwọ yoo fi tẹ awọn amokunṣika naa.
Ti kọmisana ọlọpa Olugbenga Adeyanju si ti ṣe ọpọlọpọ ipade pẹlu awọn ọba, ọdẹ ati awakọ nibi ti iṣẹlẹ yii ti maa n ṣẹlẹ lati ran iwadi lọwọ.
Igba akọkọ kọ niyii ti iṣẹlẹ yii n waye. Nibi ọsẹ kan sẹyin ni awọn ajinigbe gbe eniyan mẹẹrin; oṣiṣẹ ileewosan Federal Medical Centre to wa nilu Ọwọ, ati olukọ ileewe gbogboniṣe Rufus Giwa.
Awọn mẹta gba ominira 'lẹyin ti awọn mọlẹbi wọn san owo itusilẹ, nigba ti eniyan kan si padanu ẹmi rẹ si akata awọn ajinigbe.
Eyi si mu ki awọn dokita ileewosan naa maa dunkooko lati bẹrẹ iyanṣẹlodi tijọba ko ba wa nkan ṣe si ijinigbe to n waye ni gbogbo igba loju ọna naa.
'Tayọ̀tayọ̀ ni mó fẹ́ ṣiṣẹ́ pẹ̀lú INEC ki ìdìbò 2019 lé dára'
Bakan naa ni awọn ajinigbe gbe ọdọmọbinrin kan nilu Akurẹ lẹnu irinajo rẹ si ilu Ondo ninu oṣu Kọkanla, ko to o di pe awọn ọlọpa doola rẹ nigba ti olobó ta wọn. Ọwọ wọn si tẹ afurasi meji.
Ẹwẹ, lori ijinigbe to n waye, ẹka ẹgbẹ awọn agbẹjọro nilu Ọwọ nipinlẹ Ondo ṣe iwọde lọjọ kejila, oṣu Kejila pe ki ijọba o kede nkan o fararọ lori ijinigbe.
Ninu oṣu Kọkanla bakan naa ni wọn ji alaga ẹgbẹ oṣelu African Democratic Congress ADC), Bisi Ogungbemi, ati awọn oloye ẹgbẹ mẹta mi i, lara eyi ti oludije fun ipo sẹnetọ kan Jide Ipinsagba wa.
Wọn ji wọn gbe loju ọna Ọwọ si Ikarẹ-Akoko lasiko ti wọn n pada si ilu Akurẹ lati ilu Ikarẹ-Akoko lẹyin ipolongo oṣelu.
Laipẹ yii ni awọn ọlọpa tu awọn inu kan to wa ni oju ọna marosẹ Ọwọ si Ikarẹ ati eyi to lọ lati Akurẹ si Ọwọ nibi ti igbagbọ wa pe awọn ajinigbe naa fi ṣe ibuba wọn.
Awọn ọmọ ileeṣẹ ologun naa gbe iru igbesẹ yii ninu oṣu Karun un, ṣugbọn ko pẹ ti wọn dawọ duro ni iroyin sọ pe awọn ajinigbe naa tun bẹrẹ iṣẹ ibi wọn.
Ṣe ka sọ pe ileeṣẹ ọlọpaa ko ṣiṣẹ to ni?
Lori ibeere yii, Fẹmi Joseph sọ pe ''idojukọ kan pataki taa n ni ni pe, nitori pe ipinlẹ Ondo paala pẹlu ipinlẹ to pọ, bi a ṣe n mu ọpọlọpọ wọn ni awọn mi i tun n ṣiṣẹ.
Bi a ṣe n ge wọn lọwọ ni wọn n bọruka. Ọna naa gun de ipinlẹ Kogi. Oju kan ṣoṣo kọ lo ti n ṣẹlẹ.
"Eyi kii ṣe lati ṣe awawi, ṣugbọn ohun to ṣe pataki ni pe a n ti n lo ọna miran lati ṣiṣẹ."""
"Ọpọlọpọ nkan lati n ṣe bayii lati ri i pe ọrọ ijinigbe di afisẹyin ti eegun n fiṣọ. Ati fi kun awọn ọlọpa to n duro loju ọna. Bakan naa ni a ti pe awọn miran ti kii ṣe ọlọpa mọra lati ran wa lọwọ.
Ohun ti a fẹ lati ọdọ araalu ni pe ki wọn maa ta wa lolobo, gbadura fun wa, ki wọn si mu suuru diẹ fun wa, ao ṣiṣẹ naa bi iṣẹ
A ko mọ boya awọn ajinigbe ti kan si awọn mọlẹbi awọn ti wọn ji gbe, nitori ileeṣẹ ọlọpa kii lọwọ si. Idi ni pe ọpọlọpọ ọdaran yoo maa lo anfaani pe ileeṣẹ ọlọpa faaye gba sisan owo fun ajinigbe lati maa ṣiṣẹ ibi.
Ti a ba fun ẹnikan lowo loni, ẹlomii yoo tun wo awokọṣe naa lati ji ẹlomiran gbe.
A si maa n rọ awọn araalu lati fi to wa leti ti awọn ajinigbe ba kan si wọn, ṣugbọn o ṣeni laanu pe mọlẹbi awọn ti wọn ba ji gbe kii ṣọ fun wa lasiko ti wọn ba kan si wọn tabi san owo itusilẹ."
Gbogbo ènìyàn ló wọ agbádá ikú, ẹni tó kàn lẹnìkan kò mọ̀
''Ẹ̀mí ọ̀pọ̀lọpọ̀ ṣì n sọnù ni orilẹ̀-ede Burundi'
Àwọn òṣìṣẹ́ ilé aṣòfin Nàìjíríà bẹ̀rẹ̀ iyànṣẹ́lódì
Oríṣun àwòrán, @NgrSenate
Awọn asofin ṣi n ba iṣẹ lọ ni ile aṣofin lalai si iranlọwọ awọn oṣiṣẹ ile aṣofin
Àwọn òṣìṣẹ́ ilé aṣòfin Nàìjíríà tí mú ìlérí wọn ṣẹ láti gbegi dina iṣẹ ni ile náà  pẹlu bi wọn ti ṣe bẹrẹ iyanṣẹlodi lọjọ Ajé
Lọsẹ to kọja ni wọn leri lati da iṣẹ gbogbo duro lori bi awọn alaṣẹ ile aṣofin naa ko ti ṣe san owo oṣu wọn.
Iroyin to tẹwa lọwọ so pe niṣe ni awọn oṣiṣẹ naa yan iṣẹ lodi ni ile asofin ohun lọjọ aje tii ṣe ọjọ kẹtadinlogun oṣu kejila ọdun 2018.
Awọn oṣìṣẹ́ fẹ̀hónú hàn níle ìgbìmọ̀ Aṣofin
Saaju ni wọn ti gbe awọn ìgbésẹ̀ kan to fi mọ bi wọn ti ṣe ṣe iwọ́de ìfẹ̀hónú hàn láti dí ìgbòkègbòdò ilé ìgbìmọ̀ àsṣòfin lọ́wọ́ lọjọ́ kerin àti ọjọ́ kẹjọ oṣù kejila, ọdún 2018.
Tóhun tí iyanṣẹlodi náà, àwọn aṣòfin tí kéde orúkọ àwọn ọmọ àjọ tí yóò mójú tó ètò gbogbo nílé aṣòfin Nàìjíríà.
Ikede orukọ awọn ọmọ ajọ naa ti Aarẹ ile asofin Bukola Saraki kede ni  wọn fi sita loju opo Twitter  ile asofin lọjọ aje kannaa ti awọn oṣiṣẹ ohun da iṣẹ silẹ.
Ara iredi iyansẹlodi awọn oṣiṣẹ ile asofin ni wi pe awọn ko ri ẹtọ awọn gba nipaṣẹ owo osu ati ajẹmọnu ti o tọ si awọn .
Igbagbo wọn si ni wi pe iyanṣẹlodi naa yoo ṣe idiwọ fun iṣẹ awọn asofin eleyi ti yoo mu ki ọrọ naa ni iyanju.
'Tayọ̀tayọ̀ ni mó fẹ́ ṣiṣẹ́ pẹ̀lú INEC ki ìdìbò 2019 lé dára'
Ko ti daju boya awọn alaṣẹ yoo wa wọrọkọ fi ṣada lori ọrọ to wa nile yi ṣugbọn bi nnkan ti ṣe n lọ yi,o le ṣe akoba fun iṣakoso eto gbogbo nile asofin paapa julọ aba isuna ti Aarẹ Buhari fẹ gbe wa si iwaju ile asofin lọjọru.
Alápinni: Kò sí ẹni to fẹ́ kọ́kọ́ kọ́ iṣẹ́ òṣèré bíi ti àtẹ̀yìnwá
Iléesẹ́ ológun Nàìjíríà bẹnu àtẹ́ lu ìwádìí Amnesty International
Oríṣun àwòrán, AFP
Awọn ọmọogun ko sinmi fifigba gbaga pẹlu awọn janduku orisirisi ni Naijiria
Ileeṣẹ ologun orileede Naijiria ti tutọ soke foju gba lori abajade iwadi kan ti ajọ to n tọpinpin ẹtọ ọmọniyan lagbaye, Amnesty International,gbe jade nipa Naijiria.
Koda wọn pe fun titi fun titi oriko ajọ naa jakejado Naijiria.
Ipe yi ko ṣẹyin iwadi kan ti ajọ naa gbejade to ti sọ wi pe o le ni ẹgbẹrun mẹta eeyan ti wọn ti lugbadi iku latari aawọ laarin awọn agbe ati darandaran ni Naijiria.
Ileeṣẹ ologun ninu atẹjade kan lati ọdọ ọgagun Sani Usman to jẹ gabẹnusọ wọn ni niṣe ni ajọ naa n gbero lati tu Naijiria ka.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Bíi ẹgbẹ̀rún kan àbọ̀ ènìyàn ni ó ti kú ní Benue láti 2013
Amọ ṣa, ajọ naa ni ko si ootọ ninu nnkan ti ileeṣẹ ologun sọ nipa awọn.
Ajọ naa ni ileese ologun ko sapa to lati daa aabo bo awọn eeyan ti wọn si kọ lati ṣe iwadi tabi mu awọn ti wọn fura si wi pe wọn n ṣe iku paniyan.
Ninu iwadi ti ajọ naa gbe jadẹ, wọn ni iwadi naa dalori ikọlu awọn agbe ati darandaran to waye lagbegbe ariwa ati gbungbun  Naijiria laarin oṣu kini 2016  ati oṣu kẹwa ọdun 2018.
Oríṣun àwòrán, @HQNigerianArmy
Ọpọ awọn afyrasi lọwọ tẹ ti aimọye si jajabọ mọ awọn alaṣẹ lọwọ
Wọn salaye pe lẹyin ifọrọwanilẹnuwo  pẹlu eeyan to to igba tawọn ṣe, awọn  ri wi pe idaji awọn iku naa waye ni ọdun yi nikan.
Gẹgẹ bi ohun ti ajọ naa sọ, wọn ni awọn ileto bi mẹrindinlọgọta lawọn de lawọn ilu bi Adamawa,Banue,Kaduna Taraba ati Zamfara lati fi idi ọrọ naa mulẹ.
Eyi kii ṣe igba akọkọ ti ajọ Amnesty International ati ileeṣẹ ologun Naijiri ayoo ma gbena woju ara wọn.
Losu kọkanla ọdun yi, adele oludari ẹka iroyin ileeṣẹ́ ologun Naijiria,ọgagun John Agim so wi pe ajọ Amnesty International n  gbe iroyin ayederu jade nipa lNaijiria lati le bẹnu atẹ lu.
Lai pe yi ni ileeṣẹ́ ologun fẹsun kan ajọ to n risi itọju ọmọde kaakiri agbaye Unicef pe wọn n ṣe iranwọ fun ikọ Boko Haram.
ASSU Strike: Ìpàdé ASUU àti ìjọba tún forí sánpọ́n
Oríṣun àwòrán, other
ijọba kò ṣetan lati wọn ọn kun, ASUU naa ko fẹ gbaa ni aabọ lori ọrọ iyanṣelodi olukọ fasiti
Ipade to n waye laarin ẹgbẹ olukọni ile ẹkọ giga fasiti lorile-ede Naijiria Asuu ati ijọba Naijiria tun ti fori sanpọn.
Lọjọ Aje nilu Abuja la ti gbọ wi pe awọn ọmọ ẹgbẹ ASUU binu jade kuro ninu ipade ti o yẹ ki wọn ṣe pẹlu awọn aṣoju ijọba ti Minisita fun ọrọ iṣẹ ni Naijiria Chris Ngige le waju wọn.
Oríṣun àwòrán, @ngige
Ọrọ n bá ọrọ bọ
Chris Ngige to jẹ minista fun ọrọ iṣẹ ni Naijiria ni tootọ ni ijọba ṣe ipade pẹlu ASUU ni eyi ti wọn ti jọ n sọ asọyepọ lori awọn nkan ti ASUU n fẹ.
O ni ki awọn le jọ wa ọna abayọ naa loun ṣe pe ipade naa ati pé abọ iṣẹ ti a fun ẹnikọọkan nile iṣẹ ijọba ni a ṣẹṣẹ n to pọ ki a le mọ ọna abayọ.
Yorùbá gbà pé òrìṣà bí ìyá kò sí!
Ni ipari o  ni idi ti awọn ko ṣe yanju ọrọ naa ni pe oun ki onikaluku ri ọjọ diẹ lati wo awọn akọsilẹ naa wò ṣaaju keresimesi.
O fi idaniloju han pe awọn olukọ a fopin si iyanṣẹlodi na laipẹ ati pe awọn akẹkọọ a wọle nibẹrẹ oṣu kinni ọdun 2019.
O ni oun yoo ṣe ipade pẹlu minista fun eto inawo lati yanju ohun gbogbo ti ASUU n beere nitowo.
Gbogbo ènìyàn ló wọ agbádá ikú, ẹni tó kàn lẹnìkan kò mọ̀
Gbogbo igbiyanju lati ba alaga ASUU sọrọ lo jasi pabo nitori o ni oun ko ni ohunkohun lati sọ ki Ngige jabọ ohun to ṣẹlẹ.
Alápinni: Kò sí ẹni to fẹ́ kọ́kọ́ kọ́ iṣẹ́ òṣèré bíi ti àtẹ̀yìnwá
Oríṣun àwòrán, Twitter
Ko ti daju oun to mu ki awọn olukọni naa binu jade ninu ipade ohun ṣugbọn saaju ipade naa la gbo wi pe ọgbẹni Ngige ti sọ wi pe ohun ni ireti wi pe ọrọ yoo ni iyanju.
ASUU Strike: Bí àwọn kan se dunnú, làwọn kan fajúro
Awọn olukọni ile ẹkọ fasiti Naijiria ti dẹgun le iyansẹlodi ọlọjọgbọrọ lati ọjọ  kẹrin osu kakanla ọdun yi yi.
Ohun to mu wọn gun le iyansẹlodi naa ni awọn nnkian koko mẹta ta ti ri owo osu wọn ti wọn ni ko munadoko to,atunto ati atunṣe awọn ile ẹkọ to fi mọ ajẹmunu awọn olukọni naa.
'Tayọ̀tayọ̀ ni mó fẹ́ ṣiṣẹ́ pẹ̀lú INEC ki ìdìbò 2019 lé dára'
Fayemi: Gbèsè tí mo bá nílẹ̀ ni kò jẹ́ kí n ti yan kọmíṣọ́nà
Oríṣun àwòrán, Fayemi /twitter
Ijọba ipinlẹ Ekiti f'ofin de Fayemi fun ọdun mẹwaa losu to koja
Gomina ipinlẹ Ekiti, Kayọde Fayẹmi sọ pe ko si owo lati yan kọmiṣọna kankan fun ipinlẹ naa.
Fayẹmi la gbọ wi pe o sọ ọrọ yii lasiko eto oloṣooṣu kan to ti maa n ba awọn araalu sọrọ lori amohunmaworan.
O ṣalaye pe idi pataki ti oun ko ṣe ti i yan awọn kọmisana, to fi mọ awọn olubadamọran pataki ti yoo ba iṣakoso rẹ to ti pe oṣu meji ṣiṣẹ bayii,  ko ṣẹyin ki oun le lanfaani lati san owo oṣu awọn oṣiṣẹ ijọba ipinlẹ naa.
'Tayọ̀tayọ̀ ni mó fẹ́ ṣiṣẹ́ pẹ̀lú INEC ki ìdìbò 2019 lé dára'
Lati igba to ti di gomina ipinlẹ Ekiti l'ọjọ kẹrindinlogun, oṣu Kẹwa, Akọwe fun ijọba ipinlẹ, olori awọn oṣiṣẹ, ati Akọwe oniroyin agba fun ijọba nikan ni wọn jọ n dari ilu.
Nigba to ba BBC Yoruba sọrọ, Akọwe Ikede fun Gomina Fayẹmi, Yinka Oyebọde, sọ pe awọn gbese ti ijọba Fayẹmi ba nilẹ, paapa ajẹsilẹ owo oṣu awọn oṣiṣẹ, ni ko ti i jẹ ki anfaani ṣi silẹ lati yan kọmisana.
Igbagbọ ijọba ni pe owo oṣu awọn kọmisanna ati awọn amugbalẹgbẹ to ku yoo tun mu ki gbese ti ijọba o pọ si.
Yorùbá gbà pé òrìṣà bí ìyá kò sí!
Oyebọde sọ pe gomina Fayẹmi ro o wi pe ki oun duro lati pawo wọle diẹ, ko to o yan wọn.
O ṣalaye pe ijọba ti n gbe awọn igbesẹ bi i ṣiṣe atunṣe si awọn nkan to n pawo wọle fun ijọba; Ikọgosi Warm Spring ati awọn ileesẹ ijọba mi i. Bakan naa ni ijọba n gbero lati pe awọn ileeṣẹ ti owo ori to gọbọi ati awọn ilana ijọba ti ko fararọ, ti le kuro l'Ekiti, pada, to fi mọ ṣiṣe iṣẹ agbẹ aladanla.
Oríṣun àwòrán, Kayọde  Fayẹmi
Ẹwẹ, ijọba n gbero lati ṣe afihan ipo ti apo aṣuwọn ijọba ipinlẹ Ekiti wa l'ọjọ to ba ṣe ajọyọ ọgọrun ọjọ lori oye.
CJ Gold: ẹ̀rù kọ́ka ba ìyá mi nígbà ti mo fẹ́ bẹ̀rẹ̀ iṣẹ́ ìjà jíjà
Ati ti ijọba ba ri gba lara awọn owo ti ijọba apapọ jẹ ipinlẹ Ekiti. Gbogbo owo yii ni wọn fẹ ẹ kopọ lati yanju awọn gbese to wa lọrun ijọba.
O sọ pe lati mu ki eyi ṣeeṣe, o ni ijọba Ekiti ti n ba awọn to yẹ sọrọ.
Ẹwẹ, ijọba n gbero lati ṣe afihan ipo ti apo aṣuwọn ijọba ipinlẹ Ekiti wa l'ọjọ to ba ṣe ajọyọ ọgọrun ọjọ lori oye.
Alápinni: Kò sí ẹni to fẹ́ kọ́kọ́ kọ́ iṣẹ́ òṣèré bíi ti àtẹ̀yìnwá
Gbogbo ènìyàn ló wọ agbádá ikú, ẹni tó kàn lẹnìkan kò mọ̀
Ekiti Assembly: Ilé ìgbìmọ̀ aṣòfin júwe ilé fáwọn alága ìjọba ìbílẹ̀
Oríṣun àwòrán, Ekiti@official
Ekiti Assembly: Ilé ìgbìmọ̀ aṣòfin júwe ilé fáwọn alága ìjọba ìbílẹ̀
Ilé ìgbìmọ aṣòfin ìpínlẹ̀ Ekiti tí fún àwọn alága ìjọba ìbílẹ̀ mẹ́rẹ̀rìndílógún, awọn kansẹlọ mẹ́tàdínlọ́gọ́sàn àtí àwọn èèkàn olóṣèlú níjọba ìbílẹ̀ ní ìwé ló rókún níle aláìní gbèdéke nítori ẹ̀sùn níná owó ìjọba ìbílẹ̀ mákumaku.
Lásìkò tó ń ba àwọn akọ̀ròyìn sọ̀rọ̀ lóri ìfẹ̀nukò ilé, alága ìgbìmọ tẹ̀ẹ́kótó lóri igbóhùn sáfẹ́fẹ́ àti adarí oko-òwò ijọba Họnọrabu Gbenga Aribisọgan, sàlàyé pé ìgbésẹ̀ ọ̀hún wáyé nílànà ofín ọdún 1999.
Ó ní  lẹ́yìn tí ìgbìmọ tẹẹ́kótó lóri iwé owó tí wọn gbé iṣẹ́ fún jábọ lóri abájáde ìwádìí wọn lóri ìṣúnà àwọn ìjọba ìbílẹ̀ ní arídájú ti jẹyọ pé wọn ń ṣe owó ìlú mọkumọku tí ìgbìmọ ò sí lé mójúkúrò
''A ṣiṣẹ́ lórí àwọ ìwé wọn à sì rí àrídájú pé àwọn alága ìjọba ìbílẹ̀ ṣe ǹkan tó wù wọn láti ṣe i'sẹ́ àkànṣe tó ju ǹkan tó yẹ kí wọn ṣe lọ, èyí ló fún wọn ní ànfàní láti hùwà jẹgúdújẹra''
Aribisogan bẹnu àtẹ lu àhesọ ọ̀rọ̀ pé àwọn alága fún ilé ìgbìmọ aṣofin ní mílíọ̀nù mẹ́jọ láti dáwọ́ ìdádúró náá dúró, ó fi kún-un pé àwọn ọmọ ìgbìmọ tẹ̀ẹ́kótó nìkan ló sàbẹ̀wó sí gbogbo ètò tó wáye ní àwọn ìjọba.
LASEMA: kí àwọn ará ìlú tó ba kẹ́fin oníṣẹ́ ibi tètè máa jáde sọ̀rọ̀
Iná sọ lẹ́yìn táwọn ajépo gbé bẹ́ àgbá epo l'Abule Egba
Ọpọlọpọ padanu mọto lataari ọpa epo rọbi to jona l'Abule Ẹgba nipinlẹ Eko loru oni.
Ajọ  LASEMA ti wọn n mojuto iṣẹlẹ pajawiri ni ipinlẹ Eko ni àwọn ti gbe gbogbo awọn to fi ara pa ninu iṣẹlẹ naa lọ fun itọju nile iwosan.
Ogbẹni Tiamiyu Adeṣina to jẹ ọga agba ajọ LASEMA ni awọn oniṣẹ ibi ti wọn n ji epo rọbi lati inu ọpa epo lo ṣokunfa ina to ṣẹ naa.
O ni ko sẹni kankan to sọ ẹmi rẹ nu ninu iṣẹlẹ ọhun ṣugbọn ọpọlọpọ ile lo jona ni Awori ni Abule Ẹgba ti ọpọlọpo si n ṣofọ awọn nkan ti wọn padanu.
Buruji Kashamu: Èmi ṣì ni olùdíje PDP ní Ìpínlẹ̀ Ogun
Republic of Benin: ìtàn tó bí abẹ́sàn án kọjá bẹ́ẹ̀!
Ọga agba LASEMA gba awọn ara ilu niyanju lati maa tete sọrọ jade ni kete ti wọn ba ti kẹfin ohunkohun ladugbo wọn.
O ni awọn ti ri oriṣii itọni ati awọn igbese to yẹ ki ajọ awọn agbofinro gbe ni eyi ti o fi ṣeeṣe lati fopin siru iṣẹlẹ yii nibi ifọrọwanilẹnuwo ti awọn ti ṣe pelu awọn ara Abule Ẹgba.
Oríṣun àwòrán, @trafficbutter
ọpọlọpọ mọto, ọjà ati nkan amuludun lo jona ni Abule Egba nidaji
Seun Kuti: Fela ló n pọ́n gbogbo òǹkọrin Afrobeat lagbaye
APC Ogun: Ẹjọ́ ti wà ní kóòtù, kò sẹ́ni tó lè tú ìgbìmọ̀
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Àjọ amusẹya ni ẹgbẹ oselu APC ti tu igbimọ ẹgbẹ ka ni ipinlẹ Ogun ati Imo gẹ́gẹ́bí àbájáde ìpàdé ẹgbẹ́ gbogboògbò.
Ẹgbẹ oselu APC ni ipinlẹ Ogun ti faake kọri wi pe ko si ẹni to le e tu igbimọ ẹgbẹ oselu APC ka ni ipinlẹ Ogun.
Ipinnu yii waye lẹyin ajọ amusẹya ni ẹgbẹ oselu APC pase lati tu igbimọ ẹgbẹ ka ni ipinlẹ Ogun ati Imo gẹgẹbi abajade ipade ẹgbẹ gbogbogbo.
Awọn adari ẹgbẹ oselu APC ni Ogun bu ẹnu atẹ lu asẹ yii, ati wi pe digbidigbi ni ẹgbẹ naa wa ni ipinlẹ naa, ti ko si si mimi kan to le yẹ wọn.
Wùnmí Toríọlá: Toyin Abraham kìí se ọ̀gá mi nínú tíátà
Wọn fikun wi pe ẹjo ẹni to jẹ adari ẹgbẹ ni ipinlẹ naa ti wa ni ile ẹjọ, ti ko si si asẹ ti o kọja ti ile ẹjọ lọwọlọwọ, nitorina asẹ ti ko lẹsẹ nilẹ ni asẹ ti ajọ amusẹya pa ni ipade to waye ni Abuja naa.
Ninu iwe ipejọ No CV/363/2018, ẹgbẹ oselu APC ni ipinlẹ Ogun ti rọ ile ẹjọ lati dẹkun igbimọ amusẹya ti APC lapaapọ lati le tu igbimọ abẹlẹ APC ni ipinlẹ Ogun.
Ile ẹjọ ti fagile idibo to yan Rahman Rasaq gẹgẹ bi alaga ẹgbẹ oselu APC ni ipinlẹ Kwara ati awọn ti wọn yan si ipo.
Ile ẹjọ ni Balogun-Fulani ni alaga ti wọn yan lọna to ba ofin mu.
Ile ẹjọ giga naa tun fagile gbogbo idibo abẹlẹ ti igun Bashir Bolarinwa se abojuto rẹ, ti ile ẹjọ naa si fagile igun naa wi pe alakalẹ rẹ ko ba ofin mu.
Ohun ti eyi tun mọ si ni pe ẹgbẹ oselu APC ni ipinlẹ Kwara ko lee fa oludije miran kalẹ fun Ajo eleto idibo INEC yato si eleyiii ti igun Ishola Balogun-Fulani pa fa silẹ.
Idajọ ile ẹjọ giga naa tun ti mu ifasẹyin ba ẹgbẹ oselu APC ni ipinlẹ Kwara ti o ti mẹhẹ, lẹyin ti Aarẹ Ile Igbimọ Asofin,Bukola Saraki ti kuro ni ẹgbẹ oselu APC naa ti o si fa ipinya laarin awọn ọmọ ẹgbeẹ ni ipinlẹ Kwara.
Oríṣun àwòrán, @APCNigeria
Ọpọ ipinlẹ lo n koju aawọ abẹnu ninu ẹgbẹ APC lorilẹede Naijiria
Bakan naa, ajọ amusẹya ni ẹgbẹ oselu APC ti tu igbimọ ẹgbẹ ka ni ipinlẹ Ogun ati Imo.
Ninu atẹjade ti ẹgbẹ oselu APC fi lede, ti tu igbimọ naa jẹ abajade ipade ti ajọ amusẹya naa se ti Alaga ẹgbẹ, Adam Oshiomọle se adari fun ni ilu Abuja.
Republic of Benin: ìtàn tó bí abẹ́sàn án kọjá bẹ́ẹ̀!
Igbimọ amusẹya naa ni yoo yan awọn igbimọ alabojuto ti yoo dele titi wọn yoo fi yan awọn alaga ẹgbẹ ni awọn ipinlẹ mejeeji.
Agbébọn pa ènìyàn 14, ọmọọ̀gun Naijiria sígun ni Kaduna
Kíni yóò sẹlẹ̀ sí àwọn òsìsẹ́ Diamond Bank?
Fayemi: Gbèsè tí mo bá nílẹ̀ ni kò jẹ́ kí n ti yan kọmíṣọ́nà
2019 Budget: Ètò àbò, ètò ẹ̀kọ́, gbégbá orókè nínú àbádòfin N8.83 trillion tí Buhari gbé kalẹ̀
Oríṣun àwòrán, Bashir Ahmad
Aarẹ Buhari ni abadofin oju awo lawo fi n gbọbẹ lawọn fẹ fi eto iṣuna ọdun 2019 ṣe
Aarẹ muhammadu Buhari ti gbe abadofin iṣuna fun ọdun 2019 jade, o si ti gbe e kalẹ siwaju awọn aṣofin apapọ.
Iṣuna to din diẹ ni triliọnu mẹsan naira ni aarẹ  gbe kalẹ.
Amọṣa, ẹka ileeṣẹ ọrọ abẹle, ọrọ abo, eto ẹkọ ati ilera ni o lewaju ninu ipin owo lẹkajẹka ninu eto iṣuna naa.
Ninu agbekalẹ aarẹ lori iṣuna ọdun 2019, ileeṣẹ ọrọ abẹle lo gba ipin owo ti o pọju pẹlu ẹẹdẹgbẹta biliọnu naira o le diẹ, (N569.07bilion), ileeṣẹ ọrọ abo yoo gba ojilenirinwo o din marun un biliọnu naira (N435.62b), ọtalenirinwo o le meji biliọnu naira (N462.24b) fun eto Ẹkọ ati okoolelọọdunrun o din marun naira (N315.62b) fun eto ilera.
Aarẹ ni eto abo ati idagbasoke ọmọniyan wa lara koko ohun ti iṣuna naa yoo mu gbọ julọ.
Oríṣun àwòrán, Bashir Ahmad
Aarẹ Buhari ni afojusun abadofin naa ni lati tubọ fi ẹsẹ eto ọrọ aje Naijiria rinlẹ daradara
O fi kun un pe iṣuna to din diẹ ni triliọnu mẹsan naira naa ni wọn pin si owoona atigbadegba (Recurrent N4.04 trn), owoona lori sisan gbese (Debt Servicing N2.14trn), Owoona lori awọn iṣẹ pataki gbogbo (Statutory transfer N492.36b), owoona lori awọn akanṣe iṣẹ (Capital Expenditure N2.031trn)
Aarẹ Muhammadu Buhari gbe abadofin iṣuna ti o din diẹ ni triliọnu mẹsan naira kalẹ fun ọdun 2019.
Aarẹ kede eyi lasiko ti o fi n gbe abadofin iṣuna naa kalẹ niwaju awọn aṣofin apapọ ni ọjọru.
Aarẹ Buhari ni afojusun abadofin naa ni lati tubọ fi ẹsẹ eto ọrọ aje Naijiria rinlẹ ni oju ọna ọrọ aje ti o ko akoyawọ lati mu awọn ọmọ orilẹede Naijiria kuro ni ọgbun oṣi ati iṣẹ.
Aarẹ Buhari ni abadofin oju awo lawo fi n gbọbẹ lawọn fẹ fi eto iṣuna ọdun 2019 ṣe.
Gẹgẹ bi o ṣe sọ, ori ọgọta dọla lori jala epo kan ni wọn gbe eto iṣuna naa pẹlu ireti pe orilẹede Naijiria yoo maa pọn jala epo rọbi ti o le ni miliọnu meji lojumọ.
Bakan naa ni o fi kun un pe iṣuna naa yoo da lori paṣiparọ owo ni naira marunlelọọdunrun si dọla owo ilẹ Amẹrika kan.
Aarẹ Buhari ni awọn aṣepati akanṣe iṣẹ ti o wa nilẹ ni wọn yoo tubọ mojuto ni inu saa eto iṣuna ọdun 2019 gẹgẹ bi ijọba apapọ ṣe ṣe ni saa iṣuna 2018 ti o n pari lọ.
Davy dèrò ọ̀run nítorí 'Eré orí ẹní' ní ìlú Eko
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ọwọ keje ibalopọ wọn ni wọn n ṣe lọwọ ti arakunrin yii fi ṣubu lulẹ ti o si ku lori obinrin yii
Idije talo mọ ere ori ẹni n ṣe ju ti ran arakunrin kan lọ sọrun apapandodo ni ilu Eko.
Arakunrin naa ti orukọ rẹ n jẹ Davy dagbere faye ni ile igbafẹ kan lagbegbe Ikọtun nilu Eko.
Gẹgẹ bi iroyin ti ṣe sọ, arakunrin yii gbe ọmọbinrin kan ti orukọ rẹ n jẹ Loveth lọ si ile igbafẹ naa lati lọ ree mọ ẹni ti o lẹmi ibalopọ julọ laarin awọn mejeeji ni akukọ ba fi kọ lẹyin ọmọkunrin rẹ.
Iroyin fi idi rẹ mulẹ siwaju sii pe awọn mejeeji yii ti halẹ mọ ara wọn lori ẹni ti o lẹmi ere ori ẹni ṣiṣe julọ ni wọn fi fi ipade si ile igbafẹ naa lai mọ pe aṣe gbẹyin ori ẹni niyi fun arakunrin Davy.
Ẹgbẹrun lọna aadọta naira ni awọn ti iṣẹlẹ naa ṣe oju wọn sọ pe arakunrin naa gbe kalẹ pe bi ọmọbinrin naa ba lee gbẹyẹ mọ ohun lọwọ lori ẹni ohun yoo fun un ni owo naa.
Lẹyin ti Loveth gbọ ọrọ yii lo ti mura silẹ ti o si lọ duro de arakunrin naa ni ile igbafẹ ọhun.
Omi titun ti rú nínú oríṣii ètò ìgbéyàwó Yorùbá lásìkò yí
Ọwọ keje ibalopọ wọn ni wọn n ṣe lọwọ ti arakunrin yii fi ṣubu lulẹ ti o si ku lori obinrin yii.
Eyi lo mu arabinrin yii fi igbe ta lati pe awọn alakoso ile igbafẹ naati wọn faa le awọn ọlọpaa lọwọ ti wọn si gbe oku arakunrin naa lọ si ile igbokupamọ si ni ile iwosan kan ti wọn ko darukọ rẹ.
Àwọn olùgbé Maiduguri ìṣoro ni àpọ̀jù iná mọ̀nàmọ́nà ń da àwọn láàmú
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Iná mọ̀nàmọ́nà tí a ní tí pọ̀jù Grindin
Àwọn olùgbé iluu Maiduguri tí ṣe olú ìlùú Borno ti farígá, wọn ní àwọn ò nílò iná mọ̀nàmóna oní wákàtí mẹ́rìnlèlógun mọ bíkòṣe pé kí wọn pada sí wákàti méjìlá ti wọn ń fún àwọn tẹ́lẹ̀.
Gẹ́gẹ́ bí àwọn olùgbé Maikduguri ṣe sọ mímú iná wá dede ń ṣe àkóba fún àpò àwọn nítorí owó gọbọi ní àwọn Yola Electricity  Distribution Company (YEDC) ń fún àwọn nítori iná náà kò wúlò.
Nínú ọ̀rọ̀ rẹ, Ibrahim Suleiman tó bá akọ̀ròyìn NAN  sọ̀rọ̀ sàlàyé pé kíì ilé iṣẹ́ YEDC pada sí iná wákàtí méjìlá nítori pé iná náà kò wúlò ní àsìkò tí àwọn bá lọ sí ibiṣẹ́, sùgbọn owó ti YEDC ń mú wa ti pọ jú agbára ohun lọ.
Seun Kuti: Fela ló n pọ́n gbogbo òǹkọrin Afrobeat lagbaye
Esther Chukwuma sàlàyé pé oun tí ó ti ń san ẹgbẹ̀rún mẹ́fà àbọ̀ náírà tẹ́lẹ̀ di ẹni tó ń san ẹgbẹ̀rùn mẹ́rìnlá fún iyé owó kan náà.
Nínú àwọn tó fẹ̀hónú han sàlàyé pé ilé yàrá kan tún ń san ẹgbẹ̀rúndínlógún náírà, èyí sì túmọ sí ìyànjẹ .
Wọn rọ àwọn ilé iṣẹ́ náà láti ṣe atúnṣe tó to nítorí iná wákàti mẹ́rìnlelógún
NNPC: Òpó ọ̀pá epo tí wọn ń rì lọ́wọ́ ló fa ìṣẹ̀lẹ̀ ìbúgbàmú náà
Oríṣun àwòrán, Others
Ile iṣẹ to n risi ọrọ epo rọbi ni Naijiria, NNPC ti salaye bi iṣẹlẹ to pa oṣiṣẹ meje ṣe waye ni agbegbe Gbetiokun, OML 40, in ilu Benin, ipinlẹ Edo.
Ninu atẹjade kan ti Adari eto Iroyin fun ileesẹ NNPC, Dokita Kennie Obateru fi sita lo ti salaye pe, isbugbamu ọpa epo naa waye lasiko ti wọn n ri opo ọpa epo mọlẹ.
Ajọ NNPC fikun pe, iwadii ni kikun ti bẹrẹ lori bi ibugbamu naa ṣe ṣẹlẹ.
Bakan naa ni wọn salaye pe, wọn ti gbe oku awọn eniyan naa lọ si ibudo igbokusi ni Sapele, ti wọn si ti fi isẹlẹ naa to awọn ẹbi ati ara wọn leti.
Ajọ NNPC ni, gbogbo awọn to wa ni ibi iṣẹlẹ naa ni awọn ti fi orukọ wọn sita, ti ko si si ẹni to sọnu.
Oríṣun àwòrán, NNPC
Ileesẹ elepo rọbi naa wa ba awọn ẹbi ati ara awọn to ku ninu isẹlẹ ibugbamu yii kẹdun, ti wọn si gbadura pe Ọ́lọ́run yoo fun wọn ni ẹmi lati la akoko iku ololufẹ wọn kọja lai lewu.
Oríṣun àwòrán, @trafficbutter
Ọpọlọpọ mọto, ọjà ati nkan amuludun lo jona ni Abule Egba nidaji ọjọru
Saaju la ti fi to yin leti ni osu kejila lọdun 2018 pe, ajọ elepo rọbi lorilẹede Naijiria, NNPC ti bẹrẹ iwadii lori iṣẹlẹ ijamba ina to ṣẹyọ ni ori ọpa epo rẹ kan lagbegbe abule ẹgba ni Eko.
Iṣẹlẹ ijamba ina naa sọ ni idaji ọjọru lori ọkan lara awọn ọpa epo ajọ naa kan ti awọn ọbayejẹ ti bajẹ.
Ọpọlọpọ mọto, ọja ati nkan amuludun lo jona ninu iṣẹlẹ ohun.
Oludari agba ajọ NNPC, Ọmọwe Maikanti Baru ninu atẹjade kan ṣalaye pe oun ti paṣẹ fun ọkan lara awọn ẹka ajọ naa to n ṣamojuto ọpa epo ati kiko epo pamọ, NPSC lati tete lọ tu iṣu de isalẹ ikoko ọrọ naa ki wọn lee mọ  ohun to ṣokunfa ijamba ina naa.
Bakan naa lo ni iṣẹlẹ naa ko ni fa ọwọngogo epo ni agbegbe ipinlẹ Eko atawọn ipinlẹ to yii ka ati pe atunṣe yoo de ba ọpa epo ti o jona naa lẹyẹ-o-ṣọka.
'Mo ti gba kádàrá lórí bí Ọlọrun ṣe dá mi'
Oludari ajọ NNPC naa ṣalaye pe ko si idi fun araalu lati ko aya soke lori boya ijamba ina naa yoo ṣokunfa ọwọngogo epo rọbi nitori, gẹgẹ bi Ọmọwe Baru ṣe sọ, ajọ NNPC ni epo bẹntiro atawọn ẹya epo miran ninu aka rẹ, eleyi ti yoo to orilẹede Naijiria  lo fun ọjọ marundinlaadọta bi omiran ko ba tilẹ wọle.
APC Kwara: Abdulrahman ṣì ni olùdíje wa fún ipò Gómìnà
Oríṣun àwòrán, APC KWARA
Igbimọ amuṣẹya ẹgbẹ lo ṣe idibo abẹnu to gbe Abdulrahaman Abdulrazaq wọle gẹgẹ bi oludije ipo Gomina
Akowe ipolongo apapọ ẹgbẹ APC, Lanre Issa Onilu ti tako idajo ile ẹjọ giga kan nilu Ilorin to ni igbimọ ẹgbẹ labẹ akoso Ishola Blogun Fulani ni ojulowo igbimọ ẹgbẹ.
Issa Onilu fi ọrọ rẹ to tako idajọ yi sita ninu atẹjade kan.
Lọjọru  ni ile ẹjọ giga kan nilu ilorin fi idajọ sita eleyi to tunmọ si wi pe oludije ti idibo abẹnu Ishola Balogun sakoso rẹ ni o tọ lati du ipo Gomina labẹ asia ẹgbẹ APC.
Onilu salaye pe ẹgbẹ APC le Ishola Balogun Fulani  ati awọn ọmọ igbimọ kuro ninu ẹgbẹ lẹyin iwadi to safihan wi pe o n gbe igbesẹ to tako ẹgbẹ.
Akọroyin nigba kan ri ni yoo ṣoju APC dupò gomina Kwara
Fun idi eyi o ni ,awọn oludije ti igbimọ amuseya ṣe idibo abẹnu fun ti wọn si jaweolubori ni ojulowo oludije ẹgbẹ APC ninu ibo 2019.
''A rọ awọn ara ilu Kwara  lati ma ṣe korẹwẹsi ọkan  ki wọn si gbaruku ti wa ninu ilakaka ati tu Kwara ninu oko amunisin''
Bi a ko ba gbagbe,ikọ Ishola Balogun Fulani ti saaju ṣeto idibo abẹnu eleyi to gbe AbdulWahab Omotose Kayode  jade gẹgẹ bi ẹni to jawe olubori nínu idibo abẹnu ẹgbẹ APC ni  ipinlẹ Kwara.
2019 Nigeria Budget: Wo pàsán ojú Buhari tó dá awuyewuye sílẹ
Oríṣun àwòrán, Channels TV
Aarẹ Buhari nibi ti o ti n ṣe agbekalẹ abadofin 2019 niwaju ile asofin
Lọjọru ni Aarẹ orileede Naijiria Buhari lewaju awọn ọmọ igbimọ rẹ lo ṣe agbekalẹ abadofin isuna ọdun 2019 ṣugbọn oun ti awọn asofin ṣe fun lawọn eeyan n sọrọ nipa rẹ.
Awọn asofin lati ẹgbẹ APC to wa lori ijọba ati awọn akẹgbẹ wọn lati ẹgbẹ PDP ko fun ara wọn ni ọrọ sọ nigba ti Aarẹ Buhari n bawọn sọrọ.
Awọn alatilẹyin rẹ n ke dansaaki rẹ ti awọn alatakọ si n ṣe ọọbi fun un.
Bi Aarẹ Buhari ti ṣe n mẹnu ba awọn akanṣe iṣẹ ti ijọba rẹ ti gbeṣe ni 2018 ni asofin kan ti a ko ri oju rẹ bẹrẹ si ni pariwo ''irọ ni,kii ṣe ootọ
Ohun ọkunrin naa gbalẹ debi wi pe Aarẹ Buhari gbọ ohun to so ti o si danuduro lati wo ẹni to sọ ọrọ naa.
Awọn ọmọ Naijiria ṣe akiyesi bi Buhari ti ṣe na ẹni naa ni pasan ọju ti wọn si fi iriwisi ọtọọtọ sita lori nnkan to fa.
Ẹyin naa ẹ wo fọnran  fidio naa:
Ati awọn iriwisi to tele
Budget 2019: Wo àwọn aṣíwájú àgbáyé míràn táwọn èèyàn dẹ́yẹsí lágbayé
Oríṣun àwòrán, Ahmad Bashir
Diẹ lara awọn to ti ba irufẹ itiju ati ariwo idẹyẹsi bayii pade ni Donald Trump, Theresa May, Jacob Zuma ati George Bush
Idarudapọ ti ko kere lo waye nigba ti aarẹ Muhammadu Buhari tọ awọn aṣofin apapọ lọ lati gbe aba eto iṣuna orilẹede Naijiria ọdun 2019 kalẹ niwaju wọn fun agbeyẹwo.
Amọ ṣa, iran kọ wiwo nigba ti aarẹ yoo fi pari agbekalẹ rẹ pẹlu bi o ṣe di sinima agbelewo ninu eyi ti awọn aṣofin kan ti n dẹyẹsi aarẹ ti awọn ti o ṣe tirẹ pẹlu si n yin in.
Kii ṣe ojuti diẹ ni ọrọ yii gbe kalẹ fun aarẹ nitori lai ṣi aniani eyi ni igba akọkọ ti aarẹ kan lorilẹede Naijiria yoo dojukọ irufẹ idẹyẹsi ati ojuti bẹẹ lasiko ti wọn n gbe irufẹ aba iṣuna bẹẹ kalẹ niwaju awọn aṣofin apapọ.
Àwọn agba bọ wọn ni a ko ri iru eyi rii, ẹru la fi n da bara ẹni; Aarẹ Buhari kọ ni aarẹ akọkọ ti yoo foju wina atako awọn eeyan rẹ ti wọn yoo gbe ka ori pepele itiju kaakiri agbaye.
Diẹ lara awọn to ti ba irufẹ itiju ati ariwo idẹyẹsi bayii pade niwọnyii:
Donald Trump:
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ọrọ kii si n lẹyin Aarẹ Donald Trump ti Amẹrika; Bi o ṣe n dẹyẹsi awọn ọmọ orileede rẹ lawọn naa n da pada fun un
Aarẹ orilẹede Amẹrika, Donald Trump kii ṣe ajeji si idẹyẹsi; paapaa lati igba ti o ti di aarẹ orilẹede Amẹrika ni ọdun 2016. ọpọ igba ni o si maa n forigbari pẹlu awọn oniroyin. Ọkan lara igba ti wọn dẹyẹ sii rẹ ni ita gbangba naa ni asiko kan ti o lọ si ibi ipadeeto ọrọ aje agbaye, World Economic Forum, (WEF) ni Davos nigba ti o fi ẹsun iroyin ofege kan awọn oniroyin.
Ẹrin ati ọpọ idẹyẹsi ni awọn ero ti o n wo o ifọrọwerọ rẹ lọjọ naa fi pade rẹ.
George Bush:
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Aarẹ Buhari kọ ni aarẹ akọkọ ti yoo foju wina atako awọn eeyan rẹ ti wọn yoo gbe ka ori pepele itiju kaakiri agbaye
Lasiko ti o fi n ba awọn oniroyin sọrọ ni aafin olotu ijọba orilẹede Iraq to wa ni ilu Baghdad, aarẹ orilẹede Amẹrika nigba naa pẹlu foju wina irufẹ idẹyẹsi  to fa idoju nlanla kaakiri agbaye nigba ti akọroyin kan, Muntadhar al-Zaidi ju bata ẹsẹ rẹ lu aarẹ George Bush.
Igba meji ọtọọtọ ni arakunrin yii ju bata lu aarẹ ilẹ Amẹrika ti oun pẹlu si yẹẹ nigba mejeeji ọhun.
Okiki iṣẹlẹ yii kan kaakiri agbaye ti ọpọ si rii gẹgẹ bii itiju fun odindi aarẹ orilẹede Amẹrika.
Afihan idẹyẹsi ati ikorira ni aṣa jiju bata lu eniyan ni aṣa awọn larubawa.
Theresa May:
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Awọn aṣofin kan dẹyẹsi aarẹ, awọn ti o ṣe tirẹ pẹlu si n yin in niwaju ile aṣofin apapọ
Olotu ijọba ilẹ Gẹẹsi pẹlu ti ni ipin tirẹ ninu irufẹ idẹyẹsi bayii.
Ọrọ igbesẹ lati fa ilẹ Gẹẹsi jade kuro ninu ajọ orilẹede Yuroopu, EU eleyii ti wọn da pe ni BREXIT lo n fun un ni ẹfọri julọ bayii.
Amọṣa diẹ lara awọn asiko ti wọn ti dẹyẹsi rẹ pẹlu ariwo ṣiọ ṣiọ ni igba ti o farahan nibi ajọdun Edinburgh Festival Fringe.
Olotu ijọba ilẹ Gẹẹsi naa lọ wo awọn akọrin Soweto Gospel Choir ti wọn n kọrin ni olu ilu orilẹede Scotland gẹgẹ bii ara ajọdun nla naa.
Ṣugbọn ni kete ti o gunlẹ nibẹ bayii ni ariwo hee, hẹẹ ti bẹrẹ pẹlu oniruuru idẹyẹsi.
Jacob Zuma:
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Afihan idẹyẹsi ati ikorira ni aṣa jiju bata lu eniyan ni aṣa awọn larubawa
Lasiko ajọyọ iranti Nelson Mandela ti wọn ṣe ni  ilu Johannesbourg ni awọn eeyan to wa nibẹ ti pariwo idẹyẹsi le Zuma lori lẹyin ti wọn ti kigbe ẹyẹ nigba ti wọn pe orukọ aarẹ amẹrika nigba naa, Barack Obama.
Lootọ ni wi pe irufẹ iwa yi a ma mu iriwisi ọtọọtọ wa ṣugbọn ko daju wi pe awọn ara ilu ko ni ye wu iru iwa bayi si awọn olori wọn.
Idi ni wi pe ofin fi aye silẹ fun isọrọ gẹgẹ bi ẹtọ ọmoniyan.
Ohun to wa ku ni ki onikalulku lo ẹtọ yi lọna ti ko fi ni koja ofin to fi aaye gba wọn.
Adams Oshiomole: Buhari ló lè gba Naijiria ní oko ẹrú
Oríṣun àwòrán, Facebook
Alagba gbogboògbò fún ẹgbẹ́ òsèlú APC ti rọ àwọn ará Nazarawa láti di ìbò wọn fún Ààrẹ Muhammadu Buhari.
Alagba gbogboogbo fun ẹgbẹ oselu APC, Adams Oshiomole ti ni Ọlọrun ko ni jẹ ki ẹgbẹ oselu PDP pada si ipo lorilẹede Naijria.
Oshiomole to sọ eyi ni Nazarawa, wi pe ọdun mẹrindinlogun ti PDP fi wa nipo ni wọn fi ba ilẹ jẹ, ti wọn jẹ ilu run.
O ni Aarẹ Buhari nikan lo lee tun orilẹede yii se, ti yoo si da gbogbo ikolọ ti awọn asebaje ti kolọ pada.
Alagba gbogboogbo fun ẹgbẹ oselu APC naa wa fikun wi pe ọdun mẹta ko to lati fi yi igba pada lorilẹede Naijiria.
Amọ, ni ọpọ igba ni ẹgbẹ alatakọ PDP ti ma n sọ wi pe isejọba awọn daraju igba ti Aarẹ Buhari Muhammadu.
APC Kwara: Igun Bolarinwa ní àwọn ni alága ẹgbẹ́ tọ́ sí
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ilé ẹjọ́ gíga ti Ilorin ní Ọjọ́ọ̀rú ọ̀sẹ̀ yìí dá ẹjọ́ pé Ishola Balogun -Fulani ni Alaga ẹgbẹ òsèlú APC ní ìpínlẹ̀ Kwara.
Igun Bashir Bolarinwa ti ẹgbẹ oselu APC ni ipinlẹ Kwara ti gba ile ẹjọ kotẹmilọrun lọ, lẹyin ti ile  ẹjọ giga ni ipinlẹ Ilorin sọ wi pe awọn kọ ni wọn yọ ni alaga ẹgbẹ.
Ọjọbọ ọsẹ yii ni ile ẹjọ giga ni ipinlẹ naa sọ pe Ishola Balogun Fulani ati ikọ rẹ ni alaga ẹgbẹ naa ni ipinlẹ Kwara.
Igun Bashir wa n rọ ile ẹjọ kotẹmilọrun lati da ẹjọ naa nu, ki wọn si da awọn pada si ipo gẹgẹbi alaga ẹgbẹ to yanju.
Ti a ko ba gbagbe, alaga gbogboogbo fun ẹgbẹ oselu APC, Adams Oshiomole naa sọ ni Ọgbọnjọ, Osu Keje, ọdun 2018 wi pe oun ti tu igbimọ ẹgbẹ ka ni ipinlẹ Kwara, lẹyin ti aarẹ Ile Igbimọ Asofin Agba, Bukola Saraki fi ẹgbẹ silẹ lọ si ẹgbẹ oselu PDP.
Logo Benz: Ìtanijí ni orin wa wà fún, Ẹ má ká wa lọ́wọ́ kò -Olamide
Oríṣun àwòrán, Olamide/Facebook
Gbajugbaja ilumọka olorin takasufe ni Olamide
Igbe Olamide ati Lil Kesh lo gbẹnu awọn ọmọ Naijiria loju opo Twitter bayii.
O ṣeeṣe ki ẹ ma beere wi pe kini wọn ṣe
Ọlọpa ko ka igbo mọ wọn lọwọ tabi ibọn ṣugbọn lọdọ awọn ololufẹ orin takasufe,wọn ti da ọran kabiti.
Ọrọ inu orin tuntun kan ti wọn pe akọle rẹ ni Logo Benz lo n dagboro ru o.
Awọn ọmọ Naijiria  gbo orin naa sugbọn kaka ki wọn  gboriyin fun wọn lori orin tuntun naa,iriwisi ọtọọtọ lo ba de.
Loju opo Twitter awọn kan ko tilẹ pẹ ọrọ sọ pe orin naa  gboriyin fun pipa eeyan lati fi ṣe ogun owo tabi wiwa ọna ẹburu lati ni owo eleyi ti awọn eeyan mọ si ''yahoo plus''
Ọrọ naa le ma bi awọn kan ninu ṣugbọn Olamide fun ara rẹ ti jade soju opo Twitter rẹ lati slaye pe oun ko ri nnkan to buru ninu orin naa.
O ni ohun to n ṣẹlẹ lawujọ ni oun n sọ ko siyẹ ki awọn eeyan ma ka awọn olorin lọwọ ko
Irori Wilson Israel ati ti Chinex papọ pẹlu ti Olamide.
Lọdọ wọn orin lasan lo kọ, o si ṣe pataki ki awọn eeyan gbo ẹkọ ti orin naa n kọ wọn
Awọn kan tun mu Fela Anikulapo wọ inu ọrọ yi.
Ọrọ iru orin ti awọn olorin asiko yi n kọ jẹ eleyi ti awọn ara ilu ma n mẹnu baa nigbakigba ti orin to ba ṣe bi ẹni yatọ ninu ẹkọ to kọ tabi bi wọn ti ṣe ṣe fidio rẹ.
Bi a ko ba gbagbe laipe yi ni iriwisi waye lori fidio orin Falz to pe akọle rẹ ni 'This is Nigeria'
Fidio orin naa to ṣe afihan awọn ọmọ obinrin to n jo  Shaku Shaku pẹlu Hijab mu inu bi awọn ẹgbẹ Musulumi kan ti wọn ni orin naa tabuku ba ẹsin awọn.
TraderMoni: Igbákejì ààrẹ Osinbajo ní owóòyá TraderMoni kìí ṣe owó ìbò rírà
Oríṣun àwòrán, AAAjimobi
Oṣinbajo ní ó dín díẹ̀ ní mílíọ́nù kan àbọ̀ oníṣòwò tó ti jàǹfàní ètò owóòyá náà
Igbakeji aarẹ orilẹede Naijiria, Yẹmi Oṣinbajo ti pariwo sita pe owo iranwo fawọn ọlọja ati oniṣowo ti wọn pe ni 'TraderMoni' eleyii ti ijọba apapọ n pin kaakiri awọn ọja bayii kii ṣe fun rira ibo awọn araalu.
Ọpọ awọn onwoye, paapaa awọn ẹgbẹ alatako, ni wọn ti ke ibosi sita lori owo naa pe adọgbọn fi owo tu oju awọn ọlọja ki wọn lee dibo ni.
Oṣinbajo ni igbesoke  aye awọn ọmọ orilẹede Naijiria, paapaa awọn oniṣowo kekeke, ni owo TraderMoni wa fun.
Ipenija ojú kò di Ademola lọ́wọ́ láti kẹkọọ gboye
'Mo ti gba kádàrá lórí bí Ọlọrun ṣe dá mi'
O ni awọn ọta oniṣowo ni wọn n pe owo naa ni owo raborabo.
Oríṣun àwòrán, Yemi Osinbajo
Osinbajo ni awọn aṣofin apapọ buwọ lu owo naa
Gẹgẹ bi o ṣe sọ, awọn aṣofin apapọ buwọ lu owo naa ki ijọba apapọ to bẹrẹ pinpin rẹ kaakiri.
Igbakeji aarẹ ni owo naa kii ṣe owo ọfẹ nitoripe ẹka banki idaṣẹsilẹ, BOI kan wa ti o n mojuto nina ati gbigba pada wọle owo naa.
Oríṣun àwòrán, yemi osinbajo
O ni awọn ọta oniṣowo ni wọn n pe owo naa ni owo raborabo
O ni aarẹ Buhari lo ti kọkọ bẹrẹ irufẹ eto bayii ni ilu rẹ ki o to de ipo aarẹ pẹlu ajọ kan eyi ti o n ṣeto ẹyawo alabọde fun awọn oniṣowo kerejekereje bi alakara atawọn okoowo miran.
O fi kun un pe o din diẹ ni miliọnu kan abọ eeyan ti wọn ti janfani eto owooya na.
Election 2019: Afẹ́nifẹ́re pín nítorí Buhari àti Atiku
Election 2019: Afẹ́nifẹ́re pín nítorí Buhari àti Atiku
Lati ọjọ pipẹ wa ni awọn agba Yoruba ti maa n ko ipa ti o jọju ninu ilana eto oṣelu ti ilẹ Yoruba yoo tọ.
Eyi tẹ siwaju pẹlu ipa pataki ti oloogbe Oloye Awolọwọ pẹlu ẹgbẹ ọmọ oduduwa to yirapada di ẹgbẹ Oṣelu Action group ko ninu idagbasoke oṣelu ilẹ Yoruba titi de ori Afẹnifẹre ati NADECO to jija gbara fun iṣejọba tiwantiwa.
Ko si jẹ ohun tuntun lati ri awọn ẹgbẹ aṣiwaju ilẹ Yoruba bii Afẹnifẹre, Igbimọ agba, OPC ati bẹẹbẹẹ lọ lati dide kede ohun ti wọn wo pe o yẹ ni ṣiṣe fun ilẹ Yoruba ni irinajo oṣelu.
Ṣugbọn nigba ti ẹgbẹ kan ba tun ti n tako ara rẹ lori ọna ti wọn fẹ tọ tabi fẹ ki Yoruba tọ lasiko oṣelu kan tabi omiiran, o n fẹ amojuto.
Ẹgbẹ Afẹnifẹre ni oun ti buwọlu idapada sipo aarẹ fun aarẹ Muhammadu Buhari ati igbakeji rẹ, Yẹmi Oṣinbajo ninu ibo 2019.
Agbẹnusọ fun ẹgbẹ naa, Oloye Biọdun Akin-Faṣae lo kede eyi lẹyin ipade kan eyi ti o waye laarin awọn aṣoju ẹgbẹ naa kaakiri ipinlẹ mẹfa ilẹ Yoruba lorilẹede Naijiria ni Gbọngan awọn lọbalọba ni ile ijọba nilu Ibadan.
Oríṣun àwòrán, @atiku
Atiku ni igun ẹgbẹ Afẹnifẹre kan n tẹle
"Ẹgbẹ Afẹnifẹre ni ọna itẹsiwaju ni oloye Awolọwọ to da ẹgbẹ naa silẹ maa n tọ, idi niyi ti awọn si fẹ fi tẹlẹ aarẹ Buhari nitori pe ""o n sa ipa rẹ bi o ti mọ"""
Amọṣa ohun ti o wa n ṣe ọpọ onwoye ni kayefi ni bi ẹgbẹ Afẹnifẹre yii kan naa ti ṣe kede ni ọsẹ diẹ sẹyin pe Atiku Abubakar to jẹ oludije ẹgbẹ oṣelu PDP ni awọn n ba lọ.
Ṣugbọn igun Afẹnifẹre to fi atilẹyin han fun Atiku Abubakar ti ṣalaye pe ẹgbẹ afẹnifẹre kan ṣoṣo ni o wa, Alagba Faṣọranti si ni olori ẹgbẹ naa.
Oríṣun àwòrán, @MBuhari
Nǹkan ti rí bákan lẹ́gbẹ́ Afẹ́nifẹ́re báyìí pẹ́lú bí àwọn àgbà ẹgbẹ́ náà ṣe pínyà lórí àtìlẹ́yìn wọn fún Ààrẹ Buhari ti APC àti Atiku ti ẹgbẹ́ òṣèlú PDP
Ninu ọrọ to ba BBC News Yoruba sọ, agbẹnusọ fun Afẹnifẹre, Yinka Odumakin ni awọn oloṣelu ni awọn to korajọpọ lati fi atilẹyin wọn han fun Buhari ati Oṣinbajo kii ṣe Afẹnifẹre.
Gẹgẹ bi o ṣe wi, lẹyin oloye Fasanmi, ko si eyikeyi ninu awọn to ṣe ipade ni ilu ibadan ti o wa ninu ẹgbẹ naa.
Nibi ọrọ de duro yii, ibeere ti o n gba ẹnu ọpọ bayii ni pe, ewo gan an ni Afẹnifẹre ninu awọn mejeeji yii ati pe ewo gan an ni ki Yoruba o tẹle ninu wọn?
Obìrin kògbérégbè mẹ́ta nínú òṣèré Yorùbá
Oríṣun àwòrán, Instagram/Lola_Idije
Oríṣìríṣi àwọn òṣeré ló wà nínú àwọn òsèré sinimá àgbéléwó tí wọ́n sì ń kópa ọlọ́kan ò jọ̀ kan níbẹ̀.
Ṣùgbọ́n àwọn obìnrin kan wà tí wọ́n máa ń ṣe ipa ẹni tí kò gba ìgbàkugbà nínú eré.
Ọ̀kan lára àwọn òṣèré yìí ni Toyin Afolayan ti ọ̀pọ̀ èèyàn mọ̀ sí Lọla Idije.
Idijẹ ti pọẹ́ nínú ere sinimá Yorùbá, nínú eré náà ló sì ti rí ìnagijẹ rẹ̀.
Eré Obìnrin Àsìkò tí olóògbé Alade Aromire ṣe ni Toyin Afolayan ti rí ìnagijẹ rẹ̀ tíi ṣe Lola Idijẹ.
Idijẹ ṣe ìyá ìta tí kò gbàgbàkugbà nínú eré náà tí àwọn okùnrin sì mọ̀ ọ́ sí èyí.
Obìnrin náà ṣì ń kópa nínú àwọn eré sinimá àgbéléwò Yorùbá ni ọlọ́kan-ọ̀-jọ̀-kan.
'Mí ò ya wèrè, mí ò burú, ọ̀nà àtijẹ là ń wá'
Ó ti pẹ́ tí Sola Sobawale tí ń ṣe iṣẹ́ sinimá àgbéléwò. Ó darapọ̀ mọ́ ẹgbẹ́ Awada Kẹríkẹrì lábẹ́ àṣẹ àgba òṣèré, Adebayo Salami.
Bẹ́ẹ̀ náà ni òṣere náà ti kọ́kọ́ ṣe iṣẹ́ ní iléeṣẹ́ amóhùnmáwòran NTA láì gba owó.
Gbajúgbajà òṣèré náà ti kópa nínú àwọn orísíríṣí eré bíi Asẹwo to re Mecca, Ohun Ọkọ sọ mi da, Asewo Kano àti bẹ́ẹ̀bẹ́ẹ̀ lọ.
Ṣùgbọ́n tòun ti pé kò kìn ín gba ìgbàkugbà nínú eré, Sobowale ṣàlàyé fún BBC pé òun kìí ṣe ènìyàn tó burú.
Ó ṣe àfikún pé gbogbo nǹkan tí òun ń ṣe lórí eré ìtàgé kìí ṣe ìwà òun ni.
Oríṣun àwòrán, Mide
Ọ̀kan nínú àwọn Kògbérégbè láàrín àwọn ọ̀dọ́ tí wọ́n jẹ́ obìnrin tí wọ́n ń ṣe sinimá àgbéléwò Yorùbá ni Mide Funmi Martins Abiodun tó jẹ́ ọmo fún olóògbé Funmi Martin, ó sì jé aya fún òṣèré Hafeez Owo.
Mide náà ti kópa nínú àìmọye eré tó ti hùwà kògbérégbé gẹ́gẹ́ bí obìnrin.
Lára àwọn eré tó ti kópa ni Abami Eda, Ibeji Gbajumọ, Mama Iyawo Ika, Pregnancy Test, Owo ni koko àti bẹ́ẹ̀ bẹ́ẹ̀ lọ.
Yemi Alade: Bí a bá ní ìdí nlá bàa ní, kó sí ẹni tí kò rẹ́wà
Oríṣun àwòrán, Tiwa Savage/Yemi Alade/ Instagram
Ija ti pari
Ija to waye lori Twitter laarin gbajugbaja akọrin Tiwa Savage ati Yemi Alade jọ bi ẹni pe o ti pari.
Fun bi wakati meloo kan lori ayelujara lawọn mejeeji n tahun si ara wọn lori ọrọ idi nla.
Yemi Alade  fi ọrọ sita loju opo Twiiter  lati tọrọ aforijin.
Mo n wa'yawo - Falz
Yemi Alade Promo
Ninu ọrọ rẹ o ni oun fẹ ki awọn obinrin gbogbo mọ iyi ara wọn ati wi pe ko si ẹni ti ko rẹwa laaye tirẹ
''ati ẹni tirin,ati ẹni sanra,bo ni idi nla,bo ni,gbogbo wa la rẹwa''
Tiwa Savage ko ti fẹsi si ọrọ yi sugbọn awọn obinrin miran ti gbosuba kare fun Yemi Alade fun pe o wu iwa yi
Ija bum bum,ere lasan abi ootọ
Lọjọ ẹti lawọn olorin mejeeji naa Tiwa Savage ati Yemi Alade bẹrẹ ija lori ẹni ti idi rẹ tobi julọ laarin wọn.
Yemi Alade lo kọkọ fi ọrọ sita pe ki Tiwa Savage ye ma paro tan awọn  eeyan pẹlu bi o ti ṣe n ṣe afikun idi rẹ ninu aworan.
Kiakia ni Tiwa Savage naa da esi pada fun
Awọn ololufẹ awọn ol;orin mejeeji ko gbeyin ti awọn naa si n fi ọrọ sita lori ija bum bum ohun
Awọn kan tilẹ ni ainiṣe lo n da awọn to n sọ ọrọ nipa idi nla laamu.
Union Bank: Àwa la ni owó tí EFCC gbà ní pápákọ̀ òfúrufú Enugu
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ko ti daju ibi ti ọrọ yi yoo kangu si
Ile ifowopamọ Union Bank ti figbe sita pe awọn lawọn ni owo ti ajọ EFCC gba lọwọ awọn arakunrin meji kan ni papakọ ofurufu Akanu Ibiam nilu Enugu.
Wọn ni awọn okunrin naa n ba awọn gbe owo naa ni ati wi pe ko si ohun to buru ninu rẹ
Loju opo Twitter wọn ni wọn fi ikede yi si
Saaju lọjọ ẹti ni  EFCC kede wi pe awọn mu awọn arakunrin meji kan ti wọn fura si wi pe wọn ṣe fayawọ owo.
Ninu ọrọ ti wọn fi sita loju opo Twitter, wọn fi hastag #MoneyLaundering si iwaju ọrọ wọn eleyi to tọka si wi pe owo naa ki ṣe owo etọ.
Efcc sọ ninu ọrọ wọn wi pe awọn arakunrin naa jẹwọ pe ile ifowopamọ kan lawọn n ba gbe owo naa ati wi pe o ti to ọdun mẹfa ti awọn ti n ba awọn ile ifowopamọ to loruko gbe iru owo bẹ.
''Won ni o ti pe  ẹmẹrin tawọn ti gbe iru owo bẹ lọdun yi.''
Ko ti daju boya ile ifowopamọ naa yoo gbe Efcc lọ ile ẹjọ lati gba owo wọn ṣugbọn iṣẹlẹ yi ti mu iriwisi ọtọọtọ wa lori Twitter
Bi awọn kan ti ṣe n da Efcc lẹbi lawọn kan ṣe kayefi nipa bi ile ifowopamọ a ṣe tun ma gbe owo wọ baalu lati ilu kan si omiran
Ìkíni kú oríire ti ya bo Funke Akindele àti ọkọ rẹ̀ JJC Skillz
Oríṣun àwòrán, funke akindele
Gbajugbaja oṣere tiata Funke Akindele ti ọpọlọpọ n pe ni Jenifa ti di iya ibeji bayi, to ba jẹ pe ootọ ni awọn ikinni oriṣiriṣi to gba ori afẹfẹ lati aarọ ọjọ Abamẹta.
Bo tilẹ jẹ pè oun funra rẹ ko ti i sọrọ lori Twitter tabi Instagram lati sọ wipe ootọ ni oun bimọ lorilẹede Amerika, awọn ọrẹ rẹ ti n ki oun ati ọkọ rẹ Abdul Rasheed Bello ti aye mọ si JJC Skillz pe wọn ku ori ire.
Japheth Omojuwa wa lara awọn to ki ku ori ire.
Bẹẹ naa ni Reuben Abati to jẹ agbẹnusọ aarẹ ana, Goodluck Jonathan fi iroyin naa sori atẹ Twitter rẹ pee Akindele ti bimọ ni tootọ.
Oṣere tiata Mercy Aigbe ati sọrọsọrọ Toke Makinwa naa wa lara awọn to ba dunnu fun iroyin ayọ yii.
Oríṣun àwòrán, Mercy Aigbe/Instagram
Oríṣun àwòrán, Toke Makinwa/Instagram
Ni deede ọdun mẹta sẹyin ni wooli kan nilu Eko, Olagorioye Faleyimu ti ijọ Mountain of Blessing and Miracle ni o lè ma ri ọmọ bi.
Oríṣun àwòrán, Mountain of Blessing and Miracle Church of Christ
Wooli Faleyimu sọ nigba naa wipe ti ko ba ṣe awọn akanṣe adura kan, ko ni ri ọmọ bi titi to fi maa jade laye.
"Ni ọdun 2017, wooli naa tun ni oun ko kabamọ pe oun ri ""iran"" yii. 2017 kan naa ni iroyin tan kaakiri wipe, Akindele loyun ṣugbọn o ti padanu rẹ, ni ọpọlọpọ ba n daro wipe boya ""iran"" wooli naa ti n wa si imuṣẹ ni."
Wooli yii ti ri awọn iran kan sẹyin. Ni ọdun meelo kan sẹyin lo sọ iran wipe awọn eekan oloṣelu kan bi Bola Tinubu yoo ku, ṣugbọn wọn ṣi wa laye bayii.
Wòlíì Àrólé sọ àsọtẹ́lẹ̀ s'áyé BBC ní London
NLC: Gbogbo òṣiṣẹ ló n fẹ́ ilọsiwaju Naijiria
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Owó oṣu ti oṣiṣẹ n beere fun ko pọju
Ẹgbẹ NLC kede pé ìwọ́de ni wọn yoo fi ṣide iyanṣẹlodi naa ni 2019.
Nibi ipade apapọ oloye ẹgbẹ ajọ awọn oṣiṣẹ ni Naijiria ni wọn ti fẹnuko pe ti ijọba Buhari ba kọ̀ lati san ẹkunwo owo oṣu ti awọn oṣiṣẹ n jà fun lo fi ṣeeṣe ki nkan má ni ṣenu ire lọdun tuntun.
Wọn ni ẹgbẹrun naira lọna ọgbọn to jẹ odiwọn owó oṣu to kere julọ ti awọn n beere fun ko pọju rara Ojú ń kán wa, a fẹ́ gba àfikún owó osù tuntun- NLC.
Egbe awọn osiṣẹ ati ijọba ti ṣe ọpọlọpọ ipade sẹyin Ojú ń kán wa, a fẹ́ gba àfikún owó osù tuntun- NLC pẹlu iwọde ati iyanṣelodi Ẹgbẹ́ òṣìṣẹ́ so ìyanṣẹ́lódì rọ̀ ti wọn fi kilọ fún ijọba pe ọwọngogo ni nkan ti onikaluku n rà lọja lasiko yii NLC: A ò ní dìbò wa fún àwọn gómìnà ọ̀tá òṣìṣẹ́
Ọgbẹni Ayuba Wabba to jẹ aarẹ ẹgbẹ oṣiṣẹ Naijiria ati Peter Ozo-Eson to jẹ akọwe ṣalaye pe ni gbogbo olú ilu ipinlẹ kọọkan ni Naijiria ni ìwọde naa a ti waye pẹlu Abuja.
Larisa: Má jẹ́ kí ọjọ́ orí rẹ dí ẹ lọ́wọ́ láti bẹ̀rẹ̀ ohunkóhun to wù ọ
Àwa ò fún ìjọba ní gbèdéke láti sanwó wa- ẹgbẹ́ òṣìṣẹ́
Atẹjade ti wọn fi sita ni gbogbo oṣiṣẹ ati onikarakata lẹgbẹ kọọkan ni wọn jọ maa ṣe iwọde naa.
Wọn ni o jẹ ohun to bani lọkan jẹ pe ijọba Buhari kọ lati ṣe ohun to yẹ lati ọjọ kẹfa, oṣu kọkanla ti awọn igbimọ tẹẹkoto ti jabọ fun Aarẹ Buhari pe ẹgbẹrun lọna ọgbọn naira ni wọn fenuko le lori.
Wọn ni o jọniloju pe aarẹ Buhari tun le sọ fun awọn aṣofin pe oun tun fẹ ṣẹṣẹ gbe igbimọ tuntun kalẹ lati ri si ọrọ owo oṣu tuntun naa lasiko to n gbe iṣuna 2019 wa siwaju ilé.
Egbẹ oṣiṣẹ ni àwọn gba pe ko yẹ ki ọrọ igbimọ ṣi wa ninu ọrọ owo oṣu yii mọ.
Atẹjade naa fidi ẹ mulẹ pé igbese ijọba yii fihan pé ọrọ awọn oṣiṣẹ, ẹbí oṣiṣẹ ati àwọn eniyan Naijiria ko jẹ ijọba logun to.
Ipenija ojú kò di Ademola lọ́wọ́ láti kẹkọọ gboye
Àṣà àti iṣẹṣe Yorùbá dì apewo ní Cotonou
'Yorùbá yóò gba ìjọba ni 2023 ti wọ́n bá gbé Buhari wọlé ni 2019'
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ọṣinbajọ n ṣe ipolongo ojule si ojule ki awọn eniyan le dibo fun Buhari
Ọṣinbajo ṣabẹwo si aafin iku baba yeye ti Ọyọ.
Lọjọ Abamẹta ni igbakeji aarẹ, ọjọgbọn Yẹmi Ọṣinbajo kan si Alaafin Ọyọ, Ọba Lamidi Olayiwọla Adeyẹmi.
Oṣinbajo parọwa fun iran Yoruba lati dibo gbe Buhari wọle lẹẹkan sii ni 2019 ki iṣejọba le kan wọn pada ni 2023.
O sọrọ yii laafin Ọba Adeyẹmi ko to maa lọ sibi ipade itagbangba gbọngan Atiba nilu Ọyọ.
Oṣinbajo ṣeleri fawọn eniyan Ọyọ pe laipẹ ni wọn yoo wa pin owo okowo 'Trader money' nibẹ lasiko to n gba wọn nimọran lati dibo fun Buhari nitori pe olootọ ni.
O ni ki iran Yoruba ronu lori nkan to m bọ fun wọn ni 2023 lai naani ipenija to n ṣẹlẹ bayii.
O ni irọ ni ahesọ pe APC n gba kaadi idibo lọwọ awọn olokowo ti wọn n fun ni 'trader money'.
Alaafin gbadura pé gbogbo ohun ti iran Yoruba n fẹ ni ọwọ wọn yoo tẹ.
Awọn kan gba pe iran Igbo lo kan lati dari Naijiria nitori pe ọwọ wọn ni agbara yẹ ko wa bayii
Bẹẹ ni awọn miran n kilọ fun ijọba yii lati ṣọra nipa ileri ṣiṣe fun iran kankan nitori alaafia
Larisa: Má jẹ́ kí ọjọ́ orí rẹ dí ẹ lọ́wọ́ láti bẹ̀rẹ̀ ohunkóhun to wù ọ
Awọn mii gba pé ileri yii naa ni wọn ti ṣe fun iran Igbo tẹlẹ ni eyi to fi fẹ jọ irọ́ loju ti wọn pé
Nigba ti awọn kan gbà pé iwa yii ku diẹ káà to nitori pe iran Yoruba ti gbọ́n sii.
Eto idibo 2019 lo ti n kanlẹkun gbọngbọn ni eyi ti awọn oludije ti n tẹra mọ eto ipolongo wọn kaakiri Naijiria.
Ipenija ojú kò di Ademola lọ́wọ́ láti kẹkọọ gboye
Wòlíì Àrólé sọ àsọtẹ́lẹ̀ s'áyé BBC ní London
Mr Latin wọlé di ààrẹ ẹgbẹ́ tíátà, TAMPAN
Oríṣun àwòrán, MR LATIN
Bọlaji Amuṣan, Mr Latin ti sọ pe afojusun oun gẹgẹ bi aarẹ ẹgbẹ Theatre And Movies Practitioners Association of Nigeria (TAMPAN) ni lati ri daju pe awọn ọmọ ẹgbẹ n ṣe nkan ti awọn araalu fẹ lati ọdọ wọn.
Ninu ọrọ to ba BBC News Yoruba sọ, Mr. Latin sọ pe o ṣeeṣe ki ẹgbẹ TAMPAN ati ANTP pada ni ajọsẹpọ lọjọ iwaju, ṣugbọn kii ṣe nkan to le waye bayi.
Ọjọ kẹrinla, oṣu Kejila, ọdun 2018 ni ẹgbẹ TAMPAN ṣe eto idibo lati yan awọn oloye ẹgbẹ tuntun.
Lopin eto idibo naa to waye niluu Ibadan, Bọlaji Amuṣan ti awọn ololufẹ rẹ mọ si Mr Latin, lo wọle gẹgẹ bi aarẹ ẹgbẹ, nigba ti awọn oṣere bi Ọdunlade Adekọla, Yọmi Fash-Lanso ati Fathia Balogun naa ri ipo di mu.
Funke Akindele ti di ìyábejì
Àwọn arẹwà obinrin Yollywood, tá ló mọ iṣẹ́ rẹ̀ jù?
Kí lo mọ̀ nípa Eniọla Badmus?
Igba ti ijọba wa ba fi idi mulẹ, ta a joko, ti a jọ sọrọ pọ lati mọ boya ki a wa lọtọọtọ tabi ṣepọ ni yoo dara fun wa, nkan ti a ba fẹnuko le lori ni yoo sọ ibi ti ọrọ nlọ.
O tẹsiwaju lati sọ pe ohun to ṣe pataki ni pe ajọṣepọ to dan mọran ti wa laarin ẹgbẹ mejeeji lati igba ti oun ti de ipo.
Ati wi pe ohun to jẹ afojusun oun ni lati ri i daju wi pe awọn ọmọ ẹgbẹ ṣe nkan ti awọn eniyan n fẹ lati ọdọ wọn, gẹgẹ bi olukọ ti awọn eniyan n wo; ninu iwọṣọ, ihuwasi ati isọrọ si wọn.
Ẹgbẹ TAMPAN jẹ ẹgbẹ́ to ya kuro lara, Association of Nigeria Theatre Arts Practitioners, ANTP l'ọdun 2014.
Gbajúgbajà òsèré tó tún mọ́ ọbẹ̀ sè
Ó pé ọdún 17 tí Bọla Ige kú; àwọn nkan tó yẹ́ kí o mọ̀ nípa rẹ̀ rè é
Oríṣun àwòrán, Other
Wọn bi James Ajibọla Adekoge Ige l'ọjọ kẹtala, oṣu Kẹsan, ọdun 1930.
Ilu Zaria ni ipinlẹ Kaduna ni wọn bi si, bi o tilẹ jẹ pe ọmọ ilu Ẹsa-oke, nitosi Ileṣa nipinlẹ Ọṣun ni awọn obi rẹ.
O kawa nileewe girama Ibadan Grammar School laarin ọdun 1943 si 1948, ko to o di pe o lọ si fasiti ilu Ibadan.
Lẹyin naa lo tun lọ si University College, to wa nilu London, nibi to ti gboye imọ ijinlẹ nipa iṣẹ amofin lọdun 1959.
Bọla Ige jẹ kọmisana fun eto ọgbin ni ẹkùn Iwọ Oorun Naijiria laarin ọdun 1967 si 1970 labẹ lasiko iṣejọba Ọgagun Yakubu Gowon.
Ẹfunsetan Aniwura, obìnrin tó ju ọkùnrin lọ
June 12: Kíni o mọ nípa M.K.O Abiola?
'IBB da Abiola lẹ́yìn tó búra pẹ̀lú Quran'
Wọn dibo yan an si ipo gomina ipinlẹ Ọyọ labẹ asia ẹgbẹ oṣelu Unity Party of Nigeria, lasiko Ọgagun Oluṣẹgun Ọbasanjọ fi asiko eto oṣelu ẹlẹẹkeji lọlẹ ni Naijiria.
O wa ni ipo naa di ọdun 1983.
Lasiko eto idibo to waye ni 1983, Ige gbe apoti ibo lẹẹkan si, ṣugbọn Dokita Victor Ọmọlolu Olunlọyọ fi ẹyin rẹ janlẹ.
Lẹyin oṣu mẹta, Olunlọyọ padanu ipo naa nitori iditẹ gbajọba ti Ọgagun Muhammadu Buhari ati Tunde Idiagbọn ṣagbatẹru rẹ.
Lẹyin iditẹgbajọba naa, wọn fi Bọla Ige si ihamọ, wọn si fi ẹsun kan an pe o ko owo ẹgbẹ oṣelu rẹ jẹ. Ṣugbọn, o gba ominira l'ọdun 1985, o si pada si idi iṣẹ amofin ati iwe kikọ.
Wọ́n rò pé mo ya wèrè ni Saudi lẹ́yìn ikú ọkọ mi
Bọla Ige jẹ ọkan pataki lara awọn to bẹrẹ ẹgbẹ ọmọ Yoruba, Afẹnifẹre.
Nigba ti eto oṣelu awaarawa tun pada l'ọdun 1999, Ige gbiyanju lati dupo aarẹ Naijiria labẹ ẹgbẹ oṣelu Alliance for Democracy (AD), ṣugbọn wọn ko gba fun.
Aarẹ Olusẹgun Ọbasanjọ to wọle nigba naa yan Bọla Ige gẹgẹ bi Minisita fun Iwakusa ati ipese ina mọna-mọna. O wa ni ipo naa laarin ọdun 1999 si 2000, ko to o di pe o di Minisita fun eto idajọ ati Agbẹjọro Agba fun orilẹede Naijiria.
Amọ, ọjọ kẹtalelogun, oṣu Kejila, ọdun 2001 ni awọn agbebọn yinbọn pa Ige nile rẹ to wa ni ilu Ibadan.
Àwọn olórin Naijiria pọ̀ tó fakọyọ nilẹ̀ Adulawọ ni 2018
Oríṣun àwòrán, others
Wizkid ati Tiwa da igboro ru p#elu fidio orin yii
Àwọn olórin Naijiria, Ghana àti Cameroon da bira ninu ọdun 2018.
Ọpọlọpọ ninu orin naa ni o bi èso oriṣiiriṣi lawujọ.
Diẹ lara awọn orin to tà dáadáa ti awọn eeyan ilẹ iwọ oorun adulawọ tẹwọgba ni 2018 niwọnyii; nọmba yi ko nii ṣe lori bi wọn ṣe ta tó:
1) Wizkid - Fever
Wizkid onkọrin ọmọ Naijiria kan lo kọ orin 'Fever' ni eyi to gbajugbaja nigba ti wọn gbe awo naa sita.
Fọnran fidio ẹ to jade ni oṣu kẹwa ọdun yii lo tun sọ orin naa di kariaye nigba ti fidio naa ṣafihan Wizkid ati Tiwa Savage.
Bi wọn ṣe jọ jẹyọpọ ninu fidio naa di ọrọ ijiroro lori ẹrọ ayelujara ni eyi ti awọn eeyan mii ṣi n sọrọ le lori di isinyii.
O le ni  miliọnu meji eeya to wo fidio naa laarin ọjọ meji ti wọn gbee si ẹrọ ayelujara You tube.
2) Davido - Assurance
Orin yii di orin ti tọmọde tagba n jo si ni kete to jade.
Onkọrin Naijiria, Davido lo fi orin naa fọn rere Chioma to pe ni assurance ololufẹ oun.
Orin yii gba igboro debi pe awọn ololufẹ n beere ẹbun assurance lọwọ ara wọn bi Davido ṣe fun Chioma ololufẹ ẹ.
Oríṣun àwòrán, @Davido
ọrọ ifẹ lagbara
Davido fi ọkọ̀ Porsche ṣe ayẹyẹ ọjọ́ ìbí fún Chioma Avril
3) Star Boy to gbé Terri, Spotless, Ceeza Milli ati Wizkid sita - Soco
Awọn Wizkid naa ni wọn gbe orin yii jade. O fi ṣe igi kan ko le da igbo ṣe ni nitori oun ati Terri ati Spotless pẹlu Ceeza Milli ni wọn jọ sọ àwo naa di odindin.
Gbogbo eeyan lo kan sáárá si wọn nigba ti fidio ẹ ṣafihan Chris Brown olorin ilẹ Amẹrika to n jo si orin naa.
4) Burna Boy - Ye
Àrà ọ̀tọ̀ inú orin tó jáde 'Ye' ti Burna gbé sita lọ́dún 2018 ní Nàìjíríà. 'Outside' ni awo na ba jade. Kanye West ọmọ ilẹ́ America gbe awo 'Ye' sita ni eyi to ta pupọ lori itunes.
Ipenija ojú kò di Ademola lọ́wọ́ láti kẹkọọ gboye
5) Falz - This is Nigeria
Ọmọ Naijiria to n kọrin taka sufe Falz lo fi orin to pé akọle rẹ ni 'This is Nigeria' da igboro ru lọdun yii.
Orin naa ṣafihan awọn nkan to n ṣẹlẹ ni Naijiria lasiko yii ni eyi to fi gbe awon idojukọ awọn kan ni Naijiria sita.
Orin yii bi ige ati adubi laarin awọn eniyan Naijiria ni eyi ti awọn kan gbà si òdì debi pe ajọ to n mojuto ere idanilaraya ti a n gbe sita ni Naijiria, iyẹn, National Broadcasting Commission fi ofin dee.
Lẹyin eyi ni ajọ Islam ti wọn pe ni Muslim Rights Concern ni ko ko awọn awo rẹ kuro lori igbá. Orin yii ṣi n ta ni ori You tube di isinyi.
Oríṣun àwòrán, other
Falz ni ki araye wo Naijiria ti a n gbe loni ninu awo rẹ kan
6) Olamide - Science Student
Orin yii wà lára orin to kọkọ jade ni 2018 ni eyi to da wahala nla silẹ.
Opọlọpọ lo ni orin yii n fọn rere pe ki awọn eeyan maa mu oogun oloro ni eyi to jẹ ki ajọ to n mojuto ere idanilaraya ti a n gbe sita ni Naijiria, iyẹn, National Broadcasting Commission fi ofin dee.
Olamide ni ọtọ ni ọrọ naa ri nitori pe ko sẹni to mọ ede ayan bii ẹni to mu ọpa ẹ dani, pe oun ti oun mu omele dani ni oun mọ nkan ti oun n sọ.
Olamide gbe fidio orin naa sita ni oṣu keji ọdun lẹyin to sọ pe oun n fi orin naa kilọ oogun oloro ni.
7) Davido - Nwa Baby
Orin yii jẹ ọkan lara awọn orin to wọnu ipele nkan ti wọn wá julọ lori google ni Naijiria lọdun 2018. Eyi fihan pe ọpọ ero lo n wa orin yii lori ayelujara.
Won n sọrọ fidio rẹ ti wọn gba pe o dún pupọ ni eyi ti Meji Alabi dari rẹ.
8) Guilty Beatz, Mr Eazi, Patapaa àti Pappy Kojo -Akwaaba
Onkọrin ọmọ ilẹ Ghana, Guilty Beatz lo kọ orin naa. Awọn Banku music lo baa gbe Sample You bo sita ti ọgbẹni Eazi. Akwaaba jẹ orin to mu ẹsẹ ijo tuntun dani ti gbogbo eeyan n jo si ni iwọ oorun ilẹ Afrika.
Orin yii gba ami ẹyẹ meji nibi eto ifami ẹyẹ dani lọla forin to pegede julọ lọdun 2018 nilẹ Adulawọ.
9) Tiwa Savage to ṣe pẹlu Duncan Mighty - Lova lova
Ajọṣepọ yii jẹ ọkan lara awọn to mu eso rere jade julọ lọdun 2018.
Koda Duncan Mighty funra rẹ ṣalaye ninu ifọrọwanilẹnuwo kan pe ajọṣepọ yii lo ta julọ lẹyin Fake Love ti oun ṣe sẹyin. Orin yii de ori igba awọn orin to peleke julọ ni Apple Music fọdun 2018.
Larisa: Má jẹ́ kí ọjọ́ orí rẹ dí ẹ lọ́wọ́ láti bẹ̀rẹ̀ ohunkóhun to wù ọ
Àrà ọ̀tọ̀ inú orin tó jáde lọ́dún 2018 ní Nàìjíríà
10) Kuami Eugene -Wish me well
Olorin gbajugba ọmọ Ghana, Kuami Eugene lo gbe orin 'wish me well'yii sita lọdun 2018.
O ni orin naa jẹ koriya fawọn eeyan to n la iṣoro kan tabi omiran kọja . O ni oun tun kọọ lati fi ta awọn oluranlọwọ ji ki wọn le ṣe iranlọwọ to ye fawọn to sun mọ wọn.
O tun orin naa sè pọ pẹlu onkọrinayara bi àṣá Naijiria, Ice Prince.
'Wàhálà Boko Haram ló lé mi wá sí Eko tí mo fi di èrò abẹ́ afárá'
11) Daphne - My Lover
Daphne jẹ ọkan lara awọn onkọrin ọmọ Cameroon ti Ọlọrin gab fun lọwọlọwọ ni Cameroon.
Oun lo gba onkọrin obinrin to dara julọ ni aarin gbungbun Afrika lọdun 2018 ninu eto ifami ẹyẹ danilọla fun orin to pegede lọdun 2018.
Wòlíì Àrólé sọ àsọtẹ́lẹ̀ s'áyé BBC ní London
12) Mr Real - Legbẹgbẹ
Eyi jẹ ọkan lara awọn orin to sọ ipede ṣakuṣaku di gbajugbaja ni Naijri alọdun 2018.
Oṣu kejila, ọdun 2017 lo jade ṣugbọn ọdun 2018 ni fidio ẹ jade sita.
Ọgọ́rùn ún èèyàn tí pàdánù ẹ̀mí wọn nínú ìkọlù Zamfara
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Awọn ọdọ dana sun taya loju ọna
Iroyin to n tẹwa lọwọ lati ipinlẹ Zamfara ni pé awọn olugbe ilu naa ti gbegi dina opopona marosẹ to wọnu ilu lati fẹhonu han lori ipaniyan ati ijinigbe to peleke nibẹ.
Awọn ara ilu Tsafe to jẹ olu ileese ijọba ibilẹ Tsafe ti n fapajanu lori bi awọn ogunlende ati awọn janduku le kuro ni ilu ti wọn ti ṣe yabo ilu tiwọn.
Awọn oluwọde to gbegi dina naa ni o ti ṣu awọn bi awọn alaṣe ko ti ṣe yasi ọrọ aabo titi de ibi to de bayi.
Niṣe ni wọn n sun taya loju ọna lati fidi ẹhonu wọn han lori bi ipaniyan yi ti ṣe peleke.
Alaga ijọba ibilẹ Tsafe, Abubakar Aliyu sọ fun ile iṣẹ BBC pe o le ni eeyan ogoji ti o ti padanu ẹmi wọn ninu abule laarin ọsẹ meji.
Àarẹ Muhamadu Buhari se àbẹ̀wò sí ágbèègbè náà laipe yii
Lọsẹ to kọja ni awọn janduku wọn yi pa ọpọ eeyan nilu Birnin Magaji tii ṣe ilu Minisita eto aabo Naijiria.
Awọn  eleto abọ ti ran ọlọpaa ati ọmọ ogun lati pẹtu saawọ lagbegbe naa.
Larisa: Má jẹ́ kí ọjọ́ orí rẹ dí ẹ lọ́wọ́ láti bẹ̀rẹ̀ ohunkóhun to wù ọ
'Wàhálà Boko Haram ló lé mi wá sí Eko tí mo fi di èrò abẹ́ afárá'
'EFCC mo dé' àti àwọn àṣà míì táwọn olóṣèlú fi dagbo rú ní 2018
Oríṣun àwòrán, @OfficialPDPNig
Niṣe ni Ayo Fayose daku gbaranganda nibi ipolongo idibo Gomina Ekiti
Awọn oloṣelu Naijiria dagbo oṣelu ru daadaa lọdun 2018
Bi wọn ti ṣe sọ awọn nnkan to ṣe awọn eeyan ni kayefi, ni ọrọ wọn miran mu inu bi ara ilu ti awọn mii si n dẹrin pa wọn.
Awọn eeyan a ma fi oju apọnlẹ wo oloṣelu gẹgẹ bi ẹni ọwọ, ati olori to mọ iwe daadaa. Nitori eyi,gbogbo nnkan ti wọn ba ṣe a ma mu iriwisi orisirisi wa.
Ẹ jẹ ki a ran ara wa leti diẹ ninu awọn asiko manigbagbe ni 2018 ati ọrọ ti awọn ọmọ Naijiria ko le gbagbe ati ju bẹ lọ.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Eyi kii ṣe igba akọkọ ti Aarẹ Buhari yoo ko iyan awọn ara ilu rẹ kere lẹyin odi
#LazyNigerianYouths - Muhammadu Buhari / oṣu kẹrin, 2018
Yoruba bọ,wọn ni bi a ba ta ara ile ẹni lọpọ, a ko le ri ra l'ọwọn.
Rẹgi lọrọ yi ṣe losu kẹrin ọdun 2018 nigba ti awọn ọdọ Naijiria tutọ soke, foju gba lori bi wọn ti ṣe ni Ààrẹ Buhari sọ wípé àwọn ọ̀dọ́ Nàìjíríà kò fẹ ǹkan ṣe.
Kia ni wọn ti bẹrẹ 'hash-tag' lori ayelujara lati fẹhonu han. Esi ti awọn eeyan fun un pada wi pe awọn kii ṣe ọlẹ  lori Twitter ko rẹrin rara.
Ajimọbi: Pé Ayefẹlẹ jẹ́ àkàndá kò fún láṣẹ láti rú òfin
Eeyan ko gbọdọ sọ pe t'ori oun jẹ alaabọ ara ko máa rufin-Abiola Ajumọbi
Gbolohun yi jẹ ọkan ti awọn ọmọ kaarọ ojiire ko ni gbagbe lọdun 2018.
O jẹyọ nigba ti Gomina Ajimobi ti ipinlẹ Oyo n fesi si ẹsun wi pe o paṣẹ ki wọn wo ile iṣẹ rẹdio gbajugbaja akọrin, Yinka Ayefẹlẹ niluu Ibadan.
Ọpọ lo bẹnu atẹ lu igbesẹ yi sugbọn lẹyin o rẹyin Ajimọbi ati Ayefẹlẹ pari ija ti Gomina Ajimọbi si tun ṣe iranwọ lati tun ile iṣẹ naa kọ.
Ayefẹlẹ - Ara ìjọba ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́ kọ òtítọ́ ní wọ́n ṣe fẹ́ wó iléèṣẹ́ rédíò mi
'Am in pains' - Ayodele Fayose / Oṣu keje, 2018
Awọn oloṣelu naa a ma sunkun. Bi a ko ba mọ telẹ, Gomina ipinlẹ Ekiti ana Ayodele Fayose lo jẹ ki a mọ.
Oríṣun àwòrán, @Ogundamisi
Fayose sọ wi pe awọn ọlọpaa lo ṣe ohun leṣe
Nibi ipolongo ẹgbẹ oselu PDP lasiko ti idibo gomina waye ni ipinlẹ Ekiti, ni Fayose ti fara han lori ẹrọ amohunmaworan ti o si figbe ta wi pe awọn ọlọpaa na oun.
Ki ilẹ ọjọ naa to ṣu ,Fayose sun gbalaja sori ibusun alaisan ti gbogbo aye si ri bi wọn ti ṣe gbe digbadigba wọnu ọkọ alaisan.
Larisa: Má jẹ́ kí ọjọ́ orí rẹ dí ẹ lọ́wọ́ láti bẹ̀rẹ̀ ohunkóhun to wù ọ
Transmission, Transmission - Ibrahim Idris / Oṣu karun un, 2018
Yoruba ni, aṣiwi ko to aṣisọ.
Lootọ, Ọga agba ọlọpaa Naijiria, Ibrahim Idris kii ṣe oloṣelu ṣugbọn lọdun 2018, awọn kan gba wi pe iṣesi rẹ kan ko jẹ ki a fẹ mọ iyatọ laarin oun ati awọn oloṣelu.
Oríṣun àwòrán, @PoliceNG
Ibrahim Idris, ọga agba ọlọpa Naijiria
Idi rẹ ti o fi da bi wi pe awọn ọmọ Naijiria ko gbagbe rẹ ni bi o ti ṣe n kalolo nibi to ti n sọrọ lode kan nibi ti o ti fẹ ṣe ifilọlẹ kan.
Gbolohun 'Transmission Transmission' rẹ ti o n tẹnumọ pa ọpọ eeyan lẹrin ti o si mu ki awọn kan ṣe kayefi iṣẹlẹ naa.
Ipenija ojú kò di Ademola lọ́wọ́ láti kẹkọọ gboye
Wòlíì Àrólé sọ àsọtẹ́lẹ̀ s'áyé BBC ní London
Wakati mọkanla ni mo lo lori igi - Dino Melaye / Oṣu keje, 2018
Saaju ki o to kuro ninu ẹgbẹ APC lọ si PDP, ilumọọka oloṣelu to jẹ Sẹnatọ to n ṣoju ipinlẹ Kogi, Dino Melaye ti halẹmọ awọn ọlọpaa wi pe oun yoo pa ara oun si wọn lọrun .
Dino Melaye lórí ìbùsùn
Ninu ọdun 2018 kan naa lo pada tun sọ pe oun sa si ori igi fun wakati mọkanla nigba ti o ni awọn kan fẹ gbẹmi oun.
Melaye ni ori lo ko oun yọ lọwọ awọn apaniyan ọhun ati wi pe bi ki baa ṣe wi pe oun sapamọ sori igi, ọta ko ba ti ri oun gbeṣe.
Awọn ọlọpaa ni irọ pọnbele ni Melaye pa lori iṣẹlẹ naa to lo waye loju ọna marosẹ Abuja si Lọkọja.
'Wàhálà Boko Haram ló lé mi wá sí Eko tí mo fi di èrò abẹ́ afárá'
EFCC mo de! - Ayodele Fayose / Oṣu kẹwaa, 2018
A o ka ẹsẹ eto yi nilẹ pẹlu Gomina Ekiti ana, Ayodele Fayose lẹẹkansi.
Ajọ to n gbogun ti jẹgudujẹra lorileede Naijiria, EFCC kede  pe ni kete to ba pari saa ijọba rẹ lawọn yoo wọ lọ si ile ẹjọ.
Lere Ọlayinka: Ayo Fayose sí wà ní gbaga àwọn EFCC
"Fayose ko tilẹ jẹ ki wọn wa ki o to yọju si ile iṣẹ ajọ naa ni Abuja ti o si wọ aṣọ dudu ti wọn kọ akori  ""EFCC I am here"" si."
Ọrọ yi dagboro ru gan an ti awọn kan si bẹrẹ si ni ta aṣọ ti wọn kọ ọrọ yi silara ni witiwiti.
Oríṣun àwòrán, Lere Olayinka
Gomina Wike ati Fani-Kayode kọwọrin pẹlu Fayose lọ si ile iṣẹ ajọ Efcc
Sophie Oluwole: Màmá Onímọ̀ Òye kọjá lọ lẹ́ni ọdún 83
Oríṣun àwòrán, WIKIPEDIA
Sophie Oluwole tó jẹ́ Ọ̀jọ̀gbọ́n nínú ìmọ̀ àsà àti ìse Yoruba àti ilẹ́ Afirika lápaapọ̀ ti papòdà ní ẹni ọdún 83
Awọn ọmọ kaarọ oojiire ti n kẹdun Ọjọgbọn Sophie Oluwole to dagbere fun aye ni ẹni ọdun mẹtalelọgọrin.
Sophie Oluwole ni wọn bi ni agbeegbe Igbara-Oke ni ipinlẹ Ondo ni ọdun 1936, ti o si kawe gboye lati fasiti Ile-Ifẹ ni bi ogoji odun seyin.
Akẹẹkọ gboye onimọ oye, Sophie Oluwole to tun jẹ Ọjọgbọn ninu imọ asa, ise Yoruba ati ti ilẹ Afirika lapapọ dagbere fun aye ni ọsan Ọjọ Isinmi, lẹyin aisan ọlọjọ pipẹ.
Èpo ọwọn, sunkere-fakere ọkọ àti àwọn olósà jẹ́ ipenija lójú pópó
Gbajugbaja oniroyin, Funmi Iyanda sọ nipa igbe aye oloogbe naa to bu iyi kun imọ ilẹ adunlawo nipa oselu, idagbasoke ile Afirika ati ọrọ aje naa.
"Taiwo Obe naa fikun wipe Sophie Oluwole ti awọn eniyan ma n pe ni  ""mamalawo"" lo jẹ obinrin akọkọ to kawe gboye ọmọwe ni orilẹede Naijiria."
Ọjọgbọn Oluwole naa to kọ ọpọlọpọ akẹẹkọ ni fasiti ilu Eko, ni ọpọ eniyan mo wi pe o sa ipa rẹ fun igbelarugẹ awọn obinrin, imọ ijinlẹ Yoruba ati ti ilẹ adulawo lapaapọ.
2019 Elections: Ìpínlẹ Akwa Ibom ti gbà kí Buhari lo pápá ìṣeré fún ìpolongo
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Awọn ididje ere bọọlu lorisirisi ni wọn ti gba ni aaye yi
Lẹyin ti o kọ lati yọnda ki ẹgbẹ oṣelu All Progressives Congress (APC) lo papa iṣere Godswill Akpabio to wa ni ilu Uyo fun ipolongo ibo ni ipinlẹ Akwa Ibom, ijọba ipinlẹ naa ti fọwọ si pe ki ẹgbẹ naa tẹsiwaju lati lo papa isere ọhun.
Kọmisọna fun ọrọ ọdọ ati ere idaraya Monday Uko lo fọrọ naa lede.
Ṣaaju nijọba Ipinlẹ Akwa sọ pe ohun ko ni yọnda papa iṣere ọhun nitori pe ile-iṣẹ to mojuto papa isẹre naa ti lọ fun isinmi opin ọdun.
Buhari kí àwọn kìrìsìtẹ́nì kú ọdún
Buhari, Atiku fẹ́ tú Afẹ́nifẹ́re ká
Èpo ọwọn, sunkere-fakere ọkọ àti àwọn olósà jẹ́ ipenija lójú pópó
Amọ bayii, Kọmisọna Uko ṣalaye pe ile iṣẹ naa lati yọnda awọn oṣisẹ rẹ lati mojuto papa isere naa lẹyin ti wọn ba lo tan.
Kọmisọna fikun ọrọ rẹ pe ijọba Ipinlẹ naa kọ tẹlẹ lati jẹki wọn lo papa iṣere naa nitori o le ṣakoba fun koriko.
APC bu ẹnu atẹ lu igbesẹ ijọba Akwa Ibom lori papa iṣere rẹ
Agbẹnusọ fun APC ni ipinlẹ naa, Nkereuwem Enyongekere sọ fun BBC Pidgin pe igbesẹ ijọba lati ma jẹ ki awọn lo papa iṣere naa ko bojumu.
"O sọ pe ''to ba jẹ oludije fun ipo aarẹ ninu ẹgbẹ oṣelu wọn (PDP) lo fẹ ẹ lo papa iṣere naa, wọn ko ni i kọ. Aarẹ Naijiria fẹ ẹ lo papa iṣere naa, ni wọn n sọ awawi oriṣiriṣi bayii."""
O ṣalaye pe papa iṣere miran ti ijọba yọnda ko le gba gbogbo awọn eniyan ẹkùn Niger Delta to n bọ fun eto naa.
"A ṣi n ba wọn duna-dura lati yọnda papa iṣere naa fun wa lati gbalejo aarẹ.''
Ṣaaju ni ijọba ipinlẹ naa fi atẹjade kan sita lati ṣalaye idi ti ijọba ko ṣe fẹ ki Aarẹ Muhammadu Buhari ati ẹgbẹ APC lo papa iṣere naa, to le gba  ọgbọ̀n ẹgbẹrun eeyan lati joko fun ipolongo.
Ninu atẹjade naa, kọmisana fun ere idaraya, Monday Uko sọ pe ti wọn ba fi lo papa iṣere naa fun eto ti kii ṣe ere idaraya, wọn ko ni le gbin koriko miran si' ko to o di pe Premier League Naijiria yoo bẹrẹ lọjọ kẹtala, oṣu Kinni, ọdun 2019.
Papa iṣere Akwa Ibom wa lara awọn eleyi to gbaaye julọ ni Naijiria
Bakan naa ni ijọba sọ pe ileeṣẹ Julius Berger to n mojuto papa iṣere naa ti lọ fun isinmi opin ọdun, ti wọn ko si nile ṣi i titi di ọjọ keje, oṣu Kinni, ti wọn ba pada bẹrẹ iṣẹ.
Ati wi pe nitori awọn idi naa ni ijọba paapa ko fi ṣe eto orin Keresimesi to maa n ṣe lọdọọdun nibẹ.
Broadcasting Service of Ekiti State di ṣíṣí padà lẹ́yìn oṣù máàrùn
Oríṣun àwòrán, @nbcgovng
NBC ni ileesẹ igbohun-safẹfẹ Ekiti n hu awọn iwa to tako ofin isẹ igbohunsafẹfẹ.
Gomina ipinlẹ Ekiti, Dokita Kayọde Fayẹmi, ti fi ontẹ lu u pe ki ileeṣẹ igbohunsafẹfẹ ijọba ipinlẹ naa bẹrẹ iṣẹ pada lọjọ kinni, oṣu Kejila, ọdun 2019.
L'ọjọ kẹẹdogun, oṣu Keje ni ajọ to n mojuto isẹ igbohunsafẹfẹ ni Naijiria, National Broadcasting Commission (NBC), ti ileeṣẹ naa pa fun pe o kede esi ibo ti ajọ eleto idibo ko fọwọ si lasiko eto idibo gomina to waye lọjọ kẹrinla, oṣu Keje, ọdun 2018.
Gẹgẹ bi ikede kan ti ijọba ipinlẹ naa fi sita loju opo ayelujara rẹ, ṣiṣi ti ajọ NBC pada ṣi ileeṣẹ igbohunsafẹfẹ ọhun waye lẹyin ti igbimọ ti ijọba gbe kalẹ lati wadii awọn ohun to ṣokunfa bi wọn ṣe ti i pa, ti gomina Fayẹmi naa si da si ọrọ naa.
Oríṣun àwòrán, ekitistate.gov.ng
Amọ ṣa, lẹyin ipade ti gomina ṣe pẹlu awọn alaṣẹ ajọ NBC, ajọ naa gba lati ṣi i, ati pe wọn gbọdọ san owo itanran ti wọn bu fun wọn.
Gomina ti wa paṣẹ pe ki ọkan lara awọn ọga agba ileesẹ igbohunsafẹfẹ naa, Idowu Oguntuaṣe, di Ọga Agba fidiẹ titi ti igbesẹ yoo waye lori abọ iwadi igbimọ naa.
The seed: Àwa sì wá láti mú ẹ̀bùn fún Ọba tí a bí lónìí
Ipenija ojú kò di Ademola lọ́wọ́ láti kẹkọọ gboye
Èpo ọwọn, sunkere-fakere ọkọ àti àwọn olósà jẹ́ ipenija lójú pópó
Iléèṣẹ́ ọlọ́pàá sbum ẹnu àtẹ́ lu ìròyìn pé àwọn ọlọ́pàá kan sá lọ
Oríṣun àwòrán, Rueters
Ileeṣẹ ọlọpaa Naijiria koro oju si bi awọn ileeṣẹ iroyin kan ṣe fi iroyin sita pe ọlọpaa mẹtadinlaadọsan sa kuro ni ibudo ikọṣẹ lẹyin ti wọn gbọ wi pe Boko Haram ni wọn yoo d'ojukọ.
Iwe Iroyin Premium Times ati Punch jabọ pe 'awọn ọlọpaa adigboluja' to sa lọ ọhun jẹ ara ẹgbẹrun meji ọlọpaa ti Ọga Agba ọlọpaa, Ibrahim Idris, ṣeleri pe yoo ṣe iranlọwọ fun ileeṣẹ ọmọ ogun Naijiria lati d'oju ija kọ awọn agbesunmọmi ni ẹkùn Ila Oorun ariwa Naijiria.
Amọ gẹgẹ bi ohun ti agbẹnusọ fun ileeṣẹ ọlọpaa Jimoh Moshood sọ, gbogbo ẹgbẹrun meji ọlọpaa ti wọn ran lọ si ila oorun ariwa lo ti wa ni ibudo ikẹẹkọ, ti wọn si ti ṣetan lati darapọ mọ awọn ọmọ ogun lati gbogun ti Boko Haram.
''Koda, tidunnu-tidunnu ni awọn ọlọpaa naa fi darapọ mọ akanṣe iṣẹ naa. Ẹnikẹni ko sa lọ lara wọn.''
Ẹwẹ, awọn iroyin to kọkọ jade naa sọ pe ijiya to lagbara lo n duro de awọn ọlọpaa to sa lọ ọhun.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Boko Haram ti ṣe ọpọlọpọ iṣẹ ibi ni ila oorun ariwa Naijiria
Iye ọlọpaa ti olu ileeṣẹ ọlọpa n wa fun 'ẹsun naa' ati igbẹjọ ko ti i foju han, nitori awọn ileeṣẹ iroyin kan sọ pe aadọwa, awọn miran si sọ pe mẹtadinlaadọsan ni.
Bo tilẹ jẹ wi pe ileeṣẹ ologun ko tii sọ ohunkohun nipa ọrọ naa, ṣugbọn iwe iroyin Premium Times fi orukọ ọlọpa mẹtadinlaadọsan sita loju opo ayelujara rẹ gẹgẹ bi awọn ti wọn n wa.
Oríṣun àwòrán, Premium Times
Oríṣun àwòrán, Premium Times
Oríṣun àwòrán, Premium Times
Oríṣun àwòrán, Premium Times
Oríṣun àwòrán, Premium Times
Alex Badeh: Àwọn agbenipa ojú pópó lásán ló paá
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Alex Badeh: Ọwọ́ ba afunra sí mejì
Ọwọ́ sìkún àjọ ọlọ́pàá orílẹ̀-èdè Náíjíríà tí ba àwọn ọdaràn tó pa ajagún fẹyinti ọmọogun ojú òfurufú Alex Badeh.
Awọn ọdaràn to ṣiṣẹ́ ńlá ibi yìí ní àjọ ọlọ́pàá ní wọn yóò fóju wọn han fún gbogbo oníròyìn lónìí lólú ilé iṣẹ́ ọlọ́pàá nílu Abuja.
Ìwádìí náà wà láàrín ọmọogun ojú òfurufu, ọgá àgbà ọlọpàá àti ajọ ọlọ́páà ìpínlẹ̀ Nasarawa.
Ijó Bàtá ti Yorùbá gb'oríyìn ní Calabar Festival 2018
A ti ṣe àṣeyọri lóri ọ̀rọ̀ yìí nítori àti mú àwọn afunra sí méjì tí à ó fojú wọn han lónìí ọjọbọ̀"""
Ẹ ní tó bá akọròyìn Punch sọ̀rọ̀ sàlàyé pé àwọn kan tí na papa bora sùgbọ́n ọwọ́ yóò tẹ̀ wọn láìpẹ́
Gẹ́gẹ́ bí wọn ṣe sọ àwọn tó wà nínú àhámọ ọlọpàá jẹ́ àwọn adigunjalè lórí títì márosẹ̀ tí won tí ń pa èèyàn tàbí jí èèyàn gbé látẹ̀yìn wá ní sùgbọ́n ẹjọ́ wọn ò dé ìwájú àwọn ọlọ́pàá nítorí wọn ò kà wọn kún ọdaràn tó léwu.
Alex Badeh kú ní alẹ́ ọjọ́ kejìdínlógún ọdún yìí lásìkò tó ń bọ̀ lati oko rẹ̀.
Nínú àwọn mẹ́ta tó wà nínú mótò náà, Badeh nìkan ní wọn pa, èyí ló mú kí àwọn ènìyàn máa ròò pé bóyá àwọn agbénipa ló ṣiṣẹ́ náà
Awọn ọ̀daràn náà gbé ọ̀rẹ́ Badeh ti wọn jọ wà nínú mótò sùgban wọn fi sílẹ̀ lẹ́yìn ti àwọn ẹbi rẹ̀ sàn owó kí wọn to túu sílẹ̀
Ẹ̀wẹ̀ àwọn ọmọ ogun mẹ́rin tó ń sọ́ọ ní wọn ni wọn wà ní kìlómità diẹ̀ sí ibi tó wà, àwọn náà ti wà ní atìmọlé báyìí
Inec Oyo: Kò sí olóṣèlú tó fẹ fí owó rà káàdì lọwọ wà
Oríṣun àwòrán, @inecnigeria
Iye kaadi idibo ti awọn eeyan ko tii gba n kan ọpọ lominu
Alakoso ajọ eleto idibo nipinlẹ  Oyo Mutiu Agboke ti tako iroyin kan to gbode pe o sọ pe awọn oloṣelu n fi owo daamu ohun lati ta kaadi idibo fun wọn.
O salaye yi ninu ifọrọwanilẹnuwo  to ṣe pẹlu BBC Yoruba
Agboke ni ọtọ ni ohun ti oun sọ ati wi pe ''o ya mi lẹnu pe awọn akoroyin kan  gbe iroyin ohun ti mi o sọ sita''
''Nkan ti mo sọ ko ni iwe iroyin yẹn gbe jade.Awọn eeyan lo tami lolobo nigboro wi pe wọn  ni mo sọ wi pe awọn oloselu n fi owo damu mi.''
O fikun wi pe ''oun ti mo sọ ni wipe kaka ki ọpọlọpọ oloselu pawọ pọ pẹlu wa lati ri wi pe awọn oludibo gba kaadi to pọ nilẹ, kaadi ti ko si ni tita ni wọn wa kaakiri.
Nipa kaadi ti o wa nilẹ, o tẹnumọ bo ṣe ṣe pataki ki awọn ara ilu wa gba kaadi wọn saaju idibo.
''Kaadi ti  awọn eeyan ti gba lọdọ wa ti to 240,000 ti a si ni akọsilẹ pe eyi ti wọn ko ti gba ju 900,000 lọ.''
''Idi ti a fi ni ki awọn oloselu ke si awọn eeyan lati wa gba kaadi re.Eni ti ko ba ni kaadi ko le ni anfaani lati dibo nitori Inec ti fagile lilo foomu 'incidence' ti  a ma n lo tẹlẹ ti kaadi ko ba si tabi ti ko ṣisẹ''
Wòlíì Kasali sọrọ nípa awuyewuye pé o lè ìyàwó rẹ̀ jáde nílé
INEC yoo sun miliọnu meje kaadi idibo
BBC Yoruba bere lọwọ ogbẹni Mutiu pe kini yoo ṣẹlẹ si awọn kaadi ti ara ilu ko ba wa gba.
Alaye to ṣe ni wi pe awọn yoo da irufẹ kaadi bẹ pada lọ si ẹka ijọba ipinlẹ Inec lati ijọba ibilẹ ni kete ti idibo ba ku bi ọsẹ kan.
''Bi eeyan ba ti lẹ ri kaadi onikaadi gba ko le sanfani fun nitori ko ni le fi dibo. Ohun to pe Inec ni ki awọn eeyan wa gba kaadi wọn ki eto idibo baa le lọ deede.''
Zamfara killings: Ṣé lóòótọ́ ni ìjọba fẹ́ kéde, state of emergency, nítorí ìpànìyàn Zamfara?
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Awọn eeyan kan n pariwo pe o tọ ki ijọba o gbe ijọba kogberegbe, state of emergency, kalẹ ni Zamfara
Gbogbo igba ti iroyin ikọlu awọn agbebọn ba waye ni ipinlẹ Zamfara ni jinijini maa nbo ọkan awọn eeyan orilẹ-ede Naijiria paapaa julọ lori awọn ẹmi ti o maa n sọnu sinu ikọlu ọhun.
Amọṣa, ohun ti o n ko jinijini bo ọkan ọpọ bayii lori ikọlu to n waye ni ipinlẹ naa ni iroyin kan ti o n lọ kaakiri pe o ṣeeṣe ki ijọba apapọ o kede ijọba kogberegbe, 'state of emergency' ni ipinlẹ naa.
Bi o tilẹ jẹ wi pe aarẹ lo laṣẹ ati kede ijọba kogberegbe ni ipinlẹ kan labẹ ofin orilẹede Naijiria, ijọba apapọ ko tii sọ boya lootọ ni ọrọ yii.
Gomina ana ni ipinlẹ Ekiti, Ayọdele Fayoṣe, gẹgẹ bi iṣe rẹ, lo kọkọ pariwo sita pe ikede ijọba kogberegbe n rugbo bọ ni ipinlẹ naa. Ninu atẹjade kan ti o fi sita lori ikanni itakurọsọ ayelujara twitter rẹ ni ọjọ ọdun keresimesi ni Fayoṣe ti kọkọ lu awo iroyin yii.
Oríṣun àwòrán, Ayodele Fayose/Facebook
Ayọdele Fayoṣe ti máa ń tako ìjọba Ààrẹ Muhammadu Buhari
Ohun ti o sọ nigba naa ni wi pe ọgbọn ati lee sun eto idibo gomina ati ile aṣofin nipinlẹ naa siwaju ni ijọba fẹ da lati fi gbe ijọba naa kalẹ.
Fayoṣe ni eredi ipinnu yii ko yẹ lori bi ajọ eleto idibo lorilẹede Naijiria, INEC ṣe faake kọri pe ko saye fun ẹgbẹ oṣelu APC lati fa oludije kalẹ fun idibo apapọ lọdun 2019 lẹyin ti ẹgbẹ oṣelu APC kuna lati ṣeto idibo abẹnu rẹ lakoko ni ibamu pẹlu gbedeke ti ajọ eleto idibo naa gbe kalẹ.
Wọn ti ta mi lolobo pe ijọba apapọ n gbeero lati sa pamọ si abẹ wahala ikọlu ati ipaniyan to n waye nipinlẹ Zamfara lati fikede ijọba kogberegbe ni ipinlẹ naa. Eyi si ni idahun rẹ si bi ajọ INEC ṣe faake kọri pe ohun ko ni gba ẹgbẹ oṣelu APC laaye lati fa oludije kalẹ fun idibo ọdun 2019 ni ipinlẹ naa.
Nibayii, gomina ipinlẹ Zamfara funrarẹ, Abdulaziz Yari pẹlu ti wa kede ni ọjọbọ pe gba-gba-gba bayii ni oun wa lẹyin awọn to n pe ipe fun agbekalẹ ijọba kogbere ni ipinlẹ naa.
Yari ṣalaye nibi ipade kan to ṣe pẹlawọn oniroyin pe inu oun yoo dun pupọ bi aarẹ Buhari ba lee kede ijọba kogberegbe ni ipinlẹ naa.
Mo wa lẹyin ikede ijọba kogberegbe bi o ba jẹ pe ohun ni yoo doola ẹmi awọn araalu nipinlẹ yii.
Wòlíì Kasali sọrọ nípa awuyewuye pé o lè ìyàwó rẹ̀ jáde nílé
Eyi ti wa n fa ọpọlọpọ itakurọsọ bayii laarin awọn ọmọ orilẹede Naijiria.
Bi awọn eeyan kan ṣe n pariwo pe lootọ ni ki ijọba o gbe ijọba kogberegbe, state of emergency, kalẹ nibẹ.
Eleyii ti Ayọdele Fayoṣe ni o jẹ iyalẹnu pe gomina ipinlẹ kan lee maa beere fun agbekalẹ ijọba kogberegbe naa. Fayoṣe ti ni iriri ikede yii ri nitori lasiko ijọba ayọdele fayose ni aarẹ orilẹede Naijiria nigbakan ri, Oluṣẹgun Ọbasanjọ kede ijọba kogberegbe ni ipinlẹ Ekiti.
Fayoṣe nikan kọ lo n tako ikede yii, iyẹn ti o ba maa waye o.
Osun 2019: Ajàfẹ́tọ̀ọ́ gbé gómìnà ìpínlẹ̀ Ọ̀ṣun lọ sílé ẹjọ́ nítorí ìbúra
Oríṣun àwòrán, Gboyega Jesuleke
Ajafẹtọọ Kanmi Ajibọla kii ṣe ajeji si ijọba ipinlẹ Ọṣun lori ilana antẹle nipa ofin
Ajafẹtọ ọmọniyan kan, Kanmi Ajibọla ti gbe gomina tuntun ti wọn ṣẹṣẹ bura fun loṣu kọkanla ọdun 2018, Gboyega Oyetọla ati igbakeji rẹ, Benedict Alabi lọ si ile ẹjọ.
Ohun to tori rẹ gbe igbesẹ yi ni pe wọn ṣe ibura wọle si ipo wọn labẹ orukọ 'state of Osun' dipo 'Osun state' lasiko ti wọn ṣebura fun wọn ni ọjọ kẹtadinlọgbọn oṣu kejila ọdun 2018.
Ninu iwe ipẹjọ oloju ewe mejidinlọgbọn to gbe kalẹ niwaju ile ẹjọ giga ipinlẹ Ọṣun, to wa nilu Ileṣa, amofin Kanmi Ajibọla n fẹ ki ile ẹjọ o wọgile ibura wọle awọn mejeeji gẹgẹ bi eyi ti ko ba ofin ati iwe ofin orilẹede Naijiria mu nitori naa, o ni ko lẹsẹ nilẹ.
Bi a ko ba ni gbagbe, Onidajọ Yinka Afọlabi ti ile ẹjọ giga ipinlẹ Ọṣun to wa ni ilu Ileṣa kan naa ti kọkọ gbe idajọ kalẹ loṣu kejila ọdun 2018 pe lilo orukọ 'state of Osun' fun ipinlẹ Ọṣun tako ofin orilẹede Naijiria.
Kanmi Ajibọla ni oun  fẹ ki ileẹjọ o yannana boya labẹ ofin to da awọn ipinlẹ silẹ ati eyi to wa fun iburawọle fun awọn to dipo oṣelu mu, o lẹtọ fun gomina ipinlẹ naa lati ṣebura wọle pẹlu orukọ naa.
Oríṣun àwòrán, @State of osun APC
Ṣáajú ni ilé ẹjọ́ gíga kan ní ìpínlẹ̀ Ọ̀ṣun ti pàsẹ pé orúkọ 'state of Osun' tí ìjọba ń lò ní ìpínlẹ̀ Ọ̀ṣun
Bakan naa lo tun n rọ ile ẹjọ naa lati dajọ boya ibura ti wọn ṣe fun gomina Oyetọla ati igbakeji rẹ lẹsẹ nlẹ labẹ ofin.
O ni ki ile ẹjọ si paṣẹ pe eto ibura wọle naa ko lẹsẹ nlẹ nitori naa ki wọn da gbogbo owo ilu ti wọn na fi ṣe aayan ayẹyẹ naa pada si aṣuwọn ijọba.
Bakan naa lo ni ki wọn da owo oṣu gbogbo ti wọn ti gba pada.
Wòlíì Kasali sọrọ nípa awuyewuye pé o lè ìyàwó rẹ̀ jáde nílé
O tun rọ ile ẹjọ lati paṣẹ fun gomina Oyetọla ati igbakeji rẹ pe wọn ko gbọdọ fi ipo wọn eyi ti wọn bura fun labẹ iṣakoso 'state of Osun' gba, tabi ya owo lorukọ 'Osun state' eyi ti o wa ninu iwe ofin Naijiria.
Yoruba Films: Iṣẹ́ amòfin tí mo kọ́ ni Fáṣítì kò mú owó wọlé fún mi bíi iṣẹ́ tíátà - Femi Adebayo
Oríṣun àwòrán, @Loveranger18
Gbajumọ osere tíátà, Femi Adebayo tí sísọ lójú rẹ pé, isẹ agbẹjọro tí òun kọ nílé ìwé Fáṣítì kò mú owó wá fún òun, bíi isẹ tíátà.
Femi, ẹni tó ṣàlàyé bẹẹ lásìkò to ń kópa lórí ètò ileesẹ BBC Yoruba kan, tun fikun pé òun kò kabamọ pé òun fi iṣẹ agbejoro silẹ, máa ṣíṣẹ tíátà.
Kò to di pé mo dara pọ mọ iṣẹ́ tíátà, láàrin odidi ọdún méjì tí mo fi ṣiṣẹ́ amofin, mo ń gba ẹgbẹ̀rún mẹẹdogun náírà losu, nígbà tí mo sì ń rí ẹgbẹ̀rún marundinlaadọta laarin ọjọ́ mẹ́rin nínú isẹ tíátà.
Àmọ́ Femi, tí ọ̀pọ̀ olólùfẹ́ rẹ tún ń pè ní Jelili Oniso wá yàn pé, òun kó tíì fi iṣẹ agbejoro sílè, nítorí òun sì ń gbèrò láti lọ gba òye ọmọwe nípa imọ òfin nílé ẹ̀kọ́ Fáṣítì, erongba òun sì ni lati maa kọ àwọn amofin nisẹ
Lórí èrò àwọn èèyàn pé òfin Nàìjíríà àti ẹ̀ka èto ìdájọ́ wá fún olówó nìkan, tí idajọ sì ń fi iya jẹ àwọn mẹkunnu, Femi ni èyí kò rí bẹ́ẹ̀ nítorí ilé ẹjọ́ di ojú ni, tó sì ń fi etí gbọ ẹjọ́, bẹ́ẹ̀ lo ni ida láti ṣèdájọ́ fún ẹni tó bá jẹbi, bóyá olówó ni àbí mẹkunnu.
Jelili Oniso wá gba àwọn aráàlú nímọ̀ràn láti máa ṣèwádìí nípa àṣeyọrí agbejoro kan ni ẹnu isẹ, kí wọn tó máa gbé ẹjọ́ fún láti dènà ijakulẹ.
Oríṣun àwòrán, others
Nígbà tó ń ṣàlàyé bo se dára pọ mọ eto òṣèlú, Femi ni ìjọba Abdulfatai Ahmed tó kogba wọlé ni Kwara, lo yàn òun sì ipò Oludanimọran, tí òun si rí ìpè náà, bíi ọ̀nà láti súnmọ́ àwọn mẹkunnu ni.
"Eto oselu Nàìjíríà lágbára pupọ, tẹ́lẹ̀ tẹ́lẹ̀ boo bá ọ pá, boo bá o bù lẹsẹ wá, sugbon ìjọba tó wà lóde báyìí tí dènà irú ìwà yìí, tí kò sì tún faaye silẹ fún ajẹbanu.
Bákan lo fikùn pé, oselu kò pá isẹ tíátà tí òun ń ṣe lára nítorí pé, Ọlọ́run fún òun ní aya tó di ilé mú dáadáa, tí Gomina tí òun sì bá ṣíṣẹ náà fún òun ní ààyè láti máa lọ síbi ère tíátà, ni àwọn ọjọ́ kan.
Wo ìdí tí àwọn orílẹ̀èdè fi ń dẹwọ òfin kónílé-ó-gbélé Coronavirus
Nígbà tó ń sọ̀rọ̀ lórí bí ọ̀pọ̀lọpọ̀ ìdílé àwọn osere tíátà ṣe máa ń tètè dàrú, Jelili Oniso ṣàlàyé pé, ẹni tí yóò bá jẹ ọkọ àbí ìyàwó gbajumọ gbọdọ ni ìfaradà púpọ̀ nítorí tí gbogbo ayé ni ọkọ àti aya tó ń pè ní tiẹ̀ nìkan, kí wọn sì máa bẹ Ọlọ́run pé kí onitohun má sìṣe ."
 Ọ̀pọ̀ àbùkù lo máa ń bá ilumọọka àmọ́ ọpọ ìgbéyàwó lo ń dàrú yàtọ̀ sí ti àwọn onitiata. Ohun tó já ju ni pé tá bá fẹ́ gbajumọ lọkọ àbí láyà, a gbọ́dọ̀ ṣe sùúrù gidigidi.
Femi, ẹni tó kọ orin Sakara lórí ayélujára lásìkò ígbélé Covid-19 yìí ni, òun kò ní ẹ̀bùn orin kíkọ, àmọ́ osere gidi yẹ kó leè dibọn, kò sì farajọ ẹni tó ń sìn jẹ́.
O wá rọ àwọn èèyàn tó nífẹ̀ẹ́ láti se ère tíátà, pé kí wọ́n lọ sí orí ayelujara àmọ́  ó ni òun gan ni ileesẹ tó ń kọ àwọn èèyàn ní iṣẹ́ tíátà.
Oríṣun àwòrán, others
Femi, to tí lo ọdún marundinlogoji lẹ́nu iṣẹ́ tíátà, tún pàrọwà sawon èèyàn láti ṣe ìwádìí kíkún kí wọn tó dárapọ mọ iléèwé tíátà kan.
"O wa sísọ lójú rẹ pé, ""ẹgbẹ́ àwọn osere tíátà, Tanpan, tí ń gbé igbesẹ láti maa fún àwọn iléèwé"
"náà niwe àṣẹ, kí wọn má bàa yapa kúrò ní ìdí ìlànà tó tọ́."""
Femi ni òun máa ń fi iṣẹ àgbẹ̀ pawọda n'ilu Ilorin, lẹ́yìn iṣẹ́ tíátà, tí òun sì ń sìn àwọn ohun ọ̀sìn pẹ̀lú, tí òun sì tún máa ń bá àwọn èèyàn ta ilẹ̀ tàbí ra ilé, èyí tí kò ní jẹ́ kí wọn bọ sọwọ alagbeda.
O wa gba àwọn aráàlú láti gba agbẹjọro, lásìkò tí wọn ba fẹ́ tá àbí ra ilẹ̀ ati ile, kò leè bá wọn ṣe ìwádìí nípa dúkìá náà lábẹ́ òfin, tí wọn yóò sì gba ojúlówó ìwé ilẹ̀ àbí ilé náà.
Femi, nígbà tó ń dáhùn ìbéèrè lórí bí àwọn osere tíátà ṣe máa ń safihan ibalopọ àti wiwọ aṣọ iwọkuwọ ninu sinima, ṣàlàyé pé ẹgbẹ́ Tanpan tí ń ṣíṣẹ pelu àjọ  ti ìjọba gbé kalẹ fún akoso sinima, láti dẹkùn irú ìwà aidaa báyìí.
Báwo ni èèyàn ṣe le mọ pé òun ti ní àrùn Coronavirus?
Femi tún ṣàlàyé pé, lára ìpènija tí òun koju bíi osere tíátà ni pé, òun kò leè gbé ayé ara òun mọ nítorí pé òun ti di gbajumọ, tí òun kò sì leè ṣe bo se wù òun.
Femi, tíì ṣe ọmọ àgbà ọjẹ osere tíátà, Adebayo Salami, wá fìdí rẹ múlẹ̀ pé, orúkọ Baba òun là ọ̀nà pupọ fún òun nínú isẹ tíátà nítorí láti kékeré òun ti ń kó isẹ tíátà lára wọn.
Ọpẹ bàbà mi lára mi, ti ìṣẹ̀lẹ̀ kan bá wáyé, tàbí táwọn oniroyin bá kọ nkan ti kii se òótọ́ nípa mi, ní máa béèrè ìmọ̀ràn lọ́wọ́ wọn, bí kii bá sì ṣe ìtọ́sọ́nà bàbà mi, afaimọ kí n má tí kọsẹ̀ nínú isẹ tíátà.
Ẹsẹ̀ bàtà, èso kukumba ni wọ́n fi ń já àbálé àwọn ọmọ Nàìjíríà ní Libya
"Femi, ẹni tó ṣe àlàyé lórí ohun tó fa tí òun fi ṣe fíìmù Jelili ní, ""mo rí pé ìlú kan gógó , táwọn èèyàn ń rìn tikanra-tikanra pẹ̀lú aìdùnnú, lo mú kí n fi ṣe sinima tó jẹ́ awada, láti pa àwọn èèyàn ní  ẹrin, tí mo sì gbọ́ nílé ìwòsàn UCH pé, fíìmù náà pá àwọn aláìsàn ni ẹrin púpọ̀, tó sì tètè mú kí ara wọn yà."""
Femi Adebayo wá kadi ọ̀rọ̀ rẹ nilẹ pé, ẹgbẹ́ àwọn osere tíátà tí ń gbé ìgbésẹ láti kan sì àwọn onileesẹ ibaraenisọrọ láti máa fún àwọn nínú owó tí àwọn èèyàn fi ń rà káàdì gùn ìlò ojú òpó ayélujára, taa mọ sì data, èyí tí wọn fi ń wo fíìmù lórí ayélujára.
Oríṣun àwòrán, Gabriel Afolayan
Gabriel Afọlayan, Gfresh
Oniruuru ni awọn oṣere tiata ni ilẹ Yoruba.
Pẹlu bi o ṣe jẹ pe eka ere ori itage lorilẹ-ede Naijiria, ti a mọ si Nollywood ni awọn onwoye ti kede gẹgẹ bii ileeṣẹ tiata ti o n goke ju lọ lorilẹ-ede agbaye, ẹka ere tiata ilẹ Yoruba, Yollywood si jẹ ọkan lara awọn ti o gbe e soke.
Oríṣun àwòrán, odunlade adekola
Ẹwà àwọn òṣèré ọkùnrin wọ̀nyí leè mú kí obìnrin maa pariwo 'bi eleyi o jẹ ọkọ ẹni ko saa ti jẹ ale ẹni'
Lara awọn oṣere yii ni a ti ri awọn ọkunrin oloṣere ti wọn jẹ ọdọ, ti aye n fẹ, ṣugbọn ju gbogbo rẹ lọ, ti ẹwa wọn lee sọ obinrin maa pariwo 'bi eleyi o jẹ ọkọ ẹni ko saa ti jẹ ale ẹni'.
Oríṣun àwòrán, Odunlade Adekola
Ọdunlade Adekola
Odunlade Adekọla ni a lee pe ni irawọ ti o n tan lagbo ere tiata Yoruba bayii.
Ko si si tọmọde tagba ti ko fẹran rẹ nitori oniruuru ipa ti o ti ko ninu awọn ere itage yala apanilẹrin ni tabi eyi to da lori iwa ọdaran.
Lati igba ti o ti bẹrẹ iṣẹ rẹ, yoo ti le ni ọgọrun un fidio agbelewo ti o ti ṣe.
Ọpọ awọn obinrin ni o si maa n woo gẹgẹ bi arimalee lọ ọkunrin eleyii ti o farahan ninu awọn ti o n tẹ lee lori ikanni instagram rẹ.
Oríṣun àwòrán, Gabriel Afolayan
Gabriel Afọlayan, Gfresh
Ọkan lara awọn ọmọ agba oṣere tiata Yoruba ti o ti doloogbe, Adeyẹmi Josiah Afọlayan, ti ọpọ mọ ni Ade Love ni Gabriel, ti ọpọ mọ si Gfresh.
Ọmọ ilu Agbamu nipinlẹ Kwara ni awọn Afọlayan.  Bi o ti n kọrin naa lo n ṣe ere tiata. Bakan naa lo n ṣe aṣoju awọn ipolowo ọja gidigidi.
Ki a ma si parọ, ọpọ omidan ladugbo ni o mọ pe ọmọ daa sibẹ. Ekọ nipa ere itage ni Gabriel ka ni fasiti ibadan.
2020: Oloye Awurela Ifaleke ti wúré ọdún ìgbéga fún kóówá
Oríṣun àwòrán, Kunle Afolayan
Kunle Afolayan
KunleAfọlayan.
Ko yanilẹnu rara pe Arẹmu ọmọ agba oṣere tiata Yoruba ti o ti doloogbe, Adeyẹmi Josiah Afọlayan, ti ọpọ mọ ni Ade Love naa wọ ọkan lara awọn oṣere tiata Yoruba lọkunrin ti oju wọn gunrege.
O jẹ ọkan lara awọn ti obinrin ko si lee fi oju kere nipa ti ẹwa.
Idi ni pe baba wọn pẹlu nigba aye rẹ kii ṣe oburẹwa rara.
'Mí ò ya wèrè, mí ò burú, ọ̀nà àtijẹ là ń wá'
Adari ere tiata ni iṣẹ ti Kunle gbaju mọ julọ.
Awọn iṣẹ gbogbo ti o si ti ṣe ni wọn maa n gbayi lorilẹ-ede yii ati loke okun.
Awọn iṣẹẹ rẹ bii October 1, CEO ati bẹẹ bẹẹ lọ ti gba amiẹyẹ lorilẹ-ede Naijiria ati loke okun.
Oríṣun àwòrán, Presidency
Kunle Afolayan pẹlu awọn adanilaraya miran lọdọ Aarẹ Buhari
Bẹẹni ko yanilẹnu nigba ti orukọ rẹ jẹyọ ninu awọn adanilaraya kaakiri orilẹede Naijiria ti aarẹ Muhammadu Buhari gba lalejo ni ọdun 2018.
Ẹrin ẹnu rẹ ati iduro rẹ jẹ eyi ti o lee mu ki abo fi akọ ti o n tẹle silẹ.
Oríṣun àwòrán, Ninalowo bolanle
Bolanle Ninalowo
Ṣaṣa ni obinrin ti yoo ri Ọgbẹni Bọlanle Ninalowo ti ko ni ki Ọlọrun ku iṣẹ nitori ẹwa rẹ.
Iṣẹ iṣiro owo ni Ninalowo kọ ni faisiti lorilẹ-ede Amẹrika ti o si fi ṣe iṣẹ fun ni ile ifowopamọsi ki o to tẹle ohun ti ọkan rẹ fẹ, iyẹn iṣẹ ere ori itage.
Wòlíì Kasali sọrọ nípa awuyewuye pé o lè ìyàwó rẹ̀ jáde nílé
Oríṣun àwòrán, Femi Adebayo
Fẹmi Adebayọ
Ajogunba ni ere itage ṣiṣe fun Ọgbẹni Fẹmi Adebayọ.
Lara awọn eekan ati opomulero to gbe fidio ṣiṣe lede Yoruba goke ni baba rẹ, Adebayọ Salami, ti ọpọ eeyan mọ si 'Bello'.
Agbẹjọro ni iṣẹ ti Fẹmi kọ jade ni fasiti ki o to gba ọna iṣẹ tiata lọ.
Eledumare pari ẹwa si ara Fẹmi pẹlu, bẹẹni ko si obinrin ti yoo pade rẹ ti yoo ni oun ko ri eniyan rara.
Oríṣun àwòrán, Muyiwa Ademola
Muyiwa Ademọla
Ẹgan ni hẹẹ pẹlu ẹwa ti Ọlọrun fun Muyiwa Ademọla. Fasiti ibadan ni oun pẹlu ti ṣetan, o si wa lara awọn eekan agbo oṣere tiata nilẹ Yoruba ati lorilẹede Naijiria lapapọ.
Eree 'Ori' ni ọdun 2004 lo pokiki Muyiwa, lati igba naa wa ni o si ti n lọ siwaju lai kaarẹ
Asisat Oshoala: ìbẹ̀rẹ̀ mi kò rọrùn rárá nínú eré bọ́ọ̀lù
Shehu Shagari dágbére f'áyé
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Alhaji Shehu Shagari
Ìròyìn tó ń tẹ̀ wa lọ́wọ́lọ́wọ́ ní wí pé Aare orílẹ̀èdè Nàìjíríà tẹ́lẹ̀ rí, Alhaji Shehu Shagari ti jẹ Ọlọ́hun ní'pe.
Ọmọ ọmọ olóògbé, Bello Shagari ti kéde rẹ̀ lójú opó Twitter tirẹ̀ pé lẹ́yìn àìsàn ránpẹ́ ló kú ní ilé ìwòsàn National Hospital l'Abuja.
Àwọn olóṣelu Nàìjíríà  bákan náà ti bẹ̀rẹ̀ sí ni kéde rẹ̀ tí wọ́n sì ń fi ọ̀rọ̀ ìbánikẹ́dùn wọn ránṣẹ́.
"Oluranlọ́wọ́ fún Ààrẹ Buhari fi tirẹ̀ síta lójú opó Twitter pé ""máa sinmi  lọ́run Alhaji Shehu Shagari. Ki Allah kó forí jì í""."
Aarẹ ile igbimọ aṣofin, Bukola Saraki náà ṣadura fun ẹmi oloogbe
Ẹni ọdún mẹ́tàléláàdọ́rùn-ún ni Alhaji Shehu Shagari to fi dágbére f'áyé.
A n se akojọpọ ẹkunrẹrẹ iroyin yajoyajo lọwọ, a o maa gbe ẹkunrẹrẹ iroyin naa sori atẹ iroyin wa laipẹ. Ẹ jọwọ, ẹ tun oju opo iroyin yi yẹwo, ki ẹ lee ri ẹkunrẹrẹ iroyin ọtun laipẹ.
Miss Africa 2018: Àwọn nkan tó ṣẹlẹ̀ ní Miss Africa 2018, Calabar
Oríṣun àwòrán, @JFriks
Àwọn nkan tó ṣẹlẹ̀ ní Miss Africa 2018, Calabar
Diẹ lo ku ki eto yiyan omidan ilẹ Afrika, ikẹta iru rẹ to waye nilu Calabar lọjọ kẹtadinlọgbọn, oṣu Kejila, 2018, di nkan mi i lẹyin ti wọn kede ẹni to jawe olubori.
Omidan Dorcas Dienda, to jẹ́ aṣoju orilẹede Congo lo jawe olubori nibi eto naa.
Àrà ọ̀tọ̀ inú orin tó jáde lọ́dún 2018 ní Nàìjíríà
Àwọn òṣèré tíátà Yorùbá ọkùnrin tí ó rẹwà
Ni kete ti wọn kede rẹ pe oun ni omidan tuntun fun ilẹ Afrika, to si n rin, yan fanda lori itage ni ina dede gba mọ irun ori rẹ.
Niṣe ni ina fo lati ara awọn ina igbalode ti wọn fi ma n dawọ idunnu nibi ayẹyẹ fo si i lori, ti irun rẹ si gbina.
Ṣugbọn, awọn kan lara awọn to ṣe akoso eto naa ti sọ wi pe irun agbebọ ori, wiigi, to de sori lo gbina, kii ṣe irun rẹ gan n gan.
Gomina ipinlẹ Cross River to gbelejo eto naa, Ben Ayade, sọ pe eto naa ni afojusun lati ṣafihan ẹwa ilẹ Afrika ati ohun to yẹ ki ọkunrin mọ tabi reti lati ọdọ obinrin ilẹ Afrika.
Gomina Ben ayade ati ẹni to di Omidan Afrika tuntun
Oríṣun àwòrán, Miss Africa
Diẹ lara awọn oludije pẹlu asia orilẹede ẹnikọọkan wọn
Oríṣun àwòrán, Miss Africa
Ẹbun ẹgbẹrun marundinlogoji Dọla ni ẹni to bori gba pẹlu ọkọ ayọkẹlẹ SUV kan
Orilẹede mẹẹdọgbọn lo kopa ninu idije naa. Congo, Sierra Leone, Ghana, Cameroon, Zambia, Burundi, South Africa, Zimbabwe, Malawi, Tunisia, Tanzania, Botswana, Angola, Uganda, Somalia, Algeria, Togo, South Sudan, Kenya, Gambia, Namibia, Rwanda, Mozambique, Morocco ati Nigeria.
Àwọn oludije
Shehu Shagari; Àwọn ohun tó yẹ kí o mọ̀ nípa olóògbé
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Oun ni aarẹ alagbada akọkọ ati aarẹ kan ṣoṣo to jẹ lasiko eto oṣelu awaarawa keji (1979-1983).
Wọn bi Shehu Usman Aliyu Shagari ni ọjọ kẹẹdọgbọn, oṣu Keji, ọdun 1925, ni abule Shagari to wa ni ipinlẹ Sokoto.
O wa lati ile olorogun, oun si ni ọmọ kẹfa ti wsn bi ninu ẹbi rẹ.
Shagari bẹrẹ iwe kika nileewe ti wọn ti n kọ Keu, ko to o di pe o lọ si ileewe alakọbẹrẹ Yabo Elementary School lọdun 1931 si 1935.
Bakan naa lo lọ si ileewe Kaduna College laarin ọdun 1941 si 1944.
O gboye imọ ijinlẹ gẹgẹ bi olukọ ni nileewe giga Teachers Training College to wa ni Zaria, nipinlẹ Kaduna.
O si siṣẹ olukọ lati ọdun 1953 di 1958 ni ẹkùn Sokoto.
Tunde Kelani k'ẹdun iku Akinwunmi Ishola
Oun ni aarẹ alagbada akọkọ ati aarẹ kan ṣoṣo to jẹ lasiko eto oṣelu awaarawa keji (1979-1983).
Bakan naa lo jẹ minisita ati ọmọ igbimọ oluṣakoso ninu ijọba apapọ lẹẹmeje laarin ọdun 1958 si 1975.
Shehu Shagari darapọ mọ oṣelu lọdun 1951 lasiko to fi di akọwe ẹgbẹ Northern People's Congress ni Sokoto. O si wa ni ipo naa di ọdun 1956.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Shagari lasiko to bẹ Ọbabinrin Elisabẹti keji wo nilu London lọjọ kẹtadinlogun, oṣu Kẹta, ọdun 1981.
Lọdun 1954, wọn dibo yan an fun igba akọkọ si ipo ọmọ ile aṣofin apapọ lati ṣoju ẹkùn idibo Iwọ Oorun Sokoto. O di akọwe fun Olotu Ijọba Nigeria nigba naa, Sir Abubakar Tafawa Balewa lọdun 1958, ko to o di pe o di minisita fun kata-kara ati ọrọ awọn ileeṣẹ lọdun 1959.
Lọdun 1959 si 1960, Shagari jẹ Minisita fun idagbasoke eto ọrọ aje. Ipo naa lo wa di ọdun 1960 ti wọn tun sọ ọ di minisita fun ọrọ awọn oṣiṣẹ fẹhinti di ọdun 1962.
Lati ọdun 1962 si 1965, Shagari wa ni ipo Minisita fun ọrọ abẹle. Ipo  minisita fun akanṣe iṣẹ lo wa ti iditẹ gbajọba akọkọ fi waye ninu oṣu Kini, lọdun 1966
Lẹyin ogun abẹle to waye, Ọgagun to wa ni iṣakoso nigba naa, Yakubu Gowon, fi Shagari jẹ Kọmisana ijọba apapọ fun idagbasoke eto ọrọ aje, imupadabọsipo ati atunto laarin ọdun 1970 si 1971.
Ọmọge Campus: Lọla Alao ní Aisha ti ni àìsàn jẹjẹrẹ ti pẹ́
Ẹwẹ, o jẹ minisita fun eto ẹnawo lọdun 1971 si 1975. Lasiko yii bakan naa lo jẹ gomina fun Banki Agbaye ati ọmọ igbimọ ajọ to ayanilowo lagbaye, International Monetary Fund (IMF).
Lọdun 1978, Shehu Shagari jẹ ọkan lara awọn ọmọ ẹgbẹ to bẹrẹ ẹgbẹ oṣelu National People's Party. Ẹgbẹ naa si yan an lọdun 1979 lati dije fun ipo aarẹ orilẹede Naijiria.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ọkan lara awọn eto ipolongo ibo ti shagari ṣe nigba to fẹ du ipo aarẹ Naijiria
Ninu eto idibo naa, o jawe olubori, o si di aarẹ Naijiria.
Shagari gbe apoti ibo saa ọlọdun mẹrin fun igba keji lọdun 1983, o si tun wọle.
Awọn ẹsun bi iwa ijẹkujẹ, to fi mọ ṣiṣe mago-mago lasiko eto idibo ọdun 1983 ni wọn fi kan iṣakoso Sahgari. Eyi ati bi eto ẹnawo ijọba ṣe dẹnu kọlẹ, ti ìṣẹ si pọ laarin ilu mu ki awọn araalu bẹrẹ si ni korira iṣejọba rẹ.
Ọgagun Muhammadu Buhari ja ijọba gba mọ lọwọ lọjọ kọkanlelọgbọn, oṣu Kejila, ọdun 1983.
Lasiko ti orilẹede Naijiria ri ọpọlọpọ owo latara epo bẹtiro, Shagari fi ipese ile gibgbe, kikọ ileesẹ ati idagbasoke eto irinna ati iṣẹ agbẹ ṣe afojusun ijọba rẹ.
Lọdun 1980, ijọba rẹ pari kikọ ibudo ifọpo Kaduna refinery, o si bẹrẹ iṣẹ lọdun naa. Bakan naa lo àri kikọ awọn ibi kan ni ileeṣẹ ti wọn ti n wa irin tutu ni Ajaokuta.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Gẹgẹ bi ikede ti ọmọọmọ rẹ kan fi sita, Shagari ku lẹyin aisan ra npẹ sileewosan gbogboogbo to wa nilu Abuja.
Oun kan naa lo pari ileeṣẹ to n ṣe irin, Delta Steel Complex lọdun 1982. O si tun da ilee'sẹ ti wọn ti n jo irin mọ irin, Aluminium Smelter Company of Nigeria, silẹ nilu Ikot Abasi, to wa nipinlẹ Akwa Ibom ode oni.
Iyawo mẹta ni Oloogbe Shehu Shagari fẹ: Amina, Aishatu ati Hadiza Shagari. O bi ọpọlọpọ ọmọ.
Ọkan lara awọn iyawo rẹ, Aishatu Shagari dagbere faye nileewosan kan nilu London lọjọ lẹrinlelogun, oṣu Kẹjọ, ọdun 2001 lẹyin aisan ra npẹ.
Ọjọ kejidinlọgbọn, oṣu Kejila, ọdun 2018 ni Shehu Shagari jade laye lẹni ọdun mẹtalelaadọrun.
Gẹgẹ bi ikede ti ọmọọmọ rẹ kan fi sita, Shagari ku lẹyin aisan ra npẹ sileewosan gbogboogbo to wa nilu Abuja.
Anambra mortuary: Ọ̀pọ̀lọpọ̀ òkú jóná di eérú nínú iná tó jó ní mọ́ṣúárì Anambra
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ayẹyẹ ti wọn fi n jo oku nina ni India
Ijọba ipinlẹ Anambra ti bẹrẹ eto lati da awọn oku to jona ninu iṣẹlẹ ijamba ina to waye ni mọṣuari ileewosan gbogboogbo Enugwu-Ukwu, nijọba ibilẹ Njikoka lọjọ Abamẹta.
Kọmisana eto iroyin nipinlẹ naa, Don Adinuba sọ fun BBC Yoruba pe oku bi aadọta lo jona guru-guru ninu iṣẹlẹ ina ọhun to waye ni nkan bi aago maarun irọlẹ.
O ṣalaye wi pe kọmisana fun eto ilera, Joe Akabuike ati awọn onimọ nipa ayẹwo ẹya ara ti gunlẹ si mọṣuari naa lati ṣe ayẹwo ati akọsilẹ awọn oku to jona ọhun.
Ati pe wọn yoo lo ayẹwo DNA lati tọpinpin awọn oku to jona kọja nkan ti ẹnikẹni le damọ.
Kọmisana fun eto ilera ninu ọrọ tiẹ naa sọ wi pe ''igbo kan ti wọn dana sun nitosi mọṣuari naa lo ran mọ ọ.
Ati pe nikete ti ayẹwo ba pari ni wọn yoo yọnda awọn oku fun awọn ẹbi wọn.''
Agbẹnusọ fun ileeṣẹ ọlọpaa ni ipinlẹ Anambra, Haruna Mohammed sọ ninu atẹjade kan pe ina ọhun ba mọṣuari naa jẹ pupọ, to si tun jo awọn oku kọja boṣeyẹ.
'Obìnrin tí kó ba fẹ́ òṣìṣẹ́ Mọ́ṣúárì, ìpinu rẹ̀ mẹ́hẹ'
O sọ pe ''ọpẹlọpẹ awọn ọlọpaa to n rin kiri ni agbegbe naa to sare si ibi ti iṣẹlẹ naa ti waye, ki awọn janduku ma ba a lo anfaani naa lati jale.''
"A ti wi pe nigba ti agbara awọn pana-pana ati araalu yoo fi ka ina naa, o ti ba nkan jẹ pupọ nitori pe gbogbo oku to wa nibẹ lo ti fẹ ẹ jona tan kọja nkan ti ẹnikẹni le damọ."""
Amọ ṣa, Mohammed sọ pe ileeṣẹ ọlọpaa ko ti i le sọ koko nkan to fa iṣẹlẹ ina naa.
Logo Benz: Ọba ìlú Benin kìlọ̀ fáwọn ọ̀dọ́ lórí ṣíṣe òògùn owó òjijì.
Oríṣun àwòrán, @adelovecom
Ọba Benin ni atunbọtan oṣo ṣiṣẹ kii dara
Awọn ọdọ ti wọn n lepa owo gbigbona nipa pipa eeyan tabi jiji awọtẹlẹ awọn obinrin ko ni ṣai foju wina atunbọtan gbigbona.
Eyi ni ọrọ ikilọ ti Ọba ilu Benin, Ọba Ewuare II gbe kalẹ nibi aṣekagba ọdun Igue to waye nilu Benin.
Alapinni Oosa ṣàdúrà fún gogbo ọmọ kúoótù, oò jíire bí?
Ninu ọrọ to sọ nibi ayẹyẹ naa, ko pamọ pe ọba alayeluwa naa n kọminu lori bi awọn ọdọ ṣe n lọwọ ninu ogun owo ṣiṣe bayii.
Ọba Ewuare II ni iwa oṣo ṣiṣẹ, yatọ si pe o ṣajeji si aṣa ati iṣe ilẹ Benin, ko si ninu iwa ati aṣa itẹwọgba ni ilẹ kilẹ lorilẹ Afirika.
Tsunami: Lẹ́yìn ọ̀sẹ̀ kan ti Jumasil ti sọnù ni wọ́n rii padà
O ni ki awọn ọdọ o ṣọra fun ilepa owo ojiji lai ṣiṣẹ nitoripe bopẹ boya igbẹyin rẹ kii san fun awọn to ba ṣee.
Afro Brazilians: ìlú Rio ni a máa kọ ilé ìṣẹmbáyé náà sí
2019: INEC ní àwọn kò tíì gbọ́ nípa ikú aṣòfin ìpínlẹ̀ Eko to kú
Oríṣun àwòrán, Nigeria National Assembly
Ileewosan aladani ni ilu Eko ni aṣofin Ayeọla dakẹ si lẹyin aisan ranpẹ
Ọkan lara awọn aṣofin to n ṣoju ipinlẹ Eko nile aṣoju-ṣofin, Abayọmi Ayeọla jade laye ni ọjọ Aiku.
Amọṣa, awọn alaṣẹ ajọ eleto idibo apapọ orilẹ-ede Naijiria, INEC ti sọ pe awọn ko tii gbọ nipa iku rẹ ati pe o di igba ti wọn ba gbọ ki wọn to mọ igbesẹ to kan lati gbe.
Ninu ọrọ to ba BBC Yoruba sọ, alukoro fun ajọ eleto idibo lorilẹ-ede Naijiria (INEC), Ọgbẹni Oluwọle Uzzi ni o ni ilana ti iroyin bẹẹ maa n gba ki o to de ọdọ ajọ naa.
"O ṣafikun pé: 'bi a ṣe n sọrọ yii, iroyin naa ko tii de ọdọ ajọ INEC. Koda, ẹyin gan an ní BBC ni ẹ n tufọ iku rẹ fun wa bayi."""
Aṣofin Ayeọla to n ṣoju fun ẹkun idibo apapọ Ibeju Lẹkki nile aṣoju-ṣofin dagbere faye nileewosan kan nilu Eko lẹyin aisan ranpẹ.
Alapinni Oosa ṣàdúrà fún gogbo ọmọ kúoótù, oò jíire bí?
Ẹgbẹ oṣelu APC ti ṣapejuwe iku rẹ gẹgẹ bii adanu nla fun ẹgbẹ oṣelu naa.
Labẹ ofin, lẹyin oṣu mẹfa, ko lee si aye fun atundi ibo mọ lawọn ẹkun idibo ti o ba padanu aṣofin wọn.
Pẹlu bi ọrọ ṣe ri yii, ọpọ lo ṣi n woye boya aye yoo si lee wa fun atundi ibo fun aṣofin miran fun ẹkun idibo Ibeju Lekki laigbagbe pe ibo apapọ si ile aṣofin apapọ yoo waye ni oṣu keji ọdun 2019.
Ṣọla Allyson: Obìnrin tí kò bá rẹwà ni yóò máa ṣí ara sílẹ̀
Tsunami: Lẹ́yìn ọ̀sẹ̀ kan ti Jumasil ti sọnù ni wọ́n rii padà
Asisat Oshoala: ìbẹ̀rẹ̀ mi kò rọrùn rárá nínú eré bọ́ọ̀lù
NCAA: A fún àwọn adarí ní ọ̀sẹ̀ méjì si láti dá wọn lóhùn
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Murtala Muhammed international Airport 2
Àpapọ̀ àwọn òṣìṣẹ́ ẹka irina ofurufu iyẹn NUATE ati ATSSSAN ti fagile iyansẹlodi ti wọn sọ wi pe awọn yoo gunle ni Ọjọ Keji, Osu Kini, ọdun 2019.
Alaga ẹgbẹ osisẹ National Union of Air Transport Employee (NCAA), Paul Igene ni awọn da iyansẹlodi naa duro nitori pe awọn adari ẹka eto irina ofurufu pẹtu si wọn ninu wi pe awọn ti kọ iwe ransẹ si ile-isẹ irina, pẹlu adehun wi pe awọn yoo da wọn lohun laarin osẹ meji.
Laipẹ yii ni awọn oṣisẹ labẹ asia awọn oṣiṣẹ agba fun awọn to n pese iṣẹ lẹka ofurufu, ATSSSAN ati awọn oṣiṣẹ ẹka ofurufuru Naijiria, NUATE sọ fun awọn oniroyin nipa ipinnu wọn lati bẹrẹ iyanṣẹlodi lọjọ keji, oṣu kinni, ọdun 2019.
Awọn alaga ẹgbẹ mejeeji ni o ti to ọdun mẹta ti wọn ti ṣe ìgbega lẹnu iṣẹ f'awọn ọmọ ẹgbẹ awọn to wa labẹ akoso NCAA.
Lucky Izebhokun ti o jẹ alaga ATSSSAN ati Ayodele Sofolayan ti NUATE ni o to gẹ pẹlu bi wọn ti ṣe n ko iyan awọn ọmọ ẹgbẹ awọn kere.
Wọn ni o jẹ ohun ti o kọ ni lominu bi awọn alakoso NCAA ti ṣe ma n gbe awọn eeyan wa lati ita lati wa jẹ olori le awọn ọmọ ẹgbẹ awọn ti o kun ọju oṣunwọn.
Lucky Izebhokun ni awọn yoo jọ wọya ija pẹlu NCAA ti wọn ba kọ lati ṣe igbega lẹnu iṣẹ fun awọn ọmọ ẹgbẹ awọn ki ọdun 2018 to pari.
Lọdun 2018, awọn oṣisẹ ẹka ọkọ ofurufu gun le iyanṣelodi kan ti ikọ BBC Yoruba si ba awọn arinrinajo sọrọ ni papakọ ofurufu Murtala Muhammed l'Eko.
'Nígbà tí kò ṣeéṣe fún wa láti fò, a ó lọ́ wọkọ̀'
Ṣọla Allyson: Obìnrin tí kò bá rẹwà ni yóò máa ṣí ara sílẹ̀
Iroyin ta gbo sọ wi pe awọn ti ọrọ kan lẹka yi ti n gbe igbese lati ri wi pe wọn dena iyanṣẹlodi yi ti o le mu inira ba awọn arinrinajo ofurufu ni Naijiria.
Oludari to n ri si eto iroyin Ncaa ọgbẹni Sam Adurogboye ni awọn alaṣẹ ncaa kii ṣe ajojisi awọn osiṣẹ wọn yio ati wi pe lai pe yi wọn yoo wa wọrọkọ fi sada lori oro yi.
Bakannaa ni olori awọn akoroyin ẹka ofurufu nigba kan ri, Chuks Iwelumo sọ fun BBC Yoruba ninu ifọrọwanilẹnuwo pe oun ni igbagbo pe ọrọ naa yoo niyanju ki o to di gbedeke ọjọ keji osu kini ti awọn ọmọ ẹgbẹ naa fẹ bẹrẹ iyanṣelodi.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Àwọn arìnrìàjò ní pápákọ̀ òfúrufú MMA2
Wọn ti fi ọrọ yi to Minisita fun ọrọ ofurufu leti o si damiloju wi pe ko ni fẹ ki iyanṣelodi yi waye nitori pe yoo mu inira ba ara ilu
Chuks ni nnkan to n ṣelẹ labẹ NCAA ku diẹ kaato ati wi pe ifẹhonu han awọn oṣiṣẹ naa ko kọja ala.
''Ko si ẹni ti yoo gba ki wọn gbe ẹlomiran wa jẹ ọga le lori lati ita ti kii ṣe wi pe ko kaju oṣunwọn.Ọrọ yi ti fẹ di aṣeju ti o si yẹ ki atunto waye ni kiakia''
Afro Brazilians: ìlú Rio ni a máa kọ ilé ìṣẹmbáyé náà sí
Iléeṣẹ́ ọmọogun Nàìjíríà ní fídíò tó ti pẹ́ ní fídíò ọmọogun tí kò fẹ́ kojú Boko Haram
Oríṣun àwòrán, Twitter
Fidio naa ti n ja rainrain lori ẹrọ ayelujara
Ileeṣẹ ọmọogun Naijiria ti fẹsi si fọnran fidio kan to gbode lori ayelujara nibi ti ọmọogun kan ti n fapa janu lori aisi nkan ija lati koju ikọ Boko Haram.
Wọn ni kii ṣe ootọ ni ohun ti fidio naa n sọ- pẹlu alaye.
Ọgagun Sani Usman to jẹ agbẹnusọ fun ileeṣẹ ologun ni lọdun 2014 ni fọnran fidio naa jade ati wi pe ohun ti o wa ninu rẹ kii ṣe atọna bi nnkan ti ṣe ri lasiko yi.
Ọpọ eeyan lo ti ṣe alabapin fidio naa to fi mọ oluranlọwọ fun Aarẹ ana Goodluck Jonathan Reno Omokri
Lati ọdun 2009 ni Boko Haram ti n da wahala silẹ́ lorileede Naijiria ati awọn orileede to yii ka bi Niger, Chad ati Cameroon.
Losu kọkanla, ọdun 2018, awọn ọmọ ileeṣẹ ologun Naijiria kan fifidio sita nibi ti wọn ti ni o kere tan ọgọrun ọmọogun lo padanu ẹmi wn ninu ikọlu pẹlu Boko Haram .
Wọn tun sọ ninu fidio naa wi pe awọn ko ni nnkan ija to koju oṣunwọn.
Eleyi ṣẹlẹ lẹyin igba ti ileeṣẹ ọmọogun ni awọn ti ra nnkan ija fun awọn ọmọogun Naijiria.
Boko Haram ti pa to eeyan ẹgbẹrun lọna ọgun ti wọn si ti ṣidi awọn aimọye eeyan kuro nile wọn laarin ọdun mẹjọ ti wọn ti n koju awọn ọmọogun orileede Naijiria.
Afro Brazilians: ìlú Rio ni a máa kọ ilé ìṣẹmbáyé náà sí
Awakọ̀ àti ọmọ mẹta mọribọ nínú ìjàmbá ọkọ l'Eko
Ijamba ọkọ kan ti waye loju ọna marose Eko si Ibadan lagbegbe Iyana Oworo.
Akoroyin wa ti iṣẹlẹ naa soju rẹ ni ko si eeyan kankan to padanu ẹmi ninu iṣẹlẹ naa ṣugbọn ọkọ mẹfa  kolu ara wọn ninu ijamba naa
Ọkọ agbepo kan la gbo pe o ya lọ ba awọn awakọ  ti o si kọlu ọkọ mẹfa loju popo.
Ijamba ọkọ le m'ẹmi lọ
Ninu awọn awakọ naa la ti ri arakunrin kan ati ọmọ rẹ mẹta ti wọn jijọ wa ninu ọkọ naa.
Orin ọpẹ ati iyin lo gba ẹnu rẹ pe ohun ati awọn ọmọ rẹ ko padanu ẹmi wọn.
Awọn oṣisẹ eleto pajawiri Lastma ti wa ni ibi iṣẹlẹ naa ti wọn si tin gbiyanju lati wọ awọn ọkọ naa kuro loju ọna.
Idẹnukọlẹ ìṣèjọba Amẹrika: Ọ́fíìsì Amẹrika ni Nàìjíríà ṣi ń pín ìwé ìrìnna
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ise ti bere fun eni to ba fe gba iwe irinna
Idẹnukọlẹ ìṣèjọba Amẹrika lo nawo d'orile-ede Naijiria pẹlu bi wọn ti ṣe so iṣẹ gbogbo rọ nileeṣẹ Amerika to wa ni Naijiria lọsẹ to kọja.
Bayii ni ile iṣẹ ijọba Amẹrika to n fun arinrin ajo ni Naijiria niwe iriina ti fi léde pe iṣẹ n lọ ni pẹrẹwu nile iṣẹ wọn to wa ni Abuja ati ipinlẹ Eko.
Wọn ni ki ẹnikẹni to ba yẹ ko wa fun ifọrọwanilẹnuwo lati gba iwe irinna yọjú lasiko to yẹ.
Ìwà ipá nínú ìdílé máa ń bí ìgè àti àdùbí ni tó lè já sí ikú
Kí lo fàá ti wọn fi ti i pa tẹ́lẹ̀?
Wọn so ohun gbogbo to ni ṣe pẹlu iwe irina nileeṣẹ orileede Amerika leko ati Abuja rọ titi di igba ti wọn ba yanju idẹnukọlẹ ìṣèjọba to n ja rain lamẹrika.
A gbo pe awọn ẹka  ileeṣẹ orileede Amerika nilu Eko ati nilu Abuja lọrọ yi kan.
Gẹgẹ bi ohun ti awọn oṣiṣẹ ọ́fíìsì Amẹrika ni Nàìjíríà fi sita loju opo Facebook wọn, wọn ni ohun to de ba orileede awọn losokunfa titi ile iṣẹ wọn pa .
Lati ọjọ kejilelogun oṣu kejila ọdun 2018 ni iṣejọba ni Amerika ti dẹnu kọlẹ nitori pe awọn ọmọ ile asofin kọ lati buwọlu owo ti Aarẹ Trump fẹ fi kọ ogiri ti yoo ya Amerika ati Mexico lọtọọtọ.
Ileeṣẹ orileede Amerika ni Naijiria sọ wi pe awọn yoo bẹrẹ iṣẹ pada ni kete ti wọn ba ti ribi yanju aawọ naa.
Ohun ti igbeṣẹ́ yi tunmọ si fun awọn to ba fẹ gba pali irina ni wi pe wọn yoo ni lati ṣe suuru titi di igba ti wọn ba bẹrẹ iṣẹ.
Oríṣun àwòrán, Twitter/@USEmbassyAbuja
US Embassy Abuja
Idẹnukọlẹ naa ti lapa lara wọn nilẹ Amerika pẹlu bi awọn agbaṣẹṣe ko ti ṣe riṣẹ gba ti ọpọ oṣiṣẹ ijọba ko si ribi rin irinajo nitori pe wọn ko ri owo osu gba.
Nnkan bi eeyan  420,000  lagbo wipe wọn ko ti ri owo osu gba laisun ọdun tuntun.
Ṣọla Allyson: Obìnrin tí kò bá rẹwà ni yóò máa ṣí ara sílẹ̀
New year message: Buhari, Jonathan, Atiku, kí àwọn ọmọ orílẹ̀èdè Nàìjíríà
UNICEF: ọmọ tuntun 395, 072 máa wá sáyé lagbaye lónìí
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Abiyamọ ku ọrọ ọmọ
Ajọ agbaye to n risi ọrọ awọn ọmọde, UNICEF, ni ọmọ 395, 072 ni awọn eeyan yoo bi loni ọjọ kinni, oṣu kinni, ọdun 2019 kaakiri agbaye.
Awọn odiwọn ti ajọ UNICEF fi gba pe awọn ọmọ tuntun naa a waye niyi:
India lo wa ni ipo akọkọ pẹlu ọmọ 69, 944
China ni ipo keji pẹlu ọmọ 44, 940
Naijiria ipo kẹta lagbaye, ipo kinni ni Adulawọ pẹlu ọmọ 25, 685.
Pakistan pẹlu ọmọ 15, 112.
Indonesia pẹlu ọmọ 13, 256.
Amerika pẹlu ọmọ 11, 086.
DRC pẹlu 10, 053.
Bagladesh pẹlu ọmọ 8, 428.
New year message: Buhari, Jonathan, Atiku, kí àwọn ọmọ orílẹ̀èdè Nàìjíríà
Ironside Pernille, to jẹ adele aṣoju UNICEF ni Naijiria ṣalaye pẹ odiwọn  ẹmi gigun awọn ọmọ ti wọn maa bi ni Naijiria loni ko ju ọdun marundinlọgọta.
O ni iwadii fihan pe o ṣeeṣe ki wọn ku ni 2074 nigba ti kò ri béé ni awọn orilẹ-ede mii.
Ironside ṣalaye pé ọmọ kan ninu ọmọ mẹta ti a bi ni Naijiria lo maa n ṣalaisi lataari awọn aisan to ṣee dena ni eyi ti o n mu ẹdinku ninu ẹmi gigun ba wọn.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Inu ile pẹlu agbẹbi ni aboyun mii fẹran
Ajọ UNICEF parọwa pe o yẹ ki a tubọ ṣiṣe sii ni Naijiria lati din iku awọn ọmọ ọwọ ku sii lasiko yii.
Itọju oloyun, jijẹ ounjẹ aṣaraloore lai ṣe wahala tabi hílàhílo maa n jẹ ki eso inu aboyun dara.
Opọlọpọ àwọn Alaboyun Naijiria ni wọn maa n fẹ bimọ sinu ilé wọn tabi lọdọ awọn agbẹbi ladugbo tabi ki iyale wọn gbẹbi fun wọn
Nigba ti awọn mii maa n fi oyun inu wọn bí abíọ́nà nibikibi ti ọmọ ba ti mu wọn ni wọn a bii si bii opopona, ọna ọja, oko, tabi loju titi laiyọ lẹnu irin ajo silẹ.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
loju ọna ni ọmọ ti n mu wọn
Alapinni Oosa ṣàdúrà fún gogbo ọmọ kúoótù, oò jíire bí?
Ọpọlọpọ àwọn Alaboyin Naijiria maa n fẹ bimọ sile ijọsin tabi ibudo adura wọn nitori awọn miran gbagbọ pe ogun ti inu ẹmi a di ṣíṣẹ́ lataari adura ti wọn ba gba si Olorun wọn.
Ajọ UNICEF sọ pataki omi tó mọ́ ni mimu fun alaboyun ati irufẹ ounjẹ to dara fun un bii èso bii ọsan, ọgẹdẹ, ibẹpẹ; ewébẹ̀ bii ẹfọ ugwu, ẹfọ tẹtẹ, ewedu, karọọti, ẹfọ gbure; ẹ̀wà, ẹja àti bẹẹ bẹẹ lọ
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Adura gbigba ni awọn alaboyun mii gbagbọ ninu ẹ
Bakan naa ni awọn alaboyun mii gbagbọ pupọ ninu awọn iya alagbo ti awọn mii n pe ni iya elewe ọmọ ati iya Ijaw.
Awọn elewe ọmọ yii ni ìrírí to pọ̀ lori oyun ninu, ọmọ bibi, ati ọmọ titọ ninu igbagbọ awọn alaboyun kan.
Ajo UNICEF gba awọn alaboyun nimọran lati lọ sile iwosan ijọba tabi ti aladani to kun oju owo ti wón ni awọn ohun eelo itọju alaboyun ati ọmọ tuntun.
Wọn ni ẹtọ ọmọ ko faaye gba ki aṣiṣe iya tabi baba maa dá ẹmi ọmọ ọwọ́ légbodò lọdun 2019.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Iṣẹ nla niṣẹ abiyamọ kaakiri agbaye
Ikorodu Bois: Ko si ẹni ti a kò lè sín jẹ!
Ajọ UNICEF gba pe airitọju to peye fun awọn alaboyun lo maa n fa iku ọmọ tuntun.
Ọgbẹni Ironside gba awọn alaboyun nimọran lati maa lọ si ileewosan gidi fun itọju to peye.
O ni ọdun 2019 ni UNICEF yoo sami ọgbọn ọdun ti wọn gba abadofin ẹtọ awọn ọmọ wẹwẹ wọle lagbaye.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ọmọ tuntun káàbọ̀
Bakan naa ni wọn gba awọn baale ati ẹbi alaboyun nimọran lati maa ṣe iranlọwọ fun wọn lai daamu ọkan alaboyun.
Pẹlu imọran pe ki alaboyun maa ṣe ere idaraya ti kò lera pupọ ki o le ran an lọwọ lasiko ìrọbí.
2019 Prophesies: Kíni ohun tí àwọn ìránṣẹ́ Ọlọ́run sọ nípa ọdún 2019
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ọdún 2019 ti wọlé, àwọn olórí ẹ̀sìn gbogbo si ti ń sọ àsọtẹ́lẹ̀ wọn fún ọdún tuntun náà.
Gẹgẹ bi iṣe bi ọdun tuntun ba ti n wọle wẹrẹ ni awọn ojiṣẹ Ọlọrun, Alufaa, Imaamu atawọn olori ẹsin gbogbo yoo maa jade pẹlu ohun ti wọn ba ni Ọlọrun ba awọn sọ.
Ti ọdun 2019 naa ko yẹ pẹlu bi awọn olori ẹsin kan ti ṣe n jade pẹlu iran ti Ọlọrun fi han wọn fun ọdun 2019.
Oríṣun àwòrán, Mfm
Ọmọwe Daniel Olukọya, Alufa agba ijọ MFM
Iran mọkanlelọgbọn ni Alufa Olukọya fi sita ninu akojọpọ iran ti Ọlọrun fi han an fun ọdun 2019, eyi to dà pe ni ọdun irọrun ati alekun ọla.
Marun un pataki ninu iran ti Alufaa Olukọya gbe kalẹ fun ọdun 2019 ni:
1) Ọdun ara ọtọ ni ti o si nilo adura ọtọ.
2) Idojuti fun golayati ni orilẹede ati lagbaye.
3) Awọn aṣiri ohun ikọkọ ti eti ko gbọri yoo jade.
4) Awọn to n ṣẹṣo yoo pade wahala nla.
Ikorodu Bois: Ko si ẹni ti a kò lè sín jẹ!
Fada Mbaka. Ijọ Aguda Adoration Ministry
Oríṣun àwòrán, Rev Fr Ejike mbaka
Fada Mbaka. Ijọ aguda Adoration Ministry
Ko sẹni ti ko mọ alufaa Mbaka ti ijọ Aguda,  Adoration Ministry, to wa ni ilu Enugu lẹkun ila oorun Naijiria.
Ninu ọrọ asọtẹlẹ rẹ fun ọdun  2019, o ni idaamu ati iṣoro nlanla lo wa lọna fun orilẹ-ede Naijiria ni ọdun 2019.
Gẹgẹ bi o ṣe wi, irufẹ idaamu ti orilẹ-ede Naijiria yoo koju yoo jẹ eyi ti ko tii waye ri ninu itan rẹ.
Oríṣun àwòrán, RCCG
Pasitọ Enoch Adeboye. RCCG
Alufa Adeboye ti ijọ Redeemed Christian Church of God ko fi gbogbo ẹnu sọrọ tan lori asọtẹlẹ rẹ fun ọdun 2019.
O ni ọbẹ̀ kìí mì nikun àgbà ni ati pé ọlọgbọn nikan lo le jó ilu agidigbo ti asọtẹlẹ ọdun 2019 jẹ fun Naijiria.
Ohun to sọ ni agbekalẹ iwe Ẹkun Jerimaya, ori kẹta, ẹsẹ kejilelogun ati ikẹtalelogun ninu Bibeli mimọ eyi to ka pe:
"22. Nítorí ìfẹ́ OLÚWA tí ó lágbára ni àwa kò fi ṣègbé, nítorí ti àánú rẹ kì í kùnà.
23. Wọ́n jẹ́ ọ̀tún ní àárọ̀; títóbi ni òdodo rẹ̀."
Oríṣun àwòrán, David oyedepo min
Biṣọọbu David Oyedepo, Ijọ Winners Chapel
Ninu ọrs asọtẹlẹ tirẹ Biṣọọbu agba David Oyedepo ti Ijọ Winners Chapel ni awọn ẹri awoyanu ni yoo farahan ninu ọdun 2019.
O ni ko si ohun ti yoo damu alaafia orilẹ-ede Naijiria ati pe Naijiria ko ni foju kan itajẹsilẹ mọ, bẹẹ ni ko ni si ogun mọ nitori nnkan yoo yipada si rere fun orilẹ-ede Naijiria.
Yoruba gba pẹ ẹnu ẹni la fi n kọ meje ni ọrọ asọtẹlẹ, eyi to ba wuni lati gbà ni eeyan n gbà nibẹ.
Ṣọla Allyson: Obìnrin tí kò bá rẹwà ni yóò máa ṣí ara sílẹ̀
Alapinni Oosa ṣàdúrà fún gogbo ọmọ kúoótù, oò jíire bí?
New Minimum wage: Ẹgbẹ́ òṣìṣẹ̀ yóò bẹ̀rẹ̀ ìyanṣẹ́lódì ní Jan. 8
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ẹgbẹ́ òṣìṣẹ́ NLC, TUC àti ULC ní èyí ni ẹ̀bùn ọ̀dún tuntun fún Nàìjíríà àyàfi tí ìjọba bá gbé ìgbésẹ̀ tó tọ́ lórí ẹ̀kúnwó oṣù tuntun
Ẹgbẹ oṣiṣẹ lorilẹede Naijiria ti ni awọn ni ẹbun nla fun orilẹ-ede Naijiria bi ijọba apapọ atawọn ijọba ipinlẹ ba kuna lati fi ẹnu ọrọ ẹkunwo oṣu tuntun jo ibikan ṣaaju gbendeke ọjọ kọkanlelọgbọn, oṣu kejila, ọdun 2018.
Nisinyi ti gbendeke naa ti kọja ti ọdun tuntun ti wọle bayii, ibeere to gbẹnu ọpọ onwoye ni irufẹ ẹbun wo ati pe ọna wo ni ẹbun yii yoo gba wa.
Amọṣa, akọwe agba ẹgbẹ oṣiṣẹ NLC, Peter Ozo-Esan ti ṣalaye pe gbogbo ẹgbẹ oṣiṣẹ ti bẹrẹ igbesẹ lati gbe iwọde ti yoo se ilẹkun mọ gbogbo ohun amuṣọrọ aje orilẹ-ede Naijiria bẹrẹ lati ọjọ kẹjọ, oṣu kinni,
ọdun 2019.
Ozo-Esan ni ko si ohun to kan ẹgbẹ oṣiṣẹ pẹlu igbimọ amuṣẹya ti aarẹ tun ni oun yoo gbe kalẹ lori ọrọ ẹkunwo oṣu tuntun naa.
Ikorodu Bois: Ko si ẹni ti a kò lè sín jẹ!
New year message: Buhari, Jonathan, Atiku, kí àwọn ọmọ orílẹ̀èdè Nàìjíríà
O ni ko si ohun meji ti ẹgbẹ oṣiṣẹ n fẹ bayii ju ki aarẹ fi aba lori ẹkunwo oṣu naa ṣọwọ sawọn aṣofin apapọ fun bibuwọlu ki iṣẹ lee bẹrẹ lori sisan rẹ.
Dino Melaye: Ọlọ́pàá ti fẹ́ wó ilé mi lulẹ̀ báyìí o
Oríṣun àwòrán, DINO MELAYE
Sẹnetọ Dino Melaye
Iroyin to n tẹ wa lọwọ ni wi pe awọn ọlọpaa ti gbe apoti to n dena ibaraẹni sọrọ lori ẹrọ gunlẹ si ile Sẹnetọ Dino Melaye.
Lara awọn akọroyin to wa digbi nibi iṣẹlẹ yii lo fidi ọrọ naa mulẹ fun ile iṣẹ iroyin BBC Yoruba.
Lọjọru ọjọ keji oṣu kinni ọdun yii ni igbesẹ yii waye ni ile Dino Melaye, Sẹnetọ to n ṣoju ẹkun Iwọ Oorun ipinlẹ Kogi.
Awuyewuye laaarin ileeṣẹ ọlọpaa ati sẹnetọ Dino Melaye bẹrẹ lopin ọdun 2018 o si tun gbera wọ ọdun 2019.
Ninu iroyin kan to fi ṣọwọ lori ikanni ayelujara twitter rẹ ni owurọ ọjọru, Sẹnetọ melaye ni  nibayii, awọn ọlọpaa ti fẹ ja ilẹkun ile ohun pẹlu ipa.
Lati bii ọsẹ kan sẹyin bayii lawọn ọlọpaa ti gẹgun yika ile Sẹnetọ Dino Melaye. Ohun ti awọn alaṣẹ ileeṣẹ ọlọpaa lorilẹede Naijiria si sọ pe o fa eyi Ọlọpaa gbé àpótí adènà ẹ̀rọ ìbánisọ̀rọ̀ sílé Dinoni ẹsun ti wọn fi kan aṣofin naa pe o lẹdi apo pọ pẹlawọn janduku kan lati yinbọn lu ọlọpaa kan lẹnu iṣẹ rẹ ni ọdun 2018.
Bi o tilẹ jẹ pe aṣofin Dino Melaye ti sọ pe oun ko si nile lọwọ yii ati pe ni kete ti oun ba de oun yoo yọju sileeṣẹ ọlọpaa l'Abuja, awọn ọlọpaa ti faake kọri pe ko soun to jọ o ati pe awọn ko ni ṣi ẹsẹ kuro layika ile rẹ afi ti o ba jọwọ ara rẹ fawọn ọlọpaa nitori ẹsun naa.
Melaye ṣalaye lori ikanni twitter rẹ naa pe awọn  oṣiṣẹ to n mojuto ọrọ ado oloro nileeṣẹ ọlọpaa lorilẹede Naijiria, EOD ni wọn ko awọn ohun elo ti wọn yoo fi wo ẹnu iloro oun lulẹ wa.
Eyi ni ọjọ keje ti awọn ọlọpaa ti gẹgun yi ile aṣofin Dino Melaye ka.
Oríṣun àwòrán, INSTAGRAM/@DINOMELAYE
Sẹnetọ Dino Melaye
Sẹnetọ Dino Melaye to n ṣoju ẹkun Iwọ Oorun ipinlẹ Kogi ni iha aarin gbungbun orilẹede yii fi ikini ọdun tirẹ ranṣẹ lati ibi ipamọ rẹ nibi to ti n gbadura pe ki Ọlọrun tu oun silẹ.
Lati ọjọ ti ọjọ kejidinlọgbọn ni awọn ọlọpaa ti taku si ẹnu ọna ile rẹ pe afi dandan ti awọn ba fi panpẹ ọba mu u.
Dino Melaye ni 'torí ọ̀rọ̀ òtótọ́ tí òun máa ń sọ ni wọ́n fi ń lépa òun.
Eyi da lori ẹsun ti wọn fi kan an pe oun ati awọn janduku rẹ tawọn ti ibọn lọwọ gbiyanju lati yin in lu ọlọpaa kan, Sajẹnti Danjuma Saliu ni ipinlẹ Kogi nigba to wa lẹnu iṣẹ rẹ ninu oṣu keje ọdun 2018.
Ẹwẹ, loju opo Twitter rẹ, Dino sọ pe oun ko bẹru ọla nitori pe ẹni to ni ọla, baba oun ni.
Lafikun Dino fiba f'Ọlọrun lede Yoruba:
Ikorodu Bois: Ko si ẹni ti a kò lè sín jẹ!
"Paba n bari rẹ ni pe Dino Melaye fi fidio sita loju opo Twitter rẹ kan naa ninu eyi to ti ni oun ko beerealafia fun awọn ọta oun  nitori wọn ti sẹ́ Ọlọrun oun. O ni ""ki Ọlọrun ṣe fun awọn ọta mi bo ṣe ṣe ni ilẹ Ijibiti nitori awọn ọmọ Isrẹli."
Agbẹnusọ awọn ọlọpaa, Jimoh Moshood sọ pe awọn ti kọ iwe si ile igbimọ aṣofin pe ki  Dino Melaye wa fara han ni ile iṣẹ Ọlọpaa ipinlẹ̀ Kogi lati wa dahun ẹsun rẹ ṣugbọn o kọjaalẹ.
Lọsẹ to kọja ni Sẹnet Dino ba figbe ta pe awọn ọlọpaa fẹ mu ohun ki wọn si gun oun labẹrẹ iku.
Awọn ọlọpaa naa fesi pe, irọ patapata ni. Wọn ni awọn sọ fun Dino pe bi o ba mọ pe oun ṣẹ, ko jẹwọ.
Ekiti: Ìyàwó gómìnà Èkìtì rọ àwọn obìnrin lóríi gbígbẹ̀bí sílé
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Awọn ajọ agbaye fi idi rẹ mulẹ pe iku ọwọọwọ laarin awọn obinrin ati ọmọ wẹwẹ pọ lorilẹede Naijiria
Oniruuru iburdo ìrọbí ni awọn obinrin n gba bimọ sí.
Paapaa ni ilẹ Afirika atawọn orilẹ-ede to ku diẹ kaa to fun lagbaye, awọn ọna miran yatọ si ileewosan ni awọn eeyan n lo fun igbẹbi nitori ọpọlọpọ ipenija ninu eyi ti ọda owo wa.
Iwadii ajọ UNICEF, WHO, UNFPA ati banki agbaye kan fi idi rẹ mulẹ pe ninu ẹgbẹrun lọna ọgọrun igbẹbi, o din diẹ ni ẹgbẹta ninu wọn ni kii ruu la.
Bakan naa si ni iwadi kan ti banki agbaye gbe sita lọdun 2011 fihan pe ida mọkandinlaadọta ninu ọgọrun un awọn to n bimọ lorilẹ-ede Naijiria lo jẹ wi pe kii ṣe ileewosan ni wọn bimọ si.
Nibayii, iyawo gomina ipinlẹ Ekiti, Bisi Fayẹmi ti rọ awọn obinrin nipinlẹ Ekiti lati yago fun bibimọ sile tabi si ọdọ awọn  agbẹbi agboole ati ibilẹ.
O ni ewu to wa ninu awọn igbẹbi bẹẹ kun ara wahala iṣoro igbẹbi ti awọn iwadii wọnyii gbe kalẹ.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ìwadìí gbogbo ń fi ìdí rẹ̀ múlẹ̀ pé ọ̀gọ̀ọ̀rọ̀ làwọn aboyún àti ọmọ wẹ́wẹ́ tó ń kú nítorí ìgbẹ̀bí lórílẹ̀èdè Nàìjíríà
O ni ko si idi fun obinrin kankan ni ipinlẹ Ekiti lati bi ọmọ sile tabi awọn ile agbẹbi ibilẹ.
Amọṣa bi a ba woo finifini, iṣẹ oun oṣi, aṣa ati iṣẹṣe tofi mọ aisi eto ilera alabọde kun ara ohun ti o n sun awọn aboyun lọ si ile igbẹbi ibilẹ.
O ni ipa gbogbo ni ijọba yoo sa lati rii pe eto ilera to mu irọrun dani wa larọwọto mutumuwa, paapaa julọ awọn obinrin ati ọmọ wẹwẹ.
ASUU ní ìjọba àpapọ̀ ni kò fẹ́ kí ìyanṣẹ́lódì àwọn o pari
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Àwọn olùkọ́ fásitì lórílẹ̀èdè Nàìjíríà bẹ̀rẹ̀ ìyanṣẹ́lódì nítorí àwọn àdéhun tí ìjọba àpapọ̀ kùnà láti mú ṣẹ
Iyanṣẹlodi ẹgbẹ olukọ fasiti lorilẹ-ede Naijiria ti wọ oṣu meji bayii.
Ọpọ awọn akẹkọ to yẹ ko ti kẹkọ gboye bayii ni irinajo wọn ti n fi ẹsẹ kan tiro bayii ti ọpọ akẹkọ atawọn obi si n ti pẹpẹ adura kan bọ si omiran nitori atiwọle pada awọn akẹkọ yii.
Nitori naa nigbati iroyin jade pe ijọba apapọ ti gbe N15.89 biliọnu silẹ gẹgẹ ara ohun ti awọn olukọ fasiti naa n ja fun, idunnu nla lo gba ọkan ọpọ.
Amọṣa ko daju pe idunnu to fi ẹsẹ rinlẹ ni eyi yoo jẹ nitori ASUU ti sọ laifọtape pe yatọ si  pe awọn ko tii mọ si owo ti wọn ni ijọba apapọ gbe silẹ naa, owo naa, to ba jẹ lootọ jinna si ohun ti o so adehun to wa laaarin awọn ati ijọba apapọ rọ.
Ninu ọrọ to ba BBC News Yoruba sọ aarẹ apapọ ẹgbẹ olukọ fasiti, ASUU lorilẹede Naijiria, Ọjọgbọn Biọdun Ogunyẹmi ṣalaye pe aijolootọ ijọba apapọ lori ijiroro to n waye lori imuṣẹ adehun eyi to fa iyanṣẹlodi naa.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ní oṣù kọkànlá ọdun 2018 ni àwọn olùkọ́ fásitì lórílẹ̀èdè Nàìjíríà bẹ̀rẹ̀ ìyanṣẹ́lódì
Ọjọgbọn Ogunyẹmi  ni ipele mẹta ni ohun ti awọn n ja fun wa. Owo ajẹẹlẹ owo oṣu fun awọn olukọ fasiti kan, owo fun atunṣe awọn fasiti, ati owo ajẹmọnu ti wọn pe earned Allowance. O ni ninu gbogbo ohun wọnyii eleyi ti wọn ni ijọba apapọ gbe kalẹ yii lo kere ju ati pe kii tilẹ n ṣe gbogbo fasiti lo kan.
Awa kọ lo n pagidina bi iyanju yoo ṣe de ba iyanṣẹlodi yii bi ko ṣe ijọba. A rii pe, n ṣe ni ijọba kan n ṣe lilọ bibọ loju kan naa lori awọn ijiroro wa gbogbo. Owo ti wọn ni ijọba gbe jade yii ko ja mọ ohunkohun ninu ohun gan an ti a n beere. Ijọba pẹlu si mọ eyii.
Ìwà ipá nínú ìdílé máa ń bí ìgè àti àdùbí ni tó lè já sí ikú
Nigba ti yoo dahun ibeere lori boya opin iyanṣẹlodi wọn wa nitosi, aarẹ apapọ ẹgbẹ olukọ fasiti lorilẹede Naijiria, ASUU ni ni bi ọrọ ṣe n lọ yii ko daju o nitori ijọba ko tii sunmọ ibeere adehun wọn.
Ko si igba kan ti a binu jade kuro nibi ipade wa pẹlu ijọba ṣugbọn ijọba apapọ ko jẹ olootọ si ijiroro pẹlu ASUU lori adehun yii. Ni temi o, ijọba apapọ gan an lo n fa iyanṣlodi yii siwaju.
NCAA: A fún àwọn adarí ní ọ̀sẹ̀ méjì si láti dá wọn lóhùn
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Murtala Muhammed international Airport 2
Àpapọ̀ àwọn òṣìṣẹ́ ẹka irina ofurufu iyẹn NUATE ati ATSSSAN ti fagile iyansẹlodi ti wọn sọ wi pe awọn yoo gunle ni Ọjọ Keji, Osu Kini, ọdun 2019.
Alaga ẹgbẹ osisẹ National Union of Air Transport Employee (NCAA), Paul Igene ni awọn da iyansẹlodi naa duro nitori pe awọn adari ẹka eto irina ofurufu pẹtu si wọn ninu wi pe awọn ti kọ iwe ransẹ si ile-isẹ irina, pẹlu adehun wi pe awọn yoo da wọn lohun laarin osẹ meji.
Laipẹ yii ni awọn oṣisẹ labẹ asia awọn oṣiṣẹ agba fun awọn to n pese iṣẹ lẹka ofurufu, ATSSSAN ati awọn oṣiṣẹ ẹka ofurufuru Naijiria, NUATE sọ fun awọn oniroyin nipa ipinnu wọn lati bẹrẹ iyanṣẹlodi lọjọ keji, oṣu kinni, ọdun 2019.
Awọn alaga ẹgbẹ mejeeji ni o ti to ọdun mẹta ti wọn ti ṣe ìgbega lẹnu iṣẹ f'awọn ọmọ ẹgbẹ awọn to wa labẹ akoso NCAA.
Lucky Izebhokun ti o jẹ alaga ATSSSAN ati Ayodele Sofolayan ti NUATE ni o to gẹ pẹlu bi wọn ti ṣe n ko iyan awọn ọmọ ẹgbẹ awọn kere.
Wọn ni o jẹ ohun ti o kọ ni lominu bi awọn alakoso NCAA ti ṣe ma n gbe awọn eeyan wa lati ita lati wa jẹ olori le awọn ọmọ ẹgbẹ awọn ti o kun ọju oṣunwọn.
Lucky Izebhokun ni awọn yoo jọ wọya ija pẹlu NCAA ti wọn ba kọ lati ṣe igbega lẹnu iṣẹ fun awọn ọmọ ẹgbẹ awọn ki ọdun 2018 to pari.
Lọdun 2018, awọn oṣisẹ ẹka ọkọ ofurufu gun le iyanṣelodi kan ti ikọ BBC Yoruba si ba awọn arinrinajo sọrọ ni papakọ ofurufu Murtala Muhammed l'Eko.
'Nígbà tí kò ṣeéṣe fún wa láti fò, a ó lọ́ wọkọ̀'
Ṣọla Allyson: Obìnrin tí kò bá rẹwà ni yóò máa ṣí ara sílẹ̀
Ikú Djxgee: DJsosogee ní olóògbé fẹ́ràn ẹbí àti ọmọ
Oríṣun àwòrán, @djxgee
Lẹyin ti okiki kan pe gbajugbaja aforin-danilaraya nibi ayẹyẹ, DJ Seun Ọmọgaji, ti ọpọ mọ si DJXGee ti gbẹmi ara rẹ lẹyin wakati diẹ to fi atẹjade kan sita lori ikanni ayelujara Instagram rẹ ni ọjọru, ọpọ awọn ilumọọka adanilaraya ni wọn ti n ṣe idaro rẹ.
Ninu awọn to ti ṣedaro rẹ ni awọn adẹrin poṣonu bii Alibaba, Bovi, Seyi law, Ushbebe ati bẹẹ bẹẹ lọ.
Amọṣa, ọkan lara awọn ọrọ rẹ, Moshood Abiọdun, ti ọpọ eeyan mọ si DJ Sosogee, ṣalaye fun BBC News Yoruba pe, eeyan ti o fẹran lati maa mu inu awọn eeyan to wa layika rẹ dun ni Djxgee.
DJXgee: DJSosogee, ọ̀rẹ́ DJXgee ṣàlàyé ìgbé ayé gbajúgbajà DJ to 'gbẹ̀mí ara rẹ̀'
O fikun pe o fẹran lati maa 'fi ibanujẹ ara rẹ sẹgbẹ kan lati mu inu awọn eeyan ti o ba ba pade dun.'
Sosogee ni oun ko ri idi kan fun Djxgee lati pa ara rẹ nitori iṣẹ to fẹran naa lo n ṣe, ti o si jẹ awokọṣe fun ọpọlọpọ awọn eeyan, paapaa julọ awọn aforin-danilaraya nibi ayẹyẹ, iyẹn DJ ẹgbẹ rẹ.
Mọrèmi: Ọọ̀ni ní láìsi Mọrèmi, kò leè sí ilẹ̀ Yorùbá
Amọ ju gbogbo rẹ lọ, DJ Sosogee ni ohun kan ti ko ṣee gbagbe ni pe, oloogbe DJXgee jẹ ẹni ti o fẹran awọn ọmọ rẹ gidigidi ti ko si fi ẹbi rẹ ṣere rara.
 O fẹran awọn ọmọ rẹ, bi ẹ ba wo awọn oju opo ayelujara rẹ gbogbo, ẹ o ba aworan awọn ọmọ rẹ nibẹ, bẹẹ naa lo jẹ ẹni to fẹran ẹbi, iyawo ati ọmọ rẹ gidigidi.
Amọṣa, DJ Sosogee ni oun ko lee sọ boya 'nitori iyawo rẹ fi ile silẹ tabi nitori awọn ẹbi rẹ toju bọ ọrọ wọn' lo ṣokunfa bi o ṣe gbẹmi arar rẹ.
Bakan naa, ninu ọrọ tirẹ, Afọlabi Ọlalekan to ni oun jẹ ọkan lara awọn akẹkọ to lọ si ileewe kan naa pẹlu oloogbe naa ṣalaye pe, eeyan ti o fẹran lati maa saapọn fun igbayegbadun awọn eeyan to ba wa ni ayika r ni Djxgee jẹ.
Olalekan sọ pe, DJXgee ni 'baba isalẹ' iyẹn 'School father' fun oun lasiko ti wọn wa ni ile iwe girama.
Papalolo ní ìlépa owó ni ìyàtọ̀ tó wà láàárín àwọn òṣèré tíátà àtijọ́ àti ìsisìnyí
Ẹwẹ, awọn sanmọri lagbo idanilaraya lorilẹede Naijiria pẹlu ti sọrọ nipa rẹ lori ikanni ayelujara.
Basket mouth to ṣapejuwe oloogbe naa gẹgẹ bii 'ẹjẹ'rẹ ati 'ọrẹ'rẹ sọrọ nipa awọn asiko manigbagbe ti wọn jumọ ni.
Bakan naa Seyilaw sapejuwe rẹ gẹgẹ bii ọrọ ti wọn jumọ lọ si ile iwe ti iṣẹ amuludun si tun pa wọn pọ daro rẹ. O ni awọn ṣi jọ wa pọ ni ọjọ abamẹta.
Adura gbogbo ọmọ Naijiria ni pe ki Ọlọrun da ẹmi awọn si lati se ọpọ ọdun laye ni kete taa wọ inu ọdun tuntun 2019.
Amọ eyi ko ri bẹẹ fun ọkunrin kan to gbajugbaja ninu isẹ gbogbo elere fun orin taka-sufe, Seun Ọmọgaji, taa mọ si DJ Xgee.
Ọjọ keji ọdun tuntun ni ọkunrin naa ge okun ẹmi ara rẹ kuru, to si gbe oogun apakokoro jẹ.
Bi o tilẹ jẹ pe ko si ẹni to lee sọ pato ohun to mu ko pa ara rẹ gẹgẹ bi o se kede lori Instagram, iroyin sọ pe iyawo rẹ, lo sadede ko kuro ninu ile fun-un, eyi to sokunfa orisun ibanujẹ nla fun.
Sugbọn ohun ara meeriri ti Djxgee se, ko to ki aye pe o digbose ni pe, o lọ si oju opo ikansira ẹni rẹ loju opo Instagram, to si kọ sibẹ pe, asọ funfun ni ohun fẹ kawọn eeyan wọ fi se ọfọ oun, tori oun ko nifẹ asọ dudu rara, o ni o duro fun asọ ọfọ.
Bakan naa lo tun dupẹ lọwọ gbogbo awọn eeyan to ti mu kii ẹrin pa ẹẹkẹ rẹ latẹyinwa, , to si tun n ki awọn ọmọ rẹ ni ọkọọkan pe oun nifẹ wọn, to fi mọ iya to bii.
Oríṣun àwòrán, @djxgee
"Iyatọ yoo ba ọna tawọn eeyan fi maa n se ẹyẹ ikẹyin fun ololufẹ wọn to ba rekọja lọ.... Asọ dudu duro fun ibanujẹ, sugbọn fun ti emi, asọ funfun ni kẹ wọ, tori mo nifẹ asọ funfun pupọ̀.
Fun gbogbo ẹyin ti mo ti pa rẹrin ri, ati ẹyin ti mo ti mu binu, ẹ gba pe ẹlẹran ara ni mi. Ẹnikorewa, mo nifẹ rẹ pupọ, Ẹniayọ, orukọ rẹ ti salaye ọrọ, iwọ gan ni orisun ayọ mi.
Ọmọbọlanle Ajọkẹ, se o mọ pe mo naani rẹ..... Moradekẹ iya mi, Ọlọrun yoo wo ọgbẹ ọkan yin san ati awọn ana mi. Ki Ọlọrun bu kun yin ni gbogbo igba."
Àṣà Yorùbá: Èèwọ̀ ni kí obìnrin wọ igbó orò
Oríṣun àwòrán, @Khemeticchurch
Àwọn àṣà àti ìse tó yọ obìnrin sílẹ̀ nílẹ̀ Yorùbá
Ni ilẹ́ Yoruba, oniruuru asa, ise ati igbagbọ lo wa, eyi ti o de awọn obinrin lati mase kopa ninu rẹ.
Ọpọ awọn asa yii ni awọn asaaju wa n lo lati se akoso awujọ wa, ki ohun gbogbo lee tuba-tusẹ nitori ilu ti ko ba si ofin, ẹsẹ ko si nibẹ.
Nigba miran, o si lee jẹ pe awọn orisa lo tako awọn iwa naa lati ọdọ awọn obinrin.
Laye ode oni, awọn asa ati ise aye atijọ naa ni ofin ode oni tako, ti a ko si fi bẹẹ naani wọn mọ.
Bi o tilẹ́ jẹ pe aye ti laju, ti ọpọ awọn asa ati ise yii si ti n lọ sokun igbagbe, sibẹ ọpọ wọn lo ni anfaani, iwulo ati awọn aleebu kọọkan ninu rẹ.
Mọrèmi: Ọọ̀ni ní láìsi Mọrèmi, kò leè sí ilẹ̀ Yorùbá
Àwọn asa ati ise ti obinrin ko gbọdọ gunle nilẹ Yoruba:
Àwọn nǹkan tí obìnrin lè ṣe pẹ̀lú olólùfẹ́ oníwà ipá lásìkò ìgbélé Coronavirus yìí
Coronavirus: Ǹjẹ́ àwọn dókítà tó ń tọ́jú eyín ń ṣisẹ́ lásìkò pàjáwìrì? Àti àwọn ìbéèrè míràn
Coronavirus: Kíni àwọn àmì tuntun tó n fihàn?
Owó ìtanràn N40,000 ni mo san nítorí pé mí ò wọ ìbòmú- Vincent
Sogidi Lake: Kòṣẹja-kòṣèèyàn lá bá nínú adágún odò náà -Ojedele
Kíni ìwọ mọ̀ nípa Funmilayọ Ransome-Kuti?
Ẹfunsetan Aniwura, obìnrin tó ju ọkùnrin lọ
Hubert Ogunde rèé, baba àwọn òsèré tíátà
Kí lo fẹ́ mọ̀ nípa ‘Ajala Travels’?
Wòlíì Kasali ní Dolapo Awosika kò lé ìyàwó òun jáde
Oríṣun àwòrán, @jide2816
Lootọ ni awọn asa ati ise yii pọ lọ jantirẹrẹ, bo si se wa fawọn obinrin, naa ni tawọn ọkunrin wa, ti gbogbo awujọ ilẹ Yoruba si ni awọn eewọ to n dari wọn, nitori idalu ni iselu.
Sugbọn o yẹ ko ye wa pe awọn ara ijọhun gbọn pupọ, o si ni idi ti wọn se gbe awọn eewọ yii kalẹ lati dari awujọ wa, eyi ti ọpọ wọn wa fun aabo lọwọ ewu.
2019 Elections: Ìpàdé ìtagbangba BBC Yorùba ń ṣẹlẹ̀ ní gbọ̀ngàn fásitì ìlú Ilorin
Ipade itagbangba
Nibayii ti eto idibo gbogbo gboo n kanlẹkun gbọn-gbọn ni orilẹ-ede Naijiria, oniruuru aayan ni ileesẹ BBC Yoruba ti n ṣe lati rii daju pe awọn araalu ni anfaani lati yan aarẹ, awọn gomina ati awọn aṣofin to pegede, fi gbọọrọ jẹka.
Yatọ si pe a n kede awọn iroyin nipa eto idibo to n bọ naa loore-koore, BBC Yoruba ti ṣeto lati ṣe ariyanjiyan fawọn eeyan to n dije lati du ipo gomina ninu eto idibo naa, paapa awọn to wa lẹkun ilẹ Oodua.
Ipinlẹ Kwara làkọ́kọ́, lónìí sì ni yóò wáyé gẹ́gẹ́ bí BBC Yoruba ti ṣide ipade itagbangba naa, nibi ti eto ariyanjiyan yoo ti waye laarin awọn oludije latinu ẹgbẹ oselu marun un tawọn eeyan nifẹ si.
Kwara yóò gbàlejò BBC Yoruba
Inu ọgba fasiti Ilọrin ni eto naa yoo ti waye ni Ọjọbọ, ọjọ kẹwaa, osu Kinni, ọdun 2019.
Oríṣun àwòrán, Razak Atunwa
Saaju ka to mu awọn oludije latinu ẹgbẹ oṣelu maraarun naa, ni BBC Yoruba ti kọkọ beere ero awọn araalu ni ipinlẹ kọọkan, nipa awọn ẹgbẹ oṣelu marun ti wọn gbaju-gbaja julọ ninu gbogbo ẹgbẹ oṣelu to wa lorilẹede yii, ti wọn n fẹ ki awọn oludije wọn kopa ninu ariyanjiyan naa.
Oríṣun àwòrán, @Ayorinde Adedoyin
Awọn ẹgbẹ oselu marun un to lewaju ni ẹgbẹ oselu PDP, APC, Accord, Labour ati ANRP.
Nitori naa, awọn asoju ẹgbẹ oselu maraarun, ni ireti wa pe yoo kopa ninu eto ipade ita gbangba naa, iyẹn Ọmọọba Ayọrinde Adedoyin ti ẹgbẹ oṣelu Accord, Alhaji Abdulrazak Abdulrahman, ti ẹgbẹ oṣelu APC ati Komuredi issa Arẹmu, ti ẹgbẹ oṣelu Labour.
Oríṣun àwòrán, @Abdulrazak Abdulrahman
Awọn iyoku ni Asofin Abdulrasak Atunwa, ti ẹgbẹ oṣelu PDP, ati Ọmọwe Abdulmunin Yinka Ajia, ti ẹgbé oṣelu ANRP.
Oríṣun àwòrán, @Issa Aremu
BBC Yoruba wa n kesi awọn eeyan ipinlẹ Kwara to ba nifẹ lati peju sibi ipade ita gbangba naa pe, ki wọn lọ fi orukọ wọn silẹ lori ikanni isalẹ yii.
https://bit.ly/2rHOXzO
Oríṣun àwòrán, Yinka Ajia
Ẹ ku oju lọna ipade yii o pẹlu BBC Yoruba!
Minimum wage: NLC ní Gómìnà tí kò bá san ẹ̀kúnwó oṣù ń tàpá sí òfin Nàìjíríà
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ẹgbẹ́ òṣìṣẹ́ ní ẹ̀ṣẹ̀ tó la ìyọnípò kúrò lọ fáwọn gómìnà ni bí wọ́n bá kùnà láti san ẹ̀kúnwó oṣù tuntun fún òṣìṣẹ́
Ẹgbẹ oṣiṣẹ ti ni ko si idi fun awọn gomina to ba ni awọn ko lee san ẹkunwo oṣu tuntun fawọn oṣiṣẹ lati ṣi maa wa nipo.
Ẹgbẹ oṣiṣẹ ṣalaye pe, gomina yowu to ba ni oun ko lee san ẹkunwo oṣu tuntun naa, n tapa si iwe ofin orilẹede Naijiria, eyi ti wọn bura lati maa tẹlẹ ni tiku-tiye.
Akọwe agba fun ẹgbẹ oṣiṣẹ NLC lorilẹede Naijiria, Peter Ozo-Eson ṣalaye pe, ilakalẹ ofin ni sisan owo oṣu tuntun fun oṣiṣẹ, atipe gomina ipinlẹ to ba nipa lati san ju bẹẹ lọ lee san an.
Ẹgbẹ oṣiṣẹ ko ṣetan lati gbẹyin bẹbọjẹ lori eto idibo apapọ to n bọ lọna. A ti bẹrẹ ọrọ lori ẹkunwo oṣu tuntun yii fun ọdun meji, nitorinaa, eeyan kan ko lee wa maa halẹ mọ wa pe a fẹ da ilana idibo ru.
Mọrèmi: Ọọ̀ni ní láìsi Mọrèmi, kò leè sí ilẹ̀ Yorùbá
Ẹgbẹ oṣiṣẹ NLC ni bi ohunkohun ba ṣe eto idibo apapọ ọdun 2019, ijọba apapọ ni ki awọn araalu o dimu.
Ẹgbẹ́ òṣìṣẹ́ fi kun pe, ẹ̀ṣẹ̀ tó la ìyọnípò kúrò lọ fáwọn gómìnà ni bí wọ́n bá kùnà láti san ẹ̀kúnwó oṣù tuntun fún òṣìṣẹ́.
Boko Haram: Bàlúù ogun Nàìjíríà kan ti já lójú ìjà pẹ̀lú Boko Haram
Oríṣun àwòrán, NAF
Iléeṣẹ́ ogun òfúrufú Nàìjíríà kò tíì sọ ní pàtó bóyá àwọn ikọ̀ Boko Haram ló já bàlúù náà tàbí ó ṣe aṣemáṣe
Ilé iṣẹ́ ogun oju ofurufu Naijiria ti sọ pe ọmọ ogun marun-un lo ti ku ninu baluu awọn ọmọ ogun ofurufu to ja nirọlẹ ọjọru lẹkun ila oorun ariwa orilẹede Naijiria.
Eyi ṣẹlẹ nigba ti awọn ọmọ ogun n koju ẹgbẹ Boko Haram ni agbegbe Damasak lẹba ibode Naijiria pẹlu orilẹede Niger.
Ọrọ kan ti agbẹnusọ ile iṣẹ ogun ofurufu fi sita jẹ ko di mimọ pe wọn ti ri oku wọn. Ẹwẹ, ko ṣi tii si aridaju ohun to fa ijamba inu afẹfẹ naa.
Baalu ogun naa, eleyi ti wọn ni o wa lara awọn baalu ogun ti wọn n lo fi kọju ija sawọn agbebọn Boko Haram, ja lasiko ti ina ogun nlọ lakọlakọ laarin awọn ọmọ ogun Naijiria atawọn agbebọn Boko Haram.
Ninu atẹjade kan eyi ti ileeṣẹ ọmọogun ofurufu orilẹede Naijiria fi sita, baluu naa n ṣe atilẹyin fawọn ọmọogun oriilẹ ti wọn n doju kọ awọn ikọ Boko Haram kan lagbegbe Damasak nitosi aala orilẹede Naijiria pẹlu Niger.
Ileeṣẹ ọmọogun ofurufu ṣi n beere ibeere lori ohun to ṣokunfa jija ti baluu ogun na ja.
Mọrèmi: Ọọ̀ni ní láìsi Mọrèmi, kò leè sí ilẹ̀ Yorùbá
Itaporogan laarin awọn ọmọogun atawọn ikọ Boko haram lẹnu lọwọlọwọ yii n gbona janjan eleyii to si ti ṣokunfa iku ọpọ awọn ọmọogun, ti awọn eeyan naa si tun ti ko nnkan ogun wọn lọ.
Ẹbí Melaye: Ẹ̀rù ń bá wá lóri ilera Dino, ìgbésẹ̀ ọlọ́páà sì jẹ́ ìpálara fún
Oríṣun àwòrán, @Dino Melaye
Dino Melaye ni ikọ́ sẹ́mìí-sẹmìí- Ebi Dino
Ile ẹjọ giga kan labuja ti fagile ẹbẹ agbejoro Sẹnetọ Dino Melaye pe ki awọn ọlọpaa kuro niwaju ile rẹ.
Idajọ yi wa ni idahun si ẹbẹ ti agbẹjọro rẹ Nkem Okoro  gbe lọ si iwaju adajọ N.E Maha pe ki ile ẹjọ paṣẹ ki awọn ọlọpaa ye dun koko mọ Dino Melaye ki wọn si jẹ ki awọn mọlẹbi rẹ lanfaani ati ri.
Adajọ N.E Maha kọ lati gbọ ẹjọ lori ọrọ yi ti o si ni ohun yoo nawọ ẹjọ naa si adajọ agba lati gbe fun adajọ miran nitori pe isinmi ọdọọdun ohun yoo pari ni ọjọ kẹrin osu kini.
Amọ ṣa bí ọjọ́ ṣe ń gorí ọjọ, tí ilé iṣẹ́ ọlọ́pàá si ń gbìyànjú láti mú sẹnatọ Dino Melaye si àhámọ́ wọn, àwọn ẹbi Dino ti ké gbàjare pé, ibi ti ọ̀rọ̀ ń lọ yii, ẹrú ilera Dino ń bà awọn lẹ́rù.
Lásìkò tí àbúrò Sẹnatọ Dino, Bolarinwa Moses Melaye bá BBC Yorùbá sọ̀rọ̀ lóri ẹ̀rọ ìbánisọ̀rọ̀, ó sàlàyé pé àwọn ò mọ ibi ti ẹgbọ́n àwọn wà, àti pé àwọn ìgbésẹ̀ ti ọlọ́páà ń gbé le jẹ́ ìpálara fún ilera ẹgbọ́n òun.
Mọrèmi: Ọọ̀ni ní láìsi Mọrèmi, kò leè sí ilẹ̀ Yorùbá
Bolarinwa ní, yàtọ sí ẹgbọ́n oun, gbogbo àwọn olùgbé ilé náà ni wọn ti ti mọ ìtá, wọn fi ṣẹ́kẹ́sẹkẹ̀ sí ọwọ ẹni tó ń sọ ẹnu ọ̀nà ilé náà, àti pé, ìyá àwọn to jẹ́ aláìlera pẹ̀lú kò ri ọ̀nà wọlé.
O ni títí di àsìkò yìí, kò sí ọ̀nà láti bá ẹgbọ́n àwọn sọ̀rọ̀.
Nígbà ti àkọròyìn BBC Yoruba bèèrè nípa gbogbo àwọn ọ̀rọ̀ tí wọn ń tẹ̀ ránṣẹ́ loju opo twitter Dino, ó sàlàyé pé kò sí àrídájú pé sẹnátọ Dino fúnra rẹ̀ ló ń tẹ jáde.
Ohùn Bolarinwa tó jẹ́ àbúrò Sẹnatọ Dino Melaye rèé:
Ẹ̀rù ń bá wá lóri ilera sẹnatọ Dino Melaye
Bákàn náà ló tun sọ fún BBC yoruba pé, ẹgbọ́n òun ni àìsàn ikọ́ sémìí-semìí ( Asthma) àti pé, kò lè dúró pẹ́ nínú ilé tí wọn ti já iná rẹ, tí wọn sì tún ti gbogbo rẹ̀ pa.
O ní ìlera sẹnatọ, jijẹ àti mimu, pẹ̀lú ìléra rẹ̀ ló jẹ àwọn lógún báyìí.
Yomi Fabiyi: Èmi ti dáríjì ẹ́, kí ìwọ náà jọ̀wọ́ dáríjì mí
Oríṣun àwòrán, Instagram
Ìjà yíí bẹ̀rẹ̀ ní ǹkan bí ọdún díẹ̀ sẹ́yìn lẹ́yìn tí Yomi Fabiyi pe Toyin Abraham ní alágàbàgebè nítorí ìjà pẹ̀lú Mercy Aigbe.
Gbajugbaja osere, Yomi Fabiyi ti kesi akẹgbẹ rẹ, Toyin Abraham wi pe ki wọn pari ija to wa laarin awọn mejeeji.
Yomi Fabiyi tọrọ idariji lọwọ Toyin Abraham lori ẹrọ ikansiraẹni Instagram rẹ, ki Toyin si fọwọ wọnu ninu ọdun tuntun.
Fabiyi fi kun un wi pe gbogbo ẹṣẹ ti Toyin ṣẹ oun ni oun ti dariji, ki Toyin naa ṣe bakan naa, ki ohun gbogbo si pada si ipo laarin wọn.
Ti a ko ba gbagbe, ija laarin Toyin Abraham ati Yomi Fabiyi bẹrẹ ni nkan bii ọdun diẹ sẹyin, lẹyin ti Yomi Fabiyi pe Toyin Abraham ni alagabagebe nitori ija to wa laaarin Toyin Abraham ati oṣerebinrin miiran, Mercy Aigbe.
ASUU Strike: Irọ̀ ni pé ìjọba fún wa ní owó tó tó N15.89bn
Oríṣun àwòrán, Twitter
Ẹgbẹ awọn Olukọ Fasiti, ASSU ti ni awọn ko mọ nkankan nipa owo to le ni biliọnu mẹẹdogun ti iroyin ni wọn fun ile ẹkọ giga fasiti.
ASSU sọ eyi lẹyin ti wọn gunle iyansẹlodi lati osu meji sẹhin lori ẹsun pe ijọba ko san awọn owo ajẹmọnu wọn ati awọn owo osu ti wọn jẹ awọn olukọ.
Aarẹ ẹgbẹ ASSU, Ọjogbon Biodun Ogunyemi lo fi eleyii lede ni ipinlẹ Eko lasiko to n ba awọn oniroyin sọrọ.
Ogunyẹmi fikun un wi pe lootọ ni minisita fun ọrọ osisẹ pe oun lori aago pe awọn ti gbe igbesẹ lori iyansẹlodi wọn, amọ o ni oun ko mọ iru igbesẹ ti ijọba gbe.
Aarẹ ẹgbẹ ASSU ni minisita naa ni ijiroro ati ipade yoo waye ni Ọjọ Aje, ọsẹ to n bọ.
Wòlíì Kasali sọrọ nípa awuyewuye pé o lè ìyàwó rẹ̀ jáde nílé
Lagos-Ibadan Rail: Amaechi ní ojú irin Ìjú Àgbàdo gbọdọ̀ se rìn láìpẹ́
Rotimi Amaechi ti ní òun yóò wá dán ojú irin náà wò láti mọ ibi tí wọ́n bá isẹ́ dé ní Ọjọ́ Kẹrìnlá, Osu Kini, ọdun 2019.
Minisita fun Eto Irina, Rotimi Amaechi ti pasẹ fun awọn osisẹ to n la oju irin Eko silu Ibadan, CCECC lati ri daju wi pe, wọn pari ọna reluwe naa laarin ọsẹ meji.
Amaechi pa asẹ yii ni Ọjọbo lasiko to n wọ ọkọ reluwe lori oju irin Ibadan si Eko ti wọn n se lọwọ, eyi ti yoo gba Abeokuta, Ibadan ati Eko.
O wa rọ ile isẹ ilẹ China to n se oju ọna naa lati mura si isẹ, ki oju irin naa le see gba fun awọn osisẹ to n sisẹ ni agbeegbe iju ni ilu Eko ati Agbado ni ipinlẹ Ogun.
Ìgunnukó: Àwọn Tápà gbà pé ẹni tó bá ń sin Ìgunnukó kò ní ráùn ohun rere
Minisita fun eto irina naa fikun wi pe, oun n pada bọ fun ayẹwo oju irin naa ni Ọjọ Kẹrinla, Osu Kini, ọdun 2019, lati ri daju pe won ti pari ọna naa.
Lori ọna oju irin ti Itakpe si Warri, Amaechi ni, o di Osu Karun ọdun yii ki wọn to pari oju irin naa, lati bẹrẹ si ni gbe awọn eniyan.
PDP: A ò fẹ́ ẹ̀jẹ̀ Buhari gẹ́gẹ́ bí alábojútó ìbò kíkà
Oríṣun àwòrán, INEC OFFICIAL
Ọjọgbọn Mahmoud Yakubu pẹlu Amina Zakari
Ẹgbẹ òṣèlú Peoples Democratic Party (PDP) ti ní awọn kọ bi wọn ṣe yan Amina Zakari to jẹ ọmọ sí ọmọ iya aarẹ Buhari gẹgẹ bi alaga igbimọ ti yoo ka ibo to n bọ lọna ni Naijiria.
Ẹgbẹ oṣelu naa ni bi ajọ eleto idibo ba fi le ṣe eyi, a jẹ pe alaga ajọ naa, Ọjọgbọn Mahmoud Yakubu n san ọna ati wọle pada fun aarẹ ni.
Bakan naa, ẹgbẹ oṣelu PDP fi sita loju opo Twitter wọn pe awọn fi gbogbo ẹnu sọ ọ pe awọn kọ yiyan sipo Amina Zakari to jẹ̀ ẹjẹ aarẹ Muhammadu Buhari ninu idibo kan naa ti Buhari ti jẹ oludije.
Kola Ọlọgbọndiyan to jẹ adari ẹka iroyin fun igbimọ ipolongo idibo ẹgbẹ naa sọ fun awọn oniroyin nibi ipade apero ti wọn ṣe peawọn ko gba  Zakari to jẹ kọmisna ajọ eleto idibo to nboju to eto ilera ati itọju nitori ọpọlọpọ ẹsun to ti wa lọrun rẹ.
Mọrèmi: Ọọ̀ni ní láìsi Mọrèmi, kò leè sí ilẹ̀ Yorùbá
Nigeria Swearing in 2019: Kà nípa gómìnà tuntun ni Kwara
Ìlú Ilọrin ni a ti bí Abdulrahman Abdulrazaq tó jẹ́ onísòwò epo pàtàkì tí bàbá rẹ̀ sì jẹ́ agbẹjọ́rò pàtàkì ní àríwá Nàìjíríà.
Nínú àwọn ọmọ ìya rẹ̀ ni sínátọ̀ tó ṣe ojú Abuja nílé asòfin àgbà nígbà kan rí, Khairat Abdulrazaq-Gwadabe.
Abdulrahman jẹ́ olùdíje gómìnà Kwara kan sọsọ tí kò ní ìbaṣepọ̀ pẹ̀lú ìdílé Saraki láti ìgbà tí Nààjíríà ti padà sí ìlànà ijọba awa ara wa ní ọdún 1999.
Eléyìí le jẹ́ ọnà àtìlẹyìn fún un tàbí kó jẹ́ ìdàkejì rẹ̀ . Ọ̀rọ̀ náà wà lórí bí àwọn èèyàn Kwara bá ṣe dìbò.
Láti ìgbà tí Nàìjíríà ti padà sí ìlànà Democracy, ni Abdulrahman àti ọmọ ìya rẹ̀, Alimi Abdulrahman, ti ń gbìyànjú láti gba agbára ìṣèjọba kúrò lọ́wọ́ ìdílé Saraki.
Oríṣun àwòrán, Twitter/@RealAARahman
Ọjọ́ ti pẹ́ tí Abddulraman ti dá ilé iṣe alágbàta epo ọkọ̀, First Fuels Limited sílẹ̀, ilé iṣé náà jẹ́  gbajúmọ̀ lórí ọrọ̀ epo ọkọ̀ ní gúúsù iwò oòrùn Nàìjíríà, tó jẹ́ ilẹ̀ Yorùbá.
Ọ̀pọ̀ àwọn ọ̀dọ́ onísòwò ló ti jẹ àǹfàní lára rẹ̀. Nínú wọn ni Tonye Cole, Ade Shounbi, Ade Odunsi àti Omamofe Boye àti bẹ́ẹ̀-bẹ́ẹ̀ lọ.
Abdulrahman ti du ipò gómìnà Kwara rí ní ọdún 2011 l'ábẹ́ àsìyá ẹgbẹ́ CPC àná, ṣùgbọ́n Abdulfatah Ahmed ti ẹgbẹ́ PDP lo di gómìná ìpínlẹ̀ náà l'ọ́dún náà.
Sugbọn ni ọdun 2019, lasiko ibo gomina to waye ni ipinlẹ Kwara, Abdulrahman Abdulrazaq jawe olubori, gẹgẹ bii gomina ipinlẹ Kwara lọjọ Kẹsan, osu Kẹta.
Ọjọru, ọjọ Kọkandinlọgbọn, oṣu Karun ọdun yii kanna si ni wọn bura fun gẹgẹ bii gomina alasẹ ipinlẹ Kwara.
EFCC: Á sọ iye èèyàn ta rán lẹ́wọ̀n di ìlọ́po méjì ní 2019
Oríṣun àwòrán, @officialEFCC
Adele alaga fun ajọ EFCC, Ibrahim Magu ti n leri, leka, to si n fi ọwọ sọya pe, mariwo lasan lawọn ọmọ Naijiria ri, nidi iye eeyan ti ajọ EFCC ran lọ sẹwọn lọdun 2018.
Magu wa kede pe egungun si n bọ lẹyin rẹ ninu ọdun 2019, tori ọpọ eeyan to jẹ oniwa ibajẹ si lawọn yoo ri daju pe o da asọ ẹwọn bora.
Gẹgẹ bi agbẹnusọ fun ajọ EFCC, Tony Orilade, to gbẹnu Magu sọrọ ti wi, ajọ naa ti n se afikun aayan ri lati ri daju pe oun sọiye eeyan ti yoo lọ swọn ni 2019 di ilọpo meji awọn eeyan ti ajọ naa ran lẹwọn lọdun to kọja.
Ìgunnukó: Àwọn Tápà gbà pé ẹni tó bá ń sin Ìgunnukó kò ní ráùn ohun rere
"Eeyan okoolelọọdunrun o din mẹjọ (312) pere la ni ko lọ naju ni ọgba ẹwọn lọdun 2018, am ni 2019 ta wa yii, ajọ EFCC yoo ri daju pe a sọ iye awọn taa ju sẹwọn di okoolelẹgbẹta ati mẹrin (624).
Magu, ẹni to kede bẹẹ lasiko to n bawọn osisẹ ajọ naa sọrọ nigba to n rin yika inu ọọfisi ajọ EFCC, o tun fi kun pe, ajọ EFCC ti gba idajọ mẹta ninu ọdun tuntun taa bẹrẹ yii, eyi to ni o jẹ ibẹrẹ to dara.
Oríṣun àwòrán, @officialEFCC
Nigba to n gbosuba fun adajọ agba lorilẹede yii, Walter Onnoghen fun aseyọri rẹ lọdun to kọja, Magu ko sai yan pe ẹka eto idajọ ni kọkọrọ ti EFCC lo lati bori ọpọ ẹjọ to wa niwaju rẹ.
Amina Zakari: INEC ní Amina Zakari kọ́ ni yóò wà ní ìdí ìbò kíkà lásìkò ìdìbò 2019
Oríṣun àwòrán, INEC
Ìgbàkejì nìyí tí ìyànsípò Amina Zakari yóò máa fa awuyewuye lórílẹ̀èdè Nàìjíríà nítorí àhesọ ọ̀rọ̀ pé ó tan mọ́ Ààrẹ Buhari
Ajọ INEC ti sọrọ lori awuyewuye to n ja ranyinranyin lori iyansipo Amina Zakari gẹgẹ bi olori igbimọ ibudo ikabo aarẹ ti yoo waye loṣu keji ọdun 2019.
Ọpọ awọn eeyan pẹlawọn ẹgbẹ alatako gbogbo ni wọn ti tako iyansipo Amina Zakari ti o jẹ ana fun Buhari.
Amọṣa, oludari ipolongo ati idanilẹkọ lajọ INEC, Oluwọle Osaze-Uzzi ṣalaye fun BBC News Yoruba pe ko si nnkan ti o kan Hajia Zakari pẹlu ibo kika ni ipo tuntun ti wọn ṣẹṣẹ yan an si naa.
Ọgbẹni Osaze-Uzzi to jẹ agbẹnusọ fun ajọ INEC ṣalaye pe ojuṣe igbimọ ti wọn fi Amina Zakari ṣe olori fun ni lati ṣaayan eto gbogbo fun lilọ wọọrọwọ eto ibo kika ati pe Alaga ajọ naa ni Ọga agba patapata lori eto ibo kika ti ko si si ohun kan ti o lee yii pada.
Aini imọ to kunna lori igbimọ yii lo n fa gbọyi-sọyi ati awuyewuye to n waye naa"", Osaze-Uzzi ṣalaye fun BBC News Yoruba."
Ojuṣe igbimọ ti alaga ajọ yii fi arabinrin Amina Zakari ṣe olori fun ni lati rii pe gbọngan ti wọn yoo lo fun ibo kika wa ni sẹpẹ, gbogbo eto ati ohun elo ti wọn yoo lo nibẹ pẹlu bii eto abo, ohun elo ayelujara ati bẹẹ bẹẹ wa ni sẹpẹ lai si idiwọ. Ko si ohun to kan an pẹlu ibo kika nitori ojuṣe alaga ajọ INEC niyẹn.
O ni arabinrin Zakari kun oju iwọn lati di ipo yii mu nitori ọkan lara awọn ọmọ igbimọ alakoso ajọ INEC ni ti kii sii ṣe oni lo ti wa nibẹ.
O wa fi da awọn ọmọ orilẹede Naijiria loju pe eera kan ko ni rin ibo wọn nitori ajọ naa ṣetan lati rii pe eto idibo apapọ ọdun 2019 kẹsẹjari.
Ọrọ iyansipo Amina Zakari gẹgẹ bii alamojuto ibudo ikabo fun ọdun 2019 ti n fa ọpọ awuyewuye lati igba ti ajọ INEC ti kede rẹ ni ọjọbọ.
Ohun ti ọpọ si n ke ibosi le lori naa ni pe, arabinrin Amina Zakari tan mọ aarẹ Muhammadu Buhari, ọkan lara awọn eeyan ti yoo dije fun ipo aarẹ lorilẹede Naijiria ni ọjọ kẹrindinlogun oṣu keji, ọdun 2019.
Ìgunnukó: Àwọn Tápà gbà pé ẹni tó bá ń sin Ìgunnukó kò ní ráùn ohun rere
Ohun ti wọn n sọ ni pe, ko tọna labẹ ilana pin in re-la a re, ọkan ko gbọdọ jukan lọ pe, ki ibatan oludije kan tun lọwọ ninu eto kika ibo ti o ti n kopa.
Bi o tilẹ jẹ wi pe, alaga ajọ INEC lo laṣẹ lati ṣeto iyansipo ajọ naa, ti o si jẹ pe oun lo ṣe eto iyansipo tuntun yii, aarẹ Buhari ko lagbara rẹ labẹ ofin lati yii pada.
Amọ sibẹ awọn eeyan ati onwoye ko yee sọrọ lori ipa ti o ṣee ṣe ki igbesẹ yii ni, lori oju ti awọn eeyan yoo fi wo abajade eto idibo apapọ naa.
Oríṣun àwòrán, INEC
Oniruuru iha lawọn eeyan, lẹgbẹlẹgbẹ, ati lajọlajọ ti sọ lori igbesẹ yii
Boya ka bi ara wa leere ibeere yii; bawo gan ni Amina Zakari ṣe tan mọ Buhari?
Bi o ba ri bẹẹ, bawo wa ni Zakari ati Buhari ṣe wa tan ?
Kwara yóò gbàlejò BBC Yoruba
Oniruuru iha lawọn eeyan, lẹgbẹlẹgbẹ, ati lajọlajọ ti sọ lori igbesẹ yii.
Gomina ana ni ipinlẹ Ekiti, Ayọdele Fayoṣe ni 'boya ki wọn kuku yan ọmọ aarẹ gẹgẹ bii  alaga ajọ eleto idibo INEC?'
Gbajugbaja oniroyin, Dele Momodu ni tirẹ ṣalaye lori ikanni twitter rẹ pe '...Haba!'
Ohun ti Dokita Rafiq Raji ati Ajibade Adegbitẹ fi ṣakawe rẹ ni tiwọn ni pe '...igbesẹ ti ko bojumu ni eyi.'
Nollywood: Bàbá Sàlá, Ọmọgé Campus, Ajimajasan àtàwọn òṣèré mí ì jáde láyé ní 2018
Bi o ṣe jẹ pe ilakak lati dun ara ilu ninu lawọn oṣere sinima n le, ọdun 2018 mu ọpọ awọn eekan kan lọ ni lagbo naa lọdun 2018.
Bi o tilẹ pe awọn kan ni aarin wọn dagba, wọn dogbo, amọ iku awọn miran ninu wọn jẹ agbọ-sọ-gbanu.
Eyi ni awọn oṣere sinima ede Yoruba ti wọn ku ni ọdun 2018.
Ayẹyẹ ikẹyin fun Baba Sala
Ni irọlẹ, ọjọ aiku ọjọ keje oṣu kẹwa ọdun 2018 ni alagba Moses Adejumọ ti ọpọ eeyan mọ si baba sala jade laye.
Ọmọ ọdun mẹtalelọgọrin, 83 ni ki o to jade laye.
Oríṣun àwòrán, leadership
Ọjọ keje oṣu kẹwa ọdun 2018 ni alagba Moses Adejumọ ti ọpọ eeyan mọ si baba sala jade laye
Ko si eeyan to lee kọ iyan Baba sala kere lagbo orin, itan kikọ, ere itage ati sinima paapaa julọ ka pani lẹrin.
Ni ọjọ aje ọjọ kẹjọ, oṣu kẹwa ni ọmọ rẹ tufọ rẹ faye.
Oríṣun àwòrán, AISHAT ABIMBOLA/FACEBOOK
Aishat Abimbola jáde láyé lẹ́yin tí ó ní ààrùn jẹjẹrẹ ọyàn
Ọmọge campus ni ọpọ mọ Aishat Abimbọla si nigba aye rẹ. Inu sinima kan to ṣe pẹlu orukọ yii, si ni inagijẹ naa ti jade fun un.
Lasiko to fi n gba itọju fun aisan jẹjẹrẹ lo jade laye ni orilẹede Canada.
Ẹni ọdun mẹrindinlaadọta ni nigba to jade laye ni ọjọ Iṣẹgun, ọjọ Karundinlogun oṣu Karun ọdun 2018 ni ilu Toronto.
Oríṣun àwòrán, Kola Carew Facebook
Ọkan lara awọn ere ti Tunrayọ Adeoye se, to fi di ilumọọka ni fiimu kan ti wọn pe ni Igbekun.
Ọkan lara awọn agba ọjẹ sinima Yoruba ni Motunrayọ Adeoye, owurọ ọjọ kinni, oṣu kẹfa ọdun 2018 lo faye silẹ lẹyin aisan ọgbẹ inu.
Mama Adeoye, gẹgẹ bi ọpọ ṣe n pee nigba aye rẹ jẹ aburo Alaafin ilu Ọyọ. Ipa ti o ko ninu sinima ‘Igbekun’ ti Kunle Afod ṣe, lo gbe han faye.
Ile rẹ to wa ni adugbo Akobọ Ojurin nilu Ibadan, ni wọn sin si.
Ere ọlọsọọsẹ ni o mu ki Ajimajaṣan o di gbajugbaja
Ni ọjọ kejidinlogun oṣu kẹwa ọdun 2018 ni alagba Ọla Ọmọnitan ti ọpọ mọ si Ajimajaṣan jade laye.
Ẹni Ọgọrin ọdun ni alagba naa ki o to dagbere laye.
Ṣaaju ọjọ ti o ku ni o ti lọ gba itọju ni ileewosan.
Ere ọlọsọọsẹ ni o mu ki Ajimajaṣan o di gbajugbaja.
Remi Surutu: Tilu - tifọn ni ayẹyẹ ìdána ọmọbìnrin rẹ fi wáyé
Oríṣun àwòrán, Instagram/@therealremisurutu
Bii ọdun melo kan ṣẹyin ni osere tiata, Remi Surutu padanu ọmọ kan
Yoruba bọ wọn ni bi ẹkun pẹ titi di alẹ kan, ayọ n bọ lowurọ.
Bẹẹ ni ọrọ igbe aye gbajumọ oṣere tiata lobinrin, Remilekun Oshodi, ti ọpọ eeyan mọ si Remi Surutu ri.
Ìdílé tí ọkọ da ọmọ síta tóríi ojú Búlùú tí wọ́n ní bá BBC sọ̀rọ̀
Mama Rainbow:  Toyin Adegbola àti Razak Olayiwola ní ìyá rere àti àwòkọ́ṣe gidi ní
Idi ni pe ariwo ayọ tun sọ nile rẹ lọjọ Iṣẹgun nigba ti ọmọ rẹ obìnrin, Abiola Ajike, mu ọkọ wale.
Ayẹyẹ idana ọhun lo dun, to si larinrin, ti ọpọ eeyan si n ba yọ ayọ oriire naa, paapaa awọn akẹẹgbẹ rẹ ninu isẹ tiata.
Surutu to wọ aṣọ funfun lasiko ayẹyẹ idana naa, bi eeyan ba gun ẹṣin ninu rẹ, ko lee kọsẹ rara paapaa nigba to n rọ ojo adura le ọmọ naa lori.
Bẹẹ ba gbagbe, ọjọ kinni osu keje ọdun 2017 ni osere tiata padanu ọmọbìnrin kan, ẹni to jẹ alaisi lati ipasẹ arun foniku fọlande.
Oríṣun àwòrán, Instagram/@therealremisurutu
Awa naa wa n ba Remi Surutu yọ pe o ku oriire idana ọmọ rẹ, ọba oke yoo jẹ ka ri adun pupọ nibẹ
Àsọtẹ́lẹ̀: Pásítọ̀ ríran pé Ìmáàmù yóò kú
Oríṣun àwòrán, Glorious world power ministry/Facebook
Ghana: Aṣọtẹ́lẹ̀ kó pàsítọ Isaac si wàhálà
Àwọn ọ̀dọ́ mùsùlùmí tí ya wọ ilé ìjọsìn kan ní orílẹ̀-èdè Ghana, lẹ́yìn ti pásítọ̀ sọ àsọtẹ́lẹ̀ pé Imaamu àgbà orilẹ̀-èdè Ghana yóò kú lọ́dún 2019.
Ohun èlò orin, fèrèsé, àti àga inú ṣọ́sọ̀sì ní wọn bàjẹ́ nígbà ti àwọn ọ̀dọ́ ọ̀hún ya wọ ilé ìjọsìn ẹni ọ̀wọ̀, Isaac Owusu-bempah ní ìlú Accra.
Ìgunnukó: Àwọn Tápà gbà pé ẹni tó bá ń sin Ìgunnukó kò ní ráùn ohun rere
Bó tilẹ̀ jẹ́ pé Imaam Nuhu Sharabutu lòdì sí ìgbésẹ̀ tí àwọn ọdọ́ náà gbé.
Sisọ asọtẹ́lẹ̀ lopin ọdun laarin awọn ìjọ ọmọlẹyin Kristi kan jẹ́ ǹkan tó wọ́pọ̀, tí àwọn ènìyàn kan sì máà ń fẹ ní ilẹ̀ Afíríka, èyí máa ń sábà sọ àsọtẹ́lẹ̀ ǹkan gbòógì tí yóò ṣẹlẹ̀, tó fi mọ́ ikú àwọn èèkan nínú ìlú.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ghana: Aṣọtẹ́lẹ̀ kó pàsítọ Isaac si wàhálà
Irú rẹ̀ ní èyí tó wáyé ní ọdún 2016, nígbà ti ìlú mọ̀ọ́ká pásítọ̀ T.B Joshua sọ tẹ́lẹ̀ pé, Hillary Clinton yoo bori Donald Trump lati di ààrẹ orilẹ̀-èdè Amẹ́ríkà.
Àwọn alátako rẹ̀ fí ṣe yẹ̀yẹ́ lẹ́yìn ti Trump jáwé olúbori. Ẹyìn náà lo pa asọtẹ́lẹ̀ náà rẹ́.
Lásìkò  tó ń wàásù ní òpín ọdún, Owusu-Bempah sọ àsọ́tẹ́lẹ̀ tí ọdún 2019, tó fí mọ ikú Imaam Sharabutu.
Àwọn ọ̀dọ́ mùsùlùmí to tako iran náà sọ fún olùsọ́-àgùtàn ọ̀hún pé, kó tọrọ àforíjì, sùgbọ́n ó kọ̀ láti ṣe bẹ́ẹ̀.
Idi ree ti wọn se fa ibinu yọ, ti wọn si ba awọn ohun eelo kan jẹ ninu ile ijọsin naa.
Imaam Sharabutu tí wa pè fún ìdákẹ́rọ́rọ́, o ní kí wọn dáríji pàsítọ̀ náà tó jẹ́ ọ̀kan gbòógi nínú àwọn pasítọ̀ ní orílẹ̀-èdè Ghana.
Ghana jẹ́ orílẹ̀-èdè tí kìrìstẹ́nì pọ sí, kò sì tíì si nínu 'ìtàn orilẹ̀-èdè náà pé ìjà ẹ̀sin bẹ́ sílẹ̀ ri.
Dino gba àgọ́ Ọlọ́pàá ré sílé ìwòsàn
Dino Melaye
Sẹnetọ Dino Melaye tó ṣẹṣẹ yọju si agọ Ọlọpáà lati yọju si ọga agba awn ọlọpaa ti di ero ile iwosan.
Ṣaaju, Sẹ́nétọ̀ Dino Melaye tó ń ṣojú ẹkùn Iwọ̀ Oòrun ìpínlẹ̀ Kogi ti jọ̀wọ́ ara rẹ̀ fún àwọn ọlọ́pàá.
Dino Melaye
Lonii, ọjọ ẹti, ọjọ kẹrin oṣu kinni ni èyí wáyé gẹgẹ bi iroyin ṣe sọ ọ wi pe awọn akẹgbẹ Melaye kan lo ba a sọrọ.
Akọroyin BBC to ṣe ibẹwo si ile rẹ fabọ jẹ ni pe wọn ti gbe aṣofin naa lọ si ọfiisi awọn ọlọpaa kogberegbe SARS fun ifọrọwanilẹnuwo.
Oríṣun àwòrán, Getty Images, @DinoMelaye
Dino àti Ọ̀gá Ọlọ́pàá
Dino lọ si olu ile iṣẹ ọlọpaa to wa nilu Abuja lati le yọju si ọga agba ọlọpaa ṣugbọn a gbọ pe wọn ni ko lee ri ọga tori o wa ninu ipade.
Laarin awọn akẹgbẹ rẹ lo ti gba ile iṣẹ awọn ọlọpaa kogberegbe lọ.
A n se akojọpọ ẹkunrẹrẹ iroyin yajoyajo lọwọ, a o maa gbe ẹkunrẹrẹ iroyin naa sori atẹ iroyin wa laipẹ. Ẹ jọwọ, ẹ tun oju opo iroyin yi yẹwo, ki ẹ lee ri ẹkunrẹrẹ iroyin ọtun laipẹ.
NLC: Ìpàdé ọjọ́ Ajé ni yóò sọ bóyá á yansẹ́ lódì
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ẹja pọnbele ni ipade to waye laarin minisita fọ̀rọ̀ osisẹ́ ati ijọba apapọ lọjọ Ẹti, nitori igun mejeeji ko lee fi ẹnu ọrọ jona lori igbesẹ sisan ẹgbẹrun lọna ọgbọn naira gẹgẹ bii owo osu to kere julọ fun osisẹ kan ni orilẹede yii.
Ipade ọhun, to gba wọn to wakati meje gbako, ni wọn tun sun siwaju di ọjọ Aje, ọjọ Keje osu Kinni ọdun 2019.
Nigba to n bawọn akọroyin sọrọ lẹyin ipade naa, aarẹ apapọ fun ẹgbẹ osisẹ NLC, Ayuba Wabba ati akẹẹgbẹ rẹ fun TUC, Kaigama Bobboi, sọ fun awọn akọroyin pe lootọ ni ilọsiwaju wa nipa aawọ to wa nilẹ.
Ìgunnukó: Àwọn Tápà gbà pé ẹni tó bá ń sin Ìgunnukó kò ní ráùn ohun rere
Amọ wọn fikun pe ipade miran ti yoo waye lọjọ Aje ni yoo sọ boya ẹgbẹ osisẹ yoo tẹsiwaju pẹlu iyansẹlodi to fẹ gunle lọjọ Isẹgun abi bẹẹ kọ.
"Wabba ni ""A ti joko jiroro lori ọrọ to nii se pẹlu owo osu, amọ a pinnu nibi ipade naa lati sun ijiroro naa siwaju di ọjọ Aje, ka to lee fi ẹnu ọrọ jona nipa aawọ to wa nilẹ."
O fikun pe ẹgbẹ osisẹ fẹ ri daju pe wọn gbe aba sisan owo osu naa lọ sile asofin apapọ lati buwọlu, ki owo osu to kere julọ naa lee de apo awọn osisẹ kọọkan .
Ninu ọrọ tiẹ, Minisita fọrọ osisẹ, Dokita Chris Ngige salaye pe, oun to mumu julọ laya aarẹ Muhammadu Buhari bayii ni sisan owo osu tuntun fawọn osisẹ ilẹ yii.
O fikun pe ọjọ Aje lawọn yoo fẹnu ọrọ jona lori igbesẹ gbigbe aba sisan owo osu tuntun naa de ile asofin apapọ, pẹlu afikun pe ijọba yoo rọ awọn ijọba ipinlẹ lati wa owo fi san alekun owo osu naa.
NANS: Àwọn aráàlú ní se ló yẹ kí NANS bẹ̀bẹ̀ fún òpin ìyansẹ́lódì ASUU
Oríṣun àwòrán, @AsoRock
Ọpọ ọmọ Naijiria lo ti n sọrọ lori fidio kan to n ja rainrain nilẹ pe aarẹ ẹgbẹ awọn akẹ́kọ ile ẹkọ giga nilẹ wa, NANS, Danielson Bamidele Akpan, sọ fun aarẹ Muhammadu Buhari pe, yoo ri ibo ogun miliọnu laarin awn akẹkọ ilẹ yii.
Ọrọ yii ni wọn lo jẹyọ lasiko ti ẹgbẹ NANS lọ se abẹwo si aarẹ Buhari nile ijọba Aso Rock nilu Abuja.
Ninu fọnran aworan to lu sita lẹyin abẹwo naa, ni Akpan ti salaye pe awọn akẹkọ Naijiria pọ pupọ, ti wọn si fẹẹ to ọgọrin miliọnu niye.
Akpan wa rọ aarẹ Muhammadu Buhari pe to ba lee lo ẹka yii bo se yẹ, oun n fi da loju pe, yoo ri ibo ti yoo to ogun miliọnu laarin awọn ọdọ naa.
Bakan naa ni awọn asaaju ẹgbẹ akẹkọ lo anfaani abẹwo wọn ọhun si ọdọ Buhari, lati ki ku ayẹyẹ oriire ọjọ ibi ọdun mẹrindinlọgọrin to pe loke eepẹ.
Rashidat Fawẹhinmi: Sísọ èdè Yorùbá kò leè ba Gẹ̀ẹ́sì jẹ́ lẹ́yìn odi
Akpan tun gbadura fun Buhari pe, aseye ni yoo se ninu eto idibo aarẹ ti yoo waye losu keji ọdun yii.
Sugbọn ẹyin lohun, to ba ti jabọ, ko tun se ko mọ, awọn ọmọ orilẹede yii ti n sọ ero ọkan wọn lori ọrọ ti ohun ti aarẹ ẹgbẹ akẹkọ ilẹ wa naa sọ.
Lero tawọn eeyan kan, ohun ti Akpan ba lọ si Aso Rock kọ lo kọju mọ, kaka ko si maa bẹ Buhari pe ko dahun awọn ibeere tawọn olukọ fasiti n beere lọwọ ijọba, ọrọ oselu lo mojuto.
Oríṣun àwòrán, @AsoRock
Lawọn oju opo ikansiraẹni, paapa Twitter, awọn ọmọ Naijiria kan ni, bi ẹgbẹ awọn olukọ fasiti se n wo isẹ niran lo yẹ ko mumu julọ laya awọn akẹkọ yii, ki wọn si wa ọna ti ijọba ati ASUU yoo se fi eegun otolo to aawọ aarin wọ.
Koda, awọn miran tiẹ foju laifi wo kaadi ọjọ ibi ti ẹgbẹ akẹkọ naa gbe fun Buhari lati fi ki ku oriire ọjọ ibi.
Oríṣun àwòrán, @AsoRock
Jikan Sabo, @Usmern_ssg, o ni se ẹgbẹ NANs to n dun mahuru-mahuru laipẹ yii lati tẹsẹ bọ sokoto kanna pẹ́lu Buhari, lo wa n pada fun ni kaadi ọjọ ibi yii?
Ogeadiro_official, @ogeadiro1 naa kin Jikan lẹyin pẹlu afikun pe Naijiria yoo maa bajẹ si ni.
Coker Pẹlumi, @ cokeroluwapelu2 woye pe ileri ibo ti aar ẹgbẹ NANS se fun Buhari yii, lo se afihan bi ẹka asaaju ẹgbẹ NANs ti bajẹ, to si jẹra si.
@mrtsmilez lero tiẹ ni orilẹede Naijiria ree, nibi ti gbogbo wa ti jẹ ọdaran, ti aarẹ ẹgbẹ akẹkọ si ti gba owo.
Ogunranti Abiodun, @Wonder_11 sọ loju opo Twitter rẹ pe, ọkan aarẹ ẹgbẹ NANs ti daru, to si n mu idarudapọ wa gẹgẹ bi orukọ rẹ ti fihan, o ni ko yara tete yọ orukọ toun kuro ninu ogun miliọnu akẹkọ ti yoo dibo fun Buhari.
Pinnick: Àwọn ọ̀tá mi ló fẹ́ b'orúkọ mi jẹ́
Oríṣun àwòrán, @thenff
Aarẹ ajọ elere bọọlu nilẹ wa, NFF, Amaju Pinnick ti ní kò sí òótọ́ kan ninu ìròyìn pé oun n koju ẹsun iwa ajẹbanu bayii, eyi ti owo rẹ to aimọye biliọnu naira.
Iroyin ti kọkọ sọ pé aarẹ Muhammadu Buhari ti pasẹ pe ki aarẹ NFF naa lọ foju winna igbẹjọ, lori awọn ẹsun ti wọn fi kan ọhun.
Bakan naa iroyin naa tun sọ pe ijọba apapọ ti fofin de Amaju Pinnick lati rinrin ajo lọ si oke okun lasiko yii titi ti igbẹjọ rẹ yoo fi buse.
Ni kete ti iroyin naa de afẹfẹ ni Pinnick ke gbajare lori Twitter pe ko si ootọ kan nibẹ.
Iwadi naa, gẹgẹ bi iroyin ṣe sọ, lo da lori owo ti ajọ elere bọọlu lagbaye FIFA, gbe fun ajọ elere bọọlu ilẹ wa, NFF, laarin ọdun 2014 si 2016.
Ìwádìí Anas: $1000 ni rìbá tí akọ́ni-mọ̀ọ́gbá Super Eagles gba
Àwọn wòòlí ń takora lórí ẹni tí yóò di ààrẹ láàrin Buhari àti Atiku
Guru Maharaj: Buhari ní yóò wolé nínú ìdìbò 2019
Olùdásílẹ̀ ìjọ One Love Family, Satguru Maharaj ní ààrẹ Muhammadu Buhari tó ń dije lábẹ àsía ẹgbẹ́ òṣèlú All Progressives Party (APC), ni yóò fidi alátako rẹ̀ Alhaji Atiku Abubakar, tó ń dije lábẹ́ égbẹ́ òṣèlú People's Democratic Party(PDP) janlẹ̀. níbi idibo gbogboogbo ti yóò wáyé lósù tó ń bọ.
Asọtẹlẹ yii waye lẹyin Osun meji ti adari ijọ Divine Seed of God ti ilu Ibadan Wooli Wale Olagunju sọ asọtẹlẹ wipe, ki Buhari ma  ṣe wahala pupọ o, nitori wipe Atiku ni yoo gbe igba oroke.
O ba awọn oniroyin sọrọ ninu ifọrọwanilẹnuwo kan nibi to ti sọ wipe, oun n ki Atiku ku ori ire, nitori wipe, yoo bori ninu idibo 2019.
Oríṣun àwòrán, Wale Olagunju
Wooli Wale Olagunju
Mọrèmi: Ọọ̀ni ní láìsi Mọrèmi, kò leè sí ilẹ̀ Yorùbá
Buhari, Atiku, Ezekwesili, Sowore àti àwọn méjìléláàdọ́rin míràqn ló ń dije dupò ààrẹ Nàìjíríà.
Oríṣun àwòrán, Bayo Omoboriowo
Guru salayepe ààrẹ Buhari ni yóò jawe olúbori ninu ìdìbò ọdún 2019
Lásìkò tí Gúrú ń bá àwọn àkọ̀ròyìn sọ̀rọ̀ nibi àpérò láti se ayẹyẹ ọdún mọ́kàndínlógojí rẹ̀ lórilẹ̀-èdè Nàìjíríà, ló ti sàlàyé pé òun rí pe Buhari ló jáwé olúbori nínu ìdíje ìdìbò ọdún 2019.
Ó nií ti àwọn olùdíje tó kù yóò ba gbọ́ ti toun kí gbogbo wọn gbárùkù tí Buhari ní yóò ṣe wọn láǹfàní.
INEC: Òpómúléró ni ASUU jẹ́ fún àṣeyọrí ìbò 2019
Oríṣun àwòrán,  INEC
ìfọ́wọ́sowọ́pọ̀ ASUU ló le jẹ́ kí ìdìbò wa ó kẹ́sẹjári
Àwọn ọmọ ẹgbẹ́ ASUU ti gba láti kópa nínú ètò ìdìbò ọdún 2019.
Sáájú ní wọn ti ń dágúnla pé àwọn olùkọ́ ati akẹ́kọ́ọ̀ kò ní lè kópa nítorí ìyanṣẹ́lódì tó ń lọ lọ́wọ́.
Ọjọ̀gbọ́n Mahmood Yakubu, alága INEC náà ti kédé pé, àwọn yóò ṣe ìpàdé pọ̀ pẹ̀lú ẹgbẹ́ ASUU.
"Yakubu ni '' Eyi wa láti wa ojúùtú sí ọ̀rọ̀ ìyànṣẹ́lódì tó ń lọwọ́, sùgbọ́n ìpàdé náà kò ní kọjáa ọ̀rọ̀ nípa ìmúrasílẹ̀ fún ìdìbò gbogboogbo tó n bọ̀ nínú oṣù kejì ọdún"""
" Ǹkan tó kàn wá jùlọ ní àwọn ipa pàtàkì tí àwọn olukọ tí INEC ti yan ní àwọn Fasiti láti kopa nínú ètò ìdìbò yoo ni.
ASUU: A ó kópa nínú ètò ìdìbò 2019
A ti ní ìpinu pé ètò ìdìbò náà kò gbọdọ̀ ní kọ́nu-n-kọhọ nítori ìyanṣẹ́lodì àwọn oṣìṣẹ́ Fasiti. ASUU jẹ́ pàtàkì igun ilé fún àjọ wa láti ṣe ètò ìdìbo tó ṣe mú yangan láwujọ àwọn orílẹ̀-èdè.
À ń fojú sọ́nà fún ìpadé ti yóò mú àbájade rere jade wá "
Ẹwẹ̀, ìkéde pé àwọn yóò kopa yìí wáye lọjọ́ Jimọ, lẹ́yìn ìpàdé INEC àti ASUU.
Pátá Jíjí : Agbẹnusọ ọlọ́pàá ní àwọn olè ajípátá ń gbìdánwò ìpànìyàn ni
Oríṣun àwòrán, Tori.ng
Ọwọ tẹ awọn afunrasi meji ni Delta to ji pata eniyan mewaa
Isẹlẹ jiji pata awọn obinrin lo ti di iroyin to n gbalẹ bii ọwara ojo lawujọ wa bayii.
Awọn iroyin kan lo ni, awọn eeyan kan to n lu jibiti, ti wọn n pe ni ọmọ Yahoo, lo n ji pata awọn obinrin lati fi se oogun owo.
Ọpọ awọn afurasi tọwọ ba lori ẹsun yii, ni wọn ti n naju ni agọ ọlọpaa.
Rashidat Fawẹhinmi: Sísọ èdè Yorùbá kò leè ba Gẹ̀ẹ́sì jẹ́ lẹ́yìn odi
Nigba to n sọrọ lori isẹlẹ ọtun to gba awujọ wa kan yii, Dolapo Badmos, tó jẹ́ agbẹnusọ iléeṣẹ́ ọlọpàá Ẹkun keji, to wa ni ipínlẹ̀ Eko ní, ó ṣéeṣe kí àwọn olè ajípáta naa jẹ́jọ́ ẹ̀sùn ìpànìyàn, tí ọwọ́ bá tẹ̀ wọ́n.
Badmos ṣàlàyé loju opo ikansiraẹni nstagram rẹ̀ pé, irú ẹ̀sùn náà ṣeéṣe nítorí àwọn olè ajípátá tí ọwọ́ tẹ̀, ní wọn n gbero lati se oògùn owó tí yóò ṣe ikú pa ẹni to ni pata naa.
Oríṣun àwòrán, Dolapo Badmos/Twitter
Dolapo Badmos àwọn ole ajipata lo jẹ́jọ́ ipaniyan
Bi ọ̀rọ̀ oogun owo ṣe n  wọ́pọ̀ si, ni ọwọ n tẹ awọn afunrasi tí wọn ní o ń jí awọ̀tẹ́lẹ̀ awọn obinrin, nibi ti wọ́n ba sá wọn sí.
Ní ọjọ́ kẹta oṣu kinni ọdun 2019, ni ọwọ awọn agbófinró tẹ awọn ọmọdekunrin mejì tí wọ́n fẹ̀sun kan pe, wọn ji pata awọn obinrin mẹ̀wàá ká lórí okùn níbi tí wọ́n sá wọn si nílu Agbarha, nijọba ibilẹ̀ Ukwuani ni Ipinlẹ̀ Delta.
Asiko kan naa ni ọwọ tun tẹ ọmọdekunrin kan ni ilu Benin ni Ipinlẹ̀ Edo, ti wọn fi ẹsun kan pe o lọ ji pata awọn obinrin ka lori okùn.
Ọwọ tẹ afẹsunkan naa lẹyin igba ti Ọba Benin, Ọba Ewuare keji, kilọ̀ fun awọn ọdọ ki wọn ye ti ọwọ bọ sise oogun owo, ti yoo jẹ ki wọn maa ji pata kiri.
Oríṣun àwòrán, Thegeniusmedia.com.ng
Ẹ mà sọ pátá tí ẹ ò lò mọ́ sọnù - Òsèré Mosun Filani
Ọ̀rọ̀ pátá jíjí yìí ti sọ oun tí àwọn obinrin lè ṣe si àwọ̀tẹ́lẹ̀ tí wọn kò bá nílò mọ́ di ọ̀rọ̀ ńlá báyìí.
Òun ló jẹ́ kí gbajúgbajọ̀ òsèré tíátà, Mosun Filani gba àwọn obìnrin ní ìmòràn, pe kí wọ́n máà fi abẹ gé àwọ̀tẹ́lẹ̀ tí wọn kò bá nílò mọ́ wẹlẹwẹlẹ, dípò pe kí wọ́n máa sọ́ si ibi tí àwọn tó lè fi ṣe oogun owó yóò ti ri i.
Oun tó sọ sọrí ayélujára rèé:
"Torí  bá kó ọ yọ lọ́wọ́ àwọn ajínigbé, àmọ́ tí pátá rẹ̀ bọ́ sọ́wọ́ àwọn ẹni ibi, o ò jájábọ́ o. Inú balùwẹ̀ ni kí ẹ máà sá pátá yín sí, ẹ má sa sí ẹ̀gbẹ́ fèrèsé.
Ẹ máse sọ pátá tí ẹ kò lò mọ́ sibi kan ṣáá. ẹ gée wẹ́lẹ́wẹ́lẹ́ tàbí kí ẹ fi iná sun ún. Ní 2019 yìí, ayé kò ní ká pátá wa lọ o."
Dino Melaye: Mí ò sí lára àwọn aṣòfin tó bú Buhari
Dino Melaye jọ̀wọ́ ara a rẹ fun awọn ọlọpa lẹyin ọṣẹ kan ti wọn ti gẹ̀gùn de e
Sẹnetọ to n ṣoju ẹkùn idibo nipinlẹ Kogi, Dino Melaye ti sọ pe oun ko si lara awọn aṣofin to pariwo le Aarẹ Muhammadu Buhari lori lasiko to n ka aba eto iṣuna ọdun 2019 niwaju awọn aṣofin Naijiria lọjọ kọkandinlogun, oṣu Kejila, ọdun 2019.
Melaye to n bẹ nileewosan gbogboogbo l'Abuja lọwọlọwọ, sọ ninu atẹjade kan ti oluranlọwọ rẹ, Gideon Ayọdele, fi sita pe irọ ni ẹsun ti awọn kan fi n kan oun pe awọn jọ bu Aarẹ Buhari.
Kwara yóò gbàlejò BBC Yoruba
Melaye sọ pe ''ko ṣeesẹ ki oun wa lara awọn aṣofin tó pariwo ẹlẹya le Buhari lori, nitpri pe oun ko si nibi eto ti Buhari ti gbe aba eto iṣuna naa kalẹ.
Ati wi pe kii ṣe ẹ̀rù lo mu ki oun ṣọ pe oun ko jẹbi ẹsun naa, ati pe ki ẹnikẹni to ba ni ẹri pe oun ba wọn kopa ninu rẹ jáde wa sọ.
Mọrèmi: Ọọ̀ni ní láìsi Mọrèmi, kò leè sí ilẹ̀ Yorùbá
Ronke Oṣodi: òótọ́ ọ̀rọ̀ máa ń korò gan ni f'áwa èèyàn
Àwòrán Amosun, Adekunle àti Buhari tó n dá awuyewuye sílẹ̀
Oríṣun àwòrán, @AHMAD BASHIR
Aworan yi n kan awọn ọmọ ẹgbẹ APC kan lominu
Lọjọ́ Aiku ni Gómìnà ìpínlẹ̀ Ogun, Ibikunle Amosun kọwọrin lọ si ọdọ Aarẹ Buhari pẹlu oludije Gomina ayanfẹ rẹ Adekunle Akinlade.
Ipade kan ti waye nile ijọba orile-ede Naijiria nilu Abuja laarin Gomina Ipinlẹ Ogun, Ibikunle Amosun ati Aarẹ orile-ede Naijiria Muhammadu.
Ipade naa kii ṣe akọkọ ti awọn mejeeji yoo jọ ṣe ṣugbọn ohun to ya awọn eeyan lẹnu nipa ipade naa ni pe Gomina Ibikunle Amosun kọwọrin lọ ipade naa pẹlu oludije ipo Gomina lẹgbẹ oṣelu APM, Adekunle Akinlade.
Iyẹn nikan kọ, ati Gomina Amosun Akinlade ati Aarẹ Buhari wọn jijọ ya awọran kan nibi ti wọn ti nawọ soke lati ṣe afihan pe awọn faramọ iṣejọba ọdun mẹrin miran sii fun Aarẹ Buhari.
Claudiah: ìrẹ̀wẹ̀sì ọkàn bá mi fínra fún ọpọlọpọ ọdún
Oríṣun àwòrán, @Mr Khaleed
Ohun ti Aarẹ Buhari sọ nipa Adekunle ko ti jẹyọ si awọn eeyan
Aworan yi ati awọn miiran ti wọn ya nibi ipade naa ti n da awuyewuye loju opo Twitter ti awọn ọmọ ẹgbẹ APC kan si ti ni iru iwa bayi fidi rẹ mule pe Aarẹ Muhammadu Buhari lo n fi ọwọ ararẹ sakoba fun irẹpọ ninu ẹgbẹ.
Bi a ko ba gbagbe, lai pẹ yi ni Gomina Amosun lewaju awọn ọmọ ẹgbẹ APM la ti lọ fun Aarẹ Buhari ni iwe atilẹyin lati ọdọ ẹgbẹ naa gẹgẹ bi oludije ipo Aarẹ ti wọn yan laayo.
Ìwà ipá nínú ìdílé máa ń bí ìgè àti àdùbí ni tó lè já sí ikú
Ko daju boya Aarẹ Buhari jan oludije ẹgbẹ yi ni òǹtẹ̀ nibi ipade naa ṣugbọn ko sọ bakan naa pe oun lodi si iwa Amosun ti awọn ọmọ ẹgbẹ APC kan ri gẹgẹ bi iwa to lodi si aṣẹ ẹgbẹ.
Amosun ti sọ nita gbangba pe oun ko nigbe lẹyin oludije ẹgbẹ APC nipo Gomina mii bi kii ṣe Adekunle to jẹ aayo rẹ.
Mọrèmi: Ọọ̀ni ní láìsi Mọrèmi, kò leè sí ilẹ̀ Yorùbá
Ronke Oṣodi: òótọ́ ọ̀rọ̀ máa ń korò gan ni f'áwa èèyàn
Daily Trust: A kò mọ̀ ohùn tó mú Iléeṣẹ́ ológun tí ọọfisi wà ní Maiduguri àti Abuja
Oríṣun àwòrán, @nigeriaarmy
Ileeṣẹ ologun orileede Naijiria ti ti ile iroyin Daily Trust pa ni ilu Maiduguri ati ilu Abuja.
Ile iṣẹ ọmoogun Naijiria ti ni Daily Trust fi gbogbo aṣiri bi awọn ṣe n gbogun ti Boko Haram lede ni awọn ṣe ti ọọfisi wọn pa.
Ninu atẹjade ti wọn fi si ori itakun ibanisọrọ Facebook wọn, ile iṣẹ ọmọogun naa ni aṣiri ti ile iṣẹ iroyin naa fi lede mu ki awọn ikọ agbesunmọmi Boko Haram mọ gbogbo irinsi wọn, eleyi ti o le fa ikọlu si orilẹ-ede naa.
Wọn fikun wi pe awọn ko ṣe ikọlu si ile iṣẹ iroyin naa lati pa wọn le nu mọ, amọ lati ṣe iwadii bi wọn ṣe ri awọn iroyin ti ko yẹ ko jade sita naa.
Alao Akala:Èmi àti Ajimọbi kò ṣe ìlérí kankan fún ara wa
Lẹyin awuye wuye to ṣẹlẹ lori bi ileeṣe Ologun Naijiria ṣe ti ile iṣẹ iwe iroyin Daily Trust pa ni ìjọba Naijiria paṣẹ fawọn ọmọ ogun lati ṣi Daily Trust padà.
Agbẹnusọ fun Aarẹ Mohammadu Buhari, Garba Shehu lo fi eyi lede lori ikanni twitter ẹ pé:
Bakan naa lo fi idi eyi mulẹ pe, ni kete tijọba fi àṣẹ yii sita ni wọn ti ṣi ile iṣẹ Daily Trust pada.
Díẹ̀ lára èrò àwọn eniyan Naijiria ni pé:
Loju àwọn kan, wahala ni eleyii maa bi ninu ijọba to ba faaye gba awọn ologun lati maa ṣe ohun to wu wọn nigba to wu wọn.
Awọn bii Lade, àti Ijai gbà pe eyi n fihan pe nkan ko fararọ ninu ijọba ni bayii
Kwara yóò gbàlejò BBC Yoruba
Opọlọpọ lo gba pe ominira ọrọ yẹ ko jẹ ẹ̀tọ́ àwọn eniyan ati pe ko si ijọba to yẹ ko kọja ariwisi ki wọn le tubọ huwa akin sii.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Awọn ọmọogun jẹwọ idi ti wọn ko fi lee pa ina Boko haram
Awọn miran n sọrọ si aarẹ Buhari pé o yẹ ko ṣe ohun to yẹ gẹgẹ bii ọgagun to mọ nipa iṣakoso ati pe o yẹ ki wọn fiya to tọ jẹ awọn ọmọ ogun to ṣe eyi
Awọn miran fi lede pe, ọmọ ẹbi kan naa ni Daily Trust ati APC fun idi eyi...
Loju Garba Shehu, ijọba Buhari paṣẹ yii ki agbara òfin lè fi di mimuṣẹ ni
Kí ló ṣelẹ̀ sẹ́yìn?
Ileeṣẹ ologun orileede Naijiria ti ti ile iroyin Daily Trust pa nilu Maiduguri ati ilu Abuja.
Koda wọn ko awọn akoroyin meji lọ ni ileeṣẹ naa to wa ni Maiduguri.
Ẹka Ile iṣe iwe iroyin Daily Trust to wa ni ilu Maiduguri la kọkọ gbo pe wọn yabo ti wọn gbe Uthman Abubakar to jẹ olootu iwe iroyin naa lagbegbe ohun pẹlu akoroyin rẹ kan Ibrahim Sawab lọ.
Oríṣun àwòrán, @FACEBOOK/UTHMAN ABUBAKAR/IBRAHIM SAWAB
Awọn oṣojumikoro ni awọn mejeeji ni awọn ọmọogun gbe lo nigba ti wọn wa si ile iṣẹ iroyin naa
Ileeṣẹ iroyin ko ti sọrọ nipa ohun to fa iṣẹlẹ yi titi di bi a ti ṣe nkoroyin yi.
Loju opo Twitter iwe Iroyin Daily Trust ni wọn fi ọrọ yi si  lọjọ aiku ti wọn si  ni ko si ẹni to mọ ibi ti wọn gbe awọn akoroyin naa lọ.
Wọn ti paṣẹ ki wọn ṣi Daily Trust pada
Ninu ọrọ ti iwe iroyin naa kọ, wọn ni awọn fura si wi pe igbesẹ awọn ọmọogun Naijiria yi ko sẹyin iroyin kan ti awọn  gbe jade lọjọ aiku nipa iṣẹ awọn ologun lagbegbe ila oorun ariwa Naijiria.
Wọn ni bakannaa ni wọn n bere Hamza Idris ti orukọ rẹ wa lori iroyin naa.
Oríṣun àwòrán, @Daily Trust
Iléesẹ́ ológun Nàíjíríà ti Daily Trust pa ní Maiduguri àti Abuja
Oríṣun àwòrán, @Daily Trust
Ko pe si igba ti wọn yabo ileeṣẹ iroyin naa ni Maiduguri, ni awọn ọmọogun tun ṣigun lọ si ile iṣẹ iroyin naa ni Abuja lọjọ aiku kanna ti wọn si ko awọn Komputa awọn akoroyin nibẹ.
Lọwọlọwọ bi a ti ṣe nkọroyin yi, agbo pe wọn ti da awọn oṣiṣẹ ile iroyin naa sita kuro ni ọfisi wọn to wa ni adugbo Jabi nilu Abuja.
Akoroyin kan pẹlu ileeṣẹ Daily Trust sọ fun BBC pe awọn akegbe oun nileeṣẹ iroyin naa l'Abuja wa ni ibẹrubojo lẹyin ti awọn ologun ya bo ileeṣẹ  wọn.
''Wọn fẹ dunkoko mọ wa ni,eyi si lodi sofin to fayegba wiwi tẹnu ẹni.''
O ni awọn gbiyanju lati ba awọn ileeṣẹ ologun sọrọ ṣugbọn awọn ko laanfaani lati ri wọn ba sọrọ.
Oríṣun àwòrán, @Daily Trust
Lẹnu ọjọ mẹta yi, ileeṣẹ ologun Naijiria n ba awọn to ba sọrọ nipa ija rẹ pẹlu Boko Haram fa wahala.
Bi a ko ba gbagbe, ileeṣẹ ologun lọdun tokọja bẹnu àtẹ́ lu ìwádìí Amnesty International pe wọn fẹ tu Naijiria ka pẹlu abajade iwadii wọn pe o le ni ẹgbẹrun mẹta eeyan ti wọn ti lugbadi iku lataari aawọ laarin awọn agbe ati darandaran ni Naijiria.
Ileeṣẹ ologun ninu atẹjade kan lati ọdọ ọgagun Sani Usman to jẹ agbẹnusọ wọn ni niṣe ni ajọ naa n gbero lati tu Naijiria ka.
Koda wọn pe fun titi fun titi oriko ajọ naa jakejado Naijiria.
Ìwà ipá nínú ìdílé máa ń bí ìgè àti àdùbí ni tó lè já sí ikú
Gabon: Àlááfíà ti padà, a ti mú àwọn ológun tó fẹ́ gba ìjọba
Oríṣun àwòrán, Reuters
Ààrẹ orílẹ̀èdè Gabon, Ali Bongo tó ń se àìsàn lọ́wọ́ ti gba ìjọba láti àádọ́ta ọdún sẹ́yìn.
Ijọba ilẹ Gabon ti ni alaafia ti pada si eto oṣelu orilẹede naa lẹyin ti awọn ologun gbiyanju lati gba ijọba orilẹede naa.
Agbẹnusọ fun ijọba orilẹede naa, Guy-Bertrand Mapangou ti sọ fun BBC pe awọn ti mu awọn ọmọ ogun mẹrin ninu marun to gbe igbeṣe naa,to si ni awọn si n wa ẹni ikarun.
Awọn ọmọ ogun to wa ni ipo kekere naa sọ wi pe awọn gba nitori awọn fẹ da ijọba tiwantiwa pada si orilẹede naa.
Ile iṣẹ ologun ni orilẹede Gabon sọ wi pe awọn ti gba ijọba ti ile Gabon to kun fun ọpọlọpọ ohun alumọni epo rọọbi.
Awọn ọmọ ologun ni agbeegbe Iwọ-oorun ilẹ Afirika naa ni awọn gbe igbese naa lati da eto oselu tiwantiwa pada si orilẹede naa.
Alao Akala:Èmi àti Ajimọbi kò ṣe ìlérí kankan fún ara wa
Awọn ologun naa ti gba ile isẹ redio ti ijọba ni aago mẹrin owurọ oni ti wọn si polongo ‘Ajọ National Restoration Council’ to ti gba ijọba.
Aarẹ Ali Bongo gba ipo ni ọdun 2009 ti o si ti fi orilẹede naa silẹ lati bi osu meji sẹhin.
iroyin ni Aarẹ Bongo to bẹrẹ aarun rọpa rọsẹ ni Osu Kẹwa, ọdun to kọja, ti o si n gba itọju ni orilẹede Morocco.
NUJ: Kò yẹ kí akọ̀ròyìn fi ìròyìn tú àsírí ológun fún Boko Haram
NUJ: Ẹ̀yin Akọ̀ròyìn, ẹ sọ́ra nípa kíkọ ìròyìn tó léwu fétò ààbò
Ẹgbẹ awọn akọroyin lorilẹede Naijiria, ti kesi awọn awọn ọmọ ẹgbẹ naa lati mu eto aabo ilu lọkunkundun nipa didẹkun kikọ iroyin ti o le jẹ ki eto aabo mẹhẹ lorilẹede Naijiria.
Alaga ẹgbẹ akọroyin ni ipinlẹ Ọyo, Kọmureedi Adewunmi Faniran lo sọ eyi fun BBC Yoruba, lasiko to n fesi si bi ile iṣẹ ologun Naijiria, ṣe yabo ile iṣẹ iroyin Daily Trust ni Maiduguri ati Abuja.
Adewunmi ni, awọn akọroyin gbọdọ rọra lori eto aabo ilu, ki wọn si ṣọra lati ma a kọ awọn iroyin ti yoo fi han awọn ikọ Boko Haram wi pe, awọn ọmọogun n bọ wa ṣigun bo wọn.
Alao Akala:Èmi àti Ajimọbi kò ṣe ìlérí kankan fún ara wa
O fikun wi pe, idunnu lo jẹ fun awọn wi pe awọn ologun ko lu ẹnikẹni, bẹẹ si ni wọn ko pa ẹnikẹni lasiko ti wọn yabo ileeṣẹ naa.
O wa parọwa si awọn ọmọogun ati awọn akọroyin lati ri wi pe, wọn n ṣe ijiroro lati igba de igba ki agbọye le wa laarin awọn agbofinro ati akọ̀ròyìn nigba gbogbo.
Kwara yóò gbàlejò BBC Yoruba
Ti a ko ba gbagbe, Ọjọ Isinmi ni iroyin gbe jade wi pe, awọn ọmọogun Naijiria ṣigun bo ile iṣẹ Daily Trust.
Awọn ọmọ ologun kede pe, awọn gbe igbesẹ naa, nitori bi ilesẹ iroyin naa se fi aṣiri igbogun ti Boko Haram awọn lede ninu iroyin ti wọn gbe sita ninu iwe iroyin Daily Trust ni Ọjọ Karun, Osu Kini, ọdun 2019.
Presidency: Buhari kò leè ṣàtìlẹyìn fún olùdíje Amosun l'Ogun
Oríṣun àwòrán, oGUN STATE GOVERNMENT
Èdèàìyedè ti ń wáyé nípínlẹ̀ Ogùn láàárín Gómìnà Amosun àtàwọn adarí ẹgbẹ́ òṣèlú APC lápapọ̀
Ileeṣẹ aarẹ orilẹ-ede Naijiria ti sọ pe ko si idi kan fun Buhari lati ṣatilẹyin fun oludije ipo gomina n lẹgbẹ oṣelu APM nipinlẹ Ogun, Adekunle Akinlade ti gomina Ibikunle Amosun mu wa baa ni ọjọ aiku.
Olubadamọran fun aarẹ lori ọrọ iroyin, Garba Shehu lo ṣalaye ọrọ yii lori ohun to pe ni omilẹgbẹ ibeere awọn  oniroyin lori bi Aarẹ Buhari ṣe gbalejo Adekunle Akinlade ti gomina Amosun mu lọ baa niluu Abuja lẹyin ti o ti kọkọ gbalejo  Dapọ Abiọdunti Oloye Oluṣẹgun Ọṣọba mu wa baa ṣaaju.
Ohun ti o ru ọpọ loju lori ọrọ naa ni bi aarẹ yoo ṣe ṣatilẹyin fun oludije meji lati ẹgbẹ oṣelu meji ọtọọtọ ni ipinlẹ kan naa.
Ṣugbọn ileeṣẹ aarẹ, lati ẹnu Garba Shehu, ṣalaye pe gbogbo awọn oludije to wa lati abẹ aṣia ẹgbẹ oṣelu APC kaakiri orilẹede Naijiria ni aarẹ Buhari yoo ṣe ipolongo fun.
Oríṣun àwòrán, oGUN STATE GOVERNMENT
Ohun to ru ọpọ loju ni oludije ti kan aarẹ Buhari wa pẹlu ni ipinlẹ Ogun
O ni aarẹ ko lee kọ ipakọ si ẹnikẹni tabi oludije lati awọn ẹgbẹ oṣelu miran ti o ba wa kii; bẹẹni ko lee sọ pe ohun ko fẹ atilẹyin wọn.
Ti ẹgbẹ oṣelu APC ni Buhari nṣe, ko si edeaiyede kankan nibẹ. Awọn oludije APC ni aarẹ Buhari yoo ṣe ipolongo fun.
Gomina Amosun ati awọn adari ẹgbẹ oṣelu APC n forigbari bayii lori tani yoo dije fun ipo gomina ni ipinlẹ Ogun. Amosun n fẹ ki Adekunle Akinlade dije ṣugbọn Dapọ Abiọdun ni awọn adari ẹgbẹ oṣelu naa n fẹ.
Alao Akala:Èmi àti Ajimọbi kò ṣe ìlérí kankan fún ara wa
Coptic Christian: January 7 ni ọjọ́ àjọ̀dún kérésìmésì fún ẹ̀yà Krìstẹ́ní lágbègbè Lárúbáwá
Oríṣun àwòrán, Analodu agency
Ṣaaju ajọdun keresimesi yii, ọjọ mẹtalelogoji ni wọn fi n gba awẹ
Ọjọ karundinlọgbọn oṣu kejila ọdun ni gbogbo onigbagbọ maa n ṣe ajọyọ keresimesi. Ọpọ lo si ti fẹẹ gbagbe pe awọn ṣe ọdun keresimesi ti ọdun 2018, ṣugbọn ọjọ keje oṣu Kini ni awọn ẹya Kristẹni kan ti a mọ si Coptic Christians n ṣe ti wọn.
Gẹgẹ bii iwe onka ọjọ ti atijọ, ti a mọ si Orthodox Calendar ti ṣe fi lelẹ, ọjọ keje oṣu kini ni a bi Jesu Kristi. Idi si niyi to fi jẹ pe ọjọ keje oṣu kinni ọdun ni awọn kristẹni ẹya wọnyii ni agbegbe ilẹ larubawa atawọn to wa ni orilẹede Russia ti o n tẹle iwe onka ọjọ yii maa n ṣe ajọyọ ọdun keresimesi tiwọn.
Ni orilẹede Egypt, ko din ni miliọnu mẹwa awọn eeyan orilẹede Egypt ti o jẹ Kristẹni, pupọ ninu wọn lo si jẹ ẹya Coptic Christian.
Awọn si ni ẹya kristẹni to pọ julọ lagbegbe Larubawa.
Oríṣun àwòrán, Nurphoto
Ọjọ keje oṣu kinni ni ọjọ ajọdun keresimesi wọn
Ṣaaju ajọdun keresimesi yii, ọjọ mẹtalelogoji ni wọn fi n gba awẹ lati pese ara wọn silẹ fun gbigba Kristi.
Lasiko awẹ yii, wọn ko gbọdọ jẹ ohunkohun to ba wa lati ara ẹranko. Ọjọ karundinlọgbọn oṣu kọkanla ọdun ni wọn maa n bẹrẹ awẹ yii titi di ọjọ kẹfa oṣu kini ti o jẹ ọjọ aisun keresimesi tiwọn.
Baba Suwe: Ilé iṣẹ́ aṣọ́bodè kò fún bàbá mi ní kọ́bọ̀, igbákejì Ààrẹ kàn tọrọ àforíjìn ni - Ọmọ Bàbá Sùwé
Oríṣun àwòrán, Bababsuwe/ instagram
Oloogbe Muyideen Aromirẹ lo gbe sinima agbelewo akọkọ jade ni ọdun 1988
Ọpọ eniyan lo ti n ṣe aaro ilumọọka adẹrinposonu nni, Babatunde Omidina, ti ọpọ eeyan mọ si Baba Suwe nitori bi oju rẹ ṣe sọwọn lasiko yii ninu ọpọ ere sinima.
Eyi ko si sẹyin aisan ara to ṣee laipẹ yii, to mu ki wọn gbee lọ soke okun fun itọju pẹlu atilẹyin awọn ẹlẹyinju aanu ọmọ Naijiria kan.
Bi awọn ọmọ Naijiria si ṣe n poungbẹ adẹrinposonu naa, lo mu ka fi ọrọ wa Baba Suwe lẹnu wo, ki ọkan araalu le balẹ pe, alaafia ni baba wa.
Nigba to n ba BBC Yoruba sọrọ, Baba Suwe ti ohun rẹ ko fi bẹẹ ja gaara ni oun dupẹ lọwọ Ọlọrun pe o da ẹmi oun si ninu ipenija ara ti oun la kọja.
O salaye pe ẹgbẹ osere TANPAN duro ti oun lasiko ti oun ṣe aisan, to fi de ori awọn alagbata sinima ati ọpọ eeyan miran, ko to di pe Ọlọrun la oun.
Baba Suwe, ẹni to ranti iku aya rẹ, Mọladun Kẹnkẹlẹwu, to jẹ gbajumọ oṣere tiata miran nigba aye rẹ, lasiko ifọrọwerọ naa wa fajuro pe, oun mọ iku iyawo oun naa lara, ti oun si n ṣe aaro rẹ ni ojoojumọ.
Oríṣun àwòrán, @Austynzogs
"Baba Suwe ni ""n ko tii ni iyawo miran tabi ọrẹbinrin kankan rara lẹyin iku Moladun aya mi titi di akoko yii, kii si ṣe pe o wu emi naa lati da duro."""
Nigba to n sọrọ lori aheso ọrọ kan to ni Baba Suwe lo lu iyawo rẹ titi ti onitọun fi jade laye,
Baba Suwe ni eyi ko ri bẹẹ rara nitori ko si ija abi ita ni aarin awọn, oun ko si lọwọ ninu iku obinrin naa.
Lori oju to fi wo ipo ti awada ṣiṣe ninu ere tiata de duro lode oni, adẹrinposonu naa tun woye pe, ọpọ awọn eeyan to n ṣe awada lasiko yii ni wọn n ṣe gudugudu meje ati ya ya mẹfa nitori ko rọrun lati pa awọn eeyan ni ẹrin.
"Emi gan an ti ni ọmọ to n ṣe awada lagbo iṣẹ tiata, orukọ rẹ si ni Olusola Omidina.
Nigba toun naa bẹrẹ si i ba BBC Yoruba sọrọ, Olusola ọmọ baba Suwe ni, aṣeyọri ti baba oun ṣe ninu isẹ tiata lo ṣe iwuri fun oun, lati dara pọ mọ awọn oṣere tiata.
Olusola, ẹni to kọ ẹkọ nipa sinima ṣiṣe nilẹ Amẹrika fikun un pe, ọpọ ipenija ni oun n koju nidii isẹ naa, ti awọn osere yoku kii si fẹ pe oun lati wa ṣiṣẹ pẹlu wọn.
Nigba to n sọrọ lori aisan to n ṣe Baba rẹ, Olusola ni nkan ko fi bẹẹ dabi mọ fun baba mi nitori oju apa ko jọ oju ara fun un, bi aisan naa si ṣe n lọ, lo tun n pada, ti ọrọ naa ko si ye mi mọ rara."""
Òwe: Kí ni ìtumọ̀ òwe ikú tó ń pa ojúgbà ẹni?
Olusola wa gba ẹnikẹni to ba nifẹ si ere tiata nimọran pe onitọhun gbọdọ kawe bo ṣe yẹ, ko ni suuru, ko ma si tori owo se iṣẹ ọhun, nitori iṣẹ tiata ko ni owo gidi lori.
Bẹẹ ba gbagbe, ileesẹ aṣọbode nilẹ wa gbe Baba Suwe si ahamọ lọjọ kẹrinla, oṣu kẹwaa, ọdun 2011, eyiun ọdun mẹsan an sẹyin lori ẹsun pe o gbe oogun oloro.
Ọrọ naa di tile ẹjọ, ti Baba Suwe si jare bo tile ẹjọ si ni ki Ileesẹ aṣọbode san ẹgbẹrun lọna ọgọrun un pọun fun un, gẹgẹ bii owo 'gba ma binu'.
Nigba to n fi idi rẹ mulẹ boya baba rẹ ti ri owo naa gba lọwọ Ileesẹ aṣọbode, Olusola ni Ileesẹ aṣọbode nilẹ wa ko fun baba oun ni kọbọ ninu owo tile ẹjọ ni ki wọn san fun baba oun, lori iya ti wọn fi jẹ ẹ ní ahamọ.
"Amọ ko sai yan ọrọ rẹ pe, ""igbakeji aarẹ, ni orukọ ijọba apapọ, ti tọrọ aforijin lọwọ baba mi lori iṣẹlẹ naa, ti a si ti fi ija fun Ọlọrun ja, fọwọ lẹran."""
O ni iku agbẹjọrọ to n ba baba oun ṣe ẹjọ ifiyajẹni lọna aitọ naa, Bamidele Aturu, lo mu akude nla ba igbesẹ gbigba owo naa.
Ṣugbọn a ti gba kamu nitori owo tile ẹjọ ni ki Ileesẹ aṣọbode san fun baba mi gan an kere, si iye owo to fi tọju ara rẹ fun aisan loke okun.
Damilọla Ajayi: Ọ̀dá owó ló ṣún mi dé ìdí lílo ìyarun bíi fèrè
Oríṣun àwòrán, Baba wande/aluwe/Elẹṣọ/baba suwe/  suwe/ Inst
Ni ọdun 1988 ni sinima agbelewo akọkọ jade lorilẹede Naijiria
Ere sinima agbelewo ede Yoruba ti gbẹrẹgẹjigẹ di igi alọye, ti owo rẹ si ti to ẹgbẹlẹgbẹ biliọnu naira bayii.
Sugbọn lara awọn osere to gbe ẹka amuludun naa de ipo nla to wa loni, ni awọn adẹrinpoṣonu ti wọn wa lasiko ipilẹ sinima Yoruba.
Ko si ani-ani pe, Yoruba lo pilẹ ere sinima agbelewo lorilẹede Naijiria, ti awọn agba oṣere Yoruba bii, Hubert Ogunde, Iṣọla Ogunṣọla, Ogunmọla, Ade Afọlayan, Adelove, Baba sala ati bẹẹbẹẹ si gbe ere itage de ibi to ga.
Lẹyin eyi ni Muyideen Aromirẹ gbe sinima agbelewo akọkọ, to pe akọle rẹ ni 'Ẹkun' jade ni ọdun 1988.
Ohun kan pataki ti awọn sinima bii Aṣiri nla, Ti Oluwa nilẹ, ati bẹẹ bẹẹ lọ lo lati fi fa oju awọn eeyan mọra lasiko naa ni lilo awọn adẹrinpoṣonu ninu awọn sinima wọn nigba naa.
Eyi ni akojọpọ awọn adẹrinpoṣonu ti wọn ti logba ni agbo sinima ni ilẹ Yoruba, amọ ti oju wọn ko fi bẹẹ se deede mọ ninu awọn fiimu agbelewo.
Baba Suwe:
Gbajugbaja ati ilumọọka apanilẹ́rìn ín ni Babatunde Omidina, ti ọpọ eeyan mọ si 'baba suwe' lagbo adẹrinpoṣonu ninu sinima ni ilẹ Yoruba. O si jẹ orukọ kan to lọ fun ọpọ ọdun.
Ni ipilẹ sinima ni ilẹ Yoruba, gbogbo awọn onworan ni igba naa ni wọn maa n foju wa arakunrin rọgbọdọ aboju dudu họhọhọ pẹlu ṣokoto ti o tobi juu lọ, ti o fi okun ẹran nla so pẹlu ẹwu agbotutu lọrun.
Ko si ile ti ko fẹrẹ mọ Baba Suwe ni igba naa.
Ikorodu Bois: Ko si ẹni ti a kò lè sín jẹ!
Ọdun 1958 ni wọn bi Babatunde Omidina, ti ọpọ mọ si Baba Suwe ni  ilu Eko.
Ni ọdun 1972 ni Baba Suwe di osere tiata sugbọn sinima Ọbalende lo gbe orukọ rẹ jade. Bakan naa ni awọn sinima bii Iru ẹsin, Baba jayejaye ati ọpọ sinima miran tun gbe orukọ rẹ jade.
Lẹnu lọwọlọwọ yii, oju gbajugbaja adẹrinpoṣonu yii ko fi bẹẹ han mọ ninu sinima.
Aluwẹ, ọmọ iya Alaro:
Oríṣun àwòrán, Aluwe/instagram
Ko si aniani pe yoruba lo pilẹ ere sinima agbelewo lorilẹede Naijiria
Ṣaṣa ni awọn ti o mọ ipilẹ ere sinima ede Yoruba, ti ko mọ nipa Sunday Ọmọbọlanle ti ọpọ eeyan mọ si Aluwẹ tabi Papi Luwẹ.
Baba Mero, Ọga mi lo fun ni orukọ Aluwẹ ti mo n jẹ ninu ere, ṣugbọn agba olorin, Sunny Ade lo fi Papiluwẹ kun un.
Ilu Ilọra ni ipinlẹ Ọyọ, ni wọn bi Aluwẹ si ni ọdun 1954. Lati aye ere ori itage wọ sinima onifọnran celulloid ni Aluwẹ ti n da bira.
Nitori ipa ti o ko ninu ẹka amuludun lorilẹede Naijiria, ni ijọba apapọ se fi ami ẹyẹ orilẹede Naijiria, MON daa lọla.
Lori mohunmaworan akọkọ nilẹ wa, to wa nilu Ibadan, (NTA Ibadan) ni orukọ Aluwẹ ti kọkọ gbalẹ kan, nigba to n sere Awada Kẹrikẹri pẹlu ọga rẹ, baba Mero ati Adebayọ Salami, ta mọ si ọga Bello.
Nigba to ya ni oju rẹ di gbjumọ ninu awọn ere sinima bii, Adun Ewuro, Konkobilo, Oba Alatise ati bẹẹ bẹẹ lọ.
Opẹbẹ:
Oríṣun àwòrán, Miliki express
Yọmi King ti ọpọ Ọpẹbẹ
Yọmi King ni orukọ abisọ rẹ ṣugbọn Ọpọbẹ ni orukọ ti ọpọ eeyan mọọ si gẹgẹ bii orukọ ti o maa n jẹ ninu awọn sinima.
Ẹyẹ meji kii jẹ aṣa ni ọrọ Ọpẹbẹ ninu sinima nitori oun naa ni oṣere apanilẹrin ti o maa n gbe iwa akanda ẹda ti ọwọ n dun wọ, ninu sinima Yoruba.
Ọmọ ipinlẹ Ogun ni, ere ọlọsọọsẹ ori mohunmaworan ti wọn n pe ni 'Ẹrin keeke' ni o gbe Ọpẹbẹ saye ni ọdun 1987 lori ikanni mọhunmaworan Channel 8.
Ọpọ ere ti baba Suwe ba ti kopa, naa ni Ọpọbẹ maa saba n kopa ninu rẹ.
Ẹlẹṣọ ẹnu n ja waya:
Oríṣun àwòrán, Eleso adewale/ facebook
Afin to da yatọ ninu sinima ni Adewale Ẹlẹṣọ ti ọpọ mọ si ẹlẹṣọ ẹnu n jawaya
Afin to da yatọ ninu sinima ni Adewale Ẹlẹṣọ, ti ọpọ mọ si Ẹlẹṣọ ẹnu n jawaya. Nitori awọn ọrọ nlanla ti o maa n sọ ninu sinima, lo faa ti awọn eeyan fi n pee ni orukọ yii.
Iṣẹ nọọsi, iyẹn olutọju alaisan ni ẹlẹṣọ n ṣe ki o to di elere itage.
Ohun ti o da Ẹlẹsọ yatọ si awọn adẹrinpoṣonu yoku ni ọrọ kabiti ẹnu rẹ ti ko lee ṣai dẹrin pẹrẹkẹ eniyan to ba wo sinima ti o ba wa.
Amọ oju tiẹ gan ko fi bẹẹ se deede mọ ninu ere tiata.
Dẹjọ Tunfulu:
Oríṣun àwòrán, Dejo tunfulu
Ohun ọmọde ni o da Dẹjọ yatọ laarin awọn adẹrinpoṣonu yooku ẹgbẹ rẹ
Ọkan lara awọn apanilẹrin to gbajugbaja ni ipele sinima agbelewo ede Yoruba ni Kunle Makinde Tokunbọ ti ọpọ mọ si Dẹjọ Tunfulu.
Agbegbe Idumọta ni ilu Eko ni wọn bi Dẹjọ tunfulu si ni ọdun 1969, ṣugbọn ọmọ ilu Abẹokuta ni.
Ohun ẹnu rẹ ti o dabi ti ọmọde ni o da Dẹjọ yatọ laarin awọn adẹrinpoṣonu yooku. Ohun yii gan ni o fa orukọ 'tunfulu' ti wọn n pe e ninu awọn sinimọ ti o ti kopa.
Ọdun 1987 ni mo ti bẹrẹ si nii ṣe ere itage. Mo si maa nkopa ninu 'Tiata Ọmọde' lori ikanni Channel 7 mohumaworan apapọ ilẹ Naijiria, NTA .
Dẹjọ ti kopa ninu awọn sinima bii Tori ife, Aya rere, Owo o mo agọ, Born boy, Ẹrọ ibanisọrọ, Ejide, Itọ, adigun ati bẹẹbẹẹ lọ.
Baba Wande:
Oríṣun àwòrán, Babawande/instagram
Manigbagbe ni sinima 'Ti Oluwa nilẹ' pẹlu ipa ti Baba Wande ko gẹgẹ bii Oloye Ọtun
Ara awọn agba ọjẹ ere sinima ede Yoruba ni Alhaji Kareem Adepọju, ti ọpọ mọ si 'Baba Wande' , o si ti lo to ọdun marunlelaadọta ninu ere itage ati sinima.
Ẹgbẹ Oṣere oloogbe alagba Oyin Adejọbi ni baba wande ba ṣiṣẹ pọ fun ọpọlọpọ ọdun, ṣugbọn ninu ere 'Ti Oluwa ni ilẹ’ ti o jade ni ọdun 1993 ni Baba Wande ti di gbajugbaja ni Naijiria titi de oke okun.
Ipa 'oloye Ọtun' ti o ta ilẹ oriṣa ninu sinima naa, si ni baba Wande se.
Awọn sinima bii Ti oluwa ni ile (1993), Obukọ Dudu, Ẹkun Ọkọ Oke, Ayọ ni mo fẹ (1994), Nkan asiri (2005), Oyatọ (2002) Obinrin Sọwanu(2004), Aya mi ọwọn: Madam Dearest (2005) Durodọla (2005) Atanpako ọtun (2007) ati bẹẹbẹẹ lọ ni diẹ lara awọn iṣẹ ti Baba wande ti ṣe.
Sugbọn nibo ni Baba Wande wa lasiko yii ninu ere tiata, gẹgẹ bii awọn yoku ti a ti mẹnuba saaju?
'Logo Benz yóò lẹ́yìn fún àwọn ọ̀dọ́ tó bá ṣògùn owó'
Olamide ati Lil Kesh dá wàhálà sílẹ pẹ̀lú 'Logo Benz'
Minimum wage: Gbogbo ìpínlẹ̀ tó wà ní Nàíjíríà ní ìwọ́de NLC yóò ti wáyé
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ọ̀rọ̀ ẹ̀kúnwó oṣù tuntun ló ń fa èdèàìyedè láàárín ìjọba àpapọ̀ àti àwọn ẹgbẹ́ òṣìṣẹ́ lórílẹ̀èdè Nàìjíríà
Ẹgbẹ oṣiṣẹ lorilẹede Naijiria ti kede pe lọjọ Isẹgun ni iwọde apapọ awọn oṣiṣẹ yoo bẹrẹ jakejado orilẹede Naijiria.
Dipo iyanṣẹlodi, eyi ti ọpọ ọmọ orilẹede Naijiria n fọkan si tẹlẹ, ẹgbẹ oṣiṣẹ ni iwọde nikan ni yoo waye bayii.
"Atẹjade kan ti akọwe agba fun ẹgbẹ oṣiṣẹ NLC lorilẹede Naijiria fi sita ni ''lẹyin ipade ti agbarijọpọ ẹgbẹ oṣiṣẹ gbogbo lorilẹede fi sita ni ọjọ kẹtadinlogun oṣu Kejila ọdun 2018, ni ipinnu lati gunle iwọde dipo iyanṣẹlodi ti waye."""
 Lẹsẹkẹsẹ ni a ti fi ikede sita pe, ni ọjọ Iṣẹgun, tii ṣe ọjọ kẹjọ oṣu Kinni ọdun 2019, iwọde apapọ yoo waye lati fi ẹhonu han kaakiri gbogbo ipinlẹ lorilẹede Naijiria. Ṣugbọn eyi ko tumọ si iyanṣẹlodi.
Alao Akala:Èmi àti Ajimọbi kò ṣe ìlérí kankan fún ara wa
Agbarijọpọ ẹgbẹ oṣiṣẹ labẹ, NLC, TUC ati ULC n fi ẹhonu han lori bi ijọba apapọ ṣe kuna lati fi aba ofin nipa sisan ẹkunwo oṣu tuntun ranṣẹ si ile aṣofin apapọ fun lati fọwọsi.
Yinka Ayefele fi orin ẹ ṣeun sẹ́nu lórí ilé orin tuntun rẹ̀
Oríṣun àwòrán, yinkaayefele
Yinka Ayefele
Gbajúgbajà olórin tó tún jẹ́ alága ilé iṣẹ́ rẹ́díò Fresh FM nílùú Ibadan, yinka Ayefẹlẹ gbóríyìn fún Gómìnà Abiọla Ajimọbi pé ó tún ilé orin rẹ̀ kọ̀.
Nínú ọ̀rọ̀ tí mọ̀lúmọ̀ọ́ká olórin náà fi síta lọ́jọ́ ajé ni Ayefẹlẹ dúpẹ́ lọ́wọ́ gómìnà Ajimọbi fún ìgbésẹ̀ yìí.
Orangun: Èdè àti àṣà Yorùba ní láti jọ wá lójú
Ọdún 2018 ni wọ́n bẹ̀rẹ̀ àtúnṣe ilé náà èyí tí wọ́n ti párí báyìí gẹ́gẹ́ bí àwọn oníròyìn ṣe jábọ̀.
Ṣáájú ni ìjọba Abiọla Ajimọbi wó lára ilé náà lulẹ̀ látàrí pé wọ́n ni Yinka Ayefẹlẹ rú òfin ìpínlẹ̀ tó ní ṣe pẹ̀lú ìlànà ilé kíkọ.
Ẹ̀wẹ̀, ìgbésẹ̀ yìí ti fa ọ̀pọ̀lọpọ̀ awuyewuye káàkiri yálà láti gbè lẹ́yin ohun tí gómìnà Ajimọbi ṣe tàbí ta kò ó.
ASUU strike : Ìdí tí àwọn olùkọ́ kò ṣe tíì f'òpin sí ìyanṣẹ́lódì
Oríṣun àwòrán, Frédéric Soltan
Ijọba orileede Naijiria ti kede pe awọn ti yanju awọn olukọni ile ẹkọ fasiti  ti wọn  gun le iyanṣẹlodi.
Ikede naa waye lẹyin ipade kan ti wọn ba awọn olukọ naa ṣe lọjọ Aje.
Minisita fun ọrọ igbanisiṣẹ, Chris Ngige to kede ọrọ yi fun awọn akọroyin sọ pe ijọba ti buwọlu sisan owo to le ni biliọnu mẹẹdogun fun atunṣe awọn ile ẹkọ fasiti ati wi pe Aarẹ Buhari ti ni ki wọn san ogun biliọnu naira fun sisan owo oṣu ti ijọba jẹ awọn olukọ naa lati ọdun 2009 si 2012.
Aarẹ ẹgbẹ awọn olukọ ni fasiti Naijiria, Biọdun Ogunyẹmi ti oun naa wa nibi ipade naa sọ wi pe igbimọ alaṣẹ́ ẹgbẹ naa yoo ṣe ipade lati ṣe agbeyẹwo nnkan ti ijọba sọ.
Biodun ni lyin ipade yi ni awọn yoo sọ boya iyanṣẹlodi yoo tẹsiwaju si tabi yoo dopin.
Gẹgẹ bi oun to sọ, awọn nkankan ṣẹku tawọn yoo jiroro le lori ki wọn to le so iyanṣẹlodi naa to bẹrẹ lọjọ kẹrin ọdun 2018 rọ.
Ekiti: Lẹ́yìn t'áwọn kan gba òmìnira, wọ́n tún jí òṣìṣẹ́ kánsù míràn gbé
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Iru ijinigbe yii gbilẹ nipinlẹ Ondo to muleti ipinlẹ Ekiti ni 2018.
Alukoro fun ileeṣẹ ọlọpaa nipinlẹ Ekiti, Caleb Ikechukwu sọ pe lootọ ni awọn ajinigbe tun ji awọn oṣiṣẹ ijọba ibilẹ mi i gbe nipinlẹ naa.
Ikechukwu sọ fun BBC Yoruba pe ni ọjọ Aje, ọjọ keje Osu kinni ni awọn ajinigbe naa gbe awọn oṣiṣẹ ijọba ibilẹ Gbọnhin kan, ati awakọ rẹ gbe, ṣugbọn ileeṣẹ ọlọpaa ti doola awakọ naa lọjọ Aje yii kan naa.
Ṣaaju ni iru iṣẹlẹ yii waye ni ọjọ keji oṣu kinni ọdun 2018 nibi ti awọn ajinigbe ti ji awọn oṣiṣẹ ijọba ibilẹ Emure to wa nipinlẹ Ekiti gbe.
Awọn mejeeji ọhun, ni wọn gbe loju ọna to so Ikẹrẹ, Isẹ ati Emure pọ, ni nnkan bi aago mẹjọ alẹ.
Ṣugbọn wọn pada gba ominira lẹyin ọjọ perete.
Iru ijinigbe yii gbilẹ nipinlẹ Ondo to muleti ipinlẹ Ekiti ni 2018, paapa loju ọna to lọ lati ilu Ọwọ si Ikarẹ-Akoko, ti awọn kan si n fi ẹsun kan pe awọn daran-daran Fulani lo wa nidi iṣẹlẹ naa. Ileeṣẹ ọlọpaa tako eyi.
2019 Elections: Níbo la bá ètò ẹ̀kọ́ dé?
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Aarẹ Buhari
Awọn oludibo ni Nigeria yoo ma a dibo sipo aarẹ ni 19 February lati yan ẹni ti wọn fẹ nitori ohun ti awọn oludije naa ti sọ.
Sugbọn bawo ni wọn yoo se mọ wi pe ohun ti wọn sọ jẹ otitọ?
Lati ibẹrẹ ọsẹ yii, BBC yoo ma a se agbeyẹwo ọrọ ti awọn oludije to gbajugbaja ti sọ lori ohun ti awọn yoo se lori eto ẹkọ, eto ilera, eto ọrọ aje ati eto aabo.
Agbeyẹwo naa yoo da lori awọn akọsilẹ to han si gbangba.
Eto ẹkọ lorilẹede Nigeria ni a o kọkọ ma a gbeyẹwo.
Eto ilana ẹkọ ti ọdun 1999 ni ki ijọba pese eto ẹkọ ọfẹ fun awọn akẹẹkọ ni ile iwe alakọbẹrẹ. Awọn akẹẹkọ gbọdọ lọ si ile iwe alakọbẹrẹ ati ọdun mẹta to saaju ni girama, amọ ti ijọba ipinlẹ ko nii san owo yii.
Ilana yii ko sọ iye akọ ati abo ti wọn gbọdọ lo si  ile iwe ni igba kan naa, ṣugbọn lorilẹede Naijiria bayii, awọn ọkunrin n lọ si ile iwe ju awọn obinrin lọ.
Nitorina ipese ma n wa fun awọn obinrin lati le wọ ile iwe ki iye wọn ba le dọgba pẹlu awọn ọkunrin wọn.
Ẹka Ajọ Isọkan Agbaye to n risi eto ẹkọ, Unesco sọ wi pe eto igbani si ile iwe laarin akọ si abọ, gbọdọ jẹ 98 ati 102 awọn obinrin si iye 100 ọkunrin to ba wọle si ile iwe.
Amọ, ayẹwo fihan wi pe o din ni ipinlẹ kan ninu mẹta to n wo iye awọn obinrin si ọkunrin to wa ni ile iwe alakọbẹrẹ. Ni ile iwe girama ti ọlọdun mẹta ti ipele akọkọ, ipinlẹ mẹsan lo ni eto yii, nigbati ile iwe girama ti awọn akẹẹkọjade ko ju ipinlẹ mẹta.
Ipinlẹ Ekiti lo ṣe daadaa ju nipa wiwo alafo to wa laarin akọ sabo ni gbogbo ipele eto ẹkọ.
Katsina lo gbẹyin ninu eto yii, 170,000 ni iye ọkunrin fi ma n po ju obinrin lọ ni ile iwe alakọbẹrẹ. Nigbati ile iwe girama ọlọdun mẹta akọkọ ma n fi  43,000 po ju awọn obinrin lọ. Nigbati 44,500 ọkunrin po ju obinrin lọ ni ile iwe girama ọlọdun mẹta alakọjade.
Ṣugbọn ipinlẹ Zamfara lo buruju nipa gbi gba awọn ọmọbinrin si ile-iwe. Ni gbogbo eto ile iwe ni iye awọn ọkunrin ti pọ ju awọn obinrin lọ ni ilọpo meji.
Iru eto ẹkọ ti awọn ọmọ yii n gba ni ile iwe naa ṣe pataki. Gẹgẹ bi akọsilẹ Ajọ Nigerian Education Data Survey (NEDS) ni ọdun 2015, 44% awọn akẹẹkọ to wa ni ile-iwe alakọbẹrẹ ti ijọba lo mọ iwee ka, nigbati 74% awọn akẹẹkọ to wa ni ile iwe aladani lo mọ iwe ka. Amọ, ni ile iwe ti ọlọdun mẹta akọkọ ni girama, awọn to mọ iwee ka ati kikọ jẹ 91% ati 96%.
Aarẹ Buhari ti seleri lati fi 15% owo isuna ọdun si eto ẹko, amọ akọsilẹ isejọba rẹ fihan wi pe o nilo lati se ju bẹẹ lọ lati le mu ileri naa ṣẹ.
Ni ọdun 2016, ijọba Buhari fi 8% owo isuna si eto ẹkọ ati ni ọdun 2017 ni o walẹ si 7.4%. Ni ọdun 2018,  7% ni wọn ya sọtọ lara owo isuna ọdun to jẹ bii 650bn naira ($1.8bn, £1.4bn).
Bi Aarẹ Buhari ba fẹ mu ileri rẹ sẹ, o gbọdọ fi kun owo isuna eto ẹkọ si bii 1.3tn naira, tabi ki o din owo isuna ẹka miiran ku.
Ni ọdun 2018, ijọba apapọ fi owo to to 650bn naira si ẹka eto ẹko, ti ida meji lọna mẹta (407.8bn naira) si yẹ ko jẹ fun sisan owo oṣu awọn osisẹ.
Ẹwẹ, iye owo ti wọn fi n san owo osu yii fẹrẹ dọgba pẹlu owo isuna fun eto abo ati wi pe owo perete  (12.2bn naira) ninu rẹ ni wọn fi n san owo oṣu awọn ọmọogun ilẹ naa.
Ni ọdun yii bakan naa ni ijọba pinnu lati na N418bn lapapọ, eleyii to fẹrẹ dọgba pẹlu owo oṣu fun awọn to wa ni ẹka eto ẹkọ.
12.2bn naira ni owo ti wọn la kalẹ fun sisan owo oṣu awọn ọmọogun orilẹede Naijiria.
Ti wọn ba pa a pọ mọ owo oṣu awọn ti iṣẹ wọn jọ mọ ti ọlọgun (164bn naira), apapọ owo naa ko tii to iye owo ti ijọba n lo fi san owo oṣu awọn oṣiṣẹ ni ẹka eto ẹko, ti ko si to 1tn naira ti Atiku Abubakar sọ wi pe wọn n na.
Boya owo oṣu naa de ọdọ awọn oṣiṣẹ naa tun jẹ ọrọ miiran to yẹ lati gbe yẹwo.
Gẹgẹ bi agbeyẹwo Ajọ Sub-National Salary Survey ti wọn gbe jade ni Oṣu Kẹsan, 2018 lati ọwọ Ajọ to n tọ pipin bi ijọba se n na owo, BudgIT, ipinlẹ 12 ninu 35 ni ko i tii san owo oṣu awọn olukọ ti wọn jẹ.
Atupalẹ yii yoo mu ki awọn eniyan kiyesi eto ilana oṣelu awọn oludije yatọ si ẹgbẹ oṣelu wọn.
Atupalẹ yii yoo jẹ otitọ, ti ko si ni fi si apa kan ju ti omiran lọ pẹlu akiyesi si awọn ohun ti ẹgbẹ oṣelu yii yoo ṣe fun awọn ara ilu.
Orangun: Èdè àti àṣà Yorùba ní láti jọ wá lójú
Saraki san owó oṣù òṣìṣẹ́ ní Kwara
Oríṣun àwòrán, Bukola saraki
Ìṣòro ńlá ni sísan owó oṣù òṣìṣẹ́ jẹ́ fún ìpínlẹ̀ Kwara àti àwọn ìpínlẹ̀ gbogbo lórílẹ̀èdè Nàìjíríà.
Aarẹ ile aṣofin agba lorilẹede Naijiria, Sẹnetọ Bukọla Saraki ti san owo oṣu awọn oṣiṣẹ ijọba ibilẹ irẹpọdun ni ẹkun idibo apapọ gusu ni ipinlẹ Kwara.
Ni oṣu kejila ọdun 2018 ni Saraki ṣeleri ati san owo oṣu awọn oṣiṣẹ bẹrẹ pẹlu ijọba ibilẹ kọọkan kaakiri ẹkun idibo apapọ mẹtẹẹta to wa ni ipinlẹ Kwara.
Alaga ijọba ibilẹ Irẹpọdun, Muyiwa Ọladipọ lo kede rẹ ni ilu Omu aran.
Miliọnu mẹtadinlogun o din ẹgbẹrun lọna ọgọrun naira ni Saraki gbe kalẹ fun sisan awọn owo oṣu ti wọn jẹ awọn oṣiṣẹ.
Kii ṣe iroyin mọ pe ajẹẹlẹ owo oṣu oṣiṣẹ jẹ iṣoro nla ni ipinlẹ Kwara gẹgẹ bi o ṣe jẹ fun ọpọ ipinlẹ jakejado Naijiria. Gbogbo awọn ẹgbẹ oṣiṣẹ ni ijọba ibilẹ naa ni wọn  kan sara si igbesẹ naa ni kete ni iro owo bẹrẹ si nii dun lapo awọn oṣiṣẹ naa.
Orangun: Èdè àti àṣà Yorùba ní láti jọ wá lójú
Lagos 2019: Àwọn ọmọ ẹgbẹ́ awakọ̀ èrò ṣíná ìbọn níbi ìpolongo ìbò Sanwo-Olu l'Eko
Oríṣun àwòrán, PMnews
Gómìnà Ambọde ni ó ń sọ̀rọ̀ nígbà tí wàhálà náà bẹ́ sílẹ̀
Oniroyin mẹta lo faragbọta nibi ipolongo idibo oludije ipo gomina ipinlẹ Eko labẹ aṣia ẹgbẹ oṣelu APC, Babajide Sanwo-olu nilu Eko ni ọjọ iṣẹgun.
Nibi ipolongo idibo ọhun to waye ni gbagede Skypower field ni Ikeja nilu Eko ni wahala ti bẹ silẹ ni nnkan bii agogo kan abọ ọsan lasiko ti gomina Akinwumi Ambọde fi wa lori pepele nibi ti o ti n sọ ọrọ rẹ.
Gẹgẹ bii iroyin ti o n tẹ BBC News Yoruba lọwọ ṣe sọ, laaarin awọn igun ẹgbẹ awakọ ero NURTW meji ni ina wahala naa ti suyọ ti wọn si bẹrẹ si nii yibọn fun ara wọn.
Lara awọn ti ọta ibọn ba ni oniroyin kan lati ileeṣẹ iwe iroyin the Nation, Emmanuel Oladesu, Temitọpẹ Ogunbanke lati iwe iroyin NewsTelegraph pẹlu ayaworan ileeṣẹ mohunmaworan Ibilẹ Television, Abiọdun Yusuf atawọn eeyan miran.
Amọṣa, ileeṣẹ Ọlọpaa nipinlẹ Eko ni awọn ṣi n ṣe iwadii lori ọrọ naa ati pe laipẹ ni atẹjade yoo jade lori rẹ.
Alao Akala:Èmi àti Ajimọbi kò ṣe ìlérí kankan fún ara wa
Alukoro ileeṣẹ ọlọpaa nipinlẹ Eko, Chike Otti ni oju awọn agbofinro to gbogbo ohunkorun to ba fẹ da omi alaafia ipinlẹ naa ru.
Ninu atẹjade ti Sẹsan Daini to jẹ alukoro ileeṣẹ ipolongo ibo fun sanwo -olu, oludije ẹgbẹ oṣelu APC fun ipo gomina ni ipinlẹ Eko, lootọ ni wahala bẹ silẹ ṣugbọn laarin awọn ọmọ ẹgbẹ kan ni.
wahala to waye lopin eto naa wa laaarin awọn igun ẹgbẹ meji kan ti wọn wa nibi eto naa.
Iroyin  tun ṣalaye pe nṣe lawọn janduku lo anfani wahala to bẹ silẹ naa lati fi ja ọpọ awọn eeyan to wa fun ipolongo naa lole awọn ohun ini wọn.
Minimum wage: Ẹgbẹ́ òṣìṣẹ́ àti ìjọba àpapọ̀ fẹnukò lórí àbá òfin ẹ̀kúnwó oṣù
Ọjọ́ kẹtàlélógún oṣù kíní ni ìjọba yóò gbé àbá òfin náà lọ síwájú ilé aṣòfin àpapọ̀.
Ẹgbẹ oṣiẹ ati ijọba apapọ ti fẹnuko lori adehun bi aba ofin ẹkunwo oṣu tuntun yoo ṣe de ọwọ awọn aṣofin apapọ.
Ọjọ iṣẹgun, ti awọn ẹgbẹ oṣiṣẹ gunle iyanṣẹlodi jakejado orilẹede Naijiria ni ifẹnuko naa to kẹsẹjari lẹyin ifikunlukun ọjọ mẹta.
Gẹgẹ bii minisita fọrọ oṣiṣẹ ati igbanisiṣẹ, Dokita Chris Ngige ni ijọba apapọ yoo gbe aba ofin ẹkunwo osu tuntun naa ṣọwọ sọdọ awọn aṣofin apapọ ni ọjọ kẹtalelogun oṣu kini ọdun 2019 bi awọn aṣofin naa ba wọle pada sẹnu iṣẹ.
Orangun: Èdè àti àṣà Yorùba ní láti jọ wá lójú
O ni gbogbo awọn ipade igbimọ iṣakoso gbogbo to yẹ ni aba naa yoo de ki wọn to gbee lọ siwaju awọn aṣofin apapọ.
Amọṣa, awọn aṣaaju ẹgbẹ oṣiṣẹ ti kilọ fun ijọba apapọ pe ko gbọdọ fi ọbẹ ẹyin jẹ awọn oṣiṣẹ niṣu lori adehun naa.
Lagos APC Rally: MC Oluọmọ fara gb'ọ̀bẹ níbi ìpolongo ìbò
Nibi ipolongo ibo APC to waye nipinlẹ Eko, wahala bẹ silẹ, Musiliu Akinsanya ti gbogbo eniyan mọ si MC Oluọmọ si fara gbọgbẹ.
Ileeṣẹ ọlọpaa ni ipinlẹ Eko ti kede pe wọn n wa ọkunrin kan, Mustapha Adekunle, ti inagijẹ rẹ n jẹ seigo.
Iroyin to tẹ BBC Yoruba lọwọ ni pe wọn fi ẹsun kan Seigo ni pe o gbiyanju lati da eto ipolongo ibo ita gbangba ti ẹgbẹ oṣelu All Progressives Congress, APC ṣe nipinlẹ naa.
Bakan naa la gbọ wi pe nibi wahala to waye lasiko ipolongo ọhun ti oludije fun ipo gomina labẹ asia ẹgbẹ APC, Babajide Sanwo-Olu fi ṣide ipolongo ibo rẹ, ni ọkan lara awọn oloye ẹgbẹ awakọ eero nipinlẹ Eko, MC Oluọmọ naa fi ara pa.
Iroyin naa sọ pe gígún ni awọn janduku gún Oluọmọ to jẹ oloye ẹgbẹ awọn awakọ lasiko ti wahala naa waye.
Lara awọn ti ọta ibọn ba ni oniroyin kan lati ileeṣẹ iwe iroyin the Nation, Emmanuel Oladesu, Temitọpẹ Ogunbanke lati iwe iroyin NewsTelegraph pẹlu ayaworan ileeṣẹ mohunmaworan Ibilẹ Television, Abiọdun Yusuf atawọn eeyan miran.
Lori eyi, alukoro fun ileeṣẹ ọlọpaa l'Eko, Chike Oti ninu ikede kan to fi sita sọ pe lọgan ti iṣẹlẹ naa waye ni wọn gbe Oluọmọ ati awọn mii to tun farapa lọ si ileewosan fun itọju.
Ati wi pe ki awọn ara ilu fi to ileeṣẹ ọlọpaa leti ti wọn ba gbọ ohunkohun tabi mọ ibi ti arakunrin Mustapha Adekunle ti wọn fi ẹsun kan wa.
BBC Debate: Abdulrahaman, Olùdíje APC yọ ara rẹ̀ kúrò nínú ìfọ̀rọ̀wérọ̀ ìtagbangba BBC ní Kwara
Oríṣun àwòrán, apc kwara media
Abdulrahaman Abdulrazak ní òun yóò máa ṣàlàyé ìdí tí òun kò fi ní kópa lọ́jọ́ iwájú
Ni ọjọbọ, ọjọ kẹwa oṣu kini ọdun 2019 ni ipade ifọrọwerọ itagbangba laaarin awọn oludije ipo gomina nipinlẹ Kwara atawọn araalu, yoo waye nilu Ilọrin.
Amọṣa, awọn eeyan ipinlẹ Kwara ko ni lanfani lati gbọ ọrọ lẹnu oludije ipo gomina lẹgbẹ oṣelu APC lẹyin ti o ti han gbangba pe ko ni wa.
MC Oluọmọ, fara gb'ọ̀bẹ níbi ìpolongo ìbò APC l'Eko
Buhari kò leè ṣàtìlẹyìn fún olùdíje Amosun l'Ogun
Saraki gbé N16.9m kalẹ̀ fún owó oṣù òṣìṣẹ́ ní Kwara
Ọgbẹni Abdulrazak Abdulrahaman to dije labẹ aṣia ẹgbẹ oṣelu APC fi iwe ranṣẹ si ileeṣẹ iroyin BBC news Yoruba ni ọ̀jọ́ diẹ si asiko ti eto naa yoo bẹrẹ pe ohun ko nilee wa ati pe oun yoo maa sọ fun awọn eeyan ipinlẹ naa lọjọ iwaju idi ti oun ko fi lee wa.
Abdulraham jẹ ọkan lara awọn oludije mẹrin ti awọn eeyan fi ibo ori ayelujara gbe kalẹ  pe awọn fẹ gbọ t'ẹnu rẹ nibi ipade ifọrọwerọ itagbangba naa eleyi ti ileeṣẹ BBC news Yoruba gbe kalẹ lati fi mu oju aje konisọ laaarin awọn oludije to fẹ di gomina atawọn araalu ti wọn yoo ṣejọba le lori.
Kwara yóò gbàlejò BBC Yoruba
Iyalẹnu lo jẹ fun mi pe ileeṣẹ iroyin BBC bẹrẹ si nii polongo orukọ mi gẹgẹ bii ara awọn ti yoo farahan nibi ipade ifọrọwerọ ọjọbọ nigba ti n ko fi igba kankan sọ fun wọn pe maa wa.
Gbogbo ọna to yẹ ni yiyẹ ni ileeṣẹ BBC News Yoruba yẹ lati kan si gbogbo awọn oludije tawọn araalu mu pe awọn fẹ ri nibi ipade naa.
Koda, ileeṣẹ BBC News Yoruba tun kan si Minisita feto iroyin, Lai Mohammed, to jẹ eekan ati aṣiwaju ẹgbẹ oṣelu APC ni ipinlẹ Kwara lori ipe ti a fi ranṣẹ si Oludije ẹgbẹ oṣelu naa; ti minisita feto iroyin pẹlu si tun fi idaniloju lelẹ pe yoo farahan nibi eto ọhun.
DR Congo: Àwùjọ àgbáyé ń polongo àláàfíà nítorí èsì ìdìbò ààrẹ
Oríṣun àwòrán, Reuters
Tshisekedi jẹ ọmọ olori ẹgbẹ alatako kan to ti d'oloogbe, Etienne Tshisekedi.
Ipe ti n jade kaakiri agbaye pe ki wọn fi aaye gba alaafia ni orilẹede DR Congo nitori esi idibo aarẹ to waye laipẹ yii.
Ajọ ilẹ Afrika, AU, ti pe fun ijiroro lẹyin ti ọkan lara awọn oludije, Martin Fayulu, kọ esi ibo ọhun to gbe Felix Tshisekedi t'oun naa jẹ ọmọ ẹgbẹ alatako wọle.
Bakan naa ni ijọ Aguda naa ni oun gbagbọ pe mago-mago wa ninu esi idibo naa, nitori pe eyi ti wọn kede ko papọ mọ akọsilẹ oun.
Ijọ naa ran ogoji ẹgbẹrun awọn oluwoye idibo lati mojuto eto idibo ọhun.
Bakan naa ni ijọba orilẹede France ati Belgium naa ti n dasi ọrọ ọhun.
Fayulu sọ fun BBC pe oun yoo lo ofin lati ja tako esi ibo ti ajọ eleto idibo kede.
Oríṣun àwòrán, Reuters
Fayulu sọ pe ''esi ibo ti wọn kede jina si otitọ.''
O fi ẹsun kan Tshisekedi pe o ṣe adehun pẹlu ẹgbẹ to wa ni iṣakoso, botilẹ jẹ pe Tshisekedi ti sẹ pe ọrọ ko ri bẹ.
Ipo kẹta ni oludije labẹ ẹgbẹ to wa nipo, Emmanuel Shadary ṣe.
Ìdá bi ogoji eniyan lo jẹ ọmọ ijọ Aguda l'orilẹede DR Congo, ijọ naa si da ọpọlọpọ ileewe ati ileewosan silẹ ni orilẹede ọhun.
Bakan naa ni awọn ọmọ orilẹede Congo maa n ri ijọ naa gẹgẹ bi ohùn otitọ, l'orilẹede ti eto oṣelu ti kun fun iwa ibajẹ.
Ajọ eleto idibo ti kede ọmọ ẹgbẹ́ alatako, Felix Tshisekedi pe o bori ninu eto idibo sipo aarẹ orilẹede Democratic Republic of Congo.
Awọn esi ibo ti wọn kọkọ gbe jade fihan pe o bori ọmọ ẹgbẹ alatako mii, Martin Fayulu, to ti n fapajanu bayii pe mago-mago wa ninu esi idibo ti wọn kede.
Ti esi idibo ọhun ba fi fidimulẹ, Ọgbẹni Tshisekedi ni yoo jẹ ọmọ ẹgbẹ alatako akọkọ to bori lati igba ti DR Congo ti gba ominira lọwọ orilẹede Belgium l'ọdun 1960.
Aarẹ to wa nipo lọwọlọwọ, Joseph Kabila yoo si fi ipo naa silẹ lẹyin ọdun mejidinlogun to ti wa nipo.
Ki eto idibo naa to waye ni Kabila jẹjẹ pe oun yoo gbe ijọba silẹ lọna to ba oju mu.
Ọjọ Aiku lo yẹ ki wọn kede esi idibo ọ̀hun. Bakan naa ni wọn ṣi le fi ẹhonu han si eto idibo to wa nilẹ bayii.
Oríṣun àwòrán, Fredrik Lerneryd
Ni owurọ kutu Ọjọbọ ni olori ajọ eleto idibo DR Congo, National Electoral Commission (Ceni), Corneille Nangaa, sọ pe Ọgbẹni Tshisekedi ni ida mejidinlogoji ataabọ ninu ibo ti araalu di, eyi to mu ko yẹ ni ẹni to bori.
Bi esi ibo naa ṣe ri:
Ṣugbọn, Ọgbẹni Fayulu to ti fi igba kan jẹ oniṣowo epo, kọ esi idibo naa, to si tun sọ fun ileeṣẹ iroyin Radio France Internationale pe oun ko lọw si i.
Tshisekedi jẹ ọmọ olori ẹgbẹ alatako kan to ti d'oloogbe, Etienne Tshisekedi. O si ti jẹjẹ lati gbogun ti oṣi l'orilẹede naa.
Ẹ wo bí ìjíròrò ṣe lọ láàrin àwọn olùdíje gómìnà Kwara
Ẹ wo ìpàdé ìtagbangba BBC News Yorùbá ní ìpínlẹ̀ Kwara bó ṣe ń lọ lọ́wọ́-lọ́wọ́:
Kini ohun tawọn oludije kọọkan n sọ ni ibi ipade itagbangba to n waye lọwọ fawọn oludije ipo gomina nipinlẹ kwara;
Ko si ijoba ibilẹ kankan ni Kwara ti ko ni ibudo irinajo afẹ.
Issa Arẹmu
Oríṣun àwòrán, AFP
Yinka Ajia
Forbes 2018 list: Àwọn ọmọ Nàìjíríà dẹ́bi àdínkù tó bá owó Dangote rú Ààrẹ Buhari
Oríṣun àwòrán, ERIC PIERMONT
Pupọ ninu owo Dangote wa lati idi ọja Dangote Cement rẹ
Ilumọka oniṣowo ọmọ orileede Naijiria Aliko Dangote ṣi ni ẹni to lowo julọ nilẹ Afrika ṣugbọn o da bii wi pe adinku ti ba owo rẹ.
Iwe iroyin atigbadegba Forbes lo gbe orukọ awọn to lowo julọ lagbaye sita fun ọdun 2018 ti wọn si ni ipo kini ni Dangote wa pẹlu biliọnu mẹwa dọla o le die.
Gẹgẹ bi nnkan ti iwe iroyin naa ti sọ, Dangote padanu biliọnu mẹji dọla latari bi nnkan ko ti ṣe lọ deede lẹka Dangote Cement rẹ.
Mike Adenuga to jẹ alaṣẹ ati oludari ile iṣẹ Globacom pọnwọ le Dangote nipo keji pẹlu biliọnu mẹsan dọla.
Aje bu igba jẹ daada lọdọ tirẹ pẹlu bi owo rẹ ṣe tẹ wọn si lati biliọnu maarun le die to wa tẹlẹ lọdun to kọja si biliọnu mẹsan lọdun yii.
Amọ ṣa iyipada to de ba owo Dangote yii ti mu iriwisi wa lati ọdọ awọn ọmọ Naijiria ti awọn kan si n naka abuku si ijọba Aarẹ Buhari gẹgẹ bi igi wọrọkọ to mu adinku ba owo Dangote.
Loju opo Twitter ọrọ naa jọ bi ẹrin ṣugbọn awọn  kan ni ''Sai Baba'' lo mu ki ọrọ aje Dangote dẹnu kọlẹ.
Wande Ajayi ni tiẹ sọ pe Dangote ti wọn yan gẹgẹ bi ọmọ igbimọ ipolongo idibo Aarẹ Buhari ko le dun'nu si bi owo rẹ ṣe n dinku labẹ ijọba Buhari.
O ni ''Next Level'' Buhari ko le so eso rere fun Dangote fun idi eyi ki awọn eeyan yaa tete gba Buhari sita
Ṣugbọn kii ṣe gbogbo eeyan naa lo sun ti wọn kọri si ibi kan naa.
Omotoke ati Makinde David ni kii ṣe bi Buhari ni pe adinku ba owo Dangote
Iwe iroyin Forbes mu alaye wa pe aiṣedeede eto ọrọ aje ati owo ti ko gbe pẹli lo mu ki iye awọn to lowo to to biliọnu dinku di ogun nilẹ afrika lati mẹtalelogun ti wọn jẹ lọdun to kọja.
Orukọ awọn miiran ti wọn wa ninu olowo biliọnu nilẹ Afrika to leke re e
#BeyondFakeNews: Ẹ ta kété sí ìròyìn òfégè
Aàrẹ Buhari gbóríyìn fún BBC
Aarẹ Muhammadu Buhari ti funpe si awọn oniṣẹ lorilẹede yii lati ṣe afikun akitiyan nipa sisọ iroyin to ṣee gbẹkẹle ki wọn si yago fun sisọ ayederu iroyin.
Aarẹ n sọ eyi nigba ti oludari agba patapata ti ile iṣẹ igbohunsafẹfẹ BBC, Jamie Angus ṣebẹwo si i nile ijọba, aarẹ Buhari sọ pe aridaju lo gbudo kun inu gbogbo iroyin wọn.
O ki ile iṣẹ iroyin BBC ku oriire fun iyi ti wọn n ri gba lasiko ti ilu le bii igba ogun nilẹ Naijiria.
Aarẹ jẹ ko di mimọ pe nipa wiwa aaye ati ohun elo lati ṣewadii awọn iroyin wọn ki wọn to gbe e sita.
Oludari agba patapata ti ile iṣẹ igbohunsafẹfẹ BBC, Jamie Angus
O ni BBC ti gba oriyin fun pe o jẹ ile iṣẹ to n sọ iroyin ti ko lẹja mbakan ninu ti awọn eniyan si gbara le fun iroyin otitọ nipa ohun kohun to n sẹlẹ lode.
Bakan naa, aarẹ kan sara si ifara jin BBC lati tan iroyin kalẹ ni ede Hausa kaakiri ẹkun rẹ ati bi wọn ṣe tun bẹrẹ iroyin lede Igbo, Yoruba ati Pidgin lorilẹede Naijiria.
Eko Akete yóò gbàlejò BBC Yoruba
Ikọ̀ BBC pẹ̀lú Ààrẹ Buhari
Ikọ BBC wa ṣalaye awọn aato wọn lati ṣe agbejade iroyin gbogbo idibo to n bọ lorilẹede Naijiria to fi mọ alaye nipa gbogbo ipade itagbangba pẹlu awọn oludije gomina.
BBC
Falz f'ohùn lẹ̀ fún PDP, APC, MURIC, àwọn ọmọ Yahoo
Oríṣun àwòrán, YOUTUBE
Folarin Falana
Gbajugbaja olorin nni, Folarin Falana ti gbogbo eniyan mọ si Falz tun ti gbe iṣe rẹ de pẹlu orin bi owe bi owe rẹ̀.
Eyi to ṣẹ tun gbe jade ni fidio orin to kọ lati fi sọ oko ọrọ si awọn ẹgbẹ tabi ọlọdani lawujọ.
Lara wọn ni ẹgbẹ oṣelu PDP, APC, ẹgbẹ MURIC, àwọn obinrin oloṣo, àwọn ọmọ Yahoo atawọn oloṣelu lapapọ.
Ninu eyi to wa ninu awo to ṣẹṣẹ gbe jade, 'Moral instruction', Falz tẹnu mọ awọn iṣoro to n koju awọn eniyan orilẹede yii.
"Ko tilẹ fi akoko ṣofo rara pẹlu ọrọ oko rẹ to kọkọ ju to sọ wi pe ""Brother Muri shout finish, we no see am for court"","
"eyi lo fi n ba ẹgbẹ to nja fun ẹtọ awọn musulumi (MURIC) to ni awọn yoo gbe lọ ile ẹjọnitori orin rẹ, ""This is Nigeria"" nibi to ti lo awọn ọmọbinrin to lo Hijab."
Ẹwẹ, titi di igba to gbe orin mii tuntun sita, ẹgbẹ MURIC ko tii gbe e lọ ile ẹjọ.
Eko Akete yóò gbàlejò BBC Yoruba
Falz tun mẹnu ba ọrọ awọn oloṣelu to ma n rinrinajo lọ oke okun loore koore, nipa ipolongo idibo, nipa awọn ọmọ Yahoo Yahoo, awọn ọmọ oloṣo ati igbe aye olowo gee gee tawọn pasitọ kan n gbe.
"Gẹgẹ bi alaye, ohun ti fidio orin Falz n sọ ni pe ""a ti de ibi ti to yẹ ka ti yi iwa pada si ara wa ki a si mọ ohun to tọ yatọ si eyi ti ko tọ."
Fun Falz, eyi nikan lo le mu nkan pada bọ sipo.
"O ni, ""#Talk, o ṣe pataki fun wa lati maa sọrọ sita. A o le ri ojutuu bi a ba n dakẹ, ki t'ara wa ma ba wa dakẹ. A ni lati fesi! Nisinsiyii!"""
Ẹwẹ, lori ẹrọ ayelujara, awọn ololufẹ FalZ ti bẹrẹ si ni da si ọrọ nipa orin naa ati fidio rẹ.
Falz ni oun sọ ohun gbogbo to yẹ ki ẹ mọ nipa iṣejọba Aarẹ Buhari ninu fidio oni iṣẹju mẹta o le iṣẹju aaya mejidinlọgbọn.
O ni ootọ maa n dun eniyan ṣugbọn ẹnikan ni lati sọ ọ .
Falz tun fi ara rẹ we Fela nigba aye rẹ, didojukọ ijọba. Wọn n pe e ni ẹṣin iwaju sibẹ o n mu igbo o si n kọrin nipa ẹya ara.
'Kò sí oúnjẹ Nàìjá tí a ò sè ní Kenya'
Kí gan an ni ẹgbẹ́ NURTW ní ṣe pẹ̀lú òṣèlú Nàìjíríà?
Oríṣun àwòrán, Nurtw.com
Fun igba pipẹ, ẹgbẹ awakọ eero, National Union of Road Transport Workers, NURTW, ni ẹkùn Iwọ oorun Gusu Naijiria, maa n ko ipa to lapẹrẹ lasiko ti eto idibo ba waye.
Ni ọpọlọpọ igba ti wahala ba ṣẹlẹ nibi ipolongo ibo, tabi eto idibo, 'ko wọ pọ ki awọn ọmọ ẹgbẹ NURTW ma ba wọn kopa ninu rẹ.'
Eyi ṣi ṣeeṣe ko jẹ nitori 'wọn maa n wa ni imurasilẹ tabi finufindọ sẹtan lati yọnda ara wọn lati da wahala silẹ, ti ẹgbẹ oṣelu to ba wa nipo si maa n 'wa ojurere wọn.'
Awọn iṣẹlẹ kan to ti waye ni awọn ipinlẹ bi Ọyọ, Ondo, Ekiti ati Eko n tọka si i pe ipa ti ẹgbẹ NURTW n ko ko kere ninu eto oṣelu.
Ọkan to wa si iranti ni iṣẹlẹ to waye ni ọgbọnjọ, oṣu Kejila ọdun 2010, niluu Ibadan lasiko ti ẹgbẹ oṣelu Peoples Democratic Party (PDP), ṣe ipade ita gbangba ẹgbẹ naa ni imura silẹ fun eto idibo ọdun 2011.
Àwọn ọmọ ẹ́gbẹ́ NURTW kọjú ìjà síra wọn nítorí ipò l'Ekiti
Àyájọ́ òṣìṣẹ́: NURTW gba ẹ̀jẹ̀ lára àwọn òsìsẹ
Ipade oṣelu ọhun yọri si wahala ati itajẹsilẹ. Koda, wahala naa lo yọri si iku olori igun kan ninu ẹgbẹ NURTW nipinlẹ Ọyọ, Lateef Salakọ (Eleweọmọ), ati bi awọn ọlọpaa ṣe gbe Olori ile aṣofin agba nigba naa, Sẹnetọ Teslim Fọlarin ti wọn fi ẹsun kan pe o mọ nipa bi wọn ṣe ṣekupa Eleweọmọ.
Lasiko naa, igun meji lo wa ninu ẹgbẹ PDP nipinlẹ Ọyọ ati NURTW. Igun akọkọ ni ti Sẹnetọ Teslim Fọlarin/Rasheed Ladọja to fi igba kan jẹ gomina ipinlẹ Ọyọ. Igun yii ni ibaṣepọ pẹlu igun ti Lateef Akinṣọla (Tokyo) n dari ninu NURTW.
Bakan naa ni igun PDP ti gomina ipinlẹ Ọyọ nigba naa, Alao Akala ati Eleweọmọ.
Ṣaaju asiko yii ni Tokyo ati Eleweọmọ ti n ja si ipo alaga ẹgbẹ NURTW nipinlẹ Ọyọ.
Iṣẹlẹ mi i ti ko tun ṣe e gbagbe ni eyi to waye nipinlẹ Ondo lasiko ti awọn janduku ti igbagbọ wa pe ọmọ ẹgbẹ NURTW ni wọn ya bo ipade itagbangba ti ẹgbẹ oṣelu APC se loṣu Kẹwa ọdun 2018, ti wọn si lu awọn to dibo yan Idowu Otetubi sipo alaga ẹgbẹ APC nipinlẹ naa. Wọn tilẹ ja aṣofin to n ṣoju ijọba ibilẹ Idanre/Ifẹdọrẹ Federal Constituency, Baderinwa Bamidele, si ihoho.
Iṣẹlẹ to tun jọ eyi ni asiko ti awọn ọmọ ẹgbẹ NURTW yabo ile aṣofin ipinlẹ naa pẹlu afojusun lati da ijiroro iyọni nipo ru lọjọ kẹsan, oṣu Kọkanla ọdun 2018.
Ṣaaju ọjọ naa ni ede aiyede ti nwaye nile aṣofin naa nipa awọn adari wọn, ti aṣofin mejidinlogun ninu mẹrindinlọgbọn si yọ adari ile, Bamidele Oleyelogun ati igbakeji rẹ, Ogundeju Iroju nipo fun ẹsun aṣilo ipo.
Ondo Assembly: Gómìnà Akeredolu ń ti àwọn tó ń da ilé aṣòfin ìpínlẹ̀ Ondo rú-
Awọn ọmọ ẹgbẹ awakọ ọhun kọ oju ija si awọn aṣofin, awọn oniroyin, to fi mọ awọn oṣiṣẹ ile aṣofin.
Awọn iroyin kan tilẹ sọ wi pe ikọlu naa ko ṣẹyin awọn alaṣẹ ẹgbẹ APC nipinlẹ naa, to pe alaga  ẹgbẹ NURTW, Adebo lori ẹrọ ibaraẹnisọrọ lati lọ da ijoko ile ru, eyi to mu ki oun naa paṣẹ fun awọn ọmọ ẹgbẹ rẹ lati ṣe bẹẹ. Awọn nkan oloro bi ibọn, ada, aake, afọku igo, to fi mọ oogun abẹnu gọngọ ni wọn ko lọ sile asọfin.
Bo tilẹ jẹ wi pe ẹgbẹ NURTW sọ ni gbangba pe 'ohun lo n wa nidi ikọlu naa, ko daju pe ileeṣẹ ọlọpaa gbe igbesẹ to lagbara lori rẹ.'
Bakan naa ni ipinlẹ Ekiti, niṣe ni awọn ọmọ ẹgbẹ NURTW kọju ija sira wọn, ti igun kan si gbiyanju lati le awọn kan kuro lori oye ni kete ti wọn kede gomina Kayọde Fayẹmi gẹgẹ bi ẹni to bori ninu idibo sipo gomina to waye nipinlẹ naa lọjọ kẹrinla, oṣu Keje ọdun 2018.
Awọn igun kan gbagbọ pe o yẹ ki awọn oloye ẹgbẹ lasiko naa 'faramọ iṣejọba gomina ana, Ayọdele Fayoṣe, o si yẹ ki wọn o fi ipo silẹ fun awọn to faramọ Kayọde Fayẹmi'.
Eyi ti ko to waye laipẹ yii ni wahala to waye nibi ipolongo ibo ẹgbẹ oṣelu All Progressives Congress (APC) nipinlẹ Eko lọjọ kẹjọ, oṣu Kejila 2018.
Ipolongo ibo ọhun ti oludije fun ipo gomina ninu ẹgbẹ APC, Babajide Sanwo-Olu fi ṣide ipolongo rẹ, lo pari pẹlu wahala lasiko ti awọn ọmọ ẹgbẹ NURTW da wahala silẹ.
Oríṣun àwòrán, Mcoluomo/instagram
Iṣẹlẹ naa fa ifarapa fun awọn oniroyin, ọmọ ẹgbẹ APC, to fi mọ ọkan lara awọn oloye ẹgbẹ NURTW, Musiliu Akinsanya (MC Oluọmọ)
Iṣẹlẹ naa fa ifarapa fun awọn oniroyin, ọmọ ẹgbẹ APC, to fi mọ ọkan lara awọn oloye ẹgbẹ NURTW, Musiliu Akinsanya (MC Oluọmọ) to jẹ ọmọ ẹgbẹ APC.
'MC Oluọmọ kò kú o, kò sí ikú lójù rẹ̀'
MC Oluọmọ, fara gb'ọ̀bẹ níbi ìpolongo ìbò APC l'Eko
Iroyin fidirẹ mulẹ pe ṣeni awọn janduku naa n yinbọn laibikita, ti ibọn naa si ba akọroyin mẹta. Bakan naa ni wọn fi ọbẹ gun MC Oluọmọ, ti gbogbo wọn si di eero ileewosan.
Lootọ, gbogbo ọmọ Naijiria lo lẹtọ lati darapọ mọ ẹgbẹ oṣelu to ba wu u, ṣugbọn ibeere to ṣaba maa n wa si ọkan nipe, ṣe awọn ọmọ ẹgbẹ NURTW n darapọ mọ oṣelu nitori pe wọn fẹ jẹ ọmọ ẹgbẹ ni tabi nitori nkan ti awọn oloṣelu n lo wọn fun lasiko eto idibo?
Awọn ololufẹ BBC Yoruba sọ ero ọkan wọn lori eyi.
2019 elections: INEC gbé ìgbésẹ̀ méje fún ètò ìdìbò 2019 jáde
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Oṣù kejì àti oṣu kẹta ọdún 2019 ni ìdìbò àpapọ̀ orílẹ̀èdè Nàìjíríà yóò wáyé.
Ajọ eleto idibo Naijiria ti gbe igbesẹ bi eto idibo yoo ṣe lọ lawọn ọjọ idibo apapọ ọdun 2019 jade.
Eto idibo apapọ orilẹede Naijiria yoo waye ni ọjọ kẹrindinlogun oṣu keji ọdun 2019 ati ọjọ keji oṣu kẹta ọdun 2019 kan naa.
Igbesẹ meje ni ajọ INEC gbe kalẹ bayii pe eto idibo yoo maa gba lọjọ idibo.
Alao Akala:Èmi àti Ajimọbi kò ṣe ìlérí kankan fún ara wa
Ni kete ti o ba ti de ibudo idibo rẹ, to pẹlu awọn oludibo yooku ki o si fi ara han oṣiṣẹ idibo to ba wa nibẹ.
Kini idi eyi?
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ọjọ kẹrìndínlógún oṣù kejì ni idibo si ipo aarẹ ati ile aṣofin apapọ
Oṣiṣẹ eleto idibo keji naa  yoo beere fun kaadi idibo rẹ lọwọ rẹ
Kini idi eyi?
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ọjọ keji oṣu kẹta ni idibo si ipo gomina ati awọ̀n aṣofin ipinlẹ yoo waye
Lẹyin eyi ni yoo kan pipade oṣiṣẹ eletoi idibo miran (APO11) ti yoo tun beere fun kaadi idibo rẹ
Kini idi eyi?
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ajọ INEC ti ni gbogbo eto ni awọn n ṣe fun aṣeyọri idibo 2019
Yoo kan oṣiṣẹ eleto idibo to jẹ alamojuto eto idibo ni ibudo naa, (PO)
Kini iṣẹ tirẹ?
Oríṣun àwòrán, InEC
Igbesẹ meje ni ajọ INEC gbe kalẹ lori eto idibo ọdun 2019
Wọn yoo fun ọ ni ọda itẹka kan ninu eyi ti oo ti ika rẹ bọ lati tẹka si aaye ti wọn fi silẹ fun oludije/ẹgbẹ oṣelu ti ọkan rẹ fẹ.
Ka iwe idibo naa gẹgẹ bii alamojuto eto ibo (PO) ṣe kaa fun ọ.
Lẹyin eyi, fi kuulu idibo naa silẹ ki o si ju iwe idibo naa silẹ sinu apoti ibo loju gbogbo awọn eeyan to wa nibẹ.
Ni bayii, o lee wa fi ibudo idibo silẹ tabi ki o duro ṣugbọn lai fa wahala rara titi di asiko ikede esi idibo.
N.B.  wọn yoo lẹ esi  esi idibo ibudo kọọkan si ibi to yẹ ni ibudo idibo naa fun gbogbo awọn eeyan lati rii.
Ọkọ̀ agbépo gbiná l'Eko
Ẹgbẹrun marundinlaadọta lita epo bẹntiro ni ọkọ agbepo naa gbe lasiko ti ina naa fi suyọ
Ọkọ agbepo kan ti gbina ni agbegbe ogudu ni ilu Eko.
Awọn ti iṣẹlẹ naa ṣoju wọn ni iwaju ọkọ agbepo naa kan ṣa dede gbina lagbegbe ni agbegbe toll gate.
Ninu ọ̀rọ̀ to ba BBC News Yoruba sọ, alukoro ileeṣẹ LASEMA ni ipinlẹ Eko, Kẹhinde Adebayọ ni ko si ẹmi to ba iṣẹlẹ naa lọ.
Ọgbẹni  Adebayọ ni epo to to ẹgbẹrun marundinlaadọta lita epo disu ni ọkọ akepo naa gbe nigba ti iṣẹlẹ ina naa ṣẹlẹ.
Oríṣun àwòrán, LASEMA
O ni awọn oṣiṣẹ adoola ẹmi ati panapana tete de ibẹ ki o to ṣe ọṣẹ ju bi o ti yẹ lọ.
Ọ̀gá ọlọ̀pàá Idris ni kí ẹ mu ti nnkankan ba ṣẹlẹ́ si mi -Saraki
Oríṣun àwòrán, @bukolasaraki
Ibrahim Idris ati aarẹ ile asofin agba Bukọla Saraki ko ṣẹṣẹ ma gbena woju ara wọn
Ààrẹ ilè aṣòfin àgbà Bukola Saraki ti figbe sita pé Oga ọlọpaa orileede Naijiria, Ibrahim Idris n lepa ọna lati gbẹmi oun.
Saraki fi ọrọ yi to awọn akọroyin leti nigba ti o n bawọn sọrọ nilu Ilorin.
Bakan naa ni o kọ ọ si oju opo Twitter rẹ́ pẹlu ikilọ pe ki awọn eeyan mọ wi pe bi nnkankan ba ṣe ohun tabi mọlẹbi ohun, ọga agba ọlọpaa Idris ni ki wọn mu.
Ọlọpaa di ẹnu ọna ile Saraki pa
Saraki salaye pe awọn igbesẹ ti ọga ọlọpaa n gbe paapa julọ pẹlu awọn ọga ọlọpaa ipinlẹ́ Kwara to n parọ bi ẹni parọ aṣọ mu ifura lọwọ.
O ni lasiko yii ti ipolongo ibo yoo bẹrẹ ni pẹrẹwu, ọkan oun ko balẹ pe ọga ọlọpaa Idris ko ni gbe igbesẹ lati mu ahẹ ba abo oun.
Lọjọ ẹti ni Saraki ni awọn janduku  ọmọ ẹgbẹ APC kan yabo agbo ile oun ladugbo Agbaji nilu Ilorin .
Awọn ọlọpaa to wa nibi iṣẹlẹ naa gẹgẹ bi Saraki se sọ ko gbe igbesẹ kankan lati di awọn janduku naa lọwọ.
Ile iṣẹ ọlọpaa ti fesi si ọrọ Saraki pe awọn ko fi igba kan fi ọwọ yẹpẹrẹ mu aabo oun ati mọlẹbi rẹ.
Ninu atẹjade kan lati ọdọ alukoro ile iṣẹ ọlọpaa, Jimoh Moshood, wọn ni ''ko si ootọ ninu ọrọ ti Saraki sọ ati pe awọn rọ ara ilu lati ma ṣe da a lohun''
Moshood ni awọn ko kin awọn janduku lẹyin lati ba nnkan jẹ lagbole Saraki  ati wi pe awọn ko ri ẹsun kankan gba lawọn agọ ọlọpaa to wa nilu Ilorin ni ọjọ kẹwa  titi di ọjọ kọkanla nipa idunkoko mọ ọ tabi awọn mọlẹbi rẹ.
Aawọ laarin Oga ọlọpa ati Saraki ko ṣẹṣẹ bẹrẹ
Bi a ko ba gbagbe fa ki n fa paapa julọ lori aṣẹ ti ile asofin pa ki Ọga ọlọpaa wa yọju sile asofin lori awọn ipaniyan kan to n waye lo dabi ẹni wi pe o da wahala silẹ.
Ọga ọlọpa Idris kọ lati yọju sile ti Aarẹ ile Bukọla Saraki si ni iwa rẹ ko jọ oun loju nitori pe a maa kọ iṣẹ fun ọga rẹ ti ṣe Aarẹ Buhari.
Iṣẹlẹ idigunjale to tun waye nipinlẹ Kwara naa wa lara ohun ti o mu ki awọn mejeeji ma gba ti ara wọn.
Ninu nnkan ti Saraki sọ loju opo Twitter rẹ, o ni gbogbo ọgbọn ni ọga ọlọpaa Idris n da lati ko panpẹ si oun lọwọ
JAMB 2019: Wo àwọn ibùdó CBT tó wà nítòsí rẹ
Oríṣun àwòrán, JAMB/FACEBOOK
Àjọ JAMB
Ajọ to n ri si idanwo asewọle iwe giga JAMB ti bẹrẹ tita fọọ mu fun awọn ọmọ Naiiria  to fẹ ṣe idanwo naa.
Idanwo naa, UTME ti ọpọ maa n pe ni JAMB ni idanwo ti awọn ti awọn to ba fẹ wọ ile iwe giga lorilẹede Naijiria.
Apapọ ajọ to n se agbekalẹ idanwo yii ba ṣe ohun tuntun lọdun yii, wọn fagile fiforukọ ni ibudo cyber cafe ti awọn aṣedanwo maa n lọ tẹlẹ.
Bi fọọmu naa ṣe ti wa jade kaakiri Naijiria fun ẹni to ba fẹ gba, awọn nkankan wa ti ajọ JAMB fẹ ki awọn aṣedanwo mọ eyi ti yoo jẹ ki ilana iforukọ silẹ wọn rọrun.
Agbẹnusọ fun ajọ JAMB, ọmọwe Fabian Benjamin sọ fun BBC pe ẹgbẹrun mẹta abọ Naira (N3500) ni iye owo fọọmu.
Bi o tilẹ jẹ pe aṣedanwo lee nilo lati san ẹẹdẹgbẹrun (N500) ni ibudo CBT gẹgẹ bí owo isẹ ṣugbọn wọn gba aṣedanwo nimọran pe ẹnikẹni ko gbudọ san kọja ẹẹdẹgbẹrin Naira (N700) gẹgẹ bi owo iṣẹ.
Ajọ JAMB sọ siwaju pe lori ẹrọ alagbeka awọn aṣedanwo ni wọn yoo ti kọkọ ṣe iforukọsilẹ ki wọn tilẹ to yọ owo lapo lọ fọọmu.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ẹrọ alágbèéká
Ọfiisi JAMB to ba wa ni ipinlẹ̀ yin naa, ibudo CBT ni.
Bakan naa, ajọ JAMB ti ṣe ọna ti afọju tabi odi lee fi joko ṣe idanwo ọhun.
Loju itakun agbaye wọn, ajọ JAMB ti ṣe alakalẹ awọn ilana ti eniyan le ṣe lati forukọ silẹ lori ẹrọ alagbeka wọn (iyẹn fun Airtel ati MTN nikan).
Nọmba naa ati orukọ aṣedanwo yoo wa papọ, nitorinaa ma ṣe gbagbe àwọn nkan wọnyi.
Eko Akete yóò gbàlejò BBC Yoruba
"Ẹkunrẹrẹ ilana, ofin ati ikilọ wa ni oriko ""download pdf"" eyi ti ajọ JAMB ti fi sori itakun agbaye wọn."
'Ọkùnrin tí kò bá sanwó iléèwé ọmọ, kó lọ wẹrí'
Jamiu Abiola: Ẹ dìbò fún Buhari kí ẹ fi bu ọlá fún bàbá mi
Oríṣun àwòrán, WIKIPEDIA
Ọdún tó kọjá ni Ààrẹ Buhari bu ọlá fún Olóyè Moshood Abiola tí wọ́n sì fi June 12 se àyájọ́ Ọjọ́ Òmìnira ní Nàíjíríà.
Ọmọ oloye Moshood Abiola ti wọn kọ lati kede wi pe o jawe olubori ninu idibo si ipo aarẹ ti june 12, 1993, Jamiu Abiola ti rọ awọn ọmọ Yoruba lati di ibo wọn fun Aarẹ Buhari lọdun 2019 lati fi bu iyi fun baba oun.
Jamiu to jẹ ọkan lara awọn ọmọ ẹgbẹ to n se ipolongo fun ipada si ipo aarẹ Buhari (Directorate of Contact and Mobilisation of the Women and Youth Presidential Campaign Team) sọ wi pe Buhari kii se ẹlẹyamẹya.
Jamiu lasiko to n ba awọn oniroyin sọrọ ni ilu Eko se apejuwe Buhari gẹgẹ bi ọmọluabi nitori to bu ọla fun Moshood Abiola, lẹyin ọdun mẹẹdọgbọn ti baba oun ti jade laye.
'Twitter ló gbà mí lọ́wọ́ ikú'
O rọ awọn ọmọ Oodua lati dibo wọn fun Aarẹ buhari lẹẹkeji ni Ọjọ Kẹrindinlogun, Osu Keji, ọdun 2019 lati ma se tabuku M.K.O Abiola ati iyawo rẹ, Kudirat Abiola ti wọn sekupa.
Ti a ko ba gbagbe, ọdun to kọja ni Aarẹ Buhari bu ọla fun Oloye Moshood Abiola ti wọn si fi June 12 se Ọjọ Ayajọ Ominira(Democracy Day) ni Naijiria laaarin awọn miran naa to da lọla.
Ọlọ́pàá Ekiti: A kò lé sọ bóyá olósèlú ló ní ọkọ̀ ńlá tó kó ìrẹsì
Oríṣun àwòrán, Sunkanmi Ogunmuko
Àwọn tí ọ̀rọ̀ náà sojú rẹ̀ ní ìjánnú ọkọ̀ ló da isẹ́ sílẹ̀ tó sí yawọ ọjà tí ọ́pọ̀ ẹ̀mí ba ìsẹ̀lẹ̀ náà.
Igbakeji gomina ni ipinle Ekiti, Adebisi Adegboyega Egbeyemi lorukọ gomina ti se abẹwo si awọn ti wọn farapa ninu ijamba ọkọ naa.
O ni gomina Kayode Fayemi o si nile ni o ṣe ran oun lati wa wo ohun to ṣẹlẹ, o si ṣeleri pe ijọba yoo san owo itọju awọn to wa nile iwosan bẹẹ si ni yoo tun ọja naa ṣe.
Ileesẹ ọlọpaa ni ipinlẹ Ekiti ti ni eniyan mejila lo padanu ẹmi wọn ninu ijamba ọkọ to waye ni alẹ Ọjọ Satide ni ipinle Ekiti, ti ọpọlọpọ si farapa.
agbẹnusọ fun ileesẹ ọlọpaa naa, Caleb Chukwu lasiko to n ba BBC Yoruba sọrọ ni, ọkunrin mẹfa ati obinrin mẹfa lo ku ninu isẹlẹ naa loju ẹsẹ.
Eyi waye nigbati ọkọ naa ya lọ kọlu ọkọ ayọkẹlẹ kan, ọkọ Akọta kekere ati ile to wa ni iwaju agbeegbe ọja Iworoko ni ipinlẹ Ekiti.
Oríṣun àwòrán, Sunkanmi Ogunmuko
Amọ awọn miran sọ wi pe awọn ti o ku ninu isẹlẹ naa ju bi o se yẹ lọ, ati wi pe idile wa ninu awọn to padanu ẹmi wọn.
Lori ẹsun wi pe oloselu lo ni iresi to wa ninu ọkọ naa, Chukwu ni awọn ko lee sọ pe bi ọrọ naa se ri niyẹn, sugbọn awọn mọ wi pe ẹnikẹni lorilẹede Naijiria lo le e lo ọkọ nla lati fi ko ẹru lati ibi kan si omiran.
Amọ, eniyan kan ti ọrọ naa se oju rẹ sọ wi pe ọkọ nla naa n gbe irẹsi to jẹ ti oloselu kan ni ipinlẹ Ekiti ti oun dije du ipo sẹnatọ ti yoo ma ṣoju ipinlẹ naa nile igbimọ aṣofin agba.
Iroyin ni ìjánu ọkọ naa kọ iṣẹ́ sílẹ̀ tó sì yà lọ bá àwọn èèyàn nínú ọjà naa.
'Twitter ló gbà mí lọ́wọ́ ikú'
Amọ, awọn miiran sọ wi pe awọn ti o ku ninu isẹlẹ naa ju bi o se yẹ lọ, ati wi pe idile wa ninu awọn to padanu ẹmi wọn.
Oyin lé àwọn ènìyàn kúrò l'ábúlé kan ní Plateau
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Oyin ti le awọn ara abule Gunsun, to wa ni ijọ̀ba ibilẹ Kanam nipinlẹ Plateau kuro niluu.
Idris Mohammed to jẹ Baalẹ abule naa sọ fun BBC pe ni nkan bi aago mejila ọsan ọjọ Aiku, ni awọn deede ri ti oyin ya bo gbogbo abule.
Baalẹ naa fi kun pe loju ẹsẹ si ni gbogbo eniyan ti n sa wọ inu igbo lọ.
''Ọpọlọpọ awọ̀n ara abule to n sa a lọ lo si farapa, ti awọn kan tilẹ kan ni ẹsẹ.''
Fayemi ṣèlérí owó ìtọ́jú àwọn tó fara gbá nínú ìjámba l'Ékiti
Ajọ LASEMA sọ̀rọ̀ lórí okùnfà iná to jó l'Abule Ẹgba.
'Èṣù kìí ṣe sàtànì bí ẹ ṣe máa ń pè é'
Ọkan lara awọn ara abule, Ibrahim sọ pe awọn oyin ọhun ko yọ awọn ẹran ọsin to wa ninu abule silẹ.
Ṣugbọn, awọn ara abule naa n fura pe o ṣeeṣe ko jẹ latara igi nla kan to wa nitosi abule naa ni awọn oyin naa ti jade.
Wọn fi kun pe o ṣeeṣe ko jẹ pe awọn ọmọde to n ṣere nitosi igi naa lo fa wahala naa fun awọn.
Ẹwẹ, awọn kan tilẹ gbagbọ pe o ṣeeṣe ko jẹ oogun ti awọn kan ran si abule naa lo fa a.
Baalẹ abule naa ṣalaye pe iru iṣẹlẹ naa ti aye ri lọdun 1998, to si yọri si iku awọn kan ninu abule.
BBC Nigeria 2019: Ìtàn nípa bí ètò ìdìbò ṣe bẹ̀rẹ̀ ní Nàìjíríà
Oríṣun àwòrán, FRANCOIS ROJON/AFP/Getty Images
Ọlọpaa n fi apoti ibo han awọn oludibo nilu Eko ninu ibo Aarẹ Naijiria ni 1993
Nilẹ Afrika, Naijiria jẹ orileede kan gboogi nipa oṣelu ati ọrọ aje rẹ.
Naijiria  n kopa pataki lawujọ awọn orileede debi wi pe awọn kan ti sọ pe ohun to ba de ba oju Naijiria, yoo kan pupọ orileede ni Afrika.
Fun idi eyi, idibo gbogboogbo to n waye lorileede Naijiria jẹ nnkan ti ọpọ n sọrọ nipa rẹ lafrika ati agbaye.
Gbogbo oju lo ti wa lara Naijiria lati wo bi eto naa yoo ṣe lọ amọ ki a to mọ bi nnkan yoo ṣe ri la ni ki a da ara loye nipa itan eto idibo lorileede Naijiria
Oṣu Karun, ọdun 1919 ni wọn kọkọ fi eto idibo lelẹ ni Naijiria, lasiko ti ofin asiko naa fi ẹtọ fun diẹ lara awọn ọkunrin ilu lati dibo yan aṣoju mẹta sinu Igbimọ Oluṣakoso ilu Eko.
Ọjọ kọkandinlọgbọn, oṣu Kẹta , ọdun 1920 si ni idibo akọkọ waye.
L'ọdun 1922, iwe ofin tuntun (Clifford Constitution) jade, eyi to ṣe idasilẹ idibo yan eniyan mẹrin sile aṣofin;mẹta fun Eko, ẹyọkan fun ilu Calabar.
Awọn to si ti pe ẹni ọdun mọkanlelogun tabi ju bẹ ẹ lọ, to jẹ ẹrú ilẹ Gẹẹsi tabi jẹ ọmọ orilẹede Naijiria to ti gbe ni agbegbe kan fun oṣu mejila ṣaaju eto idibo nikan lo ni anfaani lati dibo.
Oríṣun àwòrán, FRANCOIS ROJON/GETTY
Aworan idibo ọdun 1993
Eniyan bi ẹgbẹrun mẹrin ninu ẹgbẹrun mọkandinlọgọrun to n gbe nilu lo f'orukọ silẹ lati dibo nilu Eko, nigba ti ọtalenirinwo din meje eniyan si f'orukọ silẹ ni ilu Calabar.
Ọdun maarun si ni awọn to ba jawe olubori fi wa nipo.
Eto idibo sile aṣofin waye ni Naijiria lọjọ kejila, oṣu Kejila, ọdun 1959. Ẹgbẹ oṣelu Northern People's Congress lo bori ju pẹlu bi ijoko mẹrinlelaadoje ninu ọọdurun le mejila nile aṣofin ṣe ja mọ ọ lọwọ.
Ọjọ kọkanla, oṣu Kẹjọ, ọdun 1979 ni eto idibo aarẹ kọkọ waye ni Naijiria. Shehu Shagari, ti ẹgbẹ National Party of Nigeria lo jawe olubori. Awuyewuye waye lori esi ibo naa lori, ti ọrọ si de ile ẹjọ to ga ju ni Naijiria. Shagari ni ẹjọ gbè e.
Eto idibo aarẹ tun waye lọjọ kẹfa, oṣu Kẹjọ, ọdun 1983. Shehu Shagari lo tun wọle pẹlu ìdá mẹtadinlaadọta ataabọ ninu ìdá ọgọrun ibo ti awọn araalu di.
Eto idibo aarẹ tun waye lọjọ kejila, oṣu Kẹfa, ọdun 1993, fun igba akọkọ lẹyin ti awọn ologun ditẹ gbajọba l'ọdun 1983.
Esi ibo naa fihan pe Oloogbe Moshood Kashimawo Abiọla, ti ẹgbẹ oṣelu Social Democratic Party, SDP, lo bori. O fi ẹyin Bashir Tofa, ti ẹgbẹ oṣelu National Republican Convention, janlẹ.
Ṣugbọn, olori orilẹede Naijiria nigba naa labẹ iṣejọba awọn ologun, Ibrahim Babangida fagile esi ibo naa. Igbesẹ rẹ naa yọri si rogbodiyan, eyi to tun mu ki iditẹ gbajọba mi i ti Oloogbe Ọgagun Sani Abacha le waju tun waye lọdun naa.
Oríṣun àwòrán, FRANCOIS ROJON/AFP/Getty Images
MKO Abiola
Eto idibo aarẹ tun waye lọjọ kẹtadinlọgbọn, oṣu Keji, ọdun 1999. Eyi ni idibo akọkọ to waye lati ọdun 1993 ti awọn ologun ti ditẹ gbajọba.
Oluṣẹgun Ọbasanjọ ti ẹgbẹ oṣelu People's Democratic Party, PDP, lo bori.
Ṣaaju asiko yii ni eto idibo sile aṣofin waye lọjọ kẹẹdọgbọn, oṣu Kẹrin, ọdun 1998. Eyi naa jẹ igba akọkọ ti idibo sile aṣofin waye lati ọdun 1992.
Iditẹ gbajọba ọdun1993 lo si fa a. Gbogbo ẹgbẹ oṣelu to kopa ninu idibo naa lo ni ibaṣepọ pẹlu iṣejọba ologun, ti wọn si f'ofin de awọn ẹgbẹ alatako.
Oríṣun àwòrán, Malcolm Linton/Getty
Aarẹ ana Olusegun Obasanjo nilu Eko nibi to ti n kede erongba lati du ipo Aarẹ fun awọn oniroyin lọdun 1998
Ijọba fagile esi ibo yii, eyi si mu ki atundi ibo waye lọdun to tẹle.
Eto idibo mi i tun waye lọjọ kọkandinlogun, oṣu Kẹrin, ọdun 2003. Aarẹ Oluṣẹgun Ọbasanjọ lo tun bori gẹgẹ bi aarẹ.
Eto idibo gbogboogbo miran tun waye l'ọjọ kẹrinla ati ọjọ kọkanlelogun, oṣu Kẹrin, ọdun 2007.
Oríṣun àwòrán, @inecnigeria
Eto idibo sile aṣofin ipinlẹ ati ti gomina waye lọjọ kẹrinla, nigba ti ti aarẹ waye lọjọ kọkanlelogun.
Ọsẹ to tẹle ni idibo sile aṣofin apapọ ati ti aarẹ waye l'ọsẹ to tẹle. Umaru Yar'Adua ti ẹgbẹ oṣelu PDP lo gbegba oroke. Wọn si bura fun l'ọjọ kẹẹdọgbọn, oṣu Karun, ọdun 2019.
Awọn onwoye idibo lati inu ajọ iṣọkan ilẹ Yuroopu ṣọ pe eto idibo naa lo buru ju ti awọn ti ti ni gbogbo orilẹede to waye l'aye; ṣiṣe eeru ibo, jagidijagan, jiji apoti ibo gbe ati didẹru ba awọn oludibo.''
Eto idibo gbogboogbo mi i tun waye ni ọjọ kẹrindinlogun, oṣu Kẹrin, ọdun 2011. Awuyewuye ti kọkọ waye lori boya ara Ariwa tabi ara Gusu ni ko jẹ aarẹ lẹyin iku Aarẹ Umaru Yar'Adua, to jẹ ara Ariwa.
Oríṣun àwòrán, YASUYOSHI CHIBA/GETTY
Idibo ọdun 2019 jẹ eleyi ti ọpọ ọmọ Naijiria n foju si lara
Goodluck Jonathan to jẹ aarẹ fidihẹ lẹyin iku Yar'Adua lo wọle sipo aarẹ. Ṣugbọn, lọgan ti idibo naa wa s'opin ni rogbodiyan bẹrẹ ni apa Ariwa.
Eto idibo gbogboogbo to kọja waye ni ọjọ kejidinlọgbọn ati ọjọ kọkandinlọgbọn, oṣu Kẹta, ọdun 2015.
Aarẹ nigba naa, Goodluck Jonathan tun pada dije fun ipo aarẹ, ṣugbọn ko ja mọ lọwọ.
Awọn kan tilẹ sọ pe eto idibo naa lo gba owo to pọju lọ nilẹ Afrika.
Eto idibo naa si ni igba akọkọ ti aarẹ to wa lori aga iṣakoso fidirẹmi ninu eto idibo.
Wo àwọn ohun tó yẹ kí o mọ̀ nípa DCP Kayọde Ẹgbẹdokun
Oríṣun àwòrán, Ẹgbedokun
Ọlọpaa to kawe jinlẹ ni Kayọde Ẹgbẹtokun
Awọn alaṣẹ ileeṣẹ ọlọpaa lorilẹ-ede Naijiria ti yan kọmiṣọna ọlọpaa tuntun fun ipinlẹ Eko.
Wọn gbé igbesẹ yii lẹyin ti wọn ti paṣẹ fun kọmiṣọna ọlọpaa nibẹ tẹlẹ, Edgal Imohimi, pé ko lọ gba ipo gẹgẹ bii ọga ọlọpaa tuntun fun ẹka to n n mojuto iṣẹlẹ ibugbamu ni olu ileeṣẹ ọlọpaa orilẹ-ede Naijiria to wa ni ilu Abuja.
Igbakeji Kọmiṣọna Ọlọpaa, DCP Kayọde Ẹgbẹtokun ni ọga agba ọlọpaa tuntun ti wọn yan fun ileeṣẹ ọlọpaa ipinlẹ Eko.
Ni ọjọ kẹrin, oṣu kẹsan an, ọdun 1964 ni wọn bi Ẹgbẹdokun ki o to darapọ pẹlu ileeṣẹ ọlọpaa ni ọdun 1990.
Moses Melaye: Dino Melaye sùn ìta gbangba mọ́jú níléesẹ́ DSS
Ọlọpaa to kawe jinlẹ ni ọgbẹni Ẹgbẹtokun pẹlu iwe ẹri imọ ijinlẹ akọkọ ninu imọ iṣiro, (B.Sc Mathematics), iwe ẹri imọ ijinlẹ keji ni imọẹrọ, (M.Sc Ẹngineering Analysis) iwe ẹri PGD ninu imọ ọrọ aje nipa epo rọbi, Petroleum Economics ati imọ ijinlẹ akoso okoowo, MBA.
Ile ẹkọṣẹ ọlọpaa to wa ni Ikẹja nilu Eko ni Ẹgbẹdokun wa gẹgẹ bii igbakeji ọga agba nibẹ ki wọn to yan an si ipo adele Kọmiṣọna nipinlẹ Eko.
Alao Akala:Èmi àti Ajimọbi kò ṣe ìlérí kankan fún ara wa
Claudiah: ìrẹ̀wẹ̀sì ọkàn bá mi fínra fún ọpọlọpọ ọdún
Ronke Oṣodi: òótọ́ ọ̀rọ̀ máa ń korò gan ni f'áwa èèyàn
CCT: Adájọ́ fẹ̀yìntì ní àwọn asòfin àpapọ̀ yẹ kó fòǹtẹ̀ lu ìgbẹ́jọ́ adájọ́ àgbà
Gbogbo eto ti to ni CCT fun igbejo Adajo Onnoghen
Adajọ fẹyinti Folarinwa Oloyede ti sọ pe gbigbe ti wọn gbe Adajọ agba orilẹede Naijiria, Walter Onnoghen lọ si waju ile ẹjọ to n gbo ẹsun aṣemaṣe awọn to di ipo ilu mu, CCT, ko tọna rara.
Adajọ fẹyinti Oloyede, to ba BBC Yoruba sọrọ lẹyin ti igbimọ CCT sun igbẹjọ naa siwaju, sọ pe ọna kan ṣoṣo lati yọ adajọ agba nipo, ni pe Aarẹ orilẹede Naijiria gbọdọ da laba fun apapọ ile igbimọ aṣofin l'Abuja.
O ṣalaye pe, ida meji ninu ida mẹta ile aṣofin agba l'Abuja gbọdọ faramọ mọ na, ki wọn to le gbe adajọ lọ sile ẹjọ tabi siwaju igbimọ CCT lati jẹjọ.
Adajọ fẹyinti Oloyede sọ pe, o ṣe ni laanu pe ajọ CCB ti mọ nipa ẹsun yii lati ọdun 2016, o si kọ lati fẹsun kan adajọ agba Onnoghen to fi di asiko yii.
Ile ẹjọ ọhun ti Danladi Umar jẹ adari fun, ko lee joko ni Ọjọ Aje, nibi ti Adajọ Agba Onnoghen ti tako igbẹjọ rẹ ni ile ẹjọ to n gbẹjọ iwa ibajẹ, CCT.
Umar gbe igbesẹ naa lẹyin ti agbẹjọro fun ijọba, Aliyu Umar fi ọwọ si wi pe ọna ti wọn gba fun agbẹjọro agba Walter Onnoghen ni iwe igbejọ ko tọna rara.
Tani DCP Kayọde Ẹgbẹdokun, ọ̀gá ọlọ́pàá tuntun ní ìpínlẹ̀ Eko?
Abìjà: Bàbá mi fi iṣẹ́ ọdẹ ti ń pa lémi lọ́wọ́ ni nítorí babaláwo ni
Adajọ agba naa kọ lati yọju si ile ẹjọ naa, sugbọn ọgọọrọ awọn agbẹjọrọ agba(SANs) lo lọ si ile ẹjọ naa lati se atilẹyin fun agbẹjọro agba naa.
Ṣe adajọ agba, Walter Onnoghen yoo farahan niwaju ile ẹjọ to n gbọ ẹsun aṣemaṣe awọn to dipo ilu mu lorilẹ-ede Naijiria, CCT ni ibeere ti o n gbẹnu ọpọ onwoye lati igba ti iroyin nipa ẹsun kan ti wọn fi kan adajọ agba naa ni pa kikede dukia rẹ jade sita lopin ọsẹ to kọja.
Oniruuru awọn onimọ, paapaa julọ awọn onimọ nipa ofin ni wọn ti jade ṣalaye pe o ku diẹ kaato, bẹẹni awọn onwoye miran n wii lẹnu pe ko sẹni to kọja ofin.
Kini awọn gomina iha aringbungbun guusu orilẹ-ede Naijiria, (South-South) sọ?
Oríṣun àwòrán, Channels tv
Ìbéèrè tó ń jẹyọ báyìí ni bóyá adájọ́ àgbà orílẹ̀-èdè Nàìjíríà, Walter Onnoghen yóò yọjú sílé ẹjọ́
Ni kete ti iroyin yii ti jade sita ni awọn gomina to wa lati ẹkun aringbungbun guusu orilẹ-ede Naijiria ti wọ inu ipade lọ.
'Ẹ̀ maa ṣe gbagbe pe ẹkun yii ni adajọ agba orilẹ-ede Naijiria, Onnoghen ti wa, ni pato, ọmọ ipinlẹ Cross river ni.
Nigba ti awọn gomina naa yoo si fi jade kuro nibi ipade wọn, abọ ti wọn jẹ faraalu ni ipe si adajọ agba naa pe ko gbọdọ farahan niwaju ile ẹjọ naa.
Awọn gomina naa ni ko dabi ẹni pe aarẹ Buhari ni ọ̀wọ̀ fawọn eeyan agbegbe Niger Delta, eto iṣejọba tiwantiwa ati ẹka iṣedajọ.
Oríṣun àwòrán, Nigeria Bar Association
Ṣe wọn ni ki sobiya to di egbo, oluganbẹ laa kọ ke si. Awọn agba amofin lorilẹ-ede Naijiria pẹlu ko dakẹ lori ọrọ ọhun o.
Amofin agba, Oloye Afẹ Babalọla (SAN) ni iwa idẹyẹsi iwe ofin orilẹ-ede Naijiria ni igbesẹ lati fa adajọ agba orilẹ-ede Naijiria lọ si ile ẹjọ.
"Amofin Afẹ Babalọla ninu atẹjade kan to fi sita lọjọ Aiku ṣalaye pe ""ohun ti ofin la kalẹ ni pe ki igbimọ iṣedajọ lorilẹ-ede Naijiria o kọkọ gbọ ẹsun naa ki wọn si ṣe iwadii rẹ ṣaaju igbimọ kigbimọ, nitori naa ko si awijare kankan ninu igbesẹ lati gbe adajọ agba Naijiria lọ siwaju ile ẹjọ CCT"" ."
Oríṣun àwòrán, @Nigerialawyers
Ọ̀pọ̀ amòfin ló ní ìgbésẹ̀ náà kò bá ìwé òfin Nàìjíríà mu.
Bakan naa, iwe ofin orilẹ-ede Naijiria laa kalẹ igbesẹ to yẹ fun yiyọ adajọ agba nipo. Abala 292 (1) (a) (i) ati 292 (1) (b) iwe ofin Nigeria ti ọdun 1999 laa yekeyeke.
Moses Melaye: Dino Melaye sùn ìta gbangba mọ́jú níléesẹ́ DSS
O ni n ṣe ni ijọba n jẹ ko han sawọn ọmọ Naijiria pe nnkan miran wa lẹyin ọrọ ọhun ju eyi to han faraye.
Ẹwẹ, amofin Ẹbun-Ola Adegoruwa pẹlu kin ọrọ naa lẹyin.
O ni awọn ẹsun ti ko bofinmu ni wọn fi kan adajọ agba naa.
Ninu ẹjọ Nganjiwa ati ijọba orilẹ-ede Naijiria to waye niwaju ile ẹjọ kotẹmilọrun, ko si ẹsun kankan ti a lee fi kan oṣiṣẹ eto idajọ kankan ni ile ẹjọ, ninu eyi ti adajọ agba orilẹ-ede Naijiria wa lai kọkọ gbẹsun naa lọ siwaju igbimọ iṣedajọ orilẹ-ede Naijiria, NJC
Oríṣun àwòrán, NAtional Assembly nigeria
Awọn aṣofin apapọ pe fun titẹle ilana ti ofin la kalẹ.
Awọn olori ẹka ile aṣofin apapọ mejeeji, ile aoṣofin agba ati ile aṣoju-ṣofin, Sẹnetọ Bukọla Saraki pẹlu aṣofin Yakubu Dogara ti bu ẹnu ẹ̀tẹ́ lu igbesẹ naa.
Aarẹ ile aṣofin agba, Sẹnetọ Saraki ni igbesẹ ti ofin la kalẹ ni ki ijọba apapọ tẹle lori ọrọ naa.
Saraki ni ifura wa pẹlu ọwọ́ wara-n-ṣeṣa ti wọn fi sare gbe ẹjọ naa kalẹ paapaa nigba ti ọpọ ẹjọ ti wọn ti pe fun ọpọlọpọ oṣu n bẹ nilẹ ti wọn ko fi ọwọ kan.
Bẹẹni Aṣofin Dogara to jẹ olori ile aṣoju-ṣofin ni ẹfọn to ba le eeyan ni furọ lọrọ naa, o n fẹ suuru.
Ki ni Adajọ agba Walter Onnoghen funra rẹ n sọ?
Oríṣun àwòrán, Nigeria Bar association
Adajọ agba Onnoghen ni oun ko jẹbi
Adajọ agba orilẹ-ede Naijiria, Walter Onnoghen ti sọ pe oun ko jẹbi awọn ẹsun ti wọn ka si oun lẹsẹ lori kikede dukia rẹ.
Claudiah: ìrẹ̀wẹ̀sì ọkàn bá mi fínra fún ọpọlọpọ ọdún
Onnoghen ṣalaye ninu iwe awijare to fi sọwọ si ile ẹjọ to n gbẹ ẹsun aṣemaṣe awọn to di ipo ilu mu, CCT pe iyapa to wa laarin fọọmu ikede dukia meji, No. SCN: 000014, ati SCN: 000015, ti oun fọwọ si ko ju pe oun ko tii ṣi awọn aṣuwọn ifowopamọsi naa nigba ti oun buwọlu fọọmu akọkọ ni o jẹ ki oun fi sinu fọọmu keji ti oun fọwọ si .
Pẹlu bi ọrọ seri yii, ibeere ọpọ ni pe, ṣe adajọ agba yoo tẹle ilakalẹ iwe ofin Naijiria ati oun ti awọn amofin agba n sọ pe ko si idi fun un lati fi oju han nile ẹjọ naa.
Ronke Oṣodi: òótọ́ ọ̀rọ̀ máa ń korò gan ni f'áwa èèyàn
Gani Adams: Inú ìpèbí ni Ọ̀yọ́mèsì ti pàṣẹ kí n yan olóyè mi
Gani Adams: Inú ìpèbí ni Ọ̀yọ́mèsì ti pàṣẹ kí n yan olóyè mi
Ni opin ọsẹ, ni ayẹyẹ ọdun kan Iba Gani Adams ni ori oye aarẹ ọna kakanfo ilẹ Yoruba wa sopin.
Amọṣa, ọkan lara awọn eto ti aarẹ Gani Adams gbe kalẹ lasiko ayẹyẹ naa ti n fa ọpọ awuyewuye.
Lasiko ayẹyẹ rẹ ni Iba Gani Adams yan igbimọ oloye rẹ ninu eyi to ti yan awọn ọmọ Yoruba kaakiri awọn ipinlẹ to jẹ Yoruba.
Lorilẹede Naijiria si ni igbimọ oloye Aarẹ ọna kakanfo. Eyi si ti n mu ki awọn onwoye kan atawọn ọmọ ilẹ Yoruba kan o maa beere pe ṣe o lẹtọ ki aarẹ ọna kakanfo o yan ijoye fu ara rẹ.
Ninu ifọrọwerọ pẹlu BBC News Yoruba, Iba Gani Adams funrarẹ ṣalaye pe, awọn ọyọmesi gangan lo fun oun laṣẹ lati yan igbimọ oloye ni kete ti oun ba de ori oye.
Abìjà: Bàbá mi fi iṣẹ́ ọdẹ ti ń pa lémi lọ́wọ́ ni nítorí babaláwo ni
O ni kii ṣe imọ oun nikan bikoṣe pẹlu aṣẹ Alaafin ati Ọyọmesi, oun si tun fi to Ọọni ile Ifẹ pẹlu leti.
"Lati igba ti mo ti wa ninu ipebi ni igbaradi fun ati joye, ni awọn Ọyọmesi ti jẹ ko di mimọ fun mi pe, mo gbọdọ yan oloye si igbimọ mi.
Wọn tilẹ jẹ ko di mimọ fun mi nipa awọn nnkan to ṣẹlẹ si awọn aarẹ Ọna Kakanfo ti ko yan igbimọ oloye wọn"
Eko Akete yóò gbàlejò BBC Yoruba
Iba Gani Adams ni lati aye Iba akọkọ ni wọn ti  n yan oloye si igbimọ aarẹ Ọna kakanfo ati pe, awọn oloye wọnyii ni wọn maa n ran aarẹ lọwọ lati ṣakoso ipese eto abo fun gbogbo ilẹ Yoruba, de ibi gbogbo to ruwe de tabi ta gbongbo de.
O ni ọrọ oṣelu ati okoowo to gbilẹ ni saa awọn aarẹ mejeeji to jẹ ki oun to jẹ lo faa ti ọpọ lode oni fi woo pe ko si ninu itan pe aarẹ yan igbimọ oloye laikii ṣe ọba.
Alajo Somolu: Ọdún mẹ́ta ló fi gba àjọ láì kọ ọ́ sílẹ̀, kò sì si owó àjọ san
Oríṣun àwòrán, @Dstoryteller
Lọpọ igba ni awọn eeyan maa n pa asamọ pe, ori eeyan kan pe bii alajọ Somolu, to fi ọdun mẹta gba ajọ, ti ko si kọ silẹ, bẹẹ ni ko si owo san.
Fun ọpọ eeyan ati awọn ọdọ aye ode oni, asamọ lasan tabi arosọ ni ọrọ yii, ti wọn ko si gbagbọ wipe ori eeyan kan lee pe to eyi, ti yoo gba ajọ lai kọ silẹ, ti ko si tun ni si owo san.
Sugbọn lootọ ni alajọ Somolu wa,  Alphaeus Taiwo Olunaike ni orukọ rẹ, to si gbe aarin wa nilẹ Yoruba, o bimọ, o laya, o kọle, to si tun se awọn ohun rere miran ti eeyan n gbe ile aye se.
Gẹgẹ bi akọsilẹ iroyin loju opo itakun agbaye taa ti ko iroyin yii jọ ti wi, Taiwo Sonaike gbajumọ bii baba alajọ nigba aye rẹ ladugbo Owotutu, Bariga, Awolọwọ, Oyingbo ati bẹẹ bẹẹ lọ.
The Polytechnic Ibadan: Ẹ̀rọ abẹ́lé tó ń fọ ọwọ́ àti ‘Ventilator’ ló ṣẹ̀ṣẹ̀ gbé jáde
Risikat Moromoke Azeez: Inú èmí àti Òbí mi dùn nígbà ti Risi bí ọmọ olójú búlù- Wasiu
Alaafin: Olori Aanu Adeyemi ṣàlàyé ìdí tó ṣe gẹ́ Oba Lamidi Adeyemi ti ìlú Oyo
Bi onirese Alphaeus Taiwo Olunaike, taa mọ si Alajọ Ṣomolu ko ba fin igba mọ, eyi to ti fin silẹ ninu isẹ to yan laayo, tii se ajọ gbigba ko ni parun lailai.
O si han gbangba pe, Taiwo Olunaike ko kọja nile aye bii ejo ti ko ni ipa, o ko ipa tirẹ naa si idagbasoke ọmọ niyan, ko mu ọkanmọkan, ko ja ole nidi ajọ to gba, bẹẹ ni ko wa owo ojiji.
Eyi yẹ ko jẹ ẹkọ fun awa naa pe o yẹ ka tiraka lati fi ipa manigbagbe lelẹ ninu isẹ ti a ba yan laayo nitori arise ni arika, arika ni baba iregun, ohun ta ba se loni, ọrọ itan ni yoo da lọla.
Ọba Lamidi Adeyemi pé ọdún 48 lórí ìtẹ́
Oríṣun àwòrán, Alafinofficial
Aláàfin Ọyọ pé ọdún 48 lórí àpèrè
Òní ló pé ọdún méjìdínláàdọ́ta tí aláfin Oyo, Ọba Lamidi Adeyemi kẹ́ta gori apèrè àwọn bàbá rẹ̀.
Oluwo ti Iwo Ọba AbdulRasheed Akanbi kí Aláàfin Ọyọ kú ọjọ́ ìbí
A bí Lamidi Olayiwola Adeyemi III ní ọjọ́ kẹẹ̀dógún oṣù kẹwàá ọdún 1938.
Oba Adeniran Adeyemi II ní bàbá  Lamidi  kí wọn to lé kúrò lóri oye fún ibasepọ rẹ̀ pẹ̀lú NCNC.
Lamidi Adeyemi Jọba lẹ̀yìn Gbadegesin Ladugbolu lọdún 1970 lásìkò gomínà Robert Adeyinka Adebayo lẹ́yìn ogun abẹlé Nàìjíríà, bakan naa ní ààrẹ ológun Muritala Ramat Mohammed náà yàn láti kọ́wọ̀ rìn pẹ̀lú rẹ̀ lọ sí Hajj.
Ọpọ̀ àwọn ọmọ kárọ̀ọ̀-oò- jíire ló ti ń kí ori ade kú aṣeyẹ ọdun míràn lórí aléfà, tó fi mọ olori tó kéré jùlọ laáàfin Badirat Adeyemi  nígba to lọ sójú òpó instagram rẹ̀ láti lọ kí olówó orí rẹ̀.
Bakan náà lóri atẹ̀jíṣẹ́ facebook ọ̀pọ̀ àwọn ọmọ Yorùbá ló ti gbóríyìn fún alaafin fun iṣẹ́ ribiribi ti ó ti ṣe lọ́dún méjìdínláàdọ́ta sẹ́yìn, wọn ni Ọba Lamidi ní ó mú aláfíà àti ìtẹ̀síwájú bá Ọyọ
Wọn gbàdúrà kí ọlọrun fún baba ní ẹ̀mí gígùn lórí ilẹ̀
Ṣé ìwọ láyà ti o mọ òwe Yorùbá dáadáa?
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Aṣa Yoruba dùn pupọ
Eyi ni akojọpọ diẹ lara awọn òwe ti BBC Yorùbá ti lò sẹyin.
Tẹ ibi yii ki o dahun bi o ṣe yẹ.
Oduduwa Alphabet: òmìnira èdè ti dé fún Port Novo báyìí
Arm forces Remeberance day: Naijiria ń ṣe ìrántí àwọn ológun to ṣubú lójú ogun
Oríṣun àwòrán, SODIQ ADELAKUN/AFP/Getty Images
ọpọ ọmọ ogun Naijiria lo ti fẹmi wọn silẹ
Òní ni àyájọ́ ọjọ́ àwọn ọmọ ogun tói ṣègbé sójú ogun ní Naijiria, àwọn àwọran bí iranti naa ṣe ń lọ ati oun ti àwọn ọmọ Naijria n sọ rèé.
Àwọn ẹgbégun Naijiria gbalejo Aarẹ Muhammadu Buhari ni Eagles Square fun ayajọ ọjọ naa.
Oríṣun àwòrán, Bashir Ahmad
Iṣe ologun buyi kun eniyan lawujọ
Buhari naa yan bi oloogun gẹgẹ bii olori ogun Naijiria.
Aarẹ Ile Igbimọ Aṣofin Agba Bukola Saraki ati abẹnugan Ile Igbimọ Aṣofin Kekere, Yakubu Dogara, naa juba awọn ọmọ ogun to ti ṣegbe ni Eagles Square.
Oríṣun àwòrán, Bukola Saraki
Awọn oloṣelu gan mọ riri awọn ọmọ ogun
Saraki gbori yin fun awọn obirin ati ọkunrin to n fi ẹmi wọn daabo bo ọmọ Naijiria.
Gomina Ipinlẹ Kaduna, Nasir el-Rufai na  ko gbẹyin. O sẹ ẹyẹ fun awọn ọmọ ogun to ti re kọja naa.
Oríṣun àwòrán, NASIR EL RUFAI
Aabo ẹmi ati adukia ara ilu lo jẹ wọn logun
2019 Elections: Aago mẹ́sàn-án àárọ̀ ni ìjíròrò Eko yóò bẹ̀rẹ̀
Ni Ipinlẹ Delta, Gomina Ifeanyi Okowa naa ṣe iranti awọn ọmọ ogun.
Àwọn oludije fun ipo Aarẹ bii Oby Ezekwesili na ṣe sàdáńkátà sí àwọn ọmọ oloogun.
Brexit: Ọ̀rọ̀ kò yé wa mọ́!
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Brexit? Awon wo lo kan?
Ni ọjọ Isegun, awọn aṣofin Ilẹ Gẹẹsi n dibo lori ipinnu adari ijọba, Theresa May lati ko orilẹ-ede naa kuro ninu ajọ European Union.
Idibo naa ti wọn sun siwaju lati ọjọ kọkanla, oṣu kejila, ọdun 2018 lo n ka wakati igba ti orilẹ-ede naa yoo dagbere fun EU ni ọjọ kọkandinlọgbọn, ọsu kẹta.
Ko si ẹnikẹni to mọ oun ti Brexit yoo ja si, ọrọ naa si le ma fori sibi kan titi opin ọsẹ.
Ọ̀rọ̀ lórí Brexit
Ṣugbọn oun ti a le mọ lakọkọ ni bi awọn aṣofin ṣe le gbogun ti awọn adehun ti Theresa May ni pẹlu EU ati pe boya o tilẹ ni eto kankan lori ọrọ naa.
Eyi ko daju nitori pe, ti o ba ja kulẹ ninu idibo naa ni ọjọ Isegun, o gbọdọ sọ fun awọn aṣofin ni ọjọ Aje to tẹle oun ti o n gbero lati ṣe.
Adehun Theresa May pẹlu EU lori Brexit pin si meji, ipinnu ti ofin de nipa kikuro ninu EU tabi ipinnu ti ofin ko de.
Awọn aṣofin to fẹran Brexit ninu ijọga May ni adehun naa ti jẹ ki Ilẹ Gẹẹsi sun mọ EU just ṣugbọn awọn alatako wọn ni alaye adehun naa ko ye ara ilu daradara.
Oduduwa Alphabet: òmìnira èdè ti dé fún Port Novo báyìí
BBC ni o ṣeeṣe ki ipinnu May nijakule ti wọn ko ri iru rẹ ri ni ọgọrun un ọdun. Oun ati awọn ti wọn jọ n ṣe ijọba yoo maa sare lati jẹ ki ijakulẹ naa mọ niwọnba.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Cbocbo oju wà lára Theresa May bayii
Awọn ti o n ba May ṣiṣẹ ni awọn gan ko mọ oun ti olori ijọba naa yoo ṣe to ba ja kulẹ.
Ni gbangba ati ni ikọkọ, May ni ipinnu oun dara ati wipe oun nikan ni ọna ti ilu ko fi ni bajẹ.
Awọn oun to le ṣẹlẹ rèé: pada si EU lati jẹ ki awọn adehun to sẹ pẹlu ajọ naa jẹ oun ti awọn aṣofin fẹ, ko sọ fun awọn aṣofin ki wọn ba oun wa ọna miiran to yatọ si adehun oun, tabi ko tilẹ halẹ mọ wọn.
Ki i ṣe ẹgbẹ oṣelu Conservative ni ko ni iṣokan lori ọrọ Brexit, ọrọ ẹnu awọn ọmọ ẹgbẹ oṣelu Labour naa ko ko lori ọrọ naa.
Awọn olori Labour labẹ iṣakoso Jeremy Corbyn fẹ Brexit, ṣugbọn awọn ọmọ ẹgbẹ fẹ ki Ilẹ Gẹẹsi ṣe dibo itagbangba (referendum) ẹẹkeji lati jẹ ki orilẹ-ede naa duro sinu EU.
Ẹgbẹ oṣelu Labour ti ni awọn ko ni dibo fun adehun May lori Brexit.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ko sẹni to mọ.
Lẹyin ọdun meji ati aabọ, ẹnu awọn aṣofin ko tii ko lori esi idibo itagbangba to waye lorilẹ-ede naa.
Ko si ọrọ oṣelu to buru to yii lati ọdun 1945.
2019 Election: INEC sòfin láti dènà fífi owó ràbò níbi ìdìbò 2019
"2019 Election: INEC sòfin láti dènà ""SEE & BUY"" níbi ìdìbò 2019"
Àjọ elétò ìdìbò Nàìjíríà, INEC tí ṣe àgbéjáde àwọn òfin àti àlàsílẹ̀ tuntun láti dènà owó pínpín níbi ìdìbò gbogboogbò ọdún 2019.
Nínú ìwé ofin túntun náà ní wọn ti sàlàyé pé, àti ẹ̀rọ tí wọn fi ń yẹ káàdì ìdìbò wò àti káàdì ìdìbò, ní àwọn yòó lò fún ètò ìdìbò.
Oduduwa Alphabet: òmìnira èdè ti dé fún Port Novo báyìí
Ìwé ọ̀hún pẹ̀lú ló kéde àsìkò ìdìbò ààrẹ, àti ilé ìgbìmọ̀ aṣòfin àgbà tí yòó wáyé ní ọjọ kẹrìndínlógún oṣù kejì ọdún, 2019, bákàn náà ló fi ìdí rẹ̀ múlẹ̀ pé, àwọn ìbò gómìnà àti ilé ìgbìmọ̀ aṣòfin ìbílẹ̀ yóò wáyé lẹ́yìn òsẹ̀ méji.
Àwọn ǹkan míràn tó tún wà nínú ìwé òfin náà:
Ìkọlù Kenya: èèyàn mẹ́rìnlá pàdánù ẹmi wọ́n ninu Ikọlù náà
Ìbúgbàmù ńlá ati iro ibọn gbalẹ ni ile itura Nairobi
Ikọlu iyinbọnpaniyan to waye nile itura DusitD2 lorileede Kenya ti dopin lẹyin ti awọn agbofinro pa awọn agbebọn to wa nidi ikọlu naa.
Eeyan mẹrinla lo padanu ẹmi wọn ninu iṣẹlẹ ohun .
Aarẹ orileede Kenya Uhuru Kenyatta lo kede ọrọ yi lọjọru.
Ko ti daju iye awọn to wa nidi iṣẹlẹ naa ṣugbọn ọga ọlọpa lorileede Kenya Joseph Boinnet sọ fun ile iṣẹ iroyin AFP pe awọn maarun  lawọn funra si pe o kopa ninu ikọlu naa
Awọn ọmọ ikọ Al-Shabab  ti saaju kede pe awọn lawọn wa nidi ikọlu to waye nile itura kan nilu Nairobi.
Lọjọ iṣẹgun lawọn agbebọn sadede yabo ile itura Dusit lolu ilu Kenya ti ṣe Nairobi.
Iroyin ta gbọ ni pe eeyan kan ti ku ninu iṣẹlẹ naa ti awọn agbofinro si ti n gbiyanju lati doola awọn eeyan to ha sinu ile itura naa.
Oríṣun àwòrán, AFP
Ikọlu Kenya
Ẹgbẹ Al Shabab fi ikede sita lati ọwọ agbẹnu sọ wọn kan to ba BBC Somalia to fidi joko silu Nairobi sọrọ.
O kere tan ibugbamu meji lawọn akoroyin sọ wi pe awọn ti gbo ninu ọgba ile itura naa.
Oríṣun àwòrán, AFP
Awọn eeyan ti n sa asala fun ẹmi wọn nibi ikọlu naa
Ọga ọlọpaa nilu Kenya Joseph Boinnet, ti fidi iṣẹlẹ naa mulẹ wi pe awọn agbebọn yabo ile itura Dusit, ti wọn fura si wi pe o jẹ ''ikọlu awọn agbesunmọmi.''
"O sọ pe ""A mọ wi pe awọn agbebọn kan si yi wa ninu ile itura naa, ti a si gbọ wi pe awọn agbofinro wa ti n gbiyanju lati wọ idi wọn sita.''"
O salaye pe awọn ọlọpaa ti doola ẹmi ọpọ eeyan ti o si rọ awọn ara ilu lati ma se kaya soke.
''A n gbiyanju lati dẹkun ikọlu yi ni kiakia''
Ogun 2019: Ladi Adebutu ní ìdájọ́ iléẹjọ́ kò ní nǹkan se pẹ̀lú òun
Oríṣun àwòrán, PDP
Oludije fun ipo gomina ti ẹgbẹ oṣelu PDP n ti lẹyin fun ipo gomina nipinlẹ Ogun lasiko idibo apapọ ọdun 2019, Ladi Adebutu ti sọ pe, pẹlu-pẹlu idajọ ti ile ẹjọ gbe kalẹ lọjọ Aje lori ọrọ oludije ipo gomina ipinlẹ naa, oun ṣi ni oludije ẹgbẹ oṣelu PDP nipinlẹ naa.
Ninu ifọrọwerọ rẹ pẹlu BBC News Yoruba, agbẹnusọ fun ọgbẹni Adebutu, Afọlabi Ọrẹkọya ni, idajọ naa ko ni ohunkohun ṣe pẹlu boya Adebutu ni oludije tabi Kaṣhamu.
O ni ohun ti Adebutu gbe ka iwaju ile ẹjọ naa fun ayẹwo ni pipaṣẹ fun ajọ eleto idibo INEC lati gba orukọ rẹ gẹgẹ bii oludije ti ajọ naa damọ.
2019 elections: Ladi Adebutu ní òun ṣì ni olùdíje PDP fún ipò gómìnà l'Ogun
Orukọ Sẹnetọ Kaṣamu ni ajọ INEC gba wọle lẹyin idajọ ile ẹjọ giga kan to ni, ẹgbẹ PDP ko tẹle idajọ ile ẹjọ kan saaju ki o to lọ ṣe idibo abẹnu to gbe Ladi Adebutu wọle.
Alao Akala:Èmi àti Ajimọbi kò ṣe ìlérí kankan fún ara wa
Agbẹnusọ fun Ladi Adebutu naa ni, awọn ṣi n reti ki awọn adari apapọ ẹgbẹ oṣelu naa o gbe igbesẹ ti o tọ, gẹgẹ bi o ṣe ni ile ẹjọ naa paṣẹ ki wọn lọ ṣe.
Ninu ọrọ tirẹ, ikọ Sẹnetọ Kaṣamu ni awọn yoo yẹ ọna gbogbo to yẹ lati rii pe, ifẹ awọn ọmọ ẹgbẹ lo jọba ati pe alaafia wa ninu ẹgbẹ oṣelu naa lai naani ẹni yoowu to ba dije fun ẹgbẹ oṣelu naa lẹyin o rẹyin.
2019 Elections: Aago mẹ́sàn-án àárọ̀ ni ìjíròrò Eko yóò bẹ̀rẹ̀
Ninu ọrọ ti agbẹnusọ fun Sẹnetọ Kaṣamu, Austin Oniyokor, ba BBC News Yoruba sọ, alaafia ati igbega ẹgbẹ oṣelu PDP lo jẹ Sẹnetọ Kaṣamu logun.
O ni aṣofin agba naa ṣetan lati ba Ladi Adebutu tabi ẹnikẹni sowọpọ fun idagbasoke ẹgbẹ oṣelu PDP.
2019 elections: Ọọ̀ni Ilé Ifẹ̀ rọ àwọn olóṣèlú láti ṣọ́ra ṣe fún ìdìbò ọdún 2019
Oríṣun àwòrán, Yera Moses
Ọọni ni orilẹede Naijiria tobi ju ilepa oloṣelu yoowu lọ
Lori idibo 2019, Ọọni ile ifẹ, Adeyẹyẹ Ogunwusi, Ọjaja II ti ke sawọn oloṣelu lorilẹ-ede Naijiria lati fi alaafia, idagbasoke ati igbayegbadun Naijiria ṣaaju ninu ohun gbogbo ti wọn ba n ṣe.
Amọran yii ni Ọọni Ogunwusi gbe kalẹ lasiko ti oludije fun ipo aarẹ lẹgbẹ oṣelu PDP, Abubakar Atiku bẹẹ wo ni aafin rẹ nilu Ile Ifẹ.
Atiku wa ni ipinlẹ Ọṣun ni ọjọ Iṣẹgun lati polongo idibo fun erongba rẹ lati du ipo aarẹ lasiko idibo apapọ ọdun yii.
Orilẹ-ede Naijiria ni a gbọdọ maa fi ṣiwaju ninu ohun gbogbo nitori ọrọ Naijiria ju ilepa ẹnikẹni lọ.
Oríṣun àwòrán, yera moses
Ọọ̀ni Ogunwusi ní àláfíà Nàìjíríà ju ìlépa àwọn olóṣèlú lọ.
Bi o tilẹ jẹ pe a n mu idagbasoke ba orilẹ-ede Naijiria bayii, sibẹ omi ṣi pọ lamu paapaa julọ nipa yiyago fun oṣelu onijagidijagan, yala gẹgẹ bii ọmọ ẹgbẹ oṣelu to n ṣejọba ni o tabi ẹgbẹ oṣelu alatako.
Ninu ọrọ rẹ, Atiku Abubakar to kọwọrin pẹlu iyawo rẹ, Titi Abubakar ni ọla ati ọwọ ti oun ni fun Ọọni Ile Ifẹ lo jẹ ki oun kọkọ wa foribalẹ niwaju rẹ naa ki oun to mu ohunkohun ṣe.
Woli Kasali: Angẹli mi ni orékelẹ́wà Dọlapo Awoṣika
Lara awọn to ba Atiku Abubakar kọwọrin, ni alaga apapọ ẹgbẹ oṣelu PDP, Uche Secondus, gomina tẹlẹ nipinlẹ Ọṣun, Ọlagunsoye Oyinlọla atawọn eekan ẹgbẹ oṣelu naa miran.
Wòlíì Kasali sọrọ nípa awuyewuye pé o lè ìyàwó rẹ̀ jáde nílé
e-Passport: Ààrẹ Buhari tẹ́wọ́ gba ìwé ìrìnnà Nàìjíríà tuntun
Oríṣun àwòrán, Bashir Ahmad
'iwe irinna tuntun naa ko fopin si elo ti iwe irina to wa tẹlẹ.'
Aarẹ Muhammadu Buhari ti ṣefilọlẹ iwe irinna silẹ okeere tuntun, e-Passport oni saa ọdun mẹwa ti wọn ṣẹṣẹ gbe jade.
Ọga agba ileeṣẹ to n mojuto iwọle-wọde lorilẹ-ede Naijiria, NIS Mohammed Babandele ṣalaye fawọn oniroyin pe awọn amuyẹ kan jẹyọ lara iwe irinna tuntun naa ti yoo mu ki o rọrun fun eto aabo.
Amuyẹ eto aabo to peye wa ni ara rẹ ni eyi ti yoo daabo bo awọn ọmọ Naijiria to ba n lọ si oke okun ki wọn lee maa de ileeṣẹ aṣoju ijọba Naijiria nilẹ okeere to ba wu wọn.
O ni ẹgbẹrun mẹẹdọgbọn naira ni wọn n ta iwe irinna oloju iwe mejilelọgbọn, ati pé ẹgbẹrun marundinlogoji ni toloju iwe mẹrinlelọgọta ti o jẹ ọlọdun marun.
Woli Kasali: Angẹli mi ni orékelẹ́wà Dọlapo Awoṣika
O ni ẹgbẹrun lọna aadọrin naira ni wọn n ta iwe irinna oloju iwe mẹrinlelọgọta ti wọn ṣẹṣẹ ṣe jade naa.
O ni agbejade iwe irinna tuntun naa ko fopin si lilo ti iwe irinna to wa tẹlẹ.Ati pé ọdun mẹwaa ni yoo jẹ gbendeke fun lilo tuntun.
Edgar Imohimi ṣì ni ọ̀gá ọlọ́pàá ìpínlẹ̀ Eko-Iléeṣẹ́ ọlọ́pàá
Oríṣun àwòrán, dailypost
Awuyewuye n waye lori tani ọga ọlọpaa laaarin Edgar ati Ẹgbẹtokun
Ileeṣẹ ọlọpaa ti ṣalaye pe Kọmiṣọna Ọlọpaa, Edgar Imohinmi ṣi ni ọga ọlọpaa nipinlẹ Eko.
Ọpọlọpọ ariyanjiyan ni o ti n lọ kaakiri lori ẹni gan an to jẹ ọga ọlọpaa nipinlẹ Eko lẹyin ti ọga agba ọlọpaa to n fipo silẹ, Ibrahim Idris ti ni ki Kọmiṣọna ọlọpaa, Edgar Imohimi o gba olu ileeṣẹ ọlọpaa nilu Abuja lọ ki o to kuro nipo.
Ọga ọlọpaa ana ni ki Kayọde Ẹgbẹtokun lọ gba ipo aṣẹ ileeṣẹ ọlọpaa nipilẹ Eko ni ọjọ Aje.
Amọṣa nigba ti yoo fi di ọjọ Iṣẹgun ni ọrọ ba tun yipada ti Edgar ni oun ṣi ni ẹni ti o n ṣakoso ileeṣẹ ọlọpaa nipinlẹ Eko.
'Èṣù kìí ṣe sàtànì bí ẹ ṣe máa ń pè é'
Ni bayii, ileeṣẹ Ọlọpaa nipinlẹ Eko ti sọ pe, Edgar Imohimi ni ọga ọlọpaa nipinlẹ Eko.
Alukoro ileeṣẹ ọlọpaa nipinlẹ Eko, Chike Oti ṣalaye fun BBC pe Edgar ni kọmiṣọna ọlọpaa nipinlẹ Eko bayii titi di igba ti aṣẹ miran yoo tun wa.
Ìbúgbàmù ńlá ati iro ibọn gbalẹ ni ile itura Nairobi
Iléeṣẹ́ ọlọ́pàá: Mba ti ṣiṣẹ́ rí bíi òṣìṣẹ́ alárinà lọ́dún 2012 sí 2014
Oríṣun àwòrán, @PoliceNG
Ileesẹ ọlọpa ilẹ Naijiria ti kede Ọgbẹni Frank Mba gẹgẹ bii osisẹ alarina agba fun ileesẹ naa.
Igba akọkọ si kọ ree ti Mba yoo di ipo osisẹ alarina agba fun ileesẹ ọlọpa il wa mu, tori o ti wa ni ipo naa ri lasiko ti ga ọlọpa Mohammed Abubakar wa nipo ko to fẹyinti.
Woli Kasali: Angẹli mi ni orékelẹ́wà Dọlapo Awoṣika
Ọdun meji gbako si ni Frank Mba fi sisẹ naa eyi to wa laarin ọdun 2012 si 2014.
Lọwọ lọwọ bayii, Frank Mba ti gunlẹ silu Abuja lati bẹrẹ isẹ, ti ireti si wa pe yoo foju-rinju pẹlu ọga agba ọlọpa tuntun, Adamu Mohammed lọsan oni.
Lizzy Anjọrin: Inú mi dùn láti di Bọ̀rọ̀kínnì Àdínnì
Yoruba ni oniruuru ọbẹ laa ri lọjọ iku erin, bẹẹ ni ọrọ ri lasiko ti ilumọọka elere tiata lobinrin kan, Alhaja Aisha Lizzy Anjọrin se iwuye oye ẹsin Bọrọkinni Adinni ti wọn fi jẹ.
Se ni agbegbe yaba nilu eko n ro gbarọ gbudu lasiko ayẹyẹ iwuye naa eyi ti ẹbi, ọrẹ, ololuf ati awọn alajọsepọ rẹ peju si.
Koda awọn isẹ ikinni ku oriire gan ko gbẹyin loju awn opo ikan sira ẹni Facebook ati Instagram, ti wn n ki Lizzy ku oriire oye tuntun.
Woli Kasali: Angẹli mi ni orékelẹ́wà Dọlapo Awoṣika
Mama Oloye tuntun naa, Lizzy Anjọrin, si fi awọn aworan ayẹyẹ iwuye rẹ lu oju opo Twitter rẹ kan, diẹ lara rẹ ni iwọnyi.
Lara awọn eeyan to ba Lizzy se jaginni yodo oye tuntun naa ni Alaafin tilu Ọyọ, Ọba Lamidi Ọlayiwọla Adeyẹmi Kẹta ati awọn olori rẹ meji.
Oríṣun àwòrán, Lizzy Anjorin
Kade pẹ lori laa ki ọba, ikunlẹ ati idọbalẹ si ni a ma n ki oriade nilẹ Yoruba, tori awọn arọbafin nikan lo n se lodi si eyi.
Lizzy Anjọrin ree to ba buruburu niwaju Alaaafin lati fi ẹmi imoore rẹ han si bi ori ade naa se wa yẹ si ni ọjọ iwuye rẹ.
Oríṣun àwòrán, Lizzy Anjorin
A kii ri ẹfọn ta lẹẹmeji lawọn eeyan fi fọto yiya se pẹlu Alaafin. Pinra-pinra si ni wọn nya fọto pẹ́lu baba.
Oríṣun àwòrán, Lizzy Anjorin
Mama oloye tuntun ree lagbo, Bọrọkinni Adinni tuntun, to wọ asọ olowo iyebiye, ti oju rẹ si dun wo
Oríṣun àwòrán, Lizzy Anjorin
Lara awọn eekan ilu lagbo orin kikọ to yẹ Bọrọkinni Adinni tuntun si ni Alhaja Salawa Abẹni ati Wasiu Alabi pasuma.
Oríṣun àwòrán, Lizzy Anjorin
Lizzy Anjọrin ree pẹlu awọn afẹnifẹre miran lasiko ayẹyẹ iwuye ọhun.
Oríṣun àwòrán, Lizzy Anjorin
Awọn eyin funjowo ati ẹlẹyinju ẹgẹ ree nibi ayẹyẹ Lizzy Anjọrin
Oríṣun àwòrán, Lizzy Anjorin
Iyabọ Ojo ree, ọkan lara awọn gbajugbaja elere ori itage lobinrin, ti wọn wa yẹ Lizzy Anjọrin si lọjọ iwuye rẹ.
Oríṣun àwòrán, Lizzy Anjorin
Nairobi Attack: Ọ̀pọ̀ àwọn tó há síbi ìkọlú náà ló se ó dígbà lórí Twitter, Whatsapp
Oríṣun àwòrán, EPA
Ikọlu Kenya
O to ẹ̀ẹ́dẹ̀gbẹ̀rin èèyàn ti ori ko yọ ninu ikọlu awọn alakatakiti agbebọn ti wọn ṣigun lọ awọn ile iṣẹ ati ile itura lolu ilu Kenya, Nairobi
Wakati mọkandilogun ni ikọlu naa fi waye, eyi to bẹrẹ laago mẹta ọsan lọjọ iṣẹgun fi waye.
Iriri diẹ ninu awọn eeyan to ru iṣẹlẹ naa la, ti wọn mori bọ lọwọ ikọlu ikọ Al Shabab re e:
'Ile igbọnṣẹ ni a ha ara wa mọ'
Awọn akọroyin meji kan ti wọn ba ile iṣe iroyin orileede Kenya NTV ṣiṣẹ, wa lara awọn ti wọn ha sinu ikọlu naa to waye fun nnkan bi wakati mejila.
inu ile igbọnṣẹ ni awa ati awọn akẹẹgbẹ wa kan ha si, ni iṣẹ ti akoroyin Silas Apollo fi ranṣe si ori opo Whatsapp .
"O kọ ọ sibe pe e ""Ẹru n ba mi gaan."""
Oríṣun àwòrán, Reuters
Wakati mọkandinlogun lawọn agbofinro fi koju awọn agbebọn naa
"O fi kun sinu Whatsapp pe ""Niṣe ni wọn n lọ, ti wọn n bọ, ti wọn si n yinbọn laibikita. Ọrọ naa ko rẹrin rara,"""
Awọn akọroyin naa sọ fun ile iwe iroyin Daily Nation pe, awọn ati awọn akọroyin mii ti wọn to mẹrinla ṣaa n rakoro lati inu ile igbọnṣẹ lọ si iyara kan si imiran titi ti wọn fi de gbagede nla .
Nigba ti yoo fi to aago mẹta kọja iṣẹju mẹẹdodun ni awọn agbofinro doola ẹmi wọn lọjọru.
'Mo fi ọrọ ranṣẹ loju opo Twitter'
Inu ọfisi rẹ nibi ti o ti n ṣiṣẹ gẹgẹ bi alukoro fun ajọ to n ri si eto pipin owo to n wọle si asunwọn orileede Kenya, ni Ronald Ng'eno wa, to ti gbọ iro ''ibugbamu nla kan ti ariwo ibọn yinyin si tẹle''
Ronald Ng'eno ti kowe ranse dagbere odigab si awọn mọlẹbi rẹlori Twitter
Oun ati awọn akẹgbẹ rẹ gbinyanju lati sa jade ṣugbọn awọn agbebọn naa ti wọle kan wọn lara.
"O sọ fun ileesẹ iroyin AFP PE, ""Bi wọn ṣe bẹrẹ si ni yinbọn lu wa, la sa gba ibo miran, ti a si sa pamọ si ile igbọnṣẹ to wa ni akasọ kinni. Mo ri alafo kan nibẹ ti mo sapamọ si''"
Ronald salaye fun BBC pe ''A ha ara wa mọ ile igbọnṣẹ naa, ti a si dakẹ rọrọ.''
Ni igba ti yoo fi to nnkan bi ago meje ale, ti iro ibọn si n ro, ọgbẹni Ng'eno fi ọrọ ranṣe si ori Twitter pe oun ṣi wa ni ile igbọnṣẹ:
Lẹyin ti ikọlu naa ti  to wakati maarun, ni o kọ ọrọ pe ẹrọ ibanisọrọ ohun ti fẹku.
Pupọ lo fẹsi si ọ́rọ to fi ranṣẹ sita, ti wọn si fi nọmba rẹ ranṣẹ si ọga awọn to n dari idoola ẹmi awọn eeyan.
Kia lọrọ to fi sita fọnka nitori pe o ti dagbere o digba fun awọn mọlẹbi rẹ ninu rẹ:
Awọn aworan miran nipa awọn tori koyọ ninu iṣẹlẹ naa re e:
Oríṣun àwòrán, Reuters
Awọn agbofinro lo doola ẹmi awọn eeyan kuro ninu ile naa
Oríṣun àwòrán, AFP
Orin ọpẹ ati ayo lo kun ẹnu awọn ti ori ko yọ
Oríṣun àwòrán, Reuters
Lẹyin ti wọn yinbọn lu awọn ọlọde ile itura naa,awọn agbebọn naa sọ ina si awọn ọkọ
Oríṣun àwòrán, Reuters
Ẹni ori yọ, ipade di ile lọrọ naa
Nigeria 2019: Ìròyìn ìdìbò 2019 ti gbérasọ lórí BBC pẹ̀lú #BBCNigeria 2019
Eti ọba nile,ẹti ọba loko ohun gbogbo la o ma mu wa si eti igbọ yin
Bẹrẹ lati ọjọ kẹtadinlogun oṣu kini ọdun 2019, ile iṣẹ iroyin BBC World Service yoo ma kajọ de iberẹ idibo 2019 lorileede Naijiria.
Oun ti eleyi tunmọ si ni wi pe gbogbo ohun to yẹ ki ẹ mọ nipa idibo naa ni ẹka BBC Yoruba, BBC Hausa, BBC Igbo ati BBC Pidgin yoo ma mu wa si eti igbọ yin gẹgẹ bi alakalẹ eto wa lasiko idibo yii.
2019 election: Àwọn olùdíje fún ipò gómìnà nípínlẹ̀ Kwara sọ̀rọ̀ lórí ohun tí wọ́n fẹ́ ṣe
Bi  ẹ ba n wa awọn iroyin to munadoko, paapa julọ lori ẹrọ ayelujara, hashtag#BBCNigeria2019  ni ki ẹ maa lo lasiko idibo yii.
Bi awọn iroyin naa ba ṣe n wa leṣẹẹṣe ni ẹ o maa gbọ wọn lori ikanni wa.
Ẹ ma gbagbe wi pe awọn ipade itagbangba wa naa ti n lọ lọwọlọwọ ti a si rọ yin lati maa ba wa kalọ loju opo Facebook ati itakun ayelujara pẹlu hashtag#BBCNigeria2019
Adedoyin: Tí mo bá rí Buhari, màá sọ fun kó rántí pé Ọlọ́run wà
Iko BBC Yoruba tuntun
Atiku Abubakar - Kò dájú pé ìdìbò 2019 yóò kẹ́sẹjárí
Oríṣun àwòrán, REUTERS/Temilade Adelaja
Atiku Abubakar ko ṣẹṣẹ ma fidirẹmi ninu idibo Aarẹ lorileede Naijiria
Bi idibo ọdun 2019 lorileede Naijiria ti ṣe ku osu kan, oludije sipo aarẹ labẹ ẹgbẹ oṣelu Peoples Democratic Party, ti sọ fun BBC pe oun ko ni igbagbọ pe eto ibo naa ko ni ni mago mago ninu.
Atiku Abubakar  to jẹ ọmọ ọdun mẹ́rìnléláàdọ́rin to si dipo igbakeji aarẹ mu rlaarin ọdun 1999 si 2007 ni awọn eeyan gbagbọ pe oun ni alatako gboogi ti Aarẹ Buhari ni.
Nigba ti akọroyin BBC bere lọwọ rẹ pe se yoo gba ni irọwọrọsẹ ti o ba fidirẹmi ninu idibo naa, Atiku sọ pe o da oun loju pe oun ko ni fidirẹmi.
''Ki ṣe ọrọ boya maa fidirẹmi lo delẹ yi, ohun to ṣe pataki julọ ni boya idibo yi ko ni ni mago mago ninu.
Pẹlu gbogbo igbesẹ ti ẹgbẹ oṣelu to wa nijọba n gbe, ti a si ti ri, ko si aridaju pe wọn ṣetan lati ṣeto idibo ti yoo kẹsẹ jari''
Atiku ni ohun to ṣẹlẹ ninu awọn atundi ibo to ti waye labẹ iṣakoso ẹgbẹ APC to ṣafihan bi  APC ṣe fi awọn agbofinro dun kukulaja mọ awọn oludibo n tọka si ohun ti oun n sọ.
''A n parọwa si awọn awujọ agbaye lati gbaruku ti wa ki eto idibo yi lọ ni irọwọrọsẹ''
Lori ọrọ pe ko fẹ ẹ si iyatọ laarin ẹgbẹ oṣelu rẹ, PDP ati ẹgbẹ oṣelu APC nipa afojusun wọn ati bi wọn ṣe n ṣe ipolongo ibo ti ko gbajumọ ọrọ to ṣe koko, Atiku ni iru nkan bẹ ko le ṣai waye nitori pe eto oṣelu Naijiria ko ti fẹsẹ rinlẹ daada.
''Mi o ṣe idiwọ fun ọdọ to ba fẹ du ipo. Mi o si lero wi pe o tọ lati ma dẹyẹ si mi nitori ọjọ ori mi''
Bakan naa ni Atiku, ninu ibeere mi to jẹyọ lori eto aabo ṣalaye bi yoo ti ṣe dari ipenija to n koju awọn ọmọ ileeṣẹ ologun Naijria.
O ni ẹbi bi nkan ṣe ri ki ṣe awọn ileeṣẹ ologun nikan.
"Mo lero wi pe apapọ awọn ọmọ ogun ni wọn ko gbiyanju to. O jọ bi ẹni pe o ti rẹ wọn.
Ati ọmọ ogun ofurufu ati t'oriilẹ, wọn ti pẹ nibẹ ti eleyi si n ṣe ifasẹyin fun wọ."
Àwọn ìgbésẹ̀ tó yẹ láti bá INEC ṣíṣẹ́ ìdìbò 2019
Oríṣun àwòrán, Getty Images
INEC
Ajọ eleto idibo lorileede Naijiria kede lọjọru pe awọn n wa awọn eeyan ti yoo ba wọn ṣiṣẹ lasiko idibo gbogbo gbo ọdun 2019.
Ikede ọhun ti wọn fi si oju opo Twitter wọn salye pe awọn ipo maarun kan lawọn n wa eeyan to kun oju osunwọn fun lẹni ti yoo pese iranwlọwọ lawọn ibudo iforukọsilẹ ati awọn ijọba ibilẹ.
Awọn ipo to wa nilẹ ọhun ni ipo Alamojuto eto idibo( Supervisory Presiding offcer), oludari aye iforukọsilẹ(Registration Area Center -RAC Manager), alamojuto eto ibo(Presiding Officer - PO), igbakeji alamojuto eto idibo(Assistant Presiding Officer ), ati amoju ẹrọ lawọn aye iforukọsilẹ nijọba ibilẹ(Registration Area Technical Support)
Awọn to n wa ipo naa le lọ si oju opo INEC eleyi tii ṣe  http://pres.inecnigeria.org/
Awọn agunbaniro ati oṣiṣẹ Inec miran lasiko idibo
Se gbogbo eeyan lo le forukọ silẹ?
Ṣaaju ki o to bẹrẹ iforukọsilẹ, o ni awọn nnkan to yẹ ki o ni gẹgẹ bi nnkan ti INEC n bere fun.
Ẹnikẹni to ba fẹ forukọ silẹ gbudọ ni apo ifiweransẹ ori ẹrọ ayelujara, e-mail, aworan fọto pelebe  ti ko ju 50kb ni iwọn ati adirẹsi awọn oniduro rẹ.
Awọn to n wa iṣẹ gbọdọ ni nọmba ṣiṣe agunbanirọ eleyi  to bẹrẹ lati ọdun 2017 pẹlu ami idanimo to koju owo.
Bi o ba n gbero lati forukọ silẹ yara tete nitori iforukọsilẹ yoo dopin lọjọ kọkanlelogun oṣu kini ọdun 2019.
Nigerian 2019 Elections: Àwọn wo ni ọ̀rẹ́ Atiku tó fẹ́ sọ di olówó tó bá di ààrẹ?
Oríṣun àwòrán, @Atiku
Lasiko ti eto idibo ba n kanlẹkun, oriṣiriṣi ileri ni awọn oloṣelu maa n ṣe fun awọn araalu.
Ọpọlọpọ awọn ileri tabi ọrọ ti wọn ba sọ yii lo maa n saba fa awuyewuye laarin awọn oludibo, nitori ọpọ maa n beere pe ọna wo ni wọn fẹ gbe e gba lati mu u ṣẹ.
Atiku Abubakar ninu ọrọ to sọ lasiko to kopa nibi eto kan ti wọn fi sori riro eto ọrọ aje Naijiria lagbara to waye pẹlu awọn oniṣowo nilu Eko.
Eto naa ti ileeṣẹ amohunmaworan Channels ṣafihan rẹ, ni fidio ọhun ti Atiku sọ ti n fa ariyanjiyan lori ayelujara.
Atiku sọ pe oun ko ni sọ awọn mọlẹbi oun di olowo, bi ko ṣe awọn ọrẹ oun bi o ba fi le di aarẹ Naijiria, pẹlu ibeere ti o beere pe ṣe ko tọ ki awọn ọrẹ oun o di olowo ni?
Atiku: Ó dámilójú pé mi ò le fìdírẹmi nínú ètò ìdìbò ààrẹ
Ọbasanjọ yòǹbó Atiku, ó ní kò ní já Nàíjíríà kulẹ̀
Eyi si ti n fa awuyewuye laarin awọn ọmọ orilẹede Naijiria, ti ọpọlọpọ n beere pe awọn wo gan an ni ọrẹ Atiku? Ati pe ọna wo lo fẹ fi sọ wọn di olowo, niwọn igba ti ko ba ti ni ọwọ iwa ibajẹ ninu.
Ọpọlọpọ ọmọ orilẹede Naijria lo si ti n beere wi pe awọn wo ni ọrẹ Atiku? Ati pe ọna wo lo fẹ gba sọ wọn di olowo?
Ọpọ tilẹ n tọka si bo ṣe sọ pe oun yoo sọ ileeṣẹ epo rọbi Naijiria, NNPC, di ti aladani, pe ṣe awọn ọrẹ rẹ l'oun gbero lati ta a fun.
Nibi eto naa ni Atiku ti sọ pe oun yoo sọ ileeṣẹ NNPC di aladani, koda 'bi yoo ba gba ẹmi oun.'
BBC ti bẹ̀rẹ̀ síí kajọ́ de ìdìbò 2019 Nàìjíríà
Ẹwẹ, awọn kan ni igbagbọ pe ọrọ ti Atiku sọ yii fihan pe awọn to jẹ 'ọrẹ' rẹ nikan ni ijọba rẹ yoo gbe, ti yoo si sọ gbogbo ọmọ Naijria to ku di talaka.
Ṣugbọn, bi awọn kan ṣe n bu ẹnu ẹtẹ lu ọrọ ti Atiku sọ, ni awọn kan n sọ pe igbesẹ to tọ ni lati sọ ileeṣẹ NNPC di ti aladani. Awọn to sọ bẹ ẹ woye pe ṣiṣe bẹẹ yoo mu opin de ba 'iwa ibajẹ to wọpọ ninu ajọ naa.'
Adekunle Gold: Ọdún márùn ún ni mo fi mọ Simi ká tó ṣègbéyàwó
Oríṣun àwòrán, @adekunleGOLD
Iyalẹnu lo jẹ fawọn ololufẹ wọn nigba ti wọn fi eto igbeyawo naa ṣe bonkẹlẹ.
Orin ẹ ku oriire ati eyi wuwa lawọn ololufẹ awọn gbajugbaja olorin takasufe Adekunle Gold ati Simi n kọ si orin tuntun ti awọn mejeeji gbe jade lati fi ṣami igbeyawo wọn to waye laipẹ yii.
"Orin ọhun eyi ti wọn pe akọle rẹ ni ""Promise"" ni wọn gbe jade sori ikanni twitter ati youtube eyi ti awọn ololufẹ wọn si ti n kan saara si wọn lorii rẹ."
Àwọn wo ni ọ̀rẹ́ Atiku tó fẹ́  sọ di olówó?
Aláàfin yẹ́ Lizzy Anjọrin sí níbi ayẹyẹ ìwúyè rẹ̀
Òṣìṣẹ́ ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́ gúnle ìyanṣẹ́lódì
Ọpọlọpọ awọn ololufẹ awọn akọrin naa ni wọn n woye nigbati iroyin jade pe igbeyawo wọn yoo waye ṣugbọn iyalẹnu lo jẹ nigba ti wọn fi eto igbeyawo naa ṣe bonkẹlẹ.
Amọṣa ninu iwe kan ti awọn iwe iroyin lorilẹede Naijiria gbe jade pe akọrin 'Orente' naa fi iroyin kan sita pe
'Ṣaaju ni ọdun 2018, mo ke si afẹsọna mi ọdun marun pe ko wa di iyawo mi. Pẹlu pe o mọ gbogbo aiṣedede mi, o jẹ mi ni oo!'
"Adekunle Gold ni  ọdun marun sẹyin ni oun ti mọ Simisọla Bọlatito Ogunlẹyẹ ti ọpọ mọ si ""Simi"""
Oríṣun àwòrán, @adekunleGOLD
Ọdún márùn ún ni mo fi mọ Simi ká tó ṣègbéyàwó
O ni idi ti awọn fi ṣe igbeyawo awọn ni bonkẹlẹ ni wi pe, kii pẹ ti afẹfẹ ilumọọka maa fi n gbe eniyan lọ, nitori naa ni awọn fi fẹ jẹ ki igbeyawo ati igbe aye awọn o wa ni bonkẹlẹ.
Ohun kan to tun da yatọ ninu fọran fidio orin naa ni bi wọn ṣe lo awọn eto ayẹyẹ igbeyawo wọn ninu rẹ.
Bi awọn kan to ti ṣe iyawo tẹlẹ ṣe n pariwo pe orin naa ati ajọṣepọ awọn mejeeji ki wọn to di lọkọlaya mu ori awọn wu, igbeyawo wọn pẹlu ko si ja wọn kulẹ
Ohun ti awọn miiran n sọ ni pe orin yii ni orin igbeyawo ti awọn lọkọlaya to ba fẹ ṣayẹyẹ igbeyawo lọdun 2019 yoo maa lo.
2019 Election: Ṣé Ogboru ni ààrẹ Buhari fẹ́ fa oyè ààrẹ lé lọ́wọ́ ni?
Oríṣun àwòrán, Bashir Ahmad
Ọpọ awuyewuye lawọn eeyan ti nṣe lori aṣiwi ọrọ naa eyi ti aarẹ Buhari ṣe ni ilu Warri
Ṣe lootọ ni aarẹ Buhari fi ojo pe aina nibi ipolongo idibo ẹgbẹ oṣelu APC to waye ni ilu Warri ni ọjọru.
Ohun ti awọn eeyan n pariwo le lori lori ikanni ayelujara gbogbo bayii ni bi aarẹ Buhari ṣe n ṣi ipo pe lasiko to fẹ gbe aṣia ẹgbẹ le oludije fun ipo gomina nipinlẹ Delta, lọwọ.
"Dipo ki aarẹ pe oludije naa ni oludije fun ipo gomina, o ni "" Mo n fa aṣia yii le oludije ipo aarẹ wa lọwọ."""
"Nigba ti ara awọn amugbalẹgbẹ rẹ tun ṣalaye fun pe ipo gomina ni, kaka ki aarẹ tun pe ipo gomina, lo ba tun pe, "" fun oludije ipo sẹnets wa"""
"Amugbalẹgbẹ rẹ tun tun pe fun, nipa siss pe oludije ipo gomina ni, ki aarẹ to wa kuku pe ipo oludije gomina""'"
Amọṣa ileeṣẹ aarẹ tabi ẹgbẹ oṣelu APC ko tii sọ ohunkohun lori ọrọ yii.
Bi awọn ọmọ Naijiria kan ṣe n pariwo pe aṣiwi ko to aṣisọ lọrọ ọhun ati wi pe ko si ẹni ti iru rẹ ko lee ṣe, ni awọn miran n pariwo pe ọjọ ogbo lo n jiṣẹ lara aarẹ ati pe asiko isinmi to.
Itakurọsọ lori iroyin yii n waye lẹyin ọjọ kan ti aworan ibi ti ẹsẹ aarẹ ti tase lori akasọ pepele ti o ti lọ ṣe ipolongo ni  ilu Kogi.
Sarumi Ni obìnrin àkọ́kọ́ tí yóò gbégbá ipò gómìnà l'Ọyọ
Oríṣun àwòrán, Bolasarumialiyu
Oun ni obìnrin àkọ́kọ́ tó ń dupò gómìnà ní ìpínlẹ̀ ọyọ
Ojoojumọ kọ ni a n gbọ pe obinrin n dupo gomina ni ipinlẹ Ọyọ, lati igba ti wọn ti da ipinlẹ naa silẹ ni ọdun 1976.
Arabinrin Omobolanle Sarumi Aliyu ni obinrin akọkọ ti yoo jade lati dije ipo gomina ipinlẹ Ọyọ.
A bii ni ọjọ kejilelogun oṣù kẹta, ọdún 1979, nibi ọdun mẹta lẹyin ti wọn da ipinlẹ naa silẹ. Ọmọ ilẹ Gẹẹsi ni Iya rẹ, baba rẹ Ali Balógun Sarumi si jẹ ọmọ ile Oluyọle.
Oríṣun àwòrán, Bolasarumialiyu/Instagram
Ọmọ bíbí ìlú Ibadan ni
Ilẹ Ibadan lo ti kawe alakọbẹẹrẹ, ati girama , ko to gba Fasiti Anglia Ruskin Cambridge, ilẹ Gẹẹsi lọ fun iwe giga.
O ti fi igba kan jẹ oluranlọwọ pataki fun Minisita olu ilu Naijiria , Oloye Jumoke Akinjide , o si ti bẹrẹ oṣelu lati igba naa pẹlu ẹkọ to kọ lara baba rẹ.
Oríṣun àwòrán, Bolasarumialiyu/Instagram
Ọmọ Ilẹ̀ Gẹ̀ẹ́sì ni Ìyá rẹ̀
Abẹ ẹgbẹ oṣelu Nationla Interst Party (NIP) ni arabinrain naa ti n dije gẹgẹ bi gomina.
O ni afojusun ohun ni lati mu igbe aye irọrun ba awọn eeyan ipinlẹ Ọyọ, ati la ọna to tọ ninu oṣelu lorilẹede Naijiria .
Nigeria 2019 Elections: INEC gbé orúkọ àwọn olùdíje fún ipò ààrẹ àti ilé aṣòfin jáde
Oríṣun àwòrán, INEC Situation room
INEC ti gbe orukọ awọn ti yoo dije ninu ibo gbogbogbo 2019 jade
Ajọ eleto idibo Naijiria (INEC) ti gbé orúkọ awọn oludije to kógojá lati dije ninu idibo gbogbogbo ti ọdun 2019 jade.
Àwọn orukọ to jade naa ni awọn oludije ipo aarẹ ti idibo wọn yoo waye ni ọjọ kẹrindinlogun oṣu keji ati ile igbimọ aṣofin agba oun ile aṣoju-ṣofin ti idibo wọn yoo waye ni ọjọ keji oṣu kẹta.
Orukọ oludije aarẹ mẹtalelaadọrin ni INEC gbe jade pẹlu awọn amugbalẹgbẹ wọn.
Oríṣun àwòrán, INEC
Oríṣun àwòrán, INEC
Oríṣun àwòrán, INEC
Oríṣun àwòrán, INEC
Oríṣun àwòrán, INEC
Oríṣun àwòrán, INEC
Oríṣun àwòrán, INEC
Oríṣun àwòrán, INEC
Oríṣun àwòrán, INEC
Oríṣun àwòrán, INEC
Oríṣun àwòrán, INEC
Oríṣun àwòrán, INEC
Oríṣun àwòrán, INEC
Oríṣun àwòrán, INEC
Oríṣun àwòrán, INEC
Oríṣun àwòrán, INEC
Oríṣun àwòrán, INEC
Oríṣun àwòrán, INEC
Oríṣun àwòrán, INEC
Oríṣun àwòrán, INEC
Oríṣun àwòrán, INEC
Orukọ gbogbo awọn ti yoo dije fun ile igbimọ aṣofin agba wa ati aṣoju-ṣofin wa lori atẹ ayelujara INEC.
Da Rocha: Ìlú Iléṣà ni bàbá miliọníà àkọ́kọ́ ti wá, àmọ́ ó ṣe ẹrú ní Brazil
Oríṣun àwòrán, NigerianMuseum
Ni ọpọ igba, lawọn eeyan maa n ṣe apejuwe eeyan kan to ba ri jajẹ ni awujọ pe ẹni naa lowo bii Da Rocha tabi pe o lowo ju Da Rocha lọ.
Fun ọpọ ọmọ ilẹ Yoruba to wa loke eepẹ loni, eti lasan ni wọn fi n gbọ orukọ Da Rocha, wọn ko mọ iru eeyan to jẹ, ti awọn miran tiẹ ro pe arosọ lasan ni, ati pe Da Rocha kii ṣe ọmọ ilẹ Yoruba rara.
Ṣugbọn akọsilẹ lati loju opo itakun agbaye taa ti ko iroyin yii jọ fi ye wa pe, lootọ ni Da Rocha gbe nilu Eko, o lowo lọwọ pupọ nigba aye rẹ, oun si laa lee pe ni Miliọnia akọkọ nil Yoruba.
A gbọ pe Da Rocha ba owo nile ni, tori pe baba rẹ ni owo lọwọ, amọ ti Candido funra rẹ ṣiṣẹ mo owo to ba nile.
Iroyin fi ye wa pe Da Rocha kọle, o kọ aasẹ silu Eko, to si ṣiṣẹ takuntakun lati ri daju pe ilu Eko ni idagbasoke ati awọn ohun eelo amayedẹrun to yẹ nigba to fi wa loke eepẹ.
N jẹ taa wa ni Miliọnia akọkọ nilẹ Yoruba naa, Da Rocha?
Toyin Atoyebi mechanic: Ẹ wo Toyin, ọmọbinrin ọdún 16 tó ń tún skadà àti gẹnẹrátọ̀ ṣe ní
Sogidi Lake: Kòṣẹja-kòṣèèyàn lá bá nínú adágún odò náà -Ojedele
Cancer: Àṣe ara mi ni iso ti n run gbogbo bí mo ṣe n ṣèrànwọ́ lórí jẹjẹrẹ
Painter: Samuel ni ìdàgbàsókè Nàìjíríà ló jẹ òun lógún!
Candido Da Rocha wa saye, o se aye loore, o fi owo rẹ mọ ẹbi ara, ọrẹ ati awọn ojulumọ, taa si lee pe ni olowo to n fi owo saanu laye igba tiẹ.
Oríṣun àwòrán, Nigeria Museum
O lẹmi iwa ikora ẹni nijanu, to si korira irọ pipa.
Awọn abuda rere Da Rocha lo yẹ ki awa naa fi se awokọse rere, ka si tun jẹ ọmọ ti yoo sọ ọla di pupọ, dipo ka jẹ agboju logun ati akotileta.
Etí òkun: Ọ̀pọ̀ ẹlẹ́ṣin ń pa tó ₦10,000 lójúmọ́
Awọn to n gbe niluu Eko, maa n lọ si eti okun lati gba afẹfẹ to yatọ si ti aarin ilu.
Wọn maa n wọ ọkọ oju omi, gbafẹ, gba bọọlu tabi ṣe ayẹyẹ. Ṣugbọn, awọn to laya le san owo lati gun ẹṣin - pẹlu iranlọwọ awọn ẹlẹṣin to wa leti okun.
Quadri Raji, ẹni ọdun mọkandinlogun n ṣiṣẹ atun foonu ṣe larin ọṣẹ, ṣugbọn o maa n fi ẹṣin siṣẹ leti òkun Atlantic l'opin ọsẹ.
O pa ẹ̀kọ́ rẹ ti nileewe girama nigba ti wọn ge ẹsẹ iya rẹ lẹyin ijamba kan.
Nibayi, oun n tọju ara rẹ, o si ni ireti pe ẹṣin yii yoo pa owo ti yoo to, lati ṣe idanwo aṣejade ileewe girama.
''O wumi lati tẹsiwaju ninu ẹ̀kọ́ mi, àmọ́ bayii iṣẹ kan yii ni mo n ṣe lati pawo wọle.
Leti okun, Quadri maa n pa to ẹgbẹrun mẹwa Naira lójúmọ́.
Ẹṣin rẹ, Jack, maa n jo lasiko awọn ọdun ibilẹ, ṣugbọn Quadri ti n kọ ọ lati ṣiṣẹ leti òkun.
O si maa n ṣe daada.
Tunde Sanni (to wa lapa òsì), jẹ ẹni ọdun mejidinlọgbọn. O si ti n gun ẹṣin leti òkun ju ọdun mẹtala lọ, oun si ni alaga ẹgbẹ awọn to n gun ẹṣin ni eti okun Atican.
Ọdun 2008 ni awọn obi rẹ ku, o si tun n ṣiṣẹ ajorin-mọrin.
Ẹṣin gigun si ti gba ole jija lọwọ mi.
Àpá kan wa niwaju ori Tunde, eyi to waye lasiko to jabọ lori ẹṣin nigba ti ọkọ ayọkẹlẹ kan gba a lasiko to n gun ẹṣin lọdun 2010.
'Stone' jẹ ọkan lara ẹṣin mẹta to ni, Oun naa lo ni 'Prince ati 'Pale.'
Ẹni ọgbọn ọdun ni Lanre, o si ti n ṣiṣẹ ẹṣin gigun leti okun fun ọdun mẹta.
Bakan naa lo maa n ta ewurẹ ati tolotolo ni ọja ẹran ọsin. Opin ọsẹ lo maa n mu ẹṣin rẹ, 'Spaghetti', lọ si eti okun lati pawo si i.
"Mo niyawo ati ọmọ meji ti mo n bọ ọ, nitori naa ni mo ṣe n gba ọna mi i lati pawo wọle.''
Ẹṣin Adebọwale Dada, Jerry, maa n ṣiṣẹ tẹlẹ fun ere sisa. O ra a ni igba ẹgbẹrun ati mẹtalelaadọta Naira, niluu Kano lọdun to kọja.
Iṣẹ kan ti mo n ṣe niyii, mo si niyawo ti mo n tọju. Bakan naa ni mo n fi owo pamọ fun owo ileewe awọn ọmọ mi."""
Bi ẹẹdẹgbẹta Naira si ẹgbẹrun kan Naira ni awọn eniyan maa n san lati gun ẹṣin, awọn ẹlẹṣin a si maa rin pẹlu wọn.
Igba akọkọ niyii ti Favour Eric yoo gun ẹṣin. ''Ẹru ba mi o, ṣugbọn mo gbadun ara mi.''
Awọn ẹlẹṣin yii jẹ diẹ lara awọn ẹgbẹ wọn o n wa awọn ọna ti ko wọpọ lati wa owo, nigba ti iṣẹ oṣu ko si nigboro.
Awọn aworan yii wa lati ọwọ oṣiṣẹ BBC, Grace Ekpu.
Dino Melaye: Ọjọ́ mẹ́rìnlá gbáko ló lò láhàámọ́
Sẹnẹtọ Dino Melaye
Ile ẹjọ giga kan to wa nilu Abuja ti gba oniduro sẹnatọ to n ṣoju ẹkùn Iwọ Oòrun ipinlẹ Kogi, Dino Melaye.
Adajọ Yusuf Halilu gba ẹbẹ agbẹjọro rẹ, Mike Ozekhome, wọle ninu idajọ kan to gbekalẹ lọjọ Ẹti.
Adajọ ni ki wọ̀n gba oniduro Melaye nitori ailera rẹ.
Moses Melaye: Dino Melaye sùn ìta gbangba mọ́jú níléesẹ́ DSS
Amọ ṣa, Adajọ naa ni Melaye gbọdọ mu oniduro mẹta wa sile ẹjọ, ki igbesẹ naa to o le fidimulẹ.
Ọjọ kẹrin, oṣu Kinini ọdun 2018 ni Melaye jọwọ ara rẹ fun awọn agbofinro, lẹyin bi ọsẹ kan ti wọn ti yi ile rẹ, to wa niluu Abuja,po.
Wọn fi ẹsun kan Dino pe, o lọwọ si bi awọ̀n kan ṣe yinbọn mọ ọlọpaa kan lọjọ kọkandinlogun, oṣu Keje ọdun 2018.
Lai Mohammed: Ọwọ́ Atiku kò mọ́ lórí ₦156m owó báńkì PHB tó wọmi
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Atiku Abubakar
Ijọba apapọ Naijiria ti kede pe, ni kete ti oludije ẹgbẹ oṣelu PDP, Atiku Abubakar ba ti irinajo to se lọ si Amerika de, ni yoo wa wi tẹnu rẹ nipa ẹsun ajẹbanu kan ti wọn fi kan.
Minisita fun eto iroyin, Lai Mohammed,  lo fi ọrọ yi sita nigba ti o n ba awọn akọroyin sọrọ nile ijọba labuja.
Mohammed sọ pe ko si anfaani kankan ti irinajo Atiku lọ si Amerika yoo mu ba ilẹ Naijiria.
''Ko yẹ ki a ma ran Atiku leti wi pe, kii ṣe Amerika ni wọn yoo ti dibo fun ati wi pe ti o ba pada de, o ni ẹjọ ti yoo jẹ''
Lai Mohammed ni, awọn ni ẹri tuntun lọwọ nipa owo ti Atiku gba bii owo ajẹbanu, eyi to ṣokunfa bi  ile ifowopamo PHB ṣe wọlẹ
Mọrèmi: Ọọ̀ni ní láìsi Mọrèmi, kò leè sí ilẹ̀ Yorùbá
''Ẹri to wa ni ọwọ wa fi han wi pe, miliọnu mẹ́rìndínlọgọ́jọ naira ni Atiku Abubakar  gba ninu owo yi ''
O tẹsiwaju pe, koda ki Atiku gba iwe igbele Amerika, Green card, iyẹn ko ni ko ma fidi rẹmi ninu idibo to n bọ lọna.
Bi a ko ba gbagbe, ẹgbẹ oṣelu APC ti n ti Atiku lọpọnpọn tẹlẹ, pe ko lọ si Amerika bo ba to bẹẹ.
Oríṣun àwòrán, Bukola Saraki/Twitter
Idi ti wọn fi sọ bẹẹ ni pe, awọn kan ni Atiku lẹjọ lati jẹ ni Amerika ati wi pe, bi o ba fi le lọ si ibẹ, awọn agbofinro yoo mu.
Amọ ni bayi ti Atiku ti lọ si Amerika, iriwisi orisirisi lo ti n tele irinajo rẹ, ti esi Lai Mohammed si jẹ akọkọ ti alaṣẹ kankan labẹ ijọba to wa lode fi sita nipa iṣẹlẹ naa.
Presidential Debate:Atiku yọjú, ó kọ̀ láti kópa
Oríṣun àwòrán, @Atiku
Atiku Abubakar ati Kingsley Moghalu
ìjíròrò laarin awọn oludije ipo Aarẹ orileede Naijiria ti n waye lolu ilu Naijiria Abuja.
Ṣugbọn oludije ẹgbẹ oṣelu PDP Atiku Abubakar kọ lati kopa nibẹ botilẹ jẹ pe o yọju si gbọgan eto naa.
Alaye to ṣe ni wi pe ohun ko le kopa nitori Aarẹ Muhammadu Buhari ko lati  yọju.
O fi ikede idi ti ko fi kopa yi soju opo Twitter rẹ
Atiku ti o kọwọrin pẹlu Aarẹ ile asofin Naijiria Bukola Saraki ṣẹṣẹ dari lati ilẹ Amerika lọjọ abamẹta ni o si sọ wi pe ''Ko tọ ki a ma fa ori lẹyin olori.Ijiroro ta wa ṣe a wa ṣe pẹlu ẹni ti o wa ni ijọba ni''
Atiku wa ta aarẹ Buhari laya lati pade ohun to ba to bẹ fun ijiroro.
Lara awọn to yọju la ti ri Oby Ezekwesili ti ẹgbẹ ACPN,Fela Dutoye ẹgbẹ Alliance for New Nigeria ANN ati Kingsley Moghalu ti ẹgbẹ Young Progressives Party
Oríṣun àwòrán, Durotoye/obyezeks/Moghalu Instagram
Ki wa ni awọn to wa n sọ
Fela Durotoye:
Awọn eeyan ko san owo ori ti Naijiria nitori wi pe wọn ko ri anfaani kankan lati owo ori ti wọn n san.
Ohun ti ijọba wa yoo ṣe ni lati ri wi pe a mu adinku ba iye owo ti a n naa gẹgẹ bi ijọba
Ọkọ akero ni maa ma lọ gẹgẹ bi Aarẹ.Mi o lo ọkọ pupọ.
Kingsley Moghalu:
Ijọba mi yoo mu idagbasoke ba awọn igberiko latara pipese imọ ẹrọ ICT ati ohun amayederun paapa julọ fun awọn ọdọ.
A o ṣe ijọba ajumọṣe laarin ọlọdani ati ijọba.
Awa ko niṣe ijọ́ba
Oby Ezekwesili:Ko ya mi lẹnu wipe Atiku ati Buhari ko yọju.
Wọn fi aiyọju wọn kede pe awọ́n ti dagbere fun awa ra ilu.
Bi wọn ba bikita ara ilu ni,wọn yoo yọju.
Asiko lo de bayi fun awọn ara ilu lati yan ijọba tuntun ni  Naijiria
Igberaga ni o n saaju iparun.
Bi awọn olori to wa ni ijọba ko ti ṣe yọju fi han wi pe wọn ko mu awọn ara ilu nipataki
Asiko to lati gba ominira lọwọ awọn olori ti ko kun oju osuwọn.
2019 Elections: Buhari ní wàhálà ìpolongo ìbò ló ṣèdíwọ́ wíwá síbi ìjíròrò
Oríṣun àwòrán, @MBuhari
Ọpọ lo ti n reti Aarẹ Buhariu nibi ijiroro naa
Ariwisi ọtọọtọ lo ti n tẹle aiyọju Aarẹ Buhari si ibi gbagede ijiroro oludije Aarẹ lọjọ abamẹta.
Bi awọn kan ti ṣe n bẹnu atẹ lu igbesẹ rẹ lati mase yọju sibi ijiroro naa, lawọn miran n sọrọ si Atiku Abubakar, to jẹ oludije ẹgbẹ oṣelu PDP to yọju sibi ijiroro naa sugbọn to kọ lati kopa.
Amọ ṣa, agbẹnusọ fun igbimọ ìpolongo ìdìbò Ààrẹ Buhari, Festus Keyamo, ti mu alaye wa lori idi ti Aarẹ Buhari ko fi yọju.
Ninu atejade kan to fi sita, Keyamo sọ pe wàhálà igbokegbodo ìpolongo ìdìbò ti Aarẹ n se lẹnu ọjọ mẹta yii, lo mu ko ma wa.
Bakannaa lo ni, laipẹ yii ni Aarẹ Buhari ti kopa ninu ipade itagbangba kan pẹlu igbakeji rẹ, Yemi Osinbajo, nibi ti wọn ti yannana ohun ti wọn ti gbe ṣe.
O tẹsiwaju pe, Aarẹ́ Buhari pẹ de lati ibi ifilọlẹ awọn iṣẹ akanṣe ati ipolongo to lọ ṣe nipinlẹ Niger lọjọ abamẹta.
Igbimọ ipolongo naa, ninu atẹjade to fi sita fesi si ọrọ ti oludije ipo Aarẹ ẹgbẹ oṣelu PDP sọ pe, oun ko le jiroro lai si Aarẹ Buhari nibẹ.
Wọn ni igbesẹ Atiku ti ṣe afihan wi pe, ohun ati ẹgbẹ PDP kan fẹ fi idibo ọdun 2019 koju ija si Aarẹ Buhari ni.
''Ti wọn ko ba ti ri Buhari koju ija si ,ọrọ ofifo lo ku ti wọn a ma sọ nibi ipolongo''
Ààrẹ Buhari àti Atiku ní Oludije méjì tí kò kópa nínú ijiroro náà eléyìí tí ọ̀pọ̀lọpọ̀ èèyàn tí n retí wọ́n.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí:
ASUU: Ìpádé míràn pẹ̀lú ìjọba yóò wáyé lọ́jọ́ Ajé
Oríṣun àwòrán, @Official_ASUU
Ẹgbẹ awọn olukọ fasiti ASUU, ati ijọba apapọ yoo tẹsiwaju lọjs aje ninu ijiroro ti wọn n se lati fopin si iyansẹlodi olosu meji tawọn olukọ naa gunle.
Aarẹ apapọ fun ẹgbẹ ASUU, Ọjọgbọn Biọdun Ogunyẹmi lo fidi eyi mulẹ lasiko to n bawọn akọroyin sọrọ nilu Abuja.
Amọ ko sai yan pe ipade naa ko tums si pe opin yoo ba iyansẹlodi awọn olukọ fasiti naa ni kiakia.
Ezekwesili: Àfojúsùn mi ni láti mú ààbò ẹ̀mí ọmọ Nàíjíríà ní ọ̀kúnkúndùn
Ọjọgbọn Ogunyẹmi ni lọwọlọwọ bayii, ko tii si idagbasoke kankan da bi alara nidi idahun ijọba sawọn ibeere ẹgbẹ ASUU, pẹlu afikun pe lọdun to kọja, ijọba jẹjẹ lati gbe owo kalẹ fawọn ileẹkọ fasiti, amọ to kọ lati se bẹẹ, titi ti iyansẹlodi awọn fi bẹrẹ.
Oríṣun àwòrán, @Official_ASUU
Awọn ọmọ ẹgbẹ wa ni awọn ko fẹ ileri ori ahọn lasan mọ, igbesẹ to loorin lawọn n fẹ nidi gbigbe owo kalẹ fawọn ileẹkọ fasiti. Ijọba si gbọdọ fi da awọn ọmọ ẹgbẹ ASUU loju pe, oun ko tii fi ọwọ rọ adehun wọn danu nipa gbigbe ida owo kan silẹ ninu owo ti wọn n beere fun
Ọjọgbọn Ogunyẹmi ni lọna ati dena igbesẹ ki ASUU ati ijọba tun sẹsẹ maa jiroro lori sisan ajẹsilẹ owo ajẹmọnu awọn ọmọ ẹgbẹ naa, igun mejeeji ti fẹnu ọrọ jona pe owo ajẹsilẹ naa yoo wọnu eto isun ọdun 2019.
Dipo Jimoh: Àburo Jimoh Ibrahim ti ní àìbìkítà ẹbí ló pa ìyá òun
Oríṣun àwòrán, @LAG_FireService
Ọjọ buruku, esu gbomimu, tii se ọjọ manigbagbe ni ọjọ Satide, ọjọ Kọkandinlogun osu Kinni ọdun 2019 jẹ, ninu ile gbajugbaja olokooowo kan, Jimoh Ibrahim nigba ti ijamba ina sadede sẹlẹ ninu ile rẹ, to si mu ẹmi iya to bi saye lọ.
Ọmọ iya to doloogbe naa, Dipo Jimoh to si jẹ aburo Jimoh Ibrahim, ti fi atẹjade sita to sọ wi pe kii se ina abẹla lo pa iya oun ni inu ile Jimọh Ibrahim to wa ni adugbo Victoria Garden City, ni Lekki ni ina ọhun ti sẹyọ ni deede aago kan oru alẹ ọjọ Satide.
Jimoh ni aibikita ẹbi lo se okunfa iku to pa iya oun, ati wi pe kii se ina abẹla lo pa iya oun bii iroyin se gbe e jade.
O fikun wi pe lai pẹ ni oun yoo fi lede lẹkun rẹrẹ bi isẹlẹ naa se waye.
Ezekwesili: Àfojúsùn mi ni láti mú ààbò ẹ̀mí ọmọ Nàíjíríà ní ọ̀kúnkúndùn
Iroyin to tẹ wa lọwọ tẹlẹ ni pe iya gbajumọ olokoowo naa, ti orukọ rẹ n jẹ Theresa Jimoh, lo tan abẹla lati fi se adura nitori pe ẹlẹsin ijọ Aguda, Katoliki nii se.
Iroyin naa ni mama Ibrahim Jimoh yii lo sun lọ fọn-fọn lasiko to n gba adura lọwọ, eyi to jo ile ọhun kanlẹ.
Iya agba naa si dagbere faye kawọn osisẹ panapana to de sibi isẹlẹ ọhun lati doola isẹlẹ naa, ti wọn si ti gbe oku rẹ si ile igbokusi.
Nigba to n fidi isẹlẹ naa mulẹ, Ọgbẹni Ahmadu Sakiru, to jẹ osisẹ alarina fun ileesẹ panapana ipinlẹ Eko ni lootọ ni isẹlẹ naa waye, gbogbo aayan awọn lati doola ẹmi mama agba ọhun lo ja si pabo.
''Iná àbẹ́là ló ṣokùnfà bí màmá Jimoh Ibrahim jóná mọ́lé
Tunde Bakare: Ọmọ Nàíjíríà, ẹ gbáradì fún àgbékalẹ̀ Nàíjíríà tuntun
Oríṣun àwòrán, @T_Bakare
Olusọ̀ aguntan agba fun ijọ Latter rain Assembly, Pasitọ Tunde Bakare ti kesi awọn ọmọ Naijiria to fẹ agbekalẹ orilẹede Naijiria tuntun lati darapọ mọoun fun ijagudu fun agbekalẹ orilẹede Naijria tuntun.
Pasitọ Bakare pe ipe yii lasiko to n bawọ̀n ọmọ Naijiria sọrọ lori ipo ti orilẹede yii wa lọwọ-lọwọ bayii, eyi to se lasiko isin ọjọ isinmi ninu ijọ rẹ.
Bakare ni lasiko ipalẹmọ fun eto idibo yii, Buhari ti n salaye ohun to se lati daabo bo Naijiria ati ọna ti wọn fẹ gba gbe Naijiria lọ si ipele to kan, ti Atiku Abubakar naa si ti n bu ẹnu atẹ lu awọn aseyọri yii, to si pinnu lati se atunto ẹka eto isejọba.
Bakare tun wa bu ẹnu atẹ lu irinajo ti oludije fẹgbẹ oselu PDP naa rin lọ silẹ Amẹrika, pẹlu afikun peeyi gan lo jẹ logun.
Nibayi ti Atiku ti de lati Amẹrika, yoo joko bayi lati koju isejọba, ki ni lilọ Amẹrika nii se pẹlu atiku. O fihan pe ko fẹ si iyatọ laarin Atiku ati Buhari nitori awọn mejeeji dijọ n wa ohun ti ko sọ̀nu kiri ni.
'Mi o fẹẹkan ni mo fẹ dupo aarẹ'
Pasitọ agba fun ijọ Latter Rain naa ni laarin awọn ọdọ to fẹ se aarẹ lorilẹede yii, ko si eyi to ni ọgbọn agba to Oby Ezekwesili, tii se oludije ACPN.
"Ọlọpọlọ pipe, to ni ilana isejọba to pegede ati eto Ọlọrun fun Naijiria ni Ezekwesili. Mo kan saara si pe o jade lati du ipo aarẹ, mo si mọ pe pẹlu jijade rẹ ati awọn oluidije yoku to jẹ ọdọ, ko si ẹni ti yoo sọ mọ lẹyin idibo pe, ko si oludije to pegede lasiko ibo naa.
Bakare ni ọrọ oun ko nii se pẹlu atilẹyin fun oludije kankan, amọ ohun ti Naijiria nilo ni ikọ oloselu ti yoo mu atunto ba ilẹ yii, ti ko ni jẹ alajẹbanu, ti yoo sisẹ pẹlu ẹka alasẹ ati asofin lati mu isọkan ba ilẹ yii.
O fikun pe o wa wa lọwọ ileesẹ aarẹ lati sawari awọn ikọ alatunto yii, eyi to pe ni ‘Team Restructuring’.
Oríṣun àwòrán, @T_Bakare
Tunde Bakare tun sọrọ lori eto atrunto il yii ati ileri awn oludije aar kọọkan lati mu Naijiria de ebute ogo.
Ohun to jẹ ki n gba lati dije bii igbakeji fun Buhari tẹlẹ ni eto atunto Naijiria to mu ni ọkunkundun nigba naa, eyi ti ileesẹ aarẹ ni ko se koko mọ̀ bayii."""
O ni idi ti oun fi se agbekalẹ ikọ Save Nigeria Group (SNG) ree, eyi to kun fun awọn ọlọpọlọ pipe awọn ọmọ ilẹ yii.
Bakare tun gbadura pe, ko to di ọjọ Kẹrindinlogun osu Keji ọdun 2019, ki oluwa fi iji lile gba awọn ọta Naijiria kuro, ki omirira lee ba orilẹ́ede yii lọwọ awọn amunilẹru.
Tunde Bakare, ẹni to tun kesi awọn ọmọ ogun orilẹede Naijria lati dẹkun yiyaju sawọn araalu, tun rọ wọn lati maa se isẹ wọn tọwọ tọwọ.
Oríṣun àwòrán, @T_Bakare
A gbọdọ maa se iranti awọn ologun to ti ku soju ogun, ka si mase gbagbe awọn ẹbi wọn.
Iku wọn ko gbọdọ ja sasan nipa sise agbekalẹ isejọba rere eyi ti wọn ku fun.
O ni bi awọn ọmọ ogun Naijiria se n se ojo lo yẹ ka fi bi ara wa leere pe ohun ija taa lo ni agbara ju laarin awn ologun Naijira ati awọn adunkooko mọni.
Nigba to n beere pe iru orilẹede wo lo yẹ ki eeyan fi ẹmi rẹ lelẹ fun, Bakare ni ko sẹni ti yoo fi ẹmi rẹ lelẹ fun orilẹede ti ko lee san owo osu to yẹ fawọn ologun atawọn osisẹ rẹ, tawọn oloselu rẹ si n gba owo gọbọi.
Oríṣun àwòrán, @T_Bakare
O fikun pe, orilẹede ti eto ẹkọ rẹ́ ti dẹnu kọlẹ, ti awọ̀n akẹkọ ati olukọ si joko sile fun ọjọ pipẹ, ko yẹ ni eyi ti eeyan ku fun.
Pasitọ Bakare wa tọka si orilẹ ede ti eeyan lee ku fun bii:
Bakare ni nitori pe orilẹede Naijria ko se ku fun, ni awọn ọmọ Naijiria se setan lati ta kaadi idibo wọn, tori ko si ohun iwuri kankan to lee mu ki wọn fi ẹmi wọn lelẹ fun ilẹ baba wọn.
Ojisẹ Ọlọrun naa wa n rọ awọn ọmọ ilẹ yii pe, ireti si wa fun wa ni orilẹede Naijiria, to si se agbekalẹ iru orilẹede ti Naijiria yoo jẹ lọjọ iwaju bii eyi:
Lẹyin idibo 2019, orilẹede naijiria ni yoo si papa bori lai naani ẹgbẹ oselu to moke tabi fidi rẹmi.
O wa kesi awọn oludije fun ipo aasrẹ lati fọwọ sowọpọ sugba ẹni to ba wọle alti gbe Naijiria goke agba lati se agbekalẹ Naijiria tuntun.
2019 Elections: Ẹ̀mí èèyàn àti ilé ìjọba ń bẹ nínú ewu lásìkò ìbò 2019
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ọrọ lori idibo ọdun 2019
Ijọba ilẹ Amẹrika sọ ẹgbẹ agbsumọmi ISIS ati Boko Haram n gbero lati da idibo gbogbogbo ọdun 2019 ru.
Bakan naa ni ijọba ilẹ Amẹrika kilọ fun awọn ọmọ orilẹede naa to wa ni Naijiria wi pe, oju lalakan fi sọri.
Ijọba Amẹrika fọrọ naa lede loju opo ayelujara rẹ, nibi ti o ti sọ pe ISIS ati Boko haram n gbero lati ṣọṣẹ laarin awọn eeyan ati ile iṣẹ ijọba.
Ezekwesili: Àfojúsùn mi ni láti mú ààbò ẹ̀mí ọmọ Nàíjíríà ní ọ̀kúnkúndùn
Olu ile iṣẹ ilẹ Amẹrika ni Naijiria ni, ko daju boya awọn ẹgbẹ agbesumọmi naa yoo ṣe ikolu si olu ile isẹ Amẹrika, ṣugbọn o ṣe ikilọ fun awọn ọmọ orilẹede naa lati maa kiyesara ni gbogbo igba.
Bakan naa, olu ile iṣẹ Amẹrika rọ awọn ọmọ ilẹ naa lati yago fun ipejọpọ ti ero ba ti pọ, bẹẹ ni ki wọn jinna si ibi ti wọn awọn eeyan ba ti n fi ẹhonu han.
Koda ile iṣẹ naa tun rọ awọn ọmọ Amẹrika lati kiyesara nigba ti wọn ba wa ni ile iwe, ile iwosan, ibudokọ tabi ile ijọsin papa.
Bẹẹ ba gbagbe, idibo aarẹ ati ile aṣofin agba l'Abuja ni yoo kọkọ waye lọjọ Kẹrindinlogun oṣu Keji ọdun 2019, ki idibo gomina to tẹlee lọjọ Keji oṣu Kẹta.
Olusegun Obasanjo: Ìjọba Ààrẹ Buhari kò yàtọ̀ sí ti Abacha
Oríṣun àwòrán, Google
Ní ilé rẹ̀ ní Oke-Mosan, OOPL ,Abeokuta ni ààrẹ tẹ́lẹ̀rí náà ti bá àwọn akọ̀ròyìn sọ̀rọ lọ́jọ́ Àìkú lórí ipò tí Naijiria wà.
Aarẹ tẹlẹri Olusegun Obasanjo, ti rọ osisẹ Ajọ INEC Amina zakari lati kọwe fi ipo rẹ silẹ gẹgẹbi kọmisọnna gbogboogbo fun Ajọ INEC ninu idibo 2019.
Ọbasanjo ni ti ko ba fi ipọ rẹ silẹ, yoo soro lati ri osisẹ ajọ eleto idibo naa gẹgẹbi ẹni to kunjuwọn fun idibo ọdun 2019, ti kii si se wi pe ijọba to wa lode fẹ lo Amina Zakari lati da oju ibo ru lasiko ibo.
O fikun wi pe ti ko ba fipo rẹ silẹ,a jẹ wi pe wọn fẹ lo o lati yii ibo ati lati tẹ ika lọna ẹburu.
Amina Zakari: Ojúṣe mi kìí ṣe láti ka ìbò
Ọpọlọpọ awuyewuye lo wa lori iyansipo Amina Zakari,ẹni ti iroyin sọ wi pe o jẹ ibatan aarẹ Buhari, amọ Zakari sọ wi pe oun ko tan mọ aarẹ Buhari lọna kankan.
Aarẹ tẹlẹri Olusegun Obasanjo, ti fi ijọba Aarẹ Muhammadu Buhari we ti ijọba ologun ti ọgagun Sani Abacha to fi aye ni awọn eniyan nigba aye rẹ.
Ọbasanjo sọ eyi lasiko to n ba awọn akọroyin sọrọ ni ile rẹ to wa ni Abeokuta ni ipinlẹ Ogun.
Oríṣun àwòrán, @dondekojo
Nigba to n fi ijọba Buhari we ti Sani Abacha, Ọbasanjọ ni o yẹ ki awọn ọmọ Naijiria dide lati se ohun ti wọn se lasiko ijọba Abacha, to fi mọ awujọ agbaye pẹlu.
Bakan naa, O ni oun ko ni igbagbọ ninu Ajọ INEC lati se eto idibo ti yoo muna doko ni idibo gbogboogbo ti yoo waye ni 2019.
Obasanjo ni idibo si ipo gomina ni ipinlẹ Osun ko nilo atundi idibo to waye lawọn agbeegbe kan, amọ O ni nitori ijọba to wa lode ni Ajọ INEC fi gbe igbesẹ naa, eyi ti o mu ki APC o wọle sipo gomina ni ipinlẹ naa.
Amọ, o fikun wi pe orẹ oun to sun mọ ọga agba Ajo Inec fi oun lọkan balẹ wi pe ohun gbogbo yoo lo ni iroworose, amo baba obasanjo ni opo oro ko kun agbon ni oro naa ri, ati wi pe ki ajo inec o fi ododo leke ni idibo gbogboogbo naa.
Oríṣun àwòrán, @OOFoundation
Ọbasanjọ fikun pe orilẹede Naijiria nilo olori ti ọpọlọ rẹ ji pepe, ti ilera ara rẹ si dangajia pipọ.
Lagos Fire Service: Ẹ máse tan àbẹ́là lórí ike tàbí pákó
Oríṣun àwòrán, @LAG_FireService
Ọga agba fun ile-isẹ panapana ni ipinlẹ Eko, Rasaki Musibau ti darukọ awọn nkan kekeeke ti a le se, lati dẹkun ijamba ina ninu ile.
Musibau sọ eyi lasiko to n ba BBC Yoruba sọrọ lori awọn nkan to n fa ijamba ina ninu ile.
O sọrọ nipa pipa ina ọba nigba kiigba ti eniyan ba n jade kuro ninu ile, ati rira agolo ilewọ iyẹfun panapana si inu ile (fire extinguisher).
Atiku ní òun kò dènà kí ọ̀dọ́ kankan dupò ààrẹ ní Nàìjíríà
Ọga agba ile isẹ panapana naa wa tọka lẹsẹẹsẹ, awọn ohun to n se okunfa ijamba ina ninu ile ati awọn ọna abayọ si ijamba ina ninu ile naa:
Ọ̀gá àgbà ilé isẹ́ panápaná ní Eko ti pàrọwà sí àwọn ènìyàn láti má se mu sìgá nínú ilé.
Ti ijamba ina ba sẹlẹ, e tete pe ile isẹ panapana lori nọmba wọn: 767 ati 112 ni ipinlẹ Eko.
Ìgbẹ́jọ́ Onnoghen: Ìgbàkejì rèé tí iléẹjọ́ òṣìṣẹ́ yóò dáwọ́ ìgbẹ́jọ́ Onnoghen dúró
Oríṣun àwòrán, @phrekee
Ileẹjọ to n gbọ aawọ laarin awọn osisẹ ati agbanisisẹ nilẹ Naijiria, NIC, tun ti pasẹ lẹẹkan si pe ki igbimọ olugbẹjọ lori aikede dukia ẹni, CCT, dawọ duro na lori igbẹjọ adajọ agba ilẹwa, Walter Onneghen to fẹ gunle.
Onnoghen lo n koju ẹsun onikoko mẹfa to nii se pẹlu ẹsun pe o kuna lati kede awọn dukia rẹ kan eyiti ileẹjọ to n gbọ ẹsun aikede dukia fi kan-an.
Atiku ní òun kò dènà kí ọ̀dọ́ kankan dupò ààrẹ ní Nàìjíríà
Bẹẹ ba gbagbe, ileẹjọ to n gbọ aawọ laarin awọn osisẹ ati agbanisisẹ naa ti kọkọ kede lọjọ kẹẹdogun osu Kinni ọdun 2019 pe igbimọ olugbẹjọ aikede dukia, CCT, dawọ duro naa lori gbigbọ ẹsun naa, ti wọn si sun igbẹjọ ọhun siwaju di ọjọ kejilelogun osu Kinni ọdun 2019 naa.
Bi ileẹjọ awọn osisẹ naa si tun se n bẹrẹ isẹ loni lo tun pasẹ lẹẹkeji pe igbimọ olugbẹjọ  CCT, ko tun gbọdọ joko gbọ ẹjọ naa.
Ọ̀gá Ọlọ́pàá: Àwọn ọ̀gá ọlọ́pàá ìpínlẹ̀ ni yóò máa ṣàkósó FSARS báyìí
Oríṣun àwòrán, @NPF_NIGERIA
Ọga agba ọlọpa tuntun lorilẹede Naijiria, Muhammed Adamu ti kede lọsan ọjọ Aje pe, oun ti se atunto ikọ ọlọpaa to n gbogun ti iwa idigunjale lorilẹede Naijiria.
Adamu, ẹni to kede bẹẹ lasiko ipade r pẹlu awọn Kọmisọna ọlọpaa lawọn ipinlẹ gbogbo nilẹ yii nilu Abuja, tun salaye pe abẹ awọn Kọmisọna ọlọpa lawọn ipinlẹ ni ikọ SARS yoo maa wa bayii.
O fikun pe ikọ SARs to wa labẹ́ ijọba apapọ̀ ni igbakeji ọga agba ọlọpaa ati ẹka to wa fun isẹ iwadi ati ọtẹlẹmuyẹ yoo maa dari.
Atiku ní òun kò dènà kí ọ̀dọ́ kankan dupò ààrẹ ní Nàìjíríà
O fikun pe awọn iwe ilana isọwọsisẹ to de ikọ to n gbogun ti iwa idigunjale naa, ni yoo jade laipẹ.
Adele ọga agba naa wa kede agbekalẹ ikọ oluwadi kan feto idibo, ti yoo wa fun iwadi ati igbẹjọ awọn to ba sẹ si ofin eto idibo.
Lai Muhammed: Alátakò ti sanwó fún Boko Haram láti ṣèkọlù yíká Nàíjíríà
Oríṣun àwòrán, Leadership
Lai Mohammed ti fi ọpọlọpọ ẹsun
Agbẹnusọ fún ìjọba apapọ, Lai Mohammed ti ni ijọba ti ni ẹri to daju pe, awọn kan ninu ẹgbẹ oṣẹlu alatako fẹ lo awọn jaduku fun iwa jagidi-jagan lati doju ibo 2019 bolẹ.
Amọ Lai Muhammed ko darukọ awọn ti wọn fura si pe wọn n gbimọ ọtẹ naa ninu ẹgbẹ alatako, bẹẹ si ni ko fi han boya ijọba ti gbe igbesẹ kankan lati fi panpẹ ofin gbe wọn.
Ni ọjọ Aje nigba ti Mohammed ba awọn akọroyin sọrọ, o ni ẹri fi han wipe, wọn ti sanwo fun ikọ Boko Haram lati ṣe awọn ikọlu kakakiri orilẹede Naijiria.
Atiku ní òun kò dènà kí ọ̀dọ́ kankan dupò ààrẹ ní Nàìjíríà
O ni ọgbọn lati doju ijọba bolẹ ki ijọba fidihẹ le wọle ni.
Yatọ si Boko Haram, Mohammed ni ẹri wa pe, ikọ janduku kan ti orukọ rẹ n jẹ Terwase Akwasa, ti gba owo lati ṣe ikọlu ni awọn ipinlẹ Benue, Nasarawa, ati Taraba.
Bẹẹ lo tun ni wọn fẹ lo awọn janduku lati orilẹede Niger Republic lati ṣe ikọlu si awọn eekan ilu kan.
O wa pari ọrọ rẹ pẹlu ileri wipe, ijọba ko ni jẹ ki awọn ete ati ero buruku ẹgbẹ alatako, to fi ẹsun naa kan ko wa si imuṣẹ.
Melaye: Iléeṣẹ́ ọlọ́pàá tún ka ẹ̀ṣùn mẹ́sàn-án mọ́ Dino lọ́rùn
Bi o tilẹ jẹ pe ileẹjọ giga ilu Abuja ti pasẹ pe ki wọn gba oniduro sẹnatọ to n soju ẹkun idibo iwọ oorun Kogi, Dino Melaye kuro ni ahamọ awọn ọlọpa, sib aasofin agba naa ko lee lọ sile.
Ọjọ Aje ni Melaye pari gbogbo gbedeke ti adajọ so mọ gbigba oniduro rẹ, to si n reti ati lọ sile, amọ ireti naa ja si pabo, pẹlu bawọn ọlọpaa se tun we awọn ẹsun miran kọ lọrun.
Obasanjo: Atiku kìí se Áńgẹ́lì, àmọ́ yóò se dáadáa ní ìlọ́po méjì ju Buhari lọ
Ọrọ Dino Melaye yii, lo tun di egbinrin ọtẹ, ba ti n pakan, ni omiran n ru, pẹlu ẹsun onikoko mẹsan tileesẹ ọlọpa tun to mọ lọrun, ati ẹ́nikan ti wọn pe ni Silas Omenka.
Ninu ẹsun tuntun yii ni wn ti tọkasi pe Melaye tapa si ofin pe kawọn ọlọpa gbee, to si tun fẹsun kan ọga agba ọlọpa tẹlẹ, Ibrahim Idris, pe o n gbero lati gun oun ni abẹrẹ iku, eyi ti wọn lo tapa si ofin ilẹ wa.
Ọjọ Isẹgun si ni ireti wa pe Dino yoo tun pada yọju sile ẹjọ lori awọn ẹsun tuntun yii.
Nigeria Elections 2019: Àwọn àkànlò èdè wo lo fẹ́ mọ ìtumọ̀ wọn lásìkò ìbò?
Kini iyatọ to wa laarin titọpinpin idibo ati onwoye idibo? Atundi idibo ati atundi idibo ti ko ba si ẹni to jawe olubori?
Gẹgẹ bi eto idibo ọdun 2019 ṣe ti n kanlẹkun ni oṣu keji ati ikẹta, oriṣiiriṣii ọrọ bayii ni o maa maa jẹ jade. Eyi ni ilana to rọrun ti yoo jẹ ki o mọ itumọ awọn ọrọ to ta koko
A
Accreditation                                         (Ayẹwo orukọ)                                     :                                     Eyi ni igbese lati se ayẹwo orukọ ki idibo to bẹrẹ.
B
Ballot box                                         (Apoti idibo)                                     :                                     Eyi ni apoti idibo ti wọn ti pa, amọ to ni oju iho kekere ti awọn oludibo le ju ibo wọn si, ki wọn to maa kaa.
Ballot paper                                         (Iwe idibo)                                     :                                     Iwe idibo ni iwe ti orukọ awọn ti o n dije ni ẹkun kọọkan wa.
Bye-election                                         (Idibo si ipo asofin)                                     :                                     Eyi ni eto idibo to waye lati yan asofin miran sipo, lẹyin iku ẹni to wa nibẹ tẹlẹ. Eyi tun le waye lẹyin ti awọn oludibo ba yọ ẹni to wa nipo kuro nitori magomago tabi aṣemaṣe.
C
CVR                 :
Card reader                                         (Kaadi itẹka)                                     :                                     Kaadi itẹka ni ohun elo ti wọn maa n lo lati fi se ayẹwo ika ti oludibo fẹ lo, boya tirẹ ni tabi tirẹ kọ.
Claim                 :                                     Eyi ni igbese ti awọn eniyan maa n gbe lẹyin ti wọn ba ri abawọn tabi aisedede ninu iforukọsilẹ ti wọn se.
D
Display                 :                                     Eyi ni sise afihan orukọ awọn to fi orukọ silẹ lati le dibo, ki awọn eniyan ti ko ba tẹ lọrun le pe akiyesi Ajọ INEC si.
E
EMB                 :                                     Ajọ to n ṣakoso eto idibo.(ẹka mẹtadinlogoji lo wa ni Naijiria. i.e Ajọ INEC ati Ajọ SIEC ni ipinlẹ kọọkan (36).
Election Monitors                                         (Olutọpinpin idibo)                                     :                                     Awọn wọn yii jẹ osisẹ Ajọ INEC ti wọn n ṣabẹwo si awọn agbegbe idibo lati mọ bo se n lọ.
Election Observers                                         (Onwoye lasiko idibo)                                     :                                     Awọn wọn yii ni ajọ tabi ẹgbẹ to n se onwoye lasiko idibo, wọn maa n lọ si agbegbe ti idibo ti n waye lati bojuto eto idibo lati ibẹrẹ titi de opin. Awọn onwoye idibo meji lo wa. i.e. Onwoye idibo abẹlẹ ati onwoye lati ilẹ okeere.
Eto idibo ni gbangba                 :                                     Eyi ni ọna ti awọn awọn oludibo n gba dibo ni kọrọ, sugbọn ti wọn yoo wa fi iwe idibo wọn sinu apo idibo ni gbangba.
G
General Elections                                         (Idibo gbogboogbo)                                     :                                     Idibo gbogboogbo jẹ eto idibo to ma n waye kaakiri awọn ipinlẹ to wa lorilẹ-ede lati yan awọn oludibo si ipo,  lẹyin ti awọn to wa nibẹ tẹlẹ ba ti pari saa wọn.
I
INEC                 :                                     Ajọ eleto idibo lorilẹ-ede Naijria
Inconclusive election                                         (Eto idibo ti ko ni ẹni to jawe olubori)                                     :                                     Eyi ni eto idibo ti o sẹle leyin ti iye awọn to se iforukọsilẹ lasiko idibo to iye eniyan ti o le sọ bi esi idibo yoo se ri.
M
Manifesto                                         (Iwe ipolongo)                                     :                                     Eyi ni iwe to kun fun awọn ohun ti ẹgbẹ oselu kan nireti lati se ti wọn ba jawe olubori lasiko idibo. Iwe yii ma n se afihan ohun ti ẹgbẹ duro fun ati ọna ti wọn fẹ gba lati mu aye dẹrun fun awọn eniyan.
N
Nomination                                         (Yiyan oludije)                                     :                                     Yiyan oludije sipo jẹ ọkan lara awọn eto ti awọn ẹgbẹ oselu fi n se eto lati gbe oludije jade lẹgbẹ oselu wọn.
O
Objection                 :                                     Eyi ni igbese kotẹmilorun ti awọn eniyan maa n gbe ti wọn ko ba faramọ atẹjade ti Ajọ INEC fi sita lasiko ti wọn n le orukọ awọn to forukọsilẹ fun eto idibo.
Opposition                                         (egbe alatako)                                     :                                     Ẹgbẹ alatako ni ẹgbẹ ti ko si ni ijọba, amọ to jẹ awọn lo poju lẹyin ẹgbẹ to wa ni ijọba.
P
PRV                 :                                     Eyi ni iwe ti orukọ awọn ti o ti se iforukọsilẹ wa. Ajọ INEC ma n le iwe yii ki awọn eniyan le lọ yẹ orukọ wọn wo bọya orukọ wọn wa ni pese, ati bi o ti yẹ.
PVC                 :
Party Agent                                         (Asoju ẹgbẹ oselu)                                     :                                     Eyi ni ẹni ti o n soju ẹgbẹ oselu tabi oludije ni ibi ti wọn ti n ka ibo ni ọjọ idibo.
Party primary                                         (Idibo abẹle)                                     :                                     idibo yii ma n waye ninu ẹgbẹ oselu kọọkan lati yan ẹni ti yoo gbe asia ẹgbẹ lati dije dupo ni ọjọ idibo.
Polling Unit                                         (Agọ idibo)                                     :                                     Agọ idibo ni agbegbe to wa ni itagbangba nibi ti Ajọ INEC fi ọwọ si wi pe idibo yoo ti waye.
R
Re-run election                                         (Atundi idibo)                                     :                                     Idibo yi ma n waye ti idibo alakọkọ ba ni magomago ninu, tabi ti awọn eleto idibo ko ba tẹlẹ alakalẹ eto idibo.
Recall                                         (Yiyọ oloselu)                                     :                                     Yiyọ oloselu jẹ eto ti awọn oludibo le gbe lati yọ asoju ni Ile Igbimo Asofin Ipinlẹ ati ti ijọba apapọ kuro ni ipo.
Rejected ballot                                         (Awọn ibo ti wọn kọ)                                     :                                     Awọn ibo ti wọn kọ ni awọn ibo ti ko ṣafhan eni ti oludibo naa dibo fun daadaa, nitori wọn ko tẹ ika si iwaju ẹni ti wọn fẹ dibo fun bi o ti yẹ, nitori naa, awọn eleto idibo a da ibo naa nu nitori itẹka naa ko si loju ibi to yẹ ko wa.
Return                                         (Dida oludije pada)                                     :                                     Eyi ma n waye ti oludije to ti wa ni ipo tẹlẹ ba jawe olubori, ti Ajọ INEC wa fun ni iwe lati da a pada si ipo.
Returning Officer (RO)                                         (Oṣiṣẹ Ajo INEC)                                     :                                     Eyi ni osisẹ Ajo INEC ti yoo sọ esi idibo lẹyin ti wọn ba ti ka a.
Run-off election                                         (Atundi idibo)                                     :                                     Idibo eyi maa n waye ti ko ba si ẹni to jawe olubori lọna to lamilaaka si ipo gomina tabi aarẹ orilẹ-ede. Eyi le waye ti ẹni to ba jawe olubori ko ba bori lawọn agbegbe to se pataki lati jawe olubori.
S
SIEC                                         (Ajọ eleto idibo ni ipinlẹ.)                                     :                                     Ajọ eleto idibo ni ipinlẹ ni o wa ni isakoso idibo ni awọn ijọba ibilẹ. Ipinlẹ kọọkan lo ni ajọ yii lati le sakoso eto ibo.
T
Tactile Ballot Paper                                         (Iwe idibo awọn akanda ẹda)                                     :                                     Iwe idibo yii wa fun awọn ti o ni aisan oju ti ko si le riran daradara, ki wọn baa le dibo wọn ni ikọkọ lai si iranwọ ẹnikẹni (i.e ni idakọnkọ ati lai si iranwọ ẹnikẹni)
Tendered ballot paper                                         (Idibo to ni bosejẹ)                                     :                                     Eyi ni iwe idibo fun oludibo, lẹyin ti ẹlomiran ti lo orukọ rẹ lati fi dibo. Nitori naa ni wọn yoo se fun un ni iwe idibo miran, amo ti o ba ti dibo tan, asoju Ajọ INEC to wa nibẹ ko ni fi sinu apoti idibo, yoo fi si ibomiran.
Turnout                 :                                     Eyi ni lati se akawe oye awọn eniyan to jade lati wa dibo lasiko eto idibo ni agbeegbe ti wọn ti n dibo.
Àtúntò FSARS: Àwọn ọmọ Nàìjíríà bẹ̀nu ẹ̀tẹ́ lu àtúntò FSARS
Oríṣun àwòrán, @OfficialSARS
Àwọn aláṣẹ Iléeṣẹ́ ọlọ́pàá ní ìlànà iṣẹ́ ikọ̀ ọlọ́pàá kògbérégbè FSARS kò fi ààyè ìrégbè sílẹ̀ fún wọn
Eero awọn ọmọ orilẹede Naijiria ṣọtọọtọ si bi ọga ileeṣẹ ọlọpaa Naijiria, Mohammed Adamu ṣe da awọn ọlọpaa FSARS pada, ti ọpọlọpọ si n fapa janu lori ẹrọ ayelujara.
Bi awọn kan ṣe n gboriyin fun igbesẹ yii ni awọn kan gbagbọ pe yoo da iwa ifiyajẹni ati inilara to googo laarin awọn oṣiṣẹ SARS pada saarin ilu.
Tẹlẹ ni Ọga ọlọpaa ana, Ibrahim Idris gbe ẹka ileeṣẹ ọlọaa SARS sabẹ igbakeji Ọga Agba Ọlọpaa. Ṣugbọn ni bayii, awọn kọmisana ọlọpaa l'awọn ipinlẹ to wa lorilẹede yii ni yoo maa mojuto awọn ọlọpaa SARS.
Ǹjẹ́ o rí ọlọ́pàá SARS tó ń hùwà àìtọ́ láwùjọ?
AAUA; Ọ̀pọ̀ ìgbà ni SARS ma ń lu àwọn akẹ́kọ̀ọ́ fásitì wa
Ṣaaju asiko yii ni awọn ọmọ orilẹede Naijiria ti n pe fun opin si iṣẹ awọn ọlọpaa SARS pẹlu ami ipolongo #EndSARS nitori awọn ẹsun ifiyajẹni ati titẹ ẹtọ ọmọniyan mọlẹ ti wọn fi n kan wọn.
Lara awọn to ti bu ẹnu ẹtẹ lu igbesẹ ọga ọlọpaa ni ajọ ajafẹtọ ọmọniyan lagbaye, Amnesty International, ẹka ti Naijiria.
Ajọ naa loju opo Twitter rẹ sọ pe atunto ti ọga ọlọpaa kede gbọdọ tumọ si fifi opin si ifiyajẹni, fifini si ihamọ lọna aitọ, iwa ilọnilọwọgba, ati iṣekupani 'ti awọn oṣiṣẹ SARS ti hu jakejado orilẹede Naijiria fun ọpọlọpọ ọdun.
Bakan naa ni awọn kan ni asiko tun ti to lati ji ipolongo #EndSARS dide pada nitori igbesẹ ti ọga ọlọpaa gbe yii, nitori pe fifi opin si SARS patapata ni awọn ọmọ Naijiria n fẹ.
Lọjọ Aje ni ọga agba ọlọpaa kede pe igbesẹ atunto ti oun kede rẹ jẹ ọna lati mu atunṣe ba ajọ SARS.
Àfojúsùn àtúntò FSARS ni láti mú àgbéga bá iṣẹ́ ọlọ́pàá- IG
SARS: Awọn ará ìlú fi ẹ̀rí síta nípa ìrírí wọn
Fayemi: Ẹ̀sùn àjẹbánu àti lílo owó básubàsu la fi kàn wọn
Oríṣun àwòrán, Twitter
Awọn tí ìfipòsílẹ̀ náà kàn ni adarí ilé ẹ̀kọ́ fásitì EKSU, adarí ilé ìwòsàn tó wà ní ìpínlẹ̀ Ekiti, EKSUTH.
Gomina ipinlẹ Ekiti, Ọmọwe Kayode Fayemi ti fasẹ si pe ki adari fasiti ipinlẹ Ekiti, EKSU, Ọjọgbọn Samuel Oye Bandele.
Awọn miran ti wọn tun jawe lọ gbe ile rẹ fun ni, Adari ile iwosan ẹkọsẹ isegun fasiti naa, KSUTH, Kolawole Ogundipe ati adari ile ẹkọ giga to wa ni Ikẹrẹ-Ekiti, Ọjọgbọn Mojisola Oyaraqua.
Igbimọ majẹ ko bajẹ ni ipinlẹ naa, lasiko ipade wọn ni awọn rọ gomina lati gbe igbese iyọni nipo naa, lẹyin ti wọn se abẹwo si awọn ọgba ile-ẹko giga ọhun ati si awọn ile-isẹ ti ọrọ naa kan.
Murphy Elégungun Rọba: Mo fẹ́ di ẹnití egungun rẹ rọ jùlọ ní àgbáyé
Ẹsun ajẹbanu ati lilo owo ile iwe basubasu, ni wọn fi kan awọn adari ile iwe giga.
NLC: Àwọn òsìsẹ́ Naijiria ló ń gba owó osù tó kéré jù!
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ẹgbẹ́ òsìsẹ́ NLC ti ní N33,000 ni gbèdéke owó osù òsìsẹ́, lẹ́yìn tí ìgbìmọ̀ májẹ̀kóbàjẹ́ fi ọwọ́ sí N27,000.
Ẹgbẹ osisẹ lorilẹede Naijiria,NLC ti ni idi ti awọn fi kọ ẹgbẹrun lọna mẹtadinlọgbọn(27,000) Naira ti ijọba fi ọwọ si gẹgẹ bi gbendeke owo osu awọn osisẹ lorilẹede Naijiria ni wi pe ijọba ko mu adehun wọn sẹ.
Alaga ẹgbẹ osisẹ ni ipinlẹ Osun, Komreedi Babatunde Adekomi to sọ eyi lasiko to n ba BBC Yoruba sọrọ lori idi ti wọn fi kọ gbedeke owo osu osisẹ, ni awọn osisẹ Naijiria lo n gba owo osu to kere ju lọ ni Afirika.
Adekomi ni ẹgbẹrun lọna mẹtalelọgbọn (33,000) Naira ni igbimọ ti ijọba gbe kalẹ bu ọwọ lu lasiko ipade wọn , ki wọn to lo o gbe e fun ijọba apapọ lati fi ontẹ lu u.
Murphy Elégungun Rọba: Mo fẹ́ di ẹnití egungun rẹ rọ jùlọ ní àgbáyé
O ni gbogbo nkan ni awọn gbeyẹwo ko to di wi pe awọn fẹnuko lori gbedeke owo osu ti awọn fẹ ma a gba.
Alaga ẹgbẹ osisẹ naa ni awọn gbe ọrọ aje Naijiria wo, owo ti awọn eniyan fi n wọ ọkọ, ile ti awọn eniyan n gbe, ati ọpọlọpọ nkan miran ni awọn gbe yẹwo.
Komreedi Babatunde Adekomi fikun wi pe awọn osisẹ lorilẹede Naijiria lo gba owo osu to kerejulọ lagbaye, ti iya ati isẹ si n koju awọn eniyan.
Obasanjo: Atiku kìí se Áńgẹ́lì, àmọ́ yóò se dáadáa ní ìlọ́po méjì ju Buhari lọ
O wa fikun wi pe ijọba o sọ idi ti wọn fi din owo naa ku, ati wi pe ẹgbẹ osisẹ yoo ma se ipade ni Ọjọ Ẹti, ọsẹ yii ni ilu Abuja lati mọ igbesẹ to ku ti wọn yoo gbe.
Danjuma: Ète ń lọ láti dá wàhálà sílẹ̀ láwọn ìpínlẹ̀ kan torí mọ̀kàrúrù ìbò
Oríṣun àwòrán, @tarabavoices
Minisita tẹlẹ feto aabo, Ajagunfẹyinti Theophilus Danjuma, ti ke gbajare lori ete awọn eeyan kan lati se mọkaruru ibo gbogbo gboo to n bọ.
Danjuma, ẹni to ke gbajare yii lasiko to sefilọlẹ ibudo kan nipinlẹ Taraba, tun fi kun pe, eto iselu taa n se ni Naijiria luko pupọ, ti ko si laju rara.
Bakan naa lo sisọ loju rẹ pe, ete kan tun ti n lọ lati da wahala silẹ lawọn ipinlẹ kan lorilẹede yii, afojusun igbesẹ yii si ni lati dabaru esi ibo ti yoo wa lawọn ipinlẹ ọhun.
Murphy Elégungun Rọba: Mo fẹ́ di ẹnití egungun rẹ rọ jùlọ ní àgbáyé
Danjuma wa fi ewe ọmọ mọ awọn eeyan ipinlẹ Taraba leti pe, ki wọn raga bo ibo ti wọn ba di, ki awọn alaparutu ma baa ri ji.
"A gbọdọ sisẹ kara ki alaafia lee jọba, yatọ si pe a fi orukọ silẹ, taa si tun gba kaadi idibo alalopẹ wa.
Ko si idi fun wa lati maa doju ija kọ ara wa nitori wọn yoo lo awọn ọlọpaa ati sọja lati da wa riboribo, ti wọn yoo si raye ji ibo wa."
Oríṣun àwòrán, @tarabavoices
Minisita tẹlẹ naa tun fikun pe, awọn ti wọn n pete idaluru yii mọ pe awọn ko lee bori ibo ti alaafia ba n jọba.
O si rọ awọn eeyan rẹ lati mase ta ibo wọn, tori yoo da bii igba ti wọn n ta ogun ibi wọn ni, ti wọn ba se bẹẹ.
Fake News: BBC kọ́ lọ́ ṣe ètò ìrànwọ́ ìwé kíkà
Oríṣun àwòrán, Facebook
Àwọn èèyàn ti ń fi àlàyé arawọn sílẹ̀ lórí òpó náà, ṣùgbọ́n BBC kò mọ̀ nípa ètò ìrànwọ́ ìkàwé kankan tó jọ mọ́ bẹ́ẹ̀
Ìròyìn òfegè ni ìròyìn tó ń lọ pé iléeṣẹ́ BBC ń ṣe ètò ìrànwọ́ ìwé kíkà lóríi www.giveaway-bbc.com.
Àwọn èèyàn ti ń lọ sí orí òpó ayélujára ọ̀hún àti òpó Facebook rẹ̀, https://www.facebook.com/GiveawayBBC/ tipẹ́.
Ṣùgbọ́n ilé iṣẹ́ BBC kò ní nǹkankan ṣe pẹ̀lú òpó náà.
ìpàdé ìtagbangba ìfọ̀rọ̀wánilẹ́nuwò pẹ̀lú àwọn olùdíje sípò gomina ní ìpínlẹ̀ Eko.
Eléyìí jẹ́ ọ̀kan lára àwọn ìròyìn òfegè tí àwọn èèyàn ń gbé ka lóde òní.
A rọ àwọn èèyàn kí wọ́n mọ̀ dájú pe ilé iṣẹ́ BBC kò ní nǹkankan ṣe pẹ̀lú òpó náà.
Nigba kigba ti BBC ba fẹ ṣe eto ni a maa n gbee soju opo wa ni bbcnewsyoruba lori facebook ati instagram pelu lori www.bbc.com/yoruba lori ikanni website wa.
Murphy Elégungun Rọba: Mo fẹ́ di ẹnití egungun rẹ rọ jùlọ ní àgbáyé
'Obìnrin ló ni ilé àti àdúgbò fún ìdí èyí wọ́n lè ṣe ìlú dáadáa'
Obasanjo: Atiku kìí se Áńgẹ́lì, àmọ́ yóò se dáadáa ní ìlọ́po méjì ju Buhari lọ
Ò ti pẹ́ jù fún Ezekwesili láti yọwọ́, orúkọ ẹgbẹ́ rẹ̀ ACPN yóo hàn lórí ìwé ìdìbò #BBCNigeria2019
Oríṣun àwòrán, @Oby
O ti to oṣu mẹta ti a ti n sọrọ pọ lori igbesẹ mi yii
Lẹ́yin wakati melòó kan ti oludije fun ipo aarẹ labẹ ẹgbẹ́ oṣelu ACPN fi han pe oun ti jawọ ninu idije naa, ajọ  eleto Idibo (INEC) ni o ti pẹ́ ju lati gbe igbesẹ naa.
Agbẹnusọ ajọ naa kan Oluwole Osaze-Uzzi ni INEC ko tun le pa orukọ ẹgbẹ oṣelu rẹ̀ ACPN to ti wa lori iwe idibo mọ
Oby ṣe ikede lori ikanni twitter rẹ pé oun yọwọ ki oun lè pa ọkan pọ láti fopin si ijẹgaba ẹgbẹ APC ati PDP ninu iṣelu Naijiria.
Ezekwesili: Mo fẹ́ sọ Nàíjíríà di ilẹ̀ tí àǹfàní ọgbọọgba wà
Oby Ezekwesili ni oun gbé igbesẹ yii ki oun le fi ọgbọn kun ọgbọn fun awọn oludije to ku lati jọ di òṣùṣu ọwọ̀ to máa ra iṣejọba Tiwa-n-Tiwa padà ni Naijiria ni.
O ni oun yoo maa figba gbogbo fọn rere rẹ pé ijọba Naijiria yẹ ko dara ju gbogbo eyi ti ẹgbẹ PDP ati APC n ṣe yii.
Fẹla Durotoye ọkan lára awọn oludije fún ipo aarẹ lẹgbẹ oṣelu ANN naa sọrọ lori ifọwọsowọpọ ti àwọn ẹgbẹ oṣelu keekeeke n gbiyanju lati ṣe ki wọn fi le bori ninu idibo 2019.
Oby Ezekwesili ni nitootọ ni igbesẹ oun yii ko tẹ gbogbo ọmọ ẹgbẹ Allied Congress Party of Nigeria (ACPN) lọrun, ṣugbọn oun ti ṣetan lati fipinnu ijọba rere ni Naijiria hàn dipo erongba ọkan oun gẹgẹ bii oludije
Ezekwesili: Àfojúsùn mi ni láti mú ààbò ẹ̀mí ọmọ Nàíjíríà ní ọ̀kúnkúndùn
Oby gba awọn eniyan niyanju lati ma ro idagbasoke Naijiria pin nitori pe ohun ti a ba jọ ja fun lo n mu itẹsiwaju wa.
2019 Elections: Èrò àwọn ọmọ Nàíjíríà se ọ̀tọ̀ọ̀tọ̀ lóri ètó àlùfáà tàbí ìmámù lásìkò ìbò
ìpàdé ìtagbangba ìfọ̀rọ̀wánilẹ́nuwò pẹ̀lú àwọn olùdíje sípò gomina ní ìpínlẹ̀ Eko.
Osinbajo: Ikẹnnẹ yẹ kó jẹ́ Mẹ́kà òṣèlú ni
Miliọnu kan naira nileeṣẹ to ba fiya jẹ àkàndá ẹ̀dá a san lówó ìtanràn
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ẹnikẹni ko gbọdọ dẹyẹ si akanda ẹda ni ibudo idikọ, ati wi pe awọn to ni ileeṣẹ irinna gbọdọ ṣeto to yẹ fun awọn ti ko le rin
Aarẹ Muhammadu Buhari ti buwọlu ofin ti yoo maa sọ didẹyẹsi awọn akanda ẹda di iwa ọdaran ni Naijiria.
Ìyá àkàndá ẹ̀dá: Àwọn ẹbí mi fẹ́ kí n pa ọmọ mi torí ó jẹ́ àkàndá ẹ̀dá
Aṣoju aarẹ nile aṣofin, Ita Enang to fi ikede naa sita ṣalaye fun awọn akọroyin lalẹ Ọjọru pe ofin tuntun ọhun, ni yoo ma rii daju pe awọn ileeṣẹ tabi ẹnikọọkan to ba hu iwa ti ko tọ si akanda ẹda jẹ iya to tọ labẹ ofin.
Labẹ ofin tuntun naa, ileeṣẹ to ba jẹbi ẹsun fifi iya jẹ akanda ẹda kankan yoo san miliọnu kan Naira gẹgẹ bi owo itanran, ti ẹnikan yoo si san ọgọrun un ẹgbẹrun Naira tabi lọ si ẹwọn oṣu mẹfa pẹlu rẹ.
Ogundiya: Àṣìṣe Dókítà ló sọ mi di aláàbọ̀ ara lórí kẹ̀kẹ́
Bakan naa ni ofin naa yoo fi aaye ọdun marun un silẹ fun awọn ile to wa fun lilo araalu lati ṣe atunṣe ti yoo mu ki awọn akanda ẹda, to fi mọ awọn to n lo kẹẹkẹ lara wọn lati le wọ awọn ile bẹ pẹlu irọrun.
Yorùbá gbà pé òrìṣà bí ìyá kò sí!
Ẹnikẹni to ba fẹ kọ ile ti araalu yoo maa lo(ile ounjẹ, ileewosan, ile itaja ati bẹẹbẹ lọ), awọn ajọ to wa fun ile kikọ gbọdọ ṣayẹwo ilana ti wsn la kalẹ fun kikọ ile naa lati ri daju pe o pa ofin ọhun mọ.
2016 ni Angel kọ́kọ́ gbé àwo orin rẹ̀ síta láti fi bèrè ìdí tí òun fi yàtọ̀
Ati wi pe oṣiṣẹ tabi ileeṣẹ ijọba to ba buwọlu kikọ ile ti ko pa ofin naa mọ yoo san miliọnu kan Naira owo itanran, fi ẹwọn ọdun meji jura tabi mejeeji.
Murphy Elégungun Rọba: Mo fẹ́ di ẹnití egungun rẹ rọ jùlọ ní àgbáyé
"Ẹnikẹni ko gbọdọ dẹyẹ si akanda ẹda ni ibudo idikọ, awọn to ni ileeṣẹ irinna gbọdọ ṣeto to yẹ fun awọn ti ko le rin, rina tabi gbọrọ, ati awọn akanda to ku. Eyi wa fun awọn to n ṣeto irinna loju omi, ofurufu ati oju'rin.
Ipenija ojú kò di Ademola lọ́wọ́ láti kẹkọọ gboye
Ẹwẹ, ofin naa fi mulẹ pe gbogbo ileeṣẹ ijọba gbọdọ fi aaye ida maarun silẹ fun awọn akanda ẹda ninu eto igbanisiṣẹ wọn."
Ọmọ̀bìnrin tí wọ̀n bí láì ní ẹsẹ̀: Ati kekere ni ìyá mí ti kọ̀mí sílẹ̀
Àwọn nkan márùn ún tó gbajúmọ̀ nípa ìlú abínibí Buhari #BBCNigeria2019
Kẹtẹkẹtẹ jẹ ọkan lara àwọn nkan irinna to wọpọ ni Daura
Ipinlẹ Katsina, ni ẹkùn Iwọ oorun Ariwa Naijiria ni ilu Daura wa. O si pa aala pẹlu orilẹ-ede Niger lati Damagaram.
Bakan naa lo pa ààlà pẹlu ipinlẹ Jigawa ni ilu Kazaure.
Daura ni ilu to ti pẹ ju ninu itan ẹya Hausa, koda, awọn oluwadii kan tilẹ gbagbọ pe Daura ni orisun ede Hausa.
Daura jẹ ilu abinibi Aarẹ Muhammadu Buhari, ibẹ lo si ti lo eyi to pọju ninu ọjọ aye rẹ.
BBC ṣe akọsilẹ awọn nkan marun un to ṣe koko, to si sọ ilu Daura di gbaju-gbaja kaakiri agbaye.
Oríṣun àwòrán, @DAURA
Ibrahim Issa to n figbadun ṣayọ
1.  Ìtàn ilu naa
Nkan akọkọ ti Daura gbajumọ fun ni ìtàn iṣẹdalẹ ilu naa.
Akọsilẹ ìtan tilẹ sọ pe Daura ni orisun ede Hausa ati awọn ẹya Hausa. Botilẹ jẹ wi pe awọn onimọ kan ko faramọ eyi.
Ṣugbọn ohun to daju ni pe, Daura jẹ ọkan lara awọn ilu meje to jẹ orisun ẹya Hausa.
Oriṣiriṣi ọba ati iṣakoso to ti ara Ayaba Daurama jade lo ti jẹ ni Daura titi di oni. Bakan naa ni ilu naa ni awọn ilẹkun abalaye ati ilu olodi, to wọpọ ni ọpọlọpọ ilu to wa ni ilẹ Hausa.
'A máa ń bẹ́ orí ẹni tó bá gbé imọlẹ̀ ọdún ìjẹṣu tó bá ṣubú ni'
2.  Daurama
A ko le sọrọ nipa ilu Daura, lai mẹnuba Ayaba Daurama - oun ni Ọbabinrin to jẹ kẹyin ni Daura.
Ìtan fihan pe Daurama ni Ọbabinrin to wa lori itẹ lasiko ti akọni igbanni, Bayajidda lọ si Daura, to si pa ejo nla to n ba awọn araalu l'ẹru. Daurama fẹ ẹ fun iwa akikanju rẹ.
Daurama lo bi awọn ọmọkunrin meje to pilẹ awọn ipinlẹ ẹya Hausa mejeeje - Bawo, Biram, Kano, Katsina, Zazzau, Gobir and Rano.
Ìtan ẹya Hausa kò pe, lai si ọrọ Ọbabinrin Daurama ninu rẹ.
3.  Bayajidda
Ọpọlọpọ eniyan gbagbọ pe orilẹ-ede Baghdad ni orisun Bayajidda, ko to o di pe o wa si Borno nibi to gbe fun igba diẹ. Lẹyin naa lo lọ si Daura.
Asiko naa lo ṣawari ìdà to fi pa ejo nla ti ko jẹ ki awọn araalu Daura o raaye pọn omi ninu kanga Kusugu.
"Lẹyin naa, Ọbabinrin Daurama fẹ Bayajidda l'ọkọ. ""Daurama si di iya nla ẹya Hausa ati awọn eniyan rẹ."""
Ṣugbọn, awọn onimọ kan bi i Muhammad Tahar Adama (Baba Impossible) ati Ọjọgbọn Uba Adamu sọ pe ìtàn naa kii ṣe otitọ.
Obasanjo: Atiku kìí se Áńgẹ́lì, àmọ́ yóò se dáadáa ní ìlọ́po méjì ju Buhari lọ
4.  Kusugu
Nigba ti Bayajidda de si ilu Daura, o de si ile obirin arugbo kan, Ayyana. O si beere fun omi, ṣugbọn o sọ fun un pe oun ko ni, nitori pe ejo kan fi inu kanga ti awọn n pọn ṣe ibugbe.
Ọjọ Ẹti nikan ni ejo naa maa n fi aaye gba omi pipọn.
Ni Bayajidda ba gba gooro ipọnmi kan lọwọ rẹ, o si lọ si ibi ti kanga naa wa. O pa ejo yii, o bẹ ẹ lori, o si pọn omi jade ninu kanga.
'Ó ṣojú mi kòró, ẹ wọ bí ìgbà ayé Bàbá Fagunwa ṣe rí'
Nitori naa ni Ọbabinrin Daurama ṣe fẹ ẹ.
Kanga naa ṣi wa nilu Daura titi di oni, wọn si n pọn omi ninu rẹ. Ṣugbọn, o ti di nkan ti awọn eniyan n rin irinajo igbafẹ lati wo.
Ìtan ilu Daura ko pe rara lai sọ nipa kanga Kusugu.
Bimpe: Èèyàn bíi tiyín ni àfín, ẹ dẹ́kun dídẹ́yẹsí àfín
5.  Awọn olokiki eniyan
Yatọ si wi pe ìtàn fi Daura si ipo pataki ni ilẹ Hausa ati Naijiria, Daura tun ni ọpọlọpọ awọn olokiki eniyan.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ọgagun Muhammadu Buhari: Olori ijọba ologun nigba kan ni Naijiria, to si tun jẹ aarẹ lọwọlọwọ. Ọmọ ilu Daura ni, ibẹ lo si ti lo pupọ ninu igbesi aye rẹ.
O ṣoro fun ẹnikẹni to mọ Buhari lati ma mọ pe ọmọ bibi ilu Daura ni, nitori pe ibẹ lo ti maa n ṣe ọpọ ayẹyẹ rẹ.
O ni ile, oko, ẹbi ati ọrẹ nibẹ.
Ogundiya: Àṣìṣe Dókítà ló sọ mi di aláàbọ̀ ara lórí kẹ̀kẹ́
2019 Elections: Èrò àwọn ọmọ Nàíjíríà se ọ̀tọ̀ọ̀tọ̀ lóri ètó àlùfáà tàbí ìmámù lásìkò ìbò
Ọba Umar Faruk Umar: Lọwọlọwọ, oun ni Emir ilu Daura. Oun si ni Emir ọgọta to jẹ ni Daura. Gbaju-gbaja ni kaakiri apa Ariwa Naijiria.
Alhaji Usman Daura: Oun ni olori ẹṣọ alaabo fun Aarẹ Shehu Shagari, Ọgagun Muhammadu Buhari ati Ọgagun Ibrahim Babangida laarin ọdun 1981 si 1989.
Sani Ahmed Daura: Gomina akọkọ to jẹ ni ipinlẹ Yobe lọdun 1991 si 1998.
Sani Zangon Daura: Minisita fun iṣẹ agbẹ ati idagbasoke igberiko laarin ọdun 1999 si 2000, ati Minisita fun ayika lọdun 2000 si 2001.
Ja'afar Mahmud Adam: Gbaju-gbaja onimọ ẹsin Islam ni, o si lo pupọ ninu igbesi aye rẹ ni ilu Kano. Ṣugbọn ọpọ mọ pe ilu Daura lo ti wa.
Lawal Musa Daura: Ọga agba nigba kan fun ajọ alaabo DSS.
Ambassador Mamman Daura: O ti ṣe aṣoju orilẹede Naijiria si Uganda, Saudi Arabia, South Korea, Belgium ati Cameroon.
Oríṣun àwòrán, Presidency
Awọn eekan lo ti jade lati ilu Daura sẹyin
Ilu Daura ti di orukọ ilumọọka kaakiri lẹyin ti Buhari di aarẹ lẹẹkeji
Ayẹyẹ pataki nilẹ Hausa, Durbar, maa n waye lasiko ọdun ileya. O si maa n larinrin. Igbagbọ wa pe ilu Daura lo ti bẹrẹ.
Awọn olukopa nibi ayẹyẹ naa sọ pe asiko Bayajjida lo bẹrẹ lati le mu ki iṣọkan wa laarin awọn Ọba ilẹ Hausa, ṣugbọn atunṣe ba a lẹyin ti ẹsin Islam de.
Ọ̀tọ̀ ni nkan tí wọ́n sọ fún ẹbí rẹ̀, iṣẹ́ aṣẹ́wó ni wọ́n fi n ṣe
Ezekwesili sọ ìdí tí ko fi dídu ipò sílẹ̀
Oríṣun àwòrán, @SHEWENZI
Ezekwesili tó jẹ́ ọ̀kan lára olùdásílẹ̀ ẹgbẹ́ Bring Back our Girls #BBOG ní ẹni tó mọ̀ nípa mẹ̀kúnù ni òun yàn ní igbákejì.
Minisita tẹlẹ ri fun eto ẹkọ, ọmọwe Obiageli Ezekwesili ti da ẹbi le ohun ti ẹgbẹ oṣelu rẹ sọ si bi o ṣe yọ ara rẹ kuro lara awọn oludije fun ipo aarẹ.
Ni tirẹ, o ni oun pinu lati tete fi didu ipo naa ji lati le gbe opo iwa ire rẹ ro.
'Obìnrin ló ni ilé àti àdúgbò fún ìdí èyí wọ́n lè ṣe ìlú dáadáa'
"Orilẹede Naijiria nilo ilana ọtun ati awọn adari to kun oju osuwọn to si to gbangba sun lọyẹ. Mo si lero tẹlẹ pe ACPN pawọpọ pẹlu mi lati ṣe eyi afi igba ti wọn pa awọ da.
Igba ti ibi a kori si ti wa di ọtọọtọ lo fa sababi bi mo ṣe yẹra fun ere ije didupo aarẹ labẹ asia wọn. O tẹnu mọ ọ.
Esi Oby Ezekwesili jẹ jade ni orilẹede Mexico nibi ipade Albert Einstein's Genius Visionaries to dara pọ mọ ninu ọrọ rẹ to sọ wi pe ko si irọ kankan to le di oṣelu ọtun lọwọ."
"Ni ti ọrọ ibanilorukọ jẹ ti adari ẹgbẹ ACPN sọ nipa mi, mo fẹ ki awọn ọmọ Naijiria mọ pe ko si ẹyọ ootọ kankan ninu gbogbo rẹ.
Ezekwesili ni ohun ko tii le fesi si ifọrọwanilẹnuwo kankan afiti oun ba pada de si orilẹede Naijiria ti oun yoo si pe ipade oniroyin lati ba awọn ọmọ Naijiria sọrọ.
ACPN: Ìdí tí ẹgbẹ́ wa fi padà lẹ́yìn Ezekwesili
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ezekwesili ti fi ìgbà kan jẹ́ igbakeji ààrẹ Banki Agbaye éka ilẹ̀ Afrika
Ẹgbẹ ti olùdíje obinrin si ipo aarẹ tẹlẹ ri, Oby Ezekwesili ti n dupo, Allied Congress Party of Nigeria (ACPN) ti yọwọ lawo ṣiṣe atilẹyin fun Ezekwesili.
Ni bayii, ẹgbẹ naa ti ṣi lọ sẹyin aarẹ Muhammadu Buhari ti ẹgbẹ oṣelu All People's Congress wọn si ni awọn fọwọ si ki aarẹ Buhari maa baṣẹ lọ.
Osinbajo: Ikẹnnẹ yẹ kó jẹ́ Mẹ́kà òṣèlú ni
Nigba ti BBC Yoruba ba alaga ẹgbẹ oṣelu ACPN, Alhaji Ganiyu O. Galadima sọrọ, o j ko di mimọ pe otitọ ni pe awọn ti pada lẹyin arabinrin Ezekwesili
Ẹgbẹ́ ACPN ti ṣáájú fii hande ninu atẹjade ti ẹgbẹ oṣelu fi sita pe Oby Ezekwesili kan ran kankan mọ ipolongo lasan ni lai ni alakalẹ kankan nilẹ.
Oby Ezekwesili
Alhaji Ganiyu sọ pe latẹnu oluranlọwọ Oby ni awọn ti ko aridaju jọ wi pe gbogbo ilakaka rẹ lati ọjọ yii kii ṣe lati di aarẹ gan bi ko ṣe lati san ọna dide ipo minisita fun eto isuna.
O ni nibi ipade oniroyin to waye gan, bi Oby ṣe fi ipinu rẹ han j ohun ti o ti ro tẹlẹ ni.
Lowurọ ọjọbọ ni Oby Ezekwesili kede ipinu rẹ lati ma dupo aarẹ mọ lori oniruuru atẹjade rẹ ni ikanni Twitter.
Ọjọ́ ńlá ní DR Congo, bí ààrẹ tuntun ṣe gbaṣẹ́
Oríṣun àwòrán, AFP
Aarẹ tuntun ti gba ijọba ni orilẹede DR Congo. Orukọ rẹ ni Félix Tshisekedi.
O sọ fun awọn ọgọọrọ alatilẹyin rẹ nile ijọba ni Kinshasa wi pe oun yoo rii pe iṣọkan wa ni orilẹede naa.
Eyi to yani lẹnu ju ni oun to ṣẹlẹ si aarẹ tuntun naa nigba ti wọn n bura fun wọle ti o si n sọ ọrọ akọkọ rẹ.
Ṣe ni ko le sọrọ daradara ti o si tọrọ aforiji wipe ara oun ko ya. Ko pẹ lẹyin rẹ ni o pada sori ọrọ akọsọ naa. O ni o rẹ oun ni nitori wahala ipolongo ibo.
Tshisekedi gbajọba lọwọ Joseph Kabila fun igba akọkọ ni bi ọgọta ọdun ti wọn yoo gbe ijọba fun aarẹ miiran ni irọwọ-rọsẹ.
Day 22: Njẹ́ ẹni tí yóó borí ní ìdìbò 2019 ṣe pàtàkì bí?
Ewo lo ṣee gbọkanle ninu awọn oludije?
Kini o ṣe pataki julọ lati ri ninu ẹni ti yoo jawe olubori nibi idibo Naijiria?
Ero ọpọlọpọ ni pe gbogbo ibo Naijiria, ko nii ṣe nipa ohun ti awọn oludije yoo ṣe fun ara ilu bikoṣe nipa erongba tara wọn nikan.
Nitori naa, njẹ idibo yi yoo tẹle ipasẹ ti atẹyinwa? Njẹ ẹni ti yoo wọle ṣe pataki si ara ilu tabi orukọ ẹgbẹ wọn tabi orukọ ẹbi wọn lo ṣe koko?
Obasanjo: Atiku kìí se Áńgẹ́lì, àmọ́ yóò se dáadáa ní ìlọ́po méjì ju Buhari lọ
Ohun ti akọroyin BBC ba bọ ree.
Idibo de, gbogbo eniyan ni o si n ṣọrọ nipa rẹ ati awọn oludije to lokiki ju lọ.
Ni ọpọlọpọ ibi ipolongo ibo ni awọn eniyan ti maa n pariwo orukọ oludije. Ṣugbọn o jọ bi ẹni pe, idibo naa, orukọ ni yoo da le lori, ki i ṣe ipa ti awọn oludije le ko ninu iṣejọba.
Labẹ aṣia ẹgbẹ oṣelu mejeeji to tobi ju - APC ati PDP - ni Aarẹ Muhammadu Buhari ati igbakeji aarẹ nigba kan ri, Atiku Abubakar ti n dije.
'Obìnrin ló ni ilé àti àdúgbò fún ìdí èyí wọ́n lè ṣe ìlú dáadáa'
Oludije mejilelaadọrin ni o n dupo aarẹ bayi, ṣugbọn o jọ bi ẹni pe ohun ti awọn oludibo n wo nikan ni ẹni to ni irú ẹni ti oludije naa ba duro fun.
ìpàdé ìtagbangba ìfọ̀rọ̀wánilẹ́nuwò pẹ̀lú àwọn olùdíje sípò gomina ní ìpínlẹ̀ Eko.
Arakunri Ernest Ereke to jẹ olukọ ni fasiti Abuja ni oun ro pe oriṣiriṣi nkan lo yẹ ni wiwo lati mọ irufẹ ẹni to yẹ ki awọn ara ilu yoo dibo fun.
Ṣugbọn njẹ awọn ara ilu bikita nipa ẹni ti yoo wọle ibo aarẹ?
Osinbajo: Ikẹnnẹ yẹ kó jẹ́ Mẹ́kà òṣèlú ni
Akoroyin BBC beere ni awọn adugbo Abuja, pe kini iyatọ ti iru ẹni to ba wọle ibo naa yo mu wa.
Murphy Elégungun Rọba: Mo fẹ́ di ẹnití egungun rẹ rọ jùlọ ní àgbáyé
Oriṣiri ni ero ọmọ Naijiria, ṣugbọn iwadii ti fihan pe ọpọlọpọ lo ti gba kamu pé iwọnba ni ibo awọn nii fi ṣe pẹlu ẹni ti yoo wọle.
Itanjẹ atẹyin wa ninu ileri awọn oloṣelu ti jẹ ki awọn kan kunlẹ adura lati bẹ Ọlọrun ki awọn oludije le mu ileri wọn ṣẹ.
Awọn ti iṣejọba alagbada jẹ logun ti n poungbẹ pé asiko ti to lati mu awọn oludije mọlẹ ki wọn mu ileri wọn ṣe fara ilu to n to ninu ojo ati ninu oorun fi jade dibo fun won.
Ọpọ lo ti ni oye kikun pé nkan ti yipada si ti atẹyinwa ti awọn oloṣelu a kan maa tan oludibo jẹ lasiko idibo.
Bayii, imọran ti n wa pe ki ẹbi, ara, ọrẹ ati alabaṣiṣe fun oludije kọọkan maa ran wọn leti ileri wọn loorekoore.
Ati pe, oludije to ba kuna lati mu ileri rẹ ṣẹ ni saa akọkọ ko ni wọle lẹẹkeji nitori pe awọn oludibo ko ni dibo fun.
Festus keyamo: Ọ̀rọ̀ Obasanjọ sí Buhari ti di ìrégbè
Ilé ńlá àràmàndà tó di ọgbà ẹ̀wọ́n
Oríṣun àwòrán, ARCHIVO FOTOGRAFÍA URBANA / PROYECTO HELICOIDE
Caracas, Venezuela
Ni aarin gbungbun olu ilu orilẹede Venezuela, Caracas ni ile aramanda yii wa.
Ile naa, El Helicoide ti figba kan jẹ ohun to n soju orilẹede naa gẹgẹ bi ilu ọlọrọ to si ni ọjọ iwaju rere.
Ṣugbọn lonii, o ti di ibi ti wọn nko awọn ti wọn ran lẹ ẹwọn si to si ti wa n sọ ti ijakulẹ orilẹede naa gẹgẹ bi ile ile nla to niyi ju ni ẹkun Latin America ati ibi ti idarudapọ ti wa n ṣẹlẹ.
'Obìnrin ló ni ilé àti àdúgbò fún ìdí èyí wọ́n lè ṣe ìlú dáadáa'
Nkan bi ọdun 1950s ni wọn kọ El Helicoide laye igba naa ti orilẹede Venezuela ni ala ire to si n pa ọpọlọpọ owo wọle latara epo rọbi.
Ọgagun Marcos Perez Jimenez nigba naa lọhun fẹ ki iṣẹ akanṣe yii jẹ apẹrẹ orilẹede bi ẹṣin iwaju ti awọn tẹyin n wo sare.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Caracas, Venezuela
Venezuela jẹ orilẹede to jẹ wi pe lati ọdun 1948 lo ti wọ ijọba ologun, koko ọrọ aatẹle wọn si ni a o tẹsiwaju bi a ba n kọ ile""."
El Helicoide lo yẹ ko jẹ ile itaja to lokiki ju lagbaye plu ọṣọ rẹ to ga lọ soke roo ro to fi to iwọn iye ile itaja ọọdunrun eleyi ti wn la kalẹ pe yoo wa ninu ile naa.
O tobi gan to bẹẹ ti wọn lee foju rii ni ibi kibi ninu ilu Caracas.
Wo fidio 'ẹwọn idẹra'
O yẹ ko ni ọkọ baalu tirẹ lọtọ, ile igbalejo si, akasọ onina ati oke tente ti yoo wa pataki jul fun ile naa.
Ṣugbọn lọdun 1958 ni gbogbo ala ire Marcos Perez pe ki iṣẹ akanṣe yii di ẹṣin iwaju ja sofo to si di ẹsin inu iwe lasan lasan.
Oríṣun àwòrán, Archivo Fotografía Urbana / Proyecto Helicoide
This space-age building was carved into the rock with ramps spiralling up past 300 planned boutiques
Fun ọplọpọ ọdun, tandi ni ile naa duro soju kan ti ọpọlọpọ igbiyanju lati mu u pada bọ sipo si n ja si pabo.
Nigba 1980s, ijọba bẹrẹ si ni gbe awọn ajọ kan lọ si El Helicoide. Ṣugbọn lati igba naa, o ti di ile ibẹru eyi ti wọn n ko ati ọdaran atawọn oloṣelu ẹlẹwọn si
Ile iṣẹ BBC ti ba awọn to ti kuro lọgba ẹwọn yii, ẹbi wọn, awọn aṣoju onimọ ofin, ẹgbẹ ti ko rọgbọ ku le ijọba to fi mọ aṣọgba ẹwọn meji lati sọ itan gẹlẹ bi igba aye El Helicoide ṣe ri.
Oríṣun àwòrán, Reuters
Caracas, Venezuela
Igbe aye awọn eniyanm ni Venezuela bẹrẹ́ si ni le koko plu ifasẹyin ọrọ aje, aito ounjẹ ati oogun to fi mọ ọrọ iṣẹ oojọ ti gbogbo ti fẹ di akurẹtẹ.
Ikọlukọgba wa pọ ni El Helicoide gẹgẹ bi ọkọ to kun fun awọn ẹlẹwọn ṣe n wọ ọgba ẹwọn lojoojumọ.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Caracas, Venezuela
'Ifoya de fun gbogbo araalu'
Oṣiṣẹ ọgba ẹwọn tẹlẹ ri ti ko fẹ fi oju ara rẹ han sọ fun BBC pe idi ti wọn fi n ṣe eyi ni lati dẹru ba awọn eniyan ni.
"Mo dẹ ro wi pe wọn ṣe bẹ́ẹ́. Nitori kete ti iwọde tabi ifẹhonu kan han ba bẹ́ si igboro,  ọpọlọ araalu lo maa n bẹru ki ọlọpaa ma mu wọn.
Ojoojumọ, ọsọọsẹ koda, oṣooṣu lawọn ẹlẹwọn ni El Helicoide ma n foju ba ile ẹjọ.
Gbogbo igba lo maa n la ala ifiyajẹni to n waye lojojumọ ni ọgba ẹwọn naa.
Caracas, Venezuela
Bi lẹwọn ṣe n pọ sii ni El Helicoide ni awọn aṣọgba n wa ọna ati tun wa aaye sii.
Ọfiisi, ile igbọnsẹ, atawọn akaba to yẹ ko da wa fun ile iṣẹ naa ni wọn ti pa ti wọn sọ di ọgba ẹwọn.
Ko si ina, ko si omi, ko si ile igbọns bẹẹ ni ko si imọtoto kankan. Ṣe ni gbogbo ogiri kun fun idọti ẹjẹ ati igbẹ.
Ẹlẹwọn le ma wẹ fun odidi ọsẹ kan. Inu ike rọba ni wọn n tọ si, inu ọra ni wọn si n ṣe igbọnsẹ si.
Caracas, Venezuela
Mo ti gbọ awọn ti wọn fi awọn nkan to lewu ba lo pọ pẹlu ipa.
Mo ri awọn ti wọn so lokun mọ oke ti wọn si da ori wọn kodo ko maa mi jolojolo. Wọn a maa ki batiiri bọ ina lati fi maa gun wọn lara.
Bi wọn ṣe n tẹ ẹtọ awọn eniyan loju mọlẹ yii lagbara. Tori naa, awọn ile iṣẹ to n ja fun ẹtọ ọmọniyan ti ni akọsilẹ gbogbo eyi loṣu keji ọdun 2018 ti wọn si n gbe igbesẹ pẹlu ifọwọsowọpọ ijọba orilẹede Venezuela.
Caracas, Venezuela
Ninu oṣu karun un ọdun 2018, awọn ẹlẹwọn El Helicoide fi ẹhonu han lori ohun ti wọn n la kọja. Lẹyin ọpọlọpọ iṣẹlẹ to ti waye, wọn da awọn ẹlẹwọn kan silẹ pẹlu ileri lati mu ayipada ba aye wọn.
Ṣugbọn pẹlu alaye awọn to wa ninu ọgba ẹwọn, ko fibẹẹ tii si ohun ti wọn ṣe gẹgẹ bi atunṣe si El Helicoide.
pẹlu gbogbo akitiyan lati kan si ile iṣẹ to n ri si ibanisọrọ ni Caracas ati aṣoju ijọba Venezuela nilẹ United Kingdom, BBC ko tii ri esi kankan si awọn ibeere yii.
Tanko Mohammed: Agbẹjọ́rò 250 ni Adájọ́ Àgbà ṣe ìbúra fún
Oríṣun àwòrán, Aliyu Tukur
Adájọ́ Àgbà tí Ààrẹ Buhari sẹ̀sẹ̀ yàn,Tanko Mohammed ti se ìbúra wọlé fún àwọn agbẹjọ́rọ̀ tó ń gbọ́ ẹjọ́ ètò ìdìbò.
Ọgọọrọ awọn agbẹjọrọ lo pejọ pọ si ibi  ibura wọle fun awọn agbẹjọrọ ti yoo ma gbọ ẹjọ to nii se pẹlu eto idibo.
Adajọ Agba tuntun lorilẹede Naijiria, Ibrahim Tanko ti Aarẹ Buhari sẹsẹ yan lo ṣe ibura wọle fun ajọ to n gbọ ẹjọ eto idibo naa.
Ile ẹjọ to gaju lorilẹede Naijiria ni wọn ti ṣe iburawọle fun awọn alaga ati awọn ọmọ ẹgbẹ ajọ ti yoo ma gbọ ẹjọ to nii se pẹlu eto idibo naa.
Oríṣun àwòrán, Aliyu Tukur
Laipe yii, Aarẹ Muhammadu Buhari yọ Adajọ Agba, Walter Onnoghen kuro nipo fun igba diẹ, titi ile ẹjọ to n gbọ ẹjọ iwa ibajẹ yoo fi abajade ẹsun iwa ibajẹ ti wọn fi kan an.
Ìjọba àpapọ̀ Nàìjíríà fèsì sí ilẹ̀ gẹ̀ẹ́sì,EU àti Amẹ́ríkà
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ijọba orileede Naijiria ti fẹsi si orileede Amerika, ajọ iṣọkan ilẹ Yuroopu ati ilẹ Gẹẹsi lori ọrọ adajọ agba Walter Onnoghen ti wọn ni aṣẹ lọ rọọkun nile rẹ ko boju mu.
Esi yi jẹ idahun si atẹjade kan ti awọn orileede mejeeji fi sita lọjọ ẹti nibi ti wọn ti ni ko tọ bi ẹka alaṣẹ ijọba Naijiria ti ṣe yọ adajọ agba naa ni ogunjọ si idibo apapọ
Ninu atejade kan ti agbẹnusọ ijọba Garba Shehu fi sita ti a ri ka loju opo ile iṣẹ iroyin Naijiria NAN, ijọba ni ''awọn lodi si ayọnusọ kankan to n gbero lati da ifoya silẹ́ laarin ara ilu tabi to fẹ ṣe idiwọ fun eto idibo to n bọ lọna.''
Garba Sheu tẹsiwaju pe ijọba Naijiria  lẹtọ lati gba tabi kọ amọran lori akoso ilu ti o si tọ ki awọn orileede agbaye to ku naa bọwọ fun ẹtọ yi.
O ni ijọba ko lodi si ibaṣepo ti yoo mu ki eto idibo to n bọ lọna kẹsẹjari.
Awuyewuye ọrọ aṣẹ lọ́rọkunle ti ijọba Naijiria pa fun afdajọ agba Walter Onnoghen ati bi wọn ti ṣe yan adajọ miran dipo rẹ jẹ ọrọ to gbode ni Naijiria toun ti bi idibo ọdun 2019 ti ṣe n sunmọ le.
Yatọ si iriwisi lọdọ awọn amofin,ẹgbẹ alatako, Ile Asofin agba Naijiria ti ni awọn yoo ṣe ijoko pajawiri kan lati mẹnu ba ọrọ yi lọjọ iṣẹgun.
Báyìí ni àwọn olùdíje ìpínlẹ̀ Eko ṣe fẹ́ kojú ìṣòro ìlera
Oríṣun àwòrán, Babatunde Olalere Gbadamosi/Facebook
àwọn olùdíje ìpínlẹ̀ Eko
Ọpọlọpọ ni ipenija to maa n koju ilu kan, bẹẹ naa ni ipinlẹ Eko n koju tirẹ.
Nibi ipade ifọrọwerọ awọn oludije gomina ni ipinlẹ Eko eyi ti BBC Yoruba ṣe agbekalẹ rẹ, awọn oludije ṣalaye lọlọkan o jọkan.
Nipa eto ilera ni ipinlẹ Eko, gbogbo awọn oludije lo ṣalaye ilana eto ti wọn ni fun ilera.
Babatunde Gbadamọsi (ADP)
àwọn olùdíje ìpínlẹ̀ Eko
Gbadamọsi tẹnu mọ eto ilera ọfẹ fun tolori tẹlẹmu ni ipinlẹ Eko. O ni ẹni to lowo lo n san owo eto adojutofo ṣugbọn ni ijọba toun, ilera ọfẹ ni.
Bakan naa, ni ti ọmọde ati arugbo, Babatunde ni wọn a fi wọn ṣe akọkọ bi wọn ba n boju to awọn alaisan ti wọn ba jọ wa lori ila.
O ni iṣejọba oun yoo kọ ibudo ilera ti ijọba si awọn apa ibi ti ko tii si ile iwosan ni ipinlẹ Eko bẹẹ si ni wọn yoo kọ ile iwosan si awọn ijọba ibilẹ ti ko tii ni ile iwosan.
Ọmọlara Adesanya (YPP)
àwọn olùdíje ìpínlẹ̀ Eko
Arabinrin Ọmọlara Adesanya gbagbọ pe kii ṣe keeyan kan ni ibudo ilera tabi ile iwosan ti ijọba nikan ṣugbọn pipese oogun ṣe pataki.
Gbogbo nkan ti yoo jẹ ki awọn ibudo ilera kekeke ni fun iṣẹ ni ijọba rẹ yoo pese. Wọn yoo kọ awọn nọọsi niṣẹ wọn yeke yeke.
Bẹẹ si ni yoo rii daju pe bi o tilẹ ṣe ẹyọkan ti wọn yoo si maa sanwo fun, dokita yoo maa wa lawọn ibudo ilera alabọde.
Awọn ẹrọ amuna wa naa yoo wa dipo awọn daku daji tokunbọ tabi aloku to n da ẹmi awọn eeyan legbodo bii ni akoko ti wọn ba n ṣe iṣẹ abẹ
àwọn olùdíje ìpínlẹ̀ Eko
Fafowora gbagbọ pe ilu Eko lowo gan o si gbagbọ pe ọ̀pọ ninu isuna ipinlẹ lo yẹ ki wọn na sori eto ilera.
Eto ilera adojutofo ni Fafowora yan lati ṣe leyi ti awọn eniyan yoo maa da owo kọbọ kọbọ bii irinwo naira si ibi ti wọn yoo ti maa mu u lo nigba ti ailera ba de.
Awọn to si jẹ arugbo ti ko lagbara ati san owo mọda mọda yii ni wọn yoo ṣe e fun lọfẹ.
Ẹ wo ọ̀nà àbáyọ tí àwọn olùdíje gómìnà pèsè sí ìṣòro Eko
àwọn olùdíje ìpínlẹ̀ Eko
Adebisi Ogunsanyan ni ijọba oun yoo yẹ owo ti awọn eleto ilera n gba ni owo oṣu wo wọn yoo si fi kun un nitori ọpọlọpọ wọn ni ko gba owo ti ko peye.
'Obìnrin ló ni ilé àti àdúgbò fún ìdí èyí wọ́n lè ṣe ìlú dáadáa'
Bakan naa o mẹnu ba pipese oogun, awọn ẹrọ igbalode to tọ si awọn ile iwosan to yẹ. Bakan naa wọn a ri i pe wọn mo ju to ago ti awọn ile iwosan mii ma n tilẹkun ki awọn eniyan le maa ba wọn bi wọn ba gbe alaisan lọ.
ìpàdé ìtagbangba ìfọ̀rọ̀wánilẹ́nuwò pẹ̀lú àwọn olùdíje sípò gomina ní ìpínlẹ̀ Eko.
Banky W ní àjọ INEC ṣe àṣìṣe orúkọ rẹ̀ àti ti ẹgbẹ́ òṣèlú rẹ̀ nínú ìwé ìdìbò 2019
Oríṣun àwòrán, Banky W/ instagram
Ìjòkó ilé aṣojú-ṣòfin ní Ilé aṣòfin àpapọ̀ ni Bankọle Wellington tí ọ̀pọ̀ mọ̀ sí 'Banky W' ń díje fún
Gbajugbaja olorin takasufe lorilẹede Naijiria, Bankọle Wellington ti ọpọ mọ si Banky W ti pariwo sita pe ajọ eleto idibo, INEC ṣi orukọ oun kọ ninu orukọ awọn oludije ti ti wọn gbe jade laipẹ yii.
Bakan naa lo ni ajọ INEC ṣi ami idanimọ ẹgbẹ oṣelu oun, iyẹn, Modern Democratic Party, tẹ si ori iwe idibo ti ajọ naa fẹ lo.
Onnoghen: Ẹ má yọ́nú sí ọ̀rọ̀ orílẹ́èdè wa - Buhari
Day 20: Ìgbà mélòó ni Ṣeyi Makinde ti dupò rí? #BBCNigeria2019
Ìbúgbàmù àdó olóró pá èèyàn 27 nílé ìjọsìn
Banky W. gbe e jade lori ikanni instagram rẹ pe gbogbo ọna ti awọn mọ ni awọn ti gba lati rii boya wọn lee tun ami idanimọ naa tẹ ṣugbọn o dabi ẹni pe ko lee bọ sii.
Ami idanimọ ti yoo ṣafihan ẹgbẹ oṣelu MDP lọjọ idibo kọ ni wọn tẹ. A ti gbiyanju lati mọ boya wọn lee tun iwe idibo naa tẹ ṣugbọn ko daju pe yoo ṣe e ṣe."""
O ni eyi ko ni domi tutu si ọkan ẹgbẹ oṣelu naa nitori afojusun rẹ.
Bakan naa ni wọn tun ṣi orukọọ mi kọ, ṣugbọn ko si iṣoro lori eyi nitori ko kuku ni si orukọ oludije lori iwe idibo ni ọjọ idibo.
Banky W. n dije fun ipo aṣoju-ṣofin ti yoo maa ṣoju ẹkun apapọ Eti-Osa ni ile aṣofin apapọ orilẹede Naijiria.
Sanwo-Olu, Jimi Agbaje yọ kúrò nínú ìfọ̀rọ̀wérọ̀ ìtagbangba BBC ní Eko
INEC ni orúkọ ẹgbẹ́ òṣèlú Ezekwesili yóo hàn lórí ìwé ìdìbò #BBCNigeria2019
Adájọ́ àgbà tuntun búra wọlé fún àwọn olùgbẹ́jọ́ ètò ìdìbò
Fela Durotoye, olùdíje ipò ààrẹ ẹgbẹ́ òṣèlù ANN #BBCNigeria2019
Ẹ wo ọ̀nà àbáyọ tí àwọn olùdíje gómìnà pèsè sí ìṣòro Eko
Ìgbìmọ̀ iṣedajọ orílè-èdè Nàìjíríà NJC fẹ́ ṣèpàdé lórí Onnoghen
Oríṣun àwòrán, NJC
Ìgbìmọ̀ iṣedajọ orílè-èdè Nàìjíríà NJC lagbara lati jiroro nipa yiyọ adajọ kankan lorileede Naijiria
Igbimọ iṣedajọ orile-ede Naijiria n palẹmọ lati ṣe ipade pajawiri lori ọrọ adajọ agba Naijiria Walet Onnoghen ti ijọba apapọ fun ni iwe lọọrọkun nile.
Ohun ti a gbọ ni pe ipade naa yoo waye lọjọ Aje ni deede agogo mẹwaa owurọ.
Iwe Iroyin Cable ni ọkan lara awọn ọmọ igbimọ naa ti wọn tu kẹkẹ ọrọ yi ni awọn ko ni jẹ ki adajọ agba Onnoghen tabi adele rẹ ti ijọba ṣẹṣẹ yan kopa ninu ipade naa.
Oríṣun àwòrán, @CREVO360_NG
Adajọ agba Naijiria, Walter Onnoghen
Igbimọ iṣedajọ yi labẹ ofin ni Naijiria lo lagbara lati jiroro tabi paṣẹ, lẹyin agbeyẹwọ ẹri, yiyọ adajọ kankan kuro nipo titi to fi de ori adajọ agba orile-ede Naijiria.
Ẹ wo ọ̀nà àbáyọ tí àwọn olùdíje gómìnà pèsè sí ìṣòro Eko
Ipade to yẹ ki igbimọ naa ṣe laipe yi ko waye nitori pe adajọ agba Walter Onnoghen sun un siwaju.
Lọwọlọwọ, ọrọ yiyọ adajọ Onnoghen nipo ti n da awuyewuye silẹ laarin awọn amofin ati ẹka alaṣẹ ijọba ti a si gbọ pe awọn ọmọ ẹgbẹ agbẹjọro ati awọn ẹgbẹ ajafẹtọ ẹni kanna fẹ ṣe ipade pajawiri ati iwọde.
Lọjọ Iṣẹgun ni ile igbimọ aṣofin agba Naijiria naa fi ọjọ ipade pajawiri si lati jiroro lori ọrọ yi kan naa.
Ninu ọrọ tirẹ agbẹnusọ fun Aarẹ Buhari, Garba Sheu sọ lalẹ ọjọ Aiku pe nitori ti Aarẹ Buhari ko fi ẹlẹ yọ Onnoghen lawọn eeyan Naijiria ti ṣe n binu.
O salaye pe aṣẹ ile ẹjọ ni Aarẹ tele lati yọ Onnoghen nipo ti ko si ni nkankan ṣe pẹlu lilo agbara.
Osinbajo: Ikẹnnẹ yẹ kó jẹ́ Mẹ́kà òṣèlú ni
'Obìnrin ló ni ilé àti àdúgbò fún ìdí èyí wọ́n lè ṣe ìlú dáadáa'
Sharafadeen All ni olùdíje sí ipò gómìnà ZLP ní ìpínlẹ̀ Ọyọ
Oríṣun àwòrán, Sharafadeen Alli/facebook
Lọwọlọwọ, oun ni Asaju Balogun Olubadan ilẹ Ibadan.
Wọn bi Sharafadeen Abiodun Alli ni ọdun 1963, ni ilu Ibadan.
O kẹkọ gboye nipa imọ ofin ni Fasiti ilu Ibadan lọdun 1986. O bẹrẹ iṣẹ amofin ni ileesẹ ofin R.A Sarumi & Co ni ilu Ibadan laarin ọdun 1988 si 1991.
Lẹni ọdun mejidinlọgbọn, o di Alaga ijọba ibilẹ Ariwa Ibadan lọdun 1991.
Wọn fi jẹ oye Asiwaju Balogun ilu Bakatari ni ijọba ibilẹ Ido, lọdun 1992 lẹni ọdun mọkandinlọgbọn.
Wọn dibo yan an ni aṣoju ẹkun idibo Guusu Ọyọ labẹ ẹgbẹ osẹlu UNCP lọdun 1996, ṣugbọn wọn ko bura fun nitori igbesẹ awọn ọmọ ologun to waye.
Oríṣun àwòrán, Sharafadeen Alli/facebook
Ṣaaju asiko yii, o jẹ ọmọ igbimọ ẹlẹni mẹjọ to wa fun idasilẹ Ibadan City Development Corporation labẹ iṣakoso Gomina Kọlapọ Iṣhọla lọdun 1992.
O di Akọwe ẹka ẹgbẹ oṣelu Peoples Democratic Party(PDP) nipinlẹ Ọyọ lọdun 1999. Bakan naa lo jẹ Adele Alaga ẹgbẹ naa ninu Oṣu Kẹsan, ọdun 1999.
Wọn yan an sipo Akọwe ijọba ipinlẹ ọyọ labẹ iṣakoso Gomina Rashidi Ladọja lọdun 2003.
O jẹ oye Akọgun ilẹ Ibadan lọdun 2004.
Lọdun 2005, o jẹ Olori oṣiṣẹ fun Gomina Rashidi Ladọja.
Wọn yan an sipo gẹgẹ bi Alaga ileeṣẹ Odu'a Investment Company Limited lọdun 2011.
Lọwọlọwọ, oun ni Asaju Balogun Olubadan ilẹ Ibadan.
Lọdun 2015, o dije dupo igbakeji gomina labẹ ẹgbẹ oṣelu Labour ni ipinlẹ Ọyọ.
Nibayii, oun ni oludije fun ipo gomina ipinlẹ Ọyọ labẹ ẹgbẹ oṣelu Zenith Labour Party fun eto idibo ọdun 2019.
Onnoghen: Ọlọ́pàá ti ọ́fíísì adajọ́ àgbà, wọn tún lé àwọn òṣìṣẹ́ rẹ̀ jáde
Igbimọ to n gbọ̀ ẹsun ti wọn ba fi kan awọn to di ipo mu nilu, CCT ti dun igbẹjọ Adajọ agba nigba kan fun Naijiria, Walter Onnoghen siwaju.
Lasiko igbẹjọ to yẹ ko waye lọjọ Aje lori ẹsun ṣiṣe mago-mago dukia ti wọn fi kan Onnoghen ni Alaga igbimọ naa, Danladi Usman kede pe wọn ko ti i le sọ ọjọ ti igbẹjọ naa yoo tun tẹsiwaju nitori pe wọn n duro de idajọ ile ẹjọ kotẹmilọrun ti Onnoghen ti pe ẹjọ tako igbesẹ igbimọ naa.
Ṣaaju ni iroyin tẹ BBC Yoruba lọwọ pe ileeṣẹ ọlọpaa orilẹede Naijiria ti ofiisi Adajọ Agba Walter Onnoghen pa, ti wọ́n si tun le awọn oṣiṣẹ́ to n ṣiṣẹ pẹlu rẹ jade.
Aarọ kutu ọjọ Aje ni a gbọ pe awọn ọlọpaa ya bo ofiisi adajọ agba naa, lẹyin ọjọ mẹta ti Aarẹ Muhammadu Buhari ni ko lo fidi mọ 'le.
Iroyin ni igbesẹ naa waye lati ri pe Onnoghen ko ri aye wọ ofiisi naa nigbakugba.
Agbẹnusọ ileeṣẹ ọlọpaa Frank Mba ko ti i sọrọ lori igbeṣẹ yii, ṣugbọn agbẹnusọ fun Onnghen, Awusam Bassey ni ootọ ni pe wọn ti ti ofiisi naa pa.
Awọn oniroyin ti ọrọ ṣe oju wọn ni, ṣe ni awọn ọlọpaa de ofiisi naa ti wọn si sọ fun awọn oṣiṣẹ to wa ninu awọn ofiisi to yii ka ki wọn fi ijoko wọn silẹ lẹyin ti wọn si tii pa.
Iwọ́de ń wáyé ní Abuja, Eko ati Enugu
Iroyin to n tẹ BBC Yoruba lọ́wọ́ fi han wipe iwọde n lọ lọwọ ni Abuja, Ilu Eko ati Enugu lati fi ẹhonu han lori bi Buhari ṣe yọ Onnoghen.
Ni Abuja, awọn ọmọ ẹgbẹ amofin kan ti bẹrẹ si ni ṣe iwọde ni oriko ẹgbẹ awọn amofin Naijiria (NBA) ni Abuja bayii.
Akọ̀royin BBC ni, kò pẹ́ tí iwọde naa bẹrẹ ti awọn kan de ninu ọ̀kọ̀ nla mérin ti wón si da aarìn wón ru. Wọn ni awọn n  ṣe atilẹyin fun igbesẹ̀ ijọba ni.
Ifẹhonu han n lọ lọwọ ni oriko NBA nipa ọrọ Onnoghen
Ẹ o ranti wipe ni ọjọ Ẹti, amofin agba Olisa Agbakoba to bẹnu atẹ lu igbesẹ Buhari lati yọ Onnoghen ti ni awọn yoo ṣe iwọde lati fi ẹhonu han lori igbesẹ aarẹ naa.
Agbakoba tun fa ijọba apapọ lọ ile ẹjọ lori ọrọ naa.
Ile Asofin Eko: Ọjọ́ Kẹrin oṣù Kejì ni Ambọde yóò yọjú síwájú ilé
Oríṣun àwòrán, Google
Ọjọ Aje ni iroyin gba ilẹ kan pe ile asofin ni ipinlẹ Eko ti n gbe igbesẹ lati yọ gomina Ambode kuro ni ipo.
Ile igbimọ Asofin ni ipinlẹ Eko ti fi iwe pe gomina ipinlẹ Eko, Akinwunmi Ambode lati wa jẹjọ ẹsun iwa ibajẹ ti wọn fi kan an, ko lee ni anfaani lati wa sọ tẹnu rẹ.
Ile igbimọ Asofin gbe igbesẹ yii pẹlu awijare pe gomina Ambọde n na owo ti ile asofin ko fọwọsi.
O si ti to ọjọ mẹta bayii ti ẹnu ti n kun gomina Ambode pe, oun lo n dọgbọn se agbatẹru eto ipolongo oludije gomina labẹ asia ẹgbẹ oselu PDP, Jimi Agbaje, to si n gbe owo kalẹ fun.
Nibi ijoko ile asofin to waye lojọ Aje, ni wọn ti ka awọn ẹsun sise owo ilu basubasu si gomina Ambọde lọrun, ti wọn si ransẹ pe ko wa sọ tẹnu rẹ.
Ile ti wa pasẹ fun gomina Ambọde pe ko yọju sibi ijoko ile ti yoo waye lọjọ kẹrin osu keji ọdun yii lati wa wi awuijare rẹ.
Wọn ti wa sun ijoko ile di Ọjọ Kẹrin,Osu Keji, ọdun to n bọ.
Àwọn olùgbọ́ BBC Yoruba fi èrò han lẹ́yìn #BBCGovDebate Eko
Nibi ijoko ile to waye ni iroyin ti tan kalẹ pe wọn n gbimọ lati yọ gomina naa kuro ni ipo.
Lọwọlọwọ bayii, ijoko ile asofin si n tẹsiwaju, a o ma a mu iroyin wa fun yin lẹkunrẹrẹ.
NBA: Á kọ́ ilé aṣòfin àpapọ̀ nípa agbára tó ní lórí Ààrẹ tó bá tẹ òfin lójú
Oríṣun àwòrán, @Nigerialawyers
Àwọn amòfin náà ní gbogbo ọ̀nà tí òfin là kalẹ̀ làwọn yóò tọ̀
Awọn amofin kaakiri ẹkun iwọ oorun guusu orilẹede Naijiria, darapọ mọ awọn agbẹjọro kaakiri orilẹede Naijiria, lati bẹrẹ igbesẹ idẹyẹsi ile ẹjọ.
Wọn n gbe igbesẹ yii lati fi ẹhonu han si bi aarẹ Muhammadu Buhari ṣe ni ki adajọ agba orilẹede Naijiria, Water Onoghen yẹ̀bá si ẹgbẹ kan naa lori ẹsun aijolootọ ninu iwe akojọpọ dukia rẹ.
Awọn amofin lorilẹede Naijiria labẹ agboorun NBA ni ohun ti aarẹ ṣe tako agbekalẹ iwe ofin Naijiria ti ọdun 1999.
Àwọn olùgbọ́ BBC Yoruba fi èrò han lẹ́yìn #BBCGovDebate Eko
Ni ọjọ iṣẹgun ti igbesẹ naa bẹrẹ si ni fi idi mulẹ, awọn amofin kaakiri awọn ipinlẹ bii Ondo, Ọṣun, Ọyọ , Ogun ati Ekiti naa darapọ.
Alaga ẹgbẹ awọn agbẹjọro ni ilu Akurẹ, Amofin Ọla Dan Ọlawale ni gbogbo awọn amofin ipinlẹ naa ni wọn tẹle aṣẹ ti olu ileeṣẹ ẹgbẹ naa pa.
O ni gẹgẹ bii ọmọ ẹgbẹ amofin NBA, ko si amofin kankan to tẹ awọn ile ẹjọ ni ipinlẹ naa.
Oríṣun àwòrán, @Nigerialawyers
Àwọn amòfin náà ní ẹ̀ka ìṣèdájọ́ yóò padà sí ẹsẹ̀ ògo rẹ̀.
O ni lootọ ọrọ naa yoo kan awọn eeyan to ni ẹjs niwaju ile ẹjọ kan tabi omiran  lọjọ mejeeji ti igbesẹ naa yoo fi waye, sibẹ 'Ki ọrọ maa baa bajẹ' lawọn amofin fi gbe igbesẹ naa.
Ni tirẹ alaga ẹgbẹ awọn agbẹjọro ni agbegbe Ileṣa nipinlẹ Ọṣun, Amofin Kanmi Ajibọla ṣalaye pe gẹgẹbii ara smọ igbimọ ẹgbẹ amofin NBA to joko lori ọrọ naa, iroyin lati gbogbo tibu-toro orilẹede Naijiria fihan pe aṣẹ naa fidi mulẹ kaakiri gbogbo ẹkun igbẹjọ lorilẹede Naijiria.
Oríṣun àwòrán, @Nigerialawyers
Awọn alaga ẹgbẹ amofin ni Akurẹ ati Ilesa ni awọn agbẹjọro n tẹle aṣẹ naa
O ni awọn amofin ṣetan lati gbe igbesẹ gbogbo to tọ lati rii pe wọn pe Aarẹ Buhari pada lori igbesẹ naa.
Lara awọn igbesẹ ti a o gbe lẹyin ti gbedeke ọjọ meji naa ba pari ni lati wo boya ki a tẹ siwaju tabi ki a gba ile aṣofin apapọ lọ, lati da wọn lẹkọ lori awọn ọna ati agbara ti ofin fun wọn lati da sẹria to ba yẹ fun Aarẹ to ba ya aletilapa lori ọrọ ibọwọ fun ofin.
New Minimum Wage: Ilé ìgbìmọ̀ aṣojú ṣòfin bọwọ́ lu #30,000 fáwọn òṣìsẹ́
Oríṣun àwòrán, Twitter/NLC
Owo oṣu tuntun fawọn oṣiṣẹ
Ile igbimọ aṣoju ṣofin l'Abuja ti buwọ lu aba lati maa san ẹgbẹrun lọna ọgbọn naira gẹgẹ bi owo oṣu oṣiṣẹ to kere julọ.
Igbesẹ naa waye lẹyin ti igbimọ to n ri si alekun owo oṣu oṣiṣẹ tuntun jabọ fun ile.
Gbogbo ile lo fọwọ si pe ki ijọba bẹrẹ si san ẹgbẹrun lọna ọgbọn naira gẹgẹ bi owo oṣu tuntun fun oṣiṣẹ to kere julọ fawọn oṣiṣẹ.
Falana: Awọn to n dije dupo ìdìbò 2019 fẹ́ fa ogun si Naijiria
Eleyi wa ni ibamu pẹlu aba ti igbimọ ti Aarẹ Muhammadu Buhari gbe kalẹ lati ṣiṣẹ lori alekun owo oṣu tuntun fawọn oṣiṣẹ da.
Aarẹ Buhari ti kọkọ fọwọ si ẹgbẹ mẹtadinlọgbọn naira tẹlẹ ṣugbọn awọn oṣiṣẹ kọ jalẹ pe ẹgbẹrun lọna ọgbọn naira lawọn yoo gba gẹgẹ bi owo oṣu oṣiṣẹ to kere julọ.
Onnoghen: Àjọ NJC fún Onnoghen lọ́jọ́ méje láti wá sọ tẹnu rẹ̀
Oríṣun àwòrán, Nigeria Bar Association
Ajọ NJC pe awọn adajọ agba mejeeji
Ajọ to n ri si idajọ lorilẹede Naijiria NJC ti fun adajọ agba Walter Onnoghen ti Aarẹ Muhammadu Buhari ni ko lọ rọku nile ati adajọ agba tuntun to gba ipo rẹ Ibrahim Tanko Mohammed lọjọ meje lati fesi si awọn ẹsun ti wọn fi kan wọn.
Ajọ NJC ni ki adajọ agba Onnoghen fesi si ẹsun ti wọn kan an pe o kuna lati kede dukia rẹ gẹgẹ bi ofin Naijiria ti fi lelẹ.
Bakan naa, ajọ NJC ni ki adajọ agba tuntun Mohammed ti Aarẹ Buhari ṣẹṣẹ bura fun wa sọ tẹnu rẹ idi ti o fi gba iyansipo naa lai jẹ pe ajọ NJC fọwọ si.
Ti o ba ṣẹlẹ pe awọn adajọ agba mejeeji jẹbi ẹsun ti wọn fi kan wọn ti wọn si da wọn duro, adajọ Ọlabọde Rhodes-Vivour to jẹ adajọ kẹta to ni iriri julọ ni ile ẹjọ to ga julọ ni Naijiria ni yoo gori aleefa gẹgẹ bi adajọ agbajọ tuntun.
Atiku fẹjọ́ Buhari sun US, UK, France àti EU lórí ọ̀rọ̀ Onnoghen
Ẹwẹ, oludije aarẹ fẹgbẹ oṣelu alatako PDP, Atiku Abubakar ti fẹjọ aarẹ Muhammadu Buhari sun orilẹede Faranse, Germany, Amẹrika, Ilẹ Gẹẹsi ati ajọ ilẹ alawọ funfun lori bi o ti ni ki adajọ agba Walter Onnoghen lọ rọkun nle.
Oríṣun àwòrán, Twitter/PDP
Ọrọ lori adajọ agba tẹlẹ Walter Onnoghen
Bakan naa ni Atiku tun fẹsun kan Aarẹ Buhari ninu ẹjọ to fi sun pe o n gbe igbesẹ ti ko ba ijọba awa arawa mu.
Atiku ni Aarẹ Buhari n tapa ṣofin orilẹede Naijiria, bẹẹ lo si n o ṣe awọn ẹka ijọba bi o ṣe wu u lati le tẹ ara rẹ nikan lọrun.
Oludije fun ipo aarẹ ẹgbẹ PDP sọ pe lẹyin ọrọ adajọ agba ti Buhari yọ bii jiga, o ni bakan ni o ti bọwọ lu biliọnu dọla kan fun inanwo ile isẹ ologun ko to gbe aba rẹ de iwaju ile aṣofin agba l'Abuja.
Atiku tun fikun ọrọ rẹ pe, Buhari ko bọwọ fun aṣẹ ile ẹjọ lorilẹede Naijiria, bẹẹ lo tun fẹsun kan-an lori rira ọkọ ofurufu Tucano.
Ọlọ́pàá Ondo: Ìyá ọmọ tó kú yóò fojú balé ẹjọ́
Oríṣun àwòrán, @Sazisokhango
Ile isẹ ọlọpaa ni ipinlẹ Ondo ti fi idi rẹ mulẹ wi pe, lootọ ni iya kan lu ọmọ rẹ pa ni Akure, ni ipinlẹ Ondo.
Ọmọ naa to papoda, ti orukọ rẹ n jẹ Mattew, wa ni ile -iwe girama onipele ikẹta.
Agbẹnusọ fun ile isẹ ọlọpaa ni ipinlẹ Ondo, Femi Joseph to fi idi ọrọ naa mulẹ fun BBC Yoruba sọ wi pe iwadii n lọ lọwọ lori isẹlẹ to waye ni agbeegbe Ọda, Akure ni ipinlẹ Ondo.
Ondo: Iya lu ọmọ pa nítori ẹgbẹ̀rún mọkànlélógun Naira
Awọn ti ọrọ naa soju rẹ wi pe Abilekọ Ajọkẹ Adebayo lo fi lulu ba ti ọmọ rẹ jẹ, lẹyin to ni ọmọ ọdun mẹrinla naa ji ẹgbẹ̀rún mọkànlélógun Naira(21,000) kuro ninu apo isuna rẹ ni ile ifowopamọsi.
Wọn fikun wi pe lẹyin ti iya naa ri wi pe ọmọ oun ji owo naa, o pe ọkọ rẹ to jẹ ọlọpaa lati fi ẹjọ ọmọ naa sun, ti baba ọmọ naa si pasẹ wi pe ki wọn na ọmọ naa.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ìyá ọmọ tí ó kú yóò fojú balé ẹjọ́
Iya ọmọ ati aburo ọkọ na ọmọ naa, wọn si tii mọ inu ile. Ọrẹ ọmọ naa lo wa wọ ọmọ naa ,ti wọn si ri wi pe o ti daku, ko to di wi pe o gbe ẹmi mi ni ile iwosan.
Awọn ọlọpaa ti fi panpẹ ọba mu iya ọmọ naa, ti wọn si n wa baba ọmọ naa.
UK: Fiona Onasanya parọ́ pé òun kọ́ ló wa ọkọ̀ sáré àsájù
Oríṣun àwòrán, PA
Fiona Onasanya nigba to de ile ẹjọ Old Bailey
Aṣòfin kan to tun jẹ oloṣelu akọkọ ti yoo di ero ẹwọn fun oṣù mẹ́ta , Fiona Onasanya, lo jẹbi ẹsun pe o purọ fun awọn ọlọpaa nigba ti wọn jawe fun wipe o n fi ọkọ rẹ sare ju.
Fiona Onasanya to jẹ amofin ni, ki i ṣe oun lo n wa ọko ti awọn ọlọpaa ri to sare ju gbedeke 30mph, ti ofin gba laaye ni popona kan ni orilẹede naa ni oṣu keje ọdun 2017 in July 2017.
Aṣofin naa, to n ṣoju Peterborough ni ẹgbẹ oṣelu rẹ jawe gbele-ẹ fun, lẹyin ti wọn ni o tẹ oju ofin mọlẹ.
Ẹwọn oṣu mẹta ni wọn fun un lẹyin ti wọn tun igbẹjọ rẹ ṣe ni ile ẹjọ Old Bailey.
Inu ọkọ Nissan Micra yii ni wọn ti ni Onasanya sara asapajude naa.
Oríṣun àwòrán, Jonathan Brady/PA
Fiona Onasanya de si ile ẹjọ Old Bailey fun igbẹjọ rẹ ni ọjọ Iṣẹgun
Ile ẹjọ naa gbọ wipe, Onasanya n fi ẹrọ ilewọ rẹ tẹ atẹjiṣẹ nigba ti o n wa ọkọ rẹ ti o si n sare.
Oun ni aṣofin ti wọn yoo kọkọ sọ sẹwọn lẹyin ti Terry Fields lọ ẹwọn ọgọta ọdun, nitori wipe ko san owo ori £373 ni ọdun 1991.
Aburo Onasanya, Festus  naa lọ ẹwọn oṣu mẹwa fun ipa to ko niinu ọrọ naa.
Oríṣun àwòrán, PA
Festus to jẹ aburo ọnasanya lọ ẹwọn oṣu mẹwaa
A ò ṣe àyọnusọ lóri ọ̀rọ̀ abẹ́lé Nàìjíríà-UK
America: Ẹ má dúró ju ìṣẹ́jú mẹ́wàá lọ níta ìlú yóò tutù kọjá àlà
Oríṣun àwòrán, Getty Images
America yóò tutù ju bó ti yẹ lọ
Lọsẹ yii, awọn alasọtẹlẹ oju ọjọ ti ni awọn ara ilẹ Amẹrika yoo gbọn pẹpẹpẹ ninu otutu to lagbara ju bo ti yẹ lọ.
Awọn onimọ nipa oju ọjọ sọ pe o jẹ iṣẹlẹ to maa n sẹlẹ lẹẹkan laarin iran kan.
Wọn ni o maa n waye nigba ti oju ọrun ba ran afẹfẹ to tutu gan si ile aye to si fa ọpọlọpọ iṣlẹ to mu otutu dani. Pẹlu eyi, yoo mu iwọn oju ọjọ walẹ si 53C (-64F).
Day 17: Àwọn olórí tó wà ní Kwara ń ṣe fún ara wọn nìkan ni #BBCNigeria2019
Ẹwẹ awọn onimọ nipa oju ọjọ ni ipinlẹ Iowa ti kilọ fun awọn ara ilu naa pe ki wọn ṣọra fun mimi kanlẹ ki wọn si din ọrọ sisọ ku bi wọn ba wa ni ita.
o kere tan eniyan miliọnu marun le laadọta ni yoo fara gba ninu iṣẹlẹ otutu to le yii.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
America yóò tutù ju bó ti yẹ lọ
Koda wọn ti kede konile o gbele lawọn apa ibi kọkan ni il naa.
Awọn onimọ nipa oju ọjọ sọ pe ohun ti yoo fa ijamba ni ki eniyan duro si ita ninu otutu to lagbara naa fun iṣẹju mẹwaa.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
America yóò tutù ju bó ti yẹ lọ
Laarin ọjọ iṣgun si ọjọbọ si ni  ni awọn alasọtẹlẹ oju ọjọ ni yoo waye ti wọn si ni pe Chicago yoo tutu ju ẹkun Antarctica.
Bẹẹ si ni ni awọn apa ibomiiran, yinyin ti wọn yoo foju ri yoo le gan.
Libya Refugees: Àtìpó 162 míì dé padà láti Libya
Oríṣun àwòrán, NEMA
Awọn Naijiria nilẹ Libya
Ajọ to n ri si iṣẹlẹ pajawiri lorilẹede Naijiria, NEMA ti gba awọn ọmọ Naijiria mẹrindinlaadọrin to jẹ atipo ni orilẹede Libya.
Alabojuto ọfiisi ajọ NEMA to wa ni ipinlẹ Eko, Alhaji Idris Muhammed lo gba alejo awọn abọde Libya naa ni papak ofurufu Murtala Muhammed, Ikeja ni nkan bii agogo mẹta abọ oru ọjọru.
Ẹtàn ni àwọn ọ̀rẹ́ fi ń tan èèyàn lọ si Libya pé iṣẹ́ gidi wà níbẹ̀
Ọgọrun ninu awọn atipo naa jẹ obinrin ti mẹrin ninu wọn jẹ aboyun, mejilelgọta si ni ọkunrin. Gbogbo wọn jẹ agbalagba obinrin mejilelọgọrin, ọmdebinrin mẹtala, ikoko obinri marun un; ati aadọta ọkunrin agbalagba, ọmdekunrin mrin ati ikoko ọmọkunrin mẹtala. Ninu wọn si ni eniyan meji to ni iṣoro ilera wa.
Oríṣun àwòrán, NEMA
Awọn Naijiria nilẹ Libya
Alabojuto ajọ NEMA nilu Eko gba awọn eniyan to ba n gbero lati rin iru irinajo na aitọ bayii lati yẹra fun un.
Day 17: Àwọn olórí tó wà ní Kwara ń ṣe fún ara wọn nìkan ni #BBCNigeria2019
O ni bi eeyan ba fẹ ṣi lọ si ilu miiran paapaa nilẹ okeere, ilana to tọwa lati tẹle ninu iwe ti yoo da abo bo wọn lọwọ ewu.
O ni iwa ti awọn to n ṣi lọ si orilede mii lọna aitọ yii n kọ awọn tọrọ kan lominu.
Oríṣun àwòrán, NEMA
Awọn Naijiria nilẹ Libya
Ẹwẹ, o ni fun awọn to ti baba ha sinu panpẹ yii, wn ti ṣeto baalu ti yoo da wọn pada sile. Eto naa ni wọn ni o bẹrẹ ninu oṣu kẹrin ọdun 2017 ti yoo si wa sopin ninu oṣu kẹrin ọdun 2020.
Nigeria 2019 Elections: Èwo nínú ìlérí tí Buhari ṣe ní 2015 ló ti mú ṣẹ?
Oríṣun àwòrán, AFP
Lasiko eto ipolongo ibo aarẹ lọdun 2014 si 2015 ṣaaju eto idibo gbogboogbo to waye lọdun 2015, Aarẹ Muhammadu Buhari ṣeleri awọn nkan ti iṣakoso rẹ yoo ṣe fun araalu ti wọn ba fi dibo yan an sipo aarẹ Naijiria.
Ọpọlọpọ ileri ati ẹjẹ ni Buhari jẹ nigba naa ninu akọsilẹ to pe ni ''Majẹmu mi pẹlu awọn ọmọ Naijiria.''
Laipẹ yii ni aarẹ Buhari sọ nibi eto ipolongo ibo to ṣe ni ipinlẹ Imo ati Abia fun saa keji nipo sọ pe oun ti mu gbogbo ileri t'oun ṣe lọdun 2015 ṣẹ fun awọn ọmọ Naijiria.
A ṣe agbeyẹwo diẹ lara awọn ileri naa.
Igbe aye Irọrun
Ileri to ṣe: Idasilẹ eto fifun awọn ọmọ ileewe alakọbẹrẹ ni ounjẹ ọfẹ
Eto yii jẹ ọkan lara eto oni ẹẹdẹgbẹta biliọnu Naira ti iṣakoso Buhari jẹjẹ fun igbeaye idẹrun fun araalu.
Wọn ni fifun awọn ọmọ ileewe alakọbẹrẹ bi miiọnu mẹẹdogun ni ounjẹ ọfẹ yoo mu idagbasoke ba ipese ounjẹ, ti yoo si tun pese iṣẹ.
Ileri: Idasilẹ eto iranlọwọ owo fun awọn to ku diẹ kaato fun lawujọ
Eto Ilera
Ileri: O sọ pe oun yoo ri i daju pe ọmọ Naijiria ko ni idi kankan lati lọ gba iwosan nilẹ okeere.
Ipese Iṣẹ
Ileri: Mimojuto idasilẹ miliọnu mẹta iṣẹ lọdun kan nipa dida ileeṣẹ silẹ, iṣẹ ijọba ati fifẹ iṣẹ agbẹ l'oju si i.
Eto aabo
Ileri: Riri daju pe 'ipa tabi agbara kankan labẹle tabi llyin odi ridi joko ni Naijiria.
Paapa gbigbogun ti igbesunmọmi.
Iwa Ibajẹ
Ileri: Lati ṣiṣẹ pẹlu ile aṣofin apapọ lati ṣe ofin eto 'olofofo' whistle blower
Eto naa wa fun ṣiṣe koriya fun ẹnikẹni to ba mọ ohunkohun nipa iwa ti ko tọ lawujọ lati fito awọn alaṣẹ leti.
Fun 'ofofo' to ba jẹ mọ iwa ibajẹ, ẹni to ba tu aṣiri ọrọ naa yoo gba ida meji ataabọ owo ti ijọba ba ri gba.
Owo ti wọn fi n ṣe iṣakoso
Ileri:Lati ṣiṣẹ pọ pẹlu ile aṣofin lati mu adinku ba iye owo ti wọn fi n gbọ bukata iṣakoso.
Ipese ina mọna-mọna
Ileri: Iṣakoso ẹgbẹ oṣelu APC yoo ri daju pe ipese ina mọna-mọna dara si ti yoo to ogoji ẹgbẹrun laarin ọdun mẹẹrin si mẹjọ.
Atiku: Màá foríji àwọn tó bá dá owó ìlú tí wọ́n kó jẹ padà
Oríṣun àwòrán, Facebook/@PeterObi
Oludije fun ipo aarẹ ninu ẹgbẹ oṣelu Peoples Democratic Party, PDP, Atiku Abubakar ti sọ pe oun yoo dariji awọn to ba ko owo ilu jẹ, ti oun ba fi di aarẹ Naijiria ninu eto idibo to n bọ.
Atiku sọ ọrọ naa nibi ipade itagbangba ti ajọ MAcArthur Foundation, ileeṣẹ amohunmaworan NTA ati Daria media pawọpọ ṣe nilu Abuja.
Nibi ipade naa, Atiku sọ pe oun yoo dariji awọn ti ọwọ ba tẹ pe o wu iwa ibajẹ niwọn igba ti wọn ba ṣetan lati fi iru owo bẹẹ da iṣẹ́ silẹ l'orilẹede Naijiria, ti eto idariji ọhun yoo si ṣe iwuri fun awọn to n kowo ilu jẹ lati finufindọ da a pada lara owo ilu ti wọn ko jẹ pada.
Igbakeji Atiku, Peter Obi naa to da si ọrọ naa, sọ pe eto naa kii ṣe idariji nikan, o ni eyi yoo ran ijọba lọwọ̀ lati tete ri owo ilu ti wọn ji gba pada.
YPP, ADC, PPC ni tòótọ́ ni pé ọmọ oninakuna nijọba Eko lasiko yii
Ẹwẹ, Atiku sọ pe iṣakoso oun yoo ri i daju pe opin de ba bi awọn ọmọ ogun ṣe n padanu ẹmi wọn, ati nkan ijagun si ọwọ̀ awọn agbesunmọmi.
"Lori ẹsun kan to sọ pe ọkan lara awọn iyawo rẹ, Jennifer Douglas ṣe mago-mago owo nilẹ Amẹrika, Atiku sọ pe ''Ko ti i si ẹnikẹni to sọ ẹsun naa ni gbangba, bẹẹni wọn ko ti i gbe iyawo mi lọ sile ẹjọ, nitori naa, ẹ ko le fidirẹmulẹ pe lootọ lo ṣe bẹ, nitori pe o ti rinrinajo lọ silẹ amẹrika laimọye igba."""
Nigba ti wọn beere lọwọ rẹ boya yoo fọwọ wọnu to ba fidirẹmi ninu eto idibo sipo aarẹ, Atiku sọ pe nkan to le mu oun ṣe bẹ ni ti 'eto idibo naa ko ba ni mago-mago ninu.'
Àtúpalẹ̀ ìlànà bí Atiku ṣe fẹ́ kojú ìwà ìbàjẹ́
Oríṣun àwòrán, Atiku Abubakar/Twitter
Awọn orilẹede bi i Turkey ati Malaysia n lo iru ilana ti Atiku Abubakar fẹ ẹ gba gbogun ti iwa ibajẹ.
Oludije sipo aarẹ labẹ ẹgbẹ oṣelu Peoples Democratic Party, PDP, Atiku Abubakar sọ pe oun  yoo dari ji awọn to ba ko owo orilẹede Naijiria jẹ, niwọn igba ti wọn ba gba lati da owo naa pada tabi fi da ileeṣẹ silẹ ni Naijiria.
Ọjọru ni Abubakar sọ ọrọ naa nibi ipade itagbangba kan ti ajọ MAcArthur Foundation, ileeṣẹ amohunmaworan NTA ati Daria media pawọpọ ṣe nilu Abuja fun awọn oludije fun ipo aarẹ ati igbakeji wọn.
Atiku: Màá foríji àwọn tó kówó ìlú jẹ́ tí mo bá di àárẹ
‘Ìjọba kò tẹ̀lẹ́ ìlànà òfin lòrí ọ̀rọ̀ Onnoghen’
Onwoye nipa bi nkan ṣe n lọ ni agbo oṣelu Naijiria, to tun jẹ olupolongo tako iwa ibajẹ ninu ajọ Children Anti-corruption Initiative, Akinwande Ọmọlolu ṣe atupalẹ rẹ.
O dara ti Atiku Abubakar ba le se bẹẹ.
O ṣalaye pe oun ti o tumọ si ni pe awọn to ti kowo ilu jẹ tẹlẹ yoo da a pada fun ijọba, ti ijọba yoo si na owo naa sori eto ọrọ aje Naijiria.
Eyi dara ju ki ijọba o maa gbe wọn lọ sile ẹjọ lọ. Gẹgẹ bi ẹni to n polongo tako iwa ibajẹ, bi eto idajọ wa ṣe ri ko jẹ ki igbogun ti iwa ibajẹ o ṣaṣeyọri.
"O san ki ijọba ba iru ẹni bẹẹ duna-dura lati da owo naa pada, niwọn igba ti awọn miiran ko ni ko owo jẹ mọ, de bi ti iru eto bẹ yoo tẹsiwaju.
Ọna ti ijọba le gba yanju eyi ni lati ṣe ofin pe ki  gbogbo awọn osisẹ ijọba to fi mọ awọn to di ipo oṣelu mu lati maa kede dukia wọn, ki wọn to de ipo. Ayẹwo si gbọdọ maa waye lọdun maarun maarun lori awọn dukia bẹ ẹ."
"O tẹsiwaju wi pe ""Mo gbagbọ pe a ko fi bẹẹ tẹle ofin to de awọn to di ipo iṣakoso mu ni Naijiria. Ijọba si le ṣe idasilẹ oju opo ti wọn o maa fi iru awọn nkan bẹẹ to araalu leti."
"Yoo mu ko soro fun wọn lati maa ko dukia jọ. Awọn ọmọ Naijiria yoo si le jẹ oye oju lalakan fi n sọri. Aarẹ Buhari ko ṣe to ninu igbogun ti iwa ibajẹ. Amọ o ṣeni laanu pe afojusun rẹ ti yẹ."""
Ko buru ti a ba dan ilana ti Atiku fẹ ẹ gba gbogun ti iwajẹ wo, ka wo esi ti yoo fun wa.
Ṣiṣe bẹ yoo ran ijọba lọwọ lati mọ iwọn dukia ti owo oṣu oṣiṣẹ kọọkan le ko jọ fun un. Ni Akinwande Ọmọlolu wi.
Igbesẹ ti Atiku fẹ gbe yii lo dara fun Naijiria.
Aarẹ orilẹede Naijiria, Muhammadu Buhari gbe iru igbesẹ pe ki awọn to di ipo iṣakoso mu o maa kede dukia wọn, nigba to kọkọ de ipo.
Awọn ọmọ Naijiria loju opo Facebook BBC Yoruba kan gbagbọ pe ki Atiku kọkọ ko owo ilu to wa lọwọ rẹ silẹ naa, ko to gbe igbesẹ naa.
Bakan naa ni awọn kan ni ọna to dara ni Atiku fẹ tọ̀ lati gbogun ti iwa ibajẹ.
Awọn orilẹede bi i Turkey ati Malaysia n lo iru ilana ti Atiku Abubakar fẹ gba gbogun ti iwa ibajẹ.
Ẹjọ́ Walter Onnoghen: NJC nìkan ló lásẹ láti yọ Adájọ́ Ágbá
Ilé ẹjọ́ kòtẹ́milọ́rùn ti fi ọwọ́ òsì di ẹjọ́ tí Adájọ́ Àgbà lórílẹèdè Naijiria pè mọ́ ìjọba àpàpọ̀.
Adajọ fẹhinti lorilẹede Naijiria, Ret.Justice Folaranmi Oloyede ti ni ijọba apapọ ko bọwọ fun eto idajọ orilẹede Naijiria to ba ilana ati ofin mu.
Adajọ oloyede nigba to n ba BBC sọrọ, wi pe Ajọ to n bojuto eto idajọ lorilẹede Naijiria (National Judicial Council) nikan lo lasẹ lati parọwa si Aarẹ orilẹede Naijiria lati kowe lọ gbe ile rẹ abi ki o lọ rọkun nile fun Adajo Agba lẹyin ti wọn ba ti se iwadii to fihan pe, o jẹbi ẹsun iwa ibajẹ.
Oríṣun àwòrán, Twitter
O fikun wi pe, NJC lo ma a fi lẹta ransẹ si ile ẹjọ to n gbọ ẹjọ iwa ibajẹ,Code of Conduct Tribunal lati le se iwadii ẹsun ti wọn fi kan an.
Lẹyin naa ni Aarẹ yoo gbe imọran naa lọ si Ile Igbimo Asofin Agba, nibi ti awọn asofin yoo ti dibo lati yọ Adajọ Agba naa kuro.
Adajọ fẹyinti Oloyede naa fikun wi pe, lẹyin igbesẹ wọnyii nikan ni aarẹ le yọ Adajo Agba kuro ni ipo.
Hubert Ogunde ló m'órí mi yá láti di òṣèré
Lori idajọ ti ile ẹjọ kọtẹmilọrun ti da ẹjọ ti Onnoghen pe nu, adajọ fẹyinti naa ni ile ẹjọ kotẹmilọrun ni asẹ lati da ẹjọ rẹ nu nitori wi pe Ajọ CCT naa ni asẹ lati gbọ ẹjọ rẹ.
Ile ẹjọ kotẹmilọrun ti da ẹjọ ti Adajọ Agba Walter Onnoghen pe tako ijọba apapọ.
Onnoghen pe ẹjọ lati tako igbesẹ ijọba to fi ọwọ osi juwe ile fun titi wọn yoo fi gbọ idajọ lori iwa ibajẹ ti wọn fi kan an ati lati tako ile ẹjọ to n gbẹjọ iwa ibajẹ(CCT) lati ma se gbọ ẹjọ rẹ.
Ile ẹjọ kotẹmilọrun nigba to n da ẹjọ ni dandan Adajọ Agba naa gbọdọ lọ jẹjọ iwa ibajẹ.
Ile ẹjọ naa ni Onnoghen ko ni awijare to le mu ki ile ẹjọ naa sọ wi pe ko ma se jẹjọ, nitori wi pe ko si ẹni to kọja ofin.
Day 17: Àwọn olórí tó wà ní Kwara ń ṣe fún ara wọn nìkan ni #BBCNigeria2019
Idajọ naa tumọ si wi pe ile ẹjo to n gbọ ẹsun lori iwa ibajẹ le tẹsiwaju lati gbọ ẹjọ iwa ibajẹ ti wọn fi kan Adajọ Agba Walter Onnoghen.
Ìpàdé ìtagbangba BBC Yorùbá: Gbọ̀ngàn Mapo ṣeé mú yangàn ní Ibadan
Ọjọ kan ṣosọ lo ku ti ipade ita gbangba ti BBC Yoruba ṣe agbekalẹ rẹ fun awọn oludije fun ipo gomina nipinlẹ Oyo.
Ni agogo mẹsan aarọ ọjọ Ẹti ni eto naa yoo bẹrẹ ni gbangan Ọjọgbọn Theophilus Ogunlesi nidojukọ ọgba UCH.
Ṣugbọn ẹ jẹ ki a sọrọ nipa gbangan Mapo to kalẹ si ilu Ibadan nibi ti ole ti n jare olohun.
Ipade itagbangba BBC Yoruba
Gbọngan Mapo re e to kalẹ sori oke Mapo ti wọn fi sọ orukọ rẹ nilu Ibadan. Nibi ni awọn ọmọbibi ilu ti maa n ṣepade ọrọ oṣelu, ọrọ idagbasoke ati ilọsiwaju ilu Ibadan.
Ipade itagbangba BBC Yoruba
Ẹni to ba duro lori oke Mapo, kedere ni yoo maa ri gbogbo ilu Ibadan ninu ogo rẹ.
Ipade itagbangba BBC Yoruba
Awọn opo to di gbọngan Mapo mu lo n ṣe apejuwe oke meje to yi ilu Ibadan ka. Gbogbo oke yii ni wọn si mọ opo si.
Ipade ita gbangba BBC Yoruba
Tabili yii ni wọn maa n tẹ awọn oku Olubadan to ba ti waja si ki gbogbo ara ilu le rii.
Ipade Itagbangba BBC Yoruba
Gbọngan Mapo tobi gan, bẹẹ lo laye daadaa lati gba ọpọlọpọ eeyan. Nibayii gbogbo eto lo ti wa ni ṣẹpẹ bayi ṣaaju ipade itagbangba BBC Yoruba lọjọ Ẹti, ẹ jẹki a jọ pade nibẹ lọla.
2019 Elections: Ṣoyinka ní irú kan náà ni Buhari àti Atiku
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Idibo aarẹ Naijiria
Ọkan ko gbe kan bi owu jango ni Aarẹ Muhammadu Buhari ati oludije aarẹ fẹgbẹ oṣelu PDP Atiku Abubakar, bẹẹ ni ko si ẹni to yẹ fun aarẹ orilẹede Naijira ninu idibo to n bọ, Ọjọgbọn Wole Ṣoyinka lo sọ bẹẹ.
Ọpọ lo kọkọ ro pe Aarẹ Buhari ni Ọjọgbọn Ṣoyinka n ṣe atilẹyin fun nigba ti o bu ẹnu atẹ lu bi aarẹ ana Oluṣegun Obasanjo ti kede atilẹyin rẹ loṣu to lọ fun Atiku.
Ṣugbọn Ọjọgbọn naa ya ọpọ eeyan lẹnu nigba ti o sọ oju abẹ niko l'Ọjọru nilu Eko nibi to ti fidi rẹ mulẹ pe asiko ti to fawọn ọmọ Naijiria lati wa olori miiran yatọ si Buhari ati Atiku.
Ìpínlẹ̀ Oyo gbàlejò ìpàdé ìfọ̀rọ̀wérọ̀ BBC Yorùbá
Ṣoyinka ṣalaye pe oun gẹgẹ bi ẹnikan, ko ni dibo fun Buhari ati Atiku ninu ibo to n bọ nitori kosi ẹni to yẹ lati dibo fun ninu awọn mejeeji.
Ọjọgbọn naa oun ṣetan lati dibo bi oludije miiran to yatọ si awọn mejeeji ba yọju, bakan naa ni o ṣalaye pe ipade n lọ nilu Eko ati Abuja lori bi oludije miiran yoo ṣe jade.
Ṣoyinka fi kun ọrọ rẹ pe asiko ti to fawọn ọmọ Naijiria lati yọ ara wọn loko ẹru awọn oloṣelu to ti pẹ.
BBC Gov Debates: Ìṣẹ̀lẹ̀ mánigbàgbé níbi ìfọ̀rọ̀wérọ̀ BBC Yorùbá l'Ọyọ
ìfọ̀rọ̀wérọ̀ BBC Yorùbá
Ni kete ti oju opo facebook BBC News Yoruba ti ṣi silẹ fun akanṣe Facebook Live ipade ifọrọwerọ awọn oludije gomina ipinlẹ Ọyọ ni oniruuru eto ti a le gbadun ti bẹrẹ.
Lakọkọ, lati ibẹrẹ ni ara ọtọ eyi ti BBC Yoruba ṣe - fifi ọrọ wa awọn akopa lẹnu wo nibi iforukọ silẹ lori ki ni wọn wa ṣe ati ireti wọn latọdọ awọn oludije ti yoo kopa nibi eto naa.
Awọn akopa ko figba kan bọkan ninu idahun wọn si BBC Yoruba nitori wọn nifẹ lati mọ ẹni to ni alakalẹ gidi fun awọn araalu.
BBC Gov Debates: Ètò ẹ̀kọ́ ọ̀fẹ́ ni àwọn olùdíje yóò ṣe
ìfọ̀rọ̀wérọ̀ BBC Yorùbá
Bakan naa ṣaaju eto ni wọn wọ inu ibi igbalejo ti gbogbo awọn oludije naa wa ki eto to bẹrẹ lati bere iwoye wọn nipa ipade ifọrọwerọ yii paapaa ti yoo ko atọrẹ ati alatako pọ soju kan naa leyii to jẹ wi pe loriṣiriṣi ọna ni wọn ti fi ọ̀rọ̀ ati iṣe ta ko ara wọn tẹlẹ nitori idibo.
ìfọ̀rọ̀wérọ̀ BBC Yorùbá
Fun apẹrẹ, lasiko yii, oludije fun ẹgbẹ oṣelu APC, Adebayo Adelabu ni kò ṣe oun lara bakan bakan pe gbogbo awọn kọkọ jọ wa ninu yara kan naa tori baba, ẹgbọn ati ọrẹ ni awọn toku jẹ si oun.
Ademọla Ogunbanjo: A nílò bàbá ìsàlẹ̀ nínú òsèlú
Sẹnetọ Olufẹmi Lanlẹhin ti ẹgbẹ oṣelu ADC ṣalaye pe ireti oun nibi eto yii ni ki ijọba tiwa n tiwa ko lọ deede lai si aawọ tabi ija. Olufẹmi Lanlẹhin kan sara si ile iṣ BBC fun agbekalẹ eto. O ni ọm ipinlẹ Ọyọ ni gbogbo awọn oludije ti awọn jọ joko, ẹgbọn ati aburo si ni gbogbo awọn.
ìfọ̀rọ̀wérọ̀ BBC Yorùbá
Ni ti Ọtunba Alao Akala, o gboriyin fun BBC fun akitiyan yii lati gbe ede ati aṣa Yoruba larugẹ. O ni ko sohun to tuntun ninu pe awọn jọ joko sinu ibi kan tori gbogbo awọn lawọn m ara awn ti ko si si ija kankan laarin wọn.
Falana: Awọn to n dije dupo ìdìbò 2019 fẹ́ fa ogun si Naijiria
Lasiko ipade itagbangba nigba ti ifọrọwerọ naa bẹrẹ, awọn ọrọ kanka kanka n jẹ jade ninu awọn ọrọ ti awọn oludije sọ ti ọpọlọpọ ko si ni gbagbe.
"Alao Akala ti ẹgbẹ oṣelu ADC juwe ara rẹ gẹgẹ bi aloku ọlọpaa. ""Aloku Ọlọ́pàá ni mí nítorínáà mo mọ̀ nípa àbò dáadáa""."
ìfọ̀rọ̀wérọ̀ BBC Yorùbá l'Ọyọ
"Bakan naa, oun lo ni ""àtàrí àjànàkú ni ọ̀rọ̀ ìpínlẹ̀ Ọyọ ..., ọ̀rọ̀ ìpínlẹ̀ Ọyọ àtàrí àjànàkú ni, àgbàlagbà bíi tèmi ló nílò""."
"Oun lo kọkọ sọ wi pe iṣejọba oun yoo san N30,000 owo oṣu ti àwọn òṣìṣẹ́ n ja fun. O ni ""owó ti pọ̀ nísisìyìí ju ìgbà tí mo kọ́kọ́ wà nípò lọ"". Lẹyin naa ni atọkun bere ọrọ N30,000 yii lọwọ awọn to ku ti gbogbo wọn si ni awọn yoo san awọn."
Ọmọbọlanle Sarumi-Aliyu ko kẹrẹ rara pẹlu awọn ọrọ rẹ lati ibẹrẹ titi de opin to bẹẹ to fi jẹ wi pe bi awn kan ṣe n kan sara sii ni awn mii ni idakeji n bu ẹnu atẹ lu bi o ṣe sọrọ.
ìfọ̀rọ̀wérọ̀ BBC Yorùbá l'Ọyọ
ìfọ̀rọ̀wérọ̀ BBC Yorùbá l'Ọyọ
"Nipa eto ẹkọ o ni ""wọn kò fẹ́ kọ́mọ́ mẹ́kúnù di Dókítà"" nitori naa oun yoo mojuto eto ẹkọ. O tun fa oju awọn ọdọ ilu gan mọra, o ni ""mo fẹ́ sọ àwọn Area Boys di ọmọ mi"" o ni ki awọn ọdọ ma jẹ ki oloṣelu kankan lo wọn nilokulo mọ ti ""wọn ko si fun un yin niṣẹ tabi ki ẹ tilẹ̀ le fẹ ọmọ wọn ṣugbọn tọrọ kọbọ ni wọn fi n gun yin lọwọ bi ẹ ba ti dibo tan wọn a tun rọọ yin sẹyin"". Fun eyi, awọn eniyan roo latẹwọ waa waa."
ìfọ̀rọ̀wérọ̀ BBC Yorùbá
"O ni ""bí Ọyọ bá dán obìnrin wò, Ọyọ a dùn ún wò, kò ní sí ọ́fíìsì ọkọ gómìnà"" nitori naa, oun yoo ṣe owo ilu ti wọn ko ki n lo daadaa tẹlẹ daadaa bayii."
"Sarumi ni ""maa gba Lautech pada, maa fun ijọba ibilẹ lagbara wọn pada."
ìfọ̀rọ̀wérọ̀ BBC Yorùbá
Fun Sẹnetọ Olufẹmi Lanlẹyin, eniyan kan fi ibeere ranṣẹ wi pe baba isalẹ kan lo n pọn ọn sẹyin kiri pe bi o ba di gomina tan ṣe ko ni maa fi ti baba isalẹ yii ṣe akọkọ ninu ohun gbogbo.
O dahun pe oun ko m nipa baba isal ti wọn n sọ. O si ni ṣugbọn ọmọde gbọn agba gbọn la fi da Ile Ifẹ. Awọn ko yọ ẹnikẹni sil ninu ẹgb oṣelu oun. Pataki julọ, o ni orukọ rere ti oun ti ni lati igba ti oun ti ṣe Sẹnetọ ko ni bajẹ.
"O ni ""A o tun ile iwe awọn akanda ṣe, ọrẹ araalu ni Senator Lanlẹhin nitori naa a o ni yan ọrẹ ati ojulumọ sipo afi ara ilu. Ijọba tiyin lo maa jẹ. Baba to bi mi ṣe aṣeyọri emi naa yoo si ṣe e""."
ìfọ̀rọ̀wérọ̀ BBC Yorùbá
"Adebayo Adelabu ti  ẹgbẹ oṣelu APC ni wn bi pe bawo lo ṣe fẹ ṣee lai ni iriri kankan ri to fi fẹ bẹrẹ pẹlu jijẹ gomina. O fesi pe ""inú mi dùn pé mi o ní ìrírí nínú òṣèlú nítori òṣèlú Nàìjíríà kò ṣe é mú yangàn,"" o ni ọna ati ṣejọba gangan lo yẹ kii ṣe ka fi oṣelu wọle ka tun tẹsiwaju ninu oṣelu ti a ba de ipo. O ni ọna atiṣejọba ni wn fi kọ oun lẹkọọ kii ṣe ka kan maa ṣe oṣelu."
O ni gẹgẹ bi ẹni to ti ṣe igbakeji gomina banki ile ifowopamọ to ga ju ri nitori naa ati ṣe gomina ko le nira.
O lodi si oun ti Oloye Alao Akala sọ pe atari ajanaku ni ọrọ ipinl Ọyọ.
Fọfọ ni gbọngan ibi ipade kun fun ero latoke de isalẹ gẹgẹ bi awọn ara ipinlẹ Ọyọ ṣe wa lati kaakiri ki wọn lee mọ nipa aato awọn oludije.
ìfọ̀rọ̀wérọ̀ BBC Yorùbá l'Ọyọ
BBC Gov Debate: Àwọn olùdíje gómìnà Oyo gbà lati san 30,000N owó osù òsìsẹ́
Àwọn olùdíje gómìnà Oyo
Awon oludije mẹrin lo kopa nibi ipade itagbangba BBC News Yoruba to waye nilu Ibadan. Awọn to wa nibẹ ni, Adebayo Alao Akala ADP, Adebayo Adelabu APC, Olufemi Lanlẹhin ADC ati Bolanle Sarumi Aliyu NIP.
Lori ọrọ owo oṣu oṣiṣẹ ti wọn beere lọwọ awọn oludije, gbogbo wọn pa ẹnu pọ lati sọ pe awọn yoo san N30,000 gẹgẹ bi owo oṣu oṣisẹ to kere ju. Bakan naa, wọn mnu ba ọna ti wọn yoo gba lati ri owo ọhun san.
Ẹwẹ, nigba ti Ọtunba Alao Akala da nikan sọ pe ohun iwuri ni oṣelu Naijiria latyin wa, idakeji ni awọn oludije mẹta to ku fnu ko le lori pe oṣelu Naijiria ko ṣee mu yangan.
Lara awọn koko ọrọ mii ti wọn mẹnu ba lọlọkan ojọkan niyii.
Bolanle Sarumi-Aliyu - NIP
ìpàdé ìfọ̀rọ̀wérọ̀ BBC Yorùbá
Bolanle Sarumi ni gbogbo awon ọmọ wẹwẹ ti ọjọ ori wọn ko ju marun lọ yoo gba eto ilera ofe. Bakan naa ni awon arugbo ti ọjọ ori wọn ko din ni odun marundinlaadota yoo maa janfani eto ilera ọfẹ bi oun ba wọlé.
"O ni iru awọn ọna ti ko tọ ti awọn kan n lo lati kowo jẹ ko ni ṣi silẹ ni ijọba oun. Fun apẹrẹ, ""ko ni si ọfiisi ọkọ gomina ninu iṣejọba temi""."
Lori ọrọ abo, Sarumi ni aisi olori gidi ni kii mu ki ilu toro. O ni ko lee si abo laisi iṣẹ. O ni oun yoo ro awọn ọdọ lagbara.
ìpàdé ìfọ̀rọ̀wérọ̀ BBC Yorùbá
Pẹlu iwadii ati ibẹwo ti Akala ni awọn ṣe kaakiri wọn rii pe eto ilera ko koju osuwọn to. O sọrọ lori aṣeyọri iṣejọba rẹ akọkọ nigba to jẹ gomina ipinlẹ Ọyọ.
Nitorinaa, Akala ni agbalagba bii t'oun to ni ọpọlọpọ iriri ni ipo gomina Ọyọ tọ si lọdun 2019.
Alao Akala ni saa isejọba oun akọkọ ohun da awọn eto ilera alabode ẹsẹ kuku silẹ. O ni ni ile iwosan nla Adeoyo ko sí ẹrọ amunawa to dara. Ati pe ohun yoo ṣe agbekalẹ ilera ọfẹ.
Alao akala ni gẹgẹ bii Ọlọpaa to ti feyinti oun mọ ọna abayọ si ipenija ọrọ abo. Oun yoo ṣiṣẹ pọ pẹlu awọn agbofinro lati mu eto abo gbopọn sii.
ìpàdé ìfọ̀rọ̀wérọ̀ BBC Yorùbá
Lori ọrọ eto ilera, Adelabu ni ilera jẹ ara ohun mẹta ti iṣejọba oun la kalẹ. Awọn to ku ni iṣẹ agbe, eto ẹkọ ati ilera.
Eto ilera alabọde ni Adelabu ni awọn yoo kọ si awọn igberiko. Aisan to le koko ni wọn n gbe lọ ile iwosan ijọba tabi ti akọṣẹmọṣẹ.
Ni ti abo, o ni ohun ti ko ni jẹ ki nkan buruku sẹlẹ ni ijọba oun yoo gbajumọ. O fi kun un pe awọn yoo rii pe awọn ọdọ n kọ iṣẹ ọwọ wọn si n kopa ninu ere idaraya bọọlu
Ẹ̀yin ọmọ Yorùba, kí ló le nínú fí fí àmì sí A-la-pa-n-dẹ-dẹ?
Olufẹmi Lanlẹhin - ADC
ìpàdé ìfọ̀rọ̀wérọ̀ àwọn olùdíje gómìnà ìpínlẹ̀ Ọyọ
Lanlẹhin ni tirẹ salaye pe nitori bi ipinlẹ Ọyọ ṣe tobi kun ara ohun to n fa ipenija eto ilera. Nitori naa iṣejoba oun yoo pese ileewosan alabọde kaakiri wọọdu.
"Lanlẹhin ni lori eto abo ni ohun to n fa wahala ni ilu yoo gba amojuto nipa ipese iṣẹ. ""Ko si ẹni fẹ ṣe jagidijagan to ba ri iṣẹ ṣe."" O ni eto idaṣẹsilẹ, eto ọgbin ati ileeṣẹ kereje fun igbaniisiṣẹ."
UK, Europe, US, Canada: Ọ̀pọ̀lọ̀pọ̀ ọkọ̀ ayókẹ́lẹ́ ló ti rì sàbẹ̀ yìnyín
Oríṣun àwòrán, Press Eye
Òtútù àti yìnyín ló ti ń sọsẹ́ nílẹ̀ Europe àti Amẹrika,Canada ati Ilẹ̀ Gẹ̀ẹ́sì lo faragba ninu otutu yii.
O kere tan eniyan mọkanlelogun lo ti gbe ẹmi mi latari otutu ati yinyin arọọrọda, iru eleyi ti wọn ko ti ri ri lati bi ogun ọdun sẹhin to gbalẹ kan ni ilẹ Amerika.
Ile iwosan kaakiri ni wọn ti n toju awọn ti otutu ati yinyin ti fa aisan si lara bayii.
Tani otutu ma n mu ju laarin Ọkunrin ati Obinrin?
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Bakan naa, ni Ilẹ Gẹẹsi, ni se ni yinyin bo gbogbo ọkọ ayọkẹlẹ, ti ko si ẹni ti o le jade sita ju igba diẹ lọ.
Oju ọjọ naa ti fa ki wọn da ọkọ ofurufu duro lati ma se isẹ, bẹẹ si ni wọn ti ọgọọrọ ile iwe pa, eleyii ti o dina awọn eniyan lati ma le e lọ lati ibi kan si ibomiran.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Iroyin ni ọsẹẹsẹ ki otutu yii posi, nitori idinwọn fun bi oju ọjọ yoo se ri fihan wi pe, yoo ma tutu si ni lasiko ti awa yii.
Lagos City Marathon: Sintayehu Legese láti Ethiopia ló jáwé olúborí
Oríṣun àwòrán, TWITTER/MYACCESSBANK
Ẹni tó jáwé olúborí lọ́dún tó kọjá,Joshuna Kipkorir ló se ipò kejì ní ipele àwọn okùrin láti ilẹ̀ Ethiopia.
Ọmọ ilẹ Ethiopia, Sintayehu Legese lo jawe olubori ninu idije ipinlẹ Eko, Lagos City Marathon pẹlu ẹbun owo $50,000.
Wakati meji, o le isẹju mẹtadinlogun ni ẹni to gbe igba oroke naa lo lati fi sare lati papa isere ti Surulere de Eko Atlantic City.
Bakan naa, Ọmọ Naijiria to kọkọ kọja ori ila, Gideon Goyet yoo gba miliọnu mẹta naira lọ si ile, nigba ti ẹni keji ati ẹni kẹta to jẹ ọmọ Naijiria to kọkọ de ori ila naa yoo gba miliọnu meji ati miliọnu kan lọ sile.
Ẹni to jawe olubori lọdun to kọja, Joshuna Kipkorir lo se ipo keji ni ipele awọn ọkunrin lati ilẹ Ethiopia.
Obinrin akọkọ to kọkọ kọja ori ila ni Meleka Meseret Dinke lati ilẹ Ethiopia bakan naa.
ASUU Strike: Ìpàdé láàárín ẹgbẹ́ olùkọ́ fásitì àti ìjọba jásí pàbó!
Oríṣun àwòrán, FEDERAL MINISTRY OF LABOUR
Láti Ọjọ́ Kẹ́rin, Osù Kọkànlá, ọdún 2018 ni àwọn olùkọ́ fásitì náà tí bẹ̀rẹ̀ ìyansẹ́lódì lórí ìwà àìbíkítà sí ìsòro àwọn.
Ipade to waye laaarin ijọba apapọ ati awọn adari ẹgbẹ awọn oluko fasiti ASUU ti fori sanpọn.
Asoju ijọba ati ẹgbẹ ASUU to ba awọn oniroyin sọrọ lẹyin ipade naa sọ wi pe wọn ti sun ipade si waju di Ọjọ Keje, Osu Keji, ọdun 2019.
Ijọba apapọ ni awọn ko ni aadọta miliọnu naira ti awọn fẹ san bayii, amọ aarẹ ẹgbẹ ASUU ni awọn yoo lọ ba awọn eniyan awọn sọrọ ṣaaju ọjọ ti wọn sun ipade si.
Báwo ni àwọn olùdíje Oyo ṣe fẹ́ kojú ìṣòro ìlera?
Ipade kẹsan niyii ti ẹgbẹ olukọ fasiti ASUU n se pẹlu Minisita fun ọrọ osisẹ ati igbanisisẹ, Chris Ngige lati bii oṣu mẹta.
Lati Ọjọ Kẹrin, Osu Kọkanla, ọdun 2018 ni awọn oṣisẹ fasiti naa ti bẹrẹ iyansẹlodi lori iwa aibikita si ipo ti ile ẹkọ giga wa lorilẹede Naijiria, ti wọn si n bere fun ki ijọba tun awọn ile ẹkọ giga ṣe pẹlu awọn ohun eto ẹkọ ti igbalode.
Komla Dumor Award 2019: BBC ń wa ìràwọ̀-oníròyìn tó ṣẹ̀ ń dide l'Áfíríkà
Ile iṣẹ BBC fẹ ki o kopa ninu ami ẹyẹ 2019 BBC World News Komla Dumor
Ileeṣẹ BBC n wa awọn irawọ to ṣẹṣẹ n dide ninu iṣẹ iroyin nilẹ Afrika fun ami ẹyẹ 'Komla Dumor' tileeṣẹ BBC lagbaye ní igba ikarun un.
Awọn akọroyin jakejado ilẹ Afrika ni wọn n pe lati kopa ninu ami ẹyẹ yii, eyi ti afojusun rẹ wa lati sawari ati agbelarugẹ awọn irawọ tuntun latilẹ Afrika.
Ẹni to ba yege yoo lo osu mẹta ni olu ileesẹ BBC nilu London, yoo ni ọpọ imọ kikun ati iriri.
Deede aago mejila ku isẹju kan loru ọjọ kẹtalelogun, osu kẹta, ọdun 2018 ni ikọwe beere lati kopa ninu ami ẹyẹ naa yoo wa sopin.
Wọn gbe ami ẹyẹ naa kalẹ lati bu ọla fun Komla Dumor, gbajugbaja agbohunsafẹfẹ to dantọ lati orilẹ-ede Ghana.
O tun jẹ oniroyin fun ikanni iroyin BBC lagbaye. Lojiji lo dagbere faye lọdun 2014 lẹni ọdun mọkanlelogoji.
Ilu Eko ni orilẹ-ede Naijiria ni wọn ti n sefilọlẹ ami ẹyẹ tọdun yii.
Oríṣun àwòrán, Joshua Wanyama
Akọ̀ròyìn Kenya to gba tọdun 2018
Ẹni ti yoo jawe olubori fun ami ẹyẹ yii gbudọ jẹ ẹni to tayọ, ti o n gbe ni ọkọkan ninu awọn orilẹ-ede Afrika.
O si tun gbọdọ maa sisẹ nilẹ Afrika, o ni lati ni ọgbọn atinuda fun isẹ akọroyin papọ mọ ẹbun to tayọ lori afẹfẹ ati ẹbun to pegede ninu sisọ awọn itan to jẹ mọ tilẹ Afrika pẹlu ilakaka ati aayan lati di irawọ ọjọ ọla.
Waihiga Mwaura ti Kenya gba àmì ẹ̀yẹ Komlar Dumor
Yatọ si pe ẹni to ba yege lati gba ami ẹyẹ naa yoo lọ lo akoko kan ni olu ile iṣẹ BBC nilu London, bakan naa ni onitọun yoo tun se abẹwo si Afrika lati kọ iroyin-ti wọn yoo si se alabapin iroyin naa jakejado ilẹ Afrika ati lagbaye.
2015: Nancy Kacungira lati orilẹ-ede Uganda,
2016: Didi Akinyẹlurẹ lati orilẹ-ede Naijiria,
2017: Amina Yuguda lati orilẹ-ede Naijiria,
2018: Waihiga Mwaura lati orilẹ-ede Kenya.
Akọroyin ọmọ orilẹ-ede Kenya, Waihiga Mwaura lo jawe olubori lọdun to kọja o si jabọ iroyin lati ilẹ Togo nipa awọn ọjẹ wẹwẹ to n sọ akisa di ohun to wulo.
Waihiga ni eniyan yoo mọ iru itara ti Komla maa fi n sọ itan Afirika.
Waihiga yoo kopa ninu eto ifilọlẹ ti ọdun 2019 ti yoo si ṣe atọkun lara awọn ipade ita gbangba ile iṣ BBC lagbaye nipa agbara awọn ọdọ Naijiria ninu idibo to m bọ.
Nigba to n sọrọ nibi eto ifilọlẹ naa, Jamie Angus to jẹ oludari apapọ ile iṣẹ BBC lagbaye sọ pe:
"Ninu saa yi ti kikọ iroyin otitọ to si ṣee di mu ko fi bẹẹ fẹsẹ mulẹ, o ṣe pataki lati wo awọn oniroyin to ni imọ to si le ṣalaye itan Afirika faye gbọ ki a le ni imọ kikun nipa ohun to n ṣẹlẹ kaakiri ẹkun naa.
Gbogbo awọn to jawe olubori sẹyin lo ti fi didantọ wọn han ninu iṣẹ iroyin, wọn si ti ni imọ sii nipa ṣiṣe iroyin lẹsẹ kuku."
Ori wa wu lati tẹsiwaju ninu titọ ipasẹ ọna ti Komla la kalẹ. a si n wa oniroyin miiran to dangajia lati ẹkun Afirika.
Yemi Osinbajo: Fídíò tó ṣàfihàn bí ìjàmbá bàálù rẹ̀ ṣe wáyé
Oríṣun àwòrán, Twitter/@akandeoj
Baalu naa lẹyin to ja lulẹ.
Ẹgbẹ oṣelu All Progressives Congress, APC ti fi fidio kan sita, ti wọn fi ṣapejuwe bi ijamba baalu to ṣẹlẹ si Igbakeji aarẹ, Yẹmi Ọṣinbajo ṣe waye lọjọ Abamẹta, ọjọ keji, oṣu keji.
Ni ọsan ọj Abamẹta ni iroyin jade pe Ọṣinbajo ni ijamba lasiko to n lọ si ilu Kabba, ni ipinlẹ Kogi fun ipolongo ibo oun ati Aarẹ Muhammadu Buhari.
Botilẹjẹ wi pe ori ko Ọṣinbajo atawọn to wa ninu baalu naa yọ, ọpọlọpọ ọmọ Naijiria ti ba kẹdun, ti wọn si n ba dupẹ lọwọ Ọlrun fun idasi ẹmi rẹ.
Amọ ṣa, oludije fun ipo aarẹ ninu ẹgbẹ oṣelu alatako, PDP, Atiku Abubakar ti ki Ọṣinbajo ku oriire fun bi ori ṣe ko o yọ ninu ijamba baalu lọjọ Abamẹta.
Ninu ọrọ tiẹ, Aarẹ ile aṣofin agba, Bukọla Saraki naa fogo fun Ọlọrun fun igbeaye Igbakeji Aarẹ.
"O ni ''Mo darapọ mọ gbogbo ọmọ Naijiria lati dupẹ lọwọ Ọlọrun to da ẹmi Igbakeji Aarẹ, Yẹmi Ọṣinbajo si, to mu kori ko o yọ̀ ninu ijamba baalu ni Kabba loni."""
Bakan naa ni akẹgbẹ rẹ nile aṣofin kekere, Yakubu Dogara to ba Ọṣinbajo yọ, sọ pe ki awọn alaṣẹ to n mojuto awọn ọkọ ofurufu ijọba maa ṣe ayẹwo wọn daada lati ri daju pe iru iṣẹlẹ bayi ko waye mọ.
Ninu ọrọ tiẹ, Gomina tẹlẹ ni ipinlẹ Ekiti, Ayọdele Fayoṣe, sọ pe ''Mo ba Igbakeji Aarẹ yọ, mo si dupẹ lọwọ Ọlọrun fun pe o da ẹmi rẹ si. Mo gbadura pe ọgbẹ yowu to ba ni yoo tete san.
Ni iwoye temi o, ọrọ ẹmi lagbara ju oṣelu lọ, mo si gbadura pe ki Ọlọrun tubọ maa da ẹmi rẹ si.''
Yatọ si awọn oloṣelu, awọn ọmọ Naijiria naa n ba igbakeji aarẹ yọ fun idasi ẹmi rẹ.
"Amọ ṣa, atẹjade kan ti ọọfisi Igbakeji Aarẹ fi sita, Ọṣinbajo dupẹ lọwọ gbogbo ọmọ Naijiria to ba a dawọ idunnu, o si fi da wọn loju pe alaafia ni oun ati awọn to wa ninu baalu to ja ọhun wa."""
Ati pe ''Ọlọrun gba wa lọwọ iku, ki a le raaye ṣe ọpọ nkan fun awọn eniyan wa ati orilẹede yii.''
Nigeria 2019 Elections: Àna Awolowo, ọ̀jọ̀gbọ́n lẹ́ni ogójì ọdún àti àwọn ǹkan mìíran tí ẹ kò mọ̀ nípa Osinbajo
Oríṣun àwòrán, Profosinbajo/Instagram
Ki ti ẹ̀ ni àwọn oun tí ẹ mọ̀ nípa ayé ọ̀jọ̀gbọ́n Yemi Osinbajo tó ń díje dupò fún sáà kejì gẹ́gẹ́ bíi amúgbálẹ́gbẹ̀ẹ́ Ààrẹ Muhammadu Buhari?
Ọlọ́run dóólà ẹ̀mí rẹ̀ ọjọ́ Abamẹ́ta níbi to ti lọ ṣe ìpolongo ìbò ní Kabba, Ìpínlẹ̀ Kogi.
Ṣe ni ọkọ̀ rẹ̀ dojú dé nígbà tí ó fẹ́ gbéra, ṣugbọ́n ko fi ara pa rárá, èyí tí àwọn ènìyàn fi ríi gẹ́gẹ́ bí ènìyàn ọ̀tọ̀.
Àwọn ǹkan méje tí ẹ lè má ràntí nípa ayé rẹ̀ rèé:
1. Ọmọ ọdún nmẹ́tàlélógún ló di olùkọ́ni ní fásitì
Ọdún 1957 ni a bí Oluyemi Oluleke Osinbajo nílé ìwòsàn kan nílùú Eko tí ó sì bẹ̀rẹ̀ ilé ìwé nígbà tó pé ọmọ ọdún méjìla ní 1969 ní ilé ìwé àkọ̀bẹ̀rẹ̀ Corona nílùú Eko. Ó tẹ̀ síwájú lọ ilé ìwé girama Igbobi to wa ni Yaba nibi to ti gba ọpọlọpọ àwọn ẹ̀bùn fún orípípé.
Ó ló fásitì Eko, ó sì kẹ́kọ̀ọ́ gboyè ìmọ̀ òfin ní  ọdún 1978 nígbà tó wà ní ọmọ ọdún mọ̀kànlélógún. Ọdún méjì lẹ́yìn rẹ̀, wọ́n gbàá gẹ́gẹ́bíi olùkọ̀ nílé ìwé náà lẹ́yìn tó ti gbóye àgbà ni London School of Economics.
Oríṣun àwòrán, Profosinbajo/Instagram
Oṣinbajo fẹ Dolapo Soyọde, ọkan lára àwọn ọmọọmọ Oloye Obafẹmi Awolọwọ ọkan lara awọn agbaagba ilẹ Yoruba. Iya Dolapo ni ọmọbinrin Awolọwọ to ti ṣe alaisi, Ayo Soyode, ẹgbọn Tokunbo Awolowo Dosunmu.
Ita fi han wípé, nígbà tí Osinbajo wa ni ọmọ ọwọ, Awolọwọ gbọ́wọ́ lée lórí tó sì gbádúrà fun nígba tó pàdé àwọn òní rẹ̀.
Oríṣun àwòrán, Profosinbajo/Instagram
Láàrin ọdún 1988 sí ọdun 1992, Amòfin Àgbà orílẹ̀èdè Naijiria nígbà náà Bola Ajibola yàn án gẹ́gẹ́ bíi olùrànlọ́wọ́. Ibẹ̀ ló ti kọ́kọ́ rí ìtọ́wò ọ̀rọ̀ òṣèlú.
4. Ó di ọ̀jọ̀gbọ́n nígbà tó wà ní ẹni ogójì ọdún
Ní ọdún 1997, Osinbajo di ọjọ ní fásiti Eko ní ẹ̀ka imọ̀ òfin ti ìlú.
Oríṣun àwòrán, Profosinbajo/Instagram
Lẹ́yin ọdun méjì ti di ọ̀jọ̀gbọ́n ni Gomina Ipinlẹ Eko nígba náà Bola Tinubu sọ́ di amòfin àgbà àti kómọíṣọ́nà fún ìdájọ́ láàrin ọdiun 1999 sí ọdún 2007.
Bó ṣe kúrò ní ipò yìí ló padà sí ipò rẹ̀ gẹ́gẹ́ bíi ọ̀jọ̀gbọ́n onímọ̀ nípa ofin ìlú ní fásitì Eko.
Ní ọdún 2007 tó kùrò nínú ipòi òṣèlú ni Ilé Iṣẹ́ àwọn amòfin Simmons Cooper Partners sọ́ di ọ̀gá.
Oríṣun àwòrán, Profosinbajo/Instagram
Kí Osinbajo to di igbákeji ààrẹ ní ọdún 2015, oun ni àlùfáà olórí ijọ Redeemed (RCCG) kan tó wà ní Ikoyi. O máa ń sọ wípé òun ṣì ni olórí ìjọ náà àti wípé ìjọba àpapọ̀ yá òun lò ni.
Oríṣun àwòrán, Profosinbajo/Instagram
Festus keyamo: Ọ̀rọ̀ Obasanjọ sí Buhari ti di ìrégbè
Ààrẹ Gani Adams: Olùdíje tó bá ṣetán lórí àtúntò ìlànà ìṣèjọba ni Yorùbá yóò dìbò fún
Gani Adams ní pẹ̀lú bí nǹkan ṣe rí báyìí àtúntò ìlànà ìṣèjọba ti di pàtàkì fún ìlọsíwájú Nàìjíríà
Aarẹ Ọna kakanfi ilẹ Yoruba, Iba Gani Adams ti ṣalaye wi pe irufẹ aarẹ ti ilẹ Yoruba yoo dibo fun ni eyikeyi ninu awọn oludije fun ipo aarẹ to ba ṣetan lati mu atunto ilana iṣejọba (Restructuring) lọkunkundun.
Iba Gani Adams ni ohun to n ṣẹlẹ lẹnu oṣelu ati iṣejọba lorilẹede Naijiria bayii fihan pe pataki ni atunto ilana iṣejọba ki gbogbo ẹya ati ede lee tubọ ni ipin to yẹ ninu eto Naijiria gbogbo.
Ọ̀nà tí àwọn olùdíje ipò gómínà ní Ìpínlẹ̀ Ọyọ fẹ̀ gbà yànjú ọ̀rọ̀ ààbò rèé
"Ninu ọrọ to ba BBC News Yoruba sọ, Iba Gani Adams ni oun ko lee sọ pe oloṣelu bayii ni yoo ṣe daradara tabi omiran ṣugbọn ""ohun kan ti mo lee sọ ni pe eyikeyi ninu wọn to ba daju pe yoo ṣe atunto ilana iṣejsba ni ki Yoruba dibo fun."""
Awọn ẹgbẹ ọmọbibi Yoruba bii Afẹnifẹre ati ẹgbẹ agba Yoruba ni wọn ti pin lori oludije ipo aarẹ ti ilẹ Yoruba yoo tẹle. Bi Afẹnifẹre ṣe n sọ pe Atiku lawọn yoo tẹle ni ẹgbẹ agb Yoruba pẹlu n fi atilẹyin wọn han fun Aarẹ Buhari.
Iba Gani Adams ni lootọ ipo oun gẹgẹ bii aarẹ ilẹ Yoruba ko faye oṣelu silẹ, sibẹ ohun ti yoo san ilẹ Yoruba ati awọn eeyan rẹ ni oun yoo maa le lẹka ọmọniyan gbogbo.
2019 elections: INEC ní káàdì ìdìbò 15,000 táwọn ọ̀daran jó ní iléeṣẹ́ INEC kò leè dáwọ́ ìdìbò dúró
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ìwé orúkọ olùdìbò àti káàdì ìdìbò ni wọ́n jó ní iléeṣẹ́ àjọ INEC kan ní ìpínlẹ̀ Abia.
Awọn eeyan kan ti dana sun ọpọlọpọ kaadi idibo to to ẹgbẹrun marundinlogun ni iye nileeṣẹ ajọ INEC to wa ni ipinlẹ Abia.
Gẹgẹ bii awọn alaṣẹ ajọ eleto idibo INEC lagbegbe naa ṣe sọ, awọn kaadi idibo ti wọn dana sun naa ni awọn ti o ku ti awọn oludibo to ni wọn ko tii wa gba.
Ààrẹ ní kí wọ́n wádìí oun tó fa ìjàmbá bààlú Osinbajo
Ààrẹ Gani Adams sọ ẹni tí Yorùbá yóò dìbò fún ní ọdun 2019 #BBCNigeria2019
Àkójọpọ̀ àwòrán láti ìpàdé ìtagbangba pẹ̀lú àwọn olùdije ní Ọyọ
Iṣẹlẹ yii waye ni owurọ ọjọ aiku.
Bakan naa lawọn leṣebi-leṣeka ẹda naa tun dana sun iwe orukọ awọn oludibo nibẹ.
Oríṣun àwòrán, INEC
INEC ni ko sibẹru nitori iṣẹlẹ naa
Kọmiṣọna feto idibo nipinlẹ Abia, Joseph Iloh fi idi iṣẹlẹ naa mulẹ fawọn oniroyin lọjọ aiku. O ni oju ferese lawọn omiṣẹ ibi naa gba wọle.
O ni lootọ awọn eeyan yii jo iwe orukọ ati kaadi idibo awọn oludibo nibẹ ṣugbọn ojulowo iwe orukọ oludibo wa ni olu ileeṣẹ ajọ naa to wa ni ilu Umuahia.
Nibayii naa, awọn ọlọpaa ti bẹrẹ iwadii lori awọn to wa nidi iṣẹ ibi naa.
Ọ̀nà tí àwọn olùdíje ipò gómínà ní Ìpínlẹ̀ Ọyọ fẹ̀ gbà yànjú ọ̀rọ̀ ààbò rèé
Lagos Impeachment: Tinubu parí aáws Ambode àtàwọn aṣòfin ìpínlẹ̀ Eko
Ó ti tó bí ọ̀sẹ̀ díẹ̀ báyìí tí awuyewuye láàárín gómìnà Ambọde àtàwọn aṣòfin ìpínlẹ̀ Eko ti ń jà rànyìnrànyìn ní ìgboro
O ṣeeṣe ki gbun-gbun-gbun to wa laaarin gomina ipinlẹ Eko, Akinwunmi Ambọde atawọn aṣofin ipinlẹ Eko, eleyi to ti n mu ariwo iyọnipo gomina naa kari aye o pari bayii lẹyin ti aṣiwaju ẹgbẹ oṣelu APC lorilẹede Naijiria, Bọla Tinubu da sii.
Nibi ipade kan eyi ti gomina ipinlẹ Eko tẹlẹ naa ṣe pẹlawọn aṣofin naa ati gomina Ambọde pẹlawọn eekan ẹgbẹ oṣẹlu APC nipinlẹ Eko, GAC ni iroyin sọ pe wọn ti yanju aawọ naa.
Ninu ọrọ to ba awọn oniroyin ss lẹyin ipade naa, Tinubu ṣalaye pe, 'loots ni edeaiyede ti n waye laarin ẹka iṣejọba mejeeji yii lati nnkan bii ọsẹ kan bayii.
"A gbe ẹdun ọkan igun mejeeji yi yẹwo. Gẹgẹ bii aṣiwaju, a tun gbe awọn agbegbe ti o yẹ ki awọn mejeeji o ti bu omi suuru mu. Lọna ati gbe eto iṣejsba ro, a ni lati ṣe ohun gbogbo to tọ.
Ko si ohun to jọ yiyọ ẹnikẹni nipo. O yẹ ki ibaraẹnisọrọ to loorin o wa gẹgẹ bii ara eroja eto iṣejọba tiwa-n-tiwa."
Tinubu ni ko sọrọ mọ lori yiyọ Ambọde nipo
Lara awọn to wa nibi ipade naa ni Tinubu, aṣiwaju ẹgbẹ oṣelu APC lẹkun aringbungbun ipinlẹ Eko, Ọmọba Tajudeen Olusi, Gomina Ambode, Igbakeji rẹ, Adebule, olori ile aṣofin ipinlẹ Eko Mudashiru Obasa, ati igbakeji rẹ, Wasiu Esinlokun.
Bakan naa ni oludije fun ipo gomina lẹgbẹ Oṣelu APC nipinlẹ Eko Babajide Sanwo-Olu ati igbakeji rẹ, Fẹmi Hamzat naa wa nibẹ pẹlu.
SERAP gbé Fashola lọ sílé ẹjọ́ nítorí ìpèsè iná mànàmáná
Oríṣun àwòrán, @lagosstategov
Ofin ọfẹ lohun, FOI ni SERAP n lo lati fi pe Fashola lẹjọ
Ẹgbẹ ajafẹtọ kan, SERAP ti gbe minisita fun ipese ina ọba, iṣẹ ode ati ile gbigbe, Raji Fashọla lọ si ile ẹjọ lori ẹsun pe o kuna lati daruks awọn ileeṣẹ agbaṣẹṣe to ni o gba owo iṣẹ ipese ina manamana lọwọ ijọba lai ṣe iṣẹ naa.
Ajọ naa n fẹ ki ile ẹjọ giga apapọ to wa ni Ikoyi, nipinlẹ Eko o kan an nipa fun minisita Fashọla lati gbe orukọ ati awọn ẹkunrẹrẹ iroyin nipa awọn ileeṣẹ tọrọ kan jade.
Tinubu parí aáwọ̀ Ambode àtàwọn aṣòfin ìpínlẹ̀ Eko #BBCNigeria2019
Ààrẹ Gani Adams sọ ẹni tí Yorùbá yóò dìbò fún ní ọdun 2019 #BBCNigeria2019
Ipẹjọ naa ko ṣẹyin igbesẹ ajọ ọhun lati lo ofin ọfẹ lohun (FOI) labẹ eyi ti wọn ti fun Fashọla ni gbedeke ọjọ mẹrinla lati fi orukọ naa sita  bẹrẹ lati ọjọ kẹrin oṣu kini ọdun 2019.
Oríṣun àwòrán, @lagosstategov
SERAP ní kò yẹ kí mínísítà fún iná ọba ó ṣe orúkọ àwọn kọngílá tó gbowó láì ṣiṣẹ́ ìpèsè iná ọba lóòkú òru
Ajs naa ni bi minisita naa ba lee daruks awọn ileeṣẹ naa si gbangba, yoo mu ko di iṣoro fun wọn lati ko owo naa jẹ.
Bi Fashọla ba lee daruks wọn, awọn sms orilẹede Naijiria yoo lee so wọn mu fun gbigbe owo ilu to yẹ fun akanṣe iṣẹ lori ipese ina manamana sa lọ.
Ọ̀nà tí àwọn olùdíje ipò gómínà ní Ìpínlẹ̀ Ọyọ fẹ̀ gbà yànjú ọ̀rọ̀ ààbò rèé
#BBCRepDebate: Ìjíròrò náà fáwọn olùdìbò l‘Eko ní ànfàni láti bèèrè ohun tó jẹ wọ́n lógún
Awon oludije Ile igbimọ asoju sofin Eti Osa
Onírúurú ìlérí ní àwọn tó ń dije dupò nílè ìgbìmọ̀ aṣojú sòfin fún ẹkun Eti Osa ti ṣe fún àwọn olùdibò níbi ìpàdè ìtagbangba tí BBC sagbátẹrù rẹ̀ pẹ̀lú ìfọwọ́sowọpọ̀  Media Room Hub àti Pulse Nigeria.
Awọn oludíje márùn-ún tó péju síbẹ̀ ní Olubankole Wellington (Banky W) láti ẹgbẹ́ òṣèlú Modern Democratic Party (MDP).
#BBCRepDebate: Ìjíròrò náà fáwọn olùdìbò l'Eko ní ànfàni láti bèèrè ohun tó jẹ wọ́n lógún
Awọn yoku ni Ibrahim Obanikoro lábẹ́ àsíá ẹgbẹ́ All Progressives Party (APC), Tessy Owolabi tí ẹgbẹ́ òṣèlú Social Democratic Party (SDP) ati Omotesho Tony Bakare ti People's Democratic Party.
Ọ̀rọ̀ ẹkún omi Eti Ọsa ló jẹwa lógun - Àwọn olùdíje aṣojú-sòfin
Bakan naa ni Ferdinand Ladi Adimefe tí ẹgbẹ òṣèlú Alliance for New Nigeria (ANN) ko gbẹyin nibẹ.
Nínú ìfọ̀rọ̀jomitoro ọ̀rọ̀ tó wáye fún bii wákàti méji, gbogbo àwọn olùdíje ló sàlaàyé pé, ohun tó jẹ àwọn lógun jùlọ ní láti móju tó ọrọ̀ ẹ̀kún omíyale àgbàrá ya ṣọ́ọ̀bù tó ń da àwọn ènìyàn etí ọsà láàmú láti ọjọ́ pípẹ́ wá.
Adimefe ti ẹgbẹ́ òṣèlú ANN sàlàyé pé òhun yóò kọ́kọ́ ṣe àgbékalẹ̀ ọ̀ná táwọn ọ̀dọ̀ yóò gbà ni ìmọ̀, lẹ́yìn èyí ni wọn yóò wá pèsè irinṣẹ́ ti wọn yoo lọ.
Bakan náà, lori ọ̀rọ̀ àwọn ọ̀dọ́ tí kò níṣẹ́ lọ́wọ́, Adimefe ti ẹgbẹ́ òṣèlú ANN sàlàyé pé, òun yóò kọ́kọ́ ṣe àgbékalẹ̀ ọ̀ná táwọn ọ̀dọ̀ yóò gbà ni ìmọ̀ lẹ́yìn èyí ni wọn yóò wá pèsè irinṣẹ́ ti wọn yoo lo.
#BBCRepDebate: Ìjíròrò náà fáwọn olùdìbò l'Eko ní ànfàni láti bèèrè ohun tó jẹ wọ́n lógún
'A ni òfin púpọ̀ ní Naijiria ṣùgbọ́n a kò bọ́wọ́ fún un ni'
Ní ti Obanikoro, ti ẹgbẹ́ òṣèlú APC, ó ni ohun tó ṣe patàkì jùlọ ni láti tẹti sílẹ̀ fún ohun ti àwọn ènìyàn fẹ, èyí ni yóò sọ ohun ti àwọn yóò ṣe, tí ètò amúludùn kò sì ni wọn ni agbegbe Eti Osa.
Ọ̀rọ̀ ẹkún omi Eti Ọsa ló jẹwa lógun - Àwọn olùdíje aṣojú-sòfin
Ogbẹni Bakare ti ẹgbẹ́ òṣèlú PDP ní ó ṣe pàtàkì láti jẹ aṣojú tòótọ, èyí ni yóò fún àwọn ènìyàn àti láti le dúna dúrà pẹ̀lú wọn.
Ètò ijiroro náà fún àwọn olùdìbò ní ànfàni láti bèèrè ohun to jẹ wọn logun lọ́wọ́ awọn oludije to n gbero lati lọ soju wọn nile asoju-sofin ilẹ wa.
Nigeria election 2019: Ipa tí àwọn bàbá ìsàlẹ̀ ń kó nínú ètò òṣèlú rèé
Baba isalẹ oṣelu Naijiria
Baba isalẹ ninu eto oṣelu orilẹ-ede Naijiria kii saaba dije fun ipo oṣelu fun rara wọn.
Ọpọ gbagbọ pe awọn gan an ni wọn maa n ṣagbatẹru awọn ti yoo wọle ibo ati wọn ti yoo kùnà nigba idibo.
Bi idibo gbogboogbo ọdun 2019 ti n kan lẹkun, awọn baba isalẹ yii ni wọn maa gbowo kalẹ lati ṣatilẹyin fun awọn oludije idibo ti wọn ba fa kalẹ.
Awọn eeyan tun gbagbọ pe awọn ti wọn ba fa kalẹ yii kii saba jẹ agbaọjẹ oloṣelu, ṣugbọn wọn maa n di ipo oṣelu mu lati sanjọ fawọn baba isalẹ to ba fa wọn kalẹ to ba ya.
'A ni òfin púpọ̀ ní Naijiria ṣùgbọ́n a kò bọ́wọ́ fún un ni'
Eleyi ni olukọ agba ni ẹka eto ẹkọ oṣelu nile iwe giga fasiti ilu Eko Ọmọwe Dele Ashiru n pe ni baba isalẹ ninu oṣelu.
O sọ ninu ọrọ rẹ pe ko si ohun ti awọn baba isalẹ yii ko le ṣe lati ri i pe ẹni ti wọn fa kalẹ wọle.
O fikun ọrọ rẹ pe lọpọ igba awọn baba isalẹ yii maa n jẹ oloṣelu to di ipo kan tabi omiran mu.
Ni apa gusu orilẹ-ede Naijiria ni nipinlẹ Akwa Ibom, ọpọ lo gbagbọ pe Ọgbẹni Godswill Akpbio ni baba isalẹ oṣelu ipinlẹ naa, Akpabio jẹ ọmọ ile igbimọ aṣofin agba l'Abuja.
ọrọ oṣelu Naijiria
Gomina Ipinlẹ Akwa Ibom tẹlẹ ri Akpabio si tun lẹnu ninu eto oselu ipinlẹ naa bo tilẹ jẹ pe o jẹ sẹnẹtọ lọwọlọwọ.
Bi Akpabio ṣe fi ẹgbẹ osẹlu PDP silẹ darapọ mọ APC laipẹ yii tiẹ jẹki ọpọ ro pe APC le jawe olubori ninu eto idibo to n bọ nipinlẹ naa fun igba akọkọ lati igba ti Naijiria ti pada si ijọbo awa ara wa.
Ẹwẹ, sẹnẹtọ Akpabio fun ra rẹ sọ pe oun kii ṣe baba isalẹ fun ẹnikankan ninu eto oṣelu Ipinlẹ Akwa Ibom.
Ṣugbọn o ni igba to dabi ẹni pe oun wuwa bi baba isalẹ oṣelu ni ọdun 2015 ti oun fa gomina Ipinlẹ Akwa Ibom kalẹ.
Baba isalẹ ninu eto oṣelu
Ademọla Ogunbanjo: A nílò bàbá ìsàlẹ̀ nínú òsèlú
Amugbalẹgbẹ Akpabio tẹlẹ ri tiẹ ṣalaye pe o ṣe iranwọ owo fun oun nigba ti oun ṣe igbeyawo ati ọjọ ibi ogoji ọdun. O ni oun lo jẹ ki oun gberi ninu eto oṣelu.
Baba isalẹ ninu oṣelu
Eto oṣelu apa ariwa Naijiria
Eto oṣelu ni ipinlẹ Kano to jẹ pe awọn ẹlẹsin musulumi lo pọ nibẹ nii ṣe pẹlu baba isalẹ eto oṣelu ipinlẹ naa.
Ọrọ osẹlu Ipinlẹ kano
Ipinlẹ Kano lo si keji ninu awọn ipinlẹ to ni awọn oludibo ju lorilẹede Naijiria, eleyi to jẹ ko ṣe pataki fun ẹgbẹ oṣelu mejeeji APC ati PDP lati jawe olubori ninu ibo to n bọ.
Gomina ipinlẹ kano tẹlẹ, Rabiu Kwankwaso ni atilẹyin ọpọ eeyan ni ipinlẹ naa, eleyi ṣẹlẹ lẹyin ti ṣe eto ẹkọ ọfẹ nigba ti o ṣe ijọba gẹgẹ bi gomina.
Kwankwaso tiẹ ni ẹka osẹlu rẹ ti wọn n pe ni Kwankwasiyya Movement nipinlẹ Kano.
Kwankwaso n ṣatilẹyin fun Abba kabiru Yusuf to n dije fun ipo gomina labẹ asia ẹgbẹ oṣelu PDP.
BBC Gov Debates: Ètò ẹ̀kọ́ ọ̀fẹ́ ni àwọn olùdíje yóò ṣe
Oríṣun àwòrán, Facebook/Rabiu Kwankwaso
Oṣelu ipinlẹ Knao
Ṣugbọn ohun to saaba maa n sẹlẹ ni pe awọn baba isalẹ ati awọn ti wọn ba fa kalẹ saaba maa n ni ede aiyede.
Ọrọ oṣelu Naijiria
Eto idibo to n bọ yoo fihan bo ya awọn ẹni ti Akpabio ati Kwankwaso fa kalẹ yoo wọle tabi wọn yoo kuna.
Falana: Awọn to n dije dupo ìdìbò 2019 fẹ́ fa ogun si Naijiria
APC Rally: Àdúgbò Festac ni ìjàmbá tó mú ẹ̀mí lọ ti wáyé
Oríṣun àwòrán, @APCNigeria
Ọmọ ẹgbẹ oṣelu APC mẹta ti padanu ẹmi wọn ninu ijamba ọkọto waye nigba ti wọn n lọ sibi ipolongo idibo fun oludije fun ipo sẹnẹt fun ẹkun idibo iwọ oorun Ipinlẹ Eko, Ọgbẹni Solomon Olamilekan Adeola lọjọ Aje.
Ile iṣẹ ọlọpaa Ipinlẹ Eko, to fidi ọrọ naa mulẹ pẹlu BBC Yoruba ṣalaye pe, awọn ọmọ ẹgbẹ ọhun ko ti de ibi Ipolongo ti wọn n lọ lagbegbe Festac, ti iṣẹlẹ naa fi ṣẹlẹ.
Agbẹnusọ fun ile iṣe ọlọpaa ipinlẹ Eko fikun ọrọ rẹ pe, ọpọ eeyan lo fara pa ninu ijamba ọkọ.
O ni awakọ naa ko le dari ọkọ ti awọn ọmọ ẹgbẹ APC wa ninu rẹ mọ, lẹyin naa ni ọkọ yii gbokiti.
'A ni òfin púpọ̀ ní Naijiria ṣùgbọ́n a kò bọ́wọ́ fún un ni'
Eleyi yatọ si awọn iroyin kan to lu ori ayelujara pa pe ẹmi awọn ọmọ ẹgbẹ APC kan bọ nibi ipolongo idibo.
Agbegbe Festac ni iṣẹlẹ naa ti ṣẹlẹ.
Ilé ẹjọ́ dájọ́ ikú fún àwọn tó pa Tìmílẹ́hìn, akẹ́kọ̀ọ́ fásitì UNIOSUN l'Oṣogbo
Oríṣun àwòrán, Ope'biosu
Oṣù kẹfà ọdún 2017 ni wọ́n ṣekúpa akẹ́kọ̀ọ́ fásitì UNIOSUN náà nílùú Òṣogbo
Ile ẹjọ giga ipinlẹ Ọṣun kan to fikalẹ silu Oṣogbo ti dajọ iku fun awọn ọdaran mẹta kan ninu marun ti wọn fi ẹsun kan pe wọn lọwọ ninu pipa akẹkọ fasiti ipinlẹ Ọṣun kan ti orukọ rẹ n jẹ Ṣonibarẹ Timilẹhin.
Ni ọjọ kẹrindinlọgbọn, oṣu kẹfa, ọdun 2017 ni awọn agbenipaṣowo kan pa akẹkọ onipele kẹrin fasiti UNIOSUN ni agbegbe Oke Baalẹ ni ilu Oṣogbo.
Ademọla Ogunbanjo: A nílò bàbá ìsàlẹ̀ nínú òsèlú
Odo ni wọn fi pa ọdọkunrin naa nigba naa ki wọn to ko oku rẹ si inu odo ninu ibi ti wọn ti n gun un.
Ẹkunrẹrẹ iroyin yii n bọ laipẹ...
'A ni òfin púpọ̀ ní Naijiria ṣùgbọ́n a kò bọ́wọ́ fún un ni'
Falana: Awọn to n dije dupo ìdìbò 2019 fẹ́ fa ogun si Naijiria
Ọbanikoro: Àjọṣepọ̀ tó wà láàárín èmi àti Fayose kò ní jẹ́ ki ń tú àṣírí
Ọbanikoro ni inu oun ko dun lori igbẹjọ naa
Igbẹjọ gomina ana ni ipinlẹ Ekiti, Ayọdele Fayoṣe lori ẹsun ṣiṣe owo to le ni biliọnu meje naira (N7.2b) baṣubaṣu ti ajọ EFCC fi kan an, waye lọjọ Aje ni ile ẹjọ giga apapọ to wa ni Eko.
Minisista abẹle feto aabo nigbakanri, Musiliu Obanikoro lo n jẹjọ tako Fayoṣe niwaju ile ẹjọ, lori bo ṣe ni oun fun Fayoṣe ni miliọnu marun un dọla owo ilẹ Amẹrika lara owo iyasọtọ fun ofiisi alamojuto eto aabo lorilẹ-ede Naijiria.
Agbẹjọro fun Fayoṣe fi ọrọ wa Ọbanikoro lẹnu wo fun nnkan bii wakati meji, ki Onidajọ Mojisọla Olatoregun to kede isinmi ranpẹ ọlọgbọn iṣẹju lati gbọ ẹjọ miran.
Wọn bi minisita tẹlẹ naa leere pe awọn inawo kan to ṣe nigba naa, eleyii to ni oun ko lee ranti mọ.
BBC Gov Debates: Ètò ẹ̀kọ́ ọ̀fẹ́ ni àwọn olùdíje yóò ṣe
O ni ohun ti Fayoṣe beere fun ni oun fi fi owo naa ranṣẹ sii gẹgẹ bi o ṣe han ninu awọn ẹri ti awọn agbẹjọro Fayoṣe gbe kalẹ.
EFCC ń pe Fayoṣe lẹ́jọ́ lórí ẹ̀sùn ìkówójẹ oní biliọ̀nù méje dọ́la ó lé
Obanikoro ni ajọṣepọ to dan mọran to wa laarin oun ati Fayoṣe, ko ni lee jẹ ki oun ko tu ọpọlọpọ aṣiri ohun to waye laarin awọn.
Amọṣa, o ni gbogbo ilakaka oun lasiko ti oun wa nipinlẹ Ekiti ni lati rii pe Fayoṣe di gomina ati pe inu oun bajẹ gidigidi lati wa jẹjọ tako Fayoṣe naa bayii.
Ademọla Ogunbanjo: A nílò bàbá ìsàlẹ̀ nínú òsèlú
Falana: Awọn to n dije dupo ìdìbò 2019 fẹ́ fa ogun si Naijiria
Ẹ̀ṣùn àjẹbánu: Alamieyeseigha ni gómìnà àkọ́kọ́ tó lọ sẹ́wọ̀n láti ọdún 1999
Oríṣun àwòrán, Getty Images/Ayodele Fayose
Lati igba ti orilẹede wa Naijiria ti bẹrẹ isejọbna alagbada pada lọdun 1999, ọpọ ojo lo ti rọ, ti ilẹ ti fi mu taa ba n sọrọ awọn gomina to ti kawọ pọnyin rojọ nidi ẹsun iwa ajẹbanu.
Ta ba si ni ka maa ka ni eni, eji, ẹta, a ka to ori aadọta tabi ju bẹ lọ, ka to dawọ duro.
Ko si si agbegbe kankan ti ọrọ yii yọ silẹ, bawọn eeyan to ti jẹ gomina ri lapa oke ọya se n kawọ pọnyin, naa ni awọn ti ẹkun guusu Naijiria n se.
'Wọn ko ni nkan ṣe fún ipinlẹ Ọyọ ni' #BBCGovDebate
Alaye si ree nipa awọn eeyan to ti jẹ gomina ri, ti wọn ti jẹjọ̀ nile ẹjọ lori ẹsun ajẹbanu.
Lati igba ti orilẹede wa Naijiria ti bẹrẹ isejọbna alagbada pada lọdun 1999, ọpọ ojo lo ti rọ, ti ilẹ ti fi mu taa ba n sọrọ awọn gomina to ti kawọ pọnyin rojọ nidi ẹsun iwa ajẹbanu.
Gomina ipinlẹ Taraba nigba kan, ni ile ẹjọ giga ijọba apapọ nilu Abuja ju si ẹwọn ọdun mẹrinla fun ẹsun pe o da owo ipinlẹ naa, eyi to to biliọnu kan le diẹ́ (1.64billion) sapo ara rẹ.
Bakan naa ni ile ẹjọ sọ pe, ko tun da owo to ji ko ọhun pada si apo ijọba. Oṣu Karun, ọdun 2007 ni ajọ EFCC fi ẹsun kan an.
Wọn fi ẹsun kan Nyame pe, o dari owo naa lati inu apo asunwọn ipinlẹ rẹ si apo ile isẹ kan, Saman Global lati ra awọn irinṣẹ ati eroja ikọwe lọọfisi, amọ alọ owo ni wọn ri, wọ̀n ko ri aabọ.
Bakan naa ni wọn fi ẹsun kan an pe, o fi ọna eeru ko ọrọ jọ fun ara rẹ, to si ja ireti awọn araalu kulẹ.
Joshua Dariye:
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ẹwọn ọdun mẹrinla ni ile ẹjọ ju Joshua Dariye si, ẹni to ti fi igba kan jẹ gomina ipinlẹ Plateau.
Ẹsun ti wọn fi kan ni pe, o dari biliọnu kan o le diẹ (1.16 billion) owo idagbasoke ayika si apo ileeṣẹ to jẹ tiẹ, Ebenezer Ratnen ventures, lasiko to fi jẹ gomina lọdun 1999 si 2007.
Ẹsun mẹtalelogun ni ajọ EFCC fi kan an, ti adajọ to gbọ ẹjọ rẹ si sọ pe o jẹbi mẹẹdogun ninu rẹ.
Lẹyin ọdun mẹwa ni wọn to o da ẹjọ rẹ. Ọdun 2007 ni ajọ EFCC fi ẹsun kiko owo ipinlẹ Plateau pamọ kan Dariye. Ọdun 1999 si 2007 ni Dariye fi jẹ gomina nipinlẹ naa.
Amọ ṣaa, Dariye pe ẹjọ kotẹmilọrun, ile ẹjọ si din ẹwọn rẹ si ọdun mẹwa.
James Bala Ngilari:
Gomina ipinlẹ Adamawa, James Bala Ngilari, naa lọ si ẹwọn ọdun maarun lai san owo itanran lori ẹsun pe o lu ipinlẹ rẹ ni jibiti miliọnu mẹtadinlaadọsan naira.
Lucky Igbinedion:
Gomina ipinlẹ Edo nigba kan, Lucky Igbinedion ni wọn dajọ ẹwọn oṣu mẹfa fun, fun pe o ji miliọnu mẹẹdọgbọn naira owo ipinlẹ rẹ, sugbọn o pada duna-dura lati san miliọnu mẹta aabọ Naira owo itanran.
Ile ẹjọ si fi silẹ.
James Ibori:
Ẹwọn ọdun mẹtala ni ile ẹjọ kan ni London ju James Ibori si, ẹni to ti fi igba kan jẹ gomina ipinlẹ Delta si.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ile ẹjọ naa sọ pe, o jẹbi ẹsun kiko ọtalerugba miliọnu Naira owo ipinlẹ rẹ.
Oun si ni oloṣelu akọkọ lati Naijiria to gba idajọ ẹwọn nilẹ okeere fun ẹsun jiji owo ilu.
Igba naa si ni igba kẹta ti Ibori gba idajọ ẹwọn fun ole jija.
Diepreye Alamieyesegha:
Bakan naa ni Oloogbe Diepreye Alamieyesegha to jẹ gomina ni ipinlẹ Bayelsa gba idajọ ẹwọn ọdun meji, lẹyin ti wọn fi ẹsun kan an pe, o ji owo to din diẹ ni biliọnu mẹrin Naira lasiko to fi jẹ gomina.
Ati pe o parọ ninu kikede dukia rẹ.
Ile ẹjọ gbẹsẹ le ile rẹ mẹrin, miliọnu mọkandinlọgbọn Pọun, ipin idokowo towo rẹ jẹ biliọnu kan Naira nile ifowopamọ ati awọn owo mi i.
Alamieyeseigha ni gomina akọkọ to lọ sẹwọn fun iwa ibajẹ lati igba ti orilẹede Naijiria ti pada si iṣejọba awaarawa lọdun 1999.
Ayọdele Fayoṣe:
Gomina nigba kan fun ipinlẹ̀ Ekiti n jẹjọ lọwọ fun ẹsun kiko owo ipinlẹ Ekiti si apo ara rẹ, ati pe o gba owo ti ko tọ ọ lati ṣe ipolongo ibo gomina to gbe wọle lọdun 2014 lọwọ Sẹnetọ Musiliu Ọbanikoro.
Oríṣun àwòrán, @Ayodele Fayose
Ni kete ti Fayose kuro ni iṣakoso gẹgẹ bi gomina lọdun 2018 ni ajọ EFCC ti gbe awọn ẹsun naa sita
Ni kete ti Fayose kuro ni iṣakoso gẹgẹ bi gomina lọdun 2018, ni ajọ EFCC ti gbe awọn ẹsun naa sita, ti wọn si gbe ọrọ rẹ lọ sile ẹjọ. Igbẹjọ ṣi n lọ lori ẹsun mọkanla ti wọn fi kan an.
Àwọn nkan tó ṣe kókó nípa olùdíje gómìnà ADP l'Ogun, Dimeji Bankọle
Oríṣun àwòrán, dimeji bankole/facebook
Ninu awọn ọdọ orileede Naijiria to ti di ipo to lamilaka mu nijọba ni Dimeji Bankole wa-ọmọ ọdun mẹtadinlogoji lo jẹ nigba ti o di ọmọ ile asojusofin.
Saaju ki o to di olori ile asojusofin labuja pupọ ninu awọn ọmọ Naijiria ni ko fẹrẹ gbọ orukọ rẹ ri.
Wọn bi Sabur Ọladimeji Bankọle ni ọjọ kẹrinla, oṣu Kọkanla ọdun 1969 nilu Abẹokuta nipinlẹ Ogun.
O kẹkọ nileewe Baptist Boys'High School lati ọdun 1979;
Lọdun 2002, wọn dibo yan Bankọle sile igbimọ aṣojuṣofin labẹ asia ẹgbẹ oṣelu Peoples Democratic Party, lati ṣoju ẹkun idibo Gusu Abẹokuta nipinlẹ Ogun.
Lasiko to fi wa nile aṣojusofin, o jẹ Igbakeji Alaga igbimọ to n mojuto eto ẹnawo. Wọn pada dibo yan Bankọle lọdun 2007.
Ninu oṣu Kẹsan ọdun 2007, igbimọ kan nile aṣofin naa ṣewadi Olori ile nigba naa, Patricia Etteh fun nina ọpọlọpọ owo lati fi tun ile rẹ ṣe , ati fi ra ọkọ ayọkẹlẹ. Ọrọ naa pada yọri si ki Etteh kọwe fipo silẹ ninu oṣu Kẹwa.
Lọjọ kini, oṣu Kọkanla, wọn dibo yan Bankọle nile aṣofin lati rọpo Etteh. Eyi to sọ ọ di Olori ile aṣojusofin to kere julọ ni ọjọ ori. Ẹni ọdun mẹtadinlogoji ni lasiko naa.
Oun si ni Olori ile aṣojuṣofin kẹsan ni Naijiria.
Asiko Dimeji Bankole lati ri awọn igbesẹ kọọkan nile asofin to fi mọ bi wọn ti ṣe paṣẹ lọrọọkun nile fun awọn ọmọ ile asofin to ko si ija ninu ile,bibuwọlu aba to fi aye gba iwadi lori ohun ti ijọba tabi ẹka rẹ ba n ṣe,Freedom of Information Bill ati bẹbẹ lọ.
Saa kan pere lo ṣe nile asofin ti ọrọ biliọnu mẹwa ẹyawo owo fun awọn asofin si jẹ epo ti o ta si asọ aala rẹ.
Amọ sa,lati igba ti o ti kuro lori oye ni o ti pada sile ti ko sifi taratara da si ọrọ oṣelu bi kii ṣe igba ti o gbapoti ibo lati du ipo Gomina nipinlẹ Ogun.
Oun ni oludije fun ipo gomina labẹ asia ẹgbẹ oselu Action Democratic Party, ADP nipinlẹ Ogun.
BBCGovDebates: Kí lo mọ̀ nípa Kashamu tó fẹ́ jẹ gómìnà l'Ogun?
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Kashamu kawe gboye ninu amojuto eto okooweo lati ile ẹkọ Pitman College, to wa ni ilu London.
Ọjọ kọkandinlogun, oṣu Karun, ọdun 1958 ni wọn bi Buruji Kashamu nipinlẹ Ogun. O si n ṣoju ẹkun idibo ila oorun ipinlẹ Ogun nile aṣofin agba Naijiria.
O lọ si ileewe alakọbẹrẹ Ansarudeen nilu Ijẹbu Igbo. Bakan naa lo lọ si ileewe Igbobi College , ko to o di pe o kawe gba oye ninu amojuto okoowo ni Pitman College nilu London.
'Bukola Saraki ni adari wa' - Razaq Atunwa, Kwara
O jẹ ọkan lara awọn oloye ẹgbẹ oṣelu Peoples Democratic Party nipinlẹ Ogun.
Kashamu ni Sẹnetọ to n ṣoju ẹkùn idibo Ila Oorun Ogun nile aṣofin agba Naijiria.
Wọn le e kuro lẹgbẹ PDP lọdun 2018, sugbọn ile ẹjọ giga kan nilu Abuja pada wọgile igbesẹ ẹgbẹ.
Kashamu kawe gboye ninu amojuto eto okooweo lati ile ẹkọ Pitman College, to wa ni ilu London.
Iṣẹ kata-kara ni Kashamu n ṣe.
Lọdun 1998, wọn fi ofin mu Kashamu ni ilẹ Gẹẹsi fun awọn ẹsun to ni i ṣe pẹlu oogun oloro, lẹyin to gbiyanju lati wọ orilẹede naa pẹlu owo igba le ọgbọn ẹgbẹrun Dọla. Wọn si da a silẹ lọdun 2003.
#BBCGovDebate: Olùdíje 5 ni yóò kópa nínú ìpàdé ìtagbangba l‘Ogun
Àwọn nnkan tó yẹ kí o mọ nípa Adekunle Akinlade ti ADM
Oríṣun àwòrán, @AHMAD BASHIR
Aworan yi n kan awọn ọmọ ẹgbẹ APC kan lominu
Bi eeyan ba gbiyanju lati kọ itan irinajo aṣoju Adekunle Akinlade ninu agbami oṣelu Naijiria o ṣeeṣe ki  iwe kun.
Lootọ ni pe ko ju ọmọ odun mọkandinlaadọta lọ ṣugbọn lẹnu igba ti o gbe apoti ibo lati du ipo Gomina ni ipinlẹ Ogun, ọrọ ko sin lẹyin rẹ.
#BBCGovDebate: Olùdíje 5 ni yóò kópa nínú ìpàdé ìtagbangba l‘Ogun
Fun awọn to ti n tẹle ọrọ rẹ bọ tipẹ, ko ni ya wọn lẹnu ti a ba ṣe apejuwe  Adekunle Akinlade  gẹgẹ bi oludije ti Gomina ipinlẹ Ogun, Ibikunle Amosun yan laayo lati jẹ Gomina lẹyin rẹ.
Oríṣun àwòrán, oGUN STATE GOVERNMENT
Èdèàìyedè ti ń wáyé nípínlẹ̀ Ogùn láàárín Gómìnà Amosun àtàwọn adarí ẹgbẹ́ òṣèlú APC lápapọ̀
Toun ti bi Gomina Amosun ṣe gbaruku ti i to, Adekunle padanu tikẹti ẹgbẹ oselu APC lẹyin ti igbimọ amuṣẹya ẹgbẹ APC kede Dapọ Abiọdun gẹgẹ bi aṣoju ẹgbẹ ninu idibo Gomina ọdun 2019.
Igbeṣẹ yii mu ki Adekunle fi ẹgbẹ oṣelu APC silẹ ti o si lọ gba tikẹti ipo Gomina labẹ asia ẹgbẹ Allied Peoples Movement, ADM.
Ohun to yẹ ki ẹ mọ nipa Adekunle
Bọlanle Aliyu: N kò nílò bàbá ìsàlẹ̀ láti di gómìnà
Samuel Ajayi Crowther: Baba nlá Herbert Macaulay, tó túmọ̀ Bíbélì sí Yorùbá
Oríṣun àwòrán, @BAMEAnglican
àlùfáà tó túmọ̀ Bíbélì sí Yorùbá , tó tún jẹ́ baba nlá Herbert Macaulay
Kii se igba akọkọ ree ti a gbọ orukọ Bisọọbu Samuel Ajayi Crowther nilẹ Yoruba ati ni orilẹ-ede wa Naijiria lapapọ.
Odu ni, kii se aimọ fun oloko paapaa ninu itan ẹsin awọn ọmọlẹyin Kristi ni orilẹ-ede Naijiria ati iwa imunilẹru jake-jado agbaye.
Ogbontagi ọmọ Oodua to gbe ogo ilẹ Adulawọ ga ni, ko si yẹ ka ma mọ itan igbesi aye rẹ, ati ọgbọn ta lee ri kọ ninu rẹ.
Gẹgẹ bi a ti se akojọpọ itan igbe aye Samuel Ajayi Crowther lori itakun agbaye, ololufẹ oniruuru ede ni, to si kọ ẹkọ nipa ede to to mẹrin.
Awọn ohun to yẹ ko mọ nipa Samuel Ajayi Crowther:
Oríṣun àwòrán, @BAMEAnglican
Cancer: Àṣe ara mi ni iso ti n run gbogbo bí mo ṣe n ṣèrànwọ́ lórí jẹjẹrẹ
Oríṣun àwòrán, Twitter/YorubaHistory
Wòlíì Kasali ní Dolapo Awosika kò lé ìyàwó òun jáde
'Alífábẹ́ẹ́tì Ohùn Oduduwa di ìtẹ́wọ́gbà ni Ajaṣẹ'
Ṣẹ gbọ́ nípa Alájọ Ṣómólú, tó ta mọ́tò ra kẹ̀kẹ́?
Yorùbá dùn lédè, ẹ máa sọọ́
O yẹ ki gbogbo wa ri ọgbọn kọ ninu itan igbe aye akọni ọmọ Oodua yii, ẹni to jẹ ẹru, amọ to ta ara rẹ yọ.
Ipokipo ti a ba wa, o yẹ ka maa ri daju pe a sa ipa wa, lati fi ọgbọn ori wa han, ka si se iwọn ti a lee se.
Akinwunmi Ambode: Ìsúná 2019 fi N1trn kéré sí ti 2018
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Adarí Ilé Asòfin, Modashiru Obasa ní inú òun dùn báyìí pé Gomina Ambode gbé àbá ìsúná 2019 sílẹ̀.
Gomina ipinlẹ Eko, Ọgbẹni Akinwunmi Ambode ti gbe eto isuna to to ọtalelẹgbẹrin o din mẹjọ biliọnu Naira (N852.13bn) siwaju Ile Asofin ipinlẹ naa.
Iroyin ni eto isuna ti ọdun yii kere ju ti ọdun to kọja lọ pẹlu triliọnu Naira kan (N1.046trn).
Ambode sọ wi pe, awọn pese eto isuna naa lati le koju awọn ise akanse to niise pẹlu awọn opopona ti wọn n se, bii Oshodi si Murtala Mohammed International Airport Road ni agbeegbe Agege.
Ambode
Adari Ile Asofin, Modashiru Obasa ni inu oun dun bayii si bi Gomina Ambode gbe aba isuna 2019 silẹ.
Laipẹ yii ni Ile Igbimọ Asofin ipinlẹ naa gbe igbesẹ lati yọ Gomina Ambode kuro nipo, amọ Adari Ẹgbẹ Oselu APC, Asiwaju Bola Ahmed Tinubu lo pẹẹtu saawọ awọn mejeeji.
Uganda FGM: 'Ìdí tí mo fi lọ d'ábẹ́ lòdì sí òfin'
Sylvia Yeko ni ayọ oun kun lọjọ ti oun d'abẹ
Abẹ dida fun obirin paapa fun ẹni to ba ti gbọnju dagba a ma mu ẹru wa.
Ṣugbọn lọdọ arabirin kan lorileede Uganda, ifẹhonu han si ijọba lo sọ wi pe o mu ki oun  jọwọ ara rẹ fun abẹ dida.
Sylvia Yeko pinu funra rẹ lati da abẹ eyi ti awọn oloyinbo n pe ni Female Genital Mutilation ni ọsẹ mẹta sẹyin nigba to pe ọmọọdun mẹrindinlọgbọn.
Aṣa yii ti wọn maa n ṣe e fun awọn ọdọ langba to jẹ ọmọbinrin lorileede Uganda ṣugbọn wọn ti fi ofin de lati ọdun 2010.
Nita gbangba ni wọn ti ṣe ayẹyẹ abẹ dida rẹ ti o si fi fọnran fidio ti wọn ya nipa rẹ han wa.
Aburu abẹ dida f'ọmọbinrin
Ìwà ipá nínú ìdílé máa ń bí ìgè àti àdùbí ni tó lè já sí ikú
Ninu fọnran naa, awọn eeyan n daraya ti wọn si rọ yika Yeko ati obinrin miiran.
Wọn fi iyẹfun ra awọn mejeeji loju. Lori koriko nita lawọn mejeeji dubulẹ si ti obirin kan si ya ẹsẹ wọn ki o to ge ẹran ara ibi nkan ọmọbinrin wọn kuro.
Ko si ẹni to kigbe ninu wọn nitori pe ẹkun kike lodi si aṣa wọn nipa eto ti obirin gbọdọ ṣe ki o to lọ ile ọkọ lagbegbe yii to wa ni ariwa Uganda.
"Abilekọ Yeko sọ fun BBC bi o ti ṣe n tun fọnran fidio naa wo pe""niṣe ni inu mi kan n dun lọjọ naa''"
"Oju ọmọde ni wọn fi n wo mi ki n to dabẹ amọ bayi ti mo ti ṣee, mo ti di ẹni apọnle''
Yeko mọ wi pe oun le ṣẹwọn to to ọdun marun un fun abẹ dida ṣugbọn o ni oun ko bikita bi awọn agbofinro ba mọ.
Awọn ti wọn jijọ ṣiṣẹ abẹ naa le fẹwọn ọdun mẹwa jura bakan naa.
Sylvia Yeko joko ni iwaju ile rẹ ti o si ni oun ko foya ki awọn ọlọpaa wa mu oun
Lati ọṣu kejila ọdun to kọja, irufẹ ayẹyẹ abẹ dida bayii ti waye lagbegbe Sebei lariwa Uganda-pupọ waye ni adugbo Kween eleyi to sunmọ ibode ilu Kenya.
Awọn eeyan mẹta kan ti fẹwọn gbara fun  aṣa abẹ dida yii to fi mọ ọmọbirin ọdun mẹẹdogun kan ati obirin mii. Eeyan mọkandilogun lo wa ni atimọle ti wọn n reti idajọ lori  pe wọn kopa ninu aṣa yii.
Abẹ dida a ma da ẹmi legbodo. Ewu to wa nibẹ a maa ṣẹlẹ ti ẹjẹ ba kọ lati da latara abẹ dida.
Kokoro a tun maa wọ inu egbo naa. Ninu fọnran fidio ti a wo, iyẹfun lasan ni wọn gbọn si oju ara awọn ti wọn dabẹ fun ko si daju wi pe wọn lo abẹ ọtọọtọ fi d'abẹ fun wọn.
Aburu ti o ma n sẹlẹ ni ki apa oju abẹ naa ko inira ba ẹni ti wọn dabẹ fun tabi ki o ko inira ba wọn ti wọn ba fẹ bimọ.
Toun ti gbogbo nnkan ti a ka silẹ wọnyii, Yeko ti di ilumọọka ni Sebei-nigba ti a bi leere pe kini ero rẹ nipa awọn ọmọbirin kekeeke ti wọn wo awokọṣe rẹ, o ni ohun ko ri nnkan to buru ninu abẹ dida.
Kini itumọ abẹ dida fun awọn obirin?
Orisun: Ajọ isọkan agbaye
Lọdọ Yeko, aṣa abẹ dida kii ṣe aṣa nikan bi kii ṣe ọna tirẹ lati koju ijọba ti o ni wọn kọ lati mu ileri ti wọn ṣe pe awọn yoo ṣe  idanilẹkọ fun awọn obinrin ati mimu agbega ba awọn obinrin lẹyin ti wọn fofin de aṣa abẹ dida.
Awọn ti wọn wa ni awọn agbegbe ti oṣi pọ si wọnyii ti ireti wa wi pe ijọba yẹ ki wọn pese ohun amayederun fun ti wọn ba jawọ kuro ninu abẹ dida.
Ọpọ idile ni Sebei ni ko ni agbara lati ran awọn ọmọ obinrin wọn lọ si ile ẹkọ
Ki ọrọ naa ba le yewa daada, abilekọ Yeko mu wa lọ si ile iwe girama fun awọn obinrin  Kwosir Girl's Boarding Secondary School nibi ti a ti ri patako kan ti wọn kọ ileri aarẹ orileede lati mu opin ba abẹ dida.
O ni toun ti bi wọn ti ṣe kọ ileewe naa lẹyin ti wọn fi ofin de abẹ dida, kii ṣe gbogbo ọmọbirin lo laanfaani lati kẹkọ nibẹ ti iye owo ile ẹkọ naa gunpa fun ọpọ lagbegbe naa.
Yeko so pe Ki wọn fọwọ di ileewe wọn mu nitori ko si anfaani kankan ti a n ri nibẹ''"
Pupọ awọn eeyan nigberiko Sebei n tiraka lati ri ọna ijẹ ati imu
Agbegbe Kween wa lara awọn agbegbe ti ko ṣe daada to nipa eto ẹkọ.
Gẹgẹ bi ohun ti a ri ka ninu iroyin ti ijọba ko jọ, nnkan bi ẹgbẹrun mẹfa akẹkọ ni wọn maa n forukọsilẹ nile ẹkọ alakọbẹrẹ ṣugbọn nigba ti wọn yoo fi de ile ẹkọ girama, wọn kii ju igba lọ ti o ma n ṣẹku ni kilasi.
Abilekọ Yeko ni oun gbiyanju lati kawe pari amọ bi awọn eeyan pupọ lorileede Uganda,ko ti ri iṣẹ.
Sylvia Yeko koti ikun si ikilọ awọn obi rẹ lati ma ṣe da abẹ
O tẹsiwaju pe nnkan to mu oun kopa ninu abẹ dida naa ko ju wi pe oun fẹ fi ẹhonu han si bi ijọba ko ṣe kọbi ara si ọrọ ara ilu.
Koda o kọ iwe si ọga ọlọpaa saaju ayẹyẹ idabẹ rẹ ki wọn baa le mọ nipa igbesẹ rẹ.
'Wọn n foju ọmọde wo wa'
Obinrin miiran kan to ba BBC sọrọ ni ohun  nikan loun le salaye ipinu to mu ki oun gba ki wọn dabẹ fun oun.
Obinrin naa ti ko fẹ ki wọn darukọ rẹ ni laarin awọn eya Sabiny ti oun ti wa, wọn  n dẹyẹ si oun ti wọn ko si gba oun laaye lati ṣe awọn nkankan nitori pe oun ko tii dabẹ.
Abẹ dida jẹ aṣa laarin awọn eeyan Sebei
"Ni Sebei, obinrin ti ko ba ti d'abẹ ko le bawọn ṣiṣẹ ajumọṣe tabi ko ba wọn ko bọtọ''
Isẹ fifi bọtọ kun ile jẹ iṣẹ ti wọn ya sọtọ fun awọn obinrin.
O ni Okunrin le fẹ iyawo mii ti oun ti da'bẹ ti wọn a si maa fi eleyi bu ẹni ti ko tii da'bẹ pe ọmọde ṣi ni''"
Amọ ṣa obinrin naa to ti bi ọmọ mẹta ni ohun ko lero lati da abẹ fun awn ọmọ rẹ ti o si ni igbagbo wi pe wọn yoo kawe lọjọ iwaju.
Lagos Budget: Onímọ̀ nípa ìsúná ṣàlàyé ìgbésẹ̀ Ambode
Oríṣun àwòrán, @followlasg
Gomina Ambode nile aṣofin Eko
Ọpọlọpọ lo ti n sọ ero wọn nipa eto isuna ti gomina ipinlẹ Eko Akinwumi Ambode ṣẹṣẹ gbe sita.
Awọn kan ni oun to tọ ni gomina Ambode ṣe nigba ti awọn miiran n beere wi pe bawo ni yoo ti ṣe e yanju pẹlu bi o ṣe ku perete oṣu mẹta fun un lori alefa.
Nigba ti BBC Yoruba ba onimọ nipa eto isuna sọ̀rọ̀ lori isuna yii, Ọgbẹni Tunde Bello jẹ ko di mimọ pe igba ti gomina kan ba gbe iru eto isuna yii jade, kii ṣe ẹbi rẹ nitori wi pe ọpọlọpọ eniyan ni yoo lọwọ si eto isuna ko to di gbigbe sita.
O ni o yẹ ki awọn amofin ti ṣa ipa tiwọn lati inu oṣu kẹsan ọdun to kọja. Onimọ yii sọ pe o jẹ ilana ọlọgbọn nitori pe iye ti wọn ro pe awọn maa ri lowo ti wọn pa wọle lọdun to kọja pọ kọ ni wọn ri nitori ọrọ aje Naijiria.
Bọlanle Aliyu: N kò nílò bàbá ìsàlẹ̀ láti di gómìnà
O jẹ igba akọkọ ti a maa ri ni orilede Naijiria pe wọn ṣe eto isuna ti iye owo rẹ lọlẹ. Idi si ni wi pe o yabọ rara ju ki wọn kan kọ owo gọbọi sinu rẹ lọ. O le ma kari gbogbo eniyan ṣugbọn yoo ṣi rin jina.
O ni eyi lo mu ki gomina wo o pe dipo ki wọn maa reti ohun ti ko si rara, o ṣi gbiyanju lati gbe eto isuna sita.
Diẹ lara awọn ipa ti Ọgbẹni Tunde Bello mẹnu ba gẹgẹ bi ipa ti eto isuna naa yoo ko ni:
#BBCGovDebate: Olùdíje 5 ni yóò kópa nínú ìpàdé ìtagbangba l‘Ogun
Bi o til jẹ pe oṣu mkta lo ku fun gomina Ambode lori alefa, Tunde fi hande pe ijọba kan n lọ ijọba kan n bọ ni. Eyi tumọ si pe bi ijọba ti yoo gba iṣẹ lọwọ Ambode ba ni aato kan naa bii tirẹ ti yoo mu alafia ati ilera wa fun gbogbo eniyan, yoo tẹsiwaju bi ko ba si gbagbọ ninu tirẹ, aato tiwọn naa yoo wulo fun awọn ara ilu.
Tunde Bello ṣalaye siwaju pe o han gedegbe wi pe kii ṣe pe gomina Amobode ṣi fẹ gbe igba ibo nitori pe o gbe eto isuna naa siwaju awọn eniyan, wn si gba a wọle.
Nigeria Election 2019:Awọn wò ní Gómìnà El Rufai n ba wi pẹlu ihalẹ 'body bag'
Oríṣun àwòrán, @elrufai
Gomina El Rufai ko ṣẹṣẹ ma sọ ọrọ to ma n fa awuyewuye
'Onwoye kankan lati ilu okere to ba n bọ lati dasi idibo Naijiria ko ni fara re pada sile.'
Ikilọ yi ti a pẹ sọ nitori bi o ti ṣẹ lagbara to ni Gomina ipinlẹ Kaduna lorileede Naijiria Ahmad El Rufai fi sita  eyi to si ti n da awuyewuye silẹ
Lori eto kan to waye nileeṣẹ amohunmaworan Naijiria ni Gomina El Rufai ti  sọ ọrọ yi lalẹ ọjọ iṣẹgun.
Eyi kii ṣe igba akọkọ ti El Rufai yoo ma sọ ọrọ to n da wahala silẹ.
Lai pẹ yi ni awuyewuye waye lori bi o ti ṣe juwe olori ẹgbẹ ẹsin Shia Zakzakky gẹgẹ bi ẹrankọ ninu ifọrọwerọ kan lori ẹrọ amohunmaworan
Ninu awọn to ti n faraya lori ọrọ naa lati ri Femi Fani Kayode,Aisha Yesufu ati Sẹnẹtọ Ben Murray Bruce to fi mọ ẹgbẹ oselu PDP ti wọn bu ẹnu atẹ lu ihalẹ El Rufai yi.
Ẹgbẹ PDP ni awọn ko ni igbagbọ pe pẹlu iru ọrọ to n jade lẹnu El Rufaiu yi,awọn yoo ni lati se agbeyẹwo iwe adehun idibo alafia ti awọn buwọlu.
Kiakia ni akọwe ipolongo ẹgbẹ naa ti fi ọrọ sita loju opo Twitter nipa ọrọ yi.
Amọṣa Gomina El Rufai ti salayeidi ti o fi sọ ọrọ naa loju opo Twitter rẹ ni idahun si iriwisi orisirisi to muwa.
Nigeria Election 2019:El-Rufai, lọ tọwọ́ ọmọ rẹ bọ aṣọ! - Òǹwòye ìdìbò YIAGA
Oríṣun àwòrán, Twitter
Gómínà Nasir El-Rufai dá ogunlọ́gọ́ àwọn olùkọ́ ìpínlẹ̀ náà dúro l'ọdún tó kọjá
Ọpọlọpọ iriwisi lo ti n jẹ jade latari ọrọ ti gomina ipinlẹ Kaduna, Nasir El Rufai sọ si awọn onwoye idibo wi pe 'Onwoye kankan lati ilu okere to ba n bọ lati dasi idibo Naijiria ko ni fara re pada sile.'
Lara awọn ti wọn wi ti wọn ni ikọ onwoye idibo abẹle kan lorileede Naijiria ti orukọ wọn n jẹ 'Watching the Vote'.
Agbẹnusọ ẹgbẹ onwoye naa to jẹ eto pataki kan labẹ Yiaga Afrika, Moshood Issa sọ fun BBC Yoruba ninu ifọrọwanilẹnuwo kan pe ọrọ ti  Gomina El Rufai sọ ku diẹ kaato.
O ṣalaye pe ko si nnkankan ti awọn to wa n ṣe amojuto eto dibo fẹ jẹ lere ju pe ki eto idibo lọ ni irọwọrọsẹ.
''Lootọ lawọn onwoye ibo kan to jẹ ti abele maa n gbabọde fun awọn oloselu kọọkan ṣugbọn ni ti awọn to n bọ lati ilẹ okere wọn kii figba kan bọ ikan ninu''
Oríṣun àwòrán, SEYLLOU DIALLO/AFP/GETTY
Awọn ọdọ wọnyi n fa wahala lẹyin esi idbo ọdun 2011 nilu Kano
Moshood tẹsiwaju pe awọn oloseelu ni lati ṣọra fun ọrọ to le da 'rogbodiyan silẹ laarin awọn ara ilu paapa julọ bi eto idibo ti ṣe n kan lẹkun bayi ni Naijiria.'
O ni ko yẹ ki o si ifoya kankan nipa awọn onwoye idibo nitori pe INEC yoo ti saaju ṣe agbeyẹwọ wọn ki wọn to gba iyọnda lati wa kopa ninu eto idibo.
Moshood rọ awọn agbofinro naa lati kilọ fun awọn oloṣelu lati tọwọ ọmọ wọn basọ pẹlu ọrọ to le da wahala silẹ laarin ilu.
Ọrọ wa lori ọrọ kobakungbe ko yi pada
Oríṣun àwòrán, @inecnigeria
Adele Ọga ọlọpaa tuntun ni iṣẹ nla niwaju pẹlu idibo 2019 to n bọ lọna
Adele Ọga ọlọpaa tuntun lorileede Naijiria Mohammed Adamu naa ti da si ọrọ to wa nilẹ yii.
Nigba ti o n sọrọ nibi apero kan ti ajọ eleto idibo lorileede Naijiria INEC ṣagbatẹru rẹ nilu Abuja, Mohammed sọ pe ipinu ile iṣẹ ọlọpaa lori ọrọ kobakungbe ko yatọ si tẹyin wa.
O tẹnumọ pe ipinu yii ni idahun si ibeere tawọn akọroyin bi i nipa ọrọ Gomina El Rufai to sọ.
BBC Nigeria 2019: Àwọn èèkàn ọmọ Ogun nínú ìṣèjọba Nàìjíríà.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Àwọn èèkàn ìṣèjọba Nàìjíríà
Ninu oṣelu ati iṣejọba Naijiria, ọpọlọpọ ni awọn eekan to kara jọ sibẹ to jẹ wi pe bi wọn ba wi, kii pẹ tan kalẹ gẹgẹ bi iroyin, pupọ ninu wọn si wa lati ipinlẹ Ogun.
Bi a ba tun wa fi ti ẹya tabi ede wo o, awọn ọmọ Yoruba wọnyii kii ṣe ẹni aa fọwọ rọ sẹyin ni awọn ibi giga giga lorilẹede Naijiria.
Ki Naijiria to gba ominira ati lẹyin ominira ni a ti ri awọn wọnyii to n le waju ninu iṣakoso ati idari loniruuru ọna. Ẹwẹ, awọn to jẹ ọmọ bibi ipinlẹ Ogun ni a o gbeyẹwo.
'Bukola Saraki ni adari wa' - Razaq Atunwa, Kwara
Ọjọ karun un oṣu kẹta ọdun 1937 ni a bi Oloye Oluṣẹgun Mathew Okikiọla Arẹmu Ọbasanjọ (GCFR, PhD) ni ilu Abeokuta, ipinlẹ Ogun. Ọgagun tẹlẹ ri lo jẹ ni ile iṣẹ ogun Naijiria ko to di olori orilẹede labẹ ijọba ologun laarin ọdun 1976 si 1979 lẹyin naa lo tun di olori orilẹede labẹ ijọba atiwa n tiwa laarin ọdun 1999 si 2007 labẹ asia ẹgbẹ oṣelu Peoples Democratic Party.
Ọbasanjọ rinrin ajo pupọ lọ soke okun to si ni ibaṣepọ to dan mọran pẹlu awọn ajọ ilẹ okere ti inu awọn naa si dun lati ni ba ọmọ ilẹ adulawọ bayii dọrẹ eyi ti ko kọ esi ọrọ ẹnikẹni si igbesẹ rẹ yala nile tabi lẹyin odi ti Ọbasanjọ a si maa bori iru ẹnu atẹ wọnyii lọpọ igba.
Ọjọ kọkandilọgbọn tii ṣe ọjọ ti Oluṣẹgun Ọbasanjọ di aarẹ alagbada ni wọn lo gẹgẹ bi ayajọ ọjọ ijọba tiwa n tiwa bayii lorilẹede Naijiria.
2003 ni wn tun dibo yan Ọbasanjọ eyi to si jẹ idibo pẹlu ọpọlọpọ iwa ipa ati ipenija. Nigba naa lọhun Ọgagun Muhammadu Buhari ni oludije ẹgbẹ alatako ṣugbọn Ọbasanjo jawe olubori.
Nigba ti ipinnu rẹ lati lo saa kẹta lori alefa gẹgẹ bi aarẹ ko rọwọ mu ni o gbe eku ida kalẹ lẹyin idibodun 2007.
Oloye Ọbafẹmi Jeremiah Oyeniyi Awolọwọ (GCFR) jẹ ọmọ bibi ilu Ikenne ipinlẹ Ogun lọjọ kẹfa oṣu kẹta ọdun 1909 o si di oloogbe lọjọ kẹsan oṣu karun ọdun 1987. O jẹ agba orilẹede Naijiria ti gbogbo eniyan bọwọ fun nitori iṣẹ takuntakun rẹ ninu igbesẹ lati gba ominira fun Naijiria - lasiko ijọba amunisin to di mọ lasiko ogun. Oloṣelu nla ni pẹlu. Oun ni awọn mọ si oludasilẹ akọkọ ti Western Union o si tun jẹ Kọmisana fun eto isuna. Bakan naa, o ti jẹ igbakeji aarẹ fun igbimọ alaṣẹ orilẹede yii.
Awolọwọ lo ṣe iṣẹ ọpọlọpọ iṣofin eyi to ti sọ Najiria di ilu olokiki bayii. Wọn maa n ri Awolọwọ gẹgẹ bii aṣaju eto oṣelu ijọba awa ara wa.  O ṣe eto ẹk ọfẹ fun gbogbo gbo ati ilera ọfẹ fawọn ọmọde lẹkun Iwọ Oorun. Oun lo kọkọ da ile iṣẹ mohunmaworan akọkọ silẹ nilẹ Afirika lọdun 1959.
#BBCGovDebate: Olùdíje 5 ni yóò kópa nínú ìpàdé ìtagbangba l‘Ogun
Oloye Funmilayọ Anikulapo-Kuti jẹ ọmọ bibi ilu Abeokuta lọjọ kẹẹdgbọn oṣu kẹwa ọdun 1900 titi to fi papoda ni ọjọ kẹtala oṣu kẹrin ọdun 1978. Oluk ni o jẹ, olupolongo oṣelu, ajafẹt obinrin  ati onigbagbọ ninu aṣa. O jẹ kan lara awn aṣaju orilẹede Naijiria nigba aye rẹ. Oun naa si ni obinrin akọkọ to kọkọ wa ọkọ. Ilakaka rẹ ninu oṣelu lo mu ki wn maa sapejuwe rẹ gẹgẹ bi ''Erelu ẹtọ awọn obinrin lorilẹede Naijiria''. Wọ́n tun maa n pe e ni Iya Afirika. Afihan agbara rẹ ninu jija fẹtọ pọ to bẹẹ ti wọn tun ṣapejuwe rẹ lọdun 1947 bi ''Kiniunbinrin ti Lisabi'' fun idari rẹ lori awọn obinrin Ẹgba nipa bi wọn ṣe bere owo ori gọbọi lọwọ wọn. Funmi Kuti ni iya to bi gbajugbaja olorin ajafẹtọ ọmọniyan, Fela Anikulapo Kuti.
Ilu Odogbolu ni ipinlẹ Ogun ni a ti bi Donaldson Ọladipọ Diya ni ọj kẹta oṣu kẹrin ọdun 1944. Diya jẹ onimọ nipa ofin tro si jẹ adajọ ile ẹjọ to ga ju lọ lorilẹede Naijiria o si tun kẹkọọ nipa iṣẹ ogun.
Wọn yan an gẹgẹ bii gomina ijọba ologun ti ipinlẹ Ogun laarin 1984 si ọdun 1985. O ti jẹ ọgagun lori oriṣiriṣi ikọ ogun lorilẹede Naijiria. Wọn yan an ni Ọga agba awọn ọm ogun alaabo lọdun 1993.
Lọdun 1997, Wọn fi ẹsun kan pe Diya pẹlu awọn ọmọ ogun rẹ lati gba ijọba lọwọ ijọba Sani Abacha nigba naa ṣugbọn awn to nifẹ si iṣejba Abacha tu aṣiri igbesẹ naa wọn si ju Diya atawọn ikọ rẹ sẹwọn.
Ọjọgbọn Yẹmi Ọṣinbajo jẹ ọmọ bib ilu Ikenne ni ipinlẹ Ogun. Wọn bi i ni ọjọ kẹjọ oṣu kẹta ọdun 1957. O di igbakeji aarẹ orilẹede Naijiria lọjọ kkandinlọgbọn oṣu karun ọdun 2015 oun si tun ni igbakeji fun aarẹ Buhari ninu idije fun ipo aarẹ Naijiria lọdun 2019. O jẹ amofin agba orilẹede Naijiria. O ti jẹ kọmisana fun eto idajọ ni ipinlẹ Eko ri fun ọdun mẹjọ.
O jẹ oluṣọ aguntan ni ijọ irapada, RCCG.
lati ọdun ti Yẹmi Ọṣinbajo ti dara pọ mọ oṣelu Naijiria, awn eto ati igbesẹ rẹ labẹ asia ẹgbẹ oṣelu APC ti n fa oju ọpọ mọra yala lati to si i lẹyin tabi lodi si oun ati isejọba aarẹ to n ṣe igbakeji rẹ.
Gani Adams: Kò bá dáa tí INEC bá sùn ọjọ́ gbígba PVC síwájú
Aarẹ Gani Adams ni pupọ ni ko ni laanfaani lati dibo ti Inec ko ba sun ọjọ gbigba kaadi siwaju
Bi  o ti ṣe ku wakati perete  ki gbedeke gigba kaadi idibo PVC lorileede Naijiria pari, Aarẹ Ọna kakanfo ilẹ Yoruba Gani Adams ti funpe ki ajọ INEC sun ọjọ gbigba kaadi naa si waju.
Alaye to fi siwaju fun arowa yi ni pe pupọ ninu ọmọ orileede Naijiria ni ko ti ri kaadi idibo wọn gba.
O wa ni ki INEC sun ọjọ kaadi gbigba naa siwaju titi di ọjọ isẹgun tii ṣe ọjọ kejila oṣu keji  nitoripe ipolongo idibo yoo si waye titi di ọjọbọ  tii ṣe ọjọ kẹrinla.
'Airi kaadi yi gba yoo se akoba fun awọn to fẹ dibo.Bi kii ba ṣe wi pe mo figbe sita,emi gaan ko ba ma ni anfaani lati ri kaadi mi.'
Gani Adams ninu ifọrọwanilẹnuwo pẹlu ile iṣẹ BBC  so pe o ti to ọjọ mẹta ti ohun ti n gbiyanju lati gba kaadi idibo fun ara ohun ati iyawo ohun.
'Mo ni lati sọ fun awọn oṣiṣẹ INEC nilu Eko pe mo ti fi atẹjade sita sawọn oniroyin nipa kaadi mi ti mi o ri gba ki wọn to sare mu wa fun mi nile mi lowurọ ọjọbọ.''
Aarẹ Onakakanfo ni 'boya nitori mo jẹ ilumọka ni wọn fi mu kaadi mi wa.Ti iru ẹmi ba ni lati pariwo sita ki n to ri kaadi mi gba,ki wa ni yoo ṣẹlẹ si awọn mẹkunu lawujọ?'
Ọjọ kẹsan Oṣu keji ni gbedeke ti Inec fi kale fun gbigba kaadi idibo yoo pe.
Lalai ni kaadi lọwọ,Inec ti ni awọn ko ni gba ẹnikẹni laaye lati kopa ninu idibo ọdun 2019.
Vice Presidential Debate: Àwọn olùdíje n fọ̀rọ̀jomitoro
Awọn igbakeji Aarẹ to n dije ni yoo kopa ninu ijiroro naa
Ifọrọjomitoro ọrọ laarin awọn igbakeji oludije ipo Aarẹ ninu idibo ọdun 2019 lorileede Naijiria ti n waye nilu Abuja
Ijiroro naa ti wọn pe ni 'The Peoples Debate' yoo fun awọn oludije laanfaani lati sọ erongba wọn fun ara ilu.
Ninu awọn oludije mẹfa ti wọn fi iwe pe,mẹta lo yọju iyẹn Rabiu Ahmed Rufai AAN,Kunle Olagbegi ti National Democratic Party ati Khadijah Abdullahi  ti ẹgbẹ Alliance for New Nigeria ANN.
Gbọngan Ladi Kwali nilu Abuja ni o ti n waye.
Kunle Olagbegi ati Ahmad Rufai
100,000 ni ẹgbẹ ADC ati ẹgbẹ AAC  lawọn yoo san fun ara ilu gẹgẹ bi owo osu to kere julọ fun oṣiṣẹ
Kunle Olatẹru Olagbegi ti  o jẹ igbakeji oludije Aarẹ ẹgbẹ ADC ati Rabiu Ahmed Rufai  ti ẹgbẹ African Action Congress (AAC) nieyi nikan ni na ti awọn eeyan Naijiria yoofi jaanfaani ijọba.
Ahmed Rufai lawọn yoo gba 200,000 olukọni jakejado orileede Naijiria ati wi pe awọn yoo faye gba iṣẹ ohun amuludun lorisirisi.
Khadijat sọ pe fifikun owo osu oṣiṣẹ to kere ju lọ ki ṣe ọna abayọ fun eto ọrọ aje
Khadijat ni fifikun owo oṣu kọ ni ọna abayọ lati mu idagbasoke ba eto ọrọ aje.
O ni mimu idagbasoke ba ẹsẹpupu ni ibi ti o yẹ ki ijọba gbajumọ nipa ṣiṣe amulo awọn ohun alumọni ti Naijiria ni lọpọyanturu
Ọrọ Abo
Ahmed Rufai ni idahun si ibere ọrọ abo ni ko si iṣedeede ati idajọ ododo lorileede Naijiria.
O ni lilo ọtẹlẹmuyẹ to peye jẹ ọna lati koju ipenija Boko Haram.
O pe fun ajoṣepọ laarin awọn ajọ alaabo lorileede Naijiria.
Olori ti ko muna doko lo wa nidi gbogbo ipenija aabo.
Kola Olagbegi ni tirẹ  di ẹbi ipenija aabo ru awn alaṣẹ ti ko munadoko.
Kola Olateru Olagbegi
O pe fun ki wọn yọ awọn olori ileesẹ ọmọ ogun Naijiria ti wọn ti pẹ lori oye.
O nilabẹ ijọba awọn,awọn yoo pawọpọ plu ilẹ Gẹẹsi ati Amerika lati koju ipenija aabo to n ba Nijiria finra
Aabo to peye jẹ ọna kan gbogi ti Khadijah Abdullahi da laba lati koju ipenija aabo.
O ni ẹgbẹ awọn yoo ri pe awọn ọmọ ogun gba owo to yẹ ki wọn ba le ṣe iṣẹ wọn bo ti ṣe tọ ati bo ti ṣe yẹ
Ajọ ti ko niiṣẹ pẹlu ijọba kan ti orukọ wọn n jẹ 'Enough is Enough' lo sagbatẹru ijiroro naa pẹlu ajọsepọ ile isẹ BBC,TVC NEWS,BudgiT,One ati Transition Monitoring Group.
BBC
Ninu awọn ti o n kopa ninu itako ọrọ naa lati ri oludije igbakeji Aarẹ awọn ẹgbẹ oṣelu bi PDP,Peter Obi, Yemi Osinbajo ti ẹgbẹ APC ,Shehu Gabam SDP ati  Rabiu Ahmed Rufai AAC.
Umma Getso ti Young Progressive Party ati  Khadijah Abdulahi Alliance for New Nigeria.
Ẹwo diẹ ninu awọn awọran lati gbagede ijiroro naa
Aliyu Tanko ti ileeṣẹ BBC àti Ngozi Alaegbu
Ijiroro
‘ASUU da ìyanṣẹ́lódì dúró'
Oríṣun àwòrán, @ui
Oṣu mẹfa ni iyanṣẹlodi naa fi waye
Ìròyìn tó ń tẹ̀ wa lọ́wọ́lọ́wọ́ ní wí pé ẹgbẹ́ olùkọ́ àgbà ilé ẹ̀kọ́ gíga fásítì ASUU ti fagile iyanṣẹ́lódi oloṣumẹfa ti wọn gun lé.
Lonii, ọjọbọ, ọjọ keje oṣu keji ni èyí wáyé.
Ẹgbẹ ASUU fi ikede yi sita loju opo Twitter wọn
Ohun ta gbo ni pe ipinu lati mu iyanṣẹlodi naa wa si opin waye lẹyin ipade kan laarin ijọba ati awọn ọmọ gbẹ naa labuja.
Gẹgẹ bi ohun ti a gbo,awọn akẹkọ ati olukọ ile ẹkọ yoo pada si iṣẹ lọla.
Nigeria Elections 2019: Àjọ elétò ìdìbò f'ọjọ kún gbedeke gbígba káàdì ìdìbò
Oríṣun àwòrán, INEC NIGERIA/FACEBOOK
Àjọ elétò kéde ọjọ́ ajé tó mbọ̀ láti gba káàdì ìdìbò
Ajọ eleto idibo orileede Naijireia Inec ti fi kun gbedeke ọjọ ti awọn oludibo yoo lanfani lati gba kaadi idibo wọn pẹlu ọjọ mẹta.
Ọjọ ẹti tii ṣe ọjọ kẹjọ oṣu keji ni wọn ti saaju da lọjọ gbedeke gbigba kaadi yii amọ bayi alaga ajọ naa ọjọgbọn Mahmood Yakubu ni awọn oludibo le gba kaadi naa titi di ọjọ Aje tii ṣe ọjọ kọkanla oṣu keji 2019.
Ojọgbọn Yakubu lọ kede isunsiwaju yi ninu ipade kan ti o ṣe pẹlu awọn adari eto idibo lawọn ipinlẹ lọjọ ẹti.
Inec ni  ọjọ abamẹta ati ọjọ aiku yoo kun ọjọ ti awọn eeyan yoo fi gba kaadi naa bẹrẹ laago mẹsan aarọ di ago mẹfa irọlẹ.
Kaadi idibo ọlọjọ pipẹ PVC ni ami idanimọ ti awọn oludibo yoo lo lati fi kopa ninu idibo  gbogbogbo 2019 to wole tan.
Eyi kii ṣe igba akọkọ ti ajọ Inec yoo sun gbedeke ọjọ gigba kaadi idibo siwaju-ọjọ kọkanlelogun oṣu kini 2019 ni wọn saaju da ṣugbọn wọn sun siwaju lẹyin ti wn ri pe pupọ ara ilu ni ko ri kaadi naa gba.
Kaadi idibo yi ni wọn fi aworan ati orukọ to fi mọ awọn iroyin miran to ṣe koko nipa oludibo si.Ẹni ti ko ba ni kaadi yi ko ni le dibo bẹẹ si ni eeyan kan ko le fi kaadi elomiran dibo
Ìjọba ìpínlẹ̀ Èkó -Àbẹ̀wò Buhari kò mú ìdìwọ́ bá lílọ bíbọ̀ ará ìlú
Oríṣun àwòrán, @followlasg
Ikede naa waye lati fi ọkan ara ilu balẹ pẹ ko ni si ọna ti wọn yoo ti pa
Ijọba ipinlẹ Eko ti kede pe awọn ko ni ti ọna kankan pa lasiko abẹwo Aarẹ Muhammadu Buhari si ipinlẹ naa.
Ikede yii jẹ iyipada ikede ti wọn ti saaju fi sita pe awọn oju ọna kan yoo wa ni titi pa nigba ti Aarẹ Buhari ba wa fun ipolongo idibo ni papa iṣere agbegbe Surulere lọjọ ti.
Komisana fun irina nipinlẹ Eko Ladi Lawanson ṣalaye loju opo Twitter  ijọba Eko pe iyipada yi waye lẹyin ti awọn ṣe agbeyẹwo eto irina ti wọn ti ṣe tele ti wọn si tẹti si ohun ti ara ilu sọ.
Inu fo aya fo lawọn ara ilu Eko kan wa lati igba ti ijọba kede titi awọn oju ọna kna pa nitori abẹwo Aarẹ Buhari sipinlẹ naa.
Lọpọ igba ti awọn alaṣẹ pataki bi Aarẹ ba ṣe abẹwo si ipinlẹ Eko ni inira ma a n ba ara ilu nipasẹ sunkere fakere ọkọ ti o ma n tele iru abẹwo bẹẹ.
Bi a ko ba gbagbe, ijọba ipinlẹ Eko ya ọjọ ọjọ́ kọkàndínlọ́gbọ̀n, Osù Kẹẹ̀ta ọdun to kọja gẹ́gẹ́bí ọjọ́ Ìsinmi fún àwọn òsísẹ́ ní ìpínlẹ̀ náà lasiko ti Aarẹ Buhari ṣe abẹwo sipinlẹ naa lati ṣe ifilọlẹawọn akanṣe iṣẹ kan.
Toun ti ikede yii, awọn to jade lawọn agbegbe kan ke irora latari sunkẹrẹ fakẹrẹ ọkọ to waye.
Awakọ̀ 3rd Mainland Bridge:  Ìjọba ko yanjú súnkẹrẹ fàkẹrẹ ọ̀nà Apapa
#2019NigeriaDecides Ìká wò ló lérò wí pé o yẹ láti fí dibo?
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Oṣiṣẹ Inec n salaye bi awọn oludibo yoo ti ṣe tẹ ika soju iwe idibo
Yoruba bọ wọn ni ika to ba tọ si imu laa fi n remu.
Amọ lasiko idibo gbogboogbo Naijiria ti o ku ọjọ diẹ, ika onikaluku ni ipa ti yoo ko sugbọn kii ṣe wi pe wọn yoo fi re imu.
Ika ni awọn oludibo yoo tẹ lati yan oludije to ba wu ọkan wọn fun ipo kipo ti wọn ba n dije fun.
Ọkọ àti ìyàwó sọ àsọtẹ́lẹ̀ tani yóò wọlé nínú PDP tàbí APC
Bi idibo naa ti ṣe ku ọjọ diẹ, ọrọ ika ti awọn oludibo le lo lati fi dibo ti ko si nii ṣe akoba fun ibo wọn lawọn eeyan n ran lẹnu.
Idi ni pe ti eeyan ko ba tẹ ika rẹ bi o ti ṣe yẹ s'aye ti INEC pese lori iwe idibo, irufẹ ibo bẹẹ ko ni jẹ itẹwọgba, eyi to ja si pe eni naa sọ ibo naa danu.
2019: Wo fídíò bí wọ́n ṣe sọ nǹkan lu àwọn adarí APC l'Abẹokuta
Tori ti awọn ẹgbẹ oṣelu ko fẹ ki ibo awọn sofo, pupọ ninu wọn ti n fi ipolongo sita loju opo Twitter ati ni aye ipolongo ibo fun awọn ọmọ ẹgbẹ wọn nipa ika to yẹ lati fi dibo.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ko si ika ti o ko le tẹ, ṣaa tẹẹ daadaa ni
Lara ohun ti wọn n sọ ni pe ika aarin a ma jẹ ki ọda itẹwe ti Inec pese fun ontẹ duro daada si aarin oju aye ẹgbẹ ti oludibo fẹ dibo fun.
Wọn gba awọn oludibo niyanju lati ma ṣe lo atanpako wọn fi dibo.
INEC: Ko si ika ti ẹ ko le lo lati dibo
INEC  fi alaye sita nipa awọn igbesẹ ti oludibo yoo gbe lasiko ibo bẹrẹ lati ibi ayẹwo oruko to fi de ori ika titẹ.
Labala ika titẹ, oun ti wọn sọ ni pe ki oludibo fi ika wọn kan ọda itẹwe ki wọn si fi ika ti wọn fi ọda si yii tẹ oju aye ẹgbẹ ti wọn fẹ lori iwe idibo.
Eyikeyi ninu gbogbo ika la le fi dibo.
#BBCNigeria2019: Nnamdi Kanu sọrọ lórí àwọn oludije PDP àti APC
Nigba ti BBC tẹsiwaju lati beere alaye lori ọrọ yii, Ijeoma Igbokwe to jẹ ọkan lara awọn oṣiṣẹ Inec lẹka idanilẹkọ nipa idibo sọ pe ko si ika ti eeyan ko le lo lati fi tẹka.
O ni 'ohun to ṣe pataki ni ki oludibo ma jẹ ki ami ika rẹ re kuro laarin alafo ẹgbẹ to fẹ yan si ibo miran.'
Femi Falana: kò yé kí ìdájọ́ òfin yàtó síra wọn ni Naijiria
'Ti ami naa ba ti kọja alafo naa, ibo oludibo bẹẹ ti gbofo ni yẹn.'
Ọjọ kẹrindinlogun ni idibo Aarẹ ati ti awọn asoju ile aṣofin yoo waye jakejado orileede Naijiria.
NFF: Olóògbé Taiwo Ogunjobi gbá bọ́ọ̀lù fún Nàìjírìa nígbà ayé rẹ̀
Oríṣun àwòrán, NFF
Taiwo Ogunjobi papoda
Ọpọ lo n ṣedaro akọwe ajọ to n ri si ere bọọlu lorilẹede Nàìjíríà, NFF tẹ́lẹ̀rí, Taiwo Ogunjobi.
Ogunjọbi papoda lowurọ ọjọ Aje, ọjọ kọkanla oṣu keji odun 2019 niluu Ibadan lapa iwọ oorun gusu Naijiria.
Ajọ NFF lo kede iku rẹ loju opo Twitter wọn.
Ogunjọbi ṣe akọwe ajọ NFF laarin ọdun 2002 si ọdun 2005, bẹẹ o jẹ ọmọ igbimọ alaṣẹ ajọ NFF laari ọdun 2006 ati 2010.
Ogunjọbi jade laye lẹni ọdun marun le lọgọta nigba ti o pe ọdun marunlelọgbọn ti o ṣoju orilẹede Naijiria fun igba akọkọ ninu ifẹsẹwọnsẹ pẹlu Morocco lọdun 1984.
Ọgbẹni Tunde Shamsudeen to jẹ amugbalẹgbẹ rẹ ṣalaye pe oloogbe Ogunjobi lọ si ile iwosan lọjọ Abamẹta ki awọn dokita to ni ko lọ sinmi.
Oríṣun àwòrán, @Emiearth
Taiwo Ogunjobi
Lẹyin igba naa ni Ogunjobi di oloogbe laarọ ọjọ Aje, ile iwosan ko sọ iru aisan kan gbogi to pa oloogbe naa.
Ogunjobu gba bọọlu fun gbajugbaja ẹgbẹ agbabọọlu un ni Shooting Stars ti ilu Ibadan.
Oun ni balogun ikọ agbabọọlu Shooting Stars to kopa ninu ifẹsẹwọnsẹ aṣekagba idije Ife Ẹyẹ ilẹ Afirika lọdun 1984 ti o ti di African Champions League bayii.
Taiwo Ogunjobi di oloogbe
Wọn fẹsun wi pe o wa lara awọn mẹrin ti o mọ nipa bi miliọnu mẹjọ owo dọla ti poora lasiko ti idije ife ẹyẹ agbaye n lọ lọwọ lọdun 2010.
Ṣugbọn ile ẹjọ dajọ are fun un ko jẹbi ẹsun ti wọn kan an lẹyin iwadi ti wọn ṣe.
Ogunjọbi dije lẹẹmeji fun ipo aarẹ ajọ NFF, ṣugbọn o fidi rẹmi lẹyin ti Amaju Pinnick wọle lẹẹmejeeji.
Oloogbe Ogunjọbi jẹ alaga ajọ ere bọọlu nipinlẹ Oṣun ki ọlọjọ to de.
Walter Onnoghen: UNO bẹnu àtẹ́ lu ìdàdúró adájọ́ àgbà
Oríṣun àwòrán, NJC
Ọrọ lori idaduro Onnoghen
Ajọ iṣokan agbaye iyẹn UNO ti bu ẹnu atẹ lu bi wọn ṣe ni ki adajọ agba lorilẹede Naijiria Wallter Onnoghen lọ rọkun nle.
Ajọ UNO sọ pe igbesẹ yii tako ẹtọ ọmọniyan lagbaaye.
Agbẹnusọ fun ajọ agbaye ṣalaye pe
ile ẹjọ to dawa nikan lo laṣẹ lati yọ awọn adajọ nipo.
Ọkọ àti ìyàwó sọ àsọtẹ́lẹ̀ tani yóò wọlé nínú PDP tàbí APC
Ẹwẹ, Aarẹ Muhammadu Buhari sọ pe o gbe igbesẹ lati rọpo adajọ Onnoghen lẹyin ti ile ẹjọ to n ri si igbẹjọ iwa ibajẹ awọn oṣiṣẹ ọba paṣẹ bẹẹ.
Ṣugbọn ajọ agbaye sọ pe ile ẹjọ mẹrin ọtọtọ lo ti dajọ pe ki wọn da igbẹjọ Onnoghen duro.
Nibi osẹ meji sẹyin ni aarẹ Buhari fi adajọ Ibrahim Tanko Muhammad rọpo Onnoghen.
Bẹẹ lawọn ẹgbẹ oṣelu alako bu ẹnu atẹ lu igbesẹ ọhun, wọn ni oṣelu ni ijọba Aarẹ Buhari fi ọrọ naa ṣe.
Ilẹ Gẹẹsẹ, Amẹrika ati Ilẹ Alawọfunfun(EU) naa kuro oju si asiko ti ijọba ni ki adajọ Onnoghen lọ rọkun nle.
Adajọ agba lorilẹede Naijiria lagbara lati yanju awuyewuye lori esi idibo.
Àwọn jàǹdùkú sọ Ààrẹ Buhari, Dapọ Abiọdun lókúta nílùú Abẹokuta
Oríṣun àwòrán, Bashir Ahmad
Wàhálà ti wà nílẹ̀ láàárín gómìnà Amosun àti àwọn adarí ẹgbẹ́ òṣèlú APC lórí ẹni tí yóò díje fún gọmìnà ní ìpínlẹ̀ Ogun.
Yanpọnyanrin bẹ silẹ nibi ipade ipolongo ibo ti ẹgbẹ oṣelu APC ṣe ni ipinlẹ Ogun nibi ti aarẹ Muhammadu Buhari ati ikọ ipolongo rẹ ti n polongo ibo aarẹ ti yoo waye ni ọjọ abamẹta ọsẹ yii.
Ọkọ àti ìyàwó sọ àsọtẹ́lẹ̀ tani yóò wọlé nínú PDP tàbí APC
Bi awọn ero ti ṣe wa ni gbagede papa iṣire MKO Abiola nilu Abẹokuta lati pade aarẹ Buhari ni awọn eeyan kan ti ọpọ gbagbe pe wọn jẹ ọmọ ẹgbẹ oṣelu kan ṣa dede bẹrẹ si ni le awọn ololufẹ oludije ipo gomina lẹgbẹ oṣelu APC, Dapọ Abiọdun kuro ni ori ijoko wọn.
Iroyin sọ pe awọn janduku naa bẹrẹ si nii lọ kaakiri ijoko ni papa iṣire naa ti wọn si n le awọn ti wọn ba funra si pe wọn jẹ ololufẹ Dapọ Abiọdun kuro ni aye wọn.
Oríṣun àwòrán, Bashir Ahmad
Awọn janduku kọlu Buahri atawọn adari ẹgbẹ oṣelu APC
Nṣe lawọn eeyan naa n sare gun ori odi ti wọn mọ yii papa iṣire naa ka lati sa asala fun ẹmi wọn.
Iroyin sọ pe, oniruuru ohun ija bii apola igi ati ogun abẹnugọngọ ni awọn janduku naa ko da ni ti wọn si n kọlu ẹnikẹni ti wọn ba ri to wọ aṣọ alawọ rẹsurẹsu , iyẹn awọ ti wọn mọ mọ awọn ololufẹ Dapọ Abiọdun, oludije ipo gomina ni ipinlẹ Ogun.
Nṣe ni wọn fara gbọgbẹ loriṣiriṣi lasiko ti wọn fi n gbiyanju lati sa asala fun ẹmi wọn.
Nitori ati yẹra fun ikọlu awọn janduku naa, nṣe ni gbogbo wọn n bọ aṣọ ti wọn wọ gbogbo to ni ami idanimọ Dapọ Abiọdun lara
Onnoghen: Nítorí EFCC, ìgbìmọ̀ ìṣèdájọ́ tó ga jùlọ, NJC kọ̀wé ìfisùn tuntun ránṣẹ́ sí Onnoghen
Oríṣun àwòrán, concisenews
Ìgbìmọ̀ ìṣèdájọ́ tó ga jùlọ, NJC ní àwọn yóò pàdé lọ́jọ́rú láti yẹ àbájáde rẹ̀ wò.
Igbimọ idajọ orilẹede Naijiria, NJC ti kọ iwe tuntun ranṣẹ si adajọ agba orilẹede Naijiria, ti wọn ni ko lọ rọọkun nile fun igba diẹ, Walter Onnoghen lati wa wi tẹnu rẹ lori iwe ẹsun tuntun ti ajọ to n risi iwa ijẹkujẹ lorilẹede Naijiria, EFCC kọ ranṣẹ si igbimọ naa n itori Onnoghen.
Ni ọjọ aje ni igbimọ naa gbe igbesẹ ati kọwe naa nibi ipade pajawiri to ṣe nilu Abuja.
Igbimọ naa tun pinnu lati gbe igbimọ alabẹṣekele kan kalẹ lati wo awọn ẹsun ti wọn fi kan Onnoghen ati adele adajọ agba, Tanko Muhammad.
Igbimọ NJC ti kọkọ kọwe ranṣẹ si awọn adajọ agba mejeeji yii nibi ijoko rẹ lọjọ kọkandinlọgbọn oṣu kinni ti wọn si fun wọn ni gbedeke ọjọ meje lati dahun si ẹsun ti wọn fi kan wọn.
'Gbogbo olùdíje Ogun fi dá àwọn ènìyàn lójú pé...'
Alukoro igbimọ iṣedajọ agba orilẹede Naijiria, Sọji Oye ni igbims naa tẹwọ gba iwe ifisun tuntun latọdọ ajọ EFCC lo faa ti wọn fi tun kọwe pada si adajọ agba naa lati fi esi sii laarin ọjọ meje.
O ni ọjọru tii ṣe ọjọ kẹtala oṣu keji ọdun 2019 ni igbims naa fi ipade si lati  tẹwọ gba abajade iṣẹ igbimọ alabẹ ṣekele ti wọn gbe kalẹ lori rẹ ni ibamu pẹlu abala kẹtadinlogun iwe ofin igbimọ iṣedajọ to ga julọ lorilẹede Naijiria.
NIgeria 2019 Elections: Clinton ní kí wọn má fojú òṣèlú wo àbẹ̀wò òun
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ọrọ idibo Naijiria
Aarẹ orilẹede Amẹrika tẹlẹ ri, Bill Clinton ti fagile abẹwo rẹ si orilẹede Naijiria.
Igbimọ to n ri si eto alaafia ṣaaju eto idibo gbogbogbo ọdun yii lo fiwe pe Clinton wa si Naijiria.
Ọgbẹni Clinton nireti wa tẹlẹ pe yoo sọrọ iyanju nibi eto fifi ọwọ si iwe adehun lori bi alaafia yoo ṣe jọba lasiko idibo.
BBC Nigeria 2019: Lekan Kingkong ní a kò fẹ́ ìtàsílẹ̀ àti ikú ọ̀dọ́ lásìkò ìbò
Ọjọ Iṣẹgun ọjọ Kejila si Ọjọru ọjọ Kẹtala osu Keji ọdun 2019 si leto naa yoo waye.
Agbẹnusọ fun aarẹ ana ni Amẹrika naa, Angel Urena, to fọrọ naa lede sọ pe, wọn fagile abẹwo Clinton ọhun tori pe awọn kan le fẹ fi ọrọ oṣelu wo abẹwo rẹ.
Day 19: Wo ohun àràmàndà tí àwọn olósèlú máa ń ṣe lásìkò ìbò #BBCNigeria2019
O ṣalaye pe, Ọgbẹni Clinton yoo ba Aarẹ Muhammadu Buhari, to jẹ oludije fun ipo aarẹ ẹgbẹ APC, ati Atiku Abubakar to n dije fun ipo aarẹ labẹ asia ẹgbẹ PDP sọrọ.
Bakan naa ni yoo tun ba olori orilẹede Naijiria tẹlẹ ri, ọgagun fẹyinti Abdulsalam Abubakar sọrọ lọsẹ yii, lori igbesẹ rẹ.
Babachir Lawal: Akọ̀wé ìjọba àpapọ̀ nígbà kan rí ní òun kò jẹ̀bi ẹ̀sùn àjẹbánu
Oríṣun àwòrán, @officialefcc
Akọwe ijọba tẹlẹ dero ile ẹjọ
Akọwe ijọba apapọ tẹlẹ ri Babachir Lawal, ti foju ba ile ẹjọ loni ọjọ Iṣẹgun l'Abuja lẹyin ti ajọ to n gbogun ti iwa ajẹbanu EFCC ju si atimọle lọjọ Aje.
Ajọ EFCC gbe Ọgbẹni Lawal ati marun un miran lọ ile ẹjọ lori ẹsun onikoko mẹwaa to da lori nina owo to ju ilaji biliọnu kan naira lati fi pa koriko.
Awọn miran ti wọn jọ fẹsun kan ni Hamidu David Lawal, Sulaiman Abubakar, Apeh John Monday, ile iṣẹ Rholavision Engineering Limited ati Josmon Technologies Limited.
Ile ẹjọ giga kan ni Abuja ni wọn gbe e lọ ti o si sọ wipe oun ko jẹbi ẹsun ṣiṣe owo ilu ni kumọkumọ.
EFCC ni, akọwe agba fun ijọba apapọ tẹlẹ ri naa ni ipin tirẹ ti yoo gba ninu iṣẹ to gbe fun ile isẹ Rholavision Engineering Limited ati Josmon Technologies Limited lati ṣe.
BBC Nigeria 2019: Lekan Kingkong ní a kò fẹ́ ìtàsílẹ̀ àti ikú ọ̀dọ́ lásìkò ìbò
2019 Elections: PDP ní àmì pé ayé ti kọ ìjọba Buhari ní wọn ṣe ju òkúta lù wọ́n
Oríṣun àwòrán, @ledon_ng
Ọpọ eeyan lo ti n sọ ero ọkan lori isẹlẹ to waye nilu Abẹokuta lọjọ Aje nigba ti awọn eeyan kan to peju sibi ipolongo ibo, bẹrẹ si ni sọ oko ati ọra omi lu awọn asaaju ẹ́ẹgbẹ oselu APC.
Aarẹ Muhammadu Buhari gan wa nikalẹ lasiko ti isẹlẹ ọhun waye.
Nigba to n fesi lori isẹlẹ yii, ẹgbẹ alatako gboogi ninu idibo to n bọ, PDP, ninu atẹjade kan to fisita ni, o yẹ ko ye ẹgbẹ oselu APC pe ami pe aye ti kẹyin si ẹgbẹ oselu naa, ni isẹlẹ naa jẹ.
PDP ni o yẹ ka kiyesi pe awọn eeyan naa ju oko lu Buhari lẹyin ọjọ kan soso pere ti ipolongo ibo waye nipinlẹ Zamfara, nibi ti Buhari ti n ru awọ̀n eeyan ibẹ lọkan lati dara pọ ẹgbẹ APC ninu ete lati da rogbodiyan silẹ lasiko ibo to n bọ.
Ẹgbẹ oselu alatako naa ni, awọn eeyan ipinlẹ́ Ogun ati Naijiria lapapọ ti kọ ijọba aarẹ Muhammadu Buhari, nirori irora, iṣẹ, oṣi, iwa ajẹbanu ati itajẹsilẹ to n waye laarin ọdun mẹrin to fi dari Naijiria.
BBC Nigeria 2019: Lekan Kingkong ní a kò fẹ́ ìtàsílẹ̀ àti ikú ọ̀dọ́ lásìkò ìbò
Sugbọn loju opo ikansira ẹni lori ẹrọ ayelujara, oju ọtọtọ ni awọn eeyan fi wo isẹlẹ naa.
@mynameisgafar loju opo Twitter rẹ ni, oun foju laifi wo iwa awọn eeyan to sọ okuta lu aarẹ Buhari. O ni bi o tilẹ jẹ pe oun ko nifẹ rẹ, sugbọn o yẹ ka bu ọwọ nla fun nitori ipo nla to di mu, ibi ti a sa pe ni ori, ẹnikan kii fi ibẹ tẹ ilẹ.
@Chizybae, lero tiẹ ni ohun ti yoo sẹlẹ ree ti eeyan ba ko ilu sinu isẹ ati ọwọn gogo ọja.
@kcnaija loju opo Twitter tiẹ ni, o yẹ ka takete si ohunkohun to lee farajọ iwa jagidi jagan lasiko ibo to n bọ, paapa ninu eto oselu wa. Ko si baa ti korira igun keji si, ti a ko fara mọ wọn.
Ìtàn Mánigbàgbé: Bí Ẹfunroye Tinubu ṣe di ilú Ẹ̀gbá mú, ló ń pàṣẹ ní Eko
Oríṣun àwòrán, @pin_africa
Ti a ba n sọrọ awọn akọni obinrin nilẹ Yoruba, ti a ko ba ti darukọ Iyalode akọkọ nilẹ Ẹgba, Ẹfunroye Tinubu, a jẹ pe itan naa ko ti kun ni.
Ni ilu Eko, Badagry ati Ẹgba, okiki arabinrin Ẹfunroye Tinubu tan kaakiri nitori pe ọlọla ni, o gbajumọ, to si tun jẹ gbajumọ onisowo ẹru, ọti oyinbo ati awọn ohun ija oloro.
Ko fẹẹ si ọba kankan laye Tinubu, ti yoo kọ iyan akọni obinrin naa, ti ko ni fi ewe boo, nitori pe alagbara ni, to si n fi ọba jẹ, bẹẹ lo n rọ ọba loye.
Oríṣun àwòrán, @DradrockE
Gẹgẹ bi a ti se akojọ rẹ loju opo itakun agbaye, ibẹru Ẹfunroye Tinubu laye igba rẹ, ni ipilẹsẹ ọgbọn fun awọn oriade nilu Eko ati Ẹgba.
Awaye ku ko si, ọrun ma kanju, gbogbo wa la n bọ, ti ina yoo si dilẹ lẹyin asunsun jẹ.
A ba jẹ obinrin, tabi ọkunrin, o yẹ ka ranti pe isẹ ọwọ wa, yoo maa tọ wa lẹyin ta ba lọ tan.
Ohun ta ba se laye lo ja ju, tori naa, ẹjẹ ka gbe ile aye se rere nitori bo pẹ, bo ya, bi onirese wa ko ba fin igba mọ, eyi to ti fin silẹ ko lee parun.
#BBCNigeria2019: Ajọ UN ṣètò ìlanilọ́yẹ̀ láti dènà màgòmágó ìbò
Ajọ to n wa idagbasoke ilẹ adulawọ labẹ ajọ isọkan orilẹede agbaye, UNDP pẹlu ifọwọsowọpọ ajọ eleto idibo nil wa, INEC ati igbimọ ajọ to n wa ifẹsẹmulẹ alafia, ti ṣe agbekalẹ ilanilọyẹ fun àwon ẹgbẹ oṣelu ni Ipinlẹ Kwara.
Ninu ọrọ rẹ, aṣoju akowe agba fun ajọ UN, Mohamed Ibn Chambas salaye pe, wọn ṣe agbekale eto naa lati rii daju pe, ko si magomago ninu idibo to n bọ yii.
Chambas ni ipo Naijiria ṣe pataki nilẹ Afrika ati ni agbaye, eyi lo fi ṣe pataki ki orilẹede yii ṣe idibo ti ko ni mu wahala wa, ti yoo si lọ ni irọwọrọsẹ.
Aṣoju akowe agba fun ajọ UN, Mohamed Ibn Chambas ni ko gbọdọ si magomago ninu idibo 2019
Ninu ọrọ rẹ, ọga agba eleto idibo ní ipinlẹ Kwara, Malam Garba Attahiru lasiko to n ba awọn eniyan sọrọ salaye pe, gbogbo awọn oloṣelu gbọdọ ṣe awari ara wọn.
O fikun pe o yẹ ki wọn si maa fi eri ọkan ṣe lasiko idibo. O  fi kun pe awọn n ṣe aṣepọ pelu gbogbo akojọpọ awọn eleto aabo ki eto aabo le kẹsẹ jari.
O ni laisi alafia, idibo ko le waye, o si ṣe pataki ki awon obi b'oju to awọn ọmọ wọn daradara ki awọn oloṣelu maa baa lo won lo lasiko ibo.
Eto ipade alafia naa to waye ni ilu ilorin, ni awọn aṣoju ẹgbẹ oṣelu, CAN, IPAC, UN, awọn iyalọja, aṣoju awọn eleto aabo pẹlu awọn lọbalọba peju si.
Ọ̀gá àgbà Fásitì Eko sọ ohun tí àwọ́n obìnrin lè fi tayọ
2019 Elecftions: Ìyàwó Atiku ní dídùn lọsàn yóò so fún ọkọ òun
Ìyàwó Atiku Abubakar ṣalàyé pé ó dájú pé Atiku Abubakar ni ààrẹ tó kàn lórílẹ̀èdè Nàìjíríà
Iyawo oludije fun ipo aarẹ lẹgbẹ oṣelu PDP, Atiku Abubakar, arabinrin Titi Abubakar ti sọ pe ọkọ oun, Atiku Abubakar ni aayo awọn araalu kaakiri orilẹede Naijiria.
Titi Abubakar ṣalaye ọrọ yii, lasiko ti ikọ ipolongo ẹgbẹ oṣelu PDP pẹlu oludije fun ipo aarẹ labẹ aṣia ẹgbẹ oṣelu naa, balẹ si gbagede Tafawa Balewa Square, TBS nilu Eko.
BBC Nigeria 2019: Lekan Kingkong ní a kò fẹ́ ìtàsílẹ̀ àti ikú ọ̀dọ́ lásìkò ìbò
Ninu ifọrọwerọ rẹ pẹlu BBC News Yoruba, Arabinrin Titi Abubakar ni, o da oun loju pe Atiku Abubakar ni yoo bori ibo aarẹ ti yoo waye lọjọ abamẹta jakejado orilẹede Naijiria.
Omilẹgbẹ awọn ero ni wọn ti gunlẹ si gbagede Tafawa Balewa (TBS) lati pade oludije fun ipo aarẹ lẹgbẹ oṣelu naa, Atiku Abubakar ati ikọ rẹ.
Titi Abubakar tun ṣalaye pe, bi ọkọ oun ba fidirẹmi ninu idibo naa, oun yoo gba fun Ọlọrun lori rẹ.
Awọn ero ni gbagede TBS nibi ipolongo PDP
Amọṣa, o ni 'bi gbogbo nnkan ṣe n lọ lasiko ipolongo kaakiri tibu-toro Naijiria, o daju pe Atiku ni yoo di aarẹ Naijiria.'
Awọn adari ẹgbẹ oṣelu PDP miran to tun ba BBC News Yoruba sọrọ pẹlu ni, didun lọsan yoo so fun ẹgbẹ oṣelu naa lọjọ abamẹta.
Wọn fi idaniloju han pe ko sewu fun ilepa Atiku Abubakar lati di aarẹ orilẹede Naijiria.
2019: Wo fídíò bí wọ́n ṣe sọ nǹkan lu àwọn adarí APC l'Abẹokuta
2019 Elections: APC ní Amosun l‘eku ẹdá ìṣẹ̀lẹ̀ ìkọlù Buhari l'Abẹokuta
Oríṣun àwòrán, APC
Ẹgbẹ́ òṣèlú APC ní àwọn kábámọ̀ ìdójútì ńlá tí àwọn jàǹdùkú náà kó bá Ààrẹ Buhari
Lẹyin yanpọnyanrin to waye nibi ipolongo idibo aarẹ Buhari ati APC nilu Abẹokuta ni ọjọ Aje, ẹgbẹ oṣelu APC ti sọ pe gomina Ibikunle Amosun ko ni lọ lai fara gb'ẹgba sẹria to ba tọ, lati ọdọ awọn alaṣẹ ẹgbẹ oṣelu naa.
Okiki kan ni ọjọ Aje nipa ipolongo idibo ti aarẹ Muhammadu Buhari pẹlu ẹgbẹ oṣelu rẹ, iyẹn APC ṣe ni ilu Abẹokuta.
Okiki to kan kii ṣe tori pe aarẹ lọ ṣe ipade ipolongo ibo nibẹ nitori omilẹgbẹ irufẹ eto ipolongo ni aarẹ ti gbe ṣe lati igba ti o ti bẹrẹ ilepa fun saa keji gẹgẹ bii aarẹ orilẹede Naijiria.
Amọṣa ohun to mu ki eyi ṣaraọtọ ni ti yanpọnyanrin to waye, iyẹn bi awọn kan ṣe bẹrẹ si ni ju oko atawọn nnkan miran ti ọwọ wọn ba ba, lu awọn aṣaaju ẹgbẹ oṣelu naa ninu eyi ti aarẹ paapaa ko gbẹyin nibẹ.
BBC Nigeria 2019: Lekan Kingkong ní a kò fẹ́ ìtàsílẹ̀ àti ikú ọ̀dọ́ lásìkò ìbò
Eleyii ti ko tii ṣẹlẹ rii lati igba ti aarẹ ti bẹrẹ ipolongo rẹ kaakiri orilẹede Naijiria.
Ibeere ti ọpọ n beere bayii ni pe, niwọn igba to jẹ pe gomina Amosun to ni aawọ pẹlawọn eekan ẹgbẹ oṣelu naa kan, lawọn eeyan n tọka si gẹgẹ bii eku ẹda to da rukerudo naa silẹ, ṣe ẹgbẹ yoo da sẹria fun?
Oríṣun àwòrán, APC
APC ni sẹria to tọ yoo wa fun Amosun
"Ninu atẹjade kan ti alukoro ẹgbẹ oṣelu APC, Lanre Issa-Onilu fi sita ni ọjọ Iṣẹgun, ẹgbẹ oṣelu APC ""yoo gbe iwa aṣemaṣe naa yẹwo lati gbe igbesẹ to ba yẹ ni kete ti idibo ba pari""."
O ni ẹgbẹ APC kabamọ iwa naa, eleyii to ni gomina Amosun ṣe agbatẹru rẹ atipe, ko si aniani kan lori agbara ẹgbẹ oṣelu ati iwa ọmọluabi gẹgẹ bii iwe ofin ẹgbẹ oṣelu APC ti ṣe laa kalẹ fun gbogbo ọmọ ẹgbẹ lai yọ ẹnikẹni silẹ.
2019 Elections: Ṣé òṣì n pọ̀ si tàbí o n dínkù láwùjọ?
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Orilẹede Naijiria ni eto ọrọ aje rẹ tobi julọ ni Afrika, oun naa si lo n pese eporọbi julọ.
Ṣugbọn, oun kan naa ni orilẹede nibi ti ilaji awọn to n gbe ninu rẹ si n gbe ninu ìṣẹ́ ati òṣì- ìdá ọgọta ninu wọn ni ko si le gba ile gbigbe to dinwo julọ.
Bakan naa ni awọn to lowo pupọ naa wa, alaafo to si wa laarin olowo ati talaka ko farapamọ rara, gbogbo oju lo n ri ni awọn ilu nlanla to wa ni Naijiria.
Ni ipalẹmọ fun eto idibo ti yoo waye lọjọ kẹrindinlogun, oṣu Keji, BBC Reality Check ṣe agbayẹwo rẹ boya awọn talaka n talaka si, ati boya alaafo to wa laarin olowo ati talaka n pọ si.
Ijọba to wa ni iṣakoso n tẹnumọ pe oun ti pa ìṣẹ́ run, to si n di ẹbi ru awọn iṣakoso to kọja pe wọn ṣe aṣilo ileeṣẹ eporọbi ati ọrọ aje.
Ọjọgbọn Ọṣinabajo to jẹ igbakeji aarẹ Muhammadu Buhari sọ pe ''kii ṣe pe oṣi ti tan patapata o. Nnkan ti mo n sọ ni pe ọrọ ìṣẹ́ ati oṣi la n ba a finra lọwọlọwọ.
Oríṣun àwòrán, AFP
Olori alatako Buhari ninu eto idibo to n bọ, Atiku Atiku Abubakar, sọ pe eto ọrọ aje Naijiria ko buru to boṣe wa bayi ri.
Ibeere to ṣe koko ju lasiko eto idibo yii ni pe: ṣe igbeaye rẹ dara ju boṣe wa ni dun mẹrin sẹyin, ṣe o lowo si ni tabi o toṣi si?
Laipẹ yii ni ọrọ aje Naijiria ṣẹṣẹ fi àpẹrẹ ipadabọ sipo han, lẹyin ti didojuru rẹ dopin lọdun 2017.
Akọsilẹ iye awọn ti ko niṣẹ lọwọ ti ileeṣẹ National Bureau of Statistics fi sita ju ìdá ogun lọ.
Akọsilẹ miran tun niyi - bi ìdá ọgọta ni awọn to n gbe ninu òṣì tó pọ̀ - ohun ti wọn fi ṣe odiwọn rẹ ni iye awọn to jẹ pe ile gbigbe, ounjẹ ati aṣọ nikan ni agbara wọn ka.
Botilẹjẹ wi pe ko si akọsilẹ tuntun, awọn onimọ ri i pe igbeaye awọn to toṣi ju ko fi bẹ ẹ dara ju ti tẹlẹ lọ.
Oríṣun àwòrán, Alamy Stock Photo
Ajọ agbaye woye pe ọpọ awọn to n gbe ni igboro ni orilẹede Naijiria lo n gbe awọn agbegbe ti ko bojumu
"Ìṣẹ́ ati oṣi ""ko parapọ rara"""
Ọpọ̀ lo gbagbọ pe aidọgba n pọ si lojoojumọ.
Onimọ kan, Abdulazeez Musa tilẹ sọ pe ọjọ ti pẹ ti inakuna, iwa ibajẹ ati aibọwọ fun ilana ti wa ni Naijiria, eyi naa si lọwọ si bi ọpọ eniyan ṣe n gbe ninu oṣi.
Oríṣun àwòrán, AFP
Sokoto ni awọn to toṣi pọ ju si ni Naijiria
Awọn ipinlẹ to wa ni Ariwa Naijiria ni òṣì pọ si ju awọ̀n to wa ni Gusu lọ.
Ipinlẹ Sokoto to wa ni ẹkùn Iwọ oorun Ariwa ni oṣi pọ si julọ, pẹlu ìdá mọkanlelọgọrin, nigba ti ipinlẹ Eko, ni ẹkun Iwọ oorun Gusu wa ni ìdá mẹrinlelọgbọn.
Ọkan lara awọn oludije fun ipo gomina nipinlẹ Eko, Omolara Adesanya sọ pe ''oṣi to n ba wa finra, ko farapamọ rara.''
Bi ilaji awọn to n gbe ni Naijiria lo n gbe ni igboro - ọpọlọpọ awọn ile ti wọn ṣẹṣẹ kọ si awọn adugbo to joju ni gbese ni ilu Eko lo ṣófo, ti awọn adugbo ti ko ri bẹ si kun fọfọ.
Ajọ awọn orilẹede (UN), woye pe ida mọkandinlaadọrin awọn to n gbe ni igboro l'orilẹede Naijiria lo n gbe ni awọn agbegbe to ku diẹ kaato, ti awọn ti ko rile gbe si n lọ si bi miliọnu mejidinlogun.
Ìdá bi ogoji pere ni mọlẹbi to lowo lati gba ile tuntun ti owo rẹ kere ju.
Oríṣun àwòrán, AFP
Orilẹede Naijiria wa lara awọn ti eniyan rẹ n pọ si ju lagbaye
Banki agbaye paapa sọ pe orilẹede Naijiria lo ni awọn akuṣẹ julẹ ni agbaye bayii.
Nigeria Elections 2019: Aranṣọ, olórin àti àwọn mì í tó maa n fẹ́ kí ìdìbò wáyé ní Nàìjíríà lójoojúmọ́
Okunnrin yi wa gbiyanju aje nibi ipade apapọ ẹgbẹ PDP ti wọn ti yan oludije sipo Aarẹ ẹgbẹ naa
Asiko eto idibo jẹ asiko to n pa ọpọlọpọ owo wọle fun Naijiria, ti awọn oloṣelu ati ẹgbẹ oṣelu wọn si maa na baba nla owo lati ri i daju pe ẹgbẹ wọn lo bori.
Amọ bi wọn ṣe n na owo wọn, o ni awọn kan to n janfaani gbogbo mudun-mudun gbogbo nkan. Ṣe ti awọn to n tẹwe ni ka sọ ni, tabi awọn ọlọkọ ero to fi mọ awọn janduku.
Oya, ẹ jẹ ka jọ wo awọn ti asiko idibo jẹ asiko yata-yoto fun.
Asiko idibo maa n pese iṣẹ ati owo pupọ fun awọn to n tẹwe.
Nitori pe awọn ni yoo tẹ iwe ipolongo, fila, aṣọ, patako ipolongo, ankara ẹgbẹjọda, ati ṣiṣe ọkọ awọn oloṣelu loge pẹlu iwe ipolongo.
Awọn oloṣelu maa n haya ọkọ lati gbe awọn alatilẹyin wn kaakiri lasiko ipolongo wọn.
Awakọ kan nipinlẹ Eko, Adaba Iyiola sọ fun BBC pe awọn fẹran lati maa ṣiṣẹ fun awọn oloṣelu nitori pe owo maa n wọle daada botilẹ jẹ pe wn maa n gbafẹ ni nibi ipolongo.
"O ni ''owo ti wọn maa n san fun wa maa n ju owo to yẹ ki a pa loojọ lọ."""
Awọn wọnyii lo n ṣakoso adugbo kọọkan ni awọn ilu nlanla. Wọn si maa n tẹle awọn oloṣelu kaakiri.
Botilẹ jẹ wi pe koko iṣẹ ti wọn n ṣe ko ṣe e sọ, awọn ọmọ ita yi maa n gba owo 'iṣakọlẹ' ki wọn le jẹ ki alaafia o jọba nibi ati lasiko ti awọn oloṣelu ba ti n polongo.
Ipolongo ibo laisi orin ati ijo dabi ounjẹ ti ko ni iyọ.
Awọn olorin ati onijo maa n wa nikalẹ lati da awọn to wa fun ipolongo laraya, ko si ba ọfẹ de o.
Awọn olorin bi i Wasiu Ayinde (K1), Small Doctor, Davido, Saheed Oṣupa, Ọlamide, ati bẹẹbẹ lọ naa ti se e ri.
Awọn miran a tilẹ maa fi orin wọn sọko eebu si awọn ẹgbẹ alatako.
Asiko ipolongo jẹ asiko iṣẹ fun awọn eleto aabo naa, nitori wọn maa n wa ni awọn ibudo ipolongo ibo lati ri i pe wahala kankan ko ṣẹlẹ.
Awọn miran tilẹ maa n ṣiṣẹ loru, ṣugbọn wọn maa n gba owo fun pe wọn ṣiṣẹ tayọ akoko to yẹ.
Ajọ INEC maa n ṣeto to yẹ fun awọn naa.
Asiko iṣẹ ni asiko eto idibo jẹ fun awọn to maa nkiri ọja. Ko si ibi ti ipolongo ibo ti n waye, ti ki i ṣe awọn ni yoo kọkọ de ibẹ.
Bẹrẹ lati ori irẹsi sise, to fi mọ ipanu loriṣiriṣi ati omi tutu. Ọti ati awọn nkan mimu yooku gan kii gbẹyin.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Plenti politicians dey buy local cloth wey dem dey call ankara dey share am to dia supporters. Ọpọ oloṣelu lo maa n ra awn aṣọ ankara lati pin fun awọn alatilẹyin wọn.
Eyi maa n mu ki awọn to n ta aṣọ ankara ati awọn aranṣọ ta daada.
Lasiko eto idibo, ajọ eleto idibo Naijiria, INEC, maa n gba awọn ọdọ to n sinru ilu lati ba a ṣiṣẹ.
O si ni eto owo ti wọn maa n san fun awọn agunbanirọ naa. Eyi to tumọ si wi pe awọn ọdọ to ba sinru ilu lasiko eto idibo maa n ri owo yatọ si alawi wọn.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
2019 Elections: NCC ní ìròyìn òfégè ni pé ìjọba yóò ti afẹ́fẹ́ ìbánisọ̀rọ̀ pa lọ́jọ́ ìbò
Oríṣun àwòrán, @VeridicTech
Ileeṣẹ to n mojuto eto ibanisọrọ ayelujara lorilẹ-ede Naijiria, NCC ti sọ pe, ko si ootọ ninu iroyin kan to n lọ kaakiri pe ijọba apapọ n gbero lati ti oju opo ibanisọrọ GSM gbogbo lorilẹ-ede Naijiria pa.
Iroyin ti ajọ NCC ni ofege ni naa ni ijọba fẹ ṣe eyi lasiko idibo apapọ to n bọ.
BBC Yorùbá: Ìbò rẹ ni agbára rẹ, jáde lọ dìbò
Ninu ọrọ to ba BBC News Yoruba sọ, agbẹnusọ fun ajọ NCC lorilẹ-ede Naijiria, Nnamdi Nwokike ṣalaye pe, iroyin ẹlẹjẹ lasan ni iroyin naa ati pe kii ṣe iroyin to ṣee gbọ seti rara.
Ni ọjọ Iṣẹgun ni gomina tẹlẹ ni ipinlẹ Ekiti, Ayọdele Fayoṣe gbe si ori ikanni twitter rẹ pe, iroyin ti lu si oun lọwọ pe ijọba apapọ yoo sọ agadangodo si ibanisọrọ GSM ati ikanni ayelujara, laarin agogo marun un idaji ọjọ Abamẹta tii ṣe ọjọ idibo aarẹ, di agogo marun un irọlẹ ọjọ Aiku.
Ademọla Ogunbanjo: A nílò bàbá ìsàlẹ̀ nínú òsèlú
Agbẹnusọ fun ileeṣẹ NCC, Nnamdi Nwokike ni iroyin ofege ni eyi ati pe ko si bi ijọba apapọ ṣe lee maa gbe iru igbesẹ ni iru saa ti oju la de lorilẹ-ede Naijiria bayii.
O ni gẹgẹ bii ajọ to n mojuto ibanisọrọ lorilẹ-ede Naijiria, awọn ko tii gbọ ohun to jọ eyi.
Amọṣa, gbogbo akitiyan lati kan si minisita fun eto iroyin, Lai Mohammed lo ja si pabo lasiko ti a fi n ko iroyin yii jọ.
World Radio Day: Àwọn aráàlú ní Rédíò ni àgbára àwọn, òògùn ẹ̀jẹ̀ rúru ni
Gomina ana nipinlẹ Ekiti, Ayodele Fayose, ti keboosi too sita faraye pe, bi ijọba apapọ ti n yọ so, ni oun naa n yọ gbọ, to si ti de etigbọ̀ oun pe ijọba apapọ ti n dete lati mase jẹ kawọn ẹrọ ibaraẹnisọrọ alagbeka sisẹ lọjọ idibo.
Gomina ana nipinlẹ Ekiti tun fikun pe, wọn ti se idanrawo ni Ọjọbọ ati ọjọ Ẹti to kọja, lati mọ bi awọn ẹrọ ti wọn fẹ lo fun igbesẹ yii yoo ti sisẹ si, eyi ti wọn ko wa lati orilẹede Israel.
Nigba to n kebosi loju opo ikansiraẹni Twitter rẹ, Fayose ni lati aago marun un idaji ọjọ Satide ti idibo gomina yoo waye, si aago marun un aarọ ọjọ Aiku ọjọ keji idibo aarẹ, ni ijọba apapọ yoo ti gbohun lẹnu awọn ẹrọ ibaraẹni sọrọ ni Naijiria.
Oríṣun àwòrán, @GovAyoFayose
O fikun pe eyi yoo jẹ ko nira fun ẹnikẹni lati pe jade tabi gba ipe lori ẹrọ ibanisọrọ alagbeka rẹ, bẹẹ ni ko nii seese fun awọn ọmọ orilẹede yii lati fi ohunkohun ransẹ si ara wọn lawọn oju opo ikansira ẹni wọn bii Facebook, Twitter, Instagram ati bẹẹ bẹẹ lọ.
'Wọn ko ni nkan ṣe fún ipinlẹ Ọyọ ni' #BBCGovDebate
Ènìyàn 26,000 ni àìsàn jẹjẹrẹ ń pa lóòjọ́
Afẹnifẹre ni ọrọ atunto lawọ́n tori ẹ yan Atiku laayo
Madam Sajẹ: Mò ń rọ àwọn akẹẹgbẹ́ mi nínú tíátà láti máṣe kánjú
Oríṣun àwòrán, Sajetiologa
Ẹ ni ti ọdun ba ba laye, o yẹ ko maa dupẹ nitori aimọye ojo lo ti rọ ti ilẹ ti fi mu.
Idi ree ti Alhaja Fausat Balogun, ti gbogbo eeyan mọ si Madam Sajẹ ninu ere tiata Yoruba, se n dupẹ lọwọ Ọlọrun fun aanu ati aabo rẹ nibayii to pe ẹni ọgọta ọdun loke eepẹ.
Ọjọ Kẹtala osu Keji ọdun 1959 ni wọn bi gbajugbaja osere tiata naa, to si di olokiki ninu isẹ tiata lati ipasẹ ere kan to se lori mohun maworan, eyiti wọn pe akọle rẹ ni Ẹrin Keke lọdun 1990.
Madam Sajẹ si ti kopa ninu awọn ere tiata to le ni ọgọrin.
Lasiko to n ba BBC Yoruba sọrọ ni ayajọ ọjọ ibi rẹ, Alhaja Balogun ni ko si agbẹkẹle mii fun ohun ju Ọlọrunlọ, to si tun n gbadura ẹmi gigun ati alaafia fun ara rẹ ni ọjọ iwaju.
Oríṣun àwòrán, Sajetiologa
Bakan naa lo gba awọn akẹẹgbẹ rẹ ninu isẹ tiata nimọran pe ki wọn mase kanju lati di ohunkohun laye, amọ ki wọn se suuru de asiko Ọlọrun.
Ẹgbọ ọ̀rọ Madam Sajẹ siwaju-
Sajẹ: Mo n rọ awọn akẹẹgbẹ mi lati se suuru de asiko Ọlọrun
Lara awọn ere ti Madam Sajẹ ti se, eyi to fun ni okiki ninu isẹ tiata ni Nkan Okunkun, Ọmọ Ẹlẹmọsọ, Serekode, Moriyeba, Olowo laye mọ, Ọjọ Ikunlẹ ati bẹẹ bẹẹ lọ.
BBC Yoruba wa n ki Alhaja Fausat Balogun pe oju yoo maa ri ọdun, Ọlọrun yoo si fun wọn ni ẹmi gigun ati alaafia lati lo iyoku ọjọ aye wọn ninu irọrun.
2019 El;ections: Ìjàmbá iná tó ń wáyé lemọ́lemọ́ ń kọ àjọ INEC lóminú
Oríṣun àwòrán, Tvc
Àmọ́ṣá àjọ náà ní kó sí ìfòyà lórí àṣeyọrí ìdìbò ọdún 2019
Ajọ eleto idibo INEC ti sọ pe, ẹrọ to n yẹ kaadi idibo wo, to din diẹ ni ẹgbẹrun marun lo jona ni ọfiisi ajọ naa to wa nilu Awka nipinlẹ Anambra lọjọ iṣẹgun.
Amọṣa, ajọ INEC ni eyi ko lee pagidina aṣeyọri eto idibo apapọ to n bọ lọna.
Ninu atẹjade kan eyii ti Amofin Festus Okoye, to jẹ Kọmiṣọna agba feto iroyin ati idanilẹkọ labẹ ajọ Inec fisita fawọn oludibo, o ni ajọ INEC iwadi ti bẹrẹ lori to ohun to fa ijamba ina to jo awọn ohun elo idibo ọhun.
O ni ajọ INEC ti gbe igbesẹ lori kiko awọn kaadi idibo to ku lawọn ipinlẹ miran wa si ipinlẹ Anambra.
World Radio Day: Àwọn aráàlú ní Rédíò ni àgbára àwọn, òògùn ẹ̀jẹ̀ rúru ni
"Eyi ni ẹlẹẹkẹta irufẹ iṣẹlẹ ijamba ina yii ti yoo maa waye laaarin ọjọ mejila, lẹyin eyi to waye lawọn ọfiisi ajọ naa ni ijọba ibilẹ Isiala Ngwa nipinlẹ Abia ati Qua'an Pan ni ipinlẹ Plateau.
A ti fi iṣẹlẹ naa to awọn ọlọpaa ati ileeṣẹ panapana leti, wọn si ti bẹrẹ iwadii lori ohun to sokunfa iṣẹlẹ ijamba ina naa."""
2019 Elections: NCC ní ìròyìn òfégè ni pé ìjọba yóò ti afẹ́fẹ́ ìbánisọ̀rọ̀ pa lọ́jọ́ ìbò
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Fáyòṣé ló sọ̀ pé ìjọba àpapọ̀ ti parí ètò gbogbo láti dí ètò ìbáraẹnisọ̀rọ̀ pa pẹ̀lú àwọn irinṣẹ láti ilẹ̀ òkèèrè
Ileeṣẹ to n mojuto eto ibanisọrọ ayelujara lorilẹede Naijiria, NCC ti sọ pe ko si ootọ ninu iroyin kan to n lọ kaakiri pe ijọba apapọ n gbero lati ti oju opo ibanisọrọ GSM gbogbo lorilẹede Naijiria pa lasiko idibo apapọ to n bọ.
BBC Yorùbá: Ìbò rẹ ni agbára rẹ, jáde lọ dìbò
Ninu ọrọ to ba BBC News Yoruba sọ, agbẹnusọ fun ajọ NCC lorilẹede Naijiria, Nnamdi Nwokike ṣalaye pe iroyin ẹlẹjẹ lasan ni iroyin naa ati pe kii ṣe iroyin to ṣee gbọ seti rara.
Ni ọjọ iṣẹgun ni gomina tẹlẹ ni ipinlẹ Ekiti, Ayọdele Fayoṣe kọ ọ si ori ikanni twitter rẹ pe iroyin ti lu si oun lọwọ pe ijọba apapọ yoo sọ agadangodo si ibanisọrọ GSM ati ikanni ayelujara laarin agogo marun idaji ọjọ abamẹta tii ṣe ọjọ idibo aarẹ di agogo marun irọlẹ ọjọ aiku.
Agbẹnusọ fun ileeṣẹ NCC, Nnamdi Nwokike ni iroyin ofege ni eyi ati pe ko si bi ijsba apapọ ṣe lee maa gbe iru igbesẹ ni iru saa ti oju la de lorilẹede Naijiria bayii. O ni gẹgẹ bii ajs to n mojuto ibanisọrọ lorilẹede Naijiria, awọn ko tii gbọ ohun to jọ eyi.
Amọṣa gbogbo akitiyan lati kan si minisita fun eto iroyin, Lai Mohammed lo ja si pabo lasiko ti a fi n ko iroyin yii jọ.
World Radio Day: Àwọn aráàlú ní Rédíò ni àgbára àwọn, òògùn ẹ̀jẹ̀ rúru ni
2019 Elections: Bá wo ni ipa àwọn olórí ẹ̀sìn ṣe lágbára tó nínú èsì ìdìbò?
Oríṣun àwòrán, Premiumtimes
Bi orilẹede Naijiria ṣe jẹ ilu ti awọn eniyan ti mu ọrọ ẹsin ni ọkunkundun, lo fara hàn ninu ọrọ oṣelu.
Ni gbogbo akoko ni awọn oloṣelu maa n beere fun adura, ti awọn adari ẹsin si maa n fi adura da wọn lọla.
Ọpọ igba ni awọn adari ẹsin maa n fi ero ọkan wọn han nipa ẹni ti awọn n ṣe atilẹyin fun, ti wọn si maa n rọ awọn ọmọ ijọ wọn ki wọn tẹle iṣisẹ awọn.
Awọn igba ọtọtọ ti awọn oloṣelu ti lọ beere fun adura lọdọ awọn asaaju ẹsin rèé:
Aarẹ anaGoodluck Jonathan ati CAN
Oríṣun àwòrán, NAiraland
Bi idibo aarẹ 2015 ṣe n sumọ, ni aarẹ nigba naa, Goodluck Jonathan lọ beere adura lọdọ awọn alufaa labẹ aṣia ẹgbẹ awọn ọmọlẹyin Kristi (CAN).
Ọkan lara ohun to ṣe apẹrẹ bi awọn adari ijọ ṣe ṣe atilẹyin fun ni aworan to wa loke yii, nibi ti awọn ọmọ ẹgbẹ CAN ti n gbadura fun aarẹ ana naa, nigba to ko awọn ikọ Naijiria lọ irinajo lo si ilẹ mimọ, Israel.
BBC Yorùbá: Ìbò rẹ ni agbára rẹ, jáde lọ dìbò
Ọpọlọpọ igba si ni a ri Jonathan ti o lọ ṣe abẹwo si awọn ile ijọsin bi ijọ RCCG lati gba akanṣe adura.
Ẹgbẹ NIFROP to jẹ akojọpọ awọn adari ẹsin oriṣiriṣi ni oṣu Kọkanla ọdun 2018, pe fun adura ogoji ọjọ, eyi ti wọn pe akori rẹ ni 'Buhari gbọdọ pada wa ni 2019'.
Iru adura wọnyii wọpọ ni gbogbo igba ididbo. Adari ijọ to pe fun adura naa nigba naa, Biṣọọbu Sunday Garuba sọ fun awọn akọroyin ni Plateau, nipinlẹ Jos pe, Ọlọrun ran Aarẹ Muhammadu Buhari lati gba orilẹede Naijiria kuro ninu oko ẹru ni.,
Ti ẹ ba ranti naa, nigba ti Aarẹ Buhari ṣe aarẹ, awọn wolii ati alufa ko ara wọn jọ lati gbadura alaafia fun.
Oríṣun àwòrán, NAiraland
Ni oṣu kọkanla iroyin kan pe Aarẹ ana, Olusegun Obasanjo ti dari ji igbakeji rẹ nigba kan ri, Atiku Abubakar to jẹ oludije fun ipo aarẹ labẹ ẹgbẹ oṣelu PDP.
Aworan to jade lati ibi ipade Obasanjo ati Atiku fi han loju ẹsẹ wipe, awọn adari ijọ bii Biṣọọbu ẹka ijọ Aguda to wa ni Sokoto, Martin Kukah, alfa ijọ musulumi, Ahmed Gumi.
Bakan naa ni olori ijọ Winners Chapel, Biṣọọbu David Oyedepo wa lara awọn to pari ija laarin awọn mejeeji.
Ọpọ eniyan si lo ti fi ero wọn han wipe, awọn asaaju ẹsin naa n ṣe atilẹyin fun Atiku ki o le di aarẹ.
Oríṣun àwòrán, The News
Ṣugbọn fun awọn ọmọ Naijiria, njẹ iru atilẹyin awọn olori ijọ wọnyii le yi ọkan wọn pada? Oun ti awọn ti a ba sọrọ sọ ree:
Oladega, Bidemi ati Abayomi
Sọrọsọrọ, Oladega ni, ko si ọna miiran lati mu ilọsiwaju ba orilẹede ti onikaluku ko ba dibo fun ẹni to wu u.
O ni bi awọn oloṣelu ṣe n polongo ni awọn adari ẹsin naa n polongo, ṣugbọn ọmọ Naijiria gbọdọ dibo fun ẹni to wu wọn.
Ko si oun to kan alufaa mi nipa ibo mi - Bidemi Longe
Arabinrin Bidemi Longe sọ fun BBC Yoruba wipe, bo tilẹ jẹ pe onigbagbọ ni oun, oun ko  le jẹ ki ero adari ijọ oun sọ ẹni ti oun yoo dibo fun.
O ni bi ero ati ireti alufaa oun ṣe yatọ si ti oun ni ẹni ti ounb yoo dibo fun yoo ṣe yatọ. O ni ẹni ti oun yoo dibo fun, yoo jẹ ẹni ti o ni agbara lati mu irọrun ba awọn ara ilu.
Alufaa to ba fẹ ki n dibo fun oludije oun n tan 'ra rẹ - Abayọmi Ogunremi
Arakunrin Abayọmi Ogunrẹmi ni 'gbadura nṣaamim ko si ija ni ṣọọṣi' ni ọrọ ibaṣepo oun ati adari ijọ oun.
Ninu ọrọ rẹ, o ni alufaa to fẹ ki oun ṣe atilẹyin fun ẹni to oun n ṣe atilẹyin fun n tan ara rẹ jẹ. O ni nitori ki i ṣe gbogbo oun ti alufaa ba fi waasu ni oun maa n tẹle, bẹẹ si ni ọrọ oṣelu naa ri.
"O sọ pe, ""Alufaa mi ni ero tirẹ, bẹẹ si ni emi naa ni ero temi."""
Nigeria Elections 2019: Ènìyàn 15 kú lẹ́yìn tí ìpolongo APC parí ní Port Harcourt
Oríṣun àwòrán, Tonye P Cole
Ko din ni eniyan mejila to padanu ẹmi wọn nibi ipolongo ibo ti ẹgbẹ oṣelu All Progressives Congress, APC, ṣe nilu Port Harcourt.
Ile iwosan ikọṣẹ iṣegun oyinbo ti Fasiti ilu Port Harcourt fi idi rẹ mulẹ fun BBC pe, eniyan mẹẹdogun lo ku lasiko ti awọn ero n to kopa nibi eto naa ni papa iṣere Adokiye Amiesimaka n da giiri jade nigba ti ipolongo ibo aarẹ ẹgbẹ APC pari lọjọ Iṣẹgun, ọjọ kejila, oṣu Keji ọdun 2019.
Ẹ̀rọ káàdì ìdìbò 4,695 ló jóná lọ́fíìsì INEC ní Anambra
Aranṣọ, olórin àti àwọn mì í ti ko fẹ́ kí ìdìbò kásẹ̀ nílẹ̀ ní Nàìjíríà
2019: Wo fídíò bí wọ́n ṣe sọ nǹkan lu àwọn adarí APC l'Abẹokuta
Agbẹnusọ fun ileewosan naa, Kem Elebiga sọ pe akọsilẹ ẹka to n mojuto itọju pajawiri ati ijamba ọkọ nileewosan naa fihan pe oku eniyan mẹẹdogun ni wọn gbe wa si ileewosan naa lati papa iṣere ọhun - ọkunrin mẹta, obinrin mejila.
Oríṣun àwòrán, Tonye P Cole
Ati wi pe eniyan mejila to farapa ni awọn dokita ṣi n tọju lọwọ, ti awọn mẹta si ti pada sile.
Iroyin to tẹ wa lọwọ ni pe, bi awọn eniyan ṣe n da giiri jade ninu papa iṣere naa nigba ti eto ipolongo ibo pari, ni wọn bẹrẹ si ni ti ara wọn ṣubu nitori ero to pọ.
Amọ ṣa, agbẹnusọ fun ileeṣẹ ọlọpaa nipinlẹ Rivers, sọ pe kọmisana ọlọpaa nipinlẹ naa, Usman Belel ti paṣẹ iwadi ohun to fa titẹra ẹni pa ọhun.
Awọn ibo mii ti awọn eniyan ti ku nibi iwọde oṣelu ni 2019
Lootọ lo da bi ẹni pe ilu Port Harcourt ni awọ̀n eniyan ti padanu ẹmi wọn ju lati igba ti eto ipolongo ibo ọdun 2019 ti bẹrẹ, ṣugbọn iru iṣẹlẹ yii ti waye ni awọn ilu mi i.
Nipinlẹ Borno, awọn eniyan tẹ ara wọn pa, bakan naa ni Taraba, eniyan mẹjọ lo jẹ Ọlọrun nipe.
Bakan naa ni nkan ri nipinlẹ Sokoto lasiko ipolongo ibo. Gbogbo rẹ si waye nibi ipolongo ibo aarẹ ẹgbẹ oṣelu APC.
Fun ẹgbẹ oṣelu PDP, ìtàgé wo lulẹ nibi ipolongo kan ti wọn ṣe ni ipinlẹ Kebbi ko si fijuhan boya ẹnikẹni ku tabi bẹẹkọ.
Murtala Mohammed: Aṣaájú tó kọ́kọ́ gbógun tàwọn alájẹbánu, tó sì ta oúnjẹ lọ́pọ̀
Oríṣun àwòrán, @AgbaAkin_MA
Bi wọn ba darukọ ọgagun Murtala Mohammed letigbọ awọn ọdọ lode oni,ohun ti wọn yoo fi ranti rẹ ni owo beba ogun Naira, eleyi ti wọn ya aworan rẹ si.
Bẹẹ si ni Murtala Mohammed ju ogun Naira lọ, ta ba n sọ nipa ipa to ko lorileede Naijiria ati isẹ iadagbasoke to se fun orilẹede yii.
Bi a ba ka ni meni meji, o ti to ọdun mẹrinlelogoji ti akọni ologun yii re irinajo aremabọ, nigba ti awọn agbebọn da ẹmi rẹ legbodo.
Oríṣun àwòrán, @AgbaAkin_MA
Loni ti awọn ọmọ Naijiria si tun n ṣe iranti rẹ, a ni ki a mu awọn ohun to gbe ṣe lasiko to fi wa lori oye fun ọjọ mejidinnigba wa si iranti yin, nitori bi onirese rẹ ko ba fingba mọ, awọn eyi to ti fin silẹ, ko lee parun laelae.
Gẹgẹ ba ti woye rẹ, awọn agbekalẹ ilana isejọba rẹ naa lo si n ṣe atọna awọn ilana isẹjọba laye ijọba alagbada taa wa yii, lai naani pe ijọba ologun ni Murtala Mohammed se adari rẹ nigba naa.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Kikede dukia gẹgẹ bi olori:
Lọdun 2015 lorileede Ghana, nigbati Aarẹ Naijiria Muhammadu Buhari n dahun ibeere awọn akoroyin nipa bi o ti ṣe le jẹ ki awọn olori ilẹ Afrika miran kọ iṣe rẹ nipa kikede dukia.
Buhari fi apẹẹrẹ ọgagun Muritala Muhammed sakawe, to si ni ki gbogbo awọn Minisita ati Gomina to fi mọ awọn akowe agba to siwaju rẹ, kede dukia wọn.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Murtala Muhammed ni olori Naijiria akọkọ to fẹsẹ iwa ikede dukia ẹni mulẹ lori aleefa pẹlu bo se kede dukia rẹ setigbọ araye.
Titi di oni, iṣe yii ti di ohun ti awọn eeyan fi n sagbeyẹwo ijọba ti o duro deede ni Naijiria.
Fifi panpẹ ofin mu awọn onijẹgudujẹra:
Orukọ EFCC loni tabi ti ICPC a ma mu ibẹrubojo ba awọn ti wọn ba jẹ ajẹbanu tabi ti wọn ṣe owo ijọba basubasu.
Saaju ki a to ni EFCC ni ọgagun Murtala Muhammed ti paṣẹ ki wọn ṣe iwadi awọn oṣiṣẹ ijọba ti ọwọ wọn ko mọ.
Oríṣun àwòrán, Pius Utomi Ekpe/Getty Images
Ipenija nla ni ajebanu je fun orileede Naijiria
Bakannna ni Murtala Mohammed ni ki wọn se iwadi nipa awọn dukia ijọba to jẹ alopati lawọn ipinlẹ mẹta kan to wa ni agbegbe ila oorun Naijiria nigba naa.
Yiyọ adajọ agba orilẹede Naijiria:
Awuyewuye ọrọ adajọ agba orileede Naijiria, adajọ Walter Onnoghen ti ijọba Buhari yọ nipo, ko ṣẹṣẹ maa waye ni Naijiria.
Lasiko ti ọgagun Murtala Mohammed fi ṣe ijọba, oun naa yọ adajọ agba orilẹede Naijiria, eyiun adajọ Teslim Elias losu kẹjọ ọdun 1975.
Oríṣun àwòrán, @AgbaAkin_MA
Amọ ko pẹ lẹyin igba naa, ti ijọba Murtala Muhammed yii kanna ṣagbega adajọ Elias lọ si ile ẹjọ agbaye taa mọ si International Court of Justice (Hague). O tọ ki a salaye pe yiyọ adajọ Elias ko ni ohunkohun ṣe pẹlu pe o wuwa ajẹbanu.
Oríṣun àwòrán, @AgbaAkin_MA
Tita ounjẹ fun ara ilu lowo pọọku:
Lasiko ijọba Murtala Mohammed, awọn ara ilu ri mudunmudun ijọba jẹ paapa julọ, pẹlu pipese ounjẹ bii gaari ati adiẹ lowo pọọku.
Loni ti pupọ ọmọ Naijiria n lọgun ebi, iru igbesẹ ti Murtala Muhammed gbe yii jẹ ọna kan gboogi ti awọn ara ilu n parọwa si ijọba Buhari, lati dẹkun ebi oun iṣẹ to peleke lawujọ.
Nigeria 2019 Elections: Àwọn nọmbà yìí ló le fi bá iléèṣẹ́ ológun sọ̀rọ̀ lásìkò ètò ìdìbò
Oríṣun àwòrán, Nigerian Army/twitter
Ileeṣẹ ologun Naijiria ti ṣe ifilọlẹ awọn nọmba ẹrọ ibanisọrọ ti awọn araalu le pe ti wahala ba ṣẹlẹ lagbegbe wọn, ṣaaju, lasiko ati lẹyin eto idibo gbogboogbo ti yoo waye.
Nibi eto naa to waye nilu Abuja, ni Ọga agba ileeṣẹ ologun, Ọgagun Tukur Buratai ti ṣe ifilọlẹ yàrá agbára nibi ti awọn ọmọ ogun yoo ti maa ṣe ọfin toto bi nkan ṣe n lọ kaakiri Naijiria lasiko eto idibo.
Buratai ṣalaye pe awọn rogbodiyan to waye lasiko awọn eto idibo to kọja lorilẹ-ede Naijiria lo mu ki ileesẹ ologun naa tun ero rẹ pa.
Afẹnifẹre ni ọrọ atunto lawọ́n tori ẹ yan Atiku laayo
Lati yàrá agbára naa ni wọn yoo ti maa mojuto awọn wahala bi jagidijagan lasiko idibo, jiji tabi jija apoti ibo gbe, to fi mọ jiji awọn oṣiṣẹ ajọ eleto idibo gbe ati awọn aṣoju ẹgbẹ oṣelu.
Bakan naa, ileeṣẹ ologun yoo mojuto awọn ayederu iroyin to le jade lori ẹrọ ayelujara pẹlu erongba lati da wahala silẹ lasiko eto idibo.
BBC Yorùbá: Ìbò rẹ ni agbára rẹ, jáde lọ dìbò
Lati fi to ileeṣẹ ologun to wa ni agbegbe kọọkan lorilẹede Naijiria leti nipa wahala to ba jẹyọ nibudo idibo rẹ, awọn numba yii ni ko o pe si tabi fi atẹjiṣẹ ṣi, ati fun ẹrọ ayelujara Whatsapp.
07017222225, 09060005290, 08099900131 ati 08077444303.
Bakan naa lo le le pe nọmber pelebe 193 lati ori eikeyi oju opo ibaraẹnisọrọ ti o ba n lo.
Ademọla Ogunbanjo: A nílò bàbá ìsàlẹ̀ nínú òsèlú
Àwọn ìṣẹ̀lẹ̀ kàyéfì àti mánigbàgbé tó wáyé lásìkò ìpolongo ìbò
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Oriṣiriṣi iṣẹlẹ apanilẹrin, ipaya ati malegbagbe lo maa n waye nibi ipolongo ibo ẹgbẹ oṣelu, ko si yọ oludije tabi ẹgbẹ oṣelu kankan silẹ.
Bi ipolongo ibo fun eto idibo aarẹ ṣe wa ṣopin loni, ọjọ kẹrinla oṣu Keji, ọdun 2019, a ṣe akojọpọ diẹ lara awọn iṣẹlẹ ti ko ṣe e gbagbe lasiko ti awọn ẹgbẹ oṣelu ṣe ipolongo ibo wọn.
Aarẹ Muhammadu to n dije fun saa keji gẹgẹ bi oludije fun ẹgbẹ oṣelu All Progressives Congress ṣe awọn 'aṣiṣe manigbagbe kan lasiko ipolongo ibo rẹ.
Nipinlẹ Cross River, Buhari ṣe aṣiṣe lasiko to fẹ ẹ fi oludije fun ipo gomina fun ẹgbẹ APC han nibi ipolongo rẹ. Niṣe ni aarẹ na ọwọ amugbalẹgbẹ rẹ kan to duro ni tosi soke, dipo Owan Enoh to jẹ oludije gan-n-gan.
Omiran to tun waye ni ti ipinlẹ Delta, nibi to yẹ ki Aarẹ Buhari ti gbe asia ẹgbẹ oṣelu APC fun Great Ogboru to jẹ oludije ẹgbẹ naa fun ipo gomina, gẹgẹ bi bi o ṣe maa n waye nibi ipolongo gbogbo.
Obasanjo: Atiku kìí se Áńgẹ́lì, àmọ́ yóò se dáadáa ní ìlọ́po méjì ju Buhari lọ
Amọ nigba ti Buhari yoo ṣọrọ, dipo ko sọ pe 'mo gbe asia yii fun oludije wa fun ipo gomina...'', niṣe ni Buhari sọ pe 'mo gbe asia iyi yii fun oludije wa fun ipo aarẹ.''
Lootọ, aṣiwi ko to aṣiṣọ, ọkan lara awọn to duro lori itage pẹlu rẹ ṣe atunṣe loju ẹsẹ, ṣugbọn ọtọ ni nkan ti Buhari sọ. O ni 'fun oludije wa fun ipo sẹnetọ''.
Aṣiṣe ọhun tun waye nigba kẹta.
#BBCNigeria2019: Nnamdi Kanu sọrọ lórí àwọn oludije PDP àti APC
Bakan naa ni aarẹ nigba kan ni Naijiria, Oluṣẹgun Ọbasanjọ yi ohùn pada lori ọrọ igbakeji rẹ nigba to fi jẹ aarẹ, Atiku Abubakar. Atiku ni oludije fun ipo aarẹ ninu ẹgbẹ oṣelu PDP.
Ṣaaju asiko idibo ọdun 2019, Ọbasanjọ sọ pe ti oun ba ṣatilẹyin fun Atiku lati di aarẹ Naijiria, Ọlọrun ko ni dariji oun. Ṣugbọn, iyalẹnu lo jẹ nigba ti Ọbasanjọ yii ọrọ̀ rẹ pada, to si bẹrẹ si ni polongo ibo fun Atiku.
2019 Elections:Bi Ibo rírà ṣe ṣákoba fún iṣẹ ìwé títẹ̀
Iṣẹlẹ miran to le 'panilẹrin', amọ to tun le dunni nitori awọn to farapa ni eyi to waye lọjọ Aje, ọjọ kejidinlọgbọn, oṣu Kini ọdun 2019 nibi ipolongo kan ti ẹgbẹ oṣelu alatako, Peoples Democratic Party, PDP ṣe nipinlẹ Kebbi.
Niṣe ni ìtàgé ti awọn agbaagba ẹgbẹ naa, to fi mọ oludije fun ipo gomina, Isah Muhammad Galaudi, deede wo lulẹ, ti gbogbo awọn to duro sori rẹ si ṣubu.
Fidio 'to ṣafihan iṣẹlẹ naa gbajumọ lori ẹrọ ayelujara, to si jẹ wi pe iha ọtọọtọ ni olukaluku ọmọ Naijiria kọ si i.
Bi awọn kan ṣe sọ pe 'boya awọn to mojuto eto naa ko owo ipolongo ibo jẹ ni ẹni to ṣe ìtàgé naa ṣe ṣe iṣẹ ti ko pojuowo', ni awọn kan sọ pe ere iṣẹ ọwọ awọn oloṣelu naa ni wọn jẹ, nitori wọn lasiko ti wọn n pe orukọ Ọlọrun lati yawọn ya satani, ni ede Larubawa, ni ìtàgé naa wo lulẹ.
Ṣaaju ki ti ipinlẹ Kebbi to o waye, ni iru iṣẹlẹ bẹ ẹ waye ni ilu Maiduguri, nipinlẹ Borno, lasiko ti ẹgbẹ oṣelu APC n ṣe ipolongo ibo aarẹ.
Abala kan lara ibi ti awọn alatilẹyin ẹgbẹ naa duro si wo lulẹ, ti ọpọ eniyan si farapa. Iroyin ti a ko fidirẹmulẹ tilẹ sọ wi pe ẹnikan padanu ẹmi rẹ nitori ijamba naa.
Ẹwẹ, ojo okuta ni awọn janduku rọ le Aarẹ Muhammadu Buhari ati awọn oloye ẹgbẹ oṣelu APC lori nipinlẹ Ogun, lasiko ti ipolongo ibo aarẹ n lọ lọwọ. Botilẹjẹ wi pe oun naa wa nibi eto naa, ẹgbẹ oṣelu APC fẹsun kan Gomina Ibikunle Amosun pe 'oun lo wa nidi iṣẹlẹ naa.
Ṣaaju asiko naa ni aarin Gomina Amosun ati ẹgbẹ oṣelu APC ko tooro, nitori ẹni ti yoo dije fun ipo gomina ninu ẹgbẹ naa.
Amosun n ṣe atilẹyin fun Adekunle Akinlade, ṣugbọn ẹgbẹ faramọ Dapọ Abiọdun.
Bo tilẹ jẹ wi pe Akinlade ti darapọ mọ ẹgbẹ Allied Peoples Movement (APM), to si tun jẹ oludije wọn fun ipo gomina, Amosun ṣi n ṣatilẹyin fun. O si tun n sọ pe ti APC l'oun n ṣe ninu idibo aarẹ.
O tilẹ tun mu Akinlade lọ ọ ki Aarẹ Buhari l'Abuja. Lori eyi, ileeṣẹ aarẹ ni ko si nkan to buru ninu ki awọn oludije tabi ẹgbẹ oṣelu lọ ọ ki aarẹ Buhari, eyi ko si ni  nkankan se pẹlu atilẹyin rẹ fun gbogbo oludije ẹgbk APC.
Bakan naa ni ẹgbẹ oṣelu Social Democratic Party (SDP) ati Alliance Congress Party of Nigeria (ACPN) naa fi oludije wọn fun ipo aarẹ, Donald Duke ati Oby Ezekwesili silẹ, ti wọn si sọ pe Muhammadu Buhari ni awọ̀n n ṣatilẹyin fun.
JOHESU: L'Oṣogbo, àwọn òṣìṣẹ́ iléèwòsàn LAUTECHTH wọ́de lórí àìsan owó oṣù
Awọn alaṣẹ ileewosan nla LAUTECHTH sọ pe awọn ko mọ nipa ẹhonu kankan to ta ko awọn
Awọn oṣiṣẹ ileewosan nla LAUTECH niluu Oṣogbo labẹ aṣia JOHESUti faake kọri pe bi awọn ko ba gba owo oṣu wọn awọn ko ni jade lọ dibo ni ọjọ abamẹta.
Awọn oṣiṣẹ ile ẹkọṣẹ iṣegun naa ṣeleri yii lasiko iwọde ti wọn ṣe ni ọgba ileewosan nla naa nibi ti wọn ti ke sawọn alaṣẹ ileewosan naa lati wa wọrọkọ fi ṣada lori sisan owo oṣu ati ajẹmọnu wọn gbogbo.
#BBCNigeria2019: Nnamdi Kanu sọrọ lórí àwọn oludije PDP àti APC
Alaga ẹgbẹ oṣiṣẹ JOHESU nipinlẹ Ọṣun, Morounkeji Adelẹyẹ ṣalaye pe asiko to fun ijọba apapọ lati dẹkun iwa idẹyẹsi awọn oṣiṣẹ yooku nẹka eto ilera
Lati ọdun 2009 lawọn smọ ẹgbẹ yii ko ti ri ajẹẹlẹ owo oṣu wọn gba titi di asiko yii. Laipẹ yii ni wọn san ajẹẹlẹ owo fawọn dokita iṣegun ti wọn si yọ awọn ọmọ ẹgbẹ JOHESU sẹyin
Femi Falana: kò yé kí ìdájọ́ òfin yàtó síra wọn ni Naijiria
Wọn ni lara awọn ohun ti wọn n ja fun ni sisan ajẹẹlẹ owo osu wọn, ati agbega awọn oṣiṣẹ to wa ni akasọ kẹrinla iṣẹ ilera siwaju.
Afẹnifẹre ni ọrọ atunto lawọ́n tori ẹ yan Atiku laayo
Amọṣa awọn alaṣẹ ileewosan nla LAUTECHTH ti sọ pe awọn ko mọ nipa ẹhonu awọn oṣiṣẹ tako awọn bikoṣe lati tẹle aṣẹ awọn aṣiwaju ẹgbẹ wọn loke patapata.
Alukoro ileewosan nla LAUTECHTH, Ayọdele Adeyẹmọ ni alaafia ti pada si ileewosan naa lẹyin wakati diẹ tawọn oṣiṣẹ naa fi ṣe ifẹhonu han wọn.
2019 Elections:Bi Ibo rírà ṣe ṣákoba fún iṣẹ ìwé títẹ̀
Ekiti: Ìjọba ti iléeṣẹ́ rẹ́díò Fayose pa nipinlẹ Ekiti
Iléeṣẹ́ ààtò ìlú ní iléeṣẹ́ rẹ́díò náà kò gba ìwé àṣẹ ìkọ́lé.
Ijọba ipinlẹ Ekiti ti gbe ileeṣẹ rẹdio People F.M. to wa ni iluu Ado Ekiti ti pa bayii.
Ileeṣẹ ato ilu nipinlẹ Ekiti gbe ileeṣẹ rẹdio naa ti pa ni owurọ ọjọbọ lori ẹsun pe ko gba iwe aṣẹ ikọle.
Afẹnifẹre ni ọrọ atunto lawọ́n tori ẹ yan Atiku laayo
Ileeṣẹ rẹdio naa ni wọn ni o jẹ ti gomina ana ni ipinlẹ Ekiti, Ayọdele Fayoṣe.
Femi Falana: kò yé kí ìdájọ́ òfin yàtó síra wọn ni Naijiria
Oludari ẹka ato ilu nipinlẹ Ekiti lo buwọlu Iwe aṣẹ ti wọn fi ti ileeṣẹ rẹdio naa pa.
Gomina Fayose ko tii sọrọ lori iṣẹlẹ yii.
#BBCNigeria2019: Nnamdi Kanu sọrọ lórí àwọn oludije PDP àti APC
2019 elections: Èyí ní òdíwọ̀n ọ̀rọ̀ àwọn olùdíje ipò ààrẹ ní Nàìjíríà sọ lórí ọrọ̀ ajé?
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Kò si ànìànì pé ọrọ ajé Nàìjíríà kò ṣeé mú yangàn ṣùgbọ́n kí ni àwọn olùdíje lee ṣe síi
Eyi ni abala kẹta iwadii BBC ti wọn ṣe lati ma ṣe itọpinpin awọn oludije ipo Aarẹ Naijiria
Awọn oludibo yoo yan aayo wọn laarin awọn oludije pẹlu nnkan ti wọn ba sọ fun wọn.
Iwaadi ti a gbe kalẹ yi wa lati dari ibeere kuro nibi iroyin idibo si koko ohun ti awọn oludibo fẹ ṣe fun awọn ara ilu.
Bawo ni wọn ti ṣe fẹ mọ boya ootọ ni nnkan ti awọn oludije ba sọ?
Ẹ jẹ ki a sagbeyẹwo rẹ
Oṣi si n ba awọn eeyan pupọ finra lorileede Naijiria ti o si jọ wi pe Atiku Abubakar n ṣọ wi pe nnkan ko yi pada laarin ọdun mẹrin ti ijọba yi ti wa lori oye ati wi pe o jọ pe nnkan  n buru si ni.
Iroyin to wa ni lẹ n ṣe afihan wi pe ọrọ yi le jẹ ootọ.
Bi a ba gbe gbogbo eto ọrọ aje Naijiria le osuwọn iye owo to n wọle s'apo ilu (GDP), o ti n bọ lọwọ ifasẹyin lati igba ti iye owo epo rọbi ti walẹ ni ọdun 2016 .
Laarin 2014 si 2017 owo igbe aye to kere julọ fun eeyan kan walẹ lati US$3,222 si US$1,968 gẹgẹ bi nnkan ti ile ifọwopamọsi agbaye,World Bank, ṣe agbelewọn rẹ.
Ẹwẹ,iyapa to wa laarin awọn alaini ati awọn ọlọrọ n pọ si gaan ni.
Aliko Dangote ni o jẹ ẹni to lowo julọ lafrika gẹgẹ bi ohun ti iwe iroyin atigbadegba Forbes sọ.Forbes foju sun pe owo rẹ to  $10.5 billion.
O fẹ to idaji eeyan Naijiria ti wọn ko ri ju naira 133.5 lowo ina lojumọ kan.Lọdun mẹrin sẹyin,miliọnu 85 awọn eeyan Naijiria ni wọn ka kun awọn ti osi n ba finra ti iye yi si ti n lọ soke si lọdọọdun.Ni ọdun 2016,awọn ti o jẹ mẹkunu jẹ miliọnu 90 ati miliọnu 94 lọdun 2017.Lọdun to kọja banki agbaye World Bank foju sun pe eeyan miliọnu 97 niwọnjẹ mẹkunu ni Naijiria.
Oṣi  n peleke si ni Naijiria ti wọn si lero wi pe eeyan mẹfa ni osi n ta lojumọ ti iye yi si jẹ miliọnu 3.2 lọdọọdun.Banki agbaye n foju sun pe iyen eeyan ti yoo jẹ mẹkunu lọdun 2030 yoo jẹ miliọnu120.
Ọrọ naa buru jayi ni ariwa Naijiria ju Guusu Naijiria .Laarin ọdun 2004 si 2013 iye eeyan to wa nipo otoṣi dinku pẹlu iye to fẹ to miliọnu mẹfa tiiye awọn ti oṣi ta ni ariwa si lẹkun pẹlu miliọnu meje.
Ni iwọ oorun ariwa ati ila oorun ariwa,iye eeyan ti osi n ba ja ko dinku ti o si yi duro ni ida 47.6% ati 59% lawọn agbegbe wọn yi.
Boko Haram  ti ṣe akoba fun awọn eeyan ariwa orileede Naijiria ti aini idagbasoke ọrọ aje naa lati owo ijọba naa si kun.
Aarẹ Buhari ko sọ ootọ nipa ọrọ yi.
Lootọ ni pe ijọba apapọ ṣe agbekalẹ ilana lati na owo si ẹka agbẹ ninu ilana idagbasoke ti wọn pe ni Economic Recovery and Growth Plan 2017-2020.
Wọn gbe ilana yi kalẹ lati jẹ ki Naijiria maa gbin gbogbo irẹsi ti wọn yoo ma lo lọdun 2018 ati alikama baknanna lọdun 2020.Amọ ṣ,wọn ko ri ileri yi muṣẹ fun gbingbin irẹsi lopin ọdun to kọja ko si daju wi pe wọn yoo ri afojusun yi ba fun alikama.
Bo ti lẹ jẹwi pe ọgbin iresi ti n pọsi laarin ọdun maarun sẹyin,ti wọn si ni ireti pe yoo lekun si ni ọdun 2019,Naijiria ṣi wa lara awọn orileede to n ra irẹsi lati ilẹ okere julọ lagbaye.
Ni ọdun 2014,iye tọọnuiẹsi kan jẹ bi owo dọla 425.Ni igba naa,Naijiria n gbe irẹsi to to tọọnu miliọnu 2,600,000 wole ti ye owo rẹ si jẹ $3,027,400.Eyi jasi miliọnu mẹta dọla lojumọ yatọ si owo ori ti wọn gbe le.
Ni ọdun 2018,iye owo tọọnu irẹsi ko yato to bẹ.Iye ti wọn n ta tọọnu kan si wa ni  dọla 421.Toun ti bi iye tọọnu ti wọn gbe wole ti ṣe walẹ si  2,400,000 lọdun 2018, Naijiria yoo ṣi ma na  $2,766,027.40 lojumọ kan lati gbe irẹsi wọle.
Iye irẹsi tara ilu n jẹ n ga si ni bi iye ara ilu ti ṣe n pọsi.Awọn ọmọ Naijiria ko fi ọrọ jọllof ṣere rara.
Ipenija ounjẹ ṣi n ba Naijiria finra  toun ti aawọ to n waye lagbegbe ariwa ati arin gbungbun Naijiria eleyi to mu adinku ba iye ounje ti ara ilu n ri fun jijẹ ati tita.
Gẹgẹ bi ohun ti ajọ to n risi ọrọ ẹ bilagbaye Global Hunger Index gbe jade Naijiria jẹ orileede kẹtalelọgọrun laarin orileede mọ́kàndínlọ́gọ́fà ti wọn koju ipenija ebi eleyi to jẹ ipenija nla fun wọn.
Ni oṣu kẹta ọdun 2018,Aarẹ Buhari  ṣe ifilọlẹ igbimọ to n ri si ipese ounje eleyi ti o jẹ wi pe oun gaan fun ara rẹ lo n dari igbimọ naa lati koju ipenija ounje ni Naijiria.
Gẹgẹ bi iroyin to tẹwa lọwọ,gbese ti Naijiria jẹ lọwọlọwọ ti lo soke si lati N7.55tn ($24.66b) ni 2012 si  N22.43tn ($73.21b) ni 2018, eyi to tunmọ si alekun ida 196.9%
Lati le san gbese yi,ọmọ Naijiria kọọkan yo ni lati san owo Naira N118,046.33 nto ṣe deede dọla $385.33.
Lọdun 2017,iye owo to n wọ akoto Naijiria jẹ N2.71tn ($8.89b) ti  N1.62tn ($5.3b) si wa fun gbese sisan eleyi to tunmọ si ida 59.68%.
Eleyi ko tunmọ si pe ohun ti Moghalu sọ jẹ ootọ nitori ọna orisirisi ni wọn fi n san gbese..Ko si na ti a fi le mọ boya owo N1.62tn ($5.3b) ti wọn ya sọtọ fun gbese sisan wa lati inu apapọ owo to wọ akoto Naijiria.
Gbese si iye ti o ọrọ aje orilẹede kan n gbe wọle,iyẹn GDP ni wọn fi ṣe odinwọn bi orilẹede kan ṣe lee fi irọrun san gbese to ba jẹ nipa ṣiṣe afiwe gbese ti orilẹede jẹ si ohun ti ọrọ aje rẹ n gbe jade. Bi gbese ba kere si odiwọn GDP rẹ, o tumọ si pe eto ọrọ aje orilẹede bẹẹ ni agbara lati san gbese rẹ. Bi gbese rẹ ba pọ pupọ ju odinwọn agbara ọrọ aje rẹ, iyẹn GDP, o tumọ si pe orilẹede bẹẹ yoo nira fun un lati san gbese rẹ.
Ni ọdun 2018, odinwọn agbara eto ọrọ aje Naijiria si gbese to jẹ jẹ ida mọkandinlogun o le diẹ, 19.72%, eleyi to jẹ ilọsiwaju  lati ida mejila o le diẹ ninu ọgọrun, 12.65% ni ọdun 2013.
Gbese kan wa ti orilẹede n jẹ awọn orilẹede miran pẹlu ileeṣẹ ati lajọlajọ okeere. Ida mọkandinlọgbọn o le diẹ ninu ọgọrun, 29.49% gbogbo gbese ti orilẹede Naijiria jẹ si okeere; banki agbaye si ni orilẹede Naijiria jẹ ni gbese julọ lokeere.
Ni ọdun 2017,ẹka ilera,igbayegbadun ara ilu,iṣẹ agbẹ,eto irina ni awọn ẹka ti wọn fi owo iya lati ita ṣe eto wọn.
Ninu aba isuna ọdun 2019,nnkan bi ida 25.65% ni wọn ya sọtọ fun sisan gbese.
Ni ọdun 2012, ile iṣẹ ijọba to n ri si ọrọ ile gbee ṣalaye pe miliọnu mẹtadinlogun eeyan ni ko rile gbe. Ijọba woye pe ko too di ọdun 2014, awọn ti ko rile gbe yoo too miliọnu ọgbọn eeyan si ogoji
Ṣugbọn ajọ banki agbaye sọ pe afojusun ọdun 2012 lori ile gbigbe ku diẹ kaato nitori eeyan mẹfa lo yẹ ko wa nile kan, eleyi to ju eeyan mẹrin lọ fun ile kan.  Ṣugbọn banki agbaye ni awọn ti ko rile gbe to ọgbọn miliọnu idile
Lati ọdun 2012, o ṣoro lati mọ iye ile gbigbe ti awọn ọmọ Naijiria nilo
Miliọnu mẹtadinlogun ile ti wọn maa n wi ko tọna nitori ko sọ nipa bi awọn eeyan ṣe n pọ si ati aikọle ijọba fawọn eeyan
O nira lati mọ iye awọn ti ko rile gbe nitori ko tii si eto ikaniyan lati ọdun 2006 ati pe awọn ikọlu ati rogbodiyan to n ṣẹlẹ ti sọ ọpọ di alainile lori
Ṣugbọn lọdun 2017, ajọ to n ri si iṣẹ ijọba ni eeyan meji din ni aadọfa miliọnu eeyan ni ko nile lori
Ti a ba wo pe eeyan marun un sile kan, aadọfa miliọnu eeyan ti ko nile lori, ile ti yoo to lati gbe jẹ miliọnu mẹrindinlọgbọn
Mili ọnu $3.6m ti Sowore bere fun le to lati pese ile ọta le lọọdunrun
Awọn to n ṣiṣẹ agbẹ lo pọju ninu awọn oṣiṣẹ ni Naijiria. Ida mejidinlaadọta awọn oṣiṣẹ lo n ṣiṣẹ agbẹ ti ọpọlọpọ wọn si mu iṣẹ ọgbin ni baada
Ida mẹrinla ninu ọgọrun iye awọn eeyan to wa lorilẹede Naijiria ni ẹka eto karakata, ti o jẹ ẹka keji to gba eeyan si iṣẹ julọ gba siṣẹ ti awọn ẹka miran si gba ida meje o le diẹ ninu ọgọrun siṣẹ, ti ẹka idannkanṣe, Manufacturing, si gba ida meje ninu ọgọrun awọn eeyan orilẹede Naijiria siṣẹ.
Otitọ ni Fẹla Durotoye sọ nigba ti o wi pe ẹka eto ọgbin lo gba eeyan siṣẹ julọ, ṣugbọn iye ida ti o ko ninu ọgọrun kere ju iye ti o darukọ lọ.
Ọrọ Ọgbẹni Durotoye ko jina si ootọ nigba ti o wi pe ida marundinlogoji ilẹ to ṣee ṣe eto ọgbin ni a n lo bayii.
Iwọnba ida mẹtadinlogoji ninu ọgọrun ilẹ to ṣee lo fun ọgbin (miliọnu mẹrinlelọgbọn saare ilẹ) ni a n lo fun eto ọgbin gẹgẹ bi iroyin kan ti banki agbaye fi sita ni ọdun 2016. Iyats ti de ba eyi lati ọdun 2011.
Banki agbaye ṣe iṣiro rẹ pe ida mẹtadinlọgọrin o le diẹ ninu ọgọrun gbogbo ilẹ to wa lorilẹede Naijiria ni o ṣee fi ṣe eto ọgbin
A gbiyanju lati gbe awọn ohun to n lọ lagbo oṣelu kalẹ lai ṣegbe, lori awọn ohun to wa lojutaye jade.
Awọn ohun to ṣe pataki si awọn igberiko ni a gbaju mọ, gẹgẹ bii awọn ẹgbẹ oṣelu ṣe ṣalaye rẹ.
#BBCNigeria2019: Ààrẹ Buhari ní ìdìbò ọjọ́ Àbámẹ́ta yóò lọ n'ìrọwọ́ rọsẹ̀
Oríṣun àwòrán, Presidency
Aarẹ Muhammadu Buhari sọrọ lori idibo
Aarẹ Muhammadu Buhari ti rọ awọn ọdọ lati maa jẹki awọn oloṣelu lo wọn fun jagidijagan ninu idibo gbogbo ti yoo bẹrẹ pẹlu ibo aarẹ ati ile aṣofin agba lọjọ Abamẹta.
Aarẹ Buhari sọrọ yii nigba to ba awọn ọmọ Naijiria sọrọ lori ẹrọ amohun-maworan ṣaaju ibo opin ọsẹ yii.
Aarẹ ni awọn oloṣelu le fẹ  lo awọn ọdọ lati da rogbodiyan silẹ lasiko ibo nitori wọn ti mọ wi pe awọn ko le wọle.
Femi Falana: kò yé kí ìdájọ́ òfin yàtó síra wọn ni Naijiria
Afẹnifẹre ni ọrọ atunto lawọ́n tori ẹ yan Atiku laayo
Aarẹ Buhari tun fi da ọmọ Naijiria loju pe idibo ọjọ Abamẹta yoo lọ ni irọwọ rọsẹ, o ni ijọba oun koni faye gba iwa jagidijagan lasiko idibo ati lẹyin eto idibo.
Aarẹ ni ijọba oun yoo gbiyanju lati ri wi pe alaafia jọba lakoko idibo, Aarẹ Buhari ni idi ni yii ti oun fi fọwọ si adehun alaafia pẹlu awọn oludije aarẹ mejilelaadọrin miran l'Ọjọru.
Oríṣun àwòrán, Presidency
Aarẹ Muhammadu Buhari sọrọ lori eto idibo
Aarẹ rọ awọn ọmọ Naijiria lati tu yaya jade lọjọ Abamẹta lati dibo fun ẹni ti wọn fẹ.
Aarẹ Buhari tun parọwa pe ki gbogbo eeyan lepa alaafia lọjọ idibo, ki wọn si yago fun ohunkohun to ba le da eto idibo ọjọ Abamẹta ru.
INEC: Ohùn gbogbo tí wà ní ṣepé fún ìdìbò ní Quan Pan
Oríṣun àwòrán, @inecnigeria
Awọn oṣiṣẹ Inec n ṣe eto awọn ẹrọ kaadi idibo ati nnkan elo idibo miran
Ajọ eleto idibo orile-ede Naijiria ti kede pe ohun gbogbo ti bọ sipo lati mu ki dibo waye ni ijọba ibilẹ Quan Pan nipinlẹ Plateau.
Ni nnkan bi ọjọ marun un sẹyin ni ina jo awọn nnkan elo idibo ni ileeṣẹ Inec naa to wa ni agbegbe ohun.
Loju opo Twitter Inec ni wọn fi ikede yi si pẹlu aworan ọk ti wọn fi gbe awọn nnkan elo idibo tuntun wa si agbegbe ohun.
#BBCNigeriaElections: Ọmọ Ogun iṣẹ́ yá -Adarí àjọ elétò ìdìbò Ogun
Gẹgẹ bi ohun ti wọn salaye ninu ikede naa, gbogbo iwe orukọ awọn oludibo ni ijọba ibilẹ naa ni INEC sọ pe awọn ti tun tẹ pada ti wọn si ti sipo lọ si ọfisi tuntun miran.
Ẹwẹ, ajọ naa tun fi ikede sita l'Ọjọbọ pe awọn ti fi ẹrọ kaadi idibo miran parọ awọn eleyi ti o jona ninu ijamba ina to waye ni ileeṣẹ ajọ naa ni Awka nipinlẹ Anambra.
Wọn ni ẹrọ kaadi idibo fun ijọba ibilẹ mẹrinla lawọn ti pese ti iṣẹ si n lọ lọwọ lati ri wipe awọn ijọba ibilẹ meje to ku naa ri ti wọn gba.
Lẹnu ọjọ mẹta yi,ileeṣẹ INEC mẹta ni ina ti sọ ti ọpọ awọn nnkan elo idibo ti ṣofo.
Iṣẹlẹ yi jẹ ohun to kan ọpọ eeyan lominu pẹlu bi idibo Aarẹ ti ṣe sunmọle.
Lọjọ Abamẹta ni orile-ede Naijiria yoo dibo yan Aarẹ tuntun ati awọn ọmọ ile asofin ti yoo sejọba fun saa ọdun mẹrin.
Afẹnifẹre ni ọrọ atunto lawọ́n tori ẹ yan Atiku laayo
Nnamdi Kanu: Kí gan-an ní àwọn nnkan tí Kanu bèrè fún tí ọwọ rẹ tí tẹ?
Oríṣun àwòrán, AFP
O ti to osu mẹfa ti wọn ti gburo Nnamdi Kanu sẹhin
Ta a ba sọ pe eegun ẹni o jo, ti o si tun jo mọ nkọ?
Ọrọ yi ṣe rẹgi pẹlu olori ikọ to n pe fun idasilẹ orilẹ-ede Biafra, Nnamdi Kanu to ni kawọn ẹya igbo jade dibo lọjọ Abamẹta.
Idibo ko ni waye ti wọn ko ba mu ọkọ mi jade
Ninu ọrọ kan ti o fi sita loju opo Twitter Kanu ni ohun yi ipinnu pada ''nitori ọwọ awọn ti tẹ gbogbo nkan tawọn n beere''
#BBCNigeria2019: Nnamdi Kanu sọrọ lórí àwọn oludije PDP àti APC
Saaju ni Nnamdi Kanu ti kede pe ẹya naa ko gbọdọ kopa ninu idibo lọjọ Abamẹta to jẹ ọjọ ti awọn yoo ṣe eto idibo laarin awọn ẹya Igbo lati mọ boya awọn yoo duro si orile-ede Naijiria tabi ki wọn lọ.
#BBCNigeriaElections: Ọmọ Ogun iṣẹ́ yá -Adarí àjọ elétò ìdìbò Ogun
Ko ti daju ohun gbogbo ti wọn bere fun ti ọwọ wọn tẹ amọ loju opo Twitter niṣe ni awọn eeyan ti n sọ tẹnu wọn nipa iyipada yi.
Emmanuel Nwoke ni tiẹ sọrọ lori bi Kanu ti ṣe yi ipinnu pada ni ọjọ diẹ si idibo ti o si ni ohun n fura si igbesẹ yi
Nnamdi Kanu ti ṣàlàyé bí ó ṣe rìn lẹ́yìn ọdún kan tó dàwátì
Abatta Godfather ati Onyema ni tiwọn n bere pe  ki lo de ti Nnamdi Kanu ko ṣe sọ ohun ti wọn bere fun ti ọwọ wọn tẹ?
Iha miran ni ọrọ yi kọ si awọn alatilẹyin Kanumirn ti wọn si ti bẹrẹ si ni sọ ẹgbẹ tawọn yoo dibo fun
Afẹnifẹre ni ọrọ atunto lawọ́n tori ẹ yan Atiku laayo
NigeriaDecides2019 : Kíni àwọn ohùn tó ṣé kókó tó yẹ ká mọ ṣáájú ìdìbò
Ko si ẹni ti ko si aaye fun lati dibo,lopin igba ti o ba ti ni kaadi dibo
Ọjọ a da ti ko ti gbogbo ọmọ Naijiria yoo jade lati dibo yan aarẹ tuntun ti yoo tukọ orileede naa fun ọdun mẹrin.
Jakejado Naijiria ni awọn oludibo ti n jẹ ọrọ idibo yi lẹnu ti ajọ eleto idibo naa ko dawọ iṣe duro nipa eto idibo ohun.
Ẹgbẹ oṣelu mẹtalelaadorin ni yoo dije du ipo Aarẹ ti oludije 1,848 ti 1,615 ninu wọn jẹ okunrin ti obinrin  233 ṣi n du ipo 109 asoju ile asofin agba.
#NigeriaDecides: BBC ti wa ni gbogbo ìpínlẹ̀ Naijiria láti firoyin gbogbo tóo yin létí
Fun aaye 360 to wa fun ile asojusofin, awọn oludije 4,635 ni wọn du ipo ohun ti a ri ọkunrin 4,066  to n du ipo naa ti obinrin si jẹ 569 to n gbero lati soju awọn eeyan wọn.
Awọn nnkan wọnyi se pataki lati mọ nipa idibo naa, ni eyi ti a fi ṣe atupalẹ ni ṣoki si isalẹ bayi:
Rii wi pe PVC rẹ wa ni tosi
Ko si ani ani pe ẹni to ba ni PVC lọ́wọ lo le kopa ninu idibo ọla ati ọmiran ti o ba waye lasiko ibo gbogboogbo yii.
Bi o ba mọ ibi ti o fi kaadi idibo rẹ si ri wi pe o wa kalẹ ki o si ma ṣeṣi mu kaadi miran dipo rẹ.
Kaadi idanimọ foju jọ kaadi idibo ṣugbọn ko ṣiṣẹ kannaa
Asiko yi kii ṣe igba ti eeyan ma n ya elomiran ni kaadi rẹ,kaadi rẹ ni agbara rẹ, ri wi pe o mojuto daada
Femi Falana: kò yé kí ìdájọ́ òfin yàtó síra wọn ni Naijiria
Gẹgẹ bi ohun gbogbo to ni eto, ajọ INEC fi gbedeke si asiko ti idibo yoo fi waye.
Ti o ba jẹ ẹni ti ko fẹ pẹ pupọ lori ila, yara kuro nile rẹ lasiko ki o ba le dibo lasiko.
Awọn oludibo a ma tu yaya lati dibo-yara kuro nile
Ma ṣe gbagbe pe ijọba ti kede eto irinna laarin aago mẹfa si aago mẹfa irọle.Oun ti eyi tunmọ si ni wi pe ko ni si irina ọkọ laarin igba yi nitori naa tete ṣe eto bi o ti ṣe de aaye idibo rẹ lasiko
BBC Yorùbá: Ìbò rẹ ni agbára rẹ, jáde lọ dìbò
Awọn ajọ eleto idibo Inec ti n lọgun ọrọ yi ti pe ṣugbọn a ko ni ye fi to arawa leti.
Bi o ba n bọ wa si ibudo idibo, o le mu foonu rẹ lọwọ ṣugbọn to ba ti wọ inu aaye idibo gangan, ko ni si aaye fun ọ lati lo.
Ko si aaye fun lilo ẹrọ ibanisọrọ ninu aaye idibo
Idi ti Inec lawọn lodi si lilo foonu ni ki awọn eeyan ma ba le lo foonu wọn fun ibo rira ati tita.
Gbogbo ipolongo idibo fun ipo Aarẹ ati awọn ile asofin orile-ede Naijiria ti de opin lọjọ kẹrinla, osu keji.
Fun idi eyi ko tọna lati wọ aṣọ ti yoo ma polongo ẹgbẹ kankan.
Awọn oṣiṣẹ Inec nibi ti wọn ti n ṣeto idibo Gomina nipinlẹ Ekiti lọdun 2018
Fun aabo tara rẹ naa lọwọ awọn to le fẹ dẹyẹsi ọmọ ẹgbẹ oṣelu kan tabi omiran,o ṣe pataki ki o ma fun wọn laaye pẹlu pe o wọ aṣọ to jẹ ti ẹgbẹ oṣe
lu kankan.
Jẹun tabi ki o ni etokale de inu rẹ
Okun inu laa fi gbe ti ita.
Toun ti bi o ti ṣe wuwa ki ẹ dibo yin bo ti 'ṣe tọ ati bo ti ṣe yẹ,a ko ni fẹ ki ẹ ma lokun lati kopa ninu idibo naa
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Awọn to n kiri oun mimu ẹlẹrindodo a ma ṣaba wa si aaye idibo
Lọjọ idibo ko ni si lilobibọ ti pupọ ninu awọn olounjẹ ko si ni patẹ.
Fun idi eyi, ri wi pe o jẹun ki o to kuro nile tabi ki o si ṣeto ounjẹ rẹ lọwọ.
A ki baa mọ,ti o ba ri awọn to gbe ounjẹ jijẹ wa si ibi eto idibo naa,ko si ofin to de wi pe ki a jẹun ti ebi ba n pa wa.Ṣaa ti mu owo lọwọ lati ra ounjẹ naa
Aaye idibo kii ṣe ibi ti eeyan n di owo pupọ lọwọ lọ.
Fun idi meji la fẹ ki ẹ sọra pẹlu owo pupọ.
Ekiti Election: Ẹ́gbẹ̀rún  mẹ́rin nàirà ni ẹnikọ̀ọ̀kan ń gbà
Akọkọ ni pe awọn ole le jin owo naa mọ ẹ lara nibi wọduwọdu idibo.
Ẹkeji ni pe awọn agbofinro ni ẹni to ba di owo to ju ẹgbẹrun lọna ọgọrun un naira lọwọ wa si ibi idibo yoo salaye ti awọn ba ri iru owo bẹ,oun ti o fẹ fi ṣe.
Abọ ọrọ laa sọfun ọmọlouabi, ẹ ri wi pe ẹ tele ofin idibo ki ẹ si yago fun wahala lọjọ ibo.
Nigeria 2019 Elections: Àwọn tí ìdìbò kò dí lọ́wọ́ iṣẹ́
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Okun inu la fi n gbé tita
Lasiko ti eto idibo ba n waye ni Naijiria, ki i si lilọ bibọ ọkọ lọjọ idibo.
Bakan naa ni gbogbo ileeṣẹ maa n wa ni titi pa, ayafi awọn kan ti iṣẹ wọn ṣe koko, ti aiṣi ilẹkun wọn le ṣe akoba fun araalu.
#NigeriaDecides: BBC ti wa ni gbogbo ìpínlẹ̀ Naijiria láti firoyin gbogbo tóo yin létí
Ileeṣẹ ọlọpaa: Ileeṣẹ ọlọpaa gẹgẹ bi ọkan gboogi lara awọn ileeṣẹ eto aabo ni Naijiria ti wọn ko le ṣalaikopa ninu eto idibo Naijiria.
Eto aabo ṣe pataki lasiko idibo
Bo tilẹ jẹ pe ileeṣẹ ọlọpaa yoo ko awọn oṣiṣẹ rẹ si ibudo idibo kọọkan, ọga agba fun ileeṣẹ ọlọpaa ti kede pe ileesẹ ọlọpaa kankan ko ni i jẹ titi pa lasiko eto diibo.
BBC Yorùbá: Ìbò rẹ ni agbára rẹ, jáde lọ dìbò
Awọn ọmọ ogun:  Awọn ọmọ ileeṣẹ ologun naa ko ni i gbẹyin ninu lilọ bibọ lasiko eto idibo gbogboogbo ọdun 2019.
Iṣẹ wọn si ni lati daabo bo gbogbo ọmọ orilẹ-ede Naijiria. Ati lati dena awọn janduku to le fẹ da wahala silẹ lasiko ti eto idibo ba n lọ lọwọ.
Oṣiṣẹ eto ilera: Bi gbogbo oṣiṣẹ ko ba ti ẹ le jade lasiko idibo, kii ṣe bi ti awọn eleto ilera, nitori pe iṣẹ irapada ẹmi ṣe koko. Nitori naa ẹnikẹni to ba jẹ oṣiṣẹ eto ilera ni anfaani lati lọ si ibi iṣẹ rẹ ti eto idibo ba n lọ lọwọ, ti ẹnikẹni ko si ni i da a duro.
Oríṣun àwòrán, Media for Medical
Awọn olutọju alaisan
Awọn kan lara awọn eleto ilera yii, lati awọn ileewosan, ati ajọ aladani tilẹ maa n lọ kaakiri ibudo idibo lati pese itọju pajawiri fun ẹnikẹni to ba farapa tabi nilo rẹ lasiko eto idibo.
Oṣiṣẹ ina mọna-mọna ati panapana: Awọn oṣiṣẹ to n mojuto ina mọna-mọna, ati awọn oṣiṣẹ pana-pana naa maa n wa nibi iṣẹ wọn lasiko ti idibo ba n lọ lọwọ, nitori ki wsn le mojuto awọn iṣẹlẹ ijamba ina to ba waye.
#BBCNigeriaElections: Ọmọ Ogun iṣẹ́ yá -Adarí àjọ elétò ìdìbò Ogun
Awọn akọroyin : Ṣe Yoruba bọ, wọn ni 'eti ọba nile, eti ọba l'oko, eeyan lo n jẹbẹ. Iṣẹ kekere kọ ni awọn ileeṣẹ iroyin n ṣe ṣaaju, lasiko ati lẹyin ti eto idibo ba waye. Awọn akọroyin a si maa lọ kaakiri ibudo idibo lati maa fi bi nkan ṣe n lọ to awọn araalu leti.
Awọn to n ta ounjẹ: Ipa kekere kọ ni awọn to n ta ounjẹ, nkan ipanu loriṣiriṣi, omi ati nkan mimu ẹlẹrin-dodo, nko lasiko eto idibo Naijiria.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Olounjẹ ṣe pataki lasiko idibo
Eyi ribẹ nitori pe ọpọlọpọ oludibo ni yoo ti fi ile wọn silẹ lati owurọ kutu lọ si ibudo idibo wọn. Ṣe okun inu lasi fi n gbe titi, eyi ni kii jẹki awọn olounjẹ bi irẹsi, amala, awọn ipanu ti wọn n fi iyẹfun ṣe ati bẹẹbẹ lọ ṣe maa n patẹ si awsn ibudo idibo.
Femi Falana: kò yé kí ìdájọ́ òfin yàtó síra wọn ni Naijiria
Onnoghen: Adájọ́ àgbà ní òun kò jẹ̀bi ẹ̀sùn tí ìjọba fi kan òun
Oríṣun àwòrán, @todayng, @SERAPNigeria
Èrò àwọn ènìyàn sọ̀tọ̀ọ̀tọ̀ lórí ẹ̀sùn Onnoghen
Ile ẹjọ CCB ti fi gbé Adajọ́ Agba Walter Onnoghen lọ ilé ẹjọ́ CCT níbi tí wọ́n ti fi ẹ̀sùn alábala mẹ́fa, eyí tó dá lórí pe kò jẹ́wọ́ awọn dukia rẹ̀ ati awọn owo kan to ni sile ifowopamọ.
Ọjọ́ Ẹti lo farahan niwaju ile ẹjọ naa, ti wọ́n si ka awọn ẹsun rẹ sii. Onnoghen ni oun ko jẹbi awọn ẹsun naa.
Ile ẹjọ́ naa si gba oniduro, wọ́n ni nitori ilumọ̀ọ́ká ni, ko le sálọ.
Agbẹjọ́rò rẹ̀ Oloye Chris Uche (SAN) ní o bẹ̀bẹ̀ lọ́wọ́ ile ẹjọ́ lati sun igbẹjọ́ naa di ẹyin idibo.
Uche tun rọ ile ẹjọ́ latí fagile iwe 'farahàn tipátipá' tí ajọ naa fi gbé Onnoghen, nitori pe adajọ agba naa ti funra rẹ wa sile ẹjọ.
Alaga ile ẹjọ naa, Adajọ Danladi Umar gba si agbẹjọro Onnoghen lẹnu, o gba oniduro rẹ, o si fagi le iwe 'farahàn-tipátipá' ti wọn ti gbe jade tẹlẹ.
Oríṣun àwòrán, Yomi Shogunle/Twitter
Onnoghen farahan niwaju ile ẹjọ CCT
Ọjọ karundinlọgbọn, oṣu kinni, ọdun yii ni Aarẹ Muhammadu Buhari ni ki Onnoghen lọ rọkun nile ti o si fi Adajọ Mohammed Tanko rọpo rẹ.
Awọn ọmọ Naijiria, ẹgbẹ awọn agbẹjọro fi ẹhonu wọn han wipe, igbesẹ̀ aarẹ naa ko tọ́na.
Afẹnifẹre ni ọrọ atunto lawọ́n tori ẹ yan Atiku laayo
#NigeriaDecides: Àwọn ohun to ní láti mọ̀ ní pa idibò 2019
Pẹ̀lú bí àwọn oloṣelu ṣe ń naá owo ni akoko idibo ni Naijiria, ọpọlọpọ ni yoo ro pe, ko si iye ti wọn ko le naa lori oṣelu.
Ṣugbọn ko ri bẹẹ. Ofin orilẹede Naijiria ṣe alakalẹ gbedeke iye owo ti wọn le naa lori didije.
#BBCNigeriaElections: Ọmọ Ogun iṣẹ́ yá -Adarí àjọ elétò ìdìbò Ogun
Ìjọba Kaduna: Gbogbo àwọn tó wà nídìí ìṣẹ̀lẹ̀ ìpànìyàn yóò gé ìka jẹ
Oríṣun àwòrán, @elrufai
Gomina ipinlẹ Kaduna, Mallam Nasil El-Rufai ti figbe ta pe eeyan mẹrindinlaadọrin ni awọn gende agbebọn sekuta nijọba ibilẹ Kajuru.
El Rufai, ninu atẹjade kan to fisita ni, ọmọde mejilelogun ati obinrin mejila lo fori sọta isẹlẹ ipaniyan naa.
Amọ sa, atẹjade naa ko salayeohun to fa sababi isẹlẹ naa.
Atẹjade naa wa leri leka pe, gbogbo awọn eeyan to ba lọwọ ninu isẹlẹ isekupani yii ni yoo finmu kata ofin.
Loju opo twitter re, @elrufai, gomina ipinlẹ́ Kaduna foju laifi wo isẹlẹ naa, to si n fewe ọmọ mọ awọn eeyan agbegbe naa leti lati mase gbẹsan.
Nigeria Elections 2019: Àwọn ọmọ Nàìjíríà n ṣé hèèmọ̀ bí INEC ṣé dajọ sí ibo
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Awón eeyan n faraya lori bi Yakub ṣe sun idibo Naijiria siwaju
Kini ka ti ṣe eyi si?
Ọrọ ti o gba ẹnu ọpọ ọmọ Naijiria ree lẹyin ti ajọ eleto idibo orile-ede Naijiria da ọjọ si idibo Aarẹ ati ti awọn aṣoju ile aṣofin ti o yẹ ki o waye lọjọ Abamẹta.
Ọrọ naa ṣe ọpọ ni kayefi lataari pe ajọ naa ko tawọn lolobo pe irufẹ iṣẹlẹ bayi yoo waye.
Loju opo Twitter iyalẹnu ni o kọkọ bẹrẹ iriwisi awọn ọmọ Naijiria nigba ti iroyin naa wọ wọn lara tan, ṣeni ọpọ bẹnu ẹ̀tẹ́ lu INEC
Femi Falana: kò yé kí ìdájọ́ òfin yàtó síra wọn ni Naijiria
Ikanra lawọn miran fi n fẹsi si ikede yi.
Ogbeni Dipo yatọ si pe o gba adura fun itusilẹ Naijira faraya pe awọn ọmọ orile-ede kan rin irinajo wakati marun un lati le lọ dibo eleyi ti ko waye mọ
#NigeriaDecides: BBC ti wa ni gbogbo ìpínlẹ̀ Naijiria láti firoyin gbogbo tóo yin létí
Iha miran lọrọ yi kọ si ẹlomiran bi Naturalguy4eva ti o n kaanu awọn ti wọn ti dajọ igbeyawo si ọjọ kẹtalelogun Osu keji ti Inec sun idibo naa si
#NigeriaDecides2019: ‘Kò sí àríyá lónìí, kò tún sí ìbò dídì, irú Sátidé mímọ́ wo rèé’
Oríṣun àwòrán, Ronke Fajerokun
Kii se iroyin mọ pe ajọ eleto idibo nilẹ wa, INEC, ti wọgile eto idibo aarẹ to yẹ ko waye lọjọ Satide oni.
Ni kete tawọn ọmọ Naijiria si ti gbọ iroyin agbọgbọntinu ọhun ni wọn ti n sọ oniruuru ero wọn nipa ikede yiii.
Lori awọn opo ikansiraẹni lori ayelujara bii Facebook, Twitter, Instagram ati Whats App, ẹnu ko gba iroyin nipa ohun tawọn eeyan n wi lori isẹlẹ yii.
Lara awọn ohun ti wọn kọ to pa ni lẹrin ni bi awọn eeyan kan se ni orilẹede Naijiria su awọn, ti wọn si n wa ọna lati tẹ ọkọ leti lọ soke okun.
Lawọn oju opo Facebook, igbe to gba ibẹ kan ni pe ‘Ko si ayẹyẹ igbeyawo ta fẹ lọ loni ọjọ, ko si ayẹyẹ oku sise, ko si ibi kankan ta fẹ lọ, wọn tun wa ni a ko lee dibo mọ. Iru Satide mimọ wo ni eyi lorilẹede Naijiria.’
Oríṣun àwòrán, Ronke fajemirokun
@raph_shalom, ọpọ ibeere lo n beere lati sa kuro ni Naijiria.
@d_boy_nextdoor, o ni orilẹede Naijiria nikan lati lee gbọ iru iroyin YajoYajo bayii, to si fi aworan kan to pa ni lẹrin sidi rẹ.
Ademola Aremu lori Facebook ni ‘o seni laanu pe awọn wolii ariran wa ko ri saaju pe ajọ eleto idibo yoo sun ibo siwaju ni Naijiria sugbọn awọn ti yoo bori ibo ni wọn n ri.’
Oríṣun àwòrán, Ademola Aremu
Bakan naa ni awọn eeyan orilẹede Ghana tun n fi wa se yẹyẹ ni Naijiria lori ba se sun ibo aarẹ siwaju lọjọ idibo gangan.
IssahakuB.Gbene lori Facebook ni ‘Awọn ọmọ Naija yii saa, Wọn ko lee se raisi Jọllọfu, bẹẹ ni wọn ko tun lee seto idibo lasan. Yatọ si ẹba ati ọbẹ ewuro tẹ mọ se, ki lẹ tun lee se gan?
Oríṣun àwòrán, iSsaku B.Gbene
Nigeria Elections 2019: Ìjàmbá iná àti àwọn nkan mi i tó mú INEC sún ìdìbò
Oríṣun àwòrán, InEC
Alaga ajọ eleto idibo Naijiria, INEC, Yakubu Mahmood ti sọ wi pe kii ṣe aṣẹ ẹnikẹni lo mu ki ajọ naa sun eto idibo aarẹ ati ti ile aṣofin apapọ to yẹ ko waye lọjọ Abamẹta, ọjọ kẹrindinlogun, oṣu Keji siwaju.
Ọ̀nà apanilẹ́rìń táwọn ọmọ Nàíjíríà gbà fèsì sí ìṣúnsíwájú ìbò ààrẹ
Àwòrán rèé lórí bí ìgboro ṣe rí lẹ́yìn tí ìbò kò wáyé mọ́#NigeriaDecides2019
Yakubu, lasiko to n ba awọn eniyan sọrọ ni gbọngan ti wọn ti maa n ko esi isibo jọ to wa ni ilu Abuja sọ pe ''ijamba ina, oju ọjọ ti ko dara to lati fi baalu gbe eroja idibo, ati idiwọ ninu eto gbigbe awọn eroja idibo lo mu ka sun eto idibo naa siwaju.
'Ko ni nkankan ṣe pẹlu eto aabo tabi aṣẹ lati ọdọ ẹnikẹni.''
O tọka si ijamba ina to waye ni awọn ileeṣẹ ajọ naa to wa ni ipinlẹ Anambra, Abia ati Plateau.
Mahmood sọ pe 'oun tọrọ aforiji fun sisun eto idibo naa siwaju, ati pe oun gba gbogbo ẹbi naa mọra.
Inec já mi kulẹ̀ lẹ́yìn ìgbaradì ọlọ̀jọ́ gbọọrọ - Buhari #NigeriaDecides2019
'Ọrọ Nàìjíríà fẹ itusilẹ' àti àwọn èsì míràn tó tẹlé bí INEC ṣé dajọ sí ìdìbò
Bakan naa ni Ọjọgbọn Yakubu kede pe ko si aaye fun ẹgbẹ oṣelu kankan lati polongo ibo nitori sisun ti wọn sun eto idibo siwaju.
Ati pe ko ẹnikẹni ko ni le ri kaadi idibo gba titi di ẹyin idibo.
Ọjọ Abamẹta, ọjọ kẹtadinlogun, osu Keji ọdun 2019 ni idibo aarẹ yoo waye.
Nigeria 2019 Elections: Canada yá, àti àwọn ọ̀nà mì t'ọmọ Nàìjíríá fi bínú sí sísún ìdìbò
Oríṣun àwòrán, Twitter
Ọpọlọpọ ọmọ Naijiria lo fẹ ẹ lọ mu ile si orilẹede Canada lẹyin ti eto idibo aarẹ ati ti ile aṣofin agba ko waye mọ.
Lootọ ni ko fojuhan ẹni to bẹrẹ ipolongo Canada ọhun, amọ ohun ni ijiroro to gbajumọ loju opo Twitter lẹyin ti ajọ INEC kede pe eto idibo ko ni le waye mọ.
Awọn ọmọ Naijiria ọhun to n fi ibinu wọn han n sọ pe, niwọn igba ti ajọ INEC ti jawọn kulẹ, awọn yoo fi Naijiria silẹ lọ si Canada.
Amọ ṣaa, yẹyẹ ni ọpọ fi ọrọ naa ṣe.
Diẹ lara awọn ipolongo Canada ọhun re:
Ọkan lara wọn @PaultwinOkoye fi aworan ọpọlọpọ baalu to n fo lẹẹkan naa han.
Ẹlomii, @laffbro ni tiẹ fi aworan ọkọ moluẹ ti wọn n lo ni ipinlẹ Eko pẹlu ọpọ eniyan to fẹ ẹ wọ inu rẹ lẹẹkan naa.
O ni ''nigba ti awọn ọmọ Naijiria gbọ pe igba Naira ni ọkọ ti yoo gbe wọn de orilẹede Canada.''
Bakan naa ni @YoungSaeed ko gbẹyin. O lo aworan awọn eero nibudo kan lati sọ pe awọn ọmọ Naijiria n sa lọ si Canada.
Fake News: Ayédèrú Dino fẹ́ fún èèyàn mẹ́wàá ní mílíọ̀nù mẹ́wàá náírà tí Atiku bá wọlé
Oríṣun àwòrán, Instagram/dinomelaye
Ilumọka oloṣelu ni Sẹnẹtọ Dino Melaye
Ibeere ''ki lo yẹ ki a fi ṣajọyọ ti Atiku ba pegede ninu ibo Aarẹ?'' ni Sẹnẹto Melaye @dinomelaye14  kọkọ fi bẹrẹ loju opo Twitter.
Kato wi ka to fọ ọ, o ti ṣe'pinu pe ohun yoo fun eeyan mẹwa ni miliọnu Naira kọọkan ti @atiku ba wole gẹgẹ bi Aarẹ orileede Naijiria!
Milọnu mẹwa lasiko ọgbẹlẹ yii?
Ere abi awada? kia lawa na bẹrẹ iwaadi  ti a si pada wa ri i wi pe kii ṣe Dino Melaye gangan lo fi ikede yi sita.
Ayederu ni orukọ Twitter naa jẹ nitori pe @dino_melaye lorukọ  ojulowo Senetọ Dino Melaye loju opo Twitter.
Bi o ba ti n bawọn pin ọrọ yii, iwọ naa ti dara pọ mọ awọn ti BBC ati ọpọ awọn amoye lawujo ni wọn n dakun wahala iroyin ẹlẹjẹ to gbode.
Sẹneto Dino Melaye to n soju awọn eeyan iwọ oorun ipinlẹ Kogi ni gbungbun orileede Naijiria kii ṣe aimọ lagbo oṣelu Naijiria.
Bi ko ba maa ba awọn ọlọpaa woya ija, oun ati Gomina ipinlẹ rẹ ko ni ma salai ni aawọ.
Lẹnu ọjọ mẹta yii ti idibo Aarẹ sunmọ, awọn ọmọ Naijiria ko fi bẹẹ gbohun rẹ amọ ni bayii ti ayederu ''Dino Melaye'' ti fi ikede miliọnu mẹwaa Naira sita, awọn eeyan ti n fun un lesi loju opo Twitter.
Ohun to ṣeni laanu ni wi pe Sẹnẹtọ Dino Melaye to jẹ ojulowo gangan kọ ni ka awọn esi yi .
Bi a ti ṣe n sọrọ yi, Sẹnetọ Dino Melaye ko tii fesi pada si ọrọ pe o fẹ pin miliọnu mẹwa Naira fun awọn eeyan.
O ṣeeṣe ki o jẹ wahala idibo ile asofin agba to n kopa ninu rẹ eleyi ti Inec sun siwaju lo n ba po o.
Amọ ṣa loju opo Twitter rẹ, ọrọ to nii ṣe pẹlu iwọde ti awọn obinrin Ebira kan ṣe lati fi ẹhonu han si ijọba ''ọta rẹ'' Gomina Yahaya Bello ni o fi sita.
Iléeṣẹ́ ọlọ́pàá ìpínlẹ̀ Kaduna láwọn kò lè ṣọ pé èèyàn 66 kú ní Kajuru
Oríṣun àwòrán, El-Rufai
Gomina Nasir El Rufai kii ṣe ajoji si ọrọ to ma n da awuyewuye silẹ
Ileeṣẹ ọlọpaa Naijiria ni ipinlẹ Kaduna lawọn ko le fidi ọrọ mulẹ pe eeyan mẹ́rìndínláàdọ́rin lo padanu ẹmi wọn ninu ikọlu to waye niijọba ibilẹ Kajuru nipinlẹ Kaduna.
Ẹni to jẹ agbẹnusọ fun ileeṣẹ ọlọpaa nipinlẹ naa Yakubu Sabo sọ fun BBC pe Kọmisana ọlọpaa nipinlẹ ọhun yoo ba awọn akọrọyin sọrọ nipa rẹ lọjọ aiku.
Nigba ti akọroyin bere lọwọ pe ki o tilẹ salaye ohun ti ọlọpaa mọ nipa iṣẹlẹ naa,  o ni ọga ohun yoo sọ gbogbo rẹ nigba ti o ba ba awọn akọroyin sọrọ.
'Kaduna ni àjọ NYSC pín mi sí sùgbọ́n...'
Lọjọ ẹti ni Gomina ipinlẹ Kaduna fiikede sita pe  awọn agbebọn pa awọn eeyan Fulani mẹ́rìndínláàdọ́rin lawọn agbegbe kan ni ijọba ibilẹ naa.
Amọ, awọn eeyan kan to wa ni ipinlẹ naa ti lodi si ohun to sọ.
Ọgbẹni  Ishaya Chinoko to jẹ ọga ajọ to n mojuto iṣẹlẹ pajawiri ni agbegbe iwọ oorun Naijiria sọ fun BBC pe ohun ko mọ wi pe iru nnkan bẹẹ ṣẹlẹ.
Ọga ajọ to n ja fun ẹtọ ọmọniyan tẹlẹ ni Naijiria ọjọgbọn Chidi Odinkalu naa da si ọrọ naa pẹlu bo ṣe ni ohun ko ro wi pe ootọ ni pe iṣẹlẹ naa waye.
Bakan naa ni iwe iroyin Punch lawọn ba olori awọn ọmọ lẹyin Kristẹni lorileede Naijiria  sọrọ ti alaga ẹgbẹ ni ipinlẹ Kaduna Joseph Hayab si sọ ninu atẹjade pe Gomina lo ọgbọn ẹwẹ lati tanawọn ọmọ Naijiria ati awọn onwoye lati ilẹ okere ni.
Ipinlẹ Kaduna jẹ ipinlẹ kan lariwa Naijiria ti ija ẹlẹsinmẹsin ati ẹlẹyamẹwa ti wọpọ laarin awọn darandaran Musulumi ati awọn agbẹ Kristẹni to wa lagbegbe naa.
Bakanna ni Gomina ipinlẹ Kaduna sọ laipẹ yii pe awọn ara ilu okere to ba fẹ toju bọ eto idibo Naijiria yoo jẹ iyanwọn niṣu.
Amọ ṣa o ti ṣalaye pe itunmọ ọrọ ti ohun sọ kọ ni yẹn.
Nigeria 2019 Elections: Ta ni Sani tó ń ṣe PVC fún INEC, tó tún ńdupò sẹ́nétọ̀?
Oríṣun àwòrán, Sani Musa 313/Facebook
Lọjọ Abamẹta ni ẹgbẹ oṣelu alatako nipasẹ Osita Chidoka to ṣoju alaga ẹgbẹ oṣelu Peoples democratic Party, PDP nibi ipade ijiroro ti aj INEC n ṣe pẹlu awọn eekan ilu nilu Abuja lẹyin ti wọn kede isunsiwaju eto idibo, fi ẹsun kan pe ileeṣẹ to n pese kaadi oludibo fun INEC jẹ ti ọkan lara ọmọ ẹgbẹ All Progressives Congress, APC, to tun n dije fun ipo sẹnetọ ni ẹkun idibo ila oorun ipinlẹ Niger.
Iroyin fidirẹmulẹ pe ọdun 2011 ni ileeṣẹ naa labẹ orukọ Act Technologies Limited ti n gba iṣẹ agbaṣe lọwọ ajọ INEC, ati pe ohun lo pese awọn ẹrọ ti INEC fi tẹ kaadi oludibo fun eto idibo ọdun 2015.
Ẹgbẹ oṣelu PDP n fẹsun kan pe 'ko yẹ ki ọkunrin naa, nipa alakalẹ ọmọluabi, jẹ ki ileeṣẹ rẹ gba iṣẹ agbaṣe naa lati ṣe kaadi oludibo ninu eto idibo ti oun funra rẹ ti n kopa.
Ati pe kini idi ti INEC tun fi gbe iṣẹ agbaṣe lati tẹ kaadi oludibo fun eto idibo 2019 t'oun funra rẹ ti n kopa gẹgẹ bi oludije?
Nigba ti wọn fi ẹsun naa kan, alaga ajọ INEC, Mahmood Yakubu fesi pe lootọ ni ajọ ti n ṣiṣẹ pẹlu ileeṣẹ naa lati ọdun 2011 , Activate Technologies Limited, amọ 'ko ni ṣe idiwọ fun eto idibo ti ko ni mago-mago ninu.''
Ati wi pe oṣiṣẹ INEC kankan ko ni i gbabọde.
Kini a mọ nipa ọkunrin naa?
Iwadi wa lori ayelujara fihan pe Mohammed Sani Musa di ẹni to ni ileeṣẹ Activate Technologies Limited ninu oṣu Kini, ọdun 2012. Ileeṣẹ naa maa n ṣe awọn nkan to wulo fun imọ ijinlẹ ibaraẹnisọrọ (ICT).
O jẹ oludamọran pataki fun ijọba ipinlẹ Niger laarin ọdun 2008 si 2011.
Ileeṣẹ rẹ, Activate Technologies Limited to maa n ṣe awọn kaadi ẹrọ ayarabiaṣa maa n gba iṣẹ agbaṣe lọwọ awọn ileeṣẹ ijọba Naijiria bii:
Nigeria Elections 2019: IPMAN kéde àdínkù ìyè owó epo bẹntiróòlù
Oríṣun àwòrán, PIUS UTOMI EKPEI
Pupọ ọmọ Naijiria lo ti pe fun gba ma binu latari isunsiwaju idibo Aarẹ
Ẹgbẹ alagbata epo aladani lorileede Naijiria IPMAN ti paṣẹ ki awọn ọmọ ẹgbẹ wọn jakejado Naijiria mu adinku ba iye owo epo bẹntiro lati mu irọrun ba awọn eeyan lasiko idibo.
Adinku ti wọn kede ọhun ni lati naira márùndínláàdọ́jọ (N145) lita kan si naira méjìlélógóje N142 tabi ogóje naira N140
Aarẹ ẹgbẹ naa Chindeu Okoronwo to ba ikọ BBC Pidgin sọrọ sọ pe onagba lati mu idagbasoke ba Naijiria ni awọn fi ṣe bẹẹ.
"Ohun ta gbero ni lati mu idẹkun ba awọn ọmọ Naijiria paapa jullasiko idibo yii. Ọna lati ṣe koriya fun awọn oludibo ni nitori pe ti eeyan ba jade lati dibo,ojuṣe rẹ pataki ni o ti ṣe yẹn.''
Janduku yinbọn nilu Iwara
O ṣafikun pe adinku naa yoo bẹrẹ lati ọjọ Aje ti ṣe ọjọ kejidinlogun Oṣu keji titi di ọjọ kejila Oṣu kẹta ọdun 2019.
Ọgbẹni Okoronkwo salaye pe kii ṣe ẹgbẹ oṣelu lo n gbe igbesẹ yi bi kii ṣe ẹgbẹ IPMAN.
Ẹ ma jẹ ki a sọrọ nipa owo ti a o padanu.Alafia ti yoo mu ba ilu ni ki ẹ jẹ ki a sọ.A ko le ko iye owo kankan le nini alafia nilu''"
Ko ti daju bi ikede yi yoo ti ṣe lapa lara owo irina amọ awọn eeyan n reti ki awọn awakọ din owo irina ọkọ ku nigba ti wọn ko nira epo to iye ti wọn n ra tẹlẹ.
Ajọ eleto idibo Naijiria kede isunsiwajuiboAarẹ ati tawnile asofin orileede Naijiria lati ọjọ kẹrindinlogun Oṣu keji si ọjọ kẹtalelogun Oṣu keji ti idibo Gomina to yẹ ki o waye lọjọ keji Oṣu kẹta ti sun si ọjọ kẹsan Oṣu kẹta .
Ọ̀gá ọlọ́pàá pàṣẹ kí wọ́n ṣé ìwádìí ọlọ́pàá inú àwòrán 4+4
Oríṣun àwòrán, @kekeTony
Ṣadede ni aworan awọn ọlọpaa ti wọn na ika 4+4 yi lu sita loju opo ayelujara
Adele ọga ọlọpaa lorileede Naijiria Mohammed Adamu ti pasẹ ki ẹka to n ṣewadi nnkan aworan bẹrẹ iwaadi lori aworan awọn ọlọpaa mta kan ti wọn jọ bi ẹ ni naka soke lati ṣe atilẹyin fun ẹgbẹ oṣelu APC ati Aarẹ Buhari to n du ipo lẹẹkansi.
Loju opo Twitter ileeṣẹ naa ni wọn fi ikede yi si lọjọ Aje.
Gẹgẹ bi ohun ti ikede naa sọ,bi wọn ba ti pari iwaadi na wọn yoo fi abajade rẹ sita fun gbogbo ara ilu.
Àjọ Ọlọ́pàa Naijiria: A ó fi òsìsẹ́ SARS tó se isẹ́ ibi náà jófin
Ohun to ṣe okunfa iwaadi yi ko silẹyin bi arakunrin kan ti ṣe fiwe ranṣẹ si ileeṣẹ ọlọpa loju opo Twitter nipa aitọ iwa ti awọn ọlọpaa to na ika 4+4 naa hu.
Lẹnu ọjọ mẹta yi, awọn ọmọ Naijiria ti n bẹnu atẹ lu ileeṣẹ ọlọpaa fun bi wọn ti ṣe ni wọn n ṣegbe lẹyin ẹgbẹ oṣelu to wa ni ijọba.
Ọrọ naa lagbara pupọ lasiko igba ti ọga ọlọpaa  ana ,Ibrahim Kpotun Idris , wa nipo ọga ọlọpaa.
Lasiko rẹ, ọpọ awuyewuye waye laarin awọn oloṣelu paapa awọn ti ile asofin agba to fi mọ awọn ajafẹtọmọniyan kan ti wọn jijọ wọya ija.
Igbesẹ adele ọga ọlọpaa tuntun yi yoo ma ṣe afihan boya nnkan ti yi pada tabi oun naa n ṣe bi ẹni gbe lẹyin ẹgbẹ oṣelu kan.
BBC Yorùbá: Olóòtú ní àwọn ṣẹ̀ṣẹ̀ ń mú ẹyẹ bọ̀ lápò ni, ẹ tì rí nkànkan
Ọjọ oni yii lo pe ọdun kan geerege ti ileesẹ iroyin BBC lagbaye sefilọlẹ ileesẹ iroyin BBC lede Yoruba.
Lati ọjọ Kọkandinlogun osu Keji ti ala wọn lori idasilẹ ileesẹ BBC Yoruba si ti di ohun, ọpọ akanse isẹ ni wọn ti gbe seni idi isẹ iroyin agbohunsafẹfẹ nilẹ Naijiria.
Nigba to n salaye bii irinajo ọdun kan yii se lọ, Olootu ileesẹ agbohunsafẹfẹ BBC Yoruba, Temidayọ Ọlọfinsawo ni ọpọ ojo lo ti rọ, ti ilẹ si ti fi mu.
Nkan ti awọn eeyan nsọ lori BBC Yoruba
Ninu ọrọ rẹ, o ni ọjọ́ rèé bí àná yìí, tí ilé isẹ BBC láàgbáyé, BBC World Service, sàgbékalẹ ilé isẹ ìròyìn BBC News Yorùbá.
Temidayọ ni nígbàtí tí oun kọkọ rí ìkéde ìpòlońgo igbanisisẹ naa, oun ro o lọkan oun wipe, njẹ BBC le da ile ise iroyin Yoruba sile sa?
"Mi o jafara, mo yara fi iwe iwasẹ (CV) mi ranse lori itakun agbaye, mo si n reti esi.
Igbati wọn pemi fun ifọrọwanilẹnuwo, iyalẹnu lo jẹ, nitori mo salabade awọn oyinbo nibẹ. Oyinbo wa gbọ Yoruba bi? Ẹnu  ẹ la wa yẹn. Ka ma fa ọrọ gun, mo yege, wọn pemi, mo si bẹrẹ ise."
A sẹ awa naa lee ni BBC tiwa
Gbogbo wa ti a wọsẹ lọjọ naa yọ mọ ara wa, a mu tíì ati bisikiti. Ahmed Ambali fẹrẹ mu garawa tíì kan, ko to siju lara tíì ọhun.
"Eyi ta n sọ dun, gẹgẹ bi olootu agba ile isẹ BBC News Yoruba, ẹru bami lakọkọ pe, se awọn eniyan maa tẹwọ gba wa, amọ ju bi mo se ro lọ, iroyin wa tan ka orilẹede Naijiria, titi de ọdọ awọn ọmọ Naijiria to wa loke ọkun.
Mo wa ri daju pe , ise gidi ni awọn akẹẹgbẹ mi nibi isẹ n se."
BBC Yoruba n'iseju kan
"Eyi ta n sọ dun, gẹgẹ bi olootu agba ile isẹ BBC News Yoruba, ẹru bami lakọkọ pe, se awọn eniyan maa tẹwọ gba wa, amọ ju bi mo se ro lọ, iroyin wa tan ka orilẹede Naijiria, titi de ọdọ awọn ọmọ Naijiria to wa loke ọkun.
Mo wa ri daju pe , ise gidi ni awọn akẹẹgbẹ mi nibi isẹ n se."
Olootu BBC Yoruba fikun pe, awọn ọdọ nifẹ si irufẹ iroyin ti awọn ma a n gbejade, wọn kii jẹ ki iroyin awọn dilẹ lori Facebook, ki wọn to salabapin rẹ, eyi to n wu awọn lori.
Omi tuntun ti ru, ẹja tuntun ti jade
"Ohun to dun mọ mi ninu julọ nipa ise naa ni wipe, gbogbo awọn to je osisẹ BBC News Yoruba, ni wọn to gbangba sun lọyẹ. Ifọwọsowọpọ to dan mọran wa laarin wa. Eyi lo n mu ki iroyin ati agbekale awọn itan wa jẹ ara meeriri.
Bakana, ohun to jẹ ipenija fun mi julọ, ni sise adari awọn ti mo n ba sisẹ, awọn to jẹ onmoye, ti wọn ti ni iriri isẹ iroyin kaakiri, sugbọn ti wọn ni ẹmi itẹriba ati ifọkantan gidi ni idi isẹ yii."
"O tẹsiwaju pe, ""Ko si igbesẹ ti mo gbe ti wọn ki fi yemi pe, 'bo lọmọ ogun, boo lọmọ ogun, wẹyin rẹ wo'. Igbaruku wọn jẹ ohun iyalẹnu, oju ko si ni tiwa."
"BBC News Yoruba, asẹsẹ bẹrẹ ni, ẹ o ti ri nkankan nitoripe BBC Yoruba, awa gangan lara."""
2019 Elections: Iléeṣé ológun ṣèlérí láti mú àṣẹ Buhari ṣẹ
Oríṣun àwòrán, @HQNigeria
Ileesẹ ologun orilẹede Naijiria ti kede pe, o di dandan ki oun tẹle asẹ ‘ji apoti ibo, ko fi iku se ifa jẹ’, to ba jẹ pe aarẹ Muhammadu Buhari lo pa asẹ naa fun oun.
Lasiko to n fọwọ idaniloju sọya fawọn akọroyin, agbẹnusọ fun ileesẹ ologun, Sagir Musa salaye pe, ẹni to ba ran ni nisẹ laa bẹru, a kii bẹru ẹni ti a jẹ fun.
Musa fikun pe, lootọ ni ileesẹ ologun ilẹ wa yoo fi awọn ọmọ ogun sọwọ fun eto aabo to peye lasiko eto idibo naa, amọ wọn ko ni duro sawọn agọ idibo gangan bikose awọn agbegbe to sun mọ ibẹ.
"To ba jẹ pe olori orilẹede yii ati alasẹ patapata fun ilẹ Naijiria lo pa asẹ fun wa pe, ka mu ẹyin ẹnikẹni to ba ji ibo balẹ, ẹ jẹ ko da yin loju pe, a mu asẹ naa sẹ laisi tabi sugbọn kankan nipa rẹ.
Awọn ọmọ orilẹede yii, ninu eyi ti a ti ri awọn oloselu, ajafẹtọ ẹni, awọn agbẹjọrọ, agbarijọpọ ẹgbẹ oselu ati awọn eekan ilu kan ti foju laifi wo ọrọ to jade lẹnu aarẹ Mohammadu Buhari lasiko ipade ẹgbẹ APC lọjọ Aje.
Bẹẹ ba gbagbe, nibi ipade pajawiri ti aarẹ se pẹlu ẹgbẹ oselu rẹ, APC, lo ti kede pe ẹnikẹni to ba ji apoti ibo gbe lasiko eto idibo to n bọ, yoo fi ẹmi ara rẹ di nitori ijọba ti pasẹ fawọn osisẹ agbofinro lati gbe igbesẹ to yẹ.
Nigba to n fesi lori ọrọ ti aarẹ Buhari sọ yii, alaga ẹgbẹ oselu PDP, Uche Secondus ni o ti foju han bayii pe gbogbo ọna ni Buhari n san lati wa nipo, pẹlu asẹ to pa fun awọn osisẹ ologun ati ọlọpaa naa, eyi ti yoo awọn asaaju APC maa fija jẹ awọn oludibo.
Oríṣun àwòrán, @MBuhari
Secondus ni ikede Buhari ọhun lo fara pẹ ikede ogun jija lori awọn oludibo ati iwa riru ọkan awọn agbofinro soke si wọn.
Nigba toun naa n fesi lori ikede Buhari yii, ẹgbẹ agbarijọpọ awọn ẹlẹgbẹjẹgbẹ oselu lorilẹede Naijiria, CUPP, kesi awujọ agbaye lapapọ lati tete di ẹru ẹmi to ba bọ lasiko idibo ru aarẹ Buhari.
Agbẹnusọ fun CUPP, Imo Ugochinyere, to sọrọ lorikọ ẹgbẹ naa ni iwa ikede nita gbangba to tii buru julọ, to si jẹ ikede iwa ika ni Buhari se yii.
Lero ti olori ile asoju sofin nilu Abuja, Yakubu Dogara, lasiko ipade akọroyin to se lori ikede naa ni, o se ni laanu pe eto iselu alagbada wa ti bọ sọwọ olori apasẹ waa.
Nkan ti awọn eeyan nsọ lori BBC Yoruba
Dogara ni o si ya oun lẹnu pe ẹni ti wọn pe ni olori orilẹede kan lee sọ iru ọrọ yii jade, eyi to tako ẹjẹ to jẹ lati daabo bo ẹmi ọm orilẹede yii kọọkan lasiko ibura rẹ.
Ninu ọrọ ti awọn agbarijọpọ awọn ẹgbẹ ajafẹtọẹni, wọn ni ipe Buhari yii tako ofin orilẹede wa,
Aarẹ apapọ fun ẹgbẹ naa, Malachy Ugwummandu ni ọrọ Buhari naa dabi igba to n gba ojuse ẹka eto idajọ se ni, eyi ti ojuse rẹ wa lati maa tumọ iwe ofin orilẹede yii.
Nigeria 2019 Elections: INEC kéde pé àwọn ẹgbẹ́ òṣèlú lé tẹ̀síwájú pẹ̀lú ìpolongo
Oríṣun àwòrán, @inecnigeria
Ajọ eleto idibo Naijiria, INEC ti fi aṣẹ si pe awọn ẹgbẹ oṣelu le tẹsiwaju pẹlu ipolongo ibo wọn, ni imurasilẹ fun eto idibo aarẹ ati tile aṣofin apapọ ti yoo waye lọjọ Abamẹta.
Alẹ ọjọ Aje ni alaga ajọ naa, Ọjọgbọn Mahmood Yakubu kede asẹ tuntun naa.
Atẹjade kan ti ajọ naa fisita lori Twitter fihan pe, igbesẹ tuntun naa waye lẹyin ti INEC ṣe ipade pẹlu awọn ẹgbẹ oṣelu.
Ṣaaju ni Yakubu kede lọjọ Abamẹta to kọja pe, ko si aaye fun ẹgbẹ oṣelu kankan lati tẹsiwaju ninu ipolongo ibo nitori pe ajọ naa sun idibo siwaju.
Ọjọ Abamẹta, ọjọ Kẹrindinlogun, oṣu Keji lo yẹ ki eto idibo aarẹ ati tile aṣofin o waye, ṣugbọn ajs INEC sun un siwaju.
Ọjọgbọn Yakubu tọka si awọn idi kan, bii eto aabo to mẹhẹ, idiwọ fun pipin eroja idibo ati awọn nkan mi i gẹgẹ bi ohun to fa a ti INEC fi sun idibo siwaju.
Lọgan ti ajọ naa si kede ainile tẹsiwaju pẹlu ipolongo ibo, ni awọn ẹgbẹ oṣelu kan ti n fi ibinu han si igbesẹ ajọ naa.
Oríṣun àwòrán, @inecnigeria
Alaye wọn ni pe, to ba ku wakati mẹrinlelogun ki idibo waye, ni ofin Naijiria sọ pe ipolongo gbọdọ pari. Ati pe, INEC gbọdọ faaye gba wọn niwọn igba to ti sun idibo siwaju.
Nibayii, oru Ọjọbọ, ọjọ kọkanlelogun, oṣu Keji ni ipolongo ibo aarẹ ati tile aṣofin apapọ yoo wa sopin.
Ìṣẹ̀lẹ̀ ìpànìyàn: Iléeṣẹ́ aṣọ́bodè ní àṣìta ìbọn ló fa sábàbí
Oríṣun àwòrán, Nigeria Customs Service
Ajọ aṣọbode gba pe lootọ ni oṣiṣẹ wọn to yinbọn pa ọkunrin naa ko tẹ ohun to le dena ki ibọn naa o maa yin ara rẹ.
Ileeṣẹ irinna Iyare Motors to ni ọkọ ti awọn oṣiṣẹ ajọ aṣọbode Naijiria mu, ninu fidio kan to ṣafihan bi wọn ṣe yinbọn mọ arakunrin kan , ti sọ pe, awọn oṣiṣẹ aṣọbode naa ti mu ti yo.
Bo tilẹ jẹ wipe atẹjade kan ti ajọ aṣọbode fi sita sọ pe ''oṣiṣẹ awọn ti wọn lọ yinbọn mọ arakunrin naa, ko ni ọkan lati ṣe bẹ, amọ ibọn to gbe dani lo ṣeeṣi yin ara rẹ.''
Amọ ṣaa, aṣoju ileeṣẹ Iyare Motors to ba BBC sọrọ, Solomon, ṣalaye pe, awakọ wọn jabọ pe awọn oṣiṣẹ aṣọbode ọhun ti mu ọti yo ni owurọ ọjọ Kẹtadinlogun, oṣu Keji ti iṣẹlẹ naa waye.
Eyi lo mu ki wọn maa huwa kebe-kebe, ti wọn si da ọkọ awọn duro lati beere fun owo.
Ṣugbọn, agbẹnusọ fun ileeṣẹ aṣọbode, Joseph Attah, to ti kọkọ fi atẹjade sita, sọ pe irọ ni ileeṣẹ Iyare Motors n pa.
''Ẹhn ẹhn, àwọn da ẹni to mu ọti yoo mọ? Ibeere ti Attah bi akọroyin wa niyi, bo tilẹ jẹ pe o gba pe lootọ ni oṣiṣẹ aṣọbode to yinbọn pa ọkunrin naa, ko tẹ ohun to le dena ki ibọn naa o maa yin ara rẹ.
Bakan naa lori ẹsun ti ajọ aṣọbode fi kan pe, bọọsi naa ko aṣọ ti ofin ko faaye gba ni awọn oṣiṣẹ awọn ṣe da a duro, Solomon sọ pe:
Irọ ni, wọn kan n wa ọna lati bo iwa ti wọn hu mọlẹ ni, kiiṣe 'tori pe ọkọ bọọsi wa ko aṣọ ti ofin ko fọwọ si."
"Owo ni wọn fẹ ẹ gba lọwọ awọn eniyan wa."""
Fidio naa ṣafihan awọn kan to duro, awọn oṣiṣẹ aṣọbọde, ati arakunrin kan ti ara rẹ kun fun ẹjẹ, to si da bi ẹni to ti ku.
Iroyin to gbalẹ kan lẹyin ti fidio naa jade sori ayelujara ni pe, oṣiṣẹ aṣọbode kan lo yinbọn pa ọkunrin naa to jẹ ọkan lara awọn ero ọkọ bọọsi to n rinrinajo ni opopona Ọ̀rẹ̀ si Benin, nitori owo.
Bakan naa ni Attah ko sọ ni pato, ijiya ti yoo wa fun oṣiṣẹ aṣọbode to yinbọn pa ọkunrin naa, tabi boya owo ti wọn fẹ ẹ gba lọwọ awakọ bọọsi naa ni wọn ṣe daa duro.
Nigeria 2019 Elections: Jonathan, Buhari, Obasanjọ sọ̀kò ọ̀rọ̀ lórí làáṣìgbò ìbò
Aarẹ Muhammadu Buhari sọ pe ẹnikẹni to ba ji apoti ibo gbe lasiko eto idibo to n bọ, yoo fi ẹmi ara rẹ di, nitori ijọba ti pasẹ fawọn osisẹ agbofinro lati gbe igbesẹ to yẹ.
BBC Yoruba ti wa wọnu itan lọ lati lọ wu awọn ọrọ to jọra, ti awọn awọn olori Naijiria ti sọ ṣeyin lasiko ibo.
Awọn ọrọ miiran ti awọn aarẹ naa n sọ, si lo n faa bi awọn araalu se n bu ẹnu atẹ lu wọn, ti awọn miiran si n gba oriyin.
Ní ọdun 2015, nigba ti gbogbo Naijiria n mura kirakita fun idibo gbogbogbo ninu eyi ti aarẹ igba naa, Goodluck Jonathan ati Muhammadu Buhari jẹ oludije fun ẹgbẹ oṣelu PDP ati APC, Jonathan sọ ọrọ kan to mu iwuri ba ọpọlọpọ:
Sugbọn Buhari lo jawe olu bori ninu idibo naa.
Amọ ki ni Buhari gan funra rẹ sọ lori idibo 2015 ti o mu awuyewuye dani nigba naa?
Ẹ o ranti wipe, o ti dije ni ẹẹmẹta ṣaaju 2015 ti o si kuna. Buhari sọ ọrọ  yìí ní ọdun mẹ́ta ṣaaju idibo 2015, Oun to sọ rèé:
Àarẹ ana Olusegun Obasanjo, ti o ṣe olori Naijiria laarin ọdun 1999 si 2007 naa ko gbẹyin ninu ọrọ kanka to mu awuyewuye dani.
Ni ọdun 2007 nigba to n ṣe ipolongo ibo fun Umaru Musa Yar'Adua to rọpo rẹ, Ọbasanjọ sọ ọrọ kan ti ọpọlọpọ eniyan bẹnu atẹ lu.
O ni, tiku-tiye ni idibo naa fun ẹgbẹ oselu PDP.
BBC Yorùbá: Ọ̀pọ̀ òjò ti rọ̀, ilẹ̀ ti fimu láàrin ọdún kan BBC Yorùbá
Ní ọjọ́ kọkàndínlógún ọdún 2018 ni wọ́n ṣe ìfilọ́lẹ̀ BBC News Yorùbá ní ìlú Eko gẹ́gẹ́ bíi ara àwọn ìkànnì tuntun méjìlá BBC lágbáyé
Ni aarin ọdun kan ti BBC News Yoruba ti bọ sori afẹfẹ, oniruuru iroyin manigbagbe ni o ti gbe sita eleyi ti o ti rinlẹ kọja orilẹede Naijiria.
Bi a ti ṣe n mu iroyin ijinlẹ pẹlu iwaadi ti ko lẹjanbakan ninu wa, lawọn ọdọ naa n gba ẹtọ tiwọn.
Gbogbo aṣa ati iṣe Yoruba ni a n ṣi aṣọ lawọn oju opo rẹ fun igbadun ati idanilẹkọ fawọn eeyan kaakiri.
Diẹ lara awọn iroyin manigbagbe to waye laarin ọdun kan naa niwọnyii:
"Ọkan pataki lara awọn iroyin to waye ni ifọrọwanilẹnuwo kan pẹlu agba ọjọgbọn, Wọle Soyinka, nibi to ti pariwo pe ""Ti mo ba dara pọ m'ẹgbẹ Ọbasanjọ, wọn gbọdọ yẹ mi lọpọlọ wo"""
Iroyin yii di itẹwọgba kaakiri agbaye bi ọmọ tuntun. O si wa lara awọn akọṣe iṣẹ BBC News Yoruba ti o fọn rere rẹ kari aye.
Eyi ni ifọrọwanilẹnuwo pẹlu gbajugbaja pasitọ Tunde Bakare lasiko ti ọrọ idamẹwa sisan n fa ariyanjiyan lorilẹede Naijiria.
Bi BBC News Yoruba ṣe fọrọ wa Daddy Freeze, to n lewaju igun to ni pe idamẹwa ko lẹtọ, lasiko naa ni o tun ba Pasitọ Bakare sọrọ pẹlu nigba naa.
Eyi ni itan Obinrin kan ti o di alabọ ara nitori ijamba ọkọ to waye ni ilẹ Saudi, ninu eyi ti ọkọ rẹ, Dokita Ajani Raji ti di oloogbe.
Okiki iroyin yii kan to bẹẹ gẹẹ, ti awọn akanda ẹda lawujọ pẹlu fi gba pe BBC News Yoruba jẹ ohun wọn, lati fi sọ ẹdun ọkan ti wọn naa faraye.
Ṣe ẹ ranti ọdun ijẹṣu ni ilu Ilaramọkin, nibi ti awọn ọdọ ti n yọ pankẹrẹ ati atori si ara wọn lati fi sami ajọyọ ọdun ijẹṣu nibẹ. Bi wọn ṣe n ṣe, BBC news Yoruba naa wa nibẹ.
Nigba ti wahala wiwo ile iṣẹ redio gbajugbaja akọrin ni, Yinka Ayefẹlẹ waye ni Ibadan, BBC News Yoruba lo lewaju iroyin ohun gbogbo to n lọ nigba naa, lai jẹ ki eti araalu di si bi ọrọ naa ṣe lọ.
Ko rọrun, ṣugbọn nitori pe ilepa ileeṣẹ BBC News Yoruba ni lati rii pe gbogbo eeyan lawujọ lo lanfani ati sọ ẹdun ọkan wọn, a ko tẹti
Nigba ti eto idibo ipinlẹ Ekiti ati Ọṣun waye, lati ibẹrẹ de opin ni ileeṣẹ BBC News Yoruba ti gbe iroyin mejeeji yi lai fi ohunkohun pamọ fun araalu.
"Koda, aṣa "" Dibo koo sebẹ""  to di gbajugbaja ọrọ lawujọ oṣelu Naijiria bayii, ko ṣẹyin BBC NEWS Yoruba, nitori awa gan an lara."
Nipasẹ iṣẹ iwaadi iroyin to rinlẹ ni BBC News Yoruba fi ṣawari ibudo ti wọn ti n fi ẹgbẹrun mẹrin naira ra ibo ni ilu Ado Ekiti.
Osun Election Results 2018: Ademola Adeleke ní wọ́n jà òun lólè
Ṣe ẹ ranti Sẹneto onijo, iyẹn Sẹnetọ Ademọla Adeleke?
BBC ni ileeṣẹ iroyin akọkọ ti o kọkọ ba Adeleke sọrọ, lẹyin ti ọrọ idibo rẹ ipinlẹ Ọṣun ri bo ṣe ri fun un.
Ko si si idi meji fun eyi ju igbẹkẹle ati igbagbọ ti o ni ninu ileeṣẹ BBC News Yoruba gẹgẹ bii ikanni ti ko ni fi igba kan bọ ọkan ninu.
#67yearoldmother: Ọ̀pọ̀ gbà pé àdúrà ló gbà lóri tọkọtaya Otubusin
Ṣe ẹ ranti iroyin iya ọmọ ọdun mẹtadinlọgọrin to bi akọbi rẹ ni ilu Abẹokuta?
Nigba ti o ṣẹlẹ, BBC News Yoruba lo ṣaaju lati tu iṣu de isalẹ ọrọ naa.
Lori awọn aṣa to ti fẹ parun, BBC News Yoruba gbe iroyin kan jade nipa ọmọbinrin awẹlẹwa kan ti o kọ ila ati iriri rẹ lori ila naa.
Eyi si mu ipakiyesi wa fun aṣa ila kikọ ni ilẹ Yoruba ati ohun tawọn eeyan n koju nipa rẹ.
Bakan naa ni BBC News tun gbe iroyin Mike Ifabunmi, ọmọ ilẹ Brazil, ti o di ẹlẹsin ifa pẹlu Yoruba to dan mọran lẹnu rẹ.
Ninu ifọrọwerọ BBC News pẹlu aarẹ Naijiria nigbakan ri, Oloye Oluṣẹgun Ọbasanjọ, ẹ ri bi o ṣe lọ kaakiri agbaye.
Koda titi de awọn orilẹede bii Amẹrika, ilẹ Gẹẹsi ati Canada, ka fi mọọ nibẹ, ni wọn gba iroyin naa ti wọn si da sii pẹlu.
Fun igba akọkọ, BBC News Yoruba ṣagbekalẹ ifojurinju laarin awọn oludije ipo oṣelu ati araalu ni ipinlẹ Oṣun ṣaaju idibo gomina nipinlẹ naa.
Eyii ni igba akọkọ ti wọn yoo fi ede abinibi ṣe ifọrọwerọ bayii lorilẹede Naijiria.
Ipinlẹ Kwara, Eko, Ọyọ ati Ogun lo tun tẹlee eyi ti o yi iha ti ọpọ kọ si eto oṣelu lorilẹede Naijiria titi de oke okun pada.
Nigeria 2019 Elections: Alága INEC, Mahmood Yakubu ní àṣẹ Ààrẹ Buhari lórí pípa ẹni tó bá jí ìbò gbé tako ohun tí òfin sọ
Oríṣun àwòrán, @inecnigeria
Alaga ajọ INEC ti tako aarẹ Buhari lori aṣẹ to pa pe ki awọn ologun o maa yinbọn fun ẹnikẹni to ba ji apoti ibo gbe lasiko idibo apapọ to n bọ.
Alaga ajọ INEC, Ọjọgbọn Mahmood Yakubu ni ofin idibo lorilẹede Naijiria ti la ijiya to yẹ fun ẹnikẹni to ba tapa si ofin idibo nitori naa ajọ INEC ko lee faye gba ofin tabi aṣẹ miran to ba yatọ si ilakalẹ ofin yii.
Ni akoko to fi n ba awọn oniroyin ati alẹnulọrọ lori eto idibo sọrọ nilu Abuja.
Alaga ajọ INEC naa ni ajọ ọhun ko naani ọrọ yoowu  ti aarẹ Buhari lee sọ si nitori aṣẹ ati ilana ajọ naa wa lọwọ ajọ naa gẹgẹ bii ajọ to da duro ni ominira.
Nkan ti awọn eeyan nsọ lori BBC Yoruba
Lori iroyin kan tawọn iwe iroyin abẹle kan gbe ni ọjọ iṣẹgun pe awọn agbofinro DSS ti gbe ọkan lara awọn kọmiṣọna rẹ, Ọjọgbọn Yakubu ni pe ko si ootọ ninu iroyin naa.
O ni awọn agbofinro ko wọ ile eyikeyi ninu awọn oṣiẹ rẹ rara.
O wa gbe ilana ti eto idibo ọjọ abamẹta yoo ba jade kalẹ.
2019 Elections: INEC fún àwọn èèyàn ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́ ní ìdánilójú ṣáájú ìdìbò ọjọ́ àbámẹ́ta
Kọmisọna ọlọpa nipinlẹ Ọyọ, naa ṣe afihan igbaradi ajọ ọlọpa nibi akanṣe apero naa.
Ajọ eleto idibo orilẹede yii, INEC ẹka ti ipinlẹ Ọyọ ṣe akanṣe apero pẹlu awọn aṣoju ẹgbẹ oṣelu ati awon agbofinro ti yoo kopa ninu eto idibo gbogbogbo ti yoo waye lọjọ Abamẹta.Ipade naa to waye lọjọ Iṣẹgun ni olu ile iṣẹ ajọ eleto idibo ẹka ti ipinlẹ Ọyọ tokalẹ silu Ibadan lo da lorii oniruuruu idahun si awọn ọkanojọkan ibeere to ni ṣe pẹlu idibo si ipo aarẹ ati ile igbimọ aṣofin ti yoo waye jakejado orilẹede yii lọjọ Abamẹta.
INEC tako àṣẹ Buhari lórí pípa ẹni tó bá jí ìbò gbé
Kà nípa ìròyìn mánigbàgbé tí BBC News Yorùbá ṣe láàárín ọdún kan
Jí àpótí ìbò, ko fi ikú ṣe ìfà jẹ - Iléeṣé ológun laago ìkìlọ̀
Ninu ọrọ rẹ nibi ipejọpọ naa, Kọmisana ajọ eleto idibo nipinlẹ Ọyọ, amofin Mutiu Agboke ṣe alaye wi pe gbogbo eto lo ti to lati rii daju pe eto idibo baa kẹsẹ jari.O tẹsiwaju pe gbogbo kudiẹkudiẹ to ṣokunfa isunsiwaju ibo ni ijọba ti ṣe atunṣe rẹ bayii, bẹrẹ lati ori igba ibo ati awọn iwe to n ṣe akẹsilẹ esi ibo.O fi kun ọrọ rẹ pe omimi kan ko ni mi ibo ọjọ Abamẹta.
Bakan naa ni awọn agbofinro pẹlu naa jabọ eto abo ti wọn ti gbe kalẹ fun idibo naa faraalu
Kọmisọna tuntun fun ajọ ọlọpa nipinlẹ Ọyọ, Shina Tairu Olukolu naa ṣe afihan igbaradi ajọ ọlọpa nibi akanṣe apero naa.O ni ajọ naa ti n sa gbogbo ipa rẹ lati le jẹ ki ohun gbogbo lọ ni irọwọrọsẹ saaju, lasiko ati lẹhin ibo.Komisọna ọlọpa fi kun ọrọ rẹ pe amojuto to pe ye yoo wa lori ayunlọ ati ayunbọ awọn ohun elo fun eto idibo naa.
Nigeria 2019 Elections: Àwọn aráàlú kan ní ìṣúnsíwájú ìbò ṣàkóbá fún ọrọ̀ ajé
Ẹgbẹ oṣelu kọọkan lo ni aṣoju nibi apero naa, gbogbo wọn sini wọn ni anfani lati beere ohun gbogbo to ru wọn loju nipa eto idibo ati ojuṣe awọn agbofinro.Satide ọjọ kẹrindinlogun oṣu keji odun yii lo ti yẹ ki eto idibo naa waye ṣugbọn ajọ INEC sun eto naa siwaju nitori awọn kọkọrọ kan to ba eyin aja jẹ nipasẹ imurasilẹ ajọ naa.Nibayii, ọjọ kẹtalelogun oṣu keji ni eto idido naa yoo waye.
Nig-Ghana: Ìjọba àpapọ̀ faraya lórí bí Ghana ṣe lé àwọn ọmọ Naijiria padà sílé
Oríṣun àwòrán, @alessabocchi
Kii se igba akọkọ ree ti wọn yoo le awọn ọmọ naijiria pada wa sile lati orilẹede miran
Ijọba apapọ ni Naijiria ti fapa janu lori bi ilẹ Ghana se fọwọ osi juwe ile fawọn ọmọ Naijiria to le ni ẹẹdẹgbẹrin laarin ọdun 2018 si 2019.
Asoju ilẹ Naijiria ni Ghana, Ambassador Micheal Abikoye lo sọ eyi di mimọ lasiko to n se ipade pẹlu adari eto irinna ni ilẹ Ghana, Kwame Takyi.
Abikoye ni, iwa ifiyajẹni lọna aitọ ni awọn osisẹ eleto irina ati asọbode ni ilẹ Ghana hu si awọn ọmọ Naijiria.
Amọ nigba ti Asoju Ile Ghana ,Kwame Takyi n fesi, o ni awọn ti wọn le wale naa ni ilẹ Ghana fẹsun kan wi pe, wọn n se asemase bii hihu iwa ole, gbigbe ilu lọna ti ko bofin mu, sise isẹ asẹwo ati lilu awọn eniyan ni jibiti.
Takyi tun fikun pe, ọgọrin ninu awọn ọmọ Naijiria ti wọn le naa n se gbajuẹ ni ilẹ naa ni Osu Kinni ọdun 2019 ati bẹẹ bẹẹ lọ.
Adari eto irinna ni ilẹ Ghana naa wa parọwa si awọn ara ile Ghana lati ma a wu iwa daradara si awọn ọmọ Naijiria.
Bird Flu: Onímọ̀ ní kò sí òògùn tó leè pa àrùn lùkúlùkú ní Nàíjíríà
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Àìsàn lùkúlùkú tí àwọn olóyìnbó ń pè ní bird flu ti pa adìye 3900 ní ìpínlẹ̀ Plateau, lẹ́yìn tó bẹ̀rẹ̀ ní Bauchi.
Onimọ kan nipa isegun ẹranko ati awọn ohun ọsin abiyẹ ti ni, ko si oogun fun aisan lukuluku (bird flu), lẹyin ti aisan lukuluku pa adiye ẹgbẹrin o din ọgọrun ni ipinlẹ Plateau.
Dokita John Jesuwale lasiko to n ba BBC Yoruba sọrọ ni, wọn ko ti i gba abẹrẹ oogun lukuluku (vaccine) fun aisan lukuluku laaye lorilẹede Naijiria, ati wi pe, ẹnikẹni to ba ko wọle, yoo finmu kata ofin.
Damilọla Ajayi: Ọ̀dá owó ló ṣún mi dé ìdí lílo ìyarun bíi fèrè
Dokita Jesuwale ni, afẹfẹ ni aisan yii ma n ba rin, ati pe, ti wọn ba si da adiẹ to ni aisan naa papọ mọ adiẹ ti ko ba ni, ewu nla nbẹ fun wọn.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Aisan lukuluku ti awọn oloyinbo n pe ni Bird flu, ti wọn n pẹ ni avian influenza, ma n pa adiyẹ, awon eranko miran ati eniyan pelu. H5N1 ni aisan lukuluku to wọpọ ju.
Dokita onimọ nipa ọsin ẹranko ọhun se alakalẹ awọn ami to ma n jẹyọ lara adiẹ to ba ni aisan lukuluku, eyi taa to sisalẹ yii:
Awọn ami ti ẹ o fi mọ adiẹ to ni aisan lukuluku (bird flu)
Kini ọna abayọ si aisan lukuluku:
Dokita nipa ohun ọsin adie naa, John Jesuwale ni, ki eniyan kọkọ fun awọn adiyẹ ni abẹrẹ ti yoo dẹna aisan lara wọn ati eleyii ti yoo mu wọn ji pepe.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Dokita onimọ nipa ohun ọsin naa wa parọwa si awọn to n si adiyẹ lati ri daju wi pe wọn fun wọn loogun lasiko ti yoo dena aarun gbogbo.
Dokita Jesuwale fikun wi pe, adiẹ to ba ti ni aisan naa, pipa ni wọn yoo pa wọn, ko ma baa ran awọn yoo ku.
O fikun wi pe, ijọba gbọdọ dena ki maa ko adiẹ wa si lati apa ariwa orilẹede Naijiria, nibi ti aarun lukuluku ti gbinlẹ, to si ti pa ọgọọrọ adiẹ bayii.
Ninu ọrọ rẹ, o ni ijọba apapọ ma n se iranwọ fun ẹni to ba n sisẹ ohun ọsin, to si padanu ẹran ọsin rẹ.
Dokita onimọ nipa ohun ọsin naa wa parọwa si awọn to n sin adiyẹ, lati ri daju wi pe wọn fun wọn loogun lasiko, eyi ti yoo dena aarun gbogbo lara awọn ohun ọsin naa.
Nigeria 2019 Elections: Ohun mẹ́rin tó jẹyọ nínú ọ̀rọ̀ Atiku níbi ìpàdé PDP
Oríṣun àwòrán, NAIRALAND
Lẹyin ti ẹgbẹ oṣelu APC ṣe ipade igbimọ alaṣẹ rẹ, nibi ti Aarẹ Muhammadu Buhari ti sọ ọrọ to mu awuyewuye wa pe, ẹnikẹni to ba ji apoti ibo gbe n fẹmi ara rẹ wewu ni.
Ẹgbẹ oṣelu PDP naa ti wa ṣe ipade tirẹ lọjọ Isẹgun, nibi ti gbogbo awọn ogunna-gbongbo ẹgbẹ PDP, to ni ọrọ kan tabi omiran sọ nipa idibo ti wọn sun siwaju ati ọrọ Buhari, ti ri aaye sọ tẹnu wọn.
Damilọla Ajayi: Ọ̀dá owó ló ṣún mi dé ìdí lílo ìyarun bíi fèrè
Awọn ohun meje to jẹyọ ninu ọrọ ti oludije fun ipo aarẹ ninu ẹgbẹ oselu PDP, Alhaji Atiku Abubakar naa ree:
Ninu ọrọ rẹ, Alhaji Atiku Abubakar ni ẹgbẹ oṣelu APC ti ran awọn kan lọ sorilẹede China lati lọ kọ iṣẹ, ti wọn si ti ko ẹrọ igbalode le wọn lọwọ.
O ni awọn ẹrọ yii lo le fa ọwọ isẹ awọn ẹrọ kaadi idibo ṣeyin tabi ko sayipada bawọn ẹrọ naa ṣe n ṣiṣẹ pada.
Oludije fun ipo aarẹ naa ni, awọn ẹrọ kaadi idibo ni awọn agbegbe kan lorilẹede Naijiria, ti awọn alatilẹyin oun pọ si, lo ṣeeṣe ko ma ṣiṣẹ daradara.
Atiku ni o lodi si ofin ijọba tiwan-tiwa lati da awọn oloogun sita nigba idibo.
O ni ko si ofin kankan to ṣe atilẹyin fun lilo awọn ọmọ ogun nigba idibo. Ọrọ yi waye lati tako ọrọ Buhari wipe oun ti paṣẹ fun awọn agbofinro ki wọn fi ọwọ lile mu ẹnikẹni to ba ko awọn janduku wa si ibi idibo.
Atiku ti wa ke pe ajọ INEC pe, wọn ko gbọdọ ṣegbe lẹyin ẹgbẹ oṣelu kankan.
O tun sọ fun ajọ naa wipe, ki wọn gbiyanju lati pin gbogbo oun elo idibo laarin akoko yii si ọjọ Satide, ki wọn si ri daju pe awọn ẹgbẹ oṣelu ni anfani lati yẹ awọn ẹrọ naa wo finifini, ki idibo to bẹrẹ ni ọjọ Satide.
Ninu ọrọ rẹ, 'ọgagun' ni Atiku pe Buhari dipo ti yoo fi pe e ni 'aarẹ'.
O ni ọrọ 'ọgagun' Buhari wipe ki awọn agbofinro fi ọwọ lile mu ẹnikẹni to ba ji apoti idibo, jẹ ọrọ to bani ninu jẹ, ti ko si yẹ ki adari ilu kankan sọ jade lẹnu.
Ìtàn Mánigbàgbé: Mọrèmi Àjàṣorò fi ọmọkùnrin rẹ̀ kanṣoṣo rúbọ fún odò nítorí ìlú
Oríṣun àwòrán, Ooni Adeyeye Ogunwusu, Ojaja 11
Ilu Ile Ifẹ ni orirun ilẹ Yoruba, nibiti ojumọ ti n mọ waye.
Amọ bi Ile Ifẹ se lagbara, to si gbajumọ to yii gẹgẹ bii ilu olokiki, asiko kan wa to la awọn ohun to lagbara kọja ninu itan, ti ilu naa si fẹ parun, gẹgẹ baa ti gbọ.
Akoko yii si ni awọn Igbo ( kii se awọn eeyan to wa lẹkun ariwa orilede Naijiria o) maa n ko awọn eeyan Ile Ifẹ lẹru, to si nira pupọ fun awọn akọni alagbara ọkunrin ni ilu naa, lati gba Ile Ifẹ silẹ lọwọ awọn ọmọ ogun Igbo, to wa n ko wọn lẹru.
Niwọn igba to si jẹ pe ko si ohun ti ọkunrin lee se, ti obinrin ko lee se ju bẹẹ lọ, eyi lo mu ki Mọremi fi ara rẹ silẹ lati gba ilu rẹ la lọwọ ikonilẹru.
Gẹgẹ baa se ka itan Mọremi lori itakun agbaye Wikipedia, taa si tun gbọ lẹnu awọn onpitan, ẹwa ti Ọlọrun fun ọmọbinrin naa, to jẹ ayaba, lo lo lati sẹgun fun ilu rẹ.
Oríṣun àwòrán, Ooni Adeyeye Ogunwusu, Ojaja 11
A si lee ni laisi iranlọwọ Mọremi ni, boya ni ilu ta n pe ni Ile Ifẹ ko ba ti si mọ loni yii, bẹẹ si ni a ko lee sọ itan ilu Ile Ifẹ, ka gbagbe ipa ti Mọremi ko si ilọsiwaju ilu naa.
Ọpọlọpọ itan ni igbesi aye Mọremi Ajasoro kọ wa, to si yẹ ki awa eeyan iwoyi, ati obinrin, ati ọkunrin fi se arikọgbọn.
Mọremi ni ifẹ ilu rẹ lọkan, to si maa n wa igbega ati alaafia rẹ, bakan naa lo y ki awa pẹlu nifẹ iran Yoruba ati orilẹede wa Naijiria lapapọ.
Oríṣun àwòrán, Ooni Adeyeye Ogunwusu, Ojaja 11
Mọremi ko ri ara rẹ bii obinrin lasan, ti ko lagbara lati se ohunkohun, amọ pẹlu ọgbọn atinuda, lilo ẹwa rẹ lọ to tọ pẹlu igboya, o gba ilu rẹ silẹ lọwọ igbekun.
O yẹ ki awa naa maa ronu, ka si maa gbe awọn igbesẹ lori ohun to lee mu alaafia, idagbasoke ati ominira ba awujọ wa, boya obinrin ni wa, abi ọkunrin, ọmọde ni wa, abi agba.
Mọremi ko jẹ ki ohunkohun jọ oun loju lati fi gba ilu rẹ silẹ lọwọ awọn ọta, bakan naa lo yẹ kawa pẹlu fi ifẹ orilẹede wa siwaju ju ohunkohun lọ, ti a ko si gbọdọ maa ko dukia jọ lati pa orilẹede wa lara.
Oyo: Abass Bello rọ́pò ọmọ Akala bíi alága káńsù Ogbomọṣọ North
Oríṣun àwòrán, Insideoyo
Awuyewuye ti ń wáyé fún ọjọ́ díẹ̀ báyìí lórí bí Ọlamiju Alao-Akala ṣe tẹ̀lé bàbá rẹ̀ lọ sí ẹgbẹ́ òṣèlú ADP
Lẹyin ti wọn yọ Ọlamiju Alao Akala, to jẹ ọmọ gomina ana nipinlẹ Ọyọ kuro nipo gẹgẹ bii alaga ijọba ibilẹ ariwa Ogbomoṣọ, iyẹn Ogbomoso Noirth, ijọba ipinlẹ Ọyọ ti ṣebura fun igbakeji rẹ, Abass Bello Bayewuwọn gẹgẹ bii alaga ijọba ibilẹ naa.
Kọmiṣọna fun amojuto ijọba ibilẹ ati oye jijẹ, Bimbọ Kọlade lo ṣeto ibura naa nileeṣẹ ijọba ibilẹ Ogbomọṣọ North.
APC ní Atiku parọ́ lórí ẹ̀sùn pé yóò jẹ́ kí ẹ̀rọ káádì ṣe aṣemáṣe
N ṣe ni awọn agbofinro pọ babi si ayika ileeṣẹ ijọba ibilẹ naa, gẹgẹ bii awọn tisẹlẹ naa ṣoju wọn ṣe sọ.
Laipẹ yii ni awọn kansilọ mẹrin ninu mẹwa to wa ni ijọba ibilẹ naa, dibo yọ Ọlamiju lẹyin to kede pe oun n fi ẹgbẹ oṣelu APC silẹ lọ si ẹgbẹ oṣelu ADP, nibi ti baba rẹ ti n gbe igba dije fun ipo gomina ipinlẹ Ọyọ.
Nigeria 2019 Elections: Akala ní APC kò tó bẹ́ẹ̀ láti yọ ọmọ òun nípò alága
Ni owurọ ọjọru ni gomina tẹlẹ nipinlẹ Ọyọ, Adebayọ Alao Akala ṣi n fi to ileeṣẹ BBC news Yoruba leti pe, iwa kotọ ti ko lee duro niwaju ofin ni yiyọ ti wọn yọ ọmọ oun nipo ati pe, oun ṣi ni alaga ijọba ibilẹ Ogbomọṣọ North.
Nigeria 2019 Elections: Ṣé ọwọ́ ti ká Boko Haram ní Nàìjíríà
O ti le ni ọdun mẹwa ti ẹgbẹ agbebọn Boko Haram ti n da wahala silẹ lẹkun ila oorun ariwa orilẹede Naijiria.
Aarẹ Buhari ni adinku ti de ba ọwọja wahala awọn ikọ agbebọn Boko Haram naa, lati igba ti oun ti de ori oye ni ọdun 2015.
Awọn alatako rẹ si ti koju rẹ pe, eyi jinna si ootọ nitori, gẹgẹ bi wọn ṣe sọ, ọwọja awọn agbebọn naa tun ti gberu sii.
Ṣaaju idibo orilẹede Naijiria ni ọjọ Kẹrindinlogun loṣu Keji, ikọ ayẹwo oluwadi fun ileesẹ BBC, (BBC reality Check) gbe awọn ohun tawọn eeyan n sọ lori bi eto abo ṣe ri lorilẹede Naijiria.
Ni ọdun 2002 ni wọn da ẹgbẹ Boko Haram silẹ, gẹgẹ bii ẹgbẹ ti kii se oniwahala pẹlu afojusun ati ṣe afọmọ ilana ẹsin Islam lẹkun ariwa orilẹede Naijiria.
Amọṣa ẹgbẹ naa yi pada di agbebọn ninu ilepa awọn afojusun rẹ.
Kii ṣe orilẹede Naijiria nikan ni Boko Haram wa mọ bayii, itakun rẹ ti kan de awọn orilẹede to fẹgbẹkẹgbẹ pẹlu Naijiria bii Chad, Niger ati Cameroun.
Ọkẹ aimoye awọn eeyan ni wọn ti ran lọ sọrun apapandodo, ti awọn bi miliọnu meji miran si ti di atipo.
Boko Haram kii ye ji awọn akẹkọ gbe eleyi to mu ki oju orilẹede agbaye ṣi si ọdọ rẹ lọdun 2014, lẹyin to ji nnkan bii ọọdunrun akẹkọbinrin gbe nileewe kan to wa ni ilu Chibok nipinlẹ Borno, ipinlẹ ti Boko Haram ti kọkọ di agbebọn.
Ni ọdun 2015, Boko Haram gba idanimọ gẹgẹ bii ẹgbẹ agbesunmọmi to buru julọ lagbaye, gẹgẹ bi ajọ to wa fun ọrọ aje ati alaafia lagbaye ṣe sọ.
Lati igba yi wa ni awọn agbegbe ti ẹgbẹ agbebọn naa gba ti dinku, bi o tilẹ jẹ wi pe o ṣi n ṣọṣẹ lẹkun naa.
Aarẹ tẹlẹ, Oluṣẹgun Ọbasanjọ to n ṣatilẹyin fun oludije ẹgbẹ alatako, Atiku Abubakar, ti bu ẹnu atẹ lu Aarẹ Buhari lori igbesẹ gbigbogun ti  Boko Haram.
Eto abo ti dẹnukọlẹ gidigidi, ijinigbe si wa kaakiri ni ọrọ ti Ọbasanjọ sọ ni oṣu kinni.
"Amọ Buhari ni eto abo ti yatọ. O ni wọn ti ""wagbo dẹkun"" si wọn lati ọdun 2015 ni ipinlẹ Borno."
Oríṣun àwòrán, Getty Images
O le ni ẹgbẹrun meji eeyan to ti di atipo nitori Boko Haram
Aisi abo to peye ati ibanisọrọ to ye kooro n mu ko nira fun ijọba atawsn ajs aladani gbogbo lati ṣe ayẹwo to tọ.
Ajọ aṣeṣiro orilẹede Naijiria, NBS lo n pese awọn iroyin iwadi nipa ọrọ aje, ọrọ ilu ati abo kaakiri Naijiria, ṣugbọn agbẹnusọ wọn kan ṣalaye fun BBC pe, awọn ko ni iroyin to kuna lori iṣẹ Boko Haram.
Amọṣa, iwadii ti ajọ Armed Conflict Location & Event Data Project (ACLED) ṣe, ayẹwo awọn iroyin to n jade ninu awọn ileeṣẹ iroyin abẹle atawọn iroyin miran.
Lati nnkan bii ẹgbẹrun marun eeyan lọdun 2015, iye awọn eeyan to ku nipasẹ ikọlu Boko Haram ti wa silẹ si bii ẹgbẹrun kan laarin ọdun mẹta sẹyin.
Eyi waye lẹyin tawọn ologun kọju oro si Boko Haram ni ọdun 2015, pẹlu atilẹyin awọn orilẹede agbaye ti wọn si gba awọn ilu ti o wa labẹ iṣakoso iks agbebọn naa pada.
Nitori naa, ootọ ni Aarẹ Buhari sọ pe, ipaniyan awọn agbebọn naa ti ls silẹ gidigidi lati igba ti o ti de ipo ni ọdun 2015, amọṣa o tun ti peleke sii ni ọdun 2019.
Bi ọrọ ṣe ri bayii buru pupọ ni iwoye temi. O si jina si pe wọn ti bori ikọ naa. Ni ọrọ Alex Thurston to jẹ ajọgbọn ims nipa oṣelu ati ọrọ ẹsin ni fasiti Miami ni Ohio.
Ilana ayẹwo ti ajọ ajọṣepọ ilẹ okeere, CFR, to wa ni ilu Washington lo n gbe awọn iroyin ijinigbe lawọn iroyin abẹle yẹwo eleyi to fihan pe laaarin ọdun 2014 si 2015 ti agbara Boko Haram le kenka julọ ni iṣẹlẹ ijinigbe pọ julọ.
Amọṣa, pẹlu adinku to de ba ijinigbe ni ọdun 2016, o tun ti gbe ẹnu soke bayii paapaa pẹlu iṣẹlẹ ọọdunrun o le mẹwa to waye ni ọdun to kọja.
"Nitori naa nigba ti Aarẹ tẹlẹ, Oluṣẹgun Ọbasanjọ sọ pe "" eto abo ti dẹnu kọlẹ pẹlu ijinigbe ni ibi gbogbo"" oots ọrs lo sọ nitori pe ijigbe tun ti burẹkẹ sii, ni pataki julọ pẹlu bi wọn ṣe ji awọn akẹkọbinrin to le ni ọgọrun gbe ni Dapchi ni ọdun 2018."
Ohun ti o n ba spọ lẹru ni bi awọn agbebọn Boko Haram ṣe n lo awọn smọde gẹgẹ bi irinsẹ iku pẹlu ado oloro. Ni ọdun 2017 ati 2018, iṣẹlẹ ikọlu ado oloro bi  mẹtadinlọgọrin ati mẹrindinlọgbọn ni ṣiṣẹ n tẹle nipasẹ awọn ọmọde lo waye. Ni ọdun 2016 mẹsan lo waye gẹgẹ bii ajọ UNICEF ṣe sọ.
Agbeyẹwo bi iṣẹlẹ yii ṣe n waye kaakiri Naijiria, eyi ko ri bẹẹ pẹlu bi o ṣe jẹ pe iha ila oorun ariwa orilẹede Naijiria ni wọn ti n ṣọṣẹ.
Bakan naa ni ijinigbe n waye ni ẹkun aringbungbun gusu orilẹede Naijiria nibi ti iwapo rọbi ti n waye-eyi ko ni ohunkohun n ṣe pẹlu Boko Haram.
Nigeria 2019 Elections: Tinubu ní òun yóò sàjọyọ̀ ìsẹ́gun lọ́sẹ̀ tó ń bọ̀
Oríṣun àwòrán, @AsiwajuTinubu
Eekan kan ninu ẹgbẹ oselu APC, Bola Ahmed Tinubu ti woye pe jinnijinni ti n ba awọn ọmọ ẹgbẹ oselu PDP, ti wọn si ti n sa kijokijo kiri.
Tinubu ni niwọn igba ti ara awọn ọmọ ẹgbẹ oselu alatako naa ko balẹ mọ, o yẹ kawọn ọdọ ninu ẹgbẹ APC bẹrẹ si ni se koriya lati ri daju pe wọn tẹnpẹlẹ mọ eto koriya ti wọn n se fawọn ọdọ lati dibo.
Oloye Tinubu kede ọrọ yii lasiko to n ba awọn ọmọ ẹgbẹ oṣelu APC sọrọ nilu Eko lọjọru.
Bakan naa ni asiwaju ninu ẹgbẹ APC ọhun fikun pe o yẹ kawọn ẹya Igbo dibo fun ẹgbẹ APC nitori ko si igba kankan ti ijọba APC fọwọ rọ wọn sẹyin tabi dẹyẹ si wọn ninu pinpin ere ijọba tiwantiwa.
Àyájọ́ èdè abínibí: Onímọ̀ ní èdè Yorùbá kò ṣe é fọwọ́ rọ́ sẹ́yìn, ó rẹwà
Tinubu tun rawọ ẹbẹ sawọn ọmọ ẹgbẹ APC lati ko awọn ọmọ ẹgbẹ PDPto n ya wa sinu ẹgbẹ oselu ọhun mọra nitori gbogbo wọn ni wọn ti di ojulowo ọmọ ẹgbẹ.
Aṣiwaju ẹgbẹ oṣelu APC, Bọla Tinubu ti paroko ikilọ ranṣẹ sawọn ọdọ nipinlẹ Eko pe ki wọn yago fun jiji apoti idibo gbe lasiko idibo aarẹ ati ile aṣofin apapọ to n bọ lọjọ abamẹta.
"Otinubu ni "" Ẹ ti gbọ ohun ti Buhari sọ nipa jiji apoti ibo gbe. Mi o ran ẹnikẹni lati lọ ji apoti ibo gbe o. Kaadi idibo mi lemi fi n ja nitemi o.bi ẹ ba ji apoti ibo gbe tabi da wahala silẹ tọwọ ba ba yin, mi o lọwọ ninu iyẹn o."""
O ni awọn ti tẹwọ gba isunsiwaju idibo naa latọwọ ajs INEC nitori ọdọ ajọ INEC ni ofin fi si lori irufẹ iṣẹlẹ ba waye.
Aṣíwájú ẹgbẹ́ òṣèlú APC, Bọla Tinubu kìlọ̀ fáwọn ọ̀dọ́ lórí jíjí àpótí ìbò gbé
Iro opolopo awon oniroyin po. Eleyi ti mi o so l'ose to koja, won ni mo so, a so niyen. Olori egbe APC Bola Tinubu ro awon omo egbe pe ki won jade dibo fun Aare Muhammadu Buhari ni idibo ojo Satide.
Ninu oro re, o so pe PDP ni awon ba ja. Pe awon o ba ajo INEC ja nitori pe ofin wa leyin won ati pe o sese ki won ni ipenija ni won fi sun idibo naa siwaju. O gba l'adura pe ajo INEC yoo so layo lori idibo yii ti APC yoo si jawe olubori. O benu ate lu egbe PDP wipe won lo d'ogbon lo fina bo'le l'Abia, won pale oko mo ati bee bee lo. O fi orin ayajo Sunny Ade kan ba won wi pelu ijo lese.O gba awon omo egbe n'iyanju pe ki won ma ba enikankan ja. O ni ki won gba awon omo PDP ti won darapo mo egbe APC wole.
Nigeria 2019 Election: Àgbà Yorùbá ní Ila Ọrangun pèpàdé àlàáfíà
Oríṣun àwòrán, @deeplookers
Ọga ọlọpa to n mojuto ẹkun Kọkanla, ninu eyi ta ti ri ipinlẹ Ọyọ, Ọsun ati Ondo, Ọgbẹni Adelẹyẹ Oyebade, ti sọọ di mimọ pe gbogbo eto ti to, lati ri daju pe idibo gbogbo-gboo to n bọ lọna kẹsẹjari laisi wahala tabi kọnu-n-kọhọ kankan.
Oyebade kede ọrọ yii, lasiko to n bawọn akọroyin sọrọ lori abọ iwadi awọn osisẹ eleto aabo lori eto idibo to n bọ naa.
O salaye pe, awọn ọga agba ati ipẹẹrẹ ọlọpa ti mura tan lati sisẹ takuntakun ki eto idibo naa lee rọ nirọwọ-rọsẹ.
Bakan naa lo fikun pe, aabo to peye yoo wa fawọn ohun eelo idibo, ko ma baa bọ sibi ti kotọ.
Nigba to n sekilọ fawọn eeyan to lee maa gbero lati da wahala silẹ lasiko eto idibo naa, ọga agba ọlọpa naa wa fewe ọmọ mọ awọn janduku ẹda leti.
O kilọ fawọn tọọgi oloselu ti wọn n da omi alaafia ilu ru nilu Ila Ọrangun, Igangan, Ilesa ati kaakiri ipinlẹ Ọsun pe, yoo dara ki wọn so ewe gbejẹ mọwọ lasiko ibo naa, tori awọn ọlọpa ko ni gba igbakugba lasiko ibo naa.
Àyájọ́ èdè abínibí: Onímọ̀ ní èdè Yorùbá kò ṣe é fọwọ́ rọ́ sẹ́yìn, ó rẹwà
Wayi o, ni imura silẹ fun idibo aarẹ ti yoo waye lọjọ abamẹta, agbẹnusọ fun Igbimọ awon agbagba ilu ila Ọrangun, Gabriel Ajiboye ti sọ yayayanya pe, ki gbogbo awon egbe oselu ati oludije won gba alafia laaye ninu gbogbo  idibo ti yoo waye.Ajiboye so di mimo pe, ipade e jeki alafia joba yii ni o je ẹkẹta iru re, awon meji akoko ti awon se yori si rere.
Agbenuso fun Igbimo awon agbagba ni Ila naa wa bu enu ate nu ikolukogba ati iro ibon ti o waye ni awon agbegbe kan ni Ipinle Osun, to bee ge ti okan awon ara Ilu ko fi bale rara.
O wa rawo ẹbẹ si ọga agba ọlọpaa ni Naijiria lati fun won ni aabo to peye, ko si se ikilo fun awon babasale fawon oloselu ni awon ijoba ibile bii Boluwaduro, Ifedayo ati Ila Orangun.
O ni eyi ni yoo jẹ ki won lee yago fun iwa jagidijagan, paapa julo lasiko idibo, ki awon oludibo le raye se ẹtọ won laisi idiwọ.
Ìpànìyàn: Agbébọn pa 16 ní Benue, jàǹdùkú 59 kú ní Zamfara
Oríṣun àwòrán, @WetinNaija
Awọn agbẹbọn ti wọn funra si pe o jẹ Fulani darandaran, ti ṣe ikọlu si agbegbe Agatu kan ni Ipinlẹ Benue, níbi tí wọ́n ti pa ènìyàn mẹ́rìndínlógún.
Bẹẹ naa ni awọn janduku to ṣe ikọlu si ilu Dan Jibga ni ijọba ibilẹ Tsafe ni Zamfara ri iku he, nigba ti awọn ara ilu naa pa mọkandinlọgọta lara wọn.
Iroyin fi han pe, ni bii agogo kan oru ni awọn darandaran ṣe ikọlu naa ni abule Agatu, ti wọn n pe ni Ebete ni Ipinlẹ Benue.
Bi wọn ṣe n yinbọn pà awọn eniyan, ni wọn dana sun ile wọn.
Agbẹnusọ fun ileeṣẹ ọlọpaa ni ipinlẹ naa, Catherin Anene sọ fun awọn akọroyin wipe, iwadii n lọ lọwọ lori ikọlu naa.
Ni Zamfara, a gbọ pe awọn janduku bi ọgọsan lo ya bo ilu Dan Jibga, ti wọn si pa eniyan meje.
Àyájọ́ èdè abínibí: Onímọ̀ ní èdè Yorùbá kò ṣe é fọwọ́ rọ́ sẹ́yìn, ó rẹwà
Ni kia ni a gbọ pe, awọn ara ilu naa mu awọn mọkandinlọgọta lara awọn janduku naa, ti wọn si pa wọn.
Ija naa lọ fun bii wakati mẹrin, ki awọn agbofinro to de ilu naa.
Agbẹnusọ fun ileeṣẹ ọmọogun Naijirai, Clement Abiade ni awọn ti n gbiyanju lati ṣe iwadii lori bi ọrọ naa ṣe ṣẹlẹ.
Nigeria 2019 Elections: Atiku ní káwọn olùdìbò lo káádì ìbò wọn fi yọ ààrẹ òní, ba ṣe yọ tàná
Oludije fun ipo aarẹ labẹ ẹgbẹ oṣelu PDP, Alhaji Atiku Abubakar, ba awọn alatilẹyin rẹ sọrọ ni ori Twitter ati Facebook ní Ọjọbọ, nibi to ti rọ wọn pe ki wọn jade lọ dibo lọjọ Abamẹta.
Atiku ni, ori oun wu nigba ti awọn ọmọ Naijiria fi kaadi idibo wọn yọ aarẹ ana, lasiko idibo to waye ni ọjọ Kejidinlọgbọn oṣu Kẹta ọdun 2015.
"O ni, ""Awa eniyan Naijiria lọ si ibi idibo pẹlu kaadi idibo wa nikan, a si yọ olori orilẹede yii nigba naa. Oun to jẹ ki ori mi wu niyẹn gẹgẹbii ọmọ Naijiria. Ni ọsẹ yii, a o ni anfani lati ṣe bẹẹ lẹẹkan si."""
Atiku tẹsiwaju, o ni eni yowu ti awọn ọmọ Naijiria ba fẹ dibo fun, ki wọn gbiyanju lati jade dibo lọjọ Abamẹta.
O ni ni ọjọ idibo, ibo kan ko lagbara ju omiran lọ.
"O sọ wipe, ""Ẹni ti ko ba dibo, o fẹ ki ọdun mẹrin to n bọ ri bi ọdun mẹrin to lọ niyẹn. Agbara lati ri pe Naijiria bọ pada sipo, o wa ni ọwọ rẹ."""
APC ní Atiku parọ́ lórí ẹ̀sùn pé yóò jẹ́ kí ẹ̀rọ káádì ṣe aṣemáṣe
Yemi Osinbajo: Igbákejì ààrẹ ní ìṣẹ́ àti òsí tí Covid-19 kó bá wa, kò ṣe dúró wò
Oríṣun àwòrán, Others
Yoruba ni oye ni agba n wo, bẹẹ si ni agba ti ko ba kẹhun sọrọ, afaimọ ko ma kẹtan sare.
Boya eyi lo mu ki igbakeji aarẹ nilẹ wa, Yemi Osinbajo fi n lọgun nipa isẹ ati osi to n bawọn ọmọ Naijiria mulẹ, bii ẹgbẹ isu.
Osinbajo ni ipa nla ti arun Coronavirus nni lori ọrọ aje ati igbayegbadun wa ni Naijiria lojoojumọ lagbara pupọ.
Ninu atẹjade kan ti akọwe eto iroyin rẹ, Laolu Akande fisiti lo ti jẹyọ pe Osinbajo ke gbajare yii nibi agbeyẹwo isẹ iriju ọdun kinni awọn to dipo ilu mu.
Mayowa Omoniyi: Kò sí orin Obey, Sunny Ade abí tàkasúfèé tí ń kò le ta gìtá sí
Osinbajo wa kesi awọn minisita lati gbe igbesẹ ni kanmọ n kia lori owo triliọnu meji o le diẹ naira tijọba gbe kalẹ lati mu adinku ba ipa arun naa lori ọrọ aje Naijiria.
"Osinbajo ni ""ọjọ kẹtadinladọrin ree ta ti se ifilọlẹ eto naa, idi si ree ta fi gbọdọ se amusẹ rẹ ni kiakia, ki ori to ta araalu jinna."
Bakan naa si la gbọdọ ri daju pe a n se odiwọn awọn aseyọri wa lojoojumọ, ta si n se gbogbo ohun to yẹ ni sise.
"Akoko kii se ọrẹ wa mọ, isẹ ati osi si n jinlẹ laarin ilu si lojoojumọ ni."""
Oríṣun àwòrán, Others
Nigba to n sọrọ lori eto ọgbin ọlọpọ eniyan, Osinbajo ni ijọba ti se akọsilẹ miliọnu mẹrin agbẹ lati kopa ninu rẹ.
Lori eto ilegbe, o ni ijọba yoo kọ ilegbe ẹgbẹrun lọna ọọdunrun jake jado Naijiria eyi towo rẹ ko ni ju miliọnu meji naira lọ.
O fikun pe, gbogbo awọn igbesẹ naa lo wa lati pese isẹ oojọ fun araalu.
Oríṣun àwòrán, Profosinbajo/Instagram
Igbakeji Ààrẹ Yemi Osinbajo ti fesi si ahesọ ọrọ kan n to tan kalẹ lori ayelujara wipe, o ti binu kọwe fipo sile.
Ọsinbajo sọ lori itakun Twitter rẹ wipe, iroyin ofege ti wọpọ ni orilẹede Nigeria nitori oṣelu.
"O ni ""Mi o ti i kọwe fipo silẹ o. Mo duro digbi lati siṣẹ sin awọn ọmọ Naijiria labẹ iṣakoso Aarẹ Muhammadu Buhari."
A gbọ wipe awọn iroyin ofege naa sọ wipe, Osinbajo ti fi ibinu kọwe fipo silẹ nitori wipe wọn ko pe e si ibi ipade kan ni ile ijọba.
Àyájọ́ èdè abínibí: Ọjọ́ ìsinmi ni àyájọ́ èdè abínibí jẹ́ ní Bangladesh
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ede abinibi dun pupọ lati fi ṣalaye nkan
Njẹ ẹyin mọ adape fèrèsé lede Gẹẹsi?
Agadagodo nkọ tabi ikeemu?
Orukọ awọn nnkan eelo ile wọnyi ti a darukọ, fun awọn ti ko ba munadoko ninu ede Yoruba, yoo dabi nnkan to le.
Amọ awọn itumọ wọn ko le rara.
Ohun to jẹ ki a lo awọn ọrọ wọnyi ninu iroyin wa lonii, to wa fun ayajọ ọjọ agbelaruge ede abinibi lagbaye, ni ki a ba le tọka pataki ede abinibi ati bi pupọ ninu ede abinibi lagbaye ṣe n lọ si oko iparun.
Ọrọ pupọ ni ẹ le ti ka nipa ayajọ ọjọ yii, ṣugbọn fun anfaani wa, a fẹ ki a la ara wa loye nipa nnkan maarun ti a ko mọ nipa ayajọ ọjọ yii.
Ki gan an ni orisun ọjọ yii?
Ọdun 1999 ni ajọ UNESCO ya ọjọ kọkanlelogun, Osu Keji sọtọ lati fi gbe ede abinibi larugẹ.
Oduduwa Alphabet: òmìnira èdè ti dé fún Port Novo báyìí
Ohun to ṣe atọna igbesẹ yii ni akitiyan awọn oluwọde lorile-ede Bangladesh, nigba ti wọn ko ti ya kuro lara Pakistan.
Ijọba igba naa ni ki wọn maa lo ede Urdu ni dandan dipo ede abinibi wọn, tii ṣe Bangla.
Ọrọ yi ko dun mọ ara ilu ninu rara.
Oríṣun àwòrán, Rehman Asad/Barcroft Media/Getty
Awọn eeyan wọn yi n wọde ni Bangladesh nitori pe wn fẹ kiwọn ma lo ede abinibi wọn lati kọ awọnmn akẹkọ alakọbẹrẹ
Àyájọ́ èdè abínibí: Onímọ̀ ní èdè Yorùbá kò ṣe é fọwọ́ rọ́ sẹ́yìn, ó rẹwà
Eeyan marun un lo padanu ẹmi wọn nigba ti ọlọpaa yinbọn lu awọn oluwọde lọdun 1952.
Ifẹhonu han ti wọn ṣe nitori lilo ede abinibi wọn, lo faa ti ijọba fi pada wa gbe ofin sita pe ki wọn pada maa lo ede ti wọn fẹ.
Ilu Ubang, jẹ ilu kan nibiti ede ti awọn ọkunrin wọn n sọ yatọ si ti awọn obinrin wọn.
Titi di oni, ayajọ ede abinibi jẹ ọjọ isinmi lorileede Bangladesh, ti wọn si fi n ranti awọn akọni ti wọn padanu ẹmi wọn ninu iwọde to sokunfa lilo ede abinibi wọn.
Scrabble: Yorúbà Scrabble ni àkọ́kọ́ ní èdè abínibí nílẹ̀ Afrika
Awọn ede to ti parun ni Naijiria:
Lara idi pataki ti wọn fi ya ọjọ yi sọtọ ni ki awọn ede abinibi ma ba parun.
Bi o tilẹ jẹ pe a n sami ayajọ yii, sibẹ ọpọ ede lo ti parun kaakiri agbaye.
Ìgunnukó: Àwọn Tápà gbà pé ẹni tó bá ń sin Ìgunnukó kò ní ráùn ohun rere
Ohun ti eyi tumọ si ni pe, ko si awọn eeyan to n sọ awọn ede to ti ku wọnyi, ti ko si si awọn arọmọdọmọ wọn to n sọ ede naa.
Awọn ede Naijiria to parun ni iwọnyi:
Àwọn òṣìṣẹ́ BBC News Yorùbá sọ̀rọ̀ ìdùnnú lórí ayẹyẹ ọdún kan iléeṣẹ́ náà
Awọn ede to wa ninu ewu iparun ni Naijiria:
Mẹtadinlọgbọn ni awọn ede abinibi ti o wa ninu ewu iparun ni Naijiria, gẹgẹ bi nnkan ti a ri ka lori Wikipedia.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Sọ ede abinibi rẹ daadaa ko ma le parun
Àyájọ́ èdè abínibí: Ǹ jẹ́ o ní ìfẹ́ sí èdè abínibí rẹ?
Ko si ede kankan nilẹ kaarọ ojiire ti ọrọ yi kan, ṣugbọn pupọ awọn ede ti ọrọ yi kan ni awọn to wa ni agbegbe iwọ oorun ati awọn apa kan lariwa Naijiria.
Lara wọn la ti ri
Awọn ami ẹyẹ fun igbelarugẹ ede
Inu didun lo n mu ori yiya wa. Fun awọn to n ṣapa lati gbe ede abinibi larugẹ, awọn ami ẹyẹ kan wa ti wọn la kalẹ lati fi ṣe iwuri fun wọn.
Mẹta ninu awọn ami ẹyẹ to lamilaaka niwọn yi:
Link
#NigeriaDecides: BBC ti wa ni gbogbo ìpínlẹ̀ Naijiria láti firoyin gbogbo tóo yin létí
Ki la le ṣe ki ede fi ma parun?
Femi Falana: kò yé kí ìdájọ́ òfin yàtó síra wọn ni Naijiria
Nigeria 2019 Election: Ààrẹ Buhari ní k'áwọn ọmọ Nàìjíríà dìbò yan ẹni tó wù wọ́n
Oríṣun àwòrán, NTA
Aarẹ Muhammadu sọrọ lori idibo ọjọ Satide
Aarẹ Muhammmadu Buhari ni idibo aarẹ ati tile igbimọ aṣofin agba ọjọ Satide yoo lọ n'irọwọ rọsẹ, bẹẹ lo rọ awọn ọmọ orilẹede Naijiria lati jade dibo fun ẹni to ba wu wọn.
Aarẹ sọrọ yii nigba to ba awọn ọmọ Naijiria sọrọ lori ẹro amohun-maworan ti ijọba apapọ, NTA ati ile iṣẹ Radio Naijiria laarọ ọjọ Ẹti ṣaaju idibo ọjọ Abamẹta
Aarẹ Buhari awọn oṣiṣẹ eleto aabo ti wa ni digbi lati daabo bo eeyan nibi ti wọn ba ti n dibo.
#NigeriaDecides: BBC ti wa ni gbogbo ìpínlẹ̀ Naijiria láti firoyin gbogbo tóo yin létí
Aarẹ ko si iyi to ju ki awọn eeyan dibo fun olori ti wọn fẹ ko maa dari wọn lọ gẹgẹ ọmọ orilẹede tootọ.
Scrabble: Yorúbà Scrabble ni àkọ́kọ́ ní èdè abínibí nílẹ̀ Afrika
''A ò mọ ohun tí á fẹ́ ṣe báyìí''
Aarẹ Buhari fikun ọrọ pe ajọ eleto idibo INEC ti ṣetan lati ṣagbatẹru idibo ti yoo lọ ni irọwọ rọsẹ lọjọ Abamẹta.
Nigeria 2019 Elections: Akala ní APC kò tó bẹ́ẹ̀ láti yọ ọmọ òun nípò alága
Aarẹ tun fi da awọn onwoye loju pe ko si ewu rara fun wọn, o ni aabo to peye yoo wa fun wọn lọjọ idibo.
Aarẹ Buhari bawọn ọmọ Naijiria sọrọ lọsẹ to kọja ki ajọ eleto idibo INEC to sun ibo to yẹ ko waye lọjọ kẹrindinlogun, oṣu keji siwaju.
Akala: Kọmísánà kò láṣẹ láti búra fún igbákejì mi bíi alága ìbílẹ̀
Nigeria 2019 Election: Fayoṣe ní EFCC ń wá owó Atiku bọ̀ wálé òun l'Ekiti
Oríṣun àwòrán, Twitter/Peter Ayodele Fayose
EFCC tun fẹ yabo ile Fayose
Ile lapoti n joko dedi lorin ti gomina ana ipinlẹ Ekiti, Ayo Fayoṣe fi bọnu loju opo Twitter rẹ.
Fayoṣe ni oun gbọ pe awọn oṣiṣẹ ajọ to n gbogun ti iwa ajẹbaanu ati iṣowo ilu kumọkumọ EFCC ti de silu Ekiti lati yabo ile oun to wa ni Afao Ekiti laarọ ọjọ Ẹti.
Fayọṣe ni oun gbọ pe owo ti oludije fun ipo aarẹ labẹ asia ẹgbẹ oṣelu PDP, Atiku Abubakar fi n ṣe ipolongo ni wọn wa.
Scrabble: Yorúbà Scrabble ni àkọ́kọ́ ní èdè abínibí nílẹ̀ Afrika
Gomina ana ipinlẹ Ekiti tun ṣalaye loju opo Twitter rẹ pe ko si ẹni to le dunkoko mọ awọn eeyan ipinlẹ Ekiti.
''A ò mọ ohun tí á fẹ́ ṣe báyìí''
Fayoṣe ni ifẹ awọn ọmọ ipinlẹ Ekiti ni yoo wa si imuṣẹ ni igbẹyin-gbẹyin.
#NigeriaDecides: BBC ti wa ni gbogbo ìpínlẹ̀ Naijiria láti firoyin gbogbo tóo yin létí
Fayoṣe ni awọn kan ti gba idajọ wọn, bẹẹ ni ti awọm miran si n bọ lọna laipẹ.
O fikun ọrọ pe gbogbo rẹ yoo dopin lọjọ Abamẹta lẹyin ti idibo aarẹ ati tile aṣofin agba ba waye tan.
Àwọn òṣìṣẹ́ BBC News Yorùbá sọ̀rọ̀ ìdùnnú lórí ayẹyẹ ọdún kan iléeṣẹ́ náà
Nàìjíríà - orísun àwọn ọlọpọlọ pipe ninu iṣẹ litireṣọ
Oríṣun àwòrán, AFP
Orilẹ ede to n ṣan fun wara ati oyin awọn ọlọpọlọ pipe
O le ni miliọnu mẹrinlelọgọrin oludibo to forukọ silẹ fun idibo ọdun 2019.
Wo akọsilẹ awọn nkan abuda adamọ to fi Naijiria han gẹgẹ bii orilẹ-ede ilẹ̀ Adulawọ ti eto ọrọ ajé ẹ pọju.
1) Orin Takasufe Afro kíkọ lọ́nà àrà
Ọpọlọpọ ọmọ Naijiria lo ti gbe  ògo orin Takasufe ti wọn n pe ni Afro Beats ga nile ati lẹyin odi.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Wizkid jẹ ọkan lara awọn ọdọmọde olowo to bẹrẹ orin kikọ lọmọ ọdun 11 nile ijọsin
Eyi tun pegede si ti orin oloogbe Fela Anikulapo Kuti to n kọ Afro Beat nigba aye rẹ ninu eyi to ti ṣadapọ orin alariwo ati takasufe papọ.
Tunde Kelani; Èmi ò jẹ́ Baba Wande ní owó lórí fíímù Tolúwanilẹ̀
‘Tunde Kelani yan mi jẹ lori fiimu ‘Toluwanilẹ’
Awọn èèkàn ti Ọlọrun ti gba fun ni Naijiria lẹnu orin kikọ lasiko yii kuro ni keremi.
Gbogbo ènìyàn ló wọ agbádá ikú, ẹni tó kàn lẹnìkan kò mọ̀
Diẹ lara wọn ni Wizkid, Davido, Tiwa Savage ati Jidenna.
Davido fi ọkọ̀ Porsche ṣe ayẹyẹ ọjọ́ ìbí fún Chioma Avril
Ipa wọn ninu orin lagbaye ti gba okùn de ibi pé ile iṣẹ olorin nlanla bii Universal Music Group ati Sony ti da ẹka ileeṣẹ wọn silẹ ni Naijiria.
Falz: MURIC ní ọ̀rọ yí kọjá orin, wọ́n ni ó dilé ẹjọ́
Orin Davido to gbe jade lọdun 2017 jẹ orin to ta julọ ni Naijiria ri.
Awọn onkorin lasiko yii gba pé orin Afro Beats ti n nipa lori ọna iṣọwọ kọrin awọn miran ni ori ayelujara ni eyi to tun n fun Naijiria lokiki sii lagbaye.
Ayanbinrin Ara fi ilu kọ'rin ibilẹ Naijiria
Eyi lo bi ẹya orin bii Afro-pop, azonto, hiplife atawọn mii laarin awọn eniyan Ghana ati Naijiria bi apẹrẹ orin Oliver Twist ti DBanj tun ṣi oju awọn eniyan si i.
Awọn olorin Naijiria mii to tun ti di ilumọọka ni Yemi Alade, Tekno, Falz, Olamide, Simi, Mr Eazi, Mologo ati Patoranking.
Obinrin lo mu mi fẹran orin kikọ - Patoranking
2) Awọn ogbontarigi òǹkọ̀wé
Orilẹ-ede Naijiria ti bi awọn onkọwe to ju onkọwe lọ lagbaye bẹrẹ lati ara Chinua Achebe to kọ iwe Things Fall Apart nibi ti wọn ti ta iwọn to le ni miliọnu ogun lati 1958 to ti tẹẹ.
Oríṣun àwòrán, AFP
Chinua Achebe onkọwe to kọja bẹẹ
Wole Soyinka na tun jẹ eekan to ti digi araba lai yọ Ben Okri, Oloogbe D O Fagunwa, Chigozie Obioma, Helon Habila, Chibundu Onuzo, Sefi Atta, JF Odunjọ, Chimamanda Adichie atawọn mii.
Ifọrọwanilẹnuwo pẹlu Ọjogbọn Wọle Soyinka
Àyájọ́ èdè abínibí: Onímọ̀ ní èdè Yorùbá kò ṣe é fọwọ́ rọ́ sẹ́yìn, ó rẹwà
3) Ojoojumọ ni awọn ọmọ Naijiria n pọ sii, ti wọn n bi sii
Opọlọpọ ọmọ ni awọn eniyan Naijiria n bi sii ni eyi ti odiwọn idagbasoek wọn ti fi di ajitannawo lagbaye.
Odiwọn ọmọ ti Naijira n bi sii lọdọodun
Iwadii fihan pe to ba fi maa di ọdun 2017, Naijiria ṣeeṣe ko ti di orilẹ-ede kẹta to tobi ju lagbaye.
Hubert Ogunde ló m'órí mi yá láti di òṣèré
Eyi ni awọn ọdọ to ni agbara lati dibo tọdun 2019 yii tun fi n pariwo pe iṣẹ to wa ko to ṣe rara nitori ero ti pọ ju.
Beautiful Nubia: Kò sí wàhálà tó ń ṣẹlẹ̀ láàgbáyé tí kò ní ọwọ́ ẹ̀sìn lábẹ́nú
Oloye Obnasanjọ Oluṣegun to ti dari NAijiria ri kilọ ọjọ iwaju ti a ko ba ṣọra lori ọna abayọ siṣoro yii.
Reminisce: Àwọn ọ̀dọ́ ló mọ ìtumọ̀ orin 'Problem'
4) Owó epo rọ̀bì tó yapa ni Naijiria láì sí iná ọba púpọ̀
Awọn kan tilẹ maa n sọ pe kii ṣe awọn olorin takasufe nikan la fi n mọ Naijiria yatọ bi ko ṣe ti ariwo ẹrọ amunawa kaakiri adugbo.
Oríṣun àwòrán, AFP
Aṣaraloge n fina ẹrọ ibanisọrọ ṣiṣẹ aje rẹ nigab tina ọba lọ
Opọ igba ni awọn agbegbe kan ko ni ina mọnamọna fun ọpọlọpọ ọ̀sẹ̀ ni eyi ti onikaluku fi ma n wa ọna abayọ.
Àwọn ọmọ Yorùbá àtàtà: Báwo lẹ se gbọ́ òwe sí ?
Bẹẹ, Naijiria ni orilẹ-ede to n pese epo rọbi julọ lagbaye ninu orilẹ-ede ilẹ Afrika. O le ni miliọnu meji àgbá epo rọbi ti wọn n pese lojumọ.Banki agbayẹ pẹsẹ iranwọ fun Naijiria
DJ Spinall: Orin tí kò ní ìtumọ̀ ni ayé ń tẹ́wẹ́gbà
Owó ti wọn n ri n ninu epo rọbi pọ nitootọ ṣugbọn iṣoro ina ọba ṣi n gbẹbọ lọwọ wọn.
5) Naijiria- Ilé Boko Haram alakatakiti ẹsin Islam
Awọn alakatakiti ẹsin Islam lo bẹrẹ ogun Boko Haram ni apa ariwa iwọ oorun Naijiria ni eyi ti o ti gba ọpọ ẹmi ati dukia.
Orọ ogun yii lo bi ipede bring bag our girls lori ayelujara ti awọn ajajangbara kan ṣe n beere fun awọn ọmọdebinrin Chibok ti Boko Haram ji gbe lọ.
Oríṣun àwòrán, AFP
O ṣi ku ọmọdebinrin Chibok 112 ti ijọba ṣi n wa
Odun 2002 ni wọn ni wọn da Boko Haram silẹ ni agbegbe Maiduguri nipinlẹ Borno.
Orukọ won tumọ si pe eewọ ni imọ ẹkọ ọlaju iwe ni eyi ti ijọba Naijiria ṣi n wa ojutu sii titi di asiko yii.
Oríṣun àwòrán, AFP
Opo igba ni Boko Haram ti fi fọnran sita pé awọn ti bori ọmọ ogun Naijiria
Ni asiko kan ni awọn ọmọ ogun olotẹ yii gba ijọba agbegbe kan ni ila oorun ariwa Naijiria pẹlu ofin Sheria ki ijọba Naijiria to gab wọn pada.
Boko Haram yóò dá Leah sílé
Bayii, omodebinrin Leah Sharibu, akẹkọọ ile iwe Dapchi kan lo ku ti ijọba ko tii ri gba ninu awọn omodebinrin mii ti wọn tun jigbe.
Femi Falana: kò yé kí ìdájọ́ òfin yàtó síra wọn ni Naijiria
Ṣọla Allyson: Obìnrin tí kò bá rẹwà ni yóò máa ṣí ara sílẹ̀
Lassa Fever:Ondo, Oyo, Kwara wà lára ìpínlẹ̀ tó kásáa ibà Lassa
Arun lassa ni Naijiria
Ibùdó tó ń kojú àwọn àìsàn tó bá súyọ ní Nàìjíríà ní láàrin ọjọ́ kọkànlá sí ọjọ́ kẹẹ̀dọ́gbọ̀n oṣù kejì ọdun 2019, àkọsílẹ̀ mẹ́ẹ̀dọ́gbọ̀n ló ti wà nípa ibà Lassa lórílẹ̀èdè Nàìjíríà.
Oludari ibudo yii, Chike Ihekweazu sọ eyi di mimọ pe afikun iṣẹlẹ mẹẹdọgbọ́n yii ti sọ gbogbo rẹ laarin oṣu kinni si isisiyii di ọọdunrun o le marun le laadọta ni ipinlẹ mọkandinlogun to fi mọ olu ilu orilẹede yii.
'Àwọn Dókítà fẹ́ kẹ́yin s'awọ̀n alárùn lassa'
Kíni ọ̀nà àbáyọ sí àìsàn Lassa Fever?
O ni o ti to eniyan marunlelaadọrin to ti gbẹmi mi latari iba Lassa lati igba to ti bẹrẹ.
Gẹgẹ bo ṣe sọ ọ, ni bayii, ipinlẹ Edo, Ondo, Bauchi, Nasarawa, Ebonyi, Plateau, Taraba, Adamawa, Gombe, Kaduna, Kwara, Benue, Rivers, Kogi, Enugu, Imo, Delta, Oyo ati Kebbi to fi mọ ilu Abuja ni kọọkan lo ti ni akọsilẹ iṣẹlẹ iba Lassa.
O j ko di mimọ pe, oṣiṣẹ eleto ilera kan naa tun ti fara ko o ni ipinlẹ Edo eyi to sọ ọ di mtala oṣiṣẹ eleto ilera to ti fara gba a lati igba to bẹ silẹ.
2019 elections: INEC ní kò sáyè fún màjèṣín láti dìbò
Oríṣun àwòrán, Getty Images
INEC ni iwa irufin ni fun majeṣin lati dibo lorilẹede Naijiria.
Ajọ INEC ti ṣalaye pe oun ko ni fi oju rere wo ọmọde ti ọjọ ori rẹ ko tii to dibo yoowu ti ọwọ ba tẹ ni ibudo idibo.
Alaga ajọ eleto idibo lorilẹede Naijiria, INEC, Ọjọgbọn Mahmood Yakubu ṣalaye yii ni ọjọ ẹti lasiko to fi n ba awọn alẹnulọrọ ninu eto idibo lorilẹede Naijiria sọrọ nilu Abuja lori igbaradi fun idibo aarẹ atawọn aṣofin apapọ ti yoo waye lọjọ abamẹta.
Ọjọgbọn Yakubu ni iwa irufin ni fun majeṣin lati dibo lorilẹede Naijiria.
O ni ajọ INEC ati ọga ọlọpaa lorilẹede Naijiria yoo ṣiṣẹ pọ lati rii pe gbogbo awọn ọmọ ti ọjọ ori wọn ko tii to dibo ni wọn fi panpẹ ofin mu.
Ẹ wo oun tí ìbejì yìí ṣe nítorí ìgbéyàwó wọn bọ́ sí ọjọ́ ìdìbò ààrẹ
Awọn ọmọ Naijiria ti ọjọ ori wọn jẹ ọdun mejidinlogun tabi ju bẹẹ lọ lo lẹtọ ati dibo. Iwa ti ko ba ofin mu ni fun ẹnikẹni ti ọjọ ori rẹ kere si eyi lati dibo. Nitori naa mo fi asiko yii jawe ikilọ ranṣẹ sawọn to ba fẹ ṣe agbodegba fawọn majeṣin bẹẹ pe ọwọ ofin yoo ba wọn.
Iroyin okiki awọn majeṣin to n dibo gba ile kan lasiko idibo apapọ ọdun 2015. Yatọ si eyi, ajọ INEC ti ke gbajare lori bi awọn majesin ṣe tun forukọ silẹ lati dibo lasiko iforukọsilẹ oludibo to waye lọdun 2018.
Nigeria Election 2019: Báwo ni ìdìbò ònì yóò ṣe lọ?
Oni lọjọ ti gbogo ọmọ Naijiria ti n reti bẹẹ si ni awọn orilẹede agbaye náà si n reti lati mọ iru ọmọ ti idibo yii yoo bi.
Ọjọ abamẹta ọjọ kẹrindinlogun oṣu keji lo yẹ ki idibo naa kọkọ waye ṣugbọn fun awọn idi ti ajọ INEC ṣalaye, wọn sun ibo naa siwaju lowurọ ọjọ kẹrindinlogun si ọjọ kẹtalelogun oṣu keji ọdun 2019.
Awọn oju ti kii ṣaimọ f'oloko ni Naijiria ti yoo maa du ipo aarẹ da lori ifẹ onikaluku oludibo.
Oríṣun àwòrán, Getty Images/@Sowore/@Atiku/@Moghalu/@Durotoye
Awọn oludije to lewaju ninu idibo Aarẹ Naijiria
Ọpọ ọmọ Naijiria lo ti ṣe ipinu lati ṣi lọ dibo dipo isunsiwaju ti ajọ INEC ṣe.
Deede agogo mẹjọ owurọ ni eto idibo yoo bẹrẹ pẹlu ṣiṣe ayẹwo orukọ awọn oludibo kaakiri awọn ibudo idibo to wa.
Oríṣun àwòrán, YASUYOSHI CHIBA
Awọn oṣiṣẹ ajọ eleto idibo
Ẹ wo oun tí ìbejì yìí ṣe nítorí ìgbéyàwó wọn bọ́ sí ọjọ́ ìdìbò ààrẹ
Ko si ṣiṣe ko ṣaiṣe, gbogbo oju opo iroyin ni yoo kun fọfọ bi awọn eniyan lagbaye yoo ṣe maa reti ẹkunrẹrẹ iroyin.
Bi o ba wa ṣe ti iroyin to yanranti ti ko lẹja n bakan ninu, nipa idibo to n lọ, lede abinibi, itakun ayelujara bbc.com/yoruba, facebook bbcnewsyoruba, instagram @bbcnewsyoruba nikan lẹ́ ti lee ri iru ẹ nitori naa, ẹ maa pin awọn iroyin wa kaakiri ki gbogbo eniyan lee janfani rẹ.
#NigeriaDecides: BBC ti wa ni gbogbo ìpínlẹ̀ Naijiria láti firoyin gbogbo tóo yin létí
Nigeria 2019 Elections: Eko, Anambra àti Rivers ló ṣeéṣe kí àtúnbì ìbò ti wáyé
Eto idibo aarẹ ati tawọn asofin agba to lọ nirọwọ rọsẹ lawọn agbegbe kan ni orilẹede naijiria, ni ko ri bẹẹ lawọn agbegbe miran, nitori isẹlẹ idaluru, jiji apoti ibo gbe ati itajẹsilẹ.
Gẹgẹbi awọn akọroyin BBC to tọpinpin bi eto idibo naa se lọ si yika orilẹede Naijiria ti wi, nkan ko fararọ lawọn agbegbe kan nilu Eko, Oyo, Ọsun, Rivers ati Anambra.
Ni agbegbe Agọ Palace, Ọkọta nilu Eko, rogbodiyan to waye nibẹ mu ẹmi eeyan kan lọ, ti ọ̀pọ ibo ti wọn di lawọn agọ idibo to wa nibẹ si sofo.
Damilọla Ajayi: Ọ̀dá owó ló ṣún mi dé ìdí lílo ìyarun bíi fèrè
Koda, a tiẹ ri ibi ti wọn ti dana sun ọkada kan ati awọn iwe idibo, ti wọn si tun sọ ọkunrin kan ti wọn fẹsun kan pe oun lo wa nidi idaluru naa, ni oko pa.
Ni ipinlẹ Rivers bakan naa, ko din ni eeyan mẹẹdogun taa gbọ pe o gbẹmi mi lasiko rogbodiyan to waye lawn ọpọ agọ idibo to wa yika ipinlẹ ọhun.
Iroyin to tẹ wa lọwọ ni isoro ẹrọ kaadi to n yẹ orukọ awọn oludibo wo, to n se segesege gan tun da kun ọpọ isoro to wa nidi kudiẹkudiẹ to ba eto idibo naa.
Nigba to n fidi awọn isẹlẹ yii mulẹ, Kọmisana kan labẹ ajọ eleto idibo eyi to wa fun eto ilanilọyẹ awọn oludibo, Festus Okoye ni lootọ ni awọn gbọ nipa isẹlẹ yii.
Okoye ni iroyin ti de eti ajọ Inec lori bi wọn se n ji apoti idibo gbe ni agbegbe Akokotoro ati Bonny nipinlẹ Rivers, Eko ati ni Anambra.tawọn si n duro de abọ nipa isẹlẹ ọhun lati ọdọ awọn kọmisana fun ajọ eleto idibo lawọn ipinlẹ naa.
Eto idibo lawọn agbegbe yii, paapa eto idibo sile asoju-sofin ati asofin agba ni ko lee waye, ti ajọ INEC yoo si pinnu to ba ya nipa akoko ti atundi ibo yoo waye lawọn agbegbe naa, lẹyin tawn ba ti gbọ ẹkunrẹrẹ alaye.
Nigeria 2019 Elections: Ọwọ́ ọlọ́pàá kò tíì tẹ àwọn jàńdùkú tó ṣiṣẹ́ náà
Ọwọ́ ọlọ́pàá kò tíì tẹ àwọn jàńdùkú tó ṣiṣẹ́ náà
Ipaya, ifooro ati ẹru nla lo ba awọn eeyan ilu Ijẹbu-Jẹsa, nijọba ibilẹ Oriade nipinlẹ Ọsun lasiko ti awọn janduku oloselu kan ba wọn lalejo ni oru ganjọ lẹyin idibo.
Gẹgẹ bi akọroyin BBC Yoruba to kan si ilu ọhun lẹyin rogbodiyan naa ti wi, deede aago mẹta oru ni awọn janduku oloselu naa ba ilu Ijẹbu-Jẹsa lalejo, ti wọn si n yinbọn takotako kaakiri.
Gbogbo awọn eeyan to sun lo dide, ti jinnijinni si da bo wọn lori ibusun wọn, ti wọn ko si lee jade.
Awọn osisẹ eleto idibo to le ni igba to n sun lọwọ ni ileesẹ ajọ INEC to wa nilu Ijẹbu-Jẹsa si ni wọn dojukọ.
A gbọ pe ko si ọlọpaa tabi agbofinro kankan larọwọto eyi to mu kawọn janduku oloselu ọhun ri aye pa itu ọwọ wọn.
Igba wo ni ẹda yoo sinmi ogun ni Naijiria
Lẹyin ti wọn pari isẹ ibi ọhun tan, gbogbo aloku iwe idibo ni wọn sun gburu-gburu, to fi mọ awọn ohun eelo miran bii ẹni, ike iwẹ́ ati ẹrọ gẹnẹretọ meji.
Iroyin naa ni awọn agunbanirọ meji to tun jẹ osisẹ eleto idibo nibẹ, ni ọta ibọn ba.
Nigba to n fi idi isẹlẹ yii mulẹ, Kọmiṣọna fun ajọ eleto idibo nipinlẹ Ọsun, Olusẹgun Agbaje salaye pe, awọn osisẹ INEC ti ka ibo tan ki wọn to ko ẹru ti wọn lo pada si ijọba ibilẹ Oriade.
Bakan naa ni ọga ọlọpaa nipinlẹ naa Abiodun Ige fidi ọrọ naa mulẹ nigba ti o ba BBC Yoruba sọrọ.
Àwọn jàndùkú dáná sun ohun èlò ìdìbò l'Osun
Awọn agunbanirọ fara gbọgbẹ
Idaji ti awọn osisẹ wa n ko ẹru ti wọn lo bọ wa si ijọba ibilẹ wọn, ni awọn eeyan kan n yinbọn soke, eyi to mu kawọn osisẹ ọhun juba ehoro. Awọn eroja bii ẹni, apoti ti wọn fi dibo ati ẹrọ amunawa nikan ni wọn wa ja silẹ.
Agbaje, lasiko to n fọwọ idaniloju sọya ni esi ibo ti de ibiti wọn ti n kojọpọ, isẹlẹ naa ko si lee sokunfa atundi ibo rara lagbegbe naa.
#NigeriaDecides: BBC ti wa ni gbogbo ìpínlẹ̀ Naijiria láti firoyin gbogbo tóo yin létí
NIgeria 2019 Election: INEC gba òṣùbà káre lórí àṣeyọrí ìdìbò
Oríṣun àwòrán, Presidency
Awọn aarẹ ana sọrọ lori eto idibo
Awọn olori orilẹede Naijiria tẹlẹri, Oluṣẹgun Obasanjọ, Goodluck Jonathan ati ajagun fẹyinti Abdulsalami Abubakar ti dunnu si bi idibo aarẹ ati tile aṣofin agba ṣe lọ.
Obasanjọ kọkọ koro oju si bi eto idibo ko tete bẹrẹ ni ibudo idibo ni gbogbo nnkan lọ nirọwọ 'rosẹ ni agboole Olusomi lagbegbe Ṣokori niluu Abeokuta to ti dibo.
Aarẹ ana rọ gbogbo awọn oludije lati gba esi ibo naa yala wọn jawe olubori tabi wọn fidi rẹmi.
Obasanjọ ni ẹnikan naa ni yoo bori ninu idije nigba ti ẹlomiran yoo fidi rẹmi.
Ninu ọrọ tiẹ, ajagun fẹyinti Abdulsalami Abubakar, lẹyin to dibo tan ni ibudo idibo Uphil Water Tank niluu Minna, rọ awọn oludije lati jẹ ki ifẹ orilẹede Naijiria wa lọkan wọn ṣaaju ohun kohun miran.
Damilọla Ajayi: Ọ̀dá owó ló ṣún mi dé ìdí lílo ìyarun bíi fèrè
Bakan naa ọgagun fẹyinti Abubakar ni ki awọn oludije gba esi ibo gẹgẹ bi amuwa Ọlọrun.
Abubakar tun gboriyin fajọ eleto idibo INEC lori bi o ti ṣagbatẹru eto idibo aarẹ ati tile aṣofin agba lọjọ Abamẹta kaakiri orilẹede Naijiria.
Aarẹ ana miran Goodluck Jonathan, to jẹ ọmọ ẹgbẹ oṣelu PDP naa rọ awọn oludije lati fọwọ wọnu ti esi idibo ba jade.
Jonathan salaye pe eto idibo ni ọna kan gbogi ti awọn ọmọ Naijiria fi le yan adari rere.
Ọgbẹni Jonathan wa gbe oṣuba kare fun ajọ INEC fun iṣe takuntakun ti o ṣe lori eto idibo aarẹ ati tile igbimọ aṣofin agba.
Nigeria 2019 Election: Àwọn èsì ìbò tí n jáde diẹ diẹ
Esi idibo lawọn ibudo idibo ti n jade diẹ diẹ lẹyin ti wọn ti ka ibo lawọn ibudo idibo jakejado Naijiria.
Ninu awọn ibudo idibo ti akọrọyin BBC foju ri ibo kika, wọn jabọ pe awọn ẹgbẹ oṣelu APC ati PDP ni wọn jijọ n fagba han ara wọn.
Saaju ki a to fi awọn esi ohun sọwọ, a fẹ ki ẹ mọ wi pe eyi ke ṣe akojọpọ esi ibo lapapọ, bi kii ṣe awọn esi to waye lawọn ibudo idibo awọn eekan oloṣelu ti a ṣe akojọpọ wọn paapa julọ ninu ibo Aarẹ.
Oríṣun àwòrán, @Yemi Osinbajo
Igbakeji Yemi Osinbajo
Awọn oludibo  to wa ni  wọọdu idibo kẹrin, agọ idibo kẹtalelọgbọn ni agbegbe VGC, Lekki ikate ti igbakeji Aarẹ Yemi Osinbajo ti dibo,wọn ti fi ibo wọn da sẹria, ti ẹgbẹ PDP si bori APC nibẹ.
Ninu esi eleyi ti akọroyin wa jabọ lati ẹnu oṣiṣẹ Inec nibẹ, bayi ni nnkan ti ṣe lọ ninu idibo Aarẹ:
PYO Ward 4 unit 033 Esi ibo Aarẹ: ANN : 39, APC: 197, PDP: 384
Unit 033 A Esi ibo Aarẹ: ANN: 2, APC: 32, PDP: 41
Buhari na Atiku pẹlu ibo 19 lagọ idibo rẹ ni Yola
Oludije ipo Aarẹ fun ẹgbẹ APC, Muhammadu Buhari na fẹyin akẹgbẹ rẹ, Atiku Abubakar, to n soju ẹgbẹ PDP janlẹ ni agọ idibo Atiku pẹlu ibo mọkandinlogun.
Aworan esi ibo aaye idibo Atiku
Buhari ri ibo 186 gba  ni agọ idibo Ajiya unit 02 ni Yola, Adamawa nibit Atiku ti ri ibo 167 gba .
Atiku fẹyin Buhari gbolẹ ni Aso Rock villa
Lẹyin ti wọn tun ibo ka ni agọ idibo to wa nile ijọba Presidential villa l'Abuja, apapọ esi ibo ni agọ idibo 021 ati 022 Aso Rock Villa lọ bayi:
Buhari ati Atiku nibi ti wọn ti n dibo
Esi ibo Aarẹ APC - Buhari: 1017, PDP - Atiku: 1027,
Ile Asofin agba: APC 1009, PDP 1082
Donald Duke fidirẹmi lọwọ PDP lagọ idibo rẹ
Ibo mẹfa pere ni oludije ipo Aarẹ labẹ asia SDP, Donald Duke ri gba nibudo idibo rẹ
Atiku Abubakar, ti ẹgbẹ PDP lo jawe olubori mọ lọwọ.
Egbe SDP niDonald Duke to ti jẹ Gomina ri n soju
Bi esi ṣe lọ ree ni agọ idibo rẹ tii ṣe AME Zion School unit 005 ni Calabar, ipinlẹ Cross River :
APC - Buhari: 98, PDP - Atiku: 291, SDP - Duke: 6
Bi nnkan ti ṣe lọ re agọ idibo Saraki Ajikobi ward, opobiyi PU 06 :
Esi Ibo Aarẹ APC 152, PDP 234, GPPN 1, AA 1, PCP 3
Election Update 2019: APC fá gbogbo ìbò tó pọ̀ jù fún ilé aṣòfin Ekiti
Ipinlẹ Ekiti
Àjọ elétò ìdìbò INEC ti kede pe awọn oludije ẹgbẹ oṣelu APC lo jawe olubori fun aga mẹtẹẹta ti ile igbimọ aṣofin agba ati gbogbo aga mẹfa ile igbimọ aṣojuṣofin ipinlẹ Ekiti.
Gẹgẹ bi ajọ INEC ṣe kede rẹ, Ọmọọba Dayo Adeyeye ti APC ni wọn kede gẹgẹ bi ajawe olubori ni ẹkun idibo Guusu Ekiti.
Bakan naa, ọmọ ile igbimọ aṣojuṣofin ẹgbẹ APC kan ni aarin gbungbun Ekiti, Họnọrebu Ọpẹyẹmi Bamidele lo jawe olubori fun ipo Sẹnetọ.
Bamidele to jẹ ọmọ ile aṣoju ṣofin tẹlẹ laarin ọdun 2011 si 2015 gba a mọ oludije ti PDP, Obafẹmi Adewale lọwọ.
Lara awọn adari ajọ INEC, Ọjọgbọn Laide Lawal lo kede esi yii lowurọ ọjọ aiku ni ilu Ikere.
Yatọ fun APC ati PDP, awọn ẹgbẹ oṣelu mii to dije ni Democratic Alliance (DA), Green Party of Nigeria (GPN), Peoples Party of Nigeria (PPN), NAC atawọn ẹgbẹ mii.
Bakan naa ni adari ajọ INEC mii, Ọjọgbọn Abayọmi Fasina nipinlẹ naa kede Sẹnetọ Adetunmbi ti APC gẹg bi ẹni to jawe olubori ni ẹkun idibo ariwa Ekiti.
Ẹwẹ, awọn oludije APC ni ẹkun idibo Guusu Ekiti ati ariwa Ekiti keji, Yemi Adaramodu ati Olarewaju Ibrahim naa ni wọn kede ti wọn si laami laaka pẹlu alafo to pọ jọjọ.
Adedoyin: Tí mo bá rí Buhari, màá sọ fun kó rántí pé Ọlọ́run wà
Oludije APC ni ẹkun idibo ariwa kinni, Ọgbẹni Peter Owolabi fidi alatako rẹ, Kehinde Agboola ti PDP janlẹ.
Si eyi, Gomina ipinlẹ Ekiti, Kayode Fayemi kan sara si esi idibo naa to ṣ'ọmọ 're fun gbogbo oludije ile aṣofin lẹgbẹ oṣelu rẹ.
Election Update 2019: Malaye padà sílé aṣòfin àgbà fún sàá kejì
Oríṣun àwòrán, Dino Melaye/twitter
Ijọba ibilẹ meje lo wa ni ẹkùn idibo Iwọ oorun Kogi ti Melaye yoo tun pada lọ ọ ṣoju nile aṣofin agba
Sẹnetọ Dino Melaye ti jawe olubori ninu eto idibo gbogboogbo lati ṣoju ẹkùn idibo Iwọ oorun Kogi nile aṣofin agba Naijiria.
Sẹnetọ naa to dije labẹ asia ẹgbẹ oṣelu Peoples Democratic Party, PDP, fi ẹyin alatako rẹ gboogi, Smart Adeyẹmi ti ẹgbẹ oṣelu APC janlẹ.
Melaye ni apapọ ẹgbẹrun marunlelọgọrin ati irinwo din maarun ibo lati fi bori alatako rẹ to ni ibo ẹgblrun mẹrindinlaadọrin ati mejilelẹẹdẹgbẹerun.
Ilé ẹjọ́ ti gba onídùúró Dino Melaye
Moses Melaye: Dino Melaye sùn ìta gbangba mọ́jú níléesẹ́ DSS
Ijọba ibilẹ meje lo wa ni ẹkùn idibo Iwọ oorun Kogi ti Melaye yoo tun pada lọ ọ ṣoju nile aṣofin agba:Lokoja, Kogi/Koton Karfe, Kabba/Bunu
Ijumu, Yagba East ati Yagba West. Malaye si jawe olubori ninu mẹfa lara wọn.
Bi awọn esi ibo naa ṣe ri niyii:
Lokoja LGA
PDP = 24576
Yagba East LGA
PDP = 8638
APC = 5077
Mopa Amuro LGA
PDP = 5112
APC = 3658
YAGBA WEST LGA
PDP 8942
APC 6799
IJUMU LGA
PDP 11,749
APC 8,517
KABBA BUNU LGA
APC 8,971
PDP14, 756
Kogi LGA
APC 15,728
PDP 11,622
Ṣẹnetọ naa ti ki ara a rẹ ku oriire lori Twitter.
Election Update 2019: Ta a ni Kọla Balogun tó já ipò sẹ́nétọ̀ gbà lọ́wọ́ Ajimọbi?
Oríṣun àwòrán, Kola Balogun
Wọn bi Kọlawọle Mohammed Balogun ni ọjọ kẹtalelogun oṣu Keje, ọdun 1956 ni agboole Olubadan Ali-Iwo niluu Ibadan.
O kẹkọ gboye imọ ijinlẹ akọkọ ati ti Ọmọwe ninu imọ oṣelu ni Fasiti North Texas, Denton Texas, nilẹ Amẹrika.
O ti wa ninu oṣelu lati nkan bi ọdun 1980, bẹrẹ pẹlu ẹgbẹ oṣelu Social Democratic Party, SDP.
O jẹ oye oludari eto ẹnawo ati amojuto fun igbimọ ipolongo ibo fun Dokita Abubakar Oluṣọla Saraki.
Tani Ibrahim Oloriegbe tó gbà ipò aṣòfin lọwọ Saraki?
Melaye fẹ̀yìn Smart Adeyẹmi janlẹ̀
Bakan naa lo jẹ kọmisana fun akanṣe iṣẹ ati eto irinna nipinlẹ Ọyọ labẹ gomina Adebayọ Alao Akala lọdun 2006.
O tun jẹ kọmisana fun eto okoowo ati ẹgbẹ alajẹṣẹku nipinlẹ Ọyọ lọdun 2007 si 2011.
O dije dupo sẹnetọ labẹ ẹgbẹ oṣelu Peoples Democratic Party.
Nigeria 2019 Elections: Àwọn ẹbí rẹ̀ ní àwọn agbébọn tó ya wọ àgọ́ ìdìbò ló ta á níbọn
Ninu eto idibo naa to waye lọjọ kẹtalelogun oṣu Keji, ọdun 2019, Kọla Balogun ni ibo ẹgbẹrun lọna marunlelọgọrun ati okoolelẹẹdẹgbẹrin o din mẹrin, (105,716), ti Abiọla Ajimọbi si ni ibo ẹgbẹrun mejilelaadọrun ati okoolerugba o din mẹta.
Election Update 2019: Àwọn ohùn tó yẹ kí ẹ mọ nípa Oloriegbe tó rọ́pò Saraki
Oríṣun àwòrán, Facebook/oloriegbe4senate
Mo wa lati wa tu awọn eeyan mi silẹ loko ẹru ni
Ajọsepo Ibrahim Oloriẹgbẹ ati Bukọla Saraki ko ṣẹṣẹ bẹrẹ.
Fun awọn ti wọn gbọ orukọ rẹ fun igba akọkọ nigba ti wọn kede rẹ pe o fidi Seneto Bukola Saraki rẹmi, ninu idibo asofin agba, o ṣeeṣe ki wọn maa bere pe tani Oloriegbe yi gaa an?
Ohun to han si ọpọ eeyan ni pe oludije egbẹ oṣelu APC nii ṣe ti o si jẹ ọmọ bibi ilu Ilorin.
Adedoyin: Tí mo bá rí Buhari, màá sọ fun kó rántí pé Ọlọ́run wà
Amọ saaju idije ati esi tawọn eeyan n jaran rẹ lẹnu, awọn  nnkan miran wa nipa rẹ ti o yẹ ki a mọ.
Kii ṣe akọkọ re ti yoo koju Saraki
Awọn mejeeji ti kọkọ koju ara wọn lọdun 2011 nigba ti Saraki bẹrẹ irinajo rẹ gẹgẹ bi asofin agba.
Aburo Bukola Saraki, Sẹnẹto Gbemi Saraki lo ṣẹṣẹ pari saa rẹ gẹgẹ bi Senẹtọ ti awọn mejeeji sijọ du ipo naa.
Labẹ asia ẹgbẹ ACN ni Oloriẹgbẹ́ ti dupo amọ Saraki to wa ni PDP nigba naa fẹyin rẹ janlẹ.
Oloriegbe ko ṣeṣẹ ma ṣe olori, O jẹ olori ile asofin Kwara nigba kan ri
Laarin ọdun 1999 si 2003, Ibrahim Oloriegbe jẹ olori awọn ọmọ ẹgbẹ to pọju lọ nile asofin ipinlẹ Kwara.
O tun joye alaga igbimọ ile to n mojuto ọrọ ilera ati eyi to n ri si ọrọ ijọba ibilẹ.
Lẹyin to pari nile asofin ko ti di ipo oṣelu kankan mu mọ lati igba naa.
Nigeria 2019 Elections: Àwọn ẹbí rẹ̀ ní àwọn agbébọn tó ya wọ àgọ́ ìdìbò ló ta á níbọn
Oloriegbe loun wa tu ara Ilorin silẹ loko ẹru ni
Koko pataki kan ti Ibrahim Oloriegbe dimu, ninu ipolongo rẹ ni pe oun wa lati wa tu awọn ara ilu Ilorin silẹ loko ẹru ni.
Ninu ọpọ ifọrọwanilnuwọ to ṣe pẹlu awọn akọroyin, kii ma salai tẹnumọ pe, iṣẹ ati oṣi to pọ nilu jẹ ohun kan gboogi ti oun yoo fopin si, bi oun ba de ipo asofin.
Lọdun 2018, ijọba apapọ sọ pe awọn pin biliọnu meji naira fun awọn mẹkunu tole ni ẹgbẹrun mẹrinla lati ọdun 2014, labẹeto gbọnṣẹ gbọnyanu wọn, National  Conditional Cash Transfer Programme.
Iriri to to ọgbọn ọdun ni Dokita Ibrahim Oloriẹgbẹ ni, ninu eto iṣakoso lẹka ijọba ati gẹgẹ bii aladani.
Amọ Irinajo to gbe de ipo yii lagbo oṣelu lawọn eeyan yoo ma fi ranti rẹ.
O ti bẹrẹ oṣelu ti pẹ, ti a si ri ka ninu akọsilẹ pe, o wa lara awọn ọmọ ẹgbẹ ACN ti wọn jijọ darapọ mọ awọn ẹgbẹ oṣelu miran, to da APC silẹ nipinlẹ Kwara.
Election Update 2019: Kíni ifidirẹmi Saraki tumọ fún òṣèlú Kwara
Oríṣun àwòrán, Facebook/@bukola.saraki/@gbemisola.saraki
Olusola Saraki to wa laarin lo pẹka awọn eekan meji Bukola ati Gbemininu oṣelu Kwara
Igba kan o lọ bi orere lawọn agba maa n wi.
Lẹyin ọdun mẹjọ ni ipo Gomina ati ọdun mẹjọ gẹgẹ bi asofin agba, Bukola Saraki yoo bẹrẹ igbe aye tuntun gẹgẹ bi ẹni ti ko di ipo ijọba kankan mu.
Ko tii si esi kankan to jade lọdọ gbajugbaja oloṣelu yii lati igba ti o ti fidirẹmi ninu ibo si ipo asoju ile asofin agba fun aarin-gbungbun Kwara titi di bi a ṣe n sọrọ yii.
Nigeria 2019 Elections: Àwọn ẹbí rẹ̀ ní àwọn agbébọn tó ya wọ àgọ́ ìdìbò ló ta á níbọn
Ki a to gbọ nnkankan lẹnu rẹ, la ni  ki a wo bi ifidirẹmi rẹ yoo ṣe nipa lara oṣelu ipinlẹ Kwara ati ti orile-ede Naijiria lapapọ.
Kwara ti padanu ipo ẹnikẹta to lagbara loṣelu Naijiria
Ni kété ti ariwo idunnu awọn ololufẹ Ibrahim Oloriegbe ba pari ti oju si la, ni gbogbo Kwara yoo pada si okodoro ohun to ba aṣeyọri yi wa.
Eyi si ni pe wọn ko ni ni ọmọ Ilorin nipo igbakẹta ijọba.
Oríṣun àwòrán, @Bashir Ahmaad
Pẹlu ijakulẹ rẹ ninu ibo asofin, ipo igbakẹta orileede Naijiria ti bọ lọwọ Saraki ati Ilorin
Ipo Aarẹ ile asofin kii ṣe eleyi ti asofin to ba ṣẹṣẹ wole si ile asofin maa n jẹ.
Ki Saraki naa to de ipo ọhun, o ti lo saa kan gẹgẹ bi asofin ti o si lo ipo rẹ gẹgẹ bi alaga ẹgbẹ awọn Gomina lati ri atilẹyin awọn Sẹnẹtọ akẹgbẹ rẹ gba.
Ibo gomina to n bọ lọna -iṣẹ nla ni yoo jẹ fun PDP
Ẹgbẹ oṣelu PDP yoo ni lati mura daada ti wọn ba fẹ ṣaṣeyọri ninu ibo gomina to m bọ.
Iku to n pa ojugba ẹni lọrọ to wa nilẹ yi, owe lo n pa fun ẹgbẹ naa ati oludije wọn ninu ibo gomina.
Oríṣun àwòrán, Facebook/atunwaone/@RealAARahman
Awọn oludije APC ati PDP ni yi ti yoo waako loṣu kẹta
Pẹlu bi nnkan ti ṣe ri ninu esi ibo aarẹ eleyi ti aarẹ Buhari tipegede nipinlẹ naa, o ṣeesẹ ki awọn eeyan tẹsiwaju lati pari iṣẹ fun APC ninu ibo to ṣẹku.
Scrabble: Yorúbà Scrabble ni àkọ́kọ́ ní èdè abínibí nílẹ̀ Afrika
Saraki kan lọ, Saraki mii n bọ?
Nigba ti Gbemi Saraki aburo Bukọla Saraki fi ile asofin kalẹ ti o gbiyanju ati dije dupo gomina, ifidirẹmi lo gbẹyin rẹ.
Lati igba naa lo ti jọ bi ẹni pe ko fi taratara da si ọrọ oṣelu ipinlẹ Kwara.
Oríṣun àwòrán, Facebook/gbemisola.saraki
Gbemi Saraki ti dije dupo gomina Kwara ri
Lẹnu ọjọ mẹta yi, o ti n ko ipa ribiribi ninu oṣelu paapa labẹ asia APC ti o si wa lara awọn to lewaju lati gba alejo aarẹ ati igbakeji rẹ nigba ti wọn ṣabẹwo si Kwara.
Ibeere ti yoo ma wa si ọkan bayi ni wi pe, ṣe Gbemi Saraki ni Saraki ti awọn eeyan Ilorin ati Kwara lapapọ yoo maa wo gẹgẹ bi adari ''aafin iṣejọba idile Saraki'' bayii?
#NigeriaDecides: BBC ti wa ni gbogbo ìpínlẹ̀ Naijiria láti firoyin gbogbo tóo yin létí
Nigeria 2019 Elections: Àwọn ẹbí rẹ̀ ní àwọn agbébọn tó ya wọ àgọ́ ìdìbò ló ta á níbọn
Election Update 2019: Amúgbálẹgbẹ̀ẹ́ Saraki ní ọ̀gá òun kò kí olùdíje APC kú oríire
Oríṣun àwòrán, @bukolasaraki
Ààrẹ ilé aṣòfin àgbà, Bukọla Saraki ní òun kò kí APC kú oríire gẹ́gẹ́ bí ìròyìn kan tó ń káàkiri ṣe ń sọ
Aarẹ ile aṣofin, Bukọla Saraki ko ni si ni ile aṣofin naa fun saa iṣejọba to n bọ, eyii kii sii ṣe iroyin mọ; ṣugbọn iroyin to yọ nibẹ bayii ni pe lẹyin to padanu idibo ẹkun aṣofin apapọ ti aringbungbun Kwara, Saraki ko ki Oloriẹlgbẹ ti ẹgbẹ oṣelu APC to bori  ku oriire o.
Sẹnetọ Bukọla Saraki lo sọ bẹẹ ninu atẹjade kan ti, Yusuph Ọlaniyọni to jẹ amugbalẹgbẹ fun un lori ọrọ iroyin sita.
ninu eyi ti o ti n yọ ara rẹ kuro ninu iroyin kan ti awọn kan n pin kaakiri ikanni ibanisọrọ Whatsapp pe ẹgbẹ oṣelu PDP ati Saraki ti gba ijakulẹ wọn, wọn si ti ki ẹgbẹ oṣelu APC atawọn oludije rẹ ku oriire.
Atẹjade naa to fi sita ni ọjọ aje tun ṣalaye siwaju sii pe laipẹ laijina ni agọ asofin agba  Saraki yoo sọrọ lori iha ti wọn kọ si eto idibo naa.
Nigeria 2019 Elections: Àwọn ẹbí rẹ̀ ní àwọn agbébọn tó ya wọ àgọ́ ìdìbò ló ta á níbọn
"Ki araalu keti ikun si iroyin ẹlẹjẹ tawọn ẹgbẹ PDP n gbe kaakiri ori ikanni ibanisọrs Whatsapp.
Nitori naa ki ẹgbẹ oṣelu APC yee gbe iroyin sita lati ki ara rẹ ku oriirẹ ki wọn maa so ms ẹgbẹ wa lọrun."
Bi ẹ ko ba gbagbe, ni alẹ ọjọ aiku ni INEC kede esi idibo sile aṣofin agba lẹkun aringbungbun Kwara ninu eyi ti oludije ẹbẹ oṣelu APC, Oloriẹgbẹ ti fagba han Bukọla Saraki.
Election Update 2019: Ajimọbi lóun yoo gbà èsì ìbò tí kò bá sì magomago
Oríṣun àwòrán, Abiola Ajimobi
Gomina Abiola Ajimobi Ipinlẹ Oyo ti fesi si ifidirẹmi rẹ ninu esi ibo ile asofin agba to waye lọjọ abamẹta.
Ninu esi rẹ, o dupẹ lọdọ ara ilu Oyo  ṣugbọn ko ki akẹgbẹ rẹ to jawe olubori ku orire aṣeyọri rẹ.
Ikini yi la ri ninu fọnran fidio kan ti o ti sọ fun oniroyin Delel Momodu pe inu ohun dun si bi ibo naa ti ṣe lọ.
Oju opo Instagram ni fọnran naa wa nibi ti Gomina Ajimobi ti dupe lọwọ Olorun fun anfaani ti ohun ni lati sin awọn eeyan ipinlẹ Oyo.
O ka awọn aṣeyọri rẹ lori idibo to n lọ lọwọ ti o si ni ohun ko ipa ribi ribi lati ri wi pe ipinlẹ Oyo dibo fun Aarẹ Muhammadu Buhari ẹgbẹ APC.
Toun ti bi o ti ṣe ni inu ohun dun gaan lori ibo naa, oni ohun ko ni ki akẹgbẹ ohun to jaweolubori aya fii ti ohun ba ri aridaju pe ko si magomago ninu idibo.
Ẹgbẹ oselu APC nipinlẹ Ọyọ ti kọwe ẹhonu si ajọ eleto idibo nilẹ wa, INEC, nipa awọn aisedeede to sọ pe o suyọ lasiko eto idibo sile asofin agba lẹkun guusu ipinlẹ Ọyọ.
Ẹgbẹ oselu APC salaye pe, awọn aisedeede naa lo sokunfa bi gomina Abiola Ajimọbi se fidirẹmi ninu ibo naa, ti wọn si ti fi iwe ẹhonu naa pẹlu abọ iwadi awọn ọlọpa silẹ fun ajọ INEC.
Ọmọwe Azeez Ọlatunde, tii se oludari fun eto iwadi ati aato fẹgbẹ APC, lo gbe iwe ẹhonu naa kalẹ lọjọ Aje, lẹyin ti ajọ INEC kede Ọmọwe Kọla Balogun pe oun lo bori ninu ibo sile asofin agba naa.
Saaju ni Ọmọwe Azeez Ọlatunde , tii se asoju ẹgbẹ oselu APC ni ibudo ti wọn ti n ka ibo sile asofin agba naa, ti kọkọ fapa janu ni ibudo ti wọn ti n ka ibo naa pe, wọn ko gbọdọ kede esi ibo ọhun.
Ọlatunde ni awọn janduku kan lo wa da ibo ru ni wọọdu mẹta kan lẹkun idibo ọhun, eyi to mu ki awọn ibo ti wọn padanu pọ pupọ.
Oríṣun àwòrán, Abiola Ajimọbi
Sugbọn osisẹ ajọ eleto idibo, to n se kokari esi ibo naa, Ọjọgbọn Wọle Akinsọla ni ki asoju ẹgbẹ oselu APC ko gbogbo ẹhonu to ba ni lọ si olu ileesẹ ajọ eleto idibo, to si kede esi ibo naa.
Ọmọwe Kọla Balogun si lo jawe olubori ninu ibo naa, ti Senetọ Abiọla Ajimọbi si se ipo keji.
Election Update 2019: Àwọn aráàlú ń fapá jánú lórí ìdádúró tó bá kíka èsì ìbò ààrẹ
Ọpọ awọn ọmọ orilẹede Naijiria lo ti n fapa janu lori bi alaga ajọ eleto idibo, Mahmood Yakubu se n kede idanuduro lọpọ igba lasiko ti wọn n ka esi ibo aarẹ nilu Abuja.
Esi ibo aarẹ naa ti wọn bẹrẹ kika rẹ ni aago mejila ọsan titi di aago kan oru, ni wọn siwọ kika rẹ, ti wọn si n lọ fun isinmi ranpẹ ni igba mẹrin ọtọọtọ.
Awọn idanuduro to n waye yii lo bọ si apo ibinu awọn ọmọ Naijiria ti oju wọn wa lọna lati mọ ẹni ti yoo jawe olubori gẹgẹ bii aarẹ tuntun fun orilẹede yii.
Loju awọn opo ikansiraẹni bii Twitter, Facebook ati Instagram, ẹnu awọn ọmọ naijiria ko duro, ti wọn si n kun lori bi ajọ eleto idibo se n danu duro lọpọ igba
Lero tọpọ eeyan, wọn ni ibo taa ti di lati ọjọ Satide se wa n sun wọ ọjọ isẹgun ki wọn to kede ẹni to jawe olubori.
@meizam0 loju opo Twitter, o ni, isinmi ranpẹ melo gan ni ajọ Inec fẹ gba gan?
Wicked Majidi @BodaMagidi ni idaduro ranpẹ miran? Se o ti yararẹ ọga Yakubu lẹẹkan si ni?
Ta ba tete se nkan si, ajọ eleto idibo yoo lo ida ọgọta ninu ọdun mẹrin to yẹ ki ẹni to jawe olubori lo lati fi kede esi ibo. O ya, se a lee dawo jọ fun ọga agba ajọ INEC lati ra Lucozade fun?
@nnekish ni Alaga ajọ INEC yii gan sa. Isẹ gan soso lo ni, isẹ kan pere, o si n lọ fun isinmi ranpẹ ni gbogbo igba, o da mi loju pe o ni ju iyawo kansoso lọ.
@Buzzifyer, o sọ pe eeyan kan nilo lati se bii Orubebe fun alaga ajọ INEC yii, ki lo nilo isinmi wakati mẹsan fun? Pẹlu bo se n lọ yii, yoo gbato ọsẹ kan ko to le kede ẹni to wọle sipo aarẹ.
@alayeburna n tiẹ ni Se bi alaga INEC ni oun ni awọn ojulowo esi ibo ni ori ẹrọ ayarabiasa rẹ ni?
Se ko da loju mọ ni? Asiko yii gan lo yẹ ka maa fi ojulowo esi ibo ko ajọ INEC loju.
@iam_stephenakin n beere pe Ki ni gbogbo eleyi gan?
Sallie_junaid, o ni Se aisan n se alaga ajọ INEC ni? Ki lo de to n lọ fun isinmi ni gbogbo igba?
@governordhaniel, o ni a jọ ku sibi ni. Se INEC ro pe a lọ sun, ko wa lọ paarọ esi ibo. Ọga Mahmood, lọ fun isinmi rẹ, awa yoo la oju wa silẹ laisun.
Election Update 2019: Saraki sọ ìdí tó fi fìdírẹmi nínú ìdìbò àpapọ̀
Oríṣun àwòrán, Saraki
Saraki ní yoo ohun tó ṣẹlẹ̀ yóò fun awọn eeyan lanfani ati ṣe àfiwé àwọn igun òṣèlú mejeeji
Aarẹ ile aṣofin agba, Bukọla Saraki ti ṣalaye awọn idi ti oun atawọn oludije ẹgbẹ oṣelu PDP nipinlẹ Kwara fi fidirẹmi, ninu eto idibo apapọ to waye ni ọjọ Satide.
Saraki sọ eyi di mimọ ninu atẹjade kan to fi sita, to fi ki awọn to gbe'gba oroke nibi eto idibo naa ku oriire.
Saraki ni, bi o tilẹ jẹ wi pe alaafia jọba lasiko idibo naa, sibẹ aikun oju oṣuwọn awọn ẹrọ ayẹkaadi idibo wo, titẹka kọja iye ibo to yẹ atawọn iwa aitọ miran kaakiri awọn ibudo idibo ni ipinlẹ naa, kun ohun to faa ijakulẹ ẹgbẹ oṣelu PDP nipinlẹ Kwara.
Dokita Saraki ni, oun ki gbogbo awọn ti INEC kede gẹgẹ bii olubori ku oriire ṣugbọn ẹgbẹ oṣelu oun yoo gbe igbesẹ to ba tọ, nigba to ba ya lori awọn kudiẹkudiẹ naa.
Election Update 2019: Lẹ́yìn lílọ Saraki, Kwara yóò ṣún síwájú ni
"Gẹgẹ bii ẹni to wa lati inu ẹbi ati eto oṣelu to gbilẹ lati ibẹrẹ pẹpẹ ninu iṣiṣẹ sin araalu ati idagbasoke awọn eniyan rẹ, ireti mi ni pe awọn eeyan wa yoo maa ri ere pipe ni igba gbogbo.
Ohun to ṣẹlẹ yii yoo tilẹ tun fun awọn eeyan lanfani ati gbe ẹgbẹ mejeeji si ẹgbẹ ara wọn fun ayẹwo ati afiwe. Ju gbogbo rẹ lọ awọn to bori ni idibo satide kii ṣe ọta mi. ọmọ ipinlẹ Kwara kan naa bii temi ni wọn jẹ."
Ibrahim Oloriẹgbẹ lo gbẹyẹ mọ Saraki lọwọ ninu idije fun ijoko aṣofin agba, fun ẹkun idibo guusu ipinlẹ Kwara.
2019 elections update: PDP pè fún ìwọ́gilé èsì ìdìbò ààrẹ ní ìpínlẹ̀ mẹ́rin
Oríṣun àwòrán, Atiku Abubakar
PDP fẹ̀sùn kan àwọn agbófinró àti INEC lórí ìdìbò ààrẹ àti ilé aṣòfin àpapọ̀
Ẹgbẹ oṣelu PDP ti pe fun iwọgile awọn esi idibo aarẹ lati ipinlẹ Zamfara, Nasarawa, Bornu ati Yobe.
Ẹgbẹ oṣelu PDP pe ipe yii nibi ipade kan ti wọn ṣe pẹlawọn oniroyin ni alẹ ọjọ iṣẹgun ni ilu Abuja.
Ẹgbẹ oṣelu PDP ṣalaye pe ni ipinlẹ Yobe iye awọn eeyan to dibo pọ ju iye awọn oludibo ti wọn forukọ silẹ ni ipinlẹ naa.
Kabiru Taminu Turaki to jẹ igbakeji oludari agba igbimọ ipolongo PDP ṣalaye pe nipasẹ ofin eto idibo orilẹede Naijiria, iru ibo bẹ ko lẹsẹ nlẹ.
O sọ siwaju sii pe ni ipinlẹ Zamfara, ko si idibo kọkan nibẹ nitori ko si awọn iwe akọsilẹ esi idibo ni eyikeyi awọn ibudo idbo to wa kaakiri ipinlẹ naa.
Wọn ni awọn esi idibo to wa lati ipinlẹ naa jẹ eyi ti awọn oṣiṣẹ ajọ INEC kan gbe kalẹ gẹgẹ bii idari awọn eekan ẹgbẹ oṣelu APC nibẹ.
Oríṣun àwòrán, Atiku abubakar
PDP pe fun iwọgile esi idibo aarẹ ni Zamfara, Plateau,Abuja ati Yobe
O fi kun un pe ni ipinlẹ Borno, n ṣe ni awọn eeyan kan joko gbe esi didibo naa kalẹ nibẹ nitori gẹgẹ bi o ṣe wi, 'Ko si idibo nibẹ'
Bakan naa ni ẹgbẹ oṣelu PDP tun beere fun ibo rẹ to din diẹ ni ẹgbẹrun lọna ọgọjọ nipinlẹ Nasarawa ati mọkandinlọgọrin ibo ni ipinlẹ Kogi to ni INEC wọgile lọna ti ko bofin mu.
Ẹgbẹ PDP tun mẹnu ba ipinlẹ Plateau, olu ilu ilẹẹwa Abuja gẹgẹ bii ara awọn ipinlẹ ti INEC ti wọgile, tabi yọ ninu ibo wọn.
Election Update 2019: Lẹ́yìn lílọ Saraki, Kwara yóò ṣún síwájú ni
O wa ke si ajọ INEC lati ko awọn iroyin inu ẹrọ ayẹwo kaadi idibo rẹ sita fun araye, paapaa julọ awọn ẹgbẹ oṣelu to kopa, lati yẹwo.
PDP ko tun ṣai fi ẹsun kan awọn ileeṣẹ agbofinro ati alaabo pe wọn ṣe agbodegba fun ẹgbẹ oṣelu APC lati 'tẹ ifẹ araalu mọlẹ' lasiko idibo naa.
Nigeria Election 2019: Saraki àti àwọn sẹ́nẹ́tọ̀ tó fẹ̀yìn gbálẹ̀ nínú ìdìbò ilé aṣòfin
Oríṣun àwòrán, Senate
Saraki kuna ninu ibo ile aṣofin
Esi idibo gbogbogbo orilẹede Naijiria jẹ iya lẹnu papaa julọ idibo ile aṣofin agba l'Abuja.
Olori ile igbimo aṣofin l'Abuja Bukola Saraki ati awọn gbajugbaja sẹnẹtọ kan ko ni lanfani lati pada sile mọ lẹyin ti wọn fidi rẹmi ninu idibo ọjọ ile aṣofin ọjọ Abamẹta.
Saraki to jẹ ọmọ ẹgbẹ oṣelu PDP lo n ṣoju ẹkun arin gbungbun ipinlẹ Kwara nile aṣofin agba l'Abuja.
Election Update 2019: Lẹ́yìn lílọ Saraki, Kwara yóò ṣún síwájú ni
Ṣugbọn Saraki ko ni le pada sile aṣofin lẹyin ti Ọmọwe Ibrahim Oloriegbe to jẹ ọmọ ẹgbẹ APC fagba han an ninu idibo ọjọ Satide.
Saraki darapọ mọ PDP lati APC, o si ni ijakulẹ ninu idibo abẹle PDP fun ipo aarẹ eleyi ti Atiku Abubakar ti jawe olubori.
2. Abiọdun Olujinmi:
Oríṣun àwòrán, Abiodun Olujinmi
Sẹnetọ̀ to n soju ẹkun idibo Guusu Ekiti, to tun jẹ ọmọ ẹgbẹ oselu PDP, Abiọdun Olujinmi, naa ko lee pada sile asofin agba mọ̀.
Idi ni pe o fidi rẹmi ninu ibo ile asofin agba to waye lọjọ Satide.
Olujinmi ni olori ọmọ ẹgbẹ oselu to kere julọ nile asofin apapọ ilẹ wa lọwọ lọwọ bayii.
3.Godswill Akpabio
Oríṣun àwòrán, Nigerian Senate
Akpabio fẹyin gbo lẹ ninu idibo ile aṣofin
Sẹnẹtọ mii ti ko tun wọle ni Godswill Akpabio to jẹ ọmọ ẹgbẹ APC o n ṣoju ẹkun iwọ oorun  ipinlẹ Akwa Ibom.
Akpabio to jẹ Gomina ipinlẹ Akwa Ibom tẹlẹ ri fidi rẹmi ninu idibo ti igbakeji gomina ipinlẹ ọhun tẹlẹ ri Christopher Ekpenyong tii ṣe ọmọ ẹgbẹ PDP ti jawe olubori.
Akpabio ni abẹnugan ẹgbẹ oṣelu alako nile aṣofin agba ṣugbọn o kọwe fipo naa silẹ nigba to darapọ mọ ẹgbẹ APC lati PDP.
Shehu Sani
Oríṣun àwòrán, Nigerian Senate
Shehu Sani fidi rẹmi
Ṣẹnẹtọ Shehu Sanni jẹ ọkan lara awọn alẹnulọrọ nile igbimọ aṣofin agba l'Abuja.
Oun lo n ṣoju ẹkun aarin gbungbun ipinlẹ Kaduna, ṣugbọn o fidi rẹmi ninu ibo ọjọ Satide.
Uba Sani to dije labẹ asia ẹgbẹ oṣelu APC lo wọle idibo naa. Ẹgbẹ oṣelu APC lo gbe Shehu Sanni gẹgẹ bi sẹnẹtọ.
Ṣugbọn o darapọ mọ ẹgbẹ osẹlu PRP lẹyin to fidi rẹmi ninu ibo abẹle APC.
Binta Masi Garba
Oríṣun àwòrán, Nigerian Senate
Binta Masi Garba padanu
Binta Masi Garba ni sẹnẹtọ obinrin kan ṣoṣo to to wa lati ariwa orilẹede Naijiria.
Oun lo n ṣoju ẹkun ariwa ipinlẹ Adamawa, o si jẹ ọmọ ẹgbẹ oṣelu APC.
Ishaku Cliff to jẹ ọmọ ẹgbẹ PDP lo fẹyin rẹ gbo lẹ ninu idibo ile aṣofin agba to waye lọjọ kẹtalelogun oṣun keji.
Andy Ubah
Oríṣun àwòrán, Nigerian Senate
Andy Uba padanu ibo
Sẹnẹtọ Andy Ubah n ṣoju ẹkun gusu ipinlẹ Anambra nile igbimọ aṣofin agba.
Ubah to jẹ ọmọ ẹgbẹ oṣelu APC ko ni le pada sile mọ lẹyin idibo gbogbogbo lẹyin Ifeanyi Ubah, ọmọ ẹgbẹ YPP fagba han an.
Ifeanyi Ubah ni sẹnẹtọ akọkọ ti yoo wọle labẹ asia ẹgbẹ YPP.
2019 Election update: Buhari borí; ó di ààrẹ Nàìjíríà tuntun
Oríṣun àwòrán, Buhari/Twitter
Buhari wọle leẹkeji
PDP pè fún ìwọ́gilé èsì ìdìbò ààrẹ ní ìpínlẹ̀ mẹ́rin
Aarẹ Muhammadu Buhari lo jawe olubori ninu ibo aarẹ orilẹede Naijiria to waye lọjọ Abamẹta, ọjọ kẹtalelogun, ọdun 2019.
Ajọ eleto idibo INEC lo kede pe aarẹ pe Buhari to dije dupo labẹ asia ẹgbẹ oṣelu APC fẹyin Atiku Abubakar to dije fẹgbẹ osẹlu alatako PDP gba lẹ ninu idibo ọhun.
Oríṣun àwòrán, Presidency
Buhari wọle leẹkeji
Pẹlu esi idibo yii tumọ si pe aarẹ Buhari ni yoo tukọ orilẹede Naijiria fun ọdun mẹrin miran.
Ẹwẹ, ẹgbẹ alako PDP ti sọ pe awọn ko ni gba esi idibo ti ajọ INEC kede lati igba ti wọn ti n ka esi ibo naa.
Buahari jawe olubori ni awọn ipinlẹ bi Kano, Katsina, Bauchi, Kaduna, Bornu, Yobe pẹlu ibo to pọ yanturu.
Oríṣun àwòrán, Presidency
Buhari fẹyin Atiku gba lẹ
Aarẹ Buhari tun la Atiku mọ lẹ nipinlẹ Osun, Ekiti, Kwara, Kogi ati awọn ipinlẹ miran.
Bakan naa ni Atiku la Buhari fẹyin Buhari gbo lẹ lawọn ipinlẹ bi Adamawa, Benue, Cross River, Abia ati olu ilu Naijiria Abuja
2019 Elections Update: Inec so ìkéde èsì ìbò ààré rọ̀ di aago mẹ́ta òru
Oríṣun àwòrán, InEC Twitter
Ọrọ lori esi idibo aarẹ
Ajọ eleto idibo INEC ti ka esi ibo aarẹ ni gbogbo ipinlẹ mẹrindinlogoji ati olu ilu Naijiria Abuja tan.
Ohun ti o ku bayii ni ki alaga ajọ Ọjọgbọn Mamood Yakubu kede ẹni to wọle ibo aarẹ ninu Atiku ati aarẹ Muhammadu Buhari.
Ẹwẹ, Ọjọgbọn Yakubu kede pe iṣẹ si pọ fawọn lati ṣe lori esi idibo aarẹ ọhun.
Lẹyin naa ni alaga ajọ INEC kede pe awọn fẹ lọ simi diẹ, o ni wa yoo tẹsiwaju laago mẹta orun Ọjọru.
Ibo aarẹ
Ẹwẹ, ẹgbẹ alako PDP ti sọ pe awọn ko ni gba esi idibo ti ajọ INEC kede lati igba ti wọn ti n ka esi ibo naa.
Buahari jawe olubori ni awọn ipinlẹ bi Kano, Katsina, Bauchi, Kaduna, Bornu, Yobe pẹlu ibo to pọ yanturu.
Bakan naa ni Atiku la Buhari fẹyin Buhari gbo lẹ lawọn ipinlẹ bi Adamawa, Benue, Cross River, Abia ati olu ilu Naijiria Abuja
Election Update 2019: Iléeṣẹ́ ológunní Wike gbówó ńlá fáwọn láti da ìbò rú
Ileeṣẹ ologun Naijiria fẹsun kan gomina ipinlẹ Rivers, pe o gbiyanju lati fi owo ra awọn ọmọ ogun lasiko idibo to waye nipinlẹ Rivers.
Ileeṣẹ ologun orilẹede Naijiria ti fẹsun kan gomina ipinlẹ Rivers, Nyesom Wike pe o gbiyanju lati fi owo ra awọn ọmọ ogun lasiko idibo to waye nipinlẹ Rivers.
Ninu atẹjade kan ti ileeṣẹ ologun fi sita, wọn ni Gomina Wike gbe owo banta-banta lọ fun awọn ọmọ ogun Ẹkun kẹfa ileesẹ ologun, lati da eto idibo ru fun anfaani ara a rẹ, to si tun n fi ẹsun ṣiṣe ègbè kan awọn ọga ileeṣẹ ologun.
Wọn fi ẹsun kan pe awọn oluranlọwọ fun Wike gbe owo lọ si ọgba banki apapọ Naijiria to wa nilu Port Harcourt gẹgẹ bi owo ẹyin fun awọn ọmọ ogun to wa nibẹ lọjọ kẹtalelogun oṣu Keji, ti i ṣe ọjọ idibo.
Awọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí:
Ninu ayẹwo ileesẹ ologun lo ti farahan pe, Ọgagun kan, AP Ubah ati awọn ọlọpaa mẹta; DSP Oyoku Ifelle, Inspẹkitọ Hycent Oboi  ati Sajẹnti Nketan Chuks ati Akanu Garba, gba owo ẹyin lọwọ awọn oluranlọwọ Gomina Wike.
Lara ohun ti wọn ba lọwọ wọn bi ẹri ni miliọnu meji ati ẹgbẹrun lọna ọtalerugba o din mẹwa Naira ti wọn ba ninu ọkọ DSP ọlọpaa naa.
Bakan naa ni wọn ba ẹgbẹrun lọna ẹẹdẹgbẹta Naira ninu ọkọ ayọkẹlẹ Ọgagun AP Ubah.
Oríṣun àwòrán, @Gov_Wike
Oun paapa si jẹwọ pe awọn oluranlọwọ Gomina Wike lo fun oun ni owo naa pẹlu ileri ile to jọju fun, lasiko ti yoo fi wa ni ipinlẹ naa.
Awọn nkan mi i tawọn ologun tun ri ni kaadi pelebe ajọ INEC mẹẹrin, ati awọn apo iwe to jẹ ti ile ijọba ipinlẹ Rivers.
Sugbọn, lọsan ọjọ Iṣẹgun, ileesẹ ologun nibi ipade oniroyin to ṣe, tun fi awọn eniyan  kan han, pẹlu ẹsun pe wọn se mago-mago ibo.
Bo tilẹ jẹ wi pe awọn ti wọn fi ẹsun kan sọ pe bẹẹkọ.
2019 Election update: Buhari àti Ọṣinbajo gba ìwé ẹ̀rí Mo yege
Aarẹ Muhammadu Buhari, to sẹsẹ jawe olubori fun saa keji ti lọ gba iwe ẹri 'Mo yege' lọdọ ajọ eleto idibo nilu Abuja.
Aarẹ Buhari ati igbakeji rẹ, Yẹmi Ọsinbajo ni wọn dijọ lọ gba iwe ẹri naa.
Nigba to n fun wọn ni iwe ẹri naa ni gbọngan nla ICC to wa nilu Abuja, Igbakeji aarẹ ati iyawo rẹ ni wọn kọks lọ gba iwe ẹri naa, ko to kan aarẹ funra rẹ.
Ninu ọrọ rẹ nibi ayẹyẹ gbigba iwe ẹri Mo yege ọhun, eyi ti ọpọ eeyan peju si, aarẹ Muhammadu Buhari ni oun dupẹ lọwọ Ọlọrun pe eto idibo naa tọri si rere.
O ni o daju pe eto idibo naa lọ lai si kọnu n kọhọ ninu, taa ba wo iwoye awọn eeyan to wa tọpinpin ibo naa lati ilẹ okeere.
Election Update 2019: Lẹ́yìn lílọ Saraki, Kwara yóò ṣún síwájú ni
Buhari wa kesi awọn alatilẹyin rẹ lati mase yọ awọn igun alatako, amọ ki gbogbo wọn dijọ gbaruku ti oun lati mu ki Naijiria tẹsiwaju.
O ni oun yoo gbe isejọba ti yoo lọwọ gbogbo eeyan ninu, ti yoo si ba ala gbogbo wa mu fun orilẹede Naijiria to dara, ti aabo to peye wa nibẹ.
Buhari ni oun ko ni afojusun miran bikose lati sin Naijiria tọkantọkan, eyi ti yoo duro re, tinu awọn ọiran to n bọ yoo si fi yangan,
Aarẹ orilẹede yii tun fi ọwọ idaniloju sọya pe oun yoo ms le ọpọ aseyọri oun nipa tita ọrs aje orilẹede yii ji, pipese eto aabo to duro re ati gbigbogun ti iwa ajẹbanu.
Bakan naa ni Buhari daro pẹlu awọn eeyan ti ẹmi wọn bọ lasiko eto idibo yii, boya nitori laasigbo to waye ni abi lati ipasẹ ijamba ọkọ, to si gbadura pe ki Ọlọrun tk wsn si afẹfẹ rere.
Aarẹ Buhari woye pe eto idibo kii se ogun tabi ọtẹ, bẹẹ ni kii se boo ba o pa, boo ba, ko bu lẹsẹ.
Aarẹ orileede Naijiria to wọle fun saa keji, Muhammadu Buhari ti dupẹ lọwọ awọn eeyan orileede wa fun aseyọri rẹ ninu idibo aarẹ to waye.
Lowurọ Ọjọru ni ajọ eleto idibo Inec kede rẹ gẹgẹ bi ẹni to jawe olubori ninu idibo aarẹ to waye lọjọ abamẹta.
Oríṣun àwòrán, @Ahmad Bashir
Aworan aarẹ Buhari
Ko pẹ pupọ lẹyin ikede yii ti Buhari ati awọn ọmọ ẹgbẹ APC ti peju si olu ileeṣẹ ẹgbẹ naa ni Abuja nibi ti o ti fi ọrọ ikini ranṣẹ.
Oríṣun àwòrán, Ahmad Bashir
Aworan aarẹ Buhari
Ni iwaju awọn ọmọ ẹgbẹ APC lolu ile ẹgbẹ naa, Buhari ni ayọ ohun kun nitori ifẹ ti awọn eeyan fi han si ohun lati jẹ aarẹ lẹẹkansi.
O ni inu oun bajẹ pe awọn eeyan padanu ẹmi wọn ninu idibo naa, to si rọ awọn osisẹ eleto aabo lati tẹramọ iṣẹ wọn lasiko idibo Gomina to n bọ lọna.
Lara awọn ti wọn jijọ peju si ile ẹgbẹ naa ni awọn eekan ẹgbẹ oṣelu APC ati awọn alatilẹyin ẹgbẹ naa.
Bi ibo aarẹ ti ṣe lọ
Aarẹ Buhari wa rọ awọn alatilẹyin rẹ lati mase fi awọn alatako ṣe yẹyẹ .
Buhari ni ijọba ohun yoo tẹramọ mimu agbega ba eto aabo,ọrọ aje ati kikoju iwa ajẹbanu.
Election Update 2019: Ohun tó ṣẹlẹ̀ ní Kwara yóò kọ́ àwọn ìpínlẹ̀ yókù lọ́gbọ́n
Oríṣun àwòrán, @Ogundamisi
Onwoye nipa awọn ohun to n lọ lawujọ wa, to fi ilẹ Gẹẹsi se ibujoko, Kayọde Ogundamisi, ti woye pe oniruuru ẹkọ ni eto idibo aarẹ ati tawọn asofin apapọ to kọja kọ wa.
Ogundamisi, lasiko to n ba BBC Yoruba sọrọ lẹyin ti ajọ eleto idibo kede esi ibo aarẹ ati ẹni to jawe olubori, salaye pe, ọpọ oloselu lo ti kẹkọ bayii pe ọrọ araalu lo se pataki ju ohun ti wọn yoo jẹ lọ.
Nigba to n mẹnuba ihuwasi awọn asofin agba ilẹ wa ni saa eto isejọba taa wa yii, Ogundamisi mẹnuba olori ile asofin agba, Bukọla Saraki pe, yoo fi abajade esi idibo to kọja kẹkọ pe ilu nikan lo dara lati sin ju ara ẹni lọ.
Bakan naa lo ni, isẹlẹ to waye nipinlẹ Kwara yoo jẹ ẹkọ fun awọn ipinlẹ yoku, ti adari wọn ko ba ro tawọn mẹkunnu mọ eto isejọba wọn, pẹlu afikun pe, inu oun dun pe Bukọla Saraki ko ni pada sile asofin agba mọ ni saa isejọba to n bọ.
Ogundamiloju wa kesi aarẹ Muhammadu Buhari lati maa ba awọn araalu sọrọ loorekoore ko lee mọ awọn ohun ti awọn eeyan n fẹ.
Election Update 2019: Lẹ́yìn lílọ Saraki, Kwara yóò ṣún síwájú ni
Lori ifilọlẹ saa isejọba to n bọ, onwoye nipa ohun to n lọ lawujọ naa ni Buhari yẹ ko yọ awọn oloye rẹ ti ko ba sisẹ bo se yẹ nipo, ko si fi awọn eeyan to da loju pe wọn yoo sisẹ kara sipo.
Ogundamisi tun ni isẹ ti isejọba Buhari se laarin ọdun mẹrin pọ pups, amọ iroyin ati ipolongo nipa awọn akanse isẹ naa mẹyẹ pupọ.
Election Update 2019: Àwọn olórí orílẹ̀èdè lágbàyéé ń kí Buhari kú oríire
Oríṣun àwòrán, @MBuhari
Minisita fun ọrọ Afrika labẹ ijọba Ilẹ Gẹẹsi Harriet Baldwin ti ki Aarẹ Muhammadu Buhari ku ori ire, o si ke pe awọn ti esi idibo naa ko ba tẹ lọrun lati gbe igbesẹ to yẹ lọna alaafia.
Baldwin ni ijọba Ilẹ Gẹẹsi lero wipe esi idibo naa yoo ba awọn ọmọ Naijiria lara mu. O ni esi idibo ti INEC kede ba eyi ti awọn ajọ alamojuto ko jọ.
Wọn tun ba awọn ti o  ẹmi won ba idibo naa lọ kẹdun, ti wọn si sọ wipe ko yẹ ki ẹnikẹni ku nibi to ti n gbẹ igbesẹ fun ijọba awa arawa.
Awọn asaaju orilẹede ti n fi isẹ ikini wọn ransẹ si aarẹ Muhammadu Buhari to jawe olubori lati lọ fun saa keji ninu eto idibo to kọja.
Atẹjade kan ti oludamọran si aarẹ Buhari feto iroyin, Fẹmi Adesina fisita ni aarẹ orilẹede Ghana, Nana Koffi Addo, Mahamadou Issoufou tilẹ Niger ati Macky Sall ti orilẹede Senegal ti fi fi isk ikinni ku oriire ransẹ si aarẹ Muhammadu Buhair.
Gẹgẹ bi atẹjade naa ti wi, awọn asaaju orilẹ ede naa ni aarẹ Buhari moke ninu eto idibo naa lati lọ fun saa keji, nitori igbẹkẹle ati igboya tawọn ọmọ Naijiria ni ninu rẹ.
Wọn wa gbadura fun aarẹ Buhari pe yoo se aseye ti alakan n se epo ni saa keji to gba yii.
Election Update 2019: Sowore dẹ́bi aijáde dibo àwọn èèyàn rú ìhàlẹ̀ Buhari
Oríṣun àwòrán, Omoyele Sowore
Ẹgbẹ Sowore ti wọn daalẹ laipẹ yi lo ṣe ipo kẹta ninu ibo aarẹ Naijiria
Oludije ipo aarẹ labẹ  ẹgbẹ oṣelu  African Action Congress, AAC, Omoyele Sowore ti fesi si ijawe olubori Aarẹ Muhammadu Buhari ninu idibo aarẹ Naijiria.
Soworẹ ni ki awọn ọmọ Naijiria ma gbaradi nitori ijọba pasan ni wọn dibo fun ti gbogbo wọn yoo si ni ipin ninu rẹ.
Soworẹ salaye ọrọ yi wa nigba to n ba BBC Yoruba sọrọ lori akanṣe eto nipa idibo aarẹ Naijiria.
''Ibo yi ko bojumu.Ti ẹ ba wo daada, ẹ o ri wi pe awọn eeyan ko tuyaya jade paapa julọ nilu Eko lati dọwọ idunnu esi ibo''
Sowore tẹsiwaju pe, pupo eeyan ni ko ri bi dibo latari kọnukọhọ to wa ninu eto idibo naa.
O si da ẹbi aijade dibo daada awọn ara ilu ru ọrọ ihalẹ ti aarẹ Buhari sọ saaju idibo.
Sowore dupe lọwọ awọn ọmọ  Naijiria to gbaruku ti ẹgbẹ rẹ ti wọn fi ṣe ipo kẹta ninu ibo naa.
O ni bayi ti awọn ti ri ipa ti awọn oludije ọdo ko,iṣoro ko ni si lọjọ iwaaju fun awọn ọdọ lati de ipo oṣelu.
''Asiko ọ̀dọ́ ni ọdun mẹrin to n bọ lọna.''
Sowore wa pe fun atunto eto oṣelu ki o ba le jẹ ki awọn ọmọ Naijiria laanfaani lati kopa daada.
Nigba ti atọkun eto beere lọwọ rẹ pe, ki ni yoo ṣe, to ba jẹ oun lo wole gẹgẹ bi Buhari? Sowore ni kiakia lohun yoo yan awọn ti yoo ṣe ijọba ti awọn ko si ni dawọ iṣejọba duro.
"''O ti wa lori oye tẹlẹ, ko si yẹ ki idiwọ kankan waye lati maa tẹsiwaju pẹlu iṣejọba. Ọsẹ kan pere ni mo ma fikede Minisita tuntun, ka ni emi ni Buhari."""
Ṣẹ rántí pásítọ̀ South Afrika tó ní òun jí òkú díde? Àwọn agbókùú fẹ́ fàá lọ ilé ẹjọ́
Oríṣun àwòrán, Alph Lukau/Facebook
Pasitọ Alph Lukau (ní aṣọ buluu) ni oun jí arakunrin yii dide
Ẹgbẹ awọn agbokujo ni South Afrika ti ni awọn yoo gbe pasitọ to ni oun ji oku arakunrin kan dide lọ ile ẹjọ́.
Fidio kan ṣe afihan pasitọ Alph Lukau, nibi to ti n pariwo sinu poosi kan to si n sọ fun arakunrin kan ti oku rẹ wa ninu rẹ pe ko ji dide, bi awọn ara ijọ ṣe n patẹwọ.
Ohun ti pasitọ se yii, to waye lẹba ile ijọsin rẹ ti ko jinna silu Johannesburg, ni ọpọlọpọ ti bẹnu atẹ lu bi fidio naa ṣe tan kakakiri.
Awọn eeyan kan ni ọna lati gba owo lọwọ awọn ara ilu ni igbesẹ yii, kii se ootọ rara.
'Obìnrin tí kó ba fẹ́ òṣìṣẹ́ Mọ́ṣúárì, ìpinu rẹ̀ mẹ́hẹ'
Ileeṣẹ agbokujo mẹta ti kede faraye pe igbesẹ pasitọ naa ba orukọ awọn jẹ, nitori naa, awọn n lọ ile ẹjọ.
Ileesẹ agbokujo Kingdom Blue, Kings & Queens Funeral Services ati Black Phoenix sọ fun awọn akọroyin wipe, awọn oṣiṣẹ ile ijọsin naa tan awọn jẹ.
"Wọn ni awon kan ti wọn pe ara wọn ni awọn idile ""oloogbe"", wa si ọdọ awọn ile agbokujo naa wipe awọn fẹ fun wọn niṣẹ."
Ṣugbọn awọn iwe iroyin ni arakunrin ti wọn pe ni oloogbe naa ko ku.
Ọrọ naa si tun ti mu ki ẹnu tubọ maa kun awọn ayederu pasitọ ni South Afrika.
Ibikunle Amosun- Ẹgbẹ́ onípákí ni kí ẹ dìbò fún Gómìnà nìpínlẹ̀ Ogun
Oríṣun àwòrán, @Ibikunle Amosun
Mo fẹ ki ẹ jade dibo fun oludije ẹgbẹ APM
Gomina Ibikunle Amosun  ti salaye lẹkunrẹrẹ ohun ti o wa nidi aawọ to n fa ipinya ninu ẹgbẹ oṣelu APC  nipinlẹ Ogun.
Ninu ifọrọwanilẹnuwo kan ti o ṣe lọjọbọ ti wọn fihan lori ẹrọ ayelujara,Amosun ni awọn to wa lati Abuja lasiko idibo abẹnu ẹgbẹ APC lo da wahala silẹ laarin awọn ọmọ ẹgbẹ.
Amosun to wọle gẹgẹ bi Sẹnẹtọ labẹ ẹgbẹ APC ninu idibo ile asofin to waye wa rọ awọn alatilẹyin rẹ lati dibo fun Adekunle Akinlade ti ẹgbẹ APM gẹgẹ bi Gomina.
''Mo dupe fun bi ẹ ṣe di ibo aarẹ gbe Aarẹ Buhari wole ṣugbọn ni ti Gomina to n bọ lọna yii, ẹgbẹ paki ni ki ẹ di ibo Gomina yin fun''
Amosun ni ohun fa awọn to wa nidi dida ipinlẹ Ogun ru le Olorun lọwọ ti o si rọ awọn agba oṣelu ilẹ kaarọ o jiire lati kiye sara ki ẹgbẹ APC ma baa fidirẹmi.
''Ṣebi ẹ ri bi ibo ti ṣe lọ lawọn ipinlẹ kaarọ ojiire lasiko ibo aarẹ, bi a ko ba duro sinsin, o ṣeeṣe ki a fidirẹmi''.
APM ni ẹgbẹ ti a n ṣe bayi ni ipinlẹ Ogun
Ni idahun si ibeere pe bawo ni ohun ṣe wa ninu ẹgbẹ APC ti o si ni ki awọn eeyan dibo fun oludije ẹgbẹ APM, Gomina Amosun ṣalaye pe wọn fi eru gba ibukun lọwọ Adekunle Akinlade ni.
''Ogun West la ti jijọ sadehun pe a o fun ni ipo Gomina ti gbogbo wa si ti faramọ. Ṣugbọn nigba ti awọn to ti lọ lati ọdun mẹrin sẹyin pada de lati Abuja, niṣe ni wọn da ọrọ ru''
O fi akawe ọrọ awọn obinrin meji ti wọn ja si ọmọ ninu bibeli kin ọrọ rẹ lẹyin ti o si ni awọn yan an ni ki Adekunle Akinlade lọ si ẹgbẹ APM nitori ki ẹgbẹ ma bajẹ ni.
Election Update 2019: Àwọn ọlọ́pàá dá ìpàdé àwọn alátakò Tinubu dúró l'Eko
Oríṣun àwòrán, Facebook/Tinubu
Ọrọ lori ibo gomina nipinlẹ Eko
Awọn ọlọpaa yabo ile itura Airport Hotel ni Ikeja nipinlẹ Eko nibi ti awọn ajijagbara olosẹlu kan ti n ṣe ipolongo ibo lati ta ko Asiwaju Bola Tinubu ṣaaju ibo gomina ọjọ Abamẹta ọsẹ to n bọ.
Awọn ajijagbara ọhun ti orukọ wọn n jẹ Orange Movement wa ni gbọngan Oramiyan ninu ile itura ọhun nibi ti iroyin ni wọn ti n gbero lati ta ko erongba Tinubu ninu idibo gomina to n bọ ni ipinlẹ Eko.
Ọkan lara awọn ọmọ ẹgbẹ Orange Movement sọ fun awọn oniroyin pe awọn ọlọpaa ni pe ẹgbẹ naa ko gbaaye lati ọdọ awọn alaṣẹ ki wọn to sẹ agbekalẹ eto ti wọn ṣe nibẹ.
Àdéhùn èmi àti Ọlọ́run ni pé èèyàn láti Yewa yóò jẹ́ Gómìnà -Amosun
Àwọn oun àjòjì tó ṣẹlẹ̀ nígboro níbi àjọyọ̀ ìṣẹ́gun Buhari
Àwọn kókó márùn-un tí ìdìbò ààrẹ Naijiria kọ́ wa
Wale Ahmed: APC kò ṣe mọ̀dàrú, PDP ló fẹ́ gbà'jọba tipátipá
Babajide Sanwo-Olu to n dije fun ipo gomina labẹ asia ẹgbẹ oṣelu APC ni Tinubu n ṣe atilẹyin fun ninu ibo gomina ọsẹ to n bọ.
Awọn alako Tinubu ati awọn ọmọ oṣelu PDP kan ṣalaye pe saa karun un ni yoo jẹ fun Tinubu ti ẹgbẹ APC ba tun wọle ninu ibo gomina to n bọ nipinlẹ Eko.
Ẹgbẹ Orange Movement ti bẹrẹ si ni pariwo ''O to gẹ'' iru orin ti wọn kọ abẹnugan ile aṣofin agba l'Abuja, Bukola Saraki ko to fidi rẹmi ninu ibo ile aṣofin agba ọjọ kẹtalelogun oṣu Keji.
Election Update 2019: Kínni àwọn oun tí ìdìbò ààrẹ Naijiria kọ́ wa?
Oríṣun àwòrán, AFP
Isegun Buahari lo gba awọn iwe iroyin kan
Aarẹ orilẹede Muhammadu Buhari ti jawe olu bori ninu idibo aarẹ  ti yoo fun laanfani lati ṣe ijọba fun saa ọlọdun mẹrin miiran.
Alatako rẹ to gbe ipo keji, Atiku Abubakar, ti ni idojuti nla fun Naijiria ni esi idibo naa ati wipe oun yoo gbe ọrọ naa lọ ile ẹjọ.
Amọ ṣa bi awọn kan ti ṣe n dunnu si ibo naa ti awọn miran si n fapajanu, a ni ki a ṣe agbeyẹwo awọn oun marun-un ti idibo naa fi han wa ti o mu lamilaka.
1. Ó yátọ̀ sí ti àtijọ́ gedegbe,bó tilẹ̀ jẹ́ pe ohun to mu iyatọ yi wa kii ṣe oun to dára
Pupọ lo fi orukọ silẹ lati kopa ninu idibo yi .Koda akọsil fi han wa pe eeyan mẹtalelaadọrin ni o laanfani lati dibo.
Ohun ti eyi si tọka si ni pe idibo Naijiria leyi to ni oludibo to pọju lọ ni Afrika.
Wale Ahmed: APC kò ṣe mọ̀dàrú, PDP ló fẹ́ gbà'jọba tipátipá
O ṣe ni laanu pe ida mẹta ninu awọn oludibo to forukọ le lo jade wa dibo.
Idibo gbogbogbo 2019 lo ri oludibo to kere ju lati ogun ọdun ti Naijria ti pada si ijọba awa arawa.
Ati ọdun 2003 ni iye awọn oludibo ti n kere si ni orilẹede yii.
2. Eniyan ńlá ṣì ni Buhari ni òkè ọya
Atiku Abubakar to ṣe ipo keji ninu idibo aarẹ ni jibiti wa ninu akojọ esi ibo naa.
O ni o yani lẹnu wipe akojọ ibo ni awọn agbegbe ti oun ti ni okiki ju bii Ipinlẹ Akwa Ibom fi bi ilaji kere ju ti 2015
Ẹkọ ta ri kọ ni pe Buhari ni atilẹyin to pọ ni Ariwa Naijiria nibi ti wọn ṣi ri bi eniyan rere.
Lati bi idibo marun sẹyin ni iye awọn oludibo rẹ ti pọ.
Awọn oludibo ko jade to ni Guusu Naijiria nibi ti Atiku ro pe o yẹ ki iye awọn to dibo fun oun pọ. O bori ni Guusu Naijiria ṣugbọn iye ibo to fi bori ko to lati koju miliọnu mẹrin ti Buhari fi wọle.
Oríṣun àwòrán, AFP
Atiku Abubakar ti kọ esi idibo naa
3. Wahala ọrọ aabo ko di awọn alatilẹyin Buhari lọwọ lati dibo
Atiku ti beere pe bawo lo ṣe jẹ ti awọn agbegbe oke ọya nibi ti ọrọ aabo ti jẹ ipenija ṣe ni awọn oludibo to pọ.
Ipinlẹ Borno ati Yobe jẹ awọn ipinlẹ ti ẹgbẹ oṣelu APC ti ri ọwọ mu daada. Atilẹyin wọn ko ti i dinku bo tilẹ jẹ wipe aisi aabo ti le miliọnu meji eniyan kuro lagbegbe naa.
Oríṣun àwòrán, AFP
Ko ni si aworan awọn oludije fun ọdun mẹriin miiran
4. Isunsiwaju idibo ṣe ijamba fun  alatilẹyin awọn oludije mejeeji to lewaju
Bi ajọ INEC ṣe sun idibo si iwaju pẹlu ọsẹ kan mu inu bi ọpọ ọmọ Naijiria  eyi to ṣe okunfa ki awọn kan ma fẹ rin irinajo lẹẹmeji lati le wa dibo.
Awọn oludije mejeeji ni ọrọ yii ṣakoba fun.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ajọ Inec ni ipolongo ọjọ idibo saaju ọdun naa yoo mu idagbasoke ba eto oselu lorilẹede Naijria
5. Idibo pẹlu ẹrọ igbalode lo dara ju.
Awọn onwoye kan sọ pe, ẹrọ igbalode ko ni jẹ ki awọn kan ṣe aṣiṣe to pọ, ko si ni jẹ ki awọn kan le yi ibo.
Bo tilẹ jẹ pe ẹrọ ti wọn fi n yẹ orukọ wo ṣe ṣegeṣege ni awọn ibi kan, ẹrọ igbalode lo le fi ifẹ awọn eniyan han, ti yoo si foju magomago han.
Eze Ndigbo Alex Anozie: Irọ́ ni pé àwọn ọlọ́jà gbọ́dọ̀ dìbò fún APC
Oríṣun àwòrán, WIKIPEDIA
Ìròyìn kan ní ẹgbẹ́ òsèlú APC fipá mú àwọn ọlọ́jà tó wá láti ẹ̀yà Igbo láti ri pé wọ́n dìbò yan gomina lábẹ́ ẹgbẹ́ òsèlú APC.
Adari awọn ẹya Igbo to wa ni ipinlẹ Oyo ti sọ wi pe irọ patapata ni pe ẹgbẹ oselu APC fipa mu wọn lati dibo wọn fun ẹgbẹ naa ninu idibo sipo gomina to n bọ.
Iroyin to jade ninu iwe iroyin kan lorilẹede Naijiria fi lede wipe awọn ọlọja to jẹ ẹya Igbo ni Iwo ni wọn ko jẹ ki wọn taja wọn, ti ọpọlọpọ ile itaja wọn si wa ni titi.
Àwọn obìnrin Eko ní àwọ́n kò ṣàṣedànù lórí Sai baba
Iroyin naa fi lede wi pe obinrin ọlọja ti ko fẹ ki wọn darukọ rẹ lo ni wọn fun wọn ni gbẹndeke pe ẹni ti ko ba dibo fun oludije sipo gomina labẹ ẹgbẹ oselu APC, wọn ko ni si ile itaja rẹ.
Oríṣun àwòrán, Wikipedia
Eze Ndigbo Alex Anozie to jẹ adari awọn Igbo naa lasiko to n ba BBC Yoruba sọrọ ni irọ ni ẹsun naa, ati wi pe ohun yoo gb si ti iru isẹlẹ bẹẹ ba waye.
'Mi ò ní Bàbá ìsàlẹ̀ ṣùgbọ́n mo ní Bàbá òkè' - Adedoyin
O fikun wi pe ohun tun ti beere daradara lọwọ awọn adari to wa ni ilu Ibadan, ti wọn si sọ wi pe ko si ohun to jọ bii isẹlẹ naa.
Gbogbo igbiyanju lati kan si ile isẹ ọlọpaa lati fi idi ọrọ naa mulẹ ni o jasi pabo.
#Otogelagos: Ilé iṣẹ́ ọlọ́pàá Eko ní àwọn alátakò Tinubu ṣẹ̀ṣẹ̀ pe ọlọ́pàá nígbà tọ́rọ̀ gbẹ̀yìn yọ ni
Oríṣun àwòrán, Tinubu/Facebook, Chike Oti/Facebook
Agbẹnusọ ọlọpaa ipinlẹ Eko ati Aṣiwaju Tinubu
Ayalo ọrọ ni #Otogelagos, eyi to ti gbalẹ kan lori ẹrọ ayelujara laarin ọjọ perete bayii.
"Iwadii fi han pe ni ipinlẹ Kwara gangan ni adape ọrọ ""O to gẹ"" ti bẹrẹ to si wọpọ eleyii ti wọn fi n ṣapejuwe igbesẹ ti awọn ara ipinlẹ Kwara gbe lati dibo yọ Sẹnetọ Bukola Saraki kuro gẹgẹ bi aṣoju ẹkun aarin gbungbun ipinlẹ naa nile aṣofin."
Ẹwẹ, kete ti Ibrahim Oloriegbe yẹ aga nidi Sẹnetọ Saraki ti wọn si gbagbọ pe amulo ọrọ yii wulo gan ninu igbesẹ wọn, ọrọ naa pẹlu afikun orukọ ipinlẹ Eko eyi to di #Otogelagos bẹrẹ si ni gbilẹ sii lori ayelujara Twitter niOkay Eko.
Koda, awọn ipade ati iwọde kan waye ni ilu Eko ti ọpọlọpọ eeyan ti n lọdi rẹ mọ adape ọrọ yii to ti gbẹnu awọn kan ni ipinlẹ Eko.
"Fun apẹrẹ, iroyin kan jade laipẹ pe Àwọn ọlọ́pàá dá ìpàdé àwọn alátakò Tinubu dúró l'Eko. Bẹẹ si ni ninu awọn iwe iroyin to gbe e jade, wọn ni ẹgbẹ Orange Movement to ṣe ipade naa ṣe e pẹlu akori ""Titu Eko silẹ ninu igbekun Bourdillon"" eleyii ni wọn fi n salaye pe o ti togẹ lEko."
Ẹwẹ, nigba ti BBC Yoruba kan si agbẹnusọ ile iṣẹ ọlọpaa ipinlẹ Eko Chike Otti, o jẹ ko di mimọ pe awọn to ṣe agbekalẹ ipade naa gan lo jẹbi tori wọn ko fi to ile iṣẹ ọlọpaa leti.
O ni pataki fifi to ọlọpaa leti naa ni ohun to pada ṣẹlẹ nibi ipade ọhun nitori iru ipade bayii ṣeeṣe ki awọn kan fẹ daa ru.
Àwọn obìnrin Eko ní àwọ́n kò ṣàṣedànù lórí Sai baba
Ọgbẹni Chike ṣalaye lẹkunrẹrẹ wi pe, ẹgbẹ yii ti baba bẹrẹ ipade wọn ki a to gbọ pe idarudapọ n waye nibẹ. Awn gan ni wọn kan si ọlpaa ti a si lọ ran wọn lọwọ.
"O ni ""kii ṣe ọlọpaa lo da ipade wọn ru, ọlọpaa gan lo lọ ba wọn pẹtu saawọ to n ṣẹlẹ nigba ti a gba ipe latọdọ awọn to gbe ipade kalẹ pe o ti n daru""."
Nigba ti akọroyin BBC bere pe ṣe o daju pe ẹgbẹ Orange Movement pẹlu awọn oloṣelu nla to jẹ adari rẹ ko ṣe eto abo kankan, Otti ni bi wọn ba ṣe e, yoo de ọdọ ohun gẹgẹ bi ipo ti oun di mu.
"Amọ ṣa akọroyin ni ṣe o le fi aridaju han ninu iwadii awọn ọlọpaa boya igbesẹ ẹgbẹ ni nkankan ṣe pẹlu #Otogelagos, loju ẹsẹ ni alukoro ọlọpaa fesi pe ""mo fi tọwọ tọwọ ni ki a da ipe yii duro. Mi o kii n ṣe oloṣelu nitori naa, mi o si lero lati di ọkan"""
'Mẹ̀kúnù á rí iṣẹ́ tí mo bá di gómìnà Eko' - Adesanya, PPC Eko
Election Update 2019: ‘Ìgbìmọ̀ amúsẹ́yá APC pàṣẹ lọ rọọ́kún nílé fún Amosun, Okorocha
Oríṣun àwòrán, Facebook/Senator Ibikunle Amosun/Governor Rochas O
Awọn Gomina mejeeji ni ẹnu ko sin lara wọn nipa iwa ti o tako ti ẹgbẹ APC ti wọn hu
Iroyin to n tẹwa lọwọ ni pe ẹgbẹ oṣelu APC ti paṣẹ lọ rọọkun nile fun awọn Gomina Ibikunle Amosun ti ipinlẹ Ogun ati Rochas Okorocha ipinlẹ Imo.
Igbimọ amuṣẹya ẹgbẹ naa lo daba yii lẹyin ipade wọn ti o waye nilu Abuja.
Lanre Issa Onilu to jẹ akọwe ipolongo ẹgbẹ naa ni lootọ ni ẹgbẹ gbe igbesẹ ọhun amọ awọn ṣi n ṣiṣẹ lori atẹjade lori ọrọ naa.
Igbesẹ ẹgbẹ yi tako ohun ti wọn ti sọ saaju nipa awọn Gomina wọn yi  wi pe awọn ko ni ijiya kankan lati fi jẹ wọn lori awọn iwuwasi wọn to jọ bi ẹni tako aṣẹ ẹgbẹ.
Election Update 2019: Inec kéde ọ́jọ́ kẹsàn oṣù kẹ̀ta fún àfikún ìdìbò ààrẹ
Oríṣun àwòrán, InEC
Afikun idibo
Ajọ eleto idibo lorilẹede Naijiria ti afikun idibo aarẹ yoo waye lọjọ Abamẹta ọsẹ to n bọ tii ṣe ọjẹ kẹsan oṣu kẹta.
Afikun idibo aarẹ yoo waye lọjọ kan naa pẹlu idibo gomina ati tile aṣofin ipinlẹ.
Ọga ajọ INec to n ri si ọrọ iroyin ati ilanilọyẹ awọn oludibo, Festus Okoye salayẹ pe idibo aarẹ naa yoo waye nibi gbogbo ti ajọ Inec ti wọgile ibo aarẹ lọjọ Satide to kọ ja.
Ohun márùn-ún tí Atiku ń bèrè lọ́wọ́ Buhari níbi ìpàdé rẹ̀ pẹlú Abdulsalam, Kukah
#Otogelagos: 'Ọlọ́pàá kọ́ ló da ìpàdé àwọn alátakò Tinubu rú'
Amẹ́ríkà náà kí ààrẹ Buhari kú oríire
O fikun ọrọ rẹ pe igbesẹ naa waye nibi ipade awọn ọga Inec ti ipinlẹ kọọkan l'Abuja.
Ajọ Inec ko le ran awọn oṣisẹ rẹ lọ si awọn ibudo idibo kan nitori rukerudo to bẹ silẹ lawọn agbegbe ọhun.
Ìpàdé ẹgbẹ́ alátakò: Makinde,Lanlehin kò tíì sọ ìgbésẹ̀ tí ọrọ kàn
Ohun ti Seyi Makinde sọ lẹyin ipade awọn ẹgbẹ alatako
Ipade laarin awọn ẹgbẹ oṣelu alatako niluu Ibadan lori bi wọn yoo ṣe darapọ jẹ ọkan lati koju ẹgbẹ oṣelu APC ninu idibo gomina ọsẹ to n bọ ko tii fẹnu ko sibi kan.
Ipade naa to waye ni Bodija nile gomina ipinlẹ Oyo tẹlẹ ri Rashidi Ladoja ti wa sopin fun ti ọjọ Ẹti ṣugbọn yoo tẹsiwaju lọjọ Abamẹta.
Agba n ba agba ṣe ipade lori ọrọ ipinlẹ Oyo
Oludije fun ipo gomina fẹgbẹ ADP Adebayo Alao Akala ko ti sọ igbesẹ rẹ titi di asiko yii
Sẹnẹtọ Olufemi Lanlẹhin ti ẹgbẹ ADC pẹlu Seyi Makinde naa wa nibi ipade ọhun.
Oludije fẹgbẹ SDP Bolaji Ayorinde, Sharafedeen Alli ti ẹgbẹ ZLP naa wa nibi ipade naa.
Ipade oṣelu ni Ibadan
Akala ti kọkọ ṣepade pẹlu eekan ninu ẹgbẹ APC Bola Tinubu l'Ọjọru lori idibo gomina osẹ to n bọ yii naa.
Nigeria Election 2019: Akala padà sí APC fún ìbò gómìnà Oyo
Oríṣun àwòrán, APC
Eto idibo gomina ipinlẹ Oyo
Oludije fu ipo gomina labẹ asia ẹgbẹ oṣelu ADP Otunba Christopher Adebayo Alao-Akala ti kede pe oun ti darapọ mọ Adebayo Adekola Adelabu to jẹ oludije fẹgbẹ APC fun ibo gomina ọjọ Abamẹta ọsẹ to n bọ.
Ṣugbọn Akala ṣalaye pe oun yoo ṣatilẹyin fawọn oludije fun ile igbimọ aṣofin ipinlẹ Oyo labẹ asia ẹgbẹ ADP.
Akala ni otitọ l'oun ṣepade pẹlu awọn ẹgbẹ alatako bi PDP, ADC ati ZLP, wi pe Gomina Ipinlẹ Oyo tẹlẹ ri Rashidi Ladoja lo ṣagbatẹru ipade ọhun.
Gomina ipinlẹ Oyo tẹlẹ Akala nigba ti ipade oun pẹlu ẹgbẹ awọn alatako n lọ lọwọ ni oun gba ipe lati ile iṣẹ aarẹ.
O ni nibi ipade oun pẹlu ile iṣẹ aarẹ l'oun ti gba lati ṣiṣẹ pẹlu ẹgbẹ osẹlu APC nipinlẹ Oyo.
Akala Ladoja sọ fun oun nibi ipade naa pe oun ko le lanfani lati dije fun ipo gomina nitori oun kii ṣe ọmọ Ibadan.
O ni idi eleyi lo mu oun gba lati ṣiṣẹ pelẹ ẹgbẹ APC ni ipinlẹ Oyo.
NBC ní kí àwọn ilésẹ to tẹ ofin lóju san #500,000
Oríṣun àwòrán, NBC
2019 Elections: NBC na ilí iṣẹ́ ìròyìn 45 ní pàsán
Ile ise iroyin marundinlaadota ni ajọ NBC ni ko sanwo ìtanran fún àwọn aṣe máse tó wáye lásiko ìdìbò gbogboogbo tó wáye lọ́jọ́ kẹtalélógún oṣu tó kọja.
Awọn ile iṣẹ iroyin tí igbá ọ̀rọ̀ náà kan náà ṣí mọ lóri ni Channels, TVC, NTA, AIT, Vision Fm, Arewa radio, Radio Lagos àti àwọn míràn.
Oríṣun àwòrán, Nbc
2019 Elections: NBC na ilí iṣẹ́ ìròyìn 45 ní pàsán
Oríṣun àwòrán, Nbc
NBC ní kí àwọn ilésẹ ti tẹ ofin lóju san #500,000
Gẹgẹ bi olorí àjọ náà Mallam Modibo Kawu ni gbogbo àwọn ile iṣẹ́ yìí ni yóò fi ẹgbẹrun lọ́nà ẹ̀ẹ́dẹ́gbẹ̀ta naira jura.
Yinka Ajia: ìbẹ̀rù Ọlọrun ni mo fẹ́ fi tukọ̀ Kwara ti mo ba wọlé
O ni ọ̀pọ̀lọpọ̀ àwọn ilanilọyẹ ni àjọ oun ti ṣe láti ri dáju pẹ ẹnikẹni ò tẹ ojú òfin mọ́lẹ̀, sùgbọn o ṣe ni láànú pé gbogbo rẹ̀ pàbó ló jási lásiko ìdìbọ ààrẹ tó wáye ní ọjọ kẹtàlélogun osu kéji.
O ní ẹsẹ ti àwọn ile iṣẹ yii sẹ jẹ oríṣiriṣi, sùgbọn kò kéré sí àwọn ilé ìròyìn tó wọn jẹ ki wọn fi ilé iṣẹ́ wọn tẹ́ pẹpẹ èèbu àti sisọ àwọn ọ̀rọ̀ alufansa.
O fi kún pé àwọn ile iṣẹ́ Radio mi fààyè gba  ọ̀rọ̀ ìbàjẹ́ àti àwọn ọ̀rọ̀ tó lé dá rògbòdiyàn sílẹ̀ láwùjọ.
2019 Election: Àwọn oloṣelu tó yege àti àwọn to fidirẹmi
Oríṣun àwòrán, AFP
Àwọn to n dáwọ́ọ̀ ìdùnu fun wiwọle ààrẹ Buhari
Ǹnkan tó báni lójiji jùlọ ni tí ìjákulẹ̀ ọ̀pọ̀ àwọn baba ìsàlẹ̀ alágbára ti wọn ń fi owo wọn àti agbára láti yan ẹni to ba wù wọn sípò lásìkò ìdìbò. Awọn míràn tó tún yapa kúrò nínú ẹgbẹ́ tó wà lórí àléfà sáájú ìdìbò náà tún fìdírẹ̀mi.
Ọ̀pọ̀ àwọn oléṣèlú nla tó fidirẹmi àti àwọn to yege níbi ìdìbò tó wáye lọ́jọ́ kẹtàlélógun osu keji ọdun, 2019
Awọn to fidirẹmi
Bukola Saraki - Ile Igbimọ Aṣofin Àgbà
2019 Election: Àwọn oloṣelu tó yege àti àwọn to fidirẹmi
Dídojú ẹni to jẹ ẹni kẹta ninu ọmọ orílẹ̀-èdè Nàìjíríà nínú òṣèlú jẹ ohun to runi nínú púpọ̀. Ẹni ọdún mẹ́rìndínlọ́gọ́ta  tó jẹ àọàrẹ ile ìgbìmọ̀ aṣofin sùgbọ́n òun tún ni alága ìgbìmọ̀ ẹgbẹ́ òṣèlú Peopl's Democractic Party (PDP).
Yinka Ajia: ìbẹ̀rù Ọlọrun ni mo fẹ́ fi tukọ̀ Kwara ti mo ba wọlé
O hàn gbangba-gbàngbà pé ǹkan  ò lọ dédé láàrin ààrẹ Muhammadu Buhari àti Bukola Saraki  nítori ààrẹ gbé ìwádìí dìde síì nítori ẹsún ìwà ajẹbánu. Sùgbọ́n ilé ẹjọ to ga jùlọ dájọ pé ó yege nínú gbogbo ẹ̀sùn ti wọn fi kàn-án nínú osù keje tó si lọ si inu ẹgbk òṣèlú PDP ní oṣù to tèlé.
O gbìyànju láti pada síle igbimọ asofin agba gẹ́gẹ́ bíi àsoju gbungbun ìpínlẹ̀ Kwara sùgbọ́n olùdíje lábẹ APC.
Dokita Ibrahim Oloriegbẹ yẹ aga mọ nídìí, èyí sì ló fi òpin si ìjẹgaba idile Saraki to tí ń fọba jẹ láti bíì ààdọta ọdún sẹ́yìn.
"O hàn gbangba -gbangba pé ìfọba jẹ Saraki ti ṣú ọ̀pọ̀ àwọn ọmọ ìpínlẹ̀ Kwara nítori wọn ń rẹ̀yìn ninu ìdagbasoke àti gbogbo àwọn ohun amuludun, èyí sì ló mú ki àwọn eniyan bẹ̀rẹ̀ ariwo ""O TO GẸ'' ti wọn si rẹ́yìn ìjọba rẹ̀."
Godswill Akpabio- Omo ile igbimọ Aṣofin tí ń soju Akwa Ibom North-West
Oríṣun àwòrán, Akpabio
2019 Election: Àwọn oloṣelu tó yege àti àwọn to fidirẹmi
Bábá ìsàlẹ kan náà ni èyí ní ìpínlẹ̀ Akwa Ibom ní bi to ti jẹ gomina léèmeji, sùgbọ́n lọtẹ̀ ojúgbà rẹ nínú ẹgbẹ́ òsèlú PDP Chris Ekpenyong ló gbàá mọ lọ́wọ́.
Akpabio ti oun náà jẹ ọmọ ọdún mẹ́rìndínlọ́gọ́ta kúrò nínu ẹgbk oselu PDP lọ APC sùgbọ́n àwọn èniyan fi ìbò wọn wu nidi lóri oye.
Rabiu Musa Kwankwaso- Baba Isale Ipinlẹ Kano
Kwankwaso ni baba isale ipinlẹ Kano
Sẹnatọ tó wà nile asofin, tó tun jẹ Gomina léèmeji ní ìpinle Kan, Rabiu Musa Kwankwaso kò wá ipo kànkan mọ sùgbọn gbogbo àwọn oloṣelu tó  ńṣe baba isalẹ fun pátá lo fìdírẹmi.
Ẹni ọmọ ọdun mejilélọ́gọ́ta kúrò nínú ẹgbẹ́ òṣèlú APC lọ si PDP lẹ́yìn ti ìjà bẹ́ sílẹ̀ láàrin oun àti ẹni to gba ipo gomìnà lọ́wọ́ rẹ̀ gómìnà Umar Ganduje.
Sheun Sani-Sẹnatọ Aarin Gbungbun Kaduna
Oríṣun àwòrán, Sheu Sanni
Ìtúnyànsípò ààrẹ Muhammadu Buhari gẹ́gẹ́ bíi ààrẹ Nàijíríà kò bá ọ̀pọ̀ àwọn ènìyàn ni òjijì, sùgbọ̀n ǹkan ìrunnu pọ̀ nínú ìdìbò tí àwọn ọmọ ilé ìgbìmọ̀ aṣòfin.
Sheu Sanni tó  jẹ́ ọ̀kan lára àwọn alátakò ìṣèjọba ààrẹ Muhammadu Buhari náà fìdí rẹmi nínú ìdìbò to kọja. Ẹni ọmọ ọdun mọ́kànléláàdọ́ta yìí le máà ṣe àjoji si àwọn ènìyàn nítori ìhà ti òun àti gomina ipinlẹ Kaduna El-Rufai bótilẹ jẹ́ pé inu ẹgbẹ́ kan náà ni wọn jọ wà.
Awọn to Jawe olubori
Dino Melaye - Sẹnatọ Kogi West
Oríṣun àwòrán, Dino Melaye
2019 Election: Àwọn oloṣelu tó yege àti àwọn to fidirẹmi
Ṣẹnatọ Dino Melaye tí ẹnu kìí sì lára rẹ̀ bóri ohun gbogbo láti jáwé olúbori, gẹgẹ bii orukọ rẹ Singing Senator, oníruúru ìdojúkọ nínú òṣèlú pẹ̀lú ìjọba.
#BBCNigeria2019: Ètò tí mo ní fún Kwara yàtọ̀ sí ti ẹgbẹ́ ANRP ni mo ṣe fẹgbẹ́ wọ́n sílẹ̀
O pada han si mi pe ibi ti emi n lọ ati itẹsiwaju ti mo n wa fun ipinlẹ Kwara yatọ si ti awọn adari ẹgbẹ oṣelu naa.
Oludije fun ipo gomina ipinlẹ Kwara ninu ẹgbẹ oṣelu Abundant Nigeria Renewal Party, Yinka Ajia ti fi ẹgbẹ oṣelu naa silẹ.
Ninu ikede kan to fi si oju opo Facebook rẹ, Ajia sọ pe bo tilẹ jẹ pe oun ko dije fun ipo gomina mọ, oun yoo ṣatilẹyin fun oludije fun ipo gomina ninu ẹgbẹ APC, Abdulraman Abdulrazak ninu eto idibo naa.
Yinka Ajia: ìbẹ̀rù Ọlọrun ni mo fẹ́ fi tukọ̀ Kwara ti mo ba wọlé
Lori idi to fi fi ẹgbẹ oṣelu ANRP silẹ ni ọjọ diẹ si idibo gomina, Ajia sọ fun BBC Yoruba pe oun fi ẹgbẹ ANRP silẹ nitori pe afojusun ati erongba ti oun ni fun awọn eniyan ipinlẹ Kwara yatọ si ti awọn olori ẹgbẹ oṣelu naa.
"Kiiṣe pe mo darapọ mọ ẹgbẹ oṣelu APC, mo ri pe Abdulraman Abdulrazak ni awọn eniyan Kwara n fẹ, ni mo ṣe fẹ ẹ ṣatilẹyin fun un.
Ẹwẹ, o ni ireti oun ni pe awọn yoo jọ fi imọ kun imọ lori ipinnu awọn fun ipinlẹ Kwara lati mọ ibi ti oun ti le ran ijọba rẹ lọwọ.
O pada han si mi pe ibi ti emi n lọ ati itẹsiwaju ti mo n wa fun ipinlẹ Kwara yatọ si ti awọn adari ẹgbẹ oṣelu naa."
Emi o si fẹ ẹ jẹ alatako fun ipinlẹ Kwara nitori awọn eniyan mi jẹmi logun ju ẹgbẹ oṣelu kankan lọ.
"Eyi lo mu ki n kọkọ kọwe fi ẹgbẹ naa silẹ ki n to bẹrẹ atilẹyin fun Abdulraman Abdurazak  ti awọn ara ilu n fẹ."""
#NigeriaDecides: BBC ti wa ni gbogbo ìpínlẹ̀ Naijiria láti firoyin gbogbo tóo yin létí
Olamiju Akala: Ẹgbẹ́ APC dá ọmọ Alao Akala padà sípò alága Ogbomọṣọ North
Oríṣun àwòrán, Adebayo Alao-Akala
Ọlamiju sọ pe 'wọn sọ pe awọn da oun pada lẹyin ti iwadi awọn fihan pe oun ko ṣẹ.'
Ẹgbẹ oṣelu All Progressives Congress, APC ti da Olamiju Akala pada si ipo rẹ gẹgẹ bi alaga ijọba ibilẹ Ogbomọṣọ North.
Eyi waye lẹyin wakati diẹ ti baba rẹ, to jẹ oludije fun ipo gomina ipinlẹ Ọyọ ninu ẹgbẹ oṣelu Action Democratic Party, ADP, wọgile erongba rẹ, to si ni oun yoo ṣatilẹyin fun oludije ẹgbẹ oṣelu APC, Adebayọ Adelabu.
Botilẹjẹ wi pe Ọlamiju sọ pe dida ti wọn da oun pada ko ni nkankan ṣe pẹlu igbesẹ ti baba oun gbe.
Ọlamiju sọ pe 'wọn sọ pe awọn da oun pada lẹyin ti iwadi awọn fihan pe oun ko ṣẹ.'
#BBC Nigeria Decides: Akala darapọ̀ mọ́ APC fún ìbò gómìnà
Akala: Kọmísánà kò láṣẹ láti búra fún igbákejì mi bíi alága ìbílẹ̀
Ọjọ Abamẹta ni wọn da a pada si ipo rẹ gẹgẹ bi alaga, ti yoo si bẹrẹ iṣẹ pada lọjọ Aje, ọjọ kẹrin, oṣu Kẹta 2019.
Ọjọ diẹ lẹyin ti Ọlamiju ṣatilẹyin gbangba fun baba rẹ to n dupo gomina ni wọn yọ nipo, ti wọn si bura fun igbakeji rẹ gẹgẹ bi alaga tuntun.
O ṣalaye ninu ifọrọwanilẹnuwo to ṣe pẹlu BBC Yoruba pe wọn yọ oun kuro nipo nitori pe oun kuro lẹgbẹ APC lọ ọ darapọ mọ ẹgbẹ ADP lati ṣatilẹyin fun baba oun.
O si leri lati gbe ijọba ipinlẹ Ọyọ lọ sile ẹjọ.
Nigeria Election 2019: PDP àti SDP ìpínlẹ̀ Ọyọ fa Seyi Makinde sílẹ̀ ní olùdíje nigba ti ADC àti ZLP n ṣe ipinnu lọwọ
PDP, SDP, ZLP ati ADC fa Seyi Makinde kalẹ̀
Apapọ ẹgbẹ oṣelu Social Democratic Party ati Peoples Democratic Party ti fa oludije kan ṣoṣo silẹ lati ṣoju wọn ninu idibo gomina ipinlẹ Ọyọ.
Seyi Makinde n ri atilẹyin ẹgbẹ mii, idibo Oyo n dùn síi
Eyi waye nibi ipade kan ti awọn oludije fun ipo gomina ninu ẹgbẹ oṣelu mẹtẹẹta, ati awọn agbaagba ẹgbẹ ṣe nile gomina ipinlẹ Ọyọ nigba kan, Oloye Rashidi Ladọja nilu Ibadan lọjọ Abamẹta.
Awọn oludije ti iroyin ni wọn ṣi n ronu lori ipinnu wọn lọwọ ni lati fa Makinde tabi bẹẹ kọ.
Yinka Ajia: ìbẹ̀rù Ọlọrun ni mo fẹ́ fi tukọ̀ Kwara ti mo ba wọlé
Ṣaaju ni iru ipade bẹ ti waye ninu ẹgbẹ All Progressives Congress, APC pẹlu ADP nipinlẹ Oyo.
Nibi ti Alao Akala si wọgile erongba rẹ lati dije fun ipo gomina ninu eto idibo ti yoo waye lọjọ kẹsan an, oṣu Kẹta, to si sọ pe oludije ẹgbẹ APC, Adebayọ Adelabu l'oun yoo ṣe atilẹyin fun.
Ọpọ àwọn eniyan ipinlẹ Ọyọ lo n wo ohun ti gbogbo ifọwọsowọpọ yii ṣeeṣe ko bi fun idibo gomina nipinlẹ Ọyọ to m bọ lọna.
#NigeriaDecides: BBC ti wa ni gbogbo ìpínlẹ̀ Naijiria láti firoyin gbogbo tóo yin létí
2019 Elections: Sowore ní pàṣán ni Buhari yóò fi bá Nàìjíríà ṣe ní sáà kejì
Oríṣun àwòrán, Omoyele sowore
Sowore ni omi n bẹ laamu fun idagbasoke eto idibo lorilẹede Naijiria
Oludije fun ipo aarẹ to kọja labẹ oṣelu AAC lorilẹ-ede Naijiria, Ọmọyẹle Ṣoworẹ ti sọ pe oun ko lee pe aarẹ Buhari lati kii ku oriire.
O ni nitori pe ko si idaniloju fun oun pe lootọ ni aarẹ Buhari bori lọna to tọ lasiko idibo naa.
Ṣoworẹ ṣalaye ọrọ yii lasiko to fi n ba BBC News Yoruba sorọ lori ikanni ayelujara facebook.
Ọmọyẹle Ṣoworẹ ni afi bi oun yoo ba pa irọ tan ara oun atawọn to n tẹle oun lẹyin ni oun yoo fi sọ pe lootọ ni Buhari bori lọna to tọ.
Issa Aremu: ṣàlàyé kíkún nípa èròńgbà ẹgbẹ́ Labour to bá jáde
Oludije ẹgbẹ oṣelu AAC nibi idibo sipo aarẹ naa tun ṣalaye siwaju sii pe ijọba paṣan ni ijọba Buhari ni saa keji rẹ yii yoo jẹ fun awọn ọmọ orilẹede Naijiria.
Ọmọyẹle Ṣoworẹ ni lara awọn ohun to kọ oun lominu nipa eto idibo sipo aarẹ lorilẹ-ede Naijiria ni iha kokan mi ti awọn oludije kọ si idibo naa.
Yinka Ajia: ìbẹ̀rù Ọlọrun ni mo fẹ́ fi tukọ̀ Kwara ti mo ba wọlé
Gẹgẹ bi o ṣe sọ, o ni iye awọn eeyan to jade fun eto idibo apapọ to kọja lo fẹẹ kere julọ lati igba ti orilẹede Naijiria ti pada sinu eto iṣejọba tiwantiwa lọdun 2019.
O ni aṣẹ ti aarẹ pa pe ki wọn gbẹmi lẹnu ẹnikẹni to ba ji apoti ibo gbe ati bi awọn ologun ṣe pọ biba lasiko idibo naa kun ara ohun to fa bi awọn eeyan ṣe dẹyẹ si eto idibo naa.
Oríṣun àwòrán, omoyele sowore
Ṣòwòrẹ́ tó jẹ́ olùdíje AAC ní ìdí tí òun kò fi leè kí ààrẹ Buhari kú oríire ni pé ọ̀na èrú ló fi wọlé
Oludije fun ipo aarẹ labẹ aṣia ẹgbẹ oṣelu AAC naa ni omi ṣi n bẹ lamu fun eto idibo lorilẹ-ede Naijiria.
O ni gbigba kaadi idibo alalopẹ ṣaaju idibo naa ku diẹ kaato ati pe ajọ eleto idibo INEC ko sa ipa to to lati rii pe awọn eeyan gba kaadi naa bi o ti tọ ati bi o ti yẹ.
Nigba ti o wa n sọrọ lori ọna abayọ fun eto idibo to dan mọran lorilẹ-ede Naijiria, Ṣoworẹ ni gbigba ilana idibo igbalode, (electronic voting) laaye yoo ṣe ọpọ anfani fun ilọsiwaju eto idibo ati iṣejọba awarawa lorilẹede Naijiria.
Ohun to kun fun Naijiria lati ṣe ni ilana idibo igbalode (electronic voting) ki awọn eeyan lee wa ninu ile wọn ki wọn si dibo lai si inira. Inira pọ pupọ ju fun eto idibo o wa mu ki idibo naa maa fa bi igbin.
O ni ara awọn ohun rere to farahan lasiko eto idibo apapọ naa ni omilẹgbẹ awọn ọdọ to jade dije ti wọn si gbiyanju kọja bi awọn eeyan ati onwoye ṣe lero ṣaaju idibo naa lọ.
O rọ aarẹ Buhari lati tete yan awọn minisita ti yoo baa ṣiṣẹ, idagbasoke ọrọ aje, ipese iṣẹ ati ọrọ ajelẹgbẹ oṣelu
#NigeriaDecides: BBC ti wa ni gbogbo ìpínlẹ̀ Naijiria láti firoyin gbogbo tóo yin létí
Nítorí ìwọ́de, Amosun àti ẹgbẹ́ òṣìṣẹ́ NLC tutọ́ síra wọn lójú nípínlẹ̀ Ògùn
Oríṣun àwòrán, Amosun ibikunle
NLC fẹ́ ṣe ìwọ́de nítorí àìsan owó òṣìṣẹ́, ṣùgbọ́n gómìnà Amosun ní kò sóhun tó jọọ́
Ẹgbẹ oṣiṣẹ NLC ati Gomina ipinlẹ Ogun, Ibikunle Amosun ṣi wa lẹnu ileri 'bi ikun lo loko, bi pakute ni'.
Ọrọ lori iwọde tawọn ẹgbẹ oṣiṣẹ n gbero lati ṣe ni ọjọ Iṣẹgun, ọjọ karun un,  oṣu kẹta, ọdun 2019 ni ilu Abẹokuta.
Awọn oṣiṣẹ nipinlẹ Ogun pẹlu atilẹyin awọn alaṣẹ apapọ ẹgbẹ naa lorilẹ-ede Naijiria n leri ati gunle iwọde nitori owo oṣu oṣiṣẹ ati oṣiṣẹfẹyinti nipinlẹ naa eyi ti wọn ni o ti wọ ọdun mẹjọ bayii.
Issa Aremu: ṣàlàyé kíkún nípa èròńgbà ẹgbẹ́ Labour to bá jáde
Amọṣa, gomina Ibikunle Amosun ti fesi ṣaaju pe oun yoo yẹyẹ awọn ẹgbẹ oṣiṣẹ to ba gbiyanju tabi san aṣọ bẹẹ ṣoro ni ipinlẹ naa.
Nibayii, aarẹ ẹgbẹ oṣiṣẹ NLC lorilẹ-ede Naijiria, Ayuba Wabba ati igbimọ iṣakoso apapọ ẹgbẹ oṣiṣẹ lorilẹ-ede Naijiria ti ranṣẹ pada si gomina Amosun pe awọn ti gbọ ohun to sọ o, ṣugbọn apo ara rẹ lo sọ ọ si.
Yinka Ajia: ìbẹ̀rù Ọlọrun ni mo fẹ́ fi tukọ̀ Kwara ti mo ba wọlé
A fẹ fi da aloju pe ihalẹ rẹ ko lee tu irun kan lara erongba wa lati dide daabo bo awọn oṣiṣẹ ni ipinlẹ Ogun ti wọn n tẹ ẹtọ wọn mọlẹ baṣubaṣu.
Awọn ohun to kan wa ju ni aisan awọn owo ti wọn yọ ninu owo oṣu awọn oṣiṣẹ fun ifẹyinti, alajẹṣẹku, ọdun ileya, keresi ati bẹẹbẹẹlọ fun oṣu marunlelọgọrun lai san an pada fawọn oṣiṣẹ.
#NigeriaDecides: BBC ti wa ni gbogbo ìpínlẹ̀ Naijiria láti firoyin gbogbo tóo yin létí
Kamaru Usman: Ọmọ Áfíríkà àkọ́kọ́ tó gba ìgbànú ẹ̀yẹ ẹ̀ṣẹ́ kíkàn UFC
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Kamaru Usman borí Tyron Woodle ní ìpele Welterweight.
Kamaru Usman ti orukọ inagijẹ rẹ n jẹ Nigerian Nightmare ti di ọmọ ilẹ Afirika akọkọ ti yoo gba igbanu ẹyẹ fun ẹṣẹ kikan ti idije Ultimate Fighting Championship.
Usman din dundun iya fun Tyron Woodley lati di ọmọ Afirika akọkọ ti yoo bori ni idije naa.
Sekinat Quadri ọmọ ọdun meje ajẹsẹ to fẹ dabi Anthony Joshua
Eyi si tun mu ko di ọmọ orilẹ-ede Naijiria akọkọ ti yoo gba igbanu ẹyẹ Welterweight.
Idajọ awọn adajọ idije ẹṣẹ kikan naa to fi ni ami 50-44, 50-44 ati 50-45 lo fi bori.
Issa Aremu: ṣàlàyé kíkún nípa èròńgbà ẹgbẹ́ Labour to bá jáde
Nibayii, ọkan-o-jọkan ọrọ si ni awọn eeyan ti n sọ lori ikanni ayelujara lori rẹ bayii.
#NigeriaDecides: BBC ti wa ni gbogbo ìpínlẹ̀ Naijiria láti firoyin gbogbo tóo yin létí
Ó tó gẹ́ ní àṣà ìpolongo tó fakọyọ lásìkò ìbò 2019
Oríṣun àwòrán, @RealAARahman
Oofisi lo n rẹyin akọwe ni igbagbọ ọpọ eniyan
Lagbo oṣelu,ti awọn oloṣelu ba fẹ ṣe koriya fun awọn alatilẹyin wọn, wọn a máa fun wọn ni awọn ọrọ akọmọna eleyi ti yoo ma da wọn laraya.
Eyi ti yoo si maa fi rinlẹ lọkan wọn pe ki wọn dibo fun ẹgbẹ oṣelu tiwọn.
Lasiko idibo gbogboogbo Naijiria eleyi ti o ku abala keji yi, awọn ọrọ akọmọna kan dagboro ru ti wọn si ko ipa ribi ribi ninu oṣelu lawọn ipinlẹ kan.
Ni meni meji, a o ma gbe awọn ọrọ wọn yi wo ati iru ipa ti wọn ko lasiko idibo aarẹ to kọja.
Ó tó gẹ́!
Nilu Ilorin ni aṣa yi ti bẹrẹ ti o si ṣe atọkun bi ifidirẹmi gbajugbaja oloṣelu ọmọ ilu naa, Bukola Saraki ati ẹgbẹ PDP ti ṣe waye.
Akọmọna Ó to gẹẹ gaan ni akawe kan gbogi to ṣe apejuwe bi ọrọ akọmọna ti ṣe lagbara lati ṣe iwuri fun awọn oludibo.
Oríṣun àwòrán, @RealAARahman
Abdurrahman Abdurazaq to n du ipo Gomina ni Kwara wa lara awọn agbatẹru O to gẹ
Bi wọn ba ti ṣe n lọgun oto gẹẹ, bẹ ni awọn oludibo lọmọde ati lagba yoo ma dahun pe ''Lilọ lẹ lọ.''
Ninu awọn akọmọna, pupọ eeyan lo gbagbo pe o to gẹẹ lo fakọyọ.
Aarẹ Muhammadu Buhari lo fun ara rẹ jan aṣa ipolongo yi lontẹ nigba ti o lọ si iwaju ile asofin Naijiria lati gbe aba isuna ọdun 2019 kalẹ.
4+4 ko ni ṣe pupọ pẹlu ọrọ bi kii ṣe nina ika mẹrin owo mejeeji soke lati fi han pe lẹyin ọdun mẹrin ti APC lo ni ijọba,wọn yoo lo mrin miran si.
Oríṣun àwòrán, @kekeTony
Ṣadede ni aworan awọn ọlọpaa ti wọn na ika 4+4 yi lu sita loju opo ayelujara
Aṣa yi gbalẹ laarin awọn alatilẹyin APC ti awọn ọmọ ogun kan ati ọlọpaa naa si ba wọn da ninu aṣa naa.
Yinka Ajia: ìbẹ̀rù Ọlọrun ni mo fẹ́ fi tukọ̀ Kwara ti mo ba wọlé
Awọn ọdọ Naijiria ni wọn ni aṣa yi ti Omoyele Sowore ti ẹgbẹ AAC ṣagbatẹru rẹ. Ni ṣoki, ohun to tun mọ si ni ''gba a pada''.
Oríṣun àwòrán, @Sowore2019
Omoyele Sowore lo fi n s#o faw#on #od#o lati gba ipo olori pada l#ow#o arugbo
Awọn alatilẹyin rẹ a ma lo akọmọna yi lati fi ipinu wọn rinlẹ nipasẹ gbigba ijọba pada lọdọ awọn agbaagba oloṣelu ti wọn ti wa lori oye ti pẹ.
Akọmọna yi gbiyanju amọ omi pọju ọka lọ fun un nito ri pe Sowore ko ri ijọba gba pada lọwọ Muhammadu Buhari ti o pegede ninu ibo aarẹ 2019.
Latara orukọ oludije ipo aarẹ fun ẹgbẹ oṣelu PDP ni wọn ti da aṣa ipolongo Atikulated kalẹ.
Aṣa naa lalẹ ti awọn olorin kọọkan naa tun sọ di akọmọna ti awọn ọmọ gbẹ PDP n kọ kaakiri.
Wọn fi orukọ igbakeji Atiku, Peter Obi naa kun ti wọn si n dawọn laṣa pọ pe Atikulated Obi-diently.
Oríṣun àwòrán, @Atiku
Atiku Abubakar
#Otogelagos
Ẹda O to gẹ̀ẹ́ ti Kwara ni #Otogelagos eleyi ti o ti n gbalẹ diẹ diẹ.
Kete ti Ibrahim Oloriegbe yẹ aga nidi Sẹnetọ Saraki pẹlu atilẹyin o to gẹẹ ni awọn kan nilu Eko naa bẹrẹ #Otogelagos.
Koda, awọn ipade ati iwọde kan waye ni ilu Eko ti ọpọlọpọ eeyan si  lọdi wọn mọ adape ọrọ yii to ti gbẹnu awọn kan ni ipinlẹ Eko.
Wọn yi lawọn ariran ti o kùnà lórí ẹni tí yóò di ààrẹ Naijiria.
Guru Maharaj: Buhari ní yóò wolé nínú ìdìbò 2019
Ko jẹ tuntun mọ pe awọn wolii orilẹ-ede Naijiria a máa riran nipa ohun gbogbo.
Bi wọn ko ba riran nipa ajalu ti yoo ṣẹlẹ, wọn a si ma fun ara ilu ni iro nipa awọn ti yoo padanu ẹmi wọn tabi ti yoo jẹ ipo kan tabi omiran ninu ijọba.
Saaju idibo ọdun 2019 awọn olori ẹsin Naijiria kan kede asọtẹlẹ nipa ẹni ti yoo jẹ oye Aarẹ Naijiria, awọn Sẹnẹtọ ti yoo jawe olubori ati awọn ipo miran ninu ijọba lawọn ipinlẹ kan ni Naijiria.
Idibo aarẹ ti waye a si ti mọ ẹni to gbegba oroke.
Bakan naa ni ti ibo awọn aṣofin. Njẹ awọn olori ẹlẹsin wọnyi jana nipa asọtẹlẹ wọn abi ofutufẹtẹ lasan ni iriran wọn jẹ?
A ṣe agbeyẹwo awọn kan ati asọtẹlẹ wọn nipa ẹni ti yoo jẹ oye nijọba ,njẹ wọn jana abi wọn kuna ni?
Oniwaasu ẹlẹsin Islam yi ninu fọnran fidio kan ti o gbalẹ loju opo ayelujara ṣeleri pe ko si ẹni ti yoo yọ Aarẹ ile aṣofin agba Bukola Saraki kuro nipo rẹ.
Ọrọ yi mu ikunsinu wa fun awọn eeyan Ilorin paapa julọ awọn ti wọn kọrin o to gẹ fun Saraki.
Awọn eeyan ka ọrọ rẹ wewo wọn si lọ dibo, ababọ ibo ni pe Bukola Saraki fidirẹmi ninu ibo.
Jimi Agbaje: èmi kò faramó owó ẹnubodè Toll Gate Eko rárá
Wolii Austin Moses ati Omoyele Sowore
Omoyele Sowore ni wolii yi riran si wi pe yoo jẹ aarẹ Naijiria ti o si ni Olorun ni o fi iran naa han oun.
Ninu fọnran fidio rẹ́ towa loju opo You tube, o ni o nira fun oun lati jẹ́ iṣẹ yi pe Sowore ni Olọrun fẹ lo lati tun Naijiria ṣe ṣugbọn oun yoo jẹ.
Oríṣun àwòrán, @Austin Moses
Asọtẹlẹ nipa ẹni ti yoo jawe olubori ninu ibo jẹ nnkan ti awọn arìran kan tẹnumọ saaju idibo; ṣugbọn ṣe wọn jana?
Sowore kopa ninu idibo lootọ ṣugbọn ko jawe olubori ninu idibo, koda orukọ rẹ ko si lara awọn mẹta to lewaju ninu ibo aarẹ.
Buhari gbọ́dọ̀ yọ àwọn mínísítà tí kò wúlò ní sáà kejì yí-Ogundamisi
Ikilọ ni wolii yi tilẹ fi sita fun Aarẹ Buhari pe ki o ma ṣe daba ati dije dupo aarẹ.
Gẹgẹ bi ohun ti o sọ, o ni Olorun sọfun oun pe saa kan ṣoṣo ni Buhari yoo ṣe ati wi pe ti o ba ṣesi polongo idibo yoo ku ni.
Oríṣun àwòrán, Facebook
Asọtẹlẹ nipa ẹni ti yoo jawe olubori ninu ibo jẹ nnkan ti awọn arìran kan tẹnumọ saaju idibo; ṣugbọn ṣe wọn jana?
Buhari kopa ninu ipolongo idibo koda o tun dije dupo aarẹ. Ẹyin naa mọ ibi ti ọrọ pada ja si pẹlu abajade ibo.
Aarẹ ọmọ ọdun mẹ́rìndínlọ́gọ́rin ni Naijiria dibo yan, Muhammadu Buhari si ni orukọ rẹ.
Atiku Abubakar ni oludije ti wolii yi sọ pe oun riran si ti o si fẹ le fi ogun rẹ gbari pe bẹẹ ni yoo ri.
Oríṣun àwòrán, Facebook
Asọtẹlẹ nipa ẹni ti yoo jawe olubori ninu ibo jẹ nnkan ti awọn arìran kan tẹnumọ saaju idibo; ṣugbọn ṣe wọn jana?
Ninu fọnran fidio rẹ́ to wa lori ayelujara o sọ pe ''Lọdun maarun un sẹyin mo sọ bẹ nipa Atiku,lọdun mrin sẹyin Olorun sọ b fun mi nipa Atiku''
Abalọ ababọ asọtẹlẹ r ni pe Atiku fidirẹmi ninu idibo aarẹ ọdun 2019.
#NigeriaDecides: BBC ti wa ni gbogbo ìpínlẹ̀ Naijiria láti firoyin gbogbo tóo yin létí
Guru Maharaj: Buhari ní yóò wolé nínú ìdìbò 2019
Ni tirẹ Olùdásílẹ̀ ìjọ One Love Family, Satguru Maharaj sọ pe ààrẹ Muhammadu Buhari tó ń dije lábẹ àsía ẹgbẹ́ òṣèlú All Progressives Party (APC), ni yóò fidi alátako rẹ̀ Alhaji Atiku Abubakar, tó ń dije lábẹ́ égbẹ́ òṣèlú People's Democratic Party(PDP) janlẹ̀ .
Ni èyí tí o dẹ padà ri bẹẹ.
Yinka Ajia: ìbẹ̀rù Ọlọrun ni mo fẹ́ fi tukọ̀ Kwara ti mo ba wọlé
ASUU Strike: Òtítọ́ wo ló wà nínú pé ASUU tún fẹ́ yanṣẹ́lódì?
Ẹgbẹ awọn olukọ fasiti to jẹ ti ijọba l'orilẹede Naijiria ti sọ pe awọn ko gberero lati tun lọ fun iyanṣẹlodi oloṣu mẹta mi i.
Awọn olukọ naa, nipasẹ ọrọ kan ti ẹgbẹ ASUU fi sita lori ayelujara pe awọn n ro o lati tun lọ fun iyanṣẹlodi oṣu mẹta mi i, ti mu ki ọpọlọpọ eniyan fi ibinu han
Amọ ṣa, aarẹ ẹgbẹ naa, Ọjọgbọn Biọdun Ogunyẹmi ti kede pe irọ ni ọrọ naa ti awọn araalu ko gbọdọ ka si.
Oṣu Kọkanla ọdun 2018 ni ẹgbẹ ASUU lọ fun iyanṣẹlodi, o si lọ fun oṣu mẹta, ko to o di pe o wa sopin lọjọ keje, oṣu Keji ọdun 2019.
Election update 2019: Àgbère ẹgbẹ́ ló wà nídìí ọ̀rọ̀ Amosun àti APC - Jiti Ogunye
Amosun
Koda, ẹgbẹ oṣelu kan o baa jẹ Ajinigbe Party of Nigeria, niwọn igba to ba ti le gbe wọn de ipo ti wọn n wa. wọn yoo dara pọ mọ ọ.
Laipẹ yii ni ẹgbẹ oṣelu APC paṣẹ lọ rọọkun nile fun Gomina Ibikunle Amosun ti ipinlẹ Ogun latari pe ẹgbẹ ni o ṣe lodi si ofin ẹgbẹ nipa atilẹyin rẹ oludije gomina lab asia ẹgbẹ oṣelu mii, Abdulkabir Akinlade.
Igbimọ amuṣẹya ẹgbẹ naa lo daba yii lẹyin ipade wọn ti o waye nilu Abuja.
Ẹwẹ, onimọ nipa ofin kan, Jiti Ogunye nigba to ba BBC Yoruba sọrọ ṣalaye pe pupọ ninu igbesẹ awọn ẹgbẹ oṣelu lorilẹede Naijiria mọ ohun ti wọn n ṣe.
Lotitọ igbesẹ gomina Amosun yoo jẹ ki awọn ẹgb mọ pe ṣekuṣẹyẹ ni iwa to wu to si lodi si ofin ẹgbẹ wọn.
O jẹ ko di mimọ wi pe olori ọrọ inu rẹ ni wi pe ohun ti ẹgbẹ ba ṣe naa lawọn araalu yoo gba.
Niwọn igba to jẹ pe ẹgbẹ APC naa lo fun un ni aaye lati dije fun ipo Sẹnetọ, ki lo de to jẹ pe igba ti wọn dibo tan ni wọn to mọ pe awọn ko fara mọ ohun ti Amosun ṣe?
Ibikunle Amosun: Owo adani ni'ṣẹ ẹran dida, ko kan ijọba
O ni agabagebe ni ẹgbẹ oṣelu APC ṣe ti wọn fi ni ki gomina Amosun lọ rọọkun nile.
"Amoṣa, Amofin Jiti jẹ ko di mimọ pe niwọn ti ko jẹ tuntun pe awọn oloṣelu n ṣi kuro lati ẹgbẹ kan lọ si omiran, ""ti a ba ba akata wi pe o lọ jẹ laatan, o yẹ ki a ba adiyẹ naa wi""."
Nitorinaa, o ni ohun ti Amosun naa ṣe ku diẹ kaato nitori ipo lawn oloṣelu n wa kaakiri. Ohun ti Amosun ṣe, awọn gomina mii naa ti ṣe e nipinlẹ mii.
Olusegun Obasanjo: Ọmú ìyá mi ti mo fi ń mùkọ ni kekere ló jẹ ki ń lókun
O ran awọn araalu leti wi pe o le da bii wi pe awọn oloṣelu n ja loju araalu ṣugbọn bo ba di ọla, wọn di ọrẹ ti wọn a maa rẹrin kaa kaa.
Latari ohun ti yoo bi ni saa Amosun gẹgẹ bii Sẹnetọ labẹ asia APC, Jiti ni ọrọ oloṣelu ko ṣee da si taara nigba mii nitori bi idibo ti gomina yii ba ti pari ti wọn bura wọle fun un gẹgẹ bii sẹnetọ, fun apẹẹrẹ bi oludije aayo rẹ ko ba pegede, o le tun pinu lati pada si APC ti ẹgbẹ APC naa a si tun fọwọ paa lori.
Ẹgbẹ́ agbésùnmọ̀mí IS yọ Al-Barnawi ọmọ olùdásílẹ̀ Boko Haram nípò gẹ́gẹ́ bíi adarí ISWAP
Oríṣun àwòrán, LeBabi.net
Abu Musab Al-Barnawi ni akọbi ọmọ Mohammed Yusuf, iyẹn oludasile Boko Haram ti wọn pa ni ọdun 2009.
Ẹgbẹ agbesunmọmi Islamic State ti yọ Abu Musab Al-Barnawi, to jẹ adari ẹka IS to wa ni iwọ oorun Afrika, ISWAP kuro nipo.
Ahmad Salkida kan, akọroyin ti awọn eniyan mọ gẹgẹ bii ọkan gboogi ninu ọmọ Naijiria to maa n ri aaye wọ ọdọ awọn adari ẹgbẹ Boko Haram lo ṣe ikede yii lori ayelujara Twitter ni ọjọ Aje.
Akọroyin naa ni Abu Abdullah Ibn Umar-Al-Barnawi ni wọn fi rọpo rẹ.
Salkida ni ẹgbẹ naa ko sọ idi ti wọn fi yọ Abu Musab nipo ninu igbohunsilẹ ti wọn ti ṣe ikede naa. Oun lo jẹ akọbi ọmọ Mohammed Yusuf, iyẹn oludasile Boko Haram ti wọn pa ni ọdun 2009.
ISWAP jẹ ọkan lara awọn ẹya Boko Haram. Ọdun 2005 ni Boko Haram dara pọ mọ IS nigba ti Abu Musab jẹ agbẹnusọ.
Akọroyin naa ni ko si oun to ṣe Abu Musab, ati wi pe o ṣi wa labẹ ISWAP bo tilẹ jẹ wipe wọn yọ ọ nipo.
Buhari gbọ́dọ̀ yọ àwọn mínísítà tí kò wúlò ní sáà kejì yí-Ogundamisi
Champions league: Àwọn ẹgbẹ́ agbábọ́ọ̀lù wo ni yóò tẹ̀síwájú?
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ìpele olójú mẹ́jọ (Quarter finals) làwọn ẹgbẹ́ agbábọ́ọ̀lù mẹ́rìndínlógún tó kù nínú ìdíje náà ń lépa rẹ̀ báyìí
Tani yoo tẹsiwaju lọ si ipele olójú mẹ́jọ (Quarter finals) idije Champions league ilẹ Yuroopu lọṣẹ yii?
Ibeere yii ni yoo maa gba ọkan awọn ololufẹ ere bọọlu kaakiri agbaye bi ifẹsẹwọnsẹ to kẹyin ni ipele komẹsẹ-o-yọ akọkọ ni Champions league yoo ṣe waye lọjọ iṣẹgun ati ọjọru.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Borussia Dortmund yoo koju Tottenham
Ẹgbẹ agbabọọlu Borussia Dortmund ti orilẹede Germany yoo maa gbalejo Tottenham hotspur ti ilẹ Gẹẹsi ni orilẹede Germany.
Goolu mẹta ni Tottenham gba wọle Borussia Dortmund nigba ti wọn pade ni ọsẹ meji sẹyin ni papa iṣire Wembley.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Real Madrid n gba Ajax lalejo
Igba mẹta ọtọọtọ ni Real Madrid ti gba ife ẹyẹ Champions league laarin ọdun mẹrin sẹyin. Awọn si ni ikọ agbabọọlu akọkọ ti yoo gba ife ẹyẹ naa ni ọdun mẹta tẹleri.
Madrid yoo maa gbalejọ Ajax lọjọ iṣẹgun lẹyin ti wọn ti kọkọ rinrinajo lọ si orilẹede Holland ni ọsẹ meji sẹyin nibi ti wọn ti po ẹkọ iya fun Ajax nilu Amsterdam pẹlu ayo meji si ẹyọkan.
Ṣe Madrid ni yoo tẹsiwaju ni tabi Ajax, ipade di papa iṣire Barnebaeu ni orilẹede Spain.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
FC Porto yoo koju Roma
Ni ọjọru ni FC Porto orilẹede Portugal yoo gbalejo Roma ti ilẹ Italy. Nigba ti wọn pade ni ọsẹ meji sẹyin ni ilu Romu, ami ayo meji si ẹyọkan ni Roma fi na FC Porto.
Ireti ọpọ si ni pe boya Porto yoo lo anfani ọdẹdẹ rẹ to wa lati yii oju ọrọ pada ki wọn lee tẹsiwaju.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Paris Saint Germain PSG yoo gbalejo Manchester United
Anọmọle ni PSG na Manchester United mọ old Trafford nigba ti ikọ mejeeji yii pade ni old Trafford ni ilẹ Gẹẹsi.
Lootọ awọn agbabọọlu Man United n ta biọbiọ lẹnu lọọlọọ yii ni idije liigi premiership ilẹ naa ṣugbọn ọpọ n woye pe agbara wọn yoo ku diẹ lati ka PSG, paapaa julọ bo ṣe jẹ pe ojude PSG lorilẹede France ni ifẹsẹwọnsẹ naa yoo ti waye.
Pẹlu awọn ifẹsẹwọnsẹ mẹrin yii lọsẹ yii awọn ololufẹ bọọlu yoo mọ awọn mẹrin akọkọ ti yoo lọ si ipele to kan ni idije Champions league.
Ìtàn Mánigbàgbé: Oluṣẹgun Ọbasanjọ di aarẹ Nàíjíríà lẹ́yìn tó ti ẹ̀wọ̀n de
Oríṣun àwòrán, Olusegun Obasanjo presidential library
Asamọ kan lo ni ori lo mọ oloye, ori lo mọ ọlọla, ẹni ti yoo jẹ oriade ati ọrun ilẹkẹ si wa lọwọ ori.
Bẹẹ ni ọrọ ri pẹlu igbesi aye Oloye Matthew Olusẹgun Arẹmu Okikiọla Ọbasanjọ, ẹni to jẹ pe ọmọ orukan lasan ni lati igba to ti pe ẹni ọdun mọkalelogun amọ to pada wa di olori ilẹ Naijiria fun igba mẹta ọtọọtọ.
Igbesi aye akanda ẹda yii, ti awọn eeyan kan n pe ni Ẹbọra Owu, yẹ ko jẹ agbọkọgbọn ati awokọse fun awọn ọmọ Oodua nitori ẹsin iwaju ni tẹyin n wo sare.
Nibayii ti agba oselu ati eekan ọmọ ilẹ Kaarọ Oojire naa pe ẹni ọdun mejilelọgọrin loke eepẹ, BBC Yoruba lọ si ori itakun agbaye Wikipedia lati mọ nipa ilu mọọka ọmọ Yoruba yii, eyi to yẹ ki ẹyin naa mọ pẹlu.
Diẹ lara awọn nkan ti Oluṣẹgun Ọbasanjọ ti gbe se loke eepẹ ree, ti ireti si wa pe yoo tun se ju bẹ lọ niwọn igba to si wa loke eepẹ.
Oríṣun àwòrán, @OOFoundation
O si yẹ ka fi igbe aye rẹ kọgbọn pe, laisi obi tabi ẹbi, sibẹ, o ta ara rẹ yọ lode aye lai gboju logun tabi ibatan kankan.
A wa n gbaa ni adura bayii pe ọba oke yoo tubọ fun Oloye Oluṣẹgun Ọbasanjọ ni ẹmi gigun ati alaafia lati se ọpọlọpọ ọdun laye.
Kwara Bursary: Àwọn akẹ́kọ̀ọ́ Kwara Poly ṣèwọ́de fún owó ìrànwọ́ ẹ̀kọ́
Àwọn akẹ́kọ̀ọ́ ileẹkọ gbogbonse Poly tipinlẹ Kwara, ti wọn jé ọmọ bíbí ìpínlè Kwara yà bo ileesẹ eto isuna ìpínlè náà (Kwara State Internal Revenue Service) láti béèrè fún owó iranwọ eto ẹkọ (Bursary) wọn.Àwọn akẹ́kọ̀ọ́ náà, to gbé ìwé ilewọ ati patako to ni akọle oríṣiríṣi lọ́wọ́, ni wọn n béèrè fún owó iranwọ náà, gẹgẹ bii ẹtọ wọn.
Awọn akẹkọ naa, Moshood Walik, lasiko ti wọn n ba BBC Yoruba sọrọ fi ẹṣun kàn ijọba ipinlẹ Kwara pe, o n fun awọn ni ẹgbẹrun marun naira pere fun owo iranwọ eto ẹkọ, to si tun ti pẹ tijọba ti san owo naa.
Agbẹnusọ fawọn akẹkọ naa ni ẹgbẹrun lọna ogun naira ni ijọba ipinlẹ Eko n san bii owo iranwọ eto ẹkọ fawọn akẹkọ rẹ, tijọba ipinlẹ Kwara ko si ranti awọn.
Wọn fikun pe lẹyin tawọn se iwọde lọsẹ to kọja, ijọba ipinlẹ Kwara gbe ogun miliọnu naira kalẹ fun sisan owo iranwọ eto ẹkọ naa amọ titi di asiko yii, awọn ko mọ ibi ti owo naa wọlẹ si mọ.
Àwọn akẹ́kọ̀ọ́ náà ni, àwọn tí lọ sí ilé ìṣe tó wà fún eto isuna láti mọ nkan tó se okùnfà idiwo láti sàn owó naa, amọ gbogbo igbinyanju awọn nibẹ lo ja si pabo.
Ẹgbẹ awọn akẹkọ to jẹ ọmọ bibi ipinlẹ Kwara wa n rọ awọn alasẹ ipinlẹ naa lati wa nkan se si ọrọ yii nitori iwọde awọn ko mu ija lọwọ.;
Oyo Election: ADP, ZLP SDP fa ọwọ́ Seyi makinde sókè bíi gómìnà wọn
Apapọ awọn ẹgbẹ oṣelu alatako nipinlẹ Ọyọ ṣe akanṣe ipade awọn akọroyin, lati kede atilẹhin wọn fun Oludije si ipo gomina ipinlẹ Ọyọ ninu ẹgbẹ oṣelu PDP, Onimọ-ẹrọ Ṣeyi Makinde.Ipade naa waye lọjọ Iṣẹgun ni olu ile ẹgbẹ awọn akọroyin to kalẹ si Iyaganku niluu Ibadan.Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí:
Lara awọn eeyan pataki to peju-pesẹ sibi ipade naa ni gomina ipinlẹ Ọyọ tẹlẹri, Oloye Rashidi Ladọja, awọn oludije si ipo gomina nipinlẹ Ọyọ ninu ẹgbẹ oṣelu ADC, ZLP, ati SDP.
Lara awọn oludije gomina tẹlẹ to wa nibẹ ni Sẹnetọ Olufẹmi Lanlẹhin, Oloye Sharafadeen Alli ati Oloye Bolaji Ayọrinde ni ṣisẹ-n-tẹle.
Awọn ẹgbẹ naa kede atilẹhin wọn, bẹẹ si ni wọn fi igbagbọ wọn han wi pe, oludije fun ipo gomina ipinlẹ Ọyọ ninu ẹgbẹ ọṣelu PDP, Onimọẹrọ Ṣeyi Makinde ni yoo jawe olubori ninu eto idibo ọjọ Abamẹta.
Elections Update 2019: Ẹ fún wa ní ìbò wa lẹgbẹ́ PDP ń kigbe
Àwọn ọmọ ẹgbẹ́ òṣèlú People Democratic Party (PDP) tí bẹ̀rẹ̀ ìfẹ̀hónú han pẹ̀lú ìwọ́de lọ si olú ilé iṣẹ́ àjọ elétò ìdìbò INEC, lórí èsì ìdìbò tó wáyé ní ọjọ́ Kẹtàlélógun oṣù Kéji ọdún 2019.
"Àwọn tó péjú níbi ìwóde náà ni alága ẹgbẹ́ òṣèlú PDP, Uche Secondus, àgbẹnusọ ẹgbẹ́ PDP, Kola Ọlọgbọndiyan, pélù àwọn ọmọ ẹgbẹ́ míràn bii ẹgbẹ́run ti wọn si ń kígbe ""Atikulated"""
Olusegun Obasanjo: Ọmú ìyá mi ti mo fi ń mùkọ ni kekere ló jẹ ki ń lókun
Tí ẹ ò bá gbàgbé, ẹgbẹ́ òsèlú PDP tí Alhaji Atiku Abubakar soju fun bii oludíje sipo ààrẹ, kọ èsì ìdìbò ààrẹ tó wáyé nínú oṣù tó kọja
Lockdown school feeding programme: To bá ní ọmọ ni kíláàsì Kínní dé ìkẹta nílé ẹ̀kọ́ alákọ̀ọ́bẹ̀rẹ̀ tìjọba, lọ gba oúnjẹ fún ọmọ rẹ - Ìjọba àpapọ̀
Oríṣun àwòrán, Federal Ministry of Humanitarian Affairs
Ijọba apapọ ti kede pe Ọjọbọ ọla ni eto ipese ounjẹ fawọn akẹkọọ jakejado Naijiria yoo bẹrẹ nilu Abuja, Eko ati Ogun.
Ileesẹ to wa fun ipese ohun iranwọ nilẹ wa lo sisọ loju ọrọ yii ninu atẹjade kan tó fisita loju opo Twitter rẹ.
Atẹjade naa ni gbogbo ipinlẹ tó wa ni Naijiria ni wọn ti rọ lati lo gbogbo akọsilẹ to wa nikawọ wọn lati tọ ipaṣẹ ilegbe awọn akẹkọọ to wa lawọn ile ẹkọ alakọọbẹrẹ ijọba.
Ṣugbọn yatọ si bo ṣe n waye tẹlẹ, ijọba ni awọn obi ati alagbatọọ awọn akẹkọọ to lẹtọ si ounjẹ ijọba naa, ni wọn yoo gbe fun.
Kikida awọn akẹkọọ to wa ni kilaasi kinni si ikẹta lawọn ile ẹkọ alakọọbẹrẹ ijọba nìkan, ni yoo jẹ anfaani ipese ounjẹ naa, eyi ti yoo kan ojule biliọnu mẹta o le diẹ, 3,131,971.
Oríṣun àwòrán, Federal Ministry of Humanitarian Affairs
Lara awọn eroja ounjẹ ti ijọba yoo pin fun idile akẹkọọ kọọkan to lẹtọọ si ounjẹ naa ni, apo irẹsi oni kilogiramu marun-un (5kg), apo ẹwa oni kilogiramu marun-un bakan naa, ororo  ẹẹdẹgbẹta mililita, 500ml, epo Pupa oni ọtalelẹẹdẹgbẹrin o din mẹwaa mililita, 750ml, iyọ oni ẹẹdẹgbẹta miligiramu, 500mg, ẹyin ẹyọ mẹẹdogun ati tomato lílọ lubu-lubu oni miligiramu ogoje, 140gm.
Ijọba ni apapọ gbogbo owo awọn eroja ti wọn fẹ pin fun awọn obi akẹkọọ to lẹtọọ si ounjẹ naa, jẹ ẹgbẹrun mẹrin ati igba Naira, N4,200.
Oríṣun àwòrán, Federal Ministry of Humanitarian Affairs
Ijọba apapọ tun ni ilana tawọn fẹ lo yii, ni yoo jẹ ko rọrun lati ri awọn akẹkọọ naa fun ni ounjẹ lasiko yii ti gbogbo ile ẹkọ wa ni titi pa nitori igbele arun Coronavirus.
Igbesẹ pinpin iwe ẹtọ si ounjẹ naa, ta pe ni Voucher ti n waye lọwọ nilu Abuja ati Eko, ti ijọba si ti n pese owo fun awọn ijọba ipinlẹ lati seto ipese ounjẹ fun akẹkọọ nipinlẹ koowa wọn.
Oríṣun àwòrán, ZDENEK NEMEC/MAFRA/PROFIMEDIA
Czech Republic: Kìnìùn ṣe ikú pa olówó rẹ̀
Atẹjade naa ni lati ojule de ojule ni wọn yoo pin 'voucher' naa, eyi ti yoo ni sitampu, ọjọ ati akoko ti gbigba ounjẹ yoo kan ile kọọkan, ti wọn yoo si loo lati gba ounjẹ ni ibudo ti wọn ti n pin ounjẹ naa.
Michal Prasek ni olóńgbò nla, eyiun kiniun to ti n sin fun ọdún mẹ́sàn, bó tilẹ̀ jẹ́ pé àwọn aládugbò n ké gbàjarè lórí ọ̀rọ̀ náà tẹ́lẹ̀.
Bàbá Prasek yii lo sadede ri òkú ọmọ rẹ̀ nínú ilé kìnìún, to sí ké sí àwọn akọròyìn abẹ́le lati kede ohun to ṣélẹ̀ àti pé, ilẹkùn ilé kìnìún náà wà ni títì sínú.
Awọn ọlọpàá ti wọn pè wá wo ohun to ṣẹlẹ̀, kọ́kọ́ pa awọn ẹranko míràn to wà nínú àgò tó fara ti kìnìún náà.
Agbẹ́nusọ ọlọpàá ní, pípa ti wọn pa àwọn ẹranko tó ku náà ṣe pàtàkì láti le kọja sọ́dọ̀ ẹni ti kìnìún pa.
Ọgbẹ́ni Prasek, ẹni ọdún mẹ́tàlélọ́gbọ̀n, ra kìnìún lọ́dún 2016, o tún wa ra abo ni ọdun to kọja, to si kó àwọn méjèèjì pọ̀ sinu àgò kannáà lẹ́yìnkùlé rẹ ni abúle Zdechov.
Seyi Makinde: Màá fẹ́ káwọn aráàlú mọ ìpa ìjọba mi lára sí rere
Sáájú ní ìjọba ti kọ láti fun láàyè láti kọ́lé fún pé, ó ń sí eranko lọ́nà àìtọ́, sùgbọ́n èdè àìyedè bẹ́ sílẹ̀ nígbà to kọ̀ láti jẹ́ ki àwọn aláṣẹ̀ wọ inú ọgbà rẹ.
Sugbọn wahala bẹ silẹ nigba ti ẹnikan to n wa kẹkẹ sadede kọlu abo kiniun rẹ lasiko to n mu gba atẹgun lọ loju popo, to si fi okun si lọrun bii aja.
Nibayii, kiniun to n sin naa, lo papa ran an sọrun ọsan gangan.
Ọbasanjọ: N kò ní dẹ́kun láti máa tako Buhari
Oríṣun àwòrán, @NGRPresident
Ọbasanjọ ti kọ lẹta si Buhari eleyi to di gbajugbaja kaakiri agbaye
Aarẹ tẹlẹri lorilẹede Naijiria, Olusegun Obasanjo ti ni, idi ti oun fi n tako Aarẹ Buhari ni wi pe isejọba tiwantiwa fayegba ki eniyan o sọrọ nipa ijọba to wa lode.
Aarẹ Obasanjo ni asiko to n se ayẹyẹ ọdun kejilelogun ni ilu abeokuta sọ wi pe ko si ija laaarin oun ati Aarẹ Muhammadu Buhari.
O ni isẹ ilu kii se ohun ti eniyan fi n se ibatan, amọ o nii se pẹlu titako igbesẹ ijọba ti ko ba ba awọn eniyan lara mu.
Ni ọpọ igba, Aarẹ tẹlẹri lorilẹede Naijiria, Olusegun Obasanjo ti ma n bu ẹnu atẹ lu isejọba Aarẹ Muhammadu Buhari.
Olusegun Obasanjo: Ọmú ìyá mi ti mo fi ń mùkọ ni kekere ló jẹ ki ń lókun
Buhari: Ìpèsè ààbò, ọrọ̀ ajé, iṣẹ́ òòjọ́, ohun èèlò ni yóò jẹ mí lógún
Oríṣun àwòrán, @MBuhari
Aarẹ orilẹede Naijira, Muhammadu Buhari ti jẹjẹ pe oun yoo sisẹ kara lati mọ le awọn aseyọri oun ni saa isejọba oun akọkọ.
Buhari ni awọn ẹka ti oun ko ti ni tẹti ni ipese eto aabo to yanranti, ọrọ aje to duro re, ipese isẹ oojọ, igbogun tiwa ajẹbanu ati ipese awọn ohuneelo amayedẹrun to duro re.
Aarẹ Buhari jẹjẹ yii lasiko to n gbalejo awọn asaaju ẹgbẹ Arẹwa to wa se ẹ ku oriire si nile ijọba nilu Abuja.
Aarẹ Buhari ni oun ko ni ja awọn ọmọ Naijiria to ni igbẹkẹle ninu oun kulẹ ni saa keji yii pẹlu afikun pe gbogbo ipa ni oun yoo sa lati tẹ awọn araalu lọrun.
Atẹjade kan ti amugbalẹgbẹ fun aarẹ lori eto irofin, Garba Shehu fisita ni aarẹ wa dupẹ pupọ lọwọ awọn agbaagba Arẹwa fun apọnle ti wọn fun oun ati atilẹyin wọn.
Igbesẹ to kẹyin fun mi ni eyi jẹ. Ma sa gbogbo ipa mi lati sisẹ kara ju bi mo ti se tẹlẹ lọ, ti n ko si ni ja yin kulẹ rara.
Oríṣun àwòrán, Twitter
Àwọn lọbalọba labẹ ẹgbẹ National Council of Traditional Rulers lọ kí Ààrẹ ní Abuja lẹ́yìn tó jáwé olúborí nínú ìdìbò sípò Ààrẹ.
Aarẹ Muhammadu Buhari ti kesi awọn ọba lorilẹede Naijiria lati fọwọsowọpọ pẹlu ijọba lati gbogun ti iwa ibajẹ lorilẹede Naijiria.
Aarẹ Buhari sọ eyi lasiko to n gbalejo awọn ọba ni ile aarẹ ni ilu Abuja, lasiko to n ki wọn kaabọ si saa keji rẹ gẹgẹbi aarẹ orilẹede Naijiria.
Seyi Makinde: Màá fẹ́ káwọn aráàlú mọ ìpa ìjọba mi lára sí rere
O fikun wi pe, oun yoo pada si ile oun ni Daura ni ipinlẹ Katsina lẹyin saa keji oun gẹgẹ bi aarẹ.
Oríṣun àwòrán, Twitter
Aarẹ orilẹede Naijiria ni, lọpọ igba awọn ọba mọ awọn idile ti awọn ọdaran wa, nitori naa ni wọn se nilo awọn ọba ti wọn yoo soju awọn eniyan lọna to lamilaaka.
Oríṣun àwòrán, Twitter
Sultan ti ilu Sokoto, Alhaji Muhammad Sa'ad Abubakar III lo saaju awọn ọba naa lọ si ile aarẹ.
Kylie Jenner ń pa $360m lọ́dún kan, tó sì ta adarí Facebook yọ
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Atẹjade kan ti ajọ Forbes Billionaires fi lede wi pe, Kylie Jenner ni ọdọmọde olowo julọ ni agbaye.
Kylie Jenner to jẹ abikẹyin ninu idile wọn, di ọlọla ni pasẹ ohun elo amaradan ati asaraloge ti oun ta.
Seyi Makinde: Màá fẹ́ káwọn aráàlú mọ ìpa ìjọba mi lára sí rere
Ọmọ ọdun mọkanlelogun naa, to da ile isẹ rẹ Kylie Cosmetics silẹ ni bi ọdun mẹta sẹhin, ti ni ere to to miliọnu lọna ọtalelọọdunrun dọla ni ọdun to kọja.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Arabinrin naa tun ta Mark Zuckerberg yọ, ẹni to da oju opo ikansiraẹni Facebook silẹ, ti wọn si ri bii ọdọmọde olowo to ni ọpọ biliọnu dọla lẹni ọdun mẹtalelogun.
Amọ Mark Zuckerberg ti ja wa sẹyin ninu awọn ọlọla agbaye ni ọdun to kọja, ti oludasilẹ ile isẹ Amazon, Jeff Bezos, si di ọkunrin to lowo julọ lagbaye.
Amọ ninu gbogbo awọn ọlọla ti iwe atẹjade Forbes Billionaire gbe jade, awọn obinrin mejilelaadọrin lo ti di ọlọla ni pase isẹ ọwọ wọn, eleyii ti ko waye lati bi ọdun mẹrindinlọgọta sẹhin.
Orilẹede Amẹrika lo ni awọn ọlọla to pọju lọ pẹlu awọn olowo toto ẹgbẹta le meje (607), nigba ti orilẹede China tele won pelu olola to to okoolelọọdurun ati mẹrin (324), nigba ti Ilẹ Gẹẹsi si ni ọlọla mejilelaadọrun.
Ash Wednesday: Ọjọ́ eérú ń rán wa létí eérú fún eérú, erùpẹ̀ fún erùpẹ̀
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ọdọọdun ni awọn ọmọlẹyin Kristi ma n se ayẹyẹ Ọjọ Eerú to jẹ ọjọ kẹrindinlaadọrin saaju ọdun Ajinde.
Ọjọ Eeru yii ni wọn fi n bẹrẹ isera ati aawẹ fun ọdun Ajinde ti awọn onigbagbọ, to tumọ si iku ati Ajinde Jesu Kristi.
Lasiko Ọjọ Ẹẹru naa, to ma n waye ni Osu Keji tabi Osu Kẹta ni ọdọọdun, la maa ri awọn eniyan ti wọn yoo ma n rin kaakiri pẹlu ami agbelebu ti wọn fi eeru kọ siwaju ori wọn.
Awọn ọmọlẹyin Kristi gbagbọ wi pe, asiko aawẹ fun ogoji ọjọ yii safihan asiko ti Jesu Kristi fi wa ninu aginju pẹlu aawẹ ati adura, ki satani to wa dan wo.
Awọn onigbagbọ maa n lo asiko naa lati gbadura, ati lati kọ ẹkọ nipa igbe aye Jesu Kristi, iku rẹ, isẹ rẹ loke erupẹ, ati ajinde rẹ kuro ninu oku.
Ki ni pataki Ọjọ Eeru ninu Igbe aye awọn Onigbagbọ?
Ọjọ eeru to wọpọ laaarin awọn onigbagbọ ti Ijọ Aguda, Ijọ Anglican, Methodist ati awọn Ijọ igbalode miran.
Ni ọpọlọpọ awọn ijọ onigbagbọ, wọn ma n lo eeru ti wọn jo ku lara imọ ọpe ti wọn lo fun ọdun Ọjọ imọọpe (Palm Sunday), to waye ni ọdun to kọja.
Seyi Makinde: Màá fẹ́ káwọn aráàlú mọ ìpa ìjọba mi lára sí rere
Ọpọlọpọ awọn oluso agutan ati pasito ma n lo ọjọ naa lati fi se iwaasu to ba asiko naa mu.
Eeru ti ayajọ ọjọ yii se apejuwe iku ati ironupiwada eleyii ti awọn adari ijọ ma n fi si awọn ara ilu lori, pẹlu ọrọ wi pe' éeru fun eeru, iyẹpẹ ni wa, ati wi pe ilẹ la o padasi.
Bakan naa ni wọn gbagbọ wi pe ti awọn onigbagbọ ba se n gba ami agbelebu yii sori, wọn n jẹwọ ẹsẹ wọn fun Ọlọrun.
Ọjọ Kẹfa, Osu Kẹta ni Ọjọ Eeru ti ọdun yi waye, nigba ti awọn ọjọ miran to so mọ ọjọ eeru bii ọjọ ti Jesu wọ Jerusalem pẹlu ariwo ayọ ti yoo waye ni Ọjọ Kẹrinla, Osu Kẹrin, ọdun 2019.
Ọjọ Iwẹsẹ yoo waye, bakan naa ni Ọjọ Friday rere yoo waye ni Ọjọ Kọkandinlogun, Osu Kẹrin, ọdun 2019 ati Ọjọ Ajinde Kristi yoo waye ni Ọjọ Kọkanlelogun, Osu Kẹrin, ọdun 2019.
Buhari: Obasanjo ló mú ìgbéga bá òṣèlú Nàìjíríà, ó yẹ ká yìn-ín
Oríṣun àwòrán, Obasanjo Official
Muhammadu Buhari: Obasanjo ló mú ìdàgbàsókè bá ìjọba àwa-àra-wa Nàìjíríà
Ààrẹ Muhammadu Buhari ti ṣe àfiwé ààrẹ àná, Olusegun Obasanjo gẹ́gẹ́ bíi olùfarajì tòótọ fún ìdàgbàsóke Nàìjíríà tó sì yẹ láti máà gbóríyìn fún.
Buhari ni gbogbo àwọn iṣẹ́ ribiribi ti Ọbasanjọ ti gbése lo mu ki ìjọba awa ara wa àti ìsọ̀kàn orílẹ̀-èdè Nàìjíríà ó gbòòrò si.
Nínú àtẹjáde kan ti Garba Sheu, to jẹ oluranlọwọ pataki fún ààrẹ kọ láti fi ki ààrẹ ànà Olusegun Obasanjo fún ayẹyẹ ọjọ́ ìbí ọdún kẹrìnlélọgọrin rẹ, ni Buhari ti woye ọrọ yii.
Olusegun Obasanjo: Ọmú ìyá mi ti mo fi ń mùkọ ni kekere ló jẹ ki ń lókun
"Ààrẹ Buhari ni ""bó tilẹ jẹ pé èmi àti Obasanjo ò jọ dúró si ibi kan náà lórí ọ̀rọ̀ ètò òṣèlú, síbẹ̀ mi ò fi ọwọ́ yẹpẹrẹ múu nítori gbogbo àwọn iranwọ rẹ̀ lórí ìdàgbàsókè Nàìjíríà.""O ní, ""àwọn àlàyé ti Oloye Olusegun ṣe nipa ara rẹ̀ àti àwọn amuyẹ adarí to ni, máà ń fún àwọn ọmọlẹ́yìn rẹ̀ ni ìwúrí. """
Seyi Makinde: Màá fẹ́ káwọn aráàlú mọ ìpa ìjọba mi lára sí rere
"Gẹ́gẹ́ bi Buhari ṣe sọ, ""ọ̀nà ti Nàìjíríà gba láti kúrò nínú ìjọba ológun sí ti alágbáda lọdún 1979, kò ṣẹ̀yìn àwọn iṣẹ́ribiribi ti Obasanjo gbé se fun ìdagbasoke àpapọ orilẹ̀-èdè Nàijiríà""."
"Ààrẹ Buhari ni, ""Bí ó ṣe wá ń ṣe ayẹyẹ ọjọ́ ìbì ọdún méjìlélọ́gọ́rin, mo gbàdura fún àlékun àláfíà, ọgbọ́n àti ìmọ̀ nínú sínsin Ọlọrun àti ènìyàn"""
Nigeria Elections 2019: Dandan ni lílo ẹ̀rọ tó ń yẹ káàdì ìbò wo
Oríṣun àwòrán, INEC NIGERIA/FACEBOOK
Àjọ elétò kéde ọjọ́ ajé tó mbọ̀ láti gba káàdì ìdìbò
Laipẹ yii ni Alaga ajọ eleto idibo Naijiria, INEC, Ọjọgbọn Mahmood Yakubu kede pe, dandan ni ki ajọ naa lo ẹrọ to n ṣayẹwo kaadi oludibo ni gbogbo ibudo idibo ni Naijiria.
O ni eyi yoo mu ki ajọ INEC ṣe eto idibo ti awọn eniyan yoo ni igbagbọ ninu rẹ.
Lilo ẹrọ to n ṣayẹwo kaadi oludibo fa ede aiyede, lẹyin ti eto idibo aarẹ waye lọjọ kẹtalelogun, oṣu Keji, paapa nitori bi awọn kan ko ṣe lanfaani lati dibo, nitori pe ẹrọ naa ko gba kaadi wọn.
Bakan naa ni oludije fun ipo aarẹ ninu ẹgbẹ oṣelu Peoples Democratic Party, PDP, Atiku Abubakar naa sọ pe, ara nkan ti oun fi kọ esi idibo naa ni pe oun ko gbagbọ pe oun fidirẹmi nitori pe, wọn ko lo ẹrọ naa ni awọn agbegbe kan.
Kíní yóò ṣẹlẹ̀ ni ibùdó tí ẹ̀rọ ayẹkaadi ìdìbò wò kó ba ṣiṣẹ́
Ọga agba fun ẹka eto idanilẹkọ fun awọn oludibo lọọfisi ajọ INEC, ẹka ti ipinlẹ Kwara, Amofin Jacob Ayanda salaye fun BBC pe, wọn yoo wọgile esi ibo ni ibudo idibo ti wọn ba ti dibo lai lo ẹrọ to n ṣayẹwo kaadi oludibo.
Bakan naa lo sọ pe, ẹnikẹni ti ẹrọ naa ko ba gba ika idibo rẹ̀, ṣugbọn to gba kaadi, iru ẹni bẹẹ yoo lanfaani lati dibo, amọ yoo kọ nọmba ẹrọ ibanisọrọ rẹ silẹ.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Sugbọn, ẹni ti ẹrọ naa ko ba gba kaadi, ti ko si tun gba ika, o tumọ si wipe ko si akọsilẹ nipa oludibo ọhun nibudo idibo naa.
Ati wi pe, ofin eto idibo ni Naijiria sọ pe eto idibo yoo waye ni ọjọ keji ọjọ idibo ni ibudo yoowu ti ẹrọ to n ṣayẹwo kaadi oludibo ko ba ti ṣiṣẹ rara fun gbogbo awọn oludibo to wa nibẹ, titi di aago meji ọsan to yẹ ki idibo pari.
Algeria: Ààrẹ Bouteflika ti ń ṣàárẹ̀ láti ọdun márun, tó tún fẹ́ dìje padà
Oríṣun àwòrán, AFP
Algeria: Bawo ni ààrẹ tíí kìí sọrọ̀ yoo ṣe dari olrilẹ-èdè
Ni orilẹede Algeria, ó soro láti róye bíi ààrẹ orilẹ̀-ede naa, Abdelaziz Bouteflika to jẹ́ ẹni ọdun mẹ́jìlélọ́gọ́rin, yoo se dari orilẹede naa, nitori pe ó ti ni àìsàn rọ́pa rọsẹ̀ láti bii ọdun mẹ́fà sẹ́yin, ìnira si ní ìrìn àti ọ̀rọ̀ sísọ gan jẹ fun un.
Oyo Election: Makinde ní ìpínlẹ̀ Ọyọ kò fk ajẹ́lẹ̀ mọ́
Ó jẹ́ ohun ti ènìyàn kò si lée gbàgbọ́ nígba ti wọn kédé pé Abdelaziz Bouteflika, yoo tun dije fun ìgbà káàrún nínú osu kẹ́rin, Bouteflika ko tilẹ yoju lọjọ àìkú láti wa forukọ silẹ̀ pé òun fẹ dije.
Eyi kún ohun to faa ti onírúru iwa ehonu ṣe bẹ̀rẹ̀ lórílẹ̀-èdè Algeria, ti àwọn akẹkọ̀ọ́, olùkọ́, agbẹjọrò àti àwọn akọroyin bẹ́rẹ̀ si ni fẹhonu han, ti wọn sì ń wọ́de kiri ìgboro, èyi to n fìdí rẹ̀ múlẹ̀ pé, wọn kò fẹ́ ki ààrẹ ti kò le pasẹ ó dari àwọn mọ.
Ọ̀pọ̀ araalu ni ọ̀rọ̀ náà ń kọ lóminu pé, ti ko ba si elòmíràn ti wọn lee fi rọ́pò ààrẹ Bouteflika, to ti di ààrẹ láti ọdun 1999, eyi lée da omí ètò ijọba rú, to ba fi kú sórí aleefa.
Kwara Election: Àwọn ẹgbẹ́ òṣèlú náà ní gbígbá PDP kúrò ní Kwara ló jẹ àwọn lógún
Awọn ẹgbẹ oselu to to marundinlogoji lo ti korajọ pọ ni ipinlẹ Kwara, lati se atilẹyin alailẹgbẹ fun ẹgbẹ oselu APC, ko lee moke ninu ibo gomina nipinlẹ naa.
Awọn ẹgbẹ oselu naa, lasiko ti wọn n sepade pẹlu awọn akọroyin lati kede ipinnu wọn naa, wa rọ awọn ọmọ ẹgbẹ wọn lati di ibo wn fun oludije ibo gomina fẹgbẹ oselu APC nipinlẹ Kwara, Abdulrazaq Abdulrahman.
Nigba to n ki awọn ẹlẹgbẹjẹgbẹ oloselu naa kaabọ nibi ipade akọroyin naa, alaga fẹgbẹ oselu APC nipinlẹ Kwara, Bashir Bọlarinwa ni ohun to dara ni bawọn ẹgbẹ oselu naa se pinnu lati sugba oludije ipo gomina fẹgbẹ APC.
Ninu ọrọ tiẹ naa, agbẹnusọ fun awọn ẹgbẹ ti imọ wọn sọkan naa, Oladele Oluseun naa kesi awọn ololufẹ ẹgbẹ wọn, lati se atilẹyin fun ẹgbẹ oselu APC ninu ibo gomina ọjọ Satide.
Lara awọn ẹgbẹ oselu to korajọ lati se atilẹyin fun ẹgbẹ APC ni ẹgbẹ oselu Kowa, PPN, ADC, NCP ati PDC sugbọn ẹgbẹ oselu Labour ko si lara awọn ẹgbẹ oselu to peju sibi ipade akọroyin naa.
Saaju nigba to n ba akọroyin BBC Yoruba sọrọ, ni kete to gunlẹ si npapakọ ofurufu ilu Ilọrin, oludije fun ipo gomina labẹ egbe oselu Labour nipinlẹ Kwara, Comrade Issa Aremu sọ pe, egbe oun ati APC si n fọrọ jomitoro ọrọ lọwọ nipa idibo gomina ati tawon asofin ipinle Kwara to de tan.
Seyi Makinde: Màá fẹ́ káwọn aráàlú mọ ìpa ìjọba mi lára sí rere
Amọ ko sọ pato boya ẹgbẹ oselu Labour yoo juwọ silẹ fun ẹgbẹ oselu APC lati di gomina lasiko ibo ti yoo waye lọjọ Satide, sugbọn Arẹmu ni eyikeyi ninu oludije fẹgbẹ APC ati Labour to ba wọle, ko si eyi ti ko dara nibẹ.
"Arẹmu ni "" Ohun kan soso lo se pataki si wa, eyi si ni ba se gba ẹgbẹ oselu PDP kuro lori aleefa. Ati awa, ANRP ati APC si ni ọrọ wa Papọ."
Nigeria 2019 Election: Ilé iṣé ológun ní àwọn olóṣèlú kan fẹ́ yin àdó olóró lásìkò ìbò gómìnà
Oríṣun àwòrán, Nigerian army
Ọrọ lori ibo gomina
Olori ile isẹ ologun oriilẹede Naijiria, Ọgagun agba Tukur Buratai sọ pe, iwadi awọn fihan pe awọn olosẹlu kan n gbero lati da rogbodiyan silẹ lasiko idibo gomina ọjọ Abamẹta.
Ọgagun Burutai ni awọn eeyan kan n gbero lati tajẹ silẹ, bẹẹ ni wọn si fẹ ju ado oloro lati da ibo iru lọjọ Satide.
Ṣugbọn Burutai ni ile iṣẹ ologun ko ni gba wọn laye lati mu ipinnu wọn ṣẹ.
Oyo Election: Makinde ní ìpínlẹ̀ Ọyọ kò fk ajẹ́lẹ̀ mọ́
Ọgagun BUrutai fọrọ yii lede nibi ipade to ṣe l'Abuja l'Ọjọru pẹlu awọn lọgalọga ninu iṣẹ ologun.
Burutai salaye pẹlu ẹdun ọkan pe, awọn ọmọgun mẹta ati oṣiṣẹ eleto idibo kan padanu ẹmi wọn lasiko ibo aarẹ lọjọ kẹtalelogun oṣu keji to lọ.
O fi asiko ipade naa kilọ fawọn ologun lati mase tẹle olosẹlu kankan lasiko idibo ṣugbọn ki wọn gbiyanju lati dẹkun iwa jagidijagan lasiko ibo.
2019 Election Update: Ìgbìmọ̀ ìgbẹ́jọ́ fún Atiku láyè láti ṣàyẹ̀wò ohun èlò ìdìbò ààrẹ
Oríṣun àwòrán, Facebook/Atiku Ababakar
Ibo aarẹ orilẹede Naijiria
Igbimọ igbẹjọ kotẹmilọrun lori ibo ti fun oludije si ipo aarẹ fẹgbẹ oṣelu PDP Atiku Abubakar lanfani lati ṣayẹwo ohun elo idibo ti ajọ INEC lo lasiko ibo aarẹ ọjọ kẹtalelogun oṣu keji.
Ninu idajọ rẹ, adajọ Abdul Aboki sọ pe Atiku lẹtọ lati ṣayẹwo ohun elo idibo ti ajọ INEC lo gẹgẹ bi ofin to de eto idibo lorilẹede Naijiria ti sọẹ agbekalẹ rẹ.
Ṣugbọn adajọ Aboki ni Atiku ko ni lanfani lati ṣe ẹda awọn ohun idibo naa nitori ofin ko faye gba a.
Nigeria Elections 2019:Ìbò la ní kí ẹ dì, àwa kò bá tìjà wá
Awọn meji yoku Peter Ige ati Emmanuel Agim ti wọn wa ninu igbimọ ẹlẹni mẹta naa faramọ idajọ ọhun.
Aarẹ Muhammadu Buhari ati ẹgbẹ osẹlu APC ti wọn fẹsun kan ko si nibi igbẹjọ ọhun.
Agbẹjọro agba Livy Ozoukwu lo ṣoju Atiku Abubakar ati ẹgbẹ oṣelu PDP nibi igbẹjọ naa.
Ekiti: Lẹ́yìn ààwọ òṣèlú, gómìnà Ekiti méjì fẹ̀rín pàdé ara wọn
Oríṣun àwòrán, Twitter/Govt. of Ekiti State
Ọrọ lori eto oṣelu ipinlẹ Ekiti
Ta ba gbagbe ọrọ ana, a ko ni rẹni ba sere. Eyi lo mu ki gomina ipinlẹ Ekiti Kayode Fayemi ati gomina ana nipinlẹ naa, Ayo Fayoṣe, di mọ ara wọn nibi ayẹyẹ kan l'Ọjọru.
Fayẹmi to sọ ọrọ apilẹkọ nibi ayẹyẹ idanilọla ni iranti ọjọ ibi Oloye Obafemi Awolọwọ, eyi ti agbẹjọro agba Afẹ Babalọla se agbatẹru rẹ niluu Eko, n pada lọ si ijoko rẹ, nigba ti Fayose dide lati lọ ki, ti awọm mejeeji si so mọ ara wọn.
Bo tilẹ je pe Fayẹmi ti fi ọgbọn sọrọ si Fayoṣe ninu ọrọ apilẹkọ rẹ, ninu eyi to ti sọ pe agbẹjọro Afẹ Babalọla ti da iyi ipinlẹ Ekiti pada, yatọ si awọn kan to jẹ pe ohun amayedẹrun to n mu inu kun nikan ni wọn mọ.
Nigeria Elections 2019:Ìbò la ní kí ẹ dì, àwa kò bá tìjà wá
Ṣugbọn Fayoṣe kọ eti ikun si ọrọ naa, o si dide lati ki Fayẹmi nibi ayẹyẹ ọhun.
Awọn eeyan to wa nijoko bu sẹrin, bi Fayẹmi ati Fayoṣe ti na ọwọ ara wọn soke.
Bẹẹ ba gbagbe, Kayọde Fayẹmi lo gbo ewuro soju Kolapọ Olusọla ti ẹgbẹ PDP, ti Ayọdele Fasoye n se atilẹyin fun, ninu ibo gomina ipinlẹ Ekiti, amọ ti Fayoṣe sọ pe eeru ni ẹgbẹ APC fi wọle ibo naa.
2019 Election: Akala ní aráàlú kò ní kábàámọ̀ tí Adelabu bá wọlé
Idibo gomina ipinlẹ Oyo
Bi idibo gomina se wọ le de, gomina ipinlẹ Oyo tẹlẹ ri, Otunba Adebayo Alao-Akala ti kede pe oludije labẹ asia ẹgbẹ APC, Oloye Adebayo Adelabu yoo sọ ipinlẹ Oyo ji to ba wọle gẹgẹ bi gomina.
Akala fọrọ yii lede nibi ipolongo idibo fun oludije APC niluu Ogbomoso ni Ọjọru.
Akala rọ awọn eeyan ilu Ogbomọṣọ lati tu yaya jade dibo fun Adelabu Penkelemesi lọjọ Abamẹta.
Nigeria Elections 2019:Ìbò la ní kí ẹ dì, àwa kò bá tìjà wá
O ni wọn ko ni kabamọ ti wọn ba dibo yan Adelabu  gẹgẹ bi gomina tuntun nipinlẹ Oyo.
Bẹẹ ba gbagbe, awọn oludije fẹgbẹ oṣelu ADC, Sẹnẹtọ Olufemi Lanlehin, ZLP, Oloye Sharafadeen Alli. SDP, Oloye Bolaji Ayorinde ati oludije fẹgbẹ oṣelu NPM, Edward Ladoye naa ti gba lati ṣatilẹyin fun oludije fẹgbẹ oselu PDP, Seyi Makinde, ninu idibo ọjọ Abamẹta.
Atiku: N36m ni àwọn kan ń tọrọ fún mi láì mọ̀ lórí ayélujára
Oríṣun àwòrán, @Atiku
Oludije fun ipo aarẹ fẹgbẹ PDP, Atiku Abubakar, ti kede faraye pe oun ko mọwọ tabi mẹsẹ ninu ikede agbe sise ti awọn eeyan kan n se fun oun lori itakun agbaye.
Atiku ni agbe ti wọn tẹ pẹpẹ rẹ naa ni wọn sọ pe o wa lati se atilẹyin fun oun lori ẹjọ ti oun pe lati tako esi ibo aarẹ, ti Muahammadu Buhari bori.
Nigba to n fesi si ọrọ yii, ọgbẹni Phrank Shaibu tii se agbẹnusọ fun Atiku lori eto ibaraẹnisọrọ ati aabo ni ko si ohunkohun to kan Atiku ninu bara ori itakun agbaye naa, eyi to ti n fa ariyanjiyan.
Afojusun ati oju inu ẹni to se agbatẹru eto ẹdawo naa ni eyi jẹ, eto adani rẹ si ni pẹlu, tori, Atiku ko mọ nipa rẹ rara.
Oríṣun àwòrán, @InstaKwara
Bakan naa ni Shaibu salaye siwaju si pe, owo to to ẹgbẹrun lọna ọgọrun dọla, eyi tii se miliọnu mẹrindinlogoji naira, ni awọn eeyan ọhun kede pe awọn fẹ kojọ fun Atiku lati fi se ẹjọ to pe lori esi ibo aarẹ, to si jẹ pe ni ọjọ kansoso pere, wọn ti ri owo to to ẹgbẹrun lọna ẹẹdẹgbẹrin naira.
Nigeria Election 2019: Ará Eko pariwo ohun márùn-ún tí wọn ń fẹ́ lọ́wọ́ ìjọba tó ń bọ̀
Bi o tilẹ jẹ pe wọn ti pa ikede ọhun rẹ lori oju opo ikansira ẹni Twitter ti wọn gbe si, sibẹ agbẹnusọ fun oludije ẹgbẹ APC naa wa n kesi awọn araalu lati takete si ẹdawo ọhun nitori kii se eyi ti Abubakar Atiku lọwọ si.
Nigeria Elections 2019: Iléẹjọ́ ní Adebutu pẹ́ kó tó pe ẹjọ́ tako Kashamu
Oríṣun àwòrán, Buruji Kashamu
Ile ẹjọ giga ijọba apapọ to wa nilu Abẹokuta tun ti fidi rẹ mulẹ pe sẹnetọ to n soju ẹkùn idibo Ila oorun ipinlẹ Ogun, Buruji Kashamu ni oludije fun ipo gomina ipinlẹ Ogun labẹ asia ẹgbẹ oṣelu PDP.
Ile ẹjọ fagile ẹjọ ti ọmọ ẹgbẹ PDP, to tun jẹ ọmọ ile igbimọ aṣoju-ṣofin, Ọladipupọ Adebutu pe, tako yiyan Kashamu gẹgẹ bi oludije ẹgbẹ.
Adajọ Abubakar Shittu fidi rẹ mulẹ pe, olupẹjọ pẹ ko to o gbe ẹjọ naa wa sile ẹjọ, pẹlu alaye pe, ọjọ Kejila oṣu Kẹrin ọdun 2018 ni igbesẹ ẹgbẹ waye, ṣugbọn Adebutu ko pe ẹjọ titi di oṣu Kejila ọdun 2018.
Bakan naa lo sọ pe, ẹgbẹ oṣelu PDP tapa si aṣẹ ti ile ẹjọ pa fun wọn pe, wọn ko gbọdọ pe ẹjọ mi i lori ẹni to lẹtọ lati ṣeto idibo abẹle tabi fun ajọ eleto idibo ni orukọ awọn oludije ẹgbẹ.
Nigeria Elections 2019: Àwa Mọ́gàjí ilẹ̀ Ibadan kìí dásí ọ̀rọ̀ òṣèlú'
Ipade itagbangba BBC Yoruba
Lọjọbọ ni iroyin kan jade lori ẹrọ ayelujara pe, awọn Mọgaji ilẹ Ibadan ti kilọ fun eekan kan ninu ẹgbẹ oṣelu All Progressives Congress, APC, Bọla Tinubu, lati mase da si ọrọ oṣelu ipinlẹ Ọyọ.
Iroyin naa to ni awọn igbimọ Mọgaji ilẹ Ibadan sọ, lo tun n fewe ọmọ mọ gomina nigba kan nipinlẹ Ọyọ, Alao Akala leti pe, ko sọ ohun ti yoo maa sọ nipa Osi Olubadan, Rashidi Ladọja.
Ṣugbọn ṣaa, ọkan lara awọn Mọgaji ilẹ Ibadan, Oloye Waheed Yusuf Fadairo, tii se Mọgaji ile Ado ni Oke-Ado, Ibadan sọ fun BBC Yoruba pe, awọn kan to ṣẹṣẹ jẹ oye Mọgaji, ti ko ju bi mẹta lọ, lo maa n sọ iru awọn ọrọ bẹẹ.
O ni awọn Mọgaji to wa ni igun Olubadan kii ba wọn dasi tabi sọ iru ọrọ bẹẹ.
Alao Akala:Èmi àti Ajimọbi kò ṣe ìlérí kankan fún ara wa
Lori iha ti wọn kọ si eto idibo gomina ti yoo waye nipinlẹ Ọyọ, Fadairo sọ pe, awọn mọgaji kii dasi ọrọ oṣelu, nitori pe ẹni ti awọn araalu ba ba lọ, naa ni awọn fọwọsi.
''Ẹni to ba si jawe olubori naa lo jawe olubori.''
Lori eto aabo lagboole ẹnikọọkan wọn lasiko idibo, o salaye pe, awọn gẹgẹ bi Mọgaji ti sọ fun awọn to wa ni agboole kọọkan, lati mojuto adugbo wọn, ati pe, ki wọ̀n mase bo aṣiri ọmọ to ba n hu iwakiwa.
O ni ki wọn o fi awọn isẹlẹ to ba waye ni sakani wọn to awọn alaṣẹ agboole leti, lati le jẹ ki awọn ọlọpaa mọ si.
Ọdọkunrin kan padanu ẹmi rẹ sọwọ awọn janduku ni agbegbe Kudẹti niluu Ibadan, lasiko idibo aarẹ to waye lọjọ kẹtalelogun oṣu Keji.
R Kelly: Èmi kò jẹ̀bi ẹ̀ṣùn fífi ipá bá ọmọdé lòpọ̀
Oríṣun àwòrán, CBS
R Kelly ń sukun lóri TV bó ṣe kọ ẹ̀sun ìfipábáni lòpọ̀
Olórin tàkasúfèé ọmọ ilẹ̀ Amẹ́ríkà ń sunkún pẹ̀lú ìbínú lóri ẹ̀sùn pé, ó fi tipá banilòpọ̀ lásìkò to ṣe ìfòrọ̀wánilẹ̀nùwò àkọ́kọ́ lẹ́yìn to ti wà lágọ̀ọ́ ọlọpàá láti oṣù tó kọja.
"''Emì ko ṣe ǹkan ti wọn ní mo ṣe. kìí ṣe èmi nìyí"" ǹkan ti Kelly sọ niyi lásìkò tó ń ṣe ìfọ̀rọ̀wánílẹ́nuwò pẹlú ilé iṣẹ́ ìròyìn CBS, ó fi kún pé ""mò ń gbìyànjú láti móríbọ nínú ẹ̀sùn yìí."""
Ọwọ́ sìnkún àwọn agbófinro tẹ Kelly ní Chicago, pẹ̀lú ẹsùn oní kókó mẹ́wàá tó jẹ mọ ẹsun fífi ipá bá àwọn ọmọ mẹ́rin sùn, ti mẹ́ta nínú wọn sí jẹ ọmọde lásìkò ti ọ̀rọ̀ náà sẹlẹ̀.
Ó sọ pé òun kò jẹ̀bi ẹ̀sùn ti wọn fi kan òun kí wọn to yọ̀nda rẹ̀ lẹ́wọ̀n.
Tí R Kelly bá jẹ̀bi àwọn ẹsun ti wọn fi kàn án , ó ṣeeṣe kí ó lọ ẹwọn ọdun mẹ́ta sí méjé fún ẹsun kọ̀ọ̀kan.
Ìgbà míràn niyi lẹ́yìn èyí tó ṣẹ́lẹ̀ lọ́dun 2002, tí Kelly yoo kojú ẹsùn mọ́kànlélógùn tó fi mọ sísàfihan àworàn ìhòhò àwọn ọmọ kéèkéé, ti ọmọ kan nínú wọn si jẹ́ ọmọ kékeré
Sùgbọ́n àṣẹ̀yìn wá àṣẹ̀yìn bọ, adájọ nígbà náà sọ pé, kò si àrídájú pé ọmọ tó wà nínú fọ́nran ti wọn gbé yọjú sílẹ̀ ẹjọ jẹ ọmọ kékéré.
Wọn fẹnukò pé Kelly kò jẹbi ẹsùn kankan.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
R Kelly ń sukun lóri TV bó ṣe kọ ẹ̀sun ìfipábáni lòpọ̀
Kelly sọ fún akọ̀ròyìn CBS Gayle King pé, wọn lo ẹsun ọjọsí gẹgẹ bíi 'gbèdéke fún ẹsun túntún tí wọn wé mọ òun lẹ̀sẹ̀.
"Kelly ní ""wọn padà sórí ẹsùn ti ó wáyé lọ́jọ́sí láti jẹ ki gbogbo ǹkan to ṣẹ̀lẹ̀ lásìkò yìí dàbi tòòtọ́ lóju àwọn ènìyàn."""
Bákan náà ló tako ẹsùn ti wọn fi kàn nínú fónrán ti wọn pè ni Surviving R Kelly pé, ó kó àwọn obinrin pamọ lòdi sí ìpinu wọn, tó sì ń gba fóònù wọn, sàmójútó ounjẹ wọn, kò sì fún wọn láànfàní láti rí àwọn ẹbi wọn.
" A  jẹ pé aṣiwere ni R Kelly, pẹ̀lú gbogbo ǹkan ti ojú mí ti rí, kí ń wá ma mú àwọn ọmọde lòdì si ìfẹ́ wọn, ''lo ọ̀pọ̀lọ  ẹ,'' èyí ní Kelly sọ fun àkọròyìn níwájú ayawòràn.
''Gbàgbe nípa àwọn akọiroyin òfégé, gbàgbé nípa ǹkan to rò nípa mi. Kórira mí to ba wù ọ, fẹ́ràn mi tó ba wù ọ, sùgbọ́n lo ọpọlọ ẹ''
''Báwọ ni mó ṣe ya asìwere tó pẹ̀lú bí ǹkan ṣe ri láti ẹ̀yìn wá, àti gbogbo ǹkan ti mo ti là kọja, ṣe mó fẹ́ di aṣerubani ni, tí maa wá mú ọmọ obinrin lọ de wọn mọlẹ sí inú ilé kan?"
"Simi èré ṣíṣé, simi eré ṣíṣe,  bó se sọ èyí ló búsẹkún, ""Kìí ṣe èmi ní èyí''"
Oríṣun àwòrán, Getty Images
R Kelly ń sukun lóri TV bó ṣe kọ ẹ̀sun ìfipábáni lòpọ̀
"Gbogbo yín ń gbìyànjú lati pa mí? Ǹkan ti Kelly sọ niyi.
Kelly gbà pé mo ti ṣe àwọn ǹkan tí kò da tó pọ̀ pàápàá lóri ọ̀rọ̀ obìnrin"" sùgbọ́n ""Mo tọrọ aforijin lásìkò àwọn ajọṣepọ̀ nígbà náà."""
Ó ní ìrírí òun pẹ́lú ìbálopọ̀ tipatipá gẹ́gẹ́ bíí ọmọde kò nípa lára òun, ti òun yóò fi wa má fi hùwa gẹ́gẹ́ bi àgbàlàgbà.
"Mó nílò ìrànlọ́wọ́, Kelly sọ fun King. Mo nílò ìrànlọwọ láti kọ mi ní ọ̀nà ti ǹ ko fi ni máá ṣe oore púpọ̀ nítori oore ti mò ń ṣe, ní àwọn eniyan fi ń jámi kulẹ̀ báyìí, ti mò sì ń dárijì wọn ní gbogbo igbà"""
Sááju ní King ti ṣe ìfọ̀rọ̀wánílẹ̀núwò pẹ̀lú àwọn obìnrin méjì, Azriel Clary àti Joycelyn Savage, tí wọn n jẹ wọ́le-wọde Kelly lọ́wọ́lọ́wọ́.
Fọnran aworan kan fi ọ̀kan nínú àwọn obinrin náà, Clary to jẹ ọmọ ọdun mọ́kànlélógún hàn, bó ṣe ń sunkún lásiko tó ń satilẹyin fun olokiki akọrin náà.
Oríṣun àwòrán, CBS
Kelly sọ pe Azriel Clary àti Joyceln Savage jẹ ọ̀rẹ́binrin òun
"O ní "" Mó ń sunkún, ẹ mọ òòtọ́,"" Ìrọ́ lásàn nítorí owó ní èyí"""
Ẹ̀wẹ̀, àwọn òbi Alice àti Angelo Clary ti gbe àtẹjadé kan sita, tí wọn si tako iroyin to ni olokiki akọrin naa mu àwọn ọmọ àwọn pamọ, lòdì si ìfẹ́ inú wọn.
"Sugbọn iroyin naa ni Azriel ní ààrùn ọpọlọ tó lágbàra, taa ba wo iru ìjìyà to ti rí lọ́wọ́ R Kelly. Wọn ni o seese ko ti ni ààrún ti wọn ń pè ní ""Stockholm"", tí ènìyàn yóò máà nífẹ̀ si ẹni to mú ní tipatipa."
2019 elections: Ọwọ́ ọlọ́pàá tẹ afurasí pẹ̀lú ìbọn nípínlẹ̀ Ọyọ
Ọga ọlọpaa ni ko saye iregbe lasiko idibo to n bọ nipinlẹ Ọyọ
Awọn ọlọpaa nipinlẹ Ọyọ ti mu awọn afurasi ọdaran kan ti wọn ka awọn ohun ija oloro mọ lọwọ
Kọmiṣọna ọlọpaa Shina Olukolu ni eyi jẹ afihan ara igbaradi ileeṣẹ ọlọpaa fun ipese abo lasiko idibo ọjọ abamẹta.
O ni ko si aniani pe awọn agbofinro ti tubọ jawe sobi lori eto abo nipinlẹ Ọyọ.
Gẹgẹbi o ṣe sọ, oju gbogbo yoo wa lara ipinlẹ Ọyọ lasiko idibo naa, idi si niyi ti ileeṣẹ ọlọpaa ko fi ni wọn ọn laabọ fun ẹnikẹni to ba fẹ da aṣọ iwa janduku, iwa ọdaran tabi jagidijagan kan ṣoro, ṣaaju tabi lasiko idibo naa.
Bákan náà ni ọlọ́pàá tún mú afunrasí míràn pẹ̀lú agbarí èèyàn kan
Oniruru ohun ija oloro ati ọta ibọn ni awọn ọlọpaa naa ri gba mọ awọn afurasi naa lọwọ.
Bakan naa ni ọwọ tun tẹ arakunrin ọmọ ọgbọn ọdun kan pẹlu agbari eeyan lọwọ.
Nigeria Elections 2019:Ìbò la ní kí ẹ dì, àwa kò bá tìjà wá
Afurasi naa ni agbẹ ati darandaran ni oun ṣugbọn awọn ọlọpaa ni lasiko ti o n bọ wa si ilu Ibadan, ni ọwọ palaba rẹ segi.
2019 elections: Awọn jàǹdùkú yìnbọn f'éèyàn méjì nítorí owó ní Kwara
Ṣọ́ọ̀bù àti ọkọ lóríṣiríṣi ni wọ́n bàjẹ́ lásìkò tí àwọn agbébọn naa kọlu àdúgbò náà
Nṣe ni ọrọ di pẹntuka, boolọ o yago fun mi nilu Ilọrin loru ọjọru mọ ọjọbọ ninu eyi ti eyan meji ọtọọtọ ti ṣe kongẹ ọta ibọn.
Akala lè ṣàtìlẹ́yìn fẹ́ni tó bá wù ú
Wahala yii waye lagbegbe Adabata si Kuntu nigbati awọn olugbe ibẹ ni awọn janduku agbebọn kan ti wọn funra si pe wọn jẹ oniṣẹ iku awọn oloṣelu kan ya bo adugbo naa ti wọn si ba ọpọlọpọ dukia jẹ.
Ṣọ́ọ̀bù àti ọkọ lóríṣiríṣi ni wọ́n bàjẹ́ lásìkò tí àwọn agbébọn naa kọlu àdúgbò náà
Nigba ti akọroyin BBC News Yoruba yoo fi de adugbo naa ni ọjọbọ nṣe ni gbogbo adugbo naa pa lọọlọ.
Ṣọ́ọ̀bù àti ọkọ lóríṣiríṣi ni wọ́n bàjẹ́ lásìkò tí àwọn agbébọn naa kọlu àdúgbò náà
Ọpọlọpọ ọkọ ati sọọbu lawọn janduku naa bajẹ.
Awọn eeyan adugbo naa ni owo lawọn janduku naa n ja si
Ninu ọrọ tawọn olugbe adugbo naa ba BBC News Yoruba sọ, ija lori owo lo ṣokunfa rogbodiyan ọhun.
Bílíọ̀nù kan náírà ni INEC ń san fún CBN àti ọmọogun oju òfurufú
Oríṣun àwòrán, @inecnigeria
Bílíọ̀nù kan náírà ní àjọ elétò ìdìbò (INEC) yóò náá lóri kíkó àwọn ohun èlò ìdìbò ẹlẹgẹ́ pamọ si ilé ìfowopamọ àpapọ.
O tún wà fún gbígbé wọn lọ sí ìpínlẹ̀ mẹ́rẹ̀ẹrìndínlógoji tó fi mọ olúlùú orílẹ̀-èdè Nàìjíríà, Abuja pẹ̀lú ìrànwọ àwọn ọmọ ogun ojú òfurufú.
Bí INEC ṣe ń mójú tó kíkó àwọn ohun eèlò ìdìbò pamọ jákèjádo orílẹ̀-èdè Nàìjíríà ní àwọn ọmọ ogun ojú òfurufú ń gba lọ si ìpínlẹ̀ ti wọn tọ́ sí.
"Gẹ́gẹ́ bí iwé ètò INEC fún ìdìbò ọdun 2019 se ka rèé "" ìpèsè owó fun ilé ìfòwópamọ àpapọ̀ fún kíko àwọn ohun eèlò ẹlégẹ́ pamọ́ to fi mọ́ owó àwọn ọmọ ogun ojú òfurufú N1,050,000,00"
Kíkó àwọn ohun èlò pamọ́ fún ìdìbò ni àwọn ìpínlẹ̀ mẹ́rìndílógójì àti olúlu Nàjíríà nínú ìdìbò mééjèjì na wa ni: N28,378,378.38
Akala lè ṣàtìlẹ́yìn fẹ́ni tó bá wù ú
BBC Yorùbá: Àwọn akọ̀ròyìn wa ti lọ káàkiri láti jábọ̀ ìròyìn ìbò
Ọgá àgbà ọmọ ogun òfurufú, ti sọ lásiko tó ń ṣe àpérò pẹ̀lú àwọn oníròyìn ní'lú Abuja pé ọkọ òfurufú mẹ́jọ ni àwọn ti rán jáde láti gbé àwọn ohun eèlò ẹlẹgẹ́ lọ sí ibùdó ìdìbò wọn.
Nigeria Election 2019: Ará Eko pariwo ohun márùn-ún tí wọn ń fẹ́ lọ́wọ́ ìjọba tó ń bọ̀
Ó fí kún un pé àwọn bàálú fó fun wákati òjìlélọ́ọdúnrún pẹ̀lú òsìṣẹ́ ọgọ́fà to fi mọ awakọ̀ ofurufu àti àwọn òṣìṣẹ́ amoju ẹ̀rọ míràn.
#NigeriaDecides: BBC ti wa ni gbogbo ìpínlẹ̀ Naijiria láti firoyin gbogbo tóo yin létí
Kò sí ìwé ẹ̀rí fun olùdíje tí tó ba wóle lábẹ hílàhílo
Oríṣun àwòrán, @inec
Mahmood ti fawon eeyan Naijiria lokan bale pe, didun losan a so ninu idibo 2019 nitori INEC a ṣiṣẹ bo ti yẹ
Àjọ elétò ìdìbò Nàìjíríà (INEC) ti ni kò sí ìwé ẹ̀rí fun olùdíje kankan tí ó ba jáwé olúbori lábẹ ìdìbo to ní hílàhílo.
O tun ni ajọ naa ko ni pin iwe ẹri fun ẹnikẹni to ba jawe olubori lasiko ti òṣìṣẹ́ eléto ìdìbò ba sọ èsì ìdìbò nítori pé ẹ̀mi rẹ̀ wà lábẹ́ ewu nínú níbi ìdìbò gómìnà tí yóò wáye lọ́la Satide, ọjọ kẹsàn osù Kẹ́ta, ọdún 2019.
Bákaǹ náà ni àjọ náà fi kún pé gbogbo ibi tí òṣìṣẹ́ INEC bá ti mọ̀ọ́mọ̀ maa lo ẹ̀rọ ayẹ káàdì ìdìbò wò ní àwọn yóò wọ́gilé ìdìbò wọn.
Akala lè ṣàtìlẹ́yìn fẹ́ni tó bá wù ú
Ìbádọ́gba nínú ìsèlú àti iṣẹ́ láwùjọ ṣe pàtàkì fún ìdàgbàsóké
Alága àjọ INEC, ọjọgbọ́n Mahmood Yakubu ló sọ èyí di mímọ lásìkò to ń ṣe ìpàdé pẹ̀lú àwọn àjọ tó ni ṣe pẹ̀lú ọ̀rọ̀ ìdìbò tó fi mọ àwọn elétò ààbò lólú ìlé ìṣẹ́ INEC l'Abuja lánà
"Yakubu ní "" Ohun tó kọmilominú ni àwọn ǹkan eèlò ìdìbò tó fi mọ ẹrọ ayẹ káàdì ìdìbò, ìwé ìdìbò, ati àwọn ohun eèlò míràn tó sọnu nítóri àwọn ìwà ìpánle tó wáye láwọn ìpínlẹ̀ kan pàápàá jùlọ ìkọlù ti wọn ń se sí àwọn osìṣẹ́ elétò ìdìbò."""
BBC Yorùbá: Àwọn akọ̀ròyìn wa ti lọ káàkiri láti jábọ̀ ìròyìn ìbò
"Ọ̀pọ̀ àwọn òsìsẹ́ wa ní wọn jígbé pamọ́ lójùnà àti da ètò ìdìbò rú tábi ṣe màgòmágó sí abájade èsì ìbò, kódà àwọn àtundi ìbò tí yóò wáye jẹ́yọ látàrí àwọn ìdí wọnyí.
Ẹ̀wẹ̀ àjọ INEC kò ni fọ́wọ́leràn láti máà woran kí wọn máà jí òṣìṣẹ́ àjọ náà gbé pamọ tàbí mú wọn ni dandan láti kéde ẹni to jáwé olúbori nínú ìbẹ̀rù bojo, nítori naa àjọ wá ko ni máa san ẹsan fún aburu láti máa kéde'pé wọn jáwe olubori.''"
#NigeriaDecides: BBC ti wa ni gbogbo ìpínlẹ̀ Naijiria láti firoyin gbogbo tóo yin létí
Gẹ́gẹ́ bi ó ṣe sọ ìpínlẹ̀ mọ́kàndínlọgbọ̀n ní ìdìbò gómìnà yóò ti wáye tí wọ́n yóò sì dìbò yan ènìyàn ẹgbẹ́rún kàn ó dí mẹ́sàn sílé ìgbìmọ̀ aṣòfin nígbogbo ìpínlẹ̀ pátápáta, alága mẹ́fà àtí kànsẹ́lọ mẹ́jìlélọ́gọ́ta ní olú ìlú Nàìjíríà l'Abuja.
Nigeria Election 2019: Ará Eko pariwo ohun márùn-ún tí wọn ń fẹ́ lọ́wọ́ ìjọba tó ń bọ̀
Ajọ náà yóò tún ṣe àtúndi ìbò ní ìpínlẹ̀ mẹ́rìnla àti ẹkún ìdìbò mẹ́rìnlélógún.
2019 elections: Ganduje ní òun yóò gba èsì yóòwù tó bá jáde ní ìdìbò gómìnà Kano
Oríṣun àwòrán, kabiru gaya
Gandije ni oun gba pe Ọlọrun mọ̀ sí èsì yóówù tó bá jáde nínú ìdìbò náà.
Gomina ipinlẹ kano, Abdullahi Ganduje ti ṣalaye ohun ti yoo ṣe bi okete ba padi ọrẹ da fun ninu idibo gomina ọjọ satide.
Ganduje ni ko si meni meji fun oun bi oun ba fidirẹmi ninu idibo naa ju pe ki oun ki ẹni to ba bori ku oriire.
Ìbádọ́gba nínú ìsèlú àti iṣẹ́ láwùjọ ṣe pàtàkì fún ìdàgbàsóké
Gomina Ganduje sọ eyi di mimọ lasiko ti o fi n tọwọ bọwe adehun alaafia ni ilu Kano.
Gomina ipinlẹ Kano ọhun ni oun to ye oun ni pe Ọlọrun nii fi ọba jẹ oun naa si nii rọ ọba loye.
BBC Yorùbá: Àwọn akọ̀ròyìn wa ti lọ káàkiri láti jábọ̀ ìròyìn ìbò
"O ni: ""Bẹẹni, mo ṣetan lati gba bi esi idibo naa ba ti ṣe lọ si gẹgẹ bii ifẹ Ọlọrun, mo si ni igbagbọ to jinlẹ ninu ifẹ Ọlọrun."""
Nigeria Election 2019: Ará Eko pariwo ohun márùn-ún tí wọn ń fẹ́ lọ́wọ́ ìjọba tó ń bọ̀
2019 elections: Ilé iṣẹ́ ológun ní ìwé òfin Nàìjíríà fàyè sílẹ̀ fáwọn láti wà níta fún àmójútó ìdìbò
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ileeṣẹ ologun ni iwe ofin Naijiria faye gba wọn ninu eto idibo
Ileeṣẹ ologun orilẹede Naijiria ti sọ wi pe awọn ko ṣe ayọjuran si eto idi idibo to n lọ lọwọ lorilẹede Naijiria.
Olu ileeṣẹ ọmọogun orilẹede Naijiria ṣalaye fun awọn akọroyin lọjọ ẹti pe atilẹyin fun awọn ọlọpaa ni ojuṣe ti wọn yan fun awọn ninu eto idibo naa.
Alukoro fun ileeṣẹ ọmọ ogun orilẹede Naijiria. Onyema nwachukwu ni ojuṣe yii wa ni ibamu pẹlu ilakalẹ abala iwe ofin ọdun 1999.
"Abala ikọkanlelaadọrin o le igba 271 iwe ofin ọdun 1999 naa ṣalaye pe a lee ko awọn ọmọogun sita ""lati ran awọn ọlọpaa lọwọ lasiko idibo"""
Amọ ṣa, o ni ninu ṣiṣe ojuṣe yii ilana gbogbo wa fun awọn ọmọogun lati tẹle ki wọn maa baa kọja aye wọn.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ileeṣẹ ologun orilẹede Naijiria tun sọ wi pe ọmọogun kankan ko gbọdọ wọ aṣọ ogun lọ si ibudo idibo kankan
O ni yatọ si eyi awọn ọmọogun naa lẹtọ lati dibo, ṣugbọn ko si eyikeyi wọn to gbọdọ wọ aṣọ iṣẹ wọn lọ si ibudo idibo.
Bakan naa lo tun fi ọkan araalu balẹ pe, awọn ologun ko nii lọkan lati gbẹsan lori awọn ọmọogun ti awọn janduku kan kọlu lasiko idibo aarẹ to waye laipẹ yii.
Ìpànìyàn l'Eko: Ilé ẹjọ́ dá ẹjọ́ ikú fún ọkùnrin tó pa ìyàwó rẹ̀
Oríṣun àwòrán, Google
Ìjọba ìpínlẹ̀ Eko fẹ̀sùn kan Lekan Shonde pé ó lu ìyàwó rẹ̀ pa, lẹ̀yín to fi ẹ̀sùn kan pé iyawo rẹ̀ pé óún yan àlè.
Ile ẹjọ giga ti da ẹjọ iku fun ọkunrin kan, Lekan Shonde to lu iyawo rẹ Ronkẹ pa, ni bii ọdun mẹta sẹyin.
Onidajo Agba, Josephine Oyefeso lasiko to n se idajọ naa ni Ọjọ Ẹti sọ wi pe o jẹbi ẹsun ẹyọkan ti ijọba ipinlẹ Eko fi kan an.
Adajọ ile ẹjọ giga ipinlẹ Eko ni gbogbo ẹri fihan wi pe lootọọ ni Lekan Shonde pa iyawo rẹ Ronke.
Ìbádọ́gba nínú ìsèlú àti iṣẹ́ láwùjọ ṣe pàtàkì fún ìdàgbàsóké
Ọdun mẹta sẹyin ni iroyin gbe e wi pe ọkunrin ẹni ọdun mọkanlelaadọta kan ti lu iyawo rẹ pa ni ile wọn ni agbeegbe ẹgbẹda-idinmu ni ipinlẹ Eko.
Wọn ni ọkunrin naa ti ilẹkun mọ oku iyawo rẹ pẹlu awọn ọmọ meji ko to di wi pe ọmọ ọdọ wọn wa lọ fi ẹjọ sun ni agọ ọlọpaa.
Ethiopian Airlines crash: Èèyàn 157 dèrò ọ̀run nínú bàálú tó já
Ajọ iṣọkan agbaye n ṣọfọ àwọn eniyan wọn to lọ
Bayii, apero ajọ iṣọkan agbaye to yẹ kó bẹ̀rẹ̀ loni ti mọ iṣẹlẹ ijamba yii lára pupọ.
Kete ti wọn ṣide ipade ẹka ijiroro lori ọrọ awujọ oni lajọ iṣọkan agbaye ni Nairobi ni wọn ti dide iṣẹju kan fun gbogbo oloogbe inu iṣẹlẹ ijamba ọhun.
Ajọ UN ṣalaye fun BBC pé awọn eniyan wọn naa wa ninu iṣẹlẹ ibi naa to dùn wón gidigidi.
APC jáwé olúborí nípínlẹ̀ Ekiti
Iroyin fihan e ọmọ Naijiria meji wa lara awọn to ku ninu baalu orilẹ-ede Ethiopia kan, Boeing 737 to ja lulẹ loju ọna rẹ lati Addis Ababa si Nairobi.
Ojogbon Abiodun Bashua to jẹ oṣiṣẹ fẹyinti aṣoju Naijiria ni Sudan ati ọjọgbọn Pius Adesanmi to jẹ olukọ agba lori aṣa ilẹ Adulawọ ni fasiti ni Canada.
Oríṣun àwòrán, Ethiopian Airlines
Ileeṣẹ baalu Ethiopia ṣe afihan aworan ibi ti ọga agba ileeṣẹ naa Tewolde Gebremariam ti lọ sibi ti baalu naa ti ja
Baalu naa ko eero mọkandinlaadọjọ, to fi mọ awọn oṣiṣẹ baalu mẹjọ. Awọn alaṣẹ ileeṣẹ baalu naa ni iṣeju mẹta pere ti baalu naa gbera ni o ja lulẹ
Baalu naa ko eero mọkandinlaadọjọ, to fi mọ awọn oṣiṣẹ baalu mẹjọ.
Awọn orilẹede mẹtalelọgbọn ti awọn eniyan wọn ku nibẹ ree:
Kenya (32), Canada (18), Ethiopian (9), China (8), Italy (8), American (8), French (7), British (7), Egypt (6), Netherlands (5), UN passport (5), India (4), Russia (3), Morocco (23), Israel (2), Belgium (1), Uganda (1), Yemen (1), Sudan (1), Togo (1), Mozambique (1), Norway (1), Nigeria (1)
Oríṣun àwòrán, FlightRadar24
Irinajo ọkọ naa re ninu ẹrọ FlightRadar 24
Awọn oṣiṣẹ aranilọwọ ti ijọ aguda mẹrin naa wa ninu ijamba naa.
Oríṣun àwòrán, Reuters
Awọn ara orilẹede China kan n reti awọn eniyan wọn to wa ninu baalu naa
Agbẹnusọ ileeṣẹ naa sọ pe ijamba naa waye ni nkan bi aago mẹsan ku iṣẹju mẹrindinlogun lowurọ ọjọ Aiku, laipẹ to kuro ni olu ilu oeillede Thiopia.
Aago meje aabọ (GMT) ni ọkọ ofururu naa yẹ ko balẹ si papa'kọ ofurufu Jomo Kenyatta to wa ni Kenya.
Akọroyin BBC  kan ba arakunrin kan ti iṣlẹ naa ṣoju rẹ Bekele Gutema to wa ni agbegbe naa nigba sọ wipe:
"''Ibugbamu to lagbara kan ni a gbọ ti ina si sọ, o pọ to bẹẹ ti a ko le sun mọ ibẹ. Gbogbo nkan to wa nibẹ lo ju run. Awọn panapana de ibẹ ni bi i wakati mẹta lẹyin ti ọkọ naa ja lulẹ. Ko si ẹnikan kan to le yè."""
Oríṣun àwòrán, Reuters
wọn panapana de ibẹ ni bi i wakati mẹta lẹyin ti ọkọ naa ja lulẹ
Olootu orilẹ-ede naa, Abiy Ahmed fi sori Twitter pe ''oun ba awọn mọlẹbi to padanu eniyan wọn kẹdun iku awọn to ku sinu ijamba naa.''
Awọn ọmọ Naijiria to tun wọ ọkọ to ja lulẹ naa ri ti n fi ibanujẹ wọn han lori iṣẹlẹ naa. Ọkan ninu wọn ni Ọjọgbọn Joe Abah.
Sugar: Ilé ìwòsàn UCH ló dákẹ́ sí torí ọgbẹ́ ọta ìbọn
Oríṣun àwòrán, Temitope Sugar
Ọmọ agboole Efungade-Onigbodogi, Alafara Oje ni ijọba ibilẹ Ibadan North East ni ipinlẹ Ọyọ, ni Ọlatoye Temitọpẹ ti ọpọ mọ si Sugar.
Onigbodogi ati Alape ni ọlọkọ to wa Temitọpẹ wa sile aye lọdun 1973, ṣe wọn ni ọmọ Ibadan ti ko ba ni agboole ati oko kii ṣe ojulowo ọmọ Ibadan.
Ileewe alakọbẹẹrẹ St Michael Primary School, Yemetu ati I.M.G Primary School, Beyerunka, Alafara Oje ni Temitọpẹ lọ.
Lẹyin naa lo gba ileewe girama Ikolaba Grammar School, St Luke's College, Molete ati Alugbo Comprehensive High School, Egbeda lọ, ti gbogbo rẹ ni ilu Ibadan.
Sugar gba iwe ẹri olukọni onipo kini ni ileewe ẹkọṣẹ olukọni NCE Federal College of Education, to wa ni Osiẹlẹ nilu Abeokuta, ipinlẹ Ogun, ki o to lọ si ileewe giga fasiti Ibadan lati gba iwe ẹri imọ ijinlẹ akọkọ, B.Sc, ati iwe ẹri imọ ijinlẹ keji.
Oríṣun àwòrán, Temitope olatoye
Sugar fara gba ọta ibọn ni lalupọn lasiko idibo lọjọ abamẹta
Kansilọ ni ijọba ibilẹ Ọdẹda lo fi bẹrẹ irinajo oṣelu rẹ. Wọn yan an gẹgẹ bii amugbalẹgbẹ fun ijọba ipinlẹ Ogun lasiko iṣejọba Ọtunba Gbenga Daniel.
Lẹyin to ti jẹ olori ẹka ọdọ fun ẹgbẹ oṣelu PDP ni ẹkun idibo apapọ aringbungbun ipinlẹ Ogun, lo wa lọ du ipo alaga ijọba ibilẹ Lagelu ni ipinlẹ Ọyọ ni ọdun 2007.
Oríṣun àwòrán, olatoye sugar
Ile iwosan nla UCH ni ilu Ibadan lo ku
Ni ọdun 2011, ni wọn fi ibo yan an si ile aṣofin ipinlẹ Ọyọ labẹ aṣia ẹgbẹ oṣelu Accord, ki o to wọle gẹgẹ bii ọmọ ile igbimọ aṣoju-ṣofin to n soju ẹkun idibo Lagelu/Akinyele, labẹ aṣia ẹgbẹ oṣelu APC.
Ni ọdun 2018 lo darapọ mọ ẹgbẹ oṣelu ADP lati du ipo Sẹnetọ ki o to fidirẹmi.
Ile iwosan nla UCH ni ilu Ibadan lo ku si ni ọjọ kẹsan oṣu kẹta ọdun 2019,  lẹyin ti o fara gba ọta ibọn ni agbegbe Lalupọn lasiko idibo sipo gomina to waye nibẹ.
Arsenal vs Manchester United: Arsenal borí i Manchester United ní Premier league
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Arsenal lo fi o to gẹẹ si irinajo olubori ti Manchester United ti bẹrẹ si nii rin lati igba ti olukọni wọn, Ole Gun Solkjaer ti gba iṣẹ
Ẹgbẹ agbabọọlu Arsenal gbo ewuro si oju  Manchester United lọjọ aiku ninu ifẹsẹwọnsẹ Premier league ilẹ Gẹẹsi to waye ni papa iṣire Emirate.
Ami ayo meji si odo ni Arsenal fi gbẹyẹ mọ Manchester United lọwọ ninu ifẹsẹwọnsẹ naa.
Kanu ní ikọ̀ Ajax lè gba ìdíje Champions League ní sáà yìí
Xhaka lo gba goolu akọkọ wọle ni iṣẹju kejila ifẹsẹwọnsẹ naa, nigba ti Aubameyang gba gbeelẹ ko gba si goli, (Penalty) wọle nigba ti ifẹsẹwọnsẹ naa wọ iṣẹju mọkandinlaadọrin.
Pẹlu esi yii Arsenal yoo maa fi ami meji la Manchester United lori atẹ liigi ilẹ Gẹẹsi pẹlu bi ere ije tani yoo wa laaarin ipo mẹrin akọkọ ninu  liigi naa ṣe n gbona sii.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Igba akọkọ ni yii ti Manchester United yoo maa fidirẹmi ninu idije liigi ilẹ Gẹẹsi lati oṣu kejila ọdun 2018
Ṣaaju ifẹsẹwọnsẹ yii ọpọ itakurọsọ lo ti n waye laarin awọn onwoye, onimọ ere bọọlu atawọn ololufẹ ẹgbẹ agbabọọlu mejeeji lori pataki ifẹsẹwọnsẹ ọhun fun ati kopa awọn mejeeji ninu idije Champions league ni saa bọọlu to n bọ.
Arsenal lo fi o to gẹẹ si irinajo olubori ti Manchester United ti bẹrẹ si nii rin lati igba ti olukọni wọn, Ole Gun Solkjaer ti gba iṣẹ ni ọjọ kọkandinlogun oṣu kejila ọdun to 2018.
Diaspora: Ẹyin nikan kọ́ ni ọ̀rọ̀ idibo Naijiria kàn nílé
Igba akọkọ ni yii ti Manchester  United yoo maa fidirẹmi ninu idije liigi ilẹ Gẹẹsi lati oṣu kejila ọdun 2018. Ninu ifẹsẹwọnsẹ mejila ti wọn ti gba lati igba naa, wọn bori mẹwaa wọn si ta ọmi meji.
APC jáwé olúborí nípínlẹ̀ Ekiti
2019 Nigeria Election: Àgbùnbánirọ̀ pàdánù ẹ̀mí rẹ̀ nínú ìjàmbà ọkọ̀ ojú omi l'Ondo
Oríṣun àwòrán, NYSC
Iku agunbanirọ
Iroyin to tẹ wa lọwọ sọ pe agunbanirọ kan, Ibrahim Okanlawon to ṣiṣẹ pẹlu ajọ eleto idibo INEC ninu ibo gomina ati ile igbimọ aṣofin ipinlẹ lagbegbe Ewerebubou, wọọdu Arogbo ni ipinlẹ Ondo padanu ẹmi rẹ.
Iroyin naa tun sọ pe agunbanirọ miran tun ti dero ile iwosan nipinlẹ Ondo kan naa.
Okanlawọn ni o padanu ẹmi rẹ nigba ti ọkọ oju omi ti wọn wọ pada si ibugbe wọn doju de lẹyin idibo ọjọ nirọlẹ ọjọ Satide.
APC jáwé olúborí nípínlẹ̀ Ekiti
Ẹni ti iṣẹlẹ naa ṣoju rẹ ni ruru omi ati iji lile lo da ọkọ oju omi naa nu.
Ẹwẹ, igbakeji gomina ipinlẹ Ondo Ọgbẹni Agboola Ajayi ti ranṣẹ ikẹdun si ẹbi agunbanirọ to ba iṣẹlẹ naa lọ.
BBC Yorùbá: Àwọn akọ̀ròyìn wa ti lọ káàkiri láti jábọ̀ ìròyìn ìbò
Awọn meje miran ti ori yọ ninu iṣẹlẹ ọhun n gba itọju nile iwosan bayi.
Akala lè ṣàtìlẹ́yìn fẹ́ni tó bá wù ú
Diaspora: Ẹyin nikan kọ́ ni ọ̀rọ̀ idibo Naijiria kàn nílé
Pius Adesanmi: Ọ̀gọ̀ọ̀rọ̀ èèyàn ń dárò ọ̀jọ̀gbọ́n ọmọ Nàìjíríà tó kú nínú ìjàmbá bàálù Ethiopia
Oríṣun àwòrán, @pius
Ko sẹni ti kò ni ku laye!
Iku doro, iku sẹka. Iku mu ẹni re lọ.
Ọgọọrọ ọmọ orilẹ-ede Naijiria lo ṣedaro Ọjọgbọn Pius Adesanmi to wa lara awọn to padanu ẹmi wọn ninu ijamba baalu Ethiopia to ja lulẹ lọna Nairobi.
Adesanmi n lọ fun ipade ajọ ilẹ Afirika ni Nairobi ko to ṣagbako iku ojiji ninu ijamba baalu ọhun.
Ta ni Ọjọgbọn Pius Adesanmi gan an?
Ọjọgbọn Adesanmi lọ sile iwe Titcombe College niluu Egbe, bẹẹ lo tun kawe ni ile iwe giga fasiti ti ilu ijọba apapọ ni Ilorin, nipinlẹ Kwara nibi to ti gboye ninu ẹkọ ede Faranse.
Oríṣun àwòrán, Facebook/Pius Adesanmi
Iku mu Pius Adesanmi lọ
O tun tẹsiwaju nigba to gboye miran ninu ẹkọ ede Faranse ni fasiti ilu Ibadan.
Ọjọgbọn Adesanmi tun kẹkọọ ni fasiti British Columbia niluu Vancouver lorilẹ-ede Canada.
Oríṣun àwòrán, Twitter/Pius Adeasanmi
Iku mu Pius Adesanmi lọ
Adesanmi jẹ Ọjọgbọn ninu ede oyinbo ni fasiti Carleton nibi to ti n ṣiṣẹ ki ọlọjọ to de gẹgẹ bi oludari ẹkọ nipa ilẹ Afirika.
Iroyin kan sọ pe ọmọ orilẹ-ede Canada mẹjọ lo wa ninu ijamba baalu ọhun.
Oríṣun àwòrán, @pius
Ojogbon to mọ oyun inu ikarahun igbin ninu imọ aṣa ilẹ Adulawọ
Nitori naa o ṣeeṣe ko jẹ pe wọn ka Ọjọgbọn Adesanmi mọ awọn ọmọ Canada to ku ninu iṣẹlẹ ọhun nitori fọto rẹ to wa loju opo Facebook rẹ gan fihan pe iwe irinna rẹ si wa lọwọ rẹ nigba to wa ni papakọ ofurufu lọjọ Abamẹta.
Awọn awada to sọ bi ọrọ to kẹyin lori opo Twitter rẹ re e.
Ojọgbọn Pius Adesanmi kagbako ninu ijamba ọkọ to waye ni oṣu keje, ọdun 2018.
Eyi ṣẹlẹ nigba ti o n rinrin ajo ni ipinlẹ Ọyọ nigba to wa si Naijiria.
Oríṣun àwòrán, saharareporter
ọkọ ti ọjọgbọn Pius ti fi kọkọ ni ijamba ọkọ
Nigba ti BBC kan si awọn eniyan to mọọ daadaa bii akọwe fun gomina nile ijọba ipinlẹ Kogi, Petra Akiti-Oyegbule, ẹkun ni wọn bu si lori aago.
Ojọgbọn Naijiria miran naa ṣalaisi ninu ijamba ọkọ ofurufu ọhun
Ohun ti a tun gbọ ni pe Ọjọgbọn Abiọbun Bashua wa lara awọn ọmọ Naijiria to lugbadi iku ojiji ninu iṣẹlẹ baalu Ethiopia naa.
Ọjọgbọn Bashua ti ṣiṣẹ pẹlu ajọ iṣọkan agbaye gẹgẹ bi oludari ikọ to n ṣoju ajọ naa (UNAMID) ọdun 2015 lo fipo naa silẹ.
Aworan to ya kẹyin nigba to dipo naa mu re e.
Oríṣun àwòrán, Twitter/Abiodun Bashua
Iku pa ọjọgbọn meji ọmọ Naijiria
Opolopo awọn eniyan lo ti n ṣọfọ ọjọgbọn Bashua lori ayelujara.
Ki Ọlọrun dẹlẹ fun awọn eni rere, ọjọgbọn kikun to re iwalẹ àṣà.
Governorship Election Updates: Ajimọbi gba Makinde nimọran lati gbaradì fún iṣẹ́ ńla
Oríṣun àwòrán, Abiola Ajimobi
Gomina ipinlẹ Ọyọ, Abiola Ajimọbi ti ki gomina ti ilu sẹsẹ dibo yan, Onimọ ẹrọ Seyi Makinde ku oriire pe o jawe olubori ninu idibo gomina to kọja.
Ninu iwe ikini ku oriire naa ti Ajimọbi kọ, eyi ti oludamọran rẹ feto iroyin, Bọlaji Tunji fisita, lo ti gba Makinde nimọran pe nibayii ti eto idibo ti tan, yoo dara ko ko gbogb o awn eeyan tọrọ kan nidi isejọba ipinlẹ Ọyọ mọra ninu ijọba rẹ.
Ajimọbi tun rọ gomina tilu sẹsẹ dibo yan ọhun lati bẹrẹ si ni gbaradi fun isẹ nla to wa niwaju rẹ, ko si gbagbe gbogbo awọn ohun to sẹlẹ lasiko idibo, bẹẹ lo ni ko rọ awọn alatilẹyin rẹ lati dẹkun sisọ awọn ọrọ to lee tun da wahala silẹ nipinlẹ Ọyọ.
Oríṣun àwòrán, Seyi Makinde
Lati ọdun mẹjọ sẹyin, a ri daju pe ofin fẹsẹ mulẹ, ti idagbasoke ati agbega si ba ipinlẹ Ọyọ lati ipasẹ awọn aseyọri to fojuhan, gẹgẹ bawọn mẹkunnu labẹle ati awujọ agbaye ti n sọ.
Ni bayii ti mo n ki ọ ku oriire, mo gbadura pe wa se aseye ti alakan n se epo, mo si rọ ọ pe ko gbajumọ awọn eto idagbasoke ti mo ti se ni ẹka ipeese alaafia, eto aabo ẹmi ati dukia ti awọn araalu ti jẹ anfaani rẹ lati ọ̀dun mẹjọ sẹyin.
Kwara governorship: Gómìnà tí wọ́n yàn ní Kwara, Abdulrazaq ní òun yóò tún ìdigunjalè Offa yẹ̀wò
Oríṣun àwòrán, Rasaq Abdulrahaman
Ó ní òun yóò foríkorí pẹ̀lú agbófinró láti ṣàwárí àwọn tó wà ní ìdí ìdigunjalè náà
Gomina tuntun ti wọn ṣẹṣẹ dibo yan ni Kwara, Abdulrahaman Abdulrazaq ti ṣeleri ati fikunlukun pẹlu awọn ọlọpaa lati rii pe gbogbo awọn ti wọn lẹbọ lẹru lori idigunjale to waye ni ilu Ọffa jẹjọ bi o ti tọ ati bi o ti yẹ.
O ni oun yoo ri daju pe gbogbo ilana ofin to yẹ ni wọn tẹle ki gbogbo awọn to lọwọ ninu rẹ si lee jẹjọ.
#Governorship Election: Òjò ni wá, a kò bẹ́nì kan ṣọ̀tá -Sanwo Olu
Lasiko to fi n sọ ọrọ idupẹ rẹ lẹyin ti ajọ INEC kede rẹ gẹgẹ bii olubori idibo gomina to waye ni ipinlẹ Kwara lo sọ eyi di mimọ.
O ni oun ti o han si oun ati ọpọ ọmọ ipinlẹ naa ni pe awọn oniṣẹ ibi ti gbajọba ni ipinlẹ naa de ibi pe awọn olugbe ibẹ ko lee di oju sun mọ.
O ni ọpọ awọn banki ni ẹkun idibo guusu ipinlẹ Kwara ni wọn ko ṣi banki wọn mọ lẹyin idigunjale to waye ni ilu Offa naa.
APC jáwé olúborí nípínlẹ̀ Ekiti
"Eyi si n ṣe ọpọ akoba fun idagbasoke eto ọrọ aje ni ẹkun naa. A o forikori pẹlu awọn ọlọpaa lati mojuto ipenija eto abo .
Eeyan mẹtalelọgbọn lo padanu ẹmi wọn ninu iṣẹlẹ idigunjale ilu Offa, gẹgẹ bii awọn ọlọpaa si ti ṣe sọ, awọn oṣiṣẹ ijọba kan lọwọ ninu rẹ."""
Governorship Election Results: Seyi Makinde sọ ọ̀rọ̀ àkọ́sọ lẹ́yin èsì ìbò
2019 elections: INEC ní òṣìṣẹ́ rẹ̀ tó sá lọ kò ní gbowó iṣẹ́ rẹ̀
Oríṣun àwòrán, @inecnigeria
Òṣìṣẹ́ INEC tó sálọ náà lo yẹ ko dari eto idibo ni ijọba ibilẹ Calabar South
Ajọ INEC ti sọ pe ko si owo fun alamojuto idibo to fi ẹsẹ fẹẹ ni ipinlẹ Cross River lasiko idibo gomina ati aṣofin ipinlẹ naa.
Kọmiṣọna fun ajọ INEC ni ipinlẹ Cross Rivers, Ọmọwe Frankland Briyai lo sọ bẹẹ lasiko to n ba awọn oniroyin sọrọ ni ilu Calabar.
#Governorship Election: Òjò ni wá, a kò bẹ́nì kan ṣọ̀tá -Sanwo Olu
O ni alamojuto idibo ti a n sọrọ rẹ yii lo yẹ ko dari eto idibo ni ijọba ibilẹ guusu Calabar ki wọn to ṣadede rii pe o ti di awati.
BBC Yorùbá: Àwọn akọ̀ròyìn wa ti lọ káàkiri láti jábọ̀ ìròyìn ìbò
O ni lootọ oun mọ idi ti o fi  fi ẹsẹ rẹ fẹẹ amọ ṣa eyi ko ṣe ipalara fun eto idibo naa rara.
Kọmiṣọna ajọ INEC naa ṣalaye fawọn oniroyin pe inu oun dun pe idibo naa lọ ni irọwọ irọsẹ.
Ìbádọ́gba nínú ìsèlú àti iṣẹ́ láwùjọ ṣe pàtàkì fún ìdàgbàsóké
Ninu esi idibo ti ajọ INEC gbe jade ni ipinlẹ Cross River, PDP lo bori pẹlu ibo 381,484, oludije fun ẹgbẹ oṣelu APC John Owan-Enoh ni 131,161.
APC jáwé olúborí nípínlẹ̀ Ekiti
Pius Adesanmi: Awọn ọmọ Nàìjíríà ń ṣelédè lẹ́yìn akọni tó lọ
Oríṣun àwòrán, Adesanmi
Pius Adesanmi: Awọn ọmọ Nàìjíríà ń ṣelédè lẹ́yìn akọni
Gbógbo ọmọ Nàìjíríà nílé àti lẹ̀yìn odi tó jẹ́ ọ̀rẹ́ àti alábaṣiṣẹ́pọ̀ ọ̀jọ̀gbọ́n Pius Adebola Adesanmi tó jẹ́ Ọlọ́run nípe, lásìkò ti bàálù boeing 737 X8 tó ń lọ si Narobi lọ́jọ́ àikú, ọjọ Kẹ́wàá oṣù Kẹ́ta ọdun 2019 já, lẹ̀yìn ìṣẹ́jú mẹ́fà to gbera.
Gbogbo àwọn tó sọ̀rọ̀ nípa ọ̀jọ̀gbọ́n Adesanmi pẹlu BBC Yoruba sàlàyé pé, oloogbe naa jẹ ẹni ti a n pe ni olùfẹ ọmọ ènìyàn, ẹni to fẹ́ràn ará ìlú ti kìí fi ti ẹya ṣe.
Pius Adesanmi ní Wole Soyinka ìran yìí - ọmọ Naijiríà
Wọn ní akikanju ẹdá ni ọjọgbọ́n Adesanmi, ẹni to ṣetan láti jàjà ominira fun ilẹ adúlawọ nípa kíkọ ìwe ati ṣise ìlanilọye fun àwọn ọdọ.
Wọn fi kun pé, ohun ti Nàìjíríà sọnu nípa ẹni to ku yìí kii ṣe ńkan to ṣe fẹnu sọ tan.
Seyi Makinde: Màá fẹ́ káwọn aráàlú mọ ìpa ìjọba mi lára sí rere
Ní àgbo àwọn ọmọwe, wọn ni ọjọgbọn Adesanmi ni wọn woye pé yóò ropò ọjọgbọ́n Wole Soyinka, nígbà ti wọn ba lọ ibi àgbà ń rè.
#Governorship Election: Òjò ni wá, a kò bẹ́nì kan ṣọ̀tá -Sanwo Olu
Bakan náà ni àwọn ènìyàn lóri ayálujara náá ń banujẹ lóri akoni naa, to fi mọ Oby Ezekwesili.
Governorship election update: PDP ní ẹgbẹ́ òun ló ń mókè láwọ̀n ìpínlẹ̀ tí ìbò kó ti parí
Oríṣun àwòrán, InEC
Eto idibo
Ẹgbẹ oṣelu alako PDP ti sọ pe, eru ati jibiti ni ajọ eleto idibo INEC fẹ ṣe lẹyin ti ajọ naa kede wi pe, eto idibo gomina nipinlẹ mẹfa kaakiri orilẹede Naijiria ko tii yanju.
Ajọ INEC kede lọjọ Aje pe idibo gomina ni ipinlẹ Kano, Sokoto, Benue, Bauchi, Adamawa ati Plateau ko tii kẹsẹ jari.
Igba akọkọ re e ti irufẹ iṣẹlẹ yii yoo waye lati igba ti orilẹede Naijiria ti pada si ijọba awarawa lọdun 1999.
Governorship Election Updates: Ṣeyi Makinde lọ kí Ladọja lẹ́yìn tó yege ìbò
Ajọ INEC tiẹ ti kọkọ so eto idibo gomina nipinlẹ Rivers rọ nitori laasigbo to n ṣẹlẹ nipinlẹ naa.
Ṣugbọn ẹgbẹ oṣelu PDP fẹsun kan alaga ajọ INEC Ọjọgbọn Mamood Yakubu pe, ohun ti ẹgbẹ APC ni ki o ṣe, gan an lo n ṣe.
PDP ni ẹgbẹ awọn lo n leke nigbogbo ipinlẹ mẹfẹẹfa ti INEC ti ni eto idibo gomina ko tii yanju.
Alukoro fẹgbẹ oṣelu PDP, Ọgbẹni Kola Ologbondiyan to bawọn oniroyin sọrọ lọjọ Aje l'Abuja sọ pe ẹgbẹ naa ti ri aṣiri pe, ile iṣẹ aarẹ lo dari ajọ INEC.
Emeka Ihedioha: Ibo 273,404 lo ni, ti Nwosu to tẹle si ni ibo 190,364.
Oríṣun àwòrán, Emeka Ihedioha/Twitter
Igbakeji Abẹnugan Ile Igbimọ Aṣoju-ṣofin nigba kan ri, Emeka Ihedioha lo jawe olu bori
Ajọ eleto idibo INEC ti kede Igbakeji olori Ile Igbimọ Aṣoju-ṣofin nigba kan ri, Emeka Ihedioha to jẹ oludije ẹgbẹ oṣelu PDP gẹ́gẹ́ bii ẹni to jawe olubori ninu idibo gomina Ipinlẹ Imo.
Ẹni to gbe ipo keji ni Uche Nwosu ti ẹgbẹ oṣelu AA, iyẹn àna gomina ipinlẹ naa Rochas Okorocha. Ibo naa fa awuyewuye to pọ ti awọn eniyan si bẹnu atẹ lu bi Okorocha ṣe fa àna rẹ kalẹ lati rọpo rẹ.
Ihedioha ni ibo 273,404 ti Nwosu si ni ibo 190,364.
Oludije ẹgbẹ oṣelu APGA, Ifeanyi Ararume ṣe ipo kẹta pẹlu ibo 114, 676 ti Hope Uzondima ti ẹgbẹ oṣelu APC si ṣe ipo kẹrin, pẹlu ibo 96,458.
Gomina Imo tẹlẹ ri, Ikedi Ohakim lo gbe ipo karun-un pẹlu ibo 6,846.
Governorship Election Updates: Sanwo-Olu se abẹwo idupẹ si Bọla Tinubu
Ki wọn to ṣe ikede naa, rogbodiyan fẹ bẹ silẹ ni ipinlẹ naa, bi awọn ọmọ ẹgbẹ AA ati PDP ṣe n leri wipe, awọn yoo da wahala silẹ ti oludije awọn ko ba bori.
Nitori naa ni INEC ṣe kọkọ da ikede naa duro.
Nigeria Elections Updates: Àkójọpọ̀ orúkọ àwọn tí yóò gbàwé ẹ̀rí mo yege rèé
Oríṣun àwòrán, DDD
SSS
Ajọ eleto idibo nil Naijiria, INEC, ti kede pe Ọ̀jọbọ, ọjọ Kẹrinla osu kẹta ọdun yii ni awọn eeyan to yege ibo sile asofin apapọ yoo gba iwe ẹri Mo yege.
Ikede kan ti INEC fi soju opo ayelujara rẹ wa fewe ọmọ mọ awọn oludije ti orukọ wọn ko ba si ninu akọsilẹ awọn eeyan to yege ibo sile asofin apapọ, eyiti INEC fi sita, lati mase yọju si ibudo ti wọn yoo ti pin iwe ẹri naa.
Ohun to wa ya ni lẹnu julọ ni pe orukọ gomina ipinlẹ Imo, Rochas Okorocha ti INEC kede pe o yege ninu idibo sile asofin agba ni orukọ rẹ ko si lara awọn orukọ ti ajọ INEC kede pe yoo gba iwe ẹri mo yege.
Nigba to n salaye idi ti orukọ gomina Okorocha fi sọnu ninu orukọ awọn eeyan to yege ibo sile asofin agba, Inec salaye pe agidi ni Okorocha lo lati fi yege ibo naa, ti ko si jẹ ki ibo naa lọ nirọwọ rọsẹ.
Bẹẹ ba gbagbe, lasiko ti wọn ka esi ibo sile asofin agba ni ipinlẹ Imo, ni osisẹ agba fun ajọ eleto idibo, to yẹ ko jabọ esi ibo naa ti kede pe, se ni wn ko ohun ni papamọra lati kede ayederu esi idibo, kii si se ojulowo esi ibo lo wa ni akọsilẹ oun.
Oríṣun àwòrán, @NationaAssembly
Wayi o, lọwọlọwọ bayii, orukọ eeyan ọgọrun ni INEC gbe sita pe o yege ibo sile asofin agba, ninu asofin agba mọkandinlaadọfa to yẹ ko wa nibẹ.
Ninu ọgọrun Sẹnetọ tuntun naa, ẹgbẹ oselu APC ni ijoko mejilelọgọta nigbati PDP ni mẹtadinlogoji, ti YPP si ni ẹyọ kansoso pere.
Oríṣun àwòrán, Inec
Oríṣun àwòrán, Inec
Oríṣun àwòrán, Inec
Oríṣun àwòrán, Nec
Oríṣun àwòrán, Inec
Oríṣun àwòrán, Inec
Oríṣun àwòrán, Inec
APC: Akeredolu ti gba ‘Kueri’lórí aṣemáṣe rẹ̀ nínú ẹgbẹ́
Oríṣun àwòrán, Saharareporters
O ṣeeṣe ki ẹgbẹ oṣelu APC ni ki gomina ipinlẹ Ondo, Rotimi Akeredolu lọ rọkun nile fun igba diẹ, lẹyin to ba fesi lori iwe wa-wi-tẹnu-rẹ to gba, lati ọwọ igbimọ amuṣẹya (NWC) ẹgbẹ naa nitori pe o n gbe awọn igbesẹ to lodi si ifẹ ẹgbẹ oṣelu naa.
Agbẹnusọ fun APC, Lanre Issa-Onilu, sọ fun BBC Yoruba pe, Akeredolu ni gomina kẹta ti wọn yoo fun ni iwe wa salaye ara rẹ (Query) lori iru ẹsun yii. Awọn meji to ku ni Gomina Ipinlẹ Ogun, Ibikunle Amosun, ati Gomina Ipinlẹ Imo, Rochas Okorocha.
Issa-Onilu ṣalaye wipe, awọn igbesẹ kan pọn dandan ti wọn ba ti jawe wa-wi-tẹnu-rẹ fun ẹnikẹni ninu ẹgbẹ APC. O ni lẹyin awọn iwadii kọọkan ti wọn ba ṣe, ti o ba jẹ pe Akeredolu kuna ninu awọn ọna to pọ, wọn le ni ko lọ rọkun nile fun igba diẹ na.
Atẹjade kan lati ọdọ Akeredolu ti kọkọ sọ wipe, irọ ni wipe wọn ti kọwe wa-wi-tẹnu-rẹ si gomina naa, sugbọn awọn iroyin miiran tun fi han wipe, gomina Akeredolu n mura lati fi ẹgbẹ APC silẹ lọ AA.
Governorship Election Updates: Sanwo-Olu se abẹwo idupẹ si Bọla Tinubu
"Nigba ti a kan si agbẹnusọ rẹ, Ọmọwe Doyin Ọdẹbọwale lati fidi rẹ mulẹ pe se lootọ ni Akeredolu n fi ẹgbẹ́ APC silẹ, o sọ ninu atẹjisẹ kan to fi dahun ibeere naa pe, ""kii se ohun to le daindain pe Aketi n fi ẹgbẹ APC silẹ́."""
"Ọdẹbọwale ni, ""O ti mọ wa lara lati maa koju ipenija, eyi to n sẹlẹ yii naa ko si yatọ. Emi ko ti i ri iwe kankan ti APC kọ si gomina. Ẹnikẹni to ba ni Aketi fẹ lọ ẹgbẹ oṣelu miiran ko mo oun to n sọ."""
Darius Ishaku: Ìbò 520,432 ló ní, tí olùdíje APC sì ní ìbò 362,735
Oríṣun àwòrán, @@dariusdishaku
Oludije fun ipo gomina fẹgbẹ oselu PDP, to tun jẹ gomina ipinlẹ Taraba, Darius Ishaku, ni ajọ eleto idibo ti kede pe o moke ninu ibo gomina ti wn di lọjọ Satide.
Ishaku lo ni ibo 520,432, to si moke ni ijọba ibilẹ mejila ninu ijọba ibilẹ mẹrindinlogun to wa ni ipinlẹ naa.
Alatako rẹ latinu ẹgbẹ oselu APC, to se ipo keji ninu ibo naa, Alhaji Sani Abubakar Danladi lo ni ibo 362,735, to si rọwọmu nijọba ibilẹ mẹrin pere.
Nigba to n kede esi ibo naa, ni olu ileesẹ ajọ Inec to wa nilu Jalingo, Ọjọgbọn Shehu Iya ni niwọn igba to j pe gomina Ishaku lo gba iye ibo to pọ julọ, oun lo bori ibo naa.
Governorship Election Updates: PDP Kwara fèsì lórí àgbéǹde ìwádìí ìdigunjalè Ọffa
Oríṣun àwòrán, Abdulrahman Abdulrazaq
Ẹgbẹ oselu PDP nipinlẹ Kwara ti fesi lori ikede kan ti gomina ti wọn sẹsẹ dibo yan nipinlẹ kwara, Abdulrahman Abdulrazaq sọ pe, oun yoo tun iwadi se lori isẹlẹ idigunjale to wale nilu Offa lọdun to kọja.
Atẹjade kan ti akọwe ipolongo fẹgbẹ oselu PDP nipinlẹ Kwara, Tunde Ashaolu fisita salaye pe, o daju pe Abdulrazaq ko ni imọ to lori isẹlẹ idigunjale to waye nilu Ọffa.
"Ashaolu ni "" Niwọn igba ti a mọ pe agbara wa lọwọ gomina lati yan oun ti yoo jẹ isejọba rẹ logun, sugbọn gbolohun to jade lẹnu gomina tuntun ti wọn dibo yan nipinlẹ Kwara fihan pe, ohun mẹta kan n sẹlẹ si."
Ọhun akọkọ lo sọ pe, boya gomina tuntun ko mọ nkankan nipa bi idigunjale nilu Ọffa se waye ni, tabi ki wọn ma salaye bi ọrọ naa se jẹ gangan fun gomina tuntun.
Ekeji ni pe koo seese ki Abdulrazaq ma mọ bi wọn ti n se iwadi iwa ọdaran ati ilana igbẹjọ tabi ko jẹ pe oun gangan n pe aja ni ọbọ funra rẹ, to si fẹ bẹrẹ eto isejọba rẹ nipa dida omi alaafia eto oselu ru.
Oríṣun àwòrán, @PoliceNG
Eyikeyi ko wu ko jẹ, awa ọmọ ẹgbẹ oselu PDP nipinlẹ Kwara yoo jẹ ki Abdulrazaq mọ pe, ileesẹ ọlọpa ilẹ wa ni ẹkunrẹrẹ iwadi lọwọ, nipa bi idigunjale ilu Ọffa ti lọ, ti wọn si ti fi abajade iwadi wọn ransẹ si agbefọba to wa nileesẹ agbẹjọro agba ilẹ wa, ni igba meji ọtọọtọ.
Ninu abajade iwadi kinni ati ikeji, o foju han pe agbefọba naa ko fi epo bọ iyọ, to si ni funfun nẹnẹ ni ọwọ aarẹ ile asofin agba ilẹ wa, Bukọla Saraki ati gomina ipinlẹ Kwara to wa lori aleefa bayii, Abdulfatai Ahmed mọ.
Oríṣun àwòrán, @bukolasaraki
Ẹgbẹ oselu PDP ni, oun wa fẹ kede faraye pe, ninu isẹ akọse gomina tilu sẹsẹ dibo yan nipinlẹ Kwara, idunkooko mọni, idẹrubani, ati didọdẹ ẹni lo kọkọ rawọle.
PDP ni dipo ki Abdulrazaq sọrọ lori ilana ti yoo gba sejọba to durore, n se lo n fihan araye pe, ifẹsẹmulẹ alaafia nipinlẹ Kwara ko si lara ohun to mumu laya ijọba oun.
BREXIT: Geoffrey Cox ni àwọn ìdíwọ́ tó leè de ilẹ̀ Gẹ̀ẹ́sì mọ́lẹ̀ kò tíì yí padà
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ida mejilelaadọta ninu ọgọrun, 52%, lo sọ pe awọn faramọ ki ilẹ Gẹẹsi o kuro ni ajọ EU
Amofin agba ilẹ Gẹẹsi ti sọ pe bi ọrọ ti ṣe n lọ yii, afaimọ ki ilẹ Gẹẹsi o maa ṣi wa labẹ ofin ajọ ilẹ Yuroopu, lẹyin ti wọn ba fi ajọ naa silẹ pẹlupẹlu awọn ayipada ti olootu ijọba ilẹ naa ti ṣe si eto naa.
Geoffery Cox ni ko si ọna abayọ miran lati yanju iṣoro orilẹede Ireland lori igbesẹ ati fi ajọ naa silẹ lai si pe ajọ EU paapaa jẹ hoo sii.
Ni igba ti olootu ijọba ilẹ Gẹẹsi, Theresa May gbe adehun yiys ilẹ Gẹẹsi kuro ni ajs naa ka iwaju awọn aṣofin ni oṣu kinni nṣe lawọn aṣofin bu omi paa.
Amọṣa, iwoye awọn amoye kan ni pe yoo fẹ nira fun olootu May lati yi oju ọrọ naa pada ti a ba wo iye awọn eeyan to tako o ni igba akọkọ.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ọdún 2016 ni àwọn èèyàn ilẹ̀ Gẹ̀ẹ́sì dìbò lórí bóyá kí orílẹ̀èdè náà ó fi àjọ ilẹ̀ Yúróòpù sílẹ̀
Lẹyin ti olootu ijọba ilẹ Gẹẹsi, Theresa May rinrinajolọ si igbimọ aṣofin ajọ orilẹede Yuroopu, EU pẹlu akọwe eto atikuro lajọ ọhun, iyẹn Brexit, Ọgbẹni  Steve Barclay fun ipade pataki pẹlu Ọgbẹni Juncker ati Michel Barnier to jẹ alarinna lori eto naa, adehun waye lori awọn iwe kan.
Iwe adehun to de awọn igun tọrọ kan lori bi ilẹ Gẹẹsi ṣe fẹ kuro eleyi ti wọn lee lo lati bẹrẹ igbesẹ ẹhonu bi ajọ EU ba fẹ de ilẹ Gẹẹsi mọlẹ tipatipa.
Governorship Election Updates: ohun táwọn ará Kwara ń fẹ́ lọ́wọ́ ìjọba tuntun
Iwe adehun lori ajọṣepọ laaarin ilẹ Gẹẹsi ati ajọ EU lọjọ iwaju eyi ti yoo wa ilana miran dipo gbogbo ọna lati de ajọ naa mọlẹ loṣu kejila ọdun 2020.
Agbekalẹ aladaṣe kan eyi to laa kalẹ pe ko si ohun kan to lee di ilẹ Gẹẹsi lọwọ bi ijiroro ba foriṣanpọn laaarin ilẹ Gẹẹsi ati ajọ ilẹ Yuroopu lọjọ iwaju.
Ọpọ awọn aṣofin lo n bẹru pe awọn igbesẹ kan eleyi ti ilẹ Gẹẹsi kọkọ ṣeto rẹ ni oṣu kejila ọdun 2017 lee di ilẹ Gẹẹọi lọwọ ki o si fẹ sọs di isọmọgbe ajọ EU.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ida mejidinlaadọta ninu ọgọrun 48% si ni rara awọn ko faramọ ki ilẹ Gẹẹsi o kuro ni ajọ EU
Ilẹ Gẹẹsi yoo fi ajọ EU silẹ ni ọjọ kọkandinlọgbọn oṣu kẹta ọdun 2019 lẹyin ti wọn ti dibo bẹni tabi bẹẹkọ laaarin awọn eeyan orilẹede naa. Ninu ibo ọhun ida mejilelaadọta ninu ọgọrun, 52%, lo sọ pe awọn faramọ ki ilẹ Gẹẹsi o kuro ni ajọ EU, ida mejidinlaadọta ninu ọgọrun 48% si ni rara awọn ko faramọ ọ. Eyi ti tums si pe, eeyan miliọnu mẹtadinlogun o le irinwo ẹgbẹrun lo dibo bẹẹni, ti eeyan miliọnu mẹrindinlogun o le ọgọrun ẹgbẹrun si dibo bẹẹkọ ni ọdun 2016.
Ọgbẹni Juncker ti kọkọ ṣekilọ fawọn aṣofin ilẹ Gẹẹsi pe ọrọ naa yoo lẹyin bi wọn ba tun dibo lati bu omi pa igbesẹ naa.
Ninu eto oṣelu, awọn asiko kan maa n wa fun anfani ẹẹkeji, nnkan ti a ba wa fi anfani naa ṣe ku si wa lọwọ. Ko lee si anfani igba kẹta.
Governorship Election Updates: Ìdí tí ìdìbò kò fi yanjú láwọn ìpínlẹ̀ kan lórílẹ̀èdè Nàìjíríà
Ìdí tí ìdìbò kò fi yanjú láwọn ìpínlẹ̀ kan lórílẹ̀èdè Nàìjíríà
Ibeere ti awọn eeyan wa n beere bayii gan ni pe ki gan ni Inconclusive tí ajọ INEC n kede bayii pe o n fa idiwọ ti ko fi si ẹni ms gomina awọn ipinlẹ  kan lorilẹede NAijiria?
yii ati pe ki lo n faa idibo ti kii yanju lorilẹede Naijiria bii ti igba kan?
Idi kan ṣoṣo ni ajọ INEC fi lee kede pe idibo ko yanju ni ibi kan eyi to si lee faa ti wọn ko fi ni kede olubori nibẹ.
Gẹgẹ bii abala kẹrindinlọgbọn abadofin eto idibo INEC, ajọ INEC ko lee kede ẹni to jawe olubori bi iye ibo ti wọn ba wọgile ba pọ to eyi to ṣi lee ni ipa lara abajade idibo ọhun.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Abadofin eto idibo INEC, ajọ INEC ko lee kede ẹni to jawe olubori bi iye ibo ti wọn ba wọgile ba pọ to eyi to ṣi lee ni ipa lara abajade idibo ọhun
Iyẹn ja si pe bi iye ibo ti wọn wọngile ba ps ju iye ibo to ya oludije to lewaju ati eyi to tẹ lee lọ, wọn yoo kede idibo bẹl pe ko tii yanju ni.
Fun apẹrẹ bi iye ibo ti ẹni to ṣe ipo kinni ba fi n la ẹni to wa ni ipo keji ba jẹ ọgọrun, iye ibo ti wọn ba wọgile ko gbọdọ ju mọkandinlọgọrun lọ.
APC jáwé olúborí nípínlẹ̀ Ekiti
Ni kete ti iye ibo ti wọn wọgile ba ti ju mọkandinlọgọrun lọ, INEC yoo kede ibo bẹẹ 'Inconclusive' ni. Iyẹn jasi pe ibo bẹẹ ko yanju.
Idi ni pe o ṣeeṣe ki gbogbo awọn oludibo to le ni mọkandinlọgọrun, ti wọn wọgile naa dibo fun ẹni to n ṣe ipo keji ki o si tipasẹ bẹẹ pada wa ṣe ipo kinni.
Pẹlu eyii atundi ibo gbọdọ waye laaarin ọjọ mọkanlelogun.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Amofin Mohammed Fawẹhinmi to ba BBC News Yoruba sọrọ ṣalaye pe aikun oju oṣunwọn ajọ eleto idibo INEC lo faa ti ọrọ idibo ti ko yanju fi wa di tọrọ fọnkale.
O ni lootọ ofin daabo bo ajọ INEC lori ikede ibo ti ko yanju ṣugbọn gẹgẹ bii ọrs rẹ, ka ni ajọ INEC ṣe iṣẹ rẹ bii iṣẹ ni ọrọ yii ko ni ri bẹẹ.
2019 elections: Fayoṣe ní kò sí ìyàtọ̀ láàárín Buhari àtàwọn ọ̀daràn bíi Shina Rambo, Evans ajọmọgbé
Oríṣun àwòrán, Ayodele Fayose
Fayoṣe ní kò dájú bóyá ààrẹ Buhari leè fi ìpìlẹ̀ ìdìbò rere lélẹ̀ lórílẹ̀èdè Nàìjíríà
Gomina ana ni ipinlẹ Ekiti, Ayọdele Fayoṣe ti ni ajọṣepọ kan n bẹ laaarin aarẹ orilẹede Naijiria, Muhammadu Buhari atawọn gbajugbaja ọdaran lorilẹede Naijiria bii Anini, Oyenusi ati Evans ajọmọgbe.
Gbogbo eeyan lo mọ awọn ọdaran wọnyii ati iwa laabi wọn lawujọ, ṣugbsn ohun to ṣokunkun naa ni ibi ti aarẹ Buhari ti wa fara jọ wọn o.
Amọṣa, Fayoṣe ṣalaye lori oju opo twitter rẹ pe bi a ba n sọrọ ṣiṣe eto idibo ti ko ni makaruru ninu, eleyi to ni aarẹ n tẹnu mọ lẹnu ọjọ mẹta yii, bi igba ti eeyan ba ni ki awsn gbajugbaja ọdaran wọnyii o maa ṣe ileri awujọ ti ko ni iwa ọdaran ninu ni.
Fayoṣe ni ileri ti aarẹ Buhari n ṣe lati ṣeto idibo alailabawọn ninu ko lee ṣeeṣe nitori bi igba ti eeyan n ni ki awọn ọdaran o maa o maa ṣe ileri ati fi ohun ti wọn fi n ṣe fuja lawujọ silẹ ni.
Ninu awọn ọrọ to fi si oju opo twitter rẹ ọhun, Fayoṣe tun bu ẹnu atẹ lu bi aarẹ ṣe kuna lati buwọ lu iwe abadofin idibo tuntun eleyii to ni o kan lilo ẹrọ ayẹkaadi idibo wo ni dandan lasiko idibo.
"Ninu awọn atẹjade oju opo twitter rẹ ọhun, Fayose ni: ""Buhari n sọ pe afojusun oun ni lati fi ogun eto idibo alailabawọn lelẹ, ileri yii dabi igba ti Oyenusi, Shina rambo, Anini ati Evans ajọmọgbe ba n leri ati fi ogun awujọ ti ko ni iwa ọdaran lelẹ fun Naijiria."""
2019 elections: APC gba ìjòkò tó pọ̀ jùlọ ní ilé aṣòfin àgbà
Oríṣun àwòrán, Senate Nigeria
Ninu awọn ọgọrun ijoko ti wọn ti kede, obinrin mẹfa ti wa ninu wọn
Ẹgbẹ oṣelu APC lo ni ijoko to pọ julọ bayii fun ile aṣofin agba ni saa iṣejọba to n bọ.
Lasiko idibo apapọ to waye ni ọjs kẹtalelogun oṣu keji ọdun 2019, ijoko mejilelọgọta ni APC ri gbamu ninu ijoko mọkandinlaadọfa, 109 to wa ni ile aṣofin agba.
Ẹgbẹ oṣelu PDP ni mẹtadinlogoji ti ẹgbẹ oṣelu YPP si di ijoko kan ṣoṣo mu.
Bi o tilẹ jẹ pe ijoko mọkandinlaadọfa lo wa ni ile aṣofin agba ijoko ọgọrun ṣi ni ajọ INEC kede ti o si ti paṣẹ atundi ibo lawọn ipinlẹ kan.
Ni ọjọ kẹsan oṣu kẹta atundi ibo waye lawọn ẹkun idibo bii Abia South, Imo West ati North, Kogi East, Ondo South, Plateau South, Rivers East, Rivers West.
Lọwọ yii wọn n reti idajs ile ẹjọ lori ẹkun idibo Bauchi south.
Ninu awọn ọgọrun ijoko ti wọn ti kede, obinrin mẹfa ti wa ninu wọn.
Governorship Election Update: Àfikún ìdìbò yóò wáyé nìpínlẹ̀ mẹ́fà lọ́jọ́ kẹtàlélógún oṣù yìí
Oríṣun àwòrán, OTHER
Awọn eeyan n bere fun ki ajọ INEC yanju ọrọ idibo
Ajọ eleto idibo lorilẹede Naijiria, INEC ti kede ọjọ kẹtalelogun gẹgẹ bi ọjọ ti afikun idibo yoo waye lawọn ipinlẹ mẹfa ti idibo gomina ko tii pari.
Ọga ajọ INEC to n ri si eto iroyin ati ilanilọyẹ, Ọgbẹni Festus Okoye lo fọrọ naa lede lẹyin ipade to ṣe pẹlu awọn lọgalọga ajọ INEC lori ibo gomina to waye lọjọ Abamẹta to kọja.
O ṣalaye pe yoo waye nipinlẹ Adamawa, Bauchi, Benue, Kano, Plateau ati Sokoto ati ni gbogbo ibudo idibo ti ibo ile igbimọ aṣofin naa ko ti kẹsẹ jari kaakiri orilẹede Naijiria.
'Amosun ṣiṣẹ́ l'Ogun ṣùgbọ́n kí Dapo ma yà wá'
Ọgbẹni Okoye ni ajọ INEC yoo kede l'Ọjọru ni kikun awọn ẹkun ati ibudo idibo ti afikun idibo yii yoo ti waye.
O ṣalaye pe idibo gomina ko niyanju lawọn ipinlẹ mẹfa nitori rogbodiyan to bẹ silẹ lawọn ibikan, dida lilo ẹrọ kaadi idibo duro ati wi pe ajọ INEC gan an kuna lati ko ẹrọ kaadi idibo de awọn ibudo idibo kan.
Ọga INEC sọ pe ajọ naa ko le kede ẹni to jawe olubori lawọn ipinlẹ tọrọ kan yii lai ṣe afikun idibo gẹgẹ bi ofin to de eto idibo ni Naijiria ti sọ.
O ni ajọ INEC yoo tun ṣepade lati jiroro lori ọrọ idibo gomina nipinlẹ Rivers ti ajọ naa da duro lẹyin ti rogbodiyan bẹ silẹ kaakiri ipinlẹ naa.
Oyo State: Kí ló ṣẹlẹ̀ níbi ìgbẹ́jọ́ Alao-Akala n'Ibadan lónìí?
Igbẹjọ Adebayo Alao-Akala
Ile ẹjọ giga ni ilu Ibadan ti sun igbẹjọ gomina ipinlẹ Oyo tẹlẹ Otunba Christopher Adebayo Alao-Akala lori ẹsun iṣowo ilu bi bililọnu mọkanla aabọ kumọkumọ siwaju.
Ile ẹjọ naa to kalẹ si agbegbe Iyaganku n'Ibadan ni aisi ẹlẹri lo fa sababi ti o fi sun igbẹjọ naa si ọjọ keji oṣu karun un ọdun yii.
Kọmiṣọna tẹlẹ ri fun ọrọ ijọba ibilẹ ati ọrọ oye, Sẹnẹtọ Hosea Agboola ati oniṣowo Ọgbẹni Femi Babalola ni ajọ EFCC jọ fẹsun iṣowo ilu kumọkumọ kan.
Ẹsun onikoko mọkanla lajọ EFCC fi kan awọn mẹtẹẹta to da lori  iditẹ, gbigbe iṣẹ fun kọgila lai se eto isuna.
Awọn ẹsun miran ti wọn fi kan wọn ni pe wọn  ni ijẹri eke, rira dukia pẹlu owo jibiti ati gbigbe dukia naa pamọ.
Oríṣun àwòrán, Facebook/Alao-Akala
Igbẹjọ jibiti
Agbẹjẹro for ajọ EFCC Ọmọwe B. Ubi sọ pe nigba ti Akala wa nipo gomina, o gbeṣẹ iṣẹ ọna ṣisẹ to to bilọnu mẹjọ aabọ fun ilẹ imọ ẹrọ Pentagon laarin ọdun 2007 si ọdun 2009.
Ọmọwe Ubi ni Ọgbẹni Babalọla lo ni ile iṣẹ ọhun, oun lo si ṣagbatẹru ni ijọba ibilẹ mẹtalelọgbọn kaakiri ipinlẹ Oyo lai se eto isuna fun isẹ naa.
Collapsed Building: Ilé alájà mẹ́rin wó l'Eko
Iye eeyan to ti jẹ Ọlọhun ni pe ninu ijamba ile to wo ni ipinlẹ Eko ti di ogun bayii, eyi jẹ ohun ti ijọba ipinlẹ̀ Ẹko sọ.
Kọmisana fun eto ilera ni ipinlẹ naa Jide Idris lo fi idi ọrọ yìí múlẹ̀ ninu atẹjade kan , ṣungbọn ko sọ iye ọmọ wẹwẹ to wa ninu wọn.
Ọjọru ni ile naa da wo ni agbeegbe Ita Faaji, Lagos Island ni Isalẹ Eko.
Awọn oṣiṣẹ to n ri si iṣẹlẹ pajawiri atawọn adoola si gbyanju lati doola ẹmi awọn ti ijamba naa ba.
Ni owurọ ọjọ Ẹti ni awọn oṣiṣẹ ijọba ipinlẹ Eko bẹrẹ si ni wo àwọn ile ti ko dara ni adugbo naa.
Ìròyìn tó ń tẹ̀ wa lọ́wọ́lọ́wọ́ ní wí pé  ilé alájà mẹta náà ni ilé ìwé alakọbẹrẹ kan wà nínú rẹ̀ ní agbègbè Ita faji ipinlẹ Eko.
A gbọ iroyin pe ile iwe alakọbẹrẹ yii lo wa loke patapata ile alaja ọhun. Bakan naa, iroyin sọ pe awọn akẹkọọ ti ha sabẹ ile naa.
awọn oṣiṣẹ ile iṣẹ pajawiri atawọn adoola ẹmi ti wa nibi iṣẹlẹ naa.
Bakan naa, ikọ oniroyin BBC Yoruba naa ti n ko iroyin jọ.
'Amosun ṣiṣẹ́ l'Ogun ṣùgbọ́n kí Dapo ma yà wá'
Minimum Wage: Saraki dúpẹ́ lọ́wọ́ àwọn òṣìṣẹ́ fún sùúrù wọn lórí owó oṣù tuntun
Oríṣun àwòrán, Senate President
Ile Igbimọ Aṣofin Agba orilẹede Naijira ti bu ọwọ lu abadofin kan to ni ẹgbẹrun lọna ọgbọn naira ni yoo jẹ owo oṣu to kere ju ni orilẹede yii.
Alaga Igbimọ tẹẹkoto lori ijiroro ọrọ owo oṣu naa, Sẹnetọ Francis Alimikhena, lo ka abajade ijiroro igbimọ naa niwaju ile.
Ninu ọrọ rẹ, Aarẹ ile igbimọ aṣofin agba, Bukola Saraki yin awọn ọmọ igbimọ naa, o si tun dupẹ lọwọ awọn oṣiṣẹ Naijiria àti awọn ẹgbẹ oṣiṣẹ fun suuru wọn lori ọrọ naa.
"O ni, ""Mo fi da yin loju wipe ijọba ko ni duro fun iyanṣẹlodi ki a to ṣe oun to dara fun ara ilu. Mo lero wipe owo oṣu to kere ju tuntun yii yoo jẹ ki awọn oṣiṣẹ jara moṣẹ daradara si."""
Minimum Wage: Ilé ìgbìmọ asofin dájọ ti sísan yóó bẹ̀rẹ̀
Ọsẹ to kọja ni Saraki yàn ìgbákeji ọmọ ilé tó pọ̀jù lọ, Sẹnatọ Francis Alimikhena, gẹ́gẹ́ bii adelé olórí ìgbìmọ náà, lẹ̀yìn ti alága ti wọn yan Sẹnatọ Olusola Adeyeye yọ aara rẹ kurò, pelú àlàyé pé òun ni àìlera.
Collapsed Building: Ayálégbé ló dára bí ìjọba ṣe wólé àmọ́ wọ́n fẹ́ ìrànwọ́ ilé míràn
Nigba naa, Alimikhena fí ọkan àwọn ọmọ Nàìjíríà balẹ̀ pé ìgbìmọ̀ náà yóò múṣẹ́ ṣe ni wàràńṣesaà láti mu àbájade to ni ìtumọ lọ́sẹ̀ tó ń bọ
Ọkan nínú àwọn ọmọ ìgbìmọ̀ náà Sẹnatọ Solomon Adeola pe àwọn yóò ṣe àtúngbéyẹ̀wò snà ti wọn ń gbà pín owó sí ìpínlẹ̀ lójúnà àti sàn ẹgbẹ̀rún náírà gẹ́gẹ́ bi owó òṣìṣẹ́ tó kéré jùlọ jákejádò ẹka ìjọba
Adeola faramọ àgbékalẹ̀ tó wà nínú àbádofin owó òṣìṣẹ́ tó kére jùlọ, ó fi kun pé ti ilé ìgbìmọ fẹ́nukò pé gbogbo ìpele ìjọba ló gbodo san owo náà.
Lagos building collapse: LASEMA ní ìwadìí yòó yàtọ̀ lórí ilé tó wó nítorí ààrẹ àtàwọn èèkàn ti gbọ́ sí ìsẹ̀lẹ̀ náà
LASEMA ni iwadii yoo waye
Ijọba ipinlẹ Eko ti ni iwadii yoo bẹrẹ laipẹ lati mọ ẹni to lẹbi gan lori iṣẹlẹ ijamba ile to wo ni agbegbe Ita faaji nilu Eko.
Ajọ to n mojuto  iṣẹlẹ pajawiri nipinlẹ Eko, LASEMA ṣalaye fawọn oniroyin nibi ipade iroyin kan lowurọ ọjọbọ pe iwadii yoo waye lati mọ awọn ohun to ṣokunkun ati awọn ohun to ku diẹ kaato ṣaaju ijamba ile wiwo naa.
Nigba ti akọroyin ileeṣẹ BBC to wa nibi ibanisọrọ naa beere boya iyatọ yoo wa lori iwadii ọtẹ yii nitori ọpọ ile lo ti wo ṣaaju ti ijọba ṣe iwadii si ni araalu ko ri abalọ-ababọ rẹ, Ọga agba LASEMA naa ni iyatọ yoo wa lọtẹ yii nitori awọn eekan ilu titi kan aarẹ Buhari ti wọn ti gbọ sii.
Ọga agba ajọ LASEMA,Tiamiyu ṣalaye pe ko si ẹni tii le sọ ni pato iye awọn ọmọ ileewe to fara kaaṣa ninu iṣẹlẹ naa nitori pe titi di asiko yii, ẹni to ni ileewe naa ṣi wa lẹsẹ kan aye, ẹsẹ kan ọrun nileewosan bayii, ko si si ẹni ti o lee ṣalaye ni pato iye awọn ọmọ ileewe to wa si ileewe ni ọjọru ti iṣẹlẹ buruku naa ṣẹlẹ.
LASEMA ni eto idoola ẹmi yoo pari ni ibudo naa ni ọjọbọ
Bakan naa ni ọga agba LASEMA naa tun ṣalaye pe ajọ naa ko tii lee sọ iye awọn to fara kaaṣa naa lapapọ ṣugbọn ireti wa pe orukọ awọn to wa ninu iṣẹlẹ naa yoo jade laipẹ.
O wa rọ awọn obi tabi alagbatọ to ṣi n wa ọmọ wọn lati tẹ siwaju lọ sawọn ileewosan ti wọn ko wọn lọ fun ayẹwo eeyan wọn.
O ni Ọjọbọ ni wọn yoo pari eto idoola ẹmi to n waye ni ibudo iṣẹlẹ naa.
2019 elections: INEC pín iwé ẹ̀rí fún àwọn aṣòfin àpapọ̀ tí wọ́n ṣẹ̀ṣẹ̀ dìbò yàn
Idibo si awọn ijoko kan yoo ṣi waye lawọn ẹkun ti ko tii yan aṣofin apapọ
Ni ọjọbọ lawọn aṣofin apapọ ti wọn dibo yan lorilẹede Naijiria gba iwe ẹri iyansipo wọn.
Ajọ INEC n fun  awọn aṣoju-ṣofin atawọn sẹnetọ ti wọn yan yoo gba iwe ẹri wọn lọwọlọwọ bayii ni gbọngan nla Main Hall (Africa Hall), International Conference Centre, ni ilu Abuja.
Háà! Fayoṣe fi Buhari wé Shina Rambo, Evans ajọmọgbé
Kò sí ìwé ẹ̀rí fun olùdíje tí tó ba wóle lábẹ hílàhílo
APC gba ìjòkò tó pọ̀ jùlọ ní ilé aṣòfin àgbà
Nibi eto naa, awọn sẹnetọ ni yoo kọkọ gba iwe ẹri ki o to kan awọn aṣoju-aṣofin ajọ.
Ajọ INEC ko tii pari gbogbo idibo si awọn ijoko ile aṣofin apapọ mejeeji yala nitori idajọ ile ẹjs lawọn agbegbe kan ati atundi idibo ti yoo waye lawọn miran.
'Amosun ṣiṣẹ́ l'Ogun ṣùgbọ́n kí Dapo ma yà wá'
Lara awọn ti ko ni gba iwe ẹri loni ni gomina ipinlẹ Imo, Rochas Okorocha ti ajọ INEC kede pe o bori ni ẹkun idibo Imo west ki wọn to tun yipada pe tipa-tikuuku lo fi mu oṣiṣẹ ajọ naa lati kede ara rẹ gẹgẹ bii olubori.
Lara awọn ti wọn n gba iwe ẹri loni ni Dino Melaye ti o n pada si ile naa ati gomina ipinlẹ Ogun, Ibikunle Amosun ti o n pada si ile naa ẹyin ti o ti kọkọ lọ ki o to wa jẹ gomina ipinlẹ Ogun fun ọdun mẹjọ.
Lẹyin ti awsn sẹnetọ ba gba iwe ẹri ti wọn tan ni yoo kan aṣoju-ṣofin gẹgẹ bii ajọ INEC ṣe sọ.
Lagos building collapse: Àwọn aráàlú, LASEMA tako ara wọn lóríi síso ètò ìdóòlà ẹmí rọ̀
Ọpọ obi lo ti ya bo awọn ileewosan lati ms ipo ti awọn ọmọ wọn wa ti awọn miran ṣi n wa eeyan wọn
Awọn oṣiṣẹ adoola ẹmi lati ileeṣẹ to n mojuto iṣẹlẹ pajawiri ni ipinlẹ Eko, LASEMA ti ko irinṣẹ wọn kuro ni ibudo iṣẹlẹ ijamba ile to wo ni ilu Eko ni ọjọru.
Awọn oṣiṣẹ adoola ẹmi ṣiṣẹ mọju ni ibudo iṣẹlẹ naa lati ṣawari awọn eeyan to ṣeeṣe ki wọn ṣi wa labẹ awoku ile naa ṣugbsn ni kete ti ilẹ ms ni wọn palẹ irinṣẹ wọn mọ kuro nibẹ.
Lagos building collapse: Àwọn òbí ń kérora lórí ikú àwọn ọmọ wọn nínú ìjàmbá ilé tó wó
Ọga agba ajọ LASEMA ti kọkọ fi to awọn oniroyin leti ni owurọ ọjọbọ pe ni kete ti awọn ba ti fi idi rẹ mulẹ pe ko si eeyan kan mọ labẹ awoku ile naa ni awọn yoo fi opin si eto idoola ẹmi nibẹ.
Titi di owurọ ọjọbọ, nnkan bii aadọta eeyan ni wọn ti yọ labẹ awoku ile yii, ti ko si din ni mọkanla ninu wọn to gbe ẹmi mi.
Amọṣa ọpọ awọn olugbe agbegbe naa ni wọn ṣi n fi apa janu ti pẹlu ibinu si ijọba pe  ko tii yẹ ki wọn so eto idoola awọn eeyan rọ nitori pe awọn ṣi lero pe awọn eeyan kan ṣi wa labẹ ile naa.
Obasanjọ pàrọọwà sí Makinde: yàgò fún òṣèlú sọ ọ́ sápò
Oríṣun àwòrán, Kehinde Akinyemi
Makinde ni o jaweolubori idibo Gomina Ipin Oyo to waye laipe yi
Aarẹ ana lorileede Naijiria oloye Olusegun Obasanjo ti parọwa si Seyi Makinde pe ki o yago fun oṣelu sọ sapo.
Arọwa yi waye nigba ti Makinde ati awọn ikọ rẹ ṣabẹwo si Obasanjo nilu Abeokuta.
Ninu atẹjade kan ti agbẹnusọ rẹ Kehinde Akinyemi fi sita Obasanjo gba Makinde lamọran pe ko''ma ṣe ba wọn kopa ninu oṣelu ti yoo ṣanfaaani fun awọn apa kaan''
Oríṣun àwòrán, @seyiamakinde
Makinde tun ṣe abẹwo si alagba Fasoranti nilu Ondo
Aarẹ ana ohun sọ pe Gomina ti wọn ṣẹṣẹ dibo yan naa ni iṣe lati ṣe nipa mimu idagbasoke ba ipinlẹ Oyo to si tun kesi awọn eeyan ipinlẹ naa lati gbaruku ti.
''Jẹ alakoyawọ ki o si dawọ le awọn akanṣe iṣẹ eleyti ti yoo mu inu ara ilu dun''
Oríṣun àwòrán, @seyiamakinde
Makinde ati Falae
O sọfun pe o gbọdọ fun ara ilu ni nnkan to da yatọ si ''eleyi ti aburo mi a ma pe ni oṣelu sọ sapo.''
''Jẹki wọn ma bere wi pe nibo ni iru ijọba yi wa lati ọjọ yi.''
Obasanjo se'leri lati gbaruku ti ijọba tuntun naa ati wi pe nigbakigba ti wọn ba nilo amọran ohun,oun yoo duro gẹgẹ bi baba fun wọn.
Ninu ọrọ ti rẹ, Makinde ni abẹwo naa wa lati dupẹ lọdọ Obasanjo ki ohun si beere amọran lọdọ agba oṣelu naa.
Yatọ si aarẹ Obasanjo, Makinde tun ṣe abẹwo si alagba Fasoranti ati alagba Olu Falae nipinlẹ Ondo.
Wakanda Forever : Aubameyang fi 'Black Panther' dáwọ̀ọ́ ìdùnnú lórí pápá
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Wakanda Forever,Aubameyang fi ifẹ rẹ han si ilẹ Afrika
Ẹgbẹ agbabọọlu Arsenal bori ifidirẹmi goolu mẹta lọwọ Rennes ti wọn si pegede lati kopa ninu abala komẹsẹoyo idije Europa League.
Ṣugbọn kii ṣe goolu mẹta ti wọn jẹ tabi aṣeyọri wọn lawọn eeyan n sọrọ nipa rẹ bi ki ṣe awọ oju ti Aubameyang wọ lati fi dawọọ idunnu.
Kete ti o jẹ goolu rẹ keji lo sare lọ mu awọ oju iru eleyi ti wọn wọ ninu fiimu ''Black Panther'' ti o si dawọọ idunnu ''Wakanda Forever''
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ko ye wa si ẹni to fi awọ naa si ibi to ti mu ṣugbọn idawọọ idunnu yi lo gba ẹnu awọn eeyan loju opo Twitter.
Koda ẹgbẹ agbabọọlu rẹ Arsenal kan sara si fun ohun to ṣe yi
Ki lo mu Aubameyang dawọ idunnu Black Panther
Pierre Emerick Aubameyang to jẹ ọmọ orileede Gabon ko ṣẹsẹ ma wọ awọ oju lati fi dawọ idunnu lori papa.
Nigba ti o wa ni ẹgbẹ agbabọọlu Borussia Dortmund, a ma saba fi awọ oju Batman ati eyi keyi miran to ba wa si lọkan  dawọ idunnu lẹyin to jẹ goolu.
Nipa ti Black Panther to wọ yi,ẹgbẹ agbabọọlu rẹ salaye lọju opo wọn pe o ni ohun wọ awo naa lati fi sapejuwe orukọ ikọ agbagbọọlu orileede wọn ti orukọ rẹ n jẹ ''Black Panthers''
Aseyọri ẹgbẹ Arsenal ninu ifẹsẹwọnsẹ wọn yi tunmọ si wi pe awọn ati ẹgbẹ Chelsea yoo jijọ siwaju lati kopa ninu abala komẹsẹoyọ idije Europa League.
Lagos building collapse: Ìjọba ìpínlẹ̀ Èkó bẹ̀rẹ̀ ilé wíwó ní Lagos Island
Iroyin to n tẹwa lọwọ ni pe ijọba ipinlẹ Eko ti bẹrẹ si ni wo awọn ile ti ko duro daada ladugbo ibi ti ile ti wo pa eeyan to to mejidinlogun.
Gẹgẹ bi iroyin to tẹwa lọwọ, ile mọkandinlogun ni yoo fara gba ninu igbesẹ yi lara awọn ile ogoje ti wọn ti fagile pe awọn yoo wo.
A gbo bakanna pe wọn ti bẹrẹ si ni wo awọn ile ni Adugbo Freeman nilu Eko.
Akọrọyin wa to kalẹ sibi ti wọn ti n wo awọn ile naa ti n fi awọn aworan ile ti wọn yoo wo ranṣẹ si wa
Aworan ọkọ katapila nibi ti ile ti wo nilu Eko
Ile ti ijọba fẹ wo ni Lagos Island
Lara ohun ti awọn eeyan ke ni gbajare lasiko ti wọn doola ẹmi awọn ti ile wo pa ni Ita faji lọjọru ni pe ki ijọba wa wọrọkọ fi ṣada lori awọn ile to fẹ wo tan ti awọn eeyan wa ninu wọn.
Ile wiwo bẹrẹ l'Eko
Ninu fọnran fidio yi ti a ti ba awọn eeyan sọrọ wọn bẹnu atẹ lu bi awọn oṣiṣẹ eleto ile kikọ kan ti ṣe n gba abẹtẹlẹ lọwọ awọn ti wọn ba ti fagile ile wọn fun wiwo.
Lagos building collapse: Àwọn òbí ń kérora lórí ikú àwọn ọmọ wọn nínú ìjàmbá ilé tó wó
Ìjọba ìpínlẹ̀ Èkó kéde ìyè èèyàn tókú ní ilé alájà tó wó l'Eko
Aworan awọn ti wọn gba itọju
Lẹyin ọjọ meji ti ile wo pa awọn eeyan nilu Eko,ijọba ipinlẹ Eko ti kede iye eeyan ti o ku ninu iṣẹlẹ ohun.
Ninu atẹjade kan ti oludari eto iroyin ni ile iṣẹ eto ilera Adeola Salako fi sita,lorukọ Komisana fun eto ilera, Jide Idris, o sọ pe oku eeyan ogun ni wọn gbe lo si  awọn ile igbokupamọ nipinlẹ Eko.
O salaye pe awọn to farapa marundinlaadọta ni wọn gbe lọ si awọn ile iwosan kaakiri Eko.
Oríṣun àwòrán, Facebook/Lagos State Ministry of Health
Jide Idris ni awọn dupẹ lọwọ gbogbo eeyan to kopa ninu idoola ẹmi awọn eeyan
Ikede iye eeyan to ku yi jẹ ohun ti awọn ara ilu ti n reti lati igba ti iṣẹlẹ naa ti waye ti awọn kan si n ro wi pe iye eeyan ti ijọba kede kere si iye ti o ku.
Ni idahun si ọrọ to n ja rainrain nipa pe  awọn kan n gba owo itọju lọdọ awọn to farapa,Idris ni awọn ti fọwọ r ahesọ yi sẹgbẹ kan nitori pe Gomina Ambode tio psaẹ ki wọn ma ṣe gba owo lọwọ ẹnikẹni to ba farapa.
''Gbigba owo lọwọ awọn to farapa kii ṣe nnkan to buru nikan bii kii ṣe iwa ọdaran''
O kesi gbogbo awọn mọlẹbi ẹni to ba fara pa kankan ti awọn oṣiṣẹ ilera ba fẹ gba owo lọwọ wọn lati mu eriwa fun awọn.
Awọn oṣiṣẹ pajawiri gbiyanju pupọ lati doola ẹmi awọn ti ile naa wo lu
Ogbẹni Idris dupe fun awọn ọlọdani ati ara ilu fun iranlọwọ ti wn ṣe fun awn to farapa.
O wa tẹsiwaju pe lowurọ ọjọ ẹti,eeyan mẹrinla,agbalagba mẹewa ati ọmọde mẹrin, ṣi n gba itọju fun oniruuru ipenija ilera ti awọn si ni ireti pe nigba ti ile o ba fi ṣu awọn dokita yoo da wọn silẹ lati lba mọlẹbi wọn.
Building Collapse: Ìdí tí ilé fi ń wó nìyí'
Oríṣun àwòrán, Reuters
Ile wo pa ọpọ eeyan l'Eko
Lẹyin ti ile alaja mẹta da wo ni Ita-Faji lagbegbe Lagos Island niluu Eko, ile iṣẹ iroyin BBC ṣe iwadii ohun to le maa ṣokunfa ile wiwo.
Bakan naa tun ni a ṣagbeyẹwo ohun ti o n fa ti iru iṣẹlẹ bayii ṣe wọ pọ nilẹ Afirika.
Bi iwadii ti n lọ lọwọ lori ohun fa sababi ile to wo l'Eko, awọn onimọ ẹrọ ti sọ fun wa awọn nnkan ti o maa n fa irufẹ iṣẹlẹ yii gan an.
1. Ipilẹ ti ko lagbara
Owo gọbọi ni ipilẹ ile to dantọ maa n jẹ, onimọ nipa ile kikọ kan, Ọjọgbọn Anthony Ede ti fasiti Covenant niluu Ota, ipinlẹ Ogun sọ pe ipilẹ ile to lagbara le gba idaji owo ti eeyan maa na sori gbogbo ile.
O ni ohun meji to ṣe pataki lori ṣiṣe ipilẹ ile ni bi ilẹ ba ṣe lagbara to ati bi ile naa maa ṣe tobi to.
Oríṣun àwòrán, AFP
Ile wiwo ni Afirika
2. Awọn ohun elo ikọle ti ko lagbara
Lọpọ igba awọn ohun elo ikọle ti awọn oṣiṣẹ mọlemọle maa n lo kii saba lagbara to.
Onimọ nipa ile kikọ Hermogene Nsengimana lo sọ bẹ, o ni awọn ibikan wa to jẹ pe awọn ohun elo ikọle ti ko lagbara nikan ni wọn maa n ta nibẹ.
Ọgbẹni Nsengimana tiẹ tun sọ pe ọpọ awọn agbaṣẹṣẹ maa n mọnmọn lo ohun elo ti ko lagbara nitori ki wọn le ri owo to pọ.
Oríṣun àwòrán, EPA
Ile wiwo ni Kenya
3. Awọn oṣiṣẹ maa n ṣe aṣiṣe
Nigba miran ti oniṣẹ ba tiẹ ra ohun elo ikọle to jẹ ojulowo, awọn oṣiṣẹ le maa po gbogbo rẹ pọ daradara.
Eyi ni ọkan lara awọn idi onimọ ẹrọ nipa ikọle Henry Mwanaki Alinaitwe ati Stephen Ekolu sọ pe o jẹ kile to wo ni orilẹede Uganda lọdun 2004 wo.
4. Ti ẹru ile ba wuwo ju bo tiyẹ lọ
Awọn onimọ ẹrọ nipa ile kikọ sọ pe kosi bi ile ko ṣe ni wo lulẹ nigba ti ẹru to wa lori ipilẹ ba ti wuwo ju.
5. Ọpọ lo n gbenu ile ti ijọba ti ṣami wiwo si
Lọpọ igba ni ijọba ti ṣami si awọn ile kan lati wo ṣugbọn ti wọn ko tii wo.
Iru eyi gan an lo ṣẹlẹ l'Ọjọru ni Ita-Faji lagbegbe Lagos Island niluu Eko
Building Collapse: Àwọn èèyàn mẹ́rìndínlọ́gbọ̀n ló n ṣiṣẹ́ níbẹ kí ilé náà tó wó
Awọn ara adugbo ni ṣadede ni ile na wo mọ awọn to n ṣiṣẹ nibe lori
Ajọ to n mojuto iṣẹlẹ pajawiri lorileede Naijiria NEMA ni ko si ẹnikankan to ku ninu iṣẹlẹ ile to wo nilu Ibadan lọjọ ẹti.
Iṣẹlẹ yi waye ni ọjọ meji lẹyin ti ile kan dawo lEko l'Ọjọru nibi ti ogun eeyan ti padanu ẹmi wọn.
Ọga ajọ naa ni iwo oorun Guusu to n mojuto awọn ilẹ kaarọ ojiire eleyi ti Ibadan wa labẹ wọn Slakku Luggard lo sọrọ yi fun BBC.
O ni eeyan meje lawọn doola labẹ ile na ṣugbọn ko si ẹnikẹni to padanu ẹmi nibẹ.
Saaju, Ikọ BBC Yoruba kan si agbegbe ibi ti  ile alaja mẹta naa ti da wo nilu Ibadan.
Gẹgẹ bi ohun ti akọroyin wa jabọ ati ohun ti awọn ara adugbo sọ, eeyan mẹrindinlogun lo n ṣiṣẹ nibẹ nigba ti ile naa dawo.
Ọga ọlọpaa nipinlẹ Ibadan Shina Olukọla na fi to awọn oniroyin leti pe awọn  doola ẹmi eeyan mẹta nibẹ.
Ile miran tun wo ni Ibadan
Ni agbegbe Ṣogoye lẹgbẹ Molete ni iṣẹlẹ naa ti ṣẹlẹ.
Kete ti o ṣelẹ lawọn kan ti ọrọ naa soju wọn ti fi ọrọ sita loju opo Twitter
O sọ ninu ọrọ rẹ pe o ṣeeṣe ki awọn si wa labẹ awoku ile naa.
Ẹgbọ́n olóògbé Suga: Wọ́n yìnbọn fún Suga lójú mi, n kò sì lè dá wọn dúró
@TopsyAshaolu ti iṣẹlẹ ọhun ṣoju rẹ ni awọn oṣiṣẹ ajọ to n ri si iṣẹlẹ pajawiri ko tete debi ti ile naa ti da wo lulẹ.
Ẹnikan to n gbe agbegbe ti ile naa ti wo ṣalaye pe wọn si n kọ ile naa lọwọ ni
Offa Bank Robbery: Àwọn afunrasi ní àwọn kò fí t'inu fẹdo jẹwo fún ọlọ́pàá
Ọwọ ti tẹ
Oríṣun àwòrán, NIGERIA POLICE
Ọjo Kerin Oṣun Kẹrin ọdun 2018 lawọn afunrasi naa yabo ile ifowopamọ nilu Offa ti wọn si pa eeyan mẹtalelọgbọn
Mẹta ninu awọn afunrasi to n jẹjọ lori ẹsun ipaniyan ati idigunjale to waye nilu Offa lọdun to kọja ti sọ fun ile ẹjọ pe iya lawọn ọlọpaa fi gba ọrọ ijẹwọ lẹnu awọn.
Agbẹjọro awọn olujẹjọ naa Mathias Emeribe lo pe igbẹjọ laarin igbẹjọ to n waye lọwọlọwọ lati fi salaye bi awọn to n soju ko ti ṣe finu fẹdọ jẹwọ fun awọn ọlọpaa.
Labẹ ofin,ile ẹjọ ko le gba ọrọ ti afunrasi ba fi ipa sọ fun ọlọpaa wole.
Gẹgẹ bi ohun ti awọn afunrasi mẹta naa Ayoade Akinnibosun,Ibikunle Ogunleye ati Adeola Abraham sọ, niṣe ni awọn ọlọpaa de awọn ni ọwọ mejeeji pẹlu irin ti wọn si fi iya jẹ awọn lati s ohun ti wọn fẹ.
Wọn tun fí ẹsun kan awọn ọlọ́pàá pe wọn yin awọn ni ibọn lẹsẹ.
Awọn olujẹjọ naa ni awọn  ọlọpaa SARS ni wọn gbe awọn lati ofisi wọn to wa nilu Ilorin lo si ile iṣẹ ọtẹlẹmuye Intelligent Response Team to wa labẹ akoso ọga ọlọpaa, Abba Kyari.
Bakanna ni awọn afunrasi naa fi ẹsun kan awọn ọlọpaa pe wọn pa awọn Fulani maarun ati ọlọpaa tẹlẹri kan Micheal Adikwu ti o jẹ olori awọn adigunjale Offa naa.
Awọn agbẹjoro mejeeji to n soju ijọba ati awọn afunrasi naa wi tẹnu wọn ni iwaju adajọ
Agbẹjọro ìjọba, Bola Gold naa fí ọrọ wa awọn afunrasi naa lẹnu wo.
Adájọ́ tó ń gbọ́ ẹjọ́ náà, Halima Salman mú Ìgbẹ́jọ́ náà wá sí òpin lẹ́yìn wákàtí méje tí ilé ẹjọ́ náà fí ọ̀rọ̀ wá afurasí náà lẹ́nu wò.
Adájọ́ Salman sún ìgbẹ́jọ́ sí ọjọ́ kẹẹdọgbọn osùn kẹrin ọdún fún tí tẹ sìwájú ẹjọ́ náà.
Lana ọ̀jọ́bọ ni Olujẹri (Police witness), Hassan Attila ṣe àlàyé fún ilé ẹjọ́ bí ọwọ sikun àwọn ọlọ́pàá tí ṣe tẹ àwọn afurasí náà tí wọ́n sì gbé wọn lọ olú ilé ìṣe àjọ ọlọ́pàá ní ìlú Abuja nínú osun karùn-ún ọdún 2018.
Àwọn afurasí márùn-ún tó ń jẹjọ fún ẹsun idigunjale  ati ipaniyan naa yabo awọn ile ifowopamọsi nìlú Ọ̀ffà nibi ti wn ti pe eeyan ọgbọn lOsu kẹrin ọdún tó kọjá .
Rivers Governorship Election: Àwọn janduku àti ọmọ ilé ìṣẹ́ ológun ló wà nìdí ìdìbò tó dàrú
Wahala to tẹyin idibo naa pọ debi wi pe awọn eeyan koribijade lo si ibi'ṣẹ
Ajọ eleto idibo orileede Naijiria ti gbe esi iwadi  ti wọnṣe jade lori ohun ti o fa wọduwọdu lasiko idibo Gomina nipinlẹ Rivers.
Ninu abajade iwadi igbimọ ti wọn ṣe agbekalẹ rẹ sọ, awọn ọmọ ileeṣẹ ologun kan ati awọn janduku to yabo ibudo ti wọn ti n ko esi ibo jọ ni o da eto idibo naa ru.
Wahala to bẹ silẹ lasiko idibo Gomina naa ni o mu ki Inec so idibo si ipo Gomina ati ti ile aṣofin rọ lọjọ kẹwa Oṣu kẹta ọdun 2019 .
Oríṣun àwòrán, @inecnigeria
Atẹjade Inec
Amọ ṣa ajọ naa ni awọn yoo ṣi yi ba awọn oṣiṣẹ alabo ilu gbogbo jiroro lori bi awọn eeyan wọn ko ṣe ni ma ṣegbe lasiko idibo.
Gẹgẹ bi ohun ti a ri ka ninu atẹjade kan tioludari eto ifọrọto ara ilu leti ati idanilẹkọ awọn oludibo Festus Okoye buwọlu,Inec ni awọn fi idi ọrọ mulẹ pe idibo waye ni pupọ ninu awọn agọ idibo ti awọn si kede esi wọn.
Ninu ẹka asoju mejilelọgbọn Inec ni awọn kede esi dibo to waye ni aaye idibo mọkanlelogun.
Oríṣun àwòrán, @inecnigeria
Atẹjade Inec
Ajọ Inec ni awọn ko ni ko irẹwẹsi ọkan lati pari eto idibo nibi ti awọn ti kede esi ibo.
Okoye wa salaye pe awọn yoo pawọpọ pẹlu gbogbo awọn ajọ to ba yẹlati ri wi pe eto idibo nipinlẹ naa ni iyanju.
O so pe Ogunjọ osu kẹta ni wọn yoo sọ igba ti idibo naa yoo pada waye ati gbogbo ilana ti awọn yoo fi ṣeto naa.
Gbenga Daniel: Ìdí tí mo fi kọ̀wé fi ẹgbẹ́ òṣèlú PDP silẹ
Oríṣun àwòrán, @Demolalanrewaju
Gbajugbaja oloṣelu to fi igba kan jẹ Gomina ipinl Ogun Gbenga Daniel ti kowe fi ẹgbẹ oṣelu PDP silẹ.
Saaju asiko yi, Daniel ni oludari ipolongo ipo aarẹ fun Atiku Abubakar to jẹ oludije gbẹ oṣelu PDP ninu idibo aarẹ to kọja.
Ikede ifiposilẹ rẹ wa ninu atẹjade kan ti o fi sọwọ si alaga ẹgbẹ oṣelu PDP,Uche Secondus.
Ninu atẹjade naa,Daniel ni oun dupe pupọ lọwọ ẹgbẹ ati awọn ọrẹ ṣugbọn oun to ku bayi ni pe oun fẹ gbajumọ ọrọ mi to yatọ si oṣelu.
Ni pato,o ni ohun ṣetan lati ṣe ajinde ẹgbẹ ohun ti ko ni owo ijọba ninu ti orukọ rẹ n jẹ Gateway Front Foundation.
Oríṣun àwòrán, Facebook/Gbenga Daniel
Gbenga Daniel fi PDP silẹ
Gbenga Daniel ni ṣe ni laanu bi ẹgbẹ PDP ti ṣe n koju ipenija to niṣe pẹlu yiyan oludije saaju idibo to waye ni ọjọ Kẹsan Osu Keta eleyi to mu ki ede aiyede wa laarin awọn ọmọ ẹgbẹ.
O lohun dupe pe ohun ti ara ilu fẹ lo pada ṣe nipa Gomina ati awọn asoju ipinlẹ Ogun ti o si ni inu ohun dun pe awọn ti mu opin ba ijba ti o n tako ifẹ ara ilu.
Gbenga Daniel ti jẹ Gomina ipinlẹ Ogun fun ọdun mẹjọ.
Bàbá tó pokùnso: Ọmọ ọdún mẹ́jọ ni ọmọdébìnrin tí baba rẹ̀ bá seré oge
Oríṣun àwòrán, Times
Ọkunrin kan, Razak Hamed ti pokunso ni ahamọ awọn osisẹ aabo ara ẹni, laabo ilu, NSCDC, nilu Akurẹ.
Ṣe bi ko ba nidi, obinrin kii jẹ Kumolu, ẹṣun to gbe ọkunrin naa de ahamọ ni pe, o ba ọmọdebinrin rẹ, ọmọ ọdun mẹjọ ni ajọsepọ.
Nigba to n salaye fun akọroyin BBC Yoruba lori bi isẹlẹ naa se waye, agbẹnusọ fun ileesẹ Civil Defence nipinlẹ Ondo, Ọgbẹni Samuel Ọladapọ sọ pe Ibrahim Ahmed, tii se ọmọkunrin oloogbe naa lo wa si ọọfisi awọn.
Ọladapọ ni Ibrahim Hamed lo wa fi ẹjọ baba rẹ sun pe o ba aburo oun, Zenab, ọmọ ọdun mẹjọ lo pọ, eyi to mu ki ẹru maa ba oun.
O ni idi ree ti awọn osisẹ awọn fi tẹle lọ sile, tawọn si mu baba rẹ wa si olu ileesẹ NSCDC ni ọjọ Aje, lati gba ọrọ ẹnu rẹ silẹ.
Alaye Ọladapọ ree siwaju si:
Sokoto ni baba to ba ọmọ rẹ lo lati pokunso
Agbẹnusọ fun ajọ NSCDC fikun pe, nigba ti afurasi naa, Razak n sọ tẹnu rẹ, o ni lootọ ni oun n ba Zenab ni ajọsepọ, iṣẹ esu si ni isẹlẹ naa.
"Nigba ta beere lọwọ rẹ pe iyawo rẹ n kọ, ọkunrin naa ni iyawo oun akọkọ to bi Ibrahim fun oun, ti ṣe alaisi nigba ti iyawo keji to bi Zenab ti kọ oun silẹ.
A gba afurasi naa laaye lati pe awọn mọlẹbi rẹ, ki wọn lee wa gba oniduro rẹ, nitori ẹsẹ to ṣẹ́, ṣe e gba oniduro rẹ."
Ọladapọ ṣalaye siwaju pe awọn ẹbi afurasi naa wa, ti wọn si n ṣẹ epe fun pe o ti jẹ eewọ. A rọ wọn lati wa fi ọwọ si iwe lati gba oniduro rẹ sugbọn wọn ko pada wa, boya nitori pe ohun to se ko dun mọ wọn ninu rara ni.
Collapsed Building: Ayálégbé ló dára bí ìjọba ṣe wólé àmọ́ wọ́n fẹ́ ìrànwọ́ ilé míràn
O ni bakan naa lawọn ni ki wọn lọ gbe ounjẹ́ wa fun. Irọlẹ ọjọ yii naa lo ni ọkunrin naa ni otutu n mu oun, tawọn si ni ko bọ asọ, ti wọn si mu sinu ahamọ ninu yara kan, oun nikan si lo wa ninu yara naa.
Ọladapọ ṣalaye pe nigba to ya, ẹnikan ninu ẹbi rẹ gbe ounjẹ rẹ wa, tawọn si ni ki wọn lọ mu wa, ko lee jẹnu.
"Igba ta de inu yara naa, lawọn osisẹ civil defence ri pe o ti fa sokoto rẹ ya, o so mọ irin kan, to si ti pokunso ninu yara to wa.
Olusegun Obasanjo: Ọmú ìyá mi ti mo fi ń mùkọ ni kekere ló jẹ ki ń lókun
Isẹlẹ yii soju ẹbi rẹ to gbe ounjẹ wa, ta si kesi awọn ọlọpa lati wa dasi isẹlẹ yii."
Ni bayii, wọn ti gbe oku Razak lọ sile iwosan lati mọ ohun to paa, ti iwadi si n tẹ siwaju.
HIV/AIDS: Ìjọba Nàìjíríà gbé èsì ìwadìí tuntun jáde lóríi ọwọ́jà HIV/AIDS
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Iye awọn to ni kokoro arun naa ti dinku lorilẹede Naijiria, gẹgẹ bii iwadii ajọ NACA naa ṣe sọ
Eeyan to din diẹ ni miliọnu meji lo ni kokoro arun HIV/AIDS lorilẹede Naijiria, ṣugbọn njẹ o mọ pe obinrin lo pọ ju laaarin wọn?
Eyi ni ọkan lara awọn koko to jẹyọ ninu iwadii ijinlẹ kan, ti ajọ to n gbogun ti itankalẹ kokoro arun HIV/AIDS lorilẹede Naijiria, NACA, ṣẹṣẹ gbe jade.
Tẹlẹ ri, ohun ti iwadii n sọ ni pe, eeyan to le diẹ ni miliọnu mẹta lo ni kokoro arun naa,.
Ṣugbọn gẹgẹ bii oludari agba fajọ NACA, Dokita Sani Aliyu, to gbe abajade iwadii naa kalẹ niwaju Aarẹ Muhammadu Buhari ṣe sọ, iwadii ọhun ti jẹ ki okodoro iroyin nipa kokoro arun naa lorilẹede Naijiria fi oju han bayii.
Collapsed Building: Ayálégbé ló dára bí ìjọba ṣe wólé àmọ́ wọ́n fẹ́ ìrànwọ́ ilé míràn
Ninu iwadii tuntun yii ẹwẹ, ẹkun aringbungbun gusu orilẹede Naijiria ni ọwọja kokoro arun HIV/AIDS pọ ju si lorilẹede Naijiria, eyi si wa laaarin awọn ọdọ ti ọjọ ori wọn wa laaarin ọdun mẹẹdogun si mẹrinlelọgọta pẹlu ida mẹta o le ẹyọ kan ninu ọgọrun (3.1%).
Ẹkun iwọ oorun ariwa orilẹede Naijiria ni ọwọja kokoro arun naa si ti lọ silẹ julọ.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
"Dokita Aliyu ni, "" Ijọba apapọ orilẹede Naijiria ni eto to rinlẹ pẹlawọn alabaṣiṣẹ pọ rẹ lori igbogun ti kokoro arun HIV/AIDS lati ṣeto iranwọ ati atilẹyin fawọn to ba ti ni kokoro arun ọhun, lati pese itọju, ati lati daabo bo awọn ẹbi wọn ki wọn lee gun lẹmi, ki wọn si gbe igbe aye alaaafia."
Lagos Building collapse: Aisha Buhari ṣàbẹ̀wò ṣàwọn tí ilé wó lù níléèwòsàn
Oríṣun àwòrán, Aishabuhari
Ko din ni ogun eeyan to ba ijamba ile to wo ni ilu Eko naa lọ
Aya aarẹ orilẹede Naijiria, Aisha Buhari ti sọ pe igbesẹ to tọ ni ijọba ipinlẹ Eko gbe, lati dena atunṣe ijamba ile to da wo ni agbegbe Itafaji ni ipinlẹ Eko.
Aisha Buhari gbe imọran yii kalẹ lasiko to ṣabẹwo sawọn akẹkọ ileewe alakọbẹrẹ, atawọn obinrin to lugbadi ijamba ile to wo naa nileewosan.
Ohun to bani ninu jẹ pupọ ni pe awọn akẹkọọ pupọ bayii padanu ẹmi wọn, ṣugbọn sibẹ a dupẹ lọwọ Ọlọrun, a si ki ijọba ipinlẹ Eko atawọn alaṣẹ ileewosan Lagos Island General Hospital ku iṣẹ, lori iṣẹlẹ naa.
O ni idunnu nla lo jẹ lati rii pe awọn ti ori ko yọ ninu iṣẹlẹ naa n gba itọju to pe ye, ara wọn si ti n pada bọ sipo.
Amọṣa o ni, ijọba ipinlẹ Eko gbọdọ ṣe ohun to tọ lati dena atunṣẹ iṣẹlẹ naa lọjọ iwaju.
Collapsed Building: Ayálégbé ló dára bí ìjọba ṣe wólé àmọ́ wọ́n fẹ́ ìrànwọ́ ilé míràn
Ni ọjọ ẹti ni ijọba ipinlẹ Eko bẹrẹ si ni wo awọn ile ti o ti di ẹbiti, kaakiri awọn agbegbe kan nipinilẹ Eko nitori iṣẹlẹ to ṣẹ naa.
Dokita agba ni ileewosan naa, Dokita Gani Kalẹ ṣalaye fun aya aarẹ pe, ọmọ wẹwẹ mẹwa ni wọn ko wọ ileewosan naa lọjọ ti iṣẹlẹ naa ṣẹlẹ.
Oríṣun àwòrán, Bashir Ahmad
Amọṣa o fi kun un pe, mẹta ninu awọn ti wọn ko wa ni wọn ti da silẹ lẹyin ti wọn gba itọju ti ara wọn si ti da ṣaka.
New Zealand: Lateef Alabi ní òun kò lérò pé agbébọn leè kọlu mọ́ṣálásí ní New Zealand
Oríṣun àwòrán, @GbenroAdegbola
A ṣe ọmọ Naijiria ni Imaamu agba fun mọsalasi kan ti agbebọn kan kọlu ni orilẹede New Zealand lọjọ Satide.
Lateef Alabi ni orukọ rẹ, oun si lo n dele bii Imaamu ni mọsalasi naa, to si n lewaju awọn olujọsin ninu adura nigba ti ọkunrin agbebọn kan, Brenton Tarrant kọlu wọn.
Alabi ni iye eeyan ti ko ba ba isẹlẹ naa lọ ko ba pọ ju iye to ku lọ, bi kii ba se ọkunrin kan to pe orukọ rẹ ni Azeez, ẹni ọdun mejidinlaadọta,  to gba gbara lọwọ agbebọn naa.
Nigba to n sọ bi isẹlẹ naa se waye fun iwe iroyin London Mail, Alabi sọ pe oun sadede gbọ ariwo ni deede aago meji ku isẹju marun ni ọsan ọjọ Ẹti naa, ti oun si bojuwo oju ferese, ti oun si ri ọkunrin kan to wọ asọ agbofinro, ti oun si ro pe ọlọpa ni.
O ni oun tun ri oku eeyan meji nilẹ, ti agbegbọ̀n naa si n sọ oniruuru ọrọ ti ko wu eti gbọ.
Collapsed Building: Ayálégbé ló dára bí ìjọba ṣe wólé àmọ́ wọ́n fẹ́ ìrànwọ́ ilé míràn
O wa ye mi pe apaniyan ni ọkunrin ọhun, ti mo si tete pariwo fun awọn olujọsin to to ọgọrin niye lati doju bolẹ. Wọn kọkọ lọra lati se bẹẹ, amọ bi Tarrant tun se yin ibọn miran to pa olujọsin miran, ni wọn se bẹẹ, nigba to ye wọn pe agbebọn ti de,
Oríṣun àwòrán, @GbenroAdegbola
Alabi sọ siwaju pe, olujọsin kan to n jẹ Aziz, nigba ti ko lee maa wo agbebọn naa niran, lo ba gba ya, to si wọya ija pẹlu rẹ, ti agbara rẹ si kaa, eyi ti ko jẹ ki agbebọn naa wọnu mọsalasi wa ba wa.
To ba jẹ pe agbebọn naa wọnu mọsalasi ni, gbogbo wa ni ko ba ti jẹ Ọlọrun nipe, ti awọn eeyan to wa ninu mọsalasi naa si ti n lakaka lati dara pọ mọ ẹbi wọn.
Oríṣun àwòrán, Agencies
"Alabi fikun pe ""Inu n bi gbogbo wa, a fẹ foju kan awọn eeyan wa to se alaisi ninu isẹlẹ naa, ka se ẹyẹ ikẹyin fun wọn, ki wọn si lọ tẹ wọn si iboji, sugbọn awọn ọlọpa fẹ pari iwadi wọn ki wọn to gbe awọn oku naa fawọn mọlẹbi wọn."""
Alabi wa n beere pe ki wọn si mọsalasi ọhun pada, pẹlu ipese eto aabo to peye, o si se afikun pe, oun ko lero laelae pe irufẹ isẹlẹ bayi lee waye ni orilẹede New Zealand, nitori pe o jẹ orilẹede to ni alaafia gidigidi.
Ọọ̀ni: Àwọ̀ méje bíi pupa, aró, ewéko ni omi àjèjì náà ní
Oríṣun àwòrán, Ooni adeyeye Enitan Ogunwusi
Ọọni tilu Ile Ifẹ, Ọba Adeyẹye Ẹnitan Ogunwusi, Ọjaja keji, ti kede faraye pe oun tun ti se awari omi ajeji miran to n da nilu Ile Ifẹ.
Ọọni kede ọrọ yii lasiko to n gbalejo awọn ọmọ igbimọ alasẹ ẹgbẹ awọn eeyan to n seto irinajo afẹ ni Naijiria (NATOP), eyi ti aarẹ wọn, Bilikisu Abdul ko sodi, ni aafin rẹ.
Oriade naa ni inu ibudo igbalode nla to wa nilu Ifẹ́, Ifẹ Grand Resort, ti oun n kọ lọwọ ni wọn ti sawari omi ajeji naa, eyi ti ni awọ meje ninu eyi ti awọ buluu, eweko. pupa ati bẹẹ bẹẹ l wa.
Ọọni ni isẹ ku diẹ ko pari ni ibudo igbafẹ naa, to ba si buse tan, ẹnu yoo ya awọn ọmọ Naijiria lori awọn ohun meremere to wa nibẹ eyi ti yoo maa ta orilẹ́ede wa fawọn ilẹ okeere lagbaye.
Lati igba ti mo ti gori itẹ awọn baba nla mi, awọn ohun adiitu ti ko wọpọ ni mo ti se awari rẹ, eyi to kọja oye eniyan ati imọ sayẹnsi pẹlu. Awọn ohun awari ijinlẹ́ yii lo fidi rẹ́ mulẹ pe Ile Ifẹ ni orirun iran ọmọniyan lagbaye.
"Ọba Ogunwusi fikun pe "" Aafin yii jẹ ti atijọ, eyi to ti le ni ẹgbẹrun mẹwa ọdun, bẹẹ ni mo tun ni awọn ile to ju ọọdunrun, irinwo ati ẹẹdẹgbẹta ọdun lọ ninu aafin yii, ti wọn ti di nkan isẹmbaye to jẹ apeyawawo fun gbogbo agbaye."""
Oriade naa wa rawọ ẹbẹ sawọn ọmọ Naijiria lati yee na owo ribiribi lọ soke okun fun irinajo afẹ nitori ohun ti wọn n wa l si Sokoto, wa ni apo sokoto wọn nile.
Oríṣun àwòrán, Ooni adeyeye Enitan Ogunwusi
Bakan naa ni Ọọni tun fi kun pe adanu nla to ti pọ julọ to ba Naijiria ni awari epo rọbi jẹ, nitori bi orilẹede yii se kẹyin si agbega eto irinajo afẹ patapata.
O fikun pe awọn ijọba Naijiria ti gbagbe pe orisun eto irinajo afẹ orilẹede kan ko lee gbẹ gẹgẹ bi epo rọbi to ni igba ati akoko to lee gbẹ.
Ọba Ogunwusi wa jẹjẹ atilẹyin rẹ fun ẹgbẹ awọn to n seto irinajo afẹ lorilẹede yii, to si ni awọn yoo jọ sisẹ pọ lati gbe Naijiria de oke agba.
IBDEC: Àyàfi tọ́wọ́ wa bá tẹ àwọn ọ̀dọ́ tó na òṣìṣẹ́ wa, ni iná yóò tó tàn nílẹ̀ Ìjẹ̀ṣà
Oríṣun àwòrán, Jude Ugwu
Ko din ni ijọba ibilẹ mẹfa nilẹ Ijẹṣa to wa ninu okunkun biribiri bayii lati Ọjọbọ to kọja.
Ohun to sokunfa isẹlẹ naa ni bawọn ọdọ kan lagbegbe Olomilagbala ati Bọlọrunduro nijọba ibilẹ ila oorun Ilesa, se fi ẹhonu han lọ si ọọfisi ajọ amunawa to wa nilu Ilesa.
Awọn ọdọ naa ni owo ina ti awọn osisẹ IBDEC n mu wa fun awọn ti pọ ju, ti ina ọba si n se segesege lati osu mẹfa sẹyin.
Sugbọn ọrọ naa bẹyin yọ, ti awọn ọdọ yii si din dundun iya fawọn osisẹ ajọ amunawa naa ni ọọfisi wọn.
Niwọn igba to si jẹ pe a kii mọ Alaja, ka na aja rẹ, eyi lo mu ki olu ileesẹ ajọ amunawa, IBDEC, to wa nilu Ibadan fi setan lati wa epo dẹkun fun awọn ọdọ to san iru asọ yii soro, lọna ati kọ ero ẹyin bii tiwọn lọgbọn.
Collapsed Building: Ayálégbé ló dára bí ìjọba ṣe wólé àmọ́ wọ́n fẹ́ ìrànwọ́ ilé míràn
Nigba to n salaye ohun ti oju awọn osisẹ ajọ amunawa ọhun ri lọwọ awọn ọdọ ọhun fawọn akọroyin, Osisẹ alarina fun ajọ IBEDC nipinlẹ Ọsun, Kikẹlọmọ Owoẹyẹ leri leka pe, inu okunkun lawọn ijọba ibilẹ naa yoo wa.
A yọ awọn ijọba ibilẹ mẹfa to wa lẹkun Ijẹsa kuro lara agbegbe ta n pin ina ọba de, titi ti wọn yoo fi se awari awọn eeyan to kọlu awọn osisẹ wa.
Oríṣun àwòrán, iSaac Haastrup
Sugbọn ọpọ awọn olugbe adugbo naa lo ti n fapa janu lori ipinnu ajọ amunawa yii, ti wọn si ni ipa nla ni aisi ina ọba lagbegbe awọn ti n ko ba ọrọ aje ati igbaye gbadun awọn.
Awọn ara adugbo naa ni, ki lo de to jẹ pe gbogbo awọn ni yoo jiya ẹsẹ ti awọn ọdọ kan da, wọn fikun pe, ko si ni dara ki ajọ IBDEC ba ẹnikan ja, ki wọn wa fi ọwọ gun gbogbo ile nimu.
Oríṣun àwòrán, iSaac Haastrup
Bi o tilẹ jẹ pe wọn gba pe ohun ti awọn ọdọ naa se ko bojumu, sibẹ wọn ni ori bibẹ kọ ni oogun ori fifọ, iwa aidaa gbaa si ni ki awọn eeyan maa jiya aisi ina ọba tori ẹsẹ aimọdi.
Koda, a tiẹ gbọ pe awọn eeyan kan ti n dunkoko lati gbe ajọ IBDEC lọ sile ẹjọ lori isẹlẹ yii.
Ethiopia Airlines Crash: Iyanrìn làwọn ẹbí olóògbé bàálù Ethiopia rí gbà dípò òkú èèyàn wọn
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ijamba baalu Ethiopia
Ibanujẹ nla lawọn ẹbi eeyan mẹtadinlọgọjọ, ti ọmọ Naijiria Ọjọgbọn Pius Adesanmi jẹ ọkan lara wọn, to padunu ẹmi ninu ijamba baalu Ethiopia babọ lọjọ Aiku lẹyin ti wọn fun wọn iyanri lati ibi ti baalu naa ja si dipo oku ẹbi wọn to ku.
Ko si ẹnikẹni to ri oku ẹbi wọn gba bayii lẹyin ti mwọn sọ fun wọn o kere tan o maa to oṣu mẹfa ki onikaluku to le da oku ẹbi wọn mọ.
Minisita fun eto irina lorilẹede Ethiopia Dagmawit Moges sọ pe wọn ti ayẹwo DNA fawọn ẹbi awọn oloogbe lati le ṣeranwọ nipa mimọ oku ẹnikọọkan.
Collapsed Building: Ayálégbé ló dára bí ìjọba ṣe wólé àmọ́ wọ́n fẹ́ ìrànwọ́ ilé míràn
Koda posi ti ko si oku ninu rẹ ni wọn bo mọ lẹ ni olu ilu Ethiopia tii ṣe Addis Ababa lati le maa ṣe iranti awọn to ku ninu iṣẹlẹ ọhun.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ijamba baalu Ethiopia
Ọgbẹni Paul Njoroge ati baba iyawo rẹ John Quindos Karanja fi ibanujẹ kuro nibi eto isinku ọhun lẹyin ti wọn ko ri oku iyawo wọn ati awọn ọmọ to ku.
Amọ ṣa, wọn iyanrin lati ibi ti baalu naa ja sinu ọra dipo oku awọn ẹbi wọn.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ijamba baalu Ethiopia
Bakan naa ni isin iranti isin iranti fawọn to ku waye loni niluu Nairobi nibi t'ọpọ eeyan ti ṣadura fawọn to doloogbe.
Elections 2019 Updates: Buhari ní àjọ INEC kájúẹ̀ láti ṣètò ìbò tó pegedé
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Bi awọn ọmọ ẹgbẹ APC ṣe n bẹnu atẹ lu Buhari ni awọn alatako n kilo fun lati ma ṣe dasi ibo atundi to n bọ lọna
Aarẹ orilẹede Naijiria Muhammadu Buhari ni, oun ko ni ṣegbe lẹyin ọmọ ẹgbẹ APC kankan lati yi abajade esi atundi ibo ti yoo waye lawọn ipinlẹ kan.
Buhari wa gba awọn oloṣelu to ba fẹ kopa ninu atundi ibo lawọn ipinlẹ naa nimọran, lati yara lọ mura si iṣe ọwọ wọn, ti wọn ba fẹ gbegba oroke.
Ninu atẹjade kan ti ileeṣẹ aarẹ fi sita lọjọ Aiku ni ọrọ yi ti lu sita.
Garba Shehu, to jẹ oluranlọwọ agba fun aarẹ Buhari feto iroyin ni, awọn aarẹ nigba kan ri a ma dasi ibo lati le gbe awọn ọmọ ẹgbẹ wọn sugbọn Buhari ko ni ṣe bẹẹ.
Ọrọ Buhari yii  si lo dabi eyi to tako nnkan ti ẹgbẹ rẹ, APC sọ pe igbesẹ Inec lati ṣeto atundi ibo ni ipinlẹ Rivers lodi si ofin.
Lanre Issa Onilu, to jẹ akọwe ipolongo APC sọ pe, ''wọle wọde laarin Gomina Nyesom Wike ati Inec jẹ ohun ti ko fi awọn lọkan balẹ''
Oríṣun àwòrán, @APCNigeria
Ami idanimọ APC
Ajọ eleto idibo Naijiria, INEC, lẹyin idibo Gomina ati ti ile asofin lawọn ipinlẹ kan, kede pe awọn yoo tun ibo di nitori awọn aiṣedede kan to waye lasiko ibo.
Ipinlẹ Adamawa ,Bauchi, Benuẹ, Kano ati Sokoto si wa lara awọn ipinlẹ ti atundi ibo yoo ti waye.
Ninu awọn ibi ti atundi ibo yoo ti waye naa, la ti ri awọn ipinlẹ ti ẹgbẹ APC ti n ṣe ijọba, ti ọrọ naa si kan awọn Gomina ipinlẹ to wa latinu ẹgbẹ alatako PDP naa .
Aṣọ òkè: Alákọ̀wé ní ọ̀nà láti wá oúnjẹ fáwọn tó ń ṣe aṣọ òkè ló ṣún òun débẹ̀
Buhari tẹsiwaju ninu ọrọ rẹ pe, bi awọn ọmọ ẹgbẹ ti ṣe n bẹnu atẹ lu oun pe, o yẹ ki oun da si ibo naa ni awọn alatako n sọ pe, ko yẹ ki oun da si.
O wa pari ọrọ rẹ pe, ajọ eleto idibo Inec kun oju osuwọn lati ṣeto idibo to yanranti gẹgẹ bi iṣe wọn.
Olè Lekki: Obìnrin méjì ni wọ́n dá lọ́nà, tọ́wọ́ ọlọ́pàá fi tẹ̀ wọ́n
Oríṣun àwòrán, @policeNG
Yoruba ni ọjọ gbogbo ni ti ole, amọ ọjọ kansoso pere ni ti olohun.
Bẹẹ lọrọ ri fun awọn ole meji kan nipinlẹ Eko, nigba ti ọwọ palaba wọn segi, ti akara wọn si tu sepo.
Awọn firi nidi ọkẹ naa, ti wọn gbajugbaja fun isẹ alọnilọwọgba lagbegbe Lekki, ni wọn pe oruk wọn ni Adebayọ Ayọmide ati Isaac David.
Aago mẹsan alẹ ni ikọ ọtẹlẹmuyẹ, ti ọga ọlọpa kan lati agọ ọlọpa Marọkọ, Isah Abdulmajid ko sodi, lọ paraaro afara kan to so adugbo Lekki pọ mọ Ikoyi, asiko yii si ni wọn ri awọn omidan meji kan, ti wọn n gbọn jinni-jinni.
Nigba ti wọn beere lọwọ awọn ọmge naa pe, ki lo se wọn, ni wn ba salaye pe awọn alọkolohunkigbe meji lo fi ibọn gba ohun ini awọn, ti wọn si tọka ọna tawọn ole ọhun morile fun awọn ọlọpa.
Aṣọ òkè: Alákọ̀wé ní ọ̀nà láti wá oúnjẹ fáwọn tó ń ṣe aṣọ òkè ló ṣún òun débẹ̀
Ọwọ sinkun awn ọlọpa yii ba awọn ole naa, ti wọn si ba ibọn ilewọ kan, ada ati ọpọ ẹrọ ibaraẹnisọrọ alagbeka lọwọ wọn.
Nigba ti wọn n ka ni agọ ọlọpaa, awọn ole naa ni ara ọmọ ẹgbẹ ikọ adigunjale kan ti wọn n da agbegbe Lekki laamu ni awọn.
Oríṣun àwòrán, @WeArePindula
Nigba to n gbosuba fun ikọ ọlọpa to se bẹbẹ yii, Kọmisana ọlọpa nipinlẹ Eko, Zubairu Muazu wa pasẹ pe ki wọn gbe ẹsun awọn ole meji ọhun sabẹ ikọ to n gbogun ti iwa idigunjale nipinlẹ Eko fun iwadi kikun.
Muazu wa fọkan awọn olugbe ipinlẹ Eko balẹ pe ileesẹ ọlọpa mu aabo ẹmi ati dukia wọn lọkunkundun, to si tun fewe ọmọ mọ awọn ọdaran leti lati tun ero wọn pa, bibẹẹkọ ikoko ko ni gba omi, ko gba ẹyin, ko tun gba ṣọṣọ.
Oyo NURTW: Tokyo ló kọ́kọ́ bá Auxillary sọ̀rọ̀ lẹ́yìn ọdún gbọọrọ
Oríṣun àwòrán, Tirbune
Arẹmaja kan ko si, ajamarẹ ni ko sunwọn., ni Yoruba wi. Wọn tun ni ta ba gbagbe ọrọ ana, a ko ni rẹni ba sere.
Eyi lo mu ki awọn asaaju ẹgbẹ awakọ meji nipinlẹ Ọyọ, Alhaji Lateef Akinsọla, ti gbogbo eeyan mọ si Tokyo, ati igbakeji rẹ lasiko to fi jẹ alaga, Alhaji Lamidi Mukaila, to tun n jẹ Auxillary, fi foju rinju lẹyin ọdun mẹwa ti wọn fi n bara wọn ja.
Gẹgẹ bi iwe iroyin Nigerian Tribune se gbe sita, Tokyo lo kọkọ pe Auxillary lori aago lẹyin ọdun mẹwa ti igbakeji rẹ naa, ti yẹ aga mọ nidi, ti Lateef Salakọ Eleweọmọ si di alaga.
Iroyin naa ni deede aago marun kọja isẹju meje ni irọlẹ ọjọ Aiku, ni Auxillary ati ikọ rẹ gunlẹ si ile Tokyo, ti wọn si ki wọn kaabọ tilu tifọn, ki awọn mejeeji to wọle lọ se ipade bonkẹlẹ alatilẹkun mọri se.
Amọ ki wọn to gbe ilẹkun ti, ni Auxillary ti sọ fun ọga rẹ atijọ pebaba ni baba rẹ yoo maa jẹ lọjọkọjọ, tori Tokyo si ni baba awọn ọmọ ẹgbẹ ọlọk ero nipinl Ọyọ.
Aṣọ òkè: Alákọ̀wé ní ọ̀nà láti wá oúnjẹ fáwọn tó ń ṣe aṣọ òkè ló ṣún òun débẹ̀
Inu ile yii ni gbogbo ọmọ ẹgbẹ ọlọkọ ero, boya alaaye ni abi oku ti bẹrẹ, ko sẹni to lee sẹ lori eyi. Inu mi si dun pupọ nigba ti ẹ pe mi lana ọjọ Satide.
Emi ko ni ohunkohun kankan lati fi tako yin, dipo bẹẹ, mo ri gbogbo ohun to ti sẹlẹ lati ẹyin wa gẹgẹ bii irubọ ti a gbọdọ se lati mu ki ẹgbẹ wa lọ siwaju. Abẹyin la ti bẹrẹ, mo si fẹ́ fun yin ni ọwọ rẹ.
Tani: Boko Haram ló lé àwọn òbí rẹ̀ lọ sí Amẹrika
Ọmọ ọdun mẹjọ ni Tanitoluwa Adewunmi wa, to fi kopa pẹ́lu awọn akẹẹgbẹ rẹ ti wọn jẹ ọjẹ wẹwẹ nilẹ́ Amẹrika, fun idije ẹni to pegede julọ ninu idije ayo Chess.
Sugbọn Ọlọrun se Tanitoluwa, ti gbogbo eeyan mọ si Tani logo, nigba to ta awọn akẹ ẹgbẹ rẹ to jẹ alawọ funfun yọ, to si di ẹni to gbe igba oroke ninu idije New York state Chess Championship
Gẹgẹ bi iwadi ikọ Newsday to wa labẹ ileesẹ iroyin BBC ti wi, Itajẹsilẹ ikọ adunkoko mọni Boko Haram lo le awọn obi Tani, eyiun Kayọde ati Oluwatoyin kuro ni Naijiria, ti wọn si lọ sorilẹede Amẹrika lati lọ se atipo.
Nkan ko san mọna fun lọkọlaya naa nigba ti wọn de Amẹrika, inu ahere ti kii se ile rara, si ni wọn n gbe pẹlu ẹgbọn ọmọ naa.
Lasiko to n ba BBC sọrọ lori aseyọri rẹ yii, Tani salaye pe inu mọto oun ni oun ti bẹrẹ si ta ayo Chess, ti oun si gbaradi fun idije naa, nipa lilo awọn ohun eelo ere Chess igbalode to wa fawọn ọmọde.
Tani fikun pe, lẹyin ti oun ba de lati ile iwe, ti oun si jẹun tan, to ba di aago meje, ni oun yoo ta ayo Chess fun wakati mẹta.
"Tani fikun pe ""Ayo Chess maa n jẹ ki eeyan lee ronu jinlẹ, tẹ ba ta bo se yẹ kẹ ta, idi niyi ti mo se fẹran rẹ."
"Mo fẹ jẹ ọmọde to dantọ julọ ninu Chess lagbaye, ki n si lewaju ninu akọsilẹ fun awọn alaseyọri to lewaju lagbaye"""
Nigba toun naa n salaye bi Tanitoluwa se bẹrẹ ayo Chess, mama rẹ, Oluwatoyin ni ọdun 2018 lo bẹrẹ ayo naa, eyiun bii ọdun kan sẹyin.
Ileewe to n lọ ni wọn ti ya ọjọ kan sọtọ fun ẹgbẹ awọn to n ta ayo Chess ni Ọjọbọ lọsọọsẹ. Boya bo se ta ayo naa lo wu wọn lori. Olukọ rẹ lo fi iwe kan ransẹ si mi pe Tanitoluwa nifẹ lati maa ta ayo Chess, yoo si dara ti mo ba lee ba olukọni wọn sọrọ.
Mama Tani salaye siwaju pe idi ree ti oun se fi email sọwọ si olukọni naa pe, se yoo gba Tani lati darapọ mọ ẹgbẹ alayo Chess wọn.
Olukọni naa ni ko si wahala, sugbọn ko si owo kankan lọwọ mi, mo si yara tete jẹwọ ipo ti mo wa fun wọn pe, inu ahoro kan ni mo n gbe, ko si si owo kankan lọwọ mi.
Lẹyin to fi mail ransẹ si olukọni naa tan, onitọun ni ko si wahala, ti oun ko ba ni owo lọwọ, o si gba Tani sagbo wọn lọfẹ.
"Oluwatoyin, pẹlu iwuri ni ""ọmọ daada ni Tani, o si ni ọpọlọ pipe, sugbọn boya nitori emi ko ta ayo chess ri, mo kan ro pe ere ayo ti wọn n ta nile iwe ni, n ko lero pe o lee ta ọmọ mi yọ si gbangba bi eyi."""
Ogo Yoruba ni tanitoluwa Akinwunmi jẹ, ọmọ to si yẹ ka maa foju sọna fun pe yoo gbe ogo ilẹ Yoruba ga loke okun ni.
Corruption: Ọ̀gá àgbà àṣọbodè ní kíkọ rìbá ṣàfihàn aṣọ́bodè tó ti di àtúnbí
O ní onífàyàwọ́ ọ̀hún tún jẹ́ẹ̀jẹ́ pé òun yóò sàn rìbá tó tún pọ̀ jùbẹ́lọ ti tí àkọ́kọ́ yìí ba ṣe dáradára
Ilé iṣẹ́ aṣọ̀bode ti ṣe àgbéga fún ọ̀gá àgbà ilé iṣẹ rẹ̀ ní Apapa, Bashir Abubakar sí ipò igbákejì ọgá agba ileeṣẹ náà.
Col. Hameed Ibrahim Ali gbé Muhammed Abba-Kura ga si ipo oludari àgbà ní agbègbè Apapa.
Abubakar kọ ààdọ́jọ mílíọ̀nù náírà, owó àbẹ̀tẹ́lẹ̀ ti olóògùn fàyàwọ́ kan fi lọ̀ọ́, láti gbé òògùn ogoji ọkọ ajagbé tó kún fún Tramadol wọle.
Aṣọ òkè: Alákọ̀wé ní ọ̀nà láti wá oúnjẹ fáwọn tó ń ṣe aṣọ òkè ló ṣún òun débẹ̀
Ìròyìn fi ye ní pé, ọgá aṣọ́bodè àti àwọn ìsọ̀gbè rẹ̀ kọ owó àbẹ̀tẹ́lẹ̀ náà, wọn si fi ìdí àwọn àjàgbé tó kúń fún àwọn oogun náà gúnlẹ̀, èyí tó lé ní bílíọ̀nù méje naira.
"Lásìkò tó ń ba àwọn akọròyin sọ̀rọ̀ lọ̀rí ọ̀rọ̀ to ṣẹ̀lẹ̀ nínú oṣù kọkànlá òsu 2018, ọgá àgbà pátápáta fawọn aṣọbodè sọ pé "" kíkọ ààdọ́jọ mílíọ̀nù náírà owó àbẹ̀tẹ̀lẹ̀, sàfihan àwọran òṣìṣẹ́ aṣọ́bode tó ti gbà àtúnṣe, ti wọn sì ń  fi ọ̀rọ̀ àrá ìlú sáájú ju imọ̀ tara ẹni nikan lọ."
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ajọ asọbóde ṣe agbéga fun osiṣẹ̀ rẹ̀ tó kọ̀ rìbá
O ní onífàyàwọ́ ọ̀hún tún jẹ́ẹ̀jẹ́ pé òun yóò sàn rìbá tó tún pọ̀ jùbẹ́lọ ti tí àkọ́kọ́ yìí ba ṣe dáradára.
Ekiti: À máa fi ojú àfipa bọ̀mọdé lòpọ̀ hàn lóri tẹlẹfísọn
Oríṣun àwòrán, AFP
Ekiti: Ìjọba gb ìgbésẹ túntún láti fí ìyà jẹ ẹni tó bá bá ọmọdé lòpọ̀
Ìjọba ìpínlẹ̀ Ekiti ní àwọn yóò maa ṣe àyẹwò ọpọlọ fún gbogbo àwọn ti ilé ẹjọ bá ti dá lẹ́jọ  pe ó jẹbi ẹsùn ìfipá bó ọmọde lòpọ̀.
Bákan náà ní wọn ó gbe orúkọ wọn jáde lóri ayélujara ile iṣẹ́ ìodájọ, àti pé wọn ó kéde orúkọ lóri rẹdíò àti tẹlẹfísọn, bẹ́ẹ̀ ni olóri tàbi ọba ìlú wọn yóò mọ̀ si pẹ̀lú ojú pátakó ni ilé iṣẹ́
Komisọna fún ètò ìdájọ ní ìpínlẹ̀ Ekiti ọgbẹ́nu Wale Fapohunda lọ fìdí ọ̀rọ̀ náà múlẹ̀ ní ìlú Ado Ekiti lọ́nìí.
Oríṣun àwòrán, Ekiti Ministry of Justice
Ekiti: À máa fi ojú àfipa bọ̀mọdé lòpọ̀ hàn lóri móhùnmáwòrán
''Àwọn ètò tí a ti ní nílẹ̀ ní pe à ó máà lẹ fótò àwọn ọdaran káàkiri ojú gbaaara ní àwọn ìlú tàbi ìletò wọn àti ìjọba ìbil.ẹ̀ ti wọn ti wá''
À ó sàlàyé fún àwọn ọba tàbi adari ìlú wọn ẹsẹ̀ ti wọn ṣẹ, gbé àwòrán wọn sóri ẹ̀rọ alátagbà ilé ìṣẹ́ ìdájọ ti ìpínlẹ̀ Ekiti
À ó ṣe àyẹ̀wò ọp;ọlọ tipátipá fún, pà'pàá jùlọ ẹni ti ilé ẹjọ ba ti ni ó jẹ̀bi ẹsun fífí ipí bá ọmọde sùn tó fi mọ́ ẹni tó bá ń jẹ́jọ lọ́wọ́
Ọgbẹ́ni Fapohunda ni ìdí ti àwọn fi ń gbé irú ìgbéṣẹ̀ yìí ni pé irú ìwà ìbàjk yìí ti ń pọ̀ jù, bótill jẹ pé òun mọ pé àwọn ìgbéṣẹ̀ yìí jẹ èyí to lágbára, síbẹ̀ ìgbàgbọ́ wà pé yóò ràn àwọn lọ̀wọ́, ọ̀pọ̀ ará ìlú ní yóò sì ni àǹfàní láti sọ èrò ọkàn wọn.
Gbogbo ẹni tó ba ti ṣẹ si òfin ní à ó lẹ orukọ wọn àti foto
''A tí ṣe ìpìdé pẹ̀lú àwọn tọ́rọ̀ kàn ní ǹkan bii ọ̀ṣẹ̀ méjì, sùgbọ́n à ń pinu láti pé gbogbo àwọn ènìyàn láti wa sọ èrò ọkàn wọn lóri ọ̀rọ̀ àwọn tó ń ba ọmọ dé lòpọ̀ tipátipá.''
Fapohunda ni ohun ìbànújẹ ló jẹ fún òun bí ẹsùn ìbọ́mọde lòpọ̀ ṣe ń pọ̀ si lójojúmọ́ p[llú gbogbo àwọn ti ilé ẹjọ ti ń dájọ fun ní ìpínlẹ̀ Ekiti àti pé ìnú gómìnà Fayemi ń bajẹ gidigidi lóri ọ̀rs náà
O ní ìgbésẹ tuntun yìí àwọn lérò pé yóò jẹ ki àsírí àwọn ọdaràn yiìí máa tu tí yóò si fún ìjọba láǹfani láti maá yọ orúkọ àwọn irú ọdaran kúrò nínú àwọn ti wọn lé sàànú lagbà ẹwọn.
Building Collapse: Wọ́n yọ èèyàn mẹ́rin níbi ilé mííràn tó wó l'Eko
Ile to tun wo l'Eko
Ile yii ti wá ní abé àwọn ile ti wọn ti pinu láti wo teletele kò tó di pé ó dawo ni ìrólé yii. Kò sí ẹ̀mí tó sínú níbi ilé náà. Àwọn tí oro naa soju wọn sọ pé àwon mẹ́rin ni ile naa wolu lásìkò tí wọn ń gbìyànjú láti ṣe àwo pale rẹ.
Ile miran tun wo l'Eko
Wọn ní ní kété tí ẹni tó ní ilé náà ṣe gbó pé ìjọba tí yaa soto láti wòó ni ó fi kú àwọn tí yóò bá ṣe iṣẹ́ ilé Wiwo náà.
Ile miran tun wo l'Eko
Ile miran ta lu lẹ
Ki ile naa to ya lu lẹ
Ile miran wo L'Eko
Àwọn tọrọ soju wọn ṣàlàyé pé, wọn tí yọ àwọn méjì tó farapa nínú àwọn merin tó wà níbè wọn sì ti kó wọn lọ sí ilé ìwòsàn
Election 2019 Updates: Makinde ní Ajimọbi fẹ́ ná owó Ọyọ tán, láti dá ìjọba òun lóró
Ọga, ẹ fẹ na owo ilu tan ni?
Gomina to ń bọ̀ lọna ni Ipinlẹ Oyo, Seyi Makinde ní ẹru n ba oun lori bi Gomina Abiola Ajimobi ṣe n na owo lẹnu ọjọ mẹta yii.
Makinde ni, ṣe ni Ajimọbi n fa owo yọ lapo ijọba bi nkan miiran nibayii ti ọjọ ti yoo fipo gomina silẹ, May 29, se n sunmọ ile.
Ṣugbọn gomina Ajimọbi ti wa fesi pada pe, oun to ba wu ẹlẹnu lo le fi ẹnu rẹ sọ, nitori pe, oun ṣi ni di ọjọ Kọkandinlọgbọn oṣu Karun-un ọdun 2019 lati ṣe ijọba.
Ohun ti Seyi Makinde sọ lẹyin ipade awọn ẹgbẹ alatako
Kọmiṣọna fun eto iroyin ati aṣa nipinlẹ Ọyọ, Toye Arulogun to gbẹnusọ gomina sọrọ ni, Ajimobi ko le ka ọwọ gbera, maa wo ilu niran titi ti ọjọ ti yoo kuro nipo yoo fi pe.
Makinde ni ṣe ni Ajimọba fẹ da ijọba oun to n bọ loro, ko ma baa ṣeeṣe ki oun ri nkan ṣe.
O tọka si pe miliọnu kan aabọ ni gomina fun ijọba ibilẹ kọọkan, ti gbogbo wọn jẹ metalelọgbọn to wa ni ipinlẹ naa, lati fi ṣe awọn iṣẹ amuṣe kan.
Kloe: Èmi kìí mu òògùn olóró, àmọ́ mo fẹ́ràn láti máa wà lẹ́bà omi
Gomina to n bọ naa tun ni, Ajimọbi tun fun ajọ to n tun opopona ṣe ni ipinlẹ Ọyọ, ni bii biliọnu marun-un naira.
Makinde ni oun ati awọn to n ba oun ṣiṣẹ n ṣọ owo to wa ninu apo ijọba ati wipe, oun yoo gbe igbesẹ lati ṣe oun to yẹ ni kete ti wọn ba bura fun ou tan.
Boko Haram: Bó ṣe ń yìnbọn, ló tún kó ìlú náà lẹ́rú
Oríṣun àwòrán, @HQNigerianArmy
Akọtun jinnijinni lo tun ba ilu Michika, nipinlẹ Adamawa lọjọ Aje, ti ariwo ẹkun si sọ, bẹẹ ni omije n san loju awọn ara ilu naa, nigba tawọn atilaawi Boko Haram tun ba wọn lalejo.
Se ni iro ibọn n dun takotako, tawọn araalu si n sa asala fun ẹmi wọn lọ sa pamọ sabẹ oke to wa nilu naa, koda, awọn ikọ elesu ọhun tun duro ra epo sinu awọn ọkọ wọn nibi ti aaye gba wọn de.
Bi o tilẹ jẹ pe ẹgbẹlẹgbẹ awọn eeyan ilu Michika lo raye ra pala lọ fara soko lori oke, sugbọn aanu awn eeyan to ku ninu ile yoo se eeyan pẹlu bi iro ibọn se n dara leti wọn.
Lasiko ti wn n salaye ohun to sẹlẹ, ọp awn araalu naa to pe lori aago lo ni, Ikọ mujẹmujẹ Boko Haram tun ti gba ilu Michika lẹẹkeji, ti ẹmi awọn ara ilu naa si wa ninu ewu nla.
Asaaju kan lagbegbe naa, Muhammed Sanusi, lasiko to n bawọn akọroyin sọrọ ni ọwọ ẹyin lawọn agbebọn naa ba wọle, ti wn si n yinbọn laibikita, bẹẹ naa si lawn ọmọogun ko dẹkun ọna ti wọn yoo gba wagbo dẹkun fun wọn.
Kloe: Èmi kìí mu òògùn olóró, àmọ́ mo fẹ́ràn láti máa wà lẹ́bà omi
O si yẹ ki atundi eto idibo waye nilu Michika yii lọjọ Satide, tawọn oloselu lọtun losi, si ti n bẹbẹ fun ibo awọn eeyan ilu naa.
Delta: Ọ̀fẹ́ nilé ìwé, kò yẹ kí wọn lé akẹ́kọ̀ọ́ torí owó
Oríṣun àwòrán, @aduakedet
Kangun kangun kangun, o ti wa kangun sibi kan fun ọga ile iwe kan to le akẹkọ rẹ lọ sile nipinlẹ Delta.
Akẹkọ naa, Success Adebor, to n lọ sile iwe alakọbẹrẹ Okotie-Ebor kinni nijọba ibilẹ Sapele, ni fidio rẹ lu awọn oju opo itakun agbaye pa, lasiko to n fapa janu pe, wọn le oun kuro nile ẹkọ tori pe oun ko ri owo ile iwe san.
Success ninu fidio naa ni, o ba oun lara mu ki wọn fi ẹgba na oun tori oun ko ri owo ile iwe san, dipo ki wọn le oun lọ sile.
Success ni wọn yoo na oun titi, nigba to ba rẹ ẹgba, ni wn yoo dawọ duro.
Fidio naa ti wa pe akiyesi ijọba ipinlẹ Delta si awọn isẹlẹ to n waye nile ẹkọ rẹ.
Lọwọlọwọ bayii, ijọba ti pasẹ fun ọga ileẹkọ alakọbẹrẹ naa, arabinrin Vero Igbigwe lati lọ rọọkun nile na, nitori bo se le akẹkọbinrin naa nile iwe rẹ.
Kloe: Èmi kìí mu òògùn olóró, àmọ́ mo fẹ́ràn láti máa wà lẹ́bà omi
Kọmisana feto ẹkọ nipinlẹ Delta, Amofin Chiedu Ebie, lasiko to n bawọn akọroyin sọrọ ni, ọga ile iwe naa ko lee se alaye ohun ti owo to n beere lọwọ Success wa fun, tori ọfẹ ni ẹkọ alakọbẹrẹ nipinlẹ naa.
Wayi o, ọ̀pọ awọn lookọ lookọ lawujọ lo ti n rọ ojo owo ati dukia fun success, to ti kekere jẹnu ṣamuṣamu ninu fidio ọhun, to si ti pada sile iwe.
Cyclone Idai: Ààrẹ Mozambique ní òun rí ọ̀pọ̀ òkú tó lé téńté lórí odò
Oríṣun àwòrán, AFP
O kere tan o le ni eeyan ẹgbẹrun kan ti ẹmi wọn ti bọ ninu ọwọja afẹfẹ iji lile, ti wọn pe ni ‘Cylone Idai’, to bẹ silẹ ni orilẹede Mozambique.
Gẹgẹ bi aarẹ Filipe Nyusi ti salaye, oun ri ọpọ oku eeyan ti wọn le tente loju oniruuru odo lasiko ti oun foninu baalu rin kaakiri orilẹede naa.
Osisẹ alaanu kan labẹ ajọ isọkan agbaye sọ fun BBC pe gbogbo ile to wa nilu Beira, ti apapọ awn eeyan to to idaji miliọnu n gbe, lo bajẹ patapata.
"Gerald Bourke, latinu aj to n risi ipese ounjẹ labẹ ajọ isọkan agbaye ni ""Ko si ile ti afẹfẹ lile naa ko fi ọwọ ba. Ko si ina ọba, ko si ẹrọ ibaraẹnisọrọ, bẹẹ si ni awọn oju popo kun fun opo ina ati waya ina ọba to ja silẹ."""
Awọn osisẹ alaanu yii lo gbogbo oru lati gbe awọn eeyan sọkalẹ lati ori igi. ti iji lile naa si ti ran eeyan to le ni ọgọsan si ọrun ọsan gangan, ni ẹkun guusu Afrika.
Ẹgbẹ alagbelebu pupa lagbaye si ti se apejuwe isẹlẹ ajalu yii gẹgẹ bii eyi to lagbara julọ, to si ba ni lẹru.
Koda gbogbo oju ọna to so ilu Beira papọ mọ awujọ agbaye lo ti bajẹ patapata, sugbọn eto irinna ofurufu ti bẹrẹ pada.
Building Collapse: 'Àjọ wa kìí ṣe àjọ wóléwólé, àwọn èàyàn lóò fá'
Ile miran tun wo l'Eko
Adari ajọ to  n ri si ọrọ ile kikọ nipinlẹ Eko, LASBCA Ọgbẹni Lekan Ṣhodẹinde sọ pe ọpọ ile ko ba ti di wiwo ti awọn onile ba tẹle ilana ajọ LASBCA nipinlẹ naa.
Shodẹinde to ba BBC Yoruba sọrọ lori ile to ya lulẹ lagbegbe Oke Aarin, Lagos Island, sọ pe o ṣeni laanu pe ọpọ onile lo maa n  kọ eti ikun si ijọba lori ofin ti ijọba la kalẹ lori ile kikọ nipinlẹ Eko.
LASBCA sọ̀rọ̀ lórí ilé wíwó
O ni ile iṣẹ LASBCA kii ṣe ile iṣẹ wole wole, o ni aitẹle ofin ijọba lori ile kikọ lo jẹ ki ajọ LASBCA maa wo awọn ile ti ko dangajia.
Àlàyé rèé lórí ilé kẹ̀ta tó wó l'Eko
Ọgbẹni Shodẹinde  fikun ọrọ rẹ pe nigba miran o le jẹ pe owo diẹ ni onile ni lati na sori ile ṣugbọn ọpọ onile kii fẹ tẹle ilana ajọ LASBCA.
Ninu alaye rẹ, ọga ajọ LASBCA sọ pe akọkọ ninu ilana ajọ naa ni pe ti awọn ba ṣakiyesi wi pe ile kan ko duro daadaa ti o si le ṣakoba fawọn to n gbe inu rẹ, ajọ LASBCA yoo fun onile niwe lati sọ fun wọn pe ile naa  yoo wo.
Ile to tun wo l'Eko
O ni lẹyin naa ni ajọ LASBCA yoo ṣayẹwo lọna sayẹnsi (Structural Test) lati mọ bo ya ile naa le gba atunṣe tabi ko le gba a.
Ọgbẹni Shodẹinde sọ pe o di dandan ki onile tun ilẹ ṣe ti ayẹwo ba fihan pe ile naa nilo atunṣe, bẹẹ lo fidi rẹ mulẹ pe gbogbo ile ti ajọ LASBCA ba fawọn onile niwe le lori kọ lo maa n di wiwo.
Ọga ajọ LASBCA ni onile to ba gbawe ayẹwo lati ọdọ awọn ti ko ba ṣe e, awọn yoo fun un ni iwe keji ti wọn n pe ni ''Quit Notice'' pe ki gbogbo awọn to wa ninu ile le ko jade.
Ki ile naa to ya lu lẹ
Lẹyin naa ni ajọ LASBCA yoo ti ile naa pa, ti wọn yoo kan si onile lati mu iwe ayẹwo aridaju pe ile naa si duro deedee.
O ni ijọba maa wo ile naa ti onile ko ba gbe igbesẹ lati tun ile ọhun ṣe.
O ni ojuṣe awọn onile ni  lati maa ṣe atunṣe ile lati igba de igba ati pe onile gbọdọ maa ṣayẹwo ile loreekoree.
Ọgbẹni Shodẹinde ni awọn ayalegbe gbọdọ rii pe iwe ẹri ijọba wa lori ile ti wọn ba fẹ gba  ki wọn to gba a.
Ile miran wo L'Eko
Ọga ajọ LASBCA tun ni ojuṣe awọn ara adugbo ni lati tawọn lolobo ti wọn ba ri ile kan ti ko ba duro daadaa.
O ni awọn eeyan le pe ajọ LASBCA lori awọn nọmba yii- 07000537222 tabi 07000050504040 ti wọn ba fẹ tawọn lolobo lori ile ti ko ba duro daadaa.
Ikú Suga: UCH ní àwọn agbẹjọ́rò òun yóò fèsì fún mọ̀lẹ́bí Sugar
Oríṣun àwòrán, Temitope Sugar
Ile iwosan ẹkọṣẹ iṣegun yunifasiti Ibadan, UCH, ti sọ fun BBC Yoruba pe, oun yoo fesi to tọ si iwe ipẹjọ ti mọlẹbi ilumọka oloṣelu Temitope Olatoye 'Sugar' fi sọwọ si oun.
Agbẹjọro mọlẹbi oloogbe naa lo ti kọkọ kowe beere fun igba miliọnu Naira lọwọ ile iwosan UCH, fun bi  ile iwosan naa ṣe ja igbẹkẹle awọn kulẹ pẹlu bo ṣe jẹki aworan iku rẹ lu sita.
Alukoro ile iwosan naa, ọgbẹni Toye Akinrinlọla, lasiko ifọrọwerọ kan pẹlu BBC Yoruba lo fi idi ọrọ yi mulẹ
''A ti gba iwe ti awọn ẹbi Olatoye kọ si wa lori iku ọmọ wọn sugbọn awọn agbẹjọro wa yoo fesi si pada fun wọn bo ti ṣe tọ ati bi o ti ṣe yẹ''
Akinrinọla ni oun ko le fesi si awọn ọrọ ti molẹbi oloogbe kọ, bi kii ṣe pe ki awọn agbẹjọro UCH wo awọn ẹsun naa wo yekeyeke, ki wọn si dahun si.
Ẹgbọ́n olóògbé Suga: Wọ́n yìnbọn fún Suga lójú mi, n kò sì lè dá wọn dúró
Ile iwosan nla UCH ni ilu Ibadan ni Olatoye ku si, ni ọjọ Kẹsan oṣu Kẹta ọdun 2019,  lẹyin ti o fara gba ọta ibọn ni agbegbe Lalupọn lasiko idibo sipo gomina to waye nibẹ.
Agbẹjọro mọlẹbi Sugar, Amofin C.C Amedu ti ile iṣẹ agbẹjọro Ikeh Sunday, Ibadan, ninu iwe ipẹjọ fẹsun kan ile iwosan UCH pe, wọn jẹ ki aworan ipọkaka iku Sugar lu sita lasiko to wa gba itọju lọdọ wọn.
Manfe-Dove: Àgbà ìlú kan ní ohùn kan ló fọ̀ sáwọn baba ńlá àwọn láti ṣe bẹ́ẹ̀
Wọn fi iwe ipẹjọ naa ṣọwọ si minisita fun eto ilera ati ẹgbẹ awọn dokita ẹka tilu Ibadan.
Iwe naa sọ siwaju pe, ti UCH ko ba fesi si ọrọ awọn laarin ọjọ meje, awọn yoo gbe igbesẹ lati pe wọn lẹjọ lori ẹsun aibikita.
Akẹ́kọ̀ọ́ dókítà: Fásitì Ìbàdàn gbọdọ̀ dín owó iléẹ̀kọ́ wa
National Assembly:Nkán mẹ́rin tí yóò ṣatọna àwọn tí yóò jẹ́ olórí ilé aṣòfin orílẹ̀-èdè Nàìjíríà
Oríṣun àwòrán, @NGRSENATE
Iwe eri iyansipo ti awọn asọfin gba lọwọ ajọ eleto idibo Naijiria lọ́jọ Kerinla Oṣu Kẹta ti ṣina fun idunadura awọn ti yoo ṣakoso ile asofin orileede Naijiria.
Nigba ti a o ba fi ri oṣu Kẹfa ọdun yii, wọn yoo ṣe ifilọlẹ awọn asofin tuntun fun saa kẹsan ile asofin Naijiria.
Bi ipalẹmọ naa ti ṣe n sunmọ dẹdẹ ibeere kan to gbẹnu awọn awoye ati pupọ ọmọ Naijiria ni ẹni ti yoo dipo aarẹ ile asofin agba ati ti olori ile asojusofin mu.
Agbodegba ẹgbẹ oṣelu APC Ogbẹni Lanre Issa Onilu lai pẹ yi s pe ẹgbẹ awọn ko ni tẹri sinu aṣiṣe iru e;eyi ti o ṣẹlẹ lọdun 2015.Fun idi eleyi,o ni awọn yoo ri pe ẹni ti yoo di awọn ipo yi mu gbọdọ jẹ ẹni ti yoo ṣiṣẹ pẹlu aarẹ lati mu erongba ẹgbẹ ṣẹ.
Lara awọn idi ti yoo satọna ẹni ti yoo di ipo yi mu ni a fẹ gbiyanju lati yanana fun yin.
''Zoning''
Ẹgbẹ oṣelu to wa lori oye ni awọn yoo pin ipo awọn ti yoo ṣakoso ile laarin awọn ẹkunjẹkun orileede Naijira ni.
Gẹgẹ bi ọgbẹni Lanre Issa Onilu ti ṣe sọ, o ni awọn yoo gbe igbeṣẹ naa lati jẹki awọn eeyan ẹkun naa laanfaani lati dije fun ipo ohun.
O tun salaye pe awọn asiwaju ẹgbẹ yoo ṣe ipade laipe lati le ṣe agbekalẹ ilana ti yoo tọ awọn aṣofin ti igbimọ amuṣẹya ẹgbẹ naa yoo si ṣe ipade lori igbesẹ naa.
Awọn ti yoo ri ipo to munadoko di mu ni ile aṣofin kẹsan yi yoo jẹ awọn ti wn jẹ odu nile asofin.
Ohun ti eleyi tunmọ si ni wi pe awọn aṣofin to n bọ wa si ile fun igba akọkọ ko ni laanfaani lati ri awọn ipo yi dimu.
Awọn to ti pẹ ati awọn Gomina to n bọwa si ile asofin yoo wa lara awọn ti o ṣeeṣe ki wọn di ipo pataki mu nile.
Ki eeyan to le ni ohun yoo di ipo pataki mu nile aṣofin, o gbọdọ jẹ ẹni ti o ni akọsilẹ daada ti awọn eeyan si n sọ ọrọ rẹ daada.
Ita Enang to jẹ oluranlọwọ agba fun aarẹ lori ọrọ ile asofin Naijiria ni aṣofin kankan ti awujọ ko ba fi oju rere wo ko ni ri ipo pataki dimu nile aṣofin.
Ohun pataki miran ti yoo ṣe atọna boya eeyan yoo di ipo pataki mu nile asofin ni bi o ba ti ṣe ni ibaṣepọ pẹlu awọn aṣofin akẹgbẹ rẹ.
Ita Enang ni ọrọ ki ṣe ohun amuṣere rara nitori pe ẹni ti ko ba duro daada laarin yi ko nidipo pataki kankan mu.
O ni ẹgbẹ oṣelu awọn yoo fọrọwerọ pẹlu awọn ẹgbẹ oṣelu ti wọn ko ni ọmọ ẹgbẹ pupọ nile lati ri wi pe ero wọn papọ pẹlu ti aarẹ.
O ni eyi se pataki lati jẹ ki awọn eto ijọba di mimuṣẹ fun anfaani gbogbo eeyan Naijiria.
Koffi Olomide: Ilé ẹjọ́ kan nílẹ̀ Faranse ló sọ́ sẹ́wọ̀n ọdún méjì
Oríṣun àwòrán, KoffiOlomide_MM
Koffi Olomidé, ọkan nínu àwọn gbajúgbàjajà olórin takansufe nìlẹ̀ Afíríkà, ní wọn ló jẹbi ẹ̀sùn pé ó fipá bá ọ̀kan lára àwọn ọmọ tó ń ba jó lopọ, nìgbà tí ò wà ní ọmọ ọdún mẹ́ẹ̀dógún.
Bó tilẹ̀ jẹ pé ó kọ̀ láti yọju sí ilé ẹjọ, síbẹ, wọ́n wọn ẹ̀wọ̀n ọdún mẹ́jì fun ní ilé ẹjọ kan ni France.
Akoroyin BBC,  Nadir Djennad jábọ̀ pé, ìtumọ̀ ìdájọ́ tí wọn dá fún gbájugbaju olorin ọmọ bibi Congo ni pe, yóò kóju àtimọ́le ní to ba tún lu òfin.
Olomidé, ẹni ọmọ ọdun méjìlélọ́gọ́ta ni wọn pàṣẹ fún pé, kó sàn ẹgbẹ̀rún márùn Euro gẹgẹ bii owó ìtanran fún oníjo rẹ̀ nígbà kan.
Oríṣun àwòrán, KoffiOlomide_MM
Bakan náà ni ilé ẹjọ Nanterre to wa ní àgbegbè Pari, tún ni ko san iye owo kan náà, nítori ó ràn àwọn obinrin méji kan lọ́wọ́ láti wọ ilẹ̀ France lanà àìtọ́
Agbéjọro Olomidé lásìkò tó ń ba àwọn akọroyin sọ̀rọ̀ sọ pé, òun ri ìgbéjọ náà gẹ́gẹ́ bi àṣeyori nítori èyí yoo yọ Koffi kúro nínú ìwé ìpẹ̀jọ àgbáyé, to fẹ fi sẹ́wọ̀n.
Manfe-Dove: Àgbà ìlú kan ní ohùn kan ló fọ̀ sáwọn baba ńlá àwọn láti ṣe bẹ́ẹ̀
Koffi Olomidé jẹ ìlúmọ̀ọ́ká olórin Rumba àti Soukous, ti gbogbo ènìyàn mọ ní ọ̀pọ̀ àwọn ilẹ̀ aduláwọ̀
Sáájú ni wọn ti pe Olomidé lẹ́jọ́ lọ́dun 2012, fún ẹ̀sùn ìbálòpọ̀ sùgbọ́n nígbà tó yá ni wọn ṣe àdínkù ẹ̀sùn náà.
Mẹ́rìn nínú àwọn tro ń jó fún gbájugbajà olórin náà ló jẹ́rìí nilé ẹjọ pe ó fi ipá ba àwọn lòpọ̀ láàrín ọdun 2002 si 2006. Wọn ni ìṣẹ̀lẹ̀ náà wáye ni DR Congo àti France.
Awọn obinrin náà tún fẹ̀sùn kàn pé ó fi àwọn pamọ sinnu ile kan ní agbegbe paris lòdi sí ìfẹ́ inu àwọn sùgbọ́n àwọn sá kúrò ni oru ọjọ́ kan lọdun 2006 ti àwọn ò si le pada si DR Congo ki ó ma ba tun mú àwọn.
Bótilẹ̀ jẹ́ pe àgbéjọro ń fẹ́ ki wọn fi si ẹ̀wọn ọdun méje síbẹ̀ adájọ dá gbogbo atotonu agbẹjọrà nù ni to fi mọ ẹsun ìjíní gbé.
Olomidé sá lọ si DR Congo lọdun 2009 pẹ̀lú ìléri pé òun yóò gbèjà ara òun sùgbọ́n ó kọ̀ láti farahan nílé ẹjọ́ ni France.
Okunrin olorin ọ̀hun tó orukọ rẹ̀ gangan ń jẹ́ Antoine Agbepa Munba tó ń ni ìsòrò pẹ̀lú òfin ní ọ̀pọ̀ ìgbà:
Ní ọdun 2018 Zambia pàṣẹ́ ki wọn fi si àtimọlé nítori pé o hùwà àitọ si ayaworan kan
Ní ọdun 2016 ọwwọ agbófinro bàá wọn si da pada sile lẹ́yìn to ṣe ọkan nínú àwọn tó ń jó fún báṣubàṣu ní Kenya.
Ni ọdún 2012 ó jẹ̀bi ẹsun ti wọn fi kan ni DR Congo nítori pe ó ṣe ẹni to ń ba gbé àwọn orin rẹ̀ síta lọ́nà ti kò tọ́, wọn si wọn ẹwọn oṣù mẹ́tà fún.
Ni ọdun 2008 wọn fi ẹsun kan pé ó gab ayàworàn kan nípàá lóri amóhùnmáworan DR Congo ti ó si fa ẹ̀rọ ayaworan rẹ̀ níbi ayẹyẹ orin itagbangba, sùgban òun àti ẹni náà fi ṣe ọ̀rọ̀ abẹ́ ilé.
Election 2019 Updates: Atiku ní ìbò 18m ni mo ní, Buhari sì ní ìbò 16.5m
Oríṣun àwòrán, Facebook/Atiku Abubakar
Ẹto idibo aarẹ
Oludije fun ipo aarẹ labẹ asia ẹgbẹ oselu PDP, Alhaji Atiku Abubakar sọ pe, ẹrọ kọmputa ajọ eleto idibo INEC fihan pe ibo to le ni miliọnu kan aabọ, l'oun fi bori aarẹ Muhammadu Buhari, to n soju ẹgbẹ oselu APC ninu idibo aarẹ to lọ.
Ọjọ Aje ni Atiku morile ile ẹjọ lati gbe atako rẹ kalẹ, nigba to ku wakati mẹrinlelogun pere ki iye ọjọ ti ofin la kalẹ fun oludije kan lati pe ẹjọ tako esi ibo pe.
Ọjọ kẹtadinlọgbọn oṣu keji to lọ ni ajọ INEC kede pe, aarẹ Buhari lo jawe olubori ninu ibo aarẹ pẹlu ibo to le ni miliọnu mẹẹdogun, ti Atiku si se ipo keji pẹlu ibo miliọnu mejila o le diẹ.
Ṣugbọn Atiku ati ẹgbẹ PDP, ti wọn jẹ olupẹjọ ni, magomago wa ninu esi idibo ti ajọ INEC kede naa.
Awọn olupẹjọ fidi rẹ mulẹ fun igbimọ olugbẹjọ ibo aarẹ naa pe, ẹrọ kọmputa ajọ INEC fihan pe, Atiku lo leke pẹlu ibo to le ni miliọnu mejidinlogun ti aarẹ Buhari si ṣe ipo keji pẹlu ibo to leni miliọnu merindinlogun ati aabọ.
Demilade Adepegba: Mo má a ń gbàgbé fèrè ni, tí mo bá wà nílé ìwé
Wọn ni iye ibo ti Atiku ati Buhari ri niyi ni ipinlẹ marunlelọgbọn nitori ko tii si esi idibo aarẹ ti ipinlẹ Rivers lori ẹrọ kọmputa INEC, lọjọ kẹẹdọgbọn oṣu keji.
Mansa Musa: Ó lówó, ó ní dúkìá rẹpẹtẹ àmọ́ kò pẹ́ láyé
Oríṣun àwòrán, @ItsMansaMusa
Oludasilẹ ile iṣẹ Amazon, Jeff Bezos lo lowo julọ lagbaye bayii gẹgẹ bi atẹjade ti iwe iroyin Forbes gbe fi lede, pẹlu owo to le ni biliọnu lọna aadoje owo dọla ($131bn)
Ṣugbọn iwadii fihan pe, ọmọ ilẹ Afririka lo lowo julọ lagbaye ninu itan ni Mansa Musa.
Musa jẹ aarẹ apaṣẹ waa ni ẹkun Gusu ilẹ Afirika laye ọjọ-un ti o fi orilẹede Mali ṣe ibujoko ijọba rẹ.
Iwadii fihan pe owo ti Musa ni nigba naa, to bi biliọnu lọna irinwo dọla ($400bn) owo ode oni.
Ọjọgbọn ninu imọ itan ni fasiti California lorilẹede Amẹrika, Rudolph Butch Ware sọ pe, ko rọrun lati sọ iye owo ti Musa ni ni pato, nibi ti o lowo to si lọrọ de laye igba yẹn.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Musa: Igi owo
Onwoye Jacob Davidson kọ nipa Musa lọdun 2015 pe, Musa lọrọ ju ohun tẹni kankan le ṣalaye lọ.
Ibi Musa
Wọn bi Mansa Musa lọdun 1280 si idile awọn to ṣe olori. Ẹgbọn Mansa, Abu-Bakr se ijọba titi di ọdun 1312.
Ọdun 1312 yii lo fipo naa silẹ, to si gbera lọ si oke okun pẹlu ẹgbẹrun meji ọkọ oju omi ati ẹgbẹẹgbẹrun ọkunrin ati obinrin ti wọn ko si pada wale mọ.
Demilade Adepegba: Mo má a ń gbàgbé fèrè ni, tí mo bá wà nílé ìwé
Bayii ni Musa bẹrẹ si ni ṣe ijọba lẹyin ti ẹgbọn rẹ lọ ajo aremabọ.
Ijọba Musa lọ ṣua bi ẹgbẹrun meji mailli lati eti okun to fi de ibi ti orilẹede Niger wa loni.
Koda ijọba rẹ tun tan ka de awọn apa kan lorilẹede Senegal, Mauritania, Burkina Faso, Gambia, Guinea Bissau, Guinea ati orilẹede Ivory Coast.
Maapu Ijọba Mansa Musa
Bi ijọba rẹ ṣe tan kalẹ to, bẹẹ naa ti alumọni goolu ati iyọ pọ yanturu ni ijọba rẹ.
Ibudo iko nnkan iṣẹnbaye lọjọ si ti ilẹ Gẹẹsi sọ pe, idaji goolu to wa lagbaye lo wa ni ijọba Musa nikan laye igba yẹn.
Ibudo okoowo goolu wa kaakiri ni ijọba rẹ, nidi okoowo yii lo ti ri owo to towo.
Irinajo Musa si Mecca
Okiki ijọba Musa kan kari aye nigba to lọ si ilu Mecca fun iṣẹ isin, to si gba ọna aṣalẹ Sahara ati orilẹede Egypt lọ irinajo ọhun.
Iwadii fihan pe, ẹgbẹrun lọna ọgọta ọkunrin lo kọwọ rin pẹlu Musa lọ si ilu Mecca.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Musa olowo aye
Bakan naa ni awọn oṣiṣẹ aafin rẹ, awọn sọja, awọn oniṣowo, awọn ti n wa kẹtẹkẹtẹ pẹlu ẹru kọwọ rin pẹlu Musa lọ si ilẹ mimọ.
Musa tun ko ọpọlọpọ ewurẹ ati agutan dani, ti wọn n pa fun ounjẹ loju ọna.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Musa jẹ musulumi gidi
Musa sọ ilu Tumbuktu lorilẹede Mali di gbajugbaja lagbaye, lẹyin ti okiki aworan ijoko ọba ti wọn fi goolu ṣe lori maapu Catalan lọdun 1375, se gba awujọ agbaye kan.
Musa ku lọdun 1337 ni ẹni ọdun mẹtadinlọgọta, lẹyin naa lawọn ọmọkunrin rẹ bẹrẹ si ni ja si ẹni ti yoo gun ori itẹ baba wọn.
Eleyi lo jẹ ki ijọba naa tu, ki awọn oyinbo to wa ko ilẹ Afirika lẹru.
Ìtàn Mánigbàgbé: Baṣọ̀run Gáà jẹ́ àgbà ìjòyè tó le è yípadà sí ẹranko tó bá wù ú
Oríṣun àwòrán, Steemit
Ko fẹẹ si ọmọ Kaarọ o jiire ti ko gbọ orukọ Basọrun Gaa ri nitori odu ni, kii se aimọ fun oloko.
Koda, owe kan wa, to jẹ mọ iwa ati ise Basọrun Gaa, eyi to ni ‘Boo laya koo ṣe ika, too ba ri iku Gaa, ko sootọ’, eyi to ṣe alaye nipa awọn iwa ika ti Basọrun Gaa hu lasiko to gbe ile aye.
Gẹgẹ bi a ti ka ni oniruuru awọn oju opo ikansiraẹni lori itakun agbaye, kii kuku se pe Basọrun Gaa ko ni ipa rere to ko si idagbasoke ilu rẹ, Ọyọ ile.;
Koda, o ṣeniyan daadaa ninu itan naa nibẹrẹ, nitori ori ti ko ba jẹ eeyan takuntakun, ko ni de ibi giga to ku si.
Itan fi ye wa pe, Basọrun Gaa ni olori igbimọ Ọyọmesi, eyi to dabi Olootu ijọba laye ode oni, lẹyin Alaafin, tii se oriade ilu Ọyọ́, Basọrun Gaa lo tun ku.
Ko si sẹni to le e sọ pe ti Basọrun Gaa ko jẹ eeyan gidi, ko sẹni to le fi jẹ oye Basọrun, to jẹ olori igbimọ lọbalọba fun Alaafin, tii se Ọyọmesi.
Ni bayii, o wa yẹ ka mọ itan igbe aye akọni yii ati ipa to ko ni ilu rẹ, boya rere ni abi buburu.
Wo itan omi gbigbona ati tutu ni Ikọgosi Ekiti
Awọn Obinrin Dahomey:  Awọn obinrin ilẹ Afirika ti wọn yii itan pada re e
Yaa Asantewaa: Ti ẹyin ọkunrin Ashanti kò bá tẹsiwaju, awa obinrin yóò lọ
Lisabi Agbongbo Akala rèé, ẹni tó fi ìfẹ́, ìṣọ̀kan àti ìrẹ́pọ̀ gba ilẹ̀ Ẹ̀gbá lọ́wọ́ ìmúnisìn
Afọnja, ẹni tó finú wénú ní Ilọrin, àmọ́ tó jẹ iwọ
Ọba Lamidi Adeyẹmi, òṣìṣẹ́ adójútòfò àti Abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò kó tó jọba
Ọ̀rọ̀ǹpọ̀tọ̀niyùn, Aláàfin obìnrin àkọ́kọ́ rèé, tó ní nǹkan ọkùnrin
Helen Paul sọ idi tó fi gba orúkọ ní kékere
Lagos King: Mátikú ọba tó lo lo ọdun mẹta lórí oyé latari rogbodiyan Eko
Ìtàn Àrọ̀gìdìgbà jẹ́ kí ń rò pé bàbá mi yan Yemọ̀ja ní àlè - Ọmọ Fagunwa
Ẹfunsetan Aniwura, ọmọ Ẹ̀gbá tó di akíkanjú obìnrin nílẹ̀ Ibadan
Ọọ̀ni obìnrin, Lúwòó Gbàgídà rèé, akọni tó ń gun ọkùnrin ní ẹṣin rìn
Sanusi Adebisi Idikan rèé, olówó tó ń san owó orí fún gbogbo ọkunrin ilẹ̀ Ibadan
Aarẹ ọna kakanfo Yoruba
Itan igbe aye Basọrun Gaa yii ni ọpọ ẹkọ to kọ wa, paapa awọn alagbara lode aye, o si kọ wọn pe ki wọn rọra se.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Bakan naa ni itan igbe aye Basọrun Gaa yii kọ wa lati mase se ika nitori ati oore, ati ika, ọkan kii gbe, ati ile aye yii si la ti n jere gbogbo iwa ta a ba hu, ta a si gba ẹsan rẹ lọrun pẹlu.
Gbogbo awa obi si lo yẹ ka ranti pe agba to ba ro ẹfọ ika, ọmọ rẹ yoo jẹ ninu rẹ, bẹẹ si lo yẹ ka wa ọna lati fi orukọ rere silẹ de iran wa to n bọ nitori orukọ rere san ju wura ati fadaka lọ.
Ìgbẹ́tì: Òkè Ìyámàpó ló gba wàá sílẹ̀ lọ́wọ́ ogun
Chinese restaurant: CDHR ní ìjọba Nàíjíríà ló fa ẹ̀gbin náà bá wa
Oríṣun àwòrán, Punch
Aarẹ ajọ ajafẹ́tọ ọmọ Naijiria ti a mọ sí CDHR, Amofin Malachy Ugwummadu ti sọ wipe, ajọ naa ṣetan lati ja fun ẹtọ ọmọ Naijiria kan, ti ile iṣẹ ounjẹ awọn ọmọ ilẹ China to wa lorilẹede Naijria ko ba gba laaye, lati wọle jẹun nibẹ.
Igbesẹ yii waye lẹyin ti iroyin gba ori ayelujara kan wipe, ile ounjẹ China kan to wa ni Ikeja nilu Eko, Shi Shi Chinese Restaurant kọ, lati jẹ ki awọn ọmọ Naijiria wa ra ounjẹ ninu ileeṣẹ wọn.
Awọn akọroyin to lọ ṣe iwadii ni ile ounjẹ naa gbọ wipe, ootọ ni ati wipe, ileeṣẹ naa ni ọmọ Naijiria to ba fẹ ra ounjẹ ninu lọdọ wọn gbọdọ mu ọmọ orilẹede China kan lẹyin.
Kloe: Èmi kìí mu òògùn olóró, àmọ́ mo fẹ́ràn láti máa wà lẹ́bà omi
Ṣugbọn Ugwummadu ni igbesẹ ileeṣẹ to ba dan iru nkan bayii wo lodi si ofin agbaye ati ti Naijiria.
Ninu ọrọ rẹ pẹlu BBC Yoruba, amofin naa ni oun ti ajọ CDHR nilo lati ọdọ ẹni ti ileeṣẹ okeere naa da pada lẹnu ọna, ni ẹri bii fidio tabi aworan ti yoo fi ohun to ṣẹlẹ han.
Oríṣun àwòrán, Bc
Ugwummadu ni ẹri nikan ni CDHR nilo lati gbe ileeṣẹ to ba da ọmọ Naijiria pada lọ ile ẹjọ
O ni ijọba orilẹede Naijiria lo fa iru ẹgbin bayii ba awọn ọmọ orilẹede yii, nitori awọn lo gbe aye le awọn ileeṣẹ okeere lọwọ.
Ijọba Ipinlẹ Eko ti fesi si ọrọ ile ounjẹ China naa pe, ko si ootọ kankan ni ọrọ naa, nitori wipe awọn ti ran awọn eeyan kan lọ si ileeṣẹ ounjẹ naa ni bonkẹlẹ, ti wọn si da wọn lohun.
Komiṣọna fun eto igbafẹ ní Ipinlẹ Eko, Steve Ayorinde, ti ni ijọba kò tíì pari iwadii rẹ lori ile ounjẹ China kan ni ipinlẹ Eko to n gbe igbesẹ ẹlẹyàmẹya ti ko jẹ ki awọn ọmọ Naijiria ra ounjẹ.
Ẹ gbọ ọrọ rẹ siwaju si:
Lagos Chinese restaurant: Ayorinde ní Ìpínlẹ̀ Eko ń gbé ìgbésẹ̀ nípa ilé oúnjẹ elẹ́yàmẹ̀yà
INEC:Ìròyìn òfégè ní pé ilé ẹjọ pàṣẹ fún wa láti dáwọ àkójọ èsì ìbò Gómìnà Rivers dúró
Oríṣun àwòrán, INEC Situation room
Alaga ajọ eleto idibo Mahmud Yakubu
Ajọ eleto idibo Naijiria ti ni ko si ootọ  ninu iroyin to n ja rain-rain pe ile ẹjọ ni ki awọn da akojọ esi idibo Gomina ipinlẹ Rivers duro.
Ọjọ kẹsan oṣu Kẹta ni idibo si ipo Gomina ati ti awọn asoju ile asofin ipinlẹ naa waye nipinlẹ naa.
Iroyin to gbode ni pe ile ẹjọ paṣẹ kan eleyi to ṣegbe fun ẹgbẹ oṣelu African Action Congress,eyi to ni ki Inec  da ọwọ kika ati akojọ awọn esi idibo to waye nipinlẹ Rivers.
Iroyin naa tun sọ pe ẹgbẹ oṣelu Labour ati Advance Peoples Democratic Alliance na kowe ẹsun tako Inec ni ile ẹjọ giga lAbuja lori ọrọ naa.
Amọ ṣa agbẹnusọ ajọ eleto idibo  Inec  Rotimi Oyekanmi sọ fun BBC pe ayederu iroyin lasan ni.
''Rara,rara rara,iroyin ẹlẹjẹ ni,ko si nnkankan to jọ bẹ lati ile ẹjọ nipinlẹ Rivers''
Oyekanmi salaye pe ''loni lo yẹ ki a gbe ilana kalẹ, ki ilẹ oni si to ṣu a o gbe jade''
Darudapọ waye nidibo Gomina ati awọn asoju ile asofin nipinlẹ Rivers
Ọrọ yi n waye lẹyin ti ile ẹjọ paṣẹ ki Inec dawọ kika ati akojọ esi idibo ni Bauchi.
Inec ti saaju dawọ kika ati ikede ẹni to jawe olubori ninu idiboipinlẹ Bauchi ki ile ẹjọ to paṣẹ ki wọn da duro.
Amọ ṣa Inec ti kọkọ da kika ati ikede esi idibo duro nipinlẹ Rivers nitori wahala ti o waye nibẹ.
Election 2019 Updates: Atiku n ṣé iranran lórí ìbò 1.6 mílíọ̀nù ni-APC
Oríṣun àwòrán,  Lanre Issa-Onilu
Ẹgbẹ oselu All Progressives Congress ti fesi si ọrọ oludije ẹgbẹ oselu Peoples Democrativc Party,PDP Atiku Abubakar to ni ohun fi ibo 1.6 miliọnu sagba Muhammadu Buhari ninu ibo aarẹ.
Lanre Onilu to jẹ akọwe ipolongo ẹgbẹ naa ni ''Atiku n ṣe iranra ni''
Ninu atẹjade kan ti o fi sita lọjọru lorukọ ẹgbẹ,Onilu sọ pe awọn ba Atiku kaanu bi awọn ọmọ Naijiria ti ṣe fi ibo wọn da sẹria fun.
O salaye pe ninu gbogbo awọn awawi ti Atiku kojo ninu iwe ipẹjọ rẹ lori esi ibo aarẹ to ti fidirẹmi,eleyi to sọ pe oju opo Inec le jẹri wsi pe ohun fi ibo1.6 miliọnu ju Buhari lọ jẹ eleyi to panilẹrin julọ.
''Ṣe Dubai lo ti ṣagbelẹrọ ibo1.6 miliọnu ni abi awọn alalufa rẹ lo ta esi ibo yi fun un?''
Onilu ni bi Atiku ti ṣe n tẹnumọ oju opo Inec yi mu ifura lọwọ nitori pe ''o jọ bi ẹ ni wi pe ohun ati ẹgbẹ PDP fẹ fi ọgbọn alumọkọrọyi lu oju opo naa lati ṣe akoba fun''
Bi a ko ba gbagbe,Atiku Abubakar ti sọ lọjọru pe ohun fi ibo miliọnu kan le ẹgbẹta ṣagba Buhari ninu ibo aarẹ ti o si tọ ki Inec kede ohun gẹgẹ bi ẹni to jawe olubori.
Lagos: Àjọ iwádìí ọrọ̀ ajé àgbáyé, EIU ní Ilu eko wà lára àwọn ìlú tó gbọ̀pọ̀ jùlọ lagbaye
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ọ̀pọ̀ olùgbé ìlú Eko ló ń pariwo pé kò rọrùn láti gbé níbẹ̀
Njẹ ẹ mọ pe ipinlẹ Eko wa lara awọn ilu mẹwa ti owo gbigbe e rẹ gba ọpọ julọ lagbaye?
Ajọ iwadi ijinlẹ nipa ọrọ aje lagbaye, Economist Intelligence Unit lo sọ bẹẹ ninu abajade iwadii ijinlẹ kan ti wọn ṣe kaakiri orilẹede agbaye.
Àlàyé rèé lórí ilé kẹ̀ta tó wó l'Eko
Bi o tilẹ jẹ pe ọpọ olugbe ipinlẹ Eko ni ko ni fẹ gba eyi gbọ nitori ohun ti oju wọn n ri lori awọn koko igbayegbadun bii ile gbigbe, ọkọ wiwọ, ohun jijẹ rira ati bẹẹbẹẹ lọ, ṣugbọn ajọ iwadii ọrọ aje agbaye naa ni sibẹsibẹ, gbigbe ni ilu Eko ṣi gba ọpọ ju ọpọ awọn ilu nlanla miran kaakiri agbaye.
Ilu Caracas lorilẹede Venezuela lo gba ipo kini, ti ilu Damascus lorilẹede Syria si tẹlee, ilu Tashkent ni orilẹede Uzbekistan, Almaty ni Kazakhstan ati Bangalore lorilẹede India lo tẹlee ni ipo kẹta, kẹrin ati ikarun ni ṣisẹ n tẹlee.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Àjọ iwádìí ọrọ̀ ajé, EIU ní nǹkan rọrùn ju bí ọ̀pọ̀ ṣe lérò lọ ni ilu Eko
Karachi (Pakistan) ati ilu Eko ni wọn jijs wa ni ipo kẹfa ti Buenos Aires ni Argentina ati Chennai India si tun pin ipo keje.  New Delhi (India) lo wa ni ipo kẹjọ.
Ọgọjọ ohun amuyẹ bii ounjẹ, ohun mimu, igbokegbodo ọkọ, owo ina atawọn nnkan miran pẹlu owo ile gbigbe ni awọn ajọ naa gbe yẹwo kaakiri awọn ilu mẹtalelaadoje, (133).
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Awọn ilu mẹtalelaadoje kaakiri agbaye ni ajọ̀ EIU gbe yẹwo
Agbejade naa wa ko ilu Paris lorilẹede France,, Hong kOng ati Singapore sita gẹgẹ bii awọn ilu ti o wọn julọ fun eeyan lati gbe lagbaye.
Zurich (Switzerland), Geneva (Switzerland), Osaka (Japan) , Seoul (South Korea), Copenhagen (Denmark)  ati New York lorilẹede Amẹrika wa ni ipo keje ti Tel Aviv (Israel) ati  Los Angeles (amẹrika) pẹlu ko gbẹyin laaarin awọn ilu mẹwa akọkọ ti owo ati gbe ibẹ gaara pupọ julọ lagbaye.
Lagos Building Collapse: Ìjọba ìpínlẹ̀ Eko gbé ìgbìmọ̀ olùwádìí kalẹ̀
Ọpọ obi lo ya bo awọn ileewosan lati mọ ipo ti awọn ọmọ wọn wa ti awọn miran ṣi n wa eeyan wọn
Ijọba ipinlẹ Eko ti yan igbimọ ẹlẹni maarun ti yoo ṣewadii awọn nkan to fa a ti ile alaja mẹta kan fi wo nipinlẹ naa.
Ijọba ipinlẹ Eko lo kede igbesẹ naa loju opo Facebook rẹ.
Ile alaja mẹta naa to wa ni Ita Faaji ni agbegbe Lagos Island lo wo lọjọ kẹtala oṣu Kẹta, to si fa ifarapa ati iku fun diẹ lara awọn to n gbe ninu ile naa.
Ọ̀pọ̀ kò ní ibití wọ́n máa sùn bí  ìjọba ìpínlẹ̀ Èkó se bẹ̀rẹ̀ ilé wíwó
LASEMA so ètò ìdóòlà ẹ̀mí rọ̀ ní ibùdó tí ilé ti wó nílùú Eko
Àlàyé rèé lórí ilé kẹ̀ta tó wó l'Eko
Lasiko to n ṣe ifilọlẹ igbimọ naa, kọmisana fun ile kikọ ati idagbasoke ilu, Prince Rotimi Ogunleye sọ pe awọn nkan pataki ti igbimọ naa yoo mojuto ni wiwa ọna ti opin fi le de ba iṣẹlẹ ile wiwo lọjọ iwaju, to fi mọ iwa aibikita awọn abanikọle tabi ẹni to nile, ati ipa ti ijọba ipinlẹ naa n ko ninu iru iṣẹlẹ bẹ.
Bakan naa ni ireti wa pe igbimọ naa yoo ṣe agbekalẹ ilana ti yoo mu ki awọn to n kọle maa ṣe isẹ to pojuowo.
Alaga igbimọ naa, Onimọ ẹrọ Wasiu Olokunola ninu ọrọ rẹ, sọ pe igbimọ naa yoo ṣe iṣẹ to ni itumọ , nitori pe 'awọn ọmọ igbimọ naa ni iriri to yẹ ninu ile kikọ.'
Deji Adeyanju vs Charley boy: Charly Boy l'óun kò gbowó, Deji ní ó já òun kulẹ̀
Oríṣun àwòrán, Instagram/Deji Adeyanju
Ọrọ lori ẹgbẹ ''Our Mumu Don Do''
Gbajugbaja ajijagbara ati olorin Charles Oputa ti ọpọ eeyan mọ si Charly Boy ti ṣalaye ohun to ṣẹlẹ gan an fanran ede-ai-yede laarin rẹ ati Deji Adeyanju.
Nigba to ba BBC sọrọ, Charly Boy fidi rẹ mulẹ lootọ l'oun gba owo lọwọ agbẹjọro Festus Kenyamo ti ẹgbẹ APC, ṣugbọn owo iṣẹ ti oun ṣe fun APC nipasẹ Kenyamo ni oun gba lọwọ rẹ.
Charly Boy ṣalaye pe irọ ni iroyin to n tan kalẹ lori ayelujara pe oun gba riba gẹgẹ bi ajafẹtọ ọmọniyan.
Ọgbẹni Oputa ni lati ọjọ to ti pẹ ni ajọṣepọ to dan mọran ti wa laarin oun ati Kenyamo, o ni pe oun ti maa n ba ṣiṣẹ tẹlẹ.
Ṣugbọn Deji Adeyanju ninu ọrọ tiẹ pẹlu BBC sọ pe Charly Boy ja oun kulẹ.
Charly Boy l'óun kò gbowó
O ni o dun oun pe nigba ti oun wa lẹwọn, awọn ti awọn jọ n ja fẹtọ ọmọniyan le laya lati lọ gbowo lọwọ ijọba
Charly Boy fikun ọrọ rẹ pe oun ko ṣegbe lẹyin ọkankan ninu ẹgbẹ oṣelu APC tabi PDP nitori, ọkan ko gbekan bi owu jango lawọn mejeeji.
O ni oun fun ra oun lo sọ fun Kenyamo pe ko gbeṣẹ f'oun, iṣẹ ọhun naa l'oun si ṣe fun un.
Oríṣun àwòrán, Twitter/Charly Boy
Ẹgbẹ Our Mumu Don Do
Charly Boy loju opo Twitter rẹ sọ pe 'ti baba ko ba sọrọ, o tumọ si pe baba ni ni tootọọ.
O tẹsiwaju pe oun ati Deji lo mọ ohun to n bii ninu, amọ ṣa oun si fẹran rẹ.
O tun sọ pe owo gọbọi l'oun gba lọwọ Kenyamo fun iṣẹ t'oun ṣe, ṣugbọn owo oogu oju oun lowo.
O  ni idi niyii t'oun ko le fi fun ẹnikankan ninu owo ti oun gba lori iṣẹ ọhun.
2019 election: Bí wọ́n ṣe ń ta káádì ìdìbò ní Kano
Oríṣun àwòrán, EFCC
Ni ọjọ Abamẹta to jẹ ọjọ kẹtalelogun oṣu kẹta ni ajọ eleto idibo INEC yoo ṣe eto ni awọn agbegbe kan ti wọn ti wọn ti fagile idibo ninu awọn ipilẹ kọkan ni orilẹede naa.
Ṣugbọn iṣoro kan ti wọn ti tu asiri rẹ lati ibẹrẹ ni bi wọn ṣe ń ṣe kara-kata lai bikita.
Ni waransesa ni ileeṣẹ ọlọpaa ipinlẹ Kano ti sọ pe ọọ awọn ti ba ti wọn fi ẹsun kan pe wọn ta ibo, wọn si sọ pe wọn n sa agbara wọn lati ri pe lati gbegidina iru iwa yii.
Sugbọn awọn akoroyin BBC, Yusuf Yakasai ati Halima Umar Saleh, ti wọn lọ si Kano lati gbe iroyin imurasilẹ fun idibo naa jade, ti ṣe iwadi lori bi wọn ṣe maa n ṣe owo kaadi ibo tita ati rira.
Iwadi wọn fi han pe awọn obirin ni wọn maa n fi ọrọ tita kaadi idibo lọ lọpọ igba.
Ati wi pe lọpọ igba wọn maa n lo ọgbọn ọtọtọ bii ọrọ awo ti yoo ṣoro lati mọ loju ẹsẹ nibi kara-kata kaadi idibo naa.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
F'apejuwe , arabirin kan to kan si Halima Umar Saleh lati ta ibo rẹ , sọ fun Halima pe 'ó yẹ kí o ra àgé (Buta ni Hausa n pe age) nítorí kí wọ́n  gbée lọ sí mọ́sálásí gẹ́gẹ́ bíi sàárà'.
Lẹyin naa lo lo èdè buta tí Hausa n pe age  to si sọ pe Buta n bẹ, buta (voter) si n bẹ.
Alaye fi han pe awọn agbofinro n wọ inu awọn adugbo ti wọn ti fẹ ṣe atundi-ibo yii lati gbegidina kaadi idibo tita.
Demilade Adepegba: Mo má a ń gbàgbé fèrè ni, tí mo bá wà nílé ìwé
Ṣugbọn iru awọn eeyan yi ti wọn fẹ ta ibo wọn maa n ni ibi ti wọn ti maa n pade l'awọn adugbo kọkan, nitori ki ọwọ awọn agbofinro ma ba wọn nigba ti wọn  fẹ ta ibo wọn..
Nigba idibo gomin ato kọja gan, awọn aworan ati fidio ti wọn s'afihan bi wọn ṣe lo owo nibi rira ibo n kakiri lori ẹrọ ayelujara.
Ileeṣẹ to n gbogun ti awọn to koba ọrọ aje Naijiria (EFCC) ati eyi to n gbogun ti iwa ibajẹ ( ICPC) wọn ṣe alaye pe ibo rira lodi si ofin ajẹbanu.
Ileeṣẹ ICPC sọ nibi apejọ ilaniloye kan ninu osu kejila ọdun 2018 pe ibo riria jẹ ijamba fun ilana democrasy.
Kọmíṣọ́nà ọlọ́pàá ó ṣeṣe kó jẹ́ pé ará ló sán pa ènìyàn mẹ́ta
Oríṣun àwòrán, Dan (catching up) Flikr
Ara ti san pa eniyan mẹta ni ijọba ibilẹ Guusu Ughelli ni Ipinlẹ Delta.
Kọmiṣọna ọlọpaa ipinlẹ naa, Adeyinka Adeleke sọ fun awọn oniroyin wipe awọn ṣi n fi oju sunukun wo ọrọ naa nitori wipe ko si iwe ayẹwo ile iwosan to fi han wipe ni tootọ ni pe ara san pa awọn oloogbe naa.
Iroyin fi han wipe iṣẹlẹ naa ṣẹlẹ ni bi aago mẹrin ọjọ Iṣẹgun nigba ti ojo arọọrọda kan rọ ni ilu Otu-Jeremi. Awọn ti ọrọ ṣe oju wọn ni awọn oloogbe naa wa ninu ile kan ti wọn n duro de ojo naa ko da ni ara ba wọ inu ile naa.
Kloe: Èmi kìí mu òògùn olóró, àmọ́ mo fẹ́ràn láti máa wà lẹ́bà omi
Igba ti awọn aladugbo maa de ibẹ, oku awọn mẹta naa ni wọn ba nilẹ. Ori ko ọkan lara awọn ti àrá naa ba yọ, ṣugbọn wọn ti gbe oku awọn to ku lọ ile iwosan ijọba to wa nilu naa.
Osun tribunal: Ta ni ilé ẹjọ́ yóò gbẹ́ adé ìdìbò gómìnà ìpínlẹ̀ Ọṣun fún?
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Nibi idajọ ileeẹjọ to n gbọ ẹjọ idibo gomina nipinlẹ Ọṣun, igbimọ idajọ naa ni oun yoo yọ ibo ẹgbẹrun meji o le mọkandinlogun ninu ibo APC ati ẹgbẹrun kan o le igba ati mẹrindinlaadọta ninu ibo PDP lawọn ibudo idibo mẹtadinlogun ti wọn ko ti tẹle ilana idibo lorilẹede Naijiria.
Bakan naa ni ile ẹjọ naa tun ṣalaye pe ẹgbẹ oṣelu PDP kuna lati fi idi rẹ mulẹ pe lootọ ni ibo adile waye lawọn ibudo idibo marundinlaadoje.
Ida yoo waye loni nilu Abuja
Paroparo ni ọ́fíìsì ẹgbẹ́ òṣèlú APC àti PDP dá ní Ìpínlẹ̀ Ọṣun ní bí àwọn ẹgbẹ́ òṣèlú méjèèjì náà ṣe ń dúró de ìdájọ́ ilé ẹjọ́ tó ń rí sí èṣùn tó súyọ lórí èsì ìbò gómìnà Ìpínlẹ̀ náà tó wáyé lọ́dún 2018
Lọwọ yii, idajọ ṣi n lọ lọwọ ni ile ẹjọ to n gbọ ẹjọ naa nilu Abuja.
Ni ọjọ kejilelogun oṣu kẹsan ọdun 2018 ni eto idibo ati yan gomina fun ipinlẹ Ọṣun waye
Ṣe wọn ni irawe kan ko ni dajọ ilẹ ko sunna. Loni ọjọ ẹti, ọjọ kejilelogun oṣu kẹta ọdun 2019 ni ile ẹjọ to n gbọ ẹjọ kotẹmilọrun to suyọ lori idibo sipo gomina ni ipinlẹ Ọṣun yoo gbe idajọ rẹ kalẹ lori ẹni gan an to bori idibo naa.
Ni ọjọ kejilelogun oṣu kẹsan ọdun 2018 ni eto idibo ati yan gomina fun ipinlẹ Ọṣun waye. Bi o tilẹ jẹ wi pe ajọ INEC to n ṣe agbatẹru eto idibo lorilẹede Naijiria ko lee fi ẹnu idibo naa jona sojukan naa lọjọ naa, nibi ti oludije fun ẹgbẹ oṣelu PDP, Ademọla Adeleke ti n lewaju; eto atundi ibo waye lawọn ẹkun idibo melo kan ni ọjọ diẹ si idibo naa lo yi ohun gbogbo pada ti oludije APC, Gboyega Oyetọla si wa bori lẹyin ajọṣepọ to waye laaarin ẹgbẹ oṣelu APC ati gbajugbaja oloṣelu ni, Iyiọla Omiṣore ti oun pẹlu jẹ oludije ni abala akọkọ idibo naa.
Oríṣun àwòrán, @IsiakaAdeleke1
Adeleke lọ si ile ẹjọ lati pẹjọ ẹhonu lori esi idibo naa
Ni bayii, ajọ INEC ti kede Gboyega Oyetọla gẹgẹ bii gomina ipinlẹ Ọṣun, wọn si ti bura fun un wọle gẹgẹ bii gomina lati oṣu kọkanla ọdun 2018.
Amọṣa, oludije fun ipo gomina lẹgbẹ oṣelu PDP, Ademọla Adeleke ti gba ile ẹjọ lọ pẹlu awijare pe oun ni o bori atipe ka yọwọ awọn iwa aitọ to sọ pe o waye lasiko idibo naa kuro, oun lo yẹ ki ajọ INEC kede gẹgẹ bii gomina.
Ile ẹjọ to n gbọ ẹhonu idibo naa bẹrẹ iṣẹ ni pẹrẹwu bi o tilẹ jẹ pe ọpọ awuyewuye lo kọkọ waye lori rẹ, ki o to di pe o gbe ijoko rẹ lọ si olu ilu ilẹ Naijiria, Abuja.
Oríṣun àwòrán, @raufaregbesola
Oyetọla ni INEC kede pe o bori idibo naa
Ni bayii ti idajọ yoo waye loni, igun mejeeji lo ti n fọwọ sọya pe lọdọ awọn ni ọsan didun yoo so si lori idajọ naa.
Adura ati awẹ, titi kan ipade adura ita gbangba ni awọn ẹgbẹ oṣelu mejeeji, APC ati PDP ṣe ṣaaju idajọ ti yoo waye loni.
Amọṣa, ilẹkẹ maa ja sile, maa ja sita, ibi kan naa ni yoo jasi. Ẹyin ẹ tẹti leko o lori bi o ba ṣe n lọ ni ile  ẹjọ naa loni.
Ilé ẹjọ́ kéde Ademọla Adeleke gẹ́gẹ́ bíi gómìnà ìpínlẹ̀ Ọṣun
Ìròyìn tó ń tẹ̀ wa lọ́wọ́lọ́wọ́ ní wí pé ilé ilé ẹjọ́ tó ń gbọ́ ẹjọ́ ìdìbò gómìnà ìpínlẹ̀ Ọṣun ti kede oludije fun ẹgbẹ oṣelu PDP, Ademọla Adeleke gẹgẹ bii  gomina ti ilu dibo yan ni Ọ̀ṣun.
Ilé ilé ẹjọ́ tó ń gbọ́ ẹjọ́ ìdìbò gómìnà ìpínlẹ̀ Ọṣun ti kede oludije fun ẹgbẹ oṣelu PDP, Ademọla Adeleke gẹgẹ bii  gomina ti ilu dibo yan ni Ọ̀ṣun.
Ile ẹjọ naa ninu idajọ to gbe kalẹ ni ọjọ ẹti, ṣalaye pe atundi ibo to waye lawọn ibudo idibo kan ni ọjọ kẹtadinlọgbọn ko ba ofin mu.
Nigba ti awọn adajọ mẹtẹẹta yoo gbe idajọ wọn kalẹ, meji ninu wọn dajọ pe oludije PDP Ademọla Adeleke ni ẹni ti ilu dibo yan.
Eeyan kan to ku, to jẹ alaga igbimọ naa, Onidajọ Ibrahim Sirajo ni tirẹ dajọ gbe Oyetọla ti ẹgbẹ oṣelu APC lẹyin.
Oríṣun àwòrán, Ademola Adeleke
ilé ilé ẹjọ́ kede oludije fun ẹgbẹ oṣelu PDP gẹgẹ bii gomina ti ilu dibo yan ni Ọ̀ṣun
Oludije fun ipo arẹ lẹgbẹ oṣelu PDP, Atiku Abubakar ti ki Adeleke ku oriire idajọ to ṣẹṣẹ gba ni ile ẹjọ.
"Atiku ni o fihan pe 'lootọ, ẹka idajọ ni ireti araalu ati olugbeja iṣejọba tiwantiwa."""
Bakan naa, gbajugbaja olorin takasufe to tun jẹ mọlẹbi Adeleke ni imọlẹ lo de si ipinlẹ Ọṣun bayii.
O wa ki aburo baba rẹ ku oriire.
Nigeria vs Seychelles: Ikọ Super Eagles bori Seychelles pẹ̀lú 3-1 nínú ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ AFCON
Oríṣun àwòrán, @thenff
Orilẹ̀ede Nigeria ati Seychelles yoo waako ni agogo mẹrin ọjọ ẹti
Orilẹede Naijiria jawe olubori ninu ifẹsẹwọnsẹ wọn Seycheles loni ọjọ Ẹti ninu idije ife ẹyẹ AFCON ti ọdun 2019.
Nigba ti ere bọọlu naa maa pari, ikọ Super Eagles ti gba ẹjẹ lẹnu Seychelles pẹlu ami ayo mẹta si ọkan.
Odion Ighalo, Henry Onyekuru ati Moses Simon lo gba ayo mẹtẹẹta wọle.
Naijiria bẹrẹ ifẹsẹwọnsẹ naa pẹlu agbara bi Alex Iwobi ṣe jẹ tẹtẹ ayo kan ni iṣẹju karun-un, ṣugbọn Ahmed Musa to yẹ ko ran an lọwọ ko jẹ ki ayo naa wọle.
Bi o tilẹ jẹ pe abajade ifẹsẹwọnsẹ naa ko lee ni ipa lara ilepa eyikeyi ikọ mejeeji ninu bi nnkan ṣe ri ṣaaju ninu idije naa, ireti wa pe awọn ikọ mejeeji yoo ta biọbiọ lati ṣe bi ọkunrin.
Ni bayii, olukọni ikọ Super eagles ti gbe orukọ awọn agbabọọlu ti yoo ṣoju orilẹede Naijiria jade bayii.
Orukọ wọn ree,  Uzoho ni aṣọle akọkọ, Shehu, Emeruo, Ekong, jamilu, Ndidi, Etebo, Musa, Onyekuru, Iwobi ati Ighalo ni yoo bẹrẹ ninu ifẹsẹwọnsẹ naa.
Bakan naa, Onuachu, Balogun, Ogu, Simon, Ezenwa, Awaziem ati ajayi naa yoo wa ni ikalẹ.
Osun elections: Ademọla Adeleke, Fayoṣe, Atiku sọ̀rọ̀ lórí ìdájọ́ ilé ẹjọ́
Oríṣun àwòrán, Davido
Ilé ilé ẹjọ́ tó ń gbọ́ ẹjọ́ ìdìbò gómìnà ìpínlẹ̀ Ọṣun ti kede oludije fun ẹgbẹ oṣelu PDP gẹgẹ bii gomina ti ilu dibo yan ni Ọ̀ṣun
Ẹni ti ile ẹjọ ṣẹṣẹ kede pe ilu dibo yan gẹgẹ bii gomina ipinlẹ Ọṣun, Sẹnetọ Ademọla Adeleke ti ṣalaye pe Ọlọrun ni oun fi ọpẹ fun lori idajọ to waye naa.
"Sẹnetọ Adeleke to sọrọ ni oju opo twitter rẹ ni 'Ogo ni fun Oluwa"""
Yatọ si Adeleke, Ọpọlọpọ awọn ọtọkulu lo ti sọrọ lori ọrọ yii.
Gomina ipinlẹ Ekiti tẹlẹ, Ayọdele Fayose ṣalaye pe lẹyin Ọṣun, Ekiti lo kan lati bọ si ọwọ ẹgbẹ oṣelu PDP.
Oludije fun ipo arẹ lẹgbẹ oṣelu PDP, Atiku Abubakar ti ki Adeleke ku oriire idajọ to ṣẹṣẹ gba ni ile ẹjọ.
"Atiku ni o fihan pe 'lootọ, ẹka idajọ ni ireti araalu ati olugbeja iṣejọba tiwantiwa."""
Bakan naa, gbajugbaja olorin takasufe to tun jẹ mọlẹbi Adeleke ni imọlẹ lo de si ipinlẹ Ọṣun bayii.
O wa ki aburo baba rẹ ku oriire.
Osun tribunal: APC ní ìdájọ́ ilé ẹjọ kò lẹ́sẹ̀ ń lẹ̀, Ó ń gba ilé ẹjọ́ kòtẹ́milọ́rùn lọ
Oríṣun àwòrán, Gboyega Oyetola
Ninu atẹjade kan ti ẹgbẹ oṣelu naa fi sita ni o ti ṣalaye pe idajọ naa ko ba ofin mu rara
Ijọba ipinlẹ Ọṣun pẹlu ti fi atẹjade sita pe wọn gomina Oyetọla ti gba ile ẹjọ kotẹmilọrun lọ ati pe pẹlu eyi, Oyetọla ṣi ni gomina ipinlẹ Ọṣun.
Atẹjade naa ni eto abo yika ile ijọba ipinlẹ naa ti gbopsn sii lati lee daaboobo dukia ati ẹmi gbogbo.
Ilé ẹjọ́ kéde Ademọla Adeleke gẹ́gẹ́ bíi gómìnà ìpínlẹ̀ Ọṣun
Ademọla Adeleke, Fayoṣe, Atiku sọ̀rọ̀ lórí ìdájọ́ ilé ẹjọ́
Ijọba ipinlẹ Ọṣun wa rọ awọn eeyan ipinlẹ naa lati maa ba iṣẹ oojọ wọn lọ lai da omi alaafia ilu laamu.
Ẹwẹ, Ẹgbẹ oṣelu APC ti kede wi pe idajọ ti ile ẹjọ gbe kalẹ, eyi to kede Sẹnetọ Ademọla Adeleke gẹgẹ bii gomina ti ilu dibo yan nipinlẹ Ọṣun, ko ni pẹ jẹ rodo lọ ree mu omi nitori pe awọn n gba ile ẹjọ lọ.
ẹgbẹ oṣelu APC ṣalaye ọrọ yii ninu atẹjade kan ti alukoro ẹgbẹ oṣelu naa ni ipinlẹ Ọṣun, Amofin Kunle Ọyatomi fi sita ni ọjọ ẹti.
Osun Election Results 2018: Adeleke sọ pé PDP yóò gba ipò gómìnà rẹ̀ padà nílé ẹjọ́
Ẹgbẹ oṣelu APC ni awọn ko lee gba idajs naa wọle ati pe ile ẹjọ kotẹmilọrun ni awọn n gba lọ bayii.
Gẹgẹ bii ẹgbẹ oṣelu naa ṣe sọ, 'idajọ ọhun ko lee duro labẹ itanna ofin. Nitori naa, a o pẹjọ kotẹmilọrun lori rẹ.
Ọ̀pọ̀ ẹ̀mí sọnù sínú ìjàmbá iná l'órílẹ̀èdè Ghana
Oríṣun àwòrán, TV3 GHANA
Ogunlọgọ eniyan lo ti padanu ẹmi wọn lẹyin ti ọkọ bọọsi meji kọlura wọn laarin gbungbun Ghana.
Botilẹjẹ wi pe iye awọn to ku ko ti i fojuhan bayii, oṣiṣẹ ijọba kan sọ fun BBC pe o le ni aadọta eniyan to ti ku, ti ọpọlọpọ si farapa.
Awọn ọlọpaa ati oṣiṣẹ pana-pana ti wa ni ibi ti ijamba naa ti waye.
Ileeṣẹ ọlọpaa sọ pe ni nkan bi aago meji oru ni ijamba naa waye ni agbegbe Kintampo South.
Iroyin sọ pe ẹmi to sọnu pọsi nigbati ọkan lara awọ̀n ọkọ naa gbina lyin ti wn kọlu ara wọn.
Ó ti di ogún èèyàn tó kú ní ilé alájà tó wó l'Eko
'Ìwadìí yòó yàtọ̀ lórí ilé tó wó nítorí ààrẹ ti gbọ́ síi'
Manfe-Dove: Àgbà ìlú kan ní ohùn kan ló fọ̀ sáwọn baba ńlá àwọn láti ṣe bẹ́ẹ̀
Kano Govnorship Re-run: Gómìnà Ganduje ní òun yóò fara mọ́bí èsì ìdìbò bá ṣe jẹ́
Gomina ipinlẹ Kano, Abdullahi Ganduje ti sọ fun BBC pe oun yoo gba kadara ti oun ba fidirẹmi ninu atundi ibo gomina ti yoo waye jakejado ijọba ibilẹ mejidinlgbọn to wa nipinlẹ naa.
Ganduje fikun pe ẹru ko ba oun rara, nitori oun mọ pe ẹni to ba wu Ọlọrun l'oun gbe agbara fun.
Idaniloju wa fun mi nipa atundi ibo yii nitori pe ati ṣe atunṣe si awọn aṣiṣe ti a ṣe lọsẹ meji sẹyin, ṣugbọn mo ti ṣetan lati gba kadara ti n ba kuna, maa si ki ẹni to ba jawe olubori ku oriire nitori mo gbagbọ pe ẹni ti Ọlọrun ba fẹ l'oun gbe agbara fun.
Ajọ eleto idibo INEC nipinlẹ Kano sọ pe oun ti gbaradi fun atundi ibo naa.
Alaga ajọ naa, Ọjọgbọn Shehu Risqua sọ fun awọn akọroyin pe ibudo idibo ọrinlerugba din ẹyọkan ni idibo naa yoo ti waye.
Bakan naa ni Ọjọgbọn Shehu fikun pe awọn yoo pin awọn eroja idibo lọjọ Ẹti, ati wi pe awọn kọmisana ajọ INEC mẹta mi i lati ipinlẹ Ogun, Kebbi ati Zamfara yoo wa si ipinlẹ Kano lati ran an lọwọ̀ ninu iṣẹ naa.
Amọ ṣa, awọn kan to wa nilu Kano n binu pe ileeṣẹ ọlọpaa ipinlẹ naa fi atẹjade sita pe ko ni i si lilọ bibọ lati aago mẹfa idaji si mẹfa irọlẹ ọjọ Abamẹta.
Ireti awọn eniyan ni pe awọn agbegbe ti idibo yoo ti waye nikan lo yẹ ki wọn o ti pa iru aṣẹ bẹ.
Ipinlẹ Kano jẹ ọkan lara awọn ipinlẹ ti atundi ibo gomina yoo ti waye lọjọ Abamẹta. Awọn ipinlẹ to ku ni Sokoto, Benue, Adamawa ati Plateau.
"Supplementary Election: ""Ijọba ìbilẹ Nasarawa nílò àfikun ọlọpàá ló jẹ ká fi kún un"""
Oríṣun àwòrán, Getty Images
"Supplementary Election: ""Ijọba ìbilẹ Nasarawa nílò àfikun ọlọpàá ló jẹ ká fi kún"""
Ilé iṣẹ́ ọlọ́pàá ìpínlẹ̀ Kano ti tún kó àwọm ọlọpàá míràn lọ si Wọọdu Gama ní ìjọba ìbílẹ̀ Nasarawa láti túbọ mú kí ètò ààbò gbópọn síi.
Agbẹnusọ fun àjọ ọlọpaa ní ìpínlẹ̀ Kano, DSP Abdullahi Haruna  lásiko tí àwọn oniroyin ń fi ọ̀rọ̀ waa lẹ́nu wò ní ìpínlẹ̀ Kano.
O ni  yíyan àwọn ọlọpaa lọ si agbegbe náà kò ṣẹyìn àbẹwo igbákeji ọgá ọlọpàá Anthony Micheal sí agbegbe náà.
O fí kún pé ìròyìn tó àwọn léti pe ètò ààbò kò gbópọn to ní agbégbè náà, èyí ló mu ki ìgbákeji ọgá àgbà ọlọ́pàá ṣe àbẹwò síbẹ̀.
Gẹ́gẹ́ bi ó ṣe sọ yíyàn àwọn ọlọpaa lọ si bẹ̀ jẹ àfikun àwọn to ti wà níbẹ̀ tẹ́lẹ̀ lójúnà àti mú ki ètò aabo dájú le wa fún ẹmi àti ohun ìní àwọn ènìyàn nibi ìdìbò tó ń lọ lọ́wọ́
Lóri awuyewuye pé wọn mú kọmisọ́na fun iṣẹ́ àkanṣe Muktar Ishiaq, agbẹnusọ ọlọpàá sọ pé irá to jìnà sí òòtọ́ ni àti pé òun kò ti gbọ́ ǹkan to jọ bẹ́ẹ̀.
2019 Supplementary election:PDP ní kí INEC wọ́gi lé àtúndì ìbó Kano nítorí ìwà jàǹdùkú
Iṣẹ̀lẹ̀ tó wáyé ni ìjọba ìbílẹ̀ Dala
Alága ẹgbẹ oṣèlú PDP ní ìpínlẹ̀ Kano, Rabiu Bichi ti ni ó ṣe pàtàkì kí àjọ elétò ìdìbò wọ́gilé àtúndi ìbò tó wáye lọjọ́ sátide, ọjọ kẹtàlélógun, ọdun 2019 nítori àwọn àwọn jàndùkú to fọ́nka ìgbòro ti kò si fún ọ̀pọ̀ láàyè láti dìbò.
Bichi sọ èyí di mímọ̀ lásìkò tó pe àwọn oníròyìn jọ lati sàlàyé pé ti wọn ò bá wọ́gilé ìdìbò náà à jẹ́ wípe ilé ẹjọ ni wọn yóò fipàdé sí nítori gbogbo àwọn ènìyàn Kano ló ti fi han pé ẹgbẹ́ òṣèlú PDP ni àwọn fẹ́ dìbò fún.
Ńkan tó ṣẹlẹ̀ ní Kano kìí ṣe ìdìbò rárá sùgbọ́n jàndùkú àti ìpánle ti gbogbo ayé sì ń wo. A rọ àjọ elétò ìdìbò INEC láti wọ́gile ìdìbo náà ti wọn bá wa kọ̀ láti wọ́gile a jẹ́ wípe ilé ẹjọ ni à ó ti gba ẹ̀tọ́ wa
"Akọwé ẹgbẹ́ òṣèlú All Progressives Congress (APC) nípinlẹ̀ náà Ibrahim Sarina sọ pé ọ̀rọ̀ ẹgbẹ́ alátakò lásan ní èyí nítori ní ibi ti òun wà ní ijọba ìbílẹ̀ Takai kò si ǹkan to jọ irú ǹkan bẹ́ẹ̀ bí ìdìbò ṣe ń lọ ni ìrọwọ́rọsẹ̀. ""Ijọba ìbílẹ̀ Takai ni mo wà ti gbogbo ǹkan sì ń lọ létòletò, ẹ gbagbé gbogbo àwọn ọ̀rọ̀ ti ẹgbẹ́ alátako ń sọ"
Eto idibo ko tete bẹrẹ ni nnkan bii ida ọgọrin ninu ọgọrun awọn ibudo idibo ti atundi idibo ti yẹ ko waye lọjọ abamẹta.
Ko si idi meji ju wi pe wahala to n bẹ silẹ laaarin awọn janduku oloṣelu pẹlu bi awsn oṣiṣẹ ajọ eleto idibo ṣe tun pẹ de pupọ awọn ibudo idibo naa.
Ni awọn ibudo idibo bii mẹwa ti BBC de, idibo ko tii bẹrẹ rara, ohun ti awọn oludibo si n sọ ni pe nṣe lawọn janduku n le awọn oludibo atawọn aṣoju ẹgbẹ alatako kuro ni ibudo idibo.
Ni agbegbe ibudo idibo Gwamamaja, ṣe ni awọn janduku le awọn aṣoju ẹgbẹ oṣelu yooku danu.
Bakan naa si ni ọmọ ṣe ori ni ibudo idibo miran ni ijọba ibilẹ Dala.
Eto idibo ti bẹrẹ ni ipinlẹ Kano lawọn agbegbe kan ti ajọ INEC ti ni atundi eto idibo yoo ti waye.
Bakan naa ni idibo ti bẹrẹ ni ipinlẹ Sokoto pẹlu.
Ni kutu owurọ ọjọ abamẹta lawọn oludibo ti tu sita lawọn agbegbe bii ijọba ibilẹ Yalwa ni ipinlẹ Kano lati dibo wọn
Oríṣun àwòrán, @AWTambuwal
INEC, awọn agbofinro ni eto gbogbo ti to fun ikẹsẹjari atundi ibo naa.
Lẹyin idibo si ipo gominato waye lorilẹede Naijiria ni ọjs kẹsan oṣu kẹta, ọdun 2019, idibo ni awọn ipinlẹ mẹfa kan bii Adamawa, Bauchi, Benue, Kano, Plateau ati Sokotoni ajọ INEC kede gẹgẹ bii eyi ti ko pari.
Amọṣa atundi ibo lawọn ipinlẹ marun ninu awọn ipinlẹ wọnyii yoo waye ni ọjọ abamẹta, ọjọ kẹtalelogun oṣu kẹta.
Ajọ INEC ni ireti wa pe gbogbo ohun to n ja ranyinranyin lori eto idibo lawọn ipinlẹ wọnyii yoo jẹ rodo lọ mumi lọjọ abamẹta.
Laaarin ẹgbẹ oṣelu APC ati PDP ni awọn atundi ibo yii yoo ti waye.
Ni ipinlẹ Sokoto, laaarin Aminu Tambuwal ti ẹgbẹ oṣelu PDP ati Aliyyu Sokoto ni idije naa wa. ṣaaju ọjọ abamẹta, ibo to le ni ẹgbẹrun mẹta lo la wọn laaarin.
Adeleke: Àwọn ará Ẹdẹ bẹ síta pẹ̀lú ìdùnnú lórí ìdájọ́ èsì ìdìbò gómínà Ọṣun
Ni ipinlẹ Bauchi laaarinBala Muhammed ti ẹgbẹ oṣelu PDP ati Gomina Mohammed Abubakar ni ọrs wa nitori ibo to le diẹ ni ẹgbẹrun mẹrin lo la wọn.
Ibo to le ni ẹgbẹrun mọkanlelọgọrin ni gomina Samuel Ortom ti ẹgbẹ oṣelu PDP fi n la Emmanuel Jime ti ẹgbẹ oṣelu APC.
Oshisko twins: Ojú wa rí, ṣùgbọ́nÌgbọ́raẹniyé ló ń ràn wá lọ́wọ́
Oju gbogbo yoo tun wa lori ipinlẹ Kano nibi ti gomina Abdullahi Ganduje yoo ti maa waako pẹlu Abba Kabir Yusuf ti ẹgbẹ oṣelu PDP.
Ibo ẹgbẹrun mẹrindinlọgbọn ni Yusuf fi n la Ganduje lọwọyii.
Gomina Simon Lalong tẹgbẹ oṣelu APC ati Jeremiah Useni ni yoo jọ ja du ipo naa. ẹgbẹrun lsna ogoji ati diẹ ni ibo to la wọn laaarin, ibo ẹgbẹrun mọkandinlaadọta si ni wọn n ja a le.
Osun tribunal: Ilé ẹjọ́ sọ Adeleke di gómínà, ṣùgbọ́n kò tó bẹ́ẹ̀ kó kó lọ ilé ìjọba
Ọpọ awọn alatilẹyin Ademola Adeleke to jẹ oludije PDP fun ipo gomina Ipinlẹ Osun ninu idibo to koja ni ipinlẹ naa lo bẹ si ita pẹlu ajọyọ ni ọjọ Ẹti bi ile ẹjọ ṣe ni Ademola Adeleke ni ojulowo gomina.
Ọpọ ni yoo si ro pe, bi ile ẹjọ ṣe kede idajọ yii, ṣe ni Adeleke yoo ko ẹru ti yoo si kọri si ile ijọba ni Oṣogbo lati lọ gba ipo rẹ lọwọ Gboyega Oyetọla ti ẹgbẹ oṣelu APC ti ajọ eleto idibo INEC ti kọkọ kede gẹgẹ bii gomina.
Osun Election Results 2018: Adeleke sọ pé PDP yóò gba ipò gómìnà rẹ̀ padà nílé ẹjọ́
Iwe ofin eto idibo Naijiria ti ọdun 2010 (Electoral Act 2010), sọ fun wa ni abala ọgọje (140) ni abẹ ipele kẹta wipe ti ile ẹjọ ba ti sọ wipe ẹni to wa lori aleefa kọ́ ni ojúlowo gomina nitori wipe ko ni iye ibo to pọ́ju, ile ẹjọ naa gbọdọ kede orukọ ẹni to ni idibo to pọju gẹgẹ bii gomina.
Eyi ni oun ti ile ẹjọ ti ṣe lori idibo gomina Osun ninu idajọ to waye ni Abuja ni ọjọ Ẹti.
Ṣugbọn abala ẹtalelogoje (143) iwe ofin naa, sọ wipe, ti ile ẹjọ ba ti ri aridaju wipe oludije to wa lori aleefa kọ́ ni ojulowo gomina, ti ẹni naa ba si lọ ile ẹjọ kotẹmilọrun wipe idajọ ile ẹjọ lori esi idibo naa ko tẹ oun lọrun laarin ọjọ mọkanlelogun (21) ti idajọ naa ti waye, ẹni tí ilé ẹjọ ní kìí ṣe ojúlowo gomina naa kò ní fipo silẹ titi di igba ti ilẹ ẹjọ kotẹmilorun ba to da ẹjọ tirẹ.
Idí rèé ti Oyetola ṣi maa ṣe gomina Osun lọ titi ti ile ẹjọ kotẹmilọrun ba to ṣe idajọ tirẹ. Idajọ ile ẹjọ kotẹmilọrun yii ni yoo si sọ boya Adeleke yoo ko lọ ile ijọba tabi idakeji rẹ.
Boko Haram: obìnrin tórí kó yọ ní omi àti ewé ńi òun jẹ nínú igbó
Oríṣun àwòrán, @elharsh
Obinrin kan ti ori ko yọ lọwọ ikọ agbesunmọmi Boko Haram, ti salaye fun pe inu tubu kan naa ni oun ati Leah Sharibu wa, ti o si wa ni alaafia.
Bẹẹ ba gbagbe, Leah Sharibu ni awujọ agbaye ti n pariwo fun idande rẹ lọwọ ikọ Boko Haram, lẹyin ti wn ji gbe pẹlu awọn akẹkọ ileewe girama kan nilu Dapchi, nipinl Yobe.
Bi o tilẹ jẹ pe Boko Haram tu awn akẹk yoku silẹ, amọ wọn ko fi Leah silẹ, nitori pe o faake kọri lati di ẹlẹsin Islam, ko si kuro ni ọmọlẹyin Kristi.
Nigba to n sọ iriri rẹ fun akọroyin Punch, obinrin naa ni osu kẹwa ọdun 2018 to kọja, ni oun fi Leah silẹ ni ahamọ, nigba ti oun sa kuro ni agọ Boko Haram.
O ni Leah ni wolii obinrin ni inu tubu ti Boko Haram fi awọn pamọ si, oun lo maa n gbadura fawọn eeyan yoku, to si tun n sisẹ iwosan lati ipasẹ adura rẹ naa.
Ọbinrin ọhun fikun pe asiko kan tiẹ wa, ti inu n run oun, Leah yii lo gbe ọwọ si inu oun, o gbadura fun oun, ti inu riru naa si lọ.
Oríṣun àwòrán, @BokoHaramWatch
Nigba to n sọ bo se de ahamọ Boko Haram, obinrin ẹni ọdun mẹẹdọgbọn naa ni, ọja ni oun wa ni Mubi, nigba ti Boko Haram wa ko awọn si ahamọ, ti wọn si fi tipa tipa sọ oun di ẹlẹsin Islam.
O salaye pe wọn mu oun ati ẹgbọn oun obinrin to ni ọmọ meji, amọ se ni Boko Haram fi ọbẹ la ọfun rẹ, nigba to taku lati di ẹlẹsin Islam, ti wn si fi awọn ọmọ rẹ si ahamọ.
Obinrin to jajabọ naa fikun pe, wọn se igbeyawo tipa fun oun pẹ́lu ọmọ ẹ́gbẹ Boko Haram kan, ti oun si bimọ obinrin kan fun, bẹẹ ni wn yi orukọ oun pada si ti musulumi.
World TB Day: Funkẹ Dosunmu ni ikọ́ ife kìí pani, ta bá lo òògùn rẹ̀ déédé
O ni oun sa kuro ni agọ Boko Hram naa pẹlu ọmọ oun ati awọn obinrin mẹjọ miran, amọ awọn yoku ku sinu igbo nitori aisan ati ebi.
Obinrin ọhun ni ewe ati omi ni oun ati ati ọmọ oun n jẹ ninu igbo fun odidi aadọrun ọjọ, eyiun osu mẹta, ki awọn ologun to ri oun ati ọmọ rẹ he ni abẹ oke kan lẹba ipinlẹ Gombe.
Oluwo: Yóò nira fún ìjọba láti sanwó oṣù tí kò bá sí àtúntò
Oríṣun àwòrán, @ObaEmperortelu
Oluwo ti ilu Iwo nipinlẹ Ọsun, Ọba Abdulrasheed Akanbi ti ke gbajare sita pe ti atunse ko ba ba isẹ ọba nipinlẹ naa, yoo nira fun ijọba lati san owo osu awọn osisẹ to kere julọ, ti i se ẹgbẹrun lọna ọgbọn naira.
Bakan naa ni oriade ọhun fikun pe awọn osisẹ ọba ni ipinlẹ Ọsun ti pọ lapọju, atunse nla si gbọdọ ba ẹka isẹ ọba nipa gbigbe awọn osisẹ ti ko ba ri isẹ se lọ sawọn ẹka ti isẹ wa fun wọn.
Oluwo ke gbajare bẹẹ nibi eto idije kan fawọn akẹkọ ile ẹkọ girama to waye ni ẹkun idibo iwọ oorun ipinlẹ Ọsun, eyi ti ẹgbẹ alaanu kan se agbatẹru rẹ.
Oluwo ni ipinlẹ Ọsun si n tiraka lọwọ ni, ti ko si dangajia to lati san owo osu to kere julọ tẹlẹ, tii se ẹgbẹrun lọna mejidinlogun naira, eyi to fihan pe omi n bẹ lamu fun wọn, ti yoo si nira lati san owo osu tuntun.
Ọba Akanbi fikun pe ohun ta mọ laa mọ, ohun to daju ni pe ẹni to n singba ko lowo lọwọ, ko si si ọna abayọ lọrun ọpẹ, ayafi tijọba ba wa atunse ati atunso si ẹka isẹ ọba ko lee dangajia si.
Ipinlẹ Ọsun n se aisan, ko si daju pw gomina yoo lee ri owo osu tuntun san. Ọba alaye ni mi, emi kii se oloselu, o si y ki n lee sọ ootọ ọrọ sita. Isẹ nla ni ti ijba yoo ba ri owo osu tuntun san, ayafi ti atunto ba ba ẹka isẹ ọba.
World TB Day: Funkẹ Dosunmu ni ikọ́ ife kìí pani, ta bá lo òògùn rẹ̀ déédé
Bawo ni awakọ mẹrindinlogoji yoo se maa pin ọkọ meji wa? eyi gbọdọ dopin, ki atunto si wa, gbogbo awọn osisẹ ti ko ba ri isẹ se ni kijọba gbe lọ sawọn agbọn ti isẹ pọ si.
Bakan naa ni Ọba Akanbi tun pe fun eto pipa owo wọle labẹle lna to se ara ọtọ , paapa ni ẹka awọn aladani, ko lee rọrun fun ijọba lati ri owo lo.
Árẹ̀wá: Bákan náà ni a kò fẹ́ Atiku torí dúkìá àjọni wà tó fẹ́ tà
Oríṣun àwòrán, @Atiku
Akọwe apapọ fun ẹgbẹ apapọ awọn eeyan apa oke ọya, Anthony Sani ti kede idi ti ẹgbẹ naa se kẹyin si oludije fun ipo aarẹ labẹ asia ẹgbẹ oselu PDP, Atiku Abubakar.
Akọwe Arẹwa to salaye ọrọ yii fawọn akọroyin , tun fikun pe, ẹgbẹ Arẹwa kede atilẹyin rẹ fun oludije fẹgbẹ oselu APC, aarẹ Muhammadu Buhari lẹyin to ti se agbeyẹwo afojusun ẹgbẹ oselu kọọkan, ileri ohun ti wọn fẹ se se ati bi oludije kọọkan se kun oju osuwọn si.
Sani to gba pe lootọ ni kii se asa ati ise ẹgbẹ Arẹwa lati pọn sẹyin oludije ẹgbẹ oselu kan fikun pe, awọn ti fi iroyin nipa oludije si etigbọ awọn oludibo, ki wọn si se idajọ fun wọn.
O ni awọn fọwọsi aarẹ Muhammadu Buhari lasiko eto idibo to kọja lai naani awọn aise deede ẹgbẹ oselu APC to n sejọba lọwọ, nitori ilọsiwaju ilẹ Naijiria ni.
O fikun pe, ẹgbẹ arẹwa to sẹyin Buhari ko ba lee rọrun fun lati pada wa se afikun awọn aseyọri to ti se tẹlẹ ni saa akọkọ rẹ.
World TB Day: Funkẹ Dosunmu ni ikọ́ ife kìí pani, ta bá lo òògùn rẹ̀ déédé
Sani ni, ko si ẹgbẹkẹgbẹ tabi ẹnikẹni to wa eekanna mọ ẹgbẹ Arẹwa lọrun lati se atilẹyin fun Buhari amọ awọn aseyọri rẹ, afojusun rẹ ninu ileri ipolongo ibo rẹ ati agbara ti ẹgbẹ oselu kọọkan ni, ni awọn se agbeyẹwo rẹ.
Akọwe ẹgbẹ Arẹwa ni, ẹgbẹ naa kẹyin si oludije fun ipo aarẹ labẹ asia ẹgbẹ oselu PDP, Atiku Abubakar, nitori bo se n polongo kiri pe oun yoo se atunto ilẹ yii, ti oun yoo si tun ta awọn dukia ajọni wa kan bii ileesẹ NNPC.
Oshisko twins: Ojú wa rí, ṣùgbọ́nÌgbọ́raẹniyé ló ń ràn wá lọ́wọ́
O fikun pe, gbogbo awọn dukia ti wọn ti ta nilẹ Naijiria tẹlẹ ko mu eso rere kan wa, bakan naa si ni eto atunto to n polongo ko nitumọ mọ ni asiko yii, tori pe, atunto ti ba awọn ẹka isejọba wa tẹlẹ bii ẹka eto iselu, ọrọ aje ati ẹkun idibo kọọkan.
Antony Sani ni ohun to ja ju lakoko yii ni akoso to peye nipa awọn ohun alumọni orilẹede yii, to si fi ohun to n waye nipinlẹ Eko se apẹẹrẹ.
Supplementary Elections: Ganduje ní ìbò 1,033,695, tí alátakò rẹ̀ sì ní 1,024,713.
Oríṣun àwòrán, Twitter/Ganduje
Atundi ibo gomina ni ipinlẹ Kano
Gómìnà Abdullahi Ganduje, olùdíje ẹgbẹ́ òṣèlú APC, wọlé fún sáà kejì ní ìpínlẹ̀ Kano lẹ́yìn àtúndì ìbò
Ajọ INEC ti kede Gomina Ganduje nirọlẹ ọjọ Aiku gẹgẹ ẹni to jawe olubori pẹlu ibo 1
Alatako Ganduje to nibo to sun mọ julọ, Abba Yusuf oludije fẹgbẹ oṣelu PDP ni ibo 10,239.
Ọjọ Abamẹta ọjọ kẹtalelogun oṣu kẹta ni atundi idibo ọhun waye nipinlẹ Kano.
Gomina Samuel Ortom, to jẹ oludije ẹgbẹ oṣelu PDP ti wọle fun saa keki gẹgẹ bi gomina ipinlẹ Benue lẹyin atundi ibo gomina nipinlẹ naa.
Oríṣun àwòrán, Facebook/Sanuel Ortom
Atundi ibo Benue
Ọga ajọ INEC, Sebastain Maimako to kede esi ibo naa ṣalaye pe Ortom ni ibo 434,473 nigba ti oludije ẹgbẹ APC to sun mọ julọ Ọgbẹni Emmanuel Jime ni 345,155.
Ki atundi ibo to waye, Ortom ni ibo 410,576 nigba ti Jime si ni ibo 329,022.
Ibudo idibo mẹrin le lugba ni atundi ibo gomina ti waye ni ijọba ibilẹ mejilelogun nipinlẹ Benue
Bala Mohammed ti ẹgbẹ oṣelu PDP lo wọle ninu atundi ibo gomina to waye  lọjọ Abamẹta to kọja ni ipinlẹ Buachi.
Alakoso ajọ INEC nipinlẹ ọhun, Ọjọgbọn Kyari Mohammed kede pe, Bala la gomina Ipinlẹ Bauchi lọwọlọwọ Mohammed Abdulahi mọ́lẹ pẹlu ibo ẹgbẹrun mẹfa o le lọdunrun un.
Ibo diẹ le lẹgbẹrun marun un ni gomina Abdulahi to jẹ oludije fẹgbẹ oṣelu APC ni, ninu esi atundi ibo ti wọn kede rẹ.
Oríṣun àwòrán, Sen Bala Muhammed
Wayi o, ajọ eleto idibo ko lee tii kede ẹni to jawe olubori ninu ibo gomina nipinlẹ Bauchi bayii nitori ibo ijba ibilẹ Tafawa Balewa to wa nile ẹjọ.
Ileejọ giga ilu Abuja lo pasẹ pe ajọ INEC ko gbọdọ tẹsiwaju pẹlu akojọpọ, ipari ati ikede esi ibo gomina nipinlẹ Bauchi.
Ole ni ẹgbẹrun kan ibo ti Bala Mohammed fi bori atundi ibo gomina ipinlẹ Bauchi.
Gómìnà Aminu tambuwal ti ipínlẹ̀ Sokoto ti lewaju ninu àtúndì ìbò gómìná tó wáyé lánàá ọjọ́ Satide.
Pẹ̀lú èsì ìbò náà, Tambuwal ti wọlé padà fún sáà keji, gẹ́gẹ́ bíi gómìnà ìpínlẹ̀ Sokoto.
Oríṣun àwòrán, @Tambuwal_2019
T
ambuwal, tó ṣojú ẹgbẹ́ PDP ló ní ìbò 512,002 nínú àpapọ̀ ìbò tí wọn kede rẹ, nigbati alátakò rẹ̀ látinú APC, Ahmada Aliyu ní 511,661.
Ìbò 341 ni Tambuwal fi ju Aliyu lọ ninu esi atundi ibo ti ajọ INEC ka.
Wayi o, gomina Lalong ti ipinlẹ Plateau naa ti bori idibo gomina ni ipinlẹ Plateau, lati pada fun saa keji ni ile ijọba ipinlẹ naa.
INEC kede Lalong gẹgẹ bi olubori lẹyin atundi ibo to waye ni ipinlẹ naa ni ọjọ Satide, ọjọ Kẹtalelogun oṣu Kẹta ọdun 2019.
Plateau wa lara awọn ipinlẹ marun un ti atundi ibo gomina ti waye.
Esi idibo lawọn ipinlẹ mẹrin yoku ko tii jade, pẹlu iroyin obitibiti wahala awọn janduku atawọn iṣẹlẹ ipa miran to waye nibẹ.
Oríṣun àwòrán, @SimonLalong
Oniruuru ẹsun iwa jagidijagan lo n kaakiri bayii lori bi awọn janduku ṣe fi oju awọn oludibo ati oniroyin ri mabo nilu Kano lasiko atundi ibo naa
Lalong ni ibo 595,582 lati gbẹyẹ mọ Ọgagunfẹyinti, Jeremiah Useni ti ẹgbẹ oṣelu PDP, ẹni to ni ibo 546,813.
World TB Day: Funkẹ Dosunmu ni ikọ́ ife kìí pani, ta bá lo òògùn rẹ̀ déédé
Ni ipinlẹ Sokoto, ọrọ ko ri bakan naa o pẹlu oniruuru iwa ipa ti iroyin ṣalaye pe o waye nibẹ.
Amọṣa ajọ INEC yoo tẹsiwaju pẹlu kika esi idibo naa.
Ẹwẹ, ni ipinlẹ Kano eeyan mẹwaa ni iroyin sọ pe ọlọpaa ti ko si ahamọ bayii, fun ẹsun iwa jaduku lasiko idibo naa.
Osun tribunal: Oyetọla ní òun kò bẹ̀rù ìdájọ́ ilé ẹjọ́ lórí èsì ìbò ìpínlẹ̀ Ọṣun
Oríṣun àwòrán, @OSUN_APC
Emi o bẹru idajọ yii rara. Gbogbo wa lo da loju pe, a ni ẹjọ to duro daradara, awọn ikọ agbẹjọro wa si ti fi eyi da wa loju. Nitori naa ko si idi kan fun ikayasoke.
Eyi ni ọrọ ti Gomina ipinlẹ Ọṣun, Gboyega Oyetọla sọ fawọn ọmọ ẹgbẹ oṣelu APC to wa kii ni ile ijọba ipinlẹ naa to wa ni ilu Oṣogbo, lori ti idajọ ti ile ẹjọ gbe kalẹ lori esi idibo ipinlẹ naa to waye loṣu Kẹsan ọdun 2018.
Ni ọjọ ẹti ni ile ẹjọ naa dajọ pe, Ademọla Adeleke ti ẹgbẹ oṣelu PDP lo yẹ ki ajọ eleto idibo, INEC kede gẹgẹ bii gomina dipo Oyetọla; ṣugbọn Oyetọla ti sọ pe, ko si ooyẹ kan to lee yẹ idi oun lori aga gomina ipinlẹ Ọṣun nitori pe, o da oun loju ṣaka pe oun lo bori ibo naa.
Emi ni mo ṣi n ṣejọba, ko si ile ẹjọ kan to yọ mi nipo ni ọrọ to tẹnu Gomina Oyetọla jade.
World TB Day: Funkẹ Dosunmu ni ikọ́ ife kìí pani, ta bá lo òògùn rẹ̀ déédé
O ni ẹgbẹ oselu APC ti pinnu lati pe ẹjọ kotẹmilọrun pẹlu afikun pe, o da oun loju pe didun ni ọsan yoo so fun oun ni ile ẹjọ kotẹmilọrun.
Bakan naa lo ṣalaye pe, awọn ọjọgbọn kan ninu imọ ofin  ti n jiroro lori idajọ naa ni kete ti ile ẹjọ gbe e kalẹ, ohun ti wọn si sọ n mu ireti wa.
O wa sọ siwaju sii pe, aṣẹ ti jade tọ awọn agbofinro lọ lati wa ni igbaradi lati rii pe, ko si idarudapọ laaarin igboro ati pe ẹnikẹni to ba gbimọran ati da omi alaaafia ilu ru, yoo jẹ iyan rẹ niṣu.
Supplementary Election: Àwọn jàndùkú yìnbọn fún òṣìṣẹ́ Inec, Ọ̀jọ̀gbọ́n Tuluen, ní Benue
Oríṣun àwòrán, Twitter/Mahmood Yakubu
Atundi ibo
Ajọ eleto idibo orilẹede Naijiria ti sọ pe, lootọọ ni wọn yinbọn fun oṣiṣẹ rẹ kan, Ọjọgbọn C.D Tuluen ni ijọba ibilẹ Gboko nipinlẹ Benue, lọjọ Abamẹta.
Ọjọgbọn C.D Tuluen ṣe kongẹ awọn agbebọn nigba to n lọ si olu ilu ipinlẹ Benue, tii ṣe Makurdi lọjọ Satide.
Alaga ajọ eleto idibo ilẹ wa lo kede iṣẹlẹ naa loju opo Twitter rẹ lọjọ Aiku.
Inec ni esi idibo ijọba ibilẹ naa wa lọwọ rẹ, nigba ti awọn janduku agbebọn kọlu ọkọ to wa ninu rẹ.
Ajọ INEC ṣalaye pe, Ọjọgbọn Tuluen farapa ninu ikọlu naa, bẹẹ lo si n gba itọju nile iwosan lọwọlọwọ.
Ajọ eleto idibo ni gbogbo oṣiṣẹ oun ni oun ṣeto adotofo fun nitori iru iṣẹlẹ bayii.
INEC fidi rẹ mulẹ pe awọn ti fi iṣẹlẹ naa awọn agbofinro leti, bẹẹ iwadii si n lọ lori rẹ
Ṣaaju akoko yii, ọga INEC nipinlẹ Benue, Ọmọwe Nentawe Yilwatda jẹri si ikọlu naa to ṣẹlẹ loju ọna ilu Gboko si Makurdi.
APC: Wọn kò fún wa láàyè láti dibo nígbà ti ẹ̀ri wà pe ẹgbẹ́ PDP ń díbo ní àìmọye ìgbà
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Aminu Tambuwal to jawé olúbori ńi ìpínll Sokoto
Ẹgbẹ́ òsèlú APC, ẹka ti ìpínlẹ̀ Sokoto ti fi ààké kọ́ri pe àwọn kò faramọ èsì àtúndi ìbò tó wáye lọjọ Sátide, nibi ti Gomina Aminu Tambuwal, oludije ẹgbẹ òṣèlú PDP ti jáwé olúbori.
Lásikò ti ó ń ba àwọn akọroyin sọ̀rọ̀ ní ìpínlẹ̀ Sokoto, agbẹ́nusọ ẹgbẹ́ APC Bello Danchadi sọ pe, irọ́ ni èsì ìdìbò ti àjọ INEC gbé jade nítori pé ètò náà ni kọ́nu-n-kọ́họ ninu lọ́jọ́ Sátide, tí àwọn si ti ń ke gbajare ki ètò ìdìbò tó pari.
O ni ẹgbẹ́ ti sááju ké si àjọ INEC nígbà ti ẹgbẹ́ òṣèlú PDP ń ṣe èrú ibò lọ́jọ́ sátide.
O fi kun pé, ìyàtọ to wa láàrin èsì ìdìbò ẹni to wọle àtí ẹni to fi ìdi rẹmi kéré gbáà si àwọn to forúkọ silẹ̀ nibi ti àtúndi ìbò ti waye, nítoripe wọn kò fún àwọn ènìyàn míràn láàyè láti dibo nígbà ti ẹ̀ri wà pe àwọn ẹgbẹ́ alátako ń díbo ní àìmọye ìgbà.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Samuel Ortom, ẹgbẹ́ òṣèlú PDP tó jáwe olúbori ní Benue
Bakan náà ní ìpínlẹ̀ Benue, ẹgbẹ́ òṣèlú APC nínú àtẹjade kan to fí síta ní Markudi sàlàye pé, èsì àtúndi ìbò to wáye lọ́jọ́ satide kò ṣe àfihan ìfẹ́ àti ìpinnu ará ìlú.
Atejade ọ̀hun ti Eugene Aliegba tó jẹ akọwe ikọ ìpolngo Jime Ode fọwọ si sàlàyé pé, ilé ẹjọ ni àwọn yóò ti yanju gbogbo ọ̀rọ̀ náà.
Ìjàmbá iná: Sitofu tó gbaná pàdé ike pẹtiró, ni iná bá sọ
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ijamba ina to waye ni agbegbe Mile 12, nijọba ibilẹ Kosọfẹ nipinlẹ Eko, ti sọ eeyan di alainile lori, tawọn eeyan miran si padanu sọọbu ọja wọn.
Isẹlẹ naa to waye lopopona Adebimpe lo sọ ọpọ ile ati ibudo itaja ti wọn fi paanu ati pako kọ di eeru.
Gẹgẹ bi Punch ti wi, obinrin kan ti wọn pe ni iya Dada ni ohun idana sitofu rẹ gbina mọ lọwọ, lo ba sọ si ita, pẹki ni sitoofu naa se alabapade kẹẹgi epo petiroolu ti eeyan kan n gbe kọja lọ, ni ina ba sọ.
Ka to wi, ka to fọ, ọwọja ina ọhun ti tan kaakiri adugbo yii, to si jo ọpọ ile ati sọọbu, ti ina ọhun si jo iya Dada kọja ala, to si wa ni ẹsẹ kan aye, ẹsẹ kan ọrun nile iwosan ijọba to wa ni Gbagada.
Bakan naa ni ẹni to fa kẹẹgi epo pẹtroolu lọwọ fara gbọgbẹ diẹ, ti oun naa si n gba itọju lọwọ nile iwosan.
Nigba ti wọn ka iye ofo to ba wọn, ọkan lara awọn aladugbo naa, Oluwo Alapinni ni awọn eeyan to n ko epo pẹtiroolu pam fun tita lna aitọ lo sokunfa bi ọwọja ina ọhun se di rẹpẹtẹ.
Èré Ọṣun: Àtáója ní wọn kò jí ère Ọṣun, ó sì wà níbi tó wà
"Gbogbo igbinyanju wa lati ẹyin wa lọdọ awọn ọlọpaa lati pinwọ iwa yii lo ja si pabo nitori pe se ni awọn agbofinro maa n kọju sẹgbẹ nigba ti wọn ba ti gba riba lọwọ wọn.
Ina naa ti jo gbogbo ohun ini wa lọ. Gbogbo ohun ta fi gbogbo ọjọ aye wa sisẹ fun, a ko si lee ko ohunkohun jade, bẹẹ ni emi ati awọn ọmọ mi ko nile lori mọ lati sun. Gbogbo awọn eeyan to si dibọn bii ẹni pe wọn n ran wa lọwọ lati ko awọn ẹru wa jade ki ina maa baa jo wọn, ni wọn tun ja wa lole."
Agbẹnusọ fun ileesẹ Ọlọpa nipinlẹ Eko, Arabinrin Bọla Ajao, fidi isẹlẹ naa mulẹ pẹ́lu afikun pe ọpọ ohun to jona ni wn fi awọn ohun eelo ti kii se ọrẹ ina kọ.
Seyi Makinde: Gbogbo iṣẹ́ àgbàṣe tí Ajimọbi ṣe lẹ́yìn ìbò ní màá gbéyẹ̀wò
Oríṣun àwòrán, Engr Seyi Makinde
Gomina tri ilu sẹsẹ dibo yan nipìnlẹ Ọyọ, Onimọ ẹrọ Seyi Makinde ko tii sinmi lori ariwo to n pa pe, gomina to wa nipo lọwọ, Abiọla Ajimọbi mọọmọ fẹ gbọn owo ilu gbẹ ni ki oun to gba ọpa asẹ lọwọ rẹ ni osu karun ọdun yii.
Atẹjade kan ti agbẹnusọ Seyi Makinde, Dọtun Oyelade fisita salaye pe, se ni ijọba Ajimọbi n fi iwanwara gbe awọn isẹ agbase kan jade pẹlu ọkẹ aimọye biliọnu naira, to si mu ifura dani.
Seyi Makinde wa leri leka pe gbogbo isẹ agbase ti Ajimọbi ba gbe jade lẹyin idibo gomina to kja ni oun yoo tu isu de isalẹ ikoko wọn ni kete ti oun ba gba ọpa asẹ tan losu karun ọdun yiii.
Eyi to ya ni lẹnu julọ ni isẹ agbase towo rẹ to biliọnu lọna ọgbọn naira ti Ajimọbi kede rẹ lẹyin ipade igbimọ alasẹ ijọba to waye lọsẹ lọsẹ to kọja, mu ifura dani, paapa nigba to jẹ pe awọn gbese kan wa nilẹ lati 2011 tijọba Ajimọbi ko san.
Èré Ọṣun: Àtáója ní wọn kò jí ère Ọṣun, ó sì wà níbi tó wà
Makinde fikun pe awọn osisẹ ti wọn ni ifẹ ilu lọkan, ti ke gbajare tọ oun wa pe, Ajimọbi ti n dete lati ri daju pe ijọba to n bọ ko ni tete ri ẹsẹ walẹ, nipa gbingbọn owo ilu gbẹ.
Abducted Child: Bàbà Aisha ní iléèwé ló ti ń bọ̀ nígbà tó bọ́ sọ́wọ́ ajínigbé lóṣù Kẹta
Oríṣun àwòrán, @PoliceNG
Ileewe ni Aisha ti n bọ nigba to lugbadi awọn eeyan ibi naa lọjọ Kẹrindinlogun osu Kẹta ọdun yii ni adugbo Ibudu nilu Warri, nipinlẹ Delta.
Ni kete tawọn obi Aisha ri pe o ti di awati, ni baba rẹ fi isẹlẹ naa to ileesẹ ọlọpa leti, tawọn onitọun naa si bẹrẹ isẹ lọgan nibamu pẹlu asẹ ọga agba ọlọpa ni orilẹede yii.
Lasiko iwadi wọn lori isẹlẹ yii ni ọwọ sinkun awọn ọlọpa ba afurasi meji kan, ti wọn si doola ẹmi ọmọdebinrin naa lọwọ wọn.
Awọn afurasi ti wọn lo gbe Aisha ni ẹni ọgbọn ọdun kan, Abdullahi Abubakar ati iya rẹ, Jummai Salihu, tii se ẹni ọdun mejilelọgọta, tawọn mejeeji wa latilu Lafia, nipinlẹ Nasarrawa.
Iroyin naa ni Abdullahi lo ji Aisha naa gbe, to si fi pamọ si ọdọ mama rẹ, nigba to n kesi awọn obi Aisha lati wa san owo idande rẹ.
Abdullahi yii la gbọ pe odu rẹ kii se aimọ fun oloko awọn obi Aisha ati Aisha funra rẹ, nitori pe o sunmọ mọlẹbi naa tipẹtipẹ ni.
Oríṣun àwòrán, @PoliceNG
Asiko to si n se iranwọ lati mu Aisha fo oju titi lasiko ti ọmọdebinrin naa n pada bọ nile iwe ni Abdullahi ji gbe pamọlaimọ si awọn obi ọmọ naa.
Awọn afurasi mejeeji si ti n ka boroboro fun awọn ọlọ[pa nipa ipa ti ikọọkan wọn ko si ijinigbe Aisha., tileesẹ ọlọpa si tun ti n sa ipa rẹ lati ri awọn eeyan miran, ti wọn ka pe o lọwọ ninu isẹlẹ yii, mu.
Èré Ọṣun: Àtáója ní wọn kò jí ère Ọṣun, ó sì wà níbi tó wà
Nigba to n tẹwọ gba ọmọ rẹ, baba Aisha, fo fayọ, to si n dupẹ lọwọ Ọlọrun ati ileesẹ ọlọpa fun isẹ takuntakun ti wọn se lati se awari ọmọ oun nitori oun ti sọ ireti nu lori rẹ tẹlẹ.
Wayi o, ọga agba ọlọpa ti wa kesi awọn obi lati maa mojuto awọn ọmọ wọn bo se yẹ nitori awọn eeyan to sun mọ awọn ọmọde yii, lo maa n pa wọn lara.Ọmọ ọdun marun kan, Aisha Ibrahim, ni ori ti ko yọ lọwọ awọn ajinigbe to gbe pamọ, to si pade alawore ọlọpaa kan, Bukan-Kwatu nilu Lafia nipinlẹ Adamawa, to gba a silẹ.
Ikú Olumegbon: Ọdún mọ́kàndínlọ́gọ́ta ló lò lókè èèpẹ̀, kó tó mí kanlẹ̀
Oríṣun àwòrán, Fatai Olumegbon
O jade laye ni orilẹede Ghana lọjọ kẹrinlelogun oṣu Kẹta lẹni ọdun mọkandinlọgọta.
Ọkan lara awọn afọbajẹ ilu Eko Oloye Fatai Abiodun Olumegbon, ti jade laye.
Olumegbon jẹ́ àgba oyè ni ilu Eko nigba aye rẹ àti ọkan lara awọn afọbajẹ ilu Eko. Bakan naa lo jẹ oloye to n mojuto agbegbe Ajah ati awọn agbegbe miran to sunmọ.
Iroyin fidirẹmulẹ p,e gbajugbaja oloye naa jade laye ni orilẹede Ghana lọjọ aiku, ọjọ Kẹrinlelogun oṣu Kẹta, lẹni ọdun mọkandinlọgọta.
A gbọ pe aisan kan, ti wọn ko darukọ, lo gba ẹmi rẹ.
Oloye Olumẹgbọn, tii se ọkan lara awọn afọbajẹ nilu Eko, nii tun se Fatai Olumegbon olori oye Idejo ni aafin ọba Eko to wa ni Iduganran.
#FreeOurGirls: Àwọn ènìyàn n fi nkan kun àwòrán àarẹ Pierre Nkurunziza
Oríṣun àwòrán, @iburundi
Ọpọlọpọ eniyan lo ti n bu ẹnu ẹtẹ lu aarẹ orilẹede Burundi, Pierre Nkurunziza fun bo ṣe paṣẹ pe ki wọn fi awọn ọmọdebinrin mẹta sẹwọn nitori pe wọn fi nnkan kun aworan rẹ ninu iwe kika wọn.
Awọn eniyan naa to n fi ibinu wọn han pẹlu 'hashtag' #FreeOurGirls, eyi to tumọ si tu awọn ọmọbinrin wa silẹ, ni wọn n fi oriṣiriṣi nkan bi irun'mu, irun obinrin and fila kun awọn aworan rẹ lati ṣatilẹyin fun awọn ọmọbinrin naa.
Ẹsun ti wọn fi kan awọn ọmọ naa gẹgẹ bi ajọ ajafẹtọ ọmọniyan kan, Campaign group Human Rights Watch, ṣe sọ ni pe 'wọn ri olori orilẹede naa fin.'
Awọn ọmọbinrin naa yoo wa l'ẹwọn titi ti ile ẹjọ yoo fi gbọ ẹjọ wọn.
Bakan naa ni ajọ naa sọ pe awọn akẹkọọ meje ni wọn kọkọ fi ofin gbe, ko to o di pe wọn fi awọn mẹẹrin silẹ. Ọmọ ọdun mẹtala kan naa wa lara wọn.
Iroyin sọ pe ọjọ ori awọn ọmọ to wa l'ẹwọn naa ko ti i to ọdun mejidinlogun.
Lọsẹ to kọja ni oludari ajọ HRW ni Central Africa, Lewis Mudge sọ pe ''pẹlu gbogbo iwa ọdaran to n waye ni Burundi, o jẹ ibanujẹ pe awọn awọn ọmọde ni wọ̀n n fi ofin gbe nitori wọn fi nkan kun aworan aarẹ.''
Ẹwọn ọdun maarun ni awọn ọmọbinrin naa yoo fi jura ti ile ẹjọ ba fi le fidi rẹ mulẹ pe wọn jẹbi.
Olùkọ́ aláàánú: Ìda mẹ́jọ sí mẹ́wàá owó oṣù Peter Tabichi, ló ń fún aláìni
Oríṣun àwòrán, Varkey Foundation
Brother Peter Tabichi ni wọn gbe oriyin fun gẹgẹ bii alaanu olukọ
Olukọ sayẹnsi kan ni abule kan ni orilẹede Kenya, ti a gbọ pe o maa n fi gbogbo owo oṣu rẹ tọrẹ fun awọn ọmọ ile iwe to jẹ alaini, ti gba ami ẹyẹ agbaye kan ti wọn fi fun un ni miliọnu kan dọla.
Peter Tabichi, to jẹ ọkan lara awọn ẹgbẹ ijọ aguda ti a mọ si Francisca order, ni o gba ami ẹyẹ naa to jẹ eyi ti wọn gbe kalẹ fun awọn olukọ to gbayi ju ni agbaye.
Ida mẹjọ ninu mẹwaa owo oṣu rẹ ni wọn ni o ya sọtọ lati maa fun awọn ọmọ alaini ni ile iwe Keriko to wa ni abule Pwani ni Nakuru.
Wọn yin Tabichi fun iṣẹ takuntakun rẹ ni ile iwe to wa ni abule kan, ni ibi ti ami ẹyẹ naa ti waye ni Dubai.
Èré Ọṣun: Àtáója ní wọn kò jí ère Ọṣun, ó sì wà níbi tó wà
Olukọ naa to jẹ ẹni ọdun mẹrinlelọgbọn ni wọn ni o n gbe ọrọ sayẹnsi larugẹ. O ṣalaye nibi ayẹyẹ naa wipe, oun fẹ ki awọn ọmọ ilẹ Afirika to jẹ alaini ni anfani lati di eniyan nla ni ibi iṣẹ wọn.
Ọpọlọpọ awọn ọmọ ile iwe rẹ ni a gbọ wipe, o maa n rin irin bii maili mẹrin ki wọn to de ile iwe.
Peter Tabichi ni alaanu to ba ami ẹyẹ
Ìjọba Máli: Ìbọn àti àdá ni wọn fi pa àwọn Fulani náà ni lagbegbe Mopti.
Oríṣun àwòrán, Alamy
Aarẹ orileede Mali Boubacar Keita ti parọ olori awọn oṣiṣẹ ile iṣẹ ologun ati olori awọn ọmọ ileeṣẹ ologun lori ikọlu to mu ẹmi awọn eeyan ẹya Fulani to le ni aadoje lọ.
Igbesẹ yi waye lọjọ kan lẹyin ikọlu to waye lagbegbe Mopti nibi ti awọn ọlọdẹ kan ti yabo abule awọn Fulani.
Ẹwẹ,ijọba ti fofin de awọn ẹgbẹ ọlọdẹ  ti wọn ni wọn wa nidi ikọlu naa to mu ẹmi eeyan aadoje le mẹrin lọ .
Lọganjọ ọjọ abamẹta ni awọn agbebọn doyika abule awọn ẹya Fulani kan, ti wọn ni wọn ni ohun ṣe pẹlu awọn agbesunmọmi jihadi.
Ohun ti awọn ọlọdẹ naa sọ ni pe, ijọba ko daabo bo awọn lọwọ awọn agbesunmọmi jihadi naa.
Ikọlu naa waye nigba ti awọn aṣoju ajọ isọkan agbaye n jiroro lati dẹkun iwa janduku.
Ikọ igbimọ aabo ajọ naa kan ṣe ipade pẹlu olootu ijọba Mali, Soumeylou Boubeye Maiga, lori ọrọ idunkoko mọni lati ọwọ awọn ajijagbara laarin gbungbun Mali.
Èré Ọṣun: Àtáója ní wọn kò jí ère Ọṣun, ó sì wà níbi tó wà
Gẹgẹ bi ohun ti iroyin kan lati ọwọ AFP sọ, ''ibọn ati ada'' ni wọn fi pa awọn eeyan ni Ogossagou lagbegbe Mopti.
Awọn ti ọrọ naa soju wọn sọ fun AFP pe, gbogbo ile to wa ni abule naa ni wọn fẹ jo nina tan.
Olori abule Ouenkoro to sunmọ ibẹ ṣapejuwe iṣẹlẹ naa, gẹgẹ bi ohun to buru pupọ.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Awọn Fulani a ama da ẹranlati abule kan si imiran
Ikọlu laarin awọn ọlọdẹ ẹya Dogon ati awọn Fulani darandaran a ma ṣaba waye lori lilo omi ati ile fun oko dida.
Awọn Dogon fẹsun kan awọn Fulanis  pẹ wọn n padi apo pọ pẹlu awọn alakatakiti Jihadi ti awọn Fulani naa si n sọ pe ile iṣẹ ologun Mali n se iranwọ nnkan ija fun awọn ọlọdẹ Dogon.
Dan Na Ambassagou eleyi to tunmọ si awọn ọlọde to fọkan tan Ọlọrun lorukọ ẹgbẹ ọlọde ti ijọba fofin de gẹgẹbiohun ti ajọ to n ja fun ẹtọ ọmniyan Human Rights Watch  sọ.
Collapsed Building: Ẹ̀mí kankan kò bọ́ nínú ilé míràn tó wó ládugbó Kakawa l'Eko
Iroyin to tẹwa lọwọ sọ pe ijọbati ti wọgile ile naa fun wiwo
Iṣẹlẹ ile wiwo nilu Eko ti wa fẹ di ohun to peleke lẹnu ọjọ mẹta yi pẹlu bi ile miran ṣe tun dawo nisale Eko.
Adugbo Kakawa ni a tun gbọ pe ile miran ti dawo lọjọ Aje.
Gẹgẹ bi iroyin ti o tẹwa lọwọ ti wi, ko si ẹmi kankan to padanu ninu iṣẹlẹ tuntun yi.
Àlàyé rèé lórí ilé kẹ̀ta tó wó l'Eko
Iṣẹlẹ ile wiwo yii ni yoo jẹ ẹlẹkẹtaa ti yoo waye nilu Eko laarin ọsu kan.
Ko ti daju ohun ti o fa iṣẹlẹ ile wiwo tuntun yii ṣugbọn asoju fun Lagos Island nile asofin ipinlẹ Eko, ọgbẹni Sola Giwa,fidi ọrọ naa mulẹ.
Ninu ohun ti o sọ, o ni ko si ẹmi kankan to padanu ninu iṣẹlẹ naa ati wi pe ijọba ti ṣami si ile naa gẹgẹ bi ọkan lara awọn ile ti wọn fẹ wo.
Lọjọ kẹtala Osu yi ni ile alajamẹrin kan dawo ladugbo Ita Faji nibi ti eeyanogun ti padanu ẹmi wọn.
Ẹni to ni ile iwe sare lati doola awọn akẹkọ ni ile wolu
Ko pẹ si igba naa, ni ile miran tun dawo ni adugbo Egerton Square, Oke Arin ni Isale Eko kannna.
Ijọba ipinlẹ Eko lẹyin iṣẹlẹ Ita Faji ti bẹrẹ si ni wo awọn ile ti ko duro daada lati dena ijamba ẹmi ati dukia.
Àwọn aladugbo ibí tí ìjọba Èkó tí n wole sọ èrò ọkàn wọn
Election Tribunal: Ẹ̀rù tó ń ba APC ni wọ́n ṣe kọ̀wé sáwọn ọ̀tẹlẹ̀múyẹ́
Oríṣun àwòrán, @OfficialPDPNig
Ẹgbẹ oselu alatako gboogi nil Naijiria, PDP, ti fesi pada lori bi ẹgbẹ oselu to n sejọba lọwọ, APC se figbe ta, lẹ́yìn tí ẹgbẹ́ PDP jáde láti sọ pé àwọn ní ẹ̀rí tí àwọn gbà láti ojú òpó INEC pé, Atiku Abubakar fi ìbò tó lé ní mílíọ̀nù kan jáwé olúborí.
Akọwe ipolongo fẹgbẹ oselu PDP, Kọla Ọlọgbọndiyan, ninu atẹjade kan to fisita loju opo Twitter ẹgbẹ PDP, lati fesi si gbajare ẹgbẹ APC ni, jinnijinni lo n da bo aarẹ ilẹ wa, Muhammadu Buhari ati ẹgbẹ oselu rẹ, APC, nitori ẹjọ ti awọn Atiku pe lati tako esi ibo to gbe BUhari wọle.
Ọlọgbọndiyan ni ọpọlọ APC ko mọ ọna odo mọ, lo ba da si awuruju, idi si ree to se n kesi awọn ileesẹ ọtẹlẹmuyẹ DSS ati ọlọpa lati fẹhonu han lori abajade awọn nipa oju opo ajọ INEC naa.
PDP wa rọ Buhari ati ẹgbẹ APC lati sinmi irọ pipa, iwa ibanilorukọjẹ ati ipolongo ẹtan, ki wọn si gbaradi lati koju igbẹjọ to wa nilẹ nipa esi ibo aarẹ to kọja.
O ni awọn ẹru aisedeede to pọ babi niwaju igbimọ olugbẹjọ ibo aarẹ, lo wọ APC ati Buhari lọrun, pẹlu ọpọ ẹri to daju pe wọn se eru ibo ni, idi si ree ti wn se n dọgbọn iwa ibanilorukọ jẹ.
Èré Ọṣun: Àtáója ní wọn kò jí ère Ọṣun, ó sì wà níbi tó wà
Pẹlu bi APC ati Buhari ti n se yii, o ti foju han pe wọn ko ni ẹri to daju lati gbe kalẹ niwaju igbimọ olugbẹjọ ibo, lati tako PDP to ni wọn se eru ibo aarẹ ni.
O tiẹ wa yani lẹnu pe Festus Keyamo, tii se agba amofin nilẹ Naijiria, to tun wa lara ikọ agbẹjọro Buhari, yẹ ko nimọ ju bayi lọ, ti ko si yẹ ko maa lọwọ si idi fifi ọwọ bo otitọ loju, eyi to foju han fawọn ọmọ Naijiria pe Atiku Abubakar lo jawe olubori ninu ibo aarẹ to kọja.
Oríṣun àwòrán, @OfficialPDPNig
PDP fikun pe ni bayii tawọn ti ri pe Buhari ati ẹgbẹ APC ko ni awijare kankan ti wọn fẹ sọ nile ẹjọ, awọn n rọ wọn lati yọ awọn ọmọ Naijiria nipa fifi tinutinu gbe ọpa asẹ le Atiku lọwọ, eyi tawọn ọmọ Naijiria gbe fun latipasẹ ibo wọn
Igbimọ ipolongo ibo aarẹ orileede Naijiria Muhammadu Buhari ti kesi ileeṣẹ ọlọpaa ati ile iṣẹ ọtẹlẹmuye,DSS lati ṣe iwadi ẹgbẹ oṣelu PDP lori ẹsun pe wọn fi ọna ẹburu wọ oju opo Inec.
Ninu iwe ẹhonu ti agbẹnusọ igbimọ naa, Festus Keyamo, kọ, wọn ni awọn eeyan kan lati gbPDP fi ọna ojoro wọ oju opo Inec ki wọn ba le gbe esi ibo ayederu wọ ibẹ.
Oríṣun àwòrán, @fkeyamo
Awọn ọdaran kan lati inu ẹgbẹ PDP gbọna ẹburu wọ oju opo INEC
Wọn fi ọrọ yi sita lẹyin ti ẹgbẹ PDP ti saaju fi iwe ehonu tiwọn naa ṣọwọ si igbimọ to n gbẹjọ ẹhonu to niṣẹ pẹlu idibo aarẹ nibi ti wọn ti ni ''awọn ni ẹri tawọn gba lati oju opo Inec to ṣafihan pe Atiku ri ibo 8,356,732 gba lati fẹyin Muhammadu Buhari to ni ibo 16,741,430 janlẹ.''
Gẹgẹ bi ohun ti Keyamo sọ, wi pe awọn ẹgbẹ PDP le ni anfaani lati gba iroyin loju opo Inec ṣafihan pe awọn ọdaran kan lati inu gbẹ naa ni na alumọkọrọyi lati le fọna ẹburu gbe esi ibo wọle.
O sọ ninu iwe ifẹhonu han naa pe igbe ti ẹgbẹ PDP n pa pe ki aarẹ Buhari buwọlu atunto ofin eto idibo eleyi to fi aye kalẹ fun fifi esi ibo ransẹ pẹlu ẹrọ ayarabiaṣa  ko koja wi pe wọn ṣe eru.
Festus keyamo: Ọ̀rọ̀ Obasanjọ sí Buhari ti di ìrégbè
Keyamo ni PDP ti ṣeto esi ibo ti wọn fẹ gbe wọ oju opo Inec amọ isunsiwaju ọjọ ibo lo kawọn lọwọ ko.
"Ẹ gbọdọ kesi gbogbo awn asaaju ẹgbẹ wọn lati le fi ọrọ wawọn lnu wo,wọn gbodo foju ba ile ẹjọ ẹ si gbọdọ ri pe awọn to ba lọwọ ninuiwa yi jẹ iyan wọn niṣu''
Keyamo kasẹ ọrọ rẹ nilẹ pe lootọ ni pe ẹgbv alatako jẹ ohun to da fun ijọba arawa ṣugbọn eleyi ko gbọdo wa jẹ anfaani lati ma fi wu iwa ojoro.
Bauchi Elections: Gómínà Abubakar ti kí Mohammed oludije PDP to jáwé olú borí
Oríṣun àwòrán, Bala Mohammed/facebook
Gomina Mohammed Abubakar ti ki  Sẹnetọ Bala Mohammed to jẹ oludije fun ipo gomina ipinlẹ Bauchi labẹ ẹgbẹ oṣelu PDP lẹyin ti ajọ eleto idibo INEC kede pe sẹnetọ naa gẹgẹ bi ẹni to bori ninu idibo gomina ipinlẹ naa.
Mohammed fi ẹyin gomina to wa ni iṣakoso, to tun jẹ oludije fun ẹgbẹ All Progressives Congress, APC, Gomina Muhammed Abubakar janlẹ.
Abubakar ki oludije naa lori atẹ Twitter rẹ, ti o si rọ ọ pe ki o sọp fun awọn alatilẹyin rẹ ki wọn so ewe agbejẹ mọ ọwọ.
Mohammed ni apapọ ibo to le ni ẹẹdẹgbẹta ẹgbẹrun (515,113) ti Gomina Abubakar si ni apapọ ibo to le ni ẹẹdẹgbẹta ẹẹgbẹrun bakanna (500,625).
Ọjọgbọn Kyari Mohammed to jẹ alamojuto eto idibo naa lo kede ẹni to bori lẹyin ti atundi ibo gomina ọhun waye.
Bala Mohammed to bori ti fi igba kan jẹ Minisita fun olu ilu orilẹede Naijiria, Abuja.
Mutiu Agboke: Ìbanilórúkọjẹ́, ìjínigbé, àti ìdúnkookò mọ́ni la kojú lásìkò ìbò
Oríṣun àwòrán, INEC
Kọmisana fun ajọ INEC nipinlẹ Ọyọ tun kede pe, Ọjọru ni gomina ti wọn dibo yan ati igbakeji rẹ yoo gba iwe mo yege ibo.
Kọmisọnna fun Ajọ eleto idibo INEC ni ipinlẹ Ọyo, Mutiu Agboke ti ni ọpẹlọpẹ isẹ akin ti awọn osisẹ  INEC se, ko ba ma si esi idibo fun eto idibo gomina fun ipinlẹ Ọyọ, nitori ko ba ti lọ ni irọwọrọsẹ.
Agboke lo sọ ọrọ yii lasiko to n gba ami ẹyẹ ‘Akinkanju ninu eto iselu tiwantiwa ti ile isẹ iroyin kan ni ilu Ibadan fun un.
O wi pe ati oun ati awọn osisẹ Ajọ INEC ni ijọba ibilẹ mẹtalelọgbọn to wa ni ipinlẹ naa, lo koju isoro ibanilorukọjẹ, ìjínigbé, àti ìdúnkookò mọ́ni lásìkò ìbò, ti wọn si fẹ rẹ salọ kuro lẹnu idibo naa.
Mutiu Agboke fi kun wi pe, lasiko ti ọrọ naa gbomi mu fun oun, ni oun pe Alaga apapọ fun Ajọ INEC, Ọjọgbọn Mahmood Yakubu wi pe, ki ni ki oun se, ti o si pasẹ fun un lati ka esi idibo naa, ki oun si se oun lori esi naa
Èré Ọṣun: Àtáója ní wọn kò jí ère Ọṣun, ó sì wà níbi tó wà
Kọmisọnna fun Ajọ eleto idibo INEC ni ipinlẹ Ọyọ naa wa fikun wi pe, Ọjọru ni gomina ti wọn dibo yan ati igbakeji rẹ yoo gba iwe mo yege ibo.
Buhari: Iṣẹ́kíṣẹ́ ni awọn akọ́lé ń ṣe pẹ̀lú ilé tó ń dàwó ní Eko lemọ́lemọ́
Aarẹ Muhammadu Buhari ti kilọ wi pe ẹnikẹni to ba ko ile lọna ẹburu yoo foju wina ofin lorilẹede Naijiria.
Aarẹ Buhari se ikilọ yii lasiko ti ẹgbẹ awọn surveyor lorilẹede Naijiria, se abẹwo si ile Aarẹ nilu Abuja.
O ni ariwo ile to n wo ni gbogbo igba, eyi to gbalẹ nipinlẹ Eko ati awọn ilu miran fi han wi pe, isẹkisẹ ni awọn akọle ma n se.
''Ẹmi awọn ọdọ to jẹ ogo orilẹede Naijiria lọla, pẹlu agba ati ọmọde ko gbọdọ sofo mọ nitori awọn akọle ko sisẹ wọn kun oju iwọn.''
Kidnapped Girl: Iyá Ikimot ní lẹ́yìn ọ̀pọ̀ ìdààmú àti owó láti wá ọmọ náà, òun sọ ìrètí nù
Aarẹ orilẹede Naijiria naa wa pa a lasẹ fun awọn ẹgbẹ awọn akọle lati ri daju wi pe, wọn kọ ile lọna igbalode to ba ofin mu, lati mu ibugbooro ba ọrọ aje lorilẹede Naijiria.
Ipaniyan: Ẹ̀wọ̀n gbére ni adájọ́ fún ọkùnrin náà pé ó jí olólùfẹ́ rẹ̀ gbé
Oríṣun àwòrán, Makawai.com
Ilé ẹjọ́ giga kan ni Ipinlẹ Ondo ti da ẹjọ iku fun ọmọkunrin kan, Chukwudi Onweniwe, ti wọn fẹsun kan pe o pa ololufẹ rẹ, Nifemi Adeyeoye.
Ọdun 2017 ni ọwọ ọlọpaa ba Onweniwe lẹyin to pa oloogbe naa, to jẹ ọmọ ile iwe Rufus Giwa Polytechnic to wa ni Owo.
Ilu Ogbese ni wọn ni Onweniwe ti pa ọmọdebinrin naa ni oṣu keji ọdun 2017.
Iroyin fi han wipe, Onweniwe fi tipa gbe Nifẹmi lọ si oko kan ni Ogbese lẹyin ti wọn ni aawọ. Ile ẹjọ ni o fipa ba oloogbe naa lopọ, ko to yin lọrun.
Oṣu karun un ọdun 2017 ni igbẹjọ bẹrẹ lori ọrọ naa ti ile ẹjọ fi ẹsun alabala mẹrin kan ọmọdekunrin naa
Nigba ti ile ẹjọ si ṣe agbeyẹwo gbogbo ẹri, adajọ ni olujẹjọ naa jẹbi mẹta ninu ẹsun mẹrin naa, sugbọn ikọ olupẹjọ ko mu aridaju wa wipe, afẹsunkan naa fipa ba oloogbe naa lo.
Rape: Oluwaseun Osowobi ní Commonwealth fún lámì ẹ̀yẹ ọ̀dọ́ tó pegedé jùlọ ní 2018
Adajọ Samuel Bola sọ wipe, iwadi ti wọn se lara oku oloogbe naa fi han wipe, ọrùn ọmọdebirin naa ti wọ́ ati wipe olujẹjọ naa ti fi nkankan fọ ọ lori.
Adajọ Samuel wa fun Onweniwe ni ẹwọn gbére lóri ẹsun ijinigbe, sugbọn lori ẹsun ipaniyan ati wipe o yin oloogbe naa lọ́rùn, adajọ da olujẹjọ naa lẹjọ iku.
Èré Ọṣun: Àtáója ní wọn kò jí ère Ọṣun, ó sì wà níbi tó wà
Tani olóṣèlú tó ṣewọn ọjọ mẹta torí pé o ní orí ààrẹ dàrú
Oríṣun àwòrán, AFP/GETTY IMAGES
Awọn ọlọpaa ati awọn ẹgbẹ alatako ko ṣeṣẹ maa ba ara wọn wọ iya ija lorileede Zambia
Ọmọ ẹgbẹ alatako kan lorileede Zambia ti  sun orun ọjọ mẹta lagọ ọlọpaa tori pe o ni ori aarẹ orileede,Edgar Lungu, ko pe.
Sean Tembo to n dari ẹgbẹ Patriots for Economic Progress (PEP),fi orisirisi ọrọ sita loju opo ayelujara eleyi to fi tọka si pe ọpọlọ aarẹ ko munadoko.
O sọ pe o ṣeeṣe ki aarun ọpọlọ ma damu aarẹ pẹlu iru awọn igbesẹ to gbe eleyi ti ku diẹ kaa to.O yari lati yi ọrọ rẹ pada toun ti pe ẹgbẹ to wa ni ijọba ni ki o da ọrọ na pada.
Ẹ gbọ ohun to sọ nipa aarẹ''a ko ni igbagbo pe ẹni ti ori rẹ pe yoo fi owo ara ilu ra ọkọ baalu fun ara rẹ lasiko ti ko tilẹ le san owo osu oṣiṣẹ ijọba lẹlẹkaa jẹka ijọba''
Agbẹnusọ ọlọpaa Esther Katongo fidi ọrọ naa mulẹ.
Ko jẹ tuntun mọ pe ijọba n mu awọn olori alatako lorileede Zambia ti awọn eeyan si ti n bẹnu atẹ lu bi ko ti ṣe si igbalaye fun titako ijọba.
Oríṣun àwòrán, AFP/GETTY IMAGES
Olori alatako lorileede Zambia Hakainde Hichilema ki ṣe aimọ fun awọn alaṣẹ nitori bi o ti ṣe n tako ijọba Zambia
Lọdun 2017,awọn ọlọpaa mu gbajugbaja olori alatako kan Hakainde Hichilema lẹyin igba ti wnni o da ọkọ aarẹ lọna.
Lọdun to kọja bakanna awọn ọlọpaa mu Fresher Siwale ti ohun naa jẹ ogunagbongbo alatako fun pe o ni ko daju pe ọmọ Zambia ni aarẹ.
Kano Supplementary Election: Àwọn ẹgbẹ́ òṣèlú 42 tàpá sí èsì ìbò àtúndì Kano
Gómìnà Ganduje ti ẹgbẹ́ APC àti akẹgbẹ́ rẹ̀ láti ẹgbẹ́ PDP
Ẹgbẹ oṣelu mejilelogoji ti tako esi ibo atundi Gomina to waye laipẹ yi nipinlẹ Kano.
Agbarijọpọ awọn ẹgbẹ naa labẹ asia Coalition of United Political Parties (CUPP) ni awọn lodi si esi ibo naa to waye lọjọ kẹtalelogun Osu kẹta.
Alaga ẹgbẹ naa Mohammed Abdullahi Rahi sọ fun awọn akọrọyin ni Kano pe wuruwuru ati iwa janduku lo mu abuku ba eto idibo naa ti ajọ Inec dari.
Gẹgẹ bi ohun to sọ, o ni awọn janduku ri iṣẹ ṣe daada lọjọ naa ti wọn si dun koko mọ awọn oludibo kaakiri awọn agọ idibo.
O ṣalaye pe awọn eeyan pupọ si tun padanu ẹmi wọn ti ibo rira si peleke.
O daju pe iwa janduku to waye lọjọ kẹsan to ṣokunfa atundiu ibo ko to ti ọjọ kẹtalelogun ti ajọ Inec si ṣebi ẹni pe awọn ko ri nnkankan ti wọn si kede esi ibo naa."
"A tako esi ibo to eyi ti wọn ti kede Abdullahi Umar Ganduje gẹgẹ bi ẹni to wole ipo Gomina nitori aisedede to waye saaju, lasiko ati lẹyin  idibo atundi to gbe wọlẹ''
Alaga ẹgbẹ alatako PDP nilu Kano,ọgbẹni Rabiu Bichi sọ fun Inec pe ki wọn wọgile idibo atundi naa nitori iwa janduku ati ailedibo awọn oludibo lọpọ agọ idibo.
Bichi lasiko to n sọrọ pẹlu awọn akọroyin ni ti Inec ko ba wọgile esi ibo naa, awọn yoo gbe ọrọ naa lọ si iwaju ile ẹjọ nitori pe awọn eeyan Kano ti fihan pe PDP lawọn yan laayo.
Adajọ yì ìgbẹ́jọ rẹ̀ padà lóri àtúndi ìbò Adamawa
Gbágbáàgbá ni àwọn òṣìṣẹ́ ètò àábò dúró ní ibi tí wan ti n pín òhun èlò ìdìbà nàá
Ajọ eléto ìdìbò INEC ti pari ètò láti ṣe àtúndi ìbò gómìnà ní ìpínlẹ̀ Adamawa lọ́jọ́bọ ti ṣe ọjọkejidínlógbọn osùn yìí.
Ikéde yìí wáye lónìí ọjọ ìṣẹ́gun lẹ́yìn ti ilé ẹjo pàṣẹ pe àjọ INEC ní àṣẹ lati ṣe àtúndi ibo nibẹ̀.
Rape: Oluwaseun Osowobi ní Commonwealth fún lámì ẹ̀yẹ ọ̀dọ́ tó pegedé jùlọ ní 2018
#EkitiDecides: 'Ìjà ẹgbẹ́ òkùnkùn ló ń ṣẹlẹ̀ kìí ṣe ti òṣèlú'
Alága àjọ náà n;í ìpínlẹ̀ Adamawa, Kassim Gaidam sàlàyé pé àjọ náà ti ṣe gbogbo ètò tó yẹ láti mú èto náà lọ ni ìrọwọrọsẹ̀ lọ́jọ́ méjì si àsìkò yìí.
Ile ẹjọ kan ní ìpínlẹ Yola ní ìpínlẹ̀ Adamawa ti yí ìgbéjọ to ṣ tẹ́lẹ̀ pada pé àjọ elétò ìdìbò kò lẹtọ láti ṣe àtúndi ìbò gómìnà ní ìpínlẹ̀ náà.
Adájọ Abdul'Aziz Waziri tun dájọ pe ilé ẹjọ náà kò le gbọ ẹjọ ti ẹgbẹ́ òṣèlú Movement for the Restoration and Defence of Democracy (MRDD) pè.
World theatre Day: Kosọkọ ní ètò adójútòfò wà fọ́jọ́ alẹ́ àwọn onítíátà
Oríṣun àwòrán, Jide Kosoko
Isẹ tiata abi ere sise kii se isẹ to see fi ọwọ rọ sẹyin ni awujọ wa nitori pataki rẹ.
Yatọ si pe ere tiata maa n dani laraya, o tun maa n kọni lẹkọ, fun ni loye, to si tun n mu ayipada ba awọn iwa ibajẹ lawujọ wa latipasẹ awọn ohun awokọgbọn to wa ninu rẹ.
Bakan naa ni ere tiata maa n se agbelarugẹ asa, ise, ede ati idaabo bo awọn ohun adayeba wa, eyi ti ko fi ni parun, ti yoo si tun maa fi isẹlẹ nipa awọn ohun to ti waye saaju kọ awọn iran ode iwoyi atawọn to n bọ.
Ni bayii ti oni ọjọ Kẹtadinlọgbọn osu Kẹta jẹ ọjọ ti ajọ isọkan agbaye ya sọtọ gẹgẹ bii ayajọ ọjọ tiata lagbaye, eyi lo mu ki BBC Yoruba maa beere pe se awọn osere tiata Yoruba n pọnmi silẹ de oungbẹ bi fun ọjọ alẹ wọn abi asiko ti ilera yoo beere?
Bakan naa la fẹ mọ awọn eto to wa nilẹ ti ẹgbẹ awọn osere tiata n se lati ri daju pe awọn ọmọ ẹgbẹ wọn ko maa laagun, ki wọn to ri itọju lasiko ti ilera wọn ba yinjẹ?
Oríṣun àwòrán, Mr Latin
Nigba to n dahun ibeere yii, agba ọjẹ kan nidi isẹ tiata, to jẹ odu, ti kii se aimọ fun oloko laarin awọn osere tiata, Ọmọọba Jide Kosọkọ ni ẹgbẹ awọn osere ori itage lede Yoruba, taa mọ si TAMPAN, labẹ akoso ọgbẹni Bọlaji Amusan, ti gbogbo eeyan mọ si Mr Latin, ti n se gudugudu meje, ati yaya mẹfa fun eto adojutodo fawọn ọmọ ẹgbẹ naa.
Ẹ gbọ́ Jide Kosọkọ siwaju si:
World theatre Day: Kosọkọ ní ètò adójútòfò wà fọ́jọ́ alẹ́ àwọm onítíátà
Kosọkọ ni amọ irufẹ eto adojutofo yii ko ba ti waye tipẹ fawọn osere tiata Yoruba, bi kii ba se ọpọ wọn to pagi dina eto naa nigba naa, apẹyinda iwa aidaa yii si ni ọpọ wọn to n saisan n jẹ loni yii.
Jide Kosọkọ wa tun rọ awọn ọmọ ẹgbẹ osere tiata lede Yoruba lati maa tọju ara wọn, ki wọn ma si lo gbogbo owo ti wọn n ri lati fi jẹnu tan, amọ ki wọn pọn omi silẹ de oungbẹ fun ọjọ alẹ.
Kidnapped Girl: Iyá Ikimot ní lẹ́yìn ọ̀pọ̀ ìdààmú àti owó láti wá ọmọ náà, òun sọ ìrètí nù
Abiola Ajimobi: Makinde fẹ́ fọwọ́ rọ́ àṣeyọrí ọlọ́dún mẹ́jọ mi sẹ́yìn
Seyi Makinde ti ẹgbẹ́ òsèlú PDP ní àwọn ènìyàn dìbò yàn gẹ́gẹ́ bí gómìnà tuntun ní ìpínlẹ̀ Ọyọ.
Gomina ipinlẹ Ọyọ, Abiola Ajimobi ti parọ̀wa si gomina tuntun ti wọn sẹsẹ yan, Seyi Makinde lati sọra fun ọrọ kubakugbe nipa oun ati isejọba ọdun mẹjọ oun.
Ajimobi ninu atẹjade to fi lede ni gbogbo isẹ Makinde lo n fihan wi pe, o fẹ fi ọwọ rọ gbogbo isẹ ti oun ti se fun ọdun mẹjọ ni ipinlẹ Ọyọ.
Ninu ọrọ rẹ, o ni ẹgbẹ oselu PDP yẹ ki wọn bẹrẹ si ni sọ ohun ti wọn ni fun awọn eniyan, ati lati mọ le akasọ lori awọn ipinlẹ ti oun ti fi silẹ gẹgẹ bi isẹ ti oun ti se.
Kidnapped Girl: Iyá Ikimot ní lẹ́yìn ọ̀pọ̀ ìdààmú àti owó láti wá ọmọ náà, òun sọ ìrètí nù
O ni ohun to buru jai ni lati ma a lo ẹrọ ayelujara lati fi tabuku oun lawujọ.
Gomina ipinlẹ Ọyọ naa wa parọwa fun wọn lati dawo gbogbo ise yii ku, ki ipinlẹ Ọyọ le tẹsiwaju.
Ondo: Ọ̀rẹ́kùnrin Khadijat Olubọyo gba ọjọ́ ikú!
Ọ̀rẹ́kùnrin Khadijat Olubọyo gba ọjọ́ ikú
Ile ẹjọ giga ni ipinlẹ Ondo ti da ẹjọ iku fun Seidu Adeyemi to pa ọmọ igbakeji gomina ipinlẹ Ondo, Khadijat Olubọyọ ní ọdun to kọja.
Seidu Adeyemi to jẹ ọrẹkunrin Khadijat Oluboyo ni wọn fẹsun kan wi pe o pa a, ti o si tun riimọle si inu yara rẹ ni Aratusi, Oke-Aro ni Akure, nipinlẹ Ondo.
Khadijat Oluboyo: Ilé ẹjọ́ sọ ọ̀rẹ́kùnrin rẹ̀ sí gbaga
Khadijat Oluboyo n mura lati jade fasiti ni ile iwe giga fasiti Adekunle Ajasin ni Akungba Akoko ni ipinlẹ Ondo ki o to jade laye
Baba Khadijat Oluboyo jẹ́rìí ọmọ rẹ̀
Àwọn wo ló kó oníkẹ̀ẹ̀kẹ́ 'Napep' wọ ìgboro ìlú Liverpool?
Oríṣun àwòrán, @LoksattaLive
Awọn kẹẹkẹ naa jẹ ọna irinna to yatọ si eleyi to ti wa nilẹ tẹlẹ bi Uber
Bi ẹ ba laanfaani lati lọ si ilu ọba, ẹ ri wi pe ẹ foju sita boya ẹ o ṣe alabapade 'Kẹẹkẹ Napep' iru eleyi ti o n gbe ero lawọn ilu kaakiri Naijiria.
Bẹẹni, 'Kẹkẹ Napep' ti n na igboro ilu Liverpool nilu Ọba.
Ọrọ yi di ootọ pẹlu bi ile iṣe ọlọkọ irina kan ti ṣe ṣe ifilọlẹ ọkọ akero 'Kẹẹkẹ Napep' fun awọn eeyan ilu Liverpool nilẹ Gẹẹsi.
Grandma Maruwa: Ó yẹ kí obìnrin sisẹ́ láì wojú ọkọ kó tó jẹun
Ko si ohun ti awọn kẹẹkẹ wọn yi fi yatọ si eyi ti awọn eeyan ma n wọ ni Naijiria, bi ko ṣe pe awọ ewe ni wọn kun awọn ọkọ naa.
Gẹgẹ bi ohun ti a ri ka, ile isẹ to bẹrẹ eto yi salalye pe awọn gbe awọn kẹẹkẹ naa kalẹ ki awọn ara ilu ba le mọ riri eto irina orisi miran yatọ si eleyi ti wọn n lo tẹlẹ.
Yatọ si orileede Naijiria,pupọ awọn orileede nilẹ Asia bi India,Bangladesh ati Singapore lawọn eeyan ti ma n wọ kẹẹkẹ ẹlẹsẹmẹta yii.
Awọn eeyan orilẹede India ni wọn kọkọ bẹrẹ si ni lo awọn ọkọ to jọ bi 'kẹẹkẹ Napep' fun awọn to n ṣe inaju ati igbafẹ.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ilu London wa lara awọn ilu ti kẹẹkẹ yi ti kọkọ gbalẹ gẹgẹ bi ohun irinna.
Awọn ọkọ yi jẹ ohun irinna pọọkulowo, ṣugbọn ipenija aabo jẹ iṣoro kan ti awọn eeyan maa n koju pẹlu wọn.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Osun Tribunal Judgement: 'Àwa ènìyàn Ọṣun kọ ìdájọ́ tó ní Oyetọla kọ́ ló wọlé sípò gómìnà'
Oríṣun àwòrán, Adejare Taofeek
Kẹtikẹti ni awọn olugbe ipinlẹ Ọṣun tu sita lọjọru lati ṣe iwọde tako idajọ igbimọ to sọ pe Sẹnetọ Ademọla Adeleke ti ẹgbẹ osẹlu Peoples Democratic Party lo jawe olubori ninu idibo sipo gomina ipinlẹ naa to waye lọdun 2018.
Oríṣun àwòrán,  Adejare Taofeek
'Awọn eniyan ipinlẹ Ọṣun kọ idajọ Jankara
Nibi iwọde naa to waye nilu Oṣogbo ni awọn to wọde ti gbe oriṣiriṣi akọle dani lati fi sọ erongba wọn.
Adeleke: Àwọn ará Ẹdẹ bẹ síta pẹ̀lú ìdùnnú lórí ìdájọ́ èsì ìdìbò gómínà Ọṣun
Oríṣun àwòrán, Adejare Taofeek
'Oyetọla ni Ọṣun dibo fun.'
Ọjọ Ẹti, ọjọ kejilelogun oṣu Kẹta 2019 ni meji ninu ọmọ igbimọ to gbọ ẹsun to jẹyọ latara idibo naa dajọ pe oludije PDP lo wọle.
Ṣugbọn, o da bi ẹni pe idajọ naa ko ba awọn kan lara mu ni ipinlẹ Ọṣun.
Oríṣun àwòrán, Adejare Taofeek
'Ọṣun kọ idajọ ti wọn fi owo ra.'
Iwọde naa ti ẹgbẹ Osun Concerned Citizens ṣe agbatẹru rẹ waye ni ilu Oṣogbo.
Oríṣun àwòrán, Adejare Taofeek
BREXIT: Kí ni ohun tó fẹ́ yọ Theresa May nípò olóòtú ìjọba Gẹ̀ẹ́sì ṣáájú àkókò rẹ̀
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Aigbọra ẹni ye lori BREXIT ti n fa ọpọ iwọde ni orilẹede naa.
O ṣeeṣe o ki orilẹede Gẹẹsi o ni olootu ijọba tuntun laipẹ.
Arabinrin Theresa May ni Olootu ijọba ilẹ naa ni lọwọlọwọ yii, saa iṣejọba rẹ ko si tii pari.
Amọṣa, Theresa May ṣeleri pe ni kete ti oun ba ti lee jajabọ lori aba ajọmọ lori adehun ati yẹra ilẹ Gẹẹsi kuro ni awujọ awọn orilẹede Yuroopu, EU, iyẹn BREXIT ti o n lepa rẹ lọwọ, ni onikoyi oun yoo lọ simi ogun.
Igba meji ọtọọtọ ni aba adehun iyapa naa ti ba ijakulẹ pade ni ile aṣofin ilẹ Gẹẹsi.
May yoo tun gbiyanju fun igba kẹta ni ọjọbọ lati tun rọ awọn aṣofin orilẹede naa lati tẹwọ gba aba adehun naa lẹyin to ti jẹ ẹjẹ ati fi ipo silẹ.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Nibi ipade kan pẹlu awọn aṣofin ẹgbẹ oṣelu Conservative party to waye ni May ti ṣalaye pe 'Mo ṣetan lati fi ipo yii silẹ ṣaaju asiko to yẹ lọna ati lee ṣe ohun to ba tọ fun orilẹedee wa.
Ọjọ kọkandinlọgbọn oṣu kẹta ọdun 2019 lo yẹ ki ilẹ Gẹẹsi of fi aaarin awujọ ilẹ Yuroopu, EU silẹ ṣugbọn nitori awọn aigbọraẹniye ti o n waye laaarin awọn adari orilẹede naa lori rẹ,ajọ EU ti fun wọn di ọjọ kejila oṣu kẹrin lati fi tun ile wọn to.
Fashọla: Àwọn ọmọ Nàìjíríà sọ̀rọ̀ lórí ìpèsè iná ọba tí mínísítà Fashọla ní ó ti ń ṣe dédé
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Kii ṣe iroyin mọ pe ina ọba ko ṣe e mu yangan ni orilẹede Naijiria
Ṣe awọn agba bọ, wọn ni ẹyin lohun, bi o ba ti jabọ ko tun ṣee ko mọ.
Lẹyin ti o ti sọrọ lori eto mohunmaworan abẹle kan lorilẹede Naijiria pe ọpọ ipinlẹ lorilẹede Naijiria ni wọn ti n ni ina ọba fun bii wakati mẹrinlelogun bayii lojumọ, ẹnu o si lẹyin minisita fun ipese ina ọba lorilẹ€de Naijiria, Raji Fashọla.
Ọpọ ọmọ Naijiria ni wọn ti n pariwo lori oju opo ayelujara, ero wọn lori ọrọ naa. Ko kere ninu awọn ọmọ orilẹede Naijiria ti o n pariwo pe ọrọ to jinna si otitọ ni minisita Fashọla sọ yii, bẹẹni ko ṣai si awọn miran ti wọn sọ pe o fẹ jọ bẹẹ lootọ.
Orilẹede Naijiria wa lara awọn orilẹede ti ina ọba rẹ ko fẹẹ ṣe dede to lagbaye, eleyi ti o si ti gba ọpọ ọrọ abuku laaarin awọn ọmọ orilẹede Naijiria ati loke okun.
Lara awọn to ti fi ohun silẹ lori rẹ ni Sẹnetọ Shehu Sani. Sẹnetọ Sani ni kii ṣe aye yii ni ipinlẹ kan yoo ti maa lo ina ọba fun wakati mẹrinlelogun.
Sẹnetọ naa to n ṣoju ipinlẹ Kano lọwọ bayii, ṣalaye lori opo twitter rẹ pe awọn ipinlẹ ti o ti lee gbadun ina fun wakati mẹrinlelogun lojumọ ni Uranus, Venus, Mars, Saturn ati Neptune."""
Bakan naa ni awọn ọmọ orilẹede yii miran naa ti n bu ẹnu atẹ lu minisita naa. Bi awọn kan ṣe n pariwo pe 'irọ ni o pa'ati pe 'ko yee pa iru iru irọ bẹẹ' ni awọn miran tilẹ n sọ pe 'ko darukọ awọn ipinlẹ naa to ba daa loju.'
Ni oju opo Facebook BBC News Yoruba, awọn eeyan kan lu minisita naa lọgọ ẹnu, wọn si tun kin ọrọ rẹ lẹyin bẹẹ ni awọn miran tun bu ẹnu atẹ lu rọ yii.
Manchester United: Gunnar Solskjaer di akónimọ̀ọ́gbá tuntun
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Gunnar Solskjaer ti jáwé olúborí ìfẹsẹ́wọnsẹ̀ eré bọ́ọ̀lù márìnlá nínú mọ́kàndínlógún láti ìgbà tí ó ti jẹ́ adelé fún osù mẹ́rin.
Ẹgbẹ agbabọọlu Manchester United ti fi ontẹ lu Ole Gunnar Solskjaer gẹgẹ bi akọnimọọgba tuntun fun ọdun mẹta.
Ole Gunnar Solskjaer ti  ti jawe olubori ifẹsẹwọnsẹ ere bọọlu mẹrinla ninu mọkandinlogun lati igba ti o ti jẹ adele fun osu mẹrin.
Osu Kejila, ọdun to kọja ni ọmọ ọdun mẹrindinlaadọta naa pada wa si Man United lati gba isẹ lọwọ Jose Mourinho  gẹgẹ bi akọnimọọgba.
Manchester United wa ni ipo kẹrin bayii ninu idije Premier League, ti wọn yoo si ma a koju Barcelona ni ifẹsẹwọnsẹ keji to kangun si asekagba idije UEFA Champions League, lẹyin ti wọn fagba han PSG pẹlu ayo meji ni Paris.
Bakan naa ni Ole Gunnar Solskjaer ni atilẹyin awọn agbabọọlu Man United tẹlẹri, ati awọn to wa nibẹ lọwọlọwọ.
Ti a ko ba gbagbe, saa mọkanla ni Ole Gunnar Solskjaer fi jẹ agbabọọlu Manchester United to si jẹ ẹni to gba bọọlu wọnu awọn ni ọdun 1999 ti wọn fi gba ami ẹyẹ Champions League ti ọdun naa.
Ekiti election appeal: Ilé ẹjọ́ kòtẹ́milọ́rùn dá Fayẹmi láàre lórí ẹjọ́ Ẹlẹka
Oríṣun àwòrán, @ekitistategov
Ẹlẹka pe ẹjọ kotẹmilọrun lẹyin to fi idi rẹmi ni ile ẹjọ akọkọ ni oṣu kini ọdun 2019
Ile ẹjọ to n gbọ ẹjọ kotẹmilọrun ti gbe idajọ kalẹ pe Kayọde Fayẹmi gan an ni oludije ti ilu fi ibo yan sipo gomina ni ipinlẹ Ekiti.
Idajọ yii waye lẹyin ti ile ẹjọ to n gbọ awuye abajade esi idibo gomina nipinlẹ Ekiti gbe kalẹ ṣaaju pe Fayẹmi lo wọle gẹgẹ bii gomina nitootọ.
Ile ẹjọ naa ni ẹjọ kotẹmilọrun ti oludije ẹgbẹ oṣelu PDP, Ọjọgbọn Oluṣọla Ẹlẹka gbe wa si iwaju rẹ ko munadoko to.
Ajọ eleto idibo, INEC ti kede Fayẹmi ati ẹgbẹ oṣelu rẹ, APC gẹgẹ bii olubori ibo gomina ipinlẹ Ekiti pẹlu ibo 197, 459 lati bori Ẹlẹka to ṣe ipo keji pẹlu ibo 178,121.
Fayẹmi bori ni ijọba ibilẹ mejila ninu mẹrindinlogun to wa ni ipinlẹ naa.
Kí ni àmì ohùn 'Aguntaṣọọlo'?
INEC ni Fayẹmi bori lawọn ijọba ibilẹ Ilejemeje, Irepodun/Ifelodun, Ido/Osi, Oye, Moba, Ijero, Gbonyin, Ekiti West, Ikole, Ise/Orun, Ekiti East ati Ekiti Southwest.
Eẹẹka si bori ni Ado, Ikere, Emure and Efon.
Bola Tinubu Colloquium: Tinubu kìlọ̀ fún Buhari lórí ohun tó leè ṣàkóbá fún sáà kejì rẹ̀
Oríṣun àwòrán, @batcolloquium
Tinubu ni agbekalẹ iṣejọba ti yoo mu ilu dẹrun fun araalu ni ki Buhari ati igbimọ iṣejọba rẹ o mojuto
Eto ipade apero eyi ti awọn ọrọ ṣe fun agba oṣelu to tun jẹ aṣiwaju ẹgbẹ oṣelu APC lorilẹede Naijiria, Bọla Tinubu waye nilu Abuja, ọpọ lo si ti n sọrọ lori awọn koko ọrọ ti agba oṣelu naa ba ijọba atawọn oloṣelu sọ. Eyi lo mu ki BBC News Yoruba o ṣe akojọpọ awọn koko mẹta ti agba oṣelu naa mẹnu le.
Lori ọrọ owo ori sisan lori ọja, VAT.
Oríṣun àwòrán, Jubril Gawat
Tinubu pe fun Atunto ẹka ipese ina ọba
Laipẹ yii ni iroyin jade pe ijọba apapọ ti n gbero lati fi kun owo ori sisan lori awọn ọja rira ati tita lorilẹede Naijiria. Ọpọ lo n sọ pe inira yoo de ba araalu bi ijọba ba gbe igbesẹ yii lootọ.
Afi bi igba ti Aṣiwaju Tinubu gba ẹnu ọpọ ọmọ orilẹede Naijiria sọrọ lori ọrọ naa. Tinubu rọ ijọba aarẹ Muhammadu Buhari ati igbakeji rẹ, Yẹmi Osinbajọ lati yago ketekete si erongba yoowu to ba nii ṣe pẹlu afikun owo ori ọja, VAT.
Mo fẹ rọ ọjọgbọn Yẹmi Ọṣinbajo ati ikọ rẹ lati da igbesẹ yoowu ti wọn ba n gbe lori afikun owo ori ọja, VAT duro, mo bẹ yin. Bi a ba mu adinku ba agbara awọn mẹkunu lati ra nnkan lọja, eyi yoo ṣe idiwọ fun idagbasoke ọrọ aje. Dipo eyi, jẹ ki a fẹ oju awọn eeyan to n san owo ori. Kii ṣe afikun owo ori ni a nilo bayii.
Oríṣun àwòrán, @MsTyma_
Tinubu ni ki Buhari o ṣọra lori ọrọ owo ori sisan lori ọja, VAT
Bọla Tinubu ni ijọba Buhari gbọdọ mojuto ọrọ ipese ina ọba nitori ko si idagbasoke ti o lee de ba orilẹede Naijiria laisi ipese ina ọba.
Awọn aba ati amọran to mu wa fun ṣiṣe labẹ atunto naa ni:
O ni ijọba Buhari gbọdọ ṣiṣẹ takuntakun lati fẹ iye agbara ina to wa fun elo awọn ọmọ orilẹede Naijiria loju sii pẹlu ida aadọta.
A nilo atunto to pegede ninu ẹka afẹfẹ gaasi lati yee fi wọn ṣofo. A gbọdọ ṣe amulo wọn fun idagbasoke ileeṣẹ lorilẹede Naijiria.
Oríṣun àwòrán, @batcolloquium
Tinubu tun pe fun imugboro ipese ina ọba ni ida aadọta ninu ọgọrun (50%) laaarin ọdun mẹrin si asiko yii
Tinubu ni asiko to fun Buhari lati gbe igbimọ ọlọpọlọ pipe kalẹ fun tita ẹka ipese ina ọba di aladani.
"O ni ""ẹgbẹ oṣelu PDP bẹrẹ igbesẹ tita ẹka to n pese ina ọba ṣugbọn wọọn ba aye ẹka to n pin ina ọba jẹ"""
O ni ẹka yii kii ṣe fun pinpin sapo awọn eeyan kan lorilẹede Naijiria bikoṣe fun idagbasoke gbogbo ilu.
Bakan naa lo niBuhari gbọdọ wa nnkan ṣe si aṣa gbigbe owo ina ti araalu ko lo wa ka wọn mọle fun sisan.
"Opin ni lati de si aṣa gbigbe owo ina ti araalu ko lo wa ka wọn mọle fun sisan. Ohun atẹyinwa leyi yẹ ko jẹ. Ina ti eeyan ba lo lo yẹ ki wọn mu owo rẹ wa fun un ni sisan.
Oríṣun àwòrán, @MBuhari
Ko si ẹni to lee sọ boya ijọba Buhari yoo tẹle awọn amọran ko tii di mimọ fun araalu
Lasiko ipolongo idibo ni ọrọ akọmọna yii jade latọdọ ikọ ipolongo aarẹ Buhari gẹgẹ bii iwe akọsilẹ opo afojusun ijọba Buhari fun saa keji.
Lasiko to n sọsọ, Bọla Tinubu ni ọrọ yii kii kan n ṣe ọrọ ipolongo lasan, bikoṣe ilepa ti ẹgbẹ APC gbọdọ mojuto lati da igba ọtun pada fun awọn eeyan orilẹede Naijiria.
O ni ohun ti o kan bayii ni lati rii pe wọn fi gbogbo awọn koko to wa ninu eto naa si iṣe.
Boya ijọba Buhari yoo tẹle awọn amọran ko tii di mimọ fun araalu.
Court of Appeal: Ilé ẹjọ́ ní òfin kò mọ Omo-Agege, Waive gẹ́gẹ́ bíi olùdíje APC ní ìpínlẹ̀ Delta
Oríṣun àwòrán, @OvieOmoAgege
Wahala ipinya laaarin awọn igun to wa ni ẹgbẹ oṣelu APC ni ipinlẹ Delta lo ṣokunfa ọrọ igbẹjọ ọhun
Ileẹjọ kotẹmilọrun to fikalẹ si ilu Benin ni ipinlẹ Edo ti wọgile ẹjọ kotẹmilọrun kan ti Sẹnetọ Ovie Omo-Agege ati Ẹniọwọ Francis Waive pe niwaju rẹ lati doju idajọ ile ẹjọ giga apapọ ilu Asaba to wọgile ibo rẹ bolẹ.
Ni idajọ ti ile ẹjọ naa gbe kalẹ ni ọjọ ẹti da ipẹjọ awọn mejeeji nu gẹgẹ bii aasa ti ko ni kaun ninu.
Tinubu ki Buhari nílọ̀ lórí àwọn ohun tó leè ṣàkóbá fún sáà kejì rẹ̀
Fintiri fi ìdí gómìnà ìpínlẹ̀ Adamawa janlẹ̀ nínú ìdìbò gómìnà
Oluwakaponeski ní iṣẹ́ ọmọogun ilẹ̀ Amẹ́ríkà ni òun tẹ́lẹ̀ kí òun tó di aláwàdà
Lati igun ẹgbẹ oṣelu APC to faramọWolii Jones Erue ni Omo-Agege ati Waive ti jade lati jawe olubori ninu idibo sile aṣofin apapọ lọdun 2019 lẹyin ti ile ẹjọ giga apapọ ti kọkọ le Wolii Erue gẹgẹ bii alaga ti ofin mọ.
Onidajọ Toyin Adegoke ninu idajọ rẹ lori ẹjọ ti alaga igun miran ninu ẹgbẹ ṣelu APC ni ipinlẹ Delta, Cyril Ogodo pe kede pe irọ nla ni gbogbo igbesẹ ti Jones Erue ba gbe gẹgẹ bii alaga ẹgbẹ oṣelu APC ati pe ko lẹsẹ nlẹ labẹ ofin.
Ile ẹjọ naa ni Ogodo gan an ni alaga ẹgbẹ oṣelu APC  ti ofin mọ ni ipinlẹ Delta.
Amọṣa ni idajọ ti ile ẹjọ kotẹmilọrun gbe kalẹ ni ọjọ ẹti, yatọ si pe ile ẹjọ naa wọgile ẹjọ rẹ, o tun ni ki Sẹnets Omo-Agege ati Waive o san ẹgbẹrun lọna ọọdunrun naira gẹgẹ bii owo gba mabinu.
Adamawa election result: Olùdíje PDP já ipò gómìnà gbà mọ́ gómínà Bindow lọ́wọ́
Oríṣun àwòrán, @AjammaS
INEC kede Ẹgbẹ alatako, APC gẹgẹ bii olubori ibo gomina ipinlẹ Adamawa
Oludije fun ipo gomina ninu ẹgbẹ oṣelu Peoples Democratic Party, Ahmadu Fintiri, ti jawe olubori gẹgẹ bi gomina ipinlẹ Adamawa.
Ajọ eleto idibo INEC, kede ni oru ọjọbọ pe Fintiri lo gbegba oroke , lẹyin atundi ibo to waye ni awọn ijọba ipinlẹ kan nipinlẹ naa.
Fintiri ti fi igba kan jẹ adele gomina ipinlẹ naa nigba kan ri, ni akojọpọ ibo 376,552, lati fi bori gomina ipinlẹ naa lọwọlọwọ, to dije labẹ ẹgbẹ oṣelu All Progressives Congress, Jibrilla Bindow to ni ibo 336, 386.
Atundi ibo naa waye lẹyin ti ile ẹjọ giga kan fagile ofin to n dena ki ajọ eleto idibo ṣe atundi ibo ni awọn ibudo idibo mẹrinlelogoji nipinlẹ naa.
Ẹgbẹ oṣelu Movement Restoration and Defence of Democracy (MRRD) lo pe ẹjọ tako ajọ INEC lati fopin si atundi ibo nipinlẹ Adamawa.
Ninu eto idibo gomina to waye lọjọ kẹsan oṣu Kẹta, oludije ẹgbẹ PDP, Hammadu Fintiri lewaju pẹlu ibo 32,476, lẹyin to ni akojọpọ ibo 367,471. Gomina Jubrilla Bindow si ni ibo 334,995.
Owanbẹ: Gari Ijẹbu, bọ̀ọ̀lì àtàwọn oúnjẹ lágbo ayẹyẹ 'owanbẹ' báyìí
Oríṣun àwòrán, www.eatdrinklagos.com
Ayipada ti de ba inawo ṣiṣe bayii
Ayẹyẹ ṣiṣe nilẹ Yoruba jẹ nkan ti o maa n kun fun oriṣiriṣi ipalẹmọ lati rii pe ọjọ naa dun, o si larinrin.
Ipalẹmọ maa n bẹrẹ lati ori aṣọ wiwọ, gbọngan ayẹyẹ, olorin ti yoo kọrin ati ounjẹ jijẹ fun awọn alejo.
Ẹwa Agọnyin jẹ aayo ounjẹ Badagry
Ọrọ ounjẹ jijẹ kii ṣe ohun afi ọwọ yẹpẹrẹ mu rara, nitorina ni ọpọ to fẹ ṣe ayẹyẹ ṣe maa n wa awọn alase ounjẹ to mọ iṣẹ lati se awọn ounjẹ fun awọn alejo wọn.
Ounjẹ bi irẹsi loriṣiriṣi, amala, iyan, sẹmo, ati awọn ọbẹ loriṣiriṣi lo maa n peju-pesẹ sibi ayẹyẹ nilẹ Yoruba.
Oríṣun àwòrán, www.eatdrinklagos.com
Ayipada ti de ba inawo ṣiṣe bayii
Ṣugbọn ṣaa, iyatọ ti n deba bi awọn alayẹyẹ ṣe n pese awọn ounjẹ kan fun awọn alejo wọn.
Aye ti n kuro ni pe ki a n ro amala lati ile oninawo, nibayii, gbọngan tabi ori papa ti ayẹyẹ naa ti n waye ni wọn ti n ro amala bayii, ti awọn alejo yoo si maa jẹ ni gbigbona fẹli-fẹli pẹlu ọbẹ ti wọn ba fẹ.
Oríṣun àwòrán, www.eatdrinklagos.com
Ayipada ti de ba inawo ṣiṣe bayii
Bakan naa ni aye ti n kuro ni fifi odó ibilẹ gun iyan.
Nibayi, aṣa to n jẹyọ nibi ayẹyẹ ni pe awọn kan maa n gba awọn to ni ẹrọ ti wọn fi n lọ ata lati lọ iṣu iyan. Nibi ti ayẹyẹ ti n waye ni wọn yoo ti se iṣu, ti wọn yoo si fi ẹrọ lọ ọ.
Oríṣun àwòrán, www.eatdrinklagos.com
Ayipada ti de ba inawo ṣiṣe bayii
Wọn yoo si maa bu u fun awọn to ba nifẹ si iyan ni gbigbona.
Lara asa ounjẹ to tun ti n jẹyọ nibi ayẹyẹ bayii ni pe awọn kan ti n fi Gaari Ijẹbu pẹlu omi tutu ati ẹja tabi ẹran adiyẹ dindin ṣe alejo.
Oríṣun àwòrán, www.eatdrinklagos.com
Ayipada ti de ba inawo ṣiṣe bayii
Laipẹ yii ni gbaju-gbaja olorin Fuji, Wasiu Ayinde Marshal fi fidio kan sita loju opo ayelujara Instagram rẹ. Fidio naa safihan Ayinde nibi to ti n mu gari Ijẹbu pẹlu ẹja dindin ati ede nibi ayẹyẹ igbeyawo kan nilu Ijẹbu Ode.
Olorin fuji naa n mu gari naa tidunnu-tidunnu. Koda, o sọ pe nkan iwuri ni ayipada to n deba awọn ounjẹ ti wọn n pin fun alejo nibi ayẹyẹ.
Bọọli ati ẹja tabi ẹran adiyẹ ti wọn yi lata naa ti n peju-pesẹ sibi ayẹyẹ bayii.
Oríṣun àwòrán, boliandgrills
Ayipada ti de ba inawo ṣiṣe bayii
Oriṣiriṣi awuyewuye lo n waye lori iru awọn ounjẹ 'tuntun' yi.  Awọn kan gbagbọ pe ifiyajẹra ẹni ni ki eniyan fi ile rẹ silẹ lọ sibi ayẹyẹ, ki wọn o wa fun ni ounjẹ bi gari ati ẹja dindin.
'Kò sí oúnjẹ Nàìjá tí a ò sè ní Kenya'
Ṣugbọn awọn kan gbagbọ pe awọn ounjẹ pẹẹpẹpẹ naa jẹ ọna lati ṣọ owo na, tabi ṣe nkan to yatọ si ti atijọ.
Niti amala ati iyan gigun nibi ayẹyẹ, awọn kan gbagbọ pe eyi jẹ igbesẹ lati dena bi awọn alejo kan ṣe maa n fi ounjẹ ṣofo.
Ekiti election appeal: Ìpèníjà ráńpẹ́ ni èsì ilé ẹjọ́ kòtẹ́milọ́rùn jẹ́ fún wa -PDP
Oríṣun àwòrán, @solaeleeka
Anfaani ile ẹjọ giga lo ṣẹku fun ọgbẹni Olusola Ẹlẹka lati tako esi ibo Gomina ipinlẹ Ekiti
Ẹgbẹ oṣelu Peoples Democratic Party nipinlẹ Ekiti ti fesi pe ''ipenija ranpẹ'' ni esi ile ẹjọ kotẹmilọrun to fagile ẹjọ ti oludije wọn ninu idibo gomina, Olusola Eleka gbe wa si iwaju rẹ.
Alaga ẹgbẹ naa, Alagba Gboyega Oguntuase lo sọ ọrọ yi ninu ifọrọwanilẹnuwo pẹlu akọroyin ile iṣẹ BBC.
Oguntuase ni ''bi nnkan o ba ku,ki n jinde,Eleka yoo jinde pada bi Lasaru inu Bibeli.''
''Ta lo mọ wi pe PDP le gba Bauchi, ta lo mọ wi pe PDP le gba Benue,ta lomọ wi pe PDP le gba Imo? Agbara Ọlọrun ni yẹn''
O fi kun pe ipenija agbara Ọlọrun ọga ogo ni ohun to n ṣẹlẹ si Ẹlẹka ti yoo si pada bori.
Lọjọbọ ni ile ẹjọ kotẹmilọrun nilu Abuja  fidi idajọ mulẹ pe Kayode Fayẹmi ti ẹgbẹ oṣelu All Progressives Congress lo gbegba oroke ninu idibo gomina ipinlẹ naa.
Idajọ naa  f'ọwọ rọ ẹjọ ti ọgbẹni Olusọla Eleka ti ẹgbẹ PDP gbe wa si iwaju rẹ pe ko fẹsẹ rinlẹ.
Ninu ọrọ tirẹ, oluranlọwọ fun Olusola Ẹlẹka, Ọgbẹni Felix Olusola sọ pe ẹjọ ti wọn da ni ile ẹjọ akọkọ ati ẹkeji ni bakan ninu.
O fesi yi ni idahun si ibeere BBC nipa esi ile ẹjọ kotẹmilọrun ni orukọ ọga rẹ,Olusola Ẹlẹka.
Olusola ni awọn ti pinu lati tẹsiwaju lọ si ile ẹjọ to ga ju ni Naijiria lati ri pe Olusola Eleka gba ẹtọ rẹ pada.
''Awa ni igbagbọ ninu ẹka eto idajọ Naijiria ,awọn kan ṣi wa nibẹ ti wọn jẹ olootọ.Ti a ba de ile ẹjọ giga pẹlu awọn ẹri ti a ni, a o ri ade to daju''
Nipa boya awọn agbẹjọro wọn ti bẹrẹ igbesẹ lati tẹsiwaju lọ si ile ẹjọ giga, o sọ pe''Laipẹ yi ni wọn yoo bẹrẹ igbesẹ wọn''
Code of Conduct Tribunal: Adájọ́ Àgbà Nàíjíríà, Walter Onnoghen ní ẹjọ́ láti rò
Oríṣun àwòrán, Google
Ìjọba àpapọ̀ fi ẹ̀sùn ìwà ìbàjẹ́ àti pípa irọ́ lóri ohun ìnì Walter Onnoghen láti ìgbà tí ó jẹ Adájọ́ Agba lórílẹ̀èdè Naijria.
Ile ẹjọ to n gbẹjọ iwa ibajẹ, ti ni dandan ni Adajọ Agba Naijiria, Walter Onnoghen ni ẹjọ lati ro lori ẹsun irọ pipa ti wọn fi kan an.
Ile ẹjọ CCT onijoko mẹta ti adajọ Danladi Umar se adari fun sọ eyi lẹyin ti Onnoghen pe ẹjọ wi pe  oun o lẹjọ iwa ibajẹ kankan.
Ajọ naa wa pa se pe Onnoghen gbọdọ wa ro ti ẹnu rẹ lori ẹsun irọ pipa  lori ohun ini rẹ.
Ile ẹjo naa wa sun igbẹjọ naa si Ọjọ Aje, ki Onnoghen fi le raye wa wi ti ẹnu rẹ lori ẹsun ti ijọba apapọ fi kan an.
Ethiopian Airlines crash: Awakọ̀ òrúrufú pariwo 'lọ sókè! lo sókè!' kí ó tó já
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Awakọ̀ òrúrufú Ethiopian Airlines pariwo lọ sókè! lo sókè!
Iroyin ti n jade lori bi ọkọ ofurufu Ethiopian Airlines to gbe eniyan mẹtadinlọgọjọ se jabọ to si pa gbogbo eniyan to wa ninu rẹ lọse mẹta sẹyin.
Iwe Iroyin Wall Street Journal gbe jade wi pe ọkan lara awọn awakọ naa pariwo ki awakọ baalu naa lọ soke, ko lọ soke, ki o ma ba a da ẹnu kọlẹ bi ose n se mọ.
Ẹrọ igbalode ti ko ni jẹ ki ọkọ ofurufu o duro lojiji loju ọrun Boeing 737 Max ni awọn oniwadii sọ wi pe o seese ko se okunfa iku awọn to wa ninu ọkọ baalu wọn.
Isẹju mẹfa ti ọkọ naa gbera kuro lati papakọ ofurufu Addis Ababa lọ si Nairobi ni orilẹede Kenya lo ja.
Premier League: Man City ti fàgbà han Fulham pẹ̀lú 2-0
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Man City ti fàgbà han Fulham pẹ̀lú àmì ayò méjì sódo nínú ìlépa rẹ̀ láti gba ife Ẹyẹ Premiership tọdún yìí.
Ẹgbẹ agbabọọlu Manchester City ti wa loke tente idije Premier League lẹyin ti wọn na ẹgbẹ agbabọọlu Fulham pẹlu ami ayo meji sodo.
Ẹlẹẹkẹjọ ni yii ti Fulham yoo ma fidi rẹmi ninu idije Premier League ti saa yii.
Sergio Aguero ati Bernado Silva lo gba bọọlu naa wọnu awọn, to si mu ki Manchester City bori ninu ifẹsẹwọnsẹ naa.
Bakan naa ni Leicester City naa  Huddersfield pẹlu ami ayo meji si ẹyọkan.
Crystal Palace naa gbena woju Bournemouth pelu ami ayo meji si eyokan.
Mother's day: Ka àwọn ìròyìn tí BBC News Yorùbá tí ṣe fún ìdàgbàsókè àwọn obìnrin
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Àyájọ́ àwọn ìyá lórílẹ̀èdè Nàìjíríà ń wáyé lónìí
Ọpọ nnkan ni oju obinrin n ri lawujọ. Ileeṣẹ iroyin BBC News Yoruba ti ṣe ọpọlọpọ iroyin nitori awọn obinrin-imuṣẹ alaa wọn, idagbasoke ati ilepa wọn lawujọ.
Eyi ni diẹ lara awọn iroyin naa ti BBC News Yoruba ti ṣe lati fi gbe awọn obinrin larugẹ ati lati mu ipenija wọn jade wa si ita gbangba.
Neha Sharma: obìnrin tó ń múra bíi ọkùnrin láti leè ṣiṣẹ́ gẹrígẹrí
Rape: Oluwaseun Osowobi ní Commonwealth fún lámì ẹ̀yẹ ọ̀dọ́ tó pegedé jùlọ ní 2018
Oluwaseun Osowobi la laalaa ifipabanilopọ kọja lati di ajafẹtọ awọn ti wọn ti la iru iṣẹlẹ bẹẹ kọja.
Ni orilẹede bii Naijiria nibi ti o jẹ iṣoro fun obinrin lati sọrọ bi wọn ba fi ipa baa lo pọ, Seun ba BBC News Yoruba sọrọ lori ipenija rẹ atawọn obinrin miran lori iwa buruku yii.
Ẹ woo nibi: https://www.bbc.com/yoruba/afrika-47703184
Sẹ́gílọlá: Arúgbó awẹ́lẹ́wà tó ń ṣiṣẹ́ omidan
Sẹgilọla, jẹ iya agba ti ọjọ ori rẹ ti le ni aadọrin. Bi o tilẹ jẹ pe ọjọ ori ti lọ lara iya'ṣugbọn ẹwa iya ko lọ.
Ni asiko ti a n ri ọpọlọpọ awọn arugbo ni igboro ti wọn n ṣagbe, a ri iya ti ọkan lara awọn ọmọ rẹ woo pe ẹwa rẹ ṣi lee ṣe anfani fun awujọ ati iwuri fun ọpọ awọn obinrin lode oni.
Ẹ ka itan arabinrin Abimbọla Ọlayinka, arugbo to n ṣe iṣẹ omidan nibi: https://www.bbc.com/yoruba/afrika-47649104
Ìwà ipá nínú ìdílé máa ń bí ìgè àti àdùbí ni tó lè já sí ikú
Lode oni, ọpọ idile ni iwa ipa ti n ṣẹlẹ. Yatọ si pe ọpọ obinrin ni o n jẹ iya lilu lọwọ ọkọ, iwa ipa ninu idile kọja ki ọkọ o gbe ọwọ soke lu iyawo rẹ. Ara awọn iwa ipa ni ki ọkọ maa foro ẹmi iyawo ni ile, ki ọkọ maa fi orun adidun jẹ iyawo rẹ niya ati bẹẹbẹẹ lọ.
Gbogbo eyi naa ni BBC News Yoruba gbe yẹwo ninu iroyin ijiroro itagbangba yii to pe akori rẹ ni 'Ìwà ipá nínú ìdílé máa ń bí ìgè àti àdùbí ni tó lè já sí ikú'
Ẹ wo ẹkunrẹrẹ rẹ nibi: https://www.bbc.com/yoruba/46733903
Mọrèmi: Ọọ̀ni ní láìsi Mọrèmi, kò leè sí ilẹ̀ Yorùbá
Iroyin yii da le ipa ti obinrin ko ninu ominira ati idagbasoke ọpọ awujọ lagbaye. BBC News Yoruba lo Moremi gẹgẹ bii apẹrẹ.
Ẹ lọ kaa nibi: https://www.bbc.com/yoruba/afrika-46744382
Kádàrá ní ọ̀rọ̀ ẹ̀dá láyé, Mo gbà pé Ọlọrun ló kọ ikú ọkọ mi ni Saudi
Yetunde Raji jẹ obinrin ti igbe aye rẹ yi pada si bi ko ṣe lero lẹyin ti oun ati ọkọ rẹ wa ninu ijamba ọkọ to waye ni orilẹede Saudi Arabia.
Omije n bọ loju arabinrin Yetunde Morẹnikeji Raji ṣugbọn o ni omije ayọ ni.
Ẹ lọ ka itan yii ni: https://www.bbc.com/yoruba/45319192
Omi titun ti rú nínú oríṣii ètò ìgbéyàwó Yorùbá lásìkò yí
Ṣe wọn ni ibi gbogbo ni ifẹ wa bi a ba lee farabalẹ waa. Eyi ni iroyin itan ọmọ orilẹede Naijiria kan to ri ifẹ ni orilẹede Kẹnya. BBC News Yoruba kuku tẹlee debẹ lati mọ ohun gan to ri lọbẹ to fi wa ro ọwọ.
Ẹ ka nipa oun pẹlu nibi: https://www.bbc.com/yoruba/afrika-46577202
#67yearoldmother: Mo kojú ọ̀pọ̀lọpọ̀ àìsàn fún ọdún 35 lẹ̀yín ìgbéyàwò
Iyi ati idunnu nla ni o maa n jẹ fun obinrin lati ṣe igbeyawo ki o si lọmọ. Fun Dokita Ogunfunmilayọ, ayọ yii pẹ pupọ fun un nitori o pe ọmọ ọdun mẹtadinlaadọrin, 67 ki o to rọmọ bi.
Ki ẹ to ṣe haa, ẹ lọ ka ọpọ iyanu miran ti o wa ninu ọrs iyaafin ogunfunmilayọ ninu iroyin BBC News Yoruba yii: https://www.bbc.com/yoruba/46008107
Ìlú Igbo-Ọra: Ijọba ipinlẹ Ọyọ ṣe ayẹyẹ ọdun ibeji fún ìgbà àkọ́kọ́
Ilu igboọra jẹ ilu kan lagbaaye to gbajugbaja fun ọwọja ibi ibeji nibẹ. Ọdọọdun si ni wọn maa n ṣe ajọyọ fawọn ibeji nibẹ.
Ṣe ko kuku si obinrin ti yoo gbọ ọrọ ọmọ ti ko ni ta kiji, eyi lo si gbe BBC News Yoruba de Igboọra lati mọ aṣiri ibi ibeji nibẹ.
Ẹ kaa nibi: https://www.bbc.com/yoruba/afrika-45851939
Ogundiya: Àṣìṣe Dókítà ló sọ mi di aláàbọ̀ ara lórí kẹ̀kẹ́
Ọtọ ni aisan ti omidan Ṣeun Ogundiya ba lọ si ileewosan, ọtọ ni oogun ti wọn fun, aile gbe ẹsẹ lo ba kuro ni ileewosan.
Ki wa ni ipenija rẹ. Ẹ lọ woo nibi: https://www.bbc.com/yoruba/afrika-45109762
Ìyá ìbarùn-ún: Mo rò pé 'scan' ń pa irọ́ niní oyún pé márùn-ún ni màá bí
Pẹlu bi nnkan ṣe ri ni ilu bayii, ọpọ ni ko fẹ bimọ mọ. Eyi lo mu ki itan tọkọtaya Imudia paapaajulọ arabinrin Oluwakẹmi Uduehi to bi ọmọ marun lẹẹkan ṣoṣo.
BBC News Yoruba kuku waa lọ lati gboṣuba fun awọn iya lori ipenija itọju ọmọ.
Ohun ti a ba bọ nigba naa niyi: https://www.bbc.com/yoruba/afrika-45028252
https://www.bbc.com/yoruba/46285924
https://www.bbc.com/yoruba/46176740
Àwọn wo ni gómìnà mẹ́rin tí yóò kojú àjọ EFCC lẹ́yìn tí wọ́n bá kúrò nípò?
Oríṣun àwòrán, EFCCofficial
Ajọ EFCC nmi to awon yoo se iwadii finifini
Kẹ̀rẹ̀ kẹ̀rẹ̀ bi àwọn aláṣẹ ijọba tuntun ti wọn dibò yàn yoo ṣe fẹ gba ijọba, àjọ to ri sí ìwà jẹudujẹra (EFCC) ti pari ètò láti bẹ̀rl ìwádìí àwọn gomínà ti wọn fẹsun kan pe wọn ṣe owo ilú maku-maku.
O kéré tán ìpínlẹ̀ méjìlá ni yóò gba gómina túntún ní ọjọ kọkandinlọgbọ̀n oṣù karun ti sáà tó n bẹ lóde yìí ba wá sópin.
Awọn ìpínlẹ̀ náà ní Lagos, Ogun, Oyo, Imo, Kwara, Nasarawa, Yobe, Borno, Adamawa, Bauchi, Gombe àti Zamfara, ẹ̀wẹ̀ nínú àwọn ìpínlẹ̀ méjìlá yìí mẹ́rin nínú àwọn gómìnà náà ni wọn ti na ìka àlébù si pé wọn ṣe ol'w ìlú mọ́ku-mọ̀ku,
Àwọn gómìnà ọ̀hún ni Rochas Okorocah ti ipínlẹ̀ Imo, Abdulfatah Ahmed ti ìpínlẹ̀ Kwara, alága àwọn ẹgbẹ́ gómìnà tó tún jẹ gómìnà ìpínlẹ̀ Zamfara Abdulaziz Yari àti gómìnà ìpínlẹ̀ Ogun Ibikunle Amosun.
Àjọ EFCC ní sáájú òhún ti mú onisiro owo ìpínlẹ̀ Imo Uzoho Casmir fún ríràn Okorocha lọ́wa láti jí owó tó to bílíọnù kan Naira kó lásiko ìdìbò gómìnà àti ilé ìgbìmọ asofin.
Ní Zamfara àjọ EFCC ń sewadìí Yari fún dídari owo to tó biliọnu naira, Saááju ni ile ẹjọ kan l'Abuja ti gbésẹ̀ lé ẹ̀ẹ̀dẹ́gbẹ̀ta mílíọnù naira lọdun 2017, owo ti wọn ji ko ninu owo paris club ti ijọba apapọ fún àwọn ìpínlẹ̀ mẹ́rìndinlógóji Nàìjíríà.
Owó ọ̀hún ní wọn ni wọn ri ni àwọn ile iṣẹ́ méji kan tó wọn si tọpasẹ̀ rẹ̀ dé ọ̀dọ gómìnà Yari.
Gónìmà Abdulfatah náà yóò káwọ pọ̀nyin rojọ́ lọ́dọ̀ àjọ EFCC lẹ́yìn to ba pari sáà rẹ̀, Abdulrahaman Abdulrazak ti wọn ṣẹ̀ṣẹ̀ dìbò yàn náà ti ni gbogbo kúlẹ̀ kúlẹ̀ gómìnà ni òhun yóò tú wo ní kete to ba ti kúro lóri oyè.
Sááju nínú osù yìí àjọ EFCC ti mú àwọn kọmisọnà mẹ́fà àti àti àwọn aláṣẹ ijọba ní ìpínlẹ̀ Kwara nítori wọn dari owo to to bílíọ̀nu kan náírà sí ọ̀nà ìbòmiran ńgbà ti ók u ọsẹ̀ kan ti ìdìbò ààrẹ àti ti ilé ìgbìmsọ̀ asofin àgbà yóò wáye
Ní ti Amosun, ìwádìí tirl kò ṣẹ̀yìn ìwé ẹsun ti àwọn ẹgbẹ́ kan ti a mọ si Committee for the protection of Peopl's Mandate kọ ránṣẹ́ lóri bi Amosun ṣe ṣe bílíọ̀nu mẹ́rìn naira owo àwọn àgbe ní ìpínlẹ̀ Ogun mọ́ku-mọ̀ku
#EndSARS: Ìbọn ba Kolade Johnson níbi tó tí ń wo bọ́ọ̀lù
Oríṣun àwòrán, PoliceEN_PCRRU/Twitter
Ariwo ẹ fopin si ọlọpaa SARS lo gba oju ayelujara kan lori ẹsun ti wọn fi awọn ọlọpaa ọhun pe wọn yinbọn pa ọmọkunrin kan ti orukọ rẹ jẹ Kolade Johnson lagbegbe Onipẹtẹsi niluu Eko lọjọ Aiku.
Iroyin to tẹ wa lọwọ sọ pe ọmọkunrin yii n wo ifẹsẹwọnsẹ laarin Liverpool ati Tottenham lori ẹrọ amohunmaworan lọwọ nile ounjẹ igbalode kan nigba ti awọn ọlọpaa SARS ya bo ibẹ ti wọn si dabọn bo lẹ.
Iroyin ni nibi ti wọn ti n yinbọn lai nidi kan pato ni ọta ibọn ba Kolade lori ijoko rẹ.
Colorado ni Amẹrika àti odò Awaye ní Naijiria nikeji àdágún órí àpáta ní gbogbo àgbáyé!
Ẹni ti ọrọ naa ṣoju rẹ ṣalaye pe awọn ọlọpaa SARS mu ọrẹ Kolade to di oloogbe ni Kolade ba beere lọwọ wọn wi pe ki lo de ti wọn fi mu ọrẹ.
Lẹyin naa ni ọkan lara awọn ọlọpaa naa ba yinbọn fun un, wọn gbe Kolade digbadigba lọ sile iwosan ṣugbọn ẹpa ko boro mọ.
Agbẹnusọ fun ile iṣẹ ọlọpaa nipinlẹ Eko Bala Elkana sọ pe awọn yoo iwadii lori iṣẹlẹ ọhun.
Ọpọ lo bu ẹnu ẹtẹ lu iṣẹlẹ naa loju opo Twitter ti gbogbo wọn si fohun sọkan pe ki wọn ọlọpaa SARS nilẹ lo dara.
AAUA; Ọ̀pọ̀ ìgbà ni SARS ma ń lu àwọn akẹ́kọ̀ọ́ fásitì wa
Iṣẹlẹ naa lo mu awọn ọdọ kan binu di oju ọna marosẹ Eko si Abeokuta ti eleyi si fa sunkẹrẹ fakẹrẹ loju popo lọjọ Aiku.
SARS ti bẹ̀rẹ̀ ìgbésẹ̀ láti yọ àwọn ọ̀bàyéjẹ́ kúro
Nnamdi Kanu: Mo lè dá wàhálà sílẹ̀ ní Nàíjíríà, tí ìjọba bá bími nínú
Oríṣun àwòrán, Elliot Ugochukwu-Ukoh
Opo igba ni Kanu ti ṣeleri pé oun to dari Biafra ti iran Igbo ba ya kuro lara Naijiria
Awọn ọmọ Naijiria ti fesi si ọrọ ti adari awọn to n ja fun idasilẹ orilẹ-ede Biafra, Nnamdi Kanu sọ.
Kanu sọ ọrọ yii lati kilọ fun ijọba apapọ lati ma ṣe ohunkohun ti yoo mu inu bi oun nitori oun le jẹ ki orilẹ-ede Naijiria gbona.
Bi awọn miran ṣe n gboriyin fun ọrọ ti Kanu Nnamdi sọ yii, ni awọn miran n bu ẹnu ẹ̀tẹ́ lu ọrọ to fi lede lasiko to n ba awọn ọmọ ilẹ Biafra sọrọ lati ilu London, ni Ile Gẹẹsi.
Kanu ni ijọba apapọ nigba tó n lo ile ẹjọ giga to wa ni Abuja lati gbẹṣẹ le aṣẹ ti o fun oun ni beeli tẹlẹ, ṣugbọn ti wọn ti yii pada ba yii lati fi panpẹ ọba mu oun, nipa lilo awọn ọlọpaa agbaye, eyi to jasi pabo.
Adari awọn to n ja fun idasilẹ orilẹ-ede Biafra naa fikun wi pe, ki ijọba apapọ ko ṣe ifẹ inu wọn o, ati wi pe ọmọbibi Ilẹ Gẹẹsi ni oun, ti ko si ẹ ni to le ṣe oun basubasu.
Lara awọn ọmọ Naijiria to jẹ alatilẹyin fun Nnamdi Kanu fesi si ọrọ naa lọri oju opo ikansiraẹni Twitter, ti wọn si gboriyin fun ipa ti Nnamdi Kanu nko lati mu iyipada ba aye awọn alatilẹyin rẹ.
Nigba ti awọn miran sọ wi pe ariwo lasan ni Kanu n pa, ati wi pe ọrọ rẹ kii se oun ti awọn ọmọ Naijiria ye ki wọn fesi si.
Colorado ni Amẹrika àti odò Awaye ní Naijiria nikeji àdágún órí àpáta ní gbogbo àgbáyé!
Wo ohun tó ṣẹlẹ̀ nilẹ̀ Adulawọ lọṣẹ tó lọ
A ni ki a fi eleyi ṣe moriwu fun yin nibẹrẹ oṣu tuntun ki a si ma gbagbe awọn ohun to ṣẹlẹ lọsẹ to pari oṣu ti a lo tan.
Diẹ ree ninu akojọpọ awọn awọran manigbagbe lati ilẹ Áfríkà lose to kọja fun igbadun yin.
Oríṣun àwòrán, AFP
Awọn eeyan ti iji Cyclone Idai ṣe akoba fun ko tii bọ lẹyin iṣẹlẹ ọhun. Awọn obinrin wọnyi ni Mozambique n to lati gba nnkan eelo lọjọ Iṣẹgun to kọja.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Iya n ronu; ọmọ n roka lo ri ni Mozambique. Bi awọn iya ti ṣe n to lawọn ọmọdebinrin wọnyi n ṣa ododo nibi awọn ile ti o wo ni ilu Beira lọjọ Aiku.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Jangilofa epo mọtọ! Nilu ti iji ti sọṣẹ niṣe ni awọn ọmọkunrin wọn yi n ṣere lori igi agbọn ti iji wo lọjọru
Oríṣun àwòrán, AFP
Lorile-ede Kenya, awọn akẹkọọ da muso fun olukọ wọn ni papakọ ofurufu Kenya nigba to dari lati ibi ti o ti gba ẹbun $1m (miliọnu dọla kan) gẹgẹ bi olukọ to pegede julọ lagbaye
Oríṣun àwòrán, @ProfOsinbajo
Igbakeji aarẹ Naijiria ati iyawo rẹ, Dolapo Osinbajo nibi ayẹyẹ isin idupe lẹyin ti wọn wọle gẹgẹ bi igbakeji aarẹ nidibo Naijiria tó kója nilu Ikenne, ipinlẹ Ogun
Oríṣun àwòrán, AFP
Lọjọ Aiku, alatilẹyin ẹgbẹ agbabọọlu Zimbabwe yi n dawọ idunnu bi ikọ rẹ ti ṣe fi ami ayo 2-0 sagba Congo-Brazzaville ninu ifẹsẹwọnsẹ lati kopa ninu idije Africa Cup of Nations
Oríṣun àwòrán, Reuters
Lọjọ Abamẹta, ajagunfẹyinti orile-ede Ethiopia yi n fẹsẹ rajo nibi ayẹyẹ kan ti wọn ṣe lati fi gba alejo irun ori Emperor Tewodros II ti ile iṣẹmbaye ilẹ Gẹẹsi, National Army Museum da pada si Ethiopia
Oríṣun àwòrán, AFP
Lọjọ keji, oludibo yi n yẹ orukọ rẹ wo loju patako lati le kopa ninu idibo aarẹ Comoros Islands
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Fọfọ ni igboro Algiers kun nibi iwọde to waye lọjọ Eti. Awọn eetan orile-ede naa fẹ ki aarẹ Abdelaziz Bouteflika kọwe fipo silẹ
Oríṣun àwòrán, EPA
Titi di ọjọ Ajẹ awọn eeyan Algeria ko dawọ iwọde naa duro
Fiditi: Àwọn olùgbé rawọ ẹbẹ sí ìjoba lẹ́yìn tí ìjì ṣí òrùlé mọ́ wọn lórí
Awọn olugbe ilu Fiditi nipinlẹ Ọyọ ti rawọ ẹbẹ si ijọba lori akoba ti atẹgun ojo ṣe fun ọpọlọpọ ile ninu ilu naa lọjọ Abamẹta.
Lasiko ti ikọ iroyin BBC Yoruba ṣe abẹwo si ilu naa, pupọ ninu awọn olugbe ilu naa ni wọn ti di asunta nitori airi'le gbe.
Ọ̀nà ọ̀fun lọ̀nà ọ̀run - omi ò jẹ́ ká ta ọjà
Botilẹ jẹ wi pe ẹmi ẹnikẹni ko ba iṣẹlẹ naa lọ, ọpọlọpọ dukia lo ṣofo, bẹẹ sini awọn ibusun ati aga ijoko di sisa sinu oorun.Lara awọn olugbe ilu naa ti o ba ikọ BBC Yoruba sọrọ ṣe alaye wi pe ṣa dede ni atẹgun ojo ka ile mọ awọn lori lọjọ Abamẹta, ti ọrọ naa si di boolọ-o-yago fun mi.Wọn ke si ijọba ipinlẹ Ọyọ lati daṣọ ro wọn lori awọn orule ti atẹgun ojo ṣi lọ.Botile jẹ wi pe awọn olugbe kan ti n ṣe atunṣe orule wọn, awọn kan ṣi wa ni gbayawu.
Lagos Beach: Àwòrán tó làmììlaaka nípa àwọn òsìsẹ́ ẹ̀ṣọ́ etí òkún
Ile igbafẹ eti okun sẹsẹ bere isẹ ni ilu Eko ni. Amọ oun to dun mọ ni ninu ni wi pe ile igbafẹ yii ni awọn asọle ti yoo ma sọ awọn eniyan to n wẹ ni eti odo.
Ọkan lara awọn osisẹ ibi igbafẹ yii, Stephen Boboly ni oun ti gba ẹmi ọpọ eniyan la ninu okun lati bii ọsẹ mẹta bayii.
Idunnu mi ni wi pe a n gba awọn eniyan la, ki wọn ma ba a ku sinu omi. inu mi dun nitori pe wọn ma n padawa lati wa dupe."" O sọfun BBC bẹẹ."
Arakunrin ẹni ọdun aadọta naa wa lati idile awọn apẹẹja,nitori naa ni awọn eniyan se bọwọ fun gẹgẹ bi omuwẹ ni ipinlẹ Eko.
Ọpọlọpọ odo igbafẹ lo pọ ni Eko, amọ eleyii to wa ni agbẹẹgbẹ Victoria Island yii ma n gba ẹgbẹwa Naira, 2,000 Naira ($5.50; £4) .
Ọkan lara awọn ẹsọ eti okun yii ma n wa ni ibi isẹ laarin ọsẹ, nigbati mẹta si n sisẹ ni opin ọsẹ ti awọn eniyan ma n pọ ni eti okun.
Lẹyin ọsẹ mẹta ti arakunrin Boboly gba isẹ, a ma a lo pa ẹja laarin aago kan si aago mẹta ki o le ri owo fi ransẹ si ile.
Akẹẹgbẹ rẹ Nicholas Paul naa kọkọ bẹrẹ gẹgẹ bi apẹẹja, ko to di wi pe o beere isẹ ẹso eti okun lati bi ọdun meje sẹyin.
Ohun ti o mu ẹni ọgọta ọdun naa di ẹsọ ẹti okun ni wi pe, ti o ba lọ pa ẹja lodo, wọn ma n ri oku awọn eniyan ti yoo wa si eti okun. Eleyii lo mu ki oun fi ara rẹ jin fun isẹ sisọ ẹti okun.
Gẹgẹ bi ọpọlọpọ awọn ẹsọ ẹti ọkun, ibi ti wọn ti ma n ri owo ni awọn ti wọn ma n fun wọn lọwọ lẹyin ti wọn ba gba wọn la lọwọ iku.
Awọn ọmọ Naijiria ko mo o wẹ, amọ ti o ba sọ fun wọn, wọn ko ni gbo, won a ma a ba ẹ jiyan  O salaye.
Apẹẹja tẹlẹri yii ni o ri isẹ lẹyin to o gba awọn oluwẹ mẹta lati ilẹ Indian la. O ni ohun to dara ni ti awọn omuwẹ ba ni awọn ohun igbalode to dara.
Samuel Omohon to jẹ omuwẹ naa kọ lati maa wẹ ni sapẹlẹ ninu omi nla Niger Delta nigba to n dagba.
Ọgbẹni Omohon ni aworan gbogbo awọn to ti gbala lati ọdun bọdun ati igba ti o lugbadi omi gbigbona, nigba ti epo gbigbona jọ ọwọ rẹ, amọ ti ko si di i lọwọ isẹ.
BBC's Grace Ekpu lo ya awọn aworan yii
Ààrẹ orílẹ̀-èdè Algeria Abdulaziz Bouteflika ti kọ̀wé fipo silẹ̀
Aàrẹ orill-èdè Algeria to tin wa lori oye lati ọdun 1999
Ààrẹ orilẹ̀-èdè Algeria Abdulaziz Bouteflika ti kowe fipo silẹ lẹ́yin ifẹhonu han ọlọjọ gbọ́ọ́rọ
Bouteflika tó ti wa lori ipo gẹ́gẹ́ bii ààrẹ láti ogun ọdun sẹyin ti fi èrongba ati di ààrẹ niẹ̀ẹ̀kaarun kálẹ si ẹgbẹ́ kan lẹ́yin ti àwọn ọdọ orilẹ̀-èdè Algeria dide lódi si ìpinu rẹ.
Ikọ ọmọ oogun Algeria ti pé ààrẹ ẹni ọmọ ọdun mẹ́jilélọgọrin ọ̀hun láti kédé pe òun okóju osùwọn láti ṣe ìjọba mọ
Láti ọdun mẹ́fa sẹ́yìn ni à[rẹ ti wa lóri akete àìsàn rapárọsẹ̀ ti ko si foju han si gbangba mọ.
Ààrẹ Bouteflika Algeria yoo kọ̀wẹ́ fipò sílẹ̀ ni 28 April
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Lati ọdun 1999 ni Aarẹ Bouteflika ti wa lori oye nilẹ Algeria
Ile iṣẹ iroyin orile-ede  Algeria sọ pe aarẹ Abdelaziz Bouteflika yoo kọwe fipo silẹ ki saa rẹ to pari ni ọjọ kejidinlọgbọn, Oṣu kẹrin ọdun.
Atẹjade kan lati ileeṣẹ aarẹ ni ọmọ ọdun méjílélọ́gọ́rin naa to ti wa lori oye fun ogun ọdun yoo ri wi pe itẹsiwaju ba eto ijọba ki o to fiṣẹ silẹ.
Iroyin yi wa lẹyin ti iwọde leralera waye eleyi ti awọn eeyan ilẹ naa fi n kesi i wi pe 'o to gẹ' , ki o kọwe fiṣẹlẹ.
Ohun ti iroyin yi tumọ si ni pe o ti jawọ ninu erongba rẹ lati du ipo fun saa karun un.
Ẹwẹ, wọn ti sun ọjọ idibo siwaju ti ijọba si ti ṣadehun pe oun yoo ṣeto apero apapọ nibi ti awọn yoo ti jiroro lori awọn atunto ti yoo mu itẹsiwaju ba ilẹ naa.
Saaju asiko yi, ko si ẹni to le sọ pato boya yoo kowe fiṣẹ silẹ tabi yoo yi wa lori oye.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ogunlọgọ awọn ọmọ orile-ede Algeria lo kopa ninu iwọde lati jẹ ki aarẹ Bouteflika fipo silẹ
Akọroyin BBC Ahmed Rouba jabọ pe ọpọ ọmọ orile-ede Algeria lo gbagbọ pe alaafia aarẹ naa ti dẹnu kodo debi pe awọn kan lo n loo lati ṣe ijọba ti awọn wọnyi ko si fẹ fi ijọba kalẹ.
Awọn wọnyi lo ni wọn pọ ninu ẹgbẹ National Liberation Front eyi ti o ti n ṣakoso Algeria bọ lati ọdun 1962 ti Algeria ti gba ominira lọwọ ilẹ Faranse.
Ọjọ kẹsan an, oṣu kẹfa ọdun 2019 lo yẹ ki saa wọ́n wà sópin
Oríṣun àwòrán, @NGRSENATE
Yoruba bọ, wọn ni ibẹrẹ kii ṣe oniṣẹ, ọpọ ọmọ Naijiria ló n woye ibi ti awọn ọmọ ile igbimọ aṣofin kẹjọ yii ba iṣẹ ilu de.
Bẹẹ, Ka pilẹ nnkan ko si tumọ si pe ẹni naa ni yoo pari rẹ.
Ọrọ yi ṣe bi ẹni ba ẹka aṣofin orile-ede Naijiria mu pẹlu awọn nnkan ti wọn dawọlẹ ti o jọ bi ẹni pe wọn ko ni le pari ki saa iṣejọba kẹjọ ti wọn n lo lọwọ yi yoo fi wa si opin.
Lara ojuṣe ti iwe ofin la kalẹ fun ẹka aṣofin ni ki wọn sagbatẹru awọn ofin eleyi ti yoo mu idagbasoke ati alafia ba awọn ara ilu.
Pẹlu ojuṣe yi lawọn omiran bi ki wọn ṣe ayẹwo finifini fun awọn ti ẹka alaṣẹ ijọba wa eleyi ti wọn a ma ṣe nigbadegba.
Ni bayi ti o ku ọjọ diẹ ki wọn pari saa wọn, a fẹ ṣe ayẹwo awọn nnkan ti wọn dawọle kọọkan ti ko daju pe wọn yoo ribi pari wọn ati iru ipa ti eleyi yoo ni lara iṣejọba ati igbayegbadun awọn ara ilu.
Eleyi jẹ ọkan gboogi ninu igbesẹ ile aṣofin Naijiria kan ti wọn ko ti ribi ba de ibi to yanju ti ko si daju pe wọn yoo ri yanju ki saa ijọba wọn to pari.
Lootọ, ẹka alaṣe lo bẹrẹ irinajo aba yii ṣugbọn lọdọ awọn aṣofin ni o yi wa bayi lẹyin ti wọn ti ka a fun igba ekeji ti wọn si ti gbe e fun awọn igbimọ lati tubọ ṣe ayẹwo finifini aba naa.
Oríṣun àwòrán, Christian C. Ozor
Wàhálà ti wáyé lórí ọ̀rọ̀ ẹ̀kúnwó oṣù tuntun fún òṣìsẹ́ láàárín ìjọba àti àwọn adarí òṣìṣẹ́
Idibo gbogboogbo to waye wa lara awọn ohun ti mu ifasẹyin ba aba naa ti ko si daju pe bi awọn aṣofin ti ṣe n palẹmọ lati pada sile wọn yoo ribi joko yẹ aba naa wo mọ.
Ti a ba n kàá ni meni meji, o yi ku ipele bii mẹta ki aarẹ to buwọlu abadofin yi ko si daju pe wọn yoo rii ṣe ki saa ijọba yi to pari.
Okùnrin SARS náà sọ pé òun máa pa èèyàn síbi ni- Aladugbo
Titi di bi a ti ṣe n sọrọ yi, Ibrahim Magu ṣi n ṣe adele ipo alaga ajọ to n gbogun ti iwa jẹgudujẹra ni Naijiria EFCC.
Lẹẹmẹji ni ile aṣofin agba Naijiria tako iyansipo Ibrahim Magu gẹgẹ bi alaga ajọ EFCC.
Oríṣun àwòrán, Efcc/Facebook
Awọn asofin kọ lati yan Magu si ipo Alaga EFCC
Ninu alaye wọn, wọn ni iroyin ti awọn ileeṣẹ ọtẹlẹmuye fun awọn nipa Magu lo mu ki awọn ṣe lodi sí iyansipo rẹ.
Ẹka alaṣẹ ko wule gbiyanju lati ni ki Magu yọju nigba kẹta .
Bi nnkan ti ṣe ri lọwọ yi, o ṣeeṣẹ ki ile asofin ma yanju ọrọ Magu ki Magu si ma ba isẹ rẹ lọ titi ti awọn asofin mii yoo fi wọle.
Owo ina ọba ti ara ilu n san jẹ ọrọ kan pataki ti ile asofin eẹlẹẹkẹjọ lorile-ede Naijiria ko tii ribi yanju.
Ohun to si jẹ awọn ara ilu logun nipa ọrọ yi ni bi awọn oṣiṣẹ ile iṣẹ mọnamọna ti ṣe n bu owo gọbọi fun awọn ti ko ni ẹrọ to n ka iye owo ina ti wọn kò lo 'pre paid meter'.
Oríṣun àwòrán, Facebook/Femi Gbajabiamila
Ibo ile aṣoju ṣofin
Asofin Femi Gbajabiamila lo sagbatẹru aba kan eleyi ti yoo yanju aawọ ọrọ owo ina ti ọpọ ara ilu n ke irora si sugbọn aba naa ko ti di ofin.
Orukọ abadofin naa ni  Electric Power Sector Reform Act (Amendment) Bill, 2018; ti ireti si wa wi pe yoo sọ di ẹsẹ fun ẹnikẹni lati ma bu owo lu awọn ara ilu fun lilo ina ọba .
Wọn ti ka abadofin yin fun igab ẹkẹta nile asoju sofin ti irinajo rẹ́ ṣi yi jina diẹ ki o to di ofin ti yoo mu irọrun ba ra ilu.
Awọn nnkan ti ile asofin ti ba de ibi to lami
Lọjọ kọkandinlọgbọn, oṣu kẹta ọdun 2018, ile asofin Naijiria kede awọn aba ti wọn ti ṣiṣẹ lori tabi ti wọn buwọlu lati igba ti wọn ti bẹrẹ saa kẹjọ lọdun 2015.
Ikede yi wa lasiko igba ti awọn eeyan n faraya lẹyin ti akara tu sepo nipa iye owo osu ti awọn asofin n gba eleyi ti aṣofin Sheu Sani lati ipinlẹ Kaduna bẹ sita.
Ọrọ pọ ninu iwe kọbọ iṣẹ ti wọn lawọn ti ṣe ṣugbọn diẹ lara wọn re e.
Lara awọ́n nnkan ti ile ti yanju de ibi to lapẹrẹ lati ri:
#EndSARS lu ayélujára pa lórí ikú Kolade Johnson
‘Ọ̀rọ ẹnu lásán ni wàhálà tí Nnamdi Kanu ní òun lè dásílẹ̀ ní Nàíjíríà’
'Fashọla, o ò sì bẹ̀rù Ọlọ́run!'
Ìjọba South Africa pèpàdé lórí ìkórìíra àlejò
Nigeria 2019: INEC ìpínlẹ̀ Rivers ṣetán láti kéde èsì ìdìbò Rivers
Oríṣun àwòrán, @pius
Wamu wamu ni awọn agbofinro duro nibudo ikede idibo Rivers
Ilana ofin ti INEC la kalẹ fun kika ibo naa jẹ eyi ti wọn kọkọ fara balẹ ṣalaye ṣaaju kika ibo.
Wọn sọ nipa esi idibo awọn ibudo idibo ti ko si iforukọsilẹ to peye  tabi ti wọn ko ri to papọ bi o ṣe yẹ.
Awọn ibi ti wọn ni akọsilẹ iforukọsilẹ to dara ti ko dẹ si oṣiṣẹ INEC ti yoo ṣe atojọ esi ijọba ibilẹ naa ni awọn yoo fi pari ikede naa lẹyin iwadii to yẹ.
Kika esi idibo ti bẹrẹ ni pẹrẹwu ni Rivers
Ajọ INEC ni atundi idibo yoo waye lawọn ẹkun ti awọn ba ti wọgile esi idibo ibẹ lataari iwa ipa to ṣẹlẹ.
Bawo ni o ṣe ti bẹrẹ lati aarọ
Ohun gbogbo ti ṣetan ni ilu Pọta ni ipinlẹ Rivers ni eyi ti ajọ INEC yoo ti kede esi idibo gomina to ku.
Ọjọ kẹsan an, oṣu kẹta, ọdun 2019 ni awọn eniyan ipinlẹ Rivers ti kopa ninu eto idibo gboogbo ti awọn eniyan Naijiria ti kopa nipinlẹ Mọkandinlọgbọn ti wọn ti n yan gomina.
Ni kete ti ohun gbogbo daru nibudo ikede esi idibo gomina ati awọn aṣojuṣofin ipinlẹ Rivers ni ajọ INEC ti sun ohun gbogbo siwaju.
Lọwọlọwọ ni àwọn agbofinro kun ibudo ikabo naa ti wọn si di opopona mejeeji to jade si olu ileeṣe ajọ INEC nilu Pọta ni opopona PortHarcourt si Aba.
Opọ awọn onile iṣẹ nlanla bii ilé ifowopamọ ati oni ṣọọbu keekeeke ni wọn ti kogba wọle lasiko yii.
Gbogbo oludibo n woju ajo INEC nipinle Rivers
Awọn agbofinro, ọtẹlẹmuyẹ, ọmọ ogun ilẹ̀ ati awọn ẹṣọ alaabo ilu ti awa ara wa ni wọn n ṣayẹwo kikun fun gbogbo awọn to ba fẹ wọnu ọgba naa.
Awọn oṣiṣẹ eleto idibo, awọn aṣoju ẹgbẹ oṣelu kọọkan ni wọn ti wa nikalẹ nibẹ.
Opọ lo ti n foju sọna lati mọ ẹni ti yoo tukọ ipinlẹ rivers fọdun mẹrin to m bọ
Okùnrin SARS náà sọ pé òun máa pa èèyàn síbi ni- Aladugbo
Cholera Vaccine: NAFDAC kìlọ̀ lórí ayédèrú òògùn ààrùn onígbáméjì
Oríṣun àwòrán, Twitter/NAFDAC Nigeria
Oogun ayederu ma n ṣakoba fun aggọ ara ni
Ajọ to n mojuto aṣilo oogun ati ounjẹ, NAFDAC ti kilọ fawọn ọmọ Naijiria pe ayederu oogun aarun onigbameji ti ọpọ mọ si Kọlẹra ti gbode kan bayii lorilẹ-ede Bangladesh.
Ọga ajọ NAFDAC, Ọjọgbọn Moji Adeyẹye ṣalaye pe ede oyinbo ati Faranse lo wa lara oogun ọhun ti orukọ n jẹ Dukoral.
Ọjọgbọn Adeyẹye fikun ọrọ rẹ pe ajọ to n ri si ọrọ ilera lagbaaye, WHO ti ko bi ẹgbẹrun lọna mẹjọ paali ayederu oogun ọhun nilẹ.
Okùnrin SARS náà sọ pé òun máa pa èèyàn síbi ni- Aladugbo
O ṣapejuwe bi paali ti oogun naa ninu rẹ bayii: 1. Orukọ oogun naa- Dukoral Oral Cholera Vaccine/ Vaccin Oral contre le Cholera
2.  Nọmba paali rẹ- KV8262B1
3. Ọjọ ti yoo bajẹ- 2020-04
4. Ile iṣẹ to ṣe e- Valneva Canada Inc.
Ọga ajọ NAFDAC ṣalaye pe ile iṣẹ to ṣe ojulowo oogun aarun onigbameji naa ni Valneva Sweden AB, ti awọn eeyan mọ si  Crucell Sweden AB tẹlẹ.
O fikun un pe ajọ NAFDAC ko fi ontẹ lu oogun kọlẹra Dukoral lorilẹ-ede Naijiria.
Bakan naa lo rọ awọn eeyan lati ko ayederu oogun kọlẹra ti wọn ba ri lọ si ile iṣẹ ajọ NAFDAC to ba wa ni tosi.
Osun Election 2018 : Ilé ẹjọ́ ní Adeleke kò lẹ́tọ̀ọ́ láti díje dupò gomina
Oríṣun àwòrán, Ademola Adeleke/Facebook
Adeleke ni oludije ẹgbẹ òṣèlú PDP nínú ìdìbò Gómìnà ìpínlẹ̀ Osun
Ile ẹjọ giga to wa ni ilu Abuja ti fagile iyansipo Ademola Adeleke gẹgẹ bi oludije sipo gomina ni ẹgbẹ oselu PDP ninu idibo gomina to waye ninú Osu Kẹsan, ọdun 2018 ni ipinlẹ Osun.
Ademola Adeleke to n soju ẹkun idibo Iwọ-Oorun ipinlẹ Osun ni Ile Igbimọ Asofin lo dije dupo gomina ni ọdun to kọja.
Wahab Raheem ati Adam Habeeb ti ẹgbẹ oselu APC lo gbe Ademọla Adeleke lọ si ile ẹjo wi pe ko ni ju sabuke ile ẹkọ girama, eleyii ti yoo fun ni anfaani lati dije.
Okùnrin SARS náà sọ pé òun máa pa èèyàn síbi ni- Aladugbo
Lasiko to n da ẹjọ naa, Adajọ Agba Oathman Musa  sọ wi pe iwadii fihan pe ọdun 1976 ni Adeleke wọ ile iwe girama, amọ ti ko si iwe ẹri to fihan pe o jade iwe mẹwa ni ọdun 1980.
Amọ, agbẹjọrọ to n soju Adeleke Nathaniel Oke bu ẹnu atẹ lu idajọ naa nitori adajọ naa tọ ọna ti ko ba ofin mu, ti o si da iwe ẹri WAEC to fihan pe Adeleke ni iwe ẹri WAEC rẹ.
Ojojúmọ ní mọ ń kẹ́kọ̀ọ́ lára ọmọ mi to jẹ akanda
Ti a ko ba gbagbe, ajọ to n risi idanwo asekagba ile ẹkọ girama, WAEC fi lede lasiko idajọ wi pe lootọ ni Adeleke se idanwo WAEC ni Osu Karun/Kẹfa, ọdun 1981.
Ìgbìmọ̀ iṣedajọ orílè-èdè Nàìjíríà NJC nikan lo le yọ adajọ-Amofin
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ilé igbimọ aṣofin n beere pe ki wọn yọ adajọ agba ipinlẹ Kogi
Awuyewuye to n waye nipinlẹ Kogi nipa yiyọ adajọ agba ipinlẹ naa ti mu ki awọn eeyan máa beere ibeere kan eleyi to niṣe pẹlu boya awọn ẹka ijọba miran lagbara lati yọ ọsiṣẹ ẹka iṣedajọ.
Ọrọ yi ko jẹ tuntun lagbo oṣelu Naijiria ṣugbọn igba kigba to ba  gbori sita, niṣe ni iriwisi ọtọtọ a ma tele.
Lọjọ kini, oṣu kẹrin ni sẹnetọ to n ṣoju ila oorun ipinlẹ Kogi, Dino Melaye ke gbajare loju opo Twitter nipa ete ti awọn kan n pa lati yọ adajọ agba ipinlẹ naa nipo.
Ninu ọrọ rẹ, o fẹsun kan pe awọn kan ti pari ipade eyi ti wọn ti paṣẹ ki olori ile aṣofin ipinlẹ naa yọ adajọ agba nipo bi bẹ kọ wọn yoo yọ ohun gaan alara.
Asẹyinwa aṣẹyinbọ ọrọ yi ni ikede ile asofin eleyi ti wọn ti daba ki wọn yọ adajọ agba Nasir Ajana nipo lori ẹsun aṣemaṣe.
Ohun nikan kọ, abajade iwadii igbimọ ile to n ri si amojuto eto owo ara ilu sọ pe ki adajọ agba naa yẹba lati le dahun si ẹsun ti ayẹwewo agba ipinlẹ naa fi kan an.
O jọ gate ko jọ gate, ibi ti ọrọ naa yoo kangun si ko ti ye wa ṣugbọn BBC beere alaye lọwọ agbẹjọro kan lori iha ti ofin kọ si yiyọ adajọ agba
Ìgbìmọ̀ iṣedajọ orílè-èdè Nàìjíríà NJC nikan lo le yọ adajọ
Agbẹjọro Solihu Adebayo nilu Ibadan ṣalaye fun ile iṣẹ BBC Yoruba pe lootọ lawọn ẹka aṣofin le daba yiyọ adajọ agba ṣugbọn igbimọ iṣedajọ orile-ede Naijiria NJC nikan lo lagbara lati yọ ọ.
O ni ipinya laarin awọn ojuṣe ati agbara ẹka ijọba ko fayegba ki ẹka iṣejọba kan máa dasi iṣẹ ẹka miran bi ki ṣe nilana ohun ti iwe ofin ilẹ Naijiria sọ.
Oríṣun àwòrán, Facebook/Adebayo Solihu
Agbẹjọro Solihu Adebayo ni aṣilo agbara ni ki awọn ẹka ijọba miran ma yọ adajọ nipo
''Ẹka ẹyọ kan ṣoṣo ti ofin sọ ti o si ni agbara lati yọ adajọ ni Naijiria ni NJC''
O salaye siwaju pe ''ko si ẹni ti ko le kọ iwe ẹsun nipa adajọ,koda ara ilu le kọ ti wọn ba fura si pe irin ẹsẹ adajọ ko mọ''
Nipa iroyin to n ja rain wi pe ijọba ipinlẹ Kogi fẹ lo awọn ọmọ ogun ati ọlọpaa lati yọ adajọ naa nipo,o ni eleyi tako ofin
''Ati ọlọpaa, ati awọn ọmọ ogun ti o ja si pe wọn wa labẹ ẹka alasẹ, ko si ẹni ti ofin gba laye ninu wọnlati yọwọ adajọ lawo bi kii ṣe wi pe aṣẹ na wa lati ọdọ  ẹka idajọ fun arawọn'' .
Àyà mi kọ́kọ́ máa ń já nígbà ti mo ṣẹ̀ṣẹ̀ bẹ̀rẹ̀ -Alaga iduro ọkùnrin
Iṣẹlẹ ẹnu ọjọ mẹta yi nipa ibaṣepọ laarin ẹka alaṣẹ ni Naijiria ati ka idajọ n tọka si pe ohun gbogbo ko lọ deede laarin awọn mejeeji.
Bi a ko ba gbagbe, laipẹ yi ni awuyewuye waye lori bi aarẹ Naijiria ti ṣe paṣẹ lọ rọọkun nile fun adajọ agba orile-ede naa, Adajọ Walter Onnoghen.
O ye mi-ko ye ẹ lori ọrọ yi mu ki awọn kan máa sọ pe ẹka alaṣẹ n dunkooko mọ ẹka idajọ ti ọrọ naa si ti mu alaye orisirisi wa lodo awọn amofin.
A ò ṣe àyọnusọ lóri ọ̀rọ̀ abẹ́lé Nàìjíríà-UK
Ọrọ yii mu ki awọn eeyan ṣi iwe kan iru igbeṣẹ bayi ti Gomina ipinlẹ Kwara nigba kan ri Bukola Saraki hu pẹlu yiyọ adajọ agba ipinlẹ naa Adajo Elelu Habeeb.
Ile ẹjọ giga dasi ọrọ naa ti o si sọ pe ofin ko fun Gomina tabi aarẹ orile-ede lagbara lati yọ adajọ kankan yala nipinlẹ tabi adajọ agba lorile-ede.
Bi ọrọ ti ṣe ri yi agbẹjọro Solihu Adebayo ni ''Ko ruju ni nnkan ti ofin sọ. Bi a ba kan fẹ tan ara wa loku, ko si agbara lọdọ ẹnikẹni yatọ si igbimọ iṣẹdajọ lati yọ adajọ''.
Okùnrin SARS náà sọ pé òun máa pa èèyàn síbi ni- Aladugbo
Ojojúmọ ní mọ ń kẹ́kọ̀ọ́ lára ọmọ mi to jẹ akanda
Osun Guber Poll: PDP ní ìdájọ́ ilé ẹjọ́ gíga lórí ọ̀rọ̀ Adeleke kò fẹsẹ̀ múlẹ̀
Oríṣun àwòrán, Facebook/Ademola Adeleke
Idibo gomina Oṣun
Adeleke ni iwe ẹri tó yẹ lati dije dupo gomina- Amofin Salami
Ẹgbẹ oṣelu PDP ti sọ pe ohun yoo lọ si sile ẹjọ kotẹmilọrun lori idajọ ile ẹjọ giga l'Abuja to fagile iyansipo Ademola Adeleke gẹgẹ bi oludije sipo gomina fẹgbẹ oselu PDP ninu idibo gomina to waye ninú Osu Kẹsan an, ọdun 2018 ni ipinlẹ Osun.
Lasiko to n da ẹjọ naa, Adajọ Agba Oathman Musa sọ wi pe iwadii fihan pe ọdun 1976 ni Adeleke wọ ile iwe girama, amọ ti ko si iwe ẹri to fihan pe o jade iwe mẹwaa ni ọdun 1980.
Ṣugbọn oluranlọwọ fun Sẹnẹtọ Adeleke lori eto iroyin, Bamidele Salami to ba BBC Yoruba sọrọ ṣalaye pe idajọ naa ko lẹsẹ nilẹ rara ati pe ajọ idanwo iwe mẹwaa ti a mọ si WAEC ti bura nile ẹjọ pe Ademola Adeleke ṣe idanwo aṣejade naa.
Okùnrin SARS náà sọ pé òun máa pa èèyàn síbi ni- Aladugbo
O ni lakọkọ, akoko lati pẹjọ lori bo ya Sẹnẹtọ Adeleke koju oṣuwọn lati dije fun ipo oṣelu ti kọ ja nitori o ti ju ọgọsan ọjọ ti ofin la kalẹ lọ.
Ọgbẹni Salami sọ pe ẹlẹẹkeji to da bii rẹ ni pe ajọ to n ri si idanwo aṣejade nile iwe girama, eyun ni WAEC jẹri nile ẹjọ tẹlẹ pe Adeleke pari iwe mẹwaa ti ofin la kalẹ gẹgẹ bi amuyẹ fun ẹnikẹni to ba fẹ dije fun ipo gomina ni Naijiria.
Ilé ẹjọ́ kòmítẹlọ́rùn yá lórí ìbò gómìnà Oṣun- PDP
O fikun ọrọ rẹ pe iwe ẹri ti oludije sipo gomina fẹgbẹ PDP nipinlẹ Oṣun lo lati dije fun ipo sẹnẹtọ naa lo lo fun ipo gomina, o ni ofin Naijiria ṣi faye gba eleyi.
Àyà mi kọ́kọ́ máa ń já nígbà ti mo ṣẹ̀ṣẹ̀ bẹ̀rẹ̀ -Alaga iduro ọkùnrin
Ọgbẹni Salami ni ẹgbẹ alatako APC lo wa nidi ọrọ yii, ati wi pe APC ko ṣetan lati gba idajọ ododo laaye.
Ojojúmọ ní mọ ń kẹ́kọ̀ọ́ lára ọmọ mi to jẹ akanda
Ṣugbọn amofin Remi Adeoye ṣalaye pe labẹ ofin, idajọ ile ẹjọ giga l'Abuja ọjọ Iṣẹgun ti fagile idajọ igbimọ igbẹjọ eto idibo(Tribunal) to sọ pe Sẹnẹtọ Ademola Adeleke lo wọle ibo gomina Ipinlẹ Oṣun.
Ilé ẹjọ́ kòmítẹlọ́rùn yá lórí ìbò gómìnà Oṣun- PDP
Agbẹjọro Adeoye ṣalaye pe ti ile ẹjọ to ga julọ ba sọ pe Sẹnẹtọ Adeleke lo jawe olubori ninu idibo gomina Oṣun, ṣugbọn ti ko ni ẹri to daju pe o pari ile iwe girama, ẹniti o jẹ igbakeji rẹ ni yoo di gomina Ipinlẹ Oṣun.
Fake Facebook: Ọkùnrin kan dèrò iléejọ́ lórí ẹ̀sùn pé ó f'orúkọ Adeboye lu jìbìtì
Oríṣun àwòrán, Twitter/Adeboye/Olukoya/Joshua
Ọkunrin kan fawọn ojiṣẹ Ọlọrun lo jibiti
Ọwọ ti ba ọkunriun kan ti wọn fẹsun kan pe, o n fi orukọ Olori ijẹ Redeem, Enoch Adeboye, ati ti ijọ Mountain of Fire, Daniel Olukọya pẹlu Olori ijọ Synagogue, Temitọpẹ Joshua lo awọn eeyan ni jibiti.
Ọkunrin naa ti orukọ rẹ n jẹ Yusuf Atanda, ni wọn fẹsun kan pe o ṣi oju opo ayederu Facebook fun awọn ojiṣẹ Ọlọrun mẹtẹẹta yii lati maa fi gba owo lọwọ awọn eeyan.
Iwadii fihan pe, Ọgbẹni Atanda fi atẹjiṣẹ sọwọ si awọn eeyan lati maa fi owo bi ẹgbẹrun kan ati ẹgbẹrun un meji naira si akoto banki to fi ranṣẹ si wọn.
Ayekofẹnifọrọ:  Ó yá, ẹ fi àmì sórí ọ̀rọ̀ náà.
Iroyin sọ pe, kete ti Ọgbẹni Atanda ba ti rowo gba lọwọ awọn eeyan ni yoo pa oju opo Facebook wọn rẹ, ki wọn ma ba le mọ ibi to wa.
Ẹwẹ, wọn gbe ọkunrin naa lọ siwaju ileejọ Magisireeti l'Ọjọru nibi to ti sọ pe oun ko jẹbi ẹsun naa.
Adajọ M.O. Tanimọla sun igbẹjọ naa siwaju si ọjọ kẹtadinlogun oṣu yii.
Oyè Ibadan: Àwọn ọba 21 ní kí Olubadan yé fẹnu yẹpẹrẹ adé àwọn
Oríṣun àwòrán, Lekan Balogun
Awọn ọba nilẹ Ibadan ti koro oju si ilana ti Olubadan ilẹ Ibadan. Ọba Saliu Adetunji n gba tabuku wọn, ki oriade naa si tete wa idahun si awọn ẹsun tawọn fi kan.
Ọtun Olubadan ilẹ Ibadan, Agba oye Lekan Balogun, ẹni to sọrọ lorukọ awọn ọba yoku salaye pe bi Olubadan se n fi ẹnu yẹpẹrẹ ade ori awọn ko jẹ itẹwọgba rara.
Bakan naa lo ni, asẹ ti ọba Adetunji pa pe ki awọn si ade ori awọn ko dara, gbolohun naa si n yẹpẹrẹ ofin to ti agbeyẹwo ilana oye jijẹ nilẹ Ibadan nidi.
Bi Olubadan se ni ka si ade ori wa, to ni ‘ko bofin mu’,  kii se ohun to dara. Dipo ki Olubadan fesi si awọn ẹsun ta fi kan, se lo tun n tabuku wa. 
Agba oye Balogun ni ọpọ ohun to n waye ni aafin Olubadan ko bojumu to, paapa nidi bi igbimọ Olubadan kii se seto ayẹwo mọ fawọn eeyan to fẹ jẹ Mọgaji ati Baalẹ, ko to di pe wọn jawe oye le wọn lori.
Ayekofẹnifọrọ:  Ó yá, ẹ fi àmì sórí ọ̀rọ̀ náà.
Bakan naa lo ni gbogbo awọn ọba yoku nilẹ Ibadan ni inu wọn kodun si ilana ‘owo ree, ọja ree’, tawọn eeyan n gba jẹ oye Mọgaji ati Baalẹ, eyi to n mu ki Mọgaji meji maa wa lati inu agbo ile kansoso.
Oloye Balogun tun ni Olubadan ti gbe asẹ to wa ninu aafin rẹ le Olori lọwọ, ohun to ba si wu olori lo n pa lasẹ.
Ìgbàjọba Seyi Makinde: Hosea Agboọla, Bisi Ilaka wà lára ọmọ ìgbìmọ̀
Oríṣun àwòrán, Seyi makinde
Gbogbo eto lo ti de  bayii fun igbesẹ igbejọbakalẹ lati ọwọ Gomina to wa lori oye Abiọla Ajimọbi si eleyi ti araluu dibo yan nipinlẹ Oyo, Seyi Makinde.
Lọjọ Aje, ọjọ Kinni, oṣu Kẹrin ọdun 2019 ni wọn ṣe ifillọlẹ awọn ọmọ igbimọ ẹlẹni mẹwaa kan ti yoo ri si eto igbejọbakalẹ naa.
Lara awọn eeyan ti yoo lewaju igbimọ naa la ti ri igbakeji akojanu tẹlẹ fun ile asofin agba nilẹ wa, Senetọ̀ Hosea Ayọọla Agboọla ati oludije tẹlẹ fun ile asofin agba lẹkun idibo Oyo North, Oloye Oyebisi Ilaka.
Awọn ọmọ igbimọ yoku ni Wale Adepọju, Debọ Ogundoyin, Oyedijọ Bọsẹde Ayọ Famọla, Ọlọlade Ajibọla, B.V Bello, Adeniyi Babatunde ati Seun Ashamu.
Ayekofẹnifọrọ:  Ó yá, ẹ fi àmì sórí ọ̀rọ̀ náà.
Bakan naa ni ẹgbẹ oselu PDP yoo tun se ifilọlẹ awọn igbimọ tẹẹkoto bii ogun mii fun eto igbajọba to n bọ lọna naa.
Ibadan Poly: Àwọn aláṣẹ ní kí àwọn akẹ́kọ̀ọ́ fún ìsìnmi nítorí jàgídíjàgan
Oríṣun àwòrán, Ibadan Poly
Awọn alasẹ ileewe giga gbogboniṣe Polytechnic Ibadan ti gbe ilẹkun ileewe naa ti pa.
Eyi waye lẹyin ti rogbodiyan waye laarin awọn akẹkọọ kan nileewe naa.
Bakan naa ni wọn ti fi ofin de gbogbo nkan to ni i ṣe pẹlu ẹgbẹ akẹkọọ nileewe naa.
Igbimọ to n mojuto awọn ileeṣẹ iroyin ninu ọgba ileewe naa, jabọ loju opo ayelujara rẹ pe wọn fi nkan gun akẹkọọ kan to jẹ oludari ere idaraya fun awọn akẹkọọ imọ ẹrọ, Oyeniyi Tobi.
Bakan naa ni akẹkọọ mi i naa tun farapa lẹyin ti wọn lu u ni alubami.
Gẹgẹ bi iroyin ti a gbọ, wahala naa bẹrẹ lẹyin idije bọọlu gbigba  to waye laarin awọn akẹkọọ imọ ẹrọ ati awọn akẹgbẹ wọn to n kọ nipa nipa okoowo ati ibaraẹnisọrọ.
Eyi lo fa a ti awọn alaṣẹ ileewe naa fi paṣẹ pe ki gbogbo akẹkọọ fi ọgba ileewe naa silẹ ni kiakia, ki wọn o si lọ fun isinmi idaji saa ni tipa-tipa.
Níbo lowó ìrànwọ́ ẹ̀kọ́ wa wà?
BBC Gov Debates: Ètò ẹ̀kọ́ ọ̀fẹ́ ni àwọn olùdíje yóò ṣe
Alukoro ileewe giga naa, Alhaji Adewọle Ṣọladoye sọ fun BBC Yoruba pe gbogbo awọn akẹkọọ to farapa nibi iṣẹlẹ naa lo ti n gba itọju nileewosan to jẹ ti ileewe.
Bakan naa lo sọ pe ọjọ kẹwa, oṣu Kẹrin ni awọn akẹkọọ naa yoo to pada si ọgba ileewe.
'A ko ti i le sọ igba ti ẹgbẹ akẹkọọ (SUG) yoo pada bẹrẹ, nitori pe nkan to kọkọ jẹ wa logun ni eto ẹkọ wọn, kiiṣe ọrọ ẹgbẹ.''
Nibayii, awọn ọlọpaa ti wa ninu ọgba ileewe naa lati ṣewadii lori iṣẹlẹ shun ati lati dena wahala to ba tun le fẹ ẹ bẹrẹ.
Ethiopian Airline crash: Àbájáde ìwádìí ọkọ̀ bàálù Ethiopia wẹ awakọ̀ bàálù mọ̀ ọ́
Oríṣun àwòrán, Ethiopian Airline
Baalu naa ko eero mọkandinlaadọjọ, to fi mọ awọn oṣiṣẹ baalu mẹjọ.
Ileeṣẹ igbokegbodo ọkọ lorileede Ethiopia ti fi esi  abajade awọn iwadi ti wọn kọkọ ṣe nipa ọkọ baalu Ethiopia Airline 302 to ja loṣu to kọja.
Iwadi naa fi han pe awakọ baalu na tẹle gbogbo ilana ti Boeing to ṣe baalu na ni ki wọn tẹle.
Eeyan mẹtadinlọgojọ lo padanu ẹmi wọn ninu iṣẹlẹ naa.
Mo ń retí láti ọ̀dọ̀ bàbá mi nígbà tí mo gbọ́ pé ó bá ìjàmbá bàálù lọ
Dagmawits Moges to jẹ Minisita fun eto irinna sọ fun awọn akọroyin pe gbogbo iwe aṣẹ to yẹ ki baalu naa ni, ni o ni, ti awọn ti o si wa ọkọ ofurufu ọhun tẹle gbogbo ilana to yẹ. Ṣugbọn baalu naa papa jabọ.
Isẹlẹ ọkọ ofurufu to ja yi ti mu ki awọn orilẹede kaakiri agbaye dawọ lilo ọkọ ofurufu Boeing 737 duro nitori pe baalu iru rẹ meji lo ja laarin oṣu maarun sirawọn.
Akure Anglican Bursar: Àwọn agbébọn gbé owó sálọ lẹ́yìn tí wọ́n pa akápò ìjọ Anglican
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Awọn agbebọn naa tẹle akapo ijọ naa lati ile ifowopamọ nibi ti o ti lọ gba owo
Awọn agbebọn kan ti  yinbọn pa akapo ijọ Anglican lẹkun Akure, Gabriel Abiodun ti wọn si gbe owo ti o lọ gba ni ile ifowopamọ salọ.
Alukoro ileeṣẹ ọlọpaa nipinlẹ Ondo,Femi Joseph lo fidi ọrọ na mulẹ fun BBC Yoruba.
O ni isẹlẹ naa to waye ladugbo Alagbaka  jẹ ajoji si ipinlẹ Ondo.
''O dabi ẹni pe ajoji ni  awọn agbebọn to hu iwa yi. Amọ ṣa a ti bẹrẹ iwadi ti ko si ni pẹ ti ọwọ wa yoo fi tẹwọn.''
Ko daju iye owo ti oloogbe naa lọ gba nile ifowopamọ .
Oríṣun àwòrán, Femi Joseph@official
Ajoji ni iru iṣẹlẹ yi jẹ fun wa nipinlẹ Ondo
Alukoro ọlọpaa ni nnkan bi ago mọkanla owurọ ọjọbọ ni awọn gburo iṣẹlẹ naa ti o si ni ki awọn to gbe ọgbẹni Gabriel de ile iwosan, o ti dakẹ.
''Wọn tọ lati ile ifowopamọ lọ si ọfisi rẹ ni.Nibẹ ni wọn ka mọ ti wọn ti yinbọn pa ki wọn to gbe owo salọ''
Buhari: Àwọn ọmọ Nàìjíríà faraya lórí Ìrìn-àjò ààrẹ lọ sí Jordan
Oríṣun àwòrán, @NGRPresident
Lẹyin ti aarẹ Buhari ba pari ipade tan ni Jordan,yoo tẹsiwaju lọ si Dubai ni UAElati kopa ninu ipade miran
Iriwisi ọtọọto lo n tele ikede ti ileeṣẹ aarẹ  Naijiria fi si oju opo Twitter wọn pe aarẹ Buhari n lọ si orileede Jordan fun ipade.
Bi awọn kan ti ṣe n ki pe ko ni asọkal ayọ lawọn kan  n faraya pe aarẹ Buhari fi ina si ori orule lawọn ipinlẹ bi Zamfara.
Wọn ni o yẹ ki o mu oju to wahala to wa nile  ki o to sọ gbera lọ si ipade nita.
Ipade ti aarẹ Buhari n lọ ṣe la gbo pe o ni ohun ṣe pẹlu awọn orileede to wa ni aarin ila oorun agbaye ati awọn ti ariwa ilẹ Afrika.
Nibi ipade naa, ileeṣẹ aarẹ ni aarẹ Buhari yoo ṣepade ti yoo mu agbega ba ọrọ aje Naijiria  pẹlu awọn olori ile iṣẹ ati olori orileede lagbegbe naa.
Awọn Gomina ipinlẹ mẹta,Yahaya Bello Kogi,Abiola Ajimobi ati Gomina Abubakar Badaru Jigawa yoo kọwọ rin pẹlu aarẹ́ Buhari.
Buhari ṣẹṣẹ dari irinajo kan si orileede Senegal ni nibi ti wọn ti bura wole sipo fun aarẹ Macky Sall.
Ati irinajo Senegal ati eyi to ṣẹsẹ n lọ yi, ko si eleyi to dun mọ awọn ara ilu kan ninu.
@Nasirmagori sọ pe inu awọn ko dunsi bi aarẹ́ ko ṣe kọbi ara si ipenija aabo to n ba awọn eeyanipinlẹ Zamfara finra
Ṣugbọn awọn kan fi ikini ranṣẹ si Buhari ti wọn si gbadura pe ki o gunlẹ layọ
Awọn kan na ọwọ awada si aarẹ ti wn si bere pe ṣe o ranti fi owo kalẹ ti wọn yoo fi toju ile
Lọjọ kejilelogun Osu Kẹta ọdun 2018,aarẹ Buhari ṣe abẹwo si ipinlẹ Zamfara nigba ti o n lọ kaakiri awọn ipinlẹ ti ikọlu ti waye kaakiri orilẹede Naijiria.
Abẹwo naa waye lasiko igba ti wahala awọn jaguda to n jin eeyan ati  maalu gbe peleke lagbegbe naa.
Lati igba naa di asiko yi,ijọba Buhari ko ti ribi koju  ipenija aabo ti o n ba awọn eeyan agbegbe ariwa Naijiria finra.
Walter Onnoghen: Ṣé lòótọ́ ní pé adájọ àgbà Nàìjíríà tí wọ́n ní kó lọ rọ́ọ́kún nílé tí kọwe fiṣẹ sílẹ?
Oríṣun àwòrán, Nigeria Bar Association
Wọn fi awọn ẹsun to jọ mọ ajẹbanu ati awọn ẹsun miran kan Adajo agba naa
Iroyin to n tẹwa lọwọ sọ pe adajọ agba Naijiria ti wọn pasẹ lọ rọọkun nile ti wa papa kọwe fi ipo silẹ.
Gẹgẹ bi ohun ti a ri ka ninu iwe iroyin Naijiria kan,The Cable, adajọ agba Onnoghen ''fi iwe ikọwefiposilẹ rẹ sọwọ si aarẹ Buhari ni ọjọbọ lẹyin ọjọ kan ti igbimọ to n risi ọrọ eto idajọ NJC fi abajade iwaadi wọn ranṣẹ si aarẹ Buhari.''
Lara ohun ti igbimọ da laba ni pe ki wọn paṣẹ ifẹyinti lẹnu iṣẹ adajọ naa lẹyin ti wọn ṣe agbeyẹwo gbogbo ẹsun ti wọn fi kan an.
Onnoghne ni ohun ko jẹbi ẹsun ti wọn fi kan.
A ṣi n ṣe akojọpọ iroyin naa ṣugbọn ni kete ti a ba ri aridaju bi nnkan ti ṣe ri, a o fi to yin leti.
Kolade Johnson: Adájọ́ pàṣẹ kí wọ́n fi ọlọ́pàá tó lọ́wọ́ nínú ikú Kolade Johnson sí àhámọ́
Inspẹkitọ ọlọpaa ti wọn yọ niṣẹ lori ọrọ arakunrin Kolade Johnson ti wọn yinbọn pa nilu Eko ti foju ba ile ẹjọ.
Adajo paṣẹ bakannaa pe ki wọn lọ fi si ahamọ titi di igba ti wọn yoo fi gbẹjọ rẹ.
Ọjọ ẹti tii ṣe ọjọ karun un ọsu Kẹrin ni ẹka ọtẹlmuye ọlọpaa to wa ni Panti nilu Eko gbe Inspẹkitọ Ogunyẹmi Olalekan lọ si iwaju adajọ.
Ninu atẹjade kan ti alukoro ile iṣẹ ọlọpaa nilu Eko,Bala Elkana fi sọwọ sawọn akọrọyin o salaye pe Adajọ ile ẹjọ kekere to wa ni Ebute Meta,Adajọ A.O Salawu  paṣẹ ki wọn fi si ahamọ titi diigba ti Oludari eka olupejo labe ijoba nipinle naa yoo fi lawọn lọyẹ lori ẹjọ naa.
Ile ise ọlọpaa ti saaju gba asọ lọrun inspektọ Ogunyẹmi Olalekan lori ipa to ko ninu iyinbọn pa Kolade Johnson.
Okùnrin SARS náà sọ pé òun máa pa èèyàn síbi ni- Aladugbo
SARS ti bẹ̀rẹ̀ ìgbésẹ̀ láti yọ àwọn ọ̀bàyéjẹ́ kúro
#justiceforstephen: Ọlọ́pàá ìpínlẹ̀ Èkó láwọn ti mú afunrasí méjì tó mọ̀ nípa ikú Dókítà Stephen Urueye
Oríṣun àwòrán, Stephen Urueye/Facebook
Stephen Urueye pari ẹkọ rẹ lọdun 2018.
Ile iṣẹ ọlọpaa nipinlẹ Eko ti kede pe awọn ti mu afunrasi meji ti o lọwọ ninu bi awọn kan ṣe gun dokita kan ni ọ̀bẹ pa ni ile ẹkọ iwosan LUTH niluu Eko.
Agbẹnusọ fun ileeṣẹ ọlọpaa nipinlẹ naa, Bala Elkana lo fi idi ọrọ naa mulẹ fun akọroyin BBC to n tọ pinpin iṣẹlẹ yi.
Dokita Stephen Urueye to jẹ akẹkọọ imọ iṣegun oyinbo lo n ṣiṣẹ pẹlu ile ẹkọ iwosan LUTH nilu Eko, ko to o padanu ẹmi rẹ lẹyin ti awọn eeyan kan gun ni ọbẹ pa.
Alukoro ọlọpaa sọ pe''niṣe ni dokita naa ati awọn ọrẹ jade faaji lalẹ Ọjọb, ki awọn janduku to pade wọn ti wọn si da ọgbẹ si lara lẹyin ti wọn gba dukia wọn.
Iṣẹlẹ yi mu ki awọn dokita to jẹ akẹkọọ bẹrẹ iwọde lati fi ẹhonu han lori iku rẹ.
Lasiko iwọde naa ,wọn kesi ijọba lati pese aabo to peye nitori pe ''eyi ki ṣe igba akọkọ ti awọn janduku yoo kọlu awọn akẹkọọ dokita lagbegbe naa.
Dr Ureya  to kẹkọ imọ iwosan ati iṣẹ abẹ la gbọ pe o ku lẹyin ọjọ meji to gba iwe ẹri moyege ẹkọ.
UI- Ìwádìí àyẹwò nìkan ló lè sọ ohùn tó pá olùkọ́ tó kù nínú ilé to jo
Oríṣun àwòrán, Tunji Oladejo
Ori ibusun ti awọn panapana ti gbe ọgbẹni Othman Zubair lọ si ile iwosan
Ile Ẹkọ fasiti ilu Ibadan,ti ọpọ mọ si UI ti fesi si iku arakunrin kan to ku mọ inu filati kan to jona laaye ibugbe awọn oṣiṣẹ agba ile Ẹkọ naa .
Ọgbẹni Aminu Othman Zubair ni iroyin kan so pe o gbẹmi ara rẹ ninu iṣẹlẹ ti ina ti jo filati rẹ nikan.
Amọ,alukoro ile Ẹkọ fasiti naa ọgbẹni Tunji Oladejo ninu ifọrọwanilẹnuwo pẹlu BBC salaye pe awọn ko ti le sọ pato nnkan to ṣokunfa iku arakunrin naa.
Oladejo ni lootọ ni aaye ibugbe Zubair jona ṣugbọn nigba ti awọn panapana yoo fi pa ina na ko si apẹrẹ pe ina jo Othman Zubair mọ ori ibusun rẹ ti wọn ti ba.
Oríṣun àwòrán, Tunji Oladejo
Awọn yara kan jo ninu ile Othman Zubair ki awọn panapana to ribi pa wọn
''Ori ibusun ti o sun si, ina yẹn ko de ibẹ,amọ gbogbo ibi iyoku ninu ile naa lo jo.Nigba ti wọn yoo fi gbe de ile iwosan Jaja, o ti ku''
O tẹsiwaju pe awọn alayẹwo ko ti gbe esi iwadi ohun to sọkunfa iku rẹ,fun idi eyi awọn ko le sọ iru iku to pa.
Oríṣun àwòrán, Tunji Oladejo
Ori lo yọ awọn olugbe ile to ku lọwọ ewu ina naa
BBC Yoruba wadi lọwọ alukoro fasiti naa boya oloogbe ohun ni ipenija ti o le mu gba ẹmi ara rẹ ti o si dahun pe ohun kan mọ pe arakunrin naa ati iyawo rẹ ni ede aiyede eleyi ti o mu ki wọn pinya.
''Nigba ti iṣẹlẹ yi yoo fi ṣẹlẹ kii ṣe oṣiṣẹ wa mọ, fun ara rẹ lo kowe pe oun ko ṣiṣẹ mọ ṣugbọn a kan fun laaye ko ma gbe ibẹ ni tori pe oju lo n roju ṣaanu''
Ogbẹni Tunji Oladejo fidi ọrọ mulẹ pe awọn mọlẹbi oloogbe naa ti sin oku rẹ si iboji oku to wa ni Akinyele.
Ààrẹ Buhari- Boko haram kò f'ẹsẹ rinlẹ l'ágbègbè kánkan ní Nàìjíríà
Oríṣun àwòrán, @NGRPresident
Bi o ba jẹ ti ọrọ ikọ Boko Haram ni, wọn ko ni agbegbe Naijiria kankan ti wọn dimu.
Aarẹ orile-ede Naijiria, Muhammadu Buhari  lọ sọ ọrọ yi di mimọ nibi ipade apero eto ọrọ aje l'agbaye ni ẹkun Middle East ati North Africa to n waye ni  Amman lorileede Jordan.
O ni awọn ọmọ ogun orileede Naijiria ti gba gbogbo agbegbe ti Boko Haram gba lọdun 2014 pada lọwọ wọn.
O ṣafikun pe ijọba ohun ti doola ẹmi awọn ti Boko Harm ko ni panpẹ mọra.
Ọrọ rẹ yi n waye lasiko ti ipenija aabo ti ṣe n koju awọn ipinlẹ kọọkan lariwa Naijiria bi Zamfara ati Kaduna.
Bo tilẹ jẹ wi pe Boko Haram ko lagbara to titẹlẹ mọ, ko ti si aridaju wi pe ijọba ti ribi yọ ọwọ wọn lawo patapata.
Aarẹ Buhari ninu ọrọ rẹ tubọ salaye pe aisi anfaani eto igbayegbadun ati aikari mudunmudun eto ọrọ aje lo mu ki ipenija aabo ma peleke si lagbaye .
O ni lorile-ede Naijiria, ijọba sapa lati mu irọrun ba awọn eeyan pẹlu ipese awọn eto kan eleyi to mu ki Naijiria ṣi sii fun karakata pẹlu awọn orile-ede miran.
Ìdájọ Ademola Adeleke l'Akure kò túmọ sí pé o kún ojú òṣùwọ̀n-Timothy Owoeye
Oríṣun àwòrán, @IsiakaAdeleke1/@Hon_Owoeye
Olori ọmọ ẹgbẹ to pojulọ nile asofin ipinlẹ Osun,Timothy Owoeye ti dasi ọrọ idajo ti ile ẹjọ kotẹmilọrun kan nilu Akure fi sita lori kikaju osuwọn Sẹnẹtọ Ademola Adeleke lati du ipo Gomina .
Lọjọ abamẹta ni igbimọ ipolongo Sẹnẹtọ Adeleke fi atẹjade sita nipa idajọ yi eleyi ti wọn ni o fihan pe lootọ ni pe Sẹnetọ Adeleke kaju iwọn lati du ipo Gomina.
Koda gbajugbaja olorin takasufe Davido ti Adeleke jẹ ibatan rẹ fi ikini soju opo Twitter rẹ lati ba Adeleke yọ lori ohun ti ile ẹjọ wi yi.
Amọ asofin Owoeye ni ki Davido ma ti yọ ju nitori pe idaj naa ko tunmọ si pe Adeleke ti gba idajo lori ọrọ yi.
Owoeye ni Adeleke ṣi yi ni ẹjọ niwaju ile ẹjọ kotẹmilọrun Abuja fun idi eyi,ki awọn eeyan ma ṣe gba ọrọ ẹgbẹ PDP gbọ lori pe Adeleke le du ipo Gomina.
O ni ọmọ ẹgbẹ PDP Akin Ogunbiyi lo gbe ẹjọ na lọ si iwaju ile ẹjọ lakure atti pe ko ni ohun kankan ṣe pẹlu idajọ ti ile ẹjọ kotmilọrun ti wọn ko ti da nilu Abuja.
Gẹgẹ bi ohun ti a ri gbọ lẹnu Dele Adeleke ati atẹjade kan ti igbimọ ipolongo Sẹnẹtọ Adeleke fi sita lorukọ agbẹjọro Niyi Owolade idajọ ti  ile ẹjọ kotẹmilọrun nilu Akure da ti fi han gbangba pe idajo ile ẹjọ giga nilu Bwari ko fẹsẹrinlẹ.
Wọn ni ohun to de ba idajọ ti awọn ọmọ ẹgbẹ PDP kan gbe lọ si ile ẹjọ kotẹmilọrun Lakure naa lo de ba ti Bwari latari pe awọn to gbejọ naa wa ko gbe ẹjọ naa wa lasiko ti ofin fi aye kalẹ fun igbẹjọ ọrọ idibo.
Ni iwoye wọn, wọn sọ pe awọn ṣe alaye yi niwaju adajọ to gbẹjọ Adeleke ni ilu Bwari L'abuja ṣugbọn wọn ko gba ọrọ naa wole.
Adeleke: Àwọn ará Ẹdẹ bẹ síta pẹ̀lú ìdùnnú lórí ìdájọ́ èsì ìdìbò gómínà Ọṣun
Ni bayi ti ile ẹjọ Akure ti ni Adeleke koju ọsuwọn,igbimọ ipolongo rẹ ni ko si nnkan mi ju ki ile ẹjọ ti yoo gbọ ẹjọ kotẹmilọrun awọn L'Abuja naa dajọ to jọ iru ti Akure.
Lọjọbọ ti ṣe ọjọ kẹrin oṣu Kẹrin ni Adeleke kọwe ẹjọ kotẹmilọrun ninu iwe ipẹjọ FCT/HC/BW/80/122/2018 lọ si ile ẹjọ giga Abuja.
Ninu iwe yi, o ni ohun fẹ ki ile ẹjọ kotẹmilọrun fọwọ rọ idajọ ile ẹjọ giga to ni ohun ko yẹ ni ẹni to n du ipo Gomina.
Bi a ko ba gbagbe lọjọ kejioṣu Kẹrin ni ile ẹjọ giga ni Bwari nilu Abuja dajọ pe Ademola Adeleke ko kaju osuwọn lati du ipo Gomina ninu idibo Gomina to waye ldun to kọja nipinl Osun.
Aliko Dangote: Mo gbà $10m ní bánkì kí o lè dami loju pé lòótọ́ ní mò lowo
Oríṣun àwòrán, BBC/GETTY
Olokoowo to lowo ju lọ ni Afrika Aliko Dangote ti ṣọ bi ohun ti ṣe gba miliọnu dọla mẹwa ni banki tori pe ohun fẹ mọ daju pe lootọ ni ohun lowo to to bẹ.
Nibi apero Mo Ibrahim to waye ni ọjọ abamẹta nilu Abidjan, ni o ti sọrọ yi.
Aliko Dangote to ni ile iṣẹ orisiriṣi sọ pe ''nigba ewe,miliọnu akọkọ to ba ni yoo ma jọ ọ loju. Amọ lẹyin igba naa, ko ni jọju mọ.''
O salaye pe ohun ṣadede lọ ile ifowopamọ lati lọ gba miliọnu mẹwa dọla ti oun si gbe si ẹyin ọkọ.
O ni ''nigba ti mo de ile,mo wo owo naa niwo pe lootọ ni pe emi ni mo ni.''
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Nigba ti o di Ọjọ Keji, Dangote ni ohun da owo naa pada si banki.
Ki a yabara kuro nidi ọrọ yi lati gbọ nnkan mi to sọ nibi apero naa.
Dangote parọwa si awọn ọdọ Afrika lati ma ṣe jẹ ki ọrọ wọn dabiowe Yoruba to niowo ti ọmọde ba kọkọ ri,akara nii fi jẹ
O ni ki wọn ni adisọkan to rinlẹ ki wọn si ma na inakuna
Oríṣun àwòrán, ERIC PIERMONT
Pupọ ninu owo Dangote wa lati idi ọja Dangote Cement rẹ
''Lọpọ igba, ati oju owo ati ere,gbogbo rẹ ni a ma n na.Ẹ ma gbagbe pe  a ko ni ma ṣalai koju ipenija ninu idokowo''
O mu apere ipenija ti ohun koju pẹlu ile iṣẹ simẹnti rẹ plu bi orileede Benin to wa ni tosi Naijiria ti ṣe yan rira simẹnti lati orileede China dipo tirẹ to wa ni arọwọtoo wọn.
Dangote kasẹ ọrọ rẹ pẹlu pe ohunn banujẹ nipa wahala gbigbe nkan gba ibode kan si omiran nilẹ Afrika.
#Zamfarakillings: Ìjọba pàṣẹ kí wọn dáwọ́ ìwakùsà ní Zamfara
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ọjọ́ Etí ni Abẹnugan Ilé Ìgbìmọ̀ Aṣòfin ìpìnlẹ̀ Zamfara fi léde àwọn jàgúdà tí pa ènìyàn 50 tó jẹ́ ọmọ ẹgbẹ JTF.
Ijọba apapọ lorilẹ-ede Naijiria ti pasẹ ki wọn dawọ duro lori gbogbo iṣẹ iwakusa lagbegbe ilu Zamfara lẹsẹkẹsẹ.
Igbesẹ yii ko sẹyin bi awọn jaguda kan se pa aadọta eniyan ni agbegbe naa lopin ọsẹ.
Ọga Agba Ajọ Ọlọpaa lorilẹ-ede Naijiria, Mohammed Adamu to fi ọrọ naa lede lasiko to n ba awọn oniroyin sọrọ ni ilu Abuja sọ wi pe awọn gbe igbesẹ naa lati ri wi pe abo to gbooro wa lori awọn osisẹ lagbegbe naa.
Adamu wa kesi awon ajeji to wa lati ilu okeere lati wa sisẹ ni bẹ lati kuro ni bẹ ni wara n ṣesa, ki ijọba ma ba a gba iwe asẹ ati ṣe iwakusa lagbegbe naa.
Aarẹ orilẹ-ede Naijiria, Muhammadu Buhari ti sọ òkò ọrọ si awọn afẹhọnu han ti wọn ni ko kọ ibi ara si ipaniyan to n waye ni ilu Zamfara.
Ninu atẹjade lori oju opo Twitter rẹ, Buhari sọ pe oun ba awọn ara ati ẹbi awọn eniyan ti jaguda pa ni Ọjọ Ẹti kẹdun.
O ni ohun ibanujẹ lo jẹ fun oun wi pe awọn adigunjale gba ẹmi awọn eniyan aadọta to jẹ ọlọde, JTF.
Aarẹ Muhammadu Buhari wa fi kun wi pe ohun to pọn dandan fun oun lọwọlọwọ bayii ni lati fi opin si iwa ipaniyan lagbegbe Ariwa orilẹ-ede Naijiria.
Laipẹ yii ni awọn eniyan bẹrẹ si ni fẹhọnu han lori awọn eniyan ti wọn n ṣekupa nipa wiwọ aṣọ pupa lati fi ibanujẹ wọn han.
Aarẹ orilẹ-ede Naijiria naa wa rọ awọn ọmọ orilẹ-ede Naijiria lati ma ṣe ti ọrọ oselu bọ ipaniyan to n waye naa, ki awọn ba le tete ri awọn to n ṣiṣẹ ibi yii, ki wọn si fi wọn jofin.
Ojojúmọ ní mọ ń kẹ́kọ̀ọ́ lára ọmọ mi to jẹ akanda
Àyà mi kọ́kọ́ máa ń já nígbà ti mo ṣẹ̀ṣẹ̀ bẹ̀rẹ̀ -Alaga iduro ọkùnrin
UNILAG Child Molestation: Ọ̀jọ̀gbọ́n Fagbohungbe ní àwọn òbí ayé òde òní kò ṣiṣẹ wọn bí iṣẹ́
Oríṣun àwòrán, Getty Images
ohun buruku ni agba fipa ba ọmọde lo pọ tabi tami oge sii lara
Ọjọgbọn Fagbohungbe Bankole Oni sọ pe awọn obi aye ode oni ko ṣiṣẹ wọn bii iṣẹ mọ.
O woye pe eleyi lo n ṣe okunfa ki awọn ara ita maa fipa ba awọn ọmọ kekeeke tage tabi ni ibalopọ pẹlu ipá.
Kọ́ ọmọ rẹ lẹ́kọ̀ọ́ ìbálọ̀pọ̀- Ọ̀jọ̀gbọ́n Fagbohungbe
O sọrọ yii ninu ifọrọwerọ pẹlu BBC Yoruba nigba ti o n sọ iwoye rẹ lori akẹkọọ ọmọ ọdun mẹrin ti awakọ kan fipa ba tage nile iwe alakọbẹrẹ nipinlẹ Eko.
O gba awọn obi niyanju lati maa kọ awọn ọmọ wọn lẹkọ ibalopọ lati igba ti wọn be ti wa ni kekeke.
Ogbẹni Akinọla Akinrọpo, to jẹ olukọni nipa itọju ọmọ laijẹbi ṣalaye pataki ipa obi ati alagbatọ lasiko yii pe:
Parental Guidance: Ọdún méjì ni kí ẹ ti bẹ̀rẹ̀ kíkọ́ ọmọ nípa ìbálòpọ̀
Ayekofẹnifọrọ:  Ó yá, ẹ fi àmì sórí ọ̀rọ̀ náà.
Olukọ ile iwe alakọbẹrẹ ti Women Society nile iwe giga fasiti UNILAG niluu Eko, Charity Madumere ni wọn ti da duro bayii pé ko lọ rọọkun nile na lori ẹsun pe awakọ ile iwe naa, Abiodun Matthew ba akẹkọọ ọmọ mẹrin tage lọna aitọ.
Igbimọ alaṣẹ ile iwe naa sọ pe iwadii fihan wi pe olukọ naa maa n fi awọn akẹkọọ ṣọ Ọgbẹni Matthew nitori ibaṣepọ to wa laarin awọn mejeeji.
Iwadii fihan pe nigba ti olukọ Madumere fawọn ọmọ kekeke ṣọ awakọ yii gan an lo fipa ba ọmọ ọdun mẹrin yii tage lọna aitọ.
Ojojúmọ ní mọ ń kẹ́kọ̀ọ́ lára ọmọ mi to jẹ akanda
Baba ọmọ ti iṣẹlẹ yii sẹlẹ si, Ọgbẹni Ade ṣalaye pe oun ṣakiyesi pe ibaṣepọ to wa laarin olukọ ti wọn da duro ati awakọ yii mu ifura dani.
Ṣugbọn Ọgbẹni Ade sọ pe iṣẹlẹ naa ṣẹlẹ si ọmọ oun nitori wọn kẹ eti ikun si ikilọ ohun.
Lẹyin naa ni awọn ọlọpaa mu olukọ yii, igbakeji rẹ ati almojuto ti wọn si juwọn si atimọle.
Ayekofẹnifọrọ:  Ó yá, ẹ fi àmì sórí ọ̀rọ̀ náà.
Àyà mi kọ́kọ́ máa ń já nígbà ti mo ṣẹ̀ṣẹ̀ bẹ̀rẹ̀ -Alaga iduro ọkùnrin
Lagos Kidnap: Wo ohun tí ọlọ́pàá ti ṣe nípa àwọn méje tí wọ́n jí gbé l'Eko
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Awọn ọlọpaa Naijiria
Ile iṣẹ Ọlọpaa ipinlẹ Eko ti sọrọ lori ibi ti wọn ba iṣẹ de lori ọrọ adari kan nile iṣẹ pana-pana, Rashidi Musbau atawọn mẹfa mii ti wọn ji gbe.
Ariwo ipaniyan, ijinigbe nihin lọhun atawọn wahala to n da silẹ n kọ ni lominu lorilẹede Naijiria.
BBC ba alukoro ile iṣẹ ọlọpaa ipinlẹ Eko, DSP Bala Elkanah sọrọ.
Elkanah jẹ ko di mimọ pe oju ọna omi Ikorodu ni awọn afurasi janduku gba yọ si wọn ti wọn da wọn lọna.
Wọn ji adari ẹka nile iṣẹ pana pana ipinlẹ Eko, Rashidi Musibau atawọn mẹfa mii ti wọn jọ n lọ gbe ni ọjọ abamẹta to kọja wọn si gbe wọn lọ si ibi ti wọn ko mọ.
"O ni ""kọmisọna ọlọpaa ti ṣe ibẹwo sibẹ, nibi ti wọn ti ri awọn ọkọ pẹlu awọn ohun kọọkan to le wulo fun wa fun iroyin""."
Ayekofẹnifọrọ:  Ó yá, ẹ fi àmì sórí ọ̀rọ̀ náà.
Ẹ̀ka alafọgbọn wadii ti ile iṣẹ ọlọpaa Eko ti wa lẹnu iṣẹẹ ṣiṣe awari awọn ti wọn ji gbe atawọn ajinigbe ọhun, yoo si di ṣiṣe lai fi ohunkohun silẹ lai ṣe.
Alukoro ọlọpaa ni ẹbi awọn ti wọn ji gbe kankan ko tii kan si ile iṣẹ ọlọpaa lati fun wọn ni iroyin kankan ṣugbọn awọn n ṣe iṣẹ awọn lọwọ lọwọ.
Gẹgẹ bi iṣẹlẹ ipaniyan ijinigbe ṣe n waye lọtun losi lorilẹede Naijiria eyi ti ariwo rẹ kọkọ pọ ni iha ariwa to fi wa di pe o tun sun de ipinlẹ Eko naa bayii ti ibẹru bojo si bo awọn eniyan lati rinrin ajo, Elkanah fesi.
O ni ọkan iru ẹ ni eleyii lati ọdun pipẹ, awọn si n ṣe iṣẹ awọn lati boju wo ohun to ṣi alafo silẹ ati ọna ati di alafo naa pẹlu.
Imo Airport Fire Outbreak: Iná sọ ní pápákọ̀ òfurufú ìpínlẹ̀ Imo
Oríṣun àwòrán, DANIEL NWACHUKWU
Papakọ ofurufu ipinlẹ Imo
Lẹyin ti ijamba ina kọ lu papakọ ofurufu ipinlẹ Imo, igbokegbodo irinajo ti gberasọ pada.
Ni ọjọ aje, ọjọ kẹjọ oṣu kẹrin ni iṣẹlẹ ijamba iná yii waye ní pápákọ̀ òfurufú ìpínlẹ̀ Imo.
Akọroyin BBC fi aridaju han pe ina naa pọ jọjọ to bẹẹ ti wọn dari irinajo pẹlu baalu lọ si ilu Portharcourt.
Oríṣun àwòrán, DANIEL NWACHUKWU
Papakọ ofurufu Imo
Ipaya bẹ silẹ gẹgẹ bi ina naa ṣe bẹrẹ si ni jo wii wii ni ẹnu ọna abawọle papak ofurufu Sam Mbakwe ni ilu Owerri, ipinlẹ Imo.
Ohun to ṣokunfa ina naa ko tii hande gẹgẹ bi a ko tii gbọ latẹnu awọn alaṣẹ tọrọ kan gan.
'Celestine fa adá yọ, ó sì gé orí ọmọ mi méjì'
Ido-Ani Robbery: Àwọn adigunjalè pa ènìyàn mẹ́fà ní báńkì kan nìpínlẹ̀ Ondo
Oríṣun àwòrán, Thenationonline
Wọn fi agidi mu awọn oṣiṣẹ ileefowopamọ lati ṣi ilẹkun rẹ, ṣugbọn owo ti wọn ba nibẹ ko jọ wọn loju rara.
Iroyin to tẹ wa lọwọ ni pe awọn adigunjale ya wọ ile ifowopamọ kan ni ipinlẹ Ondo ni ọsan ọjọ Aje.
Gẹgẹ bi alukoro fun ileeṣẹ ọlọpaa nipinlẹ Ondo, Femi Joseph ṣe sọ fun BBC Yoruba, awọn adigunjale naa ya bo ile ifowopamọ First Bank to wa ninu ilu Ido-Ani nijọba ibilẹ Ọ̀sẹ́ , ti wọn si gbiyanju lati ko owo lọ.
Ileefowopamọ ọhun nikan lo wa ni ilu Iso-Ani.
Ọwọ ọlọpa tẹ adigunjale ajọkọgbe nipinlẹ Ọsun
Offa Robbery: Àwọn aráàlú ṣi n gbé nínú ìpaya lẹ́yìn ọdún kan
Ṣugbọn gbogbo igbiyanju wọn lati ri owo ko jade nibi ti ileefowopamọ naa n ko owo si lo ja si ofo.
Ibi kan ṣoṣo ti wọn ti ri owo gbe lọ ni ibi ẹrọ igbalode to n pọ owo jade.
Wọn fi agidi mu awọn oṣiṣẹ ileefowopamọ lati ṣi ilẹkun rẹ, ṣugbọn owo ti wọn ba nibẹ ko jọ wọn loju rara.
Eyi lo si fa a ti wọn fi yinbọn pa awọn ti wọn pa.
Ibinu pe wọn ko ri nkankan mu ninu ileefowopamọ naa ni wọn fi pa oṣiṣẹ banki mẹẹrin, to fi mọ ọga agba ileewe girama kan to wa gba owo, ati ọlọpaa kan.''
Ṣé Fulani daran-daran ni àwọn tó n jí ènìyàn gbé ní ìpínlẹ̀ Ondo?
Àfojúsùn àtúntò FSARS ni láti mú àgbéga bá iṣẹ́ ọlọ́pàá- IG
Ọgbẹni Joseph ṣalaye Aado abugbamu ti wọn n pe ni 'Dynamite' ni wọn fi fọ ilẹkun wọle sinu ileefowopamọ ọhun.
Amọ ṣaa, ọwọ pada tẹ ọkan lara awọn adigunjale naa nibi ti iṣẹlẹ naa ti waye.
"Ẹni ti ọwọ tẹ yii lo kọkọ gbe ọkọ ayọkẹlẹ rẹ wọ inu ileefowopamọ wa nibi iṣẹju maarun ṣaaju ki iṣẹlẹ naa to o waye lati fi imu finlẹ lori bi ayika ṣe ri.''
Nibayii, ileeṣẹ ọlọpaa ti n fi ọrọ wa ẹni ti ọwọ tẹ lẹnu wo ninu iṣẹ iwadii wọn.
Reluwé Abuja: Amaechi ní èrò pọ̀ ní ojú ìrìn Abuja si Kaduna nítori ìjínigbé lójú pópó
Oríṣun àwòrán, Amaechiofficial
Ìjọba tí yòó ṣe àfikun yàrá ikérò si ọkọ ojú irin
Ìjọba àpapọ ti pinu lati ra iyara ikero méjì míràn láti fi kún ọkọ oju irin to n ná Abuja si Kaduna, eyi ti yoo mu àdínku ba èrò àpọjú to fẹ wọ ọkọ oju irin.
Mínísítà feto ìrìnà, ọ̀gbẹ́ni Rotimi Amaechi, ló pàsẹ bẹ́ẹ̀ ni lásìkò tó ń sàbẹ̀wò si iṣẹ́ ojú irin tó ń lọ lati ilu Eko si Ibadan, ni adugbo Ologuneru ni ìlú Ibadan.
Iròyìn NAN fi yẹ ni pé, ẹsẹ̀ kò gbà àgọ ìwọ̀kọ ojú ìrìn tó n rin Abuja si Kaduna mọ, nítori iwa ìjínigbé tó ń wáye lopopona Kaduna si Abuja lójoojúmọ.
Amaechi sọ pé, ile iṣẹ́ ọkọ oju irin (NRC) yóò gbe yàrá ìkérò si méjì míràn láti Itakpe si Warri, wá si ti Kaduna-Abuja.
Mò ń fi lẹ̀kẹ̀ ya àwọnran láti jèrè ǹkan méjì - Olaniyi Olaniyan
Ó kìlọ̀ pe, gbogbo àwọn oṣìṣẹ ti ọwọ́ pálábá ba ṣegi nínú tita tíkẹ̀ti ní owó rẹ jú iye to yẹ ko jẹ lọ, yóò fi oju wina ofin.
Amaechi ni ko ni rọrun lati lè móju to àwọn èrò to ba n  ninu ọkọ ojú irin pàápàá jùlọ lásiko ti wọn ba ń rin irin ajo
Beckham: Èdè mẹ́sàn-án ni Beckham fi gbógun ti àrùn ibà
Oríṣun àwòrán, @malariamustdie
Gbajugbaja agbabọọlu ọmọ ilẹ Gẹẹsi tẹlẹ, David Beckham tun ti gba ọna ara miran yọ sawọn eeyan agbaye, paapa awọn ololufẹ rẹ.
Ninu fidio kan to ti di tọrọ fọn kale bayii, ni a ti ri Beckham to n lewaju ipolongo tuntun lati gbogun ti aisan iba, to si sọ ede mẹsan-an gbako ọtọọtọ ninu fidio naa.
Beckham yii, lo n sọrọ ninu fidio ranpẹ naa, ni wọn lo imọ ẹrọ igbalode fun, to si n sọ ede Swahili, Kinyarwanda, Arabic, Yoruba, Faranse, Spanish, Hindi, mandarin àti bẹ́ẹ̀ bẹ́ẹ̀ lọ.
Awọn ete ati oju rẹ lo n lọ soke sisalẹ bo se yẹ lasiko to n sọ awọn ede naa, sugbọn awọn ohun to n jade lo dabi ti ohun awọn eeyan ti ori ko yọ lọwọ aisan iba.
Awọn to se agbatẹru fidio naa lero pe, awọn eeyan jakejado agbaye naa yoo wo fidio yii, ti wọn yoo si fi ohun tiwọn naa si pẹlu.
Mò ń fi lẹ̀kẹ̀ ya àwọnran láti jèrè ǹkan méjì - Olaniyi Olaniyan
Afojusun wọn nidi sise eyi ni pe, wọn yoo lo ohun awọn eeyan yii lati wa eekanna mọ awọn asaaju orilẹede agbaye lọrun, nibayi ti wọn n gbaradi lati gbe ipinnu kalẹ lori agbekalẹ apo asunwọn ẹdawo kan, eyi ti yoo maa gbogun ti aisan AIDS, ikọ ife, ati aisan iba.
Bi fidio naa se lọ ree:
Rélùwéè Eko: Alágbe tó kú náà jẹ́ ara àwọn tó ń jókòó lẹ́bàá ojú ìrìn
Oríṣun àwòrán, @Train
Ileesẹ reluwe ilẹ wa ti fidi rẹ mulẹ pe lootọ ni ọkọ oju irin kan to ko ero, tẹ alagbe kan pa lagbegbe Muslim, nilu Eko.
Lasiko to n fidi isẹlẹ naa mulẹ fun awọn akọroyin nilu Eko, Jerry Oche, tii se ọga agba fun ẹka to n risi ibasepọ pẹlu ara ilu, salaye pe ọkọ oju irin to n lọ lati agbegbe Ijoko si Iddo lo tẹ alagbe naa pa lẹba tesan reluwe to wa ni Mushin.
Iroyin naa ni onibaara ti o jẹ Ọlọrun nipe naa jẹ ọkan lara awọn alagbe to maa n joko lẹba oju irin ni tesan Mushin.
Nigba to wa n kẹdun lori iku alagbe naa, Oche tun rọ awọn ara ilu lati mase tako awọn ofin to rọ mọ lilo oju irin, ki wọn si dẹkun jijoko sẹba oju ọna reluwe, boya lati se agbe ni tabi fun idi miran.
Mò ń fi lẹ̀kẹ̀ ya àwọnran láti jèrè ǹkan méjì - Olaniyi Olaniyan
Bakan naa lo tun rọ awọn ontaja, awọn to n kiri ọja, awn onibaara atawọn araalu lapapọ, lati rin jinna kuro lawn opopona oju irin, ki wọn lee dina ijamba.
Ìtàn Mánigbàgbé: Aláàfin Ọ̀rọ̀ǹpọ̀tọ̀niyùn, jagun-jagun orí ẹṣin tí kò ṣe fi ṣeré
Oríṣun àwòrán, @kalonge93
Yoruba maa n sọ pe a ko ri iru eyi ri, a fi n dẹru ba ọlọrọ ni, nitori ko si ohun ti ko sẹlẹ ri.
Gẹgẹ baa ti ka ninu itan awọn nkan to ti sẹlẹ siwaju laye atijọ, awọn obinrin ti jẹ Alaafin ri, ti ko si gbọdọ jẹ ajeji si wa mọ lode oni.
Gẹgẹ ba ti ka itan rẹ lori itakun agbaye ati Wikipedia, Alaafin akọkọ to jẹ obinrin ni Aláàfin Ọ̀rọ̀ǹpọ̀tọ̀niyùn.
50 Year old Ajayi Folashade: Mo ti kọ́kọ́ dán an wò ní 80s àmọ́, ó kàn ṣáà ń wù mi náà ni
Itan naa ni bi ko ba si ẹsẹ, ẹsẹ kii deede sẹ, bẹẹ si ni bi ko ba ni idi, obinrin kii jẹ Kumolu.
Aisi ọkunrin mọ to wa lati idile to n jẹ Alaafin lo fa sababi bi Aláàfin Ọ̀rọ̀ǹpọ̀tọ̀niyùn se di ọba lode Ọyọ.
Ni aye ode oni, ẹkọ nla gidi ni itan igbe aye Alaafin obinrin akọkọ yii yẹ ko kọ wa, eyi to fi han wa pe ko si ohun ti ọkunrin lee se, ti obinrin ko lee se.
Bakan naa lo fi ye wa pe isẹ́ abẹ́ ko sẹsẹ bẹrẹ, o ti wa lati atetekọse, ti awn eeyan kan si gba pe Aláàfin Ọ̀rọ̀ǹpọ̀tọ̀niyùn ni ẹda akọkọ to jẹobinrin, amọ to yipada si ọkunrin, gẹgẹ bawọn eeyan kan se n se lode oni.
Oríṣun àwòrán, yorubyte
O wa yẹ ko ye gbogbo wa bayii pe, ka ma se ilakaka pe a ko bi ọkunrin, tabi obinrin nikan la n bi jọ, nitori gbogbo lọmọ, ko si eyi ti ko wulo ninu wọn.
INEC: Àwọn ẹgbẹ́ òṣèlú yóò dìbò àbẹ́lé lóṣù Kẹjọ
Ajọ eleto idibo ilẹ wa ti kede pe ọjọ́ Kejì, oṣù Kọkànla, ọdún 2019 ni ìbò gómìnà nipinlẹ́ Kogi àti Bayelsa yóò wáyé.
Atẹjade kan ti ajọ INEC fi sita lọjọ Isẹgun, ti alaga ati kọmisọna to wa fun ẹka iroyin ati ilanilọyẹ oludibo, Festus Okoye fọwọsi, lo siṣọ loju iroyin yii.
Atẹjade naa ni ọjọ kinni, osu Kẹjọ, ọdun yii ni ajọ INEC yoo fi ikede nipa ibo naa to ipinlẹ mejeeji leti, nigba ti eto idibo abẹnu laarin awọn ẹlẹgbẹjẹgbẹ oloselu yoo maa waye laarin ọjọ Keji si ọjọ ikọkandinlọgbọn, osu Kẹjọ, ọdun 2019.
Parental Guidance: Ọdún méjì ni kí ẹ ti bẹ̀rẹ̀ kíkọ́ ọmọ nípa ìbálòpọ̀
Iroyin naa ni Ọjọ Keji, osu Kẹjọ ni eto ipolongo ibo yoo bẹrẹ ni ipinlẹ mejeeji, ti yoo si wa sopin ni ọjọ Kọkanlelọgbọn, osu Kẹwa, ọdun 2019 naa.
Atẹjade ọhun wa n rọ awọn oludije labẹ ẹgbẹ oselu kọọkan lati fi orukọ awọn asoju wọn lọjọ idibo sọwọ, o pẹtan, ọjọ Keji, osu Kẹ́wa ọdun yii.
Ayekofẹnifọrọ:  Ó yá, ẹ fi àmì sórí ọ̀rọ̀ náà.
9th Assembly: Dogara kìlọ̀ fáwọn ẹgbẹ́ òṣèlú láti má dásí yìyan olórí ilé
Oríṣun àwòrán, @YakubuDogara
Adari ile aṣoju aṣofin l'Abuja, Yakubu Dogara ti rọ awọn alaṣẹ ẹgbẹ oṣelu lati jẹ ki awọn ọmọ ile aṣofin mejeeji yan awọn olori wọn fun ra wọn.
Dogara ni o ti han gbabgba pe, awọn aṣofin korira ki ẹgbẹ oṣelu kan yan awọn olori fun wọn ninu ile.
Nigba ti o n sọrọ nibi eto ilanilọyẹ fun awọn ọmọ ile tuntun niluu Abuja, Dogara sọ fawọn eekan nilu ẹgbẹ oṣelu, lati jẹ ki  awọn ọmọ aṣofin mọ igbesẹ wọn lori ati yan olori.
Dogara sọ pe oun gan ko le sọ fun awọn ọmọ ile lati yan ẹnikan, bi ko ṣe ki wọn dibo yan ẹni to ba wu wọn.
Dogara fikun ọrọ rẹ pe, awọn alaṣẹ ẹgbẹ oṣelu gbọdọ rii pe wọn ko da ile aṣofin mejeeji pada sẹyin nipa fifa olori kalẹ fun wọn.
Mò ń fi lẹ̀kẹ̀ ya àwọnran láti jèrè ǹkan méjì - Olaniyi Olaniyan
O wa rọ awọn ọmọ ile igbimọ aṣofin lati wo awọn eto ti awọn oludije fun ipo olori ni fun wọn, ki wọn si dibo fun ẹni to wu wọn.
Buhari: Ìkọlù Fulani àti ẹlẹ́gbẹ́ òkùnkùn ní Kaduna àti Rivers burú jáì
Oríṣun àwòrán, Presidency
Aarẹ Muhammadu Buhari ti bu ẹnu ẹtẹ lu ikọlu laarin awọn Fulani ati awọn eeyan lawujọ Adara ni ipinlẹ Kaduna.
Ogun eeyan lo di oloogbe latipasẹ akọtun ikọlu miran to waye lọsan ọjọ isẹgun.
Aarẹ Buhari to fọrọ naa lede lati ẹnu oluranlọwọ rẹ lori ọrọ iroyin, Garba Shehu, wa rọ awọn eeyan Adara ati awọn Fulani lati faye gba alaafia laarin wọn.
Bakan naa, Aarẹ Buhari koro oju si bi awọn ẹlẹgbẹ okunkun ti n fẹmi awọn eeyan ṣofo nipinlẹ Rivers.
Aarẹ rọ awọn eeyan nipinlẹ Rivers lati ṣiṣẹ pọ pẹlu awọn agbofinro ki wọn le dẹkun awọn ẹlẹgbẹ okunkun to n yọ ipinlẹ naa lẹnu.
Mò ń fi lẹ̀kẹ̀ ya àwọnran láti jèrè ǹkan méjì - Olaniyi Olaniyan
Aarẹ Buhari rọ awọn ọmọ Naijiria ni gbogbo ipinlẹ lati yago fun iwa bi adiẹ ba dami loogun nu, maa fọ lẹyin ti ede-aiyede ba bẹ silẹ laarin wọn.
Aarẹ tun rọ awọn olori ẹsin ati awọn ọba alade lati rii wi pe ọrọ ti yoo mu alaafia jọba, ni wọn n sọ jade lẹnu.
Dókítà yọ oyin mẹ́rin tó n gbé nínú ẹyinjú arábìnrin kán
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Irufe awon oyin ti won feran ilaagun eniyan
Arabinrin ọmọ ọdun mejidinlọgbọn kan ti wọn pé ni Ms He ni àwọn oyin mẹrin sọ ẹyinju rẹ di ibugbe.
Obinrin yii jẹ ọmọ orilẹ-ede Taiwan ni eyi ti awọn oniṣegun oyinbo rii pé awọn oyin ti wọn fẹran ilaagun eniyan sọ oju rẹ di ilé.
Dokita Hong Chi Ting ti ile iwosan Fasiti Fooyin ni Taiwan ṣalaye fun BBC pẹ ẹnu ya gbogbo àwọn nile iwosan naa nigba ti awọn ri oyin mẹrin ti ikọọkan wọn to iwọn milimita mẹrin yọ loju arabinrin naa.
Awọn onimọ fidi ẹ mulẹ ni Taiwan pé igba akọkọ ni yii ti wọn yoo ri iru iṣẹlẹ yii lẹnu iṣẹ wọn.
Dokita Hong Chi Ting ni wọn ti yọ oyin naa loju arabinrin He; wọn de ti fii silẹ ki o maa lọ sile rẹ ni alaafia.
Tóyìn Adégbọlá: Kò yẹ kí obìnrin fi ìdí gba ipò tíátà
Iwadii Kansas Entomological Society fihan pé omi ẹkun ojú kun fun eroja oriṣii.
Awọn irufẹ oyin ti wọn fẹran ilaagun bayii maa n saaba ba si ara eniyan lati la ilaagun ara wọn ni.
Iwadii fihan pe wọn tun maa n fẹ la omi ẹkún ojú eniyan nitori eroja aṣaraloore to wa ninu omi ẹkun.
Fídíò mánigbàgbé nípa ìgbà ayé Bàbá Sala
Bawo ni Oyin ṣe di onile ninu ẹyinju Obinrin yii:
Arabinrin Ms He ni oun n tu koriko ni bebe iboji mọlẹbi oun nigba ti oyin ko sinu ojú oun.
O ni asiko yii ni oun n kopa ninu ajọdun ọlọdọọdun 'Ṣiṣe atunṣe si iboji mọlẹbi'ti wọn n pe ni: Qing Ming Tomb-Sweeping Festival lọwọ.
Sibahle Zwanen fi ìmọ̀ ìṣìro da orí ayélujára rú
Arabinrin He ni ṣaa dede ni atẹgun kan fẹ wa nibi iboji ti oun ti n tu koriko yii ni eyi ti oun fi kọkọ ro pe idọti lo ko si oun loju.
O ni lẹyin wakati diẹ ti oju oun ṣi wu sibẹ ti ojú n ta oun ni oun ṣẹṣẹ gba pé kii ṣe idọti lasan ni o ko si ẹyinju oun.
Ìṣẹlẹ iyinbon APC Ekiti : Ki gaan lo ṣẹlẹ?
O ṣalaye fun akọroyin BBC pé nigba ti ọrọ oju yii fẹ maa gba ẹbọ lọwọ oun ni oun ba morile ile iwosan ni Guusu Taiwan.
Dokita Hong ni nigba to fi maa de ile iwosan, ko le pa oju rẹ de mọ, mo fi ẹrọ amunkan tobi sii wo ẹyinju rẹ ni mo ba ri awọn nkan dudu to dabi ẹsẹ kokoro ninu oju rẹ""."
Dòdò Ìkirè: Ó dúdú lára sùgbọ́n oyin ni lẹ́nu
O ni kete ti oun yọ ẹsẹ alakọkọ ni oun ri awọn kokoro oyin to ku ninu oju arabinrin naa.
Dokita naa ni oyin mẹrẹrin lo ṣi wa laaye lasiko yii.
O ni inu oun dun pe arabinrin yii ko ba iṣẹlẹ naa rin nitori pe ori koo yọ pe ko fi ọwọ gbo oju rẹ nigba ti awọn kokoro naa wa ninu ẹyinju rẹ.
Arabinrin He ni oun n wọ jingi kekere ti wọn n wọ fi bo ẹyinju (Contact lense) ni eyi ti ko jẹ ko ṣeeṣe fun oun lati fọwọ gbo ẹyinju oun ki oun to de ilé iwosan.
Eyi ni oye ṣẹṣẹ yee pe bi bẹẹ kọ ni o ṣeeṣẹ ki oju oun ti fọ lataari omi ara oyin naa ka ni oun fọwọ gbo oju ṣaaju ile iwosan ni.
Hakeem: Mo lè sọ arúgbó dí ọmọge nígbà tó bá wù mí
Dokita Hong ni awọn oyin mẹrẹrin ṣi wa laaye, ati pé wọn ti fi awọn oyin naa ranṣe si ile iṣẹ imiran ti wọn yoo ti ṣiṣẹ iwadii to peye nipa wọn nitori pe, igba akọkọ ni yii lorilẹ-ede Taiwan ti iru nkan bayii a ṣẹlẹ.
Lagos Flood: Wọ́n ṣì ń wa àwọn ọmọ méjì tí àgbàrá òjò wọ́ lọ ní Ketu l'Eko
Oríṣun àwòrán, LASEMA
Ibeere to n jẹ jade ni pe ṣe awọn ọmọ naa ṣi wa laaye abi wọn ti gba tibi agbara ojo yii re lọ sọrun?
Wọn ṣi n wa awọn ọmọ meji kan ti iroyin sọ pe agbara ojo gbe lọ lalẹ ọjọ Abamẹta ni agbegbe Ketu ni ipinlẹ Eko.
"Ariwo ""ẹ gba wa o, ko sina ni gbogbo adugbo wa o! Gbogbo agbegbe lo dudu raki raki"" ni awọn ara adugbo fi bọ ẹnu ti wọn si n kigbe pe agbara ojo ti wọ ọmọ meji lọ."
Oríṣun àwòrán, LASEMA
Ajọ to n ri si iṣẹlẹ pajawiri ni kete ti awọn gba ipe nipa iṣẹlẹ yii lawọn kan si agbami iṣẹ. Wọn ri iwadi pe nkan bii ago mẹjọ alẹ ni iṣẹlẹ naa waye ti ọmọ awọn ọmọde meji si ti ba agbara ojo ti ọwọ rẹ le ọhun lọ.
Ati ajọ LASEMA ati ileeṣẹ panapana Eko ni wọn pawọpọ fun iṣẹ naa ti ikọ adoola si kan sinu omi naa lati maa wa awọn ọmọ to sọnu.
Ohun kan ti wọn tun ri ni wipe ọna kan wa to n yọ to si lọ taara latoju gọta lọ sinuu kanaari kan, ibi yii ni wọn ni o nira lati wọ.
Ẹwẹ, ninu atẹjade ti oludari agba ajọ LASEMA, Ọmọwe Olufemi Damilola Oke-Osanyintolu fọwọ si, wọn gba gbogbo araalu nimọran lati maa moju to awọn ọmọde gidi gan lawọn agbegbe ti iṣoro omiyale n da laamu.
Atẹjade naa ko sọ boya wọn ti ri wọn, boya wọn ti ku tabi wọn wa laaye ṣugbọn ohun taa gbọ ni pe wọn ko tii ri ara wọn.
Bí rere ni àbí búburú, wo ohun tí Covid-19 leè ṣe sí àgọ́ ara rẹ
Ní Zamfara, Òjò àrọ̀ọ̀dá ló fa ìjàmbá ọkọ̀ kan, tí ọ̀pọ̀ míì si fara gbọgbẹ́
Oríṣun àwòrán, Others
Arinfẹsẹsi ko kan maili, ọba oke ni ko maa sọ wa.
Se ni ilu Gusau, nipinlẹ Zamfara kan gbinrin nipari osu Kẹjọ ọdun 2020 nigba ti eeyan mejidinlogun latinu  ọpọ ẹbi tẹri gbasọ ninu ijamba ọkọ .
Ọjọ buruku esu gbomi mu si ni ọjọ naa lopopona Tsafe si Gusau nigba ti Tirela ati ọkọ ayọkẹlẹ mẹrin kọlu ara wọn ni deede aago mẹrin abọ irọlẹ.
Lara awọn ọkọ ayọkẹlẹ naa si ni ọmọ ẹgbẹ oselu PDP mejidinlogun naa wa, ti wọn n lọ ki gomina wọn kaabọ pada waye.
Alhaji Bello Matawalle lo ti rinrin ajo lọ silu Abuja lati ọsẹ diẹ sẹyin, to si n pada bọ wa sipinlẹ Zamfara lọjọ naa.
Ọkan lara awọn eeyan tori koyọ ninu ijamba ọkọ naa, Malam Bello Bakada ni bii idan ni isẹlẹ naa waye, eyi to ba ọpọ wọn lojiji.
Mistura Oseni Akintunde: Ara múmú kìí ṣe oríṣun ìfipábánilòpọ̀, ìran àwòjù ló ń fà á
"Ojo n rọ lakọlakọ lọjọ naa, to si nira fun awakọ lati ri ọkankan, koda, a ko lee ri ọkọ to n bọ niwaju, lojiji ni tirela kan sadede rọ lu ọkan lara awọn mọto wa.
Eeyan mejeeje to wa ninu ọkọ naa ku loju ẹsẹ, ti mọto meji miran si tun rọ lu tirela naa, eyi to tun mu ẹmi eeyan mọkanla miran lọ."
Gomina Watawalle, to ti fẹrẹ wọ ilu Gusau lasiko naa pada sibi isẹlẹ ọhun, to si lo ọpọ wakati lati ko awọn oku lọ sinu ilu fun sinsin.
Oríṣun àwòrán, @Bellomatawalle1
Ko tan sibẹ, ọpọ awọn eeyan to forei sọta ijamba yii lo tun fara gba ọgbẹ lorisirisi.
"Bakada ni ""ọjọ meji ni mo fi daku, ki n to ji, ti mo si ri pe ẹsẹ mi ti da, tawọn oniruuru ọgbẹ si wa lara mi."
"Ohun ti mo ranti gbẹyin ki n to ba ara mi nile iwosan ni pe mo ri tirela to rọ lu wa, ti ohun gbogbo si pada dudu."""
Oríṣun àwòrán, Facebook/Abdul’aziz Yari
Ọrọ aabo
Amofin Oyeyemi Balogun sọ pe otitọ ni ọrọ ti gomina ipinlẹ Zamfara governor pe oun ko lagbara to to lati paṣẹ fawon soja ati awọn agbofinro mii lati dẹkun ipaniyan to n ṣẹlẹ ni ipinlẹ naa.
Nigba ti o ba BBC Yoruba sọrọ, Ọgbẹni Balogun ṣalaye wi pe fidihẹ lasan ni awọn gomina ipinlẹ lori ohun ti wọn le ṣe lori ọrọ eto aabo nipinlẹ wọn.
Gómìnà Zamfara kò lágbára ní tòtọ́ọ́ lórí ọ̀rọ̀ ààbò- amòfin
O ni awọn gomina dabi aja ti ko leyin lẹnu ti ko si tun lee gbo debi pe yoo bu eeyan jẹ,  nitori gbogbo awọn oṣiṣẹ eleto aabo pata wa labẹ aarẹ orilẹede Naijiria.
Hakeem: Mo lè sọ arúgbó dí ọmọge nígbà tó bá wù mí
Amofin Balogun fikun ọrọ rẹ pe kọmisọnan fun ilẹ iṣẹ ọlọpaa nipinlẹ le kọ eti ikun si aṣẹ ti gomina ba pa ayafi ti o ba gbasẹ lati ọdọ ọga ọlọpaa ni Naijiria.
Ọgbẹni Balogun ni ọlọpaa ipinlẹ ni ọna abayọ si iṣoro eto aabo kaakiri orilẹede Naijiria.
Ṣugbọn o sọ pe awọn gomina lorilẹede Naijiria ko ti ni iriri lati dari ọlọpaa ipinlẹ.
Amofin naa rọ awọn aṣofin ati awọn alaṣẹ ijọba lati ṣe ayẹwo iwe ofin Naijiria papaa julọ ẹka to nii ṣe pẹlu eto aabo.
Ẹwẹ, Aarẹ Muhammadu Buhari ni oun nikan ko ni oun maa maa lo agbara lori eto aabo nitori pe gomina naa ipinle kookan naa ni agbara lati daabo bo awọn eniyan ipinlẹ rẹ.
Oladejo Okediji, gbajúgbajà òǹkọ̀wé Yorùbá papòdà lẹ́ni ọdún 89
Oríṣun àwòrán, Acebook/Oladejo Okediji
Iku mu ẹni re lọ
Iku doro, iku ṣe 'ka, iku mẹ'ni 're lọ. Gbajugbaja onkọwe lede Yoruba Oladejo Okediji ti papoda lẹni ọdun mọkandinlaadọrun un.
Ọkan lara awọn ọmọ oloogbe ti orukọ rẹ n jẹ Goke ṣalaye pe idaji owurọ Ọjọru ni ẹlẹmi gbaa ti baba rewalẹ asa.
Iroyin sọ pe ọgọrọ eeyan lo lu ile baba to wa ni Mobolaje niluu Oyo pa nipinlẹ Oyo lati kẹdun ẹni 're to lọ.
Hakeem: Mo lè sọ arúgbó dí ọmọge nígbà tó bá wù mí
Diẹ lara awọn iwe ti oloogbe Okediji kọ nigba aye rẹ ni Aja Lo Leru, Rere Run, Agbalagba Akan, Atoto Arere, ati Karin Kapo.
Awọn iwe miran ti oloogbe kọ ni Opa Agbeleka, Oga Ni Bukola, Sango, Iroyin Ayo, Binu Tiri ati, Aajo Aje.
Fasiti Ọbafẹmi Awolowo University, Ọọni ile ifẹ takorawọn lórí ẹ̀sùn májèlé táwọn kan dà sómi iléèwé náà
Kò tíì dájú bóyá ọwọ́ àwọn agbófinró tíì tẹ ẹnikẹ́ni lórí ìṣẹ̀lẹ̀ náà
Ile ẹkọ to gbajumọ lagbaye ni ileewe Ọbafẹmi Awolọwọ University, OAU to fi ikalẹ si ilu ile ifẹ ni ipinlẹ Ọṣun ṣugbọn ni aipẹ yii ni okiki kan pe awọn eeyan kan ti lọ da majele si odo omi ti ileewe naa n lo fun mimu ati ọpọlọpọ iṣẹ iwadi imọ ijinlẹ gbogbo.
Iroyin sọ pe awọn eeyan kan lo ṣa dede lọ pẹlu awọn ohun ija oloro ti wọn si da majele si inu odo naa ti wọn fi n pese omi ẹrọ fawọn akẹkọ ati olugbe inu ileewe naa.
Ọ̀rọ̀ǹpọ̀tọ̀niyùn, Aláàfin obìnrin àkọ́kọ́ rèé, tó ní nǹkan ọkùnrin
Irinajo ti gbérasọ padà ní pápákọ̀ òfurufú ìpínlẹ̀ Imo lẹ́yìn ìjàmbá iná
Hakeem: Mo lè sọ arúgbó dí ọmọge nígbà tó bá wù mí
Gẹgẹ bii ọrọ ti alukoro ileewe naa, Biọdun Ọlarewaju ba BBC News Yoruba sọ, awọn oṣiṣẹ alaabo ileewe fasiti naa to ri awọn eeyan naa ni ibi ti wọn ti gbe n ṣiṣẹ laabi yii lo pariwo sita ti awo ọrọ naa si fi lu sita faye gbọ.
O ni gbogbo awọn ohun abẹmi inu odo naa lasiko ti wọn da majele naa sii lo fara gba ninu rẹ. Amọṣa o ni ojo arọọrọda ọjọ meji to rọ ni ilu ile ifẹ lo dẹkun wahala ti ko ba waye lori iṣẹlẹ ọhun.
Nibayii, giwa ileewe fasiti naa, Ọjọgbọn Eyitọpẹ Ogunbọdẹde ti kọ iwe ẹhonu si awọn agbofinro-ọlọpaa ati ileeṣẹ ọtẹlẹmuyẹ DSS lati ṣewadii ọrọ ọhun.
Ninu ọrọ to fi sita, Ọọni ile ifẹ ti ṣe akawe ọrọ ọhun gẹgẹ bii eyi ti ko fidimulẹ.
Ninu atẹjade kan eleyi ti agbẹnusọ fun ọọni ile ifẹ, Moses Ọlafare fi sita, o ni ko si bi awọn ọmọbibi ilu ile ifẹ yoo ṣe gbaa lero tabi huu ninu iwa lati gbe majele lọ da si inu omi ti awọn akẹkọ n lo fun mimu.
Ẹsun naa ko lẹsẹ nlẹ rara. Ohun ti ko tilẹ ṣee gba lero ni nitori, bawo ni eeyan ti ọpọẹọ rẹ pe kan yoo ṣe gba ẹsun yii gbọ? Ilu ile ifẹ ati ileewe giga fasiti OAU ti n gbe pọ fun ọjọ pipẹ to le ni aadọta ọdun paapaa, nitori naa ko si si igba kan ti iru nnkan bayii waye.
Amọṣa awọn alaṣẹ ileewe fasiti OAU ni ọrọ ilẹ ti awọn eeyan kan fẹ gba mọ ileewe naa lọwọ lo n fa igbesẹ yii.
Oríṣun àwòrán, citymirrornews.com
Kò tíì dájú bóyá ọwọ́ àwọn agbófinró tíì tẹ ẹnikẹ́ni lórí ìṣẹ̀lẹ̀ náà
Gẹgẹ bii ọrọ ti Abiọdun Ọlarewaju, alukoro fasiti naa sọ, ilẹ ti ijọba ti fun fasiti naa lati aye Ọọni Adesọji Aderẹmi lawọn eeyan kan fẹ gba pada.
O wa fi da awọn obi ati alagbatọ to fi mọ akẹkọ leti pe wọn ti wojutu si majele naa, ayẹwo imọ ijinlẹ ti waye eleyi to ti fidi rẹ mulẹ pe o ti daa fun mimu bayii.
Akitiyan ṣi n lọ lọwọ lati kan si awọn agbofinro lori ibi ti iṣẹ iwadii de duro lori iṣẹlẹ ọhun.
Sudan: Omar al-Bashir, oníyàwó méjì tí kò bí'mọ kankan
Oríṣun àwòrán, ASHRAF SHAZLY
Omar al-Bashir
Lẹyin ọgbọ̀n ọdun, orilẹede Sudan yoo ni adari tuntun latari bi awọn ologun orilẹede naa ṣe gba ijọba lọwọ Omar al-Bashir.
Awọn oniroyin ni yatọ si igbe aye rẹ gẹgẹ bii adari Sudan fun ọgbọn ọdun, awọn oun ti awọn eniyan mọ nipa idile rẹ ko pọ.
Ṣugbọn awọn oun ti ẹ lẹ má mọ̀ rèé:
Omar al-Bashir ko ni ọmọ kankan. Iyawo meji ni o fẹ - Fatima Khalid ati Widada Babikar Omer. Ṣugbọn ko si ikankan lara wọn to bimọ fun.
Ibatan rẹ ni iyawo akọkọ, Fatima. Widada bimọ fun ọkọ rẹ tẹlẹ to ku sinu ijamba ọkọ baalu kan ki Al-Bashir to fẹ.
3. Bawo ni ọrọ̀ Omar al-Bashir ṣe pọ to?
Iroyin fi han wi pe Al-Bashir wa lara olori orilẹede Afirika to lowo ju lọ. Luis Moreno-Ocampo, to jẹ olupẹjọ ile ẹjọ agbaye nigba kan ri sọ ni ọdun 2009 wipe Omar al-Bashir ko owo to to biliọnu mẹsan dọla (triliọnu mẹta aabọ naira) pamọ si awọn ile ifowopamọ to wa ni Ilẹ Gẹẹsi. Awọn iroyin miiran ni bii bilọnu kan dọla ni gbogbo ọrọ̀ Al-Bashir.
Oríṣun àwòrán, AFP
Ki o to di pe  awọn oloogun orilẹede Sudan yọ Al-Bashir nipo, ọpọlọpọ ọmọ  orilẹede naa lo ti ku ninu ifẹhonuhan ti wọn ti n ke si i wi pe ko fi ipo silẹ lati oṣu kejila ọdun 2018.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Igbesẹ n lọ kikankikan lati rii pe aarẹ Omar al-Bashir kọwe fi ipo rẹ silẹ
Lẹyin ti awọn ologun yọ nipo ni Ọjọbọ, wọn gbe ijọba alaranṣe kalẹ kalẹ eyi ti yoo wa nipo fun ọdun meji.
Bakan naa ni wọn si tun kede eto ilu o fararọ ọlọdun mẹta lati moju to ohun gbogbo to yẹ.
Awọn eeyan orilẹede Sudan ṣi n reti ohun ti ileeṣẹ iroyin ijsba orilẹede naa gbe jade lori ikede kan ti ileeṣẹ ọmọogun orilẹede ọhun n gbero lati ṣe lori bi eto iṣejọba orilẹede naa yoo ṣe ri.
Oniruuru iwọde lo ti n waye niorilẹede Sudan ninu eyi ti ọpọ araalu ti n pe fun igbejọbasilẹ aarẹ Omar al-Bashir.
Iroyin ti awọn eeyan orilẹede naa n wu gbọ bayii ni pe aarẹ al-Bashir ko ni pẹ gbe ijọba silẹ ṣugbọn ko tii si ikede kan ni pato lati ọdọ awọn alaṣẹ ilẹ naa.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Bi o tilẹ jẹ pe ileeṣẹ akoroyinjọ Reuters ti gbee sita pe eeyan kan ti awọn fi oruks bo laṣiri ṣalaye fun awọn pe lootọ ni aarẹ Omar al-Bashir ti kọwe fi ipo silẹ gẹgẹ bii aarẹ orilẹede naa.
Ireti ọpọ ni pe ki wọn kede eyi lori ileeṣẹ iroyin ijọba orilẹede naa pẹlu bi iwọde ṣe n tẹsiwaju kikankikan  fun ọjọ kẹfa laiduro bayii ninu eyi ti awọn eeyan ti n ke si aarẹ naa pe ko fi ipo silẹ.
Abiola Ajimobi: Bàbá mi jẹ́ aránsọ, ìyá mi sì jẹ́ ọlọ́jà wóróbo
Oríṣun àwòrán, Tobi James
Gọ́mìnà ìpínlẹ̀ Ọyọ tẹ́lẹ̀rí, Abiola Ajimobi ti sọ ìtàn ìgbìyànjú rẹ̀ gẹ́gẹ́ bí ọmọ atàpátadìde títí tó fi gòkè àgbà.
Gomina ipinlẹ Ọyo, Abiola Ajimobi ti parọwa si awọn ọdọ wi pe ibi ti eniyan ti dide ko gbọdọ jẹ idiwọ tabi idena si atigoke agba.
Ajimobi sọ eyi lasiko to n ba awọn ọdọ sọrọ nibi ipade Young African Leaders Initiative fun awọn olokowo kekeeke lorilẹede Naijiria.
JAMB 2019: A ó fagi lé ìdànwò ẹni tó bá ṣe aṣemáṣe
O ni ọmọ atapata dide ni oun bi ọpọ ọmọ Naijiria, ti baba oun si jẹ aransọ, nigba ti iya oun jẹ ọlọja. Amọ oun ko jẹ ki ipinlẹsẹ oun dina atigoke nitori naa ni oun se tẹra mọsẹ.
Oríṣun àwòrán, TOBI JAMES
Nigba ti oun ba awọn ọdọ naa sọrọ, gomina tẹlẹri naa ni awọn eniyan nilo lati ma a ni ero rere, ki ilọsiwaju to jọju le de ba aye awọn eniyan.
Oríṣun àwòrán, TOBI JAMES
Gomina ipinlẹ Ọyọ tẹlẹri naa wa rọ awọn ọdọ lati fi ọkan si oun gbogbo ti wọn ba n se, ki itẹsiwaju le ba ọrọ aje wọn.
Sudan coup: Ṣé ìfipágbàjọba àwọn ológun kò maa pọ̀ si l'Afirika?
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Lẹyin ọpọ ifẹhonu han, awọn ologun gbajọba lọwọ aarẹ orilẹede Sudan, Omar al-Bashir.
Ile iṣẹ ologun sọ pe ohun yoo ṣe amojuto bi eto idibo yoo ṣe waye laarin ọdun meji.
Aarẹ al-Bashir fun ra rẹ gori oye lẹyin ti awọn ologun fipa gba ijọba lọdun 1989, ko to di akoko yii ọpọ igba awọn ologun ti gbiyanuju lati fipa gbajọba lorilẹede Sudan.
BBC ṣe ayẹwo itan bi awọn ologun ṣe dasi iṣejọba lorilẹede Sudan ati kaakiri ilẹ Adalawọ.
Orilẹede Sudan ni iṣẹlẹ ifapajọba ti pọju ni gbogbo ilẹ adaluawọ, igba mẹẹdogun ni awọn ologun ti gbiyanju lati fipa gbajọba.
Ẹmẹrin ọtọọtọ ni wọn ri ijọba gba, ti awọn ologun ba ri ijọba Omar al-Bashir gba de lẹ, yoo di igba karun un ti ologun ri ijọba gba lorilẹede Sudan.
Ifipagbajọba nilẹ Afirika
Igba mẹfalelugba ni ifapagbajọba ti ṣẹlẹ nilẹ Afirika lati ọdun 1950, iwadii awọn onimọ eto oṣelu meji to jẹ ọmọ ilẹ Amẹrika, Jonathan Powell ati Clayton Thyne lo fidi ọrọ naa mu lẹ.
Itumọ ti wọn fun fif ipa gbajọba ni ọna ti ko tọ lati yọ olori ijọba kuro lori ipo.
Ṣugbọn ede-ai-yede saba maa n ṣẹlẹ lori itumọ ifipagbajọba, koda awọn ọga ologun ti koro oju si ifipagbajọba.
Fun apẹrẹ, ni Zimbabwe lọdun 2017 nigba ti awọn ologun gbajọba ọdun mẹtadinlogoji Robert Mugabe, ọgagun agba Sibusiso Moyo nigba naa sọrọ lori ẹrọ amuhunmaworan pe ko si ohun to jọ idtẹgbajọba.
Ọgbẹni Powell to jẹ onimọ nipa oṣelu sọ pe awọn ologun kii fẹ gbọ pe awọn fipa gbajọba.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Awọn ologun gbajọba ni Robert Mugabe
Powell ati Thyne ifipagbajọba to ba ju ọjọ meje lọ gan an ni a le pe ni ifipagbajọba.
Yatọ si eleyi to ṣẹlẹ ni Sudan, ifipagbajọba marun le lọgọrun lo ti kuna nilẹ Afirika nigba ti ọgọrun si ṣẹlẹ.
Orilẹede Burkina Faso lapa iwọ oorun Afirika ni ifipagbajọba ti ṣẹlẹ julọ, ẹmeeje ọtọọtọ ni ifipagbajọba ti ṣẹlẹ ni orilẹede naa.
Laarin ogoji ọdun(1960-2000), ifipagbajọba ṣẹlẹ nigba ogoji laarin ọdun mẹwaa.
Ṣugbọn iṣẹlẹ yii ko dabi ti tẹlẹ mọ, lati ọdun 2000, igba mejilelogun lawọn ologun ti gbiyanju lati gbajọba.
Ṣugbọn igba mẹtadinlogun ni iṣẹlẹ ifipagbajọba ti ṣẹlẹ laarin ọdun mẹwaa sẹyin bayii.
Lagbaaye, ifipagbajọba ti ṣẹlẹ nigba 476 lati ọdun 1952.
Afirika ni iṣẹlẹ ifipagbajọba ti pọju lagbaaye.
Ilẹ South Amẹrika lo tun tẹ le Afirika, igba marun un le laadọrun ni ifipagbajọba ṣẹlẹ, igba ogoji si lo kẹsẹjari.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ifẹhonu han lorilẹede Venezuela
Ni bi ogun ọdun sẹyin, iṣẹlẹ ifipagbajọba ti dinku nilẹ South America. Lọdun 2002 nigba ti irufẹ iṣẹlẹ waye lorilẹede Venezuela nigba ti awọn ologun fẹ ditẹ gbajọba aarẹ Hugo Chavez ṣugbọn wọn kuna.
Bring back our girls: Obi àwọn ọmọ Chibok 34 ló kú ní ọdún márùn ún
Oríṣun àwòrán, AFP
Bring back our girls: Obi àwọn ọmọ Chibok 34 ló kú ní ọdún márùn ún
Awọn obi awọn ọmọ Chibok lẹyin ọdun marun un ti gba ọdọ pasito lọ fun adura itusilẹ fun awọn ọmọ Chibok.
Awọn to le ni ọgọrun un lo ṣi wa ni panpẹ awọn ikọ Boko Haram lẹyin ti wọn ji wọn gbe ninu ile iwe wọn lọdun 2014.
Awọn obi awọn ọmọ Chibok lasiko ti wọn n ba Adaobi Tricia Nwaubani sọrọ ni ọrọ awọn kii se oju lasan mọ ni awọn se gba ọdọ Pasito ati Woli T.B. Joshua lọ lati ba wọn sawari awọn ọmọ wọn to wa ni panpẹ.
Òní ni àyájọ́ ọdún karùn ún tí Boko Haram jí àwọn ọmọ náà gbé ní ilẹ́ ìwé wọn, tí 100 nínú wọn sí ti di àwátì.
Parental Guidance: Ọdún méjì ni kí ẹ ti bẹ̀rẹ̀ kíkọ́ ọmọ nípa ìbálòpọ̀
Alaga ẹgbẹ awọn obi awọn ọmọ ile iwe Chibok, Yakubu Nkeki ni ibanujẹ ati ẹdun ọkan lo jẹ fun awọn nitori lẹyin ọdun marun un, ọgọrun un awọn ọmọ naa lo si wa ni panpẹ
Ni eyi ti lara awọn mọlẹbi awọn ọmọ wọnyii si ti ku nipase iku ojiji, ijamba ọkọ, aisan ati ikọlu awọn Boko Haram si awọn agbeegbe wọn.
Parental Guidance: Ọdún méjì ni kí ẹ ti bẹ̀rẹ̀ kíkọ́ ọmọ nípa ìbálòpọ̀
Oríṣun àwòrán, AFP
Òní ni àyájọ́ ọdún karùn ún tí Boko Haram jí àwọn ọmọ náà gbé ní ilẹ́ ìwé wọn, tí 100 nínú wọn sí ti di àwátì.
Arakunrin Nkeki ni awọn obi mẹrinlelọgbọn lo ti papoda lati igba ti ikọ Boko Haram ti ji awọn ọmọ wọn gbe si isinyii.
O fikun un pe ija ati asọ lo maa n waye lọjọọjọ ipade awọn obi naa, eleyii ti ko jẹ ki wọn fi imọ sọkan. Eyi lo mu ki wọn gba ile ijọsin T.B Joshua lo ni ilu Eko lati beere iranwọ lọdọ Ọlọrun.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Kíni ìdí tí àwọn ẹbí àwọn ọmọ Chibok fi ń tọ woli lọ?
Alaga ẹgbẹ awọn obi awọn ọmọ ile iwe Chibok fikun un wi pe ipa awọn ti pi.
Bakan naa ni ijọba ti gbiyanju amọ ko tii si ọna abayo, amọ awọn gba Ọlọrun gbọ nitori yoo gbọ adura awọn ati wi pe awọn ọmọ naa yoo pada wale layọ ati alaafia.
JAMB 2019: A ó fagi lé ìdànwò ẹni tó bá ṣe aṣemáṣe
Lara awọn to lo si ilu Eko fun adura lọdọ pasitọ T.B. Joshua ni alagbatọ Leah Sharibu to jẹ ọmọ ọdun mẹrinla to wa ni panpẹ Boko Haram lati oṣu keji, ọdun to kọja lasiko ti wọn ji eniyan to ju ọgọrun un gbe lo nile iwe rẹ ni ilu Dapchi, ni ipinlẹ Yobe.
Oríṣun àwòrán, AFP
Kíni ìdí tí àwọn ẹbí àwọn ọmọ Chibok fi ń tọ woli lọ?
Awọn ikọ Boko Haram ko lati fi Leah Sharibu silẹ lẹyin ti wọn yọnda awọn iyoku rẹ nitori ọmọ naa kọ lati fi ẹsin Kristẹni silẹ fun ẹsin musulumi ki wọn le tu silẹ lahamọ.
Oríṣun àwòrán, AFP
Bring back our girls: Obi àwọn ọmọ Chibok 34 ló kú ní ọdún márùn ún
Lasiko ayajọ ọdun karun un awọn ọmọ Chibok naa ni ijọba Aarẹ Muhammadu Buhari ṣalaye pe oun n sa ipa rẹ lati rii wi pe awọn to wa ni panpẹ Boko Haram naa gba itusilẹ laipẹ.
Wo bí o ṣe lè kọ́ ọmọ rẹ lẹ́kọ̀ọ́ ìbálòpọ̀
Ọ̀dọ́kùnrin tó kọ́kọ́ ṣe ẹ̀rọ tó ń tu ìyẹ́ lára adìyẹ
Obi àwọn ọmọdebinrin Chibok ṣi ni igbagbọ ninu Olọrun pe lọjọ kan ni awọn yoo foju kan awọn ọmọ awọn ti wọn jẹ mejilelaadọfa (112) laipẹ.
"Ko pẹ lẹyin ti wọn ji awọn ọmọ yii gbe ni awọn obinrin kan ko ara wọn jọ pẹlu akọle ""ẹ da ọmọbinrin wa pada: Bring back our girls)."
Bí o ṣe lè fí òǹkà, ọ̀mọ̀ ìka tàbí ìkúùkù wọn oúnjẹ́
Isreal Adesanya fàgbàhàn Kelvin Gastelum ni Atlanta
Oríṣun àwòrán, Getty Images
A ju ra wa lọ , ijakadi nikan kọ
Ninu idije oni ipele marun un ni Isreal Adesanya ti gbo ewuro soju Kelvin Gastelum.
Agbegbe Farm Arena ni Atlanta ni Georgia lo ti fagbahan Kelvin nibi idije UFC 236.
Opọ eyan lo gboriyin fun Isreal ti a bi ni Naijiria lori awọn ọna ifakayọ rẹ.
Kete ti Isreal jawe olubori yii ni o ti sun soke di 17-0 ninu akọsilẹ ija rẹ.
O gboriyin fun Kelvin ti wọn jọ gbe ina woju ara wọn pé akin ni ninu ija.
O ni: Kelvin fi ara re han ni ọmọ ogun ilẹ Mexico to jẹ akinkanju lẹnu ija ni bẹẹ mo ti pinnu lati ibẹrẹ pe ohun to ba gba ni mo maa fun un.
Ibẹrẹ kii ṣe oniṣẹ ni ọrọ ija naa jasi nitori pe Gastelum lo kọkọ n din dundun iya fun Isreal ki o to fi agbara kun agbara.
Bí o ṣe lè fí òǹkà, ọ̀mọ̀ ìka tàbí ìkúùkù wọn oúnjẹ́
Isreal to jẹ ọmọ ọdun mọkandinlọgbọn naa ba di agbo to fẹyin rin to lọ mu agbara wa, lo jẹwọ ọmọ ọkọ fun Kelvin nigba to ṣina fun un.
Nigba ti o fi maa di ipari akoko ija naa ni gbogbo awọn to n woran ni Atlanta ti bẹrẹ si ni kigbe orukọ ọmọ Naijiria olugbe New Zealand naa.
JAMB 2019: A ó fagi lé ìdànwò ẹni tó bá ṣe aṣemáṣe
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Isreal Adesanya fàgbàhàn Kelvin Gastelum ni Atlanta
Adesanya ba gba ogo pẹlu 48-46 ni eyi ti yoo jẹ ko tun lọ koju Robert Whittaker ọmọ ilẹ Australia nipele idije ẹṣẹ kikan to tẹle eyi.
Ni ibẹrẹ ọdun yii lo yẹ ki Whittaker koju Kelvin Gastelum ṣugbọn eyi ko waye lataari iṣẹ abẹ ti o ṣe.
Iroyin to gbode ni pe yoo pada soju ija laarin oṣu kẹfa si ikẹjọ ọdun yii.
Bi ori ba le jẹ ki Adesanya fagba han Whittaker, a jẹ pe o ti gba ami ẹyẹ abẹṣẹ-kubi-ojo ni yẹn.
Ọ̀dọ́kùnrin tó kọ́kọ́ ṣe ẹ̀rọ tó ń tu ìyẹ́ lára adìyẹ
Àwọn agbófinró ń wá ọlọ́pàá tó yìnbọn lu olólùfẹ̀ẹ́ méjì, lẹ́yìn tí wọ́n gbé akẹgbẹ́ẹ̀ rẹ̀
Oríṣun àwòrán, Segalink
Ọlọpaa ni awọn n wa ọkan lara awọn to wa nibẹ nigba ti wọn yinbọn naa.
Ajọ ọlọpaa Ipinlẹ Eko ti kede orukọ awọn ọlọpaa to lọwọ si bi wọn ṣe yinbọn lu awọn ololufẹ meji ni Ajegunlẹ ni ipinlẹ naa, ti arabinrin naa si gbẹmii mi.
Awọn ọlọaa naa ni Insipekitọ Adamu Usman, Sajẹnti Adeyeye Adeoye, Sajẹnti  Kashim Tijani, Sajẹnti  Lucky Akigbe ati Sajẹnti Paul Adeoye.
Agbẹnusọ ileeṣẹ ọlọpaa ni Eko, Bala Elkana ni awọn ọlọpaa naa ti n jẹjọ bayii bi kọmiṣọna ọlọpaa Zubairu Muazu si ṣe pàṣẹ pe ki wọn wa ọkan lara wọn, Insipekitọ Dania Ojo, to fẹsẹ fẹ lẹyin ti iṣẹlẹ naa ṣẹlẹ.
Oríṣun àwòrán, Nigeria Police
Kọmiṣọna ọlọọpaa ti kede pe wọn n wa Inspẹkitọ Dania Ojo
Bi iroyin ọrọ naa ṣe kan kakakiri ni awọn ọmọ Naijiria ti fi ẹhọnu wọn han lori ẹrọ ayelujara.
Iroyin ni ṣe ni awọn ọlọpaa le ọrẹkunrin ati ọrẹbinrin naa nigba ti wọn n bọ lati ile igbafẹ kan ni  agbegbe Ajegunlẹ ni ipinlẹ Eko. Nigba ti ọwọ wọn ko tete tẹ wọn, awọn ọlọpaa yinbọn lu wọn.
Arabinrin ọmọ ọgun ọdun naa,  Ada Ifeanyi, si ku loju ẹsẹ ti ibọn ọlọpaa báa.
Lẹyin ti iroyin ni awọn ọlọpaa ṣe ikọlu si wọn, ni a ti gbọ pé ọrẹọkunrin rẹ, Emmanuel Akomafuwa, naa si wa ni ile iwosan lẹsẹ kan aye, ẹsẹ kan ọrun.
JAMB 2019: A ó fagi lé ìdànwò ẹni tó bá ṣe aṣemáṣe
Iroyin ni awọn ololufẹ mejeeji naa n bọ lati ibi igbafẹ ni ki wọn to koju awọn ọlọpaa ninu eyi ti ẹmi ọmọbinrin naa ti bọ́ si.
Ninu aworan ti wọn fi lede ni obinrin naa ti n jẹ irora nilẹ, ko to di wi pe o papoda.
Ọmọ Naijiria pẹlu ibinu ni awọn fi n fi ẹhọnu han lori ẹrọ ayelujara Twitter wọn lori ẹsun pe awọn ọlọpaa ko bikita nipa ẹmi awọn eniyan.
Ni bayii, iroyin fihan pe ile iṣẹ ọlọpaa ni ipinlẹ Eko ti fi panpẹ ọba mu awọn ọlọpaa ti wọn fi ẹsun kan naa, ati wi pe iwadii n tẹsiwaju.
Gbogbo igbiyanju BBC lati beere sii nipa awọn ti iroyin ni ọwọ awọn agbofinro ti tẹ ko tii bi eso ti a n fẹ lọwọ.
SARS: Awọn ará ìlú fi ẹ̀rí síta nípa ìrírí wọn
SARS ti bẹ̀rẹ̀ ìgbésẹ̀ láti yọ àwọn ọ̀bàyéjẹ́ kúro
Àwọn ará àdúgbó Lekki rí orí àti ara ọkùnrin mẹ́ta ní àdúgbo wọn
Oríṣun àwòrán, Minkail Adesoji/Twitter
Ibeere ti gbogbo ara adugbo to lọ ibi iṣẹlẹ naa ni pe ta lo pa wọn.
Ibẹru-bojo mu awọn ara adugbo agbegbe Abraham Adesanya ni Ajah, nilu Eko bi wọn ṣe ji ni aarọ ọjọ Aiku ti wọn si ba awọn oku arakunrin mẹta kan ti wọn ti ge ori wọn silẹ.
Oun to jẹ kayefi ni bi wọn gbe ori awọn ọkunrin mẹta naa, ti wọn si náà duro ni ẹgbẹ awọn oku naa.
Ibeere ti gbogbo aye fi lẹnu ni wipe, ta lo pa awọn ọkunrin mẹta yii? Awọn ara adugbo kan ni awọn lero wipe ikọlu awọn ọmọ ẹlẹgbẹ okunkun lo fa iku awọn oloogbe naa.
Ìfipálówó: Bàbá ọmọ tí wọn gé lórí ní òun rán an láti l gbowó lẹ́nu ATM ni
Nigba ti akọroyin BBC Yoruba kan si agbenusọ ileeṣẹ ọlọpaa ni Ipinlẹ Eko, Bala Elkana, o sọ wipe iwadi n lọ lọwọ lori bi awọn ọkunrin mẹta naa ṣe ku.
Ko ti i si ẹni to mọ orukọ awọn oloogbe naa tabi ibi ti wọn ti wa. Elkana ni awọn oun ti iwadii yoo fi han ree.
Ṣe ni awọn ara adugbo naa n fi aworan awọn oku naa sori atagba Twitter ti gbogbo ero si n lọ pe wo awọn oku ati ori naa ki awọn ọlọpaa to gbee lọ.
Ghana Floods: Èèyàn méje pàdánú ẹ̀mí wọn nínú ìjàmbá ẹ̀kún omi
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ẹkun omi ni Ghana
Ojo arọọrọda ti gbẹmi eeyan meje niluu Accra tii ṣe olu ilu orilẹ-ede Ghana.
Lalẹ ọjọ Aiku lojo ọhun bẹrẹ ti o si rọ fun wakati mẹta gbako.
Nibi ti ajọ to n ri si ọrọ pajawiri lorilẹ-ede Ghana (NADMDO) ti n doola ẹmi awọn eeyan ni wọn ti ri oku eeyan mẹrin lagbegbe Ashaiman, bẹẹ ni wọn tun ri omiran lagbegbe Odorna.
Colorado ni Amẹrika àti odò Awaye ní Naijiria nikeji àdágún órí àpáta ní gbogbo àgbáyé!
Igbakeji adari ajọ to n ri si ọrọ iṣẹlẹ pajawiri, Seji Saji to ba BBC sọrọ, fidi rẹ mulẹ pe awọn ri oku eeyan mẹrin to ku ninu ọkọ awọn ologun lagbegbe Adjei-Kojo.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Omíyalé gbẹ̀mí èèyàn méje, o tún ba dúkìá púpọ̀ jẹ́
O ṣalaye pe awọn eeyan naa sa wọ inu ọkọ ologun lati sa asala fun ẹmi wọn ni, ṣugbọn eyi ko da iku wọn duro.
JAMB 2019: A ó fagi lé ìdànwò ẹni tó bá ṣe aṣemáṣe
Iroyin kan tiẹ sọ pe ina mọnamona gbe awọn kan ninu awọn eeyan to ku nigba ti awọn mii si rì somi.
Segalink:ìkùnsínú pọ̀ láàrin àwọn agbófinró bẹ́ẹ̀ wọn kò ni agbẹnusọ
Ṣugbọn ajọ NADMDO ni iwadii si n lọ lọwọ lori iṣẹlẹ ẹkun omi naa.
Ọ̀dọ́kùnrin tó kọ́kọ́ ṣe ẹ̀rọ tó ń tu ìyẹ́ lára adìyẹ
WAEC Result: Olùdíje kò nílò ìwé ẹ̀rí WAEC fún ìpò ààrẹ tàbí gómìnà
Oríṣun àwòrán, Faceboo/Kenyamo
Ọrọ iwe ẹri girama
Oludari ipolongo ibo aarẹ fun Aarẹ Muhammadu Buhari, amofin agba Festus Keyamo ni oludije ko nilo iwe ẹri WAEC lati dije fun ipo aarẹ tabi gomina lorilẹede Naijiria.
Keyamo to fọrọ naa lede loju opo Twitter ṣalaye pe awọn nnkan miiran wa to jẹ amuyẹ fun awọn oludije fun ipo gomina tabi aarẹ gẹgẹ bi akọsilẹ iwe ofin orilẹede Naijiria.
Keyamo ni koda ti oludije ba ti di ipo oṣelu mu fun igba pipẹ, ko nilo iwe ẹri girama mọ lati dije fun ipo kan tabi omiran.
Colorado ni Amẹrika àti odò Awaye ní Naijiria nikeji àdágún órí àpáta ní gbogbo àgbáyé!
JAMB 2019: A ó fagi lé ìdànwò ẹni tó bá ṣe aṣemáṣe
Ọrọ yii jẹ esi Keyamo si ọrọ to jẹyọ ninu eto kan lori ẹrọ amohunmaworan niluu Eko lọjọ Aiku nibi ti ẹgbẹ oṣelu ti sọ pe Aarẹ Buhari ko koju oṣuwọn lati jẹ aarẹ nitori awuyewuye to wa lori iwe ẹri WAEC rẹ.
Keyamo fi ọrọ oludije fun ipo gomina labẹ asia ẹgbẹ oṣelu PDP nipinlẹ Oṣun Ademola Adeleke ṣe apẹrẹ pe wọn gbe e lọ sile ẹjọ lori iwe ẹri WAEC bakan naa.
Amofin agba Keyamo ṣalaye pe ẹsẹ 318 ninu iwe ofin Naijiria sọ pe oludije gbọdọ ni iwe ẹri girama tabi eleyi to dabi rẹ, bakan naa o gbọdọ mọ ede oyinbo kọ ko si mọ ọ ka.
Keyamo ni ajọ WAEC ti jẹri si i pe Aarẹ Buhari ni iwe ẹri girama, ṣugbọn o ni ọrọ ko ri bẹẹ pẹlu Adeleke l'Oṣun.
Keyamo ni iwe ẹri ile iwe alakọbẹrẹ ni iwe ofin Naijiria sọ pe o tun dabi iwe ẹri girama.
O ni eleyi ti ko le jẹ itẹwọgba ni bi oludije ba ṣe ayederu iwe ẹri lati dije fun ipo oṣelu.
Cardless Withdrawal: Èyí ni àwọn ìlànà tí o le fi gbowó ní ATM láì lo káàdì
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Yatọ si 'Cardless Withdrawal, awọn ọrọ ti awọn ileefowopamọ tun maa n lo ni Cash-on-The-Go, Dial4Cash, Magic Cash, ati bẹẹbẹ lọ.
Laipẹ yii ni iroyin gbe iṣẹlẹ kan to waye niluu Ibadan nibi ti awọn araalu ti lu arakunrin kan ni adugbo Dugbẹ nitori pe wọn ri t'oun gba owo lẹnu ẹrọ 'ATM' lai lo kaadi.
Eyi jẹ iyalẹnu fun awọn eniyan wọnyii ti ko mọ pe iru eto bẹ ẹ ti wa, ti o si ṣeeṣe ki wọn l'ero pe onijibiti ni ọkunrin naa.
Koda, wọn ko lu u nikan, niṣe ni wọn tun fa a le ọlọpaa lọwọ gẹgẹ bi arufin.
Àmì ohùn ṣe pàtàkí nínú èdè Yoruba púpọ̀
Ṣugbọn ṣa, eto imọ ẹrọ̀ gbigba owo l'ẹnu ATM lai lo kaadi ti wa ni orilẹ-ede Naijiria lati ọdun 2014.
Igba naa si ni awọn onibara ileefowopamọ kan ti n lo o. Amọ, o da bi ẹni pe ọpọ ọmọ Naijiria ni ko ti i gbọ tabi mọ nipa ilana tuntun yii.
Imọ ẹrọ tuntun naa wulo lasiko ti o ba gbagbe tabi ti o ko ba mu kaadi ATM rẹ dani, ti o si nilo owo pajawiri.
JAMB 2019: A ó fagi lé ìdànwò ẹni tó bá ṣe aṣemáṣe
O le tẹle awọn ilana yii lati bẹrẹ si ni i lo ilana tuntun naa.
Oladejo Okediji àti ìgbé ayé ìtàn kíkọ rẹ̀
Ọ̀wọ́ngógó epo bẹntirò: NNPC ni 'ìròyìn ẹlẹ́jẹ̀' ni
Ọlọ́pàá gbé àwọn tó yìnbọn lu olólùfẹ́ ní Ajegunle
Kínni ife ẹ̀yẹ ti Tiger Woods gbà ní Augusta fi yàtọ́?
Parental Guidance: Ọdún méjì ni kí ẹ ti bẹ̀rẹ̀ kíkọ́ ọmọ nípa ìbálòpọ̀
Yatọ si pe o le bẹrẹ igbesẹ naa pẹlu 'App' lori ẹrọ ibanisọrọ rẹ, o tun le lo awọn aṣayan numba ti ileefowopamọ rẹ n lo lati fun ẹrọ ibanisọrọ (Fun apẹẹrẹ *111#).
Lẹyin naa, tẹle awọn igbesẹ ti o ba yẹ
Yatọ si 'Cardless Withdrawal, awọn ọrọ ti awọn ileefowopamọ tun maa n lo ni Cash-on-The-Go, Dial4Cash, Magic Cash, ati bẹẹbẹ lọ.
Ọ̀dọ́kùnrin tó kọ́kọ́ ṣe ẹ̀rọ tó ń tu ìyẹ́ lára adìyẹ
Senegal Artist: Ojojúmọ́ ni mo ń gbé àwòrán bàbá tó pọnmọ sẹ́yìn sójú pópó
Oríṣun àwòrán, Marta Moreiras
Sugbọn ni orilẹede Senegal, ayaworan kan, Marta Moreiras, ti kede pe aworan oun ti n fa oju awọn baba si isẹ ọmọ pipọn.
Marta Moreiras salaye pe oun ya aworan awọn baba to gbe ọmọ pọn sẹyin, ti oun si n gbe si oju popo ki awọn ero to n lọ, ati eyi to n bọ lee maa peju wo.
Igbesẹ yii si lo n mu ki ọpọ ero maa ya wa sidi aworan naa, , papaa awọn obinrin ti wọn si n kan saara si Marta Moreiras pe o seun.
Awọn eeyan n patẹwọ fun mi, tawọn obinrin yoo maa ni ki n bọ awọn lọwọ, ọpọ ni yoo pe ọkọ rẹ lori aago, tori kii se ojoojumọ ni wọn n ri iru aworan bayii, bi o tilẹ jẹ pe o nira lati ya irufẹ aworan yii.
Oríṣun àwòrán, Marta Moreiras
Gẹgẹ bi Marta Moreiras ti wi, ọdun 2008 ni ero yii wa si oun lọkan lasiko ti oun n wo ọkan ninu awọn aworan to wa ninu ile oun, to si ya aworan naa, ti wọn ti ya sọtọ fun ami ẹyẹ ayaworan to dantọ ti ileesẹ Sony fẹ se.
Oríṣun àwòrán, Marta Moreiras
"Ẹnu maa n ya mi lati ri ọpọ aworan awọn iya to pọn ọmọ sẹyin amọ ti ko si aworan kankan nipa awọn baba to pọn ọmọ sẹyin. Nigba ti mo si bẹrẹ si pe awọn ọrẹ mi ọkunrin lati wadi idi ti eyi fi ri bẹẹ, wọn ni awọn lee pọn ọmọ sẹyin ninu ile sugbọn awọn ko lee se bẹẹ ni ita gbangba.
Oríṣun àwòrán, Marta Moreiras
Iyapa nla lo n waye laarin inu ile ati ita yii, nitori eyi ni nkan se pẹlu oju ti awọn eeyan fi n wo wọn bi o tilẹ jẹ pe iwadi mi fihan pe isẹ nla lawọn baba n se ninu ile nidi itọju ọmọ.Nilẹ adulawọ, eewọ ni ki ọkunrin gbe ọmọ pọn sẹyin, nitori isẹ awọn obinrin ni ọmọ pipọn jẹ.
Oríṣun àwòrán, Marta Moreiras
Ìtàn Mánigbàgbé: Duro Ladipọ fi òjò àti àrá ńlá sàmì ìpapòdà rẹ̀
Oríṣun àwòrán, Yomi Duro Ogunmola
Ni awujọ awọn osere tiata, odu ni oloogbe Duro Ladipọ, kii si se aimọ fun oloko.
Bi onirese Duro Ladipọ ko si fingba mọ, eyi to ti fin silẹ ko to jade laye ko lee parun, tori pe o dabira lagbo tiata ko to jade laye.
Se bo se gbe isẹ tiata lọ soke okun ni ka sọ ni abi aimọye ere itage akọnilọgbọn to ti gbe se nigba to wa loke eepẹ.
Bi o tilẹ jẹ pe Duro Ladipọ ko si laye mọ, ọpọ awọn agba iwoyi ni ko lee gbagbe ere Ọba Koso, Sango, Ajagun Nla, Ẹda, Bode Wasinmi, ati bẹẹ bẹẹ lọ.
Gẹgẹ ba se ka lori itakun agbaye Wikipedia, itan manigbagbe gbaa ni itan igbe aye oloogbe Duro Ladipọ, eyi to yẹ ki awọn ode iwoyi fi se awokọse ati arikọgbọn gidi.
Ohun to yẹ ko mọ nipa Duro Ladipọ:
Wo àwọn nkan tí o le ṣe gẹ́gẹ́ bi aláboyún lásìkò àjàkálẹ̀ ààrùn Covid-19
Coronavirus: Kíni àwọn àmì tuntun tó n fihàn?
Wo ìmọràn tó lè jẹ kóo gbádùn ṣíṣe iṣẹ láti ilé lásìkò kónílé-ó-gbélé COVID 19 yìí
Kọ́ sí i nípa àwọn oúnjẹ aṣaralóore tó yẹ kí Aláboyún máa jẹ
Akomolede àti Aṣa: Ọ̀rọ̀ Ẹ̀yán ni Bunmi Femi Amao ń kọ́ wa lórí ètò Akọ́mọlédè àti Àṣà lóri BBC Yoruba
Contortionist: Mo lè gbé ìfun mi pamọ́ ki n tún se èémí!
Bisi Alimi: Ìyà mi rò pé n kò leè ṣe ni àmọ́ n kò ní ìfẹ́ abo ni mo ṣe fẹ́ akọ
Ọpọ ami ẹyẹ ni Duro Ladipọ gba ninu ere tiata lorilẹ-ede Naijiria ati loke okun.
Lara rẹ ni eyi to gba ni orilẹ-ede Germany nibi ajọdun isẹ ọna ti ilu Berlin lọdun 1964 ati ami ẹyẹ to gba ni ajọdun isẹ ọna Commonwealth lọdun 1965
SS3 ní mo wà báyìí, mo sì ti gba àmì ẹ̀yẹ̀ púpò nílé-lóko gẹ́gẹ́ bí onílù - Ayansike
Oríṣun àwòrán, Yomi Duro Ladipo
Oríṣun àwòrán, Yomi Duro Ladipo
Imọran BBC Yoruba lori itan manigbagbe akọni ọmọ Oodua yi:
Duro Ladipọ̀ ti wa sile aye, to si ti lọ amọ̀ ko kọ̀ja nile aye gẹgẹ bii ejo to kọja lori apata, ti ko ni ipa kankan.
Kii kuku se pe Duro Ladipọ ka iwe rẹpẹtẹ ko to se aseyọri, amọ o lo ẹbun atinuda ti Ọlọrun fun lati ta ara rẹ yọ, to si di ilumọọka lawujọ agbanla aye.
Ki ni awọn talẹnti ti iwọ naa ro pe o ni? bawo lo si se lee lo talẹnti naa fun agbega iran rẹ, ti orukọ rẹ ko si ni di igbagbe?
Eyi lo yẹ ko jẹ ibeere ti yoo jẹ wa logun, ka si lọ se awari talẹnti wa gẹgẹ bi Duro Ladipọ ti se, kawa naa le wọ inu iwe itan manigbagbe.
Omotola Jalade-Ekeinde: Olùrànlọ́wọ́ Ààrẹ Buhari fèsì sọ́rọ̀ Omotola
Oríṣun àwòrán, Facebook/Omotola
Ọgọrọ eeyan lori ayelujara lo ti n fesi sọrọ ti oṣere tiata Nollywood, Omotola Jalade-Ekeinde sọ nipa ijọba Aarẹ Muhammadu Buhari.
Omotola loju opo Twitter rẹ pe, orilẹede Naijiria dabi ọrun apaadi labẹ iṣejọba Aarẹ Buhari ati igbakeji rẹ, Ọjọgbọn Yemi Osinbajo.
Omotola wa kesi Aarẹ Buhari lati wa nnkan ṣe si airowo na to gbode kan ati awọn agbofinro ti wọn n pa awọn alaiṣẹ loorekoore ni kiakia.
O tẹsiwaju pẹlu ọrọ rẹ pe, ọrọ Naijiria ti kọja afarada bayii, o ni ibẹru bojo wa nibi gbogbo.
Ṣugbọn oluranlọwọ fun Aarẹ Buhari Bashir Ahmad fesi sọrọ Omotola, o ni ki o ye ṣaroye mọ nitori awọn ti wọn n ṣiṣẹ rowo lọna totọ ko ṣaroye, bẹẹ ni wọn ko si le sọ pe Naijiria da bi ọrun apaadi.
Ahmad ṣalaye pe laarin ọdun 2015 si 2018, aimọye biliọnu owo naira lo jade lati ilu Kano nikan nibi ọgbin irẹsi.
Sẹnẹtọ Shehu Sani kin ọrọ ti Omotola sọ lẹyin, o ni ohun ti ọpọ eeyan ti ko rọwọ họri n la kọ ja ni Omotola sọ jade.
Sẹnẹtọ Sani sọ pe eebu ti ọpọ n bu Omotola ko yi otitọ ọrọ ti o ti sọ pada.
Ọgbẹni J.J. Omojuwa ni tirẹ sọ pe, aisowo nilu ko sọ pe owo ti awọn kan fọna eru ko jọ ko si niluu, ṣugbọn anfani lati ri owo fun gbogbo eeyan ni ko si.
Omojuwa ni iṣorọ to n koju orilẹede Naijiria ko to lati di ẹbi rẹ ru ẹnikan.
Ninu ọrọ tiẹ, ajafẹtọ ọmọniyan, Deji Adeyanju ni, kii ṣe oni ni Omotola bẹrẹ si sọ otitọ. O ni gbajugbaja oṣere yii koju aarẹ ana to doloogbe Umaru Yar'ardua gan an.
Minisita tẹlẹ ri, Obi Ezekwesili ntiẹ́ rọ Omotola pe ko maa da awọn ti wọn n buu lohun. O ni aimoye lo da awọn ti wọn sọrọ sii laamu.
Ezekwesili sọ pe, Omotola lẹtọ lati sọrọ lori ohun ti ko ba tẹ lọrun gẹgẹ ọmọ Naijiria, bẹẹ lo rọ awọn ti wọn n sọrọ kobakungbe sii lati sọrọ ti wọn naa.
Ọgbẹni Reno Omokiri naa sọrọ, o ni idunkoko mọ Omotola pẹlu owo ori sisan ko ba ilana ijọba awarawa mu.
Omotola ni igbogun ti iwa ajẹbanu lawujọ ṣe pataki ṣugbọn ijọba gbọdọ rii wi pe awọn ọmọ Naijiria gbaye gbadun. O ni iṣẹ ijọba ni lati ṣejọba lọna ti yoo fi rọ ara ilu lọrun.
O fikun ọrọ pe, iru nnkan to mu ki orilẹede Amẹrika se ayipada ofin rẹ leyi, lati le ri pe awọn ọmọ orilẹede naa wa lailewu.
Omotola wa pari ọrọ rẹ bayii loju opo Twitter, nigba ti o ki gbogbo awọn eeyan ti wọn ti dasi ọrọ naa. O ni ẹbi kan naa ni gbogbo ọmọ Naijiria, ko si si ọta kankan laarin wọn.
O ni aifimọsọkan ni ọta to wa lorilẹede Naijiria, o si rọ awọn adari ijọba Naijiria pe ki wọn gbọ ohun tawọn eeayan n wi.
Ibe Kachikwu: Ọ̀nà àbáyọ sí èlé owó epo ni àtúnṣeàwọn ibùdó ìfọpo wa
Oríṣun àwòrán, Google
Minisita fun ọrọ to niise pẹlu bẹntirolu, Ibe Kachikwu ni Naira marundinlogoji lo ti gun iye owo ti lita epo bẹntirol n ba wọ orilẹede Naijiria.
Ibe Kachikwu sọ eyi lasiko to n sọrọ lori eto ‘Good Morning Nigeria’ ni ile isẹ Iroyin NTA lori ero ijọba lati yọ owo iranwọ ti ijọba n san lori epo bẹntirol.
Kachikwu ni ọwọngogo epo ati iye ti wọn n ra epo lagbaye to lọ soke, lo fa ọwọngogo epo bẹntirol ni ọdun 2016, ki o to di wi pe wọn tun bẹrẹ si ni san owo iranwọ epo.
'Èmi ò kí ń lu ìyàwó mi'
O fi kun wi pe, awọn gbọdọ fi ọgbọn se e ni, ti awọn ba setan lati yọ owo iranwọ ti ijọba n san lori epo bẹntirol nitori owo naa ti pọju fun ijọba lati ma a san ati wi pe owo ohun ti posi ba yii.
Ninu ọrọ minisita fun ọrọ epo bẹntirol naa, o ni oun to ba ni ninu jẹ ni wi pe, ti awọn ba yọ owo iranwọ, gbogbo awọn osisẹ ni yoo da isẹ silẹ , eleyii ti yoo ni ipa buburu lori ọrọ aje orilẹede Naijiria.
Kachikwu fikun wi pe, o se ni laanu wi pe awọn ti wọn n se karakata epo bẹntirol ko i tii gba gbogbo owo iranwọ ti ijọba n jẹ wọn.
Minisita naa wa ni ọna abayọ si ọrọ epo bẹntirol ni ki ile isẹ aladani gba isakoso karakata epo bẹntirol, ki ijọba si wa ọna abayọ kiakia lati tun gbogbo ile isẹ ibudo ifọpo to wa lorilẹede Naijiria se, ki wọn ye e dara le epo ti wọn n gbe wa lati ile okeere.
Oba Folagbade Olateru-Olagbegi wàjà lẹ́ni ọdún 77
Oríṣun àwòrán, Google
Ọlọ́wọ̀ ti Ọ̀wọ̀, Oba Folagbade Olateru Olagbegi CFR ti darapọ mọ awọn baba nla rẹ lẹni ọdun mẹtadinlọgọrin.
Agba Amofin lorilẹede Naijiria(SAN ) ni Ọba Ọlagbẹgi darapọ mọ awọn baba nla rẹ ni Ọjọ kẹtadinlogun, Osu Kẹrin, ọdun 2019.
Osu Keji, Ọdun 1999 ni o gori itẹ baba rẹ, amọ ọdun 2003 ni o gba ọpa asẹ ni ọwọ gomina tẹlẹri ni ipinlẹ Ondo, Olusegun Agagu.
'Èmi ò kí ń lu ìyàwó mi'
Tani Ọba Oba Folagbade Olateru-Olagbegi III waja?
Jega: Àwọn olùkọ́ fásitì sisẹ́ fáwọn olóṣèlú láti sèrú ìbò
Oríṣun àwòrán, @Prof_AJega
Alaga tẹlẹ fun ajọ eleto idibo nilẹ wa, Ọjọgbọn Attahiru Jega ti n naka aleebu sawọn olukọ ileẹkọ fasiti nilẹ wa pe awọn ni igi wọrọkọ to n da ina ru, nidi eto idibo ta sẹsẹ di ksja yii.
Jega salaye pe ọpọ awọn olukọ fasiti yii ni wsn lẹdi apo pọ mọ awọn oloselu lati se mago mago eto idibo to kọja.
Attahiru jega kede ọrọ yii lasiko ipade apero ẹgbẹ kan nilẹ Naijiria, ikẹẹdogun iru rẹ, eyi to waye nile ẹkọ fasiti Bayero nilu Kano.
Jega salaye pe awọn oloselu kan nipinlẹ Kano gan tiẹ lo awọn olukọ fasiti ọhun lati se ọpọ aise deede lasiko eto idibo 2019 to kọja yii.
Alaga tẹlẹ fun ajọ INEC naa ni o dabi ẹni pe a ko mu ipe wa gẹgẹ bii ẹni to ni imọ ati ẹkọ to yẹ ni ọkunkundun, emi ko si mọ boya awọn eeyan to ti yipada ni mo n ba sọrọ abi mo kan n sọ isọkusọ ni"""
Jega wa fikun pe orilẹede Naijiria ko ni bọ lọwọ awọn isoro ọrọ aje, aifararọ eto aabo ati aisi idagbasoke to yẹ, ti a ko ba sa ipa wa bo ti yẹ lati yan asaaju to kaato si ipo lati maa dari wa.
O dabi ẹnipe isoro kan gboogi to n mi naijiria logbologbo ni eto idibo wa to mẹhẹ, eyi tawọn eeyan ti eto naa wa nikawọ wọn ti se siba-sibo.
JAMB 2019: A ó fagi lé ìdànwò ẹni tó bá ṣe aṣemáṣe
O wa rawọ ẹbẹ si gbogbo ọmọ Naijiria lati mase maa fi ọwọ yẹpẹrẹ mu awọn ohun to ba jẹ mọ iyansipo awọn asaaju wa nitori idi ilana yii ni ọrọ wa ti wọ.
Malabu Oil Scandal: Iléẹjọ́ ní kí àwọn ọlọ́pàá, Interpol gbé wọn níbikíbi tí wọn bá wà
Oríṣun àwòrán, @Shell
Adajọ D.Zsenchi, lasiko to n gba ẹbẹ agbẹjọro ajọ EFCC to gbe ẹsun naa wa siwaju rẹ, salaye pe ibikibi ti wọn ba ti kofiri awọn afurasi naa ni ki wọn ti di wọn ni apanyaka boya lorilẹede yii ni abi loke okun.
Lara awọn afurasi tile ẹjọ ni ki wọn gbe ni tipa tikuuku lori ọrọ epo Malabu ni minisita fọrọ epo rọbi nigbakan, Dan Etete, Adajọ ati agbẹjọro agba tẹlẹ fun ilẹ wa, Mohammed Adoke pẹlu awọn eeyan miran ti wọn fi ẹsun kan pe ọwọ wọn ko mọ nidi katakara ibudo epo Malabu.
Awọn afurasi naa ni agbẹjọro ajọ EFCC, salaye pe wọn n sa nile ẹjọ lati igba ti ẹjọ naa ti bẹrẹ ni ọdun 2017 ti ajọ̀ naa ti n ba ileepo Shell, Eni Spa atawọ̀n yoku se ẹ́jọ̀.
Awọn yoku ti ọrọ naa kan ni Raph Wetzels, Casula Roberto, Pujato Stefeno, ati Burrato Sebastiano, ti wọn si gbe wọn lọ siwaju adajọ Senchi lọjọru oni, lori ẹsun pe wọn kọ lati wa yọju lori ẹsun ti wọn fi kan wọn naa.
'Èmi ò kí ń lu ìyàwó mi'
Nibi igbẹjọ to waye loni naa ni adajọ Senchi ti gbọ adura ajọ EFCC, to si ni ki wọn lọ di awọn eeyan naa wa sile ẹjọ ni tipa tipa, to si sun igbẹjọ ọhun siwaju di ọjọ Kọkanla osu Keje ọdun 2019.
Ileẹjọ giga to kalẹ si Jabi nilu Abuja ti pasẹ pe ki awọn ọlọpa lorilẹede Naijiria ati ajọ ọtẹlẹmuyẹ lagbaye lọ gbe awọn afurasi ti wọn fi ẹsun kan lori ẹsun ajẹbanu to nii se pẹlu ọrọ epo Malabu ti wọn ta nijooni.
Kenyan: Èyí ni bí wọ́n ṣe n lo Facebook lati ṣekupa awọn oníjàgídíjàgan
Ikọ kan ti wọn furasi pe o n sẹkupa awọn eniyan laarin awọn ọlọpaa orilẹ-ede Kenya, n lo Facebook lati mu ati lati pa awọn ọdọmọkunrin ti wọn gbagbọ pe wọn jẹ ọmọ ẹgbẹ onijagidijagan.
"Ọkọ meji ni mo ti padanu laarin ọdun kan,'' ni arabinrin kan sọ, t'ohun ti omije loju fun awọn araalu to pejọ sibi ipade kan to waye niluu Kayole loṣu Kẹta.
Bakan naa ni awọn miran naa tun sọ ẹri wọn, to farajọ ti ọdọmọbinrin naa.
Gbogbo wọn lo sọ pe awọn ti padanu awọn mọlẹbi, ti ọjọ ori wọn wa laarin ọdun mẹẹdogun si mẹrinlelogun.
Gẹgẹ bi ohun ti aṣoju oṣiṣẹ ajọ ajafẹtọ ọmọniyan kan, Wilfred Olal, ti ajọ Dandora Community Justice Centre sọ nibi ipade naa.
Ohun ti awọn apaniyan naa kọkọ maa n ṣe ni pe, wọn yoo fi orukọ ati aworan wọn sita lori Facebook gẹgẹ bi ọdaran.
Lẹyin naa ni wọn yoo yinbọn pa wọn lẹyin ọsẹ kan tabi oṣu kan.
Wọn yoo si fi aworan oku wọn sori Facebook bakan naa.
Oríṣun àwòrán, Facebook/Mwani Sparta
Mwani Sparta fi aworan ara rẹ sori facebook pẹlu ibọn lọwọ pẹlu awọn ọmọ ẹgbẹ Gaza yoku
Awọn aworan naa maa n fi oju ibi ti ibọn ti ba wọn han; bi agbari to fọ, ifun to tu jade, pẹlu ikilọ pe ohun ti yoo ṣẹlẹ si awọn ọdaran to ku naa niyẹn.
Ọpọlọpọ ọdọ lo n darapọ mọ ẹgbẹ naa lati le mọ boya wọn fi orukọ wọn sita. Awọn to ba ri orukọ wọn si n sa fi agbegbe naa silẹ.
Oríṣun àwòrán, Facebook/Nairobi Crime Free
Oju opo ẹgbẹ́ naa nibi ti wọn ti n ṣe ayẹwo fun awọn ọmọ ẹgbẹ́ tuntun
Awọn olugbe ilu Kayole sọ pe, oriṣiriṣi ẹgbẹ naa lo wa lori Facebook, ti wọn si maa n fi awọn aworan to banilọkan jẹ sibẹ lojoojumọ.
Oluwadi kan ni Fasiti Moi ni Kenya, to n tọ pinpin awọn ẹgbẹ naa lori Facebook fun ọdun mẹta, Duncan Omanga, sọ pe, 'awọn ọlọpaa ti wọn furasi maa n gba ọna ẹburu lati ṣewadi awọn ti wọn fẹ ẹ pa lori ayelujara.
Igbesẹ wọn naa si maa n mu ko dabi ẹnipe oju awọn ọlọpaa to ibi gbogbo ni awọn agbegbe naa ni Kenya.
Amọ ṣa, ọga agba ileeṣẹ ọlọpaa Kenya nigba kan sọ pe, ẹni to wa nidi awọn ẹgbẹ naa lori Facebook kii ṣe ọlọpaa, ṣugbọn araalu ti ọrọ aabo ilu ka lara ni.
Ẹ̀mí kan náà ló n darí ìrìnàjò wa táa fi jọ kọ́lé papọ̀- Ìbejì
Igbagbọ awọn kan ni pe, bi wọn ṣe n gbe awọn olowo ti wọn fura si pe wọn n ji owo ori lọ sile ẹjọ, naa lo ṣe yẹ ki wọn maa fun awọn ọdọ naa ni anfaaani lati sọ awijare wọn lori ẹsun ti wọn ba fikan wọn.
Alan García: Ààrẹ Peru nígbà kan gbẹ̀mí ara rẹ̀
Oríṣun àwòrán, AFP
Wọn fi ẹsun kan García pe o gba owo ẹyin lọwọ ileeṣẹ abanikọle kan to jẹ ti Brazil.
Aarẹ orilẹede Peru nigba kan, Alan García ti gbẹmi mi lẹyin to yinbọn mọ ara rẹ lasiko ti awọn ọlọpaa de si ile rẹ lati mu u fun ẹsun riba gbigba.
Ọgbẹni García ti wọn sare gbe lọ sileewosan ni olu ilu orilẹede naa, ko to o di pe o jade laye.
Aarẹ orilẹede naa lọwọlọwọ, Martin Vizcarra ti fidi iku rẹ mulẹ.
Wọn fi ẹsun kan García pe o gba owo ẹyin lọwọ ileeṣẹ abanikọle kan to jẹ ti Brazil, Odebrecht - amọ o ni oun ko jẹbi ẹsun naa.
Minisita fun ọrọ abẹle, Carlos Morán sọ fun awọn akọroyin pe Ọgbẹni García tọrọ aaye lati pe ẹnikan lori ẹrọ ibanisọrọ nigba ti awọn ọlọpaa de ile rẹ, to si wọ inu yaara kan lọ.
Lẹyin iṣẹju diẹ ni ìró ibọn dun.
Eyi lo si mu ki awọn ọlọpaa ja ilẹkun yaara naa, ti wọn si ba Ọgbẹni Gracía to joko sori aga kan t'ohun ti ọgbẹ ọta ibọn ni ori rẹ.
BBC Women's Footballer of the Year 2019: Wo bí o ṣe lè dìbò yan ẹni ti o bá fẹ́
Lucy Bronze ara England, ni ife ẹyẹ naa ṣi wa lọwọ ẹ bayii
Wọn ti fi orukọ awọn oludije ife ẹyẹ BBC fun agbabọọlu obinrin to pegede ju lọdun 2019 hande o si lee dibo yan ẹni ti o f ko jawe olubori bayii.
Akojọpọ awọn akọṣẹmọṣẹ bii adari ere bọọlu, awọn agbabọọlu, awọn alabojuto ere bọọlu atawọn oniroyin lo yan awọn oludije marun un ti ile iṣẹ BBC yoo gbade fun.
Awọn ti wọn yan naa ni:
Ọjọ keji ọjọbọ oṣu karun ni gbedeke ọjọ ti idibo yoo wa sopin (09:00 BST, 08:00 GMT) ti wn yoo si kede ẹni to ba jawe olubori lọjọ kejilelogun oṣu karun loju opo agbaye BBC World Service ati lori itakun ere idaraya ti BBC, BBC Sport.
Ẹ le tẹ ibi yii lati dibo.
Oun ti ẹ le fẹ mọ sii nipa awọn to n figagbaga ree
Oríṣun àwòrán, Reuters
Pernille Harder
Ọjọ́ orí: 26
Orílẹ̀èdè: Denmark
Iye ìgbà tí ó ṣójú orílẹ̀èdè rẹ̀: 110
Ẹgbẹ́ agbábọ́ọ̀lù: VFL Wolfsburg
Ipò: Ọwọ́ iwájú (Forward)
Oríṣun àwòrán, RONNY HARTMANN
Ada Hegerberg
Ọjọ́ orí: 23
Orílẹ̀èdè: Norway
Iye ìgbà tí ó ṣójú orílẹ̀èdè rẹ̀: 66
Ẹgbẹ́ agbábọ́ọ̀lù: Olympique Lyonnais
Ipò: Ọwọ́ iwájú (Forward)
Oríṣun àwòrán, MARK RALSTON
Lindsey Horan
Ọjọ́ orí: 24
Orílẹ̀èdè: USA
Iye ìgbà tí ó ṣójú orílẹ̀èdè rẹ̀: 62
Ẹgbẹ́ agbábọ́ọ̀lù: Portland Thorns
Ipò: Ọwọ́ àárín (Midfielder)
Oríṣun àwòrán, DANIEL POCKETT
Sam Kerr
Ọjọ́ orí: 25
Orílẹ̀èdè: Australia
Iye ìgbà tí ó ṣójú orílẹ̀èdè rẹ̀: 67
Ẹgbẹ́ agbábọ́ọ̀lù: Perth Glory and Chicago Red Stars
Ipò: Ọwọ́ iwájú (Forward)
Oríṣun àwòrán, FRANCK FIFE
Saki Kumagai
Ọjọ́ orí: 28
Orílẹ̀èdè: Japan
Iye ìgbà tí ó ṣójú orílẹ̀èdè rẹ̀: 102
Ẹgbẹ́ agbábọ́ọ̀lù: Olympique Lyonnais
Ipò: Agbá 'wájú ilé mọ́ ọwọ́ ààrín  (Defender/defensive midfielder)
Intersex: Abiyamọ ní dókítà kò leè sọ bóyá akọ ni ọmọ òun àbí abo
Ni ile aye ta wa yii, akọ ati abo ni ẹda lee jẹ amọ ti iyalẹnu maa n wa, ta ba ri ẹnikan ti kii se akọ abi abo.
Ni ọpọ igba ni ọba oke maa nda ara to ba wu, ti yoo si mu ki eeyan kan ni oju ara ti ọkunrin ati obinrin papọ eyi ti awọn oloyinbo n pe ni 'Hermaphrodites'.
Bẹẹ ni ọrọ ri fun obinrin yii, Catherine (kii se orukọ rẹ gangan niyi), ẹni ti dokita ko fi ẹnu sọ boya ọkunrin lo bi abi obinrin lẹyin ọjọ marun un to ti bimọ,
amọ to fi ami ibeere si ori iwe to fi yẹ ko sọ iru ẹda ti ọmọ obinrin naa n se.
Nigba to dele, ni iya ọmọ tuntun ba pe aladugbo rẹ pe ko wa wo ọmọ oun, ko si sọ boya ọkunrin abi obinrin, sugbọn dipo ki aladugbo yii fọhun, n se lo gba Catherine ni imọran lati lọ sile iwosan.
Idi ree ti abiyamọ yii ati ọkọ rẹ fi morile ile iwosan ijọba kan ni ilu Nairobi, lorilẹ-ede Kenya, nibi ti wọn ti gbọ pe ọmọ to ni nkan ọkunrin ati obinrin ni wọn bi, ti dokita si gba wọn niyanju lati wa se isẹ abẹ, ki ọmọ naa le di ọkunrin nitori nkan ọkunrin to wa lara ọmọ naa lagbara ju ti obinrin lọ.
Osinbajo yẹ́ Woli Arole sí níbi ìṣíde The Call"""
"Obinrin naa ni ""Lati igba yii ni ọkọ mi ko ti fi owo ounjẹ silẹ fun mi mọ, to si n fa sẹyin lati ba mi sere tabi sọrọ. Nigba miran, yoo pariwo mọ mi pe ko si ọmọ to ni iru oju ara akọ ati abo bẹẹ ninu iran oun, yoo si dara ki n gbe ọmọ naa pada si ibi ti mo ti gbe wa."""
Ọkọ mi bẹrẹ si ni kan mi ni abuku, o ni asẹwo ni mi, to si n sọ fun mi pe oun kọ ni oun ni ọmọ naa, oun ko mọ ibi ti mo ti rii
Catherine ni aye su oun, ti ọkan oun si daru. Idi ree ti oun fi ra oogun to n pa eku lati gbe majele jẹ, ki oun kuku ku danu.
O po oogun eku naa mọ ẹwa to fẹ jẹ, ko le pa ara rẹ ati ọmọ tuntun naa, sugbọn nigba to ku diẹ ko gbe oogun naa jẹ, lo ba yi ọọkan rk pada, to si gba ile ijọsin kan lọ lati lọ ri Olusọaguntan ibẹ.
"Pasitọ naa fi mi lọkan balẹ pe Ọlọrun wa pẹlu mi, ti ko si fi mi silẹ ninu wahala naa, ati pe a ko ri iru eyi ri, ẹru la n da ba ọlọrọ.
Pasitọ ni kii se iru ọmọ mi nikan lo wa ni agbaye, iru awọn eeyan to ni nkan ọkunrin ati obinrin sun janti rẹrẹ, kii si se iwa ẹsẹ mi lo mu ki n bi ọmọ naa."
Inu wahala yii ni obinrin ti ko jade kuro nile ọkọ rẹ lẹyin osu kan pere to bimọ, to si n lọ gbe lọdọ ẹgbọn rẹ obinrin kan pẹlu ọmọ rẹ laisi owo kankan ti yoo fi tọju ọmọ ọhun.
Catherine wa isẹ se ni ile itọju ọmọ wẹwẹ, to si pinnu lati wa owo fun isẹ abẹ ọmọ naa, ni awọn isoro miran ba tun yọju lẹyin ọdun kan.
Olusegun Obasanjo: Ọmú ìyá mi ti mo fi ń mùkọ ni kekere ló jẹ ki ń lókun
Isoro akọkọ ni pe ko lee fi ọmọ naa sile iwe nitori pe ko mọ boya ọkunrin ni ki oun pe abi obinrin, bẹẹ ni iwe ọjọ ibi to yẹ ko mu silẹ, ni dokita to gbẹ bi rẹ ti fi ami ibeere siwaju alafo ti wọn ti fẹ mọ boya ọkunrin ni ọmọ naa abi obinrin.
Se oriire ni gbe alawore ko ni, asiko yii ni Catherine pade agbẹjọro ajafẹtọ ẹni kan, John Chigiti, ẹni to gbe ọrọ yii lọ sile ẹjọ.
Àlàyé rèé lóríi ìdí tí wọ́n fi ń pe aya ní ìyàwó
Lóòtọ́ lò n lo ìbomú-bẹnu, ṣùgbọ́n ṣe bóṣeyẹ kí o wọ̀ ọ́ ló ṣe n ṣe?
East Africa: Àwọn kokoro ti ba èrè oko jẹ nílẹ̀ Afirika
Eyi ni isẹlẹ to waye ni Kenya, amọ nigba wo ni iru idajọ yii yoo waye ni Naijiria?
Ibadan Tanker Fire Accident: Ṣúnkẹrẹ fàkẹrẹ gbalẹ̀ lẹ́yìn ìjàmbá ọkọ̀ epo
Ibadan Tanker Fire Accident: Ènìyàn méji ló kú nínú ìjàmbá ọkọ̀ agbépo
Ẹni to ba jẹ ori ahun, yoo sunkun lọsan Ọjọbọ nilu Ibadan, nigbati ọkọ agbepo kan dede ṣubu ni agbegbe Sawmill-Iwo Road lopopona marosẹ Eko si Ibadan.
Ni dede aago meji kọja iṣẹju diẹ lọsan ni iṣele naa ṣẹlẹ, eyi taa gbọ pe o mu ẹmi eeyan meji lọ, awọn eeyan mejeeji yii, ti wọn jẹ ọkunrin ati obinrin si lo jona ku egungun ninu ijamba naa.
Nitori isẹlẹ yii, se ni adugbo Iwo Road di pa, ti ọ̀pọ̀ ero si n fi ẹsẹ rin, nigba ti awọn ọlọkọ to n rin irin ajo bọ lati awọn ilu miran ha sinu sunkẹrẹ fakẹrẹ ọkọ fun ọpọ wakati, ti ohun gbogbo si dẹnu kọlẹ lagbegbe naa. Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí:
Oṣojumi-koro kan fi to awọn BBC Yoruba leti wi pe jala epo bii ẹgbẹrun marundinlaadọta ni ọkọ epo naa gbe, ki o to dede ṣubu laarin ọna.
Ọgbẹni Adeleke Isiaka, ti o jẹ aṣoju ajọ panapana ipinlẹ Ọyọ fi ẹsun kan wi pe, awọn alaigbọran kan to sare lati gbọn epo bentiro to n jo danu pẹlu oniruuru ohun elo ipọnmi, lo ṣokunfa iṣẹlẹ naa.
Adeleke fi kun ọrọ rẹ wi pe ẹmi eeyan meji ọtọọtọ (ọkunrin kan ati obinrin kan) lo ba iṣẹlẹ naa lọ.
Nibayii, igbokegbodo ọkọ ti bẹrẹ pada ni opopona naa, lẹhin ti wọn bomi pa ina ọhun, ti awọn ẹṣọ abo oju popo si n se akoso awọn ọkọ to n lọ to n bọ lagbegbe naa.
Onnoghen: CCT ní Onnoghen kò gbọdọ̀ di ipò ìlú mú fún ọdún mẹ́wà
Oríṣun àwòrán, Nigeria Bar association
Adajọ agba Onnoghen ni oun ko jẹbi
Igbimọ to n gbọ ẹsun to ni i ṣe pẹlu ihuwasi lawujọ, CCT ti sọ pe, lootọ ni adajọ agba Naijiria nigba kan, Walter Onnoghen, jẹbi ẹsun ṣiṣe mago-mago ninu dukia rẹ to kede.
Onnoghen n koju iwadi nitori ẹsun ti wọ̀n fi kan an pe o parọ́ ninu dukia to kede pe oun ni gẹgẹ bi adajọ agba orilẹede Naijiria.
Igbimọ ẹlẹni mẹta naa tun sọ pe, Onnoghen ko gbọdọ di ipo ilu kankan mu fun ọdun mẹwaa, ati pe ko gbagbe gbogbo owo to ni si apo aṣunwọn maarun nileefowopamọ.
Wọn ni owo naa ti di ti ijọba apapọ Naijiria.
Bakan naa ni alaga igbimọ naa, Danladi Umar to ka idajọ sita sọ pe ki Onnoghen fi ipo rẹ gẹgẹ bi alaga Igbimọ Idajọ ni Naijiria, CJN, to fi mọ Alaga ajọ to n mojuto ọrọ awọn oṣiṣẹ lẹka idajọ.
Minimum Wage: Ààrẹ Buhari ti buwọ́lu #30,000 owó oṣù òsìsẹ́
Oríṣun àwòrán, PIUS UTOMI EKPEI
Iye owo oṣu oṣiṣẹ́ jẹ nnkan ti o n kọ ọpọ oṣiṣẹ lominu ni Naijiria
Aarẹ Muhammadu Buhari ti buwọlu eto owo oṣu tuntun fun awọn oṣiṣẹ ijọba.
Awọn ileeṣẹ iroyin l'abẹle jabọ pe l'oni ọjọ kejidinlogun oṣu Kẹrin ni Aarẹ Buhari buwọlu ofin naa lati maa san ọgbọn ẹgbẹrun Naira gẹgẹ bi owo oṣu to kere ju fun oṣiṣẹ.
Tẹ ẹ ba gbagbe, oṣu Kẹta ọdun 2019 ni ile aṣofin agba buwọlu owo naa ti ijọba apapọ ati ti ipinlẹ gbọdọ maa san fun awọn oṣiṣẹ wọn.
Eyi waye lẹyin ti igbimọ to jiroro lori ọrọ naa gbe abọ ijiroro rẹ sita.
Botilẹjẹ wi pe ẹgbẹrun mẹtadinlọgbọn ni igbimọ naa gba ijọba niyanju lati maa san, ọgbọn ẹgbẹrun Naira ni awọn aṣofin fi ọwọ si.
Minimum wage tuntun kò túmọ̀ sí pé #30,000 ni yóò gun owó oṣù rẹ - Bismark Rewane
Oríṣun àwòrán, NLC
Aworan awọn oṣiṣẹ
Alaga igbimọ amusẹya to gba ijọba apapọ Naijiria nimọran lori ọna ti wọn yoo gba sanwo oṣu tuntun fun awọn oṣiṣẹ, Bismark Rewane, sọ pe kii ṣe gbogbo owo ti oṣiṣẹ n gba ni ẹkunwo naa yoo ba.
O ṣalaye pe kii ṣe gbogbo eniyan ni ẹgbẹrun lọna ọgbọn Naira naa yoo kan.
''Awọn ti owo oṣu wọn ju ẹgbẹrun lọna ọgbọn Naira lọwọlọwọ yoo kan gba ẹkunwo kekere ni.''
Fun apẹẹrẹ, lọdun 2011, gbogbo oṣiṣẹ ijọba to n gba ju ẹgbẹrun mejidinlogun Naira lọ  gba ẹkunwo ẹẹdẹgbẹrun Naira pere.''
Ṣugbọn nigba ti akọroyin BBC beere lọwọ rẹ pe eelo ni ẹkunwo kekere ti yoo gun ori owo oṣu, o kọ̀ lati sọrọ.
Rewane tẹsiwaju ninu àlàyé naa pe, ilana ti igbimọ gba ni lati sọ owo oṣu gbogbo awọn ti ko to ẹgbẹrun lọna ọgbọn Naira si ẹgbẹrun lọna ọgbọn Naira. ''Ṣugbọ̀n ijọba apapọ ati ipinlẹ ni ilana ọtọọtọ ti wọn yoo gbe e gba.''
Oríṣun àwòrán, Presidency
Onimọ nipa eto ọrọ-aje ati owo nina ni Ọgbẹni Bismark Rewane
Bakan naa ni Ọgbẹni Rewane sọ pe lootọ lo ṣeeṣe ki owo gun iye ti wọn n ta awọn nkan l'ọja, amọ ko ni ni ipa ti ko dara lara owo to n wọ apo oṣiṣẹ.
Ati wi pe awọn anfaani tuntun ninu eto ọrọ-aje ti igbimọ naa tọka si fun ijọba apapọ tumọ si pe owo yoo pọ si niluu.
Aarẹ Buhari lasiko to bu ọwọ lu owo oṣu tuntun naa l'Ọjọbọ ṣalaye nipasẹ oluranlọwọ rẹ lori ọrọ ile aṣofin apapọ, Ita Enang, pe l'oju ẹsẹ ni sisan owo oṣu tuntun naa bẹrẹ.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ọgbẹni Enang sọ fun awọn oniroyin pe awọn ti ko ni ju oṣiṣẹ mẹẹdọgbọn lọ nikan ni owo oṣu tuntun naa yọ silẹ.
"Fun awọn ipinlẹ, Ọgbẹni Rewane sọ pe ""ilana ti igbimọ naa gbe igbesẹ naa gba yoo mu ko rọrun fun wọ̀n lati sanwo naa ju ijọba apapọ lọ, ti wọn ba le naa owo wọn pẹlu eto to yẹ."""
O ni ohun to da oun l'oju ni pe orilẹede Naijiria yoo dun n gbe ti ijọba ba le tẹle awọn nkan ti igbimọ amuṣẹya naa gba a nimọran.
Church Wall Collapse: Ògiri ṣọ́ọ̀ṣì wó pa àwọn olùjọ́sìn 13 nílé ìjọsìn South Afrika
Oríṣun àwòrán, AFP
Awọn olujọsin ẹlẹsin Kristẹni mẹtala kan  ti padanu ẹmi wọn ni South Afrika.
Iṣẹlẹ yii waye nigba ti ogiri wo pa wọn nile ijọsin ti wọn ti n kopa ninu ijọsin ọjọ ọjọbọ mimọ rere lasiko ọdun ajinde.
Awọn oṣiṣẹ pajawiri ni eeyan mọkandilogun miiran lo farapa ti awọn si ti gbe wọn lọ si ile iwosan.
Awọn alaṣẹ lagbegbe KwaZulu Natal fi idi ọrọ yii mulẹ ti wọn si ni ojo arọda lagbegbe Empageni lo jọ bi ẹ ni ṣe okunfa bi ogiri ile ijọsin ijọ igbalode naa ti ṣe wo lulẹ.
Agbẹnusọ ile iṣẹ ọlọpaa KwaZulu Natal Thembeka Mbele sọ pe atẹgun ojo lile fẹ ni agbegbe naa lalẹ ọjọbọ.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Iroyin lati agbegbe naa so pe awọn eeyan kan n sun lọwọ nigba ti ogiri naa ya lu wọn.
Awọn olori ijọ ti ba awọn eeyan agbegbe naa kẹdun iṣẹlẹ laabi ọhun.
Leicester best player award: Iheanacho, Ndidi yóò jọ du àmì ẹ̀yẹ Leicester City
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Wọn ti fi orukọ ọmọ orilẹede Naijiria, Wilfred Ndidi ati Kelechi Iheanacho silẹ fun ami ẹyẹ agbabọọlu Leicester City to tayọ ju ni saa yi (Player of the Season).
Bakan naa ni wọn fi orukọ wọn silẹ fun ami ẹyẹ ọdọmọde agbabọọlu to tayọ (Young Player of the Season).
Orukọ Ndidi ati Iheanacho wa lara awọn ti wọn fi orukọ wọn silẹ lori itakun ayelujara ikọ agbabọọlu Leicester City fun ami ẹyẹ mejeeji.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ndidi kopa ninu idije mẹrinlelọgbọn ni saa Premier League to n lọ lọwọ, to si gba bọọlu sinu awọn lẹẹmeji.
Ndidi ti gba ami ẹyẹ ọdọmọde agbabọọlu to dantọ julọ fun saa meji lẹyin to darapọ mọ Leicester lati KRC Genk ti Belgian Jupiler League.
O si ti kopa ninu idije mẹrinlelọgbọn ni saa Premier League to n lọ lọwọ, to si gba bọọlu sinu awọn lẹẹmeji.
Amọ ṣa, ko si eyi to wọ ipele ami ẹyẹ goolu to dara ju ni saa yii ninu awọn mejeeji.
Ni ti Iheanacho, o ti kopa ninu idije mejidinlọgbọn ni saa yii fun Leicester, o si gba bọọlu sinu awọn lẹẹkan ṣoṣo.
Awọn agbabọọlu mii yoo dije fun ami ẹyẹ 'Young Player of the Season' ni  Demarai Gray, Harvey Barnes, Youri Tielemans, Ben Chilwell, James Maddison, Filip Benković, Çağlar Söyüncü ati Hamza Choudhury.
Nigba ti Daniel Amartey, Nampalys Mendy,Wes Morgan, Danny Simpson, Rachid Ghezzal, Shinji Okazaki, Harry Maguire, Filip Benković, Matty James, Ricardo Pereira, Adrien Silva ati Çağlar Söyüncü yoo dije fun ami ẹyẹ agbabọọlu to dara julọ ni saa yii.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Papa iṣere Leicester City, King Power ni gbigba ami ẹyẹ naa yoo ti waye
Bakan naa ni Hamza Choudhury, Youri Tielemans, Ben Chilwell, Demarai Gray, Marc Albrighton, Danny Ward, Harvey Barnes, Jamie Vardy, Andy King, Kasper Schmeichel, Christian Fuchs, Jonny Evans, Fousseni Diabaté ati James Maddison yoo kopa.
Ọjọ keje oṣu Karun ni wọn yoo kede awọn to jawe olubori ni papa iṣere King Power l'opin saa yii.
Tanko Muhammad: Ààrẹ Buhari fikún sàá Muhammad Tanko nípò adelé adájọ́ àgbà
Oríṣun àwòrán, AsoRockVilla
Aa Buhari yan Tanko Ibrahim lati dele de adajọ Onnoghen
Iroyin kan ti a ko ti i fi bẹẹ fi mulẹ sọ pe Aarẹ Muhammadu Buhari ti fi oṣu mẹta kun ọjọ to yẹ ki adele Adajọ Agba Naijiria, Tanko Muhammad lọ n'ipo.
Oluranlọwọ pataki fun Aarẹ Buhari lori ibaraẹnisọrọ igbalode, Bashir Ahmed loju opo Twitter rẹ fidi iroyin naa mulẹ.
Oṣu Kinni ọdun 2019 ni aarẹ yan Muhammad lẹyin to paṣẹ fun Adajọ Agba tẹlẹ, Walter Onnoghen lati lọ rọọkun nile nitori ẹsun ṣiṣe mago-mago lasiko to kede dukia rẹ gẹgẹ bi adajọ agba.
Onnoghen jẹ̀bi ẹ̀sùn tí wọ́n fi kàn án, ó pàdánù owó rẹ̀
Kò tọ̀nà láti gbé adájọ́ Onnogben lọ síwájú CCT - Adájọ́ fẹ̀yìntì
Ọjọ kejidinlogun oṣu Kẹrin si ni igbimọ to n gbọ ẹjọ naa, CCT, sọ pe o jẹbi ẹsun naa, ti wọn si fi ofin de e pe ko ma di ipo ilu mu fun ọdun mẹwaa.
Onnoghen sọ pe oun ko jẹbi.
Armed Robbery: Ọmọ Nàìjíríà mẹ́jọ gba ìdájọ́ ikú ní UAE
Oríṣun àwòrán, @TosinadedaMedia
Awọn adigunjale
Ijọba orilẹede United Arab Emirate ti dajọ iku gbere fun ọmọ Naijiria mẹjọ lori ẹsun idigunjale.
Olugbani nimọran pataki fun aarẹ Naijiria lori ọrọ ilẹ okere atawọn ọmọ Naijiria to wa loke okun, Abike Dabiri-Erewa ti ṣapejuwe idajọ iku yii bi eyi to ṣe ni laanu jọjọ.
Ile ẹjọ to n gbẹjọ awọn ọdaran eyi to wa ni Sharjay ni UAE lo dajọ iku fawọn mọ Naijiria mẹjọ yii fun ẹsun ti wọn pe ni idigunlejale onipele pupọ (string of armed robbery).
Wọn ni wọn ji ọpọlọpọ nkan ni ajọ to n ri si pasiparọ owo ilẹ okere, wọn ji owo ni ẹrọ ATM atawọn ibomii ni orilẹede naa ni oṣu kejila ọdun 2016.
Abikẹ Dabiri: Iṣẹ́ pọ̀ lọ́wọ́ Naptin àti àwọn aṣọ́bodè Nàìjíríà
Gẹgẹ bi ile iṣẹ iroyin kan ni UAE, Khaleel Times ṣe jabọ lọjọbọ ọṣẹ yii, ẹni to y ko ṣe ikẹsan wọn kan fi wọn oṣu mẹfa gbara ni tori owo ti wọn ji wa lọ́wọ́ rẹ.
Wọn yoo lee kuro pada wa si Naijiria to ba jiya ẹṣẹ rẹ tan lẹwọn.
"Ninu ọrọ ti arabinrin Dabiri-Erewa sọ fun ile iṣẹ iroyin Naijiria kan, o ni ""iṣẹlẹ to ṣe ni laanu ni, ṣugbọn kii ṣe iṣẹlẹ to juwe iru eniyan ti a jẹ""."
Ile ẹjọ fi ẹsun idigunjale, fifi ipa da araalu laamu ati fifi ipa lọni lọwọ gba. Nigba ti awọn kan lara awọn ọdaran yii jẹwọ ẹṣẹ wọn, awọn kan ni awọn o jẹbi ẹsun naa.
Iwe iroyin English newspaper ni orilẹede UAE ni ọkan lara awọn ọdaran naa tilẹ ni oun ṣi le pe ẹjọ mii lori ẹjọ ni ile ẹjọ kotẹmilọrun ti idajọ ti wọn fun oun yoo si dinku si ẹwọn gbere dipo idajọ iku.
Meghan and Harry: Ohun tó yẹ kí o mọ̀ nípa ọmọ ọba tí wọ́n fẹ́ bí
Oríṣun àwòrán, AFP
Lẹyin oṣu mọkanla ti wọn ṣe igbeyawo, Ọmọ ọba Sussex ati aya rẹ,  Harry ati Meghan n reti ọmọ tuntun laipẹ.
Kinni a mọ nipa ọmọ ọba tuntun Ilẹ Gẹeṣi to n bọ yii?
Nigba wo ni wọn yoo bi ọmọ yii?
Ohun to ku ni lati maa foju sọna si igba ti ọmọ naa yoo de.
Oríṣun àwòrán, Omo obabinrin Cambridge
Ta lo mọ!
Ẹnikan ko tii mọ boya akọ tabi abo ni wọn yoo bi nitori wọn ko tii figba kan sọ iru ọmọ to wa ninu Meghan.
Meghan ti sọ fun awọn ololufẹ nigba to ṣabẹwo si agbegbe Merseyside pe awọn ko tii mọ boya akọ tabi abo lọmọ to wa ninu oun.
Nibo ni Meghan yoo bimọ si?
Ṣe ẹ ranti bi Ọmọ ọba William ati aya rẹ Catherine ṣe n jade lati ile iwosan St Mary's niluu London?
Oríṣun àwòrán, Samir Hussein
Awọn iwe iroyin kan sọ pe o ṣeeṣe ki Ọmọ ọba Harry ati aya rẹ maa bimọ sibẹ nitori ailefarapamọ nile iwosan ọhun.
Oríṣun àwòrán, Graham Prentice/Alamy
N jẹ ẹnikan mọ orukọ ọmọ yii?
Ibeere nla leyi, ko si ilana fun orukọ awọn ọmọ ọba Ilẹ Gẹẹsi.
Oríṣun àwòrán, Martin Keene/PA
Orukọ baba rẹ n kọ?
Ọmọ yii le maa nilo orukọ baba rẹ nitori ọmọba tabi ọmọbabinrin ni yoo maa jẹ nigba ti wọn ba bii.
N jẹ ọmọ yii le di ọba ile Gẹẹsi lọjọ iwaju?
Oríṣun àwòrán, Tim Graham
Bẹẹ ni ṣugbọn awọn ọmọ ọba mẹfa lo wa nilẹ siwaju rẹ ti awọn naa le jọba.
Njẹ ọmọ yii le jẹ ọmọbibi ilẹ Amẹrika?
Oríṣun àwòrán, James D. Morgan
Bẹẹ ni, nitori ọmọ ilẹ Amẹrika ṣi ni mama rẹ Meghan, fun idi eyi, ọmọ naa laṣẹ lati jẹ ọmọbibi orilẹede Amẹrika.
Bakan naa, ọmọ yii yoo laṣẹ lati jẹ ọmọ orilẹede meji nitori baba rẹ Harry jẹ ọmọ ilẹ Gẹẹsi.
Nigeria Election Update: 'Ilé iṣẹ́ DSS kò mú òṣìṣẹ́ INEC kankan lórí ẹ̀sùn Atiku'
Irọ ni wọn n gbe kiri! Ajọ ọlọpaa ọtẹlẹmuyẹ lorilẹede Naijiria, DSS ti sọ pe iroyin ofege lawọn kan n gbe kaakiri pe ajọ naa ti mu awọn oṣiṣẹ ajọ eleto idibo INEC kan.
Iroyin to lu oju ayelujara pa ni pe awọn oṣiṣe INEC fun oludije fun ipo aarẹ labẹ asia ẹgbẹ oṣelu PDP Atiku Abubakar lanfani lati ri awọn ohun elo idibo aarẹ lori ẹrọ kọmputa INEC.
Ninu atẹjade ti ile iṣẹ DSS fi sita, eyi to si loju opo Twitter ajọ INEC, DSS ni ko si otitọ kan ninu iroyin miran to tun sọ pe ajọ na mu oṣiṣẹ INEC meja, wọn si fiya jẹ wọn fun ọjọ mẹta ki wọn le jẹwọ bi ọrọ naa ṣe jẹ gan an.
Helen Paul sọ idi tó fi gba orúkọ ní kékere
Hakeem: Mo lè sọ arúgbó dí ọmọge nígbà tó bá wù mí
Atiku ti sọ tẹlẹ pe oun ṣetan lati kọwọ rin pẹlu awọn akọṣẹmọṣẹ onimọ ẹrọ Kọmputa lọ sibi igbẹjọ lori idibo aarẹ to kọja lọ ti o pe.
Bẹẹ lo sọ pe awọn eeyan ni wọn yoo fidi nọmba ẹrọ kọmputa to sọ pe ajọ INEC fihan oun nibi to ni oun ti rii pe PDP lo jawe olubori ninu ibo aarẹ to lọ.
Ọgbẹni Peter Afunanya to buwọ lu atẹjade DSS ti INEC fi sita sọ pe awọn ti wọn fẹ da rogbodiyan silẹ ni wọn n gbe iru iroyin ofege yii kaakiri.
O rọ awọn ọmọ Naijiria lati kọ eti ikun si iroyin naa.
Marina-Eko Bridge: Ìjọba gbóṣùbà fún àtìlẹyìn aráàlú lásìkò tí wọn ti afárá méjèèjì pa
Oríṣun àwòrán, Federal government
Ijọba apapọ Naijiria ti kede pe afara Marina ati Eko yoo di sisi pada lati ọjọ Aje ọla.Atẹjade kan ti wọn fisita nilu Abuja lo sísọ loju ọrọ yii pẹlu afikun pe, iṣẹ atunse afara mejeeji naa ti buse.Atẹjade ọhun tun salaye pe iṣẹ atunse yoo bẹrẹ lọgan loju ọna Alaka, tijọba si tun gboriyin fáwọn araalu fun atilẹyin ati suuru wọn lasiko ti isẹ atunse naa n lọ lọwọ.
Bẹẹ ba gbagbe, lati oṣù kẹta ọdun 2020 nijọba apapọ ti ti afara Eko pa lati ṣe atunse rẹ ko to dẹnu kọlẹ.
Ki lo ti ṣẹlẹ sẹyin?
Awọn awakọ ati awọn arinrinajo ti bẹrẹ si ni fi ero wọn han lori ẹrọ ayelujara nitori inira ti wọn la kọja lori afara Third mainland ti ijọba ti.
Alẹ Ọjọ Ẹti ni ijọba ti afara naa ni ọna mẹjeeji amọ ti wọn si fi alakalẹ lede lori igba ati akoko ti awọn eniyan yoo fi le ma a raaye kọja nibẹ ni ojoojumọ.
Ọpọlọpọ awọn to faraya ninu awọn eniyan naa sọ wi pe owo ọkọ wọn, ati wi pe awọn ibi ti wọn n gbe ni igba Naira tẹlẹ, awọn awakọ ti sọ di ẹgbẹrun Naira kan.
Bakan naa ni awọn eniyan ke irọra pẹlu sunkẹrẹ-fakẹrẹ ọkọ ti awọn ọlọkọ ajagbe da silẹ ni ọpọpọna afara Eko Bridge ni ibi to tun yẹ ki awọn eniyan ma a gba kọja.
Ninu ọrọ tirẹ, Ogbeni Dami ni awọn ole ti bẹrẹ si ni ṣọṣẹ lori afara third mainland naa ati awọn ọna miran ti ijọba lakalẹ fun awọn eniyan lati ma a gba.
Nitori naa ni wọn ṣe ke gbajare si ijọba ipinlẹ Eko lati ri pe eto aabo gbokun si lasiko yii nitori awọn janduku yoo mu aye le fun awọn eniyan lasiko ti wọn ba n wa ọna ati jẹ ati mu lọ.
Awọn miran ti lẹ fi awọran bi awọn eniyan ṣe pejọ si papakọ BRT ti awọn eniyan ti fẹ wọ ọkọ ni agbegbe Ikorodu, ti wọn si tun fihan pe ko si yiyago fun ara ẹni laaarin awọn eniyan to n tiraka lati wọ ọkọ.
Amọ, a ri awọn miran to sọ wi pe inu wọn dun si afara thrid mainland ti ijọba ti naa nitori ọpọlọpọ ileeṣẹ lo ti wa paṣẹ fun awọn oṣiṣẹ wọn lati ṣiṣẹ lati ile, eleyii to mu irọrun ba awọn eniyan.
Ijọba apapọ ni idi fi awọn fi ti afara third mainland naa ni lati ṣe atunṣe oni igba de igba ti wọn ma n sẹ ki afara naa ma ba a da ijamba silẹ fun awọn eniyan to n gba ibẹ .
Afara Third manland bridge naa ni afara keji to gun julọ ni ilẹ Afrika, o si di Osu Kini, ọdun 2021 ki wọn to ṣi i pada.
Ni idaji kutukutu ọjọ Aje ni ikọ iroyin BBC Yoruba ti jade lati mọ bi eto irinna yoo ti rọrun tabi nira si fun awọn awakọ nilu Eko.
Sunkẹrẹ fakẹrẹ
Idi ni pe oni ni ọjọ Aje akọkọ, tii tun se ọjọ kẹta tijọba apapọ bẹrẹ isẹ atunse lori abala kan lori afara Third Mainland, eyi ti wọn ti pa.
Osu mẹfa gbako si ni atunse abala mejeeji afara naa yoo fi waye.
Lasiko abẹwo BBC Yoruba si awọn adugbo bii Stadium, Ipọnrin, Shitta, titi wa si adugbo Oworonsoki, a sakiyesi pe lati aago mẹrin owurọ ni awọn ọkọ ti gbemu-lemu.
Africa Eye:  Coronavirus di adákẹ́jà ní Somalia, ikú ọ̀wọ́ọ̀wọ́ ń peléke si
Ọpọ awakọ to si fẹ gba ori afara naa kọja lo tete bẹ sita lai naani pe ilẹ si dudu, koda, oju ọna to lọ si Ikoyi gan ti kun fun ọpọ ọkọ lati aago mẹrin abọ owurọ.
Akọroyin BBC to kọja lori afara naa ni opin ọsẹ ni nnkan ti yatọ si ti tẹlẹ gẹgẹ bi òun ti oju.
Oju ọna to wa lati Iyana Oworo nikan lo wa ni ṣíṣí titi de Adeniyi-Adele, awọn ọkọ to ba n bọ lati ọna Iyana Oworo nìkan lo ni anfaani lati gba ori afara naa laarin aago mejila oru si aago kan ọsan.
Eyi tumọ si pe, awọn ọna miran ni awọn to n bọ lati Lagos Island lọ si ọna Iyana Oworo, yoo gba laarin asiko yii.
Sugbọn to ba ti di aago kan ọsan si mejila oru, awọn to n bọ lati Lagos Island nìkan ni yoo le lo ori afara, ti iyatọ diẹ si wa nibẹ.
Ni kete ti wọn ba de Adeniyi Adele, ni wọn yoo fi oju ọna ti wọn silẹ, lati ya si oju ọna to wa lati Iyana Oworo. Àwọn oṣiṣẹ to n sisẹ lori afara naa ti la ọna kan nibẹ fun eyi.
Oríṣun àwòrán, LASG
Gov Sanwo-Olu fi kun pé àwọn ọkọ èrò ńlanla ẹgbẹ̀ta yóò wo ìlú Eko ni inú oṣù kẹjọ
Ojú ọna naa ni wọn o tọ titi de Iyana Adekunle, nibi ti awọn to n bọ lati ọna Ebute Mẹta n gba jade, ki wọn o tun to ya nibi ti wọn ti la silẹ laarin meji afara, pada si ọna Iyana Oworo.
Lasiko yii, ko si ọna fun awọn to n bọ lati Mainland lati gba ori afara.
Nkan ti a ṣe akiyesi ni pe, yíyà lati ibi kan si ekeji n fa sunkẹrẹ, fakẹrẹ ọkọ.
Sugbọn, àwọn oṣiṣẹ ajọ LASTMA, ati FRSC wa nibẹ lati ma a dari.
Àmọ́, ó ṣeé ṣe ki sunkẹrẹ-fakẹrẹ ọkọ ko lagbara laarin ọsẹ ju opin ọsẹ ti a sọ yii, nitori pe ọkọ má n pọ ni oju ọna.
Oríṣun àwòrán, Twitter/Govt of Nigeria
Nkan miran tun ni pe ẹsẹ ni awọn eeyan kan fi n rin lati Iyana Oworo ni irọlẹ ti akọroyin BBC kọja.
O ṣeé ṣe ko ko jẹ nitori aisi ọkọ to n bọ lati ibẹ, tabi nitori pe wọn o fẹ ẹ lọ gba ọna to jin de Lagos Island ni wọn ṣe ko ẹsẹ si.
Ju gbogbo ẹ lọ, ẹ fi si ọkàn, yala gẹgẹ bi awakọ tabi eero ọkọ, pe o ṣe e ṣe ki ẹ há sinu sunkẹrẹ-fakẹrẹ ọkọ lasiko ti atunse afara Third Mainland Bridge.
Oríṣun àwòrán, LASG
Ọjọ́ Ajé ọjọ́ kẹtàdínlọ́gbọ̀n ọṣù keje, ọdún 2020 ti àwọn olúgbé ìpińlẹ̀ Eko yóò mọ ìpa ti àpá kan afára 3rd mainland tí ìjọba ti pa yóò ṣe ko ìnira ba àwọn arfá ìlú tó.
Tí ẹ o bá gbàgbé , oṣù mẹ́fà ni àfárá náà yóò fi wà bẹ́ẹ̀.
Gómìnà ìpińlẹ̀ Eko Babajide Sanwo-Olu ti wá kédé pé láìpẹ́ yìí ni ìjọbna yóò ṣe àfilọ́lẹ̀ ọkọ̀ ojú omí mẹ́fà míràn láti fún àwọn ará Eko ni ìwúrí láti ma wọ ọkọ̀ ojú omi fún oṣù mẹ́ta tó n bọ̀ yìí.
Èyí wáyé lẹ́yìn ti ìjọba àpapọ̀ kò yí ẹnu pada lórí ọ̀rọ̀ rẹ̀ láti ti 3rd Mainland fún oṣù mẹ́fa lati ṣe àwọn àtúnṣe yẹ ti yóò sì bẹ̀rẹ̀ lónìí ọjọ́ kẹrìndinlọ́gbọ̀n ọṣù kèje, ọdún 2020.
Oríṣun àwòrán, LASG
Ní oṣù keji ọdún ni ìjọba  Ipinle Eko kede aapu ti won n lo fun awon to n  wo ferry lái le jẹ́ ki àwọn ènìyàn máá ṣàmúlò ìrìn ojúomi ní ìlú Eko. Bótilẹ̀ jẹ́ pé kò ti si àridáju ààpu òun lórí Aplle Appstore tabi lori Goggle Playstore.
Lọ́wọ́lọ́wọ́ báyìí ọ̀ná bi ọgbọ̀n ló wà lójú omi ti ènìyàn le gbà:
Owó ọkọ̀ ojú omí kò ju ẹ̀dẹ́gbẹ́ta naira  sí ẹgbẹ̀run kan naira ló, sùgbọ́n fún ẹ̀kúnrẹrẹ àláyé lórí bi owó náà ṣe jẹ́ wan ojú òpó twitter ìjóba ìpínlẹ̀ Eko yìí:
Third mainland bridge mo foo
Àwọn ibi ti ọkọ̀ ojú omi máa n ná
Ọ̀pọ̀ ni ìbẹ̀ru ti mú pe'súnkẹrẹ fàkẹrẹ ọkọ lọ́la ọjọ́ ajé yóò lóyun sinu, yóò pọmọ kódà yóò tún fa báàgì.
Ó lè jẹ́ ìdí nìyí ti gómìnà fi rs àwọn ará ìlú láti maa sàmúlò ojú omi, nínú àtẹjáde kan ti àgbẹnusọ rẹ̀ Gboyega Akosile buwọlù lánà òdé yìí.
Wọ́n ti ti apá kan afara náà láti owúrọ̀ ọjọ́ sátide, kò si si àniàni súnkẹrẹ fàkẹrẹ ọkọ̀ yóò pọ̀, nítori naa o lé jẹ́ ojú omi ni ọ̀na àbáyọ láti sá fun wàh'\alà ojú pópó tó n bọ̀ yìí.
Third Mainland Closure: Wo ǹkan ti ojú àwọn ènìyàn ń rí lórí àfára 3rd Mainland
Sunkẹrẹ fakẹrẹ
Lorumọju oni ọjọ Abamẹta ni ijọba apapọ ti ori afara Third Mainland gẹgẹ bi wọn ṣe kede ṣaaju.
Oṣu mẹfa gbako si ni wọn kede pe wọn a fi ṣiṣẹ lori afara naa.
Wọn yoo ti apa kan fun oṣu mẹta akọkọ ati apa keji fun oṣu mẹta miran.
Ọpọ awakọ lo ti tete rinrinajo kuro ni erekuṣu to jẹ Island lọ si Mainland ki aago mejila ti ijọba kede to lu lalẹ ọjọ Eti nigba ti awọn to ni nkan ṣe lopin ọsẹ yii naa ti de lati Mainland nitori ibẹru sunkéré-fakẹrẹ ọkọ.
Owo gọbọi ni awọn agbero ati ọlọkọ gbe awọn ero ni alẹ ana ọjọ Ẹti nitori ọpọ ero to wa ni titi ti wọn ko fẹ ki awọn ṣe kongẹ idamu ọrọ afara titunṣe naa.
Sanwo Olu to n tukọ ipinlẹ Eko ti fi da awọn eeyan loju pe inira naa ko ni pọ ju nitori pe ijọb eti ṣeto silẹ ko ma ga ju ara lọ.
O ni yatọ si pe awọn ọn abuja miran ti wa lati gba lasiko iṣẹ atunṣe yii.
Ijọba ti tun awọn ọna gbegbe kọọkan ṣe ki sunkẹrẹ fakẹrẹ ọkọ le dinku ni awọn ẹkun naa.
O tun kede pe awọn oṣiṣẹ oju popo LASTMA aadọta ati ọgọrun un mẹfa ni yoo wa nibẹ lati maa ri si lilọ bibọ ọkọ.
Koda, oṣiṣẹ ẹṣọ oju popo aadọta ati igba FRSC ni yoo ṣiṣẹ ko ma baa si sunkẹrẹ-fakẹre ọkọ lasiko naa.
Pataki Afara 'Third Mainland Bridge' ati itan rẹ:
Afara yii jẹ eyi ti wọn tun n pe ni Ibrahim Babangida Boulevard, ọjọ ibi Babangida lọjọ kẹtadinlogun, oṣu kẹjọ lọdun 1990 ni wọn ṣii.
Ohun ni afara to gun julọ nipinlẹ Eko to jẹ olu ilu Naijiria tẹlẹ ki wọn to koo lọ si Abuja.
Afara yii gun fun iwon kilomita 11 ati mẹjọ. (11.8 km).
Working religious women: Ẹ̀lẹ́hàá kìí ṣe ọ̀lẹ- Aminat Adegoke
Afara 'Third Mainland' to jẹ ikẹta yii jẹ eyi to gun ju ninu awọn afara to so Mainland Eko pẹlu Erekusu Island Eko papọ, iyẹn afara Carter ati afara Eko.
Eyi to tumọ si pe ohun lo so agbegbe ọrọ aje ilu Eko mọ ti Mainland.
Eko ni o kun fun ero julọ nilẹ Adulawọ.
Laye iṣejọba Ogagun Ibrahim Babangida ati Ọgagun Raji - Rasaki to n tukọ ipinlẹ Eko nigba naa ni wọn kọọ laarin ọdun 1976 si ọdun 1980 ni apa akọkọ ti apa keji si jẹ 1988 si 1990.
Afara yii lo gun ju nilẹ Adulawọ lasiko ti wọn ṣii, o bẹrẹ lati Oworonṣoki to ja si opopona Apapa-Oshodi ati opopona Eko si Ibadan pọ.
Afara yii gba ọkọ mẹjọ papọ lẹgbẹkẹgbẹ, o si ṣafihan ilu eko lati or omi to fi kan Fasiti Eko ati Makoko lori omi.
Ijọba Babangida ko na Biliọnu kan naira tan to fi pari rẹ lẹyin ti awọn kan yọwọ ninu rẹ.
Lọdun 2013, o le ni biliọnu kan naira ti wọn fi tun apa kan
Wo àwọn ọ̀nà míràn tí o leè gbà lẹ́yìn tí wọ́n bá ti afára Third Mainland
Alakoso ileeṣẹ ijọba apapọ to n ri ọrọ iṣẹ agbegbe, Olukayode Popoola ti sọ pe ijọba ko ni boju wẹyin tabi sun ọjọ siwaju lori atunṣe afara Third Mainland to wa ni ilu Eko.
Atunṣẹ afara naa yoo bẹrẹ ni oru ọjọ kẹrinlelogun, oṣu Keje ọdun 2020, ṣugbọn ọpọ eeyan lo ti n bere pe, ṣe awọn olugbe Eko ti ṣetan fun idojukọ ti yoo waye nitori atunṣẹ naa.
Popoola sọ pe ijọba ti ṣe atunṣe awọn ọna miran ti awọn eeyan le maa gba lasiko ti iṣẹ ba n lọ lọwọ lori afara Third Mainland.
Òru òní ní ìjọba á ti afárá 'Third Mainland' ní Eko; Wo àwọn ọ̀nà míràn tí o leè gbà lẹ́yìn tí wọ́n bá tìí
Wo àwọn ọ̀nà míràn tí o leè gbà lẹ́yìn òru òní tí àtúnṣe afára Third Mainland á bẹ̀rẹ̀
Ọpọ eeyan lo n kọminu boya ijọba Naijiria ati ti ipinlẹ eko le kaju iṣoro to le tẹlẹ titi afara nla yii pa lasiko yii.
Ṣugbọn, ọga agba to n mojuto iṣẹ akanṣe naa, Ogbeni Popoọla ṣalaye pe didun lọsan atunṣe naa yoo so fawọn olugbe ipinlẹ Eko.
Peters Ijagbemi dá àrá lórí ètò 'Ṣé o láyà' ti BBC Yorùbá lọ̀sẹ̀ yìí
Wo awọn ọna abuja miran ti o le gba lai gba afara Third Mainland
Ijọba ti ṣeto awọn ọna miran ti awakọ le gab lasiko ti iṣẹ atunṣe ṣi n lọ lọwọ lori afara yii
Oríṣun àwòrán, LASG
Fun apẹẹrẹ, o ni opopona Addo/Oyingbo/Adekunle/Ebutte Metta ti wa ni sẹpẹ ti awọn eeyan le maa gba.
Bẹẹ lo tun sọ pe ọna Ikorodu si Maryland naa ti di lilo lẹyin ti ijọba ṣe atunṣẹ rẹ.
Iṣẹ n lọ lọwọ ni opopona Maryland
Ijọba ipinlẹ Eko ti rọ awọn to n gba ori afara naa lati ma foya, nitori abala kan yoo wa fun lilo lori afara ọhun.
Ileeṣẹ to n ri si ọrọ iṣẹ agbegbe ni ipinle Eko ni opopona to lọ si Oworonsoki ni yoo kọkọ di titi pa fun oṣu mẹta, lẹyin ti iṣẹ abala naa ba pari ni wọn yoo sun si iha Island.
Abẹwo ileeṣẹ iroyin BBC kaakiri ilu Eko fi han pe lootọ ni ijọba Eko ti n ṣatunṣẹ ọna Maryland atawọn opopona miran to sọ.
Funmi Adewara: Tele Medicine' ní a fi ń ṣàyẹ̀wò èèyàn ìdá ọgọtá láti dènà ìtànkálẹ̀ Covid
Ki lo ti ṣelẹ sẹyin?
Wo iye tí ọkọ̀ òfurufú náà yóò máa gbé èrò láti MM1 sí Island
Oríṣun àwòrán, others
Làìpẹ́ yìí ni ìjọba apapọ ati ijọba ipinlẹ Eko ti kede pé àwọn yóò gbé afára 3rd Mailand tì pa fun oṣù mẹ́fà lójúnà àti ṣe àtúnṣe sí àwọn ibi tó mẹ́hẹ nibẹ fún ìgbáyégbádùn àwọn ará ìlú.
Bótilẹ̀ jẹ́ pé ìjọba ti wá ọna abayọ si sunkẹrẹ-fakẹrẹ ọkọ lasiko ti iṣẹ ba n lọ lori afara Third Mainland ti wọn fẹ tunṣe ni ilu Eko.
Àwọn ilé iṣẹ́ kan ti kéde pẹ̀lú pé àwọn ni ọ̀nà àbáyọ míràn, wọ́n ni àwọn ti ṣe ètò láti máa fí ọkọ̀ òfurufu.
Nínú ọ̀rọ̀ rẹ ọkan lára àwọn tó ń bá alábàráà sọ̀rọ̀ fún ilé iṣẹ́ náà  Nonye sàlàyé pé ọkọ̀ òfurufú (Helicopter) náà yóò má gbé ènìyàn mẹ́jọ ni ìrìn ẹ̀ẹ̀kan.
Bákan náà ló sàlàyé pé owó èrò kọ̀ọ̀kan yóò máa jẹ́ ẹ̀ẹ́gbẹ́tà dọ́là (#200, 000), ìyẹn ẹ́gbẹ̀rún lọ́nà ìgbá Naira.
Ó ní ọkọ̀ náà yóò máa gbéra láti pápákọ̀ òfurufú Muritala Muhammed Way sí Ozumba Mbadiwe láti ààgo méje owúrọ tit di ààgo mẹ́rin ìrọ̀lẹ́
Sùgbọ́n ìbéèrè ni pé, ènìyàn mélòó ni ètò yìí le ṣe ìrànwọ́ fún láàrin oṣù mẹ́fà ti ìjọba yóò fi ti pápákọ̀ òfurufu.
Ènìyàn
Third Mainland Bridge: Ìjọba ìpínlẹ̀ Eko kéde bí àtúnṣe afárá Third Mainland yóò ṣe wáyé
Oríṣun àwòrán, others
Ọdun 2018 ni wọn ti afara ọhun kẹyin fun ọjọ mẹta lọna ati ṣe iwadii awọn iha to ti n dẹnukọlẹ lori rẹ
Ijọba apapọ ati ijọba ipinlẹ Eko ti kede ọna abayọ si sunkẹrẹ-fakẹrẹ ọkọ lasiko ti iṣẹ ba n lọ lori afara Third Mainland ti wọn fẹ tunṣe ni ilu Eko.
Nigba ti wọn n sọrọ nibi ifọrọwerọ pẹlu awọn akọroyin ni ipinlẹ naa, wọn ni awọn ti ṣeto biara ilu ṣe le maa gba ori afara naa lasiko atunṣe ọhun.
Lara awọn to wa nibi apero naa ni adari ileeṣẹ to n ri si ọrọ iṣẹ agbegbe ipinlẹ Eko, Olukayode Popoola; kọmiṣọnna eto irinna, Frederic Oladeinde ati olubadamọran pataki fun Gomina Babajide Sanwo-Olu lori ọrọ iṣẹ, Aramide Adeyoye.
Wọn ni abala akọkọ atunsẹ afara ọhun yoo waye fun oṣu mẹta, nigba ti abala atunṣẹ keji yoo waye fun oṣu mẹta miran.
Bayii ni wọn ṣe ṣeto bi awọn eeyan yoo ṣe maa gba ori afara naa nigba ti atunṣe ba n lọ lọwọ:
Oṣu mẹta akọkọ yoo wa fun atunṣẹ ọna to lọ si Oworonsoki lati lori afara Third Mainland.
Lasiko yii, awọn awakọ yoo maa gba ọna kan naa lati aago mejila oru si aago kan ọsan.
Nigba ti awọn awakọ yoo maa gba ọna to wa lati Lagos Island si Oworonsoki ni abala to lọ si Lagos Island lati aago kan ọsan si mejila oru.
Oríṣun àwòrán, @ericotrips
Oṣu mẹta to tẹle eyi yoo wa fun atunṣe ọna to lọ si Lagos Island lori afara naa.
Lasiko yii ni awọn awakọ yoo si maa gba abala ọna ori afara ọhun to wa lati Oworonsoki si Lagos Island, ni abala ọna naa to lọ si Lagos Island, lati aago mejila oru si aago kan ọsan.
Nigba ti awọn awakọ yoo si maa gba abala to wa lati Lagos Island si Oworonsoki ni ọna to kọju si Oworonsoki, lati aago kan ọsan si mejila oru.
Kọmiṣọnna eto irinna, Frederic Oladeinde sọ pe ijọba yoo fun awọn to n bọ lati Mainland si Island laaye ati gba ori afara ọhun ni aarọ ati ọsan nigba ti awọn ọkọ to n bọ niwaju yoo ni lati lọ gba ọna miran.
Bakan naa lo gba imọran pe ki awọn eeyan maa lo ọkọ oju omi bii lati Ikorodu si Mile 2 ati bẹẹ bẹẹ lọ.
Mama Arsenal: Màmá àgbà yìí máa ń lọ sí ìbùdó tí wọ́n ti ń wo bọ́ọ́lù láti wòran
Oladeinde fi kun un pe ijọba yoo pese awọn ọkọ akero lọpọ yanturu ki awọn eeyan le fi ọkọ wọn silẹ nile lọna ati ṣadinku ba sunkẹrẹ-fakẹrẹ loju popo.
Kọmiṣọnna naa pari ọrọ rẹ pe ki awọn eeyan joko sile to ba ṣeeṣe ki ọkọ le dinku loju popo lasiko atunṣe afara naa.
Oríṣun àwòrán, others
Ọdun 2018 ni wọn ti afara ọhun kẹyin fun ọjọ mẹta lọna ati ṣe iwadii awọn iha to ti n dẹnukọlẹ lori rẹ
Ijọba apapọ Naijiria ti n gbaradi lati ti afara Third Mainland to wa ni ipinlẹ Eko fun oṣu mẹfa lọna ati bẹrẹ iṣẹ atunṣe lori rẹ.
Adari ileeṣẹ to n ri si ọrọ iṣẹ agbegbe, Olukayode Popoola lo fi ọrọ naa lede  lọjọ Aje.
"Popoola sọ pe ""A fẹ bẹrẹ atunse afara Third Mainland laipẹ, o si ṣeeṣe ki a ti afara ọhun lati ọjọ kẹrinlelogun oṣu keje ọdun yii."""
O ni gbogbo irinṣẹ ti wọn nilo lati tun afara naa ṣe lo ti wọle si orilẹ-ede Najiria, nitori naa ijọba yoo bẹrẹ iṣẹ ọhun ni kankan.
Popoola sọ pe eto ti n lọ lọwọ lati wa ojutu si sunkẹrẹ-fakẹrẹ ti yoo waye lẹyin ti iṣẹ naa  ba bẹrẹ.
O ni lẹyin ti eto ọhun ba ti to tan ni awọn oṣiṣẹ yoo lọ bẹrẹ iṣẹ lori afara naa.
Gẹgẹ bi ileeṣẹ iroyin NAN ṣe sọ, ọdun 2018 ni wọn ti afara ọhun kẹyin fun ọjọ mẹta lọna ati ṣe iwadii awọn iha to ti n dẹnukọlẹ lori rẹ.
Ṣugbọn diẹ lara awọn ohun elo ti wọn yoo fi ṣatunsẹ afara ọhun ko si lorilẹ-ede Naijria ni ijọba ṣe pinnu lati ko wọle lati oke okun.
Afara naa ti wọn ṣi lọdun 1996 lo nasẹ ju ninu awọn afara mẹta to so agbegbe Lagos Island ati mainland pọ ni ipinlẹ Eko.
Ẹka ijọba to n ri si ọrọ ina mọnamọna, iṣẹ ṣiṣe ati ile gbigbe ti kede wi pe ko sewu pẹlu afara Third Mainland niluu Eko.
Ninu atẹjade ti Ọgbẹni Hakeem Bello to jẹ oludamọran pataki si Minista ẹka naa, Babatunde Faṣọla fi sita lọjọ Aiku lo ti sọ bẹẹ.
'Èmi ò kí ń lu ìyàwó mi'
O ni ile iṣẹ ijọba naa ni kawọn olugbe ilu Eko maa bẹru lori iroyin kan to gba oju Facebook pe afara naa ti ni iyọnu lawọn ibi kan.
Ilẹ iṣẹ ijọba ṣalaye ninu atẹjade naa pe atunṣẹ yoo waye lori awọn ibi ti wọn ti so afara naa pọ ti wọn mẹnu ba ninu fidio ti awọn kan fihan loju opo Facebook.
Wọn ṣalaye ninu atẹjade naa pe awọn onimọ ẹrọ nipa ọna ṣiṣe ni awọn bi ti wọn ti so afara naa pọ yii to nilo atunṣe ko le ṣakoba fun afara ọhun.
Oríṣun àwòrán, Twitter/Govt of Nigeria
Ti ẹ ko ba gbage, ninu oṣu kẹjọ ọdun 2018 ni ijọba apapọ ti afara Third Mainland fun ọjọ mẹta fun ayẹwo.
Ko da ayẹwo lati inu omi tun waye lori afara naa ninu oṣu kẹta ọdun lati ni idaniloju awọn ibi to nilo atunṣe lori afara naa.
Afara Third Mainland lo gun ju lọ ninu awọn afara mẹta to lọ si erkusu ilu Eko, awọn meji to ku ni Eko Bridge ati Carter Bridge.
Ọ̀dọ́kùnrin tó kọ́kọ́ ṣe ẹ̀rọ tó ń tu ìyẹ́ lára adìyẹ
Sri Lanka attack: Orílẹ̀èdè mẹjọ, yàtọ̀ sí Sri lanka ló pàdánù èèyàn wọn nínú ìṣẹ̀lẹ̀ náà
Oríṣun àwòrán, Reuters
Ile ijọsin mẹta ni wọn ṣe ikọlu si ni ọjọ Ajinde
Àwọn to gbẹmii mi ninu ikọlu ado oloro to ṣẹlẹ ni awọn ile ijọsin mẹta ati awọn ile igbafẹ kan ni Sri Lanka ni ọjọ Ajinde, ti di ọọdunrun o din mẹwaa bayii. Ọpọlọpọọ wọn si lo jẹ ọmọ orilẹede Sri Lanka.
Ileesẹ ọlọpaa orilẹede naa ni awọn mẹrinlelogun ni ọwọ ti ba bayii lori ikọlu naa, ṣugbọn ko tii ye awọn alaṣẹ nipa awọn eeyan to ṣe agbatẹru ikọlu naa.
Eniyan bii ẹẹdẹgbẹta lo fara pa, ti awọn ajoji to wa lara awọn to ku si to marundinlogoji.
Orilẹede awọn ajoji to ku ti wọn ti ri rèé:
Oríṣun àwòrán, Reuters
Àwọn alufaa ni ile ijọsin St Anthony to wa ni Kochchikade
Ọpọlọpọ oku awọn ajoji to fara kaaṣa iṣẹlẹ naa ni wọn ko ti i ri.
Ikọlu ọjọ Ajinde naa wa lara eyi to buru ju to ṣẹlẹ ni Sri Lanka ri lati igba ti ogun abẹle orilẹede naa ti pari ni 2009.
Oríṣun àwòrán, Reuters
Awọn ẹlẹsin Kristiani ko pọ ni Sri Lanka
Lẹyin ikọlu naa ni ọjọ Aiku, olori orilẹede naa, Ranil Wickremesinghe ni awọn agbofinro mọ wipe ikọlu le waye, ṣugbọn wọn ko gbe igbesẹ kankan lori ọrọ naa ki o to ṣẹlẹ.
Iroyin to kọkọ wọle fi han wipe, ado oloro kan bu ni bii aago mẹsan ku iṣeju marundinlogun ti awọn mẹfa miiran si tẹle.
Ile ijọsin mẹta ni Negombo, Batticaloa ati agbegbe Kochchikade ni awọn ikọlu naa ti waye nigba ti isin Ajinde n lọ lọwọ.
Oríṣun àwòrán, Reuters
Ile ijọsin St Sebastian's to wa ni Negombo ba jẹ tori ado oloro naa
Awọn ile igbafẹ ti wọn tun sọ ado oloro si ni Shangri-La, Kingsbury and Cinnamon to wa ni olu ilu orilẹee naa.
Oríṣun àwòrán, AFP
Ado oloro ba ile igbafẹ Shangri-La jẹ ni Colombo
Ado oloro kẹjọ ti o bu ni agbegbe  Dematagoda nigba ti ọlọpaa lọ mu awọn kan pa ọlọpaa mẹta.
Faye Mooney: Ìlú Eko ló ti lọ sóde àríyá ní Kaduna ni wọ́n yìnbọn fun
Oríṣun àwòrán, @thenewsnigeria
Ọlọrun ma jẹ ka rin ni ọjọ ti ebi yoo pa ọna tabi ti a se agbako iku ojiji.
Obinrin ọmọ ilẹ Gẹẹsi kan, Faye Mooney lo ti se alabapade iku ojiji rẹ ni ilu Kaduna lasiko to lọ se ariya lati ilu Eko.
Ibudo igbafẹ kan to wa ni ilu Kaduna lawọn gende agbebọn kan ti yinbọn mọ lasiko to wa si orilẹede Naijiria lati lo isinmi rẹ.
Gẹgẹ bi akọroyin BBC ti salaye, ọmọ ẹgbẹ alaanu kan, Mercy Corps, ni oloogbe ọmọ ilẹ Gẹẹsi ọhun, ti ko si ti si ẹnikẹni tabi ẹgbẹkẹgbẹ kankan to tii kede pe oun ni oun wa nidi isẹlẹ naa.
Gẹgẹ bi ileesẹ asoju ijọba ilẹ Gẹẹsi to wa ni Naijiria ti kede rẹ, ẹlomiran ti wọn tun yinbọn mọ ni Matthew Oguche, ẹni to n sisẹ fun ẹgbẹ alaabo kan ti kii se tijọba, ti wọn pe ni Safety Organisation.
9ice: Ǹjẹ́ olórin tàkasúfèé yìí ń mu igbó bí àwọn òṣèré mìíràn?
Sugbọn awọn ọlọpa ilẹ wa ni n se lawọn agbebọn naa n yinbọn soke laibikitalasiko ti wọn gbẹmi awọn eeyan mejeeji ọhun.
Iroyin naa ni iwa ijinigbe ti wọpọ pupọ ni ọpọ agbegbe lorilẹede Naijiria, to fi mọ ipinlẹ Kaduna, tawọn ajinigbe yii si maa n foju sun awọn ọmọ Naijiria ati awọn ajeji lati ji wọn gbe gba owo.
Child Trafficking: Ọwọ́ ṣìnkún ọlọ́pàá tẹ èèyàn 5 lórí ìṣẹ̀lẹ̀ náà
Oríṣun àwòrán, @PoliceNG
Ọkunrin kan, Amanze Anyanwu ati iyawo rẹ Chinonye Oparaocha ẹni ọdun mẹtalelogun, ti ta ọmọ wọn tuntun jojolo, ti ko tii ju ọmọ wakati mẹfa lọ ni owo to to ẹgbẹrun lọna ọtalelẹgbẹrin o din mẹwa naira (₦850,000).
Gẹgẹ bi Kọmisọna ọlọpa nipinlẹ Imo, Rabiu Ladodo ti kede rẹ lasiko to n fi oju awọn afurasi ọhun han, salaye pe,iya ọmọ tuntun naa lo gbimọ pọ pẹlu awọn eeyan miran nibi to ti bi ọmọ tuntun ọhun lati ta ọmọ rẹ fun awọn eeyan kan ni ipinlẹ Rivers.
Ladodo ni lọjọ Kẹjọ osu Keji ọdun 2019 ti obinrin naa bimọ nile iwosan kan lopopona Nekede nilu Owerri, ni wọn gbe ọmọ wakati mẹfa ọhun lọ si ilu Portharcourt nipinlẹ Rivers, ti wọn si ta fun Duru Christian, ẹni to ti mura silẹ lati gba ọmọ naa, to si gbe fun ọkunrin kan ti wọn pe ni George Iyowuna.
Iyowuna yii ni iroyin naa ni o gbe ọmọ ohun fun ẹni to fẹ ra, William Cynthia ati ọkọ rẹ, ti wọn si san ẹgbẹrun lọna ọtalelẹgbẹrin o din mẹwa naira (₦850,000) fun.
Kọmisana ọlọpa naa ni lọjọ Kẹtala osu Kẹrin ọdun 2019 ni awọn ọtẹlẹmuyẹ ileesẹ ọlọpa naa, lẹyin isẹ iwadi wọn to jinlẹ, gba awọn afurasi afọmọ sowo naa mu, to fi mọ iya ọmọ tuntun naa ati Nọọsi to gbẹbi fun.
9ice: Ǹjẹ́ olórin tàkasúfèé yìí ń mu igbó bí àwọn òṣèré mìíràn?
Ladodo, lasiko to n sapejuwe isẹlẹ yii bii eyi to ya ni lẹnu to si n ba ni ninujẹ, tun salaye pe marun ninu awọn afurasi ọhun ti ọwọ tẹ, ti n ka boroboro fun awọn ọlọpa nipa isẹlẹ naa, ti aayan si ti n lọ lati mu awọn afurasi yoku ti wọn ti na papa bora, to fi mọ baba ọmọ tuntun naa.
O fikun pe laipẹ ni wọn yoo gbe awọn afurasi naa lọ sile ẹjọ.
DR Congo Park: Olùdarí ìbùdó náà ní wọ́n ń fi fọ́tò yíyà sín olùtọ́jú wọn jẹ ni
Oríṣun àwòrán, Ranger Mathieu Shamavu
Inaki nla meji to wa ni ibudo igbafẹ nla kan, Virunga National Park, ni orilẹede DR Congo, lo fẹran lati maa ya aworan adaya, ti wọn yoo si duro bii eeyan ninu fọto ti awọn olugbafẹ to ba wa sibẹ ya.
Awọn inaki naa, ni wọ̀n n tọ̀ju nibudo igbafẹ yii lẹyin ti ẹranko buruku kan awọn obi wọn..
Gẹgẹ bi igbakeji oludari ibudo naa ti sọ fun BBC, awọn inaki naa ni wọn kọ lati maa sin awọn eeyan to n tọju wọn jẹ, lati igba ti wọn ti ri wọn he, ti wọn yoo si duro bii eeyan lati ya fọto.
O fikun pe awọn inaki naa ni wọn n ri awọn olutọju ibudo naa to wa layika wọn bii obi wọn ti wọn sekupa lọdun 2007
Ọdun meji ati osu mẹrin si lawọn inaki mejeeji ọhun lasiko ti wọn padanu obi wọn, idi si ree ti wọn fi ko wọn lọ si ibudo ti wọn n gbe ọhun.
9ice: Ǹjẹ́ olórin tàkasúfèé yìí ń mu igbó bí àwọn òṣèré mìíràn?
"Innocent Mburanumwe, tii se igbakeji oludari ibudo igbafẹ naa ni ""awọ̀n inaki yii n sin eeyan adarihunrun jẹ ni, ti wọn yoo si duro lori ẹsẹ wọn mejeeji bii eeyan lati yan fọto, bẹẹ ni wọn yoo gan pa."
Ìtàn Mánigbàgbé: Ìnà ẹgba mẹ́sàn-án ni Jesu Oyingbo fi ń kí ọmọ ìjọ ọ́kùnrin tuntun káàbọ̀
Oríṣun àwòrán, @Nigerianmuseum
Bi aye ba n yi, a maa ba aye yii ni nitori ko si ohun tuntun labẹ ọrun mọ, a ko si ri iru eyi ri, a fi n da ẹru ba ọlọrọ ni.
Oniruuru ilana ẹsin ati ijọ lo ti wa kaakiri laye atijọ, ti ihuwasi ati isesi wọn si jẹ manigbagbe, eyi ti ijọ Jesu Oyingbo jẹ ọkan ninu wọn.
Gẹgẹ bi a ti kaa ni oju opo Wikipedia lori itakun agbaye, ilana iwaasu iwa irẹlẹ ni Emmanuel Odumosu, ti gbogbo eeyan mọ si 'Jesu Oyingbo' fi bẹrẹ, ko to wa gbajumọ eto okoowo sise.
Itan igbe aye Jesu Oyingbo yii dun pupọ, to si yẹ ka ri ọgbọn kan abi meji kọ ninu rẹ nitori arise ni arika, arika si ni baba iregun, ohun ti eeyan kan ba si se ni oni, ni yoo di itan to ba di ọla.
Sogidi Lake: Kòṣẹja-kòṣèèyàn lá bá nínú adágún odò náà -Ojedele
Ikogosi-Ekiti: Ilu ti omi tutu ti dapọ mọ gbigbona
Oríṣun àwòrán, @AfricaFactsZone
Lootọ ni Jesu Oyingbo ti fi aye silẹ sugbọn awọn ohun to gbe ile aye se jẹ manigbagbe, ti yoo wa ni iranti fun igba pipẹ.
Ki ni a o sọ lẹyin ti ọlọjọ ba de fun ẹyin naa?
Ani, nigbakigba too ba fi aye silẹ, jẹ ki idahun naa wa ninu rẹ.
Ìkọlu Ifọ: Ọlọ́pàá pòórá lẹ́yìn tí àwọn jàndùkú yọ àdá sí wọn,
Oríṣun àwòrán, Ogun State/Facebook
Àwọn janduku naa lọ fi ibinu sọ ina si ọgba Kunle Oluọmó
Awuyewuye ti bẹ silẹ ni Ifọ ni Ipinlẹ Ogun bi awọn ọlọpaa ṣe yinbọn pa ọkunrin kan ti wọn funra si pe ọmọ ẹgbẹ okunkun ni.
Awọn ọdọ to jẹ akẹgbẹ oloogbe naa ti fi ibinu lọ ile oloṣelu kan ti orukọ rẹ njẹ Kunle Oluọmọ, ti wọn si jo awọn ọkọ nla ati ile to wa nibẹ.
Nigba ti BBC Yoruba kan si agbẹnusọ ọlọpaa ni ipinlẹ naa, Abimbola Oyeyemi, o ṣalaye wipe, ikọ ọlọpaa mu ọmọkunrin kan ti wọn funra si wipe, ọmọ ẹgbẹ okunkun ni.
O ni nigba ti wọn si fi ọrọ wa lẹnu wo, o jẹwọ wipe awọn akẹgbẹ oun wa ni Ifo.
"Oyeyemi sọ wipe, ""Afurasi naa tẹle wọn lọ Ifo, wọn si gbe akẹgbẹ rẹ naa, ti wọn si gba awọn ibọn ati ọta lọwọ rẹ."
"Wọn n pada si Abeokuta ni awọn akẹgbẹ awọn afurasi mejeeji ba ṣe ikọlu si wọn lọna. Inu ikọlu naa ni wọn ti yinbọn pa ọkan lara awọn janduku ti fara gbọta.
9ice: Ǹjẹ́ olórin tàkasúfèé yìí ń mu igbó bí àwọn òṣèré mìíràn?
Ni bi a ṣe n sọrọ yii, ọkan lara awọn ọlọpaa ti o wa nibẹ ti di awati, a ko mọ oun to ṣẹlẹ si."""
Oyeyemi àwọn janduku naa lọ wa kun ara wọn ti wọn si lọ ile oloṣelu ti wọn pe orukọ rẹ ni Oluọmọ lati lọ sọ ina si.
Micheal Jackson Vs Beyonce: Àwọn èèyàn sọ ẹní tó jẹ ọgá láàrín olórin méjèèjì
Ki a ma ṣebi ẹni pe a ko ri ohun tawọn eeyan n sọ lori ayelujara lori ọrọ to n ja rain rain pe, taa lọga laarin oloogbe Micheal Jackson ati Beyonce, lo mu wa  fi ibeere sita.
Esi ti awọn eeyan fọ si ọrọ yii loju opo Facebook wa kọja afẹnusọ.
Bi a ba ni ki a ka ni meni meji, oju iwe yoo kun koda, yoo tun ṣeku.
Fun ẹyin ti ẹ ko ba ti laanfaani lati dasi, boya ki ẹ ka diẹ lara ohun ti wọn n sọ ki ẹ to mọ iha ti ẹ o kọ si ọrọ yi.
Amọ saaju, ki a to bẹrẹ akojọ ọrọ wọn yi, a fẹ ki ẹ mọ wi pe ohun gbogbo ti ẹ ba ka, awa kọ la sọ, awọn ololufẹ Micheal Jackson ati Beyonce ni wọn n sọrọ.
Ki a ti ibi ibeere yi bẹrẹ nitori orukọ ti arakunrin kan Mo'Sopaiqu Odedeyi pe Micheal Jackson niyi, nigba to n fesi si ariyanjinyan naa.
9ice: Ǹjẹ́ olórin tàkasúfèé yìí ń mu igbó bí àwọn òṣèré mìíràn?
Ninu ọrọ rẹ, ko ti lẹ ro wi pe olorin kankan le ba Micheal Jackson táákà rara.
Itz Yemi Abiola Black fẹran esi yi debi wi pe ohun naa pa ''suna'' orukọ miran fun Micheal Jackson, ti o si sọ ni orukọ ''Mukaila Sẹnwẹlẹ''
A ko mọ daju ẹni to da ọrọ naa silẹ ṣugbọn ninu awọn esi to wa loju opo BBC Yoruba Facebook, ko fẹ si ẹni ti o gbe lẹyin Beyonce, pe o ga ju Michael Jackson lọ.
Ki o ma dabi ẹni wi pe a n ṣe oju saaju, a kaakiri oju opo ayelujara lati wa ẹni to fara mọ pe Beyonce ju Micheal Jackson lọ.
Loju opo facebook BBC Pidgin lati ṣe alabapade ọrọ arakunrin kan Al Hassan III to sọ pe, Beyonce wa ni ipo kini ti Bob Marley tele ki o to wa kan Micheal Jackson.
Ko ti sọrọ naa tan ti awọn eeyan bẹrẹ si ni fun ni esi pada
Ọrọ naa ṣi n ja rain-rain ti ko si ti si ni to mọ ibi ti yoo kangun si.
Dagrin: Òní ló pé ọdún mẹ́sán án ti Dagrin dágbére fún ayé
Oríṣun àwòrán, @RayceRollin
Akọgun, Omo Ogun, Lyrical werey, Okunrin Ogun...diẹ lara awọn inagijẹ ti awọn ololufẹ Dagrin mọ ọ si re e .
Nigba to wa laye,o ko ipa ribiribi lagbo orin 'Rap' pẹlu bi o ti ṣe n fi ede abinibi rẹ,Yoruba da awọn eeyan lara ya.
Oni lo pe pe ọdun mẹsan an geerege ti ilumọọka olorin Rap nii, Olaitan Oladapo Olaonipekun 'Dagrin', ti wọn tun mọ si ‘Chief Executive Omo-Ita’ jade laye.
Loju opo Twitter, awọn ẹbi rẹ, ara ati ọrẹ ko ye se idaro rẹ, ti awọn kan si n beere wipe ṣe ki ṣe pe aye ti gbagbe ilumọọka akọrin yii?
Oríṣun àwòrán, @semasir
Dj Jimmy Jatt wa lara awọn to daro rẹ loni:
K- Solo ni orin Dagrin ma n dabi ọtun leti oun nigbakigba ti oun ba ti gbọ.
Olowo Igbalode se afiwe Dagrin pẹlu 2pac Shakur ọmọ ilẹ Amerika, ti oun na ku lewe, to si ni ki ẹlẹda dẹ ilẹ fun Dagrin.
Hushpuppi naa ko gbẹyin ninu iranti Dagrin. Koda o kede pe oun yoo fun awọn eeyan lẹbun owo ni iranti rẹ.
Lọjọ Kejilelogun Oṣu Kẹrin ọdun 2010 ni Dagrin padanu ẹmi rẹ ninu ijamba ọkọ nilu Eko.
9ice: Ǹjẹ́ olórin tàkasúfèé yìí ń mu igbó bí àwọn òṣèré mìíràn?
Saaju ki awọn olorin bi Olamide ati Whizkid to di ilumọka, ni Dagrin ti n dagboro ru pẹlu Rap rẹ, to n fi ede abinibi Yoruba kọ.
Ọmọ ọdun mejilelogun ni, nigba ti o dagbere faye.
Ọọni: Ilẹ̀ ifẹ̀ ní ìran Ìgbò tí ṣẹ wá kìí ṣe ilẹ̀ juu
Oríṣun àwòrán, Yera Moses Olafare
Onimọ kan nipa igbe aye ati ihuwasi awọn eeyan aye atijọ to fi fasiti UNN Nsukka ṣe ibujoko sọ pe o ṣeeṣe ki iran Igbo ṣẹ wa lati Ile Ifẹ ni ilẹ Yoruba.
Ojọgbọn Chidi Ugwu fidi ọrọ yi mulẹ ninu ifọrọwanilẹnuwọ pẹlu BBC ni idahun si ọrọ ti Ooni Ifẹ Oba Enitan Ogunwusi Adeyeye sọ laipe yi pe ọkan naa ni ẹya Yoruba ati Igbo.
Afro Brazilians: ìlú Rio ni a máa kọ ilé ìṣẹmbáyé náà sí
Oba Adeyeye nigba ti o n ba awọn ọmọ ẹgbẹ Ohaneze Ndigbo kan to ba lalejo laafin rẹ sọ pe Ile Ifẹ ni orisun Igbo ati pe ibaṣepo laarin awọn ko ṣẹṣẹ bẹrẹ.
''A ni lati sọ ododo fun ara wa. Ọmọ iya kan naa ni wa. Ko yẹ  ki nnkankan ya wa . Mo fẹ ki ẹ ri  ibi gẹgẹ bi ile yin ki ẹ si bọwọ fun awọn ọmọ iya yin to jẹ Yoruba''
Oríṣun àwòrán, CHIEF SUNDAY JUDE IYOKE
Ninu alaye rẹ lori ọrọ naa, Ọjọgbọn Chidi ni ẹri jẹmi pe iran Igbo ṣẹ́ wa lati ile Ifẹ jẹyọ ninu orukọ awọn nnkan nilẹ Yoruba.
O mu apẹrẹ ọrọ bi Ifa lede Yoruba ati Afa ni ede Igbo, Atọ ati ẹta, owu ti awọn ẹya mejeeji jijọ n lo lati sapèjuwe owu iranṣọ ati ori jijẹ ti awọn mejeeji jọ n lo ọrọ kanna fun.
Ẹ wo àwọn ọmọ orílẹ̀-èdè Brazil tó wá síilẹ̀ Yorùbá láti mọ orisun wọn
Ọrọ miran to tun tọka si ni gbolohun Igbo eleyi ti Ọọni sọ pe o ṣẹ wa lati igba ti awọn Igbowa ni Ile Ifẹ.
''Loni, awọn Yoruba a ma  lo ''Igbo'' ninu orukọ awọn ilu wọn ti eleyi si jẹ atọka pe ọrọ na jẹ ayalo lati igba ti awọn iran Igbo wa ni ile Ifẹ''
Apẹrẹ kan ti a ri fun alaye to sọ yi ti Ọọni na fidi rẹ mulẹ ni orukọ ilu Olugbo ti olori rẹ́ si n jẹ Akarigbo.
Gẹgẹ bi alaye Ọọni,lati Ile Ifẹ ni awọn Igbo to lọ tẹdo si Olugbo ti kuro ti itan si fihan pe awọn ni wọn pada wa n damu Ile Ifẹ.
Amọ ọba alayeluwa naa ni oun rọ awọn Ndigbo lati sọ fun awọn Igbo to ku pe wọn ko ṣẹ wa lati ilẹ Juu bi kii ṣe pe Ile Ifẹ ni orisun wọn.
Abẹ́rẹ́ àjẹsára àkọ́kọ́ tó n dènà ibà yóò dì mímú lò ní Malawi
Oríṣun àwòrán, D Poland/PATH
Wọn ti saaju dan iṣẹ abẹrẹ yi wo lara awọn eeyan ti o si ṣiṣẹ daada
Iṣẹ ibẹrẹ lori pipese abẹrẹ ajẹsara eleyi ti yoo daabo bo awọn ọmọde lọwọ airun iba ti bẹrẹ lorileede Malawi.
Abẹrẹ naa ti wọn pe orukọ rẹ ni RTS, S ma kọ awọn ọmọ ogun inu ẹjẹ bi wọn yoo ṣe doju ija kọ kokoro aarun iba ti awọn ẹfọn ma n gbe kaakiri.
Saaju awọn ayẹwo diẹ diẹ kan fi han pe ida ogoji ninu ida ọgọrun awọn ọmọ ti ọjọ ori wọn ko ju osu marun un si mẹtadinlogun ni abẹrẹ naa n da aabo bo.
O jọ bi ẹni pe itankalẹ aarun iba tun ti fẹ ma gbori lyin bi ọdun mẹwa ti awọn oṣiṣẹ ilera bori aarun yi.
"Dokita Kate O'Brien to jẹ adari eto gbigba ati pipese abẹrẹ ajẹsara ni ajọ WHO sọ fun BBC pe ""Iṣẹlẹ manigbagbe ni eyi jẹ fun abẹrẹ ajẹsara,kikoju aarun iba ati ilera ara ilu''"
Gẹgẹ bi ohun ti a ri ka iye awọn ti aarun iba n ba finra n peleke si juti tẹlẹ lọ-eyi ti mu ki awọn alaṣẹ́ ma jaya lori ọrọ naa.
435,000 died of malaria worldwide
219m infectedAfrica saw more than 90% of cases and deaths
Malawi in orileede akọkọ ninu awọn mẹta ti wọn yoo ti bẹrẹ lilo abẹrẹ ajsara yi .
Afojusun wọn ni pe ki ọmọ to to ẹgbẹrun lọna ọgọfa ti ọjọ ori wọn ko ju ọdun meji lọ je anfaani rẹ. Awọn orileede meji to ku.
Ghana ati Kenya yoo bẹrẹ si ni fun awọn eeyan labẹrẹ naa lẹyin ọsẹ meji.
Wọn ṣa awọn orileede wọn yi lẹṣa to ri pe wọn ni eto ti wọn ṣe lati koju iba to fi mọ lilo awọn ṣugbọn iye eeyan ti iba n damu yi pọ nilẹ wọn
Bawo ni ipenija yi ṣe pọ to?
Lọdọọdun ni aarun iba ma n pa eeyan to to ẹgbẹrun lọna irinwo le marundinlogoji ti ọpọ wọn si jẹ ọmọde.
Gẹg bi ohun ti ajọ WHO sọ, pupọ awọn ti iba n pa wa l'Afrika nibi ti ọmọde to le ni ẹgbẹrun lọna òjìlénígba lé mewaa ma n ku.
"Dokita  O'Brien sọ pe ''iba jẹ aarun to ṣoro lati  pese abẹrẹ ajẹsara ti yoo koju rẹ'' said that malaria is ""a really difficult disease to develop a vaccine against""."
O ti lẹ ni ọgbọn ọdun ti wọn ti n ṣiṣẹ lori ti awọn onimọ sayẹnsi lati ile iṣẹ ipoogun GSK bẹrẹ iṣẹ lori rẹ.
Lẹyin ọpọ ọdun ti wọn ti n ṣiṣẹ lori rẹ o ti tobi biliọnu dọla kan ti wọn ti na lori rẹ bayi.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Awọn eeyan ti n pe fun ọna to daju lati koju aarun iba
Dokita Schellenberg ni ''Ko si ẹni to sọ pe ajẹbi idan ni abẹrẹ yi ṣugbọn yoo ni ipa ti yoo ko lati kojuaarun iba''
Ẹmẹrin ni wọn yoo fun eeyan labẹr yi,ẹmẹta  laarin oṣu ti ẹni naa yoo si gba ikẹrin loṣu mẹjidinlogun lyin igba naa.
Wọn ni ireti pe wnyoo pari idanwolilo abẹrẹ yi lọdun 2023.
Àbẹ̀wò Buhari sí Eko: Àwọn ọ̀nà láti yàgò fún àyàfi tí ẹ ba gbé ibùsùn dání
Oríṣun àwòrán, @MBuhari
Aarẹ Muhammadu Buhari yoo ṣe abẹwo si Ipinlẹ Eko ni Ọjọru lati ṣi awọn iṣẹ akanṣe ti ijọba Ipinlẹ Eko ṣe labẹ iṣakoso Gomina Akinwunmi Ambode.
Nitori naa ni ajọ ti o n moju to irinna ni ipinlẹ naa (LASTMA) ṣe fi atẹjade sita lori awọn ọna ti aarẹ yoo fẹsẹ tẹ.
Nigbakugba ti aarẹ ba ti wa si ilu Eko, iya maa n jẹ awọn olugbe ilu Eko ni atari sunkẹrẹ-fakẹrẹ ọkọ. Eyi lo jẹ ki ajọ LASTMA fi to awọn olugbe ipinlẹ naa leti awọn ọna ti irin aarẹ yoo de.
Awọn ọna wọnyii ni aarẹ yoo foju ba laarin aago mẹsan owurọ si mẹta ọsan ree:
1. Mobolaji Anthony Way (Lati papakọ ofurufu Murtala Mohammed si abẹ afara to wa niwaju ile iwosan LASUTH)
2. Ọna Kodesoh
3. Obafemi Awolowo Way
4. Kudirat Abiola Way
5. Popona Ikorodu (Laarin ọjọta si iyana Anthony)
6. Popona Owonronshoki si Apapa (Laarin Anthony si Oshodi
7. Ọna papakọ ofurufu
LASTMA ti ni awọn ọna wọnyii yoo wa ni titi nigba ti aarẹ ba n kọja tabi to ba duro lati ṣi iṣẹ akanṣe.
Ajọ naa si tun ti rọ awọn olugbe Ipinlẹ Eko ki wọn yago fun awọn ọna wọnyii.
Wo ohun tí ọkùnrin yìí ń sọ táyà ọkọ̀ dà
Osoba: Àwọn tó ń bèèrè fún àtúntò ń jà fún ikùn ara wọn ni
Oríṣun àwòrán, Google
Ọ̀jọ̀gbọ́n Olusegun osoba wà ní ara àwọn tó se àpérò lórí ìwé ìlànà àti òfin Naijiria ní ọdún 1976.
Arẹmọ Olusegun Osoba ti ni awọn ọmọ Naijiria nikan lo le gba ara wọn la lọwọ amunisin lorilẹede Naijiria.
Osoba so eyi lasiko to n fi lede wi pe ọrọ Naijiria ko nii se pẹlu atunto orilẹede, afi ki awọn Naijiria dide lati gba ara wọn.
Lasiko to n se ifilọlẹ iwe rẹ ti oun ati oloogbe Dokita Bala Usman kọ lori iwe ilana ofin Naijiria ti ọdun 1976, Osoba ni awọn to n pe fun atunto Naijiria n ja fun ikun ara wọn.
Ọ̀jọ̀gbọ́n Olusegun Osoba, to wà lara àwọn tó se àpérò lórí ìwé ìlànà àti òfin Naijiria ní ọdún 1976 tun ni ‘Irọ patapata ni atunto Naijria, awọn ti wọn beere fun ko ni otitọ, wọn fẹ dari ohun alumọni orilẹede Naijiria ni.’
Bisi Alimi: Ìyà mi rò pé n kò leè ṣe ni àmọ́ n kò ní ìfẹ́ abo ni mo ṣe fẹ́ akọ
‘O yẹ ki igbe aye awọn ipinlẹ to n pese ohun alumọni epo rọbi dara ju bo se wa lọ, amọ awọn adari ipinlẹ naa n lo owo ilu basubasu nipa didari owo si ibi ti ko yẹ.’
Oríṣun àwòrán, Google
Ọpọ igba ni awọn eniyan nla nla lawujọ ma n bere fun iyipada ofin ati ilana orilẹede Naijiria
Ọjọgbọn Olusegun Osoba wa fikun wi pe, ọna abayọ si isoro Naijiria ni ki awọn ọmọ Naijiria ma a fi ẹhọnu wọn han lati igba de igba.
Àbẹ̀wò Buhari: Mo fẹ́ kí òjò rọ̀ ní Eko, kó sì ba àbẹ̀wò Buhari jẹ́
Aarẹ Muhammadu Buhari n ṣe abẹwo si ilu Eko loni lati wa si awọn akanṣe iṣẹ kan tijọba ipinlẹ Eko ṣe.
Lara awọn akanṣe naa ni ibudo igbẹbi awọn oloyun ti wọn pe ni Ayinkẹ House to wa ni Ikẹja, Ibudo ere tiata to wa ni Ọrẹgun ati opopona olobiripo to wa ni Oshodi.
Awọn isẹ akanṣe yoku ni ọkọ bọọsi bọginni tuntun ati opopona tuntun to lọ si papakọ ofurufu.
Yoruba ni iroyin ko to afojuba lo mu ki BBC fẹsẹ kan de awọn ibudo tawọn akanṣe iṣẹ naa wa, ta si ri pe lootọ iṣẹ ko ti pari lori awọn isẹ naa rara.
Koda ijọba ipinlẹ Eko gan ti kede fawọn araalu lati mọ awọn oju ọna ti wọn yoo ti pa ati awọn eyi ti ijọba yoo si fun lilo, eyi tawọn araalu ni yoo tubọ dakun sunkẹrẹ fakẹrẹ ọkọ ni Eko lasiko abẹwo aarẹ naa ni.
Awọn oju opo ikansira ẹni lori itakun agbaye ti kun pitimu nipa ero araalu lori abẹwo aarẹ Muhammadu Buhari si ilu Eko.
Niwọn igba to si jẹ pe bakan meji ni ẹnu ọmọ araye, bi awọn eeyan kan se n foju sọna fun abẹwo naa, ni awọn eeyan kan n yinmu pe awọn isẹ wo gan ni Buhari n bọ wa si ni Eko.
Awọn eeyan kan tiẹ n gbarata lori inira ti abẹwo naa yoo mu bawọn nitori awọn opopona kan ti ijọba yoo ti pa lasiko abẹwo aarẹ Buhari naa.
Bisi Alimi: Ìyà mi rò pé n kò leè ṣe ni àmọ́ n kò ní ìfẹ́ abo ni mo ṣe fẹ́ akọ
Lero tawọn eeyan kan, wọn gbe si oju opo Twitter wọn pe ọpọ isẹ ti aarẹ Muhammadu Buhari n bọ wa si naa ni isẹ ko tii pari lori wọn, amọ ti gomina Akinwunmi Ambọde fẹ fi iwanwara si awọn isẹ naa.
Loju opo Adetayo Adeseyi, @ade_tayos, o ni oun lero pe ojo yoo rọ loni lati ba abẹwo Buhari jẹ ni Eko.
Ubong Ekpo lero tiẹ ni se ko seese ki wọn pari awọn akanse isẹ naa ki Buhari to wa si Eko ni, paapa opopona to lọ si papakọ ofurufu to wa ni Oshodi. O ni ẹru n ba oun pe wọn yoo sọ opopona ọhun di akọpati ni lẹyin ti Buhari ba ti si tan gẹgẹ bi wọn ti se ni ibudokọ to wa ni Ikẹja.
Cece @Folasade_h sọ loju opo rẹ pe ko si ẹni ti inu rẹ dun si abẹwo aarẹ naa ju iya oun lọ, ti oun ko si mọ idi ti inu rẹ fi dun.
Nicholas Ibekwe lero tiẹ lori Twitter, @nicholasibekwe salaye pe gẹgẹ bi ise rẹ, Buhari tun n bọ ni Eko lati wa si awọn akanse isẹ ti ko tii pari rara.
Soyinka: Háà, ó ṣe. Ìran mi já Nàìjíríà kulẹ̀
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Onimọ nipa iwe kikọ ati Litiresọ, Ọjọgbọn Wọle Ṣoyinka ti sọ pe, iran oun ti ja orilẹede Naijiria kulẹ patapata.
Lasiko to n sọrọ lori eto ileeṣẹ BBC kan, Hard Talk, Soyinka ṣalaye wipe, afojusun ati ala ti iran oun ni fun orilẹede yii ko ti i wa si imuṣẹ.
Ninu ọrọ rẹ, Soyinka ni  ''mo fi oni we igba ti a n d'agba, ti ọpọlọpọ wa lọ kawe nilẹ okeere, nigba ti gbogbo wa sare pada sile lẹyin ti a kẹkọọ nilẹ okeere.
A ri ara a wa gẹgẹ bi iran tuntun ti yoo gbe ilẹ Africa de ipo ti yoo 'se itẹwọgba loju gbogbo aye, ti yoo si le figa-gbaga pẹlu ẹnikẹni, ṣugbọn eyi ko ti ṣẹlẹ.''
Bisi Alimi: Ìyà mi rò pé n kò leè ṣe ni àmọ́ n kò ní ìfẹ́ abo ni mo ṣe fẹ́ akọ
Lori ọrọ eto idibo gbogboogbo to kọja, Soyinka sọ pe eto idibo ọdun 2019 jẹ ọkan lara awọn idibo to ti i bani lọkan jẹ julọ ni Naijiria.
'Fun emi gẹgẹ bi ẹnikan, ko ṣeesẹ fun mi lati yan ẹnikan laarin Aarẹ Muhammadu Buhari ati Atiku Abubakar - awọn mejeeji lo ni ìtàn to n tọ wọn lẹyin, eyi to mu ki eeyan wa ọna abayọ mi.
Ifọrọwanilẹnuwo pẹlu Ọjogbọn Wọle Soyinka
Ondo Police: À ń wá Deji Adenuga tó dáná sun ènìyàn mẹ́jọ
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ileeṣẹ ọlọpaa nipinlẹ Ondo ti fidi rẹ mulẹ pe lootọ ni ọmọkunrin kan dana sun mọlẹbi ọrẹbinrin rẹ nigba kan.
Alukoro ileeṣẹ ọlọpaa ipinlẹ naa, Fẹmi Joseph sọ fun BBC Yoruba pe, ọdọmọkunrin naa, Deji Adenuga ti awọn eniyan tun mọ si Dakar, ni wọn fura si pe o dana sun mọlẹbi naa ni ilu Igbodigo, nijọba ibilẹ Okitipupa l'oru ọjọ Aiku mọju ọjọ Aje, laarin aago meji si mẹta.
Joseph sọ pe ọmọkunrin naa n fẹ ọmọbinrin kan ninu ẹbi naa , Titi Saanu, ko to o di pe Titi ja okun ifẹ naa pe oun ko ṣe mọ.
Eyi lo si mu ki Deji fi ibinu lọ dana sun ẹbi Titi mọle.
Bisi Alimi: Ìyà mi rò pé n kò leè ṣe ni àmọ́ n kò ní ìfẹ́ abo ni mo ṣe fẹ́ akọ
'Nibayi, eniyan mẹjọ ti ku ninu ẹbi naa, nitori bi ina ṣe jo wọn. Titi funra rẹ n bẹ ni ẹsẹ kan aye, ẹsẹ kan ọrun nileewosan.
Ọgbẹni Joseph sọ pe lati igba ti iṣẹlẹ naa ti waye, ni Deji ti sa kuro niluu, ti ileeṣẹ ọlọpaa si ti n wa.
NCC: Á gbógun ti àwọn èèyàn tí kò bá fi orúkọ nọ́mbà ìpè wọn sílẹ̀
Oríṣun àwòrán, @NgComCommission
Ajọ to n bojuto awọn ileesẹ ẹrọ ibanisọrọ lorilẹede Naijiria, NCC, ti ni iwe ofin Naijiria to nii se pẹlu idabobo orilẹede,ni awọn yoo lo fi gbogun ti awọn ti ko ba se iforukọsilẹ 'Sim Card' wọn kaakiri orilẹede Naijiria.
Olori ẹka to n risi imusẹ ofin Ajọ NCC, Efosa Idehen ni oju opo ibaraẹnisọrọ Facebook ajọ naa sọ wi pe, ọpọlọpọ awọn jandugu lo n lo awọn 'Sim Card' ẹbu fun ijinigbe lati gba owo ẹmi.
Idehen ni o le ni miliọnulọna marundinlọgọjọ awọn ọmọ Naijiria to ti bẹrẹ iforukọsilẹ wọn, amọ ti idamẹta awọn nọmba wọnyii jẹ ẹbu nitori wọn ko pari iforukosilẹ naa tabi awọn ọrọ akọsilẹ wọn ko barajọ, eleyii to jẹ ko lufin ajọ NCC.
O rọ awọn ile isẹ imọ ẹrọ ibanisọrọ ati eyi to n se 'Sim Card lati fi aabo ilu saaju ohunkohun, ki wọn ba le ri wi pe `aabo awọn ara ilu jọ wọn loju, ki itẹsiwaju le ba orilẹede Naijiria.
Bakan naa, ajọ naa wa ke si awọn ọmọ Naijiria pe ki wọn ma mikan nitori awọn ko ni fi ọrọ akọsilẹ wọn lede afi ti o ba niise pẹlu eto aabo lorilẹede Naijiria.
Bisi Alimi: Ìyà mi rò pé n kò leè ṣe ni àmọ́ n kò ní ìfẹ́ abo ni mo ṣe fẹ́ akọ
Ajọ naa wa parọwa si gbogbo awọn ti ọrọ naa kan lati ri wi pe wọn se ojuse wọn ki eto aabo orilẹede naa ma ba a mẹhẹ.
Ajọ to n bojuto ẹrọ ibanisọrọ lorilẹede Naijiria, NCC, ti ni awọn ọmọ Naijiria ti wọn n lo ‘Sim Card’ ti ko ni iforukọsilẹ to miliọnu lọna ọgọrun.
Kọmisọnna fajọ NCC, Sunday Dare lo fi ọrọ naa lede ni ilu Port Harcourt lasiko to n se ilanilọyẹ fun awọn eniyan ni agbeegbe naa.
Dare ni ‘Sim Card’ awọn eniyan miran di ofutufẹtẹ nitori wọn ko tẹ ika wọn daradara soju ẹrọ ti wọn fi se iforukọsilẹ, ati wi pe wọn ko fi aworan wọn si ibẹ daradara.
O ni lara ijamba ti iforukọsilẹ ni wi pe eniyan to ba jẹbi ẹsun naa le fi ẹwọn ọdun mẹẹdọgbọn jura lori ẹsun pe o pa irọ orukọ rẹ labẹ ofin.
Bisi Alimi: Ìyà mi rò pé n kò leè ṣe ni àmọ́ n kò ní ìfẹ́ abo ni mo ṣe fẹ́ akọ
Ajọ naa wa fikun wi pe awọn yoo bẹrẹ si ni da awọn eniyan pada si gbogbo ibudoko ti wọn yoo ti lo tun iforukọsilẹ naa se.
Owó làwọn olóṣèlú mọ̀ ni wọ́n ṣe fẹ́ kí dókítà lọ sókè òkun - NMA
Oríṣun àwòrán, @Gebrekiros
Ẹgbẹ awọn dokita lorilẹede Naijiria, NMA ti bu ẹnu atẹ lu ọrọ ti minisita fọrọ isẹ, Chris Ngige sọ wi pe, awọn dokita pọ yanturu lorilẹede Naijrria, nitorina aaye si silẹ fun awọn dokita to ba fẹ kuro nilẹ yii lọ si oke okun.
Aarẹ ẹgbẹ awọn Dokita, Dokita Adedayo Faduyile lasiko to ba BBC sọro ni, awọn dokita ko to ni Naijiria nitori wi pe dokita kan lo n tọju si ẹgbẹta eniyan lo yẹ kojẹ , amọ o le ni ẹgbẹwa eniyan to n lo dokita kan.
Faduyile ni owo ni awọn oloselu mọ ni wọn se n faramọ ki awọn dokita ma a lọ si oke okun, amọ o ni ohun to buru ni ki awọn eniyan ma ni eto ẹkọ to peye lorilẹede naa.
Bisi Alimi: Ìyà mi rò pé n kò leè ṣe ni àmọ́ n kò ní ìfẹ́ abo ni mo ṣe fẹ́ akọ
O parọwa si ijọba lati jẹ ki ilera awọn ọmọ orilẹede naa jẹ awọn ijọba loju, ki wọn si se ohun to to lati ri wi pe awọn ọmọ Naijiria jẹ anfaani eto ilera to peleke.
Bẹẹ ba gbagbe, minisita fọrọ osisẹ, Chris Ngige lo ti sọ saaju pe awọn dokita ti pọ ju lorilẹede Naijiria, eyi to ba si wu ninu wọn lee kọri si oke okun lati wa isẹ aje lọ.
Oríṣun àwòrán, WHO
Ngige, ẹni to sisọ loju ọrọ̀ yii lasiko to n opa lori eto kan lori mohunmaworan tun fikun pe, ko si ohun to buru ninu kawọn dokita yii ko aasa wọn lọ si oke okun niwọn igba ti wọn yoo maa fi owo ilẹ okeere ransẹ sile.
Ido-Ani Robbery: Àhámọ́ làwọn afurasí náà yóò wà di ọjọ́ Kejì oṣù Karùn-ún
Awọn maarun lo foju ba ile ẹjọ ti ẹnikẹfa wọn to ku ti na papa bora
Ile ẹjọ magistireti to wa nilu Akure ti paṣẹ ki wọn ti awọn adijunjale mẹfa, ti wọn funra si pe wọn kopa ninu ikọlu ile ifowopamọ kan ni Idoani si ahamọ.
Ni nnkan bi oṣẹ meji sẹyin ni wọn mu wọn lori ẹsun pe wọn kopa ninu idigunjale bankii naa nibi ti eeyan meje ti padanu ẹmi wọn.
Adajọ Victoria Bob Manuel to paṣẹ yii ṣe bẹẹ lẹyin atotonu lati ọdọ awọn agbẹjọro ijọba ati tawọn afunrasi naa.
Offa Robbery: Àwọn aráàlú ṣi n gbé nínú ìpaya lẹ́yìn ọdún kan
Ninu idajọ rẹ, o ni ki wọn fi awọn adigunjale naa si ahamọ titi di ọjọ keji oṣu Karun un titi di igba ti adari ẹka olupẹjọ yoo fi gbawọn ni imọran to yẹlori ẹjọ naa.
Awọn ọlọpaa ti fi ọkọ wọn gbe awọn afunrasi naa pada si ahamọ.
Maarun un  ninu awọn adigunjale naa lo yọju siwaju adajọ lati jẹjọ lori ẹsun ti wọn fi kan wọn.
Ẹnikẹfa wọn la gbọ pe o ti na papa bora.
Oríṣun àwòrán, Thenationonline
Wọn fi agidi mu awọn oṣiṣẹ ileefowopamọ lati ṣi ilẹkun rẹ, ṣugbọn owo ti wọn ba nibẹ ko jọ wọn loju rara.
Bi a ko ba gbagbe, awọn adigunjale naa ko ibọn ati awọn ohun ija oloro miran lọwọ, ti wọn si yabo ile ifowopamọ First Bank to wa ni Idoani lọjọ Kẹjọ osu Kerin ọdun 2019.
Nigba ti wọn yoo fi pari iṣẹ aburu wọn, ẹmi meje lo ba iṣẹlẹ naa lọ.
Man Utd Vs Man City: Kò ṣèlẹ́rí! àwọn alatilẹyin Liverpool yóò gbè lẹyìn Man Utd
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Lalẹ oni, nkan ti ko fẹ ṣẹlẹri lagbo ere boolu Premiership yoo ṣẹlẹ.
Awọn alatilẹyin ẹgbẹ agbabọọlu Manchester United yoo gbe lẹyin Manchester City ti awọn ti Liverpool yoo si ma gbadura ki Manchester United fẹnu Man City gbole.
Ọrọ naa ri bakan abi? Bẹẹni awa na ti ṣe ro amọ ifẹsẹwọnse ti yoo waye lale oni lo mu ki orẹ di ọta ki ọta si di ọrẹ.
Lori afara liigi Premiership, ọrọ ipo kini ti di fa-kinfa laarin ẹgbẹ Manchester City ati Liverpool ti esi ifẹsẹwọnsẹ laarin Man United ati Man City lalẹ oni yoo si jẹ atọna ẹni ti yoo gba liigi ọdun yi.
Lọwọlọwọ, ami ayo kan ni Liverpool fi n lewaju Manchester City ti o si jẹ wi pe ti Man City ba fi le bori Man United, awọn ni yoo di ipo kini mu saaju Liverpool.
Ti Man City ba fidi rẹmi lọwọ Man U, Liverpool yoo sunmọ ki wọn gba liigi, eyi ko si jẹ nkan ti awọn alatilẹyin Man U faramọ.
Kaka ki Liverpool gba liigi, wọn ko ni kọ ki Man City gba amọ ki eleyi to le ṣẹlẹ wọn yoo fara gba idojuti ki Man City bori wọn.
Hmmm ọrọ naa buso si ni lẹnu to tun bu yọ si.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ọjọ ti pe ti ọta awọn mejeeji ti bẹrẹ ṣugbọn lnu igba ti liigi Premiership di ilumọka yi, awọn alatilyin wọn ko fẹ ri imi ara wọn lakitan.
Kii ṣe Liverpool nikan ni Manchester United ko nifẹ. Man City ti wọn jijọ wa nilu kanna kii ṣe ẹni ti wọn jijọ n fẹyin si ara wọn.
Loju opo Twitter kaakiri, ero ọkan awọn alatilẹyin ẹgbẹ mẹtẹta, Man U, Liverpool ati Man City a ma farapera ti wọn a si tun ma yapa si ara wọn
Laago mẹjọ alẹ oni ni gbangba yoo dẹkun ti kedere yoo bẹẹ wo.
Bi Manchester United ni yoo bori ni bii Man City ni, ipade di ori papa.
Child marriage: $3,500 la gbà láti fa ọmọ ọdún márùn-ún f'ọ́kọ
Oríṣun àwòrán, iSok
Omobinrin
Ọdun marun ni Nazanin ti ni ọrẹkunrin ti yoo fẹ. Nigba ti yoo si fi pe ọdun mẹwaa, o ti di iyawo lọọdẹ ọkọ. Idile ọkọ rẹ to jẹ ọmọ ọdun mejila ra a ni $3,500 ni dun mẹfa sẹyin.
Awọn obi rẹ ta a lati le kowo jọ fi tọju ọmọkunrin wn to wa ń ṣaisan iyẹn, aburo Nazanin.
Irora yii pọ fun ọmọ mi ọkunrin. nigba ti mo wo oju rẹ, mo ro o wi pe ki a gba owo naa. Baba Nazanin kọkọ lra tikọ ṣugbọn emi ni mo mu ọkọ mi lọkan le pe ko gba owo naa lati ta ọmọ wa obinrin. Iya ọmọ naa lo sọ eyi, o n gbe ni ibudo awọn ti ko rile gbe ni Shahrak e Sabz lẹba Herat, iwọ oorun Afghanistan.
Ọmọ meje ni baba ati iya Nazanin bi - obinrin mẹta ati ọkunrin mẹrin. Wọn o lọ ile iwe rara debi ti wọn yoo mọ ọ kọ tabi mọ ọ ka. Ko s'owo ko si iṣẹ.
Akọroyin BBC, Yasini Inayatulhaq ba idile yii sọ̀rọ̀ lori ipinu wọn lati ta ọmọ wọn.
"Baba ni ""lati ọmọ ọdun mẹrin ni aisan warapa ti n yọ ọmọkunrin wa lẹnu a o si lowo fun itọju rẹ"""
Nigba ti titiraka yii pọ lati doola  mi ọmọkunrin wọn ni ẹbi gba lati ta ọmọbinrin wọn.
"Mo gba owo mo si fi ọmọ wa obinrin to dagba ju le ọkọ. Mo fi owo ọhun san owo itju ọmọ mi ọkunrin. Ṣugbọn aisan to n ṣee ko gbọ bẹẹ si ni mi o le gba ọmọ ti mo ta pada ni iya wi.
Bi ẹnikẹni ba ta ọmọ rẹ ni ọna yii, o daju yoo kabamọ. Emi gan kabamọ sugbọn ko wulo mọ ni baba sọ."
Igbeyawo ọmọde
Ni orilẹede Afghan, ọdun ti ofin faaye gba ki ọmọ ṣe igbeyawo ni ọdun mẹrindinlogun fun ọmọbinrin ati mejidinlogun fun ọmọ ọkunrin. Ṣugbọn ọpọ lo ṣeyawo lai ti to awọn ọdun yii.
Gẹgẹ bi akọsilẹ ajọ Unicef ṣe sọ ọ, ida marundinlogoji ọmọbinrin Afghan lo ti maa wa nile ọk nigba ti wọn ba fi pe ọdun mejidinlogun, ida mẹsan wọn si lo ti ṣeyawo ki wn to pe ọdun mẹẹdogun.
Gbígbé nínú ìrètí
Lọwọ lọwọ, idunu jina si idile naa nitori wọn ni ko si ẹnikẹni lati ran wọn lọwọ. Eyi si n mu inu bi ọmọde ti wọn sọ di iyawo.
"Iya rẹ ni, ""Nazaninn sọ fun mi: Mama mi, ẹ ta mi lọmọde ṣugbọn ara ẹgbọn mi ko tii ya. O tun wa ni 'ṣugbọn ara aburo mi yoo ya emi naa yoo si dagba. 'Mo kabamọ pe mo fii fọkọ ṣugbọn mo ṣi ni ireti ọjọ ọla to dara"". Eyi ni iya rẹ sọ."
(A pa orukọ Nazanin da ni lati le da abo bo o)
Mike Zhang dì ọmọ China akọkọ tí wọ́n f'oye dá lọla ní ìpínlẹ̀ Kano
Báyìí ni ayẹyẹ wíwé láwàní fún ọmọ China, olóyè Zhang ṣe lọ
A o ri iru eleyi ri, a fi dẹru ba ọlọrọ ni. Bi eeyan ba si rin jina, yoo ri abuke ọkẹrẹ.
Bi ọrọ naa ṣe ri re nilu Kano nigba ti arakunrin ọmọ orileede China kan di akọkọ ọmọ orileede rẹ ti wọn yoo fi jẹ oye nipinlẹ Kano.
Onisowo Mike Zhang to ti lo ọdun mẹtadinlogun ni Kano ni, niṣe ni inu oun dun pẹlu ọla ti wọn da oun yi.
O ni oun yoo ṣapa lati rii wi pe awọn  ọmọ orileede China to wa ni Kano yoku pawọpọ lati ni ibaṣepọ to dara pẹlu awọn eeyan Kano.
Emir ilu Kano, Muhammad Sanusi ṣalaye pe idi ti oun fi fi oye da Zhang lọla ni pe o ni ipa rere laarin igba ti o lo ni ipinlẹ naa.
Awọn ọmọ China miran kọwọrin pẹlu rẹ nibi ayẹyẹ naa
"O ni ""Wakilin Yan China, mo ki ọ ku orire, o ti jẹwọ pe o ni ipa rere, mo si lero wi pe oye yii yoo mu ki o tẹramọ iṣe daada ti a mọ ọ si''"
Ojojumọ ni iye ọmọ China to n ṣowo nipinlẹ Kano n pọ sii. Lẹka awọn oniṣowo aṣọ, to fi mọ tita oogun apakokoro ati bata , awọn ọmọ China ko gbẹyin.
Awọn kan ri oye yii gẹgẹ bi ohun to n tọka si ipa ti orileede China ni kaakiri ilẹ Afrika, ti awọn kan si n bẹru pe laipẹ China yoo gba akoso ọpọlọpọ ẹka mọ awọn eeyan Afrika lọwọ.
Zhang ni oludasilẹ ile iṣẹ to n pese omi mumu
O le ni ẹgbẹrun marun un ọmọ orileede China to n gbe ni Kano.
Alaga awọn ile iṣe to n pese nkan nipinlẹ Kano, Umar Marshall ni oun idunnu ni oye yii nitori ko si awujọ ti o le ni itẹsiwaju lai fi tawọn ajoji ṣe.
World Malaria Day:Kí gaan láwọn nkán tó n fa àìsàn ibà?
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Oriísirísi ǹkan ni àwọn ènìyàn gbà wí pé o ma ń fa àìsàn ibà sí ara ènìyàn, àmọ́ tí kìí se òtító.
Ọpọlọpọ ariyanjiyan lo n lọ lori awọn nkan ti o ma n fa aisan iba si ara awọn eniyan, paapaa ni ilẹ adulawọ.
Bi awọn eeyan ko ba di ẹbi aisan naa ru wiwẹ ninu ojo,wọn a ni jijẹ agbado sisun a ma mu iba wa.
Amọ ki gaan lawọn ohun to jẹ ojulowo to n fa aisan iba?
Dokita onimọ ijinlẹ nipa aisan, Tunji Abolarin salaye fun BBC pe irọ ni wi pe ẹni ti ojo ba pa le e ni aisan iba, ati wi pe ẹrọ amuletutu kii pa ẹfọn.
Dokita Abolarin lasiko to n sọrọ ni efọn to ni iba lara nikan lo lee fa iba si ara eniyan, ati wi pe iru ẹjẹ ti eniyan ni lee jẹ ki iba tete wọ eniyan lara.
O fikun wi pe nitori otutu, ẹfọri ati ara riro wa lara awọn apẹrẹ to ma n fi aisan iba han lo jẹ ki awọn eniyan ti ojo ba pa, ti aisan iba si ti wa lara wọn sọ wi pe ojo ma n fa aisan iba.
Bakan naa ni dokita naa ni ti ayika ba tutu, o see se ki ẹfọn ma le e raye nibẹ ju igba ti ayika ba gbona, eleyii ti o ma n waye lọpọ igba ni ilẹ Afirika.
Wo bí obìnrin ṣe lè kun ojú pá pà pá
Nigeria Police: Ọ̀gá àgbà dín wákàtí iṣẹ́ ọlọ́pàá kù 'torí wàhálà
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ọga agba ileeṣẹ ọlọpaa Naijiria, Mohammed Adamu ti paṣẹ pe ki adinku de ba iye wakati ti awọn ọlọpaa fi n ṣiṣẹ l'ojoojumọ.
Ọgbẹni Adamu to sọ ọrọ naa lasiko to n ṣi ipade ijiroro kan to waye laarin awọn ọga lawọn ileewosan ileeṣẹ ọlọpaa ni olu ileeṣẹ naa sọ pe ki adinku de ba a lati wakati mejila di mẹjọ.
Ọga agba ọlọpaa sọ pe igbesẹ naa waye nitori awọn ẹsun pe ọlọpaa ṣeeṣi yinbọn, pa araalu lọna ti ko ba ofin mu, nitori pe o ti rẹ wọn nitori wahala ti wọn ṣe l'ẹni iṣẹ, eyi to n ni ipa lara ihuwasi ati afojusun wọn.
Adamu ṣalaye pe ''ohun ti eyi tumọ si ni pe ileeṣẹ ọlọpaa gbọdọ wa ọna tuntun lati maa ṣe iṣẹ wọn, ati iru anfaani ti araalu n jẹ l'ara wọn ni gbogbo ọna ti awọn ọlọpaa n gba ṣe iṣẹ wọn.''
African Drum Festival 2019: Orílẹ̀èdè 23 ló kópa níbi àjọ̀dún ìlù ọdún 2019
Ni aye atijọ, awọn ìlú nilẹ Yoruba ati kaakiri ilẹ Afrika maa n lo ìlù lati ba ara wọn sọrọ. Ìró ilu maa n jẹ ọna ibaraẹnisọrọ laarin eniyan meji tabi ju bẹẹ lọ, bi ẹrọ ibaraẹnisọrọ ṣe ri l'ode oni.
Oriṣiriṣi ọrọ aṣiri si ni awọn eniyan maa n lo ilu lati sọ, ẹni to ba si ni eti ilu nikan ni ọrọ naa le ye.
Ajọdun ilu nilẹ Afrika to maa n waye ni ipinlẹ Ogun l'orilẹede Naijria jẹ afihan ati ṣiṣe ajọyọ ipa ti ilu n ko nilẹ Afrika.
Oríṣun àwòrán, African Drum Ferstival/Facebook
Ọdun 2016 ni gomina ipinlẹ naa, Ibikunle Amosun fi ajọdun naa le lẹ. Ẹlẹẹkẹrin si ni ti ọdun 2019  to n waye nilu Abẹokuta, tii ṣe olu ilu ipinlẹ Ogun.
Àwòrán ayẹyẹ ajọ̀dún ìlù nílú Abẹ́òkúta
Àjọ̀dún ìlù bẹ̀rẹ̀ nílú Abẹ́òkúta
Ninu ọrọ to sọ ṣaaju ki ajọdun ọlọjọ mẹta naa to bẹrẹ l'ọjọ kẹẹdọgbọn, oṣu Kẹrin, Gomina Amosun sọ pe yatọ si ipinlẹ mẹrindinlọgbọn ni Naijiria ti yoo kopa nibi ajọdun naa l'ọdun yii, orilẹede ilẹ Afrika mọkanlelogun, to fi mọ orilẹede UK ati China ni yoo kopa.
Oriṣiriṣi ọrọ aṣiri si ni awọn eniyan maa n lo ilu lati sọ, ẹni to ba si ni eti ilu nikan ni ọrọ naa le ye.
Yatọ si awọn onílù to maa n kopa, awọn akọrin, awọn arinrinajo afẹ ati awọn to fẹran aṣa naa kii gbẹhin nibi ajọdun naa.
Ajọdun ilu nilẹ Afirika
Bakan naa ni afihan ijo ati aṣọ oriṣiriṣi ẹya kaakiri Naijiria maa n waye.
Ko yọ ọmọde silẹ, ko si yọ agba silẹ gẹgẹ bi akọroyin BBC ṣe ṣe alabapade awọn ọdọmọbinrin ibeji kan to jẹ ọmọ ọdun mọkanla ti wn si ti n lu ilu lati ọdun mẹta.
Oríṣun àwòrán, AFrican Drum Festival
Ajodun ilu
Ajodun ilu
Buhari fi ọ̀kadà, ọkọ̀ àti $500,000 ta orílẹ̀èdè Guinea Bissau l'ọ́rẹ fún ètò ìdìbò wọ̀n
Oríṣun àwòrán, MBuhari/Twitter
Aarẹ orilẹede Naijiria, Mohammadu Buhari ti fi ọwọ si pe ki wọn o ko ọtalelọọdunrun din mẹwa irinṣẹ idibo, ọkada mẹwaa, to fi mọ ọkọ Hilux maarun ati ọkọ akẹru meji fun orilẹede Guinea-Bissau.
Bakan naa lo fun orilẹede naa ni ẹgbẹrun lọna ẹẹdẹgbẹta Dọla lati fi ran an lọwọ fun eto idibo to fẹ ẹ ṣe.
Aarẹ Buhari paṣẹ fun Minisita fun ọrọ ilẹ okeere, Geoffrey Onyeama lati tete jẹ iṣẹ naa fun orilẹede ọhun nitori ipe iranlọwọ pajawiri ti oun gba lati ọdọ ijọba wọn.
Buhari to jẹ Alaga awọn olori orilẹede to wa ninu ajọ ECOWAS buwọlu pe ki minisita naa rinrinajo naa pẹlu Aarẹ ECOWAS, Jean-Claude Brou, lati ṣoju oun l'orilẹede Guinea.
Gẹgẹ bi aarẹ ṣe sọ, igbesẹ naa ṣe pataki lati ri i daju pe eto idibo to fẹ ẹ waye ni Guinea Bissau yoo mu nkan pada bọ sipo l'orilẹede naa.
Èyí ni bí àwọn agbébọn ṣe gbé òṣìṣẹ́ Shell méjì, wọ́n tún pa àwọ̀n aláàbò wọ̀n ní Rivers
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ileeṣẹ elepo Shell jẹ ọ̀kan pataki lara awọn ileeṣẹ to n pese epo bẹtiro ni Naijiria
Ọga gba meji nileeṣẹ elepo rọbi Shell ko ti i di riri lẹyin ti awọn ajinigbe gbe wọn, ti wọn si tun pa awọn ọlọpaa to n daabo bo wọn.
Iṣẹlẹ naa waye lasiko ti awọn oṣiṣẹ naa n pada si ilu Port Harcourt lati irinajo ẹni iṣẹ ti wọn rin lọ si ipinlẹ Bayelsa.
Awọn agbebọn naa pa awọn oṣiṣẹ alaabo ọhun, ti ọ̀kan lara wọn jẹ awakọ ọkọ̀ to gbe wọn, ki wọn to o gbe awọn oṣiṣẹ meji naa.
Agbẹnusọ kan nileeṣẹ ọlọpaa sọ pe igbesẹ ti n waye lati doola wọn.
Wọn ko si ti i fi orukọ awọn to kagbako iṣẹlẹ naa sita.
Agbẹnusọ ileeṣẹ elepo Shell ninu atẹjade kan sọ pe ''Ileeṣẹ Shell kabamọ lati fidirẹmulẹ pe ikọlu waye si awọn oṣiṣẹ rẹ ati awn alaabo ijọba ni Rumuji, loju ọna East/West nipinlẹ Rivers.
Unko Museum yìí n ran àwọn ènìyàn lọ́wọ́ láti rí ìgbọ̀nsẹ̀ bí nkan tó rẹwà
Igba akọkọ kọ niyi ti awọn ajinigbe yoo ji awọn ọmọ ilẹ okeere ni Naijiria.
Nibẹrẹ oṣu yii, obinrin kan to jẹ ọmọ orilẹede Britain jẹ ọ̀kan lara eniyan meji ti awọn agbebọn pa lasiko ti wọn kọlu ibudo igbafẹ kan niluu Kaduna.
Eniyan mẹta ni wọn jigbe nibi ikọlu naa.
Bakan naa l'oṣu Kinni ọdun 2018, ọmọ orilẹede America meji, ati Canada meji ni wọ̀n jigbe lasiko ti wọn n rinrinajo lati ilu Kafanchan nipinlẹ Kaduna lọ si ilu Abuja. Meji ninu awọn ọlọpaa to n sọ wọn ni wọn pa.
Lagos State: Oníṣòwò mẹ̀ta wọ gàù lórí títa pọ̀nmọ́ olóró
Oríṣun àwòrán, FACEBOOK/PONMO-IJEBU NEWYORK
Gbogbo ẹyin ti ẹ fẹran lati maa yi pọnmọ lata, ikilọ re e lori awọn pọnmọ oro kan to wa nita.
Ijọba ipinlẹ Eko lo fi ikilọ sita fun awọn ara ilu pe ki wọn ṣọra lati maa jẹ awọn pọnmọ oloro kan to wa lọja bayii.
Ijọba naa ni awọn ti mu eeyan mẹta ti wọn n ta awọn pọnmọ yii ni ijọba ibilẹ  Ọjọ ati Iba ti wọn si tun ko awọn pọnmọ oloro wọnyii lori igba wọn.
Ninu atẹjade kan ti Kọmisọna eto ilera nipinlẹ naa Dokita Jide Idris fi sita, ijọba ipinlẹ Eko lawọn ti ''ko awọn eeyan mẹta ti ọwọ tẹ lori pọnmọ oloro yii lọ si iwaju ile ẹjọ ti awọn si ti fi awọn pọnmọ naa ranṣẹ si ile ayẹwọ ile iṣẹ NAFDAC ti yoo sọ boya wọn ṣee jẹ''
Idris salaye ninu atẹjade naa pe ijọba  bẹrẹ si ni tojubọ ọrọ pọnmọ oloro yi lẹyin igba ti awọn kẹfin pe awọn kan n ta pọnmọ ni ago mẹrin si ago mẹfa aarọ lawọn aaye kan ni Ọjọ ati Iba.
O wa kilọ f'aralu pe ki wọn ṣe ayẹwo daada ki wọn to ra pọnmọ lọja ki wọn si tete ta awọn oṣiṣẹ  ijọba lolobo bi wọn ba funra si awọn ounjẹ kankan ti o ni kọnunkọhọ.
Ramadan: Àwọn ọlọ́pàá Sharia tí ń mú aṣéwó àti ọ̀daràn nípínlẹ̀ Kano
Oríṣun àwòrán, PIUS UTOMI EKPEI
Ramadan Fast: Àwọn ọlọpàá Sharia tí n mú aṣewo àti ọdaràn nípìnlẹ̀ Kano
Àwọn ọlọ́pàá Sharia tí mú àwọn ènìyàn to lé ni ààdọta ti wọn funra si gẹ́gẹ́ bi aṣẹwó àti ọdaran lójúnà àti  mú àdínku bá ìwá ẹsẹ̀ lásiko ààwẹ ramadani tó ń bọ̀.
Agbẹnusọ Hisbah tí a mọ si ọlọpaa Sharia Adamu Yahaya sàlàyé fún BBC pé ìgbésẹ̀ náà jẹ òhun ti wọn máa ń ṣe ni gbogbo ìgbà gẹ́gẹ́ bi imúrasilẹ̀ de osù ramadani pàápàá jùlọ àwọn agbegbe ti àwọn ǹkan burúkú ti máa ń ṣẹlẹ̀ láti lé ri pé àwọn ènìyàn Kano gbé aradi dé ààwẹ.
'500 level'' ni mo wà nígbà tí mo di adélé Ọba'
Lọ́dọọdún kí ààwẹ ramadan tó dé ni à  máa àkanṣe jákejádo láti mú àwọn tó ń hu ìwà ti kò bójú mu nílana ẹsin wa. Àsìkò ààwẹ jẹ àsikò ti ó dára jùlọ ni àyíká yìí a si fẹ ki àwọn ènìyàn sín ọlọrun kíkó irú àwọn ènìyàn báyìí kúro  ilẹ yóò mú ki àwọn ara ilú le pa ọkan wọn pọ si ojú kan láti lé ṣe iṣẹ́ ẹsin fún Ọlọrun.
Ó ku ọ̀sẹ̀ kan gbáko ló kùn ti gbogbo Musulumi lágbaye yóò bẹ̀rẹ̀ ààwẹ ọlọgbọ̀n ọjọ ti a mọ si oṣu ramadan.
Oríṣun àwòrán, kano
Sááju ààwẹ Ramadan Àwọn ọlọpàá Sharia n mú aṣewo àti ọdaràn nípìnlẹ̀ Kano
Ipínlẹ̀ Kano jẹ ọkan nínú àwọn ìpínlẹ̀ Nàìjíríà to ń lo ofin Sharia ti Hasbah si dúro gẹ́gẹ́ bii ọlọpàá ẹsin fún ipinlẹ̀ náà.
Yahaya fí kún pé ti àwọn ba wa mú ẹnikẹni to si lé mú àrídaju jáde pe òun kìí ṣe aṣẹ́wó tàbí ọ̀daràn, àwọn ó dáa silẹ̀ láti maa lọ.
"À ń bá àwọn onímọ ṣiṣẹ. Ní ọ̀pọ̀ ìgbà à ní àwọn ọtẹlẹ̀múyẹ ní àwọn bi a ti lọ ń ko àwọn aṣẹ́wó tàbi ọdaran. Ní ọ̀pọ̀ ìgbà ni ǹkan ti à  ń ṣe máa ń jẹ òòtọ sùgban ti a ba mú wọn tán ti wọn si ni ẹ̀rí máa jẹ mi nìsó à ó fi ẹni náà silẹ̀ nígba ti àwọn ti igbá ba ṣímọ lóri yóò fi ojú ba ile éjọ
Deji Adenuga : Ìdí tí mo fí jó èèyàn mẹsan mọ ilé
Deji Adenuga : Ìdí tí mo fí jó èèyàn mẹsan mọ ilé
Arakunrin ti ọlọpaa ṣe afihan rẹ nitori pe o dana sun mọlẹbi ọrẹbinrin rẹ mẹsan mọle ti salaye ohun to mu hu iru iwa bẹ.
Deji Adenuga nigba ti o n ba akọroyin sọrọ ṣalaye pe nitori pe ọrẹbinrin oun gba ẹgbẹrun lọna ogun Naira lọwọ ohun ti o si kọ lati fẹ ohun loun ṣe dana sun ile pa awọn mọlẹbi rẹ.
Lọjọ Iṣẹgun ni o sọ ọrọ yi lasiko ti ileeṣẹ ọlọpaa nilu Akure ṣe afihan rẹ.
Bi a ko ba gbagbẹ,Ọwọ ọlọpaa nipinlẹ Ondo tẹ afunrasi naa ti wọn lo mọ nipa bi ina ṣe jo eeyan mẹsan mọle nilu Akure.
Lọjọ Aje tii ṣe ọjọ ọdun Ajinde to kọja ni iroyin gbode pe ọwọ tẹ afunrasi naa, Deji Adenuga labẹ afara lẹba ibudoko ni ilu Ijebu Ode.
Gẹgẹ bi ohun ti awọn oniroyin to wa lagbegbe naa sọ, agbẹnusọ fun ileeṣẹ ọlọpaa  Femi Joseph ni awọn yoo ṣafihan afunrasi ọ̀hún faraye.
Bi a ko ba gbagbe, lọjọ Iṣẹgun to kọja ni iroyin gbode ladugbo Igbodigo nilu Okitipupa nibi ti awọn mọlẹbi kan ti padanu ẹmi wọn nigba ti eeyan kan sọ ina si ile wọn.
Ohun ti agbẹnusọ ọlọpaa Femi Joseph sọ nigba naa ni pe arakunrin kan Deji Adenuga lo sọ ina si ile ọrẹbinrin rẹ nitori ti o ni oun ko ṣe mọ.
Lati igba naa ni ọlọpaa ti bẹrẹ si ni wa arakunrin yii titi ti ọwọ fi wa tẹ ẹ bayi.
Ìbejì Àyànbìnrin tó ti ń di gbajúgbajà
Zainab Habib Arábìnrin wà ní àhámọ́ ní Saudi lórí ẹsùn tí kò mọ
Oríṣun àwòrán, Hajara Habib
Aworan Zainab Habib
Awọn akẹkọ fasiti Yusuf Maitama Sule nilu Kano yoo ṣe iwọde lọjọ Iṣẹgun tori akẹgbẹ wọn kan Zainab Habib Aliyu ti wọn fẹsun gbigbe ogun oloro kan lorileede Saudi.
Oṣu Kejila ọdun 2018 ni awọn agbofinro nilẹ naa mu Zainab nigba ti o lọ ṣe Umrah. Wọn fẹsun kan pe o gbe oogun oloro.
Ohun ti a gbọ ni pe awọn kan ni wọn fi oogun oloro naa sinu ẹru rẹ ati pe ko si mọ nipa rẹ titi ti wọn fi mu u ni Saudi.
Lati igba naa titi di bi a ti ṣe n sọrọ yii, Zainab to jẹ akẹkọ fasiti Yusuf Maitama Sule ṣi wa ni atimọle.
Ìbejì Àyànbìnrin tó ti ń di gbajúgbajà
Bawo ni wọn ṣe mu u?
Zainab lọ si orileede Saudi lati lọ ṣe Umrah ṣugbọn ko rii ṣe nitori ọjọ to de ibẹ naa ni wọn mu u.
Nilu Madinah ni wọn ti mu Zainab niṣoju iya rẹ  ati ọmọ iya rẹ ninu ile itura ti wọn de si.
Niṣe ni wọn wa si iyara wọn ti wọn si bẹrẹ si ni tu ẹru rẹ pe awọn ri ogun oloro ninu baagi rẹ tori naa o di dandan ko tẹle wọn.
Ọmọ iya rẹ Hajara to ba BBC sọrọ sọ pe ojojumọ lawọn n ba Zainab sọrọ.
''Nigba myi yoo ba ọkan jẹ, nigba mii ara rẹ yoo ya si wa ti a ba fun un ni iroyin bi ẹjọ rẹ ṣe n lọ si''
Oríṣun àwòrán, Hajara Habib
Zainab,,Iya rẹ ati ọmọ iya rẹ saaju ki wọn to mu
Awọn wọ lo ṣakoba fun Zainab?
Awọn alaṣẹ lorileede Naijiria sọ pe awọn ti mu eeyan meje to lọwọ ninu bi ogun oloro ṣe de inu ẹru Zainab.
Ajọ to n risi ọrọ to niṣe pẹlu gbigbogun ti lilo ogun oloro, NDLEA ṣe iwadii lori ọrọ Zainab ti wọn si ni ọwọ ti tẹ eeyan meje to n ṣiṣẹ ni papakọ ofurufu Aminu Kano.
Ẹwẹ, ijọba Naijiria ti tẹnu bọ ọrọ naa bayii.
Oluranlọwọ agba si Aarẹ Buhari lori ọrọ ilẹ okere Abike Dabiri ni Aarẹ ti paṣẹ ki olugbẹjọ agba wa wọrọkọ fi ṣada ki wọn si rii wi pe o lojutu.
Orileede Saudi Arabia kii fi ọrọ gbigbe ogun oloro ṣere rara.
Idajọ iku ni wọn ma n da fun pupọ awọn ti ọwọ ba tẹ wi pe wọn gbe ogun oloro.
Awọn akẹkọ fasiti Yusuf Maitama Sule ni Kano to fẹ ṣe iwọde naa lero wi pe ijọba yoo gbe igbesẹ kiakia lori ọrọ Zainab ki o ba le pada wa sile.
'500 level'' ni mo wà nígbà tí mo di adélé Ọba'
Zainab Habib:Zainab Habib tí ilẹ̀ Saudi Arabia pa irọ́ mọ́ pé o gbé cocaine tí gba sabuké NYSC!
Zainab Aliyu: Orílẹ̀-èdè Saudi túu sílẹ̀ lẹ́yìn oṣù mẹ́rin tó it wà ni ahámọ́ balẹ̀
Zainab Habib Aliyu ti ijọba orilẹede Saudi Arabia fi ẹsun kan pe o gbe oogun oloro ni ọjọ kini ana ti pari agunbanirọ rẹ.
Loṣu Kejila, ọdun 2018 ni awọn alaṣẹ ni orilẹede Saudi Arabia mu Zainab lasiko to lọ kopa ninu ijọsin Umrah pe o gbe oogun oloro.
Ọdun 2019 ni ijọba Naijiria kede pe arabinrin naa ti gba ominira, ti o si pada walẹ si Naijiria.
Adari ileeṣẹ to n risi ọrọ awọn ọmọ Naijiria to wa ni oke okun, Abike Dabiri-Erewa lo fi oju opo ikansiraẹni Twitter rẹ.
Abike Dabiri-Erewa gbadura wi pe ọna rẹ a dara.
Bi wọn ṣe fi ọmọbinrin naa sẹwọn, ni ijọba bẹẹrẹ iwadii to tu aṣiri pe awọn ikọ oloogun oloro kan lo maa n fi ọgbọn gbe oogun oloro sinu ẹrù awọn eniyan to n lọ si Saudi Arabia.
Aṣiri to tun ọhun lo mu ki wọn o yọju si ọọfisi orilẹede Saudi to wa ni ilu Abuja lati bẹrẹ igbesẹ lori bi Zainab yoo ṣe gba ominira.
Ijọba Naijiria ti kede pe wọn Zainab Habib Aliyu to wa ni ẹ̀wọ̀n l'orilẹede Saudi Arabia lori ẹsun gbigbe oogun oloro ti gba ominira.
Oríṣun àwòrán, Ministry of Foreign Affairs
Zainab ati awọn oṣiṣẹ ileeṣẹ orilẹede Naijiria niluu Jeddah lẹyin ti wọn tu u silẹ l'ọgba ẹwọn.
Akọwe agba nileeṣẹ ijọba to wa fun ọ̀rọ̀ ilẹ okeere, Mustapha Suleiman lo kede iroyin naa sita nilu Abuja.
O ṣalaye pe nigba tijọba gbọ nipa bi wọn ṣe fi ọmọbinrin naa sẹwọn, ni ijọba bẹẹrẹ iwadii to tu aṣiri pe awọn ikọ oloogun oloro kan lo maa n fi ọgbọn gbe oogun oloro sinu ẹrù awọn eniyan to n lọ si Saudi Arabia.
Aṣiri to tun ọhun lo mu ki wọn o yọju si ọọfisi orilẹede Saudi to wa ni ilu Abuja lati bẹrẹ igbesẹ lori bi Zainab yoo ṣe gba ominria.
Awọn ẹ̀rí to wa nilẹ si lo mu ki awọn alaṣẹ Saudi tu ọmọbinrin naa silẹ.
Bí Zainab ṣe dèrò ẹ̀wọ̀n Saudi lórí ẹ̀sùn ògùn olóró tí kò mọ̀
Ìbejì Àyànbìnrin tó ti ń di gbajúgbajà
O ni ọmọbinrin naa ti wa pẹlu awọn alaṣẹ ọọfisi orilẹede Naijiria to wa ni Saudi Arabia.
Baba ọmọbinrin naa, Alhaji Habibi Aliyu sọ fun BBC pe awọn oṣiṣẹ ijọba apapọ ti pe oun lori ẹrọ ibanisọrọ pe ọmọ oun ti gba ominira.
O ni botilẹjẹ wi pe oun ko ti i ba ọmọ oun sọrọ, ọkan oun balẹ bayii.
'Mo ṣẹṣẹ gba ipe naa tan ni, koda mi o le sọ bi inu mi ṣe dun to. Oni jẹ ọkan lara awọn ọjọ ti inu mi dun ju l'aye.
Bakan naa ni Alhaji Aliyu sọ pe nkan to ṣẹlẹ si ọmọ oun fihan pe ọpọ alaiṣẹ lo n jiya ẹsun ti wọn ko mọ nkankan nipa a rẹ.
Ẹwẹ, oluranlọwọ pataki fun aarẹ naa fi ikede itusilẹ rẹ sita loju opo Twitter rẹ.
Bakan naa, àwọn ọmọ Naijiria ti tú sí àwọn ojú òpó ayélujára láti bẹ̀rẹ̀ sí ni fi ọ̀pẹ́ fún ọlọ́run ti wọn si n gboriyin fun ijọba orilede Naijiria.
Abuja Nightclub: Àwọn ọmọge wọ gàù nítorí asọ péńpé
Oríṣun àwòrán, PIUS UTOMI EKPEI
Diẹ lara awọn ọmọbinrin ti ikọ̀ amuṣẹya naa mu lo fi ẹsun kan wọn pe wọn fi ipa ba diẹ lara wọn lopọ."""
Ileeṣẹ ajọ Social Development ni olu ilu orilẹede Naijiria ti sọ pe lootọ ni awọn yabo awọn ile-ijo kan nilu Abuja, lati pa iṣekuṣe run nitori bi awọn aṣẹwo ṣe pọ nilu Abuja.
Awọn ọmọ ikọ amuṣẹya ẹgbẹ naa to lọ ko awọn obinrin naa sọ pe awọn yabo awọn ile-ijo ati ile ọti nibi ti awọn ti ko awọn obinrin nikan nitori pe aṣọ pempe ni ọpọlọpọ wọn wọ.
Safiya Umar to jẹ ọga patapata fun ẹgbẹ naa sọ fun BBC  pe awọn ko ni la oju silẹ ki awọn ọmọbinrin naa maa ṣe boṣe wu wọn.
Kàyéfì rèé! Aṣẹ́wó rán awakọ̀ ajàfẹ́tọ̀ọ́ l'ẹ̀wọ̀n
'500 level'' ni mo wà nígbà tí mo di adélé Ọba'
"O ni ''Ko dara ka fi aaye gba awọn ọmọbinrin wa lati maa ṣe nkan ti ko tọ tabi ta ara awọn nile ijo. Koda, awọn ile ijo naa ko ba ofin mu nitori pe aarin adugbo ti awọn eniyan n gbe ni wọn wa."""
''Eyi kii ṣe ọrọ ofin rara. Ọmọ ilẹ Afrika ni wa, awọn obinrin si gbọdọ maa hu iwa to dara.''
O ṣalaye pe awọn ọmọbinrin tilẹ maa n bọ ara wọn si ihoho nile ijo, awọn si fẹ ẹ ri i daju pe ilu Abuja ni oṣuwọn iwa to tọ.
Oríṣun àwòrán, PIUS UTOMI EKPEI
Awọn ọmọbinrin naa ti wọn gbe lọ sile ẹjọ alagbeka kan to wa ni adugbo Old Parade Ground nilu Abuja ni ko ni agbẹjọro kankan to ṣoju wọn bi adajọ ṣe n ka ẹsun wọn sita.
Niṣe ni pupọ lara wọn dahun pe ''awọn jẹbi, nigba ti adajọ beere pe ''ṣe ẹgba pe lootọ ni ẹ n ta ara yin, ti ẹ si fi n da alaafia ilu laamu, leyi to tako ofin ilu Abuja.''
'Àṣírí ọkọ mi tú sími lọ́wọ́, ṣé mo le dáríjì í?'
''Ọrẹbinrin mi jẹ́ mí ní ₦20,000 ní mò fí dáná sún àwọn ẹbí rẹ''
Ọjọ Ẹti mọju ọjọ Abamẹta ni wahala bẹrẹ ninu aye awọn ọmọbinrin naa nigba ti awọn oṣiṣẹ alaabo yabo awọn agbegbe kan nilu Abuja.
Ileeṣẹ ọlọpaa naa sọ pe ẹ̀sìn meji to gbajumọ ju ni Naijiria
Oríṣun àwòrán, PIUS UTOMI EKPEI
Ileeṣẹ ọlọpaa naa f'esi si ọrọ naa pe ẹ̀sìn meji to gbajumọ ju ni Naijiria tako iṣẹ aṣẹwo ṣiṣe
Ọkan lara awọn ọmọbinrin naa ti a fi orukọ bo ni aṣiri, sọ pe oun sin ọrẹ oun kan lọ gbe akara oyinbo fun onibara rẹ kan ni wọn mu awọn nigba ti awọn n fẹ ẹ jade lati maa lọ sile.
Ọmọbinrin naa sọ pe ''wọn sọ fun wa pe ti a ko ba sọ pe lootọ la jẹbi, ọdọ awọn ni a o wa fun oṣu mẹfa. Ibẹru lo si mu ki a gba pe a jẹbi ẹsun ti wọn fi kan wa.''
Adajọ naa dajọ pe wọn jẹbi, o si dajọ ẹwọn oṣu mẹfa fun wọn tabi ki wọn o san ẹgbẹrun maarun Naira owo itanran. Ṣugbọn nigba ti ẹbẹ pọ, adajọ din ẹwọn naa ku si oṣu kan, tabi ẹgbẹrun mẹta fun owo itanran.
Botilẹ jẹ pe ko si ofin kankan ni Naijiria to tako wiwọ aṣọ penpe, abala karundinlogoji ofin ilu Abuja to tako ìrìn ti ko ba ofin mu ni wọn fi ka ẹsun si wọn l'ẹsẹ.
"Diẹ lara awọn ọmọbinrin ti ikọ̀ amuṣẹya naa mu lo fi ẹsun kan wọn pe ""wọn fi ipa ba diẹ lara wọn lopọ."""
Ṣugbọn, ọga patapata fun ẹgbẹ SDS, Arabinrin Safiya sọ pe irọ ni ẹsun naa.
Ilé Ìgbìmọ̀ Aṣòfin gba àbá owó ìṣuná 2019 wọlé pẹ̀lú àfikún N10bn
Oríṣun àwòrán, Pulse
Ilé Ìgbìmọ̀ Aṣofin Àgbà Naijiria ti gba àbá òfin ìṣuna owo ọdun 2019 wọlé, pẹlu afikun biliọnu mẹrindinlaadọrin ju iye ti Aarẹ Muhammadu Buhari gbe siwaju ile.
Oṣu kejila ọdun 2018 ni Aarẹ Buhari gbe abadofin naa lọ siwaju ile aṣofin, eyi to jẹ N8.83trn. Iṣuna owo ti awọn sẹnetọ gba wọle jẹ N8.916trn.
Ile Igbimọ Asofin Agba ni, biliọnu mẹwaa lara afikun ti wọn se si iṣuna owo naa yoo wa fun awọn ti rogbodiyan Ipinlẹ Zamfara pa lara.
Oríṣun àwòrán, Senate
Bi wọn ṣe buwọ lu abadofin yii yá ju ti ọdun 2018 nigba ti awọn aṣofin buwọ lu abadofin ti ọdun naa ni oṣu karun un.
Bode George s'ọrọ lori abadofin tuntun ipinlẹ Eko
Oyo government: Kí ló dé tí ọ̀rọ̀ Ìyálọ́jà àti Babalọja ń fà awuyewuye?
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Awọn obinrin niYoruba gba pe wọn jẹ alamojuto ọja ti wọn a si ma yan Iyalọja laarin wọn
Bi eeyan ba n gbe ni ilẹ Yoruba, ko jẹ kayeefi ti wọn bá darukọ Iyalọja tabi Iyalaje
Lati ijọ ti alaye ti daye ni ilẹ Yoruba ni wọn ti n yan awọn obinrin to kaju osunwọn lati di ipo náà mu.
Olaju ati iṣe ode toni lo mu ki ọpọ ma mọ ipa pataki ti Iyalọja n ko lawujọ.
Ohun ti o mu gbogbo atotonu yi wa ko ju awuyewuye to nlọ lọwọ lori jijẹ oye iyalọja ati babalọja nilu Ibadan ni ipinlẹ Oyo lasiko yii.
Eyi lo mu ki Honorebu Adeniyi Adebisi to jẹ kọmiṣọna fun ọrọ okowo nipinlẹ Oyo ni o to gẹẹ lorukọ Gomina Seyi Makinde.
Adebisi ni ijọba ti ṣetan lati wa ojutuu si ija ojoojumọ lori ọrọ iaylọja ati babalọja ni Ibadan lasiko yii ati pe ẹnikẹni ko gbọdọ pe ara rẹ bẹẹ titi ijọba Seyi Makinde a fi gbe igbesẹ to yẹ.
Ṣaaju naa ni ọrọ fifi iyalọja jẹ ni ọja ti wọn ti n ta nnkan elo kọmputa nipinlẹ Eko, Computer Village naa tri fa awuyewuye tẹlẹ.
Awọn onisowo kan n fapajanu lori bi wọn ti ṣe fẹ fi oye iyalaje ati babalaje lọlẹ ni ọja naa.
Gẹgẹ bi ohun ti wọn sọ, ọja Komputa ati ohun to jọ mọ imọ ẹrọ kii ṣe ibi ti wọn ti n yan iyalọja.
Nibo la ti le yan Iyalọja?
Ọjọgbọn Bisoye Eleṣin to jẹ olukọ ede ati aṣa Yoruba ni fasiti ijọba apapọ nilu Eko salaye pe oye iyalọja kii ṣe eleyi ti eeyan a maa fi ọwọ yẹpẹrẹ mu nitori ipa ti wọn n ko.
O ni ni ilẹ Yoruba, Ọba lo maa n yan iyalọja ati iyalaje ati pe ko si oye to n jẹ Babalọja nitori awọn obinrin ni Yoruba gba pe wọn ṣe akoso ọja.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Onisowo kan lọja Komputa Village nilu Eko
''Ki a to le yan iyalọja, a gbọdọ beere pe igba wo lo ti de ibẹ, ipa wo lo ko ninu itẹsiwaju ọja ati pe iru ọja wo lo n ta nibẹ''
Ọjọgbọn Bisoye ni pẹlu bi ohun ti ṣe wo oye nipa ọja Komputa Village nilu Eko, iruwa ogiri wa ni o wa nibẹ, ko si jọ bi igba wi pe awọn obinrin maa n kopa ninu karakata nibẹ ni eyi ti ko ri bẹẹ ni ti ọja ilu Ibadan.
Lateef Adedimeji: Owó wa kò bá máa jóná ṣùgbọ́n aàyè ọpẹ́ ń yọ fún wa
Aarẹ ẹgbẹ to n ṣe akoso ọja Komputa Village CAPDAN, Ọgbẹni Ahmed Ojikutu  sọ fun BBC pe awọn lodi si yiyan Iyalọja nitori pe kii ṣe iṣẹ ata tita lawọn n ṣe nibẹ.
O ni bi wọn ba file ri Iyalọja fi lọlẹ ni Komputa Village l'Eko,iru rẹ yoo waye ni Abuja ati awọn ibo miran.
O ni lọwọlọwọ ẹka to n risi gbigbẹ ogun ti iṣẹ n samojuto awọn ati pe ifasẹyin ni yiyan Iyalọja yoo jẹ.
Ninu esi ti rẹ, Iyalọja kaafata ni gbogbo Eko,Folashade Tinubu Ojo  ni ẹya kan lo n fi ẹhonu han.
''Ki lo de ti ẹya yi yoo dide pe awọn ko fẹ Iyalọja.Ṣe wọn ko ni awọn olori ọja nibi ti wọn ti wa ni?
Amọ ṣa Ojikutu fesi pada pe kii se ẹya kan ni o n fi ẹhonu han bi kii ṣe gbogbo awọn ti ọrọ kan ni ọja naa.
Pẹlẹ kutu lọrọ yi gba ni ohun ti ọjọgbọn Bisoye sọ nipa wiwa ọna abayọ si awuyewuye yi ọrọ iayalọja ati babalọja ni Ibadan ati ni ipinlẹ Eko.
''Komputa Village kii ṣe ọja aarọ, ọja iruwa ogiri wa ni, ti a ba wọ ọpọlọpọ awọn to n ta ọja nibi kii ṣe ẹya Yoruba nikan fun idi eyi, yiyan iyalọja le fẹ mu kọnunkọhọ wa''
Ọpọ lo ti n sọrọ lori igbesẹ ijọba ipinlẹ Oyo lati bẹrẹ iwadii to yẹ lori awọn to n ja si ipo yii ni Ibadan ati igbesẹ to yẹ ka gbe ṣaaju yiyan ni si ipo agba naa.
Oríṣun àwòrán, @iyalojageneral
Aworan Iyalaje kafata nilu Eko nibi ajọdun kan ni Ile Ifẹ
Elesin tẹsiwaju pe Oba nikan lo lagbara lati yan Iyalọja tabi ko si jẹ wi pe awọn obinrin ọja naa yan ẹnikan lara wọn ti wọn yoo si fi orukọ rẹ ranṣẹ si ọba tabi ẹka ijọba ti o n mojuto ọrọ yi.
Nnkan to yẹ ki wọn beere ni pe ta lo yan Iyalọja naa.
''To ba jẹ ijọba lo yan Iyalọja, ko si nnkan ti ẹnikankan le ṣe nitori pe ijọba lalaṣẹ lori oun gbogbo''
Ijọba ipinlẹ Oyo ti pe fun alaafia ni asiko yii laarin awọn ọja Ibadan.
Honorebu Adebisi ni iṣọkan lo n mu ọja dagba sii ni eyi ti yoo tubọ jẹki onikaluku maa ri taje ṣe.
Ti o bá dá ara ẹ lójú, ki ẹni tó n ṣe irun kí n gbọ́?
'God support stealing' fídíò ọlọ́pàá tó n da orí ayélujára rú'?
Oríṣun àwòrán, @ogundamisi
Fọnran fidio naa ti n mu iriwisi ọtọọtọ wa lori Twitter
Fọnran fidio kan to jẹyọ lori ẹrọ ayelujara Twitter ti n da igboru ru lori bi ọlọpaa kan ti ṣe sọ ninu rẹ pe ''Ọlọrun ko lodi si ole jija.''
Ọmọ orilẹede Naijiria kan, Kayode Ogundamisi lo fi fọnran fidio naa  si oju opo Twitter rẹ .
Kedere la ri arakunrin kan to wọ aṣọ ọlọpaa ti o fẹ gba owo ti a fura si pe o jẹ abẹtẹlẹ lọwọ awakọ kan ti a ko ri oju rẹ.
Awọn ọlọpaa miran wa ninu aworan naa to mu wa ro wi pe ibi ti wọn ti n da ọkọ duro fun ayẹwo,''Checkpoint'' ni iṣẹlẹ naa ti waye.
O jọ bi ẹni pe awakọ naa ko fẹ fun ọlọpaa naa ni owo to ju ẹgbẹrun kan Naira lọ ti o si mu ki ọlọpaa naa pasamọ pe ''Ki wọn ma ji mọto gbe, ki wọn ma jale, Olorun gaan faramọ ''
Fọnran naa re:
Ọpọ Naijiria lo lodi si ohun ti ọlọpaa naa sọ lori ẹrọ ayelujara, ti wọn si n kesi ijọba lati ṣe atunto ileeṣẹ ọlọpaa.
Arakunrin kan ti orukọ rẹ lori Twitter n jẹ @RaySensualCalls ni ko si ofin l'orileede Naijiria ati pe ọrọ to wa nilẹ yi dabi ọrọ Yoruba to sọ pe amúkùn ún, ẹru rẹ wọ, to ni oke lẹ n wo, ẹ ko wo isalẹ.
Iru iṣẹlẹ bayi kii ṣe ajoji pẹlu awọn ọlọpaa l'orileede Naijiria to si mu ki ọpọ eeyan ma ni ireti ninu wọn.
Alukoro ilẹeṣẹ ọlọpaa, Frank Mba nigba ti ikọ BBC Yoruba ba sọrọ ni ''oun ko ti ri fọnran fidio naa'' tori eyi ''ohun ko le fesi si''
South Africa elections: Ǹjẹ́ àlàfo tó wà láàrin àwọn olówó àti tálákà n fẹ̀ si ni?
Ọjọ kẹjọ, oṣu Karun un ni eto idibo yoo waye l'orilẹede South Africa, ti alafo to wa laarin awọn olowo ati otoṣi si jẹ ọ̀rọ̀ gboogi.
Oun lo ni idagbasoke awọn ileeṣẹ julọ ni Afrika - ṣugbọn otun jẹ ọ̀kan lara awọn orilẹede ti aidọgba pọ si ju ni agbaye.
Ẹgbẹ́ alatako sọ pe eyi ti buru si i l'abẹ iṣejọba ANC to ti wa ni iṣakoso fun bi aadọta ọdun.
Ṣugbọn ṣe lootọ ni?
Oṣuwọn kan ti awọn onimọ nipa ọrọ aje maa n lo lati mọ bi aidọgba ṣe pọ to ni orilẹede kan ni a mọ si oṣuwọn Gini. O da lori iye owo ti kaluku n gba fun iṣẹ́ to ba ṣe - bi owo naa ba ṣe pọ si, ni aidgba naa yoo ṣe pọ to.
Ko sọ gbogbo otit ibẹ, ṣugbọn o jẹ ibi ti a ti le bẹrẹ si ni ṣagbeyẹwo aidọgba ni South Africa. ati afiwe rẹ̀ pẹlu awn orilede to ku.
Nipasẹ oṣuwọn yii, ati lilo akọsilẹ ti Banki Agbaye fi sita, South Africa lo ni ipele aidọgba ju ni agbaye.
Awọn orilẹede to mu ile ti i, Namibia ati Mozambique si n tọ ọ lẹyin gbagbaagba, ti Brazil naa si ti fẹ ẹ wa ni awujọ awọn mẹẹrin to wa l'oke.
Ti a ba wo ayipada to ti ba oṣuwọn yii, ti a si ṣagbeyẹwo rẹ lati asiko ti ẹgbẹ ANC ti gba ijọba l'ọdun 1994, aidọgba ga si laarin ọdun 1990 si 2005.
Ko si si ayipada gboogi kankan lati igba naa.
Nitori naa, ti a ba lo akọsilẹ Gini, awọn to n bu ẹnu ẹ̀tẹ́ lu iṣejọba ẹgbẹ ANC ko parọ́ pe aidọgba pọ ni South Africa
Ṣugbọn irọ ni wọn pa pe o n buru u si, paapa lati bi ọdun mẹwaa sẹyin ti akọsilẹ wa fun.
Fun ọpọlọpọ dun lẹyin to de iṣakoso, ijọba ANC gbiyanju ninu mimu adinku ba ìṣẹ́, o si mu ayipada ba awọn nkan amayedrun to ṣe koko.
Eyi ṣeeṣe nitori pe ọ̀rọ̀ aje dagba soke daada - ṣugbọn ni bayii, ifasẹyin ti de ba a.
Esi rẹ̀ ni pe, awọn ọmọ orilẹede South Africa kúṣẹ̀ẹ́ lasiko yii.
Iye owo ti ẹni kọọkan n pa wọle ti dikun lati ọdun 2010.
Aisi iṣẹ́ n pọ si lojoojumọ lasiko yii.
Olori ẹgbẹ alatako, Democratic Alliance, Mmusi Maimane sọ pe ko ti i si aridaju pe alafo to wa laarin awọn olowo ati talaka yoo di pa.
Ọ̀kan lara awọn minisita to wa ni iṣakoso aarẹ South Africa, Nkosazana Dlamini -Zuma sọ pe ''aidọgba kọ̀ lati dinku.''
Pẹlu oṣuwọn ijọba South Africa fun ìṣẹ́ - ile ti owo to n wọle fun wọn ba kere si Dọla marunlelaadọta l'óṣù - akọsilẹ ijọba fihan pe afiwe yii ti dinku lati ìdá mọkanlelaadọta si mẹrindinlogoji laarin ọdun 2006 si 2011.
Ṣugbọn nigba ti yoo fi di ọdun 2015, afiwe naa ti lọ soke si ìdá ogoji.
"Ọmọ orilẹede South Africa kan to jẹ onimọ nipa ọ̀rọ̀ aje, Carlene van Westhuizen, sọ ninu abọ iwadi kan to ṣe fun ile ẹ̀kọ́ Brookings Institution to wa ni orilẹede America sọ pe ""awọn talaka ko fi bẹ ẹ janfaani idagbasoke to ba ọrọ̀ aje."""
Oríṣun àwòrán, AFP
Abọ iwadi kan ti Banki Agbaye ati ijọba South Africa jọ ṣe fihan pe awọn iyatọ to wa ninu owo ti onikaluku n gba lẹnu iṣẹ́ wọn jẹ ọ̀kan pataki lara ohun to fa aidọgba ni South Africa laarin ọdun 2006 si 2015.
"''Nini anfaani si ipele eto ẹ̀kọ́ to ga ati owo oṣu ti ko dawọ duro jẹ pataki lara awọn nkan ti yoo mu ko ṣeeṣe fun awọn ẹbí lati le ni eto ọrọ̀ aje to f'ẹsẹ mulẹ ni South Africa."""
Wọn gboriyin fun eto riran araalu lọwọ, pe o n mu adinku ba ìṣẹ́, ṣugbọn titẹsiwaju ninu rẹ yoo ni ipa to l'agbara ninu eto inawo ijọba.
Ọpọ ninu awọn ọmọ South Africa to jẹ alawọ dudu ti n gbe ninu ìṣẹ́ lati atọdun-mọdun, ta a ba ni kafiwe awọn to jẹ Asia ati awọn ọmọ South Africa to jẹ alawọ funfun.
Laarin ọdun 2011 si 2015, iyatọ to wa laarin awọn alawọ dudu ati funfun to n gbe ninu ìṣẹ́ pọ si, gẹgẹ bi akọsilẹ ijọba ṣe sọ.
Ìdá mẹwaa ati diẹ ni awọn alawọ funfun to n ṣiṣẹ - ṣugbọn wọn n gba to ilọpo mẹta owo ti awọn ọmọ South Africa to jẹ alawọ dudu, to ko ìdá mẹta ninu mẹẹrin laarin awọn oṣiṣẹ.
Banki Agbaye sọ pe, botilẹjẹ wi pe owo iṣẹ́ ti lọ soke fun gbogbo ẹya, owo ti awọn ti owo oṣu wọn pọ pupọ n lọ soke si ni bi i ilpo meji ju ti awọn ti owo iṣẹ́ wọn kere lọ
Tiwa Savage tọwọ́ bọ'wé àdéhùn pẹ̀lú UMG fún òkìkí orin rẹ̀
Oríṣun àwòrán, Universal Music Group
Tiwa pẹlu awọn onigbọwọ
Lónìí, ajọ awọn onigbọwọ orin to ga ju lagbaye (Universal Music Group) ti kede ajọṣepọ nla laarin wọn ati gbajugbaja olorin, Tiwa Savage.
Ilumọọka olorin nni, Tiwa Savage ni iroyin sọ pe oun ni obinrin akọkọ to ti gba ami ẹyẹ MTV EMA fun olorin ilẹ Afirika to dara ju.
#Bum bum war:Yemi Alade tọrọ àforíjìn lọ́wọ́ Tiwa Savage
Davido, Falz, Tiwa Savage tàn bí oòrùn ní AFRIMA
Bakan naa, o ti ba awọn gbajugba olorin to lokiki kọrin kaakiri agbaye.
Tiwa jẹ ọkan lara awọn obinrin ilẹ Afirika to ni ọpọlọpọ ololufẹ orin rẹ to fẹrẹẹ́ to miliọnu meje lori itakun ayelujara.
Oríṣun àwòrán, Universal Music Group
Tiwa Savage
Oluwo: Mo lè jẹ Ọba ní Ile Ife
"Tiwa ni ""afojusun mi to ga ju ni lati fi ilẹ Afirika yangan, nitori naa, inu mi dun gidi gan si ajọṣepọ yii mo si dupẹ lọwọ ẹbi tuntun ti mo wọ yii, UMG."
Tiwa ti di olorin to gbayii gan loke okun. Ninu oṣu kejila dun to kọja olorin Chris Martin yan an lati jọ kọrin pọ pẹlu gbajugbaja olorin Beyonce, Ed Sheeran ati Jay Z ni ilu Johannesburgh, South Africa niwaju ero to to miliọnu lọna aadọrin nigba ti wọn ṣe ayẹyẹ iranti ọjọ ibi oloogbe Nelson Mandella
O ti wa di ọ̀kan lara awọn agba akọrin Afrobeat l'Afirika pẹlu eyi to ti fun ara rẹ niyi lẹnu iṣẹ to yan laayo ati nilẹ Afirika gẹgẹ bi olorin, oniṣowo, akọni ati iyaleele.
"Adam Granite to n bojuto ẹka idagbasoke katakara fun ajọ UMG, ni ""a n foju sọna lati ni ajọṣepọ pẹlu Tiwa ati ikọ rẹ lati ran iṣẹ orin kikọ rẹ lọwọ ki o le tan ka gbogbo agbaye tori a rii pe Tiwa ni afojusun to dara""."
A kò mọ́ pé wọ́n kẹ́ òògùn olóró sí àbúrò mi l'ọ́rùn
Universal Music Group jẹ aṣaaju ninu oniruuru iṣẹ to rọ mọ orin kikọ. Latorii gbigbe orin sita, ṣiṣe alagbata orin kaakiri orilẹede  to le lọgọta. Oriṣiriṣi ẹya orin ni wọn ma fi yan olorin ti wn yoo si baa gbe orin sita titi ti wọn yoo fi ṣe agbata rẹ kaakiri agbaye ati lati jẹ ki awọn to fẹran orin wọn tun ni iriri ọtun nipa wọn.
NLC Kwara-Iṣẹ́ tí èèyàn kò bá tí ṣé, kò yẹ kó gba owó rẹ̀
Oríṣun àwòrán, Facebook/NLC
Ohun to kọju si ẹni kan,ẹyin lo kọ si ẹlomiran lọri ki ijọba yara  san owo oṣu oṣiṣẹ.
Igbesẹ Gomina ipinlẹ Cross River to yara san owo osu fawọn oṣiṣẹ lati fi ṣe moriwu ni asiko ayajọ ọjọ oṣiṣẹ lo mu ọrọ wa.
Bi awọn ẹgbẹ oṣiṣẹ ipinlẹ naa ṣe ni ìgbésẹ̀ naa ko daa to, lawọn to wa ni ipinlẹ miran ti n ni awọn ko lodi si.
Ninu ifọrọwanilẹnuwo pẹlu BBC, Alaga ana fẹgbẹ oṣiṣẹ ni ipinlẹ Oyo, Siyanbade Waheed Olojede ni ko si ohun to buru ki wọn tete san owo oṣu fun oṣiṣẹ.
Alaga tẹlẹ ri ọhun ni pẹlu bi owo oṣu ko ti ṣe ma wa deede fawọn oṣiṣẹ kan lawọn ipinlẹ kan,o yẹ ki wọn ''lu eyikeyi Gomina to yara san owo lọgọ ẹnu''
Laarin ọṣẹ si igba ti wọn gba owo oṣu to kọja ni Gomina Ben  Ayade paṣẹ ki wọn san owo oṣu eleyi ti awọn oṣiṣẹ ko ti ṣiṣẹ fun.
Oluwo: Mo lè jẹ Ọba ní Ile Ife
Siyanbade salaye pe ni ipinlẹ Oyo,''ijọba ipinlẹ ko jẹ ju owo oṣu kẹrin to ṣẹṣẹ pari lọ amọ fawọn oṣiṣẹ ijọba ibilẹ, a ri ibi ti wọn ti jẹ  oṣu kan,oṣu meji,ati oṣu mẹta''
''Ko si ohun ti ẹni to n ṣiṣẹ ọba fẹ gba lọwọ ẹni to gba ṣiṣẹ to yatọ si owo oṣu''
Nipinlẹ Kwara, ọmọ ko  sọri bakan naa nibi ti alaga ẹgbẹ oṣiṣẹ ọgbẹni Issa Ore ti ni isẹ ti eeyan ko baa ti ṣe ko yẹ ki o gba owo rẹ.
Issa ti wọn ṣẹṣẹ yan si ipo alaga sọ pe lootọ ni o da ki oṣiṣẹ tete gba owo oṣu ''amọ ko tọ ki wọn ti gba owo iṣẹ ti wọn ko ti ṣe rara''
Ipade to waye laarin minisita fọ̀rọ̀ osisẹ́ ati ijọba apapọ fori sanpọn nitori igun mejeeji ko lee fi ẹnu ọrọ jona
Nipa sisan owo oṣu fawọn oṣiṣẹ ni Kwara o ni ijọba ibilẹ ni wahala wa ti owo oṣu ko lọ deede.
''Wọn ṣi n san owo fawa oṣiṣẹ ijọba ipinlẹ,ti ibilẹ ni a ti ni ipenija''
Ko si ofin kankan to lodi si ki owo oṣu oṣiṣẹ maa di sisan saaju ki o to ṣiṣẹ tan ni Naijiria amọ ohun ti o wọpọ ni ki awọn Gomina ma j oṣiṣẹ lowo oṣu.
George Weah tí padà sí ọ́fíìsì rẹ̀ tó fí sílẹ nítorí ejò
Oríṣun àwòrán, Anadolu Agency
Mọjamọsa la fi mọ akinkaju ọkunrin.
Lẹyin to fi ọfisi rẹ silẹ tori awọn ejo meji,Aarẹ orileede Liberia George Weah George Weah ti pada sibẹ lati ma ba iṣẹ lọ.
Weah to fi igba kan jẹ iluọmọọka agbabọọlu pada si ọfisi rẹ lẹyin ọsẹ meji ti o fi ibẹ silẹ fun awọn ejo naa.
Gẹgẹ bi ohun ti a ri ka,wọn fin oogun kẹmika to lagabara si ọfisi rẹ daada ki wọn to ni pe ko pada sibẹ l'Ọjọru
Koda a gbọ pe o gab alejo lọjọ to ko wọ ofisi rẹpada ti ṣe ọjọru.
Igbakeji aarẹ tẹlẹ Joseph Boakai ti o fidirẹmi lọwọ Weah ninu idibo aarẹ 2017 lo ba lalejo.
Lati ọdun 2006 ti ina ti jo ile aarẹ ni wọn ti gbe ọfisi aarẹ lọ si ọfisi alaja mẹfa ti ileeṣẹ to n ri si ọrọ ilẹ okere n lo.
Awọn ejo to le aarẹ kuro lọfisi la gbọ pe wọn jade lati inu ilẹ ti wọn si sa wle pada nigba ti awọn eeyanfẹ pa wọn.
Arsenal vs Valencia: Arsenal gbẹ̀san fún Liverpool, Tottenham
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Chelsea ni tirẹ ta ọmi pẹlu Eintranct frankfurt ni orilẹede Germany
Lẹyin idojukọ to de ba ikọ agbabọọlu Tottenham ati Liverpool ninu idije Champions league lọsẹ yii, orilẹede Gẹẹsi yi ipin rẹ pada ni idije bọọlu laaarin awọn ẹgbẹ agbabọọlu ni ilẹ Yuroopu pẹlu bi ikọ agbabọọlu Arsenal ati Chelsea ṣe gbo ewuro si oju awọn iks ti wọn ba gba bọọlu ni idije UEROPA ni ọjọbọ.
Bakan-meji lọrọ ri fun ilẹ Gẹẹsi ninu idije bọọlu ilẹ Yuroopu. Ni ọjọ iṣẹgun ni Tottenham ti kọkọ ṣide ijiya naa nigba ti ẹgbẹ agbabọọẹu Ajax ti ilu Amsterdam lorilẹede Netherlands naa mọle pẹlu ami ayo kan.
Ni ọjọru ni  Liverpool tẹwọ gba igi ijakulẹ naa nigba ti wọn fara gba goolu mẹta ni ọwọ ikọ agbabọọlu Barcelona ti orilẹede Spain.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Chelsea ni tirẹ ta ọmi pẹlu Eintranct frankfurt ni orilẹede Germany
Amọṣa, ẹgbẹ agbabọọlu Arsenal yii ọrọ naa pada nigba ti wọn na Valencia pẹlu ami ayo mẹta si ẹyọkan ni apapa iṣire Emirates ni ilẹ Gẹẹsi.
Goolu meji ni Lacazette gba wọle lẹyin ti agbabọọẹu Valencia, Mouctar Diakhaby ti kọkọ ṣide ajọdun goolu ni ifẹsẹwọnsẹ naa ni iṣẹju kọkanla. Aubameyang, to jẹ agbabọọlu Arsenal lo wa fi ọba lee ni aadọrun iṣẹju iufẹsẹwọnsẹ naa.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Chelsea ni tirẹ ta ọmi pẹlu Eintranct frankfurt ni orilẹede Germany
Chelsea, ni tirẹ, ta ọmi pẹlu Eintranct frankfurt ni orilẹede Germany.
Ni ọṣẹ to n bọ lawọn ikọ orilẹede Gẹẹsi naa yoo ma mọ ohun ti ifa bọọlu fọ fun wọn. Boya yoo fọọre tabi fọbi, boya iwaju ni ọlọkọ idije Yuroopu n gbe wọn lọ tabi ẹyin.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Chelsea ni tirẹ ta ọmi pẹlu Eintranct frankfurt ni orilẹede Germany
Liverpool yoo koju Barcelona ni ọjọ iṣẹgun, Tottehnam yoo ba Ajax lalejo ni ọjọru ki o to kan Arsenal ati Valencia pẹlu Chelsea ati Eintranct frankfurt ni ọjọbọ ọsẹ to n bọ
Èèyàn mẹ́ta pàdánù ẹ̀mí wọn nínú ìjàmbá ọkọ̀ akérò tó ya wọ ọjà ní Ibadan
Ọkọ̀ akérò ya wọ ọjà ní òkè Mapo,èèyàn mẹ́ta pàdánù ẹ̀mí wọn
Ọkọ akero nla kan ti ṣeku pa eeyan mẹta ni ọja to wa ni oju titi to kọja ni  iwaju Oke Mapo nilu Ibadan.
Awọn tọrọ ṣoju wọn ni ọmọkekere kan ati iya kan to wa ra nnkan ọbẹ lọja wa lara awọn to farakasa iṣẹlẹ naa.
Akọroyin wa to kan si agbegbe naa jabọ pe nnkan bi ago mẹta ọsan ọjọ Ẹti ni ijamba ọkọ  naa ṣe
Oríṣun àwòrán, Yemi Akintunde
Awọran ọkọ to kọlu awọn eeyan ni ọja toi wa ni iwaju Oke Mapo ni Ibadan
Bakanna lo ni awọn ọlọja to wa nibẹ sọ pe awọn ọlọpaa ti wa gbe oku awọn to padanu ẹmi wọn lọ si ile igbokupamọsi ti wọn si ti wọ ọkọ akero naa lọ.
Ohun ta mọ ni pe ọkọ akero naa ti o jọ iru eleyi ti wọn fi n ko awọn ọmọ akẹkọ nikan lo fa ijamba yi.
Awọn ti ọrọ naa soju wọn ni sadede ni awọn n gbọ igbe ti awọn eeyan si n sa asala ẹmi wọn.Nigba ti ọrọ yoo fi  rọlẹ tan ọku mẹta ti sun ti awọn mii na si ti farapa.
Pipatẹ ọja lẹgbẹ titi jẹ nnkan ti o n kan awọn alaṣẹ lominu nitori ewu to wa nibẹ ti ọkọ ba yawọ
Pipatẹ ọja lẹsẹ titi jẹ nnkan ti awọn alaṣẹ  a ma  lọgun tantan fun awọn ọlọja paapa lawọn adugbo ibi ti ọna ba ti họ.
Gbogbo igbiyanju wa lati ba alukoro ileeṣẹ ọlọpaa nilu Ibadan ja si pabo pẹlu bi ko ti ṣe gba ipe wa lori ero ibanisọrọ rẹ.
NUT ní àìsí àbò ń ṣàkóbá fún àwọn olùkọ́ ní Nàìjíríà
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ọpọ igba lo jẹ pe awọn ileewe ni awọn agbebọn ati agbesumọmi maa n kọlu lasiko iṣigun wọn
Ko din ni ẹgbẹta olukọ ti wahala aabo to mẹhẹ ni apa ila oorun ariwa orilẹede Naijiria ti ran lọ sọrun ọsan gangan.
Ẹgbẹ awọn olukọ lorilẹede Naijiria lo tu aṣiri eyi sita to si ṣakawe eyi gẹgẹ bii ohun to buru jai to si bani ninu jẹ lọpọlọpọ.
Akọwe agba ẹgbẹ NUT lorilẹede Naijiria, Ọmọwe Mike Ike-Ene ṣalaye fawọn oniroyin pe ọpọ igba lo jẹ pe awọn olukọ nii fi ara ko ina wahala igbesunmọmi tabi rogbodiyan lasiko to ba ṣẹlẹ lawọn agbegbe oke ọya orilẹede Naijiria.
O fi kun un pe, ni ikọlu awọn agbebọn to waye ni ileewe girama awọn obinrin ni ilu Moriki, nijọba ibilẹ Zurmi, ipinlẹ Zamfara, awọn alase meji atawọn akẹkọ mẹrin ni awọn agbebọn naa ji gbe salọ.
O ni ohun to n ṣẹlẹ yii n bu omi tutu si ọkan awọn olukọ to n ṣiṣẹ ni ẹkun naa ti kii sii fẹ jẹ ki ọpọ olukọ o faramọ ki iṣẹ gbe wọn lọ sibẹ pẹlu.
Abuja Protest: À ń ṣe ìwádìí lórí àwọn obìnrin tí wọn mú nítorí aso péńpé
Abuja Protest: À ń ṣe ìwádìí àwọn lóri àwọn tí wọn mú obìnrin nítorí ìwọsọ wọn
Ilé iṣẹ́ ọlọ́pàá ti fẹ̀sì lórí ìfẹ̀honu han tí awọn kan ń ṣe lárọ satide oni lóri mímú ti àwọn ọlọpàá mu awọn obinrin ti wọn ni wọn wọ aṣọ pénpé lọ si ode ijo ní ìlú Abuja.
Usman Umar to jẹ kọmisọna ajọ ọlọpàá FCT sọ pe àwọn ko ni jọkọ fọwọleran lóri ọ̀rọ̀ náà àti pé àwọn yoo tusu de isalẹ ikoko pẹlu'ajo tó n dabo bo ayika nilu Abuja láti mọ idi ti wọn fi ń mu àwọn olbinrin satimọle.
A ti bẹ̀rẹ̀ ìwádìí lóri ọ̀rọ̀ naáà à ó mu ẹni náà a ó sì fi jofin
Oríṣun àwòrán, Twitter
Ajà fẹ́tọ ọmọniyan gbàgboro lAbuja lóri mimu obinrin sátimole nitori iwosọ
Àwọn aja fẹtọ ọmọ ènìyàn ti gbà ìgboro pẹ̀lú ìfẹhonu han nílu Abuja ti ṣe olú-ìlú orilẹ̀-èdè naijiria lóri ọ̀rọ̀ bi ọlọpàá ṣe ń mú àwọn obinrin sátìmọle, wọn a tún dóju tiwọn nítori  pé wọn wọ aṣọ pénpé lo si ilé ijo tàbi ilé ìtura.
Awọn afẹhonu han ọhun tí wọn wọ aṣọ dúdú bẹ̀rẹ̀ ìrìn wọn láti Old Parade ground nílu Abuja lọ si ile iṣẹ ọlọpàá FCT.
Nollywood: Bẹbẹ ń lọ ní ibùdó yíya sinimá Àgbésọrísùn
"Bakan náà ni àwọn afẹhonu han náà kó akole orisirisi lọ́wọ́ ti wọn kọ ọ̀rọ̀ bíi ""obinrin ni mi, bó ba ṣe wumi ni mo ṣe le múrà"""
Ọ̀pọ̀ àwọn ọmọbinrin ti àwọn ọlọpàá mú náà sàlàyé pe wọn fi ipá ba àwọn lòpọ̀ nígbà ti àwọn wà ni ahamọ.
Ajà fẹ́tọ ọmọniyan gbàgboro lAbuja lóri mimu obinrin sátimole nitori iwosọ
Ní ti àwọn ajàfẹto, wọn ni mímu wọn si atimọle kìí ṣe ǹkan ti o ba ofin mú àti pé wọn ń fi ọwọ pa ẹtọ àwọn obinrin náà lóju ni
Ajà fẹ́tọ ọmọniyan gbàgboro lAbuja lóri mimu obinrin sátimole nitori iwosọ
Ọkan nínú àwọn to jáde wa ni ajàfẹtọ obinrin Aisha Yesufu, ó sàlàye pé ìdí ti òun fi jáde wa ni pé o ti tó gẹ
" O dà bi ẹni pe ti ènìyàn ba ti jẹ obinrin, ọ̀ràn ní oluwa rẹ̀ dá, wọn kan máà ṣe obinrin báṣubaṣu, obinrin a maa rìn lọ lọ́san gangan, ọlọpàá a si jú ènìyàn si inu ọkọ̀, a wá ń gbọ pe àwọn ènìyàn ti wọn ń mu yìí, àwọn ọlọpàá a maa fi ipá ba wọn lò pọ̀ ki wọn to tú wọn silẹ̀. Aisha ló s]ọ èyí di mímọ.
Ajà fẹ́tọ ọmọniyan gbàgboro lAbuja lóri mimu obinrin sátimole nitori iwosọ
Obinrin míràn to tún jáde fún ìfẹhonu han náà sọpe ọ̀rs yìí ti toju ṣú wa"" ǹkan tó ń ṣẹlẹ̀ si obinrin lórill -èdè Naijiria kò dára, a fẹ kí ńkan yí pada, à fẹ ki ọlọpàá máa dáàbò bo obinrin."
 A o le rin a ò lé rimu mi, a o le wọṣọ, a lé lọ si ilé ijo, ọlọpaáà to yẹ ko dáàbò bò wá àwọn gan-an ló ń fipá báwa lòpọ, a fẹ ki àwọn ọmọ Naijiria mọ pe ẹ̀tọ́ obinrin náà ni ẹ̀tọ́ ọmọniyan, kò sí ìyàtọ ninu gbogbo ẹni to ń rin ni títì
countries without coronavirus: Ọwọ́jà coronavirus yóò ṣì wà pẹ̀lú àgbáyé fún ìgbà pípẹ́- Ngozi Okonjo-Iweala
Oríṣun àwòrán, Ngozi Okonjo-Iweala
Minisita feto iṣuna lorilẹede Naijiria nigbakan ri, Ọmọwe Ngozi Okonjo Iweala ti ṣalaye pe ọwọja arun coronavirus yoo ṣi wa pẹlu gbogbo agbaye fun igba pipẹ ẹẹyin ti arun naa ba kasẹ n lẹ.
Ọmọwe Ngozi Okonjo Iwealla ni ko si aniani pe eto ọrọ aje agbaye gbogbo ni yoo dẹnukọlẹ eleyi to tums si pe kini naa yoo kan awọn orilẹede Afirika pẹlu.
Amọṣa o ni ọna kan pataki lati bori wahala to lee waye lori eto ọrọ aje lẹyin ajakalẹ arun naa ni ki olukuluku orilẹede ni ilẹ Afirika o boju wo inu ile rẹ lati lo awọn ohun ti o ba ni fi gbe ara rẹ dide.
Ọmọwe Okonjo-Iwealla to ba BBC News Sọrs ṣalaye pe ko si nnkan meji ti awọn orilẹede lorilẹ Afirika lee fi gba ara wọn la ju awọn ẹka bii eto ogbin atawọn ohun alumsni miran ti Eleduwa fi jinkin wọn ati pe ki banki apapọ na ọwọ iranwọ si awọn ileeṣẹ kerejekereje nitori pe ẹka wọnyii lo gba ọpọlọpọ awọn eeyan lawsn orilẹede wọnyii si iṣẹ julọ.
O wa fi kun un pe kọkọrọ kan to n bẹnu aja jẹ lori ọrọ yii ni pe awọn orilẹede Afirika ko ni owo lati fi awọn nnkan wọnyii lọwọ; idi niyi ti wọn si fi nilo ati tọ awọn ileeṣẹ nlanla lagbaye lọ lati yawo ni ele ti ko ga ju ara lọ.
Wo bí o ṣe leè ṣe ìjìnàsíraẹni ní ibiṣẹ́ lásìkò Coronavirus yìí
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Awọn ọmọ Naijiria n ṣeranti aarẹ ana
Ọjọ́ ńlá, ọjọ́ manigbagbe ni ọjọ́ karùn-ún oṣù karùn-ún ọdún 2010, tí aarẹ tẹ́lẹ̀ ni Nàìjíríà, Umaru Musa Yar'adua jáde láyé, èyí tó pé ọdún mẹ́wàá gbáko lónìí ọjọ́ Isegun.
Lásìkò tí Umar Yar'adua sì jẹ Ààrẹ orílẹ̀ èdè yìí, ọ̀pọ̀ igbesẹ tó pegede lo gbé fún idagbasoke ilẹ̀ Nàìjíríà àti igbaye-gbadun ọmọ orílẹ̀ èdè yìí kọ̀ọ̀kan.
Yoruba sì ni bí onirese kò bá fín igbá mọ, èyí tó ti fin silẹ kò leè parun, ìdí si nìyí tí BBC Yoruba fi ń mú àwọn iṣẹ́ akainiye tó jẹ́ manigbagbe fún àwọn ọmọ Nàìjíríà, tí Ààrẹ Yar'adua gbé orí àkóso ṣe nígbà ayé rẹ.
Ohun rere tí Umar Yar'adua ṣe lórí aleefa:
Ìkéde dúkìá faraye:
Ohun àkọ́kọ́ tí Ààrẹ tó ti di olóògbé náà ṣe lórí àga àkọ́so, tí a kò leè gbàgbé ni pé òun ni aarẹ àkọ́kọ́ tó kéde dúkìá rẹ fún gbogbo ayé, lai ju ọgbọn ọjọ́ lọ tó di Aare, èyí tó sì dun mọ àwọn ọmọ Nàìjíríà nínú pupọ.
Ìkéde dúkìá tí Yar'adua ṣe yìí, si ni àwọn èèyàn fi ń ṣe odiwọn fún Ààrẹ tuntun to ń jẹ lẹ́yìn rẹ, láti mọ bóyá onítọ̀ún yóò kó akoyawọ bíi Umar Yar'adua.
Ayédèrú èsì ibo:
Ohun èkejì tí Yar'adua tún ṣe daada ni pé, ó
gbà pé èsì ìbò tó gbé òun wọlé kún fún magomago àti ayédèrú esi ibo.
Ìkéde yìí ló gbà gbogbo àgbáyé kan, tí wọn sì ń kan saara sì pe olóòótọ́ èèyàn ni.
Bákan náà lo tún fi ogun rẹ gbà rí pé ayédèrú àti magomago ibo kò ní wáyé rárá lásìkò ijoba tòun.
Ṣùgbọ́n kòkòrò kò jẹ ká gbádùn obì tó gbó, ọdún mẹta péré ni Yar'adua náà lo lórí aleefa, tí ikú fi pá ojú rẹ dé, tí kò sì dúró de asiko ìbò gbogbo gbòò miran.
Ibọwọ fún òfin ilẹ̀ wa
Ohun àrà kẹta tí Umar Yar'adua ṣe lórí aleefa ni pé ó jẹjẹ pé òun yóò máa bù ọwọ ńlá fún òfin ilẹ̀ wa yàtò si bí àwọn aṣáájú tó síwájú rẹ tí ń ṣe.
Ẹsẹ̀ bàtà, èso kukumba ni wọ́n fi ń já àbálé àwọn ọmọ Nàìjíríà ní Libya
Ó sì ṣe àṣeyọrí pupọ nídìí ìlérí rẹ náà, gbogbo àṣẹ ile ẹjọ́ àti òfin ilẹ̀ wa lo tẹ́lẹ̀ gẹ́gẹ́ bíi Ààrẹ Nàìjíríà.
Ààrẹ àkọ́kọ́ to kọjú Boko Haram, ségun wọn
Ohun ìdùnnú miran ti aarẹ Umar Musa Yar'adua tún ṣe, tàwọn ọmọ Nàìjíríà kò fi ní gbàgbé rẹ ni pé, òun ni aarẹ àkọ́kọ́ to fojú wina ikọ asekupani Boko Haram, tó sì wá ọwọ rẹ bolẹ nígbà náà, kí ikọ ọ̀hún tún tó gberi dìde.
Bí ikọ afẹjẹwẹ náà sì ṣe ń fojú hàn síta, ní ìjọba rẹ koju wọn, to sì pá asiwaju ikọ náà, Muhammad Yusuf, bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé ikọ náà padà gberi, tó sì ń dààmú Nàìjíríà di òní yìí
Ìdáríjì àti sísan owó iranwọ fún ikọ ajijagbara Niger Delta:
Lára àwọn àṣeyọrí aarẹ tẹ́lẹ̀ tó di olóògbé yìí ni wíwà àlàáfíà ni agbegbe Niger-Delta tí àwọn ajijagbara tí ń bá ọ̀rọ̀ ajé Nàìjíríà jẹ́.
Umar Yar'adua fi ori jin àwọn agbebọn náà, ó ní kí wọn jọ̀wọ́ ohun ijagun wọn, tó sì ń ṣàn owó iranwọ fún wọn.
Igbesẹ rẹ yìí ló mú kí àlàáfíà jọba lágbègbè Niger-Delta lásìkò tíẹ, tí ọ̀rọ̀ ajé Nàìjíríà si dúró rẹ.
Gbogbo àwọn àṣeyọrí aare Umar Musa Yar'adua yìí lo si wa ni ìrántí àwọn ọmọ Nàìjíríà, tá sì ń gbàdúrà pé kí Ọlọ́run tẹ si afẹ́fẹ́ rere
Niyi Akinmolayan tó ṣe fíìmu àwòrán-dèèyàn Cartoon nípa COVID-19 tó la ayé já ní N
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Awọn ọmọ Naijiria n ṣeranti aarẹ ana
Iku n pani, ilẹ n jẹ'yan. Ọjọ Aiku, ọjọ karun un oṣu karun un ni o pe ọdun mẹsan-an gerege ti aarẹ orilẹede Naijiria nigba kan ri, Umaru Musa Yar'adua re iwalẹ asa.
Ọpọ ọmọ orilẹede Naijiria lo n ṣedaro aarẹ ana. Ninu wọn ni oludije fun ipo aarẹ fẹgbẹ oṣelu PDP Atiku Abubakar wa.
Atiku to msọrọ lojun opo Twitter ni aarẹ tẹlẹ ri, Yar'adua jẹ alaanu eeyan, bẹẹ lo si fẹran orilẹede rẹ nigba to wa loke eepẹ.
Ajimobi figbe ta, ó ní 'èmi kọ́ ló pa Ṣugar o!'
‘Gboingboin ni Ilẹ̀ Gẹ̀ẹ́sì wà lẹ́yìn ìgbógun ti Boko Haram’
Àwọn ọmọge wọ gàù l'Abuja nítorí asọ péńpé
Fashola fi orúkọ àwọn ilé isẹ́ tó jẹ́ àjẹbánu síta.
Oluwo: Mo lè jẹ Ọba ní Ile Ife
'Oyin sínsìn lérè lórí ṣùgbọ́n ó tún gbé ikú karí'
Atiku gbadura pe ki Ọba oke ko dẹlẹ fun ẹni 're to lọ.
Ninu ọrọ tiẹ, aarẹ ana to tun figba kan jẹ igbakeji fun Aarẹ Yar'adua, Goodluck Jonathan ṣapejuwe Yar'Adua bi ọrẹ, iyekan ati ọga.
Jonathan ni Yar'Adua jẹ olori ti ko ni imọ tara ẹni nikan, bakan naa lo ṣapejuwe rẹ gẹgẹ ẹniti o maa n gbiyanju nigba gbogbo lati ri wi pe ifẹ orilẹede Naijiria siwaju ifẹ ọkan rẹ.
Adari ile igbimọ aṣofin agba l'Abuja, Bukọla Saraki naa ko gbẹyin ninu awọn to n ṣe iranti aarẹ to lọ.
Saraki ni iwe rere ti Yar'Adua wu nigba to jẹ aarẹ Naijiria ti di ohun manigbagbe, bẹẹ lo gbadura pe ki aanu Eleduwa maa baa nibi kibi to ba wa.
Sẹnẹtọ Shehu Sani naa sọrọ iwuri nipa Yar'Adua, o ni aarẹ to lọ jẹ olotitọ eniyan ati oloṣelu ti kii figba kan bọkan ninu.
Sẹnẹtọ Saniu fikun ọrọ rẹ pe onirẹlẹ eniyan ni Yar'Adua jẹ, bakan naa lo gbadura pe ki Eleduwa Alijana ṣẹsan 're fun un.
Ọjọ karun un oṣu karun un ọdun 2010 ni Aarẹ Umaru Musa Yar'Adua jade laye.
Muhammadu Buhari: Ààrẹ Buhari tìrìn àjò dé lẹ́yìn àbẹ̀wò sílẹ̀ Gẹẹsi
Oríṣun àwòrán, Facebook/Femi Adesina
Muhammadu Buhari pada si Naijiria
Aarẹ Muhammadu Buhari ti pada si orilẹede Naijiria lẹyin abẹwo ọlọjọ mẹwaa to ṣe silẹ Gẹẹsi.
Ni bi aago mẹfa kọja ogun iṣẹju ni ọkọ baalu to gbe aarẹ balẹ si papakọ ofurufu Nnamdi Azikwe ni olu ilu orilẹede Naijiria, Abuja nirọlẹ ọjọ Aiku.
Ọjọ kẹẹdọgbọn oṣu kẹrin to lọ ni Aarẹ Buhari rinrin ajo lọ si ilẹ Gẹẹsi lẹyin to ṣabẹwo si ilu Maiduguri tii ṣe olu ilu ipinlẹ Bornu.
'500 level'' ni mo wà nígbà tí mo di adélé Ọba'
Helen Paul sọ idi tó fi gba orúkọ ní kékere
Ṣaaju abẹwo rẹ si ilu Maiduguri, Aarẹ Buhari kọkọ wa si ipinlẹ Eko nibi ti o ti ṣi awọn akanṣe iṣẹ kan ti ijọba ipinlẹ naa ṣe.
Ẹwẹ, oludamọran aarẹ lori ọrọ iroyin, Femi Adesina sọ oko ọrọ sawọn oniroyin ori ayelujara kan to ni wọn ti n kọroyin pe Aarẹ Buhari lọ gba itọju nilẹ Gẹẹsi ni.
Ọgbẹni Adeṣina beere lọwọ wọn bo ya wọn o tọrọ aforiji lọwọ Aarẹ Buhari ati aw\pm ọmọ orilẹede Naijiria nibayii ti aarẹ ti pada si Naijiria.
John Onaiyekan: Ìtìjú ni fún mi láti rí àwọn ọmọbìnrin Nàìjíríà tó ń ṣe aṣẹ́wó ní Italy
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ọpọ awọn to n fi orilẹede Naijiria silẹ ni wọn wa lati agbegbe gusu ipinlẹ Edo
Biṣọbu agba ijọ aguda nilu Abuja, ti ṣekilọ fun awọn adari orilẹede Naijiria pe awọn gan ni wọn n sọ orilẹede Naijiria di koṣeegbe fun ọpọlọpọ awọn ọdọ eyi to si n mu wọn maa tẹ ọkọ leti roke okun.
Ẹniọwọ John Onaiyekan ṣalaye pe bi o ba jẹ pe oun ni aarẹ orilẹede Naijiria lọwọlọwọ bi nnkan ṣe ri yii, nṣe ni oun yoo kọwe fi ipo silẹ lẹyẹ o sọka.
O bu ẹnu atẹ lu awọn olori orilẹede Naijiria pe ti ara wọn nikan ni wọn n le kiri nipa kikọ ile nlanla, ti wọn si n rinrinajo kaakiri orilẹede Naijiria.
Ojiṣẹ Ọlọrun naa ṣalaye pe oju n gba oun ti fun bi awọn ọmọbinrin orilẹede Naijiria ti wọn ko lọ ṣe owo kotọ loke okun ṣe di alagbe lawọn opopona ilu Rome atawọn ilu miiran lorilẹede Italy.
Ẹniọwọ Ọnaiyekan ba awọn oniroyin sọrọ ṣaaju ipejọpọ ijọ Katoliiki lati sọrọ lori bi awọn eeyan ṣe n lọ kuro lorilẹede Naijiria eleyii ti wọn fẹ ṣe ni ọjọ iṣẹgun.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Biṣọ̀bu ijọ Katoliiki niluu Abuja, Ẹniọwọ John Onaiyekan kilọ pe awọn adari lorilẹede NAijiria gbọdọ ṣe ohun to tọ fun atunṣe ati idagbasoke orilẹede Naijiria
Ni oṣu keji ọdun yii ni aarẹ Buhari bori ninu idibo sipo aarẹ lorilẹede Naijiria to jẹ orilẹede to n pọn epo rọbi julọ nilẹ Afirika ṣugbọn ti ida kan ninu mẹrin awọn eeyan rẹ ko ri iṣẹ ṣe.
Ọpọ awọn ọmọ orilẹede Naijiria ni wọn ti gbiyanju ati rin irinajo to lewu ninu gidigidi gba aṣalẹ ilẹ Sahara Desert ati ori okun Meditaranean lati lee de ilẹ Yuroopu.
Iye awọn to n lepa irinajo yii ti n dinku lati ẹbẹrun lọna ogoji to gba ori okun gunlẹ si orilẹede Italy lọdun 2016 si ẹgbẹrun kan o le igba ati aadọta ni ọdun to kọja, eleyii ti ko yẹ lori igbesẹ mawoju ẹ eleyi ti ajọ orilẹede Yuroopu gbe lati kọ oju oro sawọn to n ṣowo fifi eeyan ṣọwọ soke okun lọna ti ko bofinmu.
Ọpọ awọn to n fi orilẹede Naijiria silẹ ni wọn wa lati agbegbe gusu ipinlẹ Edo.
Awọn obinrin ati ọdọbinrin ni wọn saba maa n ṣubu sinu ikẹkun yii ni ilepa iṣẹ, ṣugbọn lẹyin o rẹyin wọn yoo di aṣẹwo.
Onaiyekan rọ ijọba lati 'tun Naijiria ṣe'
 Ma jẹ ki n pe aja lọbọ, oju n gba mi ti, oju n timi- emi iranṣẹ Ọẹọrun lati ilu nla bii Abuja, mo n lọ ni oju popo ni ilu Rome, Milan, Naples, ki n si maa ri awọn ọmọ mi ni oju popo fun tita, Ẹniọwọ naa fi to BBC leti lẹyin ipade oniroyin wọn naa.
Oju n ti mi, maa duro lati ki awọn miran ninu wọn gan-ko tilẹ rọrun lati ba wọn jiroro nitori pupọ ninu wọn lo jẹ pe ati abule ni wọn ti wa lai ni imọ ẹkọ kankan. Imọ ti wọn ni ko ju eyi ti wọn yoo fi ṣe owo nọbi wọn loju popo orilẹede Italy.-oju n ti mi gidigidi.
O ni aini afojusun ati iran to kuna awọn oloṣelu Naijiria n ṣakoba fun orilẹede yii, bẹẹ lo rọ wọn pe bi wọn ko ba ni afojusun lori bi wọn yoo ṣe gbe orilẹede Naijiria goke agba, ki wọn yago fun ipo oṣelu.
O wa rọ ijọba lati 'tun Naijiria ṣe' ki awọn ọdọ lee dẹkun sisa kuro lorilẹede Naijiria lọ soke okun.
Royal baby: Harry ní ojú gbogbo yóò rí ọmọọba tuntun ní ọjọ́ méjì sásìkò yí
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Michelle Obama rọọ lati ṣe ohun gbogbo ni wọntunwọnsi
Ọmọọba Harry ni oun ati iyawo oun, Meghan ṣi n ronu lori orukọ ti wọn yoo sọ ọmọ wọn tuntun.
"O ni nigba ti a o ba fi ri ojọ meji si asiko yii, oun yoo ṣe ikede miran, ""ki gbogbo awọn eeyan lee ri ọmọ tuntun naa soju""."
Lẹyin ti aafin ilẹ Gẹẹsi ti kede ibi ọmọ ọkunrin tuntun fun ọmọọba Harry ati aya rẹ Meghan, wọn ti gbe iwe ikede ibi rẹ siwaju aafin Buckingham palace bayii.
"Lara awọn to kọkọ ki ẹbi naa ku oriire ni baba iya ọmọ, alagba Thomas Markle. Alagba Markle ṣe adura pe ""ọmọ naa yoo dagba, yoo si sin ori ade atawọn eeyan ilẹ Gẹẹsi pẹlu ayọ, ati iwa rere."""
Bakan naa, olotu ijọba ilẹ Gẹẹsi, Theresa May ti ranṣẹ ikini ku oriire si ọmọọba Harry ati Meghan fun ti ọmọọkunrin wọn.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ninu ọrọ tirẹ, aya aarẹ ana lorilẹede Amẹrika, Michelle Obama ki Ọmọọba Harry ati Meghan ku oriire na. O ni 'inu mi dun to bẹẹ ti n ko lee duro lati ri ọmọkunrin jojolo naa'
Ninu amọran to wa fun iya ọmọ tuntun naa, Michele ni loots ni pe Meghan ko ronu pe irufẹ igbe aye bayii yoo kan an gẹgẹ bi oun pẹlu lori ariwo ọja ti yoo maa wa nitori ipo rẹ lawujọ.
O rọọ lati ṣe ohun gbogbo ni wọntunwọnsi.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Harry ni ṣaka lara iya ati ọmọ le
Bakan naa, olori ilu Toronto, John Tory ti ki awọn baba ati iya tuntun naa ki oriire.
O dara lati gbọ pe ṣaka lara iya ati ọmọ ya, mo si n reti abẹwo ẹbi yii si ilu Toronto.
Ẹwẹ, biṣọbu Micheal Curry to waasu nibi igbeyawo Harry ati Meghan ni ọdun 2018 ni ibi ọmọkunrin naa fihan pe 'ireti n bẹ'Bẹẹni o ṣe adura ibukun fun ẹbi naaati ọmọ wọn tuntun.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Michelle ni inu oun yoo dun lati ri ọmọ̀ naa laipẹ
Amọṣa, baba ọmọ naa, iyẹn Ọmọọba Harry ni awọn ko tii jiroro lori orukọ ti ọmọ naa yoo jẹ.
"Bẹẹni tọkọtaya Harry ati Meghan ti dupẹ lọwọ gbogbo mutumuwa ninu atẹjade kan loju opo instagram wọn dun ""atilẹyin wọn ati aanu ti wọn fi han wọn"""
Atẹjade naa ni 'akoko ayọ nla lo jẹ ninu igbesi aye wọn bi wọn ṣe n ki akọbi wọn kaabọ.'
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Aafin Ọba ilẹ Gẹẹsi kede pe ni owurọ ọjọ aje ni o wọ ile igbẹbi lọ
Iyawo ọmọọba ilẹ gẹẹsi, Meghan Merkel ti bí ọmọ ọkùnrin.
Meghan bẹrẹ si nii rọbi bayii fun akọbi Ọmọọba Harry.
Aafin Ọba ilẹ Gẹẹsi, Buckingham palace lo kede eyii.
Gẹgẹ bii agbẹnusọ fun  aafin ṣe sọ, ni owuro ọjọ aje ni Merghan wọ ile igbẹbi lọ pẹlu ọkọ rẹ, Harry ni ẹgbẹ rẹ.
Ọmọ naa ni yoo jẹ ẹẹkẹjọ ọmọ-ọmọ-ọmọ fun Ọbabinrin ilẹ Gẹẹsi.
Lọkọlaya Harry and Meghan ti sọ pe o di ẹyin igba ti wọn ba ti yayọ ọmọ tuntun naa pẹlu awọn mọlẹbi wọn ki wọn to kede ibi rẹ fun aye gbọ.
Ni ọjọ kẹẹdogun oṣu kẹwa ọdun 2018 ni wọn kede pe arabinrin Meghan ti fẹraku, iyẹn lasiko abẹwo wọn si orilẹede Australia ati New Zealand.
Obafemi Awolowo University: Àwọn tó jí olùkọ́ wa gbé kò tíì sọ ohun tí wọ́n fẹ́ gbà
Oríṣun àwòrán, oau
Ní ọjọ Aiku ni wọn ji Ọjọgbọn Adegbẹhingbe gbe.
Awọn ajinigbe ti ji olukọ agba fasiti Ọbafẹmi Awolọwọ to wa nilu ile Ifẹ kan, Ọjọgbọn Yinka Adegbehingbe gbe.
Agbegbe ikire si apomu ni opopona marosẹ Ifẹ si Ibadan ni wọn ti ji ojọgbọn naa gbe.
Ninu ifọrọwerọ rẹ pẹlu BBC news Yoruba, alukoro ileewe fasiti OAU, Abiọdun Olarewaju ṣalaye pe ni nnkan bi agogo mẹjọ abọ si mẹsan alẹ ọjọ aiku ni wọn ji ọjọgbọn naa gbe.
Ileewe ẹkọ imọ ilera ati iṣegun ni ọgba fasiti naa ni ọjọgbọn Adegbẹhingbe ti n ṣiṣẹ. Ohun ati iyawo rẹ ni wọn jijọ n rinrin ajo lasiko ti awọn ajinigbe naa ṣọṣẹ.
O ni titi di asiko ti oun fi n ba BBC sọrọ, awọn ajinigbe naa ko tii kan si ẹbi tabi ileewe naa lori ohun ti wọn fẹ ki wọn to lee da Ọjọgbọn naa pada.
Wo àwọn orílẹ̀èdè tí wákàtí ààwẹ̀ wọn gùn ju ti Nàìjíríà lọ
Kókó ọ̀rọ̀: Wíwo àkókò dá lórí olú ìlú orílẹ̀èdè kọ̀ọ̀kan
Orísun: aladhan.com ati islamicfinder
State Joint Local Government Accounts: Ìjìyà ti wà fún báńkì tó bá ṣí àṣùwọ̀n ìjọba ìbílẹ̀ sílẹ̀ fún gómìnà jẹgúdújẹrá
Oríṣun àwòrán, Getty Images
NFIU ni ko saye fun awọn gomina ipinlẹ lati maa lu owo ijọba ibilẹ ni ponpo mọ
Ko saye iregbe mọ fawọn gomina to n fi owo aṣuwọn ajumọni ipinlẹ atijọba ibilẹ ta sere mọ bayii.
Ajọ to n nmojuto iwaadi to da lori iṣuna lorilẹede Naijiria, NFIU ti gbe aṣẹ kalẹ fun gbogbo awọn banki lorilẹede Naijiria lati ṣọra fun gbigbe owo jade fawọn gomina lati inu aṣuwọn naa lai jẹ pe irufẹ owo bẹẹ kọkọ wọ inu aṣuwọn ifowopamọsi ijọba ibilẹ ti ọrọ kan.
Awuyewuye lori ara tawọn gomina n fi owo inu aṣuwọn ajọni ijọba ipinlẹ ati ibilẹ lorilẹede Naijiria kii ṣe ajeji mọ fun ọjọ pipẹ, to bẹẹ gẹẹ ti ajọ to n nmojuto iwaadi to da lori iṣuna lorilẹede Naijiria, NFIU ti fi ṣapejuwe rẹ gẹgẹ bi ọpa iwa ijẹkujẹ lorilẹede Naijiria.
Ajọ naa ni bẹrẹ lati ọjọ kini oṣu kẹfa ọdun 2019, banki yoowu ti o ba tun pẹlu ọbọ jawura lori ọrọ naa yoo fi ẹnu fẹra bi abẹbẹ.
O fi kun un pe ko gbọdọ si aaye fun ẹnikẹni lati gba owo to ju ẹgbẹrun lọna ẹẹdẹgbẹta naira lojumọ. Irufẹ owo bẹẹ ti ẹnikẹni ba fẹ gba gbọdọ wa nipasẹ sọwedowo (cheques) tabi lori ayelujara.
Osun state: PDP ní nítorí ẹjọ́ lórí ìbò gómìnà Ọ̀ṣun ni Ọlọ́pàá fi mú Sẹ́nétọ̀ Ademọla Adeleke sí àhámọ́
Oríṣun àwòrán, @IsiakaAdeleke1
Ọlọpaa ti n n fi ẹsun lilo ayederu iwe ẹri kan Sẹnetọ Adeleke fun igba diẹ bayii
Ileeṣẹ ọlọpaa ti fi panpẹ ofin gbe oludije fun ipo gomina ipinlẹ Ọṣun labẹ aṣia ẹgbẹ oṣelu PDP nibi idibo gomina ipinlẹ naa to waye ni ọdun 2018.
Iroyin bọ si gboro ni ọjọ aje pe awọn ọlọpaa ti mu Sẹnetọ Ademọla Adeleke si ahamọ lori ẹsun to niiṣe pẹlu ẹsun pe o lo ayederu iwe ẹri girama.
Iroyin to n tẹ BBC News Yoruba lọwọ ṣalaye pe owurọ ọjọ aje ni Sẹnetọ Adeleke lọ yọju si ileeṣẹ ọlọpaa gẹgẹ bi awọn ọlọpaa ṣe paa laṣẹ fun.
‘Kò tọ́sí Adeleke láti díje dupò gomina Ọṣun’
Ilé ẹjọ́ kòtẹ́milọ́rùn yá lórí ọ̀rọ̀ Adeleke- PDP
Adeleke fọhùn, 'èmi ni gómìnà tí wọ́n dìbò yàn'
Gẹgẹ bii iroyin to tẹ wa lọwọ ṣe sọ, agogo mẹsan owurọ ọjọ aje ni Adeleke farahan ni olu ileeṣẹ ọlọpaa orilẹede Naijiria nilu Abuja.  Iroyin ọhun ni nibẹ ni wọn ti gbe e lọ si agọ ọlọpaa Maitama pẹlu 'erongba ati gbee lọ si ile ẹjọ magistrate ti ko si ẹni to mọ ni ọla'
Atẹjade lati ọdọ ẹgbẹ oṣelu PDP nipinlẹ Ọṣun eleyi ti alaga ẹgbẹ oṣelu naa, Sọji Adagunodo fi ọwọ si ni nṣe ni awọn ọlọpaa n fẹ halẹ mọ Sẹnetọ Adeleke nitori ẹjọ to n pe lati gba aga gomina ipinlẹ Ọṣun pada ni ile ẹjọ.
Ẹgbẹ oṣelu PDP ni ṣe ni ijọba apapọ n gbaradi ati gbogun ti Sẹnetọ naa ni lati lee gbagbe ilepa rẹ.
Ẹgbẹ oṣelu PDP ni nṣe ni awọn ọlọpaa fẹ wa ọna bomi pa igbẹj ile ẹjọ lori esi ibo gomina ipinlẹ Ọṣun.
Titi di asiko yii, ileeṣẹ ọlọpaa ko tii sọ ohunkohun lori ọrọ naa.
Oríṣun àwòrán, Ademola adeleke
Titi di asiko yii, ileeṣẹ ọlọpaa ko tii sọ ohunkohun lori ọrọ naa
Bakan naa, ileeṣẹ ipolongo ibo fun Sẹnetọ Adeleke pẹlu ti ke sawọn ẹgbẹ ajafẹtọ atawọn to ni ifọn leekanna lorilẹede Naijiria ati lagbaye lati dide fun Sẹnetọ naa.
Ninu atẹjade kan ti ileeṣẹ naa fi sita, eleyii ti agbẹnusọ rẹ, Ọgbẹni Rasheed fi ṣọwọ si BBC News Yoruba, o ni gbogbo ẹsun ti awọn ọlọpaa fi n kan an ni ile ẹjọ ti n joko le tabi gbe idajọ kalẹ le lori.
Ọga ileewe girama ti Sẹnetọ Adeleke lọ ti jẹri labẹ ibura niwaju ile ẹjọ giga kan ni agbegbe Bwari pe lootọ ni ileewe naa fun  un ni iwe ẹri. Bakan naa ni ajọ onidanwo iwe mẹwa, WAEC pẹlu ti ṣalaye pe lootọ ni Ademọla Adeleke joko ṣe idanwo naa. Fun ọlọpaa lati tun gbe ẹsun yii kan naa dide fi han pe o ni ohun miran ti wọn n wa.
Obafemi Awolowo University: Olùkọ́ fásitì OAU gbòmìnira lọ́wọ́ àwọn ajínigbé
Oríṣun àwòrán, Facebook/Adegbehingbe
Olukọ agba fasiti Ọbafẹmi Awolọwọ to wa nilu ile Ifẹ, Ọjọgbọn Yinka Adegbehingbe ti wọn ji gbe ti gba ominira lọwọ awọn ajinigbe.
Iyawo olukọ naa, Bernice Adegbehingbe lo fidi ọrọ mulẹ fawọn oniroyin.
Alukoro fun ile iṣẹ ọlọpaa ipinlẹ Oṣun, Folasade Odoro naa sọ aridaju pe Ọjọgbọn Adegbehingbe ti mori bọ lọwọ awọn ajinigbe.
'500 level'' ni mo wà nígbà tí mo di adélé Ọba'
Agbegbe Ikire si Apomu ni opopona marosẹ Ifẹ si Ibadan ni wọn ti ji ojọgbọn naa gbe.
Ninu ifọrọwerọ rẹ pẹlu BBC news Yoruba, alukoro ileewe fasiti OAU, Abiọdun Olarewaju ṣalaye pe ni nnkan bi agogo mẹjọ abọ si mẹsan alẹ ọjọ aiku ni wọn ji ọjọgbọn naa gbe.
Oríṣun àwòrán, oau
Ní ọjọ Aiku ni wọn ji Ọjọgbọn Adegbẹhingbe gbe.
Ileewe ẹkọ imọ ilera ati iṣegun ni ọgba fasiti naa ni ọjọgbọn Adegbẹhingbe ti n ṣiṣẹ. Oun ati iyawo rẹ ni wọn jijọ n rinrin ajo lasiko ti awọn ajinigbe naa ṣọṣẹ.
Oluwo: Mo lè jẹ Ọba ní Ile Ife
Ramadan: Àwọn mùsùlùmí tí kò bẹ̀rẹ̀ àwẹ̀ títí d'ìgbà tí wọ́n tó fojú r'óṣù
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Olori Musulumi ni Naijiria ni o ma n saba paṣẹ bibẹrẹ awẹ Ramdan ni Naijiria
Ninu oṣu Ramadan ọdun yi,gẹgẹ bi iṣe rẹ Sultan Sokoto kede pe ki awọn musulumi bẹrẹ awẹ lọjọ Aje lẹyin ti wọn ri oṣu lawọn ilu kọọkan.
Amọ bi awẹ naa ti ṣe di meji lọjọ iṣẹgun, niṣe ni awọn musulumi kan n sọ pe awẹ ti awọn ṣẹṣẹ di ẹyọkan ni.
Nibo ni wọn wa ati pe ki lo mu wọn faake kọri toun ti aṣẹ olori Musulumi ?
Akọroyin BBC,Mansur Abubakar jabọ lati ilu Kano nibi ti o ti ba awọn musulumi ti wọn kii bẹrẹ awe bi wọn ko ba foju ri oṣu fun ara wọn.
Ẹ gbọ awijare wọn lori igbesẹ  wọn yi i.
Jamilu Shehe ni tirẹ salaye pe lati igba toun ti wa ni kekere ni ohun kii bẹrẹ awẹ ayafi ti ohun ba foju ri oṣu.
Jamilu Shehe
"Kii ṣe wi pe mo ṣarifin  si Sultanamọ lati kekere ,bi mi o ba foju ri oṣu emi kii gba awe.Bẹẹ naa si ni ọrọ ri ni ipari awẹ.''
Ni soki, ohun ti Jamilu  n sọ pe bi ohun ko ba foju ri oṣu,ohun kii dawọ awẹ gbigba duro.
Yusha'u Abdulhamid
Iriwisi ti  Yusha'u Abdulhamid tun fẹ lagbara diẹ
O ni idi ti ohun kii ba awọn Musulumi to ku gba awẹ ni pe ''ohun ti ọkan oun ba sọ nikan loun ma n tẹle''
''Oṣu Ramadan to ba yọ,awa musulumi ta wa ni Kano gbọdọ ri,bẹẹ lo si yẹ ko ri fawọn ti ipinl mii.Mo pe awọn rẹ mi ni Yobe ati Maiduguri wọn si  pe an ko tifoju ri oṣu''
''Emi  o ṣarifin Sultan amọ ilana ti mo n lo lati gbawe leleyi ti awọn obi mi ati olukọ mi fi mọ mi''
Sani Musa
Sani Musa naa wa lara awọn ti kii bẹrẹ awẹ lai foju r'oṣu.
Ohun ti igbesẹ Sani,Yushau,Jamilu ati awọn miiran bi ti wọn n ṣe ni pe lọjọ ti awọn musulumi yoku ba n dawọ idunu itunu awẹ awọn ko ni ti dawọ awẹ gbigba duro.
Ni nnkan bi ọjọ kan tabi meji lyin ti gbogbo janmọ yoku ba pari awẹ lawọn yoo ṣọdun tiwọn.
Oríṣun àwòrán, Anadolu Agency
Awọn irinse bayi ni wọn ma fi n wa oṣu
Ni Naijiria ati ni awọn orileede miran ti musulumi wa to fi d'ori Saudi, awọn olori musulumi a ma gbe eto  oṣu wiwa le awọn igbimọ kan lọwọ.
Awọn igbimọ yi ni yoo wa jabọ fawọn olri nipa ibi ti wọn ba ti ri oṣu tuntun.
Ki eeyan to le foju ri oṣu yi nigba ti o ba jade,awọn ọmọ igbimọ a ma lo irinṣẹ igbalode  lati mọ ni pato pe oṣu naa jade.
Oṣu riri ṣe pataki nitori ohun ni yoo ṣe atọna igba ti awẹ yoo bẹrẹ ati igba ti yoo pari.
Ninu sin Islam, wọn a ma fi yiyọ oṣu tuntun mọ igba ti awọn ọdun pataki bi ọdun awẹ ati ileya yoo waye.
Ọjọ mọkandinlọgbọn abi ọgbọn ni wn fi n ka ọjọ osupa.Ti wn ko ba ri oṣu lọjọ kọkandinlọgbọn, a jẹ wi pe ọgbọn ọjọ ni oṣu naa de.Fun idi eyi,awẹ yoo bẹrẹ lọjọ kini oṣu tuntun.
Onimọ ẹsin Islam kan,Sheikh Garangamawa to ba BBC sọrọ ṣalaye pe kii ṣe awọn ọmọ igbimọ to n wa oṣu nikan lo le wa oṣu bi kii ṣe pe iwọ gbogbo musulumi ni.
Ninu ọrọ ti rẹ, Imaamu agba mọsalaṣi Kano,Abdullahi Idris ni awọn to n duro de ki wọn ri oṣu fun ara wọn ko ṣe ohun to tọ.
O ni  ''Awẹ ti Ọlọrun mọ, ti yoo si tẹwọgba ni eleyi ti gbogbo eeyan jijọ gba ni ilana pẹlu aṣẹ olri wọn.Awọn to yapa lori rọ yi ko ni awijare tofẹsẹ mulẹ. nitori pe wọn ko ni agbọye ẹsin daada.''
''Nitori eleyi,wọn gbọdọ gba awẹ kafara lati fi wa itanran ohun ti wọn ṣe. Koda bi o ba ṣe asikọ Umar Ibn Khattab to jẹ saabe agba ni wọn wu iru iwa yi, afaimọ ki wọn ma da sẹria ẹgba fun wọn''
Adeleke vs Oyetola: Ilé ẹjọ́ kòtẹmilọ́rùn yóò dájọ́ ìdìbò gómìnà Oṣun ọdún 2018
Ile ẹjọ kotẹmilọrun to n gbejọ lori ọrọ ẹni tó lẹtọ lati jẹ Gomina nipinlẹ Osun laarin Gboyega  Isiaka Oyetola ati Ademola  Adeleke  yo gbe idajọ kalẹ lọjọru.
Eto Idajọ ti wọn fi ikede rẹ sita ninu iwe ile ẹjọ naa ni awọn alatilẹyin awọn ti ọrọ naa kan fi sọwọ sawọn oniroyin yoo waye laago mẹsan owurọ.
Ninu ifọrọwanilẹnuwo lori ẹrọ alagbeka, ọkan lara awọn ọmọ igbimọ ipolongo Ademola Adeleke,  Niyi Owolade sọ fun BBC Yoruba pe lootọ ni idajọ naa yoo waye nilu Abuja.
Iriwisi àwọn ará ìlú ṣe ọtọtọ lórí èsì ìdìbò Osun
Adeleke: Àwọn ará Ẹdẹ bẹ síta pẹ̀lú ìdùnnú lórí ìdájọ́ èsì ìdìbò gómínà Ọṣun
Ẹwe, aburo Senetọ Ademola Adeleke kan ti orukọ rẹ n jẹ Dele Adeleke naa ni ohun lohun gba iwe naa nile ẹjọ kotẹmilọrun lAbuja
Aworan ikede naa re e
Oríṣun àwòrán, Dele Adeleke
Ni ọjọ kejilelogun oṣu Kẹta ọdun yi ni ile ẹjọ to n gbejọ lori ọrọ idibo Gomina ipinlẹ Osun gbe idajọ kalẹ pe Senetọ Ademola Adeleke lo jawe olubori ninu ibi Gomina ipinlẹ Osun.
Kete ti idajọ yi di mimọ ni awọn agbẹjọro Gomina Oyetola gbaile ẹjọ kotẹmilọrun lọ lati tako idajọ naa.
Idajọ ti wọn yoo kede lọla yi da lori pe Oyetola tako idajọ ti Adeleke saaju ri gba lọdọ igbimọ to n gbọ ẹjọ lori idibo naa.
Olórin tàkasúfèé pàdánù mílíọ̀nú náìrà kan lori ìfẹsẹ̀wọsẹ̀ Liverpool Vs Barcelona
Oríṣun àwòrán, @iam_kcee
Olorin takasufẹ ọmọ orileede Naijiria kan ti farakasa miliọnu Naira kan lori ifẹsẹwọnsẹ Champions League to waye laarin ẹgbẹ Liverpool ati Barcelona.
Ninu ifẹsẹwọnsẹ naa Liverpool ja ireti Barcelona kulẹ pẹlu ami ayo mẹrin si mẹta.
Gẹgẹ bi ohun ti a ri ka loju opo Twitter niṣe ni Gbajugbaja olorin takasufe ni, Kcee leri si Dike Chidozie@mrchidozie pe oun yoo fun ni miliọnu naira kna ti Liverpool ba fi le na Barcelona.
Oríṣun àwòrán, @mrchidozie
Wakati kan abọ lẹyin ti ifẹsẹwọnsẹ naa bẹrẹ, ọrọ ni iyanju ti Liverpool si pegede ti Kcee si padanu miliọnu Naira kan.
Kcee wuwa ọmọluabi ti o si ṣika adehun rẹ si Chidozie.
O san owo si akoto Chidozie ti oun naa si fi idupe sita loju opo Twitter pe oun ti ri ''alert'' gba
Nigeria Police: Ilé iṣẹ́ ọlọ́pàá fẹ́ gba ọ̀pọ̀ kọ́ńsítébù láti ranwọ́ lórí ètò ààbò
Oríṣun àwòrán, Nigeria Police Force
Eto aabo Naijiria
Lara akitiyan rẹ lati ri wi pe eto aabo gbopọn si lorilẹede Naijiria, ile iṣẹ ọlọpaa ti ṣetan lati gba ọpọlọpọ kọnsitebu ti yoo maa ṣiṣẹ pẹlu awọn agbofinro lawujọ
Alukoro fun ile iṣẹ ọlọpaa Frank Mba ṣalaye pe awọn kọnsitebu yii yoo maa ṣeranwọ fawọn ọlọpaa ṣugbọn wọn ko ni lanfani lati gbebọn.
Igbaniṣiṣẹ awọn kọnsitebu ti ile iṣẹ ọlọpaa yoo kede rẹ laipẹ niroyin sọ pe ijọba apapọ gan an fọwọ si.
Bakan naa, iroyin tun sọ pe awọn gomina gan an ko sai fọwọ si igbesẹ ile iṣẹ ọlọpaa ọhun.
Agbẹnusọ fun ile iṣẹ ọlọpaa to fọrọ naa lede sọ pe awọn eeyan ti ọjọ ori wọn bẹrẹ lati ọmọ ọdun mọkanlelogun si aadọta ọdun ni ile iṣẹ ọlọpaa fẹ gba fun iṣẹ ọhun.
A tun gbọ pe ile iṣẹ ọlọpaa n gbero lati gba awọn ọmọluabi eeyan bi alufa ijọ, imaamu, agbẹjọro, oniroyin, olukọ ati awọn ọdọ fun iṣẹ naa.
New Emirates: Ilé ẹjọ́ dá Gómìnà Ganduje dúró yíyan àwọn Emir tuntun ní Kano
Oríṣun àwòrán, Facebook/Abdullahi Ganduje
Ọrọ awọn emir tuntun ni ipinlẹ Kano
Ile ẹjọ giga kan niluu Kano ti paṣẹ fun gomina Abdullahi Ganduje lati sẹ mẹdọ lori igbesẹ rẹ lati yan awọn ọba miiran yatọ si Emir ilu kano Sanusi Lamido Sanusi.
L'Ọjọru ọsẹ yii ni gomina Ganduje buwọlu aba ti yoo jẹki Sanusi lagbara lori  ijọba ibilẹ mẹwaa pere ninu mẹrinlelogoji to wa nipinlẹ Kano.
Ṣugbọn adajọ Nasiru Saminu sọ pe ki Gomina Ganduje k'ọwọ ọmọ bọ aṣọ na lẹyin ti awọn ọmọ ile igbimọ aṣofin ipinlẹ Kano meji, Rabi'u Saleh Gwarzo ati Babangida Yusuf Sulaiman gbe Ganduje lọ sile ẹjọ lori igbesẹ rẹ.
'500 level'' ni mo wà nígbà tí mo di adélé Ọba'
Ẹ wo àrà àwọn ọmọ kékeré ń fi ẹ̀kọ́ kọ̀mpútà dá
Awọn aṣofin naa ni igbesẹ lati yan awọn Emir miiran nipinlẹ Kano lodi si ofin ipinlẹ naa.
Adajọ Saminu fidi rẹ mulẹ niu idajọ rẹ pe ki o digba ti igbẹjọ ba pari ki gomina Ganduje to lo gbe igbesẹ kan tabi omiran lori ọrọ Emir ilu Kano.
Ọjọ Abamẹta ni ijọba n gbero tẹlẹ lati fun awọn Emir tuntun to ba yan ni iwe ẹri tẹlẹ ki ile ẹjọ to daa duro.
JAMB Result 2019: 34,120 akẹ́ẹ̀kọ́ ni kò ní èsì ìdańwò JAMB
Oríṣun àwòrán, JAMB
Ajọ JAMB ní àwọn akẹ́ẹ̀kọ́ lè wo èsì ìdánwò nípa títẹ àtẹ̀jísẹ́ 'RESULT' si '55019' láti wo iye tí wọn gbà nínú ìdánwò náà.
Ajọ to n bojuto idanwo asewọle si ile iwe giga, JAMB ti ni akẹẹkọ ọdọmọkunrin ọdun mẹẹdọgun, Elene Franklin lo gba maaki to pọju lọ ninu esi idanwo JAMB.
Adari Ajọ JAMB, Ishaq Oloyede sọ eyi lasiko to n kede wi pe   awọn ti fi esi idanwo JAMB sita fun awọn akẹẹkọ lati mọ bi wọn se yege si ninu idanwo naa.
Oloyede ni Franklin gba iye maaki aadọtalelẹlọọdurundinmeji(348) ninu erinwo(400).
o wi pe  akẹẹkọ to le ni ẹgbẹrun lọna ọgbọn (34,120) ni awọn ti awọn ko ni  fi esi idanwo wọn sita.
Oloyede ni akẹẹkọ to le ni miliọnu (1,792,719) ni wọn yoo ri esi idanwo gba ninu iye awọn to se idanwo naa (1,886,508).
Ẹ wo àrà àwọn ọmọ kékeré ń fi ẹ̀kọ́ kọ̀mpútà dá
Amọ, O ni gbogbo ojude ti wọn ti se magomago ninu idanwo naa ni awon ti ti pa, ti ko si ni si idanwo ni ojude naa mọ.
Adari Ajọ JAMB naa wa parọwa si awọn akẹẹkọ naa lati wo esi idanwo wọn ti wọn ba ti tẹ atẹjisẹ 'RESULT' si '55019' lori ẹrọ ilewọ wọn, lai lọ si ori ẹrọ ayelujara lati lọ wo o.
Osun Governorship Elect: Dele àbúrò Adeleke ní PDP yóò borí nílé ẹjọ́ tó gajù lọ
Oríṣun àwòrán, Facebook/Ademola Adeleke
Ọrọ ibo gomina ipinlẹ Oṣun
Ti ina ko ba tan laṣọ, ẹjẹ kii tan leekana lọrọ igbẹjọ idibo gomina ipinlẹ Oṣun da fawọn oludije ẹgbẹ osẹlu PDP Ademola Adeleke, lẹyin ti aburo rẹ Dele sọ pe Adeleleke yoo bori nile-ẹjọ to gaju lọ.
Ẹ o ranti wi pe ile ẹjọ kotẹmilọrun l'Abuja da idajọ igbimọ igbẹjọ idibo gomina ipinlẹ Oṣun to waye lọdun 2018 to sọ pe Adeleke lo jawe olubori ninu ibo ọhun nu ti o si ni Gomina Gboyega Oyetola lo wọ le.
Ṣugbọn Dele ni o da oun loju t'ada pe ile ẹjọ to ga julọ naa yoo da idajọ ile ẹjọ kotẹmilọrun nu.
African in Greenland: Kí ló sún ilẹ̀ Afirika dénú gbígbé inú yìnyín?
Ẹ wo àrà àwọn ọmọ kékeré ń fi ẹ̀kọ́ kọ̀mpútà dá
Adeleke kọkọ bori pẹlu ibo 254,698 ti Gomina Oyetola to jẹ oludije fẹgẹ APC si ni 254,345 ninu idibo to waye lọjọ kejilelogun oṣu Kẹsan-an ọdun 2018.
Ṣugbọn Oyetola la Adeleke mọ lẹ lẹyin ti afikun idibo waye lawọn ibudo idibo kan ti wọn wọgile ibo.
Dele ṣalaye pe idajọ erefee ni ile ẹjọ kotẹmilọrun da, ati pe ile ẹjọ naa ko foju sunnunkun wo ẹjọ ọhun ki o to dajọ.
O fikun ọrọ rẹ pe gbogbo eeyan nipinlẹ Oṣun lo mọ pe Adeleke lo wọ le ibo gomina nipinlẹ Oṣun.
Ààrẹ Nàìjíríà tẹ́lẹ̀ rí Goodluck Jonathan ní òun ó ni ọrọ̀ kankan nílẹ̀ Òkèrè
Oríṣun àwòrán, PHILIP OJISUA
Aarẹ Jonathan ko jẹjọ kankan lori ọrọ to jọ mọ ajẹbanu
Aarẹ Naijiria tẹlẹri Goodluck Jonathan ti ni, ati ile ati ileeṣẹ to fi mọ akoto ikowopamọsi nilẹ okere, ohun ko nikankan ninu wọn.
Ọrọ rẹ yi jẹ esi to fọ ni idahun si iroyin kan to gbode pe awọn agbẹjọro ijọba apapọ ti forukọ rẹ sinu awọn to n gbẹjọ ajẹbanu niwaju ile ẹjọ kan nilu London pe o gba abẹtẹlẹ.
Ninu atẹjade kan ti a ri lati ọwọ oluranlọwọ rẹ lori ọrọ iroyin,Ikechukwu Eze,Aarẹ Jonathan ni awọn ko ṣẹṣẹ ma gbo iru irọ bẹ.
O ni Aarẹ tẹlẹri ko bere tabi gba abẹtẹlẹ...ko si si ohun to jọ bẹ''"
"Ọrọ ti wọn n sọ yi ti waye saaju ki Jonathan to d'ori alefa o ṣi yi tẹsiwaju lẹyin to kuro.Ọmọ ọdun mọkanlelọgọta ni Aarẹ Jonathan ko si fi igba kankan kowopamọ si ilẹ okere tabi ko ni ile lẹyin odi''
Ijọba apapọ Naijiria ni aiṣedede waye nipa bi awọn ile iṣẹ ipọnpo Eni ati Shell ṣe gba agbaṣe iṣẹ ni Naijiria ti wn si gbe wọn lọ si ile ẹjọ lati san owo itanran biliọnu dọla 3.5
Iroyin ta gbọ ni pe awọn ọga kan ni ile iṣẹ Shell to n wa epo rọbi ni Naijiria fun awọn oṣiṣẹ ijọba kan ni abẹtẹlẹ lati le gba aye ipọnpo OPL 245 lọdun 2011.
Ile ẹjọ kan ni orileede Faranse dajọ pe minisita ọrọ epo rọbi tẹlẹri Dan Etete jẹbi magomago ti o si fi owo eru ra ọkọ oju omi ati ile nla kan.
Bi ọrọ ti ṣe ri bayi, Aarẹ Jonathan ko jẹjọ kankan lori ọrọ naa.
TCN, ní kò s'óhun tí yóò ṣe iná mànàmáná ní Nàìjíríà lóní
Ẹgbẹ oṣiṣẹ TUC lo faake kọri pe oun yoo da iṣẹ ru nileeṣẹ to n pin ina ọba lorilẹede Naijiria, TCN
Ajọ to n pin ina ọba lorilẹede Naijiria, TCN ti ṣalaye fun BBC News pe iroyin ti awọn kan n gbe kiri pe ina ọba yoo lọ kaakiri orilẹede Naijiria lọjọ aje, ọjọ kẹtala oṣu karun ko lee waye.
Ileeṣẹ TCN ṣalaye ọrọ yii lasiko to n fesi si ihalẹ awọn ẹgbẹ oṣiṣẹ TUC ti wọn ni awọn yoo da họwuhọwu silẹ laggo ipese ina ọba nitori ẹsun ti wọn fi kan ileeṣẹ TCN pe o n fi iya jẹ awọn oṣiṣẹ rẹ.
Segun mu òògùn apakòkòrò tórí máàkì 167 nínú JAMB
Èmi ṣì ni alága ẹgbẹ́, wọn ò tó bẹ́ẹ̀ - Sowore
'Lórí iṣẹ́ ikàn yìí, a ti kọ́ ilé, ọmọ ti lọ ilé ìwé'
Alukoro fun ileeṣẹ to n pin ina ọba lorilẹede Naijiria, TCN, Ndidi Mbah ni awọn alaṣẹ ẹgbẹ oṣiṣẹ TUC lapapọ lo n ṣe kokari ifẹhonu han naa,eleyi to ni awọn ọmọ ẹgbẹ oṣiṣẹ naa to wa ni ileeṣẹ to n pin ina ọba, TCN gangan ti ọrọ naa gbe ru gbọn-gbọn-gbọn ko fara mọ.
O ni lootọ ni iwọọde naa n lọ lọwọ lasiko ti a fi n ko iroyin yii jọ ṣugbọn awọn oṣiṣẹ ileeṣẹ naa to jẹ ọmọ ẹgbẹ ileeṣẹ to n pin ina ọba lorilẹede Naijiria ko jade lati kopa ninu iwọde ọhun.
Ẹ gbẹ oṣiṣẹ TUC n fi ẹsun ifiya jẹ oṣiṣẹ kan ileeṣẹ to n pin ina ọba lorilẹede Naijiria, TCN
awọn oṣiṣẹ ni ileeṣẹ yii ko fara mọ apapọ ẹgbẹ oṣiṣẹ naa lori ifẹhonu han wọn naa. Koda, iwọde naa ko tu irun kan lara ijafafa iṣẹ ni ileeṣẹ yii nitori naa ko si ohun to jọ pe ina ọba yoo lọ kale-n-kako lorilẹede Naijiria loni."""
Ẹgbẹ oṣiṣẹ TUC to jẹ agbarijọpọ ẹgbẹ oṣiṣẹ n lọ kaakiri lati ti ilẹkun awọn ileeṣẹ to n pin ina mọnamọna lorilẹede Naijiria, TCN kaakiri orilẹede Naijiria lori ẹsun pe o n fi iya jẹ awọn oṣiṣẹ rẹ.
Police arrest: Kà nípa ohun mẹ́wàá tí o ní láti ṣe bí ọlọ́pàá bá mú ọ
Oríṣun àwòrán, @PoliceNG
Ileeṣẹ ọlọpaa ti bọ sita pẹlu awọn igbesẹ to yẹ fun araalu lati gbe lasiko ti awọn ọlọpaa ba fẹ mu wọn.
Ọrọ itaporogan laaarin araalu ati ọlọpaa lasiko ti wọn ba fẹ mu wọn ti di yanpọnyanrin ni ọpọlọpọ igba, koda o ti ja si iku fun ọpọ ti awọn miran si ti di alaabọ ara.
Sowore, AAC ti yọ Leonard Ezenwa tó kéde ìyọnípò Ṣòwòrẹ́
Segun, Máàkì tóo ní kọ́ ni yóò ṣé atọ́nà oríire rẹ láyé
Àwọn onímọ̀ ọpọlọ ní to bá gbé ìgésẹ̀ yí, aṣeyege dájú ní ìdánwò
Ileeṣẹ ọlọpaa ti wa fi si oju opo Twitter rẹ, igbesẹ ti o yẹ fun araalu ni gbigbe lasiko ti awọn ọlọpaa ba fẹ mu wọn.
Nnkan lee di ariwo ati yanpọnyanrin lasiko ti awọn ọlọpaa ba fẹ mu eniyan. Koda o lee tọka si eniyan gẹgẹ bii onijagidijagan ẹda tabi ki o fun ọlọpaa ni ero pe onitọhun n gbimọran ati sa mọ ọlọpaa lọwọ ni.
Awọn igbesẹ ti ileeṣẹ ọlọpaa la silẹ niyi o:
Oríṣun àwòrán, @PoliceNG
Ileeṣẹ ọlọpaa ti wa fi si oju opo twitter rẹ, igbesẹ ti o yẹ fun araalu ni gbigbe lasiko ti awọn ọlọpaa ba fẹ mu wọn.
Boya igbesẹ ọlọpaa ba ofin mu tabi ko ba ofin mu, jọwọ ara rẹ silẹ fun wọn lai fa wahala rara.
Ẹtọ rẹ ni lati mọ. Bi awọn ọlọpaa naa ko ba si tun ṣe afihan ara wọn, beere fun idanimọ wọn ati ibi ti wọn ti wa.
Oríṣun àwòrán, @PoliceNG
Beere fun idanimọ awọn ọlọpaa to wa mu ọ ati ibi ti wọn ti wa.
Eyi ṣe pataki nitori bi o ba nilo itọju. Paapaa julọ awọn ti aisan semi-semi, ẹjẹ ruru, itọ ṣuga ati warapa n ba finra.
(amọṣa kii ṣe gbogbo ipe ọlọpaa lo nilo iwe aṣẹ ofin lati mu ọ) labẹ ofin ilẹ Naijiria, agbara pupọ n bẹ lọwọ ọlọpaa lati mu s ni ọpọ igba.
(amọṣa kii ṣe gbogbo ipe ọlọpaa lo nilo iwe aṣẹ ofin lati yẹ ọ wo)
African in Greenland: Kí ló sún ilẹ̀ Afirika dénú gbígbé inú yìnyín?
Eyi wa lati rii pe wọn ko di ẹru ti kii ṣe tirẹ le ọ lori.
O ko mọ bi ẹru ọran ti onitọhun da ṣe wuwo to.
Eyi yoo fihan pe ọwọ rẹ mọ.
Bukola Saraki: Ìwà àrékérekè ni ilé mi tí EFCC tì pa
Oríṣun àwòrán, WIKIPEDIA
Ajọ to n gbogun ti iwa jẹgudujẹra, efcc ti ile saraki to wa ni 15a, 15b ati 17 to wa ni agbeegbe MacDonald Road, Ikoyi, Lagos.
Aarẹ Ile Igbimọ Asofin Agba, Bukola Saraki ti ni ìwà arekereke ati jibiti ni ile oun ti wọn ti pa ni Ikoyi ni ilu Eko.
Iroyin naa tan kalẹ pe ajọ to n gbe ogun ti iwa jẹgudujẹra, EFCC ti ile Saraki to wa ni 15a, 15b ati 17 to wa ni agbeegbe MacDonald Road, Ikoyi, Lagos.
"Bi o tilẹ jẹ pe nigba ti ile iṣẹ BBC kan si ajọ EFCC, wọn ni ""A ò tì ilé Saraki pa ní'lú Eko - EFCC"". Bẹẹ sini ṣaaju wọn ti ni Bukola Saraki kò kọjá òfin - EFCC."
Saraki ninu atẹjade to fi lede gba ọwọ agbẹnusọ rẹ, Yusuph Olaniyonu, bu ẹnu atẹ lu igbesẹ ajọ to n gbogun ti iwa ibajẹ, EFCC lori awọn ile rẹ ti wọn gbẹsẹ le.
'Bí ìrẹsì tèmi Ayinde bá ń pàkùta, kò tọ́ sẹ́nu aláàrù Barrymaade'
Saraki ni awọn ile wọnyii kii ṣe ohun ti a n fi bo, ati wi pe awọn ile ti oun sọ fun ijọba pe o wa ni ikawọ oun ni awọn ile wọnyii lasiko ti oun wa ni isejọba.
Bi o tilẹ jẹ pe Ajọ EFCC ti sọ wi pe awọn ko gbegi le ile rẹ to wa ni Ikoyi, Saraki ni EFCC tun rawọ le ẹsun ti ile ejo fi da oun lare ni.
Àwọn ìròyìn míì tí ẹ lè nífẹ sí
Whatsapp: Àwọn gbéwiri s'àtakò sí Whatsapp, yára ‘Update’ rẹ̀
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ile isẹ ẹ̀rọ ibaraẹnisọrọ Whatsapp ti ni ki awọn 1.5bn eniyan to n lo ki wọn 'update Whatsapp' wọn.
Awọn onijibiti ‘hackers’ ti fi imọ ẹrọ ‘spy software’ sori ẹrọ ilewọ awọn eniyan, eleyii ti wọn fi lee wo gbogbo ohun to wa lori ẹrọ ilewọ naa.
Nitori naa, alamojuto whatsapp ti ni ki gbogbo ẹni to n lo whatssap lọ ṣe eto ayipada ti wọn pese pẹlu 'update'.
Whatsapp to jẹ wi pe Facebook lo ni i, sọ wi pe awọn aṣebajẹ yii n lepa awọn eniyan kan ni wọn se se eyi, ati wi pe awọn gboogi ni ẹka imọ ẹrọ lo se isẹ naa.
Amọ, Facebook ni awọn ti wa wọrọkọ fi sada, ati wi pe ọna abayọ ti de si isoro naa.
'Bí ìrẹsì tèmi Ayinde bá ń pàkùta, kò tọ́ sẹ́nu aláàrù Barrymaade'
Facebook ni ‘Israeli security firm NSO Group’, lo se isẹ ibi yii. ọna ti wọn gba ni pe, wọn yoo pe ẹrọ ilewọ rẹ lori Whatsapp, boo gbe e, boo  gbe e, ‘spy software’ yoo wo ori ẹrọ ilewọ rẹ, eleyii ti yoo fun wọn ni anfaani lati wo gbogbo ohun to ba wa lori ẹrọ ilewọ rẹ.
Ti wọn si parọwa si eniyan to le ni biliọnu kan to n lo ‘Whatsapp’ lati lọ tẹ ‘Update’ ẹrọ ikansiẹni yii ki awọn asebi ma baa ri gbogbo ohun ti wọn n ko pamọ si ori ẹrọ ilewọ wọn.
Police arrest: 'Ó léwu láti kọ́kọ́ yẹ ọlọ́pàá wò ní Nàìjíríà'
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ọrọ eto aabo lorilẹede Naijiria
Eewọ, ma danwo! Onimọ nipa ọrọ eto aabo, Ọgbẹni Richard Amuwa ti gba awọn orilẹede Naijiria n'imọran pe o lewu lati kọkọ yẹ ọlọpaa wo ti o ba fẹ yẹ wọn wo.
Alukoro ile iṣẹ ọlọpaa Ọgbẹni Frank Mba lo kọkọ fi lede loju opo Twitter awọn ọlọpaa pe eeyan le fi irẹlẹ beere lati kọkọ yẹ agbofinro wo ko to yẹ ẹni naa wo.
Ọrọ yii wa lara awọn ohun ti Ọgbẹni Mba fi sita lori Twitter lori bi awọn eeyan ti le wuwa ti ọlọpaa ba fẹ mu wọn.
'500 level'' ni mo wà nígbà tí mo di adélé Ọba'
Helen Paul sọ idi tó fi gba orúkọ ní kékere
Amọ, Ọgbẹni Amuwa to ba BBC Yoruba sọrọ ṣalaye pe ko si ibi ti wọn ti n ṣe iru ẹ kaakiri agbaaye.
Amuwa sọ pe niwọn igba ti ọlọpaa ba ti gbaṣẹ lati yẹ eeyan wo, ẹni naa ko nilo lati kọkọ yẹ ọlọpaa wo ṣugbọn o ni lati fu ra ki wọn maa ba fi nnkan to le ṣakoba si i lapo.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
O fikun ọrọ rẹ pe ẹni to ba da iru laṣa yoo jẹ iyan rẹ niṣu nitori ifẹmi ara ẹni wewu gbaa ni.
O tun sọ pe ọrọ awọn ọlọpaa lorilẹede Naijiria pe fun ọgbọn, o ni kii ṣe agidi rara bibẹẹ kọ, eeyan le kabaamọ igbesẹ rẹ.
O gba awọn eeyan nimọran pe ki wọn ma ṣe kori soju kan naa ti ọlọpaa ba fẹ yẹ ile wọn tabi ọkọ wọn wo.
Pool drown: Ìbejì ọmọ ọdún méjì Mínísítà fún ọ̀rọ̀ omi bá odò lọ
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Aworan yi la fi ṣe akawe iya to padanu awọn ọmọ rẹ
Ina ọmọ ti jo Minisita fun ọrọ alumọni omi lorileede Uganda, Ronald Kibuule, pẹlu bi awọn ọmọ ibeji ọkunrin rẹ ṣe bodo lọ.
Awọn ọmọ naa ti wọn jẹ ọmọ ọdun meji ni a gbọ pe wọn ku si inu omi adagun ti wọn ṣe lọjọ si inu ile wọn to wa ni ilu Mbala.
Gẹgẹ bi iwe iroyin Vision Newspaper ṣe jabọ, Roman Kato ati Raiding Wasswa n ṣere ninu ọgba ile wọn ni lasiko ti iṣẹlẹ aburu yii waye.
Awọn ọmọ ọdọ meji ti wọn n tọju awọn ọmọ naa lawọn agbofinro ti mu lati wadi ọrọ lẹnu wọn.
Alukoro ọlọpaa nilu Kampala, Patrick Onyango sọ fun awọn akọroyin pe baba ati iya awọn ọmọ naa ko si nile nigba ti iṣẹlẹ yi ṣẹ.
Ìfipábánilòpọ̀: Abiamọ bú sẹ́kún nígbà tí ọkùnrin kan fi tipá bá ọmọ méjì lòpọ̀
Ìjàmbá Ibadan: Abiyamọ tó pọn ọmọ sẹ́yìn kú tọmọ-tọmọ
Wọn ni o ṣeeṣe ki o jẹ pe ọkan ninu awọn ibeji naa lo kọkọ jabọ sinu omi ti ikeji rẹ naa si ja sodo nigba ti o n gbiyanju lati doola rẹ.
Awọn eeyan ti n ba mọlẹbi Minisita naa kẹdun iku awọn ọmọ rẹ loju opo Twitter
US Embassy ní bí o bá fẹ gbà Visa, àfi kò yọjú funrararẹ
Oríṣun àwòrán, Twitter/@USEmbassyAbuja
US Embassy Abuja
Ileeṣẹ  aṣoju Amerika lorileede Naijiria ti mu iyipada ba eto irina lati Naijiria lọ si ilẹ wọn.
Bẹrẹ lati oni lọ,bo lọ amerika tẹlẹ, boo lọ ri,afi ko yọju sileeṣẹ wọn ki wọn to le fun ọ ni iwe irina oke okun
Wọn fi ikede yi soju opo wọn kan lori ayelujara ti awọn eeyan kan si ni awọn ri ikede yi loni ti awọn fẹ kowe gba iwe irina naa loni.
Oríṣun àwòrán, US Embassy in Nigeria
Ilana to wa nilẹ tẹlẹ fayegba ki awọn eeyan to ba fẹ tun iwe irina( B1/B2  fun awọn arinrinajo igbafẹ) gba fi iwe wọn ranṣẹ sinu apo iwe si ileeṣẹ to n ṣoju Amerika ni Naijiria.
Ohun ti eyi tumọ si ni pe wọn ko ni yọju lati ṣe ifọrọwanilnuwo kankan titi ti wọn yoo fi gba iwe irina tuntun mi.
Abiyamọ ò! Ìbejì ọmọ ọdún méjì Mínísítà fún ọ̀rọ̀ omi bá odò lọ
Leah Sharibu pé ọmọ ọdún 16 ní àhámọ́ Boko Haram
Àgbedọ̀! 'Ò ń f'ẹ̀mí ara rẹ wéwu tó bá fẹ́ kọ́kọ́ yẹ ọlọ́pàá wò'
Akeredolu, Ọgá NDLEA lọ kọ nípa gbíngbin igbó ní Thailand
Aṣẹ yi ko kan awọn ti wọn ba f gba iwe irina awọn aṣoju(Diplomatic Visa,A,G ati Nato).
Loṣu Kẹfa ọdun 2014 ni ọfisi Amerika ni Naijiria kede pe awọn ti bẹrẹ eto ilana fifi iwe irina ranṣẹ ninu apo iwe fawọn ti iwe irina wọn ko ba ti jọba fun igba to  ju ọdun meji lọ.
'Bí ìrẹsì tèmi Ayinde bá ń pàkùta, kò tọ́ sẹ́nu aláàrù Barrymaade'
Kano Emirate: Ṣé àwọn gómìnà ò máa tọwọ́ bọ àṣà lójú báyìi?
Oríṣun àwòrán, Patrick van Katwijk
Emir Muhammadu Sanusi jẹ gómìnà báǹkì àpapọ̀ Nàìjíríà láàrin 2009-2014kó to dí Emir ìlú Kano
Ìròyìn tó gbòde láìpẹ yìí lóri ìpinu ìjọba láti pin ààfin ọba to tóbi jùlọ ni orílẹ̀-èdè Nàjíríà ìyẹn pínpín ọba jíjẹ si ọ̀nà márùn ni ìpínlẹ̀ Kano ní o ti ń mú onírúurú àwọn awuyewuye jẹyọ láàrín ọmọ Naijíríà, ti ọ̀pọ̀ sì ń sọ pé èté ìjọba lásán ni láti sọ ọbá ìpínlẹ̀ Kano Muhammed Sanusi dí aláìlágbára bí àwọn ènìyàn ṣe ni ìgbàgbọ́ pé kìí fi ọ̀rọ̀ sábẹ ahọn sọ fún ìjọba tó ń bẹ lóde ni ìpínlẹ̀ Kano.
Bó tilẹ̀ jẹ́ pé nínu ìtàn to gbé ìjọba Emir kalẹ̀ ní Kano láti ọ̀ọ̀rùndún kẹẹ̀dógún sẹ́yìn ní ó ni ọwọ́ ìja Jìhádìì àti jàgídíjàgan àwọn onirúuru jagunjagun nínú láti ọdun 1903, ìjọba Emir ní Kano ti rídi joko dáada láti ẹyin wá. Ọ̀pọ̀ ìgbá si ni gbígbe ọba fún ẹni to kàn lẹ́yìn kìí níra lẹ̀yín ti Emir to wà lóri oye ba ti gbésẹ̀.
Ọ̀pọ̀ ló wá ń fòyà pé ṣe omi àlàfíà to wa ni Kano kò ni dàru báyìí, ìjọba ibilẹ̀ mẹ́rìnlélógóji pẹ̀lú ènìyàn to le nio mílíọ̀nù mẹ́sàn ni Emir ń dari, tí ó ti wá dínkù si ìjọba ìbílẹ̀ mẹ́wàá báyìí nígbà ti wón ti pín ipò Emir si mẹ́rin.
Bí wọn ṣe ti wá jan ofin tuntun ọhun lóntẹ ti ìjọba Abdullahi Umar Ganduje si ti fọ́wọ́ si i lójọ́ru to kọjá, ọjọ kẹjọ ọsù karun ọdún 2019, ìjọba Emir to ti wá láti igba ọdún sẹyin ní ìpínlẹ̀ Kano tún ti bẹ̀rẹ̀ ìtàn túntún báyìí.
Òfín tuntun yìí rii dáju pé Emir ìlú Kano Alhaji Muhammed Sanusi Lamido Sanusi keji ti gbogbo ènìyàn mọ bi alágbára to si níkì láàrín àwọn ọba àti ẹlẹ́sìn ní orilẹ̀-èdè Naijirià ní wọn ti ìdá kan nínú ìdá márùn àgbára rẹ̀ sílẹ̀ fún, Wọn ṣe àgbákalẹ̀ àwọn ìjọba mẹ́rin míràn ti àwọn náà yóò si ná ààfin wọn.
Kódà lásikò àwọn ìjọba òyìnbó amúnisìn, wọn ó fọ́wọ́ kan ìtàn Kano gẹ́gẹ́ bí èyí ti gómìnà wọn ń ṣe yìí ọjọgban Tijani Naniya ti ẹka ìmọ̀ Itan Fasíti Bayero ni Kano lo sàlàye èyí. O sàpèjúwe ìdásílẹ̀ ìjọba túntún yìí gẹ́gk bi dída ìtàn ẹ̀yà kan rú ti kò si yẹ kí ẹnikẹni gbàá láàyhe láti wá si ìmúṣẹ
Oríṣun àwòrán, ISSOUF SANOGO
Ado Bayero to waja jẹ ara ilé baba Emir Muhammed Sanui II
Ǹkan tó ṣẹ̀lẹ̀ ni ìpínlẹ̀ Kano ni ọ̀sẹ̀ to kọja ṣe àfihan gbangba ọ̀nà láti tún ìtàn àwọn ènìyàn ìpínlẹ̀ Kano kọ, ìtàn to ti pé ẹgbẹ̀rún kan ọdún, kódà nígbà ti àwọn ìjọba òyìnbó amúnisin wá wọn ó fọ́wọ́ kan ìtàn wa, kílo wá de ní àsìkò yìí? Báwo ni ìtàn ti ó ti pẹ́ to èyí yóò kan ṣe dojú bolẹ̀ láàrín ọjọ́ mẹ́ta péré, èyi ko bójú mu rárá, ọ̀rọ̀ náà lọ́wọ́ nínú.
Ẹwẹ́, ọ̀tọ̀ lójú ti ìjọba Kano fi wo ọ̀rọ̀ náà, nínú àtẹjáde kan ti wọn fi síta sọ pé ìdí ti àwọn fi pin ìjọba Emir Kano ni láti mú ki ọba súnmọ àwọn ara ilú ni ìgbèríko
Ọ̀jọ̀gbọ́n náà fí kun pé òun ni ìgbàgbọ́ pé ìlànà tuntun yìí to ni Emir marún-ùn kàkà ti yóò fi jẹ ẹyọkan ko ni pẹ ti yóò fi doju, nítori pe gómìnà ìpínlẹ̀ Kano nígbà kan rí, Abubakar Rimi ti gbìyànjú rẹ̀ ni ọdún 1982 tí gbogbo rẹ̀ sì dàyàbolẹ̀ láàrín ọdún kan
Ọ̀kan nínú àwọn olùgbé ìpínlẹ̀ Kano Zakari Mohammed sàlàyé pé láì bèrè nípa pe a tún ìtàn kọ, oun ni ìgbàgbọ́ pé ọnà túntun ni láti rii dáju pe àwọn ara ìlú yóò ni ànfani láti súmọ ìjọba àti àwọn aláṣẹ.
Abdullahi Sani to tun jẹ aráìlú Kano míràn sọ pe ọmọ ogoji ọdun ní oun, Emirati Kano si ni òun mọ  ti òun si fẹ́ràn
Ẹlòmiràn to tún ni ìpèníja ojú to si jẹ olùgbé Kano, Saifullah Mukhtar sọ pé oun ri ìgbẹ́sẹ̀ náà gẹ́gẹ́ bii ǹkan to dára ti yóò si ní ipa lára àwọn ara ìlú ti yóo si mu ki ọbá súnmọ ara ìlú, àti pe àdíkù yóò ba diduro fún ìgbà pípẹ́ láti gbọ abọ láti Emir Kano
Bótilẹ̀ jẹ́ pe àwọn ìwé ìròyín ìbílẹ̀ sàlàye pe ilé ẹjọ gíga ní ìpínlẹ̀ Kano ni ọjọ jímọ to kọja ti fi iwé síta pé gómìnà ò ní àṣẹ láti fi àwọn Emir túntun náà lọ́lẹ̀, síbẹ̀ ìjọba ti fi ọ̀pá àṣẹ́ le àwọn Emir tuntun náà lọ́wọ́ lọ́jọ́ ajé
Láàrin gbogbo ìṣẹ́lẹ̀ yìí, ó ṣe pàtaki láti mọ̀ pé ìpínlẹ̀ Kano nìkan kọ ni ìrú èyí  kọ́kọ́ ṣẹlẹ̀ si ní ǹkan to jọ bi ẹni pe o ní ọ̀rọ̀ òṣèlú nínú ní lọ́lọ́ yìí.
ÌPINLẸ̀ IMO
Ní ọdún 2015 Gómìnà Rochas Okorocha ti ìpínlẹ̀ Imo ti ṣe irú ǹkan to jọ báyìí pẹ̀lú Eze Owerri nígbakan ri, olóògbé Eze Emmanuel Emenyonu Njemanze, OzuruIgbo V ti Oweri nígbaà ti Oba ou fẹsun kan pé Rochas ń pin ilú Owerri àti gbogbo ìpínlẹ̀ Imo lápapọ.
Oríṣun àwòrán, FACEBOOK/ROCHAS
Gomínà Okorocha gbe igab ibo latia di sẹnatọ ni ọdun 2019 lẹ̀yìn to ti lo ọdun mẹ́jọ gẹ́gẹ́ bii gomina Imo
Nígba ti gbogbo ẹ gbónà tan láàrin àwọn mejèèji, ní ìjoba Okorocha fún Eze naa ni ìwé lọ gbélé ẹ gẹ́gẹ́ bi ìgbákeji alaga Eze Njemanze fún gbogbo Ndi-Eze to jẹ ẹka to n gbẹ́jọ
"The state government in a statement denied the allegation saying, ""It  has  no hand  in  the  suspension  of  the   four  traditional  rulers and  the  trial  of more  than fifty others  by  the  Ezes' Council."" It however added ""… the government will however not  hesitate to act  on  the  recommendations  of  the Ezes'  Council  as  long  as  it  would be  in  the  interest  of  the  State…"""
"Lẹ́yìn náà ni ìjjọba gbé atẹjade kan sita pe ọ̀rọ̀ náà ko ri bẹ́ẹ̀ "" A ò ní ọ́wọ́ nínú yíyọ àwọn ọba mẹ́rin ti gbigbe àwọn ààdọta lọ siwaju igbimọ àwọn Ezes lati jẹjọ, Ẹ̀wẹ̀ fikun pé ìjọba kò ni kọ ìmọran àwọn ǹkan to tọ láti ṣe fun igbimọ àwọn Eze níwọn ìgbà ti yóò ba ti mú ìlọsíwáju ba ìpínlẹ̀ Imo"
Oríṣun àwòrán, Alamy
Eze Njemanze lo ọdun mẹ́tàdínlọgbọ̀n titi to fi kún ni ọdun 2016 lẹ́yìn ọdun mẹ́rìnlélọ́gọ́rin
Nítori náà gẹ́gẹ́ bi ó ṣe sẹlẹ̀ ní Kano, bẹ́ẹ̀ ni ijọba Okorocha se pin awon lọbalọba si àgbégbe márun  ti onikaluku si ni ọba ti wọn.
Lóníì ipinlẹ Imo ni ìlú mẹ́tàdinlogojiléẹgbẹ̀ta pẹlu ọba wọn lọ́tọ̀ọ̀tọ ti o si jẹ gómìnà Okorochanáà lo yan wọn
IPINLẸ OYO
Ní ìhà Gúúsù-Iwọ̀-òòrun Nàìjíríà Ìpinlẹ̀ Oyo, àwọn ti koju ǹkan to farapẹ irú ǹkan bayiìí laipẹ yìí nígbà ti Gomina Ajimobi àti Oba Saliu Adetunji to jẹ Olubadan ti ìlú Ibadan
Oríṣun àwòrán, @AAAJIMOBI
Governor Ajimobi fìdírẹmi nínú ìpo ṣẹnatọ to dije fún lọdun 2019 lẹ́yìn to ti ṣe Gomina Oyo léèmèjì
Ní inú oṣù kẹ́jọ ọdun 2017 Ajimobi sún àwọn mogaji mọkanlélógun sí ipò ọba èyi to mu wọn duro ni ipò kan náà pẹ̀lú Olubadan.
Oríṣun àwòrán, FACEBOOK/SALIU ADETUNJI
Oba Adetunji ní Olubandan kọkanlelógoji , o gori oye ni ọdun 2016 lẹni ọmọ ọdun méji din ni ààdọrun
Pẹlu ìgbésẹ̀ yìí wọn gomina ti ti fowokan ilana asa to ti wa tipẹ, ni ìha keji, gomina ni ko si n kan to yii itan pada, ko si nkan to yi iṣenabye pada, bakan naa ni asa o lọ si ibikan nilu Ibadan, bíkose pe àwọn ń mú ìdàgbàsoke ati igbelarugẹ ba àwọn ọlọye to ti wà nilẹ tẹ́lẹ̀
Olubadan ti ọrọ náà kan gbe gomina Ajimobi lọ si ile ẹjọ pe ki ó dá aṣẹ náà pada, bakan náà ni Gomina Oyo tẹlẹ ri Alhaji Rasheed Ladoja to jẹ ọkan lára àwọn Mọgaji ti wọn gbe ga kọ ipò náà to si lodi si ìgbésẹ̀ gomina pe oun kò le jẹ ọba lai ni ààfin
Ninu oṣù kini ọdun 2018 ni ile ẹjọ giga ni ìpínlẹ Ọyo dájọ pe ìgbésẹ̀ gomina lòdi si òfin, bákan náà ni Gomina náà ti gbe ẹjọ lọ ile ẹjọ kòtẹmilọrun
Kano Sharia Police: Ènìyàn Kano ọgọ́rin lo ti wà látìmọ́lé nítorí wọn jẹun nínú ààwẹ̀.
Oríṣun àwòrán, MOhammed El-Shaeed
Ènìyàn tó lé ní ọgọ́rin ní ọlapàá Shaira Kano mu nítori Ounjẹ
Ọlọpàá Sharia ní ìpínlẹ̀ Kano ti mú ènìyàn tó tó ọgọ́rin nítori pe wọn ń jẹun ní àsìkò ààwẹ látigba ti oṣù Ramadan ti bẹ̀rẹ̀.
Agbẹnusọ ọlópàa Hisbah Adamu Yahaya sọ fún ilé iṣẹ́ BBC pe àwọn ti àwọn gbámu ni àwọn mùsùlùmí ti wọn o gbà ààwẹ̀ lásiko Ramadan.
RAMADAN: Onímọ̀ ẹ̀sin sọ nípa isẹ́ láádá àti làádà
Adamu ni iye àwọn ènìyàn ti àwọn ti mú ni àsìkò yiìí ti lọ silẹ̀ ju ti atẹyin wa lọ, èyí túmọ si pé ìgbìyànjú àwọn ti n ni ipa rere
Ọ̀pọ̀ àwọon ti a gbámu pe wọn ń jẹun, ìgbà àkọkọ rèé ti a o mú wọn fún ẹsun ounjẹ jijẹ, gẹ́gẹ́ bi iṣẹ́ wa ṣe ri àwọn ènìyàn yìí, ẹ̀tọ́ wa ni láti gbàwọn nimọran sùgbọ̀n ti a ba mú wọn ní èèkeji o di ẹ̀wọn tààrà ni
'Bí ìrẹsì tèmi Ayinde bá ń pàkùta, kò tọ́ sẹ́nu aláàrù Barrymaade'
Agbẹnusọ náà ní ti ẹnikẹni ba mọ ibi ti musulumi kankan ba ti n jẹun nile ounje ki wọn jẹ ki awọn gbọ ki àwọn ba le gbe ìgbésẹ̀.
"Ǹkan ti a mọ ni pe àwọn ènìyàn máa n sápamọ lọ jeun, ""sùgbọn ti ẹ ba mọ ile ounjẹ tabi ile itura ti àwọn ènìyàn ti ń jẹun, ẹ jẹ ki a mọ láti gbe igbesẹ̀ to yẹ""."
Kano Sharia Police: Ènìyàn Kano ọgọ́rin lo ti dèrò ẹ̀wọ̀n nítorí wọn jẹun nínú.
Adamu sọ pe àwọn musulumi nikan ni àwọn n mu, ati pe àwọn ẹlẹsin miiran ni ẹtọ láti jẹun bo se wu wọn. O fi kún un pe ti àwọn ba ṣeesì mú ẹni ti ó jẹ onígbagbọ ti ó ba ti le ṣàlàye ara rẹ àwọn yóò fi ẹni náa silẹ ni kiakia.
Òní ní ààwẹ Ramadan pe ọjọ mẹ́wàá sùgbọ́n ààwẹ ku ọjọ mọ́kandinlogun si ogunjọ ti ààwẹ náà yóò pari ti ọdun itunu ààwẹ yóò si waye.
Ajimobi: Orúkọ èmi, Akala, Ladoja, Adebayo Faleti àtàwọn míì
Oríṣun àwòrán, Abiola Adeyemi Ajimobi/Facebook
Gomina Ajimobi
Ijọba ipinlẹ Oyo ti fun awọn adugbo pataki kan ni ilu Ibadan atawọn ilu mii nipinlẹ Oyo lorukọ mii.
Abiola Ajimobi, Adebayo Faleti, Alao Akala, Rashidi Ladoja atawọn mii ni wọn ti yi orukọ awn adugbo ọhun padà sí.
Kọmisana eto iroyin, Toye Arulogun ni igbimọ alaṣẹ ipinlẹ ti fọwọ si igbesẹ fifun awọn adugbo naa ni orukọ tuntun.
Arulogun ni igbimọ alaṣẹ gbe igbesẹ ipinu yii ni ipade ti wọn ṣe lọjọ iṣẹgun ọjọ kẹrinla oṣu karun ọdun 2019.
O ni igbesẹ yii jẹ ọna ati mọ riri awọn eniyan to ti ko ipa ribi ribi ninu idagbasoke ipinlẹ Oyo, ninu iṣẹ wọn ati si awọn araalu.
'Bí ìrẹsì tèmi Ayinde bá ń pàkùta, kò tọ́ sẹ́nu aláàrù Barrymaade'
1. Ibi afara akọkọ lẹba ile ọ̀fíìsì ijọba kan ni Mokola ni wọn yi pada bayii si Trasmsformation Flyover
2. Ijokodo - Apete road ni wọn pe ni Ambassador Olu Sanu bayii
3. Ibudo tuntun kan ti wọn ṣẹ̀sẹ̀ ṣe to n jẹ Zonal Mediation Centre nilu Ogbomosho yoo gba orukọ Justice Atilade Ojo Mediation Centre.
4. Bakan naa Ilorin Express Junction-Ikoyi - Takie - Palace - Ogbomoso Grammar School road yoo maa jẹ Soun Oyewumi Ajagungbade.
5.  Ibadan/Oyo Express/Iseyin-Owode to lọ si Akesan-Palace ati Old Ibadan-Oyo road yoo yipada si Alaafin Lamidi Adeyemi III road.
6. Eleyele-Dugbe ANCE Road bayii ti di Oba Saliu Adetunji road.
7. Idi-Ape - Bashorun Akobo Road ti di Abiola Ajimobi way.
8. Ibarapa Polytechnic Eruwa ni wọn yoo maa pe ni Adeseun Ogundoyin Polytechnic, Eruwa.
9. Ile ẹkọ College of Agriculture, Igboora ti yipada si Lam Adesina College of Agriculture, Igboora.10. Ibudo ilera  Maternal &Peadiatric Centre, Olodo Ibadanni wọn ti pe lorukọ Abiola Ajimobi Maternal &Paediaitric Centre.
11. Elebu Road ti wa di Alao-Akala Way.
12.  Monatan - Olodo Road di Rashidi Ladoja.
13. Onireke-Agbarigo Road yoo maa jẹ Onikepo Akande Road.
14. Festac Road, Mokola ti di Adebayo Faleti Road.15. Challenge - Efunsetan Road ni yoo maa jẹ Lam Adesina road latoni lọ.
Èyí ni díẹ̀ lára ìgbà tí Buhari àti àwọn aṣòfin gbéná wojú ara wọn
Oríṣun àwòrán, Getty Images/Yakubu Dogara
Lọjọ Iṣẹgun ni Aarẹ Muhammadu Buhari sọ pe oun ko ni ibaṣepọ to dara pẹlu ile aṣofin ikẹjọ l'orilẹede Naijiria.
Buhari sọ ọrọ naa lasiko ti oun ati awọn olori ile aṣofin naa, Bukọka Saraki ati Yakubu Dogara ṣinu aawẹ pẹlu rẹ nile ijọba l'Abuja.
Aarẹ sọ pe aigbọra ẹni ye to waye lọpọ igba laarin iṣejọba oun ati awọn aṣofin naa ṣe idiwọ fun awọn anfaani to yẹ ki awọn ọmọ Naijiria  jẹ.
Oríṣun àwòrán, Bashir Ahmad
Aarẹ Buhari sọ pe oun ko ni ibaṣepọ to dara pẹlu ile aṣofin labẹ Saraki ati Dogara lasiko to ṣinu aawẹ pẹlu awọn olori ile aṣofin
Eyi lo mu ki a fẹ ṣe agbeyẹwo diẹ lara awọn igba ti Aarẹ Buhari ati awọn ọmọ ile aṣofin ti jọ gbena woju ara wọn ri
Ofẹ ẹ jẹ wi pe lati ibẹrẹ ile aṣofin kẹjọ ni aarin awọn ọmọ ile aṣofin apaọ mejeeji ati ẹka iṣakoso, paapa, aarẹ Muhammadu Buhari ko ti gún.
A le sọ pe wahala naa bẹrẹ lati ọjọ ti wọn ti yan awọn olori ile aṣofin naa. Ti ẹ ko ba gbagbe, lọjọ ti eto idibo naa waye, ọtọ ni awọn ti ẹgbẹ oṣelu All Progressives Congress to jẹ ẹgbẹ to wa ni iṣakoso, ati ẹgbẹ to ni aṣofin ju n ile fi ọwọ si.
Buhari nìkan kọ́ ni aṣíwájú táwọn èèyàn dẹ́yẹsí
'Mí ò sí lára awọ̀n aṣòfin tó bú Buhari''
Amọ ṣa, niṣe ni Bukọla Saraki ati Yakubu Dogara ati awọn ọmọ ẹgbẹ oṣelu PDP gba 'ọna ẹburu' lati ṣeto idibo naa laisi awọn ọmọ ẹgbẹ APC nile, botilẹjẹ pe ọmọ ẹgbẹ naa ni awọn naa jẹ.
Awọn alaṣẹ ẹgbẹ oṣelu APC pe ipade fun awọn aṣofin to jẹ ọmọ ẹgbẹ wọn lati jiroro lori bi wọn yooo ṣe yan awọn olori ile aṣofin, ti awọn ọmọ ẹgbẹ PDP si lo anfaani naa lati sẹto idibo.
Igba miran tun ni asiko ti Aarẹ Buhari atawọn aṣofin kọlu ara wọn ni lori aba owo iṣuna ọdun 2016.
Ohun to kọkọ ṣẹlẹ si aba owo iṣuna naa ti Aarẹ Buhari gbe lọ siwaju apapọ ile aṣofin mejeeji lọjọ kejilelogun, oṣu Kejila ọdun 2015 ni pe, ile aṣofin agba sọ pe iwe àbá naa di awati nigba ti wọn pada de lẹnu isinmi ọdun loṣu Kinni ọdun 2017.
Olori ile aṣofin naa, Bukọla Saraki fi ẹsun kan oluranlọwọ fun Buhari lori ọrọ ile aṣofin, Ita Enang pe oun lo ji iwe owo iṣuna ọhun, to si fi omiran rọpo rẹ.
Botilẹ jẹ pe ile igbimọ aṣoju-ṣofin sọ pe ẹdà iwe naa to wa lọwọ oun ko sọnu, oriṣi aba owo iṣuna meji lo wa nita.
Eyi mu ki aarẹ Buhari kọ lati buwọlu u, nitori bi awọn ileeṣẹ ijọba ṣe kọ owo iṣuna wọn pe wọn ti ṣe mago-mago rẹ.
Lẹyin gbogbo wahala naa ni alaga igbimọ to ṣagbeyẹwo owo iṣuna naa nile igbimọ aṣoju-ṣofin, Abdulmumin Jibrin tu aṣiri ọrọ sita pe lootọ ni ile igbimọ aṣoju-ṣofin ṣe mago-mago owo iṣuna naa.
Ọrọ yii da wahala sil laarin aarẹ Buhari ati awọn aṣofin, eyi to mu ki owo iṣuna naa o pẹ ki wsn to fọwọ si i.
Iroyin to jade ni pe awọn aṣofin naa yọ awọn akanṣe iṣẹ kan kuro lara awọn eyi ti ẹka alaṣẹ fẹ ẹ ṣe, ti wọn si fi awọn miran ti ileesẹ aarẹ ko ni lọkan lati ṣe.
Bakan naa lọdun 2016, ile aṣofin agba kọ aba aarẹ Buhari lati ya owo to le ni biliọnu mọkanlelọgbọn Dọla ($29.9) lati ilẹ okeere.
Ẹwẹ, awọn aṣofin naa tun kọ lati fi ọwọ si yiyan Ibrahim Magu gẹgẹ bi alaga ajọ to n gbogun ti iwa ibajẹ, EFCC, ti wọn fi ẹsun kan pe 'oniwa ibajẹ ni.'
Titi di asiko yii, ipo adele alaga ajọ EFCCC ṣi ni Ibrahim Magu wa, ile aṣofin ko fọwọ si iyansipo rẹ bi alaga, eyi ti inu awọn aṣofin ko dun si i.
Ọpọlọpọ iyannisipo ti Buhari fẹ ẹ ṣe ni awọn aṣofin naa ko buwọlu, ti awọn miran si pẹ pupọ ki wọn to o fọwọ si i.
Ẹwẹ, awọn aṣofin pariwo le Aarẹ Muhammadu Buhari lori lasiko to gbe aba owo iṣuna ọdun 2019 lọ siwaju apapọ ile aṣofin mejeeji lọjọ kọkandinlogun, oṣu Kejila ọdun 2018.
Oríṣun àwòrán, Ahmad Bashir
Diẹ lara awọn to ti ba irufẹ itiju ati ariwo idẹyẹsi bayii pade ni Donald Trump, Theresa May, Jacob Zuma ati George Bush
Bi aarẹ Buhari ṣe n ṣe alaye awọn ohun to wa ninu aba owo iṣuna naa, ati awọn aṣeyọri ti iṣakoso rẹ ti ṣe, ni awọn aṣofin kan n da ọrọ mọ ọ lẹnu, ti wọn si n ho le lori.
Ihuwasi awọn ọmọ ẹgbẹ alatako yii si fa ede aiyede laarin wọn ati awọn ọmọ ẹgbẹ oṣelu APC.
Kosi aba owo iṣuna ti Aarẹ Muhammadu Buhari gbe lọ siwaju awọn aṣofin ti ko mu rogbodiyan dani.
Lori awọn ọpọ nkan to ṣẹlẹ yii ni oun ni ireti pe oun yoo ni ajọṣepọ to dara pẹlu awọn aṣofin to n bọ.
Gov Ganduje Vs Sanusi: Ganduje kò lẹ́tọ̀ọ́ láti yan Emir mẹ́rin
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Òpin ọ̀sẹ̀ ni Gomina ìpínlẹ̀ Kano, Abdullahi Ganduje fi ìwé àsẹ fún àwọn Emir tuntun mẹ́rin láti bẹ̀rẹ̀ isẹ́.
Ile ẹjọ giga to kalẹ si ipinlẹ Kano ti ni otubantẹ ni igbesẹ Gomina Ipinlẹ Kano, Abdullahi Ganduje pẹlu bo se yan Emir mẹrin miran ni ilu Kano.
Ile ẹjọ naa pasẹ fun gomina naa lati da gbogbo nkan pada si bose wa tẹlẹ ki igbẹjọ fi le waye lori igbesẹ gomina to yan Emir tuntun.
Iwe igbẹjọ naa fẹsun kan gomina Ganduje pe ikunsinu lo mu ki o gbe igbesẹ naa lati din agbara Emir Lamido Sanusi ku gẹgẹ bi Emir ilu Kano.
Opin ọsẹ to kọja ni Gomina Ipinlẹ Kano, Abdullahi Ganduje fi iwe asẹ fun awọn Emir tuntun mẹrin lati bẹrẹ isẹ.
Ekiti Sack: Kí ló dé tí àwọn ìjọba ń yọ òṣìṣẹ́ bíi ẹní yọ jìgá ní gbogbo ìgbà?
Oríṣun àwòrán, Facebook/KayodeFayemi/Ayodele Fayose
Ijọba awọn Gomina mejeeji yi dabi ẹni pe wọn taka ẹni to le yọ oṣiṣẹ laarin wọn
Bi erin meji ba n figagbagba, dajudaju koriko ibẹ ni yoo fori ko.
Rẹgi ni ọrọ yii ni ipinlẹ Ekiti nibi ti ijọ́ba to wa lori oye kede pe awọn yoo da awọn kan ti ijọba ana yọ lẹnu iṣẹ pada ti awọn yoo si mu atunṣe ba eto igbanisiṣẹ ti ijọba ana ṣe.
Ni ṣoki ohun ti ''atunṣe'' tumọ si ni pe awọn yoo wọgile eto igbanisiṣẹ ti  ijọba Fayose  ṣe ati pe awọn to gba siṣẹ ni igba perete si ipari saa ijọba rẹ yoo padanu iṣẹ wọn.
Ninu atẹjade kan ti Kọmisana feto Iroyin, irinajo igbafẹ ati ilanilọyẹ Muyiwa Olumilua fi sita, o ni a igbaniṣisẹ to waye lẹyin idibo Gomina losu Keje ọdun 2018 ko tẹle ilana to yẹ.
''Fun idi eyi, a ti wọgile ti ko si fẹsẹ rinlẹ''
Eeyan to gbajẹ lẹnu eeyan,apaayan ni
Ọmọ ipinlẹ Ekiti kan to jẹ oṣiṣẹ ijọba to ba BBC sọrọ to ni ki a fi orukọ bo ohun lasiri ti bu ẹnu atẹ lu igbeṣẹ ijọba Kayode Fayemi yii.
O ni lootọ ni pe ohun ti ijọba Fayose naa ṣe nigba ti o de ori alefa ni pe o yọ awọn ti Fayemi gba siṣẹ ṣugbọn ki wọn jijọ ma taka ẹni to le yọ oṣiṣẹ ko dara to.
Oríṣun àwòrán, EKITI STATE GOVERNMENT
Ọjọ iwaju awa ọdọ ni wọn fi n ṣere yẹn. Kini ki ni to ti n bọ iyawo ati ọmọ pẹlu iru iṣẹ bẹ wa ṣe nigba ti wọn ba le lnu iṣẹ?
Ati ẹni gba iṣẹ ati ẹni to padanu iṣẹ, Ekiti lawọn mejeeji yoo pa owo pada wa.Iru nnkan bayi ko suwọn fara ilu.
Ẹwẹ, agbẹnusọ fun Gomina tẹlẹ ri Lere Olayinka ti fi ọrọ ti rẹ naa sita loju opo Facebook pe  Fayose iwa ika gba ni bi ijọba Fayemi ti ṣe yọ eeyan ẹgbẹrun meji ti ijọba Fayose gba siṣẹ.
Olayinka ni Fayemi ti kọ orukọ rẹ sinu iwe itan gẹgẹ bi ẹni to n mu inira ba awọn eeyan ipinlẹ naa
Ohun ti o tọ ni Fayemi ṣe,igbaniṣiṣẹ makaruru ni Fayose ṣe
Arakunrin miiran to ba ikọ BBC sọrọ ti ohun naa ni ki wọn ma darukọ tirẹ naa ni ''gbogbo nnkan lo leto amọ bi ijọba ba fi oṣelu wọ gbigbani siṣẹ ko le labọ ti yoo da''
O tẹsiwaju pe ijọba Fayose ko to ri awọn eeyan ṣeto igbanisiṣẹ ati pe awọn to fun ni iṣẹ naa ko fi taratara ni igbagbọ si iṣẹ naa.
''Bi ẹ ba kaakiri ilu, ẹ ko ni gbọ ariwo lori bi wọn ti ṣe yọ wọn niṣẹ nitori awọn naa mọ pe ojoro ni iṣẹ ti wọn fun wọn.''
Awọn mejeeji ti o ba BBC Yoruba ni o di dandan ki ijọba ma tẹle ilana to yẹ nigbakigba to ba fẹ gbani siṣẹ.
Wọn ni ko bojumu ki ara ilu ma padanu iṣẹ lasiko yii ti ati ri iṣẹ jẹ ipenija nla.
Kogi, Bayelsa Governorship Elections: INEC kéde ọjọ́ tuntun
Oríṣun àwòrán, INEC
Ajọ eleto idibo Naijiria, INEC ti kede ọjọ tuntun fun eto idibo sipo gomina ti yoo waye nipinlẹ Kogi ati Bayelsa.
Eto idibo naa to yẹ ko waye l'ọjọ keji, oṣu Kọkanla, ọdun 2019, ni yoo waye bayii lọjọ kẹrindinlogun, oṣu Kọkanla, 2019.
INEC kede ọjọ tuntun naa lori opo ayelujara Twitter rẹ.
"Kí ló dé tí ìjọba Èkìtì ń fí àwọn òṣìṣẹ́ ṣé ''helo-helo testing""?"
Toma Unu: Ọmọbìnrin tó ń fi ẹsẹ̀ rẹ̀ ya àwọran nítori pe ó ni ìpènija ọpọlọ
Ajọ INEC sọ pe sisun ti wọn sun eto idibo naa siwaju ko ṣẹyin bi ijọba ipinlẹ Bayelsa, ati awọn ẹlẹgbẹ-jẹgbẹ, to fi mọ awọn olori ẹsin, ṣe kọwe ẹbẹ si ajọ naa lati sun un siwaju nitori pe ọjọ ti wọn kọkọ da fun idibo jẹ ọjọ kan naa pẹlu eto idupẹ ọdọọdun ti wọn maa n ṣe ni ipinlẹ Bayelsa.
Operation Puff Adder: Ọwọ́ ọlọ́pàá tẹ afurasí ajínigbé 93, ọ̀pọ̀lọpọ̀ ìbọn 'AK47' àti aṣọ ṣọ́jà
Oríṣun àwòrán, Nigeria Police
Yatọ si awọn nkan ija oloro, awọn ọlọpaa tun ri awọn aṣọ ọmọ ogun tgba lọwọ awọn afurasi naa.
Ọwọ ileesẹ ọlọpaa ti tẹ awọn afurasi ajinigbe mẹtalelaadọrun ni awọn agbegbe kan ni ẹkun Ariwa Naijiria.
Awọn afurasi naa ni ọwọ awọn ọmọ ikọ pataki ti ileeṣẹ ọlọpaa gbe kalẹ lati gbogun ti ijinigbe, Operation Puff Adder tẹ ni ẹkùn Ariwa Naijiria.
Lara awọn nkan ti awọn ọlọpaa ka mọ awọn afurasi naa lọwọ ni ibọn AK47 marundinogoji, ẹẹdẹgbẹta ọta ibọn, to fi mọ aṣọ ọmọ ogun mẹwaa, ọkọ ijagun meji ati awọn nkan ija oloro mi i.
Oríṣun àwòrán, Nigeria Police
Ọga Agba ọlọpaa Naijiria, Mohammed Adamu n ṣe ayẹwo awọn nkan ija oloro ti ọwọ tẹ
Nibayii, awọn ọtẹlẹmuyẹ nileeṣẹ ọlọpaa ti bẹrẹ iwadii lati mọ orisun ti awọn afurasi naa ti n ri awọn nkan ija oloro ti wọn n lo. Ati lati mọ awọn to jẹ alatilẹyin wọn.
Nigba to n sọrọ lori iṣẹlẹ naa, Ọga Agba ileeṣẹ ọlọpaa Naijiria, Muhammed Adamu dupẹ lọwọ awọn araalu fun bi wọn ṣe fun ileeṣẹ ọlọpaa ni awọn iroyin to ran an lọwọ lẹnu iṣẹ naa.
Zainab Aliyu: Mo sọkún títí, ojé tán lóju mi ni àhámọ Saudi
Bakan naa lo sọ pe kileeṣẹ ọlọpaa ko ni dawọ duro lati ri i daju pe aabo to peye wa ni awọn opopona nlanla ni Naijiria.
Adeleke: Ajayi Shuaib tí wọ́n ní ó pe Adeleke lẹ́jọ́ ní irọ́ ni wọ́n pa mọ́ òun
Adeleke fake certificate allegation: Ajayi Shuaib tí wọ́n ní ó pe Adeleke lẹ́jọ́ ní irọ́ n
A n jẹ ekuru ọrọ ko tan lawo, n ṣe lawọn kan tun n gbọn ọwọ rẹ sinu awo lọrọ awuyewuye lori ẹsun ayederu iwe ẹri ti o wa lọrun oludije fun ipo gomina ipinlẹ Ọṣun labẹ aṣia ẹgbẹ oṣelu PDP, Sẹnetọ Ademọla Adeleke bayii.
Lẹyin ti awọn ọlọpaa ti kọkọ gbe e lọ si ile ẹjọ fun ẹsun yii ni ilu Abuja laipẹ yii, ẹjọ miran tun dide lori ẹsun yii kan naa ni ọjọ kẹtala oṣu karun ni ile ẹjọ giga apapọ to wa ni ilu Oṣogbo. Gẹgẹ bii iroyin ṣe sọ, Ọgbẹni Ajayi Shuaib to pe ara rẹ ni ẹni ọrọ n dun labẹ ẹgbẹ oṣelu PDP ni wọn pe o pe ẹjọ naa.
Sugbọn bayii, arakunrin to n jẹ Ajayi Shuaib ọhun lo tun ti wa si gbangba bayii pe wọn parọ mọ ohun ni, ohun kọ lo gbe ẹjọ tako Adeleke lori ẹsun ayederu iwe ẹri naa.
Ọgbẹni Ajayii ni eeyan kan ti orukọ rẹ n jẹ Bukọla Adewale lo fi ọna eburu lo orukọ oun lati pe ẹjọ naa lẹyin to ti wa ba oun nile pe oun ti ba oun ri iṣẹ.
"O ni Bukọla Adewọle yii lo fi ye oun pe 'oun ti ba mi ri iṣẹ ti mo nwa ati pe wọn yoo nilo iwe ọmọ ẹgbẹ oṣelu PDP mi, awọnran ilewọ Passport fun iṣẹ naa."""
N1 mílíọ́nù leè mú kí, orílẹ̀èdè Nàìjíríà, Pẹ̀lúmi Akínṣọlá ó pàdánú àmì ẹ̀yẹ Olympiad
"Ni ọjọ kẹwa oṣu karun ọdun 2019 ni Bukọla Adewale tun pe mi pe ki n pade oun nilu Oṣogbo ti mo si jẹ ẹ ni hoo. Ni ibẹ lo ti mu mi lọ ba awọn eeyan kan. Wọn ni ki n buwọ lu awọn iwe kan ti mo si buwọlu wọn, wọn si gba aworan ilewọ mi, mo si gba ile lọ."""
Ajayi Shuaib ni oun ko mọ ohunkohun mọ  lẹyin eyi .
Oríṣun àwòrán, Ademola adeleke
Arakunrin Shuaib ni oun ko pe ki ẹnikẹni o lo orukọ oun lati pe ẹjọ.
Amọṣa orukọ Ajayi Shuaib ni wọn ṣalaye pe o han ninu iwe ipẹjọ ti nọmba idanimọ rẹ jẹ FHC/OS/16/19 niwaju ile ẹjọ giga apapọ to wa nilu Oṣogbo pe o pe ẹjọ lorukọ ara rẹ atawọn ọmọ ẹgbẹ oṣelu naa kan lati fi ẹhonu han lori ẹsun ayederu iwe ẹri ti wọn fi kan Sẹnetọ Ademọla Adeleke.
"Ninu iwe ibura to ṣe ni ile ẹjọ giga apapọ naa, o ni ""iyalẹnu nla lo jẹ fun mi nitori n ko sọ fun ẹnikẹni pe mo nii lọkan lati gbe ẹnikẹni lọ si ile ẹjọ, ambọsibọsi, oludije ẹgbẹ oṣelu PDP ti mo n fi gbogbo igba ṣe atilẹyin fun."""
Arakunrin naa ni oun ko pe ki ẹnikẹni o lo orukọ oun lati pe ẹjọ.
Kidnapping: ASUU kọminú lórí ọwọ́jà ìjínigbé, pè fún àbò fáwọn olùkọ́ fásitì
Kidnapping: ASUU kọminú lórí ọwọ́jà ìjínigbé, pè fún àbò fáwọn olùkọ́ fásitì
Awọn olukọ fasiti lorilẹede Naijiria ni pẹlu bi nnkan ṣe n lọ yii o ṣeeṣe ki awọn gunle iyanṣẹlodi lati fi ẹhonu han lori bi jiji awọn olukọ fasiti gbe ṣe wa di tọrọ fọnkale lorilẹede Naijiria.
Alaga, ẹgbẹ ASUU ni fasiti Ọbafẹmi Awolọwọ, Ọmọwe Adeọla Ẹgbẹdokun lo kede eyi nibi ipade awọn olukọ fasiti naa lori bi awọn ajinigbe ṣe ji ọkan ninu awọn olukọ fasiti naa gbe ni aipẹ yii.
Ṣọ́ra, 'Loom Money Nigeria' kọ́ ni ètò sogún-dogójì tí yóò kọ́kọ́ wọ Nàìjíríà
'Iṣẹ́ ni mó ń wá kí wọ́n tó lo orúkọ mi fi gbé Sẹ́nétọ̀ Adeleke lọ sí ilé ẹjọ́'
N1 mílíọ́nù leè mú kí, orílẹ̀èdè Nàìjíríà, Pẹ̀lúmi Akínṣọlá ó pàdánú àmì ẹ̀yẹ Olympiad
Ọmọwe Ẹgbẹdokun woye pe ọwọja iṣẹlẹ ijinigbe atawọn iwa ipa miran to n waye lorilẹede Naijiria bayii fihan pe ijọba ti kuna lori eto ipese abo fawọn eeyan orilẹede Naijiria.
O ni eyi ti o bani ninu jẹ julọ naa ni bi iṣẹlẹ ijinigbe ati igbesunmọmi naa ti ṣe sun de ipinlẹ Ọṣun nibi ti ọpọ n fi ọkan si gẹgẹ bii ọkan lara awọn ipinlẹ ti alaafia sodo si julọ lorilẹede Naijiria.
O ni ninu ibẹru-bojo lawọn olukọ ati akẹkọ n gbe bayii ni ọgba fasiti naa lẹyin ti awọn ajinigbe ji ọjọgbọn naa gbe ni opopona Ibadan si ifẹ to jẹ ọkan lara awọn ọna pataki to wọ ileewe naa.
Ni ọjọ karun oṣu karun ọdun 2019 lawọn ajinigbe ji Ọjọgbọn Adeyinka Adegbẹhingbe gbe ti wọn ko si fi silẹ afi igba ti wọn gba miliọnu marun naira lọwọ awọn eeyan rẹ.
Facebook: Naijiria wà lára àwọn orílẹ̀èdè tó ní ojú òpó ayédèrú
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ile isẹ Facebook sọ ni oju opo rẹ pe awọn ti yọ oju opo ayederu 265 kuro ni ori ẹrọ ikansiraẹni rẹ.
Ile isẹ ikansiraẹni Facebook ti ni ogunlọgo oju opo to jẹ ayederu ni awọn ti wọgile nitori wọn fẹ lepa ilẹ Afirika.
Facebook ni ile isẹ kan ni orilẹede Isreal lo n pin awọn iroyin ẹlẹjẹ to nii se pẹlu eto oselu ati eto idibo ni awọn orilẹede si awọn oju opo ayederu yii lati da rogbodiyan silẹ.
Ọpọlọpọ awọn eniyan ni o bu ẹnu ate lu oju opo Facebook gẹgẹ bi oju opo ti o ni ayederu iroyin to gajulọ.
N1 mílíọ́nù leè mú kí, orílẹ̀èdè Nàìjíríà, Pẹ̀lúmi Akínṣọlá ó pàdánú àmì ẹ̀yẹ Olympiad
Ile isẹ Facebook so ni oju opo rẹ pe awọn ti yọ oju opo ayederu ti ko din ni aadọrinlenigbadinmarun un ti orisun rẹ wa lati orilẹede Isreal lọ si awọn orilẹede ni Afrika kuro ori ẹrọ ikansiraẹni rẹ.
Awọn orilẹede ti ọrọ naa kan ni Nigeria, Senegal, Togo, Angola, Niger ati Tunisia pẹlu awọn agbeegbe kọọkan lati Latin America ati South East Asia.
Ti a ko ba gbagbe, ọdun 2016 ni Facebook ti bẹrẹ iwadii lori awọn iroyin ẹlẹjẹ to jade lasiko idibo sipo aarẹ ni ilẹ Amẹrika to waye ni ọdun naa, ti o si gbe aarẹ Donald Trump.
Saheed Oṣupa: Ọlọ́pọlọ pípé kò leè ṣe òṣèlú Nàìjíríà
Gbajugbaja olorin fuji lorilẹede Naijiria, Saheed Osupa ti sọ fun gbogbo awọn ololufẹ rẹ wi pe oun ko ni iyawo ni ile, amọ oun ni ọpọlọpọ ọmọ to jẹ ti ti oun.
Saheed Osupa fi eyi lede lasiko to n ba BBC Yoruba fọrọjomitoro ọrọ lori oju opo ikansiraẹni Facebook ti BBC News Yoruba.
Osupa ni o ni idi ti oun ko fi ni iyawo si ile, amọ o parọwa si awọn ololufẹ rẹ lati fọkan balẹ.
Bakan naa ni olorin gbajugbaja naa sọ wi pe ọlọ́pọlọ pípé kò leè ṣe òṣèlú lórílẹ̀èdè Nàìjíríà, nitori iwa ẹgbin bii jẹgudujẹra ti o wọpọ ninu oselu orilẹede Naijiria.
Ohun tẹ́ẹ gbúdọ mọ nípa kókó orí ọyàn yín lásìkò fífọ́mọlọ́yàn
Saheed Osupa ni oun ko ni lọkan lati se oselu bayii nitori oun jẹ olooto eniyan ti awọn eniyan fọkan tan.
Ìdílé tí ọkọ da ọmọ síta tóríi ojú Búlùú tí wọ́n ní bá BBC sọ̀rọ̀
Rochas Okorochas ní ìlàkàkà àti gbé ìpínlẹ̀ Imo sókè ti sọ mí di ọlọ́dẹ orí
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ọpọ awuyewuye lo n wọ tọ gomina Rochas lẹyin bayii ni ipinlẹ rẹ ati laarin ẹgbẹ oṣelu rẹ.
Gomina Rochas Okorocha ti ipinlẹ Imo kii ṣe ajeji si ariyanjiyan ati ede aiyede. Bi o ti ṣe n wọ iya ija ariyanjiyan pẹlu awọn adari ẹgbẹ oṣelu rẹ, APC naa loun atawọn ti ipinlẹ rẹ pẹlu n waa ko.
Amọṣa, nibayii Gomina Rochas Okorocha ti ni aigba imọran igbakeji aarẹ orilẹede Naijiria, Yẹmi Oṣinbajo lo fa wahala ti o n n koju ni ipinlẹ naa.
Mi ò ní ìyàwó nílé, àmọ́ mo ní ọmọ tó pọ̀-Saheed Oṣupa
Ọmọ ọgbọ́n ọdún pa bàbá rẹ̀ ní ìpínlẹ̀ Ogun
Sagbokoji, ìlú tó sún mọ́ ọ̀làjú pẹ́kípẹ́kí ṣùgbọ́n tí iná ẹ̀lẹ́ńtíríkì kò sí
Ẹ gbọ naa, imọran wo ni Ọjọgbọn Yẹmi Oṣinbajo fun Gomina Okorocha ti ko gba naa?
Lasiko to fi n sọrọ nibi ayẹyẹ ṣiṣi awọn akanse iṣẹ to ṣe ni ipinlẹ naa ni gomina Okorocha ti ṣe ijẹwọ yii.
O ni ni asiko ti igbakeji aarẹ ti kọkọ wa ba oun lalejo ni ipinlẹ Imo lo ti fun oun ni imọran lati maa fọnrere awọn iṣẹ ti oun ba n ṣe. Amọ'sa, Okorocha ni esi ti oun fun Oṣinbajo nigba naa ni pe owo ti oun yoo fi ṣe eto ṣiṣi awọn akanṣe iṣẹ naa, oun yoo lo fi kọ kilasi miran sawọn ileewe.
Toma Unu: Ọmọbìnrin tó ń fi ẹsẹ̀ rẹ̀ ya àwọran nítori pe ó ni ìpènija ọpọlọ
O ni aṣe igbẹyin nii dun oloku ada lọrọ oun yoo pada ja si nitori lẹyin o rẹyin ni oun to kọgbọn ninu ọrọ ti  igbakeji aarẹ sọ.
"Inu mi dun loni pe ilu Owerri tii ṣe olu ilu ipinlẹ yii ti mo ba ni ipo abule ti de ipo olu ilu nitootọ. Mo ti gba amọran yin bayii, igbakeji aarẹ. Mo si mọ pe awọn ọmọ orilẹede Naijiria yoo lee mọ bi nnkan ṣe n lọ ni ipinlẹ Imo.
N ṣe lawọn eeyan n ṣi mi gbọ ninu gbogbo ilakaka mi  lati gbe ipinlẹ Imo goke agba. Itara mi fun ipinlẹ Imo si ti sọ mi di ẹni ti ori rẹ ko pe, nitori o wumi lati yi gbogbo nnkan pada ni kiakia."""
Ninu ọrọ rẹ igbakeji aarẹ, Yẹmi Oṣinbajo ṣe akawe Gomina Rochas gẹgẹ bii ẹni to ṣe ọpọ aṣeyọri, amọ ti ko pariwo aṣeyọri rẹ sita fun aye ri.
Zainab Aliyu: Mo sọkún títí, ojé tán lóju mi ni àhámọ Saudi
Akẹ́kọ̀bìnrin Chibok kan tó ráàyè sálọ kàwé gboyè l'Amẹrika
Oríṣun àwòrán, PIUS UTOMI EKPEI
Ọkan lara awọn akẹkọbinrin Chibok to bẹ silẹ ninu ọkọ lati jajabọ lọwọ ikọ agbasunmọmi Boko Haram ti kẹkọ jade ni ileewe kan l'Amẹrika.
O kẹkọ jade nileewe Northern Virginia Community College lẹyin ọdun maarun, oṣu kan ati ọjọ mẹta ti Boko Haram ji awọn akẹkọbinrin to le ni igba gbe ni ilu Chibok.
Palmatah Mutah, ẹni ọdun mẹtalelogun, to bẹ silẹ ninu ọkọ lasiko ti wọn n gbe awọn akẹkọbinrin naa lọ, ni akẹkọọbinrin Chibok akọkọ to kẹkọ gboye imọ ijinlẹ akọkọ nilẹ okeere.
Lasiko ti ijinigbe naa waye, ọpọ ọmọ Naijiria ni ẹnu ya pe pupọ ninu awọn akẹkọ mẹtadinlọgọta to raaye salọ ko le sọ ede Gẹẹsi botilẹjẹ wi pe ipele to kẹhin ni wọn wa nileewe girama.
Ṣugbọn, Palmatah ti fihan pe oun yatọ si awọn to kù, pẹlu bo 'se ṣaṣeyọri ninu idanwo aṣewọle sileewe giga nilẹ okeere.
Oríṣun àwòrán, PIUS UTOMI EKPEI
Oun nikan ṣi lo ti i raaye wọ ileewe giga Community College lai pe ọdun akọkọ to de Amẹrika, laarin awọn akẹkọbinrin Chibok mẹwaa ti agbẹjọro kan to jẹ ajafẹtọ ọmọniyan l'agbaye, Emaanuel Ogebe, ran lọ sileewe nilẹ okeere.
L'oṣu Kinni ọdun 2016, ni Palmatah ati awọn akẹkọọ meji mi i to bọ lọwọ  Boko Haram, bẹrẹ eto ẹkọ wọn ni ileewe Community College kan ni Washington.
Awọn akẹẹgbẹ rẹ nigba kan to le ni ọgọrun lo ṣi wa ni ihamọ Boko Haram.
Akinwumi Ambode: Awọn àgbà ọ̀jẹ̀ agbábọ̀ọ̀lù ní Afíríkà yẹ́ Gomina Ambode si
Oríṣun àwòrán, Akinwumi Ambode
Akinwumi Ambode: Awọn àgbà ọ̀jẹ̀ agbábọ̀ ọ̀lù lágbàyé yẹ́ Gomina Ambode si
Ọ̀pọ̀ àwọn àgbà sjẹ̀ oníbọọ̀lù láti orilẹ̀-èdè Nàìjíríà àti Afíríkà ló péju sí pápá ìṣere Agege lọ́nìí láti yẹ gọmina ìpínll Eko Akinwumi Ambode bí ó ṣé ń fi ìpò sílẹ̀ gẹ́gẹ́ bii gómìnà.
Awọn ènìyàn bi George Weah to jẹ ààrẹ orilẹ̀-èdè Liberia, Eto'o, Toure lo yẹ ko peju  sibi ayẹyẹ ohun.
'Ó ṣojú mi kòró, ẹ wọ bí ìgbà ayé Bàbá Fagunwa ṣe rí'
Nínú ọ̀rọ̀ ìdúpẹ̀ rẹ̀ gómìnà Akinwumi Ambode ni inú òhun dùn gidigidi bí àwọn agbábọ̀ọ̀lù náà ṣe ṣe àyẹ́sí fún òhún, o ni àwọn dájọ, ọjọ́ náà sikò àti pe òun dupẹ lọ́wọ́ àwọn to ṣe àgbátẹrùn ètò náà àti gbogbo àwọn to wá si pápá ìṣèré náà láti wa wòran
Oríṣun àwòrán, AkinwumiAmbode
Akinwumi Ambode: Awọn àgbà ọ̀jẹ̀ agbábọ̀ ọ̀lù lágbàyé yẹ́ Gomina Ambode si
Awọn olólùfẹ́ gómìnà Akinwumi Ambode náà ko gbéyin lóri àtẹjiṣẹ́ twitter láti fi ìdùnú wọn han lórí ìfẹsẹwọnsẹ náà.
Osun elections: Adeleke gba iléẹjọ́ tó ga jùlọ ní Nàìjíríà lọ pẹ̀lú agbẹjọ́rò àgbà mẹ́fà, òdú amòfin mẹ́tàdínlógún míràn
Oríṣun àwòrán, Ademola adeleke
Sẹ́nétọ̀ Ademọla Adeleke ń lépa àti yí ìdájọ́ iléẹjọ́ kòtẹ́milọ́rùn tó ní Gboyega Oyetọla ti ẹgbẹ́ òṣèlú APC ló borí ìbò gómìnà l'Ọṣun padà.
Lẹyin ti ile ẹjọ kotẹmilọrun ti fi idi Gboyega Oyetọla mulẹ gẹgẹ bii gomina ipinlẹ Ọṣun, oludije fun ẹgbẹ oṣelu PDP, Sẹnetọ Ademọla Adeleke ti gba ile ẹjọ to ga julọ lorilẹede Naijiria lọ lati lee yi idajọ naa pada.
Lati lee rii pe didun lọsan so fun oun ni igbẹjọ naa, Sẹnetọ Ademọla Adeleke ti kede amofin agba mẹfa pẹlu awọn agba ọjẹ agbẹjọro mẹtadinlogun miran gẹgẹ bii ikọ ti yoo gbe awijare ẹjọ rẹ  kalẹ niwaju awọn adajọ agba orilẹede yii ti yoo gbọọ.
Adeleke ninu atẹjade kan ni oun ko reti ohun miran ni ile ẹjọ to ga julọ lorilẹede Naijiria bi ko ṣe ikede pe oun ni gomina ti ilu dibo yan. Awọn amofin agba, SAN ti yoo lewaju ikọ rẹ ni Onyeachi Ikpeazu SAN, N.O.O Oke, SAN; Dr Paul Ananaba, SAN; Emeka Etiaba, SAN; Emeka Okpoko, SAN; and Kehinde Ogunwuminju, SAN.
Awọn agba ọjẹ agbẹjọro ti yoo tun ṣoju rẹ ni Niyi Owolade, L.N.Iheanacho, Edmund Biriomoni, Wole Jimi-Bada aatawọn mẹta miran.
Ori pepele mẹrin ni Adeleke gbe ipẹjọ kotẹmilọrun rẹ le eleyi to fi n ke si ile ẹjọ to ga julọ lorilẹede Naijiria lati da idajọ ile ẹjọ kotẹmilọrun to kede Gboyega Oyetọla gẹgẹ bii gomina ti ilu dibo yan nipinlẹ Ọṣun nu.
Ondo missing baby: Òkú ọmọ tuntun di àwátì nílé ìgbókúpamọ́sí ìjọba nílùú Akurẹ
Oríṣun àwòrán, Shutterstock
Iya ọmọ ati ọmọ rẹ to dakẹ lasiko ibi ni wọn gbe wọ ile igbokupamọsi ileewosan nla Ondo state specialist Hospital nilu Akurẹ ki oku ọmọ tuntun naa to poora
Ariwo eemọ ree, ẹ maa woo niran ni ọpọ awọn ero to de gbagede ileewosan nla Ondo state specialist Hospital nilu Akurẹ ni ọjọ abamẹta nibi ti okiki ti kan pe oku smọde jojolo kan ti wọn gbe si inu ile igbokupamọsi, ileewosan naa ti poora.
Gẹgẹ bii ohun ti BBC News Yoruba gbọ, ọjọru ni wọn gbe oku arabinrin kan ati ọmọde jojolo to ṣẹṣẹ bii ni abiku wa si ileewosan nla naa lẹyin ti wọn ku nigba ti obinrin naa n rọbi ni ileewosan awọn ọlọpaa to wa ni ilu Akurẹ kan naa.
Amọṣa ọrọ di womi-n-wo ọ nigba ti awọn ẹbi arabinrin naa de ile igbokupamọsi ileewosan nla Ondo state specialist Hospital nilu Akurẹ ni ọjọ abamẹta lati gbe oku ounati ẹjẹ ọrun ti wọn jọ jalaisi naa. Si iyalẹnu wọn ati ọpọ eeyan nibẹ lati rii pe oku arabinrin naa nikan ni wọn ba, wọn ko ri oku ọmọtuntun jojolo naa gbe.
Iroyin fi idi rẹ mulẹ pe oku arabinrin yii ati ibi ọmọ tuntun to bi ni oku naa nikan ni wọn ba, ẹnikan ko si lee sọ ohun to gbe oku ọmọ tuntun naa kuro nile igbokupamọsi naa.
Oríṣun àwòrán, @Akure's PLUG
Bakan naa ni 'awọn oṣiṣẹ ile igboku pamọsi naa ko lee si bi oku ọmọ tuntun naa ṣe poora.'
Alukoro ileeṣẹ ọlọpaa ni ipinlẹ Ondo, Fẹmi Joseph to fi idi iṣẹlẹ naa mulẹ to si ni awọn ọlọpaa yoo gbe awọn oṣiṣẹ ileewosan naa ti ọrọ ọhun kan fun ifọrọwanilẹnuwo laipẹ.
"Amọṣa ọga ọlọpaa Fẹmi Joseph ni titi di igba ti a fi n ko iroyin yii jọ, ""wọn ko tii fi papnpẹ ofin mu ẹnikẹni lori ọrọ naa."
Bakan naa, Dokita Wahab Adegbenro to jẹ kọmiṣọna feto ilera ni ipinlẹ Ondo ṣalaye pe wọn ti fa ọrọ naa le awọn ọlọpaa lọwọ.
O ni ohun ti ijọba n duro de bayii ni 'abajade iwadii awọn ọlọpaa' lori ọrọ naa.
EFCC vs Naira Marley: Nítorí ẹ̀sùn 'yahoo-yahoo' Adájọ́ ní kí Naira Marley ó máa gbatẹ́gùn láhámọ́ ọgbà ẹ̀wọ̀n
Oríṣun àwòrán, EFCC
Adajọ to n gbẹjọ olorin takasufe kan lorileede Naijiria, Naira Marley lori ẹsun ''Yahoo Yahoo'' ti  paṣẹ  pe ki wọn lọ fi si ahamọ titi di igba ti wọn yoo fi gbẹjọ rẹ.
Lowurọ ọjọ aje ni Adajọ ile ẹjọ giga ni Ikoyi, Onidajọ Nicholas Oweibo ni o di ọgbọnjọ osu kaarun ọdun 2019 ki wọn to le gbẹjọ lori ẹbẹ fun gbigba oniduro rẹ.
Gẹgẹ bi ohun ti a ri ka loju opo Facebook ajọ to n gbogun ti iwa jẹgudujẹra ni Naijiria, EFCC, ẹsun mọkanla ni wọn fi kan Azeez Adeshina, ti gbogbo eeyan mọ si Naira Marley.
Ẹsun mọkanla ni wọn fi kan an; gbogbo mẹwẹẹwa lo si fesi si pe oun ko jẹbi wọn.
Ni ọjọ kẹwa oṣu karun ni awọn oṣiṣẹ ajọ EFCC gbe Naira Marley lẹyin ọpọlọpọ ifimufinlẹ lori bi o ṣe n lẹdi apo pọ pẹlawọn ti o n lu jibiti lori ayelujara.
Lara awọn ẹsun ti wọn fi kan Naira Marley ni pe: 'Iwọ, Azeez Adeshina ti inagijẹ rẹ n jẹ Naira Marley, ati Yad Isril (ti o ti na papa bora), gbimọ pọ ni ọjọ kẹrindinlọgbọn oṣu kọkanla ọdun 2018 lati lo kaadi ti numba rẹ jẹ 5264711020433662 eyi ti kii ṣe tiyin lati fi gba nnkan lọna aitọ. Eleyii to tako abala keje ofin ti o n gbogun ti iwa ọdaran ori ayelujara tọdun 2015  (the Cybercrime Prohibition, Prevention etc Act 2015 )
Bi agbẹjọro fun olupẹjọ ṣe n rọ adajọ ile ẹjọ naa lati fun wọn ni ọjọ ti igbẹjọ gan an yoo bẹrẹ ni agbẹjọro Naira Marley n beere fun ọjọ lati gbọ ẹjọ lori ẹbẹ rẹ fun gbigba oniduro rẹ.
Eyi lo mu ki Onidajọ Oweibo o kede Ọgbọn ọjọ oṣu karun ọdun 2019 fun gbigbọ ẹjọ lori boya ki wọn gba oniduro rẹ titi ti igbẹjọ yoo fi maa waye.
Laipẹ yii ni ariwo Naira Marley gbode kan lori ikanni ayelujara gbogbo lori awọn ọrọ to n sọ lati fi kan sara sawọn to n fi ẹrọ ayelujara lu jibiti.
Bi aje ẹsun yi ba ṣi mọ Naira Marley lori, o lee fi ẹwọn ọdun meje jura tabi ki o san owo itanran to to miliọnu marun naira.
Adamawa: Ọlọ́pàá mú ẹyẹ igún sí àtìmọ́lé ní ìpínlẹ̀ Adamawa
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ileeṣẹ ọlọpaa ni awọn ṣi n ṣewaadi ẹsun ti wọn fi kan ẹyẹ igunnugun naa
Kayefi nla leyi ṣugbọn ododo ọrọ ni. Ileeṣẹ ọlọpaa ni ipinlẹ Adamawa ti mu ẹyẹ igun kan si atimọle bayii ni ipinlẹ naa.
Oniruuru iroyin lawọn eeyan n gbe lori ẹyẹ igun naa ati ohun to gbe e de atimọle. Bi awọn kan ṣe n wi pe ẹyẹ naa nii ṣe pẹlu ikọ agbebọn Boko haram ni wsn ṣe muu lawọn miran n pe arakunrin kan ni o yipada di igun naa lati maa da awọn alabagbe rẹ laamu.
'Nígbà tí mò ń wà Awolowo, Gowon, Babangida, mo fi ara mi sípo ọ̀wọ̀ tóri ...'
Amọṣa ninu ọrọ to ba BBC News Yoruba sọ, alukoro ọlọpaa fun ipinlẹ Adamawa, Othman Abubakar ṣalaye pe lootọ ni awọn eeyan kan lati ijọba ibilẹ Maiha fi ẹjọ sun awọn pe eeyan kan to wa ni ahamọ ọlọpaa ti yirapada di ẹyẹ igunugun eleyii  ti o n wa si ile ati ilu wọn lati da wọn laamu.
Ọga ọlọpaa Abubakar tun ṣalaye siwaju sii pe, ko si ootọ ninu ọrọ naa nitori pe ọkunrin ti wọn ni o n yirapada naa ṣi wa ninu atimọle, ṣugbọn awọn ti lọ mu ẹyẹ igun ti wọn n sọ naa wa si ahamọ.
O ni ati ẹyẹ igun, ati ẹni ti wọn n pe o yirapada sii ni wọn jijọ wa ni atimọle bayii.
O ni iwaadi ṣi n lọ lori ọrs naa ṣugbọn ko si otitọ ninu ọrọ ti awọn eeyan naa n sọ pe arakunrin ọhun ti poora kuro ni ahamọ ọlọpaa, o si ti yirapada di ẹyẹ igunugun ti n da araalu laamu
2019 elections; INEC gba ìwé ẹ̀rí lọ́wọ́ olùdíje APC, PDP lẹ́yìn ìdìbò àpapọ̀ 2019
Oríṣun àwòrán, Inec
INEC ni aṣẹ ile ẹjọ lo fa igbesẹ ti awọn gbe naa
Ajọ eleto idibo orilẹede Naijiria, INEC ti gba iwe ẹri idiboyansipo pada lọwọ awọn oloṣelu marundinlọgbọn kan ti wọn bori lasiko idibo apapọ to waye lọdun 2019.
Igbesẹ ati gba iwe ẹri  pada lọwọ awọn oludije naa ko ṣẹyin aṣẹ ile ẹjọ.
Alaga igbimọ eto iroyin ati ilanilọyẹ fawọn oludibo, Fẹstus Okoye lo sọ eyi di mimọ niluu Enugu, nibi apero lori bawọn oniroyin ṣe ṣiṣẹ si lasiko idibo 2019.
INEC ṣalaye pe ogun ninu awsn iwe ẹrin marundinlọgbọn ti wọn gba pada naa lo kan awọn oludije ẹgbẹ oṣelu APC, meji kan awọn oludije ẹgbẹ oṣelu PDP.
Oríṣun àwòrán, Inec
Ogbẹni Okoye ni awọn iwe ẹri ti wọn gba papda naa ni wọn gba fun awọn ọmọ ẹgbẹ oṣelu kan naa ti ile ẹjs dajọ pe awọn gan lo yẹ ko dije ṣoju ẹgbẹ oṣelu wọn.
Bakan naa lo ni mẹta lara awọn iwe ẹri ti wọn gba naa ni wọn gba lati ọwọ oludije APC ati oludije PDP fun awọn oludije ẹgbẹ oṣelu miran.
Amọṣa o ni aṣẹ ti awọn ile ẹjọ kọọkan pa lori eto idibo naa lawọn n tẹle fi gbe igbesẹ ọhun.
Lagos rain: Ilé méjì, ọ̀pọ̀ igi àti òpó iná wó lẹ́yìn òjò tó rọ̀ nílùú Eko
Oríṣun àwòrán, @lasemasocial
Ajọ LASSEMA ni ọpọ ọṣẹ ni o ba ojo naa kọwọrin, awọ̀n ko si tii le sọ iye ọṣẹ to ṣe ni pato
Ojo to rọ lọjọ aje ni ilu Eko ti da ṣugbọn ọwọja rẹ ati ipa ti o fi silẹ ṣi n ja ranyinranyin.
Yatọ si pe ọpọ wakati ni awọn olugbe ilu Eko lo ninu sunkẹrẹ-fakẹrẹ ọkọ fun ọpọ wakati nitori ojo ọhun ọpọlọpọ ọṣẹ miran ni ojo oniwakati meji naa ṣe lasiko ti o fi da ti inu rẹ kalẹ sori ilu Eko.
Àkójọpọ̀ àwòrán Òjò òwúrọ̀ Ọjọ Àjé l'Eko
Èèmọ̀ rèé o! Òkú ọmọ tuntun pòórá nílé ìgbókúpamọ́sí nílùú Akurẹ
Ọwọ iji lile ti ojo naa, eyi to bẹrẹ ni nnkan bii agogo mẹjọ abọ mu dani, to si jẹ pe, ile meji lo wo, ọpọlọpọ igi ati opo ina lo si wo lulẹ.
Oríṣun àwòrán, @lasemasocial
Ajọ to n mojuto iṣẹlẹ pajawiri ni ilu Eko, LASSEMA ṣalaye pe skan lara ile to wo naa wa ni agbegbe Abule ẹgba, ti omiran si tun wo lulẹ lagbegbe Ladipo Busstop, ni Oshodi.
Oríṣun àwòrán, @lasemasocial
Bakan naa ni ajs naa tun ṣalaye pe awọn igi to wo ọhun tun wo lu awọn ọkọ ayọkẹlẹ kan ti wsn si tun da wahala irinna silẹ.
Oríṣun àwòrán, @lasemasocial
Amọṣa ajs naa ni iṣẹ ti n lọ lati ko gbogbo awọn igi ti o wo kuro loju popo.
Gbogbo oju popo lo kun fun omi
Ọpọ ọkọ ni ojo naa tun bajẹ
Bakan naa ni ojo ọhun ko ṣai tun da ọpọ iṣẹ ijọba lara.
Fun apẹrẹ, ajọ ẹṣọ oju popo lorilẹede Naijiria, FRSC ti wọn ti kede ọjọ aje gẹgẹ bii ọjọ ti wọn yoo bẹrẹ akanṣe eto kan lori fifi iwe aṣẹ iwakọ han, 'Show your Drivers Licence' ni ipinlẹ Eko lọjọ aje ko lee bẹrẹ rẹ nitori awọn gan ko gbẹyin ninu ṣiṣeranwọ lori ki irinna ọkọ lee ja geere.
Oríṣun àwòrán, @lasemasocial
Snake bite: Ejò sàn adájọ South Africa tó lọ gbàfẹ ni Zambia pá
Oríṣun àwòrán, SPL
Aworan ejo irufẹ eleyi to pa adajọ naa
Adajọ ile ẹjọ ọrọ oṣiṣẹ kan lorileede South Africa Anton Steenkamp ti ko agbako iku lẹyin ti ejo kan san an jẹ lasiko to lọ gbafẹ lorileede Zambia.
Ẹni ọmọ ọdun mẹtadinlọgọta nii ṣe.
Mọlẹbi rẹ kan Ruby Steenkamp sọ fun ile iṣẹ iroyin News24 pe ''iku rẹ ba wa lojiji. Eeyan ni. Iyawo rẹ Catherine n bọ lọna lati wa si Zambia. Awọn mejeeji jijọ n ṣe irinajo inaju ni.''
Akọroyin kan lorileede South Africa Max du Preez gbosuba fun adajọ Steenkamp to si ṣe apejuwe rẹ gẹgẹ bi ''ọlọgbọn eeyan, alaanu, ti a le fi ọkan tan''
Temidayo Adeleke: Ilé ẹjọ́ ní kí wọ́n yẹgi fún ọmọ Cameroon tó pa ọ̀gá rẹ̀ ni Ikoyi
Odindi ọdun meji ati aabọ ni igbẹ́jọ lori bi ọmọ Cameroon kan ṣe sẹku pa ọga rẹ Dayo Adeleke, ni oṣu kejila ọdun 2016, ṣugbọn ni ọjọ Iṣẹgun, ile ẹjọ agba kan ni Ipinlẹ Eko ti dajọ iku fun Leudjoe Koyemen Joel.
Ninu igbẹjọ naa, adajọ Adedayo Akintoye ni Joel jẹbi ẹsun pe o pa Adeleke ni ile rẹ to wa ni Parkview Estate, Ikoyi, lẹyin ti arabinrin naa ran an lọwọ lati fun ni iṣẹ.
Adajọ Akintoye ni ki wọn yẹgi fun Joel.
Alẹ ni iṣẹlẹ naa ṣẹlẹ lọjọ naa lọhun. Adeleke jẹ ẹni ọdun mejilelọgbọn nigba naa. Oṣu meji ṣaaju igba naa, arabinrin naa gba Joel sile lati di alase rẹ lai mọ pe iku ni oun gba sinu ile.
Iroyin ni, Joel jẹ atipo lati orilẹede Cameroon ti ijọ kan ran lọwọ nigba to kọkọ wọ Naijiria. Adari ijọ naa ni a gbọ pe o rọ Adeleke pe ki o ran ọmọkunrin naa lọwọ lati gbaa gẹgẹ bii oluranlọwọ inu ile.
Ni ọjọ buruku naa, adajọ ni, oun to bi Joel ninu ni wipe, Adeleke sọ fun ọmọkunrin naa wipe oun ko le san owo ọsẹ meji eyi ti ko tii ṣiṣẹ rẹ fun.
Oríṣun àwòrán, William Smith/Instagram
Fidio kan ṣe afihan ibi ti afẹsunkan naa ti n jo lẹyin to pa ọga rẹ.
Fidio kan ṣe afihan ibi ti afẹsunkan naa ti n jo lẹyin to pa ọga rẹ lori atẹ Instagram rẹ ninu eyi to ti n jẹ inagijẹ Wil.iam Smith.
'Ohùn gooro ló gbé mi dé ọ̀dọ̀ ààrẹ̀ Bush, Obama, Obasanjo, Goodluck, Buhari'
Adajọ ni bi Joel ṣe pa alaanu rẹ, oo gba anfani igbeyawo, ọmọ bibi ati ẹmi gigun lọwọ Adeleke. Iroyin fi han wipe ọjọ igbeyawo arabinrin ku diẹ nigba ti alase rẹ naa ṣe iku pa.
Elomiiran ti oṣiṣẹ inu gun pa ni Parkview Estate
Yatọ si Adeleke, ni Parkview Estate yii naa, ọmọ orilẹede Togo kan to jẹ alase gun ọga rẹ Oloye Opeyemi Bademosi pa ni ile rẹ to wa ni Onikoyi Lane, Parkview Estate ni oṣu kẹwaa ọdun 2018.
Ọjọ kẹta lẹyin ti wọn gba Sunday Anani, si iṣé ni o fi ọbẹ gun ọga rẹ pa ti o si ko awọn dukia ọga rẹ salọ.
Oríṣun àwòrán, Ope bademosi/facebook.com
Àwọn ọlọpàá sọ wípé ọmọ̀ ọ̀dọ̀ Sunday Adefonou Anani ti jẹ́wọ́ pé òun ló pa ọ̀ga rẹ̀, Ọpẹ Bademọsi, tó wà nínú àwọran yìí
Ọlọ́pàá Ondo: A bá òkú ọmọ  igbákeji gómínà tẹ́lẹ̀rí nílé ọ̀rẹ́kùnrin rẹ̀
NASS media coverage: À n ṣe àgbéyẹ̀wò ìlànà túntún fún àwọn akọ̀ròyìn
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Awọn alasẹ ile igbimọ aṣofin apapọ Naijiria ti ṣe atungbeyẹwo awọn ofin ati ilana ti awọn akọroyin ti yoo ṣiṣẹ nile aṣofin kẹsan gbọdọ tẹle.
Agbẹnusọ fun ile aṣofin, Emmanuel Agada, sọ fun BBC pe awọn ti bẹrẹ si ni ṣe ayẹwo awọn ilana ti yoo mu ko ṣeeṣe fun wọn lati yanju awọn awuyewuye to n jẹyọ lori iṣẹ awọn akọroyin.
Ṣaaju ni Ọgbẹni Agada fi ikede kan sita pe lọgan ti ile aṣofin kẹjọ ba wa sopin ni aṣẹ ti awọn akọroyin n lo fi ṣiṣẹ nile aṣofin naa wa sopin, ati pe akọroyin to ba fẹ ẹ ṣiṣẹ nile aṣofin kẹsan an gbọdọ tun orukọ fi silẹ.
Ṣugbọn, awọn akọroyin n fi ẹhonu han pe ọgbọn lati di ọna mọ ominira awọn oniroyin ni igbesẹ naa.
Eyi si lo mu ki awọn alaṣẹ ile aṣofin tun awọn ilana naa yẹwo.
'Ohùn gooro ló gbé mi dé ọ̀dọ̀ ààrẹ̀ Bush, Obama, Obasanjo, Goodluck, Buhari'
Ọgbẹni Agada sọ pe lati asiko diẹ sẹyin, ọpọlọpọ onijibiti eniyan lo ti wọ ile aṣofin wa, ti wọn si n pe ara wọn ni akọroyin.
O sọ pe pupọ ninu wọn yoo kan darukọ ileeṣẹ iroyin to ba wu wọn, lati le ni anfaani lati wọ ile aṣofin lati tọrọ owo, jale tabi yẹyẹ awọn aṣofin.
'Nígbà tí mò ń wà Awolowo, Gowon, Babangida, mo fi ara mi sípo ọ̀wọ̀ tóri ...'
Oríṣun àwòrán, AFP
"'A ni ju igba akọroyin lọwọlọwọ to n ṣiṣẹ nile aṣofin, eyi si ti mu ki eero o pọju nile aṣofin."""
Bakan naa lo fi kun pe ilana tuntun naa yoo mu ki eto aabo ko fẹsẹ mulẹ daada nile aṣofin.
Tọkọ-taya Aràrá: Àwọn èèyàn máa ń wò wá, ta bá fa ọwọ́ ara wa ní títì
Ofin ogún ni awọn alaṣẹ la kalẹ fun gbogbo akọroyin lati maa tẹle, diẹ lara wọn niyii:
Simon Lalong: Gómìnà ìpínlẹ̀ Plateau ni ẹni tó bá fẹ́ ipò ní ìjọba òun gbọ̀dọ̀ yan ẹranko kan láàyò
Oríṣun àwòrán, Nigeriagalleria.com
Lalong ni iyawo oun yan kiniun meji ti oun naa si mu erin kan.
Gomina Ipinlẹ Plateau, Simon Lalong ti ni ẹnikẹni to ba fẹ ipo oṣelu labẹ ijọba oun gbọdọ lọ si ọgba ẹranko to wa ni ipinlẹ naa lati yan ẹranko kan laayo, eyi ti yoo maa tọju.
Lalong  sọ pe eyi ri bẹ nitori wipe oun ati iyawo oun fẹran ẹranko pupọ, awọn si ti yan awọn ẹranko kan laayo ninu ọgba ẹranko to wa ni ilu Jos lati maa tọju.
O n i iyawo oun yan kiniun meji, ti oun naa si mu erin kan.
Lalong sọrọ kayeefi yii nibi ayẹyẹ ọgọrun ọjọ ti adari ajọ irin ajo afẹ ti ipinlẹ naa, Salome Bidda ti lo lori aleefa.
Oríṣun àwòrán, Nigeriagalleria
Lalong ni ọkan lara awọn ẹkun to wa ni ọgba naa ku ni ọdun meji sẹyin.
Lalong ni igbesẹ naa wa lati fa awọn to n rin irinajo igbafẹ wa si ipinlẹ Plateau.
O ni ti ijọba oun ba ṣe bẹẹ, awọn ẹranko igbẹ to wa ni ọgba naa yoo ni itọju daradara.
Èré Ọṣun: Àtáója ní wọn kò jí ère Ọṣun, ó sì wà níbi tó wà
Nitori naa, o ni ọkọọkan lara awọn aṣofin mẹrinlelogun to wa ni ipinlẹ naa, ati awọn to jẹ amugbalẹgbẹ oun gbọdọ yan ẹranko ti wọn o maa tọju.
Bẹẹ lo si rọ awọn ara ipinlẹ naa lati ṣe bẹẹ gẹgẹ.
O ni ọkan lara awọn ẹkùn to wa ni ọgba naa ku ni ọdun meji sẹyin. Gomina naa ni ọjọ marun ni oun fi gbaawẹ nigba naa, ti ọfọ si ṣe oun nitori wipe ẹkùn naa n mu owo wa si ipinlẹ naa lọpọlọpọ.
Òkè Ìdànrè: Òkè tó kéré jùlọ jẹ́ ẹsẹ̀ bàtà 3000
Ọkọ̀ akérò BRT gbiná lórí afárá 3rd Mainland
Oríṣun àwòrán, @AlliAdekola @chuachebe @StockmanNigerian
Ọkọ̀ BRT
Ìròyìn tó ń tẹ̀ wa lọ́wọ́lọ́wọ́ ní wí pé ọkọ̀ akérò ńla kan tí wọ́n mọ̀ sí BRT nípinlẹ̀ Eko ń jóná lórí afárá 3rd Mainland.
Eyi ti fa sunkẹrẹ fakẹrẹ ọkọ lori afara naa.
Ẹwẹ, iroyin ti tẹ wa lọwọ pe awọn oṣiṣẹ panapana ti de bi iṣẹlẹ naa ti wọn si ti pa gbogbo ina to n jo.
Boya ẹnikẹni ba iṣẹlẹ yi rin tabi bẹẹ kọ ko tii ye.
A n se akojọpọ ẹkunrẹrẹ iroyin yajoyajo lọwọ, a o maa gbe ẹkunrẹrẹ iroyin naa sori atẹ iroyin wa laipẹ. Ẹ jọwọ, ẹ tun oju opo iroyin yi yẹwo, ki ẹ lee ri ẹkunrẹrẹ iroyin ọtun laipẹ.
Àwọn ǹkan tí yóò t'ẹyin kíkógbá iléeṣẹ́ tó n sójú Nàìjíríà nílẹ̀ láwọn orílè-èdè márùn
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Owo ni b'oun o ba si nile ki wọn ma da imọran kankan lẹyin ohun.
Ẹyin odi ni owo ko ti si ti eleyi si mu ki ijọba orileede Naijiria kede pe ohun yoo  kogba awọn ọfisi kan to n soju rẹ nilẹ okere wọle.
Sri Lanka, Czech Republic ati Serbia ni Minisita fọrọ ilẹ okere kede pe awọn yoo ti pa.
Àìríṣẹ́ṣe ló mú àwọn ọ̀dọ̀ fẹ̀mí wọn wéwu
Ẹtàn ni àwọn ọ̀rẹ́ fi ń tan èèyàn lọ si Libya pé iṣẹ́ gidi wà níbẹ̀
O fi kun un pe awọn yoo mu adinku ba iye eeyan to n ṣiṣẹ ni ile iṣẹ Naijiria to wa ni orileede Ukraine tori pe ko si owo.
Lapapọ wọn ti ile iṣẹ orileede Naijiria mẹta  pa.
Onwoye kan lori ọrọ aje ati oṣelu to fi ilu Eko ṣe ibujoko, Sam Olisha sọ fun BBC pe o ṣeni laaanu pe iru nkan bayi n ṣẹlẹ.
O ni nibi ti awọn orileede miiran ti n ṣi ileeṣẹ aṣoju kaakiri, o jẹ ohun ibanujẹ pe Naijiria n ti awọn tiẹ pa.
O ni ko jọ ohun loju nitori pe tẹlẹ naa ko si ipa ti awọn ileeṣẹ aṣoju orileede Naijiria n ṣe fawọn to wa nilẹ okere.
'A fẹ́ kí àwọn sẹ́nétọ̀ gba ẹlòmíì láàyè'
''Nibi ti a ti ni awọn ileeṣẹ wọnyii, ki ni ipa ti wọn ni? Lọpọ igba ti o ba ti kuro ni Naijiria, o ku ọ ku iwa rẹ lẹyin odi''
Ọgbẹni ni ara kudiẹ́kudiẹ to wa lara ijọba nile lo lọ farahan han lẹyin odi.
Amọ ṣa o ni kaka ki wọn ni ileeṣẹ ti ko ni ṣanfani fọmọ Naijiria, o san ki wọn kuku ti wọn pa.
Ṣaṣa ni orileede agbaye ti eeyan yoo de ti ko ti ni ba ọmọ Naijiria.
Yala wọn lọ kawe ni tabi lati lọ ṣowo, ileeṣẹ orileede wọn ni ilẹ ti wọn lọ a ma ṣe awọn iṣẹ kan ti yoo mu igbayegbadun rọrun fun wọn nibẹ.
Diẹ lara awọn nnkan ti igbesẹ yi yoo mu ba awọn ọmọ Naijiria nibẹ ni:
Lai pẹ yii ni Minisita fọrọ ilẹ okere ni ijọba yoo ti awọn ile iṣẹ aṣoju Naijiria kan pa nitori aisi owo to to.
Apapa Gridlock: Ààrẹ Buhari ti pàṣẹ kí wọ́n ó kó àwọn ọkọ̀ kúrò láàrin ọjọ́ díẹ̀
Ileeṣẹ aarẹ Naijiria ti paṣẹ pe ki wọn o ko gbogbo awọn ọkọ nlanla to wa ni papakọ oju omi Apapa kuro laarin ọsẹ meji pere.
Aṣẹ naa n fẹ ki wọn o ko gbogbo awọn ọkọ akẹru ti wọn wa gunlẹ si awọn ojupopo ati ori afara to wa ni Apapa ati awọn agbegbe to wa nitosi rẹ kuro.
Lati le mu ki eyi o ṣeeṣe , ijọba ti paṣẹ fun gbogbo awọn ileeṣẹ to ni ọkọ akẹru ati ọkọ agbepo lati ko ẹru wọn kuro ni awọn oju ọna to wọ ibudokọ oju omi naa laarin wakati mejilelaadọrin.
Aṣẹ yii waye lẹyin ipade pajawiri ti Aarẹ Muhammadu Buhari ati Igbakeji rẹ, Yẹmi Ọṣinbajo ṣe lọjọ kẹẹdọgbọn, oṣu Kẹrin, ọdun 2019.
Àwọn èèyàn àti awakọ̀ ké igbe ìrora bí àwọn ọkọ̀ ńlá ṣe dí ọ̀nà mọ́rosẹ̀ Apapa-Oshodi pa
Nibi ipade naa ni wọn ti ri ọna abayọ ti yoo yanju sunkẹrẹ-fakẹrẹ ọkọ to n waye ni awọn ibudokọ oju omi l'Eko, eyi to n se akoba fun igbeaye awọn eniyan l'agbegbe naa.
Lara awọn to wa nibi ipade naa ni asoju awọn ileeṣẹ ijọba ti ọrọ kan, lajọ-lajọ, Minisita fun ipese ina, iṣẹ ode ati ilegbigbe, Babatunde Raji Faṣhọla; Ọga Agba ileeṣẹ ọlọpaa, Ọgbẹni Mohammed Adamu; Akọwe Agba nileeṣẹ to n risi eto irinna nipinlẹ Eko, ati Oludari Agba fun igbokegbeodo ọkọ ori omi, ati ileeṣẹ to n mojuto ibudokọ oju omi ni Naijiria, Ọmọwe Sokonte Davies.
Awakọ̀ 3rd Mainland Bridge:  Ìjọba ko yanjú súnkẹrẹ fàkẹrẹ ọ̀nà Apapa
Iṣoro nla ni sunkẹrẹ-fakẹrẹ ọkọ n ko o ba awọn to n gbe ni agbegbe Apapa, ti wọn si n fi ojoojumọ fi ibanujẹ han lori awọn ọna ti ko dara.
Igbakeji Aarẹ, Ọṣinbajo ni alaga ikọ̀ amuṣẹya ti yoo ri si bi eto irinna ọkọ̀ yoo ṣe pada sipo ni oju ọna naa.
Ikọ̀ naa yoo si maa ṣiṣẹ pọ pẹlu ileeṣẹ ọlọpaa, Ẹgbẹ awọn ọkọ akẹru, ati ajọ to n mojuto igboke-gbodo ọkọ̀ nipinlẹ Eko (LASTMA) lati ri i daju pe aṣẹ naa fidimulẹ.
Bakan naa ni ijọba ti paṣẹ pe ki awọn ọmọ ogun ori omi ati awọn ọmọ ologun mi i to n dari ọkọ̀ nibẹ dawọ iṣẹ duro, ki wọn o si ko awọn ibudo ti wọn ti n da ọkọ̀ duro fun ayẹwo kuro.
Onitsha Building Collapse: Ilé alájà mẹ́ta wó lúlẹ̀, ènìyàn kan ti kú
Oríṣun àwòrán, Nnamdi Nwoye
Eniyanrin ti di eero ile iwosan
Ile alaja mẹta kan ti wọn n kọ lọwọ ti dawo lulẹ nilu Onitsha, nipinlẹ Anambra.
Ilu naa lo wo lulẹ l'ọsan oni lasiko ti awọn oṣiṣẹ abanikọle n ṣiṣẹ lọwọ.
Lagos building collapse: Àwọn òbí ń kérora lórí ikú àwọn ọmọ wọn nínú ìjàmbá ilé tó wó
A gbọ wi pe eniyan meje ni ile naa wo lu mọlẹ. Wọn ti ri awọn mẹẹrin gbe lọ sile iwosan lara wọn.
Oríṣun àwòrán, Nnamdi Nwoye
Ṣugbọn o ṣeni laanu pe onimọ-ẹrọ to n mojuto kikọ ile naa ti jẹ Ọlọrun ni pe.
Wọn ko si ti i ri awọn to ku yọ
Wo àwọn ohun tó yẹ kóo mọ̀ nípa ajọ àwọn gomina Naijiria
Oríṣun àwòrán, Twitter/Kayode Fayemi
Ẹgbẹ awọn gomina Naijiria
Gomina Ipinlẹ Ekiti, Ọmọwe Kayode Fayemi ni alaga tuntun awọn gomina lorilẹ-ede Naijiria bayii.
Lalẹ Ọjọru ni Fayemi di alaga tuntun awọn gomina lẹyin idibo- afọwọ sii to waye nibi ipade awọn gomina lolu-ilu Naijiria, Abuja.
Fayemi to jẹ minisita tẹlẹ fun ẹka iwakusa ati irin ni ibo to le ni ida aadọrin lati jawe olubori ninu ibo ọhun.
Kayode Fayemi : Awọn osisẹ ni Ekiti ko i tii gba owo osu ni ọdun yii
Gomina Ipinlẹ Kaduna, Nasir El-Rufai, ati ti Delta, Ifeanyi Okowa lo fa Fayemi kalẹ fun didije ninu idibo naa.
Gomina Abdul Aziz Yari lati ipinlẹ Zamfara lo ju awà silẹ lẹyin to ti tukọ ajọ naa lẹẹmeji laarin ọdun mẹrin
Gomina ipinlẹ Sokoto, Aminu Tambuwal ni igbakeji fun Fayemi ninu ajọ awón gomina lorilẹ-ede Naijiria.
Fayẹmi bá BBC sọ̀rọ̀ ní kété tó di gómìnà Ekiti
Gomina Fayemi yoo gbajọba lọwọ Gomina ipinlẹ Zamfara Abdul-aziz Yari Abubakar ti ijọba rẹ tan lalẹ Ọjọru.
Saaju ni gomina Dickson tipinlẹ Bayelsa ti ni awọn gomina lati ẹgbẹ oṣelu PDP ko ni dije dupo alaga naa lasiko yii.
Ni kete ti wọn yan Fayẹmi tan lo ti parọwa fawọn akẹgbẹ rẹ lati tubọ mojuto ọrọ eto aabo Naijiria to ti n gbẹbọ lọwọ koowa bayii.
Kayode Fayemi fi iwe eri moyege han Aare Buhari
Ohun to yẹ koo mọ nipa ajọ gpmina Naijiria
Ọdun 1999 ni  wọn da ajọ awọn gomina ipinlẹ mẹrindinlogoji to wa ni Naijiria silẹ.
Wọn daa silẹ pẹlu erongba pe ki awọn gomina le maa mojuto ohunkohun to n ṣẹlẹ ni Naijiria bẹrẹ lati ipinlẹ koowa wọn.
ọpọ igba ni igbesẹ ajọ awọn gomina yii maa n yatọ si ti ijọba apapọ bii aifẹnuko lori odiwọn iye owo ọya awọn oṣiṣẹ eyi to yatọ lati ipinlẹ kan si ikeji.
Lọwọlọwọ ni ẹnu wọn kò kò lori sisan owo sapo awọn alaga ijọba ibilẹ bi o ti yẹ ni eyi tijọba apapọ ṣẹṣẹ fẹ mojuto lasiko yii.
Lọdun 2017 ni wọn tun forigbari nigba ti ajọ EFCC to n risi ọrọ ṣiṣe owo ilu ni mọkumọku fẹ tojubọ bi wọn ṣe n na owo iranwọ ojiji ti Paris Club tijọba apapọ pin fun wọn.
Fayẹmi: Ọ̀pọ̀ èèkàn ìlú ló bá se ayẹyẹ ìbúra
Kinni o mọ nipa Kayode Fayemí?
Kayode Fayemi jẹ ọmọ Ilu Isan-Ekiti ni ijọba ibilẹ Oye nipinlẹ Ekiti.
Ọjọ kẹsan an, oṣu keji, ọdun 1965 ni wọn bi Ọmọwe Fayemi.
Fayẹmi ti ṣiṣẹ gẹgẹ bi olukọ kaakiri ilẹ Afirika, Yuropu, Amẹrika ati ilẹ Asia.
Fayemi jẹ Gomina ipinlẹ Ekiti lọdun 2010 labẹ asia ẹgbẹ oṣelu Action Congress of Nigeria (ACN).
Ọmọwe Fayẹmi tun ti ṣiṣẹ gẹgẹ bi oniroyin, oniṣẹ iwadi ati olugbani-nomọran lori ọrọ idagbasoke tẹlẹ ri.
Fayemi gẹgẹ akọkọ ni ilẹ iwe giga fasiti Ilu Eko(UNILAG), bẹẹ lo gba oye keji ni fasiti Ile Ife.
Contortionist: Mo lè gbé ìfun mi pamọ́ ki n tún se èémí!
Fayemi gba oye Ọmọwe ni Fasiti Kings College niluu London.
O ṣe igbeyawo pẹlu Olabisi Fayemi, wọn si bi ọmọ.
Ekiti Election: Kọmisana feto idibo ni ibo kika si n lọ lọwọ
Ọwọ́ tẹ ọkunrìn tó n fi kẹ́míkà ṣe ìtọ́jú àìsàn jẹjẹrẹ àti ibà.
Oríṣun àwòrán, AFP
Oríṣiríṣi nkan bí ìwé ìrìnnà sílẹ̀ òkèèrè ni àwọn ọmọ orílẹ̀èdè Uganda ma n gba àdúrà fún
Ọwọ ileeṣẹ ọlọpaa ti tẹ ọkunrin ọmọ orilẹ-ede Britain kan, to n pin kẹmika to n yọ idọti 'bleach' fun awọn eniyan gẹgẹ bi omi iyanu.
Ọwọ ọlọpaa orilẹ-ede Uganda tẹ Sam Little, ati ọmọ orilẹ-ede Uganda meji: Sauel Albert, ati Samula Tadeop ni Ọjọbọ niluu Fort Portal lorilẹ-ede naa.
Wọn fi ẹsun kan awọn ọkunrin mẹtẹẹta ọhun pe wọn fun awọn ọmọ orilẹ-ede Uganda kan ni kẹmika ti wọn ṣe latara 'Chlorine Dioxide'.
Kẹmika yii jẹ eyi ti awọn ileeṣẹ fi n yọ idọti ninu eyi to hande pe wọn pe e fun wọn ni Omi iṣẹ iyanu, ti wọn si ni o n wo aisan bi i jẹjẹrẹ ati ibà san lara.
Woli Kasali: Angẹli mi ni orékelẹ́wà Dọlapo Awoṣika
Ọgbẹni Little ti sọ ọ ri pe oun n ran awọn ọmọ Uganda lọwọ nipa pipese iwosan olowo pọọku fun wọn.
Sugbọn, ko ti i sọ ohunkohun lati igba ti awọn ọlọpaa ti mu u.
Nínú sọ́ọ̀sì, wọ́n ń sáré lọ síwájú fún ìwòsàn sùgbọ́n lẹ́yìnkùlé,...
Agbẹnusọ ileeṣẹ ọlọpaa sọ pe wọn ba igbó ati omi iyanu naa nile rẹ.
Abdulfatah Ahmed: Àwọn Kwara fẹ́ dán ilé ọkọ kejì wo ni lásìkò yí
Wọn ti fi ofin de omi iyanu naa ni ọpọlọpọ orilẹ-ede, wọn si ni o n fa eebi, ati aisan inu ẹjẹ.
Ileeṣẹ ọlọpaa ti kesi awọn to ti gba omi iyanu naa lati yọju sita fun ẹrí.
"Osinbajo yẹ́ Woli Arole sí níbi ìṣíde ""The Call"""
Facebook yóò bẹ̀rẹ̀ ìnáwó orí ayélujára 'GlobalCoin' lọ́dún 2020
Oríṣun àwòrán, AFP
Ileeṣẹ ayelujara nla naa yóò bẹ̀rẹ̀ ìnáwó orí ayélujára to jẹ ti ara rẹ
Facebook ti  n gbero lati gbe eto iṣuna ori ayelujara, Crypto-currency jade ni ọdun to n bọ.
Eto naa wa lati mu eto sisan owo lori ikanni igbalode ṣeeṣe lawọn orilẹ-ede mejila kan nigba ti a o ba fi ri oṣu mẹta akọkọ lọdun 2020.
Ileeṣẹ ayelujara naa fẹ bẹrẹ si nii gbe owo ori ayelujara tirẹ, eyi to pe orukọ rẹ ni Global Coin yẹwo ni opin ọdun yii.
Facebook ti n ba gomina banki ilẹ Gẹẹsi, Mark Carney fikunlukun lori rẹ.
Wo ọna ti o le gba lati fi daabo bo ara rẹ lori Facebook.
Oludasilẹ Facebook, Mark Zuckerberg ṣe ipade pẹlu Ọgbẹni Carney loṣu to kọja lati jiroro lori awọn anfani to wa ninu eto naa ati awọn wahala to lee ti inu rẹ jẹyọ.
Abdulfatah Ahmed: Àwọn Kwara fẹ́ dán ilé ọkọ kejì wo ni lásìkò yí
Facebook tun ti gba imọran lori awọn ohun to nii ṣe pẹlu ofin ati ilana eto iṣuna ori ayelujara naa lọdọ awọn adari eto iṣuna ilẹ Amẹrika.
Bakan naa lo tun n ba awọn ileeṣẹ agboworin ori ayelujara kan bii Wester Union sọrọ nitori awọn ọna olowo pọọku ati ayarabi aṣa ti o n wa fun awọn eeyan ti ko ni apo ifowopamọsi lati fi owo ranṣẹ tabi gba owo.
Facebook fẹ da owo ori ẹrọ kọmputa silẹ eyi ti ko ni ga ju ara lọ ti yoo tun pese abo to peye fun awọn ina isanwo lori ayelujara lai naani boya ẹni bẹẹ ni aṣuwọn ifowopamọsi ni banki tabi ko ni.
Eto ọhun ti wọn da pe ni Project Libra eleyi ti facebook n gbero rẹ yii yoo wa bọ si gbangba ni oṣu kejila ọdun.
Lábẹ́ odò! Ìgbéyawó yìí lárinrin
Szu Ping Chan
Adamawa: Ọlọ́pàá mú ẹyẹ igún sí àtìmọ́lé ní ìpínlẹ̀ Adamawa
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ileeṣẹ ọlọpaa ni awọn ṣi n ṣewaadi ẹsun ti wọn fi kan ẹyẹ igunnugun naa
Ile iṣẹ ọlọpaa ni #30, 000 ($86, £67) ni awọn fi bọ igun naa ati olowo rẹ laarin ọjọ mẹfa to fi wà ni atimọle.
Agbegbe Maiha nipinlẹ Adamawa ni wọn ti mu ẹyẹ igun naa gẹgẹ bii afurasi pé o n ṣalamí fawọn alakatakiti ẹsin Islam, Boko Haram.
Oga agba ọlọpaa Othman Abubakar, to tun jẹ alukoro ajọ ọlọpaa nipinlẹ Adamawa ni owo ti awọn fi n bọ igun yii ko ba pọ sii ka ni awọn ṣi fi si atimọle.
Oga ọlọpaa ni iṣẹ iwadii naa ṣi n lọ lọwọ nitori awọn olugbe agbegbe Mahia n fura si obinrin to ni ẹyẹ igun naa.
Baba agba kan nilu naa ni igba ikẹyin ti ẹnikan mu ẹyẹ abami igun yii wa si agbegbe wọn ni Boko Haram.
FFK: Buhari ló ń fún àwọn Fulani láàyè láti máa pa ènìyàn'
Awọn ẹgbẹ ti wọn n ja fun itọju nkan ayika ati nkan adayeba ni Naijiria ti n sọ fun awọn agbofinro lati tu igun yii silẹ.
Báwo ni ọwọ́n ṣe mú igún náà satimọlẹ ṣaaju iwadii?
Kayefi nla leyi ṣugbọn ododo ọrọ ni. Ileeṣẹ ọlọpaa ni ipinlẹ Adamawa ti mu ẹyẹ igun kan si atimọle bayii ni ipinlẹ naa.
Oniruuru iroyin lawọn eeyan n gbe lori ẹyẹ igun naa ati ohun to gbe e de atimọle. Bi awọn kan ṣe n wi pe ẹyẹ naa nii ṣe pẹlu ikọ agbebọn Boko haram ni wsn ṣe muu lawọn miran n pe arakunrin kan ni o yipada di igun naa lati maa da awọn alabagbe rẹ laamu.
'Nígbà tí mò ń wà Awolowo, Gowon, Babangida, mo fi ara mi sípo ọ̀wọ̀ tóri ...'
Amọ ṣa ninu ọrọ to ba BBC News Yoruba sọ, alukoro ọlọpaa fun ipinlẹ Adamawa, Othman Abubakar ṣalaye pe lootọ ni awọn eeyan kan lati ijọba ibilẹ Maiha fi ẹjọ sun awọn pe eeyan kan to wa ni ahamọ ọlọpaa ti yirapada di ẹyẹ igunugun eleyii  ti o n wa si ile ati ilu wọn lati da wọn laamu.
Ọga ọlọpaa Abubakar tun ṣalaye siwaju sii pe, ko si ootọ ninu ọrọ naa nitori pe ọkunrin ti wọn ni o n yirapada naa ṣi wa ninu atimọle, ṣugbọn awọn ti lọ mu ẹyẹ igun ti wọn n sọ naa wa si ahamọ.
O ni ati ẹyẹ igun, ati ẹni ti wọn n pe o yirapada sii ni wọn jijọ wa ni atimọle bayii.
O ni iwaadi ṣi n lọ lori ọrs naa ṣugbọn ko si otitọ ninu ọrọ ti awọn eeyan naa n sọ pe arakunrin ọhun ti poora kuro ni ahamọ ọlọpaa, o si ti yirapada di ẹyẹ igunugun ti n da araalu laamu
May 29 Inauguration: Minista mẹ́fà tí kò tẹ́ àwọ ènìyàn lọ́rùn
ẹ ko gbiyanju tó ni saa kinni Buhari loju wa
Aarẹ Buhari to n tukọ Naijiria lati 2015 ti ṣeto idagbere fawọn minista ti wọn jọ ṣiṣẹ.
Aarẹ ki gbogbo wọn ku iṣẹ takuntakun ṣugbọn ọpọ ninu awọn ọmọ Naijiria lo n binu si diẹ ninu awọn minista naa pé wọn ko ṣe daadaa tó.
Buhari ni ki gbogbo minista ju awa iṣẹ wọn silẹ fawọn akọwe agba ile iṣẹ ijoba apapọ ti ẹni kọọkan wọn n ṣe minista le lori.
Jiti Ogunye: Ìjọba àkóbá lológun gbé kalẹ̀ ni 1999
Ọpọ ojo lo ti rọ tilẹ ti fi mu ni iṣẹ awọn minista ti wọn ba Buhari ṣe ijọba lọdun mẹrin to n kogba wọle yii.
Awọn ara ilu ti wi nkan oriṣii si awọn minsta yii lataari ihuwasi, ọrọ ẹnu wọn ati ohun to ṣẹlẹ ni  ile iṣẹ ijọba apapọ ti wọn n mojuto.
Ibura Buhari ni Saa iṣejọba keji
Lọjọ kọkandinlọgbọn, oṣu karun un, ọdun 2019 ni wọn yoo ṣe ibura fun Aarẹ Buahri to tun jawe olubori lẹẹkeji gẹgẹ bii aarẹ Naijiria.
Wọn ti ni ayẹyẹ ibura fun ni naa ko pọ pupọ lọtẹ yii ni Abuja.
Diẹ lara awọn minista ti awọn eniyan sọrọ julọ laida nipa wọn ni:
Solomon Dalung- Minista fun ọrọ ọ̀dọ́ ati ere idaraya
Oríṣun àwòrán, @solomon
Oun lo kọkọ koju iṣoro ibere ta ni adari ajọ NFF ni Naijiria?
Minista yii lo kọkọ fi ọrọ ajọ to n mojuto eto ere bọọlu alafẹsẹgba ni Naijiria, NFF ṣide iṣẹ nigba to wọle.
Oun lo kọkọ koju iṣoro ibeere ta ni adari ajọ NFF ni Naijiria? Amaju Pinnick di ààrẹ àjọ NFF tuntun
Victor Moses, Oshoala gba ami ẹyẹ Wahala rẹ pẹlu Amaju Pinnick ati Chris Giwa lo jẹ ki ajọ elere bọọlu lagbaye, FIFA kuku fofin de Naijiria ati ere bọọlu alafẹsẹgba ki Yẹmi Oṣinbajo igbakeji aarẹ to da sii.NFF sadehun pẹlu Dennerby fun Falcons
Labẹ iṣakoso rẹ ni awọn ẹka ere idaraya ti n ni adari meji bii eyi to n ṣẹlẹ lọwọ lẹka ere bọọlu alajusawọngba.
Onigbinde àti Owolabi: Ààrẹ NFF tuntun gbọdọ̀ sàwárí ọ̀jẹ̀ wẹ́wẹ́ agbábọ́ọ́lù
Iṣorọ mii tawọn eniyan ko tun fi gba ti ẹ ni bii ti eyi ti ajọ elere sisa Naijiria ko tii rẹnu ṣalaye ohun ti wọn fi ẹgbẹrun lọna aadoje owo dọla ilẹ okeere ti ajọ elere sisa agabye ṣeṣi san sinu asunwọn banki wọn.
Adebayo Shittu: Minista fun ibanisọrọ
Oriṣiiriṣii ẹsun ni wọn fi kan minista yii ni kete to ti gbe igba ibo lati dije dupo gomina ipinlẹ Oyo ninu saa yii.
Oríṣun àwòrán, @Shittu
O wu mi lati tukọ ipinlẹ Oyo
Ọpọ gba pe oun naa ko ni iwe ẹri agunbanirọ lati fi sọ pe oun sin ilẹ baba oun bii ti Kemi AdeosunAPC yọ orúkọ Shittu kúrò láti kópa nínú ìdìbò abẹ́lé.
Awọn mii ni awon ko ri laarinja iṣẹ to ṣe yanju Nàìjíríà fẹ́ yá $100m lọ́wọ́ India fún ìtàkùn àgbáyéni ẹka ile iṣẹ ijọba apapo to moujto naa.
Oun naa sọrọ oṣelu aini ibadọgba anfani ninu ẹgbe nigab ti ko pada ri tikẹẹti lati dije dupo gomina Oyo'Ó ku Shittu, ó ku Ọlọ́run lórí ohun tó fẹ́ fi san ẹgbẹ́ APC l'ẹ́san'
Chris Ngige: Minista fun igbode iṣẹ
Oríṣun àwòrán, @NGF
Ọkan lara awọn ọna naa ni eyi to sọ laipẹ lori awọn oniṣegun oyinbo ti wọn sa kuro ni Naijiria lasiko yii.
Ọpọ igba lorukọ rẹ ti jade pẹlu eebu to pọ lori ẹrọ ayelujara lori ọrọ ẹnu rẹ.
Ọkan lara awọn ọna naa ni eyi to sọ laipẹ lori awọn oniṣegun oyinbo ti wọn sa kuro ni Naijiria lasiko yii.
Ọpọlọpọ iyanṣẹlodi Ìpàdé ìjọba ati ASUU forí sánpọ́n, ifẹhonuhan Àwòrán ìwọ́de NLC, TUC, ULC lónìí ati NLC, TUC: Àwa ò gba owó lọ́wọ́ Fayose ooo ileri titi ilẹkun ọrọ aje Kíni ìdí tí NLC fi kọ N27,000 owó osù òsìsẹ́? ni o ṣẹlẹ ninu ọdun mẹrin ti Ngige fi ṣe minista yii.‘ASUU da ìyanṣẹ́lódì dúró'
Grandma Maruwa: Ó yẹ kí obìnrin sisẹ́ láì wojú ọkọ kó tó jẹun
Sibẹ laisko re ni ijọba apapọ gba lati maa san N30,000 gẹgẹ bii owo ọya oṣiṣẹ to kere julọ ni NaijiriaBuhari ti buwọ́lu #30,000 owó oṣù òsìsẹ́ .
Minista fun eto ẹ̀kọ́: Adamu Adamu
Awọn eeyan ko fi bẹẹ sọrọ nipa minista yii pupọ ni eyi ti awọn kan gba pe ko fi daa tó.
Awon mii ni ko ṣiṣẹ to lori eto ẹkọ ni ko jẹ kawọn eniyan mọ Ọjọgbọn yii bii minista to lagbara.
Oríṣun àwòrán, @NGF
Adamu ṣalaye pataki radio Fulfulde pe kawọn darandaran le ni ẹkọ to peye ni
Nibi ipade asegbẹyin awọn minista yii ni Adamu ti ni inu oun ko dun to nitori oun ko ri awọn ọmọ ko pe lọ sile iwe de idaji.
Oun ati Ngige, to jẹ minista igbode iṣẹ ni wọn jọ winá iyanṣẹlodi awọn olukọ Fasiti, ASUU fun odindin oṣu mẹta.
Isaac Adewọle: Minsita fun eto ilera
Oríṣun àwòrán, @Isaac Adewole
Iyanṣẹlodi ti pọ ju lasiko iṣejọba yii
Koko ọrọ ti awon eniyan fi binu si minista fun eto ilera julọ lori ayelujara ni nigba ti o ni: kii ṣe gbogbo oniṣegun oyinbo lo maa fi ṣe iṣẹ ṣe, awọn mii a lọ ṣiṣẹ agbẹ.
Àwọn aláìsàn rawọ́ ẹ̀bẹ̀ sí ẹgbẹ́ JOHESU
Ọpọlopo lo bu ẹnu ẹ̀tẹ́ lu ọrọ ọjọgbọn to ti tukọ fasiti Ibadan nibi ti sanmọnti gbe dunlẹ fun ọpọlọpọ ọdun ko tẹ jẹ minista yii.Awọn ipinlẹ kan fara kaasa arun iba
Ogundiya: Àṣìṣe Dókítà ló sọ mi di aláàbọ̀ ara lórí kẹ̀kẹ́
Iyanṣẹlodi Òsìsẹ́ ìlera fẹ́ náa tán bíi owó pẹ̀lú ìjọba ni oriṣii ẹka eto ilera Naijira pọ pupọ lasiko iṣejọba rẹ gẹgẹ bii  minista ni NaijiriaJohesu sẹ́wé lé ìyanṣẹ́lódì.
Opọ awọn akọṣẹmọṣẹ oniṣegun lo sa kuro ni Naijiria lọ si UK, Canada àti Saudi.Dokita ọmọ Naijiria jàjàbọ́ nílẹ̀ Ọba
Abdulrafiu Adeniji sọrọ lori isorogun Dokita ati osìsẹ́  ilera
Koko miran ti awọn eeyan tun fi n tasi minista yii lori ayelujara ni pé Aarẹ Buhari lọ si London fun ọpọlọpọ ọsẹ fun itọju ni eyi ti o fihan pe eto ilera Naijiria ko ti i goke agab tó.
Wọn ni ṣebi Buhari n polongo pe ko si irinajo lọ silẹ okeere fun itọju mọ ti oun ba wọle nitori pe wọn a tun eto ilera Naijiria ṣe
Kemi Adeosun: Minista fun eto iṣuna
Oríṣun àwòrán, @Kemi
O wu mi lati ṣiṣẹ fun Naijiria
A ko le ṣai menuba ọrọ Kemi Adeosun to jẹ minista fun eto iṣuna Naijiria tẹlẹ.'A sinmi ìwádìí lóri Kemi Adeosun'
Ọrọ aini ojulowo iwe ẹri NYSC ní Adeosun kòwé ransẹ́ láti gbààyè pe o sin ilẹ̀ baba rẹ nipa agunbanirọ lo jẹ ki o kọwe fipo silẹ.Itse Sagay wọ gàu lórí ọ̀rọ̀ Adeosun
Bi o ṣe kọwe fipo silẹ ni ọpọ gboriyin fun un pe o ṣe ohun to yẹ lori ayelujara nigba ti awọn miran tabuku ijọba Buhari ti wọn ni wọn n gbogun tiwa ibajẹ jẹgudu jẹra ni Naijiria.
Kemi Adeosun ni iroyin ni ko si ni Naijiria mọ.
'Obìnrin tí kó ba fẹ́ òṣìṣẹ́ Mọ́ṣúárì, ìpinu rẹ̀ mẹ́hẹ'
South Africa: Èrò àwọn èèyàn ṣọ̀tọ̀ọ̀tọ̀ lórí fidio ti Aisha Buhari fi síta
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Aisha Buhari si aarẹ South Africa
Ọrọ̀ n bọ́rọ̀ bọ... ni owe awọn agba n wi ati pe lowe lowe ni a n lu ìlù ogidigbo.
Ọkan lara awọn aṣofin ni orilẹ-ede South Africa, Julius Malema lo sọju abẹ niko ninu imọran to fun Aarẹ Ramaphosa ti wọn ṣẹṣẹ tun yan ni South Africa.
Malema gba Ramaphosa niyanju pe ko kọ̀ lati gbọran sawọn alagabagebe, arijẹ-nidi-madaru lẹnu.
Ìdílé tó gba olùkọ́ èdè Yorùbá fún àwọn ọmọ nílẹ̀ Gẹ̀ẹ́sì
O ni wọn kan ma maa tan aarẹ ni ṣugbọn wọn ko ni maa so ootọ ọrọ to nilo lati maa gbọ loorekoore fun idagbasoke ilẹ̀ South Africa.
Fọnran fidio ti Malema fi gbamọran yii ni Ayisha Buhari, iyawo aarẹ Mohammadu Buhari ti a ṣẹṣẹ dibo yan lẹẹkeji ni Naijiria naa fi soju opo twitter rẹ.
Kini àwọn eniyan Naijiria n sọ nipa Fọnra ti Aisha fi sita naa:
Ọpọlọpọ àwọn eniyan ni wọn ti n sọ oriṣiiriṣii nipa fọnran fidio naa lori ayelujara. Awọn kan n gboriyin fun aya aarẹ pé akin obinrin to n soju abẹ niko ni.
Ariṣe ni arika, arika ni baba iregun ni ero awọn mii pe aya aarẹ ti lo iru ọgbọn arekereke yii sẹyin lati fi ri ohun to n fẹ ni, ati pe ina èṣìṣì kii jo ni lẹẹmeji.
Ikorodu Bois: Ko si ẹni ti a kò lè sín jẹ!
'Nígbà tí mò ń wà Awolowo, Gowon, Babangida, mo fi ara mi sípo ọ̀wọ̀ tóri ...'
Awọn miran gba pé ohun ti aya aarẹ fẹ jẹ ni o n fọgbọn wa pe
Bẹẹ lawọn mii ni ṣebi aṣọ to kangun si egun ni wọn n pè ni jẹ̀pẹ̀, niṣe lo yẹ ki Aisha ba ọkọ rẹ sọ ododo ọrọ ninu iyara ko le gbọran daadaa
Jiti Ogunye: Ìjọba àkóbá lológun gbé kalẹ̀ ni 1999
Loju àwọn ọmọ Naijiria omiran, aarẹ Buhari ti n kuna lati gbọ oo) tọ nkan to n ṣẹlẹ nitori pe awọn alatẹnujẹ kan ti rọgba yi aarẹ ka. Won gba aya aarẹ nimọran lati ba aarẹ Buhari sọ ootọ ọrọ.
Olusegun Obasanjo: Ọmú ìyá mi ti mo fi ń mùkọ ni kekere ló jẹ ki ń lókun
Ọpọlọpọ lo n gboṣuba fun Malema pé o sọ ohun to jẹ awokọṣẹ fun gbogbo olori orilẹ-ede agbaye pe:
Oríṣun àwòrán, @ayisha
Aisha, iwọ naa kọkọ lọ ba ọkọ rẹ sọrọ niyara kẹta!
Tọmaasi alaigbagbọ ni oye awọn miran lori ayelujara, wọn ko gbagbọ pe aya aarẹ funra rẹ gan an lo fi fidio naa sori ayelujara
Ohun kan ṣoṣo to hande ni pe, ọlọgbọn lo n jo ìlù agidigbo, ọmọran lo si n mọọ, asiko ti to fun awọn olori kaakiri agbaye lati dẹkun fifi awọn opurọ alatẹnujẹ yi ara wọn ka ki wọn gbe igbesẹ lati maa mọ okodoro ohun ti ara ilu to jade ninu ojo ati ninu oorun wa dibo yan awọn sipo n fẹ ni tootọ ki idagbasoke to yẹ le wa ni alaafia.
Awọn mii ni ki Buhari kẹkọ lara bi aarẹ Ramaphosa ṣe dahun si imọran Malema.
Footballers: ìkà láwọn aṣojú agbábọ̀ọ̀lù míì lágbàyé
2019 Guber Polls: Ẹ wo àwọn baba ìsàlẹ̀ òṣèlú tí wọ́n bá ìtìjú bọ̀ nínú ìbò gómìnà
Oríṣun àwòrán, Facebook/Ibikunle Amosun
Idibo gomina ipinlẹ Ogun
Baba isalẹ ni itumọ oriṣirisi si awọn eeyan lorilẹede Naijiria. Ninu oṣelu Naijiria, baba isalẹ jẹ ẹnikan to lagbara lati rii wi pe oun funra rẹ wọle ibo tabi ẹni to ba ṣatilẹyin fun wọ le.
Ninu idibo gbogbogbo ọdun 2019 papaa julọ idibo gomina, ọpọ ninu awọn baba isalẹ oloṣelu lo gbere itiju.
Eyi ni diẹ lara awọn baba isalẹ oloṣelu ti nnkan ko ṣẹnu 're fun ninu idibo gomina to waye ni Naijiria lọdun 2019.
Jiti Ogunye: Ìjọba àkóbá lológun gbé kalẹ̀ ni 1999
Abiola Ajimobi
Bi o tilẹ jẹ wi pe Gomina Abiola Ajimobi ni gomina akọkọ ti yoo wọle lẹẹmeji gẹgẹ bi gomina ipinlẹ Oyo, o kuna lati wọ le ibo sile igbimọ aṣofin agba l'Abuja.
Oríṣun àwòrán, Facebook/Abiola Ajimobi
Idibo Ipinlẹ Oyo
Ọgbẹni Kola Balogun ti ẹgbẹ PDP lo wọ le dipo Ajimobi fun Ẹkun Gusu Ipinlẹ Oyo.
Ko wa tan sibẹ o, Adebayo Adelabu to jẹ oludije si ipo gomina fẹgbẹ osẹlu APC naa tun fidi rẹmi lẹyin ti Ṣeyin Makinde ti ẹgbẹ PDP wọ le ibo ọhun.
Bukola Saraki
Sẹnẹtọ Bukola Saraki to jẹ Adari ile igbimo aṣofin agba l'Abuja kọkọ fidi rẹmi ninu ibo lati pada sile aṣofin agba mi olu olu orilẹede Naijiria.
Oríṣun àwòrán, Facebook/Bukola Saraki
Ibo gomina ipinlẹ Kwara
Bi iya nla ba gbe ni san lẹ, kekere a gori ẹni, Abdulrazaq Atunwa, oludije fẹgbẹ PDP ti Saraki tun ṣatilẹyin fun ninu ibo gomina ipinlẹ Kwara tun fidi rẹmi.
Abdulrahman Abdulrasaq ti ẹgbẹ APC la Atunwa mọ lẹ ni gbogbo ijọba ibilẹ mẹrindinlogun to wa nipinlẹ naa.
Ariwo ''O TO GẸ'' ni ọpọ eeyan n pa nipinlẹ Kwara eyi to tumọ si pe awọn ko ni dibo fun Saraki ati ẹnikẹni to ba fa silẹ mọ.
Olusegun Obasanjo: Ọmú ìyá mi ti mo fi ń mùkọ ni kekere ló jẹ ki ń lókun
Ibikunle Amosun
Lootọ ni Gomina Ipinlẹ Ogun Ibikunle Amosun jawe olubori ninu ibo ile igbimọ aṣofin agba l'Abuja, ṣugbọn o ni ijakulẹ ninu ibo gomina lẹyin ti Adekunle Akinlade oludije ẹgbẹ APM to ṣatilẹyin fun fidi rẹmi.
Ogun: Amosun, ẹgbẹ́ òṣìṣẹ́ NLC fẹ́ forígbárí l'Ógùn
‘Gómìnà Amosun kò fẹ́ràn àwọn ará Ìjẹ̀bú’
Oríṣun àwòrán, Facebook/Ibikunle Amosun
Idibo gomina ipinlẹ Ogun
Loṣu kejila ọdun 2018 ni Gomina Amosun pinu pe oun ko ni gbaruku ti oludije fun ipo gomina labẹ asia ẹgbẹ oṣelu APC, Dapo Abiodun.
Eleyi lo jẹ ko ṣatilẹyin fun Akinlade, ṣugbọn pabo ni gbogbo igbiyanju rẹ ja si lẹyin ti Dapo Abiodun fẹyin Akinlade gbo lẹ.
Ikorodu Bois: Ko si ẹni ti a kò lè sín jẹ!
Rochas Okorocha
Gẹgẹ bi Gomina Ibikunle Amosun ṣe ṣatilẹyin fun oludije ẹgbẹ oṣelu miran fun ipo gomina nipinlẹ Ogun, bẹẹ naa ni Gomina Rochas Okorocha naa ṣe nipinlẹ Imo.
Gbogbo igbiyanju Okorocha lati rii pe ana rẹ, Uche Nwosu oludigbe ẹgbẹ oṣelu Action Alliance(AA) ni yoo gba ijọba lọwọ rẹ gẹgẹ bi gomina ipinlẹ Imo, pabo lo ja si.
Oríṣun àwòrán, Rochas Okorocha
Ibo gomina ipinlẹ Imo
Emeka Ihedioha oludije ẹgbẹ PDP lo jawe olubori ninu ibo gomina ipinlẹ Imo.
Kannywood: A ó fòfín dé eré ìfẹ ṣíṣe fún ọdun díẹ̀
Oríṣun àwòrán, Kannywood
A ó fòfín dé eré ìfẹ ṣíṣe ni Kannywood fún ọdun díẹ̀
Kannywood tó jẹ ẹka àwọn oní fiìmù ní ilẹ̀ Hausa lórilẹ̀-èdè Nàìjíríà tí bẹ̀rẹ̀ ètò láti fòfinde síṣe eré àgbélé wò fún títà fún ọdún díẹ̀ lánà àti taná wó àwọn ìhà ibomíràn.
Òfin tuntun yìí yóò bẹ̀rẹ̀ sí ní múlẹ̀ láti inú oṣù kẹ́fa gẹ́gẹ́ bi àlága ẹgbẹ́ àwọn óní fíìmù ní ìpínlẹ̀ Kano ti a mọ si Motion Pictures Practitioners Association of Nigeria (MOPPAN) ọgbẹni Kabiru Maikaba tó bá BBC sọ̀rọ̀ ṣe sọ.
Abdulfatah Ahmed: Àwọn Kwara fẹ́ dán ilé ọkọ kejì wo ni lásìkò yí
Bode George: òòtọ́ ni ìkìlọ̀ Obasanjọ ati Soyinka
Maikaba fí kún-un pé fún ìgbà díẹ̀ báyìí, fíìmù àgbẹ́léwò eléré ìfẹ́ ló kó ìdá ọgọ́rin nínú ìdá ọgọ̀ru fíìmù tó ń jáde ní Aréwà, ṣùgbọ́n èyí kò yẹ ko ri bẹ́ẹ̀.
Oríṣun àwòrán, Kannywood
Alága ẹgbẹ́ àwọn óní fíìmù ní ìpínlẹ̀ Kano ti a mọ si Motion Pictures Practitioners Association of Nigeria (MOPPAN) ọgbẹni Kabiru Maikaba
kílódé to jẹ pe fíìimù ìfẹ́ ni wọn a máa ṣe, ni ìgbà tó yẹ kí wọn móju tó àwọn àgbègbè tó kù. Ìhà Arewa ní àwọn ìtàn to làmìlaka  pẹ̀lú àwọn ènìyàn to tí ṣe orire, gbogbo àwọn ǹkan wọnyii ló yẹ ki a kọ ibi ara sí
Nítori náà ni aṣe sọ pé láìpẹ́ yìí ti a ba ti pari ìdìbò ẹgbẹ́, a ti pinu lati máa wo ìwé ere ti àwọn ènìyàn ba kọ, èyí to ba ti jẹ mọ èrè ìfẹ́ ni a ó kó ni gbàá láye lati di ṣíṣe titi ti à ó fi ríì dáju pe àwọn ìhà toku náà ri amoju to
Oríṣun àwòrán, KAnnywood
Onijo ni Ali Ali
Ìgbẹ́sẹ̀ yìí kìí ṣe ǹkan to dùn mo awọn kan nínú, Ali Ali tó jẹ ọ̀kan lára àwọn to máa n kọ àwọn ènìyàn ní ijo ni kannywood sọ pé àbá ti wọn ń da ọhun ko le múlẹ̀ rára àyà fi ti wọn ó ba pa Kannywood run pátápáta.
" Kò si fíìmù ti àwọn ènìyàn fẹ́ràn tó fíìmù ì fẹ́, ọ̀nà wo ni ẹ fẹ gba láti fi òfin de? Afi ti ẹka yìí ko ba ni si mọ. Mo gba pé ó ye kí àwọn to n kọ fiimu ó moju to ẹka míràn, sùgban ki wọn maa ṣe eré ìfẹ́ rárá, kò le siṣẹ́ rárá.
Oríṣun àwòrán, Kannywood
Ibi ere Makanta Biyu to jẹ ere ikfe ti Kannywood ṣe ti BBC si gbe e
Lóri bóyá fífòfinde ere ìfẹ yóò sọ àwọn kan di ẹdun arinlẹ gẹ́gk bi olori akoni nijo  Ali ni ni ere ìfẹ ni o pọ̀ ti oun maa n ṣe nítori nínú eré ìfẹ́ ni orin àti ijo ti maa n waye.
Mí ò rò pe èyí le ṣe akoba kankan fún mi nítori mi o gbagbọ pe o ṣeeṣe ki wọn fofinde eré ifé ni Kannywood"""
Oríṣun àwòrán, Kannywood
Ogun ọdún ni Ali Nuhu ti lò gẹ́gẹ́ bi òṣèrè ni Kannywood
Nínú ìfọ̀rọ̀wanilẹ́nu wò ti BBC ṣe pẹ̀lú gbájúgbaja oṣèré Kannywood Ali Nuhu lọ́dun to kọja, sọ pe ìdí ti Kannywood ṣe máa ń ṣe ere ifẹ ni pé, òhun lo n ṣe àfihan àwọn ènìyàn, Awọn Hausa dágbà nínú wíwo eré àgbéléwò India, ti gbogbo ènìyàn si mọ pe inú rẹ ni eré ìfẹ́ ti bẹ̀rẹ̀.
Nuhu to ni ile iṣe to n gbe fiimu jáde FKD yóò ṣe àgbéjade fiimu tó ṣẹṣẹ ṣe ti àkọlé rẹ̀ jẹ 'Ki yarda da ni' tósi jẹ fíìmù ìfẹ́ lósù tó n bọ, èyí ni Maikaba ń pinu láti fofinde.
NBC fọwọ́ sí ìdásílẹ̀ ilé iṣẹ́ Fulani Radio
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ọrọ lori Fulani radio
Ajọ to n ri si igbohunsafẹfẹ lorilede Naijiria, NBC ti fun 'pe si gbogbo ile iṣẹ igbohunsafẹfẹ lati yago fun ọrọ to le ṣakoba fun irẹpọ ati iduroṣinṣin Naijiria.
"Eyi waye gẹgẹ bi esi si gbọyii sọyii to n waye laarin awn ile iṣẹ iroyin lori iwe aṣẹ ""maa ṣiṣẹ"" lati bẹrẹ ile iṣẹ rẹdio Fulani fun anfani ati le maa kọ awọn Fulani lẹkọọ."
Fun idi eyi, ajọ NBC rọ awọn ile iṣẹ igbohunsafẹfẹ lati jẹ akọṣẹmọṣẹ ki wn si tẹle ilana ajọ naa ni gbogbo igba nitori ojuṣe wọn ni lati mu ilsiwaju ba ibagbepọ alafia lorilẹede Naijiria nipa igbohunsafẹfẹ.
Oríṣun àwòrán, NBC
NBC
Wọn ni ajọ to n bojuto ikẹkọọ awọn Fulani lorilẹede Naijiria kọwe bo ṣe tọ lati gba iwe aṣẹ igbohunsafẹfẹ fun ilọsiwaju ipolongo ikẹkọọ to fi mọ lori afẹfẹ.
Ìdílé tó gba olùkọ́ èdè Yorùbá fún àwọn ọmọ nílẹ̀ Gẹ̀ẹ́sì
Alakalẹ inu lẹta naa ni  pe awn eto ori rẹdio naa yoo jẹ eyi to n kọ ni lẹkọ pọnbele ti wọn si ṣeto rẹ fun awọn arinrinajo bii apẹja, daran daran, ọdẹ, agbẹ ati bi iru rẹ.
Ẹwẹ, iroyin to wa n ja kalẹ ni wi pe ile iṣẹ rẹdio yii kan wa fun ẹgbẹ kan ni.
Ajọ NBC jẹ ko di mimọ pe iru iwe aṣẹ yii kan naa ni wn ti fun awọn ile ẹkọ giga atawọn ile iṣẹ ijọba mii lati maa gbohun safẹfẹ eyi to da lori ohun ti wọn nilo rẹ fun.
Children's Day: Àwọn ọmọdé tó ń ṣe bẹbẹ láwùjọ Afíríkà
Òun ní ẹni tó kr jùlọ tó sì gba àmì ẹ̀yẹ ní òrílẹ̀-èdè GhanaChildren's Day: Àwọn ọmọde tó ti bẹ́bẹ́ láwùjọ Afíríkà
Òní ni àyájọ ọjọ́ àwọn èwé lórílẹ̀-èdè Nàìjíríà, gẹ́gẹ́ bí àjọ tó ń ri sí ẹ̀tọ́ ọmọ wẹ́wẹ́ lágbàyé (UNICEF) ṣe là á kalẹ̀.
"Gbogbo ọjọ́ kẹtàdínlọ́gbọ̀n, oṣù karùn ún, ọdọọdún ni ó máa ń wáye, ṣùgbọ́n ní ọ̀dún yìí àjọ náà pé àkọlé rẹ̀ ní ""Gbogbo ọmọ ló ní ẹ̀tọ́"""
Àjọ UNICEF ní pé bó tilẹ̀ jẹ pé àwọn ò sinmi, sùgbọ́n àwọn ọmọde ní Nàìjíríà kò sì tii ní ẹ̀tọ́ sí ètò ìlera, oúnjẹ, ètò ẹ̀kọ́ àtí àwọn ẹ̀tọ́ mìíràn.
Megabite: Ilé-ìwé ni mo ti bẹ̀rẹ̀ orin kíkọ
"Lọdun 2019 yìí, UNICEF ṣe àfilọ́lẹ̀ ìwé pélébé ti wọ́n pe àkọlé rẹ̀ ni ""Passport to Your Right"" tí yóò wà ni èdè Hausa, Igbo àti Yorùbá pẹ̀lú ìléri pé ọmọ kọ̀ọ̀kan yóò ni ẹ̀tọ́ sii ni ọdún 2030. láti ṣe àyájọ́ ọjọ́ ọmọ wẹ́wẹ́."
Ẹ wo àrà àwọn ọmọ kékeré ń fi ẹ̀kọ́ kọ̀mpútà dá
Àwọn ti ìlé iṣẹ́ BBC Yorùbá n gbe yẹwo fi sami ayẹyẹ ọmọ wẹ́wẹ́ t'orílẹ̀-èdè Nàìjíríà tó tí làmìlaaka nínú ǹkan ti wọ́n yàn láàyò lagbaye ni:
Jeremaiah Owura Addo (GHANA)
Jeremiah Addo: Ọmọ ọdún méjì tó ṣeeṣe kò mọ̀wé jù l'ágbàáyé
Ọmọ yìí gan an ni à bá sọ pé orí rẹ̀ pé bii ti alájọ Ṣomolu.
Ọmọ ọdún mejì yìí kò dé iléèwé rí, àmọ́ ó mọ olú ìlú orílẹ̀-èdè ogójì àti àwọn ìṣẹ̀lẹ̀ mii tó wà láyé.
Àwọn ènìyàn tilẹ̀ ni òun ló yẹ kí ó gba àmì ẹ̀yẹ ọmọ tó jáfáfá jù lọ lágbàyé.
Ṣekinat Quardir(NAIJIRIA)
Sekinat Quadri
Ọmọdébìnrin yìí Sekinat Quadri jẹ́ kí àwọn òbí rẹ̀ mọ́ pé abẹ̀sẹ́kùbíòjò ló wu òun, wọ́n sì ń tíì lẹ́yìn.
BBC Yorùbá bá ọmọdébìnrin náà tó fẹ́ dà bí Anthony Joshua, lálejò, ó kọjá àfẹnusọ.
Sekinat Quadri ọmọ ọdun meje ajẹsẹ to fẹ dabi Anthony Joshua
DJ Switch (GHANA)
Children's Day: Àwọn ọmọde tó ti bẹ́bẹ́ láwùjọ Afíríkà
Ọmọdébìnrin, ọmọ ọdún mẹ́ẹ̀wá tó jẹ́ apo orin tàkasufe pọ yìí 'DJ switch' ní àṣírí márùn-ún fún ẹnì tó bá fẹ́ dà bíi rẹ.
Bode George: òòtọ́ ni ìkìlọ̀ Obasanjọ ati Soyinka
Òun ní ẹni tó kéré jù lọ tó sì gba àmì ẹ̀yẹ ní òrílẹ̀-èdè Ghana Children's Day: Àwọn ọmọde tó ti bẹ́bẹ́ láwùjọ Afíríkà
Demilade Adepegba( NAIJIRIA)
Ọmọ ọdún mẹ́wàá ni Damilola Adepegba, tó ń fi fèrè dá bí ẹdun, rọ̀ bí òwè!
Demilade nínú fídíò yìí sọ fún BBC Yorùbá pé gbogbo ìgbà tí òun bá ń fọn fèrè ni inú òun máa ń dùn.
Ìkorodu Boiz (NAIJIRIA)
Ikorodu Bois: Ko si ẹni ti a kò lè sín jẹ!
Ǹkan ti àwọn ọmọ wọ̀nyìí yàn láàyò ni láti maa sín àwọn olókìkí ènìyàn jẹ, Muiz Sanni (14), Fawas Sanni (10) àti Malik Sanni (8) jẹ́ ọmọ ìyá kan náà ti wọ́n sì máa ń dẹ́rin pa àwọn ènìyàn.
Joshua Robert Poshjosh (NAIJIRIA)
Josh Posh: Inú mi máa ń dùn láti kọrin fún àbúrò mi ní kékeré
Joshua Robert (Poshjosh) jẹ ọmọ bíbí Nàìjíríà tí a bí sí òkè òkun.
Obí rẹ̀ gbìyànjú láti fí èdè àti àṣà kọ́ ọ tó si dí ohun àmúyangan láàrin àwọn òyìnbó lókè òkún.
Ohun to máa n mú inú rẹ̀ dùn jùlọ ni pé, ó fẹ̀ràn láti máa kọrin fún àbúrò rẹ̀.
Oluwapamilerin Mihael Ayanlere (NAIJIRIA)
Àyàn: Ti mo bá ti gbọ́ ohùn ìlù ni àárẹ́ mi ma ń lọ!
Kékere àkin ní Oluwapamilerin, ọmọ ọdún mọ́kànlá to yan ìṣẹ́ bàbá rẹ̀ láàyò láti kekere, bó se ń lu omele, gángan, ìyá ìlù, bákàn náà lo n lu àpapọ̀ ìlù ìgbàlódé tí wọ́n ń pe ni (Drum Set).
'Àsìkò Amojúẹ̀rọ Seyi ni ló fi wọlé l'Oyo, kìí ṣe àsìkò èmi Omobolanle'
Kareem Waris (NAIJIRIA)
Waris Kareem: Emmanuel Macron kan sáárá lórí àwòrán tó yà
Gbájúgbaja ayàwòrán yìí di ìlúmọ̀ọ́ká nígbà ti ààrẹ orílẹ̀èdè Faranse, Emmanuel Macron ti gbé oríyìn fún un.
Ọmọkùnrin, ọmọ ọdún mọ́kànlá náà, nígbà tó ya àwórán ààrẹ náà láàrin wákàti méjì tó sì gbé e fún un ní Africa Shrine.
Láti ìgbà yìí ni ọmọ náà tí di ènìyàn ǹlá tí iṣẹ́ ọwọ rẹ̀ si ti dí èyí ti wọ́n ń rà káàkírí.
Rain: Ìgbà òjò léwu, ohun tó o ní láti mọ̀ rèé
Oríṣun àwòrán, Pulse
Ni ọdọọdun ni agbara ojo maa n gbẹmi ara ilu ni orilẹ-ede Naijiria.
Eyi lo jẹ ki ọrọ ọpọ ẹ̀mí àti dukia sọnu ni Naijiria.
Onimọ nipa ọrọ aabo ayika kan, Ọgbẹni Ehi Iden sọ fun BBC wi pe, ọrọ agbara ojo lagbara ju bi awọn eniyan ṣe ro o lọ.
Omiyalé Àkútè: N50 si N100 làwọn èèyàn fi ń kọjá lórí ẹ̀kún omi l‘Ákútè
1.  Mọ bi ọna adugbo rẹ ṣe ri daradara loju mọmọ:
Iden ni ki o to le yago fun ijamba ti agbara ojo ba ka ọ mọ adugbo rẹ, o ni lati mọ bi ọna adugbo rẹ ṣe ri daju.
Eyi ni yo lè jẹ ki ọ mọ ibi ti oju gọ́tà tabi ihò wà láti yago fun.
Afeez Agoro: O ṣòro fún mi láti wọ Danfo jáde
Onimọ naa ni, fun apẹẹrẹ, bi agbara ojo ṣe n ṣọsẹ ni adugbo kọọkan ni Ipinlẹ Eko lagbara ju'ra wọn lọ.
Ehi ni ọpọlọpọ awọn iho ti oloyinbo n pe ni 'manhole' pọ̀ ni oju popo Ipinlẹ Eko to jẹ ewu fun awọn eniyan ni ọsan lai tii sọ iru ewu ti wọn jẹ fun ara ilu ni alẹ tabi nigba ti ojo ba rọ.
Oríṣun àwòrán, Stelladimokorkus
Eyi ni yo lè jẹ ki ọ mọ ibi ti oju gọ́tà tabi ihò wà láti yago fun.
2. Agbara ojo kii ṣe oun afojudi rara:
Awọn onimọ ni agbara ojo to ga to iwọn bata ẹsẹ kan le wọ ọkọ lọ loju popo.
Idi ree ti wọn fi gba awọn awakọ ni iyanju lati ri wi pe wọn ko gbe ọkọ sita nigba ti agbara ojo ba wa lori popo.
'Àsìkò Amojúẹ̀rọ Seyi ni ló fi wọlé l'Oyo, kìí ṣe àsìkò èmi Omobolanle'
Fun awọn ti agbara ojo naa ba ka mọ irinajo, ni wọn ni ki wọn yẹra fun ijamba, wọn ni lati wa ọna lati wa ọkọ wọn sibi kan, ki wọn si jade ninu rẹ ni kiakia.
Ijọba gbọdọ gbé igbimọ alaabo kalẹ laarin awọn olugbe awọn adugbo ti agbara ojo ti maa n ṣọsẹ.
Oríṣun àwòrán, Pulse
Ijọba gbọdọ gbé igbimọ alaabo kalẹ laarin awọn olugbe awọn adugbo ti agbara ojo ti maa n ṣọsẹ.
3. Imọran deede nipa agbara ojo:
Ehi ni ọpọlọpọ igba ni iroyin ti fi han bi awọn ọmọ ile iwe ṣe ba agbara ojo lọ nigba ti wọn ba n bọ nile iwe.
O ni idi ti iru eyi fi n ṣẹlẹ ni wi pe, awọn obi ko ni imọran to to lori ewu to wa ninu ki awọn ọmọ wọn jade nigba ti agbara ojo ba wa lori popo.
O ṣalaye pe, ko si oṣiṣẹ kankan to yẹ ko padanu ẹmi rẹ nitori wi pe ko fẹ pẹ de ibi iṣẹ ni ọjọ ti ojo ba rọ.
Idi ree to fi sọ wi pe ẹrọ rẹdio lo yẹ ki ijọba fi maa polongo imọran nipa bi awọn eniyan ṣe le ṣọra lasiko ojo.
Oríṣun àwòrán, TVC
Ehi Iden ni ko si oṣiṣẹ kankan to yẹ ko padanu ẹmi rẹ nitori wipe ko fẹ pẹ de ibi iṣẹ ni ọjọ ti ojo ba rọ.
Ni ọdun 2011, o to ọgọrun un eniyan ti ajọ Red Cross ni o padanu ẹmi wọn ninu agbara ojo ni ilu Ibadan.
Yatọ si awọn to gbẹmi mi, ọpọlọpọ ni o padanu dukia ati awọn ọrọ aje wọn.
Ni oṣu keje, ọdun to tẹlee, 2012, o din diẹ ni irinwo eniyan ti omiyale ati agbara ojo pa kaakiri orilẹ-ede Naijira, ni paapaa, Ipinlẹ Eko nibi ti ọpọlọpọ eniyan ti ku.
Ajọ to n ri si iṣẹlẹ pajawiri, NEMA sọ nigba naa wi pe o le ni miliọnu meji ọmọ Naijiria ti agbara ojo sọ di alainile lori nigba naa.
Olusegun Obasanjo: Ọmú ìyá mi ti mo fi ń mùkọ ni kekere ló jẹ ki ń lókun
Children's Day: Èwe ni ọjọ́ ìwájú ìran ènìyàn-Adeyeye Enitan Ogunwusi
Kabiesi Ojaja 11 sami ayẹyẹ ayajọ àwọn ewe pẹlu àrà
Ooni Adeyeye Enitan Ogunwusi Ojaja II gbalejo awọn ewe kaakiri ile iwe ni Ile Ife ati agbegbe rẹ.
Loni ayajọ ọjọ awọn ewe kaakiri agbaye gẹgẹ bi UNICEF ṣe laa kalẹ naa ni Oba Ile Ifẹ darapọ mọ gbogbo òbí agbaye lati sami ayẹyẹ yii pẹlu awọn ọmọde.
Lasiko ti Kabiesi n gbalejo awọn ọmọ wọnyii lo fara balẹ ṣalaye itan Oodua àti ìtẹ́ ni aafin fawọn ogo wẹẹrẹ wọnyii.
Tọkunrin-tobinrin lo yọ ayọ ayajọ awọn ewe tọdun 2019 laafin Ojaja 11 nile Ifẹ.
'Àsìkò Amojúẹ̀rọ Seyi ni ló fi wọlé l'Oyo, kìí ṣe àsìkò èmi Omobolanle'
Ọọ̀ni Ilé Ifẹ̀ gbàlejò àwọn èwé sí ìdùnnú àwọn ọ̀dọ́ tilu tifọn ni ile Ifẹ.
Oba yii fidunnu rẹ han lori awọn ọmọde nipa bi bawọn kọrin ati jijo ijo ayọ laarin wọn.
Tayotayo ni Kabiesi gbalejo awon ogo weere
Baba gbogbo ọmọ Oodua wure aṣeyọri fun gbogbo awọn ọmọ ti wọn wa sibi eto naa atawọn ti wọn ko le wa lapapọ.
Afro Brazilians: ìlú Rio ni a máa kọ ilé ìṣẹmbáyé náà sí
Kabiesi ni oju kii pọn iṣin ki ọmọ inu ẹ ma là, o di dandan ki ori awọn ogo wẹẹrẹ yii kan oke.
Ọọni gba pe, oriṣa ti a ko ba fidi ẹ han ọmọde kii pẹ parun, o yẹ kawọn ọmọ yii mọ pataki iran wọn.
idije orisi lo sele to mu inu awon omode dun ni Ife
Lẹyin eyi ni awọn ọdọ yii ni oore-ọfẹ lati dije ninu ere idaraya loriṣirisi bii gbigba bọọlu ori tabili, kẹkẹ gigun ati bẹẹ bẹẹ lọ.
Ọọni Ogunwusi Adeyẹye pe fun itọju awọn ọdọ
Ọpọlọpọ obi, alagbatọ ati awọn olukọ awọn akẹkọọ wọnyii ni wọn kọwọrin wa pẹlu awọn ọmọ wọn.
Ooni: Mo ti fi ọ̀rọ̀ obinrin tó ń parọ́ ìfẹ́ mọ́ mi sun agbófinró
Gbogbo wọn pata ni Kabiesi wure ipese fun pe onikaluku a jere iṣẹ ati làálàá wọn lori awọn ọmọ yii.
Tẹrin tọyaya tagbara n rin ko odo lọna lawọn ewe rin pade Oba Alayeluwa loni
Bode George: òòtọ́ ni ìkìlọ̀ Obasanjọ ati Soyinka
Ọpọlọpọ idije Tan-mọọ lo waye nibi eto akanṣe fawọn ewe naa bii ti idije ìṣirò, ijo ibilẹ ati afihan aṣa Yoruba loriṣiiriṣii.
Opolopo ẹbun ni awọn ọmọ ko lọ sile pẹlu idunnu lẹyin ti wọn ti yan bi ologun tan fun Oba atawọn alejo to wa nibẹ.
Opolopo ẹbun ni awọn ọmọ ko lọ sile pẹlu idunnu lẹyin ti wọn ti yan bi ologun tan fun Oba atawọn alejo to wa nibẹ.
Àwọn Olukọ paapaa fẹsẹ rajo ninu idije ti onikaluku rẹrin pẹlu idunnu ti awọn kan si gbegba oroke ninu idije naa.
Diẹ lara awọn to ṣajọyọ yii pẹlu Alayeluwa ni alaga awọn onimọ ẹrọ ẹka ti ipinlẹ Oyo / Osun / Ondo / Ekiti, Ogbẹni Kola Akosile atawọn mii.
Nigeria 2019 budget: Ààrẹ Muhammadu Buhari buwọ́lu owó ìṣúná ọdún 2019
Oríṣun àwòrán, Bashir Ahmad
Ààrẹ orílẹ̀-èdè Nàìjíríà buwọ́lu owó ìṣúná 2019
Aarẹ Muhammadu Buhari ti buwọlu owo iṣuna ọdun 2019.
Lọjọ Aje ni Buhari buwọlu owo iṣuna naa to ku diẹ ko pe triliọnu mẹsan an Naira (8.92 trillion) eyi to ti sọ aba owo iṣuna naa di lilo bayii.
Amọ ṣa, Minisita fun eto iṣuna ati aato ilu, Udoma Udo-Udoma kede pe gbogbo akọsilẹ to wa ninu owo iṣuna ti aarẹ buwọlu ọhun yoo jẹ fifi si ita gbangba fun ara ilu nibi eto kan ti yoo waye lọjọ Iṣẹgun.
Oríṣun àwòrán, Bashir Ahmad
Ààrẹ orílẹ̀-èdè Nàìjíríà buwọ́lu owó ìṣúná 2019
Lara awọn to peju sibi eto naa ni igbakeji aarẹ, Yẹmi Ọṣinbajo, olori ile igbimọ aṣoju-ṣofin, Yakubu Dogara, igbakeji olori ile aṣofin agba, Ike Ekweremadu.
Bode George: òòtọ́ ni ìkìlọ̀ Obasanjọ ati Soyinka
Kannywood Kidnapping: 'Mọ́ngòrò nìkan ni wọ́n fún mi jẹ ní àhámọ́ ajínigbé'
Oríṣun àwòrán, Salisu Muazu/Facebook
Aworan akọkọ ti Muazu ya re e, lẹyin ti wọn tu u silẹ lọsan ọjọ Aiku
Gbaju-gbaja oludari ere Kannywood ti awọn ajinigbe tusilẹ lọjọ Abamẹta, Salisu Muazu ti sọ fun BBC pe mọngoro nikan ni awọn ajinigbe naa fun oun ati ọrẹ mẹta ti wọn jigbe jẹ fun ọjọ mẹta.
Oludari ere ọhun to n gbe niluu Jos lo n rinrinajo lọ si ipinlẹ Plateau lati Kaduna lọjọbọ to kọja pẹlu aburo rẹ, ati awọn ọrẹ nigba ti awọn ajinigbe naa da wọn lọna.
Ile ti wọn fi wa si ko ni orule rara. Ori wa ni ojo n rọle, mọngoro nikan si ni wọn n ka fun wa jẹ lori igi kan to wa nitosi ibẹ fun ọjọ mẹta.
Awọn ajinigbe naa sọ fun wa pe awọn yoo san owo ibọn AK47 ti awọn ya, owo ọga wọn lara miliọnu mẹwaa Naira ti a ba san.
Afeez Agoro: O ṣòro fún mi láti wọ Danfo jáde
Muazu ṣalaye pe awọn ajinigbe naa sọ fun awọn pe awọn kan to wa ni ipo pataki n lọwọ si awọn ijinigbe to n waye ni Naijiria.
Oríṣun àwòrán, Salizu Muazu
Salisu sọ pe mọngoro nikan ni awọn ajinigbe naa fun awọn jẹ f'ọjọ mẹta.
Muazu sọ pe gẹgẹ bi oludari ere, oun yoo lo iriri naa lati ṣe sinima ti yoo gba ami ẹyẹ fun oun.
Bode George: òòtọ́ ni ìkìlọ̀ Obasanjọ ati Soyinka
Miliọnu mẹwaa Naira ni mọlẹbi Muazu san ki wọn o to tu wọn silẹ.
Ojoojumọ ni iroyin ijinigbe n jade lorilẹ-ede Naijria, botilẹjẹ pe ọga agba ileeṣẹ ọlọpaa sọ laipẹ yii pe o ti dinku lẹyin ti awọn ọlọpaa so okun aa bo le lawọn opopona nla.
'Àsìkò Amojúẹ̀rọ Seyi ni ló fi wọlé l'Oyo, kìí ṣe àsìkò èmi Omobolanle'
Oyo NLC: A kò bẹ̀rẹ̀ ìyanṣẹ́lódì láti d'ẹ́rù ba ìjọba tuntun
Oyo NLC mú ìlérí rẹ̀ ṣẹ, ó bẹ̀rẹ̀ ìyanṣẹ́lódì
Ẹgbẹ oṣiṣẹ ijọba nipinlẹ Ọyọ, NLC, ti so iyanṣẹlodi rẹ rọ.
Lasiko to n kede igbesẹ naa, Alaga ẹgbẹ NLC nipinlẹ Ọyọ, Comrade Bayọ Titilọla-Sodo, sọ pe awọn bẹrẹ iyanṣẹlodi pẹlu ireti pe ọjọ diẹ to ku ninu iṣejọba to wa nita lọwọlọwọ nipinlẹ Ọyọ yoo so eso rere fun awọn oṣiṣẹ.
O ni kii ṣe ọna tabi erongba lati dẹru ba ijọba to n bọ.
Lara awọn ohun to fa a ti awọn oṣiṣẹ naa fi yanṣẹlodi gẹgẹ bi Titilọla-Sodo ṣe sọ ni ajẹsilẹ owo oṣu ati owo ifẹhinti awọn oṣiṣẹ fẹhinti, eyi toto ọgọta billiọnu Naira.
Bakan naa ni fifi opin si aṣẹ ti ko jẹ ki wọn o gbe awọn oṣiṣẹ lati ibikan si omii, gbigba awọn oṣiṣẹ ti wsn da duro lọna aitọ pada, ajẹsilẹ owo oṣu awọn olukọ ileewe alakọbẹrẹ ati awsn oṣiṣẹ ijọba ibilẹ kan.
Toma Unu: Ọmọbìnrin tó ń fi ẹsẹ̀ rẹ̀ ya àwọran nítori pe ó ni ìpènija ọpọlọ
O wa kesi gomina tuntun fun ipinlẹ Ọyọ, Onimọ Erọ Seyi Makinde, pe ko ma ṣe yi ohùn pada lori awọn ileri to ṣe lasiko to n polongo ibo.
Àwọn kan ń dunú, àwọn kan ń ṣe ìkìlọ̀ lórí èsì ìdìbò ààrẹ
Ọjọ Ẹti to kọja ni ẹgbẹ oṣiṣẹ naa bẹrẹ iyanṣẹlodi.
Contortionist: Mo lè gbé ìfun mi pamọ́ ki n tún se èémí!
Buhari: Iléeṣẹ́ ọlọ́pàá àti ológun ti kùnà lórí ètò ààbò Nàìjíríà
Oríṣun àwòrán, Presidency
Ifọrọwerọ pẹlu aarẹ Muhammadu Buhari
Aarẹ orilẹede Naijiria Muhammadu Buhari sọ gbankọgbi ọrọ ninu ifọrọwerọ to ṣe lalẹ ọjọ Aje lori ẹrọ amohunmaworan ijọba apapọ, NTA.
Eyi ni koko marun un ninu awọn ọrọ ti Aarẹ Buhari sọ ninu ifọrọwerọ naa.
Ọrọ lori eto iṣuna
Aarẹ Buahri sọ oko ọrọ si awọn adari ile aṣofin agba l'Abuja, Bukọla Saraki ati Yakubu Dogara, lori ọrọ eto iṣuna ọdun 2019. O ni wọn ko nifẹ orilẹede Naijiria l'ọkan.
Aarẹ ni ti Saraki ati Dogara ba ni ifẹ Naijiria lọkan, wọn ko ni gba ki aba iṣuna wa ni iwaju ile fun oṣu meje lai buwọ lu u.
''Baba go slow''
Aarẹ Buhari sọ ninu ọrọ rẹ tun fesi pada fun awọn to n pe ni ''baba slow'' pe, yoo rii gbangba ni saa keji oun, boya lootọ tabi irọ ni oun lọra ninu iṣejọba oun.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Aarẹ sọ pe Saraki ati Dogara ko ni ifẹ Naijiria lọkan, ni wọn ṣe mu idiwọ ba aba iṣuna fun oṣu meje.
Buhari ni oun yoo ya agbado haa si awọn to n pe oun ni ''baba go slow'' lẹnu ni saa keji yii.
Ọrọ eto aabo
Aarẹ Naijiria tun dẹbi eto aabo to mẹhẹ lorilẹede yii ru awọn ọlọpaa ti wọn ko ṣiṣẹ wọn bi iṣẹ.
Oríṣun àwòrán, Nigeria Presidency
O ni kudiẹkudiẹ nileeṣẹ ọlọpaa ati awọn ologun lati igba ti oun ti fiṣẹ ologun silẹ lo ṣe okunfa eto aabo ti ko mọyan lori ni Naijiria.
Buhari ni oun fẹ ki ẹka eto aabo ṣiṣẹ takuntakun sii, lati ri pe eto aabo duro daada l'orilẹede Naijiria.
Jiti Ogunye: Ìjọba àkóbá lológun gbé kalẹ̀ ni 1999
Ọrọ lori awọn minisita
Lori ọrọ awọn minisita ti Aarẹ Buhari yoo yan fun saa keji ijọba rẹ, o ni oun ko tii sọ fun ẹnikan nipa wọn.
Aarẹ ni, o yẹ ki awọn eeyan ni igbẹkẹle ninu oun, nitori pe ko si ẹnikan to le tọka si ọkankan ninu awọn minisita to ba oun ṣiṣẹ pe wọn wuwa ibajẹ kan tabi omiiran lati ọdun mẹrin sẹyin.
Aarẹ ni oun ko le sọ bo ya awọn minisita kan yoo si di ipo wọn mu, tabi oun yoo dagbere fun awọn kan lara wọn.
Àgbà ni Obasanjo, oun tó ń sọ yé e, ìjọba ni kó tají - Wale oke
Ọrọ lori awọn gbajumọ ati ọmọwe
Aarẹ Buhari sọ pe ata akara ti ko ran ikọ ni ọrọ awọn gbajumọ ati ọmọwe to n tako ijọba oun jẹ.
Aarẹ ni awọn gbajumọ ati ọmọwe maa n tako ijọba oun, lati le gba iyi lọwọ awọn ọmọ orilẹede Naijiria lasan ni.
Aarẹ tun sọ pe, oun yoo gbiyanju lati ri wi pe ile iṣẹ ọlọpaa ati ẹka eto idajọ gbopọn si ni saa keji ijọba oun.
Nollywood gba àlejò ọmọkùnrin jòjòló
Oríṣun àwòrán, Bidemi Kosoko
Idunnu subu layọ ni lowurọ ọjọ Iṣẹgun nigba ti ariwo gba ilẹ kan pe gbajugbaja oṣere ori itage lobinrin kan, Abidemi Kosọkọ ti di iya ikoko.
Bẹẹ ba gbagbe, laipẹ yii ni ọmọbinrin naa ṣe idana, to si lọ sile ọkọ.
Nigba to n kede pe oun ti ru re, ti oun si sọ re, Bidemi kede loju opo ikansira ẹni Instagram rẹ pe ọmọkunrin tuntun jojolo ni ọba oke fi ta oun lọrẹ.
Ni kete ti iroyin naa si tan kalẹ, ni ọpọ awọn eeyan ti n ki ku oriire aruye yii.
Bidemi, tii baba rẹ naa jẹ gbajumọ oṣere tiata, Jide Kosokọ, naa fi tayọtayọ kede pe oluwaseun fun ẹbun ọmọ naa ti oun si bi layọ ati alaafia.
Àgbà ni Obasanjo, oun tó ń sọ yé e, ìjọba ni kó tají - Wale oke
Lara awọn osere tiata to ti ki Bidemi ku ayọ abara tintin la ti ri Antar Laniyan, Madam Sajẹ, Wumi Toriọla, Ronkẹ Oshodi Oke, Ọdunlade Adekọla ati bẹẹ bẹẹ lọ.
EFCC: Akẹ́kọ̀ọ́ mẹ́rin tó ń kọ́ iṣẹ́ Yahoo l‘Eko lọwọ́ EFCC tẹ̀
Oríṣun àwòrán, EFCC
Ajọ to n gbogun ti iwa ọdaran nidi owona lorilẹede Naijiria, EFCC, ti kede loju opo ikansira ẹni Facebook rẹ pe, ọwọ palaba oludasilẹ ileẹkọ kan ti wọn ti n kọ nipa iwa lilu jibiti lori ayelujara, taa mọ si Yahoo ti segi.
Atẹjade kan, ti agbẹnusọ fun ajọ EFCC, Tony Orilade fisita lọjọ isẹgun lo sisọ loju ọrọ yii.
Atẹjade naa ni awọn osisẹ ajọ EFCC to wa nilu Eko, lo ya bo ileẹkọ naa, to wa ni ojule Kẹrinla, opopona Animasaun, ladugbo Ojodu-Berger nilu Eko, lasiko ti awọn akẹkọ ileẹkọ naa n gba idanilẹkọ lọwọ.
Lara awọn eeyan ti ọwọ awọn osisẹ ajọ EFCC naa tẹ ni ẹnikan ti wọn furasi bii oludasilẹ ileẹkọ naa, Frank Chinedu, tii se ẹni ọdun mejilelogun.
Awọn eeyan yoku ni akẹkọ mẹjọ, ti wọn n gba idanilẹkọ lọwọ lasiko ti awn osisẹ EFCC wọ ileẹkọ Yahoo naa.
Àgbà ni Obasanjo, oun tó ń sọ yé e, ìjọba ni kó tají - Wale oke
Lara awọn ohun ti awọn osisẹ EFCC ka mọ awọn afurasi naa lọwọ ni ẹrọ ayarabiasa agbeletan mẹsan, foonu alagbeka mẹrindinlogun, pẹ́lu ọkọ Toyota Camry ti nọmba rẹ jẹ EPE 406FN.
Oríṣun àwòrán, EFCC
Wayio, ajọ EFCC ti sọ agadagodo si ẹnu ọna ileẹkọ Yahoo naa, to si ti fi ọda pupa kọ akọle si ara ile naa pe ẹnikẹni ko gbọdọ sun mọ ibẹ.
Swearing in 2019: Seyi Makinde ní òun kò yan igun ẹgbẹ NURTW kankan nípọ̀sìn
Oríṣun àwòrán, Seyi Makinde
Yoruba ni o n bọ, o n bọ, awọn laa dẹ de, amọ ni ti gomina ti ilu dibo yan nipinlẹ Ọyọ, Onimọ ẹrọ Seyi Makinde, oju lo fẹ mu to.
Idi ree to fi n lọgun tantan tan pe, ọmọ ẹgbẹ ọlọkọ ero kankan abi ẹnikẹni to ba gbero lati fa wahala lẹsẹ lasiko ayẹyẹ ibura oun sipo gomina, eyi ti yoo waye lọjọru, yoo jẹ iyan rẹ nisu.
Atẹjade kan ti agbẹnusọ fun Seyi Makinde, eyiun Ọmọọba Dọtun Oyelade fisita , lo sisọ loju ọrọ yii.
Atẹjade naa tun n fi ewe ọmọ mọ igun ẹgbẹ ọlọkọ ero NURTW to ba gbero lati da omi alaafia ipinlẹ Ọyọ ru ki wọn to se ibura, lasiko ibura ati lẹyin rẹ, yoo ge ika abamọ jẹ.
Seyi Makinde ni ohun ti n hu gbọ pe awọn eeyan kan ti n leri leka lati da rogbodiyan silẹ lọjọru , to si n rọ an igun ẹgbẹ NURTW to n se asọ, lati so ewe gbejẹ mọwọ.
Lagosians: Eni tó ní owó ló ń kọ Will
Seyi Makinde wa fi ọwọ idaniloju sọya pe oun ko yan igun ẹgbẹ awakọero kankan nipọsin, nitori ko si ẹmi to kọja ofin,pẹlu afikun pe oun ti kesi ileesẹ ọlọpaa lati fi imu ẹnikẹni to ba sokunfa rogbodiyan danrin.
Seyi Makinde wa n mu da awọn araalu loju, to fi mọ awọn iyalọja, lati maa ba isẹ oojọ wọn lọ̀, ti ijọba oun si ti pinnu lati jẹ ki eto aabo fẹsẹ rinlẹ ni ipinlẹ Ọyọ.
Alapinni Oosa ṣàdúrà fún gogbo ọmọ kúoótù, oò jíire bí?
Democracy Day: Àkójọpọ̀ àwòrán láti ìpínlẹ̀ Ọyọ, Ogun àti Kwara fún ìbúra gómìnà tuntun
Ẹ wo awọn aworan igbaradi fun iburawole ni awọn ipinlẹ:
Ipinlẹ Ọyọ:
N jẹ ẹ mọ pe gomina ti yoo se ibura lọjọru ni ipinlẹ Ọyọ, Onimọ ẹrọ Seyi Makinde ti kan si papa iṣere Obafemi Awolowo nibi ti ayẹyẹ ibura naa yoo ti waye.
Lasiko to si wa ni ibudo naa, lo se idanilẹkọ nipa bi eto igbaradi naa yoo se waye. Koda, o tun wọ inu ọkọ ti yoo gbe kaakiri wo .
Koda, Awọn ase ibudo lọṣọ atawọn ohun eelo ikọrin gan ti wa nikalẹ fun ayẹyẹ ibura naa.
Igbaradi ni pẹrẹwu! Seyi Makinde n gbaradi fun ayẹyẹ ibura rẹ
Awọn ara ipinlẹ Ọyọ ti ni gomina tuntun
Makinde n yan fanda lori papa saaju ọjọ iburawọle
Papa isere idaraya Obafemi Awolowo gbe awọ tuntun wọ fun ayẹyẹ ibura Seyi Makinde
Atibaba ree fun awọn alejo, o lee daboo bo awọn ero lọwọ ojo ati oorun
Papa isere Obafemi Awolowo ti yatọ gbaa fun ibura Seyi Makinde
Pẹpẹyẹ yoopọn ọmọ nibi ibura Seyi Makinde lọla. Kekere kọ
Ipinlẹ́ Ogun:
Gbogbo eto lo ti to bayii ni papa isere idaraya MKO Abiola nilu Abẹokuta fun ayẹyẹ ibura gomina ti ilu dibo yan ni ipinlẹ Ogun, Ọmọọba Dapọ Abiọdun.
Akọroyin BBC Yoruba to ti balẹ silu Abẹokuta fi awọn aworan ransẹ nipa ibi ti igbaradi naa de duro.
Gbogbo eto ti to saaju ibuwarawọle fun gomina nipinlẹ Ogun
Dapo Abiodun ati Noimot Salaki Oyedele ni wọn yoo ma a bura fun gẹgẹ bi gomina ati igbakeji rẹ.
Awọn ohun elo orin lọlọkan o jọkan ko gbẹyin nibi igbaradi naa.
Awọn asofin ipinlẹ Ogun naa wa lara awọn ti wọn yoo ma burawọle fun ni Ọjọru
Ipinlẹ Kwara:
Bi o tilẹ jẹ pe awọn ipinlẹ kan ko mu ayẹyẹ ibura awọn gomina tuntun ni kekere, ti wọn si fẹ ṣe ayẹyẹ ibura naa tilu-tifọn, amọ eyi ko ri bẹẹ rara ni ipinlẹ Kwara.
Idi ni pe wọọrọwọ ni wọn fẹ se ibura gomina ti ilu dibo yan, Abdulrahman Abdulrazak ti ipinlẹ Kwara, ti ayẹyẹ naa ko si ni kọja ile ijọba ipinlẹ naa.
Akọroyin BBC Yoruba to ti kalẹ silu Ilọrin fi ye wa pe, ko si pọpọsinsin kankan to n waye nipa ibura naa.
Gbunkẹlẹ ni ayẹyẹ iburawọle ni ipinlẹ Kwara yoo jẹ lọla pẹlu bi ohun gbogbo se dakẹ rọrọ
Awọn o sisẹ naa n gbaradi fun ọla
Akojọpọ aworan naa wa lati BBC
Fire: Táńkà epo méjì tó forí gbárí ló fa sábàbí iná ọ̀hún
Oríṣun àwòrán, Trace
Nibi ti awọn alayọ ti n yọ fun ayẹyẹ ibura aarẹ Muhammadu Buhari ati tawọn gomina gbogbo lawọn ipinlẹ lọjọru, ijamba ati ofo nla lo n ba awọn eeyan kan to gba opopona marosẹ ibadan silu Eko kọja lọjọ naa.
Iroyin to n tẹ wa lọwọ ni yajo-yajo lo fi ye ni pe, ijamba ọkọ kan to lagbara waye ni deede aago mẹwa ọjọru yii, ni abẹ afara Fidiwọ, lopopona marosẹ Ibadan silu Eko.
Iroyin naa ni, ọkọ tanka epo meji lo fi ori sọ ara wọn lojiji, ti ina si dahun lara wọn, eyi to mu ki eeyan marun fi ara pa yanna-yanna, ti ọpọ ọkọ ayọkẹlẹ, ọkọ akẹru ati awọn ọkọ nla-nla si jona kọja ala.
Oríṣun àwòrán, Trace
Amọ ko si ẹmi kankan to bọ ninu ijamba naa, ti awọn sisẹ alaabo atawọn araalu si ti pa ina ọhun.
Oríṣun àwòrán, Trace
Sugbọn ijamba naa se okunfa sunkẹrẹ-fakẹrẹ ọkọ lopopona marosẹ Ibadan si ilu Eko ni ọjọru.
Oríṣun àwòrán, Trace
Nigeria Swearing in 2019: Makinde ní omi tuntun rú, ìgbà ọ̀tun dé sí ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́
Gomina tuntun ti wọn ṣẹṣẹ bura fun nipinlẹ Ọyọ, Onimọ-ẹrọ Ṣeyi Makinde ti ṣe alaye wi pe, asiko ti to fun imuṣẹ awọn ileri ti oun ṣe lasiko ipolongo idibo.
Makinde fidi ọrọ naa mulẹ ni Ọjọru, lẹhin to bura wọle gẹgẹ bii gomina tuntun nipinlẹ Ọyọ, eyi to waye ni papa Iṣere Ọbafẹmi Awọlọwọ, tokalẹ si opopona Liberty niluu Ibadan.Ohun akọkọ ti gomina wọgile ni igbesẹ sisan ẹgbẹrun mẹta naira, ti awọn ọmọ ilẹ ẹkọ girama n san nipinlẹ Ọyọ.
O ṣe alaye wi pe, ko bojumu ki awọn obi maa lakaka ki wọn to ri owo san fun awọn ọmọ wọn to n bẹ nile ẹkọ girama to jẹ ti ijọba.Ṣeyi Makinde tun mẹnuba pataki eto ẹkọ ati igbiyanju rẹ lati mu ko di irọrun f'awọn akẹkọọ.
Àgbà ni Obasanjo, oun tó ń sọ yé e, ìjọba ni kó tají - Wale oke
O fi kun ọrọ rẹ pe, bii ẹgbẹrun lọna irinwo akẹkọọ ni ko lanfani lati tẹsiwaju lẹnu ẹkọ wọn nipinlẹ Ọyọ, nitori ipenija owo.
Ẹni bá láyà kó wá wọ̀ọ́! Ta ni Ìgè Àdùbí nílẹ̀ Oodua?
"O ni, ""A ba obi awọn ọmọ to n lọ si ile ẹkọ girama to jẹ ti ijọba ipinlẹ Ọyọ sọrọ, a si ṣe awari ẹ pe, gbogbo wọn n tiraka lati san ẹgbẹrun mẹta naira ti ijọba ana n gba lọwọ wọn. Lati asiko yii lọ, mo paṣẹ gẹgẹ bii gomina wipe ki wọn wọgile sisan iru owo bẹẹ."""
"O ni, ""lasiko ipolongo idibo, bi a ti n lọ lati jọba ibilẹ kan si ikeji, a tẹti gbọ ẹdun ọkan ti awọn eeyan ni."
Mo mọ pe ohun ti awọn eeyan ipinlẹ Ọyọ n beere fun ko pọ ju.
"A ba awọn olokoowo sọrọ lori awọn ipenija to niṣẹ pẹluu owo ori sisan."""
Afeez Agoro: O ṣòro fún mi láti wọ Danfo jáde
Nigeria Population: Báwọn ọmọ Nàíjíríà ṣe ń pọ̀ si jẹ́ ìpèníjà fún Buhari
Awọn agbẹ naa sọrọ lori awọn ipenija ti wọn n dojuko nitori aisi awọn ohun elo amayedẹrun, paapa ọna to ja gara lasiko ti wọn ba fẹ ko ere oko.
Lasiko to n sọrọ lori owo oṣu oṣiṣẹ to kere ju, Makinde ni lọwọlọwọ bayii, ipinlẹ Ọyọ ko lee san ẹgbẹrun lọna ọgbọn naira fawọn osisẹ.
Oríṣun àwòrán, Seyi Makinde
Sugbọn o salaye pe bi ohun gbogbo ba lọ botiyẹ, o ṣeeṣe ki owo osu oṣiṣẹ nipinlẹ Ọyọ jẹ eyi ti yoo pọ julọ loriẹede Naijiria.
Jiti Ogunye: Ìjọba àkóbá lológun gbé kalẹ̀ ni 1999
Gomina tuntun naa wa dupẹ lọwọ awọn lẹgbẹlẹgbẹ, loyeloye to fimọ awọn adari ẹgbẹ oṣẹlu to ṣe atilẹhin fun un lasiko ipolongo idibo.
O ṣe ileri wipe, oun yoo ṣiṣẹ gẹgẹ bii gomina to ni eero awọn ara ilu lọkan.
Oríṣun àwòrán, Seyi Makinde
Lara awọn eeyan pataki to peju-pesẹ sibi ayẹyẹ iburawọle naa ni adajọ agba nipinlẹ Ọyọ, Muktar Abimbola ati aṣoju alaga apapọ ẹgbẹ oṣelu PDP ni ẹkun guusu orilẹede yii.
Awọn yoku ni gomina tẹlẹri nipinlẹ Ekiti, Ayodele Fayoṣe, gomina tẹlẹri nipinlẹ Ọyọ Adebayọ Alao Akala, Olubadan ti ilẹ Ibadan Ọba Saliu Adetunji, Alaafin ti ilu Ọyọ, Ọba Lamidi Adeyẹmi ati bẹẹbẹẹ lọ.
Bode George: òòtọ́ ni ìkìlọ̀ Obasanjọ ati Soyinka
Nigeria swearing-in 2019: Wo àwòrán tó jẹ ojú ní gbèsè nípa ìbúra ààrẹ àtàwọn gómìnà
Gele mi ga ju tiẹ lọ lawọn obinrin fi ibura se ni Naijiria
E wo akojọpọ awọn iroyin to lamilaaka nipa ibura awọn gomina ati aarẹ:
Olu-ilu Naijiria, Abuja:
Igba ọtun wọle de, ọmọ Naijiria, Aarẹ Muhammadu Buhari lo sọ bẹẹ bo se n bẹrẹ saa keji pẹlu iburawọle
Oríṣun àwòrán, VON
Igbakeji aarẹ Yemi Osinbajo naa se ibura
Oye naa tun ko sile wa lẹẹkeji. Orin yii ni awọn eeyan n kọ bi Buhari se n kọja lọ
Bi a ko ba gbagbe ọrọ ana, a kii ri ẹnikan a ba ṣere.
Ipinlẹ Eko:
Gomina sanwo-olu ti ipinlẹ Eko ati ẹbi rẹ.
Awọn ara Eko pejọ si ibi iburawọle fun Gomina tuntun ati igbakeji rẹ.
Igbakeji gomina tuntun ni ipinlẹ Eko ati mọlẹbi rẹ.
Ọwọ ẹrọ ni ibura gomina mu dani ni Eko, Ojo wẹliwẹli rọ le gomina Sanwo-Olu lori
Sokoto penpe ọlọpaa, a fi bii igba ti Naijiria ko i tii gba ominira
Olori eto ẹsọ alaabo ni ipinlẹ Eko di ihamọ ogun wọ.
Onimọẹrọ Ṣeyi Makinde ati igbakeji rẹ, Rauf Olaniyan ti bura wọle gege bii gomina ati igbakeji gomina ipinlẹ Ọyọ
Gomina tuntun naa nipinlẹ Oyo ni oun ni imọ rere fun awọn ara ilu
Igbakeji gomina Oyo, Rauf Aderẹmi Ọlaniyan ree to n se ibura niduro pẹlu aya ati ọmọbinrin rẹ
Ẹgbẹ olorin ni ipinlẹ Ọyọ fi ijo ati ayẹ̀yẹ pada gomina tuntun ni ipinlẹ naa.
Awọn ara ipinlẹ Oyo naa tu yaya tu yaya si gbagede ibi ti wọn ti se iburawọle fun gomina tuntun naa.
Awọn ara ilorin naa ko gbẹyin ni ibi iburawọle naa
Igbakeji Gomina tuntun ati iyawo re ni ipinlẹ Kwara
Emir ti ilu Ilorin, Zulu Gambarie naa ko gbẹyin ni ibi iburawọle to waye.
Gomina ipinlẹ Kwara tuntun ati iyawo rẹ wọle.
Aṣọ ń pe aṣọ ránṣẹ́ ni lásìkò ìbúra gómìnà àti ààrẹ
Akojọpọ awọn aworan yii wa lati ile isẹ BBC ati Twitter
Obasanjo: Ilé ni bàbá wà, kò wọkọ̀ òfurufu kankan
Ko si ootọ kankan ninu iroyin kan to n ja rain-rain nilẹ pe, Aarẹ ana ni Naijiria, Oloye Olusegun Obasanjo, ni ori ko yọ ninu iṣẹlẹ ijamba ọkọ ofurufu kan.
Iroyin naa, ti ko sọ ibi ti Obasanjọ n rinrin ajo lọ ṣalaye wipe, inu ọkọ ofurufu Ethiopian Airlines ni ori ti ko Obasanjọ yọ.
Ṣugbọn ni kete ti akọroyin BBC Yoruba kan si agbẹnusọ rẹ, Ọgbẹni Kehinde Akinyemi, lo ṣalaye wipe, aarẹ ana naa wa ni ẹgbẹ oun gan nilu Abẹokuta, ti ko si rin irinajo kankan kuro ni Naijiria.
Lọna ati fi idi okodoro ọrọ yii mulẹ, Akinyẹmi tun yii ẹrọ ibaraẹnisọrọ naa soke, ki akọroyin BBC le gbọ ohun Obasanjọ, ti oun funra rẹ naa tun sọ pe, ko si oun to ṣe oun ati wipe oun ko lọ ibi kankan, tabi wọ ọkọ ofurufu kankan.
Akinyẹmi tun mu da BBC Yoruba loju pe, baba n gbalejo kan nile rẹ nilu Abẹokuta, lọwọlọwọ ni.
Olusegun Obasanjo: Ọmú ìyá mi ti mo fi ń mùkọ ni kekere ló jẹ ki ń lókun
Aarẹ ana naa ko lọ ibi iburawọle fun aarẹ Muhammadu Buhari to waye ni Ọjọru ni Abuja. Ọpọ eeyan lo ni o ṣeeṣe ki aarẹ ana naa rinrin ajo kuro ni Naijiria ṣugbọn, ọrọ agbẹnusọ rẹ fi han wipe, ile rẹ ni Abeokuta lo wa nigba ti iburawọle naa n lọ lọwọ ni Abuja.
Wo àwọn ìlérí tàwọn Gómìnà tuntun ṣe nínú ìbúra wọn
Oríṣun àwòrán, NIG/PRESIDENCY
Ọrọ mi koi tii ya - Buhari
Lọjọ kọkandinlọgbọn, oṣu karun un, ọdun 2019 ni wọn ṣe ibura fun aarẹ Buhari lẹekeji pẹlu awọn gomina tuntun.
Ni Gbagede Eagle Square ni wọn ti bura fun aarẹ Buhari ati Ọjọgbọn Yemi Oṣinbajo to jẹ igbakeji rẹ nibi ti arẹ Buhari ko ti ka ọrọ akọsọ rẹ fun igba akọkọ ninu itan Naijiria.
Buhari búra láti bọwọ fún ofin Naijiria ni saa keji rẹ.
Awọn gomina ti wọn bura fun ni awọn ipinlẹ wọn naa ṣe awọn ileri kan fawọn ara ilu ni eyi to maa mu ki ọsan so didun ti wọn ba muu ṣẹ.
BBC Yoruba ṣagbeyẹwo diẹ lara awọn ileri ti wọn ti n fọn rere ẹ koda ṣaaju eto ibura wọn
Gomina Abdulrazaq Abdulrahman ti ẹgbẹ́ oṣelu APC ti wọn bura fun lati tukọ ipinlẹ Kwara titi di 2023 ṣeleri lati ṣatunṣe si eto ọgbin atawọn ohun amayedẹrun.
Mo ṣetan lati mojuto ọrọ airiṣẹṣe awọn ọ̀dọ́ Kwara.
Oun lo le igba oṣelu PDP wọle ni Kwara pẹlu 'O tó gẹ'.
Bakan na lo tun ṣeleri lati tun awọn opopona ṣe ati mimojuto gbigbẹ odo Niger ki opin de ba omiyale ni Kwara paapaa lati ẹkun Patigi.
Ẹni bá láyà kó wá wọ̀ọ́! Ta ni Ìgè Àdùbí nílẹ̀ Oodua?
Mo kéde ìlú-kò-fararọ lori eto ẹkọ ipinlẹ Yobe! - Mala
Gomina Mala Buni to maa tukọ ipinlẹ Yobe di 2023 ni oun ti ṣetan lati kọ opọlọpọ ile iwe alakọbẹrẹ ati ti girama pupọ sii.
O ni oun mọ ọṣẹ́ buruku tawọn alakatakiti ẹsin Islam Boko Haram ti ṣe ni ẹkun yii to ti sọ eto ẹkọ wọn di nkan miran.
Oríṣun àwòrán, @Bego
Ijọba mi maa ṣeto ilana ti eto ẹkọ ipinlẹ Yobe a gunle lati isisinyi lọ
Maa tún àwọn Kọmiṣọnna tó ba ṣiṣẹ daadaa lò lẹẹkansii- Gomina Ebonyi
Gomina Dave Umahi ti ipinlẹ Ebonyi ṣeleri láti ṣe itọju awọn arugbo ni saa iṣejọba rẹ ikeji yii
Maa gbiyanju lati san owo ọya oṣiṣẹ bi o ti yẹ
Gomina Dave lo gboriyin fawọn to baa ṣiṣẹ sẹyin pe wọn gbiyanju.
O ṣeleri lati ri si itọju awọn obinrin, ati lati mojuto eto ilera awọn ewe sii.
Jiti Ogunye: Ìjọba àkóbá lológun gbé kalẹ̀ ni 1999
Ganduje: mo ṣetań lati pèsè ẹkọ ọ̀fẹ́ fawọn Akanda ẹ̀dá
Gomina ipinlẹ Kano to ṣe ibura lẹẹkeji, Abdullahi Umar Ganduje ni saa keji oun yii, awọn akanda ẹda a gbadun ẹkọ ọfe lati ile iwe alakọbẹrẹ titi de ti girama ni.
Oríṣun àwòrán, @Yakasai
Mo ṣetan lati tunra mu ninu iṣẹ ilu ti mo n ṣe ni Kano- Ganduje
Sanwo Olu- Ijọba mi ko ni yọ ẹnikẹni silẹ nipinlẹ Eko
Babajide Sanwo Olu to jawe olubori gẹgẹ bi gomina ipinlẹ Eko labẹ Asia ẹgbẹ oṣelu APC naa ṣe ọpọlọpọ ileri fawọn olugbe ipinlẹ Eko.
Maa ṣiṣe pẹlu Hamzat igbakeji mi lati mu gbogbo ileri wa lasiko ipolongo ṣẹ fun ẹyin eeyan ipinlẹ Eko
Sanwo Olu ki àwọn eniyan ipinlẹ Eko fun ifarada si bi igba ti ri lasiko yii.
O ni ki wọn fọkan balẹ nitori didun ni ọsan ipinlẹ Eko yoo so nitori itẹsiwaju Eko lo jẹ oun logun.
Sanwo Olu ni ijọba oun yoo jẹ eyi to n gbọ ọrọ awọn ara ilu to dibo yan oun.
Àgbà ni Obasanjo, oun tó ń sọ yé e, ìjọba ni kó tají - Wale oke
Mo wọgile gbogbo iṣẹ́ akanṣe tijọba to kọja lọ ti gbe sita tẹlẹ- Yahaya ipinlẹ Gombe
Gomina Inuwa Yahaya ti ẹgbẹ oṣelu APC lo wọle bayii ni ipinlẹ Gombe.
Oríṣun àwòrán, @yahaya
A maa fiya to tọ jẹ àwọn ti wọn ko nkan ìní ijọba jẹ
Gomina tuntun fun ipinlẹ Gombe ni oun ko ni tẹlẹ awọn awuyewuye to ti n waye lati oṣu kẹta ni Gombe rara.
O ni ipade apero tẹẹkoto ti gomina PDP tẹlẹ n ṣe ni Gombe ti dopin bayii nitori pe omi tuntun ti ru, ẹja tuntun ti wọ inu iṣejọba ipinlẹ Gombe bayii.
Ẹ darijin mi, Maa gbe igbesẹ to yẹ bayii- El Rufai
Gomina ipinlẹ Kaduna, Mallam Nasir El Rufai to ṣe ibura lẹẹkeji lati tun tukọ ipinlẹ Kaduna ti tọrọ aforijin lọwọ awọn eniyan Kaduna.
Oríṣun àwòrán, @Elrufai
Ijọba mi ko ni gbe igbesẹ ipanilara ni saa keji yii
Nasir El Rufai ni oun n bẹbẹ silẹ nitori pe ijọba oun ti ṣetan lati gbe awọn igbesẹ akin to yẹ ni saa yii.
O ni oun n riran ọjọ iwaju rere to kun fun owó ati iṣẹ lọpọ yanturu fawọn eniyan ipinlẹ Kaduna ni saa iṣejọba keji oun yii.
'Kaduna ni àjọ NYSC pín mi sí sùgbọ́n...'
Dapọ Abiọdun: Mo kọ̀ láti ko ẹ̀bi mi nikan si ijọba mi
Gomina tuntun ti wọn bura fun lati tukọ ipinlẹ Ogun di 2023 ni ko nii si adanikan jẹ ninu iṣejọba oun nipinlẹ Ogun rara.
Maa nu gbogbo omije atẹyinwa nù loju àwọn eniyan ipinlẹ Ogun ni -Dapo
Dapo Abiọdun ni oun bura lati fi ootọ inu ṣiṣẹ si alaafia ati idagbasoke awọn eniyan ipinlẹ Ogun lapapọ ni.
O ni oun ko ni da ẹnikẹni ninu adehun ati awọn ileri ti oun ti ṣe ṣaaju idibo.
Ni papa iṣere MKO Abiola to wa ni Kutọ, nilu Abẹokuta ni Dapo ti ṣeleri lati ṣe atunṣe si igbe aye awọn oṣiṣẹ ijọba ipinlẹ Ogun.
'Gbogbo olùdíje Ogun fi dá àwọn ènìyàn lójú pé...'
Alaafia eniyan Enugu lo jẹ mi logun -Ugwuanyi
Oríṣun àwòrán, @ugwuanyi
Mo kọ láti gba ẹmi imọ-tara-ẹni-nikan-laaye ni Enugu
Gomina Ifeanyi Ugwuanyi lo jawe olubori labẹ ẹgbẹ oṣelu PDP nipinlẹ Enugu ninu idibo ọjọ kẹsan an, oṣu kẹta, ọdun yii.
O ni oun yoo gbajumọ eto aabo awọn eniyan oun ni saa keji ti o ṣẹṣẹ ṣe ibura rẹ yii.
Bode George: òòtọ́ ni ìkìlọ̀ Obasanjọ ati Soyinka
Mo wọgile #3,000 tawọn akẹkọọ ipinlẹ Oyo n san - Makinde
Seyi Makinde to jawe olubori labẹ ẹgbẹ oṣelu PDP ni yoo tukọ ipinlẹ Oyo titi di ọdun 2023.
Eto ẹkọ ọfẹ ti bẹre nipinlẹ Oyo bayii
Ìjọba Naijiria ti ṣe ìlérí lóríṣíiríṣi látẹnu àwọn Gomina tuntun ti wọ́n ṣe ìbúra ni àná ni èyí tó lè mú ọsàn so dídùn fáwọn ara ilu.
Afeez Agoro: O ṣòro fún mi láti wọ Danfo jáde
Africa Free Trade Zone: Kò sí ìdènà láti kó ọjà láti orílẹ̀èdè kan sí òmíràn
Agbekalẹ adehun yii ni wọn gba pé o maa jẹ ki ọja tita tubọ rọrun fawọn olokowo keekeeke
Naijiria jẹ orilẹ-ede ti eto ọrọ aje ẹ tobi julọ nilẹ Adulawọ.
Adehun yii laarin awọn olori ilẹ Afrika ni wọn gba pé yoo mu ọja tita rọrun sii fawọn olokowo keekeeke nigba ti wọn ko ba san owo ori ọja ni awọn ẹkun ti ọrọ kan.
Wọn tun gba pe adehun yii yoo jẹ ki ibaṣepọ awọn olokowo lati orilẹ-ede ilẹ̀ Adulawọ dan mọran sii.
Ni oru Ọjọru, ọjọ Kọkandinlọgbọn, osu Karun un, ọdun 2019 mọjumọ ọjọ keji rẹ, tii se Ọjọbọ, ni agbekalẹ ibudo okoowo ọfẹ fun ilẹ Afirika, ti ko ni owo ori ninu gberasọ, eyi to jẹ eto okoowo to tii tobi julọ lati igba ti wọn ti bẹrẹ ajọ eleto okoowo lagbaye (World Trade Organisation).
Àdéhùn ètò ọrọ̀ ajé ilẹ̀ Afirika le lẹ́yìn
Sugbọn bi ọpọ anfaani se sodo sinu eto okoowo ọfẹ laarin awọn orilẹ-ede nilẹ Afirika yii, orilẹ-ede Naijiria ati Cameroon ko si lara awọn orilẹ-ede mẹtalelogun ti wọn ti buwọ luu.
Aarẹ Buhari ṣalaye fun Cyril Ramaphosa ti ilẹ South Africa pé oun ko ni pé tọwọbọ iwe adehun naa.
O ni oun kan fẹ ṣe iwadii sii lori abajade iru igbesẹ bẹẹ ni.
Òru òní, ọjọ́rú ni àdéhùn níní ibùdó olókoòwò ọ̀fẹ́ nílẹ̀ Adúláwọ̀ bẹ̀rẹ̀ ni èyí tí Aarẹ Buhari ti Naijiria kòì tíì fọwọ́síi.
Oríṣun àwòrán, @vera
Àwọn obinrin yoo ri anfaani to pọ jẹ - Vera Songwe
Akọṣẹmọṣẹ Vera Songwe to jẹ akọwe ajọ iṣokan agbaye UN lori eto ọrọ aje nilẹ Afrika sọrọ kikun lori anfaani fawọn oloko owo obinrin.
O ni ti awọn orilẹ-ede mẹrinlelaadọta ilẹ Adulawọ ba fọwọ si adehun yii, yoo rọrun fawọn olokowo paapaa obinrin lati rin laifoya lati orilẹ-ede kan si ikeji.
Barister lo bi gbogbo oníṣẹ́ fújì -Oṣupa
Vera Songwe gba pé olori isọro okowo nilẹ Adulawọ ni eto irinna.
O ni ọkan awọn obinrin yoo balẹ sii nidi okowo wọn lati ẹkun kan si ikeji ni eyi ti yoo mu ibugbooro ba okowo wọn sii.
Afeez Agoro: O ṣòro fún mi láti wọ Danfo jáde
Vera ni eto aabo ati igbọraẹni ye yoo wa laarin wọn sii nidii ọja wọn nigba ti owo ibode, owo ori ọja ati owo ori ọlọja ba ti kuro nibẹ.
Ẹni bá láyà kó wá wọ̀ọ́! Ta ni Ìgè Àdùbí nílẹ̀ Oodua?
Organisation of Islamic Cooperation: Àǹfààní wo ló wà nínú ẹgbẹ́ OIC?
Oríṣun àwòrán, Getty Images
OIC n ṣepade
Wọn da ẹgbẹ Organisation of Islamic Cooperation ti ọpọ mọ si OIC silẹ lọdun 1969 pẹlu orilẹede mẹtadinlọgọta.
Ọrilẹede mẹtalelaadọta ninu awọn orilẹede to jẹ ọmọ ẹgbẹ OIC lo jẹ awọn orilẹede ti awọn ẹlẹsin musulumi ti pọ ju.
Ẹgbẹ OIC ni aṣoju ni ajọ iṣọkan agbaye ati ajọ ilẹ alawọfunfun ti wọn n pe ni European Union.
Nigeria Population: Báwọn ọmọ Nàíjíríà ṣe ń pọ̀ si jẹ́ ìpèníjà fún Buhari
Kinni erongba OIC?
Gẹgẹ bi adehun ti wọn ṣe, ẹgbẹ OIC pinnu lati maa gbe ohun to jẹ mọ ẹsin musulumi larugẹ lawọn orilẹede to jẹ ọmọ ẹgbẹ naa.
Ẹgbẹ OIC tun pinnu pe awọn yoo ṣe imugbooro aṣa ati imọ sayẹnsi lawọn orilẹede to jẹ ọmọ ọhun.
OIC tun pinnu lati mu eto aabo lọkun-kundun ati lati lepa alaafia kaakiri gbogbo orilẹede ti ẹgbẹ naa wa.
OIC tun pinnu lati maa ṣe igbelarugẹ eto ẹkọ imọ-ijinlẹ ni gbogbo orilẹede to jẹ ọmọ ẹgbẹ naa.
Akitiyan OIC lori awọn to ṣatipo
Ẹgbẹ OIC ti gbalejo awọn atipo bi miliọnu mejidinlogun lati igba ti ẹgbẹ ọhun ti wa titi di ọdun 2010
Awọn orilẹede to jọ ọmọ ẹgbẹ OIC ti n gbalejo awọn atipo lati awọn orilẹede ti rukerudo ti n ṣẹlẹ lati ọdun 2010
Oríṣun àwòrán, Wilkipedia
Kinni o mọ nipa OIC?
Lọdun 2011 ni ẹgbẹ OIC yi orukọ rẹ pada Organisation of Islamic Conferencde ssi Organisation of Islamic Cooperation.
Buhari mórí lé Saudi lẹ́yìn ìbúrawọlé fún sáà kejì
Lẹyin iburawọle fun saa keji l'Ọjọru, Aarẹ Muhammadu Buhari mo ri le orilẹ-ede Saudi Arabia lonii Ọjọbọ.
Oríṣun àwòrán, Facebook/Femi Adesina
Aarẹ Muhammadu Buhari n lọ fun ipade OIC
Aarẹ n lọ fun apero ẹgbẹ Organisation of Islamic Cooperation ti ọpọ mọ si OIC ti yoo waye lọjọ Ẹti niluu Makkah.
Ọjọ keji, oṣu kẹfa ni Aarẹ Buhari yoo pada si orilẹ-ede Naijiria.
Nigeria Population: Báwọn ọmọ Nàíjíríà ṣe ń pọ̀ si jẹ́ ìpèníjà fún Buhari
Ninu atẹjade ti oludamọran agba fun aarẹ lori ọrọ iroyin, Garba Shehu sita, Aarẹ Buhari yoo sọrọ nibi apero ọhun.
Atẹjade naa sọ pe aarẹ yoo sọrọ lori iṣepataki ki awọn orilẹ-ede to jẹ ọmọ ẹgbẹ OIC wa ni iṣọkan lati le jọ koju ipenija bi awọn agbesumọmi ti wọn n da rogbodiyan kalẹ kaakiri.
Aarẹ Buhari yoo tun sọrọ lori anfaani to wa nibi idokowo awọn orilẹ-ede ilẹ okere ni Naijiria.
Àgbà ni Obasanjo, oun tó ń sọ yé e, ìjọba ni kó tají - Wale oke
Buhari ni aarẹ orilẹ-ede Naijiria kẹta ti yoo lọ fun apero ẹgbẹ OIC lẹyin oloogbe aarẹ tẹlẹ ri, Umaru Yar'Adua ati aarẹ ana, Goodluck Jonathan ti kọkọ lọ fun irun apero bẹẹ.
Gomina ipinlẹ Jigawa, Mohammed Badaru Abubakar, Gomina Oṣun, Gboyega Oyetola ati Gomina ipinlẹ Niger, Abubakar Sani Bello wa lara awọn ti yoo kọwọ rin pẹlu aarẹ lọ ilẹ Saudi.
Ẹni bá láyà kó wá wọ̀ọ́! Ta ni Ìgè Àdùbí nílẹ̀ Oodua?
Nigeria Swearing in 2019:Olókoòwò tó dáńtọ́ ni gómìnà Ogun tuntun
Ori lo mọ ọlọrọ, ori lo mọ ọba.
Ori lo mọ ọlọrọ, ori lo mọ ọba.
Ori ẹni si lo n gbe ni, ti a fi de ade owo, ori ẹni naa lo n gbe ni, ti a fi tẹ ọpa ilẹkẹ, ori yii naa si lo gb'Ọmọọba Dapọ Abiọdun, to fi di gomina tuntun ni ipinlẹ Ogun.
Ọjọ Kọkandinlọgbọn, osu Karun un, ọdun 1960, ni idile Ọba kan nilu Ipẹru Rẹmọ gba alejo ọmọ tuntun jojolo, eyi to tọ Dokita Emmanuel Abiodun ati aya rẹ, Victoria wa, eyi ti wọn pe orukọ rẹ ni Adedapọ Abiọdun.
Ohun to si tun yani lẹnu julọ ni pe, nigba to ku ọdun kan pere ki Dapọ yii pe ẹni ọgọta ọdun, ni ori gbe e de ipo gomina, to si bura wọle ni ọjọ yii kan naa.
Sugbọn niwọn igba to jẹ pe ọjọ ti eeyan ba gun kọ lo n kan ọrun, ojo ti n pa igun Dapọ bọ nidi ko lee jẹ eeyan laye, ọjọ ti pẹ.
O ti ko ipa ribiribi ni agbọn kan abi omiran, ko to de ipo gomina.
Ori lo mọ ọlọrọ, ori lo mọ ọba.
Dapọ Abiọdun lọ sile ẹkọ alakọbẹrẹ ati girama, ko to morile ileẹkọ fasiti Ọbafẹmi Awolọwọ nilu Ile Ifẹ, nibi to ti kẹkọ gboye imọ nipa iṣẹ ẹrọ.
Lẹyin eyi lo tẹkọ ofurufu leti lọ sile ẹkọ fasiti Kennsaw ni Atlanta Georgia, lorilẹ-ede Amẹrika.
Nibẹ lo tun ti gba imọ kun imọ nipa iṣiro owo, to si ni iwe ẹri imọ ijinlẹ keji, taa mọ si Masters.
Ni kete ti Dapọ pada sile lati oke okun, lo tun morile ile ẹkọ fasiti ipinlẹ Ekiti lati gba oye ọmọwe, ti a mọ si PhD ninu imọ nipa ìnáwò, to si tun gba oye ọmọwe keji lẹka imọ nipa akoso okoowo nile ẹkọ fasiti Adeleke to wa nilu Ẹdẹ, nipinlẹ Ọṣun.
IRIRI DAPỌ LẸNU IṢẸ:
Lẹyin ti Dapọ pari iwe lo di gbajugbajaolokoowo ati oloselu. Oun si ni oludasilẹ ileeṣẹ kan to wa fun ipese ohun amuṣagbara.
Bakan naa ni Dapọ jẹ odu, ti kii ṣe aimọ fun oloko ni ẹka katakara awọn eroja epo rọbi ati afẹfẹ idana gaasi, to si ni ileeṣẹ aladani tiẹ fun eroja epo rọbi.
Ori lo mọ ọlọrọ, ori lo mọ ọba.
Lọdun 1998, ẹrin pa ẹẹkẹ Dapọ, ti wọn si dibo yan-an gẹgẹ bii aṣofin agba sile aṣofin ni Abuja, lati lọ ṣoju ẹkun idibo rẹ, labẹ ẹgbẹ oṣelu UNCP.
Oniruuru igbimọ si ni Dapọ ti ṣiṣẹ lasiko to wa ni aṣofin agba naa.
Dapọ Abiọdun tun tirakalọdun 2015, to si tun pada dije sile aṣofin agba fun saa keji ni ẹkun ila oorun Ogun labẹ ẹgbẹ oṣelu APC, amọ to fidi rẹmi.
Ẹni bá láyà kó wá wọ̀ọ́! Ta ni Ìgè Àdùbí nílẹ̀ Oodua?
Ṣugbọn ori gbe Dapọ de ibi giga, eyi to ju ipo kọja ero rẹ, nigba to dije wọle bii gomina lọdun 2019, to si jawe olubori gẹgẹ bii gomina tuntun fun ipinlẹ Ogun labẹ asia ẹgbẹ oṣelu APC.
Ọmọlẹyin Kristi to dantọ ni Dapọ Abiọdun n ṣe, to si gbagbọ pe Ọlọrun lo gbe oun de ipo gomina, laifi ti ọpọ atako to dide si oun ṣe.
Adeleke: APC ní ìdájọ́ ileẹjọ́ kòtẹ́milọ́rùn kò fún Adeleke ní ìrètí kankan
Oríṣun àwòrán, Ademola Adeleke
Lẹyin ti ileẹjọ kotẹmilọrun wọgile idajọ to ni Adeleke ko yẹ lati du ipo gomina, eyi tí Wahab Raheem and Adam Habeeb gbe wa siwaju rẹ, ẹgbẹ oṣelu APC ti fesi wipe, idajọ naa ko tumọ si wipe, Adeleke yoo di gomina.
Akọwe ẹgbẹ naa ni Ipinlẹ Osun, Kunle Oyatomi sọ fun BBC Yoruba wipe, igbẹjọ naa ko yẹ ireti ẹgbẹ APC wipe, Adeleke ko le de ipo gomina ipinlẹ naa lailai.
"Oyatomi ni, ""Ṣebi ki i kuku ṣe ẹgbẹ wa APC lo gbe ẹjọ yii lọ iwaju ile ẹjọ giga Abuja, eyi to ni Adeleke ko ni ẹtọ lati dije fun ipo gomina ni ibẹrẹ pẹpẹ. Ọmọ ẹgbẹ oṣelu PDP ni awọn olupẹjọ mejeeji naa."""
Ti ẹ ba ranti, ile ẹjọ giga ilu Abuja da ẹjọ lọjọ keji osu kẹrin ọdun 2019 pe, oludije fun ipo gomina ni ipinlẹ Ọsun fun ẹgbẹ oselu PODP, Sẹnetọ Ademọla Adeleke ko lẹtọ lati du ipo gomina nitori ko ni iwe ẹri iwe mẹwa.
Ṣugbọn nigba ti ile ẹjọ kotẹmilọrun do doju ẹjọ naa bolẹ  gbe idajọ rẹ kalẹ, igbimọ ẹlẹni mẹta naa lo panupọ kede pe ile ẹjọ giga naa ko yẹ lati dajọ pe Adeleke ko pari ile ẹkọ girama, ati pe, irọ lo pa lori iwe ẹri to ni oun ni.
Ẹni bá láyà kó wá wọ̀ọ́! Ta ni Ìgè Àdùbí nílẹ̀ Oodua?
Adajọ to lewaju igbimọ ẹlẹnu mẹta naa, Emmanuel Agim, tọkasi kudiẹ-kudiẹ to wa ninu idajọ akọkọ naa, paapa lori bi ileẹjọ giga ọhun se gba pe oun ni aṣẹ lati gbọ ẹjọ naa, lẹyin ọjọ mẹrinla ti ofin la kalẹ lati pe ẹjọ saaju idibo.
Adajọ Agim ni awọn olupẹjọ ko tẹle ohun ti ofin ilẹ wa naa la kalẹ nidi pipe ẹjọ, ti adajọ to gbọ ẹjọ naa nile ẹjọ giga pẹlu tun kuna lati gbe idajọ rẹ kalẹ laarin ọgọrin ọjọ
Adajọ naa wa kede pe kawọn olupẹjọ lọ san milliọnu mẹta naira fun Adeleke fun bi wọn ṣe da a laamu.
Naira Marley gba àṣẹ onídúró nílé ẹjọ́ pẹ̀lú mílíọ́nù méjì náírà
Oríṣun àwòrán, Efcc
Àjọ EFCC fi panpẹ́ òfin gbé Naira Marley láìpẹ́ yìí fún ẹ̀sùn lílu jìbìtì lórí ayélujára
Ile ẹjọ giga apapọ kan to fikalẹ si Ikoyi nilu Eko ti da akọrin taka-sufe ni Naira Marley ti wọn fi ẹsun jibiti ori ayelujara kan laipẹ yii silẹ.
Nibi igbẹjọ to waye ni ọjọbọ, onidajọ Nicholas Oweibo to gbọ ẹjọ ati gba oniduro rẹ gba ki wọn gba oniduro akọrin naa pẹlu milliọnu meji naira ati oniduroi meji.
Onidajọ Oweibo gbe idajs yii kalẹ lẹyin to gbọ awijare awọn agbẹjọro rẹ ati ti ajọ EFCC to n pe e lẹjọ.
Barister lo bi gbogbo oníṣẹ́ fújì -Oṣupa
Bi o tilẹ jẹ pe agbẹjọro fun ajọ EFCC, Rotimi Oyedepo rọ ile ẹjọ lati gbọ ẹjọ ti wọn fi kan an ni wara-n-ṣeṣa, agbẹjọro fun Naira Marley ni akọrin naa lẹtọ si beeli labẹ abala ofin orilẹede Naijiria.
'Bí ìrẹsì tèmi Ayinde bá ń pàkùta, kò tọ́ sẹ́nu aláàrù Barrymaade'
Onidajọ Oweibo wa sun igbẹjọ si ọjọ kejilelogun, ọjọ kẹtalelogun ati kẹrinlelogun, oṣu kẹwaa, ọdun 2019.
Ẹni bá láyà kó wá wọ̀ọ́! Ta ni Ìgè Àdùbí nílẹ̀ Oodua?
Agbẹjọro fun olupẹjọ ni niwọn igba ti agbẹjọro rẹ ti fi idi rẹ mulẹ pe ilumọọka ni Naira Marley, iwa ati iṣe rẹ yoo jẹ awokọṣe fun ọpọ awọn ọdọ lorilẹ-ede Naijiria eyii to lee ni ipa ti ko kere laarin wọn.
Rochas Okorocha: Fayose rọ Rochas Okorocha, Ibikunle Amosun láti jọ̀wọ́ ara wọn fún EFCC
Oríṣun àwòrán, Twitter/Rochas Okorocha/Ayo Fayose
Fáyòṣe ní kò yẹ kí ọ̀rọ̀ EFCC ó ya Rochas Okorocha lẹ́nu
Gomina ipinlẹ Ekiti nigba kan ri, Ayọdele Fayoṣe ti ke si gomina to ṣẹṣẹ fi ipo silẹ ni ipinlẹ Imo, Rochas Okorocha pe, ko tete jọwọ ara rẹ silẹ fawọn oṣiṣẹ ajọ EFCC, to ba jẹ pe lootọ ni wọn wa lati muu.
Fayoṣe sọrọ yii ni Ọjọbọ lẹyin ti iroyin bọ sita pe Rochas Okorocha pẹlu iyawo rẹ ti wọ gbaga ajọ EFCC, bi o tilẹ jẹ pe, ajọ naa ti kede sita pe ko si ohun to jọọ, oun ko mu Okorocha.
Fayose fi sita loju opo twitter rẹ pe, oun ki Rochas Okorocha kaabọ si ẹgbẹ awọn gomina ti EFCC n wa kiri. O ni o yẹ ki Rochas o mọ pe irufẹ ọjọ bayii yoo waye lai jẹ pe ẹnikẹni wi fun un.
Amọṣa, mo ki i kaabọ si ẹgbẹ awọn ti EFCC n wa, mo si tun rọ ajọ naa lati maṣe gbagbe Amosun naa.
Bi ẹ ko ba gbagbe, gomina Ayọ Fayoṣe naa n jẹjọ niwaju ile ẹjọ lori awọn ẹsun ti ajọ EFCC fi kan an.
Ni kete to pari saa iṣejọba rẹ lo ti lọ jọwọ ara rẹ fun ajọ naa ni ọdun 2018.
Ọkùnrin kan bẹ́ orí ẹ̀gbọ́n rẹ̀ ní Cross River, ni ará ìlú bá sin ín láàyè
Oríṣun àwòrán, Saharareporters
Arákunrin náà ti ara rẹ̀ mọ inu ilé, ó sì ń kìlọ̀ pé ẹnikẹ́ni tó bá sún mọ́ òun, yóò fara gbọgbẹ́ bí i ti ẹ̀gbọ́n òun.
Arákunrin náà ti ara rẹ̀ mọ inu ilé, ó sì ń kìlọ̀ pé ẹnikẹ́ni tó bá sún mọ́ òun, yóò fara gbọgbẹ́ bí i ti ẹ̀gbọ́n òun.
Iroyin ni arakunrin kan ti orukọ rẹ n jẹ Ojemba fi ibinnu bẹ ori ẹgbọn rẹ ni abule Liokom to wa Ijọba Ibilẹ Yala ni Ipinlẹ Cross River.
Awọn ara abule naa ti da a lẹjọ oro, wọn si sin in láàyè pẹlu oku ẹgbọn rẹ naa.
Awọn ara abule naa ni awọn gbe igbesẹ naa nitori pe eewọ ni iku ti Ojemba fi pa ẹgbọn rẹ, Obok.
Kọmiṣọna ọlọpaa ni ipinlẹ naa, Austine Agbonlahor ni oun ko ti i gbọ nipa iṣẹlẹ naa.
Makinde: Ẹgbẹ́ òṣìṣẹ́ faramọ́ wíwọ́gilé ₦3000 táwọn akẹ́kọ̀ọ́ girama ń san
Ṣugbọn ki lo faa ti Ojemba fi bẹ ori ẹgbọn rẹ?
Iroyin ọsẹ diẹ ṣẹyin ni iya awọn ọkunrin mejeeji ku. Iroyin ni awọn mejeeji ko ja rara ṣaaju iṣẹlẹ naa.
Ara adugbo ti ọrọ naa ṣoju rẹ ni ṣe ni Obok pada de lati ode ti iyawo rẹ si gbe ounjẹ siwaju rẹ.
Obok n jẹun lọwọ ni a gbọ pe Ọjemba ba fi ada ge ori ẹgbọn rẹ bọ silẹ.
Okùnrin SARS náà sọ pé òun máa pa èèyàn síbi ni- Aladugbo
Awọn ara adugbo ni ariwo iyawo oloogbe naa ni awọn gbọ ti wọn si sa lọ ibi iṣẹlẹ naa nibi ti wọn ti ba Obok ninu agbara ẹjẹ.
Barister lo bi gbogbo oníṣẹ́ fújì -Oṣupa
Igba ti wọn gbiyanju lati mu Ojemba, ṣe ni arakunrin naa ti ara rẹ mọ inu ile ti o si n kilọ pe ẹnikẹni to ba sun mọ oun, yoo fara gbọgbẹ́ bí i ti ẹgbọn oun.
Ṣugbọn awọn ọdọ mẹta ni abule naa ja lẹkun wọle, wọn si ra afẹsunkan naa mu, ki wọn to de e lọwọ ati ẹsẹ.
Ṣe ni wọn gbe e sinu iho ti wọn ti gbẹ́ fun oku ẹgbọn rẹ. Wọn sọ ọ sinu iho naa, ki wọn to gbe oku ẹgbọn rẹ lu u laya, ti wọn si fi yẹpẹ bo o mọlẹ laaye.
N11trn subsidy: Ǹjẹ́ ẹ mọ̀ pé owó ìrànwọ́ epo lè kọ Second Niger Bridge méjìléláàdọ́ta?
Oríṣun àwòrán, Pulse
Kíni N11trn owó ìrànwọ́ epo tí ìjọba àpapọ̀ san fún àwọn agbépo lè rà?
Lọdun 2012, ọpọlọpọ ọmọ Naijiria jade lati fi ẹhonu han lori ipinnu ijọba aarẹ Goodluck Jonathan nigba naa lati yọ owo iranwọ epo (subsidy).
Ṣugbọn ni Ọjọbọ, Ile Igbimọ Aṣofin Agba Naijiria fi to ọmọ Naijiria lẹti pe ijọba apapọ na triliọnu mọkanla naira gẹgẹ bii owo iranwọ epo rọbi (subsidy) ni ọdun mẹfa.
Ṣugbọn ki ti ẹ ni iye owo yii tumọ si? Ki ni owo yi le da ṣe ni orilẹ-ede Naijiria?
Àwọn aworan yii ṣe alaye bi owo yii ṣe to:
1. Triliọnu mọkanla yoo kọ aadọta afara keji Niger (Second Niger Bridge).
Nigba ti ijọba apapọ bẹrẹ iṣe lori afara Niger keji (Second Niger Bridge) wọn sọ pe iṣẹ akanṣe naa yoo gba igba ati ogun biliọnu.
Oríṣun àwòrán, Ministry of Works
Ta a ba pin triliọnu lọna mọkanla owo iranwọ epo yii si iye owo ti wọn fẹ fi kọ afara yii, yoo kọ to aadọta iru afara naa.
Ki i tun ṣe eyi nikan, àwọn ijọba China ni afara ori omi to gun ju ni agbaye to wa ni orilẹ-ede China kò ná wọn ju triliọnu meje o le diẹ lọ.
Nigeria Population: Báwọn ọmọ Nàíjíríà ṣe ń pọ̀ si jẹ́ ìpèníjà fún Buhari
Odun 2018 ni wọn pari afara naa ti yoo maa gbe awọn arinrinajo lati Hong Kong lọ Zhuhai. Kilomita marunlelaadọta ni afara naa.
Kilomita marunlelaadọta ni afara naa
2. Owo iranwọ epo naa le kọ ibudo papakọ ofurufu to din diẹ niẹgbẹrin
Ijọba apapọ fi to awọn oniroyin leti laipẹ yii pe wọn ti pinnu lati wo ibudo (terminal) papakọ ofurufu Murtala Muhammad to wa ni Ipinlẹ Eko.
Ijọba ni biliọnu mẹrinla ni iṣẹ naa yoo gba.
Ti ijọba ba ni ki wọn fi owo iranwọ epo rọbi kọ iru ibudo papakọ ofurufu yii, yoo fẹ kọ to ẹgbẹrin iru rẹ.
3. Yoo kọ mejidinlogoji ile iwosan igbalode iru eyi to wà ni Texas yii
Ile iwosan yii ni Ile Iwosan Southwestern to wa ni fasiti Texas ni orilẹ-ede Amerika.
Ile iwosan naa wa lara eyi to dara ju ni agbaye nitori awọn irinṣẹ igbalode to wa nibẹ.
Oríṣun àwòrán, University of Texas Southwestern hospital
O din diẹ ni ọọdurun biliọnu naira ti wọn fi pari ile iwosan naa.
Iye owo iranwọ epo yii yoo kọ iru ile iwosan yii mejidinlogoji.
Ondo: Dejí sun ọmọ méje àtagbalagba meji mọ́lé nítorí pé ó ń bínú
Iye ile iwe meloo ni ẹ ro pe triliọnu mọkanla yii le kọ lagbegbe ti yin?
Àgbà ni Obasanjo, oun tó ń sọ yé e, ìjọba ni kó tají - Wale oke
Ọpọ awọn ọmọ Naijiria lo n kọminu lori bi ijọba ṣe n san iru owo bayii lai nii fi ṣe awọn ibo miran ti wọn gab pe o le ṣe anfaani ti wọn ba naa sibẹ.
Afeez Agoro: O ṣòro fún mi láti wọ Danfo jáde
JAMB: Ẹ̀ṣùn oníkókó mẹ́jọ ni EFCC fi kan Philomina àtàwọn 5 míràn
Ajọ EFCC lo gbe arabinrin Philomina atawọn to ku lọ sile ẹjọ lori sise owo ajọ to n sedanwo JAMB kumọ-kumọ.
Arabinrin Philomina Chieshe ni wọn fẹsun kan pe, o na owo ajọ to n mojuto ṣiṣe idanwo igbaniwọle sile iwe giga ni Naijiria, JAMB.
Miliọnu lọna mẹrindinlogoji ni wọn ni pé o gbe nigba naa ti wọn si ni o sọ pé ejo lo gbe owo naa mi.
Iyalẹnu lo jẹ fawọn eeyan nigba ti obinrin yii gbọrọ naa kalẹ niluu Makurdi, nipinlẹ Benue lọdun 2018.
Ile ẹjọ giga l'Abuja ni wọn gbe obinrin naa lọ pẹlu awọn meji miiran, ti wọn si fi ẹsun onikoko mẹjọ kan wọn.
Ṣugbọn Philomina atawọn meji yoku lawọn o jẹbi ẹsun ti kan wọn.
Ondo: Dejí sun ọmọ méje àtagbalagba meji mọ́lé nítorí pé ó ń bínú
Agbẹjọro wọn rọ ileẹjọ lati pe ki adajọ fun wọn ni beeli nibi igbẹjọ ọhun.
Ṣugbọn adajọ Peter Afen sun igbẹjọ naa siwaju di ọjọ kẹta, oṣu kẹfa, bakan naa lo paṣẹ pe ki wọn si wa ni kolo ajọ EFCC titi di ọjọ naa.
NURTW Oyo: Ìwà ìdàlùrù ní Ibadan ló mú kí Makinde gbẹ́sẹ̀ lé NURTW
Oríṣun àwòrán, @Oyoaffairs
Ẹgbẹ awakọ ero NURTW nipinlẹ Ọyọ tijọba fofin de, ti fesi lori bi ijọba ipinlẹ Ọyọ se fi ofin de ẹgbẹ naa lọjọ keji ti gomina Seyi makinde gba ọpa asẹ, to si ni pe eegun rẹ ko gbọdọ sẹ mọ jakejado ipinlẹ naa.
Nigba to n ba BBC Yoruba sọrọ, alaga ẹgbẹ ọlọkọ ero nipinlẹ Ọyọ, Waheed Adeọyọ, ti gbogbo eeyan mọ si Ejiogbe, ẹni ti akọwe ẹgbẹ, Sunday Yeye gbẹnu rẹ sọrọ, salaye pe laipẹ ni awọn yoo pe ipade gbogbo ọmọ ẹgbẹ awakọ ero nipinlẹ Ọyọ, lati fi asẹ ijọba naa to wọn leti
Ejiogbe wa rọ awọn awakọ ero nipinlẹ Ọyọ lati mase fa wahala kankan nitori asẹ ijọba yii, amọ ki wọn maa ba isẹ oojọ wọn lọ nitori asẹ ijọba naa ko di awọn lọwọ lati sisẹ oojọ awọn, sugbọn awọn ọmọ igbimọ alasẹ ẹgbẹ ni asẹ yii ba wi.
Oríṣun àwòrán, Adedayo Owolabi
"Bakan naa lo fikun pe, ""igbimọ̀ alasẹ́ ẹ́gbẹawakọ ero nipinlẹ Ọyọ ti fi isẹlẹ yii to olu ile ẹgbẹ NURTW ni Abuja leti, bi o tilẹ jẹ pe wọn wa nilu Mecca lọwọ-lọwọ fun eto Umura."""
"Ni kete ti awọn alasẹ ẹgbẹ ni Abuja ba si ti de si orilẹede yii ni wọn yoo wa kan si gomina Makinde lati yanju ọrọ yii ni itubi n nubi.
Oríṣun àwòrán, @Oyoaffairs
Bẹẹ ba gbagbe, owurọ ọjọ Ẹti ni ijọba ipinlẹ Ọyọ kede pe oun ti fofin de ẹgbẹ awakọ ero nipinlẹ Ọyọ, NURTW, to si pasẹ pe eegun wọn ko tun gbọdọ sẹ mọ.
Lasiko to n bawọn akọroyin sọrọ, olori osisẹ lọọfisi gomina, oloye Bisi Ilaka salaye pe iwa idaluru ti awọn ẹgbẹ ọlọkọ ero yii n hu lawọn agbegbe kan nilu Ibadan lo fa sababi igbesẹ ijọba naa.
Bakan naa lo fikun un pe, ikankan ninu awọn ọmọ igbimọ alasẹ ẹgbẹ ọlọkọ ero naa ko gbọdọ safihan ara wọn mọ laarin igboro jakejado ipinlẹ Ọyọ.
Ilaka wa rawọ ẹbẹ sawọn araalu lati maa ba isẹ oojọ wọn lọ pẹlu alaafia laisi ifoya kankan, pẹlu afikun pe ijọba ipinlẹ Ọyọ ti gba akoso awọn ibudokọ gbogbo yika ipinlẹ Ọyọ, ti eegun awọn asaaju ẹgbẹ ọlọkọ ero ko si gbọdọ sẹ mọ nibẹ.
Ondo: Dejí sun ọmọ méje àtagbalagba meji mọ́lé nítorí pé ó ń bínú
Nigba ti ikọ iroyin BBC Yoruba kan si olori eto iroyin fun ipolongo ibo gomina Seyi Makinde, Ọmọọba Dọtun Oyelade, o sọ fun wa pe ijọba yoo fi akọsilẹ iroyin nipa igbesẹ rẹ ọhun sita laipẹ.
Bo ba si se n jade, ni a maa mu iroyin rẹ wa fun un yin.
Makinde: Ẹgbẹ́ òṣìṣẹ́ faramọ́ wíwọ́gilé ₦3000 táwọn akẹ́kọ̀ọ́ girama ń san
Oyo: Bisi Ilaka ní ìdìbò àwọn alága ìjọba ìbílẹ̀ lòdì sófin
Oríṣun àwòrán, Oyo State Government
Ijọba Ipinlẹ Oyo ti salaye idi abajọ ti Gomina Ṣeyi Makinde fi paṣe wi pe, ki gbogbo awọn alaga ijọba ibilẹ nipinlẹ naa fi ipo wọn silẹ ni kiakia.
Olori oṣiṣẹ ọba lọfiisi gomina, Oloye Oyebisi Ilaka sọ fawọn akọroyin lọjọ Ẹti pe, idibo ijọba ibilẹ to waye lasiko ijọba Gomina ana, Abiola Ajimọbi ko wa ni ibanu pẹlu ofin, ati pe eto idibo to gbe awọn alaga ibilẹ naa wọle lodi si aṣẹ ileẹjọ.
Oloye Ilaka ṣalaye pe, ijọba to ṣẹṣẹ gori aleefa ṣetan lati tele ofin ninu iṣejọba ipinlẹ Oyo.
Olori oṣiṣẹ ọba lọfiisi gomina sọ pe, ijọba n reti ki awọn alaga naa lọ si ileẹjọ, ti igbesẹ yii ko ba tẹ wọn lọrun.
O fikun ọrọ rẹ pe, ijọba ti yan awọn amofin to dantọ lati ṣoju rẹ, ti ọrọ naa ba dọrọ ileẹjọ.
Oríṣun àwòrán, Seyi Makinde
Bẹẹ ba gbagbe, ọjọru, ọjọ Kọkandinlọgbọn, oṣu Karun un ọdun 2019, to jẹ ọjọ ti wọn bura fun un gẹgẹ bi gomina tuntun ni ipinlẹ Ọyọ, ni Gomina Seyi Makinde paṣẹ pe ki gbogbo awọn alaga ijọba ibilẹ nipinlẹ naa fi ipo wọn silẹ ni kiakia.
Gomina Makinde kede ọrọ naa latẹnu olori oṣiṣẹ rẹ, Bisi Ilaka, pẹlu afikun pe ki awọn alaga naa gbe iṣakoso silẹ fun awọn olori awọn oṣiṣẹ tabi oludari agba lawọn ijọba ibilẹ wọn.
Gomina Seyi Makinde tun paṣẹ pe ki gbogbo igbimọ oluṣakoso ni awọn ileeṣẹ ati lajọ-lajọ to jẹ tijọba Ọyọ di tituka.
Seyi Makinde kò ní ẹ̀tọ́ láti yọ alága ìjọba ìbílẹ̀ tì kò yàn sípò - Amòfin
Sugbọn nigba to n ba BBC Yoruba sọrọ lori igbesẹ gomina tuntun naa,, Amofin Oludare Falana sọ pe, Gomina Makinde ko ni ẹtọ kankan labẹ ofin orilẹede Naijiria lati yọ alaga ijọba ibilẹ ti kii ṣe oun lo yan-an sipo.
O ṣalaye pe abala keje ofin orilẹede Naijiria to sọrọ nipa awọn ijọba ibilẹ pe, bi a ṣe n dibo yan awọn aṣofin tabi gomina naa ni awọn alaga ijọba ibilẹ ni ẹtọ lati jẹ yiyan si ipo.
Oríṣun àwòrán, Oyo State Government
Eyi naa ni ofin eto idibo faramọ. Ti mejeeji si sọ pe awọn alaga ijọba ibilẹ ti awọn ara ilu dibo yan ni ẹtọ lati pari saa iṣakoso wọn."""
"O ni ""nibi ti ọrọ de bayii, awọn alaga ti Makinde sọ pe ko fi ipo silẹ ni ẹtọ lati lọ sile ẹjọ."""
"O ni  ""o jẹ ohun to ku diẹ kaato pe, Seyi Makinde gẹgẹ bi gomina tuntun ti ko ti i yan agbẹjọro ijọba nipinlẹ naa, n yọ alaga nipo. Nitori pe agbẹjọro agba naa lo yẹ ko tọ ọ sọna lori ọrọ naa.    """
Ondo: Dejí sun ọmọ méje àtagbalagba meji mọ́lé nítorí pé ó ń bínú
Oṣu Karun un, ọdun 2018 ni gomina to ṣẹṣẹ fi ipo silẹ nipinlẹ Ọyọ, Abiọla Ajimọbi, ṣeto idibo ijọba ibilẹ.
Idibo naa waye lẹyin ọdun bi i mẹwa ti iru rẹ ti waye kẹhin nipinlẹ naa. Ọdun 2007 ni idibo ijọba ibilẹ waye kẹhin lasiko ti Adebayọ Alao Akala fi wa ni ipi gomina.
Lọgan to kede aṣẹ yii naa ni awọn alaga ijọba ibilẹ ti ọrọ kan ti ṣepade, ti awọn naa si n leri peko si ẹnikẹni to le ṣi awọn nidi kuro ni ipo alaga.
Makinde: Ẹgbẹ́ òṣìṣẹ́ faramọ́ wíwọ́gilé ₦3000 táwọn akẹ́kọ̀ọ́ girama ń san
Awọn alaga naa ṣapejuwe igbesẹ Makinde gẹgẹ bi aṣẹ onikumọ.
Ọkan lara awọn alaga naa, Abass Alẹṣinlọyẹ sọ pe awọn alaga naa ti kọwe si gbogbo awọn  to le ranwọn lọwọ lori ọrọ naa.
Kenyan Woman: Aláboyún fi bílédìì gbé ọmọ jádé nínú ara a rẹ̀ ní Tanzania
Oríṣun àwòrán, Getty Images
N ṣe ni Joyce mu bileedi, to si fi la ara a rẹ ni ikun ko to o gbe ọmọ tuntun naa jade.
Ileesẹ ọlọpaa orilẹ-ede Tanzania ti fidirẹmulẹ pe, lootọ ni arabinrin alaboyun kan ṣe iṣẹ abẹ fun ara rẹ, lati gbe ọmọ inu rẹ jade.
Obinrin naa, ẹni ọgbọn ọdun, Joyce Kalinda ni wọn sọ pe, o sọ ara rẹ di onimọ iṣegun oyinbo ọsan gangan, to si gbẹbi ara rẹ.
N ṣe ni Joyce mu bileedi, to si fi la ara a rẹ ni ikun, ko to o gbe ọmọ tuntun naa jade.
Ọjọbọ, ọgbọnjọ, oṣu Karun un, ọdun 2019, ni iṣẹlẹ yii waye ni ilu Kirando, to wa ni ẹkùn Rukwa l'orilẹ-ede Tanzania.
Myanmar: kékeré ni wọ́n ti n kọ́ àwọn ọmọ nípa ọ̀nà oge ṣiṣe
A gbọ pe wọn ti kọkọ gbe obinrin naa lọ sileewosan ilu Kirando fun itọju ko to o bimọ.
Amọ, ṣe lo sa kuro nileewosan, to si pada sile.
Wo ewu tó wà nínú fífi ọṣẹ ìfọyín àti omi gbígbóná ṣe ìtọ́jú okùn tó so olúbi pọ̀ mọ́ ìyá ọmọ
Ẹ yé kóra jọ pọ̀ láti d'ẹ́rù b'olẹ̀ pé ọwọ́ Yorùbá ni Ààrẹ 2023 gbọ́dọ̀ bọ́ sí - Shekarau
67 year old mother: Mo kojú ọ̀pọ̀lọpọ̀ àìsàn fún ọdún 35 lẹ̀yín ìgbéyàwò
Igba to de ile lo ran ọmọ rẹ to kere julọ lati lọ ọ pe ẹgbọn oun kan wa, ni adugbo ti ko jinna si wọn.
Ni kete to si ku oun nikan sinu ile, lo mu bileedi, to la ikun ara rẹ, to si gbe ọmọ tuntun jade.
Barister lo bi gbogbo oníṣẹ́ fújì -Oṣupa
Igba ti ọmọ to ran niṣẹ pada de, lo ba iya rẹ ati ọmọ tuntun ninu ile, eyi lo si mu ko pariwo 'ẹ gba mi' si awọn alajọgbelepọ wọn fun iranlọwọ.
Wọn si pinnu lati gbe e pada sileewosan to ti sa kuro.
Ọmọ kẹjọ ti obinrin naa yoo bi niyii.
Igbesẹ arabinrin yii ti fa n ha-hin ni agbegbe naa.
Ondo: Dejí sun ọmọ méje àtagbalagba meji mọ́lé nítorí pé ó ń bínú
UEFA Champions League 2019: ilé ló máa bọ́sí fàwọn ọmọ Afrika loni
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ọmọ Afirika mẹfa lo wa ninu ẹgbẹ agbabọọlu mejeeji yii
Agbábọ́ọ̀lù ọmọ Áfíríkà mẹ́fà tó ṣeéṣe kó gba ife  ẹ̀yẹ UEFA Champions league lónìí.
Loni ni ko ni dọla ti agbaye yoo mọ ẹgbẹ agbabọọlu ti yoo pegede, fi gbọọrọ jẹ ka ninu idije UEFA champions league ti ọdun 2019.
Ẹgbẹ agbabọọlu Liverpool ati Tottenham ni yoo maa figagbaga ni ipele aṣekagba idije naa lalẹ ọjọ Satide.
Amọṣa, eyi o wu ko gbe'gba oroke laarin awọn ẹgbẹ agbabọọlu mejeeji yii, o daju ṣaka pe ọwọ ilẹ Afirika ko ni gbẹyin lara ife ẹyẹ naa lọdun yii.
Ko si idi meji fun eyi ju pe agbabọọlu ọmọ ilẹ Afirika mẹfa ọtọọtọ ni yoo kopa ninu ifẹsẹwọnsẹ naa.
Oríṣun àwòrán, @SpursOfficial
Igba akọkọ ree fun Tottenham ni ipele aṣekagba UEFA Champions league
Eyi si tumọ si pe ikọ yoo wu to ba bori ninu ifẹsẹwọnsẹ naa, ọmọ Afrika yoo wa nikalẹ lati gba ife ẹyẹ naa.
Fun ikọ Liverpool, agbabọọlu ọmọ ilẹ Afirika mẹrin lo wa ninu ikọ naa.
Myanmar: kékeré ni wọ́n ti n kọ́ àwọn ọmọ nípa ọ̀nà oge ṣiṣe
Agbabọọlu orilẹ-ede Guinea, Nabi Keita (lootọ oun ko ni kopa ninu ifẹsẹwọnsẹ yii nitori o fara ṣeṣe), Sadio Mane lati orilẹede Senegal, Joel Matip lati orilẹ-ede Cameroun pẹlu Mohammed Salah to jẹ agbabọọlu ọmọ orilẹ-ede Egypt.
Fun ikọ Tottenham ni tirẹ, agbabọọlu orilẹ-ede Ivory Coast, Serge Aurier yoo wa n kalẹ lati darapọ mọ awọn ọmọ ilu rẹ bii Didier Drogba, Yayah Toure ati Solomon Kalou ti wọn ti f'igba kan ri gba ife ẹyẹ UEFA Champions League.
Oríṣun àwòrán, @LFC
Salah, Mane, Aurier, Wanyama yoo wọ ṣòkòtò kan náà láti gba ife ẹ̀yẹ UEFA Champions league ní ìlú Madrid
Bakan naa ni Victor Wanyama, ọmọ orilẹede Kenya naa yoo wa nikalẹ fun ẹgbẹ agbabọọlu Tottenham hotspur.
Odu ni ẹgbẹ agbabọọlu Liverpool ninu idije UEFA Champions league. Igba marun un ọtọọtọ ni wọn ti gba ife ẹyẹ yii; AC Milan ati Real Madrid nikan lo gba ife ẹyẹ yii ju wọn lọ. Real Madrid lo ṣi wọn lọwọ ninu awo ikẹfa ti wọn fẹ gba lọdun 2018.
Ondo: Dejí sun ọmọ méje àtagbalagba meji mọ́lé nítorí pé ó ń bínú
NCC: A ti ri owó ti Iléeṣé MTN sannáà gbà
Oríṣun àwòrán, Getty Images
MTN ti san owó ìtanran wọn tán fún Naijiria
Biliọnu ọgbọn lé ni ọọdunrun naira ni owó itanran ti Naijiria bù fún ileeṣẹ MTN.
Ileeṣẹ MTN jẹ ọkan lara awọn ileeṣẹ to n ṣeto ibanisọrọ ni orilẹ-ede Naijiria yatọ si GLO, Airtel, Etisalat atawọn miran.
Loṣu kẹwaa, ọdun 2015 ni NCC bu owó itanran to le ni tiriliọnu kan naira fun ileeṣẹ MTN.
Naijiria bu owó itanran yii fun ileeṣẹ yii nitoripe wọn ko tẹlẹ aṣẹ pe ki wọn re awọn onibara ti ko kopa ninu eto iforukọ silẹ tijọba pa kúrọ lasiko.
Ijọba Naijiria paṣẹ pe ki gbogbo ẹni to n lo ẹrọ ibanisọrọ forukọ silẹ ki wọn le gbogun ti awọn alakatakiti ẹsin Islam, Boko Haram to n dunkooko ni Naijiria.
Àjọ Nigeria Communications Commission (NCC) to n mojuto ọrọ eto ibanisọrọ ni Naijiria fifidi ẹ mulẹ pe awọn ti ri ifitonileti banki lori owó naa gbà lọjọ Eti.
Loṣu kẹwaa, ọdun 2015 ni NCC bu owó itanran to le ni tiriliọnu kan naira fun ileeṣẹ MTN.
Lẹyin idunadura ni wọn wa din owó naa ku si ọgbọn biliọnu naira le ni ọọdunrun ni eyi ti wọn fun MTN lọdun mẹta lati san.
Àjọ NLC Naijiria : MTN kọ̀ jẹ́ kí òsìsẹ́ wọn darapọ̀ mọ́ àjọ òsìsẹ́
Bakan naa ni ileeṣẹ MTN ti darapọ mọ Nigeria Stock Exchange bayii to jẹ ọkan lara gbendeke ti ajọ NCC fun wọn nigba naa.
Ọpọ adanu lo de ba MTN lara awọn onibara to le ni miliọnu ọgọta ti wọn ni lọwọ lọdun 2016 tẹlẹ lataari sisan owó itanran yii.
Myanmar: kékeré ni wọ́n ti n kọ́ àwọn ọmọ nípa ọ̀nà oge ṣiṣe
Iroyin ni ileeṣẹ MTN ti wọn da silẹ lati orilẹ-ede South Africa yii ko tii yọ awọn onibara to le ni miliọnu marun un ti wọn ko kopa ninu iforukọ silẹ naa.
Egbẹrun owo dọla kan lori nọmba kọọkan ti MTN ko forukọ wọn silẹ ni ajọ NCC kọkọ sọ pe ki wọn san gẹgẹ bii owo itanran.
Barister lo bi gbogbo oníṣẹ́ fújì -Oṣupa
Ki wọn to jọ sọ asọyepọ ti wọn fi din owo itanran naa.
Ondo: Dejí sun ọmọ méje àtagbalagba meji mọ́lé nítorí pé ó ń bínú
Bayii ileeṣẹ MTN ti san owo itanran naa tán fún ajọ NCC Naijiria.
Makinde: Ẹgbẹ́ òṣìṣẹ́ faramọ́ wíwọ́gilé ₦3000 táwọn akẹ́kọ̀ọ́ girama ń san
Oando bọ́ si abẹ́ ìwádìí àjọ eto aàbò okòwò àti pàṣípààrọ̀ Naijiria-SEC
Oando bọ́ si abẹ́ ìwádìí àjọ eto aàbò okòwò àti pàṣípààrọ̀ Naijiria
A ṣi máa gbe ọrọ lọ si ọdọ FIRS, NSE ati CAC -SEC
Àjọ eto aàbò okòwò àti pàṣípààrọ̀ okòwò ní Naijiria (SEC) ti kede pe Wale Tinubu to jẹ oludari ileeṣẹ epo OANDO kò gbọdọ ṣe oludari ileeṣe ijọba kankan fun ọdun marun un.
Ajọ SEC ṣe ikede yii lẹyin iwadii ti wọn ṣe lori gbogbo kudiẹ-kudiẹ to ṣẹlẹ ninu awọn akọsilẹ ile iṣẹ naa.
Ajọ SEC tun fi ofin de igbakeji oludari ileeṣẹ Oando pẹlu pe iwa ti wọn hu na ko bojumu rara.
Ajọ SEC ni wọn fi ara balẹ ṣiṣẹ  iwadii ileeṣẹ naa ti wọn fi lọlẹ labẹ Nigerian and Johannesburg Stock Exchange ni.
Nigeria Elections 2019:Ìbò la ní kí ẹ dì, àwa kò bá tìjà wá
Bakan naa ni SEC tun paṣẹ pé ki gbogbo awọn ọmọ igbimọ alaṣẹ to n ṣakoso ileeṣẹ ọhun tọrọ kan kọwe fipo wọn silẹ.
O tun ni wọn gbọdọ pe ipade gbogbo ile ni pajawiri ṣaaju ọjọ kinni, oṣu keje, ọdun yii ni kia.
Loju opo itakun agbaye SEC ni wọn ti ṣalaye ni kikun awọn magomago ati aifootọ ṣe akọsilẹ loriṣiiriṣii ti wọn ri ni OANDO.
Bọla Tinubu: Ìpínlẹ̀ Ọ̀ṣun kò ní owó mi lọ́wọ́
Wọn ni awọn tun ri pe awọn ọmọ igbimọ n ṣe aṣilo awọn nkan ini ileeṣẹ naa ni eyi ti wọn ti paṣẹ pe ki wọn da pada bayii.
Ajọ SEC ni ki awọn ẹni kọọkan ati ileeṣe OANDO san owo itanran bẹrẹ lati ọdọ awọn oludari ileeṣẹ ọhun .
SEC tun ni ẹsun meji ti awọn ri gba lori ileeṣẹ yii lọdun 2017 lo bi iṣẹ iwadii ti awọn ṣe ni eyi to n bi eso itanran lasiko yii.
Tinubu: Nítorí Tinubu, àwọn ọmọge Sanwo-Olu da ìlù bolẹ̀
Osun poly: Ọ̀pọ̀ òògùn, àti ohun eèlò ni àwọn akẹ́kọ̀ọ́ tó ṣèwọ́de náà dá iná sun
Oríṣun àwòrán, citymirror news
Ọ̀pọ̀ òògùn, àti ohun èlò ni àwọn akẹ́kọ̀ọ́ tó ṣèwọ́de náà dá iná sun.
Akẹkọọ fò ṣanlẹ, o kú lẹyin idanwo.
Akẹkọọ onipele kẹta ileewe giga gbogboniṣe Poly ipinlẹ Ọṣun ni Iree kan, Aminu Sheu, ni iroyin sọ pe o ku lẹyin to pari idanwo aṣewọ ipele aṣekagba ẹkọ rẹ ni ọjọ Ẹti nilu Iree nipinlẹ Ọṣun.
Iroyin taa gbọ sọ pe, bi Sheu ṣe fi iwe idahun idanwo rẹ le awọn alamojuto idanwo lọwọ lo ba ṣubu lulẹ ti wọn si gbee digba-digba lọ si ileewosan.
Amọṣa, ẹpa ko boro mọ fun un nitori pe ileewosan ọhun lo dakẹ si lẹyin wakati diẹ.
Nitori eyi, n ṣe ni awọn akẹkọọ ileewe giga naa ya bo ileewosan to wa ni ọgba ileewe naa ti wọn si dana sun oko atawọn ohun elo miran to wa nibẹ.
Ondo: Dejí sun ọmọ méje àtagbalagba meji mọ́lé nítorí pé ó ń bínú
Ẹhonu awọn akẹkọọ naa ni pe aikun oju iwọn awọn oṣiṣẹ to wa ni ileewosan ileewe naa lo ṣokunfa iku akẹgbẹ wọn ọhun.
Myanmar: kékeré ni wọ́n ti n kọ́ àwọn ọmọ nípa ọ̀nà oge ṣiṣe
Amọṣa, ninu ọrọ to ba awọn oniroyin kan sọ, alukoro ileewe gbogboniṣe Poly Iree, Tọpẹ Abiọla ṣalaye fawọn akọroyin pe ko si ẹbi lọwọ awọn oṣiṣẹ ileewosan to jẹ ti ileewe naa.
O ni nnkan bii agogo mẹrin abọ irọlẹ ni wọn gbe e de ti awọn oṣiṣẹ iṣegun oyinbo to wa nibẹ si sa ipa wọn lati doola ẹmi rẹ ṣugbọn to ja si pabo.
Ọgbẹni Abiọla n ṣalaye siwaju sii pe wọn gbe akẹkọọ naa lọ sileewosan miran ni igboro ilu Iree nibẹ ni o si dakẹ si.
"O ni 'Musulumi ni, o si n gba aawẹ Ramadan lọwọ. O ṣeeṣe ko jẹ pe aisi okun tó ninu lo faa to fi ṣubu to si daku."""
Awọn akẹkọọ akẹgbẹ rẹ to ṣe iwọde lati fi ẹhonu han lori iku rẹ ni owurọ ọjọ Satide ko fojuure wo ileewosan ileewe naa rara.
Ṣe ni wọn dana sun awọn ohun Eelo, oogun atawọn ohun miran ti ọwọ wọn ba nibẹ lasiko iwọde naa.
Ọpọlọpẹ awọn oṣiṣẹ alaabo ileewe naa ni ko jẹ ki wọn raaye ati sun gbogbo ileewosan naa ni ina.
Lẹyin eyi ni awọn alaṣẹ ileewe naa ba gbe ilẹkun rẹ ti pa ti wọn si paṣẹ fun gbogbo akẹkọọ ki wọn maa gba ile obi ati alagbatọ wọn lọ.
Visa Application: Amẹ́ríkà ń béèrè ìròyìn ojú òpó arìnrìnàjò
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Oṣù kẹta ọdún 2019 ni àṣẹ yìí kọ́kọ́ jáde
Gbogbo awọn eeyan to ba fẹ rinrin ajo lọ sorilẹede Amẹrika bayii gbọdọ ṣetan ati ko gbogbo iroyin to ba jọ mọ iṣe wọn lori ayelujara kalẹ.
Eyi fihan pe gbogbo iroyin to ba jọ mọ Facebook, Twitter ni awọn to n wa iwe aṣẹ irinna sorilẹede Amẹrika bayii gbọdọ ṣetan ati fa le awọn oṣiṣẹ ileeṣẹ aṣoju ilẹ Amẹrika lọwọ lasiko eto naa.
Eyi ri bẹẹ nitori pe bayii, orilẹede Amẹrika ti ni lara awọn ohun amuyẹ ti oun yoo maa beere lọwọ awọn to ba fẹ gba iwe aṣẹ irinna silẹ okeere ni iroyin nipa oju opo wọn lori ikanni ayelujara Facebook, twitter atawọn miran. Ko din ni miliọnu mẹrinla awọn arinrinajo lọdun to fi mọ awọn atipo to le ni ẹgbẹrun lọna ẹẹdẹgbẹrin ti aṣẹ yii lee kan.
Ni oṣu kẹta ọdun 2019 ni ileeṣẹ ọrọ ilẹ okeere ni ilẹ Amẹrika kọkọ kede igbesẹ tuntun yii lẹyin aṣẹ aarẹ orilẹede naa, Donald Trump pe ki wọn tubọ san okun ayẹwo fawọn arinrinajo si orilẹede naa ko gbopọn sii.
Ṣaaju aṣẹ tuntun yii, awọn arinrinajo ti wọn ba fura si nikan ni wọn maa n beere iroyin nipa oju opo ayelujara lọwọ wọn, papaa awọn to ba ti rinrinajo lọ sawọn orilẹede to ni ajọṣepọ pẹlu awọn ẹgbẹ agbesumọmi.
Osogbo Building collapse: Ògiri ilé wó pa Jide ọmọ ọdún mọ́kànlá l'Oṣogbo
Oríṣun àwòrán, citymirrornews.com
Kò sí ẹni tó tíì leè sọ ohun tó fa wíwó ilé náà
Ọfọ nla lo ṣẹ lagbegbe Kajọla ni ilu Oṣogbo lọjọ Aiku nigba ti ile alamọ kan da wo ti o si pa ọmọ ọdun mọkanla kan ti wọn pe orukọ rẹ ni Jide.
Ile ọlọjọ pipẹ naa to wa ni agboole Kegbe ni agbegbe Kajọla ni ilu Oṣogbo da wo lu Jide lasiko to fi n gba ẹgbẹ ile naa kọja lọ ni tirẹ.
Collapsed Building: Ayálégbé ló dára bí ìjọba ṣe wólé àmọ́ wọ́n fẹ́ ìrànwọ́ ilé míràn
Iroyin to tẹ BBC News Yoruba lọwọ ṣalaye pe awọn aladugbo gbe e lọ si ileewosan kan ni agbegbe Oke-Baalẹ ṣugbọn ti awọn oṣiṣẹ ileewosan naa ni ọrọ rẹ kọja agbara awọn.
Awọn aladugbo tun dari rẹ lọ si ileewosan nla ti LAUTECH, ṣugbọn Jide jade laye ki wọn to gbe e de'bẹ.
"Ọkan lara awọn olugbe ile naa to ba awọn akọroyin sọrọ ṣalaye pe ""inu ile mi ni mo wa ti mo si ṣa dede gbọ iro nla kan, mo jade lati wo ohun to ṣẹlẹ ni mo ba rii pe apa kan ile ti mo n gbe ti wo lulẹ. Ogiri ile naa wo lu ọmọdekunrin kan to n kọja lọ, o si ku."""
Ko tii si ẹni lee sọ ohun to fa ijamba ile to wo naa titi di igba ti a fi ko iroyin yii jọ.
Ramadan: Sultan pàṣẹ fún àwọn mùsùlùmí láti ṣ'ọdẹ òṣùpá lónìí
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ìtúnu àwẹ̀ leè wáyé ní ọjọ́ ìṣẹ́gun tàbí ọjọ́rú ọ̀sẹ̀ yìí
Sultan ti ilu Sokoto, Alhaji Muhammad Saád Abubakar ti ni ki awọn musulumi lorilẹede Naijiria bẹrẹ si ni ṣọ oṣupa tuntun.
O ni ki wọn maa ṣọ ọ fun oṣu Shawwal 1440AH ni kete ti oorun ba wọ lọjọ Aje, ọjọ kẹta, oṣu Kẹfa, ọdun 2019.
Aṣẹ yii wa lati lee mọ ọjọ ti awẹ yoo pari ti awọn Musulumi yoo ṣi tunu.
Omar Al-Bashir ti wọ́n gbajọba lọ́wọ́ ẹ ló di wàhálà
Ninu atẹjade kan eleyi ti ajọ to ga julọ fun ẹsin Islam lorilẹ-ede Naijiria, NSCIA fi sita ni wọn ti sọ eyi.
RAMADAN: Onímọ̀ ẹ̀sin sọ nípa isẹ́ láádá àti làádà
Igbakeji akọwe agba ajọ naa, Ọjọgbọn Salisu Shehu lo fọwọsi atẹjade naa.
Sultan Abubakar ni bi awọn eeyan ba ri oṣupa ni ọjọ Aje, oun yoo kede ọjọ Iṣẹgun, ọjọ kẹrin, oṣu kẹfa, ọdun 2019 gẹgẹ bii ọjọ akọkọ ninu oṣu Shawwal ti yoo si jẹ ọjọ ọdun 'Eidel fitr' iyẹn, itunu awẹ.
Atẹjade naa tun tẹsiwaju, o ni bi o ba si jẹ pe oṣupa ko le ni ọjọ aje, a jẹ wi pe, ọjọru, ọjọ karun oṣu kẹfa ni ọdun itunu awẹ fawọn Musulumi yoo bọ si.
'Mo ń ṣa ike jọ láti san owó ilé iwé ọmọ mẹ́ta'
APC: Kí ni àwọn ẹ̀ṣẹ̀ tó ń da Oshiomole láàmú?
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ìjì ńlá ló ń ja alága ẹgbẹ́ òṣèlú APC, Adams Oshiomhole lọ́wọ́; ṣùgbọ́n kí ni ẹ̀ṣẹ̀ rẹ̀ gan
Iji nla lo n ja lagbo ẹgbẹ oṣelu APC bayii. Iji naa si n fi alaga ẹgbẹ oṣelu naa lakalaka lọwọlọwọ.
Awọn eekan ẹgbẹ oṣelu naa ni wọn ti n ke si Adams Oshiomhole pe ko kọwe fi ipo silẹ nitori pe igba rẹ ko fẹ ṣe bi ẹni san ẹgbẹ oṣelu naa.
Ninu awọn to n pe ipe yii ni igbakeji Adams Oshiomohle gan funrarẹ fun iha ariwa, Sẹnetọ Lawan Shu'aib ati alaga ẹgbẹ naa to fi ipo silẹ.
Amọṣa awọn alaga ẹgbẹ oṣelu APC lẹkun aaringbungbun Gusu ti dide atilẹyin fun un.
Ki ni awọn ohun ti Adams Oshiomhole ṣe gan an to n fẹ bu u lẹsẹ bayii? Eyi ni atupalẹ diẹ nibẹ.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Eyi ni atupalẹ diẹ nibẹ.
Kii ṣe wahala kekere ni ọrọ abẹnu to waye laarin agbo APC ni ipinlẹ Zamfara ati Rivers ko ba ẹgbẹ oṣelu naa.
Ọpọlọpọ lo reti ki alaga ẹgbẹ oṣelu APC naa o gbe igbesẹ lati tete yanju ọrọ naa ki o to burẹkẹ.
Ṣugbọn kaka ki Oshiomole ko awọn adari ẹgbẹ oṣelu naa sodi lati tete pa ina rẹ ki eefin rẹ to ru sita, idakeji rẹ lo waye.
Nitori dukuu wọnyii, ipinlẹ mejeeji yii ni APC padanu. Wọn ko tilẹ jẹ ko fa oludije kalẹ ni ipinlẹ Rivers lasiko idibo to kọja.
Ipinlẹ Zamfara ti wọn tun ti fa eeyan silẹ, lọsẹ to kọja ni ile ẹjọ to ga ju lorilẹ-ede Naijiria ti wọgile gbogbo awọn oludije to jẹ ti APC nipinlẹ naa.
Ọpọ awọn ọmọ ẹgbẹ oṣelu naa ni ko ṣebi ẹni dunnu si bi awọn adari ẹgbẹ oṣelu naa ṣe mu ọrọ naa.
'Mo ń ṣa ike jọ láti san owó ilé iwé ọmọ mẹ́ta'
Lootọ ọpọ le sọ pe ẹsẹ wọn ti wa ni ita ṣaaju ibọsipo Adams Oshiomole gẹgẹ bii alaga ẹgbẹ oṣelu APC.
Sibẹ ọpọ ọmọ ẹgbẹ lo ṣi n wo o pe iye awọn eekan ẹgbẹ oṣelu APC lọdun 2018 si asiko eto idibo apapọ ọdun 2019 ku diẹ kaa to.
Lara awọn eekan to fi ẹgbẹ oṣelu naa silẹ ni aarẹ ile aṣofin agba, Sẹnetọ Bukọla Saraki, ati olori ile aṣoju-ṣofin, Dogara, gomina Aminu Tambuwal atawọn eekan miran.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ìjì ńlá ló ń ja alága ẹgbẹ́ òṣèlú APC, Adams Oshiomhole lọ́wọ́; ṣùgbọ́n kí ni ẹ̀ṣẹ̀ rẹ̀ gan
Kii ṣe iroyin pe titi ti wọn fi kuro ni ipo gomina ni ipinlẹ koowa wọn, ati Amosun pẹlu Rochas Okorocha, ko si eyi to fojuure wo Adams Oshiomole titi ti wọn fi kuro ni ipo.
Ohun to si fa aawọ aarin wọn ko ju bi alaga ẹgbẹ APC naa ṣe faake kọri pe oun ko ni fọwọ si eeyan ti wọn fa kalẹ gẹgẹ bi oludije awọn ipo oṣelu nibẹ lai yan ipo gomina silẹ.
'Mo ń ṣa ike jọ láti san owó ilé iwé ọmọ mẹ́ta'
Rochas Okorocha fa ọkọ ọmọ rẹ, Uche Nwosu siilẹ gẹgẹ bii gomina, Amosun ni tirẹ naa fa eeyan tirẹ silẹ ni ipinlẹ Ogun.
Ọpọ lo wo o pe bi APC ṣe kuna ni ipinlẹ Imo ko ṣẹyin eyii.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ọpọ awọn alagbara ẹgbẹ oṣelu APC lo ṣi n fapa janu pe awọn iwa ati ọrọ Adams Oshiomole kun ara ohun to fa a ti ẹgbẹ oṣelu APC fi padanu awọn ipinlẹ bii, Zamfara, Imo Oyo ati Adamawa.
"Ninu iwe to kọ, igbakeji alaga APC fun ẹkun ariwa Sẹnetọ Lawal Shu'aibu ni ""ipinlẹ mẹtalelogun ni a ni lọdun 2015, ṣugbọn nigba to di ọdun 2019 a padanu meje""."
A tun ni ọgọta sẹnetọ lọdun 2015, nibayii mẹtadinlọgọta la ni. A ko gbe ọ wọle lati wa fidirẹmi ninu idibo, a ko lee gba eyii rara.
Bi eniyan ba tun wa wo awọn ẹsun ti Sẹnetọ Shu'aibu ka silẹ fun Oshiomhle ninu lẹta to kọ si i pe ko fi ipo silẹ gẹgẹ bii alaga ẹgbẹ oṣelu naa, aigbọ ọrọ lẹnu awọn ọmọ ẹgbẹ jẹ awọn ẹsun ti wọn fi kan an.
Bakan naa, ibinu awọn ọmọ ẹgbẹ oṣelu APC, eto ati ilana ti awọn alaṣẹ naa n gba to eto ẹgbẹ oṣelu APC naa ko gbẹyin ninu awọn ẹsun ti wọn fi kan Adams Oshiomole.
Nigba ti BBC News Yoruba kan si alukoro ẹgẹ oṣelu APC, Ọgbẹni Issa Onilu, o ni ẹgbẹ oṣelu APC yoo fi ero rẹ han lori ọrọ ọhun ni ọsan ọjọ aje.
Sudan Protest: Àwọn òṣìṣẹ́ aláàbò kọlu àwọn tó n ṣe ìwọ́de ní Sudan
Oríṣun àwòrán, AFP/Getty Images
Ija Sudan
Awọn ikọ alaabo l'orilẹede Sudan fi tipa-tipa wọ aarin awọn to n ṣe iwọde ifẹhonuhan ni ilu Khartoum to jẹ olu ilu orilẹeede naa ni owurọ kutu-kutu ọjọ Aje.
Awọn ti iṣẹlẹ naa ṣoju wọn sọ fun ileeṣẹ amohunmaworan Arab television pe niṣe ni awọn oṣiṣẹ alaabo ọhun bẹrẹ si ni yin ibọn, ti awọn afẹhonuhan naa si n sọ pe ọna lati da iwọde ti wọn n ṣe ni ita ileeṣẹ ijọba to wa fun eto aabo ru ni.
Iroyin sọ pe eniyan kan ti padanu ẹmi rẹ, ti ọpọ eniyan si tun farapa.
Lati igba ti awọn ologun ti gbajọba lọwọ Aarẹ Omar al-Bashir ninu oṣu Kẹrin ni awọn ọmọ ogun ti n ṣe iṣakoso orilẹede naa.
Ọgbọn ọdun ni Aarẹ al-Bashir ti lo ni iṣakoso, ki awọn ọmọ ogun to o gba ijọba lọwọ rẹ.
Awọn afẹhonuhan si n sẹ iwọde ni gbogbo igba pe ki ijọba alagbada pada sori aga iṣakoso.
"Ẹgbẹ to n ṣiwaju ifẹhonuhan naa sọ ninu atẹjade kan pe ''ipenija ati wahala nla ni awọn afẹhonuhan to wa niwaju olu ileeṣẹ ologun n koju, nitori bi awọn ologun ṣe n gbiyanju lati le wọn kuro."" Ẹgbẹ naa n fẹ ki awọn eniyan orilẹede Sudan dide fun iranlọwọ wọn."
Ọjọ kẹfa, oṣu Kẹrin, to jẹ ọjọ maarun ṣaaju ki awọn ologun to gbajọba ni awọn to n fi ẹhonu han ti wa niwaju olu ileeṣẹ ologun.
Donald Trump ti gúnlẹ̀ sí UK fún àbẹ̀wò ọlọ́jọ́ mẹ́ta
Trump ti gbé òdòdó ìrántí sójú oórì akọni lójú ìjà
Lojo Iṣẹgun ni ipade aarẹ Trump ati Theresa May yoo bẹrẹ.
Abẹwo aarẹ Trump ṣe kongẹ pẹlu iranti ikariudinlọgọrin D -Day Landings ti Obabinrin Elizabeth àti aarẹ Trump atawọn olori orilẹ-ede miran a jọ ṣe ni ọjọru.
Donald Trump ti pàdé Ọbabìnrin Elisabeth tilẹ̀ Gẹ̀ẹ̀sì
Eto ikini-kaabọ n lọ lọwọ ni aafin Obabinrin ilẹ̀ Gẹẹsi fun aarẹ Amerika, Donald Trump.
Eto igbalejo ounjẹ ọsan yii kò wa fun gbogboogbo ni ilu Ọba.
Oríṣun àwòrán, PA
Awa ara wa la ri ara wa, bi ologinni ba ri ọmọ ẹkun
'Air Force One' ni ọkọ baalu to gbe Trump wa si UK nibi ti wọn ti kọkọ lọ si ọdọ aṣoju ilẹ Amerika fun UK ni agbegbe Central London.
'Mo ń ṣa ike jọ láti san owó ilé iwé ọmọ mẹ́ta'
Ṣaaju ki ọkọ afurufu Trump to balẹ lo ti bẹnu ẹ̀tẹ́ lu Sadiq Khan to jẹ olori London lẹyin ìkọlu wọn atẹyinwa.
Aàrẹ Donald Trump àti Melania aya rẹ̀ ti n jẹ oúnjẹ ọ̀sán pẹ̀lù Obabìnrin Elisa ni Buckingham Palace.
Ìfẹ̀hònúhàn ni àwọn ará UK fi ki Donald Trump káàbọ̀
Odindin ọjọ́ mẹ̀ta ni Trump a lo ni ilẹ̀ Gẹẹsi.
Aarẹ Donald Trump to n dari ilẹ Amerika ati iyawo rẹ, Melania Trump ni wọn jọ de si UK bayii.
Aarẹ Donald Trump ti gunlẹ si UK
Papa iṣere Stansted lo balẹ si ti wọn ti lọ kii kaabọ.
Abẹwo yii ti bi awọn ifẹhonuhan lawọn ẹkun bii London, Manchester, Belfast, Birmingham.
Awọn ikọ 'Stop Trump Coalition'ati  'Stand Up to Trump' ni awọn a jọ ṣe iwọde naa ni.
Ninu abẹwo ọlọjọ mẹta yii ni Trump yoo ti ṣe ipade pọ pẹlu Theresa May to jẹ olootu to ti kọwe fipo silẹ bayii lori ọrọ ayipada oju ọjọ.
Bakan naa ni wọn yoo jiroro lori ọrọ ile ìṣẹ Huawei ti China ti Amerika yọwọ ẹ lawo lataari eto aabo.
Saaju abẹwo yii ni Trump ti fihan pe oun wa lẹyin Boris Johnson pe ko gba ipo Theresa May.
Awọn ibi ti aarẹ Trump a ṣabẹwo si ni Westminister Abbey ati ọdọ Omọba Charles ati aya rẹ.
Bakan naa ni Trump a kan si Obabinrin Elizabeth ni Burckingham Palace ninu abẹwo yii.
London, Manchester, Belfast àtàwọn ẹkùn míì ni wọ́n ti n fẹ̀hónúhàn lónìí fí kí aàrẹ Trump káàbọ̀ sí UK
'O yé kí ìbáṣepọ̀ Nàìjíríà àti UK dán mọ́rán síi lẹ́yìn àbẹ̀wò May'
Curruption Scandal: Ọ̀gá NIMASA tẹ́lẹ̀ r'ẹ́wọ̀n ọdún méjìlélógójì he
Oríṣun àwòrán, EFCC
Ọ̀gá NIMASA tẹ́lẹ̀ r'ẹ́wọ̀n ọdún méjìlélógójì he
Ile ẹjọ giga kan niluu Eko ti dajọ ẹwọn ọdun mejilelogoji fun adele ọga ajọ NIMASA (Nigerian Maritime Administration and Safety Agency), Ọgbẹni Calistus Obi.
Ajọ to n gbogun ti iwa ajẹbanu lorilẹ-ede Naijiria EFCC lo gbe Ọgbẹni Obi lọ sile ẹjọ lori ẹsun iṣowo to to miliọnu mẹrindinlogoje (#136m) kumọkumọ.
Amọ, ile ẹjọ fun Obi lanfaani lati san owo itanran to le igba miliọnu (N252 million) fun ẹsun ti wọn kan an.
'Mo ń ṣa ike jọ láti san owó ilé iwé ọmọ mẹ́ta'
Ileẹjọ tun dajọ ẹwọn ọdun mejilelogoji fun Ọgbẹni Alu Dismas to jẹ oluranlọwọ fun ọga NIMASA tẹlẹ, Patrick Akpobolokemi.
Omar Al-Bashir ti wọ́n gbajọba lọ́wọ́ ẹ ló di wàhálà
Wọn ni wọn jẹbi ẹsun 2, 3, 4. 6, 7 ati 8 ti ajọ EFCC fi kan wọn nile ẹjọ lọjọ kejila, oṣu kẹrin, ọdun 2016.
Oríṣun àwòrán, NJC
Ninu oṣu kẹrin,  ọdun 2016 ni EFCC kọkọ gbe awọn mejeeji lọ sile ẹjọ, ṣugbọn wọn ni awọn ko jẹbi ẹsun ti wọn fi kan wọn nigba ti igbẹjọ naa bẹrẹ.
Ẹlẹri mẹjọ ati ọpọ akọsilẹ ninu iwe lawọn olupẹjọ lo gẹgẹ bi idaniloju nigba ti igbẹjọ naa n lọ lọwọ.
Ileeṣe Global Sea Investment ati Grand PAct Limited ni wọn jọ fẹsun ọhun kàn.
Igbẹjọ iwa ajẹbanu yii jẹ ọkan lara awọn ẹsun igbogun ti iwa ibajẹ tijọba Buhari ri ṣe lati ọdun 2015 to ti gori aleefa.
Ramadan 2020: Buhari, Ọọni, Sultan Sokoto ní kí àwọn ọmọ Nàìjíríà láti fi ìtúnu àwẹ̀ gbàdúrà fún Nàìjíríà
Oríṣun àwòrán, others
Aarẹ orilẹede Naijiria, Muhammadu Buhari ti kesi awọn ọmọ Naijiria lati gbadura ni ile lasiko ọdun itunu aawẹ Ramadan, lẹyin to kọ fun awọn eniyan lati maṣe wa si Ile Aarẹ ni Abuja.
Aare Buhari fi ikede naa sita lati gba ọwọ agbẹnusọ rẹ, Garba Shehu.
Buhari to rọ awọn ẹlẹsin Musulumi lati gbadura ni ile, ni oun gbe igbeṣẹ yii lati dena itankalẹ arun Coronavirus.
Ninu ọrọ tirẹ, Ọọni Ile Ife, Ọba Adeyeye Enitan Ogunwusi  rọ awọn Mususlumi lati lo asiko fi dupẹ fun idasi ẹmi ati ojurere Allah si awọn ọmọ Naijiria.
Ọọni rọ awọn  ọmọ Naijiria lati gbaruku ti ijọba ki wọn balẹ bori arun Coronavirus to n ja tan kaakiri agbaye.
Ondo: Dejí sun ọmọ méje àtagbalagba meji mọ́lé nítorí pé ó ń bínú
O ni ọna ti awọn eniyan le gba ṣe atilẹyin fun gbogbo ilakalẹ ijọba apapọ ni lati ri wi pe aarun naa dinku lawujọ, ki ohun gbogbo le pada si ipo.
Bakan naa, Sultan ti ilu Sokoto naa rọ gbogbo awọn Musulumi lagbaye lati tẹlẹ ofin titakete sirani lasiko ọdun Ramadan yii, ki wọn si gbadura nile wọn.
Sultan ni awọn gbe ẹsẹ le ipejọpọ awọn Musulumi lasiko ọdun yii kaakiri orilẹede Naijiria, lati le daabo bo  awọn eniyan lọwọ arun Coronavirus.
Gomina Ipinlẹ Ogun, Dapo Abiodun naa kesi awọn ọmọ Niajiria lati ni igbagbọ pe arun Coronavirus yii yoo dopin.
'Mo ń ṣa ike jọ láti san owó ilé iwé ọmọ mẹ́ta'
Gomina Abiodun sọ eyi ninu atẹjade to fi sita lati ki awọn ẹlẹsin musulumi ku ọdun itunu aawẹ Ramadan.
O kesi awọn ọmọ Naijiria lati gbe ni alaafia pẹlu ara wọn,paapaa lasiko arun Coronavirus yii ti gbogbo eniyan ni agbaye n la kọja.
Gomina ipinlẹ Ogun naa parọwa si awọn eniyan lati jawọ ninu sisọ ohun ti wọn ko mọ nipa arun Coronavirus, amọ ki wọn gbiyanju lati tẹlẹ gbogbo ofin ati ilakalẹ ijọba lọna ati bori ajakalẹ arun Coronavirus naa.
Lẹyin isenu fun oṣu Ramadan, olori ijọ ẹsin Islam gbogbo lorilẹede Naijiria, to tun jẹ Sultan ti ilu Sokoto, Alhaji Saád Abubakar III ti kede oni, ọjọ iṣẹgun ọjọ kẹrin oṣu kẹfa gẹgẹ bii ọjọ ọdun itunu aawẹ, Eid-el-Fitr fun gbogbo musulumi lorilẹede Naijiria.
Sultan ti ilu Sokoto ṣe ikede yii lori Redio ati Tẹlifiṣan kan ni ilu Sokoto lẹyin ti wọn ri oṣu to le fun oṣu Shawwal.
Ṣaaju ni Sultan pàṣẹ fún àwọn mùsùlùmí láti ṣ'ọdẹ òṣùpá lónìí ṣugbọn bayii oun funra rẹ ti ri i o si ti kede rẹ.
O ni awọn eeyan ti ri oṣu lawọn ipinlẹ bii Kaduna, Kebbi, Yobe, Borno, Jigawa ati Sokoto.
"O ni, ""Ni ibamu pẹlu ofin Islam, a ni oreọfẹ lati kede pe oni ọjọ aje, ọjọ kọkandinlọgbọn oṣu Ramadan, 1440 AH to bọ si ọjọ kẹta oṣu kẹfa ọdun 2019 ni awẹ oṣu Ramadan wa sopin ti oṣu tuntun Shawwal si bẹrẹ."
Bakan naa ni ìjọba Nàìjíríà ti kéde ìsinmi lọ́jọ́ Ìṣẹ́gun àti Ọjọ́rú ọjọ karun oṣu kẹfa gẹgẹ bii ọjọ isinmi lẹnu iṣẹ lati ṣajọyọ itunu awẹ Ramadan lorilẹede Naijiria.
State Police: Buhari pariwo síta, ó ní èmi kò buwọ́lu ètò ọlọ́pàá agbègbè o!
Oríṣun àwòrán, @BashirAhmaad
Buhari tẹ́wọ́ gba àbájáde ìwadìí ìgbìmọ̀ lórí àtúntò ikọ̀ ọlọ́pàá SARS
Iroyin ayọ meji lo gbode kan fun ọpọ awọn ọmọ Naijiria ni ṣisẹ n tẹle lọjọ aje ṣugbọn ko pẹ ti awọn ọmọ Naijiria fi gbọ pe ahesọ lasan ni ekeji ninu iroyin naa.
Akọkọ ninu iroyin yii ni pe aarẹ ti tẹwọ gba abajade iwadi igbimọ ti aarẹ gbe kalẹ fun atunto ikọ agboguntiwa idigunjale nileeṣẹ Ọlọpaa, SARS, ekeji iroyin si ni pe aarẹ Buhari ti buwọlu eto ọlọpa agbegbe fun orilẹede Naijiria.
Bi awọn eeyan kan ṣe n kan sara si igbesẹ naa ni awọn eeyan kan n pariwo pe ko ṣeeṣe nitori eto to jẹ mọ ilana iwe ofin orilẹede Naijiria ni ọrọ ọlọpaa agbegbe ti yoo si nilo atunṣe ile igbimọ aṣofin apapọ.
Lẹyin-o-rẹyin ni o to han gbangba pe ọrọ naa ko ri bẹẹ rara. Aarẹ Buhari yanju ọrọ yii nigba to ṣalaye pe oun ko figba kankan fọwọsi ilana ọlọpaa agbegbe o.
Lẹyin ti o gba abajade iwadii ti igbimọ naa gbe kalẹ ni Aarẹ Buhari ti paṣẹ fun ileeṣẹ eto idajọ nijọba apapọ, ajọ to n risi ibọwọ fun ẹtọ ọmọniyan lorilẹede Naijiria, NHRC pẹlu ọga agba ileeṣẹ ọlọpaa lorilẹede Naijiria lati lọ tan imọlẹ si ọna ti wọn yoo gba lati ṣe amulo awọn aba ti igbimọ naa gbe kalẹ ninu iwadi rẹ.
Oríṣun àwòrán, @BashirAhmaad
Buhari fun ileeṣẹ eto idajọ, ajọ NHRC pẹlu ọga agba ileeṣẹ ọlọpaa lorilẹede Naijiria ni gbedeke oṣu mẹta
Ibeere to wa n gbẹnu ọpọ kan ni pe, o daa o, bi aarẹ ko ba gbe igbesẹ yii, awọn wo lo wa wa nidi iroyin ẹlẹjẹ eyi to fun araalu ni ọpọ idunnu fun akoko diẹ lọjọ aje ọjọ kẹta oṣu kẹfa ọdun 2019?
Gbogbo agbaye lo mọ pe ọrọ idasilẹ ọlọpaa agbegbe ti pẹ lori igba agbeyẹwo lagbo oṣelu lorilẹede Naijiria. Gulegule awọn ọlọpaa, paapaa julọ ẹka adamọlẹkun ariṣe kandu-kandu, SARS ti mu ki ipe fun idasilẹ ọlọpaa agbegbe tubọ peleke sii.
Lootọ iroyin sọ pe idasilẹ ọlọpaa agbegbe (State and LG police) wa lara awọn ohun ti igbimọ yii da laba fun Aarẹ Buhari ninu abajade iwadii rẹ ṣugbọn gẹgẹ bii amugbalẹgbẹ fun aarẹ lori ọrọ iroyin ati ipolongo, Garba Shehu ṣe sọ, eyi ko tumọ si pe aarẹ ti buwọlu u. O ni o di igba ti iwe aṣẹ ijọba, 'whitepaper' ba jade ki ẹnikẹni to lee sọ ohun gan ti aarẹ fẹ lori rẹ.
Ramadan: Kí ni Buhari, Saraki, àtàwọn gómìnà kan sọ?
Oríṣun àwòrán, @BashirAhmaad
Ààrẹ Buhari, Saraki, Dogara àtàwọn gómìnà kan tí ránṣẹ́ ìkíni kú ọdún sí àwọn mùsùlùmí
Aarẹ Muhammadu Buhari ti fi da awọn ọmọ orilẹede Naijiria loju pe opin ko ni pẹ de si iwa ijinigbe, igbesunmọmi atawọn iwa miran to n tigi boju alaafia lorilẹede Naijiria.
Ninu ọrọ ikini ku ọdun Eid-el-Fitir rẹ to fi ransẹ si awọn musulumi lo ti kede eyi. Aarẹ Buhari ni gbogbo ipa to ba yẹ ni ijọba oun yoo sa lati rii pe wọn dẹkun wahala igbesumọmi ati ijinigbe gbogbo to n waye lorilẹede Naijiria ati pe gbogbo awọn to ba wa ni idi ibajẹ ni wọn yoo lọ si i.
Bakan naa lo dupẹ lọwọ awọn ọmọ Naijiria fun fifi ile, ọna ati okoowo wọn silẹ lati jade dibo lasiko idibo apapọ to waye ṣaaju lọdun yii, lai naani ohun to pe ni ọrọ alufansa to ni awọn eeyan kan ṣaaju ọdun yii lori ohun ti yoo ti ẹyin idibo naa jade pe ko ni rọgbọ.
"O ni awọn ọmọ orilẹede Naijiria, paapaa julọ, awọn musulumi ni ọpọ ẹkọ lati kọ lara Ramadan eleyi to ni o wa lati 'ro awọn eeyan lagbara nipa ti ẹmi. Awọn amuyẹ Ramadan gbọdọ wa pẹlu wa kọja asiko wẹjẹwẹmu yii lọ."""
Oríṣun àwòrán, @bukolasaraki
Adura fun orilẹede Naijiria gbọdọ tẹ siwaju
Ninu ọrọ tirẹ, aarẹ ile aṣofin agba, Bukọla Saraki rọ awọn musulumi lati ma ṣe rẹyin ninu iwa ikoraẹni nijanu, ati ifẹ ọmọnikeji wọn.
A ko gbọdọ rẹyin ninu adura fun iṣọkan orilẹede Naijiria ati alaafia laarin awọn eeyan rẹ.
Yakubu Dogara: Ẹ maṣe gbagbe ẹkọ nipa ifiraẹnijin, idariji, ijọsin fun Ọlọrun ati ikoraẹni-ni- ijanu pẹlu ifẹ tootọ fun ọmọlakeji
Oríṣun àwòrán, @YakubDogara
Ẹ maṣe gbagbe ẹkọ nipa ifaraẹnijin, idariji, ijọsin fun Ọlọrun ati ikoraẹni-ni- ijanu pẹlu ifẹ tootọ fun ọmọlakeji
Olori ile aṣoju-ṣofin, Yakubu Dogara rọ awọn musulumi lati fi asiko opin awẹ yii ṣe arojinlẹ lori ẹkọ ti wọn ba kọ, ki wọn si ranti awọn to ku diẹ kaa to fun lawujọ.
Mo rọ yin lati ro arojinlẹ lori awọn ẹkọ bii ifaraẹnijin, idariji, ijọsin fun Ọlọrun ati ikoraẹni-ni- ijanu pẹlu ifẹ tootọ fun ọmọlakeji, eyi to suyọ lasiko Ramadan.
Gomina Dapọ Abiọdun (Ogun): Ẹ jẹ ki ifarajin ti ẹ ṣe lasiko Ramadan tubọ fa yin sunmọ Ọlọrun.
Oríṣun àwòrán, @ogun_state
Ẹ jẹ ki ifarajin ti ẹ ṣe lasiko Ramadan yẹ ko tubọ fa yin sin mọ Ọlọrun
Gomina Abiọdun rọ awọn musulumi lati ma ṣe gbagbe ẹkọ ifara ẹni jin ati titẹle ilana, iwa ati ẹkọ Anọbi Mohammed.
Awọn ifarajin ti ẹ ṣe lasiko Ramadan yẹ ko tubọ fa yin sunmọ Ọlọrun sii
Babajide Sanwo-Olu: Ẹ ranti awọn eeyan miiran ninu ajọyọ yin
Oríṣun àwòrán, @jidesanwoolu
Ẹ ranti awọn eeyan miran ninu ajọyọ yin
Adura ni gomina ipinlẹ Eko, Babajide Sanwo-Olu gba fun awọn musulumi ni tirẹ.
Ninu atẹjade kan to fi si oju opo twitter rẹ, Sanwo-Olu gbadura fun alaafia, ilọsiwaju ati igberusi fun awọn musulumi bi wọn ṣe n ṣajọyọ naa.
ki Ọlọrun ko fi ifẹ kun ile yin, ki o si gba gbogbo adura yin.
NURTW Oyo: Ìfikùnlukùn yóò wàyé pẹ̀lú Gómìnà Makinde láìpẹ́
Oríṣun àwòrán, @seyiamakinde
NURTW rọ Gómìnà Makinde láti jèbùrẹ́ lórí ọ̀rọ̀ àwọn ọmọ ẹgbẹ́ awakọ̀ èrò ní ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́
Aarẹ ẹgbẹ awakọ ero lorilẹ-ede Naijiria, Alhaji Najeem Yasin ti ke si gomina ipinlẹ Ọyọ, Seyi Makinde lati fi oju miran wo igbesẹ to gbe lati gbẹsẹle ẹgbẹ naa nipinlẹ Ọyọ.
Alhaji Yasin ni awọn yoo ṣepade pẹlu gomina Makinde laipẹ lati wa ojuutu si ọrọ naa.
Ni ọjọ Ẹti to kọja ni Makinde paṣẹ pe eegun ẹgbẹ awakọ ero, NURTW ko gbọdọ ṣẹyọ fun igba diẹ nipinlẹ Ọyọ lẹyin ti wọn fi ẹsun kan awọn ọmọ ẹgbẹ naa pe wọn n da omi alaafia ru lọna ati gba ibudokọ lọwọ ara wọn.
Pẹ̀lú gbogbo bùkátà, Bàbá 80 gboyè Masters
Ọrọ yii jade ninu ọrọ ti aarẹ ẹgbẹ awakọ ero NURTW, Najeem Yasin fi ranṣẹ lati orilẹ-ede Saudi Arabia nibi ti o ti lọ ṣe Umrah fun ọdun Ramadan.
Amọṣa ni ọjọ Aje ni ileeṣẹ ọlọpaa nipinlẹ Ọyọ fi oju awọn ọmọ ẹgbẹ awakọ ero ipinlẹ Ọyọ mọkandinlọgbọn han fawọn oniroyin lẹyin ti wọn ni ọwọ tẹ wọn ni ibi ti wọn ti n gbero ati da wahala silẹ lawọn ibudokọ kan nipinlẹ naa.
Ajayi: ṣé  ìwọ mọ irúfẹ́ ọmọ tí Yorùbá ń pè bẹ́ẹ̀?
Kọmiṣọna ọlọpaa nipinlẹ Ọyọ, Shina Olukolu ni marundinlogun ninu awọn afurasi naa ni ọwọ ba lasiko ti wọn fẹ da omi alaafia ilu ru lagbegbe Idi Arẹrẹ, Bẹẹrẹ, Orita Aperin, Iwo road ati ibudokọ ni Eruwa, Ilu Ibadan.
Ondo: Dejí sun ọmọ méje àtagbalagba meji mọ́lé nítorí pé ó ń bínú
Emir Sulu Gambari kú ara fẹ́rakù
Oríṣun àwòrán, @official_IYO
Emir Ilorin
Iya Emir ti ilu Ilorin, Alhaji Sulu Gambari, Alhaja  Aishat Nma Sulukarnaini ti re ibi agba n re.
Gẹgẹ bi iroyin to jade lati aafin Emir, o ti ṣe diẹ ti Mama Nma ti n ba aisan ọjọ ogbo fa a ko to wa di pe o jẹ Ọlọhun nipe ni ile iwosan Fasiti Ilorin.
Ondo: Dejí sun ọmọ méje àtagbalagba meji mọ́lé nítorí pé ó ń bínú
Lẹyin ti wọn kirun Ishai tan lalẹ ọjọ aje oṣu kẹfa ọdun 2019 ni Mama Nma jade laye.
Iya Emir Sulu Gambari ni ọmọ ọmọ Emir ikeeje to jẹ ni ilu Ilorin, ọmọ Emir ikẹjọ, to fi wa jẹ iyawo Emir ikẹsan, oloogbe Alhaji Sulu Karnaini Gambari.
Oríṣun àwòrán, Ilorin
Alhaja Aishat Nma Sulukarnaini
Awọn eekan lorilẹede Naijiria ati ni ilu Ilorin ti n fi ikini ranṣẹ si Emir Sulu Gambari.
Mama Nma tun jẹ aburo si Emir ikẹwaa to jẹ ni Ilorin ati iya to bi Emir to wa lori oye bayii, Alhaji Ibrahim Sulu-Gambari CFR.
Ẹni ọdun marunlelọgọrun ni mama yii nigba to pade ọlọjọ.
Olusegun Obasanjo: Ọmú ìyá mi ti mo fi ń mùkọ ni kekere ló jẹ ki ń lókun
Obasanjo - Ó dára bí Aisha ṣe ń gbarata lórí ètò áábó tó mẹ́hẹ
Oríṣun àwòrán, @AsoRock
Aarẹ ana ni Naijiria, Oloye Olusẹgun Ọbasanjọ ti kesi aya aarẹ Muhammadu Buhari, Aisha, lati pe ọkọ rẹ wọ yara, ko si ba sọ ootọ ọrọ nipa eto aabo to mẹhẹ lorilẹede Naijiria, pẹlu awọn ipenija miran lọkanojọkan ti a n fara gba.
Bakan naa ni Ọbasanjọ tun faramọ ọpọ koko ọrọ ti aya aarẹ n mẹnuba ninu awọn igbe gbajare to n ke pe, eto aabo Naijiria ko yanranti to , to si rọ Aisha Buhari pe ko pe ọkọ rẹ tẹ lori awọn ọrọ naa.
Ọbasanjọ gbe imọran yii kalẹ ninu atẹjade kan ti amugbalẹgbẹ rẹ feto iroyin, Kẹhinde Akinyẹmi fisita, eyi to ni o waye lasiko ti Ọbasanjọ n gbalejo awọn ọmọ igbimọ oludari feto iroyin ori ayelujara nibudo iyawe kawe rẹ.
Atẹjade naa fikun pe, Ọbasanjọ ni oun fara mọ igbe ti Aisha n mu bọnu lasiko yii, ti nkan ko fara rọ lẹka eto aabo wa nitori bi ara ile ba n jẹ kokoro buruku, bi a ko ba tete kigbe sita, huru-hẹrẹ rẹ ko ni jẹ ka sun lori.
Ọbasanjọ wa se kare, obinrin bii ọkunrin ni ọ si aya aarẹ, fun bi ko se bu ẹẹkẹ diwọ lasiko yii ti ara ko rọ okun, ti ko si rọ adiẹ lẹka eto aabo wa lorilẹede Naijiria.
Oríṣun àwòrán, Olusegun Obasanjo
O yẹ ka da silẹ, ka tun ṣa ni lasiko yii, ka lee wa ojutu sawọn isoro to n mi ẹka eto aabo Naijira logbo-logbo, o si yẹ ka ba ara wa sọ ootọ ọrọ lori rẹ, lai fi epo bọyọ. Aya aarẹ ṣe daada pẹlu bo se n kigbe sita yii, sugbọn o tun ku, nibọn n ro. O yẹ ko pe ọkọ rẹ tẹ si yara ni, lati baa jiroro lori aifaraọ eto aabo naa.
Pẹ̀lú gbogbo bùkátà, Bàbá 80 gboyè Masters
Bakan naa ni aarẹ tẹlẹ naa tun gbe imọran kalẹ pe o yẹ ki alekun eto ilanilọyẹ wa, ki awọn ọmọ Naijiria lee ni iyipada rere ti wọn n fi oju sọna fun.
Kudirat Abiola: Akọni obìnrin tó jẹ́ igilẹ́yìn ọgbà fún ọkọ rẹ̀
Oríṣun àwòrán, Yusuf A
A bí Kudirat Abiola ni ọdún 1951 ní ]ilú Zaria, òun ni ìyàwó keji ti Abiola fẹ́ tó si bi ọmọ mẹ́fa.
Kò sí àní àní pé, ti à bá ti ń sọ̀rọ̀ iromi Moshood Kasimawo Olawale (MKO) Abiola to n jo lori omi, à máa gbúròó Kudirat Abiola, akọni obinrin tó jẹ onilu to ń lu ilu fun lábẹ omi.
Alhaja Kudirat Abiola pé ọdún mẹ́tàlélógún lónìí to wọ káà ilẹ̀ sùn, ọ̀pọ̀ ló gbàgbọ́ pé ìkú rẹ̀ kìí ṣe àmúwá ọlọrun nítori àwọn agbanípa ló pa a, nígbà ti ìjọba fi ọkọ rẹ̀ sẹ́wọ̀n.
Wọn mú ọkọ rẹ̀ nígbà ti wọn rii pe oun ló ń jawé olúbori nínú ìdìbò àpàpọ̀ orílẹ̀-èdè Nàìjíríà lọdun 1993.
'Ẹ dá owó padà f’áwọn ẹbí MKO Abiọla'
A bí Kudirat Abiola ni ọdún 1951 ní ilú Zaria, òun ni ìyàwó keji ti Abiola fẹ́, tó si bi ọmọ mẹ́fa.
Bí o tilẹ̀ jẹ́ pé oríṣirísi ìwádìí ló wáyé lẹ́yìn ikú Kudirat, ní ọ̀pọ̀ ọdún lẹ̀yìn ti ó ti kú, gẹ́gẹ́ bí ohun ti ìròyìn sọ, wọn pàṣẹ fún ènìyàn ẹlẹni mẹ́fà kan láti parí iṣẹ́ ọhun ni.
Wọ́n pa Kudirat sínú ọkọ rẹ̀ pẹ̀lú ìbọn, bẹ́ẹ̀ ni awakọ̀ rẹ̀ náà bá ìṣèlẹ̀ yìí lọ pẹ̀lú, ṣùgbọ́n olùrànlọ́wọ́ pàtàkì rẹ̀ tí wọn fẹ̀sùn kàn pé ó lọ́wọ́ nínú iku rẹ̀, to wà nínú ọkọ pẹ̀lú rẹ̀, kò fi ara pa rárá.
Lẹ́yìn ikú Kudirat Abiola ní wọn yíi orúkọ ilé iṣẹ́ rẹdíò tí wọn pé ni Radio Democracy, ti wọ́n ṣẹṣe dá sílẹ̀ ní Norway, pada sí Radio Kudirat.
Eyi waye pẹ̀lú àtilẹ̀yin àwọn orilẹede bii Amẹríkà, ilẹ̀ Gẹ̀ẹ́sì, Swedish, Danish àti ijọba Norway, lọna áti fí òpin si ìṣèjọba ológun ní Nàìjíríà pada, sí Radio Kudirat.
Ní ọdún 1998, òpópónà kan ni New York náà tún yi orukọ pada láti máà jẹ́ Kudirat Abiola Corner.
Lọ́dún 1998 bákan náà, Hamzat Al-Mustapha fara hàn nílé ẹjọ́ pẹ̀lú ọmọ ààrẹ ológun àna Abacha, Mohammed ti wọn fi ẹsùn ikú Kudirat Abiola kan.
Níbi ìgbẹ́jọ́ náà àwọn ti wọn jẹ́rìí pé àwọn ní àwọn pa Kudirat ni Sergeant Barnabas Jabila sọ pé àṣẹ Al-Mustapha ni àwọn tẹ̀lé.
Ní ọgbọ̀n ọjọ́ nínú oṣù kẹfà ọdún 2012, wọ́n dá ẹjọ́ ikú fún Hamza Al-Mustapha àti Alhaji Lateef Shofolahan lóri pípa Kudirat Abiola.
Ọlórí ẹ̀sọ́ ààrẹ ni Al-Mustapha jẹ́ nígbà ti Shofolahan jẹ olùránlọ́wọ́ pàtàkì fún olóògbé náà.
Ondo: Dejí sun ọmọ méje àtagbalagba meji mọ́lé nítorí pé ó ń bínú
UN General Assembly: Buhari ní ìgbà ọtun ni ìyànsípò Bande jẹ́ lẹ́ka òṣèlú
Oríṣun àwòrán, @BashirAhmad
Tijanni Bande
Tijanni Muhammed Bande ni wọ́n yan gege bi ààrẹ fún ipejopọ ajọ ìsọ̀kan agbaye ( UN General Assembly).
Tijani Bande je ọjọgbọn àti oga agba ile ẹkọ fasiti Usman Danfodiyo ti ìpínlẹ Sokoto nigba kan ri, kò ni enikẹni tí ó ba du ipò náà nínú ìdìbò tó wáyé lónìí ọjọ́ ìṣẹ́gun ní ìbi ìjokò ile ẹlẹkẹrinléni ààdọrin irú rẹ̀.
Muhammad Bande ni ọmọ orílẹ̀-èdè Nàìjíríà kejì tí yóò dé orí ipò náà, lẹ́yìn Joseph Garba tó jẹ ajagunfẹ̀yìntì, tó si tún jẹ asojú orílẹ̀-èdè Nàìjíríà lókè òkun.
Ọpọ ọmọ Naijiria le maa wo wi pe ki lorukọ aṣọ Tijanni Bande nile alaro Naijiria, Ta ni Ọ̀jọ̀gbọ́n Tijjani Bande tó di Ààrẹ ẹ̀ka Isọ̀kan Àgbáyé UNGA?
Garba jẹ oyè náà láàrin ọdún 1989 sí ọdún 1990.
Sáájú ìdìbò náà ní ààrẹ Muhammadu Buhari ti rán àwọn asojú ìjọba àpapọ̀ lọ láti lọ gbárùkù tí Muhammadu Bande.
Akọ̀wé àgbà fún ilé iṣẹ́ tó n ri si ọ̀rọ̀ ilẹ̀ okèrè Mustapha Suleiman, lo sáaju àwọn asoju ijọba,
Ladoja: Àwọn èèyàn Oyo fì ìbò sọ̀rọ̀ pé ìjọba Ajimobi kò dára
Ààrẹ Muhammadu ni ìgbà ọtun  yìí yóò fún orilẹ̀-èdè Nàìjíríà àǹfàní, láti pè fún ètò òṣèlú, ìgbáyegbadùn tó dára, eto ọ̀rọ̀ ajé to yanrantí àtí láti mu ọ̀rọ̀ àyíka tó n da gbogbo àye láàmu gbọ.
Ààrẹ Buhari ni orilẹ̀-èdè Nàìjíríà ń woye lọ́nà to gbòòrò, láti ba àwọn ọmọ ajọ ìsọkan àgbáye tó kù ṣiṣẹ́,eyi ti yoo mu ìtẹ̀síwáju ba ètò àlááfíà lágbàyé, ètò ààbò, dídènà wàhálà àti lati mú ki ìbáṣepọ̀ túbọ̀ gbópọ̀n si ni àgbáyé, riro àwọn ọ̀dọ́ àti àwọn obinrin lagbara, pẹ́lú fífàyè gba ẹ̀tọ́ ara ilú.
Sani Abacha Loots: $6.5m ni ilẹ̀ Ireland fẹ́ fún Nàíjíríà lára owó tí olórí ológun tẹ́lẹ̀ jí kó
Oríṣun àwòrán, Nigeria High Commision
Owo Abacha
Ko si ibi ti iranwọ ko ti lee dide fun ẹda, koda, oku gan n se iranwọ owo fun orilẹede Naijiria.
Bẹẹ ni ọrọ ri pẹlu owo ti adari ijọba ologun tẹlẹ lorilẹede Naijiria, Oloogbe Sani Abacha n fi ransẹ lati ajule ọrun ri bayii.
Idi ni pe orilẹede Naijiria tun ti n reti owo miran to jẹ eyi ti Abacha ko pamọ lasiko to n dari orilẹede yii.
Lọtẹ yii, orilẹede Ireland ni owo to to miliọnu mẹfa ati aabọ dọla ($6.5m) ti n bọ, eyi to to biliọnu meji ati aabọ owo Naira ilẹ wa.
The Polytechnic Ibadan: Ẹ̀rọ abẹ́lé tó ń fọ ọwọ́ àti ‘Ventilator’ ló ṣẹ̀ṣẹ̀ gbé jáde
Minisita feto idajọ ati agbẹjọro agba, Abubakar Malami lo sisọ loju ọrọ yii fun ileesẹ akoroyinjọ Reuters.
Minisita feto idajọ nilẹ Ireland, Helen McEntee ni owo naa jẹ eyi ti orilẹede rẹ gbẹsẹle lara owo ti Abach ji ko.
O ni ijọba ilẹ Naijiria ati Ireland si ti tọwọ bọ iwe adehun lori ọna ti wọn fi da owo naa pada silẹ wa.
Igba akọkọ si ree ti orilẹede Ireland yoo da owo Abacha pada eyi to gbẹsẹle lọdun 2014.
Mr Macaroni sọ nípa eré tí Fraky freaky, Sugar Daddy, You are doing well, freaky spicy fẹ́
Owo naa si jẹ ara biliọnu kan dọla ti wọn gbẹsẹle jakejado agbaye.
Bẹẹ ba gbagbe, eyi kii se igba akọkọ ti orilẹede Naijiria yoo gba owo ti Abacha ji ko pada lati ilẹ okeere.
Losu Karun ọdun 2020 yii, Naijiria gba ọọdunrun miliọnu dọla owo Abacha lati ọwọ ijọba ilẹ Amẹrika ati ẹkun Jersey.
Oríṣun àwòrán, @MaziAsochukwu
Ijọba ilẹ̀ Amẹ́ríkà tún ti sísọ lójú rẹ pé, owó tó to okoolelọọdunrun ó dín kan dọla ($319m), owó tí Abacha jí kò pamọ sì ìlú ọba, UK àti Faranse sì tún wà nilẹ.
Atẹjade kan ti ileesẹ aṣojú ìjọba Amẹ́ríkà fisita ni Ọjọru lo sísọ lójú ọ̀rọ̀ yìí pẹlu àfikún pé, ọgọ́jọ mílíọ̀nù àti méje dọla ($167m) ni Abacha ko pamọ sì ilẹ̀ Faranse nígbà tí mílíọ̀nù mejilelaadọjọ dọla ($152m) miran tún wà ní ilẹ̀ UK, tí wọn sì ti gbé ọ̀rọ̀ náà lọ sile ẹjọ́.
Atẹjade náà ni owó tuntun yìí, tí àpapọ̀ rẹ jẹ bílíọ̀nù lọ́nà mejidinlọgọfa náírà, (N118bn) tún yàtọ̀ sí aadọsan mílíọ̀nù dọla ó dín mẹta ($167m) tí ìjọba ilẹ̀ UK àti Faranse gbé ẹsẹ le, tó fi mọ mílíọ̀nù mejilelaadọjọ dola ($152m) miran ti wọn n bá ìjọba UK ṣe ẹjọ́ le lori.
Lọ́wọ́ lọ́wọ́ báyìí, ìjọba Nàìjíríà tí gbé ilẹ UK lọ sile ẹjọ́ láti gba àwọn owó náà, kò tó ko ìdá àádọ́rin fún Atiku Bagudu, tíì ṣe alájọsisẹpọ Sani Abacha, tí àdéhùn jọ wà láàrin òun àti ìjọba Nàìjíríà nípa owó náà.
Wo àwọn nǹkan mẹ́rin tó yẹ kó wà nínú báàgì rẹ lásìkò Covid-19 yìí
Oríṣun àwòrán, Nigeria High Commision
Owo Abacha
Akoójọ pọ iye ìgbà tí Nàìjíríà rí owó tí olórí ìjọba ológun tó ti di olóògbé, Sani Abacha kó pamọ si òkè òkun gbà, tó fi mọ $311m tí ilẹ̀ Amẹ́ríkà ṣẹ̀ṣẹ̀ fi ransẹ lọ́jọ́ Ajé.
Láti ọdún 1998 tí olórí ìjọba ológun tẹ́lẹ̀, ọgagun Sani Abacha tí dagbere faye, ọ̀pọ̀ ìgbà ni orílẹ̀ èdè Nàìjíríà tí rí owó tó ko pamọ sókè òkun gbà padà.
Loore koore sì ni ìjọba àpapọ̀ máa ń kéde pé owó tuntun wọlé láti ara owó Naijiria ti Abacha kò pamọ sókè òkun, tí àwọn ọmọ Nàìjíríà kò sì leè sọ iye tí àpapọ̀ owó náà jẹ́ báyìí.
Ìdí rèé tí BBC Yoruba fi ṣe ìwádìí nípa àkójọ pọ àwọn owó yìí, àwọn orílẹ̀ èdè tó tú àṣírí owó náà, tí wọn sì fún wa àti ọjọ́ tí ìjọba àpapọ̀ tẹ́wọ́ gba owó náà.
Bi ẹ bá sì rántí, ọjọ́ Ajé, ọjọ́ kẹrin, oṣù karùn-ún ni ìjọba Naijiria tún kéde pé, òun rí owó tó lè díẹ̀ ni mílíọ̀nù lọ́nà okoolelọọdunrun ó dín mẹsan an dọla ($311,797,866m) miran gbà padà láti orílẹ̀-èdè Amẹ́ríkà,
Eyi jẹ nínú owó ilẹ wá ti olórí ìjọba ológun náà fi ọ̀nà aitọ kó lọ sókè òkun.
Èyí sì ni àkójọ pọ owó ti Sani Abacha kò lọ sókè òkun, tí Nàìjíríà tí gbà pada:
* Oṣu karun un, ọdun 2002:
Ààrẹ tẹ́lẹ̀, Olusegun Obasanjo bá ìdílé Sani Abacha ṣe ẹjọ́ láti gba bílíọ̀nù kan àti ìgbà mílíọ̀nù dọla pada ni oṣù karùn-ún, ọdún 2002
Oṣu kọkanla, ọdun  2003:
Minisita feto isuna lọ́dún 2003, Ngozi Okonjo-Iweala kéde pé Nàìjíríà tún ti rí mílíọ̀nù lọ́nà mọkandinlaadọjọ dọla ($149m) gbà láti Jersey Island.
Nínú owó tí Abacha jí kó lọ sókè òkun, ní oṣù kọkànlá ọdún 2003.
Irokotọla: Báwo ló ṣe rọrùn láti fi àmì sí ọ̀rọ̀ yìí, ‘Irokotọla’
*Oṣu kẹsan an, ọdun 2007:
Minisita feto isuna lọ́dún 2007, Nenadi Usman náà tún kéde pé, Nàìjíríà tún ti rí bílíọ̀nù méjì àti àbọ̀ dọla ($2.5bn) owó tí Sani Abacha kó pamọ sókè òkun gba.
Ó ní owó ohun ni ìjọba pín fún ileesẹ tó wà fún ohun amusagbara, isẹ òde, eto ìlera, ètò ẹ̀kọ́ àti ohun àlùmọ́ọ́nì inú omi láti fi ṣe àkànṣe isẹ.*Ọdún 2014:
Minisita feto isunna, Ngozi Okonjo-Iweala tún padà kéde pé mílíọ̀nù lọ́nà ẹẹdẹgbẹta dọla ($500m), tí ìjọba Olusegun Obasanjo tún rí gbà lára owó tí Sani Abacha kò lọ sókè òkun,
táwọn sì ti lo owó náà fún isẹ ìdàgbàsókè agbègbè.
Asa Trokosi nibi ti ọmọde ti n jiyan ẹsẹ mọlẹbi rẹ , wọpọ  ni Ghana, Togo ati Benin.
*Oṣu kẹfa, ọdun 2014:
Nígbà tó tún di oṣù kẹfà, ọdún 2014 ni Lienchtenstein tún dá mílíọ̀nù lọ́nà okòólénígba àti méjì dọla ($227m) padà fún Nàìjíríà gẹ́gẹ́ bíi ara owó tí Sani Abacha jí kò lọ sókè òkun*Oṣu kẹjọ,ọdun  2014:
Ileesẹ ètò ìdájọ́ ni orílẹ̀-èdè Amẹ́ríkà, ní ọjọ́ keje, oṣù kẹjọ ọdún 2014 kéde pé, owó tó tíì pọju nínú ìtàn orílẹ̀-èdè náà, tí àwọn yóò tíì dá padà ní mílíọ̀nù lọ́nà ọrinlenirinwo dola ($480m),
Eyi tàwọn fẹ́ gbé fún ìjọba Nàìjíríà, tíì ṣe ara owó tí Sani Abacha fi ẹyin pọn wá si orílẹ̀ èdè awon*ọdún 2016:
Orílẹ̀ èdè Switzerland náà fìdí rẹ múlẹ̀ pé, òun ti dá owó tó tó mílíọ̀nù lọ́nà okoolelẹẹdẹgbẹrin àti mẹta dọla ($723m) padà fún ìjọba Nàìjíríà lára owó tí Abacha jí kò, táwọn si gbé ẹsẹ le lọ́wọ́ mọlẹbi rẹ
*Oṣu kejila, ọdun 2019:
Oṣù Kejìlá, ọdún 2019 ni orílẹ̀-èdè Switzerland tún kéde pé, òun fe dá mílíọ̀nù lọ́nà
Okoolelọọdunrun àti ẹyọ kan dọla ($321m) padà fún ìjọba Naijiria lati inu owó tí Sani Abacha ko lọ sókè òkun
*Ọjọ karun un, oṣu karun un, ọdun 2020:
Ìjọba Nàìjíríà kéde pé, òun tún ti gba owó tó lè díẹ̀ ni mílíọ̀nù lọ́nà okoolelọọdunrun ó dín mẹsan an dọla ($311,797,866m) míràn gba lọ́wọ́ ilẹ Amẹ́ríkà lára owó tí Sani Abacha ko lọ sókè òkun.
Owó wọgbó! Gẹ̀ẹ́sì gbẹ́sẹ̀ lé ₦82bn owó Abacha
Abacha Loot: Ilẹ̀ Gẹ̀ẹ́sì rí owó Abacha bíi owó ọ̀daràn, ló ṣe gbẹ́sẹ̀ le
Wọ́n tún ti rí lára owó tí olórí orílẹ́èdè Nàìjíríà tẹ́lẹ̀, olóògbé Sani Abacha kó lọ sílẹ̀ òkèrè.
Ẹgbẹlẹgbẹ owo to to biliọnu mejilelọgọrin naira (£211m) to jẹ ti olori tẹlẹ fun orilẹede Naijiria, oloogbe Ọgagun Sani Abacha, ni wọn ti ri nile ifowopamọ Jersey bank nilẹ okeere.
Abacha, to jẹ olori orilẹede Naijiria laarin ọdun 1993 si 1998 to ti jalaisi, niroyin sọ pe o kowo naa lọ si Channel Islands nilẹ Yuropu, lati ilẹ Amẹrika.
Iwe iroyin Metro nilẹ Gẹẹsi fidi rẹ mulẹ pe, ninu apo aṣuwọn ile iṣẹ Doraville Properties Corporation ni ile ifowopamọ Jersey ti ri owo naa.
Ni bayii, ijọba ilẹ Gẹẹsi ti gbẹsẹ le owo naa titi digba ti awọn alaṣẹ Jersey, ilẹ Amẹrika ati Naijiria ba sọ asọyepọ lori bi wọn yoo ṣe pin owo naa.
Ijọba ilẹ Gẹeṣi maa n gbẹsẹ le owo kowo ti wọn ba ri ni ilu Jersey, ijọba maa n ri owo bẹe bi owo ti awọn ọdaran ji ko.
Ladoja: Àwọn èèyàn Oyo fì ìbò sọ̀rọ̀ pé ìjọba Ajimobi kò dára
Ijọba maa n lo iru owo bẹẹ fun idagbasoke agọ ọlọpaa kaakiri ilẹ Gẹẹsi, ati fun awọn oriṣiiriṣii akanṣe iṣẹ miiran.
Ẹgbẹlẹgbẹ owo ti oloogbe Abacha ko pamọ silẹ okeere nigba to wa lori oye ni ijọba Naijiria ti gba.
Adesoji Aderemi: Ọba Yorùbá tó tiraka láti dí àlàfo láàrin olówó àti olòṣì
Oríṣun àwòrán, Adesoji Aderemi Family
Adesoji Aderemi: Ọba Yorùbá tó tiraka láti dí àlàfo láàrin olówó àti olòṣì
Ti a ba n sọrọ awọn oriade nilẹ Yoruba, ọkan pataki ni Ọba Ọlọla Titus Martins Adesọji Tadeniawo Aderẹmi, Atọbatẹlẹ Kinni, tii se Ọọni tilu Ile Ifẹ.
Oun ni ọba alaye akọkọ ti yoo pa ipo ọba mọ sise olootu ijọba lẹkun Iwọ Oorun Guusu Naijiria ijọhun.
Eeyan ko si lee pe ori akọni, ko ma fi ida lalẹ gaaraga ni ọrọ Ọba Aderẹmi, tI a ba wo bi ori ade naa se lami-laaka si nigba to wa loke eepẹ.
O jẹ ara awọn eeyan to kọkọ laju, o kọ ẹkọ iwe, o lowo, o lọla, o gbajumọ, o si jẹ asaaju ilu.
Ko si si bi a se maa sọ nipa itan awọn ọmọ Oodua to jẹ akinkanju ati ọlọpọlọ pipe, ti a ko ni sọrọ Ọba alaye naa.
Ko wọpọ rara lasiko tirẹ ki odidi ọba ilu nla bii ilu Ile Ifẹ, tun maa se akoso ẹkun rẹ, tii se ipo oselu.
Gẹgẹ bi a se ka a ninu akọsilẹ oju opo ayelujara Wikipedia, ipa ti Ọba Adesọji Aderẹmi ko lati di alafo to wa laarin olowo ati ọlọrọ kii se keremi.
Bakan naa lo tun fi igbe aye rẹ silẹ fun ilọsiwaju awọn ọmọ Yoruba ati ilẹ Kaarọ Oojire lapapọ.
Oríṣun àwòrán, Adesoji Aderemi Family
O jẹ ọkan lara awọn eeyan to kọkọ laju, o kọ ẹkọ iwe, o lowo, o lọla, o gbajumọ, o si jẹ asaaju ilu.
Adesọji Aderẹmi ti pe ogoji ọdun ti ọba naa papoda bayii, ko si ni dara ki iran asiko yii ma mọ ẹni ti Ọba Adesọji Aderẹmi se
O si tun yẹ ki wọn mọ awọn ipa ribiribi to ti ko si igbega iran rẹ, bi o tilẹ jẹ pe onirese rẹ ko fin igba mọ, amọ ko yẹ ka jẹ ki eyi to fin silẹ parun.
O tun jẹ alaga titi laelae fun igbimọ awọn lọbalọba lẹkun Iwọ Oorun Guusu Naijiria, bẹrẹ lati ọdun 1966 si 1980 to darapọ mọ awọn baba nla rẹ
Ọba Adesọji Aderẹmi jẹ gomina fẹkun Iwọ Oorun Guusu Naijiria ijọun laarin ọdun 1960 si 1962, nitori pe o tun jẹ ogbontarigi oloselu yatọ si pe o jẹ ọba alaye
Oun si ni alawọ dudu akọkọ ti yoo jẹ gomina ni awọn agbegbe ti ilẹ Gẹẹsi n dari, ọwọ eebo Ọlọla John Ranklin si lo ti gba ipo naa
Lasiko isejọba amunisin, Ọba Adesọji Aderẹmi gba agbara kun agbara lọwọ awọn ajẹlẹ, tawọn oyinbo gan si kọ nipa asa ati ise ilẹ Kaarọ Oojire lọwọ rẹ
Ẹkọ wo ni a ri kọ lara Ọba Adesọji Aderẹmi?
Bi o tilẹ jẹ pe ofin ilẹ wa ko gba awọn ọba alaye laaye mọ lati maa kopa ninu oselu, amọ o yẹ ki wọn fi igbe aye Ọba Adesọji Aderẹmi se awokọse rere.
O si yẹ ki wọn maa lo agbara wọn fi mu ilọsiwaju alailẹgbẹ ba agbegbe wọn.
O si tun yẹ ka kọ ẹkọ pe, aisi baba abi iya ko ni ki ọmọ ma mọ ohun to fẹ se lati di eeyan nla lọjọ ọla.
Oríṣun àwòrán, Adesoji Aderemi family
Ọba Adesọji Aderẹmi ni ọpọ iyawo ati ọmọ, alagbo nla si la le e pe, ọkan ninu awọn ọmọ rẹ si ni Arabinrin Tẹjumade Alakija, to ti di oloogbe
A wa gbadura pe Ọlọrun yoo tubọ dẹ ilẹ fun ni Ọba Ọlọla Titus Martins Adesọji Tadeniawo Aderẹmi, Atọbatẹlẹ Kinni, tii se Ọọni tilu Ile Ifẹ to se gudugudu meje ati yaya mẹfa fun iran Yoruba.
Ọba Adesoji Aderemi wàjà ni ọjọ́ Kẹta, oṣù Keje, ọdún 1980.
Nikesuliat: Ọ̀dọ́mọdébìnrin akéwì tó n fi ẹ̀ṣà kìlọ̀ ìwá lásìkò yìí
Guru Maharaji: Ó yẹ kí ìjọba àpapọ̀ fíkún owó oṣù òṣìṣẹ́ àti ti adájọ́
Ààrẹ Buhari fí mí jẹ olùrànlọ́wọ́ pàtàkì lóri epo rọ̀ọ̀bì- Guru Maharaji
Ohun tó ba ń dun ni, ṣebí wọ́n ni òhun ló máa ń pọ̀ lọ́rọ́ ẹni, adari àti olùdásilẹ̀ One Love Family, Sat Guru Maharaji ti ke pe ààrẹ Muhammedu Buhari, láti yan òun gẹ́gẹ́ bi olùbádámọ̀ràn pàtàkì fọ́rọ̀ epo rọ̀bi.
Maharaji kesi aarẹ Buhari bẹẹ, lasiko ipade akọroyin to se eyi to fi n sami ajọdun ọdun kẹrindinlọgbọn to kede Naijiria bii ilẹ mimọ lagbaye.
Maharaji ní èyí se pàtàkì gẹ́gẹ́ bi àwọn ẹlẹ́sìn àti olóri ẹ̀sìn to kù ṣe ń kùnà, ó ní ọ̀kan nínú àwọn èròńgbà òun ni pe kí ààrẹ yan òun láti máá moju to ile iṣẹ́ ọ̀rọ̀ omi àti àlùmọ́ni, ilé iṣẹ́ ọ̀gbìn àti ọ̀rs epo rọ̀ọ̀bi àti afẹ́fẹ́.
Yàtọ̀ si èyí, Guru Maharaji ní ó yẹ ki ìjọba àpapọ fí kún owó oṣù òṣìṣẹ́, kí wọ̀n si mú kí ìgbáyégbádùn àwọn adájọ lọkunkundun, kí wọ́n ma ba máá ṣe ojúkokoro láti gba àbẹ̀tẹ́lẹ̀.
Ladoja: Àwọn èèyàn Oyo fì ìbò sọ̀rọ̀ pé ìjọba Ajimobi kò dára
Olórí ẹ̀sin ọ̀hun ní, o ṣe pàtàkì ki wọ́n se ìdásílẹ̀ àwọn ọlọ́pàá ìpínlẹ̀ nítori pe, èyí yóò mú ki ààbò to dáju wà láárín àwùjọ.
8th National Assembly: Ilé ìgbìmọ̀ aṣòfin kẹ̀jọ kógbá sílé lónìí
Oríṣun àwòrán, Twitter/The Senate President
Ile Igbimọ aṣofin kẹjọ
Oni ọjọ kẹfa, oṣu kẹfa, ọdun 2019 ni ile igbimọ aṣofin agba ikẹjọ l'Abuja yoo kogba sile.
Koda, adari ile Sẹnẹtọ Bukọla Saraki naa yoo dagbere fun ile aṣofin lẹyin to fidi rẹmi ninu idibo gbogboogbo to lọ.
Ọpọ lo ti tako awọn aṣofin laarin ọdun to kọ ja ti wọn ti n ṣofin ni olu ilu Naijiria, Abuja.
Ṣugbọn iwadii fidi rẹ mu lẹ pe ile igbimọ aṣofin agba kẹjọ to n ko gba sile lonii lo ṣaṣeyọri julọ ninu itan eto oṣelu orilẹ-ede Naijiria.
Eyi ni diẹ lara awọn aṣeyọri ile igbimọ aṣofin agba kẹjọ l'Abuja.
'500 level'' ni mo wà nígbà tí mo di adélé Ọba'
Gbigbe eto iṣuna ile sita
Lẹyin ọpọ atotonu awọn ọmọ orilẹ-ede Naijiria, ile igbimọ aṣofin fi eto iṣuna ile sita lọdun 2017.
Eyi ni igba akọkọ ti iru rẹ yoo ṣẹlẹ lati ọdun 2010 ti adari ile tẹlẹ, David Mark ti n ṣe ọrọ eto iṣuna ile ni oku oru.
Oríṣun àwòrán, Twitter/The Senate President
Ijiroro gbagade lori eto iṣuna ile
Ile igbimọ aṣofin agba l'Abuja ṣe ijiroro gbagade ẹlẹẹkẹta iru rẹ lori eto iṣuna ile ninu oṣu kẹta, ọdun 2019.
Ile bẹrẹ eto yii labẹ adari Sẹnẹtọ Bukola Saraki lọdun 2016. Eto yii ti fun ọpọ ọmọ Naijiria lanfaani lati beere oniruuru ibeere lori eto iṣuna ile.
Ajayi: ṣé  ìwọ mọ irúfẹ́ ọmọ tí Yorùbá ń pè bẹ́ẹ̀?
Ofin ọdọ o kere lati ṣejọba
Ile igbimọ aṣofin gbe abadofin ọdọ o kere lati ṣejọba lọ siwaju Aarẹ Muhammadu Buhari, eleyi ti aarẹ buwọlu lọdun 2018.
Ofin naa din ọjọ ori awọn oludije fun ipo aarẹ ku lati ogoji ọdun si ọdun marundinlogoji, ati tawọn gomina ku lati ọdun marundinlogoji si ọgbọn ọdun.
Ṣisẹ ofin to pọju lọ
Oríṣun àwòrán, Twitter/The Senate President
Ile igbimọ aṣofin agba kẹjọ ṣiṣẹ lori abadofin to din meje lọọdunrun un(293) lati igba ti wọn ti bẹrẹ di oṣu karun un, ọdun 2019.
Meji din ni aadoje(128) ni ile igbimọ aṣofin keje le ṣiṣẹ le lori, nigba ti ile kẹfa ṣiṣẹ ofin mejilelaadọrin (72).
Eto aabo
Lootọọ, kii ṣe ojuṣe ile aṣofin lati pese eto to mọnyan lori fawọn ara ilu, ṣugbọn ile aṣofin kẹjọ ṣe apero lori eto aabo ninu oṣu keji ọdun 2019.
Yatọ si apero yii, ile jiroro lọsọọsẹ lori bi eto aabo yoo ṣe gbopọn si lorilẹedee Naijiria bo tilẹ jẹ pe diẹ ninu aba wọn ni igbimọ alaṣẹ ṣiṣẹ le lori.
A kii mọ rin, kori o ma min, eyi ni awọn kudiẹkudiẹ ti ile igbimọ aṣofin agba kẹjọ ni, bi wọn ti kogba sile lonii.
Ondo: Dejí sun ọmọ méje àtagbalagba meji mọ́lé nítorí pé ó ń bínú
Yinka Ayefẹlẹ: Àdúrà lẹ ṣe pé mo bí ìbẹta, yóò sì rí bẹ́ẹ̀
Oríṣun àwòrán, yinkaayefele
Yinka Ayefẹlẹ: Àdúrà lẹ ṣe pé mo bí ìbẹta, yóò sì rí bẹ́ẹ̀
Gbajugbaja akọrin Tungba nni, Yinka Ayefẹlẹ ti kigbe sita faraye pe oun ko bi ibẹta gẹgẹ bi awọn eeyan kan ti n tan iroyin naa kalẹ lawọn oju opo ikansiraẹni lori ayelujara.
Yinka Ayefẹlẹ, loju opo Instagram rẹ ti salaye pe ofo, ọjọ keji ọja ni iroyin kan to n ja rain-rain nilẹ pe iyawo oun bi ibẹta ni orilẹede Amẹrika ni owurọ ọjobọ.
O ni aworan oun ati iyawo oun ti wọn lo lati fi kọ iroyin naa jẹ eyi ti awọn jọ ya ni ọdun meje sẹyin lasiko ikomọ ọmọ aburo oun nilu Ibadan.
Ayefẹlẹ wa rawọ ẹbẹ sawọn ololufẹ rẹ pe ki wọn kẹyin si iroyin eke naa ati aworan ofege to n gbe kiri.
Oríṣun àwòrán, yinkaayefele
Mo dupẹ lọwọ gbogbo yin pe ẹ ro ire ro emi ati ẹbi mi, mo si gbadura pe yoo ri bẹ ti wi ni orukọ Jesu.
Ọpọ awọn eeyan loju opo Instagram naa si lo n gbarata lori iroyin ofege naa.Gbajugbaja akọrin Tungba nni, Yinka Ayefẹlẹ ti kigbe sita faraye pe oun ko bi ibẹta gẹgẹ bi awọn eeyan kan ti n tan iroyin naa kalẹ lawọn oju opo ikansiraẹni lori ayelujara.
Pẹ̀lú gbogbo bùkátà, Bàbá 80 gboyè Masters
CAF Champions League: CAF pàṣẹ àtúngbá ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ àṣekágbá CAF Champions League
Oríṣun àwòrán, Getty Images
CAF ní ifẹ ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ àṣekágbá tí wọ́n kọ́kọ́ gbá tako àṣẹ àtò ìdíje bọ́ọ̀lu
Ajọ to n ṣakoso ere bọọlu afẹsẹgba ni ilẹ Afirika, CAF ti paṣẹ ki wọn tun ifẹsẹwọnsẹ aṣekagba idije CAF Champions league to waye ni ọjọ kọkanlelọgbọn oṣu karun ọdun 2019 gba.
Bi o tilẹ jẹ pe igbesẹ ati aṣẹ ọhun ṣe ọpọlọpọ onwoye ere bọọlu afẹsgba ni haa-hinn, ajọ CAF ni bi eto ati ato gbogbo ṣe lọ si lasiko ifẹsẹwọnsẹ naa ku diẹ kaa to eyi lo si faa ti oun fi gbe igbesẹ atungba ifẹsẹwọnsẹ naa.
Nibi ipade igbimọ alaṣẹ ajọ CAF to waye ni ilu Paris lorilẹede France lọjọru ni aṣẹ yii ti jade.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Lara awọn ohun ti gbogbo ọmọ igbimọ naa fẹnuko si ni iwọnyii:
Offa Robbery: Àwọn aráàlú ṣi n gbé nínú ìpaya lẹ́yìn ọdún kan
Emir Kano: Ganduje fẹ̀sùn ìkọ́wójẹ kan Emir Sanusi
Oríṣun àwòrán, @Lamidoofficial
Ajọ tó ń gbógun ti ìwá àjẹbánu àti gbigbọ́ ẹ̀sun ara ìlú ní ìpínlẹ̀ Kano ló fẹ̀sún kan Emir tí wọn si dábàá pé kí Emir lo rọ́kun nílé.
Gómìnà ìpínlẹ̀ Kano, Abdullahi Ganduje tí fún Emir Kano, Muhammadu Lamido Sanusi keji ní ìwé wá wi tẹnu rẹ lọ́nìí ọjọ́bọ̀, lóri ẹ̀sùn pé ó ṣe owó mọ́kumọ̀ku.
Ajọ tó ń gbógun ti ìwá àjẹbánu àti gbigbọ́ ẹ̀sun ara ìlú ní ìpínlẹ̀ Kano, ló fẹ̀sún kan Emir tí wọn si dábàá pé kí Emir lo rọ́kun nílé.
Olóri oṣisẹ̀ láàfin Emir, Munir Sanusi tó jẹ́ri si gbigba ìwé ẹsùn náà, sọ pe, ìjọba ní ki Emir fesi láàrin wákàti mẹ́rìnlélogun lóri ẹ̀sùn náà.
"''A ti gba ìwé ẹ̀sún náà, ìjọba si ti bèèrè fún èsì láàrin wákàtí mẹ́rinlélógún. Awọn ìjòye Emir ń fojú sùnukùn wó ẹ̀sùn náà""."
Saraki: Àwọn aṣòfin àpapọ̀ ṣ'àfihàn ìṣọ̀kan lásìkò tí jàǹdùkù jí ọ̀pá àṣẹ ilé gbé
Oríṣun àwòrán, @NGRSenate
Sáà kẹjọ ilé aṣòfin àpapọ̀ parí ní Ọjọ́bọ̀, ọjọ́ kẹfà oṣù kẹfà ọdún 2019
Aarẹ ile aṣofin agba, Bukọla Saraki ti ṣalaye ọjọ ti inu rẹ bajẹ julọ lasiko to fi jẹ aarẹ fun ile aṣofin apapọ lorilẹ-ede Naijiria.
Ninu ọrọ idagbere rẹ lo ti sọ eyi nibi eto idagbere ti ile aṣofin saa kẹjọ ṣe ni ọjọbọ.
Saraki wa lara awọn aṣofin ti ko ni pada fun saa tuntun mọ ni ile aṣofin apapọ orilẹ-ede Naijiria ti yoo bẹrẹ saa kẹsan an ni ọjọ kọkanla, oṣu kẹfa,  ọdun 2019.
Ladoja: Àwọn èèyàn Oyo fì ìbò sọ̀rọ̀ pé ìjọba Ajimobi kò dára
Saraki ni ọjọ ti awọn janduku wa da ile aṣofin ru ti wọn si ji ọpa aṣẹ ile naa gbe ni o ba oun ninu julọ.
O ni ọjọ yii yoo duro ninu itan gẹgẹ bii ọjọ ti awọn eeyan kan jẹ eewọ nitori aidọgba ironu lori oṣelu.
O ni lẹyin o rẹyin iṣẹlẹ naa ja sayọ ni nitori o fun awọn aṣofin lanfani lati fi ẹsẹ wọn tilẹ pe aguda awọn ko jẹ labẹ Gẹẹsi ẹnikẹni tabi ẹka iṣejọba kankan.
Ọjọ naa yi pada lati di ọjọ afihan okun ọmọ iya to wa laarin ile yii ati awọn aṣoju-ṣofin, pẹlu bi awọn aṣofin naa ṣe dide lati gbaruku ti awọn aṣofin agba lati koju awọn to wọ ile naa.
Bakan naa, lo ni lara ohun ti awọn to dide ogun si ile aṣofin apapọ ṣe ni ti awọn agbofinro to ṣingun wọ gbagede ile aṣofin apapọ ni oṣu kẹjọ, ọdun 2018.
Saraki ni eyi yoo wa ninu iwe itan, ṣugbọn awọn aṣofin dide lati gba ara wọn silẹ.
Pẹ̀lú gbogbo bùkátà, Bàbá 80 gboyè Masters
DAAR Communications: AIT, RayPower padà lẹ́yìn àṣẹ ilé ẹjọ́
Oríṣun àwòrán, @AIT
NBC: AIT kọ̀ láti tẹ̀le ìlànà òfin ìgbóhùnsáfẹ́fẹ́ Naijiria
Ileeṣẹ amohunmaworan AIT ati ti asọrọmagbesi RayPower FM pada si ori afẹfẹ.
Lẹyin ti Ile ẹjọ giga ti ijọba apapọ to wa ni Abuja paṣẹ pe ki ajọ to n mojuto ọrọ igbọhunsafẹfẹ ni Naijiria (NBC) ti ọwọ ọmọ rẹ bọ aṣọ fun igba diẹ lori ọrọ DAAR Communications, AIT ati RayPower FM ti pada sori afẹfẹ.
Ajo naa ti awọn ileeṣẹ DAAR Communications, AIT ati Raypower lori ẹsun aṣemaṣe ni ọjọbọ, eyi to mu ọpọ awọn eniyan bẹnu ẹ̀tẹ́ lu igbesẹ ajọ naa.
Ṣugbọn ile ẹjọ ni kí ajọ NBC lọ ni suuru titi di igba ti wọn yoo fi dajọ lori ẹjọ ti DAAR Communications fi ta ko igbeṣẹ ajọ naa.
Ninu idajọ rẹ lori ọrọ naa ni ọjọ Ẹti, Adajọ Inyang Ekwo ni ki gbogbo awọn ti ọrọ kan pada si bi ọrọ ṣe ri ni ọgbọn ọjọ, oṣu karun un.
Adajọ naa kepe ajọ NBC, ileeṣẹ ijọba apapọ lori iroyin ati agbẹjọro agba ti Naijiria, lati farahan ki wọn si sọ idi ti ile ẹjọ ko fi gbọdọ da aṣẹ NBC lori ọrọ naa danu ni ọjọ kẹtala, oṣu kẹfa nigba ti wọn yoo tun gbọ ẹjọ naa.
Oríṣun àwòrán, @daar
DAAR Communications: AIT kò kọ̀ láti tẹ̀le ìlànà òfin ìgbóhùnsáfẹ́fẹ́ Naijiria
Ṣíwájú lórí ọ̀rọ̀ náà:
Ẹgbẹ awọn akọroyin ti pàṣẹ ìyípadà laarin ọjọ kan.
Ẹgbẹ awon akoroyin Naijiria ti a mọ si Nigerian Union of Journalists ti paṣẹ pe ki ajọ NBC tun ero wọn pa.
Wọn ni awọn fun ajọ NBC ni wakati mẹrinlelogun pere ki wọn fi gbesẹ kuro lori ọrọ ileeṣẹ igbohunsafẹfẹ AIT ati Ray Power.
Chris Isiguzo to jẹ aarẹ ẹgbẹ naa lo ni awada ni oun kọkọ pe ọrọ naa tẹlẹ nigba ti oun gbọ ki oun to fidiẹ mulẹ pe ootọ ni.
O ni oun ko gbagbọ pe iru eyi le waye lasiko ijọba awa ara wa nilu to ni Ọba to ni ijoye.
NUJ: Ẹ̀yin Akọ̀ròyìn, ẹ sọ́ra nípa kíkọ ìròyìn tó léwu fétò ààbò
O ni igbesẹ NBC yii ko faaye gba ominira awọn akoroyin to yẹ ko wa ni Naijiria bayii.
Odebiyi: ìgbà gbogbo ni Bàbá mi ń polówó iṣẹ́ mi fáráyé
Alaga NUJ ni oun gbagbọ pe awọn ọna miran wa to yẹ ki ajọ NBC gbe lati fidi ofin wọn mulẹ ju ki wọn ṣe oun to tabuku gbogbo ẹgbẹ.
O ni oun kọ lati fọwọ lẹran lori ọrọ yii ati p\w ohun ti ẹgbẹ n fẹ ni ki ajọ NBC tete yi ipinnu rẹ pada.
Bawo ni ọrọ ṣe jẹ tẹlẹ?
Ileeṣẹ amohunmaworan AIT wa lara awọn ileeṣe aladani akọkọ ni Naijiria.
Wọn gba àṣẹ̀ ìgbóhùnsáfẹ́fẹ́ lọ́wọ́ iléeṣẹ́ AIT àti Ray Power.
Oríṣun àwòrán, @AIT
NBC: AIT kọ̀ láti tẹ̀le ìlànà òfin ìgbóhùnsáfẹ́fẹ́ Naijiria
Àjọ National Broadcasting Commission to n mójútó ọ̀rọ̀ ìgbóhùnsáfẹ́fẹ́ ní Naijiria ti gba àṣẹ̀ ìgbóhùnsáfẹ́fẹ́ lọ́wọ́ iléeṣẹ́ AIT àti Ray Power lọjọbọ.
Wọn ni ki ileeṣẹ African Independent Television ati Ray Power FM lọ rọọkun nile na.
NUJ: A fẹ mọ ẹsẹ awọn akọroyin tẹ da duro
Omowe Modibo Kawu to jẹ adari ajọ NBC ti ṣalaye pe ileeṣẹ amohunmaworan AIT kii san owo idiyele ominira lati ṣiṣẹ wọn lasiko.
O ni bakan naa ni AIt kii bọwọ fun ofin igbohunsafẹfẹ.
Pẹ̀lú gbogbo bùkátà, Bàbá 80 gboyè Masters
Kawu ni AIT ṣafihan iṣẹ iwadii kan lasiko idibo to kọja ni Naijiria, eyi ti ọrọ eto idibo aarẹ nipa rẹ dẹ ṣi wa nile ẹjọ.
O tun ni wọn maa n ṣafihan awọn nkan to le fa wahala lawujọ ninu eto araarọ wọn ti wọn pe ni Kakaki Social.
Oga agba fun ajọ NBC ni ọpọ igba ni awọn ti ri ẹsun gab lati ọdọ awọn ara ilu lori akoonu eto tile iṣẹ AIT ati Ray Power n gbe jade.
Oríṣun àwòrán, other
O tun ni wọn maa n ṣafihan awọn nkan to le fa wahala lawujọ ninu eto araarọ wọn ti wọn pe ni Kakaki Social.
O ni ajọ NBC ti fawọn leti lọpọ igba paapaa lasiko eto idibo Naijiria to kọja ki wọn le so ewe agbejẹ mọwọ.
Bayii ni ajọ NBC ti kede pe ileeṣẹ mejeeji to jẹ ti DAAR Communications ko gbọdọ ṣiṣẹ titi awọn yoo fi gbẹsẹ kuro lori ofin to de wọn yii.
Asisat Oshoala: ìbẹ̀rẹ̀ mi kò rọrùn rárá nínú eré bọ́ọ̀lù
Ki lo ti ṣẹlẹ tẹlẹ?
Laarọ ọjọbọ ni ọga agba  fún ileeṣẹ DAAR Communications, Raymond Dokpesi ti ṣaaju awọn eniyan rẹ lọ ṣe iwọde ko tẹ mi lọrun kaakiri ilu Abuja.
Ni olu ilu Naijiria, ni Dokpesi ti fẹhonuhan pe ko yẹ kijọba tile iṣẹ oun pa.
Kinni AIT ri sọ si ọrọ yii?
Raymond Dokpesi to ni DAAR Communications ti ṣalaye pé awọn ko tete san owo idiyele igbohunsafẹfẹ ti saa yi nitootọ.
O ni idi ti eyi fi ri bẹẹ ni pe gbogbo wọn gba pe ẹẹdẹgbẹta miliọnu naira ti ajọ NBC ni ki ileeṣẹ aladani san ti pọju ni.
Ajayi: ṣé  ìwọ mọ irúfẹ́ ọmọ tí Yorùbá ń pè bẹ́ẹ̀?
O ni eyi lo jẹ ki ẹgbẹ awọn onile iṣẹ akọroyin BON fẹnuko pe eto ọrọ aje Naijiria ko burẹkẹ to lasiko yii.
Bakan naa ni Dokpesi sọrọ lori eto Kakaki ti NBC fi ẹsun kan pe, eto naa wa fun ero inu awọn ara ilu.
O mẹnuba ominira lati sọrọ ti ara ilu yẹ ko ni ni Naijiria bayii.
Celestine Egbunuche: Òun àti ọmọkùnrin rẹ̀ ti lo ọdún 18 l‘ẹ́wọ̀n, kó tó rí ìdáǹdè
Oríṣun àwòrán, Global Society for anti corruption
Yoruba ni bi isẹ ba sẹ ọmọ fun ogun ọdun, ti iya ba jẹ ọmọ fun ọgbọn osu, bi ko ba pa ọmọ, yoo kuku pada lẹyin ọmọ ni.
Bẹẹ ni ọrọ baba ẹni ọgọrun ọdun kan ri, Celestine Egbunuche, ẹni ti ijọba tu silẹ ni ọgba ẹwọn lẹyin ọdun mejidinlogun to ti fi asọ penpe ro oko ọba.
Ohun to wa jẹ kayeefi pẹlu baba yii ni pe oun ati ọmọkunrin rẹ, Paul, ni wọn dijọ dajọ ẹwọn fun lori ẹsun pe wọn gbindanwo lati seku pa eeyan kan.
Celestine Egbunuche, ni ẹgbẹ kan ti kii se tijọba, eyi to n gbogun ti iwa ajẹbanu, Global Society for Anti Corruption (GSAC), ja fun idande rẹ rẹ ati ọmọ rẹ lọgba ẹwọn.
Amọ baba naa, ẹni to ti n se aisan atọgbẹ, ti ko si riran daada, ni ijọba tu silẹ lọgba ẹwọn to wa nilu Enugu, ti ọmọbinrin rẹ, Chisom Celestine ati awọn asoju ẹgbẹ GSAC, si lọ pade rẹ ni kede ti wọn tu silẹ lọgba ẹwọn ọhun.
Oríṣun àwòrán, Global Society for anti corruption
Nigba to n ba ikọ iroyin BBC sọrọ, Chisom Celestine salaye pe inu oun dun pupọ pe baba oun pada ri itusilẹ lọgba ẹwọn sugbọn o se oun laanu pe oun ko ni agbara lati lee setọju baba naa bo se yẹ.
Lọwọ-lọwọ bayii, wọn ti gbe baba Celestine lọ sile iwosan fun itọju, ti ko si si ẹni to lee sọ ohun ti yoo sẹlẹ sii nitori Paul, ọmọ baba naa lo n tọju rẹ lasiko ti awọn mejeeji wa lọgba ẹwọn.
Odebiyi: ìgbà gbogbo ni Bàbá mi ń polówó iṣẹ́ mi fáráyé
Saa isejọba gomina Rochas Okorocha ni ipinlẹ Imo, to bẹbẹ fun isiju aanu wo baba naa ti kogba wọle, ti ijọba tuntun si ti wa nijọba, a ko si mọ boya o seese ki wọn seto iranwọ fun baba naa.
Adewale Ayuba: Ogun ń ja àgbo Fújì, ni wọ́n ṣe ń jà
Oríṣun àwòrán, @officialayuba
Ilumọọka olorin Fuji, to jẹ odu, ti kii se aimọ fun oloko, Ọmọwe Adewale Ayuba ti woye pe, ogun lo n ja awọn olorin to wa ni agbo ile Fuji lo sokunfa ede aiyede ati ariyanjiyan to n waye lori ẹni to da orin Fuji silẹ atawọn aawọ miran.
Adewale Ayuba, lasiko to n kopa lori akanse eto ileesẹ wa BBC Yoruba, salaye pe ẹni ta ba laba, ni baba,  lọrọ awọn to da orin Fuji silẹ, tii se Sikiru Ayinde Barrister ati Ayinla Kollington, ko si si ọrọ ansiyemeji nipa wọn.
Ẹ wo fídíò to ti sọrọ naa lori akanse eto BBC Yoruba nibi:
O fikun pe bi awọn olorin to n kọ Fuji se n lo ohun to kẹ bii tawọn ọmọ isọta, ko sọ pe ọmọ buruku ni wọn, amọ ohun ti wọn fi n sọrọ tabi kọrin lo mu kawọn eeyan maa fi wọn we ọmọ onimọto.
Nigba to n dahun ibeere lori boya lootọ lo ti di ẹlẹsin Kristi, Ayuba ni lootọ ni oun jẹ Musulumi, amọ oun ko mọ keu ka, awọn Aafa ni oun maa n pe lati wa gbadura fun oun, ti oun si lọ sin Ọlọrun ni ilu Mecca.
Sugbọn Ayuba ni o rọrun fun oun lati ka bibeli lai ke si ẹnikẹni, ti bibeli funrarẹ si maa n fa oun, eyi to mu ki oun fara mọ ẹsin Kristiẹni.
Odebiyi: ìgbà gbogbo ni Bàbá mi ń polówó iṣẹ́ mi fáráyé
Nigba to n sọ pataki orin Fuji fun iran Yoruba, gbajugbaja olorin Bọnsue naa rọ ọmọ Yoruba kọọkan, lati tẹwọgba orin Fuji .
O ni nitori ara idamọ ti wọn mọ iran Yoruba mọ ni orin Fuji jẹ́, gẹgẹ bi wọn se mọ awọn orilẹede bii Jamaica, Amẹrika, India ati Brazil mọ irufẹ orin ti wọn n kọ ni ikọọkan awọn orilẹede yii.
Minimum wage: Àwọn gómìnà PDP láwọn yóò san #30,000 owó oṣù fáwọn òṣìṣẹ́
Oríṣun àwòrán, Facecook/Seriake Dickson
Awọn gomina labẹ asia ẹgbẹ oṣelu PDP lawọn ti ṣetan lati san ọgbọn ẹgbẹrun un naira owo oṣu to kere julọ fawọn oṣiṣẹ.
Eleyi ni Aarẹ Muhammadu Buhari buwọ lu laipẹ yii.
Alaga awọn gomina PDP, Seriake Dickson ti ipinlẹ Bayelsa lo sọrọ naa fawọn akọroyin l'Abuja lọjọ Ẹti.
Dickson ṣalaye pe awọn ti gba lati sanwo naa lati din iṣẹ ku laarin awọn oṣiṣẹ lawọn ipinlẹ ti ẹgbẹ osẹlu PDP ti wọ le.
Ladoja: Àwọn èèyàn Oyo fì ìbò sọ̀rọ̀ pé ìjọba Ajimobi kò dára
Gomina ipinlẹ Bayelsa ni asiko mti to lati ṣe ẹkunwo gidi fawọn oṣiṣẹ nitori ọjọ ti pẹ ti wọn n ti n gba owo kekere.
Ọgbẹni Dickson fikun ọrọ rẹ pe o ṣe pataki lati san ọgbọn ẹgbẹrun un nairia owo oṣu to kere julọ fawọn oṣiṣẹ nitori ọrọ aje Naijiria to dẹnu ko lẹ labẹ ijọba ẹgbẹ oṣelu APC.
Odebiyi: ìgbà gbogbo ni Bàbá mi ń polówó iṣẹ́ mi fáráyé
Gomina Bayelsa tun sọ pe ko si gomina PDP to lọwọ ninu nina owo ijọba ibilẹ tabi fifi ṣe nnkan miran.
O kepe ijọba apapọ lati fi orukọ awọn gomina to n dari owo ijọba ibilẹ si ibo miiran.
Sanwo-Olu: Àtàrí Àjànàkú ni àkóso Eko, kì í ṣe ẹrù ọmọdé
Oríṣun àwòrán, Babajide Sanwoolu/Twitter
Gomina Ipinlẹ Eko, Babajide Sanwo-Olu ti figbe ta pe, oun ti ru laarin ọsẹ kan ṣoṣo ti wọn bura fun oun, gẹgẹ bi gomina.
Sanwo-Olu ni o si jọ bi ẹni wipe oun yoo ṣi tun ru si lori ohun ti oju oun n ri gẹgẹbi ẹni to n tukọ Eko.
O ba awọn akọroyin sọrọ lẹyin ipade kan to ṣe pẹlu Igbakeji Aarẹ Yemi Osinbajo, saaju ipade naa si ni gbogbo awọn gomina nilẹ wa ti ṣe ipade pọ pẹlu aarẹ Muhammadu Buhari ni Abuja.
Sanwo-Olu ni didari Ipinlẹ Eko kii ṣe ere ọmọde nitori atari ajanaku ni, kii ṣe ẹru ọmọde.
Pẹ̀lú gbogbo bùkátà, Bàbá 80 gboyè Masters
Gomina Sanwo-Olu ni oun ko le e sun, ki oun ji pẹlu ero wipe wahala sunkẹrẹ-fakẹẹrẹ ọkọ yoo ti dopin, bẹẹ si ni oun ko le e sun, ki oun ji pẹlu ireti wipe ọrọ sunkẹrẹ-fakẹẹrẹ Apapa yoo ti poora.
Odebiyi: ìgbà gbogbo ni Bàbá mi ń polówó iṣẹ́ mi fáráyé
Gomina ipinlẹ Eko ni oun ti awọn ara Eko fẹ ni pe, ki awọn ri amusẹ awọn ohun ti oun ti ṣe ileri fun wọn.
O tun rọ gbogbo awọn olugbe Ipinlẹ Eko lati gbaruku ti oun, ki iṣẹ ilu baa le tẹsiwaju.
Ajayi: ṣé  ìwọ mọ irúfẹ́ ọmọ tí Yorùbá ń pè bẹ́ẹ̀?
Àwọn gómínà ilẹ̀ Yoruba ní àwọn yòò dojú ijà kọ jàndùku Fulani
Oríṣun àwòrán, Osun State Government
A kò lè gba àwọn jandùkú Fulani láàyé nílẹ̀ Yoruba -Awọn gómínà
Ailaṣọ-lọrun pakàá, ti n gba apero ọmọ eríwo bayii ni ipinlẹ Yoruba.
Àwọn gomina ipinlẹ Eko, Osun, Oyo, Ondo ati Ekiti ti n fori kori lati wa ọna abayọ si iṣoro yii.
Babajide Sanwo-Olu,  Gboyega Oyetola,  Kayode Fayemi, Seyi Makinde ati Rotimi Akeredolu ti leri wi pe awọn yoo sa gbogbo ipa wọn lati doju ija kọ awọn janduku darandaran to n ṣoṣẹ ni agbegbe naa.
Awọn gomina naa ṣe ipade ni ẹka ile ijọba Ipinlẹ Ondo to wa ni Abuja ni ọjọ Ẹti nibi ti wọn ti fẹnu ko lori ọrọ aabo ni apa ila oorun Naijiria.
Atẹjade kan lati ọwọ adari awọn gomina apa ila oorun Naijiria naa, Rotimi Akeredolu sọ pe o ti di oun to pan dandan bayii lati dẹkun iwa janduku to n gbilẹ.
Baba Khadijat Oluboyo jẹ́rìí ọmọ rẹ̀
Ijinigbe ni awọn opopona bi Ileṣa si Akurẹ, Ileṣa si Iwaraja, Orẹ si Ondo ti di ẹru bi awọn arinrinajo ṣe n mu iroyin ikọlu awọn darandaran wa.
Gbogbo àwọn gomina yii lo gba pé ti awọn ko ba tete gbe igbesẹ to yẹ lasiko, o ṣeeṣe ki ọrọ yii maa gba ẹbọ lọwọ awọn laipẹ.
Pius Adesanmi: Ìdílé ọ̀jọ̀gbọ́n tó kú níjàmbá Ethiopian Airlines ló ilé ẹjọ́
Pius Adesanmi: Awọn ọmọ Nàìjíríà ń ṣelédè lẹ́yìn akọni
Gbogbo ọmọ Naijiria ṣe ìdárò ọjọgbọn Adesanmi
Idile oloogbe Pius Adesanmi, ọjọgbọn ọmọ Naijiria to ku sinu iṣẹlẹ ijamba ọkọ ofurufu Ethiopian Airlines  (ET302) to waye ni oṣu kẹta ti gbe ileesẹ to n ṣe ọkọ ofurufu Boeing lọ ile ẹjọ.
Boeing lo ṣe ọkọ ofurufu 737 Max 8 naa to pa eniyan metadinlọgọjọ, ki awọn oluwadii to wa fi han pe, ọkọ naa ni abawọn.
BBC Africa Eye: Akọroyin fẹ ìdí àwọn oníṣẹ́ ibi ọmọ ogun síta
Iyawo ati ọmọ oloogbe Adesanmi ni orukọ wọn wa lori iwe ipẹjo ti awọn agbẹjọro lati ileesẹ mẹta - Nomaan Hussain, Floyed Wisner ati Omar Khawaja - fi ranṣẹ si ileeṣẹ Boeing.
Iroyin fi han pe ilu Chicago ni orile-ede Amerika ni wọn ti pe ẹjọ naa.
Odebiyi: ìgbà gbogbo ni Bàbá mi ń polówó iṣẹ́ mi fáráyé
Ẹjọ naa da lori pe ileeṣẹ naa ko fi to awọn awakọ ofurufu leti awọn ewu to rọ mọ awọn irinṣẹ tuntun ti wọn fi n rinna ofururu to wa ninu Max 8 naa.
Mo ń retí láti ọ̀dọ̀ bàbá mi nígbà tí mo gbọ́ pé ó bá ìjàmbá bàálù lọ
Adesanmi to jẹ ọjọgbọn ni fasiti kan ni orilẹ-ede Canada in rinrin ajọ lọ orilẹ-ede Nairobi lati Addis Ababa nigba ti ọkọ naa ja lulẹ laarin iṣeju mẹfa to gbera.
Pius Adesanmi ní Wole Soyinka ìran yìí - ọmọ Naijiríà
Ọ̀sẹ̀ ilẹ̀ Afíríkà rèé nínú àwòràn: 31 May - 6 June 2019
Oríṣun àwòrán, AFP
Arìnrìn oge Ọmọ bíbí South Sudan Alek Wek takes tyan fanda ni ibi ayẹyẹ CFDA fún àmì ẹ̀yẹ fún ohun àmusoge tó wáye ní New York lọ́jọ́ ajé
Oríṣun àwòrán, FIFA/Getty Images
Ní ọjọ́rú, àgbábọ̀ọ̀lù ọmọ ilẹ̀ South Africa fẹ́yin kẹẹ si ẹ̀rọ ayàwòràn sáájú ife ẹ̀yẹ àgbáye àwọn obìnrin tó ń lọ niFrance.
Ní Ìpínlẹ̀ Ọyọ lórilẹ̀ èdè Naijíríà àwọn mùsùlúmi ó gbẹ́yìn láti lọ sàdúra ní yidi fún ìtúnu àwẹ
Oríṣun àwòrán, Reuters
Ní ọjọru kan náà ní àwọn mùsúlùmí ṣe ọdún Ramanda, bẹẹni ọmọdebínrin yìí kọ́ọ̀wọ́rin lọ fún àdúra yídì ní olú ilú Kenya tí a mọ si Nairobi.
Oríṣun àwòrán, AFP
Ni Nairobi bakan náà a rí ọmọdékúnrin yiìí ni bi tí ó fi gbogbo ọkan gbàdúrà ní pápá yídi
Oríṣun àwòrán, AFP
"O ní dá ounjẹ jẹ èyí jẹ ohun ti wọn kọ si àra apoti ounjé ní ]ilú Cairo ní ọjọ jimọ sáájú aṣekaágbá Liigi Uefa. Mo Salah tó jẹ ìlú mọ̀ọ́ka agbábọọlu ni Liverpool, èyi ti wọn ti yí pada si ""Liver fuul""Egyptian footballer Mo Salah is the star player of winning side Liverpool, which has been changed here to ""Liver Fuul"" nínu ere kan ni Sudan ti wọn pe ni ounje ẹwa ""Fuul""."
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Lẹ́yìn ti South Africa fìdí rẹmi nínú ìfigagbága wọn pẹ̀lú Bangladesh lọjọ àìkú, èyí ti àwọn onímọ pè ni ìdíje to mú ìrunu báni jùlọ nínú eré ìdáya ife ẹyẹ agbaye Krikẹti ìmúra ọkan lára àwọn olólùfẹ ereidaraya ni Bangladesh.
Oríṣun àwòrán, Reuters
Lẹ́yìn ọdún meji ti ó ti ku, wọn ṣẹṣẹ gbe posi ọga ẹgbẹ alátako Etienne Tshisekedi Káàkiri ní orilẹ̀-èdè DR Congo laja Jimọ... ní ìjọ Martyhrs of Pencost ní pápá ìṣere Kinshasa ní ọjọkọkanlelọgbọ̀n osu kaarun
Oríṣun àwòrán, AFP
Ọ̀pọ̀ ẹgbẹ̀run olólùfẹ́ rẹ ní wọn fọ́n sita láti fin ẹdun ọkan wọn han bi wọn se ń gbe oku rẹ̀ kọja ni opopona oluilu Dr Congo Kinshaha ní ọjọ kini oṣù kẹfa.
Oríṣun àwòrán, Reuters
Orílẹ̀-èdè Egypt ni ilu Cairo ni a rti ri oorun to yọ yìí lọjọ satude.
Aworan wa lati ọwọ Reuters, AFP, Getty Images ati EPA.
Dangote, Fayemi pari ìjà láàrin Gomina Ganduje àti Emir Kano Sanusi II
Emir Kano Sanusi Lamido àti Gómìnà Abdullahi Ganduje
Gómìnà ìpínlẹ̀ Kano Abdullahi Ganduje ki Emir ilú Kano Muhammedu Sanusi ní ìlú Abuja ní ọjọ Jimọ lásìkò ti wọn fẹ yanju ààwọ to wà láàrin wọn.
Gẹ́gẹ́ bí àgbẹnusọ fún gọ́mìnà Abbaa Anwar ṣe sọ gbájúgbaja ọmọ bibi Kano àti alága àwọn gomina Nàìjíríà Kayode Fayemi  ló pe ìpàdé ti wọ́n fi pẹ̀tù sí ààwọ̀ àwọn méèjì.
Awọn adari méèjì ssrs papọ bí wọn ṣe rọ àwọn musulumi láti túbọ máa[tèlé àwọn ẹ̀kọ́ ti wọn kọ ninu ààwẹ Ramadan, bákan náà ni Emir fi asìkò náà kí gómìnà kú ori ire ìwọle fún sáà keji.
Láti ìgbà díẹ̀ sẹyin ni ààrin Gomina ipinlẹ Kano Ganduje àti gómìnà ilé ifowopamọ apapọ tẹ́lẹ̀ri Sanusi Lamido Sanusi kò ti gún. ìròyìn sọ pé àì gbáruku ti ìjọba Ganduje ni inú ìdìbò tó koja ló fàá.
Èyí ló fa gbọ́nmisi-omi o to lẹ̀yìn ti ìdìbò pari ti gómínà Ganduje si wolé fún sáà keji, Gomina Ganduje buwọ lu abádofin láti ṣe ìdásilẹ̀ àwọn ààfin tuntun míràn ni Gaya, Rano àti Karaye ti wọn ó si jọ ni agbára àti àṣẹ kan náà bi ti Emir Kano gẹ́gk bi ọba onipo kíní
Ní ọjọ́bọ ni ìjọba tún fi ìwé wá wi tẹnu rẹ ránsẹ si Emir Sanusi láti sàlàye bí ọ ṣe ná bílíoọnù mẹ́ta o lé ọwọ́ mẹ́rìn  ti Emir ṣe mọ́umọ̀ku
Olubadamọran gómìnà Saliu Tanko sọ fún BBC pé ìpàdé láti pẹtu sí ààwọ náà ló wáye fún ìgbà aàkọkọ ní alẹ́ ọjọ Jimọ
Emir Sanusi kìí ṣe akápò tàbí akọ̀wé ìgbìmọ ẹ́míréètì- Abba Yusuf àgbẹnusọ Emir Kano
Oríṣun àwòrán, Kano Emirate Council
Àjàku akáta ní ọ̀rọ̀ gómìnà ìpínlẹ̀ Kano àti Emir kano láti ìgbà ti ìdìbò gbogboogbò ọdún 2019 ti pari.
Emir Kano Muhammedu Sanusi II tí fèsì sí ìwé ẹ̀sùn ti Gómìnà ìpínlẹ̀ Kano kọ síi ni ọjọ́ pé kó wá wi tẹ́nu rẹ̀ lóri bí ó ṣe na bílíọ̀nu mẹ́ta lé ọwọ́ mẹ́rin náírà owó igbìmọ ẹmireeetì.
Gẹ́gẹ́ bii ǹkan ti Abba Yusuf sọ, ó ni ọwọ́ Emir kò le wọ sọ̀ọ̀lọ̀ nítori pe kìí ṣe akápò tàbí akọwé fún ìgbìmọ ẹmireeti.
'Mo ń ṣa ike jọ láti san owó ilé iwé ọmọ mẹ́ta'
Yusuf fi kun pe wọn yan Sanusi gẹ́gk bi Emir ni ọdún 2014, owó ti ó wà ni àpò ẹmireeti ko ju bílíọnu kan lé díẹ̀ l, èyí jìnì gédégédé si bílíọnu mẹta lé ọwọ mẹ́rìn tí àwọn ajọ to gbógun ti ṣ\iṣe owó ìlú makumọ̀ku ń sọ pe Emir na láàrin ọdún 2014 si 2017 lọ.
Oríṣun àwòrán, Kano Emirate council
Emir Muhammedu Sanusi II ti fẹsi sí ẹsún Gómìnà Kano
Ní ọjọ́ru ni àjọ tó ń ri si iwa àjẹbanu ni ìpínlẹ̀ Kano dábàá pe ki wọn yọ Sanusi nipò nítori ó ṣe owo ìgbìmọ ẹmireeti niṣekuṣe.
Àbá yìí wà nínú àbájade ìwádìí ti àjọ náà ṣe ti àlága wọn Muhuyi Magaji si fọ́wọ́ si.
Ẹ̀wẹ̀, akọwé ìjọba ìpínlẹ̀ Kano tó kọ ìwé ẹsun náà Usman Alhaji sàlàye pe èsì Sanusi yoo fún ìjọba láàfàní láti gbé ìgbésẹ̀ to tọ àti èyí to yẹ
8th Assembly: Saraki pín owó ìyọ̀nda rẹ̀ fún ẹbí Leah Sharibu àtàwọn míì
Oríṣun àwòrán, Twitter/Dr Abubakar Bukola Saraki
Adari ile igbimọ aṣofin agba ikẹjọ to ṣeṣẹ kogba sile, Sẹnẹtọ Bukola Saraki ti fi owo iyọnda rẹ ranṣẹ si awọn ẹbi akẹkọọbinrin Leah Sharibu to wa lakata Boko Haram atawọn oṣiṣẹ oluranlọwọ ti Boko Haram sẹkupa.
Saraki sọrọ di mimọ ninu atẹjade ti oluranwọ rẹ lori ọrọ iroyin, Yusuph Olaniyonu fi sita.
Saraki tun sọ pe ki awọn alaṣẹ ile tun pin owo naa kan awọn ọmọ ṣẹnẹtọ to ku nigba to jẹ adari ile igbimọ aṣofin agba l'Abuja.
Ladoja: Àwọn èèyàn Oyo fì ìbò sọ̀rọ̀ pé ìjọba Ajimobi kò dára
Sẹnẹtọ Saraki ni oun gbe igbesẹ yii nitori pe ko si igba ti ile ba ṣe apero lori ọṣẹ tawọn agbsumọmi n ṣe papaajulọ lagbegbe ila-oorun ariwa, ti kii ba oun lọkan jẹ.
O rọ ile igbimọ aṣofin kẹsan an to sẹṣẹ bẹrẹ iṣẹ lati ya owo kan s'ọtọ gẹgẹ owo iranwọ fawọn ti ko rọwọ họri.
Ondo: Dejí sun ọmọ méje àtagbalagba meji mọ́lé nítorí pé ó ń bínú
Barister lo bi gbogbo oníṣẹ́ fújì -Oṣupa
Ida ogun ninu ida ọgọrun owo iyọnda rẹ lo ṣo pe ki wọn fun ẹbi Leah, iye kan naa lo ni ki wọn fun idile Hauwa Liman ati Hussaini Ahmed Khoisan, awọn oṣiṣẹ oluranlọwọ ti Boko Haram pa.
Saraki ni ki ile lo ida ogoji lati ṣeranwọn feto ẹkọ awọn ọmọ sẹnẹtọ to ku nigba to jẹ adari ile lati ọdun 2015 si 2019.
Walter Onnoghen kọ̀wé ìfẹ́yìntì ara rẹ̀ gẹ́gẹ́ bí adájọ́ àgbà Nàìjíríà
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Adajọ agba, Walter Onnoghen
Aarẹ Muhammadu Buhari ti tẹ́wọ́ gba iwe ifẹyinti eyi ti adajọ agba, Walter Onnoghen kọ funra rẹ.
Ṣaaju wọn ti jawe lọ sinmi nile fun Onnoghen latari ọrọ to ni ṣe pẹlu aikede dukia rẹ laipẹ rẹ si ni iroyin kan n ja rayin rain pe Ṣé lòótọ́ ní pé adájọ àgbà Nàìjíríà Walter Onnoghen  tí kọwe fiṣe sílẹ?
Gẹgẹ bi akọsilẹ inu iwe naa, ifẹyinti Onnnoghen gẹgẹ bi adajọ Naijiria yoo bẹrẹ ni ọjọ kejidinlọgbọn oṣu karun un.
Ninu ọrọ̀ ti oluranlọwọ agba fun aarẹ, Garba Shehu fi sita, o ni aarẹ Buhari dupẹ lọwọ rẹ fun iṣẹ isin rẹ si orilẹede o si gbadura ifẹyinti ayọ fun un.
Ninu oṣu kinni ọdun 2019 ni  aarẹ Buhari jawe lọ rọọkun nile fun Onnoghen gẹgẹ bi alakalẹ ofin ile ẹjọ to n gbọ ẹsun awọn to du ipo nla mu lawujọ.
Iba Gani Adams: Bẹ́ẹ gbé màláíkà kan lọ sí Aso Rock, kò lè ṣàṣeyọrí
Ni oṣu kẹrin, ile ẹjọ dajọ pe Walter Onnoghen jẹbi awọn ẹsun ti wọn fi kan an ti wọn si ni ko lọ rọọkun nile.
Bakan naa, oluranlọwọ agba fun aarẹ sọ pe aarẹ Buhari ti kọwe si adele adajọ agba Tanko Muhammed lati yan adajọ marun un mii si ile ẹjọ giga ju lọ ti orilẹede Naijiria.
Eyi jẹ lati fi kun iye awọn adajọ to wa ki wọn le pe mọkanlelogun gẹgẹ bi o ṣe wa ninu ofin.
State Assembly: Adebo, Oluomo di adarí ilé aṣòfin ìpínlẹ̀ Oyo, Ogun
Oríṣun àwòrán, @Adebo_ogund, Olakunle Taiwo Oluomo
Họnọrebu Adebo Edward Ogundoyin ati Họnọrebu Olakunle Taiwo Oluomo
Awọn Ile igbimọ aṣofin ipinlẹ Oyo ati Ogun ti kede awọn to jawe olubori gẹgẹ bii adari ile.
Ni ipinlẹ Oyo, Họnọrebu Adebo Edward Ogundoyin ti ẹgbẹ oṣelu Peoples Democratic Party to n ṣoju ẹkun idibo Ila Oorun Ibarapa nipinlẹ Oyo lo bori.
Bakan naa ni wọn yan Họnọrebu Abiodun Muhammed Fadeyi to n ṣoju ẹkun idibo Ona Ara ni igbakeji adari ile aṣofin ipinlẹ Oyo.
Iba Gani Adams: Bẹ́ẹ gbé màláíkà kan lọ sí Aso Rock, kò lè ṣàṣeyọrí
Ẹwẹ, bo ṣe n waye nipinlẹ Oyo naa lo n ri bakan naa ni Oke-Mosan, Abeokuta ipinlẹ Ogun nibi ti Họnọrebu Olakunle Taiwo Oluomo jawe olubori gẹgẹ bii adari ile igbimọ aṣofin ipinlẹ Ogun.
Olakunle n ṣoju ẹkun idibo Ifo 1 nile igbimọ aṣofin ipinlẹ Ogunti wọn si yan an lai ni alatako kankan.
Olusegun Obasanjo: Ọmú ìyá mi ti mo fi ń mùkọ ni kekere ló jẹ ki ń lókun
Bẹẹ si ni wọn yan Họnọrebu Abiodun Muhammed Fadeyi to n ṣoju ẹkun idibo Ijebu North II gẹgẹ bii igbakeji adari ni ipinlẹ Ogun.
Idibo awọn mejeji si igbimọ aṣofin ikẹsan waye lai si alatako kankan.
Gómìnà Makinde fẹ́ dá àjọ tó ń gbógun ti ìwà ìbàjẹ́ sílẹ̀ l'Oyo
Oríṣun àwòrán, WIKIPEDIA
Ipinlẹ Kano wa lara awọn ipinlẹ to wa lara awọn ipinlẹ to ni ajọ to n gbogun ti iwa ibajẹ ni ipinlẹ naa.
Gomina ipinlẹ Ọyọ, Seyi Makinde ti fi ipinnu rẹ han lati da ajọ silẹ ti yoo ma a gbogun ti iwa ibajẹ ni ipinlẹ naa.
Gomina Makinde sọ eyi lasiko ti wọn n se ibura wọle fun awọn aṣofin ipinlẹ ti wọn dibo yan si Ile Igbimọ aṣofin ipinlẹ naa.
Iba Gani Adams: Bẹ́ẹ gbé màláíkà kan lọ sí Aso Rock, kò lè ṣàṣeyọrí
O ni ijọba oun ṣe tan lati gbogun ti iwa ibajẹ, nitorina ni awọn yoo ṣe rii daju wi pe awọn gbe abadofin jade ti yoo se ifilọlẹ ile-iṣẹ ijọba ipinlẹ ti yoo maa gbogun ti iwa ibajẹ.
Agbẹnusọ fun gomina naa, Taiwo Adisa fi kun un wi pe gomina Makinde ṣe tan lati jẹjọ ti ajọ naa ba ri i wi pe oun ru ofin iwa ibajẹ.
Osun State: Gómìnà Oyetola wọ́gilé ìrìnàjò àwọn alága sí UAE
Oríṣun àwòrán, Facebook/Adegboyega Oyetola
Ọrọ lori inrinajo awọn alaga ijọba ibilẹ nipinlẹ Osun
Gomina Ipinlẹ Oṣun, Adegboyega Oyetola ti wọgile irinajo si ilu okere tawọn alaga mejidinlaadọrin ipinlẹ naa n gbero lati lọ fun ijiroro.
Gomina Oyetola sọrọ yii di mimọ ninu atẹjade ti akọwe iroyin rẹ, Adeniyi Adesina fi lede.
Awọn alaga naa ti kọkọ fi atẹjade kan sita pe awọn yoo lọ si  ilu Dubai loṣu kẹfa yii.
Iba Gani Adams: Bẹ́ẹ gbé màláíkà kan lọ sí Aso Rock, kò lè ṣàṣeyọrí
Ondo: Dejí sun ọmọ méje àtagbalagba meji mọ́lé nítorí pé ó ń bínú
Wọn ni idi abajọ irinajo naa ni lati jẹ ki awọn alaga ipinlẹ naa ni iriri iṣejọba ibilẹ, gẹgẹ bi o ti rii kaakiri agbaye.
Ẹwẹ, gomina Oyetola sọ pe asiko ko tii to fun iru irinajo yii bo tilẹ je pe ohun ti wọn fẹ ṣe lorilẹede UAE ṣe pataki.
BBC Africa Eye: Akọroyin fẹ ìdí àwọn oníṣẹ́ ibi ọmọ ogun síta
Gomina ipinlẹ Oṣun ṣalaye pe ijọba oun yoo tẹsiwaju lati maa fun awọn oṣiṣẹ ọba lanfaani lati maa lọ fun idanilẹkọọ loorekoore bi agbara rẹ ba ti mọ.
Awọn alaga ọhun fi sinu atẹjade pe ijọba ipinlẹ Oṣun ni yoo san owo fisa, owo baalu ati ile itura ti wọn yoo de si lorilẹede UAE.
9th Assembly: Olùdíje mẹ́rin ṣàtìlẹyìn fún Gbajabiamila ṣáájú ìbò ilé aṣojú ṣòfin
Oríṣun àwòrán, @femigbaja
Femi Gbajabiamila
Bi idibo adari ile igbimọ aṣoju ṣofin l'Abuja ti wọle de, awọn oludije mẹrin ọtọọtọ lo ti sọ pe awọn ko ni dupo naa mọ, ti wọn ṣeleri lati ṣatilẹyin fun Femi Gbajabiamila.
Aṣoju ṣofin Gbajabiamila gan ni ẹgbẹ oṣelu All Progressive Congress(APC) fọwọ sii pe ko jẹ adari ile aṣoju ṣofin l'Abuja.
Ọkan gboogi lara awọn oludije naa, Nkeiruka Onyejiocha lo kọkọ kede atilẹyin rẹ fun Gbajabiamila.
Dokita Jibrin Abdulmumini to jẹ oludari ipolongo ibo fun Gbajabianmila lo fọrọ naa lede lẹyin ipade to waye laarin awọn alatilẹyin Gbajabiamila ati oun funra rẹ l'Abuja.
Awọn oludije miiran to tun ṣeleri atilẹyin wọn fun Gbajabiamila ni Buba Yakubu, Aliyu Betara, ati Abdulrazak Namdas.
Aṣoju ṣofin Abdulmumini fikun ọrọ rẹ pe Gbajabiamila lawọn ọmọ ile igbimọ aṣoju ṣofin lati iwọ oorun gusu naa fẹdibo fun un.
Ladoja: Àwọn èèyàn Oyo fì ìbò sọ̀rọ̀ pé ìjọba Ajimobi kò dára
Iba Gani Adams: Bẹ́ẹ gbé màláíkà kan lọ sí Aso Rock, kò lè ṣàṣeyọrí
Amọ, John Dyegh to n ṣoju ẹkun Gboko/Tarka nipinlẹ Benue to si tun jẹ ọmọ ẹgbẹ osẹlu APC loun si wa maa dije fun ipo adari ile igbimọ aṣoju ṣofin.
Ọjọ Iṣẹgun, ọjọ kọkanla, oṣu kẹfa ni ibo naa yoo waye niluu Abuja.
Mali: O kéré tán, ẹ̀mí 95 ti sọnù ní Mali
Oríṣun àwòrán, Getty Images
ọpọ ìgbà ni ìkọlu ti maa n waye laarin Fulani atawọn ara Dogon ni aaring gbungbun Mali
Eniyan mọkandinlogun tun ti dawati ni Mali.
Ijọba orilẹ-ede Mali ti ke gbajare fun gbogbo agbaye lori ikọlu to n ṣẹlẹ ni ẹkun Mpoti.
Ikọlu awọn alakatakiti ẹsin Islam ti wọn n pe ni Al Qaeda ati Islamic State Group ti n wọpọ sii ni Mali bayii.
Akọroyin BBC to wa nibẹ ni wọn dana sun ilu naa ni ti ọpọ ẹmi ati dukia si ti sọnu.
Ijọba ilẹ Mali ni iṣẹlẹ ibi yii ko ṣeyin awọn agbesunmọmi ṣugbọn awọn ara agbegbe naa n kigbe pe awọn Fulani lo wa nidi ọrọ naa.
Iba Gani Adams: Bẹ́ẹ gbé màláíkà kan lọ sí Aso Rock, kò lè ṣàṣeyọrí
Ajọ ipese alaafia ninu ajọ Iṣọkan Agbaye, United Nations ti kede pe oun ti gbe igbeṣẹ lati dẹkun iwa ibi yii.
UN ni wọn ti fi awọn ọmọ ogun ranṣẹ si ẹkun yii ki iru ikọlu yii ma tun le waye mọ.
Ajọ UN ni oun tun ti fi awọn oluwadii nipa ẹtọ ọmọniyan ranṣẹ sijọba Mali ki wọn le pese iranlọwọ fun ijọba Mali ninu iwadii ti wọn n ṣe.
Ki lo ti ṣẹlẹ sẹyin?
Lojiji ni awọn agbebọn kan ya wọ ilu Dongon ti wọn si fi ọpọ ẹmi ṣòfò.
Ó kéré tán, ẹ̀mí 95 ti sọnù nínú ìkọlù Fulani ní Mali
Agbegbe Sobane-Kou nitosi Sanga ni iṣẹlẹ yii ti ṣẹlẹ ni aarin gbungubn orilẹ-ede Mali.
Awọn ti iṣẹlẹ naa ṣoju wọn ṣalaye fun BBC pé awọn oniṣẹ ibi yii tun jo ọpọlọpọ ilé ni ina.
Oṣiṣẹ eleto aabo abẹlẹ kan ṣalaye fun BBC pe, niṣe ni wọn n sun awọn eniyan naa lẹyin ti wọn pa wọn tan.
O ni oun ti bẹrẹ iṣẹ iwadii lori ninu awọn oku ti wọn ti ri yọ sita.
FFK: Buhari ló ń fún àwọn Fulani láàyè láti máa pa ènìyàn'
Ogun ẹlẹyamẹya ti maa n figba gbogbo ṣẹlẹ laarin awọn Fulani ati awọn eniyan ẹya Dongon ni aarin gbungbun Mali tipẹ.
Opọ igba ni wọn maa n fẹsun kan ara wọn pé wọn n ji ẹran ọsin ara wọn ko.
Lọjọ kẹtalelogun, oṣu kẹta, ọdun ni wọn ni o kere tan ọgọjọ awọn jagunjagun ni aja awọn ọlọdẹ pa ni agbegbe Ogossagou to sunmọ Burkina Faso.
Arakunrin Fulani ni aigbede ara eni ni orisun ija pelu agbe
Yatọ si ija ẹlẹyamẹya to n ṣẹlẹ leralera, lati ọdun 2012 ni wọn ti bẹrẹ ija ẹsin to ti mu ọpọlọpọ ẹmi lọ.
'Fulani Ilorin l'ọkọ mi'
Awọn Fulani ti wọn jẹ alakatakiti ẹsin Islam ati awọn ti ko gba ẹsin kankan gbọ ni wọn n fẹsun ikọlu yii kan julọ.
"Bakan naa ni wọn fẹsun kan awọn agbebọn kan ni Dongon ti wọn n pè ni ""Dan Na Ambassagou'."
Wọn tun ni ko le ṣẹyin awọn agbesunmọmi ni ẹkun yii.
Odumakin sọrọ lori Fulani darandaran
"Ijọba Mali ti gbogun ti awọn ẹgbẹ ""Dan Na Ambassagou' lẹyin ikọlu Ogossagou."
9th Assembly: Èrò ṣe ọ̀tọ̀ọ̀tọ̀ lórí ẹní tí àṣẹ ilé aṣòfin àgbà Nàìjíríà yóò já mọ́ lọ́wọ́
Ko ti daju ẹni ti yoo jamọ lọwọ laarin Lawal ati Ndume
Ipo igba kini ninu oṣelu awa ara wa ṣe pataki ṣugbọn a ko le fi ọwọ rọ awọn igba to ku naa ṣẹyin.
Idi ree ti awọn eeyan Naijiria ṣe n foju sọna lati mọ ẹni ti yoo di ipo aarẹ ile aṣofin agba mu labẹ saa kẹsan ile aṣofin Naijiria.
Lọjọ kọkanla oṣu Kaarun ni awọn ọmọ ile aṣofin agba  yoo dibo yan ẹni ti yoo jẹ olori wọn.
Tani yoo jẹ aarẹ laarin awọn to n du ipo yi ni ibeere nla ti awọn eeyan n reti idahun si.
Odu lawọn mejeeji ti wọn du ipo aarẹ lẹyin ti Bukola Saraki pari saa rẹ.
Ifidirẹmi ninu idibo gbogbogbo to kọja lo sokunfa bi Bukola Saraki ko ṣe pada wa si ile aṣofin agba bo tilẹ jẹ pe yoo fẹ ṣoro diẹ fun un lati di ipo naa mu.
Awọn meji to lewaju lati di ipo yii mu ni Sẹnẹtọ Ahmad Ibrahim Lawan to n ṣoju ẹkun ariwa ipinlẹ Yobe.
Oríṣun àwòrán, The Nigerian Senate
Ali Ndume
Akẹgbẹ rẹ ni Sẹnẹtọ Mohammed Ali Ndume lati ipinlẹ Borno to n soju ẹkun guusu Borno. Lati ọdun 2011 lo ti wa ni ile gẹgẹ bi Sẹnẹtọ labẹ asia ẹgbẹ PDP.
Ṣugbọn nigba ti awọn kan kora jọ lati gba ijọba lọwọ ẹgbẹ PDP, o darapọ mọ wọn ti o si jẹ olori ọmọ ile to pọ ju lọ labẹ asia APC.
Adebo bórí l'Oyo, Oluomo ní ìpínlẹ̀ Ogun gẹ́gẹ́ bí adarí ilé aṣòfin
Ó dára kí ìjọba ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́ ní àjọ tó ń gbógun ti ìwà ìbàjẹ́!
Òfin má wàásù láì gbàṣẹ nìpínlẹ̀ Kaduna ti ń gba àpérò
Iba Gani Adams: Bẹ́ẹ gbé màláíkà kan lọ sí Aso Rock, kò lè ṣàṣeyọrí
Sẹnẹtọ Ndume ni adisọkan oun ni bi ile aṣofin yoo ṣe ni ominira tirẹ ti ko si ni si wi pe eeyan kan yoo ma dunkoko mọ awọn aṣofin nidi iṣẹ wọn.
O ni oun yoo rii pe atunto ba ipo aarẹ ile asofin agba ti oun yoo si ṣapa lati koju iwa jẹgudujẹra.
Ko fẹrẹẹ si iyatọ pupọ ninu nnkan ti Sẹnẹtọ Lawan naa fẹ ṣe ti o ba di aarẹ ile asofin agba.
Oríṣun àwòrán, The Nigerian Senate
Ahmad Lawan
Ohun naa ko fẹ ki awuyewuye pupọ wa laarin ẹka aṣofin ati ti alaṣẹ ijọba.
Lawan kii ṣe aimọ lagbo oṣelu ti ọpọ awọn Sẹnẹtọ si ti lawọn yoo gbaruku ti lati di aarẹ ile asofin.
Olusegun Obasanjo: Ọmú ìyá mi ti mo fi ń mùkọ ni kekere ló jẹ ki ń lókun
Ati aarẹ ile asofin ati igbakeji rẹ ni wọn yoo yan lọjọ iṣẹgun.
Gbogbo awọn asofin mọ́kàndínláàdọ́fà ni yoo dibo yan ẹni tọkan wọn fẹ.
Labẹ ofin idibo ile,idibo bonkẹlẹ alafihan(open secret ballot) ni iwe ofin la kalẹ.
Ko ti daju boya wọn yoo fi ibo tẹnikọọkan ba di han ṣugbọn eyi keyi to ba jẹ,bi oludije kan ba ti le ni ibo to pọju tẹni keji rẹ, oun ni yoo di aarẹ.
Ondo: Dejí sun ọmọ méje àtagbalagba meji mọ́lé nítorí pé ó ń bínú
Ṣe aṣẹ ẹgbẹ APC yoo ṣẹ lọtẹ yi?
Awọn onwoye ni idanwo ni idibo aarẹ ile asofin yi yoo jẹ lati mọ boya awọn ọmọ ẹgbẹ APC yoo tẹle aṣẹ ẹgbẹ.
Aṣẹ ti a n sọ yi ni eleyi ti o wa lati ọdọ awọn adari ẹgbẹ to fi mọ aarẹ Buhari pe ki awọn ọmọ gbẹ dibo fun sẹnẹtọ Lawan ati Omo Agege gẹgẹ bi aarẹ ati igbakeji aarẹ.
Oríṣun àwòrán, SPNigeria
Sẹnẹtọ Bukola Saraki ati Ike Ekweremadu ni won di ipo aarẹ ati igbakeji aarẹ ile asofin mu ni saa to kọja
Bi a ko ba gbagbe, lasiko ti idibo ile asofin agba waye ni saa to kọja ẹnu ẹgbẹ ko ṣebi ẹni papọ soju kan eleyi to mu ki Sẹnẹtọ Bukola Saraki ati Sẹnẹtọ Ike Ekweremadu gbegba oroke.
Ninu iwoye tirẹ, amofin kan to fi ilu Ibadan ṣe ibujoko, Saliu Adebayo, ni APC ti kọgbọn latara ohun to ṣẹlẹ ni saa to kọja.
''Gbogbo wahala ti aarẹ koju pẹlu ile aṣofin ni saa to kọja ko ṣẹyin pe ẹnu ẹgbẹ ko ko. O da mi loju pe wọn ko ni fi ina sori orule sun lọtẹ yi''
Amofin Adebayo tẹsiwaju pe esi abajade ibo yi yoo tubọ fi rinlẹ boya APC ṣetan lati di agbara mu ni gbogbo ẹka ijọba lalai fi ọkan jafara.
9th Assembly: Femi Gbajabiamila ni ẹgbẹ́ APC fọwọ́sí sùgbọ́n...
Oríṣun àwòrán, @femigbaja, @HonBago
Bago àti Gbajabiamila
O kéré tan ènìyàn mẹ́ẹ̀dógún ló bẹ̀rẹ̀ eré ìje láti di agbẹnusọ ilé ìgbìmọ̀ àṣojú-ṣòfin orílẹ̀-èdè Nàìjíríà láti gba ipò Yakubu Dogara to jẹ ẹ́ ní ilé ìgbìmọ̀ aṣojú-ṣòfín ti ẹlẹ́kẹjọ.
Ọ̀pọ̀ àwọn mííràn ò kéde síta nígbà ti àwọn mííràn ni àwọn ń ba àwọn akẹgbẹ́ àwọn sọ̀rọ̀ lábẹ́lẹ̀. Femi Gbajabiamila, olùranlọ́wọ́ pàtàkì fún ààrẹ lọ́rí ọ̀rọ̀ ilé ìgbìmọ̀ aṣòfin Abdulrahman Sumaila, Ahmed Wase Muhammed Monguno àti àwọn míì.
Ní báyìí, awọn ẹgbẹ́ amúṣẹyá ẹgbẹ òṣèlú PDP ní àwọn ti fọ́wọ́ sí láti dibò yan Ali Ndume gẹ́gk bii ààrẹ ilé ìgbìmọ aṣòfin nígbà ti wọ́n fọwọ si Umar Mohammed Bago gẹ́gẹ́ agbẹ́nusọ ilé ìgbìmọ aṣojú-ṣòfin.
Eyí ní ẹgbẹ́ òṣèlú PDP fí ìdí rẹ̀ múlẹ̀ níní àtẹjáde kan tí wọn fi sita ní ààgo kan àbọ owúrọ oni tí àkọwé àpapọ̀ ẹgbẹ́ sẹnatọ Umar Ibrahim Tsauri sí fọwọ́ sí
'Mo ń ṣa ike jọ láti san owó ilé iwé ọmọ mẹ́ta'
Àwọn to ti jẹ Agbẹnusọ láti ọdún 1999
Salisu Buhari                   1999-2000 PDP  Iwọ-òòrun -Arewa
Ghali Umar Na'Abba       2000-2003   Iwọ-òòrun -Arewa
Aminu Bello Masari        2003-2007 Ìwọ-òòrun -Arewa
Patricai Etteh                   2007  Iwọ-òòrun -Guusu
Dimeji Bankole                2007-2011 Iwọ-òòrun- Guusu
Aminu Waziri Tambuwal  2011-2015 wọ-òòrun -Arewa
Yakubu Dogara                2015-2019  Ila-òòrun Arewa
Iba Gani Adams: Bẹ́ẹ gbé màláíkà kan lọ sí Aso Rock, kò lè ṣàṣeyọrí
Àwọn tó ń dupo agbénusọ ilé ìgbìmọ̀ aṣojú-ṣòfin
Ẹgbẹ́ òṣèlú APC tí pín ipò agbẹnusọ sí ìwọ̀-òòrun -Guusu tí wọ́n sì yan asoju ọmọ ilé to pọ jù lọ, Femi Gbajabiamila gẹgẹ́ bi ẹni tí wọ́n fọ́wọ́ sí nígbà ti wọ́n pín ìgbá keji sí gbùngbùn Ariwa.
Ṣùgbọ́n o, ìdìde Umar Mohammed Bago láti ìpínlẹ̀ Niger àti John Dyegh láti ìpinlẹ̀ Benue.
Mohammed Bago ti dide pe àṣìṣe ńlá ni ẹgbẹ́ APC ṣe láti pín ipò agbẹnusọ sí ìhà iwọ oorun Guusu nítori náà oun kò fara mọ ọ  àti pé ìhà gbungbu Arewa kò ti de ipò agbẹnusọ ilé ìgbìmọ aṣoju sofin ri, nítori náà òun náà yóò dije fún ipò Agbẹnusọ
Muhammed nínú àtẹjade kan sàlàyé pé iha Ila-òòrun-Gusu àti Gbungbun -Arewa ní ẹgbẹ ń fiya pínpín wọn jẹ jùlọ
Ní báyìí, ìdìbò tí yóò wáye ní òní ọjọ kọkanlá oṣù kẹfà ódún 2019 ń pè kí Gbajabiamila kò ni ẹtọ láti lọ nítori ó yẹ ki àwọn àṣojú ẹgbẹ́ ó tún ètò náà ṣe.
Ìtàn tó wà nídi òwe ‘Sebótimọ Ẹlẹ́wà Sàpọ́n’
Olusegun Obasanjo: Ọmú ìyá mi ti mo fi ń mùkọ ni kekere ló jẹ ki ń lókun
Ìdìbò ilé ìgbìmọ̀ aṣojú-sòfin fún sáà 2015-2019
Ẹwẹ̀, lòdì si ìpínu ẹgbẹ́ òṣèlú APC ní sáà tó kọja ni àwọn ọmọ ẹgbẹ́ APC kan pàdí àpò pọ pẹlú ẹgbẹ́ alátako láti gbé Bukola Saraki  wolé gẹ́gẹ́ bíi ààrẹ ilé ìgbìmọ̀ aṣofin àti Yakubu Dogara wolé gẹ́gẹ́ bi aggbẹ́nusọ ilé aṣojú-ṣòfin.
Ní bayìí aṣoju ọmọ ile to kéré jùlọ nígbà kan rí George Akime ti rọ gbogbo ọmọ ilé ìgbìmọ̀ aṣofin àgbà àti aṣojú-ṣòfin láti ri dáju pe wọn bọ̀wọ̀ fún ipinu ẹgbẹ́ láti dibò fún Ahmed Lawan gẹ́gẹ́ bi ààrẹ ilé ìgbìmọ aṣòfin àti Femi Gbajabiamila bi agbẹ́nusọ aṣoju-ṣòfin kí ǹkan tó ṣẹlẹ̀ ní ọdún mẹ́rin sẹyìn máà tún wáye.
Imo: Aléjò mẹ́wàá ṣòfò ẹmí níbi ayẹyẹ ìgbéyawó
Ìjàmba ṣẹ̀ ní ìpínlẹ̀ Imo lọ́jọ́ ajé lẹ́yìn ti alejò mẹ́wàá jẹ ọlọ́run nípe nípasẹ̀ èèfi ẹrọ amúna wá  níbi ayẹyẹ ìgbéyàwó ìlànà ìbílẹ̀.
Yàtọ̀ sí èyí, ènìyàn bii ọgbọ̀n ló wá ní ẹsẹ̀ kan ayé ẹsẹ̀ kan ọ̀rún ni onírúurú ilé ìwòsàn ní ìjọba ìbílẹ̀ Ikeduru àti Mbatoli ìpínlẹ̀ náà báyìí nítori wọ́n fa èèfi ẹ̀rọ amúna wá símú.
Ìròyìn sọ pé Favour àti Ifeanyi ṣe ìgbéyàwó ìlànà ìbílẹ̀ ní agbolé Uzoegbu Umuomumu Mbieri ní ìjọba ìbílẹ̀ Mbatoli ní ọjọ́ àìkú, ìjàmbá ọ̀hún ṣẹ̀ lẹ́yìn ti ọkọ àti ìyàwó parí gbogbo ètò tí wọn sí kúrò ṣùgbọ́n ti àwọn ẹbi tí ọ̀nà wọ́n jìn pinu láti dúro sùn ní agbolé náà.
Lásìkò tí Ezuruke tó jẹ́ olóri ìlú náà ń ṣàlàyè ìṣẹ̀lẹ̀ abúrú ọ̀hún o ní ó hàn gbangba pé èèfí gẹnẹretọ̀ tó ń ṣiṣẹ́ títí di ààrọ ọjọ ajé ní nígbà ti wọ́n fi tipátipá ṣí ìlẹ̀kùn, àwọn kan ti jẹ́ ọlọrun nípè.
"Mo mọ̀ pé kí ṣe ọ̀rọ̀ májèlé oúnjẹ, bíkò ṣe èèfi gẹnẹrátọ̀ ló pá wọ́n , èèfi náà ń kì mọ́ èèyàn láyà, àwọn obi ìyawó wà láàyé sùgbọ́n enìkeji tó jẹ ìbejì fún ìyàwó àti àwọn abúrò rẹ̀ ló bá ìṣẹ̀lẹ̀ náà lọ.
Kọmísọ́nà ọlọ́pàá ní ìpínlẹ̀ Imo Rabiu Ladodo tó fi ìdí ọ̀rọ̀ náà múlẹ̀ ṣàlàyé pé àwọ́n ti bẹ̀rẹ̀ ìwádìí ní pẹrẹwu lóri ọ̀rọ̀ náà.
Ladodo ní  ẹ̀rọ amúná wá náà sì wà ní títàn sílẹ̀ nínú yàrá ìdána títí ilẹ̀ fi mọ tí ilẹkun àti fèrèsé ti àwọn alejo sùn si wà ni títì pa."
Nigeria Democracy: Buhari buwọ́lu àbádòfin 'June 12' gẹ́gẹ́ bí àyájọ́ ọjọ́ ìjọba àwarawa
Oríṣun àwòrán, Twittter/Muhammadu Buhari
Lẹyin ọ rẹyin, ''June 12'' pada ayajọ ọjọ isinmi ijọba awarawa lorilẹede Naijiria lẹyin ti Aarẹ Muhammadu Buhari buwọ lu abadofin naa.
Oluranlọwọ aarẹ lori ọrọ ile igbimọ aṣofin agba l'Abuja lo fọrọ naa lede.
Ohun ti igbesẹ yii tumọ si ni pe lati akoko yii lọ, ko ni si isinmi lọjọ kọkandinlọgbọn oṣu karun un mọ to jẹ ayajọ ọjọ ijọba awarawa tẹlẹ.
NASS 2019: Gbùngbùn Àríwá ní Agbẹnusọ kàn- Umar Bago
Nigeria Senate Decides: Ta ni àṣẹ ilé aṣòfin àgbà Nàìjíríà yóò já mọ́ lọ́wọ́?
Ladoja: Àwọn èèyàn Oyo fì ìbò sọ̀rọ̀ pé ìjọba Ajimobi kò dára
Iba Gani Adams: Bẹ́ẹ gbé màláíkà kan lọ sí Aso Rock, kò lè ṣàṣeyọrí
Ọjọ kọkandinlọgbọn yoo kan jẹ ọjọ ifilọlẹ ati iburawọle ijọba tuntun lorilẹede Naijiria.
Igbesẹ aarẹ lati buwọlu ''June 12'' waye ni ọjọ meji peri si ọjọ kejila oṣu kẹfa tii ṣe Ọjọru.
Laipẹ yii ni ile igbimọ aṣofin agba mejeeji l'Abuja fi abadofin naa ranṣẹ si Aarẹ Buhari.
June 12: Ọjọ́ tí ọ̀pọ̀ ẹ̀yà, èdè àti ẹlẹ́sìnjẹ̀sìn ní Nàíjíríà papọ̀ di ọ̀kan
Oríṣun àwòrán, @mko_abiola
Ọjọ nla, ọjọ manigbagbe ni ọjọ Kejila osu Kẹfa ọdun 1993, ti gbogbo eeyan mọ si June 12 jẹ ninu itan orilẹede Naijiria.
Ta a ba si n sọrọ nipa eto ijọba alagbada lorilẹede Naijria, a ko lee kọ iyan eto iselu naa, ka ma fi ewe bo ayajọ June 12 nitori ọpọ isẹlẹ kayeefi to waye lasiko naa ati ẹkọ to kọ orilẹede Naijiria.
Àwọn ìtàn mánigbàgbé tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí:
Bí wọ́n ṣe ya Sinima Ayinla Omowura rèé, BBC Yorùbá  fọ̀rọ̀ wá àwọn òṣèré lẹ́nu wò
Ọdun 1993 yii ni aarẹ ologun, Ibrahim Badamọsi Babangida wa lori aleefa, ti gbogbo ọmọ Naijiria si n ke boosi fun agbekalẹ ijọba alagbada lẹyin ti Babangida ti lo ọdun mẹjọ lori aleefa.
'IBB da Abiola lẹ́yìn tó búra pẹ̀lú Quran'
Ijagudu awọn ọmọ Naijiria fun isejọba tiwa n tiwa lo mu ki Ibrahim Babangida fi se agbekalẹ ẹgbẹ oṣelu meji, eyiun ẹgbẹ oṣelu Social Democratic Party, SDP, ti ami idamọ rẹ jẹ Ẹṣin, ti ọpọ eeyan si mọ si ẹgbẹ oselu ẹlẹṣin.
Ẹgbẹ oṣelu keji ni ẹgbẹ National Republican Convention, NRC, eyi ti ami idamọ rẹ jẹ Ẹyẹ, tawọn eeyan si mọ si ẹgbẹ ẹlẹyẹ.
Awọn ẹgbẹ oṣelu mejeeji yii lo ṣeto idibo abẹnu ti wọn si fa oludije fun ipo aarẹ kalẹ lati gbe asia ẹgbẹ oṣelu koowa wọn.
Oludije ipo aarẹ fun ẹgbẹ oṣelu SDP ni Oloye Moshood Kashimawo Ọlawale Abiọla, ti gbogbo eeyan mọ si MKO Abiọla, nigbati igbakeji rẹ jẹ Alhaji Babagana Kingibe.
Olusegun Obasanjo: Ọmú ìyá mi ti mo fi ń mùkọ ni kekere ló jẹ ki ń lókun
Alatako fun ipo aarẹ latinu ẹgbẹ oṣelu NRC ni Bashir Tofa, ẹni to jẹ ọdọmọde, to si wa lati ẹkun ariwa orilẹede yii, nigbati igbakeji rẹ jẹ Sylvester Ugoh.
Oloye Abiọla ni tiẹ jẹ olowo, olokiki, gbajumọ, oloju aanu ati onisowo to ni ileesẹ nla-nla, ti awọn eeyan mọ bii isana ẹlẹẹta, nitori oju aanu to maa n se yika awọn ẹkun idibo to wa ni Naijiria, ko tiẹ to di pe o pinnu lati gbe igba ibo aarẹ rara.
Wọle Ṣoyinka: Owe maa n ran mi leti MKO Abiọla
Lọna ati fi opin si aṣa ṣiṣe mọkaruru esi ibo, eyi to wọpọ ni Naijiria latẹyinwa, lo mu ki Ọgagun Babangida se agbekalẹ ilana eto idibo gbangba laṣa n ta, eyi ti awọn oloyinbo n pe ni Option A4.
Eto ilana idibo yii ni yoo fun awọn araalu ati oludibo ni agọ idibo kọọkan ni anfaani lati to si ẹyin aworan oludije fun ipo aarẹ to ba wu wọn.
Oríṣun àwòrán, @MuhammadSageer
Lẹyin eyi ni awọn osisẹ ajọ eleto idibo to wa nikalẹ yoo si ka iye oludibo to to si ẹyin aworan naa, eyi ti yoo kọ silẹ bii esi idibo, tawọn asoju ẹgbẹ oselu kọọkan yoo si buwọlu, lati gba esi ibo naa wọle.
Ni ọjọ Kejila osu Kẹfa ọdun 1993 ti ibo naa waye, ilana gbangba laṣa n ta yii jẹ ki eto ibo naa lọ geerege, ti awọn eeyan si dibo fun oludije to wọn lai fi ti ẹya, ẹsin ati ede ṣe.
Sé o ti rí ère MKO Abiola tuntun?
Ilé tó yẹ kí Abiọla gbé, àwọn wo ló ń gbé níbẹ̀?
Amọ o se ni laanu pe, wọn ka ibo naa de idaji, ni ijọba ologun nigba naa lọhun  lai ni idi kan pato kede pe, wọn ko gbọdọ ka esi ibo naa mọ.
Ṣugbọn ninu idaji esi ibo ti wọn ka, Oloye MKO Abiọla lo n leke, ti awọn eeyan si gba pe oun lo jawe olubori ninu ibo naa, nitori oun lo ni ibo to pọ julọ.
Oniruuru iporogan, ifẹhonu han, wahala, rogbodiyan ati jagidi-jagan si lo tẹle bi wọn se wọgile esi ibo aarẹ ọjọ Kejila osu Kẹfa ọdun 1993 naa.
Awọn eeyan si faake kọri pe ajọ eleto idibo, ti Humprey Nwosu lewaju rẹ, gbọdọ kede MKO Abiọla gẹgẹ bii ẹni to bori ibo aarẹ naa.
Àwọn ará ìlú Abiola ní Abẹokuta bá BBC sọ̀rọ̀
Ọpọ wahala to suyọ yii lo mu ki Ọgagun Ibrahim Babangida yẹba lori aleefa, ti Ọgagun Sani Abacha si gba ipo rẹ.
Ṣugbọn kaka ki ewe agbọn dẹ lori ọrọ ibo ọjọ Kejila osu Kẹfa ọdun 1993, ko ko ko lo tun n le si, ti rogbodiyan si tun suyọ lasiko ti wọn n ṣami ayajọ ọdun kan ti idibo naa waye.
Oríṣun àwòrán, @mko_abiola
MKO Abiọla kede ara rẹ bii aarẹ fun Naijiria, ti wọn si sọ ọ si ahamọ. Rogbodiyan yii maa n waye ni ọdọọdun, titi ti ọgagun Abacha fi tẹri gbasọ lojiji, ti MKO Abiọla naa si tẹle.
Ọgagun Abdulsalami Abubakar di olori ijọba ologun ni Naijiria, to si ṣeto idibo aarẹ miran, eyi to gbe oloye Olusẹgun Ọbasanjọ wọle bii aarẹ orilẹede Naijiria.
Aarẹ ọna kakanfo Yoruba
Ọdalẹ ni Babangida ati Abacha - Ọmọ Abiola
Ohun to mu ki ayajọ June 12 ṣe pataki fun Naijiria:
Ahmed Lawan: Àwọn ohun tó yẹ ko mọ̀ nípa ààrẹ aṣòfin àgbà tuntun
Oríṣun àwòrán, @nassnigeria
Ọjọ Isẹgun ọjọ Kọkanla osu Kẹfa ọdun 2019 jẹ ọjọ manigbagbe ninu itan igbesi aye Ahmed Ibrahim Lawan nigba ti awọn akẹẹgbẹ rẹ dibo yan gẹgẹ bii aarẹ ile asofin agba ilẹ Naijiria tuntun.
Lawan, ọmọ ẹgbẹ iselu APC ati Ali Ndume, latinu ẹgbẹ oselu APC kan naa,  ni wọn dijọ figagbaga lati du ipo naa, amọ ori Lawan ni wọn gbe ade aarẹ ile asofin agba le lori pẹlu ibo mọkandinlọgọrin, nigba ti alatako rẹ ni ibo mejidinlọgbọn pere.
Ahmed Lawan, tii se olori ile asofin agba tuntun yii lo n soju ẹkun idibo ariwa ipinlẹ Yobe, ko to di aarẹ ile tuntun.
Oríṣun àwòrán, @nassnigeria
9th Assembly: PDP ní láìpẹ́ làwọn aráàlú yóò mọ ìyàtọ̀ lórí àkóso ilé aṣòfin
Oríṣun àwòrán, @OfficialPDPNig
Ẹgbẹ oselu alatako gboogi ni Naijiria, PDP, ti fesi lori bi idibo ile asofin agba ilẹ wa se lọ ni ọjọ Isẹgun.
Gẹgẹ bi PDP ti wi, o ni awọn n fọwọ lẹran maa woye ohun ti yoo jẹ atubọtan ẹgbẹ oselu APC ati isejọba rẹ, nibayii ti akoso ile asofin agba ti bọ sọwọ wọn gẹgẹ bi wọn se n poungbẹ rẹ.
Nigba to n ba BBC Yoruba sọrọ, igbakeji akọwe ipolongo fun ẹgbẹ oselu PDP lorilẹede yii, Ọgbẹni Diran Ọdẹyẹmi ni laipẹ lai jinna ni awọn araalu funra wọn yoo mọ iyatọ laarin akoko ti ẹgbẹ oselu PDP n se akoso ile asofin apapọ ilẹ wa ati akoko ti APC n dari rẹ yii.
Ọdẹyẹmi ni lootọ ni kii se gbogbo igba lo yẹ ki awọn asofin maa tako ifẹ inu aarẹ ati ẹgbẹ oselu rẹ.
Amọ ko bojumu to ki awọn asofin sọ ara wọn di abẹsinkawọ fun aarẹ, ki wọn si ma ni ọkan akin lati yẹ ohun to ba n se, ti ko dara wo.
Oríṣun àwòrán, @nassnigeria
Nigba to n ki aarẹ ile asofin agba tuntun ati igbakeji rẹ ku oriire ipo tuntun to ja mọ wọn lọwọ naa, ẹgbẹ PDP wa gba wọn nimọran lati mase lọ nipa ilana ẹlẹgbẹ oselu de, amọ ki wọn fi ifẹ ati idagbasoke Naijiria si ookan aya wọn, lasiko ti wọn ba n sisẹ ti ofin gbe le wọn lọwọ.
Ladoja: Àwọn èèyàn Oyo fì ìbò sọ̀rọ̀ pé ìjọba Ajimobi kò dára
Ọdẹyẹmi, lasiko to n sọrọ lori bi awọn ọmọ ẹgbẹ oselu PDP kan se pọn lẹyin Ahmed Lawan dipo Alli Ndume, ti ẹgbẹ PDP fẹ lati se atilẹyin fun lasiko idibo naa, igbakeji akọwe ipolongo fẹgbẹ PDP ni, ko si ohun to buru ninu ohun ti awọn asofin PDP naa se nitori o pẹ diẹ ki ẹgbẹ PDP gan to sọ ẹni ti wọn yoo dibo fun, fun wọn.
June 12: Àjọ eléto ìdìbò gbọdọ̀ kéde MKO Abiola bí ààrẹ Nigeria
NADECO tún pè fún ìdápada ètò ìjọba awa ara wá nítori pe ètò ìjọba to ń lọ lọ́wa yìí jẹ ti ìjọba ọlọgún, èyí ti ó gbé àgbára fún ìjọba àpapọ̀.
Ààrẹ orílẹ̀-èdè Nàìjíríà Muhammadu Buhari ti buwọ́lu àbádofin láti sọ June 12 di àyájọ ọjọ́ ìjọba àwa ara wa lórilẹ̀-èdè Nàìjíríà.
Sáájú àsìkò yìí ni gbogbo ìhà Iwọ-òòrun -Guusu Nàíjíríà ti rí June 12 gẹ́gẹ́ bíì ayájọ ọjọ ìjọba àwa arawa, tí wọn si n ṣe ajọyọ rẹ̀.
Sùgbọ́n lẹ́yìn ọ̀pọ̀lọpọ atótónú láti ọdọ àwọn ọmọ Nàìjíríà, ààrẹ Muhammadu Buhari, lọdun tó kọja kéde pé Nàìjíríà yóò ma ya June 12 sọ́tọ̀, láti fi ṣe àyájọ ọjọ ìjọba àwa ara wa, bákan náà ni ile ìgbìmọ aṣofin jan abádofin náà lóntẹ.
Ààrẹ Buhari tún fún Abiola ati ẹbi rẹ̀ ni àmi ẹ̀yẹ ní Abuja, tí ìjọba tún tọrọ àforíjìn lọ́wọ́ ẹbí Abiọla lórí ìjájkulẹ̀ June 12.
Kí ni ìdí ti June 12 fi ṣe pàtàkì sí ẹkùn Iwọ-òòrun Guusu Nàíjíríà:
Ní ọjọ́ Kejila oṣù Kẹfa ọdun 1993, ní ẹ̀yá Yoruba gbà pé, ìjọba awa ara wa wọle tọ wa ni Naijiria, lẹ́yìn ìdìbò ti wọ́n gbàgbọ́ pé kò ni ẹja ń bakan, nínú ìtàn orílẹ̀ ede Nàìjíríà.
Moshood Kashimawo Abiola jáde láti di ààrẹ orilẹ̀-èdè Naijírìa, ti Bahir Tofa náà si ta ko o latinu ẹgbẹ oselu miran, Abiola ri ìbò tó pọ láti ìhà Arewa, bákan náà ní wọn dibo fun ni iha Iwọ-òòrun Guusu nítori pe ó jẹ Yoruba.
Eyìn o rẹyin, Abiola ti léwáju ninu ìdìbò náà ní ìpínlẹ̀ Mọ́kandínlógun nígbà ti Tofa bori ibo ní ìpínlẹ̀ mọkanla, Sùgbọ́n ààrẹ ológun nigbà náà, Ọ̀gágun Ibrahim Babangida wọgile ìdìbò náà, kí wọn to ka èsì ìdìbò naa tan.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
June 12 declaration: Àjọ eléto ìdìbò gbọdọ̀ kéde MKO Abiola bí ààrẹ Nigeria
Lẹ́yìn èyí, ní wọ́n mu Abiola si atimọle tí ọ̀pọ̀ ọmọ Nàìjíríà sì gba ìgboro láti fẹ̀honu han ní ìpínlẹ̀ Eko àti Abuja pé kí wọ́n fi Abiola silẹ̀ lẹ́wọ̀n nítori pé wọ́n ni ìgbàgbọ pé òun ló jáwe olúbori nínú ìdìbò náà.
Ní ọ̀jọ̀ keje oṣù keje ọdún 1998 tí ó yẹ ki Abiola jáde kúrò lẹ́wọn ni òkìkí ikú rẹ̀ kan, èyí tún fa ìfẹhonu hàn míràn.
Láti ìgbà yìí ní àwọn ènìyàn ti ya June 12 sọ́tọ̀ láti máa'fi ṣe àyájọ ìjọba àwa ara wa.
Ó dàbi ẹni pé ìgbésẹ̀ ààrẹ Buhari kò ti tó, Kini NADECO tún fẹ?
Nígbà ti BBC Yoruba bá àkọ̀wé gbogbo-gboo fún àgbájọpọ̀ ẹgbẹ́ àwọn to ń ja fun ìjọba awa ara wa (NADECO), Ayo Opadoku nsọ̀rọ̀, o sàlàyé pé, ìgbẹ́ṣẹ̀ ààrẹ ko tíì kún ojú òṣùwọ̀n to ǹkan ti àwọn ń fẹ.
Ayo Ọpadokun ni, ó ti pẹ́ ti àwọ́n ti ń bèèrè fun JUne 12 gẹ́gẹ́ bi àyájọ ọjọ́ ìjọba awa ara wa, nítori pe ọjọ náà ni gbogbo Nàìjíríà gbà pé ìdìbò àwọn ló gbé Abiola wọle.
O ní ìjọba olọgun ló de, to ba gbogbo ètò ìṣèjọba Nàìjíríà jẹ́ gẹ́gẹ́ bi ìlàna ìwé ofin, nítori pe ẹyàmẹya ló pa Nàìjíríà pọ, kìí ṣe ẹ̀yà kan náà.
Kò yẹ ki ìjọba àpàpọ lágbára lóri ìjọbá ìpínlẹ̀ nígbà ti wọn dé, èyí si ni ó gba àgbà lọ́wọ́ àwọn gómìnà ìpínlẹ̀, àti pé ìjọba kò ti ṣe òun ti ó tọ, ti wọ̀n ò bá pàdà sí ìgbà ti àwọn gómìnà ìpínlẹ̀ ba ní akoso ohun to tọ si wọn, láti fí mú ìdàgbàsóke bá ìpínlẹ̀ wọ́n láì kọ́kọ́ lọ si Abuja.
Nǹkan ti NADECO ń bèèrè fún:
9th Assembly: Àwọn ohùn tó yẹ kí ẹ mọ nípa Femi Gbajabiamila tó di Olórí Ilé Asojú-sòfin Nàìjíríà tuntun
Oríṣun àwòrán, @femigbaja
Ọjọ ti pẹ ti Femi Gbajabiamila ti n wa ipo olori ile aṣoju-ṣofin orileede Naijiria, ala naa si ti wa di ohun bayi.
Fun awọn ti wọn ba n gbọ orukọ rẹ fun igba akọkọ nigba ti wọn kede rẹ pe o fidi akẹgbẹ rẹ, Umar Bago janlẹ, anfaani ree lati mọ nipa ẹni ti Fẹmi Gbajabiamila jẹ.
Ki a kọkọ bẹrẹ pe oun ni o gba ipo olori ile aṣoju-ṣofin lọwọ Yakubu Dogara gẹgẹ bi olori ile kẹẹdogun lorilẹede Naijiria.
Kii ṣe akọkọ ree ti Gbajabiamila yoo du ipo olori ile
Lọdun 2015,Femi Gbajabiamila koju Yakubu Dogara fun ipo olori ile amọ Dogara lo jawe olubori.
Saaju ki o to di aṣoju nile aṣofin, Femi Gbajabiamila ti a bi ni ọjọ kẹẹdọgbọn oṣu Kẹfa ọdun 1962, bẹrẹ iṣẹ agbẹjọro lọdun 1984 lẹyin to gboye nile Ẹkọ imọ ofin Naijiria.
Oríṣun àwòrán, Femi Gbajabiamila/Facebook
Femi Gbajabiamila
Laarin igba naa titi di ọdun 2003 ti o kọkọ di aṣoju fun ẹkun Surulere nilu Eko nile aṣoju-ṣofin Naijiria, Femi Gbajabiamila da ile iṣẹ agbẹjọro tirẹ silẹ, ti o si tun bẹrẹ si ni kopa diẹ diẹ ninu oṣelu.
Labẹ asia ẹgbẹ Alliance for Democracy, AD, lo ti bẹrẹ irinajo oṣelu rẹ, ti o si sun lọ si ACN ki o to pada kangun sinu ẹgbẹ oselu APC, nibi to ti wa jẹ olori ile lọjọ Iṣẹgun, ọjọ Kọkanla oṣu Kẹfa ọdun 2019.
Kí ló mú kí àyájọ́ June 12 ṣe pàtàkì ní Nàìjíríà
Ìtàn tó wà nídi òwe ‘Sebótimọ Ẹlẹ́wà Sàpọ́n’
Ki lawọn ipa to ti ko lagbo oṣelu?
Laarin awọn akẹgbẹ rẹ nile aṣofin, ọpọ lo ma n fi oju ọlọgbọn wo Gbajabiamila, ti wọn a si ma bọwọ fun, nipa bo ti ṣe ma n se agbekalẹ ọrọ rẹ.
Oríṣun àwòrán, FemiGbajabiamila/FACEBOOK
Femi Gbajabiamila ati Ahmad Lawan aarẹ ile aṣofin Naijiria ti wọn ṣẹṣẹ yan
Femi Gbajabiamila ni aṣofin to da ọrọ ofin pajawiri kan silẹ, eyi to faye gba ki igbakeji aarẹ laṣẹ lati dari ijọba, nigba ti aarẹ ko ba lagbara lati dari ijọba.
Abadofin yii ni wọn gbe kalẹ labẹ ilana ''Doctrine of Necessity''
Femi Gabjabiamila ni wọn yan gẹgẹ bi olori ọmọ ẹgbẹ to pọju lọ, ni ile aṣofin kẹjọ ni Naijiria.
Amọ ṣa...
Toun ti bi Gbajabiamila ti ṣe jẹ ilumọka oloṣelu, o ni awọn iṣẹlẹ kan to ṣe bi ẹni tapo saṣọ ala rẹ.
Akọkọ ni iroyin ti awọn alatako rẹ n gbe ka pe, o lọwọ ninu aṣemase kan nigba ti o n ṣiṣẹ gẹgẹ bi agbẹjọro nilẹ Amẹrika.
Ninu esi ọrọ yi, Gbajabiamila ni oun ṣẹ labẹ ofin awọn to n ṣe akoso eto amofin ni, ti oun si ti gba ijiya to tọ.
Oríṣun àwòrán, Femi Gbajabiamila/Facebook
Ọrọ yii to tun jẹyọ lasiko to n du ipo olori ile, eleyi ti awọn alatako rẹ fi n sọ pe ko tọ ni ẹni to n di ipo olori ile asofin mu.
Isẹlẹ miran ni i ṣe pẹlu bo ti ṣe na owo ribiribi lasiko ayẹyẹ ọjọ ibi iyawo rẹ.
Oríṣun àwòrán, ebalstv/facebook
Owo ribiribi ti Gbajabiamila fi ra ọkọ ayọkẹlẹ ati aṣọ lasiko ayẹyẹ ọjọ ibi iyawo rẹ bi awọn eeyan ninu
Ọrọ yii bi awọn eeyan ninu, ti Gbajabiamila si pada tọrọ aforijin pe oun ko ko iyan awọn ara ilu kere pẹlu rira ẹbun olowo iyebiye fun iyawo oun.
Eto ẹkọ ati ọrọ awọn oṣisẹ wa lara awọn ohun ti Gbajabiamila gbajumọ, to si ma n sọrọ nipa mimu idẹrun ba ara ilu.
Gbajabiamila tun nifẹ si mimu idagbasoke ba ere idaraya ni Naijiria.
Seyi Makinde: Àwọn iléẹkọ́ àdáni le è lọ fún ìsinmi ìdajì táámù
Oríṣun àwòrán, Google
Ìjọba ní ìdí tí àwọn fi gbé ìgbẹ́sẹ̀ náà ni pé àwọn akẹ́ẹ̀kọ́ ti dúró nílé nítorí ìyansẹ́lódì ọlọ́jọ́ gbọọrọ.
Ijọba ipinlẹ Ọyọ ti kede pe awọn ti fagile isinmi aarin taamu ti wọn ma n fun awọn akẹkọọ nipinlẹ naa.
Ijọba ipinlẹ Oyo ni, idi ti awọn fi gbe igbesẹ naa ni pe, awọn akẹkọọ ti duro nile nitori iyansẹlodi ọlọjọ gbọọrọ ti awọn osisẹ gule, awọn ọjọ isinmi ti ijọba fun awọn eniyan lati se ọdun tabi ayajọ.
Adari ile isẹ to n risi eto ẹkọ ni ipinlẹ Ọyọ,  Idowu Adeosun lo fi ọrọ naa lede ninu atẹjade to fi sita.
Wọn fi asiko yii sọ fun awọn olukọ ati akẹẹko lati lo asiko naa lati fi sisẹ ati kọ awọn ẹkọ ti o yẹ ki wọn ti kọ lati ọjọ melo sẹyin.
Amọ ijọba fikun wi pe, ọrọ naa ko nii se pẹlu awọn ile ẹkọ aladani ni ipinlẹ naa.
Ọba Abdulrasheed Akanbi rọ àwọn Ọba aláde yoruba láti dẹ́kun ẹgbẹ́ òkùnkùn síṣe
Oríṣun àwòrán, emprotelu1
Ọba Abdulrasheed Akanbi rọ àwọn ọba aláde yoruba láti dẹ́kun ẹgbẹ́ okunkun síṣe
Olúwo ti ìlú Iwo Oba Abdulrasheed Akanbi ti ké si àwọn Ọba aládé ní gbogbo ilẹ̀ Káàrọ oò-jííre láti kúrò nínú ẹgbẹ́ òkùnkùn ti wọ́n ń ṣe.
Olúwo ni gbogbo àwọn ẹgbẹ́ báwọnyìí máa ń sọ wọ́n di ẹrú ni nígbá ti wọ́n ba jẹ́jẹ̀ẹ́ owó àtí àwọn agbára ẹmi àìrí.
Gẹ́gẹ́ bó ṣe sọ nínú àtẹjade kan to fi síta láti ọwọ́ akọwé rẹ̀ Alli Ibraheem, Oba Abdulrasheed ní okiki wọ́n ti dínku nípa àwọn ẹgbẹ́ ti wọ́n ń ṣe.
O ní ọ̀pọ̀ Ọba ní ìhà ìwọ̀ -òòrun -Guusu ní láti dári jọ ṣe àgbékalẹ̀ ìgbìmọ ti yóò dá ògo Yorùba àti àṣẹ ti Ọlọrun fún wọ́n pada gẹgẹ bii Ọba.
Imam Fuad tako Oluwo lori wiwe lawani
Oluwo Ìwo ṣ'àlàye lori oyé oba oni lawàni
Ọba Akanbi ké si Alaafin Oyo, Oba Lamidi àti Awujale ti Ijebu Oba Sikiru láti sááju ìjàgbara kúrò lọ́wọ́ ẹgbẹ́ okunkun.
"O ní "" Àwọn ẹgbẹ́ òkùnkùn ti gbá gbogbo ẹtọ Ọba. Ọ̀nà àbáyọ kan ṣoṣo tó wà ní pe kí àwọn asáájú ọba jìjàgbara. Mo ri Alaafin àti Awùjalẹ̀ gẹ́gẹ àwọn tí wọ́n ni ìgboyà. Baba Alaafin lé sááju ìpolongo pẹ̀lú Awujale, wọn mọ ìtàn."""
Èmi ni Awùjalẹ̀ ti Iwo
Oluwo Ìwo ṣ'àlàye lori oye Emir
'Buhari, Saraki, Dangote, abẹ́ mi ni wọ́n wà'
June 12: Buhari fi orúkọ Abiola sọ pápá ìṣeré l'Abuja
Aarẹ Muhammadu Buhari kede pe papa iṣere ijọba apapọ to wa l'Abuja yoo maa jẹ Moshood Olawale Abiola Stadium bayii.
Aarẹ Buhari sọrọ yii ninu ọrọ apilẹkọ rẹ to sọ nibi ayajọ ọjọ ijọba awarawa akọkọ iru rẹ l'Abuja lonii.
Aarẹ Buhari
Aarẹ Buhari ni ipa ti Abiola ati igbakeji rẹ, Baba  Gana Kinjibe ti wọn jọ gbegba ibo lọdun 1993 kii ṣe kekere ninu eto oṣelu orilẹede Naijiria.
Ọpọ awọn ajafẹtọ ọmọniyan lo ti n sọ fun ijọba apapọ lati fi orukọ Abiola sọ nnkan kan to jẹ ti ijọba apapọ ko le jẹ iranti nitori pa rẹ ninu eto oṣelu Naijiria.
Aarẹ Buhari tun sọ pe ijọba oun yoo gbiyanju lati yọ ọpọ ọmọ Naijiria kuro ninu iṣẹ ati oṣi to n ba ọpọ eeyan finra.
Aarẹ sọ pe orilẹede Naijiria lagbara lati yọ ọgọrun miliọnu ọmọ Nigeria ninu iṣẹ laarin ọdun mẹwaa.
Aarẹ Buhari tun fikun ọrọ pe ijọba oun yoo tubọ ṣiṣẹ takuntakun si lati rii wi pe eto aabo mọnyan lori, ati pe ijọba tun ọrọ aje Naijiria ṣe sii.
Aarẹ tun sọ pe ijọba oun ko ni foju re wo ẹnikẹni to ba fẹ da rogbodiyan silẹ nibi kibi kaakiri orilẹede Naijria ati awọn to ba kowo ilu jẹ.
Aarẹ Naijiria sọ pe laarin ọdun mẹrin saa keji ijọba oun, oun yoo jẹ ki ina mọnamọna wa lowo pọọku fawọn ọmọ Naijiria.
Ilu Abuja rosomu
Ilu Abuja rosomu fun ayajọ ijọba awa ara wa eyi ti Aarẹ Muhammadu Buhari ṣẹṣẹ buwọlu pe ko maa waye ni gbogbo jọkejila oṣu kẹfa dun latoni lọ.
Kẹti kẹti ni ero n tu ni gbagede Eagle Square ni olu ilu orilẹede yii, Abuja nibi ti eto naa ti n waye.
Aarẹ Buhari
Ṣaaju ọdun 2019, ọj ikọkandinlọgbn oṣu ikarun un ni orilẹede Naijiria maa n yẹ si tẹlẹ gẹgẹ bi ayajọ ijọba awa ara wa.
Ni ọjọ kẹrindinlogun oṣu karun un ọdun 2019 ni aarẹ Buhari ṣẹṣẹ buwọlu u pe June 12 ti kii ṣe ajoji si gbogbo ọmọ Naijiria ni wọn yoo maa ṣe ayajọ ijọba awa ara wa ni Naijiria.
Aarẹ Buhari
Pataki rẹ julọ fun iran Yoruba ati awọn ọmọ Naijiria lapapọ to ṣi ranti iṣẹlẹ ọjọ kejila oṣu kẹfa ọdun 1993 ni pe ọjọ naa lọhun ni ti ibo waye ni NAijiria.
Ilana idibo gbangba laṣa n ta yii jẹ ki eto ibo naa lọ geerege, ti awọn eeyan si dibo fun oludije to wọn lai fi ti ẹya, ẹsin ati ede ṣe.
Agbára wo ni June 12 fún MKO Abiola tó ṣì ń fọhùn lẹ́yìn ikú rẹ̀?
Sé o ti rí ère MKO Abiola tuntun?
Ilé tó yẹ kí Abiọla gbé, àwọn wo ló ń gbé níbẹ̀?
Wọn ka ibo naa de idaji, ni ijọba ologun nigba naa lọhun  lai ni idi kan pato kede pe, wọn ko gbọdọ ka esi ibo naa mọ.
Ṣugbọn ninu idaji esi ibo ti wọn ka, Oloye MKO Abiọla lo n leke, ti awọn eeyan si gba pe oun lo jawe olubori ninu ibo naa, nitori oun lo ni ibo to pọ julọ.
Eyi jẹ diẹ ninu itan to mu ki June 12 ṣe pataki fun iran Yoruba.
#FIFAWWC: Amẹ́ríkà to pàṣán má r'ágbà fín sí ìdí Thailand
Oríṣun àwòrán, fifa.com
Ẹrù ìyà ni Norway dì lé Super Falcons lórí ní 2019 Women's World Cu
Fun igba akọkọ ninu itan idije ife ẹyẹ bọọlu awọn obinrin lagbaye, orilẹede kan yoo maa gbo ewuro soju orilẹede miran pẹlu ami ayo mẹtala.
Orilẹede Amẹrika gb'ogo lọwọ ẹgbẹ agbabọọlu obinrin orilẹede Thailand pẹlu ami ayo mẹtala ninu ifẹsẹwọnsẹ akọkọ wọn ni idije ife ẹyẹ fawọn obinrin to n lọ lọwọ lorilẹede France.
BBC Africa Eye: Akọroyin fẹ ìdí àwọn oníṣẹ́ ibi ọmọ ogun síta
Koda, ko si idije ife ẹyẹ bọọlu ajọ FIFA kankan ti irufẹ eyi ti ṣẹlẹ.
Agbabọọlu  orilẹede Amẹrika, Alex Morgan gba goolu marun un wọle ninu ifẹsẹwọnsẹ naa, Lavelle (meji), Mewis (meji), Horan, Megan Rapinoe, Mallory Pugh ati Carli Lloyd  pẹlu naa gba goolu kọọkan wọle ninu ifẹsẹwọnsẹ naa.
Iba Gani Adams: Bẹ́ẹ gbé màláíkà kan lọ sí Aso Rock, kò lè ṣàṣeyọrí
Ifẹsẹwọnsẹ ọhun ni akọkọ fun orilẹ€de Thailand ninu idije ife ẹyẹ agbaye.
MKO Abiola: Ọmọ 23 ni bàbá MKO Abiọla bí saájú rẹ̀, àmọ́ òun ni àkọ́bí
Oríṣun àwòrán, @mko_abiola
Ti a ba n sọrọ awọn ọlọla, olowo, ọlọrọ, oloselu, ẹlẹyinju aanu ati onisowo pataki lorilẹede Naijiria, o loju ẹni to lee bọ sita pe oun siwaju Moshood Kashimawo Ọlawale Abiọla, ti gbogbo eeyan mọ si MKO Abiọla.
Idi ni pe ọpọ ipa ribiribi ni MKO Abiọla ko si ẹka oselu, okoowo, aanu sise, agbega ọrọ aje ati ipese awọn ohun eelo amayedẹrun yika tibu tooro Naijiria.
Ni igba aye rẹ, ọpọ eeyan lo tumọ orukọ MKO si Money, Kudi, Owo, eyi to jẹ owo apekanuko lede Yoruba. Idi ni pe MKO Abiọla ri taje se, Ọlọrun bẹ igi ọla fun, to si jẹ ilumọọka kaakiri agbaye nitori buruji to ni, to si n ṣe aanu fun awọn mẹkunnu.
Iwa aanu rẹ yii si lo mu ki ọpọ eeyan jade lati dibo fun pe ko di aarẹ Naijiria lọjọ Kejila, osu Kẹfa ọdun 1993, bi o tilẹ jẹ pe wọn ko kede rẹ bii aarẹ, eyi to fa rogbodiyan ni Naijiria, to si tun da ẹmi MKO Abiọla legbodo, amọ ti awọn eeyan n seranti rẹ titi di oni oloni.
Oríṣun àwòrán, @mko_abiola
Bi onirese MKO Abiọla ko ba wa fin igba mọ, eyi to ti fin ko lee parun laelae, idi si ree to fi yẹ ka mọ nkan kan, abi meji nipa igbe aye oloore yii, gẹgẹ ba ṣe ka loju opo itakun agbaye Wikipedia, ẹni to fi ẹmi rẹ lelẹ fun ifẹsẹmulẹ ijọba alagbada ati idagbasoke orilẹede Naijiria.
Oríṣun àwòrán, @mko_abiola
Ọdalẹ ni Babangida ati Abacha - Ọmọ Abiola
Yooba ni baa ku laa dere, eeyan ko sunwọn ni aaye, wọn fi oye igbẹyin da MKO Abiọla lọla lẹyin ogun ọdun to ti tẹri gbasọ, nigba ti aarẹ Muhammadu Buhari fi oye GCFR da lọla lọdun 2018, oye yii si ni wọn maa n fun ọwọ awọn eeyan to jẹ adari lorilẹede Naijiria.
Obasanjo: Ìpasẹ̀ ìparun ni Nàíjíríà ń tọ̀ lábẹ́ Buhari
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ààrẹ tẹ́lẹ̀rí lórílẹ̀èdè Nàíjíríà náà se àtìlẹyìn fún olùdíje lábeẹ́ ẹgbẹ́ òsèlú PDP, Atiku Abubakar nínú ìdìbò sípò ààrẹ tó kọjá.
Aarẹ orilẹede Naijiria tẹlẹri, Olusegun Obasanjo ti ni orilẹede Naijiria n tọ ipasẹ iparun labẹ isejọba Aarẹ Muhammadu Buhari.
Ọbasanjọ, to sọ eyi lasiko ifọrọwanilẹnuwo pẹlu ile isẹ iroyin Premium Times ni, eto ọrọ aje orilẹede Naijiria ti dẹnu kọlẹ labẹ isejọba to wa lode.
O fikun wi pe, irọ patapata ni ijọba to wa lode yii n pa lori igbogun ti iwa ibajẹ ati ajẹbanu, nitori awọn ẹgbẹ alatako nikan ni ijọba n gbogun ti lori iwa ibajẹ.
Aarẹ orilẹede Naijria tẹlẹri naa ni, bi o tilẹ jẹ wi pe Aarẹ Buhari wọle fun saa keji, ko seese ki ọrọ aje Naijiria gbooro si, nitori nkan ko sẹnu ire lọwọlọwọ.
Ti a ko ba gbagbe, Atiku Abubakar to jẹ oludije fun ipo aarẹ labẹ ẹgbẹ oselu PDP ni Ọbasanjo se atilẹyin fun, ninu idibo gbogbo-gboo to waye lọdun 2019.
June 12: Buhari yóò la ọ̀na 2,000 kìlómítà, èèyàn 100 yóò yọ nínú òṣì
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Mo fe gbajumo oro eto aabo lasiko yii
Lasiko ayajọ June 12, ti i se ayajọ ijọba Tiwantiwa, aarẹ Muhammadu Buhari fi akoko naa sọ ọrọ apilkọ rẹ fun saa keji eyi to kun fun ọpọ ileri itunu fawọn ọmọ orilẹede yii.
Bẹẹ ba gbagbe, Aarẹ Buhari bẹrẹ saa keji iṣejọba rẹ ni ọjọ Kọkandinlọgbọn, oṣu Karun un, ọdun 2019, amọ ti ko ba awọn ọmọ Naijiria sọrọ lẹyin ti wọn bura fun un tan.
Oríṣun àwòrán, @Buhari
Kókó ọ̀rọ̀ tí Buhari sọ ní àyájọ́ June 12
Gbagede Eagle Square nibi ti Naijiria ti n sami ayẹyẹ iṣejọba Awa ara wa ni Abuja, ni aarẹ Buhari ti wa ba awọn ọmọ Naijira sọrọ.
Ninu ọrọ rẹ fun ayajọ June 12, Buhari ṣeleri lati tubọ ri si eto aabo fun ẹ̀mí àti dukia.
Aarẹ Buhari ni, oun gba pe ajọṣepọ wa laarin ìṣẹ́, eto ọrọ ajé ti ko daa pẹlu iwa jẹgudujẹra, lai yọ eto aabo ti ko fini lọkan balẹ silẹ.
Aarẹ Buhari tun ni, ko si nkan to le di Naijiria lọwọ idagbasoke gẹgẹ bii ti China, India ati Indonesia.
Kókó inu ọrọ Aarẹ Buhari:
Aarẹ Buhari bẹrẹ nipa ṣiṣe alaye kikun lori pataki Naijiria ninu idagbasoke iṣejọba alagbada nilẹ Adulawọ.
O mẹnuba awọn aṣeyọri ijọba rẹ ni saa to kọja (2015 si 2019).
Oríṣun àwòrán, @pius
Aarẹ Buhari kede fifi orukọ MKO Abiola pe papa iṣere Abuja
Aarẹ Buhari ni oun ti jagun Boko Haram de ibi to lapẹrẹ lati 2015.
O ni nitootọ iṣẹ yii pọ lati gbogun ti awọn ajinigbe ati agbesunmọmi, ṣugbọn eyi ti di ankoo fawẹẹli gbogbo agbaye.
Oríṣun àwòrán, @others
Awọn eniyan ilẹ okeere wa ba Buhari yọ ayọ ayajọ iṣejọba alagbada
O ni ijọba oun ti mojuto ọrọ atunṣe eto ẹkọ ati idagbasoke eto ọrọ aje Naijiria, yatọ si titun awọn opopona ṣe.
Oríṣun àwòrán, @others
Aṣepari awọn iṣẹ akanṣe ti ijọba rẹ ti bẹrẹ tẹlẹ.
Ileri ti Buhari fẹ gbajumọ ni saa keji iṣejọba rẹ:
Nitootọ Aarẹ Buhari ko soju abẹ niko ni pato lori ileri rẹ, ṣugbọn o ṣapejuwe awọn koko ti ijọba oun yoo gbajumọ lasiko yii bii:
Oríṣun àwòrán, @others
Buhari gbe ipinnu rẹ fun Naijiria jade loju ọpọ ero ni Eagle Square
Awọn olori orilẹ-ede to wa nijoko nibẹ pẹlu Buhari lasiko ayajọ ijọba tiwa n tiwa naa ni aarẹ orilẹ-ede Rwanda, Chad, Niger ati Gambia.
9th Assembly: Aráàlú ní àwọn ń fẹ́ ìpèsè àwọn ohun èèlò amáyédẹrùn
Lagos/Ibadan Expressway: Èèyàn mẹ́jọ ló kù nínú ìjàmbá ọkọ̀ kìí ṣé mẹ́ẹ̀dógún
Lagos/Ibadan Expressway: Ọpọ̀ èrò ló farapa tí mọ́tò ṣòfò
Ọkunrin mẹfa,obinrin kan ati ọmọdekunrin kan lo ku ninu ijamba ọkọ to waye lopopona marose Eko si Ibadan.
Eeyan mejila si farapa.
Ajọ ẹsọ alabo oju popo lo sọ eyi di mimọ fun BBC Yoruba ninu ifọrọwero pẹlu olori ẹka wọn ni ipinlẹ Ogun,Clement Oladele.
Oladele salaye pe ere asapajude lo ṣokunfa iṣẹlẹ yi ti ọkọ meje si farakasa ijamba naa.
Saaju ni awọn ti ọrọ naa soju wọn kan ti ni o to eeyan mẹẹdogun ti o ku ninu iṣẹlẹ yi.
Ijamba ọkọ naa la gbọ wi pe akọkọ rẹ ṣẹlẹ ni nnkan bi ago meje ọjọru ti awọn miran si tun ṣelẹ lowurọ ọjọbọ.
Lagbegbe kan ti wọn n pe ni Danko saaju ki a to  de Sagamu ni o ti waye.
Isẹlẹ naa ti da sunkẹrẹ fakẹrẹ ọkọ silẹ ti awọn ẹsọ ajọ oju popo si n gbiyanju lati dari lilọ bibọ ọkọ.
Lagbegbe kan ti wọn n pe ni Danko saaju ki a to de Sagamu ni o ti waye.
Akọroyin BBC Yoruba, Olu Alebiosu ti oun naa n rin loju ọna naa jabọ pe awọn ti ọrọ naa soju wọn sọ pe ọkọ nla kan to ya si ibi ti ko yẹ lo mu ki ijamba naa sẹlẹ.
Gẹgẹ bi ohun ti o sọ, O ni awọn alafojuri nibi iṣẹlẹ naa bi ọkọ naa ṣe ya lojiji lo mu ki awọn miran to n bọ lẹyin rẹ fori sọ ara wọn.
Ninu awọn ọkọ to farakasa la ti ri ọkọ akero kan to fi mọ awọn ọkọ ayọkẹlẹ miran.
A ko ti ri aridaju lati ọdọ awọn ajọ to n risi iṣẹlẹ pajawiri lori iye eeyan to ku ṣugbọn awọn to wa nibẹ ni ko le kere ju mẹẹdogun lọ
Ijamba ọkọ naa da sunkẹrẹ fakẹrẹ silẹ loju ọna naa
Akọroyin wa jabọ pe nisoju oun, awọn ẹsọ abo oju popo n fi ọkọ alaarẹ gbe awọn eeyan kan  to farapa  lọ si ile iwosan.
Ni kete ti a ba ti ni iroyin miran nipa iṣẹlẹ yi ni a o fi too yin leti.
9th Assembly: Aráàlú ní àwọn ń fẹ́ ìpèsè àwọn ohun èèlò amáyédẹrùn
Ikú Dagunro: Sajẹ ní èèyàn tó ṣe gbáralé ni Dagunro, ọ̀pọ̀ èèyàn ló dìde láti ara rẹ̀
Oríṣun àwòrán, Sajetiologa
Awọn agba ọjẹ ninu isẹ tiata ni ẹka ti Yoruba ti n sọrọ nipa gbajugbaja osere tiata, Fasasi Ọlabankẹwin, ti gbogbo eeyan mọ si Dagunro. to mi kanlẹ lowurọ Ọjọbọ.
Gẹgẹ bi BBC Yoruba se gbọ, idaji ọjọbọ ni Dagunro mi kanlẹ nile rẹ nilu Eko lasiko aisan ranpẹ to ti n ba finra lati bii ọdun melo kan sẹyin, eyi ti a ko tii lee sọ iru aisan ti o jẹ.
Nigba to n sedaro Dagunro, Adebayọ Salami, ti a mọ si ọga Bello, se apejuwe Dagunro bii ẹni to gbe asa Yoruba ga ni nigba aye re.
Nigba to n ba BBC Yoruba sọrọ, Oga Bello ni oninu ire ni Dagunro, to si ni itẹriba fun awọn asaaju ninu osere tiata nitori o ri oun gẹgẹ bi oga rẹ, to si bọwọ fun oun.
O fikun un wi pe iku rẹ dun oun, ati wi pe, agbo osere tiata Nollywood ko lee gbagbe rẹ mọ lai.
Bakan naa, gbajugbaja oserebinrin, Alhaja Fausat Balogun, ta a mọ si Madam Sajẹ, naa ti ni eniyan to se e gbarale ni Dagunro nigba aye rẹ.
Oríṣun àwòrán, Sajetiologa
Saje ni ọpọlọpọ awọn olosere lo dide lati ara rẹ, ti gbogbo wọn si mọ Dagunro si ẹni to nifẹ si iserere awọn akẹgbẹ rẹ.
O fikun wi pe, ipa ribiribi ti Dagunro ko si ere tiata ni pe awọn eniyan ti ara rẹ dide, ti wọn si di olokiki eniyan.
Pẹlu idunnu ọkan ni Madam Saje fi sọ wi pe, awọn fẹran Dagunro, amọ Ọlọrun fẹran rẹ ju awọn lọ.
Lara awọn ere ti Dagunro ti se nigba aye rẹ ni Ija Abija, Dagunro, Jagunmolu, Ibinu Ọmọ Eleye, Abẹni Agbọn, Kakaki 'leku, Ikilọ agba ati Inu bibi.
Iku ti pa agbe, bii ẹni ti ko lee daro; iku ti pa aluko, bii ẹni ti ko lee kun osun; iku ti pa lekenleke, bii ẹni ti ko lee kun ẹfun.
Iku ti pa ojú ilumọọka agba osere kan de, Fasasi Ọlabankẹwin, ti gbogbo eeyan mọ si Dagunro Alakija oogun
Oríṣun àwòrán, Sajetiologa
A gbọ pe irọlẹ ọjọbọ ni wọn yoo sinku agba osere to tẹri gbasọ naa ni ile rẹ ni Oṣogbo.
Dagunro lo maa n se ere to jẹ mọ ti asa ibilẹ, to si maa n se ere oloogun pẹlu ọfọ, oun si ni osere tiata keje  ti yoo silẹ bora ninu awọn osere tiata Yoruba lọdun yii.
Ọmọkunrin meji ni Dagunro bi, awọn mejeeji naa si lo n se isẹ tiata. Orukọ wọn ni Kazeem Iyanda Olabankẹwin ati Jamiu Olabankẹwin.
Oríṣun àwòrán, Sajetiologa
Wayi o, ọpọ awọn osere tiata lede Yoruba lo ti n sedaro akọni osere to lọ naa, ti ọpọ awọn oju opo ikansira ẹni lori itakun agbaye si ti kun fun idaro iku Dagunro.
Loju opo Instagram rẹ, Alhaja Fausat Balogun, ti gbogbo eeyan mọ si Sajẹtiologa naa ti kede iku gbajugbaja osere naa.
Ọba orin Saheed Osupa naa ti saaro Dagunro.
Bakan naa ni idaro yii ko yọ Sanyẹri silẹ.
BBC Yoruba naa wa n gbadura pe ki Ọlọrun dẹ ilẹ fun Fasasi Ọlabankẹ, ti gbogbo eeyan mọ si Dagunro.
Obasanjọ-Kufuor: AU, ECOWAS gbọdọ̀ dá sí ọ̀rọ̀ Benin
Oríṣun àwòrán, Getty Images/GEORGES GOBET
Aarẹ nigba kan ri lorilẹede Ghana, John Kufuor ati Aarẹ tẹlẹ ni Naijiria Olusẹgun Ọbasanjọ, ti ke pe ajọ iṣọkan awọn orilẹede ni Afirika (AU), ati ajọ ECOWAS, lati da si oṣelu orilẹede Benin to n kọni lominu bayii.
Ninu atẹjade kan ti Obasanjo ati Kufuor jijọ gbe sita, eyi ti agbẹnusọ Obasanjo, Kehinde Akinyemi fi tẹ BBC Yoruba lọwọ, awọn agba Afirika naa ni asiko ti to lati da si ọrọ oselu Benin ko ti di yanpọn-yanrin.
Wọn ṣalaye wi pe, idibo to waye ni orilẹede Benin ni ọjọ Kejildinlọgbọn oṣu Kẹrin ọdun 2019, ninu eyi ti wọn ko jẹ ki awọn ẹgbẹ alatako ti kopa, jẹ ohun to tẹ ẹtọ awọn aarẹ ana lorilẹede Benin, Boni Yayi ati awọn olori ẹgbẹ alatako to ku mọlẹ.
Kufuor ati Obasanjo ni, bo tilẹ jẹ pe ọrọ idibo jẹ ohun ti tẹru-tọmọ yẹ ko pa, amọ ohun to n ṣẹlẹ ni Benin ko ri bẹẹ.
Nitori naa, wọn n gba awọn olori orilẹede to wa ni Afirika ni imọran wọn yii:
afin pupa
Oyo Police: Àwọn àkẹ́kọ̀ọ́ náà jẹ́wọ́ pé ọmọ ẹgbẹ́ òkùnkùn Ẹyẹ ni àwọn
Oríṣun àwòrán, @PoliceNG
Ọwọ palaba awọn akẹkọ mẹẹdogun nile ẹkọ fasiti imọ ẹrọ Ladoke Akintọla, LAUTECH, nilu Ogbomọsọ ti segi lori ẹsun pe wọn digun jale, sise ẹgbẹ okunkun ati iwa agbodegba fun ọdaran.
Kọmisọna ọlọpa fun ipinlẹ Ọyọ, Sina Olukọlu lo sisọ loju ọrọ yii lasiko to n bawọn akọroyin sepade ni olu ileesẹ ọlọpa to wa ni Ẹlẹyẹle nilu Ibadan.
Olukọlu ni awọn osisẹ ọlọpa to n gbogun ti iwa idigunjale, SARS, ni wọn ta mọra, ni kete ti iroyin iwa ọdaran awọn afurasi ọhun de etigbọ wọn, ti wọn si gba wọn mu.
O fikun pe orukọ awọn afurasi ọdaran naa ti wa ni akssilẹ awọn lati ọjọ pipẹ fun oniruuru ẹsun iwa ọdaran, tọwọ sinkun awọn osisẹ SARS naa si tẹ wọn lọjọ Kẹfa osu Kẹfa ladugbo Arojẹ, nilu Ogbomosọ ni deede aago meje abọ alẹ.
Ninu ọrọ rẹ, Olukọlu fikun pe awọn akẹkọ naa ti jẹwọ pe ọmọ ẹgbẹ okunkun Ẹyẹ ni awọn, tawọn si ti n foju awọn eeyan akẹkọ ẹlẹgbẹ awọn ati araalu danrin.
afin pupa
O wa fọwọ idaniloju sọya pe ileesọ ọlọpa ipinlẹ Ọyọ ti setan lati ri pe adinku nla ba iwa ọdaran nipinlẹ yii.
Lara awọn eeyan to ti fori sọta iwa ọdaran lati awọn afurasi ọhun ni arabinrin kan ọga rẹ ran nisẹ, ti wọn si fi oogun gba miliọnu kan ati ẹgbẹrun lọna ẹgbẹrin naira (N1.4M) lọwọ rẹ lasiko to n lọ sile ifowopamọ ladugbo Dugbẹ.
First Lady: Kí ló mú Aisha Buhari gbà oyè tó kọ tẹlẹ?
Oríṣun àwòrán, @aishambuhari
Lati wakati yi lọ,'First Lady', eyi tii se obinrin akọkọ ni Naijiria, ni ki ẹ ma pe mi.
Ọrọ to n ja rainrain ree, eyi to jade lẹnu iyawo aarẹ Naijiria, Aisha Buhari.
Iyawo aarẹ lorileede Naijiria, Aisha Buhari ki i ṣe ẹni to n bẹru lati sọ ohun to wa lọkan rẹ.
Pupọ ninu awọn nkan to ba sọ lawọn eeyan ma n ran mọ ẹnu, to si maa n da awuyewuye silẹ nigba mi.
Aisha sọ ọrọ naa lọjọbo, ti oju opo Twitter si ti gbana jẹ lori rẹ.
Nibi apejẹ kan fawọn iyawo Gomina ti wọn ṣẹṣẹ yan, ati awọn ti ọkọ wọn pari saa wọn,ni aya aarẹ ti sọ ọrọ to nii ṣe pẹlu yiyi orukọ oye ara rẹ pada lati Wife of the President, iyawo aarẹ si First Lady, obinrin akọkọ.
Sogidi Lake: Kòṣẹja-kòṣèèyàn lá bá nínú adágún odò náà -Ojedele
Koda, o tun tọrọ aforijin pe oun sọ fun wọn saaju lati maa pe oun ni aya aarẹ dipo obinrin akọkọ ni Naijiria.
Kini o mu ipinnu tuntun Aisha yii wa?
Saaju ko to di pe Muhammadu Buhari, tii se ọkọ rẹ di aarẹ, ni Aisha Buhari ninu ifọrọwero kan pẹlu ile iṣẹ Iroyin TVC lọdun 2015 sọ pe, oun gbagbọ pe iyawo aarẹ ologun nigba kan ri, Mariam Babangida lo fi ipo First Lady lọlẹ.
Aya Buhari ni ''lati igba ti Mariam Babangida ti ku ni ipo yi ti wọmi, ni temi ti ọkọ mi ba wọle gẹgẹ bi aarẹ, mi o ni jẹ oye First Lady, bii kii ṣe ki wọn ma a pe mi ni iyawo aarẹ''
O si dabi ẹni pe ọrọ ọkọ rẹ to ni oun ko ni faye gba ipo First Lady labẹ ijọba oun, ni Aisha Buhari tẹle.
Oríṣun àwòrán, George Okoro
Aisha Buhari ko ṣẹsẹ ma f'ọ̀rọ̀ da ìgboro rú lórí ìjọba ọkọ rẹ̀
Bẹẹ ba gbagbe, Aarẹ Buhari sọ fun awọn akọroyin saaju ko to di aarẹ pe, iwe ofin ko faye gba ipo First Lady, fun idi eyi, oun ko ni fi aaye gba.
Fọdun mẹrin tọkọ rẹ fi ṣe ijọba, wọn ko pe Aisha Buhari ni First Lady, amọ aarẹ Buhari yan awọn amugbalẹgbẹ fun Aisha Buhari, ti iṣẹ wọn ko si fi bẹẹ yatọ si ki wọn ma ba First Lady ṣiṣẹ.
Iyipada tuntun yii, gẹgẹ bi Aisha Buhari ṣe sọ nibi apeje awọn iyawo Gomina, ko ṣẹyin ki iyemeji ma baa waye lori bi wọn yoo ṣe ma pe awọn iyawo Gomina tuntun, paapa julọ, awọn ti ọkọ wọn ba ni ju iyawo kan lọ.
afin pupa
Lọpọ igba, ti aarẹ ba ni ju iyawo kan lọ, iyale ninu awọn iyawo naa ni wọn ma n pe ni First Lady, ti awọn iyawo yoku yoo si maa jẹ iyawo aarẹ, wife of the President.
Ọrọ ti Aisha Buhari sọ yii kọ ni yoo jẹ igba akọkọ, ti ọrọ rẹ ati ti ọkọ rẹ yoo ma a tase ara wọn.
Ninu ọrọ akọroyin onwoye kan to ba BBC sọrọ, Abdulaziz Abdulaziz, o ni ọrọ yii ko ya oun lẹnu nitori pe, irori Aisha Buhari ati Buhari to jẹ ọkọ rẹ, kii papọ lọpọ igba.
Oríṣun àwòrán, Aisha buhari
''A ko mọ ẹni ti yoo bori lọtẹ yi nipa ipo First Lady, nitori nnkan ti Aisha loun fẹ ree''
O salaye pe, ọrọ ọọfisi 'First Lady' ohun gan tẹlẹ dabi arumọjẹ nitori ''kii ṣe wi pe nnkan ti Aisha n ṣe gẹgẹ bi Iyawo aarẹ, Wife of the President, yatọ si nkan ti ẹni to jẹ 'First Lady' n ṣe''
Abdulaziz pari ọrọ rẹ pe ''orukọ lasan ni wọn fẹ yii pada, ko si iyatọ''
8TH Assembly: FRSC kò yan Saraki sọjú pé kó dá nọ́mbà ọkọ̀ tó lò padà
Oríṣun àwòrán, Facebook/Bukola Saraki
8TH Assembly: FRSC kò yan Saraki sọjú pé kó dá nọ́mbà ọkọ̀ tó lò padà
Ko si idi kankan fún wa lati yan Saraki sọju -FRSC
Ajọ to n ri si igbokegbodo ọkọ lorilẹ-ede Naijiria, FRSC ti sọ pe oun ko yan adari ile igbimọ aṣofin ana ṣoju.
O fidi eyi mulẹ lẹyin ti ajọ naa sọ fun awọn aṣofin ti ko pada sile lati da nọmba mọtọ ti wọn lo pada.
Alukoro fun ajọ FRSC, Bisi Kareem to ba BBC sọrọ fidi rẹ mu lẹ pe awọn aṣofin ti ko pada sile le lo nọmba yii laarin ọdun 2015 titi di oṣu kẹfa, ọdun 2019.
Sẹnẹtọ mọkandinlaadọrin pẹlu aṣoju ṣofin mọkanlelaadọjọ ni FRSC n beere pe ki wọn dá awọn nọmba ọkọ yii pada.
Sogidi Lake: Kòṣẹja-kòṣèèyàn lá bá nínú adágún odò náà -Ojedele
Bisi Kareem ṣalaye pe ko si otitọ kan ninu iroyin to n tan kalẹ pe ajọ FRSC yan Saraki ṣọju ni.
Ọgbẹni Kareem sọ pe ọrọ naa ko nii ṣe pẹlu Saraki nikan, gbogbo ọmọ ile ti ko pada sile lo kan.
Barister lo bi gbogbo oníṣẹ́ fújì -Oṣupa
Alukoro fun ajọ FRSC fikun ọrọ rẹ pe ajọ naa sọ fun akọwe ile igbimọ aṣofin agba lati awọn nọmba ọhun nitori oun lo sun mọ wọn ju.
Ladoja: Àwọn èèyàn Oyo fì ìbò sọ̀rọ̀ pé ìjọba Ajimobi kò dára
Awọn ilumọọka Sẹnẹtọ bi Tayo Alasoadura, Yele Omogunwa ti wọn ṣoju ipinlẹ Ondo pẹlu Godswill Akpabio lati ipinlẹ Akwa Ibom lo fidi rẹmi ninu ibo ile igbimọ aṣofin agba to lọ.
Election Tribunal: INEC ní òfin kò ní kí èsì ìbò ààrẹ wà lórí ''server''
Oríṣun àwòrán, Twitter/INEC
Ọwọ́ ni INEC fi kọ èsì ìbò ààrẹ, kò sí lórí ''server''-Okoye
Ala ti ko lee ṣẹ ni ''server'' ti oludije ipo aarẹ fẹgbẹ oṣelu PDP, Atiku Abubakar n beere fun.
Atiku n beere esi idibo ibo aarẹ orilẹ-ede Naijiria to waye ninu oṣu keji, ọdun 2019.
Kọmiṣọna ajọ eleto idibo INEC, Festus Okoye lo ṣalaye ọrọ naa nigba to ba BBC sọrọ lọjọ Ẹti.
Ọgbẹni Okoye sọ pe esi ibo aarẹ ko si ninu ''server'' INEC tabi ẹrọ kọmputa nibi kankan.
O ṣalaye pe ofin eto idibo lorilẹ-ede Naijiria ko sọ pe ki ajọ INEC ko esi idibo aarẹ sinu ''server'' kọmputa INEC.
Barister lo bi gbogbo oníṣẹ́ fújì -Oṣupa
Okoye ni ọwọ ni wọn fi kọ esi ibo ni gbogbo ibudo idibo kaakiri orilẹ-ede Naijiria, eleyi ti gbogbo awọn aṣoju ẹgbẹ osẹlu to wa nibẹ foju ri ti wọn si ni ẹda rẹ.
Ladoja: Àwọn èèyàn Oyo fì ìbò sọ̀rọ̀ pé ìjọba Ajimobi kò dára
O sọ pe awọn esi ibo yii ni wọn fi ṣọwọ si ajọ INEC lawọn ipinlẹ to fi de olu ile iṣẹ INEC nilu Abuja.
Ẹwẹ, l'Ọjọbọ ni ajọ INEC ṣi aṣọ loju ọrọ yii nigba to sọ fun igbimọ igbẹjọ ibo aarẹ l'Abuja pe oun ko ni ''server'' ti Atiku ati PDP n beere fun.
Sogidi Lake: Kòṣẹja-kòṣèèyàn lá bá nínú adágún odò náà -Ojedele
Kano Gorilla: Òṣìṣẹ́ 10 wọ gàù lórí ọ̀rọ̀ Ìnàkí tí wọ́n ló gbé owó tí wọn pa lásìkò ìtúnu ààwẹ̀
Oríṣun àwòrán, JOHN MACDOUGALL
Ipinlẹ Kano Ìnàkí jí mílíọ̀nù méje náírà ní sgbà ẹranko
Ọjọ́rú ni ọ̀gá àgbà tó ń ṣe àkóso owó lọgba ẹranko ni Kano ké gbàjare pé, owó to ku díẹ̀ ko pé mílíọnù méje ti àwọn pa lásíkò ọdún itunu aawẹ, nígbà ti àwọ̀n ènìyàn wá wo ẹranko ló dédé pòòrá, nínú akoto ti àwọn ko owo si.
Bó tilẹ̀ jẹ́ wípé BBC Yorùbá kò lè fìdí ọotọ mulẹ pe inaki mi owo náà, àmọ̀ awọn akọròyìn Freedom radio ní ìpínlẹ̀ Kano royìn lọ́jọ́bọ pé, ọkan nínú àwọn oṣìṣẹ́ ní ẹ̀ka akoso owó ló sàlàyé pé, ìnàkí ńla kan lo wọ inú ọfíísì àwọn láti gbé owó náà.
Nígbà ti BBC ba ọgá àgbà lọgba eranko náà sọ̀rọ̀, ó kọ̀ láti fí ìdí ọ̀rọ̀ yii múlẹ̀ yálà pé ó ṣẹlẹ̀ tàbí kò ṣẹlẹ̀, ó ni ìwádìí ń lọ lọ́wọ́ lórí ọ̀rọ̀ náà, òun kò si ní ẹ̀tọ́ láti sọ̀rọ̀ le lóri.
 Ọ̀rọ̀ náà wa lábẹ́ ìwádìí, mí ò ṣetán láti sọ̀rọ̀ le lóri, ọ̀pọ̀ àwọn oníròyìn ló ti wá bá mi lórí ọ̀rọ̀ náà, ǹkan ti mo kàn le sọ ni pé owó sọnu èyí ní ọ̀rọ̀ Kashekobo.
Ọkan nínú osiṣẹ ọgbà náà tó ní ki BBC má dá orúkọ oun sàlàyé pe, ọlọ́pàá ti mú gbogbo àwọn to wà lẹ́nu iṣẹ́ lásikò ti owó náà pòòrá
Sogidi Lake: Kòṣẹja-kòṣèèyàn lá bá nínú adágún odò náà -Ojedele
Bákan náà ni ilé iṣẹ́ ọlọ́pàá fi ìdí ọ̀rọ̀ náà múlẹ̀.
Agbẹnusọ ọlọ́pàá ní ìpínlẹ̀ Kano, DSP Adbdullahi Haruna sàlàyé pé, ìwádìí ń lọ lọ́wọ́ lóri ọ̀rọ̀ náà.
Òòtọ́ ní pé owó sọnu ní ilé ti wọ́n ń ko eranko si ní Kano, èyí to jẹ owó ti wọn pa ní ọ̀jọ́ márùn ti wọ́n fi ṣe ayẹyẹ ọdún ìtúnu ààwẹ. Ó ni bí oun ṣe ń sọrọ̀ yìí, àwọn oṣìṣẹ́ mẹ́wàá lo ti wà ní agọ́ ọlọ́pàá.
"Lára àwọn ti ọlọ́pàá mú ni ọlọdẹ àti àwọn to n siṣẹ́ ní eka owó, sùgbọ́n ǹkan ti a fẹ wadi ni pe, kí ni ìdí ti wọ́n fi kó owó pamọ si ọfíísi fún odidi ọjọ márùn láì ko lọ si ilé ìfowopamọ. Èyi ni ọ̀rọ̀ agbẹ́nusọ ọlọ́pàá.
NURTW: Yasin ní àbẹ̀wò òun sí Makinde dá lórí ọ̀rọ̀ ẹgbẹ́ awakọ̀ èrò tó fòfin dè
Oríṣun àwòrán, Seyi Makinde
Ààrẹ àpapọ̀ fún ẹgbẹ́ àwọn awakọ̀ lorílẹ̀-èdè Nàìjíríà (NURTW), Alhaji Nojeem Yasin tí fí ọkàn àwọn awakọ ìpínlẹ̀ Ọyọ́ balẹ̀.
O ni pé gómìnà ìpínlẹ̀ Ọyọ onímọ-ẹ̀rọ Seyi Makinde yóò yí ìpínnu rẹ̀ padà lóri gbígbẹsẹlé ẹgbẹ́ náà.
Yasin sọ èyí di mímọ̀ lásìkò tó ń ba àwọn akọròyìn sọ́rọ̀ lẹ́yìn ìpàdé rẹ̀ pẹ̀lú gómìnà ní ilé ìjọba ni agodi Ibadan.
Ààrẹ àwọn awakọ̀ òhun tó kọ́wọ̀ọ́ rìn pẹ̀lú àwọn olóyè ẹgbẹ́, sàlàyé pé, gómìnà Makinde ti fí ọkàn àwọn balẹ̀ pé òun ti ṣetan láti kásẹ̀ òfin náà nilẹ̀, ti àwọn ọmọ ẹgbẹ́ awakọ̀ ìpínlẹ̀ Ọyọ bá ti ṣetan láti tọpasẹ̀ aláfíà.
Yasin ni  Èrèdí ìrìnàjo mi si ìpínlẹ̀ Ọyọ ni láti rí Gomina Makinde lóri ọ̀rọ̀ àwọn ẹgbẹ́ awakọ, sùgbọ́n gomìnà ni òun fofin de ẹgbẹ awakọ, nítori àláfíà àwọn ènìyàn ìpínlẹ̀ Ọyọ ni."
Sogidi Lake: Kòṣẹja-kòṣèèyàn lá bá nínú adágún odò náà -Ojedele
"O ni ètò ààbo mẹ́hẹ lasiko naa, ni òun ṣe dá ìgbàkegbodo wọn dúro."""
Ọlọ́paà Ọ̀ṣun: Ààbò wà fún ẹ̀mí àti dúkìá aráàlú
Oríṣun àwòrán, @PoliceNG
Ileeṣẹ ọlọpaa Ipinlẹ Osun ti mu awọn janduku mẹtala ti wọn n ṣọṣẹ ni awọn opopona to wa ni ipinlẹ naa.
Alukoro fun ileesẹ ọlọpaa nipinlẹ Ọsun, Folasade Odoro rọ awọn ara ilu ninu atẹjade kan wipe, ki wọn ye gbe ahesọ ti ko fẹsẹ mulẹ sori ayelujara nipa bi ọrọ aabo ipinlẹ naa ṣe ri.
Ṣugbọn ọrọ rẹ yii kọ ẹyin si awọn iroyin to n ti ipinlẹ naa jade wipe, lẹnu ọjọ mẹta yii, awọn awọn janduku oju popo ti pa awọn awakọ ati arinrinajo ni popona Ibadan si Ife, ati oju ona Iwaraja ni agbegbe Ilesa.
Iroyin naa ti lẹ ni wọn ji awọn eeyan miiran gbe.
Odoro sọ pe, Kọmiṣọna ọlọpaa ipinlẹ naa Abiodun Ige ti mu da awọn ara ilu loju wi pe, aabo wa fun ẹmi ati dukia wọn.
O ni awọn ọlọpaa mu awọn janduku naa, lẹyin ti wọn ya bo ibùba awọn janduku to wa ni awọn opopona to wa kaakiri ipinlẹ Osun.
Sogidi Lake: Kòṣẹja-kòṣèèyàn lá bá nínú adágún odò náà -Ojedele
Agbẹnusọ naa ni, ileesẹ ọlọpaa ipinlẹ naa yoo tubọ maa gbiyanju lati mu alaafia ati aabo duro ni ipinlẹ naa.
Apapa gridlock: Ìjọba àpapọ̀ ní òun kò ní gbà kí wọ́n ba ọrọ̀ ajé ilẹ̀ yìí jẹ́
Igbakeji Aarẹ Yemi Osinbajo ti sun gbedeke igba to fun awọn awakọ tirela ti wọn wa loju ọna Apapa ni ọsẹ meji si, lati palẹ gbogbo ọkọ wọn mọ.
Aṣẹ ileeṣẹ aarẹ lori ọrọ naa ni oṣu kẹrin, lo dun mọ ọmọ Naijiria ninu. Ọsẹ meji pere ni wọn fun awọn ọlọkọ epo naa nigba naa, lati ko aasa wọn.
Ṣugbọn bi ijọba ṣe sun gbedeke ọsẹ meji yii siwaju fun ọsẹ meji miiran, n kọ ọmọ Naijiria lominu wipe, o seeṣe ki aṣẹ naa ma fẹsẹ  mulẹ.
Atẹjade kan lati ileeṣẹ igbakeji aarẹ ni wọn buwọ lu, bi wọn ṣe sun gbedeke naa siwaju ninu ipade kan pẹlu awọn ti ọrọ kan ni ibẹrẹ ọsẹ yii.
Igbakeji aarẹ ni, wọn gbọdọ jabọ ni ọjọ Kẹrinlelogun oṣu kẹfa ọdun 2019 bayii.
Aarẹ ni ijọba ko ni jẹ ki awọn kan fi imọtara ẹni ba ọrọ aje Naijiria jẹ nitori wipe, Apapa jẹ agbegbe gboogi ninu ọrọ aje Naijiria nitori ebute to wa nibẹ
Àwọn èèyàn àti awakọ̀ ké igbe ìrora bí àwọn ọkọ̀ ńlá ṣe dí ọ̀nà mọ́rosẹ̀ Apapa-Oshodi pa
Kayode Opeifa to jẹ igbakeji igbimọ amuṣẹṣe lori ọrọ naa ni, ijọba ti n gbe igbesẹ lati kọ awọn ibudokọ fun awọn ọkọ ajagbe to ba fẹ ko ẹru ni Apapa.
ASUU- Tírílíọ̀nù 1.1 lowó àdéhùn tó wà láàrin wa àti Buhari, kìí ṣe bílíọ́nù N208
Oríṣun àwòrán, BASHIR AHMAD
ASUU ni ijọba kan fẹ fi ikede yi wa oju rere awọn arailu ni ati pe kii ṣe owo tawọn beere ni ijọba san.
Ẹgbẹ oṣiṣẹ fasiti ni Naijiria ti bẹnu atẹ lu biliọnu méjídínláàdọ́fà Naira owo iranwọ ti ijọba Naijiria buwọlu fawọn ile ẹkọ giga lorileede naa.
Aarẹ ẹgbẹ naa ọjọgbọn Biodun Ogunyemi ninu ifọrọwanilẹnuwo pẹlu BBC sọ pe arumọjẹ lasan ni owo yi jẹ ati pe kii ṣe owo tawọn beere ninu adehun pẹlu ijọba.
'Èmi kìí ṣe ọmọ ẹgbẹ́ ASUU'
ASUU Strike: Bí àwọn kan se dunnú, làwọn kan fajúro
Ogunyemi ni triliọnu kan naira le diẹ lawọn ati ijọba ṣadehun pe o yẹ ki wọn fi mu idagbasoke ba awọn fasiti Naijiria laarin ọdun 2013 si 2018.
Loju opo Twitter ọkan lara awọn oluranlowo Aarẹ Buhari,Bashir Ahmad ni ikede ibuwọlu owo yi ti jẹyọ ti ọpọ eeyan si n sọ pe yoo tan iṣoro iyanṣelodi ASUUni Naijiria.
Kete ti o fi ọrọ yi sita lawọn eeyan ti n kan sara si ijọba fun igbesẹ yi
Gẹgẹ bi alaye ti aarẹ ASUU Biodun Ogunyemi ṣe lalaye, o ni ọna orisirisi ni ijọba ma n gba na owo fun idagbasoke eto ẹkọ ni Naijiria.
O ni yatọ si owo igbadegba ti ijọba ma n fun awọn ile ẹkọ fasiti,ile ẹkọ gbogboniṣe ati ile ẹkọ awọn olukọni,ijọba ṣe adehun lẹyin iwadi lori ipenija to n dojukọ idagbasoke fasiti lati san owo to le ni triliọnu kan naira laarin dun mẹfa.
''Owo ti wọn san yi, TETFUND lo n ṣe akoso rẹ wọn yoo si pin fun fasiti awọn ile ẹkọ poly ati ile ẹkọ awọn olukọni.Nibo wa lo ti tan iṣoro idagbasoke ta fẹ ki wọn ṣe ni fasiti?''
Ogunyemi ni ninu adehun awọn pẹlu ijọba o yẹ ki wọn san ''200 biliọnu naira lọdun 2013,ninu 1.3 triliọnu tawọn ṣadehun ki wọn si san eleyi to ku ni ipele 220 bilọnu naira laarin ọdun 2014,2015,2016 2017 ati 2018.''
O tẹsiwaju pe lẹyin 200 biliọnu ti wọn san ni 2013 ati 20 biliọnu nipari 2018,ijọba ko ṣika adehun tawọn jijọ ṣe pọ.
O tẹnumọ pe ohun tawọn bere kọ ni ijọba ṣe ati pe ijọba yi jẹ 1.1 triliọnu to yẹ ki o san fun idagbasoke fasiti ni Naijiria.
Nibẹrẹ ọdun 2019 ijọba Naijiria san biliọnu mọ́kànlélọ́gọ́jọ naira fawọn ile ẹkọ giga lorileede naa gẹgẹ bi owo iranwọ fọdun 2018 eleyi ti TETFUND ṣe eto pinpin rẹ.
Ninu owo yi, awọn fasiti ijọba kọọkan gba N785,832,700,awọn ile ẹkọ gbogbo niṣe kọọkan gba N536,703,502 ti awọn ile ẹkọ olukọni si gba N510,084,900.
Suicide attack: Ìlú Konduga Pàdánù ọ̀gọ̀ọ̀rọ̀ ènìyàn
Oríṣun àwòrán, @HQNigerianArmy
Ipinlẹ Borno
Iroyin to n tẹ wa lọwọ lati ipinlẹ Borno ni wi pe ọgọrọ eniyan ti dero ọrun nirọlẹ ọjọ aiku.
Akọroyin kan sọ fun BBC pe eniyan mẹta to gbe ado oloro si ara wọn jẹ ki ado oloro naa ro gbamu lara wọn.
Éégún tó wà nídí Yoruba Bollywood, Samo Baba f'ojú hàn o!
Eyi waye ni iwaju ita gbọngan kan  ni ilu Konduga nibi ti awọn ololufẹ ere bọọlu ti maa n woran lori ẹrọ amohumaworan.
"Oṣiṣẹ ajọ to n ri si iṣẹlẹ pajawiri ni ipinlẹ naa, usman Kachalla wi fun ile iṣẹ iroyin AFP pe ""iye ẹmi to nu ti to ọgbọn ti o si le ni ogoji to fara pa."
Ladoja
AD,LP, fìdírẹmii lórí ẹ́jọ́ tí wọn fí takò iyansipo Sanwo Olu
Oríṣun àwòrán, @jidesanwoolu
Sanwo Olu bori igbẹjọ iyansipo rẹ
Sanwo Olu ti bori ẹjọ ti AD ati LP pè.
Igbimọ igbẹjọ lori idibo Gomina ipinlẹ Eko ti fagile ẹjọ ti ẹgbẹ oṣelu Alliance for Democracy, AD ati Labour Party, LP gbe wa siwaju rẹ.
Wọn mu ẹjọ yi wa ni itako iyansipo Gomina Babajide Sanwo Olu ti ẹgbẹ APC.
Gẹgẹ bi ohun ti a ri gbọ, alaga igbimọ to n gbẹjọ naa T.T Asua wọgile ẹjọ naa tori pe awọn olupẹjọ kuna lati fi iwe ranṣẹ saaju gbendeke ọjọ meje ti ofin la kalẹ.
Igbimọ ẹlẹni mẹta naa ni titete kọ iwe yi jẹ opa kutẹlẹ pataki ninu pipe ẹjọ ati pe bi eeyan ko ba file kọ iwe yi lasiko, ẹjọ naa ko le tẹsiwaju.
Ladoja
Loju opo Twitter agbẹnusọ fun Gomina Sanwo Olu ni wọn ti fi tayọtayọ kede aṣeyọri Sanwo Olu pẹlu igbesẹ igbimọ yi
Agbẹjọro fun ẹgbẹ AD ati LP, agbẹjọro Bola Aidi loun dupe lọwọ igbimọ naa fun idajọ ti wọn gbe kalẹ.
Awọn oludije labẹ asia ẹgbẹ AD, Oloye Owolabi Salis ati akẹgbẹ rẹ lati inu ẹgbẹ LP, Ọjọgbọn Ifagbemi Awamaridi ti saaju kọwe ẹjọ tako iyansipo Sanwoolu pe ko koju oṣunwọn lati dije ipo Gomina.
Bakan naa ni wọn sọ pe ibo Gomina ipinlẹ Eko to waye lọjọ kẹsan an, oṣu Kẹta ni aisedeede ati magomago kun inu rẹ.
O ni Sanwo Olu funra rẹ ko ni kaadi idibo eyi to jẹ ko kuna lati dibo tabi ki wọn dibo fun un.
Éégún tó wà nídí Yoruba Bollywood, Samo Baba f'ojú hàn o!
Ààrẹ Morsi orílè-èdè Egypt dákú,o gbà bẹ d'ero Alakeji
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Aarẹ tẹlẹ ri orileede Egypt Mohammed Morsi, ti awọn ologun yọ loye lọdun 2013  ti  fo sanlẹ ku ninu ile ẹjọ gẹgẹ bi oun ti ile iṣẹ amounmaworan ilẹ naa kede.
Iroyin naa ni ibi ti aarẹ naa ti n dahun ibeere lo ti kọkọ daku gbọnrangandan ki o to di pe o gba ibẹ lọ alakeji
Ẹni ọmọ ọdun mẹtalelọgọta nii ṣe
A o maa mu ẹkunrẹrẹ iroyin naa wa fun yin laipẹ.
Egypt President: Aàrẹ Morsi torílè-èdè Egypt dákú,ó gba ibẹ̀ derò alákeji
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Iku mu Aarẹ Egypt tẹlẹ lọ
Ta ni Mohammed Morsi to ku nile ẹjọ Egypt?
Odun 1951 ni wọn bi Mohammed Morsi ni abule El-Adwah ni ẹkun Nile Delta ti Sharqiya.
O ka ẹkọ nipa iṣẹ imọ ẹ̀rọ ni fasiti Cairo ko to lọ gba oye ọmọwe (Ph.D) ni fasiti kan ni Amẹrika.
Awọn ẹgbẹ Muslim Brotherhood ni wọn fa Morsi kalẹ gẹgẹ bii oludije fun ipo aarẹ ninu idibo ọdun 2012 ni Egypt.
Éégún tó wà nídí Yoruba Bollywood, Samo Baba f'ojú hàn o!
Diẹ ni odiwọn nọmba to fi bori alatako rẹ ninu idibo to gbe Morsi wọle.
Awọn eniyan Egypt ni ko mu awọn ileri rẹ ṣe lọdun kan to fi ṣe ijọba ki awọn ologun to gba ijọba lọwọ rẹ.
Opolopo iwode lo waye titi ti o fi fipo aarẹ naa silẹ fun awọn ologun.
Gẹgẹ bi ohun ti ile iṣẹ amohunmaworan orile-ede naa sọ aarẹ naa ti awọn ologun yẹ aga nidi rẹ ku nile ẹjọ loni.
Bawo ni Mohammed Morsi ṣe doloogbe?
Aarẹ tẹlẹ ri lorile-ede Egypt, Mohammed Morsi, ti awọn ologun yọ loye lọdun 2013 ti fo sanlẹ ku ninu ile ẹjọ.
Ile iṣẹ amohunmaworan orilẹ-ede Egypt ni o kọkọ daku nile ẹjọ ni ki ọlọjọ to de.
Iroyin naa ni ibi ti aarẹ naa ti n dahun ibeere lo ti kọkọ daku gbọnrangandan ki o to di pe o gba ibẹ re ọrun alakeji.
Ẹni ọdun mẹtadinlaadọrin nii ṣe.
Ẹsun ìgbéjọ lori gbigba ifitonileti nipa awọn kan labẹlẹ laigba ọna to tọ ni olori ẹsun ti wọn fi kan aarẹ ana naa.
Iwọde nla to ṣẹlẹ lọdun kan lẹyin to gori aleefa lo ṣokunfa bi wọn ṣe yọo nipo.
Oun ni aarẹ akọkọ ti wọn dibo yan lorilẹ-ede Egypt.
Oríṣun àwòrán, others
Ta ni Morsi?
Aarẹ Morsi Mohammed wa ni atimọle lati igba ti ẹjọ naa ti bẹrẹ .
Ile iṣẹ amohunmaworan Nile News ni wọn ti gbe oku oloogbe naa lọ sile iwosan fun iwadii to yẹ.
Huda Shaarawi: Kò dára kí obìnrin sè’yàwó lọ́mọ ọdún mẹ́tàlá
Ọjọ kẹta, oṣu keje, ọdun 2013 ni awọn ologun gba ijọba lọwọ Mohammed Morsi ni Egypt.
Awọn kan gba pe iwọde to ṣẹlẹ lasiko ijọba Morsi yi lo buru ju lẹyin ti Hosni Mubarak to ṣẹlẹ lọdun 2011.
Ondo State: Àwọn aláṣẹ Poly Rufus Giwa di ítì pa di ọjọ́ iwájú
Oríṣun àwòrán, Google
Poly Rufus Giwa
O ṣeese ki igbesẹ awọn alaṣẹ ile iwe giga gbogboniṣe Rufus Giwa to wa ni ilu Owo, ipinlẹ Ondo pa awọn akẹkọọ lara.
Iṣẹju diẹ sẹyin ni ikede naa jade pe lati oni ọjọ iṣẹgun ikejidinlogun oṣu ikẹfa pe ile iwe giga gbogboniṣe Rufus Giwa Polytechnic di titi pa.
'Èmi ni afunfèrè àkọ́kọ́ lágbo eré KWAM 1 ní 1983'
Eyi waye lẹyin atẹjade ti igbimọ alaṣẹ ile iwe naa fi sita pe awọn fi ikede ranṣẹ si gbogbo ọmọ ile iwe lati kuro ninu ile iwe ko to di agogo mẹta ọsan oni.
Oríṣun àwòrán, Rufus Giwa Polytechnic
Lẹta
Iwe naa ti Sule Atiku to jẹ adele Giwa ile iwe naa fọwọ si ṣalaye pe igbesẹ naa ṣe pataki lati yanju ọrọ to ni ṣe pẹlu riru ofin.
Ẹ̀wẹ̀, nigba ti BBC Yoruba kan si alaga ẹgbẹ awọn olukọni ile iwe giga naa ASUP, Ọgbẹni Ijawo Rafiu jẹ ko di mimọ pe oun woye pe tori iwọde alafia ti awọn gun le lo fa a.
Éégún tó wà nídí Yoruba Bollywood, Samo Baba f'ojú hàn o!
Ẹgbẹ ASUP ni  iwọde awọn wa lati fi ẹhonu han lori ainaani itọju oṣiṣẹ ti awọn alaṣẹ gbe wọ bi ẹwu. Ko da tori eyi wọn ni awọn atawn alaṣẹ jọ pa ẹnu pọ pe ki wọn sun idanwo awọn akẹkọọ to yẹ ko bẹrẹ ni ọjọ kẹtadinlogun oṣu ikẹfa siwaju.
Iwọde ẹgbẹ ASUP tun da lori owo oṣu ti wọn n jẹ wọ fun odidi oṣu mẹfa, ai ṣe igbega lẹnu iṣẹ lati ọdun 2017 wọn si tun din yọ ninu owo oṣu wọn.
Oríṣun àwòrán, Rufus Giwa Polytechnic
Lẹta
Bakan naa ni ẹgbẹ ASUP fi iwe sita to ṣalaye bi awọn ati awọn alaṣẹ ile iwe naa ṣe jọ tọwọ bọ'we adehun lori awọn koko ti wọn bere fun ati esi awọn alaṣẹ naa.
Iwe adehun yii yanana ọrọ igbega lẹnu iṣẹ, owo oṣu ati dida owo oṣu ti wọn yọ pada.
Igbiyanju lati kan si Giwa ile iwe naa ko tii yọri si rere bo tilẹ jẹ wi pe awọn aṣoju alaṣẹ naa buwọlu iwe adehun naa nibi ipade to waye laarin wọn ati ẹgbẹ ASUP.
Howards Graduates: Barrack Obama gba àwọn akẹ́kọ̀ọ́jáde nímọ̀ràn láti fi àwọ̀ wọn yangàn
Oríṣun àwòrán, @ObamaFoundation
Yoruba ni bi eegun ni ba jo re, ori a maa ya atọkun rẹ, bẹẹ si ni inu ẹni kii dun, ka pa mọra.
Bẹẹ lọrọ ri ni fasiti Howard to wa lorilẹede Amẹrika, nigba ti awọn ọmọ Naijiria fakọyọ julọ laarin awọn akẹkọjade to n kuro nile ẹkọ fasiti naa.
Ileẹkọ fasiti Howard lo ko akẹkọjade mẹrindinlọgọrun silẹ, ti mẹrindinlaadọta ninu wọn si jẹ ọmọ Naijiria.
Sugbọn iyalẹnu lo jẹ fun gbogbo awọn alejo to wa nibi ayẹyẹ ikẹkọjade ileẹkọ naa, ti wọn si la ẹnu silẹ, lai lee pa de, nigba ti akẹkọjade ti wọn jẹ ọmọ Naijiria, gba ami ẹyẹ mẹrindinlogun ninu ami ẹyẹ mẹtadinlọgbọn ti fasiti naa ko silẹ fawọn akẹkọ ti ọpọlọ wọn jipepe julọ.
Iroyin naa ni iru isẹlẹ bayii ko tii waye ri ni ile ẹkọ fasiti Howard tabi ni ile ẹkọ fasiti kankan ni orilẹede Amẹrika, awọn ọmọ Nigeria yii si ni oju gbogbo n wo nibi ayẹyẹ naa pẹlu itan ara ọtọ ti wọn fi lelẹ yii.
Oríṣun àwòrán, @BarackObama
Nigba to n sọrọ nibi ayẹyẹ ikẹkọjade naa gẹgẹ bii alejo pataki, aarẹ tẹlẹ ni orilẹede Amẹrika, Barrack Obama, ti oun naa jẹ adulawọ, lo sọrọ nipa ẹlẹyamẹya, to si rọ awọn akẹkọjade ileẹkọ naa lati maa fi awọ wọn yangan, ki wọn si nifẹ bi Ọlọrun se da wọn.
'Èmi ni afunfèrè àkọ́kọ́ lágbo eré KWAM 1 ní 1983'
Obama ni, pẹlu iriri oun lasiko ti oun wa nipo aarẹ, oun gba pe lootọ ni iwa ẹlẹyamẹya wa, to si wọpọ ni orilẹede naa, amọ o ni ilẹ naa si lee ni agbega siwaju si, tawọn oniruuru ẹya ba gbagbọ ninu ẹya wọn, ti wọn ko si gba kamu.
Ìtàn Mánigbàgbé: Oyenusi ní òun kò bá tí digunjalè, táwọn òbí òun bá lágbára láti rán òun níléèwé
Oríṣun àwòrán, AFP
Yoruba ni ẹni ba jale lo ba ọmọ jẹ, ati pe, bi ole ba da aran bori, asọ ole lo da bora, bi ẹni to ba si jale ba ni ọla laye, ko lee ri ọrun wọ bi ọlọjọ ba de.
Ti eeyan ba gbọ itan igbe aye Isọla Oyenusi, yoo gba lootọ pe bi eeyan ba ni aya, ko sika, amọ to ba ri iku Gaa, yoo sọ ootọ nitori bo se gbajumọ bii isana ẹlẹẹta to lasiko aye rẹ fun iwa idigunjale, sibẹ iku ẹsin ati itiju lo ku.
Gẹgẹ ba se ka lori opo Wikipedia lori itakun agbaye, o ni idi ti Oyenusi se gbe igba idigunjale bii isẹ, lẹyin ti ogun abẹle si pari tan lorilẹede Naijiria lo bẹrẹ si fooro awọn ọmọ Yoruba.
Sugbọn bi Oyenusi se daamu awọn olugbe ipinlẹ Eko to yii, ina papa dilẹ lẹyin asunsunjẹ rẹ naa ni. Bi itan igbe aye rẹ si se lọ ree:
Dokita Iṣọla Oyenusi waye amọ ko se aye re. Ori awọn obi rẹ si lo di ẹbi igbe aye buburu to gbe naa le, eyi to yẹ ko jẹ ẹkọ fun awa obi pe, o yẹ ka kọ ọmọ wa, ko lee fun wa ni isinmi.
Obi ti ko ba lagbara lati kọ ọmọ rẹ ni ẹkọ iwe, yẹ ko fi si ẹnu ẹkọsẹ abi okoowo nitori ọwọ to ba dilẹ ni esu n bẹ lọwẹ.
Oríṣun àwòrán, AFP
Bakan naa si lawọn ọdọlangba gbọdọ kọgbọn pe, ifẹ abo tabi akọ ko gbọdọ ti awọn ni itikuti lati siwa hu nitori to ba buru tan, iwọ nikan ni yoo ku.
Iná Ibadan: Àwọn olùgbé inú ilé ń rawọ́ ẹ̀bẹ̀ fún ìrànwọ́
Ijamba nla ṣẹ ni adugbo oke Ado nilu Ibadan lowurọ ọjọ isẹgun nigba ti ile alaja kan gbina.
Iroyin kan ti ko fidi mulẹ, to n ja rainrain lori ayelujara salaye pe, ọmọde kan to n se ounjẹ lasiko ti iya rẹ n wo ere lori mohunmaworan lọwọ, lo se okunfa ijamba ina naa.
Awọn olugbe ile naa ṣe alaye fun ikọ BBC Yoruba wi pe, ina ọba to de lojiji si adugbo naa, lo ṣokunfa iṣẹlẹ agbọgbarimu ọhun.
Lasiko ti ikọ iroyin BBC Yoruba se abẹwo si ile to jona naa, a ri pe rẹrẹ run nibẹ, ti ọpọ dukia si sofo, bi o tilẹ jẹ pe ko si ẹmi kankan to sofo lasiko isẹlẹ naa.
Lasiko ti wọn n ba BBC Yoruba sọrọ, awọn olugbe inu ile naa rawọ ẹbẹ si awọn ẹlẹyinju aanu ọmọ ilẹ yii lati se iranwọ fun wọn, lori awọn dukia wọn to jona mọle.Wọn salaye pe, awọn gbiyanju lati sare ko awọn ohun elo to n bẹ ninu ile naa jade lasiko eefin bẹrẹ sini ru, ṣugbọn pupọ ninu awọn ohun elo naa ni ina ọmọ ọrara ti sọ di eeru, ki awọn aladugbo to gbe omi ati awọn ohun elo mii ti wọn fẹ fi pa ina to de.
Pupọ ninu awọn olugbe ile naa lo padanu owo, awọn ohun elo to n lo ina ijọba, ati ọpọlọpọ dukia sinu iṣẹlẹ naa.
Oyo Algon: Agbẹjọ́rò ìjọba Ọyọ ní Makinde kò tí ì rí ìwé ìpẹ̀jọ́
Oríṣun àwòrán, Seyi@official
Local Government Dissolusion: Ọgbọ̀n ọjọ́ oṣù keje ní igbéjọ yóò wáye ló ìjọba ibílẹ̀ Ọyọ.
Ilé ẹjọ tó ga jùlọ ní Ibadan ní ohun yóò bẹ̀rẹ̀ ìgbẹ́jọ lóri ẹjọ tí àwọn ẹgbẹ́ alága ìjọba ìbílẹ̀ nipinlẹ Ọyọ, (ALGON) gbé wá lóri àṣẹ tí gómìnà Seyi Makinde pa pé ki gbogbo alága ìjọba ìbílẹ̀ ọ̀yọ́ mẹ́tàlélọ́gbọ̀n ló maa simi nilé.
Ẹgbẹ́ ALGON, tí Ọgbẹ́ni Kunle Sobaloju jẹ́ agbẹjọ́rò wọn, dárukọ agbẹnusọ ilé ìgbìmọ̀ asofin , kọmisọna fọrọ ijọba ibilẹ̀, kọmisọna fun ètò ìdájọ àtí agbẹjọrò àgbà ìpínlẹ̀ Oyo nínú ìwé ẹsùn náà.
Sobaloju ni, sááju ni ilé ẹjọ ti pàṣẹ fun Makinde lati máṣe tú àwọn alága ijọba ìbílẹ̀ náà ka, sùgban gómìnà kọti ọgbọnin si aṣẹ náà, ní kéte ti wọ́n bura fún-un wọle tan.
Sobaloju sàlàyé fún ile ẹjọ́ pe, iwé ìpẹ̀jọ láti da gomina duro lóri aṣẹ̀ náà ní wọ́n gbé wá silé ẹjọ ni ọjọ kẹwàá oṣù kẹfa.
'Èmi ni afunfèrè àkọ́kọ́ lágbo eré KWAM 1 ní 1983'
O sàlàyé pe, gómìnà ń gbé ìgbéṣẹ̀ láti yan àwọn ọmọ ìgbìmọ̀ alámojuto fún àwọn ìjọba ibilẹ.
Ẹ̀wẹ̀, agbẹjọrò fún ìjọba ìpínlẹ̀ Oyo, Ọgbẹ́ni Oluwaseun Dada sọ fún ilé ẹjọ́ pe, iwé ìpẹ̀jọ pe ki Makinde ma tú ilé ka kò ti dé ọdọ àwọ̀n, nítori náà ko tíi yẹ fún ìgbẹ́jọ.
Erin fara gbọgbẹ̀, ó ṣekú pa ènìyàn méjì ni Liberia
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Erin
Erin kan to fara gbọgbẹ ti doju ija kọ awọn eeyan agbegbe ila oorun ariwa Liberia ti o si ṣeku pa eeyan meji.
Lara awọn to fara kasa ibinu erin naa ni baba ẹni ọdun mejidinlọgọta kan ati ọmọ rẹ ọkunrin.
Gẹgẹ bi iroyin to tẹ wa lọwọ, awọn to n pa ẹran lọna aitọ lo yinbọn lu erin naa ninu igbo Gbarpolu.
Nibi ti o ti n sa asala fun ẹmi rẹ lo ti pade baba naa ti o si ṣeku pa.
Éégún tó wà nídí Yoruba Bollywood, Samo Baba f'ojú hàn o!
Ọmọ baba ọhun ti o n tọ baba rẹ lọ naa pade agbako iku lọdọ erin naa.
Iṣẹlẹ pipa awọn erin lọna aitọ kii ṣe tuntun lawọn orileede kan ni Afrika.
Lọpọ igba awọn to n pa awọn ẹranko wọnyii a ma ta ẹya ara wọn lowo iyebiye.
Ladoja
Kí ló mú Sanusi kọrin bù Gómìnà ìpínlẹ̀ Kano, Abdullahi Ganduje?
Oríṣun àwòrán, @Dawisu
Lọdun to kọja ni fọnran fidio kan jade to ṣe afihan Gomina Ganduje nibi ti o ti ko owo dọla sapo
Wọn fi ẹsun kan Sanusi pe o kọrin bu Gomina lootọ, amọ kii ṣe Emir Sanusi Lamido Sanusi  la n sọ.
Olorin kan nipinlẹ Kano ti orukọ rẹ n jẹ Sanusi Abdullahi, lo ri ibinu ọlọpaa lori ẹsun pe o kọrin bu Gomina Abdullahi Ganduje.
Lati ọjọ abamẹta ni ileesẹ ọlọọpa ni Sanusi ti wa ni ahamọ lọdọ awọn.
Fọnran fidio orin naa ti n ja rainrain loju opo Whatsapp. Ninu rẹ, a ko ri oju ẹni to kọrin naa nitori pe iha ati ẹyin lo kọ si oju kamẹra.
Eyi si ti mu ki awọn eeyan maa beere pe, bawo ni ọlọpaa ṣe mọ pe Sanusi lo kọrin bu Gomina, nigba ti wọn ko ri oju rẹ.
Amọ ṣa, agbẹnusọ ọlọpaa nilu Kano, DSP Abdullahi Haruna sọ fun BBC pe, awọn ti wọ Sanusi lọ si iwaju adajọ nibi ti yoo ti wi tẹnu rẹ.
''Mi o le sọ bo kọrin bi ko kọrin, amọ a ti gbe lọ si ile ẹjọ lati wi tẹnu rẹ''
Lẹnu lọọlọ yi ni Gomina Ganduje ati Emir Sanusi pari ija wọn
Lati igba ti wọn ti mu Abdullahi, awọn mọlẹbi rẹ ti n ja fitafita lati ri pe wọn tu silẹ.
Ọrọ gbọna mi yọ lọjọ Iṣẹgun, nigba ti iroyin lu sita pe awọn ọlọpa ti mu olorin to kọ orin naa gangan, nibi ti o ti n di ẹru lati sa nilu.
Awọn mọlẹbi Abdullahi lero pe eleyi yoo mu ki wọn tu silẹ.
Ẹgbọn rẹ, Jamilu Abdullahi to ba BBC sọrọ ni, awọn yoo wa owo itanran lọdọ ọlọpaa lẹyin ti wọn ba tu silẹ.
Jamilu salaye pe, ''wọn mu Sanusi ni iṣoju iyawo rẹ lọjọ abamẹta. Iṣẹlẹ yii fọwọ bani lẹmi tori pe, oun kọ lo kọ orin to n ja rainrain yii''
Iṣẹju mẹsan gbako ni ẹkunrẹrẹ orin naa, to si ni awọn ọrọ eleyi to bẹnu atẹ lu Gomina Ganduje.
Ìjọba Ọṣun: Ẹ sowọ́pọ̀ pẹ̀lú wa láti gbé Ọṣun Oṣogbo dé ibi gíga ní 2019
Oríṣun àwòrán, @osunosogbo2019
Ijọba ipinlẹ Ọsun ti fọwọ idaniloju sọya pe, didun ni ọsan yoo so lasiko ọdun Ọsun Osogbo ti yoo waye lọdun 2019 ta wa yii, ti ohun gbogbo yoo si lọ ni irọwọrọsẹ, eyi ti yoo jẹ iwuri fun gbogbo ọmọ orilẹede Naijiria.
Alakoso feto abẹle, asa ati irinajo afẹ nipinlẹ Ọsun, Ọmọwe Ọbawale Adebisi lo fọwọ idaniloju yii sọya lorukọ ijọba ipinlẹ naa, lasiko to lọ se abẹwo si ileesẹ kan to n soju fun ileesẹ eto irinajo afẹ ni Naijiria ati ibudo ise nkan isẹmbaye lọjọ si, eyi ti Ọgbẹni Toye Arulogun n dari rẹ.
Ọmọwe Adebisi ni ohun amuyangan ni Ọsun Osogbo jẹ, o si yẹ ka wa ọna lati jẹ ki ọwọ okiki ati anfaani okoowo to n mu wa maa tẹsiwaju fun ipinlẹ Ọsun ni, gẹgẹ bii ipinlẹ to n dokoowo ninu asa ibilẹ wa.
"Adebisi ni "" A maa tẹsiwaju lati wa ajọsepọ pẹlu ẹlẹgbẹjẹgbẹ, ẹnikẹni tabi ileesẹ kileesẹ to ba setan lati mu agbega ba eto irinajo afẹ ni ipinlẹ Ọsun, a si n fi oju sọna fun ajọsepọ to loorin pẹlu ẹka aladani."""
Ninu ọrọ rẹ, Ọgbẹni  Toye Arulogun jẹjẹ atilẹyin ileesẹ naa lati ri daju pe asa ọdun Ọsun Osogbo ko yinjẹ, ti awọn yoo si tun fi akọtun ọgbọn si ọna ti wọn n gba se ọdun naa.
Oríṣun àwòrán, @osunosogbo2019
O ni eyi yoo tubọ fa oju awọn eeyan mọra si jakejado agbaye, eyi ti yoo mu ki ọdun asa ibilẹ, irin ajo afẹ ati ogun abalaye wa naa se aseye, ti alakan n se epo lọdun 2019.
'Èmi ni afunfèrè àkọ́kọ́ lágbo eré KWAM 1 ní 1983'
"Arulogun fikun pe ""a fẹ ki ọdun Ọsun Osogbo si tẹsiwaju lati maa jẹ ọdun fun eto  irinajo afẹ lagbaye pẹlu ifọwọsowọpọ ijọba ipinlẹ Ọsun. Atilẹyin ijọba ipinlẹ Ọsun si se pataki fun aseyọri ọdun Ọsun Osogbo lọdun 2019 yii, baa se n dijọ se agbelarugẹ, itaniji, idaabobo ati ifẹsẹmulẹ ọdun Ọsun Osogbo to se ara ọtọ naa."""
Kidnapping: Kò sẹ́ni tó mọ̀ bóyá àwọn ajínigbé gba owó ìtúsílẹ̀
Oríṣun àwòrán, @IsaacFAdewole
Iroyin to n tẹ wa lọwọ ni ọmọ minisita tẹlẹri fun eto ilera, Dayọ Adewọle ti gba itusilẹ lọwọ awọn ajinigbe.
Iwe iroyin Punch lo gbe e jade wi pe, ọkunrin naa gba itusilẹ lai pe wakati mẹrinlelogun ti wọn jigbe lọ.
Amọ, iroyin naa fikun wi pe, awọn ko mọ boya wọn san owo itusilẹ.
Owurọ Ọjọru ni iroyin gbe e jade pé lójúnà oko ni wọ́n ti jí Deji Adewole gbe ní ìlú Fiditi, ipinlẹ Oyo.
Ile isẹ ọlọpaa ni ipinlẹ Ọyọ ti mu afurasi mẹta to jẹ osisẹ ni oko ti wọn ti ji Dayo Adewole, to jẹ ọmọ minisita fun eto ilera tẹlẹri Isaac Adewole naa gbe.
Alukoro ile isẹ ọlọpaa ni ipinlẹ Ọyọ, Olugbenga Fadeyi lo fi ọrọ yii lede, lasiko to n ba BBC Yoruba sọrọ lori ibi ti wọn ba isẹ de lori iwadii itọpinpin lori ijinigbe ọmọ minisita naa.
Fadeyi ni kete ti isẹlẹ naa waye, ni wọn ti bẹrẹ iwadii, ti wọn si ti ri ọkọ mejeeji ti wọn fi ji ọmọ minisita naa gbe ninu igbo, ti wọn si ti gba a pada.
O fikun wi pe, awọn ajinigbe naa ko i ti i kan si ẹbi ati ara ẹni ti wọn jigbe. Bakan naa ni wọn ko i tii beere owo itusilẹ ni ọwọ awọn ẹbi.
Alukoro ile isẹ ọlọpaa naa wa rọ awọn ara ilu, lati ran awọn lọwọ lati fi iroyin lede ti wọn ba gbọ nkankan, nitori awọn ọlọpaa gbagbọ wi pe awọn ajinigbe yii n gbe laaarin awọn eniyan ninu ilu.
Ọmọ ọkunrin minisita tẹlẹ ri fun eto ilera Isaac Adewole, iyẹn Dayo Adewole ti bọ sọwọ̀ awọn ajinigbe.
Iroyin to tẹ wa lọwọ sọ pe lojuna oko ni wọn ti ji i gbe nilu Iroko nitosi Fiditi, ipinlẹ Ọyọ.
Iná Ibadan: Gbogbo dúkìá tó wà lókè ilé alájà kan náà ló jóná tán
Iṣẹlẹ ijinigbe laipẹ yii lorilẹede Naijiria paapaa iha Guusu Iwọ-Oorun ti di ohun to n kọ ọpọlọpọ lomiinu ti ko si yọ olowo tabi talaka silẹ.
Dayo Adewole to jẹ ọmọ minisita tẹlẹ ri fun eto ilera ni àwọ̀n àwọn ajinigbe tun gbe lọtẹ yii.
Iroyin sọ pe ṣe lawọn agbebọn da a lọna oko ti wọn si ji i gbe lọ ibi aimọ. Eyi tilẹ ti mu ki minisita ana, Ọjọgbọn Isaac Adewole ge irinajo rẹ lo soke okun kuru lojiji.
Lọwọ lọwọ, awọn ọlọpaa, oṣiṣẹ alaabo atawọn ọlọdẹ ibilẹ ti kan lu agbami iṣẹ wiwa Dayo.
Awọn ajinigbe kọ, wọn ko tii kan si idile ọmọ naa lori ohun to ṣokunfa eyi ati ipo ti ọmọ naa wa bayii.
Wo bí o ṣe lè kọ ẹ̀nu ìfẹ́ sí obìnrin pẹ̀lú ohun èlò orin yìí
Awọn oṣiṣẹ baba rẹ to n kọwọ rin pẹlu rẹ ti ori yọ lo figbe ta si awọn araalu ti Oniroko ti ilu Iroko si tete ko awọn ọlọdẹ jọ.
Ṣugbọn di bi a ṣe n sọrọ yii, wọn ko tii mọ ipo tabi ibi ti Dayo Adewole to fi mọ awọn to ji i gbe wa.
Babajide Sanwo-Olu 'pa'lù ẹnu dá',o lóun kò ṣèlérí nípa súnkẹrẹ-fàkẹrẹ Apapa láàrín ọgọta ọjọ
Oríṣun àwòrán, @jimidisu
Ti a ba ni ka ka gbedeke ti ileri ọgbọn ọjọ ti wọn ni Gomina ṣe yi,yoo pe ni ọjọ kọkandinlọgbọn oṣu Keje ọdun 2019.
Yoruba ni ẹni to ba fẹ parọ laa ni ẹlẹri oun wa lọrun.
Lori awuyewuye oun ti Gomina ipinlẹ Eko, Babajide Sanwoolu sọ nipa didẹkun sunkẹrẹ fakẹrẹ Apapa, ile iṣẹ BBC ṣewadi, a si ri ẹri pe o sọ bẹẹ.
Ninu awọn fọnran fidio kan ti a fidi rẹ mulẹ pe oun lo wa ninu rẹ ni ẹri yii ti waye.
Lọjọ iṣẹgun ni Gomina Sanwoolu pa ilu ẹnu da pe oun ko fi igba kankan ṣeleri lati mu opin ba sunkẹrẹ fakẹrẹ oju ọna Apapa laarin ọgọta ọjọ.
Gomina lede ọrọ yii nigba ti o n dahun ibeere lọdọ awọn akọroyin ni ile ijọba Aso Rock nilu Abuja lọjọ Iṣẹgun.
''Ohun ti mo sọ ni pe mo maa ṣe agbeyẹwo ohun to n ṣẹlẹ l'Apapa laarin ọgọta ọjọ, mi o ni mo maa mu opin ba sunkẹrẹ fakẹrẹ to n waye nibẹ
Akọkọ fọnran fidio ibi ti o ti seleri yi tọwọ wa tẹ ni  ibi to ti n ṣe ifọrọwero niwaju awọn eeyan nibi ayẹyẹ  wa wi tẹnu rẹ ti ile iṣẹ karakata ipinlẹ Eko ṣagbatẹru rẹ.
Lai si ani ani o darukọ ọgọta ọjọ gẹgẹ bi gbedeke ti oun da lati mu opin ba sunkẹrẹ fakẹrẹ Apapa
Ẹ wo fidio naa nibi
Ẹlẹkeji fidio ti a ri gẹgẹ bi ẹri pe o sọrọ yi naa ko fẹ yatọ si akọkọ nipa oun to ṣeleri lati ṣe .
Dipo ọgọta ọjọ, o ni oun yoo dẹkun ipenija yi laarin ọgọrun ọdun ti oun ba de ori alefa.
O ku ọsẹ meji ti wọn yoo dibo Gomina ni o sọ ọrọ yi ni oṣu Kini ọdun 2019
Opopona Apapa jẹ ọkan ti o ṣe pataki fun lilọ bibọ ọkọ ati awọn ero nilu Eko.
Nitori bi lilọ bibọ ti ṣe pọ nibẹ, ọpọ eeyan lo ma n ha si inu sunkẹrẹ  fakẹrẹ ati pe awọn ọkọ nla a ma saba bajẹ si ọna naa ti o si jẹ idiwọ nla.
Pupọ ninu awọn to ti jẹ Gomina ni wọn ti gbiyanju lati yanju wahala to wa loju ọna yi ti wọn ko ri yanju.
Awọn ara ilu Eko si ti n ke gbajarẹ ki ijọba wa wọrọkọ fi ṣada lori ọju ọna yi.
Iroyin to mu arinyanjiyan yii waye ni eleyi ti a gbọ pe Sanwoolu ṣe ileri naa lasiko apejẹ kan lọjọ kejidinlogun oṣu karun nigba ti wọn ṣẹṣẹ dibo yan an gẹgẹ bii Gomina.
Nibi apejẹ naa ti o ṣe pẹlu awọn akẹgbẹ rẹ ti wọn jijọ kawe gboye ni ile iwe fasiti ilu Eko laarin ọdun 1998/2000,iroyin kan pe Sanwoolu ṣeleri pe oun yoo mu opin ba sunkẹrẹ fakẹrẹ Apapa laarin ọgọta ọjọ.
O sọ gẹgẹ bi iroyin naa ti ṣe sọ, o ni lailai fi ti oṣelu ṣe, oun yoo palẹmọ awọn ọkọ agbepo nla to n ṣokunfa idiwọ lilọ bibọ lagbegbe naa.
Amọ ṣa gbogbo ọrọ yipada nigba ti Sanwoolu lọ si Abuja lati kopa ninu ipade awọn Gomina APC pẹlu Aarẹ Buhari.
Nibẹ lo ti wa sọ pe ọna abayọ lati di sunkẹrẹ fakẹrẹ Apapa ku ni ki wọn mu adinku ba igbokegbodo to n waye ni Apapa.
Ẹwẹ , ijọba apapọ Naijiria ti sun gbedeke ti igbimọ to n mojuto pipalẹmọ oju ọna Apapa mọ gbe kalẹ siwaju si .
Iná Ibadan: Gbogbo dúkìá tó wà lókè ilé alájà kan náà ló jóná tán
Oṣe meji ni ijọba apapọ buwọlu lẹyin ti igbimọ naa tọrọ aye si lọdọ ijọba..
Igbakeji aarẹ Yemi Osinbajo lo fọwọ si isunsiwaju yi lẹyin ipade kan to waye laarin oṣẹ gẹgẹ biatjade kan ti o tẹ ile iṣẹ  BBC Pidgin lọwọ.
Igbimọ naa to bẹrẹ iṣẹ wọn ni ọjọ kẹrinlelogun oṣu kaarun yoo wa fi esi iwadi wọn ṣọwọ si ijọba lọjọ kerinlelogunoṣu Kẹfa bayii.
Gani Adams: OPC ti ṣe tán láti kojú ìpèníjà ààbò ilẹ̀ Yorùbá
Oríṣun àwòrán, Gani Adams/facebook
Aarẹ Ọna Kakanfo ilẹ Yoruba, to tun jẹ olori ẹgbẹ ajijagbara Oodua Peoples Congress, OPC sọ pe ẹgbẹ naa ti ṣe tan lati ṣiṣẹ pẹlu ileeṣẹ ọlọpaa lati gbogun ti ijinigbe ati awọn ipenija mii to n koju eto aabo nilẹ Yoruba.
Aarẹ Adams sọ ọrọ yii ninu ifọrọwanilẹnuwo to ṣe pẹlu BBC Yoruba ni ifesi si ipade to laarin rẹ ati aṣoju ọga agba ileeṣẹ ọlọpaa orilẹede Naijiria nilu Eko lọjọ Iṣẹgun.
O ni ijomitoro lori ọ̀rọ̀ eto aabo ilẹ Yoruba ni ipade naa da le lori ṣugbọn ko fi bẹẹ kii ṣe ohun teeyan kan le maa sọ lori ẹrọ ibara ẹni sọrọ.
Ṣaaju ninu ifọrọrọwanilẹnuwo kan pẹlu BBC Yoruba lori eto aabo, Gani Adams sọ fun wa pe ẹgbẹ OPC ko le da si ọrọ aabo Naijiria ti ijọba ko ba pe e si.
Iba Gani Adams: Bẹ́ẹ gbé màláíkà kan lọ sí Aso Rock, kò lè ṣàṣeyọrí
Ṣugbọn nibayii ti ọga ileeṣẹ ọlọpaa ti kan si olori ẹgbẹ naa, kini yoo jẹ ṣiṣe?
"Lori eyi, Adams sọ fun  wa pe ""Ọlọpaa to ba mọ pe oun fẹ ṣe aṣeyọri kun aseyọri gbọdọ ba ẹgbẹ OPC ṣe papọ."
Ọga ọlọpaa patapata ran ẹni naa lati ṣe ipade pẹlu OPC pe oun nilo iranlọwọ ẹgbẹ naa.
Ajọ fẹnuko nibi ipade naa pe ao jọ ṣiṣẹ pọ, ṣugbọn gbogbo nkan lo ni eto. Gẹgẹ bi a ti ṣe pẹlu ileeṣẹ ọlọpaa ipinlẹ Eko lori ọrọ Badoo to n paayan.
"Ati ṣe tan lati ran wọn lọwọ, ọwọ wọn lo ku si."" O ni tori ọrọ ijọba kii ya nigba miiran bi o tilẹ jẹ pe awọn jọ ṣepade."
Ṣaaju ni ẹgbẹ kan t'oun naa n jijagbara nilẹ Yoruba, Ẹgbẹ Agbẹkọya sọ fun BBC pe 'oogun abẹnugọngọ ni na abayọ si ọrọ awọn ajinigbe.' Ati pe awọn ti ṣe tan lati koju wọn ti ijọba ba le fun wọn ni aaye lati ṣe bẹẹ.
Agbekoya: Bí a bá na oògùn abẹnugọ̀ngọ̀ s'ókè, ìjínigbé á d'ópin!
Ọmọ Mínísítà àná, Adewole bọ́ s'ọ́wọ́ ajínigbé
Lori boya o ṣeeṣe ki ẹgbẹ OPC ati ẹgbẹ ajijagbara Agbẹkọya jọ ṣiṣẹ pọ lori eto aabo, Aarẹ Adams sọ pe ẹgbẹ agbẹkọya naa ni iwulo fun ilẹ Yoruba lori eto aabo.
"Ọrọ to wa nilẹ yii kii ṣe ti OPC nikan, a fẹ ri i daju pe gbogbo awọn ẹgbẹ to ni nkan ṣe pẹlu eto aabo lati jẹ ki wọn o wulo. Pẹlu ifọwọsowọpọ awọn ọba ati alaga ijọba ibilẹ awọn gomina.
Gani Adams ni ipade apero kan n bọ laipẹ 'Yoruba Summit', ti gbogbo ẹgbẹ to ni nkan ṣe pẹlu aato aabo yoo ti jiroro lori eto aabo.
Pẹlu ipade ti a ṣe pẹlu awọn ọlọpaa yii, ao kọkọ maa dọgbọn ba wọn ṣiṣẹ papọ ki ọrọ awọn ajinigbe yii to wọ wa lara tan, nitori pe ọrọ ijọba kii ya bọrọ."
Osinbajo: Ọmọ Nàìjíríà, nǹkan kò ní pé ṣẹnure fún mẹ̀kúnù
Oríṣun àwòrán, yemi osinbajo
Ìgbákejì ààrẹ Yemi Osinbajo rọ ọmọ Nàìjíríà pé ǹkan ò ni pé ṣẹnure fún mẹ̀kúnù
Ààrẹ orílẹ̀-èdè Nàìjíríà ọ̀jọ̀gbọ́n Yemi Osinbajo ní òsí àti ìṣẹ́ tó ba orilẹ̀-èdè Nàìjíríà jà kìí jẹ ki òun ri òòrun sùn lóru.
"Osinbajo sọ èyí di mímọ̀ níbi àpérò kan ní ìpínlẹ̀ Eko, O ní "" mó ro pé ǹkan tí kìí jẹ́ ki n sùn lórun ni bí òsì àti ìṣk ṣe gbilẹ̀ tó ni orílẹ̀-èdè yiìí àti pé ọ̀pọ̀ àwọn yo dìbò fún wa ní àwọ otoṣì pátápátá yìí."""
Iná Ibadan: Gbogbo dúkìá tó wà lókè ilé alájà kan náà ló jóná tán
Ìléri ti ìjọba ṣe fún wọ́n ni pe ayé wọn yóò ni ojúùtú, sùgbọ́n ìréti wọn ni pe kò ni pẹ́ rárá
Inú mi kìí ba dùn ti mo ba rí orílẹ̀-èdè Nàìjíríà gẹ́gẹ́ bi èyí tii yóò ma ṣe ìdásilẹ̀ oníruuru ilé iṣẹ́ ni ọdun mẹ́wàá sasiko yii, tí ọ̀pọ̀ eeyan yóò si kúrò ninu iṣẹ́ to n bá wọ́n fíra.
Osinbajò ní, ọ̀pọ̀ àwọn ìlàna àmúlò ìjọba ní ó dúrò lóri fifi àwọn òtòsì sọ́kàn, pẹ̀lú àfọkan si lóri ètò ọ̀gbìn àti láti máà gbe owoya fún àwọn àgbẹ, ki wọn lee ni aníto àti ànisẹkun.
Ayinla Ọmọwura kò kàwé, àmọ́ ó kópa sí àgbéga orin àti èdè Yorùbá
Oríṣun àwòrán, Ayinla Omowura
Ni ilẹ Yoruba, awọn ẹja nla ti lọ lomi, awọn ajanaku ti sun bi oke, awọn erin ti wo niju, ti wọn ko si lee dide.
Ta ba si ni ka maa ka awọn erin nla to ti wo naa ni eni, eji, ẹta, ilẹ ti wẹ, nitori ọpọ ojo lo ti rọ, ti ilẹ si ti fi mu, ni oniruuru ẹka igbe aye ọmọniyan paapa ni ẹka awọn amuludun.
Ọkan lara awọn manigbagbe amuludun nilẹ Yoruba, ti onirese wọn ko fin igba mọ, amọ to jẹ pe eyi ti wọn ti fin silẹ ko lee parun ni Waidi Ayinla Ọmọwura, ti gbogbo eeyan mọ si Eegun Mọgaji.
Ko yẹ ki iran ode oni ma mọ itan igbe aye Ayinla Ọmọwura rara, nitori odu ni fun oloko lawujọ awọn olorin.
Bẹẹ, iyọ rẹ ko tẹ lawujọ awọn erupẹ nigba aye rẹ, idi si ree ti a se gbe itan aye rẹ wa fun un yin gẹgẹ bi a se ka a lori itakun agbaye Wikipedia ati awọn oju opo ayelujara miran.
Oríṣun àwòrán, Ayinla Omowura
Ayinla Ọmọwura, orin èébú àti oríyìn lo fi di ọ̀rẹ́ àwọ̀n obìnrin
Sogidi Lake: Kòṣẹja-kòṣèèyàn lá bá nínú adágún odò náà -Ojedele
Oríṣun àwòrán, Ayinla Omowura
Kokoro ko si jẹ ka gbadun obi Ayinla to gbo, ti iku ko jẹ ka gbadun ohun aladun ti Ẹlẹda fi jinki Ayinla Ọmọwura.
Ayinla Ọmọwura ko lọ sile iwe rara, amọ o se iwọn to lee se lati ko ipa tiẹ si idagbasoke awujọ to wa lati ipasẹ orin kikọ ati gbolohun ede Yoruba.
Ọba oke fi ohun to gbooro, to si dun un gbọ leti jinki Ayinla Ọmọwura pẹlu awọn agberin ti ọpọlọ wọn ji pepe kẹẹ.
Eyi to mu ki orin kikọ rọ Ayinla Ọmọwura lọrun. Lootọ ni Ayinla Ọmọwura jẹ ọmọ atapata dide amọ, o koju ọpọ ipenija to ba nile aye, to si bori wọn.
Ọpọ eeyan si lo gba pe akikanju akọrin ni Ayinla Ọmọwura, bẹẹ si ni ọjọ ko lọ lori awọn awo orin to ṣe lati ọpọ ọdun sẹyin, to si fi aikawe rẹ jẹ amuludun fun iran Yoruba.
A si n gbadura pe Ọlọrun yoo fi ọrun kẹ ẹ.
Orúkọ ọmọ ni Yorùbá gbà pé ó máa ń ro ọmọ nílẹ̀ Oodua
#sackFestusAdedayo: Àwọn ọmọ Naijiria kẹ̀yìn si ìyànsípò Festus Adedayo
Oríṣun àwòrán, Festus Adedayo
Awọn ọmọ Naijiria ti bu ẹnu atẹ lu igbesẹ ijọba lati yan Festus Adedayo gẹgẹ bi amugbalẹgbẹ feto iroyin fun Aarẹ Ile Igbimọ Asofin Agba, Ahmed Lawan.
Ori ẹrọ ikansiraẹni Twitter n gbona jainjain ni, lati igba ti orukọ Festus Adedayo ti jade wi pe, yoo ba Lawan sisẹ.
Ọpọlọpọ awọn to fesi pẹlu oju opo #sackFestusAdedayo sọ wi pe, arakunrin naa ko ni ẹtọ si ipo naa, nitori o pẹlu awọn alariwisi to ma n kọ iroyin buburu nipa Aarẹ Muhammadu Buhari ati isejọba rẹ, paapa saaju ati lẹyin ibo to kọja.
Awọn ẹlomiran ni, ohun to buru jai ni ki Aarẹ Ile Igbimọ Asofin fi awọn to sisẹ takuntakun fun un lasiko idibo silẹ, lati lọ mu ẹlomiran to tako ẹgbẹ oselu APC.
Nitorinaa ni wọn se ni awọn kọ jalẹ wi pe, ijọba ko gbọdọ fun Festus Adedayo ni ipo kankan.
Awọn miran tilẹ fi awon iroyin ti Adedayọ ti kọ fun awọn ile isẹ iroyin kọọkan han, nibi to ti tako isejọba ẹgbẹ APC to wa lode.
Amọ, lero ti awọn eeyan kan, ijọba ni asẹ lati se ohun to ba wu u, nitori awọn to wa ni ẹgbẹ oselu APC naa jẹ alailotọ, nitori naa ni wọn se lọ mu Festus Adedayo.
Bakan naa ni ẹlomiran gbe e jade wi pe, ko si ohun to jọọ wi pe wọn fẹ fi Festus Adedayo si ipo kankan, ati wi pe Ile Igbimọ Asofin ti gbe orukọ awọn to fẹ ba Lawan sisẹ jade, ti orukọ Adedayọ si ti poora nibẹ.
Amọ lasiko ti a pe FestusAdedayọ, pe ko wa sọ bii ọrọ naa se ri, ko gbe ẹrọ ilewọ rẹ.
Kò sí ǹkan tó ń ṣe Idris agbébọn ní Kano - Ará ilé
Oríṣun àwòrán, @others
Wọn ni lo ba wọle lọ gbe ibọn ni o si dabọn bolẹ ti ọrọ naa di pẹntuka ni Kano.
Awọn ara ilé Idris to yinbọn fun àwọn eniyan sọ pe ara Idris ya.
Nigba ti akọroyin BBC de ilé ti Idris to yinbọn fun awọn to n fi ẹṣin sare ije n gbe ni Kano ni a gbọ ọrọ kikun nipa rẹ.
Abubakar Yahaya to ni awọn ti jọ n gbe papọ fun ọgbọn ọdun ni aarẹ kankan ko ṣe Idris ni ọpọlọ.
Idris lo binu yinbọn lu eeyan meje lori ẹṣin lataari pe o ni oun ko fẹ ki wọn sare ije ẹṣin kọja ni adugbo oun.
Awọn ara ile rẹ to ku ti BBC ba sọrọ ni irọ ni pe ori rẹ daru ati pe awọn ko mọ pe Idris ni ibọn ninu ile rara.
Bawo ni ọrọ ṣe ṣẹlẹ?
Ọwọ ọlọpaa ti tẹ Idris to yinbọn ni aarin ìlú.
Lalẹ Ọjọru ni awọn eniyan kan n ṣayẹyẹ idije fifi ẹṣin sare ni agbegbe Tudun Maliki nipinlẹ Kano.
Kopẹ, ko jinna ni wọn ni ọkunrin kan da ibọn bolẹ eyi to ṣe eniyan meje lọṣẹ loju ẹsẹ.
Oríṣun àwòrán, Reuters
Agbébọn kọlu àwọn ènìyàn níbi ìdíje eré sísá ẹṣin
Ọkunrin naa ni iroyin ni o kọkọ kilọ fawọn to n fẹṣin sare naa ki wọn má gba oju titi adugbo oun kọja.
Iroyin ti a gbọ ni pe, arakunrin Idris ni oun ko fẹ ki wọn gbe ere ije ẹlẹṣin naa de adugbo oun ṣugbon awọn to n sare ko gbọ sii lẹnu.
Wọn ni lo ba wọle lọ gbe ibọn ni o si dabọn bolẹ ti ọrọ naa di pẹntuka ni Kano.
Awọn agbófinró ti mú ọkùnrin agbébọn kan to yìnbọn lu àwọn olùkópa nínú ìdíje eré sísá ẹṣin ni Kano.
Aṣoju awọn ọlọpaa ni ẹkun Kano, Abdullahi Haruna ṣalaye fun akọroyin BBC pe wọn ti ko awọn meje to ṣeṣe lọ si ile iwosan Aminu Kano fun itọju to peye.
Báyìí ni ayẹyẹ wíwé láwàní fún ọmọ China, olóyè Zhang ṣe lọ
Haruna ni awọn ti sọ Idris si gbaga ati pe ẹsun rẹ pọ bẹrẹ lati ibi ti Idris ti ri ibọn to yin atawọn ẹsun miran.
Lati asiko yii ni awọn eniyan Kano ti n bẹru pe ki ọrọ wọn ma lọ dabi ohun to n ṣẹlẹ ni Amerika pẹlu awọn agbebọn ainidi.
afin pupa
Bi ẹ ko ba gbagbe, laipẹ ni ọmọ oloṣelu kan yinbọn fi tu awọn to n ṣajọyọ pe ẹgbẹ wọn bori ninu eto idibo to kọja ka.
Ibadan expressway: Àwọn olè Fulani ló ń jí ènìyàn, pànìyàn ní òpópópónà!
Seyi Makinde: Àwọn ọba yoo ko ipa pataki lati gbogun ti aabo to mẹhẹ
Oríṣun àwòrán, Google
Gomina ipinlẹ Ọyọ naa ni awọn ọba yoo ko ipa pataki lati gbogun ti eto aabo to mẹhẹ ni ipinlẹ naa.
Gomina ipinlẹ Ọyọ, Seyi Makinde ti ni, ijọba oun yoo lo awọn ọba alaye ni agbeegbe kọọkan lati mu ibugbooro ba eto aabo ni ipinlẹ naa.
Gomina Makinde, to sọ ọrọ yii ni ibi ayẹyẹ ọjọ ibi Olugbọn ti Orile Igbon, Ọba Francis Alao, tun sọ wipe eto aabo wa lara awọn ohun ti isejọba oun duro fun.
O fikun wi pe, loore koore ni oun yoo ma a kan si awọn ọba naa, lati fun oun ni imọran ati ijiroro lori ọna abayọ si ipenija eto aabo.
Gomina ipinlẹ Ọyọ naa fikun pe, awọn ipo to jẹ gboogi ni isejọba oun ni awọn ọba naa yoo ti kopa fun ilọsiwaju ipinlẹ naa.
Orúkọ ọmọ ni Yorùbá gbà pé ó máa ń ro ọmọ nílẹ̀ Oodua
Lagos VIO - Ǹjẹ́ o mọ ìyàtọ̀ ojúṣe ọlọ́pàá, VIO, FRSC àti LASTMA lójú pópó?
Oríṣun àwòrán, @ElgivaStephen
Ileeṣẹ to n ṣe ayẹwo ọkọ nipinlẹ Eko, VIO ti sọ pe lẹyin ọlọpaa, oun nikan lofin orilẹede Naijiria ati ti ipinlẹ Eko fun laṣẹ, lati da ọkọ duro fun ayẹwo loju popo laisi pe irufẹ ọkọ bẹẹ ṣẹ ṣaaju.
Ọga agba ileeṣẹ VIO ni ipinlẹ Eko, Abdulafeez Toriọla lo sọ eyi di mimọ, lasiko to n kopa lori eto ifọrọwanilẹnuwo ori ikanni ayelujara ileeṣẹ BBC News Yoruba.
Ọgbẹni Toriọla ni, ko si idarudapọ laarin iṣẹ ọlọpaa, VIO, ẹṣọ oju popo FRSC, LASTMA atawọn ajọ agbofinro oju popo miran kaakiri orilẹede Naijiria, paapaa julọ ni ipinlẹ Eko.
O ni fun apẹẹrẹ, LASTMA ko lee ṣadede da ọkọ duro bi ọkọ ko ba ṣẹ, bakan naa pẹlu awọn ẹṣọ oju popo FRSC.
Oríṣun àwòrán, @followlastma
VIO nikan lo lee da mọto duro lati beere awọn nnkan bii iwe ọkọ ati boya mọto dangajia tabi ko dangajia. Nipasẹ abala ofin irinna ọkọ Section 12 subsection 2 iwe ofin Naijiria.
O ni ṣugbọn gbogbo awọn ajọ agbofinro wọnyii lo lee da ọkọ duro loju popo, ṣugbọn idi ti olukaluku lee fi da ọkọ duro lo yatọ, to si ju ara wọn lọ.
VIO ni ko si idarudapọ lori ojuṣe ọkọọkan awọn ajọ aggbofinro loju popo nipinlẹ Eko tabi ni ibikibi lorilẹede Naijiria.
Ọga agba ileeṣẹ VIO nipinlẹ Eko ọhun wa ke sawọn ọlọkọ, lati kun ijọba lọwọ lọna ati wagbo dẹkun si ọwọja ayederu iwe ọkọ lorilẹede Naijiria.
O ni awọn ọlọkọ gbọdọ rii daju pe ileeṣẹ VIO ni wọn ti n gba iwe wọn funrawọn.
Oríṣun àwòrán, @followlastma
O ni ileeṣẹ VIO nipinlẹ Eko ti ni awọn ohun elo igbalode, lati fi ṣe ayẹwo iwe ọkọ lati mọ ayederu yatọ si ojulowo.
Bakan naa lo ṣalaye pe, ko si eeyan to kọja ofin irinna lorilẹede Naijiria.
O  ni nipasẹ abala iwe ofin irinna Section 325, ko si eeyan titi dori awọn to di ipo oṣelu mu, to kọja ibawi, bi wọn ba tapa si ofin irinna lorilẹede Naijiria.
#FIFAWWC : Chile fi àmì àyo méjì gbógo fún Naijiria
Oríṣun àwòrán, @Daniela
Super Falcons gòkè odò bọ́ sípele ìkẹrìndínlógún ní France
Cameroun ati Naijiria ti yege fun ipele to kan ni FIFAWWC.
Ami ayo meji ni ẹgbẹ agbabọọlu orilẹ-ede Chile fi na Thailand ninu idije ifẹ ẹyẹ agbaye tawọn obinrin to n lọ lọwọ ni France.
Oríṣun àwòrán, @thenff
Cameroun ti yege fun ipele to kan ṣugbọn nnkan ko tii ṣẹnuure fun Naijiria
Ifagagbaga to waye laarin Thailand ati Chile lo sọ boya Naijiria ṣi maa tẹsiwaju ninu idije tabi bẹẹkọ nitoripe France ti na Naijiria ninu ikọ naa pẹlu ami ayo kan tẹlẹ.
Bayii Naijiria ti pegede lati kopa ninu idije oni ikẹrindinlogun ko mẹsẹ o yọ.
Florida: Ọ̀ọ̀nì àléègbà dé ba Mary lálejò lọ́gànjọ́ òru
Inú fu, àyà fu ni Naijiria wà tẹ́lẹ̀
Ikọ super Falcons, tii se agbabọọlu obinrin fun orilẹ-ede Naijiria atawọn ọmọ Naijiria, yoo kun fun adura lati gba idajọ rere nipa ati tẹ siwaju ninu idije ife ẹyẹ agbaye to n lọ lọwọ lorilẹ-ede France.
Ọjọ iṣẹgun ni orilẹ-ede Naijiria gba ifẹsẹwọnsẹ to gbẹyin ninu ipin wọn fun ipele akọkọ idije ife ẹyẹ agbaye FIFA naa, ṣugbọn ipo kẹta ni Falcons ṣe lẹyin France ati Norway.
Ami ayo meji si odo ni wọn fi na South Korea, eyi to fun wọn lanfani ati duro mọ boya wọn yoo wa lara awọn ti ori yoo ko yọ lati kopa ni ipele to kan.
Ṣiugbọn lẹyin ti orilẹ-ede Cameroun ti gbẹyẹ mọ New Zealand lọwọ pẹlu ami ayo meji si ẹyọ kan, ọwọ orilẹ-ede Thailand, tii yoo maa waako pẹlu Chile bayii ni idajọ ku si, lati mọ boya Falcons yoo tẹsiwaju tabi tẹ ọkọ leti pada sorilẹede Naijiria.
Orúkọ ọmọ ni Yorùbá gbà pé ó máa ń ro ọmọ nílẹ̀ Oodua
Bi orilẹ-ede Thailand ba gba ki Chile gba ayo to ju meji si awọn rẹ, a jẹ wi pe orilẹ-ede Naijiria yoo ja kuro ni ipele to kan.
Sugbọn ṣa, bi Thailand ba lee ṣe bi ọkunrin ti wọn ko gba ki Chile gba ayo ju ẹyọ kan tabi meji si awọn wọn, gba ọmi tabi na Chile, taara ta ni Falcons yoo lọ si ipele to kan.
Sogidi Lake: Kòṣẹja-kòṣèèyàn lá bá nínú adágún odò náà -Ojedele
Seyi Makinde: Ìrírí, ọ̀gbọ́n àti ìmọ̀ ìgbìmọ̀ yìí yóò ṣèrànwọ́ fún ìjọba mi
Oríṣun àwòrán, Oyo state Government
Igbin tẹnu mọ igi, o gun, ni Gomina Seyi Makinde fi ifilọlẹ igbimọ olugbaninimọran to kede laipẹ yii se.
Ni owurọ ọjọ Ẹti, ni Gomina Makinde se ifilọlẹ igbimọ ẹlẹnu mẹwa naa to kede laipẹ yii, ryi ti Sẹnetọ Hosea Ayọọla Agboọla ko sodi.
Nigba to n se ifilọlẹ igbimọ naa, Makinde ni afojusun agbekalẹ igbimọ naa ni lati se afikun imọ ati iriri awọn asaaju ijọba oun, nipa gbigbe imọran pataki kalẹ fun ijọba.
Makinde ẹni to ni ti ko si ba si igi lẹyin ọgba, ọgba yoo wo, wa tọka si pe awọn ileesẹ nla nla n se aseyọri nitori igbimọ olugbaninimọran ti wọn gbe kalẹ nibẹ ni.
O fikun pe o se pataki kawọn ki ijọba oun ni  awọn eeyan to ni ọgbọn, oye ati iriri ni gbogbo ẹka igbe aye ọmọniyan, ti wọn yoo maa kopa ninu eto akoso ipinlẹ Ọyọ.
Oríṣun àwòrán, Seyi Makinde
Nigba to n sọrọ lorukọ awọn ọmọ igbimọ olugbaninimọran naa, alaga igbimọ naa, Sẹnetọ Agboọla seleri pe igbimọ naa yoo maa gbe imọran kalẹ loore koore lati mu ki ipese isejọba rere tẹsiwaju ni ipinlẹ Ọyọ.
Lara awọn ọmọ igbimọ naa ni Monsurat Sunmọnu, Mulikat Adeola Akande, Bọlaji Ayọrinde, Samson Ọlaoye, ati Sarafadeen Abiọdun Alli.
Florida: Ọ̀ọ̀nì àléègbà dé ba Mary lálejò lọ́gànjọ́ òru
Sugbọn Sarafadeen Alli ko yọju sibi ibura naa.
David Bello-Monerville ni ọkùnrin kẹta nínú rẹ̀ tí wọn yóò pa ní London
Oríṣun àwòrán, Met Police
David Bello-Monerville died after reports of a fight on Welbeck Road in Barnet on Tuesday night
Ọkunrin kan ti wọn gun pa ni apa ariwa London ni Ilẹ Gẹẹsi ni awọn agbofinro ti ni orukọ rẹ n jẹ David Bello-Monerville.
Wọn pe ọlọpaa si ibi ti iṣẹlẹ naa ti waye nigba ti awọn aladugbo ri wipe ija bẹ silẹ ni Welbeck Road ni agbegbe Barnet ni alẹ ọjọ Iṣẹgun.
Wọn ti fi ẹsun kan ọmọ ọdun mẹtadinlọgbọn kan Nathan Harewood, 27 wipe o mọ nipa ọrọ naa.
Òun ni ọmọ Naijiria kejì ti wín yoo pa ni London laarin ọ̀sẹ̀ kan.
Ní ọjọ keedogun oṣu kẹfa, wọn yinbọn pa ọmọ Naijiria kan Eniola Aluko ni Plumstead. Wọn si ti mu awọn afurasi ti wọn ni o mọ nipa ọrọ naa.
Oríṣun àwòrán, Facebook
Eniola Aluko ni wọn kọkọ pa ni ọsẹ yii
Ni ọdun to kọja ọmọ Naijiria miiran ti orukọ rẹ n jẹ Harry Uzoka ku ninu ikọlu kan lẹyin ti wọn gun pa ni London kan naa.
A gbọ wọn gun David to jẹ ẹni ọdun mejidinlogoji ni ọbẹ pa lẹyin ti ija bẹ silẹ laarin awọn kan ni adugbo rẹ ti wọn si in fi ọbẹ, ada ati igi ja.
Ṣugbọn ọrọ oloogbe David ti oṣẹṣẹ ku yii ju bẹẹ lọ.
Iroyin ni oun ni ọkunrin kẹta ti idile Monerville yoo padanu nipasẹ ibọn tabi ọbẹ ni ilu London.
Ni ọdun mẹfa sẹyin, a gbọ pe David, ati awọn aburo rẹ meji ti wọn jẹ ibeji, Joseph ati Jonathan wa ninu ọkọ kan nigba ti agbebọn kan yinbọn sinu ọkọ naa ni ẹẹmẹta.
Iroyin ni ori ko David ati Jonathan yọ ninu ewu, ṣugbọn ọta ibọn ba Joseph lori. O si ku loju ẹsẹ.
Oríṣun àwòrán,  Joseph Burke-Monerville/Facebook
Joseph jẹ ẹni ọdun mọkandinlogun nigba to ku ni ọdun mẹfa sẹyin
Oríṣun àwòrán,  Joseph Burke-Monerville
Ẹni ọdun mọkandinlogun ni a gbọ pe Joseph ọmọ ile iwe fasiti London Metropolitan nigba naa wa lasiko to ku.
Ẹgbọn wọn to kọkọ padanu ẹmi rẹ ni London ni Trevor Monerville.
Ẹni ọdun mẹrindilọgbọn lo jẹ nigba ti wọn gun pa ni agbegbe Hackney ni ọdun 1994.
Nigeria Army: àṣírí àwọn ajínigbé kò bò mọ́ ni Ondo àti Ekiti
Oríṣun àwòrán, others
Nigeria Army: àṣírí àwọn ajínigbé kò bò mọ́ ni Ondo àti Ekiti
Kete ti ijọba apapọ ti paṣẹ pe ki awọn ọmọ ogun lo mojuto ọrọ awọn ajinigbe ni iṣẹ ti bẹrẹ.
Ọpọlọpọ iṣẹlẹ ijinigbe lo ṣẹlẹ kaakiri orilẹ-ede Naijiria lasiko yii ni eyi to n kọ ọpọ olori lominu.
Koda laipẹ yii ni wọn ṣi ji ọmọ minista eto ilera, Ojogbon Adewole gbe ki awọn agbofinro to rii padaỌmọ isaac Adewọle gba ìdáǹdè lọ́wọ́ ajínigbé.
Ibadan expressway: Àwọn olè Fulani ló ń jí ènìyàn, pànìyàn ní òpópópónà!
Ileeṣẹ ologun ṣalaye pe awọn ẹrọ ayaworan to n fo lofurufu yii ni awọn yoo lo lati ṣawari ibúba awọn ajinigbe lawọn ipinlẹ yii.
Lọjọ Eti ni wọn ṣe ifilọlẹ awọn ẹrọ yii ni Osi ni Akurẹ to jẹ olu ilu ipinlẹ Ondo.
Odumakin sọrọ lori Fulani darandaran
Ogagun agba Zakari Abubakar to jẹ adari ikọ ọmọ ogun ni ẹkun yii ṣalaye pe awọn ẹrọ yii a maa ṣiṣẹ laarin ipinlẹ mejeeji tọrọ kan ni
Ogagun Zakari ni Ogagaun agba Tukur Buratai ti paṣẹ lati Abuja pe ijinigbe gbọdọ dopin ni ẹkun yi lẹyẹ-o-soka.
Wo itan omi gbigbona ati tutu ni Ikọgosi Ekiti
Ọgagun Buratai to n dari gbogbo ọmọ ogun Naijiria ni lilo awọn irinṣe igbalode bi eyi yoo tete jẹ ki iṣẹ naa rọrun lati ṣe.
'Owó tí mo ń rí lórí Garri ni mo fi ń ran ọkọ lọ́wọ́'
Ogagun Abubakar ni ikọ omo ogun oriṣi meji ti wọn kọkọ gbe kalẹ lati gbogun ti ijinigbe ni yoo jọ lo ẹro yii lati mu ayipada de ba eto aabo awọn  eniyan ipinlẹ Ondo ati Ekiti
YSAN 2018: llú Ondo gbàlejò Àpérò Ẹgbẹ́ Onímọ̀ èdè Yorùbá Nàìjírìa
Ileeṣẹ ọmọ ogun ilẹ ni aja iwoyi lo mọ ehoro iwoyii lé ni awọn fi ọrọ yii ṣe.
O ni igbo kijikiji to wa ni agbegbe yii ni awọn kan ti sọ di ibuba wọn fun iṣẹ ibi.
'A máa ń bẹ́ orí ẹni tó bá gbé imọlẹ̀ ọdún ìjẹṣu tó bá ṣubú ni'
Ogagun Azinta to jẹ olori ikọ ọmọ ogun ni ẹkun yii ni wọn ti paṣẹ fun pe ko rii pe gbogbo ọmọ ogun sá ipa wọn fun alaafia awọn eniyan Ekiti ati Ondo ti wọn n gbe ninu ipaya bayii.
'Igbe àwọn ọ̀dọ́ kọ́ ló mú wa pèsè iná l'Ondo'
Awọn ọmọ ogun wa fi da gbogbo awọn arinrinajo loju pe ko nii sewu mọ lopopona lati isinyii lọ.
Ondo: Iya lu ọmọ pa nítori ẹgbẹ̀rún mọkànlélógun Naira
Wọn ni awọn ikọ tijọba ṣagbekalẹ lati gbogun ti awọn ajinigbe ti bẹrẹ iṣẹ ni pẹrẹwu ni agbegbe yii.
Ondo: Dejí sun ọmọ méje àtagbalagba meji mọ́lé nítorí pé ó ń bínú
Igbagbọ awọn eniyan ipinlẹ Ondo ati Ekiti ni pe laipẹ ni wọn yoo le tun maa fẹdọ sori oronro sun bii ti tẹlẹ pẹlu igbesẹ tuntun ti awọn ọmọ ogun gbe yii.
Ondo; 1000 si 2000 naira lowo ori ilẹ fun mẹkunu
Ekiti Election: Ẹgbẹ́ awakọ̀ Ekiti pa ìjọba dà lẹ́yìn tí wọ́n kéde Fayẹmi
Olorí ogun Ethiopia f'arapa nínú rògbòdìyàn tó wáyé ni Addis Ababa
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Lootọ ni Ọgbẹni Abiy pa ina wahala oṣelu, amọ ija ẹlẹyamẹya n pọ si
Igbakeji Adari eto aabo lorilẹede Ethiopia ti ni ọgagun to wa ni idi ifipa gba ijọba to waye ni Ethiopia ti sa lọ kuro ni ilu, ti won ko si mọ irin rẹ.
Gedebe Hailu to jẹ Igbakeji adari eto aabo lorilẹede Ethiopia lo sọ bẹẹ fun Ile Isẹ Iroyin BBC, lẹyin ti rogbodiyan sẹlẹ lorilẹede Ethiopia, ti ọpọlọpọ awọn ologun si farapa.
Haliu ni ikọlu naa waye ni awọn ile isẹ ajọ ọlọpaa lorilẹede naa ati olu ile isẹ ẹgbọ oselu (Amhara Democratic Party (ADP) to wa ni ijọba lorilẹede naa.
Asamnew Tsige ni wọn sọ wi pe o se olori akitiyan lati gbe ijọba ologun kalẹ nipa isekupa awọn adari ologun.
Tsige ko ṣẹṣẹ ma gbiyanju lati ditẹgbajọba.O ti ṣaaju gbiyanju ikọlu si ijọba ni ọdun 2008, eleyii ti o si sọ ọ di ero ẹwọn gbere.
Amọ, lẹyin to lo ọdun mẹsan lẹwọn, Olootu Ijọba, Abiy Ahmed tu silẹ ni ọdun to kọja.
Saere Mekonnen ni olori gbogbo ọmọ ogun orilẹ-ede Ethiopia nilẹ Adulawọ.
Oun lo n mojuto idari awọn ọmọ ogun lori eto aabo ẹmi ati dukia awọn eniyan Ethiopia.
Mo ń retí láti ọ̀dọ̀ bàbá mi nígbà tí mo gbọ́ pé ó bá ìjàmbá bàálù lọ
Ogagun agba Saere Mekonnen wa lara awọn ti o di ilu mu ninu iditẹ gbajọba naa to gbẹmi ọpọlọpọ.
O ṣe atunṣe si iṣẹ awọn ọmọ ogun Ethiopia ni eyi to gba pe o maa jẹ ojutu siṣoro to n koju eto aabo wọn
O faragbọta pẹlu awọn ọmọ ogun kan ti wọn si sare gbe lọ sile iwosan fun itọju.
Ṣugbọn ẹpa ko boro mọ nitori, wọn ti kede pe O ku sinu iditẹ-gbajọba to ṣẹlẹ ni Addis Ababa naa.
Oríṣun àwòrán, others
iku ogun lo n pa akikanju bi iku odo ṣe n pa omuwẹ
Olorí ogun Ethiopia ti kú sínú ìdìtẹ̀-gbàjọba Ethiopia
Ileeṣẹ iroyin Ethiopia ti kede pe olori ọmọ ogun ti gbẹmi mi.
Wọn kede pe Saere Mekonnen atawọn olori ikọ ogun mẹrin ti wọn kọkọ faragbọgbẹ ninu iṣẹlẹ naa ti doloogbe.
Bakan naa ni wọn tun kede iku Ambachew Meckonnen to jẹ gomina ẹkun Amhara ati olubadamọran rẹ ti wọn ba iṣẹlẹ iditẹ-gbajọba naa rin.
Arákùnrin Ethiopia yìí ń fi ọwọ rin
Ki lo ṣẹlẹ sẹyin:
Olootu ijọba Ethiopia, Abiy ahmed sọ pe lootọ ni olori ogun orilẹ-ede naa fi ara gba ibọn.
Eyi waye lẹyin ija ajakuakata to waye ni ẹkùn Amhara, to wa ni apa Ariwa orilẹ-ede ọhun.
Abiy tun sọ pe ọpọlọpọ awọn ọmọ ogun ni wọn ti ṣekupa ninu ikọlu kan to waye ni olu ilu agbegbe Amhara, Bahir Dar.
Ọgbẹni Abiy sọ pe lasiko ti awọn ọmọ ogun naa n ṣepade lọwọ ni 'awọn akẹgbẹ wọn kan'' kọlu wọn, ti wọn si yinbọn pa wọn.
Iroyin tilẹ sọ pe oju opo ayelujara ti dẹnu kọlẹ ni Ethiopia, ti awọn araalu ni Bahir Dar si n gbọ iro ibọn ni kikan-kikan.
Ayelujara ti ẹnu kọlẹ ni Ethiopia
Bakan naa ni ileeṣẹ Amẹrika sọ pe iroyin sọ pe iro ibọn n dun ni olu ilu Ethiopia, Addis Ababa.
Ọdun to kọja ni wọn dibo yan Ọgbẹni AhmedAbiy Ahmed di olóòtú ìjọba Ethiopia, to si ti gbe igbesẹ lati fi opin si ija oṣelu.
O ṣe eyi nipa titu awọn ẹlẹwọn oṣelu silẹ, o si tun pa ofin ti ko faaye gba ṣiṣe ẹgbẹ oṣelu rẹ.
Bakan naa ni Ahmed fi oju awọn alaṣẹ ijọba ti wọn fi ẹsun titẹ ẹtọ ọmọniyan mọlẹ wina ofin.
Widows Day 2019: Mo máa ń sá kiri wá owó ilé ni -Opó
Ṣugbọn, lati igba ti Ahmed ti de ipo ni ija ẹlẹyamẹya ti pada si Ethiopia,
O to eniyan bi miliọnu meji aabọ ti wọn ti di alainilelori gẹgẹ bi akọsilẹ ajọ Iṣọkan Agbaye, UN, ṣe sọ.
Ebola Virus: ìdí tí Ebola fi ń tàn kálẹ̀
Lagos building collapse: Àtúnṣe tí kò bófin mu ló fa ilé tó wó lu ènìyàn méjì ní Oshodi - LASEMA
Oríṣun àwòrán, lasema
Ile naa pa awọn eniyan meji lara
Lọjọ Aiku ni ilé alaja kan wo lu awọn meji nipinlẹ Eko.
Lẹ́yin ti ile alaja kan wo lu eniyan meji ni adugbo Mafoluku ni Oshodi, Ipinlẹ Eko, ni ajọ to n koju isẹlẹ pajawiri ni Ipinlẹ Eko (LASEMA) sọrọ.
Wọn ni ṣe ni awọn to ni ile naa n ṣe atunṣe ti ko bofin mu ko to di pe ile naa wo lulẹ.
Awọn mejeeji to fara kaasa iṣẹlẹ naa wa nile iwosan bayii nibi ti wọn ti n gba itọju.
Adari LASEMA, Oke Osanyintolu to ko awọn oṣiṣẹ pajawiri lọ ibi iṣẹlẹ naa ni wọn n ṣe atunṣe bonkẹlẹ lori ile naa ki ileeṣẹ to n gbogun ti awọn ile àlàpà (LASBCA) ma baa wa wo o ni.
Oríṣun àwòrán, LASEMA
Osanyintolu tun ṣalaye wi pe awọn oṣiṣẹ ijọba yoo ṣe ayẹwo ile mejeeji to wa ni ẹgbẹ ile ọhun lati mọ boya awọn naa ti di alapa.
Agbẹnusọ  ajọ LASBCA, Titi Ajirotutu ni awọn agbofinro ti fi alabojuto iṣẹ atunṣe ti wọn n ṣe lori ile to wo naa, Dada Olaniyi si ahamọ.
Ajirotutu ni wọn n tun ile naa ṣe ki wọn baa le tete ta a ni.
Ebola Virus: ìdí tí Ebola fi ń tàn kálẹ̀
Ìbéèrè pọ̀ lórí òkú ọkùnrin kan tí ọlọ́pàá bá nínú àgbá ní Oyingbo
Ìbéèrè pọ̀ lórí òkú ọkùnrin kan tí ọlọ́pàá bá nínú àgbá ní Oyingbo
Awọn ara ipinlẹ Eko n fooya lori oku ọkunrin kan.
Ọpọ àwọn olugbe iyana Borno Way ati adugbo Kano ni Yaba nilu Eko ni o n kọminú nípa òkú arakunrin kan ti wọn ba ninu agbá ni adugbo naa ni ọjọ Aiku.
Bi ọpọ awọn aladugbo ṣe n sọ pe o jẹ mọ iṣẹ ọwọ awọn agbenipa to n fi eniyan ṣe oogun owo ni awọn miran ni o ṣeeṣe ko jẹ iṣẹ ọwọ awọn ọmọ ẹgbẹ okunkun.
Akọroyin wa kàn si agbẹnusọ ileeṣẹ ọlọpaa ni Ipinlẹ Eko, Bala Elkanah lori ọrọ naa.
O ni iwadii n lọ lọwọ lori ọrọ naa ati pe o ti yaju lati sọ ni pato bi ọkunrin naa ti wọn ba ara rẹ ninu agba naa ṣe ku.
A tun beere lọwọ rẹ boya wọn tilẹ ti mọ ibi ti ọkunrin naa ti wa.
Ṣugbọn O ni rara.
Ọkan lara wọn alaabo ilu to wa ni adugbo naa to mọ nipa ọrọ naa, Ishola Agbodemu ni awọn ọmọ ẹgbẹ okunkun n ṣoṣẹ ni agbegbe naa lọpọlọpọ.
Ọwọ́ ọlọ́pàá kò tíì tẹ àwọn jàńdùkú tó ṣiṣẹ́ náà
Iroyin ni, ọmọde meji ni o ti sọnu ni agbegbe naa laarin oṣu kan sẹyin.
Agbọdẹmu ni nitori ọrọ aabo to mẹhẹ ni agbegbe naa ni oun ṣe ko igbimọ ẹlẹni ogoji kan jọ lati maa boju to awọn nkan to n lọ ni awọn adugbo.
Ati lati ri wi pe wọn mu awọn janduku to n da ilu ru laipẹ.
Tomomewo Favour: olóṣèlú kìí ṣe ọ̀daràn tàbí alágbèrè
Agbodemu ni ọwọ awọn ti ba afẹsunkan kan ti orukọ rẹ n jẹ Sola Saliu.
O jẹ ọmọ ẹgbẹ okunkun kan to n gbimọ lati ko awọn janduku wọ adugbo nitori ọmọ ẹgbẹ wọn kan to padanu ẹmi rẹ.
Ìgbìmọ̀ ìgbẹ́jọ́ ìdìbò ààrẹ kọ ẹ̀bẹ̀ ẹgbẹ́ PDP láti yẹ ojú òpó ayélujára INEC wò
Oríṣun àwòrán, @Atiku
"Igbimọ to n gbọ ẹsun to su yọ lori eto idibo aarẹ ti kọ ẹbẹ oludije ẹgbẹ oṣelu Peoples Democratic Party, PDP, lati ṣayẹwo oju opo ayelujara ajọ INEC eyi ti wọn pe ni ""Server""."
Awọn ọmọ igbimọ maraarun naa fi ẹnu ko lori igbesẹ ọhun lati ma fi aaye gba ẹgbẹ oṣelu PDP ati oludije rẹ, Atiku Abubakar, nitori awọn nkan mii to tun ti kún ẹjọ naa nipa oju opo ayelujara INEC.
Awọn adajọ naa sọ pe nibi ti nkan de bayii,  igbimọ ọhun ko tun le ti ọwọ bọ wahala boya INEC lo ẹrọ ayelujara lati ṣafihan esi idibo tabi ko lo o.
Ọnidajọ Garba to ka idajọ naa sita sọ pe ṣiṣe bẹ 'ko mu ọgbọn dani''.
Tomomewo Favour: olóṣèlú kìí ṣe ọ̀daràn tàbí alágbèrè
O ni ti ile ẹjọ ba fi aaye gba ẹgbẹ PDP, eyi tumọ si pe 'wọn ti gba pe oju opo ayelujara apapọ kan wa ti gbogbo esi idibo ọjọ kẹtalelogun, oṣu Keji wa.''
EFCC: Ẹlẹ́rìí ṣàlàyé bí wọ́n ti ṣé gbé N1.2bn fún Obanikoro
Oríṣun àwòrán, Others
EFCC: Ẹlẹ́rìí ṣàlàyé bí wọ́n ti ṣé gbé N1.2bn fún Obanikoro
Apo nla marunlelọgọta la fi gbe owo wa fun Obanikoro nigba naa.
Ẹlẹri kan ti salaye fadajọ to n gbọ ẹsun ajẹbanu ti wọn fi kan Minisita eto aabo tẹlẹri ni Naijiria,Musiliu Obanikoro, bi oun ti ṣe gbe owo to le ni biliọnu naira fun un.
Lasiko igbẹjọ to waye kẹyin niwaju adajọ Nnamdi Dimgba ti ile ẹjọ giga ni ilu Abuja lo ti tu pẹpẹ ọrọ yi.
Atẹjade kan ti agbẹnusọ ajọ to n gbogun ti iwa jẹgudujẹra fi sita ṣalaye EFCC fidiẹ mulẹ ni.
Atẹjade ti wọn fi sita naa ni Abiodun Agbele to fi'gba kan jẹ isọmọgbe gomina ana nipinlẹ Ekiti, Ayodele Fayose ti salaye bi oun ti ṣe ṣeto gbigbe owo fun Obanikoro.
Tomomewo Favour: olóṣèlú kìí ṣe ọ̀daràn tàbí alágbèrè
O ni owo ọhun le ni  biliọnu naira ki Fayose le wọle lasiko idibo gomina Ekiti lọdun 2014.
Ẹkunrẹrẹ alaye nipa bi wọn ti ṣe gbe owo naa lati papakọ ofurufu ilu Eko ti wọn si gbe e fun Obanikoro ni eleri miran Damola Otuyalo ṣe fun ile ẹjọ.
O ti to ọjọ mẹta ti igbẹjọ ẹsun jẹgudujẹra ti wọn fi kan Musiliu Obanikoro ti n waye
Otuyalo ti o jẹ adari awọn oṣiṣe eto gbigbe owo to pọ nigba kan ri nile ifowopamọ Diamond Bank ni apo nla marundinlaadọrin lawọn fi gbe owo naa.
O ni owó ọhun ni ọga oun si paṣẹ foun lori ẹrọ ibanisọrọ lati gbe fun Musiliu Obanikoro.
Ẹjọ owo yi nii ṣe pẹlu owo ti ijọba ni gomina ana nipinlẹ Ekiti, Ayodele Fayose gba lọwọ oludamọran lori ọrọ aabo fun aarẹ tẹlẹri Dasuki Sambo.
Owo naa lapapọ le ni biliọnu mẹrin naira.
Lẹyin ti awọn eleri wi tẹnu wọn ti wọn si fi iwe jẹri si ọrọ ti wọn sọ, adajọ Dimgba sun igbejọ naa siwaju titi di ọjọ kẹrin oṣu Kẹwa ọdun 2019.
Widows Day 2019: Mo máa ń sá kiri wá owó ilé ni -Opó
Ìgbà mélòó ní wọn fẹ kéde ikú ẹṣọ tó pá Ọ̀gágun Lorílè-èdè Ethiopia ?
Oríṣun àwòrán, ETV
Ẹ̀ṣọ́ tó pa Ọ̀gágun Ethiopia tí a sọ pé ó kú, kò kú mọ́! -Ọlọ́pàá
Ẹ fori jin wa, ẹni ta a lo ku tẹlẹ, ko ku mọ.
Ikede yi lo waye lati ẹnu ileeṣẹ ọlọpaa apapọ lorile-ede Ethiopia ti o kọkọ sọ pe ẹṣọ to ṣekupa olori ọmọ ọgun ilẹ naa Ọgagun, Seare Mekonnen, ti yinbọn pa ara rẹ.
Ni bayi ohun ti wọn n sọ ni pe ẹṣọ naa ko ku mọ ati pe o n gba itọju lọwọ nile iwosan ni.
Ile iṣẹ olootu ijọba ilẹ naa sọ pe ẹsọ naa lo ṣeku pa ọgagun naa pẹlu ọga ọmọ ogun mii, ọgagun Gezai Abera ninu igbiyanju ati fitẹgbajọba.
Eyi ni igba ẹlẹẹkeji ti iroyin yoo ma yipada nipa ohun to ṣẹlẹ si ẹṣọ yi.
Mo máa n forin mi kìlọ̀ ìwà ìbàjẹ́ láwùjọ ni -Hameen
Ni ọjọ Ẹti, ohun ti ileeṣẹ ọlọpaa kọkọ kede ni pe ọwọ ti tẹ ẹsọ naa, lẹyin igba naa ni wọn ni o yinbọn pa ara rẹ lẹyin to ṣeku pa awọn ọgagun mejeeji.
Ko ti si aridaju boya ẹsọ naa n gba itọju fun ọgbẹ ti o fi ọwọ ara rẹ da tabi eleyi ti wọn da si lara.
Tomomewo Favour: olóṣèlú kìí ṣe ọ̀daràn tàbí alágbèrè
NIS ní àwọn kò ṣèṣẹ̀ máa fí ìwé irinnà ránṣẹ sí àwọn tó bá fẹ
Oríṣun àwòrán, Channels TV
Fi adirési to wu ọ silẹ, ki a fi iwe irinna rẹ ranṣẹ si ẹ
Ileeṣẹ to n ṣeto igbokegbodo awọn to n wọ orilẹ-ede Naijiria ti ṣe alaye nipa fifi iwe irinna ranṣẹ si adirẹsi ti ẹni tó ba fẹ gba iwe naa fi silẹ lọdọ awọn.
Wọn ni iru anfani bẹẹ wa lati fi gba iwe irinna ati pe o ti wa tipẹ ṣugbọn awọn eeyan ko lo anfani ọhun ni.
Ninu ifọrọwanilẹnuwo pẹlu BBC Yoruba, agbẹnusọ ileeṣẹ naa, Sunday James sọ pe awọn ko ṣẹṣẹ maa ṣe bẹẹ amọ awọn eeyan ni ko lo anfani naa.
''Ohun ti wọn ni lati ṣe ni pe ki wọn fi apo iwe kalẹ, eleyi ti wọn kọ adirẹsi wọn si lasiko ti wọn ba n ṣeto ati gba iwe irina wọn.Bi wọn ba ti ṣetan, a o si fi ranṣẹ si wọn.''
O salaye pe o ṣeeṣẹ ki awọn ma ti ma sọ fun awọn eeyan to fẹ wa gba iwe yi pe irufẹ anfaani bayi wa ṣugbọn ni bayi,awọn yoo ma tẹ mọ wọn leti.
James ni ibaṣepọ wa laarin awọn ati ileeṣẹ ifiweranṣẹ ki gbogbo eto naa ba a le lọ deede.
Ki lo ṣẹlẹ sẹyin?
Laipẹ yi ni iṣẹlẹ kan waye nilẹ Gẹẹsi nibi ti ọmọ Naijiria kan ti fi ibinu fọ gilaasi ọkọ ileeṣẹ to n soju Naijiria nilẹ Gẹẹsi.
Oríṣun àwòrán, ICIR
Ohun to lo mu iwa bẹẹ wa ni pe wọn ko tete fun oun ni iwe irinna pasipọọti lẹyin ti oun ti kọwe lati gbaa.
Mo máa n forin mi kìlọ̀ ìwà ìbàjẹ́ láwùjọ ni -Hameen
Iṣẹlẹ yi mu ki ile iṣẹ Naijiria ni London kede pe bẹrẹ lati ọjọ kẹrinlelogun, oṣu yi,wọn yoo ma fi iwe irinna ranṣẹ si awọn to ba fi adirẹsi ati apo iwe kalẹ sọdọ awọn.
Gbigba iwe irina Naijiria yala nile ni tabi lẹyin odi a ma mu inira waye fun awọn ara ilu.
Widows Day 2019: Mo máa ń sá kiri wá owó ilé ni -Opó
Lọpọ igba,awọn eeyan a maa to fún ọpọlọpọ wakati ki wọn to le ri iwe irinna pasipọọti wọn gba.
Ebola Virus: ìdí tí Ebola fi ń tàn kálẹ̀
Oyo NURTW: Okùn òfin Makinde ti dí ọ̀nà ìjẹ wa
Oríṣun àwòrán, @Oyoaffairs
Ẹgbẹ awakọ ero NURTW nipinlẹ Ọyọ, ti figbe bọnu pe ki Gomina Seyi Makinde tu okun ofin to fi de awọn nitori aifararọ eto abo to n ba ipinlẹ Ọyọ finra losu karun ọdun 2019.
Alaga ẹgbẹ NURTW nipinlẹ Ọyọ, Alhaji Abideen Olajide, ti gbogbo eeyan mọ si Ejiogbe lo n parọwa bẹẹ ninu atẹjade kan to fisita, pẹlu afikun pe bi gomina Makinde se fofin de isọwọ sisẹ awọn asaaju ẹgbẹ ọlọkọ ero, ti di ọna ijẹ wọn lojumọ.
Bakan naa ni Ejigbe tun nahun kesi Olubadan ilẹ Ibadan, Ọba Saliu Adetunji Aje Ogungunnisọ Kinni, lati bawọn rawọ ẹbẹ si Makinde pe ko tu okun ofin naa lọrun awsn nitori agba ti ko binu ni ọmọ rẹ n pọ.
Alhaji Ọlajide tun salaye pe awọn ọmọ ẹgbẹ ọlọkọ ero ko fa ijangbọn kankan lẹsẹ, tawọn si n gba alaafia laaye lai naani pe ijọba fi ofin de wọn, to si tun fi ọwọ sọya pe alaafia ipinlẹ Ọyọ ko ni yinjẹ.
Mo máa n forin mi kìlọ̀ ìwà ìbàjẹ́ láwùjọ ni -Hameen
Ejiogbe wa gbe osuba kare fun aarẹ ẹgbẹ ọlọkọ ero nilẹ wa, Alhaji Najeem Yaasin fun aayan rẹ lati ri daju pe alaafia jsba pada ninu ẹgbẹ awakọ ero nipinlẹ Ọyọ.
Security Meeting: A fẹ́ àgbékalẹ̀ ọlọ́pàá agbègbè láti pèsè ààbò tó rinlẹ̀
Awọn gomina mẹfẹẹfa to n bẹ nilẹ kaarọ-oojiire lo peju-pesẹ lati jiroro, lori eto aabo jakejado awọn ipinlẹ ti wọn n ṣoju fun.
Apero naa waye lọjọ Iṣẹgun ninu gbọngan nla Theophilus Ogunlesi, to n bẹ ladojukọ ile iwosan ẹkọṣẹ iṣegun oyinbo, UCH nilẹ Ibadan.
Awọn ladelade, loyeloye, aṣoju ijọba, ẹlẹgbẹjẹgbẹ awujọ, ajọ awọn ẹṣọ alabo, to fi mọ awọn akoṣẹmọṣẹ nipa aabo ẹmi ati dukia lo kora jọpọ sibi akanṣe eto naa. Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí:
Ifojusun wọn si ni lati fi agbajọwọ wa ojutu si gbogbo awọn ipenja to nii ṣe pẹlu eto aabo ni ẹkun iwọ-oorun guuṣu orilẹede yii.
Ninu ọrọ rẹ, gomina ipinlẹ Ekiti, to tun jẹ alaga apapọ fun igbimọ awọn gomina to n bẹ lorilẹede yii, Ọmọwe Kayọde Fayemi ṣe alaye wi pe, gbogbo orilẹede yii lo n koju ipenija eto aabo.
O ni paapaa julọ nipasẹ wahala awọn ajinigbe, iwa ọdaran ati ijọgbọn awọn Fulani darandaran.
O tẹsiwaju wi pe, yoo nira lati wa ojutu si ipenija eto aabo lai ṣe amulo awọn ẹrọ igbalode.
Fayemi ni lati bii oṣu melo kan sẹyin, ni ọkanọjọkan ipade ti n waye laarin aarẹ orilẹede yii, Mohammadu Buhari ati gbogbo awọn gomina lori eto aabo.
O fi kun ọrọ rẹ wi pe, ipo ti eto aabo orilẹede yii wa ti di ohun ijaya fun awọn eeyan ilu, ọrọ yii ṣi jẹ ohun to n kọ awọn gomina lominu.
O ni gbogbo ibi ti awọn ba de ni ọpọlọpọ eeyan ti maa n beere alaye lori igbesẹ ti awọn gomina n gbe lati dẹkun ipenija eto aabo.
Fayẹmi ni, ojuṣe awọn gomina ni lati rii daju wi pe eto aabo fi ẹsẹ mulẹ ni awọn ipinlẹ wọn, lai ṣe awawi kankan bi o ti n wu, ki o mọ.
Tomomewo Favour: olóṣèlú kìí ṣe ọ̀daràn tàbí alágbèrè
Gomina ipinlẹ Ondo, ti o tun jẹ aṣoju fun awọn gomina to n bẹ ni ẹkun Iwo-oorun guusu, Arakunrin Rotimi Akeredolu, naa ba awọn eeyan sọrọ nibi apero naa.
O ni awọn gomina naa nilo ifọwọsowọpọ lai fi ti ẹgbẹ oṣelu kankan ṣe lori eto aabo ilẹ Yoruba.
Akeredolu ni, eto aabo gbọdọ fi ẹsẹ mulẹ lati ẹnu iloro ipinlẹ kan si ikeji ni ẹkun iwọ-oorun guusu.
O tẹsiwaju wipe, awọn ijọba ipinlẹ yoo nilo ajọṣepo awọn eeyan ilu lati le tete wa ojutu si ipenija awọn ajinigbe, ọdaran ati Fulani darandaran.
O ni apero naa pọn dandan, nipasẹ odiwọn awọn ipenija to nii ṣe pẹlu eto aabo lorilẹede yii.
Gomina ipinlẹ Ondo ni, ko si ohunkohun to pọju lati ṣe fun aabo ẹmi ati dukia awọn eeyan ilu.
O ni awọn ọdaran to n da omi alafia ilu ru ko bọwọ fun ipo ti ẹnikẹni wa lawujọ, tabi odiwọn ọrọ ti wọn ni.
Alaye rẹ ni pe, ati olowo ati ọlọrọ, ati ọmọde ati agba lo n foju wina ijinigbe nilẹ Yoruba.
Gomina Akeredolu parọwa si awọn eeyan ilu lati fi ọwọ sowọpọ pẹlu ijọba ati awọn agbofinro, lati le wa ojutu si awọn ipenija to n ba eto aabo wọya ija.
Bakan naa ni gomina Babajide Sanwo-Olu ti ipinlẹ Eko, Dapọ Abiọdun lati ipinlẹ Ogun, Gboyega Oyetọla ipinlẹ Ọṣun ati Ṣeyi Makinde to jẹ olugbalejo awọn akẹgbẹ rẹ naa sọrọ.
Wọn pa ẹnu pọ sọ wi pe, igbogun ti oṣi, ainiṣẹlọwọ, ailanfani si eto ẹkọ ati lilo egbogi oloro n bẹ lara awọn ọna abayọ si ipenija eto aabo.
Wọn ṣe alaye wi pe, awọn aṣoju ijọba nilo ifọwọsowọpọ awọn obi ati awọn adari awujọ ninu igbiyanju wọn, lati wa ojutu si ipenija naa.
Gbogbo awọn gomina naa ni wọn pe fun agbekale ọlọpaa agbegbe si agbegbe, ki eto aabo lee fi ẹsẹ mulẹ bi o ti yẹ.
Mo máa n forin mi kìlọ̀ ìwà ìbàjẹ́ láwùjọ ni -Hameen
Wọn tẹsiwaju pe, lai si eto aabo to fi ẹsẹ mulẹ, yoo nira lati jẹ anfani eto ọrọ aaje to rọṣọmu, bẹẹ si ni awọn oludokowo ti o le mu idagbasoke ba orilẹede yii yoo maa bẹru lati wọle wa.
Apero naa ni ireti wa wi pe yoo waye fun ọjọ mẹta gbako, gẹgẹ bi awọn gomina naa ṣe pinnu lati tẹlẹ awọn amọran ti o ba ti ibi apero naa jade.
Afenifere: Ìgbà wo ni Bola Tinubu di ọmọ ẹgbẹ Afenifere?
Kii ṣe ojulowo ọmọ ẹgbẹ afẹnifẹre lo lọ si Abuja lọdọ Buahri -Odumakin
Lẹyin ti iroyin sọ pe Aarẹ Muhammadu Buhari ti ṣe ipade pẹlu awọn ọmọ ẹgbẹ Afẹnifẹre, agbẹnusọ ẹgbẹ naa, Yinka Odumakin ti ni awọn ayederu ọmọ ẹgbẹ Afẹnifẹre lo lọ ibi ipade naa.
"Odumakin sọ fun BBC Yoruba wi pe: ""Afenifẹre ko ṣe ipade kankan pẹlu Buhari."
Igba wo ni Bola Tinubu, to ko awọn eniyan lọ iwaju Buhari di aṣoju Afẹnifẹre?
"Tinubu ko awọn ọmọ ẹgbẹ APC rẹ lọ bẹ aarẹ wo ni. Ko si ohun to kan awa Afenifere nibẹ"""
A ti kọkọ mu iroyin naa wa wi pe, ẹgbẹ Afẹnifẹre beere nibi ipade naa idi ti Buhari ṣe yọ Adajọ agba ana ni Naijiria, Walter Onnoghen niṣẹ.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí:
Ṣugbọn Afẹnifẹre ni awọn to lọ ibi ipade naa, ba ọrọ ara wọn lọ ni.
Oríṣun àwòrán, others
ọrọ airiṣẹ ṣe awọn ọdọ ati aisi ina mọnamọna ni a fẹ ki o gbajumọ bayii
Nigba ti akọroyin wa ran Odumakin leti wi pe, Baba Ayo Fasanmi wa ninu ipade naa, o ni Baba Fasanmi kii ṣe ọmọ ẹgbẹ Afẹnifẹre nitori pe ko wa si ipade ẹgbẹ naa mọ.
Lori ipade awọn gomina ilẹ Yoruba lori ọrọ aabo ti wọn ba Buhari sọrọ le lori, Odumakin ṣalaye pe, ipade ẹ̀tàn ni wọn n ṣe.
O ni awọn ti o mọ nipa ọrọ aabo ilẹ Yoruba bii adari ẹgbẹ OPC, Aarẹ Gani Adams, lo yẹ ki wọn gbọ lẹnu rẹ, ni eyi ti wọn ko gbọ lati ẹnu wọn.
International Day Against Drug Abuse and Trafficking: ìdí ti mo fi ń mu oògùn olóró
Ninu ipade naa Buhari ṣalaye kikun lori idi ti oun fi yọ olori oko eto idajọ Naijiria ni ṣe, iyẹn Walter Onnoghen lori ẹsun ajẹbanu.
Lẹyin ti wọn ni ki Onnoghen lọ rọọkun nile ni o ba kuku kọwe ifẹyinti funra rẹ lọjọ kejidinlọgbọn, oṣu karun un, ọdun yii.
Aarẹ Buhari ni ko dun mọ oun ninu lati yọ Onnoghen ṣugbọn nigba ti iwadii fihan pe owo gọbọi ni wọn ba ninu asuwọn rẹ.
O ni: o maa n yamilẹnu irufẹ ẹri ọkan ti awọn eniyan Naijiria ni, nigba ti iwọ ti o n sọ awọn eniyan sẹwọn ko tun le tẹle ofin.
Ati pe Onnoghen mọ ohun to le ṣẹlẹ si aikede dukia oun gẹgẹ bi adajọ agba ni Naijiria.
Mo máa n forin mi kìlọ̀ ìwà ìbàjẹ́ láwùjọ ni -Hameen
Buhari ni oun yoo maa tun ọrọ oun sọ lori gbigbogun ti iwa jẹgudu jẹra nitori eyi jẹ iṣe oun lati igba ti oun ti wa nijọba ologun Naijiria.
Ko si ẹni ti ọwọ́jà igbogunti iwa ajẹbanu mi ko ni kan ti aṣiri wọn ba ti tu.
Senetọ Olabiyi Durojaye tó jẹ aarẹ Afẹnifẹre ki Buhari ati Osinbajo igbakeji rẹ ku oriire wiwọle wọn leekeji.
O gboriyin fun ijọba fun yiya June 12 sọtọ ni ọjọ iṣejọba awa ara wa ni Naijiria.
Wọn kii ku iṣẹ ti ijọba n ṣe lori ọkọ oju irin ati ọna marosẹ Ibadan.
Widows Day 2019: Mo máa ń sá kiri wá owó ilé ni -Opó
Durojaye ni oun to ku ti iran Yoruba fẹ lasiko yii ni pe ki wọn gbajumọ iṣoro to n koju eto aabo Naijiria.
O ni ọrọ eto ẹkọ wa n fẹ amojuto paapaa ọrọ airiṣẹ ṣe awọn ọdọ.
Ni ipari wọn ni ojutu wahala Naijiria ni ki ijọba ri si ọrọ ina mọnamọna ati eto ọgbin fun idagbasoke to yẹ.
Amoṣun: Mo gba àṣẹ lọ́wọ́ Jonathan láti dá iléeṣẹ́ aláàbò sílẹ̀ àti ríra ohun ìjà olóró
Oríṣun àwòrán, @SIAmosun
Gomina ana nipinlẹ Ogun, Sẹnetọ Ibikunle Amosun, ti fesi lori iroyin kan to n ja rainrain nilẹ.
Iroyin na n jà kiri lori awọn oju opo ikansira ẹni lori ayelujara pe, oun ra ọpọ ohun ija oloro pamọ saaju eto idibo gboogbo to kọ̀ja, lati da rugudu silẹ nipinlẹ Ogun.
Atẹjade kan ti agbẹnusọ fun Ibikunle Amosun, Rotimi Durojaye fọwọsi kede pe, ti ko ba si ẹsẹ, ẹsẹ kii dede sẹ.
O ni aifararọ eto aabo ti Amosun ba nilẹ lasiko to tẹwọgba ọpa asẹ lati tukọ ipinlẹ Ogun losu Karun un, ọdun 2011, lo fa sababi bo se ra awọn ohun ija oloro naa.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí:
Ṣé ẹ̀yin lè ṣe jú àwọn tó f'àmì sí Awọlumatẹ?
Amosun ni, lọdun 2011, isoro nla kan gboogi to n ba ipinlẹ Ogun finra ni aifararọ eto aabo, ipaniyan nitori oselu, ipani nipakupa lainidi to pọ nigba naa, eyi to mu kawọn ileesẹ nlanla dẹnu kọlẹ, ti ọrọ aje ipinlẹ Ogun si dorikodo.
Widows Day 2019: Mo máa ń sá kiri wá owó ilé ni -Opó
O fikun un pe ọpọ ile ifowopamọ lo gbe ilẹkun wọn ti nitori eto aabo to mẹhẹ nigba naa, ti ko si sẹni to lee sun, ti yoo di oju mejeeji lasiko ọhun.
Amosun salaye pe, niwọn igba to si jẹ pe ko lee si idagbasoke nibiti rudurudu ba wa, idi ree ti oun fi se agbekalẹ ajọ ẹdawo fun eto aabo nipinlẹ Ogun, Ogun State Security Trust Fund, STF.
Tomomewo Favour: olóṣèlú kìí ṣe ọ̀daràn tàbí alágbèrè
Atẹjade naa fikun pe, Amosun tun tọ aarẹ orilẹ-ede yii nigba naa, Goodluck Jonathan lọ, lati beere asẹ fun agbekalẹ ajọ OP MESA, ti wọn si ra awọn ohun ija fun wọn pẹlu owo gọbọi.
Koda o fikun un pe, ọọfisi oludamọran feto aabo fontẹ lu rira ọkọ ijagun mẹtala, ibọn AK 47 ẹgbẹrun kan, ẹwu ayẹta ẹgbẹrun kan, awọn ohun ija lorisirisi to to miliọnu meji, ọta ibọn ẹgbẹrun kan, ate ayẹta bii ẹẹdẹgbẹta, to fi mọ awọn ohun eelo ibaraẹnisọrọ lorisirisi.
Oríṣun àwòrán, @HQNigerianArmy
Amosun ni irọ to jinna sootọ ni pe wọn tete fa awọn ohun ija oloro naa le awọn ọlọpa lọwọ, ki gomina tuntun to fẹ gba akoso, Dapọ Abiọdun ma baa ri wọn.
O ni ohun to panilẹrin ni iroyin eke naa nitori pe Dapọ Abiọdun gan lo jẹ eeyan kan gboogi to ta ọpọ awọn ohun ija naa, paapa awọn ọkọ ijagun .
International Day Against Drug Abuse and Trafficking: ìdí ti mo fi ń mu oògùn olóró
Amosun wa rọ awọn araalu lati kẹyin si iroyin eke to n lọ kiri naa pe ohun ko ohun ijagun pamọ nitori pe ko si awo kankan ninu awo ẹwa nipa awọn ohun ija oloro naa.
Mo máa n forin mi kìlọ̀ ìwà ìbàjẹ́ láwùjọ ni -Hameen
O fikun pe oju awọn akọroyin si ni ohun fa awọn ibọn AK 47 naa le awọn ọlọpa lọwọ, ti awọn ohun ijagun yoku si wa ni ipamọ nile ijọba ipinlẹ Ogun, eyi to wa labẹ abojuto awọn agbofinro.
Itsey Sagay: Irọ́ ni Ahmed Lawan pa pe ₦750,000 ni Sẹ́nétọ̀ kan nń gbà lóṣù
Oríṣun àwòrán, @Social_NG
Alaga fun igbimọ̀ oludaninimọran fun aarẹ Buhari lori iwa ajẹ́banu, Ọjọgbọn Itsay Sagay ti fesi pada lati tako ọrọ ti aarẹ ile asofin agba, Ahmed Lawan sọ pe ko si asofin agba to n fi apo sakasaka di owo lọ̀ sile.
Lasiko to n ba akọ̀royin sọ̀rọ̀, Sagay pa Lawan lẹ́nu mọ̀ pe ko dẹ́kun irọ̀ pipa, ko si ma si awọ̀n ọ̀mọ̀ Naijiria lọna, pẹlu afikun pe miliọnu mẹẹdogun naira ni asofin agba kọọkan n gba lowo osu.
Itse Sagay fikun pe irọ to jinna si ootọ ni ọrọ kan ti Lawan sọ pe ẹgbẹrun lọna ọtalelẹẹdẹgbẹrin o din mẹwa naira, (₦750,000) ni asofin kọọkan n mu ls sile losu.
Agba amofin naa sọ pe awọn ọmọ Naijiria fẹ mọ iye ti asofin kọọkan n mu lọ sile losu, ko si yẹ ki ẹnikẹni maa fi ẹkọ tanna fun wọn.
Sagay fikun pe, irọ diẹ, ootọ diẹ ni Lawan sọ, nitori gbogbo aye lo ti mọ pe inu ajẹmọnu awọn asofin ni wọn di owo to lorukọ si.
International Day Against Drug Abuse and Trafficking: ìdí ti mo fi ń mu oògùn olóró
Ta ba wo, a lee ni ootọ ọrọ ni aarẹ ile asofin agba n sọ nipa owo osu awọn asofin agba naa, amọ eelo ni apapọ owo ti wọn n mu ls sile losu, o to miliọnu mẹẹdogun naira.
Ore Helicopter: Iléeṣẹ́ ọkọ̀ òfurufú ní wọn fi ẹlikọ́pútà tó dá àríyànjiyàn sílẹ̀ dóòlà ẹmí ni
Elikoputa naa da wahala silẹ lẹyin to balẹ si aarin popo naa lati gbe eniyan kan
Ileeṣẹ ọkọ ofururu kan ti sọ fun BBC wipe, aisan to ṣadede mu ọkunrin ti ọkọ ofuruf ẹlikoputa gbe ni aarin sunkẹrẹ-gba-kẹrẹ to waye loju ọna Benin-Ore laipẹ yii.
Fidio naa to gba gbogbo ori ayelujara kan lati igba to ti jade ni ọjọ Aiku to kọja ti n fa arinyanjiyan laarin ọmọ Naijiria, ọpọ to n sọ wipe baba olowo kan ni baalu naa wa gbe nitori sunkẹrẹ-gba-kẹre ọjọ naa.
Fidio mu ki ọpọ bẹnu atẹ lu bi awọn olowo Naijiria ṣe n jaye alábátá.
Ṣugbọn ileeṣẹ to ni ẹlikoputa naa ni ko si oun to buru ninu wipe, ki awọn lọ doola ẹmi ẹni ti aisan mu ni ọna to jina.
Ọpọ lo pin fidio naa lori ayelujara ati Instagram.
Ṣugbọn Femi Adeniji, to gbẹnusọ fun ileeṣẹ Tropical Arctic Logistics sọ fun BBC wipe, oun ko mọ idi ti ọrọ naa fi fa yanpọn-yanrin.
Mo máa n forin mi kìlọ̀ ìwà ìbàjẹ́ láwùjọ ni -Hameen
O ni, ki i ṣe igba akọkọ ree ti awọn baalu ileeṣẹ naa yoo rin iru irin naa. O tilẹ ni igba mẹfa ni awọn ti ṣe bẹẹ ni ọdun to kọja.
Adeniji fikun pe, ẹni ti ọkọ naa lọ gbe ni ẹjẹ ruru ni ẹru ba ba awakọ rẹ. O ṣalaye wipe, dokita kan to wa ni oju ọna nigba iṣẹlẹ naa tilẹ n ran ọkunrin naa lọwọ, ki o to di pe ẹlikoputa naa wa gbe.
Yahaya Jammeh: Obìnrin mẹ́ta ọ̀tọ̀ọ̀tọ̀ fẹ̀ṣùn ìfipábánilòpọ̀ kan ààrẹ Gambia
Oríṣun àwòrán, Fatou Jallow
Fatou Jallow sọ pe oun sa kuro ni Gambia lẹyin ti aarẹ fi ipa ba a lopọ.
Ọmọbinrin arinrinoge nigbakan ri, ti fi ẹsun kan aarẹ ana lorilẹede Gambia, Yahaya Jammeh pe, O fi ipa ba oun lopọ lasiko to fi wa ni ipo aarẹ.
Toufah Jallow, to ti n gbe ni orilẹede Canada bayii sọ pe, oun sa kuro ni Gambia lẹyin ti Jammeh fi ipa ba a ni aṣepọ.
Ijẹri ọmọbinrin naa wa lara aabọ iwadi ti ajọ ajafẹtọ ọmọniyan, Human Rights and Trial International gbe kalẹ. Ajọ naa lo n ṣewadi ẹsun ifipabanilopọ mi i ti wọn fi kan aarẹ nigba kan ri ọhun.
Ṣé ẹ̀yin lè ṣe jú àwọn tó f'àmì sí Awọlumatẹ?
BBC gbiyanju lati ba Ọgbẹni Jammeh, to n gbe ni orilẹede Equatorial Guinea lọwọlọwọ sọrọ, lati gbọ tẹnu rẹ lori ẹsun naa.
Amọ agbẹnusọ fun ẹgbẹ oṣelu rẹ, APRC, ti sẹ lori awọn ẹsun ifipabanilopọ naa.
"Ousman Rambo Jatta sọ ninu atẹjade kan ti wọn fun BBC pe ""Gbogbo awọn ẹsun ti wọn fi n kan aarẹ wa nigba kanri ti su awa gẹgẹ bi ẹgbẹ oṣelu ati awọn eniyan orilẹede Gambia,''"
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ọdun mejilelogun ni Jammeh fi ṣe aarẹ Gambia.
"Jatta sọ siwaju si pe, ""Aarẹ nigba kan ri naa ko ni asiko lati maa sọrọ lori awọn iroyin ti kii ṣe otitọ. O jẹ ẹni to bẹru Ọlọrun, ati olori to bọwọ fun awọn obinrin ilẹ Gambia."""
Amọ Toufah Jallow sọ fun BBC pe, oun fẹ ẹ fi oju kan Jammeh nile ẹjọ ko le doju kọ idajọ.
"Mo ti gbiyanju lati pa a mọra, ki n si gbe ọrọ naa kuro l'ọkan mi, ṣugbọn, ko rọrun.
Ruga settlement: YCE ní ìjọba àpapọ̀ ko tó bẹ̀ẹ́ láti kọ́ àgọ́ Fulani sílẹ̀ Yoruba
Idi niyi ti mo fi pinnu lati sọrọ sita lasiko yii, nitori asiko yii gan an lo dara ju fun mi lati sọ iriri mi. Mo si tun fẹ ẹ ri daju pe, Yahaya Jammeh mọ nkan to ṣe."
Bakan naa lo sọ pe, oun fẹ jẹri niwaju igbimọ ti Aarẹ Adama Barrow gbe kalẹ. Barrow lo wọle sipo aarẹ ninu eto idibo to waye l'oṣu Kejila, ọdun 2016.
Igbimọ naa n wadi awọn ẹsun titẹ ẹtọ ọmọniyan mọlẹ to waye lasiko iṣejọba Jammeh. Awọn ẹsun naa ni i ṣe pẹlu ipaniyan, ifiyajẹni to waye lasiko ijọba ọlọdun mejilelogun to ṣe.
Wọn fi ipa le Jammeh kuro nipo l'oṣu Kinni, ọdun 2017 lẹyin ti awọn alaṣẹ ẹkun naa ran awọn ọmọ ogun lọ si orilẹede Gambia nigba ti Jammeh kọ lati kuro ni iṣakoso.
Kàyééfì Promo: Ìyá, ọmọ tuntun àti olubi ló wà níbùdó ìgbókùsí, àmọ́ òkú ọmọ di àwátì
Jallow sọ pe, igba ti oun wa ni ẹni ọdun mejidinlogun ni oun pade Ọgbẹni Jammeh, lẹyin ti oun jawe olubori gẹgẹ bi ọmọbinrin to rẹwa ju ni olu ilu orilẹede naa, Banjul l'ọdun 2014.
Oṣu diẹ lẹyin to bori yii, o ni aarẹ nigba kan ri naa ṣe bi baba fun oun nigba ti awọn pade. O maa n gba a ni imọran, o maa n fun ni owo ati ẹbun. Bakan naa lo fa omi ẹrọ sile mọlẹbi rẹ.
Lẹyin eyi, nibi apejẹ alẹ kan ti ọkan lara awọn amugbalẹgbẹ aarẹ ṣeto , o ni aarẹ sọ pe ki oun fẹ oun. O kọ, o si tun ko awọn ẹbun ti amugbalẹgbẹ naa fẹ ẹ fun, ko le gba lati fẹ aarẹ.
Jallow sọ pe, ẹyin eyi ni amugbalẹgbẹ naa sọ pe, dandan ni fun oun lati kopa nibi eto isin kan nile ijọba l'oṣu Kẹfa, ọdun 2015, gẹgẹ bi ọmọbinrin to rẹwa ju l'orilẹede naa.
Ṣugbọn nigba to de, ile ti aarẹ n gbe ni wọn mu u lọ.
O f'ojuhan pe, aarẹ n binu simi. Jallow sọ pe aarẹ gba oun ni eti, o si tun gun un ni abẹrẹ kan ni apá.
''O fi nkan ọmọkunrin rẹ pa mi ni oju, o ti mi subu, o bọ aṣọ l'ọrun mi, ko to o ba mi lopọ.''
Bo tilẹ jẹ wipe BBC ko ti fi idi ẹsun ti ọmọge arẹwa naa sọ mulẹ, ṣugbọn oṣiṣẹ ijọba Gambia nigba kan, ti ko fi orukọ rẹ sita sọ pe, oun mọ pe awọn iṣẹlẹ ti ko bojumu maa n waye nile aarẹ.
'Obinrin lo maa n pọ ju ninu awọn to maa n ṣiṣẹ nile aarẹ, wọn si maa n gba ọpọ wọn lati tẹ ifẹkufẹ aarẹ l'ọrun ni.''
O ni oun ranti pe, oun maa n ri Arabinrin Jallow nile ijọba, ni awọn 'aago ti ko bojumu nigba mii.''
Iléẹjọ́ Ekiti: Bàbá àti ọmọ jí igi gẹdú tó tó ₦100,000
Nítori igi gẹdú, bábá àti ọmọ rẹ̀ méji dèrò ẹwọ̀n
Ilé ẹjọ́ májísírèèti kan ni Igede Ekiti ni ìpínlẹ̀ Ekiti, ti ran bàbá kan ẹni ààdọ̀rin ọdún, Adeyeye Olorunyomi àti ọmọkúnrin rẹ̀ méji, lọ si ẹ̀wọ̀n oṣù mẹ́fa.
Àwọn ọdaràn mẹ́tẹ̀ẹ̀ta dí èrò ẹwọ́n lẹ̀yìn ti wọ́n fẹsun kan wọ́n pe, wọ́n ji igi gẹdu gbé, èyí ti owó rẹ̀ tó ẹgbẹ̀rún lọ́nà ọgọ́run náírà.
Ọlọpàá tó wà nídi ẹjọ náà, Olubu Apata sàlàyé fún ilé ẹjọ pé, àwọn ọdaran náà tẹ ofin lóju ninú oṣù kejì ọdun 2019, ní oko Awuloju ní Igede-Ekiti èyí to lòdì sofin ipinlẹ̀ Ekiti.
International Day Against Drug Abuse and Trafficking: ìdí ti mo fi ń mu oògùn olóró
O fí kún-un pé, àwọn ọdaran náà fi ìmọ̀ sọ̀kan láti ṣẹ̀ sófin lọ́na ti ó le da omi àláfíà ìlú rú, ti wọn si wọ oko tó jẹ ti Oluwadare Olowokere àti Adekunle Olowokere.
Apata ni, àwọn ọdaran náà ji igi gẹdu tó to ẹgbẹ̀rún lónà ọgọrun kan náírà to jẹ ti olufisu, bákan náà ni wọ́n ṣe ìdíwọ fún àwọn ọlọpàá mẹ́rìn kan lásiko ti wọ́n fẹ mu wọ́n.
O ni, wọ́n tun fi àdá la àwọn igi to tó méjìdínlọ́gbọ̀n ninu oko náà, èyi tó si ti mu àdinku ba iye owo to yẹ ki àwọn igi naa ta lọ́ja, bákan naa ni wọ́n sàkóba fún igi kòkó, igi obì, igi ọ̀gẹ̀dẹ̀, àti ti kókò
Ìtàn Mánigbàgbé: £100, tíí ṣe ₦42,150 àsìkò yìí, nìjọba fun Taiwo Akinkunmi lówó iṣẹ́ lọ́dún 1959
Oríṣun àwòrán, @abdullarhi
Oniruuru awọn eeyan to lami laaka lo ti jade lorilẹede Naijiria, paapa nilẹ kaarọ Oojire wa, ti ọkọọkan wọn si ti ko ipa to jọju si idagbasoke ati irẹpọ orilẹede yii.
Lootọ ni ọpọ wọn ti re iwalẹ asa, amọ awọn miran si wa loke eepẹ, ti ko si yẹ ka tete gbagbe wọn.
Ọkan lara awọn ọmọ Oodua to gbe ogo iran wa ati orilẹede yii ga, to si n se abẹmi loke eepẹ lọwọlọwọ bayii ni Baba Michael Taiwo Akinkunmi.
Kayefi BBC Yorùba: Bàbá ọmọ, Mọ́ṣúárì, Ọlọ́pàá kẹ́jọ́ rò nípa òkú ọmọ tó pòórá
Ta ba si n sọ itan idagbasoke orilẹede Naijiria, titi de ibi ta de duro yii, ti a ko ba tii ranti Taiwo Akinkunmi, itan wa ko tii kun to,  nitori ipa to ko lati ri si ifilọlẹ ilẹ Naijiria pẹlu agbekalẹ asia ilẹ wa to rẹwa, ta n pe ni National Flag.
Gẹgẹ bi a se ka a loju opo itakun agbaye Wikipedia, ọmọ bibi ilu Ibadan ni Akinkunmi, amọ ti ẹkọ funfun rẹ ti inu ikoko dudu jade.
Oríṣun àwòrán, @ayoadaniel
Ta ni Michael Taiwo Akinkunmi:
Ṣé ẹ̀yin lè ṣe jú àwọn tó f'àmì sí Awọlumatẹ?
Kàyééfì Promo: Ìyá, ọmọ tuntun àti olubi ló wà níbùdó ìgbókùsí, àmọ́ òkú ọmọ di àwátì
Oríṣun àwòrán, @noaoyodirect
Niwọn igba to jẹ pe arise ni arika, arika si ni baba iregun, ohun ta ba se loni, ọrọ itan ni yoo da bo ba dọla, asia ti Taiwo Akinkunmi se lọdun gbọọrọ sẹyin, naa ni orilẹede Naijiria n lo titi di oni.
Ọpọ iran to n bọ lẹyin, ni yoo si maa ka itan nipa ohun ribiribi ti akinkanju ọmọ Yoruba yii gbe ile aye se.
International Day Against Drug Abuse and Trafficking: ìdí ti mo fi ń mu oògùn olóró
Taiwo Akinkunmi ti pe ẹni ọdun mẹtalelọgọrin, eyiun 83 bayii, ti ogbo si ti de si baba. Bi o tilẹ jẹ pe baba yii sa ipa tiẹ fun orilẹede rẹ lasiko to wa ni opepe, ni ẹni ọdun mẹtalelogun,amọ bawo ni orilẹede rẹ se n mọriri rẹ nipa sise itọju rẹ lasiko ti agba de sii yii?
Ruga Settlement: Iléeṣẹ́ ààrẹ ní àgbékalẹ̀ àgọ́ Fulani lọ̀nà àbáyọ sí wàhálà àgbẹ̀ àti Fulani
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Aworan awọn darandaran Fulani
Ileeṣẹ aarẹ orileede Naijiria ni ohun iyalẹnu lo jẹ fawọn bi awọn Gomina ipinlẹ kan ti ṣe n tapa si idasilẹ agọ Fulani, eyi ti wọn pe ni ''Ruga Settlement.''
Wọn fi ọrọ yi sita lẹyin ti awọn Gomina ipinlẹ kan kilọ fun ijọba pe, ko ma ṣe daba lati da awọn agọ wọnyii silẹ lagbegbe awọn.
Agbẹnusọ fun ileeṣẹ aarẹ, Femi Adesina sọ fun BBC pe, awọn ni akọsilẹ ibi tawọn Gomina kan ti fọwọ si kikọ ọgba fun dida ẹran, lati fi dẹkun wahala to n waye laarin awọn agbẹ ati darandaran.
Adesina ni ''Ajọ to n ri si ọrọ ajẹ ṣe agbekalẹ igbimọ kan, ti wọn si ṣe abẹwo sawọn ipinlẹ kan nibi tawọn Gomina ti fọwọ si pe, ki wọn da awọn agọ yii silẹ lati dẹkun aawọ to ma n waye laarin awọn agbẹ ati darandaran.
Amọ Adesina ni jẹ iyalẹnu lo jẹ fun oun pẹlu oun ti wọn wa n sọ nisinyii''
Ruga settlement: YCE ní ìjọba àpapọ̀ ko tó bẹ̀ẹ́ láti kọ́ àgọ́ Fulani sílẹ̀ Yoruba
O fikun pe ''akọsilẹ wa pe awọn Gomina kan ni ọna abayọ niyi, ti wọn ba wa n tapa si, ọna abayọ miran wo ni wọn fẹ ka lo?
Nigba ti BBC beere lọwọ Adesina nipa ọrọ tawọn kan sọ pe, Ruga Settlement yii yoo gba ilẹ lọwọ awọn onilẹ, Adesina fesi pada pe''Ẹnikẹni to ba sọ iru ọrọ yii, ikorira lo fi sọ, o si yẹ ki wọn lọ fọ ọkan iru ẹni bẹẹ mọ kuro ninu ero eleyamẹya gbogbo''
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Gomina Ortom wa lara awọn Gomina ti ipinlẹ wọn koju ipenija aawọ agbe ati darandaran
Lọjọ iṣẹgun ni Gomina ipinlẹ Benue, Samuel Ortom fesi si igbese yii lẹyin ti ileeṣẹ to n risi ọrọ eto ọgbin gbe katakata wa, lati bẹrẹ isẹagbekalẹ agọ Fulani ni ipinlẹ Benue.
Ortom sọ pe ''eebu lo jẹ si awọn eeyan ipinlẹ Benue ati pe awọn lodi si''
''Awa ko faramọ dida agọ Fulani silẹ ni ipinlẹ Benue tori pe, a ko ni ilẹ lati ya sọtọ fun awọn to fẹ fi ẹran jẹ''
Ortom kasẹ ọrọ nilẹ pe ''ọta ilọsiwaju ati alaafia lawọn to n pe fun idasilẹ agọ Fulani''
YCE Crisis: Kunle Olajide ní áwọn tó déte yíyọ òun ní ákọ̀wé YCE kò lẹ́nu ńbẹ̀
Oríṣun àwòrán, nkirukanistoran
Ọmọwe Kunle Olajide
Awuyewuye to n waye lori asaaju ẹgbẹ igbimọ agba Yoruba, YCE ti n gba ọna miran yọ pẹlu bi awọn kan ninu ẹgbẹ ti ṣe jawe lọ rọkun nile fun akọwe ẹgbẹ naa, Dokita Kunle Olajide.
Amọ ṣa, Kunle Olajide ti ni awọn to korajọ yọ oun kii ṣe ọmọ ẹgbẹ tootọ fun idi eyi wọn ko lagbara lati yọ oun.
Nigba ti o n ba BBC Yoruba sọrọ, Olajide ni ''ko si ẹnikankan to di ipo mu ninu ẹgbẹ to ṣe ipade kankan loni depo pe wọn yoo wa yọ oun lẹgbẹ.''
Bakannaa lo ni, ko si nkankan to n jẹ baba agba, eyiun ''senior elder'' ninu igbimọ agbagba Yoruba.
O wa  na ika aleebu si alagba Sam Agbede gẹgẹ bi ẹni to lọ ko awọn kan jọ pe, wọn ti ju ọgọrin ọdun lọ, to si ni ''a ko mọ wọn nitori wọn ko si ninu iwe ofin ẹgbẹ''
International Day Against Drug Abuse and Trafficking: ìdí ti mo fi ń mu oògùn olóró
Olajide ni o  da oun loju pe, awọn agbagba ẹgbẹ ni ipinlẹ mejeje ko ni pẹ fesi si ọrọ yii.
Olajide ni oun ko ri iwe kankan gba pe ki oun lọ rọọkun nile lati ọdọ ẹgbẹ YCE, iroyin eke lasan si ni kede to ni wọn le oun kuro ninu igbimọ ẹgbẹ agbaagba Yoruba.
BBC Yoruba tubọ bere lọwọ rẹ boya igbesẹ lati yọ niṣe pẹlu ọrọ to sọ fun BBC Yoruba nipa pe awọn Yoruba lodi si dida agọ Fulani silẹ nilẹ Yoruba ṣugbọn o ni oun ko ro bẹ.
''Agbede kan fẹ joye ni.Mi o ro pe o ni ṣe pẹlu rẹ nitori gbogbo awọn agba ẹgbẹ lo wa nibi ti a ti sọ pe awa Yoruba ko faramọ Ruga Settlement ni ilẹ Yoruba.
Ruga settlement: YCE ní ìjọba àpapọ̀ ko tó bẹ̀ẹ́ láti kọ́ àgọ́ Fulani sílẹ̀ Yoruba
O fi kun ọrọ rẹ pe ''awọn eleyi ko ni nnkankan ṣe ni,laipẹ yi awọn to yẹ yoo da wọn loun''
Lọjọbọ ni iroyin gbode pe awọn ọmọ ẹgbẹ YCE kan pamọran pọ lati yọ Dokita Kunle Olajide gẹgẹ bi akọwe ẹgbẹ.
Nibi ipade naa to waye, gẹgẹ bi a ti ṣe riika ni Ilu Ibadan,awọn agbagba ẹgbẹ naa fi ontẹ jan Dansaaki Agbede gẹgẹ bi Aarẹ ẹgbẹ naa.
Ninu awọn to kọwọrin ni ibi ipade yi la ti gbọ pe Oloye Mike Omoleye,Jibade Oyekan,Adegboye Onigbinde,Ọjọgbọn Adetoun Ogunsheye ati Sam Agbetuyi wa.
Ipade naa lawọn fọwọ si ki Comrade Sam Agbetuyi di ipo akọwe ẹgbẹ mu gẹgẹ bi fidihẹ.
'Soapy', àwo orin tuntun Naira Marley tó ń milẹ̀ tìtì
Oríṣun àwòrán, INSTAGRAM@NAIRAMARLEY
Naira Marley
Afeez Fashola ti gbogbo eniyan mọ si Naira Marley ti gbe awo orin tuntun kan jade to n jọba oju opo ayelujara lọwọlọwọ.
ẹni ọdun mẹẹdọgbọn yii ti ṣe ọpọlọpọ orin to gbode kan jade lagbo orin ni Naijiria bii 'Issa Goal' ati eyi to ṣẹṣẹ gbe jade yii 'Soapy'.
Kayefi BBC Yorùba: Bàbá ọmọ, Mọ́ṣúárì, Ọlọ́pàá kẹ́jọ́ rò nípa òkú ọmọ tó pòórá
Ninu fọnrán fídíò náà ti Marley fi sita loju opo Instagram rẹ, o jo iru ijo kan ti o mu ọwọ lọ si apa ibi nkan ọmọ kunrin rẹ eyi to fi n ṣapejuwe ọrọ inu orin rẹ.
Ọsẹ diẹ sẹyin ni wọn tu Marley silẹ lẹwọn nibi to wa fun ọjọ diẹ latari ẹsun ole ori ẹrọ ayelujara ti EFCC fi kan an eyi ti wọn n pe ni Yahoo Boy lorilẹede Naijiria.
Marley ni oun o jẹbi gbogbo ẹsun  ti wọn fi kan an.
Ẹwẹ lati igba ti orin tuntun yii, Soapy ti jade lawọn ọmọ Naijiria ko ti sinmi ẹnu lori ẹrọ ayelujara.
Bi awọn kan ṣe n gba tiẹ ti wọn n gbe lẹyin rẹ lawọn kan n ni kii ṣe m to ṣee fi yangan.
Emi o tilẹ ni wo fọnran orin naa rara. NAiraMarley ki lohun to n ti ẹ gbọngbọn gan?
Naira Marley yii ko lọpọlọ rara, ẹni to n kọrin lodi si aidaa ijọba, lori iṣoro awọn eeyan, aidaa awnọ ọlọpaa, laasigbo, o tilẹ n ṣe bii pe o ni iru ẹmi orin Bob Marley diẹ ṣugbọn Soapy lo n kọ. Ko lawọn eeyan gidi to yi i ka.
Nigbẹyin gbẹyin mo ti ri orin ti mo le foju jọ, Soapy ti Naira Marley.
Seyi Makinde: Akọ̀wé ìjba tuntun ni Olubamiwo Adeọsun.
Oríṣun àwòrán, Oyo state government
Ijọba ipinlẹ Ọyọ ti kede iyansipo ọga agba kan nileesẹ elepo rọbi Shell, gẹgẹ bii akọwe ijọba ipinlẹ Ọyọ.
Oluwarẹ ni Arabinrin Olubamiwo Adeọsun.
Atẹjade kan ti akọwe feto iroyin fun gomina ipinlẹ Ọyọ, Taiwo Adisa fisita lọjọ Ẹti salaye pe akọsẹmọsẹ nileesẹ elepo Shell ni Adeọsun, eyi ti gomina Makinde ni yoo seranwọ lati kopa ninu minu ayipada rere ba ipinlẹ Ọyọ.
Atẹjade naa ni iyansipo arabinrin Adeọsun lo wa nibamu pẹlu igbagbọ Gomina Seyi Makinde ninu awọn obinrin ati ikopa wọn ninu eto isejọba.
Atẹjade naa fikun pe, akọsẹmọsẹ apoogun to dantọ ni Adeọsun, to si gba oye imọ ijinlẹ akọkọ nile ẹkọ fasiti Benin lọdun 1990, nigba to gba oye imọ ijinlẹ keji nile ẹkọ fasiti yii kanna lọdun 1997.
Kàyééfì Promo: Ìyá, ọmọ tuntun àti olubi ló wà níbùdó ìgbókùsí, àmọ́ òkú ọmọ di àwátì
Adebamiwo  Adeọsun jẹ ẹni ọdun mẹtalelogoji, to si jẹ ọmọ ile Matọ nilu Ibadan.
Biodun Fatoyinbo: Mò ń gbé Busola Dakolo lọ ilé ẹjọ́
Lẹyin awuyewuye tó tẹle ifòròwanilẹnuwo kan, ninu eyi ti Busola to jẹ iyawo olorin takasufe Timi Dakolo, ti fẹsun ifipabanilopọ kan Alufaa ijọ COZA ni Abuja, Biodun Fatoyinbo, pasitọ naa ti ni oun yoo gba ile ẹjọ lọ lori ọrọ naa.
Fatoyinbo ni, irọ pọnbele ni ẹsun Busola Dakolo, ati wipe yatọ si iṣẹ oun gẹgẹ bii pasitọ, oun ko ba arabinrin naa ni nkankan pọ ni ikọkọ.
Ẹsun naa gba gbogbo ori ayelujara kan lati aarọ ọjọ Ẹti, ṣugbọn Fatoyinbo ni oun ko fipa ba obinrin kankan lo pọ ri.
Ninu fidio ifọrọwanilẹnuwo naa, Busola ni igba ti oun wa ni ileewe girama, ni oun kọkọ pade Fatoyinbo ni Ilorin, Ipinlẹ Kwara, nigba to ṣẹṣẹ bẹrẹ ijọ COZA.
O sọ ninu ẹsun rẹ ti Y! NaijaTV gbe sita wipe, igba meji ọtọọtọ ni pasitọ naa fipa ba oun lo pọ.
Ṣugbọn Fatoyinbo sọ ninu atẹjade kan to fisita lọjọ Ẹti wipe, Busola ati awọn ẹbi maa n wa si ijọ oun, nigba to kọkọ bẹrẹ.
Kàyééfì Promo: Ìyá, ọmọ tuntun àti olubi ló wà níbùdó ìgbókùsí, àmọ́ òkú ọmọ di àwátì
O ni o ya oun lẹnu wipe, pẹlu iru eniyan ti Busola ati ọkọ rẹ jẹ ni awujọ, o ya oun lẹnu wipe, wọn le fi iru ẹsun naa kan oun.
Pasitọ naa ni, oun ti fi ọrọ naa to awọn agbẹjọro oun leti ati wipe, gbogbo awọn eeyan ti wọn ni nkan ṣe pẹlu ẹsun naa, ni wọn yoo foju ba ile ẹjọ.
Damasus, Omotola, Ezekwesili, Funmi Iyanda dá sí ẹ̀sùn ìfipábánilòpọ̀ Fatoyinbo
Oríṣun àwòrán, @Omotolafans
Nínú fídíò kan tó ń ja rànyìnrànyìn ni ẹ̀sùn ìfipábánilòpọ̀ yìí ti kọ́kọ́ gbèrú
Ikanni ayelujara ṣi n rọ kẹkẹ bayii lori ẹsun ifipabanilopọ ti iyawo gbajugbaja onkọrinTimi Dakolo, Busọla Dakolo fi kan pasitọ agba ijọ COZA, Biọdun Fatoyinbo.
Oniruuru ọrọ ni awọn eekan pẹlu n sọ lori rẹ lori oju opo twitter, Facebook, Instagram atawọn ọpọ miran, yala lati gbe sẹyin Busọla aya Dakolo abi Pasitọ Biọdun Dakolo.
Lara awọn to ti sọrọ ni Funmi Iyanda, gbajugbaja agbohunsafẹfẹ to ni oun gba gbogbo ọrọ ti Busọla sọ lai ku ẹyọkan gbọ ati pe ireti oun ni pe ẹwọn lo yẹ ki atubọtan iranṣẹ Ọlọrun naa jẹ.
Bakan naa ni gbajugbaja oṣere tiata, Ọmọtọla Jalade Ẹkẹinde naa sọ tirẹ si iroyin naa eleyii to ti ni iṣoro to n koju awọn to foju wina iṣẹlẹ ifipabanilopọ ni ọna ati fi idi ẹsun wọn mulẹ.
O wa rọ gbogbo awọn ti irufẹ iṣẹlẹ bayii ti ṣẹ si lati ọdọ iranṣẹ Ọlọrun naa bọ si gbangba lati wa wi tẹnu wọn
Kayefi BBC Yorùba: Bàbá ọmọ, Mọ́ṣúárì, Ọlọ́pàá kẹ́jọ́ rò nípa òkú ọmọ tó pòórá
Ni tirẹ, eekan oloṣelu, Abikẹ Dabiri-Erewa to jẹ alaga ajọ awọn ọmọ orilẹede Naijiria loke okun naa ti ṣe afihan atilẹyin rẹ fun Busọla bẹẹni o kan sara si iyawo iransẹ Ọlọrun naa gẹgẹ bii obinrin to lọkan akin ati igboya pẹlu iroyin ẹsun ifipabanilopọ ti wọn fi n kan ọks rẹ lọpọ igba bayii.
Ninu ọrọ tirẹ, minisita lorilẹ-ede Naijiria nigbakan ri, Oby Ezekwesili pẹlu kọminu lori iroyin ọhun.
Ohun ti mo ka bani ninu jẹ pupọ. Mo gbadura fun iwosan... mo rọ iranṣẹ Ọlọrun yii lati tete dahun si ẹsun nla wọnyii. Ni kiakia,
Stella Damasus to jẹ gbajugbaja oṣere naa ti jade bere ibeere nla pe ṣe awọn eeyan ko ṣì tii gba ọrọ ẹsun yii gbọ?
O ni oun ṣẹṣẹ ba ẹlomii ti o fẹsun kan Fatoyinbo pe o tun fipa ba oun lo pẹ sọrọ tan ni o
ECOWAS: Orílẹ̀èdè 15 tó wà nínú àjọ ECOWAS yóò bẹ̀rẹ̀ sí níì ná owó kan nàá l'ọ́dún 2020
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Aarẹ Buhari yoo gbe iṣakoso fun alaga ajọ ECOWAS tuntun
Awọn olori orilẹede to wa ninu ajọ Iwọ oorun Afrika, ṣe ipade nilu Abuja fun ipade karundinlọgọta lati dibo yan alaga tuntun, ti wọn si tun sọrọ lori bi ẹkùn naa yoo ṣe maa na owo kan naa.
Awọn orilẹede mẹẹdogun to wa ninu ajọ naa ti ni afojusun lati maa na owo kan naa nigba ti yoo ba fi di ọdun 2020.
Nitori afojusun yii, awọn minisita eto inawo ati awọn gomina banki apapọ lawọn orilẹede naa ṣepade laipẹ yii lati gbaradi fun ṣiṣe idasilẹ owo ti gbogbo awọn orilẹede naa yoo ma na, ati bi paṣipaarọ rẹ yoo ṣe ri.
Kayefi BBC Yorùba: Bàbá ọmọ, Mọ́ṣúárì, Ọlọ́pàá kẹ́jọ́ rò nípa òkú ọmọ tó pòórá
Nibi ipade ti awọn aarẹ n ṣe yii, wọn yoo ṣe ayẹwo ibi ti awọn minisita naa ba iṣẹ de.
Lọwọlọwọ, Aarẹ orilẹede Naijiria, Muhammadu Buhari ni alaga ajọ Ecowas.
Lara oun ti wọn yoo tun jiroro le lori nibi ipade naa ni wahala oṣelu to n waye ni Guinea Bissau.
Ijede Lagos Boat Mishap: Mi ò rí irí ìṣẹ̀lẹ̀ yìí rí láyé mi!
'Èèyàn mi mẹ́ta ló wà nínú ọkọ̀ ojú omi tó dà nù!'
Ẹbi awọn to ba iṣẹlẹ ọkọ oju omi to da nu ni agbegbe Ijede ni ilu Eko sọ ipo ti gbogbo agbegbe omi ti wọ n gba kọja yii wa.
Alhaja Fatimah Aṣabi sọ fun ik iroyin BBC pe eeyan oun mẹta lo wa ninu iṣẹlẹ naa ti wọn ko si tii ri meji ninu wọn. Bẹ́ẹ si ni ninu ile to n gbe gan eniyan mẹrẹ lo wa ninu iṣẹlẹ naa.
O bu ẹnu atẹ lu ipo ti ibudokọ oju omi Ijede si Ikorodu wa o si lo anfani yii lati parọwa si ijọba Naijiria.
Ileeṣẹ LASEMA ṣàlàyé pè ìjàmbá náà wáyé lálẹ́ ọjọ́ Abamẹta nígbà tí ọkọ̀ ojú omi ọ̀hún kọsẹ̀.
Ajọ to n risi iṣẹlẹ pajawiri nipinlẹ Eko, LASEMA, ti parọwa sara ilu lati sọra fun wiwọ ọkọ oju omi lalẹ.
Ikilọ yi waye lẹyin iṣẹlẹ ijamba ọkọ oju omi to danu ni Egbin, lagbegbe Ikorodu lalẹ ọjọ Abamẹta.
LASEMA sọ pe eeyan mẹrinla ninu awọn mọkanlelogun to wa ninu ọkọ oju omi naa ni wọn ṣi n wa.
Oríṣun àwòrán, @lasemasocial
Ọ̀pọ̀ ẹ̀mí sọnù sínú Ọkọ̀ ojú omi to dànù l'Eko
Eeyan mẹrin ni wọn ribi dooola amọ oku mẹta ni o ti foju han pe o ba iṣẹlẹ naa lọ.
Ninu atẹjade kan ti Adebayo Kehinde, agbẹnusọ LASEMA fi sita salaye pe igbiyanju lati doola ẹmi ṣi n tẹsiwaju nipaṣẹ ajọsepọ awọn pẹjapẹja lagbegbe naa ati awọn ọlọpaa oju omi.
Ijinigbe: BBC ṣe ìwádìí bí ikọ̀ IRT ṣe ń gbéjà ko awọn ajinigbe lójú
Kehinde  to n sọrọ lorukọ ọga agba LASEMA, Oluwafẹmi Oke-Osanyintolu sọrọ lori pataki ki awọn ara ilu tẹle awọn ofin to de irinna oju omi.
Omiyalé Àkútè: N50 si N100 làwọn èèyàn fi ń kọjá lórí ẹ̀kún omi l‘Ákútè
Titi di bi a ti ṣe n kọ iroyin yi, a ko tii gburo pe wọn ti ri oku awọn elomiran lẹyin awọn ti LASEMA ti kede saaju.
LASEMA rọ awọn to ba n wa mọlẹbi wọn ti wọn fura si pe o le wa ninu ijamba naa lati kan si ile iṣẹ ọlọpaa eti odo.
Iwadii ṣi n lọ lọwọ gẹgẹ bi ohun ti LASEMA sọ.
Wọn ni àwọn ṣi n ṣe iwadii lori ohun to fa ijamba ọkọ naa.
Afcon 2019: Àwọn olólùfẹ́ Super Eagles fẹ́ kí Rohr tún wọn tò
Mo máa n forin mi kìlọ̀ ìwà ìbàjẹ́ láwùjọ ni -Hameen
BBNaija 2019: Ta làwọn ọmọ Yorùbá tó ń kópa nínú ètò BB Naija
Oríṣun àwòrán, @seyiawolowo
Lori ayelujara orukọ Awolowo tun ti di ohun ti awọn eeyan n jẹ lẹnu.
Amọ kii ṣe nitori Baba Obafemi Awolowo ti gbogbo wa mọ bi ẹni mọ owo, ọmọ ọmọ rẹ kan Seyi Awolowo laye n sọrọ nipa rẹ.
Seyi Awolowo wa lara awọn ọmọ Naijiria to nkopa ninu eto idaraya ilumọọka nii, BB Naija.
Lati igba ti eto naa bẹrẹ ti o si foju han ni awọn eeyan ti n ṣe eemo ohun to mu ki ọmọ ọmọ Awolowo lọ darapọ mọ eto naa.
Ọmọ ọgbọn ọdun ni Seyi Awolowo ti a si gbọ pe o jẹ oluda ile iṣẹ silẹ. Lara ohun ti wọn kọ nipa rẹ loju opo BB Naija, wọn ni o figba kan fẹ gbẹmi ara rẹ.
G-string tàbí Hip-star, èwo lo fẹ́ràn jù?
Kloe: Èmi kìí mu òògùn olóró, àmọ́ mo fẹ́ràn láti máa wà lẹ́bà omi
Nigba ti wọn bere ohun ti yoo fi owo to ba jẹ lori eto naa ṣe, Seyi ni oun yoo da owo naa sidi owo t'oun n ṣe. O fi kun un pe oun yoo ran awọn ile alaini naa lọwọ.
Awọn ọmọ Yoruba miiran wo lo n kopa pẹlu rẹ lori BBNaija?
Ọmọ ipinlẹ Ekiti ni Khafi Kareem ti o si jẹ ọlọpaa nilu Ọba.
Khaffi a ma sọ ede maarun to fi mọ Yoruba ṣugbọn Yoruba rẹ ko dan mọran daadaa.
Oríṣun àwòrán, @KhafiKareem
Fọnran fidio yii ṣe afihan rẹ nibi ti o ti n gbiyanju lati sọ Yoruba lasiko ọdun Keresimesi ni ọdun 2016
Khafi ni oun to le mu ki oun kuro lori eto naa ni ki wọn fi dandan mu oun lati ṣe nkan to niṣe pẹlu ibalopo.
Agbẹjọro ni Esther Agunbiade to wa lati ipinlẹ Eko.
O ni igbadun, owo ati iriri to wa lori eto naa ni oun wa wa to si ni oun fẹran ounjẹ pupọ.
Oríṣun àwòrán, Instagram/ts_esther
Oun ni agbẹjọro akọkọ ti yoo kopa lori eto naa.
Ọmọ ọdun mejilelogun ni Esther ti o si kawe gboye ninu imọ nipa ofin lati fasiti Olabisi Onabanjo.
Ipinlẹ Eko naa ni baale ile yi to jẹ elere idaraya to si tun jẹ olokoowo aladani ti wa.
Mike da ile iṣẹ to n ṣe siga silẹ nilu Ọba ti o si figba kan fẹ ṣoju Naijiria nibi idije Commonwealth lọdun 2018.
Oríṣun àwòrán, @aireyys
Awuyewuye waye nipa iṣẹlẹ yii ṣugbọn Mike ni awọn pada yanju rẹ.
Ogedengbe Agbógun Gbórò, Akọni tó ń dẹ́rù ba ikú...
Oríṣun àwòrán, @Ooduavoice1
Ogedengbe Agbogungboro
Akinkanju Balogun ni Saraibi Ogedengbe to tun jẹ Obanla ilu Ijesha (Oba-Ala Ogedengbe ti Ileṣa Kinni).
Wọn a maa pe e ni alajẹ Ogedengbe Agbogungboro.
Ilu Atorin ni Ilesha, ipinlẹ Oṣun ni Eleduwa ti fi Ogedengbe ta awọn obi rẹ alagba Apasanforijiwa ati iyaafin Falupo lọrẹ.
Ilu yii ko ju iwọn ogun kilomita lọ si Ileṣa tii ṣe ilu iya rẹ.
Oke Oriṣa ni ilu baba rẹ eyi ti ko fi bẹẹ jinna ju bi Atorin naa ṣe ri si Ileṣa lọ ti wọn si jọ wa ni ijọba ibilẹ kan naa, Atakomosa East Local Government Area.
Awokọṣe rere ti oun funra rẹ di itan to si tun gbe aṣa ga lati igba ewe rẹ titi to fi wọ kaa ilẹ ni Ogedengbe.
Ọmọ Ijeṣa ni ere - Ogedengbe gboya ninu ilu rẹ o si ni ifẹ aiṣẹtan fun awọn ara ilu Ijeṣa bi o tilẹ jẹ pe o jẹ ẹnikan ti ko gba igbakugba ti ko si bẹru ẹnikẹni.
Kayefi BBC Yorùba: Bàbá ọmọ, Mọ́ṣúárì, Ọlọ́pàá kẹ́jọ́ rò nípa òkú ọmọ tó pòórá
Igbakuugba ti ogun ba de, ile logun ba a tori gudugudu ni ko figba kan turaa lẹ lati doju ija kọ ẹnikẹni to ba tọja rẹ kii sii kaarẹ afi to ba bori ija naa.
Ẹni ti gbogbo ọkunrin fẹ ba dọrẹ ni bẹẹ si ni bi obinrin ko o lọna, wọn a ni beleyi o jẹ ọkọ ẹni ṣebi a ṣi jẹ ale ẹni.
Ikogosi-Ekiti: Ilu ti omi tutu ti dapọ mọ gbigbona
Awọn oye ti wọn fi da a lọla nigba aye rẹ ko kere rara:
Ohun to wu ni lori ninu itan akinkanju yii ni wi pe ki wọn to bi i ni Ifa ti fọhun pe oun ni yoo jẹ olugbala ilu Ijeṣa.
Wọn bi i bi wọn ṣe n bi gbogbo ọmọ to ku to si dagba gẹgẹ bi ọdọ to ja fafa ninu iṣẹ ṣiṣe.
Mo máa n forin mi kìlọ̀ ìwà ìbàjẹ́ láwùjọ ni -Hameen
Eyi fi han pe o jẹ alagbara ọmọ to si tayọ awọn ẹlẹgbẹ ni gbogbo ọna.
Bi wọn ba jọ wọya ija, afi ko fẹyin wọn janlẹ ni gbogbo igba - eyi lo bi orukọ OGEDENGBE ti wọn fun un tori orukọ abisọ rẹ gan ni Saraibi.
Nigba to dagba, Ogedengbe doju ọpọ ifẹhonu ija han kọ awọn ara Ibadan ti wọn n fiya jẹ awọn ara Ijeṣa.
Lasiko kan ninu ifẹhonu ija han yii ni wọn ra a mu ti wọn si gbe e lọ Ibadan.
Widows Day 2019: Mo máa ń sá kiri wá owó ilé ni -Opó
Kii ṣe ẹni to kọla tẹlẹ, lataari eyi lawọn ara Ibadan bu ila si oju rẹ ki wọn to tu u silẹ.
Ninu ikọ ogun ilu Ibadan, Ogedengbe ja fitafita titi to fi di Ọgagun o si wa pada lati lọ dari ikọ ogun ti ilu Ijeṣa.
Ǹjẹ́ o mọ pàtàkì igi tó wà ní àyíká rẹ bí?
Lẹyin eyi, o ko ọpọlọpọ ọmọ ogun to pọ jọ ti wọn si doju ija kọ ilu Ibadan lọpọlọpọ igba.
"Kii ṣe Ibadan nikan, o tun ba iṣẹ ogun jija rẹ de Ekiti, Akoko nibi to ti ta ọpọ wọn lẹru leyii fi jade ninu oriki rẹ pe ""O ṣọkọ Ekiti ṣọkọ Akoko""."
Ọ̀ṣun Oṣogbo 2018: Ulrich Salazar wálé ọdún láti New York
Koda o tun gbe iṣẹ ogun jija rẹ ipinlẹ ti o n jẹ Edo lonii.
Ṣe ni Ọba ilu Benin ni lati tu u loju pẹlu ọpọlọpọ ilẹkẹ, ẹru, atawọn ohun pataki miiran pe ko ma gbe ogun de ọdọ awọn eeyan oun.
AFCON 2019: Àwọn ọmọ Naijiria sọ̀rọ̀ lórí ìdíje Madagascar àná
Lẹyin eyi lo pada si ilu Igbara Oke lati tẹdo sibẹ. asiko yii kan naa ni awọn ara Ibadan tun dide ogun ti Ogedengbe si gba lati jẹ Balogun Ijeṣa ati Ekiti lati koju ilu Ibadan.
Ija yii le gan an to bẹẹ to to ọdun mẹsan an ko to dawọ duro.
International Day Against Drug Abuse and Trafficking: ìdí ti mo fi ń mu oògùn olóró
Ọgagun Bower to jẹ Kọmiṣọnna Ọlọpaa ilu Ibadan nigba naa lọhun lo pari aawọ ogun yii lọdun 1886.
Gbogbo iwa akinkanju yii lo sọ Ogedengbe di akọni niluu rẹ to si fi di ọkan lara awọn ọkunrin to pataki ju lọ ni ilẹ Yoruba, orilẹ-ede Naijiria ati ilẹ Afirika.
Eyi ri bẹẹ nitori kii ṣe awọn ilu mẹrin taa ti darukọ yii nikan ti Ogedengbe ti jẹ gbajugbaja.
Ijinigbe: BBC ṣe ìwádìí bí ikọ̀ IRT ṣe ń gbéjà ko awọn ajinigbe lójú
Ko da, o kan Ife, Ilorin to fi di wi pe ọta wa pọ to fẹ doju ija kọ ilu Ibadan.
Ogun ti Ekiti-parapọ gan an waye lẹyin ti wọn jagun ṣẹgun ogun Kiriji miran laarin ọdun 1877 - 1892. Ogun nla ni Ogun Kiriji jẹ ninu itan Yoruba.
Lati jẹ ki awọn ilu to parapọ lati jẹ ọwọ ogun kan naa wọ ara wọn daadaa,
COZA: Ọpọ èrò ló jáde ṣe lòdì sí ẹ̀sùn ìfipábánilòpọ̀ Fatoyinbo
Ogedengbe fẹ iyawo kaakiri gbogbo ibi to ti lọ jagun.
Itan sọ pe o le ni iyawo mọkandinlọgọrun ti Ogedengbe fẹ kaakiri ilẹ Yoruba.
Itan Omi Erin
Itan kan tun sọ wi pe lasiko ogun kan, wọn bẹ Ogedengbe lori ṣugbọn o fi agba han iku bẹẹ si ni ara rẹ rin lọ lati gbe ori rẹ pada to si gbe e le ọrun ara rẹ.
Eyi mu ki awọn ọta rẹ tubọ maa wariri fun un tori wọn wo o pe ki wa lo lee pa Ogedengbe bi bibẹ lori ko ba lee ran an lọ salakeji.
Kunle Afolayan: èmi kò fẹ́ fi ogún sílẹ̀ fún ọmọ mi
Ọrọ pọ ninu iwe kọbọ nipa Ogedengbe Agbogungboro, ko si ṣe sọ tan nitori akọni ti ko ṣee gbagbe ni nilẹ kaarọ o jiire ni.
Titi di oni, ami idanimọ to wa niwaju ile Ogedengbe ni ida lati ran ni leti asiko jijẹ akọni ti wọn bẹẹ lori to si tun ye e.
Ẹrin Ijesa, Ọ̀ṣun Oṣogbo, àwọn ibùdó ìgbafẹ́ tí ó níi ṣe pẹ̀lú omi ní ilẹ̀ Yorùbá
Patience Jonathan gbójú kúrò lára owó ẹ - Ilé ẹjọ́ gíga lEko
Oríṣun àwòrán, Google
Patience Jonathan
Ìyàwó ààrẹ orílẹ̀èdè Nàìjíríà tẹ́lẹ̀ rí, Dame Patience Jonathan ti pàdánù $8.4m àti N9.2b sọ́wọ́ ìjọba àpapọ̀ orilẹ̀ede Nàìjíríà.
Eyi waye lẹyin abajade idajọ adajọ agba, Mojisola Olatoregun ni ile ẹjọ giga to wa ni ipinlẹ Eko to si paṣẹ pe ki iyawo aarẹ Patience Jonathan lati gbagbe $8.4m àti N9.2b rẹ tori o ti bọ sọwọ ijọba.
Ijinigbe: BBC ṣe ìwádìí bí ikọ̀ IRT ṣe ń gbéjà ko awọn ajinigbe lójú
Adajọ agba, Mojisola Olatoregun tẹ pẹlẹ mọ ọ pe wọn funra pe owo naa jade latari iwa magomago.
Nitori naa, o gba ẹjọ ti ajọ EFCC pe wi pe ki Patience padanu owo naa pata pata.
Idajọ naa sọ ajọ EFCC di ajawe olubori gẹgẹ bi adajọ ṣe ni arabinrin Jonathan ko ni aridaju lati fi han pe ọna to tọ ni oun fi ri owo naa ati idi ti wọn ko fi ni gba owo naa lọwọ rẹ.
Ile ẹjọ ni gẹgẹ bi ajọ EFCC ṣe sọ ọ, ọns ti Patience gba ri owo naa lodi si abala ofin ikẹtadinlogun to ni ṣe pẹlu jiji owo atawọn ẹsun mii to fara pẹ ẹ.
Ajọ EFCC ti fi aridaju eyi han nipa fifi si oju opo Twitter wọn.
NFF: Ilé ẹjọ́ ní k'ọ́lọ́pàá ó wọ́ Amaju Pinnick wá síwájú òun lórí ẹ̀sùn ìkówójẹ
Oríṣun àwòrán, @thenff
'Kí ni alága NFF, Amaju Pinnick ń wá ní Egypt fún AFCON?'
Amaju Pinnick ni lati foju ba ile ẹjọ lori ọrọ yii.
Ile ẹjọ giga apapọ kan nilu Abuja ti paṣẹ ki awọn agbofinro o fi panpẹ ofin gbe aarẹ ajọ ere bọọlu lorilẹede Naijiria, NFF, Amaju Pinnick atawọn oṣiṣẹ ajọ naa mẹrin miran wa siwaju oun.
Onidajọ Ijeoma Ojukwu paṣẹ naa lẹyin ti Pinnick atawọn mẹrin naa kunna lati farahan niwaju ileẹjọ lati koju ẹsun ṣiṣe owo ajọ NFF baṣubaṣu eleyii ti wọn fi kan wọn.
Rohr, Mikel, Musa ní àwọn ń padà bọ̀ bí Abija
Bi o tilẹ jẹ wi pe agbẹjọro fun Pinnick atawọn ẹmẹwaa rẹ ṣalaye fun ile ẹjọ naa pe aiwa si ile ẹjọ wọn ko ṣẹyin bi wọn ṣe wa lara awọn ikọ ti ijọba apapọ ran lọ si orilẹ-ede Egypt fun idije ife ẹyẹ AFCON to n lọ lọwọ nibẹ.
Amọṣa, agbẹjọro fun ijọba ni irọ funfun balau ni awijare naa nitori oun fidi rẹ mulẹ pe orukọ Amaju Pinnick tabi eyikeyi ninu awọn mẹrin toku ko si lara awọn ikọ ti ijọba apapọ ran lọ.
COZA: Ọpọ èrò ló jáde ṣe lòdì sí ẹ̀sùn ìfipábánilòpọ̀ Fatoyinbo
Adajọ Ojukwu ni ko si ohun to kan Pinnick ati awọn mẹrin naa ni Egypt nitori awọn kọ ni agbabọọlu ti yoo pa itu nibẹ awọn si kọ ni awọn oṣiṣẹ ikọ naa ti yoo kọ wọn ni are bọọlu gbigba.
Yatọ si aarẹ NFF, Amaju Pinnick, awọn mẹrin ti wọn tun n jẹjọ niwaju ile ẹjọ naa ni igbakeji aarẹ akọkọ Ṣeyi Akinwunmi, igbakeji aarẹ keji Shehu Dikko, Sanusi Mohammed to jẹ akọwe agba ajọ naa pẹlu Yusuff Fresh to jẹ ọkan lara awọn ọmọ igbimọ alakoso ajọ naa.
Afcon 2019: Àwọn olólùfẹ́ Super Eagles fẹ́ kí Rohr tún wọn tò
Ijọba apapọ n fi ẹsun kan wọn pe wọn ṣe owo to to miliọnu mẹjọ ati irinwo ẹgbẹrun dọla owo ilẹ Amẹrika to jẹ owo ajọ NFF baṣubaṣu.
Widows Day 2019: Mo máa ń sá kiri wá owó ilé ni -Opó
Osun elections: APC pè fún àdúrà lórí ìdájọ́ kóòtù àgbà tó ń bọ̀ lórí gómìnà l'Ọ́ṣun
Oríṣun àwòrán, @OSUN_APC
Ọjọ́ Ẹtì ni ilé ẹjọ́ tó ga jùlọ lórílẹ̀-èdè Nàìjíríà yóò kéde gómìnà tòótọ́ fún ìpínlẹ̀ Ọ̀ṣun
Ọjọ Ẹti ọsẹ yii ni ile ẹjọ to ga julọ lorilẹ-ede Naijiria yoo gbe idajọ kalẹ lori ẹni gan an ni pato ti awọn eeyan ipinlẹ Ọṣun dibo yan an gẹgẹ bii gomina wọn.
Ni oṣu kẹsan an ọdun 2018 lawọn eeyan ipinlẹ Ọṣun dibo lati yan gomina to wu wọn.
Lati igba naa wa, awọn meji to lewaju ninu esi ibo ọhun- Gboyega Oyetọla ti ẹgbẹ oṣelu APC pẹlu Ademọla Adeleke ti ẹgbẹ oṣelu PDP-ti n wọle jade nile ẹjọ kaakiri pẹlu ẹsun emi ni mo bori-iwọ kọ.
Adeleke bori ni ipele akọkọ ni ile ẹjọ to gbọ awuyewuye idibo l'Ọṣun, Oyetọla lo rẹrin bọ ni ile ẹjọ kotẹmilọrun, ni bayii ọrọ ti wa di ti ile ẹjọ to ga julọ.
Widows Day 2019: Mo máa ń sá kiri wá owó ilé ni -Opó
Eyi lo mu ki alaga ẹgbẹ oṣelu APC ni ipinlẹ Ọṣun, Gboyega Famodun o ke sawọn ọmọ ẹgbẹ oṣelu naa lati wọ inu adura lọ bayii ki nnkan lee ṣe ẹnuure bọ fun wọn lati ile ẹjọ naa.
Mo máa n forin mi kìlọ̀ ìwà ìbàjẹ́ láwùjọ ni -Hameen
Ninu atẹjade kan to fi sita, Ọmọọba Famodun ni 'adura ṣe pataki lati wawọ awọn igbesẹ awọn ẹni ibi lori  lori idajọ naa.'
International Day Against Drug Abuse and Trafficking: ìdí ti mo fi ń mu oògùn olóró
LASEMA Lagos Accident: Ọkọ̀ akóyanrìn tẹ èèyàn kan pa ní Epe
Oríṣun àwòrán, Lasema/Facebook
Ijamba ọkọ kan to waye lagbegbe oju ọna marosẹ Lekki si Epe ti ran eeyan kan lọ sọrun
Gẹgẹ bi atẹjade kan ti ajọ LASEMA fi sita, wọn doola ẹmi eeyan kan bẹẹ ni wọn gbe oku eeyan miran kan jade nibi ijamba naa.
Ijamba ọkọ naa kan ọkọ ayọkẹlẹ Camry kan ti nọmba rẹ jẹ KSF920 FF ti ọkọ akoyanrin tioa kan ti nọmba rẹ jẹ ENU 576 ZZ to ko okuta lọ rọ lu to si tẹ mọlẹ.
Lagbegbe Alasia bus stop ni Marosẹ Lekki si Epẹ; Ajọ LASEMA si jẹ ko di mimọ pe ijanu ọkọ akoyanrin lo sọ iṣẹ silẹ ti fi lọ kọlu ọkọ ayọkẹlẹ naa to si tẹ awakọ rẹ pa.
Mistura Oseni Akintunde: Ara múmú kìí ṣe oríṣun ìfipábánilòpọ̀, ìran àwòjù ló ń fà á
Eeyan meji lo wa ninu ọkọ ayọkẹlẹ naa nigba ti ijamba naa ti waye, eeyan kan ku, eeyan kan yoku si n gba itọju
Oríṣun àwòrán, Lasema/Facebook
Awọn obinrin meji to wa ninu ọkọ igboro ti padanu ẹmi wọn lasiko ti ijamba ọkọ waye ni agbegbe Anthony to wọ Gbagada ni ipinlẹ Eko.
Ọkọ tirela mẹta lo fa ijamba ọkọ naa lẹyin ti wọn kọlu ọkọ igboro to gbe awọn eniyan, eleyii ti  ọmọ kekere kan wa ninu ọkọ naa.
Ajọ oṣiṣẹ pajawiri ni ipinlẹ Eko, LASEMA fi iroyin ijamba ọkọ to waye ni alẹ Ọjọ Iṣẹgun naa lede ni  oju opo ikansiraẹni Facebook wọn.
Ajọ LASEMA ni ọkọ tipper mẹta lo lọ run ọkọ akero igboro mọlẹ pẹlu awọn ẹrọ to wa ninu ọkọ naa.
Oríṣun àwòrán, Lasema/Facebook
Wọn ni awọn doola ẹmi eniyan meje, agbalagba mẹfa ati ọmọde kan, ti wọn si farapa
Amọ,  awọn obinrin agbalagba meji sọ ẹmi wọn nu ninu ijamba ọkọ naa.
Ajọ LASEMA ni awọn ṣiṣẹ lati alẹ Ọjọ Iṣẹgun ti ijamba ọkọ naa ti waye, titi di owurọ ọjọ keji.
Oríṣun àwòrán, Lasema/Facebook
Adari ikọ LASEMA, Olufemi Oke-Osanyintolu lasiko to n ba awọn ẹbi ati ara awọn ti ijamba ọkọ naa kẹdun, parọwa si awọn eniyan lati ṣọra ṣe loju popo.
Ajọ pajawiri ni ipinlẹ Eko, LASEMA naa fikun un pe awọn awakọ loju popo, paapaa tirela gbọdọ ma a wakọ jẹjẹ loju popo, ki wọn si ye sare asapajude.
Baby abandoned on dunmpsite: Mo ti bímọ mẹ́rin tẹ́lẹ̀ fún bàbá méjì nínú òṣí- Dupe Ogbomos
Ọ̀kọ̀ ojú omi dànù, ènìyàn méjì kù, ẹnìkan di àwátì
Ọkọ oju omi to danu ti mu ẹmi eniyan meji lọ ti eniyan kan si ti awati.
Ninu atẹjade ti adari ileeṣẹ Lagos State Waterways Authority (LASWA), Oluwadamilola Emmanuel lo fi iroyin naa lede bẹẹ.
Oríṣun àwòrán, OTHERS
Emmanuel ni ọkọ oju omi naa n lọ lati Makoko pẹlu awọn eniyan mẹje ninu rẹ, awọn marun un jẹ agbalagba nigba ti awọn ọmọde meji wa nibẹ pẹlu awakọ naa.
Ọkọ oju omi naa n lọ si Ikorodu ni ibi ti wọn ti fẹ lọ ṣeto isinku mọlẹbi wọn, ko to di wi pe iṣẹlẹ naa waye to si mu ẹmi eniyan meji lọ.
Ajọ LASWA fi lede wi pe awọn doola ẹmi awọn eniyan mẹrin, amọ awọn ṣi n wa ẹnikan to ku nigba ti iṣẹlẹ ọkọ oju omi naa waye.
Oríṣun àwòrán, OTHERS
Wọn ni ohun to fa iṣẹlẹ naa ni wi pe ọkọ oju omi gbe ju iye eniyan to yẹ lọ, ti iji si bẹ silẹ laarin omi naa.
Bakan naa ni wọn fikun wi pe awọn to wa ninu ọkọ naa pẹlu awakọ oju omi naa ko wọ asọ ti kii muni ri sinu omi( life jacket) lasiko ti wọn fi wa lori omi.
Nibayii, awọn ọlọpaa to n ṣiṣẹ loju omi ati Ajọ oṣiṣẹ pajawiri ni ipinlẹ Eko, Lasema n ṣiṣẹ papọ lọna ati sawari ẹni to sọnu ninu ijamba ọkọ naa.
Bakan naa ni wọn fikun wi pe iwadii ṣi n tẹsiwaju lori iṣẹlẹ naa.
Oríṣun àwòrán, OTHERS
Kọmisọna ọlọpaa nipinlẹ Eko, Hakeem Odumosu ti foju awakọ oju omi Bimbo Elebiju han pe oun lo dẹmi awọn eniyan legbodo.
Wọn ni oun lo fa iku eniyan mejila lasiko to n gbe wọn lọ si ibudo wọn losu to kọja.
Oríṣun àwòrán, LASEMA
Awọn eniyan yii se kongẹ iku nipa bi wọn se ri somi lagbegbe Kirikiri, lẹyin ti ọwọja omi dari ọkọ lọ soju omi to jẹ dagun.
Eyi ni wọn lo waye leyin ti awakọ pa ina ọkọ oju omi nibi to ti n se ariyanjiyan pẹlu awọn ero ọkọ lori iye owo ti yoo gba.
Odumosu, lasiko to gbe Bimbo sita fun  ifọrọwanilẹnuwo ni olu ile isẹ ọlọpaa ipinlẹ Eko to wa ni Ikeja, ni ogun eniyan lo wọkọ oju omi naa lati Kirikiri.
Oríṣun àwòrán, @lasemasocial
ni nnkan bi aago mẹsan abọ alẹ ọjọ Abamẹta ni ọkọ naa yọnu ti o si da ero inu rẹ sodo
O ni wọn n lọ si Badagry, sugbọn bi wọn ṣe n lọ, ọkan ninu awọn ero ọkọ tako iye ti awakọ pe owo ọkọ.
Odumosu ni awakọ ni ẹgbẹrun kan aabọ naira ni oun yoo gba, nigba ti ero ọkọ yari si ẹgbẹfa naira, eyi si lo mu ki awakọ pana ọkọ lagbegbe lori omi nitori iyatọ ọọdunrun naira.
Bakan naa lo fi kun pe, nigba ti Bimbo ri pe atẹgun ti gba ọkọ lọwọ oun, lo ba bẹ sinu omi, to si fi gbogbo awọn ero kalẹ, ti wọn si ri somi.
Odumosu ni awọn ero ọkọ mejila ri somi, nigba ti wọn ri awọn marun yọ, awọn ti ori ko yọ yii lo salaye nnkan to ṣẹlẹ si wọn, ati nnkan ti Bimbo se.
Oríṣun àwòrán, LASEMA
Ọga ọlọpaa ni, awọn tọpasẹ awakọ naa ni awọn fi ri mu, sugbọn awọn yoo gbe lọ si ile ẹjọ laipẹ.
Odumosu ni iṣẹlẹ naa waye ni ọjọ kọkandinlọgbọn, osu keje ọdun yii.
"Ni nkan bi aago mẹfa ku iṣẹju mẹẹdogun ni awọn ọlọpaa to n bojuto oju omi gba ipe ijaya pe ọkọ oju omi akero Mount Zion transport ti n ri somi oo, to si gbe ogun ero lati Badagry.
Titi di asiko yii, eniyan marun ni wọn ri yọ laaye, eniyan mejila ku nigba ti ko si ẹni to ri awọn eniyan mẹta to ku.
Oríṣun àwòrán, @lasemasocial
Ajọ oṣiṣẹ pajawiri ni ipinlẹ Eko, LASEMA ti fi lede pe eniyan meje lo sọ ẹmi wọn nu lẹyin ti ọkọ oju omi danu ni opin ọsẹ.
Oludari Ajọ LASEMA ni ipinlẹ Eko, Olufemi Oke-Osanyintolu ninu atẹjade to fi sita ni, ijamba ọkọ oju omi naa waye nitori wọn rin lasiko ti okunkun ti ṣu, eleyii to tako ofin irinna ọkọ loju omi.
Bakan naa lo fikun pe, lara awọn eniyan naa ko wọ aṣọ idaabobo loju omi (life jacket) eleyii to ni o ṣe akoba fun wọn.
Oke-Osanyintolu ni eniyan mẹtalelogun lo wa ninu ọkọ oju omi naa, ko to yi danu.
O ni eeyan mẹrindinlogun ni awọn ri yọ kuro ninu omi, nigba ti awọn meje to jẹ kiki obinrin padanu ẹmi wọn.
Oludari Ajo LASEMA naa wa parọwa si awọn eniyan lati ri pe wọn tẹle ofin irinna ọkọ oju omi ati lilo aṣọ idaabobo, nigba kugba ti wọn ba wa loju omi.
Ẹwẹ, o kere tan eniyan mọkanlelogun ni wọn si n wa lẹyin ijamba ọkọ oju omi ni ipinlẹ Benue.
Ileeṣẹ ọlọpaa ni awọn mẹtalelogun ni wọn wa ninu ọkọ oju omi naa, ti wọn si ti doola ẹmi awọn meji ninu wọn.
Mama Arsenal: Màmá àgbà yìí máa ń lọ sí ìbùdó tí wọ́n ti ń wo bọ́ọ́lù láti wòran
Awọn ti iṣẹlẹ naa soju wọn ni ohun to sokunfa ijamba ọkọ oju omi naa ni pe awọn  eniyan to wa ninu ọkọ oju omi naa pọ ju bo ṣe yẹ lọ.
Wọn fikun wi pe awọn to wa ninu ọkọ naa n lọ si ipagọ awọn ẹlẹsin Kristẹni, ki iṣẹlẹ naa to waye
Mo máa n forin mi kìlọ̀ ìwà ìbàjẹ́ láwùjọ ni -Hameen
Oku eeyan mẹjọ ni wọn ti yọ jade ninu omi bayii nibi ijamba ọkọ oju omi kan to waye ni ọjọ Satide.
Eeyan mọkanlelogun lo wa ninu ọkọ naa lasiko to fi ri sinu agbami 'Èèyàn mi mẹ́ta ló wà nínú ọkọ̀ ojú omi tó dà nù l'Eko!'.
Ilu Ikorodu ni ọkọ naa morile lati agbegbe Ajah lasiko ti ijamba naa fi ṣẹlẹ.
Gẹgẹ bii atẹjade kan ti Ọga agba ajọ to n moju to iṣẹlẹ pajawiri nipinlẹ Eko LASEMA, Ọmọwe Oluwafẹmi Oke-Ọsanyintolu fi sita, o ni oku eeyan mẹjọ ni wọn ti fa jade ninu agbami bayii.
Meje ninu awọn ti wọn ti fi idi iku wọn mulẹ naa lo jẹ Ọkunrin ti ọkan si jẹ obinrin.
Widows Day 2019: Mo máa ń sá kiri wá owó ilé ni -Opó
Bakan naa lo ṣalaye pe ni kete ti ijamba naa ti waye ni wọn ti doola ẹmi awọn mẹta ninu awọn ero ti ọkọ naa da somi.
Ọga agba ajọ LASEMA naa ṣalaye pe eto wiwa awọn to ku ninu agbami ṣi n tẹ siwaju.
O ni ajọṣepọ laarin LASEMA, ileeṣẹ irinna oju omi nipinlẹ Eko, ẹka ileeṣẹ ọlọpaa ori omi, ileeṣẹ ọlọpaa oriilẹ, ileeṣẹ panapana pẹlu awọn omuwẹ lagbegbe naa ni iṣẹ awari awọn eeyan to da somi naa jẹ.
Iroyin ti ileeṣẹ wa gbọ tun fi kun un pe yatọ si eeyan mẹjọ ti awọn oṣiṣẹ adoola ẹmi gbe oku wọn jade yii, oku eeyan meje ni wọn ti kọkọ yọ jade ni alẹ ọjọ Satide ti iṣẹlẹ naa ṣẹlẹ.
NHIS: Lẹyin ọpọlọpọ àbájáde ìwádìí, Buhari ni ki ọjọgbọn Yusuf máa lọ
Oríṣun àwòrán, others
Ta ni Mohammad Sambo, olùdarí NHIS tuntun?
Ọjọgbọn Mohammed Sambo di alaga ajọ NHIS tuntun.
Oun ni wọn yan dipo Ọjọgbọn Usman Yusuf ti aarẹ Mohammadu Buhari yọ kuro nipo naa nitori iwa ajẹbanu.
Ajọ to n mojuto ọrọ adojutofo ninu eto ilera awọn eniyan Naijiria ni àwọn ẹsun pupọ jade nibẹ nipa ṣiṣe owo ilu mọkumọku.
Bakan naa ni aarẹ Buhari ti gba pé ki wọn tu ile awọn ọmọ igbimọ adari ajọ adojutofo NHIS ka.
Kunle Afolayan: èmi kò fẹ́ fi ogún sílẹ̀ fún ọmọ mi
Arabinrin Boade Akinola to jẹ oludari eto ifitonileti fun ileeṣẹ ijọba apapọ to n mojuto eto ilera ni Abuja lo fidi ọrọ yii mulẹ.
O ni lẹyin abajade gbogbo iwadii ti awọn igbimọ ti Buhari yan lati ṣe iwadii ẹsun ikowojẹ naa ni Aarẹ gbe igbesẹ yii.
Widows Day 2019: Mo máa ń sá kiri wá owó ilé ni -Opó
Ninu oṣu kejila, ọdun 2018 ni awọn igbimọ oluwadii yii ti gba aarẹ Buhari nimọran pe ko da ọjọgbọn Yusuf duro lẹnu iṣẹ rẹ.
Mo máa n forin mi kìlọ̀ ìwà ìbàjẹ́ láwùjọ ni -Hameen
Aarẹ Buhari ni ki ọjọgbọn Sambo maa ba iṣẹ lọ titi ti wọn yoo fi yan igbimọ miran fun ajọ adojutofo ilera NHIS.
Ọdun 2016 ni ọjọgbọn Yusuf bẹrẹ iṣẹ adari ajọ NHIS.
Ninu ọrọ tirẹ lo ti fi ẹsun kan awọn ileeṣẹ to n ṣakoso lilọ ile iwosan awọn eeyan (HMO) pe awọn ni wọn n ṣe owo awọn eniyan niṣekuṣe.
Ruga Settlement: Kí ló ń mú ìkùnsínú wá ?
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ko fẹ si ibi ti eeyan yoo kọju si lorileede Naijiria, ti ko ti ni ma gbọ ọrọ nipa Ruga settlement.
Ọrọ naa bi awọn ọrọ miran to nii ṣe pẹlu igbe aye awọn eeyan orile-ede yii, ti n mu ariwisi ọtọọtọ wa lati igba ati ijọba ti kede pe awọn fẹ ya aaye sọtọ fun un.
Bi awọn eeyan kan ṣe n tapa si agbekalẹ aagọ Fulani taa mọ si Ruga Settlement naa, lawọn miran n kan sara si ijọba lori igbesẹ naa.
Bo tilẹ jẹ pe ileesẹ BBC Yoruba ko gbe lẹyin ẹnikẹni, a lero pe o yẹ ki a ṣe alaye lori ohun ti Ruga tumọ si ati bi awọn eeyan ti ṣe n tumọ rẹ.
Ruga ati Fulani, nibo ni wọn ti papọ?
Ẹya Fulani lo pọ ninu awọn darandaran lorile-ede Naijiria.
Ọrọ Ruga ti ijọba si fi sọri aagọ to fẹ da silẹ fawọn darandaran yii, jẹ ọrọ kan ninu ede Fulani, eyi to tumọ si aaye tabi ibudo fawọn darandaran.
Oríṣun àwòrán, @ovieali
Ibudo darndaran ni ona abayo Buhari
Gẹgẹ bi ohun ti akọroyin BBC, to se iwadi iroyin yii ti ṣe salaye, awọn darandaran maa n tẹdo si ibi ti wọn ba ti ri omi ati ounjẹ fawọn nnkan ọsin wọn.
Lọpọ igba, wọn ni wọn a maa kọ ile alamọ sibẹ, ti ijọba a si maa mu awọn ohun amayederun miran ba wọn nibẹ, bii ile iwe ati ile iwosan.
Ruga ko tumọ si ki eeyan jẹ gaba lori ẹlomiran. Itumọ yii si ni ọpọ fi n wo ohun ti Ruga tumọ si.
Ki nijọba n gbero pẹlu Ruga ti wọn fẹ da silẹ:
Aawọ laarin darandaran ati agbẹ ni ijọba lawọn fẹ dẹkun pẹlu idasilẹ aagọ fawọn to n da ẹran.
Ni Naijiria, awọn darandaran ati agbẹ a maa saaba kọlu ara wọn, ti eyi a si ma mu ọpọ ẹmi lọ.
Oríṣun àwòrán, @ovieali
Aworan darandaran
Femi Adeshina, to jẹ oludamọran agba fun aarẹ feto iroyin nigba to n ṣalaye fun BBC sọ pe, ọna ati dẹkun wahala laarin agbẹ ati darandaran lawọn ṣe gbe igbimọ kalẹ lori ọrọ yii.
CAN: Samson ni ọrọ awọn ajinigbe ti gba àpérò ní Naijiria
O ni awọn Gomina fọwọ si idasilẹ aagọ ifẹranjẹ lawọn ipinlẹ (Ranching) ṣugbọn nigba ti ikede Ruga jade ọpọ awọn Gomina tapa si.
Idi ti awọn kan ninu wọn fi siwaju ni pe Ruga fẹ gba ilẹ awọn eeyan wọn ni.
Ilẹ gbigba,Orukọ ti wọn sọ ati ọrọ Aje lo wa nidi aawọ naa
Loju opo Twitter ati lawọn aaye miran, awọn eeyan n tapa si Ruga nitori awọn idi lorisirisi.
Amọ ṣa, lẹyin ti a ṣe agbeyẹwo ohun ti wọn n sọ, a rii pe awọn idi ti a ka silẹ wọn yii lo n mu ikunsinu wa:
Awọn nkan ti a ka silẹ wọnyii wa lara awọn nnkan ti o n jẹ  ki ọrọ Ruga yii ma fa awuyewuye.
A nilo agọ ọlọpa ni Orin Ekiti fún aabo wa -Falua
Nkan daadaa ti ijọba ni Ruga yoo mu wa:
Garba Sheu to jẹ agbẹnusọ fun ijọba salaye fun awọn akọroyin pe, Ruga jẹ ọna kan lati mu idagbasoke ba agbegbe ti wọn ba daa silẹ si.
O ni ijọba yoo pese gbogbo awọn ohun eelo amayedẹrun ti yoo jẹ ki sinsin ati tita ẹran gbooro si.
Ruga settlement: YCE ní ìjọba àpapọ̀ ko tó bẹ̀ẹ́ láti kọ́ àgọ́ Fulani sílẹ̀ Yoruba
Ninu alaye rẹ to ṣe, Garba ni awọn oludokowo lati ile ati lẹyin odi, yoo laanfaani lati ṣowo ẹran ati awọn nnkan miran to maa n ti ati ara rẹ jade bi awọ.
Gbogbo ohun to ka silẹ yii dara ṣugbọn aini igbagbọ ninu ijọba lo jẹ pato idi to dakun wahala to wa nilẹ yii, to fi jẹ ki awọn eeyan mase ri dada kankan ninu igbesẹ yii.
Ṣe Ruga le dẹkun wahala laarin agbẹ ati darandaran?
Ibeere yii ni ibeere to jẹ awọn onwoye logun lẹnu igba ti awuyewuye Ruga yii ti bẹrẹ.
Oríṣun àwòrán, @Mr Saleem
Ninu nnkan ti pupọ ninu wọn sọ, wọn ni aawọ darandaran ati agbẹ kọja ọrọ mo fẹ dako, iwọ fẹ daran, bi kii ṣe pe ẹlẹyamẹya ti wọ.
Wọn ni, ni awọn ipinlẹ ti wahala yii ti peleke, dida Ruga silẹ lee dẹkun rẹ ṣugbọn ko si ẹni to lee fi ọwọ sọya pe ko ni da wahala silẹ.
Wọn ni ijọba ni lati jẹ ki awọn ara ilu ri wi pe ko si erongba kankan to yatọ si mimu idagbasoke ba awọn eeyan pẹlu igbesẹ  dida Ruga settlement silẹ.
Benue Fire: Ọkọ̀ akérò 18 àtàwọn tó ń gbọ́n epo ló forí ṣọta ìjàmbá iná
Oríṣun àwòrán, @crimefightersng
Bi eeyan ba jẹ ori ahun, yoo  bu sẹkun lọjọ Aje nigba ti tanka epo kan gbina, ti ẹmi toto ogoji si baa rin, tawọn eeyan miran ti wọn to ọgọta si farapa.
Awọn eeyan ti isẹlẹ naa soju wọn sọ fun BBC pe ọkọ epo to gbina naa, lo gbokiti lasiko to n gbinyanju lati pẹ koto kan silẹ loju popo to wọ ilu Markudi, tii se olu ilu ipinlẹ Benue.
Sugbọn gẹgẹ bii ise awọn eeyan to n wa ifa, lainaani ikilọ tawọn ọlọpa to wa nibi isẹlẹ naa n se fun wọn, wọn ti ọwọ ifa bọnu, pẹlu bi wọn se n gbọn epo pẹtiroolu to da silẹ latinu tanka naa, amọ ofo nla lo wọle tọ wọn nigba ti ọkọ epo naa sadede gba ina, eyi to mu ẹmi ọpọ wọn lọ.
Koda, ọrọ naa kanlẹ, o kan baale, to si tun kan jẹjẹ ni mo joko mi, nitori ọkọ bọọsi agbero kan to ko ero mejidinlogun, to fi aake kọri pe oun yoo tiraka gba ibi ti epo naa ti n da silẹ kọja, ni ina mu mọlẹ, to si pa gbogbo ero to wa ninu rẹ.
Ọkan lara awọn tisẹlẹ naa soju wọn, to ba BBC sọrọ ni Nkan kan lo mu ki ọkọ epo naa bu gbamu fun ina, to si pa gbogbo ero to wa ninu ọkọ bọọsi kan atawọn eeyan to n gbọ epo, koda awọn ile ati sọọbu to wa nitori ibiti isẹlẹ naa ti waye, lo jona raurau."
Kunle Afolayan: èmi kò fẹ́ fi ogún sílẹ̀ fún ọmọ mi
A tun gbọ pe awọn osisẹ panapana meji lo farapa ninu ijamba ina naa, lasiko ti wọn n tiraka lati pa ina ọhun, ti wọn si ti gbe wọn lọ sile iwosan.
Bayelsa Attack: Ọ̀gá ọlápàá fọnmú pé kí wọn ṣàwárí àwọn ọ̀daràn tó pa ọlọ́pàá
Oríṣun àwòrán, @newsbookng
Gọngọ sọ ni aarọ oni nigba ti awọn gende agbebọn kan ya bo agọ ọlọpa to wa ladugbo Ekpetiama to wa ni ilu Yenegoa, tii se olu ilu Bayelsa, ti wọn si gba ẹmi ọga ọlọpa DPO to wa nibẹ, Ọla Rosanla ati awọn ọlọpa mẹta miran, tawọn meji mii si farapa.
Nigba to n sọrọ lori isẹlẹ naa, ọga agba ọlọpa ilẹ wa, M.A Adamu kede pe ileesẹ ọlọpa ti n finmu finlẹ lori isẹlẹ naa lati se awari awọn ọbayejẹ ẹda to sisẹ laabi naa, ti wọn yoo si fi imu wọn ko ata ofin.
Bakan naa ni ọga agba ọlọpa pasẹ kia mọsa fawọn ọlọpa ọtẹlẹmuyẹ, atawọn akọsẹmọsẹ oluwadi iwa ọdaran pe lẹyẹosọka pe ki wọn sugba ileesẹ ọlọpa to wa ni ilu Yenegoa lati mu ki iwadi wọn ya kankan, ki akara awọn olubi ẹda naa lee su sepo kiakia.
Oríṣun àwòrán, @PoliceNG
Adamu wa kẹdun pẹlu awọn mọlẹbi awọn agbofinro to jalaisi lọsan gangan ọhun, to si bu ọwọ nla fun wọn.
O tun rọ awọn olugbe adugbo Ekpetiama atawọn eeyan ipinlẹ Bayelsa lapapọ lati se suuru, ki wọn si fun awọn ọlọpa ni iroyin to ba yẹ, eyi ti yoo se iranwọ fun awọn ọlọpaa ninu iwadi wọn lati tete sawari awọn ọdaran naa.
Kunle Afolayan: èmi kò fẹ́ fi ogún sílẹ̀ fún ọmọ mi
Seyi Makinde: Èmi kò yẹsẹ̀ kúrò nínú àdéhùn àjùmọ̀ṣe láti pín ipò
Oríṣun àwòrán, Seyi Makinde
Ijọba ipinlẹ Ọyọ ti sẹ lori ẹsun kan ti oludije fun ipo gomina to kọja, ninu ẹgbẹ oselu ADC, Sẹnetọ Olufẹmi Lanlẹyin, fi kan gomina ipinlẹ Ọyọ, Onimọ ẹrọ Seyi Makinde pe, o n se aisododo lori adehun ti wọn fi ẹnu ko le lori nipa agbekalẹ ijọba alajumọse.
Olugbaninimọran fun gomina Seyi Makinde lori aato ati eto oselu, Asofin Babatunde Oduyọye lo kede eyi ninu atẹjade kan to fi sita, eyi to fi n fesi lori igbesẹ Lanlẹyin to ni oun yọwọ-yọsẹ kuro ninu adehun agbekalẹ ijọba alajumọse ti wọn fẹnu ko le lori saaju idibo gomina to kọja.
Nigba to n kede ipinnu rẹ naa ni owurọ ọjọ Isẹgun, Lanlẹyin salaye pe, oun gbe igbesẹ naa nitori pe o ti n foju han bayi pe gomina Makinde ti n yẹsẹ lori iwe adehun ti wọn fẹnu ko le lori.
Lanlẹyin tun fikun pe, oun gẹgẹ bii ẹnikan ko ni nkan se pẹlu adehun ajumọse naa mọ, to ba si wu ẹgbẹ oselu oun, tii se ẹgbẹ ADC, o lee tẹsiwaju pẹlu adehun naa.
Nigba to n fesi, Oduyọye ni irọ to jinna sootọ ni ọrọ ti Lanlẹyin sọ yii, koda, o ni afomọ ni ọrọ naa, ko lẹsẹ nlẹ, ti ko si ba ohun to n waye lọwọlọwọ bayii mu, nitori Makinde ti sa ipa rẹ lati ko gbogbo ẹgbẹ oselu ti wọn jọ se adehun ajumọse mọra.
Oríṣun àwòrán, Seyi Makinde
Atẹjade naa fikun pe, wọn ti gbe ilana bi wọn yoo se pin ipo kalẹ lori adehun ajumọse naa, ti eto si ti de oju ọgbagade lati ri daju pe wọn se amusẹ adehun naa, ti gbogbo ẹgbẹ oselu to kan si ti fọwọsi ilana naa.
Kunle Afolayan: èmi kò fẹ́ fi ogún sílẹ̀ fún ọmọ mi
Oduyọye wa kesi Sẹnetọ Lanlẹyin pe, ko mase wọ orukọ gomina Seyi Makinde sinu ijakulẹ to n koju ninu ẹgbẹ oselu ADC, nitori adehun ajumọse naa ko wa fun ifẹ ẹnikẹni, bikose fun ifẹ awọn olugbe ipinlẹ Ọyọ.
Daura Ruler: Ọlọ́pàá ti gba àna ẹ̀ṣọ́ ẹ̀yin Buhari silẹ̀ lọ́wọ́ ajínigbé
Oríṣun àwòrán, IRT
Musa Umar pẹ̀lú àwọn ọlọ́pàá lẹyin ti ọlọpaa gba silẹ
Awọn ajinigbe ti da ana ẹsọ ẹyin Aarẹ Muhammadu silẹ lẹyin oṣu meji ati aabọ ti wọn gbe.
Wọn ji Musa Umar, to jẹ Magajin Garin abule Daura ni Ipinlẹ Katsina gbe ni oṣu Kẹrin ọdun 2019.
Ikọ ọlọpaa taa mọ si 'Operation Puff Adder' ati ikọ IRT ti Abba Kyari n dari rẹ, lo parapọ pẹlu awọn ọlọpaa to wa ni Ipinlẹ Kano lati gba baba naa silẹ ni Gangan Ruwa, ni ijọba ibilẹ Kumbotso ni Ipinlẹ Kano lọjọ Aje.
Oríṣun àwòrán, IRT
Musa Umar lẹyin ti awọn ọlọpaa gba silẹ
Awọn alaṣe ni wọn gba Magajin Garin naa silẹ, wọn tun mu awọn afurasi kan pẹlu ibọn.
Oríṣun àwòrán, IRT
Musa Umar lẹyin ti awọn ọlọpaa gba silẹ
Elisha Abbo: Àwọn alátakò mi nínú òsèlú ló gbé fídíò mi síta
Oríṣun àwòrán, Elisha Abbo
Sẹnetọ kan to n soju ẹkun idibo ariwa Adamawa, Elisha Abbo ti di olokiki latari bi fidio kan ṣe ṣe afihan bo ṣe lu arabinrin abiyamọ kan bolẹ ninu ṣọọbu kan, ti wọn ti n ta awọn nkan ibalopọ, Banex Plaza ni Abuja.
Nigba ti BBC kan si ṣẹnetọ naa, o ni iṣẹlẹ naa ti waye lati ọjọ Kọkanla oṣu Kẹta ọdun 2019 bo tilẹ jẹ wipe awọn iroyin to n sọrọ nipa isẹlẹ naa ni ọjọ Kọkanla oṣu Karun un ọdun 2019 lo waye.
Abbo ni awọn to wa ninu ṣọọbu naa kọkọ lu aburo oun bolẹ, ti wọn si gba ẹjẹ lẹnu rẹ ni oun ṣe lu awọn naa bolẹ.
'Àjẹ́, eégún, kí ni wọn ò pè mí tán tórí Vitiligo lára mi'
Ṣugbọn ohun ti fidio naa ṣe afihan rẹ yatọ si ohun to sọ.
Ọrọ to sọ ninu fidio naa fihan wipe, ohun ti abiyamọ to lu naa sọ ni wipe, ko fi ara balẹ nigba to n pariwo, ni inu ba bi.
Abbo ni awọn ọta oun ninu oṣelu lo faa, ti fidio naa fi jade ni akoko yii lẹyin to ti pẹ ti iṣẹlẹ naa ti waye sẹyin.
A nilo agọ ọlọpa ni Orin Ekiti fún aabo wa -Falua
O tun ni oun ko lọ lati lọ ra nkan ibalopọ ninu ṣọọbu naa. O ni ṣokoto ati aṣọ ni oun fẹ lọ ra, ki aburo oun obinrin to tẹle oun to mu oun lọ inu ṣọọbu ti wọn ti n ta ohun ibalopọ.
Ajọ Amnesty International ti da si ọrọ naa, wọn ni ileeṣẹ ọlọpaa gbọdọ wadi Abbo ni kiakia. Wọn ṣalaye wipe, idajọ gbọdọ ṣẹlẹ lori ọrọ naa.
Kayefi BBC Yorùba: Bàbá ọmọ, Mọ́ṣúárì, Ọlọ́pàá kẹ́jọ́ rò nípa òkú ọmọ tó pòórá
RUGA: Ààrẹ àná, Goodluck Jonathan ní kí Buhari máà fi ọ̀rọ̀ RUGA kọ́ òun lọ́rùn
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Gomina Lalong tipinlẹ̀ Plateau lo ṣalaye fawọn oniroyin pe lasiko iṣejọba Jonathan ni ọrọ itẹdo darandaran, RUGA ti kọkọ bẹrẹ
Emi ko mọ nipa Ruga o - Goodluck Jonathan
Aarẹ ana, Goodluck Jonathan ti kọminu lori ọrọ kan ti gomina ipinlẹ Plateau sọ pe lasiko iṣejọba Jonathan ni wọn ti ṣeto itẹdo darandaran RUGA silẹ kaakiri orilẹ-ede Naijiria.
Jonathan ṣalaye pe iṣejọba oun ko figba kankan ṣe ohun to jọ bẹẹ ati pe eto ẹyawo da ibujẹko maaluu silẹ RANCHES ni oun gba lero.
CAN: Samson ni ọrọ awọn ajinigbe ti gba àpérò ní Naijiria
Eyi si yatọ patapata si agbekalẹ gaa Fulani ti Ruga ti ijọba Buhari n gbero yii.
Ninu atẹjade kan eyi ti ọkan ninu awọn agbẹnusọ rẹ, Reno Omokri, fi sita, Aarẹ Goodluck Jonathan ni ko si igba kan ti iṣejọba oun ya biliọnu mẹwaa naira (N10 billion) sọtọ fun idasilẹ itẹdo darandaran RUGA.
'Nígbà tí mò ń wà Awolowo, Gowon, Babangida, mo fi ara mi sípo ọ̀wọ̀ tóri ...'
Jonathan ni o to asiko ki aarẹ Buhari atawọn ẹmẹwaa rẹ yee da ẹbi awọn ijakulẹ wọn ru elomiran ki wọn si mojuto ipenija gbogbo 'ti wọn fi ọwọ ara wọn fa'
Oríṣun àwòrán, Getty Images
ẹ mojuto ipenija ijọba yin
"Itẹdo darandaran RUGA ti ijọba n gbero rẹ bayii kii ṣe atọwọda iṣejọba Jonathan.
A ko gbe iṣuna kalẹ fun un, a ko si ni ohunkohun un ṣe pẹlu rẹ.
Yomi Fabiyi ló ni ki òun àti ìyàwó rẹ̀ yàgò fún ra wọn
Ohun ti ijọba Jonathan ṣe ni lila eto owooya sọgbin ọlọgọrun un bilọnu naira (N100billion) kalẹ fun banki apapọ."
Mo máa n forin mi kìlọ̀ ìwà ìbàjẹ́ láwùjọ ni -Hameen
"A ṣee lati ya awọn ipinlẹ lẹkun oke ọya Naijiria ti wọn nifẹ ati kọ oko ijẹko maluu fun pipese ẹran maluu lọna igbalode eyi ti wọn yoo maa gbe ninu rẹ dipo dida ẹran maluu kaakiri."""
Widows Day 2019: Mo máa ń sá kiri wá owó ilé ni -Opó
Jonathan ni RUGA ti ijọba Buhari gbe kalẹ kii ṣe ẹyawo bikoṣe eto ijọba lati na owo ilu lati fi gbe okoowo aladani larugẹ pẹlu gbigba ilẹ ilu fun awọn okoowo adani bẹẹ.
Jonathan gba ijọba Buhari ni imọran lati tẹti si ohun ti awọn ara ilu n fẹ.
A nilo agọ ọlọpa ni Orin Ekiti fún aabo wa -Falua
Senator Elisha Abbo: Ilé aṣòfin àgbà gbé ìgbìmọ̀ kalẹ̀ lórí Sẹ́nétọ̀ tó lu obìnrin l'Abuja
Oríṣun àwòrán, SenateNGR
Ileegbimọ aṣofin agba lorilẹede Naijiria ti kede pe oun yoo ṣe iwadii ẹsun lilu ọmọbinrin kan nile itaja nilu Abuja eyi ti wọn fi kan Sẹnetọ Elisha Abboni alẹ ọjs iṣẹgun ọjọ keji oṣu keje ọdun 2019.
"Nibi ijoko ile naa to waye ni owurọ Ọjọru ni awọn aṣofin naa ti fẹnuko lati wadi ọrọ ọhun nigba ti Sẹnetọ Uba Sani mu wa si etigbọ ile naa lati tete wa nnkan ṣe sii nitori 'iṣẹlẹ naa ti ta ẹrẹ ba aṣọ ala ọpọ awọn  aṣofin agba."""
Bakan naa ni Sẹnetọ Ọpẹyẹmi Bamidele toun naa da si ijiroro ọhun ni iwa ti Sẹnetọ Abbo hu tapa si abala iwe ofin orilẹede Naijiria.
Amọṣa, olori smọ ẹgbẹ to kere julọ nile naa, Ehinaya Abaribe pẹlu olori ẹgbẹ to pọ julọ nibẹ, Abdullahi Yahaya ko awọn akẹgbẹ wọn ni ijanu lati maṣe da ẹjs lai kọkọ jẹ wi pe wọn tan ina si idi ọrọ naa.
Wọn wa pe fun agbekalẹ igbimọ kan ti yoo wadi ohun gbogbo to rọ ms iṣẹlẹ ọhun.
Kunle Afolayan: èmi kò fẹ́ fi ogún sílẹ̀ fún ọmọ mi
Ninu ọrọ tirẹ, aarẹ ile aṣofin agba, Ahmed Lawan ṣalaye pe ẹsun ṣi ni ohun gbogbo yoowu ti awọn eeyan ba ri tabi gbọ lori ọrọ naa titi di igba ti ile ba ṣe iwadii ti wọn si fun igun gbogbo ti ọrọ kan ni anfani lati wi tẹnu wọn lori iṣẹlẹ naa.
Sẹnetọ Lawan wa kede igbimọ ti yoo wadii iṣẹlẹ naa labẹ Sẹnetọ Sam Egwu gẹgẹ bii alaga ti Olurẹmi Tinubu, Mathew Rugide, Stellah Uduah, Dauda Haliru Jika, Danladi Sankara ati Mohammed Sani Musa yoo si jẹ ọmọ igbimọ naa.
A nilo agọ ọlọpa ni Orin Ekiti fún aabo wa -Falua
Oríṣun àwòrán, Don Jazzy
Don Jazzy, MrP, Kate Henshaw àtàwọn èèkàn ìlú míràn sọ̀rọ̀ lórí Sẹ́nétọ̀ tó lu obìnrin l'Abuja
Iwa ipá ninu idile ati lawujọ nilo amojuto lasiko yii.
Awọn wọọ kilu mọ lagbo afẹ lorilẹ-ede Naijiria ti n pe fun fifi ofin gbe sẹnetọ to n ṣoju ẹkun Adamawa North nile aṣofin agba Naijiria naa.
Wọn ni eyi yẹ lori fidio kan to jade ninu eyi ti o ṣafihan sẹnetọ naa to n lu obinrin kan nilu Abuja.
Fidio naa to jade sori ayelujara lọjọ Iṣẹgun fi sẹnetọ Elisha Abbo han nigba to ku giiri si obinrin to ni ṣọọbu itaja eroja adun ibalopọ nilu Abuja to si luu bi ẹni lu bara.
Bi o tilẹ jẹ wi pe Sẹnetọ Abbo sọ pe arabinrin naa yọ ṣuuti ete si oun loun fi luu, awọn eekan bii Don Jazzy atawọn miran ti gba ori oju opo ayelujara lọ lati bu ẹnu ẹ̀tẹ́ lu iwa ti Sẹnetọ naa hu.
Don Jazzy ke si igbakeji aarẹ Osinbajo lati rii pe Sẹnetọ naa ko ṣai jiya iwa to hu yii.
Ṣọla Allyson: Obìnrin tí kò bá rẹwà ni yóò máa ṣí ara sílẹ̀
Ni tirẹ, Peter Okoye, MrP ti PSquare tẹlẹ ni 'awọn eeyan bii Elisha Abbo ko tọ lati di ipo ilu mu rara' .
O ni afi ki wọn tete fi panpẹ ofin gbe aṣofin naa ni.
Gbajugbaja osere sinima, Kate Henshaw ati onkọrin takasufe, Banky W naa bu ẹnu ẹ̀tẹ́ lu aṣofin naa eleyi to ṣakawe gẹgẹ bii ojuti nla.
'Ìlù Bàtá ló yàn mi, èmi kọ́ ni mo yàn an'
Ariwo ẹhonu lori iwa iṣẹlẹ naa ko mọ lori awọn nnkan ẹka amuludun nikan.
Agba amofin to tun jẹ agbẹnusọ fun ipolongo aarẹ Buhari, Festus Keyamo naa ti pe fun igbesẹ mẹta lati ọdọ awọn ọlọpaa lori ọrọ naa.
Akọkọ, Ẹ fi panpẹ ofin gbe Ekeji, Ẹ gba ohun rẹ silẹ. Ẹkẹta, Ẹ gbee lọ sile ẹjọ
Oríṣun àwòrán, Kate Henshaw
Ẹwẹ, agba ọjọgbsn lori ọrọ oṣelu ati imọ ofin, Akin Oyebọde ti ke si igbimọ to n mojuto ẹtọ ati eto nile asofin agba, (Senate Ethics and Privileges Committee) lati tete gbe igbesẹ to tọ lori ọrọ ọhun.
A nilo agọ ọlọpa ni Orin Ekiti fún aabo wa -Falua
Osun Strike: Gbèdéke ọjọ́ méje ni àwọn olùkọ́ ilé ẹkọ́ gíga fún ìjọba
O da bi ẹni pe gbẹgẹdẹ fẹ gbina laarin awọn olukọni kaakiri awọn ileewe giga mẹrẹẹrin to wa ni ipinlẹ Ọṣun.
Ko si idi meji ju bi awọn olukọni naa ti ṣe faake kọri pe iyanṣẹlodi ọlọjọ gbọọrọ lawọn yoo fi yanju ọrọ ilaji owo osu ọdun meji ati aabọ ti ijọba ipinlẹ Ọṣun jẹ wọn.
Kunle Afolayan: èmi kò fẹ́ fi ogún sílẹ̀ fún ọmọ mi
Awọn olukọni naa, labẹ aṣia ẹgbẹ olukọni ileewe giga nipinlẹ Ọṣun, CASUOSTI, wa fun ijọba ni gbedeke ọjọ meje lati pe awọn olukọni naa si ajọ ijiroro, lori ọrọ naa bibẹẹkọ awọn yoo bẹrẹ iyanṣẹlodi ni pẹrẹu.
Adele alaga ẹgbẹ awọn olukọ ileewe giga naa, Comrade Oluṣẹgun Lana ṣalaye lẹyin ipade ẹgbẹ naa, to waye lọgba ileewe ẹkọṣẹ olukọni agba to wa nilu Ilesa pe, gbogbo igba ni ijọba n kuna lati ṣika adehun to ṣe pẹlu ẹgbẹ naa lati igba ti ijọba ana ti wa nipo.
Ijinigbe: BBC ṣe ìwádìí bí ikọ̀ IRT ṣe ń gbéjà ko awọn ajinigbe lójú
Comrade Lana mẹnuba diẹ lara awọn ẹhonu awọn olukọni ileewe giga naa, eyi to ni o kun aisan ajẹẹlẹ abọ owo oṣu wọn fun ọgbọn oṣu, ktitapa si ofin ẹdawo ifẹyinti, ati bi ijọba ko tii ṣe san owo to rọ mọ eto igbega oṣiṣẹ laarin ọdun 2014 si 2018.
Bakan naa lo ni ọrọ yiyọ ida kan abọ 1.5% ninu owo oṣu awọn oṣiṣẹ naa fun eto adojutofo ilera NHIS, ṣi n ṣe ajoji si wọn.
Amọṣa, o ni awọn olukọ naa fẹ jiroro pẹlu ijọba, iyẹn bi ijọba ba ṣetan fun ifikunlukun to dan mọran.
Awọn ileewe giga ti ọrọ naa kan, ni ileewe ẹkọṣẹ olukọni agba to wa nilu Ila Ọrangun, ileewe ẹkọṣẹ olukọni agba to wa nilu Ilesa, ileewe gbogboniṣe poly ti ilu Iree ati ileewe imọ ẹrọ OSCOTECH, Esa oke.
John Ogu bá BBC Yorúbá sọ̀rọ̀ lórí ìgbáradì Nigeria vs Madagascar
Ruga Settlement: Ààrẹ Muhammadu Buhari ti dá èròǹgbà láti dá àgọ́ daran-daran sílẹ̀ dúró
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ileeṣẹ aarẹ Naijiria ti fidi rẹ mulẹ fun BBC pe Aarẹ Muhammadu Buhari ti da erongba lati ṣe idasilẹ Agọ daran-daran, RUGA, silẹ duro.
Bashir Ahmad to jẹ oluranlọwọ fun Aarẹ Buhari sọ pe lootọ ni ijọba ti da eto RUGA duro naa.
Eyi waye lẹyin ti Igbakeji Aarẹ, Yẹmi Ọṣinbajo ati awọn gomina ṣe ipade bonkẹlẹ ni ilu Abuja lati jiroro lori erongba ijọba apapọ.
Ṣaaju ni ileeṣẹ aarẹ ṣalaye pe awọn ọmọ orilẹede Naijiria yoo mọ boya ijọba apapọ yoo tẹsiwaju pẹlu eto naa ti o ti n da ọpọ awuyewuye silẹ, l'Ọjọru.
Ati wi pe awọn gomina ipinlẹ ni yoo sọ boya idasilẹ RUGA yoo waye.
CAN: Samson ni ọrọ awọn ajinigbe ti gba àpérò ní Naijiria
Ni ọsan Ọjọru ni iroyin kan jade lati inu ọkan lara awọn iwe iroyin ori ayelujara lorilẹede Naijiria pe Aarẹ Muhammadu Buhari ti gba lati da eto naa duro.
Amọṣa, nigba ti BBC News Yoruba pe agbẹnusọ fun aarẹ, Garba Shehu lati mọ otitọ to wa ninu ọrọ naa, o ni oun gbogbo yoo han kedere sawọn ọmọ Naijiria lẹyin ipade ti igbakeji aarẹ, Yẹmi Oṣibajo n ṣe pẹlawọn gomina nilu Abuja.
Ajọ awọn gomina lorilẹede Naijiria yoo kede igbesẹ to kan lori ọrọ RUGA ni ọrọ Garba Shehu fi da ileeṣẹ wa lohun.
Senator Elisha Abbo: Ọga àgbà ọlọ́pàá Nàìjíríà ti pàṣẹ ìwádìí sí ọ̀rọ̀ Sẹ́nétọ̀ Abbo tó lu obìnrin l'Abuja
Oríṣun àwòrán, @adeyanjudeji
Ọjọ Iṣẹgun ni fidio kan jade to ṣafihan bi Sẹnetọ naa ṣe n lu obinrin kan nile itaja eroja ibalopọ
Ileeṣẹ ọlọpaa lorilẹ-ede Naijiria ti ni ko si igba kankan ti àwọn paṣẹ mimu Seneto Abbo.
O ni ọga agba ileeṣẹ ọlọpaa, Mohammed Adamu kò paṣẹ ki wọn mu Sẹnetọ Abbo ti iroyin n ja ranyinranyin pe o lu obinrin kan nilee itaja nilu Abuja.
Nigba to n ba BBC News Yoruba sọrọ, alukoro agba fun ileeṣẹ ọlọpaa lorilẹ-ede Naijiria, Frank Mba ni ọga agba ọlọpaa ti paṣẹ pe ki iwadii to rinlẹ o bẹrẹ ni pẹrẹu lori iṣẹlẹ naa.
O ni eyi ko fi ọna kankan jẹ mọ pe wọn mu aṣofin agba naa.
Ọjọ Iṣẹgun ni fidio kan jade to ṣafihan bi Sẹnetọ naa  ṣe n lu obinrin kan nile itaja eroja ibalopọ
Ọgbẹni Frank Mba ni awọn ọlọpaa ti kan si arabinrin ti iṣẹlẹ naa ṣẹlẹ si pẹlu awọn igun miran ti ọrọ kan igbesẹ iwadii si n lọ .
Oríṣun àwòrán, Elisha Ishaku abbo
Ajafẹtọ ọmọniyan kan l'orilẹede Naijiria, Comrade Deji Adeyanju kede lọjọ Iṣẹgun pe oun yoo ko awọn eniyan jọ lori ọrọ yii.
O ni awọn yoo si jọ wọde lọ si ọọfisi Ọga agba ileeṣẹ ọlọpaa, lati fun un ni iwe ẹsun lori ọrọ Sẹnetọ Elisha Abbo ti wọn lo lu arabinrin kan nile itaja kan ibalopọ l'Abuja.
Nibayii, awọ̀n olufẹ̀honu han naa ti wa ni ọọfisi ọga agba ọlọpaa.
Ọjọ Iṣẹgun ni iwe iroyin ori ayelujara, Premium Times fi fidio kan sita, to ṣafihan bi Sẹnetọ naa, to jẹ pe oun lọjọ ori rẹ kere ju nile aṣofin agba Naijiria, ṣe n lu obinrin kan nile itaja eroja ibalopọ.
Widows Day 2019: Mo máa ń sá kiri wá owó ilé ni -Opó
Ọpọ lo si ti n koro oju, bu ẹnu ẹtẹ lu ihuwasi sẹnetọ naa.
Ṣugbọn nigba ti yoo fesi, Sẹnetọ Abbo sọ fun BBC pe, oun ko mọọmọ lu obinrin naa.
CAN: Samson ni ọrọ awọn ajinigbe ti gba àpérò ní Naijiria
Koda, ajọ ajafẹtọ ọmọniyan l'agbaye, Amnesty International ti dasi ọrọ naa, to si ti kesi ileeṣẹ ọlọpaa Naijiria lati wadii rẹ.
Mo máa n forin mi kìlọ̀ ìwà ìbàjẹ́ láwùjọ ni -Hameen
'Awọn to wa ninu ile itaja naa lo kọkọ lu aburo mi bolẹ, ti wọn si gba ẹjẹ lẹnu rẹ ni emi ṣe lu awọn naa bolẹ.''
International Day Against Drug Abuse and Trafficking: ìdí ti mo fi ń mu oògùn olóró
Elisha Abbo: Ẹ̀sìn àti ẹ̀kọ́ ilé tí mo ní kò gba ká na obìnrin
Oríṣun àwòrán, @ElishaCliff
Sẹnetọ Elisha Ishaku Abbo, ti fidio ori ayelujara kan gbe jade pe o na obinrin abilekọ kan nile itaja ti tọrọ aforijin lọwọ awọn orilẹede yii, awọn abiyamọ, ati obinrin to na pe ki wọn fi ori jin oun, oun ko ni hu iru iwa aidaa bayii mọ.
Abbo tọrọ aforojin yii pẹlu ikaanu nla, lasiko ipade akọroyin to se ni olu ile ẹgbẹ PDP to wa nilu Abuja.
Asofin ẹgbẹ PDP naa, to tọrọ aforijin pẹlu lọwọ ẹgbẹ oselu rẹ, awọn mọlẹbi, ọrẹ tun mẹnuba pe, iwa bayii se ajeji si oun lati ẹyin wa, ti oun si kabamọ fun iwa toun hu yii, lainaani ohun to bi oun ninu lati se bẹẹ.
O wa rawọ ẹbẹ si tọkunrin-tobinrin ọmọ orilẹede yii lati wa aaye ninu ọkan wọn fi fori jin oun nitori eniyan lo n dẹsẹ, Ọlọrun si lo maa n fori jin ni.
Abbo, to ni ọmọ kii mọ ẹkọ jẹ ko ma ra lọwọ, tun tọrọ aforijin lọwọ ijọ Ọlọrun lagbaye lori iwa aidaa ti oun hu yii, nitori o ni gẹgẹ bii asoju Kristi, iru iwa yii ko tọ si oun.
CAN: Samson ni ọrọ awọn ajinigbe ti gba àpérò ní Naijiria
Bakan naa lo fikun pe itọni ti oun gba ninu ile ati ijọ Ọlọrun ko fọwọsi iru iwa yii, nitori idi eyi, oun tọrọ idarijin niwaju Ọlọrun ati awọn eeyan ti iwa oun yii ti jẹ ẹdun ọkan fun.
Ijegun pipeline fire: Ẹ̀mi méjì, ọkọ̀ tó lé ni 30 ṣòfò níbi ọ̀pá epo tó gbaná
"Awọn olugbe agbegbe Ijegun ni kii ṣe igba akọkọ niyii ti ọpa epo yoo gbana ni ọdọ awọn. ""O ti ṣẹlẹ lọdun 2008""."
"Wọn ni orukọ ti adugbo awọn njẹ tẹlẹ gan ni ""Five Junction tori pe ọna naa pin si marun un"" ṣugbọn wọn ni iṣẹlẹ ki ina maa jo ni gbogbo igba lo mu awọn sọ ọ lorukọ ""Fire Junction"" bayii."
Aworan afinimọna ìlú Ijegun
Bakan naa wọn ni awọn ará Ijegun kọ́ ló ń bẹ́ ọ̀pá epo ní Ijegun, ita ni wọn ti n wa nitori naa wọn ke gbajare si ijọba pe ''o ti sú awọn, kí ìjọba wá gbà wọ́n!
Ajọ to n ri si iṣẹlẹ pajawiri ni ipinlẹ Eko LASEMA ni bi awọn ṣe de ibi iṣẹlẹ naa, wọn ri i pe awọn kan to maa n bẹ ọpa epo lati jale lo fa iṣẹlẹ naa to waye ni Fire Junction Ijegun.
Agbẹnusọ to ba BBC Yoruba sọrọ ni eniyan mejila ni awọn ti doola bayii, wọn ti gbe eniyan mẹjọ ninu wọn lọ si ile iwosan ijọba tó wà ní Gbagada ti wọn si ko awọn mẹrin lọ si ile iwosan ti LASU.
Gẹgẹ bi Ọmọwe Olufemi Oke-Osanyintolu ṣe sọ ọ, awọn janduku yii ti ṣaaju ko epo sinu ọkọ akepo ti iwọn rẹ to lita ẹgbẹrun lọna mẹtalelọgbọn ti wọn si tun ti n ji omii ko sinu iru ọkọ akepo yii miiran nigba ti awọn agbofinro ya lu wọn.
Bi wọn ṣe n gbiyanju ati na papa bora ni opo ta sinu gọta ti wọn si fẹsun kan pe awọn janduku ọhun sọ ina si epo to ta silẹ lati le awọn agbofinro danu ki wọn ma baa mu wọn.
Afi kẹ̀ẹ̀, nina ba ran pada lọ si orisun ibi ti wọn ti n ji epo to si gbana pẹlu ọwọ ina giga to n jo wi wi wi.
'Àjẹ́, eégún, kí ni wọn ò pè mí tán tórí Vitiligo lára mi'
Ajọ LASEMA sọ fun BBC Yoruba pe ẹmi meji ti ba iṣẹlẹ naa rin ti o si ti le ni ọkọ ọgbọn to jona.
Wọn ki awọn to le mọ pato iye ẹmi to nu ati awọn to fara pa, o di ti awọn ba ṣe  ayẹwo to tọ, afiwe ati isiro to yẹ ki awọn ṣe.
Ajọ to n ri si iṣẹlẹ pajawiri lorilẹede Naijiria, NEMA ni awọn janduku to maa n bẹ ọpa epo bẹntiroo lati ji epo wa lo fa katakata to ṣẹlẹ lọjọbọ ni agbegbe Ijegun ti ọpa epo ti gbina.
Akọroyin BBC kan si alabojuto ẹkun Guusu-Iwọ Oorun Naijiria fun ajọ to n ri si iṣẹlẹ pajawiri, Ibrahim Farinloye ni ki awọn eniyan ṣaa bu omi suuru mu.
Oríṣun àwòrán, @theBussmarn
Ọpa epo n jona ni Ijegun, ipinlẹ Eko
Ibrahim ni awọn ti kan si awọn alaṣẹ ile iṣẹ NNPC lori iṣẹlẹ owurọ yii bẹẹ si ni awọn tun ti kan si ẹka ile iṣ awọn to n ri si ọrọ aabo lati dawọ pinpin epo bẹntiroo nipasẹ ọpa epo duro na ki ọwọ ina naa le rọlẹ na.
Gẹgẹ bi agbẹnusọ yii ṣe sọ, wọn ni awọn janduku to maa n bẹ ọpa epo lati ji epo wa lo da wahala yii silẹ.
Bakan naa a gbọ latẹnu NEMA pe wọn ti pa ina ọhun wọn si ti gbe awọn to fara pa lọ si ile iwosan fun itọju.
Ọpa epo bẹntiroo naa to gba ina ni agbegbe Ijegun/Isheri nipinlẹ Eko bẹrẹ ni owurọ kutu ni nkan bii ago marun.
Awọn ti ọ̀rọ̀ naa ka lara ti n fi ọrọ adura sita si Ọlọrun lati dawọ ibi yii duro ki ẹmi si ma nu.
Ijegun
Gẹgẹ bi ohun ta a gbọ, aarin oru ni iṣẹlẹ naa bẹrẹ, ti awọn ara adugbo bẹrẹ si ni i gbọ ariwo ibugbamu nla.
A ko ti i le fi idi nkan to fa ibugbamu ina naa mulẹ, ṣugbọn lori ayelujara, bi awọn kan ṣe  n sọ pe awọn to fẹ ẹ ji epo wa nibi ọpa epo naa, to wa nitosi ileepo kan lo fa ina naa, ni awọn kan n sọ pe ọkọ agbepo kan lo ṣubu lu  ọpa epo.
Awọn ara agbegbe naa ti n figbe sita loju opo ayelujara pe ki awọn alaṣẹ tọrọ kan tete wa seranwọ lati pa ina ọhun.
Kayefi BBC Yorùba: Bàbá ọmọ, Mọ́ṣúárì, Ọlọ́pàá kẹ́jọ́ rò nípa òkú ọmọ tó pòórá
Ẹwẹ, nigba ti BBC Yoruba bá agbẹnusọ ajọ to n ri si iṣẹlẹ pajawiri LASEMA l'Eko Ọgbẹni Kehinde Adebayo sọ̀rọ̀, o fi aridaju iṣẹlẹ naa ati agbegbe to ti n ṣẹlẹ han ati pe awọn oṣiṣẹ awọn ti wa lna Ijegun ni akoko ti akọroyin BBC Yoruba fọrọ wa a lẹnu wo.
A n se akojọpọ ẹkunrẹrẹ iroyin yajoyajo lọwọ, a o maa gbe ẹkunrẹrẹ iroyin naa sori atẹ iroyin wa laipẹ. Ẹ jọwọ, ẹ tun oju opo iroyin yi yẹwo, ki ẹ lee ri ẹkunrẹrẹ iroyin ọtun laipẹ.
Chelsea kéde Frank Lampard gẹ́gẹ́ bíi olùkọ́ni tuntun
Oríṣun àwòrán, chelseafc.com
Àdéhùn ọdún mẹ́ta ni Lampard tọwọ́bọ̀ pẹ́lúu Chelsea
Ẹgbẹ agbabọọlu Chelsea ti kede Frank Lampard gẹgẹ bii olukọni tuntun fun ikọ naa.
Adehun ọdun mẹta ni Chelsea ati Lampard tọwọ bọ.
Frank Lampard fi igba kan ri jẹ agbabọọlu ikọ naa ti orukọ rẹ ko lee parẹ laelae, oun si ni agbabọọlu to gba goolu wọle julọ fun ikọ ọhun ki o to fi ibẹ silẹ.
Ninu atẹjade kan ti ikọ Chelsea fi sita ni owurọ Ọjọbọ, oludari ẹgbẹ agbabọọlu Chelsea Marina Granovskaia ni: 'Inu wa dun lati ki Frank Lampard pada si Chelsea gẹgẹ bii olukọni agba. Frank ni oye to jinlẹ gidigidi nipa ẹgbẹ agbabọọlu yii ati bi nnkan ṣe lọ si ni saa bọọlu to kọja,  si ti fihan pe oun wa lara awọn ojẹwẹwẹ olukọni ti ọpọlọ wọn pe ninu ere bọọẹu afẹsẹgba.
'Àjẹ́, eégún, kí ni wọn ò pè mí tán tórí Vitiligo lára mi'
Ọdun mẹta ni Frank Lampard lo ni Stamford Bridge, awọn alaṣẹ Chelsea si ti fi igbẹkẹle wọn han pe asiko to yẹ ẹ gan lo pada wa yii gẹgẹ bii oluksni wọn.
Nigba ti oun pẹlu n sọrọ lẹyin ti o tọwọ bọwe adehun rẹ tan, Frank Lampard ni iyi nla lo jẹ fun oun lati di olukọni agba fun ẹgbẹ agbabọọlu Chelsea ati pe afojusun oun bayii ni 'lati mura giri fun iṣẹ naa ati lati pese ikọ naa silẹ gidigidi fun saa ere bọọlu to n bọ lọna'
Kunle Afolayan: èmi kò fẹ́ fi ogún sílẹ̀ fún ọmọ mi
Frank Lampard n bọ si ipo naa lẹyin ti Mario Sarri to wa nibẹ tẹlẹ ti lọ darapọ mọ Juventus lorilẹede Italy.
RUGA: Afenifere, Kunle Akinjide sọ̀rọ̀ lórí ìkéde ìjọba àpapọ̀ láti dáwọ́ dúró lórí RUGA
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ijọba apapọ kede lalẹ Ọjọru pe awọ̀n n dawọ duro lori idasilẹ awọn gaa darandaran RUGA to ti n fa awuyewuye fun ọjọ diẹ sẹyin bayii
Lẹyin ti aarẹ Buhari ti kede pe ijọba apapọ yoo jami lori igbesẹ ati da awọn Gaa darandaran RUGA silẹ bayii, ẹgbẹ Afẹnifẹre ti pariwo sita pe ete lasan ni ọrọ naa nitori kii ṣe pe aarẹ ni awọn wọgile e patapata.
Ẹgbẹ Afẹnifẹre ṣalaye pe niwọn igba ti ijọba apapọ ba ṣi ni i lero ati gbe igbesẹ naa dide lọjọ iwaju, awọn ko lee fi gbogbo ara dunnu si ikede naa.
Kunle Afolayan: èmi kò fẹ́ fi ogún sílẹ̀ fún ọmọ mi
Ninu ọrọ to ba BBC News Yoruba sọ lọjọbọ, agbẹnusọ fun ẹgbẹ Afẹnifẹre, Yinka Odumakin wi pe ẹtan ni ikede ijọba apapọ naa nitori kii ṣe ijọba apapọ wọgile igbesẹ naa patapata, wọn kan n jawọ lori rẹ fun igba diẹ lasan ni.
Bakan naa ni ẹgbẹ naa tun kọminu lori ẹgbẹ kan ti wọn ni o dide lapa oke Ọya to n fun ijọba apapọ ni gbedeke ọgbọn ọjọ lati bẹrẹ eto RUGA ni gbogbo ipinlẹ Naijiria bi wọn ko ba fẹ ki awọn dana wahala silẹ.
O ni ohun ti o lee dun mọ ilẹ Yoruba ninu ni ki wọn wọgile eto naa patapata.
Wòlíì Kasali sọrọ nípa awuyewuye pé o lè ìyàwó rẹ̀ jáde nílé
Ninu ọrọ tirẹ, akọwe agba ẹgbẹ awọn agba ilẹ Yoruba, YCE, Dokita Kunle Ọlajide ni igbesẹ to dara ni aarẹ gbe ṣugbọn o tun ku ni ibọn n ro.
Gẹgẹ bii ifọrọwerọ Dokita Akinjide pẹlu BBC News Yoruba, o ni o yẹ ki ijọba mọ pe ọrọ orilẹede yii ti di ti 'eyi wumi ko wu ọ'
O fi kun un pe atunto orilẹede Naijiria nikan ni ọna abays fun irufẹ edeaiyede ati awuyewuye bayii.
HIV Patients: N kò ní ìbálòpọ̀ rí kí ń tó ní HIV
Brian Omondi sọ pe ko rọrun lati ni ọrẹ tabi ololufẹ nitori aarun HIV
Brian Omondi, ti wọn bi pẹlu aarun HIV, bẹrẹ si ni lo akanṣe oogun fun aarun naa, anti-retroviral (ARV) nigba to wa ni ọmọ ọdun mẹwaa.
Amọ ṣa, igba to pe ọmọ ọdun mẹrinla, lẹyin ti iya rẹ ti ku, lo to o mọ aisan ti awọn oogun naa wa fun.
O ti pe ẹni ọdun mejilelogun bayii, o si n ṣiṣẹ ipolongo igbogun ti aarun HIV pẹlu ṣọọṣi kan.
''Kii ṣe igba ti wọn bi mi ni mo ko aarun naa. Mo kan ranti pe nigba ti mo wa l'ọmọde, mo maa n ṣaiṣan nigbogbo igba, iya mi si mu mi lọ sile iwosan fun ayẹwo.''
''Igba ti wọn ṣe ayẹwo fun mi ni wọn ri i pe aarun HIV ni mo ni. Mo bẹrẹ si ni lo oogun, ṣugbọn iya mi ko fi igba kankan sọ idi ti mo fi n lo awọn oogun naa fun mi.''
Igba to lọ gbe lọdọ ibatan rẹ kan lẹyin ti iya rẹ ku, ni awọn aladugbo mọ pe o ni HIV, awọn ẹlẹgbẹ rẹ si bẹrẹ si ni i fi ṣe ẹlẹya.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Awọn to n polongo gbigbogun ti HIV n fẹ ki awọn ọmọ Kenya to ni aarun naama tiju lati sọrọ sita
Awọn obi maa n kilọ fun awọn ọmọ wọn lati ma ba a awọn to ni aarun HIV ṣere.
Botilẹjẹ wi pe awọn ọdọmọde ati ọdọ lo pọ ju lara awọn to n gbe pẹlu HIV ni Kenya, ati ilẹ olooru Afrika, ọpọ ninu awọn ti wọn bi pẹlu aarun naa lo n gbe igbeaye wọn laijẹ ki ẹnikẹni o mọ.
Awọn obi kan l'orilẹede Kenya maa n pa aṣiri aarun HIV wọn mọ titi wọ saare, ti wọn si maa n fi awọn ọmọ wọn sinu okunkun ati ailera.
Kunle Afolayan: èmi kò fẹ́ fi ogún sílẹ̀ fún ọmọ mi
Ọgbẹni Omondi sọ pe, oun ko da iya oun l'ẹbi pe ko sọ ootọ fun oun.
'Mo ro pe o yẹ ko sọ fun mi, amọ mi o tun le da a l'ẹbi nitori pe o n gbiyanju lati daabo bo mi gẹgẹ bi ọmọde.''
Amọ, o ni o di igba ti awọn eniyan ba to o yi ihuwasi wọn pada si awọn ti wọn bi pẹlu HIV, ki awọn alarun naa to ma a gbe igbe aye ominira, tabi ni ọrẹ ati ololufẹ lai si ibẹru ati idiwọ.
'Àjẹ́, eégún, kí ni wọn ò pè mí tán tórí Vitiligo lára mi'
Bakan naa ni ọrọ ri fun Winnie Orende, to ti pe ẹni ọdun mẹtadinlọgbọn bayii. Iyalẹnu ati ibanujẹ nla lo jẹ fun nigba to mọ pe oun ni aarun HIV nigba to pe ọmọ ọdun mejila.
'Nigba ti iya mi ku, lẹyin oṣu meji, dokita ni ẹgbọn mi obinrin, o si pe mi ki n da wa si ileewosan lati ri oun.''
Dokita naa mọ pe, aarun naa lo pa iya rẹ - o si fẹ ẹ ṣe ayẹwo fun lati mọ boya oun naa ni. Esi ayẹwo fihan pe, o ni aarun naa.
CAN: Samson ni ọrọ awọn ajinigbe ti gba àpérò ní Naijiria
Ohun to buru ju ni pe, Winnie to kere julọ ninu awọn ọmọ iya rẹ, lo ni aarun naa lati ara iya wọn.
'Pẹlu ọjọ ori mi, iporuru ọkan ba mi. Mi o ni ibalopọ ri; mi o ki n ṣe aṣẹwo, bawo ni mo ṣe wa ni aarun HIV?
Ko kọkọ gba esi ayẹwo naa gbọ, afi igba to bẹrẹ aisan, ti wọn si gbe e lọ sile iwosan ni aimọye igba.
Gift Sotonye-Frank: Bó ṣe gba oyè ọ̀mọ̀wé nípa òfin, náà ló gba àmì ẹ̀yẹ
Oríṣun àwòrán, @QUBelfast
Ọmọ Naijiria kan, arabinrin Gift Sotonye-Frank, to n kẹkọ gboye ọmọwe lẹka imọ ofin ni Queen's University to wa nilu Belfast ti gba ami ẹyẹ akẹkọ to dantọ julọ nileẹkọ naa.
Ileeẹkọ fasiti Queen's lo kede ohun iwuri yii loju opo ikansira ẹni Twitter rẹ, ti Gift funra rẹ naa si ki ara rẹ ku oriire ami ẹyẹ naa loju opo Twitter tiẹ naa.
Ileẹkọ fasiti yii lo mọ iriri ẹmi ifaraẹnijin, ipamọra ati ipa ribiribi ti Sotonye n ko si iwadi lori isẹda, ibalopọ ati ẹtọ ọmọniyan, paapa bo se foju sun ẹtọ awọn obinrin ati ẹtọ si eto ẹkọ fawọn ọdọbinrin ọmọ Naijiria.
Oríṣun àwòrán, @gift_sotonye
Lasiko ayẹyẹ ikẹkọjade lawọn ẹgbẹ akẹkọjade ileewe naa gbe ami ẹyẹ ọhun fun Sotonye, to sẹsẹ gba oye ọmọwe, PHD nile ẹkọ ọhun, ami ẹyẹ naa si ni ikọkanlelogun iru rẹ, pẹlu atilẹyin ile ifowopamọ kan.
'Àjẹ́, eégún, kí ni wọn ò pè mí tán tórí Vitiligo lára mi'
Ami ẹyẹ si lo n mọriri ẹnikẹni to pegede, se aseyọri tabi sisẹ sin fun ileẹkọ naa tabi fun awujọ lapapọ.
Ooni of Ife: Ọ̀wọ́ Ọlọ́pàá ti tẹ arákùnrin tó fi tipá wọ ààfin Ọ̀ọni ilé ifẹ̀
Oríṣun àwòrán, Amiloaded media hub
Ni alẹ ọjọ Iṣẹgun ni awọn eeyan ilu Ile ifẹ ni awọn gbọ iro ibọn ni kikankikan ni ile Oodua tii ṣe aafin Ọọni ile ifẹ, Ọba Adeyẹye Ogunwusi eleyi to mu ki ọpọlọpọ awọn eeyan ilu iṣẹmabaye naa o maa ko aye soke lori alaafia Ọọni Adeyẹye Ogunwusi ni.
Iro ibọn naa ni wọn ni o dun fun iṣẹju diẹ ki o to dakẹ.
Nigba ti gbogbo rẹ yoo fi rọlẹ ni iroyin jade pe awọn eeyan mẹta kan gbiyanju lati fi ipa wọ aafin ninu ọkọ ayọkẹlẹ kan. Nigba ti wọn de iloro akọkọ ni aafin Ọọni ni awọn ẹṣọ beere ohun ti wọn wa ṣe ti meji ninu wọn si bẹ silẹ ninu mọto ti wọn si fi ẹsẹ fẹẹ.
Ẹni kẹta wọn to wa ọkọ naa ni wọn ni o fi ọkọ naa ja iloro kini ati ikeji pẹlu erongba lati wọ iloro kẹta nibi ti Kabiyesi arole Oodua, Ọọni Ogunwusi n gbe  ṣugbọn awọn agbofinro to n ṣọ aafin naa ba ya boo.
Oríṣun àwòrán, Amiloaded media hub
Gẹgẹ bi ọrọ ti alakoso ọrọ iroyin fun Ọọni, Kọmureedi Ọlafare ṣe ṣalaye fun BBC News Yoruba, Aja kan ti wọn ni arakunrin naa gbe sinu ọkọ ti o si tu silẹ ni awọn agbofinro n le kiri.
Iro ibọn ti wọn si n yin si aja naa nibi ti wọn ti n lee kiri lawọn araalu gbọ ti wọn si n lero pe boya awọn adigunjale lo wọ aafin.
Oríṣun àwòrán, Amiloaded media hub
Arakunrin naa ni wọn ni o wa ni ahamọ awọn ọlọpaa bayii ti iroyin si n jẹ ko di mimọ pe  o ti ba wọn lalejo ni ẹka ọtẹlẹmuyẹ ileeṣẹ ọlpaa ni Oṣogbo.
Ninu ọrọ to ba ileeṣẹ iroyin kan ni ilu Ọṣogbo sọ, alukoro fun ileeṣẹ ọlọpaa ni ipinlẹ Ọṣun, ASP Yẹmisi Ọpalọla, salaye wi pe darukọ arakunrin naa gẹgẹ bi Daramọla Wasiu.
Oríṣun àwòrán, INSTAGRAM
Ọdun 2018 ni Ooni ti Ile Ifẹ, Oba Adeyeye Ogunwusi gbe Olori Naomi Silekunola Ogunwusi ni iyawo.
Olori Naomi Silekunola Ogunwusi ti bu ẹnu atẹ lu iroyin ofege to sọ wi pe igbeyawo oun ati Ooni ti Ile Ifẹ, Oba Adeyeye Ogunwusi  ti fori sanpọn.
Olori Naomi to ni ko si otitọ kankan ninu iroyin yin sọ loju ẹrọ ikansiraẹni Instagram rẹ pe oun ko ko kuro ni ile Ooni.
Olori ni ayọ ati idunnu ni oun ati Ooni fi n lo igbeyawo wọn lai si pe wọn ni ariyanjiyan kankan laarin wọn.
O fikun pe awọn ọta to fẹ ki igbeyawo awọn daru lo n gbe iroyin naa kaakiri wi pe igbeyawo naa ti fori sanpọn.
Amọ Olori ni okun to sọ igbeyawo awọn papọ le ju ohun ti ọta tabi awọn eni ibi le e ja lọ.
Bakan naa ni Olori ni arun Coronavirus ti ohun kọ oun lominu lo jẹ ki oun kurọ lori ẹrọ ayelujara fun igba diẹ lati le e gbadura nipa ohun to n sẹlẹ lagbaye.
Oríṣun àwòrán, Instagram
Olori naa ni asiko arun Coronavirus yii pe fun ironujinlẹ, ti kii si ṣe fun afẹfẹ yẹyẹ nitori ọpọ ẹmi lagbaye lo n lọ si iṣẹlẹ yii.
Ọdun 2018 ni Ooni ti Ile Ifẹ, Oba Adeyeye Ogunwusi gbe Olori Naomi Silekunola Ogunwusi  ni iyawo.
Ọwọ titẹ ọba alaye kan,  Ọba David Ogungbemi ati ọmọ rẹ, Idowu, fun pe wọn fi ipa ba ọmọbinrin, ọmọ ọdun mẹrinla kan lopọ.
Ọba naa ni oriade ilu Iketewi, to wa ni ijọba ibilẹ Obokun, nipinlẹ Osun.
Oríṣun àwòrán, María Conejo/BBC
A gbọ pe ọmọbinrin naa n gbe pẹlu aburo baba rẹ, Esther Ogungbemi, nilu Ilare, to wa ni ijọba ibilẹ naa.
Iroyin sọ pe ibalopọ tipa-tipa naa di oyun, eyi to mu ki baba rẹ lọ ọ fi ẹjọ sun ni agọ ọlọpaa.
Ṣugbọn nigba to n sọrọ, alukoro fun ileeṣẹ ọlọpaa nipinlẹ Osun, Opalola Yemisi, sọ fun BBC pe lootọ ni iṣẹlẹ naa waye, ṣugbọn ko si ẹni to jẹ ọba ninu awọn mejeeji ti wọn fi ẹsun kan.
Ohun to han si ileeṣẹ ọlọpaa ni pe baba ati ọmọ ni wọn, awọn mejeeji lo si fi ipa ba ọmọ ọdun mẹrinla naa lopọ.
Bakan naa lo sọ pe ileeṣẹ ọlọpaa ti pari iwadii lori ọrọ wọn, wọn si ti gbe wọn lọ sile ẹjọ.
Oríṣun àwòrán, Others
Afurasi kan, Samuel Eze, to jẹ akanda ẹda, ti wọ panpẹ ọlọpaa lẹyin ti wọn fẹsun kan an pe, o fipa ba ọmọ ọdun mẹrinla kan lopọ, to si fun loyun ladugbo Oshodi nipinlẹ Eko.
Oyun naa ti pe oṣu marun un bayii.
Adari ajọ to n gbogun ti iwa ibajẹ si ọmọde ni ijọba ibilẹ Oshodi-Isolo, Ebenezer Omejalile ni, afurasi naa wa ni ahamọ ileeṣẹ ọlọpaa Akinpẹlu, ni Oshodi bayii.
O salaye wipe, Eze to n gbe adugbo Arowojọbẹ ni Oshodi, ran ọmọbinrin naa niṣẹ nitori pe o jẹ alaabọ ara nigba to fipa ba lo pọ.
Omejalile ni, ko tii pẹ ti baba ọmọ naa ku ati wipe iya rẹ ṣi wa ninu opo nigba ti afẹsunkan naa ki i mọlẹ.
'Àjẹ́, eégún, kí ni wọn ò pè mí tán tórí Vitiligo lára mi'
O ni nigba ti awọn fi ọrọ wa Eze lẹnu wọ, o ni ọmọ naa funra rẹ, lo gba fun oun.
Adeleke Vs Oyetola: Òní ni ilé ẹjọ́ tó ga jù lọ yóò kéde ìdájọ́ lórí èsì ìdìbò gómìnà ìpínlẹ̀ Ọṣun
PDP àti APC Osun
Ọjọ a da ti pe.
Loni ni ile ẹjọ to ga ju lọ lorileede Naiijiria yoo kede idajọ lori esi idibo Gomina ipinlẹ Osun.
Gomina Gboyega Oyetọla ati Sẹnẹtọ Ademola Adeleke ni wọn jijọ n ṣẹjọ lori ọrọ yii. Ṣaaju ni ile ẹjọ kotẹmilọrun ti sọ pe Oyetola lo jawe olubori ninu idibo naa.
Amọ ṣa oludije ẹgbẹ oṣelu PDP, Sẹnẹtọ Ademola Adeleke ta ko idajọ yIi to si gba ile ẹjọ giga lọ.
Bi nnkan ba ti ṣe n lọ si ni BBC Yoruba yoo ma fi too yin leti.
Ileeṣẹ ọlọpaa Ipinlẹ Osun naa ti ni awọn ti wa nikalẹ, lati pese aabo fun awọn ara ilu ibikibi to wu ki idajọ ile ẹjọ to ga ju lọ ni Naijiria, lori esi idibo gomina ipinlẹ Osun to waye ni ọdun to kọja ba fi si ni ọjọ Ẹti.
Alukoro ọlọpaa ni ipinlẹ naa, Folashade Odoro sọ fun awọn akọroyin ni ipinlẹ naa wi pe awọn ti wa ni digbi.
Ilé ẹjọ́ kòmítẹlọ́rùn yá lórí ìbò gómìnà Oṣun- PDP
Ẹjọ naa lọ ile ẹjọ kotẹmilọrun lẹyin ti oludije ẹgbẹ oṣelu APC Gboyega Oyetola bori oludije PDP, Ademola Adeleke, nigba ti wọn kọkọ gbe ẹjọ naa lọ iwaju ile ẹjọ kotẹmilọrun ni oṣu karun un.
Ti ẹ ba ranti, ile ẹjọ to n gbọ ẹjọ esi idibo kọkọ dajọ ni oṣu Kẹta ọdun yii wi pe, Adeleke lo jawe olubori ṣugbọn Oyetola gba ile ẹjọ kotẹmilọrun lọ lori ọrọ naa.
Adeleke fọhùn, 'èmi ni gómìnà tí wọ́n dìbò yàn'
Ṣugbọn ile ẹjọ kotẹmilọrun yii ẹjọ naa danu, ki Adeleke to gbori le ile ẹjọ agba patapata ni Naijiria.
Ọjọbọ ni Adeleke yoo mọ ibi ti ọrọ yoo fi si, ti awọn ara Ipinlẹ Osun yoo si mọ ẹni ti yoo jẹ ojulowo gomina wọn.
Dino Melaye, olùdíje sípò kẹẹ̀ta lábẹ́ àsìá PDP tó gba fọ́ọ̀mù ipò Gómìnà Kogi
Oríṣun àwòrán, dinomelaye
Dino Melaye
Ilumọka oloṣelu ọmọ ipinlẹ Kogi, Senatọ Dino Melaye ti darapọ mọ awọn to n dije dupo Gomina ni ipinlẹ naa.
O gbe igbesẹ yii pẹlu gbigba fọọmu idije lolu ile iṣẹ ẹgbẹ oṣelu PDP l'Abuja.
Dino Melaye to jẹ Sẹnẹto to n ṣoju ẹkun idibo iwọ oorun Kogi ni oludije kẹta labẹ asia PDP ti yoo gba fọọmu.
Miliọnu mọkanlelogun Nairia ni awọn oludije to fẹ du ipo Gomina labẹ asia ẹgbẹ naa n san lati gba fọọmu ọhun.
Lasiko to n gba fọọmu naa, Dino Melaye ni o da oun loju pe oun yoo jẹ Gomina Kogi ni oṣu Kọkanla ọdun yii lẹyin ti idibo ba waye.
Oríṣun àwòrán, @Dino Melaye
Bakanna lo fọwọ sọya pe oun yoo gba awọn eeyan Kogi kuro lọwọ ijọba amunisin eleyi to ṣe apejuwe rẹ gẹgẹ bi Farao tabi Nebukadinesari to n fi iya jẹ awọn ọmọ Isrẹli ninu Bibeli.
Yatọ si Dino Melaye, oludije miiran labẹ asia ẹgbẹ oṣelu PDP,Abubakar Suleiman naa gba fọọmu lati dije dupo ninu idibo Gomina ti yoo waye lọjọ Kẹrindinlogun oṣu Kọkanla.
Kayefi BBC Yorùba: Bàbá ọmọ, Mọ́ṣúárì, Ọlọ́pàá kẹ́jọ́ rò nípa òkú ọmọ tó pòórá
Libya Explosion: Èèyàn 44 ló bá ìṣẹ̀lẹ̀ náà rìn lápapọ̀
Oríṣun àwòrán, Reuters
Ajọ iṣọkan agbaye sọ pe ado oloro naa jabọ latoju ofurufu le ibudo ti eniyan to le ni ọgọrun wa
Ọmọ orilẹede Naijiria mẹsan an lo wa lara awọn to ku sinu ikọlu ado oloro to waye ni ibudo ifiniwọ kan ni Libya.
Abẹwo awọn aṣoju Naijiria si ibudo naa, Tajoura, lẹyin iṣẹlẹ naa to waye l'Ọjọru fihan pe, ọmọ Naijiria mẹsan an lo wa lara eniyan bi i mẹrinlelogoji to ku sinu isẹlẹ naa.
Lati igba ti iṣẹlẹ naa ti waye ni ijọba ati ikọ alatako ti Khalifa Haftar n dari ti n di ẹbi ru ara wọn.
Ajọ to n mojuto ọrọ to kan awọn ọmọ orilẹede Naijiria nilẹ okeere, sọ ninu atẹjade kan to fi sita pe, eto ti n lọ lati ko awọn eniyan naa pada si Naijiria ki wọn tun to kagbako iku ojiji.
Bakan naa lo sọ pe oun ṣi n duro de iroyin lori boya awọn ọmọ Naijiria ṣi ku to ku sinu iṣẹlẹ naa.
Ọga Agba ajọ naa, Abike Dabiri-Erewa sọ pe awọn aṣatipo to le ni ẹgbẹrun lọna ọgbọn nijọba Naijiria ti da pada sile.
Ẹwẹ,  o ti n polongo fun iwadii ati ijiya fun awọn to ṣe ikọlu naa.
Ikọlu yii waye lẹyin oṣe meji ti ọ̀kan ti kọkọ waye nibi ti ko fi bẹ jina si Tajoure.
Ọpọlọpọ awọn aṣatipo naa lo n wa igbeaye 'idẹrun' lọ silẹ Yuroopu, amọ to bọ si ọwọ awọn ajijagbara ni Libya.
Ajọ iṣọkan agbaye ti sọ pe abọ iwadii ti oun ri gba fihan pe niṣe ni awọn oṣiṣẹ alaabo n yinbọn mọ awọn aṣatipo to n gbiyanju lati sa fun ado oloro.
Ẹtàn ni àwọn ọ̀rẹ́ fi ń tan èèyàn lọ si Libya pé iṣẹ́ gidi wà níbẹ̀
Osun : Ilé ẹjọ́ tó ga jù lọ fi òǹtẹ̀ jan Oyetola gẹ́gẹ́ bíi Gómìnà Osun
Oríṣun àwòrán, @Oyetola Gboyega
Ilé ẹjọ́ tó ga jù lọ ní ìlú Abuja ti dá Gboyega Oyetola láre gẹ́gẹ́ bíi Gómìnà Osun.
Ninu idajọ to fi sita nilu Abuja laarin Gomina Gboyega Oyetola ati Sẹnetọ Ademọla Adeleke,Adajọ Bode Rhodes-Vivour fọwọ rọ ẹjọ ti Adeleke gbe wa lati tako idajọ ile ẹjọ kotẹmilọrun.
Adajọ naa ni tori eleyi, Gomina Oyetola ni ile ẹjọ fi ontẹ jan gẹgẹ bii Gomina.
Kete ti iroyin idajọ yi kan awọn ololufẹ Gomina Oyetola nilu Oṣogbo ni wọn tuyaya sita lati da ọwọ idunu
Loju opo Twitter ẹgbẹ oṣelu APC,awọn naa ti ki Gomina Oyetola ku orire aṣeyọri rẹ nile ẹjọ
Paro paro ni ile Adeleke da ni Ẹdẹ
Akọroyin wa to ṣe abẹwo si ilu Ẹdẹ la ti mọ bi awọn ara ilu naa ti ṣe gba iroyin ohun jabọ pe paroparo ni ita ile Ademola Adeleke da.
O sọ pe awọn to wa ni ibẹ tilẹ sọ pe Adeleke ko si ni ile rara.
Sara-Jayne King: Ọ̀nà ayé mi dàrú torí òbí mi ta mí nù fún alágbàtọ́
Ọdun 1980 ni wọn bi Sara-Jayne King silẹ South Afrika, lasiko ti awọn eebo amunisin n dari orilẹede South Afrika, awọ rẹ si jẹ amulu-mọla dudu ati funfun bi o tilẹ jẹ pe iya rẹ jẹ alawọ funfun, idi si ree to fi lọ faa kalẹ fawọn obi alagbatọ ti wọn jẹ alawọ funfun, pe ki wọn fi se ọmọ.
Sugbọn ara Sara ko lelẹ nigba to dagba, to si ri pe awọn alawọ funfun lo wo oun dagba ni ilu ọba, UK, eyi lo mu ko pinnu lati se awari orisun ibi to ti sẹ wa lagbaye, to si mu irin ajo rẹ pọn pada wa si orilẹede South Afrika.
O ti le ni ọdun mẹẹdọgbọn ti Sara ti de orilẹede South Afrika gbẹyin, koda, ọmọ ọsẹ meje lo wa ti wọn fi gbe lọ silu ọba, ti ko si niran ohunkohun nipa orilẹede naa rara, koda igbe aye nilẹ Gẹẹsi gan ko dẹrun, nitori pe kii se alawọ funfun pọnbele, to si n tiraka lati farada igbe aye rẹ nilu Surrey, bẹẹ ni ko lee sọ oun to faa, ti iya rẹ fi kọ silẹ.
Sara Jayne mọ pe oun ko fi awọ jọ awọn toun n pe ni obi oun, amọ ko wa si ero rẹ rara pe alawọ dudu ni, afi igba ti awọn eeyan ilu Surrey jẹ ki eyi ye, tawọn akẹẹgbẹ rẹ nile iwe si maa n fi irun ori rẹ we waya olowu, oun nikan si ni alawọ dudu to foju ganni ri, lọpọ igba si ni wọn maa n sọ fun pe o da yatọ.
Awọn iwa ẹlẹyamẹya ti Sara foju wina rẹ lati kekere lo jẹ ko gba pe nkan kan wa ti ko dara nipa awọn alawọ dudu. Koda, ni ilu to gbe dagba, Crowhurst, oju awọn alarinkiri ati ẹni ti ko pe ni wọn fi n wo alawọ dudu, ti ileewe rẹ kan si maa n ko ounjẹ jọ fun awọn ọmọ ti ebi n pa lorilẹede Ethiopia.
Sara ni oun tiẹ ranti pe oun maa n ri awọn ọmọde alawọ dudu lori tẹlifisan, ti esinsin maa n kun wọn, ti eruku yoo si bo gbogbo ara wọn, eyi to mu ki oun gba pe awọn eeyan to nilo aanu ati iranwọ lo wa ni Afrika, ti ko si yẹ ki eeyan tilẹ doju kọ wọn. Amọ Sara ni inu oun dun pe oun bọ lọwọ ero buruku yii lati igba ti oun ti de si Afirika.
Ni ọjọ kan to n tun yara mama to jẹ alagbatọ rẹ se nigba to wa lọmọ ọdun mẹtala, lo se alabapade lẹta kan ti iya to bi kọ si mama naa ni ọdun kan sẹyin. Ninu lẹta naa lo ti ri ka pe iya oun ni ajọsepọ pẹlu ọkunrin alawọ dudu kan nigba to ku diẹ, ko se igbeyawo pẹlu ọkọ afẹsọna rẹ to jẹ alawọ funfun.
Osu naa lo fẹra ku, ti ko si lee sọ ẹni to ni oyun, boya alawọ dudu ni abi alawọ funfun to jẹ afẹsọna rẹ. Ofin si ti wa nilẹ lorilẹede South Afrika nigba naa pe, alawọ funfun kankan ko gbọdọ ni ibalopọ pẹlu alawọ dudu, ti ẹlẹya mẹya si wọpọ pupọ lorilẹede naa nigba naa
Nigba to bimọ tan, ọmọ naa funfun lawọ, ti wọn si ro pe alawọ funfun ni, wọn sọ orukọ rẹ ni Karoline, amọ nigba ti yoo fi pe osu mẹta, akara tu sepo pe adulawọ ni ọmọ naa, to si jẹwọ fun ọkọ rẹ pe oun se asemase ni. Ọna lati daabo bo iya Sara lo mu ki oun ati ọkọ rẹ dete pe Karoline n se aisan, to si nilo itọju gidi nilu ọba.
Idi ree ti wọn se gbe Sara kuro ni South Afrika lọmọ osu meje, ti wọn si gbe fun alagbatọ nilu ọba, ẹni to ti orukọ Karoline pada si Sara, ngba ti awọn obi Sara si pada de si South Afrika, ni wọn kede pe Karoline, ọmọ wọn ti ku.
Irẹwẹsi ọkan ba Sara pe iya to bi oun mọọmọ kọ oun silẹ ni, to si jẹ ibanujẹ nla fun, amọ ko pẹ lo wọ ile ẹkọ fasiti Greenwich, lati kẹkọ gboye akọkọ lẹka imọ nipa ofin, Law. Asiko yii ni Sara lanfaani lati kọwe si iya to bi, ti onitọun si fesi pe oun yoo dahun awọn ibeere to ba fẹ bi oun amọ ko wu oun lati ni ajọsepọ kankan bi tii wu ko mọ pẹlu ọmọ naa rara, koda, ko kari bọnu lati sọrọ yii.
Idi ree ti Sara se bẹrẹ si ni banujẹ, to si n roun. O bẹrẹ ọti mimu, to si n mu oogun oloro Codeine. Sugbọn ori baa se, iwa palapala yii ko se idiwọ fun ẹkọ rẹ, o gba oye imọ ijinlẹ akọkọ ati ikeji, to si tun ri isẹ gidi lorisirisi lati se, bẹẹ lo di akọsẹmọsẹ agbohunsafẹfẹ lori redio, Amọ oogun oloro to n mu yii lo papa le lẹnu isẹ nigba ti iwa rẹ ko ba taye mu.
Ọna lati wa ibudo ti yoo ti gba itọju, eyi ti owo rẹ ko wọn lo gbe pada si orilede South Afrika, to si ri iwosan nibẹ. O se alabapade ọmọkunrin ti iya rẹ bi lẹyin rẹ, ti wọn si di ẹbi
Afẹfẹ orilẹede naa ba lara mu, ko mu oogun oloro mọ, o ri isẹ gidi, ti Sara si pada di ọmọluabi lawujọ. Nibẹ naa si lo yi orukọ rẹ pada si Karoline Kings ti wọn sọ lọjọ to dele aye, eyi si lo sọ pada di ọmọ orilẹede South Afrika tootọ lẹyin ọpọlọpọ ọdun.
Karoline bẹrẹ isẹ pada lori redio, to si kọ iwe nipa igbe aye rẹ laarin ọdun meji to de si orilẹede South Afrika. O gba ọtẹlẹmuyẹ aladani kan lati ba se awari baba to bi lọmọ lai se aseyọri. Amọ nigba to n polowo iwe rẹ lori redio lasiko to n se eto, o darukọ ara rẹ, ti baba rẹ si pe lẹyin ọjọ kẹta, ti wọn si sọrọ fun ọgbọn isẹju.
Lẹyin o rẹyin, baba ati ọmọ foju kan ara wọn fun igba akọkọ, wọn bu sẹkun, ọjọ yii si ni Karoline ri ara rẹ bii ọmọ eeyan kan, ti inu mi si dun pe mo jẹ alawọ dudu.
Ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ láàrin Uganda ati Senegal
Diezani Madueke: Díẹ̀ lára ohun ìni Diezani tí ilé ẹjọ́ gbẹ́sẹ̀ lé
Oríṣun àwòrán, EFCC
Diezani Allison Madueke
Ile ẹjọ ti ni ki awọn ẹṣọ ara kan, ati ẹrọ ibaraẹnisọrọ iphone oni goolu kan to jẹ ti Minisita nigba kan ri fun ọrọ epo rọbi, Diezani Alison-Madueke di igbagbe.
Gbogbo dukia ọhun ti apapọ owo wọn jẹ ogoji miliọnu dọla ni Onidajọ Nicholas Oweibo, ti ile ẹjọ giga ijọba apapọ to wa ni Ikoyi nipinlẹ Eko sọ pe ko di ti ijọba.
Ọjọbọ ni Onidajọ Oweibo gbe idajọ naa kalẹ lẹyin ti ajọ to n gbogun ti iwa ibajẹ ni Naijiria, EFCC kọ iwe ẹbẹ kan pe ki ile ẹjọ o ṣe bẹ ki igbẹjọ ẹsun iwa ibajẹ ti wọn fi kan Madueke o to maa tẹsiwaju.
Oríṣun àwòrán, Efcc
Ajọ EFCC, nipasẹ agbẹjọro rẹ, Rotimi Oyedepo, ṣalaye fun ile ẹjọ pe inu ile Madueke ni wọn ti ko awọn nkan iṣaraloge ọhun.
EFCC sọ pe ara fu oun pe owo ti olujẹjọ ko jọ lọna aitọ lo fi ra wọn.
Bukola Saraki kò kọjá òfin - EFCC
Ilé ẹjọ́ gba onídúró Naira Marley pẹ̀lú mílíọ́nù méjì náírà
Onnoghen gba ìwé ìfisùn míràn látọ̀dọ̀ ìgbìmọ̀ NJC
Magu ati Keyamo ri‘binu ijọba
Ninu idajọ rẹ, Onidajọ Oweibo paṣẹ pe ki EFCC kede gbigbẹsẹ le awọn dukia naa ninu gbaju-gbaja iwe iroyin kan laarin ọjọ mẹrinla, lati fun olujẹjọ tabi ẹlomii to ba nifẹ ninu wọn ni anfaani lati sọ idi ti ijọba ko fi gbọdọ gbẹsẹ le wọn titi lai.
Oríṣun àwòrán, Efcc
Diẹ lara awọn ẹṣọ ara ọhun ni ẹgbà ọwọ (419); oruka ọwọ (315); yẹti (304); ẹgba ọrun (267); aago ọwọ (189); ẹgba ọrun ati yẹti alaṣepọ (174).
Adeboye: Ìkìlọ̀ mẹ́ta tí àgbà ìjọ fi síta nínú ìwàásù f'áwọn Pásítọ̀ ọ̀dọ́
Oríṣun àwòrán, PASTOR E. A. ADEBOYE/FACEBOOK
Alufa Agba Adeboye
Oju opo Twitter ti n gbana lati nnkan bi wakati melo kan.
Kii ṣe nitori pe olorin kan tabi elere idaraya kan sọ ọrọ to mu awuyeyewuye wa bi kii ṣe pe ọrọ iwaasu lati ẹnu woli agba kan lo n mu iriwisi orisirisi wa.
Pasito Enoch Adeboye ti ijọ Redeem lorileede Naijiria ki ṣe aimọ foloko. Ti o ba sọrọ, pupọ ninu awọn ọmọ ijọ rẹ lo ma n tẹti lati gbọ.
Ko jẹ iyalẹnu pe o ṣe iwaasu gẹgẹ bi iṣe rẹ amọ awọn amọran kan to gba ninu iwaasu to ṣe nibi eto oloṣooṣu ijọ rẹ ti wọn pe akori rẹ ni Swimming In Glory ti n ja rainrain .
Ki gaan lawọn amọran yii?
Laipẹ yi ni iṣẹlẹ kan to niṣe pẹlu ẹsun pe Pasitọ Biodun Fatoyinbo ti ijọ Coza fipa ba obinrin lo pọ da awuyewuye silẹ.
Pupọ eeyan lo ti n reti ki Pasito Adeboye to jẹ agba ninu ẹsin mẹnu ba ọrọ naa.
Ohun naa sọ ninu fọnran fidio to jade loju opo Twitter pe oun ko fẹ da si ọrọ yii nitori pe abẹ aṣẹ awọn adari ẹgbẹ ijọ onigbagbọ ni oun wa. Amọ nigba ti yoo fi gba awọn eeyan ni amọran ọrọ naa dabi ẹni pe o nṣe afiwe ọrọ to n lọ lode nipa ifipabanilopọ ni.
Ninu fidio naa o gba awọn pasitọ ọdọ ni imọran nipa nnkan mẹta to ni o wa ninu Bibeli
Iriwisi ṣe ọtọọtọ lori ọrọ rẹ ti a mọ pupọ lo kan sara si i pe o ṣe iwaasu to m'ọgbọn wa.
Amọ awọn miran tako ọrọ rẹ to sọ nipa yiyan akowe obinrin
Awọn ẹlomiran tilẹ mu amọran tiwọn to yatọ si ti Pasito Adeboye wa lọna ati dẹkun ifẹkufẹ oju
AfCFTA:Ohun tí Nàìjíríà gbọ́dọ̀ ṣé láti jẹ adùn àdéhùn okòwò kan nàà ní Afrika
Oríṣun àwòrán, Babangida Yaya Jarmari
Aarẹ Buhari ti kọkọ sọ pe nilo akoko lati fi ikun lu ikun, gba imọran ni orilẹede oun.
Lẹ́yìn ìgbaniníyànjú lóríṣiirisii, Aarẹ Mohammadu Buhari tọwọ́ bọ ìwé àdéhùn ibúdó olókowò kan fún ilẹ̀ Afrika.
Ohun ti yoo mu anfani pupọ wa ni bi Aarẹ Naijiria Muhamadu Buhari ti ṣe fi ọwọ si adehun okoowo kan naa nibi ipade apero ajọ iṣọkan ilẹ Afrika to waye ni Niger lọjọ Aiku.
Amọ ṣa ki o to le jẹ awọn anfani wọn yi, awọn nkankan wa ti o gbọdo ṣe.
Eyi ni ero adari ile iṣe idokowo nipinlẹ Eko, Muda Yusuf nigba ti o n woye nipa bi aarẹ Muhammadu Buhari ti ṣe buwọlu adehun okowo kan naa ni Afrika.
Cerebral Palsy: àrùn tó n gba omijé lójú ẹni láìnídìí
Yusuf ni igbesẹ yi yoo ṣina oko owo nipasẹ tita ọja tawọn ile iṣẹ Naijiria n ṣe lawọn orile-ede miran.
Yusuf niiwe adehun yi yoo papa mu ki eto ọrọ aje Naijiria di eleyi ti yoo darapọ mọ tawọn orile-ede miran.
Koda o ni anfani miran tun wa.
Aarẹ Muhammadu Buhari ati Aarẹ Patrice Talon ti Benin,  ni wọn fi ọwọ si iwe adehun naa loju awọn olori orilẹ-ede to ku ni olu ilu Niger, Niamey nibi ti wọn yoo kọ ibudo ọrọ aje naa si.
Adehun okoowo naa, AfCFTA ba idiwọ pade lọdun to kọja nigba ti Naijiria yọ ọwọ kuro ninu rẹ ṣaaju ọjọ to yẹ ko buwọlu u.
Ọpọ awọn oluwoye lo n beere pe ṣe erongba ibudo okoowo ilẹ Afrika ọhun ko ni foriṣanpọn, nigba ti orilẹ-ede Naijiria to ni eto ọrọ aje rẹ tobi ju lọ ni Afrika, to tun jẹ olori ẹkun Afrika yọwọ kuro ninu rẹ.
Aarẹ Buhari sọ nigba naa pe oun ṣi nilo akoko lati fi ikun lu ikun, gba imọran ni orilẹ-ede oun.
'IBB da Abiola lẹ́yìn tó búra pẹ̀lú Quran'
Ọpọlọpọ anfaani lo wa fun Naijiria ninu adehun naa; ọpọ eniyan ni yoo maa ni anfaani si awọn nkan to ba n ṣe jade kaakiri ilẹ Afrika.
Oríṣun àwòrán, others
Naijiria darapo mo olokowo kan nile Adulawo
Pẹlu bi Naijiria ṣe ti wa fi ọwọ si iwe adehun naa, afojusun AfCFTA ni lati mu afikun ba kata-kara laarin awọn orilẹ-ede ilẹ Afrika ti n sun mọ imuṣẹ.
Titi di asiko yii, awọn orilẹ-ede Afrika n ba ilẹ Yuroopu da ọrọ aje pọ ju bi wọn ṣe n ṣe laarin ara wọn lọ.
Ipade tọdun yii ni ẹleẹkejila rẹ ni eyi ti yoo mu ki erongba Agreement Establishing the African Continental Free Trade Area nilẹ Adulawọ ṣẹ.
CAN: Samson ni ọrọ awọn ajinigbe ti gba àpérò ní Naijiria
Bí ọwọ́ ọlọ́pàá Kano ṣe tẹ ọkùnrin tó fẹ́ yọ́ wọ ilé ibùsùn obìnrin
Oríṣun àwòrán, Abdullahi Haruna
Ọjọ gbogbo ni to le
Ọwọ ọlọpaa lorile-ede Naijiria ti tẹ arakunrin ọmọ ọdun mẹẹdọgbọn kan, Umar Ali to mura bi obinrin lati yọ wọ inu ile ibusun awọn akẹkọọ obinrin ile ẹkọ olukọni ijọba apapọ Kano ni ariwa ila oorun Naijiria.
Gẹgẹ bi ohun ti ileeṣẹ ọlọpaa sọ, wọn ni Umar ti ọwọ tẹ lalẹ ọjọ Abamẹta ti jẹwọ pe oun kan fẹ lọ fọwọ kan awọn obinrin naa ni.
Umar bura pe igba akọkọ ti oun yoo hu iru iwa bẹẹ niyii ati pe iya baba oun lo ni hijab ati niqob ti oun wọ lọ ṣe iṣẹ ibi naa.
"Mo bura pe igba akọkọ ree ti maa hu iru iwa yii. Erongba mi si ni ki n wọ aṣọ obinrin wọ inu ibusun wọn ki n si fọwọ kan awọn obinrin. Mo ṣeleri pe mi o ni ṣe iru rẹ mọ''
Umar ti ile rẹ ko jina si ile ẹkọ naa ni ''aṣọ iya baba oun ni aṣọ ti oun ji ati pe bi oun ti ṣe n wọ aṣọ naa ni ọwọ tẹ oun. Ẹ fori ji mi''
Báyìí ni ayẹyẹ wíwé láwàní fún ọmọ China, olóyè Zhang ṣe lọ
DSP Abdullahi Haruna to jẹ alukoro ọlọpaa ni Kano sọ fun BBC pe ni nnkan bi ago mẹwa alẹ ni awọn mu Ali lẹyin ti ọwọ awọn ẹṣọ ile ẹkọ naa tẹ ẹ.
O tẹsiwaju pe awọn yoo gbe e lọ si ile ẹjọ lori ẹsun irina are nitori wọn ko gba awọn ọkunrin laye lati wọ aaye ibusun awọn obinrin akẹkọọ.
O ni kete ti awọn ba ti pari iwadi lawọn yoo wọ ọ lọ si iwaju ile ẹjọ lori ẹsun yii.
FIFAWWCUP: Wo ohun mẹ́rin tó jẹ́ ki America tún gbá ife ẹ̀yẹ àgbáyé
Oríṣun àwòrán, others
Ta ni ẹlẹ́sẹ̀ ayò Megan Rapinoe tó gba ife ẹyẹ àgbáyé tàwọn obìnrin?
Èyí ni ìgbà kẹrin tí America yóò gba ife ẹ̀yẹ àgbáyé nínú ìdíje tàwọn obìnrin tí kò ṣẹ̀yìn Rapinoe tó gba bàtà gòólù.
Megan Rapinoe ni Balogun ikọ ẹgbẹ agbabọọlu obinrin fun orilẹ-ede America lọdun 2019.
Repinoe lo gba ami ẹyẹ ẹlẹsẹ ayo bata goolu, bọọlu goolu àti agbabọọlu to fakọyọ julọ ninu idije ife ẹyẹ agbaye tawọn obinrin to pari ni France yii.
Igba ikeji ni yii ti Megan maa gba ife ẹyẹ agbaye tawọn obinrin lọ sile gẹgẹ bii balogun ikọ USA.
Oun lo kọkọ gba bọọlu sáwọ̀n Netherland ninu idije aṣekagba naa ni papa iṣere Lyons eleyii to sọ USA di olu ọmọ ninu idije naa.
Ọpọ ṣẹṣẹ gbagbọ nipa imọsilara rẹ pẹlu ajọṣepọ akọ si akọ ati abo si abo nigba ti o kigbe pé  Go Gays"" - Akọ si akọ; abo si abo, ẹ tẹsiwaju."
'Góòlù tí mo fẹ́ràn ní World Cup'
Irun alawọ rẹsurẹsu ni aawọ irun ori ẹlẹsẹ ayo Megan eyi ti ọpọ obinrin si ti ni wọn yoo sọ aawọ irun ori wọn da lẹyin idije naa.
Megan Rapinoe jẹ ọmọ ọdun mẹrinlelọgbọn to ti wa lẹnu owo bọọlu gbigba lọdun melo sẹyin.
O ti gba bọọlu fun ẹgbẹ oriṣii meje ni ọpọlọpọ orilẹ-ede agbaye.
Megan ti gba ami ẹyẹ bii ti NWSL Sheild pẹlu Reign FC lẹẹmeji yatọ si ti goolu olimpiiki ati ti ife ẹyẹ agbaye ẹẹmeji bayii.
Fídíò BBC yọ àwọn èèyàn FIFA níṣẹ́ ṣááju Russia 2018
Megan jẹ ẹni to fẹran lati maa ṣe nkan tawọn eniyan a maa sọrọ le lori lẹyin idije.
Bi apẹẹrẹ ninu idije tọdun 2011, o gba ẹrọ gbohungbohun lori papa ni kete to gba bọọlu sáwọ̀n Columbia ki wọn to koju Japan nibi to ti kọrin nipa ibi rẹ ni Amerika.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Awa America la tun gba ife tọdun 2019
Megan ni awọn amohunmaworan ṣafihan rẹ pe ko kọ orin ogo ilẹ Amerika jade ṣaaju idije wọn.
O wa lara awọn ti wọn n ja pe ki ajọ FIFA sọ owo idije obinrin di iye kan naa pẹlu ti ọkunrin ni agbaye nitori bi a ṣe bi ẹru ni abi ọmọ.
Asisat Oshoala: ìbẹ̀rẹ̀ mi kò rọrùn rárá nínú eré bọ́ọ̀lù
Wo ohun mẹ́rin tó jẹ́ ki America tún gbá ife ẹ̀yẹ àgbáyé
Orilẹ-ede America ati Netherland ni wọn jọ gbena woju ara wọn ninu idije aṣekagba ti awọn obinrin lagbaye lọdun 2019.
Ami ayo meji sodo ni wọn fi gbe ifẹ ẹyẹ lọ ti wọn fi na Netherland.
Fulani Kidnapping: Owó púpọ̀ la san kí wọ́n tó fi mi sílẹ̀
Orilẹ-ede France lo gba alejo idije tọdun 2019 naa.
America naa lo gba ife ẹyẹ naa lọdun 2015, fun idi eyi ilé ni wọn tun gbe e pada si.
Ẹkọ mẹ́rin ti a lè kọ́ lára America:
1) Ko si ìgbà ti a ko le da aṣọ ki a tun fi wọ́lẹ̀ pẹlu iyì: Kii ṣe dandan ko jẹ pe ninu abala idije akọkọ ni ẹgbẹ agbabọọlu ti le yege ninu idije.
Abala keji idije aṣekagba laarin Netherlands ati America ni Megan Rapinoe ati Rose Lavelle ti jẹ goolu to mu ki America gbe igba oroke ninu idije naa.
2) O ṣe pataki fun ẹgbẹ agbabọọlu to ba fẹ ṣe aṣeyọri lati ni adilemu to gbounjẹfẹgbẹ gba awo bọ.
Sari Van Veenendaal to jẹ adilemu fun America mọ iṣẹ rẹ bii iṣẹ.
Ẹẹmẹrin ọtọọtọ lo mu bọọlu ti ko ba di goolu mọ wọn lọwọ ni eyi ti wọn ko ba fi di apẹrẹ ajaṣẹ ninu idije ife ẹyẹ agbaye naa.
3) Ọpọ igba ni eeyan le goke ọla to ba ni ipinnu lai wo aṣeyọri latẹyinwa.
Ẹgbẹ agbabọọlu Amerika ko roo pe awọn ti gbe ife ẹyẹ naa lọ ri lọdun 1991, 1999 ati 2015.
Wọn tẹpa mọṣẹ lati ibẹrẹ idije naa pẹlu ipinnu lati tun gba ife ẹyẹ naa lọdun yii, eyi to pada wa si imuṣẹ fun wọn ni papa iṣere Lyon ni orilẹ-ede France.
Wo imọran Fọlọrunṣọ Alakija fun awọn ọdọ adulawọ
4) Agbajọwọ la fi n sọya, ajoji ọwọ kan kò gbéru dori lo n di aṣeyọri ẹnikọọkan ninu idije.
Rapinoe to pada jẹ ọkan ninu goolu to mu ki Amerika na Netherland ko deede ri goolu naa jẹ, awọn kan ni wọn gba bọọlu naa titi to fi de ẹsẹ tirẹ.
Goolu yii lo jẹ ki Rapinoe pada gba ami ẹyẹ ẹlẹsẹ ayo goolu ninu idije todun 2019 yii.
Eyi jẹ ki goolu rẹ pe mẹfa ti oun funra rẹ si ran awọn meta lọwọ lati jẹ goolu ninu idije ife ẹyẹ agbaye naa.
CAN: Samson ni ọrọ awọn ajinigbe ti gba àpérò ní Naijiria
Bakan naa ni Rapinoe gba ami ẹyẹ bọọlu oni goolu pe oun lo mọ ọ gba julọ ninu idije ọdun 2019.
Sibẹ ọpọlọpọ gba pe amulumala agbara ọdọ ati awọn to ti ni iriri ni akọnimọọgba Amerika lo to fi gba ife ẹyẹ tọdun 2019.
Osun Supreme: Àwọn èèyàn Ọṣun rọ Oyetọla láti jẹ́ kí àsìkò rẹ̀ tú aráàlú lára
Wole Soyinka: Kò sí ààyè fún ẹnikẹ́ni láti gba ilẹ̀ ìràn Yorùbá
Oríṣun àwòrán, @Olafare
O to gẹẹ nilẹ Yoruba, o yẹ ki a mọ ohun to kan
Kò sí ààyè fún ẹnikẹ́ni láti gba ilẹ̀ ìràn Yorùbá -Ọọni Ifẹ̀
Ọrọ awọn Fulani darandaran ati awọn agbebọn ajinigbe laarin wọn gba ipade agbaagba Yoruba.
Eyi lo ṣokunfa ipade Oba Ooni ti Ile Ifẹ, Ooni Adeyeye Eniitan Ogunwusi, Ojaja II pẹlu agba ọjẹ onkọwe agbaye ni, Ojọgbọn Wole Soyinka.
Ni Idi Aba, ni Abẹokuta nipinlẹ Ogun ni Akinlatun ti ilẹ̀ Egba ti gba alejo Arole Oodua nile rẹ fun ọrọ apero omọ eriwo naa.
Arole Oodua ni ko ni ṣeeṣẹ fun Naijiria lati tun koju ogun abẹlẹ bii ti Biafra to kọja lọ.
Wọn gba ijọba to wa lori aleefa lasiko yii lati gbe igbesẹ to yẹ lati jẹ ki alaafia jọba kaakiri Naijiria lẹyẹ o sọka.
Orangun: Èdè àti àṣà Yorùba ní láti jọ wá lójú
Awọn eekan mejeeji ni ọrọ  ki awọn kan maa ro pe ìbí ju ìbí lọ ko yẹ ko ṣẹlẹ rara ni Naijiria.
Wọn ni ki ijọba ṣe ohun to yẹ lati dẹkun iwa buruku awọn Fulani darandaran kan atawọn Myetti Allah kan ti wọn ro pe awọn kọja agbara ofin ko too tun di ọrọ Boko haram mọ wa lọwọ.
Ọdún 1940 ni wọ́n ti ń sin ọ̀ọ̀nì ilé Delesolu ní Ìbàdàn
Ṣoyinka ati Arole Oodua ni o n dun awọn gidi pe iṣọkan ati ẹmi irẹpọ to wa ni gbogbo ẹkun Naijiria tẹlẹ ti n di ohun igbagbe.
Wọn gba pe eyi ko ṣẹyin iwa ijẹgaba ti awọn kan fẹ tun maa jẹ le iran to ku lori bii amunisin ni eyi ti ko le ṣeeṣe.
Ọọ̀ni ilé Ifẹ̀, Ọba Adeyeye Ẹnitan Ogunwusi, Ọ̀jájá Kejì ń ṣe ayẹyẹ ọjọ́ ìbi ọdúnKẹrinlelo
Ojaja II ati Akọgun Iṣara fẹnuko pe ki gbogbo ogidi ọmọ Oodua daabo bo ogun idile rẹ.
Ki onikaluku ja fun ẹtọ rẹ ninu ilẹ iran baba nla rẹ nitori oko kii jẹ ti Baba tọmọ ko ma ni ààlà.
Ọọni ogunwusi bẹrẹ abẹwo si orilẹede Brazil
Awọn akọni mejeeji yii gba awọn ọdọ Naijiria lati ji dide si iṣẹ ati iwa ọmọluwabi to yẹ ki a mọ ọdọ mọ.
Oríṣun àwòrán, @olafare
Emi gana an ti setan lati fowosopo pelu gbogbo ori ade ki a tun ogo ile Yoruba se
Fulani Kidnapping: Owó púpọ̀ la san kí wọ́n tó fi mi sílẹ̀
Awọn agba ọjẹ mejjeji mẹnuba wahala to maa n jade lati ara ẹlẹyamẹya ati aini irẹpọ lorilẹ-ede ati ni agbegbe kọọkan.
Wọn gba awọn eeyan niyanju lati ni ẹmi ifarada ki Naijiria le tẹsiwaju.
Oríṣun àwòrán, @olafare
Bi a ba se ni looore, ọpẹ laa da nilẹ Oodua
Ooni ti Ile Ifẹ ati Wole Soyinka ni ki onikaluku ni ẹlẹkunjẹkun ṣe agbekalẹ aato ijọba to faaye gba ifikunlukun ati ijiroro ṣaaju igbesẹ to ba kan ara ilu.
Oríṣun àwòrán, @olafare
Oro to ba gba aaro ni siso a kii fi ale soo nile Yoruba
Wọn ni o yẹ ki ijọba maa gbiyanju lati gbọ ohun tawọn eniyan wọn ba n sọ ki onikaluku le maa fẹdọ lori oronro sun.
Cerebral Palsy: àrùn tó n gba omijé lójú ẹni láìnídìí
Ni ipari àwọn mejeeji tun ṣe ileri lati gbiyanju agbara wọn ki wọn fọwọsowọpọ pẹlu awọn to n wa alaafia ati idagbasoke iran Yoruba ati Naijiria lapapọ.
'Àjẹ́, eégún, kí ni wọn ò pè mí tán tórí Vitiligo lára mi'
COZA: Ìlú tí ọdaràn ba tí dẹṣẹ ló yẹ kí wọn tí gbẹ́jọ́ rẹ̀ -Agbẹjọ́rò
Oríṣun àwòrán, @BIODUNFATOYINBO/@BUSOLADAKOLO
Pasitọ Biodun Fatoyinbo àti Busola Dakolo
Ọrọ ibi ti wọn yoo ti gbẹjọ ẹsun ifipabanilopo ti wọn fi kan Pasito Biodun Fatoyinbo ti ijọ COZA ko yẹ ki o mu awuyewuye wa.
Eyi ni ero agbẹjọro kan, Mohammed Ghali Alaaya ti o ba ile iṣẹ BBC Yoruba sọrọ lori ọrọ yi.
Laipẹ́ yi ni awọn akojọpọ agbẹjọro kan ati awọn ajafẹtọ-ọmọniyan kan sọ pe awọn ko fẹ ki wọn gbọ ẹjọ naa ni Abuja bi ko ṣe ni Eko ti wọn ti mẹsun naa wa.
Ilu Ilorin nipinlẹ Kwara ni wọn ni Biodun Fatoyinbo ti da ẹsẹ naa ni nnkan bi ogun dun sẹyin amọ lọwọ bayi ilu Abuja lo fi ṣe ibujoko.
Ninu alaye agbẹjọro Ghali Alaaya ti ile iṣẹ agbẹjọro Tafa Ahmed & Co, o ni ''ilu ti ọdaran ba ti da ẹsẹ ti ile ẹjọ to si kaju oṣunwọn lati gbẹjọ naa ba ti wa nibẹ lo jẹ ibi akọkọ ti a ti n gbọ iru ẹjọ bẹẹ.''
O ni: ''Nkan mẹta lo máa n ṣe atọna ibi ti a ti le gbẹjọ ọdaran.Akọkọ ni awọn tọrọ naa kan,iru ẹṣẹ ti wọn gbe lọ si ile ẹjọ ati iru agbara ti ile ẹjọ naa ni lati gbọ iru ẹjọ bẹ''
Ghali sọ pe ti ile ẹjọ to ba lagbara lati gbọ ẹjọ naa ba ti wa ni ilu ti wọn ti da ẹsẹ ti ọdaran naa si n gbe ilu naa,ibẹ ni wọn yoo ti gbẹjọ rẹ.
O tẹsiwaju pe ti ko ba rọrun lati gbọ ẹjọ naa ni ile ẹjọ yi to ri pe ọdaran naa ko gbe ilu ohun,ibi ti o n gbe nibi ti ọrọ  kan lati gbọ ẹjọ naa''lopin igba ti ile ẹjọ to ba ka oju osunwọn ba ti wa nibẹ.''
Nipa ọrọ Fatoyinbo to jẹ pe ilu Eko ni wọn ti fẹsun kan an ṣugbọn to n gbe ilu Abuja, Alaaya ni ohun to sunmọ ju pe yoo ṣẹlẹ ni ''ki wọn gbẹjọ naa ni lọ ilu to ba ti dẹsẹ naa''.
''Amọ ti idiwọ ba wa ti ko ni jẹ ki igbẹjọ nibẹ rọrun,ilu ti ọdaran n gbe ni ibi to kan lati gbẹjọ naa.''
O wa fi kun ọrọ rẹ pe o ṣeeṣe lẹyin ti ọrọ naa ba de iwaju adajọ ko jẹ Eko ni wọn yoo ti gbẹjọ naa ṣugbọn ọrọ ku si ọwọ adajọ.
AFCON 2019: Orílẹ̀èdè wo ló tún leè mókè lẹ́ka míràn l‘Afirika
Oxfam: Ìjọba kìí gba owó orí púpọ̀ lọ́wọ́ àwọn olówó tàbí fìyà jẹ àwọn alájẹbánu
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ìwádìí fihàn wí pé yóò tó ọdún 46 kí ẹni tí ó ní owó jùlọ ní Naijiria fi ná owó rẹ̀ tán, bí ó tiíẹ̀ ń ná owó tó tó mílíọ́nù dọ́là kan ní ojoójúmọ́.
Awọn adari orilẹede ni Iwọ- Oorun Ilẹ Afirika (West Africa), ni ko naani lati ri wi pe ibaradọgba wa laarin awọn olowo ati awọn mẹkunnu ni agbeegbe naa.
Iwadi Oxfam lo gbe e jade bẹẹ wi pe, agbeegbe Iwọ Oorun Ilẹ Afirika lo ni aidọgba to pọ julọ laarin awọn talaka ati olowo julọ ni agbaye.
Ninu iwadii naa, Oxfam ni ida kan awọn ọlọla ni Iwọ Oorun Afirika ni owo ju gbogbo ida mọkandinlọgọrun to jẹ mẹkunnu.
Ati wi pe yoo to ọdun mẹrindinlaadọta ki ẹni to ni owo julọ ni Naijiria fi na owo rẹ tan, bi o tilẹ n na owo to to miliọnu dọla kan ni ojoojumọ.
Nigeria, Niger, Benin, Sierra Leone ati Guinea Bissau lo fi idirẹmi pẹlu maaki to kere julọ nipa nina owo ara ilu, owo ori ati kara-kata oja lorilẹede wọn.
Gẹgẹbi iwadii naa se gbe e jade, Naijiria lo se ipo kẹrindinlogun ninu awọn orilẹede mẹrindinlogun to wa ni ẹkun Iwọ-Oorun Ilẹ Afirika naa, nigba ti Sierra Leone se ipo mẹẹdogun, ti Niger ati Guinea Bissau se ipo kẹrinla ati mẹtala lọwọọwọ.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ni ẹka ẹnawo, iwadi naa sisọ loju rẹ pe awọn ijọba to wa lẹkun iwọ oorun Afrika lo n se iwuri fun aibaradọgba laarin awọn eeyan wọn nitori pe wọn ko pese owo sita fun ẹka igbe aye ọmọ niyan bii eto ẹkọ ati ilera.
Lori sisan owo ori, iwadi naa ni ijọba kii gba owo ori pupọ lọwọ awọn eeyan to lowo lọwọ atawọn ileesẹ nla nla, bakan naa lo ni wọn kii jẹ awọn eeyan ati ileesẹ to n sa fun owo ori niya bo se yẹ, ka ma sẹsẹ sọ tawọn eeyan to ko owo ilu jẹ.
Oxfam wa salaye pe, ireti si wa ti ijọba orilẹede kọọkan to wa nilẹ Afirika ba lee se awọn atunse ni agbọn kọọkan ti ọrọ yii kan.
Ìwọ́de Shiite: Ọwọ́ ọlọ́pàá tẹ ogójì ọmọ ẹgbẹ́ Shiite lẹ́yìn ìwọ́de
Oríṣun àwòrán, @Deadlinechic
Ọwọ sinku awọn ọlọpa ti tẹ ọgọọrọ awọn ọmọ ẹgbẹ ẹlẹsin Shiite ti wọn n fẹhonu han nile asofin apapọ ilẹ wa nilu Abuja.
Atẹjade kan ti osisẹ alarina ileesẹ ọlọpaa ilẹ wa, Anjuguri Manzah fisita salaye pe, oun ba imọ awọn ọmọ ẹgbẹ Shiite naa jẹ lati fi tipa gba akoso ile asofin apapọ ilẹ wa lọjọ Isẹgun.
Atẹjade naa ni iwọde wọọrọwọ lawọn ọmọ Shiite naa fi boju kọrọ to bẹyin yọ, ti wọn si fẹ fi tipa wọ ile asofin apapọ amọ tawọn ọlọpaa to wa nibẹ ko gba fun wọn.
Manza ni idi ree ti wọn fi yinbọn mọ ọlọpaa meji lẹsẹ, ti wọn si tun lo okuta ati ọkọ lati fi da ọgbẹ si ọlọpaa mẹfa lara, ti wọn si ti gbe wọn lọ sile iwosan.
Atẹjade naa ni ọwọ awọn ọlọpaa ti ba ogoji ọmọ ẹgbẹ Shiite ti wọn kopa ninu iwọde naa, ti iwadi si ti n lọ lọwọ.
Oríṣun àwòrán, @imnig_org
Shiite tún fẹ́ fi ẹ̀hónú hàn lórí 'ọ̀pọ̀' ọmọ ẹgbẹ́ wọn ti iléèṣẹ́ ológun Nàìjíríà pa.
Atẹjade naa wa rọ awọn olugbe ilu Abuja lati maa ba isẹ oojọ wọn lọ, ti alaafia si ti n pada jọba ni agbegbe naa.
Ẹgbẹ Musulumi Shia ti fẹsun kan awọn ọlọpaa pe, wọn pa eeyan meji to n fẹhọnu han lasiko ti wọn wa se iwọde ni Ile Igbimọ Asofin apapọ ni ilu Abuja.
Eyi waye lẹyin ti ẹgbẹ Shia se ifẹhọnu han lọ si Ile Igbimọ Asofin ni ilu Abuja, eleyii to fa yanpọn-yanrin laaarin Shia ati awọn ẹsọ alaabo Ile Igbimọ Asofin.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Àwọn mùsùlùmí Shiite kọlu àwọn ọlọ́pàá lọ́pọ̀ ìgbà nibi tí wọ́n ti ṣe ìwóbi pé k'ìjọba tú olórí wọn sílẹ̀
Iroyin fikun un wi pe, awọn ẹgbẹ Shia to wa se ifẹhọnu han naa le ni ẹgbẹẹrun, ti wọn si koju awọn ọlọpaa, ki o to di wi pe awọn ọlọpaa koju wọn.
Gbogbo ilẹkun to wọ ile igbimọ asofin naa ni wọn ti ti bayii, ti awọn asofin ko si le e jade.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Seyi Makinde: Ẹ̀kọ́ ọ̀fẹ́ tó pọn dandan ti bẹ̀rẹ̀ nílé ẹ̀kọ́ alákọ̀ọ́bẹ̀rẹ̀ àti girama ní Ọyọ
Oríṣun àwòrán, Seyi Makinde
Ijọba ipinlẹ Ọyọ tun ti tẹnumọ pe ilana oun lati pese ẹkọ ọfẹ to pọn dandan nipinlẹ Ọayọ lawọn ile ẹkọ ijọba si tun n fẹsẹ mulẹ o
Gomina ipinlẹ Ọyọ, Onimọ ẹrọ Seyi Makinde lo satẹnumọ ọrs yii latinu atẹjade kan ti olori osisẹ sba nipinlẹ Ọyọ, Arabinrin Ọlọlade Agboọla fisita.
Ijọba ipinlẹ Ọyọ ni oun ti gbẹsẹ le asa gbigba owo lawọn ileẹkọ alakọbẹrẹ ati girama to jẹ ti ijọba lasiko ti wọn se ibura fun oun.
Atẹjade naa, ti wọn fi sọwọ sawọn akọwe agba ati olori awọn ọọfisi to wa feto ẹkọ yika ipinlẹ naa tun kede pe lati ọjọ ti gomina Seyi Makinde ti di gomina ni owo gbigba lawọn ileẹkọ ijọba ti di eewọ.
Oríṣun àwòrán, Seyi Makinde
"Atẹjade ọhun fikun pe ""Mo fẹ tun tẹnumọ fun yin pe gbigba owo lawọn ile iwe labẹ etekete kankan jakejado ipinlẹ Ọyọ lodi sofin, ẹnikẹni to ba si tapa si asẹ yii laa ri bii abẹyinbẹbọjẹ, ijiya to jopin si n duro de onitọun."""
Ajínigbé: Afurasi Ajínigbé jí ọmọkùnrin kan gbé ní Ibadan, ọwọ́ tẹ̀ẹ́ ní Eko
Ẹnu ko gba iroyin ni deede aago meje alẹ ọjọ Isẹgun ni adugbo Ikoyi nilu Eko, nigba ti ọwọ palaba ọkunrin afurasi kan, ti a ko mọ orukọ rẹ, segi.
Ọkunrin naa, lawọn ọkọ ọlọpa kan sadede da duro lẹba titi, ti wọn si wọ bọ silẹ ninu ọkọ rẹ.
Ọmọdekunrin kan ti ko ju ọmọ ọdun mẹwa lọ, to wa lẹyin ọkọ rẹ, ni wọn ni afurasi naa ji gbe.
A gbọ pe ni kete ti mọto naa de oju titi Ikoyi ni ọmọdekunrin yii figbe ta pe, kawọn eeyan gba oun kalẹ lọwọ ajinigbe.
Eyi lo mu ki obinrin kan tete fi mọto sẹburu ọkọ afurasi ajinigbe naa, ti wọn si da duro pẹlu atilẹyin awọn ọlọpa to wa nitosi ibẹ.
Gbogbo igbiyanju wọn lati fi ọrọ wa afurasi naa lẹnu wo lo ja si pabo, nitori n se lo bẹrẹ si ni se bii ẹni to ni arun ọpọlọ.
Nigba ti a fi ọrọ wa ọmọdekunrin naa, to pe orukọ ara rẹ ni Ahmed Saka lẹnu wo, o ni oun lo n lọ si ẹba opopona marosẹ Ibadan si Eko, ladugbo Guru Maharaji ti mama oun ti n ta ẹran igbẹ ni.
Ahmed ni sadede ni ọkunrin afurasi naa gbe mọto rẹ duro lẹba oun, to si ni ki oun wọle sinu mọto, to si gbe oun wa silu Eko loni.
Ahmed Saka salaye pe aba Agbo, lẹba agbegbe Odumakin ni baba oun n gbe.
O fikun pe, awọn eeyan to wa ninu ọkọ naa to marun tawọn jọ de ilu Eko, amọ awọn yoku ti sọkalẹ, to si ku oun ati ọkunrin afurasi naa.
Ọmọdekunrin naa ni ọkunrin naa n dunkoko mọ oun pe, ti oun ba fi pariwo, oun yoo sọ oun di isu.
Lootọ ni ọpọ isu wa lẹyin mọto ọkunrin naa, amọ a ko lee sọ boya eeyan lo sọ di isu abi bẹẹ kọ, amọ se lo n kigbe pe isu lasan ni wọn, kii se eeyan ni oun sọ di isu,
Awọn ọlọpa to wa ni adugbo Ikoyi ti wa gbe ọkunrin afurasi naa, ati ọmọdekunrin ti wọn lo ji gbe, lọ si agọ wọn.
Ẹkunrẹrẹ iroyin yii ati fidio bi ọrọ naa se waye n bọ lọla, ẹ maa ba wa bọ.
'Tinubu 2023': 'Èmi kọ́ lò rán ẹgbẹ́ 'Asiwaju Reloaded Ambassadors' níṣẹ́ o'
Oríṣun àwòrán, Twitter/APC
Idibo aarẹ ọdun 2023
Asiwaju Bola Tinubu ti fesi si ọrọ to tan kalẹ pe oun dupo aarẹ ọrilẹede Naijiria lọdun 2023.
Tinubu to jẹ ọkan lara awọn olori ẹgbẹ oṣelu APC sọ pe ahesọ ọrọ lasan lawọn eeyan kan n gbe kiri.
"Tinubu fọrọ naa lede nigba to kẹyin si awọn ẹgbẹ kan t'orukọ wọn n jẹ ""Asiwaju Reloaded Ambassadors.''"
Awọn ẹgbẹ ọhun ni wọn wọ aṣọ ti wọn kọ ''Tinubu 2023'' si lara.
Tinubu sọrọ loju opo Twitter rẹ pe oun ko mọ ẹgbẹ naa ri, o ni pe wọn n ṣe ohun to wu wọn nitori oun ko ran wọn niṣẹ.
Ilé aṣòfin àgbà: Ìsìnmi olóṣù méjì wa kò le è ṣàkóbá fún àyẹ̀wò mínísítà
Oríṣun àwòrán, @Bashirahmaad
Aarẹ ile asofin agba, Ahmad Lawan ti kede pe, aarẹ Muhammadu Buhari yoo gbe orukọ awọn eeyan to fẹ yan sipo minisita wa siwaju ile asofin agba lati sagbeyẹwo wọn ki ọsẹ yii to pari.
Lasiko ijoko ile to waye lọjọru ni Lawan kede igbesẹ yii.
Aarẹ ile asofin agba salaye pe, ijọba apapọ n sisẹ kara lori akọsilẹ orukọ awọn eeyan to fẹ gba ipo minisita naa lọna ati ri daju pe awọn eeyan ti musemuse wọn da musemuse ni wọn yan lati sisẹ sin orilẹede yii.
O ti le ni osu kan bayii ti aarẹ Buhari ti sebura fun saa keji sugbọn ti ko ti kede awọn minisita ti yoo wa ninu ijọba rẹ.
Eyi si lo mu ki Senetọ Bassey Akpan fi pe akiyesi awọn akẹẹgbẹ rẹ lasiko ijoko ile naa pe, isẹlẹ ọhun se apakan jamọ, nitori pe awọn asofin naa yoo lọ fun isinmi olosu meji laipẹ.
Akpan ni bi aarẹ se fi iyansipo awọn minisita naa falẹ yoo se akoba fun eto ayẹwo ati fifi ontẹ lu wọn, eyi ti ile asofin agba fẹ se fun wọn.
Oríṣun àwòrán, @NationalAssembly
Nigba to n fesi lori akiyesi yii, Lawan fọwọ sọya fawọn akẹẹgbẹ rẹ atawọn ọmọ Naijiria pe, aarẹ Buhari ko ni pẹ fi orukọ naa sọwọ, eyiun ki ọsẹ yii to pari.
O ni ti awọn asofin agba naa yoo si se ayẹwo fun awọn to fẹ gba ipo minisita ọhun, ko to di pe wọn lọ fun isinmi olosu meji eyiti yoo bẹrẹ lọjọ Kẹrindinlọgbọn osu Keje taa wa yii.
AFCON 2019: Àmì ayò tí Nàíjíríà àti South Afrika gbá rèé
Oríṣun àwòrán, GIUSEPPE CACACE
Ẹni a ba laba ni baba
Ikọ agbabọọlu orileede Naijiria Super Eagles ti gbewuro soju ikọ Bafana Bafana ti South Africa lati tẹsiwaju ninu idije Afcon 2019 to n waye ni Egypt.
Samuel Chukwueze lo kọkọ gba bọọlu wọnu awọn South Africa ni iṣẹju kẹtadinlọgbọn ifẹswọnsẹ naa ki South Africa to da goolu pada ni iṣẹju karundinlọgọrin.
Bongani Zungu lo fi ori kan bọọlu sawọn Naijiria.
Oríṣun àwòrán, Khaled Desouki
William Troost Ekong lo de goolu lade fun Naijiria ni iṣẹju kọkandinlaadọrun.
Ni bayi Naijiria yoo koju Algeria tabi Ivory Coast ninu abala to kangun si aṣekagba idije naa.
Yemi Elebuibon: Babaláwo èké kò le è kii ẹsẹ mẹ́rin nínú odù ifá
Oríṣun àwòrán, Ile-ifa.org
Ní ìlú Ibadan ni Àjọ EFCC ti fi pańpẹ́ ọba mú ayédèrú babaláwo pẹ̀lú ọ̀pọ̀lọpọ̀ dúkìá tí wọ́n ti lù ní jìbìtì.
Agbaọjẹ nipa eto isegun ati ẹsin ibilẹ ni ilẹ Yoruba, Baba awo Yẹmi Ẹlẹbuibọn, ti se apejuwe awon ayederu babalawo ati awọn ọna ta fi lee da wọn mọ.
Baba Ẹlẹbuibọn la awọn eeyan lọyẹ nitori bi ajọ to n gbogun ti iwa ibajẹ lorilẹede Naijiria, EFCC, se fi panpẹ ọba mu ayederu babalawo kan ni ilu Ibadan.
Ọpọlọpọ dukia ati ile to ti fi ọna eru gba lọwọ awọn eniyan to lu ni jibiti si ni wọn ka mọ lọwọ, tijọba si ti gbẹsẹle.
Ẹlẹbuibọn, ninu ọrọ rẹ salaye lẹsẹẹsẹ nipa ba se le e mọ gbajuẹ babalawo, ta ba n sọrọ nipa eto isegun ati ẹsin ibilẹ.
Oríṣun àwòrán, EFCC
Ọna marun to fi lee mọ eke Babalawo:
Ẹlẹbuibọn, to jẹ eekan ni idi isegun ati ẹsin ibilẹ wa parọwa sawọn eniyan lati ma sakiyesi finifini, nipa ẹni ti wọn yoo tọ lọ bi babalawo.
NGARSA: Ọmọ Nàìjíríà ń retí ifẹ ẹ̀yẹ lọ́dọ̀ yín - Aarẹ́ Buhari
Àríyá ò lópin láti ìgbà tí Nàìjíríà ti júwe ilé fún South Africa
Ni Naijiria ati lorilẹede Egypt ni gbogbo awọn ọmọ Naijiria ti n fi idunu han si bi Super Eagles ṣe da sẹria iya fun Bafana Bafana.
Kete ti ifẹsẹwọnsẹ naa pari ni ariya ti bẹ sode lorilẹede Egypt laarin awọn ọmọ Naijiria to wa nibẹ.
Bakan naa ni ọrọ ikini n jẹyọ lọtun losi latọdọ awọn ọmọ Naijiria lati dupẹ lọwọ ikọ Super Eagles ati lati fi anfani naa sọ ireti wọn.
Aarẹ orileede Naijiria Muhammadu Buhari ti pẹlu awọn ọmọ Naijiria lati fi ikini ku orire ranṣẹ si ikọ Super Eagles lori bi wọn ṣe bori ikọ South Africa ninu idije AFCON.
Ami ayo si ọkan ni Naijiria fi ṣagba akẹgbẹ wọn lati tẹsiwaju lọ abala to kangun si aṣekagba.
Oríṣun àwòrán, Ahmad Bashir
Aworan Aarẹ Buhari ati ikọ Super Eagles ki wọn to gbera lọ ife ẹyẹ agbaye Russia 2018
Aarẹ Buhari ninu ọrọ to fi sita loju opo Twitter sọ pe ohun iwuri lo jẹ ti ikọ naa si ṣe afihan ifarajin ati ọkan akin eleyi ti a mọ Naijiria si.
O ni gbogbo ọmọ Naijiria lo n reti ki wọn gbe ife ẹyẹ AFCON wa si ile.
Yatọ si ikini ti aarẹ, awọn ọmọ Naijiria naa n gbe oṣuba kare fun ikọ Super Eagles.
Ninu ọrọ wọn, wọn kan sara si agbabọọlu Naijiria Chukwueze to fakọyọ ninu ifẹsẹwọnsẹ naa.
Pẹlu abajade yii, Naijiria ti tẹsiwaju lati kopa ninu abala to kangun si aṣekagba idije AFCON 2019.
Ọkan ninu Algeria tabi Ivory Coast ni wọn yoo ba pade ninu ifẹsẹwọnsẹ ti yoo waye lọjọ kẹrinla oṣu yii.
AFCON 2019: Ọmọ Nàijíríà rọ Super Eagles lati tubọ sápa wọn pẹlú Madagascar
Poly Ibadan: Lóòtọ́ ni a dáná sún fóònù àwọn akẹ́kọ̀ọ́ tó ṣe màgòmágó nínú ìdánwò
Oríṣun àwòrán, polyibadan
Ile ẹkọ gbogboniṣe Poly Ibadan ni ofin ileewe ko fayegba ki akẹkọ gbe ẹrọ ibanisọrọ wọ yara idanwo
Ko si irọ nibẹ, a dana sun foonu awọn akẹkọ wa ti wọn tapa si ofin pe ki wọn ma ṣe gbe ẹrọ alagbeka wọ inu yara idanwo.
Agbẹnusọ ile ẹkọ gbogboniṣe ti a mọ si Poly Ilu Ibadan, Ọgbẹni Soladoye Adewole  lo lede ọrọ yii fun ile iṣẹ Iroyin BBC Yoruba.
Adewole ni awọn ko ṣẹsẹ fi ikilọ sita fawọn akẹkọ lati ma ṣe gbe ẹrọ ibanisọrọ wọ yara idanwo mọ.
''Lati le jẹ ki wọn mọ pe a ko mu ọrọ naa bi awada lo jẹ ki a gbe igbeṣẹ yii, lootọ la dana sun awọn ẹrọ alagbeka ti a gba lọwọ wọn''
Iwa makaruru lasiko idanwo jẹ ipenija to n ba ẹka eto ẹkọ lorileede Naijiria jẹ ti awọn adari eto ẹkọ a si maa wa orisirisi ọna lati dẹkun rẹ.
Jijo foonu awọn akẹkọ yii ni ina jẹ ọna kan ti o mu iriwisi ọtọọtọ wa paapa julọ ti a ba ro iye owo ti wọn fi ra awọn foonu wọn yii.
Nigba ti BBC Yoruba beere lọwọ ọgbẹni Adewole pe ṣe biba awọn foonu naa jẹ ko ni da bi iwa basejẹ lati ọdọ ile ẹkọ naa, o sọ pe:
''Bi eeyan ba fi owo iyebiye ra nnkan ti yoo ṣe ipalara f'awujọ, ṣe a ma ni tori bẹẹ a ko ni gba a lọwọ rẹ tabi ki a baa jẹ ki o to le ṣe ipalara f'awujọ?''
O salaye pe ''ninu awọn akẹkọ wọn yi ni awọn ti yoo jẹ adari awujọ lọjọ iwaju yoo ti jade, ti a ko ba dẹkun iwa ibajẹ fun wọn nisinyii, kini ka ti wi ti o ba di ni ọla?''
Lọjọru ni awọn alaṣẹ Poly Ibadan da ina sun awọn foonu alagbeka ti iye owo wọn to miliọnu naira. Awọn aṣoju akẹkọọ ile iwe naa ati awọn akọroyin lo peju si ibi ti wọn ti dana sun awọn foonu wọnyi.
SERAP: Àwọn èèyàn Oyo gbọdọ̀ dásí àbá àjọ tó ń gbógun tìwà ìbàjẹ́
Oríṣun àwòrán, Facebook/Seyi makinde
Ajọ SERAP ti rọ awọn eeyan ipinlẹ Oyo lati sọ tẹnu wọn lori aba lati da ajọ to n gbogun tiwa ajẹbanu nipinlẹ naa silẹ.
Ọjọru ni Gomina Seyi Makinde gbe aba ọhun lọ siwaju ile igbimọ aṣofin lati ṣiṣẹ lori rẹ.
Igbakeji adari ajọ SERAP, Ọgbẹni Kola Oluwadare to ba BBC Yoruba sọrọ, rọ awọn ara ilu lati lọ sọ tẹnu wọn nigba ti awọn aṣofin ipinlẹ Oyo ba n gbe aba naa yẹwo.
O ni, o ṣe pataki ki awọn ọmọ ipinlẹ Oyo kopa gboogi ninu eto ati sọ aba naa dofin, ki wọn le sọ ohun ti wọn fẹ ko wa ninu ofin naa.
Ọgbẹni Oluwadare ni, eyi ko ni fun gomina lagbara lati fi ajọ naa dunkoko mọ awọn ẹgbẹ alatako ijọba rẹ.
Ẹwẹ, Gomina Makinde ṣalaye pe, igbogun tiwa ibajẹ yoo fawọn oludokowo ni igboya lati da okoowo silẹ nipinlẹ Oyo.
Koda Gomina fikun ọrọ re pe, oun ṣetan lati lọ jẹjọ niwaju ajọ to n gbogun tiwa ajẹbanu ti ẹnikẹni ba f'ẹsun iwa ibajẹ kan oun.
Ìtàn Mánigbàgbé: Òwe ‘aṣọ kò bá Ọ́mọ́yẹ mọ́... kọ́ wa láti máa ní ṣùúrù
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Awọn baba nla wa nilẹ Yoruba jẹ ọlọpọlọ pipe, ti ori wọn kun fun ọgbọn ati oye.Oniruuru nlkan si ni wọn fi maa n se akawe ọrọ bii owe, akanlo ede, afiwe ati awọn isẹlẹ miran to kọ ni lọgbọn.
Ọkan ninu awọn isẹlẹ to kọ ni lọgbọn, ti wọn sọ di owe, to si di ohun manigbagbe ni itan kan to nii se pẹlu Ọmọyẹ ati ọmọ iya rẹ.
"Itan naa si lo di owe, ti wọn fi n sọ pe ""Asọ ko ba Ọmọyẹ mọ, Ọmọyẹ ti rin ihoho wọja."""
Niwọn igba to jẹ pe bi ọmọ ko ba ba itan, yoo ba arọba, tii se baba itan, itan Ọmọyẹ yii lo ni ọpọ ọgbọ ati oye ninu, paapa fun itọni awọn ọdọ iwoyi, ti ko si yẹ ka ma mọ itumọ owe naa.
'Àwa táa jẹ́ alágbàtọ̀ gan, èèyàn ni wá, ẹ ye ṣe wa bí ẹranko'
Obinrin kan ti wọn pe orukọ rẹ ni Iyalufa lo n gbe ni ilu kan laye atijọ, eyi ti wọn n pe ni Ijaye, obinrin yii ati ọkọ rẹ ti pinya nitori aawọ ti ko ni ojutu, ti onitọun si ti fẹ iyawo miran si agbegbe Ibarapa, ti Iyalufa si n da gbe pẹlu awọn ọmọ rẹ.
Iyalufa bi ọmọbinrin meji, ọkan n jẹ Ọmọyẹni nigba ti ekeji si n jẹ Ọmọlufa, ti wọn mu lati ara orukọ iya rẹ.
Ọmọyẹni lo jẹ aburo fun Ọmọlufa, agba naa kii si se agba kan to pẹ lọ titi, tori ọdun meji pere ni wọn gba lọwọ ara wọn.
Gẹgẹ bii obinrin to n da gbe, Iyalufa n ko ba oju, to si n ko ba imu lati ri daju pe ile aye dun gbe fawọn ọmọ rẹ mejeeji.
O fẹ ki wọn lee jẹ oloriire lọjọ ọla, sugbọn gbogbo aayan obinrin yii lo so eso rere lori Ọmọlufa, to si ja si pabo lori Ọmọyẹni.
Ọmọlufa jẹ onirẹlẹ obinrin, o ni itẹriba, to si maa n gba imọran iya rẹ amọ onijagidi jagan ẹda, olori kunkun, alailẹkọ ati onipanle eniyan ni aburo rẹ, to n jẹ Ọmọyẹni, eyi ti apekuru rẹ n jẹ Ọmọyẹ.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ọmọyẹni lo jẹ aburo fun Ọmọlufa, agba naa kii si se agba kan to pẹ lọ titi, tori ọdun meji pere ni wọn gba lọwọ ara wọn.
Bi ọjọ ti n gori ọjọ, ti oṣu n gori oṣu, awọn ọmọbinrin mejeeji yii n dagba, wọn n to oju bọ, ti wọn si to ẹni to n yan isẹ ati okoowo ti wọn yoo se laayo.
Ọmọlufa yan iṣẹ agbẹ laayo, to si di agbẹ paraku, to ni oko nla, ti kii si ṣe imẹlẹ, ọwọ rẹ ji sowo, iṣu rẹ n ta, agbado rẹ n yọ ọmọ bọkua-bọkua, to si n fi owo, ounjẹ ati aṣọ kẹ iya wọn.
Ṣugbọn Ọmọyẹ, to jẹ aletilapa ọmọ ko kuku yan iṣẹ aayan laayo kan ni pato, ọlẹ, alapa-masisẹ ni, to si n ti ile ọkunrin kan bọ si omiran lai jẹ pe wọn fẹ sile nisu-lọka.
Kayefi BBC Yorùba: Bàbá ọmọ, Mọ́ṣúárì, Ọlọ́pàá kẹ́jọ́ rò nípa òkú ọmọ tó pòórá
Asẹyinwa-aṣẹyinbọ, Ọmọyẹ, to ti balaaga to ẹni ọdun ogun ọdun ri oyun apete he, lo ba loyun oge, kẹtẹkẹtẹ ba ku, ni iso ba pin.
Yoruba ni bi eegun ẹni ba jo re, ori a maa ya atọkun rẹ.
Inu Iyalufa n dun si ọpọ aseyọri Ọmọlufa amọ ibanujẹ nla lo n dori agba rẹ kodo lori ọrọ Ọmọyẹ.
Lẹyin osu mẹsan ti Ọmọyẹ ti fi inu se oyun lai ri ẹni gba lọwọ rẹ, o papa fi ẹyin gbe ọmọ pọn, o ru re, to si tun sọ re.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Yoruba ni bi eegun ẹni ba jo re, ori a maa ya atọkun rẹ.
Gẹgẹ bii aṣa iran Yoruba, Iyalufa n tọ Ọmọyẹ sọna lori awọn ọna ti yoo gba se abiamọ, ti yoo fi tọju ọmọ rẹ bo se yẹ ati awọn eewọ to rọ mọ itọju ọmọ.
Lara awọn eewọ ti Iyalufa ka fun Ọmọyẹ ni pe, iya ko gbọdọ pọn ọmọ rẹ sẹyin, ki ọmọ naa si jabọ lẹyin iya rẹ, bi eyi ba si ri bẹẹ, iya naa gbọdọ sare ni ihoho ọmọluabi wọ inu ọja ni kia-kia,were-were.
Bi bẹẹ kọ, ọkọ meje ni yoo ku mọ ọmọ naa lori, eyiun to ba jẹ obinrin, amọ ti ọmọ naa ba jẹ ọkunrin, aya meje ni yoo ku mọ ọmọkunrin naa lori to ba dagba tan.
Iyalufa kan sọ eewọ yii, gẹgẹ bi awọn agba atijọ ti maa n se lati dẹru ba awọn majesin, ki wọn ma baa hu awọn iwa kan ni, ti Ọmọyẹ ko si mọ pe ẹru lasan ni ọrọ naa.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Inu Iyalufa n dun si ọpọ aseyọri Ọmọlufa amọ ibanujẹ nla lo n dori agba rẹ kodo lori ọrọ Ọmọyẹ.
Wọn ni ọrọ agba bi ko sẹ lowurọ, yoo sẹ lọjọ alẹ.
Nigba to di ọjọ kan, ṣaa deede ni ọja ti Ọmọyẹ fi pọn ọmọ rẹ sẹyin ba tu lojiji laimọ nibi to ti bẹrẹ mọlẹ, to n fọ asọ.
Ọmọ naa jabọ lẹyin Ọmọyẹ, to si fi ori gba ilẹ.
Ọmọde yii bu sẹkun, ti ẹkun rẹ si gbalẹ. Igbe ẹkun yii ni Iyalufa gbọ ninu ile to wa, to si sare jade lati wa wo ohun to n sẹlẹ si ọmọ naa.
Ọmọyẹ bu sẹkun, to si sọ fun iya rẹ pe Ṣangba ti fọ, ọmọ oun ti jabọ lẹyin oun.
Iya rẹ binu gidigidi si i, to si gba ọmọ naa lọwọ Ọmọyẹ, pe ki oun lọ fi ẹrọ wọ ni gbogbo ara ninu ile, ki ara ma baa ro ọmọ naa, paapa ori to fi gbalẹ.
Fulani Kidnapping: Owó púpọ̀ la san kí wọ́n tó fi mi sílẹ̀
Bi Iyalufa ṣe n pẹyinda lati wọnu ile, ni Ọmọyẹ bẹrẹ si ni bọ asọ lara titi to fi wa ni ihooho ọmọluabi, to si ki ere mọlẹ, to n sare lọ sinu ọja to sun mọ adugbo wọn.
Bi Iyalufa ti ri ohun ti Ọmọyẹ se yii, lo ranti eewọ ijọsi ti oun ka fun Ọmọyẹ, ipa to lee ni ati ọna abayọ, ni oun naa ba sare mu iro ti Ọmọyẹ bọ silẹ, to si n sare lee lọ si aarin ọja, toun tọmọ lọwọ.
"Bo ṣe n lo n pariwo pe, ""ẹ ba mi mu Ọmọyẹ, ko duro fi aṣọ sara, ẹru lasan ni mo da baa pẹlu eewọ naa, ẹ jọwọ, ẹ ma jẹ ki Ọmọyẹ rin ihooho wọ ọja."""
O pẹ diẹ ki Iyalufa to pade ẹnikan to n ti ọja naa bọ, to si beere pe ṣe o ba oun ri Ọmọyẹ lọna ọja ni ihooho, tori oun fẹ fun un lasọ ti yoo fi bo ihooho rẹ ni.
Murphy Elégungun Rọba: Mo fẹ́ di ẹnití egungun rẹ rọ jùlọ ní àgbáyé
"Onitọhun se haa, to si da Iyalufa lohun pe, ""ASỌ KO BA ỌMỌYẸ MỌ, ỌMỌYẸ TI RIN IHOOHO WỌ ỌJA."""
Lati ọjọ naa si ni wọn ti maa n fi isẹlẹ yii pa owe fun ohun to ba ti kọja atunṣe, to ti bọwọ sori, ti ko si ni ojutu mọ.
Lizzy Anjọrin: Ilé tuntun tí mo rà yìí jẹ́ oríire ìyá mi tó jáláìsí
Oríṣun àwòrán, Lizzy Anjọrin
Ọpọ eeyan lo n dawọ idunnu pẹlu ilumọọka osere ori itage lobinrin, Lizzy Anjọrin ni Ọjọbọ, nigba to kede loju opo Twitter rẹ pe, Ọlọrun se oore ile tuntun nla kan fun oun.
Lizzy, ẹni to n dupẹ lọwọ Ọlọrun fun ile awodamiẹnu naa tun fikun un pe, bi ile naa ko tilẹ to ile idana ẹlomiran, sibẹ oun ki iya oun to ti jade laye ku oriire, pe oun kọ ile naa.
'Mí ò ya wèrè, mí ò burú, ọ̀nà àtijẹ là ń wá'
"Lizzy ni: ""Mo kọkọ fẹ fi ile yii pamọ ni ko to di pe mo niran pe, inu osu kẹfa si ikeje ni awọn ile ti mo ba n kọ maa n pari."
"Bẹẹ si ni asise ni yoo jẹ fun mi ti n ko ba sọ ẹri oore ti Ọlọrun se fun mi yii fun araye, ki awọn eeyan to ni ọkan rere lee ba mi gbe orukọ Allah ga."""
Nigba to n mu u wa si iranti nipa ọpọ iya to jẹ oun ati mama oun, Lizzy Anjọrin ni osu Kẹfa si Ikeje ọdun ni iya jẹ oun ati iya oun julọ gẹgẹ bii alarinkiri ti ko nile lori.
O fikun un pe mama oun lo kọ oun bi eeyan se lee fi ara pamọ si abẹ ẹru nla lasiko ti ojo ba n rọ lọwọ,.
O sọ bi awọn ṣe maa n so asọ ara awọn papọ, ki iji lile ati ẹkun omi maa ba gbe awọn lọ.
'Buhari, Saraki, Dangote, abẹ́ mi ni wọ́n wà'
Lizzy salaye pe, ko si bi awọn se lee sọra to, ori ẹsẹ awọn ni oun ati iya oun yoo sun lori iduro lasiko ti ẹkun omi ba de, tawọn yoo si maa ju ọpọ ohun ti awọn gba lawin danu nitori ilẹ to n yọ lasiko ojo.
Oríṣun àwòrán, Lizzy Anjorin
"Oju wa maa n kun fun omije pupọ nigba ti awọn ta jẹ ni gbese ba n fi wa se ẹlẹya, ti wọn si n pe wa ni orukọ buruku.
Ti wọn ba si kọ lati gba wa laaye pe ka ra nkan awin lọwọ wọn, se la maa n lọ he igbin abi eesan. A se e, ta si lọ ta wọn ni ọja ka to lee jẹun"
Gbaju gbaja osere tiata naa tun tẹ siwaju pe osu kẹfa si Ikeje ọdọọdun ni ebi maa n pa oun ati iya oun julọ, ti iya si maa n jẹ awọn ju.
'Èmi ò kí ń lu ìyàwó mi'
Bakan naa lo fikun un pe, osu kẹfa si Ikeje yii naa ni oun bi ọmọ oun ni ilu Jos lai si ibalẹ ọkan rara tabi ri ifẹ yatọ si lati ọdọ iya ọkọ oun, to si n dupẹ lọwọ mama Ijẹbu, eyiun iya rẹ.
Oríṣun àwòrán, Lizzy Anjọrin
"Ẹ jẹ ki n danu duro diẹ na, ma tun tẹsiwaju nipa itan igbesi aye mi lọjọ miran, ọjọ re.
Ma maa sọrọ iya mi lọjọ iwaju sugbọn mo dupẹ lọwọ rẹ pe o n rẹrin si mi, mo si mọ riri ọwọ aanu rẹ.
Mo dupẹ pe o jẹ ọrẹ mi tootọ lasiko yii ati titi aye."
Lizzy Anjọrin wa kede pe ile nla ti oun sẹsẹ kọ naa lo wa ni ijọba ibilẹ Eti-ọsa nipinlẹ Eko.
Ìjẹ̀bú: Àgbàlàgbà ni mo máa ń ṣe nínú eré tẹ́lẹ̀
Lizzy Anjorin: Àsìkò 'Honeymoon' ni mo dédé rí Aláàfin àti olorì méjì tó wá súre fún wa
Oríṣun àwòrán, @lizzyanjorin/alaafin_oyo
Ilumọọka osere tiata lobinrin to ṣẹṣẹ ṣe igbeyawo, Lizzy Anjorin ti kede pe, baalu kekere taa mọ si Private Jet ni baba oun, Alaafin fẹ gba bii owo ori lọdọ ọkọ oun.
Lizzy, ẹni to fi ikede naa sita loju opo Instagram rẹ tun kede pe lati igba ti Alaafin ti beere owo ori yii ni ọkọ oun ti n gbọn kiri.
Ìdílé tí ọkọ da ọmọ síta tóríi ojú Búlùú tí wọ́n ní bá BBC sọ̀rọ̀
Jẹjẹ ni emi ati ọkọ mi wa ninu ile, ta n gbadun akoko isera ẹni igbeyawo, 'Honeymoon' wa lọwọ, ni Olori Memunat ati iya mẹta pe mi.
Wọn sọ fun mi pe baba mi Alaafin n bọ lọna lati wa ki mi, ti wọn si ni Alaafin ni oun ko ni kuro nilu Eko lai fi oju kan emi ati ọkọ mi.
Lizzy fikun pe Baba oun Alaafin wa lootọ lati wa sure fun igbeyawo oun, to si beere lọwọ ọkọ oun pe baalu kekere ni ko san bii owo ori fun oun.
 Mo n yinmu si ni o nitori ti ko ba san owo ori naa, maa pada sile baba mi Alaafin nilu Oyo ni.
Lizzy Anjorin wa gboriyin fun Aláàfin pe abiyamo rere ní, to si tun ṣe apejuwe rẹ bii apọnmọ mawẹyin.
O wa n dupẹ lọwọ ọba Alaye naa lori bo ṣe jẹ eegun ẹyin fun oun, to si gbadura pe ade yoo pẹ lori rẹ.
Ilumọọka oṣere fiimu Yoruba ati ontaja ni Lizzy Anjorin lo ṣe da bii pe gbogbo igba lọrọ rẹ n jade lori iroyin.
Koda iṣọwọ gbe ọrọ jade tirẹ gan an a maa fa ohun tawọn ololufẹ rẹ atawọn to wa ni apa keji fifẹran rẹ n da si.
Lasiko yii ẹwẹ, akọsilẹ awọn ẹbun pataki ti iyawo tuntun aṣẹṣẹgbe gba fun igbeyawo rẹ pẹlu aayo ọkan rẹ, Akanbi ti wọn ṣẹṣẹ so yigi igbeyawo lopin ọsẹ to kọja lo fi sita.
Iyawo ọsingin yii n dupẹ lọwọ awọn eeyan latoori Iku Baba yeye, Alaafin Oyo, Ọba Lamidi titi dori awọn oṣiṣẹ rẹ to n ba a gbe.
O kọkọ fi fidio sita bo ṣe sun ẹkun iyawo nibi imana tawọn ọrẹ rẹ si n rọ ọ pe ẹkun ayọ lo n sun ati ọrọ to sọ bii ifọrọwanilẹnuwo nipa ọkọ rẹ.
Bi ẹ ko ba gbagbe, Lizzy fi lede pe o ti to ọdun mẹrinla ti oun ati ọkọ rẹ ti n fẹ ara wọn to fi mọ akoko ti ọrọ wọn wọ ati akoko ti ko wọ ṣugbọn ti Ọlọrun ba wọn ṣe aamin si i bayii.
"Lizzy ni ẹni akọkọ toun dupẹ lọwọ rẹ ni Ọba to pe ni ""Baami, Alaafin ti Oyo fun ẹbun owo""."
Oríṣun àwòrán, lizzy anjorin/instagram sceenshot
"Awọn agba ni ibi taa ti n ṣe la ti njẹ. Lizzy jẹwọ pe oniṣowo aṣọ loun gẹgẹ bo ṣe ri i pe latori aṣọ oke to fi ṣe imana, aṣọ iyawo funfun ti awọn oloyinbo n pe ni Wedding Gown"", Ẹgba ọrun ati tọwọ, gbogbo wiwọ to fi ṣara rindin, oun funrarẹ lo ṣe e si ara rẹ lọrun."
Ọpọlọpọ ẹbun lo kọ kalẹ ṣugbọn pabanbari rẹ to si n mu ibere wa latọdọ awọn ololufẹ rẹ ni aṣọ funfun ti ọmọ ẹkọṣẹ rẹ ti ọpọ eniyan mọ si Arikẹ fi fun un lẹbun.
Kuraani ati aṣọ pelebe funfun lati ṣe ayẹwo ibale mi eyi ti Arikẹ Adebayo fun mi.
Ti awọn ẹlẹgan ni Lizzy fi kasẹ idupẹ rẹ nilẹ bi o ṣe sọ pe oun dupẹ lọwọ gbogbo eeyan to si gbadura pe gbogbo awọn ẹlẹgan awọn ni oju yoo ti pẹlu i royin iṣerere awọn ni sisẹ n tẹle ti wọn yoo maa gbọ.
Funmi Adewara: Tele Medicine' ní a fi ń ṣàyẹ̀wò èèyàn ìdá ọgọtá láti dènà ìtànkálẹ̀ Covid
Awuyewuye ko ti i dawọ duro lori ọrọ igbeyawo Lizzy Anjorin.
Ọjọ Abamẹta ni iroyin gba ori ayelujara pé iyawo marun un ati ọpọlọpọ ọmọ ni ọkọ Lizzy Anjọrin kọ silẹ, nitori ko le fẹ ẹ.
Oríṣun àwòrán, Lizzy anjorin/instagram screenshot
Sugbọn ṣa, iyawo ẹlẹsẹ osun ọhun ti fun awọn to n gbe iroyin naa jade ni esi.
Ninu ọrọ kan to kọ si ori ayelujara Instagram rẹ, Lizzy sọ pe ọkọ oun ko ni agbara lati mojuto iyawo meji, de ibi mẹfa ti awọn eeyan n pariwo kiri.
"Mo tako gbogbo irọ to yi igbeyawo mi pẹlu ọkọ mi ka.
Nitori pe mo jẹ gbajumọ, dandan ni fun mi lati jẹ awokọṣe ninu iwa, iṣe ati irin mi.
Ṣugbọn eyi ko ni ki n di olundun, ti ko le f'esi si awọn ọrọ aida ti wọn n sọ kiri nipa mi lori ayelujara."
Oríṣun àwòrán, lizzy anjorin/instagram screenshot
Lizzy tẹsiwaju ninu ọrọ rẹ pe, ọdun mẹrinla ni oun fi ba ọkọ oun rin, eyi to fun oun ni anfaani lati mọ irinsi rẹ, ati awọn to ti fẹ ri, ṣugbọn ti ko si fẹsẹmulẹ ninu ofin igbeyawo.
"Eeyan daada lọkọ mi, oun si lo mọ idi ti ko fi fẹ wsn sile bi i iyawo.
Oríṣun àwòrán, others
Ẹwẹ, Lizzy sọ pe ọkọ oun ko mọ awọn obinrin ti aworan wọn gba ori ayelujara ri.
O pari ọrọ rẹ pẹlu imọran pe ki ẹnikẹni to ba bimọ fun ọkọ oun, o yọju si gbangba.
O ni pe oun ṣetan lati gba awọn ọmọ naa tọwọtẹsẹ, niwọn igba ti ayẹwo ba fi idi rẹ mulẹ pe ọkọ oun lo bi wọn.
Ti o ba bimọ fun ọkọ mi, tayọ-tayọ ni ma a fi gba a..."
ọmọ ni ini Oluwa. Ile awoṣi fila ti emi ati ọkọ mi ni tobi to lati gba ẹgbẹrun mẹwa ọmọ...alaafia.
Oríṣun àwòrán, lizzy anjorin/instagram sceenshot
Ṣebí tí kò bá nídìí, obìnrin kìí jẹ́ Kúmólú.
Èyì gan-an ló dífá fún òṣèrèbìnrin, to tún jẹ́ oníṣòwò, Lizzy Anjorin, tó sọ ìdí tí òun àti ọkọ rẹ̀ ṣe wà papọ̀ fún ọdún mẹ́rìnlá, kì wọ́n ó tó ó sẹ ìgbéyàwó.
Ọ̀pọ̀ èèyàn ló ti n bèèrè lábẹ́lẹ̀ pé kíló fàá tí olólùfẹ́ méjèéjì kò tètè di tọkọtaya, lẹ́yìn tí Lizzy kọ ọ́ sórí Instagram pe ọkọ òun ti wà pẹ́lù òun fún ọdún mẹ́rìnlá.
O sọ fun iwe iroyin The Punch pé, Lawal nìkan ni ọkùnrin tí ìyá òun fí ọwọ́ sí kó tó ò kú.
Mo sọ fún ìyá mi pé mo fẹ́ ẹ́ lówó lọ́wọ́ díẹ̀ kí n tó ṣe ìgbéyàwó, nítorí pé mí ò ní nkan tí mo le fi ṣe aya lọ́ọ̀dẹ̀ ọkọ.
Lizzy tẹ̀síwájú nínú ọ̀rọ̀ rẹ̀ pé, ààrùn Covid-19 tó wà l'óde ni kò jẹ́ kí ayẹyẹ nàá kó jẹ́ rẹpẹtẹ.
Ìròyìn ayọ ló jẹ́ nígbà ti Lizzy Anjonrin kéde pé òun ti di ìyàwó lọ́ọ̀dẹ̀ ọkọ.
Ọjọ́ kẹrìndínlógún, oṣù Keje, ni ayẹyẹ ìgbéyàwó nàá wáyé, ṣùgbọ́n ọjọ kejì ní ìròyìn nàá tó jáde.
Human trafficking: Ààrẹ Buhari, ẹ̀yin gómìnà ìpínlẹ̀ Yorùbá, ẹ rántí wa ní Oman, àwọn ọmọ
Nínú ọ̀rọ̀ tí Lizzy kọ sórí Instagram rẹ̀, ó dúpé púpọ̀ lọ́wọ́ ọkọ rẹ̀, tí a kò tíì mọ orúkọ rẹ̀, fún gbogbo oore tó ṣe fún òun (Lizzy) àti ìyá òun tó ti kú.
Bákan nàá nínú ọ̀rọ̀ rẹ̀, ó jọ bi ẹni pé, Lizzy ti n fẹ́ ọkùnrin náà láti bíi ọdún mẹ́rìnlá sẹ́yìn, ṣùgbọ́n wọ́n ṣẹ̀ṣẹ̀ ṣe ètò tó tọ́ àti èyí tó yẹ̀ ni lóri ìrìnàjò ìfẹ́ wọ́n.
Nínú fídíò yìí láti rí Lizzy tó n jó sí orin ìgbéyàwó tí àwọn alága ìdúró/ìjókòó n kọ.
Lára àwọn òṣèré tó kópa níbi ayẹyẹ nàá ni Seyi Edun. Bẹẹni oríṣiríṣi góólù n tanna yinrin-yinrin lọ́wọ́ ìyàwó ọ̀sìngín.
Oríṣun àwòrán, Others
Oríṣun àwòrán, Seyi Edun/instagram
Ọ̀pọ̀ àwọn olólùfẹ́ Lizzy lágbo òṣèré ló ti ń kí i kú oríire.
Kò tán síbẹ̀ o, àwọn òṣèré kan tún ṣe ayẹyẹ ọjọ́ ìbí wọn l'ọ́sẹ̀ yìí.
Samuel Olasehinde
Ọmọ kekere ọjọ́ si ti wá dàgbà báyìí, ǹjẹ ẹ ránti, ọmọdékùnrin tó ṣe fíìmù ìrù ẹṣín lọ́dún náà lọ́ùn, hẹn, ó ti ṣe ọjọ́bi lọ́sẹ̀ yìí.
Samuel Olaoluwa, Aduragbemi Olasehinde, tó jẹ́ ọmọ gbajúmọ òṣèré Pa James, ti àwọn ènìyàn tún máa n pè ni Bàbá Ajirebi ló ṣe ọjọ́ ìbí ọdún mẹ́tàdilólogun nínú ọ̀sẹ̀ yìí.
Ní nkan bi ọ̀ṣẹ̀ díẹ̀ sẹ́yìn bákan náà ni Samuel pari ètò ìsìnlẹ̀ baba ẹní, èyí tó túnmọ̀ si pé, ó ti gboye àkọ́kọ́.
Oríṣun àwòrán, Ẹ wo àwọn òṣèré àti àwọn ọmọ òṣèré tó sọjọ́ ìbí lọ
Ronke Ojo-Anthony
Lọ́sẹ̀ yìí bákan náà ni gbájúgbajà òṣèré Ronke Ojo-Anthony tí gbogbo ènìyàn mọ si Ronke Oshodi-Oke náà ṣe ọjọ́ ibí nínú.
"Nínú ọ̀rọ̀ rẹ̀ láti dúpẹ fún ìwàláàyè rẹ̀ ninú ọdún túntun, òṣèré náà kọọ́ pé, "" ẹbùn ni ìwàláàyè wá jẹ́ láti ọdọ̀ adáni wáyé'"
Olúwá ó ṣeun  tí ó tún fún mi lánfàni láti ṣe ohun àrà ọ̀tọ̀ lọ́dún tuntun.
Ọ̀pọ̀ àwọn olólùfẹ́ rẹ̀ náà ni wọ́n ń dáwọ ìdùnù fún ayẹyẹ náà.
Oríṣun àwòrán, other
Ronke Oshodi Oke
Bimbo Thomas
Lọ́sẹ̀ yìí bákan náà gbájúgbajà òṣèré Bimbo Thomas gbe e jáde lójú òpó Instagram rẹ̀ láti fi ìdunu rẹ̀ hàn lórí ọjọ́ ìbí ọmọ náà.
"Lójú òpó Instagram rẹ̀ ló ti kọ́ ọ pé ""Jayden Oluwatobiloba, ìwọ ni ǹkan to dára jùlọ tó ti ṣẹlẹ̀ si mi láyé"""
mo dúpẹ́ bi ó ṣe mú kí ayé mi ni ìtumọ̀ láti ọjọ́ ti ó di dáye
Femi Adebayo
Oríṣun àwòrán, Others
Femi Adebayo náà kò gbẹ́yìn níńu àwọn ti ọmọ wọ́n ń se ọjọ́ ibí fún ọmọ wọ́n lóri ayélújára.
"Nínú ìkíni rẹ̀ si ọmọbinrin rẹ̀ Fridous Inumidun Adebayo bí ó ṣe ń ṣe ọjọ́ ìbí ọdún mẹ́ẹ̀dógún lónìí, mo gbàdúrà pé Ọlọrun yóò fún ọ ni ẹmi gígún àti àlàfíà  tó pọ̀ fún ọ."""
Okiki Afolayan
Okiki Lawrence Afolayan jẹ́ gbájúgba oludari eré ti ọ̀ps ènìyàn  kò sì mọ̀ wọ́n nítori wọ́n sába máa n wà lẹ́yìn ìtàgé
O tí dari eré tó lé ni àádọ́jọ.
Sùgbọ́n ọ̀pọ̀ àwọn eléré tíátà ló ba adari eré náà dáwọ ìdunnu fún ayẹyẹ ọjọ́ ibí ọmọ rẹ̀
"Lóri àtẹ̀jísẹ Instagram rẹ̀, Okiki ni ""Ẹ wo ẹni to ṣe ódìgbòòṣe si ọdun mẹ́fà"""
"O ní Kí ọdún meje rẹ rẹwa bi ìwọ gan ṣe rẹwa, ọmọbinrin mi ọ̀wọ́n, ìdùnu àti ayọ tọ́ sí ọ, mo gbàdúra ki Ọọ́run fi ààbò rẹ̀ fún ọ ni ọdún méje yìí àti ni gbogbo ọjọ́ aye rẹ̀."""
Nollywood: Joke Silva ní ọkọ òun ni ìtànsán òòrùn tó ṣe iyebíye
Oríṣun àwòrán, joke silva
Gbaju-gbaja oṣere Nollywood, Olu Jacobs pe ọdun mẹtadinlọgọrin loni, ọjọ Kọkanla, oṣu Keje, ọdun 2019.
Jacobs ti kopa ninu ọpọlọpọ sinima nilẹ Naijiria ati okeere. Lọdun 2007, o gba ami ẹyẹ Africa Movie Academy Awards.
Bakan naa ni wọn fi ami ẹyẹ Industry Merit Award da a lọla, fun awọn aṣeyọri to ti ṣe gẹgẹ bi oṣere, nibi ayẹyẹ fifunni ni ami ẹyẹ Africa Magic Viewers Choice Awards.
Ninu iṣẹ ikini ku ọdun ti iyawo rẹ, ti oun naa jẹ oṣere, Joke Silva, ran si ọkọ rẹ, o ṣapejuwe Olu Jacobs gẹgẹ bi itansan oorun to ṣe iyebiye.
O ni Olu Jacobs ni itansan oorun, ologo didan ati aba ọkan oun ninu ifẹ.
Tọkọ-taya yii jọ da ileeṣẹ Lafodo Group silẹ. Ileeṣẹ naa n risi gbigbe sinima jade, o si tun ni ẹka ti wọn ti n kọ nipa iṣẹ sinima ṣiṣe.
Bo tilẹ jẹ wi pe ọpọlọpọ igbeyawo laarin awọn oṣere ni ki i fi bẹ tọjọ ni Naijiria, igbeyawo tọkọ-taya Olu Jacobs ati Joke Silva, jẹ apẹẹrẹ rere.
Oríṣun àwòrán, joke silva
Igbeyawo Olu Jacobs ati Joke Silva ti pe ọdun mẹtalelọgbọn
Laipẹ yii ni wọn ṣe ajọdun ọdun kẹtalelọgbọn ti wọn ṣegbeyawo.
Oríṣun àwòrán, others
Ìròyìn ayọ ló jẹ́ nígbà ti Lizzy Anjonrin kéde síta pé òun ti ṣe ìgbéyàwó lọ̀jọ́ kẹrìndínlógún, oṣu Kẹjọ.
Nínú ọ̀rọ̀ tí Lizzy gbe sojú òpó instagram rẹ̀, ó dúpẹ́ lọ́wọ́ ọkọ rẹ̀ tí a kò tí ì le fìdí orúkọ rẹ̀ múlẹ́, fún gbogbo oore tó ti ṣe òun, àti ìyá Lizzy tó ti d'ológbèé,  láti ìgbà tí wọ́n ti páde.
Nínú ọ̀rọ̀ rẹ̀, ó jọ bi ẹni pé, Lizzy ti n fẹ́ ọkùnrin náà láti bíi ọdún mẹ́rìnlá sẹ́yìn, ṣùgbọ́n wọ́n ṣẹ̀ṣẹ̀ ṣe ètò tó tọ́ àti èyí tó yẹ̀ ni lóri ìrìnàjò ìfẹ́ wọ́n.
Fídíò yìí ló ṣàfihàn Lizzy níbi tó ti n jó sí orin àwọn alága ìdúró/ìjókòó níbi ayẹyẹ nàá.
Lára àwọn òṣèré tó kópa níbi ayẹyẹ nàá ni Seyi Edun.
Oríṣun àwòrán, Seyi Edun/Instagram
Oríṣun àwòrán, others
Ọ̀pọ̀ àwọn olólùfẹ́ Lizzy lágbo òṣèré ló ti ń kí i kú oríire.
Kò tán síbẹ̀ o, àwọn òṣèrè tíátà míràn tún ṣe ayẹyẹ ọjọ́ ìbí wọn l'ọ́sẹ̀ yìí.
Samuel Olasehinde
Ọmọ kekere ọjọ́ si ti wá dàgbà báyìí, ǹjẹ ẹ ránti, ọmọdékùnrin tó ṣe fíìmù ìrù ẹṣín lọ́dún náà lọ́ùn, hẹn, ó ti ṣe ọjọ́bi lọ́sẹ̀ yìí.
Samuel Olaoluwa, Aduragbemi Olasehinde, tó jẹ́ ọmọ gbajúmọ òṣèré Pa James, ti àwọn ènìyàn tún máa n pè ni Bàbá Ajirebi ló ṣe ọjọ́ ìbí ọdún mẹ́tàdilólogun nínú ọ̀sẹ̀ yìí.
Ní nkan bi ọ̀ṣẹ̀ díẹ̀ sẹ́yìn bákan náà ni Samuel pari ètò ìsìnlẹ̀ baba ẹní, èyí tó túnmọ̀ si pé, ó ti gboye àkọ́kọ́.
Oríṣun àwòrán, Ẹ wo àwọn òṣèré àti àwọn ọmọ òṣèré tó sọjọ́ ìbí lọ
Ronke Ojo-Anthony
Lọ́sẹ̀ yìí bákan náà ni gbájúgbajà òṣèré Ronke Ojo-Anthony tí gbogbo ènìyàn mọ si Ronke Oshodi-Oke náà ṣe ọjọ́ ibí nínú.
"Nínú ọ̀rọ̀ rẹ̀ láti dúpẹ fún ìwàláàyè rẹ̀ ninú ọdún túntun, òṣèré náà kọọ́ pé, "" ẹbùn ni ìwàláàyè wá jẹ́ láti ọdọ̀ adáni wáyé'"
Olúwá ó ṣeun  tí ó tún fún mi lánfàni láti ṣe ohun àrà ọ̀tọ̀ lọ́dún tuntun.
Ọ̀pọ̀ àwọn olólùfẹ́ rẹ̀ náà ni wọ́n ń dáwọ ìdùnù fún ayẹyẹ náà.
Oríṣun àwòrán, other
Ronke Oshodi Oke
Bimbo Thomas
Lọ́sẹ̀ yìí bákan náà gbájúgbajà òṣèré Bimbo Thomas gbe e jáde lójú òpó Instagram rẹ̀ láti fi ìdunu rẹ̀ hàn lórí ọjọ́ ìbí ọmọ náà.
"Lójú òpó Instagram rẹ̀ ló ti kọ́ ọ pé ""Jayden Oluwatobiloba, ìwọ ni ǹkan to dára jùlọ tó ti ṣẹlẹ̀ si mi láyé"""
mo dúpẹ́ bi ó ṣe mú kí ayé mi ni ìtumọ̀ láti ọjọ́ ti ó di dáye
Femi Adebayo
Oríṣun àwòrán, Others
Femi Adebayo náà kò gbẹ́yìn níńu àwọn ti ọmọ wọ́n ń se ọjọ́ ibí fún ọmọ wọ́n lóri ayélújára.
"Nínú ìkíni rẹ̀ si ọmọbinrin rẹ̀ Fridous Inumidun Adebayo bí ó ṣe ń ṣe ọjọ́ ìbí ọdún mẹ́ẹ̀dógún lónìí, mo gbàdúrà pé Ọlọrun yóò fún ọ ni ẹmi gígún àti àlàfíà  tó pọ̀ fún ọ."""
Okiki Afolayan
Okiki Lawrence Afolayan jẹ́ gbájúgba oludari eré ti ọ̀ps ènìyàn  kò sì mọ̀ wọ́n nítori wọ́n sába máa n wà lẹ́yìn ìtàgé
O tí dari eré tó lé ni àádọ́jọ.
Sùgbọ́n ọ̀pọ̀ àwọn eléré tíátà ló ba adari eré náà dáwọ ìdunnu fún ayẹyẹ ọjọ́ ibí ọmọ rẹ̀
"Lóri àtẹ̀jísẹ Instagram rẹ̀, Okiki ni ""Ẹ wo ẹni to ṣe ódìgbòòṣe si ọdun mẹ́fà"""
"O ní Kí ọdún meje rẹ rẹwa bi ìwọ gan ṣe rẹwa, ọmọbinrin mi ọ̀wọ́n, ìdùnu àti ayọ tọ́ sí ọ, mo gbàdúra ki Ọọ́run fi ààbò rẹ̀ fún ọ ni ọdún méje yìí àti ni gbogbo ọjọ́ aye rẹ̀."""
Nollywood: Joke Silva ní ọkọ òun ni ìtànsán òòrùn tó ṣe iyebíye
Oríṣun àwòrán, joke silva
Gbaju-gbaja oṣere Nollywood, Olu Jacobs pe ọdun mẹtadinlọgọrin loni, ọjọ Kọkanla, oṣu Keje, ọdun 2019.
Jacobs ti kopa ninu ọpọlọpọ sinima nilẹ Naijiria ati okeere. Lọdun 2007, o gba ami ẹyẹ Africa Movie Academy Awards.
Bakan naa ni wọn fi ami ẹyẹ Industry Merit Award da a lọla, fun awọn aṣeyọri to ti ṣe gẹgẹ bi oṣere, nibi ayẹyẹ fifunni ni ami ẹyẹ Africa Magic Viewers Choice Awards.
Ninu iṣẹ ikini ku ọdun ti iyawo rẹ, ti oun naa jẹ oṣere, Joke Silva, ran si ọkọ rẹ, o ṣapejuwe Olu Jacobs gẹgẹ bi itansan oorun to ṣe iyebiye.
O ni Olu Jacobs ni itansan oorun, ologo didan ati aba ọkan oun ninu ifẹ.
Tọkọ-taya yii jọ da ileeṣẹ Lafodo Group silẹ. Ileeṣẹ naa n risi gbigbe sinima jade, o si tun ni ẹka ti wọn ti n kọ nipa iṣẹ sinima ṣiṣe.
Bo tilẹ jẹ wi pe ọpọlọpọ igbeyawo laarin awọn oṣere ni ki i fi bẹ tọjọ ni Naijiria, igbeyawo tọkọ-taya Olu Jacobs ati Joke Silva, jẹ apẹẹrẹ rere.
Oríṣun àwòrán, joke silva
Igbeyawo Olu Jacobs ati Joke Silva ti pe ọdun mẹtalelọgbọn
Laipẹ yii ni wọn ṣe ajọdun ọdun kẹtalelọgbọn ti wọn ṣegbeyawo.
Oríṣun àwòrán, others
Ìròyìn ayọ ló jẹ́ nígbà ti Lizzy Anjonrin kéde síta pé òun ti ṣe ìgbéyàwó lọ̀jọ́ kẹrìndínlógún, oṣu Kẹjọ.
Nínú ọ̀rọ̀ tí Lizzy gbe sojú òpó instagram rẹ̀, ó dúpẹ́ lọ́wọ́ ọkọ rẹ̀ tí a kò tí ì le fìdí orúkọ rẹ̀ múlẹ́, fún gbogbo oore tó ti ṣe òun, àti ìyá Lizzy tó ti d'ológbèé,  láti ìgbà tí wọ́n ti páde.
Nínú ọ̀rọ̀ rẹ̀, ó jọ bi ẹni pé, Lizzy ti n fẹ́ ọkùnrin náà láti bíi ọdún mẹ́rìnlá sẹ́yìn, ṣùgbọ́n wọ́n ṣẹ̀ṣẹ̀ ṣe ètò tó tọ́ àti èyí tó yẹ̀ ni lóri ìrìnàjò ìfẹ́ wọ́n.
Fídíò yìí ló ṣàfihàn Lizzy níbi tó ti n jó sí orin àwọn alága ìdúró/ìjókòó níbi ayẹyẹ nàá.
Lára àwọn òṣèré tó kópa níbi ayẹyẹ nàá ni Seyi Edun.
Oríṣun àwòrán, Seyi Edun/Instagram
Oríṣun àwòrán, others
Ọ̀pọ̀ àwọn olólùfẹ́ Lizzy lágbo òṣèré ló ti ń kí i kú oríire.
Kò tán síbẹ̀ o, àwọn òṣèrè tíátà míràn tún ṣe ayẹyẹ ọjọ́ ìbí wọn l'ọ́sẹ̀ yìí.
Samuel Olasehinde
Ọmọ kekere ọjọ́ si ti wá dàgbà báyìí, ǹjẹ ẹ ránti, ọmọdékùnrin tó ṣe fíìmù ìrù ẹṣín lọ́dún náà lọ́ùn, hẹn, ó ti ṣe ọjọ́bi lọ́sẹ̀ yìí.
Samuel Olaoluwa, Aduragbemi Olasehinde, tó jẹ́ ọmọ gbajúmọ òṣèré Pa James, ti àwọn ènìyàn tún máa n pè ni Bàbá Ajirebi ló ṣe ọjọ́ ìbí ọdún mẹ́tàdilólogun nínú ọ̀sẹ̀ yìí.
Ní nkan bi ọ̀ṣẹ̀ díẹ̀ sẹ́yìn bákan náà ni Samuel pari ètò ìsìnlẹ̀ baba ẹní, èyí tó túnmọ̀ si pé, ó ti gboye àkọ́kọ́.
Oríṣun àwòrán, Ẹ wo àwọn òṣèré àti àwọn ọmọ òṣèré tó sọjọ́ ìbí lọ
Ronke Ojo-Anthony
Lọ́sẹ̀ yìí bákan náà ni gbájúgbajà òṣèré Ronke Ojo-Anthony tí gbogbo ènìyàn mọ si Ronke Oshodi-Oke náà ṣe ọjọ́ ibí nínú.
"Nínú ọ̀rọ̀ rẹ̀ láti dúpẹ fún ìwàláàyè rẹ̀ ninú ọdún túntun, òṣèré náà kọọ́ pé, "" ẹbùn ni ìwàláàyè wá jẹ́ láti ọdọ̀ adáni wáyé'"
Olúwá ó ṣeun  tí ó tún fún mi lánfàni láti ṣe ohun àrà ọ̀tọ̀ lọ́dún tuntun.
Ọ̀pọ̀ àwọn olólùfẹ́ rẹ̀ náà ni wọ́n ń dáwọ ìdùnù fún ayẹyẹ náà.
Oríṣun àwòrán, other
Ronke Oshodi Oke
Bimbo Thomas
Lọ́sẹ̀ yìí bákan náà gbájúgbajà òṣèré Bimbo Thomas gbe e jáde lójú òpó Instagram rẹ̀ láti fi ìdunu rẹ̀ hàn lórí ọjọ́ ìbí ọmọ náà.
"Lójú òpó Instagram rẹ̀ ló ti kọ́ ọ pé ""Jayden Oluwatobiloba, ìwọ ni ǹkan to dára jùlọ tó ti ṣẹlẹ̀ si mi láyé"""
mo dúpẹ́ bi ó ṣe mú kí ayé mi ni ìtumọ̀ láti ọjọ́ ti ó di dáye
Femi Adebayo
Oríṣun àwòrán, Others
Femi Adebayo náà kò gbẹ́yìn níńu àwọn ti ọmọ wọ́n ń se ọjọ́ ibí fún ọmọ wọ́n lóri ayélújára.
"Nínú ìkíni rẹ̀ si ọmọbinrin rẹ̀ Fridous Inumidun Adebayo bí ó ṣe ń ṣe ọjọ́ ìbí ọdún mẹ́ẹ̀dógún lónìí, mo gbàdúrà pé Ọlọrun yóò fún ọ ni ẹmi gígún àti àlàfíà  tó pọ̀ fún ọ."""
Okiki Afolayan
Okiki Lawrence Afolayan jẹ́ gbájúgba oludari eré ti ọ̀ps ènìyàn  kò sì mọ̀ wọ́n nítori wọ́n sába máa n wà lẹ́yìn ìtàgé
O tí dari eré tó lé ni àádọ́jọ.
Sùgbọ́n ọ̀pọ̀ àwọn eléré tíátà ló ba adari eré náà dáwọ ìdunnu fún ayẹyẹ ọjọ́ ibí ọmọ rẹ̀
"Lóri àtẹ̀jísẹ Instagram rẹ̀, Okiki ni ""Ẹ wo ẹni to ṣe ódìgbòòṣe si ọdun mẹ́fà"""
"O ní Kí ọdún meje rẹ rẹwa bi ìwọ gan ṣe rẹwa, ọmọbinrin mi ọ̀wọ́n, ìdùnu àti ayọ tọ́ sí ọ, mo gbàdúra ki Ọọ́run fi ààbò rẹ̀ fún ọ ni ọdún méje yìí àti ni gbogbo ọjọ́ aye rẹ̀."""
Nollywood: Joke Silva ní ọkọ òun ni ìtànsán òòrùn tó ṣe iyebíye
Oríṣun àwòrán, joke silva
Gbaju-gbaja oṣere Nollywood, Olu Jacobs pe ọdun mẹtadinlọgọrin loni, ọjọ Kọkanla, oṣu Keje, ọdun 2019.
Jacobs ti kopa ninu ọpọlọpọ sinima nilẹ Naijiria ati okeere. Lọdun 2007, o gba ami ẹyẹ Africa Movie Academy Awards.
Bakan naa ni wọn fi ami ẹyẹ Industry Merit Award da a lọla, fun awọn aṣeyọri to ti ṣe gẹgẹ bi oṣere, nibi ayẹyẹ fifunni ni ami ẹyẹ Africa Magic Viewers Choice Awards.
Ninu iṣẹ ikini ku ọdun ti iyawo rẹ, ti oun naa jẹ oṣere, Joke Silva, ran si ọkọ rẹ, o ṣapejuwe Olu Jacobs gẹgẹ bi itansan oorun to ṣe iyebiye.
O ni Olu Jacobs ni itansan oorun, ologo didan ati aba ọkan oun ninu ifẹ.
Tọkọ-taya yii jọ da ileeṣẹ Lafodo Group silẹ. Ileeṣẹ naa n risi gbigbe sinima jade, o si tun ni ẹka ti wọn ti n kọ nipa iṣẹ sinima ṣiṣe.
Bo tilẹ jẹ wi pe ọpọlọpọ igbeyawo laarin awọn oṣere ni ki i fi bẹ tọjọ ni Naijiria, igbeyawo tọkọ-taya Olu Jacobs ati Joke Silva, jẹ apẹẹrẹ rere.
Oríṣun àwòrán, joke silva
Igbeyawo Olu Jacobs ati Joke Silva ti pe ọdun mẹtalelọgbọn
Laipẹ yii ni wọn ṣe ajọdun ọdun kẹtalelọgbọn ti wọn ṣegbeyawo.
Seyi Makinde gbàlejò Abdulsalami Abubakar ní Ibadan
Oríṣun àwòrán, Oyo state
Gomina ipinlẹ Ọyọ, Seyi Makinde ti se apejuwe adari orilẹede Naijiria nigba kan ri, Abdusalami Abubakar gẹgẹ bi baba to ni ifẹ si ilosiwaju orilẹẹde Naijiria.
Seyi Makinde sọ eyi lasiko to n gbalejọ Abubakar Abdusalami ni ilu Ibadan.
Makinde ni ijọba ti setan lati se ohun gbogbo to yẹ lati ri wi pe eto aabo gbooro si ni ipinlẹ Ọyọ.
Abdusalam, nigba to n fesi, gboriyin fun gomina Makinde, to si ni ọgbọn ati imọ to n lo nigba to n sisẹ aladani yoo ran an lọwọ lati tukọ ipinlẹ naa de ibi aseye.
Adari Naijiria nigba kan naa wa rọ ijọba ipinlẹ Ọyọ lati ri wi pe wọn seto igbaye gbadun fun awọn olugbe ipinlẹ naa.
Ọgaagun Abdulsalami Abubakar jẹ adari orilẹede Naijiria ni ọdun 1998 si ọdun 1999.
Oríṣun àwòrán, OYO STATE
Ọgaagun Abdulsalami abubakar jẹ adari orilẹede Naijiria ni ọdun 1998 si ọdun 1999.
Seyi Makinde ati Adari Ile Asofin Ipinlẹ Ọyọ, Adebo Ogundoyin lo fi tọwọtọwọ ki Abdusalami Abubakar kaabọ si ipinlẹ naa.
Gomina naa si fi ami ẹyẹ aworan ti wọn fi owo ya, da ajagunfẹyinti naa lọla.
Oríṣun àwòrán, Oyo State
Fásitì Ibadan: Kò sí àkẹ́kọ̀ọ́ obìnrin tí wọ́n fipá bá lòpọ̀
Oríṣun àwòrán, University of Ibadan
Eemọ nla lo wọ ileekọ fasiti Ibadan mọjumọ ọjọ Ẹti nigba ti awọn adigunjale to to mẹwa niye ba ibugbe awọn obinrin, Obafemi Awolowo, to wa ninu ọgba ileekọ naa lalejo.
Niwọn igba to jẹ pe ole kii wa, bikose lati jale, lati pa ati lati parun, awọn adigunjale yii se akẹkọ meji lese, ko to di pe wọn na papa bora.
Nigba to n ba BBC Yoruba sọrọ lori isẹlẹ yii, osisẹ alarina fun ileekọ fasiti Ibadan, Ọgbẹni Tunji Ọladẹjọ fi idi isẹlẹ naa mulẹ pẹlu afikun pe awọn adigunjale naa gba ọpọ ẹrọ ilewọ alagbeka lọwọ awọn akẹkọbinrin naa.
Ọladẹjọ salaye pe, irọ to jinna sootọ ni ahesọ ti awọn eeyan kan n gbe kiri pe awọn adigunjale naa fi tipa awọn awọn akẹkọbinrin ọhun lo pọ.
Osisẹ alarina fun ọgba fasiti Ibadan ni ni kete ti iroyin kan awọn osisẹ alaabo to wa lọgba ileeẹkọ naa, ni wọn ti ta mọra, ti wọn si kesi awọn ọlspa lati wa kun wọn lọwọ.
Oríṣun àwòrán, Olamide
O fikun pe, ni kete ti awọn ọlọpa naa de pẹlu ọga agba ọlọpa to n dari agọ ọlọpa to wa ni Sango nilu Ibadan, ni awọn adigunjale ọhun fẹsẹ fẹ.
Oríṣun àwòrán, University of Ibadan
Ọladẹjọ wa mu da awọn akẹkọ to wa lọgba fasiti Ibadan, awọn obi wọn ati gbogbo awujọ lapapọ pe, ko si ewu kankan loko nipa eto aabo ile ẹkọ naa, nitori awọn alasẹ ileekọ ọhun ti setan lati mu agbega ba eto aabo rẹ, ki iru isẹlẹ yii ma baa waye mọ.
Iyalode Ibadan: Olubadan jáwé oyè lé Ìyálóde tuntun lórí
Oríṣun àwòrán, Olubadan Palace
Olubadan ilẹ Ibadan, Ọba Saliu Adetunji, Aje Ogungunniso ti jawe oye fun Iyalode tuntun fun ilẹ Ibadan, Agba oye Theresa Laduntan Oyekanmi.
Ayẹyẹ iwuye naa to wa ni aafin Olubadan lọjọ Ẹti lo waye lẹyin ti gomina ipinlẹ Ọyọ, Onimọ ẹrọ Seyi Makinde fọwọsi igbega iyalode tuntun fun ilẹ Ibadan naa.
Oloye Oyekanmi yii si lo di Iyalode ilẹ Ibadan Kẹrinla, to si ni igbega si ipo naa lẹyin ti Alhaja Aminat Abiọdun, tii se Iyalode ilẹ Ibadan Kẹtala papoda lọdun to kọja.
Oloye Laduntan Oyekanmi, tii se ẹni ọ̀dun mẹrindinlaadọrun, nii se ọmọbibi agboole Ladapọ ladugbo Abẹbi ati agboole Balogun Ibikunle ladugbo Ayẹyẹ nilu Ibadan.
Akọsẹmọsẹ olutọju alaisan ni Iyalode tuntun yii to si kẹkọ gboye nilẹ Gẹẹsi lọdun 1960, o si se igbeyawo pẹlu Amofin Diti Oyekanmi to wa lati agboole Matanmi nilu Osogbo lọdun 1961.
Oríṣun àwòrán, Olubadan Palace
Iyalode Ilẹ Ibadan tuntun yii fẹyinti gẹgẹ bii Nọọsi nile iwosan Oritamẹfa (UCH) nilu Ibadan.
BBC wa gbadura pe igba Oloye Laduntan Oyekanmi gẹgẹ bii Iyalode tuntun fun ilẹ Ibadan yoo tu gbogbo olugbe Ibadan lara.
Afenifere: Àsìkò tó tá tako ìkọlù darandaran nílẹ̀ Yorùbá
Oríṣun àwòrán, @chimbiko_jerome
Iroyin to n tẹ wa lọwọ ni yajoyajo ti fiyeni pe awọn afurasi Fulani darandaran kan ti yinbọn pa ọmọbinrin alaga ẹgbẹ Afẹnifẹre, alagba Reuben Fasoranti.
Orukọ oloogbe naa ni Funkẹ Ọlakunrin, tii se ẹni ọdun mejidinlọgọta.
Lasiko to n fi idi isẹlẹ naa mulẹ fun BBC Yoruba, agbẹnusọ fun ẹgbẹ Afẹnifẹre, Yinka Odumakin salaye pe lootọ ni isẹlẹ naa waye, asiko ti Ọlakunrin n bọ lati ilu Akurẹ si lo se alabapade iku ojiji naa.
Odumakin salaye pe, obinrin ọhun ati awọn ọmọ ọdọ rẹ ni wọn n bọ lẹnu irinajo naa, asiko ti wọn de ikorita Ọrẹ si lawọn afurasi darandaran yii kọlu wọn, ti wọn si n yinbọn mọ wọn laibikita.
O ni ibọn ba Ọlakunrin ati awọn ọmọ ọdọ rẹ, amọ obinrin naa ni ẹjẹ ko tete da lara rẹ titi to fi gbe ẹmi mi, ti awọn ọmọ ọdọ rẹ si wa nile iwosan nibi ti wọn ti n gba itọju lọwọ.
Oríṣun àwòrán, Oyo state govt
Odumakin, ẹni ti isẹlẹ naa ba lojiji fikun pe, igba keji ree ti alagba Fasoranti yoo padanu ọmọ rẹ, eyi to ba eeyan ninu jẹ pupọ.
O wa gbarata pe, ilẹ Yoruba yoo dide lati tako ikọlu awọn darandaran yii nitori pe ọrọ naa ti de ojuẹ.
'Àwa táa jẹ́ alágbàtọ̀ gan, èèyàn ni wá, ẹ ye ṣe wa bí ẹranko'
O ni awọn ikọlu afurasi Fulani ti n legba kan ju ọrin lọ, to si dabi ẹni pe wọn fẹ gbogun ti ilẹ Yoruba ni.
Agbẹnusọ fun ẹgbẹ Afnifẹre ni agbara ojo awọn darandaran yii ko ni oun ko nile wo, amọ awọn onile ni ko ni gba fun.
NNPC pàṣẹ fáwọn òǹtàjà epo pé owó epo bẹntiróòlù kò gbọdọ̀ lé ní N145
Oríṣun àwòrán, @Bolarinwaiyanu
Ileeṣẹ epo rọbi lorilẹede Naijiria, NNPC ti kede pe, oun ko ni erongba lati fi owo kun owo ori epo lorilẹede Naijiria.
Ninu atẹjade kan to fi sita nilu Abuja, ajọ NNPC rọ awọn onimọto lati maṣe tẹti si ahesọ kan to n lọ kaakiri pe ajọ NNPC n gbero ati fi kun owo epo.
Ajọ naa ni, oludari agba NNPC, Mallam Mele Kyari fara han niwaju ile igbimọ́ asofin apapọ Naijiria lọjọ iṣẹgun, ko si sọ ohunkohun nibẹ to lee tọka si pe, afikun fẹ de ba owo epo bẹntiroolu.
Agbẹnusọ fun ajọ NNPC, Ndu Ughamadu ṣalaye pe, lootọ̀ ni oludari agba ajọ NNPC lọ sọdọ aarẹ ile aṣofin agba, Sẹnatọ Ahmad Lawan.
O ni lasiko ipade wọn, ohun ti wọn jiroro le lori ni pe akoso owo ori epo lorilẹede Naijiria buru pupọ, ta ba gbe yẹwo si tawọn orilẹede yoku lẹkun iwọ oorun Afirika.
Oríṣun àwòrán, @NNPCgroup
O ni eleyi lo n fi aye silẹ fun awọn ti o n ṣe fayawọ epo lati maa tẹsiwaju ninu iwa ibajẹ wọn atipe, atilẹyin ile aṣofin apapọ ni ajọ NNPC n wa lati dẹkun iwa fayawọ epo rọbi naa.
Ajọ NNPC wa rọ awọn ọmọ Naijiria lati fi ọkan wọn balẹ o nitori ko si ohun to jọ fifowo kun epo bayii.
O ni gẹgẹ bii aṣẹ to wa lati ọdọ awọn ajọ to n mojuto owo ori epo, naira marundinlaadọjọ ṣi ni iye owo bẹntiroolu, ti ko si yi pada.
O wa kii nilọ fawọn ileeṣẹ to n ta epo, lati maṣe yi owo kuro ni naira marundinlaadọjọ lori lita epo pẹtiro kan.
'Àwa táa jẹ́ alágbàtọ̀ gan, èèyàn ni wá, ẹ ye ṣe wa bí ẹranko'
MURIC pè fún ìwọ́de lẹ́yìn Jumat láti tako ìgbésẹ̀ ISI lórí Hijab wíwọ̀
Ọrọ lori gbigba ibori Hijab lori awọn akẹkọ ileewe girama ISI ni fasiti Ibadan ti fa ọpọ awuyewuye sẹyin.
Amọṣa, titi di bi a ṣe n sọrọ yii, ọrọ naa ko tii jẹ rodo lọ momi.
Ni bayii, ẹgbẹ kan to n ja fun ẹtọ awọn musulumi, MURIC ti pe fun iwọde lati fi ẹhonu han lori ọrọ naa.
Ninu ifọrọwerọ rẹ pẹlu BBC Yoruba, olori ẹgbẹ MURIC, Ọjọgbọn Ishaq Akintọla ṣalaye pe, gbogbo ọna to tọ lawọn ti gba lati yanju ọrọ naa ni tubinubi, ṣugbọn kaka ki ewe agbọn rẹ dẹ, pipele lo n pele sii.
Ọjọgbọn Ishaq Akintọla ni ẹgbẹ MURIC ti ke sawọn musulumi kaakiri ẹkun iwọ oorun gusu orilẹede Naijiria, lati gunle iwọde alaafia lẹyin isin Jumat ni ọjọ ẹti pẹlu aṣọ funfun lati fi ẹhonu han lori iṣẹlẹ naa.
Oríṣun àwòrán, University of Ibadan
O ni ko si awijare fun igbesẹ ti awọn alaṣẹ ileewe girama ISI ni fasiti ilu Ibadan n gbe, labẹ ofin nipa fifofin de elo ibori Hijab ni ileewe naa.
Oloyede ni kaakiri agbaye ni awọn ọmọbinrin ẹlẹsin musulumi ti n lo ibori Hijab sinu imura wọn, ati pe, ọgbọn ati fi ẹtọ ẹkọ dun awọn ọmọbinrin to jẹ ẹlẹsin musulumi ni ileewe naa.
Ni ọdun 2018 ni wahala lori wiwọ ibori Hijab bẹrẹ ni ileewe girama ISI ni fasiti ilu Ibadan, eleyi ti o tilẹ ti de ile ẹjọ pada.
Ọlọwọ: Olùdarí ètò ìṣúná àti àkóso ní Ondo ni Ogunoye tó di Ọlọwọ tuntun
Ilu Ọwọ ti ni ọba tuntun bayii, orukọ ọba tuntun ti awọn afọbajẹ ilu Ọwọ ṣẹṣẹ dibo yan lọjọ Ẹti ni Ọmọọba Ajibade Ogunoye.
Ogunoye, tii se oludari eto isuna ati akoso nipinlẹ́ Ondo ki wọn to yan sipo naa, ni yoo jẹ Ọlọwọ kejilelọgbọn.
Tilu tifọn ni awọn eeyan ilu Ọwọ fi jade lẹyin ti wọn gbọ ikede orukọ ọba wọn tuntun naa.
Mẹrinla ninu awọn afọbajẹ marundinlogun to wa ni ilu Ọwọ ni wọn dibo fun Ọmọọba Ajibade Ogunoye.
Ni ọjọ kẹtadinlogun oṣu kẹrin ọdun 2019 ni Ọba ana waja eleyi to ṣilẹkun fun awọn idile oye atawọn ọmọ oye lati du ipo naa.
Afenifere: Ọlọ́pàá kò le sọ bóyá Fulani darandaran ló pa Funke Olakunrin
Oríṣun àwòrán, Google
Alagbà Fasoranti àti ọmọ rẹ̀, Funke Ọlakunrin
Agbẹnusọ ileeṣẹ ọlọpaa nipinlẹ Ondo, Ọgbẹni Femi Joseph ti fidirẹmulẹ fun BBC Yoruba pe lootọ ni awọn kan ṣekupa ọmọ Alaga fun ẹgbẹ Afẹnifẹre, Oloye Reuben Fasoranti, Funke Olakunrin loju ọna Ore si Benin.
Femi Joseph sọ pe ni nkan bi aago meji ọsan ọjọ Ẹti, ọjọ kejila, oṣu Keje ni iṣẹlẹ naa waye. Ati wi pe oloogbe Olakunrin ni ibọn ba lara awọn eniyan to wa ninu ọkọ meji ti wọn da duro.
Kí ló ń fa awuyewuye nípa ikú ọmọ alága ẹgbẹ́ Afenifere?
Fulani Kidnapping: Owó púpọ̀ la san kí wọ́n tó fi mi sílẹ̀
"Nkan ti ileeṣẹ ọlọpaa le sọ ni pe agbebọn ni awọn to ṣe ikọlu naa, nitori pe a ko ti i ni aridaju pe ẹya kan, Fulani darandaran tabi adigunjale ni wọn.''
Eniyan meje mii ti wọn ji gbe ni a ri doola lanaa loju ẹsẹ ti a de ibi ti iṣẹlẹ naa ti waye, ti a si n wa ẹnikan to ku lara awọn eero ọkọ keji."
"Ọkọ Oloogbe Olakunrin ati ọkọ Toyota Camry kan ti ileeṣẹ akero The Young Shall Grow ni wọn da duro."""
CAN: Samson ni ọrọ awọn ajinigbe ti gba àpérò ní Naijiria
"Ẹlomii ko farapa, awọn ti a doola si ti n ran wa lọwọ pẹlu iwadii iṣẹlẹ naa.
Awọn ti a doola sọ fun wa pe awọn to kọlu wọn to mẹẹdogun niye, ti wọn si gbe ibọn alagbara dani.''
Oriṣiriṣi ariyanjiyan lo ti n waye lori iru eniyan ti awọn to ṣe ikọlu naa jẹ.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí:
Ààrẹ tẹ́lẹ̀, Olusegun Obasanjo kọ̀wé ìbánikẹ́dùn sí aṣíwájú Afẹ́nifẹ́re, Rueben Fáṣọ̀ràntì lórí ikú ọmọ rẹ̀
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ọpọ awọn eekan lo ti n wi tẹnu wọn lori iṣẹlẹ buruku naa
Ibi ọrọ de duro bayii ti fihan pe ipenija abo to mẹhẹ lorilẹede Naijiria nilo amojuto ni kiakia.
Aarẹ orilẹede Naijiria nigbakan ri, Oluṣẹgun Ọbasanjọ lo pariwo sita ninu lẹta ibanikẹdun to kọ ranṣẹ si aṣiwaju ẹgbẹ afẹnifẹre, alagba Rueben Faṣọranti lori ajalu iku ọmọ rẹ obinrin, Funkẹ Ọlakunrin.
Oloye Oluṣẹgun Ọbasanjọ koro oju si bi awọn agbebọn kan ṣe pa arabinrin naa to si pe awọn agbofinro nija lori riri awọn to ṣiṣẹ laabi ọhun.
Bi o tilẹ jẹ wi pe ariwo awọn ajinigbe pawo ni ileeṣẹ ọlọpaa npa lori iṣẹlẹ ọhun ṣugbọn agbẹnusọ fun ẹgbẹ Afẹnifẹre, Yinka Odumakin ni rara o, ọwọ awọn darandaran la ba nibẹ.
'Mo sun ẹkún kíkorò nígbà tí a kí ara wa kẹ́yìn'
Ọbasanjọ sọ ninu lẹta rẹ pe, iṣeku pa arabinrin Olakunrin ba ni ninu jẹ paapaa lasiko yii ti ọpọ awọn aṣiwaju orilẹede Naijiria n pe fun iṣọkan, ikonimọra ninu eto oṣelu orilẹede Naijiria.
Nibayii, aarẹ Muhammadu Buhari ti paṣẹ fawọn oṣiṣẹ alaabo gbogbo lorilẹede Naijiria lati bẹẹrẹ iṣẹ lori ṣiṣawari awọn to yinbọn pa ọmọ alagba Rueben Faṣọranti obinrin lopopona Ondo si Ọrẹ lọjọ Ẹti.
Ninu ọrọ ibanikẹdun rẹ, aarẹ Buhari pẹlu tun gbadura itunu fun alagba Faṣọranti.
Àwọn agbébọn jí ìyàwó bàbá Sẹ́nétọ̀ Abbo tó lu obìnrin nílùú Abuja gbé ní Adamawa
Oríṣun àwòrán, Nigeria National Assembly
Sẹnetọ Abbo sọ fun BBC news Yoruba pe iya oun gan ni wọn kọkọ n beere fun kí wọn to fi ipa ji iyawo baba oun to ṣẹṣẹ bimọ gbe
Ṣe ẹ ranti Sẹnetọ Ishaku Abbo ti fidio fihan laipẹ yii nibi to ti n lu arabinrin kan nile itaja nilu Abuja?
Awọn agbebọn ti pa mọlẹbi rẹ kan; wọn si tun ti ji orogun iya rẹ kan gbe lọ lasiko ti wọn kọlu ilu rẹ nipinlẹ Adamawa lọjọ satide.
Sẹnetọ Abbo ṣalaye fun BBC News Yoruba pe ile ẹbi oun lagbegbe Muchalla nijọba ibilẹ Mubi North nipinlẹ Adamawa ni nnka bii agogo kan oru.
Sẹnetọ Abbo ṣalaye pe iya oun ni awọn agbebọn naa kọkọ beere lọwọ baba oun nigba ti wọn wọle wa pẹlu ibọn AK47 lọwọ wọn ki awọn aburo oun to sọ fun wọn pe iya oun ti jade laye.
Eyi lo mu ki wọn beere fun iyawo baba oun to ṣẹṣẹ bimọ ni ọsẹ meji sẹyin.
'Àwa táa jẹ́ alágbàtọ̀ gan, èèyàn ni wá, ẹ ye ṣe wa bí ẹranko'
Sẹnetọ Abbo ṣalaye siwaju sii pe ni kete tawọn agbebọn naa gunlẹ si agbegbe ọhun, 'taarata ni wọn gba ile awọn lọ nibẹ ni wọn si ti fi ipa ji iyawo baba mi to ṣẹṣẹ bims ni ọjs mọkanla sẹyin gbe lọ tawọn ti ibọn AK 47 lọwọ.'
O tun sọ pe bi wọn ṣe fẹ maa gbe arabinrin naa lọ ni aburo baba sẹnetọ Abbo jade sita to si pariwo lẹyin to ri awọn agbebọn naa. Lẹsẹkẹsẹ lawọn agbebọn naa si yin in nibọn.
Bakan naa la gbọ pe ileeṣẹ ọlọpaa ti ran awọn ikọ kogberegbe ọga ọlọpaa tẹlẹ wọn.
Fasoranti: Wọn ní kí Buhari kìlọ̀ fáwọn darandaran tó n tẹ Yorùbá lójú mọ́lẹ̀ bí bẹ́ẹ̀ kọ́...
Oríṣun àwòrán, Ooni of ife
Ọọni Adeyẹye Ogunwusi ati Iba Gani Adams ni Yoruba lee gbe igbesẹ to le da iṣọkan Naijiria laamu bi ijọba ko ba tete gbe igbesẹ to tọ
Ọọni ile ifẹ, Ọba Adeyẹye Ogunwusi Ọjaja II pẹlu Aarẹ Ọna kakanfo ilẹ Yoruba, Iba Gani Adams ti fariga lori iku ọmọ alagba Rueben Faṣọranti, Funkẹ Olukunrin.
Obinrinn yii ni wọn ni awọn agbebọn ti awọn eeyan fura si pe o ṣeeṣe ko jẹ darandarn fulani yinbọn pa ni ọjọ Ẹti.
Ọọni ile Ifẹ ati Aarẹ ana kakanfo ilẹ Yoruba ni asiko to fun ilẹ Yoruba lati kilọ fun awọn agbenipa darandaran lati maṣe ta ẹsẹ agẹẹrẹ ni aala ilẹ Yoruba mọ.
Ìgbárùn ni ètò BB Naija kíì ṣe ìgbádùn - MURIC
Ninu atẹjade ti awọn mejeeji fi sita lọjọ Abamẹta lori iṣẹlẹ iku ọmọ aṣiwaju ẹgbẹ Afẹnifẹre naa ni wọn ti fi ibanujẹ wọn han.
Ninu atẹjade tirẹ, Ọọni Adeyẹye Ogunwusi ti ile Ifẹ kilọ fun ijọba apapọ lati tete wa wọrọkọ fi ṣada lori gulegule awọn darandaran Fulani ti wọn n da omi alaafia ilẹ Yoruba ru lọwọ yii.
Ojuṣe ijọba ni lati daabo bo araalu. Pẹlu ohun to n ṣẹlẹ si wa ni ilẹ Yoruba bayii, bi ijọba ko ba tete wa nnkan ṣe si, afaimọ ki awọn eeyan wa maa bẹrẹ si ni da ọgbọn ati daabo bo ara wọn o, eleyii ti ko ni so eso rere fun iṣọkan orilẹ-ede yii."""
"Ninu atẹjade tirẹ, Iba Gani Adams ni gbọnmọgbọnmọ awọn ""Fulani to n ya wọ ilẹ Yoruba lati ṣe iṣẹ ibi bayii"" n fẹ amojuto gidgidi."
O ni iran Yoruba kii ṣe ẹṣin inu iwe ti ko lee ta o, o kan n fẹ ki agbaye mọ awọn to tẹ ọka rẹ niru naa ni ki ọka to ja pada.
'Á rọ̀ wá lọ́rún tí wọ́n bá lè ṣí ibodè Lekki lọ̀fẹ̀ẹ́ láàrọ̀'
O yẹ ko ye wọn pe eṣinṣin wọn n jẹ elegbo bayii ni imura silẹ fun igba ti elegbo pẹlu yoo yiju pada lati jẹ eṣinṣin
Ki ẹnikẹni maa da wa lẹbi o nigba ti a ba bẹrẹ tiwa. Gani Adams lo sọ bẹẹ.
Ati Ọọni Ilẹ Ifẹ, ati Aarẹ Ọna kakanfo, awọn mejeeji wa ki Alagba Rueben Faṣọranti ku atẹmọra ti ọmọ rẹ to jade laye.
EFCC: Ìwádìí iléeṣẹ́ Alpha Beta Consulting Ltd ṣì ń tẹ̀síwáju lórí ẹ̀sùn N100b
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Eeyan kan kọwe ifisun tako Alpha Beta Consulting Limited niwaju ajọ̀ EFCC ṣugbọn ajọ naa ni iwadii ṣi n lọ
Ajọ to n gbogun ti iwa ijẹkujẹ lorilẹ-ede Naijiria, EFCC ni awọn ṣi n wadii ileeṣẹ Alpha Beta Consulting Limited.
Ile iṣẹ yii ni ọpọ n tọka si gẹgẹ bii ọkan lara awọn ileeṣẹ agba oṣelu, aṣiwaju ẹgbẹ oṣelu APC, Bọla Ahmed Tinubu lori ẹsun ṣiṣe owo ni magomago.
Ajọ EFCC kọ loju opo twitter rẹ pe ajọ naa ko kawọ gbera lori iwe ifisun kan to jade pe ọwọ ileeṣẹ Alpha Beta Consulting Limited ko mọ lori ọrọ owo kan ti iye rẹ to ọgọrun un biliọnu Naira (N100bn).
EFCC ni lootọ loun tẹwọ gba iwe ifisun  kan lori ileeṣẹ Alpha Beta Consulting Limited, 'sugbọn ẹni to kọwe ifisun naa ko fi idi ẹsun rẹ mulẹ to bi o ti yẹ pẹlu awọn ẹri to duro digbi.
"EFCC kii ṣiṣẹ lori ahesọ ọrọ bikoṣe arigbamu ẹri. Ajọ yii ko ni dẹ oju rẹ silẹ ki ẹnikẹni yi orukọ rẹ m'ẹrẹ nitori awọn idi b'adiyẹ da mi loogun maa fọ lẹyin'
EFCC tun tẹsiwaju pe, ...iwadi lori ẹsun ti wọn fi kan ileeṣẹ Alpha Beta Consulting Limited ṣi n tẹsiwaju. A ko ni ohunkohun lati fi pamọ."""
Iwe iroyin abẹle kan lorilẹ-ede Naijiria lo tẹ iroyin kan sita lọjọ Satide ninu eyi ti o ti darukọ igbakeji aarẹ orilẹ-ede Naijiria, Ọjọgbọn Yẹmi Oṣinbajo pe ọwọ rẹ wa nibẹ.
Fasoranti: Osinbajo ìṣẹ̀lẹ̀ ààbò tó mẹ́hẹ kò mọ níbì kan, káàkiri Nàìjíríà ni
O ni ijọba n sa ipa rẹ lati da abo to jọju pada sorilẹede Naijiria
Lẹyin ti iroyin iku ọmọ rẹ, Funkẹ aya Olakunrin lu si eti araye ni ọjọ Ẹti, ẹsẹ ko gbero ni ile agba ilẹ Yoruba, Alagba Rueben Faṣọranti lati ba a kẹdun.
Iye awọn eekan to ti lọ baa kẹdun tun le ọkan sii ni owurọ ọjọ Aiku nigba ti igbakeji aarẹ orilẹ-ede Naijiria, Ọjọgbọn Yẹmi Oṣinbajọ pẹlu fi ẹsẹ kan de ile rẹ ni ilu Akurẹ.
Nibẹ lo si ti ṣe ileri pe ijọba apapọ ko ni sun, bẹẹ ni ko ni wo titi ti yoo fi rẹyin ipenija aabo to mẹhẹ eleyi to n doju kọ orilẹ-ede Naijiria bayii.
O ni lara igbesẹ ti ijọba apapọ fẹ gbe naa ni lati ko awọn ologun si oju popo marosẹ kaakiri.
Fulani Kidnapping: Owó púpọ̀ la san kí wọ́n tó fi mi sílẹ̀
Lẹyin to ki alagba Rueben Faṣọranti tan ni  Igbakeji aarẹ Yẹmi Oṣinbajo to kọwọrin lọ sibẹ pẹlu gomina Rotimi Akeredolu ti ipinlẹ Ondo.
CAN: Samson ni ọrọ awọn ajinigbe ti gba àpérò ní Naijiria
O ṣalaye pe ọrọ ipenija aabo to mẹhẹ ko mọ si ẹkun kan lorilẹ-ede Naijiria, kaakiri orilẹ-ede yii lo ti n waye.
"Gẹgẹ bi ọrọ rẹ, ""ẹnu mi ko gba ọrọ bayii bi ko ṣe lati ba baba daro. Ṣugbọn ẹ jẹ ki n tun sọ fun yin pe gbogbo awọn oniṣẹ ibi to ṣe iṣẹ yii ni ọwọ yoo tẹ, bẹẹni a n sa gbogbo ipa wa lati daabo bo ẹmi awọn ọmọ orilẹede Naijiria""."
Gọngọ sọ, ẹlẹ́há pàdé àwọn tó lùú ní jìbìtì nílùú Eko lọ́jà Ibadan
International Day Against Drug Abuse and Trafficking: ìdí ti mo fi ń mu oògùn olóró
Àwọn olówó Naijiria 5 tí owó wọn ju owó ìsúnná Naijiria lọ!
Oríṣun àwòrán, Google
Ìwádìì Oxfam fihàn pé owó àwọn olówó yìí tó 29.9 billion US dola, eléyìí tó ká owó ìṣúná Naijiria fún ọdún 2017.
Olowo marun un lorilẹ-ede Naijiria ni owo to to san owo isunna lorilẹ-ede Naijiria.
Iwadii ti ile-isẹ ajafẹtọ ọmọniyan, Oxfam gbe jade lo fihan wi pe owo awọn olowo yii le ni biliọnu mọkanlelọgbọn owo ilẹ okeere dọla.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Olowo marun un lorilẹ-ede Naijiria ni owo to to san owo isunna lorilẹ-ede Naijiria.
Eleyii jẹ iye oju owo fun owo isunna Naijiria ni ọdun 2017, triliọnu meje naira o le ni o ma a jẹ iye owo Naijiria.
Fasoranti: Dẹ́rẹ́bà tó wa ọmọ Fasoranti ṣàlàyé bí wọ́n ṣe pa Funke Olakunrin
Orukọ awọn marun un ti iwe iroyin Forbes gbe jade pe wọn ni owo julọ ni orilẹ-ede Naijiria ni:
Amọ iwadii naa ni ida ọgọta awọn ọmọ Naijiria ni ko ni to miliọnu dọla kan lati na loojọ, eleyii to fi han gbangba iru iya ati isẹ to n jẹ ọpọlọpọ awọn ara orilẹ-ede Naijiria
Bakan naa ni iwadii Oxfam gbe jade ni ọpọlọpọ awọn eniyan ni orilẹ-ede Naijiria ni isẹ ati iya n ba finra.
Gọngọ sọ, ẹlẹ́há pàdé àwọn tó lùú ní jìbìtì nílùú Eko lọ́jà Ibadan
Oxfam fi kun wi pe pẹlu u bi Naijiria se jẹ orilẹ-ede to n pese epo rọbi julọ ni ilẹ Afirika, ko ye ki wọn jiya amọ iwa ibajẹ ati jẹgudujẹra lo n fa ifaseyin fun awọn araalu.
PasitoTunde Bakare: Aago Nàìjíríà ti kún àkúnwọ́sílẹ̀
Oríṣun àwòrán, @T_Bakare
Gbajugbaja Agbẹjọro ati Pasito Ijọ Latter Rain Assembly, Tunde Bakare ni awọn adari orilẹ-ede Naijiria n se oselu pẹlu ẹmi awọn araalu ni Naijiria.
Bakare sọ eyi lasiko to n ba ebi ati ara Abileko Funke Olakunrin to jẹ ọmọ baba pa Reuben Fasọnranti, ti wọn ni awọn agbebọn pa ni ọna Ọrẹ si Benin ni opin ọsẹ.
Pẹlu omije loju ni Bakare fi sọ wi pe aago Naijiria ti kun akunwọsilẹ pẹlu bi ẹmi awọn eniyan ko ṣe jọ ijọba loju mọ, ti ipaniyan n waye lọtun losi.
Fasoranti: Dẹ́rẹ́bà tó wa ọmọ Fasoranti ṣàlàyé bí wọ́n ṣe pa Funke Olakunrin
Ninu ọrọ rẹ, o ni ijọba n se aito lori bi wọn se n koju ipaniyan ati ijinigbe nitori awọn eleto aabo maa n sa gbogbo agbara wọn lati ri wi pe ki wọn má gba ẹmi awọn olowo lawujọ, sugbọn ẹmi awọn araalu ko jọ wọn loju.
Amọ, adari ẹgbẹ oselu APC lorilẹ-ede Naijiria, Asiwaju Bola Ahmed Tinubu ti ni awọn Fulani darandaran nikan kọ lo n jinigbe tabi paniyan, amọ awọn ẹya miran naa n se ibi pẹlu.
Gọngọ sọ, ẹlẹ́há pàdé àwọn tó lùú ní jìbìtì nílùú Eko lọ́jà Ibadan
Bola Tinubu: Àwọn màlúù dà níbí tí wọ́n ti pa ọmọ Fasoranti?
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Awuyewuye ló tẹ̀lẹ́ ọrọ ti Asiwaju Bola Ahmed sọ lásìkò tó ń se àbẹ̀wò ibanikẹdun si ile baba Fasọranti ti awọn agbẹbọn pa ọmọ rẹ.
Awọn ọmo Naijiria ti fesi si ọrọ ti Adari ẹgbẹ oselu APC lorilẹ-ede Naijiria, Asiwaju Bola Tinubu to ni kii se Fulani darandaran lo pa ọmọ Baba Fasọranti.
Tinubu lasiko to se abẹwo si adari ẹgbẹ afẹnifẹre, Pa Reuben Fasọranti ti wọn ni awọn agbẹbọn pa ọmọ rẹ abileko Funke Ọlakunrin ni opopona Ọrẹ ni ipinlẹ Ondo sọrọ ibanikẹdun.
Ninu ọrọ rẹ, Tinubu ni ta ni o ri awọn maalu tabi ẹran nibi ti ipaniyan naa ti waye?
Ati wi pe awọn Fulani nikan kọ lo n pa eniyan ni Naijiria pẹlu ibeere pe se Fulani ni Evans ni ti o wa ni atimole fun ẹsun ajinigbe?
Amọ Femi Fani-Kayode lasiko to n fesi lori ikanni Twitter sọ wi pe isọkusọ ni ọrọ ti Asiwaju sọ, a ti pe ọrọ oselu ni Tinubu sọ.
Gọngọ sọ, ẹlẹ́há pàdé àwọn tó lùú ní jìbìtì nílùú Eko lọ́jà Ibadan
Fani Kayode ni ki lo kan Lemọmu p\elu itan aja ni ibeere Tinubu lori Evans ati ọmọ Baba Fasoranti
CAN: Samson ni ọrọ awọn ajinigbe ti gba àpérò ní Naijiria
Bakan naa ni awọn miran ni oro to jade lẹnu Tinubu ko yẹ ko jade lẹnu rẹ gẹgẹ bi asaaju.
Amọ awọn miran sọ wi pe, Tinubu sọrọ gẹgẹ bi adari ẹgbẹ oselu ni, kii se wi pe o se atilẹyin fun ẹya kan yato si omiran.
Awọn miran gboriyin fun Asiwaju pe ko ṣe ẹlẹyamẹya ninu ọrọ rẹ:
Ninu ọrọ awọn miran adura ni Baba Fasoranti nilo ati pe idanwo nla ni eyi jẹ fun Tinubu gẹgẹ bi Asiwaju ati ẹgbẹ APC lapapọ:
Sanwo Olu dá Bello padà; ó yan kọ̀míṣọ́nnà 25 àtàwọn olùbádámọ́ràn
Oríṣun àwòrán, @Sanwoolu
Sanwo Olu yan kọ̀míṣọ́nnà 25 àtàwọn olùbádámọ́ràn ti wọn yoo jọ ṣiṣẹ
Yatọ si pe gomina Sanwo Olu forukọ awọn Kọmiṣọnna tọ fẹ ba ṣiṣẹ ranṣẹ sile, O tun yan awọn olubadamọran tuntun.
Gomina ipinle Eko, Babajide Sanwo Olu fi orukọ awọn eniyan mẹẹdọgbọn ranṣẹ sile igbimọ aṣofin nipinlẹ Eko.
Igbakeji agbenusọ fun Gomina Sanwo Olu, Gboyega Akosile lo fi atẹjade naa sita pé Sanwo Olu fi ara balẹ woye yan awọn orukọ naa sipo ni.
Awọn orúkọ naa ti Akoṣile ni Sanwo Olu fi iriri wọn yan sipo naa ni wọnyii:
Awọn ti orukọ wọn tun jade lẹyin ti wọn ti sin ipinlẹ Eko tẹlẹ ni Tunji Bello to ti ṣe akọwe ijọba tẹlẹ, Wale Ahmed to ti ṣe kọmiṣọnna tẹlẹ ati Abilekọ Uzamat Akinbile-Yusuf atawọn miran.
Governorship Election Updates: Sanwo-Olu se abẹwo idupẹ si Bọla Tinubu
Gboyega Akosile ni kete ti awọn ọmọ ile igbimọ aṣofin ipinle Eko ba ti ṣe ayẹwo to yẹ ni wọn yoo buwọlu u bi o ti yẹ labẹ ofin.
Akosile ni awọn orukọ yii ni ti ipele akọkọ nitori pe iṣẹ ṣi n lọ lọwọ lati yan awọn to ku ti wọn yoo ba Sanwo Olu ṣiṣẹ fun ilọsiwaju ipinlẹ Eko.
Akọsile ṣapejuwe awọn eeyan yii pe ọrọ wọn yoo ye ara wọn fun itẹsiwaju nitori pe awọn ọdọ ti ko tii pé ọmọ ogoji ọdun wa ninu wọn laiyọ obinrin silẹ.
Obasanjo: Ètò ààbò tó mẹ́hẹ lè dá'jà ẹlẹ́yàmẹ̀yà sílẹ̀
Oríṣun àwòrán, Twitter/Presidency
Àjálù ń bọ̀, tí Buhari kò bá ṣàtúnṣe lórí ètò ààbò- Obasanjo
Aarẹ ana orilẹ-ede Naijiria, Olusegun Obasanjo ti kọ lẹta miiran si Aarẹ Muhammadu Buhari lori eto aabo to mẹhẹ lorilẹ-ede Naijiria.
Obasanjọ sọrọ ninu lẹta to fi sita lati ọwọ oluranlọwọ pataki lori eto iroyin rẹ, Kehinde Akinyemi pe dugbẹ dugbẹ to n mi loke lori eto aabo, afai-mọ-ko-ma-ja o.
Aarẹ ana Obasanjo fikun ọrọ rẹ pe ọkan oun bajẹ nitori Aarẹ Buhari ti fi awọn ọmọ Naijiria silẹ sọwọ awọn ọdaran afurasi Fulani darandaran ti wọn dabi awọn agbesumọmi Boko Haram.
Obasanjo ẹru n ba oun pe ija ẹlẹyamẹya le bẹ silẹ tawọn ẹya miiran ba kọju ija si awọn Fulani eyi to le buru jai bi ipaniyan to ṣẹlẹ lorilẹ-ede Rwanda.
Aarẹ ana ni ọrọ eto aabo Naijiria ti kọja ohun ti oun le dakẹ le lori nitori ọwọ ti fẹ bọ sori bayii pẹlu aibikita ijọba apapọ.
Olusegun Obasanjo: Ọmú ìyá mi ti mo fi ń mùkọ ni kekere ló jẹ ki ń lókun
Obasanjo ni awọn ara ilu le bẹrẹ si ni maa ṣe ohun to wu wọn ti ijọba ko ba tete fi wọrọkọ ṣada lori eto aabo ni Naijiria.
O fikun ọrọ rẹ pe ikọlu laarin awọn agbẹ ati darandaran di nla nitori ijọba kọkọ fọwọ yẹpẹrẹ mu ọrọ naa.
Obasanjo sọ pe oju ọrun to ṣu dẹẹdẹ yii, ojo iparun, ojo ajalu ati ojo ainiṣọkan ni yoo fi rọ ti ijọba ko ba wa nnkan ṣe si ọrọ eto aabo ni Naijiria.
Obasanjo ni asọyepọ laarin awọn ẹlẹyamẹya lojutuu si ọrọ eto aabo orilẹ-ede Naijiria to mẹhẹ.
Obasanjo: Buhari ní àìlera lẹ́mìí, lára, àti lọ́kàn.
Ilupeju Killing: Àṣìta ìbọn pa ẹnìkan lásìkò t'ọ́lọ́pàá kojú adigunjalè
Oríṣun àwòrán, POLICENG_PCRRU/TWITTER
Ileeṣẹ ọlọpaa ipinlẹ Eko ti fidi rẹ mulẹ pe lootọ ni ibọn pa arakunrin kan lasiko ti awọn oṣiṣẹ ajọ ọlọpaa SARS ati awọn janduku kan koju ara wọn lagbegbe Ilupeju nipinlẹ naa.
Alukoro fun ileeṣẹ ọlọpaa Eko, Bala Elkana, ninu atẹjade kan sọ pe iṣẹlẹ naa waye lasiko ti Ọga ọlọpaa kan, Inspẹkitọ Mohammed Akeem ati awọn ọmọ ikọ rẹ n mu olori ikọ janduku kan, Ikechukwu Monye lọ si ibi ti oun ati ikọ rẹ ma n ko awọn nkan ija oloro wọn pamọ si ko to di pe awọn ọmọ ẹgbẹ rẹ pade wọn lọna ni adugbo Ajisegiri, l'agbegbe Ilupeju.
Awọn janduku naa bẹrẹ si ni yinbọn, ibọn wọn lo si ba arakunrin kan to n kọja lọ.
Elkana sọ pe ikọ janduku naa ti ṣe ọpọlọpọ idigunjale ni Ilupeju ati awọn agbegbe to wa ni tosi rẹ.
Adájọ́ pàṣẹ kí wọ́n fi ọlọ́pàá tó lọ́wọ́ nínú ikú Kolade Johnson sí àhámọ́
'Àwọn SARS ló yìnbọn pa ìyá mi'
"Ileeṣẹ ọlọpaa ti n wa wọn tipẹ fun ẹsun pe wọn pa eniyan mẹfa lasiko idigunjale mẹta ọtọọtọ ti wọn ṣe.
Ṣaaju ni aworan oloogbe kan ti wọn pe orukọ rẹ ni Francis jade si ori ayelujara. L'ẹgbẹ aworan oloogbe naa ni awọn nkan bi igbalẹ, ike ipọnmi wa.
Awọn kan lori ayelujara sọ pe agbalẹ ni ọkunrin naa jẹ ni adugbo ibi ti iṣẹlẹ yii ti waye, ati pe ibọn awọn ọlọpaa SARS to n le awọn to n mu igbo lo pa a.
Alukoro ileeṣẹ ọlọpaa sọ pe wọn ti gbe oku rẹ lọ si ile igbokupamọ si bayii fun ayẹwo.
Building Collapsed: O kéré tán, ènìyàn 10 ló ti jáláìsí níbi ìṣẹ̀lẹ̀ ilé tó wó ọ̀hún
Oríṣun àwòrán, other
Building Collapsed: O kéré tán, ènìyàn 5 ló ti jáláìsí níbi ìṣẹ̀lẹ̀ ilé tó wó ọ̀hún
O kéré tán, ènìyàn 5 ló ti jáláìsí níbi ìṣẹ̀lẹ̀ ilé tó wó ọ̀hún.
Ajọ alagbelebu pupa to n mojuto eto didoola ẹmi awọn eniyan to ri sinu ile to wo ni Jos ni oku ti wọn ri ti pọ sii.
Won ṣalaye fun akọroyin BBC pe awọn ti yọ oku mọkanla bayii ninu ile alaja mẹta ọhun.
Awọn agbofinro ni ẹkun Jos ni awọn ko tii le sọ ohun to ṣokunfa ile to wo naa.
Ajọ NEMA to n ri si iṣẹlẹ pajawiri ni Naijiria naa ni gbogbo iṣẹ lawón n ṣe lati wa gbogbo awọn to ri sinu ile to wo naa.
Agbẹnusọ awọn agbofinro ni ẹkun yii, Yyopev Mathias ni nkan bii aago mẹrin irọle ana ni awọn gba ipe lori ile to wo naa.
O ni awọn ti wọn ti ri yọ laaye ni wọn ti ko lọ sile iwosan Plateaus Specialist ati Bringham University Hospital.
Oríṣun àwòrán, lasema
Iṣẹ n tẹsiwaju lọjọ Iṣẹgun
Ile alaja mẹta lo deede dà wó ni ilu Jos ni ipinlẹ Plateau ni ariwa Naijiria.
Iroyin ni o kere tan awọn marun un ni wọn ti dologbe nibi iṣẹlẹ ọhun nigba ti ọpọlọpọ si farapa.
Akoroyin BBC ni ọpọlọpọ wakati ni awọn oṣiṣẹ ajọ to n mojuto iṣẹlẹ pajawiri àti awọn ara ilu fi ṣiṣẹ lati doola ẹmi awọn to ri sinu ile to da wo naa.
Wọn ti gbe awọn ti wọn ti ri lọ sile iwosan bi wọn ṣe yọ wọn.
Onimọ nipa ile kikọ sọwipe ijọba nilo awọn onimọ nipa owo ori ile
Akoroyin BBC ni ajọ alagbelebu pupa to n ṣiṣẹ nibẹ ti fidiẹ mulẹ pe Baba onile naa ati awọn ọmọ rẹ meji wa lara awọn ti wọn ti ri oku wọn yọ nibẹ.
Ẹni to ni ile iwe sare lati doola awọn akẹkọ ni ile wolu
Ko si ẹni to mọ iye awọn eniyan to ṣi ku sinu àwótì ile alaja mẹta naa ni eyi ti iṣẹ tun ti bẹrẹ ni aarọ kutu oni.
Ile alaja mẹta yii ni awọn iyara aladagbe to pọ ati ọpọlọpọ ile itaja ti wọn kọ papaọ ni aarin gbungbun Jos.
Olórí Ọ̀dọ́ l'Ondo ní oníkálùkù yóò bẹ̀rẹ̀ sí ní jà fúnra wọn
Seyi Makinde: Gómìnà ìpínlẹ̀ Oyo kéde dúkìá tó tó #48bn
Oríṣun àwòrán, @Seyi
A ju ara wa lọ ijakadi kọ
Gomina ipinlẹ Oyo, Seyi Makinde ti kede dukia rẹ eyi to to ogoji biliọnu naira.
Ṣaaju idibo lo ti kọkọ kede pe oun a gbe igbesẹ yii ti oun ba wọle ni eyi to ti muṣẹ bayii.
Lati igba to ti ṣe ikede yii ni ero awọn ọmọ Naijiria ti ṣotọọtọ lori ikede naa.
Ọpọlọpọ lo ti ki Seyi Makinde fun iwa akin to hu nipa mimu ileri rẹ ṣe. Eyi kò yọ oludije dupo aarẹ lẹgbẹ oṣelu PDP, Atiku Abubakar silẹ
Bẹẹ naa ni awọn kan n ṣakawe ohun ini ti Seyi kede pẹlu eyi ti aarẹ Buhari kede pe o jẹ dukia oun.
Eyi tun ti jẹ ki awọn kan maa beere orisun owo gomina Seyi Makinde ni bi eto ọrọ aje ṣe ri lasiko yii.
Oríṣun àwòrán, @Seyi
Kini orisun owo Seyi Makinde ni ibeere awọn kan?
Koda loju òpó BBC Yoruba gan an, awọn eeyan mi n gbadura ki ori awọn naa di apesin bii ti Makinde.
Oro wa ko kuku dọgba ni adura ọpọ ero
Ohun to kọ iwaju si ẹnikan, ẹyin lo kọ si ẹlomii, awọn miran ni Seyi Makinde lo kọkọ gbe iru igbesẹ bayii ninu itan ipinlẹ Oyo pe:
Awon kan tun ni o ti ṣe ju ohun ti awọn to n gbogunti iwa ibajẹ miran ko ṣe paapaa.
Oríṣun àwòrán, Facebook/Seyi Makinde
Seyi Makinde: Gómìnà ìpínlẹ̀ Oyo kéde dúkìá tó tó #48bn
Gomina Seyi Makinde ti ipinlẹ Oyo ti kede dukia to to biliọnu mejidinlaadọta naira gẹgẹ bi ohun ini rẹ.
O ni eyi jẹ imuṣẹ ileri t'oun ṣe lasiko ipolongo idibo k'oun to di gomina ipinlẹ Oyo.
Ninu atẹjade ti akọwe iroyin si gomina, Ọgbẹni Taiwo Adisa fi sita, Gomina Makinde ni owo to le ni igba miliọnu nairia nipamọ ko to gori oye gẹgẹ bii gomina.
Bakan naa, Makinde ni ẹgbẹrun un lọna ọgbọn owo dọla titi di ọjọ kejidinlọgbọn, oṣu karun un nile ifowopamọ si.
Gomina Makinde tun ni dukia to to miliọnu lọna ẹgbẹrun mẹrin o le nirinwo owo dọla nipamọ.
Mo fi iṣẹ́ Banki silẹ̀ lọ bẹ̀rẹ̀ alápatà - Derin
Ninu ikede dukia rẹ, Gomina Makinde nile mẹsan an ni Naijiria, meji l'Amẹrika pẹlu ẹyọ kan lorilẹ-ede South Africa.
Amọ, oun ati iyawo rẹ ni wọn jọ ni ọkan ninu awọn dukia rẹ to wa l'Amẹrika.
Ki ni o mọ to n jẹ owo iranwọ epo?
Wọnyi ni awọn ile iṣẹ ti gomina Makinde ni ko to di gomina ipinlẹ Oyo- Makon Engineering & Technical Services Limited, Energy Traders & Technical Services Limited, Makon Oil & Gas Limited, Makon Group Limited, Makon Construction Limited & Makon Power System Limited ati bẹẹ bẹẹ lọ.
Ibikunle Amosun: Owo adani ni'ṣẹ ẹran dida, ko kan ijọba
Gomina Makinde rọ awọn alabaṣiṣẹpọ rẹ lati ṣe bakan naa
Ejo abami to n mu owo ni ajọ Jambu
Dino Melaye: Ilé iṣẹ́ ọlọ́pàá yóò ṣèwádìí fídíò tí Dino ti ń náwó fún olórin kan
Oríṣun àwòrán, Instagram/dinomelaye
A ó gbé'gbésẹ̀ lẹ́yìn ìwádìí fídíò tí Dino ti ń náwó fún Ayefẹlẹ- Ọlọ́pàá
Ile iṣẹ ọlọpaa sọ pe awọn yoo ṣe iwadii fọnran kan to ṣafihan bi Sẹnẹtọ Dino Melaye ti n fi owo mọ olorin gbajugbaja kan lori loju agbo.
Igbakeji alukoro fun ile iṣẹ ọlọpaa Naijiria, Ọgbẹni Adeniran Aremu to ba BBC Yoruba sọrọ ṣalaye pe ile iṣẹ ọlọpaa yoo gbe igbesẹ to ba yẹ lẹyin to ba pari iṣẹ iwadi lori fọnran ọhun.
Dino Melaye nánwó fún Ayefẹlẹ lójú agbo
Ọgbẹni Aremu sọ pe o ṣe pataki lati wo fọnran finifini nitori ọpọ eeyan lo n fi ọgbọn alumọnkọrọi gbe fidio jade lori ayelujara.
O fikun ọrọ rẹ pe ile iṣẹ ọlọpaa yoo ṣa ipa rẹ lati mọ orisun fidio ti Sẹnẹtọ Dino Melaye ti nanwo loju agbo naa.
Bọndu owo nla lo wa lọwọ Ọgbẹni Dino ninu eyi ti o ti n na olorin lowo nibi inanwo oku iya rẹ nipinlẹ Kogi ninu fidio naa
Awọn ọdọ Ondo fẹ̀họ́nù hàn lórí ìṣekúpani Funke Olakunrin
Ẹwẹ, ọjọ Abamẹta to kọ ja ni ọkan lara awọn ọga agba nile ifowopamọ Naijiria (CBN), Isaac Okorafor sọ pe ile ifowopamọ naa ti ṣetan lati fọwọ ofin mu ẹnikẹni to ba n ba owo naira jẹ nipa fifi ṣe imọri loju agbo.
Mo fi iṣẹ́ Banki silẹ̀ lọ bẹ̀rẹ̀ alápatà - Derin
COZA: Lẹ́yìn ìwadìí PFN ni CAN tó leè sọ̀rọ̀ lórí ẹ̀sùn tí wọ́n fi kan Fatoyinbo
Oríṣun àwòrán, CAN/Fatoyinbo
Apapọ ẹgbẹ ọmọlẹyin Kristi ni Naijiria, CAN, ti sọ pe oun ko mọ nkankan nipa bi awọn kan ṣe ṣe abẹwo a n bẹ lẹyin rẹ si COZA.
Lọjọ Aiku to kọja ni awọn alufaa naa ṣe abẹwo ọhun si ijọ Commonwealth of Zion Assembly.
Ninu atẹjade kan ti Oludari Apapọ fun eto ofin ati ikede fun CAN, Ajihinrere Kwamkur Samuel Vondip fi sita lọjọ Aje lo ti ni ọrọ ko ri bẹẹ.
O ni ẹgbẹ CAN sọ pe oun ko lọwọ si abẹwo ọhun ati fidio rẹ to gba ori ayelujara.
COZA: Ọpọ èrò ló jáde ṣe lòdì sí ẹ̀sùn ìfipábánilòpọ̀ Fatoyinbo
Bakan naa ni Kwankur sọ pe awọn pasitọ to wa ninu fidio naa lọ sile ijọsin COZA latinu ifẹ ọkan wọn ni.
''Eyi ni lati sọ fun gbogbo eniyan pe wọn ti pe akiyesi Aarẹ ẹgbẹ CAN, Ẹni Ọwọ Samson O.A Ayokunle si iroyin ati fidio kan lori ayelujara pe ẹgbẹ CAN ran awọn aṣoju lọ sinu ijọ pe awọn ṣatilẹyin fun Pasitọ Agba ijọ naa, Biodun Fatoyinbo, ti wọn fi ẹsun ifipabanilopọ kan."
"O ni ""Atẹjade yii wa lati jẹ ki gbogbo awọn olori ẹsin Kristiẹni, araalu, ati awọn to fẹran otitọ, mọ pe ẹgbẹ CAN tabi Aarẹ CAN ko fi ọwọ si tabi mọ nkankan nipa abẹwo atilẹyin naa."""
Ẹgbẹ CAN sọ pe oun ko ti i yi ohun pada lori ọrọ ti oun sọ tẹlẹ pe lootọ ni awọn ko faramọ iwa ibajẹ kankan lati ibikibi, ṣugbọn oun ti fi aaye silẹ fun ẹgbẹ Ijọ Ẹmi Mimọ, PFN ti ijọ COZA n ṣe, lati ṣewadi ẹsun ifipabanilopọ naa, ko si jabọ fun ẹgbẹ CAN.
'' A le fi idi rẹ mulẹ pe ẹgbẹ PFN ti bẹrẹ iwadii, abọ iwadii na yoo si jade sita titi ọsẹ meji si asiko yii. A ko si ni ṣe idiwọ fun ijiya to ba tọ si ẹnikẹni to ba hu iwqa ti ko tọ ọ.
Funke Akindele jẹ àkàndá ẹ̀dá - Adaku
Aarẹ ẹgbẹ CAN, Ẹni Ọwọ Samson O.A Ayokunle, sọ fun BBC Yoruba pe ẹgbẹ CAN ko le ṣe atilẹyin fun Fatotinbo tabi Busola lai jẹ pe ẹgbẹ PFN ti CAN fun ni aṣẹ lati ṣe iwadii ọrọ naa ba jabọ.
" A gbọdọ tẹle ilana to yẹ, ao si ri i pe a tẹle nitori ki otitọ le jọba.''
Ọjọ Aiku ni fidio kan gba ori ayelujara, to si ṣafihan awọn pasitọ kan ti wọn ni awọn jẹ aṣoju ẹgbẹ CAN ẹka ilu Abuja, lẹnu abẹwo lọ si olu ijọ COZA, to wa nilu Abuja.
Nibẹ ni wọn ti sọ fun Pasitọ Biodun fatoyinbo pe digbi ni awọn wa lẹyin rẹ lori ẹsun ifipabanilopọ ti wọn fi kan an.
Fidio naa mu ki ọpọlọpọ ọmọ Naijiria o koro oju si ẹgbẹ CAN.
Oṣu Kẹfa ni iyawo gbaju-gbaja akọrin, Timi Dakolo, Busola Dakolo, ninu ifọrọwanilẹnuwo kan fi ẹsun kan Fatoyinbo pe o fi ipa ba oun lo pọ lẹẹmeji ọtọọtọ ki oun to o pe ẹni ogun ọdun.
Oríṣun àwòrán, Biodun Fatoyinbo
Iyawo gbaju-gbaja akọrin, Timi Dakolo, Busola Dakolo, fi ẹsun kan Fatoyinbo pe o fi ipa ba oun lo pọ lẹẹmeji ọtọọtọ ki oun to o pe ẹni ogun ọdun.
Ẹsun naa fa awuyewuye l'oriṣiriṣi jakejado orilẹede Naijiria. Awọn kan tilẹ ṣe iwọde lọ si ẹka ileejọsin COZA nilu Abuja ati Eko, pe ki Biodun Fatoyinbo kuro ni ipo Pasitọ ninu ijọ naa.
Lẹyin eyi ni Fatoyinbo kede pe oun ti yẹba naa. Ṣaaju lo ti fesi si ẹsun ti Dakolo fi kan an pe oun ko fi ipa ba ẹnikẹni lo pọ ri.
Goodluck: Ṣèbí ajagunfẹ̀yìntì ni Buhari, o yẹ kó mọ ohun tó yẹ láti kápá ìpèníjà ààbò
Ààrẹ àná, Goodluck Jonathan naa kún ara awọn lookọ-lookọ to ti bẹ alagba Rueben Faṣọranti wo lori iku ọmọ rẹ ti awọn agbebọn pa
Aarẹ ana lorilẹ-ede Naijiria, Goodluck Jonathan ti gba aarẹ Buhari ni imọran pe ko yi eto ati ilana ti o n lo lati gbogun ti ipenija aabo to mẹhẹ ni Naijiria.
Ọmọwe Jonathan fun aarẹ Buhari ni imọran yii lasiko to fi ṣe abẹwo si ile alagba Rueben Faṣọranti lori iku ọmọ rẹ ti wọn ni awọn agbebọn pa ni ọjọ Ẹti to kọja.
Aarẹ ana orilẹ-ede Naijiria naa ni ọjọ ti pẹ to ti yẹ ki aarẹ yi ọwọ pada lori eto igbogun ti iwa ọdaran niwọn igba ti o jẹ wi pe ajagun fẹyinti ni ko to darapọ mo oṣelu.
Ibanijẹ lo jẹ fun wa nigba ti a gbọ iṣẹlẹ buruku yii, o si yẹ ki ijsba apapọ tete wa wọrọkọ fi ṣada ki irufẹ eyi ma baa tun waye mọ."""
Asiko to lati lo imọ ẹrọ tuntun ki alaafia lee jọba ki iwa ọdaran si lee wọlẹ.
Awọn ọdọ Ondo fẹ̀họ́nù hàn lórí ìṣekúpani Funke Olakunrin
Akọwe ijọba ipinlẹ Ondo, atawọn kọmiṣọna ni ipinlẹ Ondo ni wọn ba Aarẹ ana, Goodluck Jonathan kọwọrin.
Alagba Faṣọranti dupẹ lọwọ rẹ fun abẹwo ati ibanikẹdun rẹ.
Minimum wage: Buhari ti buwọ́lu sísan ẹ̀kúnwó oṣù tuntun fáwọn òṣìṣẹ́ àpapọ̀
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Iroyin ayọ sọkalẹ fawọn oṣiṣẹ bayii paapaa awọn ti wọn ko gba ju ẹgbẹrun lọna ọgbọn naira lọ tẹlẹ.
Idi iroyin ayọ yii ko yẹ lori bi aarẹ Muhammadu Buhari ti ṣe buwọlu sisan owo oṣu tuntun naa fun awsn oṣiṣẹ apapọ ti owo ti wọn n gba ko to iye ẹkunwo oṣu tuntun naa lọwọ yii.
Alaga ajọ to n mojuto agbekalẹ owo oṣu lorilẹ-ede Naijiria, Richard Egbule ṣalaye pé igbesẹ naa bẹrẹ lẹyẹ o sọko.
O sọ fawọn oniroyin nilu Abuja pe ileeṣẹ oluṣiro owo agba Naijiria ni yoo buwọlu owo naa bayii ni ibamu pẹlu asiko ti aarẹ fọwọ si sisan rẹ.
Ẹ lọ mú ẹ̀rí ibi tí a ti gba owó wá- NLC/TUC
Gẹgẹ bi ọgbẹni Egbule ti ṣe sọ, ọjọ kejidinlogun, oṣu kẹrin ọdun 2019 ni sisan owo oṣu naa bẹrẹ ifidimulẹ; afẹfẹ rẹ yoo si kan awọn onipele owo oṣu marun un.
Awọn ti ọrọ naa kan ni awọn oṣiṣẹ ijọba apapọ to wa lori (CONPSS), awọn oṣiṣẹ eto ilera to wa lori ilana owo osu (CONHESS), awọn oṣiṣẹ ẹka miran to wa lori ilana owo osu (CONRAISS).
ọ̀rọ̀ lórí ọkọ̀ fún Fayose
Bakan naa lo kan awọn oṣiṣẹ ile ẹkọ giga to wa lori ilana owo osu (CONTISS II) ati (CONTEDISS).
Amoṣa o ni ijiroro ṣi n tẹsiwaju lori awọn ato ti yoo kan awọn oṣiṣẹ ti owo oṣu wọn ju ẹgbẹrun lọna ọgbọn naira lọ.
Mo fi iṣẹ́ Banki silẹ̀ lọ bẹ̀rẹ̀ alápatà - Derin
Fasoranti: Ẹ̀mí àwọ̀n darandaran Fulani kò dè mọ́ ní Gúsù Nàìjíríà, kí wọ́n padà sókè ọya ní kíákíá
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ẹgbẹ àgbà òkè ọya Nàìjíríà, NEF ni ọrọ idunkukulaja to n waye lẹnu awọn agba iha Gusu Naijiria lo n mu ki aṣẹ naa waye
Hmmm... a ma n pe ọrọ yii lowe o ma n laro ninu.
Lori ọrọ ipenija aabo to n ranju mọọ mọ Naijiria yii ni ẹgbẹ awọn agba loke ọya Naijiria, Northern Elders Forum (NEF) ati agbarijọpọ awọn ẹgbẹ kan nibẹ ti ni kawọn darandaran fulani o ṣẹri wale si apa oke ọya.
Wọn ni oke ọya ni awọn ti lee fi ọwọ sọya lori ẹmi wọn ati maluu wọn.
Ẹgbẹ awọn agba apa oke Ọya orilẹ-ede Naijiria naa ni ilu ogun tawọn kan n lu lapa guusu ilẹ yii lori wọn n kọ awọn lominu.
'Fulani Ilorin l'ọkọ mi'
Bi ẹ ko ba gbagbe, laipẹ yii ni awọn agbebọn kan ti ọpọ furasi gẹgẹ bi awọn darandaran Fulani pa arabinrin Funkẹ Olakunrin.
Eni to jẹ ọmọ ọkan lara awọn agba to lorukọ nilẹ Yoruba, Rueben Faṣọranti.
Eyi si ti fa ọpọ ipe da ina ogun, da ina ọtẹ lataọdọ awọn eekan kan ni ilẹ Yoruba lori lemọlemọ iṣẹlẹ ijinigbe ati igbenipa to n waye lapa iwọ oorun guusu orilẹ-ede Naijiria.
Yomi Lanso wipe ka jọ gbadun laye
Ninu ọrọ ti wọn ba awọn oniroyin sọ, Ọjọgbọn Ango Abdullahi to jẹ alaga ẹgbẹ agba oke ọya Naijiria ni nibi ti ọrọ de duro bayii, ko daju pe ẹmi awọn darandaran Fulani de mọ ni apa guusu orilẹ-ede Naijiria ti wọn wa.
O ni lootọ ni iṣọkan Naijiria jẹ awọn logun ṣugbọn ko de ibi ati fi ẹmi ẹya kan ra a pada.
O wa pe fun idasilẹ igbimọ oluwadi kan ti yoo ṣe ọfin toto ọwọja wahala awọn darandaran ati agbẹ olohun ọgbin ki wọn le e san owo ofo to ṣẹ koowa fun un.
Olórí Ọ̀dọ́ l'Ondo ní oníkálùkù yóò bẹ̀rẹ̀ sí ní jà fúnra wọn
COZA: A ti wọ́gilé ìwọ́de lórí COZA tí a fẹ́ ṣe tẹ́lẹ́ nítorí...
O ni ìdí ti a fi wọgile iwọde wa toni
Oni ni àwọn ikọ #Church Too ti wọn n ṣe iwọde ṣe lodi si ifipabanilopọ nile ijọsin kede lati ṣe iwọde ni Abuja ati Eko tẹlẹ.
Ọpọlọpọ iwọde ni wọn ti ṣe sẹyin lati igba ti ọrọ ẹsun ifipabanilopọ ti ṣẹlẹ pe pasitọ Biodun Fatoyinbo fipa ba arabinrin Busola Dakolo lo pọ
Bukky Shonibare to jẹ ọkan pataki lara awọn to fẹ ṣe iwọde naa ni idi tawọn ṣe fẹ sẹ iwọde toni ni pe ko yẹ ki ẹgbẹ CAN dọwọ bo iṣẹlẹ naa.
COZA: Ọpọ èrò ló jáde ṣe lòdì sí ẹ̀sùn ìfipábánilòpọ̀ Fatoyinbo
Bukky Shonibare ni awọn agbofinro ti kọkọ ranṣe si oun lati wa ṣalaye nipa iwọde ti wọn fẹ ṣe naa tẹlẹ.
O ni pataki idi ti wọn ṣe kọkọ fẹ ṣe iwọde naa ni tori pe awọn gbọ pe awọn olori ajọ CAN ni wọn n ṣatileyin fun pasitọ Biodun Fatoyinbo ni eyi ti wọn gba pe ko yẹ ko ri bẹẹ.
O ni inu wọn dun pe ajọ CAN ti ni iṣẹ ẹgbẹ kọ́ ni awọn to lọ ijọ COZA lọ jẹ bikoṣe iṣẹ ara wọn.
Pasito Fatoyinbo yẹba lẹyin iwọde yii
Ninu fọnran fidio kan to n tàn kalẹ ni wọn ti ri alaga CAN fun FCT ati alaga CAN fun aarin gbungbun Naijiria, ti wọn n kede atilẹyin wọn fun pasitọ COZA.
Alufaa Isreal Akanji ati Alufaa Jonah Samson ni wọn n kede atilẹyin wọn ninu fọnran naa.
Ṣaaju asiko yii ni ajọ PFN ti kede pe awọn ko ni fọwọ bo iwa ibajẹ kankan lainii fi ṣe ẹni ti ade naa ba ṣi mọ lori.
Alaga PFN, Alufaa Felix Omobude ni ọrọ ẹsun ifipabanilopọ naa ba ni ninujẹ pupọ.
Ajọ CAN ti kede pe awọn n reti abọ iwadii ajọ PFN ki awọn to mọ igbesẹ to kan lati gbe lori ọrọ ẹsun ifipabanilopọ naa.
CJN: Ilé aṣòfin ti buwọ́lu Tanko Muhammad gẹ́gẹ́ bi adájọ́ àgbà Nàìjíríà
Oríṣun àwòrán, AsoRockVilla
Aare Buhari yan Tanko Ibrahim lati dele de adajọ Onnoghen
Ile igbimọ aṣofin agba Naijiria ti buwọlu iyansipo Tanko Muhammad gẹgẹ bi Adajọ Agba Naijiria.
Wọn buwọlu u lọjọru lẹyin eto ayẹwo ti awọn aṣofin kan ṣe fun un.
Ṣaaju ni Ajọ to n mojuto eto idajọ ni Naijiria, NJC, rọ Aarẹ Buhari lati sọ Onidajọ Muhammad di Adajọ Agba Naijiria.
Ọjọbọ to kọja ni Aarẹ Muhammadu Buhari fi orukọ rẹ ranṣẹ si awọn aṣofin fun ontẹ lati le mu u ko kuro ni ipo Adele Adajọ Agba.
Ọjọ kẹẹdọgbọn, oṣu Kinni, ọdun 2019 ni Muhammad bọ si ipo Adele lẹyin ti wọn da Adajọ Agba nigba kan, Walter Onnoghen duro, nitori ẹsun ṣiṣe magomago lasiko to kede dukia rẹ.
Lẹyin naa ni Aarẹ Buhari fi oṣu mẹta mi i kun ọjọ rẹ ni ipo naa.
Fulani Heardsmen: Afenifere ní àṣẹ tó bá wu àwọn àgbàgbà agbègbè àríwá Nàìjíríà ni
Mercy Aigbe: Iṣẹ́ ọwọ́ mi ni mó n jẹ, gómìnà àbi ààrẹ kò gbọ́ bùkátà mi
Oríṣun àwòrán, Mercy aigbe
Gbaju-gbaja oṣere tiata, Mercy Aigbe ti sọrọ sita lati wẹ ara a rẹ mọ, ninu ahesọ ọrọ kan to n lọ nigboro pe 'ọkunrin lo fi n gbe bukaata ara rẹ.'
Se bi ogun ẹni ba da ni loju, aa fi gbari ni. Ninu ọrọ kan to fi si ori ayelujara Instagram rẹ, Mercy sọ pe isẹ́ loun n se, ki oun to ri taje se.
"''Mo n gbiyanju aje bayii, ko sẹni to ri mi, amọ nigba to ba ya, ti mo gbe aworan ọpọ ile mi sori ayelujara, wọ̀n yoo la ẹnu ẹlẹya wọn pe ‘gomina kan‘ abi ‘aarẹ kan’ lo ra ile awosifila, ọpọ ọkọ ayọkẹlẹ ati awọn ilegbe fun mi."""
Wọn yoo maa fi ẹnu tẹnbẹlu isẹ asekara mi...adura mi ni pe, baba, gbogbo ẹnu esu ti ko wulo, to fẹ maa tabuku ibukun rẹ ninu aye mi, ki ina ẹmi mimọ lọ kọlu wọn, ki wọn si maa sisẹ lai ni akojọ ni orukọ Jesu.
To ba jẹ iwọ ni adura yii wa fun, ko yara tete wa ọ ri ni kiamọsa.
Ọdun 2018 ni iroyin gba igboro pe, gomina ipinlẹ kan nilẹ Yoruba to jẹ ololufẹ ikọkọ Mercy, lo ra ile ti oṣere tiata naa fi aworan rẹ sita, fun.
Face app: Àwọn òṣèré tíátà kan ṣàfihàn fọ́tò ọjọ́ ogbó wọn
Oríṣun àwòrán, Woli Agba
Ayọ Ajewọle asfihan bi yoo se ri tọjọ ogbo ba de
Oríṣun àwòrán, Alamy
Haa, arugbo soge ri ree o, Ọpẹyẹmi Aiyeọla lo ti yaa di iya agba yii
Oríṣun àwòrán, Aremu Afolayan
Hun, owe nla ni awọn aworan yii n pa fun ni pe ọjọ alẹ n bọ
Oríṣun àwòrán, Laide Bakare
Arugbo sogeri, ekisa logba ri ni aworan ọjọ ogbo Laide Bakare yii
Oríṣun àwòrán, Mosunmola Filani
Gbogbo ẹyin ewe, ẹmaa ranti pe agba n bọ wa kan wa
Oríṣun àwòrán, Mike Bamiloye
Ẹru si n yọ mi ba, ti mo ba ranti ọjọ ogbo, bawo ni iwọ yoo ti ri?
Oríṣun àwòrán, Lateef Adedimeji
Ọmọde ọjọun, o n dagba ree o, kori jẹ o pẹ laye, ko to agba da.
Oríṣun àwòrán, thesolaallyson
Ẹ o rii pe ẹrin gbajugbaja olorin Sola Allyson lekan sii lọjọ ogbo?
Oríṣun àwòrán, Odunlade Adekola
Ọdunlade ọmọ Adekọla, agba n bọ wa kan ọ o
Oríṣun àwòrán, Jide Kosoko
Agba kii pẹ kan ni
Tramadol: Ọwọ́ tẹ afurasí méjì tó kó òògùn olóró N60m wọlé l'Apapa
Ọwọ awọn oṣiṣẹ aṣobode lebute ọkọ oju-omi to wa l'Apapa nipinlẹ Eko, ti tẹ awọn afurasi meji kan ti wọn ko oogun Tramadol wọ Naijiria lọna aitọ.
Alakoso awọn oṣiṣẹ aṣọbode l'Apapa, Muhammed Abba Kura ṣalaye pe, awọn oogun Tramadol ọhun to ọgọta miliọnu Naira.
O fikun ọrọ rẹ pe, ninu ọkọ itọju alaisan pajawiri taa mọ si ambulance lawọn afurasi meji ọhun kọkọ ko oogun naa si.
Lẹyin ti ọwọ tẹ wọn tan, ni awọn oṣiṣẹ aṣọbode tun rii wi pe oogun Tramadol tun kun inu agolo ikẹru si, ti wọn n pe ni ''container'' bamu.
Awakọ ati oṣiṣẹ ile iṣẹ kan lawọn afurasi meji ọhun tọwọ sinkun ofin ti ba bayii.
Awọn oṣiṣẹ aṣọde ni iwadii ṣi n lọ lọwọ lori iṣẹlẹ naa.
TUNNGR: Ta ló ṣe móríyá fún ọ jù lọ ní Super Eagles?
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ọ̀pọ̀ ènìyàn ló ti ń fi ẹni tó se móríyá fún wọn jùlọ ní ìdíje erébọ́ọ̀lù ilẹ̀ Afirika, Afcon 2019.
Ẹgbẹ agbabọọlu Super Eagles ti Naijiria ti pari ifẹsẹwọnsẹ wọn ninu idije ilẹ Afirka, lẹyin ti wọn pari pẹlu ipo kẹta ninu idije Afcon 2019.
Tunisia ni Super Eagles naijiria fi se ifajẹ ti wọn se ipo keta.
Bi awọn kan se n sọ wi pe Ighalo lo fakọyọ julọ ninu ẹgbẹ agbabọọlu Super Eagles ni idije Afcon naa.
Amọ, awọn miran ni Chukwueze ati Ighalo tiraka ṣugbon Etebo ni fun awọn, ti awọn miiran si ni ẹni miran lo se moriya fun wọn.
Fulani Heardsmen: Afenifere ní àṣẹ tó bá wu àwọn àgbàgbà agbègbè àríwá Nàìjíríà ni
"Bakan naa ni awọn kan ni gbogbo igba ni ikọ Super Eagles ma n se ipo kẹta, eleyii ti wọn tilẹ pe ni ""ogun ibi wa lorilẹede Naijiria""."
RUGA: Gbogbo ọmọ Nàìjíríà ló lásẹ láti gbé ìlú tó bá wù ú - Buhari
Oríṣun àwòrán, Google
Àjọ Northern Elders Forum (NEF) láìpé yìí késí àwọn darandaran Fulani kí wọ́n padà sókè ọya ní kíákíá.
Aarẹ Muhammadu Buhari ti ke si awọn Fulani darandaran ni Guusu iwọ Naijiria lati da asẹ ẹgbẹ Northern Elders Forum (NEF) nu to ni ki wọn pada wa si oke ọya ni kiakia.
Oluranlọwọ pataki fun aarẹ Muhammadu Buhari, Garba Shehu lo fi ọrọ yii lede ninu atẹjade ti aarẹ fi sita.
Ninu atẹjade naa, Aarẹ Buhari ni gbogbo ọmọ Naijiria lo ni anfaani ati eto lati rin kaakiri agbeegbe ti o ba wu wọn, tabi ki wọn gbe nibẹ.
Fulani Heardsmen: Afenifere ní àṣẹ tó bá wu àwọn àgbàgbà agbègbè àríwá Nàìjíríà ni
Aarẹ Buhari ni iwe ofin orilẹede Naijiria, ijọba Naijiria ati isejọba Aarẹ Muhammadu Buhari yoo da abo bo awọn ọmọ Naijiria ni ibikibi ti wọn ba wa.
Laipẹ yii ni Ajọ Northern Elders Forum (NEF)  ke si awọn darandaran Fulani  kí wọ́n padà sókè ọya ní kíákíá pé ẹmi wọn ati dukia lee wa lewu ni iha Guusu ti wọn wa.
FaceApp: Ǹjẹ́ ẹwu wà nínú lílò ẹ̀rọ yìí?
Oríṣun àwòrán, Laide Bakare
Arugbo sogeri, ekisa logba ri ni aworan ọjọ ogbo Laide Bakare yii
Ọpọlọpọ awuyewuye lo ti n lọ lori lilo ẹrọ to n pa ọjọ ori ẹni da FaceApp, ti o le mu ki aworan eniyan kere sii ni ọjọ ori, abi ki o dabi arugbo.
Oju opo Instagram ti kun pitimu bayii fun fọto awọn oṣere tiata, ti wọn parada di arugbo, amọ ṣe ewu kankan wa ninu lilo ẹrọ yii?
Iwadii fihan wi pe ile isẹ to gbe ẹro naa jade ko sọ fun awọn eniyan lẹkunrẹrẹ wi pe awọn fọto wọn ti wọn ba fi sori ẹrọ FaceApp yoo wa lọwọ wọn fun igba pipẹ.
Imọ ẹrọ artificial intelligence (AI) ni wọn n lo lati fi ma a se atunse oju, enu ati ẹrẹkẹ awọn fọtọ ti wọn ba lo.
Ṣáájú, wọn ti fẹsun kan wọn wi pe wọn n lo awọn fọto ti awọn eniyan ba fi sori erọ FaceApp lati fi da oju awọn eniyan mọ, tabi se iwadii wọn.
Kí ló máa ń wú ìyá Nike Davies lori láti wé gèlè ràbàtá?
Oríṣun àwòrán, Odunlade Adekola
Ọdunlade ọmọ Adekọla, agba n bọ wa kan ọ o
Bakan naa ni olori ẹgbẹ oselu to kereju ni Ile Igbimọ Asofin Agba ni orilẹede Amerika, Chuck Schumer ti ke si ẹka to n sewadi lorilẹede naa, FBI lati se iwadii ile isẹ FaceApp to jẹ ti orilẹede Russia.
Amọ adari ile isẹ naa, Yaroslav Goncharov sọ fun BBC pe awọn ko lo fọto awọn eniyan lati ori ẹrọ ibanisọrọ wọn, wọn ni awọn n lo eyi ti wọn ba fi si ori ẹrọ wọn lati fi pamọ.
Ẹrọ FaceApp le mu ẹni ti o ba le oju koko, ki o dabi ẹni to ba n rẹrin, bakan naa ni o le mu ẹni ti o ba darugbo, jọ ọdọ.
Bakan naa ni ohun sọ awọn ọdọ pada si arugbo, ti wọn ba ti fi aworan wọn si ori ẹrọ naa.
Afonja: Ọ̀rẹ́ àjèjì ló kó bá Afọnja, tí Ilọrin fi bọ́ lọ́wọ́ Yorùbá
Oríṣun àwòrán, Goodbooksafrica
Afọnja gba ilu Ilọrin labẹ akoso ilu Ọyọ, to si kede pe ilu naa ti di ilu olominira
Laarin ọdun 1700, paapa ọdun 1750, ọkunrin akọni kan lalẹ hu ni ilu Ọyọ ti orukọ rẹ n jẹ Afọnja, to si kẹrẹkẹrẹ di Aarẹ Ọna Kakanfo fun ilẹ Yoruba eyi to safihan bo ti jẹ akikanju to.
Lara awọn orukọ ọmọ ilẹ Kaarọ Oojiire ti a ko si lee gbagbe ni Afọnja wa, ta ba si se n ranti Afọnja, naa la ma ranti ilu Ilọrin, nibi ti Afọnja tẹdo si dọjọ alẹ.
O tun seese ki iran Yoruba ma lee gbagbe Afọnja nitori ipa to ko nilu Ilọrin ati awọn isẹlẹ to sẹlẹ nibẹ, eyi to si n ja rainrain nilẹ titi di asiko ta wa yii.
Gẹgẹ bi itan atẹnudẹnu ti jẹ ko ye wa, to fi mọ oju opo Wikipedia ati Facebook , a ko lee pe ori aja, ka ma peri ikoko ta fi se e, ni ọrọ Afọnja, ilu Ilọrin ati Ọyọ ile jẹ, nitori pe wọn tan mọ ara wọn.
N jẹ bawo ni itan igbe aye Afọnja se lọ, ipa wo lo ko si idagbasoke iran Yoruba, ki si ni awọn isẹ to gbe ile aye se ta fi n ranti rẹ di oni yii ati isẹlẹ to waye laarin rẹ ati ẹya Fulani.
Oríṣun àwòrán, @officialasanlu
Ni kete ti Afọnja pada de lati Apomu lo gba aafin Ọyọ lọ, to si ni ki Alaafin Aolẹ funra ara rẹ fi ori apere silẹ
Oríṣun àwòrán, @officialasanlu
Abdulsalam lo ede rẹ lati fi gba awọn ọmọ ogun Afọnja, ti wọn si gba ẹmi Afọnja lọdun 1817
Ibẹrẹ iṣubu Afọnja lati ọwọ Fulani nilu Ilọrin:
Ọpọ ẹkọ lo wa lara itan Afọnja yii, eyi to yẹ ka mu lo lode oni nitori ẹni to jin si koto, yẹ ko kọ awọn ara yoku lọgbọn, itakun kansoso ko si yẹ ko da wa lepo nu lẹẹkeji.
Ọgbọn ti itan Afọnja kọ wa:
Ọọ̀ni: Ìpèníjà ààbò di ìràwọ̀ ọ̀sán tó ń ba àwa àgbà lẹ́rù
Oríṣun àwòrán, Oba Adeyeye Ogunwusi
Ọọni tilu Ile Ifẹ, Ọba Ẹnitan Adeyẹye Ogunwusi, Ọjaja keji, ti keboosi too fun aarẹ Muhammadu Buhari lori ipenija eto aabo to n ba ilẹ Yoruba finra.
Ọba Ogunwusi, ẹni to ke gbajare yii tọ aarẹ Buhari lọ lọjọbọ nilu Abuja tun kede pe,  awọn ajeji ti gba akoso nilẹ Yoruba, ti ipenija eto aabo to n koju wa si jẹ ara eyi to n koju orilẹede Naijiria lapapọ.
Nigba to n sọrọ lorukọ awọn oriade to ku nilẹ Yoruba, Ọọni tun tẹnumọ pe, ominu n kọ awọn ọba alaye to wa nilẹ Kaarọ Oojire lọwọlọwọ bayii, nitori ipenija eto aabo naa ti di irawọ ọsan, to n ba awọn agba lẹru.
Arole Oodua wa jẹjẹ pe oun atawọn ọba alaye yoku ti setan lati fọwọ sowọpọ pẹlu ijọba, ti wọn si n beere fun afikun eto aabo latọdọ ijsba apapọ, ki wọn lee daabo bo awọn eeyan wọn lọwọ awọn kanda inu irẹsi, o si seese ki wọn ma jẹ ẹya Fulani.
Oríṣun àwòrán, Oba Adeyeye Ogunwusi
Amọ sa, Ọọni wa fọrọ ransẹ si awọn eeyan to n lu ilu ogun jija, to fi mọ awọn oloselu ti wọn di esu to n ta epo si ọrọ naa pe, ki wọn ti ọwọ ọmọ wọn bọ asọ lori awọn iwa naa.
O ni iru iwa yii lo lee mu idarudapọ waye lorilẹede Naijiria, toripe orilẹede yii ko tun le fi oju wina ogun.
Russia infanticide: 11,000 ọmọdé làwọn òbí ti pa láàrin ọdún 1976 sí 1997
Ọpọ ninu awọn obinrin lo maa n jẹjọ lori ẹsun pe, wọn ṣeku pa ọmọ ti wọn bi fun ra wọn.
Ọpọ ninu wọn lo jẹ iyawo ile, ti awọn miiran si jẹ gbajugbaja oniṣowo.
Amọ, kii ṣe orilẹede Russia nikan ni iru iṣẹlẹ bayii ti n ṣẹlẹ. Iwadii fihan pe, ọkan ninu awọn obinrin mẹrin l'Amẹrika lo ti gbero lati gbẹmi ọmọ wọn.
Iwadi kan lorilẹede Amẹrika fihan pe, laarin ọdun 1976 si 1997, eyiun ọdun laarin ọdun mọkanlelogun, awọn ọmọde tawọn obi wọn ti pa to ẹgbẹrun mọkanla.
Eyi tumọ si pe awọn ọmọde toto okoolelọọdunrun (340), lawọn obi wọn n sekupa pa laarin ọdun kan soso.
Ṣugbọn lorilẹede Russia, gẹgẹ bi o ti rii lọpọlọpọ orilẹede naa, o nira lati gbaye gbadun nitori ọrọ aje to dẹnu kọ lẹ.
Awọn Eewọ:
Awọn akọroyin BBC lorilẹede Russia, Olesya Gerasimenko ati Svetlana Reiter beere lọwọ awọn obinrin ni Russia, idi abajọ ti wọn n fi pa ọmọ ti wọn bi.
Iṣẹ iwadii wọn yii tun se afihan idi to fi ṣe pataki lati gbe iru aṣa bẹẹ ṣẹgbẹ kan.
Alyona:
Alyona jẹ onimọ nipa eto ọrọ-aje, o fẹ ọkọ kan ti orukọ rẹ n jẹ Pyotr, wọn si jọ n reti ọmọ.
Wọn ra aṣọ, wọn si se gbogbo eto to yẹ ni ireti ọmọ tuntun to n bọ, ṣugbọn ko sẹni to ranti nipa aisan ailera to le ṣẹyọ lẹyin ibimọ.
Lẹyin to bimọ tan, Alyona ni aarun otutu aya, eyi to ko si ninu ọpọlọ, ti iwa rẹ ko si fii bẹẹ jọ ti eeyan ti ọpọlọ rẹ pe.
Ọkọ rẹ, Pyotr ba oku ọmọ oṣu meje ni baluwẹ lọjọ kan to pada sile, o si ri Alyona iyawo rẹ lẹgbẹ odo kan ni abawọlu Moscow, nibi to ti n mu ọti Vodka.
Ni bayii, Alyona n jẹjọ lọwọ lori ẹsun naa, ti ọkọ rẹ maa n gbiyanju lati tu u ninu nigba kuugba ti wọn ba lọ si ileẹjọ.
Pyotr gbagbọ pe, iṣẹlẹ naa ko ba ti ṣẹlẹ ti awọn ba mọ nipa aisan to n se abiyamọ lẹyin ibimọ.
Irufẹ isẹlẹ ki obi gbẹmi ọmọ rẹ bayii si to mẹtalelọgbọn ti wọn gbọ ẹjọ rẹ lọdun 2018 nikan ni orilẹede Russia, awọn eeyan to n sewadi iwa ọdaran si fi idi rẹ mulẹ pe ilọpo mẹjọ irufẹ ẹsun yii lo n waye lai jẹ pe o dele ẹjọ.
Oluwo: Inú ìwé kíkà ni ọja ọ̀la àwọn Fulani wà
Oríṣun àwòrán, Instagram/Oluwo of Iwoland
Oluwo ti ilu Iwo, Ọba Abdulrosheed Adewale Akanbi, Telu Kinni, ti kesi ijọba apapọ lorilẹede Naijiria lati sọ ileewe lilọ di dandan fun awọn ọmọ ẹya Fulani.
Oluwo fi ọrọ yii sita loju opo ayelujara Instagram rẹ, lẹyin ti oun ati awọn ọba alaye to le ni ogun, ṣe abẹwo ikinni ku oriire si Gomina Gboyega Oyetọla ti ipinlẹ Ọṣun, lọọfisi rẹ.
O ni ailọ sileewe awọn ọmọ naa, to jẹ iṣẹ maalu dida kiri nikan ni wọn fi nkọ wọn, jẹ ara nkan to n fa iwa jagidijagan.
Oluwo ni o ṣe pataki ki ijọba ṣe ofin pe, ki awọn ọmọ Fulani maa lọ si ileewe, bi ko tilẹ kọja ileewe girama, lati le ṣe eto ọjọ iwaju to dara fun ẹya naa.
''Mo maa n bẹ awọn Fulani to wa ninu ilu mi wo. Bi mo ṣe maa n bẹ wọn lati ran awọn ọmọ wọn lọ sileewe, naa ni mo maa n kilọ pe, maa fi ofin gbe awọn obi wọn to ba kọ lati fun awọn ọmọ wọn ni ẹkọ to dara.''
Oluwo: Mo lè jẹ Ọba ní Ile Ife
Ọba alaye naa fikun pe aisi ẹkọ iwe lo maa n se okunfa iwa jagidi-jagan. Ijiya ẹ́sẹ́ fawọ̀n ajinigbe ko si lọ̀ titi, amọ eto ẹkọ to ye kooro si lo le wa ojutu laelae si isoro naa.
Olakunrin murder: Ọlọ́pàá ní OPC kò láṣẹ láti fipa lé ẹ̀yà kan nílẹ̀ Yorùbá
Oríṣun àwòrán, Funke Olakunrin
Ile iṣẹ ọlọpaa ti sọ pe, ẹgbẹ apapọ ọmọbibi Oodua, Oodua Peoples Congress (OPC), igun ti New Era, ko laṣẹ labẹ ofin lati fipa le eya kan kuro nilẹ Yoruba.
Eyi ni esi agbẹnusọ fun ile iṣẹ ọlọpaa Ipinlẹ Ondo, Femi Joseph si atẹjade kan ti OPC, New Era fi sita lọjọbọ.
OPC New Era ni awọn ọmọ ẹgbẹ awọn yoo bẹrẹ si ni le awọn Fulani darandaran to n hu iwa ọdaran ni gbogbo awọn ipinlẹ to jẹ ti ẹya Yoruba jade, tawọn ile iṣẹ eto aabo ko ba foju awọn to ṣeku pa arabinrin Funke Olakunrin han.
Agbẹnusọ fun ile iṣẹ ọlọpaa ni, ofin Naijiria faye gba ẹyakẹya lati lọ si ipinlẹ miiran, bakan naa lofin faye gba wọn lati ni dukia nibi kibi ti wọn ba wa lorilẹede Naijiria.
Ọgbẹni Joseph sọ pe, ijọba nikan lo laṣẹ lati sọ pe ki ẹnikẹni kuro ni ipinlẹ kan tabi nibikibi lorilẹede Naijiria.
O wa rọ ẹgbẹ OPC, New Era lati fọwọsowọpọ pẹlu ile iṣẹ ọlọpaa lori iṣẹ iwadii ti wọn n ṣe, lori iku arabinrin Olakunrin.
Oríṣun àwòrán, other
Agbẹnusọ ile iṣẹ ọlọpaa tun rọ ẹgbẹ OPC pe ki wọn ni suuru kọrọ naa maa ba di ija.
Ọgbẹni Joseph ni iṣẹ iwadii ṣi n lọ lori ọrọ naa, pẹlu afikun pe ko yẹ ki ẹgbẹ OPC maa dunkoko mọ awọn ọlọpaa nitori iṣẹ iwadii lori iṣekupani maa n gba suuru ati akoko.
Ọlọ́pàá, a fún yín ní gbèdéke ọjọ́ 21 láti mú àwọn tó pa ọmọ Fasoranti - OPC
Ẹgbẹ Oodua Peoples Congress (OPC), New Era, ti fun ileeṣẹ ọlọpaa ati awọn ileeṣẹ eto aabo mi i l'orilẹede Naijiria ni gbedeke ọjọ mọkanlelogun lati tu aṣiri awọn to pa Abilekọ Funke Olakunrin, ọmọ olori ẹgbẹ Afẹnifẹre, Alagba Reuben Fasoranti.
Ẹgbẹ naa ninu atẹjade kan to fi sita l'Ọjọru nilu Ibadan lati ọwọ Alukoro Apapọ rẹ, Comrade Adeshina Akinpẹlu, sọ pe awọn ọmọ ẹgbẹ awọn yoo bẹrẹ si ni le awọn Fulani darandaran to n hu iwa ọdaran ni gbogbo awọn ipinlẹ to jẹ ti ẹya Yoruba jade, to fi mọ awọn agbodegba wọn laarin awọn ọmọ Yoruba ati ẹya miran.
Iba Gani Adams: Bẹ́ẹ gbé màláíkà kan lọ sí Aso Rock, kò lè ṣàṣeyọrí
Ọjọ Ẹti to kọja ni awọn kan pa Abilekọ Ọlakunrin loju ọna Ore si Sagamu.
''Asiko ti to fun wa lati gbe igbesẹ, a ko kan nii kawọ gbera maa wo ki wọn maa fi ẹjẹ awọn eniyan wa daabo bo iṣọkan Naijiria.
Kikuna lati mu awọn apaniyan naa sita, ko ni ṣi nkan mii fun wa lati ṣe ju pe ka daabo bo awọn eniyan wa lọ, ka si le gbogbo awọn ọdaran Fulani darandaran kuro laarin wa.
Lori bi ẹgbẹ awọn darandaran ni Naijiria, Miyetti Allah, ṣe ni ki wọn fi ofin gbe aarẹ Naijiria nigba kan, Olusegun Obasanjo nitori lẹta to kọ si arẹ Muhammad Buhari lori ọrọ eto aabo ni Naijiria laipẹ yii, ẹgbẹ OPC sọ pe ki ẹgbẹ Miyetti Allah ''ṣọra lati maa wa ẹni ti wọn fẹ fi j'ofin fun awọn iwa ti ko tọ ti wọn n hu.''
Dandan ni bàyíì fún àwọn màálù ni Uganda láti gba ìwé ọjọ́ ìbí
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Gbogbo maalu l'orilẹede Uganda yoo bẹrẹ si ni gba iwe ọjọ ibi laipẹ, ko le baa rọrun lati tọ pinpin ibi ti wọn ti wa.
Eyi ri bẹẹ ki wọn o le maa tẹle ilana lati ọdọ ajọ ilẹ Yuroopu.
Gẹgẹ bi Minisita fun eto iṣẹ ọgbin, itọju ẹranko ati ọsin ẹja, Vincent Ssempijja, ṣe sọ, awọn orilẹede to n pese ounjẹ fun ẹja nilẹ Yuroopu gbọdọ fi ẹri ibi ti ounjẹ naa ti wa han.
O sọ pe ilana yii ṣe pataki pupọ fun awọn agbẹ nitori pe wọn yoo fẹ mọ ibi ti maalu ti wa, ati ọjọ ori maalu naa, nitori pe wọn fẹran ẹran maalu ti ọjọ ori rẹ ko ju oṣu mẹẹdogun si ọdun meji lọ.
"Bakan naa ni Minisita naa sọ pe ajọ EU ti fi igba kan gbẹsẹ le, ti wọn si tun fi ofin de awọn ọja to wa lati Uganda. O ni ""nitori eyi lo ṣe ṣe pataki ki awọn agbẹ o gba lati fi orukọ silẹ."""
"Ilana eto naa ni pe ""awọn agbẹ yoo fi oruk ara wọn silẹ, gbogbo ere oko tabi ẹran ọsin to wa lati ọdọ wọn yoo maa ni ami idanimọ pataki."
"Eyi yoo mu ki o rọrun lati mọ orisun ibi ti ọja kankan to ba ni wahala ninu ti wa."""
Iṣẹ agbẹ jẹ ọkan gboogi ninu eto ọrọ aje Uganda, nitori pe o n gba to ìdá aadọrin awọn eniyan orilẹede naa si iṣẹ.
Àgbà ni Obasanjo, oun tó ń sọ yé e, ìjọba ni kó tají - Wale oke
Africa in Pictures: Àwọn àwòràn tó ṣàrà ọ̀tọ̀ láti ilẹ̀ Afirika
Oríṣun àwòrán, Reuters
Awọn ọmọbinrin akẹkọ mẹta ni orilẹede Sierria Leone to n ti ile iwe bọ, sa si abẹ́ aburada kansoso lasiko ti ojo n rọ. Eyi tumọ̀ si pe bi ifẹ ba wa, yara kekere gba ọpọ eeyan, inu ko gba, ni aaye ko gba
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ọdọọdun ni awọn adan maa n rababa yika oju ọdun nilu London, lati fo pada wa si ilẹ Afrika. Aworan yii lo si n fi ye wa pe oju ọrun to ẹyẹ fo lai fi apa kan ara wọn
Oríṣun àwòrán, AFP
Iya ati ọmọ lo tu jade ni Khartoum, lorilẹede Sudan lati se iwọde tako ijọba ologun. Eyi tumọ si pe kaka ki ẹlulu ma dun ọbẹ, tapa titan rẹ ni yoo run si
Oríṣun àwòrán, AFP
Inu ẹni kii dun, ka pa mọra. Sugbọn ere itage alafi orin kọ ni obinrin yii n se ni orilẹede Tunisia
Oríṣun àwòrán, AFP
Ero ree lode lasiko ti akọrin adulawọ kan, Aya Nakamura bọ sori itage lati kọrin lasiko ajọdun orin lorilẹede South France. Ero yii ti pọju
Oríṣun àwòrán, Reuters
Haa, awọn obinrin lo n luwẹ bii ẹja yii, ohun ti ọkunrin lee se, awọn obinrin naa le se e. orilẹede South Korea ni idije iwẹ lilu lagbaye naa ti n lọ lọwọ
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Agbara ju agbara lọ, ọgbọn ju ọgbọn lọ. Eeyan kan ree to n dẹgbẹ lori okun lai si lori ọkọ oju omi, Huu, nkan n bẹ
Oríṣun àwòrán, AFP
Ọlọrun ma jẹ ki itan yii fa ya, ki lo le to eyi. Anice Badri ọmọ orilẹede Tunisia ree to ya itan de agbari
Oríṣun àwòrán, AFP
Ara meeriri ree o. Okuta posi kan ree ti wọ̀n ya aworan si lara eyi ti wọn se awari rẹ nilu Cairo lorilẹede Egypt lọjọ Satide
Ayinla Kollington: Ìyàwó mí títí láéláé ni Salawa Abẹni
Gbajugbaja olorin Fuji nni, Alhaji Ayinla Kollington ti kede fun araye pe titi aye ni akọrin Waka nni, Alhaja Salawa Abẹni yoo maa jẹ iyawo oun, ti awọn yoo si jọ pẹ fun ara awọn.
Kollington, ẹni to kede eyi lasiko to n dahun ibeere lori eto BBC Yoruba, tun salaye pe obinrin to bi ọmọ fun ni, ti kuro ni ale ẹni, ọmọ mẹta si ni Salawa Abẹni bi fun oun, nitori naa, iyawo oun nii se.
O tun fikun pe, laipẹ ni oun ati Salawa Abẹni yoo dijọ se awo orin jade, koda, ọmọ awọn to n kọ orin takasufe, Big Chef, ti oun gan yoo se awo orin naa papọ pẹlu awọn mejeeji.
Bakan naa ni Kollington kede pe baba Kebe ni oun, baba 'Yuppie', nitori pe to ba di ere lọkọlaya, ara oun si n ta kebe, eegun oun si tun n le.
Nigba to n salaye nipa ẹni to da orin Fuji silẹ nilẹ Yoruba, Kollington kede pe, oun ati Alhaji Sikiru Ayinde Barrister ni awọn dijọ bẹrẹ orin Fuji ni akoko kan naa tawọn dijọ wa ninu isẹ ologun, bi o tilẹ jẹ pe orin Fuji ti wa tipẹ ki awọn to bẹrẹ si ni gbe larugẹ.
Kollington, ẹni to gbosuba fun Barrister to wa wọ kuro lẹnu isẹ sọja, wa kan saara si oloogbe naa pe, ti kii ba se ti Barrister ni, isẹ asọna ni oun ko ba maa se.
O fikun pe ọpọ ija ti oun ati Barrister maa n ja kii se pe awọn n se ọta, amọ ija orogun owo lasan ni, ti awọn si maa n lọ sile ara awọn lati jẹun eyi ti ko han si ọpọ ololufẹ awọn to n tori awọn mejeeji ja lainidi.
Kollington tun salaye pe awọn ololufẹ awọn lo maa n da ija silẹ laarin oun ati Barrister nitori iwa gbọyi-sọyi ti wọn maa n se, ti wọn si maa n ti awọn lati fi orin owe bu ara awọn.
Kollington tun yannana rẹ pe oun n selede lẹyin Barrister, ti oun ko si jẹ ki ile rẹ daru, koda, awọn ọmọ rẹ gan ti ri oun bii baba wọn, ti wọn si maa n wa fi ọrọ ati ise wọn lọ oun lati tọ wọn sọna.
Baba Alatika wa kede pe oun n fẹ ọjọ ọla rere fun orin Fuji, ti oun ko si fẹ ki olorin Fuji kankan ja mọ nitori orogun owo, bakan naa lo si gba awọn olorin iwoyi nimọran lati mase maa fi ede ajeji kọ orin Fuji nitori tiwa n tiwa, akisa ni ti aatan.
Kollington lasiko to n gba ijọba ilẹ wa ni imọran, gba awọn olori wa nimọran, lati maa ranti mẹkunnu, nipa ipese awọn ohun eelo amayedẹrun, papa atunse oju popo.
Kebe n Kwara, ẹni to ni ko yẹ ki orilẹede Naijiria tii gba ominira, wa gba awọn araalu nimọran lati sugba ijọba Buhari nitori pe ilu ko rọ̀run nigba ti Buhari gba ijọba pẹlu afikun pe iwa ajẹ́banu ko lee tan lara awọn ọmọ Naijiria.
Ruga: Ọ̀pọ̀ àwọn ìpínlẹ̀ tó ń fẹ́ Ruga ló wá láti apá òkè ọya
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Agbekalẹ abule Fulani ti wọn n pe ni Ruga lo ti n fa awuyewuye ni orilẹede Naijiria lẹnu lọọlọ yii, ti awọn ipinlẹ kan si tako igbesẹ naa eyi to mu ki ijọba Muhammadu Buhari sẹwele igbesẹ ọhun.
Ọpọ awọn ẹlẹgbẹjẹgbẹ, awọn lookọ lookọ lawujọ, awọn oriade, asaaaju ẹsin to fi mọ awọn gomina ipinlẹ kọọkan lo ti sọ ero ọkan wọn lati tako tabi faramọ agbekalẹ abule Ruga naa.
Sugbọn iwadi BBC ti fihan pe, ọrọ naa ti di ẹkọ ẹlẹkọ ni ẹgba ẹlẹgba bayii nitori awọn ipinlẹ kan ti n fi ifẹ han lati se agbekalẹ abule Ruga ni ipinlẹ wọn.
Ni ipinlẹ Kano, gomina Abdullahi Ganduje ti se agbekalẹ igbimọ ẹlẹni mẹrindinlogun ti yoo sawari awọn agbegbe ti wọn yoo tẹ abule Ruga naa si.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Bakan naa ni ipinlẹ Plateau, gomina Simon Lalong ti kede pe gbagbagba ni oun n se atilẹyin fun agbekalẹ abule Ruga nitori igbesẹ naa yoo mu opin de ba aawọ to maa n fi ojoojumọ waye laarin awọn agbẹ ati darandaran yika orilẹede yii.
Ni Bauchi, Bala Muhammad tii se gomina ibẹ naa ti salaye pe, gbogbo ara ni oun fi n ti agbekalẹ abule Ruga lẹyin nitori ida aadọrin ninu ọgọrun awọn olugbe ipinlẹ Bauchi lo jẹ Fulani darandaran.
Ijọba ipinlẹ Niger naa, lati ipasẹ akọwe ijọba ipinlẹ ọhun, Ahmed Matane ti kede pe ko iyatọ laarin ibudo ifẹranjẹ ati abule Ruga, awọn alanikanjọpọn kan lo kan fẹ lo lati da wahala silẹ ni Naijiria.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Awọn ipinlẹ yoku to si ti tun kede atilẹyin wsn fun agbekalẹ abule Ruga ni iwọnyii:
Ijọba apapọ si ti sọ saaju pe agbekalẹ abule Ruga yoo jẹ ki imọtoto to yẹ wa fawọn ẹran ta n jẹ nilẹ Naijiria.
Òwe Yorùbá: Mélòó lo lè parí nínú òwe Yorùbá yìí?
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Aworan to n sọ itan
Ọpọ ọmọ Yoruba lo maa n leri pe awọn dantọ ninu imọ ijinlẹ ede Yoruba ati nipa aṣa ibilẹ wa.
Lara ohun ti eeyan le fi danrawo boya lootọ ni aayan mọ ijinlẹ ede Yoruba niyii, a ti ṣe akojọpọ diẹ lara awọn òwe ti BBC Yorùbá ti lò sẹyin fun yin.
Bi o ba wa da ọ loju pe o mọ owe Yoruba, tẹ ibi yii ki o dahun bi o ṣe yẹ.
O ni anfani lati wo maaki rẹ bi o ba ṣe tan.
Gbiyanju òwe yii nípa fifi èyí to jẹ idahun ipari rẹ̀ kan ara wọn
Fi igun ibẹrẹ òwe naa kan igun ipari òwe naa papọ
Awọn Iroyin mii ti ẹ le nifẹ si
Osun: Gboyega Oyetola, Adeleke ń ṣe àríyànjiyàn lórí èyí tó dárajù nínú 'oníjó' àti 'akówójẹ'
Oríṣun àwòrán, dailypost
Ọrọ naa bẹrẹ pẹlu gomina Gboyega Oyetola to ni inu oun bajẹ gidigidi wi pe onijo lo ba oun du ipo gomina ipinlẹ Oṣun lasiko idibo gomina to waye lọdun 2018.
Oyetola sọrọ yii lasiko to gbalejo awọn agbaagba ẹgbẹ oṣelu SDP to wa ki i ni ile ijoba nilu Osogbo.
Oyetọla ni aikun oju iwọn eto idibo orilẹede Naijiria lori yiyan awọn oludije lo fun iru awọn eeyan bi Adeleke lanfani lati dije tako oun.
Ẹ jẹ ki a wo bi o ṣe sọọ gan ni ẹkunrẹrẹ:
Ọpọ igba ti mo ba joko ti mo si ronu lọ sori pe iru Adeleke, to jẹ pe ijo jijo nikan lo ti jafafa,  ni mo n ba dije du ipo gomina, ara mi a si bu maṣọ, oju ara mi a si gba mi ti. Ajalu nla nii ba jẹ fun ipinlẹ wa ka ni ọna miran lọrọ yii ba yọ ni.
Barrister ló sọ mí di èèyàn ńlá - Ayinla Kollington
Supreme Court : Oyetola fẹ̀yìn Adeleke janlẹ̀ nílé ẹjọ́ tó ga jù lọ!
Yinka Ayefele: Oṣù àwọn ìbẹ́ta mi kò pé ní kò jẹ́ kí n kọ́kọ́ kéde ìbí wọn
Amoṣa ki ni Sẹnetọ Ademola Adeleke to jẹ oludije ẹgbẹ oṣelu PDP lasiko idibo naa gbọ eyi si, o ni wọn ko gbe ẹnu toun naa fun alagbafọ.
"Oun pẹlu wa fi gbolohun diẹ ṣọwọ si Gomina Oyetọla pe oun dupẹ toun o pe oun jẹ onijo, ṣugbọn ijo jijo kii ṣe aisan. Koda o tun tẹsiwaju, O ni o san fun oun lati jẹ onijo ki oun si fi ays inu oun han ju ki oun maa ""po ẹkọ ibinujẹ ati wahala faraalu nipa lilu aṣuwọn owo ilu ni ponpo."""
"Adeleke ni ọpọlọpọ ere lo n bẹ ninu ijo jijo. Nigba ti yoo parí ọrọ rẹ, Sẹnetọ Adeleke ni...""ijo jijo san ju ka lu owo ilu ni ponpo lọ"""
Adeleke fọhùn, 'èmi ni gómìnà tí wọ́n dìbò yàn'
"O wa ranṣẹ ọrọ si Oyetọla pe, ""Jẹ ki n ran Oyetọla leti pe iwe rẹ gẹgẹ bii olori awọn oṣiṣẹ fun Rauf Arẹgbẹṣọla fihan gbangba peko kun oju iwọn gẹgẹ bii alakoso, ṣugbọn o jafafa ninu ka lu owo ilu ni ponpo."""
Ọrọ yii ti n ja ranyinranyin laarin awọn ololufẹ igun mejeeji at'awọn onwoye. Bi awọn kan ṣe n wi pe o yẹ ki awon mejeeji o ṣọra pẹlu ọrọ wọn gẹgẹ bíi opomulero ni ipinlẹ naa l'awọn kan n jiyan lori ọrọ mejeeji.
Delta Building Colapse: Ilé wó lu ọ̀gọ̀ọ̀rọ̀ èèyàn ní Abraka
Oríṣun àwòrán, EPA
Ile wiwo
Iroyin to n tẹ wa lọwọ ni wi pe ile alaja mẹta kan ti wọn n kọ lọwọ ni ijọba ibilẹ Ethiope East, ipinlẹ Delta ti wo lulẹ.
Gẹgẹ bi alukoro ile iṣẹ Ọlọpaa ipinlẹ Delta ṣe ṣalaye fun akọroyin BBC, Onovwakpoyeya Onome sọ pe lootọ ni o ṣẹlẹ ni agbegbe Abraka.
Bi o tilẹ jẹ wi pe a ko tii le fi aridaju ohun to ṣokunfa ile wiwo naa, iroyin sọ pe lasiko ti ojo n rọ lo ṣẹlẹ lowurọ ọjọ abamẹta.
Bakan naa ni iroyin ọhun sọ pe awọn eniyan n duro ki ojo to n rọ da labẹ ile naa ni afi to di wọ̀ọ̀ nilẹ.
Oniruuru ni iroyin to ti n jade lati ṣapejuwe ohun to ṣẹlẹ gan ati iru ile ti o jẹ.
A o maa mu ẹkunrẹrẹ wa fun yin bi a ba ti ri aridaju ohun gbogbo.
Osinbajo: Ààrẹ Buhari rán mi láti wá àbáyọ sí ààbò tó mẹ́hẹ
Oríṣun àwòrán, Google
Ọ̀pọ̀lọ̀pọ̀ ènìyàn ló ń jíròrò láti wá ọ̀nà àbáyọ sí ètò ààbò tó mẹ́hẹ ní Naijiria, pàápàá ní Ìwọ-òòrùn Naijiria.
Igbakeji Aarẹ Orilẹede Naijiria, Yemi Osinbajo ti se ipade pọ pẹlu Akarigbo ti ilu Remo, Oba Babatunde Ajayi, ati Awujale ti ilu Ijebu, Oba Sikiru Adetona, lori eto aabo to mẹhẹ lorilẹede Naijiria.
Osinbajo, lasiko to n ba awọn akọroyin sọrọ pẹlu gomina ipinlẹ Ogun, Dapo Abiodun sọ wi pe, Aarẹ Buhari lo ran oun wa lati wa ọna abayọ si ipenija eto aabo to mẹhẹ ni Naijiria.
O ni awọn ọba mejeeji naa ti fun oun ni imọran lori ọna ti awọn le gba, lati mu ki eto aabo gbooro si kaakiri awọn agbegbe to wa lorilẹede Naijiria.
Oríṣun àwòrán, Yemi osinbajo
Amọ, Osinbajo fikun wi pe, awọn asebajẹ kan ni awujọ n wa ọna lati fi ọrọ eto abo to mẹhẹ naa lati da Naijiria ru.
Bakan naa, ni Igbakeji Aarẹ, Yemi Osinbajo naa fikun un wi pe, awọn yoo sepade pẹlu awọn ọba to ku nitori awọn mọ wi pe, awọn lo sun mọ awọn ara ilu julọ.
Coza Rape: Ọlọ́pàá ránṣẹ́ pe Timi Dakolo àti ìyàwó rẹ̀ lórí ẹ̀ṣùn ìfipábánilòpọ̀
Oríṣun àwòrán, @timidakolo
Ileesẹ ọlọpaa ti ti ẹsẹ ofin wọ ẹsun ifipabanilopọkan ti Timi Dakolo ati Busọla iyawo rẹ fi kan Pasitọ kan nilu Abuja, Tolu Fatoyinbo.
Lọwọlọwọ bayii, ileesẹ ọlọpaa ti ransẹ pe tọkọtaya naa pe ki wọn yọju si ilu Abuja, lọdọ ọga ọlọpa kan, Ibrahim Agu fun ifọrọwanilẹnuwo.
Iwe ipe awọn ọlọpaa yii, ti igbakeji Kọmisọna ọlọpaa lolu ileesẹ ọlọpaa ilẹ wa nilu Abuja, Kolo Yusuf fọwọsi, lo pasẹ fun tọkọtaya naa lati yọju si wọn lọjọ Iṣẹgun to n bọ, eyiun ọjọ Kẹtalelogun osu Keje ọdun 2019.
"Lara ohun ti awọn ọlọpaa kọ sinu iwe ipe ọhun ni pe "" ileesẹ naa fẹ tanna wadi ẹsun lilẹdi apo pọ lati huwa ọdaran, irọ pipa, etekete ati idunkooko mọ ẹmi ẹni, ninu eyi ti wọn ti darukọ yin. """
A si fẹ kẹ yọju si osisẹ ọlọpaa to fọwọsi lẹta yii ni lọjọ Iṣẹgun to n bọ, eyiun ọjọ Kẹtalelogun, osu Keje, ọdun 2019 ni aago mẹwa owurọ ki Ibrahim Agu le e wadi ohun gbogbo daju, ko si fi idi eyi tii se otitọ mulẹ.
Bẹẹ ba agbagbe, laipẹ yii ni ariwo sọ nigba ti Busọla sọ lori fọnran aworan kan pe Pasitọ Fatoyinbo ti ijọ COZA fi tipa ba oun ni ajọsepọ lọdun mẹrindinlogun sẹyin nilu Ilọrin lasiko ti oun si wa ni ọdọ.
Nibayii na, ileesẹ ọlọpaa ilẹ wa ti kede pe lootọ ni oun fi lẹta sita lati ransẹ pe tọkọtaya Dakolo lori ẹsun ifipabanilopọ ti wọn kede nijooni.
Atẹjade kan ti ileesẹ ọlọpaa fisita loju opo Twitter rẹ salaye pe, eyi ko tumọ̀ si pe wọn fẹ́ ti tọkọtaya naa mọle ni, amọ o jẹ ara ohun eelo iwadi lati tan imọlẹ si ẹsunkẹsun tawọn eeyan ba gbe wa siwaju awọn.
Oríṣun àwòrán, AFP
Mba wa rawọ ẹbẹ sawọn araalu lati gba alaafia laaye, nitori ileesẹ ọlọpaa ko ni segbe sẹyin igun kankan amọ yoo ri daju pe idajọ ododo fẹsẹ mulẹ lori isẹlẹ naa.
Amọ nigba to n fesi si iwe ipe ileesẹ ọlọpaa naa ati ọrọ to wa ninu rẹ, Timi Dakolo sọ loju opo Instagram rẹ pe igbesẹ naa ko ba awọn lojiji nitori agbẹjọro awọn ti sin awọn ni gbẹrẹ ipakọ tẹlẹ pe iru isẹlẹ naa le waye.
O ni ti eeyan ba ronu jinlẹ lori ọrọ to wa ninu iwe ipe awọn ọlọpaa naa, o fihan pe esuro ti n padi da, maa le aja lori ẹsun ifipabanilopọ naa, tawọn ọlọpaa si ti fẹ fi ẹsun irọ pipa ati ibanilorukọjẹ we oun ati iyawo oun lọrun.
Federal Cabinet: Onímọ̀ ní ewu ń bẹ lórí bí ìsàkóso ìjọba ṣe dúró rigidi
Oríṣun àwòrán, @MBuhari
Awọn onimọ nipa ọrọ aje ti mu igbe bọnu pe, ewu n bẹ loko Longẹ fun orilẹede Naijiria, to si seese ki ọrọ aje tun dagun lẹẹkan si ti aarẹ Muhammadu Buhari ko ba tete kede awọn ọmọ igbimọ alasẹ rẹ.
Koda, n se ni wọn n gbarata pe eto isakoso ijọba apapọ ti duro soju kan soso ju, o si yẹ ki Buhari tete mọ odo ti yoo da ọrunla si nipa yiyan awọn minisita ti yoo ba sisẹ.
Lero tawọn onimọ ọrọ aje yii, Buhari gbọdọ tete ta mọra lati fi orukọ awọn minisita rẹ sọwọ sile asofin apapọ, ki wọn to lọ fun isinmi, bi bẹẹ kọ, ọfọn lee fi iru nagba nidi ọrọ aje wa, kawọn asofin naa to pada de.
Bakan naa ni wsn tun n kọminu pe ti orukọ awọn minisita naa ba tiẹ de siwaju ile asofin apapọ lọsẹ yii, n jẹ asọ si lee ba ọmọyẹ mọ, nidi ikede awọn tile asofin ba fi ontẹ lu ninu wọn.
Awọn onimọ naa ni diẹ ni ti Alaba lọrọ ibeji taa ba n sọrọ eto isakoso ati awọn osisẹ ọba nitori iwọnba ni wọn lee si, ọpọ asẹ si lo wa lọwọ awọn minisita ti yoo ba aarẹ sisẹ.
Oríṣun àwòrán, @nassnigeria
Wọn tun woye pe, lọwọlọwọ bayii, idaduro to wa nidi yiyan awọn minisita ti n se akoba bayii fun eto ọrọ aje wa, ti Buhari ko ba si gbe igbesẹ lori rẹ ki awọn asofin to gba isinmi, eyi lee paroko ti ko dara ransẹ si awọn eeyan to fk wa dokowo sorilẹede yii lati ilẹ okeere.
Bẹẹ ba gbagbe, ọjọ kẹtalelogun osu Keji ọdun 2019 ni wsn ti seto idibo aarẹ, ti wsn si kede Buhari lẹyin ọjọ diẹ, ti eto ibura fun saa keji rẹ si waye lọjọ Kọkandinlọgbọn osu Karun ọdun 2019.
Ireti awọn ọmọ Naijiria ni pe ko yẹ ko si ohunkohun ti yoo maa da aarẹ lọwọkọ mọ lati yan awọn ọmọ igbimọ alasẹ rẹ, ki eto isejọba lee tẹsiwaju laisi idaduro rara.
SERAP: SERAP gbé ìjọba Nàìjíríà lọ iléẹjọ́ ọ̀daràn lágbàáyé, ICC
Oríṣun àwòrán, @Danjauro
Ajọ SERAP ti gbe awọn alaṣẹ ijọba orilẹede Naijria lati ọdun 1999 di isinsinyi lọ sile ẹjọ agbaye, ICC to n gbẹjọ iwa ọdaran, lori ẹsun pe wọn ko jẹ ki awọn ọmọde to le ni miliọnu mẹtala lanfani si eto ẹkọ.
Ajọ SERAP fi iwe ipẹjọ ṣọwọ si oludari igbimọ igbẹjọ nile ẹjọ ọhun, arabinrin Fatou Bensouda, lati lo ofiisi rẹ fi ṣe iwadii idi abajọ ti ọgọrọ ọmọde ko ṣe lanfani lati lọ sile ẹkọ.
Bakan naa, ajọ SERAP tun rọ Bensouda lati ṣewadi ikuna ijọba Naijiria fun ọpọlọpọ ọdun, lati wa nnkan ṣe si ọrọ naa.
Ajọ SERAP ni eyi tumọ si iwa ipa ati iwa ọdaran si awọn ọmọde.
Ajọ naa tun rọ ileẹjọ ICC lati kan si awọn aarẹ ati gomina ti to ṣe ijọba Naijiria tẹlẹ ri lati ọdun 1999, ati awọn to wa lori aleefa lọwọlọwọ lori ọrọ ọhun.
Oríṣun àwòrán, AFP
SERAP ni, ọpọ ọmọde lo ti ku iku aitọjọ, ti ọpọ si wa ninu ewu nla nitori aisi nile iwe, eyi to jẹ ikuna ijọba ni Naijiria.
Ajọ naa fidi rẹ mulẹ pe, ileẹjọ ICC ti ṣalaye tẹlẹ pe iwa ọdaran ni ki awọn ọmọde maa lanfani si ile ẹkọ.
SERAP tun rọ ileẹjọ ICC lati kan an nipa fun awọn alaṣẹ ijọba Naijiria lati rii wi pe, ọgọọrọ awọn ọmọde ti ko si nile iwe lanfani lati pada sile ẹkọ.
Kwara Kidnap: Ọlọ́pàá láwọn yóò wá àwọn ọmọ ilẹ̀ Turkey mẹ́rin tí wọ́n jígbé rí láàyè
Oríṣun àwòrán, Facebook/Kayode Egbetokun
Ile ọlọpaa ipinlẹ Kwara ti wọ igbo lọ lati doola ẹmi awọn ọmọ orilẹede Turkey mẹrin tawọn agbẹbọn mẹfa kan jigbe lalẹ ọjọ Abamẹta nibi ti wọn ti gbafẹ ni igberiko kan ti wọn ni Gbale.
Agbẹnusọ fun ile iṣẹ ọlọpaa Ipinlẹ Kwara, Ajayi Okasanmi to ba BBC Yoruba sọrọ, ni awọn agbofinro yoo wa awọn ọmọ ilẹ Turkey naa ri laaye.
Orukọ awọn mẹrin ti wọn jigbe ọun ni Seyit Keklik, Yasin Colak, Ergun Yurdakul, ati Senerapal.
Yinka Ayefele: Oṣù àwọn ìbẹ́ta mi kò pé ní kò jẹ́ kí n kọ́kọ́ kéde ìbí wọn
Okasanmi ṣalaye pe kete ti iṣẹlẹ ọhun ṣẹlẹ ni ọga ọlọpaa ipinlẹ Kwara, Kayode Egbetokun paṣẹ fawọn ọlọpaa kogberegbe, Operation Puff Adder pe ki wọn bẹrẹ si wa awọn ọmọ ilu okere naa.
Agbẹnusọ ọlọpaa naa tun sọ pe gbogbo agbara ti ile iṣẹ ọlọpaa ni lawọn agbofinro yoo fi wa awọn ti wọn jigbe ọun.
Ọgbẹni Okasanmi sọ pe laipẹ laijina, ọwọ awọn ọlọpaa yoo tẹ awọn agbebọn mẹfa ọun.
Àwọn olóṣèlú ló fẹ́ sọ darandaran Fulani lórúkọ burúkú, àwa kìí gbébọn-Miyetti allah
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Miyetti Allah ni aikọbiara si ipenija awọn gomina lẹkun oke ọya orilẹede NAijiria lo fa awuyewuye lori RUGA
Ẹgbẹ agbajọpọ awọn darandaran Fulani lorilẹede Naijiria, Miyetti Allah, ti wa jade lati pariwo ẹ ma sọ wa ni suna buruku, ko si ọmọ ẹgbẹ wa to n gbe ibsn fi daran igi ni wọn nlo.
Aarẹ ẹgbẹ Miyetti Allah, Bello Abdullahi Bodejo lo sọ bẹẹ lasiko to fi n yannana ọrọ ni ilu Bauchi.
O ni bi awọn eeyan ṣe n sọ Fulani ni suna ti kii ṣe ti wọn nipa pipe wọn ni darandaran to mu iṣẹ ọdaran mọ iṣẹ ko bojumu to.
O ni ki ẹ si maa wa wo o, awọn o jẹ nile oro jẹ nile eegun oloṣelu ni wọn wa nidi ọrọ yii ati pe awọn ọta ẹya Fulani naa wa nidi ẹ; ṣe ẹ si mọ pe eeyan kii wa laye ki o ma ni ọta tirẹ naa.
Dele Momodu : Lẹ́yìn Buhari àti Atiku, èrò ọjà làwọn olùdíje yóòkù ní ìdìbò 2019
Bello Abdullahi Bodejo tun ko aroye balẹ o ni, gbogbo ọran ijinigbe pawo tabi pa, idigun jale atawsn iwa ọdaran miran ti wọn n so akengbe ọran rẹ mọ awọn Fulani lọrun lori oju opo ayelujara gbogbo lawọn kan gbe kalẹ o lati ba orukọ awọn ọmọ ẹya Fulani jẹ.
O ni wahala laarin awọn agbẹ olohun ọgbin atawọn darandaran to jẹ Fulani ti pẹ bi ọwọ aṣọ, awsn eeyan kan lo kan fẹ bẹrẹ si ni fi oṣelu pọn jẹbẹtẹ lakisa lori rẹ
Kí ló máa ń wú ìyá Nike Davies lori láti wé gèlè ràbàtá?
Gẹgẹ bi o ṣe sọ, awọn igun mejeeji yii lo mọ bi wọn ṣe n pari aawọ ati dukuu aarin wọn.
Fulani herdsmen: Mo ti Buhari lẹ́yìn ṣùgbọ́n ìjínigbé ìgbà gbogbo yìí náà ń kọmí lóminú
Oríṣun àwòrán, Alaafin Oba Adeyemi III
Alaafin ni oun to dunni ju ni pe bi gbogbo eyi ṣe n ṣẹlẹ bọọ lawọn agbofinro n wo
Kii ṣe tuntun mọ pe aarẹ Muhammadu Buhari ri lẹta kan gba laipẹ yii lati tete wa wọrọkọ fi ṣada lori bi nnkan ṣe n lọ lorilẹede Naijiria.
Ni bayii, ọrọ ọhun ti yii kan oriade o. Alaafin ilu Ọyọ, iku baba yeye, Ọba Lamidi Adeyẹmi kẹta naa ti wa kọ lẹta tirẹ ranṣẹ si aarẹ bayii; ori ọrọ ijinigbe ati gulegule awọn darandaran Fulani ni ilẹ Yoruba naa ni koko inu iwe lẹta rẹ.
Obasanjo: Atiku kìí se Áńgẹ́lì, àmọ́ yóò se dáadáa ní ìlọ́po méjì ju Buhari lọ
Alaafin to mẹnuba awọn iṣẹlẹ haa-hinn to waye lori ọrọ abo to mẹhẹ ni ilẹ Yoruba laipẹ yii ni aarẹ Buhari ti wọn fi joye ko lee gbadiyẹ lori eto abo.
Iku baba yeye ni ẹya Yoruba lagbara lati gbe igbesẹ lati gba ara rẹ silẹ bi eto abo ko baa gbe pẹẹli si lẹkun naa.
Wòlíì Kasali sọrọ nípa awuyewuye pé o lè ìyàwó rẹ̀ jáde nílé
Alaafin ilu Ọyọ ni ko si aniani pe digbi ni oun wa lẹyin Aarẹ Buhari ati iṣejọba rẹ ṣugbọn ominu n kọ oun lẹnu ọjọ mẹta yii lori ipenija ọrọ abo jakejado orilẹede Naijiria, paapaa julọ ilẹ Yoruba titi kan ipinlẹ Kwara, Kogi ati Edo.
"Eyi nii ṣe pẹlu bi gulegule idukukulaja mọni awọn darandaran Fulani ti ṣe wa n di lemọlemọ bayi loju awọn opopona marosẹ gbogbo ni ilẹ Yoruba. Yala ni Ọwọ ni, Akurẹ ni, opopona ilIfẹ/ Ijẹsa ni titi lọ de agbegbe Ibrapa ati Ijẹbu ni ipinlẹ ogun ni ọrọ ko ti yatọ
Alaafin ni lẹyin ifikuluku ati ijiroro pẹlawọn agbaagba ati majẹobajẹ ilẹ Yoruba, o han gbangba pe inu hilahilo lawọn eeyan n gbe bayii nitori awọn kọlọransi yii ti wọn n fipa ba aya lo niwaju ọkọ, ti wọn si tun n ba nnkan ọgbin jẹ pẹlu oniruru iwa familete n tutọ miran.
O ni oun to dunni ju ni pe bi gbogbo eyi ṣe n ṣẹlẹ bọọ lawọn agbofinro n wo lai lee ṣe ohunkohun
Lórí ọ̀rọ̀ Pásítọ̀ COZA àti Dakolo, Ìwadìí ń tẹ̀ síwájú, ṣùgbọ́n a kò mọ ohunkohun nípa rẹ̀ mọ́- Iléeṣẹ́ ọlọ́pàá Èkó
Oríṣun àwòrán, @Timidakolo
Ileeṣẹ ọlọpaa ni ipinlẹ Eko ni awọn ko mọ ohunkohun mọ nipa ẹjọ ẹsun ifipabanilopo ti iyawo gbajugbaja olorin Timi Dakolo, Busọla, pe tako Pasitọ Fatoyinbo.
Gẹgẹ bii alukoro ileeṣẹ ọlọpaa nipinlẹ Eko, Ọgbẹni Bala Elkana ṣe sọ fun BBC News Yoruba, wọn ti ko iwe ẹjọ naa lọ si olu ileeṣẹ ọlọpaa lorilẹ-ede Naijiria, nilu Abuja nibi ti iwadii naa ti n tẹ siwaju.
Wòlíì Kasali sọrọ nípa awuyewuye pé o lè ìyàwó rẹ̀ jáde nílé
Amọṣa nigba ti a pe alukoro apapọ ileeṣẹ ọlọpaa lorilẹ-ede Naijiria lori ẹrọ ibanisọrọ, a ko rii ba sọrọ.
Fathia Balogun: Kò sí ẹni tó bá mi lò pọ̀, kó tó fún mi ní isẹ́
Ni opin ọsẹ to kọja ni Timi Dakolo ke ibosi sita pe lẹyin ọpọlọpọ ọsẹ ti awọn ti fi iwe ipẹjọ siwaju ileeṣẹ ọlọpaa, awọn ko tii gbọ pe wọn ti pe iranṣẹ Ọlọrun naa fun ifọrọwanilẹnuwo.
Yewande Oyediran: Kò sí ohun tó burú nínú bí Ajimobi ṣe dá Yewande tó pa ọkọ rẹ̀ sílẹ̀
Oríṣun àwòrán, @others
Oro lọkọlaya ko yẹ ko maa gba ẹmi ni ọpọ n wi lasiko yii
Yewande ni obinrin ti wọn fi ran lọ sẹwọn pe o pa ọkọ rẹ ni Ibadan tẹlẹ.
Alaga ẹgbẹ́ awọn agbẹjọro obinrin l'orilẹ̀-ede Naijiria, ẹka ti ipinlẹ Oyo, Arabinrin Deborah Collins ti sọ fun BBC Yoruba pe ko si nkan to buru ninu igbesẹ ijọba.
O ni bi ijọba ipinlẹ Oyo l'abẹ iṣakoso Abiola Ajimobi ṣe da Yewande Oyediran to pa ọkọ rẹ silẹ ko buru nitori bi ọrọ naa ṣe jẹ.
Lopin ọsẹ to kọja ni iroyin gbe e pe gomina Abiola Ajimọbi da Yewande silẹ nigba to ku bi ọsẹ kan ti yoo kuro ni ipo gomina.
Yewande, to jẹ agbẹjọro ni wọn fi ẹsun kan pe o pa ọkọ rẹ, oloogbe Lowo Oyediran lọjọ keji, oṣu Keje, ọdun 2016 ni agbegbe Akobo, nilu Ibadan.
'Bí aya bá kọ ọkọ rẹ̀ silẹ̀, kó wà láì lọ́kọ̀'
Ẹsun ti wọn ni Yewande fi kan ọkọ rẹ ni pe o ni ololufẹ ikọkọ, eyi to fa ede aiyede laarin awọn mejeeji, ko to o di pe Yewande fi ọbẹ gun ọkọ rẹ,eyi to pada yọri si iku.
Sunday Ayẹni: Damilọla, aya ọmọ mi fìgbónára sọ mi sókùnkùn alẹ́
Ṣaaju ọjọ naa ni Yewande ti fi sisọọsi gun ọkọ rẹ nitori ẹsun kan naa.
Ẹjọ naa dele ẹjọ, igbẹjọ rẹ si 'fihan pe ko mọọmọ pa ọkọ rẹ.'
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Lẹyin igbẹjọ naa ni Adajọ Munta Abimbola da ẹjọ ẹwọn ọdun meje fun un, ninu eyi to ti lo ọdun meji.
Iroyin idasilẹ Yewande fa awuyewuye lori ayelujara.
Ọpọ lo n sọ pe nitori o jẹ obinrin ni wọn ṣe da a silẹ.
Awọn miran sọ pe niroti pe awọn obi rẹ jẹ gbajumọ nipinlẹ Oyo ni. Bakan naa lawọn kan sọ pe nitori pe o jẹ agbẹjọro fun ijọba ipinlẹ Oyo ni.
Ìwà ipá nínú ìdílé máa ń bí ìgè àti àdùbí ni tó lè já sí ikú
Ninu alaye rẹ, alaga FIDA, Deborah Collins sọ pe ijọba ṣe nkan ti ofin fun un ni agbara lati ṣe ni.
Kii ṣe Yewande nikan ni ijọba da silẹ, oun ati awọn ẹlẹwọn mi ti apapọ wọn kẹ ẹẹdẹgbẹta ni wọn da silẹ."""
Fasoranti: Dẹ́rẹ́bà tó wa ọmọ Fasoranti ṣàlàyé bí wọ́n ṣe pa Funke Olakunrin
Kii ṣe pe mo n gba ẹnu rẹ sọrọ, ẹnikẹni lo le sọ niwaju ile ẹjọ pe mo ṣe nkan ti mo ṣe labẹ pe wọn mu inu bi mi. Kii ṣe pe boya tori o jẹ agbẹjọro tabi obinrin.
"Ko si ẹni ti ijọba ko le da silẹ."""
Ọ̀rọ̀ Imam yìí ṣe kòńgẹ́ bó ti ń rí láàrin lọ́kọ láya
Collins ṣalaye pe dida ẹlẹwọn silẹ ṣaaju ọjọ to yẹ ko kuro, ko ni nkan ṣe pẹlu iye ọjọ to ti lo lẹwọn ayafi ti idajọ to gbe e de ẹwọn ba sọ pe iru ẹni bẹ ko ni anfaani si itusilẹ latọwọ ijọba.
Dele Momodu : Lẹ́yìn Buhari àti Atiku, èrò ọjà làwọn olùdíje yóòkù ní ìdìbò 2019
Nigeria Air Force: Mo mọ̀ọ́mọ̀ dá €37,000 ti mo rí he padà ni -Ọmọ ogun Bashir
Oríṣun àwòrán, Nigeria Air Force
O wu mi lati jẹ awokọṣe rere ni
Omo ogun ofurufu Naijiria, Bashir Umar ni o ri owo nla tilẹ okeere he ni papakọ ofurufu ti Kano.
Bashir ri owó pọun ẹgbẹrun mẹtadinlogoji he ni eyi to to miliọnu mejila naira lasiko ti o n ṣọde ninu apo kan.
Omo ogun ofurufu Bashir Umar ni oṣiṣẹ alaabo to wa lẹnu iṣẹ lasiko ti ẹnikan gbagbe owo naa silẹ pẹlu awọn akẹgbẹ rẹ..
O wa pe nọmba to wa lara apo owo naa ki o fi ba ẹni to ni owo naa sọrọ lati wa gba owo rẹ pada.
Oga agba Sadique Abubakar to jẹ agbẹnusọ fun ileeṣẹ ologun ofurufu ti Naijiria ti paṣẹ eto idanilọla fun olootọ ọmọ ogun yii.
Ajọ SERAP sọrọ lori owo ifẹhinti awọn oloselu kan
Ogagun Sadique ni ki olori ẹka aato ileeṣẹ ologun ofurufu, Kingsley Lar bẹrẹ igbesẹ lori eto idanilọla naa.
O ni eto akanṣe yii yoo jẹ iwuri ati koriya fawọn ọdọ Naijiria nipa ootọ inu ati iwa ọmọluwabi to ti n sọnu lawujọ.
Ejo abami to n mu owo ni ajọ Jambu
Ninu ọrọ Lar to nmojuto eto idanilọla fun Bashir Umar lo ti ni ootọ inu ati iwa ọmọluwabi jẹ ọkan gboogi lára abuda adamọ ọmọ ogun ofurufu rere.
Eyi kii ṣe igba akọkọ ti iru iwa akin bayii maa ṣẹlẹ ni Naijiria.
Loṣu kẹjọ ọdun to kọja ni awọn alaṣẹ ṣeto idanilọla nipinlẹ Eko fun awọn oṣiṣẹ eleto aabo meji ti wọn da owo gọbọi ti wọn ri he pada ati awọn ohun eelo olowo iyebiye mii.
Awọn oṣiṣẹ mejeeji yii da awọn apo yii pada ni ibudo ti wọn ti ri wọn he.
Inu ọmọ ogun Bashir dùn lati ṣe ohun ti o tọ nipa jijẹ awokọṣe rere fun awọn ọdọ Naijiria.
Dele Momodu : Lẹ́yìn Buhari àti Atiku, èrò ọjà làwọn olùdíje yóòkù ní ìdìbò 2019
Funke Olakunrin Burial: Ọ̀gọ̀rọ̀ èèyàn péjú síbi ìṣẹ̀yẹ ìkẹyìn f'ẹ́ni re tó lọ
Isinku Funke Olakunrin
Eto isinku Funke Olakunrin
Eto isinku Funke Olakunrin
Eto isinku Funke Olakunrin
Ọkọ ati awọn ọmọ oloogbe nibi eto isinku fun Funke Olakunrin
Eto isinku for Funke Olakunrin
Ibadan: Òkìtì iyanrìn wó pa Wale àti Adeyemi lágbègbè Ologuneru
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Awọn miran pẹlu fi ara ṣeṣe ninu iṣẹlẹ naa.
Ibudo ìwa iyanrin ni ilu Ibadan ni ipinlẹ Oyo ni iṣẹlẹ laabi ọhun ti waye.
Eeyan meji to n ṣiṣẹ ni ibudo iwayanrin kan nilu Ibadan ti di oloogbe bayii.
Iku wọn ko si ṣẹyin bi okiti yanrin ti wọn n wà ṣe da wo lu wọn ni ibi ti wọn ti n wa yanrin si ọkọ lagbegbe Ologunẹru ni ilu Ibadan.
Gẹgẹ bi awọn ti iṣẹlẹ naa ṣoju rẹ ṣe sọ, okiti iyanrin naa ti wọn ni o fẹrẹ ga to ile alaja meji ṣa deede da wo ni ti o si bo awọn eeyan mẹta ti wọn wa ni isalẹ rẹ mọlẹ.
Bi o tilẹ jẹ wi pe awọn aladugbo sọ pe ko din ni eeyan meje to ba isẹlẹ naa lọ.
"Wọn ni 'awọn mẹta ni yanrin naa bo mọlẹ, awọn mẹta miran n ko yanrin ọhun si inu ọkọ akẹru lasiko ti ijamba yii ṣẹlẹ""."
Awọn oṣiṣẹ ajọ ẹṣọ oju popo to wa nibi iṣẹlẹ naa ni eeyan meji lo ku ninu iṣẹlẹ naa ṣugbọn awọn miran fi ara pa.
Buhari fi orukọ awọn Minisita tuntun ranṣẹ sile aṣofin
Awọn wọnyii ko ba awọn orukọ tuntun jade
Bi àwọn eeyan kan ṣe n pariwo pe awọn ko ri orukọ awọn ti wọn n fẹ ni a rii pe orukọ awọn miran ko si nibẹ.
Solomon Dalung to jẹ minista fun ere idaraya lati ipinlẹ Plateau ko wọ inu orukọ tuntun.
Shittu Adebayọ to jẹ m,inista fun etp ibararaẹnisọrọ lati ipinlẹ Oyo naa ko ba a.
Dan Bazzau to jẹ minista to n mojuto ọrọ eto abẹlẹ naa ko ni ba Buhari ṣe ijọba tuntun.
Audu Ogbeh to jẹ minista fun eto ọgbin ati awọn miran naa ko si ninu orukọ ti wọn fi ranṣẹ.
Ibe Kachukwu ti o n mojuto ile iṣẹ epo rọbi.
Dan Ali to jẹ minista fun eto aabo.
Mamora, Lai Mohammed, Gbemi Saraki wà lára minista Buhari tuntun.
Buhari fi orukọ awọn minista rẹ ranṣẹ si ile igbimọ aṣofin
Ile igbimọ aṣofin agba Naijiria ti kede orukọ awọn ti Aarẹ Buhari forukọ wọn ranṣẹ fun ipo Minisita lorile-ede Naijiria.
Aarẹ ile asofin Lawan Ahmed lo ka awọn orukọ naa sita lowurọ ọjọ Iṣẹgun.
Eeyan mẹtalelogoji ni wọn fi ranṣẹ.
Lowurọ ọjọru ni wọn yoo bẹrẹ ayewo fawọn minisita ti Aarẹ Buhari fi orukọ wọ́n ranṣe si ile aṣofin agba Naijiria.
Oru ana ni wọn fi orukọ ranṣẹ sile igbimọ aṣofin ki ile to kaa ni owurọ oni.
Dele Momodu : Lẹ́yìn Buhari àti Atiku, èrò ọjà làwọn olùdíje yóòkù ní ìdìbò 2019
Ikede yii waye ni aadọta ọjọ lẹyin ti wọn ṣe ibura fún aarẹ Mohammadu Buhari.
Diẹ orukọ awọn to wa nibẹ ni:
Rauf Arẹgbẹṣola fun ipinlẹ Osun
Goerge Akume fun ipinlẹ Benue
Tibi Pre Sylva ipinlẹ Bayelasa
Adebayo Adeniyi fun ipinlẹ Ekiti
Babatunde Fasola fun ipinle Eko
Olorunminbe Mamora fun ipinlẹ Eko
Gbemisola Saraki fun ipinlẹ Kwara
Lai Mohammed fun ipinlẹ Kwara
Tayo Alaṣo Adura fun ipinlẹ Ondo
Sunday Dare fun ipinlẹ Oyo
Olamilekan Adegbite fun ipinlẹ Ogun.
Chris Ngige fun ipinlẹ Anambra
Chris Ngige fun ipinlẹ Anambra
Godswill Akpabio fun ipinlẹ Akwa Ibom
Rotimi Amaechi fun ipinlẹ Rivers
Festus Keyamo fun ipinlẹ Delta
Baba Shehuri fun ipinlẹ Borno
Uche Ogah
Okunrounmu: Ijọba Buhari jẹ ijiya Ọlọrun fun Naijiria
Emeka Nwajuiba
Sadiya Farouk
Hadi Sirika
Sharon Ikeazor
Akpa Udo
Dr. Ikechukwu Ogah
Mohammed Musa Bello
Sharon Ikeazor
Adamu Adamu
Ambassador Maryam Katagun
George Akume
Mustapha Baba Shehuri
Goddy Jedy Agba
Ogbonnaya Onu
Osagie Ehanire
Clement Ike
Richard Adeniyi Adebayo
Geoffrey Onyeama
Ali Isa Pantami
Emeka Nwajiuba
Suleiman Adamu
Zainab Ahmed
Muhammad Mahmood
Sabo Nanono
Major General Bashir Salihi Magashi
Abubakar Malami
Ramatu Tijjani
Mohammed H. Abdullahi
Zubair Dada
Paulen Talen
Maigarai Dingyadi
Sale Mamman
Abubakar D. Aliyu
Sadiya Umar Faruk
UK Prime Minister: Boris Johnson, Olóòtú ìjọba Gẹ̀ẹ́sì tuntun sọ̀rọ̀ àkọ́kọ́
Jeremy Hunt ti ki Boris Johnson ku oriire
Boris Johnson ati Jeremy Hunt ni wọn jọ dije igbẹyin ninu eto idibo ọhun.
Kete ti wọn kede Boris Johnson ni ẹni to jawe olubori ninu ibo naa ni Jeremy Hunt ti kii ku oriire pe:
Jeremy sọrọ lori iṣẹ ipolongo takuntakun ti awọn mejeeji jó ṣe ni eyi to yẹ ko jẹ awokọṣe fawọn oludije miran.
Alatako Boris Johnson ni oun gbagbọ pe iṣẹ akinkanju ti ko ni ja ilẹ Gẹẹsi kulẹ ni Boris a ṣe ni orilẹ-ede wọn.
Nigba ti Boris Johnson ṣàpèjúwe alátakò rẹ̀ bíi ọlọ́pọlọ pípé ninu ọrọ akọsọ rẹ, bẹẹ naa lo fimoore han fun gbogbo eniyan pe:
Ijọba ilẹ Gẹẹsi ti kede ẹni to jawe olubori ninu ibo Olootu ijọba ilẹ Gẹẹsi ti wọn di lọjọ Isẹgun.
Oluwarẹ ni Boris Johnson.
Jeremy Hunt ni òun gbà pé Boris Johnson á ṣiṣẹ́ dáadáa
Ibo ẹgbẹrun lọna mejilelaadọrun ati mẹtalelaadọjọ ni Johnson ni ninu apapọ ibo ti wọn di nigba ti alatako rẹ, Jeremy Hunt ni ibo ẹgbẹrun lọna mẹrindinlaadọta, ẹgbẹta ati mẹrindinlọgọta.
Ni kete ti wọn kede esi ibo naa ni Johnson ti  yonbo alatako rẹ ti wọn dijọ fa ipo naa mọ ara wọn lọwọ, eyiun Jeremy Hunt, to si se apejuwe rẹ bii ẹni to kun fun ọpọ ọgbọn to dara.
Johnson wa seleri pe oun yoo ji mu ninu awọn ero ọgbọn alatako oun naa, to si kun kan saara si olootu ijọba ilẹ Gẹẹsi ana, Theresa May fun bo se sisẹ sin orilẹ-ede rẹ.
Ninu ọrọ akọsọ rẹ, Johnson fikun pe inu oun dun lati sisẹ ninu isejọba Theresa May, toun si ri itara rẹ ati ipinnu to ni si ọpọ igbesẹ rẹ naa, eyi to di ogun to fi silẹ bayii.
Bakan naa lo salaye pe, oun mọ pe awọn eeyan yoo maa beere idi ti wọn se yan oun ni olootu ijọba ilẹ Gẹẹsi, to si dahun pe ko si ẹnikẹni tabi ẹgbẹ oselu kankan to da nikan ni ọgbọn tara rẹ.
Ìtàn Mánigbàgbé: Ìtàn Adegbọrọ kọ́ wa láti ṣiṣẹ́ kára pẹ̀lú ìforítì
Oríṣun àwòrán, Getty Images
"Ìtàn tó rọ̀ mọ́ òwe ""Ẹni tí kò ṣe bíi aláàárù l'Oyingbo..."
Ọpọ ọmọ ilẹ Yoruba lo maa n tiraka lati ri ti aje se, ti ara wọn kii si balẹ ti buruji ko ba si lọwọ wọn.
Wọn maa n ti ilu kan lọ si ekeji lati wa ti aje ṣe, ti ọpọ ajeji si maa n di ọmọ onilu lẹyin o rẹyin nigba ti Ọba oke ba bukun wọn.
Sugbọn nigba miran, ọpọ ọmọ Yoruba to ba wa isẹ aje lọ silu miran kii gbagbe ile nitori igbagbọ wọn ni pe ọmọ to ba sọ ile nu, o so apo iya kọ.
Koda, wọn a maa figba gbogbo ranti pe ko si ibi to dabi ile.
Bẹẹ lọrọ ri pẹlu ọkunrin kan ti wọn n pe ni Adegbọrọ to n gbe ni ilu Ibadan.
Lasiko ti nnkan le koko fun Adegbọrọ, ti ko ri ba tise, ti ko ri ọna gbegba, ti isẹ n sẹ ẹ gidi, lo ba ronu jinlẹ lori ọna abayọ si ipọnju to ba a yii.
Adegbọrọ di igba ati agbọn rẹ, to si gba ilu Eko lọ lati wa isẹ Aje ṣe, ko le e riba ti se, ko si ri ọna gbegba.
Nigba to de ilu Eko, ọja Oyingbo lo balẹ si, to si n sisẹ alabaru nibẹ, bo se n fi ori rẹ gbe apo ata, lo n gbe apo ẹwa, irẹsi, apo elubọ, Sẹmo, agbado ati bẹẹ bẹẹ lọ.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ìtàn Mánigbàgbé: Ìtàn Adegbọrọ kọ́ wa láti ṣiṣẹ́ kára pẹ̀lú ìforítì
Nigba to ya, pẹlu aforiti ati iṣẹ aṣekara, to si mọ baa ṣe n pọn omi silẹ de oungbẹ, Adegbọrọ fi owo pamọ, to si ra ọmọlanke lati maa fi ṣe aaru dipo ori to fi n ru ẹru.
Bakan naa ni eyi yoo mu ki owo to n pa wọle ru gọgọ si.
Laipẹ laijinna, Ọba oke bukun Adegbọrọ, to si ra ọmọlanke bii meje kun eyi to ni.
Awọn ọmọlanke naa si lo fi n haya fun awọn alabaru miran lati maa sisẹ.
Ọjọ n gun ori ọjọ, osu n gori osu, Adegbọrọ lo ọdun mẹjọ ni sja Oyingbo, to si di gbajumọ nidi isẹ wiwa ọmọlanke.
Asiko yii si lo ra ọkọ akẹru to si lọ kọ ọkọ wiwa.
Adegbọrọ n mojuto isẹ ara rẹ funra ara rẹ, ti ko si fi ọwọ mẹwẹẹwa jẹun.
Nigba ti yoo si fi lo ọdun mẹrin nidi fifi ọkọ ko ẹru, Adegbọrọ tun ra ọkọ akẹru mẹfa sii, eyi to tun gba awọn awakọ si lati maa fi bawọn eeyan ko ẹru.
Nigba to ya, Adegbọrọ ranti pe ile ni abọsinmi oko, to si gba ilu Ibadan, tii se ilu abinibi rẹ lọ lati kọ ile. Ile awodamiẹnu, ile awosifila si ni Adegbọrọ kọ si adugbo ọja Ọba.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ìtàn Mánigbàgbé: Ìtàn Adegbọrọ kọ́ wa láti ṣiṣẹ́ kára pẹ̀lú ìforítì
Asiko yii ni irawọ Adegbọrọ bẹrẹ si ni tan, ti ogo rẹ n bu yọ nilu Ibada.
Ọpọ eeyan si n tọ ọ wa pe ko sọ asiri owo rẹ fun awọn nitori awọn naa fẹ dabi rẹ, se aye ki bani ri wahala ẹni, sokoto to balẹ nikan ni ọmọ araye n ri.
Adegbọrọ wa da wọn lohun pe ti wọn ba fẹ lowo, ki awọn naa kalọ si ọja Oyingbo.
Ki wọn wa fi ori ru aaru, amọ ọpọ wọn lo fi ọwọ osi ta ika oṣi danu pe, laalae, awọn ko le e ṣiṣẹ aaru gbigba.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
"Ìtàn tó rọ̀ mọ́ òwe ""Ẹni tí kò ṣe bíi aláàárù l'Oyingbo..."
Idi si re e ti Adegbọrọ naa fi maa n da wọn lohun pe:
Ẹni ti ko ba ṣe bii alaaru l'Oyingbo, ko lee ṣe bii Adegbọrọ l'ọja Ọba.
Eyi to tumọ si pe, ikoko ti yoo jẹ ata, idi rẹ yoo kọkọ gbona, ti a ko ba si jiya to kun agbọn, eeyan ko ni jẹ aye to kun aha.
Jakande: Osinbajo, Tinubu, Osoba kọwọrin lọ ki Jakande ọlọ́jọ́ ìbí
Oríṣun àwòrán, @followlasg
Jakande: Osinbajo, Tinubu, Osoba kọwọrin lọ ki Jakande ọlọ́jọ́ ìbí
Yoruba ni ti ọmọ ọni ba dara, o yẹ ka wi, ti pe a fẹ fi se aya kọ.
Eyi lo mu ki awọn ilumọọka oloselu, awọn akọsẹmọsẹ ati awọn ẹlẹgbẹjẹgbẹ fi n kọrin re ki gomina tẹlẹ nipinlẹ Eko, Lateef Kayọde Jakande, ẹni to pe ẹni aadọrun ọdun loke eepẹ lọjọ Isẹgun.
Igbakeji aarẹ Yẹmi Ọsinbajo, to bawọn peju sibi ayẹyẹ naa to waye nilu Eko, sapejuwe ọlọjọ ibi naa gẹgẹ bii akikanju to maa n mu ayipada rere ba nkan ninu itan eto iselu orilẹede yii.
Osinbajo ni pẹlu oju inu ati ọgbọn atinuda Jakande lo fi mu ayipada rere ba ilana eto ẹkọ nipinlẹ Eko lasiko to wa ni ipo gomina, eyi to mu ki ayipada rere ba eto ẹkọ Naijria patapata, paapa bi wọn se pa eto ẹkọ ọlọsan rẹ patapata.
Oríṣun àwòrán, @followlasg
Bakan naa ni Bola Tinubu sapejuwe Lateef Jakande bii alakoso to dantọ lasiko to nira lati dari Naijiria.
Bakan naa lo fikun pe ilana ẹkọ ọfẹ ti Jakande se lo fun ọpọ ọmọ nipinlẹ Eko lanfaani lati lọ sile ẹkọ, to si tun kọ ilegbe olowo pọọku to pọ julọ ti ijọba kankan yoo kọ ri, boya ni ipinlẹ ni abi labẹ ijọba apapọ.
Ninu ọrọ tiẹ naa, Gomina tẹlẹ nipinlẹ Eko, Bola Ahmed Tinubu ni Jakande ni o maa n kọkọ se ohun akọkọ lasiko akoso rẹ, to si jẹ alakoso to dantọ lasiko to nira lati se adari lorilẹede Naijiria.
Oríṣun àwòrán, @followlasg
Háà, ó ṣe! Jakande pé 90 láì gba àmì ẹ̀yẹ kankan ní Nàíjíríà -Osoba
"Eeyan kan to jẹ olotitọ si oloye Ọbafẹmi Awolọwọ ni Alhaji Lateef Jakande jẹ, ti ko si yapa ninu ala ati iran onitẹsiwaju ti Awolọwọ fi lelẹ.
Awọn eeyan miran to tun sọrọ nibi ayẹyẹ ọjọ ibi naa ni Oloye Olusẹgun Ọṣọba, tii se gomina nipinlẹ Ogun nigba kan ri.
Ninu ọrọ rẹ, Ọsọba kede pe ohun meji lo n dun ohun nipa Jakande, akọkọ ni pe baba naa ko kọ itan kankan nipa igbesi aye rẹ silẹ, tori ko ba yaayi pupọ lati gbọ latẹnu rẹ bo se lo akoko rẹ lẹnu isẹ iroyin ati eto iselu.
Oríṣun àwòrán, @followlasg
Gẹgẹ bo se wi, ohun keji ni pe wọn ko fi ami ẹyẹ ilẹ wa kankan da Jakande lọlka ri nigba to jẹ pe awọn eeyan lasan ti ko to nidi aseyọri ti gba ami ẹyẹ orilẹede yii.
Mo wa n daba pe ki wọn tete fi ami ẹyẹ da Jakande lọla, wọn ko si gbọdọ fun ni ami ẹyẹ to kere si Commander of the Federal Republic."""
Oríṣun àwòrán, @followlasg
Gomina ipinlẹ Eko,Babajide Sanwo-Olu ninu ọrọ tiẹ ni, ilegbe oni filaati mẹrindinlẹẹdẹgbẹta ti wọn n kọ lọwọ si adugbo Igando nilu Eko, eyi ti wọn n gbero lati si losu Kẹjọ ọdun 2019 ni wọn yoo pe ni ilegbe Laeef Jakande.
Ìwé ìrìnnà 'VISA' Amẹ́ríkà: PDP láwọn faramọ ìgbésẹ Amẹ́ríkà
Awa PDP a kò lẹ́bọ lẹ́ru rara, ipinnu Amerika yii tẹ PDP lọrun
Awọn ẹgbẹ oṣelu meji to gbajumọ lorile-ede Naijiria ti n sọ ero wọn nipa igbesẹ Ilẹ Amẹrika lati fofin de fifun awọn ọmọ Naijiria kan ni iwe irinna 'Visa'.
Igbesẹ naa ti wọn kede laipẹ yi ko yọ awọn to kopa tabi ti wọn ṣe agbatẹru dida ibo Naijiria ọdun 2019 to kọja ru.
Kola Ologbondiyan to jẹ akọwe ipolongo fẹgbẹ oṣelu PDP sọ pe rẹgi ni igbeṣẹ naa ba ẹgbẹ awọn lara mu nitori pe awọn ko lọwọ ninu iwa to kọdi si eto ijọba awarawa.
O ni awọn to lagbara lati dari eto idibo ati awọn ọmọ ogun bo ti ṣe wu wọn lo le máa foya pe ijiya Amẹrika yi yoo kan awọn.
''Awa o ni ibẹru kankan nipa eto ti ilẹ Amẹrika fẹ ṣe ṣugbọn awọn to fi agidi gba ipo, awọn ti wọn gun awọn eeyan lada ati lọbẹ ni Kanoni ẹru ma ma ba''
O ṣalaye pe igbeṣẹ yi jẹ oun to dun mọ awọn ninu ati pe awọn fẹ ki awọn orile-ede miran naa tẹle apẹrẹ Amerika yi.
''Amẹrika nikan kọ lo yẹ ki wọn gbe igbeṣẹ yi, ni Yuroopu ati ilẹ Gẹẹsi,awọn na ay ki wọn ṣe bẹ''
Ologbondiyan wa fi ifarajin ẹgbẹ oṣelu PDP han lati ma mu idagbasoke ba eto oṣelu ni Naijiria
Ninu idibo to kọja ẹgbẹ oṣelu APC lo gbegba oroke ninu idibo gbogboogbo to waye.
Gẹgẹ bi PDP awọn naa a ma saaba na ika abuku si gbẹ alatako pe awọn ni wọn wa nidi magomago tabi iwa to le mu ifasẹyin ba eto oṣelu ni Naijiria.
Oríṣun àwòrán,  Lanre Issa-Onilu
Ninu idibo to kọja ẹgbẹ oṣelu APC lo gbegba oroke ninu idibo gbogboogbo to waye.
Amọ ṣa nigba ti a kan si akọwe ipolongo ẹgbẹ naa lori ẹrọ alagbeka lori ohun ti ẹgbẹ ri si igbesẹ yi,o ni ohun ko ti le fesi si bayi.
Dele Momodu : Lẹ́yìn Buhari àti Atiku, èrò ọjà làwọn olùdíje yóòkù ní ìdìbò 2019
Mallam Lanre Issa Onilu ṣalaye pe atẹjade ṣi ni Amerika gbe jade ati pe wọn ko tii darukọ awọn ti wọn fi ofin de lati ma gba iwe irinna lọ si Amẹrika.
O ni bayi ti ko tii si ẹkunrẹrẹ alaye, ohun ko tii le sọrọ nipa ilana tuntun naa.
Awọn woo gan an ni ọrọ yi kan?
Atẹjade ti Agbẹnusọ fun ileeṣẹ Amerika, Morgan Ortagus fi sita ni Washington lorilẹ-ede Amerika ni lati ọjọ kẹrinlelogun, oṣu kinni ọdun ni Amerika ti n gbiyannju lati gbe igbesẹ yii.
O ni paapaa lori awọn oloṣelu ti ko fẹ ilọsiwaju eto oṣelu ni wọn ṣe fẹ gbe e.
Ilẹ Amẹrika ko gbe orukọ awọn ti ọrọ naa kan sita tabi ki wọn sọ igba ti wọn yoo fi orukọ naa sita.
Adio Atawẹwẹ: Orin Fuji ló gba iwé kíkà lọ́wọ́ mi
Oríṣun àwòrán, Facebook/Atawewe
Atawẹwẹ
Gbajugbaju olorin Fuji, Alhaji Sulaimọn Adio Atawẹwẹ sọ pe lati igba t'oun ti gbọ́nju, oloogbe Dr Sikiru Ayinde Barrister ni akọkọ olorin Fuji.
Atawẹwẹ fọrọ yii lede ninu ifọrọwerọ rẹ pẹlu BBC Yoruba nile rẹ niluu Ikorodu l'Ọjọru.
Alhaji Adio ni, lati kekere loun ti n gbọ awo orin ti Barrister ti kọ wéré, ko to maa kọ orin Fuji.
Amọ, o ni ti ẹnikan ba sọ pe Barrister kọ lo da Fuji silẹ, o ni ko si ija nibẹ nitori ohun to kọju si ẹnikan, ẹyin lo kọ si ẹlomiran.
Atawẹwẹ tun fikun ọrọ rẹ pe, iṣẹ Fuji lo yọ oun ninu iṣẹ alabaru lọja Ketu ati Mile 12.
O ni oun tun ṣiṣẹ apero sọkọ ati iṣẹ akọle, birikila ṣugbọn iṣẹ Fuji lo yọ ọpọ eeyan to n kọ Fuji loko ẹru.
O tun salaye pe, apọnle ti wọn ba n fun Fela lo yẹ ki wọn maa fun Barrister kaakiri gbogbo agbaye.
Oríṣun àwòrán, Facebook/Atawewe
Atawẹwẹ fikun ọrọ rẹ pe, o yẹ ki gbogbo olorin Fuji mọ ere Ayinde Barrister ati ti Alhaji Ayinla Kollington, lati fi gboṣuba fun wọn.
O ni awọn mejeeji ni wọn yọ ọpọ olorin Fuji loko ẹru lonii.
Atawẹwẹ sọ pe, ati ọmọ ọdun mẹrin ni oun ti n kọrin, orin kikọ si lo gbawe kika lọwọ oun.
O ni JSS 3 loun wa nile iwe girama ki oun to kuro nile iwe, amọ o sọ pe oun o kaba
Kidnapping: Aago méje alẹ́ ọjọ́ Ìṣẹ́gun làwọn agbégbọn dí ọ̀nà márosẹ̀ Ibadan
Oríṣun àwòrán, @renoomokri
Kaka ki ewe agbọn dẹ nidi eto aaboorilẹede naijiria to mẹhẹ, n se lo tun n le koko sii.
Idi ni pe oju ọna Ibadan silu Eko ti ọkan balẹ le lori tẹlẹ, ni ipaya tun ti n waye lori rẹ bayii nitori awọn gende agbebọn ti wọn se ọsẹ nla ni irọlẹ ọjọ Isẹgun.
Gẹgẹ bi iroyin naa se wi, agbegbe Ajebọ lopopona Ibadan silu Eko ni isẹlẹ naa ti waye ni deede aago meje alẹ.
Awọn gende agbebọn ti wọn to mẹẹdogun, lo da ọkọ kan duro ti wọn si ji eeyan mẹta gbe loju ibọn.
Ọkọ ti wọn da duro naa, Toyota Sienna, to jẹ tile iwosan kan nilu Ibadan si lawọn agbegbọn naa gbe silk lai gbe lọ, tawọn ọlọpa si ti ri nibi ti wọn gbe si, bẹẹ ni wọn ti wa lọ si agọ ọlọpa to wa ni abule Ogunmakin nipinlẹ Ogun.
Nigba to n ba akọroyin sọrọ, ọga agba ile iwosan Lafia to wa ladugbo Apata nilu Ibadan, Dokita Ọladipupọ Sule salaye pe, ọmọ oun Kayọde ati osisẹ meji nile iwosan naa ni wọn fori sọta isẹlẹ ijinigbe naa, to si pe orukọ awọn eeyan meji yoku ni Ọpẹyẹmi Abifarin ati Dele Adigun.
Lori iṣẹlẹ naa, alukoro ileeṣẹ ọlọpaa ipinlẹ Ogun, Abimbọla Oyeyẹmi sọ fun BBC Yoruba pe kọmisana ọlọpaa ipinlẹ naa, Bashir Makama ti ko awọn oṣiṣẹ alaabo lọ si ibi ti iṣẹlẹ naa ti waye lati doola awọn ti wọn jigbe ọhun.
Oyeyẹmi fikun ọrọ rẹ pe awọn eniyan meji miran to farapa lasiko iṣẹlẹ ijinigbe naa ti n gba itọju nileewosan.
Oríṣun àwòrán, @NigerianPolice
Ẹwẹ, Dokita Sule ni ọkan oun gbọgbẹ, ti inu oun si bajẹ gidigidi lori isẹlẹ naa nitori oogun lawọn eeyan mẹtẹẹta ti wọn ji gbe naa lọ ra fun ile iwosan naa nilu Eko, asiko ti wọn si n pada bọ lọwọ alẹ ni wọn ko sọwọ awọn ajinigbe.
"Dokita Sule fikun pe "" Awakọ mọto naa salaye pe, ọkan ninu awọn agbebọn naa sọrọ ni ede oyinbo, nigba tawọn yoku sọrọ ni ede Hausa ati Fulani, wọn ko si ti pe wa lati sọ iru eeyan ti wọn jẹ ati erongba wọn."""
Iléeṣẹ́ ológun: Àbájáde ìwádìí wa lórí ìṣẹ̀lẹ̀ náà yóò hàn síta láìpẹ́
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ileeṣẹ ologun Naijiria ti bẹrẹ iwadii aṣiri kan to tu pe, awọn ọmọ ogun kan salọ pẹlu owo naira to le ni miliọnu kan ati aabọ Dọla ($1.6).
Bi awọn ọmọ ogun naa, ti wọn jẹ ẹṣọ to n tẹle ọkọ agboworin, ṣe ri aaye gbe owo naa salọ, ko sẹni to mọ.
Amọ ẹnikan nileesẹ ologun fidi rẹ mulẹ fun BBC pe, owo nla kan ti sadeede poora, ati wi pe, wọn ti fi iṣede se ọgagun kan mọle rẹ, ko gbọdọ fi ile rẹ silẹ nilu Abuja.
"Osisẹ ologun kan, Onyema Nwachukwu, to ba awọn akọroyin sọrọ lọjọ Iṣẹgun ni olu ileeṣẹ ologun fidi rẹ mulẹ pe iwadii nlọ lọwọ , pẹlu afikun pe, ""abajade iwadii naa yoo di mimọ fun araalu ti asiko ba to."""
Awọn ipẹẹrẹ ọmọ ologun maarun la gbọ pe wọn ji owo naa gbe.
Bi iroyin kan sọ pe, owo naa to yẹ ki wọn fi gbọ bukata ileeṣẹ ologun ni, ni omiran sọ pe ,ọga ologun kan nigbakan ri lo ni owo naa.
Iroyin sọ pe, awọn ọmọ ogun naa tẹle ọkọ agboworin kan to gbe owo naa lati ilu Sokoto si Kaduna, lati pese aabo fun.
Asiko ti wọn si n lọ lọna ni wọn ja ọkọ gba, wọn bọ aṣọ ọmọ ogun kuro lọrun un wọn, wọn si salọ.
Owo kekere kọ ni ijọba maa n ya sọtọ fun ileeṣẹ eto aabo ninu owo iṣuna lọdọọdun, ṣugbọn awọn ọmọ ogun to wa ni oju ija, paapa, awọn to n doju kọ ikọ Boko Haram, maa n fi gbogbo igba pariwo pe, awọn ko ni irinṣẹ, awọn ko si ri owo ajẹmọnu gba.
Google Map: Ànfààní wo ló wà nínú lílo ẹ̀rọ̀ ajuwe ọnà pẹ̀l'óhùn Nàìjíríà?
Oríṣun àwòrán, TWITTER@GOOGLEAFRICA
Ohun yẹn niyen! Ile iṣẹ Google ti bẹrẹ si ni lo ohun Naijiria lati juwe ọna lawọn opopona ilẹ naa.
Ikede yii jẹyo gẹgẹ bi ile iṣẹ naa ṣe fi awọn ilu mẹrin miran kun eleyi to ti wa nilẹ nibi ti awọn eeyan yoo ti ma lo ẹrọ ajuwe ọna.
Saaju asiko yii, ohun oyinbo lo ma n juwe ọna fawọn ọmọ Naijiria lori ẹrọ naa ti a si maa mu inira ba awọn ti ko ba gbo ohun ti oyinbo n sọ.
Ramesh Nagarajan to jẹ oludari ọja tita nileeṣẹ naa sọ fun BBC pe ohun Naijiria tawọn fi si inu ẹrọ ajuweọna naa ko yatọ si ti ọmọ Naijiria.
O ṣalaye pe ohun yii yoo si ma pe awọn orukọ adugbo lede wọn gangan eyi ti awọn Naijiria yoo gbọ́.
Oríṣun àwòrán, TWITTER@GOOGLEAFRICA
Ramesh Nagarajan
''Bi eeyan ba fẹ jẹ anfaani lilo ohun Naijiria yii lori ẹrọ, yoo kan lọ yii kuro lede Gẹẹsi si ede Gẹẹsi ti Naijiria ni.
Diẹ lara awọn aworan ibi ayẹyẹ ti Google ti ṣe ifilọlẹ yii ree ladugbo Lekki nilu Eko.
Oríṣun àwòrán, Google
Aworan ayẹyẹ Google
Oríṣun àwòrán, Google
Lọpọ igba ni ohun oyinbo a maa ṣi orukọ adugbo Naijiria pe ti ẹlomiran ko si ni mọ pato ohun ti o n sọ.
Ninu awọn ilu ti Google pẹka ẹrọ ajuweọna yii de lati ri Abuja, Benin, Enugu ati Ibadan.
Nigeria Diaspora Day: Ìjọba ní láti ronú jinlẹ̀ nípa òun tó n sọ ọmọ Nàìjíríà d'ero ilẹ ókéèré
Oríṣun àwòrán, AFP
Idagbasoke orileede Naijiria kii ṣe iṣẹ ijọba nikan bi kii ṣe ki awa ti a wa nilu okere naa ṣa ipa ti wa.
Diẹ lara  ọrọ tawọn ọmọ Naijiria to n gbe loke okun sọ fun BBC ree lori oun to yẹ ki o jọba lọkan awọn eeyan layajọ awọn ọmọ Naijiria to n gbe oke okun.
Ọjọ kẹẹdọgbọn, oṣu keje ni ijọba apapọ ya sọtọ lati ṣe agbeyẹwo ohun gbogbo to ni ṣe pẹlu awọn ọmọ Naijiria lẹyin odi.
Ni ọjọ yii, wọn a maa ṣe agbeyẹwo ipa ti awọn to wa ni ilẹ okere le ko lati mu idagbasoke ba Naijiria.
Ojo yi bakan naa maa jẹ anfaani lati ṣe ayẹwo awọn ipenija to n ba awọn eeyan Naijiria nile ati lẹyin odi.
Ninu ifọrọwanilẹnuwo pẹlu ile iṣẹ BBC Yoruba, Ọjọgbọn Adetokunbo Akintayo ṣalaye pe kii ṣe pe o wu ọpọ awọn eeyan lati file silẹ bi kii ṣe pe nnkan ko rọgbọ.
Oríṣun àwòrán, BBC Sport
Ni ọjọ yii, wọn a maa ṣe agbeyẹwo ipa ti awọn to wa ni ilẹ okere le ko lati mu idagbasoke ba Naijiria.
Adetokunbo to ti ṣisẹ oniroyin ni Naijiria fọdun pipẹ ki o to di ero ilẹ Gẹẹsi ni afiwe ko si laarin bi awọn eeyan ilẹ okere ṣe n dari ilu pẹlu ti Naijiria.
''Ijọba ni lati ronu jinlẹ lati koju awọn ipenija to n mu ki awọn ọmọ Naijiria maa sa kuro nilu. Kini awa ọmọ Naijiria fun ara wa le ṣe? Awọn nkan to yẹ ki a ma bere ree lọjọ oni''
O ṣalaye pe nipa eto abo ati ilera, ijọba Naijiria ni lati ṣe ju bi wọn ti n ṣe lọ ki ilu baa le rọgbọ fara ilu.
Ninu ọrọ rẹ, o sọ pe nilẹ Gẹẹsi ko si awọn ipenija ti awọn ara ilẹ Naijiria n koju bii ti ijinigbe tabi aisi eto ilera to peye.
Omi pọ ju ọka lọ ṣugbọn...
Arabirin Halima Babamale to jẹ olukọ ni fasiti ilu Ilorin to n tẹsiwaju pẹlu ẹkọ rẹ nilu Malaysia naa sọ iriri tirẹ nipa gbigbe ilu okere.
''Ko si wahala kankan to jọ mọ iru eleyi ti a n koju ni Naijiria nipa aabo ni ilu ti mo wa. Igba to ba wuwa la n rin jade ti awọn oṣiṣẹ alaabo naa si wa ni ṣẹpẹ''
Mo le ni eto wọn nilu yi muna doko daada ti o si wu mi ki ijọba Naijiria naa wo awokọṣe lara wọn.
Oríṣun àwòrán, Halimat Babamale
Awọn ijọba ilu ta wa ṣe gbogbo eto bo ti ṣe tọ ati bo ti ṣe yẹ
O ni ti awọn to n ṣe ijọba a maa saba rin irinajo lọ si ilu okere ti wọn si ma n ri bi nnkan ti ṣe ri nibẹ.
''O yẹ ki wọn ṣe atunṣe lawọn ibi ti o ba ku diẹ kaato amọ ara ilu naa nipa ti awọn naa le ko.''
Ẹtàn ni àwọn ọ̀rẹ́ fi ń tan èèyàn lọ si Libya pé iṣẹ́ gidi wà níbẹ̀
Abikẹ Dabiri: Iṣẹ́ pọ̀ lọ́wọ́ Naptin àti àwọn aṣọ́bodè Nàìjíríà
Child Education: Mílíọ̀nù mẹ́rìndínlógún ọmọdé ni kò sí níléèwé lórílẹ̀èdè Nàìjíríà
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ninu igba miliọnu awọn eeyan to n gbe lorilẹede Naijiria loni, njẹ o mọ pe miliọnu mẹrindinlogun awọn ewe ni ko ri ileewe lọ bayii?
Ọrọ yii kii ṣe wọn ni-wọn pe o! Minisita feto ẹkọ ni saa iṣejọba akọkọ aarẹ Muhammadu Buhari, Adamu Adamu lo kede iroyin yii. Ṣe ẹ si mọ pe ọrọ ti akuwarapa ba sọ latode ọrun ni, eyi lo si n mu ki ọpọ maa kaya soke lori ọrọ yii.
Kí ló máa ń wú ìyá Nike Davies lori láti wé gèlè ràbàtá?
Niwaju awọn aṣoju orilẹede Naijiria ni Adamu Adamu ti ṣi aṣọ loju ọrọ naa.
Eyi wa tako nọmba ti awọn eeyan kan n gbe kaakiri tẹlẹ pe miliọnu mẹtala lawọn majeṣin ti ko si ni ileewe lọwọ bayii.
Adamu, to jẹ ọkan lara awọn ti orukọ wọn ṣẹṣẹ jade niwaju ile aṣofin agba gẹgẹ bii minisita ni saa keji Aarẹ Buhari ṣalaye pe ẹri maa jẹ mi niṣo lori ọrọ yii wa ninu eto onka tuntun ti wọn ṣe loṣu keji ọdun 2019.
Dele Momodu : Lẹ́yìn Buhari àti Atiku, èrò ọjà làwọn olùdíje yóòkù ní ìdìbò 2019
Nigba ti yoo tun pari ọrọ, Adamu ni miliọnu mẹwa ninu awọn majeṣin yii lo yẹ ko wa nileewe alakọbẹrẹ ṣugbọn ti wọn ko si nibẹ bayii. Miliọnu mẹfa ninu wọn ni ọkọ iwe wọn taku ni kete ti wọn pari iwe alakọbẹrẹ. Eyi tumọ si pe wọn ko lanfani ati lọ sileewe girama bayii.
Ṣe awọn agba bọ wọn ni ajala ta n naa ọ, ẹyin naa kọhun. Adamu ni ọda owo awo olokun lo n fa wahala yii o. O ni aifi owo to jọju sẹka eto ẹkọ latọdọ ijọba apapọ atawọn ijọba ipinlẹ lo fa eyi.
LASTMA Yesufa: Àwọn dókítà gbìyànjú lórí ojú mi ṣùgbọ́n...
Bakan naa lo tun fa bẹmbẹ ọrọ ya o nigba to wi pe awọn eeyan to n jẹ ajẹbanu lorilẹede Naijiria tun fẹ ṣe bi ẹni n pọ sii lọwọ yii pẹlupẹlu ipolongo igbogun tiwa ijẹkujẹ ti Aarẹ Buhari n lọgun rẹ tan-tan-tan.
Amọṣa, aarẹ ile aṣofin agba ti sọ pe awọn yoo mu gẹgẹ bi iṣẹ lati rii pe awọn ọmọ wọnyii pada sileewe lẹyẹ-o-ṣọka.
Ààrẹ Beji Caid Essebsi, torílẹ̀èdè Tunisia jáde fáyé
Oríṣun àwòrán, AFP
Ìròyìn tó ń tẹ̀ wa lọ́wọ́lọ́wọ́ ní wí pé Aarẹ  akọkọ ti wọn kọkọ finu findọ yan ni orilẹede Tunisia, Beji Caid Essebsi ti jade laye lẹni ọdun mejilelaadọrun.
Ileeṣẹ aarẹ orilẹede Tunisia lo kede rẹ.
Oun ni aarẹ to dagba julọ lagbaye.
'Jollof, Iyan, Asaro, Ewa Alagbado kìí wọ́n n'ílé oúnjẹ wá ní Egypt'
Wọn gbee lọ sileewosan ni ọjọru bi o tilẹ jẹ pe awọn alaṣẹ ilẹ naa ko sọ idi to fi lọ gba itọju nileewosan.
Ni ọdun 2014 ni ọgbẹni Essebsi bori ninu idibo apapọ ti awọn orilẹede naa ṣe lọdun 2014 lẹyin wahala awọn larubawa lagbegbe naa.
Ṣaaju ni ọdun yii, o kede pe oun ko ni dije fun ibo mọ lasiko idibo orilẹede naa ti wọn n fojusọna nigba naa pe yoo waye loṣu kọkanla ọdun yii.
Iroyin sọ pe wọn gbe aarẹ Essbsi lọ sileewosan ni oṣu to kọja nitori ohun ti awọn alaṣẹ orilẹede naa kan pe ni 'wahala ilera to lagbara gidigidi'
Yoruba Culture: àṣà ìkínni ṣe pàtàkì nílẹ̀ Oodua
Nigba naa, olotu ijọba orilẹede ọhun, Youssef Chahed to bẹẹ wo nileewosan rọ awọn eeyan lati yẹra fun iroyin irọ nipa ipo ilera rẹ nigba naa.
Wọn yọ Aarẹ Tunisia nigba kan ri, Zine el-Abedine Ben Ali ni ọdun 2011 lẹyin to lo ọdun mẹtalelogun ni ipo.
Lati igba yii wa ni orilẹede Tunisia ti gba oriyin gẹgẹ bi orilẹede kan ṣoṣo lagbaye to gba eto iṣejọba tiwantiwa labẹ abajade iwọde ẹhonu araalu eyi ti wọn pe ni arab spring.
A n se akojọpọ ẹkunrẹrẹ iroyin yajoyajo lọwọ, a o maa gbe ẹkunrẹrẹ iroyin naa sori atẹ iroyin wa laipẹ. Ẹ jọwọ, ẹ tun oju opo iroyin yi yẹwo, ki ẹ lee ri ẹkunrẹrẹ iroyin ọtun laipẹ.
Awọn Iroyin mii ti ẹ le nifẹ sii
EFCC kó akẹ́kọ̀ọ́ fásitì UNIOSUN làwọn akẹ́kọ̀ọ́ náà bá fọ́n sígboro
Oríṣun àwòrán, Efcc
Awọn oṣiṣẹ ajọ EFCC ti ko awọn akẹkọ ileewe fasiti ipinlẹ Ọṣun University of Osun State lori ẹsun pe wọn n ṣe owo gbajuẹ ati Yahoyahoo.
Iroyin ti o n tẹ wa lọwọ ṣalaye pe ni owurọ Ọjọbọ ni awọn oṣiṣẹ ajọ EFCC naa ya bo ileegbe awọn akẹkọ fasiti kan to wa lagbegbe Oke Baalẹ ni ilu Osogbo ti wọn si ko awọn akẹkọ kan nibẹ.
Agbẹnusọ fun ajọ EFCC, Tony Orilade, fi idi iroyin naa mulẹ fun BBC News Yoruba. O ni awọn oṣiṣẹ ajọ naa lo ṣe iṣẹ naa ṣugbọn ko tii le fi idi rẹ mulẹ iye awọn ti wọn mu nibẹ.
Amọṣa, alukoro ileewe fasiti UNIOSUN, Ọgbẹni Adeyẹmi pẹlu ṣalaye fun BBC pe awọn alaṣẹ ileewe naa ti n gbe igbesẹ lori rẹ.
Dele Momodu : Lẹ́yìn Buhari àti Atiku, èrò ọjà làwọn olùdíje yóòkù ní ìdìbò 2019
O ni lara awọn ileegbe aladani to wa fawọn akẹkọ ileewe naa ni o ti ṣẹlẹ.
Bakan naa lo ṣalaye pe iroyin ti awọn akẹkọ naa n fi to oun leti ni pe nnkan bi akẹkọ ọgbọn si marundinlogoji ni awọn oṣiṣẹ EFCC naa ko nibẹ.
Ọrọ ọhun fẹrẹẹ da omi alaafia ilu ru nilu Oṣogbo lọjọbọ pẹlu bi awọn akẹkọ ileewe naa ṣe fọn ka si igboro lati fi ẹhonu han lori awọn akẹgbẹ wọn ti wọn mu naa.
Kọmiṣọna ọlọpaa ni ipinlẹ Ọṣun, ni a gbọ pe o ṣẹṣẹ wa pẹtu si ọkan awọn akẹkọ naa ki wọn to bu omi suuru mu.
Yinka Ayefele: Oṣù àwọn ìbẹ́ta mi kò pé ní kò jẹ́ kí n kọ́kọ́ kéde ìbí wọn
Oyo: Ọkùnrin mẹ́tàlá, obìnrin kan ni Makinde fi orúkọ wọn sílẹ̀
Oríṣun àwòrán, Seyi makinde/instagram
Gomina ipinlẹ Ọyọ, Seyi Makinde ti kede ti o si fi orukọ awọn to fẹ yan si ipo kọmisana ipinlẹ naa ranṣẹ sile aṣofin.
Olori ile aṣofin ipinlẹ naa, Adebọ Ogundoyin, kede orukọ awọn eniyan naa sita l'Ọjọbọ.
Ninu orukọ mẹrinla ọhun lati ri ọkunrin mẹtala, ati obinrin kan.
Kò sí ìsinmi ìdajì táàmù fáwọn akẹ́kọ̀ọ́ ìjọba l‘Ọyọ - Seyi Makinde
Ìjọba mi ṣetán láti mú àgbéga bá ètò ààbò l‘Ọyọ - Seyi Makinde
Lẹ́yìn ò rẹyìn Seyi Makinde búra fún ìgbìmọ̀ olùgbaninímọ̀ràn
Awọn orukọ naa ni:
Ondo Assembly: Ejò da ìjókòó ilé rú , l'àwọn aṣòfin bá fẹsẹ̀ fẹ
Oríṣun àwòrán, MELITA VAMBERGER/SENCKENBERG RESEARCH INSTITUTE
Ọrọ di bo o lọ, ya a mi nigba ti ejo afayafa deede jabọ pi lati ori aja sinu ile igbimọ aṣofin ipinlẹ Ondo lasiko ti ijoko ile n lọ lọwọ.
Iroyin sọ pe l'Ọjọbọ ni iṣẹlẹ naa waye nigba ti ijiroro nlọ lọwọ , eyi to mu ki onikaluku awọn aṣofin ọhun o sa asala fun ẹmi wọn.
Sisa ti wọn sa yii fi opin si ijoko ati ijiroro to n lọ lọwọ.
Ejo abami to n mu owo ni ajọ Jambu
Amọ ṣa, ejo naa raaye salọ.
Awọn aṣofin si ti sọ ipade ijiroro wọn di ọjọ miran, ọjọ ire titi ti atunṣe yoo fi de ba gbọngan ile aṣofin.
Action Against Hunger: Àwọn òṣìṣẹ́ olùrànlọ́wọ́ képe ìjọba kó gbàwọn lọ́wọ́ ajínigbé
Oríṣun àwòrán, AFP
Ijọba orilẹede Naijiria ti bẹrẹ ijiroro pẹlu awọn to ji awọn oṣiṣẹ mẹfa to jẹ ti ajọ alaanu kan gbe lapa ila oorun ariwa orilẹede Naijiria.
Fidio kan lo ṣafihan awọn oṣiṣẹ naa to jẹ ti ajọ to n gbogbu ti ebi, Action Against Hunger, nibi ti wọn ti n bẹbẹ fun ominira lọwọ awọn agbesumọnmi to ji wọn gbe.
Obinrin kan to wa lara wọn sọ pe wọn fiya jẹ awọn ki wọn to gbe awọn lọ si ibi tawọn ko mọ rara.
Ṣugbọn oludamọran lori ọrọ iroyin si Aarẹ Muhammadu Buhari, Garba Shehu to ba BBC sọrọ fidi rẹ mu lẹ pe ijọba ti bẹrẹ si ni ba awọn ajinigbe naa sọrọ lori bi wọn yoo ṣe dawọn silẹ.
Shehu ni oun nigbagbọ pe awọn oṣiṣẹ mẹfa naa yoo gba ominira laipẹ lọwọ awọn ajinigbe.
Ajọ oluranlọwọ Action Against Hunger, ṣalaye pe awọn da awọn oṣiṣẹ oluranlọwọ mẹfa to wa ninu fidio naa mọ.
Ọkan lara wọn ti orukọ rẹ n jẹ, Grace da iborun alawọ buluu bori, bẹẹ lawọn ọkunrin marun un joko lẹgbẹ rẹ.
Obinrin naa ke gbajare si ijọba Naijiria ati ijọba agbaye lati gbawọn lọwọ awọn ajinigbe ni kiakia.
Ni ibẹrẹ osẹ yii ni ajọ oluranlọwọ naa fi atẹjade kan sita pe awọn eeyan kan kọlu awọn oṣiṣẹ wọn to n rinrin ajo lọ si ilu Damasak, nipinlẹ Borno.
Wọn tun sọ ninu atẹjade naa pe awakọ kan ku ninu ikọlu ọhun, bakan naa ni wọn ko ri awọn ti wọn n jọ n rinrin ajo.
Ẹwẹ, awọn ologun sọ pe awọn ti gbiyanju agbara lati fopin si awọn agbesumọmi ati ijinigbe ṣugbọn egberin ọtẹ lọrọ ọhun.
Ìtàn Mánigbàgbé: Kí ni ẹ rántí nípa Israel Adebajo, gbajúmọ́ oníṣòwò tó dá 'Stationery Stores' sílẹ̀?
Oríṣun àwòrán, Prof. Adekeye Adebajo
Gbajumọ to gbalafẹ ni Israel Adebajo
Bi a ba ka awọn gbajumọ ni meni meji lasiko ti o logba, yoo ṣoro ki a ma mẹnu ba ilumọọka oniṣowo ọmọ bibi ilu Ẹpẹ nni, Israel Adebayo Ogunyeade Adebajo.
Ninu awọn gbajumọ to gbalafẹ nilu Eko lasiko aye rẹ, ko fẹrẹẹ si ẹlẹgbẹ Israel Adebajo.
Lẹka karakata ati owo ṣiṣe, Israel Adebajọ lalẹ gaara, ti orukọ ile iṣẹ itawe rẹ Stationery Stores si kale ka'ko.
Ọjọ kọkanlelogun, oṣu kinni, ọdun 1920 ni wọn bi i ni Imobi, Epe, nilu Eko.
Nigba ti yoo fi faye silẹ lẹni ọmọ ọdun mọkandinlaadọta, orukọ Adebajo ti tan kaakiri ti o si ti lapa lagbo ere bọọlu nitori bi o ti ṣe dari ikọ ẹgbẹ agbabọọlu Stationery Stores.
'500 level'' ni mo wà nígbà tí mo di adélé Ọba'
Awọn to ba n fi ọkan tẹle ere boolu nilu Eko ati kaakiri orile-ede Naijiria lasiko igba ti ọlaju Premiership ko ti gbode, kete ti a ba darukọ Stationery Stores ni wọn yoo ranti ẹgbẹ agbabọọlu ti o milẹ titi yii.
Ẹyẹ meji kii jẹ aṣa, ti ẹ ba ti n gbọ 'Up Stores!' 'Up Super' ''Triple Flaming''ati ''Gbogbo wa lọrẹ Adebajo'' Stationery Stores lawọn eeyan n kan sara si.
Lasiko ta n wi yii, Stationery Stores ti orukọ ipilẹ rẹ jẹ Adebajo Babes jẹ ẹgbẹ agbabọọlu Naijiria akọkọ ti yoo kopa ninu idije African Champions Cup ti a mọ si CAF Champions League lonii.
Oríṣun àwòrán, Adewemimo A. Adebajo
Ọjọ kọkanlelogun, oṣu kinni, ọdun 1920 ni wọn bi i ni Imobi, Epe, nilu Eko.
Adebajo na owo, o na ara lati rii pe ẹgbẹ yi tàn bi oṣumare ti pupọ awọn alatilẹyin rẹ si kan sara si ọgbọn ati oye ti o fi ṣakoso ẹgbẹ naa.
1958 lo ra ẹgbẹ agbabọọlu ti orukọ rẹ n jẹ Oluwole Philips Football Club ti o si yi orukọ rẹ pada si Stationery Stores Football Club.
Owo to n wọle lati awọn ile itawe rẹ, Stationery Stores ti o da silẹ nilu Eko, Ibadan, Enugu ati Port Harcourt ni Adebajo fi n tukọ ẹgbẹ naa.
Ni igba ti a n sọrọ rẹ yii, awọn ile iṣẹ nla bi Leventis, UAC, Nigerian Railway Corporation, ati Electricity Corporation of Nigeria (ECN) ni wọn ni ikimi lati da ẹgbẹ agbabọọlu silẹ ni orukọ wọn.
Oríṣun àwòrán, Adégbóyèga Adébàjò
Awọn agbabọọlu ẹgbẹ Stationery Stores wa kẹdun iku oludasilẹ ẹgbẹ wọn nigba to ku
Bi awọn eeyan ṣe n gbadun ere bọọlu lati ẹsẹ awọn agbabọọlu Stationery Stores ni owo n ya wọle fun ile iṣẹ ti o n ba a jẹ orukọ.
Ipolowo ọja nla ni ibaṣepo ẹgbẹ agbabọọlu naa jẹ fun ile iṣẹ Adebajo ti eleyi si mu ki okiki rẹ ati owo rẹ maa pọ sii.
Ẹgbẹ Stationery Stores jẹ ẹgbẹ tawọn ololufẹ ere bọọlu nifẹ si pupọ ti pupọ ninu awọn agbabọọlu naa si kopa ninu idije fun ikọ agbabọọlu Naijiria Green Eagles nigba naa.
Lọdun 1968 ti Naijiria kopa ninu idije Olympics, mẹsan an ninu awọn agbabọọlu to ṣoju Naijiria ni Mexico jẹ agbabọọlu lati ẹgbẹ Stationery Stores.
Oríṣun àwòrán, Adégbóyèga Adébàjò
Adebajo ati awọn ọmọ rẹ nibi apeje ajọyọ ife ẹyẹ Challenge Cup lọdun 1968.
Nigba kigba ti Stationery Stores ba fẹ koju awọn akẹgbẹ wọn, awọn alatilẹyin ẹgbẹ naa yoo gba ọkọ lati Ibadan wa si Eko tori pe wọn fẹ wo ifẹsẹwọnsẹ wọn.
Labẹ akoso Adebajo, Stationery Stores ni awọn ilumọọka agbabọọlu bi Haruna 'Master Dribbler' Ilerika, Yomi Peters, Julius Akpele, Peter Rufai, Ike Shorounmu, Yakubu Mambo ati Mudashiru Lawal.
Wọn gba Lagos State Challenge Cup ni 1974 ati 1976; FA Cup ni 1982 ati 1990; Ife ẹyẹ Liigi ni 1992; ti wọn si kuna lati gba ife ẹyẹ African Cup Winners' Cup lọdun 1981 lẹyin ti wọn fidi rẹmi lọwọ Union Douala  Cameroon.
Ọ̀ṣọ́ Aṣọ Òkè ti kọjá lílo ìlẹ̀kẹ̀ níkan
Awọn olorin bii King Sunny Ade naa gboṣuba kare fun Stationery Stores ninu awo orin oriṣiriṣi ti wọn gbe jade lasiko naa.
Gbogbo aṣeyọri Stationery Stores wọnyii ko ṣẹyin Israel Adebajo.
Oríṣun àwòrán, Adégbóyèga Adébàjò
Gbogbo awọn agbabọọlu Stationery Stores lo jijọ gbe psoi Adebajo
Ẹwẹ, Stationery Stores gba ife ẹyẹ Challenge Cup lẹẹmeeji lera lọdun 1967 ati 1968 ti iku Adebajo si di ọna gbigba ife naa ni igba ẹkẹẹta lọdun 1969.
Ọjọ kẹẹdọgbọn, osu keje, ọdun 1969 ni Israel Adebajo dagbere faye!
Wọn sin oku rẹ si Odo-Naforija ni Epe, ilu Eko.
Lẹyin iku rẹ, pupọ awọn agbabọọlu ẹgbẹ Stationery Stores to jẹ ọmọ ilẹ Ghana pada sile ti awọn miran si lọ gba fun ẹgbẹ ECN ati Ngeria Airways.
Adebajo fi ọpọ ọmọ ati iyawo silẹ lọ.
Ìsẹ́yìn: Ilé aṣọ òkè alárà ǹ barà
Power: Ṣé ẹ̀mí ilé aṣòfin lè gbé ṣíṣe ìwádìí 16 bílíọ̀nù owó àgbàṣe iná ọba Nàìjíríà?
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Foniku fọla dide to n ba ẹka ina ọba lorile-ede Naijiria jẹ ọrọ kan to n kọ ara ilu ati ijọba lominu.
Ọrọ naa lagbara de bi pe awọn onwoye ni kete ti wọn ba ti ribi wa wọrọkọ fi ṣada lẹka yii ti ijọba si sọ ji pada, ohun gbogbo yoo bọ sipo pada.
Lati le e wa ojutu si ọrọ naa, awọn aṣojuṣofin ti wọn ṣẹṣẹ bẹrẹ iṣẹ lorile-ede Naijiria ti pinnu lati tọ pinpin bi ijọba to ti kọja laarin ọdun 1999 si 2007 ṣe na biliọnu mẹrindinlogun dọla.
Bẹẹ wọn ni wọn ko mu iyipada kankan ba ẹka ina ọba.
Lọjọbọ ni ile ṣe ipinnu yii ti wọn si ni awọn yoo tọ pinpin ijọba to kọja bẹrẹ lati ori aarẹ Olusegun Obasanjo, Umaru Musa Yar Adua, Goodluck Jonathan to fi mọ ti Muhammadu Buhari to wa lori oye bayi.
Igbesẹ yi jẹ eleyi ti awọn eeyan ti n kan sara si ṣugbọn ibeere to gba ẹnu ara ilu bayi ni pe ṣe ẹmi ile aṣofin le gbe ṣise iwaadi to peye lati le mọ wulẹwulẹ ọrọ yi?
Lati ọdun 2009 ni ọrọ iwadi owo agbaṣe lẹka yi ti n mẹhẹ.
Ni igba naa lọhun,awọn ọmọ ile fọwọ rọ iwaadi ti igbimọ ile lori ina ọba gbe jade ti wọn si tẹnbẹlu abajade iwaadi naa.
Lara ohun ti iwaadi naa daba ni pe ki ajọ to n ṣe iwadi iwa jẹ́gudujẹra ṣe iwadi aarẹ Olusegun Obasanjo ati Gomina ana ipinlẹ Ondo Olusegun Agagu lori ọrọ naa.
Lati ọdun 2009 ni ọrọ iwadi owo agbaṣe lẹka yi ti n mẹhẹ.
Koda igbimọ naa daba pe ki wọn ṣe iwadi Gomina ipinlẹ Rivers tẹlẹ ri,Senatọ Liyel Imoke ati Minisita fọrọ ohun amuṣagbara Alhaji Abdulhamid Ahmed.
Amọ ko si ohun to tẹyin iwadi naa bọ to loju tu.
Ile iṣẹ BBC gbiyanju lati ba Dimeji Bankole to jẹ olori ile nigba naa sọrọ lori igbesẹ tuntun yi amọ o ni ohun kolọrọ sọ nipa rẹ aya fi ti ile ba pari iwadi ti wọ́n lawọn fẹ ṣe yi
Bi ẹ ba ṣe iwadii, ẹ ri pe ẹ se de oju ami-SERAP
Imọran re e lati ọdọ adari ajọ SERAP, Adetokunbo Mumini fawọn aṣojuṣofin Naijiria ti wọn lawọn fẹ se iwadi owo ti ijọba ti na lori ẹka ina ọba.
Mumini sọrọ yi ninu ifọrọwanilẹnuwo pẹlu BBC Yoruba.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Amọ ko si ohun to tẹyin iwadii naa bọ to loju tu.
O ni Naijiria o ṣẹsẹ ma ṣe iwadii lori ọrọ yi,tori naa ki wọn ma wulẹ dawọ le iwadii ti wọn o ni  tele abajade rẹ.
Mumini ni o ṣeni laanu pe Naijiria ko ti ri ọrọ yanju nipa ẹka yi ati pe bi eeyan ba ṣẹṣẹ n ronu ati ṣe iwadii dipo ko ma mu ọrọ abayọ wa,apẹrẹ pe ko ni nnkan ṣe ni.
Ooni Ife ké sí olóòtú ìjọba Gẹ̀ẹ́sì tuntun pé kó má gbàgbé ìlérí tó ṣe fún gbogbo àgbáyé
Oríṣun àwòrán, Ile Oodua
Ọọni ile ifẹ, Ọba Adeyẹye Ogunwusi ti fi ohun ranṣẹ si olootu ijọba tuntun lorilẹede Gẹẹsi, Boris Johnson pe ko ma ṣe gbagbe ileri to ṣe ninu ọrọ akọsọ rẹ gẹgẹ bii olootu ni ọjọru ninu eyi to ti ni ọwọ araalu ni agbara iṣejọba wa.
Kayeefi: Facebook ni Wolii Arole Jesu fi tàn an wọ agbo, orí rẹ̀ ni wọ́n fi s'owó
Ọọni Ogunwusi ni bi Boris Johnson ba joun gbe, ko maa johun gbe o nitori gbogbo agbaye lo n reti ipa rere ti o nii ko ninu idagbasoke ọmọniyan.
Ọọni ile Ifẹ sọ eyi lasiko to gbalejo aṣoju ijọba ilẹ Gẹẹsi, Catriona Laing, ni aafin rẹ, Ile Oodua nilu ile Ifẹ.
O ni adura oun fun olootu ijọba tuntun naa lorukọ awọn alalẹ ilẹ Yoruba ni pe yoo ṣe rere ni ipo rẹ tuntun naa.
LASTMA Yesufa: Àwọn dókítà gbìyànjú lórí ojú mi ṣùgbọ́n...
"Mo nifẹ si ọrọ akọkọ ti olootu ijọba ilẹ Gẹẹsi sọ ninu eyi to ti wi pe ọwọ araalu lagbara wa. Mo si fi anfani yii rọ oun ati ikọ iṣejọba rẹ lati ṣiṣẹ takuntakun ki wọn lee mu ileri ti wọn ṣe fun gbogbo agbaye ṣẹ."""
Bakan naa lo tun kan sara si aṣoju ijọba ilẹ Gẹẹsi lorilẹede Naijiria, Arabinrin Catriona Laing fun ilakaka rẹ lati rii pe ajọṣepọ to dan mọran wa laarin orilẹede Naijiria ati ilẹ Gẹẹsi.
Ọọniriṣa, Adeyẹye Ogunwusi ko da gbalejo aṣoju ijọba ilẹ Gẹẹsi naa, oun pẹlu Olori rẹ, Yeyelua Naomi Ogunwusi atawọn agbagba Ile Ifẹ ni wọn ki arabinrin Catriona Laing kaabọ si ile Oodua nileefẹ.
Pope Francis appealed for peace after performing the rare gesture
WAEC: Ìdá 82% àwọn tó jókòó ṣedánwò WASSCE 2019 ló yege
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Miliọnu kan abọ awọn akẹkọọ to pegede ninu idanwo naa
Ajọ onidanwo mẹwaa, WAEC ti gbe esi idanwo aṣekagba ileewe girama ti oṣu kẹfa, ọdun yii, West African Senior School Certificate Examination (WASSCE) jade.
Ajọ naa sọ eyi di mimọ nilu Eko.
Ajọ naa ti wa rọ awọn akẹkọọ to joko ṣe idanwo naa lati bẹrẹ si nii lọ wo ori ayelujara fun esi wọn.
Nnkan bii miliọnu kan abọ o le diẹ lawọn akẹkọọ to joko ṣe idanwo naa lọdun yii eyi to pọ ju ti esi lọ.
Kayeefi: Facebook ni Wolii Arole Jesu fi tàn an wọ agbo, orí rẹ̀ ni wọ́n fi s'owó
Gẹgẹ bi ajọ WAEC ṣe sọ ọ, ida mejilelọgọrin ni awọn akẹkọọ to gba ami o kare, iyẹn credit ni awọn iṣẹ ọpọlọ marun un tabi ju bẹẹ lọ.
Eyi fẹrẹ to ilọpo meji awọn to ni iye ami yii ninu idanwo ọdun 2018, eleyi to jẹ ida aadọta o din diẹ, 49.98%.
Ibadan Accident: Èèyàn méjì kú, ẹnìkan wà nílé ìwòsàn
Oluwo ti Iwo: O yẹ́ ká rán àwọn Fulani lọ ìlú òyìnbó láti kẹ́kọ̀ọ́
Oríṣun àwòrán, emperortelu1
Oluwo ti Iwo
Oluwo ti ilu Iwo, Ọba Abdulrasheed Akanbi ti ni wahala to ṣẹ n de ni Naijiria yii, kii ṣe oni lo ti bẹrẹ.
"Ọba Abdulrasheed tẹnu bọ owe lati fi bẹrẹ ọrọ o ni, ""Ọmọ ta o kọ lo n gbe'le ta a kọ ta"". O fi eyi s pe awọn ọmọ aye ode ko mọ itan."
"Ẹyin ọmọde isinsinyii, ẹ o mọ itan lẹ fi n lọ sori ẹrọ ayelujara lọ kọ ohun to wu yin nipa ọrọ aabo to da orilẹ-ede Naijiria laamu lọwọlọwọ.
Awọn Fulani ti wa laarin wa ti pẹ, wọn le ni ẹgbẹrun lọna ẹẹdẹgbẹta (500,000)""."
"Oluwo ni ninu itan ilẹ Yoruba, ""o ti le ni irinwo ọdun ti Fulani ti n gbe laarin wa""."
"Oluwo ṣalaye pe inu igbo rere nile Fulani koda, wọn mọ igbo wa ju wa lọ""."
Oríṣun àwòrán, Oluwo/instagram
"Oluwo ṣalaye pe inu igbo rere nile Fulani koda, wọn mọ igbo wa ju wa lọ""."
Kabiyesi ba mẹnu ba ohun ti ijọba n sọ nipa ipaniyan lonii, ijinigbe lọla ni Naijiria.
Awọn oloṣelu ko naani eeyan lo fa ohun to n ṣẹlẹ si Naijiria bayii eyi ti ko si tii ṣẹlẹ ri.
O ni gbogbo iṣẹlẹ a n ra ibo lasiko idibo, kii ṣẹlẹ tẹlẹ ni Naijiria, oni bi wọn ba mọ itan ni, itan atijọ lo yẹ ki wọn fi yanju isoro oni.
Mo rí ogun, mo jagun, emi ni mo le sọ nipa bi asiko ogun ṣe maa n ri. Mo wa ninu ogun Liberia ni 1989.
Hitler, Latosa, Ogedengbe... ogun kọ ni gbogbo iyẹn, a ni ẹ o mọ asiko ti ẹ o mu abọ lọwọ ti ẹ o si ni ri ounjẹ jẹ.
Ẹ mu àwọn Fulani lọ ilu oyinbo ki wọn lọ kọ bi wọn ṣe n ṣe eto ẹran igbalode
Apẹrẹ gidi ni mi lori ọrọ Fulani, Ọba temi wa Fulani lọle ninu igbo rere, mo wọ inu Gaa Fulani lọ.
"Kabiyesi Akanbi ni ohun ko jọba tori ati kowo jẹ, oun fẹ fara sin ilu ni. Tori eyi, ""ọmọ Nàiìjíríà náà ni Fulani,  mu wọn bi arakunrin yin""."
"Oluwo ni ""kò sẹ́ni tó lè bá Fulani tàbí ọmọ wọn jà nínú igbó"" tori naa ọgbọn laa fi n ṣe gbogbo nkan."
"RUGA, Ruga tí wọ́n ń pariwo kò lè tó awọn 500,000 Fulani tó wà nínú igbó""."
Ọpọlọpọ eto ti yoo ṣe wọn lanfani bii idanilẹkọọ lo yẹ ki ijọba kọkọ ṣe ki wọn wa fi ofin lelẹ.
"Ẹwẹ Kabiyesi ni bí ẹnikẹni bá ti rú òfin, ko si iru ẹya to le jẹ, ""ẹ mọ̀ọ́ pa wọ́n, ẹ o ri i kò ní ṣẹlẹ̀ mọ́""."
Òfin kí wọ́n máa pa ajínigbé ló yẹ kí ìjọba ṣe.
"Oluwo ni fun apẹrẹ, ""Boo ba kowo jẹ ni China, pipa ni!""."
"Tori naa ""ọmọ Yorùbá tó bá sọ̀rọ̀ ogun, ẹ gbé e!""."
Ẹsan lo n ke lori Naijiria, eeyan tẹẹ pa ti pọ ju ni, ti ẹ fi ro pe Fulani nikan lo n pa eeyan.
"Bi bẹẹ kọ, o yẹ ki Naijiria ti di irinwo miliọnu bayii""."
Kayeefi: Facebook ni Wolii Arole Jesu fi tàn an wọ agbo, orí rẹ̀ ni wọ́n fi s'owó
Idi ti awọn kan ṣe n sọ pé mo n ṣe akọ:
Eeyan kii jẹ Oluwo, ipo ade, ti mo gba ni wọn n pe ni Oluwo
Awọn kan tilẹ ni wọn ni Gay ni mi, Yahoo yahoo ni mi...
Awọn baba yin wa ninu itan, o si yẹ ki ẹ ju awọn baba yin lọ, iyẹn lemi n ṣe aridaju rẹ laye temi.
Bóò bá ta Ọba rẹ lọ́pọ̀, òó lè rí i ní gbànjo.
"Kabiyesi ni inu maa n bi awọn eniyan pe oun n ṣakọ, o ni ""ṣe bi iwọ ba jọba oo ni ṣakọ?"""
Ṣe iwọ ti ri Iwo ri lori Google, Facebook, BBC,...
Oríṣun àwòrán, Oluwo/instagram
Oluwo ni àwọn òwe Yorùbá kan wà tó yẹ kí a yí padà lédè Yorùbá
- ṣé a ò yí ilé koríko padà máá wá kọ́ ilé bíríkì báyìí?
Ìwọ tóò bá ti fẹ́ yí ǹkan padà, ṣì lọ máa bulù sójú.
"O yẹ ki a jẹ́ ki awọn aṣa wa ba igba mu ko le maa wu awọn eniyan.
Eyi lo n jẹ ki awọn ọmọ wa maa sa fun aṣa. Emi ti n jẹ ki aṣa wa wu awọn eeyan lati ilu Iwo.
Kabiyesi ba tun fi owe pari ọrọ awn to ni oun maa n ṣakọ pe Olówó máa ń jẹun jẹ́jẹ́ ni, òtòsì nìí yọkùn gàkìa-gàkià"""
Imaamu tó ní mo fẹ́ bá ìyàwó òun sùn ti fẹ́ tẹ́:
Oluwo ni ko yẹ kí ààfáà máa sọ̀rọ̀ sí ọba jau jau.
Imam ọhun ti wa bẹbẹ lọdọ mi lọpọ igba nitori naa igba to ṣe e de ibi gẹgẹ, o ti fẹ tẹ nu un.
Tọọ ba ti ri ọba fin, o ti padanu gbogbo ohun too ni ati to n ri lọdọ ọba; a o si wa wa ọta rẹ a o gbe gbogbo ohun toun ri gba lọwọ ọba fun ọta rẹ.
Oríṣun àwòrán, Oluwo/instagram
Oluwo ati Olulufẹ rẹ
"Kabiyesi fi iyawo rẹ yangan - ""Ṣé bóo rí ìyàwó mi bó ṣe dùn, ṣe ìyàwó Ààfàá ló wá ń kàn?""."
Kò sí aáwọ̀ láàrin èmi àtàwọn Ọba Yorùbá tó kù, àhesọ ni:
Oluwo ni lori ọrọ ibaṣepọ laarin oun atawọn Ọba alaye to ku nilẹ Yoruba, awọn jọ maa n ṣepade pọ ni.
Ilu Iwo ló yẹ kó kọ́kọ́ gba Sultan àkọ́kọ́ ní Nàìjíríà.
"Oluwo ni Sultan tumọ si Ọba lede Yoruba. O ni bo ba ṣe orile-ede Germany ni, ""Konid Abdurasheed Adewale Akanbi lo yẹ ki n maa jẹ"""
"Kabiyesi ba ni ko da ""Oriṣa ni gbogbo yin"" pẹ̀lu alaye lẹnu Oluwo."
Awọn Iroyin mii ti ẹ le nifẹ sii
Kidnapped Turkish Nationals: Iléèṣẹ́ ọlọ́pàá Kwara dóòlà ọmọ Turkey mẹ́rin tí wọ́n jígbé
Oríṣun àwòrán, others
Alẹ ọjọ Abamẹta to kọja ni wọn ji awọn ọmọ ilẹ okeere naa gbe nile ọti kan.
Ileeṣẹ ọlọpaa ipinlẹ Kwara ni oun ti ri awọn ọmọ orilẹ-ede Turkey mẹrin ti awọn ajinigbe gbe pamọ ni ipinlẹ naa gba pada.
Ọgbẹni Kayode Egbetokun sọ fun BBC Yoruba pe ọjọ Ẹti ni awọn ọlọpaa ri wọn doola ninu igbo kanA óò wá àwọn ọmọ ilẹ̀ Turkey mẹ́rin tí wọ́n jígbé rí láàyè- Ọlọ́pàá Kwara.
Gbogbo awọn ọlọdẹ ibilẹ la jọ ṣiṣẹ naa. Bakan naa ni ọga agba ileeṣẹ ọlọpaa naa fi awọn kan ranṣẹ si wa lati ilu Abuja.
Ẹgbẹtokun sọ pe Ọjọbọ ni ọwọ ti kọkọ tẹ ọkan lara awọn ajinigbe naa pẹlu ibọn AK-47 lọwọ rẹ, ti ọwọ si tun tẹ awọn meji mi lọjọ Ẹti.
Oríṣun àwòrán, others
Mimu ti a mu awọn meji yii mu so eso rere nitori pe o finna mọ awọn to ku lati le yọnda awọn to wa ni igbekun wọn lai gba owo.
Ṣaaju ni awọn ajinigbe naa sọ pe awọn yoo gba irinwo miliọnu Naira ki wọn o to le tu wọn silẹ. Lẹyin eyi ni wọn tun din ku si ọgọrun un miliọnu Naira.
Amọ ṣa, Egbetokun sọ pe wọn ko san owo kankan fun itusilẹ awọn ọmọ ilẹ okeere naa.
Nibayii, ati yọnda wọn, wọn si ti wa lọna Abuja lati lọ ba awọn ọga wọn.
Dele Momodu : Lẹ́yìn Buhari àti Atiku, èrò ọjà làwọn olùdíje yóòkù ní ìdìbò 2019
Alẹ ọjọ Abamẹta to kọja ni wọn ji awọn ọmọ ilẹ okeere naa to jẹ oṣiṣẹ abanikọle gbe nile ọti kan.
Bakan naa lo ṣalaye kikun lori ipa pataki ti awọn fijilante ko ni Kwara nipa wiwọ inu igbo lọ titi wọn fi ṣawari awọn oniṣẹ ibi naa.
Ṣọla Allyson: Obìnrin tí kò bá rẹwà ni yóò máa ṣí ara sílẹ̀
Shiite Movement: Shiite fèsì lórí àṣẹ ilé ẹjọ́ láti máa pé wọ́n ní ẹgbẹ́ agbésùnmọ̀mí
Oríṣun àwòrán, @SZakzakyOffice
Mo lè kú tọmọ tọmọ bi ijọba ba kọ lati da adari wa, ElZakzaky silẹ.
Perete lara ọrọ adari ẹgbẹ ajafẹtọọ musulumi ni iha Guusu-Iwọ Oorun iyẹn ilẹ Yoruba, Comrade Muftau Zakariyah ree nigba ti BBC Yoruba kan si i.
Muftau ni awọn naa gbọ awuyewuye iroyin naa pe ile ẹjọ giga l'Abuja ti paṣẹ pe ẹgbẹ musulumi Shiite ti di agbesumọmi lati igba yii lọ.
Gẹgẹ bi iroyin ṣe sọ ọ, Ileẹjọ naa tun paṣẹ wi pe ohunkohun tẹgbẹ Shiite ba ṣe bayii ti di ti ẹgbẹ agbesumọmi.
Adari ẹgbẹ yii ni iha Guusu-Iwọ Oorun wa ni bi o ba jẹ aridaju ni pe ijọba Naijiria ṣe eyi, iwa naa ko mọgbọn dani rara.
Idajọ yii waye lẹyin ti ijọba apapọ ni ki ileẹjọ gbe igbesẹ naa lẹyin ti ọga ọlọpaa ati akọroyin Channels ku lasiko iwọde Shiite l'Abuja.
Àgùnbánirọ̀ akọ̀ròyìn Channels náà ti dágbére fáyé látààrí ìkọlù Shiite l'Abuja
Ẹ̀mí sùn níbi ìkọlù Shiite àti ọlọ́pàá
Ẹwẹ, Comrade Muftau ni igbesẹ yii kan da bii ki wọn gbe ote le awọn ẹgbẹ tabi ijọ ẹlẹsin Kristẹni ni tori Naijiria nikan kọ ni ọmọ ẹgbẹ Shiite wa.
Ṣe aṣoju Iran si Naijiria naa ti di onsunmọmi? Bi ọlọpaa Naijiria tabi ọtẹlẹmuyẹ ba jẹ ọmọ ẹgbẹ Shiite, ṣe ẹ o pe wn ni Sunmọmi.
O ni ijọba to kọkọ ni Sunmọmi ni awọn Fulani ti wọn tun pada ko ọrọ wọn jẹ pe ọmọ Naijiria ni wọn ni wọn wa n pe awọn ti o jẹ ojulowo ọmọ Naijiria bayii ni ẹgbẹ sunmọmi.
Ṣe ka wa lọ fa ara wa le ọlọpaa lọwọ ni abi ka duro sile ki ọlọpaa wa mu wa?
"Muftau ni ggẹ bi akọsilẹ, laarin ẹgbẹrun mọkanlelogun si ọgbọn ni ọmọ ẹgbẹ Shiite to wa ni Naijiria. "" Ṣe wọn wa ni ọgba ẹwọn to le gba gbogbo wa bi wn ba fẹ maa ko wa?""."
N100,000 Nairà mà ni Dino gbé dání lójú agbo, kò náwó yàlà-yòlò - Ayefele
"Muftau ni lati igba ti awọn ti maa n ṣe iwọde, ijọba ko figba kan s pe awọn gba eti ẹni kan ri tabi paayan. ""Ẹhonu lai lo ibọn tabi ada lawa n ṣe""."
"Ẹgbẹ wa kii ṣe ẹgbẹ oni jagidijagan, bo ba ṣe pe a fẹ ra ibọ ni, owo wa bẹẹ si ni a ju gbogbo ọmọ ogun Naijiria lọ ṣugbọn kii ṣe ologun tabi ọlọpaa lo ti olori wa mọle bi ko ṣe aarẹ Buhari gangan""."
Lati ọdun 2015 lawọn ọmọ ẹgbẹ ti n ṣe iwọde eyi ti wọn fi n beere pe ki ijọba da olori wọn, Sheikh Ibrahim El-Zakzaky, ati iyawo rẹ, Zeenat silẹ.
Awọn Iroyin mii ti ẹ le nifẹ sii
Kayeefi: Facebook ni Wolii Arole Jesu fi tàn an wọ agbo, orí rẹ̀ ni wọ́n fi s'owó
Gbogbo igbiyanju BBC lati kan si awọn ile iṣẹ aarẹ ko fi bẹẹ́ bimọ ire ayafi Bashir Ahmad to jẹ oluranlọwọ pataki fun aarẹ ni ko si ohun to jọ bẹẹ o.
Bashir ni ijọba ko gbe ẹjọ kankan to jọ eyi lọ sile ẹjọ.
Nigba ti akọroyin beere boya wọn ti wa bu omi suuru mu paapaa ti ijọba ko yi igbesẹ pada lori itusilẹ El-Zakzaky.
Omi suuru bawo... ki lo n jẹ bẹẹ, mi o ni gba, Igba yii gan la ṣẹṣẹ maa jade, bo ba wu wọn ki wọn pa wa.
"Mo ṣe tan lati ku tọmọ tọmọ bi wọn ko ba tu ọga wa silẹ tori ẹmi gbogbo awa ọmọ ẹgbẹ ko ni itumọ bi olori wa ba ṣi wa lahamọ""."
Marriage Certificate: Bí o ṣe lè mọ ìgbéyàwó tí kò bá òfin mu
Oríṣun àwòrán, OTHER
Ibi ijọsin irinwo le mẹrinla (314) nikan lo niwe aṣẹ lati ṣegbeyawo ki wọn si fun ni ni iwe ẹri.
Nibi ti wọn ti n ṣe ipade apero kan nipa ilana ti wọn fi n ṣe igbeyawo lọna ofin lorilẹede yii ni akọwe agba ile iṣ to n ri si ọrọ abẹnu, Georgina Ehuriah ti lede ọrọ naa.
Omi titun ti rú nínú oríṣii ètò ìgbéyàwó Yorùbá lásìkò yí
Nitori naa bi o ko ba ṣe igbeyawo nibi to ni iwe aṣẹ, o lee wọ pegé bii igba ti o ba fẹ gba iwe irina loke okun tabi bi o ba fẹ gba oku ọkọ tabi aya to papoda tabi nkan ini wọn.
"Arabinrin Ehuriah sọ fun BBC pe ""ojoojumọ ni iru nkan bayii n ṣẹlẹ to ṣe pe tọkọ taya yoo fẹ rinrinajo lọ oke okun to si ṣe pe iwe ti ṣọ́ọ̀ṣì ti ko láṣẹ fun wọn ni wọn yoo na siwaju""."
"O ṣalaye pe nibi ifọrọwanilẹnuwo fun irina wọn loju ọpọ ti maa n ja a ti ile iṣẹ afọrọwanilẹnuwo ""embassy"" ko ni gba eyi ti wọn mu wa iyẹn ti abẹle ni Naijiria eyi ti wọn n pe ni ""form E""."
N100,000 Nairà mà ni Dino gbé dání lójú agbo, kò náwó yàlà-yòlò - Ayefele
LASTMA Yesufa: Àwọn dókítà gbìyànjú lórí ojú mi ṣùgbọ́n...
"Bakan naa, bi ọkọ tabi aya kan ba ku ti ẹni keji si fẹ gba nkan ini rẹ, o ti di ọrọ rẹpẹtẹ tori oo ni le ri yanju. ""Eyi lo n mu ki awọn eeyan sọji lati maa tete lọ si ile ẹjọ ti ijọba lati lọ ṣe igbeyawo ki a to gbe ara wa lọ si ṣọọṣi lati fi ibunkun de e lade tori ẹsin ṣe pataki si wa gẹgẹ bi ọmọ Naijiria."
Ẹwẹ, ireti wa fun awọn ti ko tii ṣe igbeyawo atawọn ti ko da loju pe ojulowo ni igbeyawo awọn.
Awọn Iroyin mii ti ẹ le nifẹ sii
Ìran kan si ìkejì ló n gbèrò láti ṣe ìrú ìgbéyàwo àjùmọ̀ṣe 'Shao' fọ́mọ wọn
"Akọwe agba ni ""o ni ibi ti ẹ le lọ loju opo ayelujara ile iṣẹ to n ri si ọrọ abẹnu lati wo o boya ijọ yin ni iwe aṣẹ""."
"Ṣugbọn o ni, ko wa tumọ si pe ohun gbogbo ti bajẹ o,  tun lee pada lọ si oju opo kan naa lati kọwe ranṣẹ pe ẹ fẹ gba iwe ẹri igbeyawo""."
Arabinrin Ehuriah ni awn ile ijọsin Kristẹni lawọn maa n sába fun ni iwe ẹri ṣugbọn awọn agbo mii ko si ninu iwe ofin to ni ṣe pẹlu igbeyawo to faaye gba ọkọ kan ati aya kan.
Ìwà ipá nínú ìdílé máa ń bí ìgè àti àdùbí ni tó lè já sí ikú
NAFDAC: Ohun tí wọ́n fi ń se báàgì, bàtà ni wọ́n ń tà bíi ‘pọ̀ǹmọ́
Oríṣun àwòrán, Google
Àjọ NAFDAC ti ní àwọn ọlọ́jà káràkátà kan ń lo awọ ẹran màálù tí wọ́n fi ń ṣe báàgì tàbí bátà látì fi ṣe pọ̀nmọ́.
Ajọ to n mojuto ọrọ ounjẹ ati oogun lorilẹede Naijiria, NAFDAC ti tẹnu mọọ fun awọn ọmọ Naijiria lati sọra fun pọnmọ jijẹ.
NAFDAC, ninu atẹjade lati ọwọ adari ẹka naa, Arabinrin Mojisola Adeyeye fi lede, wi pe awọn eniyan n lo awọ ẹran maalu ti awọn ile-isẹ to n ṣe baata tabi baagi ra lati fi se pọnmọ ti awọn eniyan n jẹ.
N100,000 Nairà mà ni Dino gbé dání lójú agbo, kò náwó yàlà-yòlò - Ayefele
Adeyeye ni ọpọ igba, wọn o ti lo ‘chemical’ si ara awọn awọ ẹran maalu naa fun lilo, ko to di wi pe awọn eniyan ma a wa loo fun pọnmọ jijẹ.
Bakan naa ni NAFDAC fi kun wi pe, awọn miran tun n gbe awọ maalu wọle si Naijiria lati orilẹede Turkey ati Lebanon ni ọna ti ko ba ofin mu. Eleyii ko si ni fun wọn laaye lati woo finifini.
Ajọ naa wa parọwa si awọn ọmọ Naijiria lati sọra fun pọnmọ jijẹ, ki o ma ba a fa aisan aimọdi si ara awọn eniyan.
Kayeefi: Facebook ni Wolii Arole Jesu fi tàn an wọ agbo, orí rẹ̀ ni wọ́n fi s'owó
Oluwo of Iwo: Nàìjíríà, sọ́ra, ogun ń sọ ilé ọlá di ahoro!
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Oluwo ti ilu Iwo, Oba Abdulrasheed Akanbi ti kìlọ̀ fún ìjọba láti dojú kọ ètò ààbò tó mẹ́hẹ kí ogun ó má báa wáyé.
Oluwo ti ilu Iwo, Oba Abdulrasheed Akanbi ti kọ lẹta si Aarẹ orilẹede Naijiria, Muhammadu Buhari, fun igba akọkọ lori ipaniyan awọn Fulani darandaran ni orilẹede Naijiria.
Ninu lẹta naa, Oba Abdulrasheed Akanbi sọ wi pe oun kii kọ lẹta ni gbogbo igba, amọ lati dawọ ipaniyan duro ati ki ogun ma ba a sẹlẹ ni Naijiria ni oun fi kọ lẹta naa si Aarẹ Buhari.
Oluwo ti ilu Iwo ni ija ati asọ kọ ni ọna abayọ si eto aabo to mẹhẹ, amọ ki ijọba fi agbara fun ẹkọ ati iwe kika, eleyii ti o le mu ki awọn eniyan ni ọgbọn ati imọ wi pe ogun kọni ọna abayọ si ipenija to n koju araalu ni Naijiria.
N100,000 Nairà mà ni Dino gbé dání lójú agbo, kò náwó yàlà-yòlò - Ayefele
Bakan naa ni Ọba Akanbi wa rọ Aarẹ Buhari lati ba awọn adari ni gbogbo ẹkun lati sọra fun ọrọ ẹnu wọn, ki alaafia ba le jọba lorilẹede Naijiria.
Ruga Settlement: Ganduje ní káwọn Fulani darandaran kúrò lápá gúúsù Nàìjíríà
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Gomina ipinlẹ Kano, Abdullahi Ganduje ti woye pe tawọn Fulani darandaran ko ba kuro lapa Guusu Naijiria, ọrọ ruga ko le lojutu.
Gomina Ganduje ṣalaye pe ni wọn igba tawọn Fulani ẹlẹran ọsin ba n dẹran lati apa ariwa Naijiria lọ si aarin gbungbun ati guusu, ọrọ ruga ati isọro eto aabo to mẹhẹ ko le dopin.
O fikun ọrọ pe ko yẹ, ko lẹtọọ ki ruga wa lawọn ipinlẹ tawọn Fulani darandaran ti jẹ alejo.
Ganduje ijọba apapọ kọ lo yẹ ko ṣagbatẹru ọrọ ruga fawọn Fulani ẹlẹran ọsin, o ni awọn ipinlẹ to ba nifẹ sii lo yẹ ko ṣagbatẹru eto naa.
Gomina Ganduje fikun ọrọ pe ipinlẹ Kano ti ya ibi kan sọtọ fawọn Fulani lati maa fi ẹran jẹko.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Bakan naa, o sọ pe aikawe ọpọn ninu wọn lo ṣokunfa ki ọpọ wọn ti di agbebọn bayii.
Ganduje koro oju si bi awọn Fulani ti n ṣi kiri lati apa ariwa Naijiria lọ si apa aarin gbungbun ati Guusu Naijiria.
Bakan naa, o sọ pe aikawe ọpọ ninu wọn lo ṣokunfa ki ọpọ wọn ti di agbebọn bayii.
Ganduje ni ipese ruga lo le dẹkun iṣoro tawọn Fulani n koju, o ni ti wọn ba loju kan ni wọn fi le jẹgbadun awọn ohun ameyedẹrun bi awọn ara ilu yoku.
Nigeria Pensioners: Wàhálà àyẹ̀wò iwé ìfẹyinti yì ti pọ̀jù
Presidency: Aarẹ Buhari kẹdun ikú àwọn eniyan to kagbako Boko Haram
Oríṣun àwòrán, @Presidnecy
Ironu dori agba kodo
Aarẹ Mohammadu Buhari bu ẹnu ẹ̀tẹ́ lu ikọlu awọn alakatakiti ẹsin Islam, Boko Haram ni Borno
Mallam Garba Shehu to jẹ olubadamọran fun aarẹ Buhari lori ọrọ iroyin ati ifitonileti gbogbo sọ ninu atẹjade kan to fi sita pé nkan ibanujẹ lo ṣẹlẹ yii.
O ni awọn ọmọ ogun ilẹ ti fi da aarẹ Buhari loju pe awọn oniṣẹ ibi boko Haram to ṣiṣẹ yii a jẹ iyan wọn ni iṣu laipẹ.
Garba Shehu ni ijọba apapọ n gbe gbogbo igbesẹ to yẹ lati daabo bo ẹmi ati dukia awọn eniyan Naijiria.
Shiite: Ẹ̀mí àti ara wa kọ ohun tí ìjọba ń ṣe sìwa láti 2015
Ileeṣẹ aarẹ ni ijọba ko ni kọ ohun ti yoo na oun lati sọ ọrọ awón agbesunmọmi di ohun igabgbe ni Naijiria.
Garba Shehu ni lọwọlọwọ ni awọn ọmọ ogun ilẹ̀ ati ti ofurufu ti bẹrẹ igbesẹ lati ṣawari awọn oniṣẹ ibi yii pẹlu aṣẹ aarẹ Buhari.
Bakan naa lo fi da awọn eniyan Maiduguri ati awọn aṣatipo loju pe ijọba ti fi kun eto aabo ẹkun yii lati dena iru iṣẹlẹ bayii.
Odiwọn iye awọn to ba ikọlu Boko haram to ṣẹlẹ yii lọ ti di marun dinlaadọrin bayii.
Oríṣun àwòrán, AFP
Iṣẹlẹ yi waye nipinlẹ Borno lọsẹ ti o pe ọdun mẹwaa ti Boko Haram bẹrẹ si ni ṣoro ni Naijiria.
Ileeṣẹ amohunmaworan agbegbe Maiduguri ṣalaye pe bi wọn ṣe n pada bọ lati ibi isinku ni wọn ti kagbako awọn alakatakiti ẹsin Islam, Boko Haram.
Wọn kólu wọn ni abule Badu-Abattari to wa ni bii ọgọfa kilomita si Maiduguri to jẹ olu ilu ipinlẹ Borno.
Mohammed Bulama to jẹ alaga ijọba ibilẹ naa ni awọn eniyan mọkanlelogun ni wọn kọkọ pa ki wọn to tun wa lọ kọlu awọn ara abule to n gbeja awọn ero.
Oríṣun àwòrán, @Audu
ikú to n pa ojugba ẹni ni ọrọ yii n di ni Naijiria
Ọkan ninu awọn ọgagun ẹkun yii to ni ki BBC ma darukọ oun ṣalaye pe lojiji ni oun kọkọ gba ipe pajawiri lori iṣẹlẹ naa.
Ni eyi ti wọn ni eniyan mẹtalelogun ti gbẹmi mi lati Nganzai ni eyi ti awọn eniyan Badu Kuluwa si wa ninu ipaya.
Bẹẹ, o ti pẹ ti awọn agbesunmọmi alakatakiti ẹsin Islam boko haram ti n da ẹmi awọn eniyan legbodo.
Boko Haram ṣíná fún àwọn tó lọ ìsìnkú, èèyàn 23 pàdánù ẹ̀mí wọn.
Iṣẹlẹ yi waye nipinlẹ Borno lọsẹ ti o pe ọdun mẹwaa ti Boko Haram bẹrẹ si ni ṣoro ni Naijiria.
Oríṣun àwòrán, BBC/Boko Haram
Awọn Adunkoko mọni Boko Haram sefilọlẹ idunkuuku laja wọn lọdun 2009
Awọn eeyan mẹtalelogun to n dari bọ lati ibi isinku kan nipinlẹ Borno ti ko agbako iku lọwọ ikọ agbesunmọmi Boko Haram.
Gẹgẹ bi iroyin to tẹwa lọwọ, iṣẹlẹ naa waye lagbegbe Nganzai ni nnkan bi ago mọkanla owurọ ọjọ Abamẹta.
Ọkan lara awọn asaaju agbegbe ti iṣẹlẹ yii ti ṣẹlẹ, Bunu Bukar Mustapha ti o ba awọn ile iṣẹ iroyin AFP sọrọ ṣalaye pe lati abule Badu Kuluwu lẹba Goni Abachari ni awọn eeyan naa ti n dari bọ nibi ti wọn ti lọ sin oku kan.
Bunu ni ''oku eeyan mẹtalelogun lawọn eeyan wa gbe kuro nibi iṣẹlẹ naa lowurọ oni''
Awọn alaṣẹ ko ti i fi idi ọrọ yi mulẹ fun BBC titi di igba ti a fi ṣe akojọpọ iroyin yi.
Àwọn ìròyìn míì tí ẹ tún le nífẹ́ sí:
Lọsẹ́ to kọja yi ni o pe ọdun mẹwaa ti Naijiria bẹrẹ si ni koju ipenija awọn alakatakiti ẹsin Islam, Boko Haram ti ọpọ ẹmi ati dukia si ti ba a lọ.
Ibadan Accident: Èèyàn méjì kú, ẹnìkan wà nílé ìwòsàn
Ọlọ́pàá ilẹ̀ Gẹ̀ẹ́sì ti sanwó ìtaràn £2500 fún oníwàásù ọmọ Nàìjíríà tí wọn mú lọnà àìtọ́
Oríṣun àwòrán, Christian Concern
Paitọ Oluwole Ilesanmi yoo fi iwe ẹhonu sọwọ si ileeṣẹ ijọba eleyi ti awọn eeyan fọwọsi lati le daabo bo awọn to n ṣe iwaasu nita gbangba
Oniwaasu Kristẹni kan ni awọn ọlọpaa ilẹ Gẹẹsi ko panpẹ si lọwọ ti wọn si fipa gba bibeli lọwọ rẹ.
Lẹyin iṣẹlẹ yii lo wa di ẹni ti awọn ọlọpaa yoo san owo gba ma binu ẹgbaa le ẹdẹgbẹta pọun fun un.
Fọnran fidio ibi ti oniwaasu Oluwole Ilesanmi ti n bẹ awọn ọlọpaa ki wọn ma ṣe gba bibeli rẹ lawọn eeyan ti wo ni igba miliọnu mẹta le loju opo ayelujara.
Iwaju ibudoko ọkọ oju irin Southgate ni wọn ti da a duro losu keji ọdun yi lẹyin ti ipe kan wole pe o n sọ ọrọ to korira ẹsin Islam.
Daddy Freeze s'alaye n to faa ti oun fi n tako idamẹwa
Ile iṣẹ ọlọpaa ilẹ Gẹẹsi ni ẹtọ awọn ni lati ṣe iwadii ọrọ tawọn fura si pe o nii ṣe pẹlu idunkooko mọ awọn eeyan ẹya kan tabi ẹlẹsin miran.
Ninu fọnran fidio naa ni ọgbẹni Ilesanmi to jẹ ọmọ ọdun mẹrinlelọgọta ti n sọ fun awọn ọlọpaa naa pe ''Jesu nikan ni ọna iye''
"Ọlọpaa to mu u ninu fidio naa si n sọ pe ''Mi o ba ọ jiyan amọ ko si ẹni to fẹ gbọ ohun to n sọ. Wọn fẹ ki o kuro nibi ni' """
Oríṣun àwòrán, Christian Concern
Ninu fọnran fidio to gbode Paitọ Ilesanmi n bẹ awọn ọlọpaa lati ma ṣe gba bibeli rẹ
Nigba ti ọgbẹni Ilesanmi fẹ mu bibeli rẹ, ọlọpaa naa sọ fun un pe ''o ba ti ro o daadaa ki o to bẹrẹ si ni sọ ọrọ abuku nipa ẹlẹsin miran''
Ọgbẹni Ilesanmi ni lootọ lohun sapejuwe ẹsin Islam gẹgẹ bi ohun ti ko bojumu amọ ero ọkan tohun ni gẹgẹ bi Kristẹni kii ṣe pe ohun bẹnu atẹ lu awọn musulumi.
Shiite: Ẹ̀mí àti ara wa kọ ohun tí ìjọba ń ṣe sìwa láti 2015
Lọjọ Iṣẹgun, ọgbẹni Ilesanmi yoo fi iwe ẹhonu sọwọ si ileeṣẹ ijọba eleyi ti awọn eeyan fọwọsi lati le daabo bo awọn to n ṣe iwaasu nita gbangba.
Ileeṣẹ ọlọpaa ti gba pe awọn yoo san  owo gba ma binu  ẹgbaa le ẹdẹgbẹta poun fun un tori bi wọn ti ṣe fipa gba bibeli rẹ ti wọn si doju ti .
Ọgbẹni Ilesanmi ni ''Inu mi dun pe ọlọpaa mọ pe awọ́n ko lẹtọ lati mumi tori pe mo n fi bibeli ṣe iwaasu.''
O tẹsiwaju pe ''Iṣẹlẹ naa jami laya nigba ti wọn mu mi, ṣugbọn ko ko irẹwẹsi ọkan bami lati pada lọ Southgate lọ ma ṣe iwaasu nitagbangba.''
Emirate Cup: Lyon figbájú olóòyì méjì gba Emirate Cup lọ́wọ́ Arsenal
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ẹpa o boro mọ fun Arsenal
Ẹkun ohun oṣe ni Arsenal fi pari ifẹsẹwọnsẹ oloresọrẹ wọn ninu idije Emirate Cup ti wọn fi sọri wọn.
Ẹgbẹ agbabọọlu Lyon ti ilu Faranse lo ṣe iya fun Arsenal, ti wọn si gbe ife Emirate Cup naa mọ Arsenal lara niwaju awọn alatilẹyin Gunners.
Moussa Dembele, atamatase ti Lyon gbe wọlẹ ni o da bira pẹlu goolu meji ni abala ikeji idije naa.
Pierre Emerick Aubameyang ti saaju gba bọọlu sawọn fun Arsenal ni abala ikini ṣugbọn eleyi ko ja mọ nkankan nigba ti ifẹsẹwọnsẹ naa yoo fi wa si opin.
Ni bayi, ireti Arsenal lati fi ife ẹyẹ yi bẹrẹ saa bọọlu tuntun yi ti ja si asan ti awọn alatilẹyin ẹgbẹ naa kan si ti n faraya loju opo Twitter.
Àwọn ìròyìn míì tí ẹ tún le nífẹ́ sí:
Àwọn ọmọ Nàìjíríà kan fẹ́ kí ilé ẹjọ́ ó fagilé orúkọ Buhari gẹ́gẹ́ bi olùdíje APC
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Àwọn ọmọ Nàìjíríà kan fẹ́ kí ilé ẹjọ́ ó fagilé orúkọ Buhari gẹ́gẹ́ bi olùdíje APC
Awọn ọmọ orilẹ-ede Naijiria mẹta kan ti pe ẹjọ tako Aarẹ Muhammadu Buhari nile ẹjọ to gaju ni Naijiria.
Wọn ni pe ko ni iwe ẹri to daju lati fi du ipo aarẹ ninu eto idibo ọdun 2019.
Awọn olupẹjọ, Kalu Kalu, Labaran Ismail ati Hassy Kyari El-Keris tọ ile ẹjọ lọ pe ko fagile Buhari gẹgẹ bi oludije nitori iwe ẹri ileewe to lọ.
Awọn olupẹjọ sọ pe Buhari parọ ninu ibura to kọ silẹ ninu iwe to fun ajọ eleto idibo INEC lasiko to fi erongba rẹ lati dupo han.
Ṣaaju ni ile ẹjọ giga ijọba apapọ nilu Abuja, ati ile ẹjọ kotẹmilọrun ti da ẹjọ wọn nu ninu idajọ kan lọjọ kejila, oṣu Keje, ọdun 2019.
Ile ẹjọ ni pe oun ko le gbọ ẹjọ naa nitori pe o ti le ni ọjọ mẹrinla ti ofin la kalẹ lẹyin ti Buhari gbe igbesẹ naa ki wọn o to o gbe ẹjọ wa sile ẹjọ.
Eyi lo mu ki wọn o gbe ẹjọ lọ siwaju ile ẹjọ to gaju pe ko fagile idajọ ile ẹjọ kotẹmilọrun, ko si gbọ ẹjọ naa lọtun.
Lara awọn nkan ti wọn n fẹ ki ile ẹjọ o ṣe ni pe ko dajọ pe Buhari ko sọ otitọ fun ajọ INEC nipa iwe ẹri ileewe to lọ.
Bakan naa ni wọn fẹ ki ile ẹjọ o paṣẹ fun ajọ INEC lati yọ orukọ Buhari kuro gẹgẹ bi oludije ẹgbẹ oṣelu All Progressives Congress, APC.
Lagos Building Collapse: Ilé alájà méjì wó lu ọmọ mẹ́rin ni Bariga
Ile ọhun da wo lasiko ti atunṣe fẹ bẹrẹ
Ilé to wa ni ojule ọgbọn ni adugbo Ọsọsa ni Bariga ni ipinlẹ Eko lo wo ti awọn ọmọ mẹrin si farapa ninu ẹ.
Akọroyin BBC to wa nibẹ n ṣalalye nsiyi pe, onile naa ti bẹrẹ igbeṣẹ lati tun ile naa ṣe ki o too da wo lulẹ.
Okan lara awọn ayalegbe to n gbe nile naa, ọgbẹni Kabiru ni opo ile naa kan lo kọkọ da wo ni ijẹta ni eyi ti onile fẹ tun ṣe.
Ibeji ati Idowu wọn di ero ilé iwosan ni Bariga
Ogbẹni Kabiru ni oun ti fẹ ko kuro ninu ile naa tẹlẹ nitori pe ojoojumọ ni ibi kọọkan n ya ti iho n han nibẹ ti ile naa si n sọ òkò ifura.
Ajọ to n ri si iṣẹlẹ pajawiri ni ipinlẹ Eko, LASEMA ni nkan bii aago mẹsan an abọ alẹ ana (ọjọ Aiku) ni awọn gba ìpè sori aago wọn lori iṣẹlẹ naa.
Nọmba ti LASEMA fi sita lati maa pe fun ifitonileti iṣẹlẹ pajawiri ni 767 / 112.
LASEMA ni kete ti wọn de ibi iṣẹlẹ naa ni wọn rii pe ile alaja meji ọhun lo ti wo de ilaji to si wo lu awọn ọmọ mẹrin ninu rẹ.
Ẹni to ni ile iwe sare lati doola awọn akẹkọ ni ile wolu
Ibeji obinrin ati Idowu wọn ọkunrin lo wa ninu ilé alaja meji naa ati ọmọkunrin miran ni eyi ti wọn ti ko wọn lọ sile iwosan lẹyin ifarapa wọn.
ọpọ ile lo ti di ẹgẹrẹmiti ni ipinlẹ Eko ti ijọba si ti fẹ ṣe ayẹwo lori wọn
Iṣẹ iwadii ti wọn ṣe lori ile to wo naa fihan pe ile naa ti la ni awọn ibi kan tẹlẹ ni eyi ti ọgbẹni Ayilara to nii ko tete ṣatunṣe to yẹ si.
Onimọ nipa ile kikọ sọwipe ijọba nilo awọn onimọ nipa owo ori ile
Wọn ti ko awọn ti wọn farapa lọ si ile iwosan ijọba ni Gbagada nipinlẹ Eko.
Number ti LASEMA fi sita lati maa pe fun ifitonileti iṣẹlẹ pajawiri ni 767 / 112.
Awọn oṣiṣẹ eleto aabo ti di ọna si ile alaja meji na pa ki o ma lọ wo tan lu awọn eniyan lẹyin ti wọn ko gbogbo ayalegbe kuro.
ọpọ ile lo ti di ẹgẹrẹmiti ni ipinlẹ Eko ti ijọba si ti fẹ ṣe ayẹwo lori wọn
Omọwe Olufẹmi Oke- Osanyintolu to jẹ adari agba ajọ LASEMA ti parọwa fun baba onile naa lati jẹ ki ajọ LABSCA to n yẹ ile wo nipinlẹ Eko ṣiṣẹ wọn bi o ti yẹ.
Lagos Building Collapse: Ilé alájà méjì wó lu ọmọ mẹ́rin ni Bariga
Ọpọlọpọ ile ni awọn ijọba ti ya sọtọ lati wo ni ipinlẹ Eko bayii.
LASEMA n ke gbajare lori awọn ile ti o ti daagun
Igba akọkọ kọ ni yii ti ile a da wo nipinlẹ Eko, koda, ọkan ṣẹlẹ loṣu kéfa ọdun 2019 ni adugbo Mafoluku lasiko ti wọn n tun un ṣe lọwọ.
Shiite: Ilé ẹjọ́ gíga Kaduna sún ìgbẹ́jọ́ adarí Shiite síwájú
Ijoko ile ẹjọ giga ni Kaduna ko waye lonii lori gbigbọ ẹjọ lati gba oniduro adari ẹgbẹ Shiite, El-Zakzakky.
Nibayii ọjọ karun un, oṣu kẹjọ ni igbẹjọ naa yoo waye nitori El-Zakzakky funrarẹ ati iyawo rẹ ko fara han nile ẹjọ bi o tilẹ jẹ wi pe agbẹjọro wọn, Femi Falana sọ eredi pe tori ailera ni.
Shiite: Ẹ̀mí àti ara wa kọ ohun tí ìjọba ń ṣe sìwa láti 2015
Ọrọ aabo ti peleke sii ni olu ilu ipinlẹ naa ṣaaju igbẹjọ naa ninu eyi to si ti mu ẹmi ọlọpaa kan ati akọroyin lọ.
Lori ẹsun mẹjọ ọtọọtọ ni adari ẹgbẹ Shiite El-Zakzaky ati iyawo rẹ, Zeenat fi n koju ile ẹjọ eyi ti ijọba ipinlẹ Kaduna fi kan wọn.
Awọn ẹsun naa ni i ṣe pẹlu pipaniyan lọna aitọ, ipejọpọ ti ko bofin mu ati dida omi alaafia ilu ru ati bẹẹ bẹẹ lọ.
Lati inu ọdun 2015 ni wọn ti fi El-Zakzaky satimọle.
Awọn Iroyin mii ti ẹ le nifẹ si
Ministerial Screening: Aregbesola, Fashola àti Gbemi Saraki wí tẹnu wọn
Rauf Aregbesola
Gomina ana nipinlẹ Osun Ọgbẹni Rauf arẹgbẹsola ni inu oun dun pe ẹni to gba ipo lẹyin oun ṣi n san gbese ti oun jẹ kalẹ.
Lasiko ayẹwo to waye niwaju ile aṣofin agba fawọn ti aarẹ Buhari yan sipo Minisita ni o ti lede ọrọ yi ni ọjọ Aje.
Nibi ayẹwo Minisita niwaju ile asofin Naijiria naa ohun ati awọn miiran bii Babatunde Fashola ati Gbemisola Saraki yọju siwaju ile lati wi tẹnu wọn.
Àwọn oṣiṣẹ feyinti ni Osun ṣé iwọde
Rauf Arẹgbẹsọla ti o jẹ Gomina ipinlẹ Osun nigba kan ri ni wọn bo ti ṣe koju ipenija airi owo oṣu awọn oṣiṣẹ san ti o si fi gbese kalẹ nigba ti yoo fi kuro lori alefa.
Awọn aṣofin bii meji kan beere ọrọ yii ti o si dahun pe ''awọn to n sọrọ nipa owo osu nipinlẹ Osun lasiko toun wa lori alefa  kan n wi eleyi ti o wu wọn ni.'
Aregbesola ni ijọba oun na owo pupo lori pipese oun amayederun lo faa ti sisan owo oṣu fi mẹhẹ fawọn oṣisẹ.
Shiite: Ẹ̀mí àti ara wa kọ ohun tí ìjọba ń ṣe sìwa láti 2015
Lẹyin atotonu awọn aṣofin si gba Aregbesola laaye ki o tẹriba niwaju ile ko si maa lọ.
Iru aaye tẹriba ko maa lọ yi naa ni awọn aṣofin fi gba Gbemi Saraki to jẹ minisisita lati ipinlẹ Kwara.
Saraki to ti jẹ Ṣẹneto tẹlẹ ri to si tun jẹ obinrin ko tilẹ dahun ibeere kankan ti ile fi gba a laaye lati maa lọ.
Tá láwọn ọba aládé àti olóṣèlú tí EFCC n wà lórí owó ìrànwọ́ N2bn ní Kwara?
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Awọn olokoowo alabọde lo yẹ ki wọn pin owo yi fun ṣugbọn EFCC ni idameji owo naa bọsi owo awọn oloṣelu ati ọba alade kan
Omi ti tẹyin wọ igbin lẹnu nipinlẹ Kwara nibi ti  ọwọ ajọ to n gbogun ti iwa jẹgudujẹra EFCC ti tẹ oludari ile ise to n risi awọn olowo alabọde nibẹ,Segun Soewu lori ẹsun ajẹbanu.
Biliọnu meji naira ni ajọ naa ni oludari yi ati awọn miran lu ni ponpo.
Loju opo EFCC  lori Facebook  ni wọn fi iroyin yi si ninu atẹjade kan.
Gẹgẹ bi atẹjade naa ti ṣe sọ, oludari ileeṣẹ naa ko tẹle ilana to yẹ nipa pipin owo to yẹ ki wọn fun awọn oniṣowo kaakiri ijọba ibilẹ mẹẹdogun ipinlẹ Kwara.
EFCC sọ pe Soewu to wa ni ahamọ lọdọ awọn pin owo naa fawọn oloṣelu ati awọn Ọba alade kan.
Koda ọba alade kan gba miliọnu méjídínlọ́gọ́rin naira ninu owo naa ti ko si da pada,
EFCC ni ''oba alade yi gba owo iranwọ  naa lorukọ ileeṣẹ rẹ Yafy International Ventures Limited ti ko si tẹlẹ ilana to yẹ''
Ẹwẹ EFCC tun darukọ awọn oludari ileifowopamọ kan pe wọn mọ nipa apapin owo yi.
Titi di bi a ti ṣe n ko iroyin yi jọ.EFCC ko darukọ ọba alade ti  o bawọn pin ninu owo yi amọ ajọ naa ninu ọrọ oju opo wọn ni oludari ileeṣẹ to n risi awọn owo alabọde tawọn mu ti n wi tẹnu rẹ lọdọ awọn.
Lagos- Ibadan Express: Kò sí ìfòyà lásìkò ọdún iléyá
Kò sí ìfòyà lásìkò ọdún iléyá ní òpópónà Marosẹ Eko si Ibadan
Ìjọba àpapọ̀ ti fi ọkàn àwọn ará ìlú balẹ̀ pàápàá jùlọ àwọn to ń lo ọ̀pópónà márosẹ Lagos -Ibadan wi pé àwọn yóò fi ààyè silẹ̀ fún ìrìnnà ọkọ̀ ju ti tẹ́lẹ̀ lọ.
Wọn ni ayẹyẹ ọdún iléya tó ń bọ̀ àti ti ìpàdé àpapọ ìjọ RCCG tí yóò wáyé ní àṣẹ́ ṣe lọ pé kí kọngila tó ń siṣẹ́ ọ̀nà náà dẹwọ́ gbogbo àwọn ojú pópó ti wọ́n dí.
Ìgbésẹ̀ yìí kò ṣeyin bí àwọn ọmọ Nàìjíríà ṣe bẹnu ẹ̀tẹ́ lu ìpínnú àwọn kọngila láti dí àpá ibikan pa fún iṣẹ́ àkanse lóju pópó náà bẹ̀rẹ̀ láti ọjọ kẹta, oṣù kẹjọ ọdun.
Alákoso iṣẹ́ àti ìrìnnà ní ìpínlẹ̀ Eko, ọgbẹ́ni Adedamola Kuti sàlàyé pé pẹ̀lú ìwòye àwọn lóri bí ìgbòkègbodò ọkọ̀ yóò ṣe pọ̀ tó, ó di dandan kí ẹdínkù bá ìṣẹ́ tí wọ́n yóò ṣe ni àsìkò náà.
Adedamola Kúti ní bí i kìlómítà kan ó lé ọwọ́ mẹ́rin tí wọ́n fẹ ṣe àtúnse rẹ̀ láti Berger si afára Kara bẹ̀rẹ̀ láti ọjọ́ Satide.
Naomi Adamu se àkọsílẹ̀ ìgbé ayé rẹ̀ ni àgọ́ Boko Haram
Oríṣun àwòrán, AFP/BOKO HARAM
Mo ní ìwé àkọsílẹ̀ ìgbé ayé mi ni àgọ́ Boko Haram- Naomi Adamu
Ó pé ọdún mẹ́wàá gbáko tí ọ̀gá àwọn alakatakiti ẹsin Islam Boko Haram ti gbogbo ènìyàn mọ̀ si Mohammed Yusuf kú
Yusuf kú nígbà ti ó wà ní àhámọ́ ọlọ́pàá ní ìlú Maiduguri, sùgbọ̀n láti ìgbà tí ìṣẹ̀lẹ̀ yìí ti ṣẹ́ ní omi àláfíà ìhà árèwá Nàìjíríà àti orílẹ̀-èdè Nàìjíríà lápapọ ti dàrú.
Ọ̀pọ̀ òjò ti rọ̀ ti ilẹ̀ si ti fi mu, ọ̀pọ̀ ẹ̀mi dúkìá àti ilé ló ti bá àwọn ìṣẹ̀lẹ̀ tí o wáyé lẹ́yìn náà lọ.
Ní ọ̀pọ̀ ìgbà ní ìjínígbe àwọn ọmọ ilé ìwé tí ilé ìwé Chibok sì jẹ ọ̀kan lára wọn ti ero n sọrọ lori rẹ.
Iya Adura Esther Ajayi sọ àṣírí owó rẹ̀ tó fi ń ṣàánú
BBC ṣe ìfọ̀rọ̀wánilẹ̀núwò fún Naomi Adamu tó jẹ́ ọkan nínú àwọn ọmọ Chibok tí Boko Haram jígbé ní ọdún 2014 tó si lo ọdún mẹ́ta gbáko ni àhámọ wọn.
Naomi sàlàyé pé nínú àhámọ Boko Haram, wọ́n pin ìwé kíkà fún àwọn láti máa fi kọ ẹkọ́ ìmọ̀ Kuran.
Ẹ̀wẹ̀, ọ̀pọ̀ àwọn ọmọ yìí ń fi àwọn ìwé náà ṣe àkọsílẹ̀ àwọn ǹkan ti ó ń sẹlẹ̀ àti àṣírí tó ń tú sí wọn lọ́wọ́ nínú àhámọ́ Boko Haram.
Nígbà ti àwọn Boko Haram ri ǹkan ti àwọn ọmọ náà ń ṣe, wọn gbà á, wọ́n sì dáná sún awọn iwe naa.
Sùgbọ́n ní ti Naomi àti olólùfẹ́ rẹ̀ tí wọ́n maa ń wà papọ, Sarah Samuel tó jẹ ẹni ogún ọdún gbìyànjú láti fi ìwé tiwọn pamọ àti ìwé àwọn ọmọbinrin mẹ́ta míràn tí wọ́n máa ń kọ àwọn ìrírí wọ́n sí.
Ìwé àkọsílẹ̀ tí Naomi pamọ lásìkò tó wà ní àhámọ Boko Haram nínú ìgbó Sambisa
Èdè Oyinbo àti Hausa ní wọ́n fi kọ ìwé àkọsílẹ̀ wọn yìí, bó tilẹ̀ jẹ́ pé kò sí àkọsílẹ̀ àwọn ọjọ ìṣẹ̀lẹ̀ sùgbọ́n ó dàbí ẹni pé àkọsílẹ̀ náà wáyé ni oṣù àkọ́kọ́ tí wọ́n wọ àhámọ Boko Haram
Nkan mẹ́wàá (10) tí wọ́n ṣe àkọsílẹ̀ rẹ̀
1. Kìí ṣe àwọn ọmọ akẹ́kọ̀ọ́ ni Boko Haram fẹ́ jí gbé
Ìjínigbé àwọn akẹ́kọ̀ọ́ Chibok tó wáye ní ọjọ́ kẹrìnlá, oṣù kẹrin, ọdún 2014 kìí ṣe láti ji àwọn ọmọbinrin Chibok gbe bíkò ṣe láti jí ẹ̀rọ tí wọ́n fí ń mọ búlọkù, ìṣẹ́ ilé kíkọ to ń lọ witiwiti nínú ọgbà ilé ẹkọ́ náà ní bi ọsẹ̀ díẹ̀ sí ìgbà náà.
Nínú ìwé ti Naomi kọ, ó sàlàyé pé lẹ̀yìn gbọnmisi-omi-o-tó láàrin wọn ni wọ́n pa ọkan pọ láti ji àwọn akẹ́kọ̀ọ́, ó fi kún un pé lẹ́yìn ti àwọn dé ibẹ̀ wọ́n kò mọ ǹkan ti wọ́n ó fiwọ́n ṣe kóda wọ́n gbèrò láti sun wọ́n níná ni nibẹrẹ.
2. Ìtàn nípa bí wọ́n ṣe fẹ́ sá kúrò
Bí wọ́n ṣe ju ọ̀pọ̀ sínú ọkọ ti wọ́n gbé wá ní wọn ni ki àwọn kan máa fí ọwọ́ kọ́ àra wọn lọ́rùn.
Kí wọ́n maa rin pọ̀ pẹ̀lú ìbọ́n lẹ́yìn wọ́n ti wọ́n si fi ẹsẹ̀ rín ibi tó jìnnà.
Àkọsílẹ̀ yìí jẹ́ ti Naomi Adam àti Sarah Samuel, Rhoda Peter, Sarah Job àti Margaret ti wọn jẹ mẹ́rin nínú awọ́n tí orí kọ́ yọ̀ nínú oṣù karun un, ọdún 2017.
Sarah Samuel gbà láti fẹ́ ọ̀kan nínú wan ó sì kọ̀ láti pada wále
Iwe àkọsílẹ̀ Naomi ní èyí nibi tí ó kọ gbogbo ìrírí rẹ̀ sí
Nígbà ti wọ́n fẹ́ sálọ, ọkan nínú wọ́n ké gbàjare sí àwọn Boko Haram ní wọ́n fí wọ́n mú u pada.
3. Gbogbo Ọgbọ́n àlùmọ̀kúrọ́yin wọ́n
Oníruurú àwọn ọgbọ́n tí wọ́n maa n lo lati fi dẹ́rùba àwọn ọmọ tó wà ni àhámọ ní pe wọn tí gbé ọpọ ninu àwọn obi wọn náà.
Ìgbà míràn ẹ̀wẹ̀, wọ́n a gbé gálọọnù jáde bi pé èpo ló wà nínú rẹ̀, wọ́n a wá sọ fún wa pé tí ako ba gba Islam àwọn ó dáná sún wa, ìdí nìyí ti àwọ́n míràn fi gba ẹ̀sìn.
4. Ìnú ń bí Boko Haram pé wọ́n ń fi ẹsùn ìfípabánilò kàn wọ́n
Àwọn ọmọbinrin ti wọ́n fi ọ̀rọ̀ wá lẹ̀nu wò, sàlàyé pé wọ́n ó fi ipá bá àwọn lò tàbí fẹ́ àwọn ni túlàsì, sùgbọ́n nígbà míràn wọn máa n ba àwọn sọ ọ̀rọ ìgbéyàwó
àwọn ọmọbinrin náà fi ìwé náà pamọ
Nínú àkọsilẹ̀ wọ́n, wọn ni Boko Haram ń binu lori ìròyin pé àwọn ń fipa ba àwọn náà lajọṣepọ̀,
Bakan naa ni wọn máà ń wa wàásù sí àwọn ni alaalẹ́ ki awọn le kọ nipa Jihad ati ẹsin Islam sii.
5. O gbọdọ̀ wọ́ Hijab kí ẹmi okunkun ma ba a dé bá ọ
Mo ní ìwé àkọsílẹ̀ ìgbé ayé mi ni àgọ́ Boko Haram- Naomi Adamu
Wọ́n fún àwọn náà ni Hijab nítori wọ́n kò fẹ́ máá ri àra wọ́n, bákan náà ni wọ́n máa n ka kurani fún wọ́n nigbogbo igba.
6. Wọ́n máa n bawa sọ̀rọ̀ nípa ìgbéyàwó.
Ni àsìkò ti wọ́n ba ti ba wa sọ̀rọ̀ ìgbéyàwó wọn a fún wa ni àsìkò láti ronu sii sùgbọ́n wọn kìí fẹ́ ẹni ti kò ba gba Islam.
O gbọdọ gba Islam ni akata Boko Haram ki wọn to le fẹ ọ ni iyawo.
Ẹrú si ni irú ẹni ti ko ba gba Islam jẹ fún àwọn to ba gbà láti fẹ́ àwọn Boko Haram.
Naomi sàlàye pé ẹni ti kò ba ti fẹ wọ́n yóò fọsọ, pọnmi, yóò si maa bọ̀wọ̀ fún ìyàwó wọ́n
Oríṣun àwòrán, AFP
"ipolongo ""Bring back our girls"""
7. Àwọn ará ìlú ń da àwọn to bọ́yọ lọ́wọ́ Boko Haram padà si àgọ́ wọ́n
Pẹ̀lú bí gbogbo àyé ṣe gbe ìfẹhonu han lóri ìjínigbé àwọn ọmọ Chibok síbẹ̀ àwọn kan o bikítà ti wọ́n sì ń dá àwọn tí wọ́n sá kúrò ni àhámọ Boko Haram pada si bẹ̀.
Kò si ounjẹ gidi tàbi omí, kò sí ilé.
Ní ọ̀pọ̀ ìgbà tí a ba sá kúrò ni àhámọ ti àwọn ará ìlú sì gbọ́ pé ahamọ Boko Haram ni a ti wa, wọ́n fà wá le wọ́n lọ́wọ́ pada, nítori wọn ò fẹ́ ni ǹkan ṣe pẹ̀lú wọn.
8. Wọ́n ń fipa múwa láti dí Musulumi
Ní ọ̀pọ̀ ìgbà ni wọn máa ń sọ fún wa pé tí a ba ti gbà láti di Musulumi ní àwọn yóò dá wa padà sí ọ̀dọ̀ àwọn òbí wa.
Wọn maa n sọ pe ki a ṣe musulumi dandan nitori pe ẹni tó ba ti kọ̀ lati di musulumi kò ni kúro lọ́dò àwọn.
Ati pe awọn ko ni tu ẹni ti wọn ka si keferi ti ko tii gba Islam silẹ.
Oríṣun àwòrán, AFP/BOKO HARAM
Mo ní ìwé àkọsílẹ̀ ìgbé ayé mi ni àgọ́ Boko Haram- Naomi Adamu
9. Wọ́n fẹ́ràn láti máa fí fọ́nran síta
Àwọn Boko Haram maá ń sáabà sẹ fídíò nígbà míran kété ti wọ́n ba ti wo ìròyìn tán.
Wọ́n a bẹ̀rẹ̀ si ni pe wa ní ẹyọ kọọkan láti sọ orukọ wa, wọ́n a fẹ ki a jẹ ki ìjọba àti àwọn obi wá mọ pe àwọn ò fi ìyà jẹ wá.
Ati pe a ṣi wa laye ni ahamọ wọn
10. Awọn Boko Haram maa ń wo ìròyìn púpọ̀
Àwọn Boko haram maa ń gbọ iroyin gbogbo nkan to n ṣẹlẹ ni agbaye.
Eyi to ba kan wọn lo maa n jẹ ki wọn gbe ọ̀pọ̀ fídíò sita fi tako iroyin nipa wọn ní kété ti wọ́n ba ti wo ìròyìn tán.
Ní ọjọ kan bí wọ́n se wo ìròyìn BBC Hausa tán ní wọ́n ba pè wá ni ọkọ̀ọkan àwọn míràn kúnlẹ̀ nígbà ti àwọn kan dúró, wọ́n ni ki a maa ka kùrán sita.
Kíní ó sẹ̀lẹ̀ sí àkọwé yìí
Naomi àti àwọn mẹ́ta tó ku tó fi mọ Rhoda Peter, Sarah Job àti Magaret Yama ní wọ́n tú sílẹ̀ ní inu oṣù Karun un, ọdún 2017
Ìjọba si rán wọn lọ fásitì Yola nínú oṣù kẹsan an, ọdun 2017
Naomi sàlàyé pé òun kọ àkọsílẹ̀ nítori pé òun fẹ ki ọmọ àti àwọn òbi oun ríí.
Shiite: Ẹ̀mí àti ara wa kọ ohun tí ìjọba ń ṣe sìwa láti 2015
Boko Haram: Ṣé lóòótọ́ ní olórí ẹgbẹ́ agbẹ́sùnmọ̀mí dágbéré fáyé
Oríṣun àwòrán, Eonsintelligence/Twitter
Bi iroyin to tun gbode lojumọ Ọjọbọ lori ayelujara ba fi le ja si ootọ, o ṣeeṣe ki Naijiria ti rẹyin olori ikọ Boko Haram Abubakar Shekau.
Tabi ko si jẹ wi pe akutunku Shekau miran lo tun ti ṣẹlẹ, ti a o si tun pada gbọ wi pe ko tii ku.
Idi taa fi sọ bẹẹ ni pe ọpọ igba la ti gbọ lati ẹnu awọn ikọ ọmọ ogun Naijiria ati ijọba pe Abubakar Shekau ti ku, ṣugbọn ti ko pada ri bẹẹ.
Iroyin ori ayelujara kan lo n ja rain laarọ ọjọbọ pe ikọ ọmọogun ISWAP ya wọ igbo Sambisa ti Shekau, tii se asaaju ikọ Boko Haram wa, ti wọn si se oun ati awọn agbesunmọmi ẹyin rẹ basabasa.
Oríṣun àwòrán, @eonsintelligenc
Iroyin naa ni lasiko laasigbo ọhun ni Abubakar Shekau dagbere faye.
Iroyin eleyi ta ṣẹṣẹ gbọ yii kii ṣe eleyi ta le fi ẹsẹ rẹ rinlẹ nitori ileeṣẹ ọmọ Ogun Naijiria tabi awọn ikọ ISWAP, ti wọn lo ṣeku pa Shekau ko ti jade sita pe lootọ ni.
Bawo ni Abubakar Shekau ṣe ku lọtẹ yi?
Lọjọru la gbọ pe awọn ọmọ ikọ ISWAP to pinya lati ara ikọ Boko Haram, doju ija kọ ikọ Abubakar Shekau ni inu igbo Sambissa.
Ija yii la gbọ pe o gbona gidi gan, to si ṣe wi pe awọn ISWAP bẹrẹ si ni kapa ikọ Shekau.
Ni igba ti yoo fi to alẹ Ọjọru, alukoro ileeṣẹ ologun Naijiria tẹlẹ ri, Ajagunfẹyinti Sani Kukasheka ti kede ohun to jọ iku Shekau loju opoTwitter.
Oríṣun àwòrán, @skusman
Pupọ eeyan to ka iroyin naa, ni ko gba gbọ, ti wọn si sọ wi pe o ṣeeṣe ki Shekau tun jinde pada, gẹgẹ bo se maa n se.
Oríṣun àwòrán, @mayorlistik
Oríṣun àwòrán, @generalzango
Ẹwẹ, akọroyin kan, Ahmad Salkida to ṣọ pe oun mọ nipa ikọ agbesunmọmi naa ti sọ ohun to farapẹ pe iroyin yii le jẹ ootọ.
Ninu ọrọ tiẹ, Salkida ni opin le ti de ba bi eeyan kan ṣe n fi ara ni ọpọ eeyan.
Ko darukọ Shekau bẹẹ si ni ko sọ boya o ku tabi o wa laaye.
Eyi ti a ri aridaju ninu gbogbo ọrọ yii ni pe ijọba Naijiria tabi awọn ikọ agbesunmọmi bi ISWAP tabi Boko Haram ko ti jade sita lati fidi iroyin naa mulẹ.
Oríṣun àwòrán, @A_Salkida
Lọdun 2002 ni Mohammed Yusuf da Boko Haram silẹ lati tako ẹkọ nilana oloyinbo nibi ti aye laju si loni.
Bẹẹ, ọpọ igbesẹ lo maa n bẹrẹ pẹlu erongba rere ṣugbọn ti igbẹyin rẹ le ma dara bii ti Boko Haram to ti di igi ose ti ipa ko fẹ ka mọ.
Yusuf lo pilẹ ẹgbẹ naa amọ lẹyin iku rẹ lọwọ awọn ọlọpaa lọdun 2009 ni Abubakar Shekau kede ara rẹ lẹyin ọdun meji iku Yusuf gẹgẹ bi olori Boko Haram.
Kete ti awọn alakatakiti ẹsin Islam Boko Haram kede orilẹ-ede ara wọn ni ero awọn eniyan nipa wọn yipada.
Ariwo Shekau ku ti ko tun ku mọ to tun jinde ti waye ni ọpọ igba kaakiri Naijiria.
Titi di bi a ṣe n sọrọ yii, ko si ẹni to le fọwọ sọya boya o ku tabi ko ku.
Shiite: Ẹ̀mí àti ara wa kọ ohun tí ìjọba ń ṣe sìwa láti 2015
Ta ni Abubakar Shekau ti Boko Haram?
Omo ipinlẹ Yobe ni ariwa ila oorun Naijiria ni Abubakar Shekau jẹ.
Omo iran Kanuri ati Elẹsin musulumi ni Abubakar.
Oun ni igbakeji ẹgbẹ Boko Haram ti Mohammed Yusuf da silẹ lati tako imọ nipa iwe kika lọna igbalode.
O di olori awọn agbesunmọmi Boko Haram lẹyin iku ọga rẹ lati ọwọ awọn agbofinro lọdun 2009.
Opọ ẹmi ati dukia lo ti ba iwa ipa ati igbesunmọmi awọn Boko Haram rin ni Naijiria ni eyi ti ọpọ si ti di alarinkiri ati aṣatipo lagbaye.
Boko Haram yóò dá Leah sílé
Ọpọlọpọ igba ni wọn ti kede pe ijọba Naijiria ti rẹyin Abubakar Shekau lati ọdun 2009 ti Naijiria ti n ja ogun ikọlu awọn alakatakiti ẹsin Islam naa.
Igba akọkọ
Igba akọkọ ti wọn kede iku Shekau ni lọdun 2009.
Nigba ti awọn ọmọ ogun Naijira dawọpọ kọlu ikọ agbesunmọmi Boko Haram.
Lẹyin ti wọn pa eniyan to le ni ọgọrun un lasiko naa ni awọn kan tun ni irọ nipe Shekau ku lara wọn.
Ko pẹ lẹyin ikede oku rẹ yii lo tun sọrọ jade ninu fidio kan lori ayelujara to fi tun kede ara rẹ gẹgẹ bii ọga agba pata fun awọn Boko Haram.
Lọdun 2013 ni awọn ọmọ ogun ilẹ Naijiria tun kede pe awọn ti ṣe Abubakar Shekau leṣe lasiko ti wọn kọlu Boko Haram ni ariwa Naijiria.
Wọn ni ninu igbo Sambisa ni awọn ti kọlu Shekau ti wọn si ti ṣee lọṣẹ to kọja bẹẹ.
Nigba ti o di oṣu kẹsan an ọdun naa lẹyin ti ọpọ ti fi idunnu han pe wọn rẹyin odì ni fidio kan ba tun jade ti Shekau ti ni laaye ni oun ṣi wa.
Lọdun 2014 ni iroyin tun jade pe awọn ọmọ ogun ilẹ Naijira ti gbẹmi olori awọn oniṣẹ ibi Boko Haram.
Wọn ni ninu igbo Kodunga lawọn ti paa nigba ti awọn ọmọ ogun Naijiria gbena woju awọn agbesunmmi naa.
Ojo kejila, oṣu kẹsan an si ọjọ kẹrinla, oṣu ni wọn fi jọ n ja ijajangbara naa.
Awọn ọmọ ogun ilẹ Cameroon naa sọ pe ootọ ni iṣẹlẹ yii.
Koda wọn ko awọn aworan kan sita to ṣafihan oku Shekau.
Ko pẹ lẹyin eyi ni Shekau gbe fidio miran sita to fi yẹyẹ awọn ọmọ ogun orilẹ-ede mejeeji pe oun kú tì!
Lọdun 2015 ni aarẹ orilẹ-ede Chad, Idriss Deby sọ pe o ti tan fawọn alakatakiti ẹsin Islam Boko Haram.
O sọ eyi nigba ti ọrọ Boko Haram ti n gbẹbọ lọwọ Orilẹ-ede Naijiria, Chad, Niger ati Cameroon.
Idriss ni olori miran ti gbaṣẹ lọwọ Shekau nitori opin ti de baa.
Ara ọtọ ni Abubakar fi sọ pe oun ṣi wa laye lọtẹ yii nipa lilo fonaran olohun fi sọrọ pe oun ni oun ṣi n dari Boko Haram o.
O ni laiku ẹgiri, ẹnikan kii fawọ rẹ ran gbẹdu ni ọrọ oun o.
Awọn ọmọ ogun ofurufu Naijiria lo ṣe ikede ti ọtẹ yii.
Lọdun 2016 ni wọn ni ọfa ikọlu wọn ti ba Abubakar nibi to lapẹrẹ ati pe oku ni ẹlẹja n taa lo maa pari ikọlu ọhun.
Won ni koda awọn pa awọn olori boko Haram miran sii labule Taye.
Wọn ni eyi ṣẹlẹ lasiko ti wọn sọ ado oloro lati oju ofurufu lọjọ kọkansinlogun, oṣu kẹsan an ọdun 2016.
Ni Shekau naa ba gba ori You tube ayelujara lọ lati ṣe afihan fidio pe lakọ ni oun wa.
Down Syndrome Skill centre: Wo bí ọmọ tí ọpọlọ wọn kù díẹ̀ ṣe ń kọ́ iṣẹ́ agẹrun
Iroyin to n lọ lasiko yii ni pe awọn Boko Haram ti pin si ẹya meji pẹlu olori ọtọọtọ.
O ti le ni ọdun mẹwaa ti wọn ti n ṣọṣẹ ni ariwa ila oorun Naijiria atawọn orilẹ-ede miran.
Wọn ni awọn ẹya kan ti lọ darapọ mọ Islamic State of West Africa Province.
Diẹ lara iṣẹ ijinigbe ti wọn ti se ni jiji awọn ọmọbinrin Chibok gbe lọdun 2014 ati ti Dapchi lọdun 2018.
Leah Sharibu ni wọn ṣi gba pe o wa ni akata wọn.
Titi di isinyi ni ijọba Naijiria labẹ akoso aarẹ Buhari ṣi n kede pe awọn ti bori Boko Haram.
Wọn ni iwọnba perete ikọlu wọn lasan lo kan n ṣẹlẹ lasiko yii.
Mohammed Yusuf: Àwọn ohùn tó yẹ kí o mọ nípa olùdásílẹ̀ Boko Haram
Mohammed Yusuf: Àwọn ohùn tó yẹ kí o mọ nípa olùdásílẹ̀ Boko Haram
Bi onirese ba ni oun ko fingba mọ eyi to ti fin silẹ ko ni parun laelae lọrọ Mohammed Yusuf to jẹ oludisilẹ ẹgbẹ agbesunmọmi Boko Haram.
Ni ọdun 2002 lo da ẹgbẹ Ahlu Sunna Waljama Wal-Jihad silẹ nilu Maiduguri ti o ti n ṣe iwaasu eleyi to pada wa kale kako ni ipinlẹ naa.
Awọn to mọ Mohammed Yusuf ni o jẹ ẹni kan ti ọrọ da lẹnu rẹ ti pupọ awọn eeyan a si ma tuyaya lati gbọ waasi rẹ.
Abule Girgir ni Jakusko ni ipinlẹ Yobe ariwa ila oorun Naijiria ni wọn ti bi Yusuf lọdun 1970.
Kini wáàsí Yusuf maa n dá lé lórí:
Erongba Yusuf ni pe ki awọn eeyan maa tẹle ofin Sharia ninu igbesi aye wọn.
Gẹgẹ bi akọsilẹ, nkan ti o n fẹ ni Jihad.
Iwaasu Yusuf a maa da lori bi awọn olori yoo ti ṣe ṣe deede laarin awọn alaini ati awọn to ni lawujo.
Ọrọ rẹ ta daadaa leti awọn mẹkunnu ti a si ri ka pe awọn ọdọ to kawe miran naa to fi mọ awọn tori jajẹ lawujọ a ma tẹti gbọ waasi rẹ.
Boko Haram yóò dá Leah sílé
Ko si iye meji pe Yusuf tako ẹkọ igbalode eleyi to ni o jẹ ''haramu'' nitori pe awọn ilana rẹ ko ba ti ofin Ọlorun Sharia mu.
Nigba ti yoo fi di nnkan bi ọdun melo kan, Yusuf ti ni awọn ọmọ ẹyin pupọ ti awọn to wa ni ijọba nipinlẹ Borno si ti n kan si i lati le mu anfaani ba wọn lasiko idibo tori awọn ero to n tẹle e.
Odumakin: awọn alagbara lo wa lẹyin ijinigbe Dapchi
Iku Yusuf ati àná rẹ:
Lọdun 2009, awọn ọmọ ẹgbẹ Boko Haram yabo ileeṣẹ ọlọpaa ni ilu Borno ti wọn si bẹrẹ si ni i ṣe ikọlu pẹlu awọn agbofinro.
Ohun ti wọn lo faa tawọn fi ṣe bẹẹ ni bi awọn agbofinro ti ṣe yinbọn pa awọn ọmọ ẹgbẹ wọn.
Nigba ti wahala naa yoo fi dẹkun, ọpọ ẹmi lo ti lọ si i ti awọn ọlọpaa si kede iku Mohammed Yusuf to wa ni ahamọ lọdọ wọn.
Ọmọbinrin Dapchi: Mi o lọ sile iwe mọ
Ohun tawọn ọlọpaa sọ nipa iku Yusuf ni pe igba ti ikọlu waye ni o faragbọta.
Awọn ajafẹtọ ẹni bẹnu ẹtẹ lu iha ti awọn ọlọpaa kọ si iṣẹlẹ yii ati bi wọn ti ṣe ṣeku pa ana Mohammed Yusuf, iyẹn Baba Fugu Mohammed ni ipakupa.
Ile ẹjọ to dajọ lori iku ana Yusuf lẹyin igba naa dajọ ẹbi fawọn ọlọpaa ti awọn mọlẹbi rẹ si sọ fun BBC pe inu awọn dun si idajọ naa ati bi ile ẹjọ ti ṣe paṣẹ ki ọlọpaa san owo itanran $665,000.
Shiite: Ẹ̀mí àti ara wa kọ ohun tí ìjọba ń ṣe sìwa láti 2015
Boko Haram loni:
Lẹyin iku Yusuf, pupọ ninu awọn ọmọ ẹgbẹ Boko Haram fọn kaakiri.
Nigba ti wọn yoo fi pada toro toro ni wọn ba de ti Abubakar Shekau si kede ara rẹ gẹgẹ bi olori ẹgbẹ naa.
Ni oorun oni to mọ, ọpọ ẹmi ati dukia lo ti ba ikọlu laarin Boko Haram ati ijọba Naijiria lọ.
Ọpọ ti di alaini ile lori ti karakata lagbegbe ibi ti Boko Haram ti n ṣoro ti dẹnukọlẹ lariwa Naijiria.
O ti pe ọdun mẹwaa bayi ti gbogbo rẹ bẹrẹ.
Ijọba lawọn ti rẹyin Boko Haram ṣugbọn bi wọn ti ṣe n da oro loore-koore ko jẹ ki ara ilu le sọ boya opin ti de ba Boko Haram.
Kemi Afolabi: Dókítà ní ìrìnàjò wákàtí mẹ́jọ láti Mecca sí Medinah ló fa ibà
Oríṣun àwòrán, kemiafolabiadesipe
Ara kii se okuta, igbakuugba si lo lee beere itọju lọwọ ẹni.
Bẹẹ lọrọ ri fun gbajugbaja osere tiata lobinrin, Kẹmi Afọlabi Adesipẹ, ẹni to dubulẹ aisan nilu Mecca lasiko to n kopa ninu isẹ Hajj fun tọdun yii.
Gẹgẹ bi iroyin kan latẹnu awọn eeyan to n kopa nilu Mecca ti wi, wọn ti gbe osere tiata naa lọ sile iwosan nigba ti ara rẹ ko da pe mọ lati tẹsiwaju pẹlu isẹ hajj naa.
Iya Adura Esther Ajayi sọ àṣírí owó rẹ̀ tó fi ń ṣàánú
Iroyin ọhun salaye pe, Kẹmi lo ti n safihan pe ojojo n se ogun oun lati ilu Medinah, to si sun sinu ọkọ lasiko ti awọn olujọsin yoku lọ wo awọn ibudo manigbagbe to wa nilu Medinah.
Nigba to n salaye koko ohun to n se Kẹmi Afọlabi, dokita kan to kọwọrin pẹlu awọn arinrinajo hajj to wa latilu Eko, Abideen Aro, sọ pe awọn ami ti osere tiata naa n fihan ni iba, ori fifọ, ailee jẹun daada ati ko maa rẹ.
Dokita Aro ni, ni kete ti oun ti kofiri awọn ami aipe ara naa, ni oun ti fi to olori ikọ isegun to wa lati ipinlẹ Eko leti, tawọn si gbe lọ sile iwosan pẹlu ọkọ alaisan pajawiri, nibi ti wọn ti fidi rẹ mulẹ pe aisan iba ni Kẹmi ni, ti wọn si fun ni abẹrẹ fun ọjọ mẹta.
Oríṣun àwòrán, kemiafolabiadesipe
A ti sekilọ fawọn arinrinajo Hajj lati orilẹ-ede Naijiria pe ki wọn lo awọn oogun to n dena iba sugbọn o se ni laanu pe nitori ọkan rẹ to foo, Kẹmi Afọlabi ko lo oogun kankan.
Dokita naa fikun un pe, o seese ko jẹ pe irinajo tawọn eeyan to n sisẹ Hajj rin lati ilu Mecca si Medinah eyi to to wakati mẹjọ, lo fa sababi aisan osere tiata naa.
Boris Johnson: Olukemi Olufunto Badenosh di mínísítà ní London
Oríṣun àwòrán, Olukemi Olufunto Badenosh
Olootu ijọba ilẹ Gẹẹsi, Boris Johnson ti yan ọmọ Yoruba atata kan, Olukemi Olufunto Badenosh, gẹgẹ bii ọkan lara awọn minisita rẹ.
Badenosh yii lo jẹ ọmọ ẹgbẹ oselu Conservative ati ọmọ ile asofin apapọ nilẹ Gẹẹsi, eyi to n soju ẹkun idibo Saffron Walden.
Olukemi Olufunto Badenosh, tii se ẹni ọdun mọkandinlogoji ni Boris Johnson yan gẹgẹ bii minisita fun awọn ọmọde ati mọlẹbi.
Lara ojuse minisita tuntun yii si ni sise agbekalẹ ofin to nii se pẹlu igba ewe awọn ọmọde, abẹwo wọn ati ofin to de akoso wọn.
Nigba to n kede iyansipo tuntun naa ni oju opo Twitter rẹ, Olukemi Olufunto Badenosh @KemiBadenoch fi idunnu rẹ han si ipo nla ti Olootu ijọba Gẹẹsi yan si ọhun.
Pẹlu iwa irẹlẹ ni mo fi gba ipo minisita kekere ti wọn yan mi si. Anfaani nla ni eyi fun mi lati sisẹ sin, ki n si mu iyatọ rere ba ọpọ isẹlẹ to n waye eyi to jẹ mi logun. Mo n fi oju sọna lati sisẹ pẹlu ikọ awọn minisita ati ẹnikọọkan to wa lẹka eto ẹkọ nilẹ Gẹẹsi.
Oríṣun àwòrán, Olukemi Olufunto Badenosh
Ọṣu Kinni ọdun 1980 ni wọn bi Olukemi Olufunto Badenosh. Orukọ baba ati iya rẹ ni Fẹmi ati Feyi Adegoke.
Ilu Eko ati ilẹ Amẹrika lo ti lo igba ewe rẹ, ko to di pe wọn gba ilẹ Gẹẹsi lọ nigba ti Olukẹmi wa lọmọ ọdun mẹrindinlogun.
MKO Abiola: Buhari ní Abiọla kò bá dènà ìṣòro ẹ̀sìn àti ẹ̀yá ní Nàíjíríà
Oríṣun àwòrán, Getty Images
To ba jẹ pe Abiọla wa laye ni, ọrọ aawọ ẹlẹsinjẹsin tabi ẹlẹyamẹya ko ba ti sẹlẹ lorilẹede Naijiria lasiko yii, paapa to ba jẹ pe wọn gbaa laaye lati jẹ aarẹ Naijiria ni.
Eyi ni ọrọ to ti ẹnu aarẹ orilẹede yii, Muhammadu Buhari jade lasiko to n gbalejo awọn eekan ọmọbibi ipinlẹ Ogun, to fi mọ gomina wọn, Dapọ Abiọdun ati igbakeji rẹ, Noimot Salakọ, eyi to waye nile ijọba nilu Abuja.
Lara awọn eekan miran lati ipinlẹ Ogun to se abẹwo si aarẹ Buhari ni arẹmọ oloogbe MKO Abiọla, Kọla Abiọla, ọmọ Abiọla obinrin, Hafzat Abiọla, gomina tẹlẹ nipinlẹ Ogun, Oloye Olusẹgun Ọsọba, awọn ọba alaye ati awọn eeyan jankanjankan miran.
Oríṣun àwòrán, @MBuhari
Buhari, lasiko to n gbalejo awọn eeyan yii ni Abiọla ati igbakeji rẹ ti wọn dijọ dije, ni wọn jẹ Musulumi, bẹẹ ni aawọ ẹsin tabi ti ẹyako ba ti waye, nitori Kanuri ni ẹni to dije bii igbakeji Abiọla, ti oun naa si jẹ ilumọọka yika Naijiria.
Oríṣun àwòrán, @MBuhari
O fikun pe Abiọla lo awọn ohun alumọsni ti ọba oke fi jinki rẹ ati gbogbo agbara to ni lati fi gba awọn ọmọ Naijiria niyanju pe ohun kan soso ti oun n fẹ ni orilẹede Naijiria ti yoo duro digbi, ko si si ohunkohun miran ti oun n wa.
Oríṣun àwòrán, @MBuhari
Buhari salaye pe oun mọọmọ fi papa isere idaraya ilẹ wa sọri oloye MKO Abiọla ni, nitori oun nigbagbọ pe awọn ọdọ lọjọ ọla, yoo fẹ mọ idi ti wọn se fi papa isere nla naa sọri MKO Abiọla.
Nigba to n ki aarẹ, gomina ipinlẹ Ogun, Dapọ Abiọdun ni awọn eekan ọmọ bibi ipinlẹ Ogun tọ Buhari wa, lati wa dupẹ lọwọ rẹ, fun iyi ati ẹyẹ to fun Abiọla nitori ẹni ta se loore, ti ko dupẹ, bi ọlọsa ko ni lẹru lọ ni.
Seyi Makinde: Iléẹjọ́ ní àwọn alága ìbílẹ̀ kó gbọdọ̀ gbé ìgbésẹ̀ kankan títí ìdájọ́ iléẹjọ́ Kòtẹ́milọ́rùn
Oríṣun àwòrán, Facebook/Seyi Makinde
Ileẹjọ ti fun Gomina Ipinlẹ Oyo, Seyi Makinde laṣẹ lati yan awọn alaga tuntun si awọn ijọba ibilẹ mẹtalelọgbọn to wa nipinlẹ naa.
Agbẹjọro to n ṣoju ijọba ipinlẹ Oyo lori ẹjọ ọhun, Adeniyi Farintọ to ba BBC Yoruba sọrọ ṣalaye pe, agbẹjọro awọn alaga ko yọju sile ẹjọ lonii ọjọ Iṣẹgun.
O sọ pe, agbẹjọro awọn alaga ìjọba ibilẹ naa bẹbẹ pe ki adajọ sun igbẹjọ naa di oṣu kẹwaa, ṣugbọn agbẹjọro ipinlẹ Oyo tako ẹbẹ naa.
Agbẹjọro Farintọ ni agbẹjọro awọn alaga ibilẹ naa fẹ maa fi akoko ṣofo lori ẹjọ ọhun ni, ileẹjọ si gba pẹlu wọn.
Ẹwẹ, saaju ni amofin Farintọ ati ikọ rẹ ti wọn n ṣoju ipinlẹ Oyo, ti kọkọ rọ ileẹjọ lati fofin de awọn alaga naa, ki wọn ma baa le gbe igbesẹ kankan titi di igba ti ileẹjọ kotẹmilọrun yoo fi dajọ.
Ileẹjọ ṣi gba pẹlu awọn pe, awọn alaga ko le pada si ipo wọn, bẹẹ ni wọn ko le ṣe ohunkohun titi digba ti igbẹjọ yoo fi waye nibi oṣu meji si akoko yii.
Agbẹjọro Farintọ fikun ọrọ rẹ pe iru ẹjọ ti ileẹjọ kotẹmilọrun ba da lo maa sọ boya awọn alaga ti Gomina ipinlẹ ba yan lo maa ṣakoso awọn ijọba ibilẹ tabi awọn alaga to wa nibẹ tẹlẹ ki ijọba tuntun to de.
Jesus in Kenya:Ta ni ọkùnrin tí wọ́n ń pè ní ayédèrú Jesu yìí gan an?
Oríṣun àwòrán, Other
Ọpọ aworan ati fidio to n ṣafihan ọkunrin kan to wo aṣọ bi Jesu Kristi, ti lu oju ayelujara pa lẹnu ọjọ mẹta yii kaakiri ilẹ Afirika.
Ṣugbọn ta ni ọkunrin yii to n pe ara rẹ ni Jesu gan an, ati pe kinni o n ṣe kaakiri ilẹ adulawọ?
Ọpọ eeyan lo ti n pin aworan ati fọnran ọkunrin yii lori ayelujara, koda aṣofin kan lorilẹede South Africa, Julius Malema sọ pe, alufa ijọ kan lorilẹede ọhun gbalejo Jesu yii, lati wa ṣe iwaasu ninu ijọ rẹ.
Amọ, awọn aworan to lu ayelujara pa ọhun wa lati ibi ayẹyẹ kan niluu Kiserian, lagbegbe Nairobi lorilẹede Kenya.
Orukọ ọkunrin eke Jesu yii ni Michael Job, o jẹ ọmọ orilẹede Amẹrika. Oniwaasu ni, bakan naa lọ jẹ oṣere tiata.
Ilu Orlando nipinlẹ Florida ni ọkunrin ọhun n gbe, nibi to ti n ṣe bii Jesu.
Oríṣun àwòrán, Other
Isọ ti wọn ti n ta aga ijoko ati nnkan ọgbin lo wa ninu fidio to fi sita lori oju opo Facebook rẹ.
Ọpọ eeyan lori ayelujara lo ti n fi awọn aworan ọkunrin yii ṣe ẹfẹ ati bi awọn alufa ijọ kan nilẹ Afirika, ṣe maa n ṣe iṣẹ iyanu.
Ọkan lara awọn aworan yii ṣafihan bi alufa kan lorilẹede Kenyan sẹ sọ wi pe, oun ri Jesu to rin loju popo ni Kenya.
Michael Job ṣeleri wi pe, oun n ṣiṣẹ iyanu ati imularada ninu awọn fọnran iwaasu rẹ lorilẹede Kenya, bo tilẹ jẹ pe ọpọ lo koro oju si ọrọ yii.
Kii ṣe igba akọkọ ree ti Ọgbẹni Job wa si ilẹ Afirika, o ti wa si orilẹede Togo nibẹrẹ ọdun yii ṣugbọn ko wọ iru aṣọ bayii nigba naa, kootu lo wọ.
Olubadan: Ìpàdé àláàfíà wáyé láàrin Olubadan àti àwọn àgbà ìjòyè tí Ajimobi sọ di ọba.
Oríṣun àwòrán, Twitter/Local blog
Lẹyin oṣu mẹrindinlọgbọn ti ede aiyede ti waye laarin Olubadan ilẹ Ibadan, Ọba Saliu Akanmu Adetunji, Aje Ogungunnisọ Kinni, ati awọn ijoye rẹ ti gomina tẹlẹ nipinlẹ Oyo, Abiọla Ajimọbi gbe ade le lori, ija ti pari.
Eyi jẹyọ lasiko ti awọn ijoye naa wa si aafin Olubadan to wa ni adugbo Popoyemọja nilu Ibadan, ti ọkọọkan wọn ko si de ade.
A gbọ pe tilu-tifọn ni Olubadan fi ki awọn ijoye rẹ ọhun kaabọ pada s'aafin, ti Olubadan si sọ fun awọn ijoye naa pe, oun fi aaye gba ipade ipẹtu saawọ ọhun nitori alaafia, iṣọkan ati ilọsiwaju ilu Ibadan.
Ṣaaju asiko yii ni Olubadan ti paṣẹ pe, eyikeyi awọn ijoye naa ko gbọdọ wa si aafin oun fun ipade pẹlu ade ọba lori.
Ede aiyede naa bẹrẹ lasiko ti Gomina Abiọla Ajimọbi mu ayipada ba ilana jijẹ oye Olubadan lọdun 2017, to si sọ awọn ijoye mọkanlelogun di ọba alade.
Ọdun 1957 ni ofin oye jijẹ nilu Ibadan ti wa fun lilo.
Ọrọ naa mu ki ọpọlọpọ awuyewuye waye laarin awọn ọmọ bibi ilẹ Ibadan nile ati lẹyin odi. Ọpọ lo koro oju si igbesẹ ti Gomina Ajimọbi gbe, pe o fẹ ẹ pa ilana ti awọn baba nla ilẹ Ibadan da silẹ da.
Bo tilẹ jẹ pe ijọba  Ajimọbi ni oun ti ṣe ipade ati ijiroro pẹlu igbimọ lọbalọba ki oun to gbe igbesẹ naa, amọ Olubadan ati Osi Olubadan, Oloye Rashidi Ladoja tako igbesẹ naa, ti ọrọ si di ti ile ẹjọ, laarin aafin Olubadan ati ijọba ipinlẹ Oyo.
Nibayii, ọjọ kọkandinlogun oṣu Kẹjọ,ọdun 2019 ni ipade miran yoo tun waye ni aafin laarin Olubadan ati awọn ijoye rẹ.
Community Policing: ìjọba ìbílẹ kọọkan yóò gbà ààdọta òsìsẹ
Oríṣun àwòrán, Policeng
Community Policing: ìjọba ìbílẹ kọọkan yóò gbà ààdọta òsìsẹ
Gbogbo ijoba ibile merinleniaadorino le ni eedegbeje ni eto naa yoo ti waye.
Ìlé iṣẹ ti kẹde láti gba àwọn òṣiṣẹ ẹgbẹrún lónà ogójì tí yóò maa ṣe ọlọpàá àdúgbò tí àwọn ọmọ Nàìjíríà tí ń pè fún kí ọrọ ètò ààbò òrílẹ-èdè yìí tó dé ibi ti ó de dúró yìí.
Ìlé iṣẹ ọlọpàá ní àwọn yóò gba òsìṣẹ kọọkan láti àgbègbè tí wọn bá n gbé, ó kéré tán ẹnìyàn ààdọtá láti ìjọba ìbìlẹ kọọkàn jákejádò orílẹ-èdè Nàìjíríà
Bákan náà ni wọn fí kún un pé ènìyàn ọọdúnrún lé ni ẹgbẹrún ní àwọn ní yóò gbà sísẹ nínu àwọn akọṣẹmọṣẹ àti àwọn ẹgbẹ ọdọ ní Nàìjíríà.
Lórí òpò twitter ilé iṣẹ olopaa ní ìròyín náà ti jáde.
Bakan náà ni ọgá àgbà ọlọpàá Muhammed Adamu kédé rẹ nínú ìpàdé kan to pé fún àwọn ọgá ọlọpàá nílu Abuja níbi tó ti sàlàyé kíkún lóri fífòfin dé àwọn ọmọ egbẹ Shi'ite tó ń tèlé El-ZakyZakky, olori Islamic Movement in Nigeria (IMN).
O menuba igbese ijoba ti yoo jade laipe.
Iléẹjọ́ fún Seyi Makinde láṣẹ láti yan adelé alága ìbílẹ̀ ní ìpínlẹ̀ Oyo
Joke Silva: Olu, ó tó gẹ́ pẹ̀lú obìnrin yìí níkan tó ń ba ẹ ṣeré ìfẹ́ nínú sinimá
Tanker Accident: Ọ̀pọ̀ èèyàn tó ń lọ sẹ́nu iṣẹ́ àti okoòwò ló tàn sílẹ̀
Oríṣun àwòrán, @Gidi_Traffic
Se ni ohun gbogbo lọju pọ ni opopona Eko si Ibadan lọjọru, ti awọn ero si duro gogogo soju popo lai ri ọkọ wọ lasiko ti ọkọ epo kan to ko epo disu danu soju popo.
Ori afara gbọọrọ ti wọn n pe ni Long Bridge, nibudokọ Barewa lopopona Ibadan silu Eko ni isẹlẹ naa ti waye eyi to mu ko nira fun awọn ọlọkọ to n bọ lati oju ọna marosẹ Eko si Ibadan lati kọja.
Koda, ọrọ yii kanlẹ, o tun kan baale nitori awọn olugbe adugbo Mowe, Ibafo, Asese, magboro ati Arepo, to yẹ ko lọ wọ isẹ ni aarọ yii ni sunkẹrẹ fakẹrẹ ọks mu mọlẹ, ti wọn ko si lee lọ sẹnu isẹ ati okoowo wọn.
Amọ sa, awọn osisẹ ajọ ẹṣọ oju popo, awọn ọlọpa atawọn ẹsọ to n ri si igbokegbodo ọkọ nipinlẹ Eko ni wọn duro si adugbo naa lati ri daju pe ijamba ko waye.
A tun gbọ pe awọn osisẹ ileesẹ Julius Berger to n tun oju sna se lo wa nibẹ lati ko awọn epo to danu ọhun, ti ọrọ yii ko si yọ awọn osisẹ panapana silẹ pẹlu aibaamọ ijamba ina lee fẹ waye.
Ooni: Ọọni àti Buhari tún ṣèpàdé fún ìgbà kejì láàrin ọ̀sẹ̀ kan
Oríṣun àwòrán, @Bashir Ahmad
Ọọni ile ifẹ, Ọba Adeyẹye Ogunwusi ti sọ pe ijọba Naijiria ti n ṣe eto, lati ṣe amulo ẹrọ dironu ati CCTV gẹgẹ bi ohun elo lati daabo dukia ati ẹmi awọn eeyan ilẹ kaarọ ojiire.
Ọọni fi ọrọ yii lede lẹyin ipade ti oun ati awọn ọba alade lati agbegbe naa se pẹlu aarẹ Buhari nile ijọba.
Gẹgẹ bi ohun ta gbọ, aarẹ Buhari ti tẹwọgba aba lati ma sọ awọn igbo kijikiji to wa nilẹ Yoruba pẹlu awọn irinṣẹ aabo igbalode.
Iya Adura Esther Ajayi sọ àṣírí owó rẹ̀ tó fi ń ṣàánú
Ọba alade naa sọ pe, wọn yoo ṣe agbekalẹ ẹrọ ayaworan CCTV kaakiri opopona marosẹ.
Ipade yii to waye lọjọru ni ẹlẹkeji iru rẹ ti yoo waye laarin ọsẹ kan, ti wọn lero pe yoo wa ojutu si ipenija aabo to ba awọn ipinlẹ guusu iwọ oorun.
Oyo Grazing Bill: Ilé aṣòfin ní yóò di èèwọ̀ láìpẹ́ láti ta ilẹ̀ fún darandaran
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Laipẹ ni yoo di eewọ nipinlẹ Ọyọ fun awọn darandaran lati maa da ẹran jẹ laarin igboro tabi loju popo, ti ọkọọkan awọn daradaran yii yoo si tun lọ gba iwe idanimọ lọdọ ijọba.
Idi ni pe aba ofin kan ti wa niwaju ile asofin ipinlẹ ipinlẹ Ọyọ, eyi ti yoo sọ di eewọ fun awọn darandaran lati da ẹran jẹ loju popo, wọn si ti ka ofin naa, ti wọn pe ni Open Rearing and Grazing Regulation Bill ti ọdun 2019, fun igba keji bayii.
Awọn asofin mẹta to se onigbọwọ aba naa, eyiun Asofin Asimiyu Alarape, Sanjọ Adedoyin ati Abiọdun Fadeyi naa salaye pe, darandaran to ba tapa si aba ọhun to ba di ofin tan, yoo lọ si ẹwọn osu meje, tabi ko san owo itanran tii se ẹgbẹrun lọna igba naira tabi ko se mejeeji.
Ofin yii lo nkan nipa fun awọn ọlọsin ẹran lati ye da ẹran lati agbegbe kan si omiran, amọ wọn ni asẹ lati fi ọmọlanke abi ọkọ gbe awọn ẹran naa lati ibudo kan si ekeji, ẹnikẹni ti ọwọ ba si tẹ pe o n ko ẹran kiri pẹlu ẹsẹ yoo san ẹgbẹrun lọna aadọta naira owo itanran tabi ko lọ si ẹwọn ọdun kan abi ko se mejeeji papọ.
Koda, ofin naa tun ni awọn darandaran yoo lọ gba iwe idanimọ lọdọ ijọba eyi ti wọn yoo maa gbe kọrun ni gbogbo igba, eyikeyi wọn ti ko ba si se bẹẹ yoo san ẹgbẹrun lọna ọgọrun naira tabi ko fi ẹwọn ọdun meji jura, abi ko se mejeeji papọ.
Lakotan, ti aba ọhun ba di ofin tan, o ti di eewọ patapata fun ẹnikẹni lati gbe ilẹ fun awọn ọlọsin ẹran lati maa fi sin ẹran tabi fi haya, tabi ta fun wọn, ti eyi ba si ti waye, gomina ipinlẹ Ọyọ ni asẹ lati gbẹsẹ le iru iwe asẹ ilẹ bẹẹ.
Ibadan Airport: Ìdí rèé tí pápákọ̀ ofurufú Ibadan ṣe n dá paroparo ní gbogbo ìgbà
Ko fi bẹẹ si ilu kan ti eeyan n lọ loriẹede Naijiria ti ko ni ri ọkọ ibẹ wọ nilu Ibadan.
Bo ṣe oke ọya ni bo si ṣe ilẹ Igbo tabi Hausa, ọna gbogbo ni awọn ọkọ Ibadan maa n rin.
Ṣugbọn ohun iyalẹnu ni wi pe pupọ ninu awọn olugbẹ ilu naa ni ko mọ wi pe papakọ ofurufu to n bẹ nibẹ n ṣiṣẹ titi di asiko yii.
Ikọ iroyin BBC Yoruba ṣe abẹwo si papakọ ofurufu naa lati fi idi ọrọ mulẹ lori bi ọwọ iṣẹ ṣe n ya si ati lilọ-bibọ awọn arinrinajo ni papakọ ofurufu naa.Bo tilẹ jẹ wi pe awọn alakoso ti o yẹ ki o ba oniroyin sọrọ ko si ni ofiisi lasiko ti a ṣe abẹwo sibẹ, oṣiṣẹ kan ti o ni ki a fi orukọ bo oun lasiri lo tu iṣu de isalẹ ikoko lori papakọ ofurufu naa.
Lati bii ọdun mẹtadinlogoji sẹhin ni papakọ ofurufu naa ti wa nilu Ibadan, ṣugbọn irinajo ofurufu ko fi bẹẹ ja gara ni papakọ naa bii ti awọn ilu nla ti o ku.Titi di asiko yii, ileeṣẹ irina ofurufu to ni ọkọ baalu meji pere lo n bẹ ni papakọ naa, irinajo ti wọn si n lọ ju ni lati Ibadan si ilu Abuja.
Oṣiṣẹ papakọ naa fi idi ọrọ mulẹ wi pe aigbepẹli eto ọrọ aje ni papakọ naa lo mu ki ọga agba ileeṣẹ to n ṣe akoso irina ofurufu lorilẹede Naijiria, Captain Rabiu Yadudu ṣe abẹwo si ilu Ibadan l'Ojoru lati pe fun ajọṣepọ laarin ijọba apapọ ati ijọba ipinlẹ Ọyọ lori papakọ ofurufu naa.
Lara awọn ohun ti Yadudu beere fun lọwọ ijọba ipinlẹ Ọyọ ni lati wa ojutu si awọn ipenija to niṣe pẹlu ala ilẹ, eto aabo ati bẹẹbẹẹ lọ.O tẹsiwaju  pe ọkan lara awọn ileeṣe to n ṣe amojuto ọkọ ofurufu nilu Eko ti fi ifẹ han lati maa bọ nilu Ibadan to si ni igbesẹ naa yoo pa kun eto ọrọ aje ipinlẹ Ọyọ.Gomina ipinlẹ Ọyọ, Onimọẹrọ Ṣeyi Makinde tẹwọ gba ajọṣepọ naa pẹlu alaye wi pe isọdọtun papakọ ofurufu ilẹ Ibadan yoo mu ki eto ọrọ aje gun oke agba.
Oṣiṣẹ papakọ ofurufu naa ti o ba ikọ iroyin BBC Yoruba sọrọ tẹsiwaju wi pe ibi ti ijọba ipinlẹ Ọyọ ati ijọba apapọ yanju ọrọ naa si ni lati gbe igbesẹ akọkọ lori awọn arinrinajo to n lọ si irinajo mimọ nilu Mecca.Dipo ki awọn to n lọ lati ipinlẹ Ọyọ ṣẹṣẹ lọ gbera lati ilu Eko, papakọ ofurufu to n bẹ nilu Ibadan ni wọn o ti maa gbẹrẹ bayii.Bo tilẹ lẹ jẹ wi pe ẹẹkan lọdun ni irinajo naa yoo maa waye, ireti wa wi pe awọn onikarakata to n bẹ ni agbegbe naa yoo maa jẹ ere gọboi lasiko ti irinajo naa ba n waye.
Shiite: Suhaila El-Zakzaky ní ẹgbẹ́ àwọn kọ́ ló kéde àti dáwọ́ ìwọ́de dúró
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Awọn ọmọ ẹgbẹ́ Shiite n fẹ̀hónú hàn fún ìtúsílẹ̀ olori wọn Sheikh Ibrahim Zakzaky.
Ọrọ gba ọna mi yọ nigba ti ọmọbinrin olori ẹgbẹ Shiite, Ibrahim El-Zakzaky to wa ni ahamọ sọ pe, ẹgbẹ awọn ko kede lati dawọ duro lori iwọde ti ẹgbẹ́ shiite n se.
Suhaila Ibrahim El-Zakzaky, ninu fidio to fi sita loju opo Twitter rẹ salaye pe, iwọde ẹgbẹ naa to da lori pe ki wọn tu El-Zakzaky silẹ, ṣi n tẹ siwaju
Lọjọru ni iroyin gbode pe, aarẹ igbimọ to wa feto iroyin fẹgbẹ Shiite, Ibrahim Musa fi atẹjade ṣọwọ pe awọn so iwọde naa rọ, ti awọn si ṣetan lati gbe ijọba Naijiria lọ si ile ẹjọ lori bo ti ṣe pe wọn ni agbesunmọmi.
Suhaila ninu fidio naa ni, Musa ko le gbẹnu awọn sọrọ ati pe iwọde yoo ṣi tẹsiwaju.
O ti to ọdun marun un bayi ti aawọ ti n waye laarin ẹgbẹ Shiite ati ijọba Naijiria lori idande olori wọn, Ibrahim El Zakzaky.
Oríṣun àwòrán, @SZakzakyOffice/Twitter
Awọn ọmọ ẹgbẹ naa si ti n ja fun itusilẹ olori wọn to ti wa ni atimọle lati ọdun 2015 toun ti pe ile ẹjọ giga mi Abuja paṣẹ ki wọn tu silẹ.
Lẹnu lọlọ yii, iwọde ẹgbẹ naa ti n lagbara ti awọn eeyan kan si ti padanu ẹmi wọn nitori rẹ.
Suhaila kasẹ ọrọ rẹ ninu fidio naa pe, ''ẹni to fi atẹjade sita pe awọn wọgile iwọde ko ni nnkankan ṣe pẹlu awọn to n ṣagbatẹru iwọde to n lọ lọwọ ni Abuja, ti iwọde naa ko si ni dopin ayafi ti wọn ba tu olori awọn silẹ''
Shiite: Ẹ̀mí àti ara wa kọ ohun tí ìjọba ń ṣe sìwa láti 2015
DR Congo Ebola: Òṣìṣẹ́ ìlera méje kú torí ibínú àwọn èèyàn nípa Ebola
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Nitori ikọlu, awọn oṣiṣẹ eto ilera maa n bẹru lati wọ aṣọ iṣẹ́ ni gbangba.
"''Awọn eniyan ro pe arun Ebola kii ṣe otitọ."""
Eyi ni ọrọ Dokita Pascal Vahwere, ọkan lara awọn dokita to n gbogun ti arun naa ni orilẹede Democratic Republic of Congo, DRC.
Ikọ̀ mi n f'oju wina ikọlu, nitori pe a n ṣe iṣẹ́ wa.
Ọpọlọpọ awọn oṣiṣẹ eto ilera lo ti ku nitori pe wọn n tọju tabi polongo igbogun ti aarun Ebola ni orilẹede Democratic Republic of Congo.
Ọkan lara awọn dokita to n ṣiṣẹ lati gbogun ti arun naa, Pascal Vahwere sọ iriri rẹ fun BBC lasiko ti awọn ara abule kan ni Ariwa ẹkùn Kivu deede yi oun ati ikọ rẹ ka lasiko ti wọn fẹ fun awọn ara abule naa ni abẹrẹ ajẹsara.
Lojiji ni awọn ero to ko ada ati ibọn dani yi wa ka. A ko mọ idi ti wọn fi fẹ ẹ ṣe ijamba fun wa. Ẹru ba wa. Nipasẹ awọn olori ilu la fi ba awọn ara ilu sọrọ, a si pẹtu si awọn ero naa l'ọkan.
Bo ti lẹ jẹ pe itankalẹ arun Ebola n pa ọpọ eniyan si, sibẹ awọn oṣiṣẹ eto ilera n la ewu ibinu awọn ajijagbara ati eniyan miran kọja nitori awọn ayederu iroyin to n tan kalẹ bi ina inu ẹẹrun, paapa lori ayelujara Whatsapp.
Ko din ni oṣiṣẹ eto ilera meje ti wọn ti pa ni ọdun yii nikan. BBC ba diẹ lara awọn to n gbogun ti Ebola sọrọ, lori idi ti eyi fi n ṣẹlẹ si wọn.
Ayederu Iroyin
Awọn ayederu iroyin naa n mu ki awọn eniyan o ni igbagbọ pe, awọn oloṣelu n fi aarun Ebola pa owo si apo ara wọn.
"Dokita Vahwere, to sọ eyi fun BBC tun sọ pe ""awọn miran tiẹ maa n sọ pe iwosan ti wọn n fun awọn to ni aarun naa gan an lo n pa wọn."""
Awọn ikọlu to ti waye:
Awọn ayederu iroyin ti fa awọn ikọlu to l'agbara.
Ọga agba ni ẹka ibanisọrọ ninu ajọ eleto ilera lagbaye WHO, sọ fun BBC pe:
laarin ọjọ kinni, oṣu Kinni si ọjọ kẹrinlelogun, oṣu Keje, ọdun 2019, ikọlu igba din meji ti ajọ eto ilera l'agbaye, WHO, ṣe akọsilẹ rẹ, fa iku oṣiṣẹ eto ilera meje, ti awọn mejidinlọgọta si fi ara pa ni orilẹede DRC.
Itankalẹ aarun Ebola
Bi awọn ikọlu naa ṣe n waye, to si n fa iku ọpọlọpọ ti mu ki adinku ba bi awọn oṣiṣẹ eto ilera ṣe n dena itankalẹ aarun naa ni DR Congo.
Ebola Virus: ìdí tí Ebola fi ń tàn kálẹ̀
Lai ti i pe ọdun kan, awọn to ti ni aarun naa ti pe ẹgbẹrun meji.
Abẹrẹ Ajẹsara
Wọn ti n fun awọn eniyan ni abẹrẹ ajẹsara kan ti wọn ṣẹṣẹ ṣe jade lati dena itankalẹ aarun Ebola.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ṣugbọn bi wọn ṣe n kọlu awọn oṣiṣẹ eto ilera n fa idiwọ fun pinpin abẹrẹ ajẹsara.
Awọn eniyan bi ẹgbẹrun lọna aadọsan to ti sunmọ awọn to ni aarun Ebola lo ti gba abẹrẹ ajẹsara naa.
Ṣugbọn bi wọn ṣe n kọlu awọn oṣiṣẹ eto ilera ti fa idiwọ fun pinpin abẹrẹ naa, eyi si ti mu ki aarun naa tan kalẹ si.
Ijọba orilẹede DR Congo n di ẹbi awọn ikọlu naa ru awọn oriṣiriṣi ikọ ajijagbara to wa ni orilẹede naa.
Ṣugbọn kii ṣe awọn ajijagbara yii nikan lo n ṣe ikọlu, awọn araalu naa n kọlu awọn oṣiṣẹ eto ilera.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
ijọba ti n fi awọn ọmọ ogun ṣọ diẹ lara awọn ileewosan ti wọn ti wọn ṣẹṣẹ da silẹ.
Apẹẹrẹ iru iṣẹlẹ bẹẹ ni bi mọlẹbi ẹnikan ti arun naa pa, ṣe kọlu awọn oṣiṣẹ eto ilera to n bawọn mojuto isinku ẹbi wọn naa.
Amọ ṣa, ijọba ti n fi awọn ọmọ ogun ṣọ diẹ lara awọn ile iwosan ti wọn ti wọn ṣẹṣẹ da silẹ.
"Dokita Vahwere ti ẹ sọ pe, awọn eniyan kan ti n gbagbọ pe lootọ ni arun Ebola wa. ""Ibẹru si ti n lọ lara awọn oṣiṣẹ eto ilera naa."""
Ex Boko Haram: Àwa ọmọ ẹgbẹ́ Boko Haram kan kìí kírun, à ń mu ìmukúmu, a sì ń ṣe ṣìná
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ọ̀pọ̀ ọ̀dọ́ ló ni wọ́n darapọ̀ mọ́ ẹgbẹ́ Boko Haram, nítorí ọ̀pọ̀lọpọ̀ ìdí
Ní àsìkò tí ìjà Boko Haram pé ọdún mẹ́wàá ní àríwá Nàìjíríà, ọmọ ẹgbẹ́ náà tẹ́lẹ̀rí ti ṣàlàyé fún BBC pé, àwọn kan nínú àwọn ọmọ ẹgbẹ́ náà kìí kí ìrun rara.
Ọ̀dọ́mọkùnrin náà tó sọ pé òun ti túbá, tí òun kò sì bá ẹgbẹ́ náà ṣiṣẹ́ mọ́, tún fikun pé àìsí iṣẹ́ ló fàá tóun fi darapọ̀ mọ́ ẹgbẹ́ náà.
Ó ṣàlàyé pé, ẹgbẹ́ náà tan ẹgbẹgbẹ̀rún àwọn ọ̀dọ́ wọ inú rẹ̀, nígbà tó sì mú àwọn kan ní dandan lẹ́yìn tí wọ́n jí wọn gbé, tí wọ́n sì ń fi ikú dẹ́rù bà wọ́n tí wọ́n bá gbìyànjú àti jáde.
Ó sọ pé lẹ́yìn ìgbà tí òun wọ inú ẹgbẹ́ náà, òun rò pé òun ń ṣe gbogbo nǹkan fún ẹ̀sìn Islam ni, kí òtítọ́  tó wá padà yéè.
Nígbà tí wọ́n tàn wá wọ inú ẹgbẹ́ yìí, ẹ̀sìn Islam ni wọ́n fi tàn wá. Nígbà tí a ronú síi, a bá ríi pé kìí ṣe ẹ̀sìn Islam ni, ẹ̀tan lásán ni.
Ọ̀dọ́mọkùnrin náà tó fi Boko Haram sílẹ̀ bá BBC sọ̀rọ̀, ṣùgbọ́n kò fẹ́ ká dárúkọ rẹ̀.
Ó sọ pé  àìníṣẹ́ ló fàá tí àwọn fi wọ ẹgbẹ́ náà láti ìbẹ̀rẹ̀ . Ó ní nígbà tí àwọn yoo fi wọ̀ọ́, àwọn ríi pé ọ̀rẹ́ awọ́n kan ń máa ń mú owó wá.
O ni asiko yii si jẹ ígbà tí àwọn ń wa iṣẹ́ tí àwọn yóò máa ṣe láti fi rí owó.
Oríṣun àwòrán, @HQNigerianArmy
Ó fi kún u pé, ọ̀rẹ́ wọn ọ̀hún kọ́kọ́ bẹ̀rẹ̀ sí mú díẹ̀ nínú wọn lọ, tí wọ́n sì ń rí N3,000 gbà ní gbogbo ìgbà tí wọ́n bá jà tábí tí wọ́n bá digun jale àbí tí wọ́n gba owó ìtúsílẹ̀.
Gẹ́gẹ́ bí ọ̀dọ́mọkùrin náà ṣe sọ, nígbà tí wọ́n fi wà nínú ìlú, iṣẹ́ tí wọ́n kọ́kọ́ ṣe ni íjínigbé nítorí owó ìtúsílẹ̀.
Lẹ́yìn náà ló sọ pé, wọ́n padà sí inú igbó níbi tí wọ́n ti ń rán wọ́n níṣẹ́ láti lọ ṣe alamí àti kíkó àlàyé jọ nípa ibi tí wọ́n fẹ́ kọlù.
O sọ pé ní àsìkò náà, nǹkan tí wọ́n ń fún awọn kò ju ẹgbẹ̀rùn mẹ́ta náírà lọ. Amọ o fikun pe àwọn ni ọ̀gá tí wọn n fún wọn ní ẹgbẹrun lọna ẹẹdẹgbẹta naira, ₦500,000 tàbí ẹgbẹrun lọna ẹgbẹta naira, ₦600,000 náírà ńbẹ.
Ṣùgbọ́n ó sọ pé tití tó fi jáde kuro ninu ẹgbẹ́ náà, òun kò fi ojú kan ọ̀gá kan nínú ẹgbẹ́ náà rí, tí kìí bá ṣe àwọn kan tí wọn yóò gbé ìbọn ńlá-ńlá  ní àwọn ìgbà kọ̀kan.
Ó ní àwọn padà tẹ̀lé wọn wọnú igbó lọ níbi tí wọ́n ti bẹ̀rẹ̀ sí ko wọn ní pápámọ́ra.
Oríṣun àwòrán, AUDU MARTE
Boko Haram máa ń kọlu àwọn tí wọ́n ń lọ sìnkú.
Ọ̀dọ́mọkùnrin náà, tó lo ọdún mẹ́jọ nínú ẹgbẹ́ Boko Haram sọ pé, inú òun kọ́kọ́ dùn pe ẹ̀sìn Islam ni òun ń ṣiṣẹ́ fún.
Ṣùgbọ́n ọ̀kàn òun bàjẹ́ nígbà tó hàn sí òun pé ẹgbẹ́ náà ti kùnà níbi ẹ̀sìn náà.
"Alkurani nìyí…nígbà tí mo wòó, mo ríi pé Ọlọ́run fi òfin de ṣìná àti ìmukúmu, mo si ríi pé wọ́n ń mu ìmukúmu, wọ́n ń ṣe ṣìná ọ̀hún.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Wọn yóò mú àwọn obìnrin wá tí wọ́n á máa bá lòpọ̀. Ẹlòmíràn kò tiẹ̀ ní bìkítà nípa ìrun kíkí, wọ́n yóò sì wá pa ẹni tó ń kí irun."" Gẹ́gẹ́ bí ọ̀dọ́ náà ṣe sọ."
Ó sọ wípé, eléyìí ló fàá tí wọ́n fi pinnu pé kìí ṣe nítorí Ọlọ́run ni wọ́n ń fi ń ṣe nǹkan yìí, tí wọ́n sì pinnu láti jáde kúrò nínú ẹgbẹ́ náà.
RCCG: Àwọn Pásítọ́ ijọ Redeem márùn ún bọ́ sọ́wọ́ ajínigbé ní Ijebu Ode
Oríṣun àwòrán, @NigerianPolice
Ọga agba  ọlọpaa lorilẹede Naijiria, M.A Adamu ti pasẹ pe ki wọn se awari awọn eeyan to ji awọn pasitọ marun ti ijọ Redeem gbe.
Atẹjade kan ti osisẹ alarina agba fun ileesẹ ọlọpa ilẹ wa, Frank Mba fisita ni ọjọ Ẹti salaye pe gbogbo ẹnu ni ọga agba ọlspa ilẹ yii fi koro oju sawọn isẹlẹ eto aabo to mẹhẹ to n waye lorilẹede yii.
Bakan naa ni ọga agba ọlọpa tun pasẹ fun Kọmisana ọlọpa nipinlẹ Ogun pe awari ti obinrin n wa nkan ọbẹ ni ko fi ọrọ awọn pasitọ naa se, nipa dida awọn agbofinro sigboro lati wa awọn ajinigbe to sisẹ ibi ọhun.
"Osere tiata naa, ti oju rẹ ti gun rege pada ni ""Mo fẹ lo akoko yii lati dupẹ pupọ lọwọ awọ"
Ko tan sibẹ, ọga agba ọlọpa naa tun ni wọn gbọdọ se awari awọn olubi ẹda to seku pa Fada kan fun ijọ Aguda, Ẹni ọwọ Paul Offu ni ipinlẹ Enugu.
Bakan naa lo tun sọ fun kọmisana ọlọpa nipinlẹ Enugu lati da awọn ọlọpa sita, ki wọn lee tete mọ awọn eeyan to sisẹ ibi naa.
Oríṣun àwòrán, PAstor Adeboye/Facebook
Pásítọ̀ ìjọ RCCG
Ìròyìn tó tẹ̀ wa lọ́wọ́ ní wí pé àwọn ajínigbé ti gbé òṣìṣẹ́ ìjọ àti Pásítọ̀ ìjọ The Redeem Christian Church of God, tí gbogbo wọ́n jẹ́ márùn ún gbé ní ìlú Ijebu Ode.
Ìròyìn náà sọ wí pé lójúnà ìrìnàjò wọn lọ síbi ìpàdé àdùrà níbi ìpàgọ́ ńlá ti RCCG fún oṣu kẹjọ ni wọn ti bọ́ sí páńpẹ́ ajínigbé.
Akọroyin wa kan si ọkan lara awọn Pásítọ̀ tó ti gúnlẹ̀ síbi ètò náà, ó sì fi àrídájú hàn pé lóòtọ́ ni tórí adarí ìjọ náà, Pásítọ̀ Enoch Adeboye fúnra rẹ̀ sọ ọ́ lásìkò ìsìn kan lówùrọ̀ yìí, wọ́n sì ti pa ohùn pọ̀ gbàdúrà fún ìtúsílẹ̀ wọn.
Ọdọọdún ni ìpàgọ́ fún ìpàdé àdúrà náà máa ń wáyé èyí tó ma ń kó gbogbo ọmọ ìjọ papọ̀ káàkiri àgbáyé.
Saudi Arabia: Ìjọba ti fàyé gba òbinrin lati rìnrinajo lọ orilẹ̀-èdè to wù wọ́n
Oríṣun àwòrán, Getty Images
A o ni topinpin obinrin Saudi to ba rìrìnàjò mọ́- Ìjọba Saudi
Ṣe mo le lọ?
Ìjọba Saudi Arabia ti kéde òfin tuntun tó fààyè gba obìnrin láti rìnrìn ajò lọ orílẹ̀-èdè tó ba wù wọ́n láì gba ìwé àṣẹ tàbi kí wọ́n de ẹ̀rọ ayawòrán mọ́ wọn lára
Ìgbésẹ̀ yìí ní àwọn ènìyàn rí bi àyípàdà túntun ti ọmọ ọba Saudi Mohammad Salman ń ṣe ni orílẹ̀-èdè náà.
Òfin túntun yiìí ni wọ́n kéde ní ago mẹ́jìlà ọ̀sán ọjọ ajé ní Jiddah, ó ni ki wọ́n fi ààyè gbà àwọn ọmọ obinrin ti ọjọ́ ori wọn kò jú mọkánlélogun lọ láti gba forúkọsilẹ̀ láti gba ìwé ìrìnà kí wọ́n lọ sí òkè òkun.
O ní ìgbésẹ̀ yìí yóò fún wọ́n ni ànfàni láti ṣe gbogbo ǹkan ti àwọn akẹgbẹ́ wọ́n ọkunrin ń ṣe, bákan náà ni òfin yìí yóo jẹ́ ki wọ́n yẹ láti rí iṣẹ́ ìgbàlóde lái si ìdẹ́yẹ si.
Ẹ̀wẹ̀, kí obinrin to lọ gba ìwé àṣẹ ìrìnà ó gbọ̀dọ̀ gbàṣẹ lọ́wọ́ ìyá, Baba tàbí ọmọ ẹgbọ́n tàbí àbúrò ìyá tàbi babarẹ̀ okùnrin kó to rìnrìn àjò lọ sí òkè-òkun.
Ìgbésẹ̀ yìí kò sàì so mọ́ bi àwọn ajàfẹ́tọ ọmọniyàn ṣe ń fún ogun mọ ìjọba lóri ẹ̀tọ́ obìnrin.
Bó tilẹ̀ jẹ́ pé àwọn kan ní ìhà ìwọ̀-òòrun rí i pé ìtẹ̀síwájú ni èyí jẹ́ fún òbìnrín Saudi, síbẹ̀ àwùjọ àwọn musùlùmí kan nínú àtí lẹ́yìn odi Saudi rí i gẹ́gẹ́ bi ǹkan ti ko tọ̀nà.
Oshiomole: Ẹ pe aṣaájú olóṣèlú níjà láti lo ọrọ̀ ìpínlẹ̀ fún àìní òṣìṣẹ́
Oríṣun àwòrán, @NLCHeadquaters
Alaga apapọ fun ẹgbẹ oselu APC lorilẹede Naijiria, Adams Oshiomole, ti kesi awọn ẹlẹgbẹjẹgbẹ lorilẹede Naijiria lati maa pe awọn asaaju oloselu nija lọna ati ri daju pe wọn lo ọrọ ati ohun alumọni ipinlẹ wọn lati ba aini awọn osisẹ pade.
Oshiomole pe ipe yii nilu Abuja nibi apejẹ kan ti wọn fi n bu ọla fun oludari agba fun ajọ to n risi ọrọ osisẹ lagbaye, ILO, ọgbẹni Guy Ryder.
Oshiomole, lasiko to n sọrọ nibi ayẹyẹ naa, wa gbarata lori iha ti awọn asaaju oloselu n hu loju ọna mimu agbega ba awọn osisẹ Nigeria, pẹlu afikun pe, awọn ẹgbẹ osisẹ yii gbọdọ  mu ọwọ to le lati mu ayipada ba ipo ti wọn wa.
Oríṣun àwòrán, @OfficialAPCNg
A gbọdọ lo ọna to yatọ bayii nipa sisan owo osu to kere julọ nitori gbogbo owo ọja lo ti lọ soke lai si afikun fun owo osu awọn osisẹ, ti ohun gbogbo si wa loju kan soso.
"Oshiomole tun tẹsiwaju pe, ""ti mo ba n sọrọ gẹgẹ bii ẹni to rinu rode nipa ọrọ ẹgbẹ osisẹ, o da mi loju pe awọn ẹgbẹ osisẹ ko kan lee wa lasan amọ wọn gbọdọ ni apọn lati lo gbogbo agbara wọn lai boju wẹyin."""
O wa rọ awọn olori ẹgbẹ osisẹ lati si ri daju pe wọn lo awọn ọrọ ipinlẹ wọn fun anfaani awọn osisẹ ati mọlẹbi wọn.
#DaysOfRage: Sowore ní ìwọ́de náà kò ni gbèdéke ọjọ́ tí yóò parí
Oríṣun àwòrán, @YeleSowore
O ti to asiko lati sọ fun ijọba orilẹede Naijiria pe o to gẹẹ, bawọn ọmọ ipinlẹ Kwara ti sọ ninu idibo gbogbogbo to lọ.
Oludije fun ipo aarẹ labẹ asia ẹgbẹ oṣelu AAC, Omoyele Ṣowore lo sọ bẹẹ nigba to gba BBC Yoruba sọrọ lori ifẹhonu han ''Days of Rage'' ti yoo bẹrẹ lọjọ Aje, ọjọ Karun un oṣu kẹjọ.
Ṣowore to jẹ ọkan lara awọn to ṣagbatẹru ifẹhonu han naa ṣalaye pe, ipinlẹ mẹtalelogun ni ifẹhonu han naa yoo ti waye kaakiri orilẹede Naijiria.
Bakan naa, awọn ọmọ orilẹede Naijiria to wa loke okun naa yoo darapọ mọ ifẹhonu han ọhun kaakiri agbaye.
Ṣowore ni ifẹhonu han yii, ti yoo bẹrẹ laago meje aarọ ko ni gbedeke ọjọ ti yoo pari, o ni o digba ti ijọba ba gbe igbesẹ ti yoo mu irọrun ba awọn ọmọ Naijiria kawọn to dẹkun ifẹhonu han.
Ṣowore ṣalaye pe, lara awọn to n fẹhonu han yoo lọ si ile igbimọ aṣofin agba l'Abuja lati sọ ẹdun ọkun wọn fawọn aṣofin.
Oríṣun àwòrán, @MubailuG
O ni ebi n pa awọn ọmọ Naijiria, ati pe ijọba ko faye ilọsiwaju silẹ fawọn ọmọ Naijiria, o sọ pe asiko ti to fawọn ọmọ Naijiria lati gbara wọn silẹ loko ẹru ati airiṣẹṣe.
Ṣowore fesi si ọrọ kan tawọn eeyan kan n gbe kiri lori ayelujara pe Ṣowore wa lara awọn to n ṣagbatẹru ifẹhonu han nitori pe o fidi rẹmi ninu idibo aarẹ to lọ.
Ninu esi rẹ, Soworẹ ni o si eyi kii ṣe igba akọkọ ree t'oun yoo darapọ mọ awọn to n ṣewọde.
O ni oun ti bẹrẹ si ja fẹtọ ọmọniyan lati igba ti oun ti wa nile iwe giga Fasiti Eko titi di asiko yii.
Oríṣun àwòrán, @YeleSowore
Iroyin kan to n ja rainrain lawọn oju opo ikansira ẹni lori itakun agbaye ti fi ye ni pe iporogan, ifẹhonu han ati iwọde alagbara kan n bọ lọwọ Aje, ọjọ Karun osu kẹjọ, ni orilẹede Naijiria.
Iwọde ọhun ti wọn pe akọle rẹ ni #DaysOfRage abi #Revolution now ni awọn ẹlẹgbẹjẹgbẹ ajafẹtọ ẹni n lewaju rẹ, labẹ akoso oludije fun ipo aarẹ tẹlẹ, Ọmọyẹle Soworẹ, ti yoo si gbera ni aago mẹsan aarọ.
Koda, ẹgbẹ awọn agbẹjọro nipinlẹ Eko naa ti ikede ati fọnran aworan sita loju opo Twitter pe, awọn yoo gba ẹjọ ro lọfẹ fun ẹnikẹni tawọn agbofinro ba mu sahamọ nitori iwọde naa nitori awọn ọmọ Naijiria ni asẹ labẹ ofin lati se iwọde alaafia.
Gẹgẹ bi awọn alakoso iwọde naa ti wi, ida mẹrinlelọgọrin ninu ọgọrun awọn ọmọ orilẹede Naijiria ni wọn ti setan lati darapọ mọ iwọde naa ni orilẹede Mọkanlelogun yika Naijira.
Oríṣun àwòrán, @YeleSowore
Bakan naa ni wọn ni bi iwọde yii ba se n lọ yika Naijiria, naa ni yoo waa waye nilẹ United Kingdom, tawọn ọmọ Naijiria to wa nibẹ yoo si pejọ pọ si ileesẹ asoju ijọba Naijiria to wa nilu London fun iwọde.
Lara awọn ohun ti awọn ajafẹtọ ẹni naa n beere fun ni ilana isejọba rere eyi ti yoo dẹ awọn ọmọ Naijiria lọrun, paapa nidi ipese ina ọba to duro re pklu owo ti ko gunpa, ki ijọba si tun se atunse awọn ibudo ifọpo wa eyi ti yoo mu opin de ba asa ka maa ko epo wọle.
Salawa Abẹni: ₦50 péré làwọn èèyàn fí ń pè mí fún ayẹyẹ nígbà tí mó bẹ̀rẹ̀ orin kíkọ̀
Oríṣun àwòrán, Facebook/Abeni Salawa
Gbajugbaja olorin Waka, Alhaja Salawa Abẹni sọ pe, oun ko lọwọ si awuyewuye ta lo da Fuji silẹ tawọn olorin kan n gba bi ẹni n gba igba ọti.
Queen Salawa to sọrọ naa ninu ifọrọwerọ rẹ pẹlu BBC Yoruba lọjọ Ẹti ṣalaye pe, to ba tiẹ jẹ pe oloogbe Alhaji Sikiru Ayinde Barrister gan an lo da Fuji silẹ, o yẹ kawọn eeyan fi Barrister silẹ lati sun nibi to wa.
O wa ke si gbogbo olorin Fuji lati fọwọ ṣo ọwọ pọ lati gbe orin Fuji larugẹ, ki wọn si gbagbe ariyanjiyan lori ẹni to da Fuji silẹ.
Alhaja Abẹni fikun ọrọ rẹ pe lootọọ l'oun n kọ orin Waka, ṣugbọn oun kọ l'oun da orin Waka silẹ.
Bakan naa, Salawa tun ṣalaye ọrọ lori ibaṣepọ rẹ pẹlu Alhaji Kollington Ayinla, o ni baba ọmọ oun ni Kollington jẹ, amọ oun ko tii pada sile rẹ titi di asiko yii.
Ṣugbọn o sọ pe ọja t'ọmọ ba ti wọ, o ti dokuta.
Imperial Majesty ni Olubadadan, Royal Majesty làwa, òfin sì tẹ̀lé e - Ọtun Olubadan
Bi ifọrọwerọ BBC Yoruba naa se lọ ree pẹlu Salawa Abẹni
Salawa Abẹni sọ pe, ọmọ ọdun mẹtala wa, ti oun fi gbe awo orin waka akọkọ jade lọdun 1976, o ni iranti aarẹ ologun orilẹede Naijiria tẹlẹ ri, ologbe Ọgagun Murtala Muhammed ni awo orin naa da le lori.
Queen Salawa, to ni iwe mẹfa l'oun ka tun sọ pe, aadọta kọbọ lawọn eeyan maa fi n pe oun sode nigba t'oun bẹrẹ iṣẹ orin kikọ.
O ni baba oun ko nifẹ si iṣẹ orin kikọ, ṣugbọn mama oun nifẹ ṣii, amọ ọrẹ baba oun lo ba baba oun sọrọ, ko to gba.
Salawa tun ṣalaye pe aarẹ ara lo ṣe oun, kii ṣe ti aarun gogongo gẹgẹ bi ọpọ ti n ṣọ kaakiri.
Ayinla Kollington: ọ̀rẹ́ ni èmí àti Barrister kó tó jáde láyé
Salawa ni ''ọjọ ti inu mi dun ju laye lọjọ ti mo gbe awo akọkọ mi jade, bẹẹ ni ọjọ ti inu mi bajẹ ju ni ọjọ ti mo padanu ọmọkunrin mi.''
Queen Salawa Abẹni sọ pe ''ẹbun lorin kikọ fun emi, Ọlọrun lo fun mi. Ko si ibi ti imisi orin ko ti le wa fun mi. Mo le ri nnkan loju, ki n si sọ dorin.''
Timothy Omotosho: Ó pàdánù ìwé ìgbélú ní South Africa t'orí ẹ̀sùn ìfipábánilòpọ̀
Oríṣun àwòrán, Soweta/getty images
Ẹjọ kotẹmilọrun ti ọmọ orilẹede Naijiria kan, to jẹ oniwaasu ori amohunmaworan ni South Africa, pe tako idajọ to sọ pe o ti padanu iwe igbelu rẹ ti foriṣanpọn.
Ojisẹ Ọlọrun naa lo n n jẹjọ ẹsun ifipabanilopọ ati ṣiṣe fayawọ ọmọniyan nile ẹjọ kan ni Port Elizabeth lọwọ.
Timothy Omotosho, to jẹ oludasilẹ ijọ Jesus Dominion International church l'orilẹede South Africa, ni wọn sọ fun l'Ọjọbọ pe, gbigbe rẹ ni orilẹede naa ti tako ofin bayii.
Asiko ti igbẹjọ n lọ lati gba oniduro rẹ lori ẹsun ti wọn fi kan an ninu oṣu Kẹrin, ọdun 2017, ni ileeṣẹ ijọba to n mojuto ọrọ mọlẹbi ti kọkọ sọ fun pe, o ti padanu ẹtọ to ni lati maa gbe ni South Africa.
Idi si ree ti Ọmọtọsọ fi pe ẹjọ kotẹmilọrun lati tako aṣẹ naa.
Bo tilẹ jẹ wi pe ipa ti eyi yoo ni lori Omotosho ko ti i fi bẹẹ fi oju han, igbẹjọ rẹ yoo tun pada bẹrẹ lọjọ Iṣẹgun lẹyin ti igbẹjọ akọkọ dojubolẹ.
Eyi ri bẹẹ nitori bi adajọ to n gbọ ẹsun naa yọ ọwọ kuro ninu ẹjọ ọhun nitori o da bi ẹni pe o ṣeeṣe ko ṣe ègbè.
Ọmọ ijọ rẹ kan, Cheryl Zondi, to ti pe ẹni ọdun mejilelogun bayii lo fi ẹsun kan an l'ọdun 2018 pe o fi ipa ba oun ni ibalopọ lati igba ti oun ti pe ọmọ ọdun mẹrinla.
Oríṣun àwòrán, Soweta/getty
Omotosho si sọ nigba naa pe, oun ko jẹbi ẹsun naa.
Lọjọ ti igbẹjọ kọkọ waye, wọn ṣe afihan rẹ lori amohunmaworan, eyi ti ko waye ri ni orilẹede South Africa.
Bakan naa ni ọpọlọpọ eniyan yabo ile ijọsin rẹ lasiko naa, ti wọn ko si jẹ ki wọn raaye ṣe isin.
Iwe iroyin ori ayelujara kan, NCA sọ ni Ọjọru pe agbẹjọro rẹ ti kọkọ sọ pe diẹ lara awọn ẹsun ti wọn fi kan Omotosho ko lagbara to nkan ti onibaara oun yoo wi awijare le lori, ṣugbọn adajọ to gbọ ẹjọ naa fagile ẹbẹ rẹ.
Bakan naa ni akọroyin kan ni South Africa fi fidio kan, to ṣafihan awọn alatilẹyin pasitọ naa nibi ti wọn pejọ si niwaju ile ẹjọ ni Port Elizabeth.
BBC Pidgin Essay Competition 2019: Njẹ́ ìwọ le kọ àròkọ̀ ní èdè Pidgin?
BBC News Pidgin ṣe ifilọlẹ eto kikọ arokọ ni ede Pidgin to maa n ṣe lọdọọdun fun igba keji.
Idije naa ṣi silẹ fun gbogbo awọn akẹkọọ ile ẹkọ giga ni Afirika.
"Ẹnikẹni ti yoo ba kopa ninu idije naa gbọdọ kọ arokọ ti ko le ni ẹgbẹrin ọrọ (800 words) lori koko to da le, ""Is Africa ready for female political leadership?"""
Imperial Majesty ni Olubadadan, Royal Majesty làwa, òfin sì tẹ̀lé e - Ọtun Olubadan
Awọn ọmọ igbimọ ti yoo mu ẹni to ba jawe olubori si ti wa; awọn ọmọ igbimọ naa wa lati awọn orilẹede to wa ni Iwọ oorun Afrika, ikọọkan wọn si jẹ yala olukọ, onkọwe, ati akọroyin ni ede Pidgin.
Gbogbo arokọ gbọdọ tẹle ofin ati ilana ede Pidgin, o si gbọdọ pa ofin girama naa mọ.
Wọn yoo kede ẹni to jawe olubori nibi eto kan ti yoo waye nilu Eko ni ogunjọ, oṣu Kẹsan, ọdun 2019.
Lọdun 2018, Izeowayi Victor jáwé olúborí nínú àròkọ̀ BBC Pidgin.
Bakan naa ni olubori yoo gba ẹbun ẹẹdẹgbẹta Dọla (five hundred Dollars) lati fi ra iwe lori eto ẹkọ t'oun kọ.
Anfaani lati fi arokọ ranṣẹ ti ṣi silẹ lati ọjọ kinni, oṣu Kẹjọ, yoo si wa si opin ni ọgbọnjọ, oṣu Kẹjọ, ọdun 2019.
Ẹ fi arokọ ranṣẹ si bbcpidgin.essay@bbc.co.uk
"Ninu ọrọ rẹ, Ọga agba fun BBC News Pidgin, Adejuwon Soyinka, sọ pe ""eto arokọ kikọ ileeṣẹ iroyin BBC News Pidgin ti n di itage fun igbelarugẹ awọn ọdọ to jẹ onkọwe ati alarojinlẹ ni ede Pidgin to jẹ ede to gbajumọ laarin awọn ọdọ ilẹ Afrika."
Fun ẹkunrẹrẹ alaye lori bi o ṣe le kopa, to fi mọ ofin ati ilana, lọ si oju opo BBC Pidgin everi year essay Competition Terms and Conditions
Àwọn òṣìṣẹ́ BBC News Yorùbá sọ̀rọ̀ ìdùnnú lórí ayẹyẹ ọdún kan iléeṣẹ́ náà
Sasa Market: Seriki Hausa ní ogún èèyàn ló farapa nínú ìjà Ṣasa
Oríṣun àwòrán, @seyimakinde
Seriki Sasa, tii se olori ẹya Hausa to wa lagbegbe Sasa nilu Ibadan Alhaji Haruna Mai Yasin ti salaye ohun to sokunfa ija to bẹ silẹ lsja Sasa eyi to mu ki ijọba ipinlẹ Ọyọ ti ọja naa pa.
Gẹgẹ bi Yasin ti wi, o ti to ọsẹ kan bayii ti awọn janduku to jẹ ẹya Hausa ati Yoruba ti n san ọna wahala naa ninu ọja ọhun.
"Yasin ni ""A kan ro pe awuyewuye ati aigbọra ẹniye lasan to maa n waye ni, sugbọn laarọ yii ni awọn ọdọ Hausa ati Yoruba bẹrẹ ija eyi to mu ki wọn ba ọpọ ọja jẹ nibẹ, tawọn eroja ounjẹ si bajẹ pupọ, bẹẹ ni o to ogun eeyan to fara pa yannayanna."
Yasin fikun pe, wọn ti gbe awọn eeyan to farapa naa lọ sile iwosan fun itọju.
Ẹwẹ, awọn osisẹ agbofinro ti gba akoso ọja naa, ti wọn si ti n pese eto aabo to yẹ sibẹ.
Saaju la ti kọkọ mu iroyin wa fun yin pe, ijọba ipinlẹ Ọyọ ti paṣẹ wi pe ki awọn agbofinro sọ agadagodo si ẹnu ọna abawọle ọjọ Ṣaṣa to n bẹ ni agbegbe Moniya niluu Ibadan nitori rogbodiyan to bẹ silẹ laarin awọn ẹya Hausa to n taja nibẹ lọjọ Ẹti.Ko fi bẹẹ si ẹnikan to mọ eredi ti ija fi bẹ silẹ ni ọja naa, titi di asiko ti a ṣe akojọpọ iroyin yii.
Alakoso ọja naa, Haruna Mai Yasin to fi idi iṣẹlẹ naa mulẹ fun ikọ iroyin BBC Yoruba ṣalaye pe, ṣadede ni wọn rii wi pe awọn Hausa kan to jẹ ontaja ninu ọja naa n ba ara wọn ja debi pe, awọn kan fi ara pa ninu iṣẹlẹ naa.
A tọpinpin awọn ti wọn fi ara pa lọ si ile Iwosan Al-Salam to n bẹ ni agbegbe Mọniya, lati ti fi ọrọ wa wọn lẹnu wo lori iṣẹlẹ naa, ṣugbọn awọn ọlọpaa to duro wamuwamu si ẹnu ọna ile iwosan naa ko jẹ ki ẹnikẹni wọle sibẹ.
Ninu atẹjiṣẹ ti alukoro ileesẹ ọlọpaa nipinlẹ Ọyọ, Olugbenga Fadeyi fi ṣọwọ si ikọ iroyin BBC Yoruba, o fi idi iṣẹlẹ naa mulẹ, bakan naa lo ṣe alaye wi pe eeyan mẹsan lo fi ara pa ninu iṣẹlẹ naa.
O tẹsiwaju wi pe, awọn afurasi mẹsan ọtọọtọ ni awọn ọlọpaa ti nawọ gan, wọn si ti gbe mẹta ninu wọn lọ si ile ẹjọ.
Lọwọlọwọ bayii, alafia ti jọba lọja naa ati agbegbe rẹ.
Kemi Afolabi: Mo mọ rírì àwọn olólùfẹ́ mi, àdúrà ti wọn náà yóò gbà
Oríṣun àwòrán, kemiafolabiadesipe
Gbajugbaja osere lobinrin nni, Kẹmi Afọlabi ti fi fọnran aworan kan ransẹ lati ilu Meccah eyi to fi n fi ẹmi imoore rẹ han si awọn ọmọ Naijiria ti wọn gbarata lasiko to wa lori idubulẹ aisan nilu Meccah.
Kẹmi, loju opo ikanni Twitter rẹ lọjọ Ẹti, mọriri gbogbo ọmọ Naijiria nile ati lẹyin odi ti wọn n rọjo adura si nigba ti aarẹ n se, to si n gbadura pe wọn ko ni fi iru rẹ gba.
"Osere tiata naa, ti oju rẹ ti gun rege pada ni ""Mo fẹ lo akoko yii lati dupẹ pupọ lọwọ awọn ọmọ Naijiria fun ifẹ, adura ati igbarata wọn lasiko ti mo fi ni iba, ori mi wu fun iru ifẹ ti ẹ fi han si mi. Ara mi ya bayii, ti ara mi si ti mokun pada, irinajo ibi lo lagbara pupọ amọ o yẹ lati see, gẹgẹ bi Oluwa ti kọ wa pe irin ajo irapada ko rọrun rara."""
Kẹmi Afọlabi to gbadura naa ni Kabbah, nibi ti adura ti maa n gba, wa se ladura pe Ọlọrun yoo gbọ adura awọn ololufẹ oun.
Imperial Majesty ni Olubadadan, Royal Majesty làwa, òfin sì tẹ̀lé e - Ọtun Olubadan
Bẹẹ ba gbagbe, laipẹ yii ni BBC Yoruba mu iroyin wa fun yin pe ara osere tiata naa ko ya lasiko to fi lọ fun eto Hajj nilu Mecca, ti ọpọ ọmọ Naijiria si n gbadura fun ajinde ara rẹ.
RCCG: Ọlọ́pàá Ogun dóòlà àwọn ọmọ ìjọ Redeem mẹ́rin tó kù!
Oríṣun àwòrán, Facebook/Pastor Enoch Adeboye
Awọn ọmọ Redeem mori bọ
Ìròyìn tó ń tẹ̀ wa lọ́wọ́lọ́wọ́ ní wí pé gbogbo awọn ọmọ ijọ Redeem maraarun tawọn ajinigbe ji gbe ni Ijebu Ode ti gba itusilẹ lonii.
Iroyin to tan ka lana ni wi pe lójúnà ìrìnàjò wọn lọ síbi ìpàdé àdùrà níbi ìpàgọ́ ńlá RCCG ni wọn ti bọ́ sí ọwọ awọn ajinigbe ọhun.
BBC Yoruba kan si alukoro ile iṣẹ ọlọpaa ipinlẹ Ogun, Abimbola Oyeyemi to fi aridaju han pe lootọ ni awọn ti doola ẹmi gbogbo wọn.
Lowurọ ni wọn kọkọ gba arabinrin kan ṣoṣo ti o wa laarin wọn silẹ pe awọn si n ṣe iṣẹ lati gba awọn to ku naa silẹ.
Lana ni iroyin naa jade pe wọn ji wọn gbe ti Ọ̀gá àgbá ọlọ́pàá pàṣẹ pé kí wọn ṣàwárí àwọn pásítọ̀ tí wọn jí gbé.
Nbayii, awn lpaa ti n ko gbogbo wn lọ si olu ile iṣẹ wn ni Abeokuta nibi ti wọn yoo ti ba awọn oniroyin sọrọ fun ẹkunrẹrẹ.
Imperial Majesty ni Olubadadan, Royal Majesty làwa, òfin sì tẹ̀lé e - Ọtun Olubadan
Abimbola Oyeyemi jẹ ko di mim pe ati ri awn mẹrin to ku doola ko dẹrun tori bi awọn ọlọpaa ṣe n ri wn ko kuro ninu igbo lawọn ajinigbepa ọhun naa n gbiyanju ati doju kọ wọn.
Ẹwẹ, alukoro ọlọpaa Ogun jẹ ko di mimọ pe awọn ti n ko awọn ti n ko wọn lọ si olu ile iṣẹ awọn bayii fun abo to daju ati lati fi ẹkunrẹrẹ ọrọ fun awọn oniroyin.
Texas Walmart shooting: Èèyàn ogún pàdánù èmi wọn ninu ìyibọ́npanìyàn El Paso
Fọnran fidio awọn ọlọpaa nibi iṣẹlẹ naa
Eeyan ọgun ti dero ọrun lọwọ agbebọn ti eeyan mẹrindinlọgbọn si farapa ninu iyinbọnpaniyan kan to waye nilu El Paso Texas.
Gomina ipinlẹ naa lorileede Amẹrika ni iṣẹlẹ yi jẹ eleyi to buru julọ ti yoo ṣẹlẹ ni ibẹ.
Ile itaja Walmart kan to wa ni Cielo Vista Mall lẹgbẹ ibode ilẹ Amerika ati Mexico lo ti ṣẹlẹ.
Arakunrin ọmọ ọdun mọkanlelogun kan la gbọ pe o ti wa ni ahamọ ọlọpaa bayi. Awọn ọlọpaa ni agbegbe Allen  lo n gbe ni Dallas.
Oríṣun àwòrán, EPA
ogun eeyan ṣagbako iku ojiji lọwọ agbebọn
Awọn oniroyin ilẹ Amerika kan ti sọ pe Patrick Crusius lorukọ rẹ.
Aworan CCTV  to ṣafihan agbebọn naa nibi to ti wọ aṣọ dudu to si ti gbe ibọn dani ni wọn ti ṣe afihan rẹ  lori  amohunmaworan .
Oríṣun àwòrán, AFP
Aworan agbebọn to paniyan ni Texas
Aarẹ Amẹrika Donald Trump ti ṣe apejuwe iṣẹlẹ naa gẹgẹ bi iwa  to buru
O kọ loju opo Twitter rẹ pe'' O dami loju pe emi ati awọn eeyan ilẹ yi jijọ n bẹnu atẹ lu iṣẹlẹ yi. Ko si awijare kankan ti eeyan le ni lati fi gbẹmi alaiṣẹ''
Wọn ko ti darukọ awọn to farakasa ninu iṣẹlẹ naa amọ Aarẹ Mrexico sọ pe awọn ọmọ orilẹede oun mẹta wa ninu wọn gẹgẹ bi ile iṣẹ iroyin Reuters ṣe j'abọ.
Ipaniyan yi waye lẹyin isẹlẹ ti ilu California, nibi ti agbebọn kan ti pa eeyan mẹta nibi ayẹyẹ afihan ounjẹ kan.
Asset Declaration: Gbogbo ẹni tí ó máa búra wọlẹ́ gẹ́gẹ̀ bíi Mínísítà gbudọ̀ kéde dùkìá
Ọ̀kan lára àwọn Mínísítà tuntun
Igbimọ eleto idajọ to n gbọ ẹsun iwa aṣemaṣe awọn eeyan to dipo oselu mu ati oṣiṣẹ ọba, CCB ti paṣẹ fun awọn ti aarẹ Buhari fẹ yan sipo minisita lati kede dukia wọn ki wọn to ṣebura wọle tabi ki w n koju ofin.
Ajọ naa n gbero lati ṣewadi awọn dukia naa ni ẹka ijọba to n ṣabojuto ọrọ ilẹ, ile ifowopamọ ati awọn ile iṣẹ ti wọn ba ni, ati eyi ti wọn ba nipin ninu rẹ.
Oríṣun àwòrán, @PeckyOfficial/Twitter
Mínísítà tó bá kọ̀ láti kéde dùkìá yóò kojú òfin
Siwaju si, ajọ naa yoo tun ṣiṣẹ pẹlu ile iṣẹ otẹlẹmuyẹ lati wadi awọn dukia ti wọn ba ni ni oke okun.
Alaga CCB, Prof. Muhammed Isah wi pe ko si ẹnikẹni ninu awọn minisita tuntun naa ti wọn yoo ṣebura wọle fun lai kọkọ kede dukia wọn.
Àìsàn jẹ́ kí àwọ̀ ara Amida dàbí ara ẹja
O tun ni lara awọn minisita yii ti gba iwe ikede dukia bẹẹni awọn miran ko tii gba.
Lekki Toll Gate: Ìjọba ìpínlẹ̀ Èkó fajúro lórí ìpolówó tó ṣe àfihàn obìnrin ní ìhòòhò
Oríṣun àwòrán, @LASAAONLINE
Ijọba ipinlẹ Eko ti bẹnu atẹ lu bi ọlọkọ kan ti ṣe afihan awọn obinrin to n jo ni ihoho nitagbangba.
Ọga agba ileeṣẹ to n dari ọrọ to ni ṣe pẹlu sisẹ ipolowo ọja nitagbangba, Bolaji Sanusi lo sọ ọrọ yi ninu atejade kan .
Ọrọ yi ko ṣẹyin fọnran fidio kan to gbode lori ayelujara, nibi ti awọn obinrina kan ti ko wọ aṣọ tin jọ ninu ọkọ kan lopopona ibode Lekki si Ikoyi.
Sanusi ni labẹ akoso Gomina Babajide Sanwo-Olu, ijọba lodi si iwa kankan ti yoo tapo si aṣọ ala ilu Eko, labẹ pe wọn fẹ polowo ọja
''Ko si ẹni ti yoo sa pamọ si abẹ ika kan pe oun n ṣe ipolowo ọja lati ṣe afihan ihoho eleyi ti o lodi si aṣa wa.''
''Ijiya to tọ la o fi jẹ ẹni to ba ni ọkọ yi gẹgẹ bi ofin ti ṣe laa kalẹ.''
Ẹwẹ, Ileeṣẹ ipolowo ọja loju opo Twitter wọn lawọn ti wọgile iwe aṣẹ ileeṣẹ Provision Media System to ni ọkọ naa. Loju opo Facebook wọn ni wọn fi ọrọ yi si.
Lojuopo Twitter,orisisisi iriwisi lo ti tẹle fọnran fidio yi to ṣe afihan awọn obinrin to n jo ni ihoho ninu ọkọ kan.
Bi awọn kan ti ṣe n ṣe n bu ẹnu atẹ lu iwa yi lawọn miran n ni kii ṣe oun toju o riiri.
Labẹ ofin ipinlẹ Eko, ẹni kẹni to ba kopa ninu afihan ti ko bojumu yala pẹlu ẹlomiran, tiṣẹ si ofin, ti ẹni naa si le ṣẹwọn ọdun mẹta ti ile ẹjọ ba ni o jẹbi ẹsun naa.
Bisi Alimi: Ìyà mi rò pé n kò leè ṣe ni àmọ́ n kò ní ìfẹ́ abo ni mo ṣe fẹ́ akọ
Àwọn to n bá ẹlẹkun sunkún ní Ghana
#Revolution March: Ìjọba Buhari ń wùwà bíi ìjọba Abacha lórí ọ̀rọ̀ Ṣoworẹ- Ṣoyinka
Oríṣun àwòrán, Twitter/Presidency
Ọjọgbọn Wole Soyinka ti sọ pe ijọba aarẹ Muhammadu Buhari n wuwa bi  ijọba ologun labẹ oloogbe aarẹ Sani Abacha.
Soyinka bu ẹnu ẹtẹ lu bawọn ọlọpaa ọtẹlẹmuyẹ ṣe mu ajefẹtọ ọmọniyan, Omoyele Sowore nile rẹ.
Ọjọgbọn Soyinka ni o dabi igba tawọn agbesunmọmi mu yan lọganjọ oru nile rẹ.
Soyinka ni igbesẹ naa lodi sẹtọ ọmọniyan Soworẹ gẹgẹ bi ọmọ orilẹede Naijiria.
Soyinka ṣalaye pe ko si ohun kan to tumọ si iditẹ gbajọba ninu gbogbo ọrọ ti Sowore sọ.
Bakan naa, agbẹjọro ati ajafẹtọ ọmọniyan, Femi Falana na sọ pe ṣisẹ iwọde ko ni ohun kankan ṣee pẹlu iditẹ gbajọba.
O sọ pe ọmọ Naijiria lẹtọọ labẹ ofin lati fẹhonu wọn han lori ohun ti ko ba tẹ wọn lọrun.
Ayinla Kollington: ọ̀rẹ́ ni èmí àti Barrister kó tó jáde láyé
Àìsàn jẹ́ kí àwọ̀ ara Amida dàbí ara ẹja
Ẹwẹ, ile iṣẹ ọtẹlẹmuyẹ ti ṣalaye pe Sowore n gbero lati fi ifẹhonu han da Naijiria ru pẹlu awọn kan nilẹ okere lati ṣe mu.
Agbẹnusọ fun ile iṣe ọtẹlẹmuyẹ sọ fun BBC awọn fọwọ ofin mu Ṣoworẹ nitori o n gbero lati ditẹ gbajọba orilẹede Naijiria pẹlu ifẹhonu han.
Ile iṣẹ ọlọpaa ko sọ bo ya awọn yoo mu ẹnikẹni to ba kopa ninu iwọde ọhun lọjọ Aje.
Aláàfin: Àìrí iṣẹ́ ṣe ọ̀dọ́ lágbègbè mi ń peléke, ó sì nílò àmójútó
Oríṣun àwòrán, Alaafin Oba Adeyemi III
Alaafin tilu Ọyọ, Ọba Lamidi Ọlayiwọla Adeyeme Kẹta ti rawọ ẹbẹ si gbajugbaja olokoowo nii, Aliko Dangote lati nawọ iranwọ rẹ fi da ile iṣẹ silẹ ni agbegbe rẹ.
Oba alade naa fi arọwa yi sita lopin ọsẹ nibi ipade kan pẹlu igbimọ alakoso ile iṣẹ Dangote nilu Eko.
Oba adeyẹmi tun kan saara si Dangote fun igbiyanju rẹ lati wa ọna jijẹ-mimu fawọn ọdọ Naijiria, eleyi to ni o jẹ ọna kan gbogi lati mu idagbasoke ba orileede Naijiria.
Ninu ọrọ rẹ, Dangote seleri lati wa wọrọkọ fi ṣada lori ohun ti Alaafin beere, pẹlu afikun pe oun ṣetan lati mu anfaani ile iṣẹ ati idokoowo wa si agbegbe rẹ, eyi ti yoo mu adinku ba iye awọn ọdo ti ko niṣẹ lọwọ.
Dangote ni agbajọwọ bayi laa fi sọya ati pe, o ṣe pataki lati pese ọna iṣẹ fawọn ọdọ gẹgẹ bi ọna kan lati dẹkun iwa janduku to n peleke lawujọ wa.
Oríṣun àwòrán, Alaafin of Oyo
''Bi a ba fẹ jẹ mudunmudun ohun ta ṣiṣẹ fun, o di dandan ki a mu aabo ni pataki. Iṣẹ aabo ilu kii ṣe ti ijọba nikan, bi kii ṣe ti gbogbo wa. A si nilo owo lati le ri ṣe''
Saaju ni Alaafin ti mẹnuba ipenija aisiṣẹ fawọn ọdọ lagbegbe rẹ ati jakejado Naijiria.
Revolution protest: Àjọ DSS ṣàlàyé ìdí tí wọ́n fi gbé Sowore
Oríṣun àwòrán, omoyele
Ajọ ọlọpaa ọtẹlẹmuyẹ DSS ti fidi rẹ mulẹ pe lootọ, oun l'oun mu oludije fun ipo aarẹ tẹlẹ ninu ẹgbẹ oṣelu African Action Congress, Omoyele Sowore si ahamọ.
"Ọgbẹni Sowore, to jẹ oludasilẹ ileeṣẹ iroyin Sahara Reporters, jẹ ọkan lara awọn to ṣe agbatẹru iwọde kan ti ẹgbẹ Global Coalition for Security and Democracy in Nigeria, fẹ ẹ ṣe ni ọjọ Aje, ọjọ karun un oṣu Kẹjọ ọdun 2019 ṣugbọn ileeṣẹ ọlọpaa sọ pe ""ete iditẹ gba ijọba ni iwọde naa."""
Agbẹnusọ fun ajọ DSS, Peter Afunaya sọ fun BBC pe, awọn lọ ọ gbe oludasilẹ iwọde naa, ti wọn pe 'Revolution Now' ni owurọ ajọ Abamẹta to kọja, nitori pe oun n pe fun iditẹ gba ijọba.
Ṣaaju ọjọ naa ni ikọ Coalition for Revolution ti Sowore da silẹ, ke si awọn ọmọ Naijiria kaakiri orilẹede yii lati jade si igboro, ki wọn si beere fun opin si aisi aabo ni Naijiria.
Oríṣun àwòrán, @YeleSowore
Ẹgbẹ naa tun n beere fun ẹkọ ọfẹẹ, ati eto ilera fun gbogbo eniyan, ati eto ọrọ aje to dara.
Amọ ajọ DSS ko sọ boya wọn yoo mu ẹnikẹni to ba yọju fun iwọde naa l'ọjọ Aje.
Awọn ileeṣẹ iroyin kan sọ pe, agbẹnusọ ajọ DSS, Afunaya sọ pe awọn gbe igbesẹ naa ni ibamu pẹlu ojuṣe wọn l'abẹ ofin.
Osun Osogbo: OSUCCIMA ní òun yóò lo ọdún Ọṣun Osogbo pèsè iṣẹ́ àti àgbéga okoòwò aládàáni
Oríṣun àwòrán, Osun Osogbo Festival
Nibayii ti ajọdun Ọsun Osogbo n bẹrẹ loni ọjọ Aje pẹlu eto 'Ìwọ́ Popo', ti wọn fi n fọ ilu mọ ni ilana ibilẹ wa, wọn ti gba awọn ileesẹ nlanla nimọran lati fi ọwọ sowọpọ nidi sise agbelarugẹ ajọdun naa.
Adele oludari agba fun ajọ to n ri si eto okoowo, ileesẹ nlanla, eto iwakusa ati ọgbin nipinlẹ Ọsun, OSUCCIMA, Oloye Jide Falọdun lo rawọ ẹbẹ bẹẹ, to si tun woye pe ko si orilẹede to lee goke agba laisi agbega asa rẹ.
Falọdun ẹni to woye ọrọ yii lasiko to n gbalejo ileesẹ to n fọnrere ajọdun Ọsun Osogbo fun tọdun yii, Esquire Global, tun fọwọ gbaya pe ajọ naa ti setan lati sugba ijọba ipinlẹ Ọsun ati igbimọ to wa fun agbega asa ni Ọsun lọna ati jẹ ki ajọdun ọdun yii kẹsẹ jari.
Oríṣun àwòrán, Osun Osogbo Festival
Atẹjade kan ti Tunde Muraina, tii se oludari ileesẹ naa salaye pe ajọ OSUCCIMA tun ti se agbekalẹ ajọdun miran ti wọn pe ni Community Day Cultural Festival eyi ti yoo wa fun ipese isẹ ati agbelarugẹ awọn olokoowo aladani.
Bakan naa ni Muraina kede pe, gbogbo awọn ileesẹ to ba kopa ninu ajọdun tuntun yii ni yoo ni anfaani fun afihan awọn ọja ati isẹ ọwọ wọn.
Muraina wa rọ ajọ OSUCCIMA lati pese awọn ohun eelo ibaraẹnisọrọ igbalode feto idokowo fun awọn ileesẹ ti yoo fọwọsowọpọ pẹlu ajọ naa, ki wọn lee ba ilana katakara lagbaye fun saa onka ẹgbẹrun ọdun ta wa yii mu.
Oríṣun àwòrán, Osun Osogbo Festival
O ni eyi yoo seranwọ fun awọn asaaju awujọ, asaaju ẹgbẹ oselu, awọn ọmọ Naijiria loke okun, awọn onileese nlanla atawọn olokooowo aladani ti ko lee wa sibi ajọdun Ọsun Osogbo lọdun yii, ni anfaani lati kopa latipasẹ awọn ẹrọ igbalode naa eyi ti yoo dena ẹnawo ati fifi akoko sofo.
Shiite: Ojú Zakzaky kan ti fọ́, májèlé sì wà nínú ara rẹ̀, ìyàwó rẹ̀ kò sì le è rìn mọ́
Oríṣun àwòrán, @Shuleman El-zakzaky
Awọn ọmọ ẹgbẹ Shiitee sọ pe idajọ ileẹjọ giga ipinlẹ Kaduna lọjọ Aje jẹ idajọ ododo to lodi si iwa ika ati iwa tani yoo mu mi.
Ileẹjọ fun  Ibrahim El-Zakzaky ati iyawo rẹ ni beeli lati lọ tọju ara wọn lorilẹede India, bo tilẹ jẹ pe ileẹjọ naa paṣẹ pe kawọn to n ṣeto igbẹjọ tẹ wọn lọ.
Alaga igbimọ awọn ọmọ ẹgbẹ Shiite ti wọn ti n ṣewọde, eyi ti wọn fi n sọ fun ijọba lati fun olori wọn ati iyawọ rẹ lominira, Abdurrahman Abububakar Yola ni, ẹgbẹ Shiite nigbagbọ ninu titẹle ofin ati lilepa alaafia lati yanju aawọ lai lo ipa bo tilẹ jẹ pe ijọba mọọmọ bi awọn ninu.
Ẹ o ranti pe El-Zakzaky ati iyawo rẹ beere fun beeli nitori wọn ṣaisan latimọle ti wọn wa nitori ijiya tawọn ologun fi jẹ awọn mejeeji.
Ẹgbẹ Shiite tun sọ ninu atẹjade ti wọn fi sita pe, bi wọn ti fi El-Zakzaky ati iyawo rẹ mọle nile iṣẹ ọlọpaa ọtẹlẹmuyẹ lodi si ẹtọ ọmọniyan.
Wọn tun fẹsun kan ile iṣẹ ọlọpaa ọtẹlẹmuyẹ pe wọn fun un awọn mejeeji ni mọjele jẹ latimọle, ti oju olori awọn kan si ti fọ nigba ti iyawo rẹ ko lee da rin funra rẹ mọ lai lo kẹkẹ ti wọn fi n tii kiri.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ẹgbẹ naa ni gbogbo ijiya yii latimọle ti jẹ ki El-Zakzaky ati iyawo rẹ ni aarun rọpa-rọsẹ lọpọ igba, eyi si n jẹ ki ẹru maa bawọn pe aarun yii tun le pada ṣe wọn.
Wọn ni oju El-Zakzaky kan fọ nitori ijiya tawọn ologunh fi jẹẹ, ati pe ekeji naa tun le fọ ti ko ba ri itọju gidi lasiko.
Ẹgbẹ Shiite tun sọ pe ninu irora ti ko ṣe fẹnu sọ ni iyawo El-Zakzaky wa nitori ọta ibọn tawọn ologun yin mọ si mwa lara rẹ.
Wọn ni nitori ailera awọn mejeeji ni wọn ko fi le lọ si ileẹjọ fun igbẹjọ lati gba beeli fun wọn lẹẹmeji ọtọtọ bayii.
Ẹgbẹ Shiite tun sọ siwaju si ninu atẹjade ti wọn fi sita pe awọn ile iwosan ni Naijiria ko le ṣetọju El-Zakzaky ati iyawo rẹ ninu oniruuru aarun lo ṣe wọn latimọle ti wa lati ọjọ yii.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Wọn ni afaimọ kọwọ maa bọ sori ti ileẹjọ ko ba fun wọn ni beeli lọjọ Aje.
Ẹgbẹ Shiite ni ijọba Naijiria ko bọwọ fun ofin orilẹede naa, eleyi to mu ijọba ma tẹle aṣẹ ileẹjọ wi pe ki wọn fun El-Zakzaky ati iyawo lominira.
Wọn lo atẹjade naa lati ki awọn ajafẹtọ ọmọmiyan, awọn akọroyin, ati gbogbo eeyan to gbaruku ti ẹgbẹ Shiite nigba ti wọn n ṣe iwọde lati beere idajọ otitọ fun El-Zakzaky ati iyawo rẹ atawọn ti awọn ologun pa niluu Zaria.
Oríṣun àwòrán, @Shuleman El-zakzaky
Ọpọ ẹmi lo ti sun tawọn miiran si farapa ninu ikọlu to waye laarin awọn ọlọpaa ati ẹgbẹ Shiite.
Ìròyìn tó ń tẹ̀ wa lọ́wọ́lọ́wọ́ ní sọ pé ileẹjọ giga ilu Kaduna, ti gba oniduro olori ẹsin Shiite, Ibrahim El-Zakzaky ati iyawo rẹ.
Zakzaky ati iyawo rẹ lo ti wa ni ahamọ lati bii ọdun marun sẹyin, ti ileẹjọ ko si gba oniduro rẹ.
Bakan naa ni ile ẹjọ naa ni El Zakzaky ati aya rẹ ni anfaani bayii lati rin irin ajo lọ gba itọju ni orilẹede India, amọ awọn asoju ikọ olupẹjọ gbọdọ kọwọrin pẹlu rẹ lọ si ibi ti yoo ti gba itọju naa.
Bẹẹ ba gbagbe, awọn ọmọ ẹgbẹ Shiitee lo ti gun le iwọde alagbara eyi to la ẹmi lọ lati bii ọjọ melo kan, ti wọn si n beere fun itusilẹ asaaju wọn to wa ni ahamọ naa.
Lati idaji oni ọjọ Aje, ni awọn agbofinro ti duro wa wa wa si ẹnu ọna abawọle ile ẹjọ naa, ti wọn si n se ayẹwo awn eeyan to fẹ wọle sibẹ.
Ọ̀ṣun Oṣogbo: Èyí ni àwọn ayẹyẹ tí yóò wáyé ní ọjọ́ kọ̀ọ̀kan lásìkò ọdún Ọ̀ṣun Oṣogbo
Oríṣun àwòrán, Osun Osogbo
Inu osu Kẹjọ ọdọọdun ni ọdun Ọṣun Oṣogbo maa n waye ni ojubọ Ọṣun, eyi ti ẹgbẹlẹgbẹ awọn olujọsin ati oluworan maa n peju si jakejado agbaye.
Akoko ọdun Ọṣun Oṣogbo yii jẹ asiko yatayoto nilu Osogbo, ti wọn si tun maa n lo akoko naa lati se etutu fun ilu tabi fọ ilu mọ ni ilana ti ibilẹ.
A gbọ pe ọdun Ọṣun Oṣogbo ti le ni ẹẹdẹgbẹrin ọdun to ti bẹrẹ, a ko si lee sọ nipa isẹdalẹ ọdun Ọṣun Oṣogbo, ka ma mẹnuba itan idasilẹ ilu Osogbo funra rẹ.
Gẹgẹ bi itan ti fi ye ni, awọn eeyan kan ti Olutimẹyin, ogboju ọdẹ ko sodi, lo de idi agbami odo nla kan, ti wọn n pe ni odo Ọṣun., ti wọn si tẹdo seti odo naa, lọna ati gba awọn eeyan rẹ silẹ lọwọ iyan ati ebi.
Ibudo yii ni wọn wa ti Yemoja ti wọn n pe ni Ọṣun fi yọju si Olutimẹyin, ti onitọun naa si rọ Ọṣun lati lewaju oun ati awọn eeyan rẹ ls si ibi ti wọn yoo tẹdo si ta mọ si ilu Oṣogbo bayii.
Oríṣun àwòrán, Osun osogbo
Ọṣun seleri lati raga bo wọn pẹlu ileri pe awọn naa yoo maa pada wa ni ọdọọdun lati wa maa bọ oun bii orisa.
Awọn eeyan naa faramọ oun ti Ọṣun beere yii, ti ọdun Ọṣun Oṣogbo si maa n waye lọdọọdun lati igba naa wa, titi di oni yii.
Ọsẹ meji ni wọn fi maa n se ọdun Ọṣun Oṣogbo, eyi to maa n kun fun oniruuru eto to jẹ mọ aṣa ibilẹ lati gb ajọdun naa larugẹ.
Awọn eto to maa n waye lasiko ọdun Ọṣun Oṣogbo:
Iwọ Popo ni wọn maa fi n bẹrẹ ọdun Ọṣun Oṣogbo lọdọọdun, asiko yii si ni awọn olujọsin ati awsn oluworan yoo maa yi ilu po lati fọ ilu mọ pẹlu adura ati etutu.
Oríṣun àwòrán, @osunosogbo2019
Eto keji to tun kan fun ọdun Ọṣun Oṣogbo ni titan fitila oloju mẹrindinlogun. Lẹyin ọjọ kẹta ti ọdun Ọṣun Oṣogbo  bẹrẹ si ni eto naa yoo waye.
Wọn yoo tan fita to ni oju mẹrindinlogun titi di opin ajọdun naa.
A gbọ pe fitila ti wọn n tan yii ti le ni ẹẹdẹgbẹta ọdun.
Oríṣun àwòrán, Osun osogbo
Eto kẹta to tun maa n sami ọdun Ọṣun Oṣogbo ni eto Ibọ ori ade. Eto yii lo n se akojọpọ awọn oniruuru ade isẹmbaye ti awọn ọba ilu Oṣogbo, taa mọ si Ataoja, ti lo kọja, ti wọn yoo si lo wọn fun iwure lati gba ibukun.
Lasiko eto yii ni Ataoja to wa lori oye yoo wa nikalẹ, to fi mọ Arugba Ọṣun, Yeye Ọṣun, awọn arugba to ti gbe igba Ọṣun tẹlẹ, to fi mọ awọn olujọsin Ọṣun miran.
Lara awọn eto to se pataki lasiko ọdun Ọṣun Oṣogbo ni igba riru lọ si ojubọ Ọṣun Oṣogbo.
Omidan ti ko tii mọ ọkunrin, ti wọn n pe ni arugba, ni yoo ru igba naa, tawọn eeyan si maa n ri oun gangan bii orisa ti wọn yoo maa sọ isoro wọn fun, bo ba se n lewaju wọn ru igba to kun fun ohun etutu, lọ si ojubọ Ọṣun.
Ọjọ ti wọn ba lọ si ojubọ Ọṣun Oṣogbo yii ni asekagba, ti ọpọ eeyan jakejado Naijiria ati loke okun yoo si pejọ si ojubọ Ọsun lati beere ohun kan tabi omiran tabi lati gbe bi ayẹyẹ naa se n lọ fun araye.
Oríṣun àwòrán, Osun Osogbo
Lọwọlọwọ bayii, ọdun Ọṣun Osogbo ti di itẹwọgba jakejado agbaye, tawọn onileesẹ nla nla si n wa lati ilẹ okeere wa se onigbọwọ rẹ. Bakan naa lọdun 2005 ni ajọ UNESCO ti kede pe ọdun Ọṣun Oṣogbo ti di ibudo ajogunba lagbaye.
Lara anfaani ti ọpọ eeyan n jẹri si pe o wa ninu bibọ Ọṣun Oṣogbo ni pe o jẹ orisa ọlọmọ, to si maa n pese ọmọ fun awsn agan tabi dahun awọn adura miran.
Ooni: Mo rọ àwọn àgbẹ̀ àti darandaran láti gba ìrẹ́pọ̀ láàyè
Oríṣun àwòrán, Ooni of Ife
Ọọni tilu Ile Ifẹ, Ọba Adeyẹye Ẹnitan Ogunwusi Ọjaja Keji, ti rawọ ẹbẹ si awọn agbẹ ati darandaran lati wa ni irẹpọ, ki ounjẹ lee tubọ buyaari fun wa.
Aba Adeyẹye, ẹni to parọwa yii ni aafin rẹ lasiko ayẹyẹ ọdun isu tuntun tun sọ pe, ti ọwọn gogo ounjẹ ba fi wa nitori ija awọn agbẹ ati darandaran, a jẹ pe a n kọ lẹta ipe fun aisan ni.
O ni ounjẹ aṣara loore nikan lo lee le aisan jinna si agọ ara wa.
Ọba Ogunwusi ni laipẹ ni wọn yoo pada si ohun to n waye ni atijọ nidi dida awọn ọja tuntun silẹ si ni ilu Ile Ifẹ.
Oríṣun àwòrán, Ooni of Ife
Ọọni Ifẹ ni ọja Ejigbo Mẹkun ti wa lati ẹẹdẹgbẹta ọdun sẹyin, bi wọn si se se agbende rẹ pada ni ọdun yii se afihan ohun rere to n bọ.
Eid-el Kabir: Saudi ṣàtúnṣe lílẹ òkò mọ́ Asitani láti dẹ́kun títẹra-ẹni-pa
Oríṣun àwòrán, Twitter/Nigeria Hajj Comm
Iṣẹ haji
Awọn alaṣẹ orilẹede Saudi Arabia ti ṣe atunṣe lilẹ oko mọ Asitani mẹta ni Muna lọkọ keji tawọn oniṣẹ Haji ba goke Arafat.
Wọn ti ṣagbekalẹ ẹrọ kan eleyi ti yoo dena titẹ ara ẹni nibi ti wọn ti ju oko mọ Asitani bẹrẹ lati ọdun 2019.
Aṣoju ajọ to n ri si eto Haji ni Naijiria, Dokita Tanko Aliyu lo fọrọ naa lede niluu Muna.
Snake Market: Àwọn òńtàjà ẹran ejò ní ẹran ejò dùn ju ẹran adìẹ lọ
Igbesẹ yii wa lara itọpinpin lati rii wi pe eto jiju oko mọ Asitani ti yoo waye lọjọ kẹwaa Oṣu kẹjọ lọ ni irọwọ rọsẹ.
Bakan naa, atunṣe yii waye nitori ọpọ ẹmi lo ti sun nigba tawọn oniṣẹ Haji n lẹ oko mọ Asitani fu ọpọlọpọ ọdun.
Dokita Aliyu rọ awọn ọmọ Naijiria ti wọn ni Haji lati ran ara wọn leti iṣepataki titẹle atunṣe tuntun nigba ti asiko ba to lati lẹ oko mọ Asitani lọjọ kẹwaa oṣu kẹjọ.
O ṣalaye pe ni isọri isọri lawọn to n ṣiṣẹ Haji yoo maa lọ sibi ti wọn yoo ti lẹko mọ Asitani lati le dena titẹ ara ẹni pa.
Èdè Yorùbá: Àjọ̀dún àádọ́ta ọdún Ẹgbẹ́ Akọ́mọlédè àti Àṣà Yorùbá Nàìjíríà
Ayẹyẹ lati dawọọ Ẹgbẹ Akọmọlede ati Aṣa Yoruba Naijiria ti wọn da ẹgbẹ ọhun silẹ.
Ilu Kabba nipinlẹ Kogi ni eto naa ti bẹrẹ lọjọ karun un oṣu kẹjọ, eto yii yoo tẹsiwaju di ọjọ kẹjọ oṣu kẹjọ ko to kasẹ nilẹ.
Aarẹ ẹgbẹ naa ninu ọrọ ikini sibi ipade naa fawọn oloye ẹgbẹ lami ẹyẹ fun iṣẹ takuntakun ti wọn ti ṣe.
Wọnyi ni diẹ lara aworan to ṣapejuwe bi eto naa ṣe lọ niluu Kabba nipinlẹ Kogi
Oyo SUBEB: Ayédèrú ní ìròyìn tó ní à ń gba ènìyàn sísẹ́
Oríṣun àwòrán, Ministry of information, Oyo
Ajọ to n risi eto ẹkọ ni ipinlẹ Ọyo, Oyo SUBEB ti n se iwadii lori awọn to gbe iroyin ayederu jade pe ijọba ipinlẹ Ọyọ n gba awọn olukọ sisẹ.
Alaga ajọ Oyo SUBEB, Dokita Nureni Aderemi Adeniran lo sọ eyi ninu atẹjade kan ti wọn fi lede ni ipinlẹ naa.
Adeniran ni irọ patapata ni wi pe, awọn n gba eniyan si isẹ ni ipinlẹ naa, nitori naa ki awon araalu mase jẹ ki wọn lu wọn ni jibiti owo, lasiko ti wọn ba n wa isẹ.
Adeniran wa kilọ fun awọn ara ilu wi pe, awon n sa ipa lati mu awọn to gbe iroyin ẹlẹjẹ yii ni ori ẹrọ ayelujara, ki awọn lee fi wọn jofin ijọba.
Alaga ajọ Oyo SUBEB naa wa parọwa si awọn to n wa isẹ lati farabalẹ, ki wọn ma ba a lugbadi awọn onijibiti.
Revolution Now: Deji Adeyanju ní ìwọ́de míràn ń bọ̀ ní Satide tí wọn kò bá fi Sowore sílẹ̀
Oríṣun àwòrán, @YeleSowore
Ajafẹtọ ọmọniyan kan, Deji Adeyanju ti ni Omoyele Sowore to wa ni iahamọ ọlọpaa DSS, ti kọ lati gba ounjẹ ni ọwọ awọn ọlọpaa lati ọjọ ti wọn ti ti i mọle.
Adeyanju sọ eyi lasiko to n ba BBC Yoruba sọrọ lori ipo ti Sowore wa, ẹni to jẹ adari fun awọn afẹhọnu han to n pe fun atunse eto ijọba lorilẹede Naijiria, eyii to fa a idi ti wọn fi ti i mọle.
Adeyanju ni lẹyin ti Sowore kọ lati gba ounjẹ ni ajọ DSS wa gba awọn ẹbi ati ọrẹ rẹ nimọran, lati ma a gbe ounjẹ wa fun un lojoojumọ.
Ajafẹtọ ọmọ eniyan naa, ni awọn ko le e sọ pato igba ti ijọba yoo fi Sowore silẹ nitori o ti yẹ ki wọn fi silẹ tabi ki wọn gbe lọ si ile ẹjọ gẹgẹ bi ofin ti sọ.
O fikun pe awọn yoo se ifẹhọnu han miran ni Ọjọ Satide, Ọjọ Kẹwa, Osu Kẹjọ, ọdun 2019, ti ijọba ba kọ lati fi silẹ ni Ọjọ Abamẹta.
Bakan naa ni Adeyanju ni awọn mọkanlelogun eniyan to fẹhọnu han ni ipinlẹ Eko ni Ọjọ Karun un , Osu Kẹjọ, ọdun 2019 ni o si wa ni atimole ọlọpaa ni agbeegbe Panti to jẹ Olu-ile isẹ ọlọpaa ni ipinlẹ Eko.
Ajafẹtọ naa wa fikun wi pe ifẹhọnu awọn ko nii se lati gba ijọba pẹlu ipa, amọ awọn n bere fun ijọba to bun iyi kun awọn ọmọ Naijiria, ki eto aabo orilẹede Naijiria gbooro si, ati wi pe ki alaafia ki o jọba ni Naijiria.
Yoruba ni taa ba ni eegun baba ẹni yoo jo, amọ ti ko ba jo mọ, ko si ẹni to lee mu ni si.
Bẹẹ ni ọrọ ri pẹlu awọn ọmọ ẹgbẹ Revolution Now to n se iwọde lati beere fun ijọba to duro re ni orilẹede Naijiria, nigba ti wọn pinnu pe awọn ko jade mọ fun iwọde ita gbangba ti wọn bẹrẹ lọjọ Aje.
Gẹgẹ bi akọroyin BBC Yoruba ti se akojọpọ rẹ, awọn eeyan to n se iwọde naa ni wọn ti fi ipade si oni ọjọ Isẹgun pe awọn yoo tẹsiwaju pẹlu iwọde awọn, lẹyin ti awọn ọlọpaa fi afẹfẹ alata ati tajutaju tu wọn ka lọjọ Aje.
Sugbọn iyalẹnu lo jẹ fun wa nigba ti ikọ iroyin wa de adugbo Ọjọta, amọ ti eegun awọn oluwọde Revolution Now ko sẹ nibẹ, bi o tilẹ jẹ pe awọn ọlọpaa ati ọmọ ogun ti duro wa wa wa si agbegbe naa, lati wa pade awọn oluwọde ọhun.
Nigba ti akọroyin wa pe ọkan lara awọn eeyan to n lewaju iwọde naa, Usman Oloyede lori aago, lori idi ti wọn ko fi kofiri wọn lati wa tẹsiwaju ninu iwọde ti wọn n se, Oloyede fesi pe awọn ko lee jade sita mọ wa se iwọde .
Kii se dandan ki awọn eeyan ri wa loju koroju pe a n se iwọde ni ibikibi lorilẹede Naijiria, amọ gẹgẹ bi awọn ọmọ Naijiria ti n joko sile, maa fi ẹhonu han ninu ọkan wọn, naa ni awa naa fẹ maa se pẹlu. Inu ọkan wa ni awa naa ti fẹ maa fi ẹhonu han.
Oloyede tun fikun pe, ohun to mumu ju laya awọn bayiii ni bi awọn yoo se gba idande awọn ọmọ ẹgbẹ Revolution Now tawọn ọlọpaa mu si ahamọ, ti awọn yoo si fi isu si ina, maa fi inu wa ọbẹ lori igbesẹ to ku ti awọn yoo tun mu pọn lori ifẹhonuhan wọn ọhun.
Oríṣun àwòrán, @YeleSowore
Ẹgbẹ kan to n se atilẹyin fun aarẹ Muhammadu Buhari nidi eto iroyin, BMO, ti kesi Ọjọgbọn Wọle Soyinka, Fẹmi Falana atawọn ọmọ orilẹede yii miran, to koro oju si bawọn ọtẹlẹmuyẹ se gbe asaaju ẹgbẹ Revolution Now, Omoyele Sowore si ahamọ, pe ki wọn pa ẹnu wọn mọ.
Atẹjade kan ti alaga ẹgbẹ BMO naa, Niyi Akinsiju ati akọwe rẹ, Cassidy Madueke fisita wa bu ẹnu atẹ lu Soyinka, Falana atawọn ẹlẹgbẹjẹgbẹ ajafẹtọ ẹni miran, fun bi wọn se n se koriya fun awọn eeyan ti wọn fẹ da rogbodiyan silẹ lorilẹede Naijiria.
Ẹgbẹ naa wa rọ awọn eeyan to lami laaka lorilẹede Naijiria lati maa sọrase, ki wọn si maa huwa ọlọgbọn lasiko ti wọn ba n dasi ọrọ ilu lọna ati mase bu epo eebo si rogbodiyan to wa nilẹ.
Awa mọ pe igbesẹ to tọ ni ijọba Naijiria gbe pẹlu bi wọn se da oniwahala lẹkun lati mase fi tipa gba ijọba to ni atilẹyin ofin. Gẹgẹ bii orilẹede to sẹsẹ seto ididbo tan lawọn ipinlẹ ati nijọba apapọ, ko si idi kankan fun awọn eeyan kan tabi ẹgbẹ kankan lati wa ọna ti wọn yoo fi se ayipada ijọba to wa lode.
Ẹgbẹ BMO tun ni oun fẹ ran Ọjọgbọn Soyinka atawọn eeyan rẹ yoku leti pe awọn agbofinro kii sadede gbe ẹnikẹni lọna aitọ, ayafi ti ẹri to daju ba wa nilẹ pe irufẹ awọn eeyan bẹẹlatipasẹ iwa, ise ati ọrọ ẹnu wọn, jẹ ewu nla fun eto aabo, irẹpọ ati isọkan orilẹede yii.
Police Ondo: Láìpẹ́ ni ọwọ́ yóò tẹ àwọn agbébọn tó wa òṣìṣẹ́ wa
Oríṣun àwòrán, @PoliceNG
Awọn gende agbebọn ti yinbọn pa osisẹ ọlọpa kan ti wọn pe orukọ rẹ ni Lasisis lasiko to wa loju popo se ayẹwo ọkọ lopopona Isua-Ise-Akoko nipinlẹ Ondo.
Awọn agbebọn ọhun, ti ko si ẹnikẹni to mọ idamọ wọn, lo sadede bẹ jade lati inu igbo to wa lẹba opopona naa, ti wọn si n yinbọn mọ awọn ọlọpa naa, ti wọn wa lati agọ ọlọpa Isua.
Nigba to n fi idi isẹlẹ naa mulẹ, osisẹ alarina fun ileesẹ ọlọpa ipinlẹ Ondo, Fẹmi Joseph salaye pe awọn osisẹ ọlọpa ti n finmu finlẹ lati se awari awọn olubi ẹda to sisẹ laabi ọhun.
A ti n sisẹ kara lati mọ awọn eeyan naa, laipẹ laijinna si ni ọwọ wa yoo tẹ wọn ninu igbo ti wọn sa lọ.
Joseph salaye pe, o ti le ọdun kan ti awọn ọlọpa naa ti wa loju popo lati pese eto aabo si agbegbe naa, amọ o se ni laanu pe awọn olubi ẹda naa tun lori laya lati wa kọlu awọn ọlọpa gan.
Tope Alabi: Ìlúmọ̀ọ́ká akọrin ẹ̀mi náà ní ìdílé kòlà-kòṣagbe l'òun ti wá
Oríṣun àwòrán, Instagram/Tope Alabi
Gbajugbaja akọrin ẹmi nni, Tọpẹ Alabi to pe ẹni ọdun mọkandinlaadọta lọjọ Aiku, ọjọ kẹtadinlọgbọn oṣu kẹwaa ọdun 2019 sọ fun BBC Yoruba pe, idile kola-kosagbe ni oun ti wa.
Nigba to sọ nipa igbesi aye rẹ, Tọpẹ Alabi ṣalaye pe ọmọ ọdun meje si ni oun wa, ti wọn ti sọ asọtẹlẹ fun awọn obi oun pe, oun yoo sisẹ sin Ọlọrun.
O ni ọmọ ọdun mẹjọ ni oun wa bakan naa ti oun fi darapọ mọ ẹgbẹ osere Adẹrupọkọ nilu Ibadan lati maa se ere tiata, ki oun to tun lọ sọdọ oloogbe Isọla Ogunsọla
Tọpẹ Alabi to ni oun n kọ ile iwe kan lọwọ fun iṣẹ orin, wa gba awọn eeyan nimọran lati mase lo ẹbun ẹlẹbun, tori o dara ki onikaluku mọ ẹbun ti Ọlọrun ba fun.
Oríṣun àwòrán, Tope Alabi
Nigba to n sọrọ lori awọn ipenija to n koju rẹ, Tọpẹ Alabi ni ọrọ alufansa ti awọn eeyan kan maa n sọ nipa awọn olorin ni kii fun awọn ni iwuri, to si laa pe, oun si n kọ orin nipa ijọba ọrun, tori ko si ohunkohun to lee gba orin ijọba ọrun ni ọwọ oun.
O fikun pe, ọwọ oun di pupọ ni ko jẹ ki oun maa kọ orin fun awọn elere tiata mọ bi o tilẹ jẹ pe, owo ti oun maa n gba fun orin kikọ pọ lọwọ wọn, sibẹ, wọn si maa n fi orin inu ere lọ oun.
Tọpẹ ni ojoojumọ ni oun maa n gba imisi orin lati ọdọ Ọlọrun, to ba si jẹ pe bẹẹ ni oun se n se awo orin jade ni, ilẹ yoo ti kun.
Oríṣun àwòrán, Tope Alabi
O tun salaye pe, oun ko mọ ohunkohun nipa boya awọn alawo lo sin oku adari ijọ to n lọ tẹlẹ nilu Eko, Oloogbe, Oluṣọagutan Iretiọla Ajanaku.
Lasiko to n kopa lori eto kan ni ikanni BBC Yoruba, Tọpẹ Alabi sọ pe, Ọlọrun ti sọ fun oun tẹlẹ ki Ajanaku to ku pe, oun ko gbọdọ lọ si ile ijọsin rẹ mọ, bẹẹ si ni orilẹede Amẹrika ni oun wa nigba ti Ajanaku dagbere faye ati igba ti wọn sin in.
Tọpẹ salaye pe ko si ọ̀rọ̀ ifẹ ikọkọ laarin oun ati ojisẹ Oluwa naa, gẹgẹ bi awọn eeyan kan ti n sọ kiri, pẹlu afikun pe ti iru eyi ba wa, Ọlọrun ni yoo se idajọ laarin awọn.
Oríṣun àwòrán, Instagram/Tope Alabi
O fikun pe o to ọdun meji ti oun ko ti lọ sile ijọsin Ajanaku mọ, ki ojisẹ Ọlọrun naa to jade laye pẹlu afikun pe, gbogbo aye gan lo mọ pe aarin oun ati Ajanaku ko gun mọ ki onitọun to jade laye.
Security: Ìpínlẹ̀ 9 yóò lo ẹ̀rọ ayàwòrán díróònù láti paná ìpèníjà ààbò
ẹ̀rọ ayàwòrán díróònù
Oríṣun àwòrán, @CTAflash
Awọn ipinlẹ kọọkan to wa ni ilẹ Yoruba yoo bẹrẹ si ni lo ẹrọ ofurufuru ayaworan igbalode, taa mọ si Drone, lati ma a fi sọ agbeegbe wọn lọna ati gbogun ti eto aabo to denukọlẹ lorilẹede Naijiria.
Iwadii ti ile-isẹ iroyin Punch gbe jade sọ wi pe, ipinlẹ Eko, Osun, Ogun ati Ondo wa lara awọn ipinlẹ mẹsan, ti ko ni i pẹ ma a lo ẹrọ igbalode yii.
Lara awọn ipinlẹ naa ti yoo tun ni ipin ninu lilo ẹrọ Diroonu naa ni Kaduna, Anambra, Ebonyi, Benue ati Enugu.
Amọ iwadii naa fikun wi pe, ohun to n fa ifasẹyin diẹ nipa lilo ẹrọ diroonu ni iwadii finnifinni lati ọdọ ijọba apapọ, lori iwulo ohun elo naa ni awọn agbegbe to beere fun ‘drone’.
Ti a ko ba gbagbe, laipẹ yii ni Aarẹ Buhari se adehun pẹlu awọn ọba ni iwọ-oorun orilẹede Naijiria wi pe, oun yoo sa ipa oun lati ri wi pe awọn ipinlẹ yii tete ri ẹrọ drone gba, lati gbogun ti eto aabo to mẹhẹ.
Ilé ẹjọ́ pàṣẹ kí EFCC gbẹ̀sẹ̀ lé àpò àsùwọ̀n kan tó ní nkan ṣe pẹ̀lú Akinwumi Ambode
Oríṣun àwòrán, Google
Ile ẹjọ giga ijọba apapọ to wa ni adugbo Ikoyi nilu Eko ti paṣẹ pe ki owo kan to to biliọnu mẹwa Naira, N9.9bn, to jẹ ti ijọba ipinlẹ Eko.
Onidajọ Chuka Obiozor paṣẹ naa lọjọ Aje lẹyin ti ajọ to n gbogun ti iwa ibajẹ ni Naijiria, EFCC, kọ iwe ẹbẹ si ile ẹjọ pe ko ṣe bẹ ki oun le ri aaye ṣe iwadi iwa jibiti kan.
EFCC sọ fun ile ẹjọ lati ti apo aṣuwọn naa titi ti wọn yoo fi pari iwadii kan ti wọn n ṣe. Iwadii naa ni wọn ni o ṣeesẹ ko yọri si ki wọn o fi oju akọwe agba lọọfisi Olori awọn oṣiṣẹ fun Gomina tẹlẹ, Akinwumi Ambode, Adewale Adesanya ba ile ẹjọ.
Gẹgẹ bi agbẹnusọ ajọ EFCC, Tony Orilade ṣe sọ, owo naa, N9,927,714,443.29, lo jade lati inu apo asuwọn ijọba ipinlẹ Eko, to si wọ apo asuwọn miran nile ifowopamọ FCMB kan ti wọn ṣi ni ọjọ kẹtadinlogun, oṣu Kẹsan, ọdun 2017 lasiko iṣakoso gomina ipinlẹ Eko tẹlẹ, Akinwumi Ambode.
Ninu iwe ti EFCC gbe lọ siwaju ile ẹjọ, o fojuhan bi Adesanya ati awọn kan to ni anfaani si apo asuwọn naa ṣe n gba owo jade ninu apo asuwọn ijọba ti wọn si n da a si apo asuwọn miran.
"Agbẹjọro fun EFCC, Mohammed Abbas sọ nile ẹjọ pe ""akọsilẹ fihan bi owo nlanla ṣe n wọ apo asuwọn ti Adesanya n mojuto lati inu aka-nti ijọba ipinlẹ Eko."""
Abbas fi kun pe wọn ti n gbiyanju lati na owo naa, ati pe wọn ko ni i dẹkun iwa jibiti wọn ti ile ẹjọ ko ba gbẹsẹ le apo asuwọn naa.
Eyi lo mi ki Onidajọ Obiozor gba ẹbẹ EFCC wọle, to si sun igbẹjọ si ọjọ kẹsan, oṣu Kẹsan, ọdun 2019.
Seyi Makinde: ₦60m ní mo gbé kalẹ̀ fún ìtọ́jú àwọn akẹ́kọ̀ọ́ ìmọ̀ òfin fún ọdún kan
Oríṣun àwòrán, Seyi Makinde
‘Ẹnikọ̀ọ̀kan nínú àwọn 120 ọmọ ìpínlẹ̀ Ọyọ tó ń kẹ́ẹ̀kọ́ ìmọ̀ òfin yóò gba N500,000’
Gomina Ipinlẹ Ọyọ, Seyi Makinde ti buwọlu owo to to ẹgbẹrun lọna ẹẹdẹgbẹta naira (₦500,000) bii owo iranwọ eto ẹkọ, fun akẹẹkọ kọọkan to wa lati ipinlẹ Ọyọ, ti wọn n kọ ẹkọ imọ nipa ofin ni ileewe imọ ofin(Law School).
Gomina Seyi Makinde lo sọ eyi lasiko to n gba awọn ọmọ ile-iwe imọ ofin naa lalejo ni ilu Ibadan.
Agbẹnusọ fun gomina feto iroyin, Ọgbẹni Taiwo Adisa lo ni gomina naa fi ọgọta miliọnu Naira silẹ lati fi tọju awọn ọmọ alaini lati ipinlẹ Ọyọ to n kẹkọ gboye imọ ofin ni saa ọdun 2019/2020.
Gomina Makinde ni oun gbe igbesẹ naa lati le se koriya fun awọn akẹkọ imọ ofin, ki wọn lee tẹra mọ iwe wọn fun aseyori to lamilaaka.
Seyi Makinde ni owo naa wa fun iranwọ, to si gba awọn akẹẹkọ imọ ofin naa ni imọran, lati ma se na owo ọhun ni inakuna.
Ọdún 2012 ni awọn akẹ́ẹ̀kọ́ ilé ìwé ìmọ̀ òfin tó wà láti ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́ ti gba N100,000 kẹ́hìn gẹ́gẹ́ bí owó ìrànwọ́.
Adewale Adeyemo: Òun ni wọ́n ṣẹ̀ṣẹ̀ yàn sípò ààrẹ fún àjọ Obama Foundation
Oríṣun àwòrán, @tvnigerian
Adewale Adeyẹmọ tii se ọmọ Yoruba ni wọn ti kede bii aarẹ fun ajọ alaanu kan ti aarẹ ana nilẹ Amẹrika, Barrack Obama da silẹ, ti wọn pe ni Obama Foundation.
Adeyẹmọ, ti gbogbo eeyan mọ si Willy, jẹ ẹni ọdun mẹrinlelọgbọn, oun si ni yoo maa se akoso ojuse ati isọwọ sisẹ ajọ naa lati igba de igba, ti yoo si maa ri si amusẹ awọn afojusun ajọ ọhun.
Nigba to n kede Adeyẹmọ bii aarẹ fun ajọ naa, ọkan lara awọn oludari ajọ ajọ alaanu Obama, Martin Nesbitt salaye pe Adeyẹmọ ni ẹni to tọ lati gba ipo naa, ika to tọ si ni awọn fi re imu pẹlu iyansipo rẹ ọhun.
"Ta ba wo iriri to ni lẹnu isẹ ọba ati ti aladani, ati bo se fi tọkan tara sisẹ fun aarẹ tẹlẹ, Barrack Obama, Adeyẹmọ nikan lo kunju osunwọn lati se amusẹ awọn afojusun ajọ yii, ti yoo fi de ibi giga.
Oríṣun àwòrán, @tvnigerian
Adeyẹmọ lo ti sisẹ saaju gẹgẹ bii oludamọran fun ijọba aarẹ Obama lori eto ọrọ aje lọdun 2015, ti ojuse rẹ nigba naa si jẹ sise akoso awọn ilana to jẹ mọ eto ẹnawo, okoowo ati idokowo, ohun amusagbara ati ọrọ to jẹ mọ ayika.
Awọn obi Adewale Adeyẹmọ la gbọ pe wọn wa jijẹ mimu lọ silẹ Amẹrika lati orilẹede Naijiria.
Ẹgbẹ́ Akọ́mọlédè: A kan sáárá sí ìpínlẹ̀ Eko fún sísọ èdè Yorùbá di dandan nílé ẹ̀kọ́
Aarẹ ẹgbẹ Akọmọlede ati Aṣa, Arabinrin Ọmọwumi Falẹyẹ ti parọwa si awọn ijọba ipinlẹ to wa nilẹ Kaarọ Oojiire, lati tẹwọgba ede Yoruba, ki wọn si maa se agbega rẹ nigba gbogbo.
Aya Falẹyẹ rawọ ẹbẹ yii ninu ọrọ ikinni kaabọ rẹ nibi ayẹyẹ iside ipade apero ọlọdọọdun ẹgbẹ Akọmọlede ati Aṣa Yoruba, eyi ti wọn tun fi n sami aadọta ọdun ti wọn da ẹgbẹ naa silẹ, to waye nilu Kabba, nipinlẹ Kogi.
Aarẹ ẹgbẹ Akọmọlede, ẹni to mọ riri awọn ijọba ipinlẹ to sọ ede Yoruba sisọ ati kika lawọn ileewe di kanpa, tun mọọmọ gbe osuba fun ijọba ipinlẹ Eko fun igbesẹ naa, to si rọ awọn ipinlẹ yoku ti ko ba tii se bẹẹ lati fi ipinlẹ Eko ṣe awokọṣe rere.
Mo n rọ awọn ijọba to n dari awọn ipinlẹ to wa nilẹ Yoruba lati sọ ede Yoruba sisọ ati kika di kanpa lawọn ileẹkọ alakọbẹrẹ ati girama ni ipinlẹ koowa wọn, ki gbogbo wa si pawọpọ maa polongo agbega ede Yoruba kari aye."""
Bakan naa lo tun rọ awọn obi lati fọwọsowọpọ pẹlu awọn olukọ, nipa sise afihan ifẹ wọn si ede abinibi, aṣa ati iṣe ilẹ Kaarọ Oojire lasiko ti awọn ọmọ wọn ba wa nile tabi nile ẹkọ laisi ifiyajẹni.
Nigba to n mẹnuba awọn iṣoro to n ba ẹgbẹ Akọmọlede ati Aṣa Yoruba finra, aarẹ ẹgbẹ naa beere fun atilẹyin awọn ẹlẹyinju aanu, oninu rere, awọn eeyan ti Ọlọrun  bẹ igi ọla fun lawujọ ati awọn ileeṣẹ nlanla, lati wa yọ ẹgbẹ naa ni ọfin awọn iṣoro to jin si, nipa aini irinṣẹ to pegede.
Ẹgbẹ Akọmọlede wa dupẹ lọwọ ijọba ipinlẹ Kogi fun bo se gba ẹgbẹ naa lalejo, fun ayẹyẹ aadọta ọdun wọn, ti wọn si gbadura pe iwaju ni ọpa ẹbiti ipinlẹ naa yoo maa re si.
Lara awọn eto pataki to waye lasiko ajọdun aadọta ẹgbẹ naa ni gige akara oyinbo, ọdun Ogun bibọ, abẹwo si awọn ibudo manigbagbe ati fifun awọ̀n eeyan jankan jankan lami ẹyẹ.
Busola Dakolo: Ẹ̀sùn tí mo fi kan pásítọ̀ ìjọ COZA ṣì dúró digbí
Oríṣun àwòrán, Busola dakolo
Busola Dakolo sọ fun BBC lọsan Ọjọru pe oun ko tọwọ bọ iwe kankan to tako ẹsun ifipabanilopọ to fi kan Pasitọ agba ijọ Commonwealth of Zian Assembly, Biodun Fatoyinbo.
Ṣaaju ni iwe iroyin UK Guardian fi iroyin sita pe awọn fi ọrọ wa Busola lẹnu wo, o si sọ fun awọn pe awọn ọlọpaa to di ihamọra nkan ijagun fi ipa mu oun tibọn-tibọn lati fi ọwọ si iwe kan ti wọn kọ oriṣiriṣi nkan to le jẹ ẹri pe irọ ni gbogbo ẹsun to fi kan Fatoyinbo si.
Iwe iroyin UK Guardian jabọ pe Dakolo ṣalaye pe ọlọpaa kan gbe ibọn dani, ti ikeji si ni ki oun tọwọ bọ iwe ti wọn lo wa lati ọdọ ọga agba ọlọpaa.
''Ọkan ninu wọn mu ibọn dani ti mo si ri wi pe ẹni keji mu iwe kan lọwọ. Wọn sọ fun mi pe lati ọdọ ọga agba ọlọpaa ni Abuja lawọn ti wa, ti wọn si ni mo ni lati buwọ lu iwe tawọn mu wa.''
Nile Busola Dakolo ati ọkọ rẹ Timi nilu Eko ni wọn ni iṣẹlẹ yi ti waye.
Arabinrin Dakolo sọ pe ọsẹ bi i meji sẹyin ni oun ṣe ifọrọwanilẹnuwo naa pẹlu UK Guardian.
O fi idi rẹ mulẹ lori Instagram pe irọ ni iroyin to n lọ kaakiri igboro pe oun fi ọwọ si iwe naa. O sọ pe ẹjọ ti oun pe sọdọ awọn ọlọpaa ṣi n tẹsiwaju.
Ọlọ́pàá Eko: A ti fi Tekno sílẹ̀ àmọ́ ìwádìí sì ń lọ lọ́wọ́
Oríṣun àwòrán, Social media
Ileeṣẹ ọlọpaa ti fi ọrọ wa gbajugbaja akọrin takasufe, Augustine Kelechi, ti awọn eniyan mọ si Tekno lẹnu wo, lẹyin to rin kiri igboro ilu Eko ninu ọkọ kan pẹlu awọn obinrin to wa ni ihoho.
Fidio kan, to da bi ẹni pe lati inu ọkọ miran ni ẹni to ya a ti ya aworan naa, ṣafihan ọkunrin kan to joko sinu ọkọ akẹru naa, ti wọn fi gilaasi sẹ ara rẹ, to si n nawo fun awọn obinrin to n jo pẹlu awọtẹlẹ wọn nikan.
Tekno ti sọ pe fidio naa kii ṣe ipolowo fun ile faaji onihoho kankan.
O sọ pe, oun wa ninu apoti oni gilaasi ọhun ti wọn gbe sinu ọkọ akẹru, ti oun si n lọ lati ibikan si ibomiran lati ya fidio awo orin tuntun.
Oríṣun àwòrán, Tekno/instagram
Laipẹ yii ni Tekno kọrin ninu awo orin gbajugbaja akọrin agbaye, Beyonce.
Alukoro ileeṣẹ ọlọpaa ipinlẹ Eko, Bala Elkana sọ fun BBC pe, awọn ọlọpaa bẹrẹ iwadii lẹyin ti fidio naa fa awuyewuye lori ayelujara.
Iroyin ti kọkọ jade pe, awọn ọlọpaa ti fi panpẹ gbe Tekno, ṣugbọn Ọgbẹni Elkana sọ pe, awọn kan pe e fun ifọrọwanilẹnuwo ni, ati pe fun ra a rẹ lo wa si agọ ọlọpaa lọjọ Iṣẹgun lati sọ tẹnu rẹ lori ọrọ naa.
Wayi o, Tekno tọrọ aforiji lori ayelujara Instagram, fun ẹnikẹni ti fidio naa ba bi ninu.
"O ni ""A n ya fidio awo orin lọwọ ni diẹ lara awọn ọkọ ayọkẹlẹ ti a n lo bajẹ, a si nilo ọkọ lati ko awọn eniyan lọ si ibomiran ti a ti fẹ lọ ṣiṣẹ, lo jẹ ka lo ọkọ to ni apoti oni gilaasi naa."""
Ṣugbọn ko ṣalaye idi to fi n ju owo lu awọn obirnin naa lasiko ti wọn n rinrinajo.
Awọn ọlọpaa sọ pe, awọn ti yọnda Tekno, ṣugbọn iwadii ṣi n tẹsiwaju.
Babangida: Èròǹgbà ọmọ Nàíjíríà pọ̀ èyí tó ṣòro láti bá pàdé
Oríṣun àwòrán, Twitter/Presidency
Ọrọ lori orilẹede Naijiria
Olori orilẹede Naijiria tẹlẹ ri, ajagunfẹhinti Ibrahim Babangida ti ṣapejuwe Naijiria gẹgẹ bi orilẹede to ṣoro lati dari.
Babangida fọrọ yii lede lasiko tawọn alaṣẹ ẹgbẹ oṣelu PDP kan sii nile rẹ niluu Minna, ni ipinlẹ Niger.
Babangida tun lo anfani naa lati kepe awọn aṣofin gbọdọ ṣiṣẹ takuntakun lati rii wi pe orilẹede Naijiria wa ni iṣọkan.
O ṣalaye pe, gbogbo ohun to n ṣẹlẹ ni Naijiria ni oun n fi ọkan ba lọ, to si gbe oṣuba kare fawọn alaṣẹ ile igbimọ aṣoju ṣofin l'Abuja, adari ile ati gbogbo ile lapapọ.
O rọ wọn wi pe, ki wọn maa kaarẹ ninu akitiyan lati ri wi pe Naijiria toro, nitori oriiṣiriiṣi erongba lawọn ọmọ Naijiria ni eyi to jẹ ko ṣoro fun awọn alaṣẹ lati dari.
Babangida fun wọn ni idaniloju pe, oun wa pẹlu wọn ninu igbesẹ wiwa ilọsiwaju fun orilẹede Naijiria.
O tun gba wọn nimọran pe, ki wọn mase gbagbe lati mu awọn ileri ti wọn ṣe fawọn to dibo yan wọn lẹkun ti wọn n ṣoju sẹ, nibayii ti wọn ti wa nile aṣofin l'Abuja.
Revolution Now: Iléejọ́ ní àjọ DSS kò láṣẹ láti ti Sowore mọ́lé ju ọjọ́ 45 lọ
Oríṣun àwòrán, @YeleSowore
Ileẹjọ giga ijọba apapọ to wa nilu Abuja ti pasẹ fun ajọ ọtẹlẹmuyẹ ilẹ wa pe ko gbọdọ fi asaaju ikọ to n se iwọde Revolution Now, Omoyele Sowore, si ahamọ kọja ọjọ marundinlaadọta lọ.
Omoyele Sowore ni awọn osisẹ ajọ ọtẹlẹmuyẹ mu si ahamọ wọn lọjọ Satide to kọja saaju iwọde ẹgbẹ Revolution Now to waye lọjọ Aje, ti wọn si tun gba ile ẹjọ lọ pe awọn fẹ gba asẹ lati fi asaaju ikọ oluwọde naa si ahamọ fun aadọrun ọjọ, tii se osu mẹta gbako.
Amọ lasiko to n gbe idajọ rẹ kalẹ lori ẹjọ kanmọ n kia ti ajọ ọtẹlẹmuyẹ naa pe, Adajọ Taiwo Taiwo salaye pe ajọ agbofinro naa lee pada wa beere afikun ọjọ to fẹ fi fi Sowore si ahamọ rẹ, lẹyin asẹ ọjọ marundinlaadọta ti oun pa fun.
Adajọ Taiwo ni oun fun ajọ DSS lasẹ lati fi Sowore si ahamọ ko fi pari iwadi rẹ to n se ni nitori ajọ naa nilo akoko si lati fi ẹnu iwadi rẹ jona.
Nibi igbẹjọ naa ni ajọ DSS ti se afihan awọn fidio gẹgẹ bii ẹri to n se afihan pe Sowore lọ se ipade pẹlu olori ikọ Biafra tijọba ti fofin de, Nnamdi Kanu, ati eyi to fi n parọwa si awọn ọmọ ẹgbẹ Shiite lati dara pọ mọ ikọ Revolution Now, ki wọn le doju ijọba ilẹ wa bolẹ.
Adajọ Taiwo ti wa sun igbẹjọ naa di ọjọ Kọkanlelogun osu Kẹsan ọdun 2019.
Shiite: Ìjọba Kaduna ní òun yóò pe ẹjọ́ láti tako El-Zakzaky tó fẹ́ gba ìtọ́jú ní India
Oríṣun àwòrán, Shuhaila El-Zakzaky
Ijọba ipinlẹ Kaduna ti kede pe oun ko faramọ asẹ ti ileẹjọ pa pe ki wọn fun olori ijọ Shiite, Ibrahim El Zakzaky ati iyawo rẹ ni aaye lati lọ gba itọju loke okun.
Amọ o fikun pe ti asẹ naa yoo ba mulẹ, awọn gbedeke kan wa ti oun yoo gbe kalẹ, eyi ti olori ijọ Shiite naa ati iyawo rẹ ti wọn dijọ n jẹjọ lọwọ, gbọdọ tẹle ki ọna to si silẹ fun wọn.
Ninu atẹjade kan ti ijọba ipinlẹ Kaduna fisita lati ipasẹ Kọmisana rẹ fun eto iroyin, Samuel Aruwan ni eyi ti jẹyọ pẹlu afikun pe ijọba ipinlẹ Kaduna yoo pe ẹjọ tako asẹ ileeẹjọ naa, eyi to fun El Zakzaky ati iyawo rẹ laaye lati lọ gba itọju loke okun.
Ijọba Kaduna ni bi o tilẹ jẹ pe oun maa n bọwọ fun ẹtọ ọmọniyan lati wa itọju fun ara rẹ ni ibikibi lagbaye amọ nibamu pẹlu aṣẹ ileẹjọ naa, awọn igbesẹ kan gbọdọ wa ti olori ẹsin naa gbọdọ tẹle, ki oun to lọ.
Oríṣun àwòrán, Shuhaila El-Zakzaky
Revolution Now: NLC ní bí agbófinró ṣe mú Soworẹ àti àwọn yókù rẹ̀ sí àhámọ́ tẹ ẹ̀tọ́ ọmọnìyàn lójú
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ẹgbẹ oṣiṣẹ l'orilẹede Nigeria, NLC, ti keboosi pe ki wọn o tu Omoyele Sowore ati awọn oludije miran silẹ ni kiakia.
"Ẹgbẹ osisẹ, ninu atẹjade kan ti Akọwe apapọ rẹ, Comrade Peter Ozo-Eson fi sita, kede pe o jẹ iyalẹnu bi awọn oṣiṣẹ alaabo ""ṣe kọlu awọn to ṣe iwọde Revolution Now l'ọjọ Aje, ti wọn si mu wọn lọ si ahamọ."
NLC tọka si i pe, ẹtọ gbogbo ọmọ Naijiria ni labẹ abala ofin ikọkandinlogoji ati ogoji ninu iwe ofin Naijiria, lati ṣe iwọde ti ko ni jagidijagan, ti wọn si tun ni ẹtọ lati korajọpọ tabi darapọ mọ ipejọpọ to ba wu wọn.
"O ni ""Oju ti a fi wo bi awọn oṣiṣẹ alaabo ṣe kọlu awọn oluwọde alaafia ọhun, ni titẹ ẹtọ ọmọniyan loju."""
"Iwọde alaafia tako iṣejọba ti ko dara tabi awọn igbesẹ ati ilana ijọba ti ko dara fun araalu, jẹ ọkan lara awọn ẹtọ ọmọniyan to ṣe koko, to si n mu ki eto iṣejọba awaarawa o dagba si.
A ko si gbọdọ fi aaye gba awọn oṣiṣẹ alaabo wa, lati maa fi ara wọn han gẹgẹ bi ọta iṣejọba awa ara wa gẹgẹ bo ṣe han ninu iwa wọn l'ọjọ Aje."
RevolutionNow: Ẹ̀rù ò bàwá, a ṣetan láti wà ní àtì mọ́lé- olùfẹ̀hónúhàn
Bakan naa ni Ọgbẹni Ozo-Eson tun sọ pe, bi awọn oṣiṣẹ ajọ alaabo DSS ṣe fi oludasilẹ iwọde Revolution Now, Omoyele Sowore si ahamọ, ko ba oju mu to, nitori pe igbesẹ Sowore ko fi ibi kankan dunkooko mọ iṣọkan tabi ijọba Naijiria.
Iléeṣẹ́ ọlọ́pàá: Irọ́ ni kìí ṣe èèsì, ẹ mọ̀ pé ọlọ́pàá ni wọ́n, kẹ tó yìnbọn
Oríṣun àwòrán, Alamy
Ileesẹ ologun ati ọlọpaa ti n tako ra lori idi tawọ̀n ologun se yinbọn pa ọlọpa mẹta ati araalu kan lasiko ti wọn gbe gbajumọ ajinigbe kan.
Aarẹ Muhammadu Buhari ti pa asẹ fun olu-ile isẹ ọmọogun lorilẹede Naijiria lati bere iwadii lori isẹlẹ to mu ẹmi ọlọpaa mẹta lọ.
Oluranlọwọ Aarẹ Muhammadu Buhari lori ọrọ iroyin, Bashir Ahmad lo fi lede lori ẹrọ ikansiraẹni Twitter rẹ.
Aarẹ Buhari ni ibanujẹ lo jẹ fun oun pe ẹmi awọn akọgun to lọ lẹnu isẹ nitori naa lo se pe fun iwadii lẹsẹkẹsẹ lori isẹlẹ naa.
Isẹlẹ naa ni se pẹlu ikọ ọmọogun 93 Battalion ni ilu Takum, ni ipinlẹ Taraba.
Ileesẹ ologun ati ọlọpaa ti n tako ra lori idi tawọ̀n ologun se yinbọn pa ọlọpa mẹta ati araalu kan lasiko ti wọn gbe gbajumọ ajinigbe kan.
Ileeṣẹ ologun Naijiria ti sọ pe awọn ọmọ ogun oun ko mọọmọ yinbọn pa awọn ọlọpaa ati araalu to ku ní ìpinlẹ Taraba.
Adele Oludari ẹka ibaṣepọ araalu nileeṣẹ ologun  Ọgagun Sagir Musa, lasiko to n fesi si atẹjade kan lati ileeṣẹ ọlọpaa pe, salaye pe awọn ọmọogun lo gba ipe lati wa doola ẹnikan ti awọn ajinigbe ji gbe, loju ọna Ibi-Wukari nipinlẹ Taraba.
Musa ṣalaye wi pe, awọn bẹrẹ si ni le ọkọ 'awọn afurasi ajinigbe' naa nitori wọn kọ lati duro ni ibudo ayẹwo mẹta, ti awọn ọmọ ogun ti da wọn duro.
"Asiko ti awọn ọmọ ogun n le wọn yii ni awọn afurasi naa bẹrẹ si ni yinbọn si awọn ọmọ ogun, eyi to mu ki awọn naa da a pada fun wọn.
Lasiko naa ni ibọn pa ‘afurasi’ mẹrin loju ẹsẹ, ninu eyi ti ọlọpaa mẹta ati araalu kan wa, ti awọn mẹrin miran si fara gba ọgbẹ ibọn, awọn meji mii si di awati."
Lẹyin eyi ni ọkan lara awọn ọlọpaa to fi ara pa ṣẹṣẹ sọ pe ọlọpaa ni awọn, ati pe, lati olu ileeṣẹ ọlọpaa l'Abuja ni wọn ti ran awọn niṣẹ ikọkọ naa lati lọ gbe balogun ikọ ajinigbe kan.
Oríṣun àwòrán, @HQNigerianArmy
Ileeṣẹ ologun sọ pe, o yẹ ki ileeṣẹ ọlọpaa maa fi to awọn leti to ba fẹ ṣe iru iṣẹ ikọkọ bẹẹ, nitori pe afojusun kan naa ni awọn jọ ni lati fi opin si awọn iwa ọdaran bi ijinigbe, ati awọn ipenija eto aabo miran ni Naijiria, lati le dena iru iṣẹlẹ bẹ ẹ.
Ṣugbọn ileeṣẹ ọlọpaa sọ pe, awọn ọmọ ogun naa tu ogbontagi balogun ajinigbe kan, Alhaji Hamisu silẹ ni ipinlẹ Taraba, to si salọ lẹyin ti wọn  yinbọn pa mẹta lara awọn ọlọpaa to n gbe e lọ si olu ileeṣẹ ọlọpaa, ati araalu kan.
Oríṣun àwòrán, @NPF_NIGERIA
"Ileeṣẹ ọlọpaa sọ loju opo Twitter rẹ pe ""awọn ọmọ ogun yinbọn laimọye igba mọ awọn ọlọpaa naa, botilẹ jẹ pe o fojuhan pe ọlọpaa ni wọn, ti wọn si wa lẹnu iṣẹ ilu."
O ti pẹ ti ileeṣẹ ọlọpaa ti n wa Hamisu fun ijinigbe l'oriṣiriṣi to ti waye lati ọwọ rẹ. Eyi to ṣe kẹyin ni ti oniṣowo epo ti wọn jigbe, ti wọn si gba ọgọrun miliọnu Naira, ki wọn to tu u silẹ.
Ni bayii, ileeṣẹ ọlọpaa sọ pe iwadii ti n lọ lori nkan to fa iṣẹlẹ iṣekupani ọhun.
Operation Amotekun: Amotekun dé! Ìgbáradì yóò gbérasọ l'Ekiti lọ́jọ́ Àìkú tó ń bọ̀
Oríṣun àwòrán, Western Nigeria security network
Amọtẹkun dee! Ọga ajọ ẹṣọ alaabo Amọtẹkun nipinlẹ Ekiti, Brig. Gen Joe Komolafe ti kede pe awọn to ti forukọ silẹ fun eṣọ naa pe wọn yoo bẹrẹ
igbaradi lọjọ Aiku ọjọ kẹtadinlọgbọn oṣu kẹsan an ọdun 2020.
Ọgagun Komolafe ni ọdunrun un eeyan le mẹẹdogbọn(325) lo wẹ yan kain-kain ninu awọn igba eeyan le ni ẹgbẹrun mẹta(3,261).
O ṣalaye pe fasiti ipinlẹ Ekiti  to wa ni Ifaki-Ekiti ni igbaradi naa yoo ti waye fun ọsẹ mẹta gbako.
Ọgagun Komolafe kilọ fawọn ọdaran to wa ni ipinlẹ Ekiti pe ki wọn lọ tọwọ ọmọ wọn bọ aṣọ nitori Amotekun ti gberasọ.
O ni ọgbọnjọ oṣu kẹsan Ọjọru ni ọjọ to kẹyin tawọn to forukọ silẹ naa ni lati de si ibi igbaradi ọhun.
Ọgagun Komolafe sọ pe lẹyin igbaradi ni wọn yoo gbe awọn to ti forukọ silẹ kaakiri ipinlẹ Ekiti lati ṣiṣẹ pọ pẹlu awọn oṣiṣẹ eto alaabo mii.
A kò lè gbà kí ìjọba àpapọ̀ ṣ'agbátẹrù Amotekun, ìjọba ilẹ̀ Yorùbá yarí
Ajọ to n ri idagbasoke awọn ipinlẹ Yoruba (Development Agenda for Western Nigeria Commission), DAWN ti tako ọrọ ti oludamọran Aarẹ Muhammadu Buhari sọ lori ọrọ iroyin, Garba Shehu sọ pe ọga agba ọlọpaa ni yoo sọ bi ìkọ Amotekun yoo ṣe maa ṣiṣẹ.
Shehu ni alakalẹ ọga ọlọpaa ni Naijiria ni ìkọ Amotekun yoo duro le lori.
Shehu ṣalaye pe awujọ ni Amotekun yoo ti maa ṣiṣẹ, nitori awọn awujọ yii gan an lo ni Amotekun.
Oludamọran Aarẹ ni alakalẹ kan naa ni ọlọpaa agbegbe ti ijọba apapọ fẹ da silẹ laipẹ yoo maa tẹle.
Amọ, oludari ajọ DAWN to n ri si idagbasoke awọn ipinlẹ Yoruba, Ọmọwe Seye Oyeleye ni ko sọrọ kankan ninu gbogbo ohun ti Garba Shehu sọ kalẹ.
Ọmọwe Oyeleye ṣalaye pe ile igbimọ aṣofin mẹfẹẹfa lawọn ipinlẹ Yoruba lọ ṣe agbekalẹ ofin idasilẹ Amotekun.
O ni oun ko mọ ohun ti Garba Shehu n sọ pẹlu pe ọga agba ọlọpaa ni yoo ṣagbatẹru bi Amotekun yoo ti maa ṣiṣẹ, ayafi to ba jẹ pe ofin ọga ọlọpaa gaju ofin awọn ipinlẹ Yoruba lọ loku.
Oyeleye ni idasilẹ Amotekun ko le ṣe idiwọ fun eto ọlọpaa agbegbe ti ijọba apapọ fẹ da silẹ.
Bakanna ni oludamọran fun Gomina ipinlẹ Ondo lori ọrọ aabo, Alhaji Jimoh Dojumo sọ pe bi Amotekun yoo ṣe maa ṣiṣẹ wa ninu ofin to gbe e kalẹ.
Ọgbẹni Dojumo ni ọrọ ti Shehu sọ fihan pe kọ mọ nipa ofin to da ikọ Amotekun silẹ.
'ìjà ṣẹlẹ̀ láàrín èmi àti ọ̀gá mi ní Lebanon tórí mi ò lè dá N300K padà'
Dandan ni pe ki ijọba beere lọwọ awọn babalawo lori ọrọ Amọtẹkun, bii bẹẹ kọọ, eto naa ko le kẹsẹjari.
Babalawo kan niluu Ibadan, Oloye Idowu Olukunle Adewole, Akọda Awo nijọba ibilẹ Ọna Ara lo kin ọrọ ti Oloye Sunday Adeyemo lẹyin bẹẹ.
Sunday Adeyemo, ti ọpọ mọ si Sunday Igboho lo sọ ninu fidio BBC Yoruba pe, awọn to ba fẹ darapọ mọ ikọ Amọtẹkun gbọdọ maa fi Ogun bura.
Babalawo Adewole ni fifi Ogun bura wa lara awọn ilana ti awọn to ba fẹ darapọ mọ ikọ Amọtẹkun gbọdọ tẹle gẹgẹ bi Sunday ṣe sọ.
Akoda Awo sọ pe, eto to dara ni idasilẹ Amọtẹkun, amọ ko le si aṣeyọri kankan nibẹ, ayafi ti awọn babalawo ba daa si ọrọ naa lati ṣe atọna ijọba.
Sunday Igboho: Ẹ fi Ògún búra fún wa láti jà fún ilẹ̀ Yorùbá láì gbé Amotekun sábẹ́ ìjọba
O ni Ifa nikan lo le ṣalaye ọna ti wọn le rin ti wọn ko fi ni kuna, Akoda Awo ni lọdọ awọn babalawo si ni Ifa wa.
Babalawo Adewole ni awọn babalawo lo mọ itumọ aye, o ni ilana ẹsun musulumi ati kristẹni ko le mu eto naa kẹsẹ jari.
''Iṣẹṣe lagba, iṣẹṣe lo ni ile aye, babalawo nikan lo le ṣe etutu ti ọdalẹ ko fi ni raye wọ arin ikọ Amọtẹkun,'' Akoda Awo lo woye bẹẹ.
Ọkan lara awọn agbaagba ilẹ Yoruba Ifayemi Ẹlẹbubọn sọ pe, imọran gidi ni Sunday Adeyemo ti ọpọ mọ si Sunday Igboho gbekalẹ lasiko to ba BBC Yoruba sọrọ, lori ọna lati gbogun ti awọn Fulani to n da eto aabo wa ru lawọn ipinlẹ Yoruba.
Sunday Igboho ṣalaye pe, oun atawọn eeyan kan ti setan lati lọ koju awọn Fulani, ṣugbọn awọn ọba alaye atawọn agbaagba ilẹ Yoruba gbọdọ fọwọ si pe, awọn lo ran awọn niṣẹ, ki omi maa ba tẹyin wọgbin lẹnu.
Nigba to n sọ ero rẹ lori imọran naa, Ẹlẹbubọn ni ọrọ ti Sunday Igboho sọ ṣe pataki nitori ''igi kan ko le dagbo ṣe igbo, aja to ba si lẹni lẹyin ni p'ọbọ, ẹnikan ko le maa ṣe ohun kan, ko maa lawọn eeyan to n ti lẹyin.''
Ẹlẹbubọn ṣalaye pe, ọrọ ti Sunday Igboho sọ yii pe fun apero awọn agbaagba Yoruba nitori ''ti eeyan yoo ba jagun, ọrọ lo n bẹ nidi rẹ, t'eeyan o ba si ni jagun, ọrọ naa ni n bẹ nidi rẹ.''
Oríṣun àwòrán, Yemi Elebuibon
O fikun ọrọ rẹ pe, lataye baye ni ajinigbe, ole, agbesunmọmi ati awọn ọdaran mii ti wa, ṣugbọn ilu kọọkan nilẹ kuotu ojiire lo ni nnkan iṣọra ti ogun ko fi ni ja ilu.
Ẹlẹbubọn wa ke pe awọn agbaagba ilẹ Yoruba lati ṣatunṣe ''awọn eto ogun ko jalu to wa nilẹ Yoruba kọọkan'', o ni ''ọrọ eto aabo to mẹhẹ ti gba iṣọra ati ifura bayii.''
Oríṣun àwòrán, sunday_igboho
Ọrọ lori awọn ajinigbe nilẹ Yoruba
Agba awo naa ṣalaye pe, ijọba le maa faramọ kawọn ipinlẹ lo ọna ibilẹ lati jagun awọn ajinigbe nitori ko si ninu iwe ofin orilẹede Naijiria, ṣugbọn alatiṣe ni yoo mọ atunṣe ara rẹ.
Ẹlẹbubọn ni o ṣe pataki ki Yoruba pada si awọn nnkan iṣẹnbaye nitori ẹsin ti gba ọpọlọpọ nnkan danu lọwọ ẹya Yoruba.
Orílẹ̀-èdè Togo gbe òfin tuntun silẹ̀ lórí ìwọ́de ìfẹ̀hónu hàn
Orílẹ̀-èdè Togo: Kò sí ààye ìwọ́de ìfẹ̀hónu han mọ́ lórílẹ̀-èdè yìí
Ìlé ìgbìmọ̀ aṣòfin orílẹ̀-èdè Togo, tí jan òfin tuntun tó ni kò si ààyè fún ìwọ́de ìfẹ̀hónú han lọ́ntẹ.
Èyí wáyé lẹ́yìn ti ọ̀pọ̀ àwọn ọmọ ẹgbẹ́ alátakò ń ṣe ìwọ́de lórilẹ̀-èdè náà, òfín tuntun yìí jẹ ọ̀nà láti dẹ́kun ìwọ́de wọn.
Sùgbọ́n ìjọba ní awọn ṣe òfin náà láti mú kíí ààbò tó péye wà lóri ìlú, bótilẹ̀ jẹ́ pé àwọn ọmọ ẹgbẹ́ alátakò ríí gẹ́gẹ́ ọ̀nà láti mú adíkù bá ọ̀rọ̀ ti ará ìlú ń jà sí pé ìdílé kan ṣoṣo ló ti ń ṣe ìjọba láti ọdun 1967.
Kayeefi: Facebook ni Wolii Arole Jesu fi tàn an wọ agbo, orí rẹ̀ ni wọ́n fi s'owó
Lábẹ́ òfin túntún yìí, kò ni sí ààyè fú ẹnikẹ́ni láti ṣe ìwóde lóju pópó, láàrín ìlú tàbí ní agbègbè ilé ìjọba.
Ìwọ̀de kò lè wáyé sáájú aago mọ́kanla àárọ̀ tàbí kọja ààgo mẹ́fa ní ìrọ̀lẹ́, gẹ́gẹ́ bó ti ń ṣẹlẹ̀ sáájú àsíkò yìí, ìjọba Togo lé fòfinde wọ́n pátápátá nítori àwọn ìdí yìí.
Yollywood: Sinimá Ajé Ọjà tún so Fathia àti Saheed Balogun pọ̀ nínú Sinimá
Asa Trokosi nibi ti ọmọde ti n jiyan ẹsẹ mọlẹbi rẹ , wọpọ  ni Ghana, Togo ati Benin.
Ìròyìn fi kún pé òfin náà wáye nítori pé àwọn agbásùmọmi tí n dúnkokó mọ́ ìjọba.
Atúnṣe ti wọ́n ṣe si òfin orílẹ̀-èdè náà fún ààrẹ Faure Gnassingbé wà lórí oye titi di ọdun 2030, èyí ti ó túmọ sí pé tó ba di àsìkò náà ìdíle Gnassingbé ti wà ní ìjọba fún ọdún mẹ́tà lé láàdọ́ta.
Oyo House: Ilé ìgbìmọ̀ Ìpínlẹ̀ Oyo buwọ́lu ìyànsípò kọmíṣọ́nà mẹ́rìnlá àtàwọn míì
Oríṣun àwòrán, Facebook/Oyo State House of Assembly
Ayẹwo fawọn kọmiṣọna tuntun ipinlé Oyo
Ile igbimọ aṣofin Ipinlẹ Oyo ṣayẹwo fun awọn kọmiṣọna mẹrinla ti Gomina Ṣeyi Makinde fi orukọ wọn ranṣẹ sile, bẹẹ ni wọn si buwọ lu iyansipo gbogbogbo wọn.
Orukọ awọn mẹrinla naa ni Gomina Makinde fi ṣọwọ si ile, ti adari ile Ọgbẹni Adebo Ogundoyin, si ka a nibi ijoko ile to waye lọjọbọ.
Mẹrin lara awọn eeyan to fẹ jẹ kọmiṣọna naa ti jẹ asofin ri, awọn eeyan naa ni Ọgbẹni Kehinde Ayoola (adari ile tẹlẹ ri), Amofin Adeniyi Farinto, Iyaafin Funmilayo Orisadeyi (oun nikan lobinrin) ati Ọgbẹni Muyiwa Jacob Ojekunle.
Oríṣun àwòrán, Facebook/Oyo state house of Assembly
Awọn miiran ni Oloye Bayo Ojo, Dokita Bashir Abiodun Bello, Ọjọgbọn Oyelowo Oyewo, Ọjọgbọn Dawud Sangodoyin, Ọgbẹni Olasunkanmi Olaleye ati Ọgbẹni Adeniyi Olabode AdebisiAdebisi.
Awọn to ku ti ile fọwọ si iyansipo ni Ọgbẹni Raheem Abiodun Abdulraheem, Ọgbẹni Seun Asamu, Dokita Wasiu Olatunbosun ati ỌgbẹniAkinola Ojo.
Oríṣun àwòrán, Facebook/Oyo State House of Assembly
Ayẹwo fawọn kọmiṣọna tuntun
Diẹ lara wọn to sọrọ lẹyin ti ile fọwọ si iyansipo wọn gẹgẹ bi kọmiṣọna sọ pe, awọn ri iyansipo awọn gẹgẹ bi anfani lati sin awọn eeyan ipinlẹ Oyo ati lati kopa ninu iṣejọba rere, eyi ti Gomina Ṣeyi Makinde ṣeleri fawọn eeyan ipinlẹ naa.
Bakan naa, ile tun buwọlu iyansipo Ọmọwe Nureni Adeniran gẹgẹ bi alaga igbimọ to ri si eto ẹkọ kariaye nipinlẹ Oyo, State Universal Basic Education Board(SUBEB), ti Ọgbẹni Akeem Oladeji ati Ọgbẹni Dayo Ogungbenro si jẹ ọmọ igbimọ naa.
Oríṣun àwòrán, Facebook/Oyo State House of Assembly
Ayẹwo fawọn kọmiṣọna tuntun
Adari ile, Asofin Debọ Ogundoyin, ninu ọrọ tiẹ ṣapejuwe gbogbo awọn kọmiṣọna tile buwọlu iyansipo wọn naa, gẹgẹ bi awọn to kọṣẹ mọṣẹ ti wọn si jẹ olori pipe ẹda ninu iṣẹ ti wọn yan laayo.
Gomina Makinde yoo ṣe ibura fun gbogbo wọn laipẹ.
#WhereIsEspiritDCorp: Ohun tó kọjú sẹ́nìkan, ẹ̀yìn ló kọ sí ẹ́lòmíì lọ̀rọ̀ yìí lórí ayélejára
Oríṣun àwòrán, Twitter/Nigeria Police Force
Ikọlu ọlọpaa ati ologun
Oju opo Twitter ti kun pitimu nipa ero awọn ọmọ Naijiria lori ibeere ti ileesẹ ọlọpa ilẹ wa n bi ileesẹ ologun pe, ki wọn salaye bi ọlọpa mẹta se di ero ọrun lati ipasẹ ibọn tawọn ologun yin mọ wọn niluu Takum, ni ipinlẹ Taraba.
Awijare tileesẹ ologun fisita lori isẹlẹ naa ni pe, awọn ro wi pe ajinigbe lawọn ọlọpaa ọhun, eyi lo jẹ ki awọn dabọn bo wọn.
Ileesẹ ologun ati ọlọpaa ti n tako ra lori idi tawọ̀n ologun se yinbọn pa ọlọpa naa ati araalu kan lasiko ti wọn gbe gbajumọ ajinigbe kan.
Ṣugbọn awọn ọmọ Naijiria ti dasi ọrọ naa lori ayelujara bayii, bawọn kan ti n daro awọn to ba iṣẹlẹ naa lọ, lawọn miiran n dẹbi ru awọn ologun ati aarẹ Muhammadu Buhari.
@bdexibojo ni tiẹ sọ pe, ile iṣẹ ologun loun wa lẹyin wọn nitori awọn lo n gbogun ti awọn agbesunmọmi, ti wọn si n fi ẹmi wọn lelẹ fun orilẹede Naijiria.
O ni ohun kan tawọn ọlọpaa mọ ni lati maa ge ẹmi awọn ọdọ kuru kaakiri orilẹede Naijiria.
@MakemeslayC kọ nkan to da bi ewi lori ọrọ yii, o ni ologun pa ọlọpaa, ọlọpaa n pe awọn ologun lapaniyan loju opo Twitter.
O ṣalaye siwaju si pe, ile iṣẹ ọlọpaa ni irọ ni awọn ologun n pa pe o ṣeeṣi ni, o pari rẹ pẹlu aworan Aarẹ Muhammadu Buhari nibi to ti n ta eyin.
Favour Onyeoziri sọ pe iku to n pa ojugba ẹni, owe lo n pa fun ni, o ṣalaye pe tawọn ologun ba n yinbọn pa ọlọpaa, a jẹ wi pe kawọn oloṣelu ti wọn maa n lo ọlọpaa ati awọn ologun gẹgẹ ẹṣọ kiyesara.
Onyeoziri fikun ọrọ pe, ọpọlọpọ ohun to n lọ lorilẹede Naijiria lo pe fun ki ijọba gbe igbesẹ lori wọn, ki wọn lee dẹkun wọn.
Ibeere ni Ikemba 1 fọrọ naa beere ni tiẹ. O ni iyalẹnu lo jẹ f'oun pe ile iṣẹ ọlọpaa le sọ pe ile iṣẹ ologun n huwa ta ni yoo mu mi.
O ni idunnu lo jẹ f'oun pe oun wa laaye nigba ti iru iṣẹlẹ yii ṣẹlẹ papaa julọ iha ti ile iṣẹ ọlọpaa kọ si iṣẹlẹ ọhun.
Epe rabandẹ ni @legendarylekzzy fi ranṣẹ si awọn ọlọpaa, o ni Ọlọrun lo maa fiya jẹ wọn.
O sọ pe asiko yii ni wọn ṣẹṣẹ mọ irora ti awọn ọmọ Naijiria maa ni ti iru iṣẹlẹ bayii ba ṣẹlẹ si wọn.
Soyinka: Ohun gbogbo ti dẹnu kọlẹ̀ la ṣe gbọdọ̀ gbé ìgbésẹ̀ pàjáwìrì
Oríṣun àwòrán, @Opetuyii
Yoruba ni agba ti ko ba kẹun sọrọ, yoo kẹ itan sare nitori agba kii wa lọja, ki ori ọmọ tuntun wọ.
Idi ree ti ilumọọka alami ẹyẹ agbaye, Ọjọgbọn Wọle Ṣoyinka fi n lọgun pe aarẹ orilẹede yii, Mohammadu Buhari pe yoo dara ko kede pe nnkan ko fararọ lawọn ipinlẹ to wa nilẹ Yoruba lẹka eto aabo, ti ohun gbogbo si ti dẹnu kọlẹ.
Soyinka, ẹni to mu igbe yii bọnu lasiko to n bawọn akọroyin sọrọ nilu Akurẹ nibi ayẹyẹ kan, tun salaye pe o n bọ, o n bọ, awọn laa dẹ de, amọ laye ode oni, oju ni wọn n mu to, nitori eto aabo ti mẹhẹ nilẹ Kaarọ Oojire kọja sisọ, o si yẹ ko wa nkan se nipa rẹ.
Oríṣun àwòrán, @Opetuyii
Oniruuru ọna ni eto aabo fi mẹhẹ, paapa nipinlẹ Ondo, to si tun jẹ ohun ibanujẹ nla yika orilẹede Naijiria, nitori naa, igi gogoro ma gun mi loju, ati okeere laa ti lọọ, idi si ree taa fi gbọdọ gbe igbesẹ pajawiri lati rẹyin aifararọ eto aabo naa.
Soyinka ni iwa isekupani ni aimọye ọna ti gba akoso ni gbogbo ọna lẹkun iwọ oorun guusu Naijiria, ti iwa ijinigbe naa ko si gbẹyin, wọn si ni ma fi oko mi sọna, ọjọ kan bayii ni eeyan maa n kọ ọ.
Eid el Kabir: Ọjọ́ márùn-ún ló ṣe kókó nínú iṣẹ́ Hajj
Oríṣun àwòrán, @tabir
Nibayii ti ọdun ileya n kan ilẹkun, ti awọn musulumi to wa ni orilẹede Saudi Arabia si n gbaradi lati gun oke Arafat, o yẹ ka la ara wa lọyẹ lori ohun ti isẹ Hajj wa fun, ati bi wọn se n se e ki wọn to pe eeyan ni Alhaji abi Alhaja.
Lootọ ọdọọdun ni awọn musulumi jakejado agbaye máa n peju sí orilẹede Saudi láti kópa nínú ìjọsìn fun eto Hajj sugbọn iye ọjọ ti wọn fi n ṣe eto Hajj yii gan kò fẹ jù ọjọ márùn ùn lọ,
Ọna làti ṣètò fawon obitibiti èèyàn tó máa n kópa nínú ìjọsìn yíi, ni àwọn aláṣẹ ilẹ Saudi se fi ọjọ pupọ sílẹ saaju àti lẹyìn eto Hajj, kí gbogbo ètò bàa lè lọ ní irọwọrọsẹ.
Oríṣun àwòrán, @IzetQuotes
Fún ẹni tó bá lọ̀ fun Hajj, àwọn iṣẹ kan ṣé kókó tí wọn gbọdọ kopa nínú rẹ tí Hajj náà bá fẹ jẹ itẹwọgbà, ní meni méjì, àwọn iṣẹ náà ree pẹlu àlàyé ṣókí.
Ihram ní wọn máa n pé aṣọ funfun ti awọn alalaaji máa n wọ lásìkò Hajj.
Bi èèyàn yóò bá kópa nínú Hajj, o di dandan fún àwọn ọkùnrin láti wọ asọ yí nikan lásìkò tí wọn yóò fi ṣé ìjọsìn.
Lásìkò tí wọn bá wà ni Oke Arafat, aṣọ yíi nikan ni wọn yóò wọ títí ti won yóò fi sọ oko tán lọjọ kejì.
Arafat ní ayé kan ti won n pé ni Jamrah.
Bi wọn bá soko tán lọjọ yii, ti wọn sì fà ori wọn, wọn lè e bọ asọ naa kuro lara, sugbọn awon obirin kìí bá wọn wọ asọ Ihram yii.
Gẹgẹ bí àwọn onimọ ẹsin ti ṣàlàyé, ni kete ti oorun ba tí fẹ lọ wọ lọjọ Arafat, ní àwọn Alalaaji yóò gbéra lọ sún laaye kan ti wọn n pé ni Muzdalifa.
Ita gbangba lórí ebutu ni won yóò sun si.
Ọpọ nínú Alalaaji yóò ti ra ẹni kékeré lọwọ láti fi sun níbẹ.
Tí ilẹ bá sì ti mọ,ní wọn yóò padà sí inu atibaba wọn tó wà ní ilu Mina, níbí ti wọn yóò ti lọ sọ oko mọ Asetani ní Jamrah ti a ṣàlàyé ṣaaju.
Pàtàkì  ìjọsìn yíi ni pé awọn alalaaji n fí kọ iṣé Anobi Ibrahim ati ọmọ rẹ, nígbà tí wọn sọ oko mọ Asetani to fẹ dena wọn nínú ìjọsìn.
Òkúta kekeke ni wọn má n lẹ mọ àwọn opo mẹta tí wọn fí ṣe àpèjúwe Asetani.
Gbogbo Alalaaji ló gbódò sọ òkúta yií lọjọ Kejì ti wọn ba gun Arafat ati ọjọ kẹta Arafat.
Ọjọ àpéjọ ní ọjọ yií jẹ fawọn Alalaaji, tí àkọsílẹ sí wa pé ẹni tí kò bá b'awọn lọ sí Arafat kò ní Hajj.
Àwọn orílè-èdè àti ẹyà orísirísi ló má n kópa nínú Arafat yii.
Kii ṣé dandan kí Alalaaji gún orí òkè Arafat ko to kópa nínú isọri isẹ yii.
Gbogbo ilẹ tó yí oke Arafat ká ní ilẹ mimọ.
Nítorí pé èrò máa n pọ lọjọ yí, àwọn aláṣẹ ti gbe atibaba tí wọn ti ga kalẹ pẹlú ẹrọ amuletutu (AC) sínú rẹ.
Ní ọjọ Arafat láwọn Alalaaji máa n tọrọ aforijin ẹsẹ, ti wọn sì máa n wà ìyọnu Allah.
Àwọn tí kò lọ sí Hajj naa má a n gbà awẹ lati pa ọkan mọ pẹlú àwọn tó wà ní Hajj.
Ìtàn Mánigbàgbé: Ìtàn tó rọ̀ mọ́ ìdí tí wọn ṣe ń pe aya ní ìyàwó
Oríṣun àwòrán, @jenneric
Ni aye ode oni, ede to wọpọ julọ ti awọn eeyan maa fi n pe obinrin ta ba fẹnisu-lọka, to n ba ni gbe inu ile ni 'Iyawo' eyi ti a lee sọ pe ko ri bẹẹ ni aye atijọ, tori aya ni wọn n pe obinrin ta fẹ sile, gẹgẹ bii ojulowo ede Yoruba ti kọ ni.
Koda, a lee ni ko si ohun to jọ ede ti wọn n pe ni iyawo lode oni ninu ede Yoruba, bi kii ba se isẹlẹ kan to waye lasiko kan, eyi to mu ki Iyawo wọ inu ede Yoruba, ti wọn si tun n pe awọn aya ni ọọdẹ ọkọ ni iyawo.
Ni igba iwasẹ, nigba ti oju si wa ni orunkun, ilu kan wa ti wọn n pe ni ilu Iwo lẹba ilu Osogbo, eyi to si wa titi di aye ode oni.
Aba Iwo lo bi ọmọbinrin orekelẹwa kan, to dun wo, to si jẹ oju ni gbese eyi ti wọn n pe ni Wuraọla.
Wuraọla dagba, o si di ẹni to to lọ sile ọkọ. Ọpọ ọkunrin lo n jẹ dodo ẹwa ti Ọba oke fi jinki omidan ọlọpọ ẹwa yii, to si n da gbogbo ọkunrin lọrun bii ọlẹlẹ aawẹ.
Apọnbeporẹ, ẹlẹyinju ẹgẹ, ibadi aran, idi ilẹkẹ ayilukọ ni Wuraọla, ko si si ẹni ti yoo pade omidan yii lọna, ti ko ni gbadura pe ki ori jẹ ki oun fi se aya, tori ọba oke pari isẹ si lara.
Ni aarin ilu Iwo, gbogbo ọkunrin to wa nibẹ lo n tọ Wuraọla lọ pe o wu awọn lati fi se aya, yoo si dara ko ju ọwọ silẹ fun awọn, ki awọn lee tọju rẹ.
Gẹgẹ bẹẹ se mọ pe ọmọ ọla tun ni Wuraọla yatọ si pe o tun jẹ ọlọpọ ẹwa, ọwọ ifẹ ti awọn ọkunrin si n na si omidan naa ko ni itumọ kankan sii, tori ko jẹ hoo fun ọkunrin kankan laarin wọn, to si maa n fi ọpọ wọn se akọ.
Lọpọ igba ni yoo maa yọ aleebu ara awọn ọkunrin to ba dẹnu ifẹ kọọ ni ọkọọkan lọna ati le wọn kuro ni sakani rẹ.
Oun ni yoo ri ọkunrin to mukun, eyi ti oju rẹ da, eyi ti ẹnu rẹ n run ati eyi to burẹwa, ti ko si si ọkunrin kankan to tẹ Wuraọla lọrun laarin ilu Iwo.
Ni ọpọ awọn ilu okeere naa, awọn ọkunrin ko dẹyin lati maa wa beere ọwọ Wuraọla llati fi se aya.
Awọn akinkanju ọkunrin, olowo, ọlọrọ ati ọkunrin to jẹ oju ni gbese lo n nawọ ifẹ si Wuraọla, ti wsn si n wa lati ilu odikeji.
Lara wọn la ti ri Ogun, Sango, Ọbatala ati bẹẹ bẹẹ lọ, ti wọn n ya kẹtikẹti wa silu Iwo pẹlu erongba lati fi Wuraọla se aya, sugbọn ibinu nla ni wọn n ba kuro, ti ibanujẹ yoo si dori agba wọn kodo tori Wuraọla ko setan lati fi eyikeyi wọn se ade ori rẹ.
Yatọ si pe ọmọge yi n ja wọn kulẹ lai jẹ hoo fun wọn, se ni yoo tun maa sọ ọrọ alufansa, ọrọ kobakungbe si wọn lasiko ti wọn ba dẹnu ifẹ kọọ,
eyi to mu ki gbogbo wọn tete maa ba ẹsẹ wọn sọrọ nitori wọn ko lee farada eebu to n bu wọn yii.
Ni ọjọ kan, Ọrunmila, ti oun naa jẹ arẹwa ọkunrin pinnu lati lọ silu Iwo, ko lee fi Wuraọla se aya, amọ ko to gbera kuro ni ile, lo ti kọkọ beere lọwọ Ifa atun ori ẹniti ko sunwọn se, lati beere pe bawo ni ọhun yoo ti ri.
Ifa ni ọhun yoo dara, eyiun ti ọrunmila ba ti lee se suuru pẹlu Wuraọla.
Oríṣun àwòrán, @jenneric
Ni kete ti Ọrunmila si gunlẹ si aafin Iwo, ose, oju mimọ ati eebu ni Wuraọla fi pade rẹ, sugbọn Ọrunmila kan rẹrin musẹ lai sọ ohunkohun pada. O ki ọba Iwo bo se yẹ, to si tun mu ẹbun dani fun ọba.
Ọrunmila lo ọjọ meje ni ilu Iwo amọ Wuraọla ko fi lọrun silẹ pẹlu ọrọ abuku, to si mu kile aye le fun amọ Ọrunmila ko fesi pada, koda o tun lo ọpọn Ifa Ọrunmila lati dana.
Bi o tilẹ jẹ pe eyi bi Ọrunmila ninu amọ ko gbe soju rara,ti ko si tori rẹ sa kuro nilu Iwo.
Wuraọla kọ, ko fun Ọrunmila ni ounjẹ ati omi, sibẹ Ọrunmila ko fọhun, ti ko si binu pẹlu.
East Africa: Àwọn kokoro ti ba èrè oko jẹ nílẹ̀ Afirika
Nigba to di ọjọ keje ti Ọrunmila ti n fi ara da iya yii ni ọba Iwo fa Wuraọla fun bii aya. Ọba ni Wuraọla mọọmọ n huwa ika yii si awọn to ba dẹnu kọọ ni lọna ati mọ bi wọn se ni suuru, ifarada ati ipamọra si.
Ọba ni Ọrunmila jẹ onisuuru, alaanu, ati onifarada eniyan, ti oun ati Wuraọla si kuro lọ si ilu Ọrunmila lọjọ keje.
Nigba ti Ọrunmila de ilu rẹ, inu awọn ara ilu rẹ dun lati ri pe Wuraọla papa ja mọ Ọrunmila lọwọ, ti wọn si n beere pe nibo ni aya rẹ naa wa, awọn fẹ rii.
"Ọrunmila wa nahun ke si Wuraọla pe""Iya ti mo jẹ ni Iwo"", lati igba naa wa ni wọn ti n pe Wuraọla ati gbogbo obinrin to ba wọle ọkọ ni 'iyawo' tabi 'Iya-Iwo', eyi tii se agekuru ""Iya ti mo jẹ ni Iwo."""
O yẹ ki awọn ọkunrin maa ni ipamọra, suuru ati ifarada pẹlu aọn obinrin abi ipokipo ti a ba ba ara wa
Ko yẹ ka maa gba kamu pe ko lee see se ta ba ri ijakulẹ awọn eeyan miran lori ohun kan
Suuru ni baba iwa, o yẹ ka maa mu suuru ninu ohun gbogbo, ka lee bori nigbẹyin.
Eid-el Kabir: Aisha Buhari lọ Hajj pẹ̀lú ìyàwó Ààrẹ Niger, Senegal, Gambia
Oríṣun àwòrán, Twitter/Presidency
Ààrẹ Muhammadu Buhari má a padà sí ìlú Abuja ní Ọjọ Kejidinlogun, Osù yìí lẹ́yìn Ìsinmi ọdún ilẹ́yá.
Aarẹ Muhammadu Buhari ti de si ilu rẹ ni Daura lati lo se ọdun Sallah, ti a mọ si ọdun Ileya, lẹyin ti o kuro ni ilu Abuja ni Ọjọ Kẹsan, Osu yii.
Aago marun un irọlẹ ni ọkọ ofurufu aarẹ balẹ ni papakọ ofurufu Malam Umar Musa Yar'adua ni ipinlẹ Katsina.
Gomina ipinlẹ Katsina, Aminu Masari ati igbakeji rẹ, Alhaji Mannir Yakubu pẹlu awọn to wa ki aarẹ kaabọ si ile ni papakọ ofurufu ipinlẹ naa.
Ọjọ kejidinlogun, Osu yii ni aarẹ yoo pade si ile aarẹ ni ilu Abuja saaju iburawọle fun awọn minisita tuntun ti wọn sẹsẹ yan.
Bakan naa ni iyawo aarẹ Buhari, Aisha Buhari fi si oju ikansiraẹni Instagram rẹ pe oun wa ni Mina pẹlu awọn iyawo aarẹ orilẹede miran ni Afirika lati lọ se Hajj.
Aisha wa gbadura fun alaafia ati itẹsiwaju fun awọn orilẹede lagbaye.
Oro Festival: Àwọn olórò ní ọdún Màgbó ló ń gba ibi lọ, kó ire wọlé ní Ikorodu
Revolution Now: Ẹgbẹ́ òṣèlú AAC lé Ṣowore àti àwọn 28 mííràn
Oríṣun àwòrán, OTHERS
Láìpé yìí ni Olùdíje lábẹ́ ẹgbẹ́ òsèlú AAC, Ọmọyẹle Sowore di èrò àtìmọ́lé Àjọ DSS nítorí pé ó pè fún àyípadà ètò ìsèjọba lórílẹ̀èdè Naijiria.
Ẹgbẹ oselu The African Action Congress ti le Ọmọyẹle Sowore ati awọn mejidinlọgbọn miran fun ẹsun wi pe  wọn dojuti ẹgbẹ oselu naa.
Ẹgbẹ Oselu AAC  gbe igbesẹ yii ni ipade gbogboogbo ti wọn se ni ilu Owerri, ni ipinlẹ Imo.
Ọkan lara awọn asaaju ẹgbẹ, Emeka Ezeife lo pe fun ki wọn le Sowore ati awọn mejilelọgbọn miran kuro ninu ẹgbẹ, ti awọn ọmọ ẹgbẹ to kun naa si faramọ.
RevolutionNow: Ẹ̀rù ò bàwá, a ṣetan láti wà ní àtì mọ́lé- olùfẹ̀hónúhàn
Ezeife to bu ẹnu atẹ lu igbesẹ Sowore to pe fun iyipada isejọba lorilẹede Naijiria, ni Sowore ati awọn ẹgbẹ lẹyin rẹ ti mu itiju ba ẹgbẹ oselu naa.
Lẹsẹkẹsẹ naa ni wọn yan Leonard Nzenwa gẹgẹ bi adari ẹgbẹ oselu tuntun.
#RevolutionNow: Ṣowore ké pe ilééjọ́ láti yọọ́ látìmọ́lé DSS nítorí ó lòdì s'ẹ́tọ̀ọ́ rẹ̀
Oríṣun àwòrán, Facebook/Omoyele Sowore
#RevolutionNow
Oludije fun ipo aarẹ fẹgbẹ oselu The African Action Congress to sun ṣagbatẹru iwọde RevolutionNow, Ọmọyẹle Sowore ti ke pe ileẹjọgiga l'Abuja  lati yi aṣẹ to pa pe ki ile iṣẹ ọtẹlẹmuyẹ DSS tii mọ le fun ọjọ marundinlaadọta.
Ṣowore to sọrọ yii nipaṣẹ agbẹjọro rẹ, Femi Falana ni bi ajọ DSS ṣe ti oun mọ le lodi si ẹtọ oun gẹgẹ bi iwe ofin orilẹede Naijiria ṣe laa kalẹ.
Idi mọkandinlogun ni Falana kọ ti ileẹjọ ni lati fi Ṣowore silẹ lahamọ.
Sunday Igboho: Fulani kò leè dúró, táa bá lo ohun ta jogún lọ́dọ̀ àwọ̀n bàbá wa
''Ọjà ẹran àgbò kò yá bí ti ọdún tó lọ''
Ṣowore ni idajọ ileẹjọ to fun ile iṣẹ DSS laṣẹ lati ti oun mọ le fun ọjọ marundinlaadọta tumọ si pe ki eeyan sọ ohun to lodi sofin di ohun to tọna labẹ ofin.
Ọjọ Abamẹta to lọ ni awọn DSS mu Ṣowore ṣaaju iwode #RevolutionNow protest.
Ẹsun pe o fẹ doju ijọba bo lẹ ati pe of fẹ da alaafia ru kaakiri orilẹede Naijiria ni wọn fi kan an.
Ẹwẹ, ẹgbẹ oselu The African Action Congress ti le Sowore ati awọn mejidinlọgbọn miran fun ẹsun wi pe wọn dojuti ẹgbẹ oselu naa.
Ẹgbẹ Oselu AAC gbe igbesẹ yii ni ipade gbogboogbo ti wọn se ni ilu Owerri, ni ipinlẹ Imo.
Eid-il Kabir: Iléẹjọ́ f'òfin de Oluwo pé kò gbọdọ̀ darí ìrun ní 'EID' lọ́dún Iléyá
Oríṣun àwòrán, Facebook/Emperor Abdulrasheed Adewale Akanbi
Ọrọ aṣẹ ileẹjọ
Ileẹjọ giga ipinlẹ Oṣun ti paṣẹ pe Ọba Oluwo ti ilẹ Iwo, Oba AbdulRasheed Adewale Akanbi ko gbọdọ irun Jimọh tabi ayẹyẹ ọdun Sallah ati ayẹyẹ ọdun musulumi kankan niluu Iwo.
Aṣẹ ileẹjọ naa yoo duro titi digba ti igbẹjọ lori idaduro Baṣọrun Musulumi ilẹ Iwo. Oloye Abiola Ogundokun.
Oloye Ogundokun lo rọ ileẹjọ lati paṣẹ naa fun Oluwo, o si tun pa awọn aṣoju moṣalaṣi aringbungbun ilu Iwo sọrọ naa nileẹjọ.
''Ọjà ẹran àgbò kò yá bí ti ọdún tó lọ''
Sunday Igboho: Fulani kò leè dúró, táa bá lo ohun ta jogún lọ́dọ̀ àwọ̀n bàbá wa
Adajọ A.O. Ayoola ka aṣẹ naa jade lọjọ Ẹti pe Ọba AbdulRasheed Adewale Akanbi ko gbọdọ dari eto irun lọjọ Jimọh tabi nibi ayẹyẹ ọdun awọn musulumi kankan fun asiko yii.
Agbẹjọro fun Oloye Ogundokun, Opeyemi Adewale Esq. tun rọ ileẹjọ lati fofin fe Oluwo lori awọn nnkan miiran.
Ṣugbọn ilẹjọ ti sun igbẹjọ siwaju si ọjọ kọkandinlogun oṣu kẹjọ ọdun yii.
Nigba ti BBC Yoruba kan si Oluwo lori aago, Ọba Oba AbdulRasheed Akanbi kọ lati sọrọ si aṣẹ ileẹjọ.
Eid-el Kabir: Buhari rọ àwọn mùsùlùmí láti yàgò fún ìwà ipá nínú ìkíni ọdún
Oríṣun àwòrán, Twitter/Presidency Nigeria
Ọdun Ileya
Ẹ yago fun iwa ipa! Aarẹ Muhammadu Buhari ti rọ awọn musulumi Lati yago fun iwa jagijagan bi wọn ti n ṣayẹyẹ ọdun Ileya.
Buhari ni alaafia ni ki wọn maa lepa nitori ẹsin alaafia lẹsin musulumi bo tilẹ jẹ pe awọn alajagbinla kan ti fun ẹsin naa lorukọ buruku pẹlu iwa ipa wọn.
Aarẹ Buhari to sọrọ ninu atẹjade kan to fi ki awọn musulumi ki ọdun Ileya, sọ pe ifaraẹnijin to ṣe pataki julọ fawọn musulumi ododo ni pe ki wọn fi idajọ otitọ ati ododo ṣe atọna wọn lọjoojumọ.
''Ọjà ẹran àgbò kò yá bí ti ọdún tó lọ''
Oro Festival: Àwọn olórò ní ọdún Màgbó ló ń gba ibi lọ, kó ire wọlé ní Ikorodu
Buhari iwa apanle ni ipenija to tobi julọ to n koju ẹsin musulumi lagbaaye bayii, aarẹ ni ọna kan gbogi lati din ipa buruku iwa yii ku ni pe koni kaluku yago fawọn waja awọn ti ko mọ wọ ti mẹ sẹ.
Bakan naa ni aarẹ Buhari rọ awọn obi lati mojuto awọn ọmọ wọn kawọn maa ba ya wọn lo lati fi wọn wuwa ipa lorukọ ẹsin.
Aarẹ Buhari dẹbi ru awọn musulumi lori ọrọ agbesunmọmi Boko Haram nitori wọn o tete dẹkun iwaasu odi tawọn Boko haram n gbe kiri ki wọn to di nla.
Buhari ko sai fi dawọn ọmọ Naijiria loju pe ijọba oun n ṣiṣẹ takuntakun lati fopin si Boko Haram, iṣẹlẹ ijinigbe ati awọn iwa ọdaran mii to gbode kan ni Naijiria.
Niluu rẹ, Daura nipinlẹ Katsina ni Aarẹ Buhari ti sọdun Ileya.
Police Killing: Iléeṣẹ́ ní àṣìta ìbọn ló pa obìnrin nílùú Eko lọ́jọ́ Satide
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Awọn ọlọpaa ko gberegbe
Ileeṣẹ ọlọpaa ipinlẹ Eko to ṣalaye aṣita ibọn lati ọwọ ọkan lara awọn ọlọpaa lo ṣekupa obinrin kan nipinlẹ naa lọjọ Abamẹta.
Tẹlẹ lọjọ Abamẹta ni fidio ọlọpaa SARS to joko silẹ ti ọpọ eeyan si rọgba yii ka lu ayelujara pa.
Ohun to tẹ le fidio niroyin taa gbọ pe ọlọpaa yii atawọn akẹgbẹ rẹ ni wọn ṣadeedee bẹrẹ si ni yinbọn nitori wọn mu ọmọ ''Yahoo'' kan.
Sunday Igboho: Fulani kò leè dúró, táa bá lo ohun ta jogún lọ́dọ̀ àwọ̀n bàbá wa
Oro Festival: Àwọn olórò ní ọdún Màgbó ló ń gba ibi lọ, kó ire wọlé ní Ikorodu
Nibi ti wọn ti n yinbọn ọhun lọta ibọn ti ba alaboyun kan to si paa.
Ṣugbọn atẹjade kan ti ileeṣẹ ọlọpaa fi sita yatọ si iṣẹlẹ to ṣẹlẹ yii.
Ileeṣẹ ọlọpaa ẹka to n gbogun ti awọn ajinigbe(kii ṣe SARS) lo n gbiyanju lati mu awọn afurasi ajininigbe kan lagbegbe Ijegun, lawọn afurasi ba doju ibọn ko awọn ọlọpaa.
Wọn ni nibi ti wọn jọ fija pẹta ni ọta ibọn ti lọ ba obinrin oniṣowo kan ladugbo naa.
Koda ileeṣẹ ọlọpaa ni ọga ọlọpaa kan ASP Victor Ugbegun atawọn mii farapa nibi iṣẹlẹ ọhun bẹẹ ni wọn wa nile iwosan lọwọlọwọ.
Atẹjade ti alukoro ileeṣẹ ọlọpaa ipinlẹ Eko, Bala Elkana fi sita ṣalaye pe Busayo Owoodun lorukọ obinrin tọta ibọn ba naa.
Bayelsa Election: Ẹgbẹ́ òṣèlú APC kọ̀ láti kópa nínú ìdìbò, PDP jáwé olúborí
Oríṣun àwòrán,  Bayelsa State Min of Information and Orientation
Ẹgbẹ́ òṣèlú PDP ló jáwé olúbori nínú ìdìbò alága ìjọba ìbílẹ̀ àti kánsẹ́lọ tó wáye lọ́jọ́ sátide ọjọ kẹwàá oṣù kẹ́jọ ọdun 2019 .
Ẹgbẹ́ alátakò to pọ̀ jùlọ lórílẹ̀-èdè Nàìjíríà People's Democratic Party (PDP) ti pegedé nínú ìdìbò alága kansu àti ti kánsẹlọ̀ tó wáyé lásìkò ìdìbò ìjọba ìbílẹ̀ to wáyé ní ìpínlẹ̀ Bayelsa ní ọjọ́ kẹwàá oṣù kẹ́jọ ọdun 2019.
Ìròyìn to tẹ BBC lọ́wọ́ sọ pé àwọn ènìyàn péréte lo jáde lọ si ibi idibò náà, sùgbọ́n ìrọwọ́ rọsẹ̀ ni wáye
Aláráǹbàraà! Ẹ wo àrà tí ''Ayo the Creator'' ń fi sinimá dá
"Alága, elétò ìdìbò ìpínlẹ̀ Bayelsa, ọjọgbọ́n Remember Ogbe sàlàyé fún BBC pé eto ìdìbò  náà wáyé ni ìjọba ìbílẹ̀ mẹ́jọ tó gbé ìpínlẹ̀ Bayelsa ró, ó sì jẹ ìdìbò to lọ ni ìrọwọ́rọsẹ̀ júlọ ní ìpínlẹ̀ Bayelsa.""Ìdìbò ti a lé fi ìdí rẹ̀ múlẹ̀ pé ìdá ọgọ́ta nínú àwọn olùdibò jáde wá àànú Ọlọ́run ni a fi ṣe ìdìbò náà ti kò si sí ìjà tàbi kí ẹnikẹ́ni kú, gbogbo àyíká wà ni dídákẹ́ rọ́rọ́, a dupẹ́ lọ́wọ́ Ọlọ́run"""
Ọ̀jọ̀gbọ́n Ogbe sọ pé mẹ́rìnlélógójì nínú mọ́kànléláàdọ́run àwọn ẹgbẹ́ òṣèlú to forukọ sílẹ̀ lókópa nínú ìdìbò náà, sùgbọ́n ẹgbẹ́ òṣèlu tó ń bẹ lóri àléfaà All Progressives Congress (APC) wà lára àwọn ẹgbk òṣèlú tí kò kópa nínú ìdìbò náà
Ìgbìyànjú BBC láti bá alága ẹgbẹ́ òṣèlú APC Jotan Amos sọ̀rọ̀ lórí ẹ̀rọ ayélujára, ìdí ti wọn kò fi kópa nínú ìdìbò náà, sùgban kò gbé aago rẹ̀.
Oríṣun àwòrán, Alambo Datonye
Ikede Esi idibo ijoba ibilẹ Bayelsa
BB Naija 2019: Ọlọ́pàá Gẹ̀ẹ́sì bẹ̀rẹ̀ ìwádìí lórí Khafi lórí ẹ̀sùn ṣíṣe ìbálòpọ̀
Oríṣun àwòrán, Instagram/acupofkhafi
Ẹsun ibalopọ lori BB Naija
Ọmọbinrin ọlọpaa ilẹ Gẹẹsi kan, PC Khafi Kareem ti wọ gau lẹyin to kopa ninu ere idije agbelewo ti wọn n pe ni Big Brother Naira.
Ọmọbinrin ọhun ni wọn fẹsun kan pe, o tapa sofin ile iṣẹ ọlọpaa Metropolitan Police nitori fọnran to lu ayelujara pa ṣafihan rẹ pe, o n ni ibalopọ pẹlu akẹgbẹ rẹ lori eto ọhun.
Ile iṣẹ ọlọpaa ilẹ Gẹẹsi to ṣalaye ninu atẹjade kan ti wọn fi ṣọwọ si BBC salaye pe, ọlọpaa naa beere fun aaye iyọnda lati lọ kopa ninu eto naa ṣugbọn ileeṣẹ ọlọpaa ko fun un laaye naa.
Ileeṣẹ ọlọpaa Met ni Kareem kọkọ kọwe beere fun aye lati lọ fun isinmi alaigbowo-oṣu ṣugbọn ko sọ ohun to fẹ lọ ṣe, wọn si fun laaye.
Ileeṣẹ ọlọpaa sọ pe, awọn mọ pe Kareem n kopa ninu eto agbelewo naa lọwọlọwọ lai gba iyọnda lọwọ awọn alaṣẹ ileeṣẹ ọlọpaa.
Eto BB Naija
Ileeṣẹ ọlọpaa ni awọn ko lọwọ si bi Kareem ti wa lori eto naa ati pe, kii ṣe ileeṣẹ ọlọpaa ilẹ Gẹẹsi loun n ṣoju fun niwọn igba to wa lori eto naa.
Oríṣun àwòrán, Instagram/acupofkhafi
Ẹsun ibalopọ lori BB Naija
Atẹjade ti alukoro Ileeṣẹ ọlọpaa Met, Rebecca Byng fi ṣọwọ si BBC ṣalaye pe, iwadii ti bẹrẹ lori ọrọ Kareem.
Atẹjade naa sọ siwaju si pe, o ti wa ninu ofin ati ilana ileeṣẹ ọlọpaa Met pe, wọn gbọdọ huwa bi ọmọluabi nibi kibi ti wọn ba wa.
Oríṣun àwòrán, Instagram/acupofkhafi
Eto BB Naija
Agbẹnusọ fun Khafi sọ pe Khafi yoo sọrọ si ẹsun yii nigba to ba to asiko.
Oríṣun àwòrán, The Metropolitan Police
Ẹsun ifabanilopọ lori BB Naija
Khafi jẹ aṣoju ileeṣẹ ọlọpaa Met gẹgẹ bi ọlọpaa alawọdudu nilẹ Gẹeṣi .
Ofin awọn ọlọpaa Met tun sọ pe, awọn ọlọpaa ko gbọdọ se nnkan ti yoo tabuku tabi mu ẹgbin ba orukọ ileeṣẹ ọlọpaa ilẹ Gẹẹsi.
''Ọlọpaa kọlọpaa to ba tapa si awọn ilana ati ofin wọn, yoo foju wina ofin.''
Ojúde Ọba: Ayẹyẹ tó ń ṣàfihàn àṣà àjogúnbá Yorùbá
Oríṣun àwòrán, Ojude Oba Facebook
Ninu awọn ọdun to gbajugbaja nilẹ Ijẹbu, eyi ti tọmọde-yagba, ti onile-talejo maa n kopa ninu rẹ ni ọdun Ojude Ọba jẹ, to si tun gbajugbaja nilẹ Yoruba.
Ọjọ kẹta ọdun ileya ni ọdun Ojude Ọba maa n waye, ọdun 1892 si lo bẹrẹ lasiko ti Ọba Adesunmbọ Tunwase fun awọn musulumi nilẹ lati kọ mọsalasi si.
Ọdun awọn musulumi ni ọpọ eeyan ri ọdun Ojude Ọba si nigba to bẹrẹ, to si jẹ ọdun awọn ẹlẹsin kan, asiko yii si ni awọn musulumi yoo gba aafin ọba lọ lati lọ se aku ọdun sọdọ rẹ lasiko ọdun ileya, lọna ati fi ẹmi imoore wọn han fun ọwọ aanu ati ọrẹ to se fun wọn.
Oríṣun àwòrán, Ojude Oba Facebook
Amọ kẹrẹkẹrẹ, se ni ọdun yii n fẹju si bi ọdun se n gori ọdun, to si kọja ọdun ẹlẹsin kan, lojumọ toni yii, ọdun Ojude Ọba ti di aayo nilẹ Ijẹbu, eyi ti oniruuru ẹlẹsinjẹsin, ẹlẹyamẹya, tọmọde tagba n peju lati se ajọyọ rẹ, koda, awọn eeyan, paapa awọn ọmọbibi ilu Ijẹbu maa n ti ẹyin odi wa se ayẹyẹ naa.
Lasiko ọdun Ojude Ọba, faaji maa n pin silẹ Ijẹbu ni, ti awọn Ijẹbu kii si fi ọdun Ileya sere boya ẹlẹsin Kristiẹni ni, Musulumi abi abọrisa, ti wọn yoo si wọ asọ ẹgbẹjọda lọkan o jọkan, ti gbogbo ilu yoo si maa gba yin-in lasiko ọdun Ojude Ọba.
Oríṣun àwòrán, Ojude Oba Facebook
Afojusun ọdun Ojude Ọba ni lati se amugbooro awọn aṣa, ajogunba wa ati awọn ise adayeba ọmọ ṣa, ajogunba wa ati awọn ise adayeba ọmọ Yoruba. Eyi si maa n fi oju han pẹlu ọpọ ati oniruuru asọ ẹgbẹjọda ti ẹlẹgbẹjẹgbẹ maa n wọ lasiko ọdun Ojude Ọba. Se  ni asọ maa n pe asọ ransẹ lasiko ayẹyẹ naa, ti awọn ọkunrin yoo si ko si oniruuru sitaili agbada, tawọn obinrin naa yoo si lo asọ lọ bii rẹrẹ, asọ oke yoo maa pe asọ oke ransẹ ni, to fi mọ adirẹ ati bẹẹ bẹẹ lọ.
Oniruuru irun didi, asọ ibilẹ, ounjẹ ilẹ Ijẹbu tii se Ifọkọrẹ ati ijo ibilẹ ko si ni gbẹyin.
Oríṣun àwòrán, Ojude Oba Facebook
Lara awọn ayẹyẹ to n mu ki ọdun Ojude Ọba jẹ manigbagbe nilẹ Ijẹbu ati nilẹ Yoruba lapapọ ni bi wọn trun se n se afihan ara asa wa lọna miran, eyi to nii se pẹlu ibọn yinyin, gigun ẹsin bii ọlọla ati sise idije ijo jijo laarin awọn ẹlẹgbẹjẹgbẹ lsna ti mọ ẹgbẹ to gbegba oroke.
Awọn idile to n gun ẹsin yoo maa le ara wọn lare ni, ti wọn yoo si wọ oniruuru asọ ti wọn fi n se idije ẹsin gigun laarin awọn ọkunrin, tawọn obvinrin naa yoo si maa tadi reke lati pa ara wọn layo lasiko ọdun Ojude Ọba.
Awọn ẹlẹgbẹjẹgbẹ ti wọn n pe ni Rẹgbẹrẹgbẹ to wa ni isọri-isọri ọjọ ori kọọkan ni yoo se afihan bi wọn se lee tadireke si. Ẹgbẹ to ba si gbegba oroke ni wọn yoo fun ni ẹbun to jọju lasiko ọdun Ojude Ọba, ninu eyi ti wọn yoo maa yin ibọn soke loore koore.
Oríṣun àwòrán, Ojude Oba Facebook
Lara awọn ohun pataki ti kii gbẹyin lasiko ọdun Ojude Ọba ni asa lilọ ki ọba pe ki ade pẹ lori, ki bata pẹ lẹsẹ, ki ẹsin ọba si jẹ oko pẹ. Pẹlu orin, ijo, ilu ati ayọ ọkan si ni awọn ẹlẹgbẹjẹgbẹ lọkanojọkan fi maa n lọ ki ọba naa to wa nikalẹ, lati igba ti ọdun Ojude Ọba si ti bẹrẹ lati bii ọgọrun ọdun sẹyin ni asa yii ko ti parun.
Koda, wọn yoo tun mu ẹbun eroja ounjẹ lọwọ fun ọba gẹgẹ bii ẹbun ọdun.
Oríṣun àwòrán, Ojude Oba Facebook
Awọn ẹtahoro musulumi kan lo bẹrk ọdun Ojude Ọba, ko to di pe o di itẹwọgba nilẹ Ijẹbu. Sugbọn lasiko yii, ọdun Ojude Ọba ti tayọ ẹsin kan soso, ti awọn oniruuru ẹlẹsin si ti n tẹwọgba ọdun naa nilẹ yii ati lẹyin odi.
Ni ọjọ kẹta ọdun Ileya ni awọn ọmọ bibi ilẹ Ijẹbu yoo korajọ pọ lati se ayẹyẹ ọdun Ojude Ọba pẹlu awọn ọrẹ, ẹbi ara ati ibatan wọn. Wọn si fi ayẹyẹ naa si ọjọ kẹta ọdun Ileya lọna ati fun awọn musulumi ni aaye ati anfaani lati gbadun ọdun Ileya ni ọjọ meji akọkọ.
Ni ọjọ kẹta yii ni awọn tọkunrin-tobinrin, ọmọde ati agba nilẹ yii ati lati oke okun yoo pe biba si gbagede kan lati se ọdun naa nilu Ijẹbu-Ode.
Oríṣun àwòrán, Ojude Oba Facebook
Bi ọdun Ojude Ọba si se n fẹju si, to si n di itẹwọgba, naa ni aayan n lọ lati jẹ ko di ilumọọka jakejado agbaye.
Kenyan Dance Party: Òde ijó yìí kò sí fáwọn abo tó ń fẹ́ ara wọn pẹ̀lú
Oríṣun àwòrán, The nest collective
Ti a ba n se ayẹyẹ, tọkunrin tobinrin lo maa n peju pesẹ lati fi ara kinra, eyi ti yoo mu ki ayẹyẹ naa dun, ko si larinrin.
Sugbọn iyalẹnu gbaa lo jẹ lati ri pe ode ijo kan lee wa, ti yoo wa fun kikida awọn obinrin nikan, ti wọn yoo si le awọn akọ sẹyin.
Gẹgẹ bi BBC se se awari rẹ, ilu Nairobi lorilẹede Kenya ni idan orita naa ti n waye, nibiti wọn ti haya ibudo kan to wa fun ile ijo, ti orin si n dun lakọlakọ nibẹ, sugbọn kinni kan to ba Ajao jẹ, ti apa rẹ fi gun ju itan lọ ni pe kikida awọn obinrin lo wa lagbo ijo naa, to n jo pẹlu ara wọn.
Gẹgẹ bi awọn obinrin to ba BBC sọrọ ti wi, o dara ni ẹkọọkan bayii lati maa fi ọwọ lile mu awọn ọkunrin, ti awọn obinrin nikan yoo ti da wa laisi awọn ọkunrin nibẹ.
"Jane, ẹni ọdun mẹrindinlọgbọn, lasiko to n ba BBC sọrọ ni, ""ọkan mi balẹ lati wa si agbo ijo to wa fun obinrin nikan lai lọwọ awọn ọkunrin ninu, mo wa pẹlu ọrẹ mi obinrin, eyi to mu ki inu mi dun lati wa pẹlu ẹni to loye nipa oun."""
Nibi agbo ijo naa, se ni ipese abbo to peye wa, iwọnba awọn ọkunrin ti wọn si gba laaye lo wa ja awọn obinrin silẹ, ni kete ti wọn ba si se bẹẹ tan ni wọn yoo jade kuro nibẹ.
Koda, awọn eeyan to jẹ agbọti, agbounjẹ, osisẹ eleto aabo, awọn gbogbo elere to n lu awo orin, awọn atọkun eto to fi mọ awọn asọna lo jẹ obinrin, laisi ọkunrin ninu wọn.
Ọdun 2018 ni wọn bẹrẹ agbo ijo awọn obinrin nikan naa, ti erongba idasilẹ rẹ si kọja jijẹ igbadun alẹ ọjọ kan. Idi ni pe oju awọn obinrin ri mabo lọdun to kọja naa nitori awọn isẹlẹ hihu iwa ipa si awọn obinrin ati ifipabanilopọ, eyi to mu ki awọn obinrin pinnu lati maa da wa laisi ọkunrin.
Yatọ si eyi, agbo ijo aọn obinrin naa ko si fun awọn abo to n fẹ ara wọn, taa mọ si Lesbian, ti ode naa ko si wa fun ẹlẹsin kan pato.
Ninu ifọrọwerọ rẹ pẹlu BBC, Munira, ẹni ọdun mejilelogun ati Khadija, ẹni ọdun mẹẹdọgbọn, ti wọn jẹ mususlumi salaye pe ode ijo naa ba ilana ẹsin Islam mu, eyi to faramọ ki awọn ọkunrin maa da wa loju kan.
Ọpọ wa lo maa n bọ asọ ibori (Hijab) wa lati darapọ mọ awọn akẹẹgbẹ wa lasiko ta ba n jo. Idi ni pe ti wọn ba ri wa pẹlu Hijab, wọn yoo ya ẹnu pe ki la wa se nibẹ.
Iru ipejọpọ bayii ni Munira lo dara pupọ nitori wọn ko fi aaye gba awọn lati maa fara ro ọkunrin.
Ireti si wa pe laipẹ laijinna, irufẹ ode ijo bayii yoo tan kalẹ bii ọwara ojo yika gbogbo ilẹ Afirika, nibiti wọn yoo ti maa gbe awọn obinrin larugẹ bo se yẹ.
2023 Presidency: Àwọn ọmọ Nàìjíríà ń dá awuyewuye sílẹ̀ lórí Tinubu ní Twitter
Oríṣun àwòrán, @AsiwajuTinubu
Tinubu, Tinubu, Bọla Ahmed Tinubu!!!, ko si ẹni ti ko mọ gbajugbaja oloṣelu yii yika orilẹede Naijiria.
Bi ọpọ ti mọọ si ogbontagi oloṣelu, lawọn miran mọọ si aṣiwaju ẹgbẹ oṣelu APC.  Jagaban ti ilu Borgu lawọn miran fi n gbe ọkọ Olurẹmi larugẹ.
Ṣugbọn ni ẹnu lọwọlọwọ yii, ohun to n gbe Bọla Tinubu si oju aje ayelujara naa ni ariyanjiyan lori bi awọn kan ṣe ṣalaye pe, o n gbero lati du ipo aarẹ orilẹede Naijiria ni ọdun 2023.
Aṣiwaju Tinubu ko tii kede boya ootọ wa ni ọrọ yii abi bẹẹ kọ, bakan naa ni ko wi fun araye pe oun ko gbaa lero.
Nibayii awọn ọmọ orilẹede Naijiria kan ti n ta ohun si ara wọn lori ikanni ayelujara Twitter, lori boya o tọna ki Tinubu du ipo aarẹ ni ọdun 2023 tabi ko tọna.
Oríṣun àwòrán, @AsiwajuTinubu
Ohun ti awọn ọmọ Naijiria kan to n fọwọsi Tinubu fun ipo aarẹ lọdun 2023 n sọ, loju opo Twitter ni pe, ati ranmu gangan idagbasoke to de ba ipinlẹ Eko lẹnu ọdun melo kan sẹyin, ko ṣẹyin eekan Tinubu.
Wọn ni eyi ko sẹyin ilana ti Bọla Tinubu fi lelẹ, lasiko to jẹ gomina ni ọdun 1999 si ọdun 2007, eyi ti wọn ni ọpọ awọn gomina si n tẹle.
Wọn ni bi Tinubu ba di aarẹ, o lee tun gbe ọwọ to lo ni ipinlẹ Eko lọ si ijọba apapọ, fun idagbasoke orilẹede Naijiria lapapọ.
Amọṣa, awọn eeyan miran n ṣalaye lori ẹrọ ayelujara pe ni iwoye tiwọn, Tinubu wa lara awọn iṣoro orilẹede Naijiria.
Wọn ni Tinubu wa lara awọn to mu ki ọpọ dibo fun aarẹ Buhari ni ọdun 2015 ati ni ọdun 2019.
UI: Kélé yóò gbé ọkùnrin tó bá ń rin gb;eregbére lágbègbè ibùgbé obìnrin ní fásitì Ibadan
Oríṣun àwòrán, University of Ibadan
Laipẹ yii lawọn janduku kan ya wọ ileegbe awọn obinrin lọgba fasiti naa ti wọn si ṣe ọṣẹ
Laipẹ yii ni iroyin kan pe awọn janduku kan ti ya wọ ibugbe awọn akẹkọ to jẹ obinrin ni fasiti Ibadan.
Nibayii, awọn alaṣẹ fasiti Ibadan ti wa kede ofin isede lọgba faisiti naa laarin agogo mejila oru si agogo marun idaji.
SERAP fẹ́ pe UI, AAUA lẹ́jọ́ lórí àfikún owó iléẹ̀kọ́
OAU: Ohùn ọ̀jọ̀gbọ́n Richard Akindele ni wọ́n ká sílẹ̀
Khafi wọ gàu lẹ́nu iṣẹ́ lórí ẹ̀sùn ìbálòpọ̀ ní BB Naija
Àṣìta ìbọn ló pa obìnrin nílùú Eko lọ́jọ́ Satide- Ọlọ́pàá
Lórí ìmọ̀ràn Sunday Igboho, Ẹlẹbubọn ní yóò dára kí Yorùbá padà sí àmúlò èròjà ìbílẹ̀ fún ààbò
CS Mum: Omotolani Ekene ní ọ̀pọ̀ èèyàn gbà pé ọ̀lẹ, arugún, aláìlera ni ẹni tó fi abẹ bímọ
Ofin yii yoo si bẹrẹ loru ọjọru.
Nibi ipade igbimọ abo ileewe naa ni wọn ti gbe igbesẹ yii.
Gẹgẹ bii atẹjade kan ti giwa fasiti naa, Ọjọgbọn Idowu Ọlayinka fi sita ṣalaye wi pe awọn alejo ọkunrin to ba fẹ bẹ awọn akẹkọbinrin ni ibugbe Awolowo hall, Queen Idia hall ati Elizabeth hall ko gbọdọ wọ inu ibugbe awọn obinrin naa ms o. Ita gbangba ni wọn yoo ti maa gbalejo wọn
Snake Market: Àwọn òńtàjà ẹran ejò ní ẹran ejò dùn ju ẹran adìẹ lọ
Bakan naa lo ni ọwọ afunrasi ni wọn yoo fi mu ọkunrin kankan ti o ba n rin gberegbere kaakiri ibugbe awọn obinrin nileewe naa kọja agogo mẹjọ abọ alẹ.
Sunday Igboho: Fulani kò leè dúró, táa bá lo ohun ta jogún lọ́dọ̀ àwọ̀n bàbá wa
Seyi Makinde: Gbogbo ẹ̀yin tí ipò kò tíì kàn, ẹ fọkàn balẹ̀, yóò kàn yín láìpẹ́
Oríṣun àwòrán, Facebook/Seyi Makinde
Gómìnà ìpínlẹ̀ Oyo Seyi Makinde ní àwọn agbáṣésẹ abẹ́lé ní ìjọba òun yóò maa gbé kọ́ngila ìpínlẹ̀ Oyo fún, lójunà àti kó ipa tiwọn nínú ìdàgbàsókè ìpínlẹ̀ náà.
"Makinde fọ̀rọ̀ yìí léde làsìkò to ń bá àwọn eeyan ilu Ogbomosọ sọrọ nígbà tó lọ sàbẹ̀wò ""ẹ ṣeun, mo dupẹ"" si wọ́n ní ìlú náà, fun atilẹyin ti wọn se fun lasiko eto idibo gomina to kọja."
O ní àwọn kọgila tó dáńtọ́ tí wọ́n sì mọ iṣẹ́ wọ́n bi iṣẹ́ tí akọsílẹ̀ sì ti fi hàn pé wọ́n kìí fi iṣẹ́ wọ́n ṣere ni àwọn yóò kọ́kọ́ gbé iṣẹ́ fún ní kété ti ìjọba bá ti bẹ̀rẹ̀ iṣẹ́ òde.
Gómìnà ní ìjọba ò ti gbé iṣẹ́ kankan jáde láti ìgbà ti o ti dé, àti pé kí àwọn ara ilú lọ mú ọkàn wọ́n kúrò nibi pé bóya àwọn ti gbé iṣẹ́ fún àwọn ará ìta
Oríṣun àwòrán, SeyiMakinde
Seyi Makinde, lásìkò tó ń dúpk lọ́wọ́ àwọn Ogbomoṣọ
"Dípò bẹ́ẹ̀ ""a ó gbé iṣẹ́ fún kọngilá tó jẹ ará ìlú láti mú ìdàgbàsókè bá ètò ọ̀rọ̀ ajé ìpiínlẹ̀ Oyo àti láti jẹ́ kí wọ́n ni ipa nínú ìjọba"""
O rọ gbogbo àwọn ti wọ́n ń retí ìpò kàn tàbí òmíràn nínú ìjọba rẹ̀ láti lọ fí ọkàn balẹ̀ nítorií yóò kàn wọ́n láìpẹ́.
Bakan naa lo tun rọ awọn awọn araalu pe eto idẹrun wọn lo mumu julọ ni aya ijọba oun, ti oun yoo si tukọ ipinlẹ Ọyọ pẹlu ibẹru Ọlọrun.
PDP South West: Ọ̀rọ̀ ọkọ̀ ayọ́kẹ́lẹ́ ìjọba tó pòórá kìí ṣe ìṣẹ̀lẹ̀ àfojúfò
Oríṣun àwòrán, @OfficialPDPNig
Ẹgbẹ oselu PDP lẹkun iwọ oorun guusu Naijiria ti faraya lori gbolohun kan ti gomina ana nipinlẹ Ọyọ, Abiọla Ajimọbi sọ pe, ọrọ ọkọ ayọkẹlẹ ti wọn lo poora jẹ isẹlẹ kekere ti ko lowura rara.
Idi si niyi ti ẹgbẹ oselu PDP naa fi n nahun kesi gomina ipinlẹ Ọyọ, Onimọ ẹrọ Seyi Makinde pe ni kia mọsa, ko yara tete tanna wadi bi ijọba Ajimọbi se lọ, ki awọn ohun ikọkọ lee foju han ni gbangba.
Atẹjade kan ti ẹgbẹ oselu PDP lẹkun iwọ oorun Guusu Naijiria fisita, eyi ti akọwe ẹgbẹ lẹkun naa, Ayọ Fadaka fọwọsi lo sisọ loju ọrọ yii, lasiko to n fesi si ọrọ kan ti Abiọla Ajimọbi sọ pe iti ọgẹdk lasan ni awọn ọkọ ayọkẹlẹ ti wọn lo sọnu, ko to ohun ti a n yọ ada si.
Oríṣun àwòrán, @AAAjimobi
PDP sọ siwaju si pe igbesẹ sise ayẹwo isejọba to kọja yoo fun ijsba tuntun to wa nipinlẹ Ọyọ ni anfaani lati mọ ọpọ igbesẹ ti ijọba Ajimọbi gbe lori aleefa.
"Atẹjade naa salaye pe ""Ijọba ipinlẹ Ọyọ lo n gbọ bukata lori awọn ọkọ ayọkẹlẹ ti ijọba Ajimọbi ra lati osu keji ọdun 2019, amọ ti awọn ọkọ naa ti di awati bayii, irufẹ awọn ọkọ tuntun yii si ni a ko lee sọ pe wọn ko se lo mọ."""
Ẹgbẹ oselu PDP wa n kesi Ajimsbi pe ko maa ranti atubọtan, ati itan ti ọjọ ọla yoo sọ nipa rẹ ati isejọba rẹ, ti wọn si n rọọ lati kesi awọn eeyan to yan sipo pe ki wọn tete da awọn ọkọ ayọkẹlẹ naa pada.
Ojude Oba 2019: Ọba Adetọna ní bí òun bá papòdà, ẹni tó bá dáńtọ́ ni kí wọ́n fi jẹ Awùjalẹ̀
Ṣe awọn agba bọ wọn ni, bi ẹyin agba yoo ṣe ri, oju rẹ laa tii mọ.
Eyi lo difa fun awujale ilẹ Ijẹbu Ọba Sikiru Adetọna, to fi fa awọn eeyan rẹ leti pe, a lee pe yoo pẹ ko ya, a si le pe yoo ya ko pẹ.
"Amọṣa o ni kete ti oun ba ti darapọ mọ awọn alalẹ, ""ẹni to ba dantọ ni ki wọn yan si ipo naa"" lẹyin oun."
Lasiko ọdun ojude ọba to waye nilu Ijẹbu Ode lọjọ iṣẹgun, ni Awujalẹ ti gbe sọrọ nla yii fun awọn eeyan rẹ, paapaa julọ awọn afọbajẹ.
O ni ki wọn ta kete sawọn owo-o-magọ ati olowo igbo tii n ṣilẹ f'ole, ti wọn lee fẹ fi owo ra apere ọba ilu naa nitori pe, gẹgẹ bi Ọbalaye naa ṣe sọ, ifasẹyin ni iru wọn maa n fa ba ilu.
Ọdun 1960 tii ṣe aadọta ọdun sẹyin, ni Ọba Sikiru Adetọna gun ori itẹ; ọmọ ọdun marundinlọgbọn si ni nigba naa, to gun ori itẹ.
Awujalẹ ilẹ Ijẹbu, Ọba Sikiru Adetọna ni nibi ti ọrọ idagbasoke ilẹ Ijẹbu de duro bayii, ọlanrewaju lo yẹ ki ẹni ti wọn yoo fi jẹ Ọba nibẹ o jẹ
Ohun ti ọpọ n bi ara wọn leere bayii ni pe, abi baba ti n gbaradi silẹ fun didarapọ mọ awọn alalẹ ilẹ naa ni? Ṣe wọn ni iku o dọjọ, arun o doṣu.
Ọba Adetọna ṣalaye siwaju pe, inu oun dun de ibadi lati ri awọn igbesẹ idagbasoke ati ilọsiwaju to ti de ba ilẹ Ijẹbu.
O ni awọn ọmọ ilẹ naa gbọdọ ja fitafita lati maa tẹ siwaju lori rẹ nipa riri daju pe wọn ko fi aye silẹ fun awọn kan lati fi owo ra ipo Ọbalaye ilẹ naa.
"Nigba ti asiko ba to ti mo ba lọ, mo bẹ yin, ẹni ti o to gbangba sun lọyẹ ni ki ẹ yan sipo. Ẹ kọ ipakọ si ẹnikẹni ti yoo fa ọwọ agogo ilẹ Ijẹbu si ẹyin.
Ẹ ma ṣe ti oṣelu bọ eto yiyan ẹni ti yoo gba ade lẹyin mi. Ẹ ma ṣe yan awọn ti yoo fa ọwọ Ijẹbu sẹyin."
O ni bi idile ti oye kan ko ba ri ọmọ oye to dantọ fa kalẹ, n ṣe ni ki awọn araalu kọ amulumala ọmọ oye ti wọn ba fa silẹ, ki wọn si mu ninu ọmọ oye ni idile to ba kan.
Ìjàmbá Eko: Èèyàn méjì dàwátì lásìkò ìjàmbá ọkọ̀ ojú omi
Oríṣun àwòrán, @TalktoLaswa
Eyi ni igba keji ti iṣẹlẹ ijamba oju omi yoo maa waye laarin oṣu keje si ikẹjọ ọdun 2019
Ajọ irinna oju omi nipinlẹ Eko, LASWA ti kede pe, ijamba ọkọ oju omi kan ti ran eeyan mẹta lọ sọrun ti wọn si tun n wa awọn meji miran lagbegbe ileto Irewe ni Ọjọ.
Ninu atẹjade kan ti Giwa ajọ LASWA, Emmanuel Oluwadamilọla fi sita, eeyan mẹtala ni wọn yọ laaye ninu ijamba naa to waye alẹ ọjọ iṣẹgun.
O ni awọn ọkọ oju omi akero meji kọlu ara wọn lagbegbe ijọba ibilẹ Ojo.
Ero mẹwa lo wa ninu ọkan lara awọn ọkọ oju omi naa, to nbọ lati agbegbe Ọjọ jetty, mẹjọ si wa ninu eyi to n bọ lati ileto Irewe, eyi to mu ki apapọ awọn ero to wa ninu awọn ọkọ oju omi naa, lasiko ti ijamba naa fi waye jẹ mejidinlogun.
"Eeyan mẹtala lo wa laaye, eeyan mẹta ku, agbalagba kan ati majesin kan ni wọn n wa bayii.
CBN Policy: Buhari pàṣẹ fún báńkì àpapọ́ láti dẹ́kun owó ìrànwọ́ fáwọn tó ń gbé oúnjẹ wọ Nàìjíríà
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Aarẹ ni aṣẹ naa yoo ran eto ọgbin labẹle lọwọ
Ni ọjọ iṣẹgun ni aarẹ orilẹede Naijiria, Muhammadu Buhari kede si eti awọn gomina to jẹ ọmọ ẹgbẹ oṣelu APC pe, oun ti paṣẹ fun banki apapọ ilẹ wa, lati yee se akanse pasi paarọ owo Naira ilẹ wa si tilẹ okeere fun awọn to ba fẹ ko ounjẹ wọ orilẹede Naijiria.
Gẹgẹ bi aarẹ ṣe sọ, igbesẹ yii yoo dena bi kiko ounjẹ wọle lati ilẹ okeere ṣe n ṣakoba fun idagbasoke eto ọgbin labẹle.
Ṣe ẹ si mọ wi pe ko si bi a ba ṣe fa gburu, ti gburu ko ni fa igbo, eyi lo mu ka ṣe ayẹwo awọn ounjẹ ti a n ko wọ orilẹede Naijiria lati oke okun atawọn to ṣeeṣe ko gbowo lori nitori igbesẹ yii.
Eyi ni awọn ohun jijẹ ti a n ko wọ orilẹede Naijiria lati ilẹ okeere gẹgẹ bii ajọ iṣọkan agbaye fun ọdun 2019 ti gbe kalẹ:
Iya Rainbow: Ó yẹ́ ká máa yẹ́ àwọn onítíátà sí ní ààyè, kìí ṣe òkú wọn
Oríṣun àwòrán, Iya Rainbow
Yoruba ni baa ku laa dere, eeyan ko sunwọn ni aaye.
Eyi lo mu ki ilumọọka osere tiata nni, Idowu Phillips, ti gbogbo eeyan mọ si Iya Rainbow fi n ke tantan si gbogbo agbaye.
Ariwo Iya Osumare ni pe, yoo dara ki wọn maa se ẹyẹ fun awọn osere tiata lasiko ti wọn ba wa laaye, kii se lẹyin ti wọn ba ku tan.
Iya Rainbow gbe imọran naa kalẹ, lasiko ti ileesẹ Gulf Platform n side ayẹyẹ ti wọn fi n sami ọjọ ibi ọdun kẹtadinlọgọrin rẹ ni olu ileesẹ naa to wa nilu Ibadan nigba naa.
Nibẹ naa ni a ti ri eyi ti awọn gbajumọ osere ori itage lọkan o jọkan, awọn akọroyin pẹlu sọrọ-sọrọ peju si.
Iya Rainbow, ẹni to dupẹ lọwọ Ọlọrun pe ileesẹ naa n se ẹyẹ fun oun lasiko ti oun si wa loke eepẹ.
O tun fikun pe, ọpọ isẹ ribiribi ni oun n se gẹgẹ bii agba osere laarin awọn ọjẹ wẹwẹ onitiata nidi hihu iwa to tọ lawujọ ati didẹẹkun wiwọ asọ iwọkuwọ.
End SARS, End SWAT: Ó pé mi bí SARS kò ṣe sọ mí dolówọ́- Fulani Kwajafa
Nigba to n sọ iru eeyan ti Iya Rainbow jẹ si, Oloye Toyin aya Adegbọla, ti gbogbo eeyan mọ si Aṣẹwo to re Mecca salaye pe, Iya Rainbow jẹ ẹni to ko ni mọra, oludamọran fun awọn ọdọ, ati awokọse rere ni agbo isẹ tiata nitori pe kii fi oju pa ọmọde rẹ.
Saheed Balogun, ta mọ si Walata, ti oun naa ko gbẹyin nibi ayẹyẹ naa, se apejuwe ọlọjọ ibi naa gẹgẹ bii iya rere to wulo pupọ lagbo isẹ tiata, kii wa isubu awọn ọdọ, to si maa n fun awọn ni imọran loore koore nipa bi a se n gbe ile aye se rere.
Ninu ọrọ tiẹ, Razak Ọlayiwọla, ti gbogbo eeyan mọ si Ojopagogo kede pe, Ajẹ pọnbele ati Aṣẹwo haun-haun ni Iya Rainbow.
O salaye pe Iya Rainbow maa n gba awọn ni imọran bii ẹni pe o mọ ohun to fẹ sẹlẹ lọjọ iwaju ni, ẹnikẹni to ba si tapa si imọran iya naa yoo ge ika abamọ jẹ nigbẹyin ni, idi si niyi ti oun se n pe Iya Rainbow ni Ajẹ pọnbele.
'Owó tí mo ń rí lórí Garri ni mo fi ń ran ọkọ lọ́wọ́'
Bakan naa, o ni Iya Rainbow maa n pe oun ni ọkọ oun, ti inu oun si maa n dun, amọ nigba to ya lo ye oun pe, gbogbo ọkunrin ni iya naa maa n pe ni ọkọ rẹ, eyi si tumọ si pe iya naa ko tilẹ mọ iye ọkọ to ni, eyi si lo mu ki oun maa pe ni Aṣẹwo haun-haun.
Awọn gbajugbaja osere miran to tun sọrọ nibi eto iside ọjọ ibi Iya Rainbow naa ni Peju Ogunmọla, Sẹgun Ogungbe, Bọsẹ Akinọla ati Biọla Fowosere, ti gbogbo wọn si gba pe, Iya Rainbow korira kii osere tiata maa si ara silẹ lasiko ti wọn ba n sisẹ, to si maa n rọ wọn lati gbe asa Yoruba larugẹ lọjọkọjọ.
Nigba to n salaye awọn eto ti yoo waye nilu Dubai lasiko ayẹyẹ ọjọ ibi ọdun kẹtadinlọgọrin Iya Rainbow, ati idi ti wọn fi gbe eto naa, eyi ti yoo waye laarin ọjọ Kẹtadinlọgbọn osu Kẹwa si ọjọ Kẹta osu Kọkanla ọdun 2019 lọ silu Dubai.
Gbajúgbajà òsèré tó tún mọ́ ọbẹ̀ sè
Ọkan lara awọn oludari ileesẹ to n se agbatẹru eto naa, Arabinrin  Juliana Afọ́nrewó kede pe, ọpọ ayẹyẹ ọjọ ibi ni wọn ti se fun Iya Rainbow lorilẹede Naijiria, ọna lati mu iyatọ baa, si lo mu kawọn gbe ti ọdun yii lọ si Dubai.
O fikun pe, ileesẹ naa fẹ fi ẹmi imoore rẹ han si Iya Rainbow fun ọpọ ipa takuntakun to ti ko nidi isẹ tiata, lo mu kawọn seto ayẹyẹ ọjọ ibi ọlọjọ meje naa, nibiti awọn gbajumọ olorin bii Pasuma, ati Dare Melody yoo ti kopa, ti awọn yoo si tun se abẹwo si awọn ibi to se koko nilu ọhun.
Mama Rainbow: iṣẹ́ tíátà kò ta sánsán mọ́ bíi ti ayé àtijọ́
Revolution Now: Àwọn tó ń ṣèwọ́de ní ọta ìbọn ológun àti ọlọ́pàá kò dẹ́rù ba àwọn
Agbegbe Unity Fountain nilu Abuja ko rẹrin rara lọsan ọjọru nitori iwọde ti awọn ajafẹtọ ẹni se.
Iwọde yii ni wọn fi n beere fun itusilẹ oludari ẹgbẹ Revolution Now, Omoyele Sowore to wa ni ahamọ awọn agbofinro, ati awọn eeyan miran ti ọlọpaa mu lasiko iwọde wọn to kọja.
Se ni apapọ awọn osisẹ agbofinro, ninu eyi ti a ti ri awọn ọlọpaa ati awọn osisẹ ologun wa, ti wọn si duro wa wa wa si agbegbe naa, pe ti esinsin ba ta firi, awọn yoo wọn ni.
Akọroyin BBC to wa nibi iwọde naa salaye pe, o to ọkọ nla mẹwaa to ko awọn agbofinro naa wa si ibi ti iwọde ọhun ti waye, ko to di pe awọn oluwọde de sibẹ, lati ri daju pe alaafia jọba ni agbegbe naa.
Lasiko ti wọn n fọrọ werọ pẹlu ikọ̀ BBC, awọn oluwọde naa ni ẹru awọn agbofinro ti oju wọn ko rẹrin naa ko ba awọn rara, nitori paa jẹ, baa lẹru, ko si iku ti yoo pa agba, ti wọn ko ni ba poolo ori rẹ nibẹ.
Wọn fi kun pe, awọn ko ni dẹkun lati maa se iwọde naa fun itusilẹ Soworẹ, ti ẹru ọta ibọn awọn ọlọpaa ati sọja naa ko si ba awọn, o si di igba ti wọn ba tu Soworẹ silẹ, ki awọn to sinmi iwọde.
Bẹẹ ba gbagbe, Omoyele Soworẹ ni awọn osisẹ ọtẹlẹmuyẹ gbe si ahamọ lasiko to n leri pe ẹgbẹ Revolution Now yoo se iwọde.
Ajọ DSS naa si tun ti gba asẹ ile ẹjọ lati fi Soworẹ si ahamọ fun ọjọ marundinlaadọta, ki wọn lee raye se iwadi to yẹ nipa idunkooko rẹ eyi ti wọn lo tumọ si pe, o fẹ doju ijọba Buhari bolẹ.
Money laundering: Inú ọ̀pọ̀ páálí oúnjẹ́ Nódù ní afurasí kan kó ọ̀pọ̀ ike ATM sí
Oríṣun àwòrán, @EFCC
Ọkunrin kan, Ishaq Abubakar,  ni ọwọ ti ba pe o ko ike ti wọn fi n gba owo lẹnu ẹrọ, ATM to din diẹ ni ẹgbẹrun mẹta rin.
Abubakar, to n rinrin ajo lọ si orilẹede Dubai, ti wọn ti fa le ajọ EFCC lọwọ, lo ko awọn ike ATM naa pamọ sinu paali ohun jijẹ Nodu.
Afrurasi ọhun lọwọ awọn osisẹ asọbode tẹ ni papakọ ofurufu Muritala Muhammed nilu Eko, lasiko to fẹ wọ ọkọ ofurufu lọ si Dubai.
Lasiko ipade akọroyin ti wọn fi n fa afurasi ọhun le ajọ EFCC lọwọ, igbakeji ọga agba  ajọ asọbode, Abdulmumini Bako ni afurasi naa sọ pe ilu Kano ni oun ti wa.
Oríṣun àwòrán, Others
Bako ni ọkunrin kan wa pẹlu afurasi naa to fẹ seranwọ fun lati jẹ kawọn ẹrun naa kọja lọdọ awọn agbofinro laisi ayẹwo, amọ awọn osisẹ asọbode yari pe awọn yoo yẹ gbogbo paali naa wo finni-finni.
O salaye pe o seese ki wọn lo awọn ike ATM shun fun iwa lilu jibiti ati kiko owo tuulu rin, to si leri leka pe gbogbo ẹni to ba lọwọ ninu isẹlẹ yii ni yoo fi imu ko ata ofin.
Oríṣun àwòrán, Twitter/EFCC
Ajọ to n gbogun ti iwa ajẹbanu ni Naijiria, EFCC gbe Ọgbẹni Abdullahi Babalele tawọn kan sọ pe oun ni ọkọ ọkan lara awọn ọmọbinrin Alhaji Atiku Abubakar  lọ ileẹjọ l'Ọjọru.
Ẹsun ti wọn fi kan Ọgbẹni Babalele ni pe wọn gbe owo bi ẹgbẹrun lọna ogoje owo dọla($140,000) rin ṣaaju idibo gbogbogbo ọdun 2019.
Bakan naa,  ajọ EFCC ṣafihan Ọgbẹni Uyiekpen Osagie-Giwa to wọn ọpọ gbagbọ pe oun ni agbaẹjọro Atiku lori ẹsun pe o gbe owo bi miliọnu meji dọla ṣaaju idibo gbogbogbo.
Awọn mejeeji lawọn o jẹbi ẹsun ti wọn fi kan awọn.
Atiku dije fun ipo aarẹ labẹ asia ẹgbẹ oṣelu PDP eleyi to ti fidi rẹmi ti Aarẹ Muhammadu Buhari ti jawe olubori.
Adajọ Nicholas Oweibo sun igbẹjọ siwaju si Ọjọbọ, nigba naa ni yoo dajọ lori beeli ti wọn beere fun.
Adajọ Oweibo ni ki wọn dawọn pada si atimọle ajọ EFCC.
Toyin Abraham: Òṣèré Nollywood ti daya Kolawole Ajeyemi.
Oríṣun àwòrán, Instagram/officialbroadwaytv
Ọrọ ifẹ bi adanwo ni, oṣere tiata, Toyin Abraham ti sẹ ayẹyẹ adehun igbeyawo pẹlu oṣere miiran Kolawole Ajeyemi.
Iroyin to tẹ wa lọwọ sọ pe Ajeyemi naa lo ni oyun to wa ninu rẹ.
Awọn obi Toyin, Yeyeluwa Odebunmi, Ọgbẹni Segun Odebunmi wa nikalẹ ninbi eto ọhun to waye nile awọn obi Toyin Abraham.
Yollywood: Sinimá Ajé Ọjà tún so Fathia àti Saheed Balogun pọ̀ nínú Sinimá
Ọpọ lo ti n sọ pe ọrọ ifẹ wa laarin awọn mejeeji lẹyin ti wọn ri wọn pọ loriṣiiriṣii ibi ti wọn ti n ṣe inanwo.
Toyin Abraham gan an fun ra rẹ ko tii sọ ohun kan lori adehun igbeyawo naa, ṣugbọn olusakoso rẹ, Samuel Olatunji popularly ti ọpọ mọ si Bigsam lo fọrọ naa lede loju opo Instagram rẹ.
Bigsam pin oriṣiiriṣii fọto eto adehun igbeyawo ọhun laarin Toyin Abraham ati Kolawole Ajeyemi.
Igbeyawo akọkọ ti Toyin Abraham ṣe pẹlu oṣere tiata miiran, Ọgbẹni Adeniyi Johnson fori ṣanpọn.
Obono-Obla: Buhari ti yan Dayọ Apata lati rọ́pò Obono-Obla
Oríṣun àwòrán, @NGRPresident
Aarẹ Muhammadu Buhari ti yẹ aga mọ alaga igbimọ to n sewadi lati se awari awọn dukia ijọba to ti sọnu, to si n gba wọn pada, Okoi Obono-Obla, to si ni ko lọ rọọkun nile na.
Atẹjade kan ti akọwe ijọba apapọ, Boss Mustapha fisita lo sisọ loju ọrọ yii pẹlu afikun pe Agbefọba agba fun ijọba ilẹ wa, Dayọ Apata ni yoo maa dari igbimọ to n gba dukia ijọba to sọnu pada naa, titi di ọjọ miran, ọjọ rere.
Akọwe ijọba apapọ ni aarẹ Buhari gbe igbesẹ naa lọna ati fun Obono-Obla ni anfaani lati dahun awọn ẹsun iwa ọdaran to nii se pẹlu iwa ajẹbanu ti ajọ to n tanna wadi iwa ibajẹ ICPC fi kan-an.
Oríṣun àwòrán, @NGRPresident
Bakan naa, Obono-Obla yoo tun jẹjọ lori awọn ẹsun to jẹ mọ sise ayederu iwe ẹri ati ẹsun iwa ajẹbanu lọkan o jọkan eyi ti wọn fi kan-an.
Atẹjade naa tun salaye pe, Obono-Obla yoo si maa naju nile naa titi ti ajọ ICPC yoo fi fẹnu ọrọ jona lori iwadi to n se fun-un.
Facebook: Gbogbo ojú òpó ìròyìn èké ní èdé Afirika pátá ló ń lọ
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Gbogbo ẹyin tẹ n gbe iroyin eke ni ede abinibi lori ikanni Facebook, ẹ sunmọ bi, tori ọrọ yii kan yin.
Awọn alasẹ ileesẹ Facebook nifọwọkọwọ pẹlu igbimọ to n wadi ọfintoto iroyin nilẹ Afirika, Africa Check, ti gunle isẹ sise awari awọn oju opo ikanni eke ni ede abinibi to lu oju opo Facebook pa.
Eto naa, eyi ti wọn sefilọlẹ rẹ lagbegbe Sahara nilẹ Afirika, ni yoo tun fi aan ede adulawọ miran bii Yoruba, Igbo Swahili, Wolof, Afrikaans, Zulu, Setswana ati Sotho sinu iwadi rẹ. Gbogbo awọn iroyin ti kii ba se ojulowo ti eeyan kan ba gbe jade, ni Facebook yoo maa sun si isalẹ patapata loju opo ẹni to kọọ, ti ko si ni lee maa se alabapin iroyin naa bo se yẹ.
Facebook ni oun n reti abọ lati ọdọ awujọ awọn eeyan to n lo oju opo ikanni wọn lori igbesẹ wọn yii, lọna ati se agbeyẹwo awọn iroyin ti kii se ojulowo.
Bẹẹ ba gbagbe, ọpọ ẹnu lo ti n kun oju opo Facebook latẹyinwa pe o nkopa ninu itankalẹ awọn ayederu iroyin ati ọrọ ikorira lawọn oju opo rẹ.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ni ilẹ adulawọ nikan, o le ni aadoje miliọnu eeyan to n lo oju opo ikanni Facebook.
Toyin Abraham: Ìgbéyàwó la kọ́ gbọ́, ọmọ ló tẹ̀le lọ́jọ́bọ
Oríṣun àwòrán, fathiawilliams instagram
Ayọ abara bintin, isubu ti subu lu ayọ nile gbajugbaja osere tiata nni, Toyin Abraham pẹlu bi ọba oke tun se fi ọmọkunrin kan ta lọrẹ.
Laipẹ yii ni ileesẹ BBC Yoruba mu iroyin wa fun yin pe, ilumọọkaosere tiata naa ti segbeyawo pẹlu akẹẹgbẹ rẹ kan Kọ̀lawọle Ajeyẹmi, ti wọn si n reti ọmọ nitori Toyin ti di abarameji.
A wa dupẹ bayii pe Toyin Abraham ti ruu ree, to si ti sọọ re.
Oríṣun àwòrán, fathiawilliams instagram
Nigba to n kede iroyin ayọ naa loju opo ikansira ẹni Instagram rẹ, toyinabrahamnews, osere tiata naa ni Oluwa dara, Ọmọọba wa ti de"", to si fi ijo sii."
Wayi o, gbogbo awọn akẹẹgbẹ rẹ lagbo tiata ni wọn ti n dawọ idunnu pẹlu rẹ, ti wọn si n ki pe o ku ewu ọmọ.
Bi o ba tun se n lọ, a m aa mu iroyin naa wa fun yin.
El-Zakzaky: Ọ̀pọ̀ ẹ̀sùn aṣemáṣe ni ìjọba àpapọ̀ fi kan Zakzaky ní India
Oríṣun àwòrán, @imnigeria_org
Ni Ọjọru ni okiki kan pe yangi ti n da si gaari eto iwosan ti wọn gbe kalẹ, fun aṣiwaju ijọ ẹsin shiite ni Naijiria, Ibrahim El-Zakzaky to wa lorilẹede India.
Iroyin to kun ori ayelujara sọ pe dipo iwosan ti o lọ fun lorilẹede India, awuyewuye lori eto aabo rẹ nibẹ lo tun gba aye kan ni ilu Delhi bayii.
Ni ọsẹ to kọja ni ileẹjọ kan nipinlẹ Kaduna, gba fun El-Zakzaky lati lọ gba itọju lorilẹede India, ti o si ṣe bẹẹ gẹgẹ ni ọjọ Aje.
Ko pẹ ti o de ibẹ ti iroyin ti n jade pe, aṣiwaju ẹsin naa ti n fi apa janu, to si ni wọn n fi awọn oṣiṣẹ alaabo dun mahurumahuru mọ oun atawọn dokita oun ni orilẹede India.
Amọṣa ijọba apapọ Naijiria pẹlu ti fesi pe, awọn ko mọ ohunkohun nipa ẹsun yii, ati pe n ṣe ni El-Zakzaky fẹ maa ṣe bi ọba lorilẹede India.
Oríṣun àwòrán, @imnigeria_org
Ninu atẹjade kan ti akọwe agba fun ileeṣẹ eto iroyin labẹ ijọba apapọ fi sita, o salaye pe se ni Zakzaky da ọwọ ru ni kete to gunlẹ si India.
o beere fun aaye lati maa yan fanda fanda kaakiri bo ṣe wu u, to si ni ki wọn si fi oun wọ si ile itura olowo nla kan dipo ile iwosan to yẹ ko wa eleyi ti awọn alaṣẹ orilẹede India tako nitori pe irinajo lati gba itọju lawọn gbọ pe wọn fun un laṣẹ fun, kii ṣe ti irinajo afẹ.
Ohun ti aṣiwaju ẹsin Shiite naa n sọ fun araye bayi ni pe, awọn osiṣẹ alaabo ti ilẹ yii ati orilẹede India ko faye gba a lati ri awọn dokita rẹ.
O ni  eyi lo mu ki oun faake kọri pe oun ko lee jẹ ki Dokita ajeji ti abẹrẹ bọ oun lara o.
Awọn ẹsun aṣemaṣe ti ijọba apapọ̀ fi n kan El-Zakzaky ni ilẹ India niyii:
"Awọn alaṣẹ orilẹede India ti wa pinnu lati daa pada si Naijiria nitori ""wọn ko fẹ ki o lo orilẹede wọn lati fa oju agbaye si ẹgbẹ rẹ'."
"Nitori eyi ijọba apapọ wa ni awọn ti tọrọ aforiji lọwọ ijọba orilẹede India fun 'iwa aṣemaṣe'ti El-Zakzaky hu"""
Buhari: Ọwọ́ fẹ́rẹ̀ tẹ àwọn agbébọn lókè Ọya
Oríṣun àwòrán, @GarShehu
Irọ ati arumọjẹ ni gbogbo awọn agbebọn ti wọn n paayan tan, ti wọn wa n pariwo Allahu Akbar n pa.
Aarẹ Muhammadu Buhari ni ko tọ si ọmọ ole ko maa pariwo ọlọpaa n bọ.
Aarẹ Buhari sọ ọrọ yii lasiko to ṣe abẹwo si ibudo awọn atipo eeyan ti eeyan bii ẹgbẹrun kan le aadọta, ti ogun agbebọn Boko haram le kuro nile wa, eyi to wa ni ipinlẹ Katsina.
Aarẹ si ti fi da wọn loju pe, oun yoo dẹkun awọn agbebọn to n dun mọhurumọhuru mọ awọn ọmọ orilẹede Naijiria.
Buhari ni awọn to n fi orukọ ọlọrun boju pa eniyan, kii ṣe ẹlẹsin tootọ.
O ni o ṣeeṣe o ko jẹ pe wọn ko mọ Ọlọrun ni, abi ko jẹ pe ọrọ wọn ati Ọlọrun ko wọ.
Oríṣun àwòrán, @AsoRock
"Gbogbo awọn eeyan to jẹ pe iṣẹ ti wọn mọ ni ṣiṣe ko ju ki wọn pa eeyan lọ, ki wọn si maa pariwo Allahu Akbar"", n pa irọ ni nitori Ọlọrun o ṣe ibi."
"O ko lee gbe ibọn tabi ado oloro, ida tabi ọbẹ lati pa alaiṣẹ, ki o si maa pariwo ""Allahu Akbar"". Ohun ti eyi tumọ si ni pe o ṣeeṣe ki o maa mọ Ọlọrun tabi ki o maa ni igbagbọ ninu rẹ."""
Bakan naa lo tun rọ awọn eeyan agbegbe naa lati joye oju lalakana fii n ṣọ ori nitori pe gbogbo igbesẹ ti awọn agbebọn naa n gbe ko ṣẹyin alami ti awọn kan lara araalu n ṣe fun wọn.
NCS: Òǹwòye kan ní kí ìjọba ṣe àtúnṣe ọgbà ẹ̀wọ̀n àti ìtọ́jú ẹlẹ́wọ̀n
Oríṣun àwòrán, @NLCtoday
Onwoye ohun to n lọ lawujọ kan ti sọ wi pe, bi aare Muhammadu Buhari se yi orukọ ileesẹ to n mojuto ọgba ẹwọn lorilẹede yii pada, si ileeṣẹ to n tọ ẹda sọna, jẹ ohun ti o dara pupọ, ati ohun itẹsiwaju.
Ọjọgbọn Dikirulahi Adewale Yagboyaju, tii ṣe olukọ agba ni ẹka imọ eto oselu ni ile ẹkọ giga fasiti Ibadan, lo sọ ọrọ yi ninu ifọrọwerọ rẹ pẹlu BBC Yoruba.
Bẹẹ ba gbagbe, ọjọru ni aarẹ Buhari kede pe oun ti ṣe ayipada orukọ ileeṣẹ to n mojuto ọgba ẹwọn, Nigeria Prisons Service si Nigeria Correctional Service, eyi ti yoo maa tọ awọn to ba wa ni ahamọ sọna.
"Yagboyaju sọ wipe ""igbesẹ yi jẹ igbesẹ ti o wa ni ibamu pẹlu bi awọn orilẹede ti o ti goke agba ni agbaye se n se."
"Ọgba ẹwọn ko wa lati fiya jẹ ẹnikẹni, sugbọn o tun jẹ ibi ti wọn ti n tun aye awọn eniyan ti o wa ni ahamọ se pelu."""
O tẹ siwaju ninu ọrọ rẹ wipe, yiyi orukọ pada nikan ko to, sugbọn o yẹ ki ijọba gbe awọn igbesẹ ti o wa ni ibamu pẹlu yiyi orukọ pada.
Oríṣun àwòrán, @NLCtoday
Onwoye awujọ naa ni, ijọba gbọdọ se amojuto awọn ile ti wọn n ko awọn ẹlẹwọn pamọ, ti wọn ko si ni kun akunfaya mọ.
Bakan naa lo ni bi wọn se n gba awọn osisẹ sẹnu isẹ gbọdọ di atungbeyẹwo ati bi wọn se n se iwuri fun awọn ti o jafafa lẹnu isẹ.
Yagboyaju tun tẹsiwaju pe, ijọba tun gbọdọ ri si bi wọn se n bawọn to n se imẹlẹ lẹnu isẹ wi, eyi ti yoo mu ki ayipada orukọ naa ni ipa gidi lori awọn ọgba ẹwọn wa.
Ọjọgbọn naa wa rọ ijọba apapọ lati mojuto awọn kudiẹkudiẹ to wa ni ileesẹ to n samojuto ọgba ẹwọn nilẹ wa, ki ayipada ti ijọba n se lori ileesẹ naa lee yọri si rere.
South West Security: Ọlọ́pàá Ogun àti Ọ̀ṣun ni àwọn kò lọ́wọ́ nínú àjọṣepọ̀ ọ̀hún
Oríṣun àwòrán, @PoliceNG
Ileeṣẹ Ọlọpaa ni eto abo agbegbe lawọn n tẹle; OPC ni ọrọ naa ko ti fẹnu jona sibikan
Ọrọ eto aabo to n mẹhẹ ni agbegbe iwọ oorun guusu Naijiria nibi ti ẹya Yoruba ṣodo si, ti di irawọ ọsan to n ba awọn agba lẹru bayii.
Nitorinaa, ni Ọga ọlọpaa ni ipinlẹ Ekiti se kede pe, ileeṣẹ ọlọpaa yoo ṣe aṣepọ pẹlu awọn ẹgbẹ ibilẹ to nii ṣe pẹlu ọrọ aabo ni ilẹ Yoruba bii OPC atawọn ẹgbẹ ọdẹ ibilẹ gbogbo.
Bẹẹ si ni ọpọ ọmọ kootu oojiire nile ati loke okun to gbọ iroyin naa, lo n se yaginni yodo pe ọ̀rọ̀ eto aabo to mẹhẹ ọhun ko ni pẹ lojutu.
Amọ beere to wa gba ọkan awọn eeyan ni pe se gbogbo awọn ileeṣẹ ọlọpaa ni ipinlẹ mẹfẹẹfa to wa lẹkun yii ni eto agbajọ ọwọ naa kan tabi boya ileeṣẹ ọlọpaa nipinlẹ Ekiti nikan lo n da ọwọ wu lori rẹ.
Nigba to n dahun ibeere yii, ọga ọlọpaa nipinlẹ Ekiti sọ fun BBC Yoruba pe, ni ilakaka gbogbo ti ileeṣẹ ọlọpaa n ṣe nibẹ, lo mu ki wọn fọwọsowọpọ pẹlu awọn ọlọdẹ atawọn ẹgbẹ OPC lati se ọbẹ aabo jinna ni gbogbo agbegbe to wa nilẹ Yoruba.
Kọmiṣọna ọlọpaa nipinlẹ Ekiti, Asuquo Amba wa ṣe apẹrẹ iṣẹlẹ iwadii kan eleyii ti o waye ni inu igbo to wa laala ipinlẹ Ekiti ati Kogi.
O ni awọn ṣe amulo ọgbọn inu ati bi awọn ọdẹ ati ẹgbẹ bii OPC ṣe mọ ọna gbogbo ninu aginju ọhun, lati fi ṣe awari awọn amokunṣika ti wọn fara sinko sinu igbo naa.
Oríṣun àwòrán, @PoliceNG
Amọṣa ninu ọrọ tirẹ, ọga ọlọpaa ni ipinlẹ Ọṣun, Abiọdun Ige pẹlu Akẹgbẹrẹ nipinlẹ Ọyọ, Sina Olukolu ni, awọn ko ni ajọṣepọ kankan pẹlu awọn ẹgbẹ alaabo kankan, eyi to kọja irufẹ ajọṣepọ to wa laarin ọlọpaa atawọn araalu lọ.
Awọn mejeeji ni ohun ti awọn mọ ni pe, bi ẹnikẹni ba ni iroyin to lee ṣe ọlọpaa lanfani lati lee dẹkun iwa ọdaran lawujọ, onitọhun lee mu tọ ọlọpaa wa.
Wọn ni awọn ko tii le sọ pe ajọṣepọ kankan n bẹ laarin awọn ẹgbẹ alaabo yii, ju eyi to wa laarin ọlọpaa ati araalu lọ.
Amọṣa, awọn ọga ọlọpaa ni ipinlẹ mẹtẹẹta naa ni wọn fi ohun kan sọrọ pe, isẹ ọlọpaa lẹsẹkuku jẹ eyi to jẹ ileeṣẹ ọlọpaa logun pupọ bayii.
Oríṣun àwòrán, @PoliceNG
Wọn fikun pe eyi kun ara ọna ti wọn fẹ gba lati dẹkun gulegule awọn to n da omi alaafia ilu laamu lẹkun yii.
Ileeṣẹ BBC news Yoruba tun tẹ siwaju lati kan si ẹgbẹ OPC lati mọ boya wọn mọ si igbesẹ ajọsepọ yii ati ipa ti wọn n ko ninu rẹ.
Ọgbẹni Shina Akinpẹlu, to jẹ alukoro fun igun new Era ninu ẹgbẹ OPC ṣalaye fun BBC news Yoruba pe, lootọ ni OPC n gbe igbesẹ labẹnu lati ṣe ajọṣepọ pẹlu awọn agbofinro.
Akinpẹlu ni ọrọ ajọṣepọ naa ko mọ lori ọlọpaa nikan, gbogbo awọn ẹka iṣẹ alaabo ni yoo kopa ninu igbesẹ naa gẹgẹ bi awọn agba majẹobajẹ kan ni ilẹ Yoruba ti ṣe n peelo rẹ.
Child Abuse: Oyinye Mbadike ní ìbátan òun mu ọti yó ni òun ṣe dín dùǹdú ìyà fun
Oríṣun àwòrán, InSTAGRAM/@OPETODOLAPO
Obinrin kan, Oyinye Mbadike tawọn ọlọpaa mu nitori pe o na ọmọkunrin kan, tii se ibatan rẹ, to si tun ti mọ inu akolo aja ti ṣalaye idi abajọ t'oun fi ṣe bẹẹ.
Ninu atẹjade kan ti alukoro fun ileeṣẹ ọlọpaa ipinlẹ Eko, Bala Elkanah fi ṣọwọ si BBC, Mbadike, to jẹ ẹni ọdun mẹrinlelogun sọ pe oun ṣina iya f'ọmọ ọdun mẹwaa naa, Chibike EziAmaka, nitori o ti mu ọti yoo.
Obinrin naa Chibike mu ọti amupara debi pe, o fi oko fọ gilaasi ọkọ oun nigba ti ọti to mu n pa a.
Ileeṣẹ ọlọpaa ṣalaye fun BBC pe, agbegbe Aguda nipinlẹ Eko ni iṣẹlẹ ọhun ti ṣẹlẹ.
Ọga ọlọpaa, Badmos Dolapo kede isẹlẹ naa loju opo Twitter rẹ sọ pe, lati igba ti fọnran iwa ika yii ti lu ayelujara pa, eyi to n ṣafihan bi obinrin kan ṣe na ọmọdekunrin yii, lawọn ti bẹrẹ si ni wa a kiri.
Fidio ọhun to tan kalẹ lori ayelujara ru ibinu awọn araalu soke, nigba ti wọn ri bi obinrin yii ṣe n fi bẹliiti na ọmọ naa, to si tun sọ si ile aja.
Ọpọ eeyan lo ti n pariwo pe kawọn agbofinro fọwọ sinku ofin mu obinrin yii.
Badmos sisọ loju rẹ pe iranwọ tawọn ọmọ Naijiria se fun ileeṣẹ ọlọpaa nigba ti iṣẹ iwadii n lọ lọwọ lo mu ki ọwọ ọlọpaa tete tẹ obinrin naa.
Oríṣun àwòrán, @opetodolapo
Awọn ọlọpaa ti fa ọmọ yii, tii se ọmọ orukan naa, le ijọba ipinlẹ Eko lọwọ.
Ọbinrin yii ti wa ni akolo ọlọpaa bayii, nibi ti wọn yoo ti gbee lọ si ileẹjọ laipẹ.
Seyi Makinde ṣe ìbúra fún kọmísánà tuntun mẹ́rìnlá
Oríṣun àwòrán, Seyi Makinde
Gomina Ipinlẹ Oyo, Ṣeyi Makinde ti bura fawọn kọmiṣọna mẹrinla to ṣẹṣẹ yan l'Ọjọbọ nileeṣẹ ijọba ni Agodi niluu Ibadan.
Baakan naa ni Gomina Makinde tun pin ileeṣẹ ti onikaluku wọn yoo ti ṣiṣẹ fun wọn lẹyin to bura fun wọn tan.
Wọnyi ni awọn kọmiṣọna mẹrinla naa atawọn ileeṣẹ ẹnikọọkan ti wọn yoo di mu gẹgẹ bi Gomina Ipinlẹ Oyo ti kede rẹ.
Ọ̀ṣun Oṣogbo 2019: Ìyán gbígbóná ní wọn kọ́ fi bẹ̀rẹ̀ ọdún
Iwaju aafin ti n rọ kẹkẹ fun ọdun
Ẹ poore yeeeye ooo, Ọṣun jọọ, fun wa lowo, fun wa ni ọmọ, fun wa ni alaafia
Iya olomi tutu ti Osogbo naa ti setan ọdun
Iyan gbigbona ni aarọ ni awọn obinrin kọkọ monuto
Haa, ọrọ yii gba ki awọn ọkunrin gba odo iyan
Tọmọde-tagba lo ti n ta mọra lati mura fun ọdun
Bi awọn ọkunrin se n palẹmọ, naa ni awọn ọkunrin n se
Aje yoo kuku bu igba jẹ́ fun awọn eeyan kan lonii
Ọrọ̀ aje yii naa ko yọ awọn ọkunrin silẹ, tọkunrin-tobinrin lo n wa owo
Bi esinsin ba ta firi, awa setan lati wọn lasiko ọdun ni awọn agbofinro yii n wi
Ni ṣẹpẹ la wa fun ọdun Ọṣun ni ọdun yii, ọdun yii ko yẹ
El-Zakzaky: Aago méjìlá ọ̀sán ku ogún ìṣẹ́jú lọ́jọ́ Ẹtì ni bàálù rẹ̀ gúnlẹ̀
Asaaju ikọ ẹlẹsin Shiite, Ibrahim El Zakzaky ati aya rẹ ti gunlẹ si orilẹede Naijiria bayii.
Gẹgẹ bi akọroyin BBC to wa ni papakọ ofurufu Nnamdi Azikwe nilu Abuja ti wi, deede aago mejila ku ogun isẹju lọsan ọjọ Ẹti ni baalu Ethiopia E9-11 to gbe tọkọ-taya naa balẹ.
Iroyin naa ni awọn agbofinro ko jẹ ki ẹnikẹni tabi akọroyin kankan fi oju kan Zakzaky ati aya rẹ, titi ti wọn fi gbe wọn gba ọna miran lọ fi si ahamọ.
Papakọ ofurufu Nnamdi Azikwe nilu Abuja ti kun fọfọ bayii fun awọn agbofinro ti oju wọn ko rẹrin, ti wọn gbarodan sibẹ fun igbaradi ipadabọ asaaju ẹsin Shiite, Sheik Ibrahim El-Zakzaky lati orilẹede India.
Bẹẹ ba gbagbe, iroyin ti gbalẹ kan pe Zakzaky ti pinnu lati pada si orilẹede Naijiria, lẹyin ti igbesẹ lati mu ko gba itọju nile iwosan Mandata lorilẹede India fori sanpọn.
Akọroyin BBC to wa ni papakọ ofurufu naa salaye pe, aago mejila ọsan yii lo seese ki baalu Ethiopia to gbe Zakzaky balẹ si papakọ ofurufu naa, ti igbaradi si ti doju ọgbagade lati ọdọ awọn agbofinro fun abọ asaaju ẹsin Shiite naa ati aya rẹ.
Iroyin naa ni lara awọn ikọ agbofinro to wa nikalẹ la ti ri awọn ọlọpaa, osisẹ ọtẹlẹmuyẹ DSS, awọn ologun, ati osisẹ aabo ara ẹni laabo ilu ( Civil Defence).
Oríṣun àwòrán, others
Akọroyin BBC ni, gbogbo igbiyanju oun lati ya awọn agbofinro to pọ bii esú naa lo ja si pabo, nitori wọn ko gba akọroyin kankan laaye lati duro sẹba ibi ti wọn wa.
Oríṣun àwòrán, @zakzakysupport
Kii ṣe iroyin mọ pe ede aiyede bẹ silẹ laarin ikọ aṣaaju ẹsin Shiite lorilẹede Naijiria, Ibrahim Elzakzaky ati ijọba India, eyi to n pagidina  itọju rẹ lẹyin ti ileejọ fun laaye lọsẹ to kọja.
Ba a ṣe n sọrọ yii, iroyin kan ti ni Ibrahim El-Zakzaky ti n ṣẹri bọ wa sile.
Gẹgẹ bi a ṣe gbọ, agogo marun irọlẹ ọjọbọ ni iroyin naa gbe pe yoo gbera kuro ni orilẹede India.
Gẹgẹ bi awọn iroyin abẹle ṣe sọ, pẹlu fidio kan ti El-Zakzaky funra rẹ gan ti sọrọ, anfani meji ni wọn fun olori ẹsin naa.
Wọn ni yala ko fara mọ awọn ilana ti ijọba fun un tabi ki wọn daa pada sorilẹede Naijiria, amọ o dabi ẹni pe anfani keji ni El-Zakzaky nawọ mu.
Bi o tilẹ jẹ wi pe awọn ọmọlẹyin rẹ n lọọgun pe ohun to n sẹ́lẹ yii ni ọwọ ijọba Naijiria ninu amọ ijọba paapaa n pariwo.
Ijọba ni aifi ọwọ sibi ti ọwọ ngbe aṣaaju ijọ Shitte ọhun lo n faa, ti gbogbo nnkan nipa itọju rẹ nilẹ okeere ṣe lọju pọ.
Nibayii, ibeere to gba ẹnu ọpọ eeyan ni pe, bi ọrọ ṣe wa ri yii, bi El-Zakzaky ba pada de nibo ni yoo wa?
Ṣe ile rẹ ni yoo gba lọ ni, ṣe ileewosan kan ni Naijiria ni yoo lọ ni tabi yoo pada sinu ahamọ awọn agbofinro DSS, eyi to ti wa fun bii ọdun mẹrin gbako?
El-Zakzaky pé ìpàdé pẹ̀lú àwọn àgbẹ́joro India àti àwọn àjọ ti kìí ṣe ti ìjọba
Oríṣun àwòrán, IMN
Lái fí ti ọmọluabi ṣe Gekpe sàlàyé El-Zakzaky bẹ̀rẹ̀ ìfọ̀rswérọ̀ pẹ̀lú àwọn agbẹjọrò ti Ali Zia Kabir Chaudary àti Gunjan Singh soju fún ni orilẹ̀-èdè náà.
Ìjọba Nàìjíríà ní ó di dàndàn láti fẹ̀sì lóri awuyewuye tó n lọ lóri ọga ọmọ IMN  Ibraheem El-Zakzaky to pada de láti orilẹ̀-èdè India níbi  tó yẹ kí òun àti ìyàwó rẹ̀ ti lọ gba ìtóju.
Ijọba ní nígbà ti El-Zakzaky de India ló bẹ̀rẹ̀ si ni hú àwọn ìwà tó ti ni ọkàn tẹ́ll ti kò si hàn si ìjọba ki wọ́n to kuro lorilẹ̀-èdè Nàìjíríà, èyí ló fa sábàbí ìdí tí wọ́n fi dáá pada si orilẹ̀-èdè yìí.
Ijọba sàlàyé ọ̀rọ̀ yìí ninu àtẹjáde kan tó akowe ilé iṣẹ́ ìròyìn àti àsà Grace Isu Gekpe fi  síta sàlàyé pe ìwà tí El-Zakzaky gbé wọ̀ ní India jẹ èyí to le tàbùkù orílẹ̀-èdè Nàìjíríà.
Lái fí ti ọmọluabi ṣe Gekpe sàlàyé El-Zakzaky bẹ̀rẹ̀ ìfọ̀rswérs pẹ̀lú àwọn agbẹjọrò ti Ali Zia Kabir Chaudary àti  Gunjan Singh soju fún ni orilẹ̀-èdè náà.
Bákan náà ló tún ké sí à\won ajọ kan tii ṣe ti ìjọba bí Islamic Human Right Commission (IHRC) àti àwọn ọmọ ẹgbẹ́ Shia míràn pẹ̀lú èròngbà láti dúrò sibẹ fún ààbọ tí yóò si mórí lé orílẹ̀-èdè míràn tó ba yá.
Ẹ̀wẹ̀, bi ilé ẹjọ India ba fààyé gba El-Zakzaky lati dúró nítori ààbo ẹmi rẹ̀ lórílẹ̀-èdè India, èyí yóò r-tako ìdájọ ilé ẹjọ ti Nàìjíríà to fún láàyè láti lọ tọ́ju àrà rẹ ni India ki o si pàdà wálé, èyí bákan náà yóò fún ni àfàní láti sọ ẹgbẹ́ IMN di ti gbogbo aye.
Ijọba ni èyí to dún oun jùlọ ni pé ìyàwó El-Zakzaky koju àwọn eléto ààbo India àti ti Nàìjíríà pé wọn pa àwọn ọmọ oun, gbogbo èyí jẹ́ ọ̀nà láti jẹ́ ki àwọn orilẹ̀-èdè yìí káànu wọ́n, èyí sì  ń kó àbàwọ́n ba orúkọ orilẹ̀-èdè yìí.
Oríṣun àwòrán, El-Zakzaky
Awuyewuye ṣi n waye lori bi irinajo aṣiwaju ijọ Shiite ni Naijiria, Ibrahim El-Zakzaky ṣe ní kọnu n kọhọ ninu lasiko to lọ gba itọju ni orilẹede India, eyi ti o n ṣokunfa ipadabọ rẹ wa sile.
Laarin awuyewuye yii ni El-Zakzaky funrarẹ ti gbe fidio kan sita, ninu eyi to ti sọ awọn ohun ti oju rẹ n ri lorilẹede India, bi o tilẹ jẹ wi pe ijọba apapọ naa ti sọrọ sita pe, ọrọ to sọ ko ri bẹẹ lọpọ igba.
Ni ọjọ Ẹti ni ireti wa pe El-Zakzaky yoo gunlẹ pada si Naijiria, papakọ ofurufu Nnamdi Azikwe nilu Abuja si ni yoo balẹ si.
Osun Osogbo: Àwọn èèbó aláwọ̀ funfun gbé Ọ̀ṣun lárugẹ
Ilu Oṣogbo sọkutu wọwọ loni pẹlu obitibiti ero lasiko asekagba ọdun Ọṣun Oṣogbo to waye loni.
Lati nkan bi aago mẹfa idaji ni awọn ara ilu ati orisirisi awọn onilu ti korajọ siwaju aafin Ataọja tilu Oṣogbo, lati se ajọyọ ọdun Ọṣun Oṣogbo ti ọdun yii.
Ọpọlọpọ awọn eniyan jankan-jankan lo wa lati orisirisi ipinlẹ ni orilẹede yii ati ni awọn orilẹede miran lagbaye, lati kopa ninu ọdun naa, eyi ti ko yọ awọn oyinbo alawọ funfun sẹyin.
Lara awọn wọ ki ilu mọ ni ilẹ Yoruba to wa nibi ayẹyẹ ọdun Ọsun Osogbo ti ọdun yii ni, Aare Ọna Kakanfo ti ilẹ Yoruba, Aare Gani Adams, Oloye Nikẹ Davies Okundaye, ti gbogbo eeyan mọ̀ si Nikky Afrikana ati awọn lọba lọba nilẹ Yoruba.
"Arugba Osun Osogbo jade ni deede aago mẹwa ku ogun isẹju aarọ, ti ọgọọrọ awọn eniyan siwaju rẹ pẹlu ijo ati ayọ, ti wọn si n se adura ti wọn kigbe ""Ore yeye ooooooo."""
Bi awọn onilu gangan ati bata se n lu ilu lọ niwaju arugba naa, ni awọn agbofinro n sọ ọ loju lẹsẹ, ti wọn ko si jẹ ki ẹnikẹni sunmọ ọdọ rẹ.
Ninu ifọrọwerọ pẹlu ikọ BBC Yoruba, ọkan lara awọn ontaja to wa nibi ọdun naa saroye pe aje ko bu igba jẹ lọdun yii, nitori pe witiwiti pọ lọdun to kọja ju ti ọdun yi lọ.
Lara awọn isẹlẹ arimaleelọ to waye nibi ọdun naa ni, asọ alaranbara ati asọ funfun ti awọn olujọsin Ọsun wọ, awọn alageere lọkunrin lobirin tiwọn n fi ijo da awọn eniyan laraya ati ọpọlọpọ awọn ọdọmọkunrin ti wọn mu pankẹrẹ lọwọ ti wọn si n na ara wọn.
Poposinsin odun Osun Oshogbo
Ninu ile iya Osun ni ati fi oju ganni ọpọlọpọ eniyan ti wọn n se adura, lara awọn oloye ilu ti o wa ninu ile naa wi pe ile mimọ ni ile iya Osun jẹ, ati wi pe wọn kii wọ bata wọ ibẹ.
Awọn lẹgbẹlẹgbẹ-loyeloye ati ọkanọjọkan ẹlẹgbẹjẹgbẹ lawujọ ti n ṣe ikini fun Kabiyesi Ataọja ti ilu Ọṣogbo, Ọba Jimoh Oyetunji, ti Kabiyesi naa si n wure fun wọn.
Ooni Crown Prince: Èyí ni bí wọ́n ṣe bí Àrẹ̀mọ tuntun Ọọ̀ni Adeyeye ti Ile Ife àti orúkọ tí ó kọ́kọ́ jẹ́
Oríṣun àwòrán, Olori Moronke Shilekunola Ogunwusi
Iroyin tuntun nipa Arẹmọ kabiyesi Ọọni ile ifẹ to n jade fihan pe ni ileewosan nla ti ijọba apapọ, FMC to wa ni ilu Ọwọ ni wọn bi i si.
Ni owurọ Ọjọru ni okiki kan pe kabiyesi Ọọni Adeyeye Ogunwusi ti ni Arẹmọ lẹyin ti wọn gbẹbi olori rẹ, Yeyeluwa Naomi Silekunola Ogunwusi; lati igba naa si ni wẹjẹwẹmu ti n lọ kaakiri.
Ninu ifọrọwerọ rẹ pẹlu BBC News Yoruba, agbẹnusọ fun aafin Oodua, Kọmureedi Ọlafare ṣalaye pe ileewosan nla naa ni wọn bi Arẹmọ Ọọni si.
Iroyin fi idi rẹ mulẹ pe, ni kete ti iroyin ibi arẹmọ wọle ni Kabiyesi Ọlọwọ ti ilu Ọwọ, Ọba Ajibade Ogunoye ati Olori rẹ, Adenikẹ ti n dawọ idunnu. Wọn wa lara awọn to kọkọ ṣe abẹwo si Arẹmọ tuntun ati Iya rẹ, Olori Naomi Silẹkunọla ni ileewosan nla naa.
Koda iroyin ti a tun n gbọ ni pe Kabiyesi Ọlọwọ ti ilu ọwọ ti fun Arẹmọ tuntun yii lorukọ.
"Orukọ ti kabiyesi fun arẹmọ ni 'Aderiye""."
Kabiyesi Ọba Ajibade ṣalaye pe ibi Arẹmọ naa tun tubọ fi idi ajọṣepọ lati iṣọkan ati ipilẹ to wa laarin Ifẹ ati Ọwọ mulẹ ni.
Grandma Maruwa: Ó yẹ kí obìnrin sisẹ́ láì wojú ọkọ kó tó jẹun
Olori Ọlọwọ ti ilu Ọwọ, Adenikẹ Ogunoye la gbọ pe o lewaju ikọ awọn agba oloye ilu Ọwọ gẹgẹ bi awọn to kọkọ ṣe abẹwo si Arẹmọ tuntun ati Iya rẹ, Olori Naomi Silẹkunọla ni ileewosan nla naa.
Awọn oloye to wa pẹlu Olori Adenikẹ ni Agbaoye Tunde Elerewe, Akọwe fun Ọlọwọ, Oloye Amos Aladeṣẹyẹ, Oloye Mudongho pẹlu Iyalode Ẹhin Ogbe, Oloye Ọbademi.
Bakan naa ni agbẹnusọ fun aafin Ooodua ni ile Ifẹ, Kọmureedi Ọlafare pẹlu fi idi rẹ mulẹ pe awọn oloye lati Ile Ifẹ pẹlu ti kan si Arẹmọ ni kete ti iroyin naa kan Kabiyesi Ọọni lara.
Bi o tilẹ jẹ wi pe agbẹnusọ fun aafin Oodua ko ṣalaye awọn oloye to lọ ni pato, iroyin ti a gbọ fi idi rẹ mulẹ pe alamojuto abo ibilẹ fun Ọọni, Saarun Oodua, Oloye Oriowo Oriyọmi lo lewaju awọn agba oloye Ile Ifẹ bii Akọgun Waasin, Lowaatẹ ati Ẹrẹbẹsẹ lọ ki Arẹmọ tuntun kaabọ sile aye.
Oríṣun àwòrán, Olori Moronke Shilekunola Ogunwusi
Iroyin lati aafin oodu ni ile Ifẹ ni yewa pe rẹpẹtẹ ni wẹjẹwẹmu n lọ laafin Kabiyesi Ọọni niluu ile Ifẹ lẹyin ibi Arẹmọ ile Oodua lowurọ Ọjọru.
Gẹgẹ bi a ṣe gbọ, ni kete ti awọn araalu ti gbọ iroyin naa ti bọ sita lawọn eeyan ti ya wọ aafin ti wọn si ti bẹrẹ gbogbo ijo ati ilu; bẹẹ ni orin n lọ lakọlakọ.
Bi ẹ ko ba ni gbagbe iroyin bọ̀ sita lowurọ Ọjọru ni kabiyesi, Ọọni ti Ife, Ọba Enitan Adeyeye Ogunwusi kede pe iyawo oun, olori Naomi ti bimọ.
"Ọọni fi si oju opo opo Instagram rẹ pe ""gbogbo ọpẹ ni fun Ọlọrun fun ore nla to ti ṣe."
Ọọni Adeyeye ni oun ki gbogbo ara ile Oduduwa ati Olori Silekunola to ṣẹṣẹ bi Arole ọmọ fun itẹẹ Oduduwa.
O si fi to awọn eeyan leti wipe ilera pipe ni iya ati ọmọ wa.
Ṣaaju ni nkan bii oṣu kan o le diẹ sẹyin ni awọn rẹdio ẹlẹjẹ n gbe iroyin kiri nigba ọjọ ibi ko tii to pe Ọọni ti bimọ ṣugbọn ti BBC Yoruba kan si aafin Ọọni Adimula gangan, a bu ẹnu atẹ lu iroyin ofege pe ko ri bẹẹ.
Ọọni Ogunwusi Adeyẹye pe fun itọju awọn ọdọ
A n se akojọpọ ẹkunrẹrẹ iroyin yajoyajo lọwọ, a o maa gbe ẹkunrẹrẹ iroyin naa sori atẹ iroyin wa laipẹ. Ẹ jọwọ, ẹ tun oju opo iroyin yi yẹwo, ki ẹ lee ri ẹkunrẹrẹ iroyin ọtun laipẹ.
N1M ní iléẹ́jọ́ béèrè fún béèlì olùwọ́de EndSARS, Eremosele Adene
Wo ìdí tí wọ́n fi ta ẹyẹlé kan ṣoṣo ní ₦893,000,000
Bí o bá bá ààrùn ìpẹ́pẹ́ gbígbẹ lára arẹwà obìnrin rẹ̀, kí loó ṣe?
FIFA fòfinde akoọ́nimọ̀ọ́gbá Super Eagles nigbakan ri Samson Siasia
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Iwadi naa ni ajọ FIFA se pelu ifọwọsọwọpọ awọn ẹka miran ninu ajọ bọọlu alafẹsẹgba.
"Gbájúgbàjà kàn nínú èrè  ìdárayá Collin Udoh tí fi léde lóju òpó Twitter pé òun ti bá Samson Siasia sọ̀rọ̀ àtí wi pé Siasia ní "" mí o mọ ǹkan kan nípa ọ̀rọ̀ tó wà nílẹ̀ yìí.'' Mí ò ṣe ǹkankana láì da bákan náà ní mí ò ti gbà lẹ́tà kankan láti ọ̀dọ̀ FIFA lóri ọ̀rọ̀ yìí"""
Collin Udoh fi kún pé ó fi dá òun lójú pé oun yóò jà fiktafita lati wẹ orúkọ oun mọ.
O ní Siasia tún fi kún fún oun pé kò tilẹ̀ sí ẹni tó pé òun láti fi ọ̀rọ̀ wá oun lẹ́nu wò lóri ǹkan to ṣẹlẹ̀ yálà láti sọ tẹ́nu oun tàbí láti ja fún ẹtọ oun, ati pé ìgbà àkọ́kọ́ rèé tí òun náà ń gbọ́ ǹkan tó ṣẹlẹ̀
Kíní àwọn olúlúfẹ́ bọ́ọ̀lù àti àwọn Nàìjírí[[a ń sọ lóri ìgbésẹ̀ FIFA si Samson Siasia
Àjọ FIFA fòfinde Samson Siasia titi lailai
Ajo to n se amojuto ilana ere bọọlu afẹsẹgba lagbaye  ti fi ọrọ lede wipe Samson Siasia to jẹ́ akoọ́nimọ̀ọ́gbá Super Eagles tẹ́lẹ̀rí, ti jẹbi ẹsun wipe oun lee gba riba bí ààye rẹ̀ bá yọ, pàápàá  jùlọ láti yí èsì ìfẹsẹwọnsẹ bọọlu pàda.
Ajo to ń se amojuto iwa ibajẹ naa ti bẹẹrẹ iwadi lori ọro ọgbeni Siasia láti ọjọ kankanla osu keji ọdun yi.
Eyi to waye leyin iwadi ti ajọ naa se lori bii Ọgbeni Wilson Raj se gbiyanju lati yi esi idije kan pada lati fi ta tẹtẹ.
Iwadi naa ni ajọ FIFA se pelu ifọwọsọwọpọ awọn ẹka miran ninu ajọ bọọlu alafẹsẹgba.
Ninu ipinu wọn, ajọ ti ń se amojuto ilana isẹ ere bọọlu afẹsẹgba naa wipe ọgbeni Siasia jẹbi lodi si ilana ti FIFA gbekale.
Wọn si pasẹ fun lati san owo itanran eyi ti iye  rẹ lé diẹ̀ ni miliọnu mejidinlogun naira.
Ibrahim El-Zakzaky: 'Ó ṣeésẹ kí El-Zakzaky máa lọ òkè òkun fún ìtọ́jú mọ́'
Oríṣun àwòrán, Twitter/SayyidZakzakyOffice
Ọrọ lori ailera Ibrahim El-Zakzaky
O ṣeeṣe ki olori awọn musulumi Shiite, Ibrahim El-zakzaky maa lanfani mọ lati lọ gba itọju loke okun lẹyin to pada si Naijiria latorilẹede India
Ijọba Naijiria fẹsun kan an pe o fẹ wa awọn orilẹede miiran kunra lati gbaruku tii.
Bakan naa nijọba tun koro oju si iwuwa si El-Zakzaky nigba to wa ni orilẹede India.
Eekan lara awọn oṣiṣẹ eleto aabo sọ fun iwe iroyin Punch pe yoo nira fun ijọba lati fun El-Zakzaky ni iru aye bẹẹ nitori ohun tawọn ileeṣẹ ọtẹlẹmuyẹ jabọ fun ijọba lori eto aabo nilẹ India ko tẹ ijọba lọrun.
Ẹ o ranti wi pe ijọba ti kọkọ duro lori ẹsẹ rẹ tẹlẹ pe ki El-Zakzaky gba itọju nile iwosan to wa ni Naijia.
Ṣugbọn awọn ẹsun ti ijọba fi kan an lorilẹede India lara eyi ti wọn ni o ti n gbero lati ri agbẹjọro rẹ, yoo jẹ ki ijọba ṣe agbyẹwo iroyin tawọn ọtẹlẹmuyẹ mu bọ lati India ki ijọba to gbe igbesẹ miiran.
Ijọba Naijiria figbe ta lọjọ Ẹti pe El-Zakzaky n gbero lati lọ ṣe atipo nilẹ okere, bakan naa ni ijọba sọ pe iwuwasi El-Zakzaky lorilẹede India doju ti ijọba orilẹede naa ati ti Naijiria.
Ijọba fidi rẹ mulẹ ninu atẹjade kan ti akọwe agba nileeṣẹ eto iroyin ati aṣa, Grace Gekpe fi sita pe iyawo El-Zakzaky tako awọn oṣiṣẹ eleto aabo India ati Naijiria.
Atẹjade ọhun tun sọ pe iyawo El-Zakzaky fẹsun kan awọn oṣiṣẹ eleto aabo pe awọn ni wọn pa awọn ọmọ oun.
Ṣugbọn agbẹnusọ fawọn musulumi Shiite, Ibrahim Musa ni irọ ni ijọba n pa, o ni El-Zakzaky ko gbero lati lọ ṣatipo nilẹ okere.
Bakan naa lo sọ pe ko si ẹni to le gba ijọba gbọ lori ọrọ to ba n sọ nipa Ibrahim El-Zakzaky.
Lọjọ Ẹti ni El-Zakzaky pada si orilẹede Naijiria lati India to ti lọ gba itọju pẹlu aya rẹ.
Toyin Abraham: Ọ̀pọ̀ èèyàn ní èké ni Mercy Aigbe ń ṣe lórí bó ṣe ki Adeniyi Johnson
Oríṣun àwòrán, Instagram/realmercyaigbe
Ọpọ eeyan lori ayelujara lo ti bẹnu ẹtẹ lu bi oṣere tiata Mercy Aigbe ṣe ki Adeniyi Johnson to jẹ ọkọ akọkọ Toyin Abraham to ṣẹṣẹ bimọ.
Mercy Aigbe kọ loju opo Instagram rẹ pe Adeniyi wu oun lori, bẹẹ lo tun gbadura fun un pe ''Eleduwa yoo maa tọ lọna, yoo si fi ibukun si iṣẹ ọwọ rẹ lorukọ Jesu.''
Oríṣun àwòrán, Instagram/realmercyaigbe
Bakan naa ni Mercy tun sọ ninu ọrọ rẹ pe ki Adeniyi jẹ ki ohun to ti kọ ja lọ di afisẹyin t'eegun fi aṣọ, ko si jẹ ki ifẹ bori.
Ṣugbọn ọpọ ni eke ni Mercy n ṣe lori ikini rẹ to nii ṣe pẹlu ọmọ tuntun jojolo bi Toyin Abraham ṣẹṣẹ bi pẹlu ọkọ rẹ, Kolawole Ajeyemi.
Emerald fi tiẹ ṣe loju opo Twitter rẹ, o ni ko lo ṣeeṣe ki ọrọ ifẹ da Mercy Aigbe ati Adeniyi Johnson pọ.
O ni rara ka maa ri lọrọ naa.
Awọn da  Emerald lohun pe ko si ohun ti ko le ṣẹlẹ, Olukayode Bakre ni tiẹ sọ pe ko si ibi ti ọrọ ifẹ ko ti le ṣẹlẹ.
Oríṣun àwòrán, Instagram/toyinabrahamnews
OTSWC ni o le maa si ohun kankan laarin wọn ṣugbọn ko si ohun tawọn osẹre tiata ko le sẹ.
Yẹyẹ ni Duke of Ikorodu fi ọrọ naa ṣe nigba to sọ pe ọkunrin ọun dabi ọmọ ọdun mẹẹdogun loju oun.
Bakan naa ni Emerald fikun ọrọ rẹ pe ọmọkunrin mi ni Mercy maa n pee.
Awọn eeyan mii tiẹ n beere pe ta ni ọkunrin ti wọn n sọrọ nipa rẹ gan an.
Premier league: Arsenal kọrin 'kọ́stọ́mà daada ni' fún Burnley pẹ̀lú àmì ayò méjì sí ẹyọkan
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Lacazette, Aubameyang, Ceballos ati Pepe tan yòò bí oòrùn nínú ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ náà
Nnkan gbe nnkan hanu loni ni papa iṣire Emirates tii ṣe ibuba ẹgbẹ agbabọọlu Arsenal.
Arsenal ati ikọ Burnley ni wọn jijọ gbe ina woju ara wọn.
Nigba ti ere gbogbo yoo fi pari, Arsenal lo gbogo ọjọ naa lọwọ
Pẹlu bi ifẹsẹwọnsẹ yii ṣe pari yii, ikọ Arsenal ti sọ Burnley di kọstọma daadaa ni
Arsenal lo kọkọ gba bọọlu wọ inu awọn nigba ti ifẹsẹwọnsẹ naa wọ iṣẹju mẹtala. Lacazette, atamatase ikọ Arsenal  lo gba goolu naa wọle.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Lẹyin eyi, Arọni Arsenal ko simi rirọjo bọọlu lọ si oju ile Burnley bi o tilẹ jẹ pe Burnley pẹlu ko sun asunpiye, awọn naa ja fitafita ti wọn si da goolu akskọ pada nigba ti ifẹsẹwọnsẹ naa wọ iṣẹju kẹtalelogoji.
Ọkan lara awọn atamatase to ti sọ awọn Arsenal di kọstọma daadaa, Ashley Barnes lo gba bọọlu naa wọle.
Jesus gbá góòlù sáwọ̀n gba ife Community Shield fún Man City
Òṣèré tíátà Toyin Abraham daya Kolawole Ajeyemi
Bí Khafi ṣe ní ìbálòpọ̀ ojútáyé tako àṣà Yorùbá - Ìjọba Ekiti
Ki wọn to lọ sinmi fun saa akọkọ Arsenal gba goolu miran wọle ṣugbọn oludari ere naa, wọgi lee lẹyin ti ẹrọ VAR ṣe afihan rẹ pe aṣiṣe waye ṣaaju goolu naa.
Eyi ni igba kọkanla ni ṣisẹ-n-tẹle ti Arsenal yoo maa ṣina iya fun Burnley lati oṣu kẹta ọdun 2009.
Oṣu kejila ọdun 2008 ni Burnley fi ẹyin Arsenal gbolẹ kanyin
FIFA ban: Siasia ní kò sí ìgbà tí òun àti FIFA kò ní pàdé ní kóòtù
Oríṣun àwòrán, others
Siasia, olukọni bọọlu ọmọ Naijiria ti ajọ FIFA paṣẹ fun pe eegun rẹ ko gbọdọ ṣẹ mọ lagbo ere bọọlu lagbaye titi lahun sita pe oun afaims ki oun ati ajọ FIFA maa pade ni ile ẹjọ nitori ẹsun gbigba riba.
Siasia gba ẹnu awọn aṣoju ati amofin rẹ sọrọ nibi ipade kan to ṣe pẹlu awọn oniroyin niluu Abuja.
Bi o tilẹ jẹ pe Siasia wa nibi ipade akọroyin naa sibẹ ko ba awọn akọroyin sọrọ funrarẹ pẹlu awawi pe awọn amofin oun ti n wo ọrọ naa.
O ni oun ṣi wa ninu ikaya soke lori ti iya oun ti wọn ji gbe ti wọn ni ki oun ls maa wa ẹgbẹlẹgbẹ owo wa ki ajọ FIFA to tun gbe tiwọn de.
Ni ọjọ Ẹti ni ajọ FIFA kede pe awọn ti gbẹsẹ le kikopa Sisasia ninu ohunkohun to nii ṣe pẹlu ere bọọlu lagbaye nitori ẹsun gbigbimọ lati gba owo riba ti wọn fi kan an.
Amọṣa, Siasia ti ṣalaye pe oun ko mọ ohunkohun nipa ẹsun naa atipe ko si igba kankan ti ajọ naa pe oun joko lati beere ọrọ lori ẹsun naa ki wọn to gbe idajọ wọn kalẹ.
O wa sọ ọ di mimọ nibi ipade naa pe awọn amofin oun ti n gbe igbesẹ lori ohun ti yoo kan lori ọrs naa.
Premiership league: Liverpool fẹ́rẹ̀ ẹ́ forígbá níwájú Southampton ṣùgbọ́n orí kó o yọ
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ẹgbẹ agbabọọlu Liverpool ṣi n tẹsiwaju ninu fifi agbara wọn han awọn ikọ agbabọọlu yooku pẹlu bi wọn ṣe na ikọ Southampton pẹlu ami ayo meji si ẹyọkan mọle.
Eyi ni ifẹsẹwọnsẹ meji ti Liverpool yoo maa bori laarin ọjs mẹrin si arawọn lẹyin to fagba han Chelsea lati gba ife ẹyẹ Super cup ni ọjọru.
Mane lo kọkọ gba bọọlu wọn awọn Southampton to jẹ iks to ti n gba bọọlu jẹun tẹlẹ ki Firmino to fọba lee nigba ti ifẹsẹwọnsẹ naa wọ iṣẹju mọkanlelaadọrin.
Amọṣa, Danny Ings ti oun pẹlu naa ti gba bọọlu ri fun ikọ Liverpool da ẹyọkan pada nigba ti ifẹsẹwọnsẹ naa de iṣẹju kẹtalelọgọrin.
Liverpool ni o di ipo keji mu ni saa liigi to kọja yoo si maa lepa ati gba liigi naa lọdun yii lẹyin to ti gba ife ẹyẹ Champions league ni saa bọọlu to kọja.
Premier League: Tottenham yọ ṣọ́ọ̀kì lẹ́sẹ̀ , ọ̀mì ni wọ́n ta lọ ní pápá ìṣiré Etihad
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ṣe wọn ni ẹṣin ta-ta-ta, o ku, eeyan rin-rin-rin o sọnu, gbogbo agbara emi ni mo to yii ti Manchester city fi gba ife ẹyẹ Premier league ni saa bọọlu to kọja lo sa pẹlu eyi to fi na Westham mọ ile lọsẹ to kọja ṣugbọn pabo lọrọ jasi fun iks naa nigba to gbalejo Tottenham ni gbagede papa iṣire Etihad lọjọ Abamẹta.
Raheem Sterling ti n ti n da bi ẹdun rọ bi owe lati igba ti saa bọọlu tuntun ti bẹrẹ bayii lo kọkọ gba bọọlu sinu awọn, eleyi to sọ iye goolu to ti gba sinu awọn di mẹrin.
Amọṣa, iks Totenham ko fojuure wo Manchester city lẹyin goolu yii, ni kiakia ni awọn naa daa pada. Eric Lamela lo gba wọle nigba ti ifẹsẹwọnsẹ naa wọ iṣẹju kẹtalelogun.
Eyi lo mu ki ikọ Manchester city pariwo ki lo ṣubu lu mi yii? Ni wọn ba ran Sergio Aguero niṣẹ, loun naa ba tun fi ọkan lee fun totenham lo ba di meji fun Manchester city, ẹyọkan fun Tottenham.
Awọn agbabọọlu Tottenham naa ba tun da ẹsẹ ru fun Mancity ni Lucas Moura ba tun da ekeji naa pada.
Wọ́n fi ẹyin adìyẹ lé Ike Ekweremadu, kúrò níbi àṣeyẹ kan ní Germany
Oríṣun àwòrán, Ike Ekweremadu
Ẹyin eeyan wa, aṣe nnkan n ṣẹlẹ niju ara etile o gbọ ni. Boya wọn si gbọ, wọn fi mọra ni awa o mọ o.
Ẹ n bi mi pe ki lo ṣẹlẹ?
Igbakeji aarẹ ile aṣofin agba tẹlẹ, Sẹnetọ Ike Ekweremadu lawọn ọmọ ẹya apa ila oorun gusu orilẹ-ede Naijiria kan din dundu iya fun lọjọ Abamẹta ni ilu Nuremberg lorilẹ-ede Germany.
Gẹgẹ bi iroyin ti agbọ ṣe sọ, nṣe ni wọn fi iwe pe Sẹnetọ Ekweremadu si ibi eto nla kan ti awọn ọmọ ẹya igbo to n gbe ni ilu naa gbe kalẹ.
Gẹgẹ bi ipe ti wọn pe e, oun ni yoo jẹ alejo pataki nibi eto naa.
Amọṣa, ki a maa deena pẹnu, kaka ki wọn bu ẹyẹ fun un gẹgẹ bi alejo pataki, nṣe ni wọn yẹyẹ aṣofin agba naa.
Koda, ẹyin tutu ni wọn ju luu, wọn ko si tilẹ jẹ ko ri aaye wọle debi pe yoo roju raye ṣe alejo pataki ti wọn pee fun.
Awọn amugbalẹgbẹ ati ọrẹ rẹ kan to ba ikọ BBC sọrọ fi idi rẹ mulẹ, amọṣa wọn bu ẹnu atẹ lu iwa naa.
Insecurity: Buhari ní ẹ̀ka aláàbò Nàíjíríà tiraka àmọ́ ó yẹ kí wọn ṣe jù bẹ́ẹ̀ lọ
Oríṣun àwòrán, Others
Aarẹ orilẹede Naijiria, Muhammadu Buhari ti kede pe awọn ọms Naijiria funra wọn mọ pe ijsba oun ti sa ipa rẹ lati gbogun ti aifararọ eto aabo.
Aarẹ Buhari kede bẹẹ lasiko to n bawọn akọroyin ile ijọba sọrọ nile ijọba Aso Rock nilu Abuja lati sami ọdun Ileya.
Amọ aarẹ wa fi aidunnu rẹ han lori isesi awọn asaaju ikọ alaabo wa, o ni o yẹ ki wọn se aseyọri ju bayii lọ.
"Mo fẹ kawọn ọmọ Naijiria mọ daadaa nipa orilẹede wọn ati awọn ohun ta ba nilẹ lọdun 2015.
Eyi tii se ikọlu Boko Haram ni ẹkun ariwa ati tawọn ajijagbara lẹkun aarin gbungbun guusu Naijiria.
O si da mi loju pe awọn ọmọ Naijiria gan mọ pe mo ti gbiyanju lati se ohun ti agbara mi ka lori wọn."
"Awọn ohun to n sẹlẹ lẹkun iwọ oorun ati aarin gbungbun ariwa Naijiria n ba ni ninu jẹ pupọ.
Oríṣun àwòrán, @HQNigerianArmy
Amọ mo si nigbagbọ ninu awọn osisẹ ologun, ọlọpaa atawọn osisẹ agbofinro yoku lati ipasẹ abọ ti wọn n jẹ fun mi, sugbọn mo ro pe o yẹ ki wọn si lee se ju bayii lọ."
Bakan naa ni agbẹnusọ fun aarẹ Muhammadu Buhari, Garba Shehu, fi atẹjade kan sita lọjọ ọdun Ileya.
O ni aarẹ Buhari ti fọwọ sọya fawọn ileesẹ alaabo pe oun yoo pese awọn ohun eelo to yẹ fun wọn lati lee koju aifararọ eto aabo nibikibi lorilẹede Naijiria.
Oríṣun àwòrán, Twitter/Nigerian Presidency
Ọrọ eto aabo Naijiria
Aarẹ Muhammadu Buhari ti paṣẹ fawọn ologun pe ki wọn yinbọn pa ọdọran kọdaran to ba n ṣagbatẹru rogbodiyan tabi ikọlu kaakiri orilẹede Naijiria.
Aarẹ ni o ba oun lọkan jẹ bi awọn janduku ti n pawọn alaiṣẹ ati bi wọn ti n sọ ọpọ di alaabọ ara ti wọn si n tun n jawọn lole.
Aarẹ Buhari fọrọ yii lede nibi ti o  ti n bawọn ọmọ ologun 17th Brigedi atawọn ọmọogun ofurufu 213 Operational Base niluu Katsina lọjọ Abamẹta.
"Buhari rọ awọn ologun naa ti wọn pe ọrukọ wọn ni ""Operation Hadarin Daji,"" lati ṣiṣẹ eto aabo ti ijọba gbe fun wọn takuntakun."
Aarẹ ni ijọba ''da ẹgbẹ ọmọogun yii silẹ lati daabo bo apa iwọ oorun ariwa orilẹede Naijiria lọwọ awọn janduku ti wọn da ilu ru kiri, ati pe iṣẹ wọn ni lati daabo bo orilẹede Naijiria lapaapọ.''
Aarẹ sọ pe oun gẹgẹ bi olori ileeṣẹ ologun Naijiria ''gbagbọ pe awọn ọmọogun koju oṣuwọn lati ṣiṣẹ ti ijọba gbe fun wọn,'' bakan naa ni aarẹ paṣẹ fun wọn pe ki ''wọn o wa awọn ọdanran to n da rogbodiyan silẹ lọ sibi kibi ti wọn ba n farapamọ si, ki wọn si mu wọn kuro nilẹ.''
Buhari ni o to gẹ bayii nitori Naijiria pe alaafia gbọdọ jọba lorilẹede Naijiria.
Aarẹ Buhari ṣeleri pe ijọba ṣetan lati pese ohun elo ijagun ti wọn nilo lati ṣiṣẹ to wa lọwọ wọn.
Lọjọ Abamẹta yii naa ni Aarẹ Buhari pada siluu Abuja lẹyin isinmi ọdun Sallah to lọ ṣe niluu rẹ Daura lati ọjọ kẹjọ oṣu kẹjọ.
Ike Ekweremadu attack: Igbákejì adarí ilé aṣòfìn àgbà tẹ́lẹ̀ dáríjì àwọn IPOB tó nà mí ní Germany
Oríṣun àwòrán, Facebook/Ike Ekweremadu
Ọrọ naa da bi ọrọ ti Jesu Kristi sọ lori igi agbelebu pe ''Baba dariji wọn, nitori pe wọn ko mọ ohun ti wọn n ṣe.
Bẹẹ gẹgẹ ni igbakeji adari ile igbimọ aṣofin agba l'Abuja tẹlẹ, Sẹnẹtọ Ike Ekweremadu ti fesi si bawọn ẹya Igbo to ni ọmọ ẹgbẹ IPOB ni wọn ṣe fiya jẹẹ lọjọ abamẹta ni ilu Nuremberg lorilẹede Germany.
Oríṣun àwòrán, Facebook/Ike Ekweremadu
Ninu ọrọ ti Sẹnẹtọ Ekweremadu fi soju opo Facebook rẹ, o ni oun ko ni gbe iṣẹlẹ naa sọkan nitori oun mọ pe awọn eeyan ko mọ ohun ti wọn n ṣe.
Ẹgbẹ Ndigbo lo fi iwe pe Sẹnetọ Ekweremadu si ibi eto nla kan ti awọn ọmọ ẹya igbo to n gbe ni ilu naa gbe kalẹ. Gẹgẹ bi ipe ti wọn pe e, oun ni yoo jẹ alejo pataki nibi eto naa.
Kaka ki wọn bu ẹyẹ fun un gẹgẹ bi alejo pataki, nṣe ni wọn yẹyẹ aṣofin agba naa. Koda, ẹyin tutu ni wọn ju luu, wọn ko si tilẹ jẹ ko ri aaye wọle debi pe yoo roju raye ṣe alejo pataki ti wọn pee fun.
Ẹwẹ, ọpọ eeyan atawọn eekan ninu awọn oloṣelu lo ti n sọrọ lori iṣẹlẹ ọhun, lara wọn ni alaga ajọ to n ri si ọrọ awọn ọmọ Naijiria to wa nilẹ okere, Abike Dabiri-Erewa to bẹnu ẹtẹ lu iṣẹlẹ naa.
O ni awọn to wa nidi ọrọ naa gbọdọ foju wina ofin.
Bakan naa, gomina ipinlẹ Ekiti tẹlẹ, Ayo Fayoṣe ni ẹni ilẹ ti wọn kii tẹni funh lawọn to fiya jẹ Ekweremadu lorilẹede Germany.
Fayoṣe ni ikọlu yii jẹ ikọlu fun gbogbo ẹya Igbo ati orilẹede Naijiria lapapọ nitori Sẹnẹtọ Ekweremadu jẹ ọkan lara awọn to jẹ ki ijọba awarawa fidi mu lẹ.
Fayoṣe iru awọn eeyan ko yẹ ki wọn maa gbe aarin awọn eeyan lawujọ.
Osita Chidoka ni tiẹ beere lọwọ awọn to yẹyẹ Ekweremadu lati tọrọ aforiji lọwọ rẹ nitori ko mọwọ mẹsẹ nigba ikọ ''Operation Python Dance.''
Chidoka ni Sẹnẹtọ Ekweremadu siwaju awọn igbimọ ti wọn lọ ba arẹẹ Muhammadu Buhari pe ko fi olori ẹgbẹ IPOB, Nnamdi Kanu silẹ.
Ogun kidnap: Àwọn ajínigbé gbé ọkọ̀ ojú omi ọlọ́pàá lọ lẹ́yìn tí wọ́n dóòlà ẹ̀mí ọmọ Ìmáàmù
Oríṣun àwòrán, Facebok/Bashi Makama
Ileeṣẹ ọlọpaa ipinlẹ Ogun ti sọ pe o didan awọn gbọdọ gba ọkọ oju omi agbera pa awọn pada lọwọ awọn ajinigbe.
Ileeṣẹ ọlọpaa doola ẹmi ọmọ imaamu atawọn meji mii ti wọn jigbe lọjọ Ileya lagbegbe Ọde Omi nipinlẹ Ogun.
Abdulazeez Sanni to jẹ ọmọ Imaamu ati Adamson Bamidele pẹlu Adam Jelili ti wọn jigbe leti bọda ipinlẹ Ogun ati ipinlẹ Eko ni wọn ti pada sọdọ awọn ẹbi wọn bayii.
Kọmisana ileeṣẹ ọlọpaa ipinlẹ Ogun, Bashir Makama sọ pe ko si ohun kan to ṣe awọn eeyan naa nigba tawọn ọlọpaa doola ẹmi wọn.
Ọgbẹni Makama o wa ba afurasi kan ninu wọn ti ibọn wa lọwọ rẹ.
Agbẹnusọ fun ileeṣe ọlọpaa Abimbola Oyeyemi ṣalaye pe awọn ẹbi awọn mẹrin naa ko san kọbọ fawọn ajinigbe ọun.
Ọgbẹni Oyeyemi ni ileeṣẹ ọlọpaa yoo gba ọkọ oju omi tawọn ajinigbe gbe lọ pada.
Benue clashes: Àwọn agbébọn yìnbọn pa èèyàn mẹ́sàn án ni Benue
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Aṣe ododo ọrọ pọnbele ni ọrọ awọn agba to ni oku n sunkun oku akaṣọleri n sunkun ara wọn.
Bi ọrọ ṣe ri gẹlẹ ree o ni agbegbe Tongov ni ipinlẹ Benue nigba ti awọn eeyan kan n fẹ lọ sin oku ọkan lara awọn ijoye pataki lagbegbe naa ti orukọ rẹ n jẹ, Tor Gbev Amaafu ni owurọ ọjọ Satide. Tomije-tomije ni ọgọrọ eeyan to tẹle posi oloye naa fi n sin in lọ si itẹ ikẹyin pẹlu orin aro lọlọkan-o-jọkan lẹnu wọn.
Amọṣa, lojiji ni wọn gbọ ti iro ibọn n dun lakọlakọ. Awọn agbebọn kan lo da awọn eeyan to n gbe oku lọ sin naa lọna. Ki a si to wi, ki a to fọ, eeyan mẹrin ti di oku lẹyin ti ọta ibọn ba wọn. Ọpọlọpọ ninu wọn lo tun fi ara gbọgbẹ ọta ibọn.
Ni igba ti yoo fi di ọjọ isinmi tii ṣe ọjọ Aiku, eeyan marun miran ti dero ọrun ọrun o.
Gẹgẹ bii ileeṣẹ ọlọpaa ni ipinlẹ Benue ṣe fi to araalu leti, awọn marun to ku yii kagbako iku wọn lasiko ti awọn kan fi lọ gbẹsan ikọlu wọn laarin ileto Amaafu, Sati Agirigiri ati Ikurav Tiev ni ijọba ibilẹ Katsina-Ala.
Alukoro ileeṣẹ ọlọpaa ni ipinlẹ benue, Catherine Anene ṣalaye peawọn funra pe o ṣeeṣẹ ki o jẹ wahala to n bẹ silẹ laarin ẹya Ikurav ati Shitile ni ipinlẹ Benue lẹnu ọjọ mẹta yii.
O fi kun un pe ileeṣẹ ọlọpaa ti bẹrẹ iwadii lori iṣẹẹ naa.
Àwọn ọ̀dọ́ ẹ̀yà Hausa kan àtàwọn ọmọ ẹgbẹ́ òkùnkùn 'Awawa boys' da ìgboro Eko rú
Àwọn ọ̀dọ́ ẹ̀yà Hausa kan àtàwọn ọmọ ẹgbẹ́ òkùnkùn 'Awawa boys' da ìgboro Eko rú
Wahala nla kan ti bẹ silẹ laarin awọn ọdọ kan lagbegbe Oke Odo ni ipinlẹ Eko.
Ohun ti awọn iroyin kan n sọ ni pe awọ̀n ọdọ ẹya Yoruba ati awọn akẹgbẹ wọn lati ẹya Hausa ni wọn fija pẹẹta lọjọ aiku bi o tilẹ jẹ wi pe ko tii si ẹni ti o lee sọ ohun ti o ṣokunfa rogbodiyan naa.
Oríṣun àwòrán, others
Gẹgẹ bi a ṣe gbọ, ni ọja Oke odo ni ija naa ti waye, bẹẹni ọpọ dukia lo parẹ sinu iṣẹlẹ naa ti ọpọ eeyan si fara pa pẹlu.
Oríṣun àwòrán, others
Ileeṣẹ ọlọpaa ni wahala naa waye laaring awọn ọmọ Hausa kan ti wọn maa n ṣa ilẹ  kaakiri atawọn ọmọ ẹgbẹ okunkun kan ti orukọ wọn n jẹ Awawa boys.
Oríṣun àwòrán, others
Alukoro ileeṣẹ ọlọpaa ni ipinlẹ Eko, Bala Elkana to ba ikọ BBC news sọrọ ṣalaye pe wọn ti da ikọ ọlọpaa kogberegbe kan si agbegbe naa ti wọn si ti pana wahala ọhun.
Yoruba-Hausa clash: Ọlọ́pàá mú èèyàn márùn ún lórí ìjà tó bẹ́ sílẹ̀ láàrin Hausa àti Yorùbá l'Eko
Àwọn ọ̀dọ́ ẹ̀yà Hausa kan àtàwọn ọmọ ẹgbẹ́ òkùnkùn 'Awawa boys' da ìgboro Eko rú
Ileeṣẹ ọlọpaa ipinlẹ Eko ti mu eeyan marun un lori wahala nla to bẹ silẹ laarin awọn Hausa ati Yoruba lọja Ile-epo lọjọ Aiku.
Gẹgẹ bi atẹjade ti agbẹnusọ ileeṣẹ ọlọpaa ipinlẹ Eko, Bala Elkana sọ pe awọn gba lati agọ ọlọpaa Oke Odo, ede-ai-yede bẹ silẹ nigba ti Hausa kan to n ṣa ilẹ idọti ṣeeṣi ti ọkunrin Yoruba kan to rẹru lori to si ṣubu bẹẹ.
Bayii lawọn mejeeji ṣe fija pẹta, bẹẹ lawọn ẹya wọn da si ija naa lo ba di nla ti awọn ọmọ ita kan ṣi da si ija naa.
Awọn janduku kan lo lanfani yii lati ja ole, koda wọn tun di opopona mọrosẹ ilu Eko si Abeokuta pa.
Oríṣun àwòrán, others
Ede Aiyede laarin ẹni meji di nla ni ileepo
Gẹgẹ bi a ṣe gbọ, ni ọja Oke odo ni ija naa ti waye, bẹẹni ọpọ dukia lo parẹ sinu iṣẹlẹ naa ti ọpọ eeyan si fara pa pẹlu.
Oríṣun àwòrán, others
Awon janduku miran lo ọrọ naa fi jale
Ileeṣẹ ọlọpaa ni rogbodiyan naa ko ba di ti ẹlẹyamẹya tawọn ko ba tete kọwọ ọmọ bọ aṣọ.
Alukoro ileeṣẹ ọlọpaa ni ipinlẹ Eko, Bala Elkana to ba ikọ BBC news sọrọ ṣalaye pe wọn ti da ikọ ọlọpaa kogberegbe kan si agbegbe naa to pana wahala ọhun.
Oríṣun àwòrán, others
ọpọ ọja lo ṣofo si iṣẹlẹ yii
Ileeṣẹ ọlọpaa fidi rẹ mu lẹ pe ko sẹni to ku ninu iṣẹlẹ naa, bakan naa awọn mẹrin ti wọn ṣeṣe ti n gba itọju nile iwosan.
Agbẹnusọ fun ileeṣẹ ọlọpaa ni awọn yoo gbe awọn afurasi marun un tọwọ ọlọpaa tẹ lọ si ileẹjọ.
RevolutionNow: Falana àtàwọn míì ṣe àpérò l'Eko lẹ́yìn tí DSS kọ́kọ́ ti gbọ̀ngàn tí wọ́n fẹ́ lò pa
Ileeṣẹ ọtẹlẹmuyẹ, ọlọpaa atawọn ologun kọkọ ti ibi ti awọn ajijangbara kan ti fẹ ṣe apero lori ifẹhonu han #RevolutionNow ni Lagos Centre ni Ikeja lọjọ Aje.
Ṣugbọn agbẹjọro Femi Falana jade bi awọn oṣiṣẹ eleto aabo ti sọ fawọn akọroyin pe ki wọn ba eṣẹ wọn sọrọ.
Bakan naa lo bawọn eeyan sọrọ ko to wọ gbọngan ipade ọhun lọ.
Laisi ani ani, ipade naa pada waye ni Ikeja, niluu Eko lọjọ Aje.
Àjọ DSS ti gbọ̀ngàn ìpàdé #RevolutionNow pa ní Ikeja
Awọn ilumọọka ajijagbara bi Ọjọgbọn Wole Ṣoyinka, agbẹjọro Femi Falana atawọn mii la gbọ pe wọn fẹ pade ni Lagos Centre fun apero naa tẹlẹ.
Ṣugbọn akoroyin BBC, Andrew Gift to ṣabẹwo si gbọngan naa sọ pe wamuwamu lawọn oṣiṣẹ DSS, ọlọpaa atawọn ologun duro siwaju bẹ ti wọn ko si jẹ ki ẹni kankan wọ bẹ.
Ohun ti a gbọ ni pe wọn fẹ ṣapero lori ohun ti wọn pe ni iwa tani yoo mu mi ti ijọba gunle lori bi wọn ṣe ti Omoyele Ṣowore to ṣagbatẹru iwọde Revolution Now atawọn ajijagbara mii mọ le.
Ko si aye fun ifitonileti miran ti ko ba ofin mu
Iroyin to tẹ wa lọwọ sọ pe ajọ to n ṣagbatẹru ifẹhonu han lati ja fun ẹtọ awọn ọmọ Naijiria, CORE lo fẹ pade ni Lagos Centre fun apero naa.
Yatọ si Ọjọgbọn Ṣoyinka ati agbẹjọro Falana, awọn eekan mi to tun wa lara ẹgbẹ naa ni Ọjọgbọn Omotoye Olorode, Ọgbẹni Femi Aboriṣade, Ọjọgbọn Anthony Kila, agbẹjọro Affiong L. Affiong ati bẹẹ bẹẹ lọ.
Fatai Owoseni: O dìgbà tí mo bá bẹ̀rẹ̀ iṣẹ́ kí ń tó sọ ìpinnu mi
Oríṣun àwòrán, @others
Fatai Owoseni: O dìgbà tí mo bá bẹ̀rẹ̀ iṣẹ́ kí ń tó sọ ìpinnu mi
Láìpé a máa to sọ àlákalè wa fún aṣeyọri eto aabo ipinlẹ oyo - Fatai Owoṣeni
Olubadamọran tuntun ti Gomina Seyi Makinde yan lori eto aabo ipinlẹ Oyo, Fatai Owoṣeni ti ni igbesẹ pọ ti yoo mu idagbasoke ba ipinlẹ Oyo.Fatai Owoseni to je kòmisónnà ajo ọlọ́pàá tẹ́lẹ̀ ní ìpínlè Èkó àti Benue ni Seyi Makinde kede pe ko bẹre iṣẹ loṣu kẹjọ ọdun yii.
Gege bí ikede tí akọ̀wé agba gómìnà náà Ogbeni Taiwo Adisa fi ṣòwò si awon akoroyin, ní ọjọ́ Kínní, oṣù tí a wà yìí to fidiẹ mulẹ.
O ni èyí ṣe pàtàkì láti lè fòpin sí ìkọlu àwọn daran-daran kaakiri ipinlẹ Oyo tó fi mọ ojú popona marose káàkiri ipinle naa.
Ohun ti Seyi Makinde sọ lẹyin ipade awọn ẹgbẹ alatako
Fatai Owoseni ṣàlàyé fun BBC pe ó di ìgbà tí Oun bá dé orí àga nibise kí oun to le gbe igbesẹ kankan lati dẹkùn iṣoro awọn Fulani ati awọn ajinigbe ọhun.
Owoṣeni ni o digba ti ọwọ oun ba tẹ eeku ida aṣẹ gẹgẹ bii oludamọran ki oun to le ṣalaye awọn ipinnu to ni lori eto aabo lasiko yii.
Kọmiṣonna nigba kan ri naa beere fun asiko diẹ sii ki oju fi fara balẹ rimu ki wọn fi le gbe igbesẹ to yẹ lati koju iṣoro kari aye yii.
SSANU, NASU gbé fásitì Ibadan tì pa nítorí ìyanṣẹ́lódì ọlọ́jọ́ márùn ún
Ẹgbẹ awọn oṣiṣẹ ti kii ṣe olukọ ni awọn ile ẹkọ giga lorilẹ-ede Naijiria labẹ aburada NASU, NAAT ati SSANU ẹka fasiti ilẹ Ibadan bẹrẹ iyansẹlodi.
Awọn SSANU, NASU ati NAT naa ti gunle iyanṣẹlodi ọlọjọ marun un lati kilọ fun ijọba apapọ lori awọn ẹtọ wọn ti wọn n beere fun.Iyanṣẹlodi naa bẹrẹ lowurọ Ọjọ Aje lẹyin ti awọn aṣoju ẹgbẹ naa sọ agadagodo si ẹnu ọna abawọle fasiti ilu Ibadan.
Wọn ni, ijọba apapọ n lọra lati mu adehun ṣẹ pẹlu awọn ẹgbẹ naa.
Gẹgẹ bi awọn aṣoju ẹgbẹ naa ṣe sọ, lara ohun ti wọn n bere fun ni ajẹmọnu awọn oṣiṣẹ naa.
Ọrọ to niiṣe pẹlu awọn ile ẹkọ ti ẹgbẹ awọn oṣiṣẹ da silẹ, idunadura ati adehun laarin ẹgbẹ naa ati ijọba apapọ ni'bẹrẹ ọdun yii, ati bẹẹbẹẹ lọ ni ẹdun ọkan wọn.
Alaga awọn oṣiṣẹ agba labe aburada SSANU ni ẹka fasiti Ibadan, amofin Wale Akinrẹmi, ṣe alaye fun awọn oniroyin pe eyii ti o jẹ olori ipenija ni ajẹmọnu awọn oṣiṣe ti kii ṣe olukọ.
O ni iṣẹ iwadii fi idi ẹ mulẹ wi pe irẹjẹ wa ninu iye owo ti wọn fun awọn oṣiṣẹ naa tẹlẹri.
Bo tilẹ jẹ wi pe awọn akẹkọọ ninu ọgba naa ko fẹ ki a gba ohun wọn silẹ, alaye wọn ni wi pe ki ijọba apapọ gbe igbesẹ ti o tọ lati rii daju wi pe rogbodiyan naa di ohun igbagbe.Ni bayii, ọjọ marun un pere ni awọn ẹgbẹ fẹ fi kilọ fun ijọba lati mu adehun ṣẹ.
Alaye wọn ni wi pe iyanṣẹlodi alainigbendeke yoo gbinaya bi ijọba ba kọ lati ṣe ohun ti o tọ lẹhin ọjọ marun un.
Ekiti: Fayemi gbẹ́sẹ̀ lé èdè òyìnbó sísọ fáwọn òṣìṣẹ́ nípinlẹ̀ Ekiti
Oríṣun àwòrán, Ekiti state government
Oyinbo sisọ ti di eewọọ fun awọn oṣiṣẹ ijọba ni ipinlẹ Ekiti bayii.
Ẹ maa jẹ ko ya yin lẹnu o, nitori pe gomina ipinlẹ Ekiti, Kayọde Fayẹmilo paṣẹ bẹẹ ni ọjọ aje. Gomina Fayẹmi ni ede oyinbo sibo ko gbọdọ jẹyọ nibi eto gbogbo to ba jẹ ti aṣa tabi ibilẹ.
Fayẹmi ni ohun kan to jẹ ijọba oun logun ni gbigbe aṣa ati iṣe ga ni ipinlẹ naa pẹlu gbigbe ede Yoruba ati ede Ekiti larugẹ. Gomina Fayẹmi to fi iṣẹ yii ran olori awsn oṣiṣẹ ijọba ni ipinlẹ Ekiti, Deji Ajayi fi kun un pe oṣu kejila ọdun yii ni ajọdun aṣa ipinlẹ naa yoo waye.
Lati oni lọ, ijọba ti gbẹsẹ le sisọ ede oyibo lawọn eto to ba jẹ ti aṣa. Gbogbo awọn to ba n kopa ni eto ibilẹ gbọdọ maa sọ ede Ekiti tabi ede Yoruba.
World Sàngó Festival 2019: Ìyàtọ̀ tó wà láàrín arugbá Ọ̀ṣun Òṣogbo arugbá Ṣàǹgó lóde Ọ̀yọ̀
Oríṣun àwòrán, Alaafin Oba Adeyemi III
Ko si tabi ṣugbọn pe bi  a ba n sọrọ nipa arugba ninu iṣẹṣe ati Aṣa Yoruba, ajọdun Ọṣun Oṣogbo ni ọkan ọpọ maa n lọ. Ṣugbọn, n jẹ ẹ mọ pe, ajọdun Sango ni ilu Ọyọ pẹlu maa n gbe arugba sita.
Ẹyin ni rara? Otitọ ọrọ ti ko ni abawọn irọ ninu.
Òyìnbó sísọ di èèwọ̀ ní ìpínlẹ̀ Ekiti
Falana àtàwọn míì péjú síbi àpérò #RevolutionNow l'Eko
'El-Zakzaky lè má láńfààní láti lọ gba ìtọ́jú mọ́ lókè òkun'
Fayemi fojú Alufa to fipa bá ọmọde lòpọ̀ síta l'Ekiti
"Ariwo ""Allahu Akbar"" kò tọ́ sawọn Agbébọn àti Boko Haram - Buhari"
Ike Ekweremadu, igbákejì ààrẹ ilé aṣòfin àgbà tẹ́lẹ́ rí èèmọ̀ he nilùú Germany!
Lasiko ti wọn ba n ṣe ajọdun Ṣango, paapaa lode Ọyọ, awọn oloriṣa Sango n maa yan Arugba pẹlu lati gbe igba iṣẹmbaye ti ipese fun ajọdun naa yoo wa  wa si aafin.
Oríṣun àwòrán, Alaafin Oba Adeyemi III
Iyatọ to wa laarin arugba Ọṣun ati arugba Ṣango ni pe nigba ti arugba Ọṣun jẹ obinrin, ọmọ ọkunrin ni arugba Ṣango jẹ.
Awọn ọmọdekunrin ni wọn maa n lo fun igba Sango wọn si maa n ju ẹyọkan lọ pẹlu.
Oríṣun àwòrán, Alaafin Oba Adeyemi III
Awọn arugba Sango yii ni yoo gbe igba lati Ṣango Koso ls si ọdọ Iya Naso ni aafin Alaafin.
Lasiko ajọdun ti ọdun yii to n lọ lọwọ ni ilu Ọyọ bayii, Ọtunẹfa ati Iya Naso lo gba awọn arugba mejeeji lalejo laafin Iku baba yeye.
Oríṣun àwòrán, Alaafin Oba Adeyemi III
Osun: Ìjọba kédeìsinmi fáwọn òṣìṣẹ́ láti ṣe àjọ̀dún àyájọ́ ọdún Ìṣẹ̀ṣe
Oríṣun àwòrán, Alaafin Oba Adeyemi III
Gbogbo wa la mọ pe gbogbo ọdun Kiristẹni ati musulumi lorilẹede yii ni ijọba apapọ maa n kede isinmi lẹnu iṣẹ fun.
Ọpọ ọmọ orilẹede yii, paapaa julọ awọn ti wọn  fi si idi iṣẹse ẹya kọọkan ni wọn ti n fi ẹhonu han lori ohun ti o n faa gan an ti ijọba kii fi kede isinmi lẹnu iṣẹ fun awọn oṣiṣẹ lasiko awọn ọdun iṣẹse.
Nibayii, ijọba ipinlẹ Ọṣun ti gbe igbesẹ akọ lori rẹ.
Ijsba ipinlẹ Ọṣun ti kede ọjọ iṣẹgun tii ṣe ogunjọ oṣu kẹjọ ọdun 2019 gẹgẹ bi ọjọ isinmi lẹnu iṣẹ.
Oríṣun àwòrán, Alaafin Oba Adeyemi III
Kii ṣe ori iṣejọba gomina Gboyega Oyetọla ni igbesẹ yii ti bẹrẹ bikoṣe lati ori Rauf Arẹgbẹṣọla to ṣiwaju rẹ.
Ninu atẹjade kan ti ileeṣẹ ọrs abẹle fi sita, ijọba ipinlẹ Ọṣun rọ awọn ẹlẹsin iṣẹṣe lati ṣe ọdun wọn naa ni pẹlẹ-putu ki wọn si ṣe iwure fun ijọba ki ohun gbogbo lee lọ nirọwọ rọsẹ, ki eku lee ke bi eku, ki ẹyẹ si maa ke bi ẹyẹ.
Ondo: Gómìnà Akeredolu fa ìjọba lé igbákejì rẹ̀ lọ́wọ́
Oríṣun àwòrán, @RotimiAkeredolu
Ijọba ipinlẹ Ondo ti ni gomina tuntun.
Orukọ gomina tuntun naa ni Agboọla Ajayi. Ṣaaju bibọ si ipo gomina, Ajayi ni igbakeji gomina ipinlẹ naa, Rotimi Akeredolu.
Amọṣa o, ọjọ mọkanla pere ni Agboọla yoo lo ni ipo gomina ipinlẹ naa ti yoo tun fi pada si ipo rẹ gẹgẹ bi igbakeji gomina.
Ẹ jẹ ki n laa ko yee yin daadaa.
Gomina ipinlẹ Ondo gangan ni Rotimi Akeredolu, ṣugbọn Akeredolu n ls fun isinmi ọsẹ meji to ja si ọjọ mẹrinla ni o fi fa iṣejọba le igbakeji rẹ, Agboọla Ajayi lọwọ  gẹgẹ bii adele gomina lẹyin to ti kọwe si ile aṣofin ipinlẹ naa gẹgẹ bi iwe ofin orilẹede Naijiria, ti ọdun 1999 ṣe laa kalẹ,pe igbakeji oun ni yoo maa ṣe iṣẹ gomina titi ti oun yoo fi pada de.
Ọjọ kẹrin oṣu kẹsan ni Gomina Rotimi Akeredolu yoo pada si ẹnu iṣẹ.
Makinde fi orúkọ ọmọ ọdún 27 kan ránsẹ́ sílé aṣòfin ní ìpìnlẹ̀ Ọ̀yọ́
Oríṣun àwòrán, @TopsyAshaolu
Seun Fakorede ọdọmọde to fẹ maa gbe igbesẹ agba
Ọdọmọde naa ni ọgbọn ti yoo wulo fun awujọ wa.
Gomina ipinle Ọyọ, Seyi Makinde ti fi orúkọ Seun Fakorede, ẹni ti o je ọmọ ọdun metadinlọgbọn ránsẹ́ si ile igbimọ asofin ipinlẹ naa, fún ipò kọmíṣónà.
"Seun Fakorede ti awọn eniyan mọ si ""Phakoo"" kẹkọọ jade ni ile iwe Fasiti olododo ti Ọbafẹmi Awolọwọ, Ile Ifẹ, ni Ọdun 2017."
Orukọ rẹ wa lara awọn orukọ mẹta ti gomina Seyin Makinde fi sọwọ si ile igbimọ asofin ipinlẹ  Ọyọ.
Adebo Ogundoyin, ẹni ti o jẹ agbẹnusọ ile igbimọ asofin ipinlẹ Ọyọ lo fi ọrọ naa lede loju opo Facebook rẹ ni ọjọ Aje.
Koda, ọpọ ọdọ lo ti n ki ọdọmọde yii ku oriire ti wọn si n gba imọran awokọṣe rere loju opo BBC Yoruba.
Inu ọpọ ọdọ lo ti n dun si igbesẹ ipinlẹ Oyo yii
"O ni pe: Laise ani-ani, ile igbimọ asofin ipinle Ọyọ ti gba orukọ Fakorede gẹgẹ bi okan laran awọn ti yoo di kọmiṣọna ni Ọ́yọ."""
Iru eeyan wo ni Fakorede Oluwaseun Tenidayo?
Seun Fakorede jẹ ọmọ ọdun mẹtadinlọgbọn ti a bi ni Idere ni ipinlẹ Oyo ni guusu iwọ oorun Naijiria.
O lọ sile iwe tijọba Government College ni Apata ni ilu  Ibadan.
O tun kawe ni Oladipo Alayande School of Science ko to lọ ka nipa imọ nipa ẹrọ ni Fasiti OAU Ile Ifẹ.
Seun kawe nipa ṣiṣẹ alamojuto ni Swiss E- Learning Institute ni Switzerland lọdun 2013.
O jẹ aarẹ ajọ CDS ni ilu Eko lọdun 2018 nigba ti o n sinru ilu (NYSC)
Oun naa lo jẹ aṣoju ikọ Platoon ẹ lọdun 2017 nigba ti o wa ni ipagọ fun sinsin ilẹ baba rẹ.
Ṣeun Fakorode ṣiṣẹ pẹlu ajọ to n risi idagbasoke ati ohun ini ni ipinlẹ Eko, iyẹn Lagos State Development and Property Corporation.
Oun ni oludasilẹ ile iṣẹ Home Advantage Africa to jẹ ile iṣẹ to n rani lọwọ ti kii ṣe tijọba.
Bakan naa lo jẹ ọkan lara awọn oludasilẹ Boddiemax Online Premium Fashion Brand.
Omo Fakorede naa tun ni alaga igbimọ to n mojuto ile iṣẹ Reasone Innovations.
Ogundamisi: Ọbasanjọ ni ko jẹ k'awọn ọdọ de'po
Mo ti ṣetán láti daríi ìfẹ̀họ́nú hàn lòdì sí ìpànìyàn - Olúwó
Oríṣun àwòrán, INSTAGRAM/OLUWO OF IWOLAND
Moti setan lati dari ifehonu han leyin ti ijọba ti kọ lati ri si eto aabo
Oluwo ti ilu Iwo, Ọba Abdulrasheed Adewale Akanbi, ti sọ pe oun ti ṣetan lati daríi ifẹhonuhan lodi si ipaniyan ati iwa ibajẹ ti o gbode kan lorilẹ-ede Naijiria.
O bu ẹnu ẹtẹ lu iha ti ijọba kọ si ọrọ ipaniyan ṣowo, ati pe pipaniyan fun ṣiṣe oogun owo buru ju iwa ijinigbe lọ.
Oluwo tẹsiwaju pe, eto aabo ara ilu jẹ ojuṣe akọkọ fun ijọba. O si bu ẹnu ẹtẹ lu iwa ifẹmiṣofo ti o ti di tọrọ-kọbọ lorilẹ-ede yi.
Ninu atẹjade kan lati ọwọ akọwe rẹ̀, Alli Ibraheem, Oluwo pe fun ofin ti o lagbara lodi si awọn agbenipa ati awọn oniwa ibajẹ, lona lati daabo bo emi awọn ara ilu.
"O ni pe ""O ba ni lọkan jẹ pe ijọba apapọ ko kọbi ara si iwa ipanijaye ti o gbode kan lorilẹ-ede wa."
O tẹ siwaju pe: Lọwọlọwọ yi, awọn eniyan buburu wa ni ibi ti wọn ti n pa eniyan nitori owo ati ipo. Awọn kan ro pe fifi emi eniyan se irubọ je aṣa. Sugbọn ko ri bẹẹ.
Oríṣun àwòrán, @BolanleCole
Oseni laanu wipe ijọba apapọ ko kọbi ara si iwa ipanijaye ti o gbode kan lorilẹ-ede wa
Kosi aṣa ti o faramọ fifi emi eniyan se irubọ.
Oba Akanbi wa ke pe ẹgbe Afẹnifẹre, ẹgbe ọmọ Oodua, Agbẹkọya, ati awọn ẹgbẹ ọmọ Yoruba miran lati fọwọsowọpọ pelu oun lati dide gbogun ti iwa fifi ẹmi eniyan se irubọ lorilẹ-ede Naijiria.
Àwọn èèyàn sọ́rọ́: Ẹ máà ṣi Fayemi túmọ̀ lórí àṣẹ tó pa nípa sísọ Yorùbá
Oríṣun àwòrán, facebook/Government of Ekiti State, Nigeria.
Ni ọjọ Aje ni ijọba ipinlẹ Ekiti kede pe ko saye oyinbo sisọ mọ lawọn ibi eto to ba jẹ abinibi abi ti ibilẹ.
Ninu ọrọ ti gomina Fayẹmi fi ṣọwọ si ibi ipade kan lori aṣa ati iṣe lo ti kede eyi.
Lati igba ti o si ti jade si eti araye ni ọpọ awọn eeyan nilẹ yii ati loke okun ti n fi ero wọn han lori igbesẹ naa.
Alagba S.B. Bakare to jẹ Ọga agba ileewe girama kan ṣalaye pe igbesẹ ti Gomina Fayẹmi fẹ gbe naa yoo nira diẹ.
O ni pẹlu bi aye ti ṣe di ti ayelujara ti ọwọ si ti n kan owo nipa okowo, igbeyawo atawọn nnkan miran, sisọ ede Ekiti tabi ede Yoruba nikan yoo fa ọpọlọpọ gbọnmisi omi o to ati ede-ai-yede.
"Kini yẹn ko lee fi bẹẹ rọgbọ.
Bi wọn ṣe fẹ ki a maa sọ Yoruba apapandodo yii, awọn ti wọn wa ni ilu yẹn ti wọn jẹ ede mii, bawo ni wọn ṣe fẹ maa ba ara wọn sọrọ.
O lee ṣeese ni ilu wọn lọhun ṣugbọn to ba gbe e lọ si ile aṣofin yoo nira diẹ.
Yoo fa wahala silẹ bi wọn ba kan an ni dandan.
Bawo ni wọn yoo ṣe ṣee to ba jẹ wi pe eto ti wọn n ṣe jẹ eto ẹya Ibo tabi Hausa tabi ede miran ni ṣugbọn ti wọn wa ni ipinlẹ naa.
Ṣe iyẹn ko ni fa wahala ṣa. O gbọdọ ṣọra ṣe lori rẹ."
"Bakan naa, ninu ero tirẹ, ọmọwe Ademọla Adetokun to jẹ aarẹ tẹlẹ fun ẹgbẹ Akọmọlede Yoruba ni aṣiwi o to aṣisọ lori ọrọ naa ati pe kii ṣe gbogbo eeyan ni ọrọ naa kan 'bikoṣe awọn ọmọ Ekiti nikan lati lee ran ede ati aṣa Yoruba lọwọ."""
O ni ko si ohun to buru nibẹ ti awọn eeyan ba gbọ gomina ni agbọye nitori idagabsoke ede ati aṣa ṣe pataki lasiko yii.
Taraba Killings: IGP ti jọ̀wọ́ Hamisu Wadume fún aádájọ́ àgbà Nàìjíríà
Oríṣun àwòrán, others
Taraba Killings: IGP ti jọ̀wọ́ Hamisu Wadume fún aádájọ́ àgbà Nàìjíríà
Ọ́fíísì agbẹ́jọ́rò àgbà Nàìjíríà tí gbá ẹjọ́ Bala Hamisu ti gbogbo ènìyàn mọ̀ sí Wadume tó jẹ́ gbájúgbajà ajínigbé ní ìpínlẹ̀ Taraba kúrò lọ́wọ́ ọ̀gá àgbà ọlọ́pàá Muhammed Adamu.
Ọ̀gá àgbà ọlọ́pàá ní ọjọ kẹta oṣù keji ọdun yìí fi ẹ̀sùn onípele mẹ́rìnlá, ìgbésùnmsmí, ìpànìyàn, ìjínígbé àti kíkó ǹkan olóró síkàwọ́ lọ́nà àìtọ́ pẹ̀lú àwọn ogun míràn.
Mẹ́fà nínú àwọn ogún náà ló péjú si ilé ẹjọ tó fi mọ́ Wadume lónìí ọjọ́rú.
Àwọn ọmọogun mẹ́wàá tọ́rọ̀  náà kàn kò yọjú silé ẹjọ́ lónìí, bákan náà ni wọ́n ò yọjú silé ẹjọ́ nínú oṣu kẹta ọdun.
Sááju ni agbẹ́jọ́rò fún àjọ ọlọ́pàá Simon Lough ti sọ fún àdájọ Binta Nyako pé ilé iṣẹ ọmọogun kò jọ̀wọ́ àwọn ọmọogun tọ́rọ̀ kàn láti waá sílé ẹjọ́.
Èyí ló mú kí adájọ rànṣẹ́ pe ki ọgá àgbà ilé iṣẹ́ ọmọogun jọ̀wọ́ àwọn ọmọogun mẹ́wàá tí ọ̀rọ̀ náà kàn fún àjọ ọlọ́pàá.
Ẹ̀wẹ̀, agbẹ́jọ́rò láti ọ́fíìsì agbẹjọ́rò àgbà ìjọba Labaran Magaji tó péjú sílé ẹjọ́ fún ìgbà àkọ́kọ́ lónìí sàlàyé pé, àwọn ti gba, ẹjọ́ náà lọ́wọ́ àjọ ọl\apàá lánàá ọjọ́ ìṣẹ̀gún.
O ti bèrè pé kí wọ́n sún ìgbẹ́jọ́ náà síwájú láti ríidájú pé gbogbo àwọn tí ẹjọ́ náà kan wá sílé ẹjọ́.
Adájọ́ ti sún ìgbẹ́jọ́ náà sí ọjọ́ kẹjọ oṣù kẹfà, ní dédé aago mẹ́wàá ààbọ̀ òwúrò.
Ọlọ́pàá tí tẹ Hamisu Wadume
Oríṣun àwòrán, Nigeria Police Force
Ṣe wọn ni ẹgbẹrun Saamu ko lee sa mọ Ọlọrun lọwọ. Eyi lo difa fun afurasi Ogbontarigi ajinigbe ni, Alhaji Hamisu bala Wadume.
Ọwọ palaba rẹ segi ni bi ọsẹ meji sẹyin nigba ti awọn ọlọpaa ikọ ọtẹlẹmuyẹ marindọti ti a mọ si IG intelligence Squad mu ni ipinlẹ Taraba.
Amọṣa ki a to wi ki a to fọ, nibi ti awọn oṣiṣẹ ikọ naa ti n gbee lọ ni awọn ọmọ ogun kan ti ṣina ibọn bolẹ ti wọn si pa ọlọpaa mẹta ati araalu meji.
Afurasi ajinigbe naa nikan ni ko ku ninu ikọlu naa eleyi ti awọn ọmọ ogun ọhun ni awọn ro pe awọn ajinigbe lawọn ọlapaa to gbe Wadume nigba naa.
Oríṣun àwòrán, Nigeria police force
Ọrọ yii di iṣu ata yan an yan an laarin ileeṣẹ ọlọpaa ati ileeṣẹ ọmọ ogun lorilẹ-ede Naijiria.
Koda, ni ilẹ yii ati loke okun ni awọn eeyan ti bu ẹnu ẹtẹ lu  iṣẹlẹ naa.
Amọṣa, ni ọjọ Aje ni ọwọ awọn ọtẹlẹmuyẹ ọlọpaa tun ra Wadume mu pada ni ilu Kano ti o lọ farasinko si.
Atẹjade kan ti olu ileeṣẹ ọlọpaa fi sita ṣalaye pe ọga agba ọlọpaa lorilẹ-ede Naijria, Mohammed Adamu ti kan sara sawọn ọlọpaa to mu u.
O ki wọn fun ẹmi ifọkansin wọn ati ifaraẹnijin ti wọn fi ri afurasi naa mu.
Ọga agba ọlọpaa Adamu ko ṣai ki ẹbi awọn ọlọpaa ati araalu to doloogbe nitori ati mu afurasi naa.
Bakan naa lo tun ṣalaye pe afurasi ọhun yoo ran awọn ọtẹlẹmuyẹ lọwọ lati wa idahun si ọpọlọpọ ibeere ti o n yọju lori iṣẹlẹ naa ati ọgba ajara iṣẹ laabi wọn.
Iṣẹlẹ to fa bi afurasi ajinigbe naa ti ṣe sa lọ mọ ofin lọwọ ni ọjọ kẹfa, oṣu kẹjọ, ọdun 2019 fa ọpọ arinyanjiyan laarin ile iṣẹ ọlọọpa ati awọn ọmọ ogun.
Eyi to si mu ipaya ba awọn eeyan kaakiri orilẹ-ede yii ki aarẹ Muhammadu Buhari to paṣẹ wi pe ki wọn tọpinpin iṣẹlẹ naa.
Igbimọ to n ṣewadi iṣẹlẹ ọhun ṣi wa lẹnu iṣẹ ni lọwọlọwọ.
Kidnappings in Nigeria: Ajínigbé ń bèèrè fún epo, iṣu àti ọ̀tí Schinap àti owó ìtanràn
Orọ àwọn ajinigbe n gbẹnutan ni ariwo awọn eniyan bayii.
Awọn ajinigbe ni apa iwọ oorun guusu Naijiria tun gba ọna ara ọtọ jade si ẹbi ẹni ti wọn ji gbe.
Gẹgẹ bi iroyin ti ile iṣẹ iroyin NAN ti Naijiria fi sita lẹyin iwadii pe ibeere wọn tun yatọ lọtẹ yii.
Agba kan ninu mọlẹbi awọn mẹta ti wọn ji gbe naa ṣalaye pe kete ti awọn ajinigbe ti kan si mọlẹbi ni wọn ti kede nkan ti wọn fẹ gba.
O ni lẹyin-o-rẹyin ni awọn mọlẹbi san agba epo pupa jálá lita ọgbọn, ọti Schinapu, ọpọlọpọ iṣu ati miliọnu mẹta ati aabọ naira.
Awọn mọlẹbi ṣalaye pe ọdun Ileya to kọja ku ọla ni awọn ajinigbe yii gbe awọn mẹtẹẹta.
Agbegbe Odẹ-Omi to paala laarin ẹya kan si ikeji laarin ipinlẹ Eko ati Ogun ni wọn ti ji wọn gbe.
Kọmiṣọna ọlọpaa, Bashir Makam ni wọn ko san owo itanran kanakna lati fi doola ẹmi awọn eniyan yii ṣugbọn mọlẹbi wọn ni pe irọ ni.
"Mọlẹbi yii to ni ki wọn fi orukọ bo oun laṣiri ni"" A gbe owo itanran miliọnu mẹta ati aabọ pẹlu paali Schinaapu kan ati jálá lita epo pupa ọgbọn ati iṣu nlanla mẹwaa ati ororo jala lita marun un lọ fun wọn."
O ni lẹyin eyi ni wọn to ri awọn mẹtẹẹta gba pada lẹyin ọdun Ileya.
Abimbọla oyeyẹmi to jẹ agbẹnusọ ajọ ọlọpaa ni ipinlẹ Ogun ni awọn agbofinro ko mọ nipa owo itanran ati ohun jijẹ yii rara.
"O ni: ""awa ọlọpaa ẹkun yii lo ṣokunfa bi wọn ṣe ri awọn eniyan yii gbe ṣugbọn a ko mọ nipa owo itanran rara""."
Opọ ẹmi lo ti sọnu ti awọn eniyan si ti san owo to pọ gẹgẹ bi owo itanran kaakiri Naijiria lasiko yii.
Mínísítà 43 ni Ààrẹ Muhammadu Buhari ṣe ìbúra fún to yàn sípò
Oríṣun àwòrán, @others
Buhari bẹrẹ ibura minista tuntun
Bakan naa lo tun fun awọn minisita kọọkan ni iṣẹ ati ileeṣẹ ijọba ti wọn yoo mojuto ninu iṣejọba rẹ.
Aarẹ Buhari ni oun ti tubọ fẹ awọn ileeṣẹ ijọba loju sii ki idagbasoke lee tete sun araalu bọ.
Awọn minisita naa ree pẹlu orukọ ileeṣẹ ti wọn yoo dimu:
Aare Muhammadu Buhari ti pari ikede to fi yan awọn minista tuntun sipo loni.
Aarẹ yan awon minisita tuntun si ipo loni ni ilu AbujaWo ohun tó yẹ kí o mọ̀ nípa àwọn obìnrin méje ti Buhari fẹ́ yàn sípò minista.
Ayẹyẹ yiyan awọn minisita naa ti n waye lẹyin ti aarẹ ti fi orukọ awọn mẹtalelogoji ransẹ si ile igbimọ asofin nilu Abuja fun ifọwọsi.
Boss Mustapha, ẹni ti o jẹ akówe gbogbogbo ijọba orilẹ-ede yii lo fi ọrọ naa lede ni ọjọ Isẹgun pe, ayẹyẹ yiyan awọn minisita tuntun naa yio waye ni deede aago mọkanla owuro loni.
Lara awọn minisita ti o ti wa ni ipo tẹlẹ ti o si tun n pada bọ nibẹ ni Babatunde Fashola, lati ilu Eko, eni ti o jẹ minisita fun ohun amuṣagbara, ọrọ iṣẹ ati ile gbigbe.
Oríṣun àwòrán, @TheMbuhari
Aarẹ Buhari ti n bura fobinrin meje to yan ni minista
Bakan naa ni Adamu Adamu, lati ipinlẹ Bauchi, ẹni ti o jẹ minisita fun eto ẹkọ nigba naa. Ati Lai Mohammed, minista fun eto ifitonileti, aṣa ati iroyin.
Lara awọn ti aarẹ Buhari ko ni ba ṣisẹ ni saa yi ni Audu Ogbeh, minista fun eto ọgbin.
Oríṣun àwòrán, @BuhariMediaORG
Buhari ko ni ba Audu Ogbeh, Isaac Adewwole, Solomon Dalung atawọn mii ṣiṣẹ ni sa yii
Solomon Dalung, minista fun eto ọdọ ati ere idaraya.
Beeni aare tun ja Abdur-Raheem Adebayo Shittu silẹ, eni ti o je minisita fun eto ibaraẹnisọrọ.
Kete lẹyin ibura yii ni awọn eniyan gba pe aarẹ Buhari yoo kede ipo ti onikaluku a dimu gẹgẹ bi minista.
Lẹyin ayẹwo awọn minista ki lo ti ṣẹlẹ?
Ni kete ti awọn ọmọ ile igbimọ aṣofin ti pari ayẹwo awọn ti aarẹ Buhari forukọ wọn ranṣẹ sile ni wọn ti n poungbẹ.
Ijọba Naijiria ṣeto idanilẹkọ nibi apero ọlọjọ meji to waye ni ọjọ Aje ati ọjọ Iṣẹgun ọsẹ yii, ṣaaju ibura toni n ilu Abuja.
Nibi ti aarẹ ti fi ye wọn pe iṣẹ wọn ṣẹṣẹ n bẹrẹ ni ati pe kekere kọ ni ike Ramọ iṣoro ti ijọba n wa ojutu si ni Naijria lasiko yii.
A o maa muu wa fun igbadun yin, bi ohun gbogbo ba ṣe n ṣelẹ loju opo yii...
Sanwó Olú búra fún ìgbìmọ̀ ìṣàkóso rè níbi tó ti yan àwọn 38 sípò
Oríṣun àwòrán, @Sanwo Olu
Sanwo Olu bura fun awọn kọmiṣọna tuntun ni Eko
Ni ọjọ Isegun ọ̀sẹ̀ yìí ni gomina ìpínlè Èkó, Ogbeni Babajide Sanwó Olú ṣe ifilole igbimo ìjọba rẹ ni ọ́fíìsì ijoba ni Alausa Ikeja.
Eniyan mẹta lára awọn méjìdínlogoji tí wón fi orúkọ wọn ṣọwọ sílè Ìgbìmò asofin ipinlẹ Eko ni wọn yọ kuro Sanwo Olu yan kọ̀míṣọ́nnà 25 àtàwọn olùbádámọ́ràn.
Àwọn metẹẹta ni: Àjàyí Bembe tó wá láti aarin gbùngbùn Ikoyi; Olanrewaju Sanusi láti ẹkùn Ikorodu àti Obafemi George láti ijoba ibile Eti Ọsa.Gomina Babajide Sanwó Olú, kò sai yàn àwọn ènìyàn láti ẹ̀yà mìíràn láti Gúúsù ìlà Òòrùn ilé yìí àti Ariwa Orílẹ̀ èdè yìí bakan naa.
Ẹni tí ó wà láti Gúúsù ìlà oòrùn ni Ogbeni Sam Egube.
Nigbà ti Arabinrin Uzamat Yusuf Akinbile wa lati apa ariwa Naijiria.
Oríṣun àwòrán, @Sanwo Olu
Opo ero lo n rọ awọn kọmiṣona tuntun lati ṣiṣẹ daadaa
Iroyin ni awọn ọmọ ile igbimọ aṣofin ipinlẹ Eko lo yọ orukọ wọn lẹyin ti Sanwo Olu fi ranṣẹ sile.
Opolopo awuyewuye ni ikede yii ti n bi lori ayelujara ti awọn eniyan si n fi ero ọtọọtọ han nipa iṣẹlẹ yii..Awọn kan sọ pe Sanwo Olu paapaa ko tii pade awọn miran ninu awọn kọmiṣọna naa ri rara
Awọn miran gba pe agbara to ju agabra lọ lo yan awọn eeyan yii fun gomina.
Sanwo Olu funra rẹ gba pé awọn ti oun yan yoo ran oun lọwọ lati wakọ ipinlẹ Eko de ebute ogo laipẹ
Awọn eniyan ipinle Eko kan parọwa fun gomina Sanwo Olu pe eebu alọ ni tahun ni ọrọ naa yoo di ti awọn to yan sipo ko ba ṣiṣẹ bi o ti yẹ.
Bẹẹ lawọn miran gboriyin fun gomina Sanwo Olu pe awọn agbagbọ ninu rẹ pe yoo yan awọn to yẹ sipo.
Ọpọ ni ki wọn ṣetan lati tun igbe aye awọn eniayn ipìnlẹ Eko ṣe lasiko yii ti a ti yan wọn sipo lai huwa awa ko mọ pe ebi n pa ọmọ ẹnikọọkan.
Tinubu: Nítorí Tinubu, àwọn ọmọge Sanwo-Olu da ìlù bolẹ̀
Nigeria new ministers: Obìnrin méje pèrè nínú ìgbìmọ̀ ìṣèjọba kì í ṣe ìlérí tí Buhari ṣe ní 2015
Oríṣun àwòrán, @BashirAhmaad
Aarẹ Buhari ti bura fun awọn minisita ti yoo baa ṣiṣẹ bayii lẹyin ti o ti bura fun wọn ti o si ti fun ọkọọkan wọn ni ojuṣe rẹ.
 Ẹ ba awọn akọwe agba ati olri ileeṣẹ gbogbo to wa labẹ yin ṣiṣẹ pọ daadaa. Ẹ ma si ṣe ṣalai wa ni irẹpọ pẹlawọn minisita ẹgbẹ yin. Ni ọrọ iyanju ti aarẹ fun awọn ọmọ igbimọ rẹ tuntun naa.
Ọpọ lo ri igbesẹ yiyan minisita ni oṣu kẹta saa keji iṣejọba rẹ gẹgẹ bii eyi to tun dan mọran ju bi nnkan ṣe ri ni saa akọkọ lọdun 2015.
Ko da bi ẹni pe iyatọ wa ninu iye ipo ti wọn fun awọn obinrin ninu iṣejọba yii. Meje ni awọn obinrin to wa ninu igbimọ naa, ninu eyi ti mẹrin ti wa ni ipo minisita kekere:
Sharon Ikeazor (Anambra) - Minisita abẹle fun ọrọ ayika
Mariam Katagum (Bauchi) - Minisita Abẹle fun ọrọ ileeṣẹ, idokoowo, ati karakata
Gbemisọla Saraki (Kwara) - Minisita abẹle fun igbokegbodo ọkọ
Sadiya farouq (Zamfara)  - minisita fun iṣẹlẹ pajawiri.
Pauline Tallen (Plateau)   - Minisita fun ọrọ awọn obinrin
Ramatu Tijani (Kogi)- Minisita abẹle fun olu ilu orilẹede Naijiria, FCT
Zainab Shamsuna Ahmed (Kaduna) - Minisita feto iṣuna ati aato ilẹẹwa
Ọpọ ọmọ Naijiria lo ti fi aidunu wọn han lati igba ti oruks awọn minisita tuntun naa ti bs sita nibi ti wọn ti ni aarẹ Buhari kuna ati mu adehun to ṣe fun awọn ọmọ orilẹede Naijiria ṣẹ.
Ileri ti aarẹ ṣe lọdun 2015 ni pe oun yoo mu iwe ofin aparo kan o ga jukan laarin akọ ati abo (National Gender Policy)
Bakan naa ni ọmọ ṣe ori ni ile aṣofin apapọ nibi ti o jẹ pe awọn obinrin meje pere ni ile aṣofin agba ati mọkanla ni ile aṣoju-ṣofin.
Lati iṣejọba aarẹ oluṣẹgun Obasanjọ ni ọrọ yii ti n wọ bọ lati labẹ eto iṣejọba alagbada tuntun yii.
Ti ọtẹ yii fẹ dabi eyi to fẹẹ buru julọ fun iyansipo awọn obinrin ninu eto iṣejọba lorilẹede Naijiria.
Àwọn ọmọ Yorùbá wo ni mínísítà ní ìjọba Buhari?
Oríṣun àwòrán, @SenAlasoadura
Aarẹ Buhari ti bura fawọn minisita tuntun loni
Bakan naa lo ya ileeṣẹ ijọba ti wọn yoo mojuto fun wọn.
Meje ninu awọn minisita naa ni wọn yan lati ẹkun iwọ oorun gusi orilẹede Naijiria.
Awọn meje naa niyi ati itan diẹ nipa wọn.
Oríṣun àwòrán, @tundefashola
Ni ọjọ kejidinlọgbọn ọdun 1963 ni wọn bi Babatunde Raji Faṣọla ni ilu Eko.
O lọ si ileewe Birch Freeman High school Lagos ati Igbobi College ni ilu Eko ki o to gba fasiti Benin lọ lati kawe gba imọ ijinlẹ ninu ẹkọ ofin lọdun 1987.
Faṣọla ni olori awọn oṣiṣẹ labẹ gomina ipinlẹ Eko lasiko to fi n ṣe akoso ijọba ipinlẹ Eko.
Ni ọdun 2007 ni Faṣọla di gomina ipinlẹ Eko.
Ipa ribiribi to ko pẹu iṣejọba rẹ ninu idagbasoke ipinlẹ Eko kun ara ohun ti o mu ki ọpọ awọn ọmọ orilẹede Naijiria fẹran rẹ.
Faṣọla kun ara awọn minisita ti ọpọ n wo gẹgẹ bii alagbara ni saa iṣejọba akọkọ aarẹ Buhari, paapaa julọ bi o ṣe jẹ pe ohun nikan lo di ileeṣẹ ijọba mẹta to ṣe koko mu.
Ni saa keji yii ẹru ọrun rẹ ti rọrun diẹ nitori aarẹ Buhari ti yọ ileeṣẹ kan kuro ni ileeṣẹ mẹta ti o n mojuto tẹlẹ.
Oríṣun àwòrán, @raufaregbesola
Ọgbẹni Rauf Arẹgbẹṣọla, ní a bí ni ọjọ́ karundinlọgbọn, oṣù Kàrún un, ọdún 1957.Ó ṣe kọmiṣọna fún eto ìṣẹ ode ni Ipinle Èkó ni ọdun 2009.
Bákan náà, ní ọdún 2010, ó gbé àpótí ibo láti dije fún gomina ipinle Osun labẹ ẹgbẹ oṣelu APC.
Bo tilè jẹ pe, ilé ẹjọ́ lo gbaa fún un, Rauf Aregbesola, di gomina ipinle Osun ni odun 2010 sì ọdún 2018.Ní báyìí,  Aare Muhammadu Buhari só ọ di minisita fún ọrọ abele lorile-èdè Nàìjíríà.
Oríṣun àwòrán, @SenAlasoadura
Ọtunba Nìyí Adebayọ ni a bí ní ìlú ìyìn Ekiti ni ọjọ́ kẹrin, oṣù kejì, ọdún 1954.Nìyí Adebayo ni Gomina alágbáda àkọ́kọ́ ní ìpínlè Ekiti laarin ọdun 1999 sì ọdún 2003 ni abẹ ẹgbẹ oselu AD.Ní báyìí, Ó jé ọkàn pàtàkì lára àwọn àgbààgbà egbe oselu APC ni orílè-èdè yìí.Ó jé amofin nípa eto epo àti gaasi. Ó feran boolu alafesegba. Ó sì jẹ ọmọ ẹgbẹ́ àwọn asofin ni ile wa Naijiria ati ni òkè òkun.
Abii ni ọjọ kẹrindinlogun, osu keji, odun 1953 ni ipinlẹ Eko. Ó kẹkọọ gboyè nínú ìmọ̀ ìlera, ni ile iwe olododo Fasiti Ọbafẹmi Awolọwọ, Ile Ifẹ, nibi ti o si tún ti kẹkọọ siwaju síi ni nipa iṣẹ abẹ siṣe.O jawe bori nínú idibo ti ọdun 1999, èyí tí ó gbé e wo ilẹ̀ ìgbìmò asofin ipinle, Eko nibi ti o ti jẹ agbẹnusọ fún ile naa.Lẹyin naa o tún jawe olú borí nínú idibo tí ó gbé e wo ilẹ̀ igbimọ asofin àgbà n'ilu Abuja ni odun 2003.O tún tesiwaju sì ilé ìgbìmò asofin àgbà lé èkejì ni odun 2007.
Olamilekan Adegbitẹ
O jé kòmisona fun eto ìṣe àti ohun amayederun tẹ́lẹ̀ rí ní ìpínlè Ogun. Ó kẹkoọ jáde nípa eto oro àyíká ni Fáṣítì ìjọba apapo tí ìlú Èkó. O ṣi tún kẹkọo síwájú sii nípa ìmò ilé kíkó ni Fáṣítì kan náà.
FRSC dá N443,180 padà fún ẹbí ẹni to ní ìjàmbá mọ́tò
Oríṣun àwòrán, @FRSC
Lara iṣẹ ajọ ẹṣọ oju popo ni lati pese aabo fun ẹmi ati dukia awọn ero loju popo
Eyi ko jẹ tuntun pé a n da owo pada fun ẹbi awọn to kagbako ijamba ọkọ -FRSC
Ajọ ẹṣọ oju popo ni Naijiria, Federal Road Safety Corps (FRSC) ni ipinlẹ Kebbi ni awọn ti da owo to din diẹ ni ẹgbẹrun lọna aadọta o le ni irirnwo naira pada fun ẹbi awọn to ni ijamba ọkọ.
Ogbẹni Abayọmi Asaniyan to jẹ oludari ẹka ajọ FRSC ni ipinlẹ Kebbi ni ariwa Naijiria lo sọ eyi di mimọ fawọn oniroyin nipinlẹ Kebbi.
O ni awọn ri owo yii lọna meji nibi ijamba ọkọ to ṣẹlẹ ni Birnin Kebbi ati ni ijoba ibilẹ Argungun nipinlẹ Kebbi.
Abayọmi ni ikọ ẹṣọ FRSC ri ẹgbẹrun lọna irinwo le ni ọgọjọ naira nibi ijamba ọkọ to ṣẹlẹ ni ọjọ kẹtadinlogun, oṣu kẹjọ ọdun yii ni opopona marosẹ Argungun si Birnin Kebbi.
Nigba ti wọn wọn ri ẹgbẹrun mẹtalelogoji o le ni ogun naira ni ijamba ọkọ to waye ni opopona Cemetry atijọ ni Birnin Kebbi.
Oga agba FRSC yii ni gbogbo owo naa ni ajọ FRSC ti da pada fun awọn ẹbi awọn ẹni naa lẹyin iwadii ti o yẹ.
O gba awọn oṣiṣẹ FRSC kaakiri Naijiria nimọran lati maa fi ootọ inu ṣiṣẹ bii ti awọn ọmọ abẹ oun.
Oríṣun àwòrán, @FRSC
Suuru ati ikanju ọgbaagba ni loju popo
Abayọmi ni o tọna ki wọn maa ṣe akọsilẹ ohun gbogbo ti wọn ba ri nibi ijamba ọkọ loju popo ki wọn si maa koo fun awọn ẹbi awọn ti ọrọ kan lasiko.
Bakan naa lo kilọ iwa ibajẹ fawọn oṣiṣẹ pe oju gbogbo n wa lara àwọn oṣiṣẹ ti ọwọ wọn ko ba mọ to.
Joe Igbokwe kò yẹ́ fún ipò ti wọ́n fún nípìnlẹ̀ Eko - Babatunde Gbadamosi
Ni ipari ọgbẹni Abayọmi parọwa fawọn arinrinajo ati awakọ lati ṣe pẹlẹ loju opopona nitori pe ẹmi ko laarọ.
Àwọn ọ̀dọ́ Naijiria ti sọ̀rọ̀ síta lórí ohun ti wọ́n ń retí lọ́dọ̀ minista tuntun
Kìnìún pa okùnrin ọmọ aadọrin ọdún kan lorilẹ-èdè South Africa
Oríṣun àwòrán, @others
Kinihun oloola iju kuro lẹran aa sin ninu ile
"Ọkunrin naa ti gbogbo eeyan mọ si ""The Lion Man"" ni Pretoria fẹ tun ile kiniun rẹ ṣe lo ba gba ekuru jẹ lọwọ ẹbọra."
Ọmọ aadọrin ọdun kan lo ti gbẹmi mi, nigba ti ọkan lara awọn kiniun ti o n ṣe itọju fun se ikọlu sii ni orilẹ-ede South Africa.
Okunrin naa, Leon van Biljon, ni o wọ ile awọn kiniun naa lọ, ni igba ti o fẹ tun odi ti o yi ile naa ka se, ki kiniun naa to kọluu lati ẹyin.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Kiniun kii se ara awọn ẹranko ti o yẹ ki awọn eniyan maa sin ninu ile.
Ikọlu yi lo waye ni Mahala View Lodge, ti o jẹ ile oloogbe naa, ni ila-oorun Pretoria.
Gẹgẹ bi iroyin ti o tẹwa lọwọ, bi Leon ṣe n tu odi naa se, ti o si kọ ẹyin si awọn kiniun ti oun se itoju fun, ni ọkan lara wón bu u jẹ ni ọrun.
Lẹyin ti eyi sẹlẹ ni awọn oṣiṣẹ ti o wa ni ayika yin ibọn lu mẹta ninu awọn kiniun naa, ti wọn si ku.
Awọn oṣiṣẹ yi pinnu lati yin ibọn fun awon ẹranko naa lọna lati gbe oku rẹ kuro ni ibẹ.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Agbẹnusọ fun awọn ọlọpaa, Connie Moganedi, si ti fi idi ọrọ naa mulẹ.
O sọ pe, Leon figbe ta nigba ti ọkan lara awọn kiniun rẹ kọlu u, ki awón eniyan ayika ibẹ to fi ibọn pa meta ninu awọn kiniun naa, sugbon, ẹpa ko gboro mọ.
Iku oloogbe yi ti mu ki awọn o n woye ohun to n sẹlẹ lawujọ wi pe, kiniun kii se ọkan lara ẹranko ti o yẹ ki awọn eniyan maa sin ninu ile.
Fraud Allegations: Àjọ FBI mú ọ̀pọ̀ ọmọ Nàìjíríà lórí ẹ̀sùn jìbìtì l'Amẹrika
Oríṣun àwòrán, Twitter/FBI
Ileeṣẹ ọtẹlẹmuyẹ orilẹede Amẹrika, FBI sọ pe awọn ti mu ọpọ ọmọ Naijiria ninu iwadii awọn to n lọ lọwọ lori ẹsun jibiti.
Olori eto idajọ nilẹ Amẹrika, Nick Hanna lo fidi ọrọ mu lẹ nigba to n ba awọn akọroyin sọrọ l'Ọjọbọ.
Hanna ṣalaye pe awọn ọmọ orilẹede Naijiria ọun gbimọ pọ pẹlu awọn aṣoju ijọba apapọ ati ijọba ipinlẹ lati lu awọn kan ni jibiti.
O ṣalaye pe ọgọrin lawọn afurasi ọun ti ọpọ wọn si jẹ ọmọ orilẹede Naijiria.
Hanna fikun ọrọ rẹ pe agbalagbga ti ọjọ ti lọ lori wọn lawọn eeyan yii lu ni jibiti.
Oriṣiiriṣii ẹsun to le ni ẹẹdẹgbẹta ni ajọ FBI fi kan awọn eeyan yii to to bi ọgọrin.
Ẹsun jijale owo wa lara awọn ẹsun ti wọn fi kan ọpọ Naijiria to wa lara awọn afurasi naa.
Igbákejì ààre Osinbajọ yan Tolani Alli gẹ́gẹ́ bíi ayàwòrán rẹ́ tuntun
Oríṣun àwòrán, @tolanialli
Iṣẹ tokunrin n ṣe, obirin naa le ṣe e
Igbakeji aare, Yemi Osinbajo ti yan Tolani Alli, gẹgẹ bi ayaworan rẹ tuntun.
Olubadamọran pataki fun aarẹ Muhammadu Buhari lori iroyin igbalode, Tolu Ogunlesi, lo fi ọrọ naa lede loju opo Twitter rẹ.
Tolani Alli ni o ti jẹ ayaworan fun gomina ipinlẹ Ọyọ tẹlẹ ri, Abiola Ajimobi.
Tani Tolani Alli?
Tolani Alli kẹkọọ jade ni Fasiti Michigan, ni orilẹ-ede Amẹrika, nibi ti o ti kẹkọọ nipa imọ sayẹnsi.
O bẹrẹ si nii ya aworan ni ọdun 2010 nigba ti o wa ni ile ẹkọ giga fasiti Michigan.
Tolani jẹ oludari iṣẹ ẹgbẹ awọn ọmọ ilẹ Adulawọ ni fasiti Michigan.
Bakan naa lo tun kọ ẹkọ nipa ilera lọdun 2008 si 2012 ni Michigan Flint
O tun kọ ẹkọ nipa fọto yiya ati iroyin ṣiṣe ni danish School of Media and Journalism Documentary Photography Course.
"Lara awọn isẹ ti Tolani Alli ti se tẹlẹ ri ni "" Code Girl Magic"" eyi o se ni osu kankanla, ọdun 2018."
Oríṣun àwòrán, @tolanialli
"Oun naa lo tun se "" Women in the Delta"" ni osu kejila, ọdun 2018."
Tolani jẹ oṣiṣẹ ileeṣẹ Illusions Imagery ki o to di pe igbakeji aare, Yemi Osibanjọ yan si ipo tuntun yi.
Awọn ti Tolani n wo niwaju ni awọn bii Kobe Bryant.
Ọpọlọpọ ami ẹyẹ ni Tolani ti gba lẹnu iṣẹ aworan yiya to yan laayo.
Tolani ti ba arun jẹjẹrẹ pòó, o si ti bori lo fi n figba gbogbo rọ awọn eniyan lati má sọ ireti nu laye.
Tolani ṣiṣẹ gẹgẹ bi ayaworan fun gomina Ajimobi to tukọ ipinlẹ Oyo lati oṣu kejila lọdun 2014 to fi kuro nipo.
Ọpọlopo iṣẹ rẹ lo ti jẹ itẹwọgba nilẹ yii ati loke okun.
Ede yoruba ati ede Gẹẹsi dan lẹnu Tolani daadaa.
Tolani fẹran lati maa wo ere idaraya bọọlu alajusawọn ati ko maa tun ẹrọ kọmputa ṣe tabi ko kuku maa kawe akagbadun ninu ile.
Wo imọran Fọlọrunṣọ Alakija fun awọn ọdọ adulawọ
Fraud Allegations: Abike Dabiri-Erewa rọ àwọn tọ́rọ̀ kàn láti yọjú sí FBI
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Awọn gbajuẹ ma n lo ẹro ayara bi aṣa lati lu awọn eniyan ni jibiti
Ijọba apapọ ti fi ọrọ lede pe iwa awọn ọmọ Naijiria ti ajọ FBI ṣatẹjade orukọ wọn gẹgẹ bi afurasi oni gbajuẹ, jẹ eyi ti o ti doju ti orilẹ-ede wa.
Bashir Ahmad, ẹni ti o jẹ oludamọran fun aare Muhammadu Buhari lori ọrọ ẹrọ ayelujara, lo fi ọrọ naa lede lori opo Twitter rẹ.
"Bakan naa ni awujọ awọn ọmọ Naijiria to n gbe loke okun tun sọ si ọrọ naa pe: ""Ti wọn ba fi ẹsun kan eniyan, ko tumọ si pe o ti jẹbi."
A gbagbọ pe ajọ FBI yoo ṣe iwadi fini fini lori ọrọ naa, ti gbogb wa si maa mọ okodoro ibẹ.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Olupẹjọ nilẹ Amẹrika, Nick Hanna, sọ pe, ọwọ ṣikun ijọba ti tẹ awọn mẹrinla
O wa rọ awọn ti ọrọ naa kan ti o wa lorilẹ-ede Naijiria lati yọju si ajọ FBI bi o ba dawọn loju pe, wọn ko lu ẹnikẹni ni jibiti.
Abike Dabiri-Erewa, ti n ṣe alaga ẹgbẹ naa lo sọ eyi ninu ọrọ to fi lede.
Iwa gbájúẹ̀ yii ti n bi Ige ati Adubi -Ojọgbọn Oni Fagbohungbe.
Laipẹ ni ileeṣẹ to n gbogun tiwa ibajẹ ni America gbe orukọ awọn ọmọ Naijiria sita lori iwa jibiti Ọwọ́ òfin ti tẹ ọ̀pọ̀ ọmọ Nàìjíríà lórí ẹ̀sùn jìbìtì l'Amẹrika- FBI
Ọjọgbọn kan ti ni, bi ajọ ọtẹlemuyẹ Amẹrika, FBI, ṣe fi orukọ awọn ọmọ Naijiria lede gẹgẹ bi afurasi oni jibiti, kii ṣe ohun ti o buyi fun wa.
Ọjọgbọn Oni Fagbohungbe, ẹni ti o jẹ adari ẹka imọ bi awọn eniyan ṣe n ronu ni Fasiti ijọba apapọ ti ilu Eko, ni iru iroyin bẹẹ maa n jẹ ki awọn ara ilẹ okeere ri awọn ọmọ Naijria gẹgẹ bi ọdaran ni.
"O tẹ siwaju pe: ""iru iwa jibiti yi kii jẹ ki awọn ọmọ wa ri oluranlọwọ, ati pe o lee jẹ ki awọn oludokoowo fa sẹyin lorilẹ-ede wa."
Oríṣun àwòrán, @FBI
Ogọ́rin ọmọ Nàìjíríà ni Iléesẹ́ ọ̀tẹlẹ̀múyẹ́ ilẹ̀ Amẹ́ríkà FBI, ti forúkọ wọn léde lórí èṣùn jìbìtì
Iwa buburu bayi lee mu ki awọn ọmọ Naijiria koju ọpọlọpọ isoro nigba ti wọn ba n lọ si ilẹ okeere, paapaa julọ nibudokọ ofurufu.
Onwoye naa ro pe awọn obi ni iṣẹ pupọ lati se nipa kikọ awọn ọmọ wọn lọna ti o tọ.
Kii ṣe lati maa fi wọn we awọn ojugba wọn ti o lowo lọwọ, ti wọn ko si mọ ibi ti wọn ti ri owo ti wọn n na.
Bẹẹ, ti a ba fi ọmọ we ọmọ ni owe awọn agab n wi.
Ojọgbọn Oni tẹsiwaju ninu ifọrọwerọ rẹ pẹlu BBC pe: Ijọba ni lati pese iṣẹ fun awọn ọdọ to n fẹsẹ gbalẹ kiri.
Ijọba si tun ni lati fi iya ti o tọ jẹ ẹnikẹni ti ọwọ ofin ba tẹ pe o hu iwa ibajẹ, lai ro iru ẹya ti iru ẹni bẹẹ ti wa ati ẹsin to n sìn.
Bakan naa ni ọjọgbọn Oni Fagbohungbe sọrọ siwaju pe, ijọba ni i ṣe pupọ lati ṣẹ lori igbogunti iwa ibajẹ lorilẹ-ede yi.
O ni ki obi ati alagbatọ fi ibẹru Olorun tọ awọn ọmọ wọn ki wọn si jẹ ki wọn mọ nipa iṣẹ ati ere awọn akikanju.
Joe Igbokwe kò yẹ́ fún ipò ti wọ́n fún nípìnlẹ̀ Eko - Babatunde Gbadamosi
Kò sí ẹni tó lè yọ mi nípò Sẹnetọ -Dino Melaye
Oríṣun àwòrán, @Dino
Irọ lẹ pa lori ọrọ igbẹjọ mi - Dino
Igbẹjọ to n gbọ ẹjọ ẹsun idibo lo ṣẹṣẹ gbe idajọ rẹ sita bayii.
Senetọ Dino Melaye ni ajọ INEC kede pe o wọle idibo ti o waye lọṣu keji ọdun yii nibi to ti dije lati ṣoju ẹkun iwọ oorun ipinlẹ Kogi.
Ẹgbẹ oṣelu PDP ni Dino Melaye ba dije to si ti jawe olubori ninu idibo naa to ti tun lọ bẹrẹ iṣẹ nile igbimọ aṣofin agba ni Abuja.
Dino Melaye lo ti kọkọ ṣoju ẹkun yii pẹlu oriṣiriṣi iṣẹlẹ ṣeyin.
Adajọ ile ẹjọ igbẹjọ idibo Naijiria ti ni ki wọn lọ tun ibo naa di ni ẹkun iwọ oorun ipinlẹ Kogi.
Agbẹnusọ Mélayé: Dino ti lọ yọjú sọ́dọ̀ ọlọ́paa SARS
Senetọ Dino Melaye ti ni ki awọn eniyan oun lọ fi ọkan balẹ.
O ni ko sẹni to le yọ oun nipo rara nitori pe awọn to ni ifẹ oun lo dibo yan oun wọle.
Senetọ Dino Melaye ni oun n lọ si ile ẹjọ kotẹmilọrun lati gba idajọ to yẹ.
O ni tootọ ni idibo miran maa waye nipinlẹ Kogi nitori oun yoo di gomina ti Kogi n reti.
Dino  Melaye ni ẹru ko ba odo oun rara lori ipo aṣojuṣofin oun ni abuja.
Ẹ̀rù ń bá wá lóri ilera sẹnatọ Dino Melaye
Igbẹjọ yii waye ni Lọkoja to jẹ olu ilu ipinlẹ Kogi nibi ti oludije ipo sẹnetọ fun ẹgbẹ APC, Senetọ Smart Adeyẹmi ti pe ẹjọ kotemilorun.
Loṣu kẹrin ni Adeyẹmi Smart pe ẹjọ naa pe oun lo bori ninu idibo fun ipo aṣojuṣofin ẹkun yii.
Oṣu kọkanla ọdun yii ni ajọ eleto idibo INEC ni eto idibo gomina nipinlẹ Kogi yoo waye.
Dino Melaye ni oun lo maa rẹrin igbẹyin lori gbogbo iṣẹlẹ yii.
Dino Melaye nánwó fún Ayefẹlẹ lójú agbo
Ogun Kidnap: Ìjàmbá ṣàwọn ajínigbé tó fẹ́ fipá gba akẹgbẹ́ wọn lọ́wọ́ ọlọ́pàá
Oríṣun àwòrán, Facebook/Ogun Police Command
Ọga agba ọlọpaa ipinlẹ Ogun
Ileeṣẹ ọlọpaa ipinlẹ Ogun ti kepe awọn eeyan ati ile iwosan kaakiri ipinlẹ naa pe ki wọn kan si ile iṣẹ ọlọpaa ti wọn ba ri ẹnikẹni to ba ni apa ibọn lara.
Alukoro ileeṣẹ ọlọpaa ipinlẹ Ogun, DSP Abimbola Oyeyemi to ba BBC Yoruba sọrọ, ṣalaye pe awọn akẹgbẹ awọn ajinigbe mẹrin ti ọwọ awọn ọlọpaa tẹ lo doju ija kọ awọn ọlọpaa nigba ti wọn n kọ wọn si Abeokuta lati Ode Omi ti wọn ti ji ọmọ Imaamu ati eeyan meji mii gbe.
DSP Oyeyemi fidi rẹ mu lẹ pe ibọn ọkan lara awọn to doju ika kọ awọn ọlọpaa naa gbẹmi mi tawọn yoku si farapa.
Ọgbẹni Oyeyemi ni iwadii si n lọ lọwọ lori awọn ajinigbe to fara gbọta nitori ko sẹni to tii sọ ohun kan fun ileeṣẹ ọlọpaa di akoko yii.
Ileeṣẹ ọlọpaa ti kọkọ doola awọn mẹta ti wọn jigbe lọsẹ to lọ.
Ẹwẹ, DSP Oyeyemi tun ṣalaye pe ileeṣẹ ọlọpa si n wa ọkọ oju omi agbera pa wọn tawọn ajinigbe gbe lọ nigba ti wọn fi doola ọmọ Imaamu atawọn meji ti wọn gbe lọwọ wọn.
O ṣalaye pe awọn ọlọpaa fẹ kọkọ wa awọn ajinigbe ri ki wọn to wa ọkọ oju omi.
COZA RAPE Allegation: Ìdí rèé tí mi ò fi yọjú sí ìgbìmọ̀ àjọ PFN- Fatoyinbo
Oríṣun àwòrán, Instagram/BiodunFatoyinbo & BusolaDakolo
Oludasilẹ ijọ Commonwealth Of Zion Assembly ti ọpọ mọ si COZA, Biodun Fatoyinbo ti iyawo gbajugbaja olorin Timi Dakolo, Busola Dakolo fẹsun ifipabanilopọ kan ti ṣaleye pe agbẹjọro oun lo gba oun ni imọran pe k'oun maa yọju si igbimọ ajọ PFN.
Fatoyinbo sọrọ yii ninu atẹjade kan to fi sita lati ọwọ amugbalẹgbẹ rẹ, Ademola Adetuberu.
O sọ ninu atẹjade naa pe o ti gbangba pe igbimọ PFN yoo ṣegbe lẹyin ẹnikan ni ko jẹ ki oun lọ siwaju wọn.
Adetuberu ṣalaye ninu atẹjade ọhun pe lootọ ni pasitọ Akinola Akinwale pe Fatoyinbo lori aago pe ko wa farahan niwaju igbimọ PFN, ṣugbọn COZA sọ fun un pe ko le wa nitori iwadii si n lọ lọwọ lori ẹsun ti Busola fi kan an.
O fikun ọrọ pe agbẹjọro sọ fun Fatoyinbo wi pe ko maa yọju si igbimọ naa nitori aarẹ ajọ PFN, Bisọpu Felix Omobude ti sọ tẹlẹ pe oun o mọ Fatoyinbo ri.
Adetuberu tun sọ pe niṣe ni igbimọ ajọ PFN tun kọ lati fi iwe pe Fatoyinbo.
O ni Fatoyinbo yoo yọju si igbimọ PFN tawọn ọlọpaa ba pari iṣẹ iwadii wọn lori ọrọ naa.
PFN: Fatoyinbo kọ̀ láti yọjú ni ìwádìí wa kò ṣe parí
Ajo awọn ẹni ẹmi ni Naijiria, eyi ti wọn n pé ni Pentecostal Fellowship of Nigeria (PFN), ti fi ọrọ lede pe awọn ko tii pari iwadii ti wọn n ṣe lori ẹsun ifipabanilopọ ti Busọla Dakolo fi kan Biọdun Fatoyinbo.
Ẹni ti o jẹ akọwe fun ẹgbẹ naa, Biṣọọbu Emma Isong lo fi ọrọ naa lede nigba ti o n ba ileeṣẹ BBC sọrọ nilu Eko lowurọ oni.
O sọ ninu ifọrọweró naa pe:  olusọ agutan Biodun Fatoyinbo kọ lati yọju si ibi iwadii ti ajọ naa gbe kalẹ, bi o tilẹ jẹ pe, Busọla Dakolo ti yọju nitirẹ.
Oríṣun àwòrán, Biodun Fatoyinbo/Facebook
Fatoyinbo kọ̀ láti yọjú ni ìwáàdí ò ṣe parí
Awọn ajọ tó ń rí sí ọ̀rọ̀ ilé ìjọsìn pẹntikọsita ní Nàìjíríà (PFN) ti so pe iwadi ajọ naa si ẹsun ifipabanilopọ ti Busola Dakolo fi kan oludasilẹ ijọ Commonwealth of Zion Assembly (COZA), Pasitọ Biodun Fatoyinbo ko pari.
Oríṣun àwòrán, Busola Dakolo/Facebook
Ìwáàdí ẹ̀sùn ìfipábánilòpọ̀ kò tíì parí
Ajọ PFN sọ pe iwadii naa ko pari nitori Pasitọ Fatoyinbo kọ lati yọju si igbimọ ẹlẹni marun-un to n ṣewadii ẹsun naa.
"O te siwaju ninu ọrọ pe ""iwadii ti ẹgbẹ PFN ṣe ko nii ṣe pelu iwadii ti awọn ọlọpaa."""
COZA: Ọpọ èrò ló jáde ṣe lòdì sí ẹ̀sùn ìfipábánilòpọ̀ Fatoyinbo
Iwadii ẹgbe PFN lo waye nitori awuyewuye awọn eniyan ati awọn oniroyin lori ẹsun naa.
Oríṣun àwòrán, @others
A gbọ ẹjọ ẹnikan da...
ALGON: 35% la fẹ́ kíjọba àpapọ̀ máa pín bíi owónàá fún ìjọba ìbilẹ̀
Oríṣun àwòrán, Algon
A kò lé fáramọ bí ẹ sé fẹ́ maa pín owó Nàìjíríà: ALGON
Agbarijọpọ ẹgbẹ́ awọn ìjọba ìbílẹ̀ jákèjádò orílẹ̀-èdè Nàìjíríà (ALGON), tí ké sí ìjọba apapọ̀ pé, ìlànà ti wọ́n fẹ́ máà fi pín owónàá oṣooṣù ko tẹ́ àwọn lọ́rùn rárá, àfi kí wọ́n máa pín ni ìdá márùndínlógójì nínú ìdá ọgọ́rùn.
Ẹgbẹ́ náà kọ ìdá mẹ́tàlélógun ti àwọn gómìnà ti ṣètò fún wọ́n, bó tilẹ̀ jẹ́ pé èyí gbé pééli díẹ̀ sí ìdá ogun o lé diẹ̀ ti wọ́n ń gba tẹ́lẹ̀ lọ.
Nínú ìpàdé wọn ní àwọn gómìnà mẹ́rẹ̀rìndílógójì ti sọ nínú ìbéère wọ́n pé, ìdá mejilélógóji ni àwọn fẹ́ máà gba, èyí to jìnà sí ìdá mẹ́rìndínlọ́gbọ̀n tí wọ́n ń gbà tẹ́lẹ̀.
Èyí ló mú kí wọ́n dábàá pé kijọba apapọ ṣe adínkù owó tó ń pínfun ara rẹ, eyi to jẹ́ ìdá méjìléláàdọ́ta, ko si sọ di ìdá mẹ́tàdínlógójì.
Sáájú ní alága àjọ tó n rísi bí ìjọba ṣe n setò owó (RMAFC) Elias Mbam, tí ṣe àgbékalẹ̀ ìgbìmọ̀ tẹ̀ẹ́kótó ti yóò jòkó láti jíròrò lórí bi wọ́n yóò ṣe maa pin owo sí ipele ìjọba mẹ́tẹ̀ẹ̀ta.
Mbam ní ìpínnu ìlànà ti àwọn fẹ́ gúnle yìí ni wọ́n ti dábàá tẹ́lẹ̀ láye Obasanjo, èyí ti ìjọba ìbilẹ̀ yòó ma gba ìdá mẹ́tàlélógun.
Nínú ìfọ̀rọ̀wánilẹ́nuwò ti Punch fún ààrẹ gbogbo-gboo ẹgbẹ́ ALGON, ọgbẹ́ni Alabi David sàlàyé pé, o ti wá di dandan bayìí láti gba iyé owó yìí, nítori  ìṣẹ́ ribiribi tí ó ti wà lọ́rùn àwọn alága ìjọba ìbílẹ̀ báyìí kii se kekere.
Lai Mohammed: Àtúntò yìí kò wà láti ga àwọn iléeṣẹ́ agbóhùnsẹáfẹ́fẹ́ lọ́rùn
Oríṣun àwòrán, @RadioToday
Ààrẹ Muhammadu Buhari ti buwọlu àtúnto àwọn ilé iṣẹ́ ìròyin gbogbo lórilẹ̀-èdè Nàìjíríà, pàápàá jùlọ, lóri fífún àwọn ilé iṣẹ́ ìròyìn orí ayélújára ni ìwé àṣẹ́.
Mínísítà fún ètò ìròyin àti àsà Lai Mohammed lo sọ̀rọ̀ náà, lásìkò tó ń gba àlejo àwọn ọmọ ẹgbẹ́ tó ń ri si akoso igbóhùn sáfẹ́fẹ́ (BON) nílú Abuja.
"Ní ìdáhùn sí ìbéèrè ti àdárí BON bèèrè, minisita ní ""Mo fẹ́ lo ànfàni yìí lati sọ fun yin pé, ààrẹ Buhari ti búwolu àtuntò ilana igbohun sáfẹfẹ ti yoo si moju to àwọn ibèerè yín"""
Oríṣun àwòrán, lAI MOHAMMED
Gbogbo àwọn oníròyìn ayálujara ni ó ma sanwo ori-Lai Mohammed
Ní pàtàkì jùlọ ààrẹ ti buwọ́lu pé, o ti pọn dandan fún àwọn ilé ìròyìn ori ayélujura yala tẹlẹfisan tabi rediò, tó fi mọ awọn ti ilẹ okeere, tí ohun wọn n wọ orílẹ̀ èdè yìí, lati gba iwe aṣẹ lọdọ ijọba.
Tẹ ba gbọ ọpọ ohun to n jade lori awọn redio ati tẹlifisan wa, ẹ ro pe ogun jija n waye lorilẹede yii ni, abi pe awọn Kristiẹni ati Musulumi ko lee gbe papọ, abi pe iyapa wa laarin ẹkun Guusu ati Ariwa Naijiria.
Oríṣun àwòrán, @RadioToday
Lai Muhammed wa fọwọ idaniloju sọya pe igbesẹ naa ko wa lati ga awọn ileesẹ iroyin lọrun, to si rọ ajọ BON lati sugba ijọba nidi aayan rẹ lati mu agbega ba eto igbohunsafẹfẹ ni Naijiria.
Lizzy Anjorin: Ẹ má bú mi, ọ̀pọ̀ òṣèré tíátà ni kìí bá mi yọ̀ fún ire mi
Oríṣun àwòrán, Instagram/lizzyanjorin
Oju opo Instagram tun ti n gbona jain-jain bayii nitori awọn ololufẹ awọn osere tiata obinrin meji, Toyin Abraham ati Lizzy Anjọrin, ti wsn n tahun si ara wọn.
Idi ti isẹlẹ naa se waye ni bi Lizzy Anjọrin se n ba Ronkẹ Odusanya yọ pe o ku ayọ ọmọ tuntun to bi lẹyin ọjọ diẹ ti iroyin gbalẹ pe Toyin Abraham bi ọmọ tuntun.
Ọkan lara awọn ololufẹ Toyin Abraham lo wa ta gba Lizzy pe ki lo de to fi n ba Ronkẹ yọ, to si kọ lati ba Toyin yọ lasiko to bimọ tiẹ.
Ibeere yii lo bi Lizzy ati awọn ololufẹ rẹ ninu, ti wọn si n beere pada pe igba melo gan ni Toyin funra rẹ yọ pẹlu Lizzy lasiko to ba kede loju opo Instagram rẹ pe oun n se nkan ayọ abi oriire.
"Ninu alaye rẹ loju opo Instagram rẹ, Lizzy ni ""Se bi emi ni mo dide lati ja fun Toyin Abraham lasiko tawọn eeyan n tabuku rẹ loju opo ayelujara nigba ti isẹlẹ ti Seun Ẹgbẹẹgbẹ waye, amọ titi di asiko yii, Toyin ko ki mi ri ku oriiire lasiko ti mo ba kede pe Ọlọrun se oore nla fun mi."""
Mo ti kede lọjọ Kẹjọ osu Kinni ọdun 2019 pe mo n se iranti mama mi, lọjọ kẹtala ni mo joye ẹsin, ọjọ Kẹrinla osu Kẹrin ni mo se ọjọ ibi, ti ọmọ mi si se ọjọ ibi tiẹ ni ọjọ Kẹfa osu Kẹfa, bẹẹ ni mo si ile tuntun lọjọ Kọkanla osu Keje, ams ko si ibi ti Toyin Abraham ti ba mi yọ rara lasiko awọn ayẹyẹ naa.
Oríṣun àwòrán, Instagram/lizzyanjorin
Lizzy fi kun pelọjọ Kẹtadinlọgbọn osu Keje naa ni ẹnikan n dunkoko lati pa oun, ti oun si gbe soju opo Instagram oun, amọ ẹtahoro awọn osere lo sọ le ohun ti mo fi sita yii, ti ọpọ wọn ko si fọhun lati ja fun mi, awọn ololufẹ mi ko si ba wọn ja le lori.
O ni bi oun ba n jo lati Osu Kinini ọdun wọ osu Kejila, o loju osere tiata ti yoo sọ pe oun ri oun, koda, awọn itan aye oun ti oun kọ lasiko ti oun n sile, lee gba omi loju ẹni to ba ti jẹ ori ahun, sugbọn sibẹ, diẹ ninu awọn osere yii lo da si ọrọ naa.
Lẹyin eyi ni Lizzy, ẹni to sẹsẹ ti Mecca de fun isẹ Hajj, wa fi epe silẹ fun awọn to ba n tabuku oun per oun ko ba Toyin Abraham yọ lori ọmọ to bi.
Wayi o, Lizzy wa salaye lẹyin o rẹyin pe oun kuku ki Toyin ku oriire ọmọ tuntun amọ oun ko polowo tabi gbe larugẹ gẹgẹ bi awọn osere yoku tii n se, ni ko jẹ ki ọpọ eeyan mọ pe oun ki Toyin ku ewu ọmọ.
O fikun pe Toyin naa si fesi pada fun oun pe awọn nifẹ, tawọn si ms riri oun pẹlu.
O wa kilọ fun awọn gbọyi-sọyi lati sọra gidi.
Ìjọba Ọyọ: Olówó nìkan kọ́ ni ìdájọ́ iléẹjọ́ yóò máa gbè ní Ọyọ
Oríṣun àwòrán, @Lagostalks913
Ijọba ipinlẹ Ọyọ ti fi ọwọ idaniloju sọya pe latri akoko yii lọ, oun yoo maa gbe igbesẹ lati mu adinku ba ajaga ẹru ẹjọ to wa lawọn ileeẹjọ, ti wọn yoo si maa yanju awọn ẹjọ pẹlu iyara kankan.
Kọmisana feto idajọ ati agbẹjọro agba nipinlẹ Ọyọ, Ọjọgbọn Oyelọwọ Oyewọ lo fi ọwọ idaniloju yii sọya lasiko to n bawọn akọroyin jẹwọ ni ọọfisi rẹ.
Oyewọ salaye pe bakan naa ni ijọba Ọyọ ti setan lati se atunto awọn ọgba ẹwọn wa, ti aparo kan ko fi ni ga ju ọkan lọ, ti idajọ yoo si maa waye lai fi igba kan bo ọkan ninu tabi se oju saaju.
Oyewọ tun ni aayan tun ti n lọ lati ri daju pe pepele kan wa fun atunse awọn ẹlẹwọn, ti ayipada yoo si tun ba ero araalu ti wọn gba pe awọn olowo ati ọlọrọ nikan ni idajọ ileejọ n gbe.
Oríṣun àwòrán, @Lagostalks913
A fẹ se agbekalẹ awọn ilana ofin ti ẹka eto idajọ yoo gbajumọ. Fun apẹẹrẹ, eto sisi oju aanu wo awọn ẹlẹwọn yoo bẹrẹ, ta si se atunto aye wọn. Gbogbo ẹlẹwọn to ba si gba itusilẹ lati ipasẹ oju aanu yii, ni ko tun ni pada lọ sọgba ẹwọn mọ.
Oyewọ fikun pe ijọba fẹ gbe igbesẹ naa nifọwọkọwọ pẹlu awọn asaaju ẹsin, awsn ẹlẹgbẹjẹgbẹ lawujọ ati awọn ẹgbẹ alaanu gbogbo.
Minimum Wage: Buhari ló kù tí yóò fẹnu ọ̀rọ̀ jóná lóri owó oṣù tuntun
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ọrọ gbogbo to nii se pẹlu sisan owo osu tuntun fawọn osisẹ orilẹede Naijiria ni ko tii ni ojutu bayii nitori ijiroro lori bi owo osu tuntun naa yoo se jẹ sisan lo ti dẹnu kọlẹ bayii.
Idi ni pe igbimọ to n duna dura fẹgbẹ osisẹ, JNPSNC atawọn asoju ijsba apapọ tun ti sun ipade wọn si ọjọ Kẹrin osu Kẹsan ọdun yii fun akstun ijiroro miran.
Wọn ni eyi ni yoo jẹ ki aarẹ orilẹede yii, Muhammadu Buhari bawọn da si ọrọ naa ti ko fẹẹ ni ojutu rara bayii, ti wọn yoo si ni anfaani lati se atunse si owo osu tuntun naa.
Gẹgẹ bi ajọ akoroyinjọ lorilẹede Naijiria se wi, awọn akọwe agba nileesẹ eto isuna ati ọrọ osisẹ lo peju sibi ipade naa, ti igun mejeeji si pinnu lati gba ki aarẹ da si ọrọ naa, ko lee tete ni ojutu.
Nigba to n salaye ohun to n fa aawọ laarin awọn igun ijọba ati ti ẹgbẹ osisẹ, ọkan lara awọn asaaju gb osis to wa nibi ipade idunadura naa, Lawrence Amaechi salaye pe atunto owo osu lo n fa aawọn ọhun.
Amaechi ni ọrọ sisan owo osu naa ti yẹ ko bẹrk tipẹ, to si n rọ ijsba lati tete fẹnu ọrọ jona lori rẹ, ki wọn si san ajẹsilẹ owo osu tuntun naalsna ati dena ifẹhonuhan miran latọdọ awọn osisẹ.
2023 Elections: Shehu Sani ní àfàìmọ̀ kí Yorùbá àti Igbo má kùnà nínú ìbò ààrẹ ọdún 2023
Oríṣun àwòrán, Facebook/Shehu Sani
Ibo gbogbogbo ọdun 2023
Yoruba ati Ibo le kuna lati jẹ aarẹ orilẹede Naijiria lọdun 2023 ti idibo gbogbgbo miiran yoo tun wa ye.
Sẹnẹtọ to wa lara awọn ile igbimọ aṣofin kẹjọ, Shehu Sani lo fọrọ yii lede lọjọ Abamẹta.
Sẹnẹtọ tẹlẹ ri sọ pe ti Yoruba ati Igbo ko ba fẹnu ko lori ẹni ti yoo apa guusu orilẹede Naijiria, afai mọ ki ipo aarẹ maa bọ mọ wọn lọwọ lọdun 2023.
Shehu Sani lootọ ni ko ni boju mu ki aarẹ Naijiria tun wa lati apa ariwa orilẹede yii ninu idibo ọdun 2023, amọ o le ṣẹlẹ bẹẹ ti awọn eeyan to wa lapa ila oorun ati iwọ oorun guusu ko ba fimọ sọkan.
O fikun ọrọ rẹ pe oun gbagbọ ninu pinpin ipo aarẹ lati apa kan si omiran kaakiri Naijiria.
Sani aigbọra ẹni ye laarin Yoruba ati Igbo lori oludije ti ṣoju guusu Naijiria ninu ibo aarẹ ọdun 2023 le fun awọn eeyan ariwa lanfaani lati tun jẹ aarẹ lọdun 2023.
Aarẹ Muhammadu Buhari to n ṣoju apa ariwa yoo ti lo ọdun ,mẹji lori laeefa to ba pari saa keji rẹ lọdun 2023.
Wọle Ṣoyinka: Ẹ máṣe gba gbogbo ohun tẹ bá rí lórí ayélujára gbọ́ nípa mi
Oríṣun àwòrán, @akhirebhulu
Ọjọgbọn Wọle Ṣoyinka ti sọ fun ijọba apapọ pe ko ye fi awọn oṣiṣẹ eleto aabo dunkoko mọ awọn Naijiria mọ.
Ọjọgbọn Ṣoyinka ni iwa ki awọn agbofinro ma halẹ mọ awọn eeyan nibi ti wọn ba ti n takurọsọ, ku diẹ kaato.
Ṣoyinka sọrọ yii niluu Badagry nibi to ti lọ ṣi iṣẹ ọna kan to nii ṣe pẹlu ayajọ ọjọ ibi rẹ.
Ọjọgbọn Ṣoyinka sọ pe, nigba ku gba ti ijọba ba n fi awọn ologun, ọlọpaa atawọn ọtẹlẹmuyẹ dunkoko mọ ara ilu, o tumọ si pe ijọba n bẹru ni.
O fi kun ọrọ rẹ pe, iru igbesẹ bẹẹ maa n ṣe adinku eeyan gẹgẹ bi ẹlẹran ara nitori o fihan pe, ijọba ko fẹ gbọ ohun ti ara ilu n wi ni.
Bẹẹ ba gbagbe, lọjọ Aje ọsẹ to lọ ni Ikeja niluu Eko lawọn ologun, ọlọpaa ati ọtẹlẹmuyẹ ti gbọngan kan pa, eyi tawọn ajafẹtọ ọmọniyan bii Ṣoyinka, agbẹjọro Femi Falana atawọn eeyan miran, ti fẹ ṣe apero.
Oríṣun àwòrán, @akhirebhulu
Ṣọyinka wa rọ ijọba atawọn oṣiṣẹ eleto aabo lati jawọ ninu apọn ti o yọ, ki wọn da omi ila kana.
Ọjọgbọn Ṣoyinka tun rọ awọn ọmọ Naijiria pe, ki wọn mase gba gbogbo iroyin ti wọn ri lori ayelujara gbọ.
O ṣalaye pe, ewu to wa ninu iroyin ori ayelujara pọ nitori ni iṣẹju akan ni yoo tan kalẹ kaakiri.
Ṣoyinka ni ọpọ igba lawọn eeyan maa n lo orukọ ati fọto oun fun iroyin lori ayelujara, nigba t'oun o tiẹ sọrọ kankan.
Kolawọle Ajeyẹmi: Ó yẹ ká ro ọjọ́ ìkúnlẹ̀ bímọ mọ́ aya lára lásìkò tó bá ṣẹ̀ wá
Oríṣun àwòrán, Instagram/KolawoleAjeyemi
Obiri ti wọn n pe ni obinrin! Kolawole Ajeyemi, to ṣẹṣẹ bi ọmọ tuntun jojolo pẹlu gbajugbaja oṣere tiata, Toyin Abraham, ti ṣapejuuwe awọn obinrin gẹgẹ bi ohun eelo ẹlẹgẹ lawujọ.
Ṣugbọn o ni bi wọn ṣe jẹ ohun ẹlẹgẹ, naa ni wọn ṣe lagbara to, pẹlu afikun pe ti Eleduwa ba fi obinrin rere jinki ọkunrin kan, iru ọkunrin bẹẹ ti ri ibukun, idunnu ati ẹmi gigun gba lọdọ Ọlọrun.
O ni wiwa pẹlu aya oun, Toyin lasiko to wa nile igbẹbi, to si n rọbi lọwọ, ti jẹ ki oun mọ ohun to maa n jẹ ki awọn ọkunrin kan maa n kẹ iyawo wọn gẹgẹ, toju-timu.
Oríṣun àwòrán, Instagram/KolawoleAjeyemi
Ọkọ Toyin, ẹni to sọrọ naa loju opo Instagram rẹ, @kolawoleajeyemi ni ṣe irora, omije ati ọpọ nkan miran ti ko see sọ, ti aya oun la kọja nigba to fẹ bi ọmọ ti Ọlọrun fi tawọn lọrẹ ni k'oun sọ ni, o ni ẹnu oun ko le sọọ tan.
Ajeyẹmi ohun toju awọn obinrin n ri nigba ibimọ ti to kawọn ọkọ wọn maa dariji wọn nigba ti wọn ba ṣẹ wọn.
O wa rọ awọn ọkunrin wi pe ki wọn gbiyanju lati tọju iyawo wọn nitori awọn lo jẹ iya ati iyawo fun wọn.
Amọ ko sai yan pe, arọwa oun fawọn ọkunrin lati maa tẹ jẹjẹ pẹlu awọn aya wọn ko tumọ si pe, oun n fun awọn obinrin lasẹ lati maa siwahu, sugbọn ohun ti oun n sọ ni pe awọn obinrin nilo ikẹ ọkunrin.
Oríṣun àwòrán, Instagram/KolawoleAjeyemi
"O ni "" Ẹ́ jẹ ka maa tọju, ka si maa sikẹ awọn obinrin nitori awọn ni iya ati iyawo wa, ko si ohun meji to tọ si wọn ju ojurere wa lọ, mo si bọwọ fun awọn obinrin rere."""
Ajeyẹmi wa gbadura fun gbogbo awọn obinrin rere fun ibukun Ọlọrun lori wọn, bakan naa lo gbadura pe wọn o jere iṣẹ ọwọ wọn.
Drug Trafficking: Ọmọ Yorùbá 16 ló wà nínú 23 tíjọba Saudi fẹ pa
Oríṣun àwòrán, Getty Images
O kere tan ọmọ Naijiria mẹtalelogun lo wa lara awọn ti wọn fẹ pa lorilẹede Saudi Arabia bayii lori ẹsun pe wọn gbe oogun oloro wọ ilẹ naa.
Atẹjade kan ti ijọba orilẹede Saudi Arabia fi sita lọjọ Abamẹta fihan pe, awọn ọmọ Naijiria yii wa lara awọn ti wọn mu ni papakọ ofurufu King Abdul-Aziz nilu Jeddah ati ti Prince Muhammad Bin Abdu-Aziz ni Madinah, laarin ọdun 2016 si 2017.
Awọn afurasi yii ni wọn sọ pe wọn gbe oogun oloro mii wọ ilẹ naa, eleyi to lodi si ofin orilẹede Saudi Arabia, ati pe iku ni ijiya fun iru ẹsun bẹẹ.
Gẹgẹ bi iroyin naa ti wi ọmọ Yoruba mẹrindinlogun lo wa ninu orukọ eeyan mẹtalelogun ti ijọba Saudi Arabia kede pe awọn yoo yẹgi fun lori ẹsun gbigbe oogun oloro.
Orukọ awọn eeyan ti wọn kede ọhun ree: Adeniyi Adebayo Zikri, Tunde Ibrahim, Jimoh Ishola Lawal, Lolo Babatunde, Sulaiman Tunde, Idris Adewumi Adepoju, Abdul Raimi Awela Ajibola ati Yusuf Makeen Ajiboye.
Awọn yoku ni Adam Idris Abubakar, Saka Zakaria, Biola Lawal, Isa Abubakar Adam, Ibrahim Chiroma, Hafis Amosu, Aliu Muhammad, Funmilayo Omoyemi Bishi, Mistura Yekini, Amina Ajoke Alabi, Kuburat Ibrahim, Alhaja Olufunke Alọlade Abdulqadir, Fawsat Balogun Alabi, Aisha Muhammad Amira ati Adebayo Zakariya.
Oríṣun àwòrán, Twitter/Saudi Embassy
Laipẹ yii ni wọn pa ọmọ Naijiria kan ni Saudi Arabia, Kudirat Afolabi lori ẹsun pe o gbe oogun oloro wọ orilẹede ọhun.
Bakan naa, ọmọ Naijiria mii wa lara awọn eeyan kan ti wọn fẹsun kan pe wọn ka egboogi oloro ''cocaine'' mọ lọwọ niluu Jeddah.
APC: O jẹ́ tètè jẹ́wọ́ àwọn tó rán ọ níṣẹ́ torí àwa kìí fún apààyàn lówó
Oríṣun àwòrán, @PoliceNG
Yoruba ni to ba buru tan, iwọ nikan ni yoo ku.
Bẹẹ lọrọ ri fun afurasi ajinigbe kan ti ẹnu ko sin lara rẹ lẹnu ọjọ mẹta yii, Hamisu Bala, ti gbogbo eeyan mọ si Wadume, ẹni to kede pe ẹgbẹ oselu APC fun oun ni miliọnu mẹtala naira lasiko eto idibo apapọ to kọja.
Bẹẹ ba gbagbe, afurasi yii ni awọn ọlọpa fẹ gbe nipinlẹ Taraba, amọ ti awọn ologun gbaa silẹ, ti wọn si gbẹmi ọlọpa mẹta ati araalu kan lasiko isẹlẹ naa.
Nigba ti ọwọ wa tẹ Wadume, lo ba figbe ta pe oun kii se apaayan abi ajinigbe rara, oloselu ni oun, ti ẹgbẹ oselu APC si mọ oun bii ẹni mọ owo, koda wọn fun oun ni miliọnu mẹtala naira lasiko ibo to kọja fun ipolongo ibo, amọ ti oun na miliọnu meje naira nibẹ.
Oríṣun àwòrán, @PoliceNG
Sugbọn niwọn igba to jẹ pe oku ni eeyan pa irọ mọ ti kii lee fọhun, ẹgbẹ oselu APC ti wa kigbe sita fun Wadume pe, yoo dara ko tete sọ awọn to ran nisẹ ibi nitori APC kii fun awọn apaayan ati ajinigbe ni owo.
Lanre Issa Onilu, tii se akọwe ipolongo apapọ fun ẹgbẹ APC salaye pe, ọrọ Wadume dabi afomọ to n wa gbongbo ti yoo so mọ ni lasiko to fẹ subu sinu odo, o si di dandan ki Wadume to n koju idajọ fẹ wa awọn ti yoo fẹyin ti ni.
Oríṣun àwòrán, @APC
Ẹgbẹ tiwa kii ya owo sọtọ fun awọn janduku. Asiko yii yatọ si igba ti ẹgbẹ to n sejọba maa n tọwọ bọ apo ilu lati fi owo gbọ bukata ipolongo ibo ati idibo pẹlu, bi ọwọ eku ẹgbẹ oselu wa se mọ, lo fi n họri lasiko yii.
Onilu ni, taa ba gbọ ohun ti Wadume sọ yii daada, a jẹ pe ọmọ ẹgbẹ APC ni yoo jẹ pẹlu awọn alaye to se.
Binta Ayo Mogaji: Kìí ṣe iṣẹ́ tíátà làwọn òṣèré ti rí owó ra ọkọ̀ ńlá àti ilé àwòdamiẹnu
Oríṣun àwòrán, Instagram/bintaayomogaji
Osere tiata to ba ni ọkọ gidi nile, to bimọ, to si ni ẹbi rere ko ni de idi sinima, ko maa ṣi ara silẹ tabi se afihan ihooho bi Ọlọrun se daa.
Ilumọọka osere tiata kan, Binta Ayọ Mogaji Odunẹyẹ lo woye ọrọ yii lasiko to n kopa lori eto ileesẹ tẹlifisan kan ni Naijiria.
Binta Mọgaji ni imura eeyan kan nigboro nii ohun se pẹlu idile to ti jade wa ati iwa ọmọluabi to ni, ti yoo si lee ronu jinlẹ pe iru oju wo ni aye fi n wo oun.
Binta, ẹni to sọ pe o ku diẹ ko pe ogoji ọdun ti oun ti n sere tiata, tun fikun un pe oun korira ki obinrin maa si ara silẹ lasiko to ba n sere itage,
O ni lati igba ti oun si ti bẹrẹ ere tiata, aye ko ri ihooho oun ju ejika oun lọ ri.
Nigba to n dahun ibeere to nii se lori awọn obinrin onitiata to n si ara wọn silẹ lati polowo ọsẹ tabi ipara to n bo ara, Binta salaye pe, ko tọna rara.
O ni ti eeyan ko ba maa polowo sinima onihooho tabi asọ ti wọn fi n luwẹ, taa mọ si Bikini, ko si idi kankan fun obinrin lati si ara silẹ, fi polowo ọja kankan tabi fi fa oju awọn onibara rẹ mọra,
Binta ni eyi ko nilo rarar nitori oju lasan ti to lati polowo ọsẹ tabi ipara.
Oríṣun àwòrán, Instagram/bintaayomogaji
O ni iwa ara bibo to wọpọ laarin awọn osere tiata lọkunrin ati lobinrin lode iwoyi, ni ko ba oju mu.
Awokose saa ni awọn jẹ lawujọ, bẹẹ si ni ohun ti eeyan ba ni lọpọlọ lo ja ju, kii se afihan ọyan, idi abi ara bibo.
Binta ni ọpọ igba ti oun ba wa ni ẹnu isẹ, ni oun maa n tako abala ere to ba gba ka si ara silẹ tabi wa ni ihooho,
Ati pe ẹnu oun kii duro lati gba awọn ọjẹ wẹwẹ akẹẹgbẹ oun nimọran pe ki wọn dẹkun sisi ara silẹ, tori eyi ko bojumu fun ọmọluabi ati asa wa.
Lori awọn sinima to nii se pẹlu afihan ihooho ati iwa jagidi jagan abi lilo ibọn, Gbajugbaja osere tiata naa ni asa alasa ni a n kọ pẹlu sise fiimu onijagidijagan.
O ni eyi lodi si asa, ise ati ohun ajogunba wa lorilẹ-ede Naijiria, idi si ree ti iwa ipanle se n pọ si lorilẹ-ede yii.
Oríṣun àwòrán, Instagram/bintaayomogaji
Binta Ayọ Mọgaji, lasiko to n fesi lori bi awọn osere tiata lode iwoyi se n ri owo nidi isẹ naa ju awọn osere tiata aye atijọ lọ ninu eyi ti Binta wa, osere tiata lobinrin naa ni, ohun ti onikaluku fi n jẹkọ, abẹ ewe lo wa.
"Awọn osere tiata tẹ ro pe wọn n ri owo pupọ lasiko yii ju asiko tiwa lọ, se inu isẹ tiata yii naa lẹ ro pe wọn ti n ri owo pupọ naa lati fi ra awọn ọkọ nlanla ati awọn ile awosifila tẹ ro pe wọn ni yii?
Oríṣun àwòrán, Instagram/bintaayomogaji
Se ẹ ko ro pe 'ẹbun' kọ ni awọn ile ati ọkọ naa, ti kii si se inu isẹ tiata ti wọn n se ni owo ti wọn fi ra awọn ohun meremere yii ti wa?"
Binta wa rọ awọn akẹẹgbẹ rẹ lati maa se ere to mu ọgbọn lọwọ, ti yoo se agbelarugẹ asa ati ise wa, ti yoo si kọ awọn araalu lẹkọ gidi, nitori awokọse rere lo yẹ ki awọn onitiata jẹ lawujọ wa.
World Isese Day: Àwọn oníṣẹ̀ṣe ṣàlàyé pàtàkì ọdún ìṣẹ̀ṣe àti ìdí tí ìjọba fi gbọdọ̀ kéde ìsinmi lẹ́nu iṣẹ́ bí àwọn ọdún ẹ̀sìn míràn
Oríṣun àwòrán, Alaafin oyo
Ogunjọ oṣu kẹjọ ọdun ni awọn ẹlẹsin abalaye ya sọtọ fun ayajọ ọdun iṣẹṣe lati ṣajọyọ ẹsin abalaye lagbaye.
Awọn agba awo ni ilẹ Yoruba ti sọ ọ di mimọ pe ọdun to yẹ ki gbogbo ọmọ Yoruba o mu ni koko.
Gẹgẹ bi awọn agba awo to ba BBC News Yoruba sọrọ ṣe sọ, ọdun iṣẹṣẹ jẹ ọdun iranti ipilẹ, ori, ati Olodumare.
Ninu ọrọ tirẹ, Babalawo Jogodo ni ọdun naa ni wọn fi n ranti iṣẹṣe ilẹ Yoruba ni lati dupẹ lọwọ Olodumare.
Awo Jogodo ni awọn ijọba nilo lati tubọ ṣe atilẹyin fun ọdun iṣẹṣe naa nitori ohun ni o n mu iranti wa fun awọn ọmọ karọ  o jiire lati mọ pataki wọn ni orilẹ agbaye.
Babalawo Jongodo ni iṣẹṣe ni gbongbo eeniyan ati pe o dara ki a mu imọ nipa ọdun naa kọ awọn ewe yoo mu ki ato ati idurodeede wa lawujọ; yoo si din awọn iwa kotọ gbogbo ku lawujọ.
Ninu ọrọ tirẹ, Akọda Awo ṣalaye pe awọn obi, ori, olodumare ni iṣẹṣe ati pe aimọkan lo n ṣe awọn to n ro pe idibajẹ ati iwa okunkun ni.
Sunday Igboho: Ẹ fi Ògún búra fún wa láti jà fún ilẹ̀ Yorùbá láì gbé Amotekun sábẹ́ ìjọba
Ipinlẹ Ọṣun nikan ni wọn ti n kede ọjọ isinmi lẹnu iṣẹ lati fi ṣe ajọyọ ajọdun naa.
Nibayii naa, awọn oniṣẹṣe ni ipinlẹ Ọyọ ti ke si gomina ipinlẹ Ọyọ, Seyi Makinde pe ko kede sjọ ajọdun iṣẹṣe gẹgẹ bi ọjọ isinmi lẹnu iṣẹ.
Ni aafin olubadan ti ilẹ Ibadan lawọn oniṣẹṣe ni ipinlẹ Ọyọ korajọpọ si lati ṣe ayajọ ọdun iṣẹṣe ti ọdun yii ni ipinlẹ Ọyọ.
Aarẹ Iṣẹṣe ti ipinlẹ Ọyọ, Oloye Omikẹmi Egbẹlade ni iṣejọba gomina Abiọla Ajimọbi ti  ja awọn oniṣẹṣe ni tanmọn ọn nipa kikọ lati kede isinmi lẹnu iṣẹ fun sisami ayajọ ọdun iṣẹṣe lagbaye.
Saaju ni ileegbimọ aṣofin ni ipinlẹ naa ti buwọlu ofin to rọgba yii ka ati pe igbagbọ awọn ni pe iṣejọba gomina Seyi  Makinde ko ni tọ ipasẹ rẹ.
Makinde, jọ̀ọ́ kéde Aug 20 ọdọọdún bíi ọjọ́ ìsinmi fún ìṣẹ̀ṣe - Àwọn oníṣẹ̀ṣe Ọyọ
Yoruba ni tẹni ba dakẹ, tara rẹ maa n baa dakẹ ni.
Eyi lo mu ki awọn ẹlẹsin ibilẹ yika ipinlẹ Ọyọ fi n rawọ ẹbẹ si gomina Seyi Makinde lati ya Ogunjọ osu Kẹjọ ọdọọdun sọtọ gẹgẹ bii ọjọ isinmi lẹnu isẹ fun ayajọ ọdun awọn onisẹse.
Awọn onisẹse naa, ti wọn korajọpọ si abẹ aburada ẹgbẹ kan ti wọn pe ni Traditional Religious Worshippers Association Of Nigeria (TRAWASSO) parọwa naa lasiko ti wọn ls se ago laafin si Olubadan tilẹ Ibadan, Ọba Saliu Akanmu Adetunji ni aafin rẹ lati fi sami ọdun Isẹse ti ọdun yii.
Oríṣun àwòrán, Facebook/Seyi Makinde
Nigba to n sọrọ lorukọ awọn onisẹse naa, Akọda Awo tilẹ Ibadan, Oloye Ifalere Ọdẹgbọla ni o ti le ni ọdun meji ti awọn ti gbe ibeere naa siwaju ijọba to kogba wọle.
Amọ o ni gomina ana, Abiọla Ajimọbi ko fontẹ lu ibeere awọn, ti wọn si n rọ ijọba to wa lode nipinlẹ Ọyọ bayii, labẹ gomina Seyi Makinde lati dahun si ibeere naa, gẹgẹ bi akẹẹgbẹ rẹ ni ipinlẹ Ọsun ti se.
O ni o yẹ ka jẹ ki awọn araalu mọ pe Isẹse lagba, ayajọ Isẹse yii si ni wọn yoo lo lati gbakanse adura si Ọlọrun ati awọn Alalẹ, bẹẹ si ni Orunmila lo kọkọ fi ipilẹ ilana isẹse yii lelẹ saaju ẹsin Musulumi ati ti Kristiẹni, nitori gbogbo ẹlẹsin lo n tọpasẹ ara wọn de idi ẹsin isẹse.
BBNaija: Khafi la Mercy àti Cindi mọ́lẹ̀ nínú abala tó kẹ́yìn ìdíje ọ̀rọ̀ nípa Nàíjíríà
Oríṣun àwòrán, Instagram/khafikareeem
Khafi Kareem to jẹ ọkan lara awọn to n kopa ninu eto agbelewo kan, Big Brother Nigeria, taa mọ si BBNaija ti gba ẹbun ọkọ ayọkẹlẹ lori eto naa.
Khafi to jẹ ọlọpaa nilẹ Gẹẹsi sọrọ loju opo Instagram rẹ pe, oun lẹni to ṣẹṣẹ ni ọkọ tuntun nigboro bayii.
Khafi jẹ ẹbun ọkọ ti ileeṣẹ to n ṣe mọto, Innoson Motors gbe kalẹ fun ẹni to ba gba ipo kinni, ninu idije sisọ ọrọ lori bi orilẹede Naijiria ṣe n wu wọn lori to.
Khafi ni wọn lo sọrọ iwuri nipa Naijiria julọ, lẹyin naa ni wọn kede rẹ gẹgẹ bi ẹni to jawe olubori ninu idije naa.
Oríṣun àwòrán, Instagram/acupofkhafi
Ni abala akọkọ, gbogbo oludije to wa nile lo sọrọ lọpọlọpọ nipa Naijiria, amọ Khafi, Mercy, Cindy ati Jackye nikan lo pegede de abala to kẹyin.
Mercy, Cindy ati Jackye ja fitafita lati moke ninu abala to kẹyin, ṣugbọn Khafi la gbogbo wọn mọ lẹ.
Ni ọsẹ to lọ niroyin sọ pe, ileeṣẹ ọlọpaa ilẹ Gẹẹsi n ṣewadii fọnran kan lori ayelujara eyi ti ọpọ gbagbọ pe Khafi n ni ibalopọ pẹlu akẹgbẹ rẹ, Gedoni ninu rẹ.
Koda iroyin naa ni Khafi le padanu iṣẹ lori ọrọ naa nitori iwa ibanilorukọ jẹ lo jẹ ati pe ileeṣẹ ọlọpaa ko fun laye lati lọ kopa ninu idije BB Naija.
Alaafin: Ẹ máa kọ́ àwọn ọmọ wa ní èdé àti àṣà Yorùbá
Oríṣun àwòrán, Alaafin Oba Adeyemi III
Ọdun Sango , tii se ọdun isẹnbaye to maa n waye lọdọọdun, eyi ti Alaafin tilu Ọyọ, Ọba Lamidi Ọlayiwọla Adeyẹmi Kẹta maa n se agbatẹru rẹ, ti waye lọdun yii, to si ti lọ pẹlu.
Sugbọn awọn ọrọ ti Alaafin sọ lasiko ayẹyẹ ọdun Sango naa si n ja rain-rain nilẹ.
Ọba Adeyẹmi, lasiko to n sọrọ salaye pe awọn alalẹ ati iran to n bọ lọjọ iwaju ko ni forijin oun, ti oun ba kọ lati maa se ajọdun Sango lọdọọdun, gẹgẹ bii ọkan lara awọn ọba to ti jẹ ri nilu Ọyọ.
Alaafin wa kesi awọn ọba alaye yoku nilẹ Yoruba lati maa gbe awọn asa ajogunba wa, ede, ati ise Yoruba larugẹ, ni gbogbo ilu ti wọn ba jọba le lori.
Oríṣun àwòrán, Alaafin Oba Adeyemi III
Bakan naa ni Ọba Adeyẹmi tun rọ awọn ọmọ Kaarọ Oojire lati maa fi asa ati ise wa kọ awọn ọmọ wa nitori orisa ti a ko ba fi oju ọmọde mọ, ko ni pẹ parun.
Iyatọ nla wa laarin ẹsin ati asa, ẹ mase jẹ ki oju ti yin lati maa wọ awọn asọ ajogunba Yoruba, koda asa wa gan gbọdọ fara han ninu awọn ounjẹ ta n jẹ
Oriade naa wa daba pe kawọn eeyan maa kọ awọn ogo wẹkrẹ wa ni ede abinibi ninu ile ati nile iwe.
Ìtàn mánigbàgbé: Ajayi Crowther ní ọjọ́ ìbànújẹ́ àmọ́ tó di ọjọ́ ayọ̀ ni ọjọ́ tí wọ́n kó òun lẹ́rú
Oríṣun àwòrán, @ArewaHistory
O ti pe irinwo ọdun bayii ti owo ẹru ti bẹrẹ jakejado agbaye, tawọn orilẹede agbaye si ti se ọpọ eto lati se ayẹyẹ naa, ninu eyi ti aarẹ orilẹede Naijiria, Muhammadu Buhari ti kopa.
Ọkan lara awọn eeyan to fori sọta akoko owo ẹru, to si di ẹru nigba naa, amọ ti ori ko yọ, to si pada di ojisẹ Ọlọrun ni oloogbe Samuel Ajayi Crowther.
Ninu lẹta kan ti Ajayi Crowther kọ ko to dagbere faye lo ti salaye ohun ti oju rẹ ri loko ẹru ati bi wọn se koo lẹru, ko to di pe o ri idande gba.
Oríṣun àwòrán, @ArewaHistory
Oju ẹni maa la, a ri to, oju ẹni maa la, yoo ri iyọnu. Ọ́pọ́ isẹlẹ miran to n sẹlẹ si ẹda to maa n mu omije, idaamu ati iya nla wa, ni a maa n kọ, lai ms pe ọna ti a tọ de ibi ayọ wa ni.
Itan bi wọn si se mu Samuel Ajayi Crowther lẹru yii lo n kọ wa pe bi a ko ba jiya to to agbọ̀n, a ko lee jẹ aye to to aha.
SERAP: Ọ̀rọ̀ àwọn alájẹbánu ti kúrò lọ́rọ̀ yàrá, ó ti di ọ̀rọ̀ gbangba
Oríṣun àwòrán, @SERAPNigeria
Gbogbo aye lo mọ pe ọrọ iwa ijẹkujẹ jẹ ohun kan to ti ba orukọ Naijiria jẹ nile ati loke okun fun ọpọlọpọ ọdun sẹyin.
Bẹẹ ni ọkan o jọkan akitiyan lawọn ijọba gbogbo ti gbe lori rẹ, ṣugbọn kaka ko san lara iya ajẹ, n ṣe lo tun n fi gbogbo ọmọ rẹ bi obinrin, ni ọrọ naa n jẹ.
Eyi lo wa mu ki ajọ kan to n lepa igbayegbadun araalu ati igbogun ti iwa ijẹkujẹ lawujọ, SERAP, ti ke sijọba apapọ lati gbe iwe orukọ awọn alajẹbanu sita.
SERAP ni iwe naa ni yoo ṣafihan orukọ awọn gomina ipinlẹ atawọn eekan ijọba miran, ti ile ẹjọ ti da lẹbi fun ẹsun ikowojẹ, bẹrẹ lati ọdun 1999.
Ninu lẹta kan ti SERAP kọ si agbẹjọro agba lorilẹede Naijiria, Abubakar Malami, lo ti pe ipe yii.
Ajọ SERAP tun rọ agbẹjọro agba ni Naijiria lati ri pe gbogbo orukọ to yẹ ko wa ninu iwe iforukọsilẹ naa lo wa nibẹ fun anfani araalu.
O ni eyi yoo jẹ ki wọn mọ ewolewo laarin awọn gomina ati awọn eekan ti ọbẹ ofin ti ba ni idi fun iwa ijẹkujẹ.
SERAP ni ko yẹ ko si ọrọ a n ṣe ọrọ orukọ awọn akowolujẹ ni awo mọ, nitori o ti de gbangba kii ṣe agbekọrọ yara gbọ mọ.
O ni orilẹede Naijiria lee wo awokọṣe ajọ ọtẹlẹmuyẹ ilẹ Amẹrika, to kede orukọ awọn afunrasi ẹsun ilunijibiti lorilẹede naa, nipa gbigbe igbesẹ bẹẹ ni kiakia.
Adebayo Shittu: Ìyàlẹ́nu ló jẹ́ pé ń kò jẹ mínísítà lẹ́ẹ̀kejì
Oríṣun àwòrán, @HMAdebayoShittu
Minisita tẹlẹri feto ibaraẹnisọrọ ni Naijiria, Adebayo Shittu ti ṣe'mọ bi aarẹ Buhari ko ṣe yan sipo Minisita.
Ọgbẹni Shittu to fi ọrọ yii lede ninu ifọrọwanilẹnuwo pẹlu ile iṣẹ akoroyinjọ ilẹ wa, NANS, nilu Abuja wa fikun pe, oun ti gba ọrọ naa gẹgẹ bi akọọlẹ Ọlọrun nilana ẹsin musulumi.
Ninu orukọ awọn minisita tuntun ti Buhari yan sipo, eeyan mẹrinla to ti ṣiṣẹ tẹlẹ bii minisitani saa akọkọ, lorukọ wọn wa ninu rẹ, amọ ti orukọ Shittu ko si lara wọn.
Bakanna la ri minisita obinrin meje, ninu awọn mejidinlogun to jẹ minisita tẹlẹri kuna lati ri ipo bi ti Shittu.
''Lootọ ni pe mo fi ọkan si pe wọn yoo yan mi sipo pada ṣugbọn nigba ti ọrọ ko ri bẹẹ, ko gba mi ni iṣẹju marun un lati gba wi pe akọsilẹ ni ati pe bi Ọlọrun ti ṣe fẹ ẹ ni yẹn''
O fi kun ọrọ rẹ pe ''Mo si ti ri ohun to tu mi ninu latara ẹsẹ Kurani, nibi ti Ọlọrun ti ṣe adehun pe oun to n bọ lọna, lati fun ọ ni ohun to dara ju eleyi to wa lọwọ rẹ bayi lọ''
Oríṣun àwòrán, @HMAdebayoShittu
Nigba to n sọrọ lori ohun ti yoo wa maa ṣe bayii lẹyin to kuna lati dipo minisita mu, ọgbẹni Shittu sọ pe oun yoo pada si idi iṣẹ amofin eleyi toun ti n ṣe saaju oṣelu.
Bi a ko ba gbagbe, ọmọ bibi ipinlẹ Oyo naa kuna lati ri tikẹẹti gba, eyi ti yoo fun laanfaani lati ṣoju ẹgbẹ APC ninu idibo Gomina to kọja nipinlẹ Oyo.
Idi ni pe ẹgbẹ APC ja Shittu kulẹ tori pe ko kopa ninu eto agunbanirọ ọlọdun kan, eleyi ti a mọ si NYSC.
Eletricity Tarriff: IKEDC ní sísan owó iná ọba tayọ èèyàn yókù kò lòdì sófin
Oríṣun àwòrán, Instagram/ikejaelectric
Bi wọn ba ni ko san owo ina ọba to le si eyi to n san lati le gbadun ina ọba, bi elo lo lero pe o le san?
Njẹ o si tọ ki awọn kan ma gbadun ina ọba nitori pe wọn ni agbara lati san owo ina ọba ju awọn akẹgbẹ wọn lọ?
Eyi lawọn ibeere to jẹ yọ lẹyin ti ileeṣẹ ajọ to n pin ina ọba nipinlẹ Eko, Eko Electricity Distribution Company, buwọlu iwe adehun kan pẹlu awọn olugbe kan lagbegbe Magodo Estate.
Adehun naa lo fun wọn ni anfaani lati maa san owo to pọ ju eyi to yẹ lọ, to si lowura ju tawọn ẹgbẹ wọn lọ, ki wọn lee maa ri ina ọba lo laisẹju.
Lai dena pẹnu, awọn eeyan kan ni Magodo Estate ti n gbadun ina ọba fun bi ogun wakati lojumọ tori pe, wọn buwọlu adehun ti wọn pe orukọ rẹ ni Premium Power Deal, pẹlu ajọ amunawa yii.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ninu ifọrọwanilẹnuwo BBC Yoruba pẹlu agbẹnusọ ileeṣẹ amunawa IKEDC, Felix Ofulue, o ṣalaye pe akanṣe eto adehun tawọn ni pẹlu awọn ara adugbo Magodo, lo mu igbadun ina ọba yi bawọn.
Felix Ofulue ko sọ pato iye kan pato ti awọn onibara wọn pataki yii n san, amọ o ni awọn fi owo le iye owo ti wọn n san lori lilo ina, ti eleyi si wa ni ibamu pẹlu ofin lilo ina ni Naijiria.
Ofulue fikun pe ''Lati nnkan bi ọjọ kẹẹdogun oṣu Kẹjọ ọdun 2019, lawọn eeyan Magodo ti n gbadun ina wakati mẹrinlelogun lojumọ.
Oríṣun àwòrán, @EKEDP
"A ṣe agbekalẹ ina ọba to yatọ fun wọn ni. Bi ẹnikẹni ba fẹ jẹ iru anfaani yii naa, a ṣetan lati ṣe bẹẹ ti gbogbo eto ati adehun laarin wa ba ti wa ni ṣẹpẹ"""
Ki ni kawọn ti ko ni owo wa ṣe bayi?
Kola Olubiyo to jẹ oludari ajọ to n ja fun ẹtọ araalu lẹka ohun amuṣagbara woye si ọrọ yii, to si ni labẹ ofin karakata ina ọba, ko si ohun to buru ninu iru adehun bẹẹ.
Ninu ifọrọwanilẹnuwo pẹlu BBC Yoruba, o ni ọrọ naa dabi ka ni ọlọja gbe ọja silẹ, to si n wa awọn ti yoo ra lowo to peye ni.
''Ofin gbawọn laaye lori igbesẹ yii ati pe, awọn ileeṣẹ to n pese ina ọba ti ṣadehun pẹlu ijọba lati ma san owo ina ọba ti ijọba n pese, ko si le pe wọn ti wọn ko ba ri ọja wọn ta loju owo ti wọn fi ra''
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Pupọ eeyan lo n lo ẹrọ amunawa lati pese ina fun ara wọn ni Naijiria
Olubiyo ni kii ṣe gbogbo eeyan lo le ma fara da aiṣedeede ina ọba paapa julọ, awọn to ba ni ile iṣẹ to n mu owo wa lojumọ.
O ni iru adehun yii jẹ ọna abayọ, amọ o ku ki ijọba gbe igbesẹ lati ri pe awọn mẹkunnu ko farakasa eto yii, tori pe wọn lee ma lowo lati san bii awọn olowo.
Oríṣun àwòrán, @EKEDP
''Ijọba ni lati mu atunto ba ẹka ina ọba ki awọn ara ilu baa le jẹ mudunmudun eto ijọba awarawa. Bi awọn olowo ba le san owo nla, ki wọn fi le ri ina ọba lo, ki ni ki awọn mẹkunnu ṣe?''
Olubiyo tun rọ ijọba lati yẹ ọrọ naa wo daada, ki o to kọja afẹnusọ.
BBNaija 2019: Gedoni kúrò ní BBNaija. Khafi bu sẹ́kún
Oríṣun àwòrán, khafibbn_officialfanpage
Gedoni Ekpata ati Jackye Madu ni wọn ti yọ kuro lori eto BBNaija 2019 to n lọ lọwọ.
Awọn meji yii ni wọn yọ ninu ile naa bi ẹni yọ jiga lọjọ Isinmi.
Gedoni, ẹni ti o jẹ ẹni kọkanla ti wọn yoo yọ ninu ile naa, ni o lọ lori ekun rẹ, to si n dupẹ lọwọ Ọlọrun lẹyin ti wọn ti yọọ tan.
Iroyin yiyọ ti wọn yọ Gedoni yii lo gbomi loju Khafi bi ẹni ọfọ ṣẹ, bo tilẹ jẹ pe o gbiyanju lati maṣe da omi loju.
Nigba to n sọrọ lẹyin ti wọn yọ tan, Gedoni wi pe, ọpọlọpọ ẹkọ ni oun ti kọ ninu ile Big Brother.
Oríṣun àwòrán, khafibbn_officialfanpage
O tẹ siwaju pe, ọkan oun fa si Khafi, ti oun si nifẹ rẹ nitori pe Khafi jẹ ẹni ti kii dibọn, ti kii si hu iwa oniwa.
Gedoni salaye siwaju pe, oun ko ni ifẹ si Venita rara, sugbọn khafi nikan ni ọkan oun fa si.
Oríṣun àwòrán, khafibbn_officialfanpage
O wa pari ọrọ rẹ pe o ṣeeṣe ko jẹ pe Mike lo maa jawe olubori ninu idije Big Brother naa.
Jackye ni tirẹ sọ pe, yoo jẹ didun inu oun to ba je pe Mercy lo maa jawe olubori ninu idije Big Briother naa.
Seyi Makinde: Ìyá Akurẹ àti Iya Ibadan kìlọ̀ fún mi lóru ọ̀gànjọ́ làti sọ́ra fún olóṣèlú
Oríṣun àwòrán, @seyiamakinde
Awọn eniyan rere lee darapọ mọ ẹgbẹ oṣelu
Ogbẹni Seyi Makinde, gomina ipinlẹ Ọyọ ti sọ pe, bi oun ṣe jawe olubori ninu idibo to kọja jẹ ore-ọfẹ Ọlọrun.
Makinde salaye pe iya oun ko fẹ ki oun lọwọ ninu eto oṣelu orilẹ-ede Naijiria rara, nitori igbagbọ awọn eniyan pe awọn oloṣelu kii ṣẹni ire.
Gomina Makinde sọrọ yii nigba to n ṣe idupẹ agbole ni ijọ Aguda Dafidi Mimọ, ti o wa ni Ijọmu, ni ilu Akurẹ, ni ipinlẹ Ondo.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí:
"O ni oun ko ni baba isalẹ ninu ẹgbe PDP ayafi Ọlọrun ọba. O sọ siwaju pe "" Bi mo ṣe duro niwaju yin yii, mo jẹ ẹni ti o de ipo gomina lai ni baba isalẹ, afi Ọlọrun nikan ṣoṣo."""
"Nigbati mo fẹ bẹrẹ sii kopa ninu eto oṣelu, awọn iya mi mejeji, iya Akurẹ ati iya Ibadan pe mi loru ọganjọ, wọn si kilọ fun mi lede Akure ati ni ede Ibadan pe, ti awọn oloṣelu ba fun mi ni ohun kohun, mi o gbọdọ gbaa."""
Wọn sọ eyi nitori igbagbọ wọn pe ẹni ire kan kii sẹgbẹ oṣelu.
Oríṣun àwòrán, @seyiamakinde
Mo jẹ ẹni ti o de ipo gomina lai ni baba isalẹ kankan, afi Ọlọrun Ọba
Sugbọn bi mo ṣe wa niwaju yin bayi, mo lee sọ kedere pe, ẹni ire lee darapọ mọ eto oṣelu.
Oluṣọ agutan ati oniwaasu nibi idupẹ naa, Simeon Borokini, wa rọ gomina Makinde lati mojuto ọrọ ọgbin, lọna lati gbogun airiṣẹ awọn ọdọ.
Ibadan Obaship Tussle: Mọ́gàjí Ibadan ní ìjoba ló da ọ̀rọ̀ lọ́balọ́ba rú
Oríṣun àwòrán, Facebook/Olubadan of Ibadan
O da bi ẹni pe awuyewuye lori awọn Ọba ilu ibadan ko tii loju tu, lẹyin ti ọkan lara wọn, Ọba Lekan Balogun ṣalaye fun BBC Yoruba wi pe ofin nikan lo le yọ awọn nipo gẹgẹ bi ọba ni ilu lbadan.
O ṣalaye pe ofin lo gbe awọn de ori oye fun iparapọ ati ilọsiwaju llu lbadan.
Ọba Lekan Balogun sọ pe ko si aawọ kankan laarin Olubadan ati awọn ọba yoku nitori idagbasoke ilẹ lbadan lo jẹ onikaluku logun.
O fikun ọrọ re wi pe ''ọjọ mẹẹdogun-mẹẹdogun ni a maa n ṣe ipade pelu Olubadan.
Ninu alaye rẹ, o sọ siwaju sii pe ''ori ni Olubadan jẹ fun awọn ọba, bẹẹ ni wọn ko si le di iru laelae.''
Ninu ọrọ tiẹ, Mogaji ilu Ibadan, Alhaji Moshood Atẹrẹ sọ wi pe, enikeni ko ti i le sọ pato ibi ti ọrọ naa nlọ.
Oríṣun àwòrán, Facebook/Olubadan of Ibadan
Mogaji ilu Ibadan ṣalaye pe lati ọjọ ti ijoba ti tọwọ bọ ọrọ awọn lọbalọba niluu lbadan lọrọ naa ko ti lojutu mọ.
O fi kun ọrọ rẹ pe ijọba kan ti ọwọ bọ ọrọ naa ni, awọn ọba llu lbadan ko ṣetan lati gbe ade wọn silẹ.
Mọgaji llu lbadan sọ pe oye ''His Imperial Majesty'' ti wọn fi n pe Oluban ko ni ohun kan ṣe pẹlu ọrọ to wa nilẹ yii.
Japan visit: Iléeṣẹ́ ààrẹ ní ẹgbẹ́ IPOB kò tako Buhari ní Japan
Oríṣun àwòrán, Twitter/Bashir Ahmad
Irọ funfun balau ni iroyin kan to n tan kaakiri lori ayelujara pe awọn ọmọ ẹgbẹ IPOB ti wọn yabo igbakeji ile igbimọ aṣofin agba l'Abuja tẹlẹ, Sẹnẹtọ Ike Ekweremadu lorilẹede Germany ṣewọde lati tako Aarẹ Muhammadu Buhari nigba to gunlẹ si orilẹede Japan lọjọ Aje.
Oludamọran pataki fun aarẹ lori ọrọ iroyin, Femi Adesina lo sọ fawọn ọmọ Naijiria nile ati nilẹ okere pe iroyin ofege lawọn kan n gbe kiri.
Ọgbẹni Adesina ni awọn ọmọ ẹgbẹ IPOB ko ni ohun kan ṣe pẹlu Aarẹ Buhari lati igba to ti de si ilu Yokohama lorilẹede Japan.
Femi Adesina ni awọn ma ri ma sọ eeyan kan lo gbe iru iroyin yii kiri pẹlu ayederu fọnran lati tan ọpọlọpọ jẹ.
Oludamọran aarẹ kilọ fawọn to n gbe iroyin ofege kiri pe ki wọn jawọn lapọn ti ko yọ nitori ọrọ Naijiria ti kọja iru iwa bẹẹ.
O ni Buhari ṣetan lati ṣe nnkan iwuri fun gbogbo ọmọ Naijiria nibi apero to da lorim igbasoke ilẹ Afirika ẹlẹẹkeje iru rẹ  TICAD7.
Gomina ipinlẹ Eko, Kwara, ati Borno lo kọwọ rin pẹlu aarẹ lọ si orilẹede Japan.
Seun Fakorede: Iṣẹ́ tí Seyi Makinde rán mi nipínlẹ̀ Oyo níkan ní màá jẹ́
Oríṣun àwòrán, @seyiamakinde
Seun Fakorede ẹni ọdun mẹ́tàdínlọ́gbọ̀n tí gómìnà ìpínlẹ̀ Oyo ṣẹ̀ṣẹ̀ yàn bíi Kọmísọna fún ìròyìn àtí eré ìdáráya ti ní, ẹní ran ni níṣẹ́ làá bẹ̀rù, à kìí bẹ̀rù ẹní tí àà jẹ fún.
Lásìkò tó ń dáhun ìbéèrè lórí ọ̀nà ti yóò gbà láti kóju àwọn agbààgbà nílé iṣẹ́ tí yóò maa darí pàápàá jùlọ àwọn àdari àti akọwe àgbà ilé iṣẹ́ náà tí òmíràn tilẹ̀ le bíi lọ́mọ́.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí:
Fakorede ní ọ̀rọ̀ náà dàbi ẹni ti wọ́n fi ọ̀pá àṣẹ ọba rán níṣẹ́ ni, ọ̀wọ̀ ọpá àṣẹ́ ọba ni wọ́n gbọdọ̀ máa fi wọ òun.
Oríṣun àwòrán, @seyiamakinde
O fikun pe kìí ṣe gbogbo ẹní to ba kéré lọ́jọ́ orí náà ni ọpọlọ rẹ̀ kéré, nítorí náà, tọ̀wọ̀-tọ̀wọ̀ ní òun yóò máa fi ba gbogbo àwọn àgbààgbà ilé isẹ̀ náà ṣe.
Kọmisana tuntun naa  ní orílẹ̀ èdè Nigeria jẹ́ ibi ti ìbọ̀wọ̀ fún ni ti ṣe pàtàkì, tí òun si ti ṣetan láti rii dájú pé òun ṣe ojúṣe oun botitọ́ àti botiyẹ, àti bibọwọ fun gbogbo ẹni tó ba tọ pẹ̀lú ìrẹ̀lẹ̀.
Seun fakorede ní pàtàkì júlọ, isẹ́ ti gomìnà Ṣeyi Makinde gbé lé òun lọ́wọ́ ló ṣe pàtàkì júlọ ti òun si ti ṣetan láti ṣee dé ojú àmìn.
Seun Fakorede di kọmísánà ní ìpínlẹ̀ Oyo
O ni ti gbogbo àwọn àgbààgbà ilé iṣẹ́ ijọba ti wọn pin oun si bá ni ìfẹ́ ìpínlẹ̀ Oyo lọ́kàn, kò sí ẹni ti yóò ṣe ọ̀tẹ̀ bíkòṣe pe kí wọ́n fọ́wọ́sowọ́pọ̀ pẹ̀lú oun fún àṣeyọri.
Minimum Wage: Alága òṣìṣẹ́ Ekiti ní òǹyẹ̀ kò leè yẹ sísan ₦30,000 owó oṣù
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Alága ẹgbẹ́ òṣìsẹ́ ìpínlẹ̀ Ekiti, Kolapọ Olatunde ti kéde pé ,ìjọba àpapọ yóò san ẹgbẹ̀rún lọna ọgbọn náírà owó oṣù òṣìsẹ́ tó kére jùlọ losù kẹ́sàn ọdún yìí.
Olatunde sàlàyé èyí nílu Ado -Ekiti, lásikò tó fi n dá àwọn àkọroyin lójú pé, kò sí ǹkan tó le yẹ aigbowó osù fáwọ́n òṣìṣẹ́ nínú ọ̀ṣẹ̀ àkọ́kọ́ nínú òṣù tọ ń bọ̀ yìí.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí:
O fí kún pé àwọn atúnṣe kan to yọjú tí ẹgbẹ́ òṣìṣẹ́ ń gbíyànjú láti ṣe àtúnto rẹ, ló fa ìdádúró sísàn owó náà.
Alaga ẹgbẹ́ òṣìṣẹ́ tún sàlàyé pé, atunyàn Chris Ngige sípò mínísítà fún ọ̀rọ̀ òṣìṣẹ́, jẹ́ kó mú ọ̀rọ̀ owó òṣìṣẹ́ ni òkúnkúndùn láti rii pe ó di sísàn.
Minimum Wage: Owó oṣù òsìṣẹ́ tó kéré jùlọ yòó dí sísan nínú osù kẹ̀sán
Ọ̀pọ̀ ìgbà ní ìjọba àti àwọn olórí òṣìsẹ́ ti jà túka lái fẹ́nu ọ̀rọ̀ jọ́nà lórí owó òṣìsẹ́ tó kére jùlọ.
COZA RAPE: Ilé ọlọpàá ìlú Abuja pé Fatoyinbo fún ìfọ̀rọ̀wánilẹ́nuwò
Busola Vs Fatoyin: Ilé ọlọpàá ìlú Abuja ti pé Fatoyinbo fún ìfọ̀rọ̀wánilẹ́nuwò
Olùṣọ́-àgùntàn Biodun Fatoyinbo ti ìjọ Commonwealth of Zion Church tí fára rẹ̀ sílẹ̀ ní ilẹ̀ ọlọpàá fún ìfọ̀rọ̀wánilẹ́nuwò lóri èsùn ìfipábánilòpọ̀ Busola Dakolo fí kàn -àn.
Sááju ni Fatoyinbo ti ran àwọn asojú rẹ̀ lọ sí olú ilé iṣẹ́ ọlọpàá ẹka CID tí ìlú Abuja.
Ó ṣeeṣe kí Fatiyinbo pẹ́ díẹ̀ ní ibá ìfọ̀rọ̀wánilẹ́nuwò yìí lágọ̀ọ́ ọlọpàá nítori irú ìfọ̀rọ̀wánilẹ̀núwò yìí gba àwọn Dakólò ní wákàti mẹ́jọ gbáko kí wọ́n to pari.
Èyí wáyé lẹ́yin ọ̀pọ̀ ọ̀sẹ̀ díẹ̀ tó Fatoyinbo ti kọ̀ láti fóju han ní àgọ́ ọlọpaàá lẹ́yìn ti wan ránṣẹ́ pèé fún ìfọ̀rọ̀wánilẹ́nuwò.
Bakan náà ní ẹgbẹ́ tó n ri sí ìjọ ìgbàlóde (PFN) sọ lọ́sẹ̀ tó kọ́ja pé ó kọ̀ láti yoju sí ìpáde ti àwọn pèé sí fún ìfọ̀rọ̀wánilẹ́nuwò.
Dangote-BRT Accident: Lasema ní ìjánu ọkọ̀ Dangote tó já ló fa ìjàǹbá náà
Oríṣun àwòrán, Lasema
Gẹ́gẹ́ bi olùdari LASEMA Osanyintolu Oke ṣe sọ pé kò sí ẹni ti kò farapa nínú ọkọ náà àfi ọmọbinrin kan ló pàdánu ẹmi rẹ̀.
Ilé iṣẹ́ tó ń móju tó ìṣẹ̀lẹ̀ pàjáwírì nípinlẹ̀ Eko (LASEMA) ní ọkọ̀ akẹ́run Dangote tó kún fún simẹnti, ní ìjánu rẹ̀ dédé já, tí o si lọ kọlu ọkọ èrò BRT to kó èrò ọgọta lópóna Ikorodu.
Ọkọ̀ BRT pẹ̀lú  nọmbá LSR-228 XS ọhun to forisọri pẹlu ọkọ simẹnti ní gbogbo èrò inú rẹ̀ ní ifarapa kan tábi òmiràn ti ẹsẹ̀ dẹ́rẹ́bà náà sí gé pátápátá.
Apapọ awọn ero to fara gbọgbẹ ninu ijamba naa ni mọkandinlọgọta, ti eeyan kan si gbẹ mi.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí:
Gẹ́gẹ́ bi olùdari LASEMA  Osanyintolu Oke ṣe sọ, kò sí ẹni ti kò farapa nínú ọkọ náà àfi ọmọbinrin kan ló pàdánu ẹmi rẹ̀.
Oríṣun àwòrán, Lasema
Ọkọ̀ akẹ́rùn Dangote rọ́lu ọkọ̀ Ikorodu
O fí kun pé, gbogbo àwọn osisẹ eleto alabò àti àwọn ẹṣọ́ ojú pópó pátápátá lo ti péju síbi ti isẹlẹ naa ti waye, láti ri dáju pé awọn to farapa ri ìtọ́ju àti láti mú ìgbòkegbodo ọkọ̀ rọrùn lágbègbè náà.
Online VAT: Sísan owó orí ọjà lórí ayélujára yóò mú kí ọrọ̀ ajé rú gọ́gọ́ si
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ajọ to n pawo wọle labẹle labẹ ijọba apapọ (FIRS) ti kede pe, oun yoo bẹrẹ si ni gba owo ori VAT, lori awọn ọja ti awọn ọmọ Naijiria ba ra lati ori ayelujara.
Igbesẹ sisan owo ori naa ni wọn sọ pe yoo bẹrẹ losu Kinni ọdun 2020, ti yoo si kan awọn ọja ti wọn ba ra lori ayelujara labẹle ati ni oke okun.
Babatunde Fowler, tii se alaga fun ajọ FIRS lo kede ọrọ yii nibi ipade apero kan to waye nilu Abuja.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí:
Fowler ni ọpọ awọn orilẹede lo ri ilẹ wa Naijiria bii ọja nla ti wọn ti lee se okoowo wọn lori afẹfẹ, idi si ree ti Naijiria naa fi gbọdọ lo anfaani yii lati pawo wọle.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Owo ori ọja jẹ ọna kan gboogi to n mu owo wa fun awọn orilẹede nilẹ adulawọ, to si maa n ko ida mọkanlelọgbọn ninu ọgọrun owo to n wọle nigba miran, eyi gan pọ ju iye ti ajọ to wa fun idagbasoke ọrọ aje n ri lọ tii se ida ogun ninu ọgọrun.
Amọ sa, Fowler ni asẹ wa lọwọ ijọba apapọ ti igbesẹ gbigba owo lori awọn ọja ti wọn ba ra lori ayelujara naa, yoo ba di ohun.
Olubadan: Aáwọ̀ ń parí láàrín ìgbìmọ̀ lọ́ba-lọ́ba nílẹ̀ Ibadan
Dukuu to n jẹyọ laarin Olubadan atawọn agba oye ti ijọba ana ni ipinlẹ Ọyọ gbe ade le lori, n ṣebi eyi ti n jẹ rodo lọ momi bayii.
Ni ọjọ Aje ni awọn agba oye to jẹ igbimọ Olubadan lọ ṣe baba kẹẹ pẹ si Olubadan laafin rẹ ni Popoyemọja nilu Ibadan, lasiko ayẹyẹ to fi n sami  ọjọ ibi ọdun kọkanlelaadọrun rẹ loke erupẹ.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí:
Pataki ohun toju ri nibi abẹwo wọn naa ni pe awọn agba oye naa ko wa pẹlu ade wọn, ti wọn si dọbalẹ gbalaja lati ki Olubadan.
Lara awọn agba oye mẹsan ilẹ Ibadan, mẹfa lo wa nibi abẹwo naa. Iyẹn Otun Olubadan, Lekan Balogun ati Balogun Owolabi Olakulehin.
Awọn yoku ni Osi Balogun Tajudeen Ajibola; Asipa Olubadan, Eddy Oyewole; Ekarun Olubadan Amidu Ajibade ati Ekarun Balogun Kola Adegbola.
Nibẹ ni wọn ti darapọ mọ awọn agba oye yoku bii Iyalode ilẹ Ibadan, Oloye Theresa Oyekanmi; Agbaakin Olubadan, Lekan Alabi atawọn Mọgaji ati Baalẹ.
Laipẹ yii ni iroyin gbe e pe, awọn agba oye ti wọn gbe ade le lori naa ti fi igba kan faake kọri pe, ko sẹni to lee gba kanbo lọwọ imu, ko si ẹni to lee gba ade naa lori awọn.
Sugbọn Olubadan ko dẹkun ipe rẹ pe gbogbo awọn agba oye naa lo gbọdọ gbe ade wọn silẹ nitori ọba meji kii wa ni aafin.
Ọpọ lo ti n ri igbesẹ ọjọ Aje naa gẹgẹ bii eyi ti o n ṣe afihan pe, alaafia ti n pada si aarin igbimọ lọbalọba ilu Ibadan.
Ondo Murder: Awọn ọlọ́pàá kò tíì mọ ibi tí wọn sin òkú ọmọ náà sí
Oríṣun àwòrán, sunshinetruth.com.ng
Arabinrin kan ti wọn fi ẹsun kan pe oun ati ọkọ rẹ lu ọmọ wọn pa, ti wa ni ahamọ awọn ọlọpaa bayii.
Iroyin sọ pe Testimony, ọmọ ọdun mẹrin ti wọn lu pa, ni wọn gbe lọ si ileewosan ijọba to wa nilu Akurẹ lọjọru ọsẹ to kọja pẹlu oniruru apa lara rẹ.
Nile iwosan si ni awọn dokita ti jẹ ko ye wọn pe oku ni ọmọ naa, ki wọn to gbee de ileewosan.
Lati igba naa ni awọn ọlọpaa ti bẹrẹ si ni tọ ipasẹ tọkọ-taya naa, ṣugbọn ti wọn lọ fi ara pamọ si ilu Ikarẹ Akoko.
Gbogbo ilakaka awọn ọlọpaa lati mu wọn ni ilu Ikarẹ lo ja si pabo pẹlu bi awọn iroyin kan ṣe sọ pe, awọn eeyan ilu naa ko gba awọn ọlọpaa laaye lati ṣe iṣẹ wọn, nigba ti wọn lọ lati mu tọkọ-tiyawo naa.
Oríṣun àwòrán, @PoliceNG
Bi o tilẹ jẹ wi pe ileeṣẹ ọlọpaa ni ko si ohun to jọ bẹẹ, amọṣa wọn ni arabinrin naa ti wa ni ọdọ ọlọpaa.
Alukoro ileeṣẹ ọlọpaa ni awọn ko tii ri oku ọmọde naa ati wi pe, o ṣeeṣe ki awọn lọkọlaya naa ti sin oku rẹ.
Jollof rice: Ṣé lóòtọ́ ni ìrẹsì jọ̀lọ́ọ̀fù Ghana dùn ju ìrẹsì jọ̀lọ́ọ̀fù Nàìjíríà lọ?
Oríṣun àwòrán, @EarlJoey_.
Kii ṣe ana ni ariyanjiyan laarin awọn eeyan, paapaa julọ, awọn ọmọ orilẹede Naijiria ati Ghana ti n waye lori irẹsi jọlọọfu ẹni to dun julọ ninu ti orilẹede mejeeji.
Amọṣa, ariyanjiyan naa n dabi eyi ti wọn ti wa ojutu si bayii lẹyin ti alase ọmọ ọdun mẹrinlelogun kan lati orilẹede Ghana, Sika Mortoo, fi ajulọ han akẹgbẹ rẹ lati orilẹede Naijiria, nibi idije ase kan to waye.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí:
Idije Onga Jollof Battle to waye lopin ọsẹ to kọja nilu Accra laarin awọn alase meji naa lati mọ orilẹ€de ti irẹsi jọlọọfu rẹ dun julọ.
Gbajugbaja ounjẹ, ari ma lee lọ ni irẹsi jọlọọfu ni ẹkun iwọ oorun Afirika eyi ti wọn maa n fi irẹsi, tomato atawọn eroja miran ṣe.
Oríṣun àwòrán, PrOMAISODOR GHANA
Ilumọọka ni irẹsi jọlọọfu laarin awọn  ọmọ orilẹede bii Senegal, Ghana, Naijiria, Gambia, Sierra Leone, Liberia ati cameroon.
Fun ọdun diẹ sẹyin bayii ni ariyanjiyan ti n waye laarin awọn ọmọ Naijiria ati Ghana lori ikoko irẹsi jọlọọfu to ṣee jẹ ni ajẹpọnula julọ laarin orilẹede mejeeji.
Oríṣun àwòrán, PrOMAISODOR GHANA
Lẹyin ti awọn adajọ ṣe itọwo abọ irẹsi jọlọọfu ti wọn gbe wa, awọn mẹtẹẹta lo panupọ ṣalaye pe irẹsi jọlọọfu ti ghana lọba.
Orilẹede Ghana, Naijiria ati South Africa ni awọn adajs nibi idije naa ti wa.
Sika Mortoo to gbe igba oroke nibi idije ase naa  gba ẹbun owo ẹgbẹrun meji dọla ($2000), ọmọ Naijiria to baa dije, Chef Turay, naa si gba Ẹgbẹrun kan dọla ($1000).
Gboyega Oyetola: A ṣetán láti pèsè ọkọ̀ oun ìjà fún ilẹ Yorùbá
Oríṣun àwòrán, Google
Ìjọba ipnlẹ Òsun ní kò sí òṣìṣé tí kò ní gba owó oṣu rẹ pé ní Ipínlè Ọsun .
Gomina lpinle Osun, Gboyega Oyetola  ti ṣalaye wi pe ijọba ipinlẹ Osun  ti ṣe tan lati ṣe atilẹyin fun ipenija to ba eto aabo ni ilẹ yii.
Gomina Oyetola sọ siwaju wi pe ọkọ ijagun ti ko din ni ogun ni ijọba ipinlẹ naa yoo fi ṣe atileyin latari idasilẹ ajọ tuntun fun eto abo ilẹ Yoruba.
Oyetọla sọ ọrọ yii lasiko ayẹyẹ ọdun mejidinlọgbọn ti wọn da ipinlẹ naa silẹ,O ni eto aabo ilẹ Yoruba jẹ Ohun logun.
Gẹgẹ bii alaye re, O ni, irọrun igi ilẹ Yoruba ni irọrun ẹyẹ ipinlẹ Osun, lojuna lati daabo bo dukia ati ẹmi awọn eniyan ilẹ Yoruba lapapọ.
Ìpinlẹ Òsun pé ọmọ ọduń méjìdínlógbọn, àsantán owó osù ti bèrè!
Gomina lpinle Osun, Adegboyega Oyetola ti ba awọn ọmọ ipinlẹ naa yọ latari pipe ti ipinlẹ naa pe ọdun mejidinlọgbọn.
Ninu ọrọ rẹ si awọn ọmọ ipinlẹ naa ni ọjọ Aje nibi ti o ti salaye wi pe, ayẹyẹ naa pe fun ibara ẹni yọ, sugbọn ni pẹlẹkutu ni ljoba yoo sẹ.
O sẹ alaye wi pe, arọ ipinlẹ naa fẹ jo,sugbọn ẹsẹ ni ko ni, latari aisi owo lati fẹ ayẹyẹ naa loju.
Nigba ti oun gbe osuba kare fun awọn asaaju lpinlẹ naa, ni pataki, awọn gomina ana ninu eyi ti o ka ijọba ana kun ti o pe ni'' ifẹsẹ mulẹ to muna doko''ninu eyi ti awọn to ku n gunle.
Oyetọla ko ṣai fẹnu ba a wi pe awọn eniyan ipinlẹ naa jẹ akinkanju, olufẹ aṣa ati ẹni ti igbagbọ wọn ranmọ oye awón baba n la wọn fun nini lpinlẹ ''Ọmọluabi''
Gomina naa sọ wi pe gbogbo eto isejọba lpinlẹ naa lo da lori oun ti ara ilu n fẹ. ti o si ṣe afihan rẹ nigba ti o ṣe abẹwo si llu kọọkan lati mọ oun ti wọn fẹ.
Ko ṣai gbe ọrọ rẹ lẹsẹ pẹlu ipa ti ajọ United Nations ti o wa fun idagbasoke ilu ti ko lori lpinlẹ naa.
Oyetọla ṣalaye siwaju sii pe,ijọba oun yoo maa san ẹkunrẹrẹ owo oṣu awọn oṣiṣẹ deede.
Gomina lpinle Osun naa yoo tun kọ si ile iwe, ati lati tun ọpọlọpọ ṣe. O ni kikọ yara ikawe oloju mẹrin,marun un, ati bẹẹbẹẹ lọ ko ni jẹ iṣoro fun ijọba Oun.
#Revolution Now: Ara ló ń ta ìjọba àpapọ lórí ìfèhọnú hàn ní Naijiria
Comrade Sulaiman Adeniyi ti ni o lodi si ofin bi ijọba se n tako itusilẹ Ọmọyele Sowore to ti wa ni ahamọ DSS.
Awọn ẹgbẹ ajafẹtọ ọmọniyan ti ko din ni metalelaadọta ni wọn ti ṣetan bayii lati fi ehọnu han ni Ọjọ Karun un, Oṣu Kẹsan, ọdun yii.
Oludari fun alakoso egbẹ ajafẹtọ Coalition of Human and Civil Rights Organizations(COHCRO) Comrade Sulaiman Adeniyi lo sọ eyi lasiko to n ba  ikọ ile isẹ BBC Yoruba sọrọ.
Comrade Adeniyi ni gbogbo eto lo si ti to fun ifẹhọnu han naa latari ifiyajẹni lọna aitọ ti ijọba apapọ gunle fun Oludari ikọ Revolution Now, Omoyele Soworẹ.
Sulaiman Adeniyi tẹsiwaju pe, yoo tun jẹ ọna kan pataki lati ṣe iranti ọdun kẹwa ti oloye Gani Fawehinmi di oloogbe.
Ninu ọrọ rẹ, Sulaiman Adeniyi sọ wi pe, ko si ohun ti yoo yẹ ẹ ọjọ ifẹhọnu han lati ma se waye, nitori mani gbagbe ni yoo jẹ.
Oludari fun alakoso egbẹ ajafẹtọ Coalition of Human and Civil Rights Organizations(COHCRO) fikun pe ara lo n ta ijọba apapọ nitori aiṣe deede wọn pelu ara ilu, nipa pipese ohun to tọ, to  si yẹ fun mutumuwa.
Afe Babalola: Adarí Nàíjíríà kankan kò leè ṣàṣeyọrí pẹ̀lú òfin ọdún 1999
Oríṣun àwòrán, @hartarmah1
Agba amofin nni, Afẹ Babalọla ti kede pe ofin ti orilẹede Naijiria n lo lọwọlọwọ bayii ko kun to, to si mẹhẹ lati yanju oniruuru isoro to n ba orilẹede yii finra.
Ilu Ado Ekiti ni Afẹ Babalọla ti woye ọrọ yii lasiko ti ajọ isọkan ilẹ Afirika n fi oye Awokọse rere nilẹ Afirika da lọla.
Babalọla ni ofin ilẹ wa tọdun 1999 jẹ adina fun eto idagbasoke ati ilọsiwaju Naijiria taa ba wo ọpọ kudiẹ-kudiẹ to wa ninu amulo ati amusẹ rẹ.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí:
O ni yoo nira pupọ, ti yoo si jẹ isoro nla fun eyikeyi adari orilẹede Naijiria lati se aseye ti alakan n se epo lori aleefa, ta ba si n lo ofin naa, pẹlu afikun pe ofin ọdun 199 kogbewọn to fun irufẹ akanda orilẹede ti Naijiria jẹ.
Babalọla ni ayafi ti a ba gbe igbesẹ akin lati mu ayipada ba ofin ọdun 1999 naa, se ni ọps aayan wa lati se aseyọri yoo maa ja si asan.
Oríṣun àwòrán, @hartarmah1
Bakan naa ni agba amofin yii tun woye pe, ba se n pe ofin ilẹ wa naa ni 'ofin apapọ Naijiria' jẹ eyi ti ko bojumu to, nitori ofin to wa fun igun kan ni.
Afẹ Babalọla wa rọ aarẹ Muhammadu Buhari lati pe ipade apero apapọ awọn ọmọ Naijiria, ta si mu awọn asoju lai lo ẹgbẹ oselu kankan.
O ni nibi ipade yii ni wọn yoo ti gbe ofin kalẹ fun Naijiria eyi ti yoo foju sun idagbasoke awọn ọmọ orilẹede yii.
Nigeria Debt: Gbèsè Nàíjíríà yóò pòórá, tí ìkọ̀ọ̀kan ọmọ Naijiria bá san ₦121,000
Oríṣun àwòrán, PIUS UTOMI EKPEI
Minisita feto isuna ati aato, Udoma Udo Udoma, lasiko ipade awọn ọmọ igbimọ alasẹ apapọ ni, ko si orilẹede ti kii jẹ gbese, ti aayan si n lọ lati se afikun owo ori araalu.
Bakan naa ni minisita feto ẹnawo, Zainab Ahmed kede pe gbese tilẹ Naijiria jẹ ti fo lati triliọnu mọkanlelogun ati biliọnu okoolelẹẹdẹgbẹrin ati marun naira (₦21.725trn) to wa lọdun 2017 si triliọnu mẹrinlelogun ati biliọnu lọna irinwo naira din diẹ ( ₦24.387trn) lọdun 2018.
O salaye pe gbese Naijiria lọ soke lọna ati mu ki ọrọ aje lowura, ko si tun lagbara si bi o tilẹ jẹ pe awọn araalu ko tii le foju rii.
Iwadi si fi han pe owo to to triliọnu meji ati biliọnu lọna ogoje naira (₦2.14trn) ni ijọba n na lati san ele lori awọn gbese naa lọwọ-lọwọ.
Amọ laipẹ yii ni ijọba apapọ kede pe ko sewu loko afi giri aparo nipa gbese ti orilẹede wa Naijiria jẹ silẹ okeere.
Eyi si lo mu ki oju opo ayelujara maa gbona lori bi awọn ọmọ Naijiria se n gbarata, lori bi gbese tilẹ wa jẹ se n fi ojoojums fo lọ soke.
Koda awọn eeyan kan tiẹ se alaye pe, niwọn igba ti a mọ iye eeyan to jẹ ọmọ orilẹede Naijiria, ti wọn jẹ miliọnu lọna igba eeyan, ti gbese wa si jẹ triliọnu mẹrinlelogun ati biliọnu lọna irinwo naira din diẹ ( ₦24.387trn).
Wọn ni ta ba pin iye gbese yii le ori ọmọ Naijiria kọọkan, a jẹ pe gbese okoolerugba ati ẹyọ kan naira (₦121,000) lo wa lori ọmọ Naijiria kọọkan ti yoo san.
Lero tawọn eeyan yii, wọn ni owo yii ko pọ rara fun ikọọkan ọmọ Naijiria lati san, ka lee fagile gbese ti ilẹ wa jẹ, ka si wa lai ni gbese lọrun, eyi ti yoo fun wa ni anfaani ọtun lati mu ki ọrọ aje wa ru gọgọ si.
Eyi lo wa mu ka maa beere pe, se ẹ setan lati san gbese tiyin tii se ₦121,000?
Ilé Aṣòfin Eko: A fẹ́ mọ̀ bí Ambode ṣé nà ₦45b tó fi ra BRT
Oríṣun àwòrán, Lagos Eye News
Igbimọ ti Ile Aṣofin ipinlẹ Eko gbe kalẹ lati ṣe iwadii lori bi Gomina ana nipinlẹ naa, Akinwunmi Ambode, ṣe na owo lati ra ọkọ akero BRT, ti wi pe, iwadii wọn kii ṣe lati dẹyẹ si gomina ana ọhun.
Fatai Mojeed, ẹni tii ṣe alaga igbimọ naa sọ ninu ifọrọwerọ rẹ pẹlu BBC pe, iwadii ti wọn n ṣe nipa bi Ambode ṣe na owo lori awọn ọkọ akero naa jẹ ojuṣe awọn aṣofin ipinlẹ Eko.
O ṣọ ninu ọrọ rẹ pe, ko si ẹtanu kankan ti wón ni si Ambọde, ẹni ti o ṣe ijọba ni ipinlẹ Eko laarin ọdun 2015 si 2019.
"Fatai wi pe, ""Kii ṣe pe awọn aṣofin n dẹyẹ si Ambode, sugbọn ojuṣe wa la n ṣe gẹgẹ aṣofin."""
Ile aṣofin ipinlẹ Eko ti ṣe agbekalẹ igbimọ kan lati ṣe iwadii bi Gomina ana nipinlẹ naa, Akinwumi Ambode ṣe na biliọnu marundinlaadọta naira to fi ra ọkọ akero .
Lọjọ Iṣẹgun ni ile panupọ pe, o di dandan lati wadi kulẹ kulẹ nipa bo ṣe jẹ ọkọ okolelẹgbẹrin (820) ni ijọba Ambode ra dipo ẹgbẹrun marun un ọkọ̀ (5000) ti o daba.
Bakan naa ni wọn ni ile nigba naa, lodi si rira awọn ọkọ akero yii.
Aṣofin Gbolahan Yishawu, to n ṣoju ẹkun idibo Eti Osa keji lo daba yii, to si sọ pe ijọba daba lati na biliọnu mẹtadinlogun naira (₦17b) lati ra awọn ọkọ wọn yii, ninu aba isunna ọdun 2017 ṣugbọn ile ko buwọlu.
Oríṣun àwòrán, @APCNigeria
O ni ''ninu aba isunna ọdun 2018 ati ti 2019 ijọba daba lati na biliọnu mẹrinlelogun ati biliọnu meje naira lori awọn ọkọ wọn yii, amọ ile ko fọwọ si nina owo yi''
Yishau tẹsiwaju pe ''tohun ti bẹẹ, ijọba gbe ọkọ okoolelẹgbẹrin (820) wọle lati oke okun ni biliọnu meje naira, to si jẹ pe ọkọ okoolelẹẹdẹgbẹta (520) ninu awọn ọkọ yii ṣi wa ni ibudoko ọkọ oju omi.'
Eyi to tumọ̀ si pe ọọdunrun ọkọ BRT pere lo fi owo naa ko wọ ilu, tawọn eeyan fi oju ri.
Nkan ko fẹ ṣẹnu re fun Gomina ana Akinwumi Ambode lati igba to ti kuro lori alefa nipinlẹ Eko
Lẹnu lọọlọ yii, Gomina tẹlẹri Ambode ti n koju awọn ipenija lọdọ awọn agbofinro paapaa julọ, lọdọ ajọ to n gbogun ti iwa jẹgudujẹra EFCC to yabo ile rẹ ni Epe.
Ki Ambode to kuro lori oye ni oun ati ile aṣofin ipinlẹ Eko ko ti gbọ ara wọn ye daadaa, ti iroyin si kan nigba naa pe wọn fẹ yẹ aga ni idi rẹ.
Ni nnkan bi ọsẹ mẹta sẹyin ni adajọ agba kan ni ki wọn gbẹsẹ le akoto owo ti biliọnu mẹsan naira wa ninu rẹ, eleyi ti wọn fura si pe o ni ohun ṣe pẹlu Ambode.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí:
Ambode ti tako ọrọ yi pe oun ko ni nkankan ṣe pẹlu akoto naa tabi owo to wa ninu rẹ.
Asofin Fatai Mojeed to n ṣoju Ibeju Lekki ni ile aṣofin Eko ni ko dari igbimọ ti yoo ṣe iwadii yi ti wọn si ni ko jabọ fun ile bi ọrọ ba ti ṣe ri.
Bakan naa ni olori ile paṣẹ ki wọn fiwe pe adari ile iṣẹ LAMATA to n ṣe eto awọn ọkọ akero to fi mọ awọn miran lati wa wi tẹnu wọn naa.
Sovereign Conference: Àwọn òǹwòye ní ìpàdé àpérò dára ṣùgbọ́n kò lè tàn ìṣòro Nàìjíríà
Oríṣun àwòrán, Others
Aisi ẹmi ootọ lọdọ awọn olori wa lo mu ki Naijiria ma lee tẹle abajade awọn ipade apero taa ba ṣe bayii, tabi eleyi ta ti ṣe kọja.
Eyi ni ero awọn agbejọro kan ni Naijiria kan ti wọn fesi si ipe kan ti agba amofin, Afe Babalola pe, eyi to ni ki aarẹ Buhari pe ipade apero apapo, taa mọ si 'Constitutional  Conference.'
Afe Babalọla ni asiko to lati wa wọrọkọ fi ṣada lori awọn ipenija to n koju Naijiria nitori ofin ọdun 1999 ta n lo mẹhẹ pupọ, to si daba pe ọna abayọ to wa nilẹ ni pipe ipade apero apapọ ilẹ wa.
Lero ti agbẹjọro Kanmi Ajibola, ipe yii jẹ eyi to tọ ṣugbọn ko daju pe yoo jẹ ọna abayọ si awọn ipenija to n koju Naijiria lọwọ.
Ajibola, to tun jẹ Kọmisana fun ajọ to n mojuto ẹtọ ọmọniyan, Human Rights Commission ni, ko si ẹmi ootọ lara awọn olori Naijiria lati ṣe amulo awọn aba fun irufẹ ipade bẹẹ.
Oríṣun àwòrán, others
''Ki a ṣe apero ju bẹẹ lọ, ko le dẹkun awọn aiṣedeede to wa ninu iwe ofin Naijiria. A ko ṣẹṣẹ ma ṣe apero, ko si le tan iṣoro wa bi awọn olori ko ba ṣetan lati ṣe amulo abajade wọn''
O ṣalaye pe ko boju mu bi awọn ẹya kan ti ṣe n da jẹ gbogbo mudunmudun ijọba awarawa, ti awọn to ku ko si ri anfaani ilu jẹ.
Ajibola ni awọn ikunsinu to n waye ko ṣẹyin pe pinpin ipo oselu laarin ẹkun kan si omiran, fi si apa kan ni Naijiria.
''Ipade apero gbọdọ ri pe wọn fi sinu iwe ofin Naijiria pe, ẹkun kọọkan to wa ni Naijiria (Geo political Zone) yoo ma ṣe ijọba lati igbadegba.
"Bi oke ọya ba ṣe ijọba, ki wọn tun gba awọn ẹkun miran laaye lati se bẹẹ pẹlu tori ẹnikan kii jẹ, kilẹ o fẹ."""
Ko si igba ti wọn ba pe ipade apero ti ko ni la owo lọ
Ọrọ Ajibola yii lo tun ṣe rẹgi pẹlu ti amofin James Ajibola to fi ilu Ibadan ṣe ibujoko.
Oríṣun àwòrán, Facebook/James Stephen Ajibola
Gbogbo awọn ipade apero ti a ti n ṣe bọ wa ko yatọ nipaṣe aba ti wọn n da
James Ajibola naa sọ pe, o ṣe pataki  lati ṣe apero ṣugbọn ohun to jẹ ẹdun ọkan ni pe ''oṣelu ni awọn ijọba Naijiria n fi ipade apero ṣe.''
''Ko ba ṣe wa lanfaani ti ijọba ba ṣe amulo aba ti wọn da lẹyin ipade apero to waye lasiko ijọba aarẹ Goodluck Jonathan, nitori pe awọn olori pipe lo joko se apero naa''
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ajibola ni iru iwa ki a maṣe tẹsiwaju pẹlu iṣẹ ti ijọba kan ba ṣe ku, lo n foju han lawọn ẹka ijọba lorisirisi ni Naijiria.
O ni ''Bi a ba ṣe iṣẹ ku, a ki fẹ pari rẹ nitori pe ijọba miran lo ṣe e. Bẹẹ naa la n ṣe nibi iṣẹ agbaṣe ti eleyi ko si jẹ ki idagbasoke ba Naijiria.''
Ekiti: Ọwọ́ ọlọ́pàá tẹ afurasí tó pa ìyàwò lárìnlọọ̀dù lẹ́yìn tó fipá bá a lòpọ̀
Oríṣun àwòrán, daily post
Ọwọ ọlọpaa ti tẹ arakunrin ẹni ọdun mọkandinlọgbọn kan ti orukọ rẹ n jẹ Tunmiṣe Abraham ti wọn fi ẹsun kan pe o gbẹmi obinrin onile rẹ lẹyin to fi ipa ba a lo pọ.
Ileeṣẹ ọlọpaa ni ipinlẹ Ekiti ni ọjọbọ to kọja ni iṣẹlẹ naa ṣẹ nilu Ado Ekiti.
Kọmiṣọna ọlọpaa ni ipinlẹ Ekiti, ọgbẹni Asuquo Mba ṣalaye pe, inu ile ijọsin kan ni ilu Akurẹ lọwọ ti ba Tunmiṣe lẹyin to kan si awọn mọlẹbi rẹ.
Kọmiṣọna Ọlọpaa Asuquo Mba ni ilu Akurẹ ni Afurasi naa sa lọ lẹyin to ṣe iṣẹ laabi naa ti o si lọ fara sinko si inu ṣọọṣi kan.
O ni o pe awọn mọlẹbi rẹ pe, oun pa eeyan kan ni oun ko fi lee pada wa sile mọ o.
Ọga ọlọpaa ni ẹnu ẹgbọn rẹ obinrin ni wọn ti gba iroyin gbogbo ti wọn fi tọpinpin rẹ de ibi to wa, bakan naa lo si ni Tunmise ti jẹwọ pe lootọ ni oun ṣẹ ẹsẹ naa ati pe ibinu lo faa.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Mba salaye siwaju pe Tunmise ni oun ko fipa ba oloogbe naa lopọ, arinyanjiyan lasan si lo ni o waye laarin oun ati arabinrin naa, to jẹ iyawo baba baba onile oun, Raphael Olanrewaju.
Tunmise salaye pe, iyawo larinlọọdu pe oun ni akalolo, alailẹkọ ati awọn orukọ miran ti ko ṣee gbọ seti ni oun ṣe paa.
O ni igi ti arabinrin yii fẹ la mọ oun lori ni oun gba lọwọ rẹ, ti oun si la a mọ leti.
Joint Security: Ọdẹ ìbílẹ̀, OPC, Aṣọ́gbó, ọlọ́pàá, ológun yóò máa pèsè ààbò nílẹ̀ Yorùbá
Ileesẹ ọlọọpa ipinlẹ Ogun ti fi idunnu rẹ han si idasilẹ ẹka eto aabo alajumose ni ilẹ Yoruba lati dẹkun ijinigbe ati ipaniyan.
Ọgbẹni Abimbọla Oyeyẹmi lo fi ọwọ idaniloju naa sọya nigba to n ba BBC Yoruba fọrọ jomi tooro ọrọ lori agbekalẹ ẹka aabo alajumọse nilẹ Kaarọ Oojire.
Bẹẹ ba gbagbe, iroyin kan ti tan kalẹ pe awọn gomina to wa lẹkun Guusu iwọ oorun Naijiria ti gba asẹ ni Abuja lati se agbekalẹ ẹka alaabo alajumọse ọhun.
Awọn ti yoo wa ninu igbimọ alaabo alajumọse naa ni awọn osisẹ ologun, ọlọpaa, aabo ara ẹni laabo ilu, asọgbo, ọdẹ ibilẹ, ọmọ ẹgbẹ Oodua (OPC) ati awọn osisẹ alaafia.
Oyeyẹmi salaye siwaju si pe eto aabo jẹ iṣẹ ajumọṣe fun tolori tẹlẹmu lawujọ wa, ki ifọkanbalẹ le wa kaakiri ilu.
O tẹsiwaju pe, awọn Ọlọọpa yoo ko ipa pataki lati ṣe atilẹyin fun idasilẹ ẹgbẹ alaabo tuntun naa ni ilẹ Yoruba, eyi ti yoo mu ki iwa ọdaran dinku  lawujọ wa.
Ọga ọlọpaa naa ni, gbogbo eto lo ti to lati ọdọ ajọ naa fun iranlọwọ to nipọn fun ikogoja igbimọ alaabo alajumọse naa.
Bakan naa ni alukoro fun ẹka  kan lara OPC ọgbẹni Ṣina Akinpelu ṣalaye wi pe lootọ ni OPC yoo kopa ninu eto naa.
O ni ipa ti o nipọn ni OPC yoo ko lori eto abo naa lati mu irọrun ba teru tọmọ.
Amẹrika dá akẹ́kọ́ọ̀ Harvard pada sí orílẹ̀-èdè rẹ̀ nítori ǹkan ọ̀rẹ́ rẹ̀ kọ lóri ayálujára
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Amẹrika dá akẹ́kọ́ọ̀ Harvard pada sí orílẹ̀-èdè rẹ̀ nítori ǹkan tó kọ lóri ayélujára
Àwọn aláṣẹ ilẹ̀ Amẹríka tí lé ẹni ọdún mẹ́tàdílógun kan tí wọ́n ṣẹ̀ṣẹ̀ gbà wọlé sí ilé ẹkọ́ fásìtì Harvard pada sí orilẹ̀ -èdè rẹ̀ nítori ọ̀rọ̀ kan ti ọ̀rẹ́ rẹ̀ kọ sorí ẹ̀rọ́ ayelujara Facebook.
Ismail Ajjawi tí wọ́n ṣẹ̀ṣẹ̀ gbà wọlé fún ẹ̀kọ́ ọ̀fẹ́ sí Harvard, sùgbọ́n àwọn aláṣẹ US kọ̀ láti jẹ́ kó wọ ìlú láti pápákọ̀ ofurufu ni wọ́n ti dáa pada.
Ismail tó jẹ́ ọmọ Palestine sùgbọ́n to n gbé Lẹbanon, sọ pé àwọn aláṣẹ US bere àwọn ibeere lórísírisi lọ́wọ́ oun ni pápákọ̀ ofurufu Boston lọ́ja Jimọ.
O ní wọ́n wọ́gile ìwé ìrìnà Visa òun lẹ́yìn ti wọn wo ẹrọ iléwọ àtí kọmputa alágbéletan rẹ̀.
Bí Ismail ṣe ja fitafita tó pé oun kò ni ǹkan ṣe pẹ̀lú ohun ti wọ́n ri lóri fọọnu oun tó àti pé ọ̀rk oun ló kọ síbẹ̀ àwọn ọlọpàá aṣọbode ní àwọn kò le gbà ki o wọle si ilẹ̀ Amẹrika.
Iwé ìròyìn Washington Post sàlàyé pé Ismail sọ̀rọ̀ lóri àtẹjáde kan.
Ọkan nínú àwọn òṣìṣẹ́ tó tó n ri sí ìjáde àti iwolé lorilẹ̀-èdè Amerika sọ pé òun ri èròngba ẹnikan lóri Facebook rẹ̀ tó n sọrọ òṣèlú lòdi si ìjọba orilẹ̀ èdè Amérika
Mo sọ fún wọ́n pé mí o ni ǹkankan ṣe pẹ̀lú àwọn èròngba náà, bákan náà ni mí o si gbé ìgbéṣẹ kankan lóri ǹkan ti ó kọ, mo sàlàyé pé kò yẹ ki wan múmi fún ẹ̀ṣẹ̀ ti mí o mọ nípa rẹ̀
Agbẹnusọ Aṣobode àti alábo ilẹ̀ Amerika (CBP) Michael McCarthy sàlàyé pé àwọn gbe ìgbésẹ̀ náà látàri àwọn ǹkan tí àwọn ti ṣe àwári lásìkò tí wọ́n ń ṣe àyẹwò (CBP)
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Harvard University say dem dey try to settle di mata before class go begin
McCarthy kò sàlàyé jù báyìí lọ nítori pé ṣe ǹkan tí àwọn gbọdọ máà fi gbogbo ẹni sọ.
Ismail ti wọn gbà wle fun ètò ẹ̀kọ́ ọ̀fẹ́ tí pada si Lebanon.
Ilé iwé Harvard náà ti sọ pé àwọn ń ba àwọn ẹbí ọmọ náà sọ̀rọ̀ àti pé àwọn ń gbìyànju láti pẹ̀tù sááwọ náà kí ìdánilẹ̀kọ tó bẹ̀rẹ̀ ni ọjọ́ kẹta oṣù kẹsàn
Ajọ kan ti kìí ṣe ti ìjọba tí pèsè ìrànwọ láti gbẹjọ rò fún Ismail.
Nínú Oṣù keje, ilẹ Amẹrika ti ní gbogbo ẹni tó ba ń fẹ́ láti gba iwé ìrìnà ilẹ̀ Amẹrika gbọ̀dọ̀ sàfihan àwọn ojú opó ayélujara wọn, èyí jẹ́ ọkan pàtàkì lárá òfin tuntun ti wọ́n yàn
Wọn fi kún pé arinrin ajo yóò mú orukọ to n lọ loju opo ayelujara rẹ̀ kalẹ̀, pelu gbogb atẹjisẹ tó ti gbà láti ọdún márun ṣẹyin àti nọmba foonu wọ́n
FBI List: Ìwádìí EFCC àti FBI ti ń so èso rere
Oríṣun àwòrán, @ChikeEjiofor
Awọn afurasi ọgọrin, ti ọpọlọpọ wọn jẹ ọmọ Naijiria ni ajọ FBI ti fi ẹsunn kan wi pe, wọn lu gbajuẹ nilẹ Amẹrika
Alaga fidihẹ fun ajọ EFCC,  Ibrahim Magu, ti sọ wi pe, ajọ naa ti bẹrẹ si nii ṣe akojọpọ iwadii awọn ọmọ Naijiria ti ajọ ọtẹlẹmuye Amẹrika, FBI, fi ẹsun kan lori iwa jibiti.
Ẹni ti o ṣoju Magu nibi ifọrọwerọ kan pẹlu awọn oniroyin, Friday Ebelo, lọ sọ ọrọ yi nilu Ibadan.
O salaye pe, iwadii ti ajọ EFCC n ṣe jẹ ọkan lara ibaṣepọ ti o wa laarin ajọ EFCC ati FBI, lati foju awọn afurasi naa lede.
Oríṣun àwòrán, @FBI
Friday salaye sii pe, iwadii ti wọn n ni lati mọ ibaṣepọ to wa laarin awọn afurasi ni orilẹ-ede yi ati awọn ojugba wọn to wa loke okun.
Bakan naa ni o tesiwaju pe, lara awọn iwadii ti ajọ naa ti ṣe ti ranwọn lọwọ lati fi panpẹ ọba mu ọpọlọpọ awọn afurasi.
O wa fi kun un pe, lara awọn ti àwọn ti ri mu ni Ajayi Gbenga Festus, ẹni ti ọwọ ajọ na tẹ nilu Ado-Ekiti.
Bi ẹ o ba gbagbe, awọn afurasi ọgọrin, ti ọpọlọpọ wọn jẹ ọmọ Naijiria ni ajọ FBI ti fi ẹsun kan wi pe, wọn lu gbajuẹ nilẹ Amẹrika.
Akẹ́kọ̀ọ́ ìmọ òfin ABU tí wọ́n jígbé lọnà Kaduna-Abuja ti gba ìdáǹdè -Ọlọ́pàá
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Iṣẹ ọwọ agbofinro nikan kọ lo yọ wọn, awa mọlẹbi sanwo itanran fajinigbe ni
Awọn mẹtẹẹta ti ri idande wọn gba -Ileeṣẹ ọlọpaa.
Lẹyin ti awọn agbofinro fi si ta pe wọn doola ẹmi awọn akẹkọọ ABU mẹta ti awọn ajinigbe ji gbe lọna Kaduna ni iroyin jade pe irọ ni pé awọn ọlọpaa lo kan kede riri wọn ni.
Sadiq Ango, ọkan lara mọlẹbi wọn ṣalaye pe niṣe ni awọn mọlẹbi mẹtẹẹta pawọpọ lati da owo san owo itanran ki awọn oniṣẹ ibi naa to fi wọn silẹ.
O fi soju opo twitter rẹ pe gbogbo owo itanran ti wọn beere ni awọn san.
Bakan naa ni Bashir Ahmad to jẹ oluranlọwọ fun aarẹ Buhari lori eto iroyin igblode naa fi sita pe ẹbi awọn ti ọrọ kan ti fidiẹ mulẹ pe wọn san owo itanran ni.
O ni oun tọrọ aforijin lati kọkọ gbe gbogbo oriyin fun awọn agbofinro Naijiria tẹlẹ.
Ileeṣẹ ọlọpaa nipinlẹ Kaduna ti kede itusilẹ awọn akẹkọọ Fasiti Ahmadu Bello ni Zaria mẹta ti awọn ajinigbe jigbe lọjọ Iṣẹgun loju ọna marose Kaduna si Abuja.
Alukoro ọlọpaa, DSP Yakubu Sabo lo fidi ọrọ yi mulẹ fun BBC.
O sọ pe awọn doola ẹmi awọn akẹkọọ wọnyi ti wọn si ti darapọ mọ awọn mọlẹbi wọn.
Yakubu ṣalaye pe awọn tun doola ẹmi awọn eeyan mẹta miran ti wọn jigbe loju ọna naa ni ọjọ kẹrindinlọgbọn, oṣu Kẹjọ.
O fi kun un pe iwadii ṣi n lọ lati doola awọn eeyan to ku ati pe awọn n ṣapa lati mu awọn afurasi naa.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ọlọpaa Naijiria
Gẹgẹ bi alaye ti awọn ọlọpaa ṣe, iṣẹlẹ naa waye nigba ti awọn ajinigbe to wọ aṣọ ologun ji awọn ero inu ọkọ gbe lẹba abule Masari loju ọna Kaduna si Abuja ti wọn si ṣina fawọn ọkọ to wa ni ọna naa.
Wọn ji eeyan mẹfa gbe lọjọ Aje ti iṣẹlẹ naa waye.
Adari awọn to n ṣe eto awọn akẹkọọ ni Fasiti ABU Ọjọgbọn Yahaya Bambale fi idi ọrọ naa mulẹ fun BBC to si ni lootọ lawọn ajinigbe gbe akẹkọ mta ṣugbọn awọn agbofinro ti toju bọ ọrọ naa.
Spaghetti, milíìkì, Chivita àti Àǹkàrá sọ Rabiu dèrò ẹ̀wọn ni Eko
Oríṣun àwòrán, @others
Ìbí kò gbọdọ ju ìbí nínú eto ìdájọ́
Adajọ ni ki Kabiru lọ kọ ẹkọ iwa ootọ sii nile ikọni lẹkọ ọmọluwabi tijọba.
Ileejọ Magistrate ti Ikẹja nipinlẹ Eko ti dajọ ọdun meji latimọle fun ọdọmọkunrin Kabir Rabiu.
Kabir Rabiu to jẹ ọmọ ogun ọdun ni o ni oun jẹbi ẹsun ole ti wọn fi kan oun ati pe iṣẹ eṣu ni.
DSP Ezekiel Ayorinde lo fi ẹsun kan Rabiu pe O ji Spaghett kan, maltina alagolo kan, ẹlẹrindodo Chivita meji, yogọọti agolo dudu kan, ọra ọṣẹ ifọṣọ Ariel kan ati ankara marun un.
Odiwọn iye owo gbogbo nkan to ji jẹ ẹgbẹrun mejidinlogun o le ni irinwo ati ọgbọn naira (18, 430 naira).
Wọn ni Rabiu ji awọn nkan wọnyii nile itaja kan ni agbegbe Abule Egba lọjọ kẹrindinlogun, oṣu kẹjọ ọdun yii.
Rabiu ti ko ri adirẹẹsi ile to n gbe fi silẹ nitori o ni ibi ti ilẹ ba ṣu si naa ni ile bẹbẹ pe ki adajó foju aanu wo oun.
Lẹyin igbẹjọ naa lọjọru ni Adajọ Osunsanmi ni ki Rabiu lọ lo ọdun meji nile ikọni niwa ọmọluwabi ti ijọba to wa ni agbegeb Adigbẹ nilu Abẹokuta to jẹ olu ilu ipinlẹ Ogun.
DSP Ezekiẹli ni ọja naa jẹ ti ọgbẹni Mohammed Muraina to n ta worobo ati atẹ ninu ṣọọbu rẹ ni Abule Ẹgba.
O ni wọn ti gba awọn ẹru naa pada lọwọ Kabir Rabiu lẹyin ti ọwọ ofin tẹẹ.
Iwa ole jija Kabir yii tako ofin ipinlẹ Eko ti abala 287 tọdun 2015.
Japan Visit: Ààrẹ Shinzo Abe kéde $413,000 owó ìrànwọ́ fún Nàìjíríà
Oríṣun àwòrán, Twitter/Bashir Ahmad
Ijọba orilẹede Japan ti kede iranwọn iye owo to le ni ọkandinlaadọjọ miliọnu Naira, N149,919,000m( $413,000) fun orilẹede Naijiria ni Ọjọbọ ni ilu Yokohama.
Olootu ijọba ilẹ naa, Shinzo Abe kede iranwọ owo ọhun fun ẹka eto aabo ati ilera lorilẹede Naijiria nibi ipade to sẹ pẹlu Aarẹ Muhammadu Buhari ni ilu Yokohama.
Eyi jẹ ọkan lara awọn anfaani to ti jẹyọ lati ibi apero TICAD7 lorilẹde Japan.
Olootu ijọba Japan tun sọ pe orilẹ-ede Japan yoo ṣatilẹyin fun Naijiria ninu eto idibo aarẹ igbimọ gbogboogbo ajọ iṣọkan agbaye ẹlẹẹkẹrinlelaadọrin iru rẹ.
Bakan naa ni Ọgbẹni Abe beere iranwọ Naijiria ninu ero rẹ lati di ipo olori mu lagbaaye.
Oríṣun àwòrán, Bashir Ahmad
Ẹwẹ, Aarẹ Buhari lo anfaani apero TICAD7 niluu Yokohama lati bere iranwọ ilẹ Asia lati dẹkun awọn ole oju ni ọgbun Guinea atawọn to n pẹja lọna aitọ ninu ọgbun naa.
Bakan naa ni Aarẹ Buhari buwọlu iwe adehun €50m pẹlu ajọ EU lati ṣe iranwọ lori ọna ati ṣeto idagbasoke lapa ila oorun ariwa lorilẹede Naijiria.
Ọmọ́táyọ̀ Olútóyè: Àwọn ǹkan tó yẹ kí ẹ mọ̀ nípa Ọ̀jọ̀gbọ́n obìnrin àkọ́kọ́ nínú ẹ̀kọ́ èdè Yorùbá lágbàyé
Oríṣun àwòrán, @others
Iṣẹ tokunrin n ṣe, obirin naa le ṣe e
Abi Ọjọgbọn Omọtayọ Olutoye ni ọjọ karundinlogun, oṣu kẹwa, ọdun 1935, ni ilu Eko, bi o tilẹ jẹ pe, ọmọ bibi ilu Ilogbo, ni ipinlẹ Ekiti ni.
O jẹ Ọjọgbọn obirin akọkọ ninu ẹkọ ede Yoruba ni orilẹ-ede Naijiria, ati ni gbogbo agbaye.
Oun naa tun ni obirin akọkọ ti yoo ṣíṣẹ ni ile ifowopamọ ni orilẹ-ede Naijiria.
U.I Language Centre: Yorùbá ló làṣà àti èdè
Bakan naa ni o lọ si ile iwe Queens College, ni ilu Eko, laarin ọdun 1949 si 1953.
Lẹyin naa ni o tun lọ si St Agnes College, ti o wa ni Maryland, Ikeja, ilu Eko, laarin ọdun 1955 si 1956.
Ọjọgbọn yi tun tẹ siwaju lati kawe sii, ni University College, ilu Ibadan, laarin 1960 si 1961.
O kawe lawọn ile iwe miran ni Naijiria ati loke okun. Lara wọn ni, Fasiti ijọba apapọ ipinlẹ Eko, ni ọdun 1967 si 1970, ati University of Leeds, ni ilu ọba.
Awọn ibi ti o ti ṣiṣẹ
Ọjọgbọn Omọtayọ ṣiṣẹ olukọ laarin ọdun 1957 si ọdun 1963.
O tun ṣiṣẹ oniroyin nile igbohun safẹfẹ ti ijọba apapọ Naijiria, eyi ni Radio Nigeria, ni ọdun 1970 si ọdun 1971.
Bẹẹ lotun ṣiṣẹ ni Fasiti ijọba apapọ ilu Eko, gẹgẹ bi olukọ, ni ọdun 1971 si ọdun 1978.
Lẹyin naa lo kuro nibẹ lọ si ile iwe awọn oluko to wa ni Ikẹré Ekiti, lati tẹsiwaju ninu iṣẹ olukọ, ni ọdun 1979 si ọdun 1980.
Ọjọgbọn Omọtayọ tun gba igbega sii lẹnu iṣẹ ni Ikẹrẹ, nigbati o di adari fun ileewe naa laarin ọdun 1995 si 1997.
Lẹyin eyi ni o gba oye ọjọgbọn, ti o si jẹ olukọ agba, ni ẹka imọ ede Yoruba, lati ọdun 1983.
O jẹ ọkan lara awọn ti o lọ si ipade atunṣe iṣelu orilẹ-ede, eyi ti aarẹ orilẹ-ede yi tele ri, Olusegun Obasanjọ gbekale ni ọdun 2005.
Ọjọgbọn Omọtayọ fẹran aṣọ hihun, iwe kika, o jẹ iya to fẹran ọmọ, ati aya rere lọdẹ ọkọ rẹ, eyi ni, ajagunfẹhinti Olufemi Olutoye.
Bobrisky: Olusegun Runsẹwẹ, o kéré sí nọ́mbà àwọn tí mò ń bá se!
Bobrisky fún ọ̀gá Arts & Culture lésì, ó ni àwọn ọgá rẹ̀ ló ń ba ṣe
Ọrọ n ba ọrọ bọ laarin awọn mejeeji.
Bobrisky ni Runṣewe n dunkooko mọ oun.
Lẹ́yìn ọrọ tí oludári àgbà fun ile iṣẹ to n ri si ọrọ aṣa ati iṣe lorilẹ-ede Naijiria, National Council for Arts and Culture (NCAC), Otunba Olusegun Runsewe ṣe sí Okuneye Idris Olarewaju ti gbogbo ènìyàn mọ si Bobrisky pé òun yóò fi imú rẹ̀ dárin.
Bobrisky náà ti fèsí sí alákóso Arts & Culture pé ọmọ ọwọ́ ní, àwọn to jẹ́ ọ̀gá ni ìjọba fún ni òun ń ba ṣe.
Bobrisky fún ọ̀gá Arts & Culture lésì, ó ni àwọn ọgá rẹ̀ ló ń ba ṣe
"Nínú èsì rẹ̀ tó fi léde lójú òpo Instagram, Bobrisky ní "" mo gbọ́ pé ẹnikan nínú ìjọba sọ̀rọ̀ nípa mí láìpẹ́ yìí."
 Ẹ jọ́wọ́ ẹ bá mi sọ fún un pé mo ń dúró dèé.
ìgbà yẹn ni yóò mọ pé àwọn ọgá rẹ̀ nijọba ni mò ń ba ṣe; kìí ṣe irú àwọn ọjẹ̀ wẹ́wẹ́ bí tí rẹ̀.
O fí ǹkan tó ṣe pàtàkì kálẹ̀ nínú ọ̀rọ̀ Nàìjírríà láti maa rojọ́ Bobrisky.
"Tí ẹ ò bá gbàgbé olùdári Arts & Culture nínú iwé ìròyìn Vanguard ti bura pé òun yóò fí ojú rẹ̀ hàn mabo bí o ṣe pèé ni ""adoju tini""."
Adójú ti ni àti orílẹ̀-èdè ni Bobrisky.
O bẹ̀rẹ̀ pẹ̀lú títa ìpára tí wọ́n fi n bóra, ní sin yìí ó ti gúnmú, o tún yọdi naa.
Ti Bobrisky bá n ṣe àṣeyori nínú ìwà àgberè tó n fi ṣiṣẹ́ ṣe, báwo ní a ṣe fẹ́ pàrowà si awọn ọdọ Nàìjíríà láti ṣe ǹkan to tọ̀na. Lóòtọ́ ó lẹtò sùgbọ́n kìí ṣé ni àyíká Nàìjíríà.
A ní àwọn èèyàn bi tirẹ, sùgbọ́n wọ́n o gbé Nàìjíríà. Tí a o ba tètè pẹ̀ka ìrókò rẹ̀ nísinyìí ẹbọ ni yoo ma gba.
Ekiti: Àyọjúràn ni Fayoṣe tó yọjú sí Ilé Igbìmọ̀ Aṣòfin l'Ekiti
Oríṣun àwòrán, @GovAyoFayose
Fayoṣe yọjú sílé ìgbìmọ̀ aṣòfin l'Ekiti lórí ọ̀rọ̀ owó Káńsù, óní kòséwu lòko
"Ile Igbimọ Aṣofin ipinlẹ Ekiti ti sọ wi pe, ""alejo apapandodo"" ni Fayoṣe wa se lasiko ti o yọju sile igbimọ aṣofin ipinlẹ naa."
Abẹnugan ile naa, Funminiyi Afuye  lo sọrọ yi nigba to n fọrọjomitoro ọrọ pelu ile iṣẹ BBC.
Afuye wi pe, ile igbimọ asofin Ekiti ko tii fiwe pe gomina ana oun, sugbọn o kọ pinnu lati wa bẹ ile igbimọ aṣofin naa wo lai ro tẹlẹ ni.
Abẹnugan ile naa wa  salaye siwaju pe, ile igbimọ aṣofin Ekiti ṣi maa kọwe si Fayose, lati wa farahan niwaju igbimọ to n risi ẹsun ti wọn fi kan an.
Peter Ayodele Fayoṣe, ẹni ti o jẹ gomina ana ni ipinlẹ Ekiti ti yọju si Ile igbimọ aṣofin ipinlẹ naa lori ẹsun ti wọn fi kan an nipa ọrọ owo Kansu.
Fayoṣe lo fi ọrọ yii lede lori opo Twitter rẹ nibi ti o ti sọ pe ko sewu loko, afi giri aparo.
"O salaye pe ""Mo ṣẹṣẹ kuro ni Ile igbimọ aṣofin ipinlẹ Ekiti ni, nibi ti moti ṣe ipade pelu agbẹnusọ ati awọn jankan jankan ile aṣofin naa."
"Ọwọ mi mọ, mi o si bẹru ẹsun kankan bi o ti wu ki o ri."""
Ṣe ẹ mọ Oṣokomọlẹ ipinlẹ Ekiti? hẹn ooo, gomina ana ni ipinlẹ Ekiti, Ayọdele Fayose naa ni.
Awọn ọmọ Ile igbimọ aṣofin ipinlẹ Ekiti ni fi aṣẹ ranṣẹ si gomina ana ni ipinlẹ naa pe afira, ko yara tete yọju ni o lati wa wi ti ẹnu rẹ lori bi awọn owo kan to jẹ ti ijọba ibilẹ ṣe rin kọlọkọlọ bi ọka to de inu ọka lasiko to wa lori oye.
Igbimọ to n ṣe konkaari aṣuwọn ilu ni ile aṣofin naa lo ranṣẹ pe Fayoṣe o.
Bakan naa ni wọn tun ni ki ẹni to jẹ alaga ẹgbẹ awọn alaga kansu (ALGON) tẹlẹ, Ọgbẹni Dapọ Ọlagunju, kọmiṣọna tẹlẹ fun ọrọ ijọba ibilẹ, Ọgbẹni Kọla Kọlade pẹlu gbogbo awọn alaga kansu mẹrẹẹrindinlogun tẹlẹ  ni ipinlẹ naa o yọju ni wara-n-ṣeṣa niwaju ile naa.
Ni oṣu kejila, ọdun 2018 lawọn aṣofin ipinlẹ Ekiti kọkọ gbegile awọn alaga kansu ọhun ki wọn to da mẹjọ ninu wọn pada ni oṣu keje, ọdun 2019.
Alaga igbimọ gbohun-gbaroye araalu ni ile aṣofin naa, Họnọrebu Adegoke Ọlajide ṣalaye pe lasiko ti awọn alaga kansu naa fi ara han niwaju ile ni wọn jẹwọ pe loṣooṣu lawọn maa n da owo ijọba ibilẹ wọn gba ọna miran, eyi ti wọn ni o wa ni ibamu pẹlu aṣẹ ti wọn ri gba latọdọ gomina ana ni ipinlẹ naa, Ayọ Fayoṣe.
Iye awọn ti yoo farahan niwaju ile naa ko mọ sibẹ o. Bakan naa ni wọn ni olori ile naa tẹlẹ, Pasitọ Kọla Oluwawọle pẹlu gbọdọ yọju o.
APC Kogi Primaries: Yahaya Bello la àwọn olùdíje mẹ́sàn án mọ́lẹ̀ fún àṣíá gómìnà ìpínlẹ̀ Kogi
Oríṣun àwòrán, others
Gomina Yahaya Bello lawọn ọmọ ẹgbẹ oṣelu APC ni ipinlẹ Kogi tun gbe aṣia ẹgbẹ oṣelu naa le lọwọ.
Oun ni wọn fun lati fi dije ipo gomina lasiko idibo ti yoo waye loṣu kọkanla ọdun yii.
Ibo ẹgbẹrun mẹta ati ọdunrin o le mọkandinlaadọrin ni Yahaya fi bori awọn oludije mẹsan miran ti wọn jọ sa ere ije naa eyi to waye nilu Lọkọja.
Oríṣun àwòrán, @others
APC tun ti fa Yahaya Bello aklẹ lẹẹkansii
Gẹgẹ bii gomina Abubakar Badaru ti ipinlẹ Jigawa to ṣe alaga eto idibo naa ṣe sọ, Ọgbẹni Babatunde Irukera lo gbe ipo keji pẹlu ibo mọkandinlaadọfa ti Hassan Bewa si ṣe ipo kẹta pẹlu ibo mẹrinlelogoji.
Ibo mẹwaa pere ni Yahaya Audu ni ti Sanni Abdullahi ni tirẹ si ni meje.
Oríṣun àwòrán, @others
Awọn eniyan Kogi a dibo gomina loṣu kọkanla ọdun
Ọjọ kẹrindinlogun, oṣu kọkanla, ọdun 2019 ni eto idibo si ipo gomina ni ipinlẹ Kogi yoo waye.
Amole festival in Akure: Deji pàṣẹ kí gbogbo ọjà àti ṣọ́ọ̀bù wà ní títì pa
Ọdun de, ka jọ maa ṣe amọdun laṣẹ Eledua ni adura awọn eniyan Akurẹ.
Gbogbo awọn ti o ba ti fi ọkan si ati lọ ra ọja loni ọjọ Ẹti nilu Akurẹ ko ni le e ṣe bẹẹ nitori Kabiyesi Deji ti ilu Akurẹ ti kede pe titipa ni ki gbogbo ọja ko wa.
Ko si idi meji gẹgẹ bi Ọba ilu Akurẹ ṣe sọ ju wi pe ni ọjọ Ẹti ni ayẹyẹ ọdun Amọle yoo waye nibẹ.
Gẹgẹ bii atẹjade kan ti akọwe iroyin fun igbimọ lọbalọba ilu Akurẹ, Adeyẹye Micheal fi sita, lọdọọdun ti ọdun yii ba ti fẹ waye lati igba iwasẹ wa ni wọn ti maa n ti ọja pa fun ọjọ kan ti ajọdun naa yoo fi waye.
Amọṣa wọn ni aaye wa fun igbokegbodo ọkọ ati awọn eeyan lasiko ti ọdun naa ba fi waye.
Wọn wa rọ gbogbo awọn olugbe ilu Akurẹ lati tẹle aṣẹ yii.
Bi  a ko ba gbagbe, irufẹ ilana titi ọja gbogbo yii ko ṣajeji nitori idalu ni iṣelu.
Rape: Bàbà ọmọ ọdún márùndínlọ́gọ́rin kó HIV ran ọmọ ọdún mẹ́rìnlá lẹ́yìn tó fi ipá báa lò
Baba ọmọ ọdun marundinlọgọrin kan ti ko kokoro arun HIV ran ọmọ ọdun mẹrinla kan lẹyin to fi ipa ba a lo ni ipinlẹ Rivers.
Iroyin ti a gbọ ṣalaye pe, baba agbalagba naa n gba itọju fun kokoro arun HIV ni ileewosan kan ni ipinlẹ Rivers.
Gẹgẹ bi a ṣe gbọ, ọwọ ṣinkun ọlọpaa tẹ baba agbalagba naa ti wọn pe orukọ rẹ ni Shadrack Ejinwo.
Ibanujẹ ibẹ ni pe iroyin naa ni lẹyin ọrọ pẹlu baba ọmọdebinrin wón jọ ṣe adehun lati maa san ẹgbẹrun lọna ọọdunrun ati addọrin naira loṣooṣu titi di oṣu keji ọdun 2020.
Ohun ti a gbọ ni pe, ileewosan ti baba yii ti lọ n gba itọju fun kokoro arun HIV ni ọmọdebinrin yii ti n ṣiṣẹ olubanitaja bẹẹni awọn ọlọpaa ti fi baba agba yii silẹ lẹyin idunadura yii.
Gẹgẹ bii iwe adehun idunadura naa ṣe sọ, baba agbalagba, ọmọ ọdun marundinlọgọrin yii ni yoo maa ṣe kokari inawo fun itọju ọmọdebinrin ọhun titi di oṣu keji, ọdun 2020.
Domestic Violence: Ìjà láàrin lọkọlaya sọ aya dèrò ọ̀run
Kìí ṣe gbájúẹ̀ nìkan lọmọ Nàìjá ń ṣe lókè òkun, Yoruba ń mókè, wọ́n ń gbéṣẹ́ ńlá ṣe
Oríṣun àwòrán, other
Kìí ṣe gbájúẹ̀ nìkan lọmọ Nàìjá ń ṣe lókè òkun!
Kii ṣe olè, ọlẹ ati gbajuẹ nikan ni ọmọ Naijiria paapaa Yoruba n ṣe loke okun.
Ni ẹnu ọjọ mẹta yii, oniruuru iroyin iwa kotọ nipa awọn ọmọ orilẹ-ede Naijiria to wa loke okun lo n fọn kalekako lori ayelujara.
Koda, aarẹ Muhammadu Buhari funrarẹ ko ṣai mẹnu le ọrọ yii nibi ipade idagbasoke Afirika to lọ ṣe ni Japan.
Eyi lo wa n faa ti ọpọ fi n ṣe beere boya ohun rere kan tilẹ lee ti Nasarẹti yii jade.
Ẹtàn ni àwọn ọ̀rẹ́ fi ń tan èèyàn lọ si Libya pé iṣẹ́ gidi wà níbẹ̀
Dokita agba Oluyinka Olutoye:
Oríṣun àwòrán, BBC Sport
Bi a ba fi ọmọ we ọmọ...
Dokita agba Oluyinka Olutoye jẹ ọkan lara awọn ogo orilẹ-ede Naijiria ti itanṣan wọn n tan ka gbogbo agbaye fun ipa rere ti wọn n ko kaakiri.
Lati kekere ni Dokita Oluyinka Olutoye ti ni ifẹ si iṣẹ dokitaKíni ẹ mọ̀ nípa Ọmọ́táyọ̀ Olútóyè, Ọ̀jọ̀gbọ́n obìnrin àkọ́kọ́ nínú ẹkọ́ èdè Yorùbá lágbàyé
Gẹgẹ bii ọrọ rẹ, 'lati kekere ni mo ti maa n ṣe ere dokita kaakiri inu ile wa' nitori ifẹ rẹ si iṣẹ naa.
"Koda aarẹ Muhammadu Buhari funrarẹ ko ṣai mẹnu le ọrọ yii nibi ipade idagbasoke Afirika to lọ ṣe ni Japan.A ń fikunlukun pẹ̀lú FBI láti mú àwọn ""Yahoo Boys"" tó kù- EFCC"
Eyi lo wa n faa ti ọpọ fi n ṣebeere boya ohun rere kan tilẹ lee ti Nasarẹti yii jade?Ẹ yọjú sí FBI bí ẹ kìí bá ṣe ''yahoo boys'' - Abike Dabiri-Erewa.
Ni ẹnu ọjọ mẹta yii, oniruuru iroyin iwa kotọ nipa awọn ọmọ orilẹ-ede Naijiria to wa loke okun lo n fọn kalekako lori ayelujara.
Amọṣa diẹ niyi lara awọn ọmọ Yoruba to n da bi ẹdun, rọ bi owe ni Olutoye Olayinka. Baba rẹ ni Alani ti ilu Ido-Ani, Oluwatomiloye I.
Ọmọ ilu Idoani ni Dokita Olayinka Olutoye.
Awọn obi rẹ ni Ọgagun agba Olufẹmi Olutoye to ti fẹyinti ninu iṣẹ ologun ati Ọjọgbọn Ọmọtayọ Olutoye to jẹ Ọjọgbọn akọkọ ninu ẹkọ imọ Yoruba.
Awọn mẹfa ni awọn ẹgbọn ati aburo rẹ, mẹta jẹ obinrin, meji ninu wọn si jẹ ọkunrin.
Oríṣun àwòrán, others
Lati kekere ni ọmọ ti yoo jẹ aṣamu ti maa...
Ileewe alakọbẹrẹ Lagos University Staff School ni o lọ ki o to kọri si ileewe girama King's College ni ilu Eko kan naa.
Lẹyin to pari ile ewe girama rẹ, Olutoye gba ọgba fasiti Ọbafẹmi Awolọwọ lọ lati kọṣẹ imọ iṣegun oyinbo nibẹ.
Ọdun 1988 ni o kẹkọọ gboye ninu imọ iṣegun oyinbo ati iṣẹ abẹ.
Adebayo Ogunlesi: ọmọ ọjọgbọn onimọ iṣegun to ra papakọ ofurufu Gatwick lọwọ èèbó
Oríṣun àwòrán, others
Ọdun 1988 ni o kẹkọọ gboye ninu imọ iṣegun oyinbo ati iṣẹ abẹ.
Ilu Makun ni ipinlẹ Ogun ni wọn ti bi Adebayo Ogunlesi ti o si ti wa di ilumọka agbẹjọro ati ouldukowo lagbaye
Pupo ninu awọn arinrinajo to ba gba papakọ ofurufu Gatwick kọja nilẹ Gẹẹsi a maa kan saara si bi wọn ti ṣe ṣe eto papakọ ofurufu naa.
Iyipada ti wọn mu ba papakọ naa waye lẹyin ti ile iṣẹ aladani kan raa lọwọ ajọ to n ṣamojuto rẹ BAA niye owo biliọnu pọun kan le diẹ lọdun 2009.
Ọrọ Gatwick kọ la fẹ fayọ ninu itan kekere yi bi kii ṣe ti ọmọ Yoruba to jẹ oludari ile iṣẹ Global Infrastructure Partners to ra Gatwick pa.
Ẹni ti a n sọrọ rẹ ni Adebayo Ogunlesi-ọmọ bibi ilu Makun nipinlẹ Ogun to si jẹ ilumọọka oludokowo lagbaye nii ṣe.
Ọmọ ti ẹya ba bi, ẹya nii jọ.
Lati kekere ni Adebayo ti ṣẹnu ṣamuṣamu ti a si le sọ wi pe ile lo ti baa.
Baba rẹ, ọjọgbọn Theophilus Ogunlesi ni onimọ iṣegun akọkọ to gba oye ọjọgbọn nilẹ Naijiria.
Ile iwe girama Kings College nilu Eko ni Adebayo lọ ti o si pegede nibẹ.
Lẹyin to pari ẹkọ, girama, o tẹsiwaju lọ ilẹ ẹkọ fasiti Oxford nibi to ti kawe gboye imọ nipa imọ iwa ẹda, oṣelu ati ọrọ aje, iyẹn Philosophy Politics and Economics.
'500 level'' ni mo wà nígbà tí mo di adélé Ọba'
Oríṣun àwòrán, kemi badenoch
Ko si nkan ti ọkunrin n ṣe ti obinrin ko le ṣe
Ni oṣu, keje ọdun 2019 ni Olootu ijọba ilẹ Gẹẹsi, Bori Johnson yan arabinrin Olukemi Olufunto Adegoke Badenoch gẹgẹ bii minisita abẹle fun ọrọ awọn ọmọde ati idile.
Ni oṣu kinni, ọdun 1980 ni wọn bi i ni ilu Wimbledon lorilẹ-ede Gẹẹsi ṣugbọn ọmọ orilẹ-ede Naijiria ni awọn obi rẹ,
Dokita Fẹmi Adegoke ati Ọjọgbọn Feyi Adegoke ni orukọ wọn
Wọn gbe e pada wa si orilẹ-ede Naijiria lẹyin ibi rẹ, ṣugbọn o pada si ilẹ Gẹẹsi nigba ti o pe ọmọ ọdun mẹrindinlogun.
Ilu Eko lo ti lo igba ewe rẹ.
Ni ọdun 2017 ni wọn dibo yan an si ile igbimọ aṣofin ilẹ Gẹẹsi lati ṣoju fun ẹkun Saffron Walden.
Lábẹ́ odò! Ìgbéyawó yìí lárinrin
Taraba: Àwọn Ọlọpàá ní ìwádìí ṣì ń lọ lówọ lórí ikú Fadá
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ilé isẹ́ olọ́pàá ìpínlẹ̀ náà ní àwọn jàgùdà Pipo lo se iṣẹ ibi naa ti wọn si dana sun un ninu ọkọ re.
Olopaa Ipinlẹ Taraba ti ni awọn jaguda ti pa fada ti o n lọ lati pẹtu si ija laarin ẹya Tifi ati Jukun ni ipinlẹ Taraba.
Alukoro ile-isẹ ọlọpaa ni ipinlẹ naa, David Misal ṣalaye wi pe ,awọn jaguda lo se iṣẹ ibi naa ti wọn si dana sun Fada naa ninu ọkọ re.
Iroyin ti o tẹ wa lọwọ ni pe Fada David Tanko n lọ si ilu Takum fun ipade alaafia laarin Tiv ni Benue ati ẹya Jukun ni Taraba pelu awon olori ẹlẹsin miran.
Ija ẹlẹya mẹya ti o ti gbilẹ ni ipinlẹ naa lati igba pipẹ ni o fa ipade alaafia ti awọn olori ẹlẹsin ipinlẹ naa pe.
Ni bayii, ajọ ọlọpaa ipinlẹ naa ti pe fun iwadii to loorin lati fi panpẹ ọba mu ẹni ti ade ọrọ naa ba ṣi mọ lori.
Oga agba Ọlọpaa nilẹ yii, Muhammed Adamu ti paṣẹ pe ki ọlọpaa ipinlẹ naa wa ọdaran bẹẹ ri.
Bakan naa ni ko ṣai kẹdun pẹlu Ijọ Aguda lapapọ lori iku ojiṣẹ Olọrun naa ti awọn aṣebi dẹmi rẹ legbodo lai ro tẹlẹ.
EFCC: Ọwọ́ pálábá àwọn ọmọ China méjì tó fẹ́ fún ọ̀gá EFCC ní àbẹ̀tẹ́lẹ̀ N100m ségi
Oríṣun àwòrán, Faceboo/EFCC
Ajọ to n gbogun ti iwa jẹgudujẹra lorileede Naijira EFCC ti sọ iwọ sodo ti o si ti mu ẹja nla pẹlu awọn ọmọ ilẹ China meji kan to gbiyanju lati fun ọga ajọ naa kan ni  ọgọrun miliọnu  Naira lowo abẹtẹlẹ.
Eka ileesẹ naa to wa ni Sokoto ni o gba awọn mejeeji yi mu ti wọn si ti safihan owo naa ati awọn afunrasi yi loju opo Facebook ajọ EFCC.
Ninu ohun ta ri ka nibẹ, Ọgbẹni  Meng Wei Kun ati Xu Koi fẹ fun ọga EFCC agbegbe Sokoto ni owo abẹtẹlẹ aadọta miliọnu naira ti wọn ko wa ba eleyi to jẹ idaji ọgọrun miliọnu ti wọn fẹ fun ki o ba le mẹnumọ lori iwaadi kan tajọ naa n se lori ileesẹ wọn.
EFCC sọ pe awọn n se iwaadi aṣemaṣe ti awọn fura si pe ileesẹ Zhonghao Nig. Ltd tawọn arakunrin naa n ba sisẹ mọ nipa rẹ.
Ko sẹyin isẹ agbaṣe oni aadọta biliọnu naira ti ijọba ipinlẹ Zamfara gbe fun wọn laarin ọdun 2012 si 2019.
Ninu isẹ ti EFCC n tọ pinpin yii la ti ri isẹ agbaṣẹ oju ọna laarin ilu bi ti Gummi, Bukkuyun, Anka ati Nassarawa to fi mọ isẹ agbaṣe gbigbẹ ẹrọ kanga igbalode(borehole) mejidinlaadọsan ni ijọba ibilẹ mẹrinla ni ipinlẹ naa.
A tun ri ka ninu atẹjade ti EFCC fi sita pe nigba tawọn ọmọ ilẹ China yii ri pe awọn oṣiṣẹ ajọ naa ko jawọ ninu iwaadi wọn, ni wọn ba nawọ aba lati fun wọn ni abẹtẹlẹ ọgọrun miliọnu naira ki wọn ba le gbagbe ọrọ naa.
EFCC lawọn ṣebi ẹni gba lati juwọ silẹ ni wọn ba fi gbe idaji owo naa wa ti wọn si ṣeleri lati mu iyoku wa ti ọrọ ba yanju.
Awọn aṣoju ileeṣẹ naa meji Meng Wei Kun ati Xu Kuoi ni wọn fi paali gbe owo naa wa si ileeṣẹ EFCC to wa ni opopona papakọ-ofurufu ni Sokoto.
Lana tii ṣe ọjọ kọkanla oṣu Kaarun ni ọwọ tẹ wọn.
Ọwọ́ EFCC tẹ ọ̀kan lára àwọn ti FBI fi èsún jìbìtì kàn!
EFCC sọ pé wọ́n ti fi pańpẹ́ ọba mú ọmọ ọdún mẹ́rìndínlógójì afurasi oní jìbìtì kan ní ìlú Ilọrin.
Ajọ to n gbogun ti iwa ibajẹ lorilẹ-ede Naijiria, EFCC ti sọ wi pe, wọn ti fi panpẹ ọba mu Oyediran Joseph.
O jẹ ọmọ ọdun mẹrindinlogoji ati ọkan lara awọn ti ajọ FBI fesun kan pe o lu jibiti.
Oríṣun àwòrán, @officialEFCC
Ọga agba fun ajọ EFCC ni Ilọrin, Isyaku Sharu, ti o soju alaga fidihẹ fun ajọ naa, Ibrahim Magu, lo fi ọrọ naa lede nibi ifọrọwerọ pẹlu awọn oniroyin nilu Ilọrin.
Magu wi pe, Ajọ EFCC ti ni ifọwọ sowọpọ pẹlu ajọ ọtelẹmuyẹ ilẹ Amẹrika, FBI, lati foju awọn afurasi naa lede.
"O ni ""Ni osẹ meta sẹyin ni orilẹ-ede Amẹrika kọwe siwa lati ranwọn lọwọ lọna lati mu awọn afurasi oni jibiti."
"Iwadii ti a ṣe fi yewa pe, Joseph yi ti jẹ anfani owo jibiti, ti oye rẹ to ọgọta milliọnu naira, ti wón fi ranṣẹ lati ori ẹrọ ifoworanṣẹ Western Union."""
Bi ẹ o ba gbagbe, laipẹ yii ni ajọ FBI fi orukọ ọgọrin eniyan lede ti wón fi ẹsun kan wi pe, wọn ṣe gbajuẹ nilẹ Amẹrika,  ti ọpọlọpọ wọn jẹ ọmọ Naijiria.
Ibaṣepọ to wa laarin ajọ EFCC ati FBI ni Magu sọ pe o ti n so eso rere bayii.
Lagos Police: Àwọ̀n ọlọ́kadà 123 láti Jigawa kìí se àwọn agbésùnmọ̀mì
Oríṣun àwòrán, Twitter/The Lagos State Govt
Kini aduru gbogbo ero yii n bọ wa ṣe lEko lati ariwa ni ibeere awọn eniyan
Ile iṣẹ ọlọpaa ni ipinlẹ Eko ni awọn ti fi awọn ọlọkada to le ni ọgọfa to wa lati ipinlẹ Jigawa wa si ipinlẹ Eko silẹ nitori wọn kii ṣe ọdaran.
Agbẹnusọ ile-iṣẹ ọlọpaa ni ipinlẹ Eko, Bala Elkanah ni awọn gbe igbeṣẹ naa leyin ti awọn ti ṣe iwadii iru eniyan ti wọn jẹ.
Elkanah fikun un wi pe lara awọn ọgọfa yii ti wa ni ipinlẹ Eko tẹlẹ. amọ ti wọn lọ si ile, ti wọn si padawa si Eko ni ibi ti wọn ti n ṣe iṣẹ ojo wọn.
Bakan naa lo ni ko si ewu kankan nitori ounjẹ ojo wọn ni awọn ti wọn mu naa wa wa si ipinlẹ Eko.
Adari eto to n bojuto ayika ni ipinlẹ Eko, Yinka Egbeyemi ti ni awọn ọlọkada to le ni ọgọfa to wa lati ipinlẹ Jigawa wa si ipinlẹ Eko kii ṣe agbesunmọmi tabi ọdaran.
Egbeyemi lasiko to n ba BBC sọrọ ni pe iwadii awọn fihan wi pe irọ patapata ni iroyin to sọ pe awọn agbesunmọmi ti wọ ipinlẹ Eko.
Ninu ọrọ rẹ, O ni idi ti awọn fi fi oju wọn lede ni lati fi ọkan awọn eniyan balẹ wi pe ko si ewu loko longẹ, ati pe awọn ọlọkada to wa ni ọgọọrọ si ipinlẹ Eko, wa ṣiṣẹ ounjẹ ọjọ wọn.
Amọ, o fikun un wi pe ko ba ofin ipinlẹ Eko mu, ki ọgọọrọ eniyan wọ ipinlẹ Eko lati ṣiṣẹ wiwa ọkada lai ni iwe aṣẹ tabi papakọ ti wọn ti n ṣiṣẹ.
Adari eto to n bojuto ayika ni ipinlẹ Eko naa wa parọwa si awọn eniyan lati fi ọkan balẹ wi pe, ko si ẹwu fun awọn ara ipinlẹ Eko ati wi pe o ṣeeṣe ki wọn fi awọn ọlọkada yii silẹ laipẹ.
Ibeere nla ti awọn eniyan ipinlẹ Eko n beere ni pe kini gbogbo wọn fẹ wa ṣe ni Eko?
Ajọ to n ri si imọtoto ayika atawọn iwa ọdaran mii nipinlẹ Eko (Lagos State Environment Sanitation and Special Offenses Taskforce) ti mu awọn ọdọmọkunrin mẹtalelọgọfa ti wọn n bọ wa siluu Eko lati ipinlẹ Jigawa pẹlu alupupu wọn ti ọpọ mọ si okada lọjọ Ẹti.
Alaga ajọ LSESSOT, Yinka Egbeyemi ṣalaye pe ajọ naa mu awọn eeyan naa pẹlu ọkọ akẹru ti wọn wa ninu rẹ lagbegbe Agege lẹyin tawọn olugbe ilu Eko kan ta wọn lolobo pe ihuwasi awọn ọdọmọkunrin naa le ṣakoba fun eto aabo niluu Eko.
Ajọ naa gbe awọn ọkunrin naa lọ si olu ileeṣẹ wọn l'Oshodi fun ifọrọwanilẹnuwo lẹyin ti wọn mu ọkọ ti wa ninu rẹ.
Ọkan lara wọn, Shuaibu Haruna sọ pe iṣẹ l'oun wa wa silu Eko nitori oun ni iyawo ati ọmọ nile.
Haruna ni agbegbe Isolo l'oun fẹ gbe, ati pe oun ti san ẹgbẹrun meje naira fun owo ile fun ibi t'oun fẹ de si nibẹ.
Ẹlomiran ninu awọn ti wọn mu, Mohammed Ibrahim ni tiẹ sọ pe oun wa silu Eko lati ṣiṣẹ lẹyin t'oun ti ṣiṣẹ oko dida tan.
Ibrahim ni ilu Badagry l'oun ti n lọ ba ẹgbọn  to ti n gbe nibẹ tẹlẹ.
Oríṣun àwòrán, Twitter/The Lagos State Govt
Ibrahim ni ilu Badagry l'oun ti n lọ ba ẹgbọn to ti n gbe nibẹ tẹlẹ.
Ọgbẹni Egbeyemi fikun ọrọ rẹ pe awọn mejidinlaadọta ninu wọn ṣalaye pe awọn gbe okada wa lati fi ṣiṣẹ l'Eko nigba tawọn to ku ni awọn wa ṣiṣẹ niluu Eko lati rowo ni.
Alaga ajọ LSESSOT ṣalaye siwaju si i pe awọn o ba ohun to le ṣakoba fun ẹnikẹni lara wọn ṣugbọn o ni iwadii si n tẹsiwaju lori awọn naa.
Daddy Freeze: 'Kátàkárà ni owó orí gbígbà lórí ọmọbìnrin jẹ́'
Oríṣun àwòrán, Instagram/daddyfreeze
Sisọ omo soko ẹru ni gbigba owo ori ìdána nibi igbeyawo -Daddy Freeze
Yoruba bọ, wọn ni dandan lowo ori, tulasi laṣọ ibora. Ṣugbọn Gbajugbaja atọkun eto ori redio, Ifedayo Olarinde ti ọpọ mọ si Daddy Freeze sọ pe owo ẹru ni owo ori sisan lori obinrin tumọ si.
Daddy Freeze sẹleri pe oun ko ni gba owo ori lori awọn ọmọbinrin ti Eleduwa fi ta oun lọrẹ to ba to asiko fun wọn lati ṣe igbeyawo.
O ni owo ori sisan da bi keeyan maa ta tabi ra ọmọbinrin to n lọ sile ọkọ, nitori naa o yẹ kawọn obi dẹkun ori gbigba.
Daddy Freeze to fọrọ yii lede loju opo Instagram rẹ. O ni lootọ ni owo ori sisan wa ninu Bibeli, amọ, ko wa ni ibamu pẹlu ilana ẹsin awọn ọmọlẹyin Kristẹni.
Ọgbẹni Olarinde ṣalaye pe kii ṣe gbogbo nnkan to wa ninu Bibeli lo ba ilana ẹsin Kristẹnu mu.
O fikun ọrọ rẹ pe Bibeli ko sọ nibi kankan pe o di dandan fun ẹnikẹni lati san owo ori niwọn igba to jẹ pe gbogbo awọn onigbagbọ ti di ọkan ṣoṣo ninu Kristi.
O fidi ọrọ rẹ mu lẹ ninu iwe Galatia ori kẹta ati ẹsẹ kejinlọgbọn.
Daddy Freeze ni iṣẹlẹ buruku kan to dabi owo ori sisan ninu Bibeli ni eyi ti Dafidi fi pa igba eeyan to si tun ge nnkan ọmọkunrin wọn nitori o fẹ fi ọmọbinrin Ọba Sọọlu ṣe aya.
Herbal Medicine: Gbígboyè fásítì nínú iṣẹ́ ìṣègùn ìbílẹ̀ dára, àrídájú gbọdọ̀ wà lórí rẹ̀
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Herbal Medicine: Gbígboyè fásítì nínú iṣẹ́ ìṣègùn ìbílẹ̀ dára, àrídájú gbọdọ̀ wà lórí rẹ̀
Kikọ sii nipa iṣegun ibilẹ yoo mu idagbasoke ba eto ilera -Ọjọgbọn Faduyile (NMA)
Ẹgbẹ awọn oniṣegun oyinbo ni Naijiria, (Nigeria Medical Association) ohun to dara ni tawọn ileewe giga fasiti lorilẹ-ede Naijiria ba bẹrẹ si ni fawọn akẹkọọ loye ninu ẹkọ imọ iṣegun ibilẹ.
Aarẹ ẹgbẹ naa to ba BBC Yoruba sọrọ, Ọjọgbọn Adedayo Faduyile sọ pe gbigba oye ninu eto iṣegun ibilẹ ni nileewe giga yoo ṣeranwọ ni ẹka eto ilera.
O yanana ẹ pe a gbọdo gbe igbesẹ to yẹ lori ayẹwo gidi nipa odinwọn ki o to le di ohun tawọn le maa lo lorilẹ-ede Naijiria.
O ni gbigba ẹkọ lori oogun ibilẹ yoo dẹkun ọpọ awọn eeyan ti ko yẹ ki wọn wa nibi iṣegun ibilẹ ti wọn wa nibẹ lọwọ yii.
Dokita Faduyile tun fikun ọrọ rẹ pe kikọ iṣegun ibilẹ ni ileewe giga fasiti yoo jẹ ki gbedeke wa lori odiwọn lilo ogun ibilẹ.
Aarẹ ajọ NMA fikun ọrọ rẹ pe kikọ oogun ibilẹ nileewe yoo jẹ kawọn ọmọ Naijiria ni itọju to peye eleyi ti yoo jẹ ki alaafia jọba.
O ṣalaye awọn to n ṣe oogun ibilẹ le tọ awọn olukọ imọ sayẹnsi ni ileewe sọna nitori ''iwe kọ ni gbogbo nnkaa, ọgbọn ori lo ṣe koko.''
Ṣugbọn Ọjọgbọn Faduyile ni aridaju gbọdọ wa pe bi o ṣe yẹ ki oogun ibilẹ ṣiṣẹ lo ṣe n ṣiṣẹ ko to le di wi pa awọn eeyan yoo maa kẹkọọ gboye lori rẹ ni ileewe giga fasiti.
Minisita keji fun eto ilera, Sẹnẹtọ Olọrunnibẹ Mamora lo kepe awọn ileewe giga fasiti ni Naijiria lati ṣagbekalẹ ẹkọ iṣegun ibilẹ fun eto ilera to peye ni Naijiria.
Sẹnẹtọ Mamora sọrọ naa nibi ayajọ oogun ibilẹ tọdun 2019 niluu Abuja.
A kò fòfin de owó naira tó ti pẹ́ ní Naijiria- CBN
Owo tuntun lo dun lati na
Ọpọ àwọn ọmọ Naijiria ni ẹru n ba lori iroyin to gba igboro kan pe banki apapọ Naijiria, CBN fẹ ko gbogbo owo atijọ nilẹ.
Eyi lo mu BBC kan si Mallam Aaron Musa, to jẹ ọga agba adari ọkan lara awọn banki olokowo Naijiria, iyẹn Guarantee Trust Bank (GTB) lori koko yii.
Mallam yii ṣalaye fun BBC pé aigbọraẹniye lo n yọ awọn eniyan lẹnu lori kiko owo ti ko daa mọ nilẹ.
Iwadii fihan pe awọn agbalagba kọọkan ti n ṣowo da gbese nitori wọn n ṣe paṣipaarọ owo wọn to ti dọti si tuntun ni odiwọn to keere niye.
Ero ara ilu lori owo awọn sẹnatọ Naijiria
Mallam Aaron ni nitootọ ni banki Naijiria kede pe ki awọn gba awọn owo atijọ pada wọle ni gbendeke asiko kan.
O ni ṣugbọn aṣẹ yii ko ye awọn eniyan to ni.
O ni banki CBN gbe ero kan kalẹ lati ṣatunṣe si iye owo ti ijọba n na lapapọ ni igboro. ni eyi ti ero rẹ to miliọnu meji.
Adari banki GTB ṣalaye fun BBC pe banki CBN ti paṣẹ fun gbogbo banki pe wọn ko gbọdọ fun ẹnikẹni tabi ileeṣẹ kankan ni owo to dọti to jẹ owo atijọ mọ.
IMF gba Naijiria níyànjú lórí pàsípààrọ̀ owo Dola
O ni fun idi eyi, ẹni to ni owo ti ko dara mọ nile le koo lọ sile ifowopamọsi to ba wuu lati lọ ṣe paṣipaarọ rẹ si owo tuntun.
Erongba tuntun banki CBN yii ni ṣiṣe afọmo awọn owo Naijiria si eyi to dun lati wo loju.
Ajọ SERAP sọrọ lori owo ifẹhinti awọn oloselu kan
Ni afikun, Mallam Aaron ni ofin wa fun gbogbo banki Naijiria lati paarọ awọn owo atijọ ti awọn eniyan ba ko wa.
O ni o di dandan ki banki tẹwọ gba awọn owo to ti ya tabi to ti dọti pa yii wọle ki wọn si fi owo tuntun sanwo fawọn onibara wọn sita.
Ejo abami to n mu owo ni ajọ Jambu
Oludari yii ṣalaye pe banki CBN ni banki kọọkan a gba owo idapada N200:000:00 fun odiwọn oṣu mẹta ti wọn a fi maa ṣe eto yii.
O ni lẹyin gbendeke yii ni wọn yoo maa ri ẹgbẹrun mejila gba titi wọn yoo fi pari paṣipaarọ odiwọn owo banki kọọkan.
Oríṣun àwòrán, @CBN
Owó lowó n jẹ́, irọ ni pe a fẹ fofin de Naira to ti pẹ
Ogbontarigi nidi iṣẹ ifowopamọsi yii ni koda banki Naijiria ti yọ owo ori kuro fun oṣu mẹta fun gbogbo baniki ki awọn le ri koriya fun igbesẹ owo didọti gbigba wọle yii.
O ni koda iyekiye ti ẹnikẹni ba ni to dọti ni ki wọn ko lọ fun paṣipaarọ ni banki ki wọn le maa na owo naira tuntun.
O ni koda to ba wu ọ o le san owo atijọ naa si inu asunwọn rẹ ni banki tabi ki o tun fi ranṣẹ si ara rẹ pada.
Ni ipari, o rọ awọn ọmọ Naijiria tootọ lati ṣe itọju owo naira bi o ti yẹ.
O ni o wu gbogbo banki lati ṣatunṣe si bi awọn eniyan ṣe n ṣe owo naira Naijiria jakujaku.
Ibikunle Amosun: Owo adani ni'ṣẹ ẹran dida, ko kan ijọba
Wo àwọn àwòràn tó làmìlaaka nílẹ̀ Adúláwọ̀ lọ́sẹ̀ yìí
Oríṣun àwòrán, Reuters
DJ Arafat, gbogbo Abidjan wa riri lati bu ọla fun un.
Ẹgbẹlẹgbẹ awọn eniyan ni wọn wa ṣe idaro gbajugbaja olorin n ni DJ Arafat.
Abidjan ni orilẹ-ede Ivory Caost gablejo awọn ero nibi eto isinku ọmọ ódun mẹtalelọgbọn naa to ku nibi ijamba to ni lori alupupu rẹ.
Koda, aarẹ ilẹ Ivory Coast, Alassane Quattara ati Davido gan an wa ni papa iṣere Félix Houphouet Boigny Stadium ti wọn ti ṣe ẹyẹ ikẹyin fun Arafat.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Awọn ogbontarigii olorin ile Afrika ṣe ẹyẹ ikẹyin fun Arafat
Oríṣun àwòrán, EPA
Ọkan lara awọn to n sare fun idije agbaye ṣafihan bi eeyan ṣe le fo pẹlu ara rẹ.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Lọjọ Abamẹta ni Johannesburg ni awọn ti wọn n ja ti n da awọn onworan laraya.
Ni Joannesburg to jẹ olu ilu orilẹ-ede South Africa ni awọn alagbara ti n dan ara wo ti wọn n ja fawọn onworan paapaa awọn ololufẹ.
'Òṣìṣẹ́ Bánkì ni mí l'Amẹ́ríkà kí n tó bẹ̀rẹ̀ Tíátà'
Oríṣun àwòrán, EPA
Arabinrin ọmọ Somali yii, Iman lo n ṣafihan aṣọ yii ninu irin oge rẹ ni Italy.
Lọjọru to kọja ni Iman ara Somalia to n rirnrin oge wọ aṣọ alarabra yii.
O wọọ nibi ajọdun fiimu agbaye to waye ni Vernice ni orilẹ-ede Italy.
Ìsọ̀ oníwe ìròyìn àtàwọn tó ń kà a lọ́fẹ̀ẹ́
Oríṣun àwòrán, AFP
Ogbontarigi osere ọmọ South Africa yii n fayọ ya fọto nipasẹ odo
Gbajugbaja oṣere, Candice Swanepoel to wa lati orilẹ-ede South Africa lo duro ya fọto ninu omi yii.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
D Banj lo gbogo nibi eto Brixton Academy ni London.
Eyi ni ogbontarigi olorin takasufe ọmọ Naijiria, DBanj nigba to n ṣere ni ile iwe giga Brixton Academy ni London lọjọ Aiku.
O ti kọkọ sọ fun BBC pe laipẹ ni iyawo oun a to bimọ ikoko tuntunÀwọn olórin Nàìjíríà kẹ́dùn ikú ọmọ DBanj
Oríṣun àwòrán, AFP
Diẹ lara awọn eniyan ti wọn n ṣajọyọ ọdun Fatchue ni Ivory Coast.
"Odun ""Fatchue"" ni ọdun ti awọn ọmọde fi n palẹmọ de ipo adari lọjọ iwaju."
Oríṣun àwòrán, AFP
Awon omo wonyi ti setan lati bere ikoni si ipo agba leyin odun yii
'Isẹ́ Tíátà tí mò ń se ti tó mi jẹun'
Oríṣun àwòrán, EPA
Awon omo ogun ile n so eranko yii pelu ohun gbogbo ti won ni
Ni orilẹ-ede Kenya ni a ti ri awọn ọmọ ogun ilẹ yii ti wọn n ṣo diẹ lara awọn erinmi ni Kenya.
Won n pese aabo fun eranko yii bo ṣe n wa ibi to maa ye ẹyin si lọjọ Eti to kọja.
Fela ni awokọse mi - Kunle Ajayi
Bobrisky: Ìléeṣẹ́ ọlọ́pàá ṣàlàyé ohun tó gbé wọn dé ibi ìnáwó ọjọ́ ìbí
Oríṣun àwòrán, Bobrisky
Gbogbo aye lo fẹrẹ mọ ọ tan, ọna ti olukuluku gba mọ ọ lo yatọ, Iyẹn Idris Okuneye, Bobrisky.
Ni ọjọ Abamẹta ni okiki kan nipa ayẹyẹ ọjọ ibi Bobrisky to waye lagbegbe Lekki Phase 1 nilu Eko.
Okiki to kan kii ṣe nipa awọn eekan atawọn eeyan jankanjankan to peju-pesẹ sibẹ ṣugbọn pẹlu bi ọgọrọ ọlọpaa tun ṣe ya bo ibi ayẹyẹ naa.
Ṣaaju ninu ọsẹ yii, bi ẹ ko ba gbagbe, ni Bobrisky ati alaga ajọ agbaṣaga lorilẹ-ede Naijiria, National Council for Arts and Culture, Ọtunba Oluṣẹgun Runṣewe ti ta ohùn si ara wọn.
Bi Runṣewe ṣe ni pe Bobrisky n ba oju orilẹ-ede Naijiria loju jẹ naa ni Bobrisky n da a lohun pe, o keere si nọmba nitori awọn to ju u lọ lagbo iṣejọba loun n ba dowo pọ.
Oríṣun àwòrán, Bobrisky
Lẹyin ti ariwo sọ nile loko lori ohun ti ọlọpaa n wa ni ibi ayẹyẹ ọjọ ibi rẹ; agbẹnusọ awọn ọlọpaa ni ipinlẹ Eko, Bala Elkana ṣalaye pe awo iroyin kan to lu si awọn lọwọ lo gbe awọn lọ sibi ayẹyẹ naa.
Amọṣa, ọga ọlọpaa, Ẹlkana ko sọ ni pato awo iroyin to lu si wọn lọwọ naa.
Ileeṣẹ ọlọpaa ti kọkọ fi ikilọ sita ṣaaju ni ibẹrẹ ọdun 2019 pe ki gbogbo awọn abẹya ara kan lo tete wa ibi gba.
Ẹwọn ọdun mẹrinl;a ni ofin kede fun igbeyawo akọ si akọ tabi abo si abo ni Naijiria.
Wọn ni nitori pe awọn ọlọpaa fẹ bẹrẹ si ni ko awọn ọkunrin to n ba ọkunrin lo pọ atawọn obinrin to n ba obinrin lo pọ si inu koto ọlọpaa.
Gẹgẹ bi a si ti ṣe gbọ, ọpọlọpọ awọn ọkunrin to n ba ọkunrin lo pọ atawọn obinrin to n ba obinrin lo pọ ni wọn peju pesẹ si ibi ayẹyẹ ọjọ ibi Bobrisky ti oun pẹlu jẹ akọ ti n ṣe iṣe abo.
Gbogbo igbiyanju BBC lati ba awọn agbofinro sọrọ lori iṣẹlẹ paapaa olobo ti wọn ni ẹnikan tawọn yii ja si pabo
RUGA: Adeboye ní àsìkò tó láti wá nǹkan ṣe sí ọ̀rọ̀ ètò pápá ìjẹko RUGA pátápátá
Oríṣun àwòrán, PastorEAAdeboye
RUGA: Adeboye ní àsìkò tó láti wá nǹkan ṣe sí ọ̀rọ̀ ètò pápá ìjẹko RUGA pátápátá
Bi o tilẹ jẹ pe ijọba apapọ ni awọn ti ṣẹwe le eto idasilẹ papa ijẹko RUGA ni ọsẹ diẹ sẹyin awuyewuye lori eto naa ko dẹkun o.
Ni bayii awọn iranṣẹ Ọlọrun pẹlu ti da si ọrọ naa pẹlu ipe si aarẹ Buhari lati wọgile eto ọhun patapata.
Ọkan gboogi lara awọn iranṣẹ Ọlọrun to sọrọ bayii ni Pasitọ Enoch Adeboye ti ijọ RCCG lagbaye.
Dadi G.O. gẹgẹ bi awọn ọmọ ijọ rẹ gbogbo ṣe maa n pe e, iyẹn Pasitọ Adeboye ni: niwọn igba ti awọn eeyan ba ṣi n jẹ ẹran maalu, awọn fulani yoo ṣi maa ṣe ohun to ba wu wọn.
O sọrọ yii nibi ipade apero awọn iranṣẹ Ọlọrun gbogbo lorilẹ-ede Naijiria to waye niluu Eko.
Pasitọ agba ijọ RCCG naa sọ ọrọ rẹ bi ẹna ati owe ni eyi to jẹ lowe-lowe ni a n lu ilu ogidigbo.
O sọ itan ọrẹ rẹ kan to ni o ṣalaye fun oun ni igba kan sẹyin pe darandaran kan pa arakunrin rẹ, ẹjẹ rẹ si kan si ori koriko ti maalu jẹ, iwọ pẹlu ti kopa ninu iku arakunrin rẹ niyi lọna kan abi omiran.
"Adeboye ni: ""Eeyan kan o le maa pa arakunrin rẹ ki o si tun maa jẹ maalu rẹ."
Ọrẹ mi ni bi o ba gba wọn laaye lati maa da oko ni ẹyinkule rẹ bi o ba ya wọn o le ẹ kuro ninu ile rẹ pẹlu.
"Ọrẹ mi ṣalaye pe bi a ba dẹkun ati maa jẹ ẹran maalu, arakunrin ti o n ta maalu naa a tun ero rẹ pa."""
Oríṣun àwòrán, PastorEAAdeboye
RUGA: Adeboye ní àsìkò tó láti wá nǹkan ṣe sí ọ̀rọ̀ ètò pápá ìjẹko RUGA pátápátá
Ninu ọrọ tirẹ nibi apero naa, aarẹ ẹgbẹ ọmọlẹyin Kristi lorilẹ-ede Naijiria, Ọmọwe Ṣupọ Ayọkunle ni bi eto aabo ṣe di eyi to n ko tẹru-tọmọ laya soke ni Naijiria yii ti di itiju nla gbaa fun awọn ọmọ Naijiria.
"Ẹniọwọ Ayọkunle ni 'ki ijọba fi ofin de ẹgbẹ awọn darandaran Fulani, Miyetti Allah to n ṣe agbodegba fun awọn darandaran fulani to n gbẹmi eeyan kiri ilu."""
Bakan naa lo ni ijọba gbọdọ yẹra fun ohunkohun ti o lee fa iyapa lorilẹ-ede Naijiria.
Laipẹ́, ọmọ tí kò bá pé ọdún méjìdínlógún kò ní leè jáde girama l’Ọṣun
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Laipẹ́, ọmọ tí kò bá pé ọdún méjìdínlógún kò ní leè jáde girama l'Ọṣun
Ọrọ eto ẹkọ awọn ọmọ jẹ wa logun -Owoẹyẹ
Olori ile aṣofin ipinlẹ Ọṣun, Timothy Owoẹyẹ ti fi to awọn eeyan leti pe laipẹ laijinna, ofin kan yoo jade ni ipinlẹ naa eleyi ti yoo kan an nipa fun awọn obi lati rii pe ọmọ wọn pe ọdun mejidinlogun ki wọn to jade ileewe girama.
Họnọrebu Owoẹyẹ ni ọpọ awọn obi ti n ti awọn ọmọ wọn ni itikuti kọja nileewe girama ju bo ṣe yẹ lọ.
Ati wi pe, ti irufẹ awọn ọmọ bẹẹ ba wa de ileewe giga tan lai tii pe ọdun mejidinlogun ti wọn yoo wa maa ba ipenija loriṣiriṣi pade nibẹ.
Bakan naa lo ni bi awọn iṣinwẹẹrẹ akẹkọọ ti ko tii mọ ọwọ ọtun yatọ si osi ṣe n jade nileewe girama bayii lai ni iṣẹ ọwọ kankan ti wọn mọ kun ara ohun ti o n kun wahala aisi iṣẹ lorilẹ-ede Naijiria.
Olori ile aṣofin ipinlẹ Ọṣun ni lẹyin ti wọn ba ṣe ofin naa, yoo wa ọwọ bi awọn ọmọ ti ko ti ja lẹnu ọmu ṣe n jade ileewe girama ni Naijiria.
O ni ipinlẹ Ọṣun kọ ni irufẹ ofin bayii yoo ti kọkọ waye, nitori naa ajọṣepọ yoo wa laarin pẹlu awọn aṣofin ipinlẹ miran lorilẹ-ede Naijiria lati rii pe awọn naa gbe iru ofin bayii kalẹ ni ipinlẹ koowa wọn.
Premier league: Ìjà orogún London, Arsenal ati Tottenham ranjú mọ ara wọn, ṣùgbọn iná ojú wọn kò ran tábà
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Diẹ lo ku ki omi tẹyin wọ igbin Arsenal lẹnu loni nibi ifẹsẹwọnsẹ awọn ati orogun wọn ni ilu Londọn, iyẹn Tottenham.
Tottenham ko fi ojuure wo Arsenal ninu ifẹsẹwọnsẹ naa pẹlu bi wọn ṣe side iya fun Arsenal ni iṣẹju kẹwa ifẹsẹwọnsẹ naa lati ẹsẹ Eriksen.
Ogoji iṣẹju ni Harry Kane, balogun ikọ Tottenham ba tun gba ọkan si.
Ẹgbé agbábóólù orílẹ-èdè Naìjíríà gba ẹbuǹ wúrà ilẹ Afrika
Van Dijk gbadé UEFA mọ́ Messi àti Ronaldo lọ́wọ́
Liverpool kun Arsenal wẹ́lẹ́wẹ́lẹ́ bí ẹran àsun 'lójúbọ' Anfield
Ikú dóró! Agbábọ́ọ̀lù Super Falcons tẹ́lẹ̀, Chiejine jáde láyé lẹ́ni ọdún 36
Wo àwọn eléré ìdárayá mẹ́ta tí àjọ FIFA ti fòfin dè títí ayé
Amọṣa, ṣe awọn agba bọ wọn ni bi ẹṣin ba da ni aa tuu gun ni. Ki ifẹsẹwọnsẹ naa to wọ isinmi fun saa akọkọ ni Lacazette, atamatase Arsenal da ọka pada ninu rẹ.
Arsenal jẹwọ ọmọ ọkọ fun Tottenham ni abala ikeji ifẹsẹwọnsẹ naa ṣugbọn pẹlu gbogbo kirakita wọn, goolu kan ṣoṣo ti Aubameyang gba wọle nikan ni wọn ri dimu eyi to ko wọn yọ ninu itiju naa.
Ori lo ko Tottenham pẹlu yọ lọwọ ogun atẹyinja ṣugbọn ṣa wọn sun iya ta lagba niluu London di ọjọ mii, ọjọọ re.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Bi ọrọ orogun adedigba ni ifẹsẹwọnsẹ laarin Arsenal ati Tottenham maa n jẹ nitori ifigagbaga awọn mejeeji lori mimọ tani alagbara ẹkun ariwa ilu London, eyi ti a ms si North London.
Ireti ọpọ lori ifẹsẹwọnsẹ naa ko kuku ja sofo nitori bi ajere lo ṣe gbona janjan ṣugbọn lẹyin o rẹyin.
Ninu awọn ẹgbẹ agbabọọlu mẹfa to maa n du ipo mẹrin akọkọ lori atẹ igbelewọn liigi ilẹ Gẹẹsi, iyẹn Manchester city, Liverpool, Arsenal, Manchester United, Chelsea ati Tottenham, Manchester city pẹlu  Liverpool  nikan lo bori ninu ifẹsẹwọnsẹ wọn lopin ọsẹ yii, ọmi ni Manchester United ati  Chelsea ta ninu ifẹsẹwọnsẹ tiwọn to waye lọjọ satide.
Leah Sharibu ṣì wà láàyè - Iléeṣẹ́ Aarẹ Buhari
Oríṣun àwòrán, @others
Ori Leah ko ni sun lakata awọn boko haram nigbagbọ awọn obi ẹ.
Ijọba Naijiria ni Leah Sharibu ko tii ku -Garba Shehu.
Leah Sharibu ni akẹkọbinrin ile iwe giram Dapchi ti awọn oniṣẹ ibi boko haram kọ̀ lati tu silẹ.Leah Sharibu pé ọmọ ọdún 16 ní àhámọ́ Boko Haram
Wọn ji akẹkọbinrin to le ni ọgọrun un gbe ni Government Girls Science and Technical school nipinlẹ Yobe loṣu keji ọdun 2018Dapchi School ṣí padà lẹ́yìn oṣù mẹ́sàn án.
Lẹyin eyi ni wọn tu wọn silẹ ‘Bí ẹ se gba Zainab sílẹ̀, ẹ gba Leah Sharibu lọ́wọ́ Boko Haram’ ki boko haram to mu Leah silẹ pẹlu iroyin pe o kọ̀ lati gab ẹsin Islam ni tipatipa.Àyájọ́ ọmọbìnrin gba gbogbo ayélujára tán
Olubadamọran fun aarẹ Buhari lori eto iroyin ati ifitonileti gbogbo, Garba Shehu lo sọrọ itunu yii pe ijọbamọ pe Leah ṣi wa laaye.
O ni ijọba kọ̀ lati sọ ireti nu lori ọdọmọbinrin naa. Shehu sọrọ yii lọjọ abamẹta nilu Abuja.
Boko Haram yóò dá Leah sílé
Garba Shehu ni kaka ki ijọba Mohammadu Buhari sọ ireti nu, ijọba ṣẹṣẹ n gbe awọn igbesẹ tuntun ni lati ri Leah Sharibu gba pada lọwọ awọn oniṣẹ ibi boko haram.
Olubadamọran aarẹ ni iroyin ofege lo pọ ju ninu nkan ti awọn eniyan n sọ nipa Leah Sharibu.
O ni ijọba ṣi n sọrọ pẹlu awọn alakatakiti ẹsin Islam, ISWA lori fifi Leah Sharibu silẹ.
Garba ni awọn ajọ eleto aabo Naijiria fi n da wọn loju pe Leah ṣi wa laaye ati pe irọ ni pe o ti kú.
O ni ki awọn eeyan fun ijọba ni asiko diẹ sii nitori pe ijọba ko fẹ ṣi ẹsẹ gbé lori gbigba ọmọbinrin naa silẹ lakata awọn ISWA ni.
O ni gbogbo awọn ti awọn oniṣẹ ibi yii ji gbe nijọba ni lọkan lati gab pada sile.
Wike sí Ganduje: 'Èmi kìí ṣe dọ́là tó le kó sápò'
Bótilẹ̀ jẹ́ pé ẹgbẹ́ ọtọọtọ ni Wike àti Ganduje wà síbẹ̀ ìpínlẹ̀ àwọn méjèjì lo ṣe pàtàkì ni Nàìjíríà.
Gómínà ìpínlẹ̀ Rivers Nyesom Wike, ní Gomina ìpínlẹ̀ Kano ń dógbọ́n láti lo ọ̀rọ̀ mọsálási tí kò ṣẹlẹ̀ láti maa dá rúkèrúdò òṣèlú sílẹ̀.
Nínú àtẹjáde  kan ti agbẹnusọ rẹ̀ Simeon Nwakaudu fí síta sàlàyé pé Gómìnà Ganduje ń sọ̀rọ̀  sàkàṣàkà nípa ìpínlẹ̀ Rivers.
Ní ọjọ́ Jimọ ní ìpínlẹ̀ Kano gbe àtẹjáde kan sítà pé òun ń ró láti gbe gómìnà ìpínlẹ̀ Rivers lọ sí ilé ẹjọ́ nítori ọ̀rọ̀ mọṣálási ti wọ́n wó ni àgbègbé Trans-Amadi ní ìlú Port Harcout.
Nígbà ti BBC ló síbẹ̀ láti wo ǹkan to ṣẹ̀lẹ̀ kò rí ilé kankan ti wọ́n wó lóri ilẹ̀ náà
"Nwakaudu nínú àtẹjáde rẹ̀ sọ pé Ganduje ò mọ̀ pé gòmìnà Wike kìí ṣe ""dọ́là tí Ganduje lé kò sápò bó ṣe wùú."""
Ó ń tọ́ka si fọ́nran kan tó jáde lọ́dún to kọjá níbi ti Ganduje tí ń ko dọ́la sápò, nígbà ti ti ọkunrin kan tí wọ́n pe ni kọgila tó ń ko owó fun Gbanduje.
Kò sí ẹni to ọ̀rọ̀ náà yé ìdí ti Gomina Ganduje fi karabọ ọ̀rọ̀ mọ́salási ti kìí ṣe àwọn ní wọ́n kọ́ọ
Imaamu àgbà mọsálási Trans-Amadi yìí ń rọ ìjọba ìpiínlẹ̀ Rivers láti fí ilẹ̀ náa sílẹ̀ fún àwọn
Gbọ́n misi omi o tó láàrin gómìnà alágbára méèjèjì tí wọ́n wà ni ẹgbẹ́ òṣèlú ọtọ̀ọ̀tọ yìi jẹ́ ǹkan to lè da ìjà ẹsin silẹ̀ lórilẹ̀-ède Naijiria.
Ẹsìn onigbàgbọ́ lo wọ́pọ̀ jùlọ ní ìpinlẹ̀ Rivers nígbà ti mUsulumi pọ ní ìpiínlẹ̀ Kano.
Ńkan akọkọ to ṣe kókó ni pé kò tílẹ̀ si ilé kankan tàbi pé wọ́n ti kóle si orí rẹ̀ rí wọ́n kan n pe ni mọsálási gbogboogbo ti ó wà ni Trans-Amadi ti wọ́n si ti n fa ọ̀rọ̀ náà láti bi ọjọ́ mẹ́ta.
Ìbẹ̀  jẹ́ ibi ti àwọn musùlùmí maa n dárijọ si láti kírun, èyí lo si jẹ ki  wọ́n lérò pe ilẹ̀ àwọn ní.
Imaamu àgbà mọsálásí Tran-Amadi  Haroon Mohammed sọ pé láti ọdún 2007 ní àwọn ti ra ilẹ̀ náà lọ́wọ́ ọkunrin Kan.
Gómìnà àná ní ìpínlẹ̀ Rivers Chibuike Amaechi tí wó àwọn ilé o wà ni àgbègbè Rainbow ni Trans-Amadi níbi ti ilẹ̀ náà wà. Nítori pé ibẹ̀ jẹ́ àdúgbo tí wọn kọ ilé pako sí ti kò si ni ètò kankan tẹ́lẹ̀, gẹ́gẹ́ bi ijọba ṣe ni agbára lati wó ibi ti ko ba bóju mu, ìjọba fi kun nígbà náà pé àwọn ni ètò míràn fún àdúgbò náà.
Èyí ni àdúgbo ti àwọn musulumi àti ìjọba ìpínlẹ̀ Rivers ń gbe gọ́nmisi omim o tó lé lọ́ri.
Láti ìgbà náà ni àwọn Musulumi àti ijọba ti ń fa ọ̀rọ̀ náà ti wọ́n si ti wọ́ àra wọ́n ló si ile ẹjọ́.
Àwọn ìhà méèjèjì ná ló si n sọ pé àwọn làwọn jàre bọ̀ láti ilé ẹjọ́, kọ́da àwọn ìhà ti Musulumi ná[gbé àwọn ìwé kan jáde ti wọ́n fi ti ọ̀rọ̀ wọ́n lẹ́yìn pé àwọn jàre ẹjọ́ náà.
Lásìkò ti Wike náà sí orí ilẹ̀ náà, sàlàyé pé àwọn jare bọ ti àwọn Musulumi si ti pe ẹjọ́ kòtẹmilọ́rùn
Ǹkan to dáju lóri ọ̀rọ̀ náà ni pé àwọn musulumi maa n lo ill náà láti gbàdúrà , sùgbán nigba kúùgbà ti wan ba ti fi ìpill ilé lélẹ nibẹ̀, ìjọba yóò wa láti tu gbogbo rẹ̀ ká.
Di last one wey happun na on 20 August and na from dat time di tok begin say di Rivers state goment scata di Mosque.
Eyí tó ṣẹ̀lẹ̀ gbẹ̀yìn yìí lo wáye ni ogúnjọ́ oṣù kẹ́jọ ọdun yìí, àsìkò yìí ni ẹjọ́ bẹ̀rẹ̀ pé ìjọba ìpínlẹ̀ Rivers wo mọsálásí Trans-Amadi
Góminà Wike náà si ti sàlàyé pe wọ́n ti fi ofin de ilẹ náà pé wọ́n o lé kọ ǹkankan sóri rẹ̀.
Bayelsa, Kogi Election: APC ní yóò jáwe olúbori
Oríṣun àwòrán, @tinubu
Òṣùsù ọwọ̀ ni a o fi ọ̀rọ̀ náà ṣe láti gbá gbogbo ìdọti àtẹyìn wá dánu láti jáwé olúbori ni Kogi
Olóri ẹgbẹ́ òṣèlú All Progressives Congress lórilẹ̀-èdè Nàìjíríà Asiwaju Bola Ahmed Tinubu ní ẹgbẹ́ òṣèlú APC ni yóò fẹ̀yìn gbogbo ẹgb míràn janlẹ̀ nínú ìdìbò gómǹà ti yóò wáyé ni Bayelsa àti Kogi.
Lóri pe boya gomina Kogi Yahaya Bello ṣe dáradára ni ìpínlẹ̀ Kogi ni sáà tó n lò lọ yìí, Tinubu ni tí kò ba sí ìhà tó ń fapajánu, èyí tumọ si pe kò si ijọba àwa àrawa.
O pọ́ndandan kí a tẹti si ariwo ọja nítori pe oniruuru eso ló wà nibẹ̀ bẹ́ẹ̀ náà lo ṣe ri pé ẹka oniruuru ni o wa ninu ọja, sùgbọ́n ẹgbẹ́ oní ìgbalẹ̀ yóò sọ ara rẹ̀ dí òṣùṣù ọwọ̀ láti gbá gbogbo ìdọti àti ẹyin wá dànù èyi si ni à ó lò lati jáwe olú bori
Lagos State: Ìjọba ìpínlẹ̀ Eko ní irọ́ ni àjọ EIU ń pa pé ìlú Eko ló léwu jùlọ láti gbé lágbàáyé
Lagos State: Ìjọba ìpínlẹ̀ Eko ní irọ́ ni àjọ EIU ń pa pé ìlú Eko ló léwu jùlọ láti gbé lágbàáyé
Ilu Eko kọ lo lewu julọ lati gbe lagbaye, koda ilu Eko wa lara awọn ilu ti eeyan le gbe pẹlu ifọkanbalẹ nilẹ Afirika.
Kọmiṣọna fun eto iroyin, Gbenga Omotosho ninu atẹjade to fi sita lọjọ Aiku ṣapejuwe iroyin kan ninu eyi ti ajọ Economist Intelligence Unit (EIU) fi lede pe ilu Eko lo lewu julọ lati gbe lagbaye gẹgẹ bi aimọkan.
Ajọ naa ṣe agbeyẹwo ọgọta ilu lagbaye pẹlu lilo odiwọn ti wọn pe ni Safe Cities Index lori ọrọ eto aabo, ilera ati ohun amayedẹrun.
Kọmiṣọna Omotosho ṣalaye pe iwa ọdaran ti dinku nipinlẹ Eko lati igba ti ijọba ti da ajọ pataki kan silẹ.
O ni ajọ eleto aabo Lagos State Security Trust Fund (LSSTF), to n ri si eto aabo ẹmi ati dukia awọn eniyan nipinlẹ Eko yii n ṣiṣẹ bo ti yẹ.
Ọgbẹni Omotosho ni idi ni yii tawọn oludokowo ati awọn arinrinajo fi n ṣafẹri ilu Eko.
Kọmiṣọna fikun ọrọ rẹ pe ''ilu Eko jẹ ilu kan tawọn alejo fẹran lati maa wa nitori awọn eti okun to rẹwa atawọn oriṣiiriṣii iṣẹ to wa l'Eko.''
Bakan naa lo sọ pe ibugbe idokowo nla l'Eko jẹ fawọn gbajugbaja oniṣowo papaa julọ pẹlu ọpọ eeyan to n gbe niluu Eko.
Ọgbẹni Omotosho ni ti ilu Eko ba jẹ ilu to lewu julọ lati gbe lootọ, awọn eeyan bi aarẹ ilẹ Faranse, Emmanuel Macron ati abẹṣẹ-ku-ojo Anthony kò ba tíi ṣe abẹwo wa silu Eko laipẹ.
Eko Aromisa lẹgbẹlẹgbẹ, Eko Akete, Eko ilu ọgbọn jẹ diẹ lara oriki ilu Eko.
VAT: Kò sí àǹfàní kankan tí ìjọba ti ṣe fún mi sẹ́yìn
Muhammadu Buhari: Iléẹjọ́ tó ga jùlọ bẹ̀rẹ̀ ìgbẹ́jọ́ ẹ̀sùn ayédèrú sabuké Buhari
Oríṣun àwòrán, Twitter/Presidency
Muhammadu Buhari: Iléẹjọ́ tó ga jùlọ bẹ̀rẹ̀ ìgbẹ́jọ́ ẹ̀sùn ayédèrú sabuké Buhari
Lẹyin ti wọn ti lọ ilẹ ẹjọ giga tẹlẹ, ẹjọ Buhari n bẹrẹ nile ẹjọ giga julọ ni Naijiria.
Lonii ọjọ Aje, ọjọ keji, oṣu kẹsan an ni ileẹjọ to ga julọ ni Naijiria yoo gbẹjọ kotẹmilọrun tawọn kan pe wi pe Aarẹ Muhammadu Buhari ko koju oṣuwọn to lati dije ninu ibo aarẹ oṣu keji, ọdun 2019.
Ẹjọ naa da lori ẹsun ti wọn fi kan Buhari pe o parọ lori awọn iwe ẹri rẹ to fi ṣọwọ si ajọ eleto idibo, INEC ṣaaju idibo gbogboogbo to lọ.
Ọgbẹni Kalu Kalu Agu, Labaran Ismail ati Hassy Jyari El-Kunis lo gbẹjọ naa lọ siwaju ileẹjọ to ga julọ, lẹyin ti ileẹjọ kotẹmilọrun fi ontẹ lu bi Buhari ti jawe olubori ninu idibo aarẹ ọjọ kẹtalelogun, oṣu keji.
Oludije fun ipo aarẹ fẹgbẹ oṣelu PDP, Alhaji Atiku Abubakar naa sọrọ nipa iwe ẹri Aarẹ Buhari ninu ẹsun to fi kan an niwaju igbimọ igbẹjọ to n ri si awuyewuye lori eto idibo gbogboogbo ọdun 2019.
Ṣugbọn awọn eeyan mẹta yii ti gbe Buhari lọ si ileẹjọ giga l'Abuja lati ọdun 2018 ninu eyi ti wọn ti sọ pe aarẹ Buhari ko ni awọn sabuke to sọ fun ajọ INEC pe oun ni.
Amọ, Adajọ Ahmed Mohammed ti ile ẹjọ giga l'Abuja tu ẹjọ naa ka lọjọ keji, oṣu karun un, ọdun 2019  lẹyin to sọ pe ko lẹsẹ nlẹ.
Igbimọ ile ẹjọ kotẹmilọrun ti adajọ Tinuade Akomolafe-Wilson dari wọn naa tu ẹjọ kotẹmilọrun ti wọn pe ka lọjọ kejila, oṣu keje.
Lọjọ kẹrinlelogun, oṣu keje ni agbẹjọro awọn mẹta to pe Buhari ọhun, Ukpai Ukairo gbe ọrọ naa lọ siwaju ile ẹjọ to ga julọ.
VAT: Kò sí àǹfàní kankan tí ìjọba ti ṣe fún mi sẹ́yìn
Texas shooting: Ọlapàá ní Seth Ator tó pa ọ̀pọ̀ èèyàn ní Texas ṣẹ̀ṣẹ̀ pàdánù iṣẹ́ rẹ̀ ni
Oríṣun àwòrán, Instagram/sethator
Ileeṣẹ ọlọpaa niluu Odessa lapa iwọ oorun ipinlẹ Texas lorilẹ-ede Amẹrika ti fi orukọ agbebọn, Seth Aaron Atorto to yinbọn fawọn eeyan to to bi ogun lọjọ Satide sita.
Iṣẹlẹ iṣekupani ọhun eleyi ti eeyan marun un ti gbẹmi mi waye laarin ilu Odessa ati Midland nipinlẹ Texas.Wọ́n ti pa ẹni to yìnbọn pa ará Texas márùn ún -ọlọ́pàá
Alawọ funfun ni Ator jẹ, bẹẹ ni ọmọ odun mẹrindinlogoji si ni.
Iroyin to tẹ wa lọwọ lati orilẹ-ede Amẹrika sọ pe laipẹ yii ni iṣẹ bọ lọwọ Ọgbẹni Ator, eleyi to fihan pe o ṣeeṣe ki inu si maa bi lọwọ nitori o ṣẹṣẹ padanu iṣẹ rẹ.
Okunrin naa ni wọn ni o n wa mọto rẹ lọ lati agbegbe Midland si Odessa ni ipinlẹ Texas nigba to ṣadeede yinbọn pa agbofinro to kọkọ da ọkọ rẹ duro ko too tun kọju ibọn sawọn ero atawọn awakọ nibẹ.
Iroyin ni kete to yinbọn fawọn ero tan lo fi ọkọ ara rẹ silẹ to ji ọkọ awọn to n gbe lẹta tó si salọ.
Nigba to maa fi de Cinema Complex lo ko oni tiẹ nigba ti ọlọpaa miran gbebọn fun un.
ÌP&ID: Ẹgbẹ́ àgbáríjọpọ̀ ajàfẹ́tọ̀ọ́ fẹ̀hónú hàn l'Abuja lórí ìdájọ́ tó gbẹ́sẹ̀ lé $9.6bn ohun ìní Nàìjíríà
Oríṣun àwòrán, Twitter/UK High Commission
Naijiria ko ni owo ti orilẹ-ede kankan le gba lasiko yii - Awọn oluwọde.
Agbarijọpọ ẹgbẹ ajafẹtọ kan ti wọn pe ara wọn ni Coalition of Civil Society group ṣewọde lọ si olu ileeṣẹ ilẹ Gẹeṣi  l'Abuja.
Wọn lọ fẹhonu wọn han lori idajọ ileejọ to fun ileeṣẹ Process and Industrial Development laṣẹ lati gbẹsẹ le ohun ini orilẹ-ede Naijiria to le ni biliọnu mẹsan an dọla.
Awọn olufẹhonuhan naa ni iwọde naa yoo tẹsiwaju fun ọsẹ kan gbako ayafi ti ileẹjọ ọhun ba yi idajọ rẹ pada.
Awọn to n ṣewọde ọun mu orisiiriṣii beba dani ti wọn fi n beere lọwọ ijọba ilẹ Gẹẹsi pe ki wọn wa nnkan ṣe lori ọrọ naa.
Aarẹ ati akọwe ẹgbẹ to n ṣewọde naa, Etuk Williams ati Abubakar Ibrahim ṣapejuwe idajọ naa gẹgẹ idoju otitọ bo lẹ.
Wọn tun ni idajọ ọhun tabuku Naijiria gẹgẹ bi orilẹede olominira.
Wọn rọ Olootu ijọba ilẹ Gẹẹsi, Boris Johnson pe ko gbaruku ti Aarẹ Muhammadu Buhari lati gbogun ti iwa ajẹbanu.
Lẹyin wakati kan ti wọn ti ṣe ifẹhonu han ni wọn fun oṣiṣẹ olu ileeṣẹ ilẹ Gẹẹsi kan ni lẹta ti wọn mu dani.
Bakan naa wọn tẹsiwaju ifẹhonu han wọn lọ si olu ileeṣẹ orilẹ-ede Ireland lagbegbe Maitama l'Abuja.
PDP Kogi Primaries: Tá ní àwọn ọmọ ẹgbẹ́ yóò gbé áṣíà gómìnà ìpínlẹ̀ Kogi lè lọ́wọ́?
Oríṣun àwòrán, Facebook/Wada/Grace Adejoh/Dino Melaye/Musa Wada
Ta ni yoo jamọ lọwọ?
Eewọ, mo kọ lati jawọ ninu idije yii - Dino
Bi awọn eniyan ṣe n foju sọna fun eto idibo lati mọ ẹni ti yoo jade dupo gomina ipinlẹ Kogi labẹ asia PDP ṣe n sunmọ ni iroyin kan jade pe Dino ti kuro ninu awọn oludije.
Dino Melaye ọkan pataki lara awọn to n dije dupo gomina naa ti ni ahesọ lasan ni pe oun ti yọwọ ninu idije naa.
Dino ti ni irọ nla ni eyi nitori pe aja kii jẹ obi, oun ko le yọ kuro bii ọmọ ọwọ̀ ninu idije naa.
Oríṣun àwòrán, @Dino
Mo kọ lati jawọ nini idije
Diẹ lo ku ti idibo abẹle ẹgbẹ oṣelu People's Democratic Party nipinlẹ Kogi yoo waye.
Idibo naa ni yoo ṣe atọna oludije ẹgbẹ ti yoo kopa ninu idibo gomina ti yoo waye lọjọ kọkanlelogun, oṣu Kọkanla, ọdun 2019.
Idije naa yoo pakasọ ti awọn onwoye si ti ni ko ti le si ẹnikan to le fọwọ sọya pe oun ni igba naa yoo ja mọ lọwọ.
Oludije mẹtala ni yoo kopa ninu idibo abẹle naa ti a si ri ninu wọn gomina nigba kan ri nipinlẹ Kogi, Ibrahim Wada ati gbajugbaja oloṣelu Sẹnẹtọ Dino Melaye.
Awọn oludije mọkanla miran ni wọn yoo jijọ figagbaga. Grace Adejoh nikan ni oludije obinrin to wa lara wọn.
Ipa ẹlẹyamẹya ninu idibo Kogi
Oṣelu ipinlẹ Kogi lati igba iwasẹ jẹ eleyi ti ẹya ma n ko ipa ribiribi ninu rẹ.
Bakan naa si ni ipinlẹ naa ko ti i yan obinrin sipo Gomina ri lati igba ti wọn ti ṣe idasilẹ rẹ.
Lara awọn ẹya to wa nipinlẹ naa la ti ri ẹya Igala to saaba maa n dipo gomina mu ti awọn ẹya to ku a si maa di ipo igbakeji gomina tabi omiran to ba bọ si wọn lọwọ mu.
Gomina Yahaya Bello ti ẹgbẹ APC ni gomina ẹya Ebira akọkọ ti yoo de ipo naa ti ko si jọ wi pe o fẹ fi ipo naa silẹ bayi.
Oríṣun àwòrán, Facebook/Grace Adejoh
Obinrin kan soso to wa lara awon oludije
Ibrahim Wada to ti jẹ Gomina tẹlẹri jẹ ẹya Igala lati Dekina ti o si fidirẹmi lọwọ Abubakar Audu ẹgbẹ PDP ninu idibo gomina to kọja.
Iku lo yọ ọwọ Audu lawo ti Yahaya Bello fi jẹ gomina gẹgẹ bi ẹni toṣe ipo keji ninu idibo abẹle ẹgbẹ.
Dino Melaye naa wa lara awọn ti o n lewaju lati ri asia ẹgbẹ PDP gba fun ipo gomina ti awọn kan si ni o ṣeeṣe ki o ri i gba.
Dino Melaye ni Sẹnẹtọ to n ṣoju Kabba/Bunu/Ijumu ni  iwọ orun ipinlẹ Kogi ni ile aṣofin agba lọwọlọwọ.
BBC Yoruba yoo maa mu gbogbo nkan to n ṣẹlẹ nibẹ wa si etigbọ yin:
"Xenophobic Attack:Àwọn ọmọ Naijiria sọ fun South Africa pé ""Ó tó gẹ́"""
Oríṣun àwòrán, Marco Longari
ọpọlọpọ miliọnu ọja ati ohun ini ni wọn ti jo nina
Oriṣiriṣi iroyin lo ti gba ayelujara kan lori ikọlu to n waye lọwọ lorilẹ-ede South Africa.
Awọn ọlọpaa ilẹ South Africa ni ọwọ awọn ti tẹ eniyan mọkanlelogoji ti wọn ni i ṣe pẹlu ohun to n ṣẹlẹ yii.
Wọn ni awọn ti mu awọn eniyan wọnyii si atimọle lataari ile ati ọja awọn ajoji ti wọn n jo nina ni South Africa.
Agbegbe Jeppestown to sunmọ Johannesburg to jẹ ibudo itaja nla gan an ni iṣẹlẹ yii ti kọnilominu julọ.
Milton Nkosi to jẹ akọroyin BBC to wa ni South Africa bayii ṣalaye pe ọpọlọpọ awọn eniyan lo n sa kaakiri Johannesburg.
O ni awọn oniṣẹ ibi kan n ja ṣọọbu ile itaja awọn eniyan ti wọn si n ji ọja wọn ko lọ ti wọn si n jo awọn ile itaja miran ni ina.
Milton ni eyi ti tan de awọn agbegbe miran bii Denver, Malven, Turffontein, Tembisa ati awọn adugbo miran bayii.
Awọn fọnran fidio lori ayelujara n ṣafihan bi wọn ṣe n jo ọkọ nile ita ọkọ ati awọn ile itaja miran.
Awọn agbofinro ti fọn afẹfẹ tajutaju kaakiri pẹlu ayederu ọta ibọn ki wọn le fopin si ia alo-ki-olohun-kigbe to n ṣẹlẹ lọwọ ni South Africa bayii.
Ogagun agba Elias Mawela to jẹ kọmiṣọna ọlọpaa fun ẹkun yii sọ pe awọn ti n da ohun gbogbo pada si ipo.
Ìtàn ìgbésí ayé Winnie Madikizela-Mandela
Titi di asiko yii ko tii si ẹni to le fidiẹ mulẹ irufẹ awọn eniyan to wa nidi iṣẹlẹ buruku yii laarin awọn olugbe  South Africa.
Ìyàtọ̀ tó wà láàrin ìṣesí Nàìjíríà àti South Africa
Minista fun awọn agbofinro, Bheki Cele naa ti ṣabẹwo si awọn ibudo iṣẹlẹ ọhun.
Oun naa bu ẹnu ẹ̀tẹ́ lu awọn to huwa buruku yii pe o ku diẹ kaa to.
Aarẹ orilẹede South Africa tẹlẹri Jacob Zuma
Orin idanimọ South Africa.
Lagos-Ibadan Repair: Àwọn ọ̀ná míràn ti e lè gba jáde tàbi wolé si ìpínlẹ̀ Eko
Oríṣun àwòrán, LASMA
Àtúnṣe òpópónà Lagos-Ibadan àwọn ọ̀ná míràn ti e lè gba
A ti ṣetan lati tun opopona marosẹ Eko si Ibadan ṣe ṣaaju ọdun.
Gẹ́gẹ́ bí ìròyìn ṣe jáde pé apá kan òpópónà márosẹ̀ Lagos-Ibadan yóò di títì pá kí ọdún kérésìmesì, ọ̀pọ̀ ènìyàn tó ń ṣe àmúlò ọ̀nà náà ló si ti ń ke gbàjare pe súnkẹrẹ fakẹrẹ ojú pópó náà kò ṣe fẹnu sọ.
Ilé iṣẹ́ to n ri sí ìgbokegbodo ọkọ̀ ni ìpínlẹ̀ Ogun (TRACE) tí gba àwọn awakọ àti gbogbo àwọn tó n sàmúlò ojú pópó náà láti lo àwọn ọ̀nà yìí.
Babatunde Akinbiyi to jẹ́ agbenusọ ilé iṣẹ́ náà sàlàyé pé nítori àtunṣe to n ṣẹlẹ̀ ní ìhà Berger -Ogun River kí awọn awakọ rin òpópónà Ìyànà ìpájà/ Ota/Abeokuta/Sagamu-Benin Ore.
Bákan náà ní wọ́n tun le gba òpópónà Victoria Island/Lekki/Epe/Ijebu-Ode-Benin/Ore.
Oríṣun àwòrán, LASMA
Lagos-Ibadan Repair: Àwọn ọ̀ná míràn ti e lè gba jáde tàbi wolé si ìpínlẹ̀ Eko
Tàbi  Ikorodu/ Itoikin/ Ijebu-Ode-Benin/Ore
Akínbiyi ni àtunṣe òpópónà oní kìlómítà ẹgbẹ̀ta náà yóò wáye láti ọjọ́ keji, oṣù kẹsàn an sí ọjọ́ kẹẹ̀dógun, oṣù kejila, ọdún 2019.
Bakan naa náà lo rọ gbogbo àwọn arinrinajo láti ṣeto ìrìn wọ́n ki wọ́n tó gun le.
Ìdí ti àwọn kọmísọna ṣe to láti kí ìyáwó gómìnà tuntun káàbọ̀
Oríṣun àwòrán, Shaharudeen Galaje
Gbogb àwọn amúgbálẹgbẹ́ gomina Bauchi àti àwọn kọmisona ló dúro wámuwámu de aya tuntun gomina ṣeṣẹ fẹ́
Ọkan nínú àwọn tó dúro sí pápakọ ofurufu láti gba ìyáwo tuntun ọmọ Lẹbaniisi  tí Gomina Bauchi ṣẹṣẹ fẹ́ sàlàyé pé kò sí ǹkan ti awọn ń se ju pé àwọn ń tèle àṣà àti ìṣe.
Àgbẹ̀nusọ fún gomina Bauchi Bala Mohammed Mukhtar Gidado, sọ fún BBC pé kò sí ǹkan to buru ninu ki àwọn alába siṣẹ gomina lọ pade ìyàwó rẹ̀ ni pápákọ ofurufu àti pé àṣà ní
Agbẹnusọ lori ọ̀rọ̀ ìròyìn, ń fèsi lóri fọto kan to gba ayelujara opo twitter kan nípa bi àwọn kọmisona ṣe ń duro de ìyàwọ tuntun ti gomina Bala Muhammed ṣẹsẹ fẹ
 Kiìí ṣe gomina lo ni kí a wá dúro de ìyàwó olun , à wá fun ra wa lá gbàá léro láti ṣe bẹ́ẹ̀ pàápaá julọ láti pàde rẹ̀ ni pápákọ ofurufu
Iyawo gomina ni, ẹni ọwọ sì ni, àsà wa ni lati bu ọlá fun gẹgẹ bi òṣìṣẹ́ gomina. Kò si ǹkan ti àwọn ènìyàn le sọ, kò si ọ̀rọ̀ to tóbi kankan nínú ọ̀rs to wa nilẹ̀ yìí.
Oríṣun àwòrán, Shaharudeen Galaje
Bala Muhammed ni minisita fún ilu Abuja tẹ́lẹ̀
Natasha Mariana ní ìyàwo tuntun ti Gomina Bauchi ṣẹṣeẹ fẹ́, o si dé si ìlú Bauchi fún ìgbà àkọkọ lẹ́yìn ti wọ́n ṣe ìgbéyàwo  ní opin ọ̀sẹ̀ to kọkja
Kìí ṣe gomina Bauchi ni ẹni akọkọ ti yóò gbe ìyawo tuntun ninu àwọn gomina to ṣẹṣẹ gori alef, Gomina ìpínlẹ̀ Yobe Maimala Buni yan aya tuntun lẹ́yin ọjọ kini to wọle gẹ́gẹ́ bi gomina, ọmọ gomina àná ni ìpiínlẹ̀ rẹ̀ náà sì lo fẹ́..
Bakan náà lọmọ sori ní Zamfara, bi gomina àna nibẹ  Ahmed Sani ṣe fẹ́ ọmọ ọdun mẹ́rindinlogun to jẹ́ ọmọ orilẹ̀-èdè Egypt gẹ́gk bi ìyàwo kẹta ko to kurò lori oye.
Oríṣun àwòrán, Efem
Ìdí ti àwọn kọmísọna ṣe to láti kí ìyáwó gómìnà tuntun káàbọ̀
Seyi Makinde: Inú mi dùn láti rí àwọn ìjòyè lẹ́yìn Olúbàdàn
Oríṣun àwòrán, Facebook/Seyi Makinde
Yooba ni ka rin, ka pọ, yiyẹ nii yẹ ni, bẹẹ si ni apọnle ko si fun ọba to da lọ sode.
Idi ree ti ori gomina ipinlẹ Ọyọ, Onimọ ẹrọ Seyi Makinde fi n fo fun ayọ, to si ni ori oun wu pupọ lati awọn agba ijoye ilẹ Ibadan ti wọn kọwọ rin pẹlu Olubadan ilẹ ibadan, Ọba Saliu Akanmu Adetunji, Aje Ogungunnisọ Kinni.
Gomina Makinde, ẹni to woye ọrọ yii lasiko to n side ipade apero lori eto aabo to waye nilu Ibadan lọjọ Aje, wa kan saara, to si se sadankata si Olubadan ati awọn agba ijoye nilẹ Ibadanlori bi wọn se jẹ ki ogun sinmi, ti wọn si gba alaafia laaye.
Awọn agba ijoye naa, ti wọn tẹle owe Yoruba to ni ọba meji kii wa ni aafin, bi o tilẹ jẹ pe ijoye lee pe mẹfa laafin, ni wọn de fila lasan ati ilẹkẹ sọrun lai de ade sori, to si jẹ pe Olubadan nikan ni ade wa lori rẹ.
Oríṣun àwòrán, Facebook/Seyi Makinde
"Ijoko Olubadan naa ati awọn ijoye rẹ to wu oju ri, to si jẹ pe oju gbogbo n wo wọn nibi ipade apero ọhun, lo mu ki gomina Makinde ni ""inu mi dun lati ri awọn ijoye ti wọn kọwọ rin pẹlu Olubadan wa sibi."""
Ọrọ yii lo mu ki awọn eeyan bu sẹrin ayọ, ti wọn si patẹwọ, bẹẹ ni wọn n juwọ si ibi Olubadan ati awọn ijoye rẹ naa joko si.
Bẹẹ ba gbagbe , o ti to ọdun meji ti Olubadan ati awọn agba ijoye nilẹ Ibadan ti dijọ jade sita gbangba papọ bayii, eyi ko si sẹyin wahala to waye nitori bi ijọba ana nipinlẹ Ọyọ se de ade fun awọn agba ijoye mọkanlelogun nilẹ Ibadan.
Lara awọn agba ijoye to kọwọrin pẹlu Olubadan ni Ọtun Olubadan, Agba oye Lekan Balogun, Agba oye Owolabi Ọlakulẹyin, Asipa Olubadan Eddy Oyewọle, Asipa Balogun Olubadan, agba oye Lateef Adebimpe, Ẹkarun Olubadan, agba oye Amidu Ajibade ati Ẹkarun Balogun Olubadan, agba oye Kọla Adegbọla.
SARS Operation in Nigeria: Òṣèré tíátà ń fẹ́ kíjọba pa ẹ̀ka ọlọ́pàá tó ń gbógun ti ìdigunjalè jẹ́
Oríṣun àwòrán, Instagram/dayoamusa
Gbajugbaja oṣere-binrin, Dayo Amusa, ti pe fun fifi òpin si ẹka ọlọpaa to n gbogun ti idigunjale, SARS.
Eyi waye lẹyin ti fidio kan to ṣafihan àwọn ọlọpaa kan tó yinbọn si ọkunrin kan ati idile rẹ, gba ori ayelujara.
Ninu fidio naa, ọlọpaa kan gbé ìbọn lọwọ, ti awọn ọkunrin melo kan ti wọn jọ n ṣe ariyanjiyan si di i mu.
Bo tilẹ jẹ pe nnkan to fa ariyan-jiyan naa ko han si wa, amọ o foju han pe ìbọn ba ọ̀kan lara awọn ọmọde to wa ninu ọkọ ayọkẹlẹ naa, ti awọn ọlọpaa SARS da duro.
Ariwo ẹ ma a gbe lọ sile iwosan lo gba inu fidio naa, ti obìnrin kan to ṣe e ṣe ko jẹ iya ọmọ naa, si n sunkun.
'Mo ni baba isalẹ'
Ọpọ ọmọ Naijiria lo ti bu ẹnu ẹtẹ lu ileesẹ ọlọpaa, nitori fidio naa.
Dayo Amusa ninu fidio to gbe sita naa sọ pe, o ti di iwa ọdaran ni orilẹ-ede Naijiria lati se irun atọwọda Dàda sórí.
Bakan naa lo ni níní tabi gbigbe kọmputa agbeletan (laptop) dani, ati wiwọ aṣọ to ba igba mu, ti di ọ̀ran nla bayii nilẹ wa.
"Awọn ọlọpaa to yẹ ko ma a ṣọ ẹ̀mí ati dukia wa, ti di ẹni to n yinbọn mọ àwọn ọdọ wa, ti wọn si n pa wọn bo ṣe wu wọn, nitori pe wọn ro pe gbajuẹ ni wọn.
Ki wọn ti ẹ jẹ gbajuẹ, ṣe bi ẹ le mu wọn lọ si agọ ọlọpaa..."
"Amusa wa n beere pe ""ṣe bi a o ṣe ma a ba lọ ni yii?"""
Lati bi ọdun diẹ ni ọpọ ọmọ Naijiria ti n polongo pe, ki ijọba o fi opin si ẹka ọlọpaa SARS, nitori awọn iwakiwa to kun ọwọ wọn.
Ifẹ afẹju lo maa n mu iwọ lo n se mi wa, ti ifẹ ba si ju bo se yẹ lọ, o lee fa ija.
Bi ọrọ se ri ree pẹlu ilumọọka osere tiata lobinrin kan, Dayọ Amusa, ẹni to figbe ta loju opo Instagram rẹ pe ki awọn ololufẹ oun jọwọ dakun fi oun lọrun silẹ, nitori itara wọn nipa igbesi aye oun ti pọju.
Dayọ ni oun fẹ gbe ni alaafia, ki wọn si ye wa eekanna mọ oun lọrun nitori pe oun ko tii ni ọkọ tabi di oyun sinu.
Amọ sa, o wa mọriri awsn ololufẹ rẹ ọhun fun ifẹ ti wọn ni si ati ireti ohun rere ti wọn fẹ nipa rẹ, sugbọn o wa rawọ ẹbẹ si wọn pe ki wọn jọwọ fi oun lọrun silẹ lati gbe igbe aye to wu oun.
Ni kete to fi iroyin naa soju opo Instagram rẹ naa lawọn ololufẹ rẹ yii ti bẹrẹ si ni fesi pada fun, ti wọn si n ki pe ohun to sọ dara ati pe Ọlọrun yoo gbọ adura rẹ.
Sugbọn ọkan ninu awọn ololufẹ rẹ yii, John Andrew, @johnandrew1bb, lasiko to n dahun si ohun ti Dayọ Amusa kọ naa lo ni yoo dara ki osere tiata lobinrin naa tete lọ segbeyawo, ko si ni oyun sinu, bẹẹ lo n bi Dayọ pe, se ko mọ bo se sanra to ni.
Oríṣun àwòrán, Instagram/dayoamusa
Andrew wa gba Dayọ  nimọran pe yoo dara ko lọ jo diẹ. O ni se ni pata rẹ maa n tobi to inuwọ ọmọde, ti oun ko si ri Dayọ ri ko wọ pata G-String lati igba to ti n fi pata nla ya fọto.
Ọrọ ti Andrew sọ yii lo fa ibinu awọn ololufẹ awọn ololufẹ Dayọ Amusa yọ, ti gbogbo wọn si n yọ suti ete si ọkunrin naa lara pe ko wii re rara, ti ọpọ wọn si n beere pe ki lo de ti awọn eeyan kii se bọwọ fun awọn gbajumọ lawujọ.
Xenophobic Attack: Awọn ọmọ Nàìjíria tí yarí pé àwọn náà yóò gbẹ̀san
Xenophobic Attack: Awọn ọmọ Nàìjíria tí yarí pé àwọn náà yóò gbẹsan
Àwọn ọmọ Nàìjíría ní ìpínlẹ̀ Eko ti gba ìgbòrò láti kọju ìkora ẹya miràn ti àwọn South Africa ń ṣe fún àwọn ọmọ Nàìjíríà.
Ilé ìtàjà ìgbàlóde Shoprite tí agbègbè Lekki ní ọmọbinrin kan ti gbe ìwé iléwọ láti bu ẹnu àtẹ́ lu ìwá akọlu ti àwọn South Africa n ṣe si awọn ọmọ Nàìjíríà.
Ìyàtọ̀ tó wà láàrin ìṣesí Nàìjíríà àti South Africa
Àwọn míràn tíll ń kigbe pé ki wọ́n dáná sun ilé itaja náà lójùnà àti ranṣẹ́ pada sí àwọn ènìyàn South Africa gẹ́gẹ́ bi ẹsàn.
Tí ẹ o bá gbàgbé àwọn ọmọ orílẹ̀-èdè South Africa tí ń ko sọọbu ti wọ́n sì ń pa àwọn ọmọ Nàìjíríà ni orilẹ̀-èdè wọ́n.
Ìròyìn sọ pé ọ̀pọ̀ àwọn tó ń gba ìgbòro ló ti pàdánù àwọn ẹbí wọ́n nínú wàhàlá tí àwọn ará South Africa ń dásílẹ̀.
Ní bàyìí ìwọde ti bẹ̀rẹ̀ ni ilé ìtaja ìgbàlode ti Ikeja náà.
Ẹ fi ọlọ́pàá wa sáàrin ọlọ́pàá yín ní South Africa fún ààbò àjèjì - ìjọba Nàíjíríà bèèrè
Oríṣun àwòrán, @Julisco_
Ijọba ilẹ Naijiria ti kesi ijọba ilẹ South Africa pe ko yara tete setan lati san owo gba ma binu fun awọn ọmọ Naijiria to fara kaasa ọpọ ikọlu lati ọwọ awọn ọmọ orilẹede rẹ.
Minisita fọrọ ilẹ okeere lorilẹede Naijiria, Gofferey Onyeama lo tẹ pẹpẹ ibeere naa siwaju asoju ijọba ilẹ South Africa to ransẹ pe laarọ oni.
Bakan naa lo koro oju si ijọba ilẹ South Africa pe o mọọmọ n fi ọrọ titi ọwọ bọ iwe adehun igbọraẹniye laarin orilẹede mejeeji falẹ.
Iwe igbọraẹniye ọhun lo wa lati wa ojutu si bi awọn ọmọ ilẹ South Africa se maa n kọlu awọn ajeji to wa lorilẹede wọn.
Bakan naa tun ni ijọba Naijiria n beere lọwọ ilẹ South Africa pe ko fi awọn ọlọpa Naijiria sinu awọn ọlọpa ilẹ South Africa, ki wọn si tun wa lara awọn asoju ilẹ wa ni South Africa.
Oríṣun àwòrán, @Iam_MarkPaul
Ẹnu lasan ko le dẹkun ọrọ bi awọn ọmọ bibi orilẹede South Afrika se n kọlu awọn ajeji, taa mọ si Xenophobia, eyi to ti wa n di lemọ-lemọ bayii, ayafi ki ijọba Naijiria gbe igbeṣẹ to lagbara lori rẹ.
Eyi ni ero aṣoju ilẹ Naijiria sorileede Uganda tẹlẹ ri, Ambassador Omolade Oluwateru, ẹni to tun ti jẹ igbakeji gomina tẹlẹ nipinlẹ Ondo.
Ẹ́ gbọ Oluwatẹru siwaju si:
Amb.Oluwateru:Oju bọrọ kò ṣé gbọmọ lọ́wọ́ ekurọ South Afrika lori Xenophobia
Ambassador Oluwateru daba yi gẹgẹ bii lọna abayọ nigba to n ba BBC Yoruba sọrọ, nipa ariwo to gbode lori bi awọn ọmọ orileede South Africa ṣe n dẹyẹ si awọn ọmọ Naijiria.
Oluwateru ni o ṣeni laanu pe orileede South Afrka ti Naijiria ti ṣe loore to pọ, ni yoo ma wa fi ẹ̀yin ọbẹ jẹ Naijiria niṣu.
Oríṣun àwòrán, @Julisco_
O ni bi ọwọja idẹyẹsi yii ti ṣe wa peleke bayi, ijọba Naijiria gbọdọ gbe igbese to le, ki South Afrika ba le mọ pe ko fi ọwọ yẹpẹrẹ mu ẹmi awọn ọmọ ilẹ rẹ lẹyin odi.
''Lẹyin ti Naijiria ba parọwa si South Afrika ti wọ́n ko gbọ, ohun to yẹ ni ki wọn paṣẹ ki aṣoju Naijiria ni South Afrika pada wa sile ni kiakia''
O tun ṣalaye pe ti igbeṣẹ yii ba kọ ti ko dẹkun ọrọ naa, ki Naijiria ti ileeṣẹ asoju South Afrika to wa ni Naijiria pa, ki wọn si da aṣoju wọn pada si ilẹ wọn.
Oríṣun àwòrán, Facebook/otunba.omoladeoluwateru
Oju bọrọ ko ṣe gbọmọ lọwọ ekurọ South Afrika
Nigba ti a beere boya Naijiria le gbe awọn ọmọ ilẹ rẹ to wa ni South Afrika pada wa sile, Otunba Oluwateru ni o ṣeeṣe ṣugbọn kii ṣe gbogbo eeyan naa ni yoo fẹ pada wa sile.
''Awọn miran le e ni iṣẹ ti wọn n ṣe nibẹ ati pe, ti a ba gbe wọn pada, ki ni wọn fẹ́ maa wa ṣe nile? Ẹkọ gbigbona lọrọ yi, o gba ki a fi suuru to''
Kini Ijọba Naijiria ti ṣe?
Lọwọlọwọ bayii, ijọ̀ba orilẹede Naijiria ti ransẹ ke si asoju ijọba ilẹ SZouth Africa to wa ni naijiria si ibi ipade kan.
Bakan naa, Minisita fọrọ ilẹ Okeere, Geoffrey Onyeama loju opo Twitter rẹ, ti wa bẹnu atẹ lu iṣẹlẹ yii, to si ni Naijiria yoo gbe igbesẹ to peye lori ọrọ naa.
O ni o to gẹ bi wọn ti ṣe n dana sun awọ́n ile itaja ọmọ Naijiria lorileede South Afrika.
Sugbọn ọpọ Naijiria lo n woye pe ijọba orilẹede yii ko tii se ohun to yẹ, to ba si fẹ dẹkun ikọlu yii, o gbọdọ san sokoto rẹ ko le ni.
Oríṣun àwòrán, MICHELE SPATARI/AFP/GETTY
Ija ti awọn ọmọ South Afrika gbe koju awọn ọmọ Naijiria ti la ọpọ ẹmi ati dukia lọ
Igi gogoro ma gun mi loju, ati okeere la tii wo o, o wa to asiko bayi ki ijọba Naijiria wa wọrọkọ fi ṣada lori ọrọ ikọlu South Afrika sawọn ọmọ Naijiria to n di lemọlemọ bayii.
Eyi ni ero ọkan ọpọ ọmọ Naijiria loju opo Twitter lori iwa idojule ti awọn ọmọ South Afrika n hu si awọn ọmọ Naijiria nilẹ wọn.
Kaakiri oju iwe iroyin ati loju ayelujara ni iroyin ati fọnran fidio orisirisi ti n ṣe afihan bi wọn ti ṣe n doju ija kọ awọn ọmọ Naijiria ati ọmọ ilẹ Afrika miran.
Idunkoko awọn ọmọ South Afrika mọ awọn ọmọ orileede Afrika miran lẹnu ọjọ mẹta yii jẹ ohun to n fọwọ kan ọpọ eeyan lẹmi.
Oríṣun àwòrán, @Iam_MarkPaul
Lara awọn to ti ke gbajare yii la ti ri gbajugbaja sọrọ sọrọ nii, Daddy Freeze, ti o ni oun ko ni ra ọja kankan to ba jẹ ti orileede South Afrika mọ.
Arabinrin Faithe marere da lohun pada ti o si darukọ awọn ile itaja ti o jẹ ti South Afrika, to yẹ ki awọn ọmọ Naijiria dẹyẹ si.
Ink_Hart ni ọrọ yii ko yọ ẹni kankan silẹ lara ọmọ Naijiria.
Ero ọkan gomina banki apapọ ilẹ wa, CBN Akinsola naa ko yatọ.
Idẹyẹsi awọn ọmọ ilẹ Afrika lati ọwọ awọn ọmọ South Afrika ko ṣẹṣẹ ma waye.
Lọpọ igba ni awọn ọmọ Naijiria ti ma n farakasa iṣẹlẹ yii ,ti o si ti ma n mu ki awọn eeyan kesi ijọba awọn orilẹede mejeeji lati mu opin ba iru iwa yii.
Pupọ awọn ileeṣẹ South Afrika lo ti pẹka de Naijiria ti wọn si n ri ere tabua lọdọ awọn eeyan Naijiria.
Eyi wa lara ohun ti o mu ki awọn eeyan Naijiria ma faraya, bi awọn ọmọ South Afrika ko ti ṣe ni ẹmi amumọra fun awọn eeyan miran.
Ọlọ́kadà Jigawa: Ìjọba Eko ti wá mọ́lé lọ́nà àìtọ́, a fẹ́ owó ‘gbà má bínú’
Oríṣun àwòrán, Twitter/The Lagos State Govt
Kini aduru gbogbo ero yii n bọ wa ṣe lEko lati ariwa ni ibeere awọn eniyan
Awọn eniyan mẹtalelọgọfa lati ipinlẹ Jigawa to wọ ipinlẹ Eko lẹkan soso pẹlu ọkada wọn, ti n beere fun biliọnu kan naira lọwọ ijọba ipinlẹ Eko pẹlu ẹsun pe wọn fi iya jẹ wọn.
Awọn eniyan mẹtalelọgọfa naa ni ile-isẹ eto aabo ayika ni ipinlẹ Eko fi panpẹ mu, ti wọn si fi ọrọ wa lẹnu wo, lẹyin ti awọn eniyan ta ile-isẹ aabo naa lolobo pe, awọn eniyan wọ ipinle Eko ni ọgọọrọ.
Agbẹjọro fun awọn ọlọkada naa, Abdullahi Yakubu sọ wi pe, ijọba ipinlẹ Eko gbọdọ san owo gba ma binu fun wọn, nitori wọn ti wọn mọle lọna aitọ, lai se pe wọn jẹ ọdaran.
Bakan naa ni wọn n beere fun ọkada wọn ati awọn ohun to jẹ ini wọn, ti ile-isẹ ọlọpaa ipinlẹ Eko gba lọwọ wọn lasiko ifọrọwanilẹnuwo.
Awọn ọlọkada naa ni itimọle awọn tako ofin Naijiria to fun awọn ọmọ bibi orilẹede yii ni anfaani lati lọ lati ipinlẹ kan si omiran, lai si ẹru tabi ipalara.
PDP Kogi Primary: PDP yóò yan olùdíje tí yóò gbé àsíá ẹgbẹ́ fún ipò gómìnà
Oríṣun àwòrán, Google
Sẹnatọ Dino Melaye wà lára àwọn tó ń díje dupò láti gbé àsíá ẹgbẹ́ náà nínú ìdìbò sípò gómìnà ní Kogi.
Eniyan meje ninu awọn mẹrindinlogun to n dije dupo ninu idibo abẹle ẹgbẹ oselu PDP, saaju idibo sipo gomina ni ipinlẹ Kogi, ti fi ipo silẹ.
Ninu atẹjade ti wọn fi lede, ọkan ninu awọn agbẹnusọ fun ẹgbẹ oselu PDP, Gabriel Aduku sọ wi pe, awọn mẹjo naa fi ipo silẹ fun Gomina ipinlẹ naa tẹlẹri, Idris Wada to n dije dupo ninu idibo abẹle naa.
Aduku ni awọn oludije naa gbe igbesẹ ọhun lẹyin ti wọn se ipade apero nibi ti wọn ti gba awọn eniyan ni iyanju pe, ko pọn dandan ki gbogbo wọn dije dupo ninu idibo abẹle.
Wọn wa rọ wọn lati mu oludije kan gboogi ti yoo le soju won ninu idibo si ipo gomina naa.
Sẹnetọ to n soju ẹkun idibo iwọ oorun ipinlẹ Kogi nile Asofin Agba, Sẹnetọ Dino Melaye wa lara awọn to n dije dupo gẹgẹ bii ẹni ti yoo gbe asia ẹgbẹ oselu PDP ni idibo sipo gomina to n bọ.
Nibayii, gbogbo eto lo di doju ọgbagade ninu ẹgbẹ oselu PDP bayii fun eto idibo abẹnu naa to n waye loni ọjọ Isẹgun.
Oludije to ba si moke ninu awọn oludije PDP yii ni yoo koju gomina ipinlẹ Kogi, Yahaya Bello lati ẹgbẹ oselu APC, ninu idibo gomina ti yoo waye ni Ọjọ Kẹrindinlogun, Osu Kọkanla, ọdun 2019.
Brexit: Àpẹẹrẹ́ burúkú ni ìjọba gẹ̀ẹ́sì ń fi lílẹ̀ -Ọ̀jọ̀gbọ́n Wole Soyinka
Oríṣun àwòrán, @soyinka
Brexit: Àpẹẹrẹ́ burúkú ni ìjọba gẹ̀ẹ́sì ń fi lílẹ̀ -Ọ̀jọ̀gbọ́n Wole Soyinka
Ọ̀jọ̀gbọ́n Wole Soyinka tí ke pé àgbárijọ àwọn orilẹ̀-èdè tí o gba ominira lọ́wọ́ ìjọba gẹ̀ẹ́sì láti gbe ìjgbìmọ ti yóò lọ si ilẹ̀ gẹ̀ẹ́si láti lọ ṣe ìwádìí lóri àṣẹ̀ ti aṣòjú ìjọba ilẹ̀ gẹ̀ẹ́si Boris Johnson pa lọ́sẹ̀ to kọjá láti dá àwọn ilé ìgbìmọ asọfin duró lẹ́yìn iṣẹ́ wọ́n.
Ìgbésẹ̀ Boris Johnson gẹ́gẹ́ bí àwọn kan ṣe ríi dàbi ọ̀nà láti ka àwọn ọmọ ilé ìgbìmọ aṣòfin lápákò kí wan baa le dá ilẹ̀ gẹẹsì dúro láti kurò ni àgbájọ Yúróòpù lábẹ àwọn àyàfi kan ti wọ́n lè gbe sílẹ̀.
Ẹkúnrẹ́rẹ́ èróngbà ọ̀jọ̀gbọ́n Wole Soyinka lóri ìgbésẹ̀ Boris Johnson
"Soyinka fí kún pé ìjọba ilẹ̀ Gẹẹsì ń fi àpẹrẹ ""ti kò dára lélẹ̀"""
Ọ̀rọ̀ lórí Brexit
Àṣojú ìjọba ti sọ pé ààyè yóò pọ̀ fún àwọn ọmọ ilé aṣofin láti jíròrò lóri ọ̀rọ̀ náà, bótilẹ̀ jẹ pé o yé kí ilé jòkó lóri ọ̀rọ̀ náà lọjọ iṣẹ́gun.
Mí o ti lẹ̀ mọ pé lóju ayé mi mo lé rii asoju ijóba ti yóò gbèsẹ̀ lé a[wọn ilé ìgbìmọ aṣofin láti maa pé nílẹ̀ ìgbìmọ láti ṣe iṣẹ́ tí wọ́n yàn wọ́n láti ṣe, kí ni ìtumọ èyí ṣe Oliver Cromwell ti pada dé ní? Syinka lo sọ èyí
"Soyinka fí kún pé ìjọba ilẹ̀ Gẹẹsì ń fi àpẹrẹ ""ti kò dára lélẹ̀"""
Xenophobic Attack: Ìjọba rọ ọmọ Nàìjíríà pé kí wọ́n dẹ́kun kíkọlu iléeṣẹ́ South Africa
Oríṣun àwòrán, Twitter/@Julisco
Okun kii ho ruru ka wa ruru! Bayii ni ijọba apapọ ṣe n parọwa fawọn ọmọ Naijiria pe ki wọn ye kọlu awọn ileesẹ to jẹ ti orilẹde South Africa to wa ni Naijiria lati gbẹsan iṣekupani awọn ọmọ Naijiria lorilẹde naa.
Ijọba ni kikọlu awọn ileeṣẹ orilẹede South Africa ni Naijiria yoo ni ipa ti ko dara lara ọmọ Naijiria ju South Africa lọ.
Minisita fun iroyin ati aṣa, Alhaji Lai Mohammed sọ ninu atẹjade kan pe bawọn ọmọ Naijiria kan ti fi ibinu kọlu awọn ileeṣẹ to jẹ ti orilẹede South Africa lọjọ Iṣẹgun ku diẹ kaato.
Lai Mohammed ni awọn ọmọ Naijiria ni oludokowo lawọn ileeṣẹ orilẹede South Africa, nitorinaa fifi ọwọ ara ẹni ṣera ẹni ni kawọn ọmọ Nigeria maa ba iru awọn ileeṣẹ bẹẹ jẹ.
Bakan naa ni minisita eto iroyin ati aṣa ni ọmọ Naijiria lo pọju ninu awọn oṣiṣẹ ileeṣẹ South Africa to wa ni Naijiria.
O fikun ọrọ rẹ pe awọn ọmọ Naijiria lo maa fori ko ju, ti awọn ileeṣẹ orilẹede South Africa ba di titi pa.
Minisita Aarẹ Muhammadu Buhari ti ran awọn aṣoju si aarẹ South Africa lati fi ẹdun ọkan rẹ han ati lati wa nnkan ṣe si ikọlu ati ikoriira awọn ọmọ Naijiria to n gbe ni South Africa.
Oríṣun àwòrán, Twitter/@Julisco
O ni aarẹ ti sọ fun minisita ọrọ ilẹ okere, Geoffrey Onyeama pe ko ranṣẹ pe aṣoju orilẹede South Africa ni Naijiria pe ko wa sọ tẹnu rẹ, bi o tilẹ jẹ pe aṣoju South Africa oun ti sọ pe ohun to n ṣẹlẹ kii ṣe ikoriira awọn ọmọ Naijiria.
Ẹwẹ, ẹgbẹ oṣelu alako PDP ti kepe ile igbimọ aṣofin agba l'Abuja lati pe ipade pajawiri lori ọrọ naa.
PDP bu ẹnu ẹtẹ lu ijọba Aarẹ Buhari pe ko tete ja ọrọ naa kunra, wọn ni o buru jai pe olu ileeṣẹ Naijiria to wa nilẹ South Africa tun kọ ẹyin si awọn ọmọ Naijiria to sa lọ sibi.
Xenophobia: Àwọn agbófinró dúró sẹ́nu ọ̀nà àbáwọlé Palm Mall Ibadan láti dẹ́kun ìkọlù
Ọrọ ikọlu ti awọn ọmọ Naijiria n se sawọn ileesẹ to jẹ tilẹ South Africa lati fi gbẹsan bi wọn se n kọlu awọn ọmọ Naijiria lorilẹede tiwọn naa, ti wa di ọrọ egbinrin ọtẹ, ba ti n pakan ni omiran n ru.
Idi ni pe lọjọ Isẹgun lawọn eeyan kan to n fẹhonu han morile awọn ileesẹ South Africa to wa nilu Ibadan, ti wọn si kọlu wọn, koda, wọn dana sun ileesẹ MTN to wa ni Bodija, ti wọn si ko ọpọ ẹru olowo iyebiye ni ile itaja Shoprite to wa ni Ring Road.
Niwọn igba to si jẹ pe ina eesi kii jo ni lẹẹmeji, awọn alasẹ ileesẹ Shoprite to wa ni ibudo itaja Palm Halm ni Ribgroad naa, ti wa sọ agadagodo sẹnu ọna ibudo itaja Palm Mall lapapọ lati dena ikọlu ẹẹkeji.
Nigba ti BBC Yoruba se abẹwo si ibudo itaja naa, wa wa wa ni awọn agbofinro gbarodan sẹnu ọna abawọle ibẹ, ti wọn si setan lati wọn esinsin to ba ta firi nibẹ.
Koda, awọn osisẹ ati onibara to fẹ wọle sibudo itaja naa ni jẹbẹtẹ gbe ọmọ le lọwọ nigba ti wọn foju kan awọn agbofinro naa, ti ẹnikẹni ko si lee wọle tabi jade latinu ibudo itaja naa.
Nigba to n ba BBC Yoruba sọrọ, awọn osisẹ ibudo itaja naa salaye pe ọna lati mase jẹ ki itakun kan soso da awọn lepo nu lẹẹkeji lo mu ki awọn alasẹ ileesẹ Shoprite gbe igbesẹ naa, tori owo gọbọi ni wọn padanu lọjọ Isẹgun lasiko ikọlu awọn eeyan to n fẹhonu naa, ti wọn ko ọpọ ọja wọn.
Amọ sa, igbesẹ titi ibudo itaja Palm Mall ti n se akoba nla fun awọn ọmọ Naijiria to ni sọọbu sinu ibudo itaja naa nitori kii se Shoprite nikan lo n ta ọja nibẹ.
Osisẹ agbofinro agba fun ibudo itaja naa, Tony, salaye pe ọpẹlọpẹ awọn osisẹ agbofinro, ninu eyi ta ti ri awọn ọlọpa atawọn aabo ara ẹni laabo ilu (Civil Defence) ti wọn tete pana ikọlu tawọn ọmọ Naijiria se si ibudo itaja naa lọjọ Isaẹgun eyi ti wọn fi n gbẹsan.
Igbakeji Aarẹ orilẹede Naijiria ki kesi awọn adari lorilẹede South-Africa pẹlu ibanujẹ ọkan lati dẹkun ipaniyan nitori ẹya to n lọ lọwọ lorilẹede South Africa.
Osinbajo lasiko to n ba awọn oniroyin sọrọ ni ipinlẹ Kano, sọ wi pe o lodi si igbelarugẹ ẹto ọmọniyan ti awọn adari ilẹ South Africa ja fun ni igba aye wọn.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ọ̀pọ̀lọpọ̀ adarí ní Naijiria ló ti bu ẹnu àtẹ́ lu ìpànìyàn nítorí ẹ̀yà, pàápàá àwọn ọmọ Naijiria ní South Africa.
O ni oun to buru jai ni lati kọju ija si awọn ọmọ Naijiria ti wọn wa ni South Africa bayii, nitori pe Naijiria pẹlu awọn to ja fun ominiran ilẹ naa lọwọ awọn amunisẹru.
Òun tọjú àwọn ọmọ Nàìjíríà n rí ní South Áfríkà kọjá afẹnusọ
Bẹẹ lo wa kesi ijọba orilẹede naa lati dide ati lati wa wọrọkọ fi sada lori ipaniyan naa ki oun gbogbo le pada si ipo.
'Naijiria gbọdọ̀ kọ ìrẹ́pọ̀ pẹ̀lú SouthAfrica '
Bakan naa, Igbakeji Aarẹ Ile igbimọ Asofin to kọja, Ike Ikeremadu ti kesi ijọba orilẹede Naijiria lati jawọ ninu gbogbo irẹpọ pẹlu orilẹede South Africa, titi ipaniyan awọn ọmọ Naijiria lorilẹede naa yoo fi dopin.
Ikeremadu ni o seni laanu pe ijọba orilẹede South Africa fi ọwọ yẹpẹrẹ mu ipaniyan to n waye naa, lo se di ohun to n la ẹmi ọpọlọpọ eniyan lọ.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
‘Naijiria gbọdọ̀ kọ ìrẹ́pọ̀ pẹ̀lú South Africa ’
O wa kesi ijọba Naijiria lati  ri wi pe ijọba ilẹ South Africa da gbogbo ikolọ awọn ọmọ Naijiria ti wọn bajẹ pada, bakan naa ni ki wọn fi imu awọn aseka yii fọn fere.
Ike Ekeremadu naa parọwa si Ajọ isọkan Ilẹ Afirika, Africa Union lati da si ọrọ naa, ki o to di gbọnmi si, omi o to laarin orilẹede mejeeji.
Oyo 2019 Budget: Ìjọba Ọyọ gé ₦282bn owó ìsúná 2019 sí ₦181bn
Oríṣun àwòrán, Oyo Assembly
Ile Igbimọ Asofin Ipinlẹ Ọyọ ti ge owo isuna ọdun 2019 lati biliọnu lọna ọrinlerugba ati meji naira (N282 billion) si biliọnu mọkanlelọgọsan (N181 billion) Naira.
Ọjọ Kẹta, Osu Kẹsan, ọdun 2019 ni Ile Igbimọ Asofin ipinlẹ Ọyọ buwọlu abadofin ti yoo se agbeyẹwo owo isuna ọdun 2019, ti awọn asofin si gba aba naa wọle.
Abẹnugan Ile Asofin Ipinlẹ Ọyọ, Adebo Ogundoyin ni ijọba ana ko se dara to lori eto isuna ọdun 2019, ati wi pe kii se abadofin to le wa si imusẹ ni ipinlẹ naa.
Ọsẹ to kọja ni Gomina Ipinlẹ Ọyọ, Seyi Makinde sọ wi pe eto isuna ti gomina ana, Abiola Ajimobi se kii se isuna ti awọn le e sisẹ le lori.
Xenophobia: Àdúgbò Lugbe kan gbínrín torí ìkọlù àwọn olùfẹ̀hónú hàn
Ọrọ di boo lọ, ko yago fun mi ladugbo Lugbe, nilu Abuja lọjọru nigba ti awọn eeyan kan to n fẹhonu han yari kanlẹ pe awọn yoo sun ile itaja ShopRite to wa ladugbo naa.
Ibudo itaja ọhun ni wọn gbagbọ pe o jẹ ti ọmọ orilẹede South Africa, ti wọn si setan lati gbẹsan ikọlu ti awọn ọmọ ilẹ South Africa n se sawọn ọmọ Naijiria to n gbe lọhun.
Koda, awọn eeyan to n fẹhonu han naa dana si oju popo, ti eefin si gba gbogbo agbegbe naa kan.
Ikọ BBC to se abẹwo si agbegbe naa lọjọru jabọ pe awọn agbofinro ti kalẹ si agbegbe naa, ọpẹlọpẹ wọn ohun ti a n wi yii, kọ ni a ba maa wi.
Se ni awọn agbofinro ọhun tun lo afẹfẹ tajutaju ati omi lati fọn awọn eeyan to n fẹhonu han naa ka, amọ ti wọn n lọ korajọ pọ si ẹgbẹ keji lai lọ sile koowa wọn.
Ọkọ ijagun nla ati kekere si lo wa nilẹ ti awọn ọlọpa gbe wa, ti wọn si n sọ agbegbe ibudo itaja naa bii ajẹ ti n sọ ile Olodumare, pe bi esinsin ba ta firi, awọn yoo wọn.
Bi a se n ko iroyin yii jọ, omi alaafia ko tii toro ni adugbo Lugbe ọhun nitori awọn eeyan to n sewọde ko tii kuro nibẹ.
Ibudo itaja ShopRite naa ti wa sọ agadagodo sẹnu ọna rẹ, to si ti kede pe yoo wa ni titipa fun igba diẹ naa lati dẹkun ikọlu.
Ọrọ ikọlu to n waye sawọn adulawọ ati awọn ọmọ Naijiria lorilẹede South Africa ti bẹyin yọ lọjọ Isẹgun nitori iwa igbẹsan ti awọn eeyan kan nilu Eko gunle.
Oríṣun àwòrán, @Love96047280
Ladugbo Lekki ni iroyin ti gbalẹ kan pe awọn araalu kan to n fẹhonu han ti ya bo ile itaja kan to wa nibẹ, ti wọn si n ko oniruuru ọja lati fi gbẹsan bi awọn ọmọ orilẹede South Africa se n kọlu awọn ọmọ Naijiria.
Ni bayii, osisẹ kan nile itaja naa ti n gbarata loju opo Twitter rẹ pe isẹlẹ naa ti kọja igbẹsan sawọn ọmọ orilẹede South Africa, amọ awa ara wa ni Naijiria la n doju kọ ara wa.
Lily Loveth@Love 96047280 ke gbajare pe awọn araalu ati awọn alaisẹ ni awọn eeyan to n fẹhonu han naa n dojukọ bayii, papaa bi wọn se wa kọlu ibudo itaja ti oun ti n sisẹ.
Oríṣun àwòrán, @Love96047280
O ni ọpọ ọja ti owo rẹ to aimọye miliọnu naira ni wọn ko lọ nibẹ lai jẹ pe ara South Africa lo ni ibudo itaja naa.
Bakan naa lo fikun pe o seese ki oun padanu isẹ oun nitori ikọlu yii, to si n beere pe ki lo de tawọn eeyan naa se n kọlu awọn araalu ti wọn sọ pe awọn n ja fun.
Ẹ gba mi, isẹ ti fẹ bọ lọwọ mi, ọmọ Naijiria lo ni ibudo itaja ti mo ti n sisẹ, kii se ọmọ South Africa, ija yii ti wa dojukọ alaisẹ, ki lo maa n se awọn eeyan dudu gan? Se ni wsn n lo isẹlẹ ikọlu ni South Africa lati boju fi sisẹ ibi.
Lily wa parọwa pe ki awọn eeyan fọwọ wọnu lori isẹlẹ naa, tori ta ba ro didun ifọn, a họra de egungun.
Xenophobia: Alùpùpù ni wọ́n fi gbé epo pẹtiró wá dáná ṣun iléeṣẹ́ MTN
Awọn eeyan kan to n fẹhonu han dana sun ẹka ọọfisi ileeṣẹ ikansiraẹni lati orilẹede South Africa, MTN, to n bẹ ni agbegbe Bodija niluu Ibadan lalẹ Ọjọ Iṣẹgun mọju Ọjọru.
Iṣẹlẹ naa ni ko se lẹyin ikọlu ti awọn ọmọ orilẹede South Africa n ṣe si awọn ajeji to n bẹ nilẹ wọn, ninu eyi ti ọpọ ọmọ Naijiria ti fara gba.
Aṣoju ajọ to n mojuto igbokegbodo ọkọ ni ipinlẹ Ọyọ, Ọgbeni Adeoye Ayọade ṣe alaye fun awọn akọroyin pe, alẹ Ọjọ Iṣẹgun ni isẹlẹ naa waye.
Ayọade ni awọn kan lo gbe alupupu wa, ti wọn si lu awọn ọlọdẹ to n ṣọ ọọfisi naa ni bii aago mẹwa aabọ alẹ ana, lẹyin eyii ni wọn si dana sun ọọfisi ileesẹ MTN naa pẹlu kẹgi ẹpo bẹntiro ti wọn gbe dani.
Ọkan lara awọn eeyan to n kọja lasiko ti iṣẹlẹ naa waye, Ọgbẹni Ademọla fi idi isẹlẹ naa mulẹ pe lasiko ti ohun lọ si ẹnu iṣẹ ni alẹ ana ni ina dede sọ ni ọọfisi MTN ọhun.
Bi o tilẹ jẹ pe ọpọ dukia ileesẹ naa lo jona mọle amọ ko si ẹmi to bọ ninu isẹlẹ ile jijo naa, ti ijakulẹ si ba ọpọ awọn onibara ileesẹ MTN to de sẹnu ọna ileesẹ ọhun ni aarọ Ọjọru.
Òun tọjú àwọn ọmọ Nàìjíríà n rí ní South Áfríkà kọjá afẹnusọ
Se ni jẹbẹtẹ si gbe ọmọ le ọpọ awọn onibara MTN lọwọ nigba ti wọn ri pe ileesẹ naa jona kọja aala.
Xenophophia: Lizzy Anjorin, Yinka Ayefele, Mercy Aigbe sọ̀rọ̀ ìtùnú
Ọrọ ikọlu ti awọn ọmọ Naijiria to wa lorilẹede South Africa n koju ati iwa igbẹsan to tẹle lati ọdọ awọn ọmọ Naijiria ti n ta ọpọ eeyan lara.
Lara awọn eeyan to n gbarata lori bi wọn se n se awọn ọmọ Naijiria ni isekuse ni South Africa ni awọn gbajumọ ati ilu mọọka lawujọ, to fi mọ awọn osere tiata.
Bakan naa ni awọn eekan ilu yii tun n rawọ ẹbẹ sawọn ọmọ Naijiria to n gbẹsan ikọlu ọhun lara awọn eeyan ati ileesẹ to jẹ ti ọmọ ilẹ South Africa to wa ni Naijiria pe, ki wọn bomi suuru mu nitori aforo yaro kii jẹ ki oro tan.
Loju opo Twitter, Instagram ati Facebook si ti kun fun ọpọ awọn ilumọọka yii ti wọn ko kawọ gbera lori isẹlẹ to n waye naa yika orilẹede Naijiria ati ni South Africa.
Loju opo Instagram rẹ, osere tiata lobinrin, Lizzy Anjọrin, ẹni to han loju rẹ pe inu rẹ ko dun si isẹlẹ naa, lo n kesi awọn ọmọ Naijiria pe ki wọn mase gbẹsan ikọlu awọn ara South Africa naa nitori awa ara wa ni ọrọ yii yoo kan julọ.
Bakan naa ni Yinka Ayefẹlẹ, tii se akọrin ẹmi ati sọrọsọrọ lori redio salaye pe iwa igbẹsan tawọn ọmọ Naijiria n se gbọdọ wa sopin nitori ohun ti ko dara, ko dara.
Nkechi Blessing Sunday, toun naa jẹ osere tiata Yoruba naa n rawọ ẹbẹ sawọn ọmọ Naijiria pe iwa ka jo ile itaja, ka ba dukia jẹ kọ ni ọna wiwa ojutu si ikọlu to n waye ni South Africa nitori ara wa la n pa.
Se ni Funke Etti naa n tara poro pe iru ki ni eyi, to si n rọ aarẹ Buhari lati tete dẹkun bi wọn se n pa awọn ọmọ Naijiria ni South Africa.
Ayọ Ajewọle, adẹrinposonu ti gbogbo eeyan mọ si Wolii Agba naa ko kẹyin ninu awọn gbajumọ to sọrọ sita tako ikọlu naa.
Oun naa ni ko dara to bi ijọba Naijiria ba bu ẹẹkẹ diwọ nipa bi wọn se n kọlu awọn ọmọ Naijiria ni South Africa, to si n rọ awọn alasẹ wa lati tete sọrọ sita.
Mercy Aigbe, tii se osere tiata lobinrin naa kesi awọn alawọ dudu lati yee kọju ija si ara wọn nitori iwa ailaju gbaa ni eyi.
Oxfam: Olówó mẹ́ta ní Afirika lówó ju 650m aláìní lọ
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Aarẹ ile aṣofin agba Naijiria nibi to ti joko ti awọn ọkunrin meji lara awọn to lowo julọ ni Naijiria,Aliko Dangote ati Jim Ovia.
Abajade iwadi kan ti sọ pe, owo ti awọn eeyan marun un to lowo ju ni Naijiria ni, le dẹkun oṣi oun iṣẹ lorileede naa.
Ajọ ẹlẹyinju anu ilẹ Gẹẹsi ni Oxfam Charity lo fi abajade yii sita lọjọ Iṣẹgun.
Ninu iwadi naa, wọn ni owo to wa lọwọ awọn ọkunrin mẹta to lowo julọ ni ilẹ Afrika, kọja ti awọn ẹgbẹta le ni aadọta miliọnu alaini to wa nilẹ naa.
Abajade iwadi naa, ti wọn pe orukọ rẹ ni ''A  Tale of Two Continents'' ṣafihan bi iṣẹ ṣe n lọ soke ni Naijiria ati ilẹ ni Afrika, ti aiṣedeede ọrọ aje si tun n da kun iṣoro kikoju aini nilẹ naa.
Bakannaa ni esi iwadi Oxfam tun tọka si bi ọrọ awọn to lowo julọ ni Afrika ṣe n pọ si, ti iṣẹ oun aini si n lọ si oke laarin awọn alaini.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
''Ilẹ Afrika n lewaju laarin awọn ilẹ agbaye gẹgẹ bi ibi ti oṣi oun iṣẹ ti n peleke. Bi iye awọn eeyan to n na owo ti ko to dọla meji lojumọ ṣe n dinku ni ilẹ Asia, bẹẹ lo n pọ si ni Afrika''
Ọga agba ni Oxfam, Winnie Byanyima ni ''Afrika ṣetan lati dagbasoke ṣugbọn ko le ṣeeṣe ti awọn olori ko ba lẹmi lati gbaruku ti awọn to fẹ ṣiṣẹ mu agbega ba araalu dipo awọn olowo''
Esi iwadi naa ṣe agbekalẹ ohun ti awọn orileede Afrika n ṣe lati mu opin ba iṣẹ oun oṣi.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Awọn aworan to ṣafihan aini bayi pọ kaakiri awọn ilẹ Afrika
Orileede South Afrika ati Namibia lewaju ninu ilakaka yii, ti Naijiria si ru póò nilẹ Afrika ati lori akasọ agbaye.
Awọn nnkan miran ti iwadi naa sọ ni pe:
Kogi PDP Primaries: Wada fẹ̀yìn Dino gbálẹ̀ nínú ìbò abẹ́lé PDP fún ìpò gómìnà ní Kogi
Oríṣun àwòrán, Twitter/Dino Melaye
Amoju ẹro Musa Wada la Sẹnẹtọ Dino Melaye mọ lẹ ninu ibo abẹnu ẹgbẹ oṣelu PDP fun ibo gomina ipinlẹ Kogi oṣi kọkanla.
Amoju ẹrọ Wada jawe olubori ninu eto idibo ọhun pẹlu ibo aadọta le ni ẹẹdẹgbẹrin o din meji.
Ọgbẹni Ibrahim Abubakar lo ṣe ipo keji pẹlu mẹwaa le ni ẹẹdẹgbẹrin.
Nibayii, Wada ni yoo ṣoju ẹgbẹ oṣelu PDP ninu ibo gomina ti yoo waye lọjọ kẹriundinlogun oṣu kọkanla ọdun 2019.
Wada yoo ta kaungbọn pẹlu Gomina Yahaya Bello to jẹ ọmọ ẹgbẹ APC atawọn oludigbe ẹgbẹ oṣelu miiran ninu ibo ọhun.
Àwọn èèyàn Yahaya Bello ló da ìbò abẹ́nú wa ní Kogi rú- PDP
Awọn eeyan Gomina Yahaya Bello lo wa fibọn da eto ibo abẹnu ẹgbẹ oṣelu PDP niluu Lokoja ru.
Alukoro ẹgbẹ oṣelu PDP, Kola Ọlọgbọndiyan to ba BBC Yoruba sọrọ, ṣalaye pe ayẹwo ibo lawọn n ṣe lọwọ nigba ti awọn janduku ọhun yabo gbọngan idibo naa ti wọn si bẹrẹ si ni yinbọn pẹrẹpẹ.
Oríṣun àwòrán, Other
Ọgbẹni Ọlọgbọdiyan ni ọpọ eeyan lo farapa nigba tawọn mii si dero ile iwosan ninu iṣẹlẹ ọhun lolu ilu ipinlẹ Kogi ti eto idibo naa ti waye.
O ṣalaye siwaju si pe oun ko le sọ bi Gomina Ahmadu Fintri ipinlẹ Adamawa to jẹ alaga eto idibo abẹnu naa ṣe mo ri bọ nigba tawọn agbebọn dabọn bo lẹ.
Amọ, o fikun ọrọ rẹ pe atundi ibo ko ni waye nitori eto idibo naa si n tẹsiwaju lonii, koda o sọ pe igbimọ eto idibo abẹnu yoo kede ẹni to ba bori ninu idibo abẹnu naa l'Ọjọru.
O ni ohun kan to ku ni lati kede orukọ ẹni to jawe olubori ninu ibo ki wọn to ko ibọn wọ le.
Oríṣun àwòrán, Other
Ọgbẹni Ọlọgbọndiyan sọ pe ni gbogbo igba ti Gomina Bello ipinlẹ Kogi ba ti ri wi pe ẹgbẹ mii fẹ fa eeyan ka lẹ lati koju òun ninu ibo lo maa n da iru eto bẹẹ ru.
Ẹwẹ, ẹgbẹ oṣelu PDP tun kilọ fun Gomina Yahaya Bello ati ẹgbẹ APC pe iwa jagidijagan ko le gba wọn ninu idibo gomina to n bọ ninu oṣu kọkanla.
Ọlọgbọndiyan ninu atẹjade to fi sita lorukọ ẹgbẹ PDP sọ pe mimi kan ko le mi ẹgbẹ naa ohun to wu ki ẹgbẹ APC ṣe.
Lagos State: Ẹbí èèyàn márùn ún àti àlejò kú sínú ilé l'Eko
Oríṣun àwòrán, Twitter/@sagagist
Igbe oro lawọn agbebe lawọn olugbe agbegbe Mafoluku l'Oshodi n ke l'Ọjọru lẹyin ti wọn ba oku eeyan meje pẹlu alejo wọn ninu ile laarọ Ọjọru.
Nọmba 19, Olowora ni awọn ara adugbo Mafoluku ti ri oku ọkunrin kan, ati iyawo rẹ pẹlu awọn ọmọ mẹrin ati alejo wọn ti oyun wa ninu rẹ.
Iroyin ti a gbọ ni pe iṣẹlẹ ọhun waye ninu yara kan tawọn eeyan naa sun si.
Ko si ẹni to mọ pato ohun to ṣe okunfa iku wọn ṣugbọn awọn kan ni o ṣeeṣe ki wọn jẹ majele mọ ọunjẹ.
Ileeṣẹ ọlọpaa ipinlẹ Eko ko gbe ago nigba ti BBc Yoruba pe wọn lati mọ ohun to ṣokunfa iku awọn eeyan naa.
Xenophobia: Ezekwesili ní bá ṣe yanjú ìkọlù South Africa ló fa sábàbí
Oríṣun àwòrán, @obyezeks
Obby Ezekwesili a ma bẹnu atẹ lu awọn igbesẹ ijọba Naijiria lori ọrọ iṣejọba ati aabo ara ilu
Minisita tẹlẹ ri lorilẹ́ede Naijiria,Obby Ezekwesili ti mu alaye bẹnu lori oun to mu lọ kopa ninu ijiroro agbaye lori ọrọ aje to n waye ni South Africa.
Ezekwesili ṣalaye ọrọ yii loju opo Twitter, toun ti bi awọn ọmọ Naijiria kan ṣe n bẹnu atẹ́ lu pe ko yẹ ko lọ nitori ikọlu Xenophobia to n ṣẹlẹ.
Saaju ni ijọba Naijiria ti kede pe, awọn ko nikopa ninu apero naa ti awọn ilumọọka olorin kan naa si ti ni awọn wọgile lilọ si South Afrika lati lọ ṣere.
Ninu ọrọ rẹ Ezekwesili ni oun yoo lo anfaani kikopa ninu apero naa lati daba awọn nkan to yẹ ki ijọba South Afrika ṣe lori isẹlẹ ikọlu sawọn ajeji.
Ajafẹtọmọniyan naa tun tẹsiwaju pe, ko yẹ ki orileede South Africa sa si abẹ ika pe o n gbalejo apero agbaye lai ṣe pe wọn fi ijiya to tọ jẹ.
Amọ ṣa, igbesẹ Ezekwesili yi mu ariwisi ọtọọtọ wa laarin awọn ọmọ Naijiria. bi awọn kan ṣe n gbosuba fun, lawọn miran n bẹnu atẹ lu
Koda, Bashir Ahmad to jẹ oluranlọwọ aarẹ Buhari wa lara awọn to sọ oko ọrọ si Ezekwesili.
Ọrọ naa fẹ ṣe bi itahunsiaraẹni laarin awọn mejeeji yii.
Ibi ti ọrọ naa yoo kangun si ko ti yewa, ṣugbọn eyi to daju ni pe ijọba Naijiria ni, South Africa ti ba doju ẹ ati pe, awọn ko ni mu ni kekere pẹlu wọn.
Yatọ si pe o kọ lati kopa ni apero ọrọ aje to n waye naa, Naijiria tun ti ni ki aṣoju rẹ nilẹ South Africa pada wa sile.
Kaakiri awọn ilu bi Eko, Ibadan, Uyo ati Abuja ni awọn ọmọ Naijiria ti n fi ẹhonu han lori iṣẹlẹ ikọlu ọhun, ti awọn kan si n ba ileeṣẹ ti wọn fura si pe o jẹ ti awọn ọmọ South Africa jẹ.
Gani Fawehinmi: Òní ló pé ọdún mẹ́wàá ti ajàfẹ́tọ̀ọ́ ẹni náà jadẹ́ láyé
Oríṣun àwòrán, @MichaelSolanke3
Iku n pani, ilẹ n jẹyan. Ọjọ Karun osu Kẹsan ọdun 2019 lo pe ọdun mẹwa geerege ti ilumọọka ajafẹtọmọoniyan nii, Gani Fawehinmi jade laye.
Ọjọ Karun, oṣu kẹsan, ọdun 2009 ni Fawehinmi  dagbere faye lẹyin to ti ba aisan jẹjẹrẹ wọya ija fun igba diẹ.
Loju opo Twitter, ọrọ ikini lorisirisi ati iranti nipa igbe aye rẹ ni awọn eeyan Naijiria n fi sita.
Ninu fọnran fidio yi ti EiENigeria fi sita, a ri bi Fawehinmi ṣe n gbejọro niwaju igbimọ Oputa ti ijọba gbe kalẹ, lati yẹ awọn ibaje to waye lorileede Naijiria wo.
Ẹbi, ọrẹ ati awọn ololufẹ ni wọn n ṣeranti Fawehinmi lonii.
Pupo lo n ṣe eemọ ohun ti Fawehinmi ko ba sọ nipa orisirisi nnkan to n ṣẹlẹ ni Naijiria lọwọlọwọ.
Ọmọ bibi ilu Ondo ni Gani Fawehinmi, ta si bi ni ọjọ Kejilelogun oṣu Kẹrin ọdun 1938.
Ile ẹkọ Hoborn College lo ti kẹkọ gboye nipa imọ ofin lọdun 1961.
Oríṣun àwòrán, @AbdulMahmud01
Laarin ọdun 1971 si 1973, o jẹ oye alukoro ẹgbẹ awọn agbẹjọro Naijiria.
Nigba aye rẹ, ọpọ igba ni Gani Fawehinmi ṣẹwọn lori pe o n ja fun ẹtọ ọmọniyan paapa julọ labẹ ijọba ologun Naijiria.
Ṣaṣa ni ọgba ẹwọn ti ko tii gbalejo Gani Fawehinmi, eyi to mu ki awọn eeyan Naijiria fun ni oye ‘agba ajafẹtọ mẹkunnu’, Senior Advocate of Nigerian Masses.
Oríṣun àwòrán, @NuhuRibadu
Gani Fawẹinmi kó ipa to kúrò ni kèrémí fún ìfẹsẹ̀múlẹ̀ iṣejọba alágbádá ni Naijiria
Ọdun 2001 ni wọn fi joye agba ọjẹ amofin ti a mọ si Senior Advocate of Nigeria,SAN da Fawehinmi lọla.
A nwa n gbadura pe ki Ọlọrun dẹ ilẹ fun ẹni re to lọ.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí:
Ooni: EFCC, ẹ se àtúnse sí ìgbé ayé àwọn ọdaràn tẹ bá mú
Ooni ti Ile-Ifẹ, Oba Adeyeye Ogunwusi ti ní ó seése kí àwọn ọdaràn má mọ ìjàmbá tí wọ́n ń se fún ará ìlú.
Ọọni ti Ile-Ifẹ, Oba Adeyeye Enitan Ogunwusi, ti kesi Ajọ to n gbogun ti iwa ibajẹ lorilẹede Naijiria, EFCC pe ki wọn se atunse lori awọn ọna ti wọn n gba gbogun ti iwa ọdaran lawujọ.
Ọba Ogunwusi ni o seese ki awọn ọdaran yii ma mọ ijamba ti wọn n se fun ara ilu, nitori naa, ti ọwọ ba tẹ awọn afurasi ọdaran wọn yii, ki wọn se ifọrọwanilẹnuwo fun wọn daadaa.
Ọba Ogunwusi gbe imọran ọhun kalẹ lasiko to n gbalejo awọn osisẹ agba ajọ EFCC ni aafin rẹ nilu Ile Ifẹ.
Bakan naa, ni Ọọni tun ke gbajare lori bi iwa ọdaran se peleke si ni ipinlẹ Ọsun, to si kesi awọn ọdọ lati jawọ ninu iwakiwa, bẹẹ lo tun kesi ajọ naa lati fi agbara kun bi wọn se n gbogun ti iwa ọdaran ni awujọ.
Ninu ọrọ ti wọn, ajọ EFCC naa wa rọ Oba Adeyeye Ogunwusi lati kesi awọn ọba ni ile Yoruba, ki awọn naa tiraka lati gbogun ti iwa ibajẹ ni agbeegbe wọn.
Governors 100 days: Gbadamosi ní àwọn ojú ọ̀nà Eko ń bàjẹ́ si lásìkò Sanwo-Olu
Ayẹyẹ loniranran n waye kaakiri awọn ipinlẹ ti wọn ti burawọle fun awọn gomina wọn ni ọgọrun ọjọ sẹyin, lẹyin idibo gbogboogbo to waye ni ọdun 2019.
Bakan naa ni awọn araalu n se agbeyẹwo isẹ ti awọn ijọba yii ti se laarin osu mẹta ti wọn ti de isejọba ipinlẹ wọn.
Oríṣun àwòrán, LASG
Ọpọ eto nijọba ipinlẹ Eko ti la kalẹ lati fi se ayẹyẹ ọgọrun ọjọ ti gomina Babajide Sanwo-Olu di gomina.
Lara iru awọn eto bẹẹ si ni sisi akanse isẹ kikọ ilegbe olowo pọọku kan tijọba Eko se agbatẹru rẹ to wa ladugbo Igando., ti gomina naa si tun ya biliọnu mẹrin naira sọtọ bii owoya okoowo alabọde fawọn ọmọbibi ipinlẹ naa.
Ko tan sibẹ, ijọba Sanwo-olu tun ti gboogun ti iwa dida idọ̀ti ni aibikita ni Eko to si ti se agbende awọn ajọ kolẹkọdọti ti wọn ti wọgile tẹlẹ pada, to si tun ti ro ajọ̀ LASTMA to n se amojuto eto irinna nipinlẹ́ Eko lagbara si.
Sugbọn lero ti oludije gomina labẹ asia ẹgbẹ oselu Action Democratic Party (ADP) ni ipinlẹ Eko, Babatunde Gbadamosi, ko si nkan pato ti isejọba ẹgbẹ APC naa ti se laarin ọgọrun ọjọ ti wọn ti bẹrẹ isejọba saa yii.
Babatunde Gbadamosi ni ko si atunse kankan to de ba awọn oju ọna to wa ni ipinlẹ Eko, ati wi pe awọn ti ijọba san owo fun lati se ọna naa dabi ẹni pe wọn ko owo naa jẹ lai se isẹ kankan.
Bakan naa lo ni awọn ọna yii ti ko dara lo n fa sunkẹrẹ-fakẹrẹ ọkọ ni awọn opopona to wa nipinlẹ Eko.
Oríṣun àwòrán, Babajide Sanwo-Olu
O fikun wi pe, awọn eniyan ko ri ile gbe, bẹẹ ni wọn n sun si abẹ titi, ati wi pe ipinlẹ Eko tun dọti ju ti tẹlẹ lọ ni saa yii.
Amọ, gbogbo igbiyanju wa lati ba Kọmisọnna fun Eto Iroyin, Gbenga Omotoso sọrọ, ki o le fesi si awọn ọrọ yii lo jasi pabo nitori ko gbe ẹrọ ilewọ rẹ, nigba ti a pe e.
Bakan naa ni gomina Seyi Makinde naa ti n pokiki bẹbẹ to ti se laarin ọgọrun ọjọ to ti n tukọ ipinlẹ Ọyọ.
Kọmisana feto iroyin ati asa nipinlẹ Ọyọ, Ọmọwe Wasiu Olatunbosun, lasiko to n ba BBC Yoruba sọrọ ni ijọba Seyi Makinde ti se gudugudu meje, yaaya mẹfa laarin ọgọrun ọjọ to gba ijọba.
Oríṣun àwòrán, Seyi Makinde
Ọlatunbọsun ni Seyi Makinde mu igbelarugẹ ba eto ẹkọ, ilera, owo osu awọn osisẹ, eto ọgbin ati eto aabo.
Ninu ọrọ rẹ, o ni awọn akẹẹkọ ile-iwe alakọbẹrẹ ati girama ko san owo ile iwe mọ ni ipinlẹ Ọyo, ti ẹkọ si ti di ọfẹ gẹgẹ bi Makinde ti seleri lasiko ipolongo ibo rẹ.
Bẹẹ lo ni awọn osisẹ n gba owo osu wọn lasiko, ti awọn ko si fi iya jẹ awọn osisẹ fẹyinti nitori awọn n san owo ajẹmọnu wọn lasiko.
Oríṣun àwòrán, Facebook/Seyi Makinde
Bakan naa lo ni orisirisi alakalẹ lo wa ti awọn ti gbe kalẹ lati mu igbe aye rọrun fun awọn eniyan ipinlẹ Ọyọ ni aarin ọdun mẹrin isejọba Seyi Makinde.
Igbiyanju BBC Yoruba lati gbọ ti ẹnu ẹgbẹ oselu alatako APC nipinlẹ Ọyọ lori isejọba Seyi Makinde laarin ọgọrun ọjọ lo ja si pabo, nitori akọwe ẹgbẹ oselu naa ni ọwọ rẹ di lati ba wa sọrọ.
Iyabo Ojo: Ìjà òṣèré tíàtà nìkan kọ́ nìkọlù South Africa, ti gbogbo wa ni
Oríṣun àwòrán, Instagram/iyaboojofespris
Yoruba ni itẹlẹ idi ẹni kii ri ni ti, asọ to ba si kangun si eegun ni wọn n pe ni Jẹpẹ, ko si si ẹni to lee sọrọ nipa awọn osere tiata, bi kii ba se ẹni to jẹ ara wọn.
Gbajugbaja osere tiata lobinrin, Iyabọ Ojo ti bọ soju opo Instagram rẹ lati gbarata lori ohun ti ọpọ osere tiata n la kọja, to fi mọ ohun gan alara funra rẹ.
Osere tiata naa sọrọ yii nigba to n fesi lori bi eeyan kan to n gbe loke okun, se n bu ẹnu atẹ lu awọn osere tiata ati awọn gbajumọ lawujọ lapapọ pe, ọpọ wọn gbẹnu dani lai koro oju si ọpọ ikọlu tawọn ọmọ orilẹede South Africa n se si awọn ọmọ Naijiria.
"Ninu ọrọ rẹ, Iyabọ ni ""mo wa lorilẹede Naijiria, mo si n sisẹ tọsan-toru, mo n tiraka lati bọ ọpọ eeyan. Ọmọde meje, agbalagba mẹrin ni mo n gbọ, ti mo si ni osisẹ mẹtalelogun to n ba mi sisẹ."""
Oríṣun àwòrán, Instagram/iyaboojofespris
Iyabọ Ojo ni lọpọ igba ni oun maa n rẹwẹsi ninu ọkan, ti ọkan oun si maa n yapa, bẹẹ si pẹlu gbogbo wahala oun yii, oun ko ko ere jọ fun ara oun tabi ni akoko lati sinmi rara.
O fikun pe koda ti oun ba rinrinajo lọ si oke okun, isẹ ni oun tun maa n se bii aago, ti oun yoo si maa ra orisirisi eroja ti oun fẹ wa ta lorilẹede yii nitori ọna kan ko wọja.
Osere tiata naa tun gbarata pe bi o tilẹ jẹ pe ilumọọka osere ni oun, sibẹ, oun n sisẹ kara laisinmi ni, to fi mọ ọpọ akẹẹgbẹ oun, tawọn si n ko okoowo meji, mẹta papọ ki awọn baa lee ri ọwọ mu lọ sẹnu.
N jẹ ẹ mọ bi eyi se lagbara to bi nigba miran, to si tun maa n gba akoko ẹni...igbakuugba ti mo ba si fẹ rẹwẹsi pe n ko se mọ, ti mo ba ranti awọn osisẹ mẹtalelogun ti wọn n sisẹ labẹ mi, ti wọn yoo padanu isẹ wọn, ma tun joko jẹẹ.
Oríṣun àwòrán, Instagram/iyaboojofespris
Iyabọ Ojo salaye pe oun ko kuku lee se awawi lori igbe aye oun yii, nitori aye oun kuku san ju tawọn eeyan miran lọ, ti eeyan ba si mọ inu ro, yoo mọ ọpẹ du, oun sa n ri nkan pawọda, ti oun si n bọ ẹnu awọn eeyan diẹ, tori naa, oun dupẹ lọwọ Ọlọrun fun eyi.
Lẹyin idupẹ yii lo wa bẹrẹ si ni sọ oko ọrọ si ẹni to n bu awọn osere tiata naa, to si ni sebi oke okun ni onitọun fidi kalẹ si, to ti n ri owo na, o wa gba nimọran pe ko lee mọ oun ti ọmọ Naijiria kọọkan n koju lati jẹun ayafi to ba wa gbe ni Naijiria.
O ni yoo dara ki onitọun maa bu ọwọ to tọ fun awọn ilumọọka nitori ko mọ ohun ti awọn n la kọja, ọpọ nkan si lo wa lori ero awọn, idi si ree ti esi aọn si isẹlẹ kọọkan fi n yapa nigba miran.
O ko mọ irora mi, o ko mọ boya a n jẹrora lọwọ aisan kan abi a ni isoro ninu ẹbi wa abi pe wahala jijẹ gbajumọ n pa wa ku lọ, ta kan n tiraka lati bo isoro wa mọlẹ fun araye.
Oríṣun àwòrán, Instagram/iyaboojofespris
Iyabọ ni to ba jẹ pe ijọba wa n gba imọran awọn gbajumọ ni, ko ba ti gba imọran Fẹla, ko to jade laye ati tawọn ilumọọka miran sugbọn ọpọ eeyan maa n yara tete di ẹbi fun ẹlomiran, to si gbagbe pe ika ko dọgba.
"O ni ""o ti su wa ni Naijiria, ta si n sisẹ laagun lati jẹ eeyan, ọpọ ninu awa gbajumọ si lo jẹ mẹkunnu ti ko ni owo lọwọ, bẹẹ ni inu wa ko dun rara, ẹ ma si jẹ ki ohun meremere tẹ n ri lori ayelujara nipa wa tan yin jẹ."""
Iyabọ Ojo wa kadi ọrọ rẹ nilẹ pe gbigbe ija ara wa kii se isẹ awọn gbajumọ nikan, gbogbo wa lo kan,to ba si jẹ pe ikọlu to n waye lorilẹ ede South Africa ka onitọun lara, yoo dara ko kuku maa bọ pada wa sile, ki gbogbo wa dijọ pawọpọ mu ayipada rere ba orilẹede yii.
Toyin Abraham: Àwọn ohun tó yẹ ko mọ̀ nípa Toyin Abraham
Oríṣun àwòrán, Toyin Abraham
Oni ọjọ Karun osu Kẹsan ọdun 2019 ni ayajọ ọjọ ibi gbajugbaja osere ori itage lobinrin nni, Toyin Abraham, odu si lo jẹ lagbo ere tiata Yoruba ati tawọn oloyinbo.
Toyin ti se ọpọ ere ori itage to pa ni lẹrin, kọ ni lọgbọn to si tun fun ni loye lati igba to ti darapọ mọ ere tiata naa.
Gẹgẹ bi a se kaa loju opo ikanni agbaye Wikipedia, ọpọ iroyin ti jade nipa arẹwa obinrin ọhun eyi to wu ni lori ati eyi to ku diẹ kaato, amọ awọn iroyin miran tun wa nipa rẹ ti ẹ ko tii mọ, eyi ta fẹ fi to yin leti.
Ko ti pe osu kan to bimọ tuntun naa ni oun naa tun se ọjọ ibi yii, ta si n gbadura fun pe ẹmi rẹ yoo se pupọ ọdun laye.
Xenophobia: Àwon ọmọ Nàìjíria ni aláìníṣẹ́ nìkan ló leè bá bàálù ọ̀fẹ́ padà wálé
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Xenophobia: Àwon ọmọ Nàìjíria ni aláìníṣẹ́ nìkan ló leè bá bàálù ọ̀fẹ́ padà wálé
Awọn ọmọ Naijiria kan to n gbe ni orilẹede South Africa ti sọ pe, wọn ko tii ṣetan lati fi ilu naa silẹ lasiko yii.
Ninu ọrọ ti diẹ lara awọn ọmọ Naijiria naa ba BBC Yoruba sọ, awọn ọmọ Naijiria naa ni kiko wa sile kọ lo kan, ipẹtu saawọ ni ọna abayọ si ọrọ ọhun.
Ọgbẹni Fẹmi Ọshin, to jẹ adari eto kan lori afẹfẹ lorilẹ ẹde South Africa sọ wi pe, ko si ninu ipinnu oun lati pada si Naijiria lasiko yii bi o tilẹ jẹ pe ijọba gbe baalu ọfẹ silẹ.
Ọshin salaye pe oun ni iṣẹ, dukia ati mọlẹbi ni orilẹede South Africa, ti ko si le e rọrun lati kẹru sọkọ lasiko yii.
Awọn ọmọ Naijiria naa wipe, ayafi alainisẹ ati awọn ti iwe igbelu wọn ko pe nikan lo le tẹkọ leti pada si ile.
Ninu alaye yii ni wọn ti fi idi ọrọ mulẹ pe, awọn ti da ile isẹ silẹ ti wọn si ti gbeyawo pẹlu ni South Africa.
Oríṣun àwòrán, @cobbo3
Fẹmi tun ni awọn to ba pada sile lasiko yii lee jẹ lara awọn ti o ti nifẹ lati pada sile tẹlẹ, kii ṣe nitori ikọlu to n ṣẹlẹ lakoko yii.
Lero ti Damilola Oluwatuyi, to jẹ oniṣowo ọkọ, oun naa fariga pe oun ko ṣetan lati pada sile.
O ni oun ti n gbe ni orilẹede naa fun ọdun die, ti oun si gbe ọmọ South Africa ni iyawo, bẹẹ ni ko ṣeeṣe lati dede kẹru.
Ni pari ọrọ rẹ, o ni ko si ikọlu ni agbegbe ti oun n gbe ni Johannesburg, nitori naa, oun ko ṣetan lati pada si orilẹede Naijiria.
Robert Mugabe: Awọn olori orilẹ́èdè àgbáyé ṣèdárò akọni tó lọ
Oríṣun àwòrán, @TuckersCokeDen
Aarẹ orilẹede Naijiria nigbakan ri, Oluṣegun Ọbasanjọ ti sọ pe, iku aarẹ Zimbabwe ana, Robert Mugabe jẹ adanu nla fun gbogbo ilẹ adulawọ lapapọ.
Obasanjọ lo sọ ọrọ yii nigba toun ba ileeṣẹ BBC Yoruba sọrọ.
O salaye pe Robert Mugabe jẹ ajijagbara ti o mọ pataki ki eeyan ja fun ominira.
Aare Obasanjọ wa kẹdun iku aarẹ ana ọhun, o si tun sọ pe yoo soro lati ri ẹni ti yoo lee di alafo ipo ti oloogbe naa dimu nilẹ adulawọ gẹgẹ ajijagbara.
Oríṣun àwòrán, Reuters
Baa ku laa dere, eeyan ko sunwọn laaye.
Awọn olori orilẹede Lagbaye ti n sedaro akẹẹgbẹ wọn, Robert Mugabe to siwọ isẹ ni aarọ ọjọ Ẹti.
Nigba to n daro pẹlu orilẹede Zimbabwe lori ipapoda akọni asaaju naa, aarẹ ilẹ Naijiria, Muhammadu Buhari ni oloogbe naa jẹ ajijagbara to ja fitafita fun ominira orilẹede ọhun, to si fi ọpọ igba aye rẹ sin ọmọniyan.
Ninu atẹjade kan ti amugbalẹgbẹ fun eto iroyin rẹ, Fẹmi Adesina fisita, Buhari ni ọpọ ifiraẹnijin ti Mugabe se, paapa nidi ijijagbara fun ironilagbara awọn eeyan rẹ lẹka oselu ati ọrọ aje ni iran yii ati eyi to n bọ ko ni gbagbe laalae.
Buhari wa gbadura pe ki Ọlọrun dẹ ilẹ fun akọni naa, ko si tun tu awọn ẹbi rẹ ninu lori isẹlẹ adanu nla yii.
Oríṣun àwòrán, Reuters
"Bakan naa ni aarẹ orilẹede Kenya ti se apejuwe Robert Mugabe gẹgẹ bii ""agba awujọ, ajafun ominira orilẹede ati ololufẹ ilẹ adulawọ to se ojuse ti ko kere lati mu atunse ba ifẹ ilẹ adulawọ"""
A maa ranti aarẹ Mugabe gẹgẹ bii onigboya ẹda, ti kii bẹru lati ja fun ohunkohun to ba nigbagbọ ninu rẹ, koda araye koo baa lodi si ero naa.
"Loju opo Twitter tiẹ, aarẹ orilẹede Tanzania, John Mugufuli ti sedaro lede Swahili pe ""Ilẹ Afirika ti padanu ọkan lara awọn akinkanju asaaju, ẹni to tako iwa imunisin lati ipasẹ awọn igbesẹ rẹ."""
"Ko tan sibẹ, aarẹ ilẹ Zambia Edgar Lungu naa ti kede pe ""A maa ranti Mugabe fun  bo se 'fi ẹmi aisibẹru daabo bo ilẹ Afirika'."""
"Loju opo Twitter rẹ, o ni ""oludasilẹ orilẹede Zimbabwe ati ololufẹ ilẹ adulawọ"" naa ni orukọ rẹ ko ni parẹ ninu itan ilẹ Afirika."""
Oríṣun àwòrán, @DavidColtart
Ọpọ awọn eeyan lagbo oselu lorilẹede Zimbabwe, awọn olori orilẹede lagbaye ati awọn eekanlu lawujọ agbaye ti n sọ ohun ti wọn mọ nipa Robert Mugabe.
Eyi to ya ni lẹnu julọ ni bi awọn eeyan kan se n sọrọ ti ko tọ nipa oloogbe naa.
Akọwe fọrọ ilẹ okeere ni ilu Ọba, United Kindom, Emily Thornberry kede pe oun ko lee sun ẹkun kankan nitori pe Mugabe jade laye.
O gba akoso orilẹede to si n se ọpọ ileri...sugbọn nigba to ya lo sina patapata, mo si ro pe o seranwọ lati ba anfaani ti orilẹede rẹ ni lọjọ iwaju lati de ibi giga jẹ.
Bakan naa ni akojọ iroyin kan ni Mugabe ba ọrọ aje awọn alawọ funfun jẹ ni orilẹede Zimbabwe nitori pe wọn ri ọwọ mu ni orilẹede ọlọra naa.
Iroyin naa n se ni iroyin ayọ gba gbogbo orilẹede Zimbabwe kan nigba ti wọn fi tipa yẹ aga mọ Mugabe nidi.
David Coltart tii se oloselu alatako latinu ẹgbẹ oselu MDC lorilẹede Zimbabwe ti kede pe gbogbo ọmọ orilẹede Zimbabwe ni ko ni gbagbe Mugabe nitori iwa ipa ati iwa ajẹbanu to fi silẹ nilẹ naa.
Coltart, ti Mugabe sọ ni suna 'ọta orilẹede' , ks soju opo Twitter rẹ pe wọn ko ni gbagbe oloogbe naa pe ko seese ki eeyan fi oju fo ọpọ asise oloogbe naa lasiko to wa lori oye.
Oríṣun àwòrán, @BrezhMalaba
Nigba ti Robert Mugabe n se abẹmi loke eepẹ, o kọ oniruuru itan manigbagbe to kọja ero ẹda,
Bi o tilẹ jẹ pe ọmọ atapata dide ni Mugabe, ti baba rẹ si jẹ Kafinta, sibẹ ko jẹ ki igbe aye mẹkunnu yii di oun lọwọ lati de ibi giga laye.
Robert Mugabe, tii se olukọ ni ibẹrẹ pẹpẹ aye rẹ, ni oju rẹ ri mabo lọwọ awọn oyinbo amusin ko to di pe orilẹede Zimbabwe, taa mọ si Rodesia tẹlẹ, gba ominira.
Bi ọdẹ ba ku, ọdẹ naa lo n se oro lẹyin ọdẹ.
Ni kete ti iroyin iku aarẹ ana lorilẹede Zimbabwe gba orilẹede agbaye kan, ni ọpọ eeyan ti n se idaro iku rẹ.
Oríṣun àwòrán, @soulkaayza
Niwọn igba to si jẹ pe onikangun ni ikangun, aarẹ to wa lori oye lọwọ-lọwọ bayii, Emmerson Mnangagwa, lasiko to n kede iku ọga rẹ tẹlẹ naa fi tẹdun tẹdun sọ bi iku Mugabe ti kaa lara to.
"Emmerson Mnangagwa, ẹni to daro loju opo Twitter rẹ salaye pe ""akọni fun eto ijijagbara ati  alawọ dudu to nifẹ ilẹ rẹ tọkan-tọkan ni Robert Mugabe nigba aye rẹ."
O ni Mugabe fi gbogbo aye rẹ ja fun ominira ati eto ironilagbara awọn eeyan rẹ ni, ti orilẹede Zimbabwe ati ilẹ Afirika lapapọ, ko si lee gbagbe ipa manigbagbe to ko ninu itan.
Bẹẹ ba gbagbe, Emmerson Mnangagwa lo fi tipa gba ipo aarẹ lọwọ Robert Mugabe pẹlu atilẹyin awọn ologun losu Kọkanla ọdun 2017.
Oríṣun àwòrán, AFP
Ni Zimbabwe, ẹni to lagbara bi ti Mugabe sọwọn
Ni owurọ kutukutu ọjọ Ẹti ni iroyin gbode pe aarẹ tẹlẹ ni orilẹede Zimbabwe, Robert Mugabe ti jade laye.
Ọdun marundinlọgọrun lo loke eepẹ  ki ọlọjọ to de
Robert Mugabe lo ti n gba itọju nile iwosan kan lorilẹede Singapore lẹnu ọjọ mẹta yii.
Lati ọdun 1980 lo ti n tukọ orilẹede Zimbabwe titi wọ ọdun 2017 nigba ti igbakeji rẹ yẹ aga mọ nidi pẹlu atilẹyin ileesẹ ologun.
Ẹ̀ wo àwòrán ìgbé ayé Robert Mugabe!
Àkójọpọ̀ àwọn àwòrán Robert Mugabe nígbà tó jẹ́ Ààrẹ ilẹ̀  Zimbabwe:
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Adari Ẹgbẹ oselu African National Union (Zanu) Robert Mugabe ni Olotu Orilẹede Zimbabwe, lẹyin ti wọn fopin si eto isejọba awọn alawọ funfun lorilẹede wọn.
Oríṣun àwòrán, PA
Mugabe nikan ni adari ti orilẹede Zimbabwe ti ni lati igba ti wọn ti gba ominiran . Oun re ni Osu Kẹta, ọdun 1980, pẹlu ọmọọba ilẹ Wales ati Akowe ijọba Ilẹ Gẹẹsi nigba naa loun, Lord Carrington.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Mugabe di ilumọọka lasiko to jẹ adari ikọ ọmọọgun gorilla to n koju awọn alawọ funfun ti wọn jọba le wọn lori.
Oríṣun àwòrán, PA
Mugabe re e pẹlu Olootu Ilẹ Gẹẹsi, Margaret Thatcher ni ọdun 1980.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Mugabe wa ni ipo Adari pẹlu Aarẹ Canaan Banana titi di ọdun 1987, ti o gba ijọba gẹgẹ bi aarẹ.
Oríṣun àwòrán, AFP
Awọn ọmọ orilẹede Zimbabwe sọ wi pe nkan bẹrẹ si ni wọ́ fun Mugabe nigba to fẹ akowe rẹ, Grace ni ọdun 1996.
Oríṣun àwòrán, AFP
Ọdun 1995 ni Mugabe se ipade po pẹlu Aarẹ orilẹede Amerika nigba naa, Bill Clinton lasiko ti ọrọ aje wọn dẹnukọlẹ.
Oríṣun àwòrán, PA
Mugabe fi ẹsun kan awọn alawọ funfun lorilẹede Mugabe ati Ilẹ Gẹẹsi fun isoro to koju orilẹede Zimbabwe nitori awọn lo ko wọn lẹru.
Oríṣun àwòrán, AFP
Lati ọdun 2000 si iwaju ni awọn ọmọlẹyin ikọ guerrillas tẹlẹri bẹrẹ si ni sisẹ ikọ ologun fun aarẹ Mugabe.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Awọn ikọ Guesrillas yii se ikọlu si ẹgbẹ alatako, ti wọn si danu sun awọn oko to jẹ ti awọn alawọ funfun.
Oríṣun àwòrán, AFP
O le ni ọgọrun eniyan ti ẹmi wọn lọ si ipolongo idibo ni ọdun 2003, ti o fi Mugabe silẹ ni ipo, lẹyin to ni awọn orilẹede alawọ funfun n gbimọ lati gba ipo ni ọwọ oun.
Oríṣun àwòrán, AFP
Mugabe to jẹ ọmọ ijọ Aguda sọ wi pe adura oun gba nigba ti oun rẹyin awọn ọta oun, ti wọn si gba oko pada lọwọ awọn alawọ funfun.
Oríṣun àwòrán, AFP
Ni Osu Kẹta, ọdun 2008 ni awọn eniyan mura lati dibo yan Aarẹ orilẹede Zimbabwe pẹlu ọrọ aje orilẹede naa naa to dẹnu kọlẹ, ti o si dabi ẹni pe ohun gbogbo ko sẹnu ire fun Mugabe.
Oríṣun àwòrán, AFP
Lẹyin ti Mugabe kuna ninu idibo akoko, ti alatako rẹ, Morgan Tsvangirai si bori, Mugabe fariga pẹlu ibura wi pe Olorun nikan lo le yọ oun nipo. Tsvangirai fi ipo silẹ fun lẹyin ti wọn se ikọlu si awọn alatilẹyin rẹ.
Oríṣun àwòrán, AFP
Eto idokowo orilẹede naa tunbọ dẹnukọlẹ si, eyi to mu ki Mugabe gba lati se ijọba pẹlu alatako rẹ, Morgan Tsvangirai to di Olootu ijọba.
Oríṣun àwòrán, AFP
Ni ọpọ igba lo ma n jẹ iroyin ẹlẹje wi pe Mugabe ti ku, amọ ni ọdun 2011 ni Wikileaks fi lede wi pe Aarẹ naa ni arun jẹjẹrẹ oju ara ọkunrin.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Mugabe ni ẹni ọdun mejidinlaadọrun sọ wi pe ọpọ igba ni oun ti ku, nitori iroyin ẹlẹjẹ ti o ma n sọ wi pe oun ti ku. O tilẹ fi se awada wi pe oun tobi ju Jesu Kristi lọ nitori pe oun ti ku lọpọ igba, amọ igba kan soso ni Jesu ku, ti o si jinde.
Oríṣun àwòrán, Keystone / Getty Images
Robert Mugabe ti wọn bi ni ọdun 1924 fi aye silẹ ni ọdun 2019.
Robert Mugabe: Àkójọpọ̀ àwọn ọrọ Mugabe tó sọ àti eléyì tí kò sọ tí a kò lè gbàgbé
Oríṣun àwòrán, KELD NAVNTOFT
Ninu iwuwasi ati isọrọ rẹ, ẹfẹ jẹ nnkan ti awọn kan fi fẹran aarẹ Mugabe
Iru awọn ọrọ apanilẹrin wo ni wọn ni Mugabe sọ ati eleyi ti ko sọ  ti ẹ ko le gbagbe?
Ibeere ree ti a fẹ gbiyanju lati mu idahun wa si fun yin toun ti bi awọn eeyan ṣe n ṣe iranti Robert Mugabe, aarẹ orileede Zimbabwe to ku.
Ṣọrọ sọrọ ti ọrọ da lẹnu rẹ ni aarẹ Robert Mugabe, to si maa n tako awọn ijọba ilẹ okeere alawọ funfun ninu ọrọ rẹ. Robert Mugabe di ero ọrun
Pupọ ninu awọn igba to ba n sọrọ, awọn oniroyin a ma fẹ tẹti si ọrọ rẹ nitori a ma sọko ọrọ ti awọn eeyan a ma fẹ gbọ.
Ninu awọn ọrọ rẹ, o ni awọn eleyi to jẹ otitọ ati awọn mii ti ko sọ, ṣugbọn ti awọn eeyan ni oun lo sọ.
Awọn wo lo ko awọn ọrọ ti ko sọ yi jọ?
A ko le sọ pato pe lagbaja tabi tamẹdun lo ko awọn ọrọ yi jọ ṣugbọon loju opo ayelujara paapa Facebook, wọn pọ daada.
Lori awọn opo kan to mu niṣẹ lati ma fi awọn ọrọ wọn yii da awọn eeyan lara ya, iye eeyan to n fi ọkan tẹle awọn oju opo yii ko kere rara.
Diẹ ninu awọn ọrọ naa re e:
Oríṣun àwòrán, Facebook/mugabequotes1
Oríṣun àwòrán, FACEBOOK/mugabequotes1
Oríṣun àwòrán, Facebook/mugabequotes1
Ki lo mu ki awọn eeyan fẹran awọn ọrọ wọn yii:
Awọn to ko ọrọ wọn yii jọ loju opo ayelujara naa jẹwọ pe, wọn kii ṣe ọrọ Mugabe ni tootọ.
Ṣugbọn nitori wpe awọn eeyan mọ Mugabe si ẹni to ma n da apara lọpọ igba, ko nira fun wọn lati so ọrọ ẹfẹ wọnyii mọ lẹsẹ.
Oríṣun àwòrán, Facebook/mugabequotes1
A ti pe lọpọ igba, oun ti yoo pa awọn eeyan lẹrin ni wọn ma n wa loju opo ayelujara, ti ọrọ Mugabe yii si ṣe rẹgi iru nkan ti wọn n wa.
Ki a to kasẹ ọrọ wa nilẹ, ẹ jẹ ki a wo awọn ọrọ to jẹ ootọ ti awọn eeyan ko le gbagbe.
Loju opo Twitter Ablaku Dauda fi ọkan ninu awọn ọrọ yii sita:
Awọn mii ninu ọrọ rẹ gẹgẹ bi a ti ṣe ri akọsilẹ fun wọn ree e:
MC Oluomo: Àánú ni mo rí gbà láti di alága NURTW Eko
Oríṣun àwòrán, @mcoluomo
Alhaji Musiliu Akinsanya, ti gbogbo eniyan mọ si Mc Oluomo, ti wọn sẹsẹ yan gẹgẹ bi alaga fidiẹ fun ẹgbẹ awọn awakọ ero, NURTW, ẹka ti ipinlẹ Eko, ti n dupẹ lọwọ Ọlọrun fun iyansipo rẹ naa.
Mc Oluomo lo fi ọrọ naa lede loju opo Instagram rẹ nigba toun mọriri Ọlọrun fun yiyan ti wọn yan oun sipo naa.
"Oluomo wa n beere pe ""ta lo lee ro pe iru eeyan bii ti emi to wa lati idile mẹkunnu lee de iru ipo giga bayii, abi ta lo lee gbagbọ pe iru eyi lee farahan? Aanu ni mo ri gba."""
Oluomo tẹsiwaju pe oun dupẹ lọwọ Ọlọrun fun oore ọfẹ rẹ lori oun to fi mu ki iru ọjọ bayii waye ati awọn eniyan jankan lawujọ ti wọn ṣe atilẹyin fun oun lati dori ipo naa.
Ọpẹ mi lọ si ọdọ baba mi Asiwaju Bọla Tinubu ati gomina ipinlẹ Eko, Babajide Sanwo-Olu fun agbekalẹ ayika to jiire ati iwuri ti wọn se fun isipo rọpo awọn asaaju ẹgbẹ NURTW nipinlẹ Eko.
O salaye pe oun ri ipo naa gẹgẹ ipe lati sisẹ sin awọn olugbe ilu Eko, to si rọ awọn ọmọ igbimọ fidihẹ to ko sodi, lati ṣatileyin fun ki wọn lee mu ayipada to ye kooro ba ẹgbẹ awakọ nilu Eko ati lorilẹede Naijiria lapapọ.
Mc Oluọmọ wa pari ọrọ rẹ pẹlu nipa jijẹjẹ lati satilẹhin fun aarẹ ẹgbẹ awakọ ero lorilẹede yii, ọjọgbọn Tajudeen Ibikunle Baruwa.
Lagos Waste management: Ìgbà ọ̀tun dé lóríi èto kólẹ̀kódọ̀tí ní ìpínlẹ̀ Eko
Oríṣun àwòrán, Thenation newspapers
Igba titun ti wọlu fun eto kolẹ-kodọti ni ipinlẹ Eko pẹlu bi gomina ipinlẹ naa, Babajide Sanwo-olu ṣe jẹjẹ bayii pe eto kolẹkodọti ni ipinlẹ naa yoo rin jinna, si lilo ọna atijọ lati palẹ ẹgbin mọ bayii.
Gomina Sanwo-Olu ni tọọnu ẹru to le ni ẹgbẹrun mẹwa lo n jade ni ipinlẹ Eko lọdun, eyi to ni o gba ki wọn lo imọ igbalode lati fi koju rẹ.
Lasiko to n ṣefilọlẹ akoto ikodọti alawọ buluu ti ajọ kolẹkodọti ipinlẹ Eko LAWMA ṣẹṣẹ gbe kalẹ, ti wọn pe ni LAWMA blue box ni Sanwo-olu sọ ọrọ yii sita.
O ni afojusun ipinlẹ Eko lori eto kolẹkodọti ni lati rii pe yatọ si pipalẹ ẹgbin mọ, wọn tun sọ ẹgbin gbogbo di ajilẹ fun idagbasoke ọgbin lawujọ.
Bakan naa lo ni eto tuntun ti wọn fẹ gbe wọ ilana ipalẹ ẹgbin mọ l'Eko bayii, yoo tubọ mu ki ipese iṣẹ burẹkẹ sii nipinlẹ naa.
Seyi Makinde: Ẹni tó bá pín owó àkánṣe iṣẹ́ nínú ìjọba mi yóò gé ìka jẹ
Oríṣun àwòrán, @seyiamakinde
Gomina ipinlẹ Ọyọ, Seyi Makinde ti fọgba yangan o.
Makinde ti tu aṣiri bi wọn ṣe n pin owo ti wọn ba ya sọtọ fun akanṣe iṣẹ ni ipinlẹ Ọyọ, lasiko ijọba gomina ana ni ipinlẹ naa.
Makinde ni bi gomina ana ṣe n gba, ni iyawo rẹ naa n gba owo bọbẹ lara owo ti wọn ba ya sọtọ fun ṣiṣe akanṣe iṣẹ agbaṣe ni ipinlẹ Ọyọ.
Gomina ipinlẹ Ọyọ, Onimọ ẹrọ Ṣeyi Makinde sọ ọrọ yii o lasiko to n fọrọ werọ pẹlawọn araalu lori ọgọrun ọjọ iṣejọba rẹ.
Ṣe ẹ ranti pe Seyi Makinde funrarẹ lo sọ ko to de ori oye pe, gbogbo ohun ti araalu n foju wo gẹgẹ bi aṣiri imulẹ ninu iṣejọba ni oun yoo ṣi aṣọ loju rẹ ni kiakia.
"Ohun ti a ba nilẹ ni pe ki wọn gbe owo jade fun iṣẹ agbaṣe ki o jẹ pe ida mẹwa ninu ọgọrun owo ti wọn gbe jade ni wọn yoo fi ṣe iṣẹ akanṣe ti wọn tori gbe owo naa jade.
Ohun ti wọn sọ fun wa ni pe, ilaji owo ti wọn gbe jade fun iṣẹ agbaṣe ọhun ni yoo pada si apo gomina, ida ọgbọn ninu ọgọrun owo yoo lọ si ọdọ ẹni to fi ọwọ si gbigbe owo naa jade."
"Ninu ida ọgbọn yii ni wọn yoo si tun ti yọ ida mẹwa fun iyawo gomina. Ṣugbọn emi ti wa sọ fun wọn pe, ẹnikẹni to ba san iru aṣọ bẹẹ ṣoro labẹ iṣejọba mii yoo jẹ iyan rẹ ni'ṣu."""
Oríṣun àwòrán, @seyiamakinde
Gomina Makinde ni igbesẹ to lamilaaka ni iṣejọba oun n gbe bayii, lati dẹkun iwa jẹgudujẹra lẹnu iṣejọba.
O ni idi gan an niyi ti oun fi gbe aba kan kalẹ fun idasilẹ ajọ ti yoo maa gbogun ti iwa ijẹkujẹ ni ipinlẹ Ọyọ.
Lootọ gomina Makinde ko darukọ ẹnikẹni ṣugbọn ọpọ araalu lo ti n na ika si Sẹnetọ Abiọla Ajimọbi, nitori pe oun naa lo ṣe ijọba ki Makinde to gba ipo naa ni oṣu karun ọdun yii.
Community policing: Ọ̀gá ọlọ́pàá Mohammed Adamu ní ètò ń lọ fún ọlọ́pàá agbègbè
Oríṣun àwòrán, @PoliceNG
Ọga ọlọpaa patapata lorilẹede Naijiria, Mohammed Adamu ti ṣalaye pe eto ọlọpaa agbegbe yoo bẹrẹ jakejado Naijiria ni kiakia.
Bakan naa lo fi da awọn ọlọpaa loju ko si ọlọpaa ti yoo ku soju ija gbigbogun ti iwa ọdaran mọ lorilẹede Naijiria.
Ni ilu Abẹokuta ni Ọga ọlọpaa Adamu ti gbe ọrọ yii kalẹ. O ni ominu n kọ oun pe awọn ọlọpaa lọpọ yanturu lo n di oloogbe lẹnu iṣẹ a n daabo bo ilu.
Bakan naa lo ṣalaye pe ijọba apapọ ti gbe atunto eto igbayegbadun jade fun awọn ọlọpaa paapaa lori itọju ilera wọn ati lati lee ni ilera ara wọn.
O ni ijọba n gbiyanju gẹgẹ bii ara ọna lati din alaafo to wa laarin ọlọpaa ati araalu ku, lati rii pe araalu gan lo n ṣeto akoso abo agbegbe wọn ti awọn ọlọpaa yoo si fun wọn ni atilẹyin gbogbo to ba yẹ.
o fi kun pe awọn ọlọpaa ti wọn yoo gba fun amojuto agbegbe kọskan yoo jẹ awọn ti a bi ni irufẹ agbegbe bẹẹ ki wọn lee daabo bo wọn bi o ti tọ.
Xenophobia: Ọ̀sẹ̀ tó ń bọ̀ ni bàálù yóò lọ kó ọmọ Nàíjíríà wálé
Oríṣun àwòrán, @FriendsofKashm2
Bi wọn se n ge awọn ọmọ orilẹede South Africa lọwọ ni wọn tun n bọ oruka nitori pe wọn ko dẹkun ikọlu ti wọn n se sawọn ọmọ Naijiria.
Iroyin kan tun ti kede pe se ni awọn eeyan lorilẹede South Africa tun n ja awọn sọọbu to jẹ tawọn ajeji, ti wọn si n ko wọn ni ọpọlọpọ ẹru tabi ba dukia wọn jẹ.
Gẹgẹ baa ti gbọ, awọn ọlọpa lorilẹede naa ti fidi rẹ mulẹ pe awọn eeyan naa ko tii dẹkun isẹ ibi ti wọn n se lati ọjọ Aiku, ti awọn ko si tii sinmi kika apa wọn ko ninu iwa ibajẹ naa.
Bakan naa lo fikun pe ọwọ ti ba awsn eeyan kan ti wọn ka mọ idi iwa ika yii lagbegbe Gauteng, ti eeyan mẹrinlelaadọrin si ti wa lahamọ ọlọpa lẹkun Katlehong.
Oríṣun àwòrán, @FriendsofKashm2
Wayi o, ọpọ ọmọ Naijiria taa gbọ pe wọn ti fi orukọ silẹ pe awọn n pada bọ nile pẹlu baalu ọfẹ tijọba gbe kalẹ lati ko wọn wale lati orilẹede South Africa.
Sugbọn a gbọ pe ijakulẹ diẹ ba eto naa nitori bi ọjọ ti lọ lori iwe irinna awọn ọmọ Naijiria kan to fẹ wa sile.
Nigba to n ba akọroyin BBC sọrọ, osisẹ alarina fun ileesẹ ọrọ ilẹ okeere lorilẹede Naijiria kede pe, wọn ti sun igbesẹ kiko awọn ọmọ Naijiria naa wale lati South Africa di ọsẹ to n bọ.
Oríṣun àwòrán, @uche_ezeonye
O salaye pe, eyi ri bẹẹ ki awọn lee fun asoju agba fun ileesẹ asoju ilẹ South Africa ni anfaani lati se akojọpọ orukọ awọn ọmọ Naijiria to nifẹ lati pada sorilẹede wa.
O fikun pe ọkọ baalu nla ni awọn gbe kalẹ, o si yẹ ki awọn se gbogbo eto to yẹ ki baalu naa to morile orilẹede South Africa lati ko awọn eeyan naa wale.
Lautech: Ìjọba Ọ̀ṣun ní òun kò jẹ òṣìṣẹ́ fásitì náà lówó oṣù
Oríṣun àwòrán, @Awesome206
Ijọba ipinlẹ Ọsun ti fariga, to si tako ẹsun ti gomina ipinlẹ Ọyọ, Onimọ ẹrọ Seyi Makinde fi kan ijọba ipinlẹ naa pe o tun ti kuna lati san owo osu awọn osisẹ fasiti imọ ẹrọ Ladoke Akintọla, LAUTECH.
Atẹjade kan ti alakoso feto iroyin fun ijọba ipinlẹ Ọsun, Adelani Baderinwa fisita lo sisọ loju ọrọ yii pẹlu afikun pe Makinde ko ni awọn akọsilẹ to peye lori ọrọ naa.
Bẹẹ ba gbagbe gomina Seyi Makinde lasiko to n bawọn akọroyin sọrọ lasiko ayẹyẹ ọgọrun ọjọ to gori oye, lo fẹsun kan ijọba ipinlẹ Ọsun pe o kuna lati san owo osu awọn osisẹ fasiti Lautech bẹrẹ lati idaji ọdun yii, gẹgẹ bo se wa ninu adehun.
Oríṣun àwòrán, Seyi Makinde
"Baderinwa, nigba to n fesi ni ""Ijọba ipinlẹ Ọsun ko kuna ri rara ninu awọn ojuse rẹ lati ọdun mọkandinlọgbọn ti wọn ti da silẹ, to si n se ojuse to tọ si gẹgẹ bii ipinlẹ alajọni fasiti Lautech lai naani pe ijọba ipinlẹ Ọyọ n yan awọn jẹ."""
Atẹjade naa wa kesi gomina ipinlẹ Ọyọ lati lọ ka awọn akọsilẹ to tọ nipa bi wọn se n san owo osu awọn osisẹ fasiti Lautech, bi o tilẹ jẹ pe o han si awọn pe Makinde ti seleri lasiko ipolongo ibo rẹ pe oun yoo sọ fasiti naa di ti ipinlẹ Ọyọ nikan.
Oríṣun àwòrán, @GboyegaOyetola
O wa rọ gomina Makinde lati mase gunle iwa ibanilorukọjẹ abi igbiyanju lati ru awọn osisẹ fasiti Lautech laya soke, to fi mọ awọn eeyan ipinlẹ Ọyọ lapapọ.
O ni awọn ọrọ rẹ naa lee jẹ ki wọn maa gboju agan sijọba ipinlẹ Ọsun abi gomina Adegboyega Oyetọla, ẹni to maa n tete kọbi ara sawọn ọrọ to ba jẹ mọ ti osisẹ.
41 Days Fasting: Akẹ́kọ̀ọ́ kan gba ààwẹ̀ ọlọ́jọ́ 41, ó dèrò ilé ìwòsàn
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Laipẹ yii ni iroyin gbalẹ kan pe akẹkọ kan nile ẹkọ fasiti ipinlẹ Ebonyi, Ikechukwu Oke, gba aawẹ ọlọjọ mọkanlelogoji, to si ti ru kan egungun.
Idi ree ti awọn ẹbi rẹ se gbe digbadigba lọ sile iwosan fun itọju nigba ti agọ ara rẹ ko mokun mọ
Iwadii fi ye wa wi pe, akẹkọọ naa ko ṣẹṣẹ maa gba iru aawẹ bẹẹ nitori ogun idile to ni oun n koju.
Ṣugbọn  ọpọ eeyan to gbọ nipa iroyin yii lawọn oju opo ikansira ẹni lori itakun agbaye lo n fi abuku kan Ikechukwu pe alailero ati ope ninu ẹsin ni.
Amọ ọna lati wadi ohun gbogbo daju nipa ohun ti eto ilera sọ lori aawẹ gbigba lo mu ki BBC Yoruba kan si dokita oyinsegun oyinbo kan lati salaye boya o dara fun ara lati gba aawẹ ọlọjọ gbọọrọ bii eyi.
Dokita Ọlalekan, lasiko to sọrọ lori aawẹ gbigba ni ko si ohun to buru ninu rẹ eyiun ti o ba ti ba ara wa mu.
O fikun pe onikaluku ẹda kọọkan lo gbọdọ mọ iwọn aawẹ ti ara rẹ lee gba, ko maa ba fa akoba si ilera rẹ nitori pe ohun ti Taye lee se, Kẹhinde lee ma lee se.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Onimọ isegun naa ni agọ ara ẹnikọọkan lo ni banki to n fi suga ati ounjẹ afaralokun pamọ si, ti ko si gbọdọ dinku abi ko tan rara.
"Olalekan sọ siwaju pe "" Akoba to wa ninu gbigba awẹ slọjọ gbọọrọ naa ni pe ewu nla n bẹ fun ẹni to ba gba aawẹ naa ti adinku ba fi ba iye odiwọn suga ati ounjẹ afara lokun to wa nipamọ ninu ara rẹ abi ko tiẹ tan patapata nigba ti onitọun ko ba jẹ ounjẹ miran dipo eyi to n lo nitori pe o n gba aawẹ."""
O wa gba awọn eeyan nimọran pe lootọ ni ko si ohun to buru ninu ki eeyan gba aawẹ lati fi wa oju Ọlọrun amọ ẹnikọọkan gbọdọ mọ iye aawẹ ti ara rẹ lee gba lai fa akoba si agọ ara, o si lee jẹ ọjọ kan, ọsẹ kan abi ju bẹẹ lọ, ti okun ara rẹ ba ti gbe.
Ṣugbọn o ṣalaye wi pe, ti ara ko ba ti ni anfani lati tẹsiwaju mọ, o di dandan ki a mu iru aawẹ bẹẹ wa si opin.
O ni ti irufẹ ẹni bẹẹ ko ba dẹkun aawẹ naa nigba ti gbogbo eroja ara ko ba le gba mọ, o ṣeeṣe ki ẹmi bọ lara iru ẹni bẹẹ lairo tẹlẹ.CA
Léyìn òpọ̀lọ̀pò ọdún àgbàọ̀jẹ̀ agbábọ́ọ̀lù ọmọ Cameroun ní òun ti dé wáàsimi
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Gbajugbaja agbabọọlu ọmọ ẹgbẹ Barcelona ati Inter Milan, Samuel Eto o ti ṣalaye pe oun ko gba bọọlu mọ.
Etoo to jẹ ọmọ ọdun mejidinlogoji ṣalaye lori ẹrọ ayelujara rẹ pe asiko ti to fun oun lati feyinti sinmi ninu are boolu.
Eto o ọmọ bibi ile Cameroon ti o si ti wa lẹnu boolu gbigba lati bii ọdun mejilelogun.
Ogunna gbongbo ninu are bọọlu yii ti mu igbega ati idagbasoke ba bọọlu gbigba ni ilẹ Afrika lati ọdun 1997 ti o ti bẹrẹ.
O gba ife ẹye ti ilẹ Afrika ni ọdun 2000,2002 ati Champions liigi fun ọdun 2006,2009 ati 2010.
Robert Mugabe: Àjọṣepọ̀ káfisẹ́nu-kádákẹ́ tó wà láàrín èmi àti olórí orílẹ̀èdè Zimbabwe tẹ́lẹ̀
Oríṣun àwòrán, Fairfax / Getty Images
Ki wọn to yẹ aga ijsba mọọ ni idi lọdun meji sẹyin, Robert Mugabe ni Aarẹ kan ṣoṣo ti awọn ọdọ ti wọn bi lẹyin igbominira Zimbabwe lọdun 1980 da mọ gẹgẹ bi aarẹ.
Mugabe ni aarẹ laye iya-iya mi, oun naa ni aarẹ laye iya mi, ero mi si ni pe oun naa ni yoo jẹ aarẹ fun awọn ọmọ mi obinrin pẹlu. Loju ti wa, itums aarẹ ni Robert Mugabe.
Ni ileewe a maa n gboriyin fun bi o ṣe ja fafa to ninu ọrọ sisọ. Agbọ gbọnrinu ni awọn ọrs apilẹkọ rẹ, orin iyin rẹ ko si tan lẹnu wa ni ileewe. Irufẹ iyi ti Robert Mugabe ni niyi gẹgẹ bii olorii wa.
N o ranti rẹ fun jijẹ olootọ si ohun ti o gbagbọ. Ko muti, bẹẹ ni ko mu siga. Ounjẹ abalaye orilẹede Zimbabwe lo n jẹ bẹẹ ni o si kundun ere idaraya lawn tennis.
Akin ọkunrin ni Mugabe, ko si yee gbe ara rẹ si inu aṣọ oyinbo. Ni ile, baba rere ni, ti o fẹran awọn ọmọ rẹ paapaajulọ ọmọ rẹ agba obinrin, Bona.
Iroyin iku rẹ ni ileewosan aladanla kan lorilẹede Singapore jẹ manigbagbe fun mi bi a ba wo bi eto ilera ti ṣe dẹnu kọlẹ lorilẹede Zimbabwe to fi silẹ. Eleyi ti a lee pe ni ọkan lara awọn iwa imọtaraẹninikan rẹ.
Oríṣun àwòrán, AFP
Afojusun rẹ ni lati pe ọmọ ọgọrun ọdun ki o to jade laye ati lati wonkoko mọ ipo aarẹ orilẹ€de naa titi di ọjọ iku rẹ. Amọṣa gbogbo afojusun meji yii ni ko lee bọsi.
Fun ọdun mẹtadinlogoji ni a fi farada ijọba familete-n-tutọ rẹ. Mo bẹru rẹ gidigidi.
Nitori Mugabe ni a ṣe lanfani eto ẹkọ to ye kooro. Bakan naa ni a lanfani si ẹts kan naa pẹlawọn ọmọ alawọfunfun. O jẹ adari ti o mọ anfani ati agbara to wa ninu ẹkọ. eto rẹ lori ẹkọ mu ki orilẹ€de Zimbabwe di awokọṣe ni ilẹ Afirika.
Oríṣun àwòrán, AFP
Nigba to ya, iwọnba perete awọn ọmọ ilẹ Zimbabwe lo janfani eto ironilagbara rẹ. Paapaa julọ ilana aato lori ilẹ to sọ ọpọ agbẹ ti alagbara.
Amọṣa lọdun 1997 ni akara bẹrẹ si nii tu sepo nigbati Mugabe pinnu  lati san owo ajẹmọnu fawọn ọmọogun ajijagbara ti wọn n beere fun ilakaka wọn.
Eyi lo gba gbara lọwọ owo orilẹede naa ki o to tun ran awọn ọmọogun lọ ja ogun lorilẹede DR Congo. Lọdun kan naa ni rogbodiyan lori ọrs ounjẹ bẹ silẹ lawọn ilu nla kan lorilẹ€de naa. Bẹrẹ lati igba yii wa, nnkan o ṣe ẹnuure fun orilẹede Zimbabwe mọ.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ko si aniani pe ajijagbara fun orilẹede Zimbabwe ni Mugabe jẹ, bakan naa ni o tun sọ ara rẹ di oludunkukulaja fun orilẹede naa pẹlu.
Ni orilẹede Zimbabwe, ko is ninu aṣa wọn lati maa kokiki iku ẹnikẹni, koda ko jẹ aarẹ ana. Bi iku rẹ ṣe ba mi ninu jẹ naa ni ipo to fi orilẹede mi Zimbabwe si pẹlu bami ninu jẹ gidigidi.
Oríṣun àwòrán, Reuters
South Africa killings: Ìjọba àpapọ̀ ní kò sóun tó jọ ìbúgbàmù àdó olóró níléeṣẹ́ ìjọba South Africa tó wà nílùú Abuja
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Iroyin kan gba ori itakun ayelujara pe awọn leṣebi-leṣeka ẹda kan ti ju ado oloro si olu ileeṣẹ ijọba orilẹede SouthAfrica to wa nilu Abuja.
Ko si si idi meji ti wọn so mọ ọrọ yii ju edeaiyede lori ikọlu awọn ajeji lorilẹede South Africa lọwọlọwọ.
Amọṣa, Ijọba apapọ orilẹede Naijiria ti wa bọ sigboro aye bayii lati da omi tutu si iroyin naa eyi ti wọn pe ni iroyin ẹlẹjẹ.
Ni ọjọ Satide ni minisita fun eto iroyin ati aṣa gbe atẹjade kan jade pe ko si ohun to jọ ibugbamu ado oloro ni ileeṣẹ aṣoju ijọba orilẹede South Africa ni Naijiria to wa nilu Abuja.
O ni fidio ibugbamu ado oloro ti awọn eeyan kan n gbe kiri lori itakun ayelujara kii ṣe ti ileeṣẹ aṣoju ilẹ South Africa bi ko ṣe ti ibugbamu to waye ni ibudo  Emab Plaza, nitosi Banex, nilu Abuja loṣu kẹfa ọdun 2014.
Lai Mohammed to di iroyin ofege naa ru iṣẹ ọwọ awọn alatako ṣalaye pe ọgbọn ati da omi alaafia iṣejọba ru ni awọn to gbero fidio naa n da.
Alhaji Lai Mohammed wa rs awọn ọmọ orilẹede Naijiria lati maa woye gbogbo iroyin ti wọn ba n ri gba lori ayelujara nitori oye lagba n wo.
US Open 2019: Bianca júwe ilé fún Serena Williams nínú ìdíje l'America
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Bianca gba ami ẹyẹ mọ agba ọjẹ Serena lọwọ ni New York
Idije to gbogo fun Bianca Andreescu naa waye ni Flushing Meadows ni New York laarin ọjọ kẹrindinlọgbọn, oṣu kẹjọ si ọjọ kẹjọ, oṣu kẹsan an, ọdun 2019.
Bianca Andreescu jẹ ọmọ ọdun mọkandinlogun lati orilẹ-ede Canada lo koju agbaọjẹ Serena Williams ọmọ ọdun mẹtadinlogoji naa ninu idije aṣekagba.
6-3; 7-5 ni wọn pada jọ gba ninu idije aṣekagba naa ni New York.
Child Engineer: Olamide Odukọya nílò ìrànlọ́wọ́ láti lọ síléẹ̀kọ́ ìmọ̀ ẹ̀rọ
Bianca fo fun ayọ, o ni: Odun yii ni àlá mi wa sí imuṣẹ.
O ni: inu mi dun gidi, mo mọ oore nitori mo ti n tiraka tipẹ ti mo ti n woye ọjọ ti maa pade Serena Williams ninu idije.
Serena ni gbajugbaja ti gbogbo wa n wo loke ninu ere idaraya yii.
Si iyalẹnu gbogbo ero iworan to wa lori papa ni Bianca fidi Serena janle ti o si jẹ ki Serena padanu ife ẹyẹ yii lẹẹkẹrin bayii.
Serena funra rẹ gboriyin fun ọdọmọde Bianca, o ni: Inu mi dun fun Bianca, o ṣiṣẹ bi ọmọ akin nitootọ ninu idije yii.
Bianca jẹ ọmọ orilẹ-ede Canada.
Oun ni ọdọmọde ẹni akọkọ ni Canada to maa gba ami ẹyẹ idije nla bọọlu ẹlẹyin ori tabili.
Oríṣun àwòrán, EPA
Bianca nigba to lulẹ ninu idijeẹ lọdun to kója.
Oun ni ọdọmọde ti ko tii pe ogun ọdun akọkọ to maa gba goolu Grand slam lẹyin Maria Sharapova lọdun 2006.
Oun lo tun kọkọ gba Akọkọ ṣe Slam lẹyin ọmọ Russia to gbaa lọdun 2004 ni Wimbledon
Bianca jẹ ọdọmọde to ni igbooya ati ọkan akin ninu gbogbo idawọle rẹ, eyi to han ninu idije naa.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Mo ba oloriire yọ ni ọrọ naa pada ja si
Andreescu ni ti ẹnikẹni ba sọ fun oun pe oun a koju Serena Williams ninu idije oun maa sọ pe ẹni naa ti ya were ni.
Oun ni gbogbo aye n sọrọ nipa rẹ lori ayelujara lasiko yii pe ko si ohun ti ọdọmọde ko le ṣe yanju!
Lọdun to lọ ni Bianca ja nibẹrẹ idije ti ko si si lara awọn igba akọkọ to ṣaaju ninu gbigba bọọlu ọhun.
Awọn ara Romania ni obi Bianca jẹ.
Nicu ni orukó baba rẹ nigba ti iya rẹ n jẹ Maria.
Wọn lọ ṣe atipo ni orilẹ-ede Canada nibẹre ọdun 1990.
Lati kekere ni Bianca ti n gba bọọlu ẹlẹyin ori tabili ni eyi to si ti gba ami ẹyẹ bii WTA Premier ni Indian Wells ati Toronto to si gba ẹbun owo rẹpẹte si.
Bayii, Bianca n lọ ẹni karun un ni agbaye to si n lọ sile pẹlu ẹbun owo $3.85 miliọnu.
Oríṣun àwòrán, AFP
Mo di eti mi pa ni si ariwo orukọ Serena ki n to bori!
Ẹkọ nla ti Bianca fẹ ki awọn ọdọ kọ ni pe ki wọn maa di eti wọn si ariwo ọja ati pe ki wọn ma bẹru ogbontarigi ti wọn ba fẹ koju lẹnu iṣẹ wọn.
O ni oun di eti oun si ariwo ọja awọn eniyan ni bi awọn ero lori papa naa ṣe n pariwo orukọ Serena ki oun to le bori.
Xenophobia: Kò sí wàhálà fún àwọn okòwò South Africa ni Eko
Oríṣun àwòrán, @sanwo olu
Awọn ara South Africa ko ni bẹru
Gomina Sanwo Olu fi ọkan awọn eeyan South Africa balẹ lori awọn okowo wọn.
Gomina to n tukọ ipinlẹ Eko, ti paṣẹ pe to ba ṣe di ọjọ Aje ki awọn oṣiṣẹ eleto aabo ipinlẹ Eko ṣe afikun si eto aabo awọn okowo South Africa.
O ni iṣẹlẹ ikọlu awọn ọmọ Naijiria ni orilẹ-ede South Africa ko dara to ṣugbọn ko yẹ ki awọn maa ba nkan jẹ pada.
Amb.Oluwateru:Oju bọrọ kò ṣé gbọmọ lọ́wọ́ ekurọ South Afrika lori Xenophobia
Ninu atẹjade ti Ogbẹni Gboyega Akosile to jẹ akowe eto iroyin fun gomina Sanwo Olu fi ọwọ si lo ti paṣẹ aabo yii.
Gomina Sanwo Olu bẹnu ẹ̀tẹ́ lú iwa awọn ara South Africa si alejo ṣugbọn o tẹpẹlẹ mọọ pe ko dara lati fi oro ya oro.
O sọ fun awọn eniyan South Africa pé ijọba oun a pese aabo to peye fun ileeṣẹ wọn ati awọn okowo wọn.
Oríṣun àwòrán, @others
O sọ fun awọn eniyan South Africa pé ijọba oun a pese aabo to peye fun ileeṣẹ wọn ati awọn okowo wọn.
Sanwo Olu sọrọ yii lẹyin to ṣabẹwo si Shoprite ni Sangotedo ati Surulere lati wo bi nkan ṣe bajẹ to si iroyin ti oun n gbọ lori iṣẹlẹ naa.
O ni o le ni ẹgbẹrun marun un eniyan to le padanu iṣẹ wọn lori iṣẹlẹ yii to jẹ ọmọ Naijiria.
O ni : a ti paṣẹ fawọn oṣiṣẹ eleto aabo wa lati daabo bo gbogbo ohun ini awọn ara South Africa nipinlẹ Eko.
O fi da awọn olokow South Africa loju pe ni gbogbo ileeṣẹ wọn ni awọn agbofinro a mojuto ti ilẹ ba ṣe mọ ni ọla ọjọ Aje.
Ni ipari Gomina Sanwo Olu rọ awọn ajeji to nileeṣẹ lati gbiyanju igbe aye alaafia pẹlu awọn eniyan adugbo wọn.
O ni irọrun eku lo difa fun irọrun ẹyẹ ni ati pe ti gbogbo nkan ba daru tan, ara ko ni rọ okun ati adiyẹ naa ni.
Bakan naa lo jiroro pẹlu awọn ọlọpaa lori igbesẹ ti ijọba maa gbe lori awọn ti ọwọ tẹ lọsẹ yii pe wọn n ba nkan awọn ara South Africa jẹ nileeṣẹ wọn.
O ni paapaa lori awọn to ji nkan gbe nile itaja gbogbo ọhun nitori pe iwa ole ko ni orukọ meji.
Port harcourt Bole: Mi kò mọ́ pé bọ̀ọ̀lì títà lè gbé mi dé ipò yìí láyé mi!
NNPC: Kyari ṣàlàyé ohun tó fa ẹ̀dínkù iye epo rọ̀bì tí wọ́n ń kó níbùdó ìpọnpo ní Nàìjíríà
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ọga agba NNPC Mele Kyari ni ijọba apapọ yoo tubọ tẹra mọ gbigbogun ti iwa fayawọ epo rọbi lorilẹede Naijiria.
A ti n gbe gbogbo igbese tó yẹ lati fopin si iwa fayawọ epo rọbi -Mele Kyari
Ọga agba ajọ elepo rọbi orilẹ-ede Naijiria, (NNPC) Mele Kyari ti kede pe iye agba epo ti wọn n gbe lawọn ibudo ikepo si lorilẹ-ede Naijiria ti dinku lati nnkan bii ọjọ kejilelogun, oṣu kẹjọ ọdun.
Ninu atẹjade kan ni Ọgbẹni Mele Kyari ti ṣalaye ọrọ yii lori oju opo Twitter rẹ.
O ni eyii nii ṣe pẹlu bi awọn ajọ alaabo ṣe ti awọn aala orilẹ-ede Naijiria pẹlu awọn orilẹ-ede gbogbo to yii ka lọna ati lee dẹkun fayawọ lorilẹ-ede Naijiria.
Ọga agba ajọ NNPC naa ni gbogbo igbesẹ to ba yẹ ni ijọba atawọn ajọ alaabo gbogbo yoo gbe lati dẹkun fayawọ epo rọbi lorilẹ-ede Naijiria.
Nigeria models: Ẹ má bóra mọ́, ọmọ dúdú dùn lọ́mọbìnrin
Makinde: Ẹgbẹ́ òṣèlú PDP ní àwọn kò padà lẹ́yìn Seyi Makinde, gómìnà ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́
Oríṣun àwòrán, @oyostategovt
Ọrọ Ẹgbẹ oṣelu PDP ati APC nipinlẹ Ọyọ ti di ti ologbo ati eku bayii paapaa julọ lori ọrọ gomina Ṣeyi Makinde ati iṣejọba rẹ nipinlẹ naa.
Laipẹ yii ni iroyin jade pe ẹgbẹ oṣelu APC n pariwo sita pe iṣejọba gomina naa ko ba awọn aṣaaju ẹgbẹ oṣelu rẹ, iyẹn PDP lara mu, wọn si ti n kọ ẹyin wọn sii lọkọọkan ejeeji.
Haa-hin in ni iroyin naa ṣe ọpọ onwoye nitori pe ko si ẹni lee ro pe ẹgbẹ kan to wa lori alefaa lee kẹyin si aṣoju wọn ninu iṣejọba.
Amọṣa, ẹgbẹ oṣelu PDP ti ni ko si nnkan to jọọ rara ni nitori pe ọmọ ẹnii kii ṣe idi bẹbẹrẹ ka fi ilẹẹkẹ sidi ọmọ ẹlomiran.
Atẹjade kan ti ẹgbẹ oṣelu PDP fi sita eyi ti alukoro rẹ, Akeem Ọlatunji fi ọwọ si ṣalaye pe ẹgbẹ oṣelu APC nipinlẹ Ọyọ kan Ọ̀Rọ̀ n tun irọ ta faraalu ni.
O ni gbagbagba lawọn aṣiwaju ati gbogbo ọmọ ẹgbẹ oṣelu PDP wa lẹyin Gomina Makinde atipe iṣọkan to jina denu lo wa laarin ẹgbẹ oṣelu naa.
Wòlíì Kasali sọrọ nípa awuyewuye pé o lè ìyàwó rẹ̀ jáde nílé
South Africa killings: Sanwo-Olu ní àwọn ọmọ Nàìjíríà tó gbẹ̀san ìkọlù àjòjì ní South Africa ti yọ ọmọ Nàìjíríà 5000 níṣẹ́ l'Eko
Oríṣun àwòrán, @jidesanwoolu
Ṣe awọn agba bọ wọn ni ọrẹ mi yaso emi naa a ya temi, afaimọ konitọun ma ṣe gaa sara
Eyi gan an lo difa fawọn to kọlu awọn ileeṣẹ to lọwọ orilẹede South africa ninu nilu Eko nitori ikọlu awọn ajoji to n waye lorilẹede South Africa.
Ni bi a ti ṣe n sọrọ yii, ẹgbẹrun marun eeyan lo ti padanu iṣẹ wọn nipinlẹ Eko nitori ikọlu ẹlẹsan tawọn ọmọ Naijiria kan ṣe sawọn ileeṣẹ ti wọn wo pe awọn ọmọ orilẹede South africa ni nilu Eko.
Oríṣun àwòrán, @jidesanwoolu
Gomina ipinlẹ Eko, Babajide Sanwo-olu lo fẹ idi ọrs yii sita lasiko abẹwo rẹ sawọn ileeṣẹ ati ohun elo tawọn olufẹhonuhan bajẹ nilu Eko lasiko ti wọn fi nkọlu awọn ohun to jẹ tawọn ọmọ ilẹ South Africa naa.
Sanwo-Olu fi ẹ̀gbin dá àrà tuntun l'Eko
Ṣé Zimbabwe dùn gbé bí lásìkò yìí ju àkókò ìṣèjọ̀ba Mugabe lọ?
Gani Fawehinmi lọ àmọ́ kò kú lẹ́yìn ọdún mẹ́wàá tó dará ilẹ̀
Gomina Sanwo-Olu koro oju si bi awọn eeyan kan ṣe lo anfani iṣẹlẹ naa lati lọ maa fọ awọn ile itaja nlanla l'Eko.
O ni ọrọ naa ti di ti papa to n pa ara rẹ to ni oun  n pa aja; nitoripe pẹlu ikọlu ọhun awọn ọmọ orilẹede Naijiria gan lo fara ko iṣẹlẹ naa.
Mutallab‘s Father: Ọmọ mi ti kábàmọ́ọ̀ ìwà tó wù, ẹ ṣàánú rẹ̀
Xenophobia: Àwọn ọ̀dọ́ kan ń ṣèwọ́de láti pè fún lílé àwọnjì kúrò ní South Africa
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Awọn ọmọ orilẹede South Africa ti da ọrọ ru nibi ti odu oloṣelu kan ti n sọrọ lati dẹkun ikọlu awọn ajoji nibẹ.
Alagba Mangosuthu Buthulez la gbọ pe awọn ọpọ ero kan pa ohun mọ lẹnu nigba ti awọn ọkunrin kan ya wọ agbegbe naa ti wọn si n ke sawọn ajoji lati fi orilẹede wọn silẹ.
Ko din ni eeyan mẹwa, meji ninu eyi to jẹ ajoji ni wọn ti kagbako iku ojiji laarin ọsẹ kan sẹyin.
Ni ọjọbọ lawọn ọlọpaa sọ pe okooleirinwo eeyan lọwọ ti tẹ ati pe awsn ti bomi pa ina ikọlu naa.
"Amọṣa ni ọjs aiku lawọn ọkunrin kan tun dide pẹlu apola igi lọwọ ati kums ti wọn si n kaakiri awsn opopona ilu Johanesburg tawọn ti orin 'ajoji gbọdọ fi ilẹ wa silẹ pada si ilẹ wọn"" lẹnu wọn, gẹgẹ biiileeṣẹ iroyin abẹle kan, Sowetan Live ṣe kede."
Awọn oluwọde naa kọri si agbegbe Jules Park ni Johannesburg nibi ti alagba Buthelezi, to jẹ ọkan lara awọn aṣiwaju ẹya Zulu lasiko ijsba alawọn funfun nibẹ ti fẹ ba awọn eeyan sọrọ.
Amọṣa n ṣe ni wọn pa ọrọ mọọ lẹnu nibẹ ti awọn fidio tawsn kan ya nibi eto naa ṣe afihan bi awọn eeyan kan ṣe n fi ibudo naa silẹ.
NURTW: Makinde kò tíì yí àṣẹ rẹ̀ padà lórí i gbígbẹ́sẹ̀ lé NURTW ní ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́
Oríṣun àwòrán, @ibcityannouncer
NURTW: Makinde kò tíì yí àṣẹ rẹ̀ padà lórí i gbígbẹ́sẹ̀ lé NURTW ní ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́
Ijọba ipinlẹ Ọyọ ni ko sohun to yipada lori ofin to gbẹsẹ le iṣẹ awọn ẹgbẹ awakọ ero, NURTW ni ipinlẹ Ọyọ.
Ninu atẹjade kan ti ajọ amojuto lilọ-bibọ ọkọ nipinlẹ Ọyọ, OYRTMA fi sita ni ọrọ yii ti jẹyọ.
Ijọba ipinlẹ Ọyọ ni awọn ti n gbọ finrinfinrin pe awọn eeyan kan ti n ṣe kurukẹrẹ kaakiri lọna ti ko bofinmu ti wọn si n pe ara wọn ni ọmọ ẹgbẹ awakọ ero, NURTW nipinlẹ Ọyọ.
Arumọjẹ ti wọn si n ṣe fun awọn araalu atawọn awakọ ẹgbẹ wọn ni pe, aṣẹ ti ijọba fi gbe ẹsẹ le ẹgbẹ naa ti yọ bi ori inu oorun ni ọjọ kọkanlelọgbọn, oṣu karun un, ọdun 2019.
Eleyii ti wọn ni o fun awọn lanfani lati tun bẹrẹ si nii da tabi gba garaaji atawọn ibudokọ gbogbo  nipinlẹ Ọyọ ti wọn si fi n doju ija kọ awọn oṣiṣẹ ORTMA  ati lati da omi alaafia ilu ru.
Ajọ OYRTMA nipinlẹ Ọyọ ko ṣai wa tẹnumọ pe titi di bi a ṣe n sọrọ yii, ofin ijọba eleyii ti gomina ipinlẹ naa, Seyi Makinde pa ṣi wa sibẹ.
Wọn ni aṣẹ naa gẹgẹ bii alakoso agba fun eto aabo nipinlẹ Ọyọ pa lati gbẹsẹ le eegun ẹgbẹ awakọ ero pe ko gbọdọ ṣẹyọ bayii nipinlẹ naa ṣi wa nikalẹ, ẹnikẹni to ba si fọwọ pa ida aṣẹ naa yoo jẹ iyan rẹ niṣu.
Ni ọjọ kọkanlelọgbọn, oṣu karun un, ọdun 2019 ni gomina Seyi Makinde ti wọn ṣẹṣẹ bura fun wọle nigba naa paṣẹ pe eegun ẹgbẹ awakọ ero nipinlẹ naa ko gbọdọ ṣẹyọ mọ fun asiko yii.
Makinde sọrọ naa nitori rogbodiyan ti wọn fẹ maa da silẹ nigba naa nitori ati yii ijọba pada pẹlu ayipada to de ba ijọba nigba naa.
Port harcourt Bole: Mi kò mọ́ pé bọ̀ọ̀lì títà lè gbé mi dé ipò yìí láyé mi!
Ekiti state: Nítoríi fóònù ìbánisọ̀rọ̀, géńdé méjì kú sínú u kọ̀ǹga l'Ékìtì
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Nítoríi fóònù ìbánisọ̀rọ̀, géńdé méjì kú sínú u kọ̀ǹga l'Ékìtì
Ibanujẹ dori agba kodo, bẹẹni awọn ọmọ wẹwẹ ko si lẹnu ọmu ni ileto Anaye nijọba ibilẹ Emure Ekiti bayii nigba ti awọn gende meji jabọ sinu kọnga kan nibẹ ti wọn si dagbere f'aye.
Awọn mejeeji ọhun, ti wọn pe orukọ wọn ni Foluṣọ Ajayi, Vosco pẹlu ọdọmọdekunrin kan ti inagijẹ rẹ n jẹ Alhaji ni wọn gba fun iṣẹ agbaṣe kan ni ileto ọhun.
Gẹgẹ bi a ṣe gbọ, ọkan ninu awọn mejeeji yii gbiyanju lati yọ ẹrọ ibanisọrọ alagbeka rẹ to jabọ sinu kọnga yii lasiko to fi n pọn omi lati fi jẹun lo ba di wọ ninu kọnga.
Iroyin ni foonu Vosco lo jabọ si kanga nigba to n fa omi lọwọ, lasiko igbiyanju rẹ lati yọ foonu naa lo ba rebọ.
Ni Alhaji ọrẹ rẹ naa ba fẹ sare ran an lọwọ ni oun naa ba ko si kọnga.
Awọn ti iṣẹlẹ naa ṣe oju wọn ṣalaye pe ni kete ti ọkunrin akọkọ jabọ sinu omi ni ẹnikeji rẹ gbiyanju lati yọọ jade ni oun pẹlu jabọ sinu kọnga naa to si ku.
Wọn ni awọn ọdọ ẹya Hausa marun un kan ni wọn wa gba lati gbe oku wọn jade lati inu kọnga naa.
Nibayii awọn ọlọpaa ti bẹrẹ iwadii lori iṣẹlẹ naa.
Ọwọ́ ọlọ́pàá tẹ àwọn ọmọ ẹgbẹ́ òkùnkùn ní Ikorodu
Oríṣun àwòrán, The nigeria police
Egbe okunkun laarin awọn ọdọ ti n gba apero
Ọwọ awọn ọlọpaa ti tẹ awọn ọmọ ẹgbẹ okunkun mẹsan an ni agbegbe Imọta ni Ikorodu.
Alukoro ileeṣẹ ọlọpaa, Bala Elkana ṣalaye pe awọn ọmọ ẹgbẹ okunkun ọhun ti wọn jẹ aṣiwaju ninu ẹgbẹ koowa wọn ni wọn ti sọ ara wọn di ẹrujẹjẹ si awọn eeyan agbegbe Ikorodu lọrun.
Gẹgẹ bi alukoro ileeṣẹ ọlọpaa naa ṣe sọ, o ni agogo mẹsan an alẹ ọjọ kẹfa, oṣu kẹsan an, ọdun 2019 ni awọn kan ta ọlọpaa lolobo nipa wọn.
Elkana ni pe wọn kẹẹfin awọn ọmọ ẹgbẹ okunkun ti ọlọpaa ti n wa fun igba pipẹ lagbegbe ilu Igbalu.
Oríṣun àwòrán, Nigeria police
"Ni eyi ti awọn dide si lẹyẹ o ṣọka ti wọn si  ni ikọ kogberegbe ""Operation Crush"" ileeṣẹ ọlọpaa ti tẹkọleti lọ si agbegbe naa."
Lara awọn ohun ija oloro ti wọn ba lọwọ wọn ni aake, ọbẹ ati fila bẹntigọọ to jẹ ti ẹgbẹ okunkun iyẹ.
Oríṣun àwòrán, @Others
Owo tẹ awọn ọdọ ti wọn n yọ Imọta lẹnu
Emmanuel Chinonso to jẹ ọmọ ọdun mọkanlelogun àti Thomas Isreal to jẹ ọmọ ogun ọdun ni wọn kọkọ mu bi afurasi.
Lara awọn nkan ija oloro ti wọn gba lọwọ wọn ni aake meji, ada ati fila ti o jẹ ti awọn ọmọ ẹgbẹ okunkunu ẹyẹ.
Lẹyin eyi ni awọn mejeeji jẹwọ pe awọn wa lara adari ẹgbẹ okunkun to n ṣọṣẹ ni agbegbe Imọta  ki isẹ iwadii awọn agbofinro to ṣafihan awọn meje miran.
Awọn meje yii ni: Ariyo Omonuga to jẹ ọmọ ọdun mẹẹdọgbọn; Oyerinde Omoniyi to jẹ ọmọ ọdun mẹtalelogun; Adelaja Opeyemi to jẹ ọmọ ọdun mejidinlọgbọn; Hassan Babatunde to jẹ ọmọ ọdun mẹrindinlọgbọn; Sodiq Babatunde to jẹ ọmọ ọdun mẹrinlelogun; Sodiq Oladire to jẹ ọmọ ọdun mejilelogun ati Shakiru Liasu ti oun jẹ ọmọ ọdun mejidinlogun.
Xenophobic: O lè ní ẹgbẹ́ta àwọn ọmọ Naijiria tí wọ́n ti ṣetàn láti padà sílé!
Oríṣun àwòrán, Getty Images
O to gẹ! ile labọ isinmi oko bqyii
Aṣoju ilẹ Naijiria lorilẹ-ede South Africa, Adama Godwin kede awọn ọmọ Naijiria ti wọn ti ṣetan lati pada sile lẹyin ikọlu.
Adama ni o ti le ni ẹgbẹ́ta àwọn ọmọ Naijiria tí wọ́n ti ṣetàn láti padà sílé ninu orukọ ti awọn ti ni akọsilẹ rẹ bayii.
Ikọlu to n waye lorilẹ-ede South Africa lodi si awọn alejo ni eyi ti ọpọ ẹmi ati dukia ti sọnu ninu rẹ lati ọpọlọpọ ọdun sẹyinÌjọba South Africa pèpàdé lórí ìkórìíra àlejò.
Adamu ni titi di asiko yii, awọn ko tii le sọ ni pato odiwọn iye ọmọ Naijiria to ṣetan lati pada sile.
O ni awon ṣi n ṣeto iforukọ silẹ titi di asiko yii ti BBC fi n ba wọn sọrọ.
O ni ọkọ ofurufu Air Paeace meji ti wa nilẹ lati bẹrẹ igbesẹ gbigbe awọn eniyan pada sile lalaafia kuro ni orilẹ-ede South Africa.
Adamu Godwin to n dari dida awọn ọmọ Naijiria pada sile lati South Africa ni lọjọ ruu ni awọn ikọ akọkọ a pada si Naijiria kuro ni South Africa.
O ni awọn ko tii da gbendeke igba ti wọn yoo dẹkun dida awọn eniyan pada sile.
Adamu ni ti awọn ti o ba fifẹ han lati lọ sile ba ṣi n pọ nile ni ijọba yoo maa gbe igbesẹ lati gbe wọn wa sile.
Nigba ti BBC beere lọwọ Aṣoju Naijiria ni South Africa irufẹ awọn eeyan ti wọn n da pada sile lọwọ rẹ, O ni ọpọ ninu wọn jẹ awọn ti ikọlu naa ti ba okowo wọn jẹ.
O ni awọn ti ikọlu Xenophobia to lodi si alejo naa ti jo ọja wọn ti okowo wọn si ti di nkan miran.
Bakan naa ni Adamu ni awọn maa da awọn ọmọ Naijiria ti wọn wa ni ibudo dida ajeji pada ti ko ba ni iwe igbelu to yẹ lọwọ (Deportation Camps).
O ni ko si awọn ti wọn wa ni ẹwọn ni South Africa ninu awọn ti ijọba n gbero lati da pada sile lasiko yii.
Ni afikun, Adamu ṣalaye fun BBC pe ijọba Naijiria ti n ṣe akọsilẹ awọn ọmọ Naijiria ti wọn ji ọja tabi okowo wọn ko ni Johannesburg.
O ni ti awọn ba pari iforukọsilẹ awọn ti ọrọ kan ati odiwọn ọja wọn ti ikọlu yii bajẹ ni wọn yoo to mọ igbesẹ to kan ni gbigbe.
Super Eagles kò rántí kó ohun eèlò ìgbábọọlu wọn dání
Oríṣun àwòrán, @NFF
Super Eagles kò rántí kó ohun eèlò ìgbábọọlu wọn dání.
Agbẹ ti lọ soko idije bẹẹ ko ranti ọkọ ni ọrọ Super Eagles loni.
Egbẹ agbabọọlu Super Eagles ti ilẹ Naijiria to lọ si orilẹ-ede Ukraine lati gba boolu ọlọrẹjọrẹ ninu eyi ti wọn ti gbagbe eroja wọn.
Super Eagles ti wọn jẹ agbabọọlu àgbà fun ilẹ wa ni wọn ti gunlẹ si ilu Dnipro sugbọn ti wọn ko ranti ko awọn ohun eelo igba bọolu wọn dani.
Abẹnugan fun  eto are bọọlu fún Super Eagles, Ademọla Ọlajiire lo fi iroyin naa lede ni ọjọ lsinmi ọsẹ yii.
O fi kun ọrọ rẹ pe awọn agbabọọlu mẹfa miran ni wọn tun n reti baagi ti ohun eelo wọn wa gẹgẹ bi igbaradi yoo ṣe bẹrẹ ni ọjọ Iṣẹgun ni pẹrẹwu.
Wọn ni lẹyin ti ọkọ ofurufu to gbe wọn balẹ tan naa ni wọn rii pe ko si ẹru wọn kankan ninu ọkọ ofurufu ọhun
Olori awọn ti wọn jọ kọwọ rin de ilu Dnipro, ni orile ede Ukraine, Dayọ Achor wi pe awón alaṣẹ ọkọ ofurufu Turkey yoo ṣe iranlọwọ to yẹ lati ko ẹru naa pada wa.
Dayọ tẹsiwaju pe, asọye to muna doko ti wa laarin ajọ NFF ti ilẹ Naijiria ati alaṣẹ ileeṣẹ ọkọ ofurufu naa lati tete ko awọn ohun eelo naa pada de saaju ọjọ lsẹgun.
Idije ọjọ Isẹgun yii lo maa bẹrẹ ni bii agogo meje abọ aṣaalẹ lori papa iṣere nla ti ilu Dnipro.
Busola Dakolo: Mílíọ́nù mẹ́wàá náírà tí a béèrè kì í ṣe owó gbà má-bínú
Oríṣun àwòrán, BUSOLA DAKOLO
Busola Dakolo: Mílíọ́nù mẹ́wàá náírà tí a béèrè kì í ṣe owó gbà má-bínú
Agbẹjọro Busola Dakolo ti sọ pe, irọ balau ni pe onibara oun fẹ gba miliọnu mẹwaa Naira gẹgẹ bi owo gba ma-binu lọwọ oludasilẹ ijọ COZA, Biọdun Fatoyinbo.
Pelumi Olajengbesi ti o jẹ agbẹjọro to n ṣoju Dakolo ni owo naa jẹ owo iṣẹ oun gẹgẹ bi agbẹjọro Busọla ni.
"O salaye pe ""ahesọ ọrọ ni pe onibara mi beere owo gba ma-binu lati ọwọ Pasitọ Biodun Fatoyinbo."""
Idi ti onibara wa ṣe pe Fatoyinbo lẹjọ ni ki ile ẹjọ le e ṣe idajọ ti o tọ, ati lati ran awọn elomiran ti o lee wa niru ipo yii lọwọ.
O ni o ṣe pataki lati fi ye awọn eniyan pe, miliọnu mẹwaa naira ti awọn oniroyin n sọ jẹ owo iṣẹ ti awọn agbẹjọro n ṣẹ lori ipẹjọ naa.
COZA: Iléejọ́ Abuja ké si Fatoyinbo ati Busola Dakolo pé kí wọ́n yọjú.
COZA: Ṣe Ilé ejọ́ Abuja ti ké si Fatoyinbo ati Busola Dakolo pé kí wọ́n yọjú?
Saaju lawọn iwe iroyin kaakiri Naijria ti gbe iroyin pe ile ejọ giga nilu Abuja ti ni ki pasitọ Biodun Fatoyinbo ati Arabinrin Busola Dakolo foju ba ile ẹjọ laarin ọjọ mẹrinla.
Amọ, agbẹjọro Busọla Dakolo ti fesi pe ko si ootọ ninu ọrọ naa.
Ninu atẹjade kan to fi sita lọjọ Aje o ni ileeṣẹ ọlọpaa ṣi n ṣe iwadii ọrọ naa.
O tẹnumọ pe ile ẹjọ giga lAbuja ko ti fiwe pe Busola Dakolo ati Pasito Biodun Fatoyinbo titi di bi a ti ṣe n sọrọ yi.
Ẹwẹ, Pasito Fatoyinbo naa ti fesi si ọrọ naa loju opo Instagram pe ile ẹjọ ko ti ranṣẹ pe oun naa
Gbajugba ayaworan lo fi ẹsun kan Biodun Fatoyinbo pe o fipa ba oun lo pọ ni ọpọlọpọ ọdun sẹyin ti Fatoyinbo si fariga pe ọrọ ko ribẹ.
Pasitọ Biodun Fatoyinbo ni oludasilẹ ile ijọsin Common wealth of Zion Assembly.
Agbẹjọrọ lati ile iṣẹ Pelumi Olajengbesi and Co lo gbe ẹjọ naa lọ sile ẹjọ lorukọ Busola Dakolo.
Opọ awọn eniyan ni wọn ti n woye ibi ti ọrọ naa yoo jasi.
Tax: Kíni ìdí tí orílẹ̀-èdè Nàìjíríà kò fi rí owó orí gbà?
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Epo bẹtiró ni ó mú owó wọlé jùlọ
Ijọba Naijiria ti figbe sita pe orilẹ-ede naa lee dojukọ ipenija  iṣuna, bi ko ba wa atunṣe si ọrọ owo ori gbigba.
Owo ti ijọba orilẹ-ede naa n na ti le ni ilọpo meji, ati pe owo gbese to n san ti ga ju ti tẹlẹ lọ.
Bakannna ni owo to n wọle sapo ijọba ti din ni iye ti o to ida marundinlaadọta ida ọgọrun  lati ọdun 2015.
Toun ti bẹẹ, ijọba Naijiria n gboriyin fun ajọ to n ri si ọrọ owo ori lorilẹ-ede naa (FIRS) fun akitiyan rẹ lati mu ki iye awọn to n san owo ori le sii ni ilọpo meji, lati ọdun 2015.
Gbara ti wọn fi ọrọ yi sita lawọn kan lori ẹrọ ayelujara ti beere boya ọrọ ti ijọba kede  ri bẹẹ lootọ.
Koda, wọn fi kun pe, ti o ba jẹ pe lootọ ni awọn to n san owo ori ti le sii, ki lo de ti ayipada ko  ti de ba awọn ohun amayedẹrun bii ọna oju popo, eto ẹkọ ati eto ilera?
Gẹgẹ bi ọrọ ti ijọba fi lede, miliọnu mọkandinlogun ọmọ Naijiria lo san owo ori sapo ijọba lọdun 2018.
Ọrọ ti banki agbaye sọ lọdun naa ni pe, marundinlaaadọrin ọmọ Naijiria lo nipa lati sanwo ori - bi o tilẹ jẹ pe iye awọn to n sanwo ori ti gbe pẹli sii, ko tii to ida ọgbọn awọn to n sanwo ori.
Ijọba si ti n mura mọ awọn eeyan ti o lee sanwo ori sugbọn ti wọn kọ lati san an.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Nàìjíríà kò rí owó orí gbà
Ni nkan bi ọdun meji sẹyin, ijọba  Naijiria  fun awon to kọ lati sanwo ori ni anfani ọdun kan pe ki wọn wa san owo ori ti wọn ti jẹ latẹhin wa.
Igbesẹ yi jẹ ọna akan gbogi fawọn onigbese naa lati ma ba sanwo itọnran ati ki wọn ma ba foju ba ile ẹjọ.
Banki agbaye tubọ sọ pe ninu awọn onigbese yi, ida mẹjọ pere lo san owo ori ti wọn jẹ laarin gbedeke asiko ọdun kan ti wọn la kalẹ.
Awọn ọmọ Naijiria naa ko ṣadede kọ lati ma san owo ori.
Igbagbọ ti ọpọ ni si ijọba ni pe ijọba kii na owo naa lori eto ilera, eto ẹkọ ati awọn ohun amayedẹrun miran.
Wọn gbagbọ pe awọn kan ni yoo  ko owo naa sapo.
Owo epo betiro ja walẹ
Iṣoro ti ijọba Naijiria n dojukọ bayii ni bi owo epo bẹtiro ṣe ja walẹ, ati ipadasẹhin ọrọ aje to ṣẹlẹ lorilẹ-ede naa lọdun 2016.
Owo agba epo bẹtiro ja walẹ lati ẹẹtalelaaadọfa dọla si ẹẹrinlelaadọta dọla le diẹ lọdun 2017.
Orilẹ-ede Naijiria lo n pese epo bẹtiro julọ l'Afirika laarin ọdun 2012 si 2014, ida ẹtadinlọgọta owo to wọle sapo ijọba orillẹ-ede naa lo wa lati ẹka epo.
Sugbọn eyii ja walẹ laarin ọdun 2016 si ọdun 2018.
Ijọba si sti sọ pe, owo ori to n wọle ti gbe pẹli sii lati ọdun 2015.
Ṣugbọn ọrọ ti ajọ agbaye gbe jade lọdun yii fihan pe, lọdun 2018, alafo to wa laarin owo ori VAT ti Naijiria ri gba ati iye ti wọn ro pe wọn o rigba - lo wa lara awọn eyi to pọ ju nilẹ adulawọ.
Orilẹede Naijiria sọ pe, oun n tiraka lati gba owo ori lati awọn ọna miran, bii lori karakata lori ẹrọ ayelujara. Ijọba naa ti wi pe, oun yoo kan nipa fun awọn ile ifowopamọsi lati maa gba owo ori lori karakata ti awọn ọmó orilẹ-ede naa ba n ṣe lori ẹrọ ayelujara, lati oṣu kini ọdun 2020.
Agbejade kan lati Fasiti Oxford sọ pe, owo to wọle lọna ti kii ṣe lati ori epo bẹtiro ti le sii, sugbọn ere towa lori awọn owo naa ni ọwon gogo ti sọ di yẹpẹrẹ.
Bawo ni o ṣe ri lagbaye?
Awọn iṣiro kan fihan pe, orilẹ-ede Naijiria jẹ ọkan ninu awọn orilẹede ti owo ori wọn kere julọ lagbaye.
Gẹgẹ bi ọrọ ti ajọ Iṣọkan ifọwọsowọpọ ati idagbasoke lagbaye fi lede, ida marun pere ninu awọn to le san lo n san owo ori ni Naijiria.
Ajọ naa tun sọ wi pe, iwọn owo ori ti a'won eeyan san, si bii orilẹ-ede ṣe n ṣe ọrọ aje si ni South Africa  jẹ ida mọkandinlọgbọn, ti orilẹ-ede Ghana jẹ ida mejidinlogun, ti Egypt jẹ ida marundinlogun, nigbati ti Kenya jẹ ida mejidinlogun.
Gẹgẹ bii iwadii ti ajọ banki agbaye ṣe, wọn sọ pe, iwọn owo ori ti awọn eeyan san ni Naijiria lọdun 2016 kere diẹ ni ida mẹrin.
Sugbọn lọdun 2017, ipin naa gbe pẹli diẹ sii bi ida marun din diẹ, gẹgẹ bi ọrọ ti ijọba Naijiria fi ranṣẹ si BBC.
Ileeṣẹ wa ko ni ipin ti ọdun 2018, sugbọn a lee sọ pe, ida marundinlogun lajọ banki agbaye fọwọsi pe orilẹ-ede nilo lati mu ki eto ọrọ aje wọn dagba soke ati lati din iṣẹ ku.
Ọpọlọpọ awọn orilẹ-ede to ṣẹṣẹ ndagbasoke lagbaye ni owo ori wọn kere si iye ọrọ aje wọn, awọn ifilede to n jade laipẹ yii fi han pe, o kere ju ida marundinlogun ti ajọ banki agbaye fi lọlẹ lọ.
Bernardin Akitoby, ti o jẹ igbakeji adari kan ni ajọ IMF sọ pe, owo ori orilẹ-ede to ti ni ilọsiwaju ma n jẹ bii ida ogoji si apapọ ọrọ aje wọn.
Ọgbeni Akitoby ni, ko si ọna kan sọsọ lati mu ki owo ori gbigba gboro sii, sugbọn,  alee ri ẹkọ diẹ kọ lara awọn orilẹ-ede ti o ti ṣaṣeyọri ninu owo ori gbigba, bii:
Ajọ IMF ni, ṣiṣe atunṣe ẹka owo ori ni lórilẹ-ede Naijiria lee mu ki alekun de ba eto owo ori gbigba ni bii ida mẹjọ.
Offa Descendant Union: A dupẹ́ lọ́wọ́ àwọn agbófinró tó dóòlà àwọn ọmọ Ọffa lọ́wọ́ ajínigbé
Oríṣun àwòrán, @NigerianPolice
Kí a tó sanwó ajínigbé ní àwọn agbófinró dóòlà ọmọ Ọffa mẹ́fà -ODU
Ori ti ko awọn ọmọ bibi ilu Offa mẹfa ti awọn ajinigbe jigbe yọ ninu igbekun awọn alaburu.
Lowurọ ọjọru ni awọn agbofinro tu wọn silẹ lọwọ awọn to ji wọn gbe loju ọna Kaduna si Abuja.
Alukoro ẹgbẹ ọmọ bibi ilu Offa, Maruf Olalekan Ajenifuja to fidi ọrọ yi mulẹ fun BBC ni awọn ko san owo itanran kankan fun awọn ajinigbe ki wọn to tu wọn silẹ.
O mẹnuba iṣẹ akọni ti awọn ọṣiṣẹ eleto aabo gbogbo pawọpọ ṣe ki awọn oniṣẹ ibi ajinigbe to tu awọn ọmọ wọnyii silẹ.
Ogbeni Maruf ni: ''Looto la ni erongba lati san owo fawọn ajinigbe naa ṣugbọn ki a to san owo naa lawọn agbofinro tu wọn silẹ''
O ṣalaye pe awọn eeyan meje ni wọn ribi doola ẹmi wọn ti a si ri ọmọ bibi ilu Offa ninu wọn.
Ajenifuja wa dupẹ lọwọ gbogbo awọn ara ilu Offa to fi mọ awọn to duro ti wọn lasiko ijinigbe yi.
BBC Yoruba gbiyanju lati beere lọwọ alukoro ọlọpaa ni ipinlẹ Kaduna boya wọn ri awọn ajinigbe naa mu ṣugbọn ko gbe aago ipe rẹ titi di igba ti a fi gbe iroyin yii jade.
Lọjọ Abamẹta to kọja ni wọn ji awọn ọmọ Offa yii gbe.
Ẹgbẹ ọmọ bibi ilu Offa lawọn ṣi n dunadura pẹlu awọn ajinigbe lati doola ẹmi awọn ọmọ ilu Offa mẹfa ti wọn ji gbe.
Alukoro fẹgbẹ ọmọ Ilu Offa tẹlẹri, Olayemi Olaboye lo ṣalaye ọrọ yi fun ile iṣẹ BBC Yoruba ninu ifọrọwanilẹnuwo.
Olaboye to tun jẹ akọwe igbimọ alaabo ilu Offa fidi ọrọ naa mulẹ pe awọn ti gburo lati ọdọ awọn ajinigbe naa ti wọn si ti sọ pe awọn fẹ gba owo lori awọn ti wọn jigbe.
''Gbogbo igbiyanju to wa ni ikapa wa la n gba, ti a si ti sọ fun awọn mọlẹbi awọn ti wọn jigbe pe ki wọn pa ọkan pọ.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
T'obìnrin àti t'ọmọde ni wọn ń jigbe kaakiri bayii
Titi di bi mo ti ṣe n ba yin sọrọ yi, a ko tii ri ibi doola wọn, amọ, a ni ireti pe wọn yoo pada wale layọ ati alaafia''
Lalẹ ọjọ Abamẹta ni iroyin ijinigbe naa kan gẹgẹ bi alaye ti Olaboye ṣe.
O ni awọn ti wọn farakasa iṣẹlẹ naa wọkọ nilu Offa ti wọn si n lọ si Katsina ṣugbọn nigba ti wọn de agbegbe kan ti wọn n pe ni Ajana laarin Abuja si Kaduna ni wọn ko si ọwọ awọn ajinigbe.
Muideen Ibrahim, to jẹ akọwe apapọ ẹgbẹ naa ni ohun to ṣe pataki sawọn ni lati doola ẹmi awọn ti wọn jigbe.
Oríṣun àwòrán, Facebook/hrmobaolofa
Oloffa Ilu Offa
''Ẹni to n ba wa dunadura pẹlu awọn ajinigbe ko ti i pe wa pada lati sọ iye ti wọn fẹ gba ṣugbọn ohunkohun to ba gba la ṣetan lati ṣe ki wọn ba le e doola ẹmi wọn''
Ẹni ti ọrọ ijinigbe yi ba kan lo mọ ni Naijiria ṣugbọn lẹnu ọjọ mẹta yi, iṣẹlẹ ijinigbe loju ọna Kaduna si Abuja jẹ ohun to n ko awọn arinrinajo laya soke.
Ile iṣe ọlọpaa Naijiria lawọn kaju osunwọn lati koju ipenija ijingbe yi amọ ko jọ bi pe ipa wọn ka awọn ajinigbe naa ti iroko wọn ṣebi ẹni n pẹka si.
Xenophobia: Buhari pàṣẹ pé kí wọ́n kó àwọn ọmọ Nàìjíríà kúrò ní South Africa
Oríṣun àwòrán, @MBuhari
Aarẹ Muhammadu Buhari ti paṣẹ ki minisita ilẹ okeere, Geoffrey Onyeama, ri pe ijọba South Africa gbe igbesẹ lati pana ikọlu ṣiṣe si awọn ọmọ Naijiria lorilẹede naa.
Buhari paṣẹ yii lẹyin ti ikọ to ran si South Africa, Ahmed Rufai Abubakar n jabọ irinajo rẹ si orilẹ-ede naa nile ijọba l'Abuja.
Bakanna ni o ni ki awọn ọmọ Naijiria ti o ba ṣetan lati pada wale kuro lorilẹede naa wa si Naijiria ni kiakia.
Aare Buhari lo ran ikọ rẹ  naa lọ si South Africa, lẹyin ti iroyin jade lori ikọlu ti awọn eeyan ilẹ naa n ṣẹ si awọn ọmọ orilẹ-ede Naijiria to n ibẹ.
Ijọba Naijiria wa n bere owo gba mabinu lọwọ South Africa ati pe ki ajọ ọlọpaa Naijiria pawọpọ pẹlu awọn ojugba wọn ni orilede ọhun.
Lara awọn ohun ti aṣoju aare Buhari jẹ niṣẹ fun aare Cyril Ramaphosa ti South Africa ni ikorooju ijọba orilẹede Naijiria ṣe bu ẹnu atẹ lu awọn ikọlu to n waye si awọn ọmọ orilẹ-ede yi lera lera.
Oríṣun àwòrán, @MBuahri
Ati pe ijọba Naijiria ti setan lati fọwọsowọpọ pẹlu South Africa lati foju awọn ọmọ orilẹede yi wina ofin.
Aarẹ Ramaphosa ni ikọlu naa jẹ ohun idojuti nla fun orilẹede oun, ati pe oun ṣetan lati fọwọsowọpọ pẹlu Naijiria lati daabo bo awọn orilẹede yi to n gbe ibẹ.
Ilé ẹ́jọ́ tó ń gb'ẹ́sùn ìdìbò wọ́gilé ẹjọ́ tí Ajimọbi pè tako Kọla Balogun
Iléẹ́jọ́ tó ń gb'ẹ́sùn ìdìbò wọ́gilé ẹjọ́ tí Ajimọbi pè tako Kọla Balogun
Sẹnẹtọ to n ṣoju ẹkun idibo guusu ipinlẹ Oyọ, Kola Balogun ti sọrọ lori ifidirẹmi Sẹnetọ Abiola Ajimobi to pẹjọ tako lori ipo Senetọ.
Balogun ni idajọ naa jẹ aṣeyọri fun iṣejọba awa-ara-wa ni Naijiria ati fawọn eeyan ẹkun idibo guusu ipinlẹ Oyo.
O wa sọ pe ti Sẹnẹtọ Ajimobi ba fẹ maa ba Ọlọrun ja lori idajọ naa ''ki o mura sii, a o wo ẹni ti yoo pegede.''
Sẹnetọ naa sọ ọrọ yi nigba ti o n ba awọn akọroyin sọrọ lẹyin aṣeyọri rẹ nilu Ibadan
Saaju ni Ile ẹjọ to n gb'ẹsun idibo ni agbegbe Iyaganku niluu Ibadan ti wọgile ẹjọ ti gomina tẹlẹri ni ipinlẹ Ọyọ Ṣẹnetọ Isiaka Abiọla Ajimọbi.
O pe ẹjọ yii tako ẹni ti wọn kede gẹgẹ bi olubori ninu idije si ipọ Sẹnetọ ẹkun idibo guusu ipinlẹ Ọyọ, Sẹnetọ Kọla Balogun.Adajọ Anthony Apkovi  ti o ṣoju igbimọ ẹlẹni mẹta ti o risi igbẹjọ naa lo kede abajade iṣẹ iwadii wọn lọjọ Iṣẹgun.Lara awọn ẹsun ti Abiọla Ajimọbi fi kan Kọla Balogun naa ni aiṣe eto idibo abẹnu ninu ẹgbẹ oṣelu PDP ki o to dije, ṣiṣẹ amulo awọn janduku lati ji apoti ibo gbe, titọwọ bọ akọsilẹ ẹsi ibo ati bẹẹ bẹẹ lọ.
Sugbọn ile ẹjọ ni gbogbo ẹsun naa ni ko ri ẹsẹ walẹ nitori aisi ẹri aridaju.Ninu ifọrọwanilẹnuwo pẹlu awọn akọrọyin, ọkan lara awọn agbẹjọro fun Sẹnetọ Kọla Balogun, Amofin Isiaka Abiọla Ọlagunju ṣe alaye wi pe ohun ti ko kan Ajimọbi lo n dasi.
O ni ki lo kan Ajimọbi nipasẹ ẹsun ti o fi kan pe Sẹnetọ Balogun ko kopa ninu eto idibo abẹnu ki o to dije ninu ẹgbẹ oṣẹlu PDP.
Ọlagunju tẹsiwaju wi pe ifẹ ọkan awọn ara ilu lo gbe onibara oun de ipo ti ko si ni ohunkohun ṣe pẹlu ẹsun mago-mago ti ẹgbẹ oṣelu APC fi kan an.O ni ohun idunnu nla lo jẹ wi pe idajọ naa so eso rere fun Sẹnetọ Kọla Balọgun lẹyin ọpọlọpọ atotonu.
A gbiyanju lati ba awọn agbẹjọrọ ati alatilẹyin ẹgbẹ oṣelu APC sọrọ lẹyin idajọ naa, ṣugbọn pabo lo jasi.Ariwo ọkan-o-jọkan orin lo gba ẹnu gbogbo awọn alatilẹyin Sẹnetọ Kọla Balogun kan lẹyin idajọ naa.
Kọla Balogun ti o ti fi igba kan ri jẹ kọmiṣọna fun karakata ati amojuto awọn ẹgbẹ alajẹṣẹku ni ipinlẹ Ọyọ ni wọn kede gẹgẹ bi ẹni ti o jawe olubori ninu eto idibo si ipo Ṣẹnetọ ẹkun idibo guusu ipinlẹ Ọyọ naa.
APC: òfin NYSC ti APC fi mú mi ni wọ́n kò lò fi mú Ajimọbi tí a kò jọ sìnrú ìlú
Eto idibo naa o waye lọjọ kẹtaleogun, oṣu keji ọdun 2019.
O ni akojọpọ ibo 105,720, ti gomina tẹlẹri nipinlẹ Ọyọ Abiọla Ajimobi si ṣẹ ipo keji pẹlu onka ibo 92,218.
Senetọ Ajimọbi ni oun ni oun jawe olubori ninu eto idibo to kọja nipinlẹ Oyo.
Idibo yii ni oun ati Kola Balogun ti PDP ti dijọ dupo lori ṣiṣoju guusu ipinlẹ Oyo ni Abuja.
Loni ni igbẹjo naa waye nile ẹjọ ọhun.
Ẹjọ ti Ajimọbi fi sun ni wi pe Kọla Balogun kọ ni awọn eeyan dibo fun ninu eto idibo to waye loṣu keji ọdun yii.
Gbogbo awọn alatilẹyin igun mejeeji ti ji de ile ẹjọ ni kutukutu owurọ oni ti wọn si n reti ohun ti yoo gbẹyin ẹjọ naa.
Laipe yii ni akọwe ile ẹjọ naa ranṣẹ wi pe o di aago meji ọsan oni ki idajọ to waye.
Ẹgbẹ́ IMN:ọmọ ẹgbẹ́ wa mẹ́tàlá ní ọlọ́pàá yìnbọn pa níbi ìwọ́de ìdárò Ashura
Oríṣun àwòrán, Google
Aarẹ Buhari ati Sheikh Ibrahim El-Zakzakky
Fakinfa laarin ọlọpaa Naijiria ati ẹgbẹ ọmọ Shiite( IMN) tun ti gbọna mi yọ pẹlu bi ẹgbẹ naa ti ṣe ni ọlọpaa yinbọn pa ọmọ ẹgbẹ awọn mẹtala.
Saaju lowurọ ọjọ Iṣẹgun ni ẹgbẹ naa ti ni awọn ọlọpaa yabo awọn ọmọ ẹgbẹ wọn kaakiri ibi ti wn ti ṣe iwọde ni Naijiria.
Gẹgẹ bi agbẹnusọ wọn Ibrahim Musa ti ṣe ṣalaye fun BBC, o ni awọn ọlọpaa pa eeyan mẹfa ni Bauchi,mẹta ni Kaduna ,meji meji ni Sokoto ati Gombe ati ẹnikan ni Katsina.
Musa ni o ṣeeṣe ki iye eeyan to ku ṣi lekun si nitori bi awọn ọmọ ẹgbẹ wn ti ṣe faragbọta.
Ṣugbọn ileeṣẹ ọlọpaa ti tako ọrọ yi pe awọn ko yinbọn pa ọmọ ẹgbẹ Shitte kankan bi kii ṣe pe awọn tu awọn to pejo lati ṣe iwọde ka.
Loni ni iwọde ni iranti iku Imam Hussein to jẹ ọmọ ọmọ anọbi n waye lọdọ awọn ẹlẹsin Shiite lagbaye
Lẹyin ti iroyin gba oju ayelujara pe awọn agbofinro ti pa mẹta ninu awọn ọmọ ẹyin Shiite ni Kaduna, BBC kan si abẹnugan awọn Shiite.
Ibrahim Musa to jẹ agbẹnusọ fun IMN ṣalaye fun BBC pe ootọ ni pe ọmọ ẹyin awọn mẹta ti ku ni Kaduna bayii.
Lẹyin eyi ni BBC kan si ileeṣẹ ọlọpaa ni Kaduna lati fidi ọrọ yii mulẹ.
Alukoro awọn ọlọpaa ni Kaduna, PPRO wọn ni irọ funfun balau ni awọn ẹlẹsin Shiite n sọ.
Ọga ọlọpaa Yakubu Sabo to jẹ alukoro ọlọpaa ni Kaduna ṣalaye pe ọlọpaa ko pa ẹnikẹni.
Oríṣun àwòrán, @SZakzakyOffice
Ẹgbẹ Shiite
O fidiẹ mulẹ pe ootọ ni pe awọn ọmọ ẹgbẹ Shiite kora wọn jọ fun iwọde ṣugbọn wọn ti tuka bayii nibi eto Ashura ti wọn n ṣe.
O ni ko si ẹnikọkan ti agbofinro yinbọn fun bi awọn Shiite ṣe n pa irọ kiri lori ayelujara.
Eeyan mẹta lo ti jalaisi bayii nibi irin idaro Ashura ti awọn ọmọlẹyin Shite ṣe nilu Kaduna.
Oríṣun àwòrán, @tostvnetwork
Agbẹnusọ fun ẹgbẹ IMN atawọn ọmọlẹyin Shiite ni Naijiria, Ibrahim Musa ṣalaye fun BBC pe awọn ọlọpaa lo yinbọn pa mẹta ninu awọn ọmọlẹyin Shiite naa nilu Kaduna
Bakan naa lo tun ṣalaye pe awọn ọlọpaa ti tilẹkun mọ ọmọlẹyin Shiite ni olu ileeṣẹ ẹgbẹ IMN ni ilu Ṣokoto lati kawọn lọwọ ko ki mọ maa baa jade lọ ṣe iwọde wọn.
Gẹgẹ bii ileri ti wọn ṣe, awọn ọmọlẹyin Ibrahim Elzakzakky to jẹ aṣiwaju ijọ ẹsin Shiite ni Naijiria fọn si igboro lọjọ Iṣẹgun lati ṣeto irin idaro Ashura eleyi ti gbogbo awọn ẹlẹsin Shia kaakiri agbaye maa n ṣe ni ọjọọjọ kẹwaa, oṣu kẹsan an, ọdun.
Wọn tun fi sita loju opo twitter wọn yatọ si pe wọn sọ fun BBC lori ẹrọ ibanisọrọ.
Wọn n ṣe eto yii ni iranti Imam Hussein, ọmọ ọmọ Anọbi to ku ninu ogun Karbala.
Amọṣa ni ilu Abuja, awọn ọmọlẹyin Shiite naa ko lo to ọgbọn iṣẹju fun irin wọn naa ti wọn fi ṣẹri pada sile.
Awọn onwoye ni aifẹ idojukọ pẹlu awọn ọlọpaa lo mu ki wọn tete ṣẹwe le irin naa eleyii ti o ti da ọpọ ipaya si ọkan awọn olugbe ilu Abuja lati igba ti wọn ti kede pe awọn yoo ṣee.
Ileeṣẹ ọlọpaa ti paroko ikilọ ranṣẹ sawọn ọmọlẹyin Shiite naa pe ko si aye fun wọn lati ṣe irin aro naa nitori gẹgẹ bii aṣẹ ile ẹjọ, ẹgbẹ Shiite naa kii ṣe ẹgbẹ to ba ofin mu lorilẹede Naijiria.
Gbogbo igbiyanju BBC lati ba awọn agbofinro ipinlẹ Kaduna sọrọ lori ẹseun yii ko tii bi eso rere bayii.
EFCC /FBI: Ọwọ́ EFCC / FBI tẹ àwọn gbájúẹ̀ 167, wọ́n gbà owó púpọ̀ padà
Asoju FBI ni Naijiri ati akẹgbẹ rẹ lati EFCC
"Ajọṣepọ EFCC ti Naijiria ati FBI ti America ti n bi eso irapada owo gọbọi A ń fikunlukun pẹ̀lú FBI láti mú àwọn ""Yahoo Boys"" tó kù- EFCC."
Ajọ to n gbogun tiwa jẹgudujẹra ni Naijiria, EFFC ati akẹgbẹ wọn FBI lati ilẹ Amerika ti kede aṣeyọri ajumọṣepọ wọn ti wọn pe ni 'Operation Rewire'.
Lasiko ti wọn n ba awọn akọroyin sọrọ ni ilu Eko ni wọn jabọ pe awọn ti mu awọn onijibiti orile-ede Naijiria mẹtadinlaadọsan an EFCC gba ọkọ ayọ́kẹ́lẹ́ 30, òògùn ìbilẹ̀ àti ọ̀pọ̀ fóònù lọ́wọ́ àwọn gbájúẹ̀.
Bakan naa ni wọn ni awọn ri owo apapọ Naira ati dọla to le ni miliọnu mẹtalelaadọjọ gba pada lọwọ wọn,  iyẹn $169,000 àti N92, 000, 000.
Gẹgẹ bi ohun ti akọroyin wa jabọ lati ẹnu aṣoju FBI ni Naijiria, ọgbẹni Uche Amdi ni ọwọ tẹ awọn eeyan wọn yi lẹyin ti wọn ti ṣaaju fẹsun kan awọn eeyan ọgọrin kan.
Ninu awọnti wọn fẹsun kan ni a ti a ri ọmọ Naijiria mẹtadinlọgọrin ninu wọn.
Amdi ko sọ ni pato iye ọmọ Naijiria ti wọn ti ri mu ninu awọn mẹtadinlọgọrin ti wọn fẹsun kan naa.
Amọ ṣa, o ṣalaye pe lara awọn ti awọn mu to wa ni Naijiria ni awọn yoo ko wọn lọ si ilẹ Amẹrika nitori pe awọn ọmọ Amẹrika wa lara awọn ti wọn lu ni jibiti.
Ẹwẹ, o fikun ọrọ rẹ pe o le ni ẹjọ ẹgbẹrun meji to nii ṣe pẹlu lilo akoto ifiweranṣẹ awọn eeyan lori ayelujara lọna aitọ ti awọn n tọ pinpin rẹ lati dun 2018.
Awọn ẹjọ wọn yi ti mu ki awọn eeyan padanu owo to le ni biliọnu meji dọla.
Port harcourt Bole: Mi kò mọ́ pé bọ̀ọ̀lì títà lè gbé mi dé ipò yìí láyé mi!
Ogun State: Èmi ò ní bojúwẹ̀yìn lórí ètò ẹ̀kọ́ ọ̀fẹ́ nípìnlẹ́ Ogùn- Abiọdun
Oríṣun àwòrán, @dabiodunMFR
Gomina ipinlẹ Ogun, Dapo Abiodun, ti sọ pe ijọba oun ko ni boju wẹyin lori eto ẹkọ ọfẹ ni gbogbo ileewe alakọbẹrẹ ati girama nipinlẹ ọhun.
Gomina Abiọdun lo sọ ọrọ yii ninu atẹjade kan ti agbẹnusọ fun ijọba, Kunle Somorin, buwọlu nilu Abẹokuta tó jẹ olu ilu ipinlẹ Ogun.
"O sọ ninu atẹjade naa pe ""Ipinlẹ yii ko fun alaṣẹ ileewe girama ati ileewe ikọṣẹ ọwọ kankan laṣẹ lati gba owo ileewe lọwọ ẹnikẹni, gẹgẹ bi ahesọ ti awọn kan n sọ kiri."""
Dapo Abiọdun tun rọ awọn eeyan ipinlẹ Ogun pe, ki wọn maṣe kọ ibi ara si awọn ahesọ ti awọn kan n sọ kiri.
O ni oun naa ti ka iroyin ofege kan to ni pe awọn ọmọ ileewe ni lati san owo ileewe nigba ti wón ba bẹrẹ saa tuntun losẹ to n bọ.
Lẹyin naa lo wa fi kun un pe, ki awọn eeyan ipinlẹ Ogun ni igbagbọ ninu iṣejọba oun ki oun lee dari ọkọ ipinlẹ na si ebute ayo.
Gomina na sọrọ yii leyin atẹjade kan ti ileeṣẹ to n mojuto eto ẹkọ nipinle ọhun fi kede pe, ki awọn ọmọ ileewe mura lati san ẹgbẹrun mẹrin din lọọdunrun naira fun saa kan.
Atiku vs Buhari: Adájọ́ yóò ṣẹ̀dájọ́ lóní lórí ìbò ààrẹ Naijiria
Oríṣun àwòrán, @Mhizta_Daniels
Atiku vs Buhari: Adájọ́ yóò ṣẹ̀dájọ́ lóní lórí ìbò ààrẹ Naijiria
Loni ni ileẹjọ to n ṣegbẹjọ ẹsun idibo yoo ṣedajọ lori ọrọ idibo aarẹ to waye losu keji ọdun yii l'Abuja.
Agbẹnusọ fun ileẹjọ tn s ṣteto igbẹjọ ẹsun idibo, Sadiat Kachalla, lo fi ọrọ naa lede.
Ṣaaju ni Atiku Abubakar ti ẹgbe oṣelu PDP ti pe aarẹ Muhammadu Buhari, ẹgbẹ oṣelu APC ati ajo INEC lẹjọ, lori esi ibo sipo aarẹ to waye lọjọ ketalelogun, oṣu keji ọdun yii..
Gẹgẹ bi ofin to jẹ mọ eto idibo nilẹ Naijiria ti ọdun 2010 ṣe fi lelẹ, ile ẹjọ gbọdọ ṣedajọ lori ipejọ naa, lẹyin ti Atiku ti lọ ile ẹjọ lọjọ kejidinlogun, oṣu kẹta ọdun yii, laarin ọgọsan an ọjọ.
Bi ẹ ko ba gbagbe, ni ọjọ kẹtadinlọgbọn, oṣu keji ọdun yii ni ajọ INEC kede pe Muhammadu Buhari, ti ẹgbẹ APC, lo jawe olubori ninu idibo ọhun.
INEC ni Buhari ni ibo ti iye rẹ jẹ 15,191,847, nigba ti ẹni to n sare tẹle lẹyin, Atiku Abubakar ni ibo ti iye rẹ jẹ 11,262,978.
Lẹyin esi ibo naa jade ni Atiku fariga pe oun lo bori ninu idibo naa.
Oríṣun àwòrán, Twitter/HOTCUBE2
O ni ibo ti oun fi pọ ju ti aarẹ Buhari le ni miliọnu kan ati aabọ.
Atiku ni ohun ti ẹrọ ayarabiaṣa ajọ INEC gbe jade yatọ kedere si esi ti ajọ naa gbe kalẹ lori esi idibo naa.
O ni ibo ti oun fi pọ ju ti aarẹ Buhari le ni miliọnu kan ati aabọ.
Gẹgẹ bi iṣiro rẹ, ibo ti oun ni jẹ 18,356,732, nigba ti ibo aarẹ Buhari jẹ 16,741,430, fun idi eyi, ki ile ẹjọ kede oun gẹgẹ bi ẹni to jawe olubori ninu idibo naa.
Awọn agbẹjọro Atiku, ti Ọmọwe Livy Uzoukwu n soju ṣalaye fun ile ẹjọ to n ṣegbẹjọ ẹsun idibo naa pe, ajọ INEC fun Aarẹ Buhari ti ẹgbẹ APC ni ibo ti ko yẹ laimoye ọna.
Wọn ni eyi to fi jẹ pe, iye ibo ti awọn oludibo di yatọ si iye ibo ti ajọ naa gbe fun aarẹ Buhari, ti o si gbe oludije ọhun wọle sipo leekeji.
Oríṣun àwòrán, Twitter/BestiaresG
Ta ni yoo tẹsiwaju lati tukọ Naijiria lẹyin idajọ?
Atiku tẹ siwaju pe yatọ si esi ibo ipinlẹ mọkanla ti oun ko gba wọle, Buhari parọ lori ipele iwe ti o ka nigba ti o n dije fun ipo aarẹ.
Bi o tilẹ jẹ pe olupẹjọ naa ni oun yoo pe irinwo awọn o-ṣoju mi koro lati fidi ẹjọ rẹ mulẹ, nigb ati yoo pari awijare rẹ lọjọ kankandinlogun, oṣu keje, ọdun yii, awọn mejilelọgọta pere lo yọju.
Sẹ́nẹ́tọ̀ Femi Okunronmu sọ pé Atiku ló le tún Nàìjírìa ṣe
Sugbọn adari awọn agbẹjọro fun aarẹ Buhari, oloye Wole Olanipekun fesi pe, ko si ninu ofin orilẹ-ede Naijiria fun ẹnikẹni to ba fẹ dije fun ipo aarẹ lati fi iwe ẹri pe o lọ sile iwe han gẹgẹ bi oun amuyẹ lati di aarẹ.
Oríṣun àwòrán, Twitter/@MBuhari
Emi ko nilo iwe ẹri ki n to le dije
Wole Olanipekun tun ṣalaye siwaju pe, oun kan ṣoṣo ni ofin fidi rẹ mule, eyii naa ni pe, ki ẹnikẹni to ba fẹ lati dije fun ipo aarẹ kawe, eyi ti Buhari ni amuyẹ rẹ.
'Ẹ dìbò fún Atiku nílẹ̀ Yorùbá'
Agbẹjọro fun ajọ INEC, Yunus Usman ni, ẹjọ ti olupẹjọ naa pe ko lẹsẹ n lẹ, nitori ajọ INEC tẹle gbogbo ilana ti ofin to rọ mọ eto idibo ti ọdun 2010 gbe kalẹ.
Ni ọrọ tirẹ, Lateef Fagbemi to jẹ agbẹjọro fun ẹgbẹ APC ni ejọ ti Atiku pe fuyẹ nilẹ bi iyẹ ni, nitori olupẹjọ naa ko lee ṣatilẹyin ẹjọ to pe.
Buhari: Àwọn ọ̀dọ́ ní kò rọrùn láti ṣiṣẹ́ ọ̀gbìn láìsí ohun èèlò ìgbàlódé
Aarẹ Muhammadu Buhari ti kesi awọn ọdọ lati mura giri, ki wọn si gba ọna oko lọ nitori eto ọgbin ni ọna abayọ si iṣoro Naijiria.
Aarẹ Buhari sọ eyi ni ibi ipade Ajọ to n risi ipese ounjẹ, National Food Security Council (NFSC) to waye ni Ọjọ Kẹwaa, Oṣu Kẹsan, ọdun 2020.
O ni ijọba oun ti kan ni kanpa fun Banki apapọ Naijiria lati fofin de tita owo ilẹ̀ okeere lowo pọ́ọ́ku fun awọn to ba fẹ ra ohun elo ogbin ati ounjẹ lati okeere.
Bakan naa ni aarẹ fikun wi pe, ki awọn ọdọ to ba fẹ ṣiṣẹ gba oko lọ lati lọ ṣe iṣẹ ọgbin.
Amọ ijọba ko laa kalẹ boya eto ọgbin oni ọkọ ati ada ni tabi ti ọna igbalode.
A ti ṣiṣẹ agbẹ lorilẹede Niajiria ko dẹrun rara nitori aisi iranwọ - Kehinde Olufemi
Ọdọ to n ṣiṣẹ Agbẹ lorilẹede Naijiria, Kehinde Olufemi ti wa fesi si ohun ti aarẹ Buhari sọ wi pe, ki awọn ọdọ lọ ma a ṣiṣẹ ọgbin gẹgẹ bi ọna abayọ si airiṣẹse ni Naijiria.
Olufẹmi, lasiko to n ba BBC sọrọ ni, o ṣoro fun ọdọ lati ṣe iṣẹ agbẹ ni Naijiria nitori ko si iranwọ fun wọn.
O ni ko dẹrun fun awọn ọdọ lati ma a lo ọkọ ati ada lati lọ wa ebe, amọ ti wọn ba ri iranwọ to peye, wọn le ṣe iṣẹ oko ni ọna igbalode ti wọn yoo si ri ere nibẹ.
Olufẹmi ni anfaani pupọ wa ninu iṣẹ agbẹ ni Naijiria nitori ilẹ to dara wa ni Naijiria ati oju ọjọ to sunwọn fun eto ọgbin.
''Eto ọgbin ti ran Naijiria lọwọ nigba kanri, yoo tun ran wa lọwọ ti ijọba ba ṣe oun to tọ fun awọn ọdọ''
''Ijọba gbọdọ pese awọn ẹrọ igbalode bii eleyii to n yọ okuta kuro ninu irẹsi abẹle ati bẹẹ bẹẹ lọ''
''Ko dara bii Naijiria ṣe ni awọn eso ọgbin to pọ janturu, amọ ti ko si ohun elo igbalode lati yii awọn ohun ọgbin yii pada si oun jijẹ abi ohun ti awọn eniyan nilo ni ojoojumọ''
Bakan naa ni ọdọmọde agbẹ yii fikun wi pe ọpọlọpọ iṣẹ lo wa ninu ẹka agbẹ to fi mọ rira ati tita, abi kiko ounjẹ lọ si oke okun.
Olufemi naa wa gba ijọba ni imọran lati maṣe daamu awọn ọdọ nitori iya ni yoo jẹ ki awọn ọdọ ṣe iṣẹ agbẹ  lai fun wọn ni ohun iranwọ.
Onimọ nipa eto idokowo ni Naijiria, Temitope Kolawole ti sọ wi pe yoo lẹra fun awọn eniyan to n ra ounjẹ ati nkan ọgbin lati oke okun nigba ti ijọba ti kọ lati ta owo ilẹ okeere fun wọn mọ ni owo pọọku mọ yii.
Oríṣun àwòrán, Others
Tẹmitopẹ ni awọn ẹlomiran tilẹ ma n  lọ ọna yii lati fi ra owo ile okeere, ti wọn a si ta a ni iye owo gọbọi fun awọn ẹlomiran.
Nitori naa, ẹni to ba fẹ ra ounjẹ lati ilẹ okeere gbọdọ ṣetan lati san owo lori rẹ.
''Eyi yoo fun awọn eniyan laaye lati bẹrẹ si ni ran nkan ounjẹ labẹlẹ, eleyii ti yoo mu ki a bẹrẹ si ni pese awọn oun ti a n jẹ ati eyi ti a n wọ''
Bakan naa ni o kesi ijọba lati lọ owo ti ijọba ba ri lori igbeṣẹ yii lati pese owo iranwọ fun awọn onisowo ati agbẹ kekeeke labẹle.
Ileeṣẹ to n ri si ọrọ owo yiya ni Naijiria, Debt Management Office, DMO, ti sọ pe iye gbese ti Naijiria jẹ lapapọ bayii ti le ni tiriliọnu mọkanlelọgbọn.
To n tumọ si pe lati nnkan bi ọdun marun un ṣeyin labẹ iṣejọba Aarẹ Muhammadu Buhari, gbese tun Naijiria tun pele si ni pẹlu nnkan bii tiriliọnu mejidinlogun naira.
Oríṣun àwòrán, Garba Shehu
Eyii tun n tumọ si pe iye gbese ti Naijiria jẹ ga soke sii ni ida aadọjọ.
Ẹwẹ, yatọ si awọn gbese ti Naijiria ti jẹ, ọrọ aje ti dẹnukọlẹ, bẹẹ ni nnkan ko ṣenu ire fun ọpọ ọmọ Naijiria nitori ajakalẹ arun Coronavirus to n ba gbogbo agbaye finra.
Oríṣun àwòrán, Facebook/Muhammadu Buhari
Ṣugbọn ijọba apapọ ti sọ pe ohun yoo sa gbogbo ipa oun lati ri pe nnkan pada bọ sipo, ati pe igbe aye dẹrun fun awọn ara ilu.
Eyii lo mu kii Aarẹ Buhari ṣe ifilọlẹ igbimọ kan, eyii ti yoo ṣabojuto bi ọrọ aje Naijiria yoo ṣe gberasọ pada ko to di ọdun 2050.
Lara awọn ti yoo maa tukọ igbimọ ọhun ni ọgbẹni Atedo Peterside ati minisita eto iṣuna, Zainab Ahmed.
Lara awọn nnkan to sọ nigba ti Aarẹ Buhari n kede igbimọ naa lọjọ kẹsan an, oṣe kẹsan an, ọdun 2020 ree:
Lati yọ ọgọrun miliọnu ọmọ Naijiria kuro ninu iṣẹ laarin ọdun mẹwaa sasiko yii, paapaa lẹyin ti banki agbaye ti sọ asọtẹlẹ pe Naijiria yoo jẹ ọkan pataki lara awọn orilẹ-ede ti eeyan rẹ yoo pọju lagbaye ko to di ọdun 2050.
Aarẹ ni o ṣe pataki lati ṣe awọn eto ti yoo jẹ itẹsiwaju 'Vission 2020' eyii ti yoo wa sopin lọdun yii.
Mayowa Omoniyi: Kò sí orin Obey, Sunny Ade abí tàkasúfèé tí ń kò le ta gìtá sí
Bakan naa ni Aarẹ tun paṣẹ fun igbimnọ naa lati gbe awọn eto ti yoo rọrun lati tẹlẹ kalẹ, paapaa lasiko ti awọn eeyan to wa ninu igbimọ ọhun ba pari saa wọn tan.
Buhari sọ pe ti igbimọ naa ba ṣe iṣẹ rẹ bi iṣẹ, nnkan yoo yipada si rere fun awọn ọmọ Naijiria.
Ṣugbọn ero awọn ọmọ Naijiria ṣọtọtọ lori agbekalẹ igbimọ vission 2050 naa, bi awọn kan ṣe n sọ pe ki Buhari kọkọ ṣe awọn nnka to ṣeleri lasiko to n ṣe ipolobgo ibo, lawọn miran n sọ pe awọn yoo maa wo ibi ti ọrọ ọhun yoo ja si.
Akomolede ati Aṣa lori BBC: Mọ̀ si nípa oríṣìí ẹ̀ka ìsọ̀rí ọ̀rọ̀ àti ìwúlò wọn
Ki lo ti ṣelẹ sẹyin?
Oríṣun àwòrán, Others
Aarẹ Muhammadu Buhari ti sisọ loju rẹ pe oun ni ori n ta julọ nidi wahala igba gbogbo to n waye laarin awọn agbẹ ati darandaran.
Bakan naa lo fikun pe wahala yii buru to bẹẹ to fi n mu awujọ agbaye lomi, ti aarẹ Donald Trump tilẹ Amẹrika si bi oun nigba kan ri pe ki lo de toun fi n pa awọn Kristẹni.
Buhari sisọ loju ọrọ naa lọjọ isẹgun nibi opin ipade agbeyẹwo awọn minisita to waye nile ijọba nilu Abuja.
Aarẹ wa pasẹ fawọn minisita pe ki wọn jade lọ maa gbe ijọba oun nija lọdọ araalu nipa sise afihan awọn aseyọri alailẹgbẹ ti oun ti se lori aleefa.
Buhari wa n bi awọn minisita naa pe to ba jẹ pe awọn ni Trump kọju ibeere naa si, ki ni wọn yoo se nitori ibeere naa ba oun labo.
Oríṣun àwòrán, Others
Amọ o ni oun fun Trump lesi pada lai jẹ ko mọ ero ọkan oun, toun si ni ija agbẹ atawọn darandaran ju ọjọ ori oun gan lọ, ka to wa sọ ti Trump, tori mo si fi ọdun diẹ ju lọ.
Buhari wa fikun pe, awọn asaaju saa isejọba alagbada akọkọ lo tii pegede julọ ti Naijiria tii ni.
O ni oun ti sọ fun minisita feto ọgbin lati hu akọsilẹ ofin ijọba nibẹrẹ ọdun 1960 jade eyi to sọ nipa awọn oju ọna tawọn maalu le gba.
Pẹlu ayipada oju ọjọ ati ba se n pọ si, ati asa awọn darandaran to jẹ pe to ba ni maalu aadọta, ti wọn jẹ koriko, gbogbo orisun omi ti wọn ba ri ni wọn yoo tọ lai naani ẹni yoowu to ni wọn.
Mayowa Omoniyi: Kò sí orin Obey, Sunny Ade abí tàkasúfèé tí ń kò le ta gìtá sí
"Nitori naa, darandaran  to ba fun maalu rẹ laaye lati lọ sinu oko oloko ni ijọba yoo gbe lọ sile ẹjọ. Agbẹ yoo sọ iye owo ire oko ti maalu naa jẹ, ti darandaran naa ko ba si le sanwo ọhun, wọn yoo ta maalu naa.
Buhari ni awọn asaaju to jẹ lẹrin saa ijọba alagbada akọkọ lo ba ofin naa jẹ, ti wọn si gba isẹ awọn darandaran se.
Oríṣun àwòrán, @GarShehu
Ẹyin eeyan wa, aṣe awọn alagbara naa a maa mọ iyi ounjẹ to gbamuṣe.
Abi ki ni ka ti sọ ti aarẹ Muhammadu Buhari bayii to ni oun n ṣọfọ alase oun.
Buhari Nalado Sandamu to jade laye lẹyin to se ounjẹ adidun si ẹnu aarẹ Buhari fun ọgbọn ọdun gbako.
Ninu atẹjade kan ti ileeṣẹ aarẹ orilẹ-ede Naijiria gbe jade eyi ti amugbalẹgbẹ fun aarẹ lori ọrọ iroyin ati ipolongo, Garba Shehu fọwọ si, aarẹ Buhari ni mo ti padanu olutọju mi to dara to si lootọ."""
Buhari ni alase rẹ ọhun ti ọpọ mọ si 'Commander' jẹ ẹni to tọju ile oun ni ilu Daura nipinlẹ Katsina daadaa ti ko si jẹ ki iya jẹ idile oun.
Ni ileewosan nla Aminu Kano teaching Hospital, AKTH to wa nilu Kano ni o dakẹ si ni ọjọ Aje.
Ni bi  a ṣe n sọrọ yii, aarẹ ti gbe igbimọ kan dide lati lọ ba awọn ẹbi alase rẹ naa kẹdun.
Suicide Prevention: ìwọ́de yìí wáyé láti gbógun ti pípa ara ẹni
Lara awọn to wa ninu igbimọ ti aarẹ Buhari gbe dide yii ni amugbalẹgbẹ fun aarẹ lori ọrọ itọju ile, Sarki Abba, Garba Shehu to jẹ amugbalẹgbẹ fun aarẹ lori ọrọ iroyin ati ipolongo, oludari eto ati ilana gbogbo ni ile ijọba l'Abuja, Ambasadọ Lawal Kazaure.
Ki Olorun dẹlẹ fun ẹni to lọ ni adura aarẹ.
Ìwádìí kan ní Ilééṣẹ́ Facebook leè mọ ìgbà tí àwọn tó wà lójú òpó wọn bá ní ìbálòpọ̀
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ilééṣẹ́ Facebook mọ ìgbà tí àwọn tó wà lójú wọn ń nií ìbálòpọ̀
Awọn alaye ikọkọ kan, lara eyii ti igba ti eeyan ba n ni ibalopọ, ni ileeṣẹ Facebook lee mọ.
Iwadii ti ileeṣẹ kan ṣe ti fi han pe, ileeṣẹ Facebook lee mọ igba ti awọn to wa loju opo ọhun ba n ni ibalopọ, paapaa julọ, awọn obinrin.
Ileeṣẹ Privacy International to wa nilu ọba lo ṣe iwadii lori awọn oun kan, lori ẹrọ ayelujara ti o ma n ṣe atọka igba ti obirin yoo ṣe nkan oṣu.
Iwadii naa fi han pe, awọn ohun to wa lori ẹrọ alagbeka to n ka igba ti obinrin ba n ṣe nkan oṣu yii, maa n pin lara iwadii wọn pelu ileeṣẹ Facebook.
Lara awọn iwadii ti ẹrọ naa ṣe ni lati mọ igba ti nkan oṣu maa n de, ati iru iriri ti awọn to ba n ṣe nkan oṣu n ni.
Awọn oun to wa lori ẹrọ alagbeka to n ka igba ti obirin ba n ṣe nkan oṣu yii lee mọ oun ti eniyan jẹ, ohun ti wọn mu, alaye nipa ibalopọ ati iru ohun ti won n lo lati ṣe nkan oṣu naa.
Awọn esi iwadii yii lo maa n jẹ ki wọn lee sọ igba ti eeyan lee loyun ati igba ti nkan oṣu miran lee yọju.
Ọna ti awọn ohun to wa lori ẹrọ alagbeka yii fi n pin alaye ikọkọ yii fun ileeṣe Facebook jẹ nipa oun eelo kan ti wọn pe ni SDK.
Ileeṣẹ Privacy International ni awọn ohun elo ori ẹrọ alagbeka bii Period Tracker, Period Track Flo ati Clue Period Tracker kii pin abajade iwadii wọn pẹlu Facebook.
Sugbọn awón akẹgbẹ won mii bii Maya, MIA ati My Period Tracker maa n pin iwadii wọn pelu Facebook.
Suicide Prevention: ìwọ́de yìí wáyé láti gbógun ti pípa ara ẹni
Ọdọ́bìnrin kan dáná sun ara rẹ̀ lẹ̀yin tí àwọn òbi kọ̀ fún lati fẹ́ ọlọ́kadà
Oríṣun àwòrán, @others
Ọdọbinrin kan, Aisha Aminu, ni ariwa iwọ-oorun ipinlẹ Zamfara, ti da epo bẹntiro le ori ara rẹ to si dana sii.
O gbe igbesẹ naa léyin ti awón obi rẹ kọ fun lati fẹ ololufẹ rẹ to jẹ ọlọkada.
Aisha sọ fun ileeṣe BBC pe, idi ti oun fi hu iru iwa yii ni pe, yoo ṣoro fun oun lati wa laye laisi pẹlu ololufẹ oun yii.
Aminu Mohammed, to jẹ baba Aisha ṣalaye fun BBC pe, idi ti oun fi lodi si ere ifẹn naa ni pe akuṣẹ ni okunrin ti Aisha nifẹ si.
"Aminu ni ""Nigba ti ko ni owo lọwọ ni a sọ fun un pe ko fi ọmọ wa silẹ, ki ọmọ wa lee ri elomiran to ṣetan lati fẹ"""
"O tẹsiwaju pe, ""A kọ lero pe Aisha nifẹ okunrin naa to bẹẹ, titi di igba ti o dana sun ara rẹ ki oto di pe awọn ara adugbo ba wa pa ina naa."""
Nigba ti a bii idi ti o fi hu iru iwa yii, o ni ifẹ ti oun ni si okunrin naa lo fa, ati pe oun ko fẹ di oni nabi ni oun ṣe dana sun ara oun.
Aisha salaye fun BBC pe, ọlọkada ni okunrin naa, ti ko si sọ pe oun ko ni owo lati fẹ oun.
"O ni ""Lẹhin ti mo gbọ pe o sọ fun awọn obi mi pe oun ko ni owo, ti wọn si ni ko fi mi silẹ ni mo pinnu pe iku ya jẹsin lọ."""
Iṣẹlẹ naa ti mu ki Aisha ṣeṣe lọwọ, lẹsẹ ati lẹyin, sugbón o ti n gba itọju bayii.
Asòfin Kenya fẹ́ fi òfin de isó yíyà nínú ọkọ̀ bàlúù
Oríṣun àwòrán, PARLIAMENT OF KENYA
Lilian Achieng Gogo ni iso ma n da ija silẹ ninu ọkọ baluu
Ọkan lara awọn aṣofin nile igbimọ aṣofin Kenya ti fẹ ki ijọba lorilẹ-ede naa gbe ofin kalẹ, ti yoo ran awọn oṣiṣẹ inu ọkọ baluu lọwọ lati fi iya jẹ awon to ba n yaso ninu ọkọ ofurufu.
Lilian Achieng Gogo, to n soju ẹkun idibo Rangwe, ni iwọ oorun Kenya lo mu imọran yi wa nile aṣofin.
Lilian ni, awọn to n buso ninu ọkọ baluu lee ṣe ijamba fun ẹmi awọn elomiran ninu irufẹ ọkọ bẹẹ.
Aṣofin naa lo sọ ọrọ yii nigba ti o n dasi ọrọ to nii ṣe pẹlu atunyẹwo ofin to jẹ mọ iwa ibajẹ ninu ọkọ baluu.
Lara awọn imọran ti aṣofin naa fun ile aṣofin naa ni pe, ki ijọba fun awọn oṣiṣẹ inu ọkọ baluu laṣẹ lati fun awọn ero inu ọkọ baluu ni ogun to lee din iso ku ninu ọkọ baluu.
O wa ṣalaye pe iwa ki eeyan maa buso ninu ọkọ ofurufu jẹ oun to lee da ija silẹ.
Obirin naa tun fẹ ki awọn ibudokọ baluu din otin ku ninu ọkọ ofurufu.
"Gẹgẹ bi ọrọ to sọ, o ṣalaye pe ""bi awọn eeyan ṣe n mu ọtin ninu ọkọ baluu ku diẹ kaato."
"Aṣofin naa wa pari ọrọ rẹ pe ""Iwa imutinpara awọn eeyan loju ofurufu jẹ eyi to buru ju ti awọn to wa lori ilẹ lọ."""
Xenophobia: Awọn ọmọ Naijiria n sọ ohun tó kàn lẹ́yìn ìpadàbọ̀ wọn
Seyi Makinde: Mo ti gba ₦1.2bn padà lọ́wọ́ òṣìṣẹ́ ọba kan, tí mo sì ti fi pamọ́
Oríṣun àwòrán, Facebook/Seyi Makinde
Gbogbo ẹni to ba mọ nkan fi pamọ, ko maa ranti ẹni to mọ ọ wa nitori asegbe kankan ko si, asepamọ lo wa.
Idi ree ti gomina ipinlẹ Ọyọ, Onimọ ẹrọ Seyi Makinde fi n leri leka, to si n tọ ilẹ la pe gbogbo owo ipinlẹ Ọyọ ti awọn alajẹba ba ji ko ni oun yoo gba pada lọwọ wọn, lai ku kọbọ.
Makinde seleri yii lasiko to n gbalejo awọn ọga agba ile ifowopamọ kan lọọfisi rẹ, to si fikun pe gbogbo owo ti oun ba ri gba pada naa ni oun yoo fi pamọ sinu apo asuwọn owo pataki kan nile ifowopamọ.
Bakan naa lo salaye pe ko ni si awo kankan ninu awo ẹwa nipa apo asuwọn owo pataki naa nitori pe oun yoo jẹ ki awọn eeyan ipinlẹ Ọyọ ni anfaani lati mọ nipa bi apo asuwọn owo naa se n lọ si, ko maa ba tun fun ẹnikẹni lanfaani lati ko owo naa jẹ pada.
Oríṣun àwòrán, Facebook/Seyi Makinde
O yẹ ki awọn araalu mọ bi ijọba se n na owo wọn. Gbogbo owo ti ajọ EFCC ba gba pada lọwọ alajẹbanu kọọkan ni a gba pada, ta si ko pamọ sinu apo asunwọn naa, eyi ti a maa dari ni ọna ti ko ni sokunkun si awọn eeyan ipinlẹ Ọyọ.
Makinde fikun pe ni kete ti oun de si ọọfisi gomina, ni oun kofiri owo to to biliọnu kan ati miliọnu lọna igba naira ninu apo asuwọn owo osisẹ ọba kan, ti ijọba si ti gbẹsẹle owo naa.
Gomina ipinlẹ Ọyọ ni oun ti tọ ajọ EFCC lọ lati ba oun gba awọn owo yii pada, lọna ati se atilẹyin fun eto ẹkọ to dẹnu kọlẹ nipinlẹ Ọyọ.
Election Tribunal: Lai Muhammed àti Oshiomole ní òfo ni ẹjọ́ kòtẹ́milọ́rùn PDP yóò já sí
Oríṣun àwòrán, @MBuhari
Ọrọ ko tii jẹ rodo lọ mumi lori idajọ ti igbimọ olugbẹjọ nipa awuyewuye ibo aarẹ gbe kalẹ, eyi to ni aroye oludije fun ipo aarẹ fẹgbẹ oselu PDP, Alhaji Atiku Abubakar se niwaju igbimọ naa ko lẹsẹ nlẹ.
Lara awọn ohun to n jẹyọ lẹyin idajọ naa ni bi awọn alasẹ ati ẹgbẹ oselu APC lapapọ se n fi ẹgbẹ PDP to gbe wọn lọ sile ẹjọ se yẹyẹ.
Ijọba apapọ ilẹ yii, ti ẹgbẹ oselu APC n dari lo kọkọ kesi ẹgbẹ oselu PDP pe, ta ba le ni, ta ba ba ni iwọn laa bani se ọta mọ, yoo si dara ki PDP tete yara mọ agba lẹgbọn, ko si tọrọ aforiji lọwọ APC pe ko ma binu.
Minisita feto iroyin ati asa, Lai Muhammed lo kede bẹẹ nigba to n fesi lori idajọ ti igbimọ olugbẹjọ naa gbe kalẹ lọjọru.
Oríṣun àwòrán, @OfficialAPC
Sugbọn ẹgbẹ oselu PDP naa ti wa fesi pada fun pe yoo dara ki ẹgbẹ APC ati Lai Muhammed dunnu mọ niwọn lori idajọ naa, nitori ẹni to ba rin ẹrin igbẹyin lo ri ẹrin rin.
Akọwe ipolongo fẹgbẹ PDP Kọla Ọlọgbọndiyan salaye pe, idajọ ti APC n dunnu si yii ko lee jẹyọ nile ẹjọ to ga julọ lorilẹede yii, ti awọn si ti setan lati tun ẹjọ naa gbe dide nibẹ.
Oríṣun àwòrán, @Atiku
Bakan naa ni alaga fun ẹgbẹ oselu APC, Adams Oshiomole naa ti n rẹrin keke si ọrọ PDP yii, to si ni bi wọn ba fẹ, wọn lee pe ẹjọ kotẹmilọrun ni kootu agbaye, ohun to si da ohun loju ni pe pabo naa ni ọrọ wọn yoo ja si.
Lasiko to n jẹwọ pẹlu awọn akọroyin nile ijọba nilu Abuja lẹyin to se ipade tan pẹlu aarẹ Buhari, Oshiomole salaye pe gbigba fun Ọlọrun ni isisnmi, ko si si ẹjọ kankan to tuntun ti PDP fẹ gbe lọ sile ẹjọ to ga julọ nilẹ yii nitori wọn ko ni ẹri kankan gidi to fi ẹsẹ mulẹ.
Xenophobia: Dabiri ní owóyàá, 9 gígábáítì afẹ́fẹ́ ayélujára àti káádì ìpè ₦40,000 nìjọba yóò fún wọn
Oríṣun àwòrán, @nidcom_gov
Ijọba apapọ Naijiria ti kede pe oun ko ni fi awọn ọmọ Naijiria to sẹsẹ de lati orilẹede South Africa silẹ lati jiya, ti oun yoo si pese eto iranwọ fun wọn.
Alaga fun ajọ to n riosi ọrọ awọn ọmọ Naijitia to wa lẹyin odi, Asofin Abikẹ Dabiri Erewa, lasiko to n tẹwọgba awọn sẹsẹde ọmọ ilẹ Naijiria naa ti wọn to mẹtadinlaadọwa niye, lo kede ọrọ itunu yii fun wọn.
Bakan naa lo sisọ loju rẹ pe ijọba ti gunle ijiroro pẹlu awọn alasẹ ile ifowopamọ kan lati gba owoya pẹpẹpẹ fun awọn eeyan naa to ba nifẹ si eto okoowo alabọde.
Oríṣun àwòrán, @nidcom_gov
Yatọ si owoya naa, Dabiri tun ni awọn eeyan to sẹsẹ de lati South Africa naa yoo tun gba kaadi ati owo ipe lori ẹrọ ibaraẹnisọrọ ti yoo to ẹgbẹrun lọna ogoji naira, to fi mọ afẹfẹ lilo oju opo ayelujara (Data), ti yoo to gigabaiti mẹsan eyi ti wọn yoo lo fun osu meji gbako.
Erewa tun lo akoko naa lati se sadankata sawọn alasẹ ileesẹ ọkọ ofurufu Air Peace fun ọwọ aanu ti wọn na lati ko awọn arinrinajo naa wale lai gba kọbọ.
South West Security: Akeredolu gbé ọkọ̀ ogun àti ọ̀gọ́fà ọ̀kadà kalẹ̀ fún Àmọ̀tẹ́kùn
Oríṣun àwòrán, @BateFelix
Gomina ipinlẹ Ondo, Rotimi Akeredolu ti kede pe Amotẹkun ni wọn yoo maa pe orukọ ikọ to n pese aabo yika ilẹ Yoruba.
Bẹẹ ba gbagbe, lọjọbọ ni ipade eto aabo tun waye lati wa ojutu si awọn ipenija aabo to mẹhẹ to n ba ẹkun iwọ oorun guusu Naijiria naa finra.
Awọn gomina ati ileesẹ ọlọpa si ti se agbekalẹ igbimọ alaabo kan ninu eyi taa ti ri awọn osisẹ agbofinro ati awọn ọmọ ẹgbẹ akọya fun ilẹ Yoruba, OPC, awọn ọdẹ ibilẹ ati awọn asọgbo.
Ni itẹsiwaju abọ ipade naa, gomina Akeredolu ti gbe ọkọ nla Hilux bii ogun ati ọkada ọgọfa kalẹ fun ikọ Amọtẹkun  naa, eyi ti yoo wagbo dẹkun fun awọn eeyan to n pagidina eto aabo lẹkun Kaarọ Oojire.
Oríṣun àwòrán, @RotimiAkeredolu
Lasiko to n bawọn akọroyin sọrọ, Kọmisana feto iroyin ati itaniji nipinlẹ Ondo, Donald Ojogo, salaye pe lati igbadegba ni igbogun ti eto aabo to mẹhẹ yoo maa waye, eyi ti awọn gomina n se atilẹyin fun.
Oríṣun àwòrán, @RotimiAkeredolu
Ojogo ni gbogbo awọn ọdaran to n fi igbo boju lawọn yoo fin jade bii okete, ti wọn yoo si sa kuro tefetefe jinna sawọn ilu to wa nilẹ Yoruba.
Oríṣun àwòrán, @RotimiAkeredolu
O wa fọwọ gbaya pe laipẹ ni wọn yoo si asọ loju eegun ikọ Amọtẹkun naa, ti wọn yoo si kawọ ikọlu awọn ọdaran to n waye nilẹ Kaarọ Oojire duro.
FUOYE : Segalink ní ìyàwó Fayemi ní ẹjọ́ jẹ́ lórí ikú àwọn akẹ́kọ̀ọ́ FUOYE
Ọrọ ikọlu laarin ikọ iyawo Gomina ipinlẹ Ekiti ati awọn akẹkọọ fasiti FOUYE ti gbọna miran yọ, pẹlu bi ajafẹtọmoniyan kan ṣe ni oun ṣetan lati pe Bisi Fayemi, iyawo Gomina ipinlẹ Ekiti lẹjọ.
Segun Awosanya ti ọpọ mọ si Segalinks loju opo Twitter ni lo kede bẹẹ.
Segalink ṣalaye pe ni ajọ Tech for Justice toun jẹ ọkan ninu wọn, pẹlu ifọwọsowọpọ National Human Rights Commission, awọn yoo pe iyawo Gomina lẹjọ lori iku awọn akẹkọọ naa.
Ninu fọnran fidio to fi kin ọrọ rẹ lẹyin, a ri ibi ti awọn eeyan kan ti n daro iku awọn ẹni ta ko le fi idi rẹ mulẹ bi wọn ti ṣe jẹ.
Gẹgẹ bi ohun ti wọn sọ ninu fọnran naa, wọn ni ibi isinku ọkan lara awọn ọmọkunrin ti ijọba Ekiti pa ni.
Ko pẹ ti Segalinks fi ọrọ akọkọ sita loju opo Twitter, lo tun fi omiran tẹle pe awọn kan ti n dunkoko mọ oun.
O ni aya oun ko ja ati pe, fidi idi ododo mulẹ nipa iṣẹlẹ naa ni o ṣe pataki si oun.
Titi di igba ti a n ṣe akojọpọ iroyin yi, iyawo gomina tabi ijọba ipinlẹ Ekiti ko ti fesi si ọrọ Segalinks.
Amọ ṣi saaju asiko yii, ni iyawo Gomina Bisi Fayemi ti ni ohun ko fawọn ọlọpaa laṣẹ lati yinbọn lu awọn akẹkọọ.
Iyawo gomina ipinlẹ Ekiti, Bisi Fayemi ti ni ko si otitọ kankan ninu ọrọ to n tan kaakiri pe, oun pasẹ fun awọn ọlọpaa lati sina bo awọn akẹkọọ Ile iwe giga Oye Ekiti, Fuoye to n fẹhọnu han.
Oríṣun àwòrán, TWITTER
Àwọn akẹ́kọ̀ọ́ fẹ́sùn kan ìyàwó gómìnà Ekiti wí pé òún ló pàsẹ kí àwọn ọlọ́pàá síná bo àwọn tó ń fẹ̀họ́nú hàn ní Oye Ekiti
Fayemi ninu atẹjade to fisita sọ wi pe, oun ko tilẹ pade awọn akẹkọọ kankan lọna nigba ti oun se ironilagbara kaakiri awọn ijọba ibilẹ mẹrin, ti ọkan lara wọn si waye ni Oye Ekiti.
O ni ohun ibanujẹ lo jẹ fun oun gẹgẹ bi iya pe, ọkan lara awọn akẹẹkọ sọ ẹmi nu ninu isẹlẹ naa, nitori naa ni oun se salaye ohun to sẹlẹ.
Ninu ọrọ rẹ, Fayemi ni lootọ ni awọn gbọ pe awọn akẹkọọ n se ifẹhọnu han lori aisi ina ọba ni agbeegbe naa, amọ nigba ti oun de ibẹ, awọn akẹkọọ naa ti pari ifẹhọnu han wọn.
Oríṣun àwòrán, TWITTER
Bisi Fayemi: Èmi kọ́ ló pàsẹ fún ọlọ́pàá kó yìnbọn fún akẹ́kọ̀ọ́ Fuoye
Amọ o ni o seesẹ ko jẹ pe awọn janduku kan wọ ibi ti oun ti se ironilagbara, eleyii ti o jẹ ki awọn ọlọpaa koju wọn.
Amọ, o fikun wi pe ohun ko pasẹ fun awọn ọlọpaa lati yin ibọn lu ẹnikẹni, to si kẹdun pẹlu awọn ẹbi ati ara ti ọmọ wọn doloogbe ninu isẹlẹ naa.
BBNaija 2019: Khafi ní òun àti Gedoni kò ní àjọṣepọ̀ rárá
Oríṣun àwòrán, @BBNaija
Ọlọ́pàá Ilẹ̀ Gẹ̀ẹ́sì, Khafi Kareem ti sọ wí pé òun kò tí ì bá ẹnìkẹ́ni ní àsepọ fún ọ̀pọ̀lọpọ̀ ọdún sí ìgbà yíí.
Khafi fi eyi lede lasiko ti wọn fun awọn ara ile Big Brother Naija laye lati sọ awọn nkan ti awọn eniyan ko mọ nipa wọn.
O ni ko si otitọ ninu iroyin to gba ẹrọ ayelujara kan wi pe oun ati Gedoni Ekpata ba ara wọn ni asepọ ninu ile Big brother Naija.
Khafi ni oun ko ba ẹnikeni ni asepọ lati le bori gbogbo awọn isoro to koju oun fun ọpọlọpọ ọdun.
Oríṣun àwòrán, @BBNaija
Ọrọ naa di mimọ nigba ti Ike Oyeama ati Dianne sọ wi pe, awọn fi rọba idaboobo si ẹgbẹ ibusun Khafi ati Gedoni, ni awọn se sọ wi pe wọn lo o.
Gedoni naa ti o ti kuro ni ile Big Brother Naija naa sọ wi pe, ko si ibalopọ to waye laaarin oun ati Gedoni, amọ oun fẹran Khafi lọpọlọpọ.
Ọjọ Isinmi ni a mọ boya won yoo le Khafi kuro ni Big Brother Naija, nitori awọn ara ile ti fi orukọ rẹ silẹ gẹgẹ bi ẹni ti wọn yoo le kuro ninu ile.
Ọdún ìjẹṣu 2019: Àwọn ọmọ Ilara yarí,torí Ọba kọ̀ lati kópa nínú ọdún
Ara ọtọ ni ọdun ijẹṣu ilu Ilara mọkin tọdun yi gba yọ pẹlu bi awọn ọmọ ilu ti ṣe yabo aafin tuntun Ọba to ri pe ko foju han nibi ayẹyẹ naa.
Origun pataki ayẹyẹ naa ni ki Ọba Alara ilu Ilara Mokin yọju si awọn ọdọ ilu lasiko ajọdun naa.
Amọ Kabiyesi ni ohun ko lọwọ si ajọdun naa nitori poe iwa ara oko ni ki eeyan ma na ara wọn lẹgba tori pe wọn n ṣe ajọdun
Gẹgẹ bi awọn ọdọ naa ti ṣe sọ ninu fọnran fidio ti BBC Yoruba ya lasiko ti wọn yabo aafin Ọba ,wọn ni itabukubaẹni ni bi Alara ko ti ṣe yọju sawọn.
Nibi wọduwọdu to waye niwaju aafin Ọba tuntun,arakunrin Onifansanyin Ayodeji fi ẹhonu rẹ han si Alara pẹlu bi Ọba alade naa ko ṣe kopa ninu ajọdun ijẹṣu.
''Bi a se n se nkan wa leleyi,bi ẹnikan ba si ni  ni oun ko ni ṣe bẹẹ,oju rẹ yoo ri ohun tnikan ko ri ri. Bawo ni awọn eeyan yoo ṣe nawo nara wa lati ilu Oyinbo ti Alara ko ni yọju si wọn?''
Ẹkunrẹrẹ fidio bi ọrọ ti ṣe di boolọ o ya mi re loju opo Facbook BBC
A ko ribi fidi ọrọ mulẹ boya Kabiyesi ti gba lati dara pọ mọ ọdun ijẹsu tọdun yi amọ nibi ti fọnran fidio naa pari si,inu awọn ọdọ ko dun si aikopa rẹ.
Akọroyin wa jabọ pe awọn ọdọ ba ferese ati awọn aga jẹ nibi aafin tuntun Kabiyesi Alara ilu IlaraMokin.
E foju lounjẹ pẹlu awọn aworan to jẹyọ lati ilu Ilaramọkin ti ajọdun ijẹṣu ti n waye.
World University Ranking: Ibùdó ẹ̀kọ́ṣẹ́ ìṣègùn Fásitì Ibadan dé ipò kẹrin l'Àfíríkà
Oríṣun àwòrán, @BestiaresG
Atilẹyin ti ileewe Fasiti Ibadan ṣe fun ibudo ẹkọsẹ isegun ileewe naa, lati lee jẹ ki wọn sẹ iṣẹ wọn lọna ti o tọ ati eyi ti o yẹ lo mu ki ibudo ẹ́kọ̀sẹ́ isegun ọ̀hun se ipo kẹ́rin ni Afirika.
Ọjọgbọn Olubunmi Olapade Olaopa lo salaye bẹẹ fun BBC Yoruba lasiko to n sọrọ lori bi ọpọn ibudo ẹkọsẹ isegun fasiti Ibadan se sun si ipo kẹrin ni ilẹ Afirika.
Olaopa ni pẹlu atilẹhin awọn oluranwọ miran, bi awọn akẹkọjade ileẹkọ naa, lo wa lara idi ti ileewe naa ṣe goke agba nilẹ Afirika.
"O ṣalaye pe, ""awa ọsiṣẹ ile iwe yii naa n sapa wa, ta si ti gbe awọn  igbimọ kan kalẹ lati wo bi a ṣe lee de ipo agba. Gbogbo imọran ti wọn gba wa ni a tẹle, eyii lo ran wa lọwọ lati lee de ipo ti a de yii"""
Oríṣun àwòrán, @UIbadan
Abawọle Fasiti Ibadan
Ọjọgbọn Olapade-Olaopa sọ pe, igba akọkọ ni yii ti ileewe naa yoo de ipo kẹrin ni gbogbo Afirika. Bi o tilẹ jeẹ pe ileewe naa ni aṣaju ni gbogbo agegbe aṣalẹ Sahara.
"Ninu ọrọ ọjọgbon naa, o ṣalaye pe ""Lọdun to kọja, ipo kẹjọ ni awa nilẹ Afirika lẹyin Fasiti Makerere to wa ni Uganda, sugbọn lana ode yii ni a goke agba si ipo kẹrin nilẹ adulawọ. Ti a si n tẹlẹ Egypt ati South Africa."""
Ọjọgbọn Olaopa tun ṣalaye pe, ileewe ẹkọṣẹ iṣegun naa gbe ipo kẹrin nigba, to si n tẹle Fasiti Stellenbosch to wa ni South Africa, Fasiti Cairo ati Fasiti Mansoura, to wa ni orilẹ-ede Egypt.
"Lori ọna ti ileewe naa yoo gba lati ri pe eegun ibudo iṣegun yii ko jo ajorẹyin, ọjọgbọn naa ni ""a ti sun ṣokoto wa, ti a si n wo gbogbo awọn ibi to ku diẹ kaato fun atunse to yẹ."""
"Olaopa wa seleri pe ibudo ẹkọsẹ isegun fasiti Ibadan yoo maa wa atilẹhin gbogbo awọn to ti n ran wọn lọwọ latẹyinwa ati awọn ohun tuntun miran, ki wọn le duro si ipo giga yii."""
Ìtàn Mánigbàgbé: Lúwòó Gbàgídà ló bí Adékọ́lá Telú tó tẹ ìlú Ìwó dó
Oríṣun àwòrán, Facebook/OMO Lamurudu Media
Ni aye atijọ, ọpọ ọkunrin ni ọkan wọn maa n rẹwẹsi, ti wọn kii si dunnu ti wọn ba gbọ pe wọn bi obinrin gẹgẹ bii ọmọ tuntun.
Igbagbọ wọn ni pe obinrin ko lee dabira lawujọ bii awọn ọkunrin, wọn ro pe ọkunrin nikan lo lee jẹ eeyan takuntakun, ti yoo si sọ orukọ wọn di manigbagbe lọjọ ọla.
Wọn ko si ranti pe ohun ti ọkunrin lee se, awọn obinrin gan lee se daradara ju ọkunrin lọ.
Bi ọrọ se ri ree pẹlu akọni obinrin kan to n jẹ Lúwòó Gbàgídà,ẹni tii se akinkanju, olokiki, olowo, ọlọrọ ati aya ọba nigba aye rẹ, to si se gudugudu meje ati yayaya mẹfa, lati mase jẹ ki itan rẹ parẹ ninu itan Yoruba.
Gẹgẹ ba se kaa loju opo Wikipedia, akikanju obinrin yii, Lúwòó Gbàgídà, ni Ọọni kọkanlelogun tilu Ile Ifẹ, tii se orirun gbogbo ọmọ Yoruba, to si jọba lẹyin Ọọni Giesi, Ọọni Lumọbi si lo jọba lẹyin rẹ.
Ọja Arena Oshodi ni àwọn èèyàn ti ń r'aja
O kọ wa pe gbogbo lọmọ, ko baa jẹ ọkunrin abi obinrin, ko si eyi ti ko lee jẹ olokiki
Itan yii tun kọ wa lati mase jẹ okuroro
A tun ri kọ ninu itan yii lati maa jẹ onimọtoto
Kogi Governorship: Melaye fárígá, óní òun ó ṣe olùdarí ìpolongo ìbò gómìnà ní Kogí
Oríṣun àwòrán, Instagram/dinomelaye
Sẹnetọ Dino Melaye ti kọ iyansipo rẹ gẹgẹ bi oludari ipolongo fun ibo gomina ninu ẹgbẹ PDP ni ipinlẹ Kogi.
Melaye lo kede ọrọ yii loju opo Twitter rẹ.
"O ni ""Mo fẹ sọ ni kedere pe, mo ti kọ ipo oludari ipolongo fun ibo gomina ninu ẹgbẹ PDP ni ipinlẹ Kogi. Ire ooo."""
Saaju ni alukoro apapọ fun ẹgbẹ naa, Kola Olagbodiyan, ti kede Melaye gẹge bi oludari ipolongo ibo ọhun lọjọ ẹti ki o to di pe o kọ ipo naa.
Ni ọjọ kẹrin oṣu yii ni Musa Wada, fi idi Melaye janlẹ ninu idibo abẹle sipo gomina ninu ẹgbẹ ọhun.
Wada to jẹ aburo si gomina ana ni ipinlẹ ọhun, lo fi idi Melaye janlẹ ninu idibo abẹle naa, pẹlu ibo to le ni ẹẹdẹgbẹrin, nigba ti Melaye ni ibo aadọrin pere.
Meleye ni awọn eeyan kan ti n wo bi ẹni to lee rọwọ mu ninu idibo abẹle naa, sugbon to fidi rẹmi.
Buhari: Bí kìí bá ṣe ìpàdé ìgbìmọ̀ aláṣẹ tí à ń ṣe, ìpayà kò bá bá mi kí ìgbẹ́jọ́ tó wáyé
Oríṣun àwòrán, @BashirAhmaad
Yoruba ni adiẹ a mọọ laagun, amọ iyẹ ara rẹ ni kii jẹ ka mọ, bẹẹ lọrọ ri fun aarẹ Muhammadu Buhari lori abajade igbẹjọ ibo aarẹ.
Aarẹ Buhari, lasiko to n gbalejo awọn gomina to jẹ ọmọ ẹgbẹ oselu APC to wa ki nile ijọba nilu Abuja, jẹwọ pe lootọ ni ojora mu oun ko to di pe igbimọ to n gbọ awuyewuye ibo aarẹ gbe idajọ wọn kalẹ lori ẹjọ naa.
Buhari ni ọpẹlọpẹ pe oun n dari ipade igbimọ alasẹ ijọba to n waye lọwọ lasiko ti awọn ọmọ igbimọ olugbẹjọ n gbe idajọ wọn kalẹ ni, iporuru ọkan ko ba ba oun.
Igba akọkọ ti aarẹ Buhari yoo si se ipade pẹlu awọn ọmọ igbimọ alasẹ rẹ to sẹsẹ yan fun saa keji ni ọjọ naa, ti igbẹjọ n waye bakan naa lori boya o fidi rẹmi abi o yege ibo aarẹ to kọja.
Akoko taa lo nibi ipade igbimọ alasẹ naa tun jẹ iye akoko ti igbimọ olugbẹjọ lo lati gbe idajọ wọn kalẹ, mo dupẹ pe eyi waye, bibẹẹkọ idaamu ọkan ko ba ba mi, mo kan n tiraka lati gbajumọ awọn iwe to wa niwaju mi ni.
Ijẹwọ Buhari yii si lo yatọ gedegede si ohun ti alaga ẹgbẹ oselu APC, Adams Oshiomole n sọ pe ẹgbẹ oselu APC ati aarẹ Buhari ko tiẹ mikan rara lori ibi ti igi igbẹjọ naa yoo wo si.
Ogun Police: Ìgbájú lásán ni ọkọ fún ìyàwó tó sì gba ibẹ̀ kú
Oríṣun àwòrán, Others
Ibinu ko mọ pe olowo oun ko lẹsẹ nlẹ, bẹẹ si ni ibinu isẹju kan maa n sọ ile alayọ di kikan.
Kingsley Madukwe tii se ẹni ogoji ọdun ti n kawọn pọnyin rojọ ni olu ileesẹ ọlọpa to wa nilu Abẹokuta, nipinlẹ Ogun lori ẹsun pe o lu iyawo rẹ, Glory Madukwe pa tori ibinu.
Atẹjade kan ti alukoro fun ileesẹ ọlọpa ipinlẹ Ogun, Abimbọla Oyeyẹmi fisita lori isẹlẹ naa salaye pe, ọkunrin naa, lo gba iyawo rẹ, ti oun naa jẹ ẹni ogoji ọdun, ni igbati lasan, ti onitọun si gba ibẹ dagbere faye.
Atẹjade naa ni ohun suusu ni esu su mọ tọkọtaya yii lọwọ, ti wọn ti bi ọmọ mẹjọ fun ara wọn, nigba ti ọmọ osu kan ti iyawo gbe dani n sọkun, amọ ti obinrin naa kọ lati fun ni ọmu, ko lee dakẹ ẹkun.
Oríṣun àwòrán, Others
Niwọn igba ti ibinu ko si mọ pe olowo oun ko lẹsẹ nilẹ, bi obinrin naa se dide lai dahun si ọrọ ọkọ rẹ pe ko fun ọmọ to n sunkun lọyan, ti obinrin naa si fi ọkọ gun lagidi, to n wọ inu ile lọ, ni ibinu ba gba ọkan ọkunrin yii, to si ba iyawo rẹ wa igbati.
Gẹgẹ bi Oyeyẹmi ti wi, igbati olooyi ti ọkunrin ọlọkada naa fun aya rẹ lo mu ki obinrin naa, to ti n saroye tẹlẹ pe o rẹ oun,  mu idi lọ silẹ to si gba ibẹ jẹ ipe Ọlọrun.
Oyeyẹmi ni aago mọkanla aabọ alẹ ni isẹlẹ naa sẹlẹ, ti Baalẹ adugbo naa si fi isẹlẹ yii to ileesẹ ọlọpa leti, eyi to mu ki ọwọ tete tẹ ọkunrin naa.
Osinbajo: Àwọn àwòrán bí mó ṣe ń bá Buhari sọ̀rọ̀ ni wọ́n rí bíi pé inú ń bí mi
Oríṣun àwòrán, @ProfOsinbajo
Igbakeji aarẹ, Ọjọgbọn Yemi Ọsinbajo ti sọrọ lori agbara ti awọn akọroyin ni lawujọ ati pataki wọn.
Bakan naa lo mẹnuba awọn aleebu to wa ninu abọ iroyin tawọn akọroyin n jẹ fun araalu lawọn oju opo ikansira ẹni lori ayelujara ati lawọn ileesẹ iroyin abalaye gbogbo.
Osinbajo woye ọrọ yii nibi apejẹ alẹ kan ti wọn seto fun ikọ awọn olori lleesẹ iroyin to wa nile ijọba eyi to fi soju opo Twitter rẹ.
"Nibẹ si ni Osinbajo ti salaye pe ""ti mo ba ni ki n sọ tootọ, ọpọ awada tawọn eeyan maa n se lati 'sun' emi ati Buhari laaye lawọn oju opo ikansira ẹni lori itakun agbaye, lo maa n pa mi lẹrin, ti mo si maa n ri wọn bii agbekalẹ isẹ ọpọlọ to pani lẹrin pupọ."""
Igbakeji aarẹ ni fun apẹẹrẹ, o dabi pe gbogbo aworan ti oun ba ti n ba aarẹ Buhari sọrọ ni wọn maa n woye bii ẹni pe oun ni ikunsinu tabi pe inu n bi oun.
Oríṣun àwòrán, @ProfOsinbajo
Bakan naa lo tun niran iroyin eke kan ti wọn gbe jade nipa rẹ lori ayelujara eyi to ni o ti kọwe fipo silẹ nigba ti idibo aarẹ ku ọjọ diẹ.
Ẹgbọn mi obinrin pe mi ni osu Keji ọdun ka to dibo aarẹ pe, to si n beere pe se lootọ ni mo ti kọwe fipo silẹ bii igbakeji aarẹ. Mo sọ fun wọn pe rara, ti ko si gba mi gbọ nitori pe o ti ka iroyin naa loju opo Whatsapp. Ẹ ri pe awọn awọn ileesẹ iroyin lagbara, koda, itakun agbaye lagbara pupọ ju.
Oríṣun àwòrán, @ProfOsinbajo
Amọ sa, o ni oun nigbagbọ pupọ ninu ominira fawọn akọroyin, boya awọn akọroyin to mọ isẹ wọn nisẹ ni abi awọn to n fi isẹ wọn jataa.
"Osinbajo fikun pe ""Mo dupẹ pupọ fun atilẹyin ti a ri gba lojoojumọ, fun iroyin rere ati buburu, boya ẹ kọ iroyin daadaa abi o ku diẹ kaa to, alabasisẹpọ la jẹ si ara wa, ọrẹ si laa maa se."
FUOYE: Fayemi ní ìṣẹ̀lẹ̀ bí àwọn ìrètí ọ̀la náà ṣe kú ba òun nínú jẹ́
Oríṣun àwòrán, Ekiti state government
Gomina Kayọde Fayẹmi ti ipinlẹ Ekiti ti ranṣẹ ibanikẹdun lọ ki awọn ẹbi akẹkọọ meji ti ọlọpaa yinbọn pa.
Awọn akẹkọọ naa jẹ alaisi lasiko rogbodiyan to waye laarin awọn ọlọpaa ati akẹkọ fasiti FUOYE, pẹlu awọn olugbe ilu Ọyẹ Ekiti.
Awọn akẹkọọ meji ọhun, Joseph Okunofua ati Kehinde Dada jade laye lẹyin ti iroyin sọ pe, ọta ibọn ba wọn lasiko iwọde awọn akẹkọọ ati awọn olugbe ilu naa ni ọjọ Iṣẹgun ati Ọjọru.
Họnọrebu Biọdun Oyebanji, to jẹ akọwe ijọba ipinlẹ Ekiti pẹlu Họnọrebu Biọdun Ọmọlẹyẹ, to jẹ olori awọn oṣiṣẹ to n ba gomina ipinlẹ Ekiti ṣiṣẹ, lo ṣiwaju ikọ olubanikẹdun naa.
Ikọ olubanikẹdun ọhun lọ si ilu Ido-Ekiti nibiti wọn ti ṣabẹwo si arabinrin Esther Okunofua, to jẹ iya Joseph akẹkọọ ipele kẹta ẹka imọ Biology ni fasiti FUOYE, ki o to jade laye.
Oríṣun àwòrán, Ekiti state government
Bakan naa ni wọn tun de ilu Uṣi Ekiti, nibi ti wọn ti ki alagba Adedayọ Dada to jẹ baba fun Kẹhinde.
Họnọrebu Oyebanji ṣalaye pe, iṣẹlẹ naa jẹ eyi ti o ba gomina Fayẹmi ninu jẹ pupọ ati pe, kii ṣe idunu rẹ ki awọn obi mejeeji yii padanu ọkan lara awọn ireti ọla wọn.
YouTube ń polówó àwọn iléeṣẹ ńlá pẹlú àwọn fídíò ayédèrú ìwòsàn ààrùn jẹjẹrẹ
Oju opo Youtube a maa ṣe koriya fun awọn ipolowo ọja ayederu oogun apa koko arun jẹjẹrẹ eyi ti ipolowo rẹ n waye loriṣiriṣi ede.
Oju opo naa a si maa gbe awọn ipolowo ọja fun awọn eroja ati fasiti ti o n ṣi araye lọna lori rẹ, gẹgẹ bii iwadii BBC ṣe fidi rẹ mulẹ.
Ayẹwo lori oju opo Youtube fihan gbangba fun BBC pe, o le ni ọgọrin awọn fidio aṣini lọna nipa eto ilera to wa, ninu oniruuru ede mẹwa ta tọpasẹ wọn.
Paapaa julọ nipa iwosan aisan jẹjẹrẹ ni ọpọ awọn fidio naa da le lori, mẹwa ninu wọn lo jẹ pe ẹgbẹlẹgbẹ miliọnu awọn eeyan lo ti wo o, pẹlu oniruru ipolowo ọja ninu rẹ.
Lara awọn iwosan ti ko ni ifidimulẹ wọnyi ni wọn ti tọka sawọn eroja kan bii Turmeric abi baking soda ati bẹẹbẹẹ lọ.
Awọn miran tilẹ tun n rọ awọn eeyan lati mu ọmu rakunmi tabi omi gbigbona, ko si eyikeyi ninu awọn iwosan wọnyii ti wọn ti fi idi rẹ mulẹ nipa iwadii.
Oríṣun àwòrán, YouTube
Lara awọn ipolowo ọja to n farahan ninu awọn fidio iwosan ayederu wọnyii, la ti ri awọn ipolowo ọja awọn eroja to lamilaaka bii Samsung, Heinz ati Clinique.
Pẹlu ilana ipolowo ọja Youtube, o fihan pe atohun atawọn to ṣe fidio awọn ogun ayederu wọnyii ni wọn n pa owo wọle sapo ara wọn nipa ṣiṣi araalu lọna.
Ni oṣu Kinni, YouTube kede pe oun yoo mu adinku ba iye awọn fidio to n ṣafihan awọn ohun to n ṣi araalu lọna, paapaa awọn fidio to n ṣe igbelarugẹ awọn amulumala iṣẹ iyanu to n wo awọn aisan kan san.
Amọṣa, ileeṣẹ YouTube ni ede oyinbo nikan ni eyii yoo ti kọkọ farahan ati pe, ko kan awọn ede miran lẹyin ede Gẹẹsi.
Iwadi ati ayẹwo ti BBC ṣe kan awọn ede bii Gẹẹsi, Potoki, Ruṣia, Larubawa, Paṣia, Hindi, jamani, Ukureni, Faranse pẹlu ede Aguda.
Oríṣun àwòrán, YouTube
Ọpọ awọn oluwadii ẹka BBC Monitorin ati BBC News Brasil lo tẹwọ gba awọn ipolowo ọja kan ṣaaju awọn fidio ayederu iwosan wọnyii.
Yatọ si awọn ipolowo ọja Samsung, Heinz ati Clinique, BBC tun ri awọn ipolowo ọja ikanni ayelujara kan to da lori irinajo, iwe kikọ, fiimu agbelewo Hollywood ati awọn fasiti ilẹ Gẹẹsi.
Gbogbo wọn ni wọn n farahan ni ifẹgbẹkẹgbẹ pẹlu awọn iroyin aṣinilọna wọnyii.
Samsung ni ko si ohun to kan ipolowo ọja ti wọn pẹlu ohun to wa ninu awọn fidio ayederu iwosan aisan jẹjẹrẹ naa, orin yii kan naa ni Kraft Heinz pẹlu n kọ lẹnu.
Grammarly ni oun ti kan si YouTube pe ko yọ ipolowo ọja oun kuro lori rẹ ni kete ti ọrọ naa ti lu si awọn lọwọ. Amọṣa, ileeṣẹ Clinique ni tirẹ ko fesi si ibeere ti wọn fi ranṣẹ sii lori ọrọ yii.
Ipolowo ọja lori oju opo YouTube le wa fun awọn eeyan kan lawujọ. Tim Schoyer to n mojuto bi fidio ṣe n jade loju opo YouTube ṣalaye pe, ilana yiyan fidio ti yoo lọ tabi ti araalu yoo ri, wọnu ara wọn diẹ.
Tammy Abraham lewaju,Tomori tẹle bí Chelsea ṣe dáná sun Wolves mọ́lé
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Bi wọn ba gun ẹsin ninu awọn alatilẹyin Chelsea bayi, geree ni yoo ma lọ pẹlu bi wọn ti ṣe fi goolu marun un ṣagba meji Wolves ninu ifẹsẹwọnṣẹ to waye ninu idije Premiership.
Bi a ba si ni pe ki a pe ori awọn akọni to sọ idunnu yi d'ayọ wa, orukọ awọn agbabọọlu meji ti wọn ni ẹjẹ Naijiria lara la o ma pe.
Orukọ Tammy Abraham ati Fikayọ Tomori wa lara awọn to jẹ goolu mẹrin ninu marun un ti Chelse fi pegede ọhun.
Tammy Abraham jẹ mẹta ninu ifẹsẹwọnsẹ naa, eleyi to mu ki iye goolu rẹ to ti jẹ ni Premiership di meje ninu ifẹsẹwọnsẹ mẹta to gba kọja.
Ọmọ ọdun mọkanlelogun pere ni Tammy Abraham ti o si jẹ agbabọọlu Chelsea to kere ju lọ lati jẹ goolu mẹta ninu ifẹsẹwọnsẹ kan.
Fuoye: NANS késí ẹ̀ka ẹ́gbẹ́ l‘Osun, Ondo, Kogi láti máa bọ̀ ní Ekiti
Oríṣun àwòrán, @jimidisu
Yoruba ni ojo to ba pa ikan ọrẹ, gbogbo ọrẹ ni eji n pa, bẹẹ si ni iku to n pa ojugba ẹni, owe nla lo n pa fun ni.
Idi ree ti ẹgbẹ akẹkọọ lorilẹede yii, NANS ko se fẹ kawọ gbera lori iku to pa meji lara awọn akẹkọọ fasiti Ọyẹ Ekiti lasiko ti wọn n se iwọde pe ko si ina ọba.
Ẹgbẹ naa ti wa kede pe oun n ko ibujoko oun lọ si silu Ado Ekiti bayii, bẹrẹ lati oni ọjọ Aiku lọ, lati wa wadii iku to gba akẹẹgbẹ wọn mejeeji naa.
Nigba to n kede eyi loju opo ikansira ẹni Twitter ẹgbẹ akẹkọ naa, akọwe apapọ fun ẹgbẹ NANS, Farouk Umar salaye pe nibẹ lawọn yoo ti sepade pọ pẹlu awọn alasẹ ẹgbẹ akẹkọọ ni fasiti Fuoye ati awọn eeyan miran to ni ohun se pẹlu isẹlẹ yii.
Oríṣun àwòrán, @AfricaCeleb
Bakan naa lo fikun pe, ẹgbẹ NANS yoo tun se abẹwo ibanikẹdun sawọn ẹbi oloogbe, awọn alasẹ fasiti Fuoye, awọn ọba alaye lagbegbe naa ati awọn akẹkọọ to farapa ninu laasigbo naa.
Koda, Umar tun ni awọn yoo tun yọju si ileesẹ amunawa to yẹ ko pese ina silu Ọyẹ Ekiti, ijọba ipinlẹ Ekiti funra rẹ, ileesẹ ọtẹlẹmuyẹ ati ileesẹ ọlọpaa.
Oríṣun àwòrán, @NANSNIG
Ẹgbẹ akẹkọọ yii wa n kesi awọn ẹka ẹgbẹ naa to wa nipinlẹ Kogi, Ondo, Ekiti ati Osun lati jade wa se koriya fawọn akẹkọọ Fuoye, ti iya n jẹ.
"Umar wa kadi ọrọ rẹ nilẹ pe ""A wa ko se ọfọ kankan mọ, a fẹ beere fun idajọ ododo ni lori iku akẹẹgbẹ wa, a ko si ni fara mọ iwa aibọwọ fun ofin."""
Yollywood: Toyin Abraham ní òun fẹ́ fòpin sí ìbànilórúkọjẹ́ tí Lizzy ń ṣe
Oju opo Instagram n gbona lọwọlọwọ bayii nitori ede aiyede to n waye laarin awọn gbajumọ osere obinrin meji, Toyin Abraham ati Lizzy Anjọrin.
Bẹẹ ba gbagbe eefin ija laarin awọn mejeeji lo ru sita nigba ti awọn ololufẹ Toyin fi ẹsun kan Lizzy pe ko se agbelarugẹ Toyin lasiko to bimọ gẹgẹ bo se maa n se fun awọn osere tiata yoku.
Lẹ́yin eyi ni Lizzy gbe ọpọ ọrọ to nii se pẹlu Toyin si oju opo instagram rẹ eyi to fi n fi ẹsun kan Toyin pe, oun lo ni oju opo ayelujara kan to n gbe iroyin jade, to si ta ba oun, ti oun si ni ẹri to daju lọwọ nipa rẹ.
Idi si ree ti Lizzy se n tahun si Toyin pe oun n lọ sẹba ile rẹ, ti wahala yoo si bẹrẹ, bẹẹ ni awọn ololufẹ Toyin n fun lesi pada, tawọn ololufẹ Lizzy naa si n da wọn lohun, ti ọrọ wa di ranto.
"Lizzy ni ""Onirọ, ọmọ ale... se iwọ nikan lo ni awọn ololufẹ to maa n fa wahala lẹsẹ ni? Ki lo de ti awọn ololufẹ rẹ ko se maa huwa bayii ni ọdun kan si meji sẹyin? Nibo ni wọn wa nigba ti wọn n wọ ẹ pẹlu ololufẹ rẹ, Ẹgbẹgbẹ Asiri ti tu."""
Sugbọn ni bayii, aawọ naa ti fẹju si, ti Toyin si ni lọjọ Aje ni agbẹjọro oun yoo kan si Lizzy Anjọrin lati wọ lọ sile ẹjọ lori ẹsun ibanilorukọ jẹ to n se si oun loju opo ikansira ẹni rẹ.
Nigba to n fesi lori awọn ọrọ ti Lizzy n sọ nipa rẹ yii loju opo Instagram tiẹ naa, Toyin Abraham kede pe, asiko ti to ti oun fẹ fopin si gbogbo ẹsun ibalorukọ jẹ yii, ti ileeẹjọ yoo si jọ gba awọn mejeeji.
O ti de etigbọ mi pe awọn ọjẹwẹwẹ kan to n dibọn bii osere tiata lo n wọ orukọ mi sinu ere itage ti wọn n se nigba kuugba ti wọn ba wa lori ayelujara. Emi naa ti se iru eyi sẹyin, ti n ko si wọ orukọ ẹnikẹni sinu rẹ. Osere tiata kan lobinrin lo darukọ mi lati ba mi lorukọ jẹ, ohun to si fẹ gba ko ye mi, amọ emi ko ni wọ ara mi sinu ẹrọfọ pẹlu rẹ.
Toyin ni gbogbo ẹri ti onitọhun ni pe oun lo ni oju opo iroyin kan ko ju pe, oun fesi si ọrọ ti ẹnikan sọ nibẹ, ohun ko si mọ ohun to kan oun, to si n rọ osere naa, to han pe Lizzy ni, lati dẹkun didi ẹbi ẹlomiran si ori oun.
Toyin wa kadi ọrọ rẹ nilẹ pe, Lizzy yoo gburo agbẹro oun lọjọ Aje nitori oun fẹ fi ofin kasẹ awọn iwa idunkooko mọ ni to n se si oun lori ayelujara nilẹ.
Oyo Tribunal: Ọjọ́ Ajé ní ìgbìmọ̀ olùgbẹ̀jọ́ ìbò gómìnà yóò gbé ìdájọ́ kalẹ̀
Ta ba da ọjọ, ọjọ a pe, ta ba da igba, igba yoo ko, ọla ọjọ Aje ni ọjọ pe ti igbimọ olugbẹjọ ẹsun ibo gomina nipinlẹ Ọyọ yoo gbe idajọ rẹ kalẹ.
Idajọ naa si ni yoo kede ẹni to jawe olubori ninu ibo gomina laarin Gomina Seyi Makinde ti ẹgbẹ oselu PDP ati alatako rẹ latinu ẹgbẹ oselu APC, Adebayo Adelabu.
Bẹẹ ba gbagbe, oludije fun ẹgbẹ oselu APC naa lo morile iwaju igbimọ olugbẹjọ to n gbọ awuyewuye ibo lati tako esi ibo to gbe alatako rẹ latinu ẹgbẹ oselu PDP wọle.
Ajọ eleto idibo nipinlẹ Ọyọ, lo ti kede saaju lẹyin ibo gomina naa to waye lojọ Kẹsan osu Kẹta ọdun yii pe, Onimọẹrọ Seyi Makinde lo moke ninu ibo naa pẹlu ibo to le diẹ ni ẹgbẹrun lọna ẹẹdẹgbẹta (515,621) nigbati Adebayọ Adelabu si se ipo keji pẹlu ibo to le diẹ ni ẹgbẹrun lọna ọọdunrun ati aabọ (357,982).
Bakan naa ni ajọ Inec ni Makinde yege ibo ni ijọba ibilẹ mejidinlọgbọn ninu mẹtalelọgbọn to wa nipinlẹ naa, ti Adelabu si moke ni ijọba ibilẹ mọkanla pere.
Nibayii to ku wakati mẹrinlelogun ki idajọ naa waye, gbogbo eeyan lo n foju sọna lati mọ igun ti igi ọrọ naa yoo wo si, ti gbogbo eto si ti to niwaju igbimọ naa, ti Adajọ Suraju Muhammadu ko sodi lati gbe idajọ rẹ kalẹ.
Ibeere to si n tawọ tasẹ ninu awọn eeyan ni pe ta ni yoo moke ninu idajọ ọla yii?
Bi idajọ naa ba si se n waye, naa ni BBC Yoruba yoo maa mu iroyin naa wa fun yin lọla, ẹ ku oju lọna.
Dolapo Osinbajo: Dolapo, ìyàwó igbákejì ààrẹ ránṣẹ́ mẹ́ta sáwọn obìnrin
Oríṣun àwòrán, @ProfOsinbajo
Iyawo Igbakeji aarẹ, Dọlapọ Oṣinbajo, ti ke gbajare sita pe, ni ibi ti ọrọ de duro bayii lawujọ, afi ki awọn obi yaa joye fijilante, ki wọn si mojuto awọn ọmọ wọn daradara.
Dọlapọ, to ṣọrọ yii nibi ipade adura awọn obinrin to waye ni ilu Makurdi ni ipinlẹ Benue ṣalaye pe, adura kikankikan lawọn obinrin nilo bayii fun awọn ọmọ wọn obinrin, ki wọn ma baa pokii.
O ni ko si aniani pe, awọn obinrin lo ni idile ati orilẹede, nitori naa bantẹ adura wọn gbọdọ le, bẹẹni wọn ko gbọdọ kaarẹ ninu ṣiṣe ojuṣe wọn gẹgẹ bii iya.
Oríṣun àwòrán, Dolapo osinbajo
O ni eyi ni yoo jẹ ko rọrun fun wọn lati lee wa egbo dẹkun si ọwọja iwọkuwọ aṣọ ati oge aṣesodi pẹlu ogun oloro mimu lawujọ.
Iṣẹ mẹta lo wa fi ransẹ sawọn obinrin lorilẹede Naijiria bayii. Akọkọ ni adura fun orilẹede wa, ekeji ni adura fun awọn ọmọ ilẹ yii, ti ẹkẹta si jẹ adura fun awọn idile lorilẹede Naijiria.
Tax evasion: Ìjọba ìpínlẹ̀ Èkó pariwo pé 4.8 mílíọ́nù èèyàn ló ń sá fún owó orí sísan
Oríṣun àwòrán, @jidesanwoolu
Ijọba ipinlẹ Eko ti sọ ọ di mimọ faye pe ninu nnkan bi eeyan miliọnu marun o din diẹ to yẹ ki o maa san owo ori nipinlẹ naa, iwọnba perete ẹgbẹrun lọna ẹẹdẹgbẹrin lo n san an.
Ijsba ipinlẹ Eko ni o se pataki ki awọn pariwo eyi sita nitori pe ojuse araalu si ijọba ni owo ori sisan jẹ, paapaa fun ijọba to ba n ṣe ojuse rẹ faraalu.
Kọmiṣọna fun ato ọrọ aje ati inawo, Samuel Egube lo sọ bẹẹ nibi apero ẹlẹkun jẹkun lori eto inawo ọdun 2020 eleyi ti wọn gbe tọ ẹkun aringbungbun ipinlẹ Eko lọ.
Ọgbẹni Egube ni ipinnu ijsba ni lati rii pe ifikuluku wa loorekoore pẹlu araalu lori bi eto inawo ati iṣuna ijọba yoo ṣe ri ni saa kọọkan.
Ijọba ipinlẹ Eko ni awọn fẹ ṣe agbekalẹ eto iṣuna ọdun to n bs gẹgẹ bi eyi ti yoo ni araalu gẹgẹ bi opomulero rẹ ki ipinlẹ Eko lee gbe mutumuwa lai fi ti ọjọ ori, ẹya tabi ede ṣe.
Osun: Ìjọba ìpínlẹ̀ Ọ̀ṣun fẹ́ lé òṣìṣẹ́ 422 nítorí ayédèrú ìwé ẹ̀rí
Oríṣun àwòrán, @GboyegaOyetola
Ko din ni irinwo oṣiṣẹ ijọba ipinlẹ Ọṣun ti yoo fi iṣẹ ọba pitan laipẹ, ko si si idi meji ju wi pe ilẹ mọ oloro wọn si gbangba ode, lori ẹsun pe ayederu iwe ẹri ni wọn fi gba iṣẹ ijọba.
Gẹgẹ bi a ṣe gbọ, lasiko iṣejọba ana ni ipinlẹ naa labẹ Rauf Arẹgbẹṣọla, ni wọn gbe igbimọ kan kalẹ lati tan ina wo iwe ẹri awọn oṣiṣẹ ijọba ni ibamu pẹlu ofin ati ilana iṣẹ ọba lorilẹede yii.
Ni saa ijọba Arẹgbẹṣọla, gbese owo oṣu sisan wọ ijọba ipinlẹ naa lọrun, ninu to si ni owo to le ni biliọnu mẹta abọ naira, ni wọn fi n san owo oṣu oṣiṣẹ loṣooṣu.
Oríṣun àwòrán, @GboyegaOyetola
Itaporogan to n waye laarin awọn oṣiṣẹ ati ijọba Arẹgbẹṣọla nigba naa lori aisan owo oṣu oṣiṣẹ, si lo mu ki ijọba gbe igbimọ kan kalẹ lati mọ boya iye awọn oṣiṣẹ to n ṣiṣẹ gan an ni wọn n san owo fun.
Fun awọn osisẹ ọba, ọrọ naa wa ja si ti ẹni to n wa ẹni to jẹ baba rẹ lowo lọ, to wa pade ẹni ti baba rẹ gan jẹ lowo.
Oríṣun àwòrán, @SituationRoomNg
Idi ni pe iwadi igbimọ naa tu aṣiri pe pupọ awọn oṣiṣẹ to wa lẹnu iṣẹ gan an, ni ko kun oju iwọn nitori iwe ẹri ayederu ni wọn fi wọ iṣẹ ọba.
Nigba ti abọ iwadi yoo fi jade, igbimọ naa mu aba wa pe, ki ijọba juwe ile fun ẹgbẹrun marun ninu awọn oṣiṣẹ ipinlẹ naa nitori ayederu iwe ẹri ti wọn gbe dani.
Oríṣun àwòrán, @GboyegaOyetola
Amọṣa, gẹgẹ bi a ṣe gbọ, aalọ ati ẹbẹ ẹgbẹ oṣiṣẹ lo mu ki awọn alaṣẹ nipinlẹ naa dẹ okun lọrun wọn, eyi to mu ki iye awọn ti abẹ yoo ba nidi dinku si okoolenirinwo ati meji.
Nibayii, ijọba ipinlẹ naa ti paṣẹ fawọn ẹka iṣẹ ati ileeṣẹ ijọba, lati gbe igbesẹ lori abajade igbimọ naa lẹyẹ-o-ṣọka.
US Doctor: Stephen Hunt késí Nàíjíríà láti mójútó ètò ìlera rẹ̀ lábẹ́lé
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Dokita kan to jẹ ọmọ ilẹ Amẹrika, Stephen Hunt, ti sọ pe awọn adari lorilẹ-ede Naijiria ati awọn eeyan jankan miran ma n na owo to le ni biliọnu mẹẹdogun dọla lọdun, lori eto ilera nilẹ okeere.
Oniṣegun naa lo sọ ọrọ yii nigba to n ba awọn akọroyin ṣọrọ, nibi apero kan to waye lati din bi awọn ọmọ Naijiria ṣe n lọ si ilẹ okeere fun eto ilera ku, eyi to waye ni ẹka eto ẹkọsẹ biokẹmisiri, ni Fasiti Ibadan.
Hunt, ẹni to bu ẹnu atẹ lu iṣẹlẹ yii, wa rọ awọn adari ilẹ Naijiria lati ri si ọrọ ilera, nitori owo to ju biliọnu mẹẹdogun dọla lọ ni awọn ọmọ Naijiria ma n na lọdọdun fun ilera ara wọn loke okun.
Oríṣun àwòrán, @aledeh
Aarẹ Muhammadu Buhari lẹyin to lọ gbga itọju nilẹ okeere lọdun 2018
Sugbọn eyi lee dinku ti ijọba ba lee kọ awọn eeyan lẹkọ to ye kooro, tawọn ọmọ Naijiria ko si ni ma na owo pupọ bayii fun eto ilera ni awọn orilẹ-ede miran lagbaye.
Hunt sọ siwaju si pe, ti awọn eeyan ba rin irin ajo lati tọju ara wọn loke okun, ọpọlọpọ owo lo ma n ba iru irin ajo bẹẹ lọ, bi owo ibugbe, owo ounjẹ ati bẹẹbẹẹ lọ, sugbọn ko ni ri bẹẹ ti wọn ba lee ri itọju to peye ni Naijiria.
African Migrants: Awọn arinrinajo sọ iriri wọn lọ si ilẹ Amerika
Orò Festival: 5.30 ìrọ̀lẹ́ si 5.30 ìdájí ní àwọn olórò yóò fi máa yíde ìlú
Oríṣun àwòrán, @Oyomatters
Wayi o, igbakeji alaga fun ẹgbẹ agbaagba nilu Isẹyin, Alhaji Bọlaji Kareem, ti kede pe ija ti dopin, ogun si ti tan lori aawọ ọrọ sise nilu Isẹyin.
Kareem, ẹni to soju Asẹyin nibi ipade ipẹtu saawọ kan ti ẹgbẹ agbaagba naa seto salaye pe, lasiko to n ba BBC Yoruba sọrọ ni, awọn igbimọ Imaamu ati Alfa nilu Isẹyin, to fi mọ ẹgbẹ ẹlẹsin ọmọlẹyin Kristi, CAN atawọn abọrẹ oro mẹrẹẹrin nilu naa, lo peju sibi ipade ọhun.
Nibi ipade naa lo ni wọn ti fẹnu ọrọ jona lati jẹ ki ogun o sinmi, ti awọn oloro yoo si maa se oro wọn lati aago marun aabọ irọlẹ si marun idaji, ti wọn ko si ni yaju si ẹnikẹni.
Bakan naa, etutu oro ti gbera nilu Isẹyin lọjs Aje oni pẹlu bibẹ aja sidi Ogun to wa loju ọja.
Oríṣun àwòrán, @OtunbaAlaoAkala
Asẹyin ti ilu Isẹyin ti ṣalaye pe, awọn eeyan kan ti ko da iyatọ mọ laarin ẹsin ati aṣa lo fẹ da wahala silẹ pẹlu ọdun oro ilu Isẹyin.
Kabiyesi Abdulganiyu Adekunle Salau ni lootọ ni ọdun oro yoo waye ni ilu Isẹyin fun ọjọ mẹtadinlogun ṣugbọn ọjọ mẹta pere ni wọn yoo fi gbe oro lasiko ọdun naa.
O ni awọn perete kan ti oye ko ye laarin awọn ẹlẹsin musulumi ni ilu isẹyin, lo n lewaju ifẹhonu han naa.
Ninu ọrọ to ba BBC news Yoruba sọ, Asẹyin ni  ijiroro ti waye lori rẹ, wọn si ti yanju ọrọ ọhun.
Ẹ gbọ Asẹyin siwaju si ninu fọnran ohun yii:
Orò Festival: Asẹ́yìn ní ìwọ̀nba péréte làwọn Mùsùlùmí tó ń tako ọdún orò ní ìlú Ìsẹ́yìn
Oríṣun àwòrán, @Oyomatters
Igbimọ to ga julọ fun ẹsin Musulumi, NSCIA, ẹka ti ilu isẹyin ni ipinlẹ Ọyọ, ti kilọ fun awọn to n ṣe ọdun oro ni ilu naa, lori ipinnu wọn pe ko ni si irinkerindo awọn eeyan fun ọjọ mẹtadinlogun.
NSCIA ni awọn to n ṣe ọdun oro yii lo ṣe ikọlu si awọn eeyan kan lọdun to kọja, ti wọn si pa wọn ni ipakupa. Eyi ti ẹgbẹ naa fi lọ ajọ ọlọpaa ati gomina ipinlẹ Ọyọ lọjọ kejila, oṣu kẹwa ọdun naa.
Ajọ naa sọ siwaju pe, ọwọ agbofinrro tẹ lara awọn to ṣe ikọlu naa, sugbọn ti wọn fiwọn silẹ lai foju ba ile ẹjọ.
Alaga igbimọ NSCIA, Raji Coker sọ pe, awọn to n ṣọdun oro naa kan n pariwo ẹnu lasan ni, lọna lati tan awọn agbofinro ati gomina ipinlẹ Ọyọ jẹ, pẹlu bi wọn ti sọ pe, igbimọ ọhun ko gbawọn laaye lati ṣe ọdun oro wọn.
Oríṣun àwòrán, @abati1990
Agbẹnusọ fun NSCIA ni Isẹyin, Mallam Maruf Mustapha ṣalaye fun awọn akọroyin pe, awuyewuye to waye lọsẹ to kọja lori bi ẹgbẹ Ebedi Frontliners ṣe sọ fun gomina ipinlẹ Ọyọ, Ṣeyi Makinde pe, orin ija ẹsin ni ẹgbẹ NSCIA kọ, ko ri bẹẹ rara.
Mustapha ni ẹgbe NSCIA ko gbe igbẹsẹ kankan lati da ọdun oro duro, ati pe ẹgbẹ naa ko ṣe ikọlu kankan si awọn to n ṣe ọdun oro.
Oríṣun àwòrán, @Oyomatters
Mustapha wa sọ fun awọn agbofinro lati ji giri nitori awuyewuye to lee waye, gẹgẹ bi awọn oloro naa ṣe fẹ dena ẹtọ awọn ẹlẹsin miran ni ilu ọhun lati rin bo se wu wọn fun ọjọ mẹtandinlogun, nitori ọdun oro ti wọn n ṣe.
Ṣaaju ni Oludari ikede fun ẹgbẹ Ebedi Frontliners, Sẹgun Fasasi ti fi ẹsun kan ajọ NSCIA, pe ẹgbẹ naa lọ si ile ẹjo lati da ọdun oro naa duro, to si fi kun pe, eyi jẹ ọna lati da rogbodiyan silẹ ni ilu Isẹyin.
Majek Fashek: Ṣé lóòtọ́ ni Òdú olórin Raggae, Majek Fashek jáde láyé?
Oríṣun àwòrán, Majek Fashek
Iroyin kan ni ọjọ aiku pe lo gbalẹ kan pe gbajugbaja olorin Raggae ọmọ Naijiria nni, Majek Fashek ti dagbere faye.
Ohun ti iroyin naa, eleyii to ti farahan lori ọpọlọpọ awọn oju opo aiyelujara titi kan Wikipedia ṣalaye pe, Majek Fashek mi eemi ikẹyin rẹ ni ọjọ Aiku ni ilu London, ni orilẹede Gẹẹsi.
Amọṣa, ohun ti alamojuto ẹgbẹ oṣere rẹ, Uzoma Omenka sọ ninu fidio kan, eyi to fi sita loju opo instagram Majek Fashek ni pe, ko si nnkan to ṣe Majek o.
O ni ko ku, ṣugbọn ara rẹ ko le.
Fidio naa eyi to fi sita ni nnkan bii agogo mejila oru ọjọ Aje, Uzoma Omenka ni ko yẹ ki ẹnikẹni maa gbadura iku fun agba onkọrin naa.
nigba ti BBC Yoruba kan sii, O ni ohun to nile ni owo iranwọ fun itọju rẹ ati pe ọpọ awọn eeyan lo ti n pe lọtun losi lati igba ti iroyin naa ti jade.
Majek ko ku o, ojojo diẹ̀ lo kan n ṣe ogun rẹ
Ti a ba n sọ ninu awọn onkọrin ọmọ orilẹede Naijiria ti gbogbo agbaye mọ bi ẹnii mọ owo, ti orin rẹ si ti gbe ogo ba orilẹede Naijiria ni ọpọlọpọ igba, Majek Fashek jẹ ọkan pataki ninu wọn.
Ọdun 1962 ni wọn bi Majek Fashek ni ilu Benin, ni ipinlẹ Edo.
Ni aipẹ yii ni iroyin kan kọkọ jade pe arun jẹjẹrẹ mu Majek Fashek ti wọn si n beere iranlọwọ fun un,
Iroyin iku rẹ kọkọ ti tan jade ni ọjọ diẹ sẹyin ki alamojuto ẹgbẹ akọrin rẹ, Uzoma Omenka to gbe fidio kan sita pe irọ ni ṣugbọn o fi idi rẹ mulẹ nigba naa pe lootọ ni aisan da agba akọrin naa dubu
Amọṣa iroyin naa ṣebi ẹni pe ko dawọ duro.
Lara awọn manigbagbe orin ti Majek Fashek gbe jade ni Send down the rain eyi to fun un ni inagijẹ The rainmaker. Awo orin Prisoner of Conscience and I&I Experience(1989),So long too long (1991)
Orukọ abisọ rẹ gangan ni Majẹkodunmi Fasheke.
Ile iwosan Queen Elizabeth Hospital, Woolwich ni o ti n gba iwosan ni ilu London.lẹ.
Fake Pastor: Ọlọ́pàá mú aṣaájú ẹgbẹ́ òkùnkùn 'Ẹiyẹ Confraternity'
Oríṣun àwòrán, @PoliceNG
Ọwọ ọlọpaa nipinlẹ Eko ti tẹ arakunrin kan ti wọn ni o jẹ ijakumọ laarin awọn ọmọ ẹgbẹ okunkun Ẹiyẹ Confraternity, ni agbegbe Bariga ni ilu Eko.
Inagijẹ ti ọpọ eeyan mọ arakunrin naa si ni ‘Pasitọ’ lai ni ile ijọsin kankan, ṣugbọn orukọ abisọ rẹ a maa jẹ Emmanuel Ọlatunde.
Iroyin ti a gbọ sọ pe, ọwọ tẹ arakunrin ọhun lori ẹsun ọkan o jọkan iwa ipaniyan ati idigunjale lagbegbe ijọba ibilẹ Bariga.
Gẹgẹ bi atẹjade kan ti alukoro ileeṣẹ ọlọpaa nipinlẹ Eko, Bala Elkana fi sita, Ọmọ ọdun mọkanlelọgbọn ni Ọlatunde, o si ti fi igba kan ri lọ ṣe saa diẹ lọgba ẹwọn.
O ni ọwọ rẹ lawọn ọlọpaa ba ninu iku Ọgbẹni  Ahmed Karonwi, ti oun pẹlu jẹ ilumọọka ọmọ ẹgbẹ okunkun 'Aiye Confraternity'
Ikọlu awọn ẹgbẹ okunkun ti n di tọrọfọnkale nipinlẹ Eko, eleyii ti ileeṣẹ ọẹọpaa ni ilakaka n lọ lati wa ọwọ rẹ bọlẹ.
FUOYE protest: Gómìnà Fayemi ní àsìkò tó fún ọlọ́pàá láti máa lo ọta rọ́ba fún kíkojú ìwọ́de
Oríṣun àwòrán, Ekiti state government
Gomina ipinlẹ Ekiti, Ọmọwe Kayọde Fayẹmi ni oun ti paṣẹ fun kọmiṣọna ọlọpaa ni ipinlẹ Ekiti lati bẹrẹ iwadii ni kiakia lori wahala to bẹ silẹ nilu Ọyẹ Ekiti ni ọsẹ to kọja.
Wahala naa waye laarin awọn akẹkọọ, awọn olugbe ilu naa atawọn ọlọpaa ni ọjọ Iṣẹgun to kọja.
Ninu ọrọ to ba awọn eeyan ipinlẹ Ekiti sọ lalẹ ọjọ Aiku, gomina Fayẹmi ni iwadii ọlọpaa ni yoo ṣafihan gbogbo awọn ti aje iṣẹlẹ naa ba ṣi mọ lori yala laarin awọn ọlọpaa ni tabi laarin ilu.
Mo ti rọ awọn ọlọpaa lati wa ọna lilo ọta onirọba lati koju iwọde dipo lilo ọta ibọn tootọ.
O ni oun yoo tun gbe arọwa naa de agbo ẹgbẹ awọn gomina ipinlẹ lorilẹede Naijiria, NGF ki wọn lee yẹẹ wo titi de ipele ijọba to ga ju lorilẹede yii.
O ni inu oun dun pe awọn alaṣẹ fasiti naa atawọn igbimọ adari akẹkọọ nibẹ pẹlu ti kọkọ sọọ ṣaaju pe kii ṣe iyawo oun tabi awọn oṣiṣẹ ijọba to baa kọwọrin lo paṣẹ fun awọn ọlọpaa lati yinbọn lasiko iṣẹlẹ naa. O ni o han gbangba pe iyawo oun kan rin arinfẹsẹsi ni.
Oríṣun àwòrán, Ekiti state government
Lori ọrọ aisi ina ọba to ṣokunfa iwọde awọn akẹkọọ ni owurọ ọjọ ti iṣẹlẹ naa ṣẹlẹ, Gomina Fayẹmi ni ọpọ igba ni oun ti ran ikọ lọ sọdọ awọn alaṣẹ amunawa BEDC bi o tilẹ jẹ pe gomina ipinlẹ ko laṣẹ tabi agbara kankan lori ipese ina manamana lorilẹede Naijiria.
O fi kun un pe ijọba ni yoo san owo itọju awọn to fara gbsgbẹ lasiko iṣẹlẹ naa ati wi pe ko dun mọ ijọba ipinlẹ naa ati oun ninu pe iku pa awọn ọjọ ọla orilẹede yii meji kan lasiko ti rogbodoiyan naa fi waye.
Mile 12 Accident: LASEMA ní ọkọ̀ akẹ́rù tó sọ ìjánu rẹ̀ nù lásìkò eré àsápajúdé ló fa sábàbí
Oríṣun àwòrán, LASEMA
Ijamba o nile afi ki ọba oke maa ko wa yọ, Ijamba miran tun ti sẹlẹ ni agbegbe Agric, lopopona Mile 12 si Ikorodu nilu Eko.
O kere tan eeyan meji ti dagbere faye ninu ijamba naa, awọn mẹta wa ni ẹsẹ kan aye, ẹsẹ kan ọrun nigba ti ọpọ eeyan miran farapa.
Ohun to fa sababi isẹlẹ naa ni bi ọkọ akẹru nla kan to gbe ile ẹru onirin, taa mọ si kọntena, to gun to ogun bata se wo lu ọkọ ayẹkẹlẹ Camry kan, ti nọmba rẹ jẹ FKJ 732 FS to si pa awọn eeyan to wa ninu rẹ.
Oríṣun àwòrán, LASEMA
Koda, a gbọ pe awọn ọlọkada atawọn eeyan to to n rin lọ lasiko ti ijanba naa waye naa wa lara awọn to fara pa.
Nigba to n fidi isẹlẹ naa mulẹ fun BBC Yoruba, Ọga agba fun ajọ to n mojuto isẹlẹ pajawiri nipinlẹ Eko, LASEMA, Ọmọwe Olufẹmi Oke Ọsanyintolu salaye pe gbogbo awọn osisẹ awọn lo tete lọ sibi ti isẹlẹ naa ti waye.
Oríṣun àwòrán, LASEMA
Ọsanyintolu salaye pe ọkọ akẹru naa to kun dẹnu, ti nọmba rẹ jẹ LSD 611 XU, ti wọn ko mọ ẹru to wa ninu rẹ, lo sọ ijanu rẹ nu lasiko to n sare asapajude.
Ọga agba LASEMA ni sọrọ̀ yii tun kan awọ̀n ọlọkada mẹta pẹlu.
Oríṣun àwòrán, LASEMA
Ọsanyintolu fikun pe ni kete ti awọn osisẹ Lasema  de ibi isẹlẹ naa, ni awọn ti gbe awọn eeyan to farapa nibẹ lọ sile iwosan, ti awọn ko si ti mọ iru eeyan ti ọkunrin meji to gbẹmi mi ninu isẹlẹ naa, jẹ.
O ni gbogbo ẹ́ru ti wọn ko nibi isẹlẹ naa ni wọn ti fa le agọ ọlọpaa to wa ni Owutu lọwọ.
Yollywood: Lizzy Anjorin tí fi ìwé ìpẹ̀jọ́ ránsẹ́ sí Toyin Abraham
Oríṣun àwòrán, Toyin Abraham
Lizzy Anjorin ti fẹsun kan Toyin Abraham pe o nlo oogun oloro cocaine lati fi sara rindin, eleyii to lodi sofin.
Lizzy sọ eyi lori ikanni Instagram rẹ, lẹyin to fi iwe ipẹjọ to fi ransẹ si Toyin a han si ori ayelujara.
Ninu iwe ipẹjọ naa, Lizzy fẹsun ibanilorukọjẹ kan Toyin, ati wi pe awọn ololufẹ rẹ n dunkoko mọ oun.
Bakan naa, Lizzy fẹsun kan Toyin wi pe o parọ mọ oun, pe oun gbe oogun oloro, eleyii ti o ni yoo jẹ ki ajọ to n gbogun ti lilo oogun oloro lorilẹede Naijiria, NDLEA ko iwe iransẹ si oun.
Unicycle School: Olùdarí ibùdó ìkẹ́kọ̀ kẹ̀kẹ́ alájọwà ń fẹ́ ìrànwọ́ ìjọba
Amọ, o ni awọn mejeeji ni Ajọ Ndlea yoo se iwadii, eleyii ti yoo fihan wi pe Toyin n lo oogun oloro cocaine.
Ija laarin gbajugbaja osere tiata mejeeji yii, ti mu ọpọlọpọ arinyanjiyan dani, ti awọn adari ni Nollywood naa si sọ wi pe awọn yoo pari aawọ laarin awọn mejeeji.
Kaka ki ewe agbọn dẹ lori aawọ to n waye laarin Toyin Abraham ati Lizzy Anjọrin, ko ko ko lo tun n le si.
Idi ni pe Lizzy tun ti gbe fọnran aworan kan sita lọjọ Aje, to si n tẹnumọ pe ọmọ ale ni Toyin bi o tilẹ jẹ pe agbẹjọro Toyin ti kan si lati dẹkun iwa ibajẹ Toyin to n se lori ayelujara.
Ninu fonran aworan naa ti Lizzy fi soju opo Instagram rẹ lo ti sọ pe Toyin Abraham kii ran awọn ololufẹ rẹ lọwọ ati awon akẹgbẹ rẹ ninu isẹ tiata.
Lizzy ni ko yẹ ki Toyin maa lo ọpọ ero to jẹ ololufẹ rẹ lati maa fi kọju ija sawọn osere ẹgbẹ rẹ, amọ n se lo yẹ ko maa lo wọn lati ran awọn ti ebi n pa ninu isẹ tiata lọwọ.
Osere tiata naa tun fikun pe, ile alagbo ọmọ ni Toyin bi ọmọ rẹ tuntun si, to si wa nibẹ fun odidi fun ọjọ mẹwa gbako, amọ to ni Toyin n parọ pe ilu London lo bimọ si fun araye.
O fikun wi pe, aworan lasan ni Toyin lo, lati fi parọ wi pe ilu Oyinbo ni oun ti bimọ, bẹẹ lo si ls ya asọ lo lati fi ya fọto, pẹlu afikun pe irọ nla ni Toyin maa n pa, to si ti di ẹni ijakulẹ.
Oríṣun àwòrán, Lizzy Anjorin
Lizzy wa n fọwọ gbaya pe oun kii se ẹgbẹ Toyin rara nitori ti kii ba se pe awọn dijọ n se ere tiata ni, Toyin ko ba maa kọ lẹta to mẹwa, ko to lee fi oju kan oun.
Se emi ati ẹ wa ninu ẹgbẹ ni, so ti kọ ile ni abi o ti ra mọto, iwọ wa n sọ pe mo n jowu awọn aseyọri rẹ, isẹ tiata ko fẹ abosi, abosi maa n tẹ eeyan mọlẹ ni.
Bakan naa lo fikun wi pe, ọmọọmọ ni ọmọ Toyin jẹ si oun nitori oun kii se ẹgbẹ rẹ, bi awọn tilẹ jọ n wọ sokoto kan naa bii ẹgbẹ
Lizzy fẹsun kan Toyin wi pe kii ran awọn eniyan lọwọ, amọ oun ti ri daju wi pe awọn eniyan se oriire labẹ oun, ti wọn si di ẹni iyi ni awujọ.
Oríṣun àwòrán, Toyin Abraham
Gbajumọ osere tiata, Toyin Abraham ti mu ileri to se lọjọ Aiku sẹ pe, oun yoo bẹrẹ igbesẹ ofin lori awọn ibajẹ oun ti akẹẹgbẹ rẹ lagbo osere tiata lobinrin, Lizzy Anjorin n se lẹnu ọjọ mẹta yii loju opo Instagram.
Bẹẹ ba gbagbe, a mu iroyin naa wa fun yin pe aawọ ati itahun sira ti n waye laarin awọn obinrin osere tiata mejeeji naa, ti Toyin si ti kede pe awọn agbẹjọro oun yoo kan si Lizzy loni ọjọ Aje.
Lọwọ-lọwọ bayii, awọn agbẹjọro Toyin Abraham ti kan si Lizzy bayii, ti wọn si n beere pe ko gbe igbesẹ mẹta pere lati pẹtu si aawọ naa, bi bẹẹ kọ, ọrọ naa yoo de ile ẹjọ.
Oríṣun àwòrán, Lizzy Anjorin
"Toyin Abraham, nigba to n fi lẹta naa si oju opo Instagram rẹ, tun kede lẹẹkan si pe ""kii dara ki eeyan dakẹ nigba miran, nitori dipo ki eeyan ba maa ba ẹlẹdẹ jijagudu, o kuku dara ki eeyan jẹ ko mọ pe in akamọ ni ile rẹ."""
Toyin ni oun ko ni sọrọ lori isẹlẹ naa mọ, nitori ikọ alakoso ati awọn agbẹjọro oun ti gba ọrọ naa .
Ninu lẹta naa ni wọn ti n beere pe ki Lizzy lọ pa gbogbo ohun ibajẹ to kọ nipa Toyin rẹ lẹyẹ o sọka, ti wọn si tun n beere pe ko kọ iwe ẹbẹ si ileesẹ amofin naa ati Toyin Abraham, eyi ti yoo safihan pe o ti tuuba.
Awọn agbẹjọro Toyin salaye pe ọpọ nkan ti Lizzy kọ nipa onibara awọn naa lo wa lati baa lorukọ jẹ, ti ko ba si tete tọrọ aforijin, ko si pa awọn ọrọ ibajẹ naa jẹ, ọrọ ọhun yoo beere fun atilẹyin ofin nile ẹjọ.
Oyo Tribunal: Olùdámọ̀ràn ìṣèlú fún Makinde ní Adelabu kò ní ẹ̀rí tó dájú láti pe ẹjọ́ kòtẹ́milọ́rùn
Oríṣun àwòrán, Seyi Makinde
Ìgbìmọ̀ olùgbẹ́jọ́ to n gbọ́ awuyewuye ibo gomina nipinlẹ Ọyọ ti kede pe gomina Seyi Makinde ló borí ìbò gómìnà to waye losu kẹta ọdun 2019.
Igbimọ̀ naa kede eyi lasiko to n gbe idajọ̀ kalẹ nile ẹjọ giga to wa ni Iyaganku Ibadan, lori ibo lati mọ ẹni to jawe olubori ninu ibo gomina naa.
Nigba to n gbe idajọ rẹ kalẹ, Adajọ Suraju Muhammed to ko igbimọ olugbẹjọ to n gbọ ẹhonu ibo naa sodi salaye pe, gbogbo awọn ẹsun ti ẹgbẹ oselu APC ati oludije rẹ gbe wa siwaju igbimọ naa, lo jẹ otubantẹ.
Adajọ Muhammed salaye pe, ẹsun ti Adebayọ Adelabu fi kan ajọ eleto idibo pe, iye ibo ti wọn di pọ ju awọn oludibo to tẹ ika lọ ni ko fidi mulẹ, bẹẹ ni ko si ni ẹri to daju pe iye awọn oludibo ju iye awọn ti ajọ Inec fi orukọ wọn silẹ lọ.
Oríṣun àwòrán, Seyi Makinde
Ẹwẹ, nigba to n ba BBC Yoruba sọrọ lẹyin ikede igbimọ olugbẹjọ ẹhonu ibo naa, asaaju agbẹjọro fun Adelabu ni awọn yoo lọ se asaro lori idajọ igbimọ naa lati mọ boya awọn yoo tun pe ẹjọ kotẹmilọrun abi bẹẹ kọ.
Sugbọn lero ti oludamọran agba feto iselu fun gomina Seyi Makinde, eyiun Asofin Babatunde Oduyọye salaye pe, ko si ọrọ fifi tọrọ di kọbọ loju lori agbekalẹ idajọ naa, nitori pe igun olupẹjọ ko ni ẹri to daju lati fi ti awọn ẹsun rẹ lẹyin.
Bẹẹ ba gbagbe, oludije fun ẹgbẹ oselu APC , Adebayọ Adelabu lo morile iwaju igbimọ olugbẹjọ to n gbọ awuyewuye ibo gomina, lati tako esi ibo to gbe alatako rẹ latinu ẹgbẹ oselu PDP, Seyi Makinde wọle bii gomina.
Ajọ eleto idibo nipinlẹ Ọyọ, lo ti kede saaju lẹyin ibo gomina naa to waye lojọ Kẹsan osu Kẹta ọdun yii pe, Onimọ ẹrọ Seyi Makinde lo moke ninu ibo naa.
Inec ni  ibo to le diẹ ni ẹgbẹrun lọna ẹẹdẹgbẹta (515,621) ni Seyi Makinde to gbegba oroke ko, nigbati Adebayọ Adelabu si se ipo keji pẹlu ibo to le diẹ ni ẹgbẹrun lọna ọdunrun ati aabọ (357,982).
Bakan naa ni ajọ Inec ni Makinde yege ibo ni ijọba ibilẹ mejidinlọgbọn ninu mẹtalelọgbọn to wa nipinlẹ naa, ti Adelabu si moke ni ijọba ibilẹ mọkanla pere.
Ni bayii na, se ni awọn ololufẹ gomina Seyi Makinde ati ẹgbẹ oselu PDP n fo fẹrẹ fayọ nile ẹjọ ati laarin igboro ni kete ti wọn gbọ ibi ti igi ẹjọ naa wo si.
Fake Ceritificate: Ìjọba Ọṣún ní yóò ṣoro láti gba òṣìṣẹ́ tó ní ẹbu ìwé ẹ̀rí síṣẹ́ mọ́
Oríṣun àwòrán, NLC
Kọmiṣọna ana feto iroyin, to tun jẹ alakoso fun eto iroyin bayii nipinlẹ Ọṣun, Adelani Baderinwa, ti sọ pe, yoo ṣoro lati gba awọn to ni ayederu iwe ẹri sẹnu iṣẹ nipinlẹ ọhun lasiko yii.
Baderinwa lo sọrọ yii ninu ifọrọwerọ pẹlu BBC Yoruba, lori awọn eeyan bii okoolenirinwo ati meji ti ijọba ipinlẹ naa fẹ daduro, lẹyin ti wọn fi ayederu iwe ẹri wọ iṣẹ ijọba.
O ṣalaye pe, ipinlẹ naa ko gba ẹnikẹni sẹnu iṣẹ lọwọ yii, ati pe awọn ilana ti wa ti ijọba ipinlẹ naa yoo tẹle, ti ko fi ni gba awọn to ba ni ayederu iwe ẹri sẹnu iṣẹ mọ.
Kọmiṣọna ana ọhun ṣalaye fun BBC pe, awọn osisẹ ti aje ọrọ naa ṣi mọ lori ni ijọba ti ni ki wọn lọ rọku nile, sugbọn ijọba ko pe wọn lẹjọ lẹyin ti ẹgbẹ awọn oṣiṣẹ, NLC, ẹka ti ipinlẹ Ọṣun da si ọrọ naa.
Oríṣun àwòrán, NLC
Baderinwa ni, ibaṣepọ to ye kooro wa laarin ijọba ati ẹgbẹ awọn oṣiṣẹ ipinlẹ Ọsun.
Adari ẹgbẹ oṣiṣẹ NLC ni ipinlẹ Ọṣun, Babatunde Adekomi ni, ijọba Arẹgbẹṣọla lo kọkọ pinlẹ iwadi naa, ti ọrọ si kan awọn osisẹ to le ni ẹgbẹrun marun un, sugbọn ti ajọ NLC da si ọrọ naa, ki o to di pe aje ọrọ ṣi mọ okoolenirinwo ati meji lori.
Nipa awọn ti aje ọrọ naa ṣi mọ lori yii, Adekomi sọ pe akitiyan NLC ni ko jẹ ki ijọba pe awọn eeyan ọhun lẹjọ.
O salaye siwaju pe, NLC n ṣakitiyan lati ri pe ko si ayederu oṣiṣẹ nipinlẹ ọhun, nipa ibaṣepọ pẹlu awọn ileewe giga lati ri pe wọn ni akọsilẹ to peye nipa awọn akẹkọ ti wọn n kọ.
Adekomi wa parọwa si awọn oṣiṣe ipinlẹ Ọsun lati mura siṣẹ, lẹyin naa lo rọ awọn okoolenirinwo ati meji ti ọrọ naa kan, lati wa owo miran ti wọn lee ṣe, lọna lati ri ounjẹ oojọ.
Xenophobia: South Africa bẹ Naijiria lórí ìsekúpani nítorí ẹ̀yà!
Oríṣun àwòrán, AFP
South Africa kò le kó iyán Naijiria kéré nípa ìrànlọwó àwọn akọ́ṣẹ́mọṣẹ́ tí wọn n rí lò láti Naijiria.
Aarẹ orilẹede South Africa, Cyril Ramophosa ti tọrọ afọriji lọwọ awọn ọmọ orilẹede Naijiria lori isekupani awọn ọmọ Naijiria to wa ni South Africa.
Awọn Asoju orilẹede Ilẹ South Africa lo tọrọ aforijin naa ni ilu Abuja.
Aarẹ Ramophosa naa ni ọrọ itiju gba a ni isẹlẹ naa, ti o si ran awọn asoju naa lọ si orilẹede meje ti wọn faragba ninu isẹlẹ naa.
Xenophobia: Naijiria á kọ́kọ́ pèsè ọ̀nà láti bá ẹbí sọ̀rọ̀ fún wọn
Ọpọlọpọ awọn eniyan lo ti bu ẹnu atẹ lu igbese awọn ọmọ ilẹ South Africa to n pa awọn alawọ dudu pẹlu ẹsun pe, wọn ko jẹ ki awọn ri isẹ se.
Olutoye: Ọmọ ọdọ̀ àgbà ni mí, kò sì y kí èdè Yorùbá parun
Eniyan mejila lo ku ninu isẹlẹ naa, ti mẹwaa si jẹ ọmọ orilẹede South Africa.
Oyo Tribunal: Mákindé ní àṣeyọrí òun nílé ẹjọ́ jẹ́ otítọ́ tó lékè irọ́
Oríṣun àwòrán, Seyi Makinde
Gomina ipinlẹ Ọyọ, Seyi Makinde ti juwe aṣeyọri ẹgbẹ PDP nile igbẹjọ to n risi ọrọ idibo gẹgẹ aṣeyọri otitọ to leke irọ.
Gomina naa lo dupẹ lọwọ awọn ọmọ ipinlẹ Ọyọ fun aduroti wọn, nigba idibo ati lẹyin idibo naa, to si parọwa si ẹgbẹ alatako, APC lati fọwọsowọpọ pẹlu oun lọna lati jumọ gbe ipinlẹ Ọyọ de ebute ogo.
"Makinde lo sọ ọrọ yii ninu atẹjade kan ti alukoro rẹ, ọgbẹni Taiwo Adisa buwọlu, o ni ""imọran mi fun ẹgbẹ APC ni pe, ki wọn gbe oṣelu ti sẹgbẹ kan, a le pada bẹrẹ eto oṣelu lọdun 2022. Nibayi na, ẹ jẹ ka sowọpọ fun itẹsiwaju ipinlẹ Ọyọ."""
"Gomina Makinde tun tẹ siwaju pe ""A fẹ dupẹ lọwọ gbogbo ọmọ ipinlẹ Ọyọ fun aduroti wọn ki a to dibo, nigba idibo ati lẹyin idibo. Mo mọriri atilẹyin awọn eeyan ipinlẹ Ọyọ fun igbagbọ wọn ninu wa, a maa tẹsiwaju lati sin yin tọkantọkan."""
Oríṣun àwòrán, Seyi Makinde
Bẹẹni ni gomina ọhun tun fi ẹmi imore han loju opo Twitter rẹ pe otitọ ni yoo ma leke lọjọkọjọ.
Bakan naa ni ẹgbẹ PDP ti ki gomina ọhun ku oriire, fun bi igbimọ olugbẹjọ to n gbọ awuyewuye ibo gomina nipinlẹ Ọyọ ṣe fi ountẹ lu pe oun ni ẹni to jawe olu bori ninu idibo ipinlẹ naa.
Ẹgbẹ naa yin Makinde fun akitiyan rẹ lati tun ipinlẹ Ọyọ ṣe, ti wọn si tun rọ lati ma bojuwẹyin ninu afojusun rẹ lati mu aye dẹrun fun awọn olugbe ipinlẹ Oyọ.
Lizzy Anjorin vs Toyin Abraham: Jide Kosọkọ ní ìbàjẹ́ ni Lizzy àti Toyin fi n ṣe ayọ̀
Oríṣun àwòrán, mr latin 1510
Aarẹ apapọ fun awọn osere tiata lede Yoruba Tampan, Bọlaji Amusan taa mọ si Mr Latin, ti kesi awọn araalu pe ki wọn yee sẹ epe fun awọn agba osere ninu isẹ tiata.
Bakan naa lo ni ko yẹ ki wọn maa pe wọn ni agbaaya pe wọn ko ri nkan se si aawọ laarin awọn ọmọ ẹgbẹ wọn, lasiko ti awọn ọmọ ẹgbẹ kan ba n tahun si ara wọn lori itakun agbaye.
Latin, ninu fọnran aworan kan to fisita loju opo Instagram rẹ lori aawọ to n waye lori ayelujara laarin awọn osere tiata obinrin meji, Toyin Abraham ati Lizzy Anjọrin, o salaye pe, o yẹ ki awọn araalu kọkọ beere lati mọ boya ọmọ ẹgbẹ Tampan ni awọn osere to n ja naa.
Latin ni ẹgbẹ osere tiata pin si orisirisi, ti ọpọ osere kii si se ara ọmọ ẹgbẹ awọn, nitori naa lo se loju ohun ti awọn agba osere lee da si, bi o tilẹ jẹ pe awọn lee da si bii agba osere.
Amọ o ni ti awọn osere naa ba ni awọn kii se ọmọ ẹgbẹ awọn, ti wọn ko si gba imọran si awọn lẹnu, o loju ohun ti awọn lee se.
"Latin ni"" A n gbiyanju agbara wa, gẹgẹ bii baba, gẹgẹ bii aarẹ ati gẹgẹ bii agba osere lati dẹkun rogbodiyan laarin awọn osere tiata lori itakun agbaye, ko si yẹ ki awọn araalu ro pe awọn kan dakẹ, lai se ohunkohun nipa aawọ naa."""
Latin ni ọmọ ẹgbẹ Tampan nikan lawọn lee pasẹ fun lati sinmi agbaja, osere ti kii ba si se ọmọ ẹgbẹ awọn, o loju asẹ ti awọn lee pa fun, awọn kan lee parọwa fun ni.
Aarẹ apapọ fun ẹgbẹ Tanpan naa wa fọwọ gbaya pe awọn n gbe igbesẹ to lagbara bayii lati pinwọn wahala to n waye naa, ti yoo si jẹ rodo, lọ ree mu omi laipẹ.
Oríṣun àwòrán, jidekosoko
Bakan naa, agba ọjẹ ninu ẹgbẹ osere Nollywood, Jide Kosoko ti ni ẹgbẹ awọn maa wa ọna abayọ si aawọ to wa laarin Toyin Abraham ati Lizzy Anjorin.
Kosoko sọ fun BBC Yoruba bẹ ẹ lasiko to n fesi si bi Toyin Abraham se dunkooko pe oun yoo gbe Anjorin lọ si ile ẹjọ, lẹyin t o sọ wi pe Anjorin fi orukọ oun yi ẹrẹ, ti wọn si tahun si ara wọn.
O fi kun wi pe ori ẹrọ ayelujara ni oun ti ri iroyin naa, amọ ẹgbẹ awọn yoo pe awọn mejeeji lati pẹtu si aawọ to wa laarin wọn.
Oríṣun àwòrán, mamarainbowofficial
Ninu ọrọ rẹ, Mama Rainbow naa ni oun ko mọ nkankan nipa isẹlẹ naa, ti ko si si ẹnikẹni to fi ọrọ naa lọ oun.
Mama Rainbow fikun pe, oun ko kopa ninu fiimu kankan mọ, nitori wọn kọ lati lo oun, ati wi pe Ọlọrun lo n lo oun bayii.
Saudi Arabia oil attack: Buhari ní ojú Nàìjíríà ti rí ohun tí Saudi Arabia ń rí báyìí
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Aarẹ Muhammadu Buhari ti sọ pe, igba ipọnju la n mọ ọrẹ, ti orilẹede Naijiria si wa pẹlu ijọba atawọn eeyan Saudi Arabia, lori ikọlu awọn ibudo ifọpo rẹ to wa ni Khurais ati Abqaiq.
Aarẹ Buhari ṣalaye ọrọ yii ninu atẹjade kan, eyii ti amugbalẹgbẹ rẹ feto iroyin Garba Shehu fi sita.
Buhari ni lootọ lawọn oniṣẹ ibi to wa nidi ikọlu naa ko fi oju han sita, sibẹ ohun kan to foju han ni pe, ikọlu eto ọrọ aje naa ni awọn oṣiṣẹ laabi naa fi n dojukọ ijọba atawọn ọmọ Saudi Arabia.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
O tẹsiwaju pe, ko si aniani pe wọn fẹ fi doju jijẹ-mimu awọn olugbe orilẹede naa, ti ko mọwọ tabi mọ ẹsẹ ninu eredi ikọlu naa bolẹ ni.
Awa pẹlu lorilẹede Naijiria ti foju wina irufẹ ikọlu bayii lori ibudo epo rọbi wa. Gbogbo awọn to ro wi pe nipa ṣiṣe bẹẹ awọn lee doju iṣẹ ijọba bolẹ,, ko mu erongba wọn ṣẹ nigba naa, tabi nigbakugba.
Aarẹ Buhari ni ko si ẹnikẹni lawujọ agbaye ti yoo to si ẹyin awọn to ṣe ikọlu naa, ẹni yoowu ti wọn lee jẹ tabi idaniloju wọn ninu ohun gbogbo ti wọn n gbe ṣe.
Osun Accident: Agbegbe Gádà ní ìlú Ẹdẹ ní ìṣẹ̀lẹ̀ náà ti wáyé
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Eeyan mẹta lo jade laye lalẹ ọjọ aiku ni ilu Ẹdẹ nipinlẹ Ọṣun nigba ti ọkọ bọọsi ti wọn wa ninu rẹ, jabọ sinu odo Ọṣun ni agbegbe Oke-gada ni ilu Ẹdẹ.
Awọn ti iṣẹlẹ naa ṣoju wọn ni aisi ikọ adoola ẹmi lasiko, lo ṣokunfa iku awọn eeyan naa.
Bakan naa, ni awọn eeyan ti isẹlẹ naa soju wọn salaye pe ohun jijẹ lo kun inu ọkọ naa lasiko ti o fi re bọ sinu odo naa.
Nnkan bi agogo meje alẹ ni wọn ni iṣẹlẹ naa waye lasiko ti awakọ bọọsi naa n gbiyanju lati yẹra fun awọn koto to wa kaakiri oju popo naa.
Amọṣa, wọn ni ko si iranwọ lati doola ẹmi wọn titi di nnkan bii agogo mọkanla alẹ, afi igba ti awọn eeyan kan fi dide lati doola wọn.
Sugbọn dokita ileewosan ti wọn gbe wọn lọ ni oku ni wọn gbe wọn wọ ileewosan naa.
Fayemi: Ìdápadà iléèwé Christ School fún ìjọ Anglican tó dá a sílẹ̀ wà ní ìbámu pẹ̀lú ìlérí ìpolongo ìbò
Oríṣun àwòrán, Ekiti state government
Ijọba ipinlẹ Ekiti da ileewe Christ School, Ado Ekiti pada fun ijọ Anglican to da ileewe naa silẹ.
Gomina ipinlẹ Ekiti, Kayọde Fayẹmi ni imuṣẹ ara awọn ileri ti oun ṣe lasiko ipolongo ibo ni ọdun to kọja lati da awọn ileewe pada fun awọn to ni wọn.
Gomina Kayọde Fayẹmi ti oun pẹlu jẹ akẹkọjade ileewe Christ school Ado Ekiti ni erongba igbesẹ naa ni lati lo idapada naa gẹgẹ bii ọpakutẹlẹ fun dida awọn ileewe yooku pada fun awọn to ni wọn.
Biṣọọbu ijọ Anglican ni ipinlẹ Ekiti Ẹniọwọ Christopher Ọmọtunde lo tẹwọ gba iwe idapada ileewe naa lọwọ gomina Fayẹmi.
Amọṣa bi inu awọn akẹkọjade kan ṣe n dun si iṣẹlẹ ọhun ni awọn miran n kọrun ẹsọ pẹlẹ nitori ilẹ n yọ.
Oloye Faṣohun to jẹ akẹkọjade ileewe Christ school Ado ekiti ti o tun ti figbakan ri jẹ alaga igbimọ alakoso ileewe naa ṣalaye pe ifasẹyin nla gbaa ni igbesẹ naa yoo mu ba ọla ileewe girama naa to ti roke fun ọpọlọpọ ọdun sẹyin.
Oríṣun àwòrán, Ekiti state government
Alagba Faṣohun ni ko si ipenija kan to kọja agbara ileewe naa tabi ijsba to n gbọ bukata rẹ ni lọwọlọwọ  to lee ṣokunfa ki wọn faa le ijọ Anglican pada.
O ni ara awọn ipalara ti igbesẹ naa yoo ṣe fun ileewe naa ni idaduro idagbasoke fun awọn olukọ eleyi to ni yoo le ọpọ oluks to dantọ kuro nibẹ ti yoo si faye gba awọn gbantuẹyọ.
Bakan naa lo ni eyi yoo tumọ si alekun owo ileewe ti awọn akẹkọọ yoo maa san nibẹ. Oloye Faṣohun ni eleyii yoo mu ki adinku ba iye awọn akẹkọọ ti o n wa si ileewe naa.
Amọṣa ninu ọrs tirẹ, Biṣọọbu ijọ Anglican ni ẹkun Ekiti oke, Ẹniọwọ Olubọwale ṣalaye pe ijiroro yoo waye laarin awọn Biṣọọbu ẹkun mẹta to wa ni ipinlẹ Ekiti, lori ọna ti wọn yoo gba lati mu ọjọ ọla rere bọ fun ileewe girama naa
Champions league: Chelsea gbélé fọrùn rọ́ ní Stamford Bridge, àwìn ni Valencia fi ṣẹ Lampard lọ́wọ́
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ẹgbẹ agbabọọlu Chelsea joye gbele forunrọ lalẹ ọjọ iṣẹgun nigba ti wọn gbalejo ẹgbẹ agbabọọlu Valencia ni idije Champions league.
Chelsea yoo maa pada si agbami bọọlu Champions league lẹyin ti wọn fi saa ọdun to kọja gba bọọlu ni agbami Europa. Amọṣa ipadabọ naa ko so eso rere ninu ifẹsẹwọnsẹ akọkọ ti wọn gba.
Bi o tilẹ jẹ wi pe ọdẹdẹ Chelsea ni Stamford Bridge ni ifẹsẹwọnsẹ naa ti waye, ko gbe Tammy Abraham atawọn ọmọ ikọ Frank Lampard yooku.
Rodrigo, ọmọ Valencia lo da okuta si gaari Lampard ninu ifẹsẹwọnsẹ rẹ akọkọ ni idije Champions league gẹgẹ bii olukọni Chelsea.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Iṣẹju kẹrinlelaadọrin ni ifẹsẹwọnsẹ naa wa nigba ti Rodrigo fi gba bọọlu sinu awọn Chelsea.
Eyi ti ko ba tun duro gẹgẹ bii itunu fun Chelsea ni igba ti alamojuto ere naa fun fere fun pẹnariti, iyẹn gbe e silẹ ko gba a si sawọn ṣugbọn igbo rere ni Barkley agbabọọlu Chelsea to gba a gba a si.
Champions League: Balógun ní England, akéwejẹ̀ ní Italy, Liverpool yọ̀ ṣubú níwájú Napoli pẹ̀lú àmì ayò méjì sí òdo
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Lọwọ yii, lara awọn ikọ agbabọọlu ti o n gbana jẹ ni Liverpool wa. Yatọ si pe oun ni ẹgbẹ agbabọọlu ti ife ẹyẹ Champions League wa lọwọ rẹ ni lọwọlọwọ, ohun nikan ni ẹgbẹ agbabọọlu ti ko tii sọ ami kankan nu ni gbogbo idije liigi ti saa yii.
Nitori naa, ireti ọpọ ni pe ẹran ijẹ ni wọn yoo fi Napoli ṣe ninu ifẹsẹwọnsẹ Champions league to waye ni alẹ ọjọ Iṣẹgun laarin Napoli ati Liverpool, ṣugbọn ọr ko ri bẹẹ rara fun wọn.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Napoli to gbalejo ifẹsẹwọnsẹ naa jẹwọ pe awọn kii ṣe ọmọ ale nile awọn nigba ti wọn fi ami ayo meji gbo ewuro si oju Salah, Mane atawọn akẹgbẹ wọn.
Gbee silẹ koo gba sile, iyẹn pẹnariti ti Dries Merten kọkọ gba wọle ni Napoli fi ṣide iya fun Liverpool nigba ti ifẹsẹwọnsẹ naa wọ iṣẹju kejilelọgọrin ki Llorente to fọba lee ni igba ti ifẹsẹwọnsẹ naa ku dẹdẹ ko pari.
Fayoṣe: Gómìnà Fayemi kò nílò ẹjọ́, torí àti ṣe ohun ti ìjọba àná kò leè ṣe ní wọ́n fi dìbò fún un
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Gomina Fayẹmi ti ipinlẹ Ekiti ti fi ẹsun kan iṣejọba ana ni ipinlẹ naa labẹ Ayọdele Fayose pe biliọnu mẹtadinlọgọta lo jẹ awọn oṣiṣẹ gẹgẹ bii owo oṣu ati ajẹmọnu gbogbo.
Amọṣa, Fayoṣe pẹlu ti da esi pada pe, ariwo lasan ni Fayẹmi n pa ati pe iṣẹ ni awọn eeyan ipinlẹ Ekiti yan an lati wa ṣe kii ṣe ariwo.
Nibi ipade kan pẹlu awọn oṣiṣẹ ijọba nilu Ado Ekiti ni gomina Fayẹmi ti kede ọrọ naa. O ni iṣejọba oun n sa ipa gbogbo to yẹ lati san awọn ajẹẹlẹ owo oṣu ati ajẹmọnu naa.
O ni segesege lori ilana sisan owo oṣu naa lo ṣokunfa bi o ti ṣe wa di oke nla niwaju ijọba bayii.
Fayẹmi ni ajẹsilẹ owo oṣu naa wa laarin ọdun 2014 si oṣu kẹwa ọdun 2018.
"Nigba ti o n dahun loju opo twitter rẹ, Gomina ana, Ayọdele Fayoṣe ni iyalẹnu ni ọrọ ti Fayẹmi sọ jẹ fun oun ṣugbọn o ni oun ""rọ ọ lati san owo oṣu oṣiṣẹ nitori eredi ti araalu fi dibo yan an ni lati ṣe oun ti oun ko lee ṣe"""
Champions league: Real Madrid jẹ wábiwọ́sí ìyà lọ́wọ́ PSG, Di Maria ló hun pàṣán ìyà wọn
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ode ko dara fun olukọni ikọ agbabọọlu Real Madrid, Zinedine Zidane atawọn agbabọọlu rẹ ni alẹ Ọjọru nigba ti wọn lọ koju Paris St-Germain ni idije Champions League.
Ko si si ẹni meji to doju ọla Real Madrid bolẹ bikoṣe Angel di Maria, agbabọọlu rẹ nigbakan ri ṣugbọn to ti darapọ mọ PSG bayii.
Iṣẹju kẹrinla ati ikẹtalelọgbọn ifẹsẹwọnsẹ naa ni Di Maria gba bọọlu sawọn ki Meunier to fsba lee nigba ti idije naa wọ aadọrin iṣẹju.
Nnkan ko tii fi bẹẹ ṣe ẹnure fun Zidane lati igba ti o ti pada de lẹẹkeji gẹgẹ bii olukọni fun Real Madrid.
Saa marun ni Angel di Maria lo ni Madrid ki o to gbe igba bọọlu agbajẹun rẹ lọ si PSG lorilẹede France.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Lẹyin o rẹyin goolu mẹta ti ko labula ni wọn fi na Real Madrid.
Lẹyin ti gbajugbaja agbabọọlu ni , Christiano Ronaldo ti fi Real Madrid silẹ ni ọdun 2018 ni nnkan ti dẹnukọlẹ fun Real Madrid.
Champions league: Athletico bomi paná ayọ̀ Juventus ní ìpadàbọ̀ Ronaldo sí ìlú Madrid
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Idunnu kọkọ ṣubu layọ fun Christiano Ronaldo atawọn akẹgbẹ rẹ ni Juventus nigba ti wọn kọkọ gba goolu meji wọle sinu awọn Athletico Madrid nibi ifẹsẹwọnsẹ to waye laarin wọn lalẹ ọjọ iṣẹgun nibi idije Champions league.
Amọṣa ayọ naa ko pẹ pupọ pẹlu bi Athletico ṣe jẹwọ ọmọ ọkọ fun wọn pẹlu goolu meji ni ṣiṣẹ n tẹle.
Agbabọọlu ikọ Chelsea tẹlẹ, Juan Cuadrado lo kọkọ gba gooolu wọle fun Juventus ki Blaise Matuidi to fi ori gbe ikeji wọle fun goolu Juventus keji.
Amọṣa, Stefan Savic ati Hector Herrera lo ra igba pada fun Athletico Madrid.
Ọmi ti wọn ta naa mu ki Athletico Madrid ṣi ni igberaga lati sọrọ pe ko si ẹgbẹ agbabọọlu to tii fi ẹyin wọn balẹ ninu ifẹsẹwọnsẹ mẹwaa ti wọn ti gba sẹyin nile wọn ni papa iṣire Blaise Matuidi.
Lizzy Anjorin vs Toyin Abraham: Àwọn àgbààgbà ẹgbẹ́ òṣèré tíátà fa ìbínú yọ
Oríṣun àwòrán, MRLATIN
Awọn agbaagba ẹgbẹ oṣere tiata Yoruba ti jawe joko jẹẹ le Lizzy Anjọrin ati Toyin Abraham, awọn oṣere meji ti wọn n tahun si ara wọn lati bi ọjọ mẹta bayii lori ikanni ayelujara.
Wọn kilọ pe àwọn kò ní fi àyè sílẹ̀ fún òṣèrè tíátà kankan láti dójú ti ẹgbẹ́ mọ.
Ede aiyede laarin awọn oṣere mejeeji yii bẹrẹ nigba ti iroyin jade sita pe Toyin Abraham to ṣẹṣẹ bimọ laipẹ yii kọ lẹta ipẹjọ si Lizzy eleyi to mu ki Lizzy pẹlu gbana jẹ. Lẹyin eyi ni ọrọ naa wa di fa-ki-n-fa laarin awọn mejeeji.
"Lẹyin ọpọ awuyewuye, ipẹtu si alaafia laarin awọn mejeeji, ti o si jẹ pe kaka ki ewe agbọn ọrọ naa dẹ, lile lo tun n le sii, awọn alaṣẹ ẹgbẹ oṣere tiata Yoruba ti wa paroko ""Ẹ sinmẹdọ ranṣẹ si awọn mejeeji atawọn oṣere miran ti wọn ba ni iru rẹ lọwọ tabi lọkan."
Ninu fọnran fidio kan ti wọn fi sita, aarẹ ẹgbẹ oṣere tiata Yoruba Ọgbẹni Bọlaji Amuṣan ati ọkan lara awọn agba ọjẹ ninu ere tiata lorilẹede Naijiria, Alhaji Yinka Quadri ti ti paṣẹ ki gbogbo awọn mejeeji lọ ree gbẹnu dakẹ tabi ki wọn fi kele ẹgbẹ gbe wọn.
Nibayii awọn ololufẹ awọn oṣere tiata mejeeji ti n kan sara si igbesẹ naa eleyi ti wọn ni o tọna lati mu alaafia ati irẹpọ jọba laarin ẹgbẹ naa.
Xenophobia: Ọrò ajé llè South Africa ti ń rẹ̀yìn lọ́wọ́lọ́wọ́
Alaga ati Oludari ọkọ Ofurufu Air Peace Allen Onyeama, ti ṣalaye pe Ijọba ilẹ South Africa ni imọlara awọn ọmọ Nigeria ni orilẹede wọn.
O ni inu orilẹedẹ ko dun pe ki awọn ọmọ Naijiria kuro nibẹ rara.
Ninu alaye to ṣe pẹlu ikọ ile iṣẹ BBC l'ọjọ Abamẹta lo ti sọ pe, ijọba ilẹ naa ko fẹ  ki awọn ọmọ Naijiria lọ nitori pe o ṣe akoba fun ọrọ aje wọn.
Bakan naa lo ni ko din ni ẹedẹgbẹta awọn ọmọ ilẹ yii to ṣi ku si orilẹede naa to fẹ wale sugbọn ti gbogbo eto ati da wọn pada wale ṣi ku diẹ.
O ni igba akọkọ ree ti wọn maa yẹ oun si julọ ni igbesi aye oun ti inu oun si dun ju laye.
Onyeama wi pe lọwọlọwọ yii, eto ọrọ aje ilẹ South Africa ti n mẹhẹ latari ipa pataki ti awọn ọmọ Naijiria n ko ni ilẹ naa.
Bakan naa ni ko ṣai mẹnu ba Papakọ Ofurufu ilu Enugu pe, yoo fa ijamba nla ti ijọba apapọ ko ba tete bo ju to.
O ni papakọ Ofurufu naa lo ti wa ni ipo ẹlẹgẹ bayii ti ko si dara to fun fifo ọkọ ofurufu.
Gẹgẹ bi o ti wi, o ni ki ijọba apapọ tete mura si atunṣe papakọ naa ki iṣẹ si bẹrẹ ni pẹrẹwu.
Ni tirẹ, Ọgbẹni Allen Onyeama ni ọkọ baalu oun yoo ṣi pada lọ si orilẹede South Africa lati ko awọn ọmọ Naijiria to ba ṣi nifẹ lati pada wa sile.
Ìyàtọ̀ tó wà láàrin ìṣesí Nàìjíríà àti South Africa
Osinbajo: Igbákejì ààrẹ Yemi Osinbajo ni ìwà àjẹbánu lẹ́nu iṣẹ́ ọba ló le jù nínú ìṣòro Nàìjíríà
Oríṣun àwòrán, Getty Images
O ni iṣoro NAijiria ko lee din ku ninu ojuṣe rẹ rẹ gẹgẹ bii aṣiwaju ilẹ Afirika
Igbakeji aarẹ orilẹ-ede Naijiria, Ọjọgbọn Yẹmi Oṣinbajo ti ṣalaye pe yiyan awọn ọlọpọlọ pipe si ipo gbogbo lo tọna.
O ni ko yẹ ki a maa wo ti ẹya, ede tabi ohunkohun miran lo le mu ki orilẹ-ede Naijiria o ga de ibi ti o yẹ ko de.
Igbakeji aarẹ, Oṣinbajo woye ọrọ yii nibi idanilẹkọọ to gbe kalẹ fun ayẹyẹ ikẹkọgboye ẹlẹẹkẹjọ iru rẹ ti fasiti UNIOSUN nilu Oṣogbo.
O ni lilo ilana ọmọ onilu ati ọmọ onilẹ, (Quota system) fun yiyan awọn eeyan sipo iṣẹ ọba ati iṣejọba n ṣe ọpọ akoba fun idagbasoke Naijiria.
Ọjọgbọn Oṣinbajo sọrọ lori akori to pe ni 'Ọgọta ọdun Naijiria gẹgẹ bii orilẹ-ede, Naijiria ṣi ni ilẹkun fun idagbasoke Afirika'.
O ni iṣoro to gogo ju ninu gbogbo idojukọ Naijiria lọwọ yii naa ni iwa jẹgujẹra ni ẹka iṣẹ ọba.
O ni iwa jẹgudujẹra naa gan an ti wa n dojukọ awọn to n gbogun tii bayii, bi o tilẹ jẹ wi pe o fi idi rẹ mulẹ pe iṣejọba aarẹ Buhari ko ni sun, bẹẹ ni ko ni wo lori ilakaka rẹ lati dẹkun iwa ibajẹ ati ajẹbanu lorilẹ-ede Naijiria.
O ni ko si orilẹ-ede ti o le e de ibi giga lai jẹ pe o fi awọn to tọ si ipo to tọ dipo ọmọ wa ni ẹ jẹ ko ṣe.
Ṣé ẹ fẹ́ mọ ìgbà tí ẹ̀fọn meji bá ń kọ orin ifẹ́ léti yín?
Osinabjo ni o ṣeni laanu pe ọpọ awọn ọdọ lorilẹ-ede Naijiria ni ko mọ nipa asiko idẹra ti awọn aṣiwaju bii Awolọwọ, Nnamdi Azikiwe ati Ahmadu Bello gbe kalẹ fun orilẹ-ede Naijiria.
Ati pe ohun ti wọn ba ni akoko ipenija ati wahala to de ba orilẹ-ede yii ko kere rara.
Ninu iwoye rẹ, bi awọn ipenija wọnyii ṣe pọ si lo n ṣe afihan pe awọn akẹkọgboye tuntun lawọn ileewe giga gbọdọ ji giri.
Wọn gbọdọ ṣetan lati wa ojuutu si awọn iṣoro naa ki a lee kọ orukọ wọn sinu iwe iranti orilẹ-ede Naijiria.
Yollywood: Kò sí ẹni ti òbí mi kò lè sọ̀rọ̀ sí -Sisi Quadri
Premier league: Manchester United jẹ àjẹkún ìyà góòlù méjì lọ́wọ́ Westham United
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ọwọ iya ba Manchester United ni ile Westham United ni ọjọ Aiku nibi idije Premiership ilẹ Gẹẹsi.
Irinajo ti ko lọpẹ ninu ni olukọni iks Manchester United, Ole Gunner Solkjaer ko awọn agbabọọlu rẹ rin lọ si papa iṣire....to jẹ ibuba Westham united nibi ti wọn ti lu wọn ni goolu meji sodo.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Pẹlu Esi yii, o fihan pe ifẹsẹwọnsẹ meji  pere ni Manchester united ṣi bori bayii ni mẹfa ti wọn gba bayii ni saa yii.
Andriy Yarmolenko lo kọkọ gba goolu alakọkọ wọle fun Westham ki Aaron Cresswell to fọba lee nigba ti ifẹsẹwọnsẹ naa wọ iṣẹju kẹrinlelọgọrin.
Lọwọ yii idi olukọni wọn n gbona bayii pẹlu ironu igbesẹ ti awọn alaṣẹ ẹgbẹ agbabọọlu naa lee gbe bi nnkan ko ba ṣe ẹnuure funwọn laipẹ.
English Premier league: Liverpool gun Chelsea bí ẹṣin lójúde rẹ̀ ní Stamford bridge
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Awọn agba bọ wọn ni bi ale iya ẹni ba ju baba ẹni lọ, baba laa pe.
Bẹẹ lọrọ ri fun Chelsea nigba ti wọn gbalejo Liverpool ni ifẹsẹwọnsẹ kẹfa, saa idije liigi ti ọdun yii ni ilẹ Gẹẹsi.
Trent Alexander-Arnold lo kọkọ gba goolu wọle fun Liverpool nigba ti ifẹsẹwọnsẹ naa wọ iṣẹju kẹrinla ki Roberto Firmino to dee lade funwọn.
Amọṣa lẹyin ọpọlọpọ jija raburabu, Ngolo Kante da ẹyọ kan pada fun Chelsea.
Gbogbo  akitiyan atamatase Chelsea, Tammy Abraham lati yọ ikọ rẹ jade ninu ọfin Liverpool lo ja si pabo.
Pẹlu esi yii, ifẹsẹwọnsẹ meji pere ni Chelsea ṣi bori ninu mẹfa ti wọn ti gba ninu liigi saa yi labẹ akoso olukọni wọn tuntun, Frank Lampard.
Esi yii si n fi Liverpool silẹ loke tente tabili liigi ilẹ Gẹẹsi.
Lẹyin ifẹsẹwọnsẹ mẹfa ti awọn ẹgbẹ agbabọọlu ti gba, Liverpool nikan ni ko tii padanu ifẹsẹwọnsẹ kankan bayii.
English Premier League: Arsenal jẹ́ọ́ àgbò tó tàdí mẹ́yìn fún Aston villapẹ̀lú àmì ayò mẹ́ta sí méjì
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ori lo ko Arsenal yọ lọwọ Aston Vila ni idije Premiership to waye ni papa iṣire Emirates.
Ilẹ kọkọ ṣe bi ẹni fẹ pooyi fun Arsenal ninu ifẹsẹwọnsẹ naa nigba ti John mcGinn gba bọọẹu wọle nitori aikiyesara awọn adilemu Arsenal to n woran lẹyin.
Nicolas Pepe gba gbeelẹ koo gba sile, pẹnariti wọle lẹyin ti awọn agbabọọẹu Aston Villa gbe Gendouzi, agbabọọẹu Arsenal lulẹ ninu oju iwọn alapoti
Aston villa ko jẹ ko tutu ti wọn tun ti fi  gba omiran wọle.
Lẹyin eyi ni Calum Chambers ati Aubameyang wa gba ayo kọọkan wọle lati bọ ẹwu  itiju ti aston villa fẹ da ro Arsenal ni ibuba rẹ kuro.
Pẹlu esi yii, ipo kẹrin ni Arsenal wa lori tabili liigi ilẹ Gẹẹsi bayii pẹlu ami mọkanla.
Ọkan lara awọn agbabọọlu Arsenal, Ainsley Maitland -Niles gba kaadi pupa ti wọn si lee jade nitori ikọlu rẹ si agbabọọẹu Aston Villa kan.
Osun Kidnapping: Àwọn afunrasí darandaran jí èèyàn mẹ́rìnlá gbé nńú bọ́ọ̀sì Osogbo sí Abuja
Oríṣun àwòrán, @osun247
Ọlọpaa ni awọ̀n tiri ẹni mẹ̀rin gbà pada lọwọ awọn ajinigbe naa.
Awọn eeyan kan ti wọn funra si pe wọn jẹ darandaran ti ji eeyan mẹrinla gbe ni agbegbe Ọtan Ayegbaju ni ipinlẹ Ọṣun
Awọn ti iṣẹlẹ naa ṣoju wọn ṣalaye pe lati ilu Oṣogbo ni akero to ko awọn eeyan naa ti gbera.
O si dori kọ ilu Abuja ki awọn ajinigbe pawo naa to ṣe ọṣẹ wọn ni ikorita Ajeoku ni opopona Otan-ile si Okemesi.
Awọn oniṣẹ ibi naa ni a gbọ wi pe wọn ba awọn ero wọ ọkọ gẹgẹ ero to n lọ si ilu Abuja lati ilu Oṣogbo ki wọn to ṣe ọṣẹ wọn.
Ileeṣẹ ọlọpaa ni ko tii si ẹni to lee sọ ni pato boya darandaran Fulani lawọn to ṣe iṣẹ buruku naa abi ẹya miran.
Alukoro ileeṣẹ ọlọpaa ni ipinlẹ Ọṣun, Fọlaṣade Odoro ṣalaye fun BBC News Youba pe wọn ti doola eeyan mẹrin ninu awọn ti wọn ji gbe naa.
Yollywood:Ṣàgbẹ̀lójú yòyò ni ọ̀ps àwọn òṣèré- Ojopagogo
SERAP: Ìbọ̀wọ̀ fófin ni bí wọ́n se fi Sowore sílẹ̀
Oríṣun àwòrán, TWITTER
Awọn ololufẹ rẹ lori ero ayelujara ni igbẹkẹle mẹkunu ni ile-ẹjọ, eleyii to fihan wi pe otitọ a bori dandan.
Idunnu subu layọ fun ọpọlọpọ awọn ololufẹ Ọmọyẹle Soworẹ, lẹyin ti ile ẹjọ paṣẹ fun Ajọ DSS lati fi i silẹ ni kiakia.
Awọn ololufẹ rẹ lori ero ayelujara ni igbẹkẹle mẹkunnu ni ile-ẹjọ, eleyii to fihan wi pe otitọ a bori dandan.
Ẹgbẹ ajafẹtọ ọmọniyan, SERAP ti gbori yin fun idajọ to ni ki ile-ẹjo fi Ọmọyele Sowore silẹ ni panpẹ ajọ DSS ni kiakia.
SERAP ni idunnu ati ayọ lo jẹ fun awọn bi Sowore to ti wa ni panpẹ Ajọ DSS fun ọjọ mejilelaadọta ṣe gba itusilẹ, ti yoo si pada si ọdọ ẹbi ati ara rẹ.
Ninu atẹjade to fi lede, Akọwe Ajọ SERAP, Kolawole Oluwadare ni ko lẹtọ lakọkọ ki ijọba fi si atimọle.
Omoyele Sowore ń jẹ́jọ́ igbìmọ̀dìtẹ̀ láti gba ìjọba lọ́wọ́ Ààrẹ Buhari:
Omoyele Sowore yoo fojuba ile ẹjọ giga loni nilu Abuja.
Oríṣun àwòrán, @Sowore
Oye ni eeyan n wo nigba mii
Sowore ti o ti wa ni ahamọ fun igba diẹ ni wọn fi ẹsun orisi meje kan to fi mọ pe o n gbimoditẹ lati gba ijọba, ṣiṣagbatẹru igbesunmọmi ati kiko owo ilu lọ si il okeere lọna aitọ.
Oríṣun àwòrán, @YeleSowore
Omoyele Sowore ń jẹ́jọ́ igbìmọ̀dìtẹ̀ láti gba ìjọba lọ́wọ́ Ààrẹ Buhari
Loṣu to kọja ni Sowore pe fun iwọde ati ifẹhonu han lati fi tako awọn ohun to pe ni aiṣedeede ijọba Naijiria.
Ile iṣẹ ọtẹlẹmuyẹ Naijiria to mu sọ pe o n dun ikoko mọ igbe aye alaafia ati ifọkanbalẹ awọn eeyan orile-ede Naijiria.
Sport Betting: Idí rèé tí àwọn ọ̀dọ́ kan fi n ta tẹ́tẹ́...
Ọjọ kọkanlelogun, oṣu Kẹsan ni gbedeke aṣẹ itimọle ti ileeṣẹ ọtẹlẹmuyẹ gba nile ẹjọ ko ni eyi ti wọn fi sọ Sowore si ahamọ fọjọ marundinlaadọta.
Yollywood: Kò sí ẹni ti òbí mi kò lè sọ̀rọ̀ sí -Sisi Quadri
Prince Harry, Meghan àti ọmọ wọ̀n, Archie n ṣe àbẹ̀wò ọlọ́jọ́ mẹ́wàá silẹ̀ Áfríkà
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Duke ati Duchess of Sussex ti balẹ si Africa
Ọlọla ọmọọba ilẹ Gẹẹsi Prince Harry ti a tun mọ si Duke ti Sussex, iyawo rẹ Megan ati ọmọ wọn, Archie ti bẹrẹ abẹwo ọlọjọ mẹwaa silẹ Afrika.
Orile-ede South Africa ni wọn kọkọ balẹ biba si ti a si gbọ pe irinajo ọlọjọ mẹwaa naa bẹrẹ ni ọjọ kẹtalelogun, oṣu Kẹsan titi di ọjọ keji, oṣu Kẹwaa.
Meghan ati Archie yoo lo ọjọ mẹwaa ni South Africa nigba ti iroyin sọ pe Prince Harry yoo tẹsiwaju ni tiẹ lọ si Angola, Malawi ati Botswana lọjọ Ẹti.
Lẹyin igba naa ni Prince Harry yoo pada wa si South Africa wa ba awọn mọlẹbi rẹ ti wọn yoo si jijọ pada si London.
Prince Harry n lọ si Angola lati kan sara si iṣẹ ti iya rẹ to di oloogbe Princess Diana of Wales ṣe nibẹ.
Nigba aye rẹ, o jẹ aṣaaju nibi ipolongo to waye lọdun 1997 lati fi ofin de lilo ado oloro ti wọn maa n ri mọ ilẹ (land mines).
A tun gbọ pe yoo kẹdun lori iku ọmọ ologun kan ti o padanu ẹmi rẹ ninu ọgba nla ti wọn ko awọn ẹranko si.
Lọgbọn ọjọ, oṣu Kẹsan an ni Prince Harry yoo mẹnuba ipenija ẹdinku to n ba iye ẹranko to wa ninu igbo.
Loju opo Twitter Harry ati Iyawo rẹ, wọn fi ikede sibẹ pe Ọmọọba Harry yoo tẹsiwaju pẹlu iṣẹ rere ti iya rẹ ṣe ni Angola.
Ni tirẹ, Duchess Megan yoo ṣabẹwo sawọn agbegbe kan eleyi ti yoo ṣafihan mimu idagbasoke ba awọn eeyan lẹsẹpupu.
Sport Betting: Idí rèé tí àwọn ọ̀dọ́ kan fi n ta tẹ́tẹ́...
Yoo ṣiṣẹ pẹlu awọn ẹgbẹ aladani lati mu agbega ba ọrọ eto ẹkọ awọn obinrin to fi mọ igbe aye alaafia ati ilera to peye fun wọn.
Bakan naa ni Megan yoo ṣe ipade pẹlu awọn olokoowo kan nilẹ South Africa ki wọn to pari abẹwo wọn.
Minimum Wage: A i sí ìlànà owó sisan ló n dá àfikún owó oṣù òṣìṣẹ́, dúró- NLC
Oríṣun àwòrán, others
ẹgbẹ oṣiṣe yari fun ijọba Naijiria
Lẹyin bi wakati meloo kan ti ijọba apapọ kede p'awọn ti san ẹkunwo ọgbọn Naira owo oṣu oṣiṣẹ Naijiria, awọn ẹgbẹ oṣiṣẹ nipinlẹ kan lawọn ko ti i ri apẹrẹ rẹ lọdọ awọn.
BBC fi ọrọ wa ninu awọn tọrọ kan lẹnu wo bii Comrade Ambali Akeem to jẹ alaga ana ẹgbẹ oṣiṣẹ nipinlẹ Ogun.
Comrade Ambali ni owo yii ko le di sisan lawọn ipinlẹ nitori pe ẹnu awọn ẹgbẹ oṣiṣẹ ati ijọba apapọ ko tii ko lori ilana sisan owo naa.
O ni ọgbọn arekereke ni ijọba apapọ n lo ati pe niṣe ni ''wọn n gbe ẹsin siwaju kẹkẹ lori ọrọ naa''.
Comrade Ambali ni: 'Ijọba apapọ lawọn ti san owo yi fawọn oṣiṣẹ to wa ni ipele ikini titi de ipele kẹfa, bawo leyi ṣe le ṣeeṣe nigba ti ko si oṣiṣẹ kankan to wa ni ipele ikini?''
Ambali ni bi ẹgbẹ oṣiṣẹ ko ba ri ilana owo sisan yi bo ti ṣe kaari awọn oṣiṣẹ, ko le rọrun ki ijọba ipinlẹ tabi ti ibilẹ kankan san owo afinkun owo oṣu yi.
Aṣoju awọn oṣiṣẹ yii ni ọna abayọ si ọrọ yii ni ki ijọba ṣe ohun to yẹ lasiko.
O mẹnuba owo ori awọn ounjẹ ati ohun eelo to ti gbowo lori gọbọi lasiko yii pe owo oṣu awọn oṣiṣẹ ko too naa rara.
Sport Betting: Idí rèé tí àwọn ọ̀dọ́ kan fi n ta tẹ́tẹ́...
Free Sowore: Ilé ẹjọ́ ti gba béèlì Omoyele Sowore
Oríṣun àwòrán, Omoyele Sowore
Adajọ ti tu Soworẹ silẹ
Ajọ eleto aabo, DSS ti sọ wi pe awọn n duro de iwe irinna ilẹ okeere Omoyele Sowore, ki wọn to le fi silẹ.
Agbẹjọro Sowore, Femi Falana lo sọ wi pe wọn ti n fi baalu gbe iwe irinna ile okeere naa bọ lati ilu Eko si Abuja.
Falana wa fikun wi pe wẹrẹ ti wọn ba ti gba iwe irinna okeere to jẹ bi oniduro fun un de ni Ajọ DSS yoo tusilẹ kuro ni ahamọ wọn ti o wa.
Iroyin to tẹwa lọwọ sọ pe ile ẹjọ giga l'Abuja ti gba oniduro Omoyele Sowore ti Adajọ si ti ni ki o fi iwe irina rẹ  kalẹ.
Idajọ yi waye nibi igbẹjọ to ni i ṣe pẹlu ọrọ naa lọjọ Iṣẹgun Òní lòní ń jẹ́ fún Omoyele Sowore láti fojú bá Ilé ẹjọ́ gíga
Ajọ otẹlẹmuyẹ Naijiria ti saaju beere iyọnda ile ẹjọ lati fi Sowore si ahamọ aadọrun ọjọ ṣugbọn ile ẹjọ ni ki wọn tu Sowore silẹ fagbejọro rẹ Àkójọpọ̀ àwòrán láti ibi igbẹ́jọ́ Omoyele Sowore l'Abuja.
Oríṣun àwòrán, Sahara reporters
Idajọ yi waye nibi igbẹjọ to ni i ṣe pẹlu ọrọ naa lọjọ Iṣẹgun
Femi Falana to jẹ agbẹjọro rẹ ni awọn yoo bẹrẹ iṣẹ ni pẹrẹwu lati seto itusilẹ Sowore.
Losu kẹjọ, ọdun 2019 ni ileeṣẹ ọtẹlẹmuyẹ fi Sowore si ahamọ fun pe o fẹ fi iditẹgbaijọba Naijiria.
Wọn ni ki Sowore fi paali iwe irinna rẹ silẹ.
Falana fi idi ẹ mulẹ pe o di dandan ki wọn fi Sowore sile ni kete ti ajọ ọtẹlẹmuyẹ DSS ti yọ igbẹjọ wọn kuro.
Ile ẹjọ tu Sowore silẹ pe ki o lọ sile
Adajọ Taiwo Taiwo to gbọ igbẹjọ naa lẹyin isinmi ranpẹ ṣaaju idajọ rẹ ni ki wọn fi Sowole Omoyele sile, ṣugbọn ko ma rinrin ajo kankan titi igbẹjọ naa yoo fi pari.
Agbẹjọrọ Femi Falana ṣalaye pe gbogbo wọn ti n gbe igbesẹ to yẹ bayii ki Omoyele sowore le pada lọ sile lọ ba ẹbi ati ara rẹ lonii laidi ọla.
Yollywood:Ṣàgbẹ̀lójú yòyò ni ọ̀ps àwọn òṣèré- Ojopagogo
Sport Betting: Idí rèé tí àwọn ọ̀dọ́ kan fi n ta tẹ́tẹ́...
Boris Johnson: Gbígbé ilé aṣòfin tì pa kùnà, ilé ẹjọ́ pàṣẹ
Ìgbẹ́jọ́ lórí gbígbé ilé aṣòfin tì pa
Ile ẹjọ to ga ju ni ilẹ Gẹẹsi ti dajọ pe aba ti alaṣẹ ilẹ Gẹẹsi, Boris Johnson pa lati gbe ile aṣofin ti, kuna.
Ile ẹjọ naa ni ofin ko faaye gba ohun ti Boris ṣe yii rara ti ko si boju mu.
Ogbẹni Johnson paṣẹ̀ lati ti ile aṣofin pa fun ọsẹ marun un ni ibẹrẹ oṣu kẹsan an, ọdun yi, pẹlu alaye pe Obabinrin fẹ sọrọ lori eto ilana tutun ti alaṣẹ naa.
Sugbọn ni bayi, ile ẹjọ to ga julọ ni ilẹ Geesi ti wi pe igbese naa kuna, to si jẹ ohun ti ko tọ lati di ile aṣofin lọwọ nipa ṣi ṣe iṣẹ oojọ wọn.
Aarẹ ile ẹjọ naa, Lady Hale, lo wi pe ''ipa gbese naa lori eto iṣejọba awaarawa ko kere.''
Alase ilẹ Geesi
Pataki idajọ yii fun UK ko ṣee fi ẹnu sọ tan lasiko yii nitori eyi tun fidiẹ mulẹ pe ko si ẹni to kọja ofin nilẹ Gẹẹsi.
Eyi fihan pe ibi ko gbọdọ ju ibi lọ koda, ninu iṣelu orilẹ-ede.
Adajọ mọkanla ti wọn gbọ ẹjọ naa fẹnuko pe ko yẹ ki Boris Johnson ti ile aṣofin pa ko si so ijoko ile rọ titi di oṣu kọkanla to kede.
Sọ́jà méje wọ gàù lórí ẹ̀sùn olè jíjà ní ìpínlẹ̀ Eko
Oríṣun àwòrán, Google
Ilé isẹ́ ọlọ́pàá ní ìpínlẹ̀ Eko ló ní wọ́n ti fí ọwọ́ òsì júwe ilé fún àwọn sójà mẹ́fà náà.
Ile iṣẹ ọlọpaa ni ipinlẹ Eko ti fi panpẹ ọba mu awọn afurasi ole to to mejidinlaadọrun, eleyii ti sọja meje wa ninu wọn.
Adari ile isẹ to n gbogun ti iwa ọdaran ni ipinlẹ Eko, Kọmisọnna Zubairu Muazu sọ wi pe ile isẹ naa ri awọn ọdaran yii mu laarun osu diẹ sẹyin.
Muazu ni awọn soja meje naa ti orukọ wọn ati ọjọ ori wọn jẹ;Ndidi Oluchukwu, 30;  Owolabi Adeyemo ,42; David Olufemi, 47; Iseyin Samuel Isreal, 41; Emeka Ibeh, 29, Samuel Anochime, 36, ati Ebedot Stephen, 27 ni wọn mu fun ole jija ati fifipa gba ọkọ ayokẹlẹ lọwọ awọn eniyan.
Oniru: Oba Oniru wàjà ní Eko tẹbí, tará ń ṣe ìdárò Alayeluwa
Ninu wọn ni awọn ẹlẹgbẹ okunkun nipinlẹ Eko, ti wọn si dupẹ lọwọ awọn ara agbeegbe naa to ta wọn lolobo nipa awọn asemase to n waye ni agbeegbe naa.
Ọga ọlọpaa naa wa parọwa si awọn ara ilu lati tunbọ ma a ran wọn lọwọ si, nitori awọn ile isẹ eto aabo lorilẹede Naijiria n sisẹ takuntakun lati ri wi pe aabo to daju ati eyi to peye wa ni ipinlẹ Eko lasiko ọdun Keresi ati ọdun tuntun to n kanlẹkun.
Osun Kidnapping: Àjọṣepọ̀ ọlọ́pàá, DSS, OPC gba ìtúsílẹ̀ àwọn mẹ́wàá tí wọ́n jígbé ní Ọ̀ṣun
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Awọn ero mẹwa to ku ninu ero bọọsi ti awọn ajinigbe kan ji gbe nipinlẹ Ọṣun ti di riri nipasẹ ajọṣepọ laarin awọn ọlọpaa, ọmọ ẹgbẹ OPC atawọn oṣiṣẹ agbofinro DSS.
Agbegbe ileto Ajeoku ni wọn ti ji awọn eeyan naa gbe lasiko ti ọkọ wọn fi n lọ si ilu Abuja.
Meji ninu awọn eeyan ọhun lawọn to ji wọn gbe yin ni ibọn.
Awọn marun kan ninu eyi ti mẹta jẹ smọ iya kan naa ni awọn agbofinro kọkọ ri gba pada ki wọn to tun ri marun un miran gba lẹyin ọpọlọpọ wakati ti awsn agbofinro naa si fija pẹẹta pẹlu ibọn lati koju wọn.
Awọn kan ti ọrs naa ṣoju wọn ṣalaye pe awọn ajinigbe naa ti wọn funrasi pe wọn jẹ darandaran fulani kskọ tu awọn to n tọ ọmọ lọwọ, awọn arugbo atawọn ọmọ wẹwẹ to wa ninu ọkọ naa silẹ.
Olori ẹbẹ OPC ni ipinlẹ Ọṣun, Deji Aladeṣawẹ ṣalaye fawọn akọroyin pe inu igbo Olua ni imẹsi ile lawọn ajinigbe naa ko awsn ti wọn ji gbe lọ ki wọn to sa asala fun ẹmi wọn nigba tawọn agbofinro koju wọn pẹlu ibọn.
Action Against Hunger: Ẹgbẹ́ agbésùmọ̀mí ISWAP ṣekú pa àláànú kan
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Action Against Hunger: Ẹgbẹ́ agbésùmọ̀mí ISWAP ṣekú pa àláànú kan
Ẹgbẹ agbesunmọmi Islamic State in West Africa, ISWAP ti pa ọkan lara awọn oṣiṣẹ ẹlẹyinju aanu mẹfa ajọ Action Against Hunger ti wọn mu loṣu Keje ọdun yi.
Ninu atẹjade ti ajọ naa fi sita, wọn fidi iṣẹlẹ naa mulẹ ti wọn si ni awọn ko mọ eleyi ti o jẹ ninu awọn to wa ni ahamọ.
Loṣu Keje ni ikọ agbesunmọmi yi mu oṣiṣẹ ajọ ẹlẹyinju aanu naa kan,awakọ meji ati oṣiṣẹ ile iṣẹ ilera meji ni Borno.
Saaju ni ọjọru ni akọroyin Ahmed Salkida ti kọkọ tu kẹkẹ ọrọ yi sita loju opo Twitter
Salkida ṣalaye ninu ọrọ rẹ pe ISWAP lawọn pa oṣiṣẹ naa to jẹ ọkunrin nitori pe ijọba n mu awọn ṣere ni lẹyin ọpọ oṣu ti awọn ti jọ n ṣe idunadura.
Awọn alaṣẹ Naijiria to fi mọ awọn ologun ko ti i ṣọrọ lori iṣẹlẹ yi.
Salkidatun sọ pe awọn agbesunmọmi naa ninu fọnran fidio ti oun ri ṣeleri lati pa awọn oṣiṣẹ to ku.
Iṣẹlẹ yi waye lẹyin igba diẹ ti ileeṣẹ ologun Naijiria ti ileeṣẹ Action Against Hunger pa ni Maiduguri.
Wọn fẹsun kan wọn pe wọn lẹdi apo pọ pẹlu ikọ Boko Haram.
Ẹwẹ, ajọ ẹlẹyinju aanu miran, Mercy Corps kede lọjọru pe awọn alaṣẹ Naijria ti sọ agadagodo si ileeṣẹ awọn to wa ni Maiduguri ti wọn si ni kawọn dawọ iṣẹ duro lagbegbe naa.
Trump impeachment: Àṣírí tùú, àkọsílẹ fihàn bí Trump ṣé béèrè iranwọ lọ́wọ́ ààrẹ Ukraine
Oríṣun àwòrán, Reuters
Wọn ti bẹrẹ igbesẹ lati yẹ aga nidi aarẹ Trump
Lorileede Amẹrika, ẹgbẹ oṣelu Democratic Party ti bẹrẹ iwaadi lati ṣe itọpipin aarẹ Trump, eleyi to le ja si ki wọn yọ nipo.
Igbesẹ naa ko ṣẹyin ẹsun ti wọn fi kan Trump pe, o lo ipo rẹ lati wa iranlọwọ orilẹede miran ki wọn ba le ṣakoba falatako rẹ.
Igbeṣẹ iwaadi irufẹ eleyi ti wọn n fẹ ṣe naa a ma mu ki wọn pe aarẹ ko wa wi tẹnu rẹ, ti o si ṣeeṣe ki wọn yọ nipo latari rẹ.
Ohun ti wọn n ṣe iwaadi le lori ni pe, Trump halẹ mọ orileede Ukrain pe ohun ko ni ṣe iranwọ nnkan ogun fun wọn ti wọn ko ba bẹrẹ iwaadi alatako rẹ kan to n ba du ipo.
Aarẹ Trump ni, ọwọ oun mọ, ati pe wọn fẹ fi iwadi naa dunkoko mọ oun ni; Sugbọn ọkan lara awọn eekan ẹgbẹ Democrat, Nancy Pelosi ni o di dandan ki aarẹ Trump wa wi tẹnu rẹ
Kini o mu ki iwaadi yi ṣe pataki?
Pataki iwaadi yi ni pe, o ni ṣe pẹlu aarẹ Amẹrika ati alatako rẹ to n lewaju lara awọn to fẹ gba ijọba lọwọ Trump ninu idibo aarẹ ọdun 2020.
Awọn alatako Trump ni, niṣe lo n dun mọhurumọhuru mọ ileeṣẹ aarẹ Ukraine ki wọn ba le ba ṣe akoba alatako rẹ ninu ẹgbẹ Democrat, Joe Biden
Oríṣun àwòrán, Teresa Kroeger/Getty Images
Hunter Biden n wo Baba rẹ Joe Biden, nibi to ti n ba awọn eeyan sọrọ layẹyẹ kan lọdun 2016
Ẹwẹ, ọgbẹni Trump ati awọn alatilẹyin rẹ naa n naka abuku si Biden to figba kan jẹ igbakeji aarẹ, pe o lo ipo rẹ lọna aitọ ki Ukraine ma ba ṣe iwaadi to le tu asiri pe ọmọ rẹ Hunter, ṣe aṣemaṣe.
Ọgbẹni Biden lo n lewaju lati di oludije ti wọn yoo gbe aṣia ẹgbẹ Democrat fun lati kopa ninu idibo aarẹ lọdun to n bọ.
Ni ṣoki, ọrọ yi niṣe pẹlu ẹni ti yoo di aarẹ ilẹ Amẹrika
Nibo ni ọrọ yi ti wọwa?
Aarẹ Trump ati aarẹ Ukraine, Volodymyr Zelensky jijọ sọrọ lori ẹrọ alagbeka lọjọ kẹẹdọgbọn oṣu Keje ọdun yi.
Wọn fẹsun kan aarẹ Trump pe o mura mọ aarẹ Zelensky lati ṣe iwaadi igbakeji aarẹ ana, Biden to n ba du ipo.
Oríṣun àwòrán, EPA
Ni ibẹrẹ ọdun yi ni Volodymyr Zelensky gun ori alefa gẹgẹ bi aarẹ Ukraine
Wọn ni o ṣeeṣe ki aarẹ Trump ti sọrọ nipa iranwọ òjìlénígba lé mewaa miliọnu dọla, nkan ija ogun ti ile asofin Amẹrika ti buwọlu, amọ ti ijọba Trump ko ti juwọ rẹ silẹ.
Iroyin sọ pe, aarẹ Trump paṣẹ fun adele olori oṣiṣẹ ile ijọba rẹ Mick Mulvaney, lati dawọ iranwọ naa duro titi di igba ti ohun yoo ba aarẹ Ukraine sọrọ tan lori ago.
Aarẹ Trump ni lootọ loun ba aarẹ Zelensky sọrọ nipa ọgbẹni Biden, ṣugbọn ohun ko dunkoko mọ pe ki o we ẹsun mọ alatako rẹ lẹsẹ
Njẹ aarẹ Trump ti fidi ọrọ yi mulẹ?
O jọ bẹ.
Ọgbẹni Trump ni oun ba ọgbẹni Zelensky sọrọ nipa ipenija ajẹbanu ati nipa ọgbẹni Biden ati ọmọ rẹ Hunter, to fi mọ awọn nkan miran.
O ni ọrọ naa jẹ eleyi to da lori ẹrọ ibaraẹnisọrọ - ọrọ ti ko lẹjabakan ninu.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ukraine ti ri ọpọ iranwọ gba lẹyin ti orileede Russia gba akoso iṣejọba Crimea lọdun 2014
Ki lawọn oloṣeeelu US miran n sọ?
Awọn ọmọ ile aṣofin to jẹ ọmọ ẹgbẹ Democrat ni, ipe ori ago naa eleyi ti eeyan kan tu asiri rẹ ṣe pataki, nitori o tan imọlẹ si bi aarẹ Trump ṣe n ṣe pẹlu awọn olori orileede miran.
Awọn alatakọ sọ pe, ni ṣe ni aarẹ Trump mura mọ aarẹ Zelensky ki o ba le ṣe iwaadi ọmọ alatako rẹ, lọna ati ṣe akoba fun un.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Abẹnugan ile to jẹ ọmọ ẹgbẹ Democrat, Nancy Pelosi lo lewaju iwaadi to fẹ daba ki wọn yọ aarẹ Trump
Njẹ aarẹ ṣe ohun ti ko tọ?
Ti ọrọ ba kan ẹsẹ ti wọn a fi yọ aarẹ nipo, orisirisi ni awọn ẹṣẹ naa, ti o si jẹ pe ohun ti ile ba panupọ pe o jẹ ẹsẹ aṣemaṣe naa ni wọn yoo fi yọ aarẹ nipo.
Ko daju pe awọn ọmọ ẹgbẹ Republican to jẹ ẹgbẹ Trump yoo dibo lati yọ aarẹ to jẹ ọmọ ẹgbẹ wọn.
Ọrọ naa yoo gba oye, nitori ki wọn to le ri aarẹ yọ, pupọ ninu awọn aṣofin ni yoo tẹwọgba aba naa.
Boya wọn yoo ri Trump yọ tabi ko ni ri bẹ, ni ohun to ku ti awọn eeyan n tẹti leko le lori ọrọ to wa nilẹ yi.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Bill Clinton ni aarẹ ikẹyin ti wọn buwọlu aba lati yọ nipo
Aarẹ meji ni awọn ọmọ ile aṣofin ti buwọlu aba pe ki wọn yọ nipo ninu itan Amẹrika.
Andrew Johnson jẹ ọkan ninu wọn lọdun 1868, ti ẹnikeji si jẹ Bill Clinton lọdun 1998.
Ko si kankan ninu wọn ti wọn ri aga yẹ nidi rẹ kuro nipo.
Akojọpọ iroyin tati ọwọ Anthony Zurcher a Tara McKelvey
Osinbajo fárígá: Mò ṣetán láti wàákò pẹ́lù àwọn tó ń bàmí lórúkọ jẹ́!
Oríṣun àwòrán, @ Prof. Yemi Osinbajo
Agbẹjọro ati ajafẹtọ ọmọniyan, Olukayode Ajulo ti sọ wi pe Igbakeji Aarẹ orilẹede Naijiria ko lasẹ labẹ ofin Naijiria lati yọ ofin amuniti (imunity) rẹ kuro nitori o fẹ se ẹjọ.
Ajulo lọ sọ eyi lasiko to n ba BBC Yoruba sọrọ lori igbesẹ Igbakeji Aarẹ Yemi Osinbajo lati ṣe ẹjọ pẹlu ẹsun wi pe awọn kan n ba orukọ oun jẹ.
O ni Osinbajo lasẹ labẹ ofin lati pe eniyan lẹjọ, amọ ẹnikẹni ko laṣẹ labẹ ofin la ti pe e lẹjọ tabi se iwadii rẹ lasiko to ba ṣi wa ni ipo isejọba.
O fikun un wi pe ofin kan naa lo de Osinbajo lati ma lee fun awọn asewadii lanfaani ṣiṣe iwadii rẹ, ki gbogbo aye le mọ wi pe ko wu iwa ibajẹ.
Ti a ko ba gbagbe, laipẹ yii ni Timi Frank ati awọn akẹẹgbẹ rẹ fi ẹsun kan Igbakeji Aarẹ naa wi pe o lu owo ilu ni ponpo lasiko to gba ọgọọrọ biliọnu to to aadọrun kuro ni ẹka to n risi ọrọ abẹle lorilẹede Naijiria, lati fi se idibo gbogboogbo ti ọdun 2019.
Ọpọlọpọ awọn ọmọ Naijiria lo ti fesi si igbesẹ Igbakeji aarẹ orilẹede Naijiria, Yemi Osinbajo to ni awọn eniyan kan n ba oun lorukọ jẹ, nitori naa oun gbe wọn losi ile ejọ.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Esi ti igbakeji aarẹ fọ yi wa ni idahun si ọrọ tawọn kan sọ nipa rẹ ninu iwe iroyin to ni ko si ootọ nibẹ.
Yemi Osinbajo tutọ soke foju gba pẹlu bi o ti ṣe ni awọn eeyan kan n ba orukọ oun jẹ.
Ariwisi ọtọọtọ si ti n tẹle ọrọ igbakeji aarẹ naa nitori bi awọn kan ti ṣe n bẹnu atẹ lu awọn to ni wọn n gbe iroyin ẹlẹjẹ kaakiri nipa oun ni awọn miran ni ki igbakeji aarẹ ṣe mẹdọ.
Kí ni Yorùbá ń pe ọmọ tí wọ́n bí lẹ́yìn Àlàbá?
Ninu atẹjade to fi si oju opo rẹ lori ayelujara Twitter ati Facebook,Osinbajo ni oun ṣetan lati ofin aṣemaṣebawi ti ofin faye gba oun silẹ lori ọrọ naa.
Bakanna ni Osinbajo sọ pe oun ti paṣẹ fawọn agbẹjọro oun lati gbe igbesẹ didoju ija kọ awọn to wa nidi ọrọ naa ni ile ẹjọ.
Osinbajo ni ọrọ yi ti wa n fẹ di lemọlemọ ti awọn to n ba ohun lorukọ jẹ naa ko si fẹ jawọ ninu iwa yi.
Omoyele Sowore : Àwọn orílẹ̀èdè márùn-ún tí ìjìyà ti wà fún ẹni tó bá bú ààrẹ
Oríṣun àwòrán, Omoyele Sowore
Ijọba apapọ Naijiria ni Sowore fi ifọrọwanilẹnuwo bu aarẹ
Omoyele Sowore ti pari gbogbo eto beeli rẹ lọjọru ṣugbọn awọn alaṣẹ kọ lati tu silẹ.
Eyi ni ohun ti agbẹjọro rẹ Femi Falana sọ fun BBC ni irọlẹ oni ninu ifọrọwanilẹnuwo lori ẹrọ alagbeka.
Lọjọ Iṣẹgun ni ile ẹjọ paṣẹ ki awọn ọtẹlẹmuyẹ tu agbatẹru iwọde Revolution Now ti wọn fi si ahamọ lori ẹsun pe o fẹ fiditẹgbajọba silẹ.
Lara ẹsẹ ti ijọba ni Sowore da ni pe o bu aarẹ orileede Naijiria ni ilodi si ofin Naijiria.
Labẹ ofin ẹni to ba bu aarẹ le lọ si ẹwọn ọdun mẹta tabi ko san owo itanran miliọnu meje Naira.
Amọ ṣa ni Naijiria nikan kọ ni ijiya ti wa fẹnikẹni to ba bu aarẹ.
Ki a to ka awọn orileede naa seti igbọ yin,ka sare sọ fun yin pe iyawo Sowore n lewaju iwọde nibi apero awọn olori orileede to n waye nilu New York.
Oya,ẹ jẹ ki a wo awọn orileede to la ijiya kalẹ fẹni kni to ba bu aarẹ
Losu Kẹrin  ọdun 2018, ile aṣofin  Netherlands fi ofin lelẹ pe bo nba bu ọba, o le lo to ọdun marun un lẹwọn.
"Ofin to de ọrọ yi ti wa lati dun 1881 ti wọn si n pe ni  ""lese majeste."""
Igba ti wn fi ofin yi rinl ni igba ti arakunrin kan lọ si ori Facebook to si ni apaniyan,afipabanilopo ati ole ni Oba  Willem-Alexander.
Ẹwọn ọgbọn ọjọ lo fi jura.
Oríṣun àwòrán,  Twitter
Awọn eeyan fi aworan aarẹ Burundi ṣe yẹyẹ lẹyin tawọn akẹkọbinrin kan kun oju rẹ laro
Ni Burundi o le lo to ọdun marun un lẹwọn ti o ba ṣẹ nkankan to jọ mọ pe o bẹnu atẹ lu aarẹ.
Losu Kẹta ọdun 2019 awọn akẹkọbinrin mẹta kan wọ gau lori pe wọn ya aworan yẹyẹ aarẹ Pierre Nkuruziza .
Ọpẹlọpẹ pe awọn eeyan da si ọrọ naa ni wọn fi tu wọn silẹ lahamọ.
Oríṣun àwòrán, AFP/Getty Images
Awọn eeyan ti lọ si ẹwọn nitori aja Ọba torukọ rẹ n jẹ Tongdaeng
"Thailand naa ni ofin to jọ mọ ""lese majeste""  to ni eeyan ko le bu mọlẹbi idile awọn alaṣẹ ilẹ naa ti wn si ti fi iya j ọpọ eeyan lati igba ti awọn ologun ti gba ijọba ldun 2014."
Laarin ewọn ọdun mẹta si mẹẹdogun lẹni to ba bu Ọba le fi gbara
Lọdun 2013,ile ẹjọ giga buwọlu ofin to sọ pe ẹṣẹ ni ki eeyan kọ nkan tabi sọrọ aarẹ laburu.
Eeyan le lo to ọgbọn oṣu lẹwọn to ba tasẹ agẹrẹ si ofin yi.
Ọdun 2018  ni Rwanda fofin lelẹ pe o le lọ ẹwọn ọdun marun un tabi meje to ba bu aarẹ nitori ipo pataki to dimu.
Taribo West: Àwọn aláìní ní Italy ní mò ń fi owó ìjọ mi ràn lọ́wọ́
Oríṣun àwòrán, Others
Ilumọọka agbabọọlu ọmọ Naijiria to ti di ajihinrere bayii, Taribo West ti salaye lori bo se n gba awọn ọmọ Naijiria, to lọ se asẹwo lorilẹede Italy, silẹ.
Agbabọọlu tẹlẹ naa, lasiko to n ba akọroyin Punch sọrọ ni ọpọ awọn ọmọ ilẹ yii ti ko rile gbe, atawọn asẹwo to wa nilu Milan ni oun n se iranlọwọ fun.
Taribo ni ijọ oun, The Storm Miracle Ministry of All Nations, ni oun n lo lati tọ awọn eeyan naa sọna nipa igbe aye rere to yẹ ki wọn gbe.
"Ọlọrun lo sọ fun wa pe ka lo ohun gbogbo  ta ba ri ko jọ lati inu owo to n wọle fun wa, fi mu igbe aye dẹrun fawọn eeyan to ku diẹ kaa to fun.
Bakan naa, gbogbo awọn eeyan ti awujọ ti ropin pe ko le se rere nitori ko rọrun lati gbe nilẹ Yuroopu, o dabi ilẹ awọn to n se atipo ọrọ aje ni."
Sunday Igboho: Ẹ fi Ògún búra fún wa láti jà fún ilẹ̀ Yorùbá láì gbé Amotekun sábẹ́ ìjọba
Taribo West fikun pe ọpọ awọn eeyan ti ijọ oun ti se iranlọwọ fun, tawọn si tun doola ẹmi wọn loke okun,  si ni oun maa n kan si.
Ijọba orilẹede Italy ti fagile faani ti wọn fun ọmọ orilẹede Naijiria kan to n gba ilẹ awọn adugbo kọọkan lai gba aṣẹ.
Iroyin sọ pe ni ilu Venice ni ọmọ ọkunrin naa ti n gba ilẹ adugbo ti igbimọ alaṣẹ to wa nibẹ si ni ko gba aṣẹ ko to maa gba a.
Ni ọlọpaa agbegbe Mestre lẹba Venice ba wọn ọn ni faini to fẹrẹẹ to $400 (iyẹn nkan bii N144,000).
African Migrants: Awọn arinrinajo sọ iriri wọn lọ si ilẹ Amerika
Lẹyin ọpọlọpọ ikun sinu latọdọ awn ara adugbo, awọn alaṣẹ gba pe awọn ti fun arakunrin naa ni ijiya to pọ ju.
O ti di ohun to wọpọ ki awọn arinrinajo to lọ si orilẹede italy maa gba idọti awọn adugbo orilẹede naa.
Wọn ni o pe awọn lati lọwọ si idagbasoke agbegbe naa ju ki awọn maa tọrọ owo kiri lọ.
Ṣugbọn awọn ọlọpaa agbegbe fi ẹsun kan ẹni ọdun mọkandinlọgbọn naa ti orukọ rẹ n jẹ Monday pe o n tọju adugbo lai gba aṣẹ lọwọ awọn alakoso ibẹ.
Agbẹjọro kan, Matteo D'Angelo to da eto iranwọ fun Ọgbẹni Monday silẹ lori ayelujara lati san faani rẹ sọ pe ijiya ti wọn fun un ko boju mu rara.
Iroyin sọ pe Ọgbẹni D'Angelo ko owo ti wọn ko jọ lori ipolongo ori ayelujara fun Ọgbẹni Monday lati fi di iya ti awọn ọlọpaa fi jẹ ẹ.
Kí ni Yorùbá ń pe ọmọ tí wọ́n bí lẹ́yìn Àlàbá?
Olufunke Oshonaike: Ewu ń bẹ fún àwọn obìnrin tó ń fẹ́ ọkọ ọlọ́kọ
Oríṣun àwòrán, Google
Ẹ̀ yin baálé ilé, ẹ yé sátẹ̀lé mi kiri mọ́!- Oshonaike
Agbabọọlu ẹlẹyin Table Tennis to ti gbami ẹyẹ nilẹ Afirika ri, Olufunke Oshonaike ti bu ẹnu ate lu bi awọn ọkunrin to ni iyawo sile ṣe n bere fun ibasepọ pẹlu oun.
Olufunke to sọ eleyii lori oju opo Facebook rẹ, sọ wi pe oun ti sọ ifẹ fun igbeyawo nu, lẹyin ti ọpọlọpọ ọrọ ifẹ oun ti forisanpọn.
Ninu ọrọ rẹ, Olufunke sọ wi pe awọn ọkunrin ti foju oun wina nitori ọpọlọpọ aisotitọ ati ododo ti wọn ti fi ba oun lo.
O fi kun un wi pe, ọkọ ti oun fi silẹ, Kevin irabor lo fẹ ẹlomiran lẹyin ti awọn ṣe igbeyawo, ti oun si ti bimọ meji fun un.
Bẹẹ lo kilọ fun awọn obinrin pe ki wọn ranti pe, ko si oun ti eniyan ṣe silẹ, ti ko ni ba.
Arabinrin naa wa parọwa si awọn obinrin lati ye fẹ ọkọ ọlọkọ, ki idile lee gboro sii, nitori ewu ti o n fa ninu idile ko kere rara.
Kí ni Yorùbá ń pe ọmọ tí wọ́n bí lẹ́yìn Àlàbá?
Oyo State: Ètò ìṣúná ìpínlẹ́ Oyo yóò jẹ láti ìbẹrẹ de òpin ọdún
Oríṣun àwòrán, @seyiamakinde
Akọwe agba ijọba ipinlẹ Ọyọ, Iyaafin Olubamiwo Adeosun ti ṣalaye pe Ipinlẹ naa yoo pada bẹrẹ si ni jẹ awokọse fun awọn toku.
O ni gbogbo eto lo ti wa nilẹ lati ṣamulo eto  Iṣuna Ipinlẹ naa lọna to yẹ ni ibẹrẹ ọdun si opin ọdun.
Akọwe agba yii lo sọ orọ naa ni ọjọbọ ọsẹ yii ni ilu Ibadan nibi ti o ti n ṣe idanilẹkọ lori eto Amuyẹ Iṣuna .
O tẹpẹlẹ mọ iṣamulo ati igbelarugẹ alakalẹ eto iṣuna to ye kooro lojuna ati da awọn eekan ninu iṣẹ ijọba lẹkọ ninu isẹjọba Makinde.
Adeosun ṣalaye iṣuna ijọba bii eyi ti o n ṣe afihan eto ti  ijọba ni fun idagbasoke awujọ.
Ko ṣai mẹnuba pataki ti eto iṣuna n ko ninu ọrọ aje ati inawo fun idagbasoke ilu.
O wa gba awọn oṣiṣẹ naa ni imọnran lati ri ara wọn gẹgẹ bi oniṣowo ti o fẹ jere fun araalu.
Ninu ọrọ rẹ,o ni erongba ijọba ni lati pese ohun amuludun fun ara ilu sugbọn ti ilana eto iṣuna to peye yoo jẹ anfaani nla.
Oríṣun àwòrán, Oyo govt
Awon ọmọ igbimọ alaṣẹ ipinlẹ Oyo
Arabinrin naa gboriyin fun Gomina Makinde fun dida ile iṣe eto Iṣuna ti o gbominira lati ṣiṣẹ ti yoo si fa tolori tẹlẹmu mọra.
O tẹsiwaju pe,ijọba ipinlẹ Ọyọ ti gunlẹ ilana eto iṣuna amuyẹ wọ ọdun 2020 .
Ninu ọrọ tirẹ, Olori awọn oṣiṣẹ ni ipinlẹ naa,Alhaja Ọlọlade Agboọla ṣalaye pe asiko imuṣofun iṣuna ti kọja.
Gẹgẹ bi o ti wi, o ni inakuna owo ijọba ko si mọ ni bi ijọba ti ṣetan lati gbajumọ awọn eto alakalẹ ẹ rẹ.
Oríṣun àwòrán, Oyo Govt
Ibi idanileko ni Ibadan
Awọn eto alakalẹ naa ni ; eto Ekọ, Ilera, eto aabo ati ọrọ aje ti ijọba yoo ri wi pe o de ẹsẹ kuku kaakakiri ipinlẹ naa.
Nigba ti kọmiṣọnna fun eto Iṣuna ati Ọrọ Aje lpinlẹ naa, Amofin Adeniyi Farinto n ṣalaye fun awọn akọroyin, o ni gbogbo eto naa ni yoo di mimu ṣe.
O ni ti o ba di opin ọdun yii , eto iṣuna ọdun 2020 yoo di fifi ṣọwọ si ile Igbimọ Aṣofin ki o to di fifọwọ si fun Gomina Makinde.
Omoyele Sowore: 'Fi ṣowore sílé kí ó tó pẹjù tàbí kí o ṣewọn
Oríṣun àwòrán, Omoyele Sowore
Ijoba Apapo fesun kan Sowore pe o benu ate lu Ijoba
Ile ẹjọ giga apapọ ti kilọ fun Ọga agba ajọ DSS Yusuf Bichi lati tẹle aṣẹ ile ẹjọ pe ki wọn fi Omowole Sowore sile lẹyin ti o ti gba idalare ti o si ti pari gbogbo eto to yẹ nipa gbigba oniduro.
Ile ejọ yii lo kọ lẹta janranjanran ranṣẹ pada si ajọ naa ni ọjọbọ ọsẹ yii pe ajọ naa n tapa si aṣẹ ile ẹjọ to si le e mu wọ ẹwọn lairo tẹlẹ.
Ni ile ẹjọ ba paṣẹ pada pe ki wọn o fi Ṣoworẹ silẹ  laarin wakati merinlelogun lẹyin ti ile ẹjọ ti daa silẹ ki o maa lọ.
Ṣe ni ọjọru Ọsẹ yii ni agbẹjọro rẹ, Fẹmi Falana ti lọ si ile iṣẹ ajọ naa lati ri Soworẹ sugbọn ti gbogbo akitiyan rẹ jasi pabo.
Ṣugbọn ọrọ gbẹyin yọ ni ọjọbọ ọsẹ yii nigba ti awọn Oṣiṣẹ ajọ naa ko fi aaye gba Falana lati wọle si inu ọgba wọn.
Nigba ti Falana de ẹnu ọna ile iṣẹ ajọ naa ni wọn ba bẹrẹ si i da riboribo lojuna lati maa ṣe jẹ ko ri onibara rẹ, Aguru Soworẹ lo sọ fun BBC bẹẹ.
Otẹsiwaju pe gbogbo ẹbi wọn si ti wa  ni idaamu lori ọrọ naa.
Aburo rẹ yii ṣalaye pe Idaamu nla ni gbogbo rogbodiyan yii jẹ fun, iyawo, awọn ọmọ ati gbogbo ẹbi rẹ pata.
O wa sọ wi pe ohun ti ẹgbọn ohun n la kọja lọwọ awọn ajọ yii mu ipaya bawọn ni pataki lẹyin ti ile ẹjọ ti ni ki o maa lọ sile.
Ninu alaye rẹ lo ti ni ohun itiju lojẹ pe ijọba to n kede idajọ ododo gan naa ni ko fi apẹẹrẹ rere lelẹ ti ko si le fi aṣẹ ile ẹjọ lele to jasi pe ko si ijọba tiwa n tiwa.
Agbẹjọro Soworẹ miiran,Marshal Abubakar sọ wi pe bi ajọ naa ṣe n kọ eti ikun si ọpọ idajọ ile ẹjọ ti n pọ lapọju, ti ko si bu iyi kun Orilẹ ede yii.
$9.6bn: Ilé ẹjọ́ ni Nàìjíríà lè takò ìdájọ́ ilẹ̀ Gẹ̀ẹ́sì tó fẹ́ gbẹ́sẹ̀ lé $9.6bn ohun ìní Nàìjíríà
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ijọba Nàìjíríà fẹ́ kí ilé ẹjọ́ ó fagilé idajọ to ni ki wọn sanowo yi fun ile iṣẹ ilẹ Gẹẹsi naa
Ile ẹjọ kan nilẹ Gẹẹsi ti dajọ pe orileede Naijiria le tako idajọ lori owo itanran $9.6bn ti ileeṣẹ ilẹ Gẹẹsi kan P&ID fẹ ki Naijiria san fun un.
Lọjọbọ ni wọn gbe idajọ yi kalẹ lori ọrọ meji ti Naijiria gbe wa si iwaju ile ẹjọ naa.
Akọkọ rẹ ni pe Naijiria fẹ ki ile ẹjọ gba wọn laaye lati tako idajo naa.
Ẹlẹẹkeji ni pe wọn fẹ ki ile ẹjọ paṣẹ ki wọn dawọ duro lori amuṣẹ idajọ to ti waye ṣaaju pe P&ID le gba owo naa lọwọ Naijiria.
Lati nnkan bi ọjọ melo kan lawọn alaṣẹ Naijiria ti wa ni ilẹ Gẹẹsi lori ọrọ yii.
Ninu wọn la ri Minisita fọrọ idajọ Abubabakar Malami, ọga agba banki apapọ Godwin Emefiele ati Minisita feto iroyin Lai Mohammed.
Iroyin to tẹwa lọwọ sọ pe ile ẹjọ ko tii dajọ lori abala keji ọrọ owo naa to jọ mọ pe ki wọn ma tii faaye gba ileeṣẹ P&ID lati gba owo pada.
Ise Ekiti Robbery: ìgárá ọlọ́sà ya bo banki,Ọlọ́pàá kàn pàdánù ẹmi rẹ́
Oríṣun àwòrán, Thenationonline
Aworan ile ifowopamọ kan nilu Ido Ani ti awọn ajigunjale yabo laipẹ yi
Awọn adigunjale tun ti ṣoro nipinlẹ Ekiti nibi ti wọn ti yabo ile ifowopamọ kan nibẹ.
Lọsan ọjọbọ ni awọn alọkiolounkigbe yi ṣigun bo ile ifowopamọ Wema ti wọn si pa ọlọpaa to wa nibẹ.
Nigba ti o n fi idi ọrọ yi mulẹ fun BBC Yoruba,alukoro ọlọpaa nipinlẹ Ekiti,Caleb Ikechukwu ni awọn ajigunjale mẹfa ni wọn ṣiṣẹ yi.
''O ṣeni laanu pe wọn ṣeku pa ọlọpaa kan ṣugbọn yatọ si ọlọpaa yi ko si lomiran to ku ninu iṣẹlẹ naa.''
Eyi ni igba ikeji ti awọn ajigunjale yoo maa ṣe ọṣẹ ni Ekiti laarin oṣẹ mẹta.
Ni nnkan bi ọsẹ meji sẹyin,ọlọpaa mẹta ati awọn eeyan mẹrin miran ko agbakọ lọwọ awọn ajigunjale to yabo ile ifowopamọ kan ni Ilasa Ekiti.
A gbọ pe ado oloro lawọn ajigunjale naa lo lati ja ilẹkun ile ifowopamọ si ohun.
Ọgbẹni Caleb ni awọn n tọ pinpin awọn ajigunjale naa ati pe awọn yoo ri pe ọwọ tẹ wọn laipẹ.
Ìfipábọ́mọlòò Kaduna: Ọlọ́ọ̀pá m'áwọn tó ń fipá bá èèyàn 500 àtàwọn ọmọdékùnrin lò pọ̀
Oríṣun àwòrán, Nigerian Police
Eeyan bi ẹẹdẹgbẹta tawọn ọmọde wa lara wọn lo gba ominira lẹyin tawọn ọlọpaa yabo ile kan lagbegbe Rigasa nipinlẹ Kaduna l'Ọjọbọ.
Kọmiṣọna ọlọpaa ipinlẹ Kaduna, Ali Janga ṣalaye fun BBC pe ileeṣẹ ọlọpaa yabo gbọngan naa lẹyin tawọn ara ilu kan ta wọn lolobo lori ohun to n ṣẹlẹ lagbegbe ọhun.
Ileeṣẹ ọlọpaa fidi rẹ mulẹ pe awọn eeyan naa ti gbogbo wọn jẹ ọkunrin wa lati orilẹede Burkina Faso, Mali atawọn orilẹede ile Afirika miiran.
Awọn agbofinro sọ pe awọn eeyan yii tawọn ọmọde pọju lara wọn ni wọn ju ṣẹkẹṣẹkẹ si lẹsẹ ninu ahamọ ti wọn wa.
Oríṣun àwòrán, Nigerian Police
Bakan naa ni ileeṣẹ ọlọpaa sọ pe oniruuru iya ni wọn fi jẹ awọn eeyan ọun.
Ileeṣẹ ọlọpaa yabo gbọngan naa lẹyin tawọn ara ilu kan tawọn lolobo lori ohun to n ṣẹlẹ lagbegbe naa.
Iroyin sọ pe awọn kan n ni ibalopọ tipatipa pẹlu awọn ọmọde to wa nibẹ, bakan naa ni wọn n fiya jẹ wọn lojoojumọ.
Ọpọ ninu wọn lo sọ pe awọn ẹbi awọn lo mu awọn lọ sibẹ nitori wọn ro pe ileewe ẹkọ nipa ẹsin ni.
Ileeṣẹ ọlọọpa ni iwa imunilẹru ati iwa ika si ọmọniyan ni iṣẹlẹ naa jẹ.
Ẹwẹ, awọn afurasi mẹjọ lawọn ọlọpaa ti mu bayii, nigba ti iwadii si n lọ lọwọ
ICPC vs Kashamu: Irọ́ ni ICPC ń pa mọ́ Kashamu lórí ọ̀rọ̀ ọkọ̀ áńbúlàǹsì àti ẹ̀rọ amúnáwá
Oríṣun àwòrán, @SenatorBurujiKashamu
Irọ ni ajọ to n gbogun tiwa ibajẹ, ICPC n pa mọ Sẹnẹtọ Buruji Kashamu lori ọrọ pe wọn fipa gba ọkọ anbulansi mẹta ati ẹrọ amunawa kan ni ọfdiisi rẹ niluu Ijebu Ode.
Oludamọran fun Sẹnẹtọ Kashamu lori ọrọ iroyin, Ọgbẹni Austin Oniyokor lo ṣalaye ọrọ yii fun ileeṣẹ BBC Yoruba ninu ifọrọwerọ lori aago lọjọ Ẹti.
Agbẹnusọ fun ajọ ICPC, Rasheedat Okoduwa lo kọkọ ṣalaye ninu iroyin kan tawọn iwe iroyin gbe jade pe, awọn anbulansi ati ẹrọ amunawa naa jẹ iṣẹ iriju rẹ lẹkun Ila oorun ipinlẹ Ogun ti wọn ti dibo yan an.
Okoduwa ni miliọnu mẹfa naira ni ọkọ anbulansi kọọkan naa to yẹ ki Sẹnẹtọ Kashamu fi ṣọwọ sawọn Ile Iwosan to wa ni Obada ati Oke Sopin ni ijọba ibilẹ Ijebu East ati Ile Iwosan to wa ni Ogijo ni ijọba ibilẹ Sagamu.
Okoduwa sọ di mimọ pe ajọ ICPC gbe igbesẹ yii lẹyin ti ara ilu kan tawọn lolobo nipa awọn ọkọ ati ẹrọ amunawa ọhun.
Ṣugbọn oludamọran Sẹnẹtọ Kashamu lori ọrọ iroyin sọ pe igbesẹ ajọ ICPC jẹ iyalẹnu nitori Sẹnẹtọ Kashamu fun ra rẹ fi to ajọ naa leti pe Ọgbẹni Onadeko Onamusi to gbe iṣẹ naa fun ra ọkọ anbulansi ti ko dara to.
O ṣalaye siwaju si pe ajọ ICPC gbe Onamusi lọ sile ẹjọ lori ọrọ, bakan naa ni Sẹnẹtọ Kashamu fun un ni iwe gbele ẹ.
Ọgbẹni Oniyokor ṣalaye pe awọn ọkọ yii ati ẹrọ amunawa lo duro bi ẹri niwọn igba ti ọrọ naa si wa nileejọ.
Kaduna Children-Méje ni ọwọ ti tẹ nínú àwọn Afunrasí ìka Olùkọ Kaduna - Ọlọpàá
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ileeṣẹ ọlọpaa nipinlẹ Kaduna ni awọn afunrasi to de fi ipa de awọn akẹkọ mọlẹ nile kan  ti jẹwọ ohun to mu wọn ṣe bẹ.
Awọn ika olukọ naa ni pe ọmọ ti kii gbọrọ lawọn n de mọlẹ,koda eyi to ba kọ eti kun a ma fi iku ṣefajẹ.
Ninu ifọrọwanilẹnuwo pẹlu ile isẹ BBC ni ọrọ yi ti jẹyọ lati ẹnu alukoro ọlọpaa Kaduna,ọgbẹni Yakubu Sabo.
Sabo ṣalaye pe, lara awọn ọmọ naa ni ko ni imi ati okun ninu mọ latari airi ounjẹ jẹ daada da.
O ni ọpọlọpọ wọn ni wọn ti gbẹmi mi nitori pe wọn ko ni anfaani lati jade sita ninu ahamọ ti wọn bara wọn.
Ọga ọlọpaa naa tẹsiwaju pe lara awọn ijẹwọ ọkan lara wọn ni pe, iku ni ọmọ ti ko ba gbọnran maa n ri.
Oríṣun àwòrán, BBC Africa
Awon Akekoo ile iwe kehu ni Kaduna
Nigba ti ile Iṣẹ BBC Yoruba n ba kọmiṣọnna fun eto idagbasoke awujọ ni ipinlẹ naa, Hasfat Baba,sọrọ,o ni iwa naa ko boju mu.
O ni iwa ika gidi ni ẹni ti o pe ara rẹ ni Olukọ naa hu nitori pe,ọpọ awọn ọmọ wọnyii ni aisan ti n baja ti ọpọ wọn si ti gbẹmi mi.
Gẹgẹ bi o ti wi, o ni awọn obi gan ni o yẹ ki a da lẹbi ọrọ naa nitori pe ko yẹ ki wọn fi ọmọ si iru ile iwe bẹẹ.
O tun tẹsiwaju pe awọn ọmọ wonyii ni wọn maa n fi iya jẹ lainidi ti wọn si maa n pa wọn .
Oríṣun àwòrán, Police facebook
Awon Olopaa
Ikọ awọn Ọlọpaa ni kaduna naa ṣalaye pe, ọpọ ninu awọn ọmọ wọnyii ni ko mọ ọna pade sile mọ ti awọn obi wọn ko si ni anfaani lati mu wọn.
Kí ló mú kí àwọn ọ̀yìnbó aláwọ̀ funfun gé'run Dàda ọmọ aláwọ̀dúdú?
Oríṣun àwòrán, Reuters
Ọmọ ọdun mejila ti wọn ge irun rẹ
Ọmọdebinrin alawọ dudu ilẹ Amẹrika kan ti farada ohun ti ko yẹ ki ọmọde kankan fara da pẹlu bi awọn ojugba rẹ alawọ funfunfun mẹta ṣe da dubulẹ  ti wọn si ge irun ori  rẹ.
Omọ ọdun mejila naa to ni irun dada lori ti orukọ rẹ n jẹ Amari Allensi ni wọn ge irun ori rẹ pelu abẹ.
Iṣẹlẹ naa waye ni akoko isinmi  ni ile iwe rẹ to wa ni Springfield Virginia ni ọjọ Aje ọsẹ yii.
Amari ni awọn ọmọkunrin ojugba ohun naa ni wọn pe oun si ibi iṣere ti wọn si bẹnu abuku lu irun ori oun ki wọn to bẹrẹ si ni ge.
O ni iṣẹlẹ naa waye ni ile iwe  Immanuel Christian ,ti aya Aare orilẹ ede Amẹrika  ti n ṣiṣẹ olukọ.
Awọn Ọlọpaa ile iwe naa ati Agbofinro ilu ti n ṣe iwadii ọrọ naa.
Allen bẹru lati sọ fun awọn ẹbi rẹ tori ijiya
Allen  ṣalaye pe awọn ọdọkunrin naa ni wọn wa ba oun ti wọn si mu oun ni panpa mọra.
O tesiwaju pe n ṣe ni wọn fi  ọwọ bo oun lẹnu ti wọn si n sọ oriṣiriṣi ọrọ ti wọn si bẹrẹ sini ge irun ori oun.
Ninu alaye naa lo ti sọ pe, gbogbo ounjẹ oun ni wọn jẹ ti wọn si fi oun ṣe ọpọlọpọ yẹyẹ.
Ni ọjọru ọsẹ yii ni awọn ẹbi rẹ ṣakiyesi pe irun rẹ ko gun mọ bi ti tẹlẹ ti iyatọ si wa ninu irun naa.
O ni, ki ile iwe le awọn ọmọ yii kuro ni ile iwe nitori irun naa n dun oun gidi.
Ile iwe naa ṣalaye pe, awọn ko fi ọrọ ọmọ naa ṣere rara to fi mọ eto ilera wọn ti ko si faye gba idunkoko mọra ẹni
Bakan naa ni ile iwe naa ni ọrọ naa mu wọn lomi pupọ ti wọn si n ran ẹbi naa lọwọ lati ri aridaju ẹri ọrọ naa.
Ile iwe yii n san ọpọlọpọ owo dọla lọdọọdun ni bi ti Karen Pence, ti o jẹ iyawo Igbakeji  Are orilẹ ede naa ti n ṣiṣẹ.
Di school, wey di Allen family dey spend $12,000 evri year, na wia Karen Pence - di wife of di Vice-President Mike Pence dey teach art part-time.
Ìròyìn Kàyééfì BBC Yorùbá: Bí Ọba aládé ṣe jàjà bọ́ lọ́wọ́ àwọn afurasí ajínigbé
Lori eto iroyin Kayeefi BBC Yoruba lọsẹ yii, a mu itan nipa bi awọn ajinigbe darandaran ti ṣe fẹ gbiyanju lati ji Ọba Alade gbe nilẹ Yoruba.
Oba Adedokun Abolarin ti Oke Ila: Ó ya ọ̀pọ̀ tó súnmọ́ mi lẹ́nu bí mo ṣe ń kọ́
Kabiyesi onirẹsi ilu Irẹsini ipinlẹ Ondo, Oba David Olajide ni Oba Alade ti a ba sọrọ ti wọn si tu kẹkẹ ọrọ kalẹ nipa bi awọn Fulani darandaran kan ti ṣe n ṣọṣẹ lagbegbe rẹ.
Ọrọ awọn darandaran to ti fẹ di ọdaran nilẹ Yoruba jẹ ohun ti o n kọ awọn eeyan lominu.
Ẹ wo fidio naa ni ẹkunrẹrẹ ninu fọ́nrán tó wà lókè yìí.
Adebola Ademilua: Àìrísẹ́ ṣè lẹ́yìn ìwé kíkà ló sọ mi dí ìyá onírú, mo dúpẹ́ tèmi
Tacha àti BBNaija: Bobrisky fẹ́ fi mílíọ̀nù kan náírà tọrẹ fún Tacha lẹ́yìn tí wọ́n lé e ní BBNaija
Oríṣun àwòrán, DSTV NIGERIA
Lẹyin ti Tacha ti gba idajọ kuro ni sakani mi nile ẹlẹbọn agba lọjọ Ẹti, oniruuru iha ni awọn eeyan ti kọ si ijade rẹ. Bi awọn kan ṣe gboriyin fun un lawọn kan n bu ẹnu atẹ luu.
Amọṣa ni bayii, Bobrisky ti ni oun yoo fun Tacha ni miliọnu kan naira.
Ninu ọrọ to fi si oju opo Instagram rẹ lọjọ Abamẹta, Bobrisky ni o wu oun lati ṣe ju bẹẹ lọ sugbọn agbara ku diẹ kaa to fun oun.
Ifẹ mi, mi o ni gbogbo aye yii lati gbe le ẹ lọwọ bayii!!! Sugbọn gba mi bi mo ti ri nitori mo nifẹ rẹ. Ni bayii naa, maa reti miliọnu kan ninu aṣuwọn banki rẹ lọjọ Aje  lati ọdọ mi.
Tacha to ti di mọlumọọka bayii tori kikopa rẹ lori eto agbelewo Big Brother Nigeria.
Bii lẹta gbọọrọ tabi episteli gẹgẹ bi awọn to da si ọrọ naa ṣe sọ ọ ni Tacha kọ ranṣẹ si awọn ololufẹ rẹ ati ti BBNaija.
Ninu ọrọ ituba rẹ, o jẹ ko di mimọ pe oun to yẹ ko pari lọna nla fun ohun lo wa pari lojiji tori ori inu oun to tako oun.
Tọkan tọkan, mo tọrọ aforiji fun gbogbo iwa ti mo ti wu to fi ri bayii mo si gba a lẹbi.
"O ni o wu oun ki oun wa lori eto naa di ọjọ ikọkandinlọgọrun ṣugbọn ""ẹlẹran ara ni mi, mo ja kulẹ, mo si tun jakulẹ lọpọ igba""."
Oríṣun àwòrán, Simply_Tacha
Sibẹ, wuyewuye lori ọrọ Tacha ti wọn ti ṣe fọwọ osi juwe ile fun un kuro lori eto agbelewo BBNaija ko tii tan o.
Olorin takasufe, Peter Okoye lo kọkọ sọ pe oun ko ṣeleri lati fun Tacha lẹbun ọgọta miliọnu naira.
Okoye ni faabada oun ko le fun onijagidijagan eeyan lẹbun owo.
Awọn kan faake kọri lori ayelujara pe Peter n parọ ni, wọn ni o ṣẹ ẹ nitori wọn ti le Tacha kuro ni BBNaija.
Peter ṣalaye pe ohun to sọ ni pe oun yoo ran Tacha lọwọ lati ṣiṣẹ ri owo to to ọgọta miliọnu naira.
Obong Roviel ni ọrọ Peter Okoye ko ya oun lẹnu nitori Peteru ninu Bibeli gan da Jesu.
Koda Okoye sọ pe ẹni to ba ni ẹri to daju, oun ṣetan lati fun ẹni naa lẹbun miliọnu mẹwaa naira.
Olorin takasufe, Zlatan Ibile lo kọkọ gborin jade pe lori awuyewuye to ṣẹlẹ lori ọrọ ara rirun to maa n waye laarin Tacha ati Mercy.
"Zlatan sọ ninu orin naa pe ""Tacha ko ni pa'yan pẹlu oorun ara rẹ""."
Pẹlu ijo ati ilu ni Zlatan fi kọ orin ọhun, koda oun atawọn akẹgbẹ rẹ ni wọn jọ kọ ọ́.
"Zlatan Ibile n beere ninu orin naa pe ''ki lo n run, ṣe Tacha ti wọ le?"""
Orin naa ti n mi ori ayelujara titi, o da bi ọrọ ilu gangan to jẹ pe ibi to kọ s'ẹnikan, ẹyin lo kọ si ẹlomiran.
Bawọn kan ṣe faramọ orin ọhun lawọn mii ni o ku diẹ kaato.
Muhammadu Buhari: Ààrẹ Nàìjíríà balẹ̀ bàgẹ̀ s'Abuja lẹ́yìn ìpádé UNO nílùú New York
Oríṣun àwòrán, Facebook/Femi Adesina
Ba o lọ, a kii de, eyi lo difa fun Aarẹ orilẹede Naijiria, Muhammadu Buhari to pada silu Abuja lati orilẹede Amẹrika.
Aarẹ Buhari kopa ninu ipade apero ajọ iṣọkan agbaye eleyi to waye niluu New York.
Ipade ọhun niiṣe ẹlẹẹkẹrinlelaadọrin iru'ẹ lati igba ti wọn ti da ajọ iṣọkan agbaye silẹ lọdun 1945.
Oludamọran fun aarẹ lori iroyin ori ayelujara, Bashir Ahmad lo kede loju opo Instagram ati Twitter rẹ Aarẹ ti pada silu Abuja.
Aarẹ kopa ninu oniruuru eto nibi apero awọn olori orilẹde niluu New York.
Buhari sọrọ igbiyanju ijọba rẹ lati gbogun ti oṣi ati iṣẹ to n ba ọpọ finra ni Naijiria.
Buhari tun sọrọ nipa eto ẹkọ ati ayipada oju ọjọ lorilẹede Naijiria.
Ondo state: Bàbá ọlọ́mọ méjì kú sínú àgbàrà òjò nílùú Akure
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Omi ti gbe baba ọlọmọ meji kan lọ nilu Akurẹ lẹyin ti ojo arọọrọda kan rọ lalẹ ọjọ Ẹti.
Iroyin taa gbs ṣalaye pe iṣẹlẹ buruku yii ṣẹlẹ lagbegbe Oke Iyara ni Ijọka.
Nibẹ ni wọn ni arakunrin yii atawọn ẹbi rẹ n gbe ki ọlọjọ to de.
Iṣẹ ọkada wiwa ni wọn sọ pe o n ṣe.
Owurọ ọjọ Abamẹta ni awọn aladugbo to ri oku arakunrin naa nibi ti agbara ojo naa wọ si.
Ohun ti awọn aladugbo rẹ sọ ni pe agbara ojo naa gba arakunrin ọhun ti wọn ni orukọ rẹ n jẹ Idowu Kọmọlafẹ ati alupupu rẹ nigba to n gbiyanju ati gba aarin agbara ojo naa kọja lọ si ile rẹ.
Olojo festival: Buhari kan sáárá sí Ọọ̀ni, pè fún ìgbélékè àṣà adúláwọ̀
Oríṣun àwòrán, @MBuhari
Aarẹ Buhari ti rọ awọn ọmọ orilẹede Naijiria ati gbogbo adulawọ lagbaye lati maṣe gbagbe iṣẹṣe ati aṣa wọn.
Aarẹ Buhari ṣalaye ọrọ yii ninu iṣẹ to fi ran minisita fun ọrọ abẹle, rauf Arẹgbẹṣọla lọ sibi ajọdun Ọlọjọ ti ọdun yii nilu Ifẹ.
Aarẹ Buhari ni tipẹtipẹ ni aṣa n lẹ mọ awọn eeyan to ba nii. O ni inu oun dun si bi awọn eeyan Ile ifẹ ko ṣe gba ki ohunkohun ya wọn kuro lara aṣa wọn.
O wa gba adura ki Eleduwa o lọra ẹmi Ọọni ile ifẹ, awọn ijoye rẹ ati gbogbo awọn eeyan ilu Ifẹ.
Ninu ọrs tirẹ, gomina ipinlẹ Ọṣun, Gboyega Oyetọla ki awọn eeyan ilu Ifẹ ku oriire ajọdun naa.
"O ni 'Ajọdun Ọlọjọ n ṣe agbeleke aṣa ati iṣẹṣe wa fun gbogbo agbye ni. Ọdun naa ti ṣe afihan aṣa Yoruba fun gbogbo agbye lati ri."""
Awọn Ọba alaye to wa nibi ajọdun Ọlọjọ tọdun yii ni Olubadan of Ibadan, Obi Eze Ngwu, Orangun Oke-Ila atawọn eekan miran lawujọ.
Aisha Buhari: Iléeṣẹ́ ààrẹ sọ ìdí tí Aisha Buhari kò fi tíì padà sí Nàìjíríà
Oríṣun àwòrán, Facebook/Aisha Buhari
Ileeṣẹ aarẹ ti ṣ'aṣọ loju eegun ohun to faa ti aya aarẹ orilẹede Naijiria, Aisha Buhari fi rinrin ajo lọ si ilẹ okere fun bi oṣu meji bayii.
Oluranlọwọ fun Aisha Buhari lori ọrọ to n lọ, Suleiman Haruna sọ pe aya aarẹ orilẹede Naijiria ni ominira lati rinrin ajo lọ si ibi to ba wuu nigba kugba.
Ọpọ lo ti n sọ pe Aisha lọ si ilẹ okere nitori ija tawọn kan lo n waye ni olu ileeṣẹ ijọba l'Abuja ati aiidunnu rẹ si bawọn eeyan kan ṣe n dasi iṣejọba Aarẹ Buhari.
Ṣugbọn Ọgbẹni Haruna ni iwọfa lẹnu, ohun to ba si wu ẹlẹnu lo le fẹnu rẹ sọ lọrọ tawọn kan n gbe kiri.
Haruna fi kun ọrọ rẹ pe niwọn igba ti Aisha kii ṣe oṣiṣẹ ijọba, o lanfaani lati rinrin ajo lọ si ibi to fẹ.
Aisha ti fi aidunnu rẹ han tẹlẹ lori iṣejọba Aarẹ Buhari, nigba to sọ pe awọn ti wọn ko gbaruku Buhari ko too wọ le ibo rẹ ni wọn n jẹ gaba ni ijọba rẹ.
Lati igba ti Aisha ti lọ fun iṣẹ Hajj ni Mecca ni iroyin sọ pe iyawo rẹ ko tii pada si orilẹde Naijiria.
Komla Dumor: Solomon Serwanjja jáwé olúborí nínú Àmì ẹ̀yẹ BBC
Solomon Serwanjja fẹ tẹsiwaju ninu ipasẹ rere ti Komla Dumor ti fi leelẹ nipa yiyi ọna iroyin ti awọn eeyan mọ nipa ilẹ Afirika pada.
Akọroyin ati oniroyin Solomon Serwanjja ti bori idije gbigba ami ẹyẹ BBC World News Komla Dumor Award ti ọdun 2019.
Akaroyin ni Sewanjja lori amohunmaworan NBS ni Uganda nibi to ti n ṣe atọkun awọn eto ile iṣẹ naa to pegede ju.
Bakan naa o ṣe agbejade awọn iroyin to gba ami ẹyẹ eyi ti ọkan lara rẹ han lori akanṣe eto Africa Eye ti ile iṣẹ BBC nipa bi wọn ṣe n ta oogun ti dokita ko kọ lọna aitọ.
Wọn ṣe agbekalẹ eto ami ẹyẹ naa lati maa yẹ Komla Dumor, akaroyin ile iṣẹ BBC kan to ṣaa deede ku lọdun 2014 lẹni ọdun mọkanlelogoji.
BBC ṣe'filọlẹ ami ẹyẹ Komlar Dumor
Serwanjja ni ẹni ikaarun ti yoo jawe olubori fun ami ẹyẹ naa lẹyin awọn wọnyi: Waihiga Mwaura, Amina Yuguda, Didi Akinyelure ati ọmọ Uganda mii bii tirẹ, Nancy Kacungira.
Lára àwọn mùdùǹmúdùn àmì ẹ̀yẹ náà, yóò lo oṣù mẹ́ta ní ilé iṣẹ́ BBC London yóò sì tún pada sí ilẹ̀ Áfíríkà láti gbé ìròyìǹ kan síta níbẹ̀.
Ilumọọka akọroyin ni ti iṣẹ iroyin si jẹ ẹ lọkan gidi gan an to n ṣafihan ifẹ to ni lati mu ayipada ba orilẹ-ede Uganda.
Ọ̀pọ̀lọpọ̀ ǹkan ni Komla Dumor ṣe. Ọna to n gba ṣe iṣẹ tirẹ a maa tu ni lọkan gẹgẹ bi o ṣe gbagbọ pe ilẹ Afirika ti n dagba to si fẹ ki gbogbo aye ri iyatọ.
"Serwanjja ṣalaye pe: ""Isọwọ karoyin Komla Dumor maa n ba mi lara mu to si maa n wu mi bakan naa lati ṣe bi o ti n ṣe fun ilẹ Afirika."
"Mo fẹ tẹle ipasẹ rere to fi silẹ nipa sisọ iroyin Afirika, kii ṣe lọna awọn nkan ti a n koju nikan ṣugbọn pẹlu awọn ilọsiwaju ati aṣeyọri ti a ti ni""."
Waihiga Mwaura ti Kenya gba àmì ẹ̀yẹ Komlar Dumor
Kii ṣe bi o ṣe n sọrọ ati bi o ṣe n karoyin nikan ni Serwanjja fi mu ọkan awọn adajọ, bi ko tun ṣe ifarajin rẹ ati igboya lati ṣi aṣọ loju ọrọ to ba kan araalu.
"Oludari ile iṣẹ BBC lagbaye, Jamie Angus ni: ""Lati mọ riri ati lati ṣe agbega fun awọn oniroyin to ni ẹbun ara ọtọ ni Afirika ṣe pataki si wa lorukọ Komla""."
Nkan ti awọn eeyan nsọ lori BBC Yoruba
"Jamie ni ""bi Komla ṣe maa n kọroyin ti ko ipa nla pẹlu awọn ololufẹ wa kaakiri agbaye inu wa si dun lati ni Solomon ni BBC lati fi iṣẹ kun ohun ti Komla ni ifarajin fun nipa sisọ itan Afirika""."
Iko BBC Yoruba tuntun
Samson Siasia: Orí ti kó ìyá Siasia yọ lọ́wọ́ àwọn ajínigbé lẹ́yìn oṣù méjì ààbọ̀
Oríṣun àwòrán, Facebook/Samson Siasia
Lẹyin bi oṣu meji ati aabọ, awọn ajinigbe ti fi iya akọnimọọgba ẹgbẹ agbabọọlu Naijiria tẹlẹ ri, Samson Siasia silẹ.
Ewerikumo Siasia to jẹ ẹbi Siasia lo fidi ọrọ yii mulẹ fun BBC wi pe iya agbabọọlu Naijiria nigba kan ri, Beauty Siasia kuro lakata awọn ajinigbe lalẹ ọjọ Abamẹta.
Bakan naa lo sọ fun BBC pe pe awọn ajinigbe ọun tun da awọn obinrin meji miiran silẹ yatọ si mọmọ Siasia.
Lọjọ kẹẹdogun oṣu keje ọdun 2019 lawọn ajinigbe gbe iya Siasia niluu Odoni to wa nijọba ibilẹ Sagbama nipinlẹ Bayelsa.
Alukoro fun ileeṣẹ ọlọpaa ipinlẹ Bayelsa, Butswat Asimin naa tun fidi rẹ mu lẹ pe iya Siasia ti gba ominira lọwọ awọn ajinigbe.
Baby Factory: Orí kó aboyún mọ́kàndínlógun yọ lọ́wọ́ àwọn akóni ṣòwò ẹrú
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Wọn a ma ta ọmọ ọ́kunrin ni ₦500,000 ti wọn si n ta ọmọ obinrin ni ₦300,000
Ọwọ palaba awọn akoni ṣowo ẹru kan ti ṣegi nigba tawọn ọlọpaa nipinlẹ Eko mu awọn afunrasi meji ati awọn alaboyun mọkandilogun kan nilu Eku.
Ninu atẹjade kan ti alukoro ọlọpaa nipinlẹ Eko DSP Bala Elkana fi sita, o ni ọwọ awọn agbofinro tẹ awọn aṣebi yi ni ile kan to wa ni adugbo Ikọtun nilu Eko.
Nibẹ ni wọn ti ri awọn alaboyun ti ọjọ ori wọn ko ju bi ọdun mẹẹdogun si mẹjidinlọgbọn lọ.
Koda o ni awọn tun ribi doola ẹmi awọn ọmọde mẹrin.
Gẹgẹ bi ohun ti o ṣalaye ninu atẹjade naa, wọn gbe awọn aboyun naa wa lati ipinlẹ Rivers, Cross River, Akwa Ibom, Anambra, Abia ati  Imo.
Ẹni to jẹ iya isalẹ awọn to n ko ni ṣowo ẹru naa,arabinrin Oluchi lati ilu Mbano nipinlẹ Imo  la gbọ pe o ti na papa bora.
Eredi kiko awọn oluyun yi si ibi ti wọn wa ni pe wọn yoo ta awọn ọmọ ti wọn ba bi ni iye owo ọkẹ mẹẹdogun si ọkẹ marundinlọgbọn.
Komisana ọlọpaa nipinlẹ Eko Zubairu Muazu ti ni ki wọn ti ile ti wọn ti ri awọn aboyun yi pa.
O ni ileeṣẹ ọlọpaa ati awọn ajọ miran n jijọ n pawọpọ lati mu awọn to n ṣagbatẹru owo buruku yi.
BBNaija: Elozonam ṣáájú, Ike tẹ̀lé kúrò nílé ẹlẹ́gbọ̀n àgbà
Oríṣun àwòrán, Instagram/Elozonam
Elozonam ati Ike ti darapọ mọ awọn to dagbere fun ile ẹlẹgbọn BBNaija.
Awọn ni olugbe akọkọ ti iji idagbere yoo gbe kuro lẹyin ti Tacha lọ lalaibojuwẹyin.
Ṣadede ni Ebuka to jẹ atọkun eto naa  wọle ẹlẹgbọn lọjọ  Aiku ti o si sọ fun awọn olugbe pe ẹgbọn ni ki oun jiṣẹ fun wọn pe idagbere ko ti dopin.
O ni ki awọn ti ẹsẹ wọn n mi jolojolo Elzonam,Mike ati Ike pe ki wọn dide duro-ababọ rẹ ni pe o ni ki Elzonam kẹru rẹ maa lọ.
Ki a to dijuka to la,Ike naa gba ikede idagbere ki oun naa ma kẹru rẹ l si ile.
Elozonam wa lara awọn olugbe ti Big Brother fi kun awọn olugbe ile ẹlẹgbọn ti ko si lara wọn tẹlẹ.
Nigeria at 59: Nàiajíríà ni olú ìlú àwọn tó tòṣì jùlọ làgbáyé - Atiku
Oríṣun àwòrán, @atiku
Atiku ni oun gbagbọ pe Naijiria yoo dara
Oludije sipo aarẹ labẹ asia ẹgbe PDP, Alhajai Atiku Abubakar ti ni, bi orilẹ-ede Naijiria ti n ṣe ajọyọ ọdun mọkandinlọgọta to gba ominira, nnkan le koko fun awọn ọmọ orilẹ-ede yii.
Atiku lo fi ọọ naa lede loju opo Twitter rẹ nigba to n sọrọ lori awọn kudiẹkudiẹ ti orilẹ-ede yii n dojukọ.
"O ni ""Nnkan ko rọgbọ bi orillẹ-ede yi ṣe jẹ olu ilu awọn to toṣi julọ lagbaye, bẹẹ naa ni ọpọlọpọ awọn ọmọde to yẹ ko wa ni ileewe n fẹsẹ gbalẹ kiri."""
"Atiku ṣalaye siwaju sii pe ""Awọn oniroyin ko lee sọrọ bo ti tọ ati boti yẹ lai bẹru pe awọn alagbara kan yoo fiya jẹwọn."""
Igbakeji aarẹ ana ọhun ni, bo tilẹ jẹ pe Naijiria n dojukjọ ọpọlọpọ iṣoro, ọla yoo dara fun orilẹ-ede yi.
Atiku wa gbadura fun Naijiria, lẹyin naa lo tun pe gbogbo ọmọ Naijiria lati gbagbọ pe Naijiria yoo dara.
Oríṣun àwòrán, Instagram/Osinbajo
Nigeria at 59: Osinbajọ ní Ọlọrun ti ṣèlérí Nàìjíríà tuntun, TUC ní Nàìjíríà ti kùnà
Naijiria yoo pe ọmọ ọdun mọkandinlọgọta ni ọla!
Ṣaaju ọjọ Iṣẹgun ti orilẹ-ede Naijiria yoo pe ọdun mọkandinlgọta to di ilẹ olominira, igbakeji Aarẹ, Ọjọgbọn Yemi Oṣinbajo ati Aarẹ ologun tẹlẹ ri, ajagun fẹyinti Yakubu Gowon ti sọ pe ireti si wa pe nnkan yoo ṣẹnu 're fun Naijiria.
Osinbajo ati Gowon sọrọ yii nibi ijọsin to waye lọjọ Aiku fun ayajọ ominira orilẹ-ede Naijiria niluu Abuja.
Igbakeji Aarẹ ṣalaye nibi isin naa pe Ọlọrun ti ṣetan lati mu orilẹ-ede Naijiria de ilẹ ileri.
Ọjọgbọn Oṣinbajọ ṣalaye siwaju sii pe Eleduwa lo n ṣakoso ohun gbogbo, Oun naa si lo n dari ayanmọ orilẹ-ede gbogbo atawọn eeyan to wa nibẹ.
Igbakeji aarẹ ni ''Eleduwa ti ṣetan lati fun wa ni Naijiria tuntun nibi tawọn ọmọ Naijiria yoo ti rọwọ họri, ati nibi ti iṣokan yoo ti wa laarin ẹlẹyamẹya gbogbo.''
Bakan naa nibi ijọsin ọhun, ajagun fẹyinti Gowon rawọ ẹbẹ sawọn ọmọ Naijiria lati yago fun iwa to le da wahala lorilẹede Naijiria.
Gowon ni oun gbagbọ pe Ọlọrun to ti n da Naijiria si lati igba ominira si wa sibẹ lati maa daabo boo, ṣugbọn awọn ọmọ Naijiria gbọdọ kun fun adura.
Ṣugbọn ọrọ ohun dabi ilu gangan an to jẹ pe ohun to kọju sẹnikan, ẹyin lo kọ sẹlominran.
Lẹyin ti ẹgbẹ oṣiṣẹ TUC sọ pe ipo ti Naijiria wa lawujọ awọn orilẹ-ede fihan pe Naijiria ti kuna lati dagbasoke lẹyin to ti gba ominira fọdun mejidinlọgọta.
Aarẹ ẹgbẹ TUC, Quadri Olaleye ṣalaye pe iwa ajẹbanu, awọn ologun to sọ ara wọn di oloṣelu, ija ẹlẹyemẹya ati ẹleṣinmẹsin wa lara awọn ohun to n gbogun ti idasoke Naijiria.
Awọn lọkan-o-jọkan naa lo ti n sọrọ pe ojọ iwaju Naijiria si maa dara lẹyin ọdun mọkandinlọgọta to ti gba ominira.
Ọjọ kinni, oṣu kewaa, ọdun 1960 ni orilẹ-ede gba ominira lọwọ ilẹ Gẹeṣi to koo lẹru.
Buhari Administration: Ó ti d'èèyàn mẹ́rin t'íjọba Buhari kò bọ́wọ́ fún iìdájọ́ wọn
Oríṣun àwòrán, Facebook/Omoyele Sowore
Yoruba bọ, wọn ni ẹni to buru mọ ṣugbọn o kan n duro de ẹni ti yoo sọ fun un ni, bẹẹ, kosi.
Bayii lọrọ ri pẹlu ẹgbẹ awọn agbẹjọro ni Naijiria, NBA to sọ pe ijọba Aarẹ Muhammadu Buhari ko bọwọ fun idajọ ileẹjọ, eleyi to lodi si ilana eto ijọba awaarawa.
Ajọ NBA fi aidunnu rẹ han si bi ijọba to wa lori aleefa ti kọ eti ikun sawọn idajọ ileẹjọ kan lorilẹ-ede Naijiria.
Alukoro ẹgbẹ awọn agbẹjọro ni Naijiria, Kunle Edun ijọba n lo ajọ ọtẹlẹmuyẹ lati tapa sofin idajọ ileẹjọ lorilẹede Naijirira.
Ibrahim El-Zakzaky:
Ibrahim El-Zakzaky jẹ olori ẹgbẹ musulumi Shiite lorilẹ-ede Naijiria, oun ati iyawo rẹ, Zeenat ni ijọba ju si atimọle ajọ DSS lati ọdun 2015 .
Ẹsun onikoko mẹjọ eleyi ti ipaniyan, kiko eeyan jọ lọna aitọ ati dida alaafia awujọ ru wa lara wọn.
Ajọ DSS kọ lati fun El-Zakzaky ati aya rẹ lominira lẹyin ti ileẹjọ giga l'Abuja paṣẹ pe ki wọn tu wọn silẹ lahamọ.
Sambo Dasuki:
Sambo Dasuki to jẹ oludamọran fun ijọba lori ọrọ aabo si wa latimọle ajọ DSS d'onii lẹyin ti ijọba apapọ kọ lati tẹle idajọ ileẹjọ to paṣẹ pe ki wọn gba beeli rẹ.
Ẹsun iṣowo to le ni biliọnu meji dọla ti ijọba ya sọtọ fun rira ohun elo ija ogun fun ileeṣẹ ologun Naijiria lasiko ijọba Aarẹ ana, Goodluck Jonathan kumọkumọ ati nini ohun elo ija ogun lọna aitọ.
Dasuki gbominira lọjọ kọkandinlọgbọn, oṣu kejila, ọdun 2015, ṣugbọn ajọ DSS mu pada, wọn si tun ju u satimọle.
Jones Dabiri:
Ọgbẹni Jones Dabiri to jẹ akọroyin ti wa latimọle lati ọjọ kọkanlelogun, oṣu keje, ọdun 2016 lẹyin ti ileẹjọ paṣẹ fun ajọ DSS lati fi i silẹ ati pe ki wọn sanwo kan fun un titinimọle lọna aitọ.
Ajọ DSS ko ti ẹ fawọn ẹbi, ọrẹ ati awọn dokita oniṣegun oyinbo lanfaani lati ṣabẹwo si i lahamọ.
Ẹsun igbesunmọmi ati iwa ọdaran lori ayelujara ni wọn kan an.
Omoyele Sowore
Ajọ DSS kọ lati fi ajijangbara ati akọroyin, Omoyele Sowore silẹ latimọle lẹyin ti ileẹjọ giga ijọba apapọ paṣẹ ominira rẹ.
Ẹsun wi pe o fẹ fipa doju ijọba aarẹ Buhari bo lẹ ni wọn fi kan Sowore.
Ọjọ kẹta, oṣu kẹjọ lawọn ajọ DSS mu Sowore eyi ti i ṣe ọjọ meji si ọjọ ti Sowore fẹ ṣe ifẹhonu han ti wọn ni #RevolutionNow lori bi nnkan ṣe n lọ lorilẹ-ede Naijiria.
Ẹwẹ, ajọ to n ja fẹtọ ọmọ niyan, SERAP rọ Aarẹ Buhari pe ko ṣatunṣe lori ibọwọ fun ofin nitori awọn ohun to jẹyọ ni bii ọdun mẹrin to kọja nipa ọrọ titẹle ofin kudiẹ kaato.
Ajọ SERAP sọ fun aarẹ Buhari pe iwa aibọwọ f'ofin tako eto igbogun ti iwa ibajẹ ati ajẹbanu ti ijọba Buhari gun le.
Bakan naa, ni ileeṣẹ BBC ede oyinbo fọwọ wa olori ẹka eto idajọ ni Naijiria, Abubakar Malami lori bi ijọba ti kọ eti ikun si bi Sowore si tun fi wa latimọle lẹyin ti ileẹjọ paṣẹ pe ki wọn fi silẹ.
Nigeria independence Day: Kíni àwọn ìpèníjà ẹtọ ààbò ṣáájú òmìnira Nàìjíríà?
Oríṣun àwòrán, @others
Ọmọ ogun 18,000 lo wa ni Naijiria ṣaaju ominira ọdun 1960
Eto aabo jẹ ọkan pàtaki lara iṣoro to n koju Naijiria lasiko yii.
Ola, ọjọ Iṣegun, ọjọ kinni, oṣu kẹwaa, ọdun 2019 ni orilẹ-ede Naijiria a pe ọmọ ọdun mọkandinlọgọta lẹyin ominira.
Lọdun 1960 ni Naijiria gba ominira kuro lọwọ ijọba amunisin ti ilẹ Gẹẹsi.
Titi di asiko yii ipenija eto aabo Naijiria ti n gbẹbọ lọwọ tolori tẹlẹmu.
Bẹrẹ lati ti awọn ajinigbe Ọpẹ́ o! Ìyá Siasia kúrò lákàtà àwọn ajínigbé lẹ́yìn oṣù méjì ààbọ̀, awọn alakatakiti ẹsin Islam Boko Haram, ISWAP ti ṣekú pa òṣìṣẹ́ ẹgbẹ́ aláànù Action Against Hunger  titi lọ si ti awọn agbesunmọmi loriṣiiriṣii laiyọ ti awọn fulani darandaran, atawọn adigun jale ti aye n pariwo lasiko yii.
Ogagunfẹyinti Sadiq Garba Shehu, to jẹ ọkan pataki lara awọn to mọ nipa eto aabo Naijiria ṣaaju ominira ba BBC sọrọ lori ipenija lasiko naa.
O ni awọn eniyan Naijiria ko to bayii rara lasiko ominira ati pe, ṣebi bi ori ba ṣe tobi to lo ṣe n fọ olori mọ.
O ni awọn ọlọpaa ati awọn ọmọ ogun ilẹ lo n ṣamojuto eto aabo Naijiria  ati awọn olori agbegbe kọọkan.
"Ogagunfẹyinti ni: ""Lasiko gbigba ominira Naijiria, awọn eeyan bẹru ijọba pupọ."
Wọn bẹru awọn alaṣẹ to n dari wọn fun idi eyi, iwa buruku ko pọ rara.
Ati pe, ifẹ awọn ara ilu wa lọkan koowa, ko sẹni to fẹ ṣe ẹnikeji rẹ nika pupọ.
"Ki a to ṣẹṣẹ sọ nipa agbara ofin ati ijiya to tọ si ẹṣẹ fun ẹnikeni perete to ba dẹṣẹ."""
Garba Sadiq ṣapejuwe asiko yii pe gbogbo ara ilu lo fẹsọ n gbe igbe aye alaafia ti awọn eniyan si ni itẹlọrun.
O ni ko sẹni to fẹ ki agbara ofin ba oun nitori tonile talejo lo bọwọ fun ofin Naijiria tuntun to ṣẹṣẹ gba ominira.
Ni iwoye rẹ, nkan bii ọdun to wa laarin 1970 si 1980 ni eto aabo Naijiria bẹrẹ si ni yipada.
O ni: bayii, eto ọrọ aje Naijiria ti mẹhẹ ni eyi to n ṣakoba fun eto aabo pupọ.
Kunle Afolayan: èmi kò fẹ́ fi ogún sílẹ̀ fún ọmọ mi
Sadiq Garba ni ifẹ lati di ọlọrọ ojiji ati olowo laiṣiṣẹẹ naa tun n ṣakoba fun eto aabo Naijiria lasiko yii.
Ogagunfẹyinti yii ni ojutu si iṣoro to n koju Naijiria lasiko yii ni ki ijọba tun eto ọrọ aje ṣe.
Ati pe ki ijọba fi aja iwoyi maa ṣọ ehoro iwoyi ki awọn ọdọ gbajumọ iṣẹ aje ti ko ni iwa buruku ninu.
Yollywood: Nkan tó pa Ojo pagogo àti Kunle Afolayan pọ̀
Oríṣun àwòrán, @others
ẹni ti yoo pẹgan ajanaku laa ni mo ri nkan firi
Oni, ọgbọn ọjọ, oṣu kẹsan an ọdun 1974 ni ọjọ ibi Kunle Afolayan.
Kunle Afolayan jẹ ọmọ bibi ilu Igbomina ni ipinlẹ Kwara ni aarin gbungbun Naijiria.
O jẹ ọkan lara ọmọ gbajugbaja agba oṣere ni: Ade Love.
Oríṣun àwòrán, @others
Iṣẹ ori ran mi ni mo n ṣe
Adeyemi Josiah Afolayan to jẹ baba Kunle Afolayan bio awọn ọmọ ti wọn yan iṣẹ rẹ laayo ni eyi ti Kunle ti lamilaaka lasiko yii.
O kawe gboye lori imọ ọrọ aje nile iwe giga ni eyi to fi ṣiṣẹ diẹ ni banki ki o to darapọ mọ ere ori itage ṣiṣe ni pẹrẹu ti o si ni imọ lori bi a ṣe n fiimu.
New York Film Academy ni Kunle ti lọ kọ sii nipa fiimu ṣiṣe.
Kunle Afolayan: èmi kò fẹ́ fi ogún sílẹ̀ fún ọmọ mi
Lati bii ọdun 2005 ni Kunle Afolayan ti bẹrẹ si ni ṣe ere ṣiṣe ti o si ti ṣe ọpọlọpọ ere ti wọn ti gba ami ẹyẹ ti ko lounka.
Ninu awọn ere ti o sọ ọ di ilu mọọka ni ni ere The Figurine: Araromire, ti ede Yoruba ati Phone Swap ni ede gẹẹsi ti Wale Ojo, Joke Silva naa kopa nibẹ.
Lara awọn ẹbi rẹ ti wọn jọ n ṣe iṣẹ oṣere tiata ni Moji Afolayan, Lola Idijẹ, Ẹ wo ohun tó yẹ kí ẹ mọ̀ nípa gbajúgbajà òṣèré tíátà Yoruba Tóyìn Afọlayan atawọn mii.
Yollywood: Kò sí ẹni ti òbí mi kò lè sọ̀rọ̀ sí -Sisi Quadri
Kunle Afolayan fẹ iyawo rẹ ti a mọ si Tolu ti wọn si bi ọmọ mẹrin.
Kunle Afolayan ṣlaaye fun BBC Yoruba pe oun ko ni ẹsin kankan ṣugbọn oun gbagbọ ninu iwa ọmọluwabi.
Oko ayọkẹle ara ọtọ ti wọn n pe ni Thunder bird 1965 lo fi n ṣe ẹsẹ rin ni titi.
October 1 jẹ ọkan lara awọn sinima Afolayan ti gbogbo aye tẹwọ gba.
Oríṣun àwòrán, facebook page
Ojopagogo ati Kunle Afolayan
A bi Rasak Olayiwola ni ọgbọn ọjọ, oṣu kẹsan an ọdun ni ilu Isẹyin nipinlẹ Oyo ni iwọ oorun guusu Naijiria.
Razaq Olayiwola Olasunkanmi ti gbogbo eniyan mọ si Ojopagogo, ti o jẹ odu ri kii ṣe aimọ oloko lagbo tiata ni ilẹ Yoruba.
Orukọ iya rẹ n jẹ Munirat Omowanwa Abẹkẹ sugbọn ti o ti di oloogbe bayi.
Oṣere yii lọ ile iwe Alakọbẹrẹ A.U.D Ebedi, Isẹyin. ati ile iwe girama ti Anwar-U Islam High School, Iseyin ati Ile iwe gbogboniṣe ti ipinlẹ Oyo ni ilu Ibadan
Ni ile iwe yii ni o ti kẹkọọ ijinlẹ gboye nipa orin kikọ.
Ojopagogo fidiẹ mulẹ pe oun ti n ṣe ere tiata ṣaaju ki oun to bẹrẹ ile iwe lilọ ni Ibadan.
O bẹrẹ ere tiata ni ọdun 1983 nigba ti aṣeyẹ kan waye ni Maulud ti eni ti o jẹ ọrẹ ẹgbọn rẹ, Jẹlili Raji fi si inu ere nigba naa.
Ọrẹ ẹgbọn rẹ yii ni Fakewu Baale Larinka to pe e si ere ti a mọ si Egbinrin Ọtẹ.
Yollywood:Ṣàgbẹ̀lójú yòyò ni ọ̀ps àwọn òṣèré- Ojopagogo
Ojo pagogo ti ni to ere mejidinlogun ti o ti ti ọwọ rẹ jade lati bii ọdun 1997 si ọdun 2013.
Moji Afolayan ni Olayiwola Razak gbe sile gẹgẹ bi iyawo.
Razak Olayiwola fi ilu Ibadan ṣe ibujoko si.
Ere ori itage Ola Abata ti wọn ṣe lọdun 1986 lo sọ Razak Olayiwola ni oruko tuntun: Ojo pa agogo.
Awọn ẹgbẹ oṣere Labakẹ Theatre group lo ṣe ere naa ni eyi ti alaafin Ikubaba yeye naa wa wo nigba naa.
Ojopagogo tun maa n kọrin yatọ si ere itage ṣiṣẹ.
Loṣu kẹta, ọdun 2015 lo gbe awo orin Isẹyin ati Olaniyonu jade yatọ si kikọ orin ninu awo sinima.
Oni ni ayẹyẹ ajọdun orikadun awọn agba ọjẹ oṣere mejeeji yii: Razak Olayiwola ati Kunle Afolayan.
Indonesian Youths: Òfin tó de ìbálòpọ ṣáájú ìgbéyàwó kò lè fẹsẹ múlẹ
Oríṣun àwòrán, VON
Awon Odo Ile Indonisia
Gbogbo awọn ọmọ ilẹ Indonesia ni wọn tu jade lọpọ yanturu lati fẹhonu han tako ofin ibalopọ ni ilẹ naa.
Awọn ara ilu naa ni ki alaṣẹ ilẹ naa maṣe mu erongba wọn ṣẹ pe ko maṣe si ibalopọ ṣaaju igbeyawo.
Nibi ifẹhonu han yii ni awọn Ọlọpaa ti yin tajutaju si wọn ti onikaluku si tuka ni iwaju ile Igbimọ Aṣofin ilẹ naa.
Ifẹhonu han yii tun ṣẹlẹ ni ọpọlọpọ awọn ilu miran yika orilẹ ede ọhun.
Abadofin naa ni yoo dẹkun oyun ṣiṣẹ ati ibara ẹni lopọ laini ikora ẹni ni ijanu.
Lara awón ohun ti o wa ninu abadofin naa ni wi pe;
Ẹwọn ọdun kan pere ni ibaṣepọ ṣaaju igbeyawo
Gbigbe papọ akọ ati abo lai ti i ṣe igbeyawo yoo gbe ẹwọn oṣu mẹfa pọn.
Sisọ ọrọ alufanṣa si Aarẹ, Igbakeji Aarẹ, ẹsin, ile iṣẹ ijọba ati titapa si asia ati orin orilẹ-ede yoo di ẹṣẹ.
Oyun ṣiṣẹ yoo ni ijiya ẹwọn ọdun mẹrin lori lai ki n ṣe pe o ni i ṣe pẹlu ilera obinrin naa.
Abadofin yii ni o yẹ ko wọ ile aṣẹ lọ ni ọjọ Iṣẹgun sugbọn ti Aare ilẹ naa, Joko Widodo sun un si ọjọbọ ọsẹ yii.
Oríṣun àwòrán, VON
Awon Odo n fehonuhan
Idi ifẹhonuhan naa waye ni awọn olu ilu kaakiri Indonesia bẹrẹ lati Jakarta, Yogyakarta ati Makassar ni erekuṣu Sulawesi ni eyi ti ẹru n ba awọn eniyan pe o ṣeeṣe ki ijọba sọ abadofin naa di ofin.
Awọn eniyan woye pe yoo pakun eto ọrọ aje ilẹ naa to da gẹgẹ.
Wọn tun n binu lori ọna gbigba ofin tuntun wọle laiṣe lodi si iwa jẹgudu jẹra.
Pupọ lara awọn ti o jẹ olufẹhonuhan naa ni akẹkọọ ti wọn jade lọpọ yanturu si gbogbo ilu orilẹ-ede naa.
Gbagede ibi ifẹhonu han ni Olu Ilu ilẹ naa, Jakarta nibi ti wọn ti n bere lati ri Olori awọn Aṣofin, Bambang Soesatyo.
Awọn olufẹhonu han yii ni wọn n ju okuta si awọn Ọlọpaa ti Ọlọpaa naa n yin tajutaju si wọn.
Ọkan lara patako ifehonu han kan ti obinrin kan gbe dani sọ pe, ẹya ara mi kii ṣe ti Ijọba.
Ko din ni ẹgbẹrun marun un awọn Ọlọpaa ti wọn wa ni bi ifẹhonu han naa.
Ọwó ọlọpàá tẹ adigunjalè márun un àti babaláwo tó ń ṣògùn fún wọn ni Imo
Oríṣun àwòrán, Facebook
Ojubọ Babalawo
Ọwọ ajọ ọlọpaa ti tẹ babalawo kan ati awọn adigunjale marun ni Ipinlẹ Imo.
Meji ninu awọn afunrasi naa ni wọn fara kaṣa ọta ibọn awọn Ọlọpaa, ti wọn si farapa ki ọwọ to ba wọn.
Nigba ti ajọ ọlọpaa n fi oju awọn ọdaran naa lede, Kọmiṣọna fun awọn Olọpaa ipinlẹ ọhun, Rabiu Ladodo ṣe afihan orukọ awọn ọdaran bii.
Ikenna Eze ti wọn mọ si Fela, ẹni ọdun mẹtalelogun, Harrison Okorafor ti wọn tun pe ni Doctor, ọmọ ọdun mọkanlelogun, Eze Emeka, ọmọ ọdun mẹtalelọgbọn, ati awọn miran.
Ladodo sọ pe, Ogubuike to jẹ Ogboju Ọlọṣa to ti n yọ awọn eniyan agbegbe gbungbun ati Ariwa Ideato lẹnu ni ọwọ tun tẹ.
O tẹsiwaju pe, ọjọ kẹrin Oṣu kẹsan Ọdun yii ni ọwọ palamba rẹ segi, ni dede agogo meji ọsan, ni agbegbe Rock View ti Ọga Ọlọpaa Banjoko Wẹmimọ n dari.
Oríṣun àwòrán, others
Ladodo ni, ogboju Ole naa jẹwọ ẹsun idigunjale ti wọn fi kan.
Ṣe ni ọjọ kọkanla ọsu kẹsan ọdun yi ni afurasi naa ti mu awọn Olọpaa lọ si ibi ikọkọ ti awọn ọdaran akẹgbẹ rẹ to ku wa, ni ibi ti olori awọn ọdaran naa, Ikenna Eze ati Chukwu Ezeala fi ara pamọ si.
Oga Ọlọpaa ṣalaye pe, ni ṣe ni awọn ọdaran naa n rọ ojo ibọn lemọlemọ pẹlu ọlọpaa, ti Chukwudi Ezeala ati Ikenna Eze si fara pa.
Lẹyin eyi ni ọwọ tẹ babalawo kan ti orukọ rẹ n jẹ Eze Emeka ni Enugu.
Awọn Ọlọpaa wi pe oriṣiriṣi nkan ija oloro ni wọn ba nibi ojubọ babalawo yi, to si jẹwọ pe lootọ ni ohun n ṣe iṣẹ laabi.
Olojo festival: Fídíò bí èrò ṣe darapọ̀ mọ́ Ọọ̀ni láti ṣọdún Ọlọ́jọ́ nílé Ifẹ̀ nìyí
Oyo state: 615, nọ́mbà tuntun fún ìdáàbòbò àwọn èèyàn ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ̀
Oríṣun àwòrán, @seyiamakinde
Bi ẹ ba n gbọ ariwo Ẹfa, ookan, aarun, 615 ni ipinlẹ Ọyọ, kii ṣe nọmba tẹtẹ tita tabi ti baba ijẹbu o.
Ẹ o pe ki wa ni?
Ẹfa, ookan, aarun, 615 ni nọmba tuntun ti ijọba ipinlẹ Ọyọ nipasẹ ajọṣepọ pẹlu ajọ ibaraẹnisọrọ, NCC gbe kalẹ fun araalu lati maa pe lai ni kete ti wọn ba kọlu ipenija abo ninu irinajo wọn.
Intersextuality: Dokita ni ká mu èyì tó wù wá nínú jíjẹ́ akọ tàbí abo
Gomina ipinlẹ Ọyọ, Ṣeyi Makinde ṣalaye pe nọmba naa ni nọmba fun idaabobo araalu ti wọn yoo ma lo nibẹ.
Nigba to n sọ bi nọmba naa yoo ṣe maa ṣiṣẹ, Gomina Seyi Makinde ni awọn olugbe ipinlẹ Ọyọ to ba n dojukọ ipenija aabo bi idigunjale, rogbodiyan, ijamba ina jijo, tabi awọn ijamba miran lee pe fun iranwọ ajọ gbogbo to ba yẹ ni kiakia.
Gẹgẹ bi o ṣe ṣalaye, lasiko ti awọn aṣoju ileeṣẹ ibaraẹnisọrọ NCC wa ṣe abẹwo si oun ni ọfiisi gomina to wa ni Agodi nilu Ibadan loṣu Kẹjọ ọdun 2019 ni wọn jiroro lori agbekalẹ nọmba naa.
Premier league: VAR gba ẹ̀tọ́ Aubameyan fún un ní Old Trafford, ọ̀mì ni Manchester United, Arsenal ta
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Agbababọọlu Manchester united, Scott McTominay lo kọkọ gba goolu wọle nigba ti ifẹsẹwọnsẹ naa wọ iṣẹju karundinlaadọta 45'ki wọn to lọ iṣinmi aarin ifẹsẹwọnsẹ naa. Ariwo ayọ nla lo sọ lẹnu awọn ololufẹ Manchester United.
Ko pẹ ti wọn wọle fun abala keji ni Arsenal da ẹyọ kan naa pada nigba ti Bukayọ Saka gba bọọlu fun Aubameyang lati gba sinu awọn ni ariwo ba ta tun sọ geee.
Lati ọpọ ọdun sẹyin ni ija orogun ti wa laarin Manchester United ati Arsenal; tobẹẹ gẹẹ to fi jẹ wi pe nigba kugba ti awọn  ẹgbẹ agbabọọẹu mejeeji yii ba ti koju ara wọn  ni lala maa n lu.
Itakangbọn laarin olukọni ẹgbẹ agbabọọlu mejeeji tẹẹẹ, iyẹn Alex Ferguson ati Arsene Wenger tun mu ki ifẹsẹwọnsẹ laarin awọn mejeeji yii o maa legba kan jọrin lọ.
Ifẹsẹwọnsẹ to waye laarin Manchester United ati Arsenal yii ni igba...ti awọn mejeeji yii yoo ma koju ara wọn ni idje Premier League.
ṣaaju ifẹsẹwọnsẹ yii, ipo kẹrinla ni Manchester United wa lori atẹ igbelewọn Premier league.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ipo kẹjs si ni Arsenal wa lori atẹ naa.
ṣaaju ifẹsẹwọnsẹ yii, ifẹsẹwọnsẹ kan ṣoṣo ni manchester United ṣi bori ninu mẹfa ti wọn ti gba ṣaaju ni saa yii.
Bakan naa ni Arsenal ko tii bori ifẹsẹwọnsẹ kankan ni papa iṣire Old Trafford to jẹ ibuba ẹgbẹ agbabọọlu Manchester United.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Nigba to n ba awọn oniroyin sọrọ ṣaaju ifẹsẹwọnsẹ naa, olukọni ikọ Arsenal, Unai Emery ni erongba ti awọn gbe wa si Old Trafford ni lati bori. O ni awọn si ti gbaradi niwaju ati ni ẹyin lati mu erongba yii wa si imuṣẹ.
Gbajugbaja agbabọọlu Manchester United ni, Paul Pogba ati marcus Rashford bẹrẹ ifẹsẹwọnsẹ naa lẹyin ti wọn gbọnra nu kuro ninu bi wọn ṣe fara ṣeṣe.
Awọn ikọ mejeeji lo jẹwọ ọmọọkọ ni ibẹrẹ ifẹsẹwọnsẹ naa.
BBNaija: Diane ń domi lójú bí ẹni ọ̀fọ̀ ṣẹ̀ nígbà tí ilé ẹlẹ́gbọ́n àgbà taare ìpàkọ́ rẹ̀ sílé
Oríṣun àwòrán, @BBNaija
Awọn ololufẹ rẹ ti n fi eroungba wọn lede bayii lori ẹrọ ayelujara
Wọn ti yọ Diane kuro ninu idije ẹlẹgbọn agba Big Brother to n lọ lọwọ.
Wọn sọ fun Diane pe ko kẹru rẹ kuro ni ile ẹlẹgbọn naa lẹyin ti Frod mu owo kan ti orukọ rẹ wa lara rẹ.
Ni ṣe ni Diane n domi loju bi ẹni ọfọ ṣe lẹyin ti wọn le kuro ninu ile ẹlẹgbọn agba naa, ti Omashola si n fo fayọ nigba ti ori ko yọ.
Ṣaaju ni Big Brother ti kede loju opo Twitter rẹ pe ẹnikan yoo pada sile lalẹ oni laarin Diane ati Omashola.
Lẹyin ti wọn ti ni ki Diane pada sile bayi ni awọn ololufẹ rẹ ti n fi eroungba wọn han lori ẹrọ ayelujara.
Bẹẹ ni awọn miran si ki Omashola ku ori ire pe o si wa nini ile ẹlẹgbọn naa.
Intersextuality: Dokita ni ká mu èyì tó wù wá nínú jíjẹ́ akọ tàbí abo
Moroccan Journalist: Hajar Raissouni de èrò ẹwọn lórí ẹ̀sùn àgbèrè àti oyún ṣíṣẹ́
Oríṣun àwòrán, Reuters
Awọn ajafẹtọ pẹlu aworan Hajar Raissouni nibi iwọde kan ti wọn ṣe losu to kọja
Akọroyin ọmọ orile-ede Morocco kan ti fẹwọn ọdun kan gbara lori ẹsun pe o ni ibalopo ṣaaju ki o to lọkọ ati pe o ṣẹyun.
Awọn ajafẹtọẹni ni ẹjọ rẹ ti tan imọlẹ si ilakaka ijọba lati dẹgun le awọn akọroyin to n bẹnu atẹ lu u Wọ́n gbé Akọ̀ròyìn ní Morocco lọ sílé ẹjọ́ lórí ẹ̀sùn àgbèrè àti oyún ṣíṣẹ́.
Niṣe ni awọn agbofinro mu Hajar Raissouni ati afẹsọna rẹ nigba ti wọn jade lati ile iwosan awọn alaboyun kan ni ilu Rabat loṣu Kẹjọ.
Ọmọ ọdun mejidinlọgbọn naa tako ẹsun ti wọn fi kan an, ti o si ṣalaye pe niṣe ni oun gba itọju fun bi ẹjẹ ti ṣe n ya lara oun.
Arabinrin Raissouni n ba ile iṣẹ iroyin aladani kan ṣiṣẹ eleyi ti o saaba ma n bẹnu ẹtẹ lu awọn alaṣẹ.
O ni ijọba n dun kooko mọ oun ni ati pe wọn ti ṣaaju bere nipa iṣẹ ati mọlẹbi oun ki wọn to gbe oun.
Iboju dudu ni Hajar Raissouni  wọ wa si ile ẹjọ ni Rabat, to jẹ olu ilu Morocco. Oun ati afẹsọna rẹ ti o jẹ ọmọ orile-ede Sudan sọ pe awọn ko ṣẹyun.
Agbẹjọro rẹ Abdelmoula El Marouri sọ pe:  ''iyalẹnu ni idajọ yi jẹ fun wa'' ti o si sọ pe niṣe lo yẹ ki wọn tu u silẹ pẹlu gbogbo ẹri ti awọn gbe wa siwaju ile ẹjọ.
O ni awọn yoo tako idajọ naa.
Hajar ni akọroyin to n ṣiṣẹ pẹlu ileeṣẹ iwe iroyin Akhbar Al-Yaoum.
Agbẹjọro ijọba ni bi wọn ti ṣe mu akọroyin naa ko ni ohun kankan ṣe pẹlu pe o jakọroyin ati pe ile iwosan aboyun to lọ lawọn agbofinro ti n ṣọ ọ tẹlẹ nitori pe wọn fura si pe awọn eeyan n ṣe oyun nibẹ lọna to tako ofin.
Ile ẹjọ dajọ ẹwọn ọdun kan fun afẹsọna rẹ ti dokita to wa nile iwosan naa si fẹwọn ọdun meji jura.
Awọn to n ba dokita naa ṣiṣẹ ati nọọsi to wa nibẹ naa ko lọ lai jiya.
Ahmẹd Benchemsi, oludari ajọ to n ja fẹtọ ọmọniyan lagbegbe naa ṣapejuwe idajọ yi gẹgẹ bi ''ọjọ buruku'' forile-ede Morocco.
Nigeria Independence Day: Sé ẹ mọ̀ pé ọdún 1956 ló yẹ́ ká ti dòmìnira ṣùgbọ́n....
Libya Returnees: Àtìpó 161 míì dari dé padà láti Libya layajọ́ ominira Naijiria
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ó lé l'ẹ́gbẹ̀rún mẹ́jọ àwọn ọmọ orílẹ̀èdè Nàíjíríà tí wọ́n ti kó padà dé láti orílẹ̀èdè Libya
Awọn atipo mọkanlelọgọjọ miran tun ti dari de si orile-ede Naijiria lati orile-ede Libya.
Lowurọ kutu ọjọ Iṣegun to ṣe rẹgi pẹlu ayajọ ominira Naijiria ni wọn gunlẹ si papakọ ofurufu ipinlẹ Eko.
Gẹgẹ bi ọgbẹni Ibrahim Farinloye to jẹ agbẹnusọ ajọ to n risi iṣẹlẹ pajawiri ni Naijiria, NEMA lẹka iwọ oorun Guusu Naijiria ti ṣe sọ fun BBC .
O fidiẹ mulẹ pe nkan bi aago mẹfa ku iṣẹju mẹẹdọgbọn ni wọn de nidaji aarọ yii.
O ṣalaye pe ''obinrin mẹ́rìndínlọ́gọ́ta (56) ọkunrin mẹ́tàléláàdọ́rùn ún (93) ati awọn ọmọdekunrin mejila (12) lo wa lara awọn to de naa''
Ninu ọrọ oludari ajọ NEMA nipinlẹ Eko, Idris Muhammed, lo ti ni ajọṣepo laarin NEMA, ajọ awọn arinrinajo lagbaye IOM ati ajọ EU lo mu ki ipadawasile awọ́n atipo yii rọrun.
Mohammed ni awọn ọkunrin mẹta to ni ipenija ilera lawọn ti ko lọ si ile iwosan ni kete ti wọn balẹ.
Lẹnu lọọlọ yi, ijọba Naijiria ti n gbe awọn ọmọ ilẹ naa ti wọn ṣatipo lọ si ilẹ Libya pada wa sile.
Pupọ ninu wọn ni o n kabamọ lilọ si ilẹ naa nibi ti iroyin ti ni awọn kan ti n lo wọn nilo ẹru.
Nigeria Independence Day: Sé ẹ mọ̀ pé ọdún 1956 ló yẹ́ ká ti dòmìnira ṣùgbọ́n....
Social Media Slay: Onílé kan bínú fi àwòrán iyàrá ayálágbé ré hàn lórí ayélujéra
Oríṣun àwòrán, @The Paper
Awọn ololufẹ Weibo lanu silẹ lori bi iyara Lisa Li ṣe ri bii...
Yoruba bọ wọn ni afẹfẹ fẹ, a ri furọ adiyẹ ohun lo difa fun arẹwa Lisa Li, to jẹ obinrin kan pataki lori ayelujara lorilẹ ede China sugbọn to jẹ ọbun.
Iya onile rẹ, Madam Chen lo ṣafihan aworan bi iyara ogbontarigi sọrọsọrọ lori ayelujara naa.
O ke gbajare pe ki awọn obinrin maa daa ninu ile naa bi wọn ṣe n daa lorii ẹrọ ayelujara.
Opo eeyan lo ti n pin fidio ti iya onile Lisa Li fi sita lati ṣafihan iwa ọbun rẹ lori ayelujara pe ki awọn ọdọ iwoyi yee ṣoge lasan ṣugbọn  ki wọn fi imọtoto kun iwa wọn.
Lisa Li jẹ ọkan lara awọn to ni ẹka iroyin blog ti ara rẹ lori ayelujara to dẹ ni awọn to le ni
Idakeji bi o ṣẹ n ṣe loju opo ẹrọ ayelujara ni arẹwa ọmọ obinrin naa gẹgẹ bi fidio ti iya onile rẹ fihan sita ṣe ri.
Oríṣun àwòrán, @Pear video
Iya Onile Lisa Li lo gbe fidio to ṣafihan igbe aye ọbun ti Gbajugbaja Lisa Li n gbe hande ni China
Koda, aworan naa ṣafihan igbe ẹran ọsin rẹ ninu iyara rẹ laisọ awọn ohun ẹgbin miran.
O le ni miliọnu eniyan ti wọn ti fesi si ọrọ naa lati igba ti aṣiri rẹ tu pe ọbun paraku ni lati ọwọ iya onile rẹ, Madam Chen,
Oju opo arẹwa Lisa kun fun awọn aworan to rẹwa to le mu ki ẹlomii firu rẹ tọrọ pe ọjọ wo loun naa a ni owo to to bayii.
Opo aworan rẹ lo ṣafihan Lisa lasiko to n rirnrin ajo kaakiri agbaye, nibi to ti n jẹun ni awọn ile olounjẹ to lorukọ lagbaye ati ni awọn ibi inawo eeyan jankan jankan ni awujọ.
Oríṣun àwòrán, @Pear video
Ileegbe Arewa kan
Iya onile Lisa ni oun mọọmọ gbe fidio naa sita ni ki Lisa le yipada lẹyin ọpọlọpọ igba ti oun ti kilọ iwa ibajẹ yii fun un ni kọrọ ati ni gbangba.
O ni oun fẹ ki Lisa kọ ẹkọ imọtoto ki awọn ololufẹ rẹ to le ni miliọnu kan lori Instagram naa le mọ pe iyatọ wa ninu igbe aye ori Instagram ati igbe aye ẹni loju aye.
Koda, Iya Onile naa ni oun ti fi ọrọ Lisa to ọlọpaa leti tẹlẹ nitori ko tun tete san awọn owo ina tai awọn to n tun ile ṣe.
Intersextuality: Dokita ni ká mu èyì tó wù wá nínú jíjẹ́ akọ tàbí abo
Yara naa dọti de ibi pe awọn agbalẹ kọ ti wọn si fariga lati toju yara naa.
Ṣugbọn lati igba ti ọrọ naa ti wa lori ẹrọ ayelujara ni ọmọbinrin naa ti n bẹbẹ lati yi pada.
Lisa Li jẹ olokiki ni orilẹ ede China lori ẹrọ ayelujara bii iṣana ẹlẹta, ti aworan rẹ si rẹwa lọpọlọpọ.
Oríṣun àwòrán, @Pearl video
Lisa trọ aforijin lọwọ iya Onile rẹ lẹyin ti fidio lu jade tan
Ṣugbọn lati igba ti akara rẹ ti tu sepo lo ti yipada ti o si ti fihan gbogbo eniyan ni ojule ti o wa ni ariwa Xi'an ti o si ti di ilumọọka.
Nigba ti o to asiko kan, o tọrọ aforiji lọwọ iya onile rẹ ti o ṣalaye pe iṣẹ lo faa ti iru iṣẹlẹ bẹẹ ṣe waye pe atunṣe yoo wa.
Pupọ lara awọn ololufẹ rẹ lori ẹrọ ayelujara  ti ko din nim ọgọta ẹgbẹrun lo kọ iwe ranṣẹ si lati dẹyin lẹyin rẹ ṣaaju akoko ti o fi tọrọ aforiji naa.
Eyi kii ṣe igba akọkọ ni ilẹ China ti iru rẹ yoo waye, iru rẹ waye ni Osu keje nipa ọmọ obinrin kan laimọ pe arugbo ni.
Lisa ṣalaye fun onile rẹ pe oun ti gbọ ẹkọ ti o fẹ kọ oun nitori oun ko mọ pe ile oun dọti to bẹẹ ati pe iṣẹ lo gbomi mu fun oun ti oun ko si ri aaye tun ile ṣe.
Ninu atẹjade kan ti Lisa fun ile iṣẹ iwe iroyin: The Paper lo ti tọrọ aforijin to ṣalaye pe ọpọ atẹjiṣẹ ni oun ti ri gba lati ọdọ awọn ololufẹ rẹ.
Oríṣun àwòrán, @pear video
Lisa bẹrẹ atunṣe si iyara rẹ lẹyin o rẹyin
Ni kete ti Lisa pada sile lẹyin ti ọpọlọpọ miliọnu eeyan ti sọrọ lori ayelujara ni Lisa Li ti bẹrẹ si ni tun iyara rẹ ṣe.
Ọpọ awọn ololufẹ Lisa lori ayelujara ni wọn kọkọ fi ṣe yẹyẹ nigba ti fidio kan jade to ṣafihan Lisa to n ko igbẹ aja rẹ ninu iyara rẹ.
Igbesẹ ayipada rẹ yii pada ya pupọ ninu awọn ololufẹ rẹ lẹnu ti awọn miran bẹrẹ si ni kan saara si Lisa.
Fidio naa ni imọran to le ni ẹgbẹrun lọna ọgọta laarin wakati melo to fi sita.
Awọn miran si ni awọn ko ni tẹle e mọ nitori pe o n gbe igbe aye féèkì ti ko ki n ṣe ootọ.
Oríṣun àwòrán, The paper
Fidio naa ni imọran to le ni ẹgbẹrun lọna ọgọta laarin wakati melo to fi sita.
Awọn miran ni igbesẹ to fi yọ kuro ninu awọn nkan to ti gbe sori ayelujara tẹlẹ naa ku diẹ kaato.
Awọn ololufẹ Lisa mii ni ko ni ootọ ati pe o ti ṣi awọn ọdọ miran lẹsẹ pe igbe aye ori ayelujara lo dara.
Kii ṣe igba akọkọ ti iru nkan bayii maa ṣẹlẹ ni orilẹ-ede China ni yii.
China - Rògbòdìyàn bẹ sílẹ lọjọ òmìnira àádọ́rin ọdún ilẹ China
China - Rògbòdìyàn bẹ sílẹ lọjọ òmìnira àádọ́rin ọdún ilẹ China
Loni, ọjọ kinni, oṣu kẹwaa, ọdun 2019 naa ni orilẹ-ede China n sami ayajọ ominira aadọrin ọdun lẹyin ominira.
Orilẹ-ede Naijiria naa n sami ayẹyẹ ominira ọdun mọkandinlọgọta.
Ojo kinni, oṣu kẹwaa, ọdun 1949 ni Mao-Zedong ti ọpọ mọ si Chairman Mao kede ominira orilẹ-ede China tuntun.
Ifẹhonuhan ti suyọ loni ni ilẹ China to jẹ ayajọ ọjọ ominira ilẹ naa ni eyi ti pupọ ninu awọn ọmọ ilẹ naa ti tu jade lati féhonuhan ti o si jasi wahala.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
China - Rògbòdìyàn bẹ sílẹ lọjọ òmìnira àádọ́rin ọdún ilẹ China
Iroyin fi ye wa pe, ọta ibọn ba ọkan lara awọn akọroyin to wa nibi ifẹhonu han naa.
Akọroyin naa ni o ṣeṣe nibi egbe oju rẹ ti awọn oludoola ẹmi si yara si i ki wọn to gbee lọ si ile iwosan.
Ṣaaju ni obinrin akọroyin naa ti sọ wi pe ọlọpaa kan ti kọkọ kọ oju ibọn si oun ni agọ wọn.
O ni ibọn yii lo kọ si oun ni ọna abajade si popona ila Oorun Ọmọbabinrin ilẹ naa.
Awọn ọlọpaa ati ologun ni wọn kun oju popo ti wọn si n ṣe afihan ohun ija tuntun ti ijọba ilẹ naa ṣẹṣẹ ra.
Nigeria Independence Day: Sé ẹ mọ̀ pé ọdún 1956 ló yẹ́ ká ti dòmìnira ṣùgbọ́n....
O ti di ọsẹ kẹtala bayii ti nkan ko tii fararọ ni orilẹ-ede China bayii. Boolọ o yago ni ọrọ di nigba ti ọta ibọn ati tajutaju n dun lakọ labo.
Awọn olufẹhonu han
Bayii, gbogbo oju popo lo ti pa lọlọ ti ko si si igboke gbodo ọkọ bii igba ti ilẹ ṣẹṣẹ mọ.
Awọn oluworan ni wọn n wo ọgọọrọ awọn ọlọpaa ninu aṣọ dudu ati alawọ ewe ti wọn wọ.
Pẹlu bi gbogbo oju ọjọ ṣe ri ni ilẹ naa, ọpọ awọn olutaja ọti ni wọn ṣi ṣọọbu wọn kalẹ ti wọn n reti onibara.
Ileeṣẹ ọlọpaa China ni ifẹhonuhan ti n bi ige ati adubi ni eyi ti awọn agbofinro fi ni lati gbe igbesẹ to yẹ lasiko yii:
Ni Beijing to jẹ olu ilu China ni wọn ti ṣeto ayẹyẹ ayajọ ominira China fun eto bi nkan bii wakati kan pere nibi ti awọn agbofinro ti duro wamuwamu ti wọn n ṣọ awọn eniyan.
Opo nkan ni awọn agbofinro fi di opopona ni Beijing ṣaaju ayẹyẹ ominira naa.
Sibẹ ọpọ arugbo ati ọmọde lo fi ayọ han si ayajọ ominira China pe aadọrin ọdun kuro ni keremi ninu ominira.
Nigba ti ọpọ ọdọ ko fi ayọ ominira yii han to pe o yẹ ki nkan ti ṣẹnu re ju bayii lọ ni China lẹyin aadọrin ọdun ominira.
Ọpọ awọn ti n fi ẹhonu han yii lojẹ ọdọ, ọmọ ile iwe ti o si ni atilẹyin awọn eekan ilu ninu.
Wọn ni awọn ọdọ n sọrọ nipa aini ọjọ ọla to peye ti alaṣẹ ilẹ China si n tẹ ominira ilẹ Hong Kong loju.
Eyi ni koko ohun to fa ifẹhonu naa han ti o si ti iṣu ata yanyan.
"IAAF World Championships: Abiyamọ kan di lobìnrin tó leè sáré ""100 meters"" jùlọ l'àgbáyé"
Oríṣun àwòrán, @BBCSport
"IAAF World Championships: Abiyamọ kan di lobìnrin tó leè sáré ""100 meters"" jùlọ l'àgbáyé"
Obinrin ọmọ ọdun mejilelogun kan lati orilẹ-ede Jamaica ti wọ inu iwe itan gẹgẹ bi obinrin to lee sare ori papa oniwọn ẹsẹ ọgọrun un julọ l'agbaye.
Shelly-Ann Fraser-Pryce to jẹ ọlọmọ kan tun ni ẹni to dagba ju l'gbaye to gba ife ẹyẹ naa lẹyin to gba ife wura ni idije agbaye to n lọ lọwọ ni Doha, lorilẹ-ede Qatar.
Dalemoṣu yii lo sa ere ori papa naa larin iṣẹju mẹwaa o le diẹ, lati gba ife ẹlẹẹkẹjọ iru rẹ ti yoo gba.
Lẹyin to gba ife ẹyẹ naa tan, o ni inu oun dun gidigidi.
O ṣalaye siwaju sii pe, aṣiri aṣeyọri oun ni iwa irẹlẹ ti oun ni ati bi oun ṣe mu iṣẹ oun lokunkundun.
Bi o tilẹ jẹ pe ọpọlọpọ awọn ololufe ere ori papa ni ko yọju lati wo Shelly-Ann ni igba to n sa ere naa, o ni oun ko bikita rara.
Ṣaaju akoko yii ni Shelly-Ann ti kopa ninu awọn idije agbaye miran bii; idije Olympic ti Beijin lọdun 2008, idije agbaye Berlin lọdun 2009, idije Olympic ti Londo lọdun 2012, ati bẹẹbẹẹ lọ.
Nigeria Independence Day: Sé ẹ mọ̀ pé ọdún 1956 ló yẹ́ ká ti dòmìnira ṣùgbọ́n....
Nigeria independence day: Àwọn ọmọ Nàìjíríà ń sọ èrò wọn nípa àyájọ́ òmìnira lórí ayélujára
Oríṣun àwòrán, @BashirAhmaad
Ọjọ ayajọ ọdun ominira Naijiria ni ọjọ akọkọ ninu oṣu kẹwaa gbogbo ọdun jẹ nitori ayajọ naa ni ọdun 1960 ni orilẹede Naijiria gba ominira rẹ kuro lọwọ ijọba amunisin ilẹ Gẹẹsi.
Ni ayajọ ọdun yii, oniruuru ara ni awọn ọmọ orilẹede Naijiria da lori ọkan o jọkan oju opo ayelujara.
Bakan naa lawọn kan naa tun n lo oniruuru ọrọ idakọro ori ayelujara iyẹn hashtag # bii  #NigeriaAt59#IndependenceDay, #October1st,#naijaat59, #GodBlessNigeria, #ProudlyNigerian lati fi ero ọkan wọn han nipa ajọdun naa.
Xenophobia: Áwọn ọmọ South Africa ní kí ààrẹ Ramaphosa kọ̀ láti tọrọ aforijin lọ́wọ́ ààrẹ Buhari
Oríṣun àwòrán, Bayo Omoboriowo
Aarẹ Buhari ati Aarẹ Ramaphosa yoo jijọ jiroro lori ọna abayọ si idẹyẹsi awọn ọmọ Naijiria nilẹ South Afrika
Ṣọ fun aarẹ Buhari pe a ko kabamọ pe a dẹyẹ sawọn eeyan rẹ.
Esi ti pupọ awọn ọmọ ilẹ South Afrika fi dahun ikede aarẹ wọn re e nigba ti o sọ loju opo Twitter rẹ pe oun yoo gba alejo aarẹ Buhari lati Naijiria.
Lọjọ Iṣegun ni aarẹ Ramaphosa fi ikede si oju opo Twitter rẹ pe oun yoo gbalejo aarẹ Buhari to m bọ wa ṣe abẹwo ọlọjọ mẹta si ilẹ naa.
Kete ti o fi ikede yi sita ni awọn eeyan rẹ ti fesi pada lori rẹ pe:
Bi awọn ti South Afrika ti ṣe n sọ pe awọn ko fẹ ki aarẹ awọn tọrọ aforijin lawọn eeyan Naijiria kan naa n bẹnu atẹ lu aarẹ Buhari pe ko yẹ ki o gbera lọ South Afrika rara.
Wọn ni aarẹ South Afrika lo yẹ ki aarẹ Buhari fiwe pe lati wa bẹbẹ tabi ṣalaye ohun tawọn eeyan rẹ ri lọbẹ ti wọn fi waaro ọwọ si akẹgbẹ wọn nilẹ Adulawọ.
Gẹgẹ bi oun ti wọn sọ, South Afrika lo tasẹ agẹrẹ, kii ṣe Naijiria:
Iru ọrọ bayi lati ọdọ awọn eeyan orile-ede mejeeji ni awọn onwoye kan sọ pe o yẹ ki awọn olori mejeeji yi fi jọ ronu wa wọrọkọ fi sada le lori.
Nigeria Independence Day: Sé ẹ mọ̀ pé ọdún 1956 ló yẹ́ ká ti dòmìnira ṣùgbọ́n....
Bi a ko ba gbagbe pupọ awọn ọmọ Naijiria ni ijọba Naijiria fi baalu gbe pada wa sile nigba ti idunkooko awọn ọmọ South Afrika mọ wọn peleke.
Lọjọ Iṣegun ni Ileeṣẹ aarẹ orile-ede Naijiria kede pe aarẹ Muhammadu Buhari yoo ṣe abẹwo ọlọjọ mẹta si orile-ede South Afrika.
Irinajo yi gẹgẹ bi ohun ti wọn sọ, yoo fun aarẹ Buhari ni anfani lati ṣe ipade pẹlu aarẹ South Afrika lati le wa wọrọkọ fi ṣada nipa mimu igbe aye alaafia wa laarin awọn eeyan orile-ede mejeeji.
Aarẹ Buhari yoo ṣe ipade lasiko irinajo naa pẹlu awọn ọmọ Naijiria to wa ni South Afrika lati le mọ ohun ti oju wọn n ri nilẹ naa.
Ẹwẹ, Buhari yoo dari ipade ajọ ibaṣepọ laarin Naijiria ati South Afrika nibi ti wọn yoo ti ṣe agbekalẹ iwadii ti Buhari ati aarẹ Ramaphosa yoo si buwọlu iwe adehun.
Intersextuality: Dokita ni ká mu èyì tó wù wá nínú jíjẹ́ akọ tàbí abo
Rwanda: Awakọ̀ 700 kò sí panpẹ òfin, 191 ṣẹwọn lórí ẹsùn wiwakọ lẹyìn tí wọ́n mọtí
Oríṣun àwòrán, Rwanda Police
Ọlọpaa to n yẹ iwe ẹri awakọ wo ni Rwanda
Laarin ọsẹ meji pere ni ọwọ ti tẹ awakọ ẹẹdẹgbẹrin ni Rwanda.
Awọn ọlọpaa lorile-ede Rwanda ti n tẹra mọ mimu awọn awakọ ti wọn fẹsun kan pe wọn wako lẹyin ti wọn ti muti.
Ni nnkan bi ọsẹ meji loṣu Kẹsan nikan,o kere tan wọn ti mu awakọ to le ni ẹẹdẹgbẹrin ti  mọkanlelaadọwa ninu wọn si ti ṣẹwọn lori ẹsun yi.
Ṣugbọn pupọ ninu awọn ti o ko si panpẹ ofin yi ni wọn ko tẹle ofin bo ti ṣe tọ lati mu awọn.
Wọn ni Yatọ si owo itanran aadọjọ dọla ti awọn ẹlẹsẹ yoo san, awọn ti o ba jẹbi ẹsun a maa sun ahamọ bii ọjọ marun un lai ṣe pe ile ẹjọ paṣẹ bẹẹ.
Blacksmith: èmí ni ìran keje tó jogún iṣẹ́ àgbẹ̀dẹ yii- Alatiṣe
Awọn ọlọpaa Rwanda ni awọn ko dakẹ lori idanilẹkọọ fawọn eeyan nipa aburu wiwakọ lẹyin ti eeyan ba mu ọti tan.
Arakunrin kan to ba BBC sọrọ to si ni oun ko fẹ ki wọn darukọ oun sọ pe awọn ọlọpaa ko ni irinṣẹ kankan lati jẹri pe lootọ leeyan muti.
Ofin ilẹ Rwanda sọ pe ida 0.08 BAC (blood alcohol concentration) ni igbalaaye rẹ wa fawọn awakọ amọ awọn eeyan ni ọlọpaa ko ni irinṣẹ to peye lati fi mọ aridaju iye ọti ti eeyan ba mu.
Nigeria Independence Day: Sé ẹ mọ̀ pé ọdún 1956 ló yẹ́ ká ti dòmìnira ṣùgbọ́n....
Nigeria Tribunal: Ilé ẹjọ́ kéde Ganduje gẹ́gẹ́ bí ẹni tó jáwéolúborí ninu ìdìbò sípò Gómìnà ìpínlẹ̀ Kano
Oríṣun àwòrán, @insightscoopng
Lẹyin o rẹyin, Ganduje lo jawe olubori
Ile ẹjọ to n gbẹsun idibo ni ipinlẹ Kano ti ni Gomina Abdullahi Ganduje ti ẹgbẹ oṣelu PDP ni ẹni to jawe olubori ninu idibo sipo Gomina to waye ni ipinlẹ naa.
Adajọ Halima Shamaki lo ṣe idajọ naa loni.
Aṣoju BBC to wa ni ile ẹjọ naa ni ẹsẹ ko gbero ni ile ẹjọ ọhun fun awọn to wa tẹti si ipẹjọ naa.
Bẹẹ naa ni awọn oloṣelu ko gbẹyin nibi idajọ ni bi wọn ṣe peju pesẹ si ile ẹjọ ọhun ni Kano.
Abba Yusuf lati abẹ asia ẹgbẹ PDP lo pe ẹjọ naa tako bi ajọ to n risi eto idibo ni Naijiria, INEC, ṣe kede gomina Abdullahi Ganduje gẹgẹ bi ẹni to pegede ninu idibo sipo to waye loṣu kẹta ọdun yii.
Ni ọjọ kẹrinlelogun, oṣu Kẹta, ọdun yii ni ajọ INEC kede pe idibo naa ko kẹsẹjari, to si kede idibo miran leyi ti Gandoje bori pẹlu ibo 1,033,695, ti Yusuf lati ẹgbẹ PDP si ni ibo 1,024,713.
Lẹyin eyii ni Yusuf kọ esi ibo naa to si gba ile ẹjọ lọ.
Gomina Ganduje ati alatako rẹ Abba
Igbimọ igbẹjọ to n gbẹjọ idibo Gomina nipinlẹ Kano yoo fi idajọ le lẹ loni laarin Gomina Abdullahi Umar Ganduje ti ẹgbẹ All Progressives Congress (APC) ati akẹgbẹ rẹ Abba Kabir Yusuf ti ẹgbẹ Peoples Democratic Party(PDP).
Bakan naa ni ile ẹjọ kun fọfọ ni ipinlẹ Sokoto nibi ti Gomina Aminu Waziri Tambuwal ti ẹgbẹ PDP naa n reti idajọ boya oun ni yoo yi jẹ Gomina tabi alatako rẹ Ahmed Aliyu ti ẹgbẹ All Progressives Congress (APC).
Adajọ Halima Shamaki ni yoo dajọ ẹjọ Ganduje ati akẹgbẹ rẹ ti wọn jijọ du ipo Gomina ninu idibo ọjọ kẹsan an, oṣu Kẹta, 2019.
Ganduje ni ajọ el;eto idibo INEC kede pe o jawe olubori ninu idibo naa pẹlu ibo 35,637 nigba ti APC ti ri ibo 45,876 ti PDP si ri ibo 10,239.
Ti a ba pa ibo akọkọ ati ikeji ti awọn oludije naa ri gba, APC  ri ibo 1,033,695 ti PDP si ri ibo 1,024,713.
Eyi tumọ si pe ibo 8,982 ni APC fi tayọ PDP.
Awọn eeyan joko siwaju ile idajọ ni Sokoto ni ireti esi igbẹjọ idibo Gomina
Ajọ eleto idibo INEC kede nigba naa pe idibo naa ko kẹsẹ jari lo mu ki wọn tun ibo di.
Esi ibo atundi naa ni oludije PDP ni ko tẹ oun lọrun ti o si gbe ẹjọ naa lọ si iwaju igbimọ igbẹjọ idibo.
Adajọ Halima Shamaki nigba ti o de si ile ẹjọ
Ẹwẹ Gomina ipinlẹ Sokoto Aminu Waziri Tambuwal naa  n koju itako lati ọdọ akẹgbẹ rẹ Ahmed Aliyu ti ẹgbẹ oṣelu PDP.
Tambuwal ti ẹgbẹ PDP gba ibo 512,002,  eleyi to fi ju akẹgbẹ rẹ to gba ibo 511,660.
Oríṣun àwòrán, Tambuwal/Facebook
Gomina Sokoto Aminu Waziri Tambuwal
Aye ṣi wa fẹnikẹni lati tako esi idibo naa ni ile ẹjọ kotẹmilọrun.
O  àti
Yóò dajọ bóyá àti yóò sì jẹ́ Gómìnà ìpínlẹ̀ wọ́n
Visa free: Àwọn Orílẹ-èdè tí wọn fún ọmọ Nàìjíríá lánfàní ìwé igbeluu ọ̀fẹ́
Oríṣun àwòrán, @others
Oko Ofurufu ṣetan lati gbe ẹnikẹni to ba fẹ rinrinajo lọ si awọn orilẹ-ede wọnyii.
Eto irin ajo lọ silẹ okeere awọn ọmọ Naijiria lo nilo igbaradi to muna doko latari ipo ti paali irinajo naa wa.
Bakan naa ni iwe aṣe igbelu tabi iwe aṣẹ wiwọ ilu tabi orilẹ-ede kọọkan [visa] jẹ ohun ti o gba oogun lọpọlọpọ lati ri gba fun irin ajo naa.
Sibẹ awọn orilẹ-ede kan ni ilẹ Adulawọ wa to n fi aaye gba irinajo si ọdọ wọn lai gba iwe aṣẹ igbelu tabi iwe iwọle niwọn igba ti paali irinajo to pe ye ba ti wa.
Wo awọn orilẹ-ede ti a fẹ darukọ yii fi aaye gba wiwọ ilẹ wọn lai si idaamu tabi dandan iwe aṣẹ. Ṣugbọn awọn kan beere fun iwe irinna naa lẹnu ọna ibode atiwọle si orilẹ-ede wọn.
1. Rwanda:
Orilẹ ede yii jẹ eyi ti o ni imọ toto julọ ti ọpọ awọn oludokowo ati awọn arinrin ajo afẹ si fi ṣe ibi ojukkọ ogun ni ọdun 1994,ni iyatọ ti wa.
O tun jẹ orilẹ ede ti ko ni idojukọ eto abo ti iwa ọdaran ko si ṣe bẹẹ wọpọ.
2. Djibouti:
Ni Iwọ Oorun ilẹ Afirika, ọkan pataki ibi ti o yẹ lati bẹwo lati orilẹ-ede Naijiria ni Ilu yii.
O ṣeeṣe ki o gba iwe aṣẹ igbelu ṣugbọn pẹlu owo ti ko ga ju ara lọ, ṣugbọn ti ilẹ naa ni awọn ibi abẹwo to lọọrin.
Awọon ibi abẹwo yii ni Odo Assal, ti o jẹ eyi ti o kere si ori ilẹ julọ ni ilẹ Adulawọ ti o si jẹ ikẹta iru rẹ ni agbaye lẹyin odo Galilee ati Okun pupa.
3. Morocco:
Aṣa, Oju Ọjọ ati awọn ohun amuyẹ ilu yii jẹ ko jẹ ibi aayo fun awọn ololufẹ.
Awọn ara meeriri ile ounjẹ, ibusọ, ati ibi igbafẹ kaakakiri le mu ki ololufẹ gbogbo gbagbe ile ile.
4. Cape Verde:
Orilẹ ede yii jẹ ibi omi ti o wa ni ila Oorun Adulawọ. O tun jẹ ọkan pataki lara awọn ibi igbafẹ julọ ni ilẹ Adulawọ.
Oju ọjọ ilẹ naa dara ti ayika orilẹ ede naa si rẹwa.
5. Kenya:
Ilu yii ni oriko awọn eranko nla nla, Safari ati awọn  ibi itan. Awọn ilu bii Nairobi ati Monbassa jẹ ibi ti o dara.
Enu ọna ilu naa ni eniyan ti le gba iwe irinna bakan naa.
6. Uganda:
Ila Oorun Aduilawọ ni ilu yii ti o si ni ibi itan bii obo Victoria ati awọn miiran ti o si fi aaye gba gbigba iwe ni ẹnu ọna iwọle.
7. Sudan:
Ilu yii jẹ ibi ti o ni agbegbe awọn eranko ti o si ni ojuko ibi igbafẹ ṣugbọn ti iwe irinna gbigba rẹ jẹ lati ẹnu ọna abawọle.
Awọn Orilẹ ede miran ti ko nilo iwe aṣẹ igbelu fun awọn ọmọ Nigeria ni ;
8. Barbados:
Orilẹ ede yii wa ni Ila Oorun ilẹ Afrika ti o si jẹ bii ọgọrun kilomita si Iwọ Oorun Odo Caribbean ati Odo Windward.
Abẹwo ọmọ Naijiria si ilu yii yoo fun ẹni naa ni anfaani lati lo oṣu mẹfa lai gba iwe aṣẹ.
O jẹ ilu ti o ni ibi igbafẹ ẹgbẹ omi julọ ati ẹja odo.
Orilẹ ede yii jẹ ọkan lara orilẹ ede ti o pọju lọ lagbaye.
Bakan naa ni o maa n fun awọn ọmọ Naijiria ni anfani ọgbọn ọjọ ki wọn to gba iwe aṣẹ igbelu.
Bakan naa ni iru ẹni bẹẹ yoo ṣafihan ẹẹdẹgbẹta owo dọla tikẹẹti ipada sile.
Igbadun rẹpẹtẹ n bẹ ni Ilu  Port ni Cittagong fun faaji ti ko lopin.
10. BURKINA FASO:
Ofẹ ni iwe igbelu orilẹ ede yii ti o wa ni Iwọ Oorun Alawọ dudu.
Orilẹ ede yii ni o ṣe igbalejo iṣafihan aṣa ati ohun iṣẹnbaye, Ouagadougou ti o si gba ami ẹyẹ julọ ni ilẹ adulawọ.
Burkina Faso jẹ orilẹ ede ti awọn ọmọ Naijiria fẹran lati maa lọ ti o si ni Wura ati Fadaka lọpọ yanturu.
Nigeria Independence Day: Sé ẹ mọ̀ pé ọdún 1956 ló yẹ́ ká ti dòmìnira ṣùgbọ́n....
11. BENIN REPUBLIC:
Osu Mẹta pere ni wọn fun awọn ọmọ Naijiria lati gbe ni ilu naa lai si iwe aṣẹ igbelu .
Orilẹ ede naa sun mọ Naijiria daada ti o si ni ọpọlọpọ ojuko igbafẹ bii ibi afọwọsi ajọ UNESCO ti a mọ si Pendjari Park.
O wa ni ila Oorun Adulawọ ti o si fun ọmọ Naijiria ni anfani ọgbọn ọjọ lati gbelu laisi iwe aṣẹ.
Ilu naa ni a mọ si orilẹ ede ti o mọ nipa iṣẹ ọwọ bii apẹrẹ hihun,ṣiṣe ere ati amọ mimọ.
Ọkan pataki lara ohun ti wón tun mọ ni ilu lilu. Awọn alulu fọba ti orilẹ ede naa ti wa lẹnu rẹ bayii bii Ogoji Ọdun.
Sisọ itan, alọ apagbe ati Ijala jẹ ohun amuyẹ orilẹ ede naa.
Ilu yii wa ni Ila Oorun Adulawọ ti o n fun ọmọ Naijiria ni anfaani iwe aṣẹ igbelu. Ṣaa ti ṣafihan ẹri pe kii ṣe pe lailai ni iru ẹni bẹe fẹ maa gbe ilẹ naa.
Ti gbongan ibi iko ohun Iṣẹn baye si naa ko gbẹyin.
Oṣu mẹta ni orilẹ ede yii naa fun gbigbelu awọn ọmọ Naijiria lai gba iwe Aṣẹ igbelu orilẹ ede naa. Aginju nla ti awọn ẹrenko ngbe pọ ni ilu naa.
Bakan naa ni gbongan ibi iko nkan iṣẹnbaye si wa ni Yaounde ati Mvog-Betsi ti o jẹ ibi ti ẹranko n la wa.
Àwọn ọ̀dọ́ orílẹ̀èdè Nàìjíríà sọ èrò wọn lórí Nàìjíríà
Orilẹ ede yii la n pe ni Ivory Coast tẹlẹ ti o ni ọpọ ohun alumọni ti yoo mu dide larinnrin.
Ibi igbafẹ ti Assinie , Parc National de Tai, Ori Oke Artsy jẹ ọkan lara awọn ibi igbafẹ.
O tun le jẹ igbadun ririn ajo ori omi tabi ibi itaja ti o wa ni Treichville tabi Cocody.
O le rin irin ajo lọ si orilẹ ede yii lai gba iwe aṣẹ irinna ṣugbọn ti o le ri iwe naa gba ni aadọta dọla.
Orilẹ ede yii ni igun ibi omi  mẹrin ti o si ti ni idagbasoke pẹlu yẹpẹ funfun.
Awọn adan nla ,okuta ati igbo ti o pọ jantii rẹrẹ.
Blacksmith: èmí ni ìran keje tó jogún iṣẹ́ àgbẹ̀dẹ yii- Alatiṣe
O wa ni Iwọ Oorun Afrika ti o si ni anfaani Oṣu kan lati fun ọmọ Naijiria.
Awọn alaṣẹ ilẹ naa yoo gba ẹri pe kii ṣe wi pe lati gbe ni ile naa patapata ṣugbọn fun igba diẹ.
O gbọdọ fi iwe aṣẹ igbelu rẹ han ni kete ti o ba ti n balẹ si ilu naa lẹyin ọgbọn ọjọ.
Orilẹ ede naa ni a mọ si eyi ti o ni ojuko ibi omi ti o dara fun igbafẹ ati pẹpẹ atijọ.
O le debẹ ni oṣu kejila nigba ti wọn ba n ṣe Ajọdun Omi.
Ookanlelogun ọjọ pere ni anfani mọ ni ilu yii.
Ila Oorun Afrika ni ilu yii wa ti o si bere fun aṣẹ iwe igbelu.
20. FIJI
Guusu Ibi Omi Pacific  Afrika ni ilu yii naa wa. Oṣu mẹrin ni anfaani iwe aṣẹ igbelu.
Ati awọn orilẹ-ede ti wọn ni awọn ofin isalẹ wọnyii:
GHANA - Iwọ Oorun Afrika ni ilu yii wa. Ko si dandan aṣa iwe igbelu.
GUINEA - Iwọ Oorun Afrika ni ilu yii wa ti ko nilo aṣẹ iwe igbelu,
GUINEA BISSAU - Oṣu mẹta pere ni aigbawe aṣẹ ilu yii ti o si wa ni Iwọ Oorun Afrika.
GAMBIA - Oṣu mẹta pere naa ni ohun ti o si wa ni Iwọ Oorun Afrika bakan naa.
HAITI - Agbegbe Caribbean ni ilu yii wa. Oṣu mẹta naa ni anfani iwe igbelu na.
IRAN -Aarin gbungbun Ila Oorun Afrika ni o wa.
Samoa: aṣẹ iwe igbelu fun osu meji
Senegal: Ọfẹ ni
Seychelles: Iwe aṣẹ fun ọgbọn ọjọ
Somalia: Gbigba aṣẹ iwe igbelu
Sri Lanka
Tanzania: de pelu iwe aṣẹ igbelu
Timor - Leste:   Iwe aṣe igbelu fun ọgbọn ọjọ
Togo:  laisi iwe aṣe igbelu
Tuvalu:   de pelu iwe aṣẹ lẹyin oṣu kan.
Uganda:  de pẹlu iwe aṣẹ igbelu
Vanuatu: de pelu iwe aṣẹ.
Yollywood: Kò sí ẹni ti òbí mi kò lè sọ̀rọ̀ sí -Sisi Quadri
2023 Election: Ọọfììsì Ààrẹ ni Buhari kò ní gbápotí ìbò mọ́
Buhari ati Igbakeji rẹ Yemi Oṣinbajọ
Ọfiisi Aarẹ Orilẹ-ede Naijiria ti ṣi aṣọ loju eegun ọrọ wi pe Aarẹ Buhari ko ni ipinnu lati dije fun ipo naa lẹẹkẹta.
Ọrọ yii lo suyọ latari iwọde ti awọn ẹgbẹ kan ṣe fun ipadabọ Aarẹ naa lẹẹkẹta sori aleefa.
Ṣe iwe ofin orilẹ-ede yii ko kuku faaye gba gbigbe apoti ibo lẹẹkẹta lẹyin ti o ba ti ṣe ijọba lẹẹmeji.
Abẹnugan agba fun Aarẹ Buhari lori ọrọ iroyin, Garba Shehu tẹsiwaju wi pe Aarẹ ko ni akoko tabi ero ọkan lati yi ofin orilẹ-ede yii pada.
Alẹ ọjọ lṣẹgun ni Garba sọrọ yii pe Buhari ko le yi iwe ofin ti o ṣe alakalẹ ẹẹmeji pere fun Aarẹ pada rara.
Blacksmith: èmí ni ìran keje tó jogún iṣẹ́ àgbẹ̀dẹ yii- Alatiṣe
O tẹsiwaju pe, Aarẹ naa dije ni ọdun 2015 leyin ti o pari saa kinni rẹ ti o si dije fun saa keji ni oṣu keji, ọdun 2019.
O ni fun idi eyi, o di ọdun ọdun 2023 ki o to pari saa keji ti yoo si gbe ijọba silẹ.
Shehu ṣe alaye pe, Aare yoo lo asiko saa keji naa ni ofiisi daadaa ti ko si ni gbe apoti idibo rara ni ọdun 2023.
Ṣe ṣaaju asiko ibo ni Aarẹ Buhari ti sọ wi pe ẹẹkan pere ni oun yoo ṣe ni ọdun 2015 .
Ṣugbọn ti o tun yi ohun pada to tun fi jade ni ọdun 2018 lati dije fun saa keji.
Tẹlẹ ni awọn aṣofin ilẹ yii ti fẹ yii iwe ofin naa pada fun Aarẹ ana Oluṣẹgun Ọbasanjọ ni 2007 ti ipinnu yii si fori ṣọpọn.
Aarẹ Buhari ni o ti dari orilẹ-ede yii ṣaaju ọdun 2015 nigba ti o wa ni ologun ni ọdun 1983 ati 1985 gẹgẹ bi ọga ologun.
Nigeria Independence Day: Sé ẹ mọ̀ pé ọdún 1956 ló yẹ́ ká ti dòmìnira ṣùgbọ́n....
Headies Award: Orinkórin ni Naira Marley ń kọ
Oríṣun àwòrán, @officialnairam1
Ajọ EFCC ni, naira Maley n ṣagabtẹru iwa jibiti ninu orin rẹ
Ayo Animasahun to jẹ oludasilẹ ileeṣṣẹ Hip TV ti sọ fun BBC pe, wọn pinu lati yọ orin Naira Maley kuro ni 'Headies Award' ọdun yii nitori pe orinkorin lo n kọ.
Animasahun tẹsiwaju pe, ileeṣẹ oun kii ṣagbatẹru orinkorin.
Hip TV ni ileeṣẹ to n ṣagabatẹru Headies Award lọdọdun.
Ọjọ kini oṣu yii ni wọn fi orukọ awọn ti wọn fẹ fun ni ami ẹyẹ Headies Award ọdun yii lede, sugbọn orukọ Naira Marley ko si nibẹ.
Lẹyin eyii ni awọn ololufẹ Naira Marley bẹrẹ si n fi eroungba wọn lede lori ẹrọ ayelujara, ti wọn si n bere idi ti orukọ rẹ ko ṣe si ninu orukọ awọn eeyan naa.
Naira Maley to jẹ olorin takasufe lo ti gbe oriṣiriṣi orin jade bi, 'Am I a Yahoo boy?' 'Soapy' ati 'Puta.'
Ọpọlọpọ awuyewuye lo yi olorin naa ka, lẹyin ti ajọ to n gbogun ti iwa ibajẹ, EFCC gbe lọ ile ẹjọ lori ẹsun to jọ mọ iwa jibiti ati gbajuẹ.
EFCC lo fi ṣikun ọba mu ni ibẹrẹ ọdun yii, lẹyin ti wọn ni o n gbe iwa jibiti larugẹ ninu orin rẹ.
Headies Award jẹ ọkan gboogi lara awọn ayẹyẹ ti wọn fi n yẹ awọn olorin si, ti ọpọlọpọ olorin takasufe si ma n gba ami ẹyẹ nibẹ.
Ọjọ kọkandinlogun oṣu yii ni ayẹyẹ Headies Award naa yoo waye ni ipinlẹ Eko.
Blacksmith: èmí ni ìran keje tó jogún iṣẹ́ àgbẹ̀dẹ yii- Alatiṣe
Workers Strike: Léyìn ọsẹ méjì, a máa gùnle ìyanṣẹ lódì
Oríṣun àwòrán, Labour page
Awon Olori Osise Naijiria
Ajọ awọn oṣiṣẹ ni Naijiria ti gun ijọba apapọ ni kẹṣẹ ikilọ lati gunle iyanṣẹ lodi.
Awọn Oṣiṣẹ yii ni wọn sọ ọrọ yii ninu iwe ti wọn fi lede lọjọru ọsẹ yii.
Ninu atẹjade kan ti alaga ajọ awọn oṣiṣẹ naa fọwọ si, Ayuba Wabba ni Abuja, lo ti sọ ọ.
Alaga naa ti oun ati ojugba rẹ leka awọn oniṣowo, Quadri Ọlaleyẹ ati alaga awọn oṣiṣẹ ijọba apapọ, Simion Anchaver jọ fẹnuko lori iyanṣẹlọdi naa ti wọn kede rẹ si ọjọ kẹrindinlogun, oṣu kẹwaa yii tijọba ko ba ṣe ohun to yẹ lasiko.
Gbogob wọn ti jọ fi ohun ṣọkan wi pe, n ṣe ni Ijọba apapọ n fa ọrọ naa nilẹ ti wọn si n jẹ ki o pẹ ju.
Gbogbo awọn alaga oṣiṣẹ naa wa fun Ijọba apapọ ni gbendeke ọjọ kẹrindinlogun oṣu yii lati ṣe ẹtọ.
Oríṣun àwòrán, @others
Iyanselodi la maa gunle ti ijoba ko ba .....
Wọn pinnu lati gunle iyanṣẹ lodi ti Ijọba ko ba tete fi wọrọkọ ṣada.
Lara ohun ti awọn oṣiṣẹ naa tẹpẹlẹ mọ ni wi pe, niwọn igba ti ele owo ori epo ti ga soke, o yẹ ki afikun ba owo oṣu.
Wọn ni ere gọbọi ti ba fifikun jala owo epo ti Ijọba si n jẹ to ida ọgọta ere.
Wọn wa ni pe, awuruju wa ninu bi Ijọba ṣe ṣafikun si owo oṣu oṣiṣẹ lati akasọ keje si ikẹrinla ti o jẹ bii ida mẹfa.
Oríṣun àwòrán, @others
Awon oga loga ajo osise ni won jo fenuko si iyanselodi yii
Apapọ ajọ Oṣiṣẹ naa ti wa fi imọ ṣọkan lati sọ fun ijọba pe, ko si aridaju ibaṣepọ laarin wọn ati ijọba ti ijọba ko ba tẹ ara ilu lọrun.
Nigeria Independence Day: Wo ìlérí tí àwọn ènìyàn ṣe
Maina Arrest- DSS ti mú Maina àti ọmọ rẹ ní ile Itura kan l'Abuja
Oríṣun àwòrán, EFCC page
Abdulrasheed Maina Alaga ana fun eka owo ifẹyinti
Ajọ Ọlọpaa abẹnu ti a mọ si DSS ti fi panpẹ ọba mu alaga ana fun eto owo ifẹyinti ni Naijiria, Abdulrasheed Maina.
Ninu ọrọ ti alukoro ajọ naa, Peter Afunayan,  fi lede ni ọjọru ọsẹ yii, sọ wi pe lootọ ni ọwọ ṣikun ajọ naa ti tẹ ẹ.
Ajọ naa ni ọwọ wọn tẹ Maina ati ọmọ rẹ ọkunrin kan, Faisal, ẹni ogun ọdun.
Ọwọ tẹ wọn ni ile itura kan ni, Pennysylvania Avenue, Utako, Abuja to jẹ olu ilu Naijiria ni ọgbọn ọjọ Oṣu to kọja.
Ṣe ṣaaju ni wọn ti fi ẹsun kan an wi pe owo to to bii biliọnu meji lo poora sọwọ Maina ni ọfiisi Olori awọn Oṣiṣẹ Ijọba apapọ.
Maina ni o jẹ adari ni ẹka ti o n ri si bi igbokegbodo owo ifẹyinti ti n lọ ni Naijiria fun bii ọdun meta.
Lọdun 2015 ni ajọ Ọlọpaa ọtẹlẹmuye ti kọkọ fi ẹsun ikowojẹ oni biliọnu meji naira kan an.
Maina ṣe alaga naa lati ọdun 2010 si ọdun 2013. O tun jẹ alakoso agba fun awọn Aṣọbode pẹlu awọn ti o n boju to ọgba ẹwọn.
Ni ọdun 2013 ni awọn Aṣofin ti ni ki wọn fi panpẹ ọba gbe Maina ṣugbọn ti o fẹse fẹ ẹ lo si orilẹ-ede Saudi Arabia.
Nigba ti o di ọdun 2015, ni ajọ ti o n risi iṣowo ilu baṣubaṣu EFCC, ti pe fun wiwa Maina lawari ti obinrin n wa nkan ọbẹ ri.
Ni ọdun 2016, ni Maina kede pe, awọn Aṣofin ti da oun lare ki oun si maa lọ ni alaafia.
Nigeria Independence Day: Wo ìlérí tí àwọn ènìyàn ṣe
Xenophobia Attack - Ilẹ South Afrika kò ní gbàgbé Nàìjíríà fún àtìlẹyìn wọn.
Oríṣun àwòrán, BASHIL AHMAD
Aare Buhari ati Ramaphosa ti ile South Afrika n sọrọ papọ ki alaafia le jọba
Aarẹ ilẹ South Afrika, Cyril Ramaphosa ti fi idunnu rẹ han si orilẹ-ede Naijiria lori ipa ti o ti ko fun idagbasoke South Africa sẹyin.
Aarẹ naa ni o ṣalaye pe ipa mani gbagbe ni orilẹ-ede yii ko ninu igbogunti imunilẹru awọn ọmọ ilẹ South Africa.
O sọ ọrọ naa nigba ti Aarẹ Naijiria, Muhammadu Buhari lọ ṣe ayẹwo si i lori ọrọ ifiyajẹni ti wọn ṣe fun awọn ọmọ Naijiria.
Ramaphosa sọ wi pe, Ijọba ilẹ naa kẹdun iṣẹlẹ ikọlu naa lori bi o ṣe waye ni apa kan orilẹede oun ni bii ọsẹ meji sẹyin.
Oríṣun àwòrán, BASHIL AHMED
Ayesi fun Aare Buhari ni Papako Ofurufu
Aarẹ Ramaphosa fi kun ọrọ rẹ pe, Ijọba ilẹ naa yoo ri daju pe ofin ilẹ naa fi ese mulẹ fun tolori tẹlẹmu.
Aarẹ Ramaphosa wa fi da Buhari loju pe, South Afrika yoo ṣe ohun to yẹ lati mu ifẹ ati ajọṣepọ to dan mọnran ba ilẹ Adulawọ.
O tun ni pataki ẹtọ ọmọniyan ni orilẹ-ede naa yoo tẹ pẹlẹmọ ti yoo si bọwọ fun ofin.
O tẹsiwaju pe, ni bi ilẹ naa ti n ṣe ohun to yẹ lori eto ọrọ aje ati awujọ, ti o ṣe okunfa ibinu naa, sibẹ, wọn yoo dẹkun iwa rogbodiyan.
Oríṣun àwòrán, BASHIL AHMED
Ayesi fun Aare Buhari
Lẹyin gbogbo atotonu Aarẹ Ramaphosa, Aarẹ Buhari ni ireti wa pe yoo ba awọn ọmọ Naijiria to wa ni South Afrika sọrọ lori idojukọ wọn.
Ifiyajẹni lori awọn ọmọ Naijiria naa ti mu adinku de ba ibaṣepọ to wa laarin orilẹ-ede mejeeji.
Ṣugbon nigba ti Minisita fun ọrọ ilẹ Okeere ilẹ naa, Naledi Pandor n sọrọ pelu ojugba rẹ ti ilẹ Naijiria, Geoffrey Onyeama, o ni ko si ija rara laarin orilẹ-ede mejeeji.
Lati bii ọdun 1994 ni Naijiria ati Ilẹ South Afrika ti jọ ni aṣepo lori ọrọ Oṣelu, Ọrọ aje ati ọrọ ayika nigba ti wọn ṣe eto ibo akọkọ.
Lenu aipẹ ni ọga agba fun ọkọ ofurufu Air Peace, Allen Onyeama ṣe iranlọwọ kiko ọmọ Naijiria to to irinwo pada de latari ifiyajẹni naa .
Òun tọjú àwọn ọmọ Nàìjíríà n rí ní South Áfríkà kọjá afẹnusọ
Ninu eyi to mu ki awon ọmọ Naijiria sọ wi pe ki Ijọba o tilẹkun mọ gbogbo ile iṣẹ ilẹ naa ni ilẹ yii.
Ninu atẹjade kan lati ile Ijọba ni wọn ti ni, ọna ti awọn ọmọ Naijiria to wa ni South Afrika yoo ṣe maa gbe lai si ibẹru ni Aare yoo ba wọn sọ.
Xenophobia: Naijiria á kọ́kọ́ pèsè ọ̀nà láti bá ẹbí sọ̀rọ̀ fún wọn
Aarẹ Buhari ni ọna ti aabo yoo fi wa fun dukia ati ẹmi wọn ni yoo ko ipa pataki ninu ipade ajọro naa.
Gẹgẹ bi ọrọ ti Aarẹ Ramaphosa sọ, o ni ipade oun ati Aare Buhari ni lati san okun ibaṣepọ aarin ilẹ mejeeji daaada.
Ati lati mu ifẹ ilẹ adulawọ dan mọnran si daadaa.
Ni kokari ọrọ wọn ni wọn si lọ tọwọ bọ iwe adehun laarin orilẹede mejeeji.
Nigeria Independence Day: Wo ìlérí tí àwọn ènìyàn ṣe
Police Attack: Ọ̀bẹ ni ọkùnrin kan fi pa Ọlọpàá mẹrin ni Paris
Oríṣun àwòrán, EPA
Awon Ọlọpaa ile faranse n binu
Ọkunrin kan ti o n mu ọbẹ rin ni o ti ṣeku pa Ọlọpaa mẹrin ni ilẹ Faranse ni olu ile iṣẹ ajọ naa.
Ọkunrin naa ti ko i ti si ẹni ti o mọ orukọ rẹ ni awọn Ọlọpaa ti yinbọn lu ti wọn si ran lọrun.
Iroyin fi yewa pe, ara awọn oṣiṣẹ ile iṣẹ ajọ Ọlọpaaa ni ọkunrin naa.
Lọwọlọwọ yii, ko i tii si atẹjade kankan lati lori ọrọ naa ṣugbọn ti ojuko ibi iṣẹlẹ naa si,- ilé de la Cité-  ti wa ni titi pa.
Iṣẹlẹ yii waye lẹyin iyanṣe lodi ọlọjọ kan ti awọn Ọlọpaa naa gunle ṣaaju latari akọlu atigba -degba ti o wọn ṣe si ajọ naa.
Iṣẹlẹ yii waye ni nkan bii agogo kan ni inu ile iṣẹ naa.
Minisita agba fun ilẹ Faranse , Edouard Philippe ati ojugba rẹ ni ẹka ọrọ abẹle, Christophe Castaner ni wọn wa ni ojuko iṣlẹ naa.
Oríṣun àwòrán, Reuters
Awọn Ọlopaa n pana aawọ naa
Adari agba ni ilẹ Paris, Anne Hidalgo fi idi ọrọ naa mulẹ lori itakun ayelujara rẹ pe, ọpọlọpọ awọn eniyan ni wọn ti pa.
O ni ainiye awọn tti ko mọwọ mẹse ṣugbọn ti wọn ti rọrun latari isẹlẹ naa ti awọn miran si farapa.
Gẹgẹ bi awọn oṣiṣẹ ibẹ ti wi, arakunrin naa nṣiṣẹ ni ẹka bi inkan ti n lọ ni ile iṣẹ ajọ Ọlọpaa naa.
Kaduna Kidnapping - Ọmọ iléèwé mẹfà pẹlú Olùkọ méjì ni wọn jígbé ni Kaduna.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ọlọpaa n wa awon Ajinigbe náà
Awọn Ọlọpaa ni Ipinlẹ Kaduna ti fi idi ijinigbe awọn ọmọ ileewe mẹfa mulẹ.
Awọn Ọlọpaa sọ pe níṣe ni awọn ajinigbe naa yabo ile iwe naa pẹlu ibọn .
Ileewe naa jẹ eyi ti o ni ileegbe ti o si  wa ni odi ilu naa .
Ni itosi Kakau DajiVillage ni Ijọba  Ibilẹ Chikun ni ile iwe naa wa.
Ni Owurọ kutukutu ọjọbọ ọsẹ yii ni  iṣẹlẹ naa ṣẹlẹ ti wọn si tun ji Olukọ meji gbe pelu.
Ajọ Olọpaa ni wọn ti da awọn ti o risi jijini gbe ẹka ajọ naa lati bẹrẹ si fimu finlẹ lati doola ẹmi awọn ti wọn jigbe naa.
Bakan naa ni Ọlọpaa ti wa kesi gbogbo awọn ti o ni ile iwe aladani lati sowọpọ pelu wọn lojuna ati dẹkun iru iṣẹlẹ bẹẹ.
Ọlọpaa wa ni pe ijiya nla n bẹ fun ẹnikẹni ti ade ori ọrọ naa ba ṣimọ.
Jazz music: Ayọ̀ tó ń bẹ nínú orin Jazz
Oríṣun àwòrán, AP
Olakunle Tejuoso at his record and book store in Lagos
Ni aarin ile itaja rẹkọọdu orin rẹ, The Jazzhole, lo duro si.
Ọlakunle Tẹjuoṣo mura ninu aṣọ Buba ati Sokoto rẹ, oun atawọn oṣiṣẹ rẹ si n sọrọ pọ bi wọn ṣe n tun iwe to wa lori awọn atẹ ifiwe si to.
Bi o si ti n ṣe eyi naa lo n ranti igba ewe rẹ.
"Lakọkọ naa, lati kekere ni mo ti maa n la ala pe emi naa yoo ni ile itaja rẹkọọdu temi...nitori lati kekere ni mo ti maa n ṣe akojọpọ awọn awo orin.
Africa Eye: Olùkọ́ méjì ní fásitì Eko àti Ghana lùgbàdì ọ̀fíntótó BBC lórí ìwà ìbàjẹ́
Nnkan ti mo maa n ṣe niyi lẹyin ti mo ba kuro ni ileewe ni ọrọ to ti ẹnu Tẹjuoṣo jade."
Ile itaja rẹkọọdu, The Jazzhole ti o wa ni opopona Awolọwọ ni ilu Eko bẹrẹ karakata ni ọdun 1991 ni ile kekere kan ni apa ibi kan nilu Eko kan naa.
Oríṣun àwòrán, Princess I. Abumere/BBC
The Jazzhole
Lasiko yii to jẹ wi pe orin takasufe Afrobeats lo gbode kan lori awọn ileeṣẹ redio ati ile ijo gbogbo, The Jazzhole ṣi gbin ara rẹ kalẹ gẹgẹ bii ibudo akojọpọ oniruuru orin.
Nipasẹ eyii, ile itaja rẹkọọdu ati iwe naa ti sọ ara rẹ di ọkan pataki lara awọn ibudo ti eeyan ti lee ri orin igba atijọ gbọ seti.
Nitori ati maa ta orin Jazz ati orin ilẹ Adulawọ ni a ṣe ṣi ile itaja rẹkọọdu yii silẹ.
Oríṣun àwòrán, Princess I. Abumere/BBC
The Jazzhole houses jazz music from different eras
Orin Jazz ni iyi pupọ lawọn ọdun ogun si ọgbọn sẹyin ṣugbọn o ti di agbọnrin eṣi bayii.
"Awọn saraki-saraki eeyan lonibara mi nigba naa, awo orin igbalode CD ko si tii wọpọ nigba naa.
Yatọ si pe wọn n ra awo orin, wọn mọ iyi orin nitori pe wọn ti wo oniruuru olorin.
Gbogbo wọn lo ti fẹrẹ lọ soke okun tan ti wọn si lowo lati lọ sawọn ajọdun orin ati ijo kaakiri agbaye."""
Oríṣun àwòrán, Princess I. Abumere
Yatọ si pe wọn n ra awo orin, wọn mọ iyi orin nitori pe wọn ti wo oniruuru olorin.
Amọṣa Tẹjuoṣo ṣalaye pe awọn eeyan tun ti n poungbẹ fun orin Jazz bayii.
Iyatọ wa laarin awọn ọdọ iwoyii si awọn ọdọ igba tiwa.
Oríṣun àwòrán, Princess I. Abumere/BBC
Nitori ati maa ta orin Jazz ati orin ilẹ Adulawọ ni a ṣe ṣi ile itaja rẹkọọdu yii silẹ.
Ode Alujo orin:
Ilee itaja orin The Jazzhole tun maa n gbalejo ode alujo orin.
Tẹjuoṣo ni gbogbo ode alujo orin ti wọn gbe kalẹ wa lati ta awọn orin naa.
Ọlọkan-o-jọkan awọn olorin bii Aṣa, Brymo ati Nneka ni wọn ti lọ ṣere nibẹ.
Oríṣun àwòrán, Princess I. Abumere/BBC
Nitirẹ, iyawo Tẹjuoṣo, ti wọn jijọ ni ile orin naa ni Fatai Rolling Dollars no oun ko lee gbagbe.
O ni awọn olorin agbagba wọnyii lo n wu oun nigbakugba.
Gbogbo awọn olorin naa lo si ni ode wọn jẹ manigbagbe.
Europa league: Ìjàmbà tún ṣe Ole àtàwọn ọmọ rẹ níwájú AZ Alkmaar, ọ̀mì ni wọ́n ta
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Kikankikan ni olukọ atawọn agbabọọlu ẹbẹ agbabọọlu Manchester n pariwo lori papa iṣire ti wọn ti gba ifẹsẹwọnsẹ wọn pẹlu AZ Alkmaar ninu ifẹsẹwọnsẹ idije Europa.
Ọmi ni Manchester United ta pẹlu AZ eleyi to mu ki Manchester United ṣi wa ni ipo keji ninu atẹ ipin L ninu idije naa ti Partizan belgrade si di ipo kini mu.
Manchester United ni lati pari ifẹsẹwọnsẹ naa pẹlu agbabọọẹu mẹwa dipo mọkanla nitori ọkan lara awọn agbabọọlu rẹ, Jesse Lingard to fara pa to si ni lati fi ori papa silẹ ṣaaju opin ifẹsẹwọnsẹ naa.
Pẹlu ifẹsẹwọnsẹ yii bayii, ami ayo mẹrin ni Manchester United ti ni ninu ifẹsẹwọnsẹ meji ti wọn ti gba.
FC Astana ni wọn ba pade ninu ifẹsẹwọnsẹ wọn akọkọ ti wọn si bori.
Lizzy Anjorin vs Toyin Abraham: Ẹ wòó ẹ fi wọ́n sílẹ̀, ìgbà ọtun ń bọ láipẹ́ -Toyin
Oríṣun àwòrán, Instagram/Toyin Abraham
Gbajugbaja Oṣere tiata Toyin Abraham ti gbogbo aye mọ si Toyin Aimakhu tẹlẹ ni o ti ba awọn ololufẹ rẹ sọrọ lori ẹrọ ayelujara.
Toyin Ajeyemi foju hande fun igba akọkọ lati sọrọ lati igba ti aawọ ti suyọ laarin ohun ati akẹgbẹ rẹ, Lizzy Anjọrin.
Toyin dupe lọpọlọpọ lọwọ gbogbo awọn ololufe rẹ fun atilẹyin ati ifẹ ti wọn ni si i lati ẹyin wa.
Ninu ọrọ rẹ , o dupẹ fun aduroti ati amọran ti o n ri gba lọwọ onipo jipo awọn onibara rẹ.
O wa parọwa si gbogbo awọn ololufẹ rẹ pe ki wọn ma ṣe sọrọ alufanṣa pada si ẹnikẹni to ba sọ iru ọrọ bẹẹ.
Oríṣun àwòrán, Facebook
Toyin Abraham
O ni to ba wa ni ẹnikẹni tabi eeyan keeyan to ba n binu tabi fapa jana, ki wọn o fi silẹ pe ki iru ẹni bẹẹ lee ri ogo Oluwa ninu aye ohun.
Bakan naa lo ṣe lalaye pe, oun ati gbogbo alatilẹyin oun pata kii ṣe onijagidi jagan, ti wọn si kawe bẹẹ naa ni wọn ni ọpọlọ.
Lo ba ni keṣekeṣe ni wọn ri o, pe kasakasa nbọ lọna, eyi to jẹ baba keṣekeṣe ni daada.
Ni akotan , ko ṣai dupe pupọ lọwọ awọn ti o jẹ olubadamọnran rẹ.
Omoyele Sowore: Sowore gbòmìnira láhàmọ́ọ́ DSS pẹ̀lú ọgọ́rùn ún mílíọ̀nù náírà
Oríṣun àwòrán, Instagram/Sahara Reporters
Lẹyin ọ rẹyin, ileẹjọ giga ti ijọba apapọ l'Abuja ti gba beeli Omoyele Sowore to ṣagbatẹru iwọde #RevolutionNow.
Ọgọrun un miliọnu nairia ni ileẹjọ fi fun Sowore ni beeli pẹlu oniduro meji lọsan ọjọ Ẹti.
Sowore ti wa ni ahamọ ileeṣẹ ọtẹlẹmuyẹ DSS lati ọjọ kẹta oṣu Kẹjọ ọdun yii lẹyin ti wọn mu un niluu Eko.
Adajọ Ijeoma Ojukwu paṣẹ fun Sowore pe ko gbọdọ rinrin ajo kuro l'Abuja.
Ẹwẹ ileẹjọ kan ti kọkọ paṣẹ pe ki ajọ DSS fi Sowore silẹ latimọle wọn pẹlu akẹgbẹ rẹ, Olawale Bakare, ṣugbọn ajọ DSS kọ lati tẹle aṣẹ ileẹjọ.
Aadọta miliọnu naira ni ileẹjọ fi gba beeli Bakare lẹyin ti wọn fi ẹsun onikoko meje kan wọn ninu eyi ti ifipa doju ijọba bolẹ wa ninu rẹ.
Adajọ Ojukwu ni kosi idi kan to le mu ki ileẹjọ ma fun Sowore ati Bakare ni beeli.
Ṣugbọn adajọ kilọ fun Sowore pe ko gbọdọ ba awọn akọroyin sọrọ lẹyin beeli rẹ.
Ààrẹ Magugujfuli ní ẹgba ti àwọn àkẹkọ̀ọ̀ to dána sun ilé jẹ ko ti tó
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ààrẹ Magugujfuli ní ẹgba ti àwọn àkẹkọ̀ọ̀ to dána sun ilé jẹ ko ti tó
Ààrẹ orilẹ̀-èdè Tanzania, John Magufuli tí gboriyìn fún ọgà àgbà lẹ́nu iṣẹ́ ìjọba kan tó fi ẹgba lu àwọn akẹ́kọ̀ọ́ kan ti wọ́n fẹ̀sun kan pé wọn lọ dána sún ilé igbé ilé ẹkọ.
Èyí wáye lẹ́yin ti fọ́nran kan lú sita to sì sàfìhàn bí kọmisọna ẹkun kan ṣe ń àtori dábira fún àwọn akẹ́kọ̀ọ́ tí wọ́n dána sun ositẹli wọ́n, èyi ti mínísita fún ijọba ibilẹ si bẹnu àtẹ lu ǹkan ti kọmisọna náà ṣe.
Ní báyìí à[rẹ òrílẹ̀-èdè náà ti gbé sàdánkata káre fún kọmisọna náà.
"Ìròyìn sọ pé, ààrẹ Magufuli pé  Albert Chalamila lori ààgo láti kí kare, àti pé ǹkan to dara lo ṣe fún àwọn ọmọ náà '' kóda o yẹ ki o lù wan jùbẹ́ẹ̀ lọ"""
Bákan náà ni ààrẹ tún ke fun àtúnto òfin ilẹ̀ náà láti fún àwọn olùkọ to kù ni ànfani láti máà lú àkẹkọọ ko máà ṣe olori ilé iwé nìkan ni yóò ma ṣe bẹ́ẹ̀.
Ofin Tanzania sọ pé olori ilé ikwe nìkàn lo ni ẹtọ láti na àkẹ́kọ̀ọ́, tí ko ba wa lé lùú, yóò tọka si olùkọọ míràn to ba wùú láti bá òun náa ọmọ náà.
O pọ́ jù kò gbọ̀dọ̀ ju pàsán mẹ́rin lọ, gẹ́gẹ́ bi ofin náà ṣe sọ, ẹṣẹ̀ to ṣe gbòógi bníkan ni wọ́n le tori rẹ̀ lu ọmọ sí, bóti lẹ̀ jẹ́ pé òfin náà kò sọ ǹkan ti ẹ̀ṣẹ̀ gbòógi jẹ́
Èyí jẹ́ ǹkan míràn ti à[rẹ fẹ́ ki wọ́n yí pada nínú òfin, Magujfuli nígbàgbọ́ pé kí ọmọde to jẹgba ko nilo láti ṣe ẹ̀ṣẹ̀ ńlalá
Oríṣun àwòrán, Clouds Digital
Magufuli ni o yẹ ki àwọn ọmọ náà jẹ ju ẹgba ti wọ́n jẹ lọ
Ọkan nínú 2017 Human Rights Watch  sọ pé ǹkan ti wan ń ṣe ni Tanzania ti wọ́n ba lú ọmọ kìí ṣe ìbáwi bíkò ṣe pe titẹ ofin loju mọ́lẹ̀ èyi ti ko si yẹ ko ri bẹ́ẹ̀
Àjọ to n moju to ẹtọ ọmọniyan yìí ni àkẹkọ̀ọ́ binrin kan sọ pé ǹkàn ti oju àwọn rí lọ́wọ́ àwọn olùkọ kìí ṣe kèrémi. Ọ̀pọ̀ àwọn akẹ́kọ̀ọ́ binrin ni àwọn sọ pé igi ni àwọn olùkọ maa n jan mọ àwọn lọmu, koda nigbamiran ti awọn ba n ṣe ǹkan osu lọ́wọ́ wọ́n o ni ki àwọn bẹ̀rẹ̀ jẹgba titi ti gbogbo ìtẹdi yóò fi bẹ tí ẹjẹ yòó si maa jò.
Xenophobia: Àbọ̀ ààrẹ Muhammadu Buhari rèé láti ilẹ̀ South Africa
Oríṣun àwòrán, Twitter/Bashir Ahmad
Aarẹ Muhammadu Buhari ti pada si olu ilu orilẹede Naijiria, Abuja lọjọ Ẹti lẹyin abẹwo ọlọjọ meji si orilẹede South Africa.
Aarẹ Buhari ṣe oniruuru  ipade pẹlu aarẹ ilẹ South Africa, Cyril Ramaphosa lori ibaṣepọ laarin awọn orilẹede mejeeji.
Ikọlu awọn ọmọ Naijiria laipẹ yii jẹ ọka gbogii ninu ọrọ tawọn olori orilẹede mejeeji jọ sọ.
Aarẹ Buhari fi aidunnu rẹ si bi awọn ọmọ South Africa ti fiya jẹ awọn ọmọ Naijiria ti wọn n ṣe atipo lorilẹede South Africa.
Aarẹ Ramaphosa tọrọ aforiji lọwọ Aarẹ Buhari lori bi awọn ọmọ South Africa ti ba ọpọ dukia awọn ọmọ Naijiria jẹ ninu ikọlu ọhun.
Oríṣun àwòrán, Twitter/Bashir Ahmad
Oríṣun àwòrán, Twitter/Bashir Ahmad
Ẹwẹ, ile iṣẹ ọkọ ofurufu Air Peace ti ko awọn Naijiria bi igba meji pada sile lẹyin iṣẹlẹ ikorira alejo to waye ni South Africa.
Kidnapping: Ọwọ́ ọlọ́pàá ba Pásítọ̀ olórí ikọ̀ ajínigbé tó pa èèyàn márùn ún
Oríṣun àwòrán, Facebook/Policeng
Afurasi ọmọ ikọ ajinigbe kan Musa Umar, ti tu kẹkẹ ọrọ lori bi o ti ṣe maa n gbẹmi awọn eeyan ti wọn ba jigbe.
Umar to jẹ ọmọ ọdun mejilelogun yi ni alukoro ọlọpaa Frank Mba ṣafihan rẹ, pẹlu awọn afurasi miran nilu Abuja lọjọru.
Musa sọ pe, o ti to ọdun mẹta toun ti dara pọ mọ awọn ajinigbe yii, iṣẹ toun si ni lati maa gbẹmi awọn eeyan.
Afurasi yii ṣalaye lede abinibi rẹ, Hausa pe lati igba toun ti bẹrẹ, ọkunrin mẹta ati obinrin meji ni ẹmi wọn ti tọwọ oun bọ.
''Agbẹ ni mi bẹẹ si ni mo jẹ ajinigbe. Ikọ ajinigbe gba mi ṣiṣẹ lati maa pa awọn eeyan, bi a ba si ni ka ka ni meni meji, mo ti gbẹmi eeyan marun un.
Oríṣun àwòrán, Facebook/Policeng
Ọkunrin mẹta, obinrin meji. Katsina si ni wọn ti wa''
Pasitọ to n lewaju awọn ajinigbe pawo naa ko si panpẹ ọlọpaa:
Ẹwẹ, Frank Mba ṣe afihan Paitọ ẹni ọdun mejilelaadọta kan, Adetokumbo Adenopo to jẹ baba isalẹ fawọn ajinigbe kan.
Paitọ naa to jẹ oludasilẹ ijọ New Life Ministry, Lukosi ni Shagamu sọ fawọn ọtẹlẹmuyẹ ọlọpaa pe niṣe ni oun n ji awọn eeyan gbe nitori ki ijọ oun ba le gbooro si.
Frank Mba ni afurasi Paitọ yii lẹdi apo pọ pẹlu awọn ọdaran mẹta mii, lati ji Jonathan Ekpo gbe.
Fulani Kidnapping: Owó púpọ̀ la san kí wọ́n tó fi mi sílẹ̀
O ni wọn gbe Ekpo pamọ sinu aja ilẹ to wa ninu ile ijọsin Paitọ naa ni Ogijo.
Ogun miliọnu Naira ni wọn fẹ gba lọwọ mọlẹbi arakunrin naa, ki ọwọ ọlọpaa to tẹ wọn lọjọ kẹsan osu keje, ti wọn si fi si ahamọ.
Awọn afurasi wọn yii ti ọlọpaa ṣafihan wọn wa lara awọn ọdaran marundinlogoji, ti ileeṣẹ ọlọpaa ṣafihan wọn fun orisirisi iwa ọdaran.
Bakan naa, ileeṣẹ ọlọpaa to n mojuto ilu Abuja ti mu awọn afurasi mẹrinlelogun, ti wọn si ti gba orisirisi nnkan ija lọwọ wọn ṣaaju ọdun ileya to sunmọ yii.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ọ̀pọ̀lọ̀pọ̀ ìgbà ni ìjínigbé ti wáyé ní ojú ọ̀nà ìlú Abuja si Kaduna
Bala Ciroma, to jẹ ọga agba ọlọpaa nilu naa sọ pe, awọn gba ibọn atọwọda mẹrin, ibọn ẹtu kan ati ibọn atamataṣe kekere kan.
Ko tan sibẹ, wn tun gba ọta ibọn, foonu alagbeka mẹrindinlọgbọn ati siimu foonu mejilelogun, lọwọ awọn afurasi yi.
Awọn ajinigbepawo to ji awọn akẹkọ mẹfa ati olukọ meji gbe nileewe aladani kan nilu Kaduna ti n beere fun aadọta miliọnu naira gẹgẹ bii owo itusilẹ wọn.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Awọn obi awọn akẹkọ kan nileewe naa niroyin sọ pe wọn fi idi eyi mulẹ fawọn iwe iroyin abẹle kan lorilẹde Naijiria.
Gẹgẹ bii ohun ti wọn ni ọkan ninu obi naa sọ, ọgbọn miliọnu naira ni awọn ajinigbe naa n beere lori ọmọ kọọkan ti wọn ji gbe; ṣugbọn ọgọrun miliọnu naira lapapọ lawọn alaṣẹ ileewe naa ni agbara awọn ka.
Bi o tilẹ jẹ pe ileeṣẹ ọlọpaa ko tii fi iroyin tuntun sita lori ibi ti iṣẹ de duro lori ṣiṣe awari awọn akẹkọ ati olukọ naa, awọn obi ati alaṣẹ ileewe naa fi to awọn oniroyin leti pe ijiroro ṣi n ls lori iye owo ti wọn yoo gba fun itusilẹ wọn.
Customṣ Service: Ọkọ̀ tòkunbọ̀, àpò ìrẹsì àt'ohun ìjà olóró lọwọ́ òfin ti tẹ̀
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ileeṣẹ aṣọbode orilẹede Naijiria ni titi ti wọn ti awọn ibode orilẹede Naijiria pa ti n so eso rere.
Alukoro ileeṣẹ aṣọbode orilẹede Naijiria, Ọgbẹni Joseph Attah ni ko din ni ẹgbẹrun kan ati mejilelaadọrin ọkọ tokunbọ ti wọn ti ri gba lọwọ awọn onifayawọ.
Imam tó ṣí Mọ́ṣálásì fáwọn Krístẹ́nì sọ ìdí tí kò fi lè ta wọ́n nù
O ni ọwọ tẹ awọn ọkọ naa nigba tawọn to ni wọn n gbiyanju ati gbe wọn gba oju opo ti ko bofinmu wọ orilẹede Naijiria.
Nibi eto ilanilọyẹ ti ileeṣẹ aṣọbode gbe kalẹ lori akanṣe eto titi ẹnu ibode Naijiria pa to n lọ lọwọ eyi to waye ni ilu Katsina ni alukoro ileeṣẹ naa ti sọ ọrọ yii.
Toll Gate: Ó ṣe pàtàkì kí ìjọba kọ́kọ́ tún ojú popo ṣe naa- Awakọ̀
Bakan naa lo tun fi kun un pe, ẹgbẹrun mọkandinlogun apo irẹsi ati garawa epo bẹntiroolu to din diẹ lẹgbẹrun marun ni wọn tun gba lasiko naa.
O ni pe ko tan sibẹ, awọn ohun ija oloro titi kan ajilẹ tawọn kan fẹ fi ṣe ado oloro lọwọ awọn agbofinro naa tun tẹ.
BBNaija: Kiki Osinbajo gbóṣùbà fún Seyi Awolowo, MC Oluomo gbárùkù ti Mike
Oríṣun àwòrán, Instagram/Seyi Awolowo
Ti eegun ni ba mọọ jo, ori a ya atọkun. Gẹgẹ bẹẹ lọrọ ri pẹlu ọkan lara ọmọ igbakeji Aarẹ orilẹeede Naijiria, Kiki Osinbajo pẹlu ọrọ to sọ nipa eto agbelewo BBNaija.
Kiki to jẹ ọmọ ọmọ ọmọ Oloye Obafemi Awolowo gẹgẹ bi Seyi na ṣe jẹ to si jẹ ọkan lara awọn oludije ninu ile BBNaija ni Kiki sọ pe Seyi ti ṣe nnkan iwuri lati igba to ti wa nilu ile.
Kiki to sọrọ loju opo Instagram rẹ, lo rọ awọn eeyan lati dibo fun Seyi nibayii to kudiẹ ki eto naa pari.
Ẹnikan ninu Seyi tabi Mike Edward, Mercy Eke, Chemeka 'Frodd' Okoye, ati Kola 'Omashola' Oburoh ni yoo jawe olubori lori eto ọhun lọjọ Aiku.
Ṣugbọn bi ọrọ gangan an lọrọ ọhun, nitori alaga awọn awakọ nipinlẹ Eko, Musiliu Ayinde Akinsanya ti ọpọ mọ si MC Oluọmọ ni tirẹ ni Mike loun dibo fun un.
Bakan naa lo rọ awọn ọmọ Naijiria lati dibo fun Mike ko le wọle.
Koda MC Oluọmọ kọ nọmba Mike gadagba sori opo Instagram rẹ fawọn ololufẹ rẹ pe ki wọn dibo fun Mike.
"A gbúdọ̀ wẹ̀ ọmọ tuntun pẹ̀lú epo pupa, kàìnkàìn ìbílẹ̀ àti ọṣẹ dúdú'
Chibok Girls: Jonathan n'írọ́ ni Cameron pa pé òun kọ ìrànwọ́ láti dóòlà àwọn akẹ́ẹ̀kọ́ Chibok
Oríṣun àwòrán, Facebook/Goodlucj Jonathan
Olootu ijọba ilẹ Geẹṣi tẹlẹ ri, David Cameron, irọ nla lo pa mọ mio. Aarẹ ana orilẹede Naijiria, Goodluck Ebele Jonathan lo sọ bẹẹ.
Ọgbẹni Cameron lo kọ ninu iwe rẹ, to pe akọle rẹ''For the Record pe ijọba Naijiria labẹ akoso Aarẹ Jonathan kọ eti ikun si imọran lati ṣeranwọ fun Naijiria lati doola ẹmi awọn akẹẹkọbinrin ileewe Chibok tawọn ẹgbẹ agbesunmọmi Boko Haram jigbe lọjọ kẹrinla oṣu kẹrin ọdun 2014.
Aarẹ ana orilẹede Naijiria, Jonathan ninu esi rẹ lọjọ Abamẹta sọ pe o ba oun lọkan jẹ pe Ọgbẹni Cameron le sọ iru ọrọ bayii nitori ko si ohun to jọ bẹẹ rara.
Jonathan ṣalaye pe oun kọwe iranwọ gẹgẹ aarẹ Naijiria nigba naa si Cameron, ati si Aarẹ ilẹ Amẹrika nigba naa, Barrack Obama Amẹrika pẹlu Aarẹ ilẹ Faranse, François Hollande ati olootu ijọ orilẹde Israel, Benjamin Netanyahu lasiko naa.
Jonathan sọ pe ko mu ọpọlọpọ dani pe oun toun kọ iwe iranwọ naa lo wa tun sọ pe oun ko nilo iranwọ lati ilẹ okere.
Aarẹ orilẹde Naijiria tẹlẹ ri tun sọ pe oun loun fọwọ si ki awọn ọmọ-ogun ilẹ Gẹẹsi pẹlu atilẹyin awọn ọmọ ogun bẹrẹ iṣẹ lati doola ọmọ ilẹ Gẹẹsi kan, Ọgbẹni Chris McManus ati ọmọ ilẹ Italy kan, Franco Lamolinara tawọn Boko Haram ji gbe.
Jonathan tun ṣalaye siwaju pe ijọba ilẹ Gẹẹsi labẹ aṣẹ olootu Theresa May lọjọ kẹjọ oṣu kẹta ọdun 2018 naa jẹri si wi pe ko si otititọ kan ninu ọrọ ti Cameron sọ yii.
Kwara Assembly: Ilé Arúgbó Saraki la fẹ́ lò fún ilé ìwòsàn àwọn òṣìṣẹ́
Oríṣun àwòrán, @NGRSenate
Ile Asofin Kwara ni ijọba lo ni ilẹ ati ohun ini ti awọn gbe ẹsẹ le,kii se gomina tẹlẹri, Bukola Saraki.
Ile Asofin ni ipinlẹ Kwara ti pasẹ pe ki wọn gba ilẹ ti wọn n pe ni  'Ile Arugbo' pada lọwọ Aarẹ Ile Igbimọ Asofin tẹlẹri, Bukola Saraki.
Ile asofin naa sọ wi pe ijọba ipinlẹ Kwara lo ni ilẹ naa, kii se Bukola Saraki lo san owo ilẹ naa.
Atẹjade kan ti Oluranlọwọ fun olori Ile, Ibrahim Sheriff fi lede sọ wi pe, ko ba ofin mu bi ijọba ana ni ipinlẹ naa, se fun Saraki ni ilẹ ọhun, nitori ofin to jẹ mọ eto ifẹyinti ni ipinlẹ Kwara ti pin ẹtọ Saraki fun un.
O fi kun wi pe Ile Arugbo naa ni wọn fẹ lo fun ile iwosan awọn oṣiṣẹ ati ile isẹ ijọba keji, ti ko si si ẹri pe ẹnikẹni san owo fun un.
Ile Igbimọ Asofin naa wa parọwa si ẹnikẹni ti ko ba tẹ lọrun lati fi ẹri han wi pe, awọn san owo fun ilẹ naa.
Teachers‘ new salary in Nigeria: Wike ní owó oṣù tuntun fáwọn olùkọ́ tí Buhari kéde yóò dá aáwọ̀ sílẹ̀
Oríṣun àwòrán, Facebook/Nyesom Wike
Gomina ipinlẹ Rivers, Nyesom Wike ja gudugbẹ ọrọ lulẹ lẹyin to sọ pe akanṣe owo oṣu fawọn olukọ ti ijọba apapọ kede rẹ laipẹ yii yoo da aawọ silẹ lẹka eto ẹkọ ni Naijiria.
Wike to sọrọ ọhun nipasẹ kọmiṣọnna eto iroyin ati ibaraẹnisọrọ, ṣalaye pe lotitọ ni o dara lati ṣeto owo oṣu tuntun fawọn olukọ.
Ṣugbọn o ni o ṣe pataki lati maa fi ọrọ oṣelu bọ ọrọ naa.
Ko ṣai sọ pe o dara lati mu ọrọ awọn olukọ ni baada nitori ipa ribiribi ti wọn n ko lori idasoke awujọ.
Amọ, o sọ pe ijọba apapọ fi ẹtẹ silẹ, o n pa lapalapa nitori o kọ eti ikun si ọrọ eto ati maa pin owo tuntun fawọn ipinlẹ ṣugbọn o kede akanṣe owu oṣu tuntun fawọn olukọ.
Ondo election 2020: Àwọn ara ìpínlẹ̀ Ondo ránṣẹ́ sí Akeredolu ohun ti wọ́n ń retí ní báyìí
Wike ni ikede akanṣe owo oṣu tuntun fawọn olukọ yo fikun ẹru to wa lori awọn ijọba ipinlẹ.
Ọjọ Karun osu Kẹwa ọdun 2020 yii tii ṣe ayajọ ọjọ awọn olukọ lagbaaye ni ijọba apapọ kede akanṣe owo oṣu tuntun fawọn olukọ ni Naijiria.
Oríṣun àwòrán, @UNICEF_Nigeria
Àkànṣe owó oṣù lá wa olùkọ́ ń fẹ́ yàtọ̀ sí tàwọn òṣìṣẹ́ ìjọba míì - NUT
Ọjọ Karun osu Kẹwa ọdọọdun ni ayajọ ọjọ awọn olukọ lorilẹede Naijiria eyi to ko lọjọ Abamẹta.
Sugbọn ọjọ naa ko lọ lasan lai jẹ pe awọn olukọ beere ọkan o jọkan  ohun ti wọn n poungbẹ lọwọ ijọba, pataki ibeere wọn si ni agbekalẹ akanse owo osu fun awọn osisẹ.
Nigba to n gbẹnu awọn olukọ sọrọ, aarẹ apapọ fun ẹgbẹ awọn olukọ jakejado orilẹede Naijiria lasiko ayajọ ọjọ olukọ naa, Mohammed Nasir Idris salaye pe yoo dara ki akanse owo osu wa fawọn olukọ ki ijọba lee safihan bi awọn olukọ ti se pataki si taa ba wo ọrọ aje ti ko fara rọ yii.
Igbagbọ wa ni pe akanse owo osu fawọn olukọ (TSS) yoo mu ki isẹ olukọ da yatọ, ti yoo si tun fun isẹ olukọ ni idamọ to dara, taa si to si ipo ẹyẹ lawujọ, a wa n rọ ijọba lati tete buwọlu ibeere yii."""
Oríṣun àwòrán, @GovernorObaseki
Idris, lasiko to n sọrọ lori akori ayajọ ọjọ olukọ naa, ti wọn pe ni 'Ọdọ Olukọ ni ọjọ ọla fun isẹ olukọ', tun kesi ijọba apapọ lati tete san owo ida mẹtadinlọgbọn ati aabọ owo ajẹmọnu isẹ fawọn olukọ to wa lawọn ileekọ girama tijọba apapọ, nitori eyi lo ni yoo jẹ ki ori awọn olukọ naa wu lati sisẹ bo se yẹ.
Abayọmi Aranmọlatẹ, Dr Laser: Vagino Plasty àti iṣẹ́ abẹ ẹwà Obìnrin ló jẹ mí lógún
Wayi o, agbẹjọro agba fun Naijiria Abubakar Malami, to soju fun aarẹ Buhari nibi eto ti wọn fi n sami ayajọ olukọ naa, kede pe ijọba apapọ yoo fọwọ sowọpọ pẹlu ijọba ipinlẹ lati pese eto koriya fawọn olukọ, paapa awọn to wa lagbegbe igberiko.
Oríṣun àwòrán, @UNICEF_Nigeria
Malami ni yatọ si pe eyi yoo mu kawọn ọdọ setan lati sisẹ olukọ, bakan naa tun ni ijọba yoo seto idanilẹkọ atigbadegba fun wọn.
BBNaija: Mercy ló gbadé BBNaija ọdún 2019
Oríṣun àwòrán, Instagram
Ko si ohun to ba ni ibẹrẹ, ti kii lopin, bẹẹ lọrọ ri pẹlu eto Big Brother Nigeria to ti n waye lati bi osu mẹta sẹyin.
Lẹyin ọ rẹyin Mercy lo jawe olubori lori eto ọhun, oun lo ẹbun owo ọgọta miliọnu naira lọ ile.
Mike Edwards lo ṣe ipo lẹyin to ri ibo to pọju lọ sikeji lẹyin Mercy.
Bẹẹ ba gbagbe, awọn oludije mẹrindinlọgbọn lo bẹrẹ eto BB Naija fun tọdun yii, ti wọn pe akọle rẹ ni 'Pepper Dem', ti oludije mọkanlelogun si ti ja kulẹ lasiko kan tabi omiran.
Seyi, Frodd àti Omashola dèrò ilé lórí ètò BBNaija
Ko si ohun to ba ni ibẹrẹ, ti kii lopin, bẹẹ si lọrọ ri pẹlu eto Big Brother Nigeria to ti n waye lati osu mẹta sẹyin.
Loni ọjọ Aiku si ni gbogbo eeyan yoo mọ ẹni ti yoo jaye olubori lati gba ọgọta miliọnu naira laarin awọn oludije marun to sẹkun nile BB Naija.
Oríṣun àwòrán, Instagram/Seyi Awolowo
Bẹẹ ba gbagbe, awọn oludije mẹrindinlọgbọn lo bẹrẹ eto BB Naija fun tọdun yii, ti wọn pe akọle rẹ ni 'Pepper Dem', ti oludije mọkanlelogun si ti ja kulẹ lasikokan tabi omiran.
Lara awọn oludije to ku nile ni Seyi, Omashola, Mercy, Mike ati Frodd, ti anfaani si wa fun ikọọkan wọn lati moke, ti yoo si gba ẹbun owo miliọnu lọna ọgọta naira.
Oríṣun àwòrán, Instagram
Oríṣun àwòrán, @BBNaija
Koda, ọpọ awọn ololufẹ ikọọkan awọn oludije wọnyi lo ti n dibo fun ẹni ti ọkan wọn fẹ pe ko moke lori ayelujara, ti gbogbo eeyan si n foju sọna pe taa ni owo naa yoo ja mọ lọwọ.
Idahun di alẹ oni, ẹ sa maa ba wa bọ lati gbọ abọ iroyin lori ẹni to moke nile Big Brother Nigeria fun tọdun yii.
Yollywood: Yomi Fabiyi ní ìwà aṣiwèrè ni bí ọlọ́pàá ṣe ń tẹ ẹ̀tọ́ ọmọnìyàn lójú, táwọn òṣèré tíátà náà ń lò nínú fíímù
Oríṣun àwòrán, Others
Ilumọọka osere tiata kan, Yomi Fabiyi ti gbarata loju opo Instagram rẹ pe, ohun ti ko dara ni bi awọn agbofinro se n tẹ ẹtọ ọmọniyan loju, eyi ti awọn osere tiata naa n gbe jade ninu ere.
Yomi Fabiyi, ẹni to se apejuwe iwa titẹ ẹtọ ọmọniyan loju ti awọn agbofinro lorilẹede Naijiria n se gẹgẹ bii iwa asiwere, tun kede pe awa ọmọ Naijiria kii se ẹranko, yoo si dara ki wọn dẹkun iwa ailaju naa.
Afihan iwa idojuti ati ailaju gbaa ni titẹ ẹtọ afurasi mọlẹ, eyi to n fa ọwọ aago idagbasoke orilẹede Niaijira sẹyin, to si tun n dena iwa alaafia pẹlu. Ẹ se idanilẹkọ ati itankalẹ iroyin yii, ki awọn ti ko mọ ẹtọ wọn lee mọ.
Oríṣun àwòrán, realyomifabiyi
Fabiyi wa kesi awọn akẹẹgbẹ rẹ to jẹ osere tiata pe ki wọn ti ọwọ ọmọ wọn bọ asọ nidi sise atilẹyin ninu fiimu fun awọn agbofinro lati maa fiya jẹ awọn afurasi.
O yẹ kẹ mọ isẹ yin bii isẹ, nitori pe awọn ọlọpaa n hu iwa yii, ko sọ pe ki awa naa se bẹẹ ninu ere tiata wa. Ere sinima kii se eremọde, oju taye fi n wo wa se pataki, ohun to tọ si lo yẹ ki awa osere maa gbe jade.
Fabiyi tun fi kun pe,  awọn osere tiata lee se afihan bi awọn agbofinro se tẹ ẹtọ ọmọniyan loju mọlẹ, to ba jẹ pe wọn yoo se afihan iya ti iru agbofinro naa jẹ lori iwa aidaa to hu ọhun.
Lara awọn ohun ti Fabiyi tun mẹnuba pe ko dara ninu ere, eyi to ni kawọn osere tiata yee safihan rẹ mọ ninu fiimu ree:
Boko Haram: Àwọn Alfa tíjọba Borno bẹ̀ lọ́wẹ̀ ti gbé ní Saudi fún ọ̀pọ̀ ọdún
Oríṣun àwòrán, @mzk11uk
Ijọba ipinlẹ Borno ti gbọna mii yọ lọna ati fopin si ikọlu ẹgbẹ aṣẹrubalu Boko Haram, bi gomina ipinlẹ naa, Babagana Zulum ṣe bẹ awọn alfa ọgbọn lati Saudi lọwẹ lati ba gbadura fun ipinlẹ ọhun.
Agbẹnusọ fun gomina ọhun, Isa Gusau sọ fun awọn oniroyin pe awọn alfa naa to jẹ ọmọ Naijiria, ti gbe ni ilu Makka fun ọpọlọpọ ọdun.
Gusau ni, awọn alfa ọhun lo n fi tọsan toru gbadura ni Ka'aba.
O ṣalaye pe ẹni to dagba julọ ninu awọn alfa naa ti lo ogoji ọdun ni Ka'aba.
"Agbẹnusọ fun gomina naa ni ""Ka'aba jẹ ibi mimọ julọ to wa ni moṣalaṣi Al-Haram ni Makkah."""
O sọ siwaju si pe, idi ti ijọba ọhun fi gbe igbesẹ lati bẹ awọn alfa naa lọwẹ wa lati ran awọn ọmọ ologun Nigeria lọwọ ninu ija wọn pẹlu ẹgbẹ Boko Haram.
Gusau ṣalaye pe ijọba ipinlẹ Borno nilo adura gidigidi lasiko yii ki alafia le jọba ni ipinlẹ naa.
Igbesẹ yii lo waye lẹyin ọjọ diẹ ti ọga agba fun ajọ ologun Naijiria, Tukur Buratai ni oirilẹ-ede yii nilo adura lati koju ẹgbẹgun Boko Haram.
Kunle Olasope: Lekan Alabi ní onírẹ̀lẹ bíi àgbà àgbóhùnsáfẹ́fẹ́ náà sọ̀wọ́n
Oríṣun àwòrán, Others
Kìí ṣe ohun tuntun mọ pé ọkunrin akọkọ to farahan lori amohunmaworan, Kunle Olasope ti fí duniyan silẹ sùgbọ́n àwọn alábasisẹ́ pọ̀ rẹ nigba ayé rẹ tí n jẹri si ǹkan ti wọn mọ̀ọ nipa rẹ.
BBC Yoruba ba ọkàn nínú àwọn alábasiṣẹ́ pọ rẹ lẹ́nu iṣẹ́ ìròyìn sọ̀rọ̀, tii tun se Agba oye kan nilẹ Ibadan, Lekan Alabi sàlàye pé òun mọ baba náà fún ìgbà àkọkọ ní ọdún 1964, nígbà ti òun wà ní ọmọ ọdún mẹrinla.
Oloye Lekan Alabi ní àsìkò náà ni Olasope wa fún ìdánilẹkọọ nile iwe òun, sùgbọ́n isọrọ̀ si, ìrìn àti ìwọsọ bàbá naa lo jẹ ki òun bẹ̀rẹ̀ si ni fi èrò si láti yan iṣẹ́ iroyin láàyo.
Agbaoye Alabi fí kun pé, lẹ́yìn ti oun tún pari ilé iwé , ore-ofẹ́ tún yọ láti le jọ ṣiṣẹ́ papọ tí o si fún oun ni ànfani láti le kọ ẹkọ bi ènìyàn ṣe le ṣe iṣẹ́ ìròyìn bo ti tọ́ àti bi o ti yẹ.
O ní iṣẹ́ Olasope yii jọ mọ abini nítori pe, o mọ bi a tii se àgbékalẹ̀ ìròyìn, èyí ti kò wọ́pọ̀ mọ bayìí láàrin àwọn akọroyin, pàápàá julọ bi awọn sọ̀rọ̀sọ̀rọ̀ kìí ṣe ni ìwé àkọsilẹ mọ, ki wọn to wọ yàrá ìgbóhùn sáfẹ́fẹ́.
Alabi ni bo tilẹ jẹ́ pé kìí ṣe abẹ rẹ tààrà ni oun ti ṣiṣẹ̀, síbẹ̀, ìgbé aye Olasope jẹ ǹkan ti eniyan ń tẹ̀le, ṣe ni ti èdè ni tàbí làákàyé? o tẹramọsẹ, kìí si se ọ̀lẹ̀.
"Eyi to ṣe pàtàkì jùlọ ni pé, Ọtunba Kunle Olasope kìí korira ẹnikẹni, kìí ṣe ìgbéraga tàbi ko ma foju pa ẹnikẹni rẹ.
Bí Kunle Ọlasọpe, ìlúmọ̀ọ́ká agbóhùnsáfẹ́fẹ́ ṣe lo ìgbésí ayé rẹ̀ rèé
Awaye ku ko si, ọrun ma kanju, gbogbo wa la n bọ.
Oloogbe Kunle Ọlasọpe, tii se ọkunrin akọkọ to fi oju han lori mohunmaworan ti waye, to si ti lọ, amọ o yẹ ka ran ara wa leti nipa awọn ohun ribiribi to gbe ile aye se.
Ọjọ Aiku, ọjọ Kẹfa, Osu Kẹwa, ọdun 2019 ni gbajugbaja agbohunsafẹfẹnaa, Kunle Olasope jade laye lẹni ọgọrin ọdun amọ bi onirese rẹ ko ba fin igba mọ, eyi to ti fin silẹ ko yẹ ko parun.
Kunle Olasope ní ifẹ si isẹ iroyin lo jẹ ko lọ si ileesẹ agbohunsafẹfẹ BBC lati lọ gba imọ kun imọ nipa isẹ igbohunsafẹfẹ lọdun 1962.
Gẹgẹ bi itan igbe aye rẹ ti sọ fun wa lori ayelujara, baba to bi baba Olasope ni iyawo mẹwa, ti iya tirẹ si jẹ iyawo keji, ti oun naa si jẹ ọmọ kẹfa ninu ọmọ mẹrindinlọgbọn.
Oríṣun àwòrán, Others
Ifẹ rẹ fun iroyin lo jẹ ko lọ si ileesẹ agbohunsafẹfẹ BBC lati lọ gba imọ kun imọ nipa isẹ igbohunsafẹfẹ lọdun 1962.
Nkan to yẹ ko o mọ nipa Baba Kunle Olasope:
Bobrisky: Ìjọba ní kí àwọn ọmọ Naijiria yàgò fún Bobrisky
Oríṣun àwòrán, @bobrisky222
Ijọba apapọ ti kilọ fun awọn awakọ lati ma a sọra fun Bobrisky paapaa nipa ajọlo yara igbọnsẹ.
Ijọba apapọ ni awọn fi ikilọ yii lede lẹyin ti Bobrisky da rogbodiyan kan silẹ ni papakọ ofurufu Nnamdi Azikwe ni ilu Abuja, nigba ti wọn ri i to n lo yara igbọnse awọn obinrin.
Ijọba wa rọ ẹka ilera lorilẹede Naijiria lati la awọn eniyan lọyẹ nipa ewu to wa ninu lilo yara igbọnse kan naa pẹlu Bobrisky.
Ijọba fi kun wi pe, oun to lewu pupo ni fun obinrin lati ma a ba Bobrisky lo ile igbọnsẹ pọ, wọn ni o buru ju aisan Ebola lọ.
2023 Presidency: Tunde Bakare ní ẹ̀yà kan ko jùkan lọ láti dari Nàìjíríà
Presidency 2023: Ẹ̀yà kan o jukan lọ láti dari Nàìjíríà
Alákòso ijọ Latter Rain Assembly, olusọaguntan Tunde Bakare ní kò sí ẹ̀yà kankan tó ni ẹtọ láti maa nìkàn dári orilẹ̀-èdè Nàìjíría.
Bakare láìpẹ yìí ti kédé pe oun yóò di ààrẹ lẹ́yìn ààrẹ Muhammadu Buhari lọdun 2023, sàlàye pé ó jẹ ǹkan to maa ń ru òun nínú nígbà ti àwọn ẹ̀yà kan kò ṣe fí fọkan tan ti wọ́n ba jáde.
O ní bó tilẹ̀ jẹ́ pé pinpin ipo aarẹ ní ẹlẹkun jẹkun kò si nínú akọsilẹ ofin orilẹ̀-èdè yìí, síbẹ̀ ó ti mú ki ìsọkàn wà ní Nàìjíríà.
Olùsọ àguntan Bakare sọ èyí lásìkò to n fọ̀rọjomitoro pẹ̀lú àwọn oníròyìn lẹ́yìn to pari ìwáàsu nilé ìjọsin rẹ.
Presidency 2023: Ẹ̀yà kan o jukan lọ láti dari Nàìjíríà
Bakare ní;  àsìkò ti to láti jọ jumọ jòkó ps láti jíròrò, tóri èyí ni mo se sọ pé ó yẹ ki ènìyàn bi ààrẹ Muhammadu Buhari ní láti jígìrì kúrò lóri à ń fari apákan dá apákan si pẹ̀lú ọ̀rọ̀ ẹ̀yà mẹya."""
O máa ń bí mi nínú tí mo ba ń gbọ pé àwọn ẹ̀yà kan ko ṣe fọ̀kàn tan àwọn ẹ̀yà kan láti gbé agbára ìjọba Nàìjíríà fún.
Bakare ní kí Nàìjíríà tó le tẹ̀síwájú, ó ṣe pàtàkì kí gbogbo ẹyà parapọ láti yan ẹni tó tọ, ki wọ́n yee funra si pé ẹyà kan lo le ṣe ìjọba tàbi ẹyà kan kọ́.
Ìtàn Mánigbàgbé: Adebisi Idikan ni olówó tó kọ́kọ́ ra ọkọ̀ nílẹ̀ Ibadan
Oríṣun àwòrán, Busari Adebisi
Ilu Ibadan jẹ ilu to gbajumọ nilẹ Afirika ati lawujọ agbaye, to si ni awọn akọni ẹda ti ko lonka.
Ọkan lara awọn ọmọ bibi ilẹ Ibadan to jẹ akọni ti ko see gbagbe ni Asiwaju Sanusi Adebisi Giwa Idikan.
Gẹgẹ bi itan ti sọ fun wa, olowo, ọlọrọ ati ẹlẹyinju aanu ni Adebisi nigba aye rẹ eyi to to ọgọrun un ọdun sẹyin.
Gẹgẹ bi a se rii ka loju opo itakun agbaye, olokiki ati gbajumọ nla ni ọkunrin yii, ti okiki rẹ si tan kale, ka oko ati nilẹ okeere.
Koda, Adebisi kọ ile agbayanu ati awodamiẹnu kan si agbegbe Idikan nilu Ibadan, eyi to ni ojule to lee ni ọgọrun un, eyi si lo mu kawọn ọmọ Yoruba fi maa powe pe 'N o kọle mi bii ti Adebisi, esu aini kọ ọkankan ni'
Awọn ohun arikọgbọn nipa Sanusi Adebisi Idikan:
'Èmi gan máa ń béèrè lọ́wọ́ ara mi pé ta ni Wole Soyinka gangan'
Sogidi Lake: Kòṣẹja-kòṣèèyàn lá bá nínú adágún odò náà -Ojedele
Ikogosi-Ekiti: Ilu ti omi tutu ti dapọ mọ gbigbona
Coronavirus symptoms in Nigeria: Pẹ̀lú èròjà olùgbèjà ara 'Antibodies'
Coronavirus tips: Kìí ṣe gbogbo ìbòmù ló ń dá coronavirus dúró
Coronavirus ti di ara wa, kò le è kúrò mọ láéláé - WHO
Ẹfunroye Tinubu - Ògbóǹtagí oníṣòwò, olówò ẹrú àti afọbajẹ
Samuel Ajayi Crowther, òjíṣẹ́ Ọlọ́run tó gbé èdè Yoruba lárugẹ
Mọrèmi Àjàṣorò, akọni obìnrin tó gba Ilé Ifẹ̀ sílẹ̀ lóko ẹrú
Ọ̀rọ̀ǹpọ̀tọ̀niyùn, Aláàfin obìnrin àkọ́kọ́ rèé, tó ní nǹkan ọkùnrin
Fidio ti BBC Yoruba se nipa ile Adebisi to wa ni Idikan ree nisalẹ yii:
Adebisi Idikan: Òun ló gba Ìbàdàn sílẹ̀ lọ́wọ́ ìyà owó orí sísan
A wa n gbadura pe Ọba oke yoo dẹ ilẹ fun Asiwaju Sanusi Adebisi Giwa Idikan, gẹgẹ bi a se n ranti iwa rere to gbe ile aye se lasiko yii, nitori bi onirese rẹ ko tilẹ fin igba mọ, awọn eyi to ti fin silẹ, ko parun rara.
BBNaija: Kayọde Ogundamisi ní akọ́nilọ́gbọ́n, amúlùúdùn ni BBNaija, kìí ṣe òṣèlú
Oríṣun àwòrán, @BBNaija
Eto BBNaija ti wa, to si ti lọ amọ ariyanjiyan nipa pataki eto naa sawọn ọmọ Naijiria ko tii buse.
Ọpọ ọmọ Naijiria lo n beere pe ki ni awọn ọdọ ri ti wọn se n suru bo eto naa nigba to jẹ pe awọn ọrọ miran to se koko wa nilẹ Naijiria, eyi to nilo ki wọn kọbi ara si wọn.
Yatọ si eyi, iye ibo ti awọn ọdọ di lori BBNaija ati iye owo ti irufẹ awọn ibo yii pa wọle si apo awọn eeyan to se agbatẹru eto naa gan, tun n kọ awọn ọmọ́ Naijiria kan lominu.
Gẹgẹ baa se gbọ, miliọnu lọna ogoje ni apapọ ibo tawọn ọdọ di fun oludije kan abi omiran lori eto ọhun, bi o tilẹ jẹ pe awọn miran di ibo ju igba meji tabi mẹta lọ.
Oríṣun àwòrán, @BBNaija
Olukayode Ogundamisi ti ní kí àwọn ọmọ Naijiria yé bu ẹnu àtẹ́ lu Big Brother Naija, nítorí óhún mú inú àwọn ènìyàn dùn.
Taa ba si gbe eyi fẹgbẹkẹgbẹ pẹlu apapọ ibo taa di lasiko ibo aarẹ ni Naijiria, ọna jin si ara wọn nitori ibo miliọnu mejidinlọgbọn o le diẹ ni ajọ eleto idibo kede pe ọmọ Naijiria di lasiko ibo aarẹ to kọja.
Idi si ree ti awọn ọmọ Naijiria se n beere pe, ki ni pataki eto BBNaija fawọn ọdọ, eyi to lowura ju eto iyansipo olori isejọba Naijiria lọ?
Nigba to n dahun ibeere yii, oludamọran lori ọrọ ilu ati ilẹ okeere, Olukayode Ogundamisi ni nkan arikọgbọn pọ lorisirisi ninu ere Big Brother Naija.
Ogundamisi, lasiko to n ba BBC Yoruba sọrọ, salaye siwaju pe, awọn ọmọ Naijiria n mu inu ara wọn dun lori eto naa, ati wi pe, ohun idanilaraya lo jẹ fun wọn.
Oríṣun àwòrán, @BBNaija
O fikun wi pe ọrọ ki ilu dara tabi ko gbooro ko nii se pẹlu ere idaraya, ati wi pe, a ko gbọdọ dina awon eniyan lati je ki won wo nkan to ma a mu inu wọn dun.
Oludamọran lori ọrọ ilu ati ilẹ okeere naa ni, ko si ohun to ti ni loju ninu eto adanilaraya, ati wi pe awọn eniyan fẹran idaraya ju ogun tabi ija lọ.
Ogundamisi ni ko si nkan to buru ninu rẹ nitori ko si wi pe awọn eniyan n dibo pẹlu ipaya pe, laasigbo tabi wahala le bẹ silẹ lawujọ.
Amọ, o parọwa si awọn ọdọ lati mu isẹ wọn ni ọkunkundun, ti wọn si jẹ ki ọro ilu naa ka wọn lara lati le mu igbelarugẹ ba orilẹede Naijiria.
Sex For Grades: Four Square Church tí ní kí olùkọ́ fásitì Pasitọ̀ Boniface lọ fìdímọ́lé
Oríṣun àwòrán, @unilag
UNILAG ko fọwọ si iwa ibajẹ biba akẹkọọ sun nitori maaki rara.
Àwọn aláṣẹ fásitì Eko ninu atẹjade ti ti kéde pé ki Omowe Boniface lọ rọọ́kún nílé ná
Fasiti Eko kede pe Ọmọwe Boniface ko gbọdọ lọ si agbegbe ikọwe ni fasiti naa lẹyin ipade pajawiri ti wọn ṣe.
Lẹyin ti ile iṣẹ BBC gbe iwadii wọn sita lori awọn olukọ kan nile iwe giga iwọ oorun ilẹ Adulawọ ti wọn n beere fun ibalopọ ṣaaju maaki ni oriṣiiriṣii nkan ti n ṣẹlẹ.
Iṣẹ iwadii BBC yii ṣafihan olukọ ni fasiti ijọba apapọ ni Eko ati ni Ghana ni eyi to ti n tu aṣiri oriṣiiriṣii sita bayii,
Africa Eye: Olùkọ́ méjì ní fásitì Eko àti Ghana lùgbàdì ọ̀fíntótó BBC lórí ìwà ìbàjẹ́
Fasiti Eko to gba Omowe Boniface Igbeneghu to n kọ awọn akẹkọọ nipa ede ajoji tilẹ Yuroopu ni fasiti naa ti ni ko ṣiwọ iṣẹ na.
Kete ti fidio BBC yii n ja nilẹ ni awọn alaṣẹ Fasiti Eko ti pe ipade pajawiri lori ọmọwe Boniface.
Lẹyin ti ọpọ nkan ti n ṣẹlẹ lẹyin ti iwadii BBC yii jade ni fasiti Eko ni wọn ti ni ki Boniface lọ rọọkun nile naa titi awọn yoo fi pari iwadii wọn lori ọrọ yii.
Boniface yii ni awọn ọmọ igbmọ ni fasiti UNILAG yoo ṣe iwadii to yẹ lori ẹsun fidio naa ki fasiti Eko to mọ ohun to kan.
Fasiti Eko mẹnuba awọn ilana ofin ileewe giga naa lori ibalopọ ati iwa aitọ laarin akẹkọọ ati olukọ.
Fasiti Eko ni gbogbo olukọ ti ade iwadii BBC ba si mọ lori lo maa foju wina ijiya to tọ.
Bakan naa ni fasiti yii ṣeleri lati rii pe ọkan awọn akẹkọọ wọn balẹ pẹlu fifi iya to tọ jẹ awọn ti akẹkọọ ba fẹsun kan ti iwadii si fidiẹ mulẹ.
Oríṣun àwòrán, @unilag
Koda UNILAG ti iyara Cold Room pa lẹyin fidio BBC
Odindin ọdun kan ni BBC fi ṣe iṣẹ iwadii yii to ṣafihan iwa buruku awọn olukọ kọọkan ni fasiti iwọ oorun ilẹ Adulawọ yii.
Bakan naa ni awọn alaṣẹ ijọ Olorun Four Square ti ọmọwe Boniface ti n jọsin naa kede pe ko dẹkun gigun pẹpẹ iwaasu titi iwadii wọn yoo fi pari.
Four Square Church tí ní kí olùkọ́ fásitì Eko, Pasitọ̀ Boniface, lọ fìdímọ́lé.
Ile ijọsin naa ni awọn gbe igbesẹ yi lati le sẹ iwadii ẹkunrẹrẹ lori ẹsun ti wọn fi kan olukọ fasiti naa.
Ile ijọsin Four Square Gospel Church Nigeria ti paṣẹ ki Pasito Boniface Igbenoghu lo fidi mọle titi ti awọn yoo fi pari iwadii lori rẹ.
Four Square Church tí ní kí olùkọ́ fásitì Eko, Pasitọ̀ Boniface, lọ fìdímọ́lé.
Igbesẹ yi ko ṣẹyin iroyin iwadii kan ti ile iṣẹ BBC gbe jade lori ifipabanilopo lati le fi gba maaki eleyi to ṣafihan Pasito Boniface nibi ti o ti n hu iwa aitọ si akẹkọbinrin kan.
Loju opo Twitter ati Facebook ile ijọsin naa ni wọn fi atẹjade si eleyi ti Rev. Ikechukwu Ugbaja fi ọwọ si.
Ninu atẹjade naa, ile ijọsin naa ni awọn ko ''faaye gba iru iwa buruku bayi ati pe awọn ko lọwọ si iru iwa ti Pasitọ Boniface hu yi''
Oríṣun àwòrán, @others
Four Square sọrọ lori olukọ fasityi Eko pe...
"Wọn tẹsiwaju pe ''A o gbe igbesẹ to ba yẹ lori ọrọ yii nigba ti a ba pari iwadii wa""."
"Ki o to di igba naa, a ti paṣẹ pasitọ ti ọrọ yi kan ki o maṣe kopa ninu iwaasu kankan."""
Oríṣun àwòrán, Twitter/Foursquare Gospel Church
Oludari ile ijosin Four Square Gospel Church
Ẹwẹ, awọn akẹkọọ ni fasiti ilu Eko ti o ba BBC sọrọ lawọn ko tii foju kan olukọ naa lẹyin ti BBC gbe fọnran fidio naa jade lọjọ Aje.
Ọjọ gbogbo ni t'ole..... iṣẹ olukọ ko yẹ ko mu iwa ibajẹ bayii dani
Igbagbọ awọn obi ati alagbatọ to ran akẹkọọ lọ sile iwe ni ki wọn lọ kawe, ki wọn si di eeyan lọjọ ola.
Laye atijọ olukọ dabi obi ati alagbatọ fawọn akẹkọọ, ṣugbọn nkan ti yipada lasiko yii nile ẹkọ giga gbogbo.
Ọpọ awọn olukọ lo ti n jẹ koriko abẹ wọn, ti wọn n huwa aitọ nipa biba awọn akẹkọọ sun.
Lẹyin ti ileeṣẹ BBC gbe iwadii wọn jade to ṣafihan olukọ fasiti Eko, ati ti fasiti Ghana, to n beere ibalopọ̀ lsna aitọ, ni awọn eniyan ti n fi ero ọkan wọn han lori ayelujara.
Ẹkunrẹrẹ iwadii naa ni yii:
Africa Eye: Olùkọ́ méjì ní fásitì Eko àti Ghana lùgbàdì ọ̀fíntótó BBC lórí ìwà ìbàjẹ́
Ni oju opo BBC New Yoruba ni Facebook, ọpọ ló n bu ẹnu ẹ̀tẹ́ lu iwa ti awọn olukọ yii hu nitori pe ko bojumu rara ati pe o ṣeni laanu pe ọpọ awọn olukọ to mọṣẹ olukọ daadaa lo n huwa yii.
Iwa buruku yii ko jẹ tuntun loju awọn eniyan mọ nitori ọpọ agbalagba olukọ lade iwa ibajẹ yii ti ṣimọ lori ‘Lóòótọ́ ni ọ̀jọ̀gbọ́n fẹ́ bá mi lòpọ̀’.
Fásitì OAU ní ohùn ọ̀jọ̀gbọ́n Richard Akindele ni wọ́n ká sílẹ̀
Awọn miran ni ki ileeṣẹ BBC wa si ile iwe awọn kaakiri Naijiria nitori o ti di ankoo fawẹli to n ba ni ninujẹ:
Ohun to jọ ọpọ eeyan loju, to si n bi wọn ninu julọ, ni ọjọ ori ẹni ọdun metadinlogun ti ọrọ naa kan, eyi buru jai.
Ọpọlọpọ ọmọ Naijiria lo gboriyin fun ileeṣẹ BBC fun iṣẹ ọpọlọ to n fọ awujọ mọ tó n jade lagbalaBBC nigba gbogbo:
Awọn ọmọ Naijiria miran ni ki ijọba gbe igbesẹ to yẹ lati wagbo dẹkun fawọn olukọ to n huwa ibajẹ yii ki ọkan awọn akẹkọọ le balẹ.
Godson mẹnuba iwaasu Baba Adeboye ti ijọ RCCG to fi sọrọ lori ibalopọ awọn olukọ ni fasiti lasiko to yi n ṣiṣẹ olukọ.
Iyiosa gba pe iwa yii ko ṣẹṣẹ bẹrẹ bikoṣe pe ki onikaluku ṣetan lati fopin sii bayii:
Eghosa naa sọrọ lori iriri rẹ lọdun 2015 ni fasiti Eko bi olukọ kan ṣe féèlì akẹkọọ kan lẹẹmeji nitori pe o fẹ baa sun pe idajọ Olorun lo de loju rẹ:
Ọpọ ọdọ kilọ iwa ibajẹ yii larin awọn obi pe ki wọn yee mu itiju ba awọn ọmọ wọn nitori ti aṣiri ba tu tan, tẹbi tara ni itiju yii a kàn.
Queen's College: Ohùn tó yẹ kí ẹ mọ nípa akọni Efunjoke Coker
Oríṣun àwòrán, Twitter/QcogaB
Pupọ awọn akẹkỌọ to kẹkọ labẹ Efunjoke Coker ni wọn wa nipo giga lawujọ Naijiria loni
Bi Onirese ko ba fingba mọ, eleyi to ti fin silẹ ko ni parun layelaye.
Bayii ni ọrọ ri nigba ti a ba n woye itan olukọ agba ileewe girama awọn obinrin to wa nilu Eko nii, Queens College.
Iyaafin Efunjoke Coker ni olukọ agba akọkọ ileewe naa to jẹ ọmọ bibi Naijiria, koda ni ile ẹkọ naa ni oun gan an alara ti pari ẹkọ ki o to wa pada sibẹ lati dari ẹkọ.
Ọpọ awọn akẹkọọ lo sọrọ lori akọni obinrin yii.
Awọn ti wọn ti ni anfaani lati kẹkọọ jade labẹ akoso abiyamọ yi, ṣapejuwe rẹ gẹgẹ bii abiyamọ tootọ to mu iṣẹ olukọ lọkunkundun pupọ.
Wọn ni alakitiyan ni Mama Coker jẹ ti kii si fi ọrọ awọn ọmọbinrin ti wọn wa labẹ rẹ ṣere.
Africa Eye: Olùkọ́ méjì ní fásitì Eko àti Ghana lùgbàdì ọ̀fíntótó BBC lórí ìwà ìbàjẹ́
Lọdun 1979 ni ijọba Naijiria ṣafihan imoore iṣẹ ti Efunjoke Coker ṣe ati ipa to ko lori awọn akẹkọọ ileewe naa.
Wọn fi ami ẹyẹ Member of the Order of the Federal Republic (MFR ) da a lọla ti a si tun gbọ pe o gba oye to gaju lọ nibi ayẹyẹ idanimọ 2016 KARIS award.
Oríṣun àwòrán, Legit.ng
Efunjoke Coker ni obinrin ọmọ Naijiria akọkọ to jẹ ọga agba ileewe girama awọn obinrin Queens College.
Gẹgẹ bi ọrọ ti aarẹ ẹgbẹ awọn akẹkọjade ileewe Queens College, Dokita Funmi Ajose sọ,''awokọṣe rere ni iya Coker jẹ si awọn akẹkọọ rẹ ti eyi si lapa ni igbesi aye wọn atiiṣẹ ti wọn yan laayo''
Lẹyin ti Efunjoke Coker fẹyinti nibi iṣẹ, o jẹ ọkan lara awọn Igbimọ alaṣẹ fasiti Ibadan ati ile iwe gbogboniṣe Yolanda Polythecnic.
Bakan naa lo ti ṣe aarẹ ajọ alagbelebu pupa, Red Cross fun ọpọlọpọ ọdun.
World Habitat Day: 'Ìjọba, ẹ ṣèrànwọ́ fáwọn tí kò rílé gbé ní Nàìjíríà'
Oríṣun àwòrán, Twitter/Amnesty Int. Nigeria
Ọjọ keje, oṣu kẹwaa, ọdọọdun ni ajọ iṣọkan agbaye, UNO ya sọtọ fun ayajọ ọjọ ibugbe ati lati ranti awọn ti wọn o rile gbe.
Ajọ UNO tun ya ọjọ naa sọtọ lati fihan wi pe ẹtọ awọn eeyan ti wọn ko ri ile ni lati lati ni igbegbe ti wọn naa.
Ọgbẹni Adamu Makoda, ẹni ọdun mẹrindinlaadọta to n gbe ilu Kano lorilẹ-ede Naijiria jẹ ọkan lara ogunlọgọ awọn eeya ti ko rile gbe ni Naijria.
Makoda sọ fun BBC pe airilegbe jẹ iṣoro to buru julọ ti ẹda le maa doju kọ laye.
''Ibi ti mo ti n sun niyi fun ibi ọdun marun un nitori mi o rowo ile san lẹyin ti okowo mi dẹnu kọlẹ, o ku diẹ kaato. Mi o gbadura ki ọta mi gan an koju iṣoro airilegbe.''
Ọgbẹni Makoda rọ ijọba lati ṣeranwọ fawọn ti ko rile gbe ki wọn le maa gba ile olowo pọọku.
''O ti pẹ ti mo ti n gbiyanju lati gba ile ki n le maa gbe pẹlu pọ pẹlu ẹbi mi, ṣugbọn ko si agbara.''
Makoda n kọminu lori ewu to wa ninu airilegbe rẹ nitori bi eto aabo ti mẹhẹ kaakiri orilẹ-ede Naijiria bayii.
Ẹwẹ, ajọ ajafẹtọ ọmọniyan, Amnesty Int. Nigeria ti rọ ijọba apapọ atawọn ti ipinlẹ lati dẹkun fifi ipa le awọn eeyan kuro nibi kan tabi ominiran.
Ajọ Amnesty ṣafihan ninu aworan kan ti wọn fi lede loju opo Twitter wọn awujọ kan ti ko si ile igbọnsẹ, omi mimu to dara ati ọna gidi.
Akọsilẹ fihan pe ẹgbẹlẹgbẹ ọmọ Naijiria ni kori ile gbe, awọn eeyan yii si ni ireti pe awọn naa yoo rile gbe lọjọ kan.
Africa Eye: Olùkọ́ méjì ní fásitì Eko àti Ghana lùgbàdì ọ̀fíntótó BBC lórí ìwà ìbàjẹ́
Lamido Sanusi: Èèyàn tó pọ̀ ní Nàìjíríà kìí ṣe dúkìá, gbèsè ni
Oríṣun àwòrán, AFP
Muhammadu Sanusi: Èèyàn tó pọ̀ ní Nàìjíríà kìí ṣe dúkìá, gbèsè ni
Emir ilu Kano, Mohammadu Lamido Sanusi (II) sọ oko ọrọ kan niluu Abuja lọjọ Aje nibi to ti sọ pe gbese ni iye eeyan to wa lorilẹ-ede Naijiria bayii jẹ.
O ni nitori pe Naijiria ni ero to pọ ti awọn eniyan pọ pupọ ko sọ pe o ja si èrè fun wa.
Sanusi sọrọ yii nibi apero lori ọrọ aje ẹlẹẹkẹẹdọgbọn iru rẹ to n lọ lọwọ niluu Abuja.
Gomina ipinlẹ Ekiti, Ọmọwe Kayode Fayemi ati oludasilẹ ṣọọṣi Kukah Centre, Bisọbu Matthew Kukah naa wa lara awọn to peju sibi apero ọhun.
Emir Kano ṣalaye pe lootọ ni pe Naijiria le ṣe ohun to pọ nitori iye eeyan to wa nibẹ ṣugbọn ko ri bẹẹ lasiko yii, pipọ t'eeyan pọ ni Naijiria ko tii maa mu anfaani kankan ba orilẹ-ede naa bayii.
Sanusi ni ko tii si eto ti yoo jẹ kawọn ẹgbẹlẹgbẹ ọdọ wulo fun orilẹ-ede Naijiria lọjọ iwaju.
Oríṣun àwòrán, Alamy Stock Photo
Sanusi sọrọ yii nibi apero lori ọrọ aje ẹlẹẹkẹẹdọgbọn iru rẹ to n lọ lọwọ niluu Abuja.
Emir Sanusi ni iṣẹlẹ ijinigbe, idigunjale, igbesunmọmi, ikọlu laarin agbẹ ati darandaran n waye nitori bi awọn eeyan naa ṣe n pọ si ni Naijiria.
O fikun ọrọ rẹ pe bi eeyan ṣe pọ to ni Naijiria ko tii ṣe orilẹ-ede naa loore gẹgẹ bi ọpọ ṣe ro.
Sanusi ni Naijiria ko tii dagba gẹgẹ bi orilẹ-ede de ibi ti awọn eeyan to wa nibẹ yoo jẹ dukiẹ fun un.
Sanusi gbamọran pe ki awọneniyan Naijiria naa maa ṣamulo ọpọlọ wọn si iwa daadaa ati aṣeyọri ninu imọ bii sayẹnsi lasiko yii.
Nibayii, awọn eeyan to wa ni Naijiria din mẹwaa ni igba miliọnu eeyan bayii.
Oyo Election Tribunal: Adelabu tún gbé Seyi Makinde lọ sí ilé ẹjọ́ kòtẹ́milọ́rùn
Oríṣun àwòrán, OTHERS
Bayo Adelabu ti ẹgbẹ́ òsèlú APC ní òun kò faramọ́ ìdájọ́ Àjọ Elétò Ìdìbò tó ní Seyi Makinde ló wọlé nínú ìdibò tó kojá.
Oloye Adebayo Adelabu ti ẹgbẹ oselu APC ti ni, oun ko faramọ idajọ ajọ eleto idibo to da igbẹjọ oun nu lori idibo to gbe Seyi Makinde wọle gẹgẹ bi gomina nipinlẹ Ọyọ.
Lẹyin ọjọ mọkanlelogun ti idajọ naa waye ni ilu Ibadan, ni Adelabu gbe ẹjọ lọ ile ẹjọ kotẹmilọrun.
Adelabu ati ẹgbẹ oselu APC sọ wi pe, magomago waye ninu idibo Ọjọ Kẹsan, Osu Kẹta, ọdun 2019, eleyii to gbe Seyi Makinde wọle gẹgẹ bi gomina.
Adelabu wa n beere lọwọ ile ẹjọ kotẹmilọrun lati sọ wi pe oun lo ni ibo to pọju lọ ninu idibo sipo gomina ni ipinlẹ Ọyọ abi ki wọn tun ibo naa di.
Ti a ko ba gbagbe, Alaga igbẹjọ naa, Justice Muhammed Sirajo salaye pe awọn da ẹjọ ti APC pe mọ Seyi Makinde nu nitori gbogbo awọn ẹlẹri ti Adelabu pe ko ni ẹri to daju, amọ ti wọn n sọ ahesọ lasan.
2020 Budget: Àwọn gbèsè Nàìjíríà rèé
Bi a ba wo agbekalẹ iṣiro bi idagbasoke eto isuna lorilẹede Naijiria ati iye gbese to ti wa nilẹ, o ṣeeṣe ka mọ ibi ti Naijiria n mori lọ.
Lọjọ diẹ sẹyin ni aarẹ Muhammadu Buhari ti ṣe agbekalẹ aba isuna ọdun 2020.
Nibi ayẹyẹ kan to waye loni nile aṣofin ilẹ Naijiria, Buhari sọ pe oun to jẹ ijọba logun ni pipari awọn akanṣe iṣẹ to ti wa nilẹ.
O ni bi kii ba ṣe awọn iṣẹ  pataki ti ko ba pari lati ọdun 2019 tawọn fi aye kalẹ fun, awọn ko ni dawọ le iṣẹ tuntun kankan bi kii ṣe ki ijọba pari eleyi to ti wa nilẹ.
Buhari ṣalaye pe ẹka ijọba to ba kọ lati pa to gbedeke iye owo ti awọn fun wọn wọle, yoo jẹ iyan rẹ niṣu.
Ṣaaju ki aarẹ to kan si ile igbimọ ni o ti dari ipade pataki igbimọ alaṣẹ orileede Naijiria(FEC).
Origun pataki ni agbekalẹ aba isuna yii jẹ ninu eto iṣejọba. Lẹyin tawọn ọmọ ile aṣofin ba ti gba aba yii ti wọn si mu awọn atunṣe diẹ wa, aarẹ yoo buwọ lu aba ọhun ti yoo si di ofin ṣiṣe akoso nina owo fọdun 2020.
Oríṣun àwòrán, NTA
Bakanna ni aarẹ sọ pe awọn ileeṣẹ ijọba ko gbodọ gba awọn eeyan tuntun siṣẹ bi ko ba si iyọnda lati ọdọ ijọba.
O tẹsiwaju lati ṣe atupalẹ iye owo ti awọn ẹka kankan yoo ri gba ni owo ina fawọn akanṣe iṣẹ.
Diẹ ninu awọn to ka kalẹ ree:
Africa Eye: Olùkọ́ méjì ní fásitì Eko àti Ghana lùgbàdì ọ̀fíntótó BBC lórí ìwà ìbàjẹ́
Oun táa ti jábọ̀ tẹ́lẹ̀ ṣáájú ọ̀rọ̀ ààrẹ Buhari
Gbogbo ètò lo ti tò nílé ìgbìmọ̀ asofin àgbà l'Abuja ni ìmúrasilẹ fún kíka abá ìsúna fún ọdún 2020, eyi ti aarẹ Muhammadu Buhari yoo se lonii ọjọ Isẹgun.
Gẹ́gẹ́ bi ìròyiìn ṣe sọ, apá ibikan ni ilé igbimọ asofin lo ti gba àwọ tuntun, tí ètò ààbò ni àyika gbogbo ile ìgbìmọ̀ náà si ti wà ni ṣẹpẹ́ fún ètò naa, ti yóò bẹ̀rẹ̀ ni ààgo meji ọ̀sàn òní.
Koda, a gbọ pe àrà ọ̀tọ̀ ni ètò ayẹwo iforúkọ sílẹ fàwọn akọ̀ròyìn, àwọn ọlọ́pàá àti àwọn oṣìṣẹ́ ti yóò wà níbi àyẹyẹ náà.
Gbogbo ile itaja àti ilé ifowopamọ to wà nínú ọgba náà pẹ̀lú tí gbe kọ́kọ́rọ́ le ìlẹ̀kùn wọ́n.
Bakan naa, gbogbo òṣìṣẹ́ ilé aṣofin ti kò ba ni ǹkan ṣe pẹlú ètò ìsùná  ko ni wọlé rárá sínú ilé ìgbìmọ̀ aṣòfin rárá lásìko ti ààrẹ bá ń ka ètò ìsúná.
Oríṣun àwòrán, @MBuhari
Sugbọn ohun to wa n kọ ọpọ eeyan lominu bayii ni pe, àwọn alákoso ilé ìgbìmọ̀ aṣòfin kò tíì rí ojúùtú sí gbogbo àwọn ẹ̀rọ tó wà lẹ́nu ọ̀nà abawọle ile asofin apapọ to ti dẹnu kọlẹ.
Awọn ẹrọ naa ni wọ́n fi ń ṣe àyẹwọ ẹni ti ó ba gbé ǹkan to le panilára dáni, pàápàá jùlọ, èyí to wà ni ẹnú ọ̀nà àbáwolé ibi tí ètò náà yóò ti wáyé, to ti dẹnu kọlẹ.
Ibeere to si n gba ọkan ọpọ eeyan ni pe se aabo wa fun aarẹ Buhari lonii bi, bo se n gbe aba eto isuna kalẹ.
Sex for Grades: Fídíò oní wákàtí kan BBC tún fojú olùkọ́ méjì míì hàn lórí ìwà ìbàjẹ́
Oríṣun àwòrán, Facebook/ Samuel Omoniyi Oladipo
Ọjọ nla ni ọjọ Aje, ọjọ Keje osu Kẹwa ọdun 2019 nigba ti ileesẹ BBC gbe fidio kan sita eyi to da lori awọn akẹkọ fasiti meji ti wọn n beere fun ibalopọ lọna aitọ lọwọ awọn akẹkọọ wọn.
Akori fidio naa lo pe ni 'Ibalopọ fun maaki' tawọn oloyinbo n pe ni 'Sex for Grades', eyi to ti n mu ki oju awọn opo itakun agbaye gbona jain-jain.
Ẹkunrẹrẹ fidio oniwakati kan ti BBC fisita nirọlẹ ọjọ Aje naa ree:
Bi o tilẹ jẹ pe fidio onisẹju mẹtala pere ni BBC kọkọ ju sori afẹfẹ nidaji ọjọ Aje naa, lawọn oju opo ikansira ẹni rẹ lori itakun agbaye, eyi ti BBC Yoruba ko gbẹyin nibẹ, amọ nigba ti yoo fi di aago meje irọlẹ ọjọ naa, ẹkunrẹrẹ fidio naa, to jẹ oniwakati kan ti gba afẹfẹ kan.
Olukọ kan lati fasiti Eko, UNILAG, Ọmọwe Boniface Igbenegbu pẹlu akẹẹgbẹ rẹ ni fasiti Ghana, Ọmọwe Paul Butakor, ni wọn foju han ninu fidio naa, amọ fidio oniwakati kan yii lo tun fi oju awọn olukọ meji miran han to n kopa ninu iwa idojutini yii lati fasiti mejeeji taa darukọ siwaju naa.
Orukọ awọn olukọ meji naa ni Ọmọwe Samuel Ọladipọ to wa ni ẹka ti wọn ti n kọ nipa ọrọ aje (Economics) ati Ọjọgbọn Ransford Gyampo, to wa ni ẹka imọ fun eto oselu lọgba fasiti Ghana , tii tun se onwoye ohun to n lọ ni awujọ.
Jẹjẹ kuku ni bilisi sun silẹ, ti Samuel Ọladipọ si lọ faa lẹsẹ, nitori jẹjẹ ni akọroyin to n sisẹ iwadi fun BBC lori fidio naa, Kiki Mordi, duro sẹnu iloro to si n reti akọroyin ti wọn dijọ wa, eyi to wa ni ọọfisi Boniface.
Sugbọn Ọladipọ ro pe akẹkọ ni Kiki, tori bo se duro, lo ba nawọ faa wọ inu ọọfisi rẹ lai mọ pe igbesẹ naa yoo ko ohun wọ inu wahala, nigba to ya ni onitọun naa parọ pe akẹkọ to n wa maaki lọdọ rẹ ni oun.
Kia lo ni ki akọroyin naa fun oun ni nọmba ẹrọ ipe rẹ, to si pe wa si ọọfisi rẹ pe ko wa gba idanilẹkọ ni igba mẹta ọtọọtọ
Kiki ni gbogbo iwa Ọladipọ si oun ni ko tọ, to si n sọ lọpọ igba fun oun pe oun dun pupọ ni ọmọbinrin
O fikun pe se ni Ọladipọ n wo igba aya oun laisẹju, eyi to fihan pe ọmu aya oun lo n wo, to si n fi ọwọ ra oun lọwọ loore koore.
Nigba to ya, Kiki ni Ọladipọ ni ki oun tẹle oun lọ si ile igbafẹ awọn agba olukọ to wa lọgba fasiti Eko, eyi to fi idi 'yara tutu', 'Cold Room', ti Boniface mẹnuba saaju ninu fidio naa mulẹ.
Inu yara naa sokunkun diẹ nitori ina ti wọn fi n jo ijo takasufe, taa mọ si 'Disco' ni wọn tan sibẹ, eyi ti ko ni jẹ ki oju awọn eeyan to wa nibẹ tete han si ẹlomiran
Ọpọ awọn akẹkọ obinrin lo tẹle awọn olukọ ọkunrin wa si yara tutu naa, ti wọn si n fi ọti lile lọ wọn lati mu.
Wọn n pe awọn akẹkọ obinrin naa wa sita lati jo, ti wọn si n fi ara ro wọn lara, fọwọ ra wọn ni idi, fẹnu ko wọn lẹnu tabi fi ọyan wọn sere lasiko ti wọn ba n jo.
Gẹgẹ bi iwadi BBC ti salaye, ilumọọka, agba olukọ ati ẹni ọwọ to maa n bu ẹnu atẹ lu ọpọ iwa aidaa lawujọ ni Ọjọgbọn Ransford Gyampo, to jẹ olukọ miran to tun foju han pe o n beere ibalopọ lọwọ akẹkọ lọna aidaa ninu fidio oniwakati kan ọdun.
Koda Gyampo ko tiẹ fi akoko sofo rara lati gbe akọroyin naa jade, o ra ọpọ ẹbun fun, to si n fi ọwọ raa lara titi de ọyan rẹ.
Pabambari ohun ti Gyampo tun se ninu fidio naa, to si ya ni lẹnu ni pe o n beere lọwọ akọroyin to dibọn bii akẹkọ naa boya wọn ti fẹnu koo lẹnu tipatipa ri.
SexForGrade: Awọn olùkọ́ mi ní fásìtì náà fojú mi rí- Bisi Fayemi
Mo sunkún nípa fídíò BBC torí ó jẹ́ ìtàn tó ti ṣẹlẹ̀ sí mi rí - Bisi Fayemi
Tun wẹ, aya gómìnà ìpínlẹ̀ Ekiti, Bisi Fayemi ti kún ọ̀pọ̀ àwọn ọmọ Nàìjíríà to bẹnu àtẹ lú ìwà kí olùkọ́ọ̀ fásiti máá bẹeere fún ìbálòpọ̀ láti fún àkẹ́kọ̀ọ́ ní máàkì.
Èyí wáye lẹ́yìn ti ilé iṣẹ́ BBC gbé fọ́nran ìwadìí àwọn olùkọ̀ọ́ nilé ẹ̀kọ́ kan ní Nàìjíríà àti Ghana sita, ti wọn n beere ibalopọ lna aitọ lọwọ awọn akẹkọọ.
Bisi Fayemi sàlàyé pé, o jẹ́ ǹkan to bani nínú jẹ́ pé ọ̀pọ̀ àwọn olùkọ̀ọ́ yiìí máa ń rò pé àwọn ni ẹ̀tọ́ si àgọ ara àwọn akẹ́kọ̀ọ́binrin wọ́n.
Mo sunkun nítori ǹkan ti àwọn ọmọbinrin yìí ń koju jẹ́ ìtàn ayé ọ̀pọ̀ wa tó lọ ilé ìwé ni orílẹ̀-èdè yìí.
"Lásìkò ti mó kàwé ni orílẹ̀-èdè Nàìjíríà, èmí pàápàá foju wina irú ìwà yiìí lọ́wọ́ àwọn olùkọ́ mi ní fásìtì, bo tilẹ jẹ́ pé ori tún kó èmi yọ ju àwọn eyí lọ.''
Iriri temi ko rìn jìnna sùgbọ́n kìí ṣe ìrírí to dára, kò sí ẹni ti ènìyàn le sọ fún, to bá tilẹ̀ gbìyànjú láti sọ fún ẹnikẹ́ni, wọ́n yoo ni ki o gbẹ́nu dákẹ́."
Ìyàwọ gómìnà fi kún pé, lójuna àti dẹkun ìwà ibajẹ báyìí, ìpínlẹ̀ Ekiti ti gbe ìwé àkọsílẹ̀ láti ma kọ orúkọ àwon olukọ to ba hùwà ibajẹ naa.
Sex For Grade: Ẹ̀wọ̀n ọdún márùn-ún láì sí owó ìtanràn ni ìjìyà olùkọ́ oníwà ìbàjẹ́
Oríṣun àwòrán, Gettty
Akẹ́kọ̀ọ́ náà tún lẹ́tọ̀ọ́ láti gbé olùkọ̀ọ́ náà lo sí ilé ẹjọ́ gẹ́gẹ́ bi wọ́n ṣe n ṣe ń sẹjọ tókù, pẹ̀lú ẹ̀rí tó dáju
Ilé ìgbìmọ̀ aṣòfín àpapọ̀ tí gba àbá kan wọle to wa fun ìjìyà ẹni to bá fí ìbálòpọ̀ lọ obìnrin ni tipátipá tí wọn pé ni (Sexual Harassment in Tertiary Educational Institutions Prohibition Bill, 2016).
Gẹ́gẹ́ bi aṣòfin àgbà Ovie Omo-Agege tó ṣe àgbátẹru rẹ ṣe sọ, àbádofin náà yóò jẹ ki àwọn amokun ṣèkà tó fẹ́ràn láti ma fi ìbálòpọ̀ lọ akẹ́kọ̀ọ́ fún máàkì, kọ ẹ̀kọ́ nla.
Abadofin náà fí kun pé ẹnikẹni to ba lùgbàdi gbogbo àwọn ẹsun yìí yóò lọ sẹ́wọ̀n ọdún márun gbáko tàbi ẹwọn ti ko din ní ọdún mejì láì si ore-ọ̀fẹ́ oniduro tabi sisan owo itanran.
Oríṣun àwòrán, NASS
Sexual Harassment: Mílíọn márùn àti ẹwọ̀n ọdún marún lẹ̀rọ̀ rẹ
Nígbà kigba tí ìrú ǹkan báyìí ba wáye, tí ẹnikẹni fi ìbálopọ lọ akẹ́kọ̀ọ́, àkẹ́kọ̀ọ́ ni ẹtọ́ láti lọ fi ẹjọ́ sùn ni àgọ́ ọlọ́pàá tàbi àgbẹjọrò àgbà ní ipinlẹ fún ẹ̀sún ìwà ọdaràn.
Akẹ́kọ̀ọ́ náà tún lẹ́tọ̀ọ́ láti gbé olùkọ̀ọ́ náà lọ sí ilé ẹjọ́ gẹ́gẹ́ bi wọ́n ṣe n ṣe ń sẹjọ tókù, pẹ̀lú ẹ̀rí tó dáju.
Oríṣun àwòrán, NASS
SexForGrade: Ǹjẹ o mọ ẹtọ́ rẹ lábẹ́ òfin
Kí lo de ti ofin yii ko se tii jẹ lilo?
Bó tilẹ̀ jẹ́ pé láti ọdún 2016 ní ilé ìgbìmọ̀ asòfin àgbà ti ka àbádofin yíì de ipele kẹta, síbẹ̀ kò tii rí ìmọ́lẹ láti di ofin.
Idi ni pe ààrẹ Muhammadu Buhari ko tii buwọ́lu àbádofin náà titi di akoko ti BBC gbe fidio jade lori iwa ibajẹ ọhun.
FIRS: Ijọba Nàìjíría ṣetan láti bẹ̀rẹ̀ si ni gbowó orí lóri ìbáraẹnisọ̀rọ̀
Álága ilé iṣẹ́ tón gbowo orí lórílẹ̀-èdè  Nàìjíríà (FIRS), Babatunde Fowler tií ni báyìí o, ko si ǹkan to buru ninu kí ìjọba máá gba owo orí fún ìbáraẹnisọ̀rọ̀ lori ẹ̀rọ.
Fowler sọ èyí di mímọ lásìkò tó n ba awọn akọroyin sọ̀rọ̀ níbi ìpàdé àpérò ètò ọ̀rọ̀ ajé Nàìjíríà tó wáye nilu Abuja.
Ẹ jẹ́ kí n sọ báyìí, Ọmọ Nàìjíríà máa ń sọ̀rọ̀ púpọ̀ jùlọ, wọn a maa sọ̀rọ̀ ju bo ṣe yẹ ki wọ́n sọ̀rọ̀ lọ, ẹni to ba si lágbàra láti sọ̀rọ̀ to bi wọ́n ṣe ń sọ yìí tí a bá gbé owo ori lee, ko sí ǹkan to buru níbẹ̀
A máa fi ara wa we àwọn orilẹ̀-ède to ti tó tán, sùgbọ́n ìdá méji ninu ìdá ọgọ́rùn ni Ghana ń gba lówó orí fún ìbáraẹnisọ̀rọ̀, wọ́n si maa n lo ǹkan ti wọn ba ri níbẹ̀ láti gba bùkáta àwọn fásìtì wọ́n, èyí si lo mu ki àwọn ọmọ Nàìjíríà lọ maa kawe ni Ghana.
Ọmọ Nàìjíríà ti le sọ̀rọ̀ jù, A o fi owo orí kún ìbáraẹnisọ̀rọ̀
Ní báyìí àwọn asòfin n pète ìdá mẹsàn fún owó ori ibaraẹni sọ̀rọ̀ láti fi rọ́pò ida meji owo ti ìjọba gbe lé ọjà rírà láìpẹ́ yìí.
Fowler tún sàlàye lóri owó ori ti wan fi le ọjà rírà lori ayélujara pé gbogbo àwọn ti wan ń lo ayelujara láti ta ọjà wọ́n ni àwọn banki yóò ti maa yọ ìdámarun ninu ǹkan ti wọ́n ba ta, láti fi sọ̀wọ si FIRS.
Rashidi Ladọja: Igbákejì gómìnà Ọyọ ní Ladọja ṣe bẹbẹ lẹ́ka ètò ẹkọ́
Tẹbi tara ati awọn aṣoju ijọba lo peju-pesẹ lati ṣe ajọyọ ayẹyẹ ọjọ ibi ọdun karundinlọgọrin gomina tẹlẹri nipinlẹ Ọyọ, Oloye Rashidi Adewọlu Ladọja.
Ayẹyẹ naa ti o waye ni gbọngan nla igbalejo ile itura 'Premier Hotel' ilu Ibadan l'ọjọ Aje, jẹ ọkan lara akanṣe eto to waye nibi ifilọlẹ iwe eto ẹkọọ nipa itan ati ipo adari ti aya gomina tẹlẹri naa, Arabinrin Bukọla Ladọja kọ fun awọn ile ẹkọọ to n bẹ lorilẹede yii.
Igbakeji gomina ipinlẹ Ọyọ Onimọẹrọ Rauf Ọlaniyan, ti o ṣoju ijọba ipinlẹ Ọyọ nibi ipejọpọ naa, gbosuba kare fun Oloye Rashidi Ladọja fun iṣẹ takuntakun ti o ṣe fun idagbasoke ipinlẹ Ọyọ, lasiko iṣejọba rẹ gẹgẹ bii gomina, paapaa julọ lẹka eto ẹkọ.
Ọlaniyan tẹsiwaju wi pe, ibi ti ọrọ eto ẹkọ ti wọ ni ẹkun iwọ-oorun ni Ladọja mojuto lasiko iṣejọba rẹ, ki o to di wi pe awọn ti o gba ijọba lọwọ rẹ da eto naa ru.
O fi kun ọrọ rẹ wi pe, ijọba ipinlẹ Ọyọ n tọrọ ẹmi gigun ati alafia fun baba ọlọjọ ibi, ti Kọmisana fun eto ẹkọọ ati imọ ijinlẹ nipinlẹ Ọyọ, Ọjọgbọn Kehinde Sangodoyin naa si farahan nibi ayẹyẹ ọhun.
Ninu ọrọ rẹ, Sangodoyin ṣe apejuwe Oloye Ladọja gẹgẹ bii baba gidi, o ni lati igba ti gomina tẹlẹri naa ti n dije du ipo ni oun ti ṣe alabapade rẹ.
O tẹsiwaju wi pe Ladọja jẹ ẹni ti o maa n fẹ ki nnkan rere ti akata rẹ jade wa, bẹẹ si ni o maa n fẹ ki gbogbo eeyan ṣe daadaa, bakan naa lo ni o jẹ ẹni kan ti kii bẹru, eyii si jẹ nnkan pataki to yẹ ki gbogbo eeyan ṣe awokọṣe rẹ.
Ninu ifọrọwerọ pẹlu ikọ iroyin BBC Yoruba, arabinrin Bukọla Ladọja ṣe alaye wi pe ipa ribiribi ti Oloye Ladọja ko fun idagbasoke eto ẹkọọ lasiko iṣejọba rẹ, lo mu ki wọn ṣe ayẹyẹ ọjọ ibi naa mọ ifilọlẹ iwe tuntun ti aya gomina tẹlẹri naa kọ.
Arabinrin Bukọla wa parọwa si Oloye Ladọja lati tẹsiwaju ninu iṣẹ rere, paapaa julọ lẹka eto ẹkọọ.
Ninu ọrọ idupẹ rẹ, Oloye Rashidi Ladọja dupẹ lọwọ gbogbo awọn arirebaniṣe pẹlu adura pe ohun rere ko ni tan lọdẹdẹ ẹnkẹni.
Ladọja ṣe alaye wi pe, lara awọn iredi ti idagbasoke eto ẹkọ fi jẹ oun logun ni wi pe oun gan ti jẹ anfani eto ẹkọọ ọfẹ sẹyin, bẹẹ si ni oun mọ ohun ti o tumọ si fun akẹkọọ lati joko sile nitori aisan owo ile ẹkọọ.
Gomina tẹlẹri naa fi kun ọrọ rẹ pe, lara ohun ti o yẹ ki ijọba to n bẹ lode tẹsiwaju lati maa ṣe, ni itọju awọn olukọ nipasẹ sisan owo oṣu wọn lasiko.
Ladoja ni oun ko ni dẹkun lati maa kopa ninu idagbasoke eto ẹkọ lawujọ, bo ti wu ki ara di ara agba to.
Ọkanjọkan orin ni wọn fi da awọn alejo lara ya nibi ayẹyẹ naa.
Lara awọn eeyan ti o tun wa nikalẹ ni Ọjọgbọn Bọlanle Awe, adari awọn oṣiṣẹ gomina ipinlẹ Ọyọ, Oloye Bisi Ilaka, akọwe ijọba ipinlẹ Ọyọ, Arabinrin Olubamiwo Adeoṣun, awọn lẹgbẹlẹgbẹ loyeloye ati bẹẹbẹẹ lọ.
2020 Budget: Owóyàá lábẹ́lé àti nílẹ̀ òkèèrè nìjọba fẹ́ fi gbọ́ bùkátà ìṣúná 2020
Oríṣun àwòrán, @Oshofaze
Ni ọjọ Isẹgun, ọjọ Kẹjọ, osu Kẹwa ọdun 2019 ni aarẹ Muhammadu Buhari gbe aba eto isuna ọdun 2020 kalẹ siwaju ile asofin apapọ ilẹ wa.
Apapọ owo to to Triliọnu mẹwa o le diẹ naira (₦10.33trn) ni ijọba apapọ yoo fi gbọ bukata eto isuna ọdun to n bọ naa pẹlu afikun pe, owoya labẹle ati nilẹ okeere si wa lara ọna ti wọn yoo gba ri owo gbọ bukata eto isuna naa.
Nigba to n salaye siwaju lori bi owo yoo se tẹ ijọba apapọ lọwọ, Buhari ni owo ori ọja ti lọ soke sii lati ida marun si meje ati aabọ, ti eto isuna naa si da lori ilana owo ori ọja tuntun naa.
Amọ ko sai yan pe awọn sja kan wa ti wọn ko ni gba owo ori lori wọn, lara awọn ẹka ti eyi si kan ni ẹka kata-kara oogun,eroja eto ẹkọ ati eroja ounjẹ.
Ko tan sibẹ, ijọba tun ya owo sọtọ lati fi se awọn opopona ati afara mọkandinlogun ni ipinlẹ mọkanla ni Naijiria.
Oríṣun àwòrán, OTHERS
Ààrẹ Muhammadu Buhari ti gbé àbá isúná tó lé ní triliọnu mẹwa Naira ka íwájú Ilé ìgbìmọ̀ Asòfin fún ọdún 2020.
Aarẹ Muhammadu Buhari ti sọ wi pe awọn eniyan ko ni ma a san owo ori lori awọn ounjẹ kọọkan lati jẹ ki owo rẹ dinku.
Aarẹ Buhari sọ eyi lasiko to n gbe aba isuna to le ni triliọnu mẹwa (N10.33 trillion) Naira ka Ile Igbimọ Asofin apapọ fun ọdun 2020.
Awọn ounjẹ bii isu, ẹja, miliki, awọn ounjẹ alagbado, ounjẹ ti wọn se pẹlu iyẹfun, eso, ẹfọ, oogun ibilẹ, ẹran ati omi lo bọ lọwọ owo ori naa.
Àtúpalẹ̀ àbá ètó ìsúná ọdún 2020:
Toxic Cream: Uk ní kí tọkọtaya san £17,000 owo itanran ati ṣíṣe iṣẹ́ ìlú fún ọgọ́ta wákìtí
Oríṣun àwòrán, Others
Bayii laa se nile wa, eewọ ibomiran ni.
Bi o tilẹ jẹ wipe asa tita ọsẹ ati ipara ibora wọpọ lorilẹede Naijiria, ti ko si si ẹni to n moju to ipeniye rẹ, amọ tọkọtaya kan, ti wọn jẹ ọmọ Naijiria ti ri ẹwọn he lori iwa yii nilu London.
Jonathan Ikpere ati aya rẹ, Holiness ti wọn n gbe lagbegbe Southsea nilu Ọba, lo maa n ko oniruuru ọsẹ ati ipara ibora to lewu wọle silẹ United Kingdom lati Naijiria, Pakistan ati China.
Oríṣun àwòrán, Others
Awọn ọja to n se ijamba fun awọ ara naa si ni wọn maa n polowo rẹ tantan tan lori ayelujara pe ki awọn araalu wa ra, bẹẹ si ni ọpọ eroja ọsẹ ati ipara ibora naa nijọba ti fi ofin de ninu ile wọn.
Oríṣun àwòrán, Others
Gẹgẹ bi iroyin naa ti wi, awọn tọkọtaya naa ti ri ti aje se nidi okoowo laabi ọhun, ti wọn si ti ri ẹgbẹlẹgbẹ owo pọun nidi okoowo naa.
Iwadi ijọba ilẹ UK lo mu ki afẹfẹ fẹ si idi tọkọtaya naa, ti akara si tu sepo pe awọn eroja to n bo ara naa, ti wọn n ko wọle lati ilẹ adulawọ naa lo lee ba awọn ara jẹ, ti wọn si ti gbẹsẹ le ọpọ ọja ọhun to to ẹgbẹrun mẹta to wa ninu ile Ikpere.
Oríṣun àwòrán, Others
Gbogbo awọn ẹsun yii ti wọn fi kan tọkọ́taya ọhun, ni wọn gba pe awọn jẹbi rẹ, ti ijọba si ni ki wọn lọ san owo itanran to jẹ ẹgbẹrun lọna mẹtadinlogun pọun (£17,000) ati sise isẹ ilu fun ọgọta wakati.
Italy Parliament: Ìjọba gé aṣòfin àpapọ̀ láti 630 sí 400
Oríṣun àwòrán, EPA
Àwọn asòfin ilẹ̀ Italy ti dìbò láti gé iye àwọn asòfin lórílẹ̀èdè náà láti lè pèsè owó fún ìsèjọba orílẹ̀èdè náà.
Ile Asofin orilẹede Italy ti di ibo lati ge ida mẹta iye awọn asofin ti yoo ma a soju ẹkun kọọkan lorilẹede naa.
Ile asofin kekere buwọlu ofin to ni ki wọn ge iye awọn asofin lati Ojilelẹgbẹta o din mẹwa si irinwo, ti awọn asofin agba naa yoo si dinku lati okoolelọọdunrun o din marun si igba eniyan.
Igbesẹ yii wa lara ileri ibo ti ẹgbẹ oselu Five Star Movement, to je ijọba to wa ni ipo se fun awọn araalu lasiko ipolongo ibo rẹ.
Awọn asofin naa ni adinku to ba iye awọn asofin lorilẹede naa yoo jẹ ki orilẹede Italy ni ọgọọrọ miliọnu Euro nipamọ lati ara owo osu ati owona.
Amọ, awọn alariwisi ọrọ naa ni igbese yii yoo mu ifasẹyin ba isejọba tiwantiwa lorilẹede naa.
Bakan naa ni ofin tuntun naa ko le e wa si imusẹ a fi ti wọn ba se idibo gbogbo-gboo nitori yoo mu ayipada ba ofin orilẹede naa.
Bobrisky: Ogunye ní ìwà ìṣekúpani láìtọ́ wúwo ju ọ̀rọ̀ ‘kòsakọ́-kòṣabo’ lọ
Oríṣun àwòrán, Instagram/bobrisky222
Ko sọrọ kankan ninu ohun tawọn kan sọ pe o yẹ ki awọn ko ṣakọ ko ṣabo ni ile igbọnsẹ tiwọn lawujọ, paapaa ni papakọ ofurufu ati awọn ibo miiran lawujọ.
"Ilumọọka agbẹjọro, Jiti Ogunye to ba BBC sọrọ lo fidi ọrọ yii mu lẹ. Ogunye ni ""melo ni eeyan bi Bobrisky lorilẹede Naijiria ti ijọba yoo fi kọ ile igbọnsẹ ọtọ fun wọn."""
Agbẹjọro Ogunye ni, ọrọ runrun lọrọ naa nitori iṣoro to n koju orilẹede Naijiria pọ ju pe, ki ẹnikan maa sọ pe o yẹ kawọn ko ṣakọ, ko ṣabo ni ile igbọnsẹ ti wọn lọtọ.
Amofin Ogunye ṣalaye pe, ofin ilẹ Naijiria gan an ko faye gba awọn ko ṣakọ ko ṣabo, nitorinaa, iru eleyi ko le fẹsẹ mu lẹ.
Ijọba apapọ lo kọkọ fi ikilọ lede nipa ewu to wa ninu kawọn eeyan bii Bobrisky maa ba awọn obinrin lo ibudo igbọnsẹ papọ.
Oríṣun àwòrán, Facebook/Miss Sahahra
Ikede yii waye lẹyin ti rogbodiyan ṣẹlẹ ni papakọ ofurufu Nnamdi Azikwe ni ilu Abuja, nigba ti wọn ri Bobrisky to n lo yara igbọnse awọn obinrin.
Ijọba wa rọ ẹka ilera lorilẹede Naijiria lati la awọn eniyan lọyẹ nipa ewu to wa ninu lilo yara igbọnse kan naa pẹlu Bobrisky, ti awọn eeyan kan si daba pe, ki wọn pese ile igbọnsẹ ọtọ fun awọn eeyan to jẹ ‘Kosakọ-Kosabo’ bii Bobrisky ati Miss Sahhara lawọn ibudo ajọlo.
Ṣugbọn amofin Ogunye ni awọn iṣẹlẹ bi awọn ọlọpaa ti wọn n ko awọn ara ilu satimọle lainidi, ọna ti ko dara, iṣekupa awọn ọmọ Naijiria lorilẹede India lo yẹ ki ijọba wa nnkan ṣe si bayii.
Oríṣun àwòrán, Instagram Bobrisky222
Agbẹjọro Ogunye ṣalaye siwaju si pe, ofin Naijiria si n ri Bobrisky gẹgẹ bi ọkunrin ayafi to ba lọ ṣe ibura nile ẹjọ pe oun fẹ yipada lati ọkunrin si obinrin.
O fikun ọrọ rẹ pe awọn agbofinro lẹtọ lati fọwọ ofin mu un to ba lọ si ile igbọnsẹ awọn obinrin ni Naijiria.
Sex for Grades: Fásitì Eko ní kí olùkọ́ míì lọ fìdímọ́lé lori Fídíò BBC
Oríṣun àwòrán, Facebook
Ọjọgbọn Samuel Oladipo
Ile Ẹkọ fasiti ilu Eko ti jawe lọ joko sile folukọ miran ti o han ninu fiimu iwadii BBC eyi to ṣafihan awọn olukọ ni fasiti Ghana ati Naijria ti wọn dẹnu ifẹ ko awọn akẹkọbinrin.
Ọwọ tẹ ọjọgbọn Samuel Oladipo latari fiimu BBC ninu eyi to ti n kẹnu ifẹ si akọroyin BBC to ṣe bi akẹkọ.
Ohun ni olukọ kẹrin ti wọn yoo ni ki o lọ rọọku n'le latari ipa ti wọn ko ninu fiimu naa.
Lọjọ Aje ni Unilag kọkọ kede pe awọn ti ni ki ọjọgbọn Boniface Igbeneghu, tohun naa wa ninu fiimu ọhun lọ fidi mọle.
Ikede fasiti Eko yi waye lẹyin ti fasiti Ilu Ghana kede pe awọn naa ti ni ki awọn olukọ meji ti igba ṣi mọ lori ninu fọnran fidio naa lọ fidi mọle.
Mẹta ninu awọn olukọ yii Ọjọgbọn Oladipo, Ọmọwe Ransford Gyampo ati Ọjọgbọn Paul Kwame Butakor ni awọn ko jẹbi ẹsun ti wọn fi kan wọn.
Iwaadi BBC naa ti awọn eeyan ti n kan sara si ṣafihan bi awọn olukọ ṣe n lo ipo wọn lati hu iwa aitọ pẹlu awọn akẹkọbinrin ni fasiti Eko ati Ghana.
Awọn fasiti mejeeji naa ni awọn lodi si ki awọn olukọ maa huwa aitọ pẹlu awọn akẹkọọ.
World Mental Health Day: Báyìí ni o ṣe lè sá fún èdì tí àìsàn ọpọlọ bá gbé súnmọ́ ẹ
Oríṣun àwòrán, LASEMA
LASEMA ati awọn ile ise pajawiri yo ọkọ ti o jasosa lati ṣe afihan ìṣẹlẹ pajawiri
"Kìí ṣe gbogbo ẹni to fẹ fo latori afara odo lo wu lati ku. Wọn kan fẹ mọ boya eeyan kan le wa to nifẹẹ wọn ni."""
Eyi lohun ti Kevin Hines to gbiyanju lati fo sinu odo ko le gba ẹmi ara rẹ ni Golden Gate Bridge ti San Francisco ninu oṣu kẹsan ọdun 2000.
bi o tilẹ jẹ wi pe ọpọ eniyan lo ri i lori afara ko to gbiyanju lati pa ara rẹ - koda onirinajo igbafẹ kan ni ko ya oun ni fọtọ.
Ko sẹni to mọ pe o ni iporuru ọkan tabi to bi i lere pe ki lo ṣẹlẹ̀. Nitorinaa, lo ba di gbi ninu odo.
Lọna ara, o ye iku lọwọ iwọn metre marun omi to jin ṣugbọn eniyan o le ni eniyan ẹgbẹrun meji din ni ọọdunrun lo ti gbẹmi ara wọn nipa bibẹ somi latori afara lati igba ti wọn ti fi odo Golden Gates ọhun lọọlẹ ninu oṣu karun un ọdun 1937.
Odo yii wa lara awọn ibi to gbajumọ ju tawọn eeyan ma n lo lati lọ gba ẹmi ara wọn.
Fun idi eyi,  Kevin ni ikọ tirẹ to ma n wa si ori afara naa lati foju ganni ati lati doola ẹmi awọ́n to ba bẹ dinu omi nipasẹ ilana ranpẹ.
Lọdun 2018 nikan, eniyan igba o le mẹrinla to gbiyanju lati bẹ somi iyẹn tumọ si eeyan kan lojojumọ.
Pe eeyan mẹtadinlọgbọn pere lo ba a lọ lasan to lati gboriyin fun iṣẹ awọn agbofinro atawọn ayọnda ṣiṣẹ bii ti Mia Munayer ati Kevin Briggs.
Ọlọpaa lawọn mejeji bi o tilẹ jẹ pe Briggs ti fẹyinti lẹnu iṣẹ, awọn ayọnda ṣiṣẹ Munayer, Bridgewatch Angels ni wọn ms n saba pin si iṣẹ nibẹ lati ran awọn to jẹ ọga wọn lọwọ.
Oríṣun àwòrán, Bridgewatch Angels
Ajọ eleto ilera agbaye ṣe iṣiro rẹ pe o sunmọ ẹgbẹrun lọna ẹgbẹrin eeyan to ku nipasẹ gbigba ẹmi ara wọn.
Bakan naa, ibudo orilẹede Amẹrika to n boju to itju aisan na ni akọsilẹ to sọ pe ẹgbẹrun mẹtadinlaadọta eeyan lo gba ẹmi ara wọn nilẹ amẹrika lọdun 2017 eyi si ni ohun to n ṣokunfa iku awọn ara Amẹrika larin ọdun mẹwaa si mẹrinlelọgbọn.
Gbigba ẹmi ara ẹni lee nidi ṣugbọn o maa ni ibaṣepọ to nipọn pẹlu ilera ọpọlọ paapaa iporuru kan.
"Ida aadọrun awọn to gbẹmi ara wọn lo ti ni itan aisan to ni ṣe pẹlu ọpọlọ ri tabi iṣoro fifi ipa mu ni lasiko iku wọn
Ohun ti awọn Bridgewath Angels n se ni lati dena gbigba ẹmi ara ẹni.
Oríṣun àwòrán, Ascend Books
Emi atawọn akẹgbẹ mi n ṣe idanilẹkọ kan wọn si fi fidio BBC nipa rẹ han wa.
Nigba naa mo mọ pe mo ni lati ṣe nkan ti yoo dẹkun iku awọn eniyan.
Eyi lo mu ko da ẹgbẹ awọn Angẹli silẹ ti wọn si ti n paraa odo Golden Gates lati dun 2011 paapaa lawọn ọjọ pataki bii ayajọ ọjọ awọn ololufẹ tabi ọjọ keresi -  wọn si kọ wọn bi wọn ṣe le ba ẹnikẹni ti wọn ba ro pe o ni iporuru ọkan sọrọ.
A maa n tẹti si awọn eniyan, a si maa n gbiyanju lati rii pe awọn yẹn sọrọ. O ṣe pataki lati ma fọwọ kan wọn ju ki wọn rii pe wọn n da wọn lohun""."
Oríṣun àwòrán, Pivotal Points
Briggs atawọn to ti di ọrẹ rẹ bayii to doola leti omi
Nigba mii mo maa fọrọ wa awọn eeyan ti mo doola lẹnu wo bii ọrọ to kan gbogbo eeyan. ki ni mo sọ to dara abi ti ko dara?.
Pẹlu ọgbọn, Briggs a yi awọn eeyan to le nigba lọkan pada lati gun ori irin afara pada lati ma ko somi mọ. Ko ju ẹẹmeji lọ ti ọgbọn rẹ yii ja a kulẹ ti wọn ko dahun.
Awọn ijakulẹ yii si leeyan maa n ranti ju awọn eyi to yọri teeyan ti ṣe lọ.
Oríṣun àwòrán, Golden Gate Bridge handout
Diẹ lara awọn tori yọ bọ sọrọ lori bi wọn ṣe kabamọ pe wọn pinu lati lọ bẹ sinu omi ni kete ti wọn gbera lori afara.
"Orirun iku ni afara yẹn, Kevin Hines to fẹ bẹsomi ninu oṣu kẹjọ ọdun 2000 sọ fun CNN, ṣugbọn mi o ba ma ṣe bẹẹ bi eeyan kan ba ba mi sọrọ""."
Oríṣun àwòrán, Kevin Hines
Kevin Hines to yi ọkan pada lati ma ko somi
Bí o bá rí èèyàn kan nínú ìrora, ipa rẹ ni láti tọ ẹni naa lọ ki o sì bá a ni gbolohun, rii pe wọn la ohun si ọ ki o si ri i pe wọn s ohun ti o wa lọkan wọn
O lee jẹ ohun elo fun ayipada ọkan.
World tour- Jessica Nabongo ni obìnrin akọkọ nilẹ Africa tí yóò rin àgbaye tan
Oríṣun àwòrán, Jessica Nabongo
World tour- Jessica Nabongo ni obìnrin akọkọ nilẹ Africa tí yóò rin àgbaye tan
Ninu ọdun yii ni Jessica Nabongo mu ero rẹ ṣẹ gẹgẹ bi obinrin akọkọ ni ilẹ Adulawọ ti yoo rin gbogbo orilẹ-ede agbaye.
Ni bayii, ọmọbinrin yii wa n fẹ ki ọpọlọpọ ojugba rẹ lati ilẹ Adulawọ naa gbiyanju lati mu ala ati ero wọn ṣẹ bii ti oun.
Ṣe ni ọjọ kẹfa, oṣu kẹwaa, ọdun yii ni Nabango, ọmọ ilẹ Uganda, ti a bi si ilẹ Amẹrika pari rinrin gbogbo orilẹ-ede agbaye ti o jẹ Aarundinnigba tan.
Bakan naa ni ẹni ti o jẹ Olugbani siṣẹ ajọ agbaye tẹlẹ ki arabinrin yii lori ẹro ayelujara fun iwa akọni rẹ lati rin iru irin ajo naa.
Ninu oṣu karun un ọdun yii ni o ṣi ṣalaye fun ile iṣẹ BBC wi pe irin ajo kaakakiri yii ti jẹ ki oun mọ bi o ṣe ri lati gbe igbe aye alaini.
O tẹsiwaju pe, oun gan paapaa ni ẹbi si Uganda ti ko si omi mimu fun wọn tabi ina mọnamọna.
O wa gba awọn obinrin nimọran lati ta giri si ala wọn lojuna ati maṣe bẹru ninu mimu ero wọn wa si imuṣẹ lai wo iru ẹya tabi aawọ ibi ti wọn ti wa.
Oríṣun àwòrán, Jessica Nabongo
Jessica Nabongo ọmọ ilẹ Uganda
Ko ṣai mẹnu baa wi pe, ki awọn obinrin o dẹkun wipe boya wọn ko le da rin irin ajo nitori ẹru tabi ifoya, o wi pe, irọ funfun balau ni iru ọrọ bẹẹ.
Tani otutu ma n mu ju laarin Ọkunrin ati Obinrin?
Nigba ti o n sọrọ nipa bi o ti ṣe ri owo, o ni oun ri iṣe to fi ri owo ni kete ti irin ajo ile iwe oun pari, oun si fi owo naa ra ile.
Gẹgẹ bi ko ṣe fẹran lati maa duro loju kan, o gba ile, o si tẹsiwaju lọ si ilẹ Japan lati lọ jẹ Olukọ ede Gẹẹsi.
Bakan naa ni o tun jẹ Olukọ ni ile iwe ẹkọ imọ nipa ọrọ okoowo ni ilu London, ki o to tun ṣiṣẹ pelu ajọ agbaye ti o gbe e de ilẹ Benin ati Italy.
Oríṣun àwòrán, Jessica Nabongo
Jessica Nabongo
Nibẹ ni o ti bẹrẹ si ni ko owo jọ, ti o si ṣe okoowo aṣọ ṣẹẹti wiwọ.
O ṣalaye pe lootọ ko dẹrun lati rin irin ajo bẹẹ gẹgẹ bi obinrin alawọ dudu, ti o tun gẹrun ori rẹ.
O ni iwa ẹlẹya mẹya ti ti oju oun ri ni ilẹ South Afrika ko kere ni pataki laarin awọn eniyan alawọ dudu ilẹ naa.
Bakan naa lo ni ọpọ ko fun oun ni wahala ni pataki ilẹ Senegal ti wọn fẹran eniyan dudu ti wọn si n kẹ gbogbo eniyan ibaa ṣe dudu tabi funfun.
O ni iwa awọn ọkunrin ilẹ Pakistan naa larinrin pupọ ti o si jẹ ọkan lara eyi ti o dara ju lọ.
Ko din ni Aadọjọ awọn eniyan ti o ti rin iru irin ajo bẹẹ sugbọn ti o jẹ pe Oyinbo alawọ funfun ni ọpọ wọn
Kini Yoru[bá ń pe Necklace?
Ìjọba Ekiti n gbèrò òfin tí yóò fí ìjìyà titẹ lọ́dàá jẹ àwọn afipábánilòpọ̀
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ti aba afikun ijiya titẹ awọn to ba fipabanilopo ba di gbigba wọle, nnkan ko ni ṣẹnu 're fawọn to n hu iwa aburu yii ni ipinlẹ Ekiti.
Afikun ijiya yii ti iyawo Gomina ipinlẹ Ekiti, Erelu Bisi Fayemi n ṣagbatẹru rẹ lawọn onwoye ni o ti wa di dandan bayii bi ọwọja ifipabanilopọ̀ paapa pẹlu awọn ọmọde ti ṣe gbode.
Lasiko ti wọn n ṣe agbeyẹwo ofin yii ni ile aṣofin ipinlẹ Ekiti ni iyawo Gomina ati agbẹjọro agba to tun jẹ kọmisana feto idajọ Wale Fapohunda tẹnumọ pataki afikun ofin naa.
Oríṣun àwòrán, Facebook/bisiafayemi
Fapohunda rọ awọn aṣofin ipinlẹ naa lati jara mọ ijiroro lori ofin yii lati le ran ilakaka Gomina Fayemi nipa kikoju ifipabanilopọ ati awọn iwa aburu mi lawujọ.
Ṣaaju ni ipinlẹ Ekiti ti ni ofin kan to n koju iwa ipa laarin akọ tabi abo ṣugbọn afikun ofin yIi yoo tubọ gba'gbara fawọn alaṣẹ lati koju awọn alaburu.
Aya Gomina ni niṣe ni awọn eeyan ma n fojojumọ gbe ọrọ ifiipabanilopo wa si ọfIisi oun ti o si ti wa di dandan bayIi lati jẹ ki awọn to fara kasa iṣẹlẹ yiI ni ọna abayọ.
Lara awọn ohun ti ofin naa tun fẹ koju ti atunṣe ọ̀hun ba waye ni pe wọn yoo da awọn aaye ifẹjọsun silẹ kaakiri ti awọn eeyan ko si ni maa wa si olu ilu Ekiti ki wọn to fẹjọ iwa ifipabanilopo ati awọn ẹṣẹ mii sun mọ.
Lagos Police: Tí ìrònú bá ti pọjù , ó le ṣokùnfa àìṣiṣí nǹkan ọmọkùnrin
Oríṣun àwòrán, Nigeria Police
Ọlọpapa Ilẹ Naijiria
Obinrin kan ti ko si ẹni ti o mọ orukọ rẹ titi di akoko ti a n ko iroyin yii jọ ni wọn fi ẹsun rírá nkan ọmọkunrin kan ninu ọkọ ninu Eko.
Iroyin ti o tẹ ikọ BBC lọwọ ni wi pe lootọ ni iṣẹlẹ naa waye ni ibudokọ Onipanu ni llu Eko.
Nigba ti Alukoro ajọ Ọlọpaa ni Ipinlẹ Eko, Bala Elkana, n ṣalaye fun ile iṣẹ BBC lori ọrọ naa, o ni Ọlọpaa ko gbagbọ ninu iru iṣẹlẹ bẹẹ.
O tẹsiwaju pe, nigba ti awuyewuye ọrọ yii ṣẹlẹ ni wọn fi to ọlọpaa leti ti wọn si gbe igbesẹ lati doola ẹmi arabinrin ọhun ẹni ti iwadii si n lọ lọwọ lori ọrọ rẹ.
Bala ṣalaye pe ofin ko gbagbọ ninu ọrọ naa tori pe ọpọ igba ni iru nkan bẹẹ n ṣẹlẹ ti o jẹ pe ti ironu ba ti pọ ju yoo ṣokunfa irufẹ iṣẹlẹ bẹẹ.
Alukoro naa wa ṣalaye pe, awọn ẹni ti ọrọ naa kan ni wọn ti ko lọ si ile iwosan fun itọju ti wọn si ti n fun ni itọju ti o peye bakan naa.
Ajọ ọlọpaa ti mu obinrin naa sọdọ fun aabo ati idoola ẹmi rẹ lọwọ awọn ti inu n bi ki wọn ma baa ṣe ẹmi rẹ legbodo.
Oríṣun àwòrán, BRT
Inu ọkọ Akero ni Ilu Eko
Ile iṣẹ Ọlọpaa ni Onipanu ni ilu Eko ni obinrin naa wa ti gbogbo ẹjọ naa si ti n lọ ṣugbọn idaniloju wa pe, ohun gbogbo yoo pada bọ sipo laipẹ.
Ọlọpaa ni ko si ami idaniloju pe obinrin ti wọn fi ẹsun kan yii ṣe iru nkan bẹẹ ṣugbọn ti wọn kọ gbiyanju lati diimu nitori pe o joko si ẹgbẹ wọn.
Busa 2019: Sadiya Umar Farouq - Obìnrin Olóṣelú tó lààmì laaka.
Oríṣun àwòrán, @sadiya
Ko si ẹni ti ko le ṣe igbeyawo nigba to ba wuu
Lati bii ọjọ mẹta ni iroyin ti gba ori ayelujara pe Aarẹ Muhammadu Buhari fẹ fẹ iyawo keji.
Iroyin naa ni Sadiya Umar Farouq ni ade naa fẹ ṣi mọ lori ṣugbọn ko tii si aridaju iṣẹlẹ yii lati ileeṣẹ aarẹ titi di asiko yii.
Sadiya Farouq ti fi igba kan jẹ Akapo ẹgbẹ oṣelu APC laarin oṣu kefa, ọdun 2013 si oṣu kẹfa, ọdun 2014.
O tun ṣe Akapo ẹgbẹ oṣelu CPC ti o jẹ ọkan lara ẹgbẹ ti o parapọ ni ọdun 2013 di APC, ti o jẹ ẹgbẹ alatako ti o tobi julọ to si gba ijọba lọwọ ẹgbẹ PDPWo ohun tó yẹ kí o mọ̀ nípa àwọn obìnrin méje ti Buhari fẹ́ yàn sípò minista .
Oríṣun àwòrán, @others
Iroyin to gba ayelujara kan ni pe, o maa to o ko wa ile Aarẹ Buhari
Ijọba lbilẹ Zurmi ni Ipinlẹ Zamfara ni a gbe bii.
O lọ si ile iwe Ijọba apapọ ti o jẹ kiki obinrin ni ilu Gusau, ni Ipinlẹ Zamfara naa.
Oríṣun àwòrán, OTHER
Sadiya Umar Farouq - Obìnrin Olóṣelú tó lààmì laaka.
Ile Iwe Fasiti ti Ahmadu Bello ni Zaria, ni Ipinlẹ Kaduna ni o ti kẹkọọ gboye ninu Eto Idokowo ni ọdun 1998 ti o tun gunlẹ onipele keji [Masters Degree] lori eto ilẹ okeere.
O gba oye ipele keji yii ni ọdun 2008 ati ipele keji miran lori Idokowo [MBA] ni ọdun 2011 ni ile iwe Fasiti Ahmadu Bello ,Zaria, ni Ipinlẹ Kaduna.
Oríṣun àwòrán, Sadiya
Sadiya Umar Farouq
O ti ṣiṣẹ ni ọpọlọpọ ile iṣẹ bii Ọga Agba fun igbokegbodo ni Pinnacle Travels and Tours, laarin ọdun 2001 si ọdun 2003 ki o to darapọ mọ ajọ ti o n risi eto ọrọ ile Igbimọ.
Sadiya ni wọn yan gẹgẹ bi Kọmiṣọmma Ijọba apapọ lori ọrọ awọn atipo ati awọn ti ko rile gbe ni Oṣu kẹsan an, ọdun 2016.
Kini Yoru[bá ń pe Necklace?
Ori Ipo yii lo wa di Oṣu kẹjọ, Ọdun 2019 ki o to di Minisita fun Abojuto lori ọrọ Ijamba ati Igbayegbadun ọmọniyan lorilẹ-ede yii.
CS Mum: Omotolani Ekene ní ọ̀pọ̀ èèyàn gbà pé ọ̀lẹ, arugún, aláìlera ni ẹni tó fi abẹ bímọ
BUSA19: Bí ètò ìgbéyàwó ààrẹ Buhari kò bá ṣe lọ rèé -àwọn ènìyàn Nàíjíríà
Oríṣun àwòrán, @others
Lẹyin to ti hande pe iroyin ẹlẹjẹ ni igbeyawo aarẹ Buhari ti awọn eeyan n pariwo lori ayelujara; sibẹ ọpọ aworan to panilẹrin fun ipalẹmọ lo kun ayelujara bayii
Oriṣiiriṣi aworan ati akọle to pani lẹrin lo ti kun ori ayelujara ni eyi ti awọn eniyan fi n ṣeto ipalẹmọ igbeyawo ofege ti wọn ni o yẹ ko waye laarin Aarẹ Buhari ati Hajiya Sadiya Umar Farouq.
Ṣaaju ni iroyin ẹlẹjẹ ti gba ori ayelujara pe eto igbeyawo naa yoo waye laarin minista tuntun fun Abojuto lori ọrọ Ijamba ati Igbayegbadun ọmọniyan lorilẹ-ede ati aarẹ Naijiria.
Ọpọlọpọ awọn eniyan ni wọn n gbiyanju lati mọ Ta ni Sadiya Umar Farouq tí ìròyìn ẹlẹ́jẹ̀  ń gbé pé òun ló fẹ́ dí ìyàwó tuntun Buhari? jẹ́.
Ṣugbọn lẹyin pe gbogbo nkan to n jade lati ọdọ awọn ti ọrọ kan fihan pe irọ to jina si ootọ ni iroyin ẹlẹjẹ naa; sibẹsibẹ ayelujara ti kun fun oriṣiriṣi aworan ati akọle to fihan pe apanilẹrin ni awọn eniyan Naijiria.
Lóòni ni ayẹyẹ ìgbéyàwó ààrẹ Buhari ni'lù Abuja ni eyi ti ero ti n de si Abuja:
Oríṣun àwòrán, Ogundamisi
Awọ asọ oni ni Pepper-Dem Green àti Wailers white
Ní bayìí àwọn èèkan ilú,  àwọn olóṣèlú àwọn ọmọ Naijiria jákejádo lo ti  si nń gúnlẹ̀ sí ìlú  Abuja.
Oríṣun àwòrán, Kayodebarkre
Ebora owu naa ti de ibi ayẹyẹ
Nínú ètò ti yóò wáye ni mọsàlási Jimoh nílùú Abuja lásìkò irún Jimoh toni ní wọn ti maa so wọn pọ.
Oríṣun àwòrán, MrLekan Adigun
Awon eekan ninu PDP naa de bẹ
Láìpẹ́ yìí ìròyìn kan déedé bẹ̀rẹ̀ si ni ja rainrain lójú opó twitter pe ààrẹ orilẹ̀-èdè Nàijíríà Muhammadu Buhari yóò fẹ́ ìyàwó tuntun sáàfin.
Oríṣun àwòrán, Ayourb
Awọn aarẹ orile-ede naa ti de silu Abuja
Bó tilẹ̀ jẹ́ pé ìròyìn yìí ko fẹ́sẹ̀ múlẹ, ti ko si si oun a ri gbámu kankan níbẹ̀, ọ̀pọ ọmọ Naijiria ti pari bi gbogbo ǹkan yóò ṣe lọ leto leto.
Oríṣun àwòrán, @ogbeni_Skrtel twitter
Arakunrin Ondo àti awọn gomina ilẹ Yoruba
Oko iyawo ti n mura bayii:
Láti ori ìwé ìpè àlejo tó si mo adari ètò ounjé, àti adari ounjẹ ní wọ́n ti fóju  wọ́n han bàyìí:
Oríṣun àwòrán, QOlakul
Oko iyawo ti wọ agbo
Oríṣun àwòrán, Imaam Shams
Eto iyawo ti bẹ̀rẹ̀ ni pẹrẹwu
Nínú ètò ti yóò wáye ni mọsàlási Jimoh nílùú Abuja lásìkò irún Jimoh toni ní wọn ti maa so wọn pọ.
Oríṣun àwòrán, Osi_Suave
Awon olorin ati osere tiata
Awọn alejo miran ti awọn eniyan n ṣe awada pe o ti de sibi eto naa ni:
Oríṣun àwòrán, Iwara139
Bobbriski lo wọ pepper-dem green yii oo
Oríṣun àwòrán, Optimistic-Ade
Abubakar Atiku bawọn n dáwọ idunnu nibẹ
Oríṣun àwòrán, Hassan winger
Dino ati àwọn ẹmẹwaa rẹ sááju ọjọ igbeyawo lọ ki Baba Buhari
Ayẹyẹ yiìí ko yọ Trump silẹ bi o se fí ohun ránsẹ pé òun ko ni le raye wá.
Oríṣun àwòrán, Ayo Akanji
Em aa binu si mi pe mi o ni le yóju, ọ̀rọ̀ Turkey ati Kurdish lo fàá
Àwọn tí ìbàdan, ní ìpínlẹ̀ Oyo, Porthacourt àti Imo
Oríṣun àwòrán, Tajudeen Olajide
Micra lawọn ara Ibadan yoo gbe de Abuja lati yẹ ọkọ iyawo sí
Oríṣun àwòrán, H cookey
Awon tori omi o gbẹ́yìn
Ọkọ ìyàwọ ti de nínú ọkọ bọginin rẹ̀ ti àwọn alábarin àti olólùfẹ́ rẹ̀ si n wọ́ tẹ̀le.
Oríṣun àwòrán, Kola Stephen
Awon ti pota ree ni Garaji ọkọ
Wọn ni asọ ti yóò lé wọ òde ìgbéyawo náà ni Pepper-dem àtio wailers White
Ìyá Micho àti awọn alágbàse míràn lo soju nibi iyẹyẹ náà
Oríṣun àwòrán, AbiolaGenus8
Awọn olunjẹ ti bẹ̀rẹ̀ si ni in ounjẹ
Oríṣun àwòrán, Johannx
Mr JAG naa wa lara awon kongila olounje
Oríṣun àwòrán, Bolatito
Awon ounjẹ to joju ni gbese
Oríṣun àwòrán, Bolabelyncon
Mo gbo moya ti fẹ pari oujẹ inawo
Alaga idúro fú ìdíle ayẹyẹ igbeyawo náà ti bẹ̀rẹ̀ iṣẹ́ ni pẹrẹwu
Oríṣun àwòrán, Modabba
Ogbeni Raufu ti bẹ̀rẹ̀ isẹ́
Oríṣun àwòrán, Bababosso
Won ti bẹ̀rẹ̀ sinu gbọ́wọ́ ijo gẹngẹ
Gbogbo elere fún ayẹyẹ naa ooo
Oríṣun àwòrán, Lucasscot_101
Igbakeji àarẹ ni Gbogbo elere nibi ode yii
Oríṣun àwòrán, Optimistic_Ade
Ààrẹ aná ni Naijiria, tí n mura silẹ fun ayẹyẹ yìí
Oríṣun àwòrán, HelloMilez
Awon Orẹ Oko
Awọn asọna fun ayẹyẹ igbeyawo naa
Oríṣun àwòrán, @Uwayasi
Awon asona ti yóò ma ran alejo lọ́wọ́ nibi ayẹyẹ yii
Minisita fun ere idaraya tẹlẹ ni odẹ aperin ti yóò pese gbogbẹlan ti wan nilo.
Oríṣun àwòrán, Lugard Fredo
Minisita fun ere idaraya tẹlẹ ni odẹ aperin ti yóò pese gbogbẹlan ti wan nilo
Awọn ọmọ Naijiria ba fi fidio bi igbeyawo naa ṣe lọ sita pe:
Oríṣun àwòrán, BadMAnLade
Awon mogbọ moya rèé ti wan mu iwe iwole dani
E seun ti ẹ wa, ẹbun àmurele rèé fun gbogbo awọn ti wan wa fun ayẹyẹ igbéyawo yìí:
Oríṣun àwòrán, #sirtunji
Awọn ẹbun ti wọ́n pin fun alejo
Lati bii ọjọ mẹta kan ni iroyin ti gba ori ayelujara kan pe Aarẹ Muhammadu Buhari to n tukọ Naijiria fẹ gbe iyawo miran le Ayisha aya rẹ.
Opọ awọn eniyan ni wọn n woye pe Ta ni Sadiya Umar Farouq tí ìròyìn ń gbé pé òun ló fẹ́ dí ìyàwó tuntun Buhari?
Nigba ti Ileeṣẹ BBC kan si awọn ti ọrọ kan naa ni wọn fidiẹ mulẹ pe iroyin ẹlẹjẹ ni o.
Oríṣun àwòrán, @Sadiya
Ẹ yee parọ mọ mi o! Emi ko fẹ aarẹ Buhari -Sadiya Umar Farouq
Eni ti  a ba sọrọ ni ọdọ Hajiya Sadiya Umar Farouq to jẹ minista tuntun tijọba Buhari yan fun ileeṣẹ ijọba apapọ tuntun ni Abuja ni Hajiya Sadiya wa ni Geneva bayii ni eyi to fihan pe irọ pata to jina si otitọ ni ọrọ naa.
Oṣu kẹjọ, Ọdun 2019 lo di Minisita fun Abojuto lori ọrọ Ijamba ati Igbayegbadun ọmọniyan lorilẹ-ede yii Wo ohun tó yẹ kí o mọ̀ nípa àwọn obìnrin méje ti Buhari fẹ́ yàn sípò minista.
Kini ootọ inu Fidio ti Ayisha ti n binu to n tan lori ayelujara bayii?
Nigba ti BBC bere nipa fidio to ṣafihan Ayisha to n binu lori ayelujara, pe:
 ........ Kini o de ti o fi n ti lẹkun?.......  A ni o le nigba awọn ọmọ ogun ni Aso Rock yatọ si igba ọlọpaa to n ṣọ wa.....O to gẹ........ awọn oponu dede....
Bakan naa ni ẹni ti BBC ba sọrọ nile iṣẹ aarẹ to ni ki a ma darukọ oun ṣalaye pe irọ to jina si ootọ ni pe wọn dé aya aarẹ Buhari, Aisha mọ́lé ninu Aso Rock.
Ọkan lara awọn oluranlọwọ Aisha Buhari ti BBC ba sọrọ naa ṣalaye pe fidio naa ti pẹ.
O ni fidio naa kii ṣe ohun to n ṣẹlẹ bayii rara.
Ati pe irọ ni ohun ti wọn n sọ lori ayelujara pe Aisha de pẹlu ibinu si Aso Rock ni ana.
Nipari o ni Ayisha Buhari ti lọ si London lati bii oṣu mẹrin sẹyin ni eyi ti o ni nitootọ ni irinajo yii ti n fa wahala diẹdiẹ laarin aarẹ Buhari ati Aisha aya rẹ.
Sadiya Umar Farouq ti wọn pori ẹ ninu ọrọ yii paapaa ni oun ko si ni Naijiria lasiko yii nitori o ti ba ọrọ bi yoo ṣe dara lọ si Geneva lati bii ọjọ melo sẹyin.
Dino Melaye: Bí mo tilẹ̀ fìdí rẹmi, mo f'ọpẹ́ fún Ọlọ́run
Oríṣun àwòrán, Senator Dino Melaye
Aṣofin orilẹede Naijiria, Sẹnetọ Dino Melaye ti fidi rẹmi nile ẹjọ lori ibo to gbe e wọle gẹgẹ bii sẹnetọ to n ṣoju ẹkun Iwọ Oorun ipinlẹ Kogi.
Dino Melaye funrarẹ fi iroyin yii sita loju opo Twitter rẹ pe, oun fidi rẹmi o ṣugbọn ninu ohun gbogbo, ọpẹ ni fun ọlọrun to bẹrẹ ohun gbogbo ti yoo si yọri rẹ.
Ẹ̀rù ń bá wá lóri ilera sẹnatọ Dino Melaye
Oríṣun àwòrán, Senator Dino Melaye
Melaye ni oludije labẹ asia ẹgbẹ oṣelu Peoples Democratic Party (PDP) ti wọn kede rẹ gẹgẹ bi ẹni to jawe olubori ninu idibo oṣu keji ọdun 2019.
Ẹwẹ, ṣe ni oludije Smart Adeyemi to wa ni ẹgbẹ alatako, All Progressives Congress (APC) fun ipo kan naa pe jijawe olubori rẹ nija nile ẹjọ.
Awọn ẹsun ti Smart fi kan Dino da lori ohun mẹta iyẹn ṣegeṣege eto idibo, nini ibo to koja iye to yẹ ati aitẹle ofin eto idibo.
Nitorinaa awọn adajọ gba ipẹjọ Smart wọn si pe fun atundi ibo. Ninu eyi ni Sẹnetọ Dino Melaye ti kede pe oun fidi rẹmi bayii.
Ṣugbọn o kasẹ ọrọ nilẹ pe Ọlọrun to bẹrẹ ohun gbogbo na ni yoo ṣe aṣepe rẹ.
Homosexual: Uganda yóò dá ẹ̀wọǹ gbére fún obinrin tabi okunrin tó bá fẹ́ ara wọn
Oríṣun àwòrán, AFP
Awon omo ile Uganga ko gbodo fẹ akọ si akọ ati abo si abo
Ijọba ilẹ Uganda ti bẹrẹ igbesẹ lati gbogun ti iwa pe ki ọkunrin meji tabi obinrin meji maa fẹ arawọn.
Ẹni ti o jẹ Minisita fun eto iwa amuyẹ ni ilẹ naa,lo sọrọ igbesẹ ti wa lati mu amuto ba ofin naa ti ile ẹjọ gbegi le ni ọdun 2014.
Simon Lokodo sọ fun awọn eniyan pe ti gbogbo eto ba ti to tan, ẹwọn gbere ni fun ẹnikẹni ti ade ọrọ naa ba ṣi mọ lori.
Lokodo ni wọn yoo jẹ ko ye gbogbo eniyan pe ẹnikẹni tabi eeyan keeyan to ba tasẹ agẹrẹ si ofin yii, yoo dara rẹ lẹbi ti yoo si gba idalẹbi.
Ko ṣai mẹnu baa wi pe, o jẹ ohun ajeji pata gbaa si ilẹ Uganda ki okunrin meji tabi obinrin meji maa ni ajọsepọ.
Ni ọdun 2014 ni Aarẹ Yoweri Museveni ti fọwọ si abadofin naa ṣugbọn ti ile ẹjọ ko gbaa wọle fun idi kan tabi omiran pe ki wọn pa ẹni ba dan iru rẹ wo.
Lokodo ti wa ṣalaye pe ofin tuntun naa ti gba ifọwọ si Aarẹ ati ọga Ọlọpaa pe wọn ti ṣetan lati fi iya jẹ iru ẹni bẹẹ ati ohunkohun to ba ṣẹlẹ lẹyin rẹ.
Pepe Julian Onziema ti o wa lati ẹya to kere ju ni ilẹ Uganda ti ṣalaye pe ẹru paapaa n ba awọn ọmọ ẹgbẹ oun ti ọpọ ẹniyan si ti salọ kuro ni ilẹ naa gẹgẹ bi atipo.
Kemi Lala: mo ń gbìyànjú láti mú inú òbí mi dùn
Onziema ṣalaye pe ni ọdun yii nikan, wọn ti pa ọkunrin mẹta ati obinrin kan ti wọn lọwọ ninu iru iwa yii, pe ni ọsẹ to kọja ni wọn pa ọmọkunrin kan ti o jẹbi iru ẹsun bẹẹ.
Inú mi dùn pé ọmọ obinrin nìkan ni mo bi
Awọn Orilẹ ede ti o tako iru iwa bẹẹ ti wọn si gba pe iku ni ere ẹṣẹ ẹni bẹẹ ni;
Bakan naa ni apa ila Oorun orilẹ ede Nigeria, okuta ni wọn maa n ju pa iru ẹni ti ade ọrọ naa ba ṣi mọ lori.
CS Mum: Omotolani Ekene ní ọ̀pọ̀ èèyàn gbà pé ọ̀lẹ, arugún, aláìlera ni ẹni tó fi abẹ bímọ
Kaduna kidnap: Akẹ́kọ̀ọ́ mẹ́fà mórí bọ́ lọ́wọ́ àwọn ajínigbé
Oríṣun àwòrán, Nigerian Army
Kaduna kidnap: Akẹ́kọ̀ọ́ mẹ́fà mórí bọ́ lọ́wọ́ àwọn ajínigbé
Ọpẹ o! Awọn akẹkọọ mẹfa ti wọn jigbe ni ileewe girama ni Gwagwada, nipinlẹ Kaduna ti gba ominira bayii.
Ileeṣẹ ologun orilẹ-ede Naijiria lo fọrọ naa lede ninu atẹjade kan ti wọn fi sita.
Ileesẹ ologun ṣalaye pe ọwọ ti tẹ awọn ajinigbe ọhun, ati pe awọn tun ti gba oriṣiiriṣii ohun ija lọwọ wọn.
Ileeṣẹ ologun ni awọn akẹkọọ naa n lọ si ileewe nigba ti awọn ajinigbe ọun gbe wọn lọ.
Kemi Lala: mo ń gbìyànjú láti mú inú òbí mi dùn
Lẹyin ija ajaku akata laarin awọn ologun atawọn ajinigbe ọun nibi ti ọkan ninu awọn ajinigbe naa ti farapa.
Ohun oju ri to!
Eleyi ni igba kẹta ti iṣẹlẹ ijinigbe yoo waye nile iwe laarin ọsẹ meji ni Kaduna.
Koda iṣẹlẹ ijinigbe kan tun ṣẹlẹ l'Ọjọbọ nibi ti wọn ti ji ọga ileewe kan lọ.
Ileeṣẹ ologun sọ pe awọn akẹkọọ fẹsẹ fẹ ni kete tawọn ajinigbe de ileewe wọn ti wọn si ji ọga ileewe naa lọ.
Opọ eyan Naijiria lo ti gboriyin fawọn ọmọ ogun to doola awọn akẹkọọ naa pe iṣẹ takuntakun ni wọn ṣe.
Suicide Prevention: ìwọ́de yìí wáyé láti gbógun ti pípa ara ẹni
A o maa mu ẹkunrẹrẹ iroyin naa wa fun yin laipẹ.
CS Mum: Omotolani Ekene ní ọ̀pọ̀ èèyàn gbà pé ọ̀lẹ, arugún, aláìlera ni ẹni tó fi abẹ bímọ
Kini Yoru[bá ń pe Necklace?
2020 Budget Defence: Buhari láwọn mínísítà kò gbọdọ̀ rìnrìn àjò lọ sí ilẹ̀ òkèrè
Oríṣun àwòrán, Twitter/Bashir Ahamd
Aarẹ Muhammadu Buhari f'ofin de awọn minisita atawọn oṣiṣẹ ijọba miiran ti wọn n ṣiṣẹ pẹlu ileeṣẹ aarẹ lati rinrin ajo lọ si oke okun.
Ọfiisi akọwe ijọba apapọ lo fi ọrọ yii lede lọjọ Ẹti, bakan naa lọrọ naa wa loju opo Twitter ileeṣẹ Aarẹ.
Igbesẹ yii nijọba gbe lati fun awọn minisita lanfaani lati ṣiṣẹ pọ pẹlu ile aṣofin agba lori eto isuna ọdun 2020 fun orilẹede Naijiria.
Eyi tumọ si pe awọn minisita yoo lanfaani lati maa rinrinajo pada silẹ okere lẹyin ti Aarẹ Buhari ba ti gbe eto iṣuna lọ siwaju ile aṣofin tan, ti wọn si gba a wọle.
Ọjọ Iṣẹgun ni Aaarẹ gbe aba iṣuna to le ni tiriliọnu mẹwaa lọ siwaju ile aṣofin agba l'Abuja.
Aarẹ Buhari ti sọ tẹlẹ pe oun fẹ ki orilẹede Naijiria bẹrẹ si lo eto isuna ti yoo bẹrẹ ni oṣu kinni, ti yoo si pari ni oṣu kejila.
Ẹwẹ, adari ile aṣofin agba l'Abuja, Ahmed Lawan sọ pe awọn aṣofin yoo gbiyanju agbara wọn lati ri i pe awọn ṣiṣẹ pọ pẹlu Aarẹ Buhari lori aba eto isuna to gbe wa siwaju ile.
Lawan ṣalaye pe ile ti ya oṣu kẹwaa yii sọtọ fun ẹlẹkajẹka ileeṣẹ ijọba lati wa sọ nipa eto isuna wọn ki o le ya kiakia.
2020 Budget: 'Owó oṣù sísan ni ọ̀pọ̀ àbá ètò ìṣúná fún iléeṣẹ́ ọlọ́pàá àtàwọn ológun yóò bá lọ'
Oríṣun àwòrán, Nigerian Army
Ohun ti wọn lee se ni ki wọn maa san owo ohun ti wọn ba ra diẹdiẹ -Onwoye
Njẹ eto aabo to mẹhẹ lorilẹ-ede Naijiria le lojutu ni ko pẹ ko jina?
Ibeere ti ọpọ ọmọ Naijiria n beere ni yii lẹyin ti aba eto iṣuna ọdun 2020 fihan pe ida aadọrun un le kan ni ileeṣẹ ọlọpaa atawọn ologun yoo na lori owo oṣu.
Aba eto iṣuna naa fihan pe owo ajẹmọnu ati owo oṣu awọn agbofinro atawọn ọmọ ogun lo fẹẹ gba gbogbo owo tan ninu eto iṣuna ọhunWo gbèsè tí Nàìjíríà ti jẹ láàrin ọdún 2015 sí 2019 .
Ati pe ida mẹsan an pere ninu ọgọrun un si wa fun rira ohun eelo ijagun ati awọn iṣẹ akanṣe.
Awọn onwonye sọ pe eleyi ko ni fawọn ileeṣẹ ọlọpaa ati ologun lanfaani lati ra awọn nnkan ija ogun, ohun ti wọn lee se ni ki wọn maa san owo ohun ti wọn ba ra diẹdiẹ Ilé ìgbìmọ aṣofin ti dájọ tí wọn ó fọwọsi àbádofin ìsúna 2019.
Ọjọ Iṣẹgun ni Aarẹ Muhammadu Buhari gbe aba eto iṣuna fun ọdun 2020 to le ni tiriliọnu mẹwaa lọ siwaju ile aṣofin agba l'Abuja.
Tiriliọnu to din diẹ ni marun un ni yoo ba owo sisan lọ ninu eto iṣuna na, nigba ti tiriliọnu meji pere wa fun iṣẹ akanṣeBuhari ti fòfin de àwọn mínísítà láti rìnrìn àjò lọ sí ilẹ̀ òkèrè.
Awọn onimọ ninu ọrọ eto aabo ni o ṣeeṣe ki iyatọ maa ba eto aabo to mẹhẹ lọdun 2020 nitori owo ti ijọba ya sọtọ fun ileeṣẹ ọlọpaa atawọn ologun ti kere ju.
Ọgbẹni Rekpene Bassey to jẹ onimọ lori eto aabo sọ pe owo kereje lowo ti ijọba ya sọtọ fun eto ti wọn ba parọ rẹ lati naira si owo dọlaÒpópónà àti afárá 19 níjọba fẹ́ ṣe nínú àbá ìṣúná ọdún 2020.
Kemi Lala: mo ń gbìyànjú láti mú inú òbí mi dùn
Bassey ni eto aabo yoo mẹhẹ si lọdun 2020 nitori owo to wa ninu aba eto iṣuna fọdun to n bọ ti kere ju.
David Adiatu oníṣẹ́ ọnà pẹ̀lú ìṣó àti òwú
Child sexual abuse: Ìdí rèé tí mi ò fi sọ̀rọ̀ nígbà tí ìbátan mi fipá bá mi lopọ̀ l'ọdún 67 sẹ́yìn
Child sexual abuse: Ìdí rèé tí mi ò fi sọ̀rọ̀ nígbà tí ìbátan mi fipá bá mi lopọ̀ l'ọdún 67 sẹ́yìn
Ifipabanilopọ lo yẹ ki tonile-talejo fọwọsowọpọ gbogun ti.
Ilumọọka oniroyin lorilẹ-ede Ghana, to tun jẹ minisita tẹlẹ ri, Elizabeth Ohene lo sọ iriri rẹ lori bi wọn ṣe fipa ba a lopọ ni bi ọdun mẹtadinlaadọrin sẹyin.
Ọmọ ọdun meje ni Ohene wa nigba ti iṣẹlẹ naa waye, ṣugbọn ko sọ fun ẹnikan nigba naa.
Nigba to n ṣalaye idi abajọ ti ko fi sọ iru iṣẹlẹ nla fun ẹnikẹni, Ohene ni oun o mọ ohun tawọn eeyan yoo sọ t'oun ba gbe igbesẹ lati sọ ohun to ṣẹlẹ si oun sita.
Ohene ti le ọdun mẹrinlelaadọrin ọdun bayii, ko to ṣẹṣẹ gbe igbesẹ lati sọ ohun to ṣẹlẹ sii ni ọgọta ọdun o le diẹ sẹyin.
O ni awọn iroyin ti oun n ka nipa iwa ifipabanilopọ ko dun un gbọ leti, eyi lo jẹ ki oun ṣiṣọ loju eegun iriri t'oun naa to jẹ iso inu ẹku tẹlẹ.
Ṣugbọn ibeere ti oun gbọdọ wa idahun si ni pe kilode ti oun fi sọrọ yii lasiko yii ti oun ti sun mọ ọgọrin ọdun laye?
Inú mi dùn pé ọmọ obinrin nìkan ni mo bi
Mo gbe igbesẹ lati sọ iriri ifipabanilopọ ti mo ni lati rii wi pe iru iṣẹlẹ bẹẹ ko ṣẹlẹ sawọn ọmọbinrin keekeeke bii temi nigba ti mo wa ni ọmọ ọdun mẹtala.
Ọrọ tawọn eeyan yoo sọ lawujọ ko gbami laaye lati ṣalaye ohun to ṣẹlẹ si mi ni pato.
Ohun ti mo kan sọ ni pe mo ni iriri ifipabanilopọ.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ohun ti mo kan sọ ni pe mo ni iriri ifipabanilopọ.
Ni ọdun 1952, mo wa ni ọmọ ọdun meje nigba ti mo n gbe pẹlu mama to bi mama mi ni abule wa.
Ṣugbọn lọjọ kan, ọkunrin kan to jẹ ibatan mi kan to n gbe lẹgbẹ ile wa ṣaadeede fa mi lọ si inu ile rẹ nibi to ti fipa bami lopọ.
''N ko tilẹ mọ ohun ọkunrin yii ṣe fun mi nigba naa, ṣugbọn ohun ti mo le ranti ni pe o fi ọwọ rẹ to dọti bọ oju ara mi.''
ṣugbọn ohun ti mo le ranti ni pe o fi ọwọ rẹ to dọti bọ oju ara mi.''
Ohene sọ pe oun ko le gbagbe oorun ara ọkunrin naa ati eekanna rẹ to fi bọ oju ara ohun titi di ọjọ oni ti iṣẹlẹ naa ti pe ọdun mẹtadinlaadọrin.
''Ṣugbọn lonii, o ti yemi ni pato ohun ti ọkunrin yii ṣe fun mi ni ọdun mẹtadinlaadọrin sẹyin.''
Mama mama mi ni o n ṣe itọju mi nigba naa, bo tilẹ jẹ pe mo kọ lati sọ ohun to ṣẹlẹ fun un.
''Mama mama mi kan ṣaadeede ṣakiyesi pe etutu n jade lati oju ara mi nigba ti wọn n wẹ mi, ṣugbọn wọn ko tiẹ lero wi pe bo ya ibatan wa lo ṣe okunfa rẹ.''
''Mama mama mi ko tilẹ beere ohun kan lọwọ mi, o kan ṣaa tọju mi ni.''
'Mama mama mi ko tilẹ beere ohun kan lọwọ mi, o kan ṣaa tọju mi ni.''
Ṣugbọn nigba ti mo pe ọmọ ọdun mọkanla, ọkunrin kan naa tun fipa bami lopọ!
''Mi ko si le sọ bakan naa lẹyin iṣẹlẹ keji yii pe oye iru ipa tawọn iṣẹlẹ yii yoo ni lori mi.
Ṣugbọn ohun ti mo le sọ bayii ni pe mo la awọn iṣoro yii kọja, bo tilẹ jẹ pe wọn ṣakoba fun mi ninu ero mi.''
Elizabeth ni: ''Mo gbe igbesẹ lati sọrọ yii lasiko yii nitori mo ti gbe ile aye ṣerere, gẹgẹ bi oniroyin ati minisita tẹlẹri lorilẹ-ede Ghana.
Ti mo ba ku bayii, awọn eeyan yoo ri nnkan rere tọka si nipa mi.''
''Ohun miiran to mu mi sọ iriri mi ni pe ọpọ lo ri ifipa ba awọn ọmọdebinrin lo pọ si ohun ti ko too pọn ọn.
Ọpọ awọn agbalagba ọkunrin lo n fipa bawọn ọmọde lopọ lasiko yii, tawọn eeyan ko si sọ ohun kan nipa rẹ.''
Sex for grades: Undercover in West African universities
''Ti awọn ẹbi ọmọde ti wọn ba lajọṣepọ bakẹjọ lọ sọdọ awọn ọlọpaa, ẹjọ naa ko ni lojutu nitori awọn ọlọpaa naa ni yoo gbawọn nimọran lati lọ yanju ọrọ naa ni itubi inunbi laarin ara wọn nile.''
''Ohun ti mo fi sọrọ ni pe awọn ọmọ ọdun mẹta ati ọdun meje miiran tun le ni iru iriri buruku ti mo ni yii lọpọ ọdun sẹyin.''
Ohene lo ṣe ni laanu pe ọpọ lo sọrọ tako awọn akọ to n fẹ akọ ara wọn nigba ti wọn fi awọn to n fipa bawọn ọmọde silẹ.
'Iṣẹlẹ ifipa bọmọde lopọ yoo tẹsiwaju niwọn igba ti awọn eeyan ko tii ṣetan lati maa sọ nipa rẹ.''
Oríṣun àwòrán, Getty Images
'Iṣẹlẹ ifipa bọmọde lopọ yoo tẹsiwaju niwọn igba ti awọn eeyan ko tii ṣetan lati maa sọ nipa rẹ.''
Inu mi yoo dun ti iriri mi ba ti ṣeranwọ fun ẹnikan:
Ọpọ lo ti n sọ ero wọn lati igba ti mo ti fi iriri mi sita eleyi to jẹ iwuri fun mi. Ko da ọpọ wọn lo sọ pe ko ṣee gbọ seti.
''Ko jẹ iyalẹnu fun mi pe awọn eeyan n sọ pe ohun to ṣẹlẹ si mi ko ṣee maa sọ.
Awọn kan tiẹ sọ pe ko yẹ ki n maa sọ iru iṣẹlẹ buruku yii fawọn eeyan lawujọ, ṣugbọn n ko ni ọrọ lati ba iru awọn bẹẹ sọ.''
''Bakan naa lọpọ obinrin ti sọ fun mi pe iriri mi ti fun awọn naa ni igboya lati bori iru iṣoro bayii tawọn naa n doju kọ; Eyi jẹ idunnu fun mi.''
''Maa fọwọ rọri ku, ti iriri mi yii ba le jẹ ki ọpọ bẹrẹ si sọrọ lori iwa ifipabanilopọ ati ọna abayọ si iṣoro yii.''
COZA: Ọpọ èrò ló jáde ṣe lòdì sí ẹ̀sùn ìfipábánilòpọ̀ Fatoyinbo
Yollywood: Odunlade fijó bẹ́ẹ, Lizzy padà sọ́dún 2012, Lateef gbàmì ẹ̀yẹ tuntun
Oríṣun àwòrán, Instagram
Yollywood Artists: Odunlade fijó bẹ́ẹ, Lizzy padà sọ́dún 2012, Lateef gbàmì ẹ̀yẹ tuntun
Wọnyi ni diẹ lara awọn nnkan tawọn oṣere Yollywood ṣe lọsẹ yii ti wọn si gbe sori ayelujara nipa ara wọn.
Ẹ jẹ ki a bẹrẹ pẹlu oṣere yii, Lizzy Anjọrin, lo fi ibeere lede lori oju opo Instagram rẹ pe kawọn ololufẹ oun sọ iru ọkọ ti oun n lo laarin ọdun 2012 si 2013.
Koda, o tun sọ wi pe ẹnikẹni to ba le sọ iru ọkọ ti oun n lo lọdun 2011; oun ṣetan lati fun iru ẹni bẹẹ lẹbun ẹgbẹrun un marun un owo naira.
Lizzy ṣalaye loju opo instagram rẹ pe ayelujara ti mu ayipada ba igbe aye eleyi to si n mu ọpọ eeyan parọ tawọn mii si n wuwa buruku kiri.
Toyin Abraham ni tirẹ ṣo pe oun lọ tọ nigba mẹwaa laarin iṣẹju mẹẹdogun lati ori itage nigba ti oun n kopa ninu ere #Elevatorbaby pẹlu oyun ninu oun.
Toyin fikun ọrọ rẹ pe igba marun un ni oun lọ mu omi bakan naa laarin iṣẹju mẹẹdogun lori itage.
O ni oyun inu oun ti pe oṣu mẹfa nigba ti oun kopa ninu ere yii.
Afi ki gbogbo abiyamọ jere ọmọw ọn, oyun nini ko rọrun!
'Ìdí rèé tí mo fi ṣẹ̀ṣẹ̀ sọ̀rọ̀ lẹ́yìn tí wọ́n fipá bámi lopọ̀ lọ́mọ ọdún méje lọ́gọ́ta ọdún sẹ́yìn'
Bó tilẹ̀ jẹ́ pé ìròyìn òfegè ni pé Buhari fẹ fẹ́ Sadiya, síbẹ̀ àwọn ọmọ Nàìjíríà ń ṣètò ìyàwò náà lórí ayélujára
'Títẹ àwọn afipábánilopọ̀ lọ́dàá kọ́ ni ọ̀nà àbáyọ sí ìwà ìfipábánilopọ̀'
Ọpẹ́ o! Àwọn ologun dóòlà akẹ́kọ̀ọ́ mẹ́fà lọ́wọ́ àwọn ajínigbé ní Kaduna
Funke Akindele fi fiimu to ṣẹṣẹ dari sita lori oju opo Instagram rẹ, eyi ti o pe akọle rẹ ni #Your Excellency.
O sọ nipa asiko ti ere naa yoo di wiwo ni kaakiri
Dino Melaye fìdí rẹmi, Smart borí nílé ẹjọ́ kòtẹ́milọ́rùn
Ta ni Sadiya Umar Farouq tí ìròyìn ẹlẹ́jẹ̀  ń gbé pé òun ló fẹ́ dí ìyàwó tuntun Buhari?
Olùkọ́ àgbà tó fipá bá ọmọ ọdún 13 lò yóò fojú ba ilé ẹjọ́ ni Benue
Uganda ti bẹrẹ ìgbésè láti fi ikú ṣefàjẹ fún ẹní bá ṣe ìgbéyàwó akọ si akọ ati abo si abo
Lẹyin to gboryin fun Baba Ibeji olowo ori Funkẹ pe o ku atilẹyin oun.
Inú mi dùn pé ọmọ obinrin nìkan ni mo bi
Ọjọ Aje, ọjọ keje, oṣu kẹwaa ni ọjọ ibi Laide Bakare, eyi to ṣe ni ilu Atlanta, nipinlẹ Georgia l'Amerika.
Oriṣiiriṣii fidio ni Laide fi soju opo Instagram rẹ eleyi to ṣayẹyẹ ọjọ ibi rẹ.
Ijo ni Odunlade Adekola fi bẹ ni tiẹ ninu fidio kan to fi soju opo Instagram rẹ.
Fidio yii lo ṣafihan bi Odunlade ṣe ko mọlẹ pẹlu Mike Edwards to wa lara awọn marun un to pegede julọ ninu eto BBNaija 2019 to ṣẹṣẹ pari
David Adiatu oníṣẹ́ ọnà pẹ̀lú ìṣó àti òwú
Femi Adebayo Salami to jẹ ọmọ Ọga Bello fi aworan kan sori oju opo ayelujara rẹ eleyi to fi ṣalaye pe ohun kan to rọ oun lọrun ju lati maa ṣe naa ni ere ori itage.
Koda o ni oun le ṣee lọfẹẹ, bakan naa lo bi awọn ololufẹ rẹ lati sọ ohun ti wọn fẹran ju ni ti wọn lati maa ṣe.
Àbà ètò ìṣúná 2020 tó kéré yóò mú kí ètò ààbò mẹ́hẹ síi ní Nàìjíríà-Onwoye
Èrò yapa ní mọ́ṣáláṣí Jimọ̀h láti wá fójú lóúnjẹ lórí ìgbéyàwó òfegè Buhari.
Ìbéèrè àti ìdáhùn pẹ̀lú Seyi Awolowo ti BBNaija lórí BBC Yorùbá
Buhari ti fòfin de àwọn mínísítà láti rìnrìn àjò lọ sí ilẹ̀ òkèrè
Lọsẹ yii bakan naa ni oṣerekunrin ni, Lateef Adedimeji gba ami ẹyẹ Emperor Award Stylish Actor.
O ki gbogbo awọn eeyan to dibo fun un loju opo instagram rẹ, bẹẹ naa lo fi ami ẹyẹ ọhun sọri wọn.
Ìdẹ̀ra dé l'Eko! ọkọ̀ ojú omi tuntun bẹ̀rẹ̀ iṣẹ́
Abiy Ahmed gba àmì ẹ̀yẹ̀ ti àláfíà lágbàáyé gẹ́gẹ́ bí ọmọ Africa
Ìgbẹ̀yìn ọkùnrin tó pa obìnrin 93 ni America
Òjò àrọ̀rọ̀ọ̀dá òní ṣọṣẹ́ tó pọ̀ ni Lekki nipinlẹ Eko
EkitiRapeCastration: ìgbésẹ̀ míì lè dẹ́kun ìwà ìfipábánilòpọ̀
BUSA 2019: Èrò yapa ní mọ́ṣáláṣí Jimọ̀h láti wá fójú lóúnjẹ lórí ìgbéyàwó Buhari
Kini o ṣẹlẹ ni Mọṣalaṣi Jimoh lanàá ti wọn royin ofege pe Buhari fẹ ṣe igbeyawo nibẹ?
Lati bi ọjọ mẹta kan ni iroyin ti gbori ayelujara kan pe Aarẹ Muhammadu Buhari fẹ gbe iyawo miran.
Oríṣun àwòrán, @others
Buhari kirun Jimoh laiṣe igbeyawo gẹgẹ bi awọn kan ṣe n sọ kiri
Iroyin naa ni Hajiya Sadiya Umar Farouq ni aarẹ fẹ gbe ni ọsingin ni eyi ti awọn eniyan si fẹ mọ sii nipa rẹ pe Ta ni Sadiya Umar Farouq tí ìròyìn ẹlẹ́jẹ̀  ń gbé pé òun ló fẹ́ dí ìyàwó tuntun Buhari?
Hajiya Sadiya ti ẹnu n kun yii wa ninu awọn obinrin meje ti wọn jẹ minista tuntun ti Buhari yanWo ohun tó yẹ kí o mọ̀ nípa àwọn obìnrin méje ti Buhari fẹ́ yàn sípò minista
Lori ayelujara ni awọn eniyan Naijiria ti ṣeto igbeyawo fun wọn lana Bó tilẹ̀ jẹ́ pé ìròyìn òfegè ni pé Buhari fẹ fẹ́ Sadiya, síbẹ̀ àwọn ọmọ Nàìjíríà ń ṣètò ìyàwò náà lórí ayélujára
Iroyin to n jade lati ile iṣẹ iroyin Naijiria ni pe ọpolọpọ ero lo wa kirun Jimọ lana ni mọṣalaṣi ile ijọba apapọ ni Aso Rock nilu Abuja to jẹ olu ilu Naijiria.
APC: òfin NYSC ti APC fi mú mi ni wọ́n kò lò fi mú Ajimọbi tí a kò jọ sìnrú ìlú
Lara awọn eekan to wa kirun pẹlu aarẹ Buhari lana ni Abdulaziz Yari to jẹ gomina ipinlẹ Zamfara tẹlẹ atawon minista mii.
Oríṣun àwòrán, @others
ọpọ ero lo fẹ mọ ohun ti a ṣẹlẹ lasiko Jimọh
Koda, iroyin ni ero pọ pupọ ni mọṣalaṣi naa de ibi pe wọn gba pe awọn fẹ wa woran pe boya lootọ nigbeyawo yoo waye laarin Aarẹ ati minista fawọn aṣatipo rẹ tuntun.
Awọn ti wọn tori igbeyawo Buhari ya mọṣalaṣi Aso Rock ni inu wọn ko dun to pe igbeyawo naa ko waye bi ayelujara ṣe kede rẹ.
Ileeṣẹ iroyin Naijiria ni ọpọ ninu awọn to ya wa kirun Jimọ nibẹ naa lo n ṣepe fawọn to bẹrẹ iroyin ofege naa lori ayelujara.
Bakan naa ni awọn bii Aliyu ti wọn wa kirun naa gba awọn ọmọ Naijiria nimọran lati ma gba gbogbo nkan ti wọn ba ka lori ayelujara gbọ nitori irọ pọ nibẹ.
Ni afikun ni awọn bii Malam Sidique to wa kirun ni Aso Rock naa ke si ijọba lati wa wọrọko fi ṣada lori iroyin ẹlẹjẹ to n gab ori ayelujara kan lasiko yii.
Inú mi dùn pé ọmọ obinrin nìkan ni mo bi
Ṣaaju awọn oluranlọwọ fun Aisha Buhari nileeṣẹ Aarẹ ti sọ fun BBC tẹlẹ pe irọ to jina si ootọ ni iroyin naa.
Bẹẹ minista ti wọn ni Buhari fẹ fẹ wa ni Geneva nilẹ okeere lasiko yii.
David Adiatu oníṣẹ́ ọnà pẹ̀lú ìṣó àti òwú
Lẹyin eyi ni iroyin ni Femi Adesina to jẹ olubadamọran fun Aarẹ Buhari lori eto ifitonileti ti sọ ni Tribune Online pe awọn kan ni wọn gbe irọ naa kalẹ.
Ọpọ ọmọ Naijiria lo gba pe adura lo ku ki a maa gba fun awọn adari Naijiria lai gba iroyin ofege laaye lati daamu ọkan ẹnikẹni.
Kemi Lala: mo ń gbìyànjú láti mú inú òbí mi dùn
LASEMA: Òjò nìkan kọ́, ọkọ̀ aképo méjì tó dànù náà ṣòkùnfà súnkẹrẹ-fàkẹrẹ l'Eko
Oríṣun àwòrán, lasema
LASEMA: Òjò nìkan kọ́, ọkọ̀ aképo méjì tó dànù náà ṣòkùnfà súnkẹrẹ-fàkẹrẹ l'Eko
Ọkọ akepo kan to danu lagbegbe afara Otedola nilu Eko ti mu idiwọ ba lilọ bibọ awọn ọlọkọ lopopona marosẹ Lagos- Ibadan lọjọ Abamẹta.
Eyi ni ọkọ akepo keji ti yoo danu laarin wakati mẹrinlelogun si ara wọn.
Ọga agba ileeṣẹ to n mojuto iṣẹlẹ pajawiri nilu Eko, LASEMA, Ọmọwe Femi Osanyintolu lo tu kẹkẹ ọrọ yi fun ileeṣẹ BBC.
Osanyintolu ni lowurọ ọjọ Abamẹta ni ọkọ to ko epo bẹntiroo oni lita egbẹrun marundinlaadọta, (45, 000) naa danu ti awọn si ti n gbiyanju lati da epo inu rẹ si ọkọ miran.
''Lalẹ ana (ọjọ Ẹti) ni ọkọ akepo kan to gbe epo bẹntiroo lita ẹgbẹrun mẹtalelọgbọn epo (33,000) danu ti a si pari dida epo rẹ sinu ọkọ miran lowurọ yi.
O ni, o ṣe ẹni laanu pe omiran danu ni tosi eleyi to ṣẹlẹ tẹlẹ''
Oríṣun àwòrán, LASEMA
LASEMA: Òjò nìkan kọ́, ọkọ̀ aképo méjì tó dànù náà ṣòkùnfà súnkẹrẹ-fàkẹrẹ l'Eko
Omọwe Femi, ọga agba LASEMA ni awọn ko ni pẹ pari dida epo rẹ ti lilọ bibọ ọkọ yoo si pada si ti tẹlẹ.
Niṣe ni ọpọ eeyan to n gba adugbo naa ha sinu sunkẹrẹ-fakẹrẹ ti awọn eeyan si ro pe ojo to rọ larọda lo ṣokunfa sunkẹrẹ-fakẹrẹ yi.
Inú mi dùn pé ọmọ obinrin nìkan ni mo bi
Iṣẹlẹ didanu ọkọ epo ko jẹ tuntun nilu Eko ti a si ma saaba fa ijamba ina ti o maa n mu ẹmi ati dukia lọ.
Oríṣun àwòrán, @lasema
LASEMA: Òjò nìkan kọ́, ọkọ̀ aképo méjì tó dànù náà ṣòkùnfà súnkẹrẹ-fàkẹrẹ l'Eko
Oga agba LASEMA fi da awọn eniyan loju pe, iṣẹ gidi ti n lọ lọwọ ni ori afara Otẹdọla bayii ni eyi ti nkan ko si ni pẹ yipada.
EkitiRapeCastration: ìgbésẹ̀ míì lè dẹ́kun ìwà ìfipábánilòpọ̀
Lagos: Èèyàn mẹ́rin kú l'Eko, lẹ́yìn òjò àrọ̀ọ̀rọ̀dá tó wó ilé mẹ́ta
Oríṣun àwòrán, lasema
Eeyan mẹrin ti padanu ẹmi wọn lẹyin ti omiyale wo ile mẹta nilu Eko.
Ninu awọn mẹrin to ku  naa la ti ri abiyamọ kan ati awọn ọmọ rẹ mẹta ladugbo Magodo Iseheri.
Ninu ifọrọwanilẹnuwo pẹlu BBC, ọga agba ile iṣẹ iṣẹlẹ pajawiri L'Eko Femi Osanyintolu tun fidi ọrọ mulẹ pe awọn ile meji miran mi tun wo ladugbo Ikorodu.
''Ọkan ninu awọn iṣẹlẹ yi waye ni Ita Ẹlẹwa ni Ikorodu ti ẹlẹkeeji si waye ni Agric ni Ikorodu kan naa.''
Osanyintolu ni ko si eeyan kankan to ba iṣẹlẹ mejeeji yi lọ ni Ikorodu ṣugbọn awọn ti o farakasa lawọn ribi doola ẹmi wọn ni ibẹ.
Nigba ti a beere ohun to ṣe okunfa iṣẹlẹ wọn yi, o ni oun ko le sọ pato ṣugbọn bi oju ọjọ ti ṣe ri ni nnkan ṣe pẹlu awọn ile to n wo lasiko yii.
Oríṣun àwòrán, lasema
Oríṣun àwòrán, rrslagos
Eeyan mẹrin ni wọn lo ku ninu ile yi to wo ni Magodo
Kaakiri ilu Eko ati lawọn ipinlẹ mii lorileede Naijria ni iroyin ti n gbode nipa ọṣẹ ti arọọrọda ojo n ṣe yala nipa ẹkun omi, ile wiwo tabi afara to n ja.
Loju opo Twitter ati ayelujara niṣe ni awọn eeyan n fi aworan ijamba ti arọọrọda ojo naa n ṣe ati bi oju popo ti ṣe kun fun omi paapa julọ nilu Eko.
Ẹ le wo diẹ lara awọn aworan naa nibi.
2020 Budget: ₦75m nìjọba yóò fi ra epo àti àtúnṣe ẹ̀rọ amúnáwá níléeṣẹ́ rẹ̀ lókè òkun
Oríṣun àwòrán, @Imam_Genset
O ṣeeṣe ki ọrọ ina ọba to n ṣe mọnamọna ni Naijiria maa lojutu laipẹ, lẹyin ti Aarẹ Muhammadu Buhari ya owo to le ni biliọnu mẹsan an naira sọtọ ninu aba eto iṣuna ọdun 2020 lati ra ẹrọ amunawa.
Owo naa tun wa fun rira epo ati atunṣe awọn ẹrọ amunawa kaakiri ẹka ijọba fun ọdun 2020.
Bakan naa ni ijọba apapọ tun ya miliọnu marundinlọgọrin sọtọ fun atunṣe ati rira epo si gbogbo ẹrọ amunawa to wa lolu ileeṣẹ ijọba Naijiria nilẹ okeere.
Ẹkunrẹrẹ gbogbo rẹ wa ninu aba eto iṣuna ọdun 2020 ti Aaarẹ Buhari gbe lọ siwaju ile aṣofin agba l'Abuja lọjọ Iṣẹgun ọsẹ to lọ, ti ileeṣẹ ologun nikan yoo si lo owo to le ni ẹẹdẹgbẹta miliọnu naiira lati ra epo si ẹrọ amunawa lasan.
Oríṣun àwòrán, @Imam_Genset
Ajọ to n gbogun ti iwa ajẹbanu EFCC yoo na ọdunrun un miliọnu o le mẹtala lori ẹrọ amunawa, EFCC ni yoo nanwo to pọju sikeji lori ẹrọ amunawa lọdun 2020.
Awọn onimọ nipa eto ẹnawo sọ pe, biliọnu mẹsan naira tijọba ya sọtọ fun ẹrọ amunawa yii, ju owo to wọle sapo ijọba ipinlẹ mẹtadinlogun ni Naijiria lọ, fun oṣu mẹfa akọkọ lọdun 2019.
Bakan naa ni wọn sọ pe o ṣeeṣe ki o ju owo ti ijọba ya sọtọ fun ajọ eleto idibo INEC ati ajọ to n ri si ọrọ ilera, NHIS lọ ninu aba eto iṣuna ọdun 2020.
Biliọnu mẹsan an ti ijọba yoo na lori ẹrọ amunawa jẹ iyalẹnu fun ọpọ lẹyin ti ijọba ti sọ pe ina ọba ti gberu si ni Naijiria.
Flooding: Ọ̀pọ̀ ẹ̀mí ṣòfò, tí dúkìá àìmoye mílíọ̀nú naira sì bá ẹ̀kún omi lọ
Oríṣun àwòrán, Twitter/RovingReporter
Ọjọ buruku Eṣu gbomi mu ni ọjọ Abamẹta, ọjọ Kejila oṣu Kẹwaa jẹ fun ọpọ olugbe ilu Eko atawọn ilu miran nilẹ Yoruba nigba ti arọọrọda ojo di omiyale, agbara ya ṣọọbu.
Ọpọ eeyan lo gbemi mi nigba tile wo lewọn lori, bakan naa lomi ba ọpọ dukia jẹ.
Kaakiri ilu Eko ati lawọn ipinlẹ mii lapa iwọ oorun Naijria ni arọọrọda ojo ti ṣọṣe yala nipa ẹkun omi, ile wiwo tabi afara to ja.
N ṣe lawọn eeyan fi aworan ijamba ti arọọrọda ojo naa ṣe ati bi oju popo ti kun fun omi, paapa julọ niluu Eko sori ayelujara. Diẹ ninu irufẹ aworan ọhun niyii.
Aworan yii ṣafihan ile to dawo lagbegbe Ita Ẹlẹwa ati Agric ni Ikorodu nipinlẹ Eko.
A gbọ pe  ko si eeyan kankan to ba iṣẹlẹ mejeeji yi lọ ni Ikorodu.
Oríṣun àwòrán, lasema
Eeyan mẹrin lo padanu ẹmi wọn lẹyin ti ile kan wo ladugbo Magodo Iseheri lasiko, arọọrọda ojo Satide.
Ninu awọn mẹrin to ku  naa la ti ri abiyamọ kan ati awọn ọmọ rẹ mẹta
Oríṣun àwòrán, rrslagos
Eeyan mẹrin ni wọn lo ku ninu ile yi to wo ni Magodo
Opopona Marosẹ ni Lekki nipinlẹ Eko ti wọn ngba pe o jẹ adugbo awọn to ri jajẹ diẹ ni omi ti ya wọ bayii.
Ẹkun omi naa ṣe idiwọ fun ọkọ lati lọ geregee, bakan naa lo ba ọpọ dukia jẹ.
Opopona Marosẹ ni Lekki ti wọn gba pe o jẹ adugbo awọn to ri jajẹ diẹ ni omi ti ya wọ bayii, kini ipin awọn adugbo mii a jẹ?
Adugbo Razak Eletu ni Osapa Garden Estate ni Lekki ni agbara ojo ti gba opopona mọ awọn eeyan lọwọ yii
Adugbo Razak Eletu ni Osapa Garden Estate ni Lekki lo sọ gbogbo olugbe ibẹ di konile-o-gbele lasiko yii.
Adugbo Razak Eletu ni Osapa Garden Estate ni Lekki lo sọ gbogbo olugbe ibẹ di konile-o-gbele lasiko yii
Awọn eeyan ijọba ibilẹ Waterside rawọ ẹbẹ si Gomina ipinlẹ Ogun, Dapo Abiodun lẹyin ti ẹkun omi ọjọ Satide gba ọna to lọ si ijọba ibilẹ naa.
Oríṣun àwòrán, Facebook/Olufowobi Kenny
Oríṣun àwòrán, Facebook/Olufowobi Kenny
Gomina ipinlẹ Kwara, Abdulrahman Abdulrazaq lo fi aworan ẹkun omi ni ilu Ilorin sori oju opo Twitter rẹ, nibi to ti sọ pe awọn to da ilẹ sinu kọta lo n fa omiyale.
Oríṣun àwòrán, Twitter/Abdulrahman Abdulrazaq
Ẹkun ojo ṣe bẹbẹ nipinlẹ Ondo bakan naa, koda ọkọ oju omi lawọn kan n ba wọle wọn lẹyin ti omi ti gba iwaju ile wọn tan.
Oríṣun àwòrán, Twitter/RovingReporter
Oríṣun àwòrán, Twitter/Ibromicah
No Bra Day: Àyájọ́ ‘Má wọ kọ́mú’ ló ń pe àkíyèsí àwọn obìnrin sí àìsàn jẹjẹrẹ ọyàn
Oríṣun àwòrán, Geneva_la_jade
Ọjọ Kẹtala osu Kẹwa ọdọọdun no ayajọ ọjọ 'Ma wọ kọmu' lorilẹede Naijiria eyi to n sọ fun awọn obinrin lati yan kọmu lodi lọjọ naa.
Gẹgẹ baa si se mọ, osu kẹwa yii kan naa ni awujọ agbaye ya sọtọ fun ayajọ gbigbogun ti aisan jẹjẹrẹ ọyan, lọwọ-lọwọ bayii, ori ayelujara si ti kun fun aworan awọ̀n obinrin to n yan kọmu lodi lonii lati dena arun jẹjẹrẹ ọyan.
Gẹgẹ baa se gbọ, ohun to fa idasilẹ ayajọ ọjọ 'Ma wọ kọmu' ni Naijiria ni lati pe akiyesi awọn obinrin si aisan jẹjẹrẹ ọyan ati awọn ọna ti wọn lee gba dena rẹ.
Lasiko ayajọ ọjọ 'Ma wọ kọmu' yii si ọpọ obiinrin maa n fi ọyan wọn silẹ bi Ọlọrun se daa, lai wọ kọmu taa mọ si Bra tabi Brassiere lati koo soke, nitori pe iwadi kan ti fidi rẹ mulẹ pe awọju kọmu gan maa n fa aisan jẹjẹrẹ.
Oríṣun àwòrán, https://twitter.com/Trem6676
Amọ ọpọ awọn obinrin to ti ni aisan jẹjẹrẹ, amọ ti ori ti ko yọ, ni ko lee se lai ma wọ kọmu nitori wọn nilo lati fi kọmu gbe fukẹfukẹ soke, eyi ti wọn se rọpo ọmu fun wọn lẹyin isẹ abẹ ti wọn fi ge ọyan wọn kuro.
To ba lọ se ayẹwo agọ ara rẹ nile iwosan, obinrin gbọdọ ri daju pe awọn osisẹ eleto ilera se ayẹwo ọyan fun oun lọna to peye, ti ẹnikọọkan si gbọdọ mọ baa ti se ayẹwo ọyan funra ẹni
Nibayii ti ayajọ ọjọ 'Ma wọ kọmu' tun ko loni, a n rọ gbogbo obinrin lati se ayẹwo ọyan wọn nitori ijafara lewu, ati okeere si ni oloju jinjin ti n mu ẹkun sun.
Twins Festival 2019: Àlákóso ọdún ìbejì ń fẹ́ kí àjọ ìṣọ̀kan àgbáyé gbárùkù ti ọdún náà
Oríṣun àwòrán, HRM Oba Lamidi Adeyemi III
Alaafin Ọyọ Ọba Lamidi Olayiwola Adeyemi Kẹta ti ṣe alaye pe ko si oogun kankan to n mu ki eeyan bi ibeji, yatọ si awọn ounjẹ ti a jogun ba lọwọ awọn baba wa.
Ọba Adeyẹmi ni awọn ounjẹ wonyii n ṣe anfani ti o pọ fun ọkunrin, lati ṣe ojuse rẹ lọdọ aya rẹ, lai naani ọjọ ori, pẹlu afikun pe idi niyii ti ko fi yẹ ki a gbagbe nnkan ajogunba awọn baba wa.
Alaafin ṣe alaye ọrọ naa nibi ayẹyẹ ọdun ibeji fun ọdun 2019 to waye lọjọ Abamẹta nilu Igboọra nipinlẹ Ọyọ.
Ọba Adeyẹmi, to jẹ alejo pataki nibi ayẹyẹ naa tun ṣe alaye wi pe, laye atijọ awọn baba wa maa n fi agunmu si ogi ki wọn to muu, bẹẹ si ni wọn n fi epo pupa ati ikẹtẹ jẹ iṣu to fi mọ jijẹ ilasa, ila ọrunla ati ewedu, eyi to n fun wọn lokun ati agbara gidi.
O tẹ siwaju pe, pupọ ninu awọn ogun Oyinbo ti awọn eeyan n lo, lo n ṣe akoba fun agọ ara lẹyin ti wọn ba wo aisan tan, ṣugbọn ko ri bẹẹ fun awọn ohun ibilẹ ti awọn baba wa n lo.
Alaafin Ọyọ: Asiri agbara bibi ibeji lọpọ igba
Lorii pataki ibeji, Kabiyesi ni wọn jẹ ẹda to ṣe pataki gẹgẹ bi awọn Yoruba ṣe kaa kun, ati pe, ara ti Ọlọrun fi ibeji da ni wi pe ile ọmọ to n bẹ ninu obinrin ko pe meji, sibẹ, obinrin n bi ọmọ meji si mẹta lẹẹkan ṣoṣo.
O tẹsiwaju wi pe, idunnu ati ayọ ni awọn ibeji maa n mu wọ gbogbo ile ti a ba ti bi wọn, idi si niyii ti gbogbo aye fi n tẹwọgba awọn ibeji gẹgẹ bii ohun arikẹ ariyọ.
Alaafin tun fi idunnu han lorii bi oore ibeji ṣe wọ akata ti ẹ naa, pẹlu alaye wi pe, idile ayọ ni idile ẹni to ba bi ibeji. Idile owo, idile itura si ni.
Ninu ọrọ ti ẹ, alaga igbimọ to ṣe eto ayẹyẹ ọdun ibeji, ẹlẹẹkeji iruẹ ti yoo waye nilu Igboọra, Olu-Aṣo Iberekodo, Ọba Adedamola Badmus ṣe alaye fun ikọ BBC Yoruba wi pe, goolu ti Ọlọrun fi ta ilu Igboọra lọọrẹ ni awọn ibeji jẹ.
O ni gbogbo ilu to n bẹ ni agbaye lo ni ohun alumọni ti ẹ, ṣugbọn ọgọọrọ ibeji ati ọmọ mẹta ni Eledua pin kan ilu naa.
Olu Aṣo wa parọwa si ijọba ati ajọ iṣọkan agbaye lati gbaruku ti ọdun naa, ko tun le goke agba sii.Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí:
Bakan naa ni Taye-Kehinde Oguntoye, ti o ṣe agbatẹru eto naa ṣe alaye wi pe, ilu Igboọra le di ibudo igbafẹ nla fun gbogbo agbaye ti awọn alẹnulọrọ ba le sa ipa wọn, lati ṣe ohun ti o yẹ lorii ayẹyẹ ọdun ibeji naa.
Igbagbo wọn ni wi pe ọdun naa le di ohun ti gbogbo agbaye n pe wo, ti ijọba ipinlẹ Ọyọ ati orilẹede Naijiria yoo si maa ti ibẹ pa owo gọboi.
Ọgọrọ awọn ibeji ati ọmọ mẹta lati ori awọn ọmọde titi to fi mọ awọn agbaagba lo pejupesẹ si papa iṣere ile ẹkọ Methodist ilu Igboọra nibi ti ayẹyẹ naa ti wa ye.
Lara awọn alejo pataki to darapọ mọ ipejọpọ naa ni Eleruwa ti ilu Eruwa, Ọba Samuel Adebayọ Akindele Kinni, Olu Igboọra, Ọba Jimoh Titiloye pẹlu awọn aṣoju ijọba ipinlẹ Ọyọ, lẹgbẹlẹgbẹ, loyeloye ati bẹẹbẹẹ lọ.
"Yollywood: ""Ben Murray Bruce, jọ̀ọ́ ṣàánú ajé, kó sàfihàn sinimá mí táyé ń fẹ́"""
Oríṣun àwòrán, toyin_abraham
Idi isẹ ẹni la ti n mọ ni lọlẹ, ẹni ti wọn ba si n wo, kii woran, bẹẹ ni ẹni to ba n sun, kii sun siwaju.
Idi ree ti ilumọọka osere tiata lobinrin, Toyin Abraham aya Ajeyẹmi ko se maa sun asun hanrun lẹyin igba to bimọ tuntun tan, eyi ti ko tii pe osu mẹta bayii.
Toyin tun ti wa gbe sinima tuntun kan sita eyi to pe akọle rẹ ni Elevator Baby, asiko ti oyun rẹ si pe osu mẹfa lo ya sinima naa.
Koda, sinima yii ti di wiwo lawọn ile sinima yika orilẹede yii, ti ọpọ eeyan si ti n woo fun ọgbọn ati idanilaraya.
Oríṣun àwòrán, toyin_abraham
Sugbọn ara aje n ta Toyin Abraham lọwọ-lọwọ bayii, ti ko si tii sinmi lori bi wọn se n wo sinima naa si paapa nigba ti ibudo sinima kan kọ lati se afihan sinima Elevator Baby ọhun.
Ibudo sinima ọhun si lo jẹ ti ilumọọka sẹnetọ kan ati oludasilẹ ileesẹ amohunmaworan Silverbrds nilu Eko, Ben Murray Bruce.
Nigba to n gbarata lori isẹlẹ naa loju opo Twitter rẹ, Toyin wa n fi ohun ransẹ si Sẹnetọ Ben Bruce pe ki lo de ti gbogbo ile sinims n se afihan sinima oun ayafi ibudo sinima Murray Bruce to kọ lati se bẹẹ.
"Toyin ni ""Ẹ kaarọ sir. Sinima mi, #Elevatorbaby ni wọn n se afihan wọn kaakiri awsn ibudo sinima ayafi ibudo sinima tiyin nikan ni ko gbe sita. Ki lo de ti eyi fi ri bẹẹ, paapa nigba tẹ ti jẹjẹ saaju pe ẹ maa se atilẹyin fun awọn ọdọ."""
Ko tan sibẹ o, Toyin tun tẹsiwaju pe ọpọ awọn ololufẹ oun lo n poungbẹ lati wo sinima naa lagbegbe Ikeja, eyi ti oun ya nigba ti oun wa ninu oyun osu mẹfa.
Oríṣun àwòrán, toyin_abraham
O wa n rawọ ẹbẹ si Oloye Bruce lati se atilẹyin fun isẹ oun nipa sise afihan sinima naa nitori isẹ asekara ni oun se ninu sinima ọhun, ti oun  si n fẹ ki oogun oju oun naa ma ja si asan
Toyin salaye siwaju pe ida ọgọjọ ninu awọn eeyan to kopa ninu sinima naa lo jẹ ọdọ ti ọjọ ori wọn ko ju ọdun mẹtadinlọgbọn lọ, ti oludari sinima naa si jẹ ọdun mẹrindinlọgbọn, ọdun mẹẹdọgbọn ati mẹrindinlsgbọn ni awọn olootu sinima naa, ti asaraloge oun si jẹ ẹni ọdun mẹtalelogun pere.
Minimum Wage: NLC ní àfikún owó oṣù nìkan lẹ̀rọ̀ ìyanṣẹ́lódì
Oríṣun àwòrán, @NLCHQ_ABUJA
Ẹgbẹ oṣiṣẹ lorilẹede Naijiria, NLC, ti sọ fun awọn adari ẹgbẹ ọhun lawọn ipinlẹ pe ki wọn gbaradi fun iyanṣẹlodi, bẹrẹ lati lọjọru, ọjọ Kẹrindinlogun oṣu Kẹwa ọdun 2019.
Ẹgbẹ NLC ni oun yoo gunle iyaṣẹlodi naa ti ifọrọwerọ oun pẹlu ijọba apapọ ko ba so eso rere.
Ninu atẹjade kan ti ẹgbẹ naa fi sọwọ si awọn ẹka rẹ ni awọn ipinlẹ, ti akọwe agba ẹgbẹ, Emmanuel Ugboaja fọwọ si, l oti sisọ loju ọrọ naa.
Ẹgbẹ NLC ni, gẹgẹ bi iwe ti oun ti kọ ṣaaju si awọn ọmọ ẹgbẹ naa ni Naijiria pe, ti ajọsọ egbẹ naa pẹlu ijọba apapọ lori afikun owo oṣu ko ba so eso rere, oun yoo bẹrẹ iyanṣẹlodi.
Oríṣun àwòrán, @NLCHQ_ABUJA
Ṣaaju ni ẹgbẹ awọn oṣiṣẹ ọhun ti beere afikun owo oṣu to jẹ ida mọkanla fun awọn oṣiṣẹ to wa ni ipele keje si mẹrinla, ati afikun owo oṣu ida mẹfa abọ fun awọn oṣiṣẹ ijọba to wa ni ipele karundilogun titi de ipele kẹtadinlogun.
Ni ọjọ kẹrinla oṣu karun un ọdun 2019 ni ijọba apapọ gbe igbimọ kan dide lati boju wo afikun ti ẹgbẹ oṣiṣẹ n beere fun.
Lẹyin ọpọlọpọ ipade ati ijiroro, o jọ pe ẹ́gbẹ oṣiṣẹ ati ijọba apapọ ko tii fẹnu ọrọ naa jona.
Sanwo-Olu: Etí mi kò di sí ìrora aráàlú, ẹ fara dàá pẹ̀lú mi
Oríṣun àwòrán, @Lag
Popona Marose Ilu Eko
Akọwe agba lori ọrọ iroyin fun gomina Babajide Sanwo-Olu, Gbenga Akosile, fi ọrọ naa lede lẹyin ọpọ ipade ti gomina naa ba awọn Agbaṣẹ ṣe.
Ko din ni Agbaṣẹ ṣe bii mẹjọ ti wọn jọ fọwọ si iwe adehun lati bẹrẹ iṣẹ naa lai fi akoko ṣofo, lẹyẹ o sọka.
Gomina Ipinlẹ Eko, Babajide Sanwo-Olu ti paṣẹ pe ko gbọdọ si koto mọ ni awọn popona ilu Eko.
Sanwo-Olu lo sọrọ yii ni opin Ọsẹ pe, bẹrẹ lati ọjọ Aje, ki awọn agbaṣẹ ṣe bẹrẹ iṣẹ ni kiakia.
Inú mi dùn pé ọmọ obinrin nìkan ni mo bi
Lara awọn agbaṣẹṣe oju- ọna naa ni Julius Berger, Hitech, Arab Contractors,Metropolitan Construction, Slavabogu,, China Construction, ati RCF Nigeria.
Oríṣun àwòrán, Facebook
Lara awon ona ti ko dara ni ilu Eko
Kete lẹyin ipade naa ni Gomina ti ni ki awọn agbaṣẹṣẹ yii lọ bẹrẹ iṣẹ atunṣe awọn opopona.
Nigba ti ikọ BBC ba Bọsun Aguda to jẹ olugbe ilu Eko sọrọ lori ipinnu ijọba, o fi idunnu rẹ han si igbesẹ yii.
O si ṣalaye pe, ọna ni koko iṣoro ti awọn eniyan Ipinlẹ Eko n koju ni pataki, awọn ti o n lo ọkọ.
Loju tirẹ Gomina Sanwo-Olu ṣẹṣẹ gbe igbesẹ to yẹ lasiko yii ni lati ṣatunṣe si awọn opopona.
David Adiatu oníṣẹ́ ọnà pẹ̀lú ìṣó àti òwú
Gomina Sanwo-Olu paṣẹ pe ki wọn kọkọ bẹrẹ iṣẹ pẹlu awọn popona ti o jẹ koko ti awọn eniyan maa n rin lọpọ igba lati mu adinku ba sunkẹrẹ fakẹrẹ ọkọ.
O ni ki gbogbo awọn ile iṣẹ naa lọ ko gbogbo irin iṣẹ wọn lọ si oju ọna naa ni kiakia ki iṣẹ si bẹrẹ lẹyẹ- o- sọka.
Ninu atẹjade naa ti wọn fi ṣọwọ si awọn akọroyin ni wọn ti sọ wi pe gbogbo eto ti to lati ri i pe iṣẹ bẹrẹ ni awọn ibi pataki ni ipinlẹ Eko.
Sanwo Olu wa fi da awọn eniyan loju pe ajọ ti n ri si igbokegbodo ọkọ ni Eko [LASMA] yoo maa ṣiṣẹ tọsan toru lati mu irinna ọkọ rọrun.
Olubadamọnran fun gomina naa lori ọrọ iṣẹ ati akanṣe, Aramide Adeyoye ṣalaye lori awọn opopona ti iṣẹ wọn yoo gunle bii Ojota ti o gba Ikorodu ati Kudirat Abiola kọja.
Awọn yooku ni marosẹ Apọngbọn, Babs Animaṣahun, Agric / Ishawo ati Ijẹdẹ ni ọna  Ikorodu, to fi mọ popona Marosẹ Lekki-Epe lati Abraham Adesanya si Orita Eleko.
Ti wọn yoo tun ṣe iṣẹ ọna naa de Ikoyi, ile-igbe Ijọba ni Ikeja ati Victoria Island.
Sanwo-Olu fẹ́ ṣàtúnṣe òpópónà 116, ọ̀pọ̀ aráàlú ń fẹ́ kí àtúnṣe ọ̀nà dé àdúgbò wọn:
N ṣe lawọn eeyan ilu Eko ti bẹrẹ si ni rawọ ẹbẹ si Gomina ipinlẹ naa pe, ko nawọ atunṣe opopona to fẹ bẹrẹ lọjọ Aje oni de ọdọ wọn.
Loju opo Twitter, ni wọn fi arọwa wọn yii sọwọ si gomina, lẹyin ti ijọba Eko ni oun ṣetan lati koju ipenija oju ọna to pakasọ nilu naa.
Oríṣun àwòrán, @Ijobaoflagos
Ninu ikede to fi sita bakan naa, Sanwo-Olu ni opopona bii mẹrindinlọgọfa ni yoo gba atunse yatọ̀ si igba oju ọna ti wọn ti tun se tẹlẹ laarin osu mẹta sẹyin.
Gomina Eko ni eti oun ko di si irora tawọn olugbe ipinlẹ Eko n la kọja lasiko ojo arọọrọda yii, to si rọ awọn araalu lati fara daa pẹlu ijọba, nibayii to n se aayan lati bu tutu si oju egbo naa.
Oríṣun àwòrán, @jimidisu
Lẹnu ọjọ mẹta yii, wahala sunkẹrẹ fakẹrẹ ọkọ nilu Eko fẹ lekenka, ti awọn awakọ ati arinrinajo si n ke irora nipa idiwọ ti awọn ọna to bajẹ wọn yii n  fa.
Ni meni meji ni onikaluku bẹrẹ si ni tọka adugbo wọn, ti wọn si n beere ki ijọba nawọ atunṣe de ọdọ tawọn naa, nitori tẹni ba dakẹ, tara rẹ yoo ba dakẹ ni.
Lọjọ Aiku ni Gomina Sanwo Olu fi ikede si oju opo Twitter rẹ pe, asiko to bayi lati koju ipenija awọn oju ọna Eko to nilo atunṣe.
O ni lẹyin ipade toun ṣe pẹlu awọn agbaṣẹse to n tun ọna ṣe, awọn yoo ri pe iṣẹ to peye waye lori awọn oju ọna to bajẹ naa.
Death at Airport: Ọkùnrin kan jáde láyé bó ṣe gba ìròyìn ikú aya rẹ̀
Oríṣun àwòrán, Others
Arinrinajo kan to fẹ gbera kuro ni Naijiria ni papakọ ofurufu ilu Eko ti fo sanlẹ, to si ku, lẹyin to gba ipe lori ẹrọ alagbeka pe iyawo rẹ jade laye.
Asiko ti wọn n ṣe ayẹwọ fawọn arinrinajo to fẹ lọ soke okun, ni iṣẹlẹ yii waye lopin ọsẹ.
Agbẹnusọ fun ileeṣẹ ọlọpaa ni papakọ ofurufu naa, Joseph Alabi fidi ọrọ yii mulẹ fun BBC pe, kete ti arinrinajo naa daku lawọn sare gbe lọ si ile iwosan ṣugbọn ẹpa ko boro mọ, to si salaisi.
Gẹgẹ bi Alabi ti sọ, iṣẹlẹ naa waye ni aago marun un abọ irọlẹ, ti dokita Ajayi Olamide to wa ni ile iwosan papakọ ofurufu naa si jẹri si pe arinrinajo naa ti ku.
Wọn ti gbe oku arakunrin naa lọ si ibudo igbokupamọ si ni ile iwosan awọn ọmọ ologun ofurufu.
Kafayat Sanni: Jíjẹ ọmọ ogun Nàìjíríà mú mi ṣàwárí ara mi!
Oríṣun àwòrán, hqnigerianairforce
Awọn wọnyi ni wọn ṣẹṣẹ pari ẹkọ nipa wiwa baalu.
Lọjọ kẹẹdogun, oṣu Kẹwaa, ọdun 2019 ni ileeṣẹ ọmọ ogun ofurufu Naijria yoo fami ẹyẹ da awọn ọmọ awakọ baalu ofurufu mẹtala tuntun lọla.
Awọn wọnyi ni wọn ṣẹṣẹ pari ẹkọ nipa wiwa baalu.
Toun ti bi ko ti ṣe jẹ nkan tuntun pe awọn awakọ yi n gbami ẹyẹ, ohun iwuri nla kan ti yoo ṣẹlẹ nibẹ ni bi awọn awakọ baalu obinrin mẹta kan yoo ṣe fi itan lọlẹ nibẹ.
Lara wọn la ti ri Kafayat Sanni to jẹ awakọ baalu ologun ofurufu obinrin akọkọ.
Oríṣun àwòrán, @foluoladipo
Awọn wọnyi ni wọn ṣẹṣẹ pari ẹkọ nipa wiwa baalu.
Ọmọ ọdun mejilelogun ni Kafayat Sanni ti wọn si gba a wọle si ile ẹkọ ologun NDA lọjọ kejilelogun, oṣu Kẹsan an, ọdun 2012.
Ọdun 2019 lo pari ẹkọ rẹ ti o si di obinrin akọkọ to n wa ọkọ baalu ologun ofurufu ni Naijiria.
Kafayat ninu fọnran fidio kan ti ileeṣẹ ologun gbe sita sọ pe ohun ''fẹran lati ma a dan agbara wo laarin awọn okunrin.''
Ọmọ Sanni tun sọ pe ''Mo maa n gbiyanju lati ri bi emi naa yoo ti ṣe figagbagba pẹlu awọn ọkunrin. Jijẹ ọmọ ologun si mu mi ṣawari ara mi''
Yatọ si Kafayat awọn ọmọbinrin meji miran yoo gbami ẹyẹ lara awọn awakọ baalu mẹtala.
Oríṣun àwòrán, hqnigerianairforce
Tolulope Arotile ninu ọkọ baalu ofurufu hẹlikọpta
Tolulope Arotile ati Grace Garba lorukọ awọn meji to ku.
Tolulope ni awakọ baalu hẹlikọpta obinrin akọkọ ti yoo jade lati ileeṣẹ ọmọ ologun Naijiria.
Bakan naa ni Grace Garba si jẹ ọmọ ogun ofurufu obinrin akọkọ ti yoo gba ipo Warrant Officer.
David Adiatu oníṣẹ́ ọnà pẹ̀lú ìṣó àti òwú
Inú mi dùn pé ọmọ obinrin nìkan ni mo bi
Yoruba Culture: Kò sí nínú àṣà Yorùbá kí wọ́n tú ọfọ fèèyàn lórí fóònù-Gbenga Adeoye
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Gbogbo nnkan lo ni ilana ninu aṣa Yoruba ṣugbọn ṣe ẹyin mọ bi Yoruba ti ṣe n tufọ fun eeyan?
A waye iku o si, orun nikan lare mabọ.
Bo ba ṣe wu ki eeyan ko pẹ titi lori erupẹ, lọjọ ọjọ kan ni yoo di ero ọrun.
Ti a ba wa padanu ẹbi tabi ọrẹ bawo ni o ti ṣe yẹ ki a fun iru eeyan bẹẹ ni iro iṣẹlẹ laabi yi ti ko fi ni mu ipalara ba a?
Ẹni to ti ku ti ku; amọ a gbọdọdu ẹmi ati alaafia ẹni to ṣẹku:
Oloye Adegbenga Akani Adeoye to jẹ Kabiesi Onisọkan, ẹgbẹ isọkan ọmọ Oduduwa ṣalaye fun BBC Yoruba pe nilẹ Yoruba a kii deede tufọ feeyan.
O ni iku jẹ nnkan ti a ko gbọdọ fi ọwọ yẹpẹrẹ mu nipa titu ọfọ tori naa ''aṣamọ ọrọ, owe ati afiwe iṣẹlẹ ni a gbọdọ lo lati fi tufọ''
EkitiRapeCastration: ìgbésẹ̀ míì lè dẹ́kun ìwà ìfipábánilòpọ̀
Oloye Adegbenga ni ko ba oju mu ki a maa tufọ fun eeyan lori foonu rara.
Ti a ba fẹ tufọ, a gbọdo wa awọn agbaagba ẹbi ati adugbo silẹ, ki a mu ẹni ti oku ku fun naa wọ iyẹwu, ki a wa maa fi ọgbọn beere nipa ẹni to doloogbe lọwọ ẹni ti ọfọ ṣẹ.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Oloye Adegbenga ni ko ba oju mu ki a ma tufọ fun eeyan lori foonu rara.
''O le jẹ eeyan meji tabi mẹta ṣugbọn wọn ko gbọdọ maa fi ọgbọn kọkọ beere ọrọ lọwọ ẹni naa ki o ba ma baa lojiji''
Adegbenga ni ti o ba jẹ ẹni to nifura ni yoo ti ma woye pe ki lo mu wọn pe oun ati pe ko ni baa lojiji mọ nigba ti wọn yoo ba fi tufọ naa fun un.
Lẹyin ti ọrọ naa ba ti n wọ ọ lara, a o wa bẹrẹ si ni paṣamọ fun un bi ka maa sọ pe ''eyi ma ga o!'' ''ẹ kuku mọkan naa ni o''  ''Ọlọrun a wa pẹlu yin, a dile mu''
Lode oni, awọn ọna ibaraẹnisọrọ ti mu ki awọn eeyan maa fi ọrọ ranṣẹ yala nipa atẹjiṣẹ tabi lori foonu.
Amọ ṣa, Oloye Adegbenga ni ti a ko ba fi oye tufọ, o ṣeeṣe ki oku di meji tori a ko mọ iru ipo ti ẹni ti a ba fẹ tufọ fun le wa.
Coronavirus tips: Kìí ṣe gbogbo ìbòmù ló ń dá coronavirus dúró
''Ti o ba jẹ ẹni ti o ni ifunpa to ga ti wọn wa lọ tufọ fun un lojiji, ki ni ẹ lero pe yoo tẹyin rẹ wa ti iru ni yẹn ba lọ daku?''
O kasẹ ọrọ rẹ nilẹ pe, a gbodo rọra tufọ fun iyawo oloogbe tabi ọkọ oloogbe pẹlu afiwe iṣẹlẹ to n muni lọkan le ati suuru.
Twin Festival 2019: Ṣé ọbẹ ìlasa àti àmàlà ló ń ṣokùnfà bíbí ìbejì ní ìlú Igboọrà?
NLC Strike: Mínísítà fọ́rọ̀ òṣíṣẹ́ pe ìpàdé àwọn olórí òṣìṣẹ́ lọ́jọ́ Ìṣẹ́gun
Oríṣun àwòrán, AFP
Ẹgbẹ oṣiṣẹ lorilẹede Naijiria, NLC ti fun ijọba apapọ ni gbedeke ọjọ mẹrin pere lati fi ṣiṣẹ lori awọn ohun to n beere fun lori atunto ati afikun owo oṣu awọn oṣiṣẹ lorilẹede Naijiria ni ifẹgbẹkẹgbẹ pẹlu owo oṣu tuntun to kereju fun oṣiṣẹ eleyii ti ijọba ṣẹṣẹ kede.
Ẹgbẹ NLC ṣalaye lọjọ Aiku pe, bi ijọba ko ba tete ṣee, iyanṣẹlodi kale-n-kako yoo waye lorilẹede Naijiria.
Ninu lẹta kan ti ẹgbẹ oṣiṣẹ kọ si ijọba apapọ, eleyii ti akọwe apapọ rẹ, Emmanuel Ugboaja fọwọ si lo yọju eyi sita to si n rọ awọn alakoso ẹkun ẹgbẹ oṣiṣẹ gbogbo lorilẹede Naijiria lati maa mura silẹ.
Amọṣa, bi awọn iwe iroyin abẹle kan lorilẹede Naijiria ti ṣe gbee sita, minisita fọrọ oṣiṣẹ, Chris Ngige ti n lepa ati pana wahala to ṣeeṣe ko bẹ silẹ lagbo oṣiṣẹ.
Nibayii , Ngige ti pe ipade kan pẹlu awọn aṣoju ẹgbẹ oṣiṣẹ, NLC ati igbimọ to n duna-dura lorukọ oṣiṣẹ Joint National Public Service Negotiating Council (JNPSNC) ni ọjọ Iṣẹgun.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Bakan naa ni gomina Kayọde Fayẹmi to jẹ olori ajs awọn gomina ipinlẹ lorilẹede Naijiria, NGF pẹlu ti rawọ ẹbẹ sawọn oṣiṣẹ lati bu omi suuru mu lori igbesẹ a n yanṣa lodi.
O ni ko yẹ kawọ ẹgbẹ oṣiṣẹ fẹ da luru pọ mọ ṣapa niap dida ọrọ owo oṣu tuntun to kere ju fun oṣiṣẹ pọ mọ ọrọ ẹkunwo oṣu.
Ẹgbẹ oṣiṣẹ n beere fun afikun ida mọkandinlọgbọn owo osu fun awọn oṣiṣẹ alakasọ keje si ikẹrinrinla, ati afikun ida mẹrinlelogun fun awọn oṣiṣẹ alakasọ karundinlogun si ikẹtadinlogun.
LAUTECH: Ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́ ní ìpínlẹ̀ Ọ̀ṣun ló ń jẹ owó ọdun 2019 ní LAUTECH
Oríṣun àwòrán, @lautechinfo
LAUTECH: Ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́ ní ìpínlẹ̀ Ọ̀ṣun ló ń jẹ owó ọdun 2019 ní LAUTECH
Egbinrin ọtẹ, bi a ṣe n pakan ni ikan n ru.
O ti to ọjọ mẹta wayii ti ijọba ipinlẹ mejeeji ti wọn jumọ ni ileewe giga Ladoke Akintola ti n fi ẹsun gbogbo to nii ṣe pẹlu ipese owo fun akoso fasiti naa kan ara wọn.
Amọṣa nibayii awọn ẹgbẹ kan ti wọn pe ara wọn ni ẹgbẹ Ọṣun forum ti n fi ẹsun kan awọn oṣiṣẹ fasiti naa ti wọn jẹ ọmọ ipinlẹ Ọyọ.
Wọn ni pe wọn n gbero lati kọlu Giwa fasiti naa atawọn oṣiṣẹ ibẹ ti wọn jẹ ọmọ ipinlẹ Ọṣun.
BBC Gov Debates: Ètò ẹ̀kọ́ ọ̀fẹ́ ni àwọn olùdíje yóò ṣe
Nigba ti BBC News Yoruba gbe ọrọ naa tọ awọn igun mejeeji lọ, kọmiṣọna fun eto ẹkọ nipinlẹ Ọyọ, Ọjọgbọn Ṣangodoyin ṣalaye pe ko tọna ki oṣiṣẹ kọkan lati ipinlẹ yoowu to ba maa jẹ o kọlu awọn akẹgbẹ wọn nitori bo pẹ bo ya, ọrọ naa yoo ni iyanju.
Ọjọgbọn Sangodoyin ni gbogbo ọna ni ijọba ipinlẹ Ọyọ n yẹ lati rii pe ọrọ naa pari.
Ṣugbọn agbẹnusọ fun gomina ipinlẹ Ọṣun, Ismail Omipidan ṣalaye pe ko daju pe ijọba ipinlẹ Ọyọ n wa ọna alaafia lati pẹtu si aawọ naa nitoripe gbogbo anfani alaafia ti gomina Oyetọla ti ipinlẹ Ọṣun ti la silẹ ni gomina Makinde ti kọ ipakọ si.
Bi o tilẹ jẹ pe Ọjọgbọn Ṣangodoyin ni adehun kọlọmu-dọmu iya rẹ mu ti igbimọ oluwadi labẹ amofin Ọlanipẹkun la kalẹ naa fe ku diẹ.
Blood Donor Day: Láìsí ẹ̀jẹ̀ kò sí ẹ̀mí
Adehun naa ni wọn ti sọ pe ki ijọba ipinlẹ Ọyọ maa mojuto ileẹkọṣẹ iṣegun oyinbo LAUTECHTH ni Ogbomọṣọ ki ipinlẹ Ọṣun si mojuto ti Ilu Oṣogbo.
"Agbẹnusọ fun gomina ipinlẹ Ọṣun ni ko si ohun to jọọ rara nitori pe ileewe ẹkọṣẹ iṣegun to wa nilu Ogbomọṣọ ko si ninu iwe ofin to da fasiti LAUTECH silẹ, ""atọwọda ipinlẹ Ọyọ ni"""
Àwọn tó n bọ Ṣàngó n jẹ iná níni ọdún Ọlọ́jọ́
Twin Festival 2019: Ṣé ọbẹ ìlasa àti àmàlà ló ń ṣokùnfà bíbí ìbejì ní ìlú Igboọrà?
EkitiRapeCastration: ìgbésẹ̀ míì lè dẹ́kun ìwà ìfipábánilòpọ̀
NigeriaRoadAccident- Ọkọ àjàgbé kọlu obìnrin kan lórí ọkadá ó sì kú
Oríṣun àwòrán, @LAM
Ijamba oko Ajagbe
Ọmọbinrin kan ni o ti gbekuru jẹ lọwọ ẹbọra lataari ijamba ọkọ Ajagbe ti o rọlu ọkada rẹ ni Abẹokuta.
Olori Ajọ Ẹṣọ Oju Popo (FRSC) ẹka ti Sango-Ota ni Ipinlẹ Ogun, Akeem Ganiyu ni o fi ọrọ naa lede.
O ni ọkọ Ajagbe naa pẹlu nọmba ọkọ XC 791 LSR, ti o n lọ si Ipinlẹ Eko lati Abeokuta ni o deede padanu ijanu ọkọ rẹ, ti o si ṣeku pa ọmọbinrin naa.
Ganiyu ṣalaye pe eniyan mẹta ni ọkọ ajagbe naa ṣe akolu si ṣugbọn ti eniyan kan si gbẹmi mii loju ẹsẹ.
Ọkọ Ajagbe naa lo kọlu ọkọ ayọkẹlẹ meji ti awọn ti o wa ninu ọkọ naa si fara pa ṣugbọn ti o da ẹmi arabinrin naa legbodo.
Ni bayii, oku arabinrin naa ni wọn ti gbe lọ si ile igbokupamọsi ti ile iwosan gbogboogbo Ijọba ni Ifọ, Ipinlẹ Ogun.
Bawo ni ijamba naa ṣe ṣẹlẹ?
Nigba ti o n ba ikọ BBC sọrọ, olori ajọ alaabo oju popo (FRSC), Ọladele Clement, ṣalaye pe ọkọ ajagbe naa ni o ti wa ni ahamọ ajọ naa.
O tẹsiwaju pe, pupọ ninu awọn ijamba yii lo n ṣẹlẹ lataari aini suuru awọn awakọ.
O ni awọn ọlọkada gbọdọ maa fi suuru rin lasiko ojo yii paapaa ti ọpọ opopona ko dara mọ bayii.
Oladele ni wi pe awọn ọna wọnyii ni wọn n ṣe lọwọ ṣugbọn ti aini suuru pupọ awọn awakọ yii lo n fa ijamba ba awọn ẹlomiran.
Ninu alaye rẹ lo ti mẹnu baa wi pe, ọpọ ọkọ ni abẹbẹ oju gilaasi [wiper] wọn ko dara to lasiko ojo ti wọn ko de riran ri ọkọ to n bọ daada.
O wa gba awọn awakọ ni imọran lati ya patapata kuro ni oju popo nigba ti wọn ko ba le tẹsiwaju mọ ninu irin ajo.
Clement mẹnuba ba pe, yiya ọkọ silẹ lojiji naa maa n ṣe okunfa ijamba ti o si le mu ẹmi dani.
Ganiyu, ti o jẹ olori ẹka ti Sango Ota naa wa rọ awọn ọlọkọda lati maa lo koto-adabori ki wọn si maa din ere sisa ku lati dẹkun gbigba ori mọlẹ.
Twin Festival 2019: Ṣé ọbẹ ìlasa àti àmàlà ló ń ṣokùnfà bíbí ìbejì ní ìlú Igboọrà?
EkitiRapeCastration: ìgbésẹ̀ míì lè dẹ́kun ìwà ìfipábánilòpọ̀
Aisha Buhari: Ọ̀pọ̀ aráàlú ní Aisha ti pariwo ṣáájú pé Buhari kọ ló ń darí ìjọba
Oríṣun àwòrán, @aishambuhari
Ọpọ ọmọ Naijiria lo ti n sọ ero ọkan wọn lori aawọ to n waye nile ijọba nilu Abuja laarin aya aarẹ, Aisha Buhari ati Mamman Daura.
Aawọ naa, to n ja rainrain lori ayelujara lo da lori fidio kan to lu sita lati ọdọ ọmọ Daura, Fatimọ, eyi to se afihan Aisha to n pariwo pe wọn n gbo oun lẹnu.
Aisha ati Fatimọ si ni wọn ti salaye ohun to kan wọn nipa fidio naa, ti ọkọọkan wọn si n naka aleebu si ara wọn.
Amọ nigba ti wọn n da si ọrọ yii, oniruuru ero ni awọn ọmọ Naijiria fi han nipa isẹlẹ naa.
Kayode Ogundamisi@ogundamisi ni bi fatimah se gba lootọ ni oun ya aya aarẹ nibi to ti n pariwo ni bonkẹlẹ kii se nkan kekere rara, o ti tapa si ofin eto aabo, o si yẹ ki aarẹ lee to ile rẹ.
@YoungOtutu, o ni lẹyin gbogbo atotonu yii, ẹ jẹ ka se agbẹyẹwo ọrọ awọn mejeeji, ta si lee sọ pe aarẹ Buhari ti kuna ni gbogbo ọna.
@ayemojubar, oun ni to ba jẹ pe Fatimah, ọmọ Daura ni ọkan lati gbena woju Aisha ati awọn agbofinro, ti Buhari ko si ri ohunkohun se si, ka ma sẹsẹ sọ Buhari gan funra rẹ, a jẹ pe ohun ara lo n sẹlẹ nile ijọba ni Abuja.
@dbola01 lero tiẹ ni ọjọ p ti Aisha ti n pariwo pe kii se Buhari lo n se akoso ijọba, to si darukọ Mamman Daura.
@onos_147 ni to ba jẹ ọmọ ipinlẹ Edo ni Aisha ni, Fatimah ko ba ti ge ni imu. Iranu!
Ni ọjọ Aje ni iroyin ifọrọwanilẹnuwo kan ti iyawo aarẹ, Aisha Buhari ati Fatimah, ọmọ Daura to jẹ bi ẹgbọn fun Buhari ṣe pẹlu ileeṣẹ iroyin BBC gbode kan lori ayelujara.
Ko si si idi meji bikose bi fidio kan, ninu eyi ti aya aarẹ ti n lọgun tantan se bọ sori ayelujara lọjọ Ẹti.
Oríṣun àwòrán, @aishambuhari
Lọwọ yii, Aisha to jẹ aya aarẹ Muhammadu Buhari ti n ke gbajare pe, awọn ẹbi Daura ko tan mọ ọkọ oun o, ṣugbọn wọn ti fẹ fa ẹbi oun ni itan ya.
Gẹgẹ bii ọrọ rẹ, Aisha ninu fidio ti a n sọrọ rẹ yii, n lọgun too pe ki wọn si ilẹkun fun oun lati wọle, lẹyin ti Buhari ti paṣẹ pe ki wọn fi ile onigilaasi naa silẹ fun Yusuf ọmọ oun, amọ yẹyẹ ni Fatimah to jẹ ọmọ Daura n fi oun ṣe.
Oríṣun àwòrán, @aishambuhari
Kii ṣe iroyin mọ pe, ọpọ onwoye lo ti n fi ẹsun kan Mamman Daura, to jẹ baba Fatimah pe oun atawọn eeyan kan lo ti joye alagbara, to ti gba agbara lọwọ aarẹ Buhari, ti wọn si n tukọ Naijiria labẹ aṣọ.
Nibayii, Aisha ti wa se bi ẹni fi idi ahesọ ọrọ yii mulẹ ninu ifọrọwerọ rẹ pẹlu BBC, eyi to ti fi ẹsun kan awọn agbofinro ati ẹsọ rẹ pe wọn n wo gbogbo bi Fatimah ṣe ṣe si oun.
Oríṣun àwòrán, @aishambuhari
Sugbọn awọn agbofinro naa ko lee ṣe ohunkohun nipa rẹ nitori pe ẹni ti aje ọrọ naa ṣi mọ lori jẹ ọmọ Mamman Daura.
Fatimah funra rẹ fi ọrọ mulẹ ninu ifọrọwanilẹnuwo tirẹ pe, awo ọjọ pipẹ ni baba oun, iyẹn Mamman Daura pẹlu aarẹ Muhammadu Buhari, ti ẹnikẹni ko si lee ri aarin wọn.
Ni bayii, ọpọ awọn ẹlẹgbẹjẹgbẹ ati ọlọgbajọgba ni wọn ti jade lati wi tẹnu wọn lori ọrọ yii.
Bi awọn ẹgbẹ ajafẹtọ bii Coalition in Defence of Nigerian Democracy and Constitution, CDNDC ṣe n lọgun pe, aṣilo ipo lo n da aarẹ Buhari laamu, bi bẹẹ kọ, ko laṣẹ lati gbe ile ijọba kalẹ fun Mamman Daura.
Civil Society Network Against Corruption, CSNAP naa n pariwo pe ohun to han gbangba pẹlu ohun to n ṣẹlẹ bii sinima laarin ẹbi aarẹ Buhari yii n fihan pe, Daura gan an ni alakoso orilẹede Naijiria labẹ aṣọ.
New minimum wage: Ìjọba àpapọ̀, ẹgbẹ́ òṣìṣẹ́ yóò ṣèpàdé lónìí lórí owó oṣù tuntun
Oríṣun àwòrán, AFP
Loni, ọjọ Iṣẹgun, ọjọ karundinlogun oṣu kẹwa ọdun 2019 ni ipade manigbagbe kan yoo waye laarin ijọba apapọ ati ẹgbẹ oṣiṣẹ lorilẹede Naijiria lati lee yanju wahala to n suyọ lori sisan owo oṣu tuntun to kereju fawọn oṣiṣẹ ati atunto owo osu awọn oṣiṣẹ lorilẹede Naijiria.
Ni ọjọ Aiku ni ẹgbẹ oṣiṣẹ lorilẹede Naijiria, gbe atẹjade sita ninu eyi ti wọn ti kilọ fun ijọba apapọ pe bi ko ba tete wa wọrọkọ fi ṣada lori sisan owo oṣu tuntun naa atawọn atunto akasọ owo oṣu gbogbo to kan, iyanṣẹlodi lo kan ti awọn yoo sa di.
Eeyan meji ku nibi iwọde DR Congo
'Ẹnu lásán kò lè sàn owó oṣu oṣiṣẹ l'Ekiti'
Philomina nikan kọ lo ṣe magomago owo JAMB
Ìjọba àpapọ̀ kò leè ṣùn torí ìyanṣẹ́lódì òṣìṣẹ́ tó ń bọ̀
Ejo abami to n mu owo ni ajọ Jambu
Lọna ati dena iyanṣẹlodi naa lo mu ki ijọba apapọ, nipasẹ minisita fọrọ oṣiṣẹ, Chris Ngige o pe ipade fun ifikunlukun lori rẹ ni ọjọ Iṣẹgun.
Bi o tilẹ jẹ pe ijọba apapọ n ṣalaye pe gbogbo ipa to yẹ ni sisa ni awọn ti sa ṣugbọn ti ẹgbẹ oṣiṣẹ naa ṣi n wi ohun miran.
Ninu ọrọ to sọ ṣaaju ipade naa ti yoo waye loni nilu Abuja, minisita fun ọrọ oṣiṣẹ Chris Ngige fohun silẹ pe o wu ijọba lati wa ojuutu si ọrọ ẹkunwo oṣu oṣiṣẹ naaki o to di oṣu kọkanla ọdun lati fi aye silẹ fun sisan owo osu tuntun naa ni irọwọ-rọsẹ.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
O ni ipade ọjọ iṣẹgun ni yoo sọ ibi ti wọn yoo fi okun si lori ọrọ owo oṣu tuntun naa.
Amọṣa, ẹgbẹ oṣiṣẹ ni ipade naa, ni ero tawọn, ṣe pataki fun aṣeyọri lori ọrọ owo oṣu tuntun naa.
Kogi Loan: Owó àkànṣe ìṣẹ́ ìjọba àpapọ̀ tíjọ́ba Kogi ṣe la fẹ́ dá padà
Oríṣun àwòrán, @A_Oshiomhole
Aarẹ Buhari ti kọ lẹta si ile aṣofin agba lati beere owo to le ni biliọnu mẹwa naira fun ipinlẹ Kogi.
Ninu lẹta kan to kọ si aarẹ ile aṣofin agba Ahmad Lawan, Aarẹ Buhari ni oun fẹ san owo naa fun ijọba ipinlẹ Kogi, ko lee san owo oṣu to jẹ labẹle.
Buhari ṣalaye fun awọn aṣofin agba pe gbese owo awọn akanṣe iṣẹ to jẹ ti ijọba apapọ, eleyii ti ijọba ipinlẹ Kogi na owo le lori ni oun fẹ fi owo naa san.
Oríṣun àwòrán, @A_Oshiomhole
Amọṣa, aarẹ ile aṣofin agba ti fa lẹta naa le igbimọ tẹẹkoto lori ọrọ gbese abẹle ati toke okun fun amojuto to ba yẹ ki o si jiṣẹ pada fun ile naa ni ọsẹ meji.
Ipinlẹ Kogi yoo wọ inu agbami eto idibo gomina ni oṣu kọkanla pẹlu oniruuru iroyin nipa gbese ti wọn ni ijọba jẹ oṣiṣẹ nibẹ.
Katsina: Ó di ìgbàkẹ́tà l'óṣù kan tí àṣírí ilé ìmúni nígbèkùn yóò tú síta ní àríwá Nàìjíríà
Iṣẹlẹ imuninigbekun fẹ peleke lẹnu ọjọ mẹta yi ni ariwa Naijiria
Pa lẹẹkini,pa lẹẹkeji, o ti di igba ẹlẹkẹta laarin oṣu kan bayi ti awọn ọlọpaa Naijiria tu awọn ti wọn de ni igbekun silẹ lariwa Naijiria.
Nilu Katsina ni itusilẹ to ṣẹṣẹ waye yi ti ṣẹlẹ.
Awọn meji ti asiri wọn tu sita tẹlẹ waye ni Kaduna ati ilu Daura to jẹ ilu aarẹ Muhammadu Buhari.
Agbẹnusọ ọlọpaa ni ipinlẹ Katsina,Gambo Isa, fidi ọrọ itusilẹ ẹlẹẹkẹta yi mulẹ ṣugbọn o k lati s iye eeyan ti wọn doola nibẹ.
Amọ ṣa awọn akọroyin ni o ṣeeṣe ki wọn to ọkunrin ẹẹdẹgbẹta ti wọn tu silẹ nibẹ.
Awọn ile kewu ati ile ọmọ alaigbọran pọ nilẹ ariwa ti wọn si jẹ ipenija latari bi ko ti ṣe si ofin to n dari wọn.
Ọrọ yi mu ki awọn eeyan ke si ijọ́ba lati wa wọrọkọ fi ṣada lori awọn to n dari ile imuni nigbekun wn yi.
Aarẹ Buhari ti paṣẹ ki awọn agbofinro gbe igbesẹ to y lori awn aaye imuni nigbekun wọn yi nibi ti a gbọ pe wọn ba awọn eeyan laṣepọ ni tipa.
Awọn Ọlọpa ilẹ Nigeria ti ṣalaye pe, ko din ni ọọdunrun eniyan ti wọn de ni igbekun ni ojuko ibi igbekun miiran ni ajọ naa ti tu silẹ bayii.
Awon omo ile iwe naa
Ojuko ibi igbekun yii ni wọn ri ni Ilu Daura, ti o jẹ ilu olori orilẹede Naijiria, Muhammadu Buhari ti wọn pe ni ile iwe ṣugbọn ti ko ri bẹẹ.
Alukoro ajọ Ọlọpaa ni Ipinlẹ naa, Gambo Isa ṣalaye pe ọpọ awọn ti wọn ri yii ni ọmọde ti wọn fi okun de ọwọ ati ẹsẹ wọn, ti wọn si n ba wọn ni aṣepọ.
Lara awọn ti wọn de ni igbekun yii ṣalaye itu ti wọn fi wọn pa ti o ti mu ọpọ sa kuro ti o si ṣokunfa riri ti awọn eniyan fi ṣakiyesi wọn.
Awọn Ọlọpaa ṣalaye pe pupọ ninu awọn wọnyii lo jẹ ọmọ kekere bii ọdun meje, pelu pe ni Ilu Kaduna, iru eyi naa ṣẹlẹ ni oṣu kẹsan ti wọn tu ọpọ silẹ.
Wọn ni ile iwe ikẹkọ kehu ni wọn maa n pe ṣugbọn ti o jẹ pe irọ funfun balau ni.
Ọlọpaa fi idi rẹ mulẹ wi pe awọn akọọlẹ ile iwe naa fihan pe, o le ni Ọọdunrun  akẹkọọ to wa ni ile iwe naa ti wọn ko ju ọmọ ọdun meje lọ.
Latari ifiya jẹni yii lo mu ki awọn akẹkọọ ile iwe naa fi ẹhonu han ti ọpọ si fẹsẹ fẹ.
Ọpọ ni egbo oju ibi ti wọn ti fi ṣeeni de lẹsẹ wa ni bẹ ṣugbọn ti Ẹẹtadinlaadọrin eniyan ṣi wa ninu igbekun nigba ti Ọlọpaa de ile iwe naa.
Bayii awọn eniyan naa ti n gba iwosan ni ile iwosan Ijọba ti wọn si ti mu wọn mọ awọn ebi wọn
O ti di eemeji ti iru eyi n ṣẹlẹ laarin Oṣu kan ni Orilẹ ede Naijiria.
Minimum Wage: Àlékún owó náà leè má pọ̀, àmọ́ yóò ju ₦30,000 lọ
Oríṣun àwòrán, Ijoba ipinle Eko
Gomina ipinlẹ Eko Babajide Sanwo-Olu ti ṣeleri lati san ẹgbẹrun lọna ọgbọn Naira lọ fawọn oṣiṣẹ ipinlẹ naa.
O sọ ọrọ yii lẹyin ipade kan to ṣe pẹlu awọn adari ẹgbẹ oṣiṣẹ lọjọ Iṣẹgun.
Nibi ipade naa, Sanwo-Olu ni kete ti ijọba apapọ ati awọn ẹgbẹ oṣiṣẹ ba ti pari ọrọ lori ẹkunwo yii, ni ijọba ipinlẹ Eko yoo bẹrẹ si ni san an.
Gomina naa ni oun fẹ san ju ẹgbẹrun lọna ọgbọn Naira lọ nitori pe awọn mọ riri ohun ti oju awọn oṣiṣẹ n ri lọjojumọ.
''O le ma pọ ṣugbọn a o san ju ẹgbẹrun lọna ọgbọn Naira ẹkunwo oṣu''
O tẹsiwaju pe '' A mọ pe awọn eeyan n fi oju ipinlẹ nla wo ipinlẹ Eko,a si mọ ohun ti oju awn oṣiṣẹ n ri l'Eko bakanna.Ti awọn ipinl miran ba le san iye yi, mo nigbagbọ pe o yẹ ki ijba Eko ṣafihan imoore sawọn oṣiṣẹ ti wọn ṣiṣẹ tọ idagbasoke Eko''
Oríṣun àwòrán, Alamy
NIN: Ohùn mẹ́ta pàtàkì tó yẹ kí o mọ nípa nọ́mbà ìdánimọ̀ Nàìjíríà
Oríṣun àwòrán, Google
Lẹnu lọọlọ yii, oju opo Twitter ti n sọ putuputu lori ọrọ owo sisan lati gba kaadi idanimọ mi ti ti tẹlẹ ba sọnu tabi ti ọjọ ba pe lori ti tẹlẹ.
Ohun to mu ọrọ yii wa ko ju ibeere ti eeyan kan beere loju opo Twitter ajọ to n ṣeto kaadi idanimọ ni Nigeria NIMC nipa gbigba kaadi mi ti eleyi toun ni ba sọnu.
Esi ti aṣoju ajọ naa kan fun pe yoo san ẹgbẹrun mẹta Naira lati fi gba omiran ti ọjọ ba ti pẹ lori ti tẹlẹ ko jẹ nnkan to dun mọ awọn eeyan ninu.
Yatọ si ẹgbẹrun mẹta yii, idahun naa sọ pe ẹni ti o ba sọ kaadi rẹ nu gbọdọ san ẹgbẹrun marun naira lati gba omiran.
Ọrọ yii mu iriwisi orisirisi wa ti awọn eeyan kan n si n binu pe ko yẹ ki ajọ naa ma gba owo ki o to fun awọn ọmọ Naijiria ni kaadi mi .
Bi ọrọ yi ti ṣe n ja rainrain la ba ni ki a kan si oju opo ajọ naa lati mọ pato itunmọ ati iyatọ to wa laarin awọn ọrọ bi NIN,nọmba idanimọ ati E-Card to jẹ kaadi idanimọ ti ajọ naa n fun awọn eeyan.
NIN lo se pataki ju niabi kaadi E-Card
Erongba ijọba pẹlu nọmba idanimọ ni pe ki awọn eeyan ma lo fun gbogbo ohun to ba ni ṣe pẹlu iforukọsilẹ.
Bo jẹ kaadi idibo tabi iwe irina to fi mọ iwe aṣẹ iwakọ,NIN ti ajọ NIMC  n fun eeyan ti wọn ba ti gba orukọ rẹ ati awọn nnkan idanimọ miran silẹ lo ṣe pataki julọ.
Koda ti ọjọ ba pe lori awọn elo idanimọ to ku bi kaadi idibo,iwe irina, tabi iwe aṣẹ iwakọ,bi eeyan ko ba ni NIN,ko ni le gba omiran ninu awọn eleyi ti a ka kalẹ
Ni soki, bi eeyan ba ti ni NIN, ọrọ buṣe amọ bi kaadi idanimọ rẹ ba sọnu, o di dandan ki o fi owo gba omiran.
Gbedeke iye ọjọ ti eeyan yoo fi lo wa lori kaadi E-Card amọ titi lai ni eeyan o fi ma lo NIN
Nibo ni eeyan ti le ri nọmba NIN yii?
Pupọ eeyan lo ma n ro wi pe ti oun ba ti gba kaadi idanimọ E-Card ti NIMC n fun awọn eeyan,wọn yoo ti kọ NIN rẹ si lara.
Ọrọ ko ri bẹ rara.
Awọn nọmba miran wa lara kaadi idanimọ E-Card lootọ amọ ko si NIN lara wọn.
Oríṣun àwòrán, Google
Iwe pelebe ti wọn ma n fun eeyan lẹyin to ba pari iforukọsilẹ ti aworan wa lara rẹ ni wọn kọ NIN nọmba si.
Nọmba mọkanla ni nọmba yii, ti o si wa lapa oke iwe pelebe yii.
N3500,N5000 ni wọn n gba E-Card to ba sọnu,elo ni wọn fi n gba NIN miiran?
Akọkọ naa, nọmba NIN ko le sọnu, wọn ko si le forukọ silẹ lati gbaa lẹẹmeji.
Ohun ti o ma n saba ṣẹlẹ ni ki awọn eeyan ma ri iwe pelebe ti a ṣafihan rẹ loke ti o ni nọmba NIN lara.
Ti eleyi ba ṣẹlẹ gẹgẹ bi alaye ti NIMC ṣe si oju opo wọn eeyan le ri pada yala ki o lọ si aye iforukọsilẹ tabi ki o si tẹ nọmba *346# lori ẹrọ alagbeka rẹ lati ri pada.
Ti o ba wa di dandan pe eeyan fẹ san owo lati gba nọmba yi,ko le san ju ẹẹdẹgbẹta naira lọ amọ yi o tẹle awọn igbesẹ kan ki o to le gba.
Oríṣun àwòrán, Google
Ibeere nla ti o wa ku lẹyin alaye ti a ṣe yi ni pe kini ti awọn ti ko ri kaadi gba ti NIMC ni wọn gbọdọ san owo ti ọjọ ba pe lori kaadi naa?
Ajọ naa kori esi fọ si ibeere yi ti awọn eeyan n bere botilẹjẹwipe  wọn ni awọn ko lowo lati tẹ kaadi fun awọn ọmọ Naijiria.
Ona abayọ lo ku bayi, ko si tii daju ẹni ti yoo wa abayọ si ipenija to wa nilẹ yi.
Minimum Wage: Ìpàdé ìjọba àti òṣìṣẹ́ kò wọ̀ lánàá, kí ni yóò jẹ́ àbọ̀ ìpàdé tòní?
Oríṣun àwòrán, @NLCHeadquarters
Ẹgbẹ awọn osisẹ il wa, NLC, ti sẹwe le iyansẹlodi to yẹ ko waye loni, nitori idunadura to si n tẹ siwaju nibi ipade kan ti yoo waye loni.
Igun to n soju ijọ̀ba apapọ ati igun awọn osisẹ ni wọn panupọ kede bẹẹ lẹyin ipade wọn to waye lana, eyi to ko so eso rere.
Ọpọ wakati lawọn adari ẹgbẹ oṣiṣẹ ati asoju ijọba apapọ fi joko ipade lọjọ Iṣẹgun, ti ọrọ ko si wọ laarin wọn lori bi ijọba yoo ti ṣe san ẹkunwọ oṣu oṣiṣẹ.
Nigba to n sọrọ nibi ipade to waye lana, minisita fun ọrọ osisẹ, Dokita Chris Ngige salaye pe ibeere awọn osisẹ naa yoo doju ọrọ aje Naijiria de ni, ti ko si seese rara.
Oríṣun àwòrán, @NLCHeadquarters
Sugbọn ẹgbẹ osisẹ ti wa n beere lọwọ ijọba pe ko mu ẹri to daju wa lati gbe ọrọ rẹ lẹyin , pe owo ti osisẹ n beere ti pọ ju.
Titi di igba ta n ṣe akojọpọ iroyin yii, igun to n soju ijọba apapọ ati igun awọn asaaju osisẹ ko tii ri ọrọ naa yanju, ti wọn si tun ni awọn yoo tẹsiwaju ipade naa lọjọru oni.
APC Oyo: Àkọsílẹ̀ rere wà pé Ajimobi ni gómìnà tó dáńtọ́ jùlọ ní Ọyọ
Oríṣun àwòrán, @OfficialSeyiMakinde
Igun ọdọ ninu ẹgbẹ oselu APC nipinlẹ Ọyọ ti nahun kesi gomina ipinlẹ Ọyọ, Onimọ ẹrọ Seyi Makinde lati sisẹ tọ awọn ogun isejọba to da lori ilana onidagbasoke ti asaaju rẹ, Abiọla Ajimọbi fi lelẹ nipinlẹ Ọyọ.
Alakoso igun ọdọ kan ti wọn n pe ni OFI, Ọgbẹni Ayọ Adekanmbi lo gbe imọran yii kalẹ ninu atẹjade kan to fisita nilu Ibadan eyi to da lori bijọba Seyi Makinde se fẹ gba owoya biliọnu meje ati aabọ naira.
Bakan naa ni Adekanmbi tun rọ ijọba to n tukọ ipinlẹ Ọyọ lọwọlọwọ lati gbajumọ eto isejọba pẹlu gbogbo aayan to yẹ, nitori ni ilẹ toni to mọ yii, ijọba Ajimọbi nikan lo tayọ gẹgẹ bii ijọba to duro re ti yoo tukọ ipinlẹ Ọyọ lati ọdun 1976.
Oríṣun àwòrán, Abiola Ajimobi
Akoko to taa sọ ootọ ọrọ pọnbele fun gomina Seyi Makinde pe ofuutu fẹẹtẹ, aasa ti ko ni kaun ni iwa to rawọ le lati fẹ pa oju ẹsẹ asaaju rẹ, Abiọla Ajimọbi rẹ ninu itan akọọlẹ rere nipinlẹ Ọyọ, nitori ijọba Ajimọbi lo tii pegede julọ lati ọdun 1976 ti wọn ti da ipinlẹ Ọyọ silẹ.
Adekanmbi tẹsiwaju pe, o ti wa ni akọsilẹ pe Ajimọbi gbaradi ko to gba akoso ipinlẹ Ọyọ lọdun 2011, to si fi ipilẹ rere lelẹ nipa mimu idagbasoke ba awọn ohun amayedẹrun.
Aisha Buhari: Afenifere, PDP, ajàfẹ́tọ̀ọ́ ẹni ni àgbà Buhari kò tolé
Oríṣun àwòrán, @aishambuhari
Ọrọ ọhun bẹrẹ bii awẹwa nigba ti Fatima ọmọ Mamman Daura, gbe fidio kan sita, ninu eyi ti ohun iyawo aarẹ, Aisha Buhari ti n sọrọ lohun rara.
Esi Aisha Buhari ati Fatima Daura gan funrarẹ lo tubọ fina mọ ọrọ naa, eyi to wa di ohun ti gbogbo awọn ọmọ Naijiria n gba bi ẹni n gba igba ọti, lati bii ọjọ diẹ sẹyin.
Bakan naa, fidio miran tun jade lẹyin eyi nibiti aya aarẹ, Aisha naa tun ti n ba awọn akọroyin sọrọ pe, lootọ oun lo wa ninu fidio ti Fatima Daura gbe sita naa.
Oríṣun àwòrán, Aisha M. Buhari
Fidio naa si lo fi oju rẹ han sita pe, baba Fatima, iyẹn Mamman Daura to jẹ bi aburo fun aarẹ, ti ko gbogbo awọn eeyan to wa ni ile aarẹ, titi kan awọn agbofinro, ni papa mọra.
Oniruuru awọn eeyan ati ẹlẹgbẹjẹgbẹ lorilẹede Naijiria lo ti sọrọ lori ọrọ yii, ti wọn si ti fi iha ti wọn kọ si bi nnkan ṣe n lọ laarin mọlẹbi akọkọ lorilẹede Naijiria han.
Oríṣun àwòrán, Garba Shehu
Ileeṣẹ aarẹ lorilẹede Naijiria pẹlu ti da si ọrọ naa gẹgẹ bi awọn iwe iroyin abẹle kan ti gbe e sita.
Loju opo twitter lawọn ọmọ Naijiria ti tu pẹrẹpẹrẹ ọrọ sita, nibi ti wọn ti n fi ẹhonu wọn han lori ọrọ naa.
Ọpọ ọmọ Naijiria ni wọn ti wa n beere pe, bi ọrọ ti ṣe ri yii, o n fẹ amojuto ati apero nitori ko sẹni fẹ mọ mọ bayii, boya Buhari ni aarẹ tabi Mamman Daura.
Bakan naa ni awọn miran ni bi o ti ṣe yẹ ko ri naa lo rii yẹn, nitori nigba ti ebi n pa igun aarẹ Buhari, awodi Mamman Daura ba ra.
Ẹwẹ, ẹgbẹ Yoruba, Afẹnifẹre pẹlu ti ke si Aarẹ Buhari pe ko ṣe iṣe agba to n tole nigba yiyanju ọrọ naa ni kiakia.
Yollywood: Àwọn èèyàn fèsì pé Kemi ń díbọ́n ni, tórí ọ̀rọ̀ ọkùnrin ni
Oríṣun àwòrán, @KemiAfolabi
Gbajugbaja oṣere fiimu yoruba, Kemi Afolabi ti ke gbajare pe arabinrin kan n lepa ẹmi oun lati pa.
Ọrọ naa di fa ki n fa a laarin Kemi ati ẹni kan to pe orukọ rẹ ni Gloria Johson tori pe Kemi ni o fi nọmba kan dẹru ba oun.
"O sọ ninu fidio to fi soju opo instagram pe ""orukọ rẹ ni Gloria Johnson o n dẹru ba mi lọpọlọpọ igba""."
Sajẹ: Mo n rọ awọn akẹẹgbẹ mi lati se suuru de asiko Ọlọrun
Kemi Afolabi tete fi ẹsun kan Gloria loju opo instagram rẹ pẹlu fidio Gloria to fi sita ati nọmba to ni o fi n pe oun.
Ẹwẹ, lara awọn idahun ti Kemi gba lori ọrọ to fi sita ni ti obinrin kan to ṣalaye  pe Kemi kan n dibọn bii pe ọwọ rẹ mọ ni.
O ni gbogbo lalakunfẹfẹ ariwo Kemi Afolabi yii ko ṣẹyin ija to ṣẹlẹ laarin Kemi ati ọrẹbinrin oun, Gloria lori ọrọ oṣerekunrin, Gida.
Oríṣun àwòrán, @gidabless
Mama Rainbow:  Toyin Adegbola àti Razak Olayiwola ní ìyá rere àti àwòkọ́ṣe gidi ní
Amarachi to ta ko Kemi sọ fun pe odidi iyawo ile ni to tun wa n fi ọrọ sita pẹlu ẹni to dagba ju lọ.
O ni o tun wa n fẹ ẹ loju lori ẹrọ ayelujara bẹẹ si ni awọn eeyan ko mọ pe tori Gida lo ṣe n ṣe eyi.
Oríṣun àwòrán, @gidabless
Gloria pe ọrẹ rẹ , Gida lori foonu, afi to di pe Kemi lo gbe foonu to si bẹrẹ si ni s fun Gloria pe ko fi ọkunrin rẹ lọrun silẹ to si fesi pe ki o dẹkun gbogbo radarada yẹn ki o ye ṣe bi ọmọde.
Amarachi ni alainitiju ni Kemi Afolabi o ni oun kaanu ẹni to ṣe e ni abiyamọ.
Éégún tó wà nídí Yoruba Bollywood, Samo Baba f'ojú hàn o!
Ekiti APC: Kíkọ ọjà tàbí afárá sí Ekiti kọ́ ni ìdàgbàsókè
Oríṣun àwòrán, Facebook
Kayode Fayemi
Ijọba Kayode Fayemi ni ipinlẹ Ekiti pe ọdun kan ni ọjọru ọsẹ yii ṣugbọn ẹgbẹ alatako ni ko si ipe fun ajọyọ.
Ẹni ti o jẹ abẹnugan fun gomina ana ni Ipinlẹ naa, Lere Olayinka ṣalaye pe ko si idagbasoke kan ti Fayemi gun le lati bii ọdun kan sẹyin.
O tun ṣalaye pe ko si atunṣe popona pẹlu gbogbo ọna aarin ilu ti o ti bajẹ ti ko si si ohun kan pato ti wọn le ri tọka si.
Ninu isọrọ tirẹ, alaga ẹgbẹ oṣelu PDP ni ipinlẹ naa, Adegboyega Oguntuasẹ sọ wi pe lootọ ko si oun ti a le tọka si ṣugbọn idajọ n bẹ lọwọ ara ilu.
Nigba ti yoo fesi si ọrọ naa, Akọwe agba si Gomina Fayẹmi, Yinka Oyebode sọ wi pe, Fayemi ti ṣe gudugudu meje ati yaaya mẹfa.
O tẹsiwaju pe, ẹkọ ọfẹ ti Ijọba Fayoṣe kọ lati fun awọn akẹẹkọ Ipinlẹ naa ni Fayẹmi fun wọn lai gba owo kọọkan bo ti wu ki o kere mọ.
Ko ṣai mẹnu ba atunto ti Ijọba n muba gbogbo ohun ti Ijọba ana ti bajẹ ni Ipinlẹ naa bii gbigba owo ori lọwọ awọn ọmọ ile ẹkọ.
O ṣalaye pe gbogbo owo oṣu ti ijọba Fayoṣe jẹ ni wọn san pada lati igba ti wọn ti wa lori aga iṣejọba.
Díẹ̀ lára àwon oúnjẹ ìbílẹ̀ wa tó tin ń di àwátì báyìí
Ọpọlọpọ awọn ounjẹ abalaye orilẹede wa lo ti n di awati bayii, paapaa ju lọ nilẹ Yoruba .
Pupọ ninu ounjẹ ti awọn baba nla wa n jẹ laye atijọ ni awọn ọmọ aye ode oni ko mọ, awọn miiran gan ko tilẹ gbọ orukọ irufẹ awọn ounjẹ bẹẹ ri.
Loni to jẹ ayajọ ọjọ ounjẹ lagbaye, a fẹ wo diẹ lara awọn ounjẹ ilẹ Yoruba to ti da bii pe o ti n kasẹ nilẹ laye ode oni.
Abari jẹ ọkan lara awọn ounjẹ ilẹ Yoruba to gbajumọ laye nigba kan ri. Sugbọn ọpọ lara awọn ọmọ aye ode oni ni ko mọ abari yii.
Abari fara jọ mọimọi, sugbọn agado ni wọn fi n ṣe abari dipo ẹwa.
Ni awọn ẹya kan lorilẹede Naijiria, wọn ma n pe ni Ukpo Oka, Sapala, Oka Ekusu tabi Ekoki, awọn miiran tun ma n pe nigba Ngwu Oka.
Awọn Yoruba man fi ìgbá si i, bẹẹ ni awọn Igbo ma n fi efirin tabi ẹfọ ugwu si i, ko le ni orun didun.
Lara awọn eroja ti wọn ma n fi se abari ni agbado, tataṣe, ede, igba, ata gigun, epo pupa, ati bẹẹ bẹẹ lọ.
Ewa ati agbado ni Egbo, o si jẹ ounje ilẹ Yoruba.
Bi wọn ṣe ma n  se Egbo ni pe, wọn ma se agbado gbigbe titi ti yoo fi rọ, bakan naa ni wọn ma se ẹwa lọtọ.
Wọn ma n jẹ Egbo pẹlu ata dindin to ni alubọsa, epo pupa, ẹja yiyan ati tomati ninu.
Awọn elo ti wọn fi n se egbo ni agbado, ẹwa, epo pupa, tomati, abubọsa, ata, ati bẹẹ bẹẹ lọ.
Oríṣun àwòrán, @ojogbon_yoruba
Aadun jẹ ounjẹ ipanu nilẹ Yoruba. Agbado, epo ati awọn eroja miiran ni wọn fi n ṣe.
Awọn Yoruba ma n lo aadun ni ibi aṣeyẹ tabi igbeyawo laye atijọ.
Ohun ti wọn fi n se aadun ni; agbado ti wọn ti lọ, epo pupa, iyọ, ati awọn eroja miiran.
Ọjọjọ jẹ ọkan gboogi lara awọn ounjẹ Yoruba laye atijọ.
Iṣu ewura ni wọn fi n ṣe Ọjọjọ.
Oríṣun àwòrán, Youtube/Onyx Food Hill
ọjọjọ dabi akara loju, paapaa ti eeyan ba n wo o lati okere.
Bo tilẹ jẹ pe o le to aadọta iṣẹju lati pese Ọjọjọ, ṣugbọn ko ṣoro lati pese rara.
Awọn eelo Ọjọjọ ni iṣu ewura, ororo, ata rodo, alubọsa, ede, iyọ diẹ, ati bẹẹ bẹẹ lọ.
5. Iṣu àti epo tàbí kẹ̀tẹ́
Oríṣun àwòrán, Youtube/Nigerian Food Recipes
Iṣu ati epo
Bo tilẹ jẹ pe awọn eeyan lero pe talaka nikan lo n fi epo jẹ iṣu, ṣugbọn ko ri bẹẹ rara tori ounjẹ to da yatọ ni.
Ọpọlọpọ awọn eeyan ti pa epo ti lati maa fi jẹ iṣu bayii, ti wọn si ti n lo ẹyin dindin, ṣugbọn iṣu ati epo ma n dun laye atijọ ninu oko.
Awọn mii laye atijọ nil Yoruba a maa fi kẹtẹ jẹ isu tori o ni ọpọlọpọ ororo lara.
ẹni ba fẹ gbadun iṣu ati epo ni lati se iṣu naa ṣaaju, lẹyin naa ni yoo tọ epo diẹ sori iṣu gbigbona naa, o lee fi iyọ diẹ si i.
Lobatan!
Mama Rainbow:  Toyin Adegbola àti Razak Olayiwola ní ìyá rere àti àwòkọ́ṣe gidi ní
Aisha Buhari: Aya ààrẹ tọrọ àforíjìn lórí fídìo tó ti fi ìbínú sọ̀rọ̀
Oríṣun àwòrán, Faceboo/Aisha Buhari
Aisha Buhari: Aya ààrẹ tọrọ àforíjì lórí fídìo tó ti fi ìbínú sọ̀rọ̀
Aisha Buhari ti tọrọ aforijin lori fọnran ti Fatima to jẹ ọmọ ibatan Aarẹ Muhammadu Buhari, Mamman Daura fi sita.
Aisha tọrọ aforijin lọwọ awọn ọmọ rẹ, ẹbi atawọn ọmọ Naijiria fun itiju ti fọnran naa mu wa.
Fọnran naa fihan bi iyawo aarẹ, Aisha Buhari ṣe fariga pe wọ́n tilẹkun mọ oun ninu ile ijọba to wa l'Abuja pẹlu bi awọn aṣọna si ṣe wa ninu ile ṣi n tu ọrọ sita kaakiri itakun ayelujara Taló ya fídíò ibi tí Aisha Buhari ti ń bínú ní Aso Rock?.
Ninu ifọrọwanilẹnuwo pẹlu BBC Hausa, iyaafin Buhari ni lootọ oun lo wa ninu fidio naa toun n fi ibinu sọrọ.
Ninu fidio ọhun, Aisha Buhari n pariwo pe ki ẹbi Daura ko kuro ni ile ti wọn fun wọn gbe ninu Aso Rock.
Oríṣun àwòrán, Mamman Daura
Mamman Daura
Ṣugbọn o ni fọnran naa kii ṣe ti ọdun yii rara ninu eyi to ti n fesi si awọn ẹbi Daura pe wọn ko jẹ ki oun wọ inu 'ile onidigi' (Glass house villa), Fatima si lo ya fidio naa.
Ninu atẹjade kan ti adari eto iroyin fun aya Aarẹ Naijiria, Ọgbẹni Suleiman Haruna fi sita lorukọ Aisha lo ti bẹbẹ fun idarijin.
Aya aarẹ fọrọ yii lede nigba tawọn iyawo gomina ipinlẹ mẹrẹẹrindinlọgbọn ṣabẹwo si i nile ijọba.
Aisha ni Fatima ya fọnran naa lati le doju ti oun ni, ati pe ihuwasi ẹbi Daura ko ṣẹyin bi aarẹ Buhari ṣe ni ki wọn kẹru wọn kuro nile ijọba.
Onitsha market fire: Ilé tó lé ni 100 ló bá ìṣẹ̀lẹ̀ ìjàmbá iná lọ ní Onitsha
Ọja to ṣofo nibi ijamba ina ọhun le ni ẹgbẹgbẹrun miliọnu naira
Inu ibanujẹ ati ọfọ ni ọpọlọpọ awọn olugbe ilu Onitsha wa bayii, lẹyin ina to ṣẹyọ ni igba ti ọkọ elepo kan la'na ni ilu ọhun.
Aṣojukọroyin BBC ni Onitsha jabọ pe, lẹyin wakati mẹta ti ina ọhun bẹrẹ ni ọkọ panapana kan ṣoṣo ṣẹṣẹ yọju sibi iṣelẹ naa.
O ni ọkọ kan ṣoṣo yii ko to lati pa ina ọhun, nitori ina naa pọ ju iṣẹ ọkọ panapana kan ṣoṣo lọ.
Aṣoju BBC to wa nibẹ ni awọn ile to ba iṣẹlẹ naa lọ le ni ọgọrun, ti ọpọlọpọ awọn ara ilu naa si n pohunrere ẹkun lori iṣẹlẹ ọhun.
O ṣalaye pe ọja to ṣofo nibi ijamba ina naa le ni ẹgbẹgbẹrun miliọnu naira.
Lara awọn ile itaja to jona ni, ibi ti wọn ti n ta bata, aṣọ, kapẹẹti ati ẹya ara ọkọ.
Bakan naa lo ṣalaye pe awọn olugbe Onitsha ti n bere idi ti ileeṣẹ panapana ipinlẹ ọhun ko ṣe da wọn lohun lasiko ti wọn ke si wọn, ni kete ti ina naa bẹrẹ.
O ni ọkọ to n gbe igbọnsẹ lo gbiyanju lati pa diẹ ninu ina ọhun, ṣugbọn ẹpa ko boro mọ.
O sọ siwaju pe awọn eeyan ilu naa n binu si ijọba lọwọ, paapaa julọ awọn oṣiṣẹ ileeṣẹ panapana latari bi wọn ṣe kuna lati tete pa ina ọhun.
Nigba ti aṣoju BBC ṣe abẹwo si ileeṣẹ panapana ni ilu Akwa, ti ko jina si ibi ti iṣẹlẹ naa ti ṣẹ, o ni gbogbo awọn oṣiṣe ileeṣẹ ọhun ti fẹsẹ fẹẹ nitori ibẹru awọn ọdọ ilu ti wọn sọ pe wọn fẹ se ikọlu si wọn.
Oríṣun àwòrán, facebook
Oja Ochanja ni Anambra jona; ajé wọgbo
Ṣaaju lonii ni Aarẹ  Muhammadu Buhari ti banujẹ lori iṣẹlẹ ijamba ina to ṣọṣẹ ni Ipinlẹ Anambra lọjọru ọsẹ yii titi di ọjọbọ ọjọ keji.
Iroyin fi yewa pe, Obinrin kan ati ọmọ rẹ jona ti Aarẹ Buhari si ba gbogbo ebi ati ijọba ipinlẹ Anambra kẹdun pupọ.
Bayii, ko tii si ẹni to mọ iye ẹmi to ti sọnu latari iṣẹlẹ naa ṣugbọn akọọlẹ wa pe, ọgọọrọ eru ati dukia lo ti ṣofo.
Ọpọ awọn ọmọ Naijiria lo ti fi aidunnu wọn han lori bi ijọba ko ṣe tete jigiri si ọrọ ọkọ agbepo to gbana ni Anambra.
Koda Gomina Sanwo-Olu to n tukọ ipinlẹ Eko naa kẹdun pẹlu Gomina Obiano akẹgbẹ rẹ atawọn eeyan ipinlẹ Anambra pe:
Awọn ọmọ Naijiria ni paa lẹẹkini ...ni ọrọ ijamba ina ninu ọja Anambra n di nitori baibai lo ku ti oju awọn oniṣowo n wo bayii
Ọpọ lo n di ẹbi ina yii ru gomina ipinlẹ Anambra pe ko gbe igbesẹ aabo lọwọ ina to yẹ fun ọja nla bii ti Onitsha yii
Ti o bá dá ara ẹ lójú, ki ẹni tó n ṣe irun kí n gbọ́?
Ọpọ awọn eeyan ni wọn n gbadura fawọn to padanu ọja pe Oluwa a fofo ra ẹmi fun wọn ati pe ki ijọba pese ohun to yẹ ni amayedẹrun fawọn eeyan.
Koda, awọn miran sọrọ nipa Innoson Motors to n ṣe moto bii ti panapana ni Anambra ti iṣẹlẹ yii ti ṣẹlẹ
Awọn eniyan Naijiria n beere ohun to ṣẹlẹ si ileeṣẹ panapana to wa ni ipinlẹ anambra tẹlẹ to fi jẹ panapana ipinlẹ Delta ni wọn duro de wa pa ina naa.
Ọpọ gbagbọ pe nitori pe Naijiria kii mura silẹ de ọjọ ogun lo n ṣokunfa wahala to n ṣẹlẹ yii
Ọkọ̀ agbépo tó gba iná ṣe àkóbá ní ọjà Onitsha
Bi eeyan ba jẹ ori ahun lọjọ to ti pẹ; to ba kọkọ de ibi ijamba ina to waye nilu Onitsha, o di dandan ko kawọ le ori.
Ijamba ina naa waye ni ọja Ochanya la gbọ pe o bẹrẹ lati nnkan bi aago mejila ọsan Ọjọru ti awọn kan si ni o jo titi wọ alẹ.
Ọkọ agbepo kan to lana ni wọn ni o fa ina naa ti o ṣakoba fọja Ochanja titi de agbegbe Upper Iweka.
Lẹyin ti awọn ọlọpaa ṣe ti ni ina naa ti lọlẹ, wọn ko ti i le fidi ọrọ mulẹ boya awọn eeyan ṣi yi wa ninu ina naa tabi bẹẹkọ.
Ninu awọn fọnran fidio to gba oju ayelujara niṣe ni awọn eeyan n sa asala fẹmi wọn ti awọn kan si n gbiyanju lati pa ina naa.
Lara awọn to ṣoju wọn ti BBC ba sọrọ ṣalaye pe ina naa ti ran de ọja Ochanja ati Relief Market ni Onitsha.
Ẹwẹ, Gomina ipinlẹ Anambra, Willie Obiano ti ṣe agbekalẹ́ igbimọ kan ti yoo tọpinpin ọrọ ina yi.
Gomina naa tun kesi awọn ti o farakasa ijamba ina yi lati wa si ipade kan lọjọ Aje to n bọ lati le mọ bi ijọba yoo ti ṣe ṣe iranwọ fun wọn.
Ti o bá dá ara ẹ lójú, ki ẹni tó n ṣe irun kí n gbọ́?
Funke Adesiyan: Gbajúgbajà òṣèré Yollywood di olùrànlọ́wọ́ aya ààrẹ, Aisha Buhari
Oríṣun àwòrán, Facebook/Funke Adesiyan
Funke Adesiyan, òṣèré Yollywood tó di olùrànlọ́wọ́ aya ààrẹ, Aisha Buhari
Oṣere Yollywood, Funke Adesiyan ti di oluranlọwọ aya Aarẹ orilẹ-ede Naijiria, Aisha Buhari lori ọrọ abẹle ati awujọ.
Aarẹ Muhammadu Buhari ti buwọlu iyansipo rẹ gẹgẹ bi ọkan lara awọn oluran lọwọ tuntun lofiisi aya aarẹ.
Lọsẹ to lọ ni Aisha pada silu Abuja lẹyin to ti wa nilẹ okere fun bi oṣu mẹta.
Ọjọ meji lẹyin tawọn kan n gbe iroyin ofege pe aarẹ Buhari fẹ ṣegbeyawo pẹlu obinrin mii ni Aisha pada si orilẹ-ede Naijiria.
Ọjọ kẹrinla, oṣu kẹta ni ọjọ ibi oṣere Funke Adesiyan, ọmọ ilu Ibadan nipinlẹ Oyo nii ṣe.
Funkẹ kọ ẹkọ nipa ere itage ni Fasiti Olabisi Onabanjo, bakan naa lo gboye Diploma ninu imọ ofin nile iwe yii kan naa.
Gbajugbaja oṣere Yoruba ni Funkẹ Adesiyan, o si wa lara awọn oṣere ti Eleduwa fun lẹbun ere ṣiṣe lagbo awọn oṣere.
Oríṣun àwòrán, Facebook/Funke Adesiyan
Ọjọ kẹrinla, oṣu kẹta ni ọjọ ibi oṣere Funke Adesiyan, ọmọ ilu Ibadan nipinlẹ Oyo nii ṣe.
Ni kekere lọwọ rẹ ti ji sowo, koda ọmọ ọdun mọkandinlogun lo wa nigba to kọ ile akọkọ rẹ.
Iroyin kan tiẹ sọ pe ọmọ ọdun mẹtadinlogun lo wa nigba ti o ṣiṣẹ ni miliọnu kan naira lọwọ.
Funke Adesiyan bẹrẹ pẹlu iṣẹ arinrin oge ni ọmọ ọdun mẹtala, o bẹrẹ si ni ṣe okowo fun ra rẹ, nigba to pe ọmọ ọdun mẹrinla.
O bẹrẹ si ni ṣe oṣelu lọmọdun mẹẹdọgbọn, nigba naa lo ṣe ipolongo fun oludije fun ipo aarẹ, Mallam Ibrahim  Shekarau.
Idibo gboogbo ọdun 2011 lorilẹ-ede Naijiria ni Shekarau ti dije fun ipo aarẹ, bakan naa lo si ti jẹ gomina ipinlẹ Kano ri.
Lẹyin ti Funkẹ bẹrẹ oloṣelu, lo sọ erongba rẹ lati ṣoju Ẹkun Ila Oorun Guusu Ibadan nile igbimọ aṣofin Ipinlẹ Oyo ninu eto idibo ọdun 2015.
O jawe olubori ninu idibo abẹle ṣugbọn o fidi rẹmi ninu ibo gangan an ninu eyi to ti padanu ọpọ owo ati ohun ini rẹ.
Amọ, Funkẹ ya ọpọ eeyan lẹnu nigba ti o pe apejẹ lati dupẹ lọwọ awọn ololufẹ rẹ.
Funkẹ ni lootọ ni oṣere Saheed Balogun ti jẹ ololufẹ oun ri, o ni oun nifẹ Saheed nitori oun rii gẹgẹ bi oninukan eeyan nigba naa.
O fikun ọrọ rẹ pe akitiyan Saheed lati ran awọn to ba ni iṣoro kan tabi omiiran lọwọ wa lara awọn ohun to jẹ ki oun nifẹ rẹ.
Amọ, onikaluku lọ lọna tirẹ lẹyin ti oun ri ihuwasi to yatọ ninu ihuwasi Saheed.
Ọọni Ile Ifẹ - Ọba aláàánú ni Ọba Adéyeyè Enitan Ògúnwùsì
Oríṣun àwòrán, facebook
Oba Ogunwusi Enitan, ọkunrin ti àwọn obinrin pupọ n bẹ ooṣa ko foju aanu wo wọn!
Kabiyesi Ọba Adeyeye Babatunde Enitan Ogunwusi ni a bi ni ọjọ kẹtadinlogun, Oṣu kẹwaa, ọdun 1974.
A bii si agbo ile Oluropo ati Wuraọla ni deede agogo kan ọsan ti o si jẹ ikarun un ọmọ laarin awọn ọmọ obi rẹ.
Ogunwusi ti o wa lati Idile Ọba Giesi, ni Agboole Agbedegbede ni Ilu Ile- Ife.
Ọba Alayeluwa Ogunwusi ni Ọba Ọọni ọkanlelaadọta ti ti o ti jẹ ni Ilẹ Yoruba.
Oríṣun àwòrán, Facebook
Oba Enitan Ogunwusi ti o wa lati Idile Ọba Giesi, ni Agboole Agbedegbede ni Ilu Ile- Ife.
Ṣaaju ọjọ ibi rẹ ni wọn ti sọ asọtẹlẹ iru ẹni ti yoo jẹ, idi niyi ti iya rẹ ṣe pe e ni Enitan ti baba rẹ agba si sọ ọ ni Adeyeye.
Ọba Enitan ni o jẹ ikarun un laaarin awọn ẹgbọn rẹ ti o si ni aburo meji lẹyin rẹ.
Gẹgẹ bi Ọba Alade, O ni anfaani sii lati fẹ obinrin ti o wu u, lara awọn obinrin rẹ ni; Adebukọla Bombata ti o fẹ ni ọdun 2008.
Bakan naa lo fẹ olori Wuraọla ni ọdun 2016, nigba ti ifẹ aarọ rẹ jẹ Omọlara Ọlatunbọsun.
Ọba Adeyeye Ogunwusi Enitan ni Eledumare fi ọmọ jinki rẹ ti Adeọla Aanuoluwapọ si jẹ akọbi.
Oọnirisa gbe olori SilẹkunOla Naomi niyawo ti ayọ wọn dẹ jọ pọ.
Ọba Ẹnitan bẹrẹ ile iwe alakọbẹrẹ ni ile iwe ọjẹ wẹwẹ Ṣubuọla, ni Akobọ ni ilu Ibadan.
Ti o tun tẹsiwaju ni ile iwe giga Peteru Mimọ ni ilu Ile Ifẹ ti o si gba oye Imọ lori Iṣiro owo ni ile iwe Gbogboniṣe Ilu Ibadan.
Brazil Yoruba: A n gbé àwọn ère Yorùbá káàkiri- Ọọni ti Ilé Ifẹ
O jẹ ọmọ ẹgbẹ awọn oluṣiro owo lorilẹ-ede Naijiria, oriṣiriṣi eka egbe iṣiro owo ni Kabiyesi jẹ ọmọ ẹgbẹ wọn.
Bakan naa ni wọn tun fi ami ẹyẹ ọmọ ẹgbe imọ ofin ati imọ nipa bi a ti n ṣakoso ile iṣẹ da Kabiesi lọla ni ile iwe Fasiti ti Ilu Nsukka ati fasiti Igbinedion.
Oríṣun àwòrán, facebook
Kabiyesi Oba Adeyeye Enitan ti gba ami ẹyẹ loriṣiiriṣii to pọ.
Ọba Enitan ni baba isalẹ ile iwe fasiti Orilẹ-ede Naijiria ni Ilu Nsukka.
Ṣe laarin obi ni a ti n yọfin inu rẹ ni ọrọ Ọba Enitan jẹ laarin ọpọ awọn eniyan pataki to du ipo oye Ọba naa.
Ọba Ogunwusi Enitan gun apere oye Ọọni ni ọjọ kẹrindinlọgbọn, Oṣu kẹwaa, Ódun 2015.
Gẹgẹ bi Ọba ti o fẹran alaafia, o pari ija pelu Iku baba yeye, Alaafin ti ilẹ Ọyọ lati mu iṣọkan ba ilẹ Yoruba lapapọ.
O ti gba ami ẹyẹ kaakakiri ilẹ Yoruba lori ọrọ alaafia.
Ọba Enitan ti ja fun ẹtọ awọn obinrin lọpọ igba.
Oba Ogunwusi ti mu ayapada ba lle Ife gidi nipa sisọ ilu naa di awokọṣe ati ibi Igbafẹ nipa gbingbin ododo ati mimu atunṣe ba bi ilu naa ti ri.
O jẹ alaanu ati olufifunni, ti o si n ran awọn eniyan lọwọ pupọ.
Ni ọjọ kejila, oṣu kẹfa, ọdun 2016, ni a fi kọkọrọ lati jẹ ọmọ Ipinlẹ Franklin ni orilẹ-ede Amẹrika le Kabiyesi lọwọ.
O jẹ Ọba Ilu mọọka ni orilẹ-ede yii ati loke okun.
Ti o bá dá ara ẹ lójú, ki ẹni tó n ṣe irun kí n gbọ́?
Coronavirus: Ọ̀gá iléèṣẹ́ tó n ṣe kọ́ńdọ́mù Durex sọ pé ìbálòpọ̀ dínkù lásìkò ìgbélé yìí
Laisi ani-ani, ibalopọ ti dinku lasiko konle-o-gbele nitori aarun coronavirus to wa lode.Ọga ileeṣẹ Reckitt Benckiser, ti wọn n ṣe rọba idaabobo Durex ti sọ pe awọn eeyan ko saa ba ni ibalopọ pẹlu ara wọn lasiko ajakalẹ aarun covid-19 yii.Laxman Narasimhan ni ọja rọba idaabobo ti lọọlẹ gan an lasiko yii koda to fi de orilẹede Uk.
O ṣalaye pe eleyi ṣẹlẹ nitori ofin iṣede to wa kaakiri agbaaye ko fawọn eeyan lanfaani lati ri ti ọrọ ibalopọ ro.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Narasimhan fikun ọrọ rẹ pe ọpọ lọkọ-laya gan ni ko sun mọ ara wọn mọ bi ti tẹlẹ ki coronavirus to de.Awọn nnkan mii bi ọṣẹ ifọwọ ati oogun ikọ olomi ti ileeṣẹ naa n ṣe si n ta warawara ṣugbọn ọja rọba idaabobo nikan lo wa lẹ.Ọga ileeṣẹ Reckitt Benckiser ni ọpọ eeyan papaa julọ nilẹ Gẹẹsi ati Italy ni ibaṣepọ wọn ko dọn mọran mọ lati igba ti ofin konle-o-gbele ti bẹrẹ.
Africa Eye: Olùkọ́ méjì ní fásitì Eko àti Ghana lùgbàdì ọ̀fíntótó BBC lórí ìwà ìbàjẹ́
Ṣaaju ni awọn onimọ kan sọ pe ọmọ bibi yoo pọ lọdun 2021, nitori pe ofin konile-o-gble ti mu ki ọpọ tọkọ-taya o wa papọ.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Wọn pin ẹgbẹrun lọna aadọfa rọba idaabobo nibi idije Olympic
Awọn eleto ilera orilẹede Tanzania ti ko rọba idaabobo ọgbọn miliọnu wọ orilẹede wọn lati mu adinku ba
Ni orilẹede naa, ṣe ni awọn eniyan n kun yunmu yunmu nipa bi rọba idaabobo ṣe n gbowo lori sii plu bi ijọba ṣi ṣe n pese rẹ fun awọn eniyan to.
Akọroyin BBC, Gilian Kikowe ni awọn ile itura kan ni awọn agbegbe ti katakara pọ si ati ibi igbafẹ Dar es Salaam ko fun awọn eeyan ni nkan idaabobo yii lọfẹ mọ.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Africa Eye: Olùkọ́ méjì ní fásitì Eko àti Ghana lùgbàdì ọ̀fíntótó BBC lórí ìwà ìbàjẹ́
"Awọn ile itaja kan tilẹ n ta a ni ẹgbẹrun mẹta (3,000) ṣile iye owo ilẹ Tanzania eyi to jẹ bii $1; N351, o lee jẹ 5,000 tabi 10,000 ṣile ni iye owo ilẹ Tanzania iyẹn da lori iru ẹya rọba to ba jẹ.
Awọn onibara gbudọ ni rọba idaabobo tiwọn bayii tori a o lagbara ati maa pin in lọfẹ mọ"", oṣiṣẹ ile itura kan sọ fun BBC Swahili."
Igbakeji minisita fun eto ilera, Dokita Faustine Ndugulile ni awọn rọba idaabobo naa ti wa nikalẹ bayii fun lilo.
Aarẹ Buhari kẹ́dùn ọ̀pọ̀ ẹ̀mí àti dúkìá tó jóná ni ọjà Onitsha
Ọmọ Nàìjíríà, ẹ forijìn mí! Aisha Buhari tọrọ ìdáríjì lórí fídìo tó jáde
Egbìnrìn ọ̀tẹ̀! Àṣírí ilé ìmúni nígbèkùn míràn tú síta ni Katsina
"A ti ra rọba idaabobo ọgbọn miliọnu. Ohun to yipada ni ọna ti a n gba pin in; awọn ajọ kan wa to n pin in tẹlẹ ṣugbọn nkan ti yi pada bayii a si ti ni ajọ mii ti yoo maa pin in.
Igbakeji minisita naa sọ pe awọn fẹ ki igbesẹ tuntun yii ko ipa gidi ki ipolongo awọn si kan awọn tọrọ yii kan gan ki rọba idaabobo si wa larọwọto.
Ti o bá dá ara ẹ lójú, ki ẹni tó n ṣe irun kí n gbọ́?
Katsina Den: Ilé mìíràn tí wọn ti n fi ìyà jẹni ni Olọpàá ti rí
Ibi igbekun miran ni Katsina
Awọn Ọlọpaa ni Katsina tun ti ṣe abapade oriko ti wọn ti n muni sin yatọ si eyi ti wọn ti ri tẹlẹ.
Awọn ojuko yii lo maa n fara jọ bii ile iwe keu ṣugbọn to jẹ ibi ifiya jẹni ni pataki awọn ọmọ kekere.
Ile Iṣẹ Ọlọpaa ni Ipinlẹ Katsina sọ wi pe wọn so ọpọlọpọ awọn eniyan mọlẹ bii ẹran ti wọn si n fi iya jẹ wọn.
Ni Ọsẹ to kọja ni wọn ri ogunlọgọ awọn eniyan tu silẹ ni Ipinlẹ naa, ti iru iṣẹlẹ bẹẹ tun ti ṣẹlẹ bayii.
Ajọ Ọlọpaa naa ni ainiye agbalagba ati awọn ọmọ kekeeke ti ko din ni Ọgọrun ni wọn gba kale lati inu ile meji kan.
Awọn obi ni wọn n mu awọn ọmọ wọn lọ si ile iwe yii latari pe wọn yoo ni ẹkọ keu ati pe boya igbesi aye wọn yoo dara sii.
Ninu alaye ti ajọ Ọlọpaa ṣe fun ile iṣẹ BBC ni pe wọn maa n de awọn ọmọ naa mọlẹ ti wọn si tun maa n ba wọn lo pọ.
Wọn tẹsiwaju pe wọn kii fun wọn lounjẹ ti wọn si maa n fi iya to to iya jẹ wọn ninu ayika ti o dọti ti wọn ko wọn si.
Abẹnugan fun ile iṣẹ Olọpaa Ipinlẹ naa, Gambo Isa wi pe ni adugbo Marusa ni wọn ti ri ile ọhun.
Wọn ni iya ti wọn fi jẹ awọn ọmọ naa ko pọ to ti awọn ti ọwọ tẹ ni Daura.
Ọwọ awọn Olọpaa ko tii  tẹ ẹni ti o jẹ adari ile naa ti o ti fẹsẹ fẹ. Wọn ni awọn si ti bẹrẹ si ni wa a bayii, ti Aarẹ Buhari si ti ni ki awọn Ọlọpaa bẹrẹ iwadii lori awọn iru ile bẹẹ.
NLC: Àwa àti ìjọba àpapọ̀ tí ṣé tiwá ó kù sọwọ ẹgbẹ́ òṣìṣẹ́ ìpínlẹ̀ láti yanjú tiwọn
Oríṣun àwòrán, @fkeyamo
Afikun owo oṣu yii lo waye lẹyin ọgọsan an ọjọ ti ijọba buwọ lu abadofin afinkun owo oṣu tuntun
Ijọba gbọdọ bẹrẹ si ni san afikun owo oṣu tuntun fun oṣiṣẹ bẹrẹ láti oṣu kẹrin ọdun yí.
Ẹgbẹ oṣiṣẹ Naijiria lo salaye ọrọ yi ninu ifọrọwanilnuwo pẹlu BBC Yoruba.
Issa Aremu to jẹ akọwe apapọ ẹgbẹ awọn Textile and Tailoring Union (NUTGTWN) to si wa lara awọn to kọwọrin pẹlu aarẹ ẹgbẹ oṣiṣẹ ninu idunadura pẹlu ijọba lo sọrọ yi.
O ni lootọ ni awọn ko ri ohun to wu awọn gba lọdọ ijọba gẹgẹ bi afikun ṣugbọn eyi tawọn ṣe yi yoo mu iyipada ba igbe aye awọn oṣiṣẹ Naijiria.
O ni nipele nipele ni afinku to ba owo oṣiṣẹ.
''Awọn to wa ni ipele keje yoo gba to alekun ida mẹtalelogun  ninu ọgọrun ti awọn to  wa loke patapata yoo gba  to alekun ida mẹwa ninu ida ọgọrun''
Aremu  tẹsiwaju pe bayi ti awọn ti pari eto pẹlu ijọba apapọ, ohun to ku ni ki awọn ẹgbẹ oṣiṣẹ ati awọn ijọba ipinlẹ ati ibilẹ naa joko lati ṣayẹwo afikun to ba yẹ.
''Inu wa dun pe awọn ijọba ipinlẹ kan bi ipinlẹ Eko ni awọn yoo san ju ẹgbẹrun lọna ọgbọn Naira lọ foṣiṣẹ.Iru nkan bayi laa n fẹ lọdọ awọn ijọba ipinlẹ.''
Bi a ko ba gbagbe,mọjumọ ọjọ Ẹti lẹgbẹ oṣiṣẹ ati ijọba apapọ kede pe awọn ti fẹnuko lori afikun owo oṣu oṣiṣẹ.
Idunadura naa ti bẹrẹ lati nnkan bi oṣu mẹrin sẹyin ti ijọba ti kọkọ kede pe ohun yoo fikun owo oṣu oṣiṣẹ Naijiria.
Oríṣun àwòrán, Google
O ni nipele nipele ni afinku to ba owo oṣiṣẹ.
Lẹyin ọpọlọpọ ijiroro, ijọba apapọ ati ẹgbẹ oṣiṣẹ ti fẹnuko lori afikun owo oṣu oṣiṣẹ ni Naijiria.
Minisita abẹlẹ fun iṣẹ ati igbanisiṣẹ, Festus Keyamo lo fi ọrọ naa lede loju opo Twitter rẹ.
Keyamo sọ ninu ọrọ naa pe, Lẹyin ijiroro laarin ijọba apapọ ati ẹgbẹ oṣiṣẹ, a ti fẹnu ko lori afikun owo oṣu oṣiṣẹ, a ti bẹrẹ iṣẹ lori afikun owo oṣu ọhun."""
Afikun yii lo waye lẹyin ọpọlọpọ atotonu to waye larin ijọba ati ẹgbẹ oṣiṣẹ, lẹyin ti ijọba apapọ buwọlu ẹgbẹrun un lọna ọgbọn owo ọsu oṣiṣẹ to kere julọ Ìná ẹgbẹ́ òṣìṣẹ́ NLC ati ìjọba kò wọ̀ níbi ìpadé  .
Akọwe gbogboogbo fun ẹgbẹ Trade Union Congress, Musa-Lawal Ozigi, fi idi ọrọ naa mulẹ, o si gboriyin fun ijọba apapọ ni bi o ṣe fọwọ si afikun owo oṣu ọhun.
Ti o bá dá ara ẹ lójú, ki ẹni tó n ṣe irun kí n gbọ́?
Ninu  tuntun yii, awọn oṣiṣẹ to wa ni ipele keje yoo ni afikun ida mẹtalelogun ninu ọgọrun un owo oṣu, bẹẹ naa ni awọn oṣiṣẹ ni ipele kẹjọ yoo ni afikun ida ogun.
Bakan naa ni awọn oṣiṣẹ to wa ni ipele kẹsan an yoo ni afikun ida mọkandinlogun ninu ida ọgọrun un ninu owo oṣu.
Nigba ti awọn to wa ipele kẹwaa si mẹrinla yoo ṣe ni afikun ida mẹrindinlogun ninu ida ọgọrun un, ni awọn to wa ni ipele kẹẹdogun si ipele kẹtadinlogun yoo ṣe ni afikun ida mẹrinla owo oṣu.
Oríṣun àwòrán, @OmasoroO
Minimum wage: Ìjọba àpapọ̀ àti ẹgbẹ́ òṣìṣẹ́ ti fẹnukò lórí àfikún owó oṣù tuntun- Keyamo
Ifẹnuko lori owo oṣu yii ko rọrun rara fun ẹgbẹ oṣiṣẹ, nitori ọpọlọpọ ipade lo ti waye laarin ijọba apapọ ati ẹgbẹ ọhun, sugbọn ti ko so eso rere.
Afinkun owo oṣu yii lo waye lẹyin ọgọsan an ọjọ ti aarẹ Muhammamdu Buhari buwọ lu abadofin afinkun owo oṣu tuntun fawọn oṣiṣẹ.
BBC 100 Women 2019: Wo àwọn ọmọ Afirika tó wà nínú wọn
Awọn obinrin ọhun ni BBC yẹ si lẹyin ti wọn ṣe iṣẹ takuntakun lorilẹ-ede wọn
Ileeṣẹ BBC ti ṣe afihan awọn obinrin to dantọ ju lagbaye fun ọdun 2019.
Awọn obinrin naa ni ileeṣẹ BBC ni wọn ti ṣe ohun to lami-laaka to si tọ ki wọn yẹ wọn si lagbaye.
Lara wọn ni awọn oniroyin, awọn olorin, awọn ọga agba ile iṣẹ, awọn aṣofin, awọn omuwẹ, ati bẹbẹ lọ.
Pupọ lara awọn obinrin ọhun lo jẹ ọmọ ilẹ Adulawọ ti wọn ti ṣe iṣe takuntakun lorilẹ-ede wọn.
A fẹ wo diẹ lara awọn ọbinrin ọhun to jẹ ọmọ ilẹ Adulawọ.
Kalista lo kọ ara rẹ bi wọn ṣe n kọ itan sinima, lẹyin naa lo gbe sinima ti akọle rẹ n jẹ Mistress jade, leyi to lami-laaka lorilẹ-ede rẹ ni ibẹrẹ ọdun yii.
Sinima ọhun sọ nipa awọn obinrin ilẹ Afirika to tiraka lati sọriire lai ta ara wọn lọpọ fun awọn okunrin.
Sinima naa si tun sọ nipa ohun toju obinrin n ri nile adulawọ, paapa awọn to wa lati idile olorogun ati ọrọ to jẹ mọ ilera obinrin.
Igbagbọ Kalista ni pe, awọn obinrin lee di ẹni pataki lawujọ,  lai ni i fi ṣe ohun toju wọn n ri nilẹ adulawọ.
2. Benedicte Mundele - oniṣowo ounjẹ ni DR Congo
Oríṣun àwòrán, @benesthermunde1
Benedicte gbagbọ pe, ọpọlọpọ anfani lo wa niniu ohun ti ọpọ eeyan mii n wo bi iṣoro
Benedite jẹ oniṣowo ounjẹ ati eso ọgbin lorilẹ-ede rẹ, Democratic Republic of Congo.
Oun ni oludasilẹ Suprise Tropical, illẹsẹ ti wọn ti n ta ounjẹ ajẹpọnula ati eleyii ti eeyan lee gbe rele, ni Kinshasha.
Igbagbọ Benedicte ni pe, ọpọlọpọ anfaani lo wa niniu ohun ti ọpọ eeyan mii n wo bi iṣoro.
Painter: Samuel ni ìdàgbàsókè Nàìjíríà ló jẹ òun lógún!
Lọdun 2017 ni Farida di obinrin akọkọ lorilẹ-ede Egypt, nigba to gba ami ẹyẹ ninu idije awọn omuwẹ FINA World Aquatics Championships.
"Farida lee wẹ to bẹẹ gẹ, ti wọn fi n pe ni "" Ẹja alawọ wura"" ni orilẹ-ede rẹ."
O jẹ ẹni to ma n ba ọpọ awọn akẹkọ Fasiti sọro lati ru wọn soke fun aṣeyọri to peye.
Afojusun farida ni lati gba ami gẹgẹ omuwẹ to pegede julọ ni idije Olympi ti yoo waye ni Tokyo lọdun 2020.
Rana El Kaliouby jẹ ọkan lara awọn onimọ ẹrọ kọmputa to pegede julọ lorilẹ-ede Egypt.
"Oun ni oludasilẹ ileeṣe ti wọn ti pilẹ ẹrọ ""Affectiva,"" eyi to lee mọ bi eeyan ṣe n ni imọlara si."
Lara awọn ẹrọ kọmputa ti Kaliouby pilẹ rẹ ni wọn n lo ninu ọkọ lati mọ awọn awakọ to ba n sun nigba ti wọn ba n wa ọkọ loju popo.
Igbagbọ Kaliouby ni pe, ko si ohun ti okunrin le ṣe, ti obinrin ko le ṣe jubẹ lọ.
Kayode Abiara: Ọmọ Nàíjíríà, ẹ má ba ọkàn jẹ́ lórí ààbò tó mẹ́hẹ, ewu ìgbà ìkẹyìn ló jẹ́
Nibi ifẹhonuhan kan lọdun 2013 ni wọn ti ṣeku pa ọmọ Ahlam, to jẹ ọmọ ọdun mẹtadinlogun nigba naa.
Lẹyin iṣẹlẹ yii ni Ahlam ti ṣeleri lati mu ki ijọba fi imu awọn to pa ọmọ rẹ danrin, to si ti n pe ara rẹ ni iya fun gbogbo awon ti wọn ti ṣeku pa ni Sudan.
Lati ọdun naa ni obinrin yii ti di jijangbara fun awọn ti wọn n pa lona aitọ ati awọn to deede di awati lorilẹ-ede Sudan.
Ahlam ti jẹ ọpọlopọ iya nibi ifẹhonuhan lodi si ijọba orilẹ-ede rẹ, paapa julọ nibi ifẹhonuhan lodi si ijọba aarẹ ana lorilẹ-ede ọhun, Omar al-Bashir.
Igbagbọ Ahlam ni, orilẹ-ede Sudan si maa goke agba lawujọ agbaye.
Bangladesh Brothel: Ọ̀pọ̀ àwọn àṣẹ́wó tó wà níbẹ̀ ni wọ́n bí sílé aṣẹ́wó náà
Ghana Floods: Omiyalé ní Ghana, èèyàn 28 dolóògbé!
Oríṣun àwòrán, @Albert
Ojo arooroda fa omiyale, agbara ya soobu ni Ghana
O kere tan eniyan mejilelogun lo ti doloogbe ni orilẹ-ede Ghana bayii.
Lataari arọọrọda ojo to n rọ lati ọjọ mẹjọ sẹyin lo ti fa omiyale ati agbara ya ṣọọbu ni ariwa ila oorun Ghana.
Oríṣun àwòrán, @Albert
Ọpọ ile lo dawo ti opọlọpọ dukia si bajẹ ni Ghana
O le lẹgbẹrun kan ile to ti da wo silẹ ti ọpọ eeyan ko si nile lori mọ ni ẹkun yii
Ẹru n ba awọn alaṣẹ Ghana pe ki oku ma lọ pọ sii ju bayii lọ, ti awọn ti wọn ko nile lori naa si n pọ sii.
Oríṣun àwòrán, @Albert
Opo ile ti ko duro daadaa tẹlẹ ni wọn ti wo lulẹ bayii ni Ghana
Ajọ to n mojuto iṣẹlẹ pajawiri ni Ghana, National Disaster Management Organisation ti berẹ si ni pin awọn ohun eelo fawọn ti omiyale le kuro nile.
George Ayisi to jẹ alukoro ajọ naa ṣalaye pe, oku eniyan mejilelogun ni wọn ti ri bayii ni eyi ti awọn ogoje eeyan dẹ ti di alainile lori.
Pupọ ninu awọn ti ile wọn ti wo ni wọn ti ko lọ sile ijọsin lawọn ṣọọṣi wọn ati awọn ile iwe kọọkan.
Omiyale Ile Ife: Dukia sọfọ, awọn eniyan si tun farapa
Ajọ to n woye ayipada oju ọjọ ni orilẹ-ede Ghana ti sọ pe ọpọ ojo lo ṣi maa rọ sii lọdun yii ni Ghana.
Osu kẹrin, ọdun yii niru omiyale bayii ṣẹle gbeyin ni Ghana.
È gbọ òun ti ojú  awọn ara ipinle Ogun rí  lọwọ ìṣẹlẹ omiyale
Akẹ́kọ̀ọ́ Ilaro Poly tó pegedé jù jẹ ẹ̀bùn iṣẹ́ ọ̀fẹ́ lọ́wọ́ Gómìnà Abiodun
Ẹ gbà mi o! Wọ́n tún ń lépaà mi o! - Kemi Afolabi
Njẹ́ o mọ pé N3000 ló o sàn láti gbà kaadi ìdánimọ̀ míì bí tí tẹ́lẹ̀ bá sọnù?
BBC 100 Women 2019: Wo ọmọ Nàíjíríà kan tó wà nínú wọn
Painter: Samuel ni ìdàgbàsókè Nàìjíríà ló jẹ òun lógún!
JAMB: akẹ́kọ̀ọ́ tí kò bá ní nọ́mbà ìdánimọ NIN kò ní lè kọ ìdánwò ìgbaniwọlé
Oríṣun àwòrán, @JAMB
Pupọ akẹkọọ Naijiria ni yoo kọ idanwo JAMB ki wọn to le ribi wọle si ile ẹkọ giga
Ajọ n to risi eto idanwo igbaniwọle si ile ẹkọ giga ni Naijiria, JAMB ti tẹpẹlẹ pataki nini nọmba idanimọ NIN fawọn akẹkọọ to fẹ kọ idanwo rẹ.
Ajọ naa ko ṣẹsẹ sọ ọrọ yi ṣugbọn o tun fi ikilọ yi sita loju opo Twitter rẹ pe akẹkọọ ti ko ba ni nọmba idanimọ NIN ko ni le kọ idanwo rẹ Láìsì nọ́mbà ìdánimọ̀ NIN ní 2020; kò sí ìdánwò- JAMB.
Yatọ si ikilọ yi o tun sọ fawọn akẹkọọ pe ki wọn ma ṣe san owo abẹtẹlẹ foṣiṣẹ JAMB kankan tori pe eleyi lodi sofin.
Ikilọ mejeeji yi wa loju opo Twitter wọn ni idahun si ibeere tawọn akẹkọọ kan fi ṣọwọ si oju opo naa.
Ọrọ yi ti wọn fi sita mu iriwisi ọtọọtọ wa.
Ààrẹ Muhammadu mú àdínku ba owó ìdánwo fún ìr'srún òbí-JAMB
Bi awọn kan ti ṣe n gbosuba karẹ fun Jamb fun igbesẹ yi lawọn miran n bẹnu atẹ lu u pe ọna ati dagbese sawọn akẹkọọ ati obi wọn lọrun ni.
Painter: Samuel ni ìdàgbàsókè Nàìjíríà ló jẹ òun lógún!
Lẹnu ọjọmẹta yi ni ọrọ nọmba NIN ti n mu ikunsinu wa lati ọdọ awọn ọmọ Naijiria nitori inira ti wọn n koju lati ri gba ati bi ajọ NIMC ti ṣe sọ pe awọn eeyan yoo san owo lati fi gba kaadi idanimọ ti ti tẹlẹ ba sọnu.
Pupọ ọmọ Naijiria ni o ti forukọsilẹ ti ko ti ri kaadi idanimọ yi gba ti awọn miran ko tilẹ ti ribi forukọ silẹ.
Ijọba Naijiria ti ṣaaju kede pe nọmba NIN yi ni awọn yoo maa lo latifi ṣeto to ba ni ohun ṣe pẹlu iforukọsilẹ ni Naijiria yala fun iwe irinna, iwe aṣẹ iwakọ tabi nnkan miran.
Ti o bá dá ara ẹ lójú, ki ẹni tó n ṣe irun kí n gbọ́?
Lady Gaga àti olólùfẹ́ rẹ̀ ṣubú yakata níbi tó tí ń kọrin ní Las Vegas
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ọna ọfun, ọna ọrun, olorin takasufe ilẹ Amẹrika, Lady gaga ṣubu yakata lori itage to ti n kọrin niluu Las Vegas.
Iṣẹlẹ yii waye nigba ti Lady Gaga fẹ pe ọkan lara awọn ololufẹ rẹ, Jack pe ko goke wa.
Bi Lady Gaga ṣe fo soke, to si bẹrẹ si nii jo ni ẹsẹ rẹ yẹ lori itage, lo ba ṣubu yakata.
Ẹnikan ti iṣẹlẹ ọhun ṣoju rẹ ni ọpọ lo ro pe olorin naa ti ku lẹyin to ṣubu, amọ o jẹ iyalẹnu pe, o tun goke wa pẹlu Jack to fẹ fa soke pẹlu rẹ.
Egungun ṣubu, o sọ didan ni Lady Gaga fi ṣe, lẹyin to sọ pe awọn mejeeji fẹran ara wọn debi pe awọn jọ jabọ lati ori itage.
O ni ọrọ awọn dabi Jack ati Rose ninu fiimu Titanic. Ko da Lady Gaga ni o yẹ kawọn jọ muti papọ.
Ọpọ ololufẹ Lady Gaga lo bẹru fun Lady Gaga nitori o ni nnkan to maa n jẹ ki irora pọ sii lara eeyan ti wọn n pe ni 'Fibromyalgia'.
Lọdun 2013, Lady Gaga wọgile erongba rẹ lati lọ kọ orin 'Born This Way' lẹyin to fi itan rẹ ṣeṣe.
Ṣugbọn lẹyin iṣẹlẹ naa, Lady Gaga sọ fawọn ololufẹ rẹ pe kokoko lara oun le.
Lẹ́yìn ọdún mẹ́tàlélọ́gbọ̀n; àwọn èèyàn sí n bèèrè pé: Ta ló pa Dele Giwa?
Oríṣun àwòrán, Google
Lẹ́yìn ọdún mẹ́tàlélọ́gbọ̀n; àwọn èèyàn sí n bèèrè pé: Ta ló pa Dele Giwa?
Bi a ba ni ka maa p'ori akọni laarin awọn akọroyin orile-ede Naijiria, ko si igba ti ida Dele Giwa ko ni lalẹ gaaraga.
Olootu agba iwe iroyin Newswatch jẹ ọkan lara awọn oniroyin ti o dantọ ni Naijiria ki ọlọjọ to de.
Loni to pe ọdun mẹtalelọgbọn ti ọmọ Giwa dagbere faye, ọpọ eeyan lo ṣi n daro rẹ ti wọn si n beere ẹni to wa nidi iku rẹ.
Loju opo Twitter awọn eeyan bi Ahmed Salkida n ṣe idaro Dele Giwa.
Bẹẹ lọpọ n beere ibeere nla pe awọn oniṣẹ ibi wo lo ṣe iṣẹ naa.
Ọrọ iku rẹ jẹ nnkan to ṣokunkun titi di bi a ti ṣe n sọrọ yi.
Orisirisi alaye si ni awọn eeyan ti fi sita lati na ika si awọn ti wọn lero pe o lọwọ ninu iku rẹ.
A ko ridi eyikeyi awọn alaye yi fi mulẹ ṣugbọn ohun ti ko ruju ni pe ado oloro ni wọn fi pa Dele Giwa eleyi ti wọn gbe sinu apo ifiweranṣẹ si ni.
Oríṣun àwòrán, Google
Ọrọ iku rẹ jẹ nnkan to ṣọkunkun titi di bi a ti ṣe n sọrọ yi.
Ninu ifọrọwanilẹnuwo kan pẹlu BBC, Kayode Soyinka to jẹ olootu iwe iroyin Newswatch ni London sọ pe oun ati Dele Giwa  jijọ wa nile rẹ ni GRA lọjọ kọkandinlogun, oṣu Kẹwaa, ọdun 1986 ni.
Ọjọ buruku, Eṣu gbomi mu naa bọ si ọjọ Aiku.
Iyawo Dele Giwa, Funmilayo gẹgẹ bi Kayode ti ṣe sọ gbe akara fun wọn ti wọn si jijọ n ṣaroye nipa bi awọn ọtẹlẹmuye ti ṣe fọrọ wa Dele Giwa lẹnuwo ṣaaju ọjọ naa.
Ṣaa deede ni wọn gbọ ti eeyan kan n kan ilẹkun ti ọmọ Dele Giwa, Kayode si wa jiṣe apo iwe naa fun Dele Giwa lọjọ naa.
Kete ti Dele Giwa ṣi apo iwe yii ni ado oloro bu gbamu ti o si gbina jẹ.
Ori ko Kayode Soyinka yọ ninu ibagbamu ado oloro naa amọ o farapa diẹ.
Toun ti pe wọn tara ṣaṣa gbe e lọ si ile iwosan, Kayode sọ pe ibẹ ni o dakẹ si.
Nigba ti iṣẹlẹ yi waye lọdun 1986, Naijiria si wa labẹ ijọba ologun labẹ akoso Ọgagun Ibrahim Babangida.
Igba akọkọ si re e ti wọn yoo fi ado oloro pa eeyan ni Naijiria.
Oríṣun àwòrán, Yusuf Mohammed
Dele Giwa, Yakubu Mohammed ati dokita Doyin Abiola
Iṣẹlẹ naa titi di oni jẹ eleyi ti awọn eeyan ṣi fi n ṣakawe ewu to wa nibi iṣẹ akọroyin ni Naijiria.
Yatọ si Dele Giwa, awọn ilumọọka ọmọ Naijiria miran ti o kuku ojiji ti a ko le sọ awọn to pa wọn la ti ri awọn bii:
Adebisi Olabode: Ìjọba ìpínlẹ̀ Oyo ti fòfin de oyè Ìyá àti Babalọja
Headies 2019: Adekunle Gold,Teni,Burna Boy,tá ní yóò gbà àmì ẹ̀yẹ̀ olórin to fakọyọ?
Oríṣun àwòrán, Facebook/tenientertainer/patorankingofficial/dekun
Ko ti daju ẹni ti ami ẹyẹ yi yoo ja mọ lọwọ
Oni loni njẹ ẹni a bẹ lọwe nidi ayẹyẹ fawọn akọrin to lamilaka lorileede Naijiria eleyi ta mọ si 'Headies'
Awọn olorin Yoruba to fi mọ akẹgbẹ wọn lorileede Naijiria yoo jijọ figagbagba lati gba ami ẹyẹ ni isọri orisirisi to fi mọ takọrin to fakọyọ ju lọ.
Ayẹyẹ naa yoo waye lalẹ oni ni ile itura Eko Hotel.
Lara awọn ti wọn ti fi orukọ wọn ṣọwọ fami ẹyẹ yi la ti ri Adekunle Gold,Patoranking, Teni 'Oba Orin' ati Burna Boy.
Loju opo Twitter awọn ololufẹ olorin kọọkan ti n ba ara wọn jiyan pe olorin tawọn nifẹ ni yoo gba ami naa.
Igba ẹlẹkẹta re e ti wọn yoo ṣeto ami ẹyẹ yi.
Saaju asiko yi,Hip Hop World Awards  ni orukọ ti wọn n pe ayẹyẹ yi ti Hip TV si jẹ agbatẹru rẹ.
Gbajugbaja elere sinima nii Nancy Isime ati olorin raapu Reminisce ni yoo ṣe atọkun eto naa ti yoo waye lalẹ oni tii ṣe ọjọ Abamẹta ọjọ kejidinlogun oṣu Kẹwa.
Torture Centre: Buhari pàsẹ àbẹ̀wò sí gbogbo ilé ọmọ aláìgbọràn
Kaduna Torture Centre: Ààrẹ Buhari pàsẹ kí ilé iṣẹ́ ọlọpàá gbọn ìpínlẹ̀ 36 yẹ́bẹ́yẹ́bẹ́
Ààrẹ Muhammadu Buhari ti pàsẹ kí ilé iṣẹ́ ọlọpàá ṣe ìwádìí gbogbo àwọn ilé ọmọ alàìgbọ̀nran to ba wà ní ìpínlẹ̀ mẹrẹẹrindilogoji, to fí mọ Abuja, tii se olúùlú orilẹ̀-èdè Naijiria.
Ààrẹ Buhari pa àsẹ yìí lẹ́yìn ti gómìnà ìpínlẹ̀ Kaduna, Mallam Nasir el-Rufai kọ́wọ̀rìn pẹ̀lú àwọn ọlọpàá nipinlẹ Kaduna, láti lọ tú ilé ti wọn ti n mú àwọn ọdọ́ nígbèkun fún ìbáwí, èyí ti wọ́n pe orúkọ rẹ̀ ní Mallam Niga Rehabilitation Centre, to wa ni ijọba ìbílẹ̀ Rigasa ní ìpínlẹ̀ Kaduna.
Ààrẹ ní ìjọba tó ń bẹ lóde kò fí ààyè gbà ìwá ìmúnilẹrun, àìbọwọ̀ fún ẹ̀tọ́ ọmọniyan àti ìwà ọ̀daràn tó ń foju hàn ní ẹnu ọjọ mẹ́tà yìí, láwọn ibudo ti wọ́n ko àwọn ọmọ de sí fún ìmúnilẹ́ru àti ìfìyàjẹni.
Láwọn ilé ti àwọn ọlọpàá tún ṣẹ̀ṣẹ̀ tú sílẹ̀ yìí, ènìyàn mẹ́tàdínláàdọjọ ní wọ́n tú sílẹ̀ nínú ìgbèkùn, ọkùnrin márùnlelọ́gọ́fà àti obinrin méjilélogun ni wọ́n gba ìtúsílẹ̀, tí àwọn mẹ́rin nínú wọn si jẹ́ àjejì láti Cameroon àti Niger Republic, pẹ̀lú ìdè àti ẹwọ̀n ti wọ́n fi de ọ̀pọ̀ wọ́n.
Agbẹ̀nusọ ilé isẹ́ ọlọpàá ìpínlẹ̀ Kaduna DSP Yakubu Sabo sàlàyé pé, ìwádìí yóò bẹ̀rẹ̀ lóri ọ̀rọ̀ náà làìpẹ́ yìí àti pé gbogbo àwọn tó gba ìtúsílẹ̀ ló ti wà ni ìpamọ.
Sabo Salaye pé, Gomina ìpínlẹ̀ Kaduna funra rẹ ló sááju ogun lọ sí ilé alaígbọ̀ràn yìí, láti mọ ǹkan to n ṣẹlẹ̀ nibẹ, tí àwọn eniyan ti wọ́n ba nibẹ̀ sì sọ pé, àwọn gba ìwé àṣẹ̀ láti maa kọ àwọn ènìyàn lẹ́kọ̀ọ́ iṣẹ́ ọwọ́.
Obí gbogbo àwọn ọmọ náà lo mú gbogbo wọ́n wa si àkàtà wa yálà nítori pé wọn ń mu oogun oloro tàbi wọ́n ni ààrun ọpọlọ.
Igba kèji rèé ti wọn yoo tun tu awọn onde silẹ nile ọmọ alaigbọran lẹ́yìn tí ọlọpàà tú ọọdunrun miran sílẹ̀ ni inu osu kẹsan.
Kano Zoo: Àfihàn ohun ọ̀gbìn ló mú kí wọ́n mú Kìnìún náà jáde
Kano Zoo: Kìnìún sá kúrò ní ọgbá ẹrànko lẹ́yìn to ṣe ọsẹ́ nínú ọgbà ẹranko
Iroyin to n tẹ́ wa lọ́wọ́ fi ye ni pe wọn ti ri kiniun to sa lọ lgba ẹranko nilu Kano bayii.
BBC gbọ pe inu agọ ti wọn fi awọn ewurẹ pamọ si ni wọn ti ri Kiniun naa, to si ti pa gbogbo ewurẹ to wa nibẹ patapata.
Laipẹ yii la mu iroyin naa wa fun yin ni yajoyajo pe inu ibẹ̀rù bojo làwọn olùgbé àdúgbò òpópónà Zoo ní ìpínlẹ̀ Kano wa, nìgbà ti kìnìún kan sá kúrò nínú ọgbà ẹrànko to wà ní Kano, lóru ọjọ́ Sátidé.
Ìròyìn to tẹ BBC lọ́wọ́ sọpé, ìsẹ̀lẹ̀ náà wáye nígbà ti kìnìun ọhun fipa jáde lásìkò ti olùsọ wọ́n ń gbiyanju láti dáá pada si ààye rẹ̀, lẹ̀yin ti wọ́n se ayẹyẹ àfihan ohun ọ̀gbìn.
Adari ibudo ẹranko nilu Kano, Saidu Gwadabe Gwarzo sàlàye pé, wọ́n ba Kìnìún ọhun ni ìhà ibi ti àwọn ewúrẹ wà, ti Kìnìun náà si ti ń pa àwọn ewúrẹ́ jẹ.
Oríṣun àwòrán, Others
Gwadabe fi kún-un pé, ni ọjọ sátide ni wọ́n tun sílẹ̀ ni abala tawọn ẹranko ẹgan wa ninu ọgba ẹranko naa ni Kano, amọ to salọ nigba ti wọn fẹ pada si ibudo rẹ̀.
Agbẹnusọ ọlọpàá ní ìpínlẹ̀ Kano, DSP Abdullahi Kiyawa, ti wa fi ìdì ìṣẹ̀lẹ̀ náà múlẹ̀.
Oṣeṣe ki ẹ dede pàde kìnìún lọ́na
Olùdari ọgba ẹranko naa sọ pe Kìnìún náà wa ninu ọgbà, àti pé gbogbo ẹnu ibode to wọ ibudó náà ni àwọn ti ti pa.
Àwọn alaṣẹ ti wa kesi gbogbo olùgbé ìpínlẹ̀ Kano, pàápàá jùlọ àwọn to wa ni agbegbe ọgba ẹranko naa, láti fi ọkàn wọn balẹ̀, nítori pé àwọn yóò sa gbogbo ipá àwọn láti dààbo bò wọ́n.
Adebutu: Buhari rọ Odole tuntun láti mú kí ìfẹ́ jọba láàrin Yorùbá àti ẹ̀yà míràn
Oríṣun àwòrán, @raufaregbesola
Aarẹ Muhammadu Buhari ti rọ Odole Oodua, Ọlọla Kessington Adebutu lati ri oye isẹnbaye tuntun to jẹ naa gẹgẹ bi anfaani, lati se  agbelarugẹ asa ati ise Yoruba.
Aarẹ Buhari, ẹni ti minisita fọrọ abẹle, Rauf Arẹgbẹsọla soju fun, wa se apejuwe ẹya Yoruba gẹgẹ bii ẹya to lagbara pupọ lorilẹede Naijiria, pẹlu afikun pe ki wọn to fi eeyan jẹ oye Odole, o gbọdọ jẹ pe iru ẹni bẹẹ jẹ gbajumọ, to si ti ko ipa ribiribi si isisẹ sin ọmọniyan ati idagbasoke awujọ rẹ.
Inu mi dun pe Oloye Adebutu jẹ oye Odole yii, mo si gbadura pe yoo jẹ oye naa pẹ. O si da mi loju pe o mọ pataki oye yii, nitori awsn akọni ọmọ Naijiria bii Oloye Ọbafẹmi Awolọwọ ati GOK Ajayi ti jẹ oye naa siwaju rẹ.
Oríṣun àwòrán, @raufaregbesola
Buhari ni oun mọ ipa takuntakun ti awọn Odole to siwaju yii ko si idagbasoke orilẹede Naijiria, ti wọn si ri daju pe ajọsepọ to dan mọran wa pẹlu ẹya Yoruba ati awọn ẹya miran, ti Adebutu si gbọdọ se daadaa ju awọn asaaju rẹ yii lọ.
"isẹ nla to wa niwaju Odole ni bi agbelarugẹ yoo se ba bi wọn yoo se maa kọ ede Yoruba lawọn fasiti yika ilẹ wa, mo si tun rọọ gẹgẹ bii ẹlẹyinju aanu lati maa ran awọn mẹkunnu lọwọ, ko si tun jẹ asaaju rere ti yoo maa se atọna alaafia, isọkan, idagbasoke ati ifẹ yika Naijiria.
Oríṣun àwòrán, @raufaregbesola
Nigba to n sọrọ nibi ayẹyẹ naa, Odole tuntun, Kessington Adebutu ni iran Yoruba ko ni mẹẹri rara ni Naijiria, ti oun yoo si sa ipa lati ri pe asa ati ede Yoruba ko wọọkun rara lasiko toun.
Yemi Osinbajo: Seyi Makinde, mo gbà fún ọ lórí ẹ̀kọ́ ọ̀fẹ́ tó o ṣe l‘Ọyọ
Oríṣun àwòrán, @oyostategovt
Igbakeji aarẹ ilẹ wa, Ọjọgbọn Yemi Osinbajo ti se sadankata, mo gba fun ọ, si gomina ipinlẹ Ọyọ, Onimọ ẹrọ Seyi Makinde lori ilana ẹkọ ọfẹ to gbe kalẹ nipinlẹ Ọyọ.
Atẹjade kan ti akọwe gomina ipinlẹ Ọyọ feto iroyin, Taiwo Adisa fisita salaye pe, igbakeji aarẹ gbosuba bẹẹ fun Seyi Makinde lasiko ti wọn jọ peju sibi isin ayẹyẹ ọgbọn ọdun ti wọn da ijọ Bishop Taiwo Adelakun, Victory Church silẹ nilu Ibadan.
Osinbajo salaye inu oun dun pe gomina Makinde tẹwọgba ipenija to wa nidi ipese ẹkọ ọfẹ to tun jẹ ojulowo nipinlẹ Ọyọ.
Osinbajo fikun pe ijọba Muhammadu Buhari gan sọ logunjọ osu Kẹfa ọdun 2019 pe eto ẹkọ yoo jẹ ọfẹ yika orilẹede Naijiria fun ọdun mẹsan akọkọ nile ẹkọ alakọbẹrẹ ati girama, tijsba apapọ ko si lee kan nipa fawọn ijọba ipinlẹ lati se bẹẹ.
Oríṣun àwòrán, @OfficialSeyiMakinde
O wa jẹjẹ pe ijọba apapọ yoo sisẹ pọ pẹlu awọn ipinlẹ lati se amusẹ ipese ojulowo ẹkọ ọfẹ pẹlu afikun pe ijsba yoo ran wọn lọwọ ni gbogbo ọna lati ri daju pe afojusun ipese ẹkọ ọfẹ, to tun jẹ dandan di ohun.
Nigba to n fesi, gomina Seyi Makinde ni ẹkọ ọfẹ ti di ohun nipinlẹ Ọyọ nitori ilana eto ẹkọ nikan ni ọna to daju lati mu adinku ba isẹ ati osi ati ilana ironilagbara to pegede julọ fawọn ọdọ.
Lootọ ọdun mẹrin ko to lati gbe wa de ibi ti a n ls amọ ọdun mẹrin to lati fi ipilẹ gidi lelẹ fun eto ẹkọ, eyi ti ijsba to n bs yoo mọ le lori."""
Ọpọ awọn asaaju wa lo si n royin anfaani ẹkọ ọfẹ Oloye Ọbafẹmi Awolọwọ ti wọn jẹ anfaani rẹ bi o tilẹ jẹ pe ọjọ pẹ ti Awolọwọ ti papoda. Sugbọn ipa ẹkọ ọfẹ ti Awolọwọ fi silẹ lo jẹ opo tijsba mi fẹyinti nipinlẹ Ọyọ.
USSD: Ìjọba àpapọ̀ bẹ̀rẹ̀ ìwàdíí lórí owó orí tí MTN fẹ́ yọ̀
Oríṣun àwòrán, Others
Mínísítà fùn eto ìbárẹnisọ̀rọ̀ Isa Pantami, tí pàsẹ oní wàrànsesà fún ilé iṣẹ́ MTN àti àwọn ilé iṣẹ́ ìbánisọ̀rọ̀ míràn láti dẹ́kun ìpinu rẹ̀, lóri fífi  náírà mẹ́rin owó àtẹjisẹ lorí onibara rẹ̀, tó fẹ fi owo rànsẹ́ sí ẹlòmíràn láti orí ẹ̀rọ ìbánisọ̀rọ̀ rẹ̀.
Èyí jẹ́ ìdáhun sí igbé àwọn ọmọ Nàìjíríà lori àba ti ilé iṣẹ́ MTN dá pé, yóò bẹ̀rẹ̀ si ni yọ ààdọta naira láti ọjọ kọkanlélogun osù yìí.
"Gẹ́gẹ́ bi ọ̀rọ̀ rẹ̀ "" wọ́n ti pe àkíyèsí ilé iṣẹ́ to n se akoso eto ìbáraẹnisọ̀rọ̀ Nàìjíríà, sí ìpínu ilé iṣẹ́ MTN láti máa yọ nàira mẹ́rin láàrin ogún ìṣẹ́jú ààyá bí owo àtẹjisẹ́ si bánkì."""
Atẹjade kan ti ileesẹ to wa fọrọ ibaraẹnisọ̀rọ lorilẹede yii lo kede bẹẹ nilu Abuja .
"Atẹjade naa ni ""Mínísítà fún ìbáraẹnisọ̀rọ̀, ọmọwé Isa Ali Ibrahim Pantami kò mọ̀ nípa ìgbésẹ̀ yìí, ó sì ti pàsẹ fún àwọn to n moju to ijagaara eto ibanisọrọ ni Naijiria (NCC), láti ríi dáju pé ilé iṣẹ́ ìbánisọ̀rọ̀ MTN ṣẹ́wélé ìpinu rẹ̀, títí ti wọ́n yóò fi wá wi tẹnu wọn fún Minisità"""
USSD: A ti pàssẹ fún ilké iṣẹ́ MTN láti ma gùnlé ìpinnu wọ̀n
Oríṣun àwòrán, Others
Ọrọ owo ori gbigba ti gba ọna miran yọ bayii nitori owo ori tun ti gun igbesẹ fifi owo ransẹ lati ori ẹrọ ibaraẹnisọrọ.
Se ni awọn ọmọ Naijiria bẹrẹ si ni gba atẹjisẹ kan lati ileesẹ ibaraẹnisọrọ Kan, MTN lọjọ Satide pe, nibamu pẹlu adehun ti ileesẹ ibaraẹnisọrọ naa ati awọn banki ilẹ wa, oun yoo maa yọ owo ori lori awọn owo ti onibara kọọkan ba fi ransẹ.
Awọn ọmọ Naijiria naa tun salaye pe owo ori tawọn n san ti pọ ju, ti ko si si ẹni to mọ ohun ti wọn n fi se.
Oríṣun àwòrán, Others
@EVheeky loju opo rẹ n beere pe ki lo de ti banki oun, Zenith fi ni ki ileesẹ ibaraẹnisọrọ MTN maa tun gba owo lọwọ oun, se oun lo fi wọn han ara wọn ni?
@Oluwaroll1 naa n beere pe se ileesẹ́ MTN ati banki oun , GTB ti pawọpọ ni lati ba owo jẹ mọ awọn eeyan lọwọ? Koda, ohun ti owo ori yii wa ko tii ye oun.
@JasmineEsset naa n gbarata pe se a tun maa sanwo ori fun lilo ẹrọ ibaraẹnisọrọ lati fi owo ransẹ ni? Ki wa ni orilẹede Naijiria n da bayii?
@DoctorEmto, oun tiẹ sọ yanya pe banki Zenith ti n yọ naira mẹẹdogun bii owo ori ti oun ba fi owo ransẹ lati ori ẹrọ ibaraẹnisọrọ.
@tejumania tiẹ́ n pariwo ni pe ki loun se ti Ọ́lọrun fi da oun si orilẹede Naijiria? Awọn owo ori ti wọn n gba lọwọ ara ilu ti n pọ ju lai si ohunkohun ti wọn n fi se.
Davido: Àpètàn orukọ̀ ọmọ tuntun náà ní David Adedeji Ifeanyi Adeleke
Oríṣun àwòrán, @davidoofficial
Ayọ abara tintin. David Adeleke, ti gbogbo eeyan mọ si Davido ti kede pe, Oluwa ti fi ọmọkunrin kan lanti-lanti da oun ati aya oun, Chioma,  lọla.
Owurọ ọjọ Aiku ni Davido kede bẹẹ loju opo Instagram rẹ, to si ni Ọmọọba ti de, ile iwosan kan nilu London si ni Chioma bimọ naa si.
O wa pe orukọ ọmọ ọhun ni David Adedeji Ifeanyi Adeleke Jnr pẹlu afikun pe inu oun dun pupọ si iroyin ayọ naa.
"Davido ni ""Mo nifẹ aya mi pupọ, koda obinrin alagbara ni"", to si jẹ pe nigba ti awọn olorin to jẹ akẹẹgbẹ Davido n lọ sibi ami ẹyẹ fawọn olorin, Headies Award, yara igbẹbi ni Davido wa, to n rawọ rasẹ si Ọlọrun pe, ko sọ aya oun kalẹ layọ."
Oríṣun àwòrán, @davidoofficial
Chioma, afẹsọna Davido lo ti kọkọ kede loju opo Twitter rẹ nirọlẹ ana pe oun wa nile igbẹbi, ti ọpọ eeyan si ti n se adura fun pe yoo bi wẹrẹ.
Koda, oun naa tun ti kede loju opo Instagram rẹ pe Oluwa ti sọ oun layọ.
Wayi o, awọn ọmọ Naijiria ti n se jaginni yodo pẹlu ọba orin naa fun ayọ ọmọkunrin jojolo to baa lalejo naa, bi o tilẹ jẹ pe obinrin meji ọtọọtọ ti bi ọmọbinrin meji fun tẹlẹ.
Army: Ọkọ mẹ́sàn-án tó kún fún àpò ẹja la gbà lọ́wọ́ Boko Haram
Oríṣun àwòrán, @HQNigerianArmy
Ọgbọn kii tan laye, ka wa lọ sọrun ni awọn Boko Haram n fi iwalaaye wọn se, ti wọn si n da ọgbọn orisirisi lati mu ki igbe aye idẹrun wa fun wọn.
Gẹgẹ bi ileesẹ ologun ilẹ wa ti kede bayii, se ni awọn ọmọ ẹgbẹ Boko Haram n da ọgbọn lati maa se okoowo ẹja gbigbẹ, eyi ti wọn n ko wọle lati awọn orilẹede to mule ti orilẹede Naijiria.
Atẹjade kan ti ileesẹ ologun fisita ni ọwọ tẹ ọkan lara awọn adunkooko mọni yii , ẹni to jẹ pe isẹ to yan laayo n tiẹ ni lati maa gbe ẹja gbigbẹ wa sorilẹede yii lati orilẹede Lake Chad to mule ti wa.
Oríṣun àwòrán, @HQNigerianArmy
Ọgagun Aminu Illyasu, tii se agbẹnusọ fun ileesẹ ologun ilẹ wa, ninu atẹjade naa ni iwadi ti fihan pe owo ti awọn ọmọ ẹgbẹ Boko Haram ọhun ba ri nidi katakara ẹja gbigbẹ ni wọn n lo lati fi gbọ bukata ara wọn ati isẹ ibi ti wọn n se.
Oríṣun àwòrán, @HQNigerianArmy
Ere ti wọn ri nidi tita ẹja gbigbẹ ti wọn n ko wọle ni wsn n lo lati fi ra eroja ounjẹ, eso, oogun ti wọn n lo, awọn ohun eelo ojoojumọ ninu ile, ẹya ara ọkọ ati awọn ohun eelo miran to wulo fun isẹ apaniyan ti wọn rawọ le.
Ọgagun Illiyasu fikun pe lasiko ti awọn ologun n paraaro agbegbe Bukarti, nijọba ibilẹ Geidam nipinlẹ Yobe, ni ọwọ wọn tẹ ọkọ mẹsan kan to kun fun ẹja gbigbẹ, ti wọn si mu afurasi mejidinlogun si ahamọ, to fi mọ awakọ awọn Boko haram naa, agbero ọkọ, atọkọse wọn ati awsn asoju wọn lorisirisi ọna.
Oríṣun àwòrán, @HQNigerianArmy
Ikọ ọmọogun Naijiria ti kede pe ikọ Boko Haram ti fun ra wọn ko si idẹkun ti wọn dẹ silẹ fun ikọ ọmọogun Lafia Dole.
Ninu atẹjade kan ti Adari Iroyin fun ikọ ọmọogun Naijiria, Ọgagun Aminu Iliyasu fi lede ni, awọn agbesunmọmi Boko Haram meje lo ku ninu ado oloro to bu gbamu naa, leti ẹba ọna ti wọn fi dẹkun si, ti mẹjọ si farapa.
Ikọ ọmọogun Naijiria ni, awọn ti wọn sagbako ado iku naa n sa asala fun ẹmi wọn, lẹyin ti ikọ Lafia Dole da ina bo wọn ni agbeegbe Jakana-Mainok ni ipinlẹ Borno, ti wọn sa pamọ si.
Oríṣun àwòrán, @HQNigerianArmy
Boko Haram méje faragbá àdó olóró tí wọ́n fi sí ẹ̀bá ọ̀nà!
Ọkọ ayokẹle Toyota ti ikọ Boko Haram naa n lo lati sa kuro lagbeegbe naa lo gbina, lẹyin ti wọn gun ori ado oloro ti wọn fi dẹkun silẹ.
Bakan naa ni Ikọ ọmọogun Naijiria fikun wi pe, gbogbo eto ti to lati ri wi pe ko si ikọ Boko Haram mọ ni agbegbe naa.
Revolution Now: Iléejọ́ tún wọ́gilé gbígbé ₦50m owó àsansílẹ̀ ààbò kalẹ̀
Ileejọ giga tijọba apapọ to wa nilu Abuja tun ti tun ero rẹ pa lori awọn gbedeke to gbe kalẹ lori gbigba oniduro asaaju ẹgbẹ ajijagbara Revolution Now, Ọmọyẹle Soworẹ.
Nigba to n kede ilana tuntun fun gbigba oniduro Soworẹ lasiko ijoko ile ẹjọ naa lọjọ Aje, Adajọ Ijeoma Ojukwu kede pe o nira fun oun lati gbagbọ pe iru eeyan to ni akọsilẹ nla bii Soworẹ yii ko ni ẹnikẹni ti yoo gbe ọgọrun milọnu naira kalẹ fun gbigba oniduro rẹ.
Bẹẹ ba gbagbe, ileẹjọ giga ijọba apapọ naa lo ti kọkọ kede gbigba oniduro Soworẹ pẹlu ọgọrun miliọnu naira ati oniduro meji ti wọn ni ilegbe ati ilẹ nilu Abuja.
Amọ lati bii osu kan sẹyin, tile ẹjọ naa ti gba oniduro Soworẹpklu awọn gbedeke to rọ mọọ, Soworẹ ti lee tẹle awọn ilana to rọ mọ gbigba oniduro rẹ naa, to si wa lahamọ titi di akoko yii.
Nibi ijoko ile ẹjs loni ni adajọ ti wa se adinku awọn gbedeke naa, to si kede pe ki wọn san aadọta miliọnu naira dipo ọgọrun miliọnu naira tile ẹjọ naa beere tẹlẹ.
Bakan naa nile ẹjọ tun kede pe oun ti wọgile aadọta miliọnu naira owo asẹsilẹ fun aabo ti oun n beere lọwọ Soworẹ, kiwọn to lee gba oniduro rẹ.
Lori akọroyin ti wọn jọ mu oun ati Soworẹ si ahamọ lọjọ kannaa, Adajọ tun se adinku ilana gbigba oniduro tiẹ naa, lati aadọta miliọnu naira si ogun miliọnu naira.
Kogi Crisis: Abaribe ní ìpìlẹ̀ Nàíjíríà ń mì pẹ̀lú ìwà ọ̀yájú sí ofìn ní Kogi
Oríṣun àwòrán, @EkeleHaruna
Adajọ agba nipinlẹ Kogi, Adajọ Nadir Ajana ti bura fun Edward Onoja gẹgẹ bii igbakeji gomina tuntun fun ipinlẹ Kogi.
Igbesẹ yii waye lẹyin ti ile asofin ti se ayẹwo tan fun igbakeji gomina tuntun naa.
Lasiko ayẹyẹ ibura naa, olori ile asofin ni Kogi, Matthew Kolawole sapejuwe iyansipo Onoja gẹgẹ bii ere jijẹ olootọ ati olufọkansin si gomina lasiko to fi jẹ olori awọn osisẹ lọọfisi gomina.
O wa rọ igbakeji gomina tuntun naa lati maa tubọ tẹle oju ọna otitọ ati isẹ asekara eyi to mu de ipo giga ọhun.
Oríṣun àwòrán, @EkeleHaruna
Ọjọ Ẹti to kọja ni ile asofin ipinlẹ Kogi yọ Simon Achuba gẹgẹ bii igbakeji gomina nipinlẹ naa lẹyin ti igbimọ oluwadi to tanna wadi rẹ jabọ pe ko ni ẹsẹ kankan lọrun.
Wayi o, olori ọmọ ẹgbẹ oselu to kere julọ nile asofin agba ilẹ wa, Senatọ Eyinnaya Abaribe ti kesi aarẹ Muhammadu Buhari lati dasi ọna to lodi sofin ti wọn gba yọ igbakeji gomina nipinlẹ Kogi.
Oríṣun àwòrán, @EkeleHaruna
Atẹjade kan ti Abaribe fisita nilu Abuja ni eyi ti jẹyọ pẹlu afikun pe, niwọn igba tijọba ipinlẹ Kogi ti kuna lati daabo bo ofin ilẹ wa, o yẹ ki aarẹ Buhari da si ọrọ naa lai fi ti ẹgbẹ oselu se.
Abaribe ni pẹlu iwa ọyaju tile asofin ipinlẹ Kogi hu si ofin ilẹ wa naa, a jẹ pe ipilẹ orilẹede Naijiria n mi ree.
Ilé ẹjọ́ ní pásítọ̀ yóò fi ẹ̀wọ̀n jura bí kò bá gbé ṣọ́ọ̀ṣì aláriwo rẹ̀ kúrò ládúgbò
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ile ẹjọ Majisireeti kan ni ilu Nnewi ti paṣẹ ki wọn ti ile ijọsin igbalode kan pa nitori ariwo.
Ileeṣẹ ilera ayika ati ijsba ibilẹ Ariwa Nnewi, Nnewi North lo pe awọn adari ileejọsin naa lẹjọ ti wọn si fun wọn ni ọjọ mẹwa lati fi gbe ile ijọsin wọn kuro.
Ẹsun ti wọn fi kan  ile ijọsin naa ni pe o gbe awọn ẹrọ gboungboun ati amohundungbẹmu si iwaju ile ijssin rẹ eleyii ti wọn ni o yi soke la-la-la lati fi da araalu laamu lọsan ati loru.
Awọn olupẹljọ ni ohun ti ijọ naa n ṣe lewu fun ilera ọmọniyan, o si tako ofin ilera ipinlẹ Anambra tọdun 2006.
Ninu idajs to gbe kalẹ, Adajọ Emekwe AC paṣẹ fun ileeṣẹ ilera ayika ati ijọba ibilẹ nnwi North lati ls ti ile ẹjs naa pa ki wọn si so ileejọin naa lọwọkọ lori ṣiṣe iṣẹ isin nibẹ.
Bakan naa ni il ẹjs paṣẹ pe bi ileejọsin naa ko ba gbe ile ijọsin rẹ kuro laarin ọjọ mẹwaa, yoo fi ẹwọn ọdun kan jora
Seyi Makinde: Pálí Ìṣáná la fi ń bẹ ẹlòmìí l'Oyo kí wọ́n tó ṣe ètò ìlera ọ̀fẹ́ - Kọmíṣánà
Oríṣun àwòrán, @seyiamakinde
Kọmiṣana fun eto ilera ni ipinlẹ Oyo labẹ ijọba gomina Seyi Makinde, Bashir Bello jẹ ko di mimọ pe kii ṣe pe ile iṣẹ to n ri si eto ilera ko ni eto iranwọ nilẹ.
Bashir ni arabinrin yii kan ṣaa ṣe kongẹ alaanu ninu gomina Seyi Makinde ni tori kii ṣe gbogbo eniyan lo lee duro gbọ iru ọrọ bẹẹ.
Lọjọ aje ni Gomina ipinlẹ Ọyọ, Onimọ ẹrọ Seyi Makinde nawọ aanu si abiyamọ yii atawọn alaisan mẹta miiran ti wọn ni ipenija owo lati tọju ara wọn nile iwosan to wa ni Jericho nilu Ibadan.
Gomina Makinde se alabapade awọn alaisan naa lasiko to lọ se abẹwo sile iwosan naa lati mọ ibi ti isẹ de duro nibẹ.
A gbọ pe obinrin naa ti orukọ rẹ n jẹ Tolulọpẹ Thompson lo sadede lọ sa ba gomina Makinde ni kete to foju kan-an nile iwosan ọhun, lasiko ti gomina n jade sita.
Nigba ti BBC Yoruba beere pe ṣe ile iṣẹ to n ri si eto ilera ko ni eto kankan to n ran araalu lọwọ ni, Kọmiṣana ni,
Ẹ ṣaa mọ bi awọn eeyan wa ṣe ri, bẹẹ ba fẹ sọ fun awọn eeyan alawọdudu pe ki wọn wa soriire, ẹẹ tun fẹẹ ṣe aajo si i.
Kọmiṣana ṣalaye pe oniruuru ni eto ti ijọba gomina Seyi Makinde ti gbe kalẹ lati ran eto ilera awọn araalu lọwọ.
Eto ilera alabọde, eto adojutofo ati ọpọlọpọ mii ṣugbọn iha ti ọpọ araalu n kọ si awn eto yii ni ko ba a mu.
Arabinrin naa ko ṣeto ilera ti ijọba tori ọpọ awọn ti wọn ba ni ki wọn wa seto ilera alabọde yii ko ni imọ kikun nipa rẹ; bi wọn ba tilẹ ni imọ kikun, wọn o ki n ya si i.
"Kọmiṣana ni ""afi ki ẹ tun maa fi tori Ọlọrun bẹ awọn araalu mii""."
O ṣalaye pe awọn iyalọmọ mii gan ko ki n lọ gba abẹrẹ to yẹ ki wọ́n gba fun ọmọ wọn pe afi igba ti wahala ba kan ilẹkun ni ede to maa n ye ẹlomiran.
O ni gbogbo eto lo ti wa nilẹ lati mu nkan dẹrun ṣugbọn lasiko to ba rọ wọn lọrun ni wọn maa n fẹ ṣe nkan.
Ni ti arabinrin Tolulope atawọn mii to ri owo iranwọ́ ẹgbẹrun lọna aadọta naira gba, o ni wọn kan ṣe kongẹ ire ni tori iru eniyan ti gomina Seyi makinde jẹ lawujọ.
Ẹwẹ, o ni eto ilanilọyẹ fun ilera ni o tun yẹ ki awọn fi kun ohun tawọn ti n ṣe latẹyin wa ki awọn eeyan le mọ pe eto ilera ọfẹ ti wọn  n pese, fun anfani wọn ni.
Kọmiṣana fi iha ti awọn eeyan n kọ si eto ilera ọfẹ laye ode oni we bii ọgọrin ọdun o le sẹyin lasiko ti oun wa ni kekere ti wọn maa n sare si i. Eyi lo jẹ ko sọ wi pe ọ̀tọ ni keeyan laju si iru eto iranwọ ijọba bayii, ọtọ si ni kiru ẹni bẹẹ ni laakaye kikun nipa rẹ.
Thompson lo kigbe si gomina, to si n rọ pe ko ba oun san owo ile iwosan ti wọn kọ fun eto ayẹwo ara ọmọ oun (scan), ki awọn dokita lee mọ oun to n se e.
Oríṣun àwòrán, @OEOlatunde
Nigba to n fidi isẹlẹ naa mulẹ fun BBC Yoruba, amugbalẹgbẹ fun gomina ipinlẹ Ọyọ feto iroyin, Taiwo Adisa salaye pe lootọ ni gomina Makinde fun obinrin kan to tọ gomina wa pe ọmọ ẹyin oun ti fẹ ku, ni ẹgbẹrun lọna aadọta naira.
Adisa ni ọmọ to wa lẹyin obinrin naa lo ti rọ wọjọ sẹyin rẹ, ti ẹnikẹni ko si mọ boya ọmọ naa ti daku, ti awọn ẹsọ gomina si n le obinrin naa sẹyin, amọ ti gomina ni ki wọn fi silẹ, ki awọn gbọ ohun to fẹ sọ.
O ni sadede ni obinrin ọhun kunlẹ wọ, to si n rawọ-rasẹ si gomina Makinde pe ko gba oun kalẹ, ki ọmọ oun ma baa ku, nitori agbara ko si fun lati sanwo fun ayẹwo naa tile iwosan ni ki oun lọ se.
Oríṣun àwòrán, @OfficialSeyiMakinde
Amugbalẹgbẹ gomina feto iroyin fikun pe lọgan ni gomina Makinde tẹwọgba iwe ile iwosan to mu lọwọ, to si fun aya Thompson ni ẹgbẹrun lsna aadọta naira, eyi to ju iye owo to beere lọ.
Ko pẹ ti gomina se eyi tan, to fẹ wọ yara ayẹwo laboratory ni awọn alaisan mẹta miran tun yọju siwaju gomina, tawọn naa si n beere pe ko ran awọn lọwọ lati san owo iwosan awọn.
Eyi lo mu ki gomina Makinde pasẹ pe ki wọn tun fun ikọọkan awọn alaisan mẹtẹẹta yii ni ẹgbẹrun lọna aadọta naira, gẹgẹ bo se fun Tolulọpẹ Thompson saaju.
Oríṣun àwòrán, @OfficialSeyiMakinde
Bakan naa, gomina ipinlẹ Ọyọ, Onimọ ẹrọ Seyi Makinde tun ti fọwọ mejeeji sọya fun awọn olugbe ipinlẹ Ọyọ pe, oun ko ni na owo wọn ni inakuna, gbogbo ohun ti ohun ba fi owo wọn se, ni wsn yoo fi oju ri.
Gomina Makinde jẹjẹ yii lọjọ Aje lasiko to n se ayẹwo awọn isẹ agbase mẹta nilu Ibadan, tii se olu ilu ipinlẹ Ọyọ.
Gomina Makinde lo sabẹwo gareji ọkọ to wa ni Sango, ile iwosan Jericho ati ile igbẹbi tuntun to wa ladugbo Jericho bakan naa, to si koro oju si ipo tawọn dukia ijọba ọhun wa, paapa awọn ilẹ ati ọpọ ohun eelo ti wọn ti pa ti.
Gomina ni asa ti ko dara ni ki wọn maa na owo ilu ninakuna lori awọn isẹ agbase kan, ki wọn si pada wa pa isẹ ọhun ti nigba ti isẹ naa ba de idaji, lai naani owo tuulu ti wọn ti na le lori.
Gomina Seyi Makinde n wo alaisan lori ibusun
Oríṣun àwòrán, @OfficialSeyiMakinde
Makinde ni iru asa yii lo wọpọ lasiko ijọba to kogba wọle nipinlẹ Ọyọ, to si tun seleri fawọn eeyan ipinlẹ naa pe ijọba oun yoo ri daju pe wọn fi oju ara wọn ri ohun ti oun ba fi owo ilu se.
Makinde wa pasẹ fun oludari ileesẹ to n sakoso eto irinna loju popo nipinlẹ Ọyọ, Ọmọwe Akin Fagbemi, lati gbe olu ileesẹ rẹ lọ si gareji ọkọ atijọ to wa ni Sango, pẹlu ileri pe oun yoo pese awọn ohun elo to yẹ sibẹ feto idẹrun isẹ wọn.
Bakan naa ni gomina Makinde tun seleri nile iwosan mejeeji to wa ni Jericho lati pese awọn ohun eelo iwosan igbalode sawọn ibudo mejeeji naa fun agbelarugẹ eto ilera to peye.
Ọ̀fẹ́ ni 'Bail': Ajulo ní ó lòdì sófin láti sanwóo béèlì fáwọn ọlọ́pàá, ẹ sọ́ra!
Oríṣun àwòrán, Others
Igbakejì Ọ̀gá Àgbà Ọlópàá ní ìlú Eko, Lawal Shehu ti kìlọ̀ fún àwọn ọlọ̀paa lati sọra fun gbigba beeli lọwọ awọn ti wọ́n fẹ̀sun kan.
Agbẹjọro ati ajafẹtọ ọmọniyan, Kayode Ajulo ti ni awọn ọdaran lo ma n san owo beeli fun ọlọpaa, ẹnikẹni ti o ba si lee fi ogun rẹ gbari pe oun ko dẹsẹ, ko yẹ ko sanwo kankan.
Ajulọ sọ ọrọ yii lasiko to n fesi si ọrọ ti Igbakeji Ọga Agba ọlọpaa ni ilu Eko, Lawal Shehu sọ, eyi to fi n kilọ fun awọn ọlọpaa, pe ki wọn sọra fun gbigba owo fun beeli lọwọ awọn ti wọn fẹsun kan.
O salaye pe, gbigba beeli afurasi tumọ si pe eeyan kan wa gba oniduro ẹni ti wọn fẹsun kan, ti yoo si jẹjẹ pe afurasi naa ko ni salọ.
Bakan naa lo ni beeli gbigba wa fun awọn eniyan ti wọn wa lahamọ agọ ọlọpaa, amọ ti wọn n beere fun itusilẹ lati lọ si ile pẹlu oniduro, lai ti foju ba ile ẹjọ.
Oríṣun àwòrán, @PoliceNG
Agbẹjọrọ naa ni ẹni ti ko ba daran lasẹ lati beere fun beeli lai san eepinni, pẹlu afikun pe ọmọ Naijiria lẹtọ lati fi ẹjọ ọlọpaa sun, ti wọn ba gba owo fun beeli lọwọ wọn.
Kayode Ajulọ fikun wi pe, o seese ki ẹni ti ile ejọ ko ti dajọ fun lati lọ si ẹwọn,  beere beeli pe ki wọn fi oun silẹ ki oun lo sile.
Agbẹjọro ati ajafẹtọ ọmọniyan naa ni ki awọn ọmọ Naijiria mase duro, ki ọlọpaa gbe wọn lọ sile ẹjọ, ki wọn to beere fun beeli.
Botswana: Ìdí tí erin àti òkúta Dáyámọ́ǹdì yóò fi leè sọ olúborí èsì ètò ìdìbò ààrẹ
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Orilẹede Botswana yoo ṣeto idibo apapọ rẹ lọjọ kẹtalelogun oṣu kẹwa, bẹẹni eto ifọrọwerọ ti BBC World Questions debate gbe kalẹ ti ṣe awari rẹ ni ilu Garborone pe ipa diẹ kọ ni okuta iyebiye Dayamọndi ati erin lee ko ninu esi idibo naa.
Ẹgbẹ oṣelu Botswana Democratic Party, (BDP) lo ti n bori gbogbo idibo to n waye lorilẹede Botswana lati igba ti wọn ti gba ominira lọdun 1966, amọṣa lọdun yii, o ṣeeṣe ki  ọrọ ba ibomiran yọ fun wọn.
Mẹta ninu awọn ẹgbẹ alatako lo ti ko ara wọn jọ labẹ aburada ẹgbẹ Umbrella for Democratic Change (UDC)
Eto ipolongo ti wọn gbe kalẹ ni ileri ipese ẹgbẹrun lọna ọgọrun iṣẹ lorilẹede naa bi wọn ba wọle. Ni orilẹede to jẹ pe bii ida ogun ninu ọgọrun awọn eeyan rẹ ni ko ni iṣẹ lọwọ ti ọpọ to n ri iṣẹ ṣe gan ko lee fi ẹdọ lori oronro, ileri yii jẹ eyi to fa oju ọpọlọpọ oludibo mọra.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Igbakeji  Aarẹ ẹgbẹ oṣelu UDC, Dumelang Saleshando ṣalaye fun BBC debate pe 'o da lori eto ọrọ aje eyi to yọ ọwọ awọn araalu sẹyin.'
Bi ẹ ba lọ si ẹka iṣẹ akanṣe, awọn ọmọ orilẹede China lo gba ibẹ. Bi ẹ ba lọ si ẹka karakata, awọn ọmọ ilẹ Aṣia lo n jaye ọba nibẹ...ko si ẹka ọrọ aje kankan lorilẹede yii ti awọn ọmọ orilẹede Botswana ti n moke.
Orilẹede ti a kọ sori okuta iyebiye Dayamọndi
Orilẹede Botswana ni ọpọ maa n pe ni itan aṣeyọri ilẹ Afirika - o gba ominira rẹ lai ta ẹjẹ silẹ gẹgẹ bi ọpọ awọn orilẹede to mule tii ṣe ṣe, ko fi igba kan ri ni wahala ogun abẹle bẹẹni eto idibo rẹ kii ni rogbodiyan ninu rara.
Pupọ ọrọ orilẹede Botswana lo da lori okuta iyebiye Dayamọndi. Bi o tilẹ jẹ pe orilẹede Russia n pese okuta iyebiye yii ju Botswana lọ, sibẹ ibudo iwakusa mẹrin lorilẹede Botswana lo n pese okuta iyebiye Dayamọndi to dara julọ lagbaye.
Biliọnu mẹta abọ dọla owo ilẹ Amẹrika, $3.5bn ni okuta iyebiye yii ko wọ apo ijọba orilẹede naa lọdun to kọja nikan. Eyi si ja si ida ogoji ninu ọgọrun eto ọrọ aje ilẹ naa.
Owo yii ti kọ opopona, ileewe ati ileewosan ṣugbọn lẹyin aadọta ọdun, ọpọ eeyan lo n woye pe owo to yẹ ki o maa wọle yẹ ko pọ ju eyi lọ.
Ni ọdun yii, iroyin iwa ijẹkujẹ gba ode kan lori ajọṣepọ to wa laarin ijọba orilẹede naa ati De Beers, ileeṣe kan to n wa kusa okuta Dayamọndi lagbaye.
Minisita fun ibaraẹnisọrọ ati irinajo, Dorcas Makgato ṣalaye lori iha ti ijọba orilẹede naa kọ si ijiroro idunadura pẹlu ileeṣẹ De beers.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Amọṣa, Ọgbẹni Saleshando ko gba eyi gbọ. O ni ida marundinlọgọrun ninu ọgọrun awọn eeyan orilẹede naa ni ko fi oju wọn ri okuta dayamọndi ri. O ni otitọ ibẹ ni pe nṣe ni okuta iyebiye Dayamọndi naa n pese iṣẹ fun awọn orilẹede okeere ti awọn eeyan orilẹede naa kan joye awakusa lasan.
Orilẹede Botswana ni yoo fẹẹ jẹ orilẹede kan ṣoṣo lagbaye ti ọrọ erin yoo lagbara lori eto idibo.
Bi o tilẹ jẹ pe iye awọn eeyan rẹ ko pọ, iye erin to wa lorilẹede Botswana lo pọ julọ nilẹ Afirika. Eyi si n fa wahala laarin eeyan atawọn ẹranko lojojujmọ nibẹ. Labẹ aarẹ ana, Ian Khama, gba oriyin fun eto idaabo bo awọn ẹranko fun orilẹede Botswana.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Kaakiri gbogbo agbaye ni wọn ti n gboriyin fun ijọba rẹ fun igbesẹ rẹ lati gbogun ti pipa awọn ẹranko lọna ti ko ba ofin mu.
Aarẹ Mokgweetsi Masisi ko dabi ẹni to fara si ohun ti awujọ agbaje sọ nipa aṣiwaju rẹ.
O woye pe bi o ba wu awọn ilẹ Gẹẹsi, ki wọn gbiyanju ati maa ba awọn erin orilẹede Botswana gbe bi wọn ba ni ifẹ wọn bẹẹ.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Nibayii, aarẹ Mokgweetsi Masisi ti gbe ofin to de pipa erin lọna ti ko tọ kuro eyi si wa da oniruuru awuyewuye silẹ. Amọṣa o dabi ẹni pe igbesẹ yii dun mọ ọpọlọpọ awọn araalu ninu nitori nigba ti BBC beere lọwọ awọn eeyan nigboro, wọn ni awọn faramọ ọ.
Kogi Fraca: Àwọn ẹni àìrí kan ló já iná ilé mi ní ilé Ijọba.
Oríṣun àwòrán, @Achuba
Igbakeji Gomina Ipinle Kogi
Ẹkọ ko ṣoju mimu fun ẹni ti o jẹ igbakeji gomina ipinlẹ Kogi, Simon Achuba nigba ti wọn gba awọn ọlọọpa kuro lẹyin rẹ.
Achuba ni o ti ni ede aiyede pẹlu gomina ipinlẹ naa lati bii oṣu meji sẹyin ki awọn aṣofin Ile Igbimọ Ipinlẹ naa to yọ bii ẹni yọ jiga.
Ninu ọrọ rẹ, Achuba ṣalaye pe gbogbo ọlọpaa to yẹ ki o maa ṣọ oun ni wọn ti gba kuro lẹyin rẹ ti wọn si ju u si korofo.
Achuba wi pe, lẹyin eyi ni wọn tun yọ waya ti o gbe ina wọle si ile oun ti wọn si sọ gbogbo ile si okunkun.
O tẹsiwaju ninu ọrọ to ba awọn akọroyin sọ pe, lẹyin ti wọn ja ina naa tan, ni oun tun tẹsiwaju lati tan ẹrọ amuna wa.
Ṣugbọn awọn kan bii Ọlọpaa tun mu ẹnikan wa lati ge waya ti o mu ina wa si inu ẹrọ amunatan naa ti wọn si wa sọ oun si inu okunkun patapata.
O wa n ke gbajare sita bayii pe, ẹmi oun ko de rara ti ewu n la si rọ mọ iru iwa bayii.
O wa ni ohun ti wọn ṣe yii lodi si ofin ti o si jẹ ohun itiju patapata si ipinlẹ Kogi ati orilẹede yii lapapọ ti o si le doju ti eto Ijọba awa arawa.
Ni bayii, o ti wa sọ pe oun yoo gba ile ẹjọ lọ lati beere fun idajọ ododo lori awọn iwa tani yoo mumi ti Gomina n hu.
Ni bayii, ẹni ti o jẹ igbakeji tuntun fun Gomina naa ni Edward Onoja ti wọn si ti bura wọle fun gẹgẹ bi ẹni ti yoo jẹ olukopa pẹlu gomina ninu idibo to n bọ.
Ẹ̀kún Omi: Ìgbáye-gbádún àrá Abeokuta já si òfò fáwọn ará Eko
Bí ìgbáyegbádún àrá Abeokuta ṣe já si òfò ará Eko
Adagun omi Ọyan tí wọ́n ṣí ni ìlú Abeokuta, tií sọ ọ̀pọ̀ ènìyàn di aláìnílé lórí ní ìpiínlẹ̀ Eko, tí wọ̀n si ti di ẹdún àrinlẹ, ọ̀pọ̀ ní sọ́ọ̀bù àti ilé ìjọsìn wọ́n ti di èrò abẹ́ omi.
Ọ̀pọ̀ ẹ̀mi lo ti sọnu nítori ìṣẹ̀lẹ̀ náà, àwọn olùgbé Ajegunle àti Itolowo ní ijoba ibile Ikosi Isheri àti Agboyi-Ketu tilẹ̀ ní ọ̀pọ̀ ẹ̀mí lo ti sòfò nítori ìsẹ̀lẹ̀ náà, tí omí si gbé àwọn míràn lọ.
Nítori ẹ̀kún omí náà, ìyá kan àti ọmọ rẹ̀ kan kú nígbà ti ọkọ̀ ojú omí tó n gbé wọ́n lọ dojúde, lẹ́yìn ọjọ́ kẹta si ni wọ́n to rí òkú ìyá àti ọmọ náà.
Ní àgbègbè Unity Estate Owode Onirin bákan náà, obinrin kan ti ẹnikẹni ko ti mọ orúkọ rẹ̀ ń gbìyànjú, lati wọ ọkọ oju omí lái mọ pé ejo ti wọ́ inu ọkọ náà, ti ejo naa si sàn-an, oró ejo yìí lo pa arabìnrin náà.
Ẹnikan lára olùgbé àdúgbò naa sàlàyé pé ọ̀pọ̀ àwọn olùgbé àdúgbo ọhun ni wọ́n ti sá nile wọ́n, ti wọ́n si n bẹ ìjọba láti báwọ́n ṣe oju àgbàrá, ki ẹ̀kún omi le dínku.
Afolabi ni adagun odo ti wọn si ni Abeokuta lo sọ ọ̀pọ̀ dí ẹdun arinlẹ̀, bí àwọn ènìyàn ṣe ń ko kuro nile wọ́n, ní iṣẹ́ òòjọ tí di apati, ti ilé ìwé ko si ṣe lọ mọ fún àwọn ọmọ.
Bí ìgbáyegbádún àrá Abeokuta ṣe já si òfò ará Eko
Adari Ogun-Osun Rivers Basin, Femi Dokunmu nínú ọ̀rọ̀ rẹ̀ sàlàyé pé, bó tilẹ̀ jẹ́ pé lóòtọ́ ni àwọn ṣí adagun odo Oyan to ti ku jú bo se yẹ lọ nitori òjò àrọ̀ọ̀rọ̀ dá, síbẹ̀ ìgbésẹ̀ to yẹ ni àwọn ti gbé.
Dokunmu ní ojuse adagun odo ọhun ni láti dẹkun ẹkun omí àti ki àwọn odo ma kun akunfaya sùgbọ́n ojo ọdun yìí ti pọju lo fá awọn ijamba yii.
O ni àsìkò ẹẹrun ní àwọn máa n si omi náà tẹ́lẹ̀ ki òjò míràn to dé, èyí ti o si ti n ran wọ́n lọ́wọ́ ko to di àsìkò yìí.
Dangote: Ẹ̀ yin ọmọ Nàíjíríà, ẹ máṣe sọ ìrètí nù nípa ilẹ̀ wa
Oríṣun àwòrán, @AlikoDANGOTE
Aliko Dangote, tii se ẹni to lowo julọ nilẹ Afirika ti kede pe ko ni su oun lati maa mu adinkun ba isẹ ati osi, ki oun si pin ọrọ oun kaakiri lati ipasẹ idokowo ti oun n se.
Dangote kede bẹẹ nigba to n fesi si osuba nla ti ẹni to jawe olubori ninu idije tileesẹ Dangote to n pese simẹnti se fawọn onibara rẹ nipinlẹ Ondo ati Delta.
Dangote, ẹni to rọ awọn ọmọ Naijiria lati mase sọ ireti ti wọn ni ninu orilẹede yii nu nitori pe ọla si maa dara, tun ni ohun ayọ lo maa n jẹ fun oun lati ran awọn alaini lọwọ.
Bakan naa lo salaye pe oun mọọmọ maa dokowo kaakiri nitori ifẹ ti oun ni lati maa fi ọwọ kan awọn ti ko ri jajẹ lawujọ, ki oun si mu agbega ba igbe aye ọmọ Naijiria kọọkan.
O fikun pe ohun to mu ki idije ti ileesẹ simẹnti ohun se ni irufẹ ẹbun ti awọn onibara n jẹ, nitori afojusun ileesẹ naa ni lati ro onibara wọn lagbara latipasẹ idije ọhun.
Oríṣun àwòrán, @AlikoDANGOTE
Ninu idije tileesẹ aposimẹnti Dangote se naa, ẹnikan to ti jẹ Kanselọ ri nijọba ibilẹ kan nilu Akurẹ, to ti wa di ẹni to n yọ bulọọku ile bayii lo jẹ ẹbun akọkọ.
Lara awọn ẹbun ti awọn onibara si jẹ ni ọkọ ayọkẹlẹ, kẹkẹ ẹlẹsẹ mẹta, ati ọkada, eyi ti yoo mu ki ọrọ aje awọn onibara Dangote ru gọgọ si, ti wọn yoo si tun ni anfaani lati dokowo ni ọna miran, ti owo yoo si tun maa wọle fun wọn.
Ondo Kidnap: Géńdé agbébọn jí adájọ́ gbé lọ ní ìpínlẹ̀ Ondo
Oríṣun àwòrán, @HQNigerianArmy
Iroyin kan to n tẹ wa lọwọ ni yajoyajo ti ni awọn eeyan kan ti wọn fura si bii ajinigbe ti ji adajọ ile ẹjọ giga ijọba apapọ kan gbe lọ nilu Akurẹ.
Adajọ naa, ti wọn pe orukọ rẹ ni Abdul Jogo la gbọ pe wọn ji gbe lọ pẹlu awakọ rẹ loju ọna Ibilo si Isua de Akoko, leti aala ilẹ ipinlẹ Ondo si Edo.
Iroyin naa ni adajọ Abdul Dogo lo n bọ lati ilu Abuja nigba ti awọn ajinigbe naa da lọna, ti wọn si ji gbe lọ.
Awọn agbẹjọro ati awọn osisẹ ileẹjọ to ti yẹ ki adajọ joko gbọ ẹjọ laarọ oni, lo fidi isẹlẹ naa mulẹ pe awọn ajinigbe ti ji adajọ lọ.
BBC Yoruba tiraka lati gbọ tẹnu osisẹ alarina fun ileesẹ ọlọpa nipinlẹ Ondo, Femi Joseph, ko lee fidi isẹlẹ naa mulẹ, amọ ko tii gbe ipe wa lori aago.
Iroyin kan ti ko fidi mulẹ si ti n tan kaakiri pe awọn ajinigbe naa ti n beere aadọta miliọnu naira ki wọn to fi silẹ.
A ma mu ẹkunrẹrẹ iroyin naa wa fun yin.
Ofada Rice: kíni ẹ̀yin gbádùn nínú ìrẹsì ọ̀fadà?
Ibadan Drivers Clash: Àjọ OYRTMA sọ ohun tó fa wàhálà láàrín àwọn awakọ̀
Oríṣun àwòrán, Tajudeen Olajide
Awọn awakọ Micra
Ajọ to n ri si igbokegbodo oju popo nipinlẹ Oyo, OYRTMA ti sọ pe, aitẹle ofin awọn awakọ lo ṣokunfa rogbodiyan to waye laarin ajọ naa ati awọn awakọ lagbegbe Sango, nilu Ibadan.
Adeoye Ayoade to jẹ adari ajọ ọhun lo sọ ọrọ naa ninu ifọrọwerọ pelu BBC Yoruba.
O sọ pe ajọ OYRTMA ti gbiyanju lọpọ igba lati ri i pe, adinku de ba sunkẹrẹ fakẹrẹ ọkọ lopopona Sango-Eleyele, Sango-Mokola ati Sango-Ojoo.
Adeoye ni rogbodiyan bẹ silẹ lẹyin ti awọn awakọ kan kọ ki ajọ ọhun fi ọwọ ofin mu wọn, lẹyin ti wọn ru ofin oju opopona leyi to n fa sunkẹrẹ fakẹrẹ ọkọ lagbegbe ọhun.
Adeoye ṣalaye pe awọn oṣiṣẹ OYRTMA ni ki awọn awakọ ọhun kuro ni ibi ti wọn wa tẹlẹ lọ si ibomiran, ki ọna lee ja gaara, ṣugbọn wọn kọ'ti ikun si aṣẹ ọhun.
"O ni gbogbo akitiyan ajọ naa lati ko awọn awakọ ""Micra"" kuro ni ibudokọ ti wọn ti n ko ero ki ọna ọhun le ja gaara lo ja si pabo."
Oríṣun àwòrán, @ibcityannouncer
O tẹsiwaju pe, ọpọ awọn  oṣiṣẹ OYRTMA lo farapa nibi iṣẹlẹ ọhun.
Alukoro ajọ ọlọpaa ipinlẹ Ọyọ, Fadeyi Oluwagbenga fi idi ọrọ naa mulẹ.
O ṣalaye pe lootọ ni ajọ OYRTMA fi ofin mu ọkọ meji lati fi fa awọn awakọ yoku leti ki wahala to bẹ silẹ
Oluwagbenga ni ajọ ọlọpa da si awuyewuye ọhun, ṣugbọn ko si họhuhọhu kankan laarin awọn ọlọpaa ati OYTMA.
Gomina ipinlẹ ipinlẹ Ọyọ, amojuẹrọ Seyi Makinde si ti da si ọrọ naa lọna lati yanju rẹ.
Òwe: Kí ni ìtumọ̀ òwe ikú tó ń pa ojúgbà ẹni?
Sex for Grades: Fasiti Kaduna ni ki olùkọ́ lọ rọọ́kún nílé
Oríṣun àwòrán, @kadunauniv
Sex for Grades: Fasiti Kaduna ni ki olùkọ́ lọ rọọ́kún nílé
Kete ti iroyin yii jade ni awọn alaṣẹ ile ẹkọ giga fasiti Kaduna ti kede pe ki olukọ ti wọn fi ẹsun naa kan lọ rọọkun nile.
Omowe Tukur Abdulkadir to jẹ igbakeji aarẹ ẹka to n ṣamojuto ọrọ awọn akẹkọọ ni fasiti Kaduna lo ṣiṣọ loju ọrọ naa.
O ni bi ọmọbinrin yii (ti wọn fi orukọ bo laṣiri) ṣe ti rirnirn ijajangbara abo kuro lọwọ awọn olukọ to n halẹ mọ awọn akẹkọọ ni iwadii ti bẹrẹ.
Omobinrin yii fẹsun kan olukọ yii pe o filọkulọ lọ ohun ni eyi ti awọn alaṣẹ fasiti Kaduna dẹ ti ni ko lọ rọọkun nile titi iwadii a fi pari.
Nibi ipade igbimọ alabẹṣekele ti KASU ṣe ni wọn ti ni ki Ogbeni Bala Umar ti ọpọ awọn akẹkọọ n pe ni AB Umar lọ rọọ kun nile.
Omobinrin yii fẹsun kan Umar pe wọn le Umar ni fasiti Ahmadu Bellu (ABU) ni Zaria nitori pe o n fi ilọkulọ lọ awọn akẹkọọbinrin ni eyi to wa ya oun lẹnu pe fasiti Kaduna gbaa siẹẹ.
Ojọgbọn Abdulahi Ashafa to jẹ igbakeji ọga agba ile iwe KASU lo ṣe alaga igbimọ to pe ipadepajawiri naa ni Kaduna.
Ogun flood: ọ̀ps àwọn olùgbé agbegbe yii ti fi iṣẹ́ sílẹ̀ nítorí wọn kò lè jáde
Abdulahi ni KASU ko ni faaye gba ki olukọ maa dunkooko mọ akẹkọọ rara.
Lẹyin ti fidio BBC jade lori awọn olukọ fasiti Eko ti wọn n huwa buruku yii ni ọmọbinrin naa fi soju opo twitter pe Umar ti huwa buruku yii si oun ri ni fasiti ABU.
Ashafa ni bo tilẹ jẹ pe iṣẹlẹ yii ko ṣẹlẹ ni KASU, o di dandan ki KASU gbe igbesẹ to yẹ ki ọkan awọn obi ati alagbatọ awọn akẹkọọ le balẹ.
Russia-Africa summit: Wo àdéhùn méje tí Buhari ṣe pẹ̀lú ilẹ̀ Russia
Oríṣun àwòrán, NIGERIA PRESIDENCY
Orílẹ̀-èdè mẹ́rindínláàdọ́ta ni wọ́n wà ní ibi ìpàdé ìjíròrò láàrin orílẹ̀éde Afirika àti orílẹ̀èdè Russia.
Aarẹ orilẹ-ede Naijiria, Muhammadu Buhari wa lara orilẹ-ede mẹrindinlaadọta ti wọn wa ni ibi ipade ijiroro laarin orilẹ-ede to wa ni Afirika ati Russia.
Buhari lasiko to n ba Aare orilẹ-ede Russia, Vladmir Putin sọrọ, pinnu lati rii wi pe ibasepọ to dan mọran wa laarin orilẹ-ede mejeeji.
Oríṣun àwòrán, NIGERIA PRESIDENCY
Aarẹ mejeeji pinnu lati ri wi pe wọn pari awọn akanṣe ti wọn ti bẹrẹ lorilẹ-ede Naijiria paapaa eleyii to niiṣe pẹlu ẹka epo rọọbi ni Naijiria.
Ọrọ karakata ati idokowo, eto aabo ati iranwọ fun ẹka ọmọogun orilẹ-ede Naijiria.
Wo adehun meje ti Buhari se pelu ilẹ Russia
Jumọkẹ Odetola ṣe ọjọ́ ìbí, Wumi Toriola bímọ,  Ṣé ẹ fẹ́ tẹ̀lẹ́ Funkẹ Akindele lọ si Dubai?
Kò sí àrùn 'Monkey Pox' ní Naìjiria- NCDC
Ìdí tí a ṣe yọ ọwọ́ Naira Marley kúrò láwo Headies Award ọdún yìí rèé - HipTV
'O ṣójú mí kóró bí wọ́n ṣé fí àdó olóró pa Dele Giwa lọdún 1986'
Òwe: Kí ni ìtumọ̀ òwe ikú tó ń pa ojúgbà ẹni?
Kunle Afod: Ohun mẹ́wàá tó yẹ́ kí o mọ̀ nípa Kunle Afod ti Yollywood
Oríṣun àwòrán, INSTAGRAM
Gbajúgbajà Òsèré Yoruba, Kunle Afod ti kópa nínú fíímù bíi Nkan agba, Odi ade, Ofin kokanla, Pitan ati Orindola.
Ọjọ Kẹrinlelogun, Osu Kẹwaa, ọdun 1973 ni wọn bi gbajugbaja osere Nollywood, Kunle Afod ni ilu Eko, amọ ipinlẹ Oyo ni wọn ti bi awọn obi rẹ.
Ọkunrin ilumọọka naa jẹ ẹni to mọ tinu tẹyin sisẹ ere agbelewo ni ẹka amuludun lorilẹ-ede Naijiria.
Arakunrin Afod jẹ ọkan lara awọn oṣere ti ajé ba ṣọrẹ. o n dari ere, o tun n ya aworan pẹlu.
Oríṣun àwòrán, INSTAGRAM
Ohun mii to yẹ ko mọ nipa Kunle Afod
Jumọkẹ Odetola ṣe ọjọ́ ìbí, Wumi Toriola bímọ,  Ṣé ẹ fẹ́ tẹ̀lẹ́ Funkẹ Akindele lọ si Dubai?
Kò sí àrùn 'Monkey Pox' ní Naìjiria- NCDC
Ìdí tí a ṣe yọ ọwọ́ Naira Marley kúrò láwo Headies Award ọdún yìí rèé - HipTV
'O ṣójú mí kóró bí wọ́n ṣé fí àdó olóró pa Dele Giwa lọdún 1986'
À ń gbé ìjọba ìpínlẹ̀ Ọyọ lọ si ilé ẹjọ- Ẹgbẹ́ Fulani darandaran
Wo àdẹ́hùn méje tí Buhari ṣe pẹ̀lú ilẹ̀ Russia
Kí ni àwọn olórí Áfíríkà ń wá lọ sí Russia?
Seun Egbegbe lo ọdún méjì àti oṣù méje lẹ́wọ̀n láì tìí san béèlì rẹ̀
Ogun flood: ọ̀ps àwọn olùgbé agbegbe yii ti fi iṣẹ́ sílẹ̀ nítorí wọn kò lè jáde
Ministry of Communication gba orúkọ tuntun
Oríṣun àwòrán, OTHER
Ni ireti ati mu igbega ba eto ibanisọrọ ni Naijiria, Aarẹ Muhammadu Buhari ti ṣe afikun si ile iṣẹ eto ibanisọrọ ilẹ yii.
Bayii, lati ile iṣẹ eto ibanisọrọ, o ti wa di ile iṣẹ eto ibanisọrọ ati ọrọ aje igbalode [Ministry Of Communication and Digital Economy].
Lori ọrọ yii, pupọ lara ọmọ Naijiria ni wọn ti n fesi si iyipada ti Ijọba apapọ muba ile iṣẹ naa ti ọpọ si n fi ehonu han bakan naa.
Ọpọ dahun wipe, yiyi orukọ pada kọ ni koko ṣugbọn ki Ijọba ṣe ohun to yẹ lasiko ki wọn si jẹ ki ile iṣẹ naa o ja fafa
Bakan naa ni ẹnikan tun fesi wi pe, orukọ naa ko buru ṣugbọn, kini anfaani ti yoo ṣe nigba ti ọpọ eniyan ba wa lori iduro lati gbowo ni banki.
Ẹlomiran wi pe, kii ṣe ayipada orukọ la fẹ ṣugbọn, ki a mu ayipada ba ihuwaa wa ati iṣesi wa lati mu igba ọtun wọle wa ba wa ni Naijiria.
Ninu ifesi ọkan lara awọn ti o n fọkan ba eto naa lọ, o ṣalaye pe awọn ọdọ naa le jẹ anfani naa nipa jijẹ ẹni ti o mọ nipa ẹrọ ayelujara dipo bibẹnu atelu Ijọba.
Ẹni ọrọ naa ka lara kan, ṣalaye pe, eto to daa ni ti o si rẹwa ṣugbọn  ki ijọba gbiyanju lati mu eto ikọni ba awọn ti yoo ṣiṣẹ ni ile iṣẹ naa.
Oríṣun àwòrán, @Bashir Ahmad
Eya kan lara leta naa ti o fi ayipada naa han
Rice: Kò sí ìrẹsì lọjà mọ látàrí ibodè ti ìjọba tì pa - Ọlọja
Oríṣun àwòrán, AFP
Ọpọ ile itaja irẹsi ni ojuko itaja ti Mile 1, ni Ilu Pọta lo wa ni titi pa latari igbese Ijọba lori aiko irẹsi wọle.
Alaga awọn ti o n ta irẹsi ni ọja naa, Anselm Nwachukwu ṣalaye fun ile iṣe BBC pe, pupọ ninu wọn lo ti pa ọja naa ti ti wọn si ti wa wọrọkọ ṣada.
O tẹsiwaju pe, titipa ti Ijọba ti ibode pa yii ṣe akoba pupọ fun idokowo wọn, nitori ko si irẹsi lati ta fun wọn.
Ninu ọrọ rẹ loti ṣalaye pe, ijọba ko ro ọrọ naa daada ki wọn to gbe igbesẹ ọhun, nitori ko si irẹsi lori igba ti o si mu inira ba eto okoowo wọn.
Oluraja ati Olutaja iresi
Emeka Okameme ti o jẹ gbajugbaja oniṣowo  irẹsi  sọ wi pe aisi irẹsi ko jẹ ki ọja ya.
O ni ko si irẹsi lọja mọ koda eyi to jẹ tiwa n tiwa gan ko si ti o wa jẹ ki iye owo ti wọn n ta irẹsi lọ soke.
Ko ṣai mẹnuba ọpọlọpọ wahala ti wọn doju kọ ki wọn to ri eyi ti o wa lori atẹ bayii ra, ti o wa mu ọwọn  gogo ba irẹsi.
Bayii owo gọbọi ni wọn n ta irẹsi lọja ti ko si din ni ẹgbẹrun lọna marundinlọgbọn ti ikeji si jẹ ẹgberun lọna mejilelogun naira.
Ṣe ṣaaju akoko yii ni wọn ti n ta ni ẹgbẹrunmẹtadinlogun naira fun irẹsi oke okun ti tiwa n tiwa si jẹ ẹgbẹrun mẹrinla naira.
Ẹnikan ti o n ta irẹsi sise, Brenda Owen sọ pe agolo irẹsi kan bayii ti di ọgọfa naira.
Iresi
Koda wọn ni aisi irẹsi yii ti ṣakoba fun awọn ounjẹ miiran lori atẹ.
Kii ṣe igba akọkọ ree ti ijọba yoo maa ti ibode, wọn ti i ni ọdun 2003 ati Osu kẹfa ọdun 2018.
Ni bayii, iye ti wọn n ta apo agbado ti lọ soke lati ẹgbẹrun marun naira si ẹgbẹrun mẹsan naira.
Ondo Cow Death- Mùsùlùmí òdodo ni emi, mi ò kìí pa irọ́- Olu Ikare
Oríṣun àwòrán, @others
Maalu mẹjọ di oku ni Ikarẹ / Akoko ni eyi ti Olukarẹ ni ko ni ọwọ ara ilu ninu
Ó ṣeeṣe kó jẹ ohun tí wọn jẹ ló ṣekú pawọn ṣugbọn kìí ṣe ìlú lo pa wọn- Olukarẹ ti ilu Ikarẹ.
BBC ti ba Kabiyesi Ọba Akadir Momoh, Olukare ti ilu Ikare sọrọ lataari iṣẹlẹ maalu to ku ni ilu Ikarẹ, ni Ipinlẹ Ondo.
Oba Alayeluwa naa ṣalaye pe ilu ko mọ ohunkohun nipa iṣẹlẹ naa.
Kabiyẹsi fidiẹ mulẹ pe lootọ ni iṣẹlẹ naa waye ṣugbọn ilu ko ṣe ohunkohun lati ba ẹnikẹni ja rara.
Oríṣun àwòrán, facebook
Maluu ti ara san pa ni Ondo
Ninu alaye Ọba alaye naa ni wọn ti sọrọ wi pe, o ṣeeṣe ko jẹ ohun ti awọn maluu naa jẹ lo ṣe ku pawọn ṣugbọn kii ṣe pe boya ẹnikankan to ṣokunfa iṣẹlẹ naa.
Ori Ade ni lootọ oun ko si ni ilu nigba ti iṣẹlẹ naa ṣẹ ṣugbọn gbogbo rẹ ni wọn ti fi to awọn leti.
Kabiyesi ko ṣai mẹnubaa wi pe, gẹgẹ bi Musulumi ododo, ẹsin ko faaye gba wi pe ki awọn maa lọ ile oro tabi ṣe oro to le pa awọn maalu ọhun nibi kan ṣugbọn pe iwadii n lọ lọwọ lori ọrọ naa.
Nigba ti ikọ BBC n ba Kabiyesi sọrọ lori boya awọn maalu naa wọ ilẹ Ooṣa, Ọba alaye naa ni, wọn ko le sọ boya arinfẹsẹsi lo jẹ fun awọn maaluu naa ṣugbọn gbogbo rẹ yoo ni yanju.
Ọba Akadir wa ni ilu yoo ṣe pade pẹlu awọn agbaagba lati mọ ọna abayọ.
Iṣẹlẹ kayeefi miran tun ṣẹ ni ipinlẹ Ondo lori pe àrá tun san pa maalu mẹjọ ni agbegbe Ikarẹ/ Akoko ni Ijọba ibilẹ Ila oorun ariwa Akoko ni ipinlẹ Ondo.
Iṣẹlẹ ki ara maa san pa maalu kò ṣẹṣẹ maa ṣẹlẹ ni ipinlẹ Ondo.
Loṣu kan abọ sẹyin ni irufẹ iṣẹlẹ naa ṣẹlẹ ni Ijarẹ, ni Ijọba Ibilẹ Ifẹdọrẹ, ti maalu ti ko din ni mẹrindinlọgbọn si ku.
Iṣẹlẹ yii ṣẹlẹ ni ọjọ Iṣẹgun ọsẹ yii ni ẹkan -ile, ti o jẹ pe ni kete ti iṣẹlẹ naa ṣẹlẹ ni awọn Fulani darandaran bẹrẹ si ni ta oku ẹran naa fun ara ilu jẹ.
Bayii, Ijọba Ipinlẹ Ondo ti fofin de tita ẹran maaluu ni agbegbe naa titi ti iwadii yoo fi pari lori iṣẹlẹ naa.
Bayii, ẹka ti o n ri si ilera ara ilu ati awujọ ti fi panpẹ ọba mu awọn alapata ti o n ta eran ti ara pa yii fun ara ilu lẹyin ti wọn sun wọn ti wọn ṣeto rẹ daadaa.
Yoruba Culture: ọjọ́ méje ni wọ́n fí n rẹ ẹ̀kú Danafojura kó tó jáde
Ẹni ti o jẹ adari ẹka naa, Arabinrin Yemisi Adeniyi ati ojugba rẹ Ogbẹni Ojo Anthony sọ wi pe, awọn ti wọn mu yii ti wa ni ahamọ ofin.
Iroyin ni awọn maalu naa ku nigba ti wọn ṣeṣi rin lọ ori oke kan ti Oba ilu naa ti maa n lọ ṣe etutu ọlọdọọdun.
Wọn ti wa rọ awọn eniyan ilu lati yẹra fun rira ẹran maalu lasiko yii ni pataki, ẹran ti ara pa yii fun ilera ara wọn.
Bakan naa ni ẹni ti o jẹ alaga awọn alapata ni agbegbe naa, Arakunrin Kabiru Ismaila sọ pe, gbogbo ipa ni wọn yoo sa lati ri i pe iru ẹran bẹẹ ko wọ ọja.
Ogun flood: ọ̀ps àwọn olùgbé agbegbe yii ti fi iṣẹ́ sílẹ̀ nítorí wọn kò lè jáde
Abdurasheed Maina: Adájọ́ ní kí ọ̀gá àjọ tó rí sí owó ìfẹ̀yìntì tẹ́lẹ̀ sí wà látìmọ́lé
Oríṣun àwòrán, Facebook/Abdulsheed Maina
Ile ẹjọ giga ijọba apapọ l'Abuja ti paṣẹ pe ki ọga ile isẹ to n risi owo awọn osisẹfẹyinti (pension) tẹlẹri, Abdurasheed Maina wa ni atimọle.
Adajọ Okon Abang paṣẹ yii ti ajọ to n gbogun ti iwa ibajẹ lorilẹ-ede Naijiria, EFCC gbe e lọsi ile ẹjọ, bo tilẹ jẹ pe oni oun ko jẹbi ẹsun onikoko mejila ti wọn fi kan an.
Adajọ Abang sun igbẹjọ naa si ọgbọn ọjọ, oṣu kẹwaa ati ọjọ kọkandinlogun oṣu kọkanla.
Ẹsun ikowojẹ, nini apo ikowo si ni banki tẹni kan o mọ ati iwa jibiti ni wọn fi kan Maina
EFCC gbé ọ̀gá owó ìfẹ̀yìntì tẹ́lẹ̀ lọ sÍ ilé ẹjọ́ fún ìwà ìbàjẹ́!
Ajo to n gbogun ti iwa ibajẹ lorilẹede Naijiria, EFCC ti gbe ọga ile isẹ to n risi owo awọn osisẹfẹyinti ( pension) tẹlẹri, Abdurasheed Maina ati ọmọ rẹ Fraisal lọ si ile ẹjọ giga to wa ni ilu Abuja.
Ẹ̀sun oniga mejila to niise pẹlu lilo owo ilu ni ponpo, lilo banki ayederu ati gbajuẹ ni EFCC fi kan Maina.
Oríṣun àwòrán, Others
Abdurasheed Maina àti ọmọ rẹ̀ Faisal ni wọ́n gbé ní ìlú Abuja lẹ́yìn tí wọ́n ti ń wá láti ọdún 2017 fún ẹ̀sùn lilu owo ilú ní póńpò.
Ọjọ Kejilelogun, Osu Kewaa ni Adajo Agba, Folasade Giwa-Ogunbanjo ti ile ẹjo giga pasẹ ki Maina fi dukia ile mẹtalelogun to ni silẹ.
Ile nlanla, adugbo ati ile isẹ Maina to wa ni Abuja, Kaduna, Borno ati Nasarawa wa lara awọn dukia naa ti wọn ri pe Maina lo nii.
Bakan naa ni ile ẹjọ pasẹ ki iwe iroyin ti orilẹede Naijiria fi lede pe ki Maina jọwọ gbogbo awọn dukia naa fun ijọba.
Ati wi pe ki ẹnikẹni ti ko ba fẹ jẹ ki ijọba gbẹsẹle awọn dukia naa jade pẹlu ẹri wi pe awọn ni wọn ni.
Oríṣun àwòrán, OTHERS
EFCC ń gbé ọ̀gá Pension tẹ́lẹ̀ lọ sÍ ilÉ ẹjọ́ fún ìwà ìbàjẹ́!
Adajọ Okon Abang tile ẹjọ giga ni Abuja ni igbẹjọ naa ti n lọ bayii.
Wilson Uwujaren to jẹ agbẹnusọ EFCC ni o di dandan ki Maina ri aaye wi tẹnu rẹ lori awọn ẹsun wọnyii.
2010 - Wọn fi jẹ alaga ajọ aare to n risi ọrọ ajẹmọnu ati owo osisẹfẹyinti
•2012 - Wọn fi ẹsun iwa ibajẹ kan an
•2013 - Wọn le ni isẹ ijọba apapọ
•2015 - EFCC sọ fun gbogbo eniyan pe awọn n wa Maina
Ọwọ ṣìkún òfin ti tẹ Maina, alága àná fún ọrọ owó ìfèyìntì - DSS
Khadijah, obìnrin àkọ́kọ́ tó dẹnu ìfẹ́ kọ àyànfẹ́ rẹ̀
O ṣójú mí kóró bí wọ́n ṣé fí àdó olóró pa Dele Giwa lọdún 1986- Soyinka
À ń gbé ìjọba ìpínlẹ̀ Ọyọ lọ si ilé ẹjọ- Ẹgbẹ́ Fulani darandaran
•2015 - O sa pamọ (awọn eniyan ni Dubai lo salọ)
•2017 - Wọn fi je adele fun adari ile isẹ to n risi ọrọ abẹlẹ lorilẹede Naijiria
•2017 - Ọjọ Kẹtalelogun, Osu Kẹwa ni aare yo o nise
•2017 - Iwadii ti bẹrẹ ni pẹrẹwu lori rẹ - amọ awọn eniyan ni o lo sapamọ.
Ohun mẹ́wàá tó yẹ kóo mọ̀ nípa Kunle Afod
Fasiti Kaduna ni ki olùkọ́ lọ rọọ́kún nílé látààrí ẹ̀sùn pé ó ń dúnkookò mọ́ akẹ́kọ̀ọ́
Ìlé ẹjọ́ ti pàṣẹ pé kí ilé iṣẹ́ ọ̀lọ́pàá dá ìgbaniwolé dúró
Wo àdéhùn méje tí Buhari ṣe pẹ̀lú ilẹ̀ Russia
Olùkọ kan àti àwọn mẹ́ẹ̀dógún míràn ni wọn ti yẹgi fún ní Bangladesh
Oríṣun àwòrán, FAMILY HANGOUT
Nusrat eni ti won da epo oyinbo si lara won si jo
Ijọba orilẹ-ede Bangladesh ti ran awọn mẹrindinlogun ọmọ orilẹ-ede naa ni ẹwọn gbere.
Ile ẹjọ da ẹwọn gbere fun awọn ọdaran naa lẹyin ti wọn dana sun ọmọ ile iwe kan ti orukọ rẹ n jẹ Nusrat Jahan.
Ọmọ ọdun mọkandinlogun ni Nusrat ti wọn kọlu lataari bi o ti fi ẹjọ olukọ agba ile iwe rẹ, Siraj Ud Doula, sun pe, o dẹnu ibalopọ kọ ohun.
Olukọ agba ile iwe naa ni iroyin ni ko fi ọmọbinrin naa lọrun silẹ.
Iroyin ni o tun dẹnukọ awọn ọmọbinrin meji miran ti o jẹ akẹkọọ bii Nusrat ki o to paa ni eyi to jẹ ki ile ẹjọ ni ki wọn yẹ igi fun un.
Nigba ti adajọ naa gbe idajọ rẹ kalẹ tan lori awọn ọdaran naa, ni lara wón ba bẹrẹ sini da omi loju yoloyolo ti wọn si n kigbe, ti awọn kan ni adajọ ko fun wọn ni idajọ ododo
Iku ọmọbinrin naa lo jẹ kayeefi si ọpọ awọn eniyan ti wọn si n beere idajọ ododo fun ọdọbinrin naa lori bi wọn ṣe ṣeku paa.
Oríṣun àwòrán, Reuters
Awọn ọdaran ni ile ẹjọ
Bo tilẹ jẹ pe, inu awọn mọlẹbi rẹ dun si idajọ ile ẹjọ naa, amọ ọkan iya rẹ, Shirin Akhtar bajẹ pupọ ti o si n domi loju pe, oun ko le gbagbe rẹ ati iru irora ti ọmọ oun jẹ loju iku.
Yoruba Culture: ọjọ́ méje ni wọ́n fí n rẹ ẹ̀kú Danafojura kó tó jáde
Awọn ẹbi Nusrat to kin in lẹyin lati fi ọrọ naa to Ọlọpaa leti ni wọn ti wa ni abẹ abo ajọ Ọlọpaa bayii fun aabo to daju gẹgẹ bi ẹgbọn rẹ, Muhmudul Hassan Noman ṣe sọ
Ogun flood: ọ̀ps àwọn olùgbé agbegbe yii ti fi iṣẹ́ sílẹ̀ nítorí wọn kò lè jáde
Ọmọ ogún ọdún tó fẹ́ràn kí obìnrin ní ìdí ni mí- Sophie
Oríṣun àwòrán, @Sof
Ọpọ ọkunrin lo maa n fẹran ki obinrin ni idi to tobi ni eyi to n jẹ ki awọn obinrin gbe igbesẹ loriṣiiriṣi.
Onkọroyin lori ayelujara to tun jẹ gbajugbaja lori ẹrọ mohunmaworan, Sophie Elise ṣe iṣẹ abẹ afikun idi rẹ nigba to wa lọmọ ogun ọdun.
O ṣalaye pe, ifẹ lati ni idi to tobi bii ti ojulowo ọmọbinrin lo jẹ ki oun diju ṣe iṣẹ abẹ naa ni ọdun marun un sẹyinsun ohun o.
Arabinrin yii ṣapejuwe ara rẹ bi ẹni ti ko lara rara ṣugbọn ti o kan fẹ ṣe afikun diẹ si ibi to ṣe pataki si i ninu ẹya ara rẹ yii.
Oriṣiriṣi awọn eniyan ni wọn n polowo lori ẹrọ ayelujara rẹ ati irufẹ awọn Dokita to le ṣe fifi idi tobi to fi mọ ti ilẹ Brazil.
Sophie ri ibi kan ni ilẹ Turkey ti won ti le ṣe iṣẹ abẹ naa ṣugbọn ti owo rẹ fẹ wọn ko too ri ọna abayọ.
Nigba ti o n ṣalaye fun ikọ akọroyin Radio 1 Newbeat, ni tootọ owo naa kere si bi o ti yẹ, pe o yẹ ki o wọn ju bẹẹ lọ.
Oríṣun àwòrán, facebook
Sophie yi ọkan rẹ pada lori iṣẹ abẹ idi ṣiṣe
Kini idi ti Sophie ṣe fẹ yọ ayederu idi naa lẹyin ọdun marun un ti o ti fi si?
Kete ti Sophie ti ile iwosan de ni gbogbo ara rẹ ko ti gbadun.
Ilumọọka ni Sophie ni orilẹ-ede Norway nibi to ti n gbe eto oriṣiriṣi sori afẹfẹ to tun ni awọn to le ni ẹgbẹrun ẹẹdẹgbẹta to n tẹlẹe.
Àwọn òbí mi rò pé ẹ̀jẹ́ ti ta sí ọpọlọ mi nígbà tí mo bẹ̀rẹ̀ sí ba ẹranko igbó ṣọ̀rẹ́
Bakan naa lo mẹnuba awọn ẹgbẹlẹgbẹ awọn ololufẹ rẹ lori ẹrọ ayelujara, ti wọn lodi si ayederu idi nla ti oun ṣe naa.
Awọn eniyan ni iduro rẹ ko dan mọnran bakan naa ni idi nla naa ko ba ẹya ara rẹ toku mu.
Oríṣun àwòrán, Sophie Elise
Ọmọ ogún ọdún tó fẹ́ràn kí obìnrin ní ìdí ni mí- Sophie
Gẹgẹ bi o ti wi, o ni aridaju ti wa fun ohun bayii pe okun ọrun ko yẹ adiyẹ ohun rara ti abamọ si ti n gbẹyin ọrọ bayii.
Ẹni ọmọ ọdun merinlelogun naa ti wa pinnu bayii pe ki wọn gba abẹrẹ fun oun lori idi naa ki wọn si jẹki oun ru diẹ.
Uber Lady: Bùkátà pọ̀ lọ́rùn mi ní mo ṣe ń wa taxi akérò
Ṣiṣe ayederu idi ni ọpọlọpọ aida ninu ti o si ṣeku pa awọn obinrin ilẹ Britain meji ti wọn rin irin ajo lọ si ilẹ Turkey.
O wa ni ohun ti ri i wi pe ara ohun dara pupọ ju iru wahala ti o bara rẹ yi lọ.
Sophie ti wa ri ẹni ti yoo le ba ṣe iṣẹ abẹ daada lẹyin ti o ti o ti ṣe iwadii lori ẹrọ ayelujara.
Yinka Ayefele: Oṣù àwọn ìbẹ́ta mi kò pé ní kò jẹ́ kí n kọ́kọ́ kéde ìbí wọn
Sophie ti wa pinnu ninu ọkan rẹ lati ṣe isẹ abẹ naa pẹlu Dokita to mọṣẹ lati din ẹru ẹyin rẹ ku si kekere ti ara rẹ yoo le gbe.
Bayii, sophie ti ronu ara rẹ pe, o dara ki eeyan maa gba bi ara rẹ ṣe ri ki o si maa fun ara rẹ ni iwuri.
Pottery: Àwọn onímọ̀ nípa amọ̀ wúlò púpọ̀ ju ike àbí irin lọ
High blood pressure: Lílo òògùn ẹ̀jẹ̀ ríru sùn lálẹ́ ló lè mú un ṣiṣẹ́ jùlọ
Oríṣun àwòrán, Getty Images
High blood pressure: Lílo òògùn ẹ̀jẹ̀ ríru sùn lálẹ́ ló lè mú un ṣiṣẹ́ jùlọ
Awọn ọnimọ sayẹnsi ti sọ wi pe lilo oogun ẹjẹ ruru lalẹ lo le mu oogun naa ṣiṣẹ lara ju.
Wọn ni igba to dara julọ lati loogun naa ni keeyan to sun lori ibusun rẹ lalẹ.
Iwadii fihan pe oogun yii maa n dena aarun rọpa-rọsẹ ati aarun ọkan t'eeyan ba loogun naa ko to sun lalẹ.
Awọn onimọ sayẹnsi ṣalaye pe aago to wa lara eeyan niiṣe pẹlu bi oogun ṣe maa n ṣiṣẹ lara eeyan.
Iwadii ti fihan pe o ni awọn akoko kan ti oogun le ṣiṣẹ daadaa lara eniyan ti o ba lo o.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Eeyan bi ẹgbẹrun un mọkandinlogun ni wọn fi dan oogun yii wo ki wọn to sọ pe oogun ẹjẹ ruru yoo ṣiṣẹ julọ teeyan ba lo ko tun sun lalẹ.
Awọn onimọ oogun ṣalaye pe to ba ti di pe ẹjẹ ruru n lọ soke lai wa silẹ rara, o le ṣakoba fun ọkan eniyan.
Ọjọgbọn Ramon Hermida jẹ olori iṣẹ iwadii naa sọ pe awọn dokita le maa sọ fawọn to ba laarun ẹjẹ riru lati maa loogun wọn lalẹ ki wọn to sun bayii lẹyin ti iwadii ti fidi rẹ mulẹ.
Ogun flood: ọ̀ps àwọn olùgbé agbegbe yii ti fi iṣẹ́ sílẹ̀ nítorí wọn kò lè jáde
Ẹ̀sùn àìmọ̀dí gbé Theophilous dọ́gbà ẹ̀wọ̀n, ìwé ẹ̀rí ìmọ̀ ìjìnlẹ̀ méjì ló gbé jáde
Oríṣun àwòrán, The Nigeria Lawyers
Ẹ̀sùn àìmọ̀dí gbé Theophilous dọ́gbà ẹ̀wọ̀n, ìwé ẹ̀rí ìmọ̀ ìjìnlẹ̀ méjì ló gbé jáde
Ṣe wọn ni ba o ku iṣe o tan.
Aṣamọ ọrọ yii gan an lo ṣakawe iroyin nipa Ọgbẹni Adeniyi Theophilous to gba iwe ẹri imọ ijinlẹ meji lasiko to fi wa lọgba ẹwọn.
Gẹgẹ bi ohun ti Ọgbẹni Adeniyi sọ fawọn akọroyin ni ilu Enugu, o ni n ṣe loun ronu si ọrọ awọn agba to ni iya meji ko gbọdọ jẹ okuugbẹ loun baa fi sare wa wọrọkọ fi ṣada.
O ni eyi lo mu oun lo anfani ibudo ikẹkọọ fasiti agbelegboye NOUN ti wọn da silẹ lọgba ẹwọn ilu Enugu lati fi kẹkọọ gboye ijinlẹ.
O ni iyalẹnu lo kọkọ jẹ fun ọpọ awọn ẹlẹwọn nibẹ nitori ko sẹni to gbagbọ pe o ṣeeṣe ki wọn gbe fasiti wa sọgba ẹwọn.
Bi o tilẹ jẹ pe ọgbẹni Adeniyi kọ ni ẹlẹwọn akọkọ ti yoo kẹkọ gba oye ijinlẹ lọgba ẹwọn ṣugbọn ko fẹẹ si eyi to tii gba meji nibẹ ṣaaju rẹ.
Ṣe wọn ni inu ẹni kii dun ka paa mọra, Ọga wọda ni ipinlẹ Ẹnugu, Ọgbẹni Mustapha Attah ti ko lee pa idunnu rẹ mọra kan sara sawọn ẹlẹwọn to n lo asiko wọn ni ile ọgbọn naa lati fi tun igbesi aye wọn ṣe.
Attah ni paapaa julọ nipa itẹsiwaju ẹkọ wọn pẹlu ileri pe nibayii, ileeṣẹ ọgba ẹwọn lorilẹ-ede Naijiria ni yoo maa gbọ ilaji bukata owo ileewe ẹlẹwọn yoowu to ba fẹ kẹkọ lasiko to ba wa lẹwọn.
Ọgbẹni Adeniyi ni ọdun mẹsan an sẹyin ni wọn taare oun lọ sọgba ẹwọn ni ilu Ẹnugu pe ki oun wa nibẹ titi di igba ti wọn yoo fi yanju ẹjọ lori ẹsun ti wọn fi kan oun nipa wahala ija laarin ileto si ileto kan to waye nigba naa.
Yoruba Culture: ọjọ́ méje ni wọ́n fí n rẹ ẹ̀kú Danafojura kó tó jáde
Adeniyi ni lootọ, wahala pe oun wa lẹwọn to domi tutu si ọkan oun ṣugbọn pẹlu ifaraẹnijin ati ilakaka gbogbo to yẹ oun bori nigbẹyin.
O fi kun un pe ninu awọn ẹlẹwọn marundinlọgbọn to forukọ silẹ ni ileewe naa lọdun 2015, oun nikan lo pari.
Ẹkọ nipa ipẹtusaawọ lo kọ to si yege pẹlu ami keji nileewe giga fasiti, iyẹn second class upper (2.1)
Lọjọ karun un, oṣu kẹwaa, ọdun 2015 ni wọn daa silẹ pe ko jẹbi ẹsun ti wọn fi kan an lẹyin to lo ọdun marun un ati oṣu mẹfa lọgba ẹwọn to n reti idajọ ile ẹjọ.
Ofada Rice: kíni ẹ̀yin gbádùn nínú ìrẹsì ọ̀fadà?
Ondo Kidnap: Àwọn ajínigbé tú adájọ́ kóòtù àpapọ̀ sílẹ̀ lẹ́yìn ọjọ́ márùn ún lákàtà wọn
Oríṣun àwòrán, The Nigeria Lawyers
Onidajọ Abdu Dogo ti awọn ajinigbe kan ji gbe lọjọ Iṣẹgun ọsẹ yii ti gba itusilẹ oGéńdé agbébọn jí adájọ́ gbé lọ ní ìpínlẹ̀ Ondo.
Ni agogo meji oru ọjọ Satide tii ṣe ọjọ kẹrindinlọgbọn, oṣu kẹwaa ni wọn tuu silẹ lẹyin ti awọn ajinigbe naa jii gbe lasiko to fi n rin irinajo bọ lati ilu Abuja lọ si ilu Akurẹ.
Awọn agbebọn ti ẹnikẹni ko damọ lo ji Adajọ naa gbe ti wọn ni wọn n beere fun aadọta milionu owo itanran.
Ko tii si ẹni lee sọ ohun to ṣẹlẹ ti wọn fi tuu silẹ bayii.
Yoruba Culture: ọjọ́ méje ni wọ́n fí n rẹ ẹ̀kú Danafojura kó tó jáde
Bi ẹ ko ba ni gbagbe, ni kete ti iroyin ijinigbe rẹ kan sita ni Ọga agba ọlọpaa lorilẹ-ede Naijiria, ti dari ikọ ọtẹlẹmuyẹ eleyi ti ọga ọlọpaa, Abba Kyari ko sodi lati tete ṣawari Onidajọ Abdu Dogo ni kiakia.
Adajọ ileẹjọ giga apapọ orilẹ-ede Naijiria ni ilu Akurẹ ni Onidajọ Dogo.
A o maa mu alaye kikun si wa ni kete ti a ba ti mọ bo ṣe gba itusilẹ.
Oríṣun àwòrán, The Nigeria Lawyers
Pius Adesanmi: Òní ni ẹ̀bí akọni Pius Adesanmi n ṣètò ìkẹyìn fún ogbontarigi náà
Oríṣun àwòrán, @Pius
Ilẹ n jẹ eeyan!
Ọsan oni, ni deede aago mejila ni ẹbi ara ati ọrẹ oloogbe Pius Adesanmi fẹ ṣeto isinku rẹ ni Ottawa, Ontario ni orilẹ-ede Canada.
Oloogbe Pius Adesanmi ni ogbontarigi olukọ ati onkọwe ọmọ Naijiria to fi Canada ṣe ibujoke to dollogbe nibi ijamba ọkọ ofurufu Ethiopia to waye loṣu kẹta ọdun yii.
Ojọ kẹwaa, oṣu kẹta, ọdun 2019 lo wa ninu awọn ẹmi to sọnu nigba ti ijamba ọkọ ofurufu yii ṣẹlẹ.
O n lọ irinajo lati laarin Adis Ababa ati Nairobi nibi ti eniyan mẹtadinlogojo ti doloogbe.
Ojọ kẹtadinlọgbọn, oṣu keji, ọdun 1972 ni a bi oloogbe Pius Adesanmi.
O  jẹ ọmọkunrin kan ṣoṣo ti iya rẹ bi laarin ọmọ mẹta, oun naa tun ni abigbeyin iya wọn.
Okan pataki lara awọn iwe to kọ ki ọlọjọ to de ni Naija No Dey Carry Last, A 2015 collection of satirical essays.
Ebi, ara ati awọn ojulumọ ni gbogbo wọn n ṣe idaro ẹni rere to lọ
Pius Adesanmi ní Wole Soyinka ìran yìí - ọmọ Naijiríà
Diẹ lara awọn ibi ti Pius ti ṣiṣẹ ni fasiti Pennsylvania ni America, French Institute for Research in Africa ati ti South Africa ko to wa di ọjọgbọn ni fasiti Carleton ni Ottawa, ni orilẹ-ede Canada.
Oríṣun àwòrán, @others
Oni ni wọn n ṣe ẹyẹ ikẹyin fun akọni
Ọpọ igba ni Pius Adesanmi maa n sọrọ nipa Naijiria tuntun nigba aye rẹ.
O maa n sọrọ lori awọn iṣoro to n koju awọn eniyan Naijiria, awọn wahala to de ba eto ọrọ aje ati igbe aye alaafia Naijiria nigba aye rẹ pupọ.
Capital Funeral Home and Cemetary ni wọn ti maa sin ọjọgbọn ọmọ ipinlẹ Kogi ni aarin gbungbun Naijiria yii si lọsan oni.
Tẹbi-tara tojulumọ lo maa pade lati ṣe ẹyẹ ikẹyin fun un ni Canada.
Itedo-Ijowa ni Agbegbe Isanlu, nijọba ibilẹ Ila oorun Yagba ni a ti bi Pius nipinlẹ Kogi.
Lasiko ti a bii lọdun 1972, ijọba ibilẹ Isanlu ṣi wa labẹ ipinlẹ Kwara nibi ti wọn ti yọ apa kan ipinlẹ Ondo.
Orọ igbẹyin ti Pius Adesanmi fi soju opo Facebook rẹ fi igbagbọ rẹ ninu Oluwa han pe:
Oríṣun àwòrán, @Pius
afi bii pe akọni n dagbere .....
Yoruba Culture: ọjọ́ méje ni wọ́n fí n rẹ ẹ̀kú Danafojura kó tó jáde
Russia Shooting: Ọmọ ogun mẹjọ ni ilẹ Russia ni wọn ti ríkú òjiji he tí méjì míràn si farapa.
Aworan ile Russia ti ọmọ ogun ilẹ ti da ibọn bo awọn akẹgbẹ rẹ
Ọmọ ogun ilẹ Russia kan ti ṣeku pa ojugba rẹ mẹjọ ti o si ṣe meji miran leṣe ninu ipagọ awọn ọmọ ogun ilẹ naa.
Awọn alaṣẹ ologun ilẹ naa wi pe o ṣeeṣe ko jẹ wi pe, arakunrin naa, Ramil Shamsutdinov, ni aarun ọpọlọ, ti wọn si ti fi si ihamọ.
Iṣẹlẹ yii lo waye ni aṣalẹ ọjọ Eti ni ibudo ipagọ ni abule Gorny, ti ko jinna si Chita.
Awọn alaṣẹ naa ni iwadii si ti bẹrẹ ni pẹrẹu.
Kini o ṣẹlẹ gangan nibudo ipagọ awọn ọmọ ogun?
Iṣẹlẹ yii waye ni nkan bii aago mọkanla kọja iṣẹju mẹẹdogun alẹ ọjọ Eti gẹgẹ bi ohun ti igbimọ iwadii ilẹ Russia sọ.
Ẹka ti o n ri si eto aabo ti sọ ṣaaju pe, arakunrin naa yin ibọn naa ni kete ti awọn ọmọ ogun mura ogun.
Ọgbẹni Shamsutdinov pa oṣiṣẹ meji pẹlu awọn akẹgbẹ rẹ ti wọn jọ jẹ ọmọ ogun mẹfa.
Ẹni ti o jẹ igbakeji Minisita fun eto aabo ni ilẹ naa, Andrey Kartapolov yoo ṣaaju ikọ ti yoo ṣe iwadii ọrọ naa.
O di dandan fawọn ọdọkunrin ti ọjọ ori wọn wa laarin ẹni ọdun mejidinlogun si mẹtadinlọgbọn lati darapọ mọ awọn ọmọ ogun ninu alakalẹ eto ilẹ Russia.
Ti wọn yoo si wa fun iṣẹ afi-ara-ẹni-jin bii isinru ilu ọlọdun kan ṣugbọn ti anfaani si n bẹ fẹni to ba fẹ sun siwaju si i.
Ni awọn asiko kan sẹyin, ni awọn ajafẹtọ-ọmọniyan maa n tabuku ijọba ilẹ naa lori bi wọn ṣe n dari awọn ologun lọna aitọ ṣugbọn ti wọn ti wa ni ologun ni kalẹ bayii.
Ogun Accident: Èèyàn mẹ́wàá kú nínú ìjàmbá ọkọ̀ lánà mọ́rosẹ̀ Ṣagamu sí Ijebu Ode
Oríṣun àwòrán, @AJISCO30
O kere tan eeyan mẹwaa lo d'oloogbe ninu ijamba ọkọ meji to ṣelẹ lọjọ Satide loju ọna mọrosẹ ilu Ṣagamu si Ijebu Ode.
Ọga agba fun ajọ ẹṣọ oju popo, FRSC ti ipinlẹ Ogun, Ọgbẹni Clement Oladele ṣalaye pe, eeyan mẹrindinlogun lori ko yọ ninu iṣẹlẹ ọhun.
Ọgbẹni Oladele ṣalaye pe, awọn ole ti wọn n ṣọṣẹ loju ọna naa lo ṣokunfa ijamba ọkọ akọkọ ninu eyi ti eeyan meji ti ku.
Ọga ajọ FRSC fikun ọrọ pe, awakọ kan lo ṣadeedee lọri lẹyin to kan awọn ole loju ọna lojiji, eleyi to mu wọn kọlu ọkọ akẹru nla to n bọ.
Oríṣun àwòrán, @AJISCO30
Ọgbẹni Oladele ṣalaye pe, ijamba ọkọ keji waye nigba ti ọkọ ajagbe agbepo ati ọkọ bọọsi akero to n bọ lati ilu Okitipupa kọlu ara wọn.
Ajọ FRSC ni ile iwosan ijọba to wa niluu Ijẹbu ode ni wọn ko awọn to farapa ninu ijamba ọkọ naa lọ.
Bakan naa ni won ko oku awọn to ku lọ si ile igbokusi nile iwosan yii kan naa.
Lady Jibowu: Ẹni ọdún 95 ló dágbére fáyé pé ó dìgbóṣe
Oríṣun àwòrán, Twitter/Ekiti State Government
Iku n pani, ilẹ n jẹyan, gbogbo ilẹ Yoruba ati orilẹede Naijiria n ṣedaro mama Ọlọla Deborah Opeyemi Jibowu to jẹ obinrin akọkọ ni Naijiria, to kawe gboye akọkọ ninu imọ sayẹnsi.
Opeyemi Jibowu jẹ Ọlọrun nipe lẹni ọdun marun din lọgọrun un, ti aya Gomina ipinlẹ Ekiti, Bisi Fayemi naa si ti ranṣẹ ibanikẹdun si ẹbi oloogbe Fasanmade niluu Ido-Ile nipinlẹ Ekiti.
Ta ni  mama Lady Deborah Opeyemi Jibowu gan an?
Idile Mama Deborah Opeyemi Jibowu
Mama Deborah Opeyemi Jibowu ṣe igbeyawo pẹlu Olumuyiwa Jibowu lọjọ kẹjọ oṣu keje ọdun 1950.
Ọlọrun fi ọmọkunrin meji ati ọmọbinrin ta idile naa lọrẹ.
Mama Deborah Jibowu kopa ninu eto oṣelu
Mama Deborah Jibowu jẹ ọkan lara ọmọ ẹgbẹ igbimọ ajọ to n ri si ijọba ibilẹ laarin ti ijọba iwọ oorun ni Naijiria yan larrin ọdun 1959 si ọdun 1971.
O tun jẹ kọmiṣọna ajọ to n ri si eto ikaniyan(National Population Census) lọdun 1981 si 1983.
Ilẹ Gẹeṣi fi oye 'Member of the British Empire (MBE)' da a lọla lọdun 1962, lẹyin naa ni orilẹede Naijiria fun un ni oye Officer of the Order of the Niger (OON) lọdun 1965.
Mama Deborah Opeyemi Jibowu tun jẹ oye mama isalẹ fasiti ilu Calabar lọdun 1993 si ọdun 1997.
Rehab Homes: Ọmọdébìnrin kan sọ bí òun ṣe di ẹ̀rọ ìbálòpọ̀ níbùdó aláìgbọràn
Oríṣun àwòrán, @nigeria_true
Obinrin kan, ẹni ogun ọdun ti ori ko yọ nile awọn ọmọ alaigbọran to wa nilu Ilọrin, Laide Arikewuyọ, ti salaye ohun ti oju rẹ ri lasiko to wa nile naa.
Laide, to jẹ ọkan lara awọn ọmọbinrin mejidinlaadọfa ti wọn ri idande gba kuro nile ọmọ alaigbọran naa sọ pe awọn ọmọ ati ibatan oludasilẹ ile ọmọ alaigbọran naa, lo ti sọ ohun di ẹrọ ibanilopọ, ti wọn si n sun ti oun bo se wu wọn.
Nigba to n sọ ohun ti oju rẹ ri ninu ile naa fawọn akọroyin salaye pe ẹni ta gboju okun le, ko jọ ẹni agba lọrọ awọn  eeyan ti wọn ni ki wọn maa se akoso ile alaigbọran naa, nitori iwa aidaa nidi ibalopọ lọna ti ko tọ gan lawọn naa n hu.
O fikun pe nigba ti awọn obi oun ko lee setọju oun bo se yẹ ni oun sa kuro nile, ni kete ti wọn si ri oun pada, lawọn obi oun mu ohun lọ sile alaigbọran naa, ti Mallam Abdulraheem Owotutu da silẹ.
Oríṣun àwòrán, @nigeria_true
Mo ti n gbe nibudo naa lati ọdun marun sẹyin, mo si maa n ni ibalopọ loore koore pẹlu awọn ọmọ ati mọlẹbi Mallam Owotutu, ko si din ni marun ninu awọn alakoso to n setọju ibudo naa, to ti ba mi ni ajọsepọ.
Laide fikun pe oun ranti pe oun loyun ni ẹẹmẹta ọtọọtọ, amọ wọn maa n fun oun ni oogun ti ko ni jẹ ki oyun naa duro lara oun.
Nigba ti oun naa n salaye ohun to gbe de ile ọmọ alaigbọran naa, Tọpẹ Collins Owonifaari salaye pe awọn eeyan kan ti oun ko mọ lo gbe nilu Eko, ti oun si ba ara oun nibudo to dọti naa, nibiti wọn ko awọn papọ si bii ẹran.
Tọpẹ ni ọjọ mẹrin pere ni oun ti lo nibudo naa, ki ori to ba oun se ti awọn ọlọpa fi wa fọ ibudo ọhun.
Bẹẹ ba gbagbe, a mu iroyin wa fun yin laipẹ yii pe lọjọbọ to kọja nileesẹ ọlọpa ipinlẹ Kwara safihan awọn ọmọge, ọkunrin ati ọmọde, ti wọn tu silẹ nile ọmọ alaigbọran kan to wa ladugbo Gaa Odota nilu Ilọrin.
Prepaid Meter: Ọmọ Nàíjíríà figbe ta pé owó iná táwọn ń san ju iná táwọn ń lò lọ
Oríṣun àwòrán, Ikeja Electric
Ọrọ ina ọba to n se segesege lorilẹede Naijiria ati bi ileesẹ amunawa se n beere owo ina ti wọn ko pese ti n ru awọn ọmọ Naijiria laya soke bayii.
Se ni oju opo Twitter n gbona lala, tawọn ọmọ Naijiria si ti n fohun sọkan pe ti ileesẹ to n pese ina ọba lorilẹede yii ko ba pese ẹrọ igbalode to n ka iye ina taa ba lo, taa mọ si Prepaid Meter, awọn ko ni san owo ina mọ.
Awọn ọmọ Naijiria, ti wọn se ipinnu bẹẹ loju opo Twitter wọn, labẹ akori #NoMeterNoPayment, wa salaye lẹkunrẹrẹ nipa ọpọ ohun ti oju wọn n ri lọwọ ajọ to n pese ina ọba, pẹlu bi wọn se n beere owo gege lai pese ina ọba to duro re.
Oríṣun àwòrán, Ikeja Electric
Olaniyi Alesinloye, @alesolas lasiko to n da si ọrọ naa ni ojuse awọn ọmọ Naijiria ni lati sanwo ina ọba ti wọn ba lo, ojuse awọn ileesẹ amunawa naa si ni lati si iye owo ina ti araalu kọọkan ba lo, sugbọn ọna to dara julọ lati se eleyi ni ki wọn fun araalu ni ẹrọ igbalode Prepaid meter.
June16 @jcallisto n tiẹ ni inu ile oni yara meji ni oun n gbe. Oun ni giloobu mẹjọ, ẹrọ amomitutu kan, faanu meji laisi tẹlifisan abi awọn ohun eelo amadẹrun miran, sibẹ, ileesẹ amunawa n beere ẹgbẹrun mẹrin si meje lọwọ oun losoosu.
Amọ alabagbele oun to ni awọn ohun eelo igbalode ninu ile, to fi ms ẹrọ ifọsọ n san ẹgbẹrun meji lori ẹrọ igbalode prepaid meter rẹ, nitori naa, laisi Prepaid meter, oun ko ni sanwo ina.
Sultan n tiẹ, @the Gr8t  ni awọn osisẹ amunawa yii n gbe iwe owo ina gọbọi wa fun araalu, ki awọn baa lee fun wọn ni owo abẹtẹlẹ ẹgbẹrun kan si meji naira, ti wọn yoo si tun pada wa lẹyin ọsẹ meji lati wa gba owo ibi naa.
Idi si ree ti oun se n faramọ pe laisi Prepaid meter, owo ina ko ni jẹ sisan.
Collins O @OkoroCollins lero tiẹ ni iwa jibiti to tii ga julọ lorilẹede Naijiria ni owo ina sisan, o ni wọn maa n mu awsn ni tipa lati san owo ina ti wọn ko lo, lẹyin eyi ni eeyan kan yoo wa ni oun n gbogun tiwa ajẹbanu.
Ẹ jọwọ, iru iwa ajẹbanu wo lo tun ju eyi lọ?
Ojnimi @Ojnimi sọ loju opo rẹ pe iwa ijanilole to buru jai ni eyi. Ẹ wo ileesẹ amunawa to wa ni Ikeja to ni ki n san owo ina ẹgbẹrun mẹtadinlogun losu to kọja, amọ losu yii, ẹgbẹrun lọna mejidinlogun lo tun ni ki n san.
Ki lo de na, se a pa baba yin ni? Buhari ati Osinbajo, ẹ wa nkan se lori owo ina gọbọi ko to di pe a bẹrẹ si ni fi ẹhonu han.
Bakan si ni ọpọ ọmọ Naijiria koro oju si iwe owo ina gege ti ileesẹ amunawa ni Naijiria fisita, eyi ti wọn n pariwo pe ko ba awọn lara mu.
Abu Bakr al-Baghdad: Orílẹ̀èdè Amẹrika náà ti kọlu aṣaájú ẹgbẹ́ ISIS
Oríṣun àwòrán, AFP
Awọn ologun orilẹede Amẹrika ti kọlu asaaju ẹgbẹ adunkooko mọni ISIS, Abu Bakr al-Baghdad.
Aarẹ orilẹede Amerika, Donald Trump lasiko to n soro pataki nipa isẹlẹ naa ni Abu Bakr al-Baghdad ku bi aja, ti o si n pariwo pe oun ko fẹ ku.
Aarẹ Trump sọ wi pe ko ku bi ajagun tabi akinkanju, nitori naa oun fẹ ki awọn to n tẹle mọ wi pe ọlẹ to n gbọn jinijini ni Abu Bakr al-Baghdad ki o to ku.
Ọpọ igba ni iroyin ti n ja tẹlẹ pe wọn ti pa agbesunmọmi ọhun, ti awọn oju ewe iroyin to n tọkasi awọn alasẹ ti ko darukọ ni ikọ ọmọ ogun Amẹrika dojukọ asaaju ikọ adunkokomọni naa lasiko ikọlu to waye lagbegbe Idlib, lẹkun iwọ oorun ariwa orilẹede Syria.
"Oludari ikọ ologun Syrian Democratic Forces (SDF) ti ẹya Kurd n dari, Mazloum Abdi salaye pe ""ikọlu manigbagbe to jẹ aseyọri"" lo waye lati ipasẹ ""isẹ ọpọlọ ajumọse"" pẹlu orilẹede Amẹrika."
Abu Bakr al-Baghdad nii se asaaju ẹgbẹ agbesunmọmi IS, ẹni ti wọn se apejuwe gẹgẹ bii ẹni ti wọn n wa julọ lagbaye.
Losu Kẹwa ọdun 2011, orilẹede Amẹrika kede rẹ bii 'Adunkokomọni' to si kede miliọnu mẹwa dọla bii ẹbun owo fun ẹnikẹni to ba pese iroyin lori bi wọn se lee mu tabi paa. Owo yi si ni wọn tun safikun rẹ si miliọnu mẹẹdọgbọn dọla lọdun 2017.
Ọmọ ilu Baghdad naa lo gbajumọ fun sise ọpọ ikọlu to n mu ẹmi eeyan lọ.
Ilu Samarra, lẹkun ariwa Baghdad ni wọn ti bi lọdun 1971, orukọ rẹ gangan si ni Ibrahim Awad al-Badri.
Iroyin kan ni ojisẹ Ọlọrun ni ninu mọsalasi kan lasiko ti orilẹede Amẹrika kọlu Iraq lọdun 2003, sugbọn awọn eeyan miran gbagbọ pe o ti di ajijagbara fun ẹsin Islam lasiko ti Saddam Hussein, asaaju orilẹede Iraq nigbakan ri, wa lori aleefa.
Awọn miran ni o ti di agbesunmọmi lasiko ti wọn mu nigbekun nibudo Camp Bucca, tii se ibudo kan to jẹ tilẹ Amẹrika nibiti wọn n fi awọn asaaju ikọ agbesunmọmi Al-Qaeda pamọ si.
Abu Bakr al-Baghdad lo wa di asaaju ikọ Al-Qaeda lorilẹede Iraq lọdun 2010, to si jẹ ọkan lara awọn ikọ agbesunmọmi to darapọ lati se agbekalẹ ikọ adunkooko mọni IS, to si di ilumọọka lasiko ti wọn fẹ darapọ mọ ẹgbẹ ọlọtẹ al-Nusra ti orilẹede Syria.
Ambode: Ilé aṣòfin Eko ní kí gómìnà àná wá wí tẹnu rẹ̀ lórí owó ọkọ̀ BRT
Oríṣun àwòrán, @AkinwunmiAmbode
Ile igbimọ aṣofin ipinlẹ Eko ti kọwe pe gomina ana ni ipinlẹ naa, Akinwunmi Ambọde pe ko yọju niwaju igbimọ ile naa, to n ṣewadi awọn ohun kan to ṣokunkun lasiko iṣejọba rẹ.
Ile igbimọ aṣofin ipinlẹ Eko ni Ọjọru ni wọn fun Ambọde lati farahan, ki o lee wa ṣe afọmọ ọrọ nipa awọn inawo kan to waye ni saa iṣejọba rẹ.
Bi o tilẹ jẹ wi pe o ti ṣe diẹ ti iroyin lori pipe Ambọde ti n waye nile asofin ipinlẹ Eko, ṣugbọn ọrọ naa ṣẹṣẹ ja gbangba ni pẹlu bi ile ṣe fi iwe ipe rẹ soju ewe iwe iroyin lọjọ abamẹta.
Oríṣun àwòrán, @AkinwunmiAmbode
Olori ile aṣofin ipinlẹ Eko, Mudaṣiru Ọbada gbe igbimọ ẹlẹni mẹrindinlogun kan kalẹ, lati tan ina wo eto inawo ra ọkọ akero nlanla BRT atawọn akanṣe iṣẹ miran.
Awọn akanse isẹ naa lo da lori ileeṣẹ to n fọ irẹsi ni Imọta, Imota Rice mill, ọna olobiripo to wa l'Oṣodi ati ina oju popo LED-UK streetlight project ti wọn ni gomina Ambọde ṣe nigba to wa lori aleefa.
Bakan naa ni olori ile aṣofin ni Ambọde ko gba ifọwọsi ile aṣofin ọhun ki o to rawọ le rira awọn ọkọ nla akero BRT okoolelẹgbẹrin to ra.
Yọmi Fabiyi: Ọ̀pọ̀ òṣèré ló ń ṣe ìlara akẹgbẹ́ wọn lórí ayélujára èyí tó ń fa ìjà
Oríṣun àwòrán, Yomi Fabiyi
Ọpọlọpọ awọn oṣere lo n lo oju opo ayelujara lati ṣe ibajẹ awọn oṣere ẹgbẹ wọn, asiko si ti to fun awọn alẹnulọrọ nileeṣẹ amuludun, paapaa ere tiata, lati wa nnkan ṣe si ọrọ yii.
Yọmi Fabiyi, tii se ilumọọka osere tiata kan lo woye ọrọ yii, lasiko to kopa lori eto kan ni ileeṣẹ BBC News Yoruba, pẹlu afikun pe, ọpọ awọn oṣere lo maa n ṣe koriya fun awọn ololufẹ wọn lati tako oṣere ẹgbẹ wọn.
Nigba ti o n pẹ ọrọ sọ lori ija to wa laarin Liz Anjọrin ati Toyin Abraham, Yọmi Fabiyi ni abosi ati aifẹ dojukọ otitọ ohun gan to fa wahala laarin awọn oṣere tiata mejeeji yii, lo jẹ ki ija naa wa nilẹ fun ọjọ pipẹ.
Oríṣun àwòrán, Yomi fabiyi
O ni ọpọlọpọ iwa ilara lo n farahan laarin awọn oṣere tiata eleyi ti o ti n ran awọn ololufẹ wọn.
O ni ika ti wọn ṣe fun Lizzy Anjọrin lo mu ko pariwo sita, ti oun naa si ja pada lori ọrọ to waye laarin oun ati Toyin Abraham.
Gẹgẹ bii ọrọ rẹ, n ṣe ni Toyin Abraham maa n lo ayederu oju ayelujara pẹlawọn ololufẹ rẹ kan, lati maa sọ ọrọ buruku si awọn akẹẹgbẹ rẹ ati pe, eyi to ṣe si Lizzy Anjorin lo faa ti Lizzy naa fi fesi pẹlu rẹ.
Yomi Fabiyi ni igbesẹ ti ọpọ n gbe lati pari ija laarin Lizzy Anjọrin ati Toyin Abraham lai ba awọn mejeeji wi nitori iwa ibajẹ ti wọn hu, ko lee dẹkun atunṣe irufẹ iwa bẹẹ lọjọ iwaju.
Oríṣun àwòrán, yomi fabiyi
O ni o yẹ kawọn araalu tubọ yẹ ọrọ naa wo finifini, to fi jẹ pe Toyin nikan ni awọn eeyan bii Funkẹ Akindele, Bimbọ Ọṣin, Fathia Williams ba ni gbun-gbun-gbun lai jẹ pe, oun yii naa nikan lo wa nileeṣẹ ere tiata Yoruba lorilẹede Naijiria.
O ni ka ni Toyin Abraham gbe Liz Anjọrin lọ sile ẹjọ naa, ko si bi ko ṣe ni jẹbi bọ nibẹ nitori ẹri iwa ibajẹ rẹ wa nilẹ.
Bakan naa lo tun sọrọ lori idojukọ ti gbajugbaja adẹrinpoṣonu osere tita Yoruba, Babatunde Omidina, tọpọ eeyan mọ si Baba Suwe, ni pẹlu ajọ to n gbogun ti ogun oloro lorilẹede Naijiria, NDLEA.
Yọmi Fabiyi ni didakẹ ti ẹgbẹ oṣere tiata Yoruba dakẹ lasiko idojukọ naa ku diẹ kaa to, ko si ṣapẹrẹ ẹgbẹ naa gẹgẹ bii eyi to karamasiki igbayegbadun awọn oṣere tiata.
Ẹ wo ǹkan tí àwọn ènìyàn ń sọ nípa Tiwa Savage àti Wizkid tó fẹnu ko ara wọn
Oríṣun àwòrán, Twitter
Òri ẹ̀rọ ayélujara ń gbóná jainjain lẹ́yìn tí fídíò kan jáde níbi tí Tiwa Savage àti Wizkid ti ń fẹnu ko ara wọn.
Ọpọ ololufe gbajugbaja awọn olorin takasufe ọmọ Naijiria Tiwa Savage ati Wizkid lo n fi ero wọn han lori ẹrọ ayelujara lẹyin ti wọn ri fidio kan ninu eyi ti awọn akọrin mejeeji naa ti f'ẹnu ko ara wọn lẹnu.
L'oju opo Twitter ni awọn eniayn ti n bere pe ki lo wa laarin awọn mejeeji, se ololufẹ ni wọn ni tabi ọrẹ lasan?
Bi awọn kan se n bu ẹnu atẹ lu bi awọn mejeeji se fi ẹnu ko ara wọn , ni awọn miran sọ wi pe ifẹ to wa laarin awọn mejeeji wu awọn.
Amọ, ni ọpọ igba ni Tiwa savage ati Wizkid ma n sọ wi pe ọrẹ timọtimọ ni awọn mejeeji.
Tunde Bakare: Èbù ìkà táwọn kan ń gbìn, ọmọ wọn á jẹ níbẹ̀
Oríṣun àwòrán, Facebook/Tunde Bakare
Faabada! Ẹ ko nii lọ lai pọ ohun ti ẹ ji! Pasitọ ijọ Latter Rain Assembly, Tunde Bakare lo sọrọ yii nigba to n waasu lọjọ Aiku.
Pasitọ Bakare to ṣe agbatẹru ẹgbẹ Save Nigeria Group sọrọ lowelowe ninu iwaasu ọjọ Aiku ninu ijọ rẹ.
Bakare woye pe, ''aimọkan lo mu awọn eeyan maa ki ole to ji nnkan wọn ni mẹsan an mẹwaa, wọn ni oninure ni ati wi pe o lawọ.''
Alufa Bakare to figba kan dije pẹlu Aarẹ Muhammadu Buhari gẹgẹ bi igbakeji aarẹ sọ pe, aṣiwere ni ẹnikẹni to ba le sọ pe ẹnikan ti ji owo ilu ni tootọ ṣugbọn oninure lẹni naa.
Pasitọ ijọ Latter Rain ni idi niyii ti oju titi fi kun fun koto ati gegele nitori wọn ti ko owo to yẹ ki wọn fi ṣatunṣe ọna jẹ, lati igba ti orilẹede Naijiria ti pada si ijọba awarawa.
Pasitọ Bakare ni ''niṣe ni wọn n kọle kiri bi ẹyẹ, wọn nile ni Bourdillon, bẹẹ ni wọn nile kaakiri nitori wọn ti k'owo ilu jẹ.''
O fikun ọrọ rẹ pe, ebu ika ni wọn n gbin, o si di dandan ki ọmọ wọn o jẹ nibẹ.
Bakare ni o ṣeni laanu wi pe awọn ole ti wọn ti ji owo ilu lawọn ọmọ Naijiria n gboṣuba fun, nigba ti wọn n tako awọn to n ja fun wọn.
O ni ijọba ko tii ṣe ohun to yẹ ko ṣe lori ẹkun omi to n yọ ilu Eko lẹnu lọdọọdun.
Pasitọ Latter Rain Assembly tun sọrọ lowelowe lori ibo aarẹ ọdun 2023, o ni ''ẹ ku oriire o ẹyin ti ẹ fẹ dije fun ipo aarẹ, amọ ko lee ṣeeṣe ki ẹ ji ohun to jẹ ti gbogbo ọmọ Naijiria.''
Ajọ ọtẹlẹmuyẹ DSS ti gbe Tunde Bakare ri lọdun 2002 lori ẹsun wi pe iwaasu ta ba ijọba to wa lode.
ASUU: Adari ilé aṣòfin àgbà l'Abuja ṣèpàdé pẹ̀lú wọn lórí ááwọ̀ nípa IPPIS
Oríṣun àwòrán, Twitter/ASUU
Ẹgbẹ awọn olukọ fasiti ni Naijiria, ASUU yoo ṣepade pẹlu awọn adari ile aṣofin agba mejeeji l'Abuja lọjọ Aje, ọjọ kejidinlọgbọn oṣu kẹwaa lori ilana igbalode ti ijọba fi n san owo oṣu, IPPIS.
Ẹ o ranti pe Aarẹ Muhammadu Buhari paṣẹ ninu aba eto iṣuna ọdun 2020 pe, gbogbo oṣiṣẹ ijọba gbọdọ forukọ silẹ fun ilana IPPIS lati le gbogun ti iwa ibajẹ ati lati jẹki ijọba apapọ lanfaani lati fowo pamọ.
Amọ, ajọ ASUU tako igbesẹ Aarẹ yii, wọn ni igbesẹ naa lodi sofin to fun ajọ ASUU lagbara lati maa ṣakoso ara rẹ.
Ajọ ASUU tiẹ tun sọ pe, lai sanwo fawọn olukọ fasiti, awọn ko ni ṣiṣẹ, lẹyin ti ijọba ni awọn oṣiṣẹ ti ko ba forukọ silẹ fun ilana IPPIS ko ni gbowo oṣu.
Ẹwẹ, oluṣiro owo apapọ ni Naijiria, Alhaji Ahmed Idris ni bi ajọ ASUU ṣe tako ilana IPPIS fihan pe ajọ naa fọwọ si iwa ajẹbanu.
Bakan naa, minisita eto inawo, Zainab Ahmed sọ pe gbogbo ẹka ijọba lo yẹ ko faramọ ilana IPPIS.
Oríṣun àwòrán, @favloadedblog
Amọ, aarẹ ajọ ASUU, Ọjọgbọn Biodun Ogunyemi ṣalaye pe ASUU ṣetan lati jiroro pẹlu ile aṣofin agba l'Abuja lori ọrọ IPPIS, atawọn ọrọ miiran to ni ṣe pẹlu ọrọ eto ẹkọ lapapọ lorilẹede Naijiria.
Sugbọn ibeere ti ọpọ eeyan wa n beere ni pe se ipade ti ẹgbẹ ASUU n lọ se labuja naa, yoo fi eegun otolo to aawọ yii, ti wn yoo si so ẹwu iyansẹlodi kọ abi wọn yoo papa yansẹlodi?
Awọn eeyan ti bẹrẹ si ni sọrọ lori awuyewuye IPPIS to ti di faakaja laarin ASUU ati ijọba apapọ bayii.
Ọpọ eeyan loju opo Twitter lo dẹbi ru ajọ ASUU, wọn sọ pe dundu ASUU naa ti n lata ju.
Bello El-Rufai ni tiẹ sọ pe, onijẹgudujẹra ni ajọ ASUU, ko da o ni ajọ naa nilo itusilẹ.
EL-Rufai ni pẹlu ilana IPPIS, o ṣeeṣe ki ijọba apapọ ri owo to to biliọnu mẹẹdọgbọn naira fi pamọ lori awọn oṣiṣẹ ofege lawọn fasiti ni Naijiria.
Bakan naa lawọn mii kin ọrọ El-Rufai lẹyin, wọn ni o yẹ ki ajọ ASUU naa so ewe gbejẹẹ mọwọ.
Ẹbẹ lawọn akẹkọọ n bẹ ajọ ASUU ni tiwọn, wọn ni ki wọn fiyedenu, ki wọn jẹki awọn pari eto ẹkọ awọn ki wọn to gunle iyanṣẹlodi.
Buhari Foreign Trips: Ìrìnàjò ààrẹ Buhari sílẹ̀ òkèèrè kò nípa kankan lórí ọrọ̀-ajé Nàijíríà
Oríṣun àwòrán, Instagram/Bashir Ahmad
Lẹyin ọjọ meji to de lati irinajo rẹ si orilẹ-ede Russia, Aarẹ Muhammadu Buhari tun ti mori le ilẹ Saudi Arabia bayii.
Oludamọran Aarẹ lori ọrọ iroyin, Garba Shehu ṣalaye pe aarẹ n lọ fun apero kan lori eto idokowo fun ọjọ iwaju ti wọn pe akori rẹ ni ''Ki lo kan ninu idokowo lagbaaye.''
Shehu ni eto naa yoo bẹrẹ lọjọ Iṣẹgun, ọjọ kọkandinlọgbọn, oṣu kẹwaa, yoo si wa sopin lọjọ kọkanlelọgbọn, oṣu kẹwaa.
Gomina ipinlẹ Borno, Babagana Zulum, Abubakar Bagudu ti ipinlẹ Kebbi ati Aminu Bello Masari ti ipinlẹ Katsina ni yoo kọwọ rin pẹlu aarẹ.
Oludamọran Aarẹ, Shehu ni yoo lọ fun eto Umrah niluu Mecca lẹyin apero ti yoo waye niluu Riyadh.
Amọ, onimọ ọrọ aje, Ọgbẹni Bisi Iyaniwura sọ pe irinajo Aarẹ Buhari silẹ okeere lati igba to ti dori aleefa lọdun 2015 ko tii nipa rere kan lori ọrọ-aje orilẹ-ede Naijiria.
Oríṣun àwòrán, Instagram/Bashir Ahmad
Ọgbẹni Iyaniwura sọ pe Buhari kan ṣa n kọwọbọ iwe lasan ni pẹlu ọpọlọpọ awọn olori orilẹ-ede nilẹ okeere, ṣugbọn ko tii so eso rere kankan.
Iyaniwura ni ''gbogbo irinajo ti aarẹ Buhari ti lọ ko ti mu ki ijọba da ile iṣẹ silẹ.''
O fikun ọrọ rẹ pe aarẹ kan n nawo Naijiria lori awọn irinajo yii papaa julọ bi o ti kọwọ rin pẹlu awọn gomina.
O kepe ile aṣofin agba l'Abuja lati maa beere ipa ti irinajo Buhari yoo ni lori ọrọ aje Naijiria, nigba kuugba to ba tajo de.
Irinajo Buhari silẹ okeere
Akọsilẹ fihan pe Aaarẹ Buhari ti rinrin ajo lọ silẹ okeere nigba mọkanlelaadọta lati igba to ti di aarẹ Naijiria lọdun 2015.
Akọsilẹ iwe iroyin kan ni Naijiria sọ pe Buhari lo ida kan ninu idamẹta ọdun mẹta to kọkọ lo lọfiisi ni lati igba to ti di aarẹ lọdun 2015.
Ọpọ igba yii ni aarẹ Buhari fi wa niluu London  nibi to ti n gba itọju lẹyin to ṣaarẹ.
Buhari ti rinrin ajo silẹ okeere nigba mẹrin laarin oṣu mẹta to kọja.
Lootọọ ile iṣẹ aarẹ sọ pe awọn irinajo naa ṣe pataki, ṣugbọn ọpọ ọmọ Naijiria lo sọ pe aarẹ si le ran aṣoju lọ si awọn orilẹ-ede yii k'oun le gbajumọ awọn nnkan mii nile.
Wọn ni eyi ko ba din inawo ijọba orilẹede Naijiria ku lori awọn irinajo yii ku.
Oríṣun àwòrán, Instagram/Bashir Ahmad
Irinajo si orilẹ-ede Japan
Aarẹ Buhari rinrin ajo lọ si ilẹ Japan loṣu kẹjọ fun apero lori idagbasoke fun awọn orilẹ-ede ilẹ Adulawọ, TICAD7.
Ọjọ mẹfa ni aarẹ lo niluu Tokyo fun apero naa to jẹ ẹlẹẹkeje iru rẹ.
Irinajo si orilẹ-ede Amẹrika
Ninu oṣu kẹsan an ni aarẹ Buhari lọ si ilu New York fun apejọ ajọ iṣọkan agbaye to jẹ ẹlẹẹkẹrinlaadọrin iru rẹ.
Buhari ni aarẹ orilẹ-ede karun un ti yoo sọrọ nibi to ti sọrọ lori bi oju ọjọ ṣe n yipada.
Ọjọ mẹta ni aarẹ ati awọn iṣọmọgbe rẹ lo niluu New York lorilẹ-ede Amẹrika ki wọn to pada sile.
Irinajo si orilẹ-ede South Africa
Ni ibẹrẹ oṣu kẹwaa ni Aarẹ Buhari lọ si ilẹ South Africa nibi to ti ṣepade pẹlu Aarẹ Cyril Ramaphosa lẹyin iṣẹlẹ inunibini tawọn ọmọ orilẹ-ede naa ṣe si awọn ọmọ Naijiria to n gbe nibẹ.
Aarẹ Buhari fi ẹhonu rẹ han lori iṣẹlẹ ọhun ninu ipade rẹ pẹlu aarẹ Ramphosa, ọjọ mẹta ni Buhari lo nibẹ ko to pada wale.
Irinajo si orilẹ-ede Russia
Aarẹ Buhari ṣẹṣẹ de lati orilẹ-ede Russia nibi to ti lo ọjọ mẹta.
Agbẹnusọ fun ile iṣẹ aarẹ ni ọrọ eto aabo, okowo, imọ ijinlẹ ati ipese gaasi afẹfẹ idana lo gbe Buhari lọ si Russia.
INEC: Bí olóṣelú ṣe náwó lásìkò ìbò ló kàn wá, kìí ṣe pínpín èròjà oúnjẹ
Oríṣun àwòrán, Other
Ajọ eleto idibo nilẹ wa ti kede pe ohun ti wọn ba fi Ẹlẹmọsọ toun sọ, ni oun maa n sọ, nitori naa, isẹ toun kọ ni lati tọpintọpin awọn eroja tawọn oloselu ba n pin fawọn araalu lasiko ipolongo ibo, lati fa oju wọn mọra.
Inec ni iwa pinpin iyọ, irẹsi, gaari atawọn eroja ounjẹ miran lasiko ipolongo ibo kii se ara isẹ awọn, idi ree ti awọn se n gboju kuro nibẹ.
Olori ẹka eto ilanilọyẹ fawọn oludibo ati ipolongo fun araalu labẹ ajọ eleto idibo nipinlẹ Bayelsa, Wilfred Ifogah lo sọ bẹẹ lasiko to n fesi si ẹsun naa, ti wọn fi kan awọn oloselu kan.
Oludari agba fun ikọ kan to n tọpinpin eto idibo yika ilẹ Afirika, YIAGA, Samson Itodo lo salaye fun Inec pe ni ọkọọkan ijọba ibilẹ to wa nipinlẹ Kogi ati ni Bayelsa, ti ibo gomina yoo ti waye laipẹ yii ni wọn ti n pin awọn eroja ounjẹ lati fa oju awọn oludibo mọra.
"Itodo ni ""Ajọ Inec yẹ ko se agbekalẹ eto kan nifọwọkọwọ pẹlu awọn oloselu nipinlẹ kọọkan lati ri daju pe adinku ba asa fifi owo ra ibo ati tita kaadi idibo to fi mọ oniruuru iwa aidaa miran to nii se pẹlu fifa oju awọn oludibo mọra."""
Oríṣun àwòrán, @inecnigeria
"Nigba to n fesi lori awọn ẹsun naa, Ifogar salaye pe ""Ajọ Inec kii tọpinpin iru iwa bayii bii pinpin iyọ, irẹsi atawọn ohun miran lasiko ipolongo ibo lati ra ibo amọ awọn oloselu yii maa n fiwe pe wa lati wa tọpinpin ihuwasi wọn lasiko ipolongo ibo wọn, bakan naa si la n tọpinpin inawo wọn."""
Ifogar fikun pe ẹka kan wa labẹ ajọ Inec to n ri si eto idibo, itọpinpin awọn ẹgbẹ oselu ati fifi imu finlẹ nipa owo ti wọn ba na lasiko ipolongo ibo, eyi ti wọn ti n se lasiko ti ipolongo ibo ti bẹrk nipinlẹ Kogi ati Bayelsa.
AMAA 2019: Aṣọ ń pe aṣọ ránṣẹ́ lásìkò àyẹyẹ àmi ẹ̀yẹ fáwọn òṣèré tíátà
Oríṣun àwòrán, @solasobowale
Idi isẹ ẹni laa ti mọ ni lọlẹ, ohun gbogbo si lo ni ere, ka sa maa se daada.
Gbaju gbaja osere tiata lobinrin, Sola Sobowale, ni odu rẹ kun juls lagbo awsn osere tiata lobinrin nigba ti o gba ami ẹyẹ osere tiata obinrin to pegede julọ.
Sobowale gba ami ẹyẹ naa lasiko ayẹyẹ fifi ami ẹyẹ da awọn osere tiata to se gudugudu meje ati yaya mẹfa ninu ere tiata lọla, ti wọn n pe ni AMAA 2019.
Loju opo Instagram rẹ, olorire alami ẹyẹ naa, Sola Sobowale ti ki ara rẹ ku oriire, tawsn eeyan naa si n ba yọ pẹlu.
Bakan naa ni Adesua Etomi gba ami ẹyẹ obinrin to pegede sikeji lasiko ayẹyẹ ifami ẹyẹ danilọla AMAA naa, ikẹẹdogun iru rẹ.
Oríṣun àwòrán, @adeesuaetomi
Wayi o, ẹnu ko gba iroyin lori oniruuru asọ alarabara tawọn gbajumọ osere tiata wọ lọ sibi ayẹyẹ ifamiẹyẹ danilọla naa, ti asọ si n pe asọ ransẹ nibẹ.
Oríṣun àwòrán, @AMAAWARDS
Oríṣun àwòrán, @AMAAWARDS
Oríṣun àwòrán, @AMAAWARDS
Atiku Appeal: Ilé ẹjọ́ tó ga jùlọ ní Nàìjíríà yóò gbẹjọ́ kòtẹ́milọ́rùn PDP lọ́jọ́rùú
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Oludije ẹgbẹ oṣelu PDP ninu idibo aarẹ dun 2019 Naijiria n tako ijaweolubori aarẹ Buhari
Ile ẹjọ to ga julọ lorileede Naijiria ti da Ọjọru ọgbọn ọjọ oṣu Kẹwa to n bọ gẹgẹ bi ọjọ ti yoo gbẹjọ kotẹmilrun ti oludije ẹgbẹ oṣelu PDP Atiku Abubakar n gbe bọwa lori idibo aarẹ 2019.
Igbẹjọ yi n waye lẹyin ti Atiku kọwe kotẹmilọrun lori idajọ ile ẹjọ kotẹmilọrun to ti waye ṣaaju.
Ẹgbẹ oṣelu PDP lo kede ọrọ yi loju opo Twitter wọn ti wọn si ni ''asiko to bayi lati doola Naijiria''
Ẹgbẹ alatako naa ni awọn ṣetan lati tako esi idibo to gbe aarẹ Buhari wọle  lọdun 2019.
Ninu iwe kotẹmilọrun ti wọn fi ṣọwọ sile ẹjọ to ga julọ, wọn ni igbimọ igbẹjọ idibo naa ṣe aṣiṣe ninu idajọ wọn.
Bakan naa ni wọn sọ pe aarẹ Buhari ko sọ ootọ fun INEC nipa iwe ẹri rẹ to fi kalẹ.
Loṣu kẹsan, igbimọ olugbẹjọ idibo fọwọ rọ ẹsun ti Atiku gbe wa si iwaju rẹ pe ko fi ẹsẹ mulẹ to.
Atiku ati ẹgbẹ oṣelu PDP ni awọn fẹ ki ile ẹjọ to ga julọ wọgile idajọ ile ẹjọ kotẹmilọrun, ki wọn si kede Atiku gẹgẹ bi aarẹ.
Alága SUBEB: A ṣetán lá ti gba owó ìrànwọ́ Almajiri ní ìpínlẹ̀ Oyo
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ile iṣẹ to n mojuto eto ẹkọ kariaye nipinlẹ Oyo ta mọ si UBE lawọn ko ti ri iwe gba lati ọdọ ijọba apapọ nipa eto iranwọ ẹkọ Almajiri  ni ipinlẹ naa.
Alaga ajọ naa ọmọwe Nureni Adeniran to ṣalaye ọrọ yi fun ileeṣẹ iroyin BBC sọ pe nigba kigba to ba de,awọn ṣetan lati gba tọwọ tẹsẹ.
Laipẹ yi ni ijọba apapọ kede pe awọn ti ṣeto owo iranwọ ẹgbẹrin din meje miliọnu naira feto ẹkọ Almajiri.
Eto yi la gbọ pe ipinlẹ mẹwaa yoo jẹ anfaani rẹ ti ipinlẹ Oyo si jẹ ọkan lara wọn.
Nureni Adeniran ni lọwọ bayi, awọn eto miran wa nilẹ fawọn ọmọ ti ko si ni ile ẹkọ ti ipinlẹ Oyo ni lọkan lati ṣe.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Eto yi la gbọ pe ipinlẹ mẹwaa yoo jẹ anfaani rẹ ti ipinlẹ Oyo si jẹ ọkan lara wọn.
Nigba ti a beere lọwọ rẹ boya awọn ọmọ Almajiri wa ni ipinlẹ Oyo, Nureni ni pe wọn wa, ṣugbọn ati Almajiri ati awọn miran ti ko lọ si ile iwe ni eto naa yoo ṣe lanfaani.
''A ni awọn ọmọ Almajiri yi ni adugbo Sabo ati ni Oke Ogun. Awọn ya mi yatọ si Yoruba wa ninu wọn ṣugbọn gbogbo wọn ti da papọ mọ ara wọn''
O ṣalaye pe inu awọn dun si igbese yi ti awọn si lero pe yoo mu adinku ba iye awọn ọmọ ti ko si ni ile ẹkọ nipinlẹ naa.
Ijọba apapọ pàdí ọrẹ́ dà lori Almajiri
Ko pẹ si igba yi ni ijọba Naijiria sọ pe awọn yoo gbe igbesẹ lati wọgile eto ẹkọ Almajiri ti ijọba to ṣaaju rẹ.
Ọrọ naa ṣebi fakinfa ti agbẹnusọ ileeṣẹ aarẹ Garba Shehu si pada ṣalaye pe awọn ko ni tii wọgile eto naa amọ awọn ko ni jẹ ki ohun to ba awọn ile ẹkọ Almajiri ti ijọba tẹlẹ da silẹ ṣẹlẹ sawọn naa.
O ṣalaye pe awọn yoo ṣeto tuntun eleyi ti awọn ipinlẹ tọrọ kan naa yoo da si eto wọn.
Ko ti i si alaye lẹkunrẹrẹ lori bi wọn yoo ti ṣe ṣeto yi amọ owo ti wọn fẹ naa ni wọn ti ṣe atupalẹ rẹ.
Lọdun 2019, irinwolemẹrindinlogun miliọnu Naira ni wọn yoo na, nigba ti wọn yoo na ọọdunrunlenimọkandinlọgbọn naira le diẹ ni 2020, milionu mẹrindinlogoji naira ni wọn yoo na ni 2021 ti owo ina lori eto yi lọdun 2022 si jẹ miliọnu mọkanla naira le diẹ.
Ofada Rice: kíni ẹ̀yin gbádùn nínú ìrẹsì ọ̀fadà?
Brexit: Àwọn olórí ilẹ̀ Europe fẹnukò lórí àfikún sáà tí ilẹ̀ Gẹ̀ẹ́sì yóò kúrò pátápátá ní EU
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ajọ isọkan orilẹede nilẹ Europe, Europian Union, ti gba lati sun asiko ti United Kingdom yoo fi ajọ naa silẹ́ patapata di ọjọ Kọkanlelọgbọn Oṣu kinni ọdun 2020, kii si se ọjọ Alamisi ọsẹ yii mọ.
Aarẹ fun igbimọ alakoso ajọ EU Donald Tusk ṣalaye pe aaye ti wa fun UK bayii lati kuro ninu ajọ EU ko to di ipari osu Kinni ti fẹnu ko le lori, eyiun ti ile asofin ba fi ọwọ si.
Igbesẹ naa lo waye nibayii ti awọn asofin ilẹ UK n gbaradi lati dibo lori aba ti olootu ilẹ naa, Boris Johnson gbe siwaju wọn eyi to n beere pe ki wọn fontẹ lu sise eto idibo gbogbo gboo lojọ Kejila osu kejila ọdun 2019.
Amọ ẹgbẹ oselu SNP ati Lib Dem lo ti daba saaju pe ki wọn seto idibo naa lọjọ Kẹsan osu Kejila ọdun 2019.
Amọ ijọba ko tii wọgile erongba sise idibo lọjọ ti awọn ẹgbẹ oselu naa daba rẹ, eyiun to ba kuna lati gba ontẹ ile asofin fun ọjọ to beere fun nirọlẹ oni.
Ọjọ Alamisi ọsẹ yii lo yẹ ki UK kuro ninu ajọ EU sugbọn Johnson beere fun afikun saa ti wọn yoo kuro nibẹ lẹyin ti ile asofin apapọ ilẹ naa kuna lati faramọ awọn ilana to wa nilẹ lori bi UK yoo se kuro ninu ajọ EU.
Lọpọ igba ni Johnson ti maa n tẹnumọ pe UK yoo kuro ninu ajọ EU lọjọ kọkanlelọgbọn osu Kẹwa ọdun 2019, eyiun ọjọ Alamisi ọsẹ yii tii se gbedeke ọjọ to da, eyi to ni yoo jẹ lẹrọ abi ni tipa, sugbọn ofin ti paa lasẹ fun lati gba aba ọhun.
Tusk yoo wa beere ohun ti ilẹ UK fẹnuko le lori lori kikuro rẹ ni EU, lati ipasẹ iwe kan ti yoo kọ laarin awọn orilẹede mẹtadinlọgbọn miran to wa ninu ajọ EU, eyi to seese ko fi ransẹ lọjọ Isẹgun abi Ọjọru, ko to di pe o fontẹ lu afikun saa ti UK yoo lọ naa.
Aago mẹrin irọlẹ oni ni awọn asofin ni Uk yoo dibo lori igba ti eto idibo olootu Ijọba ilẹ Gẹẹsi yoo waye.
Foluke Daramola: Ìgbé ayé gbajúmọ̀ gbọdọ̀ ṣèwúrí fún àwọn èèyàn láti dé ibi gíga
Oríṣun àwòrán, @facebook
Saa laa ni, ẹnikan ko nile aye nitori igba lasọ, igba lẹwu, igba kan n lọ, igba kan si n bọ, aye ko duro soju kan.
Boya eyi ni gbajumọ osere tiata kan lobinrin, Folukẹ Daramọla Salakọ ro, to fi kọ̀ ironu akewi soju opo Instagram rẹ, eyi to fi n gba awọn akẹẹgbẹ rẹ nimọran nipa igbe aye rere.
Foluke ni ko si bi eeyan kan se lero pe oun gbajumọ to, saa ni yoo ni, ti irawọ rẹ yoo si tan fun igba kan nitori ko lee jẹ irawọ ti yoo tan fun gbogbo igba.
O ni awọn irawọ atijọ yoo wọọkun lọjọ kan, ti awọn irawọ tuntun yoo si maa dide bii itanna lawọn akoko kan.
Osere tiata naa ni ojoojumọ ni wọn n bi awọn irawọ tuntun, ti awọn irawọ kan si n jade laye, amọ ohun to se pataki ni pe ki eeyan jẹ gbajumọ to pegede.
O ni iru ẹni bẹẹ gbọdọ jẹ ẹni to n ko ipa gidi si awujọ to wa, ati ẹni ti eeyan lee gbẹkẹle, ti wọn yoo si maa gboju soke wo lọọkan  bii awokọse rere gẹgẹ bii iwuri ati koriya lati de ibi giga, tabi ẹni to n huwa rere, ti wọn lee wo lati se imusẹ awọn afojusun wọn nile aye.
Oríṣun àwòrán, folukedaramolasalako
Daramola ni Gbajumọ kii se gbajumọ gidi ti igbe aye rẹ ko ba lee se iwuri fun awọn ẹlomiran lati se lakaka fun ohun to dara ti wsn n fẹ laye.
O wa kadi asamọ rẹ nilẹ pe gbajumọ ko nilo lati maa tẹ ifẹ awọn eeyan kan lọrun ki wọn lee nifẹ rẹ nitori irufẹ igbe aye to n gbe ati awọn aseyọri rẹ, amọ o yẹ ko lee se koriya fawọn ẹlomiran lati lakaka de ibi giga.
Fọ́tò ló ṣàfihàn ibi tí ọmọ ti Nọọsi jígbé lódún 1997 wà
Aworan fọto àdáyà to kọkọ ṣafihan awọn mejeeji papọ
Osu Kini, ọdun 2015 ni ọmọbinrin ọdun mẹtadinlogun to n lọ ile iwe girama Zwaanswyk High School ni ilu Cape Town ri ohun iyanu!.
Cassidy Nurse ni ọdọbinrin naa to woye pe ẹni ti oun ṣẹṣẹ pade yii ti jọ oun ju.
Ona ile iwe naa nibi ti o ti pade ọmọbinrin miran, Miché Solomon to sẹsẹ wọ ile iwe wọn.
Gbogbo eniyan to ri awọn mejeeji lo sọ wi pe wọn jọ ibeji, ti Miche is sọ wi pe ni se lo dabi ẹni pe awọn ti mọ ara wọn fun ọpọlọpọ ọdun, ti ọdun mẹta to wa laarin ọjọ ori wọn ko si jẹ idiwọ tabi idena fun wọn.
Oríṣun àwòrán, MPHO LAKAJE
Miche Solomon lasiko yii
Lẹyin ipade yii ni awon mejeejidi ọrẹ ti wọn si maa n so fawon eniyan to ba beere lowo won pe se ibeji ni won pe awon ko mo, amo boya ni aye miran ibeji ni awọn.
Ni ọjọ kan, ni awọn mejeeji ba jọ ya fọto àdáyà papọ, ti awọn obi Cassidy si bẹrẹ si ni beere lọwọ Miche boya Ọgbọn ọjọ, Osu Kẹrin, ọdun 1997 ni wọn bi? ti o si sọ wi pe lootọ igba naa ni wọn bi oun.
Lẹyin ọsẹ diẹ ni awọn ọga ile iwe naa pe Miche si inu oọfisi ọga ile iwe naa ti wọn si sọ fun un wi pe nise ni wọn ji i gbe ni ọmọ ọwọ ni ile Iwosan ti wọn ti bii, Groote Schuur ni Cape Town.
Wọn tun sọ fun un pe orukọ rẹ ti wọn sọ ọ ni Zephany Nurse.
Amọ Michel ko gbagbọ, o tilẹ ba wọn jiyan wi pe ile iwosan Retreat Hospital ni wọn ti bi oun, nibi ti ko jina si ile iwosan ti wọn sọ wi pe wọn ti bii.
Oríṣun àwòrán, Image copyrightHUISGENOOT/NONCEDO MATHIBELA
Celeste Nurse ati Cassidy abilekeji ọmọ rẹ
Miche gba ki wọn se iwadii ẹjẹ rẹ nipa DNA, ti iwadii naa si fihan pe looto Zephany Nurse ni wọn ji gbe ni ọdun 1997.
Ọmọbinrin naa sọ wi pe ẹru ba oun nigba ti oun gbo gbogbo iroyin naa.
Ninu iwadii ni wọn ti rii pe ohun to wa ninu iwe ẹri ọjọ ibi Zephany kii ṣe otitọ rara nitori pe wọn ko ri akọsilẹ rẹ ni ile iwosan Retreat Hospital ti wọn ni wọn bii si.
Miche nigba ti o wa lọmọ oṣu mẹjọ pẹlu Michael
Lẹyin eyi ni wọn ri aridaju pe wọn ji Zephany gbe nile iwosan Groote Schuur ti wọn bii si ni Cape Town.
Bakan naa ni o gbọ wi pe iya rẹ to to tọ ọ dagba, Lavona Solomon wa ni panpẹ ọlọpaa, ti ọkan rẹ si daru pẹlu ibeere pe ki lo sẹlẹ, bawo lo se sẹlẹ? kilode ti wọn se ṣe bẹẹ?
Amọ, o ni wi pe iwadii fihan wi pe baba to tọ oun dagba ko mọ nkankan nipa bi wọn se ji oun gbe rara, ti awọn ọlọpaa si fi i silẹ pe ko maa lọ ni alaafia.
Lavona Solomon nile lẹyin to ni oun bimọ tuntun
Ọdun 2016 ni wọn ran Lavona lọ si ẹwọn ọdun mẹwaa fun ẹsun ijinigbe ati aibọwọ fofin to tẹ itọju ọmọ kekere mọlẹ.
Lasiko igbẹjọ Lavona, o ni wi pe nọọsi ti orukọ rẹ n jẹ Sylvia, ti o n fun oun ni itọju iwosan ki oun le bimọ lasiko lo lọ gbe ọmọ jojolo naa wa, ti o si sọ fun oun pe iya rẹ kọ ọ silẹ ni.
Amọ ile ẹjọ ko ri aridaju lori nọọsi naa, ti ko si si ẹri pe eniyan kan n jẹ orukọ naa.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Lavona Solomon (to bo oju re) nile ẹjọ ni Cape Town lasiko to n wọnu ile ẹjọ lọ fun igbẹjọ
Bi o tilẹ jepe Lavona sọ wi pe oun ko jẹbi ẹsun ti wọn fi kan oun, Miche sọ wi pe oun ko gbagbọ pe iya to toju oun ko jẹbi ẹsun ti wọn fi kan an.
O ni pe o lera fun oun lati darapọ mọ awọn idile tuntun ti iwadii fihan wi pe awọn gan an lo bi oun, amọ oun n tiraka diẹ diẹ.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Noosi Morne to jẹ baba Zephany gangan nigba ti o n jade nile ẹjọ lẹyin ti Adajọ ti dajọ
Miche Solomon to jẹ orukọ ti wọn sọ ọ ni kekere ni o n jẹ, amọ o sọ wi pe o tẹ oun lọrun ki awọn eniyan pe oun ni Zephany naa, nitori orukọ oun gangan niyẹn.
Oríṣun àwòrán, others
Michael ati ọmọ Miche nigba ti wọn n lọwo Lavona ni ọgba ẹwọn
Gbogbo ipá kò tíì pin lórí ọmọ ọdún méjì tó kó sí àǹga
Oríṣun àwòrán, BBC Sport
Ebi ọmọ to ja si kọnga
Ni bayii, awọn adoola ẹmi ẹni ko tii ri ọmọ ọdun meji ti o ja si inu kọnga gbe jade ni ilẹ India.
Oni lo di ọjọ kẹrin ti wọn ti n gbiyanju lati doola ẹmi ọmọde yii to ko si kanga.
Sujith Wilson ni orukọ ọmọde to n ṣere ni eti kanga ni bii iwọn ẹsẹ bata ọgbọn si kanga naa ni agbegbe Tamil Nadu ni orilẹ-ede India.
Ko pé ni wọn deede gbọ ariwo rẹ to n ja sinu kọnga ti o jin to ọgọsan an mita silẹ.
Awọn adoola ẹmi naa fi atẹgun inu igo si ara ọmọ naa ti o wa ninu kọnga ọhun, bo tilẹ jẹ pe wọn ko le sọ pato ipo ti ọmọ naa wa.
Sibẹ wọn ti gbe koto si ẹgbẹ kọnga ti ọmọ naa ko si, wọn si n fi ẹrọ igbalode fa omi inu kanga naa sita.
Lọjọ Ẹti ni Sujith ko si kanga nigba ti o n ba awọn ọrẹ rẹ ṣere.
Itara abiyamọ n mu iya Sujith bayii de ibi pe wọn kiyesi pe o lọ n ran apo to ro pe oun a lo fi yọ ọmọ oun sita ninu kanga to ko si.
Awọn Akọroyin ṣalaye pe, ni kete ti iṣẹlẹ naa waye ni iya rẹ ti bẹrẹ si n pe e ṣugbọn ti ko si dahun.
Isṣẹlẹ yii ti pe akiyesi ọpọlọpọ awọn eniyan ilẹ naa si ni eyi ti Olootu Ijọba, Narendra Modi si ti fi si ori ẹrọ ayelujara ni ọjọ Aje ibi ti iṣẹ didoola ẹmi ọmọ naa  de duro bayii.
Òyìnbó lásán ni 'consequential adjustment' ẹ ò tún gbọdọ̀ gé owó oṣù ní ìpínlẹ̀ mọ́ - NLC
Oríṣun àwòrán, Huw Evans picture agency
Ẹgbẹ́ òsìsẹ́ NLC ti ní N33,000 ni gbèdéke owó osù òsìsẹ́, lẹ́yìn tí ìgbìmọ̀ májẹ̀kóbàjẹ́ fi ọwọ́ sí N27,000.
Ẹgbẹ oṣiṣẹ Naijiria ni ipinlẹ Oyo ti fesi si ọrọ awọn Gomina Naijiria ti wọn ni ijọba apapọ ko le mu awọn nipa lati san afikun owo oṣu oṣiṣẹ tuntun nipinlẹ wọn.
Alaga ana fẹgbẹ oṣiṣẹ nipinlẹ Oyo Comrade Siyanbade Waheed Olojede ni nibi ti ọrọ de duro yii, ko tọ ki awọn Gomina yẹ adehun lori ọrọ owo oṣiṣẹ mọ.
Siyanbade ninu ifọrọwanilẹnuwo pẹlu BBC Yoruba sọ pe ''boju ba yẹju, ko yẹ ki ijọba yẹ ohun pẹlu awọn.''
Oríṣun àwòrán, @NLCHQ_ABUJA
Awọn ijọba ipinlẹ kan n wa ibinu ẹgbẹ osisẹ ni, awa naa si ti setan fun wọn
Alaga oṣiṣẹ tẹlẹ ri sọ pe gbogbo ijiroro to yẹ ki o waye lawọn oṣiṣẹ ti ṣe pẹlu ijọba apapọ ti wọn si ti fara da gbogbo aba ti ijọba mu wa nipasẹ adinku lori iye ti awọn beere.
O ni lopin igba ti owo tawọn Gomina naa n gba lowo oṣu ko yatọ lati ipinlẹ kan si omiran ko yẹ ki wọn maa sọrọ nipa gige owo oṣu nipinlẹ kan si omiran.
"''Ọna a ti mu oṣiṣẹ lẹru ni gbogbo oyinbo ti wọn sọ nipa ""consequential adjustments"". Ki wọn to fẹnuko lori iye owo yii, ko si ẹni ti ko ṣoju rẹ ninu awọn Gomina. Ki lo wa de ti wọn n sọ pe awọn tun fi lọ joko idunadura mii?"
''Ko bojumu a o si ni fẹ ki wọn maa roko si ibi ti wọn sọrọ si''
Oríṣun àwòrán, Inside Oyo
Comrade Siyanbade wa rọ awọn oṣiṣẹ lati san bantẹ wọn ko le daada nitori ọrọ to wa nilẹ yoo gba ki wọn gbaruku ti ẹgbẹ oṣiṣẹ.
O sọ pe laiṣe bẹ, mudunmudun to yẹ ki oṣiṣẹ jẹ lori ẹkunwo oṣu ko ni jẹ ti wọn.
O seese ki alekun owo osu fawọn osisẹ ni Naijiria fori sanpọn ni ọpọ ipinlẹ to wa lorilẹede yii nitori awọn gomina ti kede pe awọn ko lee sanwo ju agbara awọn lọ, bi ọwọ awọn ba se mọ ni eku awọn yoo se fi họri.
Alaga ẹgbẹ awọn gomina ni Naijiria, tii tun se gomina ipinlẹ Ekiti, Kayọde Fayẹmi lo sisọ loju ọrọ naa lẹyin ipade awọn gomina to waye lọjọ Aje nilu Abuja.
Fayẹmi ẹni to sọ pe igbimọ alasẹ ijọba orilẹede yii ko lee se ipinnu nipa sisan owo osu tuntun naa fun awọn ipinlẹ tun salaye siwaju pe ijọba apapọ ko ro tawọn ijọba ipinlẹ rara lasiko to fi n seleri pe oun yoo san ẹgbẹrun lọna ọgbọn naira gẹgẹ bi owo osu to kere julọ fawọn osisẹ.
"Fayẹmi ni ""Ijọba ipinlẹ kọọkan lo ni igbimọ alasẹ tiẹ, to jẹ igbimọ to ga julọ lati fẹnuko lori ipinnu sise, awọn ẹgbẹ osisẹ naa si wa lawọn ipinlẹ ti wọn yoo joko dunadura lori owo osu tuntun, nitori naa, ohun ti agbara wa ba ka laa se."
Oríṣun àwòrán, @NLCHQ_ABUJA
Musa Lawal ti wa kesi Fayẹmi pe ko sọ ọrọ ẹnu rẹ nitori awọn ọrọ kobakungbe to ba sọ lee fa ibinu awọn ẹgbẹ osisẹ.
Wayi o. Akọwe apapọ fun ẹgbẹ osisẹ NLC, Ugboaja ti wa fesi pada fun Fayẹmi pe ko si ipinlẹ kankan ti yoo sọ pe kii se ori sisan ẹgbẹrun lọna ọgbọn naira bii owo osu to kere julọ, ni koko idunadura pẹlu ẹgbẹ osisẹ.
Ikọọkan ipinlẹ ni yoo dunadura lootọ bi agbara ọrọ aje wọn ba se ka a, sugbọn ohun to ja ju ni pe ẹgbẹrun lọna ọgbọn naira ni yoo jẹ owo osu to kere julọ ti osisẹ kan yoo gba nipinlẹ wọn, amọ bi wọn yoo se wa yọ sira wọn pẹlu awọn lọgalọga osisẹ ku saarin ẹgbẹ osisẹ ati ijọba nipinlẹ kọọkan.
Oríṣun àwòrán, @NLCHQ_ABUJA
Awọn ijọba ipinlẹ kan n wa ibinu ẹgbẹ osisẹ ni, awa naa si ti setan fun wọn
Sugbọn lero ti akọwe apapọ fun ẹgbẹ osisẹ TUC, Origi Musa Lawal ti wa kesi Fayẹmi pe ko sọ ọrọ ẹnu rẹ nitori awọn ọrọ kobakungbe to ba sọ lee fa ibinu awọn ẹgbẹ osisẹ.
"Musa-Lawal ni ""Awọn ijọba ipinlẹ ni asoju ninu idunadura naa, ko si lee di akoko yii ki wọn wa sẹ lori ojuse wọn. Wọn kan n wa ibinu ẹgbẹ osisẹ ni, awa naa si ti setan fun wọn."""
Ìbálé ìyàwó: Àwọn onímọ̀ sọ ìdí tí àwọn obìnrin kan kìí ṣe sẹ̀jẹ̀ lẹ́yìn ìbálòpọ̀ àkọ́kọ́
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ibi gbogbo ni wọn ti nko adiẹ alẹ, akoko lo kan yatọ bẹẹ si ni bo se n bẹ ni liki naa lo wa ni gbanja.
Ọrọ gbigba ibale iyawo lo dabi ẹnipe ko mọ laarin iran Yoruba nikan, eyi to ti n fa wahala fun awọn idile kan jakejado agbaye.
Bi o tilẹ jẹ pe asa gbigba ibale iyawo lalẹ ọjọ igbeyawo ti n wọọkun lọ laarin ẹya Yoruba, amọ asa si rinlẹ digbin laarina ẹya Larubawa, eyi to n se akoba fun ọpọ igbeyawo bayii laarin ẹya naa.
Awọn obinrin mẹrin to ba BBC sọrọ lori asa yii salaye pe alẹ ọjọ ti ọkọ awọn fẹ gba ibale awọn, amọ ti ko mu ẹjẹ lọwọ, lo mu ko gbagbọ pe oun kii se ojulowo ọmọge eyi ti ko ri bẹẹ.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Iwadi awọn onimọ ijinlẹ si ti fidi rẹ mulẹ pe, kii se gbogbo obinrin ti wọn ba gba ibale rẹ ni yoo se ẹjẹ loju ara, nigba ti awọn obinrin kan tiẹ wa ti wọn ko mu ibale wa lati ọrun, tabi ki ibale wọn ti seesi ja lasiko ti wọn wa ni kekere nitori erepa to lagbara tabi ere idaraya ti wọn se.
A tun gbọ pe awọn ibale kan wa to ki pupọ, ti ko si lee tete ja, afi ti ọmọ ba fẹ gba oju ara obinrin jade nikan ni yoo to ja.
Obinrin to ba BBC sọrọ lo wa ni iru ipo taa darukọ yii, eyi ti ko jẹ ki igbeyawo rẹ tọjọ nigba ti ọkọ rẹ ko ri ẹjẹ ibale lara rẹ.
Somayya ja fitafita pẹlu awọn obi rẹ lati ri pe o fẹ Ibrahim, tii se ololufẹ rẹ nile iwe fasiti tori pe o dara lọmọkunrin, to si ni amuyẹ ọkọ rere.
Amọ alẹ ariwo ni alẹ ọjọ igbeyawo wọn, ti okun ifẹ wọn si rẹ ja patapata nigbati oju Ibrahim koro pe iyawo oun ko ni ibale nigba ti ẹjẹ ko jade lara rẹ lẹyin ajọsepọ wọn akọkọ.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
O ni bi o tilẹ jẹ pe Ibrahim fẹ kọ oun silẹ, amọ oun yari pe oun ko lọ sibi kankan, to si daba pe kawọn lọ se ayẹwo nile iwosan lati mọ oun to sẹlẹ si ibale oun.
Ile iwosan ti wọn ti wa sewadi pe ibale Somayya nipọn pupọ, to si ki pẹlu, idi ree to fi nira fun ọkọ rẹ lati jaa lalẹ ọjọ igbeyawo wọn, afi igba ti Somayya ba fẹ bimọ nikan si ni ibale naa to lee ja.
Somayya ni lootọ ni inu ọkọ oun dun lati gbọ eyi amọ ohun to dara ti bajẹ, ẹpa ko si boro mọ nitori o ti sọ ọpọ ọrọ kobakungbe si oun, to si ti hu ọpọ iwa abuku, ki asiri ohun adiitu naa to tu.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Lẹyin eyi ni Somayaa wa pinnu pe oun yoo kọ Ibrahim silẹ nitori o ti di ajeji si oun, ti oun ko si fẹ maa pe ẹni to n tẹle asa lati ni ifẹ oun, gẹgẹ bii ọkọ.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
"Somayya ni""lootọ lo n ba mi sun lẹyin alẹ ọjọ igbeyawo wa amọ se ni mo n lera tori pe ọkan mi ko nifẹ rẹ mọ lati alẹ ọjọ to ti safihan ikorira si mi."""
Viemens Bamfo: Ọmọ ọdún méjìlá tó gbèlé kẹ́kọ̀ọ́ dì àpéwò bó tí ṣé wọ ilé ẹ́kọ́ fásítì Ghana
Oríṣun àwòrán, Facebook
Ọmọ ọdun mejila kan lorileede Ghana ti di ilumọka lẹyin to pegede idanwo, ti wọn si gba wọle si fasiti orilẹede Ghana.
Ọmọdekunrin naa ti orukọ rẹ n jẹ Bamfo, ni akẹkọ ti ọjọ ori rẹ kere julọ laarin awọn bi ẹgbẹrun mẹta din ọgọrun, to n gbele kawe ti wọn gba wọle si fasiti naa lọdun yii.
Nigba to pari ile iwe alakọbẹrẹ lawọn obi rẹ bẹrẹ si ni gbele kọ ni ẹkọ, lẹyin igba naa lo kọ idanwo ile ẹkọ girama WASSCE to si pegede.
O ti bẹrẹ si ni kawe lati gboye ẹkọ iṣakoso oṣiṣẹ ọba ni fasiti Ghana to wa nilu Legon.
Oríṣun àwòrán, Kenny Senaya/Facebook
Awọn eeyan bẹrẹ si ni semọ ọmọdekunrin naa loju opo ayelujara pẹlu bi ko ti ṣe lọ si ile iwe girama, amọ ti o si fakọyọ ninu idanwọ ile iwe girama to tun wọ fasiti lọmọ ọdun mejila.
Gẹgẹ bi ohun to sọ, o ni ohun fẹ di aarẹ orileede Ghana ni ẹni ogoji ọdun lọjọ iwaju.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí:
Kogi Prison: Kò sí ẹ̀mí kankan tó nù, a sì tí rí lára àwọn tó fẹsẹ̀ fẹ́ ẹ
Oríṣun àwòrán, Others
Awọn alaṣẹ ọgba ẹwọn agbegbe Koton-karfe ni ipinlẹ Kogi ti ẹkun omi ti ṣọṣẹ ni awọn ti ri lara awọn ẹlẹwọn to sa lọ pada ko si si ẹmi kankan to nu.
Latari ẹkun omi yii lawọn ẹlẹwọn fi fẹsẹ fẹ ẹ nigba ti wọn rii pe ogiri ibi ti wọn ko wọn pamọ si ti ya.
Ninu ọrọ ti ọgbẹni OF Enobore fọwọ si lorukọ ileeṣẹ naa, oludari agba ile iṣẹ to n ṣamojuto awọn ọgba ẹwọn ni Naijiria, Ja'afaru Ahmed paṣẹ pe ki wọn ko awọn ẹlẹwọn naa lọ sibomii kiakia.
Mọjumọ ọjọ Aje yii ni ojo naa ṣakoba fun odi ti wọn mọ yika ọgba ẹwọn ọhun, tawọn ẹlẹwọn si fẹsẹ fẹ.
Lasiko ti iṣẹlẹ yii waye, iye ẹlẹwọn ti ọgba ẹwọn yii ni jẹ ọtalerugba o din mẹta. Torinaa, nigba ti awọn to sa lọ lo anfani ẹkun omi to ya ogiri sa lọ, awọn marunlelọgọrun duro sinu ọgba lai sa lọ.
Ni bayii, a ti ri mẹẹdọgbọn pada ninu awọn to sa lọ o ṣi ku marundinlọgọrun sita ti a o tii mọ ibi ti wọn wa.
Gbogbo akitiyan ijọba ipinlẹ Kogi atawọn oṣiṣẹ alaabo gbogbo kaakiri Naijiria to fi mọ awọn figilante ibilẹ lo n ṣeranwọ fun ẹka aabo yii lati ṣawari awọn ti wọn ko tii ri.
Oludari agba ile iṣẹ to n ṣamojuto awọn ọgba ẹwọn ni Naijiria ti wa fọrọ sita si awọn araalu lati dakun pese ọrọ to ba wulo ti wn ba ri to lee muṣẹ ya lati ri awn to sa lọ yii pada.Ojo arọọrọda to ya ogiri ọgba ẹwọn nilu Koton Karfe nipinlẹ Kogi, ti mu ki awọn ẹlẹwọn aadọjọ salọ mọ awọn ọga ẹlẹwọn lọwọ.
Gẹgẹ bi ohun ti a gbọ lati ẹnu alukoro ọlọpaa ni ipinlẹ Kogi, ikọ awọn oṣiṣẹ ọgba ẹwọn naa ati awọn ajọ ori lalakanfinsọri lo dijọ n wa awọn ẹlẹwọn to na papa bora yii.
Ile isẹ akoroyinjọ ni Naijiria (NAN) sọ pe, ọga agba fun ile iṣẹ to n sakoso awọn ọgba ẹwọn ni Naijiria, ọgbẹni Jafar Ahmed lo fidi iṣẹlẹ yii mulẹ fawọn akọroyin nilu Koton Karfe.
Ahmed sọ pe awọn ẹlẹwọn okoolenigba ati mẹjọ lo wa ni ọgba naa nigba ti ẹkun omi naa ya wọ ibẹ.
Oríṣun àwòrán, @NLCtoday
O tẹsiwaju pe, lọwọlọwọ ọgba ẹwọn naa ko ti ṣe gbe pada, tori naa, wọn ti gbe awọn ẹlẹwọn ibẹ lọ si ibomiran titi ti omi yoo fi gbẹ nibẹ.
Ipenija ẹkun omi kii ṣe ohun tuntun lagbegbe Koton Karfe, to sun mọ ilu Lokoja nibi ti odo Benue ati Niger ti pade.
Loṣu Kẹfa ọdun to lọ, o le ni ọgọsan ẹlẹwọn ti awọn agbebọn tu silẹ ni ọgba ẹwọn Koton Karfe yii kanna.
Oluranlọwọ si Gomina ipinlẹ Kogi lori ọrọ aabo, Jerry Omadara naa sọ pe, o le ni ọgbọn awọn ẹlẹwọn to salọ ti awọn ti ri mu pada.
Ko ti si iroyin nipa ibi ti awọn ẹlẹwọn to ku wa tabi boya ọwọ ti tẹ wọn.
Kogi elections: Ilé ẹjọ́ ní ẹgbẹ́ AA kùnà ìlànà INEC fún ìbò gómìnà ní Kogi, Bayelsa
Oríṣun àwòrán, @AllianceAa
Ile ẹjọ giga apapọ kan nilu Abuja ti paṣẹ pe ẹgbẹ oṣelu Action Alliance (AA) ko lẹtọ lati fa oludije silẹ fun eto idibo sipo gomina ni ipinlẹ Kogi ati Bayelsa.
Adajọ Inyang Ekwo to gbe idajọ naa kalẹ ni ẹgbẹ oṣelu AA ko tẹle awọn alakalẹ ajọ eleto idibo INEC, lori fifi orukọ oludije silẹ fun eto idibo naa, ti yoo waye lọjọ kẹrindinlogun oṣu kọkanla ọdun 2019.
Ileẹjọ naa ni ilana ti ajọ INEC fi sita ni pe ki orukọ gbogbo awọn oludije to ti wọle sikawọ ajọ naa, o pẹ ju, agogo mẹfa irọlẹ ọjọ kẹsan oṣu kẹsan ọdun 2019.
Adajọ Ekwo ni nitori idi eyi, ẹjọ ti awọn oludije ẹgbẹ oṣelu naa fun ipinlẹ Bayelsa ati Kogi, Ebi Peretiemo ati Samuel Alfa pawọ pọ pe ko lẹsẹ n lẹ.
Ekwo fikun pe, awọn oludije mejeeji ko lee fi ẹri mulẹ pe lootọ ni awọn wa ni olu ileeṣẹ ajọ INEC lọjọ naa ati pe oṣiṣẹ ajọ naa lo kọ lati gba iwe iforukọsilẹ wọn, gẹgẹ bi wọn ṣe sọ.
Osogbo Police: Ọwọ́ tẹ ṣọ́jà mẹ́ta tó ya bo iléeṣẹ́ ọlọ́pàá, àwọn yókù sálọ
Oríṣun àwòrán, @PoliceNG
Iroyin kan sọ pe awọn ṣọja kan ya bo olu ileeṣẹ ọlọpaa ni ipinlẹ Ọṣun nilu Oṣogbo ni ọjọ Aje.
Gẹgẹ bi a ṣe gbọ, awọn ologun naa ti ja ilẹkun olu ileeṣẹ ọlọpaa naa, ti wọn si ti da hilahilo silẹ lagbegbe naa, ki o to di pe awọn ọlọpaa kapa wọn ti wọn si ko awọn mẹta sahamọ.
Nigba ti BBC News Yoruba pe alukoro olu ileeṣẹ ọlọpaa nipinlẹ Oṣogbo, o ni ileeṣẹ ọlọpaa yoo fi ero rẹ lori iṣẹlẹ naa sọwọ sawọn oniroyin ninu atẹjade laipẹ.
Awọn mẹta ninu awọn ṣọja naa to ti tasẹ agẹrẹ wọle si olu ileeṣẹ ọlọpaa ni wọn mu pẹlu panpẹ ofin, ti wọn si gba ohun ija ọwọ wọn ti awọn ti awọn akẹgbẹ wọn yoku si pada.
Oríṣun àwòrán, @PoliceNG
Titi di bi a ṣe n sọrọ yii, ko tii si ẹni to lee sọ ni pato ibudo ologun ti awọn ologun naa ti wa, ṣugbọn ohun ti o daju ni pe, ibudo ologun to sunmọ olu ileeṣẹ ọlọpaa naa julọ ni ibudo ologun fawọn onimọ ẹrọ to wa nilu Ẹdẹ.
Amọ ko tii si ẹni to lee fi idi rẹ mulẹ pe nibẹ ni awọn ologun yii ti wa.
Bakan naa ni iroyin to tẹ BBC News Yoruba lọwọ tun jẹ ko di mimọ pe, ṣọja kan ti awọn ọlọpaa mu lọjọ Satide laarin igboro ilu Osogbo to si wa ni ahamọ awọn ọlọpaa titi di asiko ti a fi n ko iroyin yii jọ, lawọn akẹẹgbẹ naa fẹ lọ gba silẹ.
Amotekun Recruitment: Ìròyìn ayọ̀ fún gbogbo àwọn tó forúkọ sílẹ̀ fún ikọ̀ Amotekun ní ìpínlẹ̀ Oyo
Ijọba ipinlẹ Oyo ti kede pe orukọ awọn to yege lati darapọ mọ ikọ alabo Amọtekun ti jade.
Ninu atẹjade ti adari ikọ naa ni ipinlẹ Oyo, Ajibola Kunle Togun, fi lede, o ni gbogbo awọn to forukọ silẹ  si oju opo ti ijọba gbe kalẹ fun ikọ naa lati lọ wo orukọ wọn.
"O ni ""ki gbogbo awọn to yege ninu iforukọsilẹ ọhun lọ si ile ẹkọṣẹ awọn olukọ, Emmanuel Alayande, to wa ni ilu Oyo laago mẹsan owurọ lọjọ kẹta, oṣu Kọkanla, ọdun 2020, fun eto iforukọsilẹ ni kikun."""
O fi kun pe igbaradi ati idanilẹkọọ fun awọn eeyan na yoo waye fun ọsẹ meji gbako.
Oríṣun àwòrán, Western Nigeria security network
Atẹjade ọhun tẹsiwaju pe ki awọn eeyan naa mu ṣokoto pelebe alawọ buluu, aṣọ funfun ati bata kanfasi to ṣee sare lọwọ.
Tóo bá pá lórí, Mílíìkì sóyà àtàwọn ǹkan mẹ́ta yìí leè mú irun rẹ hù padà!
Ko tan sibẹ, o tun ni ki wọn ko ike iwe, ago imumi, ṣibi, abọ ounjẹ ati igbalẹ lọwọ.
Adari ikọ naa pari ọrọ rẹ pe ki awọn ti orukọ wọn ko jade má ṣe iyọnu lati yọju si ọgba ileewe ti idanilẹkọọ ati igabradi naa yoo ti waye.
Oríṣun àwòrán, Seyi Makinde
Ijọba ipinlẹ Oyọ ti ni awọn yoo lo ọkọ tuntun to le lọgọrun naa lati fi maa na gbogbo awọn ipinlẹ to wọ ipinlẹ Oyo.
Kọmisọna fun eto iroyin, Wasiu Olatunbosun lo sọ bẹẹ fun BBC Yoruba lẹyin ti ijọba kede wi pe awọn fẹ ra ọkọ tuntun yii fun idagbasoke eto irinna ni ipinlẹ naa.
Olatunbosun ni ijọba fẹ lo iye owo to to N9.3 billiọnu lati fi ra awọn ọkọ nla fun irinna ọkọ laarin ipinlẹ naa.
Ọkọ kọọkan yoo ma a gbe to eniyan ọgọrun, ti yoo si ma a lọ si Ogbomoso, Oyo, Ibarapa ati bẹẹ bẹẹ lọ''.
Kété tí wọ́n bá ti báa yín sùn tàn torí pé ẹ tóbi, ẹ gbà pé ìfẹ́ yẹn ti parí - Auntie Remi Ọlọ́yàn ńlá
''Ọkọ naa wa lati fi pa owo si apo ijọba ni nitori awọn ọkọ to wa nilẹ ti n bajẹ, eleyii to n fa inira fun awọn eniyan wa.''
''Ti wọn ba n wọ moto naa, inira yoo dinku fun irinkerindo fun awọn eniyan naa''
''Kii ṣe ọfẹ ni o ma ba de, owo ti awọn eniyan ba n san gẹgẹ bi owo ọkọ ni a ma a fi san owo naa pada.''
'' Wọn a fun awọn oṣiṣẹ ijọba ni ọkọ ẹyọkan lati ma a wọ lọfẹ lati ibi iṣẹ ati awọn ọmọ ileewe ni ọfẹ lati ma a fi rin lati ibi kan si omiran.''
Ijọba ipinlẹ Oyo fikun wi pe awọn ọkọ naa yoo mu igbeyagbadun ba  awọn eniyan, ti ilọsiwaju yoo fi ba wọn.
'Egbò tó ti fẹ́ẹ̀ jiná ni ìtàn bí wọ́n ṣe pa Soun Ogbomoso, Ọba Olayode tẹ ń bèrè'
Nipinlẹ Oyo, wakati meji aabọ ni akẹkọọ yoo fi wa nileewe lojumọ
Bi ojumọ se n mọ, ni ofin ati ara tuntun n jade lẹka eto ẹkọ nilẹ wa, eyi to lee mu agbega abi akude ba ilana eto ẹkọ ilẹ wa.
Ni asiko ti ajakalẹ arun Coronavirus wọle de, oniruuru ilana eto ẹkọ nijọba ti gbe sita, eyi to wa lati daabo bo awọn akẹkọọ.
Nipinlẹ Ọyọ ẹwẹ, ijọba tun ti fi ilana miran sita lori ilana eto ẹkọ fawọn akẹkọọ to sẹsẹ pada sile ẹkọ lọjọ Aje to kọja.
Bẹẹ ba si gbagbe, yoo to osu mẹfa tawọn ileewe fi wa ni titipa nitori arun Coronavirus, tawọn akẹkọọ si fidi mọle wọn.
Amọ atẹjade miran tileesẹ eto ẹkọ nipinlẹ Ọyọ fisita lọjọ Ẹti, ọjọ kẹẹdọgbọn osu Kẹsan ọdun yii fihan pe atunse tun ti ba eto ẹkọ lawọn ile ẹkọ tijọba ati taladani to wa nipinlẹ naa.
Atẹjade naa ti Kọmisana feto ẹkọ nipinlẹ Ọyọ, Olasunkanmi Olaleye fọwọsi sisọ loju rẹ pe, wakati meji ati aabọ pere lawọn akẹkọọ yoo maa fi kawe bayii, ti wọn si pin wọn si isọri meji.
Oríṣun àwòrán, Oyo state ministry of education
Isọri alakọkọ ni yoo wọle sile ẹkọ lati aago mejọ aarọ si aago mẹwa abọ aarọ, ti wọn yoo si pada sile wọn.
Isọri keji awọn akẹkọọ naa ni yoo bẹrẹ ikẹkọọ ni aago mẹwa abọ aarọ, ti wọn yoo si pari ni aago kan ọsan.
Isọri kọọkan awọn akẹkọọ ọhun ni yoo wa nile ẹkọ fun wakati meji aabọ pere.
Ijọba ni awọn gbe igbesẹ ọhun lẹyin toun ti fikunlukun pẹlu awọn eeyan ati ẹka ti eto ẹkọ gberu.
Pupọ awọn obi lo pese awọn ibomu fawọn ọmọ to pada si ileewe.Ijọba ko pese rẹ fun wọn
Kọmisana feto ẹkọ salaye pe, isẹju mẹẹdọgbọn pere ni wọn yoo fi maa se idanilẹkọọ fawọn akẹkọọ lori isẹ kọọkan, ti wọn yoo si se isẹ mẹfa laarin wakati meji aabọ lojumọ.
Amọ to ba di ọjọ Ẹti, isẹ marun ni wọn yoo maa se lojumọ, ti wọn si rọ awọn ọga lati tẹle ofin naa.
Ni ibamu pẹlu aṣẹ ti ijọba pa fun gbogbo ile ẹkọ to n bẹ n'ipinlẹ Ọyọ, awọn akẹkọọ to n bẹ ni kilaasi ikẹfa nile ẹkọ alakọbẹrẹ, kilaasi ikẹta ati ikẹfa nile ẹkọ girama, ti wọle pada sẹnu ẹkọ lonii.
Gbogbo ile ẹkọ ti ikọ BBC Yoruba ṣe abẹwo si, lo ṣe amulo awọn ohun elo ti o le daabo bo akẹkọọ ati olukọ lọwọ kokoro Coronavirus, bẹrẹ lati orii omi ati ọṣẹ, iboju, to fi mọ ilana itakete si ara ẹni.
Lara awọn adari ile ẹkọ to ba wa sọrọ ṣe alaye wi pe, gbogbo ipa ni awọn n sa lati daabo bo awọn akẹkọọ ati awọn olukọ wọn gẹgẹ bi wọn ṣe wọle pada sẹnu ẹkọ.
Wọn ni akẹkọọ tabi olukọ ti ko ba lo ibomu ko ni lanfani lati wọle si inu ọgba ile ẹkọ.
Ọpọlọpọ akẹkọọ ti ko lo ibomu si ni wọn da pada sile lẹnu iloro lasiko ti ikọ BBC Yoruba ṣe abẹwo si awọn ile ẹkọ kan niluu Ibadan lọwurọ ọjọ Aje.
Awọn adari ile ẹkọ naa tẹsiwaju wi pe, ijọba ipinlẹ Ọyọ tun ti paa laṣẹ fun wọn lati maa ko awọn akẹkọọ naa si ita gbangba, fun bii ọgbọn iṣẹju.
Laarin aago mọkanla si mọkanla aabọ lojoojumọ si ni eto naa yoo maa waye, ninu igbiyanju lati mu adinku ba itankalẹ aarun aifojuri, ‘Coronavirus’.
Lori ipese awọn ohun elo idaabo bo ara ẹni bii ibomu, iboju ati ogun apakokoro, awọn aṣoju ile ẹkọ naa sọ fun akọroyin wa wi pe, lati ọwọ ara wọn ni wọn ti pese awọn ohun elo naa.
Eyi si tako ileri ti ijọba ṣe lati pese ohun elo idaabo bo ara ẹni fun awọn akẹkọọ.
Awọn aye to ṣi silẹ ni kilaasi awọn akẹkọọ ti ijọba ko tii fun ni aye lati wọle pada, lo mu ki itakete si ara ẹni di irọrun fun awọn akẹkọọ to wọle pada lonii.
Ọpọlọpọ kilaasi gan an ni awọn akẹkọọ to n bẹ ninu rẹ ko to ogun, pẹlu bi o ṣe jẹ wi pe, aye akẹkọọ bii ọgbọn ni ijọba ipinlẹ Ọyọ sọ wi pe ki wọn pese silẹ.
Oríṣun àwòrán, @OfficialSeyiMakinde
Ijọba ipinlẹ Ọyọ ti pasẹ fun awọn ọga agba ileẹkọ gurama ati ti alakọbẹrẹ jakejado ipinlẹ naa lati sa awọn akẹkọọ wọn sinu oorun fun ọgbọn isẹju lojooju.
Kọmisana feto ẹkọ, Olasunkanmu Aremu Olaleye lo sisọ loju ọrọ yii ninu atẹjade kan to fi ransẹ si awọn ọga ile ẹkọ naa ati awọn eeyan miran ti ọrọ eto ẹkọ gberu.
Atẹjade naa, to bọ sita ni ọjọ Keji osu Keje ọdun 2020 tun kede pe, kikida awọn ile ẹkọ tijọba fi ọwọsi, to si ni iwe ẹri pe o peju sibi idanilẹkọ nipa arun Coronavirus nikan ni yoo jẹ sisi lonii.
Oríṣun àwòrán, @OfficialSeyiMakinde
Awọn alaṣe ni ẹka eto ẹkọ ni ipinlẹ Oyo ti gbaradi fun aṣẹ ijọba lati jẹ ki awọn akẹkọọ pada si ileewe, lẹyin ti wọn ti ileewe nitori arun Coronavirus.
Kọmisọna fun eto ẹkọ, imọ sayẹnsi ati iṣẹ ẹrọ, Olasunkanmi Olaleye ni awọn akẹkọọ ni ileewe Alakọbẹrẹ ati Girama ti wọn ti fẹ kẹkọ jade, yoo bẹrẹ ileewe pada ni oni, Ọjọ Aje, Ọjọ Kẹfa, Oṣu Keje, ọdun 2020.
Olaleye ni ijọba ti gbe eto kalẹ lati ri pe awọn akẹkọọ wa ni alaafia lasiko arun Coronavirus yii.
Oludasilẹ ile ẹkọ adani kan naa fidi rẹ mulẹ pe, awọn ọga agba ileewe ni ipinlẹ Oyo, ti ṣe ipade lori eto ti wọn gbọdọ ti ṣe kalẹ fun awọn akẹkọọ, ki arun Coronavirus ma ba tan kalẹ si laarin awọn akẹkọọ.
Mama Arsenal: Màmá àgbà yìí máa ń lọ sí ìbùdó tí wọ́n ti ń wo bọ́ọ́lù láti wòran
"O pọn dandan ki awọn akẹkọọ to ba n bọ ni ileewe lo ohun elo ibomu, nigba ti awọn alaṣẹ ileewe yoo ri pe awọn akẹkọọ tẹle ofin ijinasiraẹni, ipese omi lati fọ ọwọ wọn lore-koore, ipese ẹrọ ti wọn fi n mọ bi ara ṣe gbona si, ati bẹẹ bẹẹ lọ.
Awọn obi kan naa ni iwọle pada awọn akẹkọọ yoo dara, ti wọn ba tẹle ofin ti ijọba lakalẹ lati dẹkun itankalẹ  arun Coronavirus.
Oríṣun àwòrán, @OfficialSeyiMakinde
Bakan naa ni awọn akẹkọjade ni inu awọn dun lati pada si ileewe, bẹẹ si ni awọn akẹẹgbẹ awọn fi idunnu wọn han si pipada si ẹnu ẹkọ wọn.
Gomina ipinlẹ Oyọ Onimọ ẹrọ Ṣeyi Makinde ti fọwọ si sisan owo to to okoolelẹẹdẹgbẹta ati mẹfa miliọnu naira (₦526) fun gbogbo ile iwe ijọba gẹgẹ bi owo ẹnawo atigbadegba fawọn ileewe ijọba bii ẹgbẹrun meji aabọ.
Atẹjade kan tijọba fisita lo sisọ loju ọrọ yii pẹlu afikun pe wọn ti fi owo to to irinwo miliọnu naira (₦400m) ṣọwọ si awọn ile iwe girama, nigba ti ile iwe alakọbẹrẹ naa si ti tẹwọ gba aadoje miliọnu naira o din mẹrin ( ₦126m) bakan naa.
Owo yii ni Ijọba lo wa fun ẹnawo atigbadegba awọ̀n ileewe naa fun taamu akọkọ ninu saa eto ẹkọ ọdun 2019 si 2020, ti wọ̀n si ti pasẹ fawọn ọga agba ileẹkọ alakọbẹrẹ ati girama naa lati lọ si apo asuwọn owo ni banki ki wọn lee gba owo naa ni kiakia.
Ojilelẹgbẹta ile iwe girama lo wa yika ipinlẹ Ọyọ, ti wọn si ti n jẹ mula owo iranwọ naa eyi to n pese ẹgbẹrun kan naira ni fun akẹkọ kan ni taamu kan.
Ti irinwo akẹkọ ba wa nileewe kan, ta si n pese ẹgbẹrun kan naira fun itọju akẹkọ kọọkan, a jẹ pe ijọba yoo maa na miliọnu lọna irinwo naira ni taamu kan lawọn ileẹkọ girama. Apapọ isiro owo yii yoo si ku si biliọnu kan ati miliọnu lọna igba naira (₦1.2bn) fun saa eto ẹkọ kan fawọn akẹkọ girama."""
Ijọba ipinlẹ Ọyọ wa rọ awọn eeyan ti eto yii gberu lawọn ileẹkọ ijọba lati lo owo naa bo se yẹ .
Oríṣun àwòrán, @OfficialSeyiMakinde
Bakan naa lo ni o yẹ ko ye wọn pe ijọba yoo beere nipa bi wọn se naa owo naa, ti yoo si fiya to jogbin jẹ ẹnikẹni to ba gbidanwo lati ya kuro loju opo ilana ipese ojulowo ẹkọ ọfẹ tabi to n dọgbọn gba owo kotọ lọwọ awọn akẹkọ.
Fake News: Lai Mohammed fa ọmọ Nàìjíríà létí lórí ìròyìn òfégè
Oríṣun àwòrán, LAi Mohammed/Facebook
À ń ṣọ́ọ yín lórí ayélujára
Minisita eto ibanisọrọ ati iroyin lorilẹede Naijiria, Lai Mohammed ti ni ijọba yoo bẹrẹẹ ṣiṣe amojuto atagba oju opo ayelujara bayii.
Igbesẹ yii ni lati ṣe afọmọ oju opo ayelujara ki adinku lee ba ayederu iroyin atawọn ọrọ kobakungbe to n jẹyọ.
Lai Mohammed sọ ọrọ yii nibi ipade oniroyin kan to waye nilu Abuja.
Nigeria Independence Day: Wo ìlérí tí àwọn ènìyàn ṣe
Minisita ni eyi ko yọ awọn oniṣẹ iroyin silẹ o. O ni ile iṣẹ iroyin to ba ta fele fele gan yoo fara ko o.
"Atunṣe ti wọn fẹ bẹrẹ yii yoo tan de oju opo ayelujara eyi to ṣapejuwe pe ""o ti kọja atunṣe""."
"Lai Mohammed tun ni ""lati igba ti a ti ṣe ifilọọlẹ eto ayipada yii ni awọn ọmọ naijiria kan ti kan si wa pe ki a boju wo bi a ṣe le ṣe ilanilọyẹ lori awọn ayelujara naa a ko si ni pa eleyi ti""."
Mohammed ni ko si ijọba gidi kan ti yoo joko kawọ gbera ki iroyin ofege si maa fo kiri toun tọrọ alufansa eleyi to lee dana sun orilẹede lai si ayẹwo kankan.
Idi niyii ti ao fi maa koju ayederu iroyin ati ọrọ alufansa ayafi bi a ba to le gbogbo rẹ danu. O ni tori awọn ti ṣe agbekalẹ igbimọ kan ti aarẹ Buhari fọwọ si lati kọju awọn ọrọ alufansa.
Owu Water Fall: Ọba Oyewole ni ibùdó ìrìn àjò afẹ́ gidi ni àmọ́ ọ̀nà ibẹ̀ burú jáì
Border Closure: Oshiomole ní kí Vietnam wá dá oko ìrẹsì sílẹ̀ ní Nàíjíríà ni èsì ẹ̀bẹ̀ rẹ̀
Oríṣun àwòrán, @CustomsNG
Bi ijọba Naijria se gbe awọn ẹnu ọna abawọle si orilẹede yii tipa ti n mu ki ori ta awọn orilẹede to mule ti wa ati awọn to wa nilẹ okeere.
Koda isoro yii pọ to bẹẹ fun orilẹede Vietnam to fi gbe asoju dide pe ko wa rawọ ẹbẹ sijọba Naijiria lati si ẹnu ibode rẹ pada, ki oun lee ko irẹsi oun wọle lọpọ yanturu.
Igbakeji Olootu ijọba Vietnam, Vuong Dinh Hue to ko awọn asoju naa wa sorilẹede Naijiria ti wa n rawọ ẹbẹ si ẹgbẹ oselu APC to n tukọ ijọba Naijiria lọwọ lati bawọn bẹ aarẹ Muhammadu Buhari, ki ẹnu bode wa lee di sisi pada.
Oríṣun àwòrán, @CustomsNG
Ilu Abuja ni igbakeji Olootu ijọba Vietnam naa ti rawọ ẹbẹ yii lasiko to sabẹwo si alaga ẹgbẹ oselu APC nilẹ wa, Adams Oshiomole lọọfisi rẹ, to si tun kede pe nitori bi ọrọ naa se ka awọn lara to, awọn yoo tun lọ dirẹbẹ niwaju igbakeji aarẹ, Yẹmi Ọsinbajo lori rẹ pẹlu.
Nigba to n ki awọn alejo rẹ kaabọ silẹ yii, to si n fesi lori ibeere wọn, Adams Oshiomole ni are ko selu, ki wọn ma fise han wa ni Naijiria nitori bayi ni n o se nkan mi ko lee yipada, bi ohun gbogbo tilẹ pada.
Oshiomole ni orilẹede Naijiria ko lee dahun si ẹbẹ wọn lati si ẹnu bode wa, to si rọ awọn asoju ilẹ Vietnam pe ki wọn wa gba ilẹ sorilẹede Naijiria lati da oko irẹsi ni yoo pe wọn.
Oríṣun àwòrán, @CustomsNG
O ni ọmọja ti kuro niye ti ana, nitori Naijiria ko ni jẹ aatan mọ fun awọn orilẹede kan, ti wọn yoo wa maa da eroja oloro asekupani wọn si ati awọn eroja to ti bajẹ.
Alaga ẹgbẹ APC fikun pe digbi ni agadagodo yoo wa lawọn ẹnbu bode wa titi tawọn orilẹede to mule ti wa yoo fi bọwọ fun ofin to de ibasepọ okoowo laarin orilẹede kan si ekeji.
Fruits and Vegetables: Ǹ jẹ́ o mọ̀ pé ó yẹ ko se Carrot rẹ, ko tó jẹ ẹ́
Oniruuru ounjẹ ni asẹda fi jinki wa nilẹ Yoruba, orilẹede Naijiria ati nilẹ adulawọ lapapọ.
Ọpọ awọn ounjẹ yii lo n sofo danu ni ayika wa, ti a ko ka wọn si, ọpọ wọn si lo lee wo awọn eeyan san lọwọ oniruuru arun to n ba wọn ja lai se wahala kankan, ti yoo si tun mu ki agọ ara wa ji pepe.
Lara awọn ounjẹ yii la ti ri eso Carrot, ewe Lettuce, eso Cucumber ati Avocado pear eyi ti wọn ni eroja asaloore ti wọn n pọ sinu agọ ara wa kii se kekere ta ba jẹ wọn.
Nigba to n ba BBC sọrọ, onimọ nipa awọn ounjẹ asaraloore, Collins Akanno mẹnuba ọpọ awọn eso ati ewebẹ to wa ni arọwọto wa, amọ ti a ko naa rara.
Ti eeyan ba ra Carrot, to fọọ, ko yẹ ki a jẹ bẹẹ, amọ o yẹ ka se lori ina fun igba ranpẹ, ki eroja Vitamin A to wa ninu rẹ lee maa jade si ẹnu wa, ba ba se n jẹẹ.
Nitori naa, lati akoko yii lọ, maa se eso carrot rẹ, ko rọ diẹ lori ina, ki o to maa jẹ.
Ọpọ eeyan ni ko mọ pe ewebẹ ni eroja isu, ounjẹ lasan la mọ si.
Lootọ ni isu ni eroja afaralookun taa mọ si Starch ninu, amọ to ba fẹ jẹ isu, mase jẹ ki isu to jẹ kọja odiwọn ikuuku tabi ẹsẹ rẹ nigba kuugba to ba n jẹ isu.
Idi ni pe eroja afaralokun to jẹ nijoko ẹẹkan ko gbọdọ tobi ju deede ẹsẹ ọwọ rẹ lọ nitori eroja Starch to wa nibẹ.
Ewe  yii wulo fun mimu ki isan ara rọ, ko si ni ilera to peye.
Ẹnikẹni ti ara rẹ kii balẹ, to maa n re galegale, ti kii le duro si oju kan, tabi to jẹ oni iwanwara, to ba n jẹ ewe Lettuce, yoo ri pe irọrun ba agọ ara rẹ.
Koda, bi o ko ba ri oorun sun, iwọ sa ti jẹ ewe Lettuce, bi ọmọ tuntun jojolo lo sun fọnfọn.
Eso miran to tun wulo fun isẹda ni eso Cucumber. Ọpọ obinrin to ba jẹ asaraloge, to si maa n setọju awọ ara wọn loore koore ni kii fi eroja Cucumber sere rara.
Bo se wulo fun itọju oju, taa ge wẹwẹ fi bo ẹyinju wa mejeeji, naa lo tun wulo fun irun ori obinrin.
Cucumber yii tun dara fun awọ ara ti yoo si mu ko maa dan yọyọ, ti yoo si mọ kedere. Bakan naa lo tun dara fun eekanna wa, ta ba si tun jẹ, se ni a ya awọn idọti kuro lagọ ara wa.
Eso pear wulo pupọ fun agọ ara wa, nitori o tun maa n mu adinku ba awọn ọra ara taa mọ si Cholesterol.
Yatọ si eyi, pear tun maa n se iranwọ fun tọkunrin-tobinrin to ba n wa ọmọ, eyi ti ko yẹ ki wọn maa fi sere rara.
Ko tan sibẹ o, eso yii tun jẹ ara eso ti ko se ko pamọ fun igba pipẹ, eyi to n mu ka maa jẹ eso rẹ ni ajaabalẹ.
Irufẹ eso ajaabalẹ yii wulo fun awọn eeyan ti ẹjẹ ara wọn ko to rara, ti eroja Iron to wa ninu rẹ yoo si tete mu ki ẹjẹ pọ lara wọn.
Awọn eso taa mẹnuba diẹ lara wọn yii wa larọwọtọ wa ati lawọn ọja wa gbogbo, nitori naa, ẹ maa ra wọn jẹ, kẹ si mase fi wọn sere rara.
Supreme Court: Atiku ní ìdájọ́ ilé ẹjọ́ tó dá Buhari láre kò b'òun nínú jẹ́
Oríṣun àwòrán, Twitter/Muhammadu Buhari
'Bi ile ẹjọ ba da idajọ ododo tabi ti wọn ba idajọ ododo nidakeji bakan naa, awọn ọmọ Naijiria lo le sọ.'
Ọrọ yii ni oludije fun ipo aarẹ fẹgbẹ osẹlu PDP, Alhaji Atiku Abubakar sọ lẹyin ti ile ẹjọ to ga julọ da a lẹbi lori ẹjọ to pe aarẹ Muhammadu Buhari lori ibo aarẹ to lọ.
Atiku ni oun ti fitafita fawọn ọmọ Naijiria gẹgẹ bi ẹni to gbagbọ ninu eto ijọba awarawa, o ni oun yoo si tẹsiwaju lati maa ja fun Naijiria, fun ijọba awarawa ati fun ododo.
Atiku fikun ọrọ rẹ pe inu oun ko bajẹ lori idajọ ile ẹjọ, o ni oun ko ronu nipa ara oun bi ko ṣe pe nipa Naijiria l'oun ro ni gbogbo igba.
Ẹwẹ, lẹ́yìn tí ilé ẹ́jọ to gá jùlọ n'9i Nàìjíría ti yí ẹ̀sùn ẹgbẹ́ òṣèlú People's Democratic Party (PDP) tó pe All Progressive Party (APC) lórí àbájáde èsì ìdìbò ọdún 2019 dànù tán, ní agbẹnusọ ẹgbẹ́ òṣèlú APC Mallam Lanre Issa Onilu ba BBC sọ̀rọ̀.
Onilu  ní láti ìgbà ti ẹgbẹ́ ò[sèlú PDP ti gbe APC lọ si ile ẹjọ ni òun ti mọ pé ẹ̀yìn igbá ni wan ń yín àgbàdo sí, nítori pé kò si àrigbámú kankan nínú ẹjọ́ ti wọ́n pé, pe ààrẹ kò ni ìwé ẹ̀rí tàbi ko lọ ilé iwé gíga.
Issa onilu ní òun gbẹ oríyìn fún ẹgbẹ́ òṣèlú PDP fún ìgbésẹ̀ tí wọ́n gbé láti lọ si ilé ẹjọ́ lórí ọ̀rọ̀ náà, nítori ọ̀na to tọ ni , súgbọ̀n ìgbẹ́jọ náà ti dé òpin báyìí, ó si pọ́ndadan ki wọ́n fún ààrẹ Buhari láàyè láti ṣe ijọba
O wá rọ ẹgbẹ́ náà láti ṣẹ́wẹ́lé ìpínu wọ́n láti da orilẹ̀-èdè rú pẹ́lú àwọn ìròyìn ẹlẹjẹ́ nítori àbájáde ìdájọ ilé ẹjọ́, o ní nigba ti o ti já si ibi ti o já si nítori pé orilẹ̀-èdè Naijiria kii ṣe tí ẹnikan, o si ṣe pàtàkì kí ifọ́wọ́sowọpọ̀ wà ki ilọsiwáju le ba ìlú.
Oríṣun àwòrán, @mbuhari
Supreme Court: Eré àsá sòfò ní ẹgbẹ́ PDP sá lọ sílé ẹjọ́
Agbẹnusọ APC wá rọ wọn pé kí wọ́n ni sùúrù fún bí ọdún mẹta àti oṣù díẹ̀ láti tun gbe igbá ìdìbò míràn lọdun 2023, kí wan fi ẹgbk APC lọ́run sílẹ̀ láti le rójú ṣe ìjọba.
Atiku fìdí rẹmi nílé ẹjọ́ tó ga jùlọ, kò sọ́rọ̀ mọ́ lórí ìbò ààrẹ
Oríṣun àwòrán, @atiku
Ile ẹjọ to ga julọ lorilẹede yii ti tun fi idi ibo to gbe aarẹ Muhammadu Buhari mulẹ gẹgẹ bii aarẹ ti ilu dibo yan lọjọ Kẹtalelogun osu Keji ọdun 2019.
Igbimọ ẹlẹni meje, ti adajọ agba ni Naijiria, Tanko Mohammed ko sodi, tun wọgile ẹjọ Kotẹmilọrun ti oludije fun ipo aarẹ labẹ asia ẹgbẹ oselu PDP, Atiku Abubakar pe, eyi to fi n tako eto idibo ọdun aarẹ 2019.
Gbogbo awọn adajọ mejeeje naa lo wọgile awọn ẹri ti Atiku ko wa siwaju wọn, ti wọn si ni ofuutu fẹẹtẹ, aasa ti ko ni kaun ni wọn.
Atiku lo wọ aarẹ Muhammadu Buhari lọ sile ẹjọ lati tako idibo to gbe wọle fun saa keji gẹgẹ bii aarẹ Naijiria.
Operation Positive Identification: Ilé aṣòfin-ṣojú ní Buhari gbọ́dọ̀ ká iléeṣẹ́ ológun lọ́wọ́ kò lórí àyẹ̀wò ìdánimọ̀
Oríṣun àwòrán, Others
Ile igbimọ aṣoju-ṣofin ti ke si Aarẹ Muhammadu Buhari pe ko tete yara paṣẹ fun ileeṣẹ ologun lati jawọ lori igbesẹ ayẹwo ati idanimọ tawọn ologun fẹ gunle kaakiri orilẹede Naijiria.
Eto idaraẹnimọ, 'Operation Positive Identification' lawọn ologun sọ pe awọn gbe kalẹ, lati ṣawari awọn eeyan to ba wa lori iwe 'a-n-wa-ọ' awọn agbofinro, atawọn ajeji to wọ ilẹ yii lai gbawe aṣẹ iwọlu.
Awọn aṣoju-ṣofin lero tiwọn ni igbesẹ naa tako agbekalẹ ofin Naijiria lori ojuṣe ileeṣẹ ologun gẹgẹ bi abala okoolelugba o din mẹfa iwe ofin ọdun 1999 ti wi.
Oríṣun àwòrán, Others
Nigba to n gbe aba lori ọrọ naa kalẹ, olori ẹgbẹ oṣelu to kere nile igbimọ aṣoju-ṣofin, Ndudi Elumelu ni igbesẹ naa kii ṣe ojuṣe ileeṣẹ ologun, ikọja aaye lasan ni.
Bakan naa ni aṣofin Toby Okechukwu ati Ahmed Jaha pẹlu woye pe, airiṣẹ ṣe lo n damu awọn ologun, paapaa awọn adari wọn.
Wọn ni bawọn adari ileeṣẹ ologun ko ba mọ ohun to kan fun idaabobo Naijiria, ki wọn yara fi ipo silẹ fun awọn adari tuntun ti ọpọlọ wọn n gba yagiyagi ni.
"Ni ọjọ karundinlọgbọn oṣu kẹsan ọdun 2019 lawọn ologun kede pe, awọn yoo fẹ eto naa loju de gbogbo tibutoro Naijiria lati ""ka awọn agbebọn, ajinigbe, adigunjale, atawọn ajimaalu gbe lọwọ ko, kaakiri ẹkun gbogbo."
Ambode: Àwọn aṣòfin Eko kò le è wádìí mi, àwọn ló fòǹtẹ̀ lu owó tí mo ná
Oríṣun àwòrán, @AkinwunmiAmbode
Sinima orita awoowo tan lọrọ iwadi ẹsun ajẹbanu to n waye laarin gomina ana ni ipinlẹ Eko, Akinwumi Ambọde atawọn aṣofin ipinlẹ naa.
Ṣe ẹ mọ pe lọsẹ to kọja lawọn aṣofin ipinlẹ Eko paṣẹ pe ki Ambọde wa farahan niwaju ile naa ni Ọjọru ọgbọn ọjọ  oṣu kẹwa lati wa wi tẹnu rẹ lori bi o ṣe na owo ti wọn ya sọtọ fun rira bọọsi bọgini akero BRT atawọn inawo akanṣe iṣẹ miran.
Bi awọn aṣofin ipinlẹ Eko ṣe n lọgun pe Ambọde ko tẹle ofin lori inawo rira ọkọ naa, ni Ambọde pẹlu n pariwo tan-tan-tan ni tirẹ pe, ṣe awọn aṣofin ipinlẹ Eko lẹ ṣingọọmu moju ni, nigba ti wọn n buwọlu owo fun rira awọn ọkọ bọọsi bọgini akero naa labẹ eto iṣuna ọdun 2018?
Koda, olori ile naa Mudashiru Ọbasa tilẹ fọwọ lalẹ pe, bi Ambọde ko ba farahan niwaju ile naa, aṣẹ ẹ fi kele ofin gbe lawọn yoo pa ki wọn fi gbe e.
Amọṣa, kaka ki Ambọde farahan, ile ẹjọ lo gba lọ toun ti lọya rẹ, Tayọ Oyetibọ, SAN lati gba iwe ile ẹjọ ti yoo ka awọn aṣofin ipinlẹ Eko lọwọ ko lori ohun ti wọn fẹ ṣe naa.
Oríṣun àwòrán, @lshaofficial
Adajọ si ti ni ki Ambọde o fi iwe ipẹjọ atawọn iwe miran gbogbo to rọ mọ ẹjọ naa naa, wa awọn aṣofin naa lọ.
Awọn ti Ambọde pe ko wa jẹjọ lori ọrọ naa bayii ni olori ile aṣofin ipinlẹ Eko, Mudashiru Ọbasa, akọwe agba ile aṣofin ipinlẹ Eko, A.A. Sanni.
Bakan naa lẹjọ tun kan awọn ọmọ igbimọ ti wọn gbe kalẹ lori rira ọkọ bọọsi naa, iyẹn họnọrebu Fatai Mojeed, Gbolahan Yishawu, A.A. Yusuff, Yinka Ogundimu, Mojisola Meranda, M.L. Makinde, Kehinde Joseph, T.A. Adewale pẹlu O.S. Afinni.
Oríṣun àwòrán, @AkinwunmiAmbode
Ambọde ni, n ṣe lawọn aṣofin ipinlẹ Eko mọọmọ n yi iwe ati akọsilẹ lori rira okoolelẹgbẹrin ọkọ bọọsi bọgini akero naa, gẹgẹ bi o ṣe wa ninu iwe ofin iṣuna ipinlẹ Eko ti ọdun 2018 eleyi tawọn aṣofin ile naa fọwọ si funrawọn.
Ṣe ẹ ri pe kannakanna n'ọmọ ẹga, ija lori ọrọ naa ṣẹṣẹ n bọ ni, ko tii de.
Schistosomiasis: Ibà fà bí ìgbín wọ ìpínlẹ̀ Eko torí ẹ̀gbin omi, wo ohun tó ń fà á
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Iroyin iwadii kan eyi ti ileeṣẹ eto ilera tijọba ipinlẹ Eko ṣe ti fi idi rẹ mulẹ pe, ijọba ibilẹ mẹfa nipinlẹ Eko ti lugbadi ọwọja arun fa bi igbin, ti oloyinbo n pe ni Schistosomiasis.
Wọn ni aisi imọtoto to peye ati omi ti ko mọ lo n fa awọn arun yii.
Awọn ijọba ibilẹ ti wọn ni ọrọ naa kan ni Mushin, Alimọṣọ, ikẹja, Ibẹju Lekki, Agege ati Koṣọfẹ.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Eyi ni awọn koko ti o yẹ ki ẹ mọ nipa arun yii:
EFCC: Ọmọ Nàíjíríà ń bèèrè pé báwo ní àjọ náà ṣé mọ èké babaláwo?
Oríṣun àwòrán, EFCC
Babalawo kan, Fatai Olalere Alli, ti inagijẹ rẹ n jẹ baba Osun to tasẹ agẹrẹ sofin, tọwọ sinkun ajọ EFCC si baa, ni adajọ kan nile ẹjọ giga nilu Ibadan ti ni ki wọn lọ fi si ahamọ.
Ajọ EFCC to fi isẹlẹ naa sita loju opo Twitter rẹ tun kede pe bakan naa tun ni oun ko awọn eeyan meji mii, Adigun Fatai Olusegun ati Olufemi Kolawole sahamọ.
Ajọ EFCC fikun pe adajọ tun faye gba oun lati gbẹsẹ le awọn ile kan to jẹ ti babalawo naa ati akoto owo ti wọn lawọn fura si pe o fi n ṣe gbajuẹ.
Ẹsun ti wọn fi kan awọn afurasi ọhun ni pe wọn lẹdi apo pọ lati gba owo lọna ti ko tọ, eyi taa mọ si 419.
Bawo ni EFCC ṣe mọ pe ayederu babalawo ni?
Ibeere yii lawọn eeyan n beere loju opo Twitter EFCC, lati fesi si ikede iroyin ti wọn fi sita naa.
Lara awọn to beere ọrọ yii la ti ri eeyan kan ti orukọ rẹ n jẹ North Boy, to ni bi babalawo naa ba jẹ ojulowo, ṣe EFCC yoo lawọn o mu?
Ni ti tiẹ, Klaus ni ṣe ẹṣẹ ni ki awọn irunmọlẹ ma gbe owo fun eeyan ni?
Skala wee tilẹ ni bi babalawo naa ba ni agbẹjọro to munadoko, kia ni yoo jaja bọ lọwọ EFCC.
Lagos Police: Davido tasẹ́ agẹ́rẹ́ lórí àwọn obìnrin tó sọ panpẹ sí lọ́wọ́
Oríṣun àwòrán, Instagram/davidoofficial/specialspesh
Davido ti pada ni ki wọn tu awọn obinrrin naa silẹ ṣugbọn ileeṣẹ ọlọpaa ni o lẹjọ ro lọdọ awọn.
Ileeṣẹ ọlọpaa nilu Eko ti bẹnu atẹ lu gbajugbaja akọrin takasufe Davido pẹlu bi o ṣe paṣẹ ki wọn sọ panpẹ sọwọ awọn obinrin kan.
Alukoro ileeṣẹ ọlọpaa Bala Elkana to sọ ọrọ yi fun ile iṣẹ BBC ni ofin ko faye gba ki ọlọdani sọ mamugari seeyan lọwọ depo pe yoo tun ṣafihan wọn bi ọlọpaa ṣe n ṣafihan ọdaran.
Ninu fọnran fidio kan ti o ṣafihan awọn obinrin meji kan ti wọn sọ panpẹ si lọwọ, ọkan lara awọn ọmọ iṣẹ Davido n beere ọrọ lọwọ awọn obinrin naa.
Oju opo Instagram ni ọkan lara awọn to n gbẹnu sọ fun Davido fi fidio yii si to si ti mu iriwisi ọtọọtọ wa.
Elkana sọ pe awọn ko mọ si bi wọn ti ṣe mu awọn obinrin naa ati pe ko tọ ki Davido paṣẹ ki wọn mu wọn botilẹjẹwipe o fẹsun kan pe wọn parọ mọ.
O ni laipẹ yi awọn yoo kan si Davido ko wa ṣalaye tẹnu rẹ lori fọnran fidio yii.
Ofin Naijiria mẹta niDavido tapa si
Nigba ti a kan si alakoso ẹka ijọba to n gbeja ara ilu (OPD) arabirin Yinka Adeyemi, o ni ofin ilẹ Naijiria mẹta ni Davido tasẹ agẹrẹ si to ba ṣe pe o mọ si fidio naa.
''Akọkọ ibẹ ni pe o gba iṣẹ ọlọpaa ṣe pẹlu bi o ti ṣe mu eeyan fun ara rẹ, ẹlẹẹkeji ni pe o tabuku ba ọmọlakeji rẹ ti ẹlẹkẹẹta si jẹ pe o fipa mu eeyan miiran silẹ lalai ṣe agbofinro''
Oríṣun àwòrán, Facebook/OPD-LAGOS
Arabinrin Adeyemi sọ pe oun to yẹ ni ki awọn agbofinro pe Davido ko wa sọ ohun to ri lọbẹ to fi garu ọwọ.
Iru iwa bayi gẹgẹ bi o ti ṣe sọọ lodi si ofin ti ko si yẹ ki a fi aaye gba iru iwa bẹẹ lawujọ.
O wa parọwa si awọn ti wọn mu yii lati tọ awọn wa ti wọn ko ba mọ ọna ti wọn yoo fi pe Davido lẹjọ.
Ni nkan bi ọjọ melo kan sẹyin ni ọrọ yi jẹyọ.
Awọn obinrin meji kan ni wọn ṣadede fi fidio si oju opo ayelujara nibi ti wn ti ni Davido  fun ọkan ninu wọn loyun.
Iroyin tan kaakiri ti awọn eeyan si n ṣemo pe iru nnkan wo leleyi.
Fọnran fidio tawọn obinrin naa ti fẹsun kan Davido ree.
Bi Davido ti ṣe halẹ mọ wọn pe oun yoo sọ wọn si ẹwọn ni wọn jade sita pẹlu fidio miiran pe awada ni awọn n ṣe.
Ṣugbọn ẹpa ko boro mọ nitori Specialspesh to jẹ ọkan lara awọn alukoro Davido fi ikede soju opo Instagram to sọ pe oun ṣetan lati gbe miliọnu naira kan kalẹ fẹni to ba le ṣatọka awọn obinrin to n parọ mọ Davido loju opo ayelujara.
O ni awọn fẹ ki wọn foju wina ofin lori nkan ti wọn ṣe yii.
Oríṣun àwòrán, Instagram/specialspesh
Abalọ ababọ ijiya ti specialspesh fẹ fi jẹ wọn lo ja si fọnran fidio ibi ti wọn ti mu awọn obinrin mejeeji ti wọn si sọ panpẹ si wọn lọwọ.
Corporal Punishment: Olùkọ́ fẹgba lu akẹ́kọ́ọ̀bìnrin ọmọ ọdún mẹ́rìnlá pa ní yàrá ìkàwé
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Agba adura ni pe ki abiyamọ ma foju sọkun ọmọ laye. N jẹ ẹ ti ri ibi ti olukọ ti fẹgba lu akẹkọọ pa ri?
Ohun to ṣẹlẹ gan gan ree niluu Bujumbura tii ṣe olu ilu orilẹede Burundi.
Chadia Nishimwe, akẹkọọbinrin ọmọ ọdun mẹrinla ni baba rẹ sọ fun BBC pe o jẹ Ọlọrun ni pe lẹyin ti olukọ kan lu u lalubolẹ.
Jean-Marie Misago ṣalaye fun BBC pe olukọ naa to ẹgba si ọrun ati ẹsẹ Nishimwe debi wi pe, o n yọ ẹjẹ ni imu ati eti rẹ.
Misago sọ pe ọmọ oun ku ninu yara ikawe lẹyin ti olukọ yii na a tan, koda ọfiisi ọga ile iwe ọhun ni wọn gbe oku rẹ si.
Ọga ile iwe gbiyanju lati gbe Chadia lọ si ile iwosan, amọ, ẹpa ko boro mọ lẹyin ti dokita sọ fun un pe ọmọ naa ti ku ki wọn to gbe e de.
Misago ni ọjọ Iṣẹgun l'oun sin ọmọ naa, ọjọ kan naa ti ọmọ yii ku.
Ohun ti wọn sọ fun baba ọmọ yii ni pe Chadia tapa si ofin kan to de awọn akẹkọọ ninu yara ikawe rẹ.
Ofin orilẹede Burundi ko faaye gba ifiyajẹni tabi fifi ẹgba lu'yan.
Àwọn ọkùnrin tó wà nínú ayé wa gbúdọ̀ bọ̀wọ̀ fún wa - Adarí FIN
Mobolaji Johnson: Olùfọkànsìn ilẹ̀ Nàìjíríà ni gómìnà àkọ́kọ́ ìpínlẹ̀ Eko - Sanwo-Olu
Oríṣun àwòrán, Facebook/Deji Johnson
Awọn to mọ Mobolaji Johnson nigba aye rẹ ni o jẹ ọlọyaya
Bi a ba pe ori akọni Mobolaji Johnson,niṣe laa o ma fi ida lalẹ garara.
Ni bayi to ti dagbere faye pe o digba,awọn ohun to gbe ṣe laye ni a o ma fi ranti rẹ.
Ninu awọn ohun to ṣe la ti ri eleyi ti awọn eeyan n gbe oṣuba fun ati awọn miran ti awọn ẹlomiran ni o ku diẹ kaato.
O ṣàkóso  manigbagbe mí tó ṣé
Amọ ṣa ki a to ṣe atupalẹ awọn nkan wọn yi,o tọ ki a ṣalaye pe Mobolaji Olufunso Johnson ni Gomina ologun akọkọ  ti wọn yan ni ipinlẹ Eko laarin oṣu kaarun ọdun 1967 titi di oṣu Keje ọdun 1975.
Ọmọ Ẹgba ni Mobolaji Johnson ti a si bi ni ọdun 1963.
Lasiko igba to jẹ Gomina labẹ ijọba Yakubu Gowon o ṣe awọn nkan orisirisi to jọ mọ idagbasoke ilu.
Pataki ninu ohun ta ri akọsilẹ pe o ṣe ni ṣiṣe agbekalẹ ilana fawọn oṣiṣẹ ijọba nipinlẹ Eko.
Oríṣun àwòrán, Facebook/Deji Johnson
Awọn to mọ Mobolaji Johnson nigba aye rẹ ni o jẹ ọlọyaya
Bakanna, o ṣe agbekalẹ ofin kan to koju bi awọn onile ti ṣe n gbowo gọbọi lori ile wọn.
Lasiko ta n sọ yi,ijọba da awọn kootu ti yoo ma dajọ lori iye owo tawọn onile n gba lọdọ ayalegbe.
Ofin yi  fi igba kan dẹwọ gbigbe ile kalẹ lowo gọbọi titi di asiko tawọn eeyan bẹrẹ si ni ṣe eleyi to wu wọn.
Lasiko ti Mobolaji jẹ Gomina ipinlẹ Eko ni wọn bẹrẹ si ni kọ afara ẹlẹẹkeji si erekusu Eko(Eko Bridge)
Awọn eeyan kan sọ pe asiko rẹ ni wọn bẹrẹ iṣẹ lori afara ẹlẹẹkẹta to lọ si erekusu Eko(Third Mainland Bridge )ṣugbọn a ko ri idi ọrọ yi fi mulẹ botilẹjẹwipe ọdun 1990 ni wọn si afara naa.
Iboji oku Ajele
Lara awọn nkan ta ri akọsilẹ pe ọgagun Mobolaji Johnson ṣe nigba aye rẹ ni pe o paṣẹ ki wọn tu iboji oku ti wọn sin ni Ajele ka ti wọn si ko awọn oku ibẹ kuro.
Oríṣun àwòrán, Facebook/Dr Raphael James
Arakunrin Raphael James nibi to ti duro lẹgbẹ iboji ti wan pada sin oku Samuel Ajayi Crowther si
Lọdun 1971 lo paṣẹ yi toripe wọn fẹ kọ ileeṣẹ ijọba ipinlẹ Eko sibẹ.
Igbesẹ yi jẹ eleyi tawọn eeyan bẹnu atẹ lu ti a si gbọ pe Samuel Ajayi Crowther ati awọn eekan mi bi Iyaafin Efunroye Tinubu wa lara awọn oku ti wọn wu kuro nibẹ.
Awọn nkan miran ti  o jẹ manigbagbe nipa rẹ:
Nigba ti ijọba ologun Murtala Muhammed de ori oye mi 1975,ọgagun Mobolaji Johnson ati ọgagun Oluwole Rotimi nikan ni Gomina meji ti  igbimọ ẹlẹni mẹta ti wọn gbe kalẹ sọ pe wọn ko jẹbi iwa ajẹbanu.
Ọdun 1975 ni Mobolaji Johnson fẹyinti nidi iṣẹ ologun ti o si bẹrẹ iṣẹ aladani ti rẹ.
Oríṣun àwòrán, Uyi Obaseki
Ọgagun Mobolaji Johnson lo wa lapa ọtun aarẹ ologun igba naa Yakubu Gowon lọdun 1972
Loni bayi,wọn fi opopona ati aye eye idaraya pe orukọ rẹ.
O jẹ ẹni to fẹran ere idaraya ti o si nifẹ si irrinajo inaju.
Ẹwẹ, Gomina Babatunde Sanwo-Olu ti ranṣẹ ibanikẹdun si idile oloogbe Mobolaji Johnson.
Sanwo-Olu ṣapejuwe oloogbe naa gẹgẹ bi olugbe ilu Eko to ṣiṣẹ takuntakun fun igbega ipinlẹ ati orilẹ-ede Naijiria lapapọ.
Sanwo-Olu sọ pe ijọba Mobolaji Johnson lo pese oniruuru nnkan amaludẹrun nipinlẹ Eko, eleyi to si tun wa doni.
Gomina ipinlẹ Eko ni lootọọ ni Mobolaji Johnson ti filẹ ṣaṣọbora, amọ, awọn eeyan yoo maa ṣe iranti rẹ lọ laelae nitori awọn iṣẹ nla nla to gbese nigba aye rẹ.
Sanwo-Olu ni ''gbogbo eeyan lo ranti bi ijọba Mobolaji Johnson ṣe kọ ile iwe girama marun un ati ọpọ ilegbee laarin ọdun kan ijọba rẹ.''
Gomina ipinlẹ Eko ni ọna kan gboogi lati maa ṣeranti Mobolaji Johnson ni lati rii pe awọn araalu n jẹ anfaani ijọba awarawa.
O dagbere fayẹ lọgbọn ọjọ oṣu Kẹwa ọdun 2019 lẹni ọdun mẹtaleọgọrin.
Àṣà àti ìgbàgbọ́ Yorùbá ni pé òbí wọn máa ń padà wá sáyé
Oshiomole: Nínú ká máa rin ìrìnàjò ilẹ òkèèrè, ọgá ṣí ní Ọbasanjọ jẹ́
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Oshiomole: Nínú ká máa rin ìrìnàjò ilẹ òkèèrè, ọgá ṣí ní Ọbasanjọ jẹ́
Alaga ẹgbẹ oṣelu APC ti sọ pe lootọ laarẹ Muhammadu Buhari le ma rin irinajo lọ si ilẹ okeere ṣugbọn lori agbelewọn ko ti ṣe to aarẹ ana,Olusegun Obasanjo.
Opọ awọn ọmọ Naijiria ti n sọrọ pe ko si koko pe Aarẹ Buhari n rin irin ajo kaakiriBuhari kàn ń kọwọ́ bọ̀wé nílẹ̀ òkèèrè kiri ni, a ò rí ipa ní Nàijíríà- Onímọ̀ ọrọ̀-ajé
Oshiomole fesi yi ni idahun si ibeere awọn oniroyin l'Abuja lori bi aarẹ Buhari ti ṣe fẹran lati ma rinrinajo lọ silẹ okeere lasiko yii.
Alaga ẹgbẹ APC naa sọ pe ko si ootọ ninu ọrọ yi.
Lati le kin ọrọ rẹ lẹyin, o ni Gani Fawehinmi kọ iwe kan nibi to ti ṣatupalẹ iye igba ti aarẹ Obasanjo fi ririn ajo nigba to wa ni ijọba.
Oshiomole ni ''Ki a ma sọ pe aarẹ Buhari fẹran ko maa rinrin ajo lọ si ilẹ ki i ṣe ootọ.
Mo ranti daadaa pe ko si aarẹ kankan lati ọdun 1999 titi di isinyi to rinrin ajo to aarẹ ana Olusegun Obasanjo''
Loju Oshiomole, irinajo Buhari ko tii pọ ''Bi ẹ ba wo akọsilẹ daadaa, ẹ o ri ibi ti oloogbe Gani Fawehinmi ti ka iye igba ti aarẹ Obasanjo ti lọ irinajo silẹ okeere. Koda o ka iye wakati to n lo lori ofurufu pẹlu iye igba to fi wa nile''
Lẹnu ọjọ mẹta yii, aarẹ Muhammadu Buhari ti n ṣe awọn irinajo lọ si ilẹ okeere eleyi to mu ki awọn ma sọrọ pe kii joko sile ṣejọba.
Nollywood: Taiwo Hassan, akọni òṣèré Yollywood tó jẹ́.....
Oríṣun àwòrán, @Ogogo
Opọ eniyan lo n ba ọlọjọ ibi yọ ayọ ọgọta ọdun
Ọpọ awọn ọmọ Naijiria lo n ki agba oṣere Taiwo Hassan ku oriire ọgọta ọdun lori oke eepẹ loni.
Yinka Quadri to jẹ ọrẹ ti wọn ti jọ n ṣere tipẹtipẹ naa kii pe ọrẹ to yatọ ni Ogogo jẹ
Opolopo awọn ololufẹ BBC naa n gboriyin fun Ogogo Kulodo ti wọn si n sọrọ nipa awọn ere Taiwo Hassan ti wọn gbadun julọ loju opo BBC News lori facebook.
Eni ọdun ba ba laye a ṣọpẹ paapaa to ba huwa ti aye n ri sọ nipa rẹ
Loju opo Facebook BBC News ni awọn eeyan ti n sọrọ nipa awọn ere Ogogo
Iya Ibeji, Eleran Igbẹ atawọn
Wo ǹkan márùn ún ti ò kò mọ̀ nípa Taiwo Hassan, Ogogo ọmọ kulodo tó n ṣeré Yorùbá.
A bi Taiwo Hassan ti gbogbo eeyan mọ si Ogogo ni ọjọ kọkanlelọgbọn, oṣu kẹwaa, ọdun 1959.
Ilu Ilaro ni ipinlẹ Ogun ni guusu iwọ oorun Naijiria ni ati bi Ogogo ọmọ Kulodo.
Oríṣun àwòrán, @Ogogo
Taiwo Hassan to jẹ Denzel Washington inu ere agbelewo Yoruba!
Oṣere ti igba oju mọ ni Taiwo Hassan, o ti ṣe awọn ere to lokiki bii Owo Blow, Sababi, Ibinu elewọn, Atitẹbi ati bẹẹ bẹẹ lọ.
Adedoyin: Tí mo bá rí Buhari, màá sọ fun kó rántí pé Ọlọ́run wà
Odindin ọdun mẹtala ni Taiwo Hassan fi ṣiṣẹ pẹlu ẹka to n mojuto omi ẹrọ ni ipinlẹ Eko.
Odun 1994 ni Ogogo fẹyinti kuro lẹnu iṣẹ Oba ipinlẹ Eko ko too gbajumọ ere ṣiṣe ni ẹkunrẹrẹ.
Taiwo Hassan lọ sile iwe alakọbẹrẹ Christ Church School nilu Ilaro.
O tun ló sile iwe Yaba Technical College nibi to ti kọ ẹkọ nipa ọkọ titunṣe.
'Oun tí Kunle Afolayan ṣe sí mi, mi ò lè ṣeé sí i'
Ogogo fẹ obinrin meji ọtọọtọ.
Taiwo Hassan bi ọmọbinrin mẹta ati ọmọkunrin kan.
Odun 1981 ni Taiwo Hassan bẹrẹ iṣẹ ere ṣiṣe ni kete to bẹrẹ iṣẹ pẹlu ijọba ipinlẹ Eko.
Ogogo ni idi ti oun fi n duro deedee bi ọmọkunrin ni ere idaraya ẹṣẹ kíkàn ti oun gbadun lati maa ṣe fi daraya.
Bakan naa lo tun ni oun fẹran lati maa gbọ orin paapaa ti awọn ọdọ iwoyi to ba mọgbọn dani
Njẹ ọkunrin nilo isinmi nigba ti iyawọ wọn ba sẹsẹ bi ọmọ?
Ogogo jẹ ọkunrin ti o ni awọn iwa kan to yaa sọtọ lagbo oṣere.
Ninu ifọrọwerọ kan lo ti ṣalaye pe oun kii fẹnuko obinrin lẹnu ninu ere nitori ko si lara abuda adamọ oun.
Ogogo ni oun ko fi bẹẹ fẹran lati maa ṣe ipa ololufẹ to n fi ifẹ han ni gbangba ninu ere agbelewo.
Kunle Afolayan: èmi kò fẹ́ fi ogún sílẹ̀ fún ọmọ mi
Pakistan train fire: Iná ńlá ti pa ènìyàn 74
Àjọ́ òsìsẹ́ pàjáwìrì ní ó seése kí iye àwọn ènìyàn tó kù ju bẹ́ yẹn lọ nítorí ènìyàn ogójì ló farapa nínú iná náà.
O kere tan eniyan mẹtalelaadọrin lo ti papoda lẹyin ti ọkọ reluwe to n ná ilu Karachi si Rawalpindi gbina lorilẹede Pakistan.
Minisita fun ọrọ reluwe lorilẹede naa, Sheikh Rashid Ahmed sọ wi pe afẹfẹ gaasi ti awọn eniyan fi n se ounjẹ owuro lo bu gbamu, to si fa ijamba ina naa.
Oríṣun àwòrán, Reuters
Ibugbamu naa ṣe akoba fun ọkọ̀ to le ni mẹta.
Oríṣun àwòrán, Rescue1122
Awọn osisẹ pajawiri sọ wi pe ọpọlọpọ awọn eniyan to ku naa n gbiyanju lati sa kuro ninu ina lasiko ti ijamba ọhun waye.
Oríṣun àwòrán, Rescue1122
Wọn ni o seese ki iye awọn eniyan to ku ju bẹẹ lọ nitori eniyan ogoji lo farapa yannayanna ninu ina naa.
Àṣà àti ìgbàgbọ́ Yorùbá ni pé òbí wọn máa ń padà wá sáyé
Yahoo Boys: Àwọn ọmọ Yahoo tí kò dín ní igba ni yóò fojú ba ilé ẹjọ - EFCC
Oríṣun àwòrán, @officialpagemagu
Ibrahim Magu
Adele alaga ajọ to n ri si iwa jẹgudujẹra lorilẹede Naijiria, Ibrahim Magu, ni o ti fi aidunnu rẹ han si iwa ti iya awọn afẹsunkan lori ọrọ jibiti lilu lori ayelujara ti a mọ si Yahoo Boys.
Magu ṣalaye ọrọ yii lọjọbọ ni ẹka ile iṣẹ naa ti o wa ni ilu Eko pe, awọn iya ọmọ wọnyii n gbiyanju lati da ẹgbẹ silẹ.
Nigba ti o n ba awọn akọroyin sọrọ, o wi pe, pupọ awọn iya wọnyii lo n sọ wi pe, awọn fi ara mọ iṣẹ ti ọmọ wọn n ṣe nigba ti ko si ọkọ tabi ti ọkọ ti sa lọ fun wọn.
Alaga yii wa fi idi ọrọ rẹ mulẹ wi pe kii ṣe pe ajọ naa yoo fi panpẹ ọba mu wọn lasan ṣugbọn wọn tun maa ṣe alakalẹ ọna ti wọn yoo fi wulo lawujọ ti wọn yoo si sọ wọn di ọtun.
Magu ni pataki apero yii ni lati gbogun ti iwa ibajẹ ati lati dẹkun gbogbo iwa iluni ni jibiti ori ẹrọ ayelujara.
O wa ni ko din ni Igba awọn iru ọmọ bẹẹ ti wọn yoo foju ba ile ẹjọ.
Àṣà àti ìgbàgbọ́ Yorùbá ni pé òbí wọn máa ń padà wá sáyé
Lagos Government: Abániwálé gbọ́dọ̀ darapọ̀ mọ́ ètò tuntun Ìjọba Ìpínlẹ Eko.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Eto Ile Gbigbe
Ijọba Ipinlẹ Eko ti ṣalaye pe opin yoo de ba gbogbo iwa jibiti to rọ mọ wiwale kiri ni Ipinlẹ naa ti awọn eniyan n doju kọ latari iṣẹ ọwọ awọn abaniwale.
Ijọba wa tẹpẹlẹ mọ wi pe, ẹrọ igbalode ni wọn yoo maa lo lati wa ile ti o tẹ wọn lọrun ti ko si ni mu idamu lọwọ mọ.
Wọn ni nigba ti gbogbo eto ba ti to tan ni yoo fun ọpọ ara ilu lanfaani lati wa iru ile, tabi ilẹ ti wọn ba fẹ lati ori ẹrọ igbalode pẹlu ẹni to jẹ alakoso iru ile bẹẹ.
Gomina Ipinlẹ Eko, Babajide Sanwo Olu ṣalaye pe, iru eto bayii ni yoo ṣe anfaani fun ara ilu nitori pe, wahala ati jibiti ọrọ ile ti pọ ju.
Ninu ọrọ ti Ijọba Ipinlẹ naa fi ṣọwọ sita, o ni gbogbo awọn ti o ni ohun kan tabi meji lati fun awọn eniyan ni lati ni ẹrọ igbalode naa ti ko si ni awuruju ninu.
Ko din ni Ọrinlenigba awọn eniyan ti abaniwale kan lu ni jibiti lagbegbe Ketu -Alapere.
Bakan naa ni bii Oṣu kan sẹyin ni enikan lu Aadọrin eniyan ni jibiti ni Gbagada lori yara olojule marun.
Gẹgẹ bi Olubada mọnran Gomina naa lori ọrọ ile gbigbe,Arabinrin Toke Benson -Awoyinka ti wi pe, ọrọ yii jẹ Ijoba logun gidigidi ti ko si le maa wo iru ọrọ bẹẹ niran.
Ni ọjọ Isinmi, ẹka ajọ Ọlọpaa ṣafihan awọn marun un kan ti wọn fẹ lu ọkunrin kan ni jibiti owo ti o to Miliọnu Mẹrin abọ naira,
O wa ni asiko ti to lati ṣatunṣe si gbogbo kudiẹkudiẹ to wa ninu iru iṣẹ bẹẹ ni Ipinlẹ Eko.
Nigba ti o n ba ile iṣẹ BBC sọrọ ni ọjọbọ lo ti ṣalaye pe awọn abaniwale ati onile ni yoo sọ fun Ijọba pe ko si iwa makaruruu lọwọ wọn ti ayẹwo yoo si wa lori dukia wọn.
Ko ṣai mẹnu ba afikun  owo ojiji ti wọn maa n fi si owo ile lẹyin ti ayalegbe ba ti san owo tan ti o si n fa idaaru fun ojulowo abaniwale.
Owo ojiji yii gan an ni Ijọba yoo boju to ti yoo si mu ifọkan balẹ ba ara ilu.
Ohun Mẹwa ti Ijọba Eko yoo ṣe lati dẹkun Jibiti lori ile gbigba lọwọ awọn abaniwale
Àwọn ọkùnrin tó wà nínú ayé wa gbúdọ̀ bọ̀wọ̀ fún wa - Adarí FIN
Ilana Ijọba yii yoo ran ara ilu lọwọ lọpọlọpọ, sugbọn o ṣeeṣe ko ma tan gbogbo iṣoro naa lẹẹkan nitori ko din ni miliọnu mejilelogun awọn eniyan to wa nilu Eko.
Gbogbo awọn onile to maa n fipa mu ayalegbe lati san owo ọdun meji ni yoo foju ba ile ẹjọ nitori o lodi sofin, ọdun kan ni ofin ṣe alakalẹ rẹ.
O wa rọ gbogbo awọn eniyan ilu Eko lati lo anfaani yii nitori yoo ṣe iranlọwọ to pọ fun wọn lẹyinwa ọla.
Olubadamọnran naa wa wi pe oju opo ti Ijọba yoo mu silẹ yii maa wulo pupọ fun gbogbo olugbe Eko ti awọn abaniwale si ti n beere fun eto naa.
Eto yii fun Ijọba Ipinlẹ Eko ni ifọkanbalẹ pe yoo késẹ jari ti yoo si ṣe adinku ba gbogbo iwa jibiti.
Trafficking in Abuja: Ọkùnrin 15 ni mò ń ba sùn lọ́ọ̀jọ áti san owó ọ̀gá mi
Trafficking in Abuja: Ọkùnrin 15 ni mo ń ba sùn lọ́ọ̀jọ áti san owó ọ̀gá mi
Kí ọmọ ọdún mẹ́ẹ̀dógun maa bá ènìyàn mẹ́ẹ̀dọógun sùn lójóoójúmọ jẹ́ ǹkan to bani nínú jẹ́ gidi.
Èyí jẹ́ ǹkan ti Ngozi (eyí kìí ṣe orúkọ rẹ̀ gangan) ń là kọjá lójoojúmọ fún ọ̀pọ̀lọ̀pọ̀ oṣù nínú ilé ìtúra kan ní agbègbè Lugbe l'Abuja to jẹ olu ilu Naijiria.
Ngozi dí èrò ilé Aṣẹ́wó lẹ́yìn ti àládúgbọ rẹ̀ ní ìpínlẹ̀ Anambra fí lọ̀ọ́ pé oun yóò ràn án lọ́wọ́ láti baa rí iṣẹ́ láti le san owó ilé-iwé rẹ̀ ti o ba lé wá si ilú Abuja.
Ọ̀gá mi a sọ pé ki ń wọ síkẹ̀tì pélébé àti búláòsì kékeré lati lọ le ara mi si ojú pópó. Ọkùnrin mẹ́ẹ̀dógun ni mò ń ba sùn ti wọ́n a sì san ẹgbẹ̀rùn kan náìrà fún ọgá mí èyí ni ọ̀rọ̀ Ngozi.
Àwọn ọkùnrin tó wà nínú ayé wa gbúdọ̀ bọ̀wọ̀ fún wa - Adarí FIN
Ajọ NAPTIP ni ìdá àádọ́rin ninu ọgọ́rùn un obinrin bii ti Ngozi ni wọ́n ti fí n ṣe aṣẹ́wo láti ìpínlẹ kan sí òmíràn ni orílẹ̀-èdè Naijiria.
Ní ti Mercy (èyí kìí ṣe orúkọ rẹ̀ gangan) náà jẹ́ ọkàn lárá wọ́n. O sọ fún BBC pé wọ́n tan oun wá si ilé aṣẹ́wo náà ni agbègbè Lugbe ni Abuja.
O ní lẹ́yin ti òun siṣẹ́ tan fún ọ̀pọ́ oṣù fun ọgá òun, ni oun wá gbìyànjú lọ́jọ́ kan lati sálọ sùgbọ́n ọ̀gá oun pada gbá òun mú, o si fi abẹ gé gbogbo ara oun yálayàla.
Trafficking in Abuja: Ọkùnrin 15 ni mo ń ba sùn lọ́ọ̀jọ áti san owó ọ̀gá mi
Ilé Aṣẹ́wó pọ̀ bàbì ní agbègbè Lugbe ni Abuja
Àdúgbọ ti ilé Aṣẹwo yìí wa jẹ́ ibi kan ti àwọn òtòsì pọ sí jùlọ, bó tilẹ̀ jẹ́ pé àdúgbò náà kò ni ojú pópó kan gidi, síbẹ̀ àwọn ilé aṣéwo ti wọ́n fi páko kọ ló pọ̀ jùlọ.
BBC ṣe àbẹwo si ilé aṣéwo yìí níbi ti ọ̀pọ́ àwọn ọdọmọbinrin pẹ̀lu aṣọ pénpé pọ si jùlọ ti àwọn ọmọ ọkùnrin àdúgbo náà si n tú iná igbó mímú ni ita otẹ̀lí náà.
Helgies Bandeira: Ọ̀pọ̀ oúnjẹ Yorùbá ni à ń jẹ ni Brazil
Akoroyin BBC náà ṣe bi ẹni pé oun ni àwọn ọmọbinrin kéèkèké ti oun fẹ́ mú wá si ibẹ̀.
Ẹni to ba pàde sàlàye fún akọroyin BBC pé ko kan lọ mu yàrá kan ko si lo mú ọmọ náà wá fún iṣẹ́ síṣe
O sọ́ fun akoroyin wa pé yóò maa san ẹgbẹ̀rún méèdógun náira lọ́sọọsẹ̀ fún owó yàrá.
O fi kun un pé ti ọmọ ti o n mú bọ ko ba ti dagbà to lọ́jọ́ ori, o ní láti maa pe ọjọ ori rẹ̀ ni ogun ọdun ati jù bẹ́ẹ lọ.
Oríṣun àwòrán, BBC
Iyara kan ninu ile aṣẹwo ni Lugbe Abuja
Wọ́n sàlàye fún akọròyìn wá pé, ọmọ to ba mu wá yoo maa san ẹgbẹ̀run mẹwàá sí ẹgbẹ̀run mẹ́ẹ̀dogun lójoojúmọ pàápàá jùlọ bi o ba ṣe le ṣiṣẹ́ si.
Ọ̀gá àgbà fun àjọ NAPTIP, Julie Okah-Donli sàlàyé fun BBC pé àwọn ọmọ kekeeke ti wọ́n ń lo fun àwọn iṣẹ́ ibi yìí ti pọ̀ gan ni orilẹ̀-èdè Naijiria.
Níwọ̀n ìgbà ti àwọn tó ń lọ ilé aṣẹ́wo ba ti wà, àwọn ọmọ keekeeke náà ni wọ́n a maa lò.
Julie ni ajọ náà ti lọ kaakiri lati ka awọn ilé aṣẹ́wo ti wọ́n ti n lo àwọn ọmọ wẹ́wẹ́ náà mọ ti àwọn si ti ti omiran pa ti àwọn si gbe ẹni to nii lọ si ile ẹjọ.
Donli ni Síbẹ̀ lẹ́yìn ti àwọn ti gbé wọ́n lọ si ilé ẹjọ, àwọn o sinmi láti maa ran àwọn ọmo ti wọn ko kúro nibẹ̀ lọ́wọ́, Ngozi àti Mercy pẹ̀lú àwọn ọmọ míràn ti ajọ náà gbà sílẹ̀ ni àwọn ti kó lọ si ibi ààbò kan ni ìlú Abuja nibi ti wọn ti n kọ́ iṣẹ́ ọwọ́.
Seyi Makinde pàṣẹ kí wọ̀n dáwọ iṣẹ́ dúró lórí iṣẹ́ àgbàṣe ₦67bn òpópónà Ibadan Lagos Bye Pass
Oríṣun àwòrán, Twitter/seyiamakinde
Gomina Seyi Makinde ko ṣẹṣẹ ma bẹnu atẹ lu iye owo agbaṣe nipinlẹ Oyo ti ijọba rẹ jogun
Ijọba ipinlẹ Oyo ti paṣẹ ki awọn agbaṣẹ to n ṣiṣẹ lori opopona Ibadan Circular road eleyi ti awọn awakọ le ma gba dipo oju ọna marosẹ Lagos Ibadan lati dawọ iṣẹ duro.
Gomina Seyi Makinde lo paṣẹ yi lasiko to n ṣe abẹwọ lati mọ bi iṣẹ ti ṣe n lọ si lọna naa.
Makinde ni lati ọdun 2017 ni wọn ti  buwọlu iwe adehun iṣe agbaṣe ọna naa.
Makinde ni ijọba yoo ṣe ipade pẹlu awọn kọngila ti wọn gbe iṣẹ naa fun lati le mọ ọna tawọn yoo fi wa owo iṣẹ naa tori pe opopona ohun ṣe pataki si ọrọ aje ipinlẹ Oyo.
Kilomita mẹtalelọgbọn ni ọna naa jẹ ti wọn si ya biliọnu mejilelọgọta kalẹ fun iṣẹ rẹ.
Makinde sọ fawọn oniroyin pe ida marun un le diẹ ninu ida ọgọrun un iṣẹ naa ni wọn ṣẹṣẹ ṣe.
Oríṣun àwòrán, Twitter/seyiamakinde
Opopona ti wọn da iṣẹ duro lori rẹ la gbọ pe ida marun ninu ida ọgorun iṣẹ ni wọn ṣẹṣẹ ṣe
Ọrọ owo lori iye ti wọn ya fun iṣẹ naa ti n mu ki ẹnu maa kọ awọn eeyan lori iye naa.
Awọn kan to wi tẹnu wọn loju opo Twitter sọ pe iye owo yii ti pọju lati fi ṣe opopona naa.
Gomina Seyi Makinde ko ṣẹṣẹ ma bẹnu atẹ lu iye owo agbaṣe nipinlẹ Oyo ti ijọba rẹ jogun.
Laipẹ si igba to gun ori alefa lo sọ pe agbaṣẹṣe kankan ko gbọdo mu owo ẹyin wa ba ohun bi wọn ti ṣe n ṣe pẹlu ijọba to kọja.
Helgies Bandeira: Ọ̀pọ̀ oúnjẹ Yorùbá ni à ń jẹ ni Brazil
Indonesia Adultery: Àwọn ẹ̀ṣẹ̀ tí ìjìyà ẹgba jíjẹ wà fún
Oríṣun àwòrán, AFP
Mukhlis to jẹ ẹni ọmọ ọdun mẹrindinlaadọta ni onimọ ẹsin akọkọ ti wọn yoo fi ijiya ẹgba jijẹ jẹ ni agbegbe Aceh,Indonesia.
Arakunrin ọmọ orileede Indonesia kan to kopa ninu bi wọn ti ṣe ṣagbekalẹ ofin ẹgba jijẹ fun iwa agbere ti faragbẹgba tori pe oun gan hu iwa agbere.
Ẹgba mejidinlọgbọn ni Mukhlis bin Muhammed to jẹ ọmọ ẹgbẹ awọn Ulama Aceh(MPU) jẹ.
Obinrin to ṣagbere pẹlu rẹ naa la gbọ pe wọn na lẹgba mẹtalelogun.
Agbegbe Aceh nibi to ṣe pe oun nikan ni ibi ti awọn eeyan ti ma n tẹle ofin Sharia ni Mukhlis ti wa.
Iwa ibalopo laarin akọ si akọ tabi abo si abo to fi mọ tẹtẹ tita ta ko ofin nibẹ ti wọn si fi  ijiya ẹgba jijẹ lélẹ̀ fawọn ẹṣẹ yii.
Husaini Wahab to jẹ igbakeji adari ilu agbegbe Aceh Besar ti Mukhlis n gbe sọ fun BBC Indonesia pe ''Ofin Ọlorun ni. Ẹni ti igba ofin ba ṣi mọ lori ti a si ri aridaju rẹ gbogbo a fara gbẹgba koda ko jẹ ọmọ ẹgbẹ MPU''.
Loṣu kẹsan ni awọn alaṣẹ lagbegbe naa ka wọn mọ ninu ọkọ kan nibi ti wọn ti n ṣe agbere.
Lọjọbọ ni wọn da sẹria ẹgba fun wọn ti ẹgbẹ MPU si sọ pe awọn yoo yọ Mukhlis kuro ninu ẹgbẹ awọn.
Mukhlis to jẹ onimọ nipa ẹsin ni akọkọ onimọ ẹsin ti wọn yoo dajọ ijiya ẹgba fun lati igba tofin naa ti fẹsẹ mulẹ lọdun 2005.
Operation Positive Identification: Ọnà àti dúnkokò mọ́ ará ìlú ni o
Oríṣun àwòrán, OTHER
Agbẹnusọ fun ẹgbẹ Afẹnifẹre, Yinka Odumakin ti bu ẹnu atẹ lu erongba ajọ Ologun nipa eto pe wọn yoo maa ṣayẹwo idanimọ awọn ọmọ Nigeria.
Olori ajọ awọn omo Ologun lorilẹede Nigeria, Ọgagun Tukur Buratai, lo ti kọkọ ṣalaye pe, ọranyan ni fun awọn ọmọ Nigeria lati ni ọna idanimọ.
Awọn Ologun sọ pe ilana yii wa lati kapa ikọ Boko Haram ti wọn ti wọle si orilẹede Nigeria ni.
Ṣugbọn, Yinka Odumakin sọ pe ọna ati dun koko mọ awọn ọmọ Nigeria ni.
Nigba to n ba BBC Yoruba sọrọ, o tẹpẹlẹ mọ ọ pe, iṣẹ Ọlọpa ati ajọ to n ri si iwọlewọde ni lati beere fun idanimọ awọn araalu kii ṣe iṣẹ ajọ Ologun rara.
Odumakin wa rọ ara ilu lati ma ṣe ba ọkan jẹ rara pe, gbogbo ribaribo ti ijọba asiko yii n ti wọn fun, igba diẹ ni.
Ko ṣai mẹnu ba a wi pe, ẹni eegun n le, ko maa rọju, bo ṣe n rẹ ara aye naa lo n rẹ ara ọrun.
Ṣaaju ni ajọ ọmọ ologun ti kede pe ọjọ Ẹti ọsẹ yii ni wọn yoo bẹrẹ eto naa lẹyẹ- o- sọka, ti awọn ọmọ ile Igbimọ Aṣofin si ti pe fun ẹkunrẹrẹ ọna ti wọn yoo gbe e gba.
Helgies Bandeira: Ọ̀pọ̀ oúnjẹ Yorùbá ni à ń jẹ ni Brazil
Ajimobi: A gùnlé ìdájó ilé Ẹjọ́ àkọkọ lórí ẹjọ Ajimobi - Adájọ
Oríṣun àwòrán, FACEBOOK
Abiola Ajimobi
Gomina ana ni Ipinlẹ ọyọ Abiola Ajimọbi ti fidi rẹmi ninu ipẹjọ rẹ lati tako ibo ti o gbe ojugba rẹ Kola Balogun wọle gẹgẹ bii Sẹnatọ.
Ile ẹjọ kotẹmilọrun ni o fagile iwe ipẹjọ ti Ajimọbi fi pe sẹnatọ naa ti o n ṣoju guusu Ipinlẹ naa lẹjọ.
Ṣe lori idibo ọjọ kẹtalelogun osu keji ọdun yii ti Balogun ni ibo 105,720 nigba ti Ajimọbi ni 92,218.
Nigba ti o n da ẹjọ naa, Justice Haruna Tsammani ni o da ipẹjọ naa nu ti o ni ko lẹsẹ n lẹ rara.
Adajọ naa ni o wa gun le igbẹjọ ile ẹjọ ti o ri si esi ibo pe idajọ ododo ni wọn ti kọkọ da.
Ile ẹjọ wa ni pe Ajimọbi ko ni aṣẹ lati sọ wi pe Balogun ko tọna lati dije labẹ aṣia ẹgbẹ oṣelu PDP.
O ni, ẹni ti ko kopa ninu eto ibo abẹle, ko ni aṣẹ lati tako ibo abẹle ẹgbẹ oṣelu kọọkan.
Adajọ naa tẹsiwaju pe, kete ti ajọ ti o n ri si eto ibo ati ẹgbẹ oṣelu ba ti fọwọ si ẹnikẹni pe o kunjuuwọn, ko si idaduro mọ fun iru ẹni bẹẹ.
Tsammani wa wi pe gbogbo ẹri ti Ajimọbi ko kalẹ ko lẹsẹ n lẹ rara lati tabuku alatako rẹ.
O wa ni ile ẹjọ ṣe idajọ to yẹ nipa dida ẹjọ are fun Balogun.
Lagos crime: Àáfà ní òun bu ọlọ́pàá jẹ nígbà tó fẹ́ yí òun lọ́rùn ní Mushin
Oríṣun àwòrán, Twitter/Nigerian Police
Lagos crime: Àáfà ní òun bu ọlọ́pàá jẹ nígbà tó fẹ́ yí òun lọ́rùn ní Mushin
Ki oju ma ri ibi, gbogbo ara loogun rẹ. Eyi lo difa fun aafa kan, Abdulfatai Solahudeen ti wọn sọ pe o bu awọn ọlọpaa jẹ.
Solahudeen ni wọn gbe lọ sile ẹjọ Magisireti lagbegbe Ogba niluu Eko ni Guusu Naijiria.
Awọn ọlọpaa mu ọkunrin yii to tun n fi Ọkada gbero lori ẹsun pe o n ṣiṣẹ ju akoko ti ofin gba a laaye lọ.
Ni bi aago mejila oru ku iṣẹju mẹẹdogun ni ọlọpaa Seyi Akindele ati awọn akẹgbẹ rẹ mu aafa yii ni Mushin nigba ti wọn n ṣe iwọde de agbgbe naa.
Irọyin sọ pe Solahudeen n wọ ya ija pẹlu awọn ọlọpaa nigba ti wọn mu un, lẹyin naa lo bu ọkan lara wọn jẹ lọwọ.
Amọ, ninu ọrọ rẹ, Solahudeen to jẹ ẹni ọdun marundinlogoji sọ pe oun bu ọlọpaa ọun jẹ nitori o fọwọ fun oun lọrun.
Aafa naa ni oun n fi Ọkada ṣiṣẹ lati pese ounjẹ fun idile oun, bakan naa lo sọ pe oun maa n kun Ọkada nigba tọjọ ba ti lọ lati ri owo gidi nibẹ.
Nigbẹyin gbẹyin, ẹsun onikoko mẹta to da lori idoju ija kọ eeyan ati aigbọran sofin oju popo ni wọn fi kan an.
Helgies Bandeira: Ọ̀pọ̀ oúnjẹ Yorùbá ni à ń jẹ ni Brazil
Amọ, Solahudeen loun ko jẹbi ẹsun ti wọn kan oun, lẹyin naa ni ileẹjọ gba oniduro rẹ pẹlu ẹgbẹrun lọna aadọta  naira.
Adajọ, Iyaafin O. Ogundare sun igbẹjọ naa siwaju di ọjọ kokanlelogun, oṣu kọkanla, ọdun 2019.
Muhammadu Buhari: Ààrẹ Nàìjíríà gba Saudi lọ sí ìlú London nílẹ̀ Gẹ̀ẹ́sì
Oríṣun àwòrán, Instagram/Bashir Ahamad
Aarẹ orilẹede Naijiria, Muhammadu Buhari ti mori le ilẹ Gẹẹsi bayii lati orilẹede Saudi Arabia, lẹyin to kopa ninu eto Umrah ati apero kan to niiṣe pẹlu idokowo lọjọ iwaju.
Iroyin to tẹ wa lọwọ sọ pe, lọsan ọjọ Satide ọjọ keji oṣu kọkanla l'aarẹ filu Makkah silẹ lọ siluu London.
Aarẹ Buhari kopa ninu apero idokowo naa fun ọjọ mẹta to bẹrẹ lati ọjọ kọkandinlọgbọn eleyi to pari ni ọjọ kọkanlelọgbọn niluu Riyadh.
Aarẹ Buhari ṣepade pọ pẹlu Ọba ilẹ Saudi, Mohammed bin Salman lori bi ajọṣepọ to dan mọran yoo ṣe wa laarin Naijiria ati orilẹede Saudi sii lori ọrọ epo rọbi ati ati afẹfẹ gaasi.
Ninu ipade ti wọn jọ ṣe papọ, Ọba Saudi pe fun idasilẹ ajọ kan ti yoo maa ṣe igbelarugẹ idokowo laarin Naijiria ati Saudi.
Oríṣun àwòrán, Instagram/Bahir Ahmad
Ẹwẹ, awọn gomina mẹta ti wọn kọwọọ rin pẹlu aarẹ Buhari lọ si Saudi Arabia ti pada silu Abuja.
Amọ, aarẹ Buhari rinrin ajo lọ si London pẹlu diẹ lara awọn iṣomọgbe rẹ ti wọn jọ lọ Saudi.
APC Crisis: Àwọn jàndùkú kọlu Ọba Eko àti Gomina ìpínlẹ̀ Edo lọ́nà ilé Oshiomole
Oríṣun àwòrán, Facebook/Godwin Obaseki
Awọn janduku kan niroyin sọ pe wọn kọlu Ọba ilu Eko, Ọba Rilwan Akiolu ati Gomina ipinlẹ Edo, Godwin Obaseki loju ọn wọn si ile alaga gbogbo ẹgbẹ oṣelu APC, Adams Oshiomole ni Iyamoh nipinlẹ Edo lọjọ Satide.
Ohun ti a gbọ ni pe awọn ọdọ janduku ri ọkunrin kan, Andrew Momodou ti wọn fẹsun kan o ṣagbatẹru ikọlu to waye nile Oshiomole niluu Benin nibi to ti n kọwọ rin pẹlu Oba Eko, Gomina Obaseki ati Baba isalẹ Fasiti ipinlẹ Edo, Ọjọgbọn T.O.K. Audu.
Gomina Obaseki atawọn alejo rẹ lọ sibi ayẹyẹ ikẹkọgboye ni fasiti ọhun niluu Iyahmo, ni ijọba iible Etsako ki wọn to mori ile ibugbe Oshiomole lagbegbe naa.
Ẹnikan ti iṣẹlẹ naa ṣoju rẹ ṣalaye pe Oshiomole lo pe Oba Eko ati Gomina Ipinlẹ Edo lati wa ṣ awẹjẹ-wẹmu nile rẹ lẹyin ayẹyẹ ikẹkọgboye ni fasiti ipinlẹ naa.
Awọn ẹṣhọ to tẹ le gomina ipinlẹ Edo lo pẹtu saawọ naa, bibẹẹkọ, afaimọ ki iṣẹlẹ ọhun ma mu ẹmi lọ.
Ẹlomiiran tọrọ naa ṣoju ni igbakeji gomina ipinlẹ Edo, Philip Shaibu to ko awọn ọlọkada bii lọ si ibi ayẹyẹ ikẹkọọgboye naa lo fa iṣẹlẹ ọhun.
Ọpọ ọkọ to te le Gomina Obaseki ati Oba Eko lawọn janduku fọ gilaasi wọn.
Àwọn orílẹ̀-èdè tí ààrẹ Buhari ti lọ láàrin ọdún márun
Àwọn orílẹ̀-èdè tí ààrẹ Buhari ti lọ láàrin ọdún márun
Àwọn ǹkan to tí n dá awuyewuye sílẹ̀ júlọ láàrin ọjọ mẹta yiìí yála lóri ayélujara tàbi láarin àwọin ènìyàn ni pé ààrẹ Muhammadu Buhari rìnrinnàjọ lọ si orilẹ̀ -èdè Saudi Arabia láti ṣe ìpádé àpérò lórí ọ̀rọ̀ ajé Nàìjíríà fún ọjọ iwáju, ti o si tí ìbẹ̀ ré si ilú London titi ti yóò fi di ọjọ kẹtadinlogún osù yìí ko to dari wále.
Sex Education: Ẹkọ ibálopọ̀ ko tó l'awọ́n ọ̀dọ́ ṣe n wá a lorí ayélujára
Ọjọ́ sátide ni ààrẹ kúrò ni Saudi Arabia lo sí ilẹ̀  Gẹẹsì níbi ti yóò ti lo ọjọ mẹ́tàdinlogun lori ǹkan ti kò niṣe pẹ̀lú orilẹ̀-èdè Naijiria
Tí ààrẹ ba wá de ni ọjọ kẹtadinlogun osù yìí, o túmọ si pé àláṣẹ káàfàta, ajagun fẹ̀yìnti  Buhari ti lo irinwo ọjọ́ àti marundinlọgbọ̀n (ọdun kan àti osu meji) nílẹ̀ okere láàrin ọdun marun to ti di ààrẹ.
BBC ṣe ìwádìí nínú àkọsílẹ̀ rẹ̀ bákan náà ló lo ìròyìn ti Daily Trust ko jọ, nípa ìrìn ajo ààrẹ àti iye ọjọ to lò ni ilú okere láti igba to ti de Aso Rock
2015
Àwọn orílẹ̀-èdè tí ààrẹ Buhari ti lọ láàrin ọdún márun
2016
Àwọn orílẹ̀-èdè tí ààrẹ Buhari ti lọ láàrin ọdún márun
2017
Àwọn orílẹ̀-èdè tí ààrẹ Buhari ti lọ láàrin ọdún márun
2018
Àwọn orílẹ̀-èdè tí ààrẹ Buhari ti lọ láàrin ọdún márun
2019
Tí a ba wo alaye yìí fínifini à o ri pé ọdun kan ati osu meji ni ààrẹ Buhari ko fi si ni ọfíìsì rẹ̀ ni Naijiaria.
Eyi lo mu ki àwọn ẹka ènìyàn meji maa sọ̀rọ̀ nipa irinajo ààrẹ, àwọn to faramọ irinajo náà àti àwọn ti wan n wo pe ko yẹ ko ri bẹ́ẹ̀ nitori ko ni ipa kankan fun ilọsiwaju Naijiria.
Aríyànjiyan yìí bẹ́rẹ̀ lẹ́yin ti agbẹnusọ ẹgbẹ́ alátako ni Naijiria Ibrahim Tsauri sọ pé gbogbo irinajo à[rẹ ko ni nkan se pẹlu ilọsoiwaju Naijiria
Sùgbọ́n ilé iṣẹ́ à[rẹ sàlàyé pé àwọn ìrìn ti ààrẹ n ri yìí ṣe patàki fún Naijiria ati ọ̀rs aje rẹ̀
Onimọ nipa ètò òṣèlú Abubakar Kari ti fasiti Abuja sàlàyé pé ìrìnajo ààré ní iṣẹ to pọ láti ṣe fun ibásepọ pẹlu orilẹ̀-èdè mírà àti ètò ọ̀rs aje Naijiria.
"But the University man add say "" di problem wey dey dia be say up till now poor Nigerians dey say dem neva see anything on ground upon all di"
"O wá fi kún pé "" isoro to wa nibẹ pé àwọn otosi Naijiria o ti ri eso rere kankan ti ìrìnajo náà ti  so"""
Bobrisky sàlàyé ipò tó wà gẹ́gẹ́ bi ọkunrin tàbí obinrin
Oríṣun àwòrán, @bobrisky
Mó fẹ́ dí obinrin to dára júlọ lágbàyé-Bobrisky
Ọ̀pọ̀ àwọn ọmọ Naijíría ló maa n sọ ni ọ̀pọ̀ ìgbà pé àwọn ko mọ ibi ti Idris Olarewaju Okuneye tó si n láàrin àkọ tà bí àbo?
Ọ̀pọ̀ a máa pe ni ọkúnrin pẹ̀lú igbàgbọ́ pé  o kan n fi ìmúra rẹ̀ ran ọ̀rọ̀ ajé rẹ̀ lọ́wọ́ lásan ní àti pé orúkọ rẹ̀ ọkùnrin ní.
Sùgbọ́n Idris Olarewaju okuneye tí gbogbvo ènìyàn mọ si Bobrisky ti jáde síta bayiìí láti sọ ipo to wà fún gbogbo ayé yálà obinrin ni o tàbi ọkunrin.
Lóri atéjiṣẹ Instagram rẹ̀ ni Bobrisky ti sàlàyé pé ìrìnajo oun láti yìí kuro ni ọkkunrin si obinrin to rẹwa, jẹ́ èyi to dun yùngbàyungba.
O ni bótilẹ̀ jẹ́ pé ìlànà àwọn iṣẹ́ abẹ ti ouhn ṣe jẹ́ eyi to wọ́n gidigidi ni ti Miílíọnu naira, síbẹ̀ oun yọlẹ se lábẹlẹ nótori àwọn ọmọ Niajiria ti yoo ma bẹ́nu atẹ lu oun.
Bobrisky fi kun pé àwọn igbésẹ̀ iṣẹ́ abẹ náà ko tii tan, sùgbọn nígba ti yóò ba fi di ìwòyí amọdun, oun fẹ́ díje fun ètò obinrin to rẹ̀wa júlọ lágbàyé (Miss World 2020)
Ajọ EFCC yóò bẹrẹ ìwádìí lórí ìwà màgòmágó láàárín elétò àbò
Oríṣun àwòrán, @diezani
EFCC kò lẹ́tọ lati ta ǹkan iní Dieziani si ilẹ̀ okere
Ajo to n ri si Iṣowo ilu baṣubaṣu, EFCC, ti ni awọn yoo yi oju ina pada bayii si gbogbo ẹka eto abo ilẹ yii.
Ibrahim Magu to jẹ olori ajọ naa, lo fi ọrọ yii lede ni ilu Abuja nigba ti o n ba awọn akọroyin sọrọ
Magu wi pe, asiko ti to wayii lati  tanna wadii gbogbo magomago to ti waye lawọn ẹka eto abo nilẹ yii bẹrẹ lati ọdọ awọn ọlopaa, ọmọ ogun,ati ti awọn ọtẹlẹmuyẹ.
O ni ajọ naa ni wọn ri bi eyi ti o saba maa n gbogun ti iwa ibajẹ laarin awọn oṣiṣẹ ṣugbọn bayii wọn yoo yẹ gbogbo inawo awọn ẹka naa wo finifini.
Alaga naa wi pe ajọ yii ni wọn yan pelu ojugba rẹ ti ICPC lati gbogun ti iwa ibajẹ lawujọ to fi mọ awọn eka toku fun ti o boju to iwa ibajẹ lawujọ.
Ko i ṣai mẹnu baa wi pe ṣaju asiko Aarẹ Buhari ni ajọ naa jẹ eyi ti o n tanna wa iwa ibajẹ awọn oṣiṣẹ, oloṣelu  ati ti ile ifowopamọ nikan.
O ṣalaye pe ajọ naa kọju si bi wọn ṣe ṣe owo ti wọn fi ra awọn nkan ija ogun ni ọdun 2015, ti ọpọ awọn ọga agba ologun si jẹbi ẹsun naa ti wọn si foju ba ile ẹjọ.
Ni bayii , o ni ajọ naa tun kọju ija si awọn aluni ni jibiti ori afẹfẹ ti a mọ si yahoo- yahoo,pẹlu ajọsepọ awọn ọtẹlẹmuyẹ ile okeere [FB].
Bakan naa ni ajọ naa ti ni awọn yoo lu gbogbo eru ati ẹṣọ olowo iyebiye ti wọn ri gba pada lọwọ Diezani Madueke ni gbanjo si ilẹ okeere.
Ṣugbọn awọn agbarijọpọ awọn ọmọ ẹgbẹ ti o n ri si bi ati n lu eru ni gbanjo lorilẹ ede yii ti bẹnu atẹ lu alaga ajọ EFCC lori ọrọ naa wi pe ko tọna lati taa si oke okun.
Wọn ni niwọn igba to jẹ wi pe owo ilẹ yii ni arabinrin naa ji lati ko ọrọ jọ, ilẹ yii naa lo yẹ ki wọn ta si ati pe, ẹgbẹ wọn lo yẹ ki Ijọba lo lati ṣe iru eto bẹẹ.
Ẹni ti o jẹ akọwe ẹgbẹ naa, Isibor Benjamin Abhulimen ni o fesi si ọrọ ti Magu sọ lorukọ gbogbo ẹgbẹ pe ko boju mu rara lati gbe tita awọn eru naa fun ara ilẹ okeere.
Ṣe ṣaaju ni ile ẹjọ kan ni ilu Eko nibi ti adajọ Nicholas Oweibo ti ni ki Ijọba Apapọ gba gbogbo goolu olowo iyebiye ati ile nla ti arabinrin naa fi ọna eburu kojọ.
Kidnapping in Nigeria: Ara sọ́ọ́bù oníṣòwò ni wọn ti rí nọ́ńbà ìpè rẹ̀, tí wọn sì tàn-án jáde lásìkò ìsìn
Oríṣun àwòrán, Others
Ọjọ gbogbo ni ti ole, amọ ọjọ kan soso ni ti olohun, bẹẹ lọrọ ri nigba tọwọ palaba awọn afurasi ajinigbe kan segi laipẹ yii.
Gẹgẹ bi ileesẹ ọlọpaa ti kede rẹ, ọwọ sinkun awọn ọlọpaa kogberegbe SARS lo mu awọn afurasi ajinigbe mẹrẹẹrin naa, lasiko ti wọn n ji olokoowo kan, Chekwas Daniel, gbe.
Kọmisana ọlọpaa Janet Agbede, to wa fun ipinlẹ Abia nibi ti isẹlẹ naa ti waye ni, awọn afurasi ajinigbe yii lo ri nọmba ipe ọkunrin ti wọn ji gbe lara sọọbu rẹ, to kọ si.
Olokoowo naa to n ta asọ, lo n jọsin ni sọọsi lọwọ nigba ti awọn afurasi ajinigbe naa pe e, ti wọn si parọ pe awọn fẹ ra obitibiti asọ olowo iyebiye.
Hospital Wedding: Oṣù kan péré ni Tash fi ṣe ìgbéyàwó pẹ̀lú Simon kó tó kú
Ara ọkunrin naa bu mọ asọ, to si sare jade kuro ni sọọsi lati lọ da awọn onibara naa lohun, ti wọn sọ pe awọn wa niwaju sọọbu rẹ.
Ni kete to de iwaju sọọbu naa, ko ri awọn onibara naa, o pe wọn pe oun ti de, to si n silẹkun ẹnu ọna sọọbu rẹ naa.
Lasiko to n si lọwọ ilẹkun sọọbu naa lọwọ, to kọ ẹyin si ita, lawọn ajinigbe naa ba wọ lojiji lọ sinu mọto wọn, ti wọn si n fi tipa ji gbe lọ.
Oríṣun àwòrán, Others
Sugbọn ori re, ti i gbe alawore ko ni, lo mu ki awọn eeyan tete fi isẹlẹ naa to awọn ọlọpaa SARS leti, ti awọn onitọun si gba ya wọn, ti ọwọ si tẹ wọn.
Agbede ni orukọ awọn ajinigbe ti ọwọ tẹ naa ni Bright Chinonso, Eze Ernest, Chisom Godwin and Chinoyerem Chineye.
O fikun pe iwadi kikun ti n waye lori isẹlẹ naa, ti wọn ko si ni pẹ gbe wọn lọ sile ẹjọ.
Oríṣun àwòrán, Nigeria Police
Ki lo le mu ki eeyan kan ra ọmọ lọmọ pẹlu erongba lati tun wọn ta?
Ibeere re to gba ẹnu awọn eeyan lẹyin ti ọwọ ọlọpaa tẹ tọkọtaya kan nilu Eko  ti wọn lawọn ra awọn ọmọkunrin meji kan ni ẹgbẹrun lọna ogoje Naira lọwọ obinrin kan nilu Jos.
Ninu atẹjade kan ti alukoro ọlọpaa nilu Eko DSP Bala Elkana fi sọwọ sawọn oniroyin, o ni obinrin kan ti orukọ rẹ n jẹ Chukwunonso Blessing lawọn gba awọn ọmọ naa lọwọ rẹ.
O ṣalaye pe awọn Ọlọpaa Ọtẹlẹmuye mu ni oju ọna ọja Alaba nibi to ti fẹ wọ ọkọ lọ si Onitsha pẹlu awọn ọmọ naa,Joshua James ọmọọdun mẹfa ati Samuel Gbawune ọmọọdun mẹta.
Nigba ti wọn koju rẹ lati mọ ibi ti o n ko awọn ọmọ naa lọ, o sọ pe ohun n ko wọn lọ ba ọkọ ohun arakunrin Chukwunonso Happiness .
Abalọ ababọ ọrọ naa, Chukwunonsọ jẹwọ pe oun ra awọn ọmọ naa ni  lọdọ arabinrin kan nile awọn ọmọ alainiya kan nilu Jos toun si ko wọn wa si Eko.
Ileeṣẹ ọlọpaa lawọn ti doola awọn ọmọ naa bayi ti awọn si rọ ẹni to ba mọ obi awọn ọmọ naa lati kan si agọ Ọlọpaa.
Border Closure: Iléeṣẹ́ asọ́bodè tí kéde ọjọ tí wọn yóò ṣí ẹnu ibodè Nàìjíríà padà
Oríṣun àwòrán, Facebook/customsng
Fawọn to ba lero pe ileeṣẹ aṣọbode Naijria yoo jẹ ki awọn ọja kan  wọle lasiko Keresimesi ti n bọ yii ,ọrọ ko ri bẹẹ.
Idi ni pe Ileeṣẹ aṣọbode orileede Naijiria ti sun ọjọ ti wọn yoo ti ibode Naijiria pẹlu awọn alabagbe rẹ pa titi di oṣu kini ọdun 2020.
Ikede yii ti wọn fi ista ninu atẹjade kan ni ọga ileeṣẹ naa kan Victor Dimka buwọlu lọjọ kini oṣu Kọkanla ọdun 2019.
Ninu iwe naa, ileeṣẹ naa sọ pe t'oun ti bi  awọn  ti ṣe  ṣe aṣeyọri to lamilaka pẹlu bode tawọn ti pa  'ASarẹ Buhari ṣi ni ki awọn tẹiwaju pẹlu titi ibode naa di oṣu Kini ọdun 2020.''
O tẹsiwaju pe owo ajẹmọnu awọn oṣiṣẹ ileeṣẹ aṣọbode to fi mọ owo epo ọkọ ti wọn yoo lo yoo jẹ ssisan laipẹ.
Oríṣun àwòrán, Facebook/Sumner Shagari Sambo
Bi a ko ba gbagbe orileede Naijiria gbe igbesẹ lati ti ibode rẹ pẹlu awọn orileede to jẹ alabagbe rẹ lati le dẹkun fayawọ irẹsi ati awọn nkan tẹnu n jẹ miiran.
Igbesẹ yi tawọn kan sọ pe o tako ofin karakata ajọ ECOWAS ni o ti mu ki awọn alabagbe Naijiria bi Benin ati Ghana ma kerora.
Koda awọn orileede miiran bi Thailand ati Vietnam naa ke gbajare si ijọba Naijiria lati ṣi ibode ki awọn ọja wọn baa le wọle.
Border Closure: Ibodè títì lè fa rògbòdìyàn láàárín orílẹ̀èdè méjì
Oríṣun àwòrán, other
Àwọn ènìyàn ń jẹ̀yà lórí ibodè tí wọ́n tìpa - Olókòwò
Onimọ nipa Idokowo,Tope Fasua ti ni ibode titi pa le fa rogbodiyan laarin orilẹede Naijiria ati awọn orilẹede ti wọn yi i ka.
Fasua fesi si ọrọ yii lasiko ti wọn fi lede wi pe o seese ki wọn tilẹ ṣi ibode naa ninu Oṣu Kini, ọdun to n bọ.
Ninu ọrọ rẹ, o ni titi ti wọn ti ibode naa ti mu ifasẹyin ba ọrọ aje awọn eniyan ti wọn n ṣe karakata laaarin orilẹede Naijiria ati omiiran.
‘Awọn ara Ghana tilẹ ni awọn ko ni pẹ ti ibode naa ti ijọba Naijiria ko ba gbọ ẹbẹ wọn pe ki wọn ṣi ibode.
Onimọ nipa idokowo ọhun ni ati mẹkunu ati olowo ni ibode ti wọn ti naa ṣe akoba fun.
Tope Fasua wa rawọ ẹbẹ si ijọba lati wa wọrọkọ fi ṣada, ki wọn si ṣi ibode ki awọn ti wọn ko lowo lee ri owo fi ṣe ọdun.
Ile iṣẹ Asọbode Naijiria ti ni ko pọn dandan fun awọn lati ṣi ibode Naijiria ni Oṣu Kini, ọdun 2020.
Alukoro Ajọ naa, Joseph Attah lo fi lede pe Osu Kini, ọdun to n bọ ni awọn yoo kọkọ pari igbesẹ wọn lati ri abayọrii titi ibode Naijiria.
Oríṣun àwòrán, Facebook/customsng
Attah ni ibode Naijiria yoo wa ni titi pa titi di igba ti orilẹede Naijiria ba kẹsẹjari ninu ilakaka wọn lati jẹ ki ọrọ aje gbe pẹẹli soke.
Bakan naa ni wọn fi kun un wi pe, ibode naa yoo wa ni titi pa titi awọn orilẹede to yi Naijiria ka yoo fi bọwọ fun ofin to rọmọ karakata ni ilẹ Iwo-Oorun Afirika.
Iléeṣẹ́ asọ́bodè: Kò jọọ́ ,gbọingbọin la ó ti ẹnu ibodè Nàìjíríà pa di Oṣù kíni 2020
Fawọn to ba lero pe ileeṣẹ aṣọbode Naijria yoo jẹ ki awọn ọja kan  wọle lasiko Keresimesi ti n bọ yii ,ọrọ ko ri bẹẹ.
Idi ni pe Ileeṣẹ aṣọbode orileede Naijiria ti sun ọjọ ti wọn yoo ti ibode Naijiria pẹlu awọn alabagbe rẹ pa titi di oṣu kini ọdun 2020.
Ikede yii ti wọn fi ista ninu atẹjade kan ni ọga ileeṣẹ naa kan Victor Dimka buwọlu lọjọ kini oṣu Kọkanla ọdun 2019.
Ninu iwe naa, ileeṣẹ naa sọ pe t'oun ti bi  awọn  ti ṣe  ṣe aṣeyọri to lamilaka pẹlu bode tawọn ti pa  'ASarẹ Buhari ṣi ni ki awọn tẹiwaju pẹlu titi ibode naa di oṣu Kini ọdun 2020.''
O tẹsiwaju pe owo ajẹmọnu awọn oṣiṣẹ ileeṣẹ aṣọbode to fi mọ owo epo ọkọ ti wọn yoo lo yoo jẹ ssisan laipẹ.
Oríṣun àwòrán, Facebook/Sumner Shagari Sambo
Bi a ko ba gbagbe orileede Naijiria gbe igbesẹ lati ti ibode rẹ pẹlu awọn orileede to jẹ alabagbe rẹ lati le dẹkun fayawọ irẹsi ati awọn nkan tẹnu n jẹ miiran.
Igbesẹ yi tawọn kan sọ pe o tako ofin karakata ajọ ECOWAS ni o ti mu ki awọn alabagbe Naijiria bi Benin ati Ghana ma kerora.
Koda awọn orileede miiran bi Thailand ati Vietnam naa ke gbajare si ijọba Naijiria lati ṣi ibode ki awọn ọja wọn baa le wọle.
Yinka Ayefele kò leè fi ìdúnú rẹ̀ pamọ́ lọ́jọ́ ìkómọ ìbẹta rẹ̀
Awọn ọba, oloṣelu, àwọn ọ̀tọ̀kúlú ìlú yẹ́ àwọn ìbẹta t'Ọ́lọ́run fi ta gbájúgbajà olórin Yinka Ayefele lọ̀rẹ níbi ìkómọ wọn.
Ninu oṣu keje ọdun 2019 ni Yinka Ayefele ko le pa ore naa mọra to si tu iroyin ayọ naa sita pe Ọlọrun ṣe idile ohun loore nla.
Nibi ikomọ awọn ibẹta yii, kii ṣe ọrọ ero pẹpẹpẹ tabi wẹ́wẹ́, ẹsẹ̀ ko gbero sibẹ awọn molumọọka lawujọ gan wa dara pọ mọ ayẹyẹ naa.
Ṣaaju eyi ni awọn eeyan ti n gbọ finifini bii pe iroyin ẹlẹjẹ ni to sọ pe iyawo onkọrin yii bimọ ṣugbọn ti oun pẹlu tete bọ si igboro lati salaye pe iyawo oun ko tii bimọẸ dákẹ́ àhesọ ọ̀rọ̀, n kò bí ìbẹta - Yinka Ayefẹlẹ.
Ẹwẹ, nigba ti ọrọ naa di ohun, olorin yii ko bo ore Ọlọrun mọra lati igba to ti kọkọ fi oju awọn ọmọ mẹta naa hande. Lara ọna idupẹ rẹ ni isin ikomọjade to waye lọjọ aiku ọjọ kẹta oṣu kẹrinla ọdun 2019.
Lọjọ ikomọ naa, awọn mọlumọọka eeyan peju sibẹ. Pẹlu ayọ ati idunu ni wọn fi n yẹ iya, baba ati awọn gaan naa si.
Yinka Ayefele fi ọpọ ore rẹ han si awọn to wa sibi ikomọ awọn ẹta tó wọle tọ idile rẹ wa.
Number Plate: Ìlànà FRSC rèé láti gba nọ́mbà àdáni fún ọkọ̀ rẹ
Oríṣun àwòrán, Twitter/FRSC
FRSC ní àwọn kò mọ̀ nípa nọ́mbà ọkọ̀'CHIP WHIP'
Wo ilana ti eeyan gbọdọ tẹle to ba fẹ gba nọmba adani si ọkọ rẹ gẹgẹ bi ajọ ẹṣhọ oju popo FRSC ṣe laa kalẹ:
Ṣe iforukọsilẹ ọkọ rẹ
Igbesẹ akọkọ ni pe eeyan gbọdọ ṣe iforukọ silẹ ọkọ loju opo ajọ ẹṣọ oju popo, FRSC (http://www.nvisng.org).
Loju opo ayelujara yii ni eeyan yoo ti fọwọ si fọọmu kan lati fihan pe ẹni naa fẹ gba nọmba aladani si ọkọ rẹ.
Fi fọọmu ranṣẹ si ọfiisi iwe aṣẹ iwakọ
Igbesẹ to kan ni lati mu fọọmu ti eeyan ba ti fọwọ si lọ si ọfiisi ti ajọ FRSC ti maa n fawọn awakọ
Nibi ni ẹni to fẹ gba nọmba adani ti gbọdọ sọ iru nọmba to fẹ gba si ọkọ rẹ gan an ninu fọọmu ti yoo ṣọwọ si ọfiisi ti wọn ti n gba iwe aṣẹ ọkọ wiwa.
Agbeyẹwo fọọmu fun nọmba adani
Ni ipele yii ni awọn oṣiṣẹ ajọ ẹṣọ oju popo yoo ṣe ayẹwo fọọmu ti wọn fi ṣọwọ si wọn finifini.
Lẹyin ayẹwo yii ni wọn yoo fi nọmba ṣọwọ si awọn alaṣẹ fun iwadii siwaju si.
Sanwo fun iforukọsilẹ nọmba rẹ
Nibayii, o ni lati gba fọọmu miiran eleyi ti wa tun fọwọ si.
Lẹyin naa ni wa sanwo fun iforukọsilẹ nọmba ti o ba fẹ, bakan naa ni wa tun sanwo fun iwe aṣẹ ọkọ wiwa loju popo.
Dida fọọmu pada
Bi ipele yii ni wa ti da fọọmu ti o ti fọwọ si pada si ọfiisi ajọ FRSC to maa n fawọn awakọ nọmba.
O gbọdọ mu iwe to jẹ ẹri idaniloju pe o ti sanwo ni tootọọ pẹlu fọọmu ti o fọwọ si lọ si ọfiisi FRSC.
Gbigba nọmba aladani ọkọ rẹ
Lẹyin ti o ba ti tẹ le gbogbo igbesẹ yii ni ajọ ẹṣọ oju popo yoo fun ọ ni nọmba ọkọ rẹ.
Bakan naa ni wọn yoo fun ọ ni gbogbo iwe to ṣe pataki fun lati ni nipa nọmba aladini rẹ.
'Èmi gan máa ń béèrè lọ́wọ́ ara mi pé ta ni Wole Soyinka gangan'
Chip Whip: A ò mọ̀ nípa àṣìkọ orúkọ nọ́mbà ọkọ̀ aṣòfin ìpínlẹ̀ Kano - FRSC
Ajọ ẹka oju popo, FRSC ti ni awọn ko mọ nkankan nipa aworan nọmba idanimọ ọkọ ‘CHIP WHIP’ ti awọn eniyan n  tan kalẹ ka lori ẹro ayelujara ni opin ọsẹ.
Ọpọlọpọ awọn ọmọ Naijiria lo bu ẹnu atẹ lu aworan naa lẹyin ti o jade lori ẹrọ ayelujara, pẹlu asisẹ aato ọrọ kikọ
Ibadan Murder: Oyún oṣù méje ló ń bẹ nínú Azeezat, kí wọ́n tó f'òkúta fọ́ ọ lórí
Alukoro Ajọ FRSC, Bisi Kazeem  ninu atẹjade ti wọn fi lede ni awọn kii ba wọn jẹ eera ti ko lọmọ ninu, nitori naa kii se ọdọ awọn ni asemase naa ti wa.
Wọn fi kun un wi pe awọn ma n se idanimọ ọkọ lorilẹede Naijiria letoleto ni, ti kii si ni abawọn.
Oríṣun àwòrán, OTHERS
FRSC ní àwọn kò mọ̀ nípa nọ́mbà ọkọ̀‘CHIP WHIP’
Bakan naa ni wọn fi kun un wi pe awọn ko nii nkankan se pẹlu nọmba ọkọ ti wọn ni o wa lati ipinlẹ Kano, ti o si seese ko jẹ ti adari Ile Igbimọ Asofin ipinlẹ naa.
Ajọ FRSC naa wa tẹnu mọ ọ wi pe awọn ti bẹrẹ iwadii ni ẹka ajọ naa to wa ni ipinlẹ naa lati mọ ibi ti nọmba ọkọ ọhun ti ṣẹ wa.
Lagos King: Mátikú ọba tó lo lo ọdun mẹta lórí oyé latari rogbodiyan Eko
Boko Haram video torture: A ṣetán láti fìyà tó tọ́ jẹ ọmọ ogun ti adé ìwà ìbàjẹ́ fídíò náà bá ṣímọ́ lórí
Oríṣun àwòrán, Nigeria Army
Ileeṣẹ ọmọ ogun ko ni fọwọ yẹpẹre mu awọn ọmọ ogun to ba n fipa mú awọn ara ilu ṣe nkan ko tọ.
Laarin opin ọsẹ to kọja ni fidio kan jade lori ayelujara to ṣafihan awọn ọmọ ogun kan to huwa ti ko ba ilasilẹ iṣẹ awọn ọmọ ogun ilẹ.
Ilé iṣẹ ọmọ ogun ni àwọn ko ni fọwọ rá ọmọ ogun ti igba iwa idajọ lọwọ ara ẹni ba ṣi mọ lori rara.
Eyi jẹ esi lori fonran kan to n tan ka lori ayelujara bi àwọn ọmọ ogun kan se pa afurasi Boko haram ti wọn si sin in si sààre ti ko jinlẹ ni ipinlẹ Borno ni ariwa ila oorun Naijiria.
Ileeṣe ọmọ ogun ile fi atẹjade sita lori ipinnu wọn lẹyin ti wọn bu ẹnu ẹ̀tẹ́ lu iwa ipá naa pe ko ba ofin awọn ọmọ ogun ilẹ̀ Naijiria mu.
Ileesẹ ọmọ ogun ilẹ Naijiria ni wọn ti bẹrẹ iṣẹ iwadii ni kikun lori fidio naa ati awọn to wa ninbẹ nitori pe iwa ti wọn hu lodi si ileeṣẹ omo ogun o si tun tabuku wọn.
'Èmi gan máa ń béèrè lọ́wọ́ ara mi pé ta ni Wole Soyinka gangan'
Ogagun agba Sagir Musa to jẹ adele adari agbẹnusọ fun ileeṣẹ omo ogun ilẹ iwa ipé yii ṣe lodi si ofin Naijiria.
Yollywood:Ṣàgbẹ̀lójú yòyò ni ọ̀ps àwọn òṣèré- Ojopagogo
Sagir ni ọpọ igba ni wọn ti kilọ fawọn ọmọ ogun lati maa ṣọra ṣe paapaa nigba ti inu ba n bi wọn tabi ti nkan ṣẹlẹ ki wọn ma baa tẹ oju ẹtọ ara ilu mọlẹ.
Ni ipari, o ni wọn ti mọ pe ijiya to tọ wa fun ẹnikẹni to ba huwa aitọ ninu awọn ọmọ ogun Naijiria.
''Ẹ̀mí ọ̀pọ̀lọpọ̀ ṣì n sọnù ni orilẹ̀-ede Burundi'
Omoyele Sowore ní Apostle Suleiman o le gba onidúro òun
Omoyele Sowore ní Àpósítù Suleiman o le gba onidúro òun
Olùdásílẹ̀ ilé iṣẹ́ Sahara, Omoyele Sowore tí kọ àǹfàní tí ààrẹ ilé ijọsin Omega Fire Ministries Worldwide Àpóstélì Johnson Suleiman fún un láti gba oníduró rẹ̀.
Suleiman ti sọ ṣááju lórí àtẹjísẹ́ twitter rẹ̀ pé òun gba a lérò láti gba onídúro Soworẹ bótilẹ jẹ́ pé o ti tẹ asọ àgbà ọ̀pọ̀ ènìyàn mọ́lẹ̀ sẹ́yìn pàápàá jùlọ òun, síbẹ̀ òun ni ìgbàgbọ́ pé kò tọ́ kí àwọn máa wò ó níran láti rà s'ẹ́wọ̀n.
Ibadan Torture House:Àṣírí ilé ìmúni nígbèkùn míràn tú síta ni Katsina
Ẹ̀wẹ̀, ọkan nínú àwọn agbẹ́jọrò Sowore Inibehe Effiong wá sàlàyé pé Suleiman o sí ni ipò láti gba oníduro Sowore tó jẹ́ ajìjàgbara.
Effiong ní ilé ẹjọ́ sàlàyé dáradára pé ẹni ti yóò gba oníduro Sowore gbọ́dọ jẹ́ olùgbé ìlú Abuja, àti pé ẹni ti yóò dásọ fun ni tọrun rẹ̀ ni à ń kọ́kọ́ wò, àwọn kùdìẹ̀-kudiẹ̀ pọ̀ lọ́run rẹ̀ pẹ̀lú, nítori náà oun àti Soworẹ o lé jọ tò pọ̀ si ìhà kan náà.
Bakan náà lo fi kún un pé, ìjọba apapọ ti sọ ọ̀rọ̀ Sowore di tí òṣèlú, àwọn ǹkan ti wọ́n si gbé silẹ̀ láti gba oníduro Sowore kò si ẹni to le sán.
Àpọsítélì Suleiman ló ṣeéṣe kí òun sàn owó onídùúró Sowore
Oríṣun àwòrán, Google
Ko le buru buru ki o ma ku ẹnikan mọ eeyan lọrọ bi Aposteli Suleiman ṣe ni oun n gbero lati san owo oniduro Omoyele Sowore to wa ni ahamọ.
Ọgọrun miliọnu ni ile ẹjọ la kalẹ ni owo oniduro fun oloṣelu naa ṣugbọn titi di bi a ṣe n sọrọ yi,ko ti si ni to ṣetan lati san owo naa.
Loju opo Twitter rẹ ni Apọsteli Suleiman ti fi ọrọ yi sita.
Ninu alaye to ṣe o ni lootọ ni pe Sowore ṣe ohun to dun awọn eeyan,ṣugbọn ọmọ ẹni ko ni buru buru ka wa le fẹkun pa jẹ.
O fi ibeere sita pe ''Njẹ o wa yẹ ki a tori eleyi ko wa ku si ẹwọn?''
Oṣu Kẹjọ ọdun 2019 ni awọn ileeṣẹ ọtẹlẹmuyẹ Naijiria mu Soworẹ ki wọn to gbe lọ si ile ẹjọ.
Ẹsun iditẹgbajọba ni wọn fi kan ṣugbọn lẹyin atotonu agbẹjọro rẹ,ile ẹjọ ni ki wọn tu silẹ lẹyin to ba san owo beeli ẹgbẹrun lọna miliọnu Naira.
'Èmi gan máa ń béèrè lọ́wọ́ ara mi pé ta ni Wole Soyinka gangan'
Lagos Housing: 'Àwọn ayálégbé máa san mílíọ̀nú mẹ́rin fún ilé oníyàrá méjì lágbègbè V.I. l'Eko '
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Wiwa ilegbe jẹ ọkan lara ipenija tawọn ọdọ n doju kọ, ṣugbọn ti ilu Eko tun le kenka.
Ọpọ onile ni wọn maa n beere fun owo agbaalẹ lọwọ awọn ayalegbe ki wọn to le gba wọn sile.
Awọn onile maa n gbe ile to ni yara meji lagbegbe Victoria Island silẹ fun miliọnu mẹrin naira, tawọn mii si maa gba miliọnu mẹjọ ni agbaalẹ.
Fun ọpọ oṣiṣẹ niluu Eko, owo ile bẹrẹ lati bi miliọnu meji si miliọnu mejidinlogun lọdun kan.
Oríṣun àwòrán, Gloria Yusuff
Ohun kan tawọn onile maa n sọ pe o jẹ ki owo ile wọn ni pe owo ilẹ ati ohun eroja ikọle pọ ju.
Awọn onile ni sisan owo silẹ pe ju niluu Eko, ko pe awọn ti wọn ba ṣẹṣẹ ri iṣẹ.
Ọgbẹni Bankole Oluwafemi to n ṣiṣẹ ara rẹ gba ile si agbegbe Lekki nibi tawọn to rọwọ họri diẹ n gbe.
Lori ayelujara ni Ọgbẹni Oluwafemi ti ri ile ọhun ko to sanwo rẹ.
'Lagos landlords think single ladies are prostitutes'
Bo tilẹ jẹ wi pe ijọba ṣofin lọdun 2011 pe kawọn onile ma gba ju owo ọdun kan lọ mọ, ofin naa ko fi bẹẹ mulẹ to.
Ọgbẹni Dolapo Olumidire to jẹ onwoye nipa ọrọ ilẹ sọ pe ilu Eko da bi ọja fun awọn onile.
Oríṣun àwòrán, Reuters
Erekusu ilu Eko
Aye nira fawọn eeyan to n gbe aarin meji erukusu ilu Eko sibi iyangbẹ ilẹ.
Wọn ni lati ji larọ kutu bi aago mẹrin lati wa okada ti yoo gbe wọn lọ si idikọ.
Yoruba Film: Ta ló leè dúró s'ẹ́gbẹ̀ẹ́ Okunnu láì rẹ́rìín?
Oríṣun àwòrán, okunu_1
Lònìí ni ọjọ́ ibi Wale Akorede ti ọpọ eniyan mọ si Okunnu latara gbogbo ere ẹfẹ rẹ to ma n ṣe.
Gbajumọ ni laarin awọn oṣere Yoruba, o si jẹ ọmọ bibi ilu Ibadan ni ipinlẹ Oyo. Wọn bi i lọjọ Karun, oṣu Kọkanla ọdun 1967.
Ẹwẹ, ati ilu Oyo ati Ogbomoṣo lo ti dagba, to si bẹrẹ si ni ṣe ọmọkunrin.
Nipasẹ molumọọka oṣere Muyiwa Ademola lo fi bẹrẹ si ni gbayii, ti ipa to n ko lati da ẹrin pa oṣonu si tun mu u da yatọ.
Oṣere Yollywood ni Wale Akorede, to kawe gboye ni ile ẹkọ akọṣẹmọṣẹ ti ilu Ibadan.
Ko to dara pọ mọ awọn oṣere, okoowo ni Wale n ṣe, to maa n lọ si Saudi lọ ko aṣọ lati wa ta lorilẹede Naijiria.
'Èmi gan máa ń béèrè lọ́wọ́ ara mi pé ta ni Wole Soyinka gangan'
Ọdun mẹtala lo fi ṣe owo aṣọ tita ko to wa papa kara bọ ere tiata. Lara awọn ere rẹ naa lo ti gba orukọ ori itage rẹ, Okunnu.
Ẹ o le wo ere rẹ ki gbogbo agbegbe kan dakẹ ṣuu, a fi ki ẹ rẹrin ni gbogbo ibi to ba ti farahan.
Baale ile ni Okunnu jẹ fun iyawo atawọn ọmọ rẹ.
Border Closure: Wíwó laá wó àwọn ilé ìkẹ́rùpamọ̀sí tó wà láwọn ibodè wa
Oríṣun àwòrán, @GeoffreyOnyeama
Ijọba apapọ ti kede erongba rẹ lori ibode orilẹede Naijiria to ti di titi pa. Ijọba ti kede ohun marun un to gbọdọ di mimu ṣẹ ki ibode to le di ṣiṣi pada.
Minisita ọrọ ilẹ okere, Geoffrey Onyeama jiroro pẹlu awọn ọmọ igbimọ ti ijọba yan lati sọ asọyepọ lori ọrọ ibode to wa ni titi pa.
Ijọba ti ti ibode Naijiria pa fun bi ọsẹ melo bayii lati jẹki ọrọ aje le gberu sii ati lati dena kiko ẹru wole lọna aitọ.
Ọpọ lo ti n ṣorọ lori igbesẹ ijọba yii, bawọn kan ṣe tako igbesẹ ọhun, lawọn mii n gboṣuba fun ijọba pe ohun to tọ ni ijọba aarẹ Muhammadu Buhari ṣe lori ibode titi pa.
Kọda ijọba to sọ pe o di oṣu kinni ọdun 2019 ki ohun to gbero lati ṣi ibode naa pada nitori igbesẹ naa ti ilọsiwaju ba ọrọ-aje Naijiria.
Wọnyi lawọn ohun ti ijọba sọ pe pe o gbọdọ ṣẹlẹ ki ibode to le di ṣiṣi pada:
Ko gbọdọ si atundi ẹru to n wọle mọ
Idi akọkọ nipe ko gbọdọ si atundi ẹru to ba n wọle lati orilẹede to jẹ ọmọ ẹgbẹ ajọ ECOWAS si orilẹede mii to jẹ ọmọ ẹgbẹ ECOWAS bakan naa.
Ijọba ni iru ẹru bẹẹ gbọdọ lọ sọdọ awọn oṣiṣẹ aṣọbode, bẹẹ ni ẹnikan ko si gbọdọ fọwọ kan an.
'Èmi gan máa ń béèrè lọ́wọ́ ara mi pé ta ni Wole Soyinka gangan'
Awọn ọja ECOWAS ko gbọdọ tapa sofin
Idi miiran ti ijọba tun sọ nipe gbogbo ọja ti wọn ba n ko wọ Naijiria lati awọn orilẹede to jẹ ọmọ ẹgbẹ ajọ ECOWAS gbọdọ wa ni ibamu pẹlu ofin ati ilana ajọ naa.
Idi eleyii sọ pe wọn gbudọ̀ bọwọ fun ofin ibilẹ eyi to nii ṣe pẹlu kiko ọja wọle ati pe ki wọn ti awọn ile ti wọn ma n kẹru pamọ si to wa lagbegbe ibode.
Onyeama sọ pe awọn ti pinu lati wo gbogbo ile ikẹrupamọsi to ba wa lọna gbogbo awọn ibode wa kaakiri.
"O ni pataki ju lọ ni pe kiko ẹru wọle gbudọ wa pẹlu ibọwọ fun ofin abẹle ""tori naa a gbudọ lodi si ki wọn maa pa ọja ti ni Naijiria""."
Mo ti sọ ìran nípa ọkọ aképo tó gbiná ní Onitsha kó tó ṣẹlẹ̀ - Prinmate Ayodele
LASEMA: Àwọn ohùn tó lè gbiná tó wà níbi ìtajà Balogun ló dá kún ìjà iná tó ṣàkóbá níbẹ̀
Balogun Fire: Àwọn èèyàn tí ìṣẹ̀lẹ̀ náà ṣojú wọn ṣàlàyé ohun tó fa iná lọ́jà Balogun
Ajọ to n risi iṣẹlẹ pajawiri nilu Eko ti ṣalaye pe awọn ohun to le gbina bi bẹntiroo ati ẹrọ amunawa tawọn eeyan gbe sinu ṣọọbu lo dakun ijamba ina ọja Idumota nilu Eko.
Ọgbẹni Oke Osanyititolu lo sọ ọrọ yi fawọn akoroyin nibi iṣẹlẹ ina naa.
O ni lọwọlọwọ bayi ko ti ṣi ẹmi kankan to ba iṣẹlẹ naa lọ.
Ninu alaye rẹ bakanna o ni awọn n gbiyanju lati dkun ina ohun ṣugbọn airaye de ibi ina naa nitori bi awọn ile itaja ti ṣe fun pọ jẹ ipenija nla.
O wa rọ awọn eeyan to n taja nibẹ lati ri wi pe wọn ko gbe ohun to le gbana si inu sọọbu wọn.
Lowurọ ọjọ Iṣegun ni iroyin gbode pe ibudo itaja nla kan ni ina ọhun ti bẹrẹ, ti gbogbo oju ọna to wọ inu ọja naa si ti di patapata.
A gbọ pe ibudo itaja naa lo wa ni ojule kẹtalelogoji, opopona Martins lagbegbe Lagos Island nilu Eko.
Iroyin to n tẹ wa lọwọ ọhun ti wa fikun pe awọn osisẹ panapana ti de sinu ọja naa lati bomi pa ina naa ko to pẹju.
Bẹẹ si ni awọn ontaja to wa ninu ile itaja naa ti n ko ẹru wọn to ku ti ina ko tii ba, ki wọn le doola rẹ lọwọ ina to n jo naa.
Bẹẹ si ni awọn ontaja to wa ninu ile itaja naa ti n ko ẹru wọn to ku ti ina ko tii ba, ki wọn le doola rẹ lọwọ ina to n jo naa.
Wayi o, awọn ọmọ Naijiria ti wa n kigbe loju opo Twitter wọn pe ki ijba tete jara mọ igbesẹ pipa ina ọhun.
@SubDeliveryZone tiẹ fi aworan bi ina ọhun se n jo soju opo Twitter rẹ
Lagos-Ibadan Express Road: Ìjọba àpapọ̀ ní òun yóò ṣí ọ̀nà tó tì padà ní Dec 15 fọ́dún Kérésì
Oríṣun àwòrán, AFP
Ijọba apapọ ti kede pe gbogbo awọn ọna ti wọn ti pa lopopona marosẹ Ibadan silu Eko ni yoo di ṣiṣi pada lati ọjọ Kẹẹdogun oṣu kejila ọdun 2019.
Oludari ẹka to wa fun amojuto awọn opopona to jẹ tijọba apapọ lẹkun iwọ oorun guusu orilẹede yii, Funsọ Adebiyi lo fọwọ idaniloju yii sọya, lasiko to n ba awọn awakọ ajagbe ejo takurọsọ ni agbegbe Ogere nipinlẹ Ogun.
Adebiyi ṣalaye pe ijọba yoo ṣi awọn oju ọna ọhun pada lati ri i daju pe sunkẹrẹ fakẹrẹ ọkọ dinku, ti opopona marosẹ Ibadan si Eko yoo si ja gaara lasiko ọdun keresi pẹlu afikun pe, isẹ yoo bẹrẹ pada lẹyin ọdun keresi.
Oríṣun àwòrán, @Biodunpen
"O fi kun un pe ""Kilomita marundinlaadọrin ti pari lopopona marosẹ ọhun, ti ogun kilomita to ti pari si wa ni abala kinni lati ẹnu bode atijọ lọ si ikorita ọna Ṣagamu eyi ti ileesẹ Julius Berger n ṣe, nigba ti kilomita marundinlaadọta naa ti pari ni abala keji eyi ti ileesẹ RCC n ṣe."""
Ko tan sibẹ, Adebiyi wa paṣẹ fun awọn ọlọkọ ajagbe naa lati gbe ọkọ wọn kuro ni agbegbe Ogere ti iṣẹ ọna lila ko ni pẹ de ibẹ tabi ki wọn rin sẹyin bii aadọta mita kuro ni ibi ti iṣẹ oju ọna ọhun yoo gba kọja.
Oríṣun àwòrán, @Biodunpen
Oludari akoso oju ọna tun fi kun un pe lootọ ni ijọba lee lo agbara lati le wọn kuro ni agbegbe yii amọ oun wa parọwa si wọn naa gẹgẹ bii ọmọ iya, nitori ijọba gba pe eyi san ju lilo iwa ipa lọ.
O wa ṣisọ loju rẹ pe, ileesẹ RCC ti so iṣẹ to n ṣe loju ọna marosẹ Ibadan si ilu Eko ni agbegbe Ogere rọ na, nitori bi awọn ọlọkọ ajagbe ejo naa ṣe duro soju ọna laibikita eyi to n di iṣẹ lila oju ọna naa lọwọ.
Balogun Fire: Ibùdó ìtajà tó jóná wà ní 43 Martins street, Lagos Island
Ọwọja ina to waye nile alaja pupọ naa lagbara, to si n jo ranin-ranin.
Pẹlu obitibiti ero to wa ni ọja Balogun, o nira pupọ fun awọn panapana lati de ibi ti ijamba ina naa ti n waye.
Diẹ diẹ, ọwọja ona naa n fẹju si, to si gba gbogbo oke ile naa kan.
Lẹyin o rẹyin, ọkọ panapana raye de ibiti ijamba ina naa ti n waye laarin ero to pọ.
Ibadan Torture House: Seyi Makinde ṣe àbẹ̀wò sí ibùdó ìtọ́jú èèyàn 200 tí ọlọ́pàá tú sílẹ̀ ní ilé Ọlọ́rẹ
Oríṣun àwòrán, Others
Gomina ipinlẹ Ọyọ, Seyi Makinde ti se abẹwo si ile Ọlọrẹ to wa ni adugbo Ọjọọ nilu Ibadan loni.
Bẹẹ ba gbagbe, ile yii ni ọwọ awọn ọlọpa ti tẹ eeyan mẹrin ti wọn ko awọn eeyan ni igbekun lọjọ Aje.
Eeyan okòólénígba àti marùn ún ni wọn tu silẹ ninu ile naa, ti wọn tun n lo bii mọsalasi.
Ibadan Torture House:Àṣírí ilé ìmúni nígbèkùn míràn tú síta ni Katsina
Lasiko to se abẹwo sibi isẹlẹ naa si ni gomina Makinde ti pasẹ pe ki wọn wo Mọsalasi ọhun patapata.
Oríṣun àwòrán, Seyi Makinde
Bakan naa lo tun se abẹwo si ibudo ti wọn ti n se itọju awọn eeyan ti wọn tu silẹ ninu igbekun ni mọsalasi ọhun.
Omo Ibadan: Ó wù mí láti kàwé di dókítà oníṣègùn òyìnbó tàbí ọ̀mọ̀wé ni Fáṣítì - Lizzy Jay ọmọ Ibadan
Oríṣun àwòrán, Lizzy Jay
Gbajugbaja adẹrinposonu nì, Adebola Adeyela, ti gbogbo eeyan mọ si Lizzy Jay ọmọ Ibadan tí salaye nipa ọpọ ohun ti oju rẹ n ri ni agbo iṣẹ amuludun.
Lizzy Jay ọmọ Ibadan, lasiko to n ba BBC Yoruba sọrọ ni, oun kii ṣe ọmọ Ibadan rara, oun kan n ya ede Ibadan lo ni, lati ṣe awada.
Adebola, tii ṣe ọmọ bibi ilu Ile-Ife ni oun n ṣe awada naa, nigba ti ọwọ oun dilẹ ni, lai mọ pe o lee di nkan nla, ti awọn eeyan kii si jẹ ki oun gbadun, ti oun ko ba ṣe.
Bakan naa lo sisọ loju rẹ pe ile ẹkọ fasiti Obafemi Awolowo gba oun wọle sile ẹkọ fasiti naa, ti oun si ni lẹta igbaniwọle si fasiti naa lọwọ amọ fun iyalẹnu oun, asiko ti oun fẹ ṣe iforukọsilẹ nile ẹkọ naa ni oun ri pe, wọn ti yọ orukọ oun kuro ninu awọn to fẹ wọle sile ẹkọ naa.
Ọmọ Ibadan, to ni oun ti ni iwe ẹri diploma kekere taa mọ si OND lọwọ tun salaye pe, ni kete ti oun padanu eto igbaniwọle si fasiti Obafemi Awolowo naa, ni oun ba kuku pada lọ sile ẹkọ Poly, lati gba iwe ẹri diploma agba, tii ṣe HND.
Lizzy Jay ọmọ Ibadan ni, iṣẹ orin kikọ gan ni oun fi bẹrẹ iṣẹ amuludun, ti oun ko si fi awada ti oun jọ ti ẹnikẹni, tabi fi ẹnikẹni ṣe awokọse.Nigba to n sọrọ lori ibasepọ rẹ pẹlu alawada miran lori ayelujara ti wọn n pe ni Cute Abiola, lizzy ni ọrẹ timọ-timọ oun ni ọmọkunrin naa, ti awọn si dijọ ma a n ṣe awada papọ lori ayelujara.
Oríṣun àwòrán, Instagram
"O fikun pe ""awọn obi mi ko tako awada ti mo n ṣe lori ayelujara, koda wọn n gbaruku ti mi ni, gbogbo ohun ti mo ba fẹ, si ni wọn maa n ba mi fẹ."
" Ọmọ Ibadan ni awada ori ayelujara naa ti gbe oun de awọn orilẹ ede lorisirisi loke okun, to si gba awọn eeyan nimọran pe ki wọn tẹra mọ ohunkohun tí wọn ba da wọle daadaa lai rẹwẹsi.
Lizzy, ẹni to sọrọ nipa ipenija to n koju ninu iṣẹ to yan laayo naa ni, oju obinrin tó wa lagbo amuludun  n ri to, nitori ọpọ ilọkulọ ti wọn n fi lọ obinrin, to si jẹ pe obinrin ko le wọ awujọ kan, lai jẹ pe ọkunrin ni yoo mu lọ sibẹ."""
"Dokita oníṣègùn oyinbo gan lo wu mi ki n ṣe lati kekere, nigba to ya ni ẹbun orin kíkọ jẹ jade lara mi, mo dara pọ mọ ẹgbẹ akọrin, lẹyin naa ni mo wa bẹrẹ ere apanilẹrin.
 Lizzy Jay ni ohun to kan fun oun bayii ni lati dara pọ mọ awọn elere tiata, ti oun si fẹ maa kopa ninu sinima ṣiṣe.""Sibẹ sibẹ, o si wu mi lati kawe si, amọ yoo jẹ loke okun."
O si wu mi ki n kawe di dokita onisegun oyinbo, amọ bi eyi ko ba ṣee se, mo fẹ kawe gba oye ọmọwe PhD, ki n si di ọmọwe dokita.
"Ọmọ Ibadan wa gba awọn ololufe rẹ nimọran lati maa bọwọ fun ofin to rọ mọ idena itankalẹ arun Coronavirus nitori ewu to wa ninu ajakalẹ arun naa.
Èdè Gẹ̀ẹ́sì tí pọju nínú tíátà Yorùbá tá n gbé jáde lóde òní - Afeez Ọwọ
Oṣere tiata Yoruba ti awọn eeyan mọbi ẹni mowo nni, Afeez Ọwọ ti bẹnu atẹ lu bi awọn oṣere tiata Yoruba ṣe n faye gba ede oyinbo pupọ ninu ere sinima wọn.
Afeez to sọ ọrọ yii lasiko to n kopa lori eto BBC Yoruba loju opo Facebook ni, bi iṣesi yii ko ba dẹwọ, o le ṣe akoba fun idagbasoke ede Yoruba.
Oríṣun àwòrán, Instagram/officialafeezowo
Yatọ si arọwa to pa yii, o tun mẹnu ba awọn koko ọrọ miran to ni ṣe pẹlu irinajo rẹ lagbo oṣere tiata ati ibaṣepo laarin oun ati iyawo rẹ, Mide Martins.
Igi to ba dara kii pẹ nigbo lọrọ Funmi Martins
Lara awọn nnkan ti Afeez mẹnuba ni iya iyawo rẹ Funmi Martins, ati ipa to ko ninu igbesi aye oun ati iyawo rẹ Mide Martins.
O sọ pe Funmi Martins jẹ abiyamọ tootọ ti o si jẹ ẹni to fẹran gbogbo eniyan sugbọn to jẹ pe, iku se emi rẹ legbodo lai pe ọjọ.
Iya to bimi ko fẹki n sere  tiata
Afeez Ọwọ, nigba to n salaye irinajo rẹ laye sọ pe iya to bi oun ko fi taratara gba pe ki oun maa ṣe ere tiata.
Oríṣun àwòrán, Instagram/mydemartins
O ni nigba ti oun wa ni kekere, gbogbo ọna lati dari ọkan oun kuro nidi ere tiata ni iya oun maa n wa, amọ akọsilẹ ti ko pe ere tiata lọna oun.
''Ni ibẹrẹ igbesi aye mi, iya to bi mi ko ri ere tiata bii nkan gidi, fun idi eyi, ko fẹ ki n yan isẹ naa laayo sugbọn loni, opẹ ni fun Ọlorun''
Nigeria vs Netherlands: Àtilẹ ló yẹ kí ìjọba ti máa mu ìdàgbàsókè bá eré bọ́ọ̀lù-Onigbinde
Oríṣun àwòrán, ALEXANDRE SCHNEIDER - FIFA
Gbajugbaja akọnimọọgba ere bọọlu ni Naijiria,Adegboye Onigbinde ti gba ajọ ti o n ri si ere bọọlu ni Naijiria, NFF ati ijọba apapọ niyanju lati maṣe da ikọ ọjẹwẹwẹ agababọọlu ilẹ naa nu.
Onigbinde sọrọ yii nigba ti o n fesi si ibeere ti ikọ ile iṣẹ BBC n beere pe kini  igbesẹ  to yẹ ki ijọba gbe lori ikọ Golden Eaglets lataari ijakulẹ wọn lọwọ Netherlands lọjọ Iṣẹgun.
Bi a ko ba gbagbe,awọn ọjẹ wẹwẹ naa ti ọjọ ori wọn ko ju ọdun mẹtadinlogun lọ ni wọn fidirẹmi ninu idije ife ẹyẹ  agbaye U-17 to n lọ lọwọ ni Brazil.
Ami ayo mẹta si meji ni Netherlands fi juwe ọna ile fun ikọ naa .
Onigbinde ṣalaye pe, ki ẹka to n ri si eto ere boolu gbiyanju lati tẹpẹlẹ mọ igbaradi awọn ọdọ wọnyii ki wọn le tunbọ ni oye ati imọ sii.
O tẹnumọ pe o ṣe pataki lati mu idagbasoke ba awọn ọdọ naa ki wọn si maa mu wọn gbaradi fun ayeye miran fọjọ  iwaju.
O ni atilẹ lo yẹ ki ijọba ati ẹka yii ti maa ran awọn ọjẹ wẹwẹ lọwọ lati mura silẹ kii ṣe igba ti wọn ba ni idije kan pato.
O tọka si pe, ọpọ awọn orilẹede to n ṣe daada ni wọn gunle iru igbesẹ bayii ti wọn si n ṣe daada ni gbogbo asiko ti wọn ba ti idije.
Ẹgbẹ agbabọọlu ọjẹ wẹwẹ orilẹ-ede Naijiria, Golden Eaglet ko r'ohun mu bọ láti Brazil nibi ti wọn ti lọ fun idije FIFA U-17.
Eyi ni onipele ikẹrindinlogun idiije awọn agbabọọlu tọjọ ori wọn ko ju ọdun mẹtadinlogun lọ lagbaye.
Jawahir Roble:Hijab tí mò n lò kó jẹ́ kọ́kọ́ jẹ́ ìyàlẹ́nu fún àwọn agbábọ́ọ̀lù mi
Ami ayo mẹta si ookan ni ẹgbẹ agbabọọlu ọjẹ wẹwẹ orilẹ-ede Netherlands fi ṣe wọn bọṣẹ ṣe n ṣoju, ni wọn ba di ẹru wọn pada wale.
Atamatase ọwọ iwaju ikọ Netherlands, Sontje Hansen lo gba goolu mẹtẹẹta ọhun s'awọn Naijiria, ni wọn ba sọ Naijiria di a lọ ma lee pada wa mọ bi wọn ti ṣe ninu ifẹsẹwọnsẹ meji kan sẹyin.
Nile ti Naijiria, Olakunle Olusegun lo jẹ goolu kan ṣoṣo ti wọn ri jẹ.
Olakunle ti jẹ olugbade fun igba marun un bayii ninu idije naa.
'Èmi gan máa ń béèrè lọ́wọ́ ara mi pé ta ni Wole Soyinka gangan'
Ibadan Torture House: Seyi Makinde ní gbogbo ẹni tó mú èèyàn nígbèkùn ní yóò kojú òfin
Oríṣun àwòrán, Seyi Makinde/Facebook
Gomina ipinlẹ Oyo, Seyi Makinde ti kilọ fun awọn obi ki wọn dẹkun kiko ọmọ lọ si awọn ile ti wọn n pe ni ibudo atunwaṣe ṣugbọn to jẹ pe ọtọ la n gbọ nipa wọn.
Nigba ti Gomina Seyi Makinde ṣe abẹwo si ile Ọlọrẹ to wa ni adugbo Ọjọọ nilu Ibadan, tii ṣe ibi ti ile imuni nigbekun ọhun wa, o pasẹ pe ki wọn wo Mọsalasi ọhun patapata.
Gomina ni ohun taa ti ri jẹ nkan ti gbogbo wa gbudọ bu ẹnu atẹ lu ni ko si yẹ ko maa ṣẹlẹ lode oni. Ẹ o le maa fi mọṣalaṣi ṣe iru iṣẹ ibi bayii""."
Ibadan Torture House:Àṣírí ilé ìmúni nígbèkùn míràn tú síta ni Katsina
Oríṣun àwòrán, @seyiamakinde
Oríṣun àwòrán, @seyimakinde
Makinde ni awọn ti ṣaami si ile naa fun wiwo, ijọba yoo si ṣe ohun to yẹ lati ri i pe iru iwa ibajẹ yii ohun itan lawujọ wa.
"O ni ṣugbọn bi awọn to n gbe lagbegbe yii naa ba ri ohun ti ko tọ bi eleyii, o yẹ ki wọn sọ fun awọn alaṣẹ tọrọ kan, ""a ko ba si ti ri aṣiri rẹ lọjọ to ti pẹ""."
Bakan naa, a fẹ gba awọn eeyan wa, obi ati ẹbi nimọran pe bi ẹ ba tilẹ fẹ ki iyipada ba aye awọn eeyan yin ti ko huwa daadaa, a ni awọn ile iṣẹ ijba to n moju to eyi fun ipinlẹ Oyo.
Oríṣun àwòrán, @seyimakinde
Seyi Makinde ni o yẹ ki a maa mu ofin ilu ẹni lọkunkundun taa ba fẹ ṣe iru nkan bayii, o si jẹ ko di mimọ pe gbogbo awọn to lọwọ ninu iṣẹ laabi yii ni yoo foju wina ofin.
"Ni ti awọn ti wọn tu silẹ nigbekun, Seyi Makinde ni awọn ti gbe iṣẹ le ileeṣẹ to n ri si ọrọ awọ́n obinrin nipinlẹ Oyo lọwọ, lati ṣetọju wọn ati lati wa ọna ati da wọn pada sọdọ ẹbi wọn, ""tori a o le fi wọn silẹ bayii""."
A gbudọ de kulẹ kulẹ ọrọ yii, awọn agbofinro yoo ṣe iṣẹ wọn de bi iwadii ao si tu ẹni tọwọ rẹ ba mọ silẹ. Eyi lọrọ ti gomina Seyi Makinde fi silẹ.
Balogun Market Fire: Àwọn òǹtàjà gbarata lórí òfò tí ìjàmbá ìná ń mú báwọn lọdọọ́dún
Awọn ontaja kan lọja Balogun ti n di ẹbi ina to jo ru ẹni to ni ibudo itaja alaja mẹfa ti ina naa ti sẹyọ pe, aibikita rẹ lo mu ki ọwọja ina ọhun fẹju ju bo se yẹ lọ.
Ọkan lara awọn ontaja naa, Busayọ Ọlalere, lasiko to n ba BBC Yoruba sọrọ ni awọn kesi ẹni to ni sọọbu naa pe ina n jo, to si ni ki awọn fi ina naa silẹ, yoo ku funra rẹ.
Olalere ni ọdọọdun abi ọdun meji sira wọn ni ina maa n jo sọọbu naa, eyi ti ko se ajeji si awọn ara ọja Balogun amọ o ni ko ba dara ki obinrin naa ti tete pa ina naa ko to burẹkẹ, eyi ti ko ni ko wahala ba awọn eeyan yoku to wa ninu ọja.
O ti yẹ ki onisọọbu ti ina jo tete lo awọn eroja panapana ki ọwọja ina naa to fẹju, ni bayii, ina ọhun ti mu ọpọ isọ, to si ti ko ba awa ta mule ti wọn. O nira fun wa lati ko ẹru wa jade nitori eefin to n bo wa mọlẹ.
"Ọlalere fikun pe ""ọja to jona kọja biliọnu lọna irinwo naira, ati igba ti iya to n ta asọ ti ra ile alaja mẹfa to jona naa, lo maa n jona lopin ọdun, to si mọ pe awọn eeyan yoo ta ọja ọdun."""
O ni obinrin naa n fi tiẹ se akoba fun awọn eeyan miran nitori bi ina se maa n jona lọdọọdun, ti a ko si mọ boya wọn yoo tun ibudo itaja naa kọ abi bẹẹ kọ, to si tun rọ ijọba lati pasẹ fun obinrin naa pe ko maa ra awọn eroja to n pa ina si ibudo itaja rẹ, lati tete maa pa ina.
Nigba toun naa n kin Busayọ Ọlalere lẹyin, Alhaji Kehinde Ajikanle naa fikun pe o yẹ kijọba se iwadi lori idi to se jẹ pe inu ibudo itaja Adebọwale Plaza nikan ni ina ti maa n sẹyọ lọja Balogun lọdọọdun.
Ajikanle ni lootọ ni ontaja asọ naa padanu awọn ọja ti owo wọn to aimoye biliọnu naira, nitori oun nikan lo n lo ibudo itaja alaja mẹfa naa, ti ọja si kun inu wọn dẹnu amọ o ni awọn eeyan to mule ti ibudo itaja naa lo maa n faragba.
Wayi o, isẹlẹ ina to n waye lọja Balogun nilu Eko ti di irawọ ọsan, to n ba awọn agbaagba lẹru bayii, ti gomina ipinlẹ Eko, Babajide Sanwo-Olu si ti sabẹwo si ibudo naa lọjọru.
Oríṣun àwòrán, Other
Lasiko to de ibi isẹlẹ naa, awọn irinsẹ ajọ panapana si n sisẹ lọwọ lati ko awọn awoku ile to jona naa, ti wọn si tun n wọn omi si awọn agbegbe ti eefin ti n ru jade titi di ọsan oni.
Lasiko abẹwo rẹ si ni Sanwo-Olu ti pasẹ pe ki wọn se ayẹwo awọn ile to wa lẹba ile to jona naa lati mọ boya ki wọn da awọn ile ọhun wo pẹlu eyi to jona abi ki wọn fi silẹ.
Gomina wa rọ awọn eeyan to n ta asọ lọja Balogun lati maa sọra se nibi ti isẹlẹ naa ti waye nitori ina ọhun si n ru eefin bi o tilẹ jẹ pe  wọn ko ti mọ ohun to sokunfa ina ọhun.
Oríṣun àwòrán, OTHER
Ina miiran ti ṣẹyọ ni ibudo itaja ti ina ti jo lana, ni ipinlẹ Eko.
Bi ẹ ko ba gbabe, lana ode yii ni ina kan dede ṣeyọ lọja ọhun ti ọpọlọpọ dukia ati ọja si ba ina ọhun lọ.
Gẹgẹ bi ọrọ ti ajọ agbofinro Rapid Response Squad ipinlẹ Eko fi lede loju opo Twitter rẹ, ẹmi ọlọpa kan ba iṣẹlẹ ọhun lọ.
Ọga Olọpaa kan ni Ipinlẹ Eko, Bode Ọjajuni ṣalaye pe, Ọlọpaa naa ni ile wolu mọlẹ ni bi ti o tin gbiyanju lati le awọn eniyan sẹyin ni bi iṣẹlẹ naa.
O ni ẹnu iṣẹ ni arakunrin naa ti o jẹ sajẹnti Ọlọpaa ku si ninu igbiyanju rẹ si awọn eniyan awujọ
Awọn oṣoju mi koro sọ pe ina tuntun yii ṣeyọ lowuro oni, ni bi aago mẹfa kọja iṣẹju diẹ.
Wọn ni o jọ pe ajọ panapana ko pari iṣẹ wọn lati pa ina naa lana, nitori ina to ṣeyọ lowurọ yii wa lati ile to fẹgbẹkẹgbẹ ile to jona lana ni.
Awọn oṣoju mi koro ọhun ṣalaye pe o ṣeṣe ko jẹ pe ajoku ina to ṣẹyọ lana lo jo wọ ile keji.
Awọn ajọ panapana ti wa ni ojuko iṣẹlẹ ọhun lati dẹkun ina naa, lati le daabo bo awọn ile miran to wa layika.
'Ǹkan tó jẹ́ kí iṣẹ́ ọ̀nà tèmi yàtọ̀ lágbàáyé ni ǹkan tí mò ń lò'
Gomina Fayemi: Dayo Adeyeye sì ń padà bọ̀ wá ṣèjọba
Oríṣun àwòrán, OfficialPDPNig
Gomina Ipinlẹ Ekiti, Kayode Fayemi ti sọ wi pe yiyọ ti ile ẹjọ yọ Agbẹnusọ fun Ile Igbimọ Asofin, Dayọ Adeyeye kuro ni Ile Igbimọ Asofin.
Eyi ko sẹyin bi ile ẹjọ kotẹmilọrun ṣe dajo wi pe sẹnẹtọ Biodun Olujinmi ti ẹgbẹ oṣelu Peoples Democratic Party (PDP) ni ẹni to wọle idibo sile aṣofin agba fẹkun idibo Guusu Ekiti, kii ṣe Adeyeye.
Fayemi ṣapejuwe Adeyeye ti wọn ye aga mọ ni idi oun gẹgẹ bi ojulowo oloṣelu to mo iyi iṣejọba awaarawa.
O fikun un wi pe idajọ naa kii se opin irinajo Sẹnetọ Adeyeye, ati wi pe yoo dide pada laipẹ.
Bakan naa ni Gomina Fayemi wa ki Seneto Olujimi ku oriire, ati wi pe oun setan lati sisẹ papọ pẹlu asofin naa fun itẹsiwaju ipinlẹ Ekiti.
Ile ẹjọ kotẹmilọrun to fi ilu Kaduna ṣe ibujoko ti dajọ pe, Sẹnẹtọ Biodun Olujimi ti ẹgbẹ oṣelu Peoples Democratic Party (PDP) ni ẹni to wọle idibo sile asofin agba fẹkun idibo guusu Ekiti.
Oríṣun àwòrán, OTHERS
Gomina Fayemi: Dayo Adeyeye sì ń pada bọ̀ wá ṣèjọba
Ohun ti eyi tumọ si ni pe, aga ti yẹ bayi nidi Ṣẹnẹtọ Dayo Adeyeye ti ẹgbẹ All Progressives Congress APC, to jẹ agbẹnusọ ile aṣofin agba ni Abuja.
Saaju ni ajọ eleto idibo Naijiria INEC ti kede, Dayo Adeyeye gẹgẹ bi ẹni to jawe olubori ninu idibo to waye ni agbegbe naa ṣugbọn Olujinmi tako esi ọhun niwaju igbimọ to n gbẹjọ idibo.
Oríṣun àwòrán, Others
Loju opo Twitter ẹgbẹ oṣelu PDP, wọn fi iṣẹ ikinni ku oriire ranṣẹ si Ṣẹnẹtọ Olujimi lori bi ile ẹjọ kotẹmilọrun se kede pe oun lo jawe olubori ibo naa.
Prepaid Meter: èrò àwọn èèyàn ṣọ̀tọ̀ọ̀tọ̀ lórí 'sisan owó iná ní Nàìjíríà
Exam Malpractices: Fọ́tò inú káàdì ìdánimọ̀ ló mú kí àkàrà tú sépo
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Exam Malpractices: Fọ́tò inú káàdì ìdánimọ̀ ló mú kí àkàrà tú sépo
Aye n bajẹ ọmọ ole n kajọ. Ki ni ka ti ṣe iru eyi si, nigba tawọn akẹkọọ ile iwe alakọbẹrẹ ba n gba eeyan kọ idanwo wọn?
Bẹẹ lawọn eeyan n ṣemọ bi iroyin ti ṣe kan pe, ọwọ ọlọpaa tẹ awọn akẹkọ ile iwe alakọbẹrẹ mejila, ti wọn gba eeyan lati ba wọn joko ṣe idanwo aṣekagba wọn.
Iroyin ta gbọ ni pe, awọn akẹkọ lati ile ẹkọ alakọbẹrẹ Sese Bugolo gba awọn akẹkọ naa lati ile ẹkọ girama to wa ni agbegbe Buike ati Mukono ni orilẹede Uganda, lati ba wọn kọ idanwo.
Ọga agba feto ẹkọ lagbegbe naa, Hassan Nkutu ṣalaye lọjọ Iṣẹgun pe, n ṣe laṣiri awọn akẹkọọ naa tu nigba tawọn ri pe aworan ori iwe idanimọ wọn ko papọ mọ ti awọn to n kọ idanwo.
Oríṣun àwòrán, Other
Hassan sọ pe ''ọkan lara awọn ọtẹlẹmuyẹ ta ni ko mojuto idanwo naa lo ri awọn afunrasi ohun. N ṣe la ri pe aworan to wa lori kaadi idanimọ wọn ko papọ mọ eleyi ti ile iṣẹ eto ẹkọ Uganda pese''
Agbẹnusọ ọlọpaa lagbegbe naa, Hellen Butoto sọ pe awọn yoo kesi awọn adari ile iwe naa lati wa ṣalaye ohun to ṣẹlẹ.
'Èmi gan máa ń béèrè lọ́wọ́ ara mi pé ta ni Wole Soyinka gangan'
Seyi Makinde: N kò ní yẹ ìdí àkóso aya Ajimobi wò lórí ọ̀rọ̀ SACA, ohun tó kọjá ti kọjá
Oríṣun àwòrán, @seyimakinde
Gomina Ipinlẹ Ọyọ, Ṣeyi Makinde ti ṣe ifilọlẹ igbimọ alakoso tuntun fun ajọ to n bojuto didẹkun ọwọja arun Aids ati kokoro rẹ, SACA, to si yan aya rẹ, Tamunominini Makinde gẹgẹ bi alaga igbimọ naa.
Gomina Makinde fikun pe ajọ SACA naa ni aya gomina ana, Florence Ajimọbi jẹ alaga rẹ tẹlẹ, amọ o ni ọpọ ninu awọn alẹnulọrọ ti n gba oun niyanju lati ṣe iwadii isakoso aya Ajimobi naa ninu ajọ Saca.
Amọ Makinde ni oun ko ni ṣe iwadi aya gomina ana naa nitori ohun to kọja ti kọja lọ.
Gomina ipinlẹ Ọyọ ni lootọ ni iwadi ti sisọ loju rẹ pe, ilana ti igbimọ alakoso ajọ Saca to kọja, labẹ aya Ajimobi n lo, ni rira awọn oogun ti ọjọ ti fẹ lọ lori wọn,
O wa rọ awọn ọmọ igbimọ alakoso tuntun fun ajọ Saca lati ta kete si iwa kiko oogun pamọ amọ ki wọn sisẹ fun rere awọn eeyan ipinlẹ Ọyọ.
Oríṣun àwòrán, @seyimakinde
Gomina, ẹni to kede pe agbega ti n ba ipese oogun iwosan fun arun Aids, tun woye pe ọna to pegede julọ lati ka ọwọja itankalẹ arun Aids ko ni tita kete si ibalopọ ti ko tọ.
Ipese eto ilera to yanranti jẹ ara opo ti isejba mi rọgbọku le lori, bẹẹ si ni isẹ kikọju oro si itankalẹ arun Aids ati kokoro rẹ lawujọ wa jẹ ohun to se pataki julọ si ijọba yii.
Oríṣun àwòrán, @seyimakinde
Mo ti lo ọpọ akoko lati se asaro lori ilana ti wọn gba dari ajọ Saca tẹlẹ, mo si lee fi gbogbo ẹnu sọ pe awọn oogun to ku diẹ ki ọjọ lọ lori wọn ni wọn n ra. Wọn ti ko diẹ lara awọn oogun naa wa han mi, amọ akoko naa ti kọja lọ, ti ko si ni waye mọ lailai nipinlẹ Ọyọ.
Gomina Makinde wa fọwọ gbaya pe ko si aniani pe awọn eeyan to kaato ni yoo maa se akoso ọrọ Aids nipinlẹ Ọyọ .
Cultural Burial: Ìdí táwọn ènìyàn South Korea ṣe ń sin èèyàn láàyè!
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Idi pataki ni pe onikaluku gbadun igbe aye rẹ nitori pe aye la maa kọkọ ṣe ki a to ṣe ọrun!
O le ni eto isinku eniyan ẹgbẹrun mẹẹdọgbọn ti ile isinku Hyowon Healing Centre ti ṣe fawọn eniyan lààyè!
Igbesẹ akọkọ fun ilana eto isinku awọn eniyan ti wọn ṣi wa laaye ti wọn ko tii ku ni pe ẹni naa a kọkọ ṣe akọsilẹ iwe ipingun rẹ to ṣafihan bo ṣe fẹ ki wọn pin ogun oun.
Lẹyin eyi o maa sanwo to yẹ nile isinku to wuu lati ṣeto isinku rẹ nigba ti ọlọjọ ba de.
Prepaid Meter: èrò àwọn èèyàn ṣọ̀tọ̀ọ̀tọ̀ lórí 'sisan owó iná ní Nàìjíríà
Orilẹ-ede South Korea ni aṣa yii ti wọpọ julọ.
Iru ẹni bẹẹ maa tun ra irufẹ posi to wuu ki wọn fi sin oun si lẹyin to ba papoda.
O maa wa sun sinu posi yii fun nkan bii iṣẹju mẹwaa o kere tan.
'Èmi gan máa ń béèrè lọ́wọ́ ara mi pé ta ni Wole Soyinka gangan'
Choi Jin-Kyu to jẹ akẹkọọ to ṣẹṣẹ pe ọmọ ọdun mejidinlọgbọn to ti kopa ninu eto isinku alaaye yii ṣalaye fawọn akọroyin pe oun ṣee nitori pe gbogbo eeyan n ṣee ni.
Choi ni pe oun ṣẹ nitori oun maa to bẹrẹ iṣẹ ati pe oun fẹ ki ọkan oun balẹ pe oun ti ṣe nkan to yẹ ni ṣiṣe.
Ojọgbọn Yu Eun-sil to jẹ dokita to n ṣayẹwo iku to pa eniyan ni o ṣe pataki fawọn ọdọ lati mọ sii nipa iku ki wọn si ṣeto to yẹ.
Ojọgbọn yii to ti kọ iwe loriṣiirisi nipa iku ẹda ni ko si ohun to buru ninu ki eeyan musilẹ de ọjọ iku rẹ.
Balogun Fire: Àwọn èèyàn tí ìṣẹ̀lẹ̀ náà ṣojú wọn ṣàlàyé ohun tó fa iná lọ́jà Balogun
Ogbeni Jeong Yong-mun to ni ileeṣẹ Hyowon ni inu oun maa n dun ti awọn eniyan ba n forijin oku ṣugbọn o san lati foirjin ara wọn nigba ti ẹni naa ba ṣi wa laaye nitori o ti le pẹ ju nigba mii lẹyin iku.
O tun ni igbese yii maa n yi ero awọn miran ti wọn ronu lati pa ara wọn pada si daadaa.
'Ǹkan tó jẹ́ kí iṣẹ́ ọ̀nà tèmi yàtọ̀ lágbàáyé ni ǹkan tí mò ń lò'
Maina Court Case - A sún ìgbéjọ síwájú láti mọ ipò tí ìlera rẹ̀ wà
Oríṣun àwòrán, Others
Adajọ Okon Abang ile ejọ giga tijọba apapọ ti sun igbẹjọ Abdulraheed Maina si ọjọ kọkanlelogun ati ikejilelogun oṣu Kọkanla ọdun 2019 lati mọ ipo ti ilera ara olujẹjọ naa wa.
Adajọ Abang wa pasẹ fun ileesẹ to n samojuto ọgba ẹwọn lati lọ ṣe iwadii ipo ti ilera Maina wa ni tootọ nitori bo ṣe wọ ile ẹjọ pẹlu kẹkẹ ni ọjọbọ.
Abang ti sọ saaju pe iwe idajọ oun lori ibeere Maina lati  gba oniduro rẹ ni ko ti si nilẹ.
Adajọ ileejọ giga naa ni ọpọlọpọ iṣẹ to wa ni iwaju ile ẹjọ naa ni ko jẹ ki iwe naa wa nilẹ, ti oun yoo fi gbe asẹ kalẹ lori gbigba oniduro Maina.
O fikun pe oun yoo fi ọjọ miran ti oun yoo gbe asẹ naa kalẹ ransẹ si igun tọrọ kan ko to di opin akoko isẹ lọjọ Iṣẹgun.
Lẹyin eyi ni adajọ wa tẹti gbọ awijare lati ọdọ awọn agbẹjọro olupẹjọ ati olujẹjọ lori boya ki igbẹjọ naa tẹsiwaju abi bẹẹ kọ nitori ipo ailera ti olujẹjọ naa wa.
Olupẹjọ sọ fun ileejọ lati sun igbẹjọ siwaju si ọjọ kọkanlelogun ati ikejilelogun oṣu Kọkanla lati fun ileesẹ to n se akoso ọgba ẹwọn ni aaye fun iwadi ipo ti ilera Maina wa gangan, igbesẹ naa si waye nitori iwe abọ ayẹwo ilera to mu wa sileẹjọ.
Amọ igun olupẹjọ salaye pe ti ile ẹjọ ko ba ṣetan lati gba ẹbẹ pe ki wọn sun igbẹjọ naa siwaju, oun ṣetan lati tẹsiwaju pẹlu ẹjọ naa, niwọn igba ti ẹlẹri rẹ akọkọ si wa ni ile ẹjọ.
Adajọ Abang ba sun igbẹjọ naa siwaju si ọjọ kọkanlelogun ati ikejilelogun oṣu Kọkanla ọdun 2019.
Oríṣun àwòrán, @others
Abdulrasheed Maina de sile ẹjọ giga ni
Saaju la ti mu iroyin wa pe ile ẹjọ giga ni olu ilu Naijiria, Abuja n gbọ ẹjọ Abdulrasheed Maina to jẹ alaga ajọ to n risi ọrọ owo ifẹyinti awọn eniyan.
Awọn oṣiṣẹ ọgba ẹwọn meji lo ti Maina wọle sinu ile ẹjọ ni aarọ yii.
Igbagbọ awọn eniyan ni pe ileẹjọ a da ẹjọ lori gbigba oniduro rẹ loni ọjọbọ.
Adajo Okon Abang lo mu oni lati fi ṣeto idajọ gbigba oni iduro Maina bi o ṣe pe ẹjọ naa.
Ẹsun mejila lori ṣiṣe owo ilu ni mọkumọku ni ajọ EFCC to n gbogun tiwa ibajẹ ni Naijiria fi kan Maina.
Bakan naa ni Maina n jẹjọ lori ileeṣẹ Common Input Properties and Investment Limited ti wọn fẹsun kan pe o niiṣe pẹlu iwa jibiti.
Awọn oṣiṣẹ ọgba ẹwọn ni Kuje ni ilu Abuja ni wọn ti Maina wọle lori kẹkẹ fawọn ti ko le rin ni nkan bii agogo mẹsan an abọ aarọ yii.
BBC Yoruba yoo maa gbe gbogbo bo ba ṣe n lọ fun un yin!
Prepaid Meter: èrò àwọn èèyàn ṣọ̀tọ̀ọ̀tọ̀ lórí 'sisan owó iná ní Nàìjíríà
Sanwo Olu: Gomina Ìpínlẹ̀ Eko kọ ‘Your Excellency’ fún ‘Mr Governor’
Oríṣun àwòrán, @jidesanwoolu
Sanwo Olu: Wo ohun tí àwon ọmọ Nàìjíríà ń sọ báyìí lórí orúkọ tuntun rẹ̀
Ọpọlọpọ awọn gomina ti wọn ti jẹ ni ẹkun Iwọ- oorun orilẹ-ede Naijiria lo ti fi igba kan sọ wi pe awọn ko fẹ ki wọn ma a pe wọn pẹlu oye ọlọla julọ 'Your Excellency' ṣaaju orukọ wọn.
Ọpọlọpọ awọn gomina yii maa n lo awọn orukọ naa lati sunmọ ara ilu ati ki ibaṣepọ to danmọran le wa laarin awọn ati awọn ara ilu.
Laarọ oni ni awọn ọmọ Naijiria bẹrọ si ni fun Gomina Ipinlẹ Eko lesi, lẹyin ti oun naa pinnu pe oun ko fẹ 'Your Excellency' mọ lara orukọ oun pe 'Mr Governor' ni oun fẹ ma a jẹ.
Idi ti gomina naa fi lede ni wi pe 'Your Excellency' ti bu iyi kun ipo oun ju iṣẹ to wa nibẹ lọ.
Ati wi pe oun wa lati wa ṣiṣẹ ni ipinlẹ Eko ni, nitori naa ti awọn eniyan ba n pe oun ni 'Mr Governor' yoo ma a ran oun leti idi ti oun fi wa ni ipo ti oun wa lọwọlọwọ.
Oríṣun àwòrán, @DiamondCelebs
Lẹyin ti gomina ipinlẹ Eko, Babajide Sanwo-Olu sọrọ loju opo Twitter rẹ pe ki awọn eeyan dẹkun lati maa pe oun ni ọlọlajulọ, ọpọ awọn Naijiria ti n fi erongba wọn lede lori ipinnu yii.
"Sanwo-Olu ni oun fẹran ki wọn ma pe oun ni ""Ọgbẹni Gomina,"" dipo Ọlọlajulọ."
Bi awọn kan ṣe ni ipinnu yii dara ni awọn mii n dẹyẹ si gomina ọhun, bẹẹ ni awọn mii n sọ fun un pe ọrọ akọle kọ lokan bayi, bi ko se ki gomina naa ṣe ohun ti awọn ara ilu n fẹ.
Awọn bii Paul Ogwa lori Twitter fara mọ ipinnu yii, wọn gboriyin fun Sanwo Olu pe:
Aisha Remi-Adedeji sọ pe ko sohun to kan ẹnikẹni nitori orukọ to wu koowa lo le jẹ́:
Ni ṣe ni Babajide Adebajo ni tirẹ fi Gomina ọhun ṣe yẹyẹ pe aṣeyọri nla ni orukọ tuntun.
'Ǹkan tó jẹ́ kí iṣẹ́ ọ̀nà tèmi yàtọ̀ lágbàáyé ni ǹkan tí mò ń lò'
Omonefe Wisdom Omare ni tirẹ sọ pe, yiyi akọle gomina pada ko da nkan nitori ki si anfani ti yoo ṣe fun awọn ara ilu.
Salawu Enitan loju opo Facebook ni, Gomina ipinlẹ Ọṣun ana, Rauf Aregbesola ti ṣe iru ohun bayin ri, nitori naa, ko jẹ tuntun.
Ẹ wo awọn ohun miran tawọn eeyan tun sọ loju opo Facebook nipa ipinu Gomina yii.
Prepaid Meter: èrò àwọn èèyàn ṣọ̀tọ̀ọ̀tọ̀ lórí 'sisan owó iná ní Nàìjíríà
Naijiria ló gba ipò kẹwàá nínú orilẹ-ede tó ni ẹ̀gbin ju- Ìwádìí
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Kano, ilu nla ti ẹgbin pọ ju ninu afẹfẹ
Iroyin kan ti sọ pe ilu Kano ni ilu to ni ìdọ̀tí inú afẹ́fẹ́ julọ ni gbogbo ilẹ Afirika- Switzerland.
Iwadii naa ni iwọn bi ilu naa ṣe dọti si le ni ida mẹtalelaadọta ninu ọgọrun un.
Gẹgẹ bi iroyin ọhun ṣe sọ, ohun mẹta lo jẹ ki ilu Kano wa ni ipo yii.
Iwadii naa ṣafihan ohun to mu Kano ni idọti inu afẹfẹ ati ayika to pọ yii pe:
Akọkọ ni pe pupọ ninu awọn olugbe ilu naa lo n fi igi, epo kerosin ati eedu da ina.
Oríṣun àwòrán, others
Ikeji ni bi awọn ojuko idalẹsi ṣe pọ kaakiri ipinlẹ Kano pẹlu idọti gọbọi.
Oríṣun àwòrán, World Air Quality report
Kano, Kampala, Port Harcourt àti Adis Ababa wa loke tente igbelewọn iwadii naa.
Idi kẹta ni eefin to n wa lati ara ọkọ oju popo, alupupu ati awọn ohun miran.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Awọn iṣẹ oriṣiiriṣii lo wa ni Kano
Iroyin naa wa fi kun un pe ilu Kampala, to wa ni Uganda lo wa ni ipo keji ninu awọn ilu to dọti ju, lẹyin naa ni ilu Port Harcourt ni guusu Naijiria tẹle.
Iwadii ti ileeṣẹ IQ Airvisual to wa lorilẹ-ede Switzerland ṣe lo fi id iroyin naa mulẹ, to si fi orilẹ-ede Naijiria si ipo kẹwaa ninu awọn orilẹ-ede to ni ìdọ̀tí inú afẹ́fẹ́ ju lagbaye.
Oríṣun àwòrán, World air Quality
Awọn afẹfẹ ti eeri inu wọn kọja sisọ ti awọn eeyan n mi sinu
IQ Airvisual ni iwọn idọti ti orilẹ-ede Naijiria ni le ni ida mẹrinlelogoji ninu ida ọgọrun un, ti orilẹ-ede Uganda ati Ethiopia si n tẹle e lẹyin.
'Èmi gan máa ń béèrè lọ́wọ́ ara mi pé ta ni Wole Soyinka gangan'
Iroyin naa ni ilẹ Afirika lo ni awọn ilu to n dagba soke julọ lagbaye nitori pe awọn olugbe ibẹ n pọ sii lojoojumọ, eyi lo mu ki idọti ọhun pọ to bẹẹ.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Awon osise lofe ti won n ran ara won lowow kole aye atijo ni Kano
Iroyin ọhun wa fi kun un pe orilẹ-ede Bangladesh lo ni afẹfẹ to buru ju lati mi sinu julọ, nigba ti Pakistan ati India wa ni ipo keji atyi ẹkẹta.
Prepaid Meter: èrò àwọn èèyàn ṣọ̀tọ̀ọ̀tọ̀ lórí 'sisan owó iná ní Nàìjíríà
Fake news: ìmọ̀ràn fáwọn ọmọ Nàìríjíà ṣaájú pínpín ìròyìn- Aṣòfin àgbà
Oríṣun àwòrán, others
Awọn aṣofin n gbiyanju lati dẹkun bi awọn eeyan ṣe n pin iroyin ẹlẹjẹ lori itakun agbaye
Igbesẹ ijọba apapọ lati dẹkun bi awọn eeyan ṣe n gbe iroyin ẹlẹjẹ kiri lori itakun ayelujara ko buru, ṣugbọn, o ku nibọn n ro.
Dayo Akinlaja to jẹ agbẹjọrọ agba ati kọmiṣọna fun eto igbẹjọ nipinlẹ Ekiti tẹlẹ lo sọ ọrọ naa ninu ifọrẹowerọ pẹlu BBC lori koko ọrọ yii.
Ni ibẹrẹ ọsẹ yii ni ile igbimọ aṣofin agba l'Abuja gunle abadofin kan, ti yoo ṣe iṣakoso bi awọn ọmọ Naijiria ṣe n lo awọn opo ikansiraẹni lori itakun agbaye.
Erongba awọn aṣofin naa ni lati dẹkun bi awọn eeyan ṣe n pin iroyin ẹlẹjẹ kiri lori itakun agbaye.
"Aṣofin agba Akinlaja sọ pe ""O yẹ ki ijọba gbiyanju lati dẹkun awọn to ba n sọrọ to le da Naijiria ru lori ẹrọ ayelujara, sugbọn ijọba ko gbọdọ fi ẹtọ ara ilu lati sọrọ dun wọn."""
Oríṣun àwòrán, others
Oro lori ayelujara ti n fẹ amojuto lasiko yii
"Akinlaja ni ""ọmọ Naijiria lẹtọ lati sọrọ, sugbọn o yẹ ki wọn sọra fun ọrọ to lee ṣe ijamba fun alaafia ilu."""
Balogun market fire: Olubadamọran gomina sọrọ lori ina náà
Akinlaja  gba awọn ọmọ Naijiria lamọran lati ṣe iwadii iroyin ti wọn ba gbọ ki wọn to gbe iru iroyin bẹẹ sori itakun agbaye, paapaa iroyin to lee ba elomiran lorukọ jẹ, ati eyi to le da ilu ru.
Prepaid Meter: èrò àwọn èèyàn ṣọ̀tọ̀ọ̀tọ̀ lórí 'sisan owó iná ní Nàìjíríà
"Oluwatosin Ajibade, ti ọpọ eeyan mọ si ""OloriSuperGal"" sọ fun BBC pe, yoo sọro funn ijọba lati mu awọn to ba n pin iroyin ẹlẹjẹ kiri lori ẹrọmibanisọrọ wọn."
Ajibade pari ọrọ rẹ pe, ojuṣe gbogbo ọmọ Naijiria ni lati ri pe wọn ṣe iwaadi iroyin ti wọn ba gbọ lati ri daju pe ojulowo ni, ki wọn to pin kaakiri.
'Èmi gan máa ń béèrè lọ́wọ́ ara mi pé ta ni Wole Soyinka gangan'
Adigunjalè ń bèérè ẹyin, ouńjẹ ati aṣọ lọ́wọ́ àwọn tí wọ́n ń jà lólè ní ìpinlẹ Niger
Aisha sọ fun BBC pe dukia ti oun fi ọpọ ọdun ko jọ ni awọn adigunjale ọhun ko lọ
Ninu ibẹru bojo ni awọn olugbe ijọba ibilẹ Rafi, ni ipinlẹ Niger n gbe bi wọn ṣe ni kosi aabo fun wọn lati ọdọ ijọba.
Awọn eniyan Kompani Madaka  n bẹru latari bi awọn adigunjale ṣe n kọlu wọn ni gbogbo igba.
Laipẹ yii ni awọn adigunjale wọ agbegbe naa ti wọn si n bere owo, ẹyin, ounjẹ ati aṣọ lọwọ awọn ti wọn n ja lole.
Ọpọ ohun ini awọn eniyan yii ni awọn ole ti fibọn gba lọ.
Bo tilẹ jẹ pe ijọba apapọ ni oun ti ran awọn alabo ilu sagbegbe ọhun, sugbọn awọn eeyan naa ni ko si ohun to jọ bẹ.
Gbogob ounje inu aka won ni awon ole ti ko lo tan
Awọn eeyan ọhun sọ fun BBC pe, awọn adigiunjale naa maa n kora wọn si ori alupupu, ti wọn si maa n pin ara wọn si ọna marun un, ki wọn to ṣọṣẹ.
Isaac ni ninu iberubojo ni gbogbo awon n gbe bayii
Adamu  Shehu to jẹ ọkan lara awọn olugbe ọhun ni, ọpọ awọn eeyan agbegbe naa lo jẹ alaini.
O ni gbogbo ere oko ti wọn ko pamọ sinu aka wọn ni ole ti ko lọ tan.
Adamu ni, ninu ọṣẹ ti awọn ole ọhun ṣe kẹyin ni wọn ti ji maluu marun un, agutan ogoji, ati ẹrọ ibanisọrọ ogoji.
O ni ko si nkan ti wọn ko ki n bere fun ti wọn ba ti de tibọntibọn si abule awọn.
Hassan: Gbogob ewure wa ni won ti ko lo tan
Olugbe agbegbe ọhun miran sọ fun BBC pe inu oun bajẹ gidi nitori awọn eeyan naa maa n kopa ninu idibo, ṣugbọn wọn ko jẹ anfani kankan lara ijọba.
Hassan ni bi wọn ṣe n gab ounjẹ ti awọn ti se silẹ ni wọn n gba ounjẹ tutu ti wọn ko tii
Prepaid Meter: èrò àwọn èèyàn ṣọ̀tọ̀ọ̀tọ̀ lórí 'sisan owó iná ní Nàìjíríà
Bayii, awọn ọmọ ogun ilẹ Naijiria ti bẹre iṣẹ akanṣe lọjọbọ ti wọn pe ni Operation Cat Race lati fi gbogun ti awọn agbebọn.
Wọn ni iṣẹ akanṣe yii maa wa titi di osu kejila ni ṣugbon nigba ti Akoroyin BBC de abule yii, ko ri agbofinro kankan nibẹ lasiko naa.
Balogun market fire: Olubadamọran gomina sọrọ lori ina náà
Ibadan Circular Road- Ilé aṣòfin ní ìṣẹ́ 5.5% ni agbaṣẹ́ṣe ṣe lọ́nà olóbìrípo láti 2017
Oríṣun àwòrán, Oyo state government
Ibadan Circular Road - Ilé aṣòfin Ọyọ ní ìṣẹ́ 5.5% ni agbaṣẹ́ṣe ṣe lọ́nà olóbìrípo láti 2017
Ile Igbimọ Asofin Ipinlẹ Oyo ti kesi ileesẹ ENL Consortium, ti wọn gbe isẹ lila opopona olobiripo ti yoo yi Ibadan ka, taa mọ si Circular Road le lọwọ, lati wa sọ tẹnu rẹ lori idi to fi pinnu lati gbe gomina Seyi Makinde lọ sile ẹjọ.
Ile Aṣofin ni igbesẹ lati kesi ileesẹ ọhun jẹ eyi ti o dara julọ, eyi ti yoo tan imọlẹ si ohun to ṣokunkun lori iṣẹ agbaseto n la oju ọna olobiripo Ibadan naa.
Awọn Aṣofin ipinlẹ Ọyọ fi ohun ṣọkan bẹẹ nibi ijoko wọn to waye lọjọbọ, ti wọn si woye pe igbesẹ ileesẹ ENL Consortium lati gbe ijọba Ọyọ lọ sile ẹjọ nilu London jẹ eyi to lee kan awọn eeyan ipinlẹ Ọyọ labuku ati ijọba Naijiria pẹlu.
Oríṣun àwòrán, Oyo state government
Bẹẹ ba gbagbe, ijọba Abiọla Ajimọbi lo gbe isẹ lila oju ọna olobiripo oni kilomita mejilelọgbọn naa fun ileesẹ agbasẹ́se yii, ni biliọnu mẹtadinlaadọrin naira.
Amọ ileesẹ naa binu nigba ti ijọba Ọyọ fẹsun kan an pe o gbe owo gun isẹ agbase ọhun lati biliọnu mẹrinla si mẹtadinlaadọrin naira, to si ni oun yoo pe ijọba lẹjọ nilẹ Gẹẹsi.
'Ǹkan tó jẹ́ kí iṣẹ́ ọ̀nà tèmi yàtọ̀ lágbàáyé ni ǹkan tí mò ń lò'
Gẹgẹ bi Aṣofin Adeola Bamidele, ti o n ṣoju ẹkun idibo Iseyin/itesiwaju sọ pe, o yẹ ki Agbaṣẹṣe naa gboriyin fun Ijọba ni dipo ko maa dunkooko mọ nitori ida marun un ni ipele ti iṣẹ oju ọna naa de lati bii ọdun meji abọ sẹyin, ti ko si fi han pe ile iṣe naa fẹ tan iṣoro ti awọn eniyan n koju.
Oríṣun àwòrán, @oyoassemblytweeter
Ile Igbimọ Asofin Ipinlẹ Oyo
O ni, iṣẹ naa lo kọkọ dawọ duro nibẹrẹ pẹpẹ nitori ọpọ nkan lo dabi eyi ti ko tọ lori isẹ naa, bẹrẹ lori iye ti iṣẹ naa jẹ dori boya ile iṣẹ naa to gbangba n sun lọyẹ.
Wayi o, gomina Seyi Makinde ti wa paṣẹ pe ki ile iṣẹ naa pari iṣẹ lila opopona olobiripo ọhun titi oṣu karun ọdun 2020 gẹgẹ bi o ti wa ninu iwe ajọsọ awọn mejeeji lojuna ati mu idẹrun ba tolori tẹlẹmu ni Ipinlẹ Ọyọ.
Prepaid Meter: èrò àwọn èèyàn ṣọ̀tọ̀ọ̀tọ̀ lórí 'sisan owó iná ní Nàìjíríà
Olori ile Aṣofin, Adebo Ogundoyin ṣalaye pe, o jẹ ohun ti o bani ninu jẹ pelu bi ile iṣẹ naa, ENL ti n dun koko mọ ijọba lẹyin ipade ajọṣepọ pe ki wọn o pada sẹnu iṣẹ.
Oríṣun àwòrán, Oyo state government
Gẹgẹ bi  Abẹnugọ naa ti wi, o ni kilo buru ninu ki wọn o beere idi ti agbaṣẹṣe ko se ti i pari iṣẹ ọdun mẹta to gba lati ọdun 2017, ti ko si ti ṣe ju ida mẹwa ni ọdun 2019, ki o si wa ṣalaye fun ara ilu.
Abẹnugọ ni, alaga ile iṣẹ naa, Clement Haastrup ti ṣetan lati fọ ara rẹ mọ kuro lara awọn ti o ṣe orilẹ ede yii baṣubaṣu.
O wa ni fun ilọsiwaju awọn eniyan, ara ilu ati Ipinlẹ Oyo, Ile fẹnu ko lati pe ile iṣẹ naa wa lati wa tan imọlẹ si okunkun ti o wa lori ọrọ naa.
'Èmi gan máa ń béèrè lọ́wọ́ ara mi pé ta ni Wole Soyinka gangan'
Illegal Rehab Centre: Feb 2008 ni wọ́n fẹ̀ṣùn kan Olore pé ó pa èèyàn 60 nígbèkùn
Oríṣun àwòrán, Seyi Makinde
Laipẹ yii ni iroyin tan kalẹ pe ileesẹ ọlọpaa nipinlẹ Ọyọ tun ti se awari ibudo miran ti wọn ti n mu awọn eeyan si igbekun eyi to n fi iya jẹ wọn.
Gẹgẹ bi iroyin naa se wi, o to awọn eeyan bii igba ti ori ko yọ ninu ile ọhun ti wọn n pe ni ile Ọlọrẹ, ẹni to jẹ agba Aafa nilu Ibadan.
Lati igba ti isẹlẹ naa ti waye, ni ẹsẹ ko ti gba ero nibi ti ile naa wa, tijọba ipinlẹ Ọyọ si ti ko awọn eeyan ti wọn mu si igbekun ninu ile Ọlọrẹ naa lọ si ibomiran fun itọju.
Bakan naa nijọba ni ki wọn wo ile ọhun nitori iwa ifiyajẹni to n waye nibẹ.
Amọ iwadi BBC Yoruba fihan pe kii se igba akọkọ niyi ti akara yoo tu sepo nipa iwa aidaa to n waye nile Ọlọrẹ nitori irufẹ isẹlẹ yii naa tun waye losu keji lọdun 2008.
Oríṣun àwòrán, Other
Ileesẹ ọlọpa yii kan naa lo se awari isẹlẹ awọn eeyan to le ni ọgọta ti wọn fi iya jẹ titi de oju iku , ti wọn si sin wọn sibẹ lai jẹ ki ọrọ naa lu sita.
Iroyin naa ni se ni wọn kan nipa fun awọn eeyan ti wọn n fiya jẹ, to wa nigbekun ninu ile naa lati maa fi tipa jẹ ẹran oku awọn akẹẹgbẹ wọn to ku lasiko ifiyajẹni.
Gẹgẹ bi ileesẹ ọlọpa ti salaye nigba naa, o to awọn eeyan bii mejilelaadọrun ti wọn tu silẹ nigbekun nile Ọlọrẹ naa, ti akoko ti awọn eeyan si fi wa nigbekun ninu ile ọhun si wa laarin ọjọ mẹta si ọdun meje.
Oríṣun àwòrán, Other
Bakan naa ni wọn mu awọn afurasi mọkanla lọdun naa ninu ile Ọlọrẹ, to fi mọ oludasilẹ ibudo naa, Alfa Mohammed Ọlọrẹ.
Nigba to n salaye ohun ti wọn n se nibẹ nigba naa, Alfa Ọlọrẹ ni o ti le ni ọdun mẹjọ ti ohun ti da ibudo naa silẹ, ijiya ẹsẹ eyikeyi awọn eeyan to ba sẹ nibẹ si lee gba to igba pankẹrẹ.
Kọmisana ọlọpa nipinlẹ Ọyọ nigba naa, Udom Ekpoudom salaye pe ikọ to n gbogun ti iwa idigunjale nileesẹ ọlọpaa lo lọ sile Ọlọrẹ naa, ti asiri ohun to n waye nibẹ fi tu.
Amọ Alfa Ọlọrẹ wa ṣẹ lori awọn ẹsun ti wọn fi kan nigba naa.
Fasola: Àwọn ọmọ Nàíjíríà kojú oro sí Fasola lórí bó ṣe ní ọ̀nà kò fi bẹ́ẹ̀ bàjẹ́
Oríṣun àwòrán, @Maryhanoh
Ọgọọrọ awọn ọmọ Naijiria lo ti n faraya loju opo ikansi ẹni Twitter fun minita fọrọ ilegbe ati eto irinna, Babatunde Raji Fasola lori ọrọ to sọ.
Fasọla lo kede lọjọru pe awọn opopona to wa lorilẹede Naijiria ko buru to bawọn araalu se n pariwo.
Fasọla ẹni to kede ọrọ naa lẹyin ipade igbimọ alasẹ ijọba tun fikun pe, asọdun lasan ni awọn ọmọ Naijiria n se pe awọn opopona to wa nilẹ yii ti di pakute iku.
Niwọn igba to jẹ pe isọrọ ni igbesi, Asoju-sofin kan, Salam to n soju ẹkun idibo Ẹdẹ/Ẹgbẹdọrẹ/Ejigbo lo kọkọ fesi pada fun Fasola pe ki oun ati awọn alasẹ yoku kẹyin si wiwọ baalu fun osu kan, ki wọn si gbe ọkọ yika Naijiria lati mọ bi awsn oju popo wa ti bajẹ to.
Oríṣun àwòrán, @nafeezi
Bakan naa, nigba ti wọn n fun Fasola lesi pada lori gbolohun to ti ẹnu rẹ jade ọhun, awọn ọmọ Naijiria loju opo Twitter ni ko ba dara ki minisita naa jawọ ninu apọn ti ko yọ, ko si da omi ila kana tori oselu ti tan.
@nafeezi n tiẹ se afihan awọn ọna kan to ti bajẹ faraye.
@112teejay ni iriri to ba ni ninu jẹ ati eyi to doju tini ni oun ri lasiko ti oun rin lati Enugu ls si Lọkọja de Ajaokuta.
@dark_lawyergirl ni iya nla ni ọkọ oun n jẹ loju popo, yoo si dara ki minisita naa dakẹ.
@AdekaunsiTemi1 ni ọrọ ti minisita naa sọ soro lati gbagbọ, yoo si dara ki minisita naa wo fidio ti oun n safihan rẹ lori Twitter.
@AyanfeOfGod ni o dabi ẹnipe orilẹ-ede Naijiria miran ni awọn alasẹ wa n pe eyi to yatọ si tawọn ọmọ Naijiria.
A ó gbé àjọ DSS lọ ilé ẹjọ́ tí wọ́n bá kọ̀ láti tú Sowore sílẹ̀ - Falana
Oríṣun àwòrán, @_ShattaBandle
A ó pe àjọ DSS lẹjọ́ tí wọ́n bá kọ̀ láti tú Sowore sílẹ̀ - Falana
Odindin wakati mẹrin ni awọn agbẹjọro wa lo fi n duro de ajọ ọtẹlẹmuyẹ DSS lanaa- Falana.
Ṣaaju ni ajọ ọtẹlẹmuyẹ ti kọkọ sọrọ pe ko sẹni to wa lati gba Soworẹ ati Bakara kuro ni ahamọ awọn lọjọ Ẹti.
Wọn fi atẹjade sita pe nitootọ lawọn gba iwe lati ile ẹjọ pe ki wọn tu Sowore ati Bakare silẹ, ṣugbọn ko si ẹni tó wa gbaa silẹ ni akata awọn.
Ati pe awọn ti fi to ilẹ ẹjọ leti pe ko sẹni to tii wa gba sowore lọwọ awọn ati pe awọn ṣetan lati tẹle aṣẹ ile ẹjọ.
Ajọ DSS ni awọn maa n tẹle ofin ile ẹjọ ṣugbọn Falana ni irọ ni nitori awọn agbẹjọro n duro lati gba Sowore ati Bakare nibẹ.
A ó pe àjọ DSS lẹjọ́ tí wọ́n bá kọ̀ láti tú Sowore sílẹ̀ - Falana
Agbẹjọro fun Omoyele Sowore, Femi Falana ti sọ pe oun yoo pe ajọ ọtẹlẹmuyẹ, DSS, lẹjọ latari bi wọn ṣe tẹsiwaju lati fi onibara rẹ re, satimọle lẹyin ti ile ẹjọ ni ki wọn da silẹ.
Oríṣun àwòrán, @chekpointchaley
Ofin orilẹ-ede Naijiria ko faye gba pe ki wọn gbe eeyan sẹwọn, lai ṣe pe ile ẹjọ paṣẹ bẹẹ
Falana lo sọrọ yii ninu ifẹorọwerọ kan pẹlu BBC.
"O ni ""Ko si ẹni to lagbara ju ile ẹjọ lọ, bẹẹ ni ko si ẹni to le ṣe ohun to wu labẹ ofin ilẹ Naijiria."""
Falana ṣalaye pe ofin orilẹ-ede Naijiria ko faye gba pe ki wọn gbe eeyan sẹwọn, lai ṣe pe ile ẹjọ paṣẹ bẹẹ.
O ṣalaye siwaju sii pe awọn agbẹjọro Sowore yoo kọ iwe si ile ẹjọ, latari bi ajọ DSS ṣe kọti ikun si aṣẹ ile ẹjọ lati tu silẹ.
Oríṣun àwòrán, Others
Sowore ṣì wà ni àgọ́ àwọn DSS lẹ́yìn ìdájọ́ ilé ẹjọ́
Agbẹjọro agba ọhun wa sọ siwaju si pe, ti ajọ DSS ba kọ lati tu Sowore silẹ, oun yoo pe ọga agba ajọ ọhun lẹjọ.
O ni oun yoo pem igbẹjọ lati mu ki ajọ DSS san owogbab mabinu fun gbogbo ọjọ ti Sowore lo latimọle.
Osteogenesis, aisan níní egungun tó rọ̀ ló ń ba Efia fínra
Ṣaaju asiko yii:
Oríṣun àwòrán, others
Sowore ṣì wà ni àgọ́ àwọn DSS lẹ́yìn ìdájọ́ ilé ẹjọ́
Omoyẹle Soworẹ to dije dupo aarẹ Naijiria loṣu keji, ọdun 2019 yii lo ṣi wa lakata awọn DSS ni abuja titi di isinyii.
Olawale Bakare ati Omoyele Sowore ni ajọ DSS ko ṣi tii fi silẹ lẹyin ti Adajọ Ijeoma Ojukwu ti ile ẹjọ giga ni Abuja ti fọwọsi itusilẹ wọn.
Lọjọru ọsẹ yii ni Adajọ Ijeoma ti ni ki wọn tu soworẹ silẹ kuro ni akata awọn ajọ DSS.
Marshal Abubakar to jẹ agbẹjọro Sowore Omoyel ni aago mẹwaa aarọ ọjọbọ ni ileẹjọ mu iwe itusilẹ naa fun wọn.
O ni lẹyin eyi ni wọn sọ fun oun pe awọn yoo kàn sí wọn to ba ya.
Balogun Fire: Àwọn èèyàn tí ìṣẹ̀lẹ̀ náà ṣojú wọn ṣàlàyé ohun tó fa iná lọ́jà Balogun
Ajọ DSS mu oludasilẹ ileeṣẹ iroyin Sahara Reporters ati Bakare ni o din diẹ ni ọgọrun un ọjọ sẹyin.
Lẹyin igbiyanju iwọde #Revolution Now ni wọn fi ẹsun kan wọn pe wọn fẹ doju ijọba bolẹ.
'Ǹkan tó jẹ́ kí iṣẹ́ ọ̀nà tèmi yàtọ̀ lágbàáyé ni ǹkan tí mò ń lò'
Ọjọ kẹrin, oṣu kẹwaa ni Adajọ Ijeoma gba oniduro awọn mejeeji ni eyi ti wọn ko tete ri ọna abayọ si awọn gbendeke gbigba oniduro wọn.
'Èmi gan máa ń béèrè lọ́wọ́ ara mi pé ta ni Wole Soyinka gangan'
Bayii, Adajọ Ijeoma ti tun gbendeke oniduro Sowore ati Bakare yẹ wo ni eyi ti awọn mejeeji si ti ri ojutuu si bayii.
Boko Haram: Ọmọ ogun Nàìjíríà méjìlá dàwátì lẹ́yìn ìkọlù Boko Haram
Oríṣun àwòrán, @Uduakkende
Lati ọdun 2018 ni lemọ lemọ awọn ẹgbẹ Boko Haram si awọn ọmọ ologun Naijiria ti n peleke sii
Iroyin kan lati ọdọ ajọ ologun orilẹ-ede Naijiria sọ pe awọn ọmọ ologun mẹwaa ti jẹ Ọlọrun nipe lẹyin ikọlu ikọ Boko Haram ni Domba, ni ipinlẹ Bornu.
Ẹnikan ti ko fẹ fi orukọ rẹ lede sọ fun ileeṣẹ iroyin AFP pe, ajọ ọhun si n wa awọn ọmọ ogun mejila lẹyin ikọlu naa lọjọru ọsẹ yii.
"O ni ""Awọn ọmọ ogun mẹwaa la padanu ninu ija pẹlu ẹgbẹ Boko Haram ni igba ti wọn da wa lọna""."
"O so siwaju sii pe ""ọmọ ogun mẹsan an ṣeṣe, a ko si mọ ibi ti awọn mejila wa."""
Ẹgbẹ Boko Haram ṣe akọlu sawọn ọmọ ogun naa nigba ti wọn bọ lopopona Damboa, to jẹ ibusọ mejidinlaadọrun un si Maiduguri.
Ninu akọlu ọhun ni alakatakiti ẹsin Islam Boko Haram ti dana sun ọkọ ologun Naijiria, ti wọn si tun ji awọn ohun ija oloro ko lọ.
Oríṣun àwòrán, @Army
Awọn ọmọ ogun n foju wina Boko Haram ni ariwa Naijiria
Lati ọdun 2018 ni lemọ lemọ awọn agbesunmọmi Boko Haram si awọn ọmọ ologun Naijiria ti n peleke sii, leyi to jẹ pe ẹgbẹ Islamic State ti iwọ orun Afirika naa ko gbẹyin ninu awọn akọlu naa.
Osteogenesis, aisan níní egungun tó rọ̀ ló ń ba Efia fínra
Oyo Budget: Kọmisánà fétò ìṣúná ní ìmúṣẹ ìlérí Seyi Makinde ni ìṣúná ọdún 2020
Oríṣun àwòrán, Twitter/Seyi Makinde
Igbesẹ ipade itagbangba lori aba eto isuna ọdun 2020 nipinlẹ Ọyọ jẹ ọna gbogi lati mu ileri ti ijọba Gomina Ṣeyi Makinde ṣe wi pe ijọba yoo maa ṣeto pẹlu ifọwọsọwọpọ ati ajọṣiṣẹpọ awọn araalu.
Kọmiṣọna feto iṣuna ati aato ọrọ aje nipinlẹ Oyo, Amofin Adeniyi Farinto lo ṣalaye bẹẹ lasiko to ba BBC Yoruba sọrọ, pẹlu afikun pe, anfaani wa sọ tẹnu rẹ ti ijọba fawọn araalu lori eto iṣuna yoo jẹ ki ijọba mọ ni pato ohun ti ilu kọọkan nilo.
Farintọ woye pe, ilana yii yoo ran ijọba lọwọ lati rii wi pe ilu to ba fẹ ipese omi, ijọba ko ni ṣe titi sibẹ ati bẹẹbẹẹ lọ.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí:
Kọmiṣọna feto iṣuna tẹsiwaju pe ijọba gbe eto yii lati jẹki gbogbo eeyan ipinlẹ Oyo ati awujọ agbaye rii pe, ilana iṣuna ọdun 2020 nipinlẹ Oyo kii ṣe ọrọ idakọnkọ.
Oríṣun àwòrán, Adeniyi Farinto
"Ọgbẹni Farintọ ni ""ijọba ni lati pada lọ sọdọ awọn eeyan lati beere ohun ti wọn fẹ lẹyin ti wọn ti dibo fun ijọba to wa lori aleefa bayii.''"
Bakan naa, akọwe agba nileesẹ eto iṣuna nipinlẹ Oyo, Foluke Adebiyi sọ pe, igbesẹ ijọba lori eto iṣuna ọdun 2020 yoo fun awọn araalu lohun ninu eto iṣejọba ipinlẹ Oyo, eyi ti ko ri bẹ tẹlẹ.
Oríṣun àwòrán, Seyi Makinde
Adebiyi ni eto yii to jẹ akọkọ iru ẹ ninu itan ipinlẹ Oyo, yoo mu aye dẹrun fawọn eeyan ipinlẹ naa.
Iyaafin Adebiyi ni iru eto yii lawọn ijọba kaakiri agbaye maa n ṣe lati fun awọn eeyan ti wọn dibo yan wọn lohun.
Ìlàná ìṣúná tí yóò mú aráàlú kúrò nínú àìní bọ́ sí ọ̀pọ̀ là fẹ́ gbékalẹ̀ - Seyi Makinde
Saaju ni ipade itagbangba lori aba eto isuna ọdun 2020 ti gberasọ lẹkun idibo guusu Ọyọ, ninu ọgba UCH nilu Ibadan.
Afojusun ipade naa ni lati bun awọn olugbe ipinlẹ Ọyọ gbọ nipa aba isuna ọdun 2020, ki wọn si se akojọpọ ero awọn araalu nipa ohun ti wọn n poungbẹ, ti yoo si wọ inu aba naa.
Nigba to n sọrọ nibi ipade ita gbangba akọkọ to waye fẹkun idibo guusu Ọyọ, ni gbọngan nla to wa loọgba iwosan UCH nilu Ibadan, gomina Seyi Makinde salaye pe ọna lati se agbekalẹ eto isuna ti yoo ba aini awọn eeyan ipinlẹ Ọyọ pade lo sokunfa ipade ọhun.
Oríṣun àwòrán, Seyi Makinde
Lati ọdun mọdun ni ariyanjiyan ti maa n waye lori ọna to dara julọ lati sejọba, se ilana ki ijọba maa gbe ilana afojusun kalẹ faraalu ni, ti yoo si fọ si wẹwẹ fun amusẹ abi ki araalu maa se ojuse nidi agbekalẹ afojusun, to si ni ilana mejeeji lawọn se amulo rẹ.
Bakan naa lo fikun pe oun ko se agbeyẹwo ilana isuna ọdun 2019 lati tabuku ẹnikẹni amọ oun sakiyesi pe ipinlẹ Ọyọ n se kọja agbara rẹ ni, ti wọn ko si samulo ofin bi ọwọ eku ba se mọ lo fi n họri.
Oríṣun àwòrán, Seyi Makinde
Saaju ninu ọrọ rẹ, Kọmisana feto isuna ati aato ọrọ aje, Amofin Adeniyi Farintọ ni ipade itagbangba ọhun lo n fidi rẹ mulẹ pe ijọba alajumọse lo wa nipinlẹ Ọyọ bayii, to si setan lati ko awọn araalu kuro nipo osi bọ si idẹrun.
Farintọ ni irufẹ ipade itagbangba yii ni yoo pese anfaani lati sagbeyẹwo oniruuru ero fun idagbasoke ati ilọsiwaju ipinlẹ Ọyọ.
Oríṣun àwòrán, Seyi Makinde
Ipade ita gbangba fun awọn olugbe ipinlẹ Ọyọ naa ni yoo si waye lẹkun idibo apapọ mẹtẹẹta to wa nipinlẹ naa.
Ìtàn Mánigbàgbé: Ṣango gbèrò ibi fún Gbọnka àti Timi, àmọ́ òun gan bá ọ̀tẹ̀ náà lọ
Oríṣun àwòrán, Others
Ìtàn Mánigbàgbé: Ṣango gbèrò ibi fún Gbọnka àti Timi, àmọ́ òun gan bá ọ̀tẹ̀ náà lọ
Ẹlẹdaa fi ọpọ awọn akọni nla jinki ilẹ Yoruba laye atijọ.
Awọn  naa ni arogun matidi, abawọnja ma se ojo, awọn ti ilu ṣee gbọkanle, iru wọn si ni Timi Agbale Ọlafa ina ati Gbọnka Ebiri.
Timi Agbale ati Gbọnka Ebiri jẹ akọni ọdẹ aperin ati jagunjagun ni Ọyọ atijọ, ti wọn ko si lee kọ iyan wọn, ki wọn ma fi ewe boo, ti itan si sọ fun wa pe Timi lo da ilu Ẹdẹ, to wa nipinlẹ Ọṣun silẹ.
Gẹgẹ baa se kaa loju opo itakun agbaye, taa si rii gbọ ninu itan atẹnudẹnu, a lee tọpasẹ itan Gbọnka ati Timi Agbale si ọdun 1500.
Eyi jẹ lasiko to n lo ọfa to maa n yọ ina lati fi ja ogun, idi si niyi ti wọn ṣe n pe e ni Timi Agbale Ọlọfa ina.
Gbọnka Ebiri ni tiẹ kii lo ọfa lati jagun amọ o ni oogun ju Arọni lọ, eyi to maa n lo lati fi sẹgun ọta.
Oríṣun àwòrán, Others
Ẹlẹdaa fi ọpọ awọn akọni nla jinki ilẹ Yoruba laye atijọ.
Itan naa sọ fun wa pe, Timi Agbale jẹ ọrẹ timọ-timọ fun Gbọnka Ebiri, ti awọn mejeeji si jẹ jagunjagun laye igba ti Alaafin Sango n jọba.
'Èmi gan máa ń béèrè lọ́wọ́ ara mi pé ta ni Wole Soyinka gangan'
Osteogenesis, aisan níní egungun tó rọ̀ ló ń ba Efia fínra
Wo itan omi gbigbona ati tutu ni Ikọgosi Ekiti
Sogidi Lake: Kòṣẹja-kòṣèèyàn lá bá nínú adágún odò náà -Ojedele
Yoruba Culture: ọjọ́ méje ni wọ́n fí n rẹ ẹ̀kú Danafojura kó tó jáde
Ẹ̀ wo bí àwọn ẹ̀ṣọ́ ojú etí òkun ṣe ń ṣiṣẹ́ l'Eko
World water day: Ẹrin Ijesa, Ọ̀ṣun Oṣogbo, àwọn ibùdó ìgbafẹ́ omi tí ó yẹ kí o mọ̀
Kí lo fẹ́ mọ̀ nípa D.O Fágúnwà?
Afárá odo ọya keji :Ta ni yóò parí rẹ?
Lagos King: Mátikú ọba tó lo lo ọdun mẹta lórí oyé latari rogbodiyan Eko
Ijebu: Ikú àbúrò mi ló ṣún mi dé ìdí orin kíkọ
Oríṣun àwòrán, Ijebu
Gbajugbaja osere tiata, Ọlatayọ Amokade ti gbogbo eeyan mọ si Ijẹbu, ti salaye lori iha ti idile rẹ kọ si isẹ to n se.
Ijẹbu, lasiko to n kopa lori eto ifọrọwanilẹnuwo lori BBC Yoruba salaye pe, inu iyawo oun kii dun si eebu ti akẹẹgbẹ oun, Ọdunlade Adekọla maa n bu oun lasiko ti awọn ba n sere tiata.
Ijẹbu ni bi o tilẹ jẹ pe eebu naa ko ni itumọ kankan si oun nitori ere lasan ni, amọ iyawo oun ko fi bẹẹ nifẹ si iru iwa bayii.
Nigba to n salaye ohun to gbe de idi isẹ tiata, Amokade salaye pe lati kekere ni oun ti nifẹ si ere itage amọ oun kọkọ lọ sile iwe gbogbonse Poly Ibadan na, lati kẹkọ imọ nipa ibaraẹnisọrọ, taa mọ si Mass Communication, ki oun to gbajumọ isẹ tiata ni sansan.
Oríṣun àwòrán, Ijebu
Ilumọọka osere tiata naa, ẹni to kede pe o ti to ọdun mẹẹdogun ti oun ti bẹrẹ isẹ ere tiata, ti aye si n fẹ oun, wa yan pe Muyiwa Ademọla, ti gbogbo eeyan mọ si Muyiwa Authentic, ni ọga to kọ oun lere tiata.
Ijẹbu, tii se ọmọ bibi ilu Ilisan Rẹmọ fikun pe yatọ si ere tiata, oun tun nifẹ si orin kikọ, to si jẹ pe orin kikọ gan ni oun fi bẹrẹ ere tiata bi o tilẹ jẹ pe oun ko yan isẹ orin laayo lati fi jẹun bii ere itage sise.
Oríṣun àwòrán, Ijebu Instagram
O tẹsiwaju pe iku aburo oun kan ni oun fi bẹrẹ orin kikọ, ti oun si maa n kọrin fun ọmọ aburo oun naa to fi silẹ saye lọ pe oun dupẹ pe oun ri aanu gba.
Ijẹbu, to saba maa n ko ipa adẹrinposonu ninu ere tiata, tun salaye iha ti awọn eeyan kan kọ si ihuwasi oun se afọmọ rẹ pe, irọ to jinna sootọ ni pe oun ni igberaga nitori onirẹlẹ pọhunbele ni oun.
Amọ ko sai yan pe ipo ti eeyan ba wa ni yoo sọ iru iwa ti yoo hu sita, eyi to lee mu kawọn eeyan kan fi oju rere abi abuku wo onitọun, ti yoo si yun se atọna irufẹ iwa ti eeyan yoo hu lasiko naa.
Lagos Fire: Ọ̀pọ̀ èèyàn tó nílé ní àárọ̀, ní kò nílé mọ́ ní alẹ́ tórí iná tó jó ilé ní Okobaba
Awọn ọdọ lagbegbe Okobaba ko duro ki awọn osisẹ panapana de, ti wn fi n bu omi pa ina naa.
Haa! rẹrẹ run ni isọ pako ni Okobaba. Haa, aje o
Aje ooo! Ọlọrun yoo fi ofo ra ẹmi fun awọn ti ajalu naa deba.
Ẹnikan lo mọ ni ọrọ ina to jo ni isọ pako ladugbo Okobaba, nkan se
Ile aye, ile asan. Ọpọ eeyan to jẹ onile laarọ lo di alainile lori mọ ni ọsan gangan, afi ki Ọ́lọrun tu wọn ninu
Gbogbo dukia ti ina ọhun fi ọwọ ba lo jona di eeru
Awọn waya ina alagbara ree to ja silẹ nitori ijamba ina. A fi ki wọn tete palẹ rẹ mọ nilẹ ko ma baa se okunfa ijamba miran lagbegbe Okobaba
Ko kuku ni tan ninu igba osun, ka ma fi pa ọmọ lara. Diẹ lara awọn pako to jona ku ree. Ọlọrun yoo da igba rere pada fawọn onisowo pako ni Okobaba
Ketu Market Violence: Rògbòdìyàn bẹ́ sílẹ̀ nigba táwọn òǹtàjà kọjú ìjà sí àjọ Task Force
Oríṣun àwòrán, Other
Rogbodiyan bẹ silẹ lọja Ketu lọjọ Ẹti nigba ti awọn oṣiṣẹ ajọ to ri si iwa ibajẹ ni ipinlẹ Eko, Task Force yabo ọja Jakande.
A gbọ ni pe ajọ Task Force naa pẹlu awọn ọlọpaa fẹ fi ipa le awọn to gbọja silẹ, ki awọn ọlọja naa to tako wọn.
Lẹyin naa ni a gbọ pe ọlọpaa yinbọn eyi ti ọta rẹ ba ọkan lara awọn olugbe adugbo Ketu.
Bayii ni awọn ọlọpaa kọju ija sawọn ọlọpaa ti ọrọ si di bọọlọ o ya n mi lọja naa.
Iroyin sọ pe, awọn ọdọ fi ibinu bẹrẹ si ni dana sun ọkọ loju popo, to fi mọ ọkọ akero BRT.
A gbọ pe awọn ọlọpaa ti lọ si agbegbe naa lati rii pe alaafia pada jọba ni agbegbe naa.
Ọkan lara awọn ọlọpaa to wa nibẹ ṣalaye pe, wọn ti gbe ẹni ti ọta ibọn ba lọsi ile iwosan, ẹmi ko si tii bọ lẹnu rẹ.
Ajọ FRSC ṣèlérí láti fọwọ́ òfín mu eegun tó bá tasẹ̀ àgẹ̀rẹ̀ lásìkò ọdún Keresi
Oríṣun àwòrán, Others
Ara ọrun to ba dena soju popo rogo lasiko ọdun Keresimesi to m bọ yii
Ajọ to n risi ẹṣọ oju popo, Federal Road Safety Commission ti kede pe wọn maa mu eegun ki eegun to ba jade lasiko ọdun keresimesi to ba dẹ fa sunkere fa kẹrẹ ọkọ.
FRSC fi eyi lede pe awọn ti woye pe asiko ọdun kekere ati ọdun nla ni awọn eegun kan maa n jade paapaa ni awọn ipinlẹ ila oorun Naijiria ni eyi to de maa n fa igbokegbodo ọkọ.
Ogbeni Kehinde Adeleye to jẹ adari ajọ ẹṣọ oju popo ni ẹkun Benini to jẹ RS5 lo ṣo eyi ni asiko ipolongo alaafia loju opopona ni ilu Onitsha, ipinlẹ Anambra lọjọbọ.
Adeleyẹ ni latẹyinwa ni wọn ti woye pe ọpọ igba ni jijade awọn ara ọrun ati bi wọn ṣe n jo loju titi maa n di igbokegbodo ọkọ lọwọ.
Oríṣun àwòrán, @others
Ara orun n fayo han ti opo si n telee
O ni lọtẹ yii, ọwọ ofin maa mu eegun ti ko ba rin bo ṣe yẹ ko rin daadaa.
Adeleye ṣalaye siwaju pe aṣẹ yii wa lati oke lọdọ Ogbeni Boboye Oyeyemi to jẹ ọga agba pata fun ajọ naa.
Oríṣun àwòrán, @others
Awon ara orun maa n sadura fawon ara aye fun odun tuntun
Ẹni to paṣẹ pe ki gbogbo ara ọrun tọwọ ọmọ wọn bọ aṣọ.
Ajọ FRSC ni opọ igba si ni awọn ijamba ọkọ to ba ṣẹlẹ yii maa n mu ẹmi dani.
Osteogenesis, aisan níní egungun tó rọ̀ ló ń ba Efia fínra
Bakan naa ni Adeleye fi imoore ajọ naa han si ijọba Anmbra fun atilẹyin wọn lati rii pe ẹmi ati dukia awọn eniyan loju popo.
'Ǹkan tó jẹ́ kí iṣẹ́ ọ̀nà tèmi yàtọ̀ lágbàáyé ni ǹkan tí mò ń lò'
Ni afikun, Adeleyẹ kilọ fawọn awakọ ati ọlọkada lati ṣora ṣe loju popo nitori pe ẹmi ko ni aarọ rara.
Adari ajọ ẹṣo oju popo fun ipinlẹ Anambra, Ogbeni Andrew Kumapayi ni ajọ FRSC ti ṣetan lati pese aabo to peye fun ẹmi ati dukia awọn eniyan lasiko ọdun kekere ati ọdun nla to m bọ.
Balogun market fire: Olubadamọran gomina sọrọ lori ina náà
Kumapayi ni awọn ajọ ẹṣo oju popo ti sami si awọn agbegbe to maa n saaba ni ipalara dani ni eyi ti wọn ti pin awọn akọṣẹmọṣẹ oṣiṣẹ lọ sibẹ lati rii pe ko si wahala lasiko ọdun keresimesi yii.
Bakan naa lo ni ki awọn eeyan fi aayọ du[pẹ oore ki wọn sa fun iwa pipa ara ẹni lasiko ọdun nitori ironu.
'Èmi gan máa ń béèrè lọ́wọ́ ara mi pé ta ni Wole Soyinka gangan'
Yemi Osinbajo: Ẹgbẹ́ àwọn àgbààgbà Yorùbá ní Osinbajo kò gbọdọ̀ kọ̀wé fipò sílẹ̀
Oríṣun àwòrán, Twitter/Yemi Osinbajo
Yemi Osinbajo: Ẹgbẹ́ àwọn àgbààgbà Yorùbá ní Osinbajo kò gbọdọ̀ kọ̀wé fipò sílẹ̀
Ọrọ n ba moko moro bọ lori aawọ to n ṣẹlẹ laarin igbakeji aarẹ, Yemi Osinbajo atawọn kan nile iṣẹ aarẹ Naijiria.
Ẹgbẹ agbaagba nilẹ Yoruba, YCE lo rọ igbakekeji aarẹ wi pe ko ma kọwe fi ipo rẹ silẹ.
Bakan naa ni ẹgbẹ YCE rọ Aarẹ Muhammadu Buhari pe ko ma ṣe gbọ ohun tawọn kan n sọ fun un lori ọrọ Osinbajo wi pe ko ranti bi Osinbajo ṣe duro ti i lati igba ti wọn ti jọ bẹrẹ.
Lọjọ Ẹti ni ileeṣẹ aarẹ fidi rẹ mulẹ pe Aarẹ Muhammadu Buhari lo paṣẹ idaduro lẹnu iṣẹ fawọn oluranlọwọ marundinlogoji igbakeji aarẹ Osinbajo.
Amọ ileeṣẹ aarẹ ṣalaye pe dida ti wọn da awọn oluranlọwọ Osinbajo duro nii ṣe pẹlu igbiyanju ijọba apapọ lati din owo ti ijọba n na fun iṣejọba ku.
Garba ṣalaye loju opo twitter rẹ pe:
Atejade naa ni ọrọ idaduro yii naa ti kọkọ kan diẹ ninu awọn oluranlọwọ Aarẹ.
Garba Shehu ni awọn ipo oloṣelu kan lawọn ti yọ kuro ti wọn ko si tun awọn eeyan miran yan si ipo mii bi buhari ṣe wọle lẹẹkeji.
O ni ko si ija laarin Buhari ati Osinabjo lasiko yii.
Ṣe Laolu Akande n parọ ni?
Ṣaaju ni Ogbeni Laolu akande to jẹ oluranlọwọ fun igbakeji aarẹ Oṣinbajo ti kọkọ fi sita pe irọ to jina si ootọ ni pe Aarẹ Buhari da awọn oluranlọwọ Oṣinbajo marundinlogoji duro lẹnu iṣẹ wọn
Ṣugbọn akọwe agba ajọ ẹgbẹ agbaagba Yoruba, Ọmọwe Kunle Olajide sọ pe awọn ti wọn n gbogun ti Osinbajo n ṣe bẹẹ nitori ibo aarẹ ọdun 2023 ni.
Ọmọwe Olajide fikun ọrọ rẹ pe ko si idi kankan to le mu ki Osinbajo kọwe fipo silẹ niwọn igba to jẹ pe awọn ọmọ Naijiria jọ dibo yan oun ati aarẹ Buhari papọ ni.
Oríṣun àwòrán, Twitter/Prof Yemi Osinbajo
Yemi Osinbajo: Ẹgbẹ́ àwọn àgbààgbà Yorùbá ní Osinbajo kò gbọdọ̀ kọ̀wé fipò sílẹ̀
O rọ igbakeji aarẹ pe ko tẹsiwaju lati maa ba aarẹ Buhari ṣiṣẹ pọ pẹlu inu kan.
Illegal Rehab Centre: A le ni ogójì tí wan n kó 'sinú ìyará kékeré kan níle Ọlọrẹ
US election 2020: Ibú-owó Bloomberg fẹ́ wàákò pẹ̀lú Trump nínú ìbò ààrẹ Amẹrika
Oríṣun àwòrán, Getty Images
US election 2020: Ibú-owó Bloomberg fẹ́ wàákò pẹ̀lú Trump nínú ìbò ààrẹ Amẹrika
Ọlọrọ Michael Bloomberg to ti figba kan jẹ Méyọ̀ to dari ilu New York ti fi erongba rẹ han lati dije dupọ aarẹ ilẹ Amẹrika ninu ibo aarẹ ọdun 2020.
Ọgbẹni Bloomberg ti kọwọ bọwe lati kopa ninu idibo abẹle ẹgbẹ oṣelu Democrat ti yoo waye nipinlẹ Alabama.
Ti o ba jawe olubori ninu ibo abẹle, a jẹ wi pe oun ni yoo tan kangbọn pẹlu Aarẹ Donald Trump ti yoo dije fun saa keji labẹ asia ẹgbẹ oselu Republican.
Ọgbẹni Bloomberg gan an ko tii kede fun ra rẹ wi pe oun yoo dije fun ipo aarẹ ninu ibo gbogbogbo ọdun to n bọ.
Ṣugbọn agbẹnusọ rẹ, Jason Schechter ti sọ f'awọn akọroyin pe Bloomberg yoo kede erongba rẹ lọsẹ to n bọ.
Iroyin sọ pe Ọgbẹni Bloomberg pinnu lati dije fun ipo aarẹ lẹyin to sọ pe ko si ẹni to le ba aarẹ Trump figagbaga ninu awọn to fẹ kopa ninu ibo abẹle ẹgbẹ oṣelu Democrat.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ko sẹni to le koju Trump ninu awọn to tii jade
Bloomberg to jẹ ẹni ọdun mẹtadinlọgọrin atawọn mẹrindinlogun miiran ni wọn yoo jọ waako ninu idibo abẹle Democrat bayii.
Joe Biden to jẹ igbakeji aarẹ ilẹ Amẹrika lo si n siwaju ninu awọn to fẹ dije fun ipo aarẹ fẹgbẹ Democrat, nigba ti Sẹnẹtọ Bernie Sanders ati Elizabeth Warren si n tẹ le e.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Aarẹ Trump tilẹ sọ lọjọ Ẹti pe enikan to le ba oun figagbaga ninu ẹgbẹ Democrat naa ni Ọgbẹni Bloomberg, amọ oun naa kere.
Bloomberg gbero lati dupo aarẹ gẹgẹ bi ọlọdanni ninu ibo aarẹ tọdun 2008 ati tọdun 2016.
Illegal Rehab Centre: A le ni ogójì tí wan n kó 'sinú ìyará kékeré kan níle Ọlọrẹ
Bakan naa lo sọ ninu oṣu kẹta ọdun yii pe oun ko ni dije ninu ibo aarẹ ọdun 2020.
Loṣu keje ọdun 2020 lẹgbẹ oṣelu Democrat yoo kede nibi apero wọn niluu Wisconsin ẹni to yoo ṣoju ẹgbẹ naa ninu idibo aarẹ ti yoo waye loṣu kọkanla.
Ọjọ kẹrinla, oṣu keji, ọdun 1942 ni wọn bi Bloomberg ni Brighton, Massachusetts, lorilẹ-ede Amẹrika.
Fasiti Johns Hopkins lo ti kọkọ kawe ko to gboye MBA ni fasiti Harvard.
O ṣe iyawo pẹlu Susan Brown-Meyer lọdun 1975, ṣugbọn wọn kọ ara wọn sile lọdun 1993.
Bloomberd to bi ọmọ meji jẹ ọkan lara awọn eeyan to lọrọ ju lagbaye nigba ti wọn ṣi ohun ini rẹ si biliọnu mẹtalelaadọta.
Bloomberg jina si aarẹ Trump ninu ọrọ nini, nitori biliọnu mẹta ni gbogbo ohun in Trump jẹ.
Osteogenesis, aisan níní egungun tó rọ̀ ló ń ba Efia fínra
Ọmọ ẹgbẹ oṣelu Democrat ni Bloomberg to fi di ọdun 2001, o darapọmọ ẹgbẹ Rupublican lọdun 2001.
Bloomberg da ẹgbẹ oṣelu ara rẹ ṣe laarin ọdun 2007 si 2018.
Ṣugbọn o pada si Democrat lọdun 2018 bibi to wa di akoko yii.
'Èmi gan máa ń béèrè lọ́wọ́ ara mi pé ta ni Wole Soyinka gangan'
Ore Falomo jẹ́ onímọ ìṣègùn tó lámì laka láàrin ìràn Yoruba
Oríṣun àwòrán, Thisday
Ore Falomo jẹ́ onímọ ìṣègùn tó lámì láàrin ìràn Yoruba
Gbogbo ọmọ yorùna lo n ṣelédè lẹ́yìn Dókítà Ore Falomo ti gbogbo ènìyàn mọ sí oníṣegun M.K.O Abiọla nígbà ayé rẹ̀.
Adarí ẹgbẹ́ Afenifẹre Ayo Adebanjo nínú ọ̀rọ̀ rẹ̀ sàlàyé pé iṣẹ́ nla ribiribi ní Ore Falomo ti ṣe nínú ìràn Yoruba, àti pe ìràn yoruba ti so ogo nla kan nù.
Adebanjo fi kún ọ̀rọ̀ rẹ pe ó ṣe pàtàkì kí gbogbo ìràn yoruba jí gírí láti gbe ogo iran rẹ gá bi Ore Falomo ṣe se nigba aye rẹ̀,
O safiwe pe pàápàá julọ gẹ́gẹ́ bíi Dokita Abiola, O dúro ti Abiola gidigidi lásìkò ìṣòrò, kò kẹyin sí i bi àwọn tọ ku ṣe ṣe nigba náà
O fí kun un pé àwokọ́se rere ni Falomo jẹ́ nígba ti fi jẹ ààrẹ àwọn ẹgbẹ́ Dokita ni Naijiria, amúyangan ni àsìkò rẹ̀ jẹ́ fún ìdári rẹ̀ àti ipo ti ọ̀rs ilera wa lásìkò náà.
Afẹnifẹre ni Dokita Falọmọ kìí ṣe ẹni ti ìràn Yoruba gbọdọ gbàgbé ni kíakía.
Ta ni Ọrẹ Falomo, dókítà MKO Abiola tó papòdà lẹ́ni ọdún mẹ́tàdínlọ́gọ́rin?
A bi Dokita Oluwatamilore Falomo lọjọ kẹrin, oṣu kẹsan an, ọdun 1942 niluu Minna to jẹ olu ilu ipinlẹ Niger bayii.
Ọgbẹni Falomo lọ ile iwe alakọbẹrẹ ni Baptist Primary School, Ijaiye laarin ọdun 1948 si ọdun 1955.
Ile iwe girama Methodist Boys High School nipinlẹ Eko ni Falomo lọ laarin ọdun 1956 si ọdun 1960.
Falomo tẹsiwaju ẹkọ rẹ nile iwe St. Andrew College, niluu Dublin lorilẹede Ireland laarin ọdun 1961 si 1962 ki o to lọ kawe ni Royal College of Surgeons ni Ireland lati ọdun 1962 si 1968.
O tun pada si ile iwe Royal College of Surgeons niluu Dublin lọdun 1978.
Ọgbẹni Falomo ṣe igbeyawo pẹlu Folashade Ṣorunke lọdun 1968.
Dokita bẹrẹ iṣẹ nile iwosan Park Hospital, Davyhulme ni Manchester lọdun 1969 si 1970.
O tun ṣiṣẹ ni ẹka eto ilera ipinlẹ Eko lagbegbe Surulrere lọdun 1971 si 1972, ko to lọ ṣiṣẹ ni ile iwosan ijọba ni Ikeja lọdun 1972 si ọdun 1973.
Dokita Falomo di oludari ile iwosan Onikoyi Clinic ni Yaba lọdun 1974 si 1979.
Falomo jẹ alaga ẹgbẹ awọn dokita lọdun 1971 si 1974, o tun jẹ ọmọ ẹgbẹ awọn dokita nilẹ Gẹeṣi ati orilẹede Ireland.
O ṣiṣẹ ni ile iwosan Maryland Specialist Hospital fun ọpọ ọdun.
'Èmi gan máa ń béèrè lọ́wọ́ ara mi pé ta ni Wole Soyinka gangan'
Dokita Falomo jẹ dokita oloogbe ati oludije fun ipo aaarẹ labẹ asia ẹgbẹ oṣelu SDP ninu ibo aarẹ ọdun 1993 ni Naijiria, MKO Abiola.
'IBB da Abiola lẹ́yìn tó búra pẹ̀lú Quran'
Wo àwọn ọ̀gá ọlọ́pàá tuntun mẹ́tàlá tí àjọ ọ̀hún fọ́nka síta
Oríṣun àwòrán, @Nigeria Police
Eyi waye lasiko ti wọn n wọ okun fun aṣẹṣẹ yan igbakeji ọga ọlọpaa ni olu ile iṣẹ ọlọpaa ni Aabuja
Oga ọlọpaa, Muhammed Adamu ti paṣẹ atunto si ẹkun igbakeji ọga ọlọpaa mẹtala ni Naijiria.
Frank Mba to jẹ agbẹnusọ awọn agbofinro lo fi atẹjade naa sita lọjọ kẹjọ, oṣu kọkanla ọdun yii ni eyi ti wọn ti ṣẹṣẹ sọ awọn kọmiṣọnna ọlọpaa kan di igbakeji ọga agba ọlọpaa Naijiria.
Frank Mba ni ọtọọtọ ni iṣẹ akanṣẹ ti ọkọọkan awọn agbofinro ti wọn ṣẹṣẹ gba igbega wọnyii a maa mojuto ninu ẹka iṣẹ ọlọpaa Naijiria.
1) AIG Dan Bature,fdc - AIG DFA FHQ
2) AIG Hyelasinda Kimo Musa - AIG PMF
3) AIG Yunana Y. Babas, mni- AIG Zone 8 Lokoja
4) AIG Dan Mallam Mohammed,fdc - AIG SPU
5) AIG Mua'zu Zubairu Halilu - AIG CTU
Illegal Rehab Centre: A le ni ogójì tí wan n kó 'sinú ìyará kékeré kan níle Ọlọrẹ
6) AIG Rabiu Yusuf - AIG ICT
7) AIG Ahmed Iliyasu - AIG Zone 2, Lagos
8) AIG Mohammed Uba Kura - AIG Maritime
9) AIG Zaki M. Ahmed - AIG Zone 6, Calabar
10) AIG Zama Bala Senchi - AIG ọlọpaa awọn agbegbe kọọkan (Community Policing)
Osteogenesis, aisan níní egungun tó rọ̀ ló ń ba Efia fínra
11) AIG Bello A. Sadiq - AIG Zone 1, Kano
12) AIG Austin Agbonlahor Iwero,fdc - AIG DOPS FHQ
13) AIG Lawal Ado - AIG Works
Oga agba pata fawọn agbofinro gba awọn aṣẹṣẹyan sipo wọnyii nimọran lati lo iriri ati ọgbọn wọn daadaa fun ipese aabo fun ẹmi ati dukia awọn eniyan Naijiria.
Lọgan ni awọn igbakeji ọga agba tuntun wọnyii a bẹrẹ iṣẹ nibi ti wọn gbe wọn lọ.
'Èmi gan máa ń béèrè lọ́wọ́ ara mi pé ta ni Wole Soyinka gangan'
NEPA: Kò ní sí iná mọ̀nàmọ́ná ní Eko láwọn èèyàn n sọ̀rọ̀ lé lọrí
Oríṣun àwòrán, Getty Images
ọpọ ero gba pe ko tọ si awọn EKEDC lati sọrọ lori ina bayii
Ileeṣẹ EKEDC àti IKEDC to n pese ina mọnamọna nipinlẹ Eko ti dẹbu ina to n ṣe segesege ru awọn irinṣẹ to n pin ina ọba.
Ọpọ awọn ọmọ Naijiria lori ayelujara lo ti  n sọrọ lori ina ọba to dorikodo nipinlẹ Eko.
Wọn n sọrọ naa nipa lilo #NEPA, #Blackout, #Nationwide lati alẹ ana, ọjọ Ẹti lataari ina ọba to di nkan mii.
Ileeṣẹ Eko Electricity Distribution Company (EKEDC) to maa n pin ina ati odiwọn iye owo ti awọn ọmọ Naijiria to n lo ina maa san nipinlẹ Eko ni aisi ina ọba kii ṣe ẹbi awọn.
Oríṣun àwòrán, Others
Kete ti wọn sọrọ lori twitter lawọn eeyan ti n da wọn lohun
EKEDC ati Ikeja Electric Distribution Company sọrọ loju opo twitter wọn pe irin iṣẹ lo dẹnu kọle to ṣokunfa aisi ina yii.
Lẹyin eyi ni wọn tun bẹ awọn eniyan ki wọn ni suuru ni eyi ti wọn fi ni iṣẹ ti n lọ lori ṣiṣe atunṣe to yẹ si awọn irin iṣẹ wọnyii to dẹnu kọlẹ.
Illegal Rehab Centre: A le ni ogójì tí wan n kó 'sinú ìyará kékeré kan níle Ọlọrẹ
Kete ti wọn fi eyi lede tan ni awọn ọmọ Naijiria ti bẹrẹ si ni fun wọn lesi pada. awọn kan ni ki PHCN naa ni suuru lori pinpin bíìlì iye owo ti àwọn maa san.
Bẹẹ naa ni awọn eniyan miran n gboriyin fun ileeṣẹ mọnamọna pe ikede naa dara ti wọn fi sita
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Aadota odun ree ti e ti n paro atunse ise yin fawon omo Naijiria lero awon kan
Awọn  mii bi hunter bu ẹnu ẹ̀tẹ́ lu PHCN pe o ti le laadọta ọdun tawọn eeyan ti n ni suuru fun wọn ti wọn ko si yipada di asiko yii.
Osteogenesis, aisan níní egungun tó rọ̀ ló ń ba Efia fínra
Awọn miran n parọwa fun PHCN ki wọn tete pari iṣẹ to yẹ nitori ooru ti n mu diẹ lasiko yii
Yoruba Films: Toyin Abraham ní 'gbogbo èèyàn loníbárà', Ijebu ta sí Odunlade
Oríṣun àwòrán, Other
Ninu iroyin ohun to ṣẹlẹ lagbo awọn gbajugbaja oṣere Yollywood lọsẹ to kọja, Toyin Abraham lo sọrọ to ya ọpọ lẹnu nigba to sọ pe gbogbo eeyan ni onibara laye.
Toyin Abraham
Toyin ṣalaye pe awọn eeyan kan wa ti wọn n tọrọ owo, o ni iru isọri awọn onibara kan niyii.
Toyin tun sọ pe awọn kan tilẹ wa to jẹ wi pe owo ko jẹ awọn niya, amọ idunnu ni wọn n wa eyi lo si jẹ ki wọn jẹ onibara.
Toyin Abraham tun ṣalaye siwaju sii pe ilera lawọn eeyan kan n tọrọ ni tiwọn lọwọ Ọlọrun bo tilẹ jẹ pe owo ko jẹ wọn niya.
Odunlade Adekola
Oṣere Odunlade Adekola ni tirẹ fi dawọn ololufẹ Yollywood loju ni pe awọn yoo maa tẹsiwaju lati maa mu inu wọn, bo tilẹ jẹ pe awọn kọlọnbiti ẹda kan si n ji iṣẹ wọn ta.
Odunlade ni sọ nipa fiimu ''Ajẹbi'dan eleyi to ṣe fun ra rẹ.
Odunlade ni kawọn eeyan foju sọna fun fiimu naa wi pe yoo jade ni ko pẹ.
Sanyẹri
Nibi ayẹyẹ ọjọ ibi ọkan ninu olori Alaafin ilu Oyo, Oba Lamidi Adeyemi ni Afonja Mukaila Olaniyi ti ọpọ mọ si Sanyeri ti ṣe opin ọsẹ yii.
Koda oun ati ilumọọka olorin Fuji, Alhaji Wasiu Alabi Pasuma jọ pade nibi ayẹyẹ ọhun to waye niluu Oyo.
Sanyẹri tilẹ rọ awọn eeyan loju opo Instagram rẹ lati mura ṣiṣẹ wọn, bakan naa lo gbadura fun ibukun Eleduwa fun wọn.
Muyiwa Ademola
Muyiwa Ademola naa sọrọ lori awọn fiimu to ti jade lati ọwọ awọn gbajugbaja oṣere Yollywood.
Oríṣun àwòrán, Other
Ọ kọkọ sọ nipa fiimu ti akọle rẹ jẹ ''Survival of Jelili'' eleyi to pe ni fiimu to le dẹrin pa oṣonu.
Bakan naa lo sọrọ nipa fiimu Ajẹbi'dan eleyi to jẹ iṣẹ ọwọ Adekola Odunlade.
Ibrahim Chatta
Gbajugbaja oṣere Ibrahim Chatta naa sọ nipa fiimu ti akọle rẹ jẹ ''Survival of Jelili'' eyi to jẹ iṣẹ ọwọ Femi Adebayo
Oun naa jẹri sii pe ẹrin arin takiti wa ninu ere ọhun eyi ti yoo jade lọjọ kẹfa oṣu kejila.
Ijebu
Gbajugbaja osere tiata, Ọlatayọ Amokade ti gbogbo eeyan mọ si Ijẹbu, ṣalaye iha ti idile rẹ kọ si isẹ to n se.
Ijẹbu, lasiko to n kopa lori eto ifọrọwanilẹnuwo lori BBC Yoruba salaye pe, inu iyawo oun kii dun si eebu ti akẹẹgbẹ oun, Ọdunlade Adekọla maa n bu oun lasiko ti awọn ba n sere tiata.
Oríṣun àwòrán, Ijebu
Ijẹbu ni bi o tilẹ jẹ pe eebu naa ko ni itumọ kankan si oun nitori ere lasan ni, amọ iyawo oun ko fi bẹẹ nifẹ si iru iwa bayii.
Omoyele Sowore: Femi Falana ní òfin ilé-ẹjọ́ ilẹ̀ òkèrè nìkan ni ìjọba lè pamọ́
Oríṣun àwòrán, Facebook/Omoyele Sowore
Yoruba ni ti ina ko ba tan laṣọ, ẹjẹ kii tan leekanna.
Ajafẹtọ, Deji Adeyanju lo sọ pe ko si awawi kankan mọ fun ajọ ọtẹlẹmuyẹ DSS lati ma fi Omoyele Sowore silẹ lọjọ Iṣẹgun.
Deji to jẹ ọkan lara awọn ajijagbara atawọn agbẹjọro ti wọn lọ si ile iṣẹ ajọ DSS lọjọ Satide, ṣalaye pe bi wọn ba tun kọ lati fi Sowore silẹ lọjọ Iṣẹgun, awọn ko ni dẹkun lilọ si ọfiisi wọn.
Deji ni ''o jẹ iyalẹnu pe ajọ DSS sọ pe ko si ẹni to yoo gba Sowore mi ko jẹ kawọn fi silẹ lahamọ lọsẹ to kọja.''
Deji Adeyanju fikun ọrọ rẹ pe oun nigbagbọ pe ajọ DSS yoo fi Sowore silẹ lahamọ lọjọ Iṣẹgun.
O ni bi ijọba ti n ṣe Sowore jẹ ibanujẹ fun awọn ọmọ Naijiria, nitori ọrọ naa ko ye ẹnikan ohun to jẹ ki ijọba kọ lati paṣẹ ileẹjọ mọ.
Sowore ati Olawale Bakare lajọ DSS ti mọle lẹyin ti Sowore gbimọ lati ṣagbatẹru iwọde #RevolutionNow lati fẹhonu han bi nnkan ṣe ri lorilẹede Naijiria.
Àṣẹ ilé-ẹjọ́ ilẹ̀ òkèèrè nìkan ni ìjọba lè pamọ́ ṣùgbọ́n tàpá sí ti Nàìjíríà lórí Sowore
Gbajugbaja agbẹjọro ati ajafẹtọ ọmọniyan, Femi Falana ti woye pe o rọrun fun ijọba apapọ lati bọwọ fun aṣẹ ti ileẹjọ ilẹ okere ba fun un.
Amọ, Falana ni o rọrun fun ijọba bakan naa lati tapa si aṣẹ ile ẹjọ lorilẹede Naijiria.
Oríṣun àwòrán, Twitter/Presidency
Ọrọ ajafẹtọ, Omoyele Sowore ati Olawale Bakare ti ajọ ọtẹlẹmuyẹ DSS kọ lati fi silẹ lahamọ lẹyin ti ile ẹjọ paṣẹ pe ki ajọ naa fun wọn lominira lo fa sababi ọrọ yii.
Falana fi ọrọ ile iṣẹ P & ID ṣapejuwe ninu eyi ti ijọba ti tete sanwo miliọnu to le marun un laadọrun un naira lẹyin ti ile ẹjọ ilẹ Gẹeṣi kan paṣẹ pe ki ijọba Naijiria sanwo naa laarin ọjọ mẹrinla ṣapejuwe.
Agbẹjọro Falana ni kiakia ni ijọba sanwo naa gẹgẹ bi ile ẹjọ giga Her Majesty's High Court niluu London ti pa a laṣẹ.
Lọsẹ to lọ nile ẹjọ paṣẹ idasilẹ Sowore ati Bakare lahamọ ajọ DSS ṣugbọn wọn kọ lati fi wọn silẹ, ohun ti wọn sọ ni pe awọn ko ri ẹni ti yoo gba awọn mejeeji nigba tawọn fẹ fun wọn lominira.
Amọ, Falana fesi sọrọ naa pe wakati mẹrin lawọn agbẹjọro fi duro ni ọfiisi ajọ DSS ṣugbọn wọn ko fi wọn silẹ.
Bakan naa lawọn agbẹjọro, awọn ajijagbara atawọn alatilẹyin Sowore tun lọ si ile iṣẹ ajọ DSS lọjọ Abamẹta, ṣugbọn gbogbo akitiyan wọn lati gba Sowore ati Bakare, pabo lo ja si.
Ìbànújẹ́ ló pọ̀ nínú òṣèlú Nàìjíríà tórí a ti lo Pásítọ̀, Wòlìí, Ọ̀jọ̀gbọ́n
Eid Maulud: Ẹ̀yin mùsùlùmí, ẹ tẹ̀lé ẹ̀kọ́ Ànọ́bì, ẹ gbógun ti ìgbésùnmọ̀mí
Oríṣun àwòrán, Instagram/Bashir Ahmad
Aarẹ Muhammadu Buhari ti rọ awọn musulumi lati maa tẹle awọn apẹrẹ ati ilana Anọbi Muhammad bi wọn ṣe n ṣe ayẹyẹ ọjọ ibi rẹ.
Aarẹ Buhari sọrọ yii ninu iṣẹ ikini ku ọdun ọjọ ibi Anọbi to fi ranṣẹ sawọn ọmọ Naijiria bi wọn ṣe n ṣọdun.
Buhari rọ awọn obi musulumi lati ma jẹ kawọn alakatakiti ẹsin tan ọmọ wọn jẹ darapọ mọ ẹgbẹ igbesunmọmi.
Aarẹ Buhari ni eleyi lewu pupọ nitori yoo ba wọn laye jẹ, yoo si tun ba ọjọ iwaju wọn jẹ.
Aarẹ tun rọ awọn musulunmi lati maa fifẹ han si ọmọlakeji wọn, ati pe ki wọn tun maa lepa alaafia ati isọkan orilẹede Naijiria.
Buhari sọ pe ''pipa alaiṣẹ, jiji awọn akẹkọọ gbe ati ṣise igbeyawo tipatipa fun wọn tako apẹrẹ rere ati ẹkọ Anọbi Muhammad.''
Aarẹ Buhari ni ''igbesunmọmi dabi aarun jẹjẹrẹ, ti eeyan ba kuna lati dẹkun rẹ nibẹrẹ pẹpẹ, yoo di nla.''
Buhari ni iyi ati ọla to ga ju lọ tawọn musulumi le fun Anọbi ni titẹle awọn apẹrẹ to fi lelẹ.
Ìbànújẹ́ ló pọ̀ nínú òṣèlú Nàìjíríà tórí a ti lo Pásítọ̀, Wòlìí, Ọ̀jọ̀gbọ́n
Aàrẹ, igbákejì aàrẹ àti aàrẹ ilé ìgbìmọ̀ aṣòfin kọ̀wé fipò sílẹ̀ lọ́jọ́ kan náà
Oríṣun àwòrán, Reuters
Awọn oluwọde n pariwo a dupẹ pe o ṣeeṣe ni bi wọn ṣe gbọ pe Aare Morales kọwe fipo silẹ.
Aarẹ Evo Morales to n tukọ orilẹ-ede Bolivia ti kọwe fipo silẹ.
Eyi waye lẹyin opọlọpọ ọsẹ ti awọn ọmọ orilẹ-ede yii ti n ṣe iwọde o tó gẹ́ẹ lẹyin eto idibo wọn to waye loṣu to kọja.
Odun mẹrinla ree ti Aarẹ Morales ti n tukọ ijọba orilẹ-ede naa.
O ṣe ikede ikọwefiposilẹ yii lẹyin ti awọn ọmọ ogun ilẹ ọhun ni awọn ko ni ṣatilẹyin fun un mọ.
Olori awọn ọmọ ogun ilẹ Bolivia sọ fun aarẹ naa pe asiko ti to ko fipo silẹ lẹyin iwọde ti awọn ara ilu fi n ṣe lodi si esi idibo oṣu to kọja to tun kede aarẹ Evo ni aarẹ lẹẹkan sii.
Opọlọpọ awọn onwoye lo ni kudiẹ-kudiẹ wa ninu idibo naa ṣugbọn Aarẹ Morales ni sabaabi ni oun ṣe koungẹ iditẹ naa.
Yorùbá dùn Egypt: Bàálù méjì yóò kún tí ìjọba bá ṣèrànwọ́ láti kó wa kúrò ní Egypt
Oun ti aarẹ naa  sọ ni pe iditẹgbajọba lo ṣẹlẹ ati pe nitori wọn kọlu ile oun ni idi ti oun ṣe kọwe fipo silẹ bayii lati daabo bo ẹbi ati ara oun pẹlu awọn ọrẹ oun ninu iṣelu ni.
O ni oun mọ pe awọn jaguda lo lọ jo ile oun lẹyin idibo to kede oun gẹgẹ bii aarẹ lẹẹkan sii.
'Èmi gan máa ń béèrè lọ́wọ́ ara mi pé ta ni Wole Soyinka gangan'
Ninu ọrọ Aarẹ Evo Morales lori amohunmaworan lo ti parọwa fawọn oluwọde pe ki wọn dẹkun kikọlu ara wọn.
O ni ki wọn fopin si didana sun ile ati dukia awọn eniyan ti wọn si n kọlu ara wọn.
Alvaro Garcia Linera to jẹ igbakeji aarẹ Morales ati Adriana Salvatierra to jẹ olori ile igbimọ aṣofin orilẹ-ede ọhun naa ti kọwe fipo wọn silẹ pẹlu aarẹ.
Kat Watson to jẹ akọroyin BBC to wa nibẹ ṣalaye pe ọpọ eniyan lo n fidunnu wọn han ni La Paz pe opin de ba iṣejọba aarẹ Evo.
Niṣe ni wọn fọnka si igboro ti wọn yọ ayọ pe wọn bọ lọwọ iṣejọba rẹ ti wọn n tan imọlẹ ọjọ tuntun ati igba ọtun ni Bolivia.
'IBB da Abiola lẹ́yìn tó búra pẹ̀lú Quran'
Koko ti ọpọ ninu wọn n sọ nipe aarẹ Morales ni pe kii ṣe adari to ṣamulo idagbasoke iṣejọba awa ara wa daadaa.
Nigba ti awọn mii n sọ pe ko fi tawọn ara ilu ṣe rara ni gbogbo o din diẹ lọdun mẹrinla to fi tukọ orilẹ-ede naa.
Illegal Rehab Centre: A le ni ogójì tí wan n kó 'sinú ìyará kékeré kan níle Ọlọrẹ
Lalẹ ọjọ idibo ni wahala ti kọkọ bẹrẹ bi wọn ti ṣe n ka esi idibo ni eyi ti awọn eniyan ti kọkọ n pariwo pè madaru pọ ninu esi ti wọn n ka.
O kere tan awọn mẹta ni wọn ti jalaisi nigba ti ọrọ naa di nla mọ awọn agbofinro lọwọ.
Abajade esi idibo naa fihan pe aarẹ Morales ni ida mẹwaa ninu ọgọrun un idibo naa ju akẹgbẹ rẹ to sun mo ọ lọ.
Ìbànújẹ́ ló pọ̀ nínú òṣèlú Nàìjíríà tórí a ti lo Pásítọ̀, Wòlìí, Ọ̀jọ̀gbọ́n
Lọjọ Aiku ni Organisation of American Ststes to jẹ onwoye lasiko idibo naa ni awọn ni ẹri to fihan pe madaru wa ninu idibo naa ti ko le jẹ ki wọn bu ontẹ lu esi idibo naa.
Ogagun agba Williams Kaliman to jẹ adari awọn ọmọ ogun ilẹ naa gba aarẹ ni imọran lati kọwe fipo rẹ silẹ.
Lọdun 2006 ni Evo Morales kọkọ gba ipo aarẹ ni orilẹ-ede Bolivia.
Loṣu kẹwaa ọdun yii lo tun dije lẹẹkẹrin lati dije dupo aarẹ ilẹ Bolivia lẹẹkan sii.
Oríṣun àwòrán, AFP
Avo Morales kede ikọwefiposilẹ rẹ lori amohuinmaworan
Eyi waye lẹyin ti wọn wọgile ipinnu ileẹjọ ilana ofin ilẹ Bolivia lati ṣatunṣe si odiwọn iye ọdun ti aarẹ orilẹ-ede naa le lo.
Lọdun 2016 ni ọpọ eeyan dibo lodi si gbendeke iye ọdun ti aarẹ le lo ṣugbọn ẹgbẹ oṣelu aarẹ Morales gbe ọrọ naa pada sile ẹjọ ilana ofin to si fun un ni idajọ.
Òwò ẹrú ọmọdé àti obìnrin lórí ayélujára
Burna Boy yí ìpinnu padà, yóò kópa ní àjọ̀dún orin lórílẹ̀-èdè South Áfríkà
Oríṣun àwòrán, Twitter/burnaboy
Burna Boy
Gbajugbaja olorin takasufe ọmọ Naijiria Burna Boy ti ni oun yoo jọwọ lara owo tawọn ba pa nibi ode orin ti yoo waye lorileede South Africa fawọn to farakasa Xenophobia.
Loju opo Twitter rẹ ni akọrin yii ti fi ọrọ naa hande.
Ṣaaju asiko yii, Burna Boy ti leri pe oun ko ni fẹsẹ tẹ ilẹ South Afrika nitori idẹyẹsi sawọn ọmọ ilẹ Afrika mIiran to n waye nibẹ.
Ìbànújẹ́ ló pọ̀ nínú òṣèlú Nàìjíríà tórí a ti lo Pásítọ̀, Wòlìí, Ọ̀jọ̀gbọ́n
Ajọdun orin ti o fẹ kopa yii ni yoo jẹ igba akọkọ ti Burna Boy yoo tẹ South Afrika lati ọdun 2017.
Lara awọn ti wọn yoo jijọ fi orin bẹnu atẹ lu idẹyẹsi awọn eeyan ilẹ miran ní South Afrika la ti ri awọn akọrin bi Kwesta Jidenna ati Busiswa.
Akori ajọdun orin naa ti yoo waye lọjọ kẹtalelogun oṣu Kọkanla ni ''Afirika, pawọ pọ''
Oyo Governorship Appeal: Ìdájọ́ Ilé ẹjọ kò sọ pàtó ẹní tó jáwé olúborí láàrín Makinde àti Adelabu
Oríṣun àwòrán, Google
Ti ile ẹjọ kan ko ba wa fidi ọrọ mulẹ ni pato nipa idajọ ohun ta gbe lọ si iwaju rẹ, kini o yẹ ka ṣe?
Bẹẹ lọrọ ri pẹlu ohun to ṣẹlẹ nile ẹjọ kotẹmilọrun nilu Ibadan to n gbẹjọ laarin Gomina Seyi Makinde ati akẹgbẹ rẹ ti wọn jọ du ipo Gomina, Adebayo Adelabu ti ẹgbẹ oṣelu APC.
Koko ọrọ to jade nipa idajọ ti adajọ ẹlẹni mẹta ile ẹjọ naa fi lelẹ ni pe awọn fọwọ rọ idajọ ile ẹjọ igbimọ to n gbẹjọ idibo sẹgbẹ kan ṣugbọn ile ẹjọ ko sọ oju abẹ niko boya Makinde tabi Adelabu lo jawe olubori.
Ni ti Adelabu, niṣe ni o n sọ pe ki ile ẹjọ wọgile esi idibo to gbe Makinde wọle ki o si kede oun gẹgẹ bi Gomina.
Amọ bayi ti ile ẹjọ naa ko ti sọ boya oun ni Gomina tabi Makinde ṣi ni, ohun to kan fawọn mejeeji ni ki wọn gba ile ẹjọ to ga julọ lorile-ede Naijiria lọ lati yananan ọrọ lori idajọ ile ẹjọ kotẹmilọrun.
Loju opo Twitter, ohun ti ile ẹjọ yi sọ ti n mu iriwisi ọtọọtọ wa tawọn eeyan si n gbiyanju lati tu ohun ti ile ẹjọ sọ bo ṣe ye wọn mọ
Koda awọn kan ti n fi ohùn ranṣẹ si aarẹ Buhari ati ẹgbẹ APC pe ki won ma ṣe dasi ọrọ naa ti wọn o ba fẹ kan abuku.
Bi ọrọ naa ti ṣe wa bayi,ohun to daju ni pe ile ẹjọ ko sọ ẹni to jawe olubori bẹẹ si ni ko kede pe wọn yoo tun ibo miran di.
Bi a ba ni ka tẹle ọrọ tawọn agbẹjọrọ oludije mejeeji yi sọ bayi, aye ṣi wa nilẹ fawọn lati kọri si ile ẹjọ to ga julọ lati sọ bi iṣu ṣe ku, bọbẹ si ti ṣe pa.
Koko kan ṣoṣo to hande lori ọrọ ẹjọ yii ni pe Ile ẹjọ giga lo maa yanjuẹ.
'IBB da Abiola lẹ́yìn tó búra pẹ̀lú Quran'
Border Closure: Ilé aṣòfin àpapọ̀ pàṣẹ fáwọn àṣọbodè láti fààyè gba èpo lẹ́nu bodè
Oríṣun àwòrán, @anaedoonline
Yoruba ni agba kii wa lọja, ki ori ọmọ tuntun wọ, eyi lo mu kile asofin apapọ ilẹ wa tete dasi ọwọn gogo epo pẹtirolu to n waye lawọn eti bode Naijiria.
Nibi ijoko wọn to waye loni, awsn asoju-sofin ti pasẹ fun ileesẹ asọbode ilẹ wa pe ko gbẹsẹ kuro lori ofin to fi de gbigbe eroja epo rọbi lọ si awsn ilu to wa leti bode orilẹede yii.
Igbesẹ yii lo waye lẹyin ti iroyin gbalẹ kan pe awọn ilu to wa leti bode ilẹ wa lo ti n jẹrora ọwọn gogo epo pẹtirolu atatawọn eroja epo rọbi miran.
Nigba to n gbarata lori isẹlẹ yii, Alaga ajọ to wa fun akoso eto ibaraẹnisọrọ ni Naijiria, NCC, Umar Danbatta kede pe ofin naa ti n ni ipa ti ko dara lori awọn ọmọ Naijiria to n gbe lawọn ẹnu bode.
Oríṣun àwòrán, @anaedoonline
Lero ti Asofin Sada Soli lati ipinlẹ Katsina, o ni asẹ ti ileesẹ asọbode pa ọhun kọja agbara ti ofin gbe le wọn lọwọ, to si kesi ile alti pasẹ fun ileesẹ assbode pe ko wọgile ofin to se naa.
Awọn asofin yoku to da si ọrọ naa ni o yẹ ki wọn maa fi oju aanu sisẹ wọn, ti wọn si sapejuwe ofin to de epo gbigbe lọ sẹnu bode bii ofin onikumọ.
Oríṣun àwòrán, @anaedoonline
A gbọ pe aye nira fun wọn nibẹ to bẹẹ ti wọn fi n ra lita epo pẹtirolu kan ni ẹgbẹta naira.
Koda, awọn ileesẹ ẹrọ ibaraẹnisọrọ naa si ti n pariwo pe idakureku eto ibaraẹnisọrọ yoo wa lawọn agbegbe ọhun, ti ko ba si eroja epo ni arọwọto wsn lawọn agbegbe naa.
Ọwọn gogo epo bẹntiro ti gbode kan bayii lawọn awujọ to sun mọ ibode orilẹede Naijiria sawọn orilẹede miiran nitori ibode Naijiria to ṣi wa ni titi pa.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Niṣe lawọn olugbe awọn ilu to wa leti bọda n ke lẹyin ti jala epo kan di ẹgbẹta naira dipo naira marundinlaadọjọ, eleyi waye nitori bi ijọpa apapọ ṣe fi ofin de gbigbe epo lọ si awọn agbegbe ti ko ju ogun kilomita lọ si ibode Naijiria sawọn orilẹede mii.
Awọn ilu to n foju wina ọwọn gogo epo yii wa ni ipinlẹ Ogun, Eko, Adamawa, Katsina ati ipinlẹ Sokoto.
Wo Bullet, ọmọ ọdun mẹjọ tó fẹ́ lùwẹ̀ wọ Olympics
Ọjọbọ ọsẹ to lọ ni ọga ile iṣẹ aṣọbode, Hameed Ali kede igbesẹ ijọba to fi ofin de gbigbe epo lọ si awọn agbegbe ti ko ju ogun kilomita lọ si ibode Naijiria si awọn orilẹede mii.
Ihunbo, Ilase, ajegunle, Idiroko ati Agosasa nijọba ibilẹ Ipokia lawọn ilu ti ọwọn gogo epo ti gbode kan nipinlẹ Ogun.
Bakan naa la gbọ pe ọwọn gogo epo mu awọn awakọ to lawọn ile epo ni Seme ''border'' nipinlẹ Eko lọjọ Aje.
Ohun ti a gbọ ni pe ile epo meji pere lo n ta epo ninu awọn ile epo to ju meje lọ nibode Seme.
Iwadii tun fihan pe ọpọ ile epo ni ijọba ti ti pa lagbegbe Ipokia nitori ko ju ogun kilomita lọ si orilẹede Benin Republic lẹyin ti ijọba ti ibode Naijiria.
Awọn ọkọ agbepo to le ẹgbẹrun un kan to fẹ gbepo kọja ni ibode Naijiria sawọn orilẹede to wa layika ni a gbọ pe awọn ile iṣẹ aṣọbode ti gbẹsẹ le ti wọn ko si jẹ ki wọn kọja.
Báwo ni Nàìjíríà ṣe gboyè orílẹ̀èdè tí ìtànkálẹ̀ òtútù ìgbá àyà tí pọ̀ jù lọ?
Oríṣun àwòrán, AFP
Ajọ to n mojuto eto ẹkọ awọn ọmọde lagbaye ti sọ pe orileede Naijiria ni ọwọja otutu igba aya ti peleke ju lọ lagbaye.
Ninu iwadi kan ti wọn ṣẹṣẹ gbe jade, ajọ naa to jẹ ẹka ajọ iṣọkan agbaye ṣalaye pe ida mọkandinlogun iye iku ọmọde ni Naijiria lọdun 2018 lo tatara otutu igba aya wa.
Ajọ ọhun tẹsiwaju pe ohun to saba ma n fa aisan yii ni aijẹun daada, eefin latara eedu ti wọn fi n dana ninu ile to fi mọ fifa atẹgun buruku simu layika.
Aisan otutu igba aya yii a maa ṣakoba fun ẹdọ foro ti ọyun a si maa ko si inu rẹ.
Ninu iwaadi ti wọn gbe jade, lagbaye lọdun 2018, otutu igba aya pa ọmọ tọjọ ori wọn ko to ọdun marun un to le ni 800,000.
Lara awọn ọmọ to ba aisan yii lọ la ti ri o kere tan ọmọ Naijiria 162,000  to tunmọ si pe ọmọ 443 lo n ku lojumọ kan ti mejidinlogun a si maa ba aisan yii lọ ni wakati kọọkan.
Jálà epo bẹntiróò di N600 nítorí ibodè títìpa
Wo Bullet, ọmọ ọdun mẹjọ tó fẹ́ lùwẹ̀ wọ Olympics
Oríṣun àwòrán, AFP
Ninu ọrọ adele aṣoju ajọ Unicef ni Naijiria, Pernille Ironside, o sọ pe ''aisan to le la ẹmi lọ ni otutu igba aya jẹ ti o si ti mu ọpọ ẹmi awọn ọmọde lọ ni Naijiria toun ti pe o ṣe dena.''
O fikun ọrọ rẹ pe pupọ awọn ileeṣẹ ati ẹka to n mojuto ilera lo ti gbagbe nipa rẹ ṣugbọn asiko to bayi lati mu ayipada wa''
Yatọ si orileede Naijiria awọn orileede mẹrin miiran ni itankalẹ aisan yi ti pakasọ.
Awọn orileede naa ni India, Pakistan, DR Congo ati Ethiopia.
#VerifiedTacha: Àwọn mánigbàgbé tí Olùdásílẹ̀ Twitter Jack Dorsey ṣé làsìkò ìrìnàjò rẹ sí Áfríkà
Oríṣun àwòrán, twitter.com/jack
Ọjọ keje oṣu Kọkanla ni Jack Dorsey, oludasilẹ ileeṣẹ Twitter balẹ biba s'orileede Naijiria ni itẹsiwaju irinajo rẹ si awọn orileede kan ni Afrika.
Gẹgẹ bi o ti ṣe sọ saaju, o ni ohun yoo ṣepade pẹlu awọn oniṣowo imọ ẹrọ ọlọdani kaakiri ilẹ Afrika loṣu Kọkanla ọdun 2019.
Lasiko to wa ni Naijiria, o ba awọn eeyan orisirisi ṣe ipade koda awọn miran tun ri ore ọfẹ anfaani lati ba a sọrọ nipa mimu idagbasoke ba iṣẹ wọn.
Ile ẹkọ fasiti ilu Eko wa lara awọn ibi to kan si ti o si jomitoro ọrọ pẹlu awọn alaṣẹ ati akẹkọ nibẹ.
Yatọ si Unilag, o tun ṣe ipade pẹlu awọn onikarakata owo ori ayelujara Bit Coin.
Oríṣun àwòrán, twitter.com/jack
Bi o ti ṣe n kaakiri, bẹẹ ni o n fi aworan awọn ipade rẹ han loju opo Twitter
Awọn ti Mercy BB Naija naa rawọ ẹbẹ si Jack Dorsey
Lasiko abẹwo rẹ, oju opo rẹ kun fun orisirisi ibeere ṣugbọn ọkan to jọ bi irawọ ẹbẹ si ni eyi tawọn ololufẹ Mercy, olukopa BBNaija kọ si i pe ki o tẹle Mercy lori Twitter.
Ṣaaju ni Jack ti tẹle Tacha lori Twitter tawọn ololufẹ Tacha si n dupẹ lọwọ rẹ pe o tẹle e.
Nigba ti ilẹ ọjọ Iṣẹgun yoo fi mọ, ariwo pe Jack Dorsey fi ontẹ jan Tacha ti bi #VerifiedTacha loju opo Twitter ti awọn ti Tacha si n ki ara wọn ku orire.
Eyi to jẹ babanbari lasiko irinajo rẹ si Naijiria ni igba to gbiyanju lati jo Soapy.
Arakunrin kan ti wọn n pe orukọ rẹ ni Real_jaeflex lo fi fidio naa soju opo Twitter ti a si ri Jack Dorsey ati Minisita feto ọrọ Aje ni Naijiria tẹlẹ ri Ngozi Okonjo Iweala ti wọn n fi ẹsẹ ra ijo pẹlu orin Naira Marley.
Irinajo rẹ tẹsiwaju si orileede Ghana lẹyin to dagbere o digba kan na fun Naijiria.
Ṣé lóòtọ́ ni Eko dá yàtọ̀ l'Áfíríkà?
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ere mẹta ti ilu Eko
Akọle orukọ ṣe ṣe pataki lorilẹede Naijiria ti wọn si maa fi n da awọn to di ipo nla nla mu mọ.
Ni ti aaye, ilu Eko ni ipinlẹ to kere ju ni Naijiria ṣugbọn nkankan ti ko ni ninu aaye yii, o ti fi di i ninu ara rẹ. Ni kete ti ẹ ba ti jade ninu papakọ ofurufu Murtala Muhammed lẹ o ti maa ri agbara to gbilẹ ninu ilu yii.
Pẹluu wi pe wọn ti fi ilu Abuja rọpo rẹ gẹgẹ bii olu ilu orilẹede Naijiria lọdun 1991, oun ṣi mi wọn n pe ni ilu nla Naijiria to ṣe pataki ju - ilu ti wọn ti n ja a mọra wọn.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
"Gbogbo ọmọ Naijiria jakejado orilẹede yii ati pẹlu oniruuru iṣẹ ti wọn yan laayo lo maa n tu kẹti kẹti lọ si ilu Eko tii adape orukọ rẹ n ṣe ""Ibudo Titayọ"" lati wa bi ayanmọ wọn yoo ṣe yan didara."
Ilu yii ni ọpọlọpọ ileeṣẹ kalẹ si latori awọn ẹka ileeṣẹ t'ọjọ ori ti lọ lori wọn bii awn ileeṣẹ to n pese atawọn ile ifowopamọ titi dori awọn to ṣe tuntun bii ti imọ ẹrọ. Ibẹ naa ni ibudokọ oju omi orilẹede yii meji pataki fi ṣe'le ti ọpọlọpọ owo si ti ngberi soke fun katakara latori iwe, iṣẹ na to fi mọ oriṣiriṣi ẹrọ amayedẹrun.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Olutawe ni Lagos Island
L'Eko, a ni aṣa didi oniṣẹ ara ẹni lọna to lagbara tẹ o si le dede ri nibomiiran, Funmi Oyatogun to jẹ oludasilẹ TVP Adventures ti wọn ti n ṣe irinajo igbafẹ sọ.
"O ni ""l'Eko, gbogbo eniyan lo n gbiyanju ati kọ ohun to kan, ati wa ojutu si iṣoro to ba tun yọju, pipese ohun elo tuntun sita gbogbo eyi si lo n fi kun ijafafa ati agbara ilu nla naa""."
Ẹmi Pọpọṣinṣin ati wọ sibi-sọhun
Ni Eko, atẹgun ib a maa ṣe bi ẹni nipọn loju ofurufu pẹlu ariwo. Afi bii orin adakọ ni fifọn awọ́n ọkọ, ẹrọ amunawa atawọn eeyan to n ba iṣẹ oojọ wọn kiri yala pẹlu ẹsẹ, gigun kada, ọkọ tabi awọn bọọsi danfo to pupa rusu rusu to ti di ami idamọ ilu nla naa tabi ti awọn bọọsi gigun ti igbalode, BRT. Gbogbo igba shaa lawọn ara Eko to to miliọnu mọkanlelogun eniyan n wa lọna.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ọja ati sunkẹrẹ fakẹrẹ ọkọ ni Eko
Iwadii afojusun fi han pe onka iye eeyan to wa ni Eko yoo to pọ sii kiakia ti yoo si fẹrẹẹ to miliọnu mejidinlaadọrun titi ọdun 2100 eyi to n da kun aisi awọn nkan amayerọrun ṣugbọn ni ti wọn, awọn ara Eko ko ki n kaarẹ.
Awọn eeyan to wa l'Eko da yatọ, ni Chiamaka Ọbuekwe to jẹ oludasilẹ founder of The Social Prfect Tours. ẹmi pọpọṣinṣin wa nibẹ. Wọn lagbara, wọn ja fafa wọn si jẹ olufẹ faaji ati akonimọra
Oríṣun àwòrán, Getty Images
"Ọkunrin kan n ra ẹran sisun ti wọn n pe ni ""Suya"""
Fun idi eyi, kii ṣe ibi kan to maa n dede ti eeyan sinu wahala bọ sibi-sọhun rẹ. Ẹmi iyara wa nibẹ ati iwa keeyan tete maa le fara mọ ibi kan ki o si le tete ba Eko yi pẹlu ohunkohun to ba gbe wa.
'Olu Ilu Aṣa'
Ṣugbọn kii ṣe ọrọ katakara nikan la mọ Eko si, o ti pẹ ti wọn ti n ri Eko gẹgẹ bii olu ilu Naijiria fun aṣa eyi si jẹ iyi to ti n fun Eko lagbara papaa ninu ẹka sinima, oge ati ori kikọ ni Naijiria.
Arinrinoge Aduke Shitta-Bey
Nollywood, ileeṣẹ fiimu to tobi ju lagbaye ni olu ileeṣẹ rẹ nibi bẹẹ si ni to ba ti n sun mọ ipari ọdun ni ọpọlọpọ afihan nkan idaraya maa n jẹ jade gidi gan ti Eko si maa n jẹ ibudo fun ọpọlọ́pọ ayẹyẹ mọ eto.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Awọn onijo Femi Kuti n da awọn eeyan lara ya ni Afrika Shrine, Eko
"Oun ṣi ni ilu to ja fafa ju ti mo ti ri nilẹ adulawo, Oyatogun ni oun lo lagbara ju ninu aṣa, ṣiṣe ayẹyẹ ati inawo bi wọ́n si ṣe maa n ṣe ajọyọ da yatọ si awọn ilu miiran ni Afirika.
O ò lè wà ni Eko kí ayé sú ọ """
Inawo tun jẹ ohun kan ti wọn mọ Eko fun ati igbe aye ibẹ laṣalẹ, ara ọtọ ni. Ko si igba ti kii si ode ariya kan tabi omiran lati lọ, ile ijo, atawọn ibudo igbadun ko gbẹyim plu oniruuru awọn gbajugbaja olorin bii Burna Boy, Wizkid, Orin Fela Kuti abi meloo lẹ fẹ ka - gbogbo rẹ lẹ o ri ni Eko.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
"awọn ololufẹ n jo ni ""Afrika Shrine"""
"Obuekwe gba pe ""O o le wa ni Eko ko su ẹ lai lai"""
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Olorin takasufee M.I
Ṣugbn bi o ko ba kii ṣe ni to fẹran ode ariya, to o si nifẹẹ aye kole kole, iru ohun too fẹ naa wa l'Eko. Okun, ibi iṣere, ibudo igbafẹ ati bẹẹ bẹẹ lọ.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Obinrin kan n rin ninu igbo ni ibudo igbafẹ Lekki
Makinde vs Adelabu: Ogunlọ́gọ̀ èrò ṣàbẹ̀wò àtìlẹyìn sí Seyi Makinde
Oríṣun àwòrán, @seyiamakinde
Gomina ipinlẹ Ọyọ, Onimọ ẹrọ Sey Makinde gbalejo obitibiti ero nileesẹ ijọba ipinlẹ Ọyọ loni, lati wa se abẹwo awa lẹyin rẹ si.
Abẹwo naa lawọn eeyan yii se pẹlu oniruuru lati safihan ifẹ ti wọn ni si gomina Seyi Makinde pe gba gba gba lawọn wa lẹyin rẹ lẹyin idajọ tileẹjọ kotẹmilọrun da lọjọ Aje.
Nigba to n gbalejo awọn ọgọọrọ eeyan naa, Gomina Seyi makinde ni se ni ẹgbẹ oselu APC dabi afomọ ti ko ni gbongbo, to si n wa gbongbo ti yoo dirọ mọ pẹlu asẹ ile ẹjọ.
O fikun pe ohun to n waye ni ipinlẹ Ọyọ ko lee dabi awọn isẹlẹ to ti waye sẹyin nipinlẹ Ọsun ati Ekiti nibi ti idajọ ile ẹjọ ti le ijọba to wa lori aleefa kuro.
Oríṣun àwòrán, @seyiamakinde
Makinde ni abajade esi ibo gomina to waye lọjọ kẹsan osu kẹta ọdun 2019 fihan pe ẹgbẹ oselu PDP jẹ itẹwọgba araalu jakejado ipinlẹ Ọyọ, ti wọn si ti kẹyin si ẹgbẹ oselu APC.
O wa fọwọ gbaya pe mimi kankan ko mi oun lori idajọ naa, ti oun si n ba isẹ oun lọ gẹgẹ bii gomina, to si rọ awọn eeyan ipinlẹ Ọyọ lati bomi suuru mu.
Oríṣun àwòrán, @seyiamakinde
"Se ibi yii jọ Ọsun abi Ekiti, wọn fẹ ba aseyẹ wa jẹ. Ko si ohunkohun to sẹlẹ si asẹ tẹ gbe le mi lọwọ lati maa dari yin, ti wọn ba sọ pe awọn jawe olubori nile ẹjọ, ki lo de ti wọn ko se wa gba akoso ile ijọba laarọ oni?'
Ibi gbogbo yika ipinlẹ Ọyọ ni wọn ti kọ wọn. Wọn kọ wọn ni Ibadan, Ọyọ, Ibarapa, Oke Ogun ati Ogbomosọ, ki lo tun wa ku ti wọn fẹ se."""
Oríṣun àwòrán, @seyiamakinde
Makinde ni kawọn eeyan ipinlẹ Ọyọ mase mikan rara, tori ẹgbẹ APC kan n wa ọna ti ko fi ni parun ni.
Oríṣun àwòrán, Facebook/Seyi Makinde
Ọrọ n ba moko moro bọ lori idajọ ile ẹjọ kotẹmilọrun to waye lọjọ Aje lori awuyewuye ibo gomina ipinlẹ Oyo.
Iyalẹnu ni idajọ ile ẹjọ kotẹmilọrun ọjọ Aje fun ọpọ eeyan lẹyin tawọn adajọ sọ pe Gomina Seyi Makinde jawe olubori ninu idibo lọna to tọ ṣugbọn ile ẹjọ wọgile idajọ igbimọ to n ri si awuyewuye idibo gomina nipinlẹ naa.
Gbajugbaja agbẹjọro, Jiti Ogunye to ba BBC Yoruba woye pe idajọ ile ẹjọ kotẹmilọrun ku diẹ kaato, ati pe o so ọlọgbọn kọ.
Ogunye ni ''idajọ aabọ ni igbimọ igbẹjọ ile ẹjọ kotẹmilọrun da nitori wọn ti ja irawọ Gomina Makinde lẹyin ti wọn wọgile idajọ ile ẹjọ kotẹmilọrun akọkọ ti wọn si tun sọ pe ki Makinde ṣi maa tẹsiwaju ni ọfiisi rẹ.''
Agbẹjọro Ogunye ṣalaye siwaju sii pe Makinde to jẹ ọmọ ẹgbẹ PDP ati Adebayo Adelabu to jẹ oludije ẹgbẹ oṣelu APC to pe e lẹjọ lo le lọ si ile ẹjọ to ga julọ bayii.
Ọgbẹni Ogunye lati igba ti ọun ti bẹrẹ iṣẹ agbẹjọro, oun ko ri iru idajọ bayii ri, amọ o sọ pe oun yoo ṣe ayẹwo idajọ naa finifini lati mọ ni pato ohun to mu awọn adajọ da iru ẹjọ bẹẹ.
Agbẹjọro Ogunye sọ pe idajọ ara o rọkun ara o rọ adiyẹ ni idajọ yii maa ja si ti ọkan ninu Makinde tabi Adelabu ko ba gbe idajọ yii lọ si ile ẹjọ to ga julọ ni Naijiria.
Ẹwẹ, Gomina Makinde ti sọrọ pe mimi kan ko le mi oun lẹyin ti ileẹjọ ti sọ pe k'oun tẹsiwaju iṣẹ oun gẹgẹ bii gomina ipinlẹ Oyo.
Ondo Kidnap: Iléeṣẹ́ ọlọ́pàá ní òun ń ṣa ipá láti rí ọmọ tó sọnù náà
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ìyá ọmọ náà ni àwọn lọ sí ilé ìjọsìn ní òun fi ọmọ sí ibi tí àwọn ọmọdé ń wà, ní ọmọ bá di àwátì.
Ile isẹ ọlọpaa ni ipinlẹ Ondo ti ni iwadii ti bẹrẹ ni pẹrẹwu lori bi ọmọ ọdun kan se di awati ni ipinlẹ Ondo.
Iroyin naa ni pe ile ijọsin kan ni ilu Akure ni ipinlẹ Ondo ni isẹlẹ naa ti waye.
Iya ọmọ naa, Abilekọ Modupe Kolawole, ni oun mu ọmọ oun lọ si ile ijọsin 'So Titobi Re Praising Chapel,' naa ni aarọ ọjọ isinmi, amọ ti ọmọ naa si di awati.
Kolawole ni ẹka ibi ti awọn ọmọde ma n duro si ni oun fi ọmọ oun si, amọ lasiko isere, oun lọ sibẹ, oun si ri ọmọ naa to n jẹ pọfu-pọọfu, ti oun si beere ibi ti o ti ri, amọ lara awọn olukọ wọn sọ wi pe, ile ijọsin naa lo fun wọn ni ipanu ọhun.
Oríṣun àwòrán, @PoliceNG
Iya ọmọ naa ni lẹyin ẹsin ni oun wa pada lọ si ibẹ lati lọ mu ọmọ oun, amọ ti wọn ko ri mọ.
Alukoro ile isẹ ọlọpaa ni ipinlẹ Ondo, Femi Joseph to fi idi ọrọ naa mulẹ, ti ni awọn ti bẹrẹ igbiyanju lati ri wi pe ọmọ naa di awari.
Alukoro Ọlọpaa ni pasitọ ijọ naa lo wa fi ẹjọ sun ni agọ ọlọpaa, lẹyin ti baba ọmọ ati awọn onijagidijagan yawọ ijọ naa, ti wọn si bẹrẹ si ni ba nkan jẹ.
Ile isẹ ọlọpaa naa fikun wi pe iwadii ti bẹrẹ ni pẹrẹwu lati ri wi pe ọmọ naa di awari, ti awọn yoo si mu tọ iya ati baba rẹ lọ.
Edo State House of Assembly: Obaseki ní Oshiomole fẹ́ fipá gbàjọba lọ́wọ́ òun
Gẹgẹ bi ara igbesẹ ki ẹnikẹni ma joko ṣe ohunkohun ni ile aṣofin ipinlẹ Edo, gomina ipinlẹ naa, Godwin Obaseki ti paṣẹ ki wọn lọ yọ awọn orule ile naa igbimọ aṣofin naa lẹyin ti gomina ọhun atawọn agbofinro to fẹ fi tipa gbe ilẹkun ile nla naa ti pa ti gbe'na woju ara wọn.
Ni kete to le awọn agbofinro naa jinna lo paṣẹ pe kawọn kọngila wa bẹrẹ atunṣe ileegbimọ naa.
Ìdílé tí ọkọ da ọmọ síta tóríi ojú Búlùú tí wọ́n ní bá BBC sọ̀rọ̀
Gomina Ọbaseki ṣalaye fun BBC News latẹnu agbẹnusọ rẹ, Crusoe Osagie pe awọn alagbara oloṣelu kan pẹlu gomina ipinlẹ kan lorilẹede Naijiria ni wọn gbimọ pọ lati fẹ fi tipa gba ileegbimọ aṣofin ipinlẹ Edo ki wọn lee da rugudu silẹ ṣaaju idibo gomina to fẹ waye nibẹ lọjọ kọkandinlogun oṣu kẹsan ọdun 2020.
"Gẹgẹ bi gomina ipinlẹ Edo ṣe sọ, ""Adams Oshiomhole atawọn ọmọ ẹgbẹ oṣelu APC kan, pẹlu gomina Hope Uzodinma lo wa nidi iṣẹlẹ naa."
Wọn fẹ fi tipatipa gba akoso ile igbimọ aṣofin ipinlẹ naa eleyii ti wọn n tun ṣe lọwọlọwọ.
A gbọ pe wọn lọ rọ ayederu ọpa aṣẹ ile naa eyi ti wọn fi fẹ ya bo ile igbimọ aṣofin ti ko si lẹnu iṣẹ bayii nitori atunṣe to n lọ lọwọ nibẹ, lati gbọna ti ko tọ ṣe agbekalẹ ileegbimọ aṣofin miran lowurọ Ọjọbọ.
Gomina ipinlẹ Edo, olori ile aṣofin nibẹ, igbakeji olori ile aṣofin ipinlẹ naa wa ni ileegbimọ aṣofin naa lati ba igbesẹ naa jẹ.
Kìí ṣe ọmọbìnrin nìkan ni Ọlọ́run pàṣẹ fún láti pa ìbálé mọ́
Fun oṣu meji bayii inu gbọngan ipade nla to wa ni ileegbimọ aṣofin naa lawọn ọmọ ileegbimọ aṣofin ipinlẹ naa ti n ṣe ipade wọn.
Agbẹnusọ fun gomina ipinlẹ Edo, ọgbẹni Crusoe Osagie fi ẹsun kan gomina ana ni ipinlẹ naa, Adams Oshiomhole to tun jẹ alaga ana fun ẹgbẹ oselu APC lo n gbiyanju lati fi ipa gba ile aṣofin naa.
Ohun taa gbọ ni wi pe Gomina ipinlẹ Edo Godwin Obaseki ati igbakeji rẹ ti lọ tu awọn ọlọpaa to duro gbagba si ẹnu ọna ile igbimọ aṣofin ipinlẹ Edo ti wọn si n gbiyanju ati fi tipa tikuuku wọle.
Obitibiti ọlọpaa lo pejọpọ si Ile Igbimọ Aṣofin ipinlẹ Edo to wa ni ilu Benin.
Awọn ọlọpaa naa yabo ile igbimọ aṣofin naa pẹlu ọkọ wọn, ti wọn si duro wamuwamu sibẹ.
Eleyii n waye lẹyin wakati diẹ ti awọn aṣofin ipinlẹ naa yọ igbakeji abẹnugan ile igbimọ aṣofin ipinlẹ naa.
Igbakeji Kọmisọnna ọlọpaa ni ipinlẹ Edo, Ayoola Ajala lo dari awọn ọlọpaa naa.
Ẹgbẹ oṣelu PDP loju opo Twitter ni ẹgbẹ oṣelu APC n lọ awọn ọlọpaa naa lati da ẹru ati ipaya silẹ ni ilu naa nitori Gomina Obaseki n gbajumọ si nipinlẹ naa.
Aug 2018 ni ìgbìmọ̀ aláṣẹ APC ti ṣe ìpàdé kẹ́yìn, Oshiomole ti kùnà
Àwọn gómìnà lábẹ́ àsía ẹgbẹ́ òṣẹ̀lú All Progressive Congress (APC) tí kési alága ẹgbẹ́ òṣèlú APC, Adams Oshiomole lati pe ipade igbimọ alakoso ẹgbẹ́ tàbi kó kọ̀wé fipò sílẹ̀.
Awọn gómìnà naa sàlàyé pé, bi alága apapọ ẹgbẹ kò se lee pe àwọn àgbàgbà ẹgbẹ́ sí ìpàdé, ti n mú idàrúdàpọ̀ bá ètò ẹgbẹ́.
Oludari agba fun ẹgbẹ́ àwọn gomina, Salihu Lukman, lo kede bẹẹ nínú àtẹjáde kan to fọwọsí lọjọru nílùú Abuja.
Oríṣun àwòrán, @SPNigeria
"Àtẹjáde náà ni "" kò sí ohunkohun miran, to ba ti yàto si ìpàdé ẹlẹgbẹ́jẹgbẹ́ tàbi ìpáde àpérò gbogboogbo, to lee parí ǹkan to ti dàrú nínú ètò ẹgbẹ́"""
O sàn kí Oshiomhole bìkítà fún ilana ẹgbẹ́ to wa nínú iwe ofin ẹgbẹ́, láti pe ìpade àwọn èèkàn ẹgbẹ ki wọn lee sọ̀rọ̀ lórí gbogbo kùdìẹ̀kudiẹ̀ to n ba ẹgbẹ́ APC fínra, tàbi ko gba pé òun ko kunju òṣùwọ̀n láti tukọ ẹgbẹ̀, ko sì kọ̀wé fipò sílẹ̀.
"Lukman sàlàyé pé, o pọ̀ndandan ki Oshiomole kọwe fipo rẹ silẹ, paapaa pẹ̀lú ìròyìn to n jáde láti ìpínlẹ̀ Edo pé, àwọn oloye ẹgbẹ̀ APC ti díbò ""a ò ní ìgbàgbọ́ nínú rẹ̀"" fun Oshiomhole."
Oríṣun àwòrán, @KBStGovt
Dipo ka gbajumọ ọna ti APC yoo fi bori ninu awọn eto idibo to wa nilẹ, n se la n foju tẹnbẹlu ara wa. Gbogbo awọn ami buruku yii to waye ni ipinlẹ Zamfara, Rivers, Bauchi ati Adamawa lo tun fẹ suyọ abyi ni Bayelsa.
Lukman fikun pe o se ni laanu pe igbimọ alakoso ẹgbẹ to yẹ ko wa ojutu sawọn isoro yii lo fẹ dabi eyi ti wọn ti so rọ. Osu kẹjọ ọdun 2018 ni wọn ti se ipade kẹyin, ti ẹka alasẹ to yẹ ko maa se amusẹ ipinnu ti igbimọ alakoso ba se, ti wa ja agbara gba mọ igbimọ alakoso ẹgbẹ lọwọ.
Oríṣun àwòrán, Jubril A. Gawat
Ọpọ onwoye gbagbọ pe omi n bẹ lamu fun Oshiomole lori iṣọkan ẹgbẹ oṣelu naa
Ẹgbẹ oṣelu APC ti bẹnu atẹ lu igbesẹ awọn ọmọ ẹgbẹ naa kan ni ipinlẹ Edo, ti wọn lawọn paṣẹ lo fidimọle fun alaga ẹgbẹ naa lapapọ, Adams Oshiomole.
Idahun yii n waye nitori bi ẹka ẹgbẹ naa nilu Benin ṣe ni oun ko ni igbagbọ mọ ninu alaga ẹgbẹ nipinlẹ ati alaga apapọ ẹgbẹ naa.
Yakubu Nabena, to jẹ igbakeji akọwe ipolongo ẹgbẹ APC ṣalaye fun ikọ BBC pe, igbesẹ to yẹ kọ ni awọn to paṣẹ lọ gbele rẹ fun Oshiomole tẹle.
O ni ''alawada lawọn to gbe iru igbesẹ yii'' nitori pe wọn ko laṣẹ lati paṣẹ lọ fidimọle fun alaga ẹgbẹ lapapọ. Ohun ti wọn ṣe ko mu ọgbọn wa rara. Wọn ni lati mọ nnkan ti ofin ẹgbẹ sọ ki wọn to gbe iru igbesẹ bẹẹ''
Oríṣun àwòrán, Getty Images
O wa ṣalaye pe, awọn igbesẹ kan wa labẹ ofin ẹgbẹ ti eeyan gbọdọ ṣe, ki o to le ni oun fẹ yọ alaga ẹgbẹ lapapọ
''Ni ipele nipele ni ohun gbogbo wa ninu eto. Ki eeyan to le yọ alaga ẹgbẹ lapapọ tabi ki wọn to le kọwe lọ joko sile fun-un, igbimọ alaṣẹ ẹgbẹ lo le se bẹẹ.''
Ohun ta ti jabọ ṣaaju lori ọrọ yii
Nkan ko ṣebi ẹni rọgbọ falaga ẹgbẹ oṣelu All Progressives Congress APC, Adams Oshiomole pẹlu bi awọn ọmọ ẹgbẹ naa kan ni ipinlẹ Edo ṣe lawọn jawe lọ rọọkun nile fun un.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Lọjọ Iṣẹgun niroyin gbori afẹfẹ kankan lẹyin ti ẹka ẹgbẹ naa ni Benin tii ṣe olu ilu Edo kede pe awọn jawe lọ rọọkun n'le falaga ẹgbẹ naa ni ipinlẹ ohuin, Anselm Ojezua.
Ko pẹ si igba naa ni ikede miran wa lati ile ijọba pe wọn ti yọ akọwe ẹgbẹ naa ati pe wọn tun kọwe lọ fidimọlẹ fun alaga ẹgbẹ naa lapapọ Adams Oshiomole.
Titi di bi a ti ṣe n ṣe akojọpọ iroyin yii, Adams Oshiomole tabi alaṣẹ ẹgbẹ naa kankan loke ko tii fesi si igbesẹ yi.
Lẹnu ọjọ mẹta yii ni fa ki n fa ti n waye laarin Gomina ipinlẹ Edo, Godwin Obaseki  ati Adams Oshiomole.
Toun ti bi awọn agbagba ẹgbẹ naa ti ṣe gbiyanju lati dẹkun aigbọraẹniye laarin wọn,iṣẹlẹ to ṣẹlẹ yi n ṣafihan pe nnkan ko rọgbọ ni ipinlẹ naa falaga ẹgbẹ APC.
Bi awọn kan ti ṣe ni awọn ko fẹ ri imi Oshiomole lakitan mọ lawọn agbarijọpọ alaga ijọba ibilẹ kan sọ pe gbọingbọin lawọn wa lẹyin rẹ.
Gẹgẹ bi ohun ta ri ka ninu iwe iroyin Naijiria kan,atẹjade kan tawọn alaga Etsako West,Etsako Central fi sita sọ pe ''awa ni alaga ijọba ibilẹ mẹrindinlogun a o si mọ nipa ipade to waye nibi ti wọn ti kọwe akoniigbagbọ ninu rẹ mọ fun alaga ẹgbẹ wa Adams Oshiomole''
Wọn tẹsiwaju pe dipo Oshiomole,Gomina Godwin Obaseki lawọn ko ni igbagbọ ninu rẹ ati alaga ẹgbẹ APC ni ipinlẹ Edo,Anselm Ojezua.
Wọn wa tẹnumọ pe Oshiomole ṣi ni alaga olori awọn ati pe ''wamuwamu lawọn wa lẹyin rẹ''
Makinde vs Adelabu: Olùdíje APC ní àkọsílẹ̀ àyànmọ́ òun nínú ìtàn Oyo kò gbọdọ̀ yẹ̀
Oríṣun àwòrán, Adebayo Adelabu
Oludije fun ipo gomina nipinlẹ Ọyọ labẹ asia ẹgbẹ oselu APC, Adebayọ Adelabu ti sọrọ fun igba akọkọ lẹyin ti ile ẹjọ Kotẹmilọrun gbe idajọ rẹ kalẹ lọjọ Aje.
Adelabu, loju opo ikansiraẹni Facebook rẹ kede pe akọsilẹ ayanmọ oun ninu itan ipinlẹ Ọyọ ko gbọdọ tase, ni oun se pinnu lati mase jami lori ẹjọ naa.
O ni lọwọlọwọ bayii, oun ti gbe ẹhonu oun lori ibo gomina naa lọ sile ẹjọ to ga julọ nilẹ wa lati ba wọn da si lẹyin ti ile ẹjọ Kotẹmilọrun ti kede pe igbimọ olugbẹjọ awuyewuye ibo naa ko fun oun lanfaani to lati sọ tẹnu oun.
Ọrọ rè láti ẹnu àwọn Agbẹjọ́rò Makinde àti Adelabu nípa ìdájọ ọ́rọ́ ìdìbò Gómìnà Oyo
Idajọ ileejọ Kotẹmilọrun yii lo tun sọ ireti mi ji pada ninu ilana eto idibo ati ẹka eto idajọ ninu igbesẹ wa lati ni akọọlẹ ninu itan.
Oríṣun àwòrán, Adebayo Adelabu
Adelabu fikun pe nigba ti ẹgbẹ oselu APC fa oun kalẹ gẹgẹ bi oludije fun ẹgbẹ naa, wọn mọ pe oun ni oludije to dantọ julọ laarin ọpọ oludije to yọju lati wa du ipo naa, ti oun si sisẹ kara kara lati safihan akọsilẹ ipinnu ti oun ni lati se atunto awọn ohun alumọọni to wa nipinlẹ Ọyọ.
Oludije fẹgbẹ APC nipinlẹ Ọyọ naa ni, o wa ni akọsilẹ pe oun seto ipolongo ibo nibamu pẹlu awọn erongba oun fun ipinlẹ Ọyọ, to si da awọn eeyan ipinlẹ naa loju pe oun kaato lati sisẹ naa, idi si niyi ti wọn se dibo rẹpẹtẹ fun oun .
Oríṣun àwòrán, Adebayo Adelabu
Amọ awọn iransẹ okunkun pinnu lati ji asẹ tawọn eeyan ipinlẹ Ọyọ gbe le mi lọwọ lati dari wọn, idi si niyi ti mo se pinnu lati lọ sile ẹjọ ki n lee se ayipada igbesẹ ti ko tọ naa.
Makinde vs Adelabu: Makinde ní ìjọba Ọyọ yàtọ̀ sí ti Ọṣun àbí Ekiti tí APC lé dànù
"Adelabu fikun pe ""nibayi ti ile ẹjọ Kotẹmilọrun ti se ayipada ohun ti ko dara naa si rere, mo rọ awọn eeyan ipinlẹ Ọyọ lati gba laafia laaye, ki wọn si maa ba isẹ to ba ofin mu ti wọn n se lọ nibayi ti a n lọ sile ẹjọ Kotẹmilọrun lati gba isẹgun wa."""
Adelabu wa kadi ọrọ rẹ nilẹ pe lẹyin okunkun imọlẹ yoo tan, ko si bo ti wu ko pẹ to, ti oorun ba ti n yọ, isẹgun daju fun oun ati awọn eeyan ipinlẹ Ọyọ.
Ibadan Refuse: Kọmísánà fọ́rọ̀ àyíká ní ìṣẹ̀lẹ̀ náà ní bó ṣe jẹ́, kò ṣàdédé wáyé
Ibadan: awon araalu figbe bonu pe ilu doti
Oriṣiriṣi awọn panti ati ilẹ ti awọn eeyan n da si aarin igboro, ti sọ awọn adugbo kan ni ilu ibadan ti o jẹ olu ilu ipinlẹ Ọyọ ti aatan.
Ikọ BBC Yoruba rin kaakiri awọn adugbo bii Ring Road, Mọkọla, Eleyẹle, Iwo Road, Mọnatan ati Iyana Church lati mọ bi imọtoto aarin ilu Ibadan se ri.
Amọ iriri wa fi idi ọrọ mulẹ pe, pupọ ninu awọn adugbo yii ni ko dun un wo nipasẹ awọn panti ti o kun gbogbo opopona kaakiri eyi ti ko wu oju ri rara.Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí:
Lara awọn araalu to ba akọroyin BBC Yoruba sọrọ ṣalaye wi pe, obitibiti idọti to gba igboro ilu Ibadan kan lee ṣe akoba fun ilera awọn ara ilu.
Wọn wa parọwa si ijọba lati pesẹ agba nla ti awọn eeyan le ko ilẹ ati idọti si, bakan naa si ni wọn lo pọn dandan fun ajọ kolẹkodọti ni ipinlẹ Ọyọ lati ṣe iṣẹ wọn gẹgẹ bi iṣẹ.
Lasiko to n fesi si ọrọ naa, kọmisana fun ọrọ ayika ni ipinlẹ Ọyọ, Asofin Kehinde Ayọọla ṣalaye wi pe lootọ ni igboro ilu Ibadan dọti ṣugbọn ọrọ ko dede ri bẹẹ, o ni bo se jẹ.
Ayọọla sọọ di mimọ pe lọjọ melo kan sẹyin ni gomina ipinlẹ Ọyọ, Onimọ-ẹrọ Ṣeyi Makinde gba iṣẹ lọwọ ileeṣẹ aladani to n ṣiṣẹ kolẹkodọti tẹlẹri nipinlẹ Ọyọ, ti o si yan adari tuntun fun ileeṣẹ to mojuto imọtoto ilu.
Kọmisana naa fi kun pe, laipẹ laijinna ohun gbogbo yoo yipada lorii imọtoto ilu Ibadan ati ipinlẹ Ọyọ lapapọ, lọgan ti adari tuntun lẹka ileeṣẹ to n ṣe imọtoto ilu, ba wọle s'ẹnu iṣẹ.
Ondo Kidnap: Ìyá ọmọ tí wọn jí gbé wà nílé iwòsàn tí wọn ń fa omi sí lára
Oríṣun àwòrán, Eniola Gold
Ninu ẹkun asundakẹ ni ikọ iroyin BBC Yoruba ba Iya Eniola Gold, ọmọ to di awati lojiji ninu ile ijọsin kan ni ilu Akure, ti i se olu Olu Ipinle Ondo lọjọ isinmi.
Nigba ti Iya ọmọ naa n salaye bi ọrọ ti rin, o ni, ko ju bii ọgbọn isẹju si igba ti oun se abẹwo si Eniola ninu Ile ijosin awon ọmọde ti ẹka ijọ naa, to fi di awati.
Iya Ẹniola naa tẹsiwaju pe, titi diỌjọru, ko tii si igbesẹ kan pato ti awọn Ọlọpaa se si isẹlẹ naa.
Nigba to n sọ bi isẹlẹ ọhun ti ka lara to, baba Eniola ni orisirisi ipe lo n wọle sori ẹrọ ibanisọrọ oun wipe, ti awọn ko ba jawọ ninu wiwa ọmọ naa, o seese ki ẹmi oun ati iya rẹ gan lọ si.
Oríṣun àwòrán, Gold Eniola
Bayii, ninu hilahilo ni awọn obi ọmọ naa wa, ti awọn onisegun oyinbo si n fa omi si iya ọmọ naa lara ni ile iwosan kan ni ilu Ondo.
Ikọ iroyin BBC Yoruba tun kan si olu ile isẹ ọlọpaa to wa ni ilu Akure, lati fi ọrọ wa wọn lẹnu wo lori ibi ti wọn ba isẹ de lori isẹlẹ naa.
Oríṣun àwòrán, Eniola Gold
Asoju fun alukoro Olopaa nipinle Ondo, Funmi J. F salaye pe, iwadii n lọ lọwọ lori bi Ẹniola ti se di awati ati pe, ileesẹ ọlọpa naa yoo se iwadii to ye kooro, ki won to sọ ohunkoun lori ọrọ naa.
Titi di igba ti a nko iroyin yii jọ, igbiyanju lati ba olori ijọ ti ọmọ naa ti sọnu, ijọ Sọ titobi rẹ, sọrọ lo ja si pabo, ti ko si gbe ẹrọ ibanisọrọ rẹ.
Wole Soyinka: Ohun ìtìjú ni fún Naijiria bíí ìjọba se ti Sowore mólé
Oríṣun àwòrán, OTHERS
Ọpọlọpọ awọn èniyàn ló ti bu ẹnu àtẹ̀ lu bí ìjọba se fi Omoyele Sowore sí àtìmólé Àjọ DSS.
Ọjọgbọn Wole Soyinka ti kesi ijọba apapọ lati fi Omoyele Sowore silẹ, ki itiju to n ba orilẹede Naijiria ba le dinku.
Ninu atẹjade kan ti Wole Soyinka fi lede fun awọn akọroyin lo ti kesi ijọba apapọ bẹẹ.
O ni ko ba ofin mu bi wọn se tii Sowore mọle, ti Ajọ ọtẹlẹmuyẹ DSS si kọ lati fi silẹ nitori pe Sowore n pe fun atunto Naijiria lọna to ba ofin mu.
Bakan naa ni Soyinka tun bu ẹnu atẹ lu bi awọn osisẹ ajọ ọtẹlẹmuyẹ DSS se da ibọn bolẹ lati le awọn afẹhọnu han ka nilu Abuja lọ̀jọ Isegun.
Ọpọlọpọ awọn eniyan lo ti bu ẹnu atẹ lu bii ijọba se fi Ọmọyẹle Sowore si atimọle ni Olu ile isẹ Ajọ DSS ni ilu Abuja.
Bayelsa Election: Ilé ẹjọ kòtẹ́milọ́rùn ti pàsẹ pe'APC díje
A ti gba aṣẹ ilé ẹjọ míì to tako àṣẹ́ ilé ẹjọ to wọ́gile olùdije APC ni Bayelsa
Oríṣun àwòrán, David
A ti gba aṣẹ ilé ẹjọ míì to tako àṣẹ́ ilé ẹjọ to wọ́gile olùdije APC ni Bayelsa
Ilé ẹjọ kò tẹmílọrun ní ìlú Abuja tí fún APC ní iwé to wọ́gile ìdájọ ilé ẹjọ ta gá jùlọ titi tí ilé ẹjọ yóò fí gbọ́ ẹjọ wà ni ìwáju rẹ̀.
Eyí túmọ sí pé aṣẹ ilé ejọ ti Jane Inyang gbe jáde to ni pé APC ko le díje nínú ìdìbò gómínà ti yóò wáye lọ́jọ́ Satide to n bọ kò ni fẹsẹ̀ múlẹ.
Ní báyìí, ajọ eletò ìdìbò le tẹ̀síwájú láti fi olùdíje APC sinú idìbò náà titi ti ilé ẹjọ kò tẹmilọ́run yóò fi gbọ́ ẹjọ náà.
Ẹgbẹ oselu APC ti kede pe oun tako idajọ ileejọ giga kan to kalẹ si ilu Yenegoa nipinlẹ Bayelsa eyi to wọgile oludije fun ibo gomina ti ẹgbẹ oselu APC fa kalẹ nipinlẹ naa.
Oríṣun àwòrán, Lyon/twitter
Laarọ yii ni ileejọ naa, ti adajọ Jane Inyang dari rẹ, kede pe ẹgbẹ oselu APC ko ni oludije  kankan mọ ninu ibo gomina ti yoo waye lọjọ Kẹrindinlogun osu Kọkanla ọdun yii, eyiun ọjọ Satide ọtunla.
Amọ nigba ti wọn n ba awọn akọroyin sọrọ nilu Abuja, ẹgbẹ oselu APC kede pe oun yoo tako idajọ naa nile ẹjọ Kotẹmilọrun, ti awọn agbẹjọro oun si ti n sisẹ lati lọ gba asẹ ti yoo tun kede pe ki gbogbo igun ti ọrọ kan duro na lori idajọ ọhun.
Oríṣun àwòrán, @APCNigeria
Saaju la ti mu iroyin wa pe, ileẹjọ giga ijọba apapọ to n joko nilu Yenegoa nipinlẹ Bayelsa ti kede pe ẹgbẹ oselu APC ko ni oludije  kankan mọ ninu ibo gomina ti yoo waye lọjọ Kẹrindinlogun osu Kọkanla ọdun yii, eyiun ọjọ Satide ọtunla.
Ileẹjọ salaye pe eto idibo abẹnu ti wọn ti yan oludije ninu ẹgbẹ APC ni Bayelsa ko ba ilana ati ofin ẹgbẹ oselu APC mu rara.
David Lyon ni oludije ẹgbẹ APC ti ibo abẹnu naa fa kalẹ, to si ti fidi rẹmi bayii nitori asẹ ileẹjọ yii, nigba ti ibo gomina ọhun ku ọjọ meji pere ko waye.
Senator Douye Diri ni alatako rẹ latinu ẹgbẹ oselu PDP.
Nígbà to n gbé ìdaájọ náà kalẹ adájọ Jane Inyang, sàlàyé pé ẹjọ ti Sẹnatọ Heineken Lokpobiri pe, fí hàn pé ìlànà tí wọ́n fi ṣe ìdìbò àbẹ́lé to gbé David Lyon wọle, ní ọjọ kẹrin oṣu kẹsan kò ba òfin ẹgbẹ́ mu.
Nítori náà, adajọ Inyang pàsẹ pe ki àjọ eletò idìbò yọ orúkọ olùdíje ẹgbẹ́ òṣèlú APC, Lyon kúro, nínú àwọn oludije ibo gomina ti yóò dije lọ́jọ́ Sátide ọsẹ̀ yìí.
Inyang ni gẹ́gẹ́ bi ilana ofin ẹgbẹ oselu APC feto idibo abẹnu fawọn oludije gomina lọdun 2019, alabojuto ibo náà, tii tun se Gomina Ipinlẹ Yobe, Kala Buni lo yẹ ko kede esi ibo ati ẹni to jawe olubori, kìí ṣe sẹnatọ Emmanuel Ochega, to jẹ akọwe ìgbìmọ to se kokari idibo abẹnu ọhun.
O tún fi kún pé, APC tẹ ofin ara rẹ̀ lóju mọ́lẹ̀ pẹlu bó ṣe yàn ìgbìmọ̀ ẹlẹni kan dípò igbimọ ẹlẹni méje ti òfin ẹgbẹ́ sọ.
"Eyí ti fidí múlẹ̀ lati ọ̀dọ̀ àwọn alásẹ nibi idájọ àti ọ̀pọ̀ àwọn ìdájọ míràn pé àwọn ẹgbẹ́ òṣèlú gbọdọ dúró lóri òfin ti wọ́n là sílẹ̀, Awọn ìgbìmọ to ságbátẹru ìdìbò abẹ́lé fi ìwà àìbíkìtà wọ́n sọ olúdijé náà si ipò to wà
Europe Returnee: Fatmata ní oṣù mẹ́fà ni wọn fi bá òun ṣùn ní aṣálẹ̀ Sahara
Ọpọ awọn ọdulawọ to kuna lati de ilẹ Europe lo pada si orilẹede abinibi wọn, sugbọn ipadabọ to mu ikoro dani lo maa n jẹ fun wọn.
Lorilẹede Sierra Leone, se lawọn mọlẹbi ati ọrẹ awọn eeyan to sẹsẹ pada de lati oke okun maa n kẹyin si wọn, ti wọn si maa n ri wọn bii ẹni ijakulẹ, paapaa nigba to jẹ pe ọpọ awọn to rinrin ajo naa lo saba maa n gbe owo awọn obi wọn, ki wọn to sa lọ soke okun.
Nigba ti obinrin kan to sẹsẹ de n sọ ohun ti oju rẹ ri fun BBC, eeyan yoo fẹ le ba a sunkun nitori a ti ju wọn lo ba lọ, amọ nigba ti yoo dari de,  ko jẹ nkankan mọ.
Ẹ jẹ ka gbọ alaye iriri ohun ti oju obinrin kan to rinrin ajo lọ soke okun naa ri ninu ifọrọwerọ wọn pẹlu BBC.
Fatmata, ẹni ọdun mejidinlọgbọn to wa latilu Freetown lorilẹede Sierra Leone bu sẹkun nigba to ranti osu mẹfa to lo loju ọna silu oyinbo, to si gba asalẹ Sahara kọja.
$2,600 owo ẹgbọn rẹ obinrin to ni ki Fatmata fi bẹrẹ okoowo asọ tita, lo ji gbe fi gba ilu oyinbo lọ pẹlu ireti pe ibẹ yoo dara.
Fatmata ni oun ni lero pe ti oun ba de ilu oyinbo, oun yoo fi ilọpo mẹta owo ti oun ji gbe ransẹ pada si anti oun, ti oun yoo si maa tọju iya ati anti oun.
Sugbọn owo ti Fatmata ji gbe yi ti pa okoowo anti rẹ lara pupọ ju, to si ti da aawọ silẹ laarin oun ati iya wọn, nitori anti rẹ gba pe iya awọn wa lẹyin Fatmata to lo fi gbe owo oun.
Fatmata sọrọ pẹlu omije loju pe, ọkunrin ẹya Tuareg kan ti wọn pe orukọ rẹ ni Ahmed, to jẹ darandaran,  lo mu ohun lẹru ni asalẹ Sahara.
O ni ọkunrin naa dabi omiran, to si dudu kirikiri lawọ, ilo ẹru si lo maa n lo mi, ti yoo si tun sọ fun awọn ọrẹ rẹ lati wa ba mi ni ajọsepọ ninu ile rẹ, ojoojumọ ni wọn n fi iya nla jẹ mi."""
Sugbọn kaka ko san lara iya ajẹ lọrọ Fatmata nitori bo se bọ lọwọ Ahmed lo tun ko sọwọ awọn akonisowoẹru ko lọ fi pamọ si aja ilẹ lorilẹede Algeria.
Idi niyi ti Fatmata se pinnu lati pada sile nigba ti iwaju ko se lọ, ẹyin yoo sa se pada si, to si bẹbẹ fun owo ọkọ lati pada sile sugbọn se ni wọn foju tẹmbẹlu rẹ pe bo se lọ lo se bọ.
Ni kete ti aburo rẹ ọkunrin gbọ pe Fatmata de si ilu Freetown lati oke okun to lọ lọwọ ofo, lo pe lori aago pe ko ba dara ko gbe si ajo ju bo se pada wa sile lọ.
Ko ba san fun ọ ko ti ku sibi to lọ ju bo se pada wa sile lọ. O ko mu ohunkohun bọ, to si san ọwọ pada wa sile lọwọ ofo, yoo dara ko ma yọju sile rara.
Koda, iya rẹ ko tiẹ sopo lati wa ki pe o kaabọ lati irinajo, ti oun gan ko si igboya lati lọ ki iya rẹ nile, ko si ri aaye wo ọmọ ọdun mẹjọ to fi silẹ lọ silu oyinbo.
Falomo Robbery: ọkunrin kan tó jáde nílé ìfowópamọ́ làwọn adigunjalè tọpasẹ̀ rẹ̀
Oríṣun àwòrán, Others
Osisẹ ọlọpa kan ti jade laye, ti ọlọpa obinrin kan ati ẹ́nikan miran si fara gba ọ̀ta ibọ̀n lori afara Onikan, ladugbo Falọmọ, nilu Eko.
Nigba to n fidi isẹ́lẹ naa mulẹ fun BBC Yoruba, osisẹ alarena fun ileesẹ ọlọpa ipinlẹ Eko, Elkana Bala salaye pe, deede aago mejila ọsan ni isẹlẹ naa waye.
O ni ohun to sokunfa iku ojiji yii ni bi awọn adigunjale se tọpasẹ ọkunrin kan to sẹsẹ gba owo nile ifowopamọ kan to wa ni adugbo Falomo de ori afara onikan, ti wọ̀n si sẹburu rẹ.
Elkana salaye pe awọn alọkolohunkigbe ọhun gba baagi ti ọkunrin naa gbe lọwọ, ti wọn si ro pe owo to lọ gba nile ifowopamọ ọhun lo wa ninu rẹ laimọ pe obinrin naa ti fi owo ọhun pamọ si ara rẹ.
O fikun pe bakan naa ni wọn tun gba ẹrọ ibanisọrọ ọkunrin naa ati ẹrọ kọmputa alagbeletan rẹ, ti wọn si fẹsẹ fẹ.
Osisẹ alarena ọlọpa Eko fikun pe, osisẹ ọlọpa to wa nisalẹ afara Onikan naa ba yinbọn mọ awọn adigunjale ọhun, amọ ibọn naa ko ba awọn adigunjale ọhun.
O ni awọn adigunjale yii naa da ibọn pada fun ọlọpa yii, to si baa laya, eyi to mu ko dagbere fun aye loju ẹsẹ, ti ọta ibọn miran si tun ba obinrin ọlọpa kan, ati eeyan kan mii, ti wn n gba itọju lọwọ nile iwosan.
Lagos Fire: Lasema ní iná ba tó gbiná nínú yàrá kan ló fa sábàbí
Oríṣun àwòrán, LASEMA
Kaka ki ewe agbọn dẹ ni ọrọ ijamba ina to n waye nilu Eko lẹnu lọọlọ yii, nitori ko ko ko lo n le si.
Idi ni pe akọtun ina miran tun ti sẹyọ lọsan oni ninu ile kan to wa ladugbo Tẹjuoso nilu Eko.
Gẹgẹ bi oludari agba fun ajọ to n risi isẹlẹ pajawiri nipinlẹ Eko, LASEMA,  Femi Oke Osanyintolu ti salaye fun BBC Yoruba, inu ile alaja kan ni isẹlẹ ina ọhun ti waye.
Ọga agba LASEMA ni ina ba to sadede gbina ninu yara kan to wa ninu ile naalo sokunfa isẹlẹ yii, to si ran ka gbogbo ile ọhun.
Oríṣun àwòrán, LASEMA
O ni ọwọja ina naa ti mu ki ogiri ile ọhun lanu, to si da wo lulẹ.
Amọ Osanyintolu fikun pe isẹlẹ ina naa ko mu ẹmi kankan lọ bi o tilẹ jẹ pe aimọye dukia lo baana ninu isẹlẹ yii.
Oríṣun àwòrán, LASEMA
Lasema ni ọkunrin meji lo farapa ninu ijamba ina naa, ti wọn si ti gbe wọn lọ fun itọju nile iwosan.
Lọwọlọwọ bayii, ọga agba Lasema ni awọn osisẹ oun ati awọn panapana ti wa nilẹ lati bomi pa ina naa ko ma baa tan ran awọn ile to mule tii.
Seyi Makinde: Màá ṣa ipá láti mú káwọn aráàlú nígbẹkẹ̀lé nínú ìjọba mi
Oríṣun àwòrán, Seyi Makinde
Gomina ipinlẹ Ọyọ, Onimọ ẹrọ Seyi makinde ti fọwọ gbaya pe oun yo sa gbogbo ipa oun lati ri daju pe awọn eeyan ipinlẹ naa ni igbẹkẹle kikun ninu ijọba oun.
Gomina Makinde fi ọwọ idaniloju ọhun sọya ninu ọrọ apilẹkọ rẹ nibi ipade itagbangba lori eto isuna ọdun 2020 to waye lẹkun idibo aarin gbungbun Ọyọ, ni gbọngan Atiba, nilu Ọyọ.
Makinde ni ijọba oun ti setan lati se atunto ilana isejọba, ki oun si se agbekalẹ ipilẹ to loorin fun isejọba alajumọse ti ilẹkun rẹ yoo si silẹ fawọn araalu.
Oríṣun àwòrán, Oyo State Government
Gomina Makinde. ẹni ti olori osisẹ lọọfisi gomina, Oloye Bisi Ilaka soju fun salaye pe afojusun ipade ita gbangba naa ni lati jẹ ki smọ ipinlẹ Ọyọ kọọkan ni ẹnu ninu isejọba, ki ijọba si le ni imọ nipa ohun ti ijọba ibilẹ kọọkan n poungbẹ rẹ nigbaradi fun amusẹ eto isuna ọdun 2020.
Makinde ni afojusun ijọba oun ni lati mu seto ilana isejọba onidagbasokenti yoo gba to ogun ọdun, eyi ti yoo wa fun ijọba mi ati awọn isejsba ti yoo tẹle mi.
Oríṣun àwòrán, Oyo State Government
Bakan naa ni mo tun fẹ mu agbega ba okun ajọsepọ laarin ijọba ati awọn araalu nipa bibeere ero wọn lori isuna ọdun to n bọ.
Yatọ si pe ma ri daju pe a lo awọn ohun alumọọni fawọn isẹ akanse to nitumọ si araalu, ati amusẹ awọn eto ti yoo mu ilọsiwaju ba eto ilera awọn eeyan ipinlẹ yii, maa tun tiraka lati ri daju pe araalu ni igbẹkẹle kikun ninu ijọba mi.
Oríṣun àwòrán, Oyo State Government
Saaju ninu ọrọ ikinni kaabọ rẹ, Kọmisana feto isuna ati aato ọrọ aje nipinlẹ Ọyọ, Amofin Adeniyi Farintọ mẹnuba pe ipade ita gbangba naa se koko nitori igba akọkọ ree ti ijọba kan ati awọn araalu yoo joko papọ lati jiroro lori eto isuna kan ki wsn to gbe kalẹ.
Farintọ ni ijọba Seyi Makinde yoo tẹsiwaju lati maa ko akoyawọ lai fi igba kan bo ọkan ninu, ninu awọn ilana to ba gbekalẹ, ti yoo si maa gba ero araalu laaye.
Oríṣun àwòrán, Oyo State Government
Nigba to n dahun si awọn ibeere araalu lasiko ijiroro naa, Makinde seleri pe oun yoo pese oju ọna to ye kooro si ẹkun idibo naa.
O ni oun yoo tun se agbekalẹ ẹka ajọ to n se atunse oju ọna nipinlẹ Ọyọ OYSTROMA si ẹkun naa pẹlu bi afikun se ba owo tijọba ipinlẹ naa n gba lati ọdọ ijọba apapọ pẹlu biliọnu marun naira.
Oríṣun àwòrán, Oyo State Government
Lori ọrọ LAUTECH, Makinde ni wọn ti gbe igbimọ kan kalẹ lati sisẹ lori bi ipinlẹ Ọyọ yoo se gba akoso ileẹkọ fasiti Ladoke Akintola to wa nilu Ogbomọsọ patapata.
Kogi & Bayelsa Polls: Buhari ní ìdìbò gómìnà gbọdọ̀ lọ nírọwọ́ rọsẹ̀
Oríṣun àwòrán, Twitter/Presidency
Kogi & Bayelsa Polls: Buhari ní ìdìbò gómìnà gbọdọ̀ lọ nírọwọ́ rọsẹ̀
Ṣaaju idibo gomina nipinlẹ Kogi ati Bayelsa lọjọ Satide ọsẹ yii, Aarẹ Muhammadu Buhari ti kilọ fawọn oṣiṣẹ eleto aabo lati dena awọn janduku to ba fẹ ji apoti idibo gbe.
Buhari ninu atẹjade to fi sita lati ọwọ oludamọran pataki lori ọrọ iroyin, Garba Shehu, sọ fawọn oṣiṣẹ eleto aabo pe ki wọn ṣiṣẹ wọn bi iṣẹ, ki wọn rii pe awọn eeyan dibo gẹgẹ bi ẹtọ wọn.
Aarẹ Buhari sọ pe gbogbo ọna ni kawọn ẹṣọ eleto idibo fi dena ẹnikẹni to ba fẹ ji apoti idibo gbe.
Aarẹ ni ẹnikẹni ko gbọdọ dunkoko mọ ẹnikan tabi dena ẹnikẹni lati dibo gẹgẹ ẹtọ wọn.
Bakan naa ni aarẹ Buhari kepe awọn oludibo nipinlẹ Bayelsa ati Kogi lati ṣe jẹẹjẹ nibudo ibudo idibo, ki wọn si dibo lalaafia gẹgẹ bi ofin ti laa kalẹ.
Buhari sọ pe, ''nibi gbogbo ti eto idibo ti n waye ni oludije kan yoo ti jawe oloubori, ti omiran yoo si fidi rẹmi, ti Bayelsa ati Kogi kogi naa ko gbọdọ yatọ.''
Makinde vs Adelabu: Makinde ní ìjọba Ọyọ yàtọ̀ sí ti Ọṣun àbí Ekiti tí APC lé dànù
Aarẹ Buhari rọ awọn oludije lati gba esi idibo ti yoo waye bi o ba ṣe ri laidarogbodiyan silẹ.
Aarẹ ni oludije ti eto idibo ko ba tẹ lọrun laṣẹ lati gbe ile ẹjọ lọ dipo ki o da wahala silẹ.
World Diabetes Day: Ọdún kọkandinlogun ti mo ti wà lẹ́nu itọ ṣúgà nìyí
Aeroplane House: Látọdún 1999 ni mo ti bẹ̀rẹ̀ kíkọ́ ilé yìí fún ìyàwó mi ọ̀wọ́n
Kenya Prisioners: Àwọn ẹlẹ́wọ̀n mórí lé ilé-ẹjọ́ kòtẹ́milọ́rùn fún ẹ̀kúnwó owó oṣù ẹlẹ́wọ̀n
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Kenya Prisioners: Àwọn ẹlẹ́wọ̀n mórí lé ilé-ẹjọ́ kòtẹ́milọ́rùn fún ẹ̀kúnwó owó oṣù ẹlẹ́wọ̀n
Awọn to ti ṣẹwọn ri mẹta lorilẹ-ede Kenya ti morile ile ẹjọ kotẹmilọrun bayii lẹyin ti ile ẹjọ giga kan da ẹjọ wọn nu
Awọn mẹta yii ni wọn pe ẹjọ fun ẹkun owo oṣu fawọn ẹlẹwọn to n ṣiṣẹ lọgba ẹwọn nibi ọdun mẹrin sẹyin.
Awọn mẹta to ṣẹwọn ri yii ṣalaye pe iyipada ilẹ naa eyi ti wọn sọ pe o mu awọn lẹru, ati pe o tapa sofin ẹtọ ọmọniyan wọn.
Ọdunrun un naira o le diẹ lawọn elewọn n gba lọdun bayii lorilẹede naa, ọdun 1979 tii ṣe ogoji ọdun sẹyin nijọba ti ṣe agbeyẹwo owo oṣu awọn ẹlẹwọn kẹyin.
Awọn ẹlẹwọn lorilẹede kenya maa n ṣe aga ijoko, tablili fawọn ile iṣẹ ijọba ati ile igbimọ aṣofin.
Bakan naa ni wọn maa n ṣe ohun ti wọn maa n kọ nọmba ọkọ si.
Awọn to ti figba kan wa lẹwọn yii tun sọ fun ile ẹjọ pe lọpọ igba lawọn ẹlẹwọn kii lanfani si awọn ohun ti wọn nilo bi ọṣẹ, ọṣẹ ifọyin atawọn nkan miran.
Ọkan lara awọn olupẹjọ naa, Aloys Onyango sọ fun ile ẹjọ pe ko paṣẹ fun awọn alaṣẹ ọgba ẹwọn lati sanwo oṣu oun fun ọdun mẹrindinlogun t'oun lo lẹwọn.
Genotype test: Ilé aṣòfin kàn án nípá fáwọn tó fẹ́ ṣèyàwó láti ṣàyẹ̀wò ẹ̀jẹ̀
Genotype test: Ilé aṣòfin kàn án nípá fáwọn tó fẹ́ ṣèyàwó láti ṣàyẹ̀wò ẹ̀jẹ̀
Dandan lowo ori; tulaasi laṣọ ibora.
Ni bayii, o ti di didan fawọn ọdọkunrin ati ọdọbinrin ti wọn ba fẹ ṣegbeyawo lati ṣe ayẹwo ẹjẹ ki wọn to lọ sori pẹpẹ.
Ile igbimọ aṣoju-ṣofin Naijiria lo kan an nipa fawọn obinrin atawọn ọkunrin to ba fẹ fẹ ara wọn ni Naijiria ninu apero wọn l'Ọjọbọ.
Awọn aṣofin ti wa kepe awọn ẹka ijọba to n ṣe eto igbeyawo, awọn ṣọọṣi atawọn mọṣalaaṣi wi pe ki wọn maa beere esi iyẹjẹwo ki wọn to so ẹnikẹni pọ.
Ile igbimọ aṣoju-ṣofin ni igbesẹ yii ṣe pataki lati dena aarun arunmọleegun ni Naijiria.
Gbogbo ile lo tẹwọgba aba naa ti aṣofin Umar Sarki to gbe e wa pe akori rẹ ni ''Kepe ile iṣẹ ijọba to n ri si ọrọ ilera lati wa ọna ati dẹkun aarun arunmọleegun ni Naijiria.''
Divorcee: Ó sàn kí wọ́n yàgò fúnra wọn ju ki wọ́n ṣe ara wọn léṣe- Fisayo
Awọn aṣofin tun kepe ẹka ijọba to n ri si eto ilera lati pese iwosan ọfẹ fawọn to laarun arunmọleegun.
Ni afikun, wọn rọ ijọba lati sọ fawọn ile ijọsin ati ẹka idajọ lati maa lo esi ayẹwo ẹjẹ gẹgẹ ọkan lara amuyẹ fun igbeyawo.
Ile igbimọ aṣoju-ṣofiun tun rọ ijọba lati fi idanilẹkọọ lori aarun arunmọleegun sinu eto ẹkọ ile iwe alakọbẹrẹ ati ti girama ni Naijiria.
Ile paa laṣẹ fun igbimọ to n ri si eto ilera, iroyin, ọrọ ilanilọyẹ ati ọrọ lati rii pe igbesẹ yii di imuṣẹ.
Ninu ọrọ rẹ, aṣofin to gbe aba naa silẹ, Ọgbẹni Sarki ni iwadii fihan pe aarun arunmọleegun ti wa nilẹ Afirika fun bi ẹgbẹrun un mejila ọdun, eleyi ti ilẹ Adulawọ ko si tii ṣe nnkan gbogi lati dẹkun rẹ.
Tọkọ-taya Aràrá: Àwọn èèyàn máa ń wò wá, ta bá fa ọwọ́ ara wa ní títì
Iwadii fihan pe Naijiria lawọn to larun arunmọleegun ti pọju lagbaaye pẹlu miliọnu mẹta aabọ eeyan o le diẹ to larun naa.
Bakan naa ni iwadii fihan pe aadọjọ ọmọ ikoko ninu ọọdunrun tawọn eeyan n bi lagbayee lọdọọdun lo wa lati Naijiria.
World Diabetes Day: Ọdún kọkandinlogun ti mo ti wà lẹ́nu itọ ṣúgà nìyí
Kogi Election: Dino Melaye náà pariwo pé àwọn apanìyàn ti gbòde ní ìbò ku ọ̀la
Oríṣun àwòrán, Dino Melaye
Nibayii ti eto idibo gomina ni ipinlẹ Kogi ku wakati mẹrinlelogun ko bẹrẹ, oniruuru ariwo ni awọn oloselu kan ti n fi sita nipa ihuwasi awọn janduku to gboke.
Obinrin kansoso to jẹ oludije fun ibo gomina ti yoo waye lọjs Satide nipinlẹ Kogi, to tun n soju ẹgbẹ oselu SDP, Natasha Akpoti ti ke gbajare fun araye pe oun n bẹru ẹmi oun.
Idi ni pe wọn lu obinrin yii bi ẹni lu bara ni olu ileesẹ ajọ INEC nibi ipade kan ti alaga apapọ fun ajọ naa pe, ti ọgọọrọ awọn ọlọpa si wa, ti wọn ko si ri janduku kankan to sisẹ naa mu sahamọ.
Oríṣun àwòrán, NAtasha Akpoti
Nigba to n ba BBC sọrọ, Akpoti ni lẹyin ti wọn na oun tan ni wsn tun ti ina bọ ibujoko ẹgbẹ oselu SDP to wa nilu Lọkọja, ti wọn si jo kanlẹ.
Bi mo se fẹ wọnu ibudo ipade naa, lawsn ọkunrin kan bẹrẹ si tabuku mi, ti wọn si n pe mi ni asẹwo, koda, wọn na mi, ti wọn si ti mi lulẹ ni igba meji niwaju awọn ọlọpa atawọn agbofinro, ti ko si si ẹni to sọ ohunkohun ninu wọn.
Ni bayii, wọn ti n dunkoko mọ mi pe awọn yoo gbẹmi mi tabi ki wọn ji mi gbe, ti kii si se oni ni awọn eeyan ti n jalaisi nitori oselu lorilẹede Naijiria sugbọn n ko ni jawọ nitori idunkoko wọn.
Oríṣun àwòrán, Dino Melaye
Bakan naa, sẹnetọ Dino Melaye ti fi igbe bọnu loju opo Twitter rẹ pe awọn janduku kan ti n dunkoko mọ ẹmi oun ati tawọn mọlẹbi oun.
Koda o se afihan ọpọ ohun ti ọta ibọn ba ninu ile aburo rẹ to ni awọn janduku wa ka mọle amọ ori lo ko yọ ti ko ba ibẹ lọ.
Edgal Imohimi: Ìpínlẹ̀ Eko ló ti kọ́kọ́ se Kọmísánà ọlọ́pàá
Oríṣun àwòrán, Edgal Imohimi
Ọjọbọ ni iroyin gbalẹ pe isipo rọpo tun ti waye nileesẹ ọlọpa ilẹ wa, ti wọn si gbe awọn Kọmisana ọlọpa kan kuro nigba ti wọn fi awọn miran rọpo wọn.
Lara awọn Kọmisana ọlọpa ti wọn ni isipo rọpo ni Edgal Imohimi, ti isẹ tun gbe wa sipinlẹ Ogun gẹgẹ bii kọmisana ọlọpa fun ipinlẹ Ogun.
Edgal Imohimi jẹ odu ninu isẹ ọlọpaa, ti kii si se aimọ fun oloko awọn araalu nitori isẹ takuntakun to ti se gẹgẹ bi Kọmisana ọlọpa, paapa nipinlẹ Eko.
O si yẹ ka mọ iru eeyan ti Edgal Imohimi, Kọmisana ọlọpa tuntun nipinlẹ Ogun jẹ.
Ọdun 1984 ni Edgal Imohimi kẹkọ gboye imọ ijinlẹ akọkọ ninu isẹ ọna nile ẹkọ fasiti Jos, to si tun gba oye imọ ijinlẹ keji ni fasiti Eko lọdun 2004.
Osu Keji ọdun 1986 ni Edgal Imohimi darapọ mọ ileesẹ ọlọpa ilẹ wa gẹgẹ bii ASP, to si sisẹ ni ọpọ awọn  ẹka ileesẹ ọlọpaa kaakiri amọ ilu Eko lo ti lo ọpọ akoko naa lẹnu isẹ.
Oríṣun àwòrán, Edgal Imohimi
Edgal Imohimi kẹkọ, to si ni imọ kikun ninu sise akojọpọ imọ fun isẹ ọlọpa ati isẹ ọlọpa ni aarin awujọ, oun si lo se agbekalẹ ipade apero akọkọ lori isẹ ọlọpa laarin awujọ ni Ikẹja, tii se olu ilu ipinlẹ Eko.
Edgal, ẹni to tun gba oye imọ Diploma ninu imọ nipa sayẹnsi isẹ ọlọpa, ti sisẹ gẹgẹ bii DPO fun agọ ọlọpa to wa ni Surulere, Ikeja laarin ọdun 1993 titi de 2011.
O tun di CSP ọlọpa ko to tun ni igbega si ipo ACP to wa lẹkun isọri ileesẹ ọlọpa kinni, ti wọn pe ni Area A to wa nipinlẹ Eko.
Edgal Imohimi tun gba iwe ẹri nileesẹ ologun ilẹ wa lọdun 2015, eyi to mu ki wọn yan gẹgẹ bii alakoso fun ẹka kiko iroyin afinuwa jọ ni olu ileesẹ ọlọpa to wa nilu Abuja.
Gẹgẹ bi akọsẹmọsẹ ninu sise isẹ ọlọpa lawujọ, Edgal ti kopa ninu ọpọ idanilẹkọ lorisirisi eyi ti ẹka to n ri si idagbasoke agbaye DFID ti United Kingdom se kokari rẹ nilu Eko, Awka ati ni Plateau.
Oríṣun àwòrán, Edgal Imohimi
Edgal Imohimi, nigba to jẹ DPO ni ẹkun ileesẹ ọlọpa to wa ni Ikeja, se ifilọlẹ sise isẹ ọlọpa awujọ taa mọ si Community Policing, akọkọ iru rẹ, to si gbalejo ọps eeyan to ni nkan se pẹlu ọlọpa nibi to ti sedanilẹkọ fun wọn nipa bi wọn se lee ran awọn ọlọpa lọwọ lawujọ.
Edgal Imohimi, gẹgẹ bii Kọmisana ọlọpa nipinlẹ Eko tun sisẹ takuntakun, lati sawari awọn akẹkọ girama mẹfa ti wọn ji gbe.
Ọjọ Kẹẹdọgbọn osu Karun ọdun 2017 nisẹlẹ naa waye ni ilegbe awọn akẹkọ girama Lagos Model College to wa ni Igbo Nla nilu Epe, ti wọn si gba idande lẹyin ọjọ marundinlaadọrin.
Edgal Imohimi ti wọ isẹ bayii gẹgẹ bii Kọmisana ọlọpa tuntun nipinlẹ Ogun.
Kogi àti Bayelsa: Èsì tó jáde láti ìpínlẹ̀ Kogi
Oríṣun àwòrán, Aseda Sunny Aseda
Ìròyìn tó ń tẹ̀ wa lọ́wọ́lọ́wọ́ ní wí pé àjọ INEC ìpínlẹ̀ Kogi ti bẹ̀rẹ̀ si ni kédé èsì ìdìbò gómìnà ti ìjọba ìbílẹ̀ tó kù ṣáájú kíkéde ẹni tó jáwé olúborí.
Bo ṣe ń jáde rèé.
Àjọ INEC so ìbò kíkà ní ìpínlẹ̀ Kogi rọ̀ dí aago mẹ́sàn án àárọ̀ ọjọ́ Ajé
A n se akojọpọ ẹkunrẹrẹ iroyin yajoyajo lọwọ, a o maa gbe ẹkunrẹrẹ iroyin naa sori atẹ iroyin wa laipẹ. Ẹ jọwọ, ẹ tun oju opo iroyin yi yẹwo, ki ẹ lee ri ẹkunrẹrẹ iroyin ọtun laipẹ.
Sri Lanka Election: Adarí ogun Sri Lanka tẹ́lẹ̀rí ṣe tán latí gba'dé
Oríṣun àwòrán, AFP
O ti han wi pe adari ẹka ogun alaabo ni orilẹede Sri Lanka, Rajapaksa ti ṣe tan láti jawe olubori gẹgẹ bi aarẹ orilede naa.
Bi o tilẹ jẹ pe Gotabaya Rajapaksa ti ni oun loun jawe olubori ti ẹni to jẹ alatako rẹ naa ti gba bẹẹ ṣugbọn wọn ko tii gbe esi gangan jade.
Idibo yii ni yoo jẹ igba akọkọ ti yoo waye lẹyin ikọlu nla kan to waye to si mu ẹmi eeyan to le ni igba le ni aadọta lọ ninu oṣu kẹrin ọdun yii.
Oludije marundinlogoji lo du ipo aarẹ orilẹede naa eyi ti yoo jẹ aarẹ kẹta lati ọdun 2009 ti opin ti de si ogun abẹle ọlọdun gbọọrọ to n waye lorilẹede naa.
Ọgbẹni Rajapaksa jẹ odu ti ko ṣee fọwọ rọ sẹyin to si jẹ ọkan lara awọn erin meji to n sare ije ipo aarẹ yii pẹlu minisita kan Sajith Premadasa.
'Àwa akódọ̀tí táà ń gba £1,500 lóṣù níbi sàn ju Sẹ́nétọ̀ lọ ní Nàìjíríà'
Orukọ aarẹ to wa lori alefa bayii ko si lori iwe orukọ awọn oludije tori o pinnu lati ma dije lẹyin awọn ọrọ to jade si i latari iṣẹlẹ ado oloro to bugbamu lọjọ ọdun ajinde.
Awọn alakatakiti ẹsin Islam doju kọ awọn ile ijọsin atawọn ile itura kaakiri orilẹede naa. Koda ikọlu yii ti mu ki ọrọ aje orilẹede naa wọkun to fi mọ ẹka igbafẹ.
Awọn oṣiṣẹ ajọ eleto idibo ni ida ọgọrin ninu ọgọrun oludibo lo jade wa dibo.
Ọgbẹni Premadasa ni ida marundinlaadọta o le diẹ (45.3%) nigba ti Ọgbẹni Rajapaksa ni ida mejidinlaadọta o le diẹ (48.2%) Rajapaksa si ni oun yoo bori.
Mo ni anfani lati gboriyin fun ipinu awọn araalu mo si ki Ọgbẹni Gotabaya Rajapaksa ku oriire idibo yii gẹgẹ bi aarẹ ikeeje Sri Lanka. Ọgbẹni Premadasa sọ gẹgẹ bi ileeṣẹ iroyin AFP ṣe jabọ rẹ.
Ajọ eleto idibo orilẹede naa sọ fun BBC pe esi idibo to tọ yoo jade ni aago mẹrin ti ilu wọn (aago mẹwa abọ lagbaye) lọjọ aje.
"'Olùkọ̀ rẹ̀ tilẹ̀ sọ fún un pé ""ẹlẹ́sẹ̀ kan ni ẹ́, oò ní 'le wẹ̀'"
Fayose: Àwòrán ìgbeyàwó ọmọ Fayose táwọn èèyàn ń kẹ́kòó nípa òṣèlú lára rẹ̀
Oríṣun àwòrán, Twitter/ekitistategov
Tẹrin tayọ lawọn mejeeji fi pade ara wọn nibi igbeyawo ọmọ Fayose
Ẹ ma gbe ọrọ oloṣelu lori, ṣe ẹ ri Fayemi ati Fayose nibi iyawo ọmọ Fayose abi ẹ ko ri wọn?.
Ọrọ to jọ mọ iru eleyi lo gba ẹnu awọn eeyan kan loju opo ayelujara lẹyin ti aworan awọn oloṣelu mejeeji lu sita nibi ti wọn ti n dọwẹkẹ nibi igbeyawo ọmọ Ayodele Fayose.
Kete ti aworan wọn yii jade sita lawọn kan ti n sọ pe o ṣe afihan pe awọn to n pariwo ija laarin awọn oloṣelu ni lati lọ yẹ ara wọn wo.
Kia lawọn eeyan tun ti wa aworan miran to safihan Minisita feto irina Naijiria Rotimi Amaechi nibi ti oun naa ti n ba Felix Obuah bawọ.
Ṣaaju asiko yii, Amaechi ti wọ Obuah lọ ile ẹjọ lori ẹsun pe o n ba oun lorukọ jẹ ti o si ni ki o san owo itanran ọ́ọ̀dúnrún biliọnu naira nigba naa.
Arakunrin Ariyo Dare Atoye tilẹ sọ apẹrẹ ni aworan ti Fayose ati Fayemi ya pọ jẹ to si n fi han pe awọn mejeeji yoo yi pada ba ara wọn ṣiṣẹ
Bi a ko ba tilẹ le sọ ohun to wa ninu ọkan wọn eyi to han ni pe agbo oṣelu ni Naijiria jẹ ibi ti a ti ma n da ọrẹ. Nibẹ naa lawọn miran a si ti ma dọta ti ija wọn ko ni pari.
Pupọ awọn alatilẹyin oloṣelu ni ija wọn kii saba pari ayafi ti awọn ti wọn n gbe lẹyin wọn ba ni o to gẹ.
Bi eeyan ba fi ti wọn ṣe, ko ni fẹrẹẹ si ẹni ti yoo ba ara wọn ṣọrẹ.
FUTA Bullies: Ìgbìmọ̀ aláṣẹ fásitì FUTA pàṣẹ lọ rọọ́kún nílé fakẹ́ẹ̀kọ́ méje tó lù akẹgbẹ́ wọ́n
Oríṣun àwòrán, Google
Igbimọ alaṣẹ fasiti imọ ẹrọ ilu Akure, FUTA ti paṣẹ lọ fidimọle fawọn akẹkọọ meje ni fasiti naa ti wọn da sẹria iya f'akẹgbẹ wọn kan to jẹ obinrin.
Ninu atẹjade kan ti Adegbenro Adebanjo to jẹ igbakeji adari eto ibaraẹnisọrọ fasiti naa fi sọwọ sita, wọn ni iwa bẹẹ lodi si ofin ati ilana ile ẹkọ awọn.
Lọjọ Abamẹta ni fidio kan to ṣe afihan awọn akẹkọọ kan to n lu akẹkọọ obinrin naa nilu bara lu sori ayelujara.
Ninu fọnran fidio naa, a ri ọkunrin kan ati awọn obinrin ti wọn n lu obinrin kan.
Fọnran fidio yi mu ki awọn akẹkọ fasiti naa faraya ti wọn si ṣigun lọ ba awọn to hu iwa yi.
Kaakiri loju opo ayelujara lawọn eeyan ti n fi iyalẹnu han lori ohun to le mu ki awọn akẹkọ wọnyi hu iru iwa bẹẹ.
Fasiti FUTA tun ṣalaye pe awọn ṣi n tẹsiwaju pẹlu iwadi lori iṣẹlẹ naa ati pe awọn yoo fi ijiya to le jẹ awọn ti o ba jẹbi ninu iṣẹlẹ ọhun.
Adegbenro Adebanjo sọ pe awọn n ṣe itọju fun akẹkọọ ti wọn lu ninu fọnran fidio naa.
Lateef Adedimeji: Toyin Abraham ní ìwọ̀fà lẹnu, Adedimeji wòye pé òbìrí nilé ayé
Oríṣun àwòrán, Instagram/lateef Adedimeji
Awọn oṣere ori itage Yoruba, Yollywood gbarada lọsẹ to koja yii. Adedimeji Lateef lo kọkọ woye pe aditu nile aye ti a wa yii.
Wọnyii ni awọn ohun tawọn oṣere Yollywood sọ ati ohun ti wọn ṣe lọsẹ to kọja.
Adedimeji Lateef
Aiye ti wọn n pe ni aye! Gbajugbaja oṣere, Lateef Adedimeji sọrọ loju opo Instagram rẹ, o ni ile aye ko gba ibikan ye oun.
Adedimeji ni oun ti ''ri onile to di ayalegbe ko to dagbare faye,'' bakan naa lo sọ pe oun ti ri akẹkọọ to di ọga ile iwe to ti mkẹkọọ jade nigba tawọn olukọ rẹ si tun wa ni ipo olukọ.
Adedimeji ni ''ko si ẹni to mọ ọla laye ti a wa yii, idi niyii ti aye fi jẹ aditu.''
Adedimeji rọ awọn eeyan lati maa ṣe daadaa nitori aye ko lọ titi.
Toyin Abraham
Oṣere Toyin Abraham naa sọrọ, o ni iwọfa lẹnu, ohun to ba wu ẹlẹnu lo le fẹnu rẹ sọ.
Toyin sọrọ loju opo Instagram rẹ pe ko si ẹni to lagbara lati dawọn eeyan duro ki wọn maa lee sọrọ rẹ, amọ, ohun to ṣeeṣe ni pe ki onikaluku mọ bi yoo ṣe fesi sọrọ awọn eeyan.
O fikun ọrọ rẹ pe ko si bi eeyan ṣe le dara to, ko le tẹ araye lọrun.
Toyin Abraham ni ọpọ eeyan ti wọn maa pẹgan fẹ lati maa sọ ohun buburu nipa ọmọlakeji nigba ti wọn dakẹ nigba ohun ti ẹni ti ṣe.
PDP, SDP ta ko ìdìbò ipò sẹ́nétọ̀ ẹkùn Ìwọ̀-òòrùn Kogi
Kogi bẹ̀rẹ̀ ìkéde ìbò gómìnà fún ìjọba ìbílẹ̀ méjì tó kù
Ẹ máa retí láti ìpínlẹ̀ Kogi!
Odunlade Adekola
Gbajugbaja oṣere Odunlade Adekola ni tiẹ sọ ohun to dun n gbọ leti nipa ara rẹ.
Odunlade sọrọ loju opo Instagram rẹ niṣe lara oun n dan an bi egbin.
Odunlade tun sọ fawọn ololufẹ pe ki wọn lọ wo fiimu oun ti akori rẹ n jẹ OGOOLUWA ati ODAJU.
Damola Olatunji
Ilumọọka oṣere Yoruba, Damola Olatunji ati iyawo rẹ, Bukola Awoyemi lọ sori ikanni BBC Yoruba fun ifọrọwerọ.
Lori eto yii Damola ti sọ pe ninu iṣẹ ere tiatia lawọn mejeeji ti pade ko to di pe wọn fẹ ara wọn gẹgẹ bi lọkọlaya.
Ọpọ awọn ololufẹ wọn lo sọrọ ikinni si awọn mejeeji lori eto naa.
Dayo Amusa
Oṣere Dayo Amusa naa ṣawada lju opo Instagram tiẹ ni, koda niṣe lo jiṣoro ara rẹ.
Dayo sọ fawọn ololufẹ pe ẹnikẹni to ba fẹ oun, ko kan si oun.
Bakan naa ni Dayo Amusa sọ pe awọn eeyan ko oju lọna pọpọṣinṣin ọdun to n bọ diẹdiẹ
David Lyon, olùdije APC tó wọlé ìbò gómìnà ní ìpínlẹ̀ Bayelsa
Oríṣun àwòrán, OTHERS
Lẹyin ogun ọdun ti PDP ti n ṣe ijọba ni ipinlẹ Bayelsa, APC ti gba ijọba bayii.
David Lyon ni awọn eniyan dibo yan ninu eto idibo sipo gomina to waye ni Ọjọ kẹtadinlogun, Oṣu Kọkanla, ọdun 2019.
Awọn eniyan marundinlaadọta lo dije dupo naa ki Lyon to wa jawe olubori.
Wo koko ohun mẹwaa nipa gomina tuntun ti wọn dibo yan ni Bayelsa.
Ẹ máa retí láti ìpínlẹ̀ Kogi!
'Àwa akódọ̀tí táà ń gba £1,500 lóṣù níbi sàn ju Sẹ́nétọ̀ lọ ní Nàìjíríà'
Bí  David Lyon ṣe fàgbà han Douye Diri ti ẹgbẹ́ PDP ní Bayelsa
Iroyin to n tẹ wa lọwọ ni pe oludije ẹgbẹ oselu APC, David Lyon ti wọle ibo gomina to waye ni ipinlẹ Bayelsa.
Eyi ni igba akọkọ ti ẹgbẹ APC yoo wọle ibo gomina nipinlẹ Bayelsa.
Esi idibo ti ajọ INEC fi sita ṣafihan rẹ pe ẹgbẹẹgbẹrun un ibo ni Lyon fi la oludije fẹgbẹ oṣelu PDP, Douye Diri to sun mọ julọ mọlẹ.
Àjọ INEC so ìbò kíkà ní ìpínlẹ̀ Kogi rọ̀ dí aago mẹ́sàn án àárọ̀ ọjọ́ Ajé
Wo ẹni tó ń léwájú gẹ́gẹ́ bíi gómìnà Kogi
Bẹ́ẹ ṣe ń retí láti Kogi àti Bayelsa, ajáwé olúborí Sri Lanka àti alátakò rẹ̀ ti fọwọ́ wẹwọ́
Iye ibo 352,552 ni Lyon ti APC fi la oludije alatako rẹ ti PDP, Duoye Diri mọlẹ toun ni ibo 133,172.
Ninu oludibo to le ni 867,000 to forukọ silẹ lati dibo ni ilu to n f'epo ṣe ọrọ̀ yii, 516,371 lo jade lọ dibo yan gómìnà wọn lọjọ ikẹrindinlogun oṣu kọkanla ọdun 2019.
Omoyele Sowore: Falana ní ìjọba ti sọ́ di àṣà láti tàpá sófin ilé-ẹjọ́ lórí àwọn tó wà látìmọ́lé
Oríṣun àwòrán, Facebook/Omoyele Sowore
Gbajugbaja agbẹjọro ajafẹtọ ọmọniyan, Femi falana lo sọ pe idi mẹta ọtọtọ ni ajọ ọtẹlẹmuyẹ DSS ti fawọn ọmọ Naijiria ti ko jẹ ki wọn tii fi Omoyele Sowore silẹ.
Falana ni fifi Sowore sahamọ lẹyin ti ile ẹjọ ti paṣẹ idasilẹ rẹ tabuku ba orilẹede Naijiria.
Ọjọ kẹta oṣu kẹjọ lawọn ajọ ọtẹlẹmuyẹ mu Sowore niluu Eku ki wọn to gbe e lọ silu Abuja nibi to ti wa lahamọ lati igba naa.
Ọpọ lo ti bu ẹnu ẹtẹ lu ajọ DSS lori bi wọn ṣe kọ lati fun Sowore lominira papaajulọ lẹyin ti ile ẹjọ ti paṣẹ pe ki wọn fi silẹ.
Ẹwẹ, agbẹnusọ fun ajọ DSS, Ọgbẹni Peter Afunanya sọ pe o wu Sowore fun ra rẹ lati wa latimọle DSS nitori ajọ naa n mojuto o.
Afunanya ni Sowore le wa lẹwọn ṣugbọn o sọ fun ile ẹjọ pe ki wọn jẹ ki oun wa lahamọ DSS.
Amọ Falana ni ijọba apapọ ti sọ di aṣa bayii lati ma pa aṣẹ ile ẹjọ mọ.
Power Supply: Òkùnkùn birimùbirimù ń bọ̀ bí NBET ò bá ṣàtúnṣe
Hee! òkùnkùn birimùbirimù ń bọ ní Nàìjíríà
Àfàìmọ̀ ni kí orílẹ̀-èdè Nàìjíríà má wọ inú òkùnkùn birimùbirmù lọ láìpẹ yìí bi àwọn ilé iṣẹ́ to n pín ina ọba ni Naijirià ṣe kọ láti gbana ojú ilé iṣẹ́ to n pín ina fún wọ́n iyẹn (NBET).
Wọn sọ èyí di mímọ lásìkò ti àkowé àgbà ẹgbẹ́ àwọn ilé iṣẹ to ń pín iná (APGC), Joy Ogaji pe ìpàdé àwọn oníroyin nílùú Abuja, o ṣálàyé pé ìpìnu NBET ni láti gbé idá 0.75% le àwọn (GENCO) lórí gẹ́gẹ́ bii owo ajẹmọnu fun sisanwo afẹfẹ gáàsi.
Bákan náà lo sàlàyé pé gbèsè ti NBET ti jẹ àwọn ilé iṣe to pin ina lojule dójulè ko ṣee fẹnusọ èyi to ni o ti tó Triliọnu kan Naira.
Iṣẹ́ NERC ni láti mójútó bi àwọn NBET ṣe n ra ina fun àtunta si àwọn ile iṣẹ́ ti yio pin in láti ojúlé de ojulé.
Nínú oṣu kẹsàn ọdun yìí NBET bèrè afikun 0.75% lati fi kun Gencos gẹ́gẹ́ bi owo ti wọ́n o maa gba lorukọ wọ́n fún ríra iná.
Ogaji sọ pé bo tilẹ jẹ pé Gencos fárigá nigba ti wọ́n gbe àbá náà jáde àti pé àwọn ajọ to n moju to owo ijọba àti NERC ko fọ́wọ́ sí i síbẹ̀ NBET bẹ̀rẹ̀ rẹ̀.
"Lásìkò to wá n bá àwọn akoròyìn sọ̀rọ̀, Ogaji ni "" ǹkan ti NBET ṣe yìí lásàn le mu ki àwọn dáwọ ina pinpin dúro to si túmọ si pé inú òkùnkùn birimù ni Naijiria yóò wà."
O ni ìnà ti jo dórí pápá lori ọ̀rọ̀ wọ́n nítori gbogbo ìgbésẹ̀ ti àwọn mọ ni àwọn ti gbé to fi mọ kíkọ lẹta si NERC ṣùgbọ́n síbẹ̀ wọ́n ketí ọgbọin sii.
'Àwa akódọ̀tí táà ń gba £1,500 lóṣù níbi sàn ju Sẹ́nétọ̀ lọ ní Nàìjíríà'
KogiDecides2019: Àjọ Ìsọ̀kan Yúròòpù àti Amẹ́ríkà bẹnu ẹ̀tẹ́ lu ìdìbò Kogi àti Bayelsa
Oríṣun àwòrán, EUinNigeria
KogiDecides2019: Àjọ Ìsọ̀kan Yúròòpù àti Amẹ́ríkà bẹnu àtẹ lu ìdìbò Kogi àti Bayelsa
Ajọ iṣọkan ilẹ Yuroopu ati ijọba orile-ede Amẹrika ti bẹnu atẹ lu bi eto idibo Gomina ni ipinlẹ Kogi ati Bayelsa ti ṣe lọ.
Awọn mejeeji ninu atẹjade kan ti wọn fi sita sọ pe o ku diẹ kaato bi iwa janduku, makaruru ati ibo rira ti ṣe gbode lasiko idibo naa.
Awọn aṣoju to woye eto idibo naa sọ pe ohun toju awọn ri lasiko idibo naa kọja afẹnusọ.
Wọn ni: ''A gbọ nipa awọn to ku ninu idibo naa ti awọn oṣiṣẹ ajọ eleto idibo miran si di awati.
Gbogbo awọn to farakaasa iṣẹlẹ naa la ba mọlẹbi wọn kẹdun''
Wọn kan sara si awọn oludibo to kopa ninu idibo mejeeji to waye lọjọ Abamẹta to kọja.
Gbogbo awọn to farakaasa iṣẹlẹ naa la ba mọlẹbi wọn kẹdun''
Bakan naa ni wọn kesi awọn alẹnulọrọ paapa julọ awọn ẹgbẹ oṣelu lati pẹtu sawọn eeyan wọn ki awọn ẹka ijọba si ri pe wọn tọ pinpin awọn to lọwọ ninu iwa ibajẹ lasiko idibo naa.
Kunle Afolayan: èmi kò fẹ́ fi ogún sílẹ̀ fún ọmọ mi
Lasiko idibo Kogi ati Bayelsa,awọn onwoye eto idibo ke gbajare lori bi awọn janduku ti ṣe n gbe apoti idibo ti wọn si n ra ibo.
O kere tan eeyan mẹta ni iroyin sọ pe o ku ninu idibo Kogi ti wọn si ni awọn oṣiṣẹ ajọ eleto idibo wa lara wọn.
Yollywood:Ṣàgbẹ̀lójú yòyò ni ọ̀ps àwọn òṣèré- Ojopagogo
Kogi 2019: Ohun mẹ́fà tó yẹ ní mímọ̀ nípa Yahaya Bello
Oríṣun àwòrán, @yahaya
Gomina ti yoo tun tukọ ipinlẹ Kogi lẹẹkeeji
Ajọ eleto idibo Naijiria, INEC ti kede Gomina Yahaya Bello pe oun lo jawe olubori ninu idibo ipinlẹ Kogi lẹẹkeji.
Oun lo ti n tukọ ipinlẹ naa bọ lati ọdun 2015 titi di asiko yii Yàjóyàjó: Èsì ìdìbò Kogi tó gbé Yahaya Bello wọlé rèé.
Lọjọ Abamẹta to kọja ni eto idibo naa waye kaakiri ijọba ibilẹ mọkanlelogun to wa ni ipinlẹ Kogi.
Ọjọ kejidinlogun, oṣu kẹfa, ọdun 1975 ni a bi Yahaya Bello ni ilu Okene ni ipinlẹ Kogi.
Yahaya ni abigbẹyin iya rẹ ninu ọmọ mẹfa ti Adédaa fun wọn.
O lọ sile iwe alakọbẹrẹ ti LGEA ni Agassa ni ijọba ibilẹ Okene lọdun 1984.
Kogi 2019: Àwọn ará ìlú sọ̀rọ̀ lórí ìrètí wọn lọ́wọ́ Yahaya Bello
Yahaya Bello kawe ipele akọkọ nile iwe girama Anyava ni Agassa community secondary school ni Okene.
Kogi vs Bayelsa: Primate Ayodele sọ àsọtẹ́lẹ̀
O gba iwe ẹri ipele girama agba oniwe mẹwaa ni Government Secondary School ni suleja ni ipinlẹ niger lọdun 1994.
Lẹyin eyi ni Yahaya lọ si ile iwe gbogboniṣe ni Zaria ni ipinlẹ Kaduna lati lọkẹkọọ nipa imọ iṣiro owo lọdun 1995.
'Àwa akódọ̀tí táà ń gba £1,500 lóṣù níbi sàn ju Sẹ́nétọ̀ lọ ní Nàìjíríà'
Yahaya gba oye imọ ijinlẹ ninu iṣiro owo ni ọdun 1999 ni fasiti Ahmadu Bello ni Zaria.
O tun gba oye imọ ijinlẹ ipele keji ti Masters lọdun 2002.
Ó di dandan kí ará India yìí sọ ìdí tó fi ń sìn kìnìhún- Egbeyemi
Yahaya Bello di akọṣẹmọṣẹ ti Association of national Accountants of Nigeria lọdun 2004.
O di gomina ipinlẹ Kogi lọdun 2015 labẹ asia ẹgbẹ oṣelu APC lati rọpo Abubakar Audu to dije dupo naa to si ṣalaisi ki wọn ti kede pe o wọle.
Ohun tawọn eeyan Kogi n sọ saaju idibo Gomina
Toilet: Nínú kó o fi omi fọ ìdi tàbí lo tííṣù fi fá a, Èwo ló rọrùn?
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Nilẹ Arab bi a ba n di ẹru lati rinrinajo, ohun mẹta ni a gbudọ rii daju pe a ni: iwe irina, owo ati ibi ti a le fọ idi si ni'rinajo. Eyi ni adẹrinpoṣonu ara ill Egypti Bassem Youssef sọ nibi ere itage akọkọ rẹ ni Uk gẹgẹ bi alawada.
(Ẹ̀rín kèékèé)!
Ṣe lo bẹrẹ si nii ju ọpa kan ti wọn n pe lede wọn ni shattaf (tabi bum gun) iyẹn ẹrọ kan to lee fọn omi jade to maa n wa lẹba ile igbọnsẹ igbalode fun idi fifọ.
"O ni ""ẹ wa, ko ye mi o, ẹ jẹ ọkan lara ilu to laju ju lagbaye, ṣugbọn to ba di ọrọ ti ẹyin wa yii, ẹyin lẹwa o."" (Ha ha ha)!"
Bẹẹ si ni ọpọ eeyan gba pẹlu Youssef pe ootọ lo sọ.
'Mo kàn máa ń lọ́ ayẹyẹ kiri torí ijó láì ṣe pé wọ́n pe mí ló sọ mí di DJ olórin Fuji nìkan'
"Shokoleeti to ri bii pẹ̀tẹ̀ -""Chocolate pudding"""
Ni ilu oyinbo, ọpọ wọn ti fẹran ki wọn maa fi nkankan nu idi ju bi wọn ba lo ile igbọnsẹ tan ju ki wọn maa bu omi ṣan idi lọ - eyi si jẹ oun to ya awọn eeyan lẹnu lagbaye.
Kẹẹ si maa wo o, omi a maa fọ idi mọ ju béébà lọ.
"Awọn to ti mọ lara ki wọn maa fi omi fọ idi wa beere tọkan tọkan wi pe "" ẹ wa, ṣe lootọ o tẹẹ yin lọrun lati fi tiiṣu nikan nu shokoleeti pẹ̀tẹ̀ kuro lara yin? (Ínyànmà)!"
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ati pe nigba ti tiiṣu ti wọ́n n lo lode oni ko le lara bii àwo sẹ̀rámííkì tawọn Greek igbaani maa n lo tabi shùkù àgbàdo tawọn Amẹrika igbaani maa n lo
(Hè hè hè hè - ẹ̀rín), gbogbo wa yoo gba pe omi ko tilẹ ki n ha ni lara to iwe to fẹlẹ ju.
Ọpọ ara ilu awọn orilẹede agbaye lo ti wa n pari abẹwo wọn sile igbọnsẹ bayii pẹlu omi.
'Àwa akódọ̀tí táà ń gba £1,500 lóṣù níbi sàn ju Sẹ́nétọ̀ lọ ní Nàìjíríà'
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Sibẹ, ni ọpọ awọ n orilede ti ẹlẹsin musulumi pọ si, omi lilo lo wọpọ nib gẹ́gẹ́ bi ẹkọ Islam ṣe kọ nipa lilo omi fun imọtoto.
Onimọ kan to ṣewadii nipa iha ti awọn eeyan n kọ si awọn nkan eelo ile igbọnsẹ, Othman fi han pe awọn musulumi ara orilẹede Australia kan ti dara pọ mọ iwa igbe aye lilo ile igbọnsẹ igbalode ati lilo tiiṣu pọ mọ age omi to kun tabi ki wọn ṣe ẹrọ to n fọn omi sẹgbẹẹ ẹrọ igbọnsẹ wọn.
Amọṣa o, ọ̀rọ̀ imọtoto yii ko duro lọdọ awọn musulumi nikan o.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
O ti mọ awọn ara orilẹede India kan lara lati maa lo tiiṣu, ṣugbọn ọpọ wa la ṣi fara mọ lilo omi nigba to ba yẹ.
"Othman ni ""nigba ti o ba fẹ ṣebẹwo si ọrẹ rẹ to jẹ ara Indian nilẹ Amẹrika, mo lee fwọ sọya pe wọn gbe ike omi tabi ife si ẹba ile igbọnsẹ wọn""."
Ẹwẹ, Othman sọ iha ti awọn eeyan kọ si lilo oriṣiriṣi beeba, o ni fun apẹrẹ akẹgbẹ oun kan ni Sheffield, UK ti lo tiiṣu rẹ tan, lo ba pada fi £20 nu idi. (Hà hà hàhà hà!)
Oríṣun àwòrán, Getty Images
'Pásítọ̀ ló sọ fún mi pé Ọlọ́run pè mí láti di Olokun tó ń bọ omi'
Idile kan, Kuo gan ti n jiroro lori ọrọ mejeji yii - ninu keeyan jokoo ya igbẹ tabi loṣoo.
Iru ile igbọnsẹ fun mejeji lo wa laye Han Dynasty (206BC-220AD) bi o tilẹ jẹ pe bibẹrẹ yẹn lo wọpọ lawọn ile igbọnsẹ itagbangba.
Koda lonii, iwadii fihan pe ida mẹta eeyan lagbaye lo maa n loṣoo ṣe 'ga.
Ka si ma parọ, fun ẹya agọ ara liloṣoo naa lo dara ju gẹgẹ bi iru ibẹrẹ yẹn ṣe maa n jẹ ko jade wọọrọwọ. (Hmmmmmn!)
Oríṣun àwòrán, Getty Images
World Toilet Day: Wo àwọn ewu tó rọ̀ mọ́ kí èèyàn máa gbọnsẹ̀ síbi tó bá wù ú
'Ìgbẹ́ tí wọ́n ń yà síbí kìí jẹ kí oníbàárà wá sọ́dọ̀ wa'
Iru ọjọ oni ni gbogbo ọdun ni ayajọ ọjọ igbọnsẹ lagbaye gẹgẹ bi ajọ UNICEF ṣe kede rẹ.
Ilé ìgbọ̀nsẹ̀ ìtagbangba n'Ibadan
Iwadii fi han pe orilẹede Naijiria lo ṣe ipo keji lagbaye ninu awọn to ṣe igbọnsẹ sita gbangba.
Ikọ BBC ba awọn ara adugbo kan ni ilu Ibadan sọrọ lori ohun ti wọn n koju lojoojumọ pẹlu bi ayika wọn ṣe kun fun ẹgbin ti wọn si ni ọpọlọpọ igba ni awọn eeyan ti sọ adugbo wọn di aaye ti wọn n ṣe igbọnsẹ si.
Ẹwẹ, ijọba kaakiri awọn ipinlẹ Naijiria ti n la awọn eeyan lọyẹ tori o n sakoba fun alafia awọn eniyan bẹẹ si ni wọn n gbẹ ṣalanga fun ṣiṣe gá ti wọn si n ṣe ipese omi ọfẹ.
'Lóṣù mẹ́ta sẹ́yìn, mò ń wa ọkọ̀ taasín, ṣùgbọ́n wọ́n sọ mí di afọ́jú lọ́san gangan'
Ilé ìgbọ̀nsẹ̀ ìtagbangba l'Eko
Nilu Eko to jẹ ọkan gboogi lara awọn ilu ti ọrọ aje ti burẹkẹ, eeyan to le ni miliọnu mọkanlelogun lo n wa jijẹ mimu nibẹ.
Bi wọn ba n lọ ti wọn n bọ, ti wọn n jẹ ti wọn si n mu bakan naa, o di dandan ki wọn ṣe 'ga nile igbọnsẹ.
Lori ọrọ ṣiṣe igbọnsẹ yii ni ipenija wa eleyi to jẹ ohun to rọ mo ayajọ ọjọ ile igbọnsẹ ti ajọ isọkan agbaye gbe kalẹ lati tọpinpin ipenija ààyè igbọnsẹ jakejado agbaye.
World Toilet Day: Aráàlú ní woléwolé yẹ kó bẹ̀rẹ̀ àyẹ̀wò ojúlé dé ojúlé
Lọpọ agbegbe niluu Eko, awọn eeyan a maa saba ṣe ibẹrẹ nitagbangba ti eleyii a si ma mu ki ayika maa run to si le mu ki itankale aisan onigba ati awọn aisan miiran pọ lawujọ.
Lati le koju ipenija yii, ijọba ati awọn ọlọdani a maa pese aye igbọnsẹ fara ilu yala lọfẹ tabi ki wọn san owo perete lati le fi lo ààyè igbọnsẹ wọn yi.
Ladugbo Ọbalende fun apẹrẹ, ikọ wa pade arakunrin kan to n pese ile igbọnsẹ fawọn eeyan lowo perete lati le fi dẹkun iwa ṣiṣe ga nitagbangba nibẹ.
Taju Ekemode fẹyin ti nidii iṣẹ ọlọpaa to si ni oun ko fẹ ki a fi aworan oun han.
Kogi vs Bayelsa: Primate Ayodele sọ àsọtẹ́lẹ̀
Nibi to kọ awọn ile igbọnsẹ si, o ni awọn kii fi igba tabi akoko da igba ti eeyan le fi lo ile igbọnsẹ.
Pẹlu bi o ti ṣe ni ile igbọnsẹ naa jẹ irọrun f'awọn to n gbe adugbo naa o ni awọn ṣi ni iṣoro pẹlu bi awọn eeyan ṣe n lo awọn ile igbọnsẹ rẹ.
''Pupọ ninu awọn to ba lo ile igbọnsẹ ni kii fiye si imọtoto ti wọn ba wa nibẹ. Bi wọn ko ba bi silẹẹlẹ, ẹlomiran a yagbẹ si gbogbo ilẹẹlẹ. Koda awọn mii a ma duro si ori awo igbọnsẹ dipo ki wọn jokoo.''
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ekemode tun sọ fun ikọ BBC Yoruba pe ile igbọnsẹ tawọn ni ko to fawọn eeyan ti ko ribi ṣe ga.
Lọdun 2018, Minisita fọrọ ipese omi ni Naijiria Suleiman Adamu nibi ipade kan sọ pe ti orileede India ba fi le mori bọ kuro ni ipo ti wọn wa gẹgẹ bi orileede ti iwa ka maa ya'gbe nitagbangba ti peleke ju lọ, idojuti nla ni yoo jẹ fun Naijiria nitori awọn ni wọn yoo gba ipo India.
Adamu ṣalaye pe laarin ọdun mẹta pere ti wọn ṣagbekalẹ eto lati koju ipenija yii, India ti kọ ile igbọnsẹ ọgọrin miliọnu ti ida marundinlọgọrun ninu ida ọgọrun awọn eeyan India si ti ni imọ nipa lilo ile igbọnsẹ lọna to ba ode oni mu.
2019 ni India lawọn fẹ jawọ ninu iwa yiyagbe sita gbangba. 2019 ọhun lo si ti fẹ dopin yii.
Oríṣun àwòrán, Getty Images, BBC
Njẹ Naijiria yoo ribi koju ipenija yiyagbe sita gbangba to gbode kan yii?
Tajudeen Ekemode ni idahun si ibeere yii ni ohun ko ro pe Naijiria le mori bọ ninu iwa yii pẹlu bi nnkan ti ṣe n lọ.
O ni kii ṣe nitoripe ijọba ko gbiyanju ṣugbọn bi ọrọ Yoruba to ni 'amukun ẹru rẹ wọ' ni ọrọ to  wa nilẹ yi ti ṣe ri.
Ekemode ni 'bi a ba wo oke ti a ko wo isalẹ, ko lee yanju.'
''Koda ki ijọba pese awọn ile igbọnsẹ yii fawọn ara ilu, iṣoro ki awọn eeyan fẹ lo awọn ile igbọnsẹ yii naa wa ti wọn gbọdọ koju.''
''Bi ẹ ba ni ki ẹlomiran wa san owo lati fi tọ, wọn a ni owo naa ti pọ ju wi pe ṣebi itọ lasan lawọn fẹ tọ?''
O ni iru awọn eeyan bẹ ni wọn kii bikita lati yọdi sita gbangba lati tọ tabi yagbẹ.
Oríṣun àwòrán, OTHER
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Koda ẹlomiran a ni ohun ma n gbadun bi atẹgun ṣe ma n fẹ si oun nidi nitagbangba ju ki ohun lọ lo ile igbọnsẹ.
Ekemode ni a fi ki a yi adisọkan awọn eeyan Naijiri pada lori lilo ile igbọnsẹ.
'Àwa akódọ̀tí táà ń gba £1,500 lóṣù níbi sàn ju Sẹ́nétọ̀ lọ ní Nàìjíríà'
EFCC: Akinwumi Sorinmade ni orúkọ tí Aroke ń lo ni ilé ìfowópamọ
Oríṣun àwòrán, Laailasnews
Ọdaran tó wà lẹ́wọ̀n tún wóke $100miílíọnu níta-EFCC
Olusegun Aroke tí àjọ tó n gbógun ti ìwà ìbàjẹ EFCC, jú ṣẹwọn ọdun mẹrinlẹ́logun ní ọgbà ẹwọn Kirikiri ní ìlú Eko ni wọ́n tún ń ṣe ìwadìí rẹ nitori pé oun ló tún wọké owó tó tó ọgọ́rùn mílíọnù naira laipẹ yìí.
Nínú ọgba ẹwọn lo ti ń ni ajọsẹpọ pẹ̀lú àwọn aráa rẹ̀ to kù nita pàápà jùlọ àwọn ti àjọ EFCC ń ṣewadiìí wọn fún kíkó owó ìlú pamọ lọ́nà àìtọ.
'Lóṣù mẹ́ta sẹ́yìn, mò ń wa ọkọ̀ taasín, ṣùgbọ́n wọ́n sọ mí di afọ́jú lọ́san gangan'
Ajọ EFCC sàlàyé pé ìwádìí fi han pé lòdi si òfin to gbe ọgbà ẹwọn ró o ní ànfani sí ẹ̀rọ ayelujara àti ẹrọ iléwọ nínú ọgbà ẹwọn to yẹ ti maa ṣẹwọn rẹ.
Wọn ni òun to tún wá yani lẹ́nu jùlọ ni pe Aroke lọ fun ìtọjú ara rẹ ni ilé ìwòsàn àwọn ọlọpàá ní Falomo nilú Eko fun àisan kan.
Láti ile ìwòsàn yìí ni o ti maa ń ló si ilé ìtura nibi tí o ti n ri ìyàwọ àti àwọn ọmọ rẹ̀ méjí, nígba miran a tún maa lọ fún awọn ayẹyẹ to ba ni.
Bakan  náà lo n lo orúkọ ti kìí jẹ Akinwumi Sorinmade, lati sí àpò ikówópamọ meji ni First Bank àti Guaratee Trust Bank (GTB), o ra oun ini si Fountain Spring Estate ni Lekki lọdun 2018 ni mílíọnù mejilélógun àti Lexus RX 350 fún iyawo rẹ̀ Maria Jennifer Aroke.
Ọdaran náà ni asẹ ǹkan ti ìyàwo rẹ̀ fi n gbowo ni Banki lọ́wọ́ nínú ọgbà ẹwọn to n lo lati rà tàbi ta bo ṣe wù ú nínú ọgbà ẹwọn to wá.
Wọn tun sàlàye pé lasìkò ti ìgbẹ́jọ rẹ̀ ń lọ lọdun 2015 ni Aroke ra ilé oni yàra mẹrin ni Plot 12, Deji Fadoju òpópònà, Megamounds Estate Lekki County Homes , Lekki  ní mílíọnù N48.
Oríṣun àwòrán, EFCC
Ọdaran tó wà lẹ́wọ̀n tún wóke $100miílíọnu níta-EFCC
Ajọ to ń gbógun ti ìwà jẹgúdújẹra ní orílẹ̀èdè Naijiria (EFCC) ní àwọn tí rí àsírí Hope Olusegun Aroke tí wọ́n jù sí ẹwọ̀n ọdún mẹ́rìnlélógun fún ìwà ọdàràn gbájuẹ̀ orí ayélujára pé o tún ni ibánisọrọ kíkún pẹ̀lú àwọn ọdàran mìíràn ti wọ́n si n ṣe ìwádiìí wọ́n lọ́wọ́.
EFCC ni àwọn ń ṣe ìwádìí wọ́n fún oníruuru ìwà ọdaran ori ayelujára àti kíko owó pamọ lọ́nà àìtọ́, àti pé ìwádìí fi han pé Olusegun Aroke lo ṣe agbódegbà fún olé ori ayelujara tó tó ọgọ́rún kan mílìọnù dọ́là bi o ṣe n ṣẹ̀wọ̀n rẹ̀ lọ́wọ́.
Kogi vs Bayelsa: Primate Ayodele sọ àsọtẹ́lẹ̀
Adajọ Lateefa Okunnu ti ilé ẹjọ giga ìlú Eko to wà ni Ikéja lo dájọ rẹ ninu osù kini ọdun 2016 láti ṣẹ̀wọ̀n ọdun mẹ́rìlélógun fun gbájuẹ̀ ori ayélujára lórí owó mílíọnù márundinlọ́gbọ̀n.
Akẹ́kọ̀ọ́ fasiti kan ni Malaysia ni Olusegun ki wọ́n tó mú u, ṣùgbọ́n kò fi ìgbà kankan simi iṣẹ́ gbájuẹ, lẹ́wọ́n gan ko dáduró láti tẹsíwájú iṣẹ́ gbájúẹ̀ rẹ to n ṣe.
'Lóṣù mẹ́ta sẹ́yìn, mò ń wa ọkọ̀ taasín, ṣùgbọ́n wọ́n sọ mí di afọ́jú lọ́san gangan'
#InternationalMensDay: Kí láwọn èèyàn fi kan sára s'áwọn ọkùnrin láyàjọ́ ọkùnrin lágbayé
Ki a to bẹrẹ ọrọ nipa ayajọ awọn ọkunrin lagbaye o tọ ki a jẹwọ pe nileeṣẹ wa lonii gan, kii ṣe gbogbo awọn obinrin to wa nibi lo ranti ki awa ọkunrin.
O tọ bakanna ki a tun sọ pe awọn ọkunrin gaan ko ranti pe wọn ya ọjọ yii sọtọ f'awọn, abi ẹ o ri nkan bii?
Bi awọn ko ti ṣe ranti la ba ni ki a kan si oju opo ayelujara lati wo boya awọn eeyan n sọrọ nipa ayajọ yii ati pe ki gaan ni ohun to rọ mọ.
Ki a to bẹrẹ si ni ṣafihan ohun ti wọn sọ, o ṣe pataki lati la ara wa lọye bi ọjọ yi ti ṣe waye
Lọdun 1992 ni wọn ṣe ifilọlẹ ọjọ yi lati pe akiyesi si awọn ohun to nii ṣe pẹlu ipa tawọn ọkunrin n ko lagbaye.
Oríṣun àwòrán, INSTAGRAM
Gbajúgbajà Òsèré Yoruba, Kunle Afod ti kópa nínú fíímù bíi Nkan agba, Odi ade, Ofin kokanla, Pitan ati Orindola.
Yatọ si awọn idi wọnyii, ọjọ naa ti wọn ṣagbekalẹ rẹ lori opo mẹfa, a maa ni akori orisirisi ti o nii ṣe pẹlu igbe alaafia f'awọn ọkunrin ati kikọ awọn ọdọkunrin ni iwa to yẹ lawujọ.
#InternationalMensDay ni awọn eeyan fi n p'akiyesi si ọjọ yii loju opo Twitter .
Labẹ hashtag yii, wọn n sọ nipa awọn ipenija to n ba awọn ọkunrin ti awọn miiran si n kan sara si ipa tawọn ọkunrin n ko lawujọ .
Arakunrin kan tilẹ sọ nipa iṣoro ti oun n koju eleyi to mu ki o fẹ gba ẹmi ara rẹ ni nnkan bi ọdun meloo kan sẹyin.
Irú kí leyi,iná jó òkú méjìlá mọ inú ílé ìgbókúpamọ́sí OAU
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ẹni ti ku ti nisinmi ni Yoruba a ma wi,ṣugbọn kini ka ti ṣe pe ti awọn oku mejila kan ti ina jo mọ aaye igbokupamọsi.
Iṣẹl yi waye ni oru ọjọ Iṣẹgun nigba ti ina kan ṣadede ṣẹyọ ni aaye igbokupamọ si ni ile iwosan ẹkọṣẹ iṣegun ti fasiti Obafemi Awolowo ni ilu Ile Ife.
Alukoro ọlọpaa nipinlẹ Osun lo fidi ọrọ yi mulẹ fun ikọ BBC Yoruba.
Folashade Odoro ṣalaye pe ko si ẹmi kankan to nuu ninu iṣẹlẹ naa ati pe aaye ikokupamọ si ni ijamba ina naa ṣakoba fun.
O tẹsiwaju pe awọn ọtẹlẹmuyẹ ọlọpaa ti bẹrẹ iwadi lori ohun to fa ina naa.
Ninu ọrọ ti wọn ta ri gbọ lati inu iwe Iroyin Naijiria,Punch,alukoro fasiti Obafemi Awolowo Abiodun Olanrewaju ninu sọ ninu atẹjade kan pe oku mejilelọgọrun lo wa nibi aye ikokupamọsi.
Gẹgẹ bi ohun to sọ, o ni nnkan bi ago mẹta oru ọjọ Iṣẹgun ni ina naa bẹrẹ.
''Ẹka fasiti naa ti ṣe eto lati fi ọrọ yi to awọn to loku ninu aye ikokupamọ si leti.''
Olanrewaju ni ọga agba fasiti naa Ọjọgbọn Eyitope Ogunbodede ti ṣe agbekalẹ igbimọ lẹni mẹta ti yoo se iwadi ohun to fa ina naa
Kogi Election: Kí ló mú àwọn jàndùkú dáná sun Aṣáájú obìnrìn ẹgbẹ́ òṣèlú PDP mọlé ?
Oríṣun àwòrán, OTHER
Awọn afunrasi janduku kan ti dana sun aṣaju awọn obinrin ẹgbẹ  oṣelu PDP kan mọ inu ile nipinlẹ Kogi.
Atẹjade kan lati ọdọ ileeṣẹ ọlọpaa ni ipinlẹ Kogi sọ pe Acheju Abuh lorukọ obinrin ti o kagbako iku ojiji ninu ile rẹ ni Ochadamu,eyi to wa ni ijọba ibilẹ Ofu, nipinlẹ Kogi.
Iṣẹlẹ naa waye  lẹyin idibo gomina ni ọjọ Àbámẹ́ta tó kọjá nipinlẹ naa.
Ileeṣẹ ọlọpaa ṣalaye pe edeaiyede waye laarin okunrin kan ti orukọ rẹ njẹ Awolu Zekeri, eni ọdun 35 to jẹ ọmọ ẹgbẹ oṣelu APC, ati Gowon Simeon to jẹ ọmọ ẹgbẹ oṣelu PDP ni agbegbe Ochadamu.
Nigbati aawọ yi waye, Gowon Simeon fi ọbẹ gun Awolu Zekeri ni itan, eyi to fa iku Zekeri lona ile iwosan.
Iṣẹlẹ aburu yi lo fa ibinu awọn ọdọ adugbo, eyi to mu ki wọn lọ si ile Simeon Abuh, eni to jẹ ẹgbọn fun Gowon, to ṣe ijamba naa.
Nibe ni wọn ti dana sun ilẹ rẹ pẹlu arabinrin Salome Abuh to wa ninu ile lasiko naa. Eni ọdun ọgọta ni Salome Abuh.
Yatọ si ile yi,Ile mẹta miran ni awọn ọdọ naa tun dana sun.
Oku arabinrin naa ni a gbọ pe wọn ti gbe lo si ile igbokupamọsi  to wa ni ile ẹko iwosan ẹkọṣẹ Ayingba fun ayẹwo.
Awọn ọlọpaa ti ko awọn ẹṣọ si agbegbe naa lati dẹkun rogbodiyan to le waye nitori iṣẹlẹ naa.
Ibadan Oba Crisis: Lekan Balogun ní ìjọba kò pe àwọn sípàdé kó tó gbé ẹjọ́ kúrò nílé ẹjọ́
Oríṣun àwòrán, Others
Awọn ọba mọkanlelogun to n de ade lẹyin Olubadan tilẹ Ibadan ti fesi lori iroyin kan to n ja rainrain nilẹ pe ileeẹjọ ti fẹ gba ade lori wọn.
Ọjọ Isẹgun lawọn iwe iroyin kan gbe sita pe, adajọ ile ẹjọ giga kan nilu Ibadan, Aderonke Aderemi ti kede pe ki wọn gbe iwe ofin to se igbega fawọn ọba mọkanlelogun nilẹ Ibadan ti sẹgbẹ kan naa, eyi to fun wọn lasẹ lati maa de ade bii ọba nilẹ Ibadan.
Iroyin naa fikun pe, gomina Seyi Makinde lo pinnu lati gbe ẹjọ fanfa laarin Olubadan ati awọn ọba alade yoku naa kuro nile ẹjọ, ki wọn lee yanju ọrọ naa nitubi n nubi, ki alaafia si pada jọba laarin Olubadan ati awọn ijoye rẹ.
Ọba Lekan Balogun, lasiko to n ba BBC Yoruba sọrọ kede pe, igbesẹ naa ko bojumu, ti awọn ko si faramọ rara nitori pe wọn kii fari lẹyin olori.
Ọba Balogun kede pe ti ijọba yoo ba gbe iru igbesẹ naa, sebi o yẹ ko bun awọn ọba mọkanlelogun naa gbọ, ki awọn si dijọ se ipinnu lori rẹ amọ eyi ko ri bẹẹ.
O fikun pe ade ori awọn wa titi laelae ni, ko si si ohunkohun to lee yẹ ade lori awọn nitori awọn yoo pada lọ pe ẹjọ miran lori igbesẹ tijọba gbe naa ni.
Oríṣun àwòrán, @pulseafricamag
Ko si ẹni to lee gba ade lori awa ọba mọkanlelogun nilẹ Ibadan nitori ọna to ba ofin mu la fi de ade naa, kii se ọna eru. Wọn ko pe wa si ipade ki wọn to ni awọn fẹ gbe ẹjọ kuro nile ẹjọ nitori naa ko lee seese. Awa naa yoo pe ẹjọ miran lati tako igbesẹ yii ni kiakia. Ko sẹ ni to lee yan wa jẹ, a ko lee gba.
Ki lo de ti ilana oye jijẹ nilẹ Ibadan ko se lee yatọ gẹgẹ bi awọn ilu miran nilẹ Yoruba. Bi ilu Eko se kere to yẹn, ọba mẹtalelaadọta lo wa nibẹ, amọ ọba kansoso lo wanilẹ Ibadan bo se tobi to. Bakan naa ni ọmọ sori nilẹ Ekiti, Ondo, Ẹgba ati bẹẹ bẹẹ lọ amọ ti Ibadan nikan lo yatọ nilẹ Yoruba.
Oríṣun àwòrán, @pulseafricamag
Ọba Lekan Balogun wa n beere pe ki lo de to jẹ ifẹ inu eeyan kansoso ni wọn fẹ tẹ lọrun lai ro idagbasoke ilẹ Ibadan lapapọ, nitori naa, o ni eyi ko lee seese, awọn yoo dijọ pade nile ẹjọ ni, ade yoo wa titi laelae ni, ko si ohun to lee yẹ lori awọn lọna to lodi sofin.
Naming of Railway stations in Nigeria: Afenifere, YCE, Akitoye, Fani-Kayode ní ẹ̀tanú Obasanjo ni Buhari ṣe
Yatọ si awuyewuye to n waye lori ayelujara, awọn ọmọ bibi ilẹ Yoruba kan ti fi èrò wọn han lori bi orúkọ aarẹ Naijiria nigba kan, Olusegun Obasanjo, ko ṣe sí lara orukọ ti ijọba apapọ kede lọjọ Aje fun awọn ibudokọ oju'rin ni Naijiria.
Akọwe ẹgbẹ ọmọ bibi ilẹ Yoruba, Afenifere, Yinka Odumakin, sọ pe ẹ̀tanú lo mu ki ijọba Buhari yọ orukọ Obasanjo sọ ibudokọ oju'rin kankan.
O ni nkan to mu ki orukọ Obafemi Awolowo wà nibẹ, naa lo yẹ ko mu ki ti Obasanjo naa pẹlu wọn.
"Nkan ti wọn ṣe yii ko bojumu, ko si le gbe wọn niyi.
Ni èrò tiẹ̀, ọmọ igbimọ Agbaagba ilẹ Yoruba, Yoruba Council of Elders, Kunle Olajide sọ pe, o da oun loju pe Aarẹ Muhammadu Buhari n wa nkan nla ti yoo fi sọ ori Oloye Obasanjo ni, kii se pe o mọọmọ ma ṣe e.
Oríṣun àwòrán, Others
O fikun ọrọ rẹ pe ko si bi a ṣe fẹ ẹ kọ ìtàn orilẹ-ede Naijiria, lai si orukọ Baba Obasanjo""."
"Ẹni ti gbogbo aye n bọ̀wọ̀ fun ni Obasanjo nitori awọn nkan to ṣe nigba to fi jẹ aarẹ ológun, ati alagbada. Nitori naa, ẹ ma jẹ ki a foya rara""."
O fi kun ọrọ rẹ pe nkan ti gbogbo ọmọ Naijiria, ati gbogbo ẹ̀yà yoo kan sara si ni wọn yoo fun Obasanjo, eyi to wúwo lọwọ ju fífi orukọ rẹ sọ ibudokọ oju'rin.
Lara awọn ọmọ ilẹ Yoruba to tun sọrọ ni Ọjọgbọn Banji Akintoye.
Oun naa sọ fun BBC pe, nkan buruku gba a ni bi ìjọba apapọ ko se fi orukọ Obasanjo si ara awọn eeyan naa.
O ni o yẹ ki ijọba fi ọrọ naa lọ awọn ọmọ ilẹ Yoruba ati ẹ̀yà to ku, lati gba akọsilẹ orukọ awọn eeyan to ṣe pataki si ẹ̀yà wọn, lati fun ni iru ọlá bẹ ẹ.
Ọrọ ti Minisita tẹlẹ fun irinna ofurufu, Femi Fani-Kayode sọ, ko yatọ si ti Ọjọgbọn Akintoye.
Kayode sọ pe orukọ Obasanjo lo yẹ ko siwaju gbogbo orukọ yoku.
Oríṣun àwòrán, Others
"Nkan ti wọn ṣe yẹn ko dara, paapa fun ẹni to ti jẹ aarẹ Naijiria lẹẹmeji.
Sugbọn sa, ọrọ naa ko le dun baba, nitori pe ọpọlọpọ ibi, oju ọna, ati agbegbe ni wọn ti fi sọ orúkọ rẹ. Awa ti a jẹ ọmọ Naijiria ni ọrọ naa n dùn."
Fani-Kayode fi kun ọrọ rẹ pe, ko tọ ọ láti maa fi ọrọ oṣelu bo ìtàn mọ́lẹ̀, nitori pe o yẹ ki wọn o bu ọlá fun ẹni to tọ si.
Oríṣun àwòrán, Others
Lori pe boya nitori pe Obasanjo ma n bu ẹnu ẹtẹ lu isejọba Aarẹ Buhari, o sọ pe eyi ko yẹ ko ribẹ.
Nise lo yẹ ki wọn o ma a kan sára si baba yẹn, nitori pe Naijiria i ba dara ka ni bi gbogbo awọn olori orilẹ-ede to ti jẹ tẹlẹ ṣe n ṣe niyẹn.
Oríṣun àwòrán, others
Oriṣiriṣi awuyewuye lo ti n waye lati igba ti ikede jade pe Aarẹ Muhammadu Buhari ti fi orukọ àwọn ọmọ Naijiria kan sọ ibudokọ oju'rin.
Bi awọn kan ṣe n kan saara si, ni awọn kan n bu ẹnu ẹtẹ lu u, paapa lẹyin ti ìwé iroyin Daily Trust, pé akiyesi si awọn orukọ naa ti ko ni orúkọ aarẹ Naijiria nigba kan, Olusegun Obasanjo ninu.
Botilẹjẹ pe awọn kan sọ oko eebu si iwe iroyin naa, fun pe o gbe 'iroyin ti ko ni itumọ' jáde, awọn kan sọ pe ko tọ ọ bi orúkọ Obasanjo ko ṣe sí nibẹ.
Amọ nigba to n fesi si awuyewuye araalu lori igbesẹ ijọba naa, agbẹnusọ fun aarẹ Muhammadu Buhari , Bashir Ahmad ni ko si ohun to jẹ pataki lori eyi.
Hepatitis: A kò leè kóo nípa dídìmọ́ ara ẹni
"Gẹgẹ bo ti wi ""Nitori pe orukọ aarẹ tẹlẹ, Olusegun Obasanjo ko si lara orukọ awọn ọmọ Naijiria tijọba fi sọri ibudo reluwe, kii se nnkan pataki."
"O ni oloye Obasanjo ni wọ̀n ti fi orukọ rẹ sọri ọpọ nnkan tẹlẹ, to fi mọ ọpọ opopona ni Kano."""
Ileesẹ ijọba apapọ to n risi igbokegbodo ọkọ ati eto irinna ni Naijiria ti fi atẹjade kan sita.
Nínú àtẹ̀jádé yii ni  wọn ti kede loni ọjọ Aje, ọjọ kẹtadinlọgbọn, osu keje pe awọn ibudokọ ọkọ oju irin ni Naijiria a gba orukọ tuntun.
Awọn ibudokọ ọkọ oju irin to wa ni opopona Eko si Ibadan to fi ya lọ ba ti Lagos Port Complex to wa ni ibudokọ ọkọ oju irin Apapa ni Aare Buhari ni ki wọn fi sọri igbakeji rẹ, Ọjọgbọ Yẹmi Osinbajo.
Fun alaye kikun, wo awọn orukọ ti awọn ibudokọ ọkọ oju irin naa n jẹ tẹlẹ ati orukọ tuntun ti ijọba Aarẹ Muhammadu Buhari fun wọn bayii:
Ibi ti ibudokọ ọkọ oju irin naa wa Orukọ ti ibudokọ ọkọ oju irin naa n jẹ tẹlẹEni ti Buhari fi orukọ ibudokọ ọkọ oju irin tuntun naa sọri bayiiOrukó tuntun ti a o maa pe ibudokọ ọkọ oju irin naa lati isinyii
Opopona Eko si Ibadan                        Ibudokọ ọkọ oju irin Kajọla          Ọjọgbọn Yemi Osinbajo (Igbakeji Aarẹ Buhari)           Ibudokọ Yemi Osinbajo
Agbegbe Apapa ni ilu Eko                         Ibudokọ ọkọ oju irin Apapa        Oloye Bola Ahmed Tinubu
(Agba ẹgbẹ o'selu APC)                          Ibudokọ Bola Tinubu
Agbegbe Ebute Metta                          Ibudokọ ọkọ oju irin Ebute Metta  Ogagun Mobolaji Johnson ( gomina ologun ipinlẹ Eko ri)        Ibudokọ Mobolaji Johnson
Agbegbe Agbado                            Ibudokọ ọkọ oju irin Agbado    Alhaji Lateef Jakande ( gomina ipinlẹ Eko ri)                        Ibudokọ Lateef Jakande
Agbegbe Agege                                          Ibudokọ ọkọ oju irin Agege                Babatunde Raji Fashola (minista isẹ àti iléègbé bayii)                           Ibudokọ Babatunde Fashola
Agbegbe Abeokuta                          Ibudokọ ọkọ oju irin Abeokuta   Ọjọgbọn Wole Soyinka (agba ọjẹ onkọwe)                                           Ibudokọ Wole Soyinka
Agbegbe Papa-Lantoro                          Ibudokọ ọkọ oju irin Papalanto  Funmilayo Ransome-Kuti (Oloogbe akinkanju obinrin Égba)    Ibudokọ Funmilayo Ransome-Kuti
Agbegbe Kila- Olodo                          Ibudokọ ọkọ oju irin OlodoOloye          Olusegun Osoba (to ti jẹ gomina ipinlẹ Ogun ri)                        Ibudokọ Segun Osoba
Agbegbe Omi Adio nitosi IbadaN Ibudokọ ọkọ oju irin Omi-Adio      Oloogbe Ladoke Akintola (to ti jẹ Olootu guusu Iwo Oorun Naijiria ri)                    Ibudokọ Ladoke Akintola
Agbegbe Ibadanibudokọ ọkọ oju irin Ibadan                                    Oloogbe Obafemi Awolowo (Baba iran Yoruba ninu oselu)                 Ibudokọ  Obafemi Awolowo
Agbegbe aarin gbungbun akoso                                     Ibudokọ akoso Operation Control CentreOloogbe Alex Ekwueme (to jẹ igbakeji aarẹ akọkọ ti a dibo yan ni Naijiria)Alex Ekwueme Operation Control Centre
Agbegbe Agbor                                                   Ibudokọ ọkọ oju irin Agbor Omowe Goodluck Jonathan (Aarẹ Naijiria tẹlẹ)                                 Ibudokọ Goodluck Ebele Jonathan
Agbegbe Itakpe                                              Ibudokọ ọkọ oju irin Itakpe                                                               Adamu Attah (Gomina Kwara akọkọ ti wọn dibo yan)
Agbegbe Ajaokuta ni ipinlẹ Kogi                   Ibudokọ ọkọ oju irin Ajaokuta        Oloogbe Olusola Saraki (agba oje oloselu ni Kwara)              Ibudoko Olusola Saraki
Agbegbe Itogbo                            Ibudokọ ọkọ oju irin Itogbo  Augustus Aikhomu (Igbakeji aarẹ labẹ ologun tẹlẹ)                                                        Ibudoko Augustus Ahikomu
Agbegbe Agenebode  Ibudokọ ọkọ oju irin AgenebodeGeorge Innih (to jẹ gomina ologun ipinle Bendel/ Kwara latijọ)                                   Ibudokọ George Innih
Agbegbe Uromi                       Ibudokọ ọkọ oju irin Uromi Oloogbe Anthony Enahoro (Ajijangbara oselu awa ara wa)                                          Ibudokọ Anthony Enahoro
Agbegbe Akehen                         Ibudokọ ọkọ oju irin Ekehen    Tom Ikimi (to jẹ minista ọrọ ilẹ okeere tẹlẹ)                                                                   Ibudokọ Tom Ikimi
Agbegbe Igbanke                         Ibudokọ ọkọ oju irin Igbanke     Samuel Ogbemudia  (To jẹ gomina ologun ipinlẹ Bendel latijọ)                        Ibudokọ Samuel Ogbemudia
Agbegbe Abraka                             Ibudokọ ọkọ oju irin Abraka ni ipinlẹ Delta David Ejoor (to jẹ ọga agba adari ologun tẹlẹ)                         Ibudokọ David Ejoor
Agbegbe Opara                           Ibudokọ ọkọ oju irin OparaMichael Ibru (to je gbajugbaja onisowo)                                                                     Ibudokọ Michael Ibru
Agbegbe Ujevwuibudokọ ọkọ oju irin Ujevwu         Oloogbe Alfred Rewane (to je igbakeji aaré lasiko ologun ri)                                      Ibudokọ Alfred Rewane
Agbegbe Agboribudokọ ọkọ oju irin ni abule Reluwe ni AgborMike Akhigbe (to ti je agba ologun ri)                                                       Ibudokọ Mike Akhigbe
Ileeese ijọba apapọ to kede yii salaye pe awọn eeyan wọnyii jk akọni ni Naijiria ti wọn ti gbe ogo ilẹ yii ga daadaa lati ọdun pipẹ sẹyin titi di asiko yii.
Oríṣun àwòrán, facebook/kunle ariyo
Lọna ati fi ẹmi imoore han si iṣẹ ribiribi to ṣe lasiko iṣejọba rẹ, aarẹ Muhammadu Buhari ti ni ki wọn fi orukọ ofiisi reluwe to wa ni Agbo, sọrii aarẹ ana, Goodluck Jonathan.
Amugbalẹgbẹ aarẹ lori ọrọ ayelujara, Tolu Ogunlesi lo fi ọrọ naa lede loju opo Twitter rẹ.
"Ogunlesi ni ""Aarẹ Muhammadu Buhari ti fọwọsi pe ki wọn fi ọfiisi reluwe to wa ni Agbo, ni ipinlẹ Delta sọri aarẹ  Goodluck Jonathan."""
Orukọ ti yoo maa jẹ bayii ni Goodluck Jonathan Railway Station & Complex.
Ọfiisi reluwe ọhun ni ojuko ileeṣẹ ọkọ oju irin to so Itakpe ati ilu Warri papọ, oun naa lo tun so oju ọna Benin mọ Onitsha, atawọn ilu miran ni Naijiria.
Oríṣun àwòrán, @ChibuikeAmaechi
Ọna oju irin naa wa lara ọna reluwe ti ijọba apapọ dawọle, eyii ti yoo so ipinlẹ Eko mọ Calabar atawọn ipinlẹ miran ni iha guusu-ila oorun Naijiria.
Iṣẹ ọhun ni wọn gbe fun ileeṣẹ agbaṣẹṣe ilẹ China, CCECC lasiko iṣejọba ọmọwe Goodluck Jonathan.
Ọdun 2015 ni aarẹ Buhari fidi Jonathan janlẹ ninu idibo sipo aarẹ to waye, eyii to ṣilẹkun akọsilẹ tuntun oludije sipo aarẹ akọkọ ti yoo gbo ewuro soju aarẹ to wa lori alefa ni Naijiria.
Oríṣun àwòrán, Facebook/Femi Adesina
Aarẹ Muhammadu Buhari ti ṣapejuwe aarẹ ana, Goodluck Jonathan gẹgẹ bi olori to jẹ olufọkansin bi Ọgbẹni Jonathan ṣe pe ẹni ọdun mejilelọgọta l'Ọjọru.
Aarẹ Buhari ni Jonathan jẹ olori ti ifọkansin rẹ yoo maa jẹ iwuri fun ọpọ irandiran to n bọ lorilẹede Naijiria.
Ninu atẹjade ti Buhari fi sita lati ọwọ oludamọran rẹ lori ọrọ iroyin, Femi Adeṣina, aarẹ Buhari ni imọran rere ni Jonathan n fun awọn olori Naijiria atawọn olori orilẹ-ede kaakiri ilẹ Afirika, lati igba to ti kuro ni ijọba.
Buhari wa gbadura ẹmi gigun ati ilera ninu ọrọ fun Jonathan ki o lee tubọ sin orilẹede Naijiria siwaju si.
Aarẹ Buhari sọ pe iwa irẹlẹ ti Jonathan ni jẹ ohun manigbagbe eleyi ti yoo mu ilọsiwaju ati idagbasoke ba awọn iran to n bọ.
Buhari tun ki gbogbo idile Jonathan pe ọpọ ọdun ni yoo ṣe loke eepẹ.
Aarẹ ana Jonathan gba pe oun fidi rẹmi ninu ibo aarẹ ọdun 2015, ki ajọ eleto idibo INEC to kede Buhari gẹgẹ bi ẹni to jawe olubori ninu ibo ọhun.
Babcock Sex Video: Láti ìgbà tí fásitì ti lé àkẹ́kọ̀ọ́ náà ló ti dùbúlẹ̀ àìsàn amọ́ ara rẹ́ ti dá
Oríṣun àwòrán, Babcock/Twitter
Arabinrin akẹkọọ fasiti Babcock ti fidio ibalopọ rẹ pẹlu ọrẹkunrin rẹ lu sori ayelujara ni ọdun sẹyin yoo lọ kawe si ileẹkọ fasiti loke okun.
Eyi ko ṣẹyin bi ileewe giga fasiti kan ni oke okun, ṣe fun arabinrin naa ni anfaani lati kawe lai san owo ileewe.
Dokita Ola Bukola to tun jẹ oluranlọwọ rẹ ni Niajiria, lo kede bẹẹ loju opo Twitter rẹ pẹlu afikun bukata ẹkọ rẹ naa ni oke okun ti gbe.
Arabinrin naa ni Fasiti Babcock fi ọwọ oṣi juwe ile fun, nitori fọnran kan to lu ayelujara pa, nibi ti ọkunrin kan ti n ba lopọ.
Dokita Bukola ni lati igba ti iṣẹlẹ naa ti ṣẹlẹ ni arabinrin naa ti n gba iwosan.
Nibayii, Dokita naa ni saka ni ara rẹ da, ti o si tun ṣe daadaa ninu gbogbo idanwo ti o ṣe.
Dokita Brown ni afojusun oun fun arabinrin naa ni ki o yege, ki o si di ẹni nla ni awujọ lọjọ iwaju.
Oríṣun àwòrán, Babcock
O ti kọkọ fi lede ni Osu Kẹfa wi pe gbogbo eto ti n to lati ri wi pe arabinrin naa lọ si ileewe giga lai si idẹyẹsi fun wọn.
Nigba naa, o ni aye arabinrin naa ti yipada si rere lati igba ti wọn ti le kuro ni ileewe, to si yege ni ẹkọ rẹ ati ihuwasi rẹ.
Ọpọ ọmọ Naijiria lo tako igbesẹ fasiti Babcock nigba naa, lori bi wọn ṣe fi ọwọ osi juwe ile fun akẹkọbinrin naa ti wọn n ba lopọ ninu fidio to lu ori ayelujara pa.
Saaju la ti mu iroyin wa fun yin pe fasiti Babcock ti fọwọ oṣi juwe ile fun akẹkọọbinrin to wa ninu fọnran to lu ayelujara pa, nibi ti ọkunrin ati obinrin kan ti ni ibalopọ.
Oríṣun àwòrán, Faceboo/Babcock University
Agbẹnusọ fun ile iwe Babcock to ba BBC sọrọ ṣalaye pe oṣu kẹrin ọdun yii awọn mejeeji ni ibalopọ ṣugbọn kii ṣe ninu ọgba ile iwe naa.
Agbẹnusọ fun ile iwe naa to ba BBC sọrọ ṣalaye pe, oṣu kẹrin ọdun yii awọn mejeeji ni ibalopọ ṣugbọn kii ṣe ninu ọgba ile iwe naa.
Ninu oṣu keji ọdun yii ni ile iwe naa kọkọ le ọkunrin to wa ninu fọnran lọ ile, lẹyin ti wọn fẹsun kan an pe o wu iwa to tapa sofin fasiti naa.
Obinrin to wa ninu fidio yii jẹ akẹkọọ ọlọdun kẹta ni ẹka ẹkọ imọ nipa iṣiro owo, Accountancy, ki wọn to sọ fun un pe ko lọ gbele ẹ.
Fasiti Babcock ni ọmọkunrin to ba ọ́kẹkọbinrin naa lopọ wa ni ile iwosan kan to ti n gba itọju nitori ogun oloro mimu, nibi ti akẹkọọ binrin naa ti lọ ba.
Atẹjade ti fasiti ọhun fi sita tun ṣalaye pe, nigba ti ile iwe naa wa ni isinmi ni akẹkọọbinrin naa lọ ba a nibẹ.
Kogi Election: Dino Melaye fẹ́ mọ bí ayédèrú ọlọ́pàá ṣé borí ọlọ́pàá gidi lásìkò ìdìbò Kogi
Oríṣun àwòrán, Dino Melaye
Oludije fẹgbẹ oṣelu PDP ninu idibo atundi Sẹnẹtọ fun ẹkun idibo iwọ oorun ipinlẹ Kogi, Dino Melaye ti ko ẹri lọ ba ajọ eleto idibo INEC lati ṣafihan magomago to waye lasiko idibo Kogi laipẹ yii.
Lọjọru ni Dino Melaye lọ pade oludari agba fẹka iroyin ati idanilẹkọ awọn oludibo labẹ ajọ INEC, Ọgbẹni Festus Okoye, ti o si gbe awọn ẹri naa to wa lori fọnran fidio DVD mọkanlelogun le lọwọ.
Dino Melaye ni pẹlu ẹri ti oun mu wa yii, ohun ti oun fẹ ni ki INEC wọgile idibo to waye naa.
Bakan naa lo fi iwe ifẹhonuhan tẹle awọn ẹri to mu wa, eleyi ti agbẹjọro rẹ, Tobechukwu Nweke buwọlu.
Lara ohun to sọ ninu iwe ẹsun rẹ ni pe ''iwa janduku, jiji apoti idibo gbe ati awọn aiṣedeede mii waye lasiko idibo naa, to fi mọ iwa ipaniyan, ti mo si fi ẹri rẹ sinu fọnran fidio ti mo mu wa, mo si n parọwa si INEC lati wọgile idibo naa''
Oríṣun àwòrán, Dino Melaye
Melaye tun bẹnu atẹ lu ọrọ ọga ọlọpaa Naijiria to sọ pe awọn oloṣelu lo ran asọ fawọn ayederu ọlọpaa to da ibo ru lawọn ibi kan ni Bayelsa ati Kogi.
Dino Melaye ni, ti iru nkan bayi ba ti n ṣẹlẹ ni Naijiria, ko si ireti pe aabo to peye le e wa fara ilu.
Awọn oṣiṣẹ ajọ INEC to gba iwe ẹsun ati ẹri to muwa lọwọ rẹ sọ fun pe, awọn yoo ṣe ayẹwo iwe ẹsun to mu wa naa.
INEC ti ṣaaju kede pe idibo ipo Sẹnẹtọ ti Dino Melaye ati Smart Adeyemi ti ẹgbẹ APC dijọ du ko kẹsẹjari.
Ajọ INEC naa ni nitori idi eyi, atundi ibo yoo waye lawọn ibi ti kudiẹ kudiẹ ti waye lasiko idibo.
Grammy Award: Burna, Sunny Ade, Femi Kuti ni àwọn akọrin Nàìjíríà tí orin wọ̀n gbà ìdánimọ̀
Oríṣun àwòrán, Twitter/burnaboy
Burna Boy
Ọmọ ti yoo ba jẹ asamu, kekere ni yoo ti maa jẹnu samusamu, bẹẹ lọrọ ri fun ilumọka akọrin takasufe ọmọ Naijiria nni, Burna Boy, ẹni to ti kọrin rẹ debi idanimọ Grammy bayii.
Loju opo ayelujara awọn alakoso eto ami ẹyẹ Grammy, ni wọn ti kede pe orukọ Burna Boy wa ninu akọsilẹ orukọ awọn eeyan ti wọn n woye fun ami ẹyẹ.
Isọri ami ẹyẹ ti wọn si fi orukọ Burna si ni ami ẹyẹ fun orin agbaye to fakọyọ julọ (Best World Music Album), orukọ awo orin rẹ to gbayi ti wọn fi faa kalẹ ni African Giant.
Ikede yii ti wa n mu ki awọn ọmọ Naijiria, akọrin ati awọn ololufẹ rẹ maa kan sara si loju opo Twitter rẹ pe o ku oriire.
Awọn akọrin miran ti wọn ti fa kalẹ fami ẹyẹ Grammy ṣaaju:
Angelique Kidjo lakọrin kan to ti gba ami ẹyẹ ni ipele ti wọn fa Burna Boy kalẹ fun yii. Lọdun 2016 si lo gba ami ẹyẹ naa.
Bi a ba ni ki a wo awọn akọrin lorilẹede Naijiria ti wọn ti fa kalẹ fun ami yii, wọn ṣe bii ẹni pọ diẹ.
Lara wọn la ti ri King Sunny Ade ti wọn fa kalẹ lẹẹmeji ọtọọtọ lọdun 1983 fun awo orin rẹ ti wọn pe ni 'Synchro System'.
Bẹẹ ni wọn fa awo orin rẹ miran 'Odu' kalẹ lọdun 1998 ni isọri ami ẹyẹ ti Burna Boy n dije fun bayii.
Awọn akọrin miran to tun ti kọrin gba idanimọ yii ni:
ODF Law: Ààrẹ Buhari ní àṣà ṣíṣe igá lójú táyé yóò di ọ̀rọ̀ ìtàn láìpẹ́
Oríṣun àwòrán, Unicef
Yoruba ni ilu ti ko ba si ofin, ẹsẹ ko si nibẹ, lati ọdun 2025 lọ, o ti di eewọ fun ẹnikẹni lorilẹede Naijiria lati yagbẹ si ibikibi to ba wu.
Idi ni pe aarẹ Muhammadu Buhari ti buwọlu ofin kan lọjọru eyi to ni o ti di eewọ lati maa yagbẹ kiri igboro lati ọdun 2025 lọ.
Ofin naa, ti wọn pe ni Executive Order 009 si nireti wa pe yoo fi opin si asa kawọn ọmọ Naijiria maa dawọ tẹlẹ laarin ilu lai lo ile iyagbẹ rara.
Nigba to n salaye ohun ti ofin 009 ọhun da le lori, Buhari ni ofin ti ileesẹ to n se akoso awọn ohun alumọọni inu omi gbe kalẹ yii, lawọn ẹka mii to ni nkan se pẹlu ọrọ ayika yoo gbaruku ti ko lee fidi mulẹ.
Oríṣun àwòrán, Unicef
Bakan naa ni ofin tuntun ọhun ti ro ileesẹ to wa fọrọ ohun alumọọni inu omi lagbara lati ri daju pe ileesẹ ijọba kọọkan, ileewe, ile itura, ileepo, ibudo ijọsin, awọn ọja gbogbo, ile iwosan ati awọn ọọfisi gbogbo ni anfaani si ile igbọnsẹ abi salanga ni ayika wọn.
Bakan naa nile asofin apapọ ati tawọn ipinlẹ yoo gbe ofin miran kalẹ eyi ti yoo  koro oju si iwa sise igbọnsẹ saarin igboro pẹlu ijiya to tọ ati owo itanran to yẹ lori ẹsẹ naa.
Sleeping at work: Ǹjẹ o yẹ kí èèyàn máa sùn lẹ́nu iṣẹ́?
Ijọba ilẹ̀ Amẹrika ti sọ pé ewú wà ti ẹnikẹni bá n sún òòrun lẹnu iṣẹ́, sùgbọ́n àwọn onimọ nipa oorun sàlàye pé ìjọba ni láti tún èrò rẹ̀ pa.
Ijọba ti pinnu láti gbé ìgbẹ́sẹ̀ to nípọn lóri ẹni to ba ń sùn lẹ́nu iṣẹ́.
John Berr to jẹ onímọ nípa oorun sọ pe bó tilẹ̀ jé pé àwọn òṣiṣẹ́ ìjọba tí ń ja ìjà yìí típẹ̀, ṣùgbọ́n ti ìjọba ko kọbíara síi.
"Wọn ò gbà àwọn ènìyàn láàyẹ lati sùn ní ẹnu iṣẹ́ pàápàá jùlọ ni àwọn ilé iṣẹ́ ìjọba àyàfi tí ẹni náà ba gba àṣẹ, èyí wà nínú àtẹjáde ti ìjọba fi síta nínú oṣù yìí.
Kò si ẹni to yé ìdí ti ìjọba fi gbé ìgbésẹ̀ yìí ṣugbọn wọ́n si kọ̀ láti sọ ǹkankan lée lóri bí gbogbo ènìyàn ṣe ń bẹnu ẹ̀tẹ́ lùú.
Oríṣun àwòrán, Nigeria police
Ǹjẹ o yẹ kí èèyàn máa sùn lẹ́nu iṣẹ́?
Ní ọdun 2018 ọfíísì agbẹjọrò àgbà fún ìpínlẹ̀ California fí àbájade ìwádìí kan nípa òṣìṣẹ́ ilé iṣẹ́ mọ́tò kan to ń sún oorun wákàti mẹ́ta lójòòjúmọ lẹ́nu iṣẹ́ sita.
Ìròyìn sọ pé ẹgbẹ̀rún lọ́nà ogójì dọ́la ni ìjọba ń pàdànú láàrin ọdún mẹrin.
Black women live matters: Ọdún 2015 ní àwọn ọlọ́pàá pa India Kager láìní ìdí- Gina Best
Bákan náà ní òṣìṣẹ́ tó ń sùn lẹ́nu iṣẹ́ n kó ìnira bá àwọn òṣìṣẹ́ to kù ni, nítorí àwọn kan ló ń ṣe iṣẹ́ rẹ̀ lásìkò tó n sùn.
Ọgá àgbà ilé ẹkọ kan ni iporuuru dé bi pé o ró pé òṣìṣẹ́ òhun ni àìsàn kan ti o ń mú kí o maa sùn lẹ́nú iṣẹ́.
Ó di dandan kí ará India yìí sọ ìdí tó fi ń sìn kìnìhún- Egbeyemi
Bó tilẹ̀ jẹ́ pé bi ìjọba ṣe dẹkun ki òṣìṣẹ́ máa sùn lẹ́nu iṣẹ́ lé mu ọkàn pòruuru, síbẹ̀ ìfọ̀rọ̀wérọ̀ o dúró lóri rẹ̀.
Ààrẹ ilé ìwòsàn obinrin Boston, Ọniṣegun oyinbo Lawrence Epstein, sọ pé o lé ni èèyan ààdọrin mílíọnù to ni ìṣòrò oorun ni ilẹ̀ Amerika.
Fake News; Àwọn iròyin ẹlẹ́jẹ̀ márùn ún tó fẹ́ẹ̀ tú Nàìjíríà ká
Oríṣun àwòrán, others
Fake News; Àwọn iròyin ẹlẹ́jẹ̀ márùn ún tó fẹ́ẹ̀ tú Nàìjíríà ká
Ilé ìgbìmọ àṣòfin àgbà ní Nàìjíríà ti ká àbádofin tí yóò maa kó àwọn ènìyàn ní ìjánú láti gbé ìròyìn òfégè tàbí sọ ọ̀rọ̀ kòbákùgbé sí olésèlú lórí ayelujára
fún ìgbà keji lánàá
Abadofin náà ni wọn pé àkọlé rẹ̀ ni 'Protection from internet Falsehood and Manipulation Bill 2019, èyí ti sẹnatọ Muhammed Musa ṣe onígbọ̀wọ́ rẹ̀.
Bó tilẹ̀ jẹ́ pé díẹ̀ ní àbádofín yìí fi yàtọ sí èyí ti àwọn ọmọ ilé ìgbìmọ asofin àgbà to kọja ṣe àgbékalẹ rẹ̀, sùgbọ́n Musa ni bí ayélujára ṣe ń ràn ìṣẹ̀jọba lọ́wọ́ ni àwọn ènìyàn ń lòó láti ṣe akóba fun ọmí aláafíà Naijíríà, nítori náà o ṣe pàtàkì láti mójú tóo.
Kíní ìdí tí àbádòfin yìí fi pọ̀ dàndàn fáwọn ọmọ ilé ìgbìmọ̀ asofin lásìkò yìí
Ọ̀pọ̀ àwọn ọmọ ilé aṣòfin to dá si ọ̀rọ̀ náà sàlàyé pé, kí ìlọsíwájú to lè wáyé, tólórí tẹ̀lẹ́mù gbọdọ wà ní ìṣọ̀kan sùgbọ́n, àwọn ènìyàn ń lò ayélujára láti gbé àwọn ìròyìn òfégè síta láti ṣátá ètò àti ìpínnú ìjọba.
Divorcee: Ó sàn kí wọ́n yàgò fúnra wọn ju ki wọ́n ṣe ara wọn léṣe- Fisayo
Wọ́n fi kún un pé ń ọ̀pọ ìgbà èyí a máa dá èdè àiyede sílẹ̀ láàrín àrá ìlú ti ó si máa n la ẹmí lọ nígbà míràn, tàbí kí o mú itẹsíwájú ǹkan rere nira.
Awọn àṣòfin fi kún un pé ni àye òdé òní, ọ̀pọ̀ àwọn ilé ìṣẹ́ ìròyìn tí ayelujara ló n dá omi aláafia ilú rú, ìlú ti kò si sí òfìn ẹ̀ṣẹ̀ ò sí ni bẹ, nítori náà òfin yìí jẹ ki olúkulùkù súnraki nítori ìjìyà to wà nibẹ̀
Oríṣun àwòrán, Senate
Wọ́n fi kún un pé ń ọ̀pọ ìgbà èyí a máa dá èdè àiyede sílẹ̀ láàrín àrá ìlú
Ilé ìgbìmọ̀ àṣofin tí ṣe àgékalẹ̀ ẹgẹ̀rún lọ́nà ọọdúrún naíra fun ọlọdani to ba lùgbàdi ẹṣẹ̀ yìí àti mílíọnù mẹ́wàá naira fún ilé iṣẹ́.
Bakan náà ni wọ́n rọ àwọn alárina fún ilé iṣẹ́ lori ayélujara láti ṣọ́rọ́ nitori kò yọ ẹnikẹni kalẹ̀.
World Diabetes Day: Ọdún kọkandinlogun ti mo ti wà lẹ́nu itọ ṣúgà nìyí
Ìròyìn òfégà Márùn-ún to ti fẹ́ẹ̀ pín Naijiria yẹ́lẹyẹ̀lẹ sẹ́yìn
Ẹ fí omí iyọ wẹ̀ nítorí Ebola:
Ní ọdún ọdún 2014 tí àìsàn ẹbola wọ orílẹ̀-èdè Naijiríà ní ìròyìn kan gba ìgbòrò kan pé báàlẹ Igala, ilú kan ipinlẹ Kogi ni ki àwọn ènìyàn máa fi omí iyọ wẹ̀ kí wọ́n máa ba ni àìsàn ebola.
Eyí mú kí ọ̀pọ̀ ènìyàn maa fi omí iyọ wẹ ti ọ̀pọ́ si di èrò ilé ìwòsàn fún àlòjù iyọ̀ nígbà ti àwọn ènìyàn mejí ku.
Iroyin ẹlẹjẹ yìí tàn ká gbogbo orílẹ̀-èdè Naijiria.
Buhari ti kú:
Ní Oṣù kẹsan an, ọdún 2017 ni Iròyìn gbòdé pé ààrẹ Nàìjíríà Muhammedu Buhari kú.
Won ni o ku lásìkò to lọ fun itọju fún ìgbà pípẹ ni ilẹ Gẹ́ẹ̀sí, wọ́n tún fi kùn un pé ayéderu Buhari lo wá si Naijira eyí ti wọ́n n pe ni ará Sudan.
Ọ̀rọ̀ yìí kọ́kọ́ jẹyọ lórí YouTube láti ẹnú Nnamdi Kanu to jẹ olórí IPOB, ọ̀rọ̀ yìí jà ranyin-ranyin lórí ayelujara tí ọ̀pọ̀ àwọn ènìyàn si n gbé ìròyìn náà kíri.
Ọ̀rọ̀ yìí pada tàn de ọ̀dọ̀ ààrẹ to si ni láti fi dá àwọn ara ìlú lóju ni ìgbà ti ìdìbò ọdun 2019 súnmọ, to si jade láti wá fi dá awọn ènìyàn lójú pé oun ni Buhari tààrà, bakán náà ni ilé iṣẹ́ ààrẹ tún fi àtẹjáde síta lórí ọ̀rọ̀ náà.
Ìjà to ṣẹ́yọ láàrin àwọn àgbẹ̀ àti Darandaran:
Àwòràn òfégè kan to tàn lori àtẹjiṣẹ́ twitter léyin ti ìjà bẹ́ silẹ̀ láàrin àgbẹ̀ àti danrandaran ti ìgbà ènìyàn sì báa lọ, ní wọ́n ni àwọn aworan náà jẹ ọkàn lara àwọn ti fúlani pa.
Nínú àwọràn náà ni obinrin kan dojubolẹ ninu àgbàrá ẹjẹ̀ rẹ̀ pẹ́lú àpá to lágbára ni apá rẹ̀, eyí ni wọ́n ni o jẹ ọkan lára àworan to wà ninu iṣẹ̀lẹ̀ náà.
Sùgbọ́n àwọran náà ti n ja lorí ayélujára láti ọdún 2011 tó si jẹ àra àwọn ìṣẹ̀lẹ̀ to wáye ninu ìjà abẹlé láàrin ọkọ ati ìyàwo ni Naijiria.
Bákàn náà ni àwọran miran tun jáde tí ọ̀pọ ẹ̀mí si sòfò, sùgbọ́n àyẹ̀wò fihan pé àwọn ènìyàn náà kìí tilẹ ṣe ara Naijiria àti pé Dominican Republic ni fóto náà ti wá, ìṣẹ̀lẹ̀ ìjàmba ojú pópó ló fàá lọ́dun 2015.
Atiku pín Ounjẹ àti owó fún ìpolongo idibò:
Laureetta Onochie to jẹ olùrànlọ́wọ́ pàtàkì fún ààrẹ Buhari lórí ọ̀rọ ayélujara padà tọ́rọ́ àfóríjìn gbàngba lẹyin tó parọ́ pé ààrẹ Buhari kọ òpòpónà túntún si Naijiria.
Ṣùgbọ́n ìwádìí fihan pé ojúlówó òpópónà náà wà ni Rwanda.
Oríṣun àwòrán, BBC Sport
Lẹ́yìn oṣù díẹ̀, Onochie tún gbée sórí Twitter ré pé Atiku Abubakar, O fi àwọn ènìyàn si inú òṣì bi o ṣe ń pín Ounjẹ àti owó lásíkò ìpolongo idibò"". Onochie gbé àwòràn Ounjé ati owó síta pe eyi wáye ni Sokoto."
Atiku yii lo jẹ́ alátakò Buhari fun ipò àarẹ lásìkò ìdìbò ọdún 2019
Buhari fẹ́ fẹ́ ìyáwó túntun:
Eyí to súnmọ etílẹ̀ jùlọ ni ìròyìn to gbòde láipẹ pé àarẹ Buhari ń mura láti fẹ́ ọkàn nínú àwọn mínísítà rẹ̀ Sadiya Umar Faruq.
Bo tilẹ̀ jẹ́ pé ìròyìn òfegè ni pé Buhari fẹ fẹ́ Sadiya, síbẹ̀ àwọn ọmọ Nàìjíríà ṣètò ìyàwò náà lórí ayélujára
Awọn iròyin ẹlẹjẹ marun to ti fẹ́ tu Naijiria ka
Ìrọ̀yìn òfégé náà gbalẹ̀ de bi pé wọ́n ṣe ìyàwò náà lóri ayelujára ni eyi ti ayé gbọ́ ti ọ̀rún náà mọ̀.
BBC n gba awọn eeyan ni imọran lati ṣọra nipa pinpin iroyin ofege kaakiri.
Nitori pe, iroyin ofege maa n da wahala silẹ ni.
Anatomy Book: Ọjọgbọn nílé ìwòsàn UCH àti UI gbé ìwé orúkọ ẹ̀yà ara lédè Yorùbá jáde
Awọn orukọ ẹya ara ọkunrin niwaju ati feremu ara lede Yoruba yii kamọmọ
Ojogbon Durotoye Adeleke salaye ni kikun nipa iwe eya ara yii ni eyi ti egbe Atunbi Yoruba ati Oasis Health Foundation se agbateru re ni UCH ni fasiti Ibadan.
Bi wọn se kọ orukọ ẹya ara ni ede Yoruba fun eniyan naa ni wọn kọ fun awọn ẹranko, a jẹ pe ise eniyan nise ẹranko
Bi inu eniiyan se ni itumọ orukọ lede Yoruba naa ni ita ni
Igbagbọ wọn ni wi pe ko tọ ki a maa fi ede gẹẹsi kọ ogidi ọmọ Yoruba ni eto ẹkọ, paapaa julọ awọn to n kẹkọ lẹka imọ iṣegun oyinbo
Ise eniyan nise ẹranko, ẹya ara ẹranko naa tun ni orukọ
Awọn ọjọgbọn marun un ọtọọtọ ni fasiti ilẹ Ibadan lo ṣe akojọpọ iwe atumọ ede naa ki ede Yoruba le tẹsiwaju
O to ọjọ mẹta ti wọn ti n gbero akanṣe iṣẹ naa ki o to di ohun ti wọn n ko jade bi ọmọ tuntun.
Iwe naa da lorii orukọ ti gbogbo ẹya ara kọọkan ti eeyan ati ẹranko n jẹ lede Yoruba pọnbele
Afojusun awọn ọjọgbọn naa ni lati tẹsiwaju ninu itumọ ede fun igbayegbadun gbogbo akẹkọ
Igbagbọ awọn ọjọgbọn ni wi pe ko tọ ki a maa fi ede gẹẹsi kọ ogidi ọmọ Yoruba ni eto ẹkọ, paapaa julọ awọn to n kẹkọ lẹka imọ iṣegun oyinbo
Opolopo ogidi omo Yoruba lo ti n fi idunnu won han lori iwe tuntun to jade lati odo awon agba ti ko fe je ki ede Yoruba parun.
Iwe yii lo ti jade fun lilo bayii, ki gbogbo omo Oodua lo ra ki a le tun ni imo kun imo nipa eya ara eniyan ati ti eranko ni ede abinibi wa gege bi awon ojogbon onimo kikun ninu ilera eda ati ede Yoruba ni fasiti Ibadan se gbee jade loni
Oyo Attack: Ilé ìwòsàn UCH ni Kọmíṣọ́nnà náà ti ń gba ìtọ́jú
Iṣẹlẹ iku awakọ kọmiṣọnna ṣeni laanu
Kọmiṣọnna fawọn ọlọpaa ni ipinlẹ Oyo ni awọn maa gbe awọn ọmọ janduku to ṣe iṣẹ buruku yii ri.
O fidiẹ mulẹ pe nitootọ ni iku awakọ kọmiṣọnna naa ba ni ninu jẹ ṣugbọn ọ́dílí to jẹ ọlọpaa to n ṣọ kọmiṣọnna ṣi n agb itọju nile iwosan ijọba bayii.
Oga agba awọn agbofinro fi da awọn eniyan ipinlẹ Oyo loju pe o di dandan ki agbara ofin mu awọn to ṣiṣẹ ibi naa.
O ni ọwọ ko ni pẹ tẹ awọn janduku naa nitori iwadiii ti bẹrẹ lọgan ti iṣẹlẹ naa ṣẹlẹ.
Awọn gende agbebọn kan ti kọlu Kọmiṣọ́nna fọrọ ilẹ ati ilegbe nipinlẹ Ọyọ, Amofin Abdulraheem Abiodun lalẹ Ọjọru ana.
Oríṣun àwòrán, Biodun Abdu-Raheem
Isẹlẹ naa la gbọ pe o waye ni deede aago mẹjọ alẹ ana nigba ti wọn n ja Kọmiṣọ́nna naa sinu ile rẹ, ti wọn si yin awakọ rẹ, Lukman Adebayo ni ibọn eyi to mu ko jade laye loju ẹsẹ, nigba ti wọn tun yin osisẹ ọlọpaa to n sọ ọ ni ibọn lapa.
Nigba to n fidi isẹlẹ naa mulẹ, agbẹnusọ fun ileesẹ ọlọpaa nipinlẹ Ọyọ, Gbenga Fadeyi salaye pe agbegbe ile Kọmiṣọ́nna naa ni Olunde Academy nilu Ibadan ni isẹlẹ naa ti waye.
Fadeyi ni Kọmiṣọ́nna ọlọpaa ti wa pasẹ pe wọn gbọdọ se awari awọn olubi ẹda to huwa laabi yii kiamọsa.
Oríṣun àwòrán, Biodun Abdu-Raheem
Agbébọn kọlu Kọmísọ́nnà fọ́rọ̀ ilẹ̀ àti ilégbèé ní Ọyọ, awakọ̀ dèrò ọ̀run
"Wọn pa awakọ kọmiṣọ́nna naa, ti wọn si tun yinbọn mọ ọlọpaa to n sọ pẹlu.
A maa wa wọn kan, ti ọwọ wa yoo si tẹ wọn, wọn si gbọdọ finmu ko ata ofin pẹlu, ti ẹlẹsẹ wọn ko si ni lọ laijiya.
Ko si ẹni to lee sọ iru ipo ti ilera Kọmiṣọna funra rẹ wa bayii nile iwosan UCH ti wọn gbe lọ,
Tabi idi ti wọn se kọ luu, bẹẹ ni awọn agbebọn naa tun mu ibọn ọlọpa to n sọ kọmiṣọnna naa lọ.
Ni bayii, ile asofin ipinlẹ Ọyọ ti pe ipade pajawiri igbimọ ile to wa fọrọ eto aabo lati jiroro lori isẹlẹ yii.
Ẹ wo fídíò Kìnìhún ní ibùgbé rẹ̀ tuntun ní Bogije, Lekki
Babcock Sex Video: Ọ̀pọ̀ èèyàn ní kò yẹ kí wọn lé akẹ́kọ̀ọ́bìnrin ọ̀hún torí kìí ṣe ọmọdé
Oríṣun àwòrán, Babcock University
Ọpọ ọmọ Naijiria lo ti n tako igbesẹ fasiti Babcock lori bo se juwe ọna ile fun akẹkọbinrin kan ti wọn n ba lopọ ninu fidio kan to lu ori ayelujara pa.
Bẹẹ ba gbagbe, ni Ọjọru ni fidio kan gba oju opo ikansira ẹni Twitter eyi to n se afihan ọmọbinrin kan ti ọkunrin kan n ba lopọ, ti oju ọmọbinrin naa si han sita fun araye ri.
Lẹyin eyi ni ileekọ fasiti Babcock fi atẹjade kan sita pe akẹkọ ileewe naa ni ọmọbinrin ti wọn n ba lopọ ninu fidio naa, to si jẹ akẹkọ ọlọdun kẹta ni ẹka ẹkọ nipa imọ isiro owo.
Bakan naa lo fikun pe ọmọkunrin to n ba obinrin naa sun ni fasiti ọhun ti le lori ẹsun oogun oloro, to si tun fikun pe oun ti juwe ọna ile fun akẹkọbinrin ti wọn n ba lopọ naa nitori idojuti to ko ba ile ẹkọ ọhun.
Oríṣun àwòrán, Babcock University
Atẹjade naa fikun pe kii se inu ọgba fasiti naa ni awọn mejeeji ti n se asemase naa to waye losu kẹrin ọdun 2019, bikose ile iwosan St Bridget to wa nilu Abeokuta nibiti ọmọkunrin naa ti n gba itọju lọwọ.
Nigba to n sọ ero rẹ lori igbesẹ fasiti Babcock naa, @Official_ubeets ni niwọn igba ti a ko ri ihooho eyikeyi ninu awọn akẹkọ naa, ti Jesu funra rẹ si sọ pe ẹni ti ko ba da ẹsẹ ri, ni ko kọkọ sọ okuta lu obinrin oni pansaga kan, ko yẹ ki wọn le akẹkọbinrin naa, ti ọga ileekọ fasiti Babcock ko ba si da ẹsẹ ri, ko jade sita.
@Cherrydoc_urch O n kesi awọn eeyan kan lati gbe igbesẹ lori bi fasiti Babcock se le akẹkọbinrin naa. O ni ọmọbinrin naa nilo igbimọ alagbara ti yoo ja fun lati pada sile ẹkọ rẹ nitori ko nilo lati se alaye kankan fun ileewe rẹ lori bi fidio naa se jẹ. Ẹ dakun, ẹ ran lọwọ.
Lero tiẹ, @lovedaisy04 naa ni ko yẹ bi fasiti babcock se le akẹkọbinrin naa niwọn igba ti kii se inu ọgba ileewe ọhun ni wọn ti n ba ara wọn lo pọ, obinrin naa si ni ẹts si ibalopọ to ba wu nitori kii se ọmọde rara. O ni o yẹ ka dẹkun iwa lile akẹkọ kuro nile iwe lọna aitọ.
@anyasi_emma n tiẹ ni kii se lile akẹkọbinrin naa kuro nile iwe lo kan, ohun si ri asọdun lori ohun to n sẹlẹ yii nitori awọn ibeere kan wa to yẹ ki fasiti Babcock kọkọ wa idahun si.
Akọkọ ni pe ta lo ju fidio naa sita to fi de oju opo Twitter, ati pe nitori ki lo mu ko se bẹẹ, awọn eeyan wo si lo n ba pin fọnran aworan naa kiri?
@Zolonye, oun ni ọmọbinrin naa nilo ifẹ ati atilẹyin awọn eeyan lasiko yii ju ki wọn maa bu lọ tabi ki ileewe rẹ le kuro.
Nàìjíríà ni orílẹ̀-èdè kẹta tí ìkọlù ìgbésùnmọ̀mí pọ̀ sí jùlọ láàgbáyé
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Nàìjíríà ni orílẹ̀-èdè kẹta tí ìkọlù ìgbésùnmọ̀mí pọ̀ sí jùlọ láàgbáyé
Abajade iwadii kan lori iwa igbesunmọmi ti kede rẹ pe Naijiria ni orilẹ-ede kẹta ti iwa igbesunmọmi ti wọpọ ju lọ lagbaye lọdun 2018.
Iwadii naa ti ajọ Development and Peace Initiative (IEP) ni ilu Sydney lorilẹ-ede Australia gbe jade ṣalaye pe ti a ba n sọrọ iwa igbesunmọmi lagbaye.
Wọn ni ọga ni kanwun lawujọ okuta ni orilẹede Afghanistan ati Irag. Lẹyin wọn lo wa kan orilẹede Naijiria ti a ba ni ki a wo iye awọn ẹmi ti o ti lọ sii.
Amọṣa, abajade iwadii naa ko ṣai tun ṣe e lalaye pe iye awọn eeyan to ku sinu ikọlu igbesunmọmi ti dinku lọdun 2019 yii si ọdun 2018 lorilẹ-ede Naijiria.
Oye ọlajingiri ni orilẹ-ede Naijiria jẹ lori igbelewọn naa nitori ipo kẹta yii kan naa ni wọn wa ni ọdun 2018.
Orilẹ-ede mẹwaa miran ni ilẹ Afirika ni wọn wa laarin ipo ogun akọkọ igbelewọn awọn orilẹ-ede ti iṣẹlẹ igbesunmọmi ti gogo julọ lagbaye.
World Diabetes Day: Ọdún kọkandinlogun ti mo ti wà lẹ́nu itọ ṣúgà nìyí
Bakan naa ni wọn tun fihan ninu iwadii naa pe iwa igbesunmọmi ti n pọ sii lagbaye.
O fi kun un pe iṣẹlẹ igbesunmọmi ọtalelẹẹdẹgbẹta ati meji, 562 lo waye lọdun yii lorilẹ-ede Naijiria eleyi to gba ẹmi ojilelugba, 2040 ti Naijiria tun fi di ipo kẹta mu.
Lorilẹ-ede Afghanistan to wa ni ipo kinni, ojilelegbeje ati mẹta, 1443 ikọlu igbesunmọmi lo waye nibẹ ninu eyi ti ẹgbẹrun meje ati ọọdunrun o le mọkandinlọgọrin, 7379 ẹmi si dero ọrun ọsan gangan.
Iraq to ṣe ipo keji foju wina ikọlu igbesunmọmi ẹẹdẹgbẹfa ati mọkanlelọgbọn 1131 to gbẹmi ẹgbẹrun kan ati mẹrinlelaadọta, 1054 eeyan.
Ẹ wo fídíò Kìnìhún ní ibùgbé rẹ̀ tuntun ní Bogije, Lekki
Abajade iwadi yii fihan pe ikọlu igbesunmọmi lorilẹ-ede Naijiria pọ ju ti orilẹ-ede Syria to wa ni ipo kẹrin pẹlu ikọlu ọtalelẹgbẹta ati meji, 662to sọ eeyan mọkanlelogoje, 131 di ero ọrun alakeji.
Ni gbogbo ilẹ Yuroopu eeyan mejilelọgọta 62 lo ba ikọlu igbesunmọmi lọ eyi si dinku si igba 200, to jẹ lọdun 2018.
Kano Emirs: Ilé ẹjọ́ wọ́gilé ìyànsípò àwọn Emir mẹ́rin tí Ganduje yan
Oríṣun àwòrán, Others
Asọ̀ ti ń waye tẹlẹ lori iyansipo awọn Emir mẹrin ti Gomina Ganduje yan loṣu kaarun ọdun yii amọ ile jọ ti da iyansipo naa nu.
Ijọba ipinlẹ Kano ti fagile idajọ ile ejọ giga to sọ wi pe Gomina ipinlẹ naa ko laṣẹ lati yan Emir tuntun ni ipinlẹ naa.
Eyi ko ṣẹyin idajọ ile ẹjọ to fagilẹ iyansipo awọn Emir tuntun mẹrin miran, ati wi pe ijọba ipinlẹ naa ko tẹle ọfin ipinlẹ naa ki wọn to yan Emir tuntun.
Ninu atẹjade ti Kọmisọnna fun ọrọ iroyin Muhammad Garba buwọlu ni wọn ti gbe ọrọ yii jade.
Garba ni awọn kọ idajọ ile ẹjọ, ati wi pe awọn Emir tuntun mẹrin naa duro gẹgẹ bi ọba ọlọla bii Emir Sanusi.
Ni ibẹrẹ ọdun yii ni Gomina ipinlẹ Kano, Abdullahi Ganduje da Emirate tuntun mẹrin si agbegbe Bichi, Karaye, Gaya ati Rano pẹlu Emir tuntun wọn.
Bo ṣe wa ni liki lo wa ni gbanja lọrọ bi ile ẹjọ nilu Kano ṣe wọgile iyansipo awọn ọba ti Gomina Ganduje yan sipo.
Bi a ko ba gbagbe, laipẹ yi ni irufẹ idajọ bẹẹ waye nilu Ibadan, ti ile ẹjọ gba awọn ọba ti Gomina ana nipinlẹ Ọyọ, Abiola Ajimobi yan sipo nilu Ibadan.
Nilu Kano, igbimọ lọbalọba ipinlẹ naa lo yan awọn ọba mẹrin tuntun yii sipo.
Adajọ Usman Na'abba to lewaju awọn adajọ to gbe idajọ naa kalẹ, fidi ọrọ mulẹ pe wọn ko tẹle iyana to tọ pẹlu iyansipo awọn ọba naa.
Losu Karun ọdun 2019 ni Gomina Abdullahi Ganduje ipinlẹ Kano buwọlu abadofin kan, to faaye gba iyansipo awọn ọba onipo kinni fawọn agbegbe mẹrin nilu ọhun.
Oríṣun àwòrán, Others
Awọn agbegbe naa ni Rano, Gaya, Karaya ati Bichiin
Igbesẹ yii ti Gomina Ganduje gbe, lawọn eeyan kan woye o wa lati fi ge iyẹ Emir Sanusi Lamido, to si mu ariwisi ọtọọtọ wa nigba naa.
Yatọ si iyansipo awọn Ọba tuntun wọnyii, Gomina Ganduje buwọlu iwe to ni ki Emir Sanusi Lamido fi ipo rẹ silẹ, lẹyin ti igbimọ lọbalọba ṣe iwaadi lori ẹsun ajẹbanu ti wọn fi kan-an.
Iyansipo awọn Ọba yii ko dun mọ awọn afọbajẹ ninu, ti wọn si gba agbẹjọro lati tako iyansipo awọn ọba wọn yii nile ẹjọ.
Oríṣun àwòrán, Alamy
Abalọ ababọ nile ẹjọ, lo pada wa ja si idajọ to waye to wọgile iyansipo awọn ọba naa.
Awọn Ọba tuntun ti ile ẹjọ paṣẹ pe ki wọn wọgile iyansipo wọn ni Emir Aminu Ado Bayero to jẹ Emir agbegbe Bichi, Ibrahim Abubakar to jẹ Emir agbegbe Karaye; Tafida Abubakar Ila tii se Emir agbegbe Rano ati Ibrahim Abdulkadir to jẹ Emir agbegbe Gaya.
Oríṣun àwòrán, Other
Ile ẹjọ ni ile aṣofin tapa si ofin yiyan ọba nipinlẹ Kano eyi to lodi sofin.
Gomina Ganduje yan ọba onipo kini mẹrin
Pneumonia: Dókítà ní kòkòrò àìfojúrí ló ń fàá
Killer Mum: Kí ló lè mú kí ìyá pa ọmọ rẹ̀ sè jẹ?
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Awọn alaṣẹ lorileede Tanzania ti ni ki awọn oṣiṣẹ ijọba agba tẹ ọkọ leti ni kiakia, lati lọ foju ri oun to n ṣẹlẹ labule kan lẹyin ti iroyin kan pe obinrin kan pa ọmọ rẹ jẹ.
Gẹgẹ bi ohun ti akọroyin BBC jabọ, wọn ni labule Mavanga ni obinrin naa ti fi ọbẹ du ọmọ rẹ, to si se e, ki o to wa bẹrẹ si ni jẹ.
Awọn agbofinro ti mu obinrin naa ati ọkọ rẹ, lati fọrọ wa wọn lẹnu wo.
Emmanule Ngalikakwa to jẹ kansilọ agbegbe naa ṣalaye fun akọroyin BBC ohun ti obinrin naa sọ fawọn aṣaaju abule.
O ni nigba ti wọn kọkọ beere ọrọ lọwọ obinrin naa, o ni oun ju oku ọmọ naa si inu ṣalanga ni  lẹyin toun pa.
Ni igba ti wọn tẹ ninu daada, o yi ọrọ pada to si  sọ pe, okuta nla loun fi fọ ọmọ naa lori, ki ohun to gbe oku rẹ lọ si inu igbo.
Aṣẹyinwa aṣẹyinbọ, nigba to de inu igbo to sọ, obinrin naa  sọ fun wọn pe, oun du ọmọ naa, ki oun to ge wẹlẹwẹlẹ ti oun si se jẹ.
Ko ti daju boya arun ọpọlọ n damu arabinrin naa ṣugbọn awọn ọlọpaa ni o yẹ ki iwaadi awọn sọ ohun to mu ki obinrin ọhun hu iru iwa bẹẹ.
Kogi àti Bayelsa: Gomina Yahaya Bello ti Kogi àti David Lyon ti Bayelsa gba ìwé ẹ̀rí INEC
Oríṣun àwòrán, others
Gomina Yahaya Bello gba iwe ẹri mo yege lọwọ ajọ eleto idibo
Ajọ eleto idibo INEC ti fun gomina ti wọn kede pe o jawe olubori ninu idibo ipinlẹ Kogi, Yahaya Adoza Bello ni iwe ẹri lati pada sipo gomina.
Edward Onaja naa gba iwe ẹri o pegede lati gba ipo igbakeji gomina ipinlẹ Kogi Adájọ́ àgbà ní Kogi búra fún igbákejì gómìnà tuntun.
Awọn mejeeji ni wọn ti jọ n tukọ ipinlẹ Kogi naa papọ lẹyin ti Yahaya Bello ti fa Onoja kalẹ gẹgẹ bi igabkeji rẹ tẹlẹ.Yahaya Bello, Gomina ìpínlẹ̀ Kogi kéde Onoja ní ìgbákejì tuntun
Oríṣun àwòrán, Inec
INEC fun David Lyon to dije dupo gomina labe APC
Bi ajọ eleto idibo INEC ṣe n fun Gomina Yahaya Bello ati Onoja igbakeji rẹ ni iwe ẹri o yege naa ni wọn n fun David Lyon ni Bayelsa.
David lo dije dfupo gomina labẹ ẹgbẹ oṣelu APC ni ipinlẹ Bayelsa pẹlu Senetọ Biobarakuma Degi-Eremienyo to jẹ igbakeji rẹ.
Arabinrin May Agbamuche-Mbu to jẹ adari ajọ eleto idibo ni ẹkun Bayelsa, Edo, ati ipinlẹ Rivers lo fun awọn mejeeji ni iwe ẹri yii ni Yenagoa Bayelsa loni.
Lyon ni oun fi iwe ẹri naa sọ ori awọn eniyan ipinlẹ Bayelsa lẹyin to dupẹ lọwọ ajo INEC, awọn agbofinro ati awọn oṣiṣẹ elto aabo gbogbo pe wọn ṣiṣẹ daadaa.
Gomina Bello ati Onoja igbakeji rẹ a bẹre iṣẹ fun saa iṣejọba tuntun yii ni ọjọ kẹtadinlọgbọn, oṣu kinni, ọdun 2020.
Ogbeni Muhammed Haruna to jẹ kọmiṣọna fun ajọ eleto idibo ni ẹkun Kogi, Kwara, ati Niger lo fun wọn ni iwe ẹri naa loni ni Lokoja.
Ohun tawọn eeyan Kogi n sọ saaju idibo Gomina
Bello naa gboriyin fawọn eniyan ipinlẹ Kogi pẹlu ileri tuntun lati ṣeto ijọba to dara lasiko yii.
Gomina tuntun naa nṣeleri lati ṣiṣẹ pẹlu awọn agbofinro lati ṣawari awọn to ṣiṣẹ ibi ṣaaju, idibo ati lasiko idibo ni ipinlẹ Kogi.
Kí ló lè mú kí ìyá pa ọmọ rẹ̀ sè jẹ?
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Awọn alaṣẹ lorileede Tanzania ti ni ki awọn oṣiṣẹ ijọba agba tẹ ọkọ leti  ni kiakia lati lo foju ri oun to n ṣẹlẹ labule kan lẹyin ti iroyin kan pe obinrin kan pa ọmọ rẹ jẹ.
Gẹgẹ bi ohun takọroyin BBC jabọ, wọn ni labule Mavanga ni obinrin naa ti fọbẹ du ọmọ rẹ,to se e ki o to wa bẹrẹ si ni jẹ.
Awọn agbofinro ti mu obinrin naa ati ọkọ rẹ lati fọrọ wa wọn lẹnu wo.
Emmanule Ngalikakwa to jẹ kansilọ agbegbe naa ṣalaye fakọroyin BBC ohun ti obinrin naa sọ fawọn aṣaaju abule.
O ni nigba ti wọn kọkọ beere ọrọ lọwọ obinrin naa, o ni ohun ju oku ọmọ naa si inu ṣalanga ni  lẹyin toun pa.
Ni igba ti wọn tẹ ninu daada, o yi ọrọ pada to si  sọ pe okuta nla loun fi fọ ọmọ naa lori ki ohun to gbe oku rẹ lọ si inu igbo.
Aṣẹyinwa aṣẹyinbọ, nigba to de inu igbo to sọ, obinrin naa  sọ fun wọn pe ohun du ọmọ naa ki ohun to ge wẹlẹwẹlẹ ti oun si se jẹ.
Ko ti daju boya arun ọpọlọ n damu arabinrin naa ṣugbọn awọn ọlọpaa ni o y ki iwaadi awọn sọ ohun to muhu iriiwa bẹ.
Polio: Bàbá kọ abẹ́rẹ́ àjẹsára kí ọmọ rẹ̀ tó ní àìsàn polio!
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Polio: Bàbá kọ abẹ́rẹ́ àjẹsára kí ọmọ rẹ̀ tó ní àìsàn polio!
Awọn osisẹ eleto ilera ti ni awọn ni abẹrẹ ajẹsara to le tọju awọn ọmọde kaakiri Naijiria, amọ awọn obi miran si n kọ fun ọmọ wọn lati gba ajẹsara.
Eyi ni iriri Arakunrin Adamu Misa lati ipinlẹ Yola, ni ẹkun Ariwa orilẹ-ede Naijiria.
Misa sọ nipa bii oun se tako lilo abẹrẹ ajẹsara fun gbogbo ọmọ ti oun bi, ko to di pe ọmọ oun kẹta wa ni arun polio, ti o si rọ apa ati ẹsẹ rẹ.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ẹ wo ìdí tí ẹ gbọdọ̀ fi gba abẹ́rẹ́ àjẹsára fún ọmọ yín!
Adamu ṣalaye fun Charles, akọroyin BBC pe: Ọmọ rẹ, ọdun mẹjọ lo sun lai si nkan to ṣe e, ki o to wa dii wi pe ko le e gbe apa gbe ẹsẹ ati apa rẹ, ki o to di wi pe wọn gbe e lọ si ile iwosan.
Adamu ti wa di eni to n gba awon eniyan ni iyanju lati ma a gba abẹrẹ ajesara ni igbakugba fun awon ọmọ won lati dena aarun to le gba ẹmi wọn.
Ki o to di asiko yii, awọn ara agbegbe naa gbagbọ pe ti awọn ba gba abẹrẹ ajẹsara fun ọmọ wọn, awọn oyinbo naa n gba nkankan ninu ẹjẹ ati egungun awọn ọmọ wọn ni.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ajọ ilera ni agbaye, WHO ni orilẹ-ede Naijiria ko i tii lugbadi aisan polio lati ọdun mẹta sẹyin.
Ni eyi ti o si seese ki wọn sọ wi pe Naijiria ko le e gburọ aisan polio mọ ti ko ba si iru aisan naa mọ titi di ọdun 2020.
Ẹ̀mí kan náà ló n darí ìrìnàjò wa táa fi jọ kọ́lé papọ̀- Ìbejì
Amọ ajọ naa n woye wi pe pẹlu ikọlu Boko Haram ni awọn agbegbe ẹkun Ariwa Naijiria, eleyii ti o le fa ki o ma si imọtoto ni agbegbe naa, o seese ki aisan naa pada.
Ajọ WHO naa wa rọ awọn obi lati ma a fun awọn ọmọ wọn ni abẹrẹ ajẹsara ti o ba yẹ nigba kugba, ki o ba le dena aarun ati iku ọmọde lorilẹ-ede Naijiria.
Mo kabamọ pe mi o gba abẹrẹ ajẹsara fun ọmọ mi
Ọpọlọpọ iwadii lo ti fihan pé ọmọ ti ko ba gba abẹrẹ ajẹsara lasiko to yẹ ko gbaa le pada lugbadi arun rọparọsẹ ati awọn ikọlu miran lọjọ iwaju.
Lagos traffic: Ohun márùn ún tó ń fa súnkẹrẹ-fàkẹrẹ nílùú Eko
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Gbogbo eeyan lo mọ pe ninu awọn ilu to tobi lagbaye ni ilu Eko wa.
Fun  ọpọlọpọ eeyan, ko si ohun meji to kọkọ n wa sọkan awọn eeyan bi wọn ba gbọ orukọ ilu Eko ju sunkẹrẹ fakẹrẹ ọkọ lọ.
Ko si idi meji lori eyi ju pe sunkẹrẹ fakẹrẹ ọkọ lo n jọba l'Eko. Amọṣa, titi di bi a ṣe n sọ yii, ko tii si ojutu fun un.
Kii ṣe aniani pe ọpọ awọn opopona ni ilu Eko ni ko dara fun lilọ-bibọ ọkọ to ja geere.
Eyi to kun fun ọpọlọpọ koto. Awọn koto wọnyii ni o maa n kun fun omi nigba ojo ti o si maa n fana atogbemulemu awọn ọkọ.
Ọpọ igba ni ijọba ipinlẹ Eko funrarẹ ti jẹwọ pe bi ọrọ ṣe ri gẹlẹ niyi.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Kii ṣe aniani pe ọpọ awọn opopona ni ilu Eko ni ko dara fun lilọ-bibọ ọkọ to ja geere.
Gbogbo eeyan lo mọ pe ninu awọn ilu to tobi lagbaye ni ilu Eko wa.
Bi awọn eeyan si ti ṣe pọ to nibẹ naa ni iye awọn ọkọ ti wọn n lo fun irinna pẹlu n pọ sii. Abajade eyii naa ni sunkẹrẹ fakẹrẹ ọkọ.
Opọlọpọ lo maa n gbe ọkọ soju titi lojoojumọ ni eyi to tun n ṣafikun si iṣoro yii.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Lagos traffic: Ohun márùn ún tó ń fa súnkẹrẹ-fàkẹrẹ nílùú Eko
Ọpọ igba ti sunkẹrẹ fakẹrẹ ba wa loju popo ni ipinlẹ Eko lo maa n jẹ afọwọfa awọn awakọ.
Ọpọ iwa kokanmi, tani yoo mumi ati aibikita awọn awakọ, yala awakọ ero ni tabi aladani, lo n fa sunkẹrẹ fakẹrẹ ọkọ.
Ọpọ awakọ ati awọn ero loju popo lo maa n huwa ti ko tọ laarin titi ati ni ẹgbẹẹgbẹ opopona.
Awon awakọ miran a bọ aṣọ silẹ maa ba ara wọn ja loju popo lai palẹ ọkọ tabi alupupu wọn mọ kuro lọna ki ẹlomii le ri aaye kọja lasiko.
Ọpọ ninu awọn onidanfo a tun duro si aarin titi maa wa ero.
Bi o tile jẹ pe a ni ọpọlọpọ awọn oṣiṣẹ rere lawọn ajọ bii ileeṣẹ ọlọpaa, LATMA, bẹẹ naa ni a ni ọpọ to jẹ kọlọransi laarin wọn.
Ṣe wọn si ni eeyan kan lo pari ni ilu ti wọn fi n pe gbogbo ilu ni apari.
Awọn kọlọransi agbefọba wọnyii ni wọn maa n lo ipo wọn ni ileeṣẹ ijọba lati wa bi wọn yoo ṣe gbowo lọwọ awọn awakọ ni tipatipa.
Ẹ̀mí kan náà ló n darí ìrìnàjò wa táa fi jọ kọ́lé papọ̀- Ìbejì
Nipasẹ ọna ti ko dara, Aletilapa awakọ, ọpọlọpọ ijamba oju popo ni o n waye loju popo ni ipinlẹ Eko.
Bi ijamba ṣe lee da wahala sunkẹrẹ-fakẹrẹ silẹ niwọnba lo jẹ wi pe aijafafa awọn ajọ gbogbo to yẹ lati tete palẹ oju popo mọ gan an ni ogunnagbongbo ohun gan an to n ṣẹlẹ.
Ọpọ igba ti ijamba ba ṣẹlẹ lopopona awọn oṣiṣẹ bii ti eleto ilera fun iṣẹlẹ pajawiri, panapana, adari ọkọ, atawọn agbefoba miran ni wọn ko ni tete ṣe ohun to yẹ lasiko.
Awọn ọkọ a wa maa to tẹle ara wọn ni eyi to tun maa fa sunkẹre-fakẹrẹ loju titi
Pneumonia: Dókítà ní kòkòrò àìfojúrí ló ń fàá
Uganda faulty condom: Uganda kó rọ́bà ìdáàbòbò mílíọ̀nù kan kúrò ní ìlú
Oríṣun àwòrán, Marie stopes Uganda
Marie Stopes salaye pe wọn ti bẹrẹ iwadii lori ohun to ṣokunfa abuku ninu ọra idaabobo wọnyii
Ile iṣẹ arannilọwọ kan ti kii ṣe ti ijọba ni orilẹ-ede Uganda ti palẹmọ awọn rọba idaabobo wọn kuro nilẹ.
Marie Stopes ti ko awọn rọba to le ni miliọnu kan ti wọn ti kọkọ pin fawọn eeyan Uganda kuro nilẹ.
Ni kete ti wọn kẹfin pe abuku wa lara awọn rọba idaabobo wọnyii ni wọn ti n ni kawọn ti wọn ti pin in fun da a pada.
Iwadii ajọ to n mojuto ilo oogun ni Uganda, iyẹn Uganda National Drug authority fihan pe iho diẹdiẹ wa lara awọn rọba idaabobo ti ileeṣẹ Life Guard ti India ba wọn ṣe.
Ileeṣẹ arannilọwọ Marie Stopes maa n pese ọna idaabobo ara ẹni, ati ifetosọmọbibi fun awọn orilẹ-ede to le ni marundinlogoji ni agbaye ni.
Ajọ iṣọkan agbaye, United Nations ni pe o to ida mẹfa ninu ọgọrun un awọn eniyan orilẹ-ede Uganda lo ni arun kogboogun HIV.
Iwadii miran tun fihan pe ida mọkanla ninu ọgọrun un oyun ti awọn eniyan Uganda n ni lo jẹ eyi to wu wọn lati ni funra wọn lasiko naa.
Loṣooṣu ni Marie Stopes maa n ko rọba idaabobo bii miliọnu kan abọ si meji wọ orilẹ-ede Uganda.
Atẹjade ti wọn fi sita fun BBC ni: Eyi ni igba akọkọ ti a ni lati gba awọn nkan iranlọwọ wa pada nitori abuku kan.
Ẹ̀mí kan náà ló n darí ìrìnàjò wa táa fi jọ kọ́lé papọ̀- Ìbejì
Marie Stopes bẹrẹ si ni gba awọn rọba idaabobo ti wọn ti pin yii pada lẹyin ti NDA kọwe si wọn lọgbọn ọjọ oṣu kẹwaa fi sọ pe ipele meji ninu awọn rọba idaabobo wọnyii ko ba gbendeke amuyẹ to yẹ ki rọba idaabobo n ni.
Ajọ Marie Stopes ni awọn n ṣiṣẹ papọ pẹlu ajọ NDA lati tete ṣe iwadii nkan to ṣẹlẹ si awọn ipele wọnyii ati ọna lati tun jẹ ki wọn daa sii.
Marie Stopes ṣalaye siwaju pe awọn ni idaniloju pe ipele meji naa ni to paali rọba idaabobo ojilelọọdunrun o dín marun un ni eyi to le ni miliọnu kan rọba idaabobo kọọkan.
Won ni awọn ti ri to idaji rẹ gba pada bayii.
Ahmed Lawan: Kó sí ǹkan tí Ààrẹ Buhari yóò fẹ́, tí mí ò ní ṣe fun
Oríṣun àwòrán, OTHERS
Agbẹjọ́rọ̀ Sulaiman bu ẹnu àtẹ́ lu ọ̀rọ̀ tí Ààrẹ ilé ìgbìmọ̀ asòfin àgbà, Ahmed Lawan sọ pé òun kòní tako ààrẹ lórí ohunkohun.
Agbẹjọrọ Sulaiman Abaya ti ni idoju ofin bolẹ ni ọrọ ti Aarẹ Ile Igbimọ Asofin Agba, Ahmed Lawan sọ pe ko si ohunkohun ti Aarẹ Buhari ba ti gbe wa si iwaju oun.
Ahmed Lawan sọ eyi lasiko ti Alaga Ajọ to n gba Aarẹ Buhari ni iyanju lori ọrọ iwa ajẹbanu, Ọjọgbon Itse Sagay ṣe abẹwo si ni ọfiisi rẹ ni Abuja.
Agbẹjọro Abaya ni ọrọ Aarẹ Ile Igbimọ Asofin naa ko bojumu nitori ijọba tiwantiwa faaye fun Ile Igbimọ Asofin lati ma a ṣe ofintoto lori ohunkohun ti aarẹ ba fẹ ṣe.
O ni awọn asofin ati aarẹ gbọdọ wo ohun gbogbo ti aarẹ ba gbe wa ni ẹẹmeji, ki wọn le wo o boya o ba ofin mu, abi boya o ba eto awọn araalu mu.
Ẹ̀mí kan náà ló n darí ìrìnàjò wa táa fi jọ kọ́lé papọ̀- Ìbejì
Agbẹjọro Sulaiman Abaya fikun un wi pe ki ilọsiwaju le ba eto aabo orilẹ-ede Naijiria, pẹlu ilọsiwaju to muna doko, wọn gbọdọ ṣe ojuṣe wọn gẹgẹ bi ẹka to n bojuto ifẹ ara ilu.
Agbẹjọro naa rọ awọn asofin naa lati ranti wi pe ipo agba ni Naijiria wa, nitori naa ki wọn jẹ apẹrẹ rere fun awon orile-ede miran to wa ni Afrika.
Ẹ wo ẹẹmẹta ti Ile Igbimọ Asofin labẹ adari Ile Igbimo Asofin tẹlẹri, Bukola Saraki kọ̀ lati buwọlu aba aarẹ Buhari
Pneumonia: Dókítà ní kòkòrò àìfojúrí ló ń fàá
Àbá ìsúná N1.3 trillion ni CBN gbé jáde fún ọdun 2020
Kìnìhún nìkan kọ́ ló burú, àwọn ajá mẹ́wàá yìí náà kò fararọ!
Àráàlú yarí fún fásitì Babcock fún bo ṣe lé akẹ́kọ̀ọ́ tí wọn bá lòpọ̀ nínú fídíò
Ó gbẹnután! Ìyá dú ọmọ rẹ̀, o yíi láta, ó sì tún jòkó jẹ ẹ́
Adigunjalè fọ́ báńkì ní Oye Ekiti, wọ́n tún ṣun ọkọ̀ ọlọ́pàá níná
Ẹ wo fídíò Kìnìhún ní ibùgbé rẹ̀ tuntun ní Bogije, Lekki
Ìtàn Mánigbàgbé: Àáró tó yẹ kí Lisabi gbà, ló fi bẹ ọ̀wẹ̀ láti kọlu Ìlàrí Ọlọyọ fún ìdáǹdè Ẹ́gbá
Oríṣun àwòrán, Others
Ìtàn Mánigbàgbé: Àáró tó yẹ kí Lisabi gbà, ló fi bẹ ọ̀wẹ̀ láti kọlu Ìlàrí Ọlọyọ fún ìdáǹdè Ẹ́gbá
Abẹokuta jẹ ilu to gbajumọ nilẹ Yoruba, a si mọ ilu naa bii ilu Ẹgba, ilu ta tẹdo labẹ Olumọ, ti wọn si maa n ki awọn ọmọ Ẹgba ni ọmọ Lisabi.
Ko si bii eeyan yoo se sọ itan Ẹgba, ti a ko ni darukọ Lisabi Agbongbo Akala.
Ẹni ti itan sọ fun wa pe o ko ipa ribiribi nidi idagbasoke, alaafia ati ilọsiwaju awọn Ẹgba ati ilu Abẹokuta, bi o tilẹ jẹ pe kii ṣe oun lo da ilu naa silẹ, gẹgẹ bi awọn eeyan kan se lero
Idi si ree ti wọn se ya ọjọ kan sọtọ nilu Abẹokuta lati maa fi ṣe iranti akọni baba Ẹgba to ti lọ naa, ti wọn n pe ni Lisabi Day.
Ọjọ Kẹrinla, osu Kẹta, ọdọọdun si ni ayajọ Lasabi naa maa n waye nilu Abẹokuta.
Pataki akọni to ti dara ilẹ yii lo mu ki BBC Yoruba se fẹ ka mọ itan igbe aye rẹ gẹgẹ bi a se rii ka loju opo ayelujara nitori bi onirese rẹ ko ba fin igba mọ, eyi to ti fin silẹ, ko lee parun.
Wo àwọn ìbejì tó lẹ́ pọ̀ lẹ́yìn àṣeyọrí ìṣẹ́ abẹ dókìtà 70
Oríṣun àwòrán, Others
Ọjọ Kẹrinla, osu Kẹta, ọdọọdun si ni ayajọ Lasabi naa maa n waye nilu Abẹokuta.
Hubert Ogunde rèé, baba àwọn òsèré tíátà
Kí lo fẹ́ mọ̀ nípa ‘Ajala Travels’?
Afárá odo ọya keji :Ta ni yóò parí rẹ?
Wole Soyinka rèé láti kékeré
Ikogosi-Ekiti: Ilu ti omi tutu ti dapọ mọ gbigbona
Sogidi Lake: Kòṣẹja-kòṣèèyàn lá bá nínú adágún odò náà -Ojedele
Yoruba Culture: ọjọ́ méje ni wọ́n fí n rẹ ẹ̀kú Danafojura kó tó jáde
'Èmi gan máa ń béèrè lọ́wọ́ ara mi pé ta ni Wole Soyinka gangan'
Kí lo fẹ́ mọ̀ nípa D.O Fágúnwà?
Ẹ̀ wo bí àwọn ẹ̀ṣọ́ ojú etí òkun ṣe ń ṣiṣẹ́ l'Eko
O ṣójú mí kóró bí wọ́n ṣé fí àdó olóró pa Dele Giwa lọdún 1986- Soyinka
Ṣòwòrẹ́, káàbọ̀ ságbo àwa tí wọ́n ti fẹ̀sùn kàn rí -Soyinka
O yẹ ki gbogbo wa sa ipa wa lati ran ilu wa lọwọ, ka si dide lati ja fun alaafia rẹ nibikibi.
Nollywood: Toyin Abraham ń ta àgbo, Wumi Toriola, Ronke oshodi Oke ń ta ìpara ìbóra
Ọpọ oju to n pawo ninu awọn fiimu agbelewo wa lo jẹ ilumọọka fun ọpọ eeyan lorilẹede Naijiria.
Koda, ọpọ eeyan si maa n fi oju ipa ti wọn n ko ninu ere se odiwọn igbe aye wọn loju aye nitori awọn miran to n ko ipa olowo ni wọn maa n fi oju olowo wo.
Sugbọn awọn osere yii lo maa n kigbe lọpọ igba pe okiki nikan ni awọn ni, awọn ko fi bẹẹ ri taje se, idi si niyi ti ọpọ awọn osere naa se mu ọna mii pọn lati ni owo lọwọ nitori ọna kan ko wọ ọja.
Eyi si ni awọn osere tiata lobinrin to mu okoowo miran mọ isẹ tiata, ati irufẹ okoowo ti wọn n se:
Ọdọmọde osere tiata ni Wunmi Toriola to sẹsẹ bi ọmọkunrin kan laipẹ yii, ti orukọ rẹ n jẹ Zion.
Oríṣun àwòrán, Instagram/teamwumitoriola
Wunmi lo tun mu isẹ pipo ipara ati ọsẹ iwẹ to n bora mọ isẹ tiata lati ri taje se, to si fi orukọ ara rẹ pe idamọ eroja ipara to n ta.
Ti eeyan ba si de oju opo Instagram rẹ, Wumi ko fi bo rara nipa okoowo to yan laayo, to si n ke si iruwa, ogiri wa lati wa ra ohun to n ta.
Ẹlomiran to tun mu okoowo mii mọ isẹ tiata ni Mide Martins aya Afeez Owo Abiọdun, ti awọ̀n mejeeji dijọ jẹ gbajumọ nidi isẹ tiata.
Oríṣun àwòrán, Instagram/zanzeespabeautynstyle
Iya alasọ tun ni a ba maa pe Mide lẹ́yin pe o jẹ́ osere tiata ti aye n gba tiẹ nitori ojoojumọ lo n polowo awọn asọ to n ta lori ayelujara.
Koda, mawọtana ni awọn aworan rẹ to n gbe sori ayelujara lojoojumọ, to si dabi ẹnipe o ni ẹnikeji ti wọn jọ da okoowo naa pọ.
Oju to pawo ni Toyin Abraham ninu awọ̀n fiimu oloyinbo ati ni ede Yoruba, to si jẹ aayo ọpọ eeyan .
Oríṣun àwòrán, Instagram/toyin_abraham
Laipẹ yii ni osere tiata naa bi ọmọkunrin kan to pe orukọ rẹ ni Ire, ti ọpọ eeyan si n ki ku oriire.
Lẹyin to bimọ tan lo wa sọ asiri ọna to gba bi ọmọ eyi to ni ko sẹyin egboogi ibilẹ kan to pe ni agbo
Lati igba naa si lo ti n polowo egboogi yii fun awọ̀n eeyan to n woju Ọlọrun fun ọmọ tiwọn pe ki wọn wa ra agbo naa, ki lọ ayọ lee sọ ninu wọn.
Egboogi yii si lo ti se nilana ti oloyinbo sinu apo kan, to fi sọ orukọ ara rẹ.
Ronke Oshodi Oke: Katakara eroja ipara ati ọsẹ ibora ati atọkun eto lo mu mọ isẹ tiata
Ronke Ojo Anthony ti a tun mọ si Ronke Oshodi Oke ko fi okoowo to n se lẹyin isẹ tiata se asiri rara nitori ojoojumọ lo n polowo ohun to n ta lori ayelujara.
Oríṣun àwòrán, Instagram/ronkeoshodioke
Koda, ọna kan ko wọja ni a ba maa pe Oshodi Oke nitori kii se okoowo kan lo mu mọ ere itage, bo se n ta ipara ati ọsẹ ibora, naa lo tun n se atọkun eto.
Yatọ si eyi, Ronke tun maa n gba isẹ alaga iduro nibi ayẹyẹ igbeyawo, gbogbo awọn okoowo naa si lo n mu ki Oshodi Oke ri taje se.
Mercy Aigbe: Asọ Ẹbi tita ni na tawọn mu pọn lẹyin fiimu sise
Mercy Aigbe ti oun naa jẹ gbajumọ osere ko kawọ gbera rara nigba ti awọn akẹẹgbẹ rẹ n wa owo.
Oríṣun àwòrán, Instagram/asoebimercy
Bi awọn akẹẹgbẹ rẹ se mu na kan pọn, ni oun naa gba ọna keji yọ, to si lọ si sọọbu asọ tita.
Asọ oloyinbo ni mama Juwọn kọkọ n ta, to si si sọọbu kaakiri to fi mọ ilu Eko ati Ibadan.
Amọ ọgbọn okoowo Mercy ti sun siwaju bayii tori o ti mu asọ ẹbi tita mọ ọja rẹ, bo si se n ta asọ fun awọn oniyawo, lo n ta tawọn ọljọ ibi ati tawọn oloku agba.
Isẹ ori ran mi ni mo n se ni ọrọ Temidayo Amusa nitori ko ta igba abi awo rara, orin lo n mu kọ lẹyin isẹ tiata.
Laipẹ yii si ni Dayo gbe awo orin tuntun kan jade eyit o milẹ titi, to si pe akọle rẹ ni Mosorire.
Yika awọn oju opo ayelujara si ni wọn ti n k awo orin naa, to fi mọ awọn ori tẹlifisan ati redio.
Ọna lati ri ọwọ mu lọ sẹnu lẹyin isẹ ere sise lo mu ki ilumọọka osere tiata lobinrin, Lizzy Anjorin fi tun si sọọbu asọ.
Oríṣun àwòrán, Instagram/Lizzy Anjorin
Ipolowo ọja asọ yii ni Lizzy kii fi sere rara lori ayelujara, bo si se n jo lati polowo fun awọn onibara, naa lo n kọrin lati fa oju wọn mọra.
Tẹ ba wo Lizzy lasiko to ba n polowo ọja rẹ, ẹ mọ pe isẹ aje le.
Lọwọlọwọ bayii, Lizzy tun ti mu okoowo ilẹ ati ile tita mọ katakara lati ri taje se.
Revolution Now: Sowore, Bakare gbé ọga DSS lọ sílé ẹjọ́, wọn ń bèèrè fún bílíọ̀nù kan náírà
Oríṣun àwòrán, Facebook/Omoyele Sowore
Omoyele Ṣowore ati Olawale Bakare ti wọn wa latimọle ajọ ọtẹlẹmuyẹ DSS ti n mugbe bọnu bayii, ti awọn mejeeji si ti gbe ọga DSS, Yusuf Bichi ati ọga ẹka eto idajọ ni Naijiria, Ọgbẹni Abubakar Malami lọ sile ẹjọ.
Ṣowore ati Bakare gbe awọn mejeeji lọ si ile ẹjọ giga l'Abuja, bakan naa ni wọn beere fun ẹẹdẹgbẹta miliọnu naira fun ẹni kọọkan wọn fun inira ti ajọ DSS fun wọn lati igba ti wọn ti wa latimọle.
Wọn ni owo yii tun wa fun bi ajọ DSS ti fi ẹtọ wọn dun wọn lẹyin ti ile ẹjọ paṣẹ idasilẹ wọn latimọle, ti wọn ko si jẹ kawọn lanfaani si eto ilera, ati ẹtọ awọn lati rin lọ si ibikibi to ba wu awọn.
Wọn fikun ọrọ wọn pe mimu ti ajọ DSS mawọn ati iya ti wọn fi jẹ awọn niluu Eko lọjọ keji oṣu kẹjọ ati niluu Oṣogbo lọjọ karun un oṣu kẹjọ tako ẹtọ ọmọniyan awọn.
Awọn agbẹjọro wọn, Femi Falana to pe ẹjọ naa lorukọ Ṣowore ati Bakare, tun ni ọga ajọ DSS ati ti ẹka eto idajọ tun tapa sofin orilẹede Naijiria gẹgẹ bi o ti wa ni akọsilẹ ninu iwe ofin.
Ọjọ kẹfa oṣu kọkanla nile ẹjọ ti paṣẹ pe ki ajọ DSS fi Ṣowore ati Bakare silẹ lahamọ, ṣugbọn DSS kọ eti ikun si aṣẹ ile ẹjọ.
Muhammadu Buhari: APC ẹ ṣọ́ra, ẹgbẹ́ kò gbọdọ̀ túká lẹ́yìn ìsàkóso mi
Oríṣun àwòrán, Instagram/Prof Yemi Osinbajo
Ko si ohun to jọọ rara! Aarẹ Muhammadu Buhari soju abẹ niko lori iroyin kan to n tan kalẹ pe aarẹ n gbero lati lọ fun saa kẹta, ti saa keji rẹ ba pari.
Aarẹ Buhari sọ pe, oun ko ni ṣe aṣiṣe lati gbegba ibo aarẹ fun saa kẹta gẹgẹ bi aarẹ orilẹede Naijiria.
Buhari sọrọ yii mimọ nibi ipade igbimọ alaṣẹ ẹgbẹ osẹlu APC to waye niluu Abuja lọjọ Ẹti.
Aarẹ Buhari ni yatọ si ọjọ ori oun, o ni oun ti bura pẹlu iwe mimọ pe oun ko ni ṣe ohun kohun to lodi si iwe ofin orilẹede Naijiria.
Buhari ni saa meji ti iwe ofin ilẹ Naijiria la kalẹ fun ipo aarẹ naa loun yoo ṣe.
Aarẹ wa kilọ fawọn ọmọ ẹgbẹ osẹlu APC nibi ipade ọhun pe ẹgbẹ APC ko gbọdọ tuka lẹyin ti oun ba pari saa keji oun tan.
Oríṣun àwòrán, Facebook/Femi Adesina
Buhari rọ awọn ọmọ ẹgbẹ APC lati ṣa ipa wọn, ki wọn si rii pe APC lẹgbẹ to siwaju ninu awọn ẹgbẹ oṣelu to wa lẹkun wọn.
Aarẹ Buhari ni iwe itan yoo sọ itan rere nipa awọn ọmọ ẹgbẹ APC lọjọ iwaju, ti onikaluku ba gbiyanju lati ri pe APC fẹsẹ mulẹ lẹkun wọn.
Anti social media bill: Ilé aṣòfin ní ìjíròrò ìtagbangba ló kù lórí àbá láti mójútó ayélujára
Oríṣun àwòrán, Facebook/Elisha Ishaku Abbo
Anti social media bill: Ilé aṣòfin ní ìjíròrò ìtagbangba ló kù lórí àbá láti mójútó ayélujára,
Iduro ko si, ibẹrẹ ko si fun ẹni to gbodo mi lọrọ aba to wa niwaju ile aṣofin lati ma mojuto ohun to n lọ lori ayelujara lọrọ da bayii o.
Ile igbimọ aṣofin l'Abuja ti sọ pe oun yoo tẹsiwaju ijiroro lori aba naa lọsẹ to n bọ.
Igbimọ to n ri si ọrọ idajọ ati ẹtọ ọmọniyan yoo kede ọjọ kan laarin ọsẹ to n bọ fun ijiroro itagbangba lori aba ọhun.
Ọjọ Iṣẹgun ni aba naa de ipele keji nile eleyi to mu ki ọpọ tako o lori ayelujara.
Ẹgbẹ awọn agbẹjọro ni Naijiria atawọn ajafẹtọ miiran lawọn ṣetan lati da si ọrọ naa nibi ijiroro itagbangba ti yoo waye lọsẹ to n bọ.
Ohun ti ile aṣofin sọ ni pe aba yii ni yoo dena iroyin ofege lori ayelujara atawọn nnkan mii to lodi sofin tawọn eeyan n ṣe lori ayelujara.
Sẹnẹtọ Sani Musa to ṣoju ẹkun ila oorun nipinlẹ Niger lo ṣagbatẹru aba ọhun.
Ẹwẹ, alaga igbimọ ile aṣofin to n ri si ọrọ idajọ ati ẹtọ ọmọniyan, Opeyemi Bamidele ṣalaye pe igbimọ yii yoo kọkọ ṣepade pẹlu Sẹnẹtọ to ṣagbatẹru aba naa kawọn eeyan to lanfaani lati da si i ninu ijiroro itagbangba ọsẹ to n bọ.
Sẹnẹtọ Chimaroke Nnamani to jẹ gomina ipinlẹ Enugu tẹlẹ ri nikan lo tako kile sọ aba naa di ofin.
Ẹ̀mí kan náà ló n darí ìrìnàjò wa táa fi jọ kọ́lé papọ̀- Ìbejì
Ẹgbẹ awọn ọdọ ati ọmọ Yoruba ati Igbo bii Ohanaeze pẹlu ẹgbẹ awọn ọdọ naa ti kilọ fun ile aṣofin pe ko jawọ lori aba ọhun.
Bakan naa ni ọgọọrọ eeyan tako aba naa lori ayelujara, niṣe lori ayelujara n gbona girigiri lati ọjọ Ẹti lori ọrọ naa.
Ganduje fi ọwọ́ òsì da ìdájọ́ ilé ẹjọ̀ nù lórí Emir tuntun mẹ́rin!
Ẹ wo ìdí tí ẹ gbọdọ̀ fi gba abẹ́rẹ́ àjẹsára fún ọmọ yín!
Ọ̀yẹ̀ yóò là fún abẹ́rẹ́ ìfètòsọ́mọbíbí fáwọn ọkùnrin láìpẹ́
Adarí Ilé ìgbìmọ̀ Asòfin tako ètò ìjọba tiwantiwa- Agbẹjọ́rọ̀
Ǹjẹ́ o mọ ohun tó ń fa súnkẹrẹ-fàkẹrẹ nílùú Eko?
Iléẹjọ́, ẹ sọ fùn ọ̀gá DSS kó fún wa ní ₦1bn torí àhámọ́ lọ́nà àìtọ́ - Sowore àti Bakare
Gbogbo ohun tó bá gbà lá máa fún un láti wa àwọn agbébọn náà- Ọlọ́pàá
Ọ̀nà kan ò wọjà fáwọn òṣèré tíátà, bí wọn ṣe ń ta ìpara ìbóra ni wọ́n ń ta aṣọ ẹbí
Ìtọ́jú ara di ìrọ̀rùn! Wo orúkọ àwọn ẹ̀yà ara rẹ̀ ní èdé Yorùbá
Àwọn iròyin ẹlẹ́jẹ̀ márùn ún tó fẹ́ẹ̀ tú Nàìjíríà ká
Adigunjalè fọ́ báńkì ní Oye Ekiti, wọ́n tún ṣun ọkọ̀ ọlọ́pàá níná
Ó gbẹnután! Ìyá dú ọmọ rẹ̀, o yíi láta, ó sì tún jòkó jẹ ẹ́
Àráàlú yarí fún fásitì Babcock fún bo ṣe lé akẹ́kọ̀ọ́ tí wọn bá lòpọ̀ nínú fídíò
Allen Onyema: Iro ni ile Amerika pa mo mi lori esun jibiti
Oríṣun àwòrán, Facebook/Allen Onyema
Allen Onyema: Amẹrika fẹ̀sùn jìbìtì $20m kan olùdàsílẹ̀ ilé iṣẹ́ ọkọ̀ òfurufú Air Peace
Alaga ilẹ isẹ ọkọ ofurufu Air Peace, Allen Onyema ti ni iro lasan ni ilẹ Amerika pa mọ oun lori ẹsun iwa jibiti ti wọn fi kan oun.
Onyema sọ eyi ninu atẹjade ti wọn fi lede si oju opo ikansiraẹni Twitter wọn.
O ni ọmọ Naijiria rere ni oun, ti kii se magomago ninu gbogbo ohun ti oun ba n se.
Owurọ ọjọ Abamẹta ni iroyin gbe e pe orilẹede Amẹrika ti fi ẹsun jibiti ogun miliọnu dọla ati kikowo pamọ silẹ okeere lọna aitọ kan oludasilẹ ile iṣẹ ọkọ ofurufu Air Peace.
Amẹrika fẹ̀sùn jìbìtì $20m kan olùdàsílẹ̀ Air Peace, Allen Onyema
Iroyin to n tẹ wa lọwọ sọ pe ilẹ Amẹrika ti fi ẹsun jibiti ogun miliọnu dọla ati kikowo pamọ silẹ okeere lọna aitọ kan oludasilẹ ile iṣẹ ọkọ ofurufu, Air Peace, Allen Onyema.
Ẹka idajọ orilẹ-ede Amẹrika lo kede ọrọ naa loju opo itakun agbaye wọn.
Ẹka naa fẹsun kan Ọgbẹni Onyema loju opo agbọrọkaye wọn pe gbe ogun miliọnu dọla lati orilẹ-ede Naijiria sawọn apo ikowosi kan l'Amẹrika.
Bakan naa ni wọn ni o lo ayederu iwe pe oun fẹ fi owo naa ra ọkọ ofurufu lorilẹ-ede Amẹrika ni.
Onyema ati Ejiroghene Eghagha to jẹ alakoso eto inawo ile iṣẹ ọkọ ofurufu Air Peace ni wọn jọ fẹsun kan papọ.
Atẹjade ti ẹka eto idajọ ilẹ Amẹrika fi sita ṣalaye pe lati ọjọ kọkandinlogun, oṣu kọkanla ni ẹka naa ti fẹsun kan wọn pe wọn jọ gbimọ pọ lati lu jibiti pẹlu ile ifowopamọ l'Amẹrika.
Byung J. to jẹ olori ẹka idajọ lapa ariwa ẹkun Georgia sọ ninu atẹjade naa pe Onyema lo ipo rẹ gẹgẹ bi gbajugbaja oniṣowo ati oludasilẹ ile iṣẹ Air Peace lati lu jibiti pẹlu ayederu iwe.
O ni ijọba Amẹrika ṣetan lati daabo bo ẹka ile iṣẹ ifowopamọ lọwọ awọn onijibiti ti wọn n fi ọrọ owo ṣiṣe boju wa si Amẹrika.
Aṣoju ẹka idajọ Amẹrika mii, Robert Hammer sọ ninu atẹjade naa pe Onyema ṣe ọpọlọpọ eto lati ra oniruuru nnkan lorilẹ-ede Amẹrika, amọ o ni jibiti naa ni gbogbo rẹ ba de.
Allen Onyema: Amẹrika fẹ̀sùn jìbìtì $20b kan olùdàsílẹ̀ ilé iṣẹ́ ọkọ̀ òfurufú Air Peace
Ni ipari atẹjade naa, ẹka idajọ ilẹ Amẹrika sọ pe alaiṣẹ si ni Onyema ati Eghagha afi ti ijọba Amẹrika ba fidi rẹ mulẹ pe lootọ ni wọn jẹbi ẹsun ti wọn kan wọn.
Nigba ti ile iṣẹ BBC kan si alakoso ile iṣẹ Air Peace, o ni oun ko tii le sọ nkankan lori ọrọ naa, amọ ile iṣẹ iroyin Punch sọ pe Onyema ni irọ ni wọn n pa mọ oun.
Ẹ̀mí kan náà ló n darí ìrìnàjò wa táa fi jọ kọ́lé papọ̀- Ìbejì
Ileeṣẹ iroyin naa ni pe Onyema ni ẹsun ti wọn fi kan oun tako iru eeyan t'oun jẹ ati pe oniṣowo to wa ilọsiwaju orilẹ-ede Naijiria ni oun.
Onyema loun ko jẹbi gbogbo ẹsun ti ẹka idajọ ilẹ Amẹrika fi kan oun, o ni oun ko tii ṣe jibiti ri pẹlu owo ti oun n ṣe.
Money transfer: Òdíwọn iye owó tí èèyàn n fi rànṣẹ́ sílé ń dínkù púpọ̀ jù
Onyema ṣalaye siwaju si pe awọn agbẹjọro oun ti wa lori ọrọ naa bayii ati pe oun o kowo lati Naijiria lọ si ilẹ okere lọna aitọ ri.
Ẹwẹ, ọpọ lo gboṣuba fun Onyema ninu oṣu kẹsan an lẹyin to lo baalu ile iṣẹ rẹ lati gbe awọn ọmọ Naijiria ti wọn ha si orilẹede South Africa lasiko ikọlu awọn ọmọ ilẹ naa sawọn ọmọ Naijiria lọfẹẹ.
Koda ile aṣoju-sofin daba pe ki ijọba fi oye da Onyema lọla fun oju aanu rẹ.
Gbogbo igbiyanju  BBC lati ba Onyema funra rẹ sọrọ ko tii so eso kankan di asiko yii.
Osun cow death: Iṣẹ̀lẹ̀ tó wáyé kò ni dá wàhálà sílẹ̀ láàrin àwa àti àwọn Fulani.
Oríṣun àwòrán, Okunoye facebook
Àmúwá Ọlọ́run lásán ní ìṣẹ̀lẹ̀ tó wáyé ní Iba-Eburu Iba Oba Okunoye
Ọba Eburù ti Iba ọba Adekunle Okunoye, ti fi ìdí ìṣẹ̀lẹ̀ to wáyé ni Iba múlẹ̀ nípa àwọn màálù Fulani to n gbé inú ìlú náà.
 Àwọn ènìyàn Iba tí ń ba àwọn Fulani gbé láti ọ̀pslọpọ̀ ọdún sẹ́yìn nínú ayọ àti aláfíà, ǹkan tó si sẹlẹ̀ yìí kò ni mú ipinya wáyé láàrin àrá ìlú àti àwọn Fulani."""
Ikú àwọn màálú tó jẹ́ ti Fulani to n gbé inú ilú Iba kò mú idí kankan dáni ju pé amúwá ọlọrun ni lọ, eyi wáye látàrí àrá tó sán nínú ìlú náà to si pa àwọn màálú náà. O fi kún pé, àti ilú àti àwọn fulani sa gbogbo ipá wọ́n la'ti dẹ́kun irú ìṣẹ̀lẹ̀ báyìí lọ́ja iwájú.
"Awọn ọmọ ìgbìmọ Eburu ti sọ fún ẹni to ni màálù náà láti lọ sún àwọn màálù náà ko ma ba fa àjàkálẹ̀ ààrùn.
Igbé ayé aláfia ni à n gbé pẹ̀lú gbogbo àwọn ajoji to wà ni inú ìlú wa tó fi ma àwọn Fulani"
Oríṣun àwòrán, Premium times
Gomina ipinlẹ Ọṣun Gboyega Oyetọla ti ba awọn eeyan ilu Iba kẹdun lori iṣẹlẹ ara to san pa awọn maluu ti ko din ni mẹtadinlogun  to jẹ tawọn darandaran Fulani nibẹ.
Gomina Oyetọla ni iroyin pe alaafia ni ibagbeps awọn eeyan ilu naa pẹlu awọn darandaran fulani nibẹ jẹ idunnu fun ohun gẹgẹ bii iṣẹlẹ naa tun ṣe jẹ ibanujẹ ọkan fun oun.
"Gomina ipinlẹ Ọṣun ti amugbalẹgbẹ rẹ lori ọrọ ọgbin ati ipese ounjẹ, Ọgbẹni Biọdun Ajiṣefini ṣoju fun ṣalaye lasiko abẹwo rẹ si ilu Iba pe 'ara wa lawọn eeyan ti adanu nla yii ṣẹ, wọn kii ṣe ajeji"""
'Àfi bí mo bá sunkún mọ́ títọrọ̀ owó, tórí gbobo wa ni ìyà ń jẹ níbí'
O fi atilẹyin ijsba ipinlẹ Ọṣun da wọn loju ninu adanu wọn naa bi o tilẹ jẹ pe ko sọ ni pato ọna ti atilẹyin naa yoo gba.
Bi ẹ ko ba gba gbagbe, Ko din ni maluu mẹtadinlogun ti ara san pa ni ileto kan ti wọn n pe ni Iba ni ijọba ibilẹ Ifẹlodun ni ipinlẹ Ọṣun.
Agbegbe kan ti wọn n pe ni Gaa Eleesun nibi ti awọn darandaran Fulani n gbe ni iṣẹlẹ yii ti waye ni irọlẹ ọjọ Ẹti lẹyin ti awọn darandaran naa ti papa ijẹko de lati sinmi fun iṣẹ ọjọ naa gẹgẹ bi a ṣe gbọ.
Iroyin sọ pe, iṣẹlẹ yii ti sọ gbogbo awọn olugbe ilu Iba sinu hilahilo bayii nitori irufẹ iṣẹlẹ naa ko waye ri ati pe alaafia ni awọn olugbe ilu naa atawọn darandaran Fulani n gbe nibẹ.
Ọgbẹni Jimoh Sọliu to jẹ olori gaa Eleesun ṣalaye pe ọfọ nla ni iku awọn maluu ati aguntan naa jẹ fun wọn. O ni ere tete ni gbogbo wọn sa wọle nigba ti ara naa san, iyalẹnu nla lo si jẹ lati rii pe ara naa ti pa awọn maluu ati aguntan naa.
Eyi ni igba kẹta ti iṣẹlẹ ajalu ara sisan pa awọn maluu yoo maa waye laarin oṣu mẹta.
Àwa ọba alayé ń wọ́nà láti ṣẹ́ eegun ẹ̀yin ọ̀daràn Fulani - Ọọ̀ni
Ẹ sọ ìwé kíkà di dandan fún ẹ̀yà Fulani - Oluwo rọ ìjọba àpapọ̀
Fulani nìkan kọ́ ló ń pa ènìyàn ní Naijiria -Tinubu
Mo fi iṣẹ́ Banki silẹ̀ lọ bẹ̀rẹ̀ alápatà - Derin
Bi ẹ ko ba gbagbe, maluu mẹrindinlogoji ni ara kọkọ san pa ni ilu Ijarẹ ni ipinlẹ Ondo lẹyin ti awọn adari ilu naa ni ori ilẹ aiwọ ni wọn ti ri awọn maluu naa ati pe titasẹ agẹrẹ wọn lo ṣokunfa iṣẹlẹ naa. Ìlú kò mọ ohunkóhun nípa iṣẹlẹ màálù tó kú nilu Ikarẹ- Oba Olukarẹ
Ko pẹ pupọ lẹyin eyi ni ara tun san pa maluu bii mẹjọ kan ni agbegbe Oyinmọ ni ilu Ikarẹ ni ijọba ibilẹ Akoko North east ni ipinlẹ Ondo kan naa.
#6thAFRIMA: Burnaboy, 2baba, tiwa Savage àti Wizkid da ilẹ̀ rú ní AFRIMA
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Stonebwoy, Tiwa Savage ati Burna boy
Lẹyin ti wọn fi orukọ rẹ silẹ fun ami ẹyẹ Grammy, Burna Boy ti gba ami ẹyẹ AFRIMA.
Amọṣa, oun nikan kọ ni akọrin orilẹede Naijiria to tan bi itanṣan oorun nibi eto ami ẹyẹ fun awọn olorin to lamilaaka nilẹ Afirika naa.
Wizkid, Tiwa Savage, Joeboy ati DJ Spinall pẹlu gba ami ẹyẹ nibi eto naa to waye ni ọjọ Aiku ni ilu Eko.
Ẹ̀mí kan náà ló n darí ìrìnàjò wa táa fi jọ kọ́lé papọ̀- Ìbejì
Oríṣun àwòrán, @burnaboy
Awo orin Burna Boy to pe akọle rẹ ni 'African giant' lo gba gba ami ẹyẹ fun awo orin to gbamuṣe ju lọ lọdun yii. Bakan naa lo gba ami ẹyẹ akọrin to gbamuṣe ju lọ lọkunrin ni ẹkun iwọ oorun Afirika fun orin rẹ ti akọle rẹ jẹ 'Ye' nigba ti orin Wizkid, ti oun pẹlu jẹ akọrin ọmọ Naijiria pẹlu gba ami ẹyẹ orin to gbayii ju lọ lọdun yii lori orin rẹ to pe akori rẹ ni 'Fever' ti oun pẹlu Tiwa Savage jumọ pa itu meje ninu rẹ.
Awọn akọrin Naijiria to tun gba ami ẹyẹ nibi ayẹyẹ AFRIMA tọdun yii ni Tiwa Savage to gba ami ẹyẹ akọrin to gbayi ju lọ lobinrin ni ẹkun iwọ orun Afirika lori orin to pe akori rẹ ni 'One', Joeboy gba ami ẹyẹ ẹgbẹ alakọrin meji (Duo) to pegede julọ ti DJ Spinnal si gba ami ẹyẹ DJ to gbayii ju lọ ni gbogbo ilẹ Afirika.
'Àfi bí mo bá sunkún mọ́ títọrọ̀ owó, tórí gbobo wa ni ìyà ń jẹ níbí'
Awọn oloriire miiran nibi ami ẹyẹ naa ni:
Air Peace: 'Rárá o, kó bá 'má jẹ́ Onyema, èyí àtàwọn ọ̀rọ̀ míì tó ń yọjú
Oríṣun àwòrán, OTHER
Bi inu ile tabi gbọngan ti ero ko ti gba ẹsẹ loju opo Twitter, Facebook, instagram atawọn ẹrọ alatagba mii kun fọ́fọ́ lori iroyin pe ilẹ Amẹrika fi ẹsun jibiti kan ọga agba ileeṣẹ ọkọ ofurufu Air Peace, Allen Onyema.
Oniruuru ọna lawọn eeyan ti n gba da si ọrọ naa ti wọn si n ke si ijọba lori igbesẹ to yẹ ki wọn gbe.
"Ṣaaju, gbajugbaja oloṣelu ati minisita f'eto ofurufu tẹlẹri ni Naijiria, Femi fani Kayode fi si oju opo Twitter rẹ pe bi wọn ba fi ẹsun kan eeyan, ko tii tumọ si pe o daju. ""Ẹsun ni ẹsun n jẹ niwọn igba ti ile ẹjọ ko ba tii fi aridaju han. Allen Onyema kii ṣe adigunjale tabi ọlọsa. Eeyan ire gbaa ni to si jẹ olufọkansin ilu. Mi o mikan pe yoo jare yoo si bori ninu ẹjọ yii""."
"Gbajugbaja ọdọ olorin Davido ni ""Mo duro pẹlu Allen Onyema."
300 mílíọ̀nù náírà ní mò fí gbé àwọn ọmọ Nàìjíríà wálé-Allen Onyeama
"Ni ti gbajugbaja ori ayelujara fun irufẹ awọn iroyin to ma n gbe sita ati ọna to n gba kọ́ iroyin rẹ, Kemi Olunloyo, o ni ""gbogbo yín lẹ ni iwa jẹgudujẹra lọwọ gẹgẹ bi olori Naira Marley ṣe kọ ọ."""
Bi mo ba sọrọ daadaa nipa eeyan kan tabi kọ iroyin mi lai lẹja mbakan ninu, ẹ o ni wọn ti san owo fun mi. O fi apẹrẹ orukọ awọn to sọrọ nipa wọn sita.
Ọpọ ọmọ Naijiria ko lee pa ẹnu mọ lori ọrọ̀ yii o. Niṣe lori ẹrọ ayelujara n du to to to leti eeyan ni gbogbo iṣẹju fun bi awọn eeyan ṣe n da si ọrọ̀ naa.
Mo duro pẹlu Allen, ayafi to ba tẹnu ile ẹjọ jade pe o jẹbi.
Ọgbẹni yii ni tirẹ ti sare ro o to si mu ni ranti ore banta banta ti Ọga ileeṣẹ ọkọ baalu Air Peace ṣe fun Naijiria to fi ko awọn ọmọ Naijiria pada wa sile lọwọ pipa ti wọn n pa wọn lorilẹede South Africa.
Ṣugbọn o ni ṣe ko wa ti ya ju lati yaa fopin si ayẹsi, ayẹyẹ ati ajọyọ ta n ṣe lori ẹmi awọn to fi ọkọ baalu rẹ gbe wale laaye.
Ẹwẹ, ọrọ naa ti wa ni ile ẹjọ lọwọ lọwọ ti eeyan ko si lẹtọ lati dede sọ ohunkohun pato nipa rẹ bo ṣe n lọ afi bi ile ẹjọ ba to fọhun lori rẹ.
'Àfi bí mo bá sunkún mọ́ títọrọ̀ owó, tórí gbobo wa ni ìyà ń jẹ níbí'
Jaiye Kuti lu àwọn aláṣìmọ̀ lọ́gọ ẹnu lórí ìbáṣepọ̀ pẹ̀lú Pasuma
Oríṣun àwòrán, OTHER
Lootọ kii ṣe ajoji ki ibaṣepọ maa wa laarin oṣere meji lagbo awọn oṣere ṣugbọn ni Jaiyeola Kuti, o ni ohun ti wọn n ro si oun ko jọ ọ rara.
Iwoye awọn ololufẹ ere ori itage eyi to si ti tan kanlẹ gidi gan ni pe Pasuma ati Jaiye n fẹ ara wọn, eyi si tilẹ ti di igbagbọ ọpọlọpọ.
Awọn kan ni bi wọn ba ti tẹ ẹ sori ẹrọ aṣewadii google lati mọ ẹni to jẹ ọkọ rẹ, aworan olorin Pasuma lo ma n jade sita pupọ.
Lateef Adedimeji: Owó wa kò bá máa jóná ṣùgbọ́n aàyè ọpẹ́ ń yọ fún wa
Ẹwẹ, bi Jaiye ṣe wa fi sita gbangba gbangba bayii pe Lanre Kuti lorukọ ọkọ toun o kii ṣe Pasuma fun ọpọlọpọ eeyan ni ifọkanbalẹ lori ohun to ti n ja nilẹ kiri tẹlẹ yii.
"Jaiye ṣalaye pe lati igba ti oun ti ṣe agbejade ere ti akọle rẹ jẹ ""Jaiye Monje"" to si ni ọpọlpọ aworan igbeyawo laarin oun ati Pasuma ninu ere naa ni ọpọlọpọ ro pe aworan igbeyawo rẹ ni lootọ."
"Fiimu lásán ni o. Idile Kuti ni mo ti lọ́kọ̀ latinu ọgbọnjọ, oṣu ikẹjọ ọdun 2000. Emi ko fẹ Pasuma o.
Oríṣun àwòrán, Jaiye Kuti
'Àfi bí mo bá sunkún mọ́ títọrọ̀ owó, tórí gbobo wa ni ìyà ń jẹ níbí'
Nibi ti awọn ololufẹ ffimu Yoruba ati awọn ololufẹ Jaiye Kuti gan funra rẹ fẹ mọ ohun to wa nidi ọrọ yii de, ṣe ni gbogbo wọn bẹrẹ si ni tẹnu bọ ọrọ ọpẹ.
Kete ti Jaiye fi ọrọ aridaju pe oun ati Pasuma ko fẹ ara wọn sita lawọn eeyan n fesi loju opo rẹ pe awọ́n dupẹ pupọ pe o ẹkunrẹrẹ alaye ọrọ naa sita.
Awọn kan ni ọkan awọn ti balẹ bayii, ẹnikan ti igbeyawo rẹ pẹlu Lanre Kuti naa sọ tẹnu rẹ bẹ́ẹ̀ si ni
Bakan naa ni awọn mii ni ṣe ni ko pa ọrọ awọn eeyan ti pe bi kii ba ṣe ẹni to wa lati ile ire to si gba ẹkọ lo fi n ṣalaye ọrọ tori naa ko pa wọn ti pe ko jẹ wọn ni alaye kankan.
Fathia Balogun, Toyin Abraham bá Funke Akindele Kẹ́dùn ikú bàbá rẹ̀
Oríṣun àwòrán, @funke
Funke Akindele n ṣelede lẹyin baba rẹ
Awọn oṣere ti n ba Funke Akindele kẹdun iku baba rẹ lẹyin ti oṣere naa kede pe baba rẹ ti pa ipo da lorii ikanni Instagram rẹ.
Ninu awọn oṣere ti wọn kọkọ ki Funke Akindele kuu ọrọ eeyan ni Toyin Abraham ati Fathia Williams.
Iyabo Ojo naa o gbẹyin ninu awọn oṣere ti wọn na Funke Akindele kẹdun lorii ikanni Instagram rẹ.
Oríṣun àwòrán, @funke
Ko sẹni ti ko ni ku!
Funkẹ Akindele sọ bi oun ṣe gbiyanju to ṣugbọn gbogbo ẹda lo wọ agbada iku ni ọrọ baba rẹ pada ja si.
Lola Idije, Fathia williams, Lala, Awelewa atawọn mii n ki aya Bello ku ara fẹraku.
Oríṣun àwòrán, @funke
Ọjọ kan ni onikaluku a dagbere faye pe o digboṣe.
Pẹtẹsi akọkọ ni Naijiria
Taiwo Hassan: Ọ̀pọ̀ èèyàn ló sá fún mi nígbà tí mo dùbúlẹ̀ àìsàn
Oríṣun àwòrán, Instagram/AlhajiTaiwo
Taiwo Hassan: Ọ̀pọ̀ èèyàn ló sá fún mi nígbà tí mo dùbúlẹ̀ àìsàn
Gbajugbaja oṣere sinima agbelewo, Taiwo Hassan ti ọpọ eeyan mọ si Ogogo to ṣọrọ lori aarẹ to ṣe fun odindin ọdun mẹjọ lati ọdun 2004 titi di 2012.
Nigba ti o n ṣe aisan naa, oriṣiriṣi iroyin ofege lo gbalukan nipa nnkan to n ṣe oṣere naa.
Nigba ti awọn kan n sọ pe o ni arun HIV ni awon kan ni egbo igi oloro lo tu sii ninu.
Bi ìyàwọ mi ṣe n jábọ́ sí kọ́tà ló jẹ́ kí n kọ́ka fura pé kò ríran mọ́- ọkọ Dorcas
Ṣugbọn agba ọjẹ oṣere naa ti ṣalaye nnkan to ṣẹlẹ sii nigba naa fun araye.
Ogogo ni ninu awẹ Ramadan ọdun 2004 ni oun mọ pe oun ni arun ọgbẹẹnu ti wọn pe ni Ulcer.
O ni oun lo to oṣu meje ti oun n ki irun lori ijokoo nitori pe oun ko to ẹru Ọlọrun to n dide duro lati gbe irun duro.
Silas Robotic Engineer: Kò sí ǹkan rere tí ọmọ Nàìjíríà kò lè ṣe
Ogogo ni oun lati pa ẹrọ ibanisọrọ ti oun n lo nigba ti iroyin n kaakiri pe oun gbe egboogi oloro ni abi pe oun ko arun HIV ni.
Tonti pe ẹlẹsin Muslumi, Kristẹni ati iṣẹṣe n gbadura fun un, awọn orẹ ati iyawo rẹ pada fi i silẹ lọ nigba ti iṣoro naa pọ.
Ogogo ni oun pada fẹ obinrin to duro ti oun nigba iṣoro naa, obinrin naa si ti bimọ meji fun oun bayii.
Ṣe obinrin kuku kọkọ bimọ fun ni ko sọ pe ko duro ti ni nigba ti iṣoro ba de.
Downsyndrome: Dayo ń wa mótò, ó fẹyawọ, o tún lọ ilú òyìnbó
Taiwo Hassan gba awọn to ba n la iṣoro kan kọja lasiko yii lati tubọ sunmọ Ọlọrun ki wọn kun fun adura.
O ni ko si iṣoro to ni ibẹrẹ ti ko ni lopin ti eeyan ba ni suuru to dẹ n gabdura.
Food Poison: Oúnjẹ márùn-ún tó lè ṣekú pa'ni kíákíá
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Gẹ́gẹ́ bí àwọn mìíran ṣe máa n dáṣà pé gbogbo ejò jíjẹ ni, ṣùgbọ́n ìwádìí ti fi hàn pé ọ̀rọ̀ kò rí bẹ́ẹ̀, àti pé kò si òunjẹ ti kò léwu ti à o bá ṣètò rẹ̀ dáradára.
Ọ̀pọ̀ oúnjẹ lo le sàkóbá fún ara wa ti a kò bá ṣe aáyan rẹ̀ bó ti tọ àti bo ti yẹ. Yíyọ àwọn ǹkan tó le ṣe àkobá fún ara kúrò ṣe pàtàkì nítorí kìí ṣe òunjẹ ọhun gan ni kò dára bi ko ṣe awọn èròjà kan lára rẹ̀.
'Buns ni ọmọ mi jẹ tán ní ṣọ́ọ̀ṣì, ló bá di àwátì'
Tí a ò bá gbé ìgbésẹ̀ yìí ọ̀pọ̀ ounjẹ lo le di ààrun, májèlé tàbi kó já si ikú, nígbà mira a maa pa ọpọlọ lára.
1. Ẹ̀wà Soya ( Soya Beans)
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Gbogbo ènìyàn ló gba pé òunjẹ to dára ni ẹwà jẹ́ sùgbọ́n ọkàn wá ti ènìyàn ko ba sọ́ra ó le di àìsàn si ni lára.
Ẹ̀wà pupa àti soya beans ọmọ iyá kan náà ni wọ́n.
Ní apá kan wọn ni èròja afúni lẹ́jẹ̀ (protein) àti àwọn fitámìn, ẹ̀wẹ̀, ẹ̀wá ní epo kan ti wọ́n ń pè ni Phytohaemagglutinin ti ẹ̀ya ará ènìyàn ko lágbára lorí rẹ̀.
Tí ènìyàn bá jẹ ẹ jù, o lé fa inú rírùn àti ati inira.
Sùgbọ́n ayọ to wà nibẹ ni pé tí ènìyàn bá ṣee ko pẹ́ lóri iná ó máa n mú àdínkù ba ewu to wà nibẹ̀.
Bákan náà lo ni Trypsin, eyi a si maa ṣàkóba fun ǹkan to n mú ounjẹ da lára.
Sùgbọ́n oo, ti a ba le rẹ ẹ somi fún bii wákàti mejila kó to di sísè, àwọn kẹmika ara rẹ yóò pòórá.
2. Ẹja Puffer
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Eyií jẹ ẹja ti wan maa ń lo bi ìpanu ní ilẹ̀ Japan
Ẹja Puffer yiìí dàbí Májèlé, ó sì le pànìyàn.
Ẹja náà ni ǹkan ti wọ́n ń pe ni 'tetrodotoxin' eyí ti oró rẹ̀ ju ti májàlé lọ.
Bí ẹja yìí ṣe wá ni oró to ó sì jẹ́ ǹkan to wọ́pọ̀ ní àwọn orílẹ̀-èdè míràn.
Ní Japan ẹjá ti wọn máa n pe ni Fugu, wọn máá n jẹ ẹ ni tútú tàbi kí wọn dín ata si i.
Ọ̀pọ̀ àwọn àlásè máa ń gba ẹkọ fún ọ̀pọ ọdún ki wọn to le gbà wọ́n láàyè láti ṣe irú ẹja bẹ́ẹ̀.
O ṣe pàtàkì kí ènìyàn yọ gbogbo ibi ti ẹjẹ le di si, àwọn ẹyà ara bii ọpọlọ, awọ, ojú àti ikùn rẹ̀ ki ènìyàn to bẹ̀rẹ si ni jẹ ẹ.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ọ̀pọ̀ àwọn alase lo maa n gba ẹkọ fun ọpọọdun ki wan to lasẹ láti se ẹja náà
3. Casuwi Csu Marzu
Ǹkan to mú ounjẹ èyí yàtọ ni pe ó dàbi aràn.
Eyi ṣe bi ẹni rini lára díẹ̀ sùgbọ́n àwọn ara Sardinia ni Italy nifẹ òun náà gidigidi.
Wọn a maa fi ẹ̀pa lílọ àti ata dindin, díẹ̀díẹ̀ yóò maa yọ yoo si di omí si inú abọ.
Sùgbọ́n ki ènìyàn to jẹ irú ounjẹ yìí, àwọn ìgbẹ́sẹ̀ kan se pàtàkì.
Ní àkọkọ, o gbọ̀dọ kó àwọn aran náà nítori o le fo ibuso mẹẹdogun lẹ́ẹ̀kan náà.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Orisirisi ni bo se maa n ri lẹnu
Ikeji ni pé ó sòro láti rí, àjọ EU ko si fi ààye gbàá nítori náà kó ṣe tà si orilẹ̀-èdè míràn
Ikẹta ni pe wọ́n ti sàpejuwe rẹ bíi ọkàn lára àwọn ounjẹ to léwu jùlọ lágbàyé nítori pé o lé ni ààbọ lori iléra ẹni to ba n jẹ ẹ.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
O jẹ okan lara ounjẹto lewu julọ lagbaye
4. Ewé Rhubarb
Ewé yìí wọ́pọ̀ láàrin àwọn ara ilẹ Gẹẹsì ti wọn maa n fi pètò ounjẹ, ọ̀pọ òunjẹ nilẹ gẹẹsi ni ewé náà wà nínú rẹ̀.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Opo òunjé ilẹ̀ Gẹẹsi lo ni ewé yìí nínú
Enìyàn ni lati sọ́ra nítori pé èyí to jẹ aláwọ ewé rẹ̀ léwu gidigidi o sì ni májèlé nínú.
Ǹkan to wà níbẹ ni pé o ni májèlé ni wan n pè ni Oxalic acid, ti ènìyàn ba wá n fi gbogbo igbe jẹ, a maa ṣeni bi èèbi osí le fá okúta ninú kídìnrín.
Ẹ̀we, ewu  yiì ti di ọ̀rọ̀ ti wọ́n ń fà nitori pe asíídìì to wà nínú rẹ̀ ga púpọ̀.
Ti ènìyàn bá n jẹ ẹ púpọ̀ o le ṣe ikú pa ẹni náà, ó sàn ki ènìyàn má jẹe rárá.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
O le fa ikú ti ènìyàn ba n jẹ ni gbogbo igbà
Èyí dàbi bara ègúsí ti a ri ni orílẹ̀-èdè Indonesia.
O ṣe pataki láti fi ṣe awọn ounjẹ bii bisikiti àti wàra, àwọn nkan ti wọn tún fi n se ni láti din ata si oduku, ẹràn tabi láti fi ṣe ọbẹ.
Ṣùgbọ́n ti ènìyàn bá jẹ ẹ jù ó ma ń ṣokunfa ǹkan to pọ̀: o maa n gbéni léèbì, kìí jẹ kí ènìyàn le mi dáada, o tun máa n jẹ ki ènìyàn ní janin-janin.
Bótilẹ̀ jẹ́ pé kò wọ́pọ̀ ṣùgbọ́n ti ènìyàn ba jẹ Nutmeg púpọ o le ja si ikú.
Kí wa ni idí ti ènìyàn yóò fi ma kó òòrun didun si inu ounjẹ púpọ lásiko kan náà?
DR Congo: Ọ̀pọ̀ ẹmí lo ti sọ́nù ninú ìjàmbá ọkọ̀ òfurufú tó wáyé lóòní
Oríṣun àwòrán, Reuters
Oko ofurufu naa ba nkan jẹ púpọ̀
O kéré tan ènìyàn mẹ́tàdinlógójì ló ti jẹ́ Ọlọrun nípe lónìí nígba ti ọkọ̀ ofúrúfú kan já ni ilú Goma ni ilà-òòrun DR Congo gẹ́gẹ́ bi àwọn aláṣẹ́ ṣe sọ.
Àwọn ti iṣẹ́lẹ̀ ajálù náà kàn jùlọ ni àwọn mẹ́sàn nínú ìdílé kan ti gbogbo wọ́n kú ni àgbègbè Mapendo.
Ọkọ̀ òfurufú kékeré òun lo dédé já lulẹ ni kété to gbéra ni pápákọ̀ òfurufú ni owúrọ ọjọ aikú, ìdí ti ọkọ náà fi já lulẹ̀ kò ti yẹ ẹnikẹni titi di àsìkò yìí.
Eniyan mẹtadínlógun ní lo wà nínú ọkọ ofurufu náà
Kìí ṣe ìgbà àkọkọ rèé ti irú ǹkan bayìí yóò ṣẹlẹ̀ ni orílẹ̀-èdè DR Congo ní tori ètò ààbo tó wà nibẹ̀ kò gbópọ̀n tó àti pé ìtójú ti wọ́n ń ṣe fún àwọn ọkọ ofurufú naa kéré jọjọ. Eyí sì ló sokùnfa ìdí ti gbogbo àwọn orilẹ̀-èdè fi ni ki wọ́n maa wọ orílẹ̀-èdè àwọn mọ, pàápàá jùlọ ni àwọn ilẹ òkere alawọ funfun.
Dornier-228 twin-turboprop ti ilé iṣẹ́ aládani kan Busy Bee ra ló dédé já lẹ́yìn ìṣẹ́jú kan to gbéra , èyí jẹ́ ǹkan ti ẹnikan sọ fun BBC ni pápákọ ofúrúfú Goma.
Bàálú náà yẹ ko kó èrò lọ sí Beni to jẹ kilomita ààdọtadinirinwo tó n lọ sí ìhà àríwá Goma.
Oríṣun àwòrán, Reuters
DR Congo: Ọ̀pọ̀ ẹmí lo ti sọ́nu ni ìjàmba ọkọ ofurufú to waye lóòní
Nkan to fa idi abájọ ko tii dájú títí di àsìkò yìí, sùgbọ́n àwọn kan sọ pé ẹnjini bàálù ló ni isoro ni kéte to gbéra, eyi ni akoroyin BBc Emery Makumeno sọ pe ẹnikan sọ ni Kinshasha.
Kété ni àwọn òṣìṣẹ́ pajáwìrì bọ sibẹ̀ láti gbé awọn ènìyàn to fara pa ti wọ́n sí gbé àwọn to ti kú náà kúrò.
Kó ti dáju iye ènìyàn to wà ninú ilé ti bàálù naa jálù
Gómìnà Kasivita fidi rẹ̀ múlẹ̀ pé ìṣẹ̀lẹ̀ yìí ti gba ẹmi àwọn ará ilú wa"" bẹ́ẹ̀ lo fi ọ̀rs ìyànjú ránṣẹ́ si àwọn ẹbi ti àjálù náà dé bá àti awọn to farapa."
Ilé Iṣẹ́  BBC ti kan si Busy Bee fun ọ̀rọ̀ lẹnu wọ́n
Witches Conference: Àjọ PFN kéde àdúrà ọjọ́ méjì láti tako àpérò àwọn àjẹ́
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ajọ awọn kristẹni, PFN ti tako apero agbarijọpọ awọn ajẹ ti yoo waye lọsẹ yii ni fasiti ijọba apapọ to wa niluu Nsukka nipinlẹ Enugu.
Ajọ PFN sọ pe ewu nla wa nibẹ ti awọn ajẹ ba ṣe bẹẹ ṣe apero wọn gẹgẹ bi wọn ṣe n gbero.
''A ko le fọwọ leran ki a jẹki ohun ti ko f'ogo fun Ọlọrun, to si tun le ṣakoba fun ọjọ iwaju ṣẹlẹ nipinlẹ Enugu,'' alaga ajọ PFN Bisọbu Godwin Madu, lo woye bẹẹ.
Alaga ajọ PFN rọ alakoso fasiti ti wọn ti fẹ ṣe apero naa, Ọjọgbọn Charles Igwe wi pe ko ma ṣe gba wọn laye, bi ko ba fẹ ri ibinu Ọlọrun.
Biṣọbu Godwin ṣalaye pe ajọ PFN ti kede ọjọ meji bayii fun akanṣe adura lati rii pe apero naa ko waye.
O fikun ọrọ rẹ pe oriṣiiriṣii iṣẹlẹ ti ko fi ogo Ọlọrun han lo ti n ṣẹlẹ lorilẹede Naijiria tẹlẹ, nitorinaa awọn onigbagbọ gbọdọ gbadura lati tako apero ọhun.
Alaga PFN sọ pe ''ọwọ Ọlọrun ni ipinlẹ Enugu wa, nitorinaa a ko ni gba ko di ipinlẹ tawọn ajẹ yoo jẹ gaba le lori.''
Biṣọbu Godwin ni gbogbo awọn onigbagbọ gbọdọ ke pe Ọlọrun ninu adura bayii pe ko wa ja ni Naijiria nitori orukọ rẹ.
'Sẹ́ríkí Fúlàní ní ìpínlẹ̀ Ọṣun ní kò sí ìdí fún àwọn darandaran láti kúrò l'Ọ́ṣun
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ni opin ọsẹ to kọja ni okiki kan nipa iṣẹlẹ kan eyi to ṣẹ ninu eyi ti ara ti san pa maluu ti ko din ni mẹtadinlogun ninu agbo ẹran darandaran fulani kan ni ilu Iba ni ipinlẹ Ọṣun.
Iṣẹlẹ naani yoo si jẹ ẹkẹta iru ẹ ti yoo maa waye laarin oṣu mẹta ni ilẹ Yoruba.
Amọṣa iroyin to wa jẹyọ lẹyin iṣẹlẹ ti ipinlẹ Ọṣun lo ko awọn eeyan laya soke pe awọn darandaran Fulani kan ti n fi ipinlẹ naa silẹ ni ibẹru-bojo pe ki atunṣẹ ikọlu ara to ti fẹ maa di lemọlemọ lori awọn maluu o ma baa kan awọn pẹlu.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Awọn ileeṣẹ iroyin abẹle kan lorilẹede Naijiria ti kọkọ gbe iroyin yii pe eyi to ti n da ariyanjiyan silẹ laarin ọpọ titi de ori ayelujara.
Ninu ọrọ to ba BBC news Yoruba sọ lori ẹrs ibanisọrọ, Seriki awọn Fulani ni ipinlẹ Ọsun Alhaji Oluwatoyin Sulaeman ṣalaye pe ko si otitọ ninu iroyin naa.
Oríṣun àwòrán, SIA KAMBOU
Ọmọ Yahoo tú àṣírí ara rẹ̀ fún, bí wọ́n ṣe ń ṣe é BBC Yorùbá
Alhaji Oluwatoyin Sulaeman ni lootọ ni ara san pa agbo ẹra arakunrin naa ṣugbọn awọn gbaa gẹgẹ bii iṣẹlẹ amuwa Eledumare eyi ti ko nii ṣe pẹlu wahala tabi edeaiyede laarin awọn darandaran ati awọn ara ilu ti wọn tẹdo sii.
Sẹriki Fulani naa tẹ siwaju pe ọkan awọn darandaran balẹ ni ipinlẹ Ọṣun, wọn ko ni ikayasoke kankan nipa abo ati alaafia awọn ati agbo ẹran wọn.
O wa rọ ijsba ipinlẹ Ọṣun lati dide iranlọwọ fun arakunrin ti adanu naa ṣẹ si nitori pe gbogbo dukia rẹ naa ni ara san pa naa.
Lai Mohammed: Kò sí ohun tó burú nínú kí ìjọba yá owọ láti fi ṣe àwọn ohun amáyédẹrùn
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Minisita fun eto iroyin ati aṣa, Lai Mohammed ti sọ pe, ko si ohun to buru ninu ki ijọba ya owo lati fi ṣe awọn ohun amayedẹrun saarin ilu.
Lai Muhammed lo sọ ọrọ naa nigba to n ṣayẹwo ibi iṣẹ de duro loju ọna oju irin Ibadan si ilu Eko.
"O ni ""A ko yá owo lati na a lori awọn nnkan miran, ṣugbọn awọn owo ti a n ya, awọn nnkan amayedẹrun bii ọna oju irin, opopona to ja gaara, afara igbalode, ina mọnamọna, atawọn nnkan miran ni a fi n ṣe."""
"Lai tẹsiwaju pe ""Ko si ohun to buru ninu ki a ya owo, niwọn igba to ba jẹ pe awọn ohun amayedẹrun la fẹ fi owo ọhun ṣe, paapaa to ba jẹ eyii ti yoo pese iṣẹ fun awọn eeyan, ti yoo gbe ọrọ aje wa soke."""
Minisita ọhun fi kun un pe inu oun dun si iṣẹ to n lọ lọwọ loju ọna oju irin ọhun.
The Polytechnic Ibadan: Ẹ̀rọ abẹ́lé tó ń fọ ọwọ́ àti ‘Ventilator’ ló ṣẹ̀ṣẹ̀ gbé jáde
O ni inu awọn ọkọ oju irin naa mọ lolo, o dun wo loju, o si ba igba mu gẹgẹ ni iru rẹ to wa lawọn orilẹ-ede miran to ti goke agba kaakiri agbaye.
Lai pari ọrọ rẹ pe minisita eto irina mu ori oun wu pẹlu aayan to fi n ṣe iṣẹ opopona oju irin naa.
Oríṣun àwòrán, @thebridgenewsng
Minisita eto iroyin ati aṣa, Lai Mohammed ti ṣalaye idi ti ijọba apapọ ṣe ṣafikun iye owo itanran fun awọn to ba sọrọ odi si ijọba lati ẹgbẹrun lọna ẹẹdeẹgbẹta naira si miliọnu marun un naira.
O ni idi naa jẹ lati kapa awọn kọlọrọsi ti yoo lo ọrọ ikorira lati da orilẹ-ede Naijiria ru.
"Lai ṣalaye pe ""Idi pataki ti a fi ṣafikun iye owo naa ni pe, awọn eeyan n ru ofin ọhun nigba ti iye owo itanran rẹ wa ni ẹgbẹrun lọna ẹẹdeẹgbẹta naira nitori o rọrun fun wọn lati san."""
O ni awọn ileeṣẹ igbohunsafẹfẹ kan yoo mọọmọ gbe ọrọ kobakungbe sita lori afẹfẹ, ti wọn yoo si gba lati san owo itaran ọhun.
Ọdun 2019 ni ọgbẹni Lai kọkọ kede pe aarẹ Muhammadu Buhari ti buwọlu afikun owo itanran ọhun eyii ti wọn fi sinu akọsilẹ iwe ofin to rọ mọ igbohunsafẹfẹ.
O ni ki awọn awọn to n bu ẹnu atẹ lu ijọba lori afikun owo itanran naa mọ pe ọrọ kobakungbe ti da rogbodiyan silẹ lawọn orilẹ-ede kan.
Ohun tẹ́ẹ gbúdọ mọ nípa kókó orí ọyàn yín lásìkò fífọ́mọlọ́yàn
Gẹgẹ bo ṣe sọ, ẹgbẹrun lọna ẹgbẹrin eeyan lo ku ni Rwanda latari ọrọ ikorira.
Bẹẹ lo tun sọ nipa orilẹ-ede Chad to dẹwọ bi awọn eeyan ṣe n lo ori ayelujara rẹ lati kapa ọrọ ikorira.
Lai pari ọrọ rẹ pe afojusun ijọba ni lati ṣakoso bi awọn eeyan ṣe n lo ori ayelujara lai tẹ oju ẹtọ wọn lati sọrọ gẹgẹ bi ọmọ Naijiria mọlẹ.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Laipẹ yii  ni ijọba orilẹede Naijiria ti ni ẹnikẹni ti ọwọ ba tẹ pe oun sọrọ kubakugbe yoo san owo itanran miliọnu marun Naira.
Minisita fun eto iroyin ni Naijiria, Alhaji Lai Mohammed lo sọ eleyii ni ilu Abuja lasiko ti wọn n ṣe ifilọlẹ atunṣe fun ofin to rọ mọ iroyin ni Naijiria.
Lai Mohammed ni oun gbe igbesẹ naa lẹyin ti oun gba aṣẹ lọwọ Aarẹ Muhammadu Buhari to paṣẹ atunṣe naa lẹyin gbogbo ọrọ kubakugbe to waye ni Naijiria saaju idibo gbogboogbo ti ọdun 2019.
Lati atẹyinwa ni awọn to di ipo mu ni Naijiria to fi mọ iyawo aarẹ Buhari, Aisha Buhari ni wọn ti ṣe ikilọ lori sisọrọ kubakugbe lorilẹede Naijiria.
Ìdílé tí ọkọ da ọmọ síta tóríi ojú Búlùú tí wọ́n ní bá BBC sọ̀rọ̀
Kìí ṣe ọmọbìnrin nìkan ni Ọlọ́run pàṣẹ fún láti pa ìbálé mọ́
Kini itumọ sisọrọ kubakugbe?
Sisọrọ kubakugbe niiṣe pẹlu sisọ ọrọ tabi lilo aworan ti o le ṣe ipalara tabi tabuku ba ẹni ti wọn n sọ ọ si lawujọ.
Sisọrọ kubakugbe tun tumọ si piparọ mọ eniyan ati iroyin ẹlẹjẹ nipa ẹnikan lọna ati fi ṣe ẹlẹya lawujọ.
Kini ofin tuntun ti ijọba ṣẹṣẹ fikun sisọrọ kubakugbe lawujọ
Minisita fun eto iroyin ni Naijiria, Lai Muhammed ni ofin tuntun naa ti wọn pe ni 'Edition of the Broadcasting Code' ti mu ayipada pa iroyin to niiṣe pẹlu oṣelu, iroyin abẹle, iroyin yajoyajo ati iroyin karakata ni Naijiria.
Ofin tuntun naa ṣe afikun iye owo ti awọn ẹni ti wọn ba mu pe oun sọrọ kubakugbe yoo ma a san lati N500,000 si N5m.
Ofin to de lilo ẹrọ ayelujara ni Naijiria fun ijọba Naijiria laaye lati ṣe ọfintoto awọn iroyin ti ileeṣẹ iroyin lati oke okun ba n gbe jade ni Naijiria, lati ri wi pe wọn ko gbe iroyin to le e da wahala silẹ ni Naijiria.
Ofin tuntun naa ni ijọba laṣẹ lati sọ igba ti awọn ileeṣẹ iroyin yoo gbe iroyin jade ti rogbodiyan ba bẹ silẹ ni Naijiria.
Amọ, awọn onimọ nipa eto iroyin ati awọn to n lo ẹrọ ayelujara ti fi ero wọn han lori ofin tuntun ti ijọba gbe kalẹ naa.
Alaga tẹlẹri fun ileeṣẹ to n sakoso eto iroyin ni Naijiria (National Broadcasting Corporation), Tony Iredia ti bu ẹnu atẹ lu ofin tuntun naa, to si sọ wi pe o tako ofin to de eto iroyin ni Naijiria.
Ninu ọrọ tirẹ, arakunrin Justin lori ẹrọ Twitter sọ wi pe ohun ko ri iṣoro pẹlu ofin tuntun naa, amọ ijọba gbọdọ le fa ala laarin ọrọ kubakugbe ati eto lati sọ ọrọ lawujọ.
Amọ, minisita fun eto iroyin naa ni ijọba ko ni naani gbogbo ọrọ ti awọn to ba tako ofin naa ba sọ, ati wi pe awon gbe ofin tuntun naa kalẹ fun idagbasoke Naijiria, eleyii o mu ki ijọba laṣẹ labẹ ofin lati ṣe atunṣe ofin to rọmọ iroyin lorilẹede Naijiria loore-koore.
'Mo fẹ́ gbé ògo ìdílé ìyá àti bàbá mi ga pẹ̀lú iṣẹ́ Mọkálìíkì'
Sẹnẹtọ to ṣagbatẹru aba to maa ṣe amujuto ọrọ ikorira eyi to wa niwaju ile igbimọ aṣofin agba l'Abuja, Sabi Abdullahi, sọ pe ile ṣetan lati yọ aba ijiya iku kuro ninu aba ti wọn gbe kalẹ ọhun.
Sẹnẹtọ Abdullahi ni ile yoo ṣiṣẹ lori aba naa lati rii wi pe o jọ ohun tawọn ọmọ Naijiria n fẹ gan an.
Abdullahi sọ pe ọrọ ti awọn to tako aba naa atawọn to fara mọ ọ sọ yoo wulo lati ṣe ofin gidi ti yoo dẹkun ọrọ ikorira lorilẹede Naijiria.
Ọmọ Yahoo tú àṣírí ara rẹ̀ fún, bí wọ́n ṣe ń ṣe é BBC Yorùbá
Abala kẹrin aba naa lo sọ pe ẹnikẹni to ba jẹbi ẹsun ikorira yoo lọ sẹwọn gbere, bakan naa iru ẹni bẹẹ tun le gba idajọ iku ti ọrọ ikorira to ba sọ ṣokunfa iku ẹlomiran.
Awọn ajafẹtọ ati ọpọ eeyan ni wọn ti tako aba ọhun, wọn ni ọna lati maa dunkoko mọ awọn eeyan ni, eleyi to lodi si ẹtọ lati maa sọrọ tawọn ọmọ Naijiria ni.
Ṣugbọn Sẹnẹtọ Abudulahi ni ọrọ ikorira ti ṣokunfa iku fun ọpọ eeyan, o ni ohun lo n fa irẹwẹsi ọkan fun ọpọ to si tun ti mu ọpọ gbẹmi ara wọn.
Sẹnẹtọ Abudulahi ṣalaye pe gẹgẹ bi akọsilẹ ajọ iṣọkan agbaye, orilẹede Naijiria ni awọn eeyan to ni irẹwẹsi ọkan ti pọ ju lọ nilẹ Afirika, bakan naa ni akọsilẹ ọhun to fihan pe Naijiria ni iṣẹlẹ ipara ẹni ti pọju ṣikarun un lagbaye.
O ṣalaye siwaju sii pe ohun ti aba yii wa fun naa ni lati dena ifẹmi ṣofo awọn Naijiria lori ọrọ ikorira tawọn kan sọ eleyii to da rogbodiyan silẹ.
Unai Emery: Àwọn olólùfẹ́ Arsenal ní Emery gbọdọ̀ fipò rẹ̀ sílẹ̀ dandan
Oríṣun àwòrán, Twitter/Arsenal FC
Ina ti jo dori koko bayii fun akọnimọọgba ẹgbẹ agbabọọlu Arsenal, Unai Emery.
Ọgọrọ awọn ololufẹ Arsenal ni wọn yabo oju opo ayelujara papaajulọ Twitter, nibi ti wọn ti sọ pe ki Emery kọwọ fipo rẹ silẹ tabi ki Arsenal juwe ile fun un.
Agidi ni Arsenal fi gba ọmọ alayo meji si meji pẹlu ikọ agbabọọlu Southampton lopin ọsẹ to kọja ninu idije Premier League.
Lẹyin ifẹsẹwọnsẹ naa lawọn ẹgbẹ alatilẹyin Arsenal kan sọ fun awọn alaṣẹ ikọ Arsenal pe ki wọm fọwọ osi juwe ile fun Emery.
Ipo kẹjọ ni Arsenal wa bayii lori tabili idije Premier League eleyi to jẹ ki ọpọ alatilẹyin Arsenal maa kọminu.
Ẹgbẹ naa ṣalaye pe awọn eeyan bi ọgọrun un mẹfa lo ti kọwọ bọwe pe ki Emery dagbere fun Arsenal.
Bakan naa lọpọ eeyan loju opo Twitter n sọ pe o ti to asiko fun Emery lati fipo rẹ silẹ.
Ọpọ lo n sọ pe kawọn alaṣẹ Arsenal gba Massimiliano Allegri tabi Mauricio Pochettino lati rọpo Emery gẹgẹ bi akọnimọọgba Arsenal.
Ọmọ Yahoo tú àṣírí ara rẹ̀ fún, bí wọ́n ṣe ń ṣe é BBC Yorùbá
Traffic gridlock: Sanwo-Olu fẹ́ sún ìrìnnà ọkọ̀ àjàgbé kúrò lọ́sàn sí òru l'Eko
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Njẹ o mọ pe o ṣeeṣe ki irinna loju popo ni ọsan di eewọ fun gbogbo awọn ọkọ ajagbe nlanla ni ipinlẹ Eko?
Ọpọlọpọ awọn eeyan ni wọn ti n pariwo lori ọṣẹ ti awọn ọkọ ajagbe, yala eyi to n gbe epo ni tabi awọn ẹru miran, maa n ṣe lawọn oju popo; paapaa julọ ni ipinlẹ Eko.
Eyi gan an fẹẹ lo faa ti gomina ipinlẹ Eko, Babatunde Sanwo-olu fi kede pe laipẹ gbogbo irinna ọkọ to ba jẹ ajagbe ni wọn yoo fi mọọ si alẹ dipo ọsan tabi ojumọmọ.
O ni ijọba ipinlẹ Eko ti n le awọn ọkọ ajagbe kuro lagbegbe Iganmu bayii ki oju ọna lee la fun awọn to fẹ rinrinajo lọ si Apapa.
Ọmọ Yahoo tú àṣírí ara rẹ̀ fún, bí wọ́n ṣe ń ṣe é BBC Yorùbá
Gomina Sanwo-Olu ni ijọba Eko ti n fi orikori lori awọn ọna lati ṣakoso irinna ọkọ ni ipinlẹ Eko ki wọn si yanju iṣoro bi oju popo ṣe maa n di gadigadi.
Bakan naa lo ṣalaye pe atunṣe awọn oju popo ati oju odo yoo waye pẹlu ki ipinlẹ Eko lee tẹsiwaju gẹgẹ bii aayo awọn oludokowo gbogbo.
LAUTECH Crisis: Makinde ní kí ìpínlẹ̀ Ọyọ gba àkóso fásitì náà ni ọ̀nà àbáyọ
Oríṣun àwòrán, Seyi Makinde
Gomina ipinlẹ Ọyọ, Onimọ ẹrọ Seyi Makinde ti se abẹwo sile ẹkọ imọ ẹrọ fasiti Ladoke Akintola LAUTECH to wa nilu Ogbomoso ni aarọ ọjọ Isẹgun.
Lasiko abẹwo ọhun ni gomina Makinde gbe miliọnu lna ẹẹdẹgbẹta naira kalẹ lati lee fopin si iyansẹlodi awọn olukọ ile ẹkọ̀ fasiti naa, to si tun se ipade pọ pẹlu awọn eeyan ti ọrọ ileẹkọ naa gberu lọna ati wa ojutu si wahala to n koju ileeẹkọ naa.
Nigba to n ba ipejọpọ naa sọrọ, gomina Makinde fọwọ gbaya pe oun yoo da si ọrọ̀ naa ki iyansẹlodi naa lee di ohun igbagbe, ti eto ẹkọ kikọ yoo si bẹrẹ lọgan.
Bakan naa lo fi ewe ọmọ mọ awọn osisẹ fasiti LAUTECH leti pe ki wọn dẹkun dida ija silẹ pẹlu ijọba ipinlẹ Ọsun, to si tun seleri pe ko si osisẹ fasiti naa ti wọn yoo le lẹnu isẹ lai naani ipinlẹ ti wọn ti wa.
Oríṣun àwòrán, Seyi Makinde
Mo tun ba awọn ẹlẹgbẹjẹgbẹ osisẹ nile ẹkọ LAUTECH sọrọ lori bi wọn yoo se se amulo owo idoola isoro ti mo gbe kalẹ, ati ọna ti wọn yoo gba fọwọsowọpọ pẹlu ijọba lati wa ọna abayọ titi laelae si awọn ipenija to n koju ileẹkọ naa.
Oríṣun àwòrán, Seyi Makinde
Bakan naa tun ni Makinde fikun pe, aba ti oun gbe kalẹ lati gba akoso ileẹkọ fasiti LAUTECH labẹ akoso ipinlẹ Ọyọ nikan ni ọna abayọ si ọpọ ohun ti fasiti naa n poungbẹ rẹ.
Oríṣun àwòrán, Seyi Makinde
"O tun tẹnumọ pe, ""eyi ko tumọ si pe mo fẹ kẹyin si awọn eeyan wa to wa nipinlẹ Ọsun nitori ẹbi kannaa ni wa amọ igbesẹ naa yoo jẹ ọna abayọ ayeraye, nitori ipinlẹ Ọyọ ti gbaradi pẹlu owo lati gbe ẹru sise akoso ileẹkọ fasiti naa gẹgẹ bii eyi to jẹ tirẹ nikan."""
Oríṣun àwòrán, Seyi Makinde
Owurọ kutu Ọjọ Iṣegun ni gomina ipinlẹ Oyo, Seyi Makinde ati ikọ rẹ gba igboro Ibadan lọ lati palẹ awọn idọti to dabi oke nilu Ibadan mọ.
Saaju ni gomina ti pasẹ fun gbogbo awọn eeyan to dipo oselu mu ninu ijọba rẹ ati awọn oludari agba nileesẹ́ ijọba kọọkan lati bọ sigboro ilu Ibadan, ki wọ̀n si ko gbogbo awọn idọti to wa laarin oju popo kuro, ki ayika lee dun wo.
Oríṣun àwòrán, FACEBOOK
Makinde ko fi ọ̀rọ̀ naa se ti ipo asaaju, funra ara rẹ loun naa bọ si ita gbangba lati mojuto eto naa lẹyin aṣẹ to pa fun awọn oṣisẹ ijọba  ati oloselu naa, ti awọn osisẹ fun ile isẹ to n risi imọtoto ayika naa si kọwọrin tẹle Gomina Makinde lati ṣe eto gbalumọ ọhun.
Ibadan: awon araalu figbe bonu pe ilu doti
Gomina Seyi Makinde ti kọkọ se ipade lọsan ọjọ aje pẹlu awọn eeyan ti eto ipalẹmọ ẹgbin nipinlẹ Ọyọ gberu ati awọn ọmọ igbimọ alakoso fun ileesẹ to wa fun ipalẹmọ ẹgbin nilu Ibadan.
Koko ipade naa si lo da lori ọna lati wa ojutu si isoro akoso ẹgbin to n ba ilu Ibadan finra, ti Makinde si fọwọ sọya pe oun yoo ri daju pe wọn ko gbogbo awọn ẹgbin to dabi oke nilu Ibadan kuro laipẹ.
Oríṣun àwòrán, Seyi Makinde
"A ri daju pe a fi ofin to de dida ilẹ kiri laibikita mulẹ nipinlẹ Ọyọ, ta si tun wa ọna abayọ si isoro ẹgbin laarin ọsẹ mẹrin pere si asiko yii.'
Mo wa n rọ awọn eeyan ipinlẹ yii lati fara da pẹlu mi nibayii ti mo n lakaka lati wa ojutu si isoro naa, ki wọn si fọwọsowọpọ pẹlu wa lati ri pe ayika wa mọ tonitoni, ti ko si lewu fun gbogbo wa lati gbe."
Oríṣun àwòrán, Seyi Makinde
Lara awọn eeyan miran to tun tẹle gomina Makinde ni lati oludamọ̀ran rẹ feto aabo, Fatai Owoseni, ti gbogbo wọn si sisẹ loru mju lati ri daju pe ọrọ ẹgbin to fọn kaakiri ilu di afiẹyin, ti eegun fi asọ.
Bẹẹ ba gbagbe, ileesẹ BBC Yoruba naa ti pe akiyesi ijọba ipinlẹ Ọyọ si obitibiti ẹgbin to n se ilu Ibadan lọsọ, ti kọmisana fọrọ ayika naa si fi da wa loju pe laipẹ ni isoro ẹgbin ayika ọhun yoo di ohun igbagbe.
Oríṣun àwòrán, FACEBOOK
Láìpẹ́ yìí ni BBC Yoruba se àfihàn bí ìgboro ìpínlẹ̀ Oyo se dòtí, àmọ tí ìjọba ní àwọn yóò wá ǹ kan se sí.
Sex Offenders: NAPTIP ní àwọn aráàlú tó jẹ́ ẹ̀jẹ̀ kannáà kìí fẹ́ kí ẹbí wọn ṣẹ̀wọ̀n ìfipábánilòpọ̀
Oríṣun àwòrán, Others
Ọjọ Aje ni igbakeji aarẹ, Ọjọgbọn Yemi Osinbajo sefilọlẹ iwe akọsilẹ ti yoo maa gbe orukọ awọn eeyan to ba jẹbi ẹsun ibalopọ lọna aitọ sita.
Iwe akọsilẹ naa si ni wọn fi n sami ayajọ ọjọ gbigbogun ti iwa sawọn obinrin eyi to maa n waye lọjọ kẹẹdọgbọn osu kọkanla ọdọọdun, to ko lọjọ aje lọdun 2019.
Iwe akọsilẹ orukọ awọn eeyan to jẹbi ẹsun ibalopọ lọna aitọ yii nii se akọkọ iru rẹ ti ajọ to n gbogun ti iwa ifinisowoẹrun NAPTIP, se agbekalẹ rẹ nifọwọkọwọ pẹlu awọn ileesẹ alaabo ati awọn ajafẹtọẹni lorilẹede Naijiria.
Nigba to n salaye ohun ti iwe akọsilẹ naa wa fun awọn awọn igbesẹ to rọ mọ lilo rẹ, oludari fun ẹka eto itaniji fun araalu labẹ ajọ Naptip, Arinze Orogwe salaye fun BBC Yoruba pe eto yii lo jẹ eyi to kan tọmọde tagba lorilẹede Naijiria.
Oríṣun àwòrán, Yemi Osinbajo
Awọn koko ohun to si mẹnuba ree pe o jẹ igbesẹ lati gbe ta ba fẹ lo iwe akọsilẹ naa, ti a si kọ̀ orukọ awọn afipabanilopọ sibẹ. yoo si wa nibẹ titi laelae.
'Buns ni ọmọ mi jẹ tán ní ṣọ́ọ̀ṣì, ló bá di àwátì'
Ninu alaye rẹ, Arinze Orogwe ni lootọ ni ijọba sefilọlẹ iwe iforukọsilẹ orukọ awọn eeyan to jẹbi ẹsun ifibanilopọ, amọ o wa n beere pe se yoo rọrun lati ri ọpọ orukọ awọn eeyan to jẹbi ẹsun naa tile ẹjọ ti se idajọ wọn.
Arinze ni awọn isoro kan wa to nii se pẹlu igbẹjọ awọn eeyan ti wọn fi ẹsun ibalopọ kan, ti awujọ ko ba si fọwọsowọpọ pẹlu ijọba, o lee soro pupọ lati sedajọ wọn, pẹlu afikun pe ti iwa ifipabanilopọ ba si n tẹsiwaju lawujọ, awọn araalu lo n faa.
Isoro to lee pagidina amulo iwe iforukọsilẹ orukọ awọn afipabanilopọ:
Amọ oludari ẹka itaniji fun araalu labẹ ajọ Naptip wa rọ awọn araalu lati mase maa sa si abẹ ojiji wọn, ki ẹlẹsẹ ma baa lọ laijiya amọ ki wọn kan si ajọ naa, ki wọn si setan lati ba ẹjọ naa de opin, ki idajọ tootọ lee wa.
FUTA: Òfin ti wà nílẹ̀ tó ní ká lé akẹ́kọ̀ọ́ tó bá na akẹẹgbẹ́ rẹ̀
Oríṣun àwòrán, Google
Ile ẹkọ fasiti imọ ẹrọ ijọba apapọ to kalẹ silu Akure, ti fi ọwọ osi juwe ile fawọn akẹkọọ mẹfa ti wọn fẹsun kan pe wọn lu akẹgbẹ wọn.
Igbesẹ yii ko ṣẹyin abajade igbimọ iwaadi ti ile ẹkọ naa gbe kalẹ, lati ṣe iwaadi bi awọn akẹkọọ naa ṣe lu akẹgbẹ wọn kan nilegbe awọn akẹkọọ.
Iṣẹlẹ naa waye lọjọ kẹrindinlogun oṣu Kọkanla ọdun 2019.
Igbakeji oludari eto ibanisọrọ fasiti Futa, Adegbenro Adebanjo lo fi ikede yii sita ninu atẹjade kan ti ile ẹkọ naa fi sita.
Gẹgẹ bi o ti ṣe sọ, wọn ni orukọ awọn akẹkọọ naa ni:
Bakanna ni wọn ni lile tawọn le awọn akẹkọọ naa wa ni ibamu pẹlu ofin ileewe to la ijiya ''lile akẹkọọ kuro ti o ba lu akẹkọọ akẹgbẹ rẹ nibikibi ti kii ṣe ọgba ile ẹkọ''
Wọn ni lnitori eleyi, awọn akẹkọ to huwa aidaa naa ko le e jẹ anfaani kankan to tọ si awọn akẹkọọ fasiti naa mọ bayi.
Ẹwẹ, fasiti FUTA tun sọ pe kii ṣe nitori pe awọn eeyan ke gbajare lori iwa awọn akẹkọọ to lu akẹgbẹ wọn naa, bi kii ṣe pe awọn tẹle ofin ti ile ẹkọ la kalẹ lori fifi iya jẹ ẹni ba tasẹ agẹrẹ sofin wọn.
EFCC: Ọ̀gá ẹlẹ́wọ̀n àti dókítà gba ẹlẹ́wọ̀n láàyè láti kúrò láhàmọ́ọ́ fún ìtọ́jú
Oríṣun àwòrán, EFCC
Ajọ to n gbogun ti iwa jẹgudujẹra ni Naijiria EFCC ti kede pe oun ti mu ọga awọn oṣiṣẹ ẹlẹwọn Kirikiri nilu Eko nitori pe o ṣe iranwọ iwe aṣẹ ayederu fun ẹlẹwọn kan lati gba itọju nile iwosan.
Emmanuel Oluwaniyi to jẹ ọga agba awọn ẹlẹwọn ati Hemeson Edson Edwin to jẹ dokita to n mojuto ilera awọn ẹlẹwọn ni EFCC sọ pe, aje iwa ibajẹ ṣi mọ lori.
Lọjọ Aje tii ṣe ọjọ kẹẹdọgbọn oṣu Kọkanla ni ajọ naa ni awọn oṣiṣẹ awọn mu awọn mejeeji.
Wilson Uwujaren to jẹ agbẹnusọ Ajọ EFCC sọ pe, awọn mejeeji buwọlu iwe aṣẹ to fun ọgbẹni Hope Aroke lanfaani lati lọ gba itọju nile iwosan nita ọgba ẹwọn.
Igbesẹ wọn yi ni EFFC sọ pe o ṣi ọna fun Aroke lati hu orisirisi iwa gbajuẹ lasiko to yẹ ko wa lọgba ẹwọn pẹlu iranwọ awọn ọdaran mii.
O ni awọn mejeeji ti n ṣwi tẹnu wọn fajọ EFCC.
Bi a ko ba gbagbe, laipẹ yi ni iroyin kan pe ọgbẹni Hope Aroke ti wọn tun un pe ni H Money n wọke lati inu ọgba ẹwọn ti wọn fi si.
Koda iye owo gbajuẹ to n ṣe lati inu ẹwọn la gbọ pe o to miliọnu dọla kan.
Aroke ti ile ẹjọ ti dajọ ẹwọn ọdun mejila fun ni ajọ EFCC sọ pe o tun n da ọran mọ ọran ninu ọgba ẹwọn ti wọn fi si.
Ìjọba Zamfara wọ́gilé owó ìfẹ̀yìntì tàbùà tabua fawọ̀n Gómìnà
Ile aṣofin ni ipinlẹ Zamfara ti wọgile owo ifẹyinti ti ijọba ana nipinlẹ naa ṣagbekalẹ rẹ fun Gomina ati igbakeji rẹ.
Gẹgẹ bi atẹjade kan ti olori ile aṣofin naa Mustapha Jafaru fi sita lọjọ Iṣẹgun, awọn aṣofin naa sọ pe lati wakati yii lọ ko ni si owo ifẹyinti ati awọn ajẹmọnu miiran mọ fun Gomina ati igbakeji rẹ.
Aba naa ti olori ọmọ ẹgbẹ to pọju lọ nile Faruq Musa Dosara ṣe agbekalẹ rẹ ni o sọ pe yoo dina owo  to to ẹẹdẹgbẹrin miliọnu tawọn Gomina n gba lasiko tara ilu n kerora.
Ẹgbẹ oṣelu PDP ni o wa lori alefa ni ipinlẹ naa bayi ti o si jẹ wi pe ijọba APC lo ṣe agbekalẹ ofin yi ki wọn to kuro lori oye.
Igbesẹ Gomina ana Abdulaziz Yari to kọwe si ijọba ki wọn san owo ifẹyinti ti wọn jẹ ohun lo mu gbogbo awuyewuye to pada wa bi iyipada ofin yi waye.
Owo oṣu meji ni wọn jẹ Yari ti o si kọwe pe ki wọn san owo naa fun ohun ni ibamu pẹlu ofin to wa nilẹ.
'Buns ni ọmọ mi jẹ tán ní ṣọ́ọ̀ṣì, ló bá di àwátì'
Esi ti ijọba Gomina Matawalle fi sita ni pe o jẹ iyalẹnu fawọn pe Yari yoo ma beere owo yi nitori ko si Gomina kankan to ti foye silẹ to n kọwe beere owo ti wọn jẹ wọn.
Ni bayi ti wọn ti gbe abadofin kalẹ,ti Gomina Matawaale ba file buwọlu,ko ni si Gomina kankan ti yoo ma gba owo ifẹyinti miran lọdọ ijọba ipinlẹ yatọ si eleyi ti igbimọ to n risi pipin owo oṣu fawọn to fi ipo oṣelu silẹ ba la kalẹ fun wọn.
Pupọ ninu awọn Gomina ipinlẹ Naijiria ni o n gba owo yi ti awọn ile aṣofin la kalẹ ṣaaju ki wọn to kuro lori oye.
GRIDCo: Àpọ̀jù iná mọ̀nàmọ́ná ló sọ Ghana sí òkùnkùn birimù
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ṣaadede ni awọn waya to gbe ina lọ si Mali bẹrẹ si ni gbona ti wọn si da ina ọhun pada si ori ibudo amunawa Ghana.
Ile iṣẹ eleto ina ọba nilẹ Ghana, Ghana Grid Company(GRIDCo) sọ pe aisina lawọn agbegbe kan lorileede Ghana ko ṣẹyin apọju ina to pada si ori opo nilẹ naa ti o si mu ki awọn ẹrọ amunawa dakẹ iṣẹ.
Ọga agba  GRIDCo, Jonathan Amoako Baah ṣalaye pe niṣe ni aisina yi waye nigba ti ina ti wọn fi ranṣẹ si orileede Côte d'Ivoire pada si ori opo ina ti ilẹ Ghana.
'Buns ni ọmọ mi jẹ tán ní ṣọ́ọ̀ṣì, ló bá di àwátì'
Orileede Ghana n ta to ọgọrun Megawatts ina ọba ninu ina ti wọn n pese lati ibudo amunawa wọn fun orileede Côte d'Ivoire.
Ṣe ni awọn waya to gbe ina lọ si Mali bẹrẹ si ni gbona ti wọn si da ina ọhun pada si ori ibudo amunawa Ghana.
Ileeṣẹ eleto ina ọba Ghana fi ikede yi soju opo ayelujara wọn lati tọrọ aforijin lọdọ ara ilu.
"Ninu atẹjade naa ti  ọga ileeṣẹ naa Amoako Baah  fọwọ si,wọn ni ""Iṣẹlẹ naa kọja agbara wa ṣugbọn kete ti a ba ti yanju rẹ nia o da ina pada si awọn agbegbe ti ọrọ naa kan.''"
Niṣe lawọn ọmọ ilẹ Ghana gba ori opo ayelujara lọ lati fi ẹhonu han nitori ina ọba ti ko si fun wakati mẹrinlelogun yii.
Retirement Benefits: Èyí ni mùdùnmúdùn tó wà nínú owó ifẹ̀yìntì àwọn Gómìnà tẹ́lẹ̀ ní Nàìjíríà
Oríṣun àwòrán, Google
Ko jẹ tuntun mọ pe awọn aṣofin ipinlẹ Zamfara ti wọgile owo ifẹyinti tabua ti awọn Gomina to fi ipo silẹ n gba.
Eyi ko ṣẹyin bi Gomina ana Abdulaziz Yari ṣe kọwe beere owo ifẹyinti rẹ oṣu meji ti wọn ko ti san fun.
Igbesẹ yii mu iriwisi ọtọọtọ wa, ti o si tun mi ki awọn eeyan ma sọrọ nipa bi owo obitibiti ṣe rọ mọ didi ipo mu lagbo oṣelu Naijiria.
Ki ọrọ naa ba le ye wa daada, a ni ki a darukọ awọn ipinlẹ miran ti wọn ṣe agbekalẹ ofin owo ifẹhinti fawọn Gomina ati igbakeji wọn, lẹyin ti wọn pari saa ijọba wọn.
Iru mudunmudun wo lo ba awọn owo ifẹhinti yii wa, eyi to yẹ ki a dijọ yẹ wo lawọn ipinlẹ kọọkan lorileede Naijiria, ti iru eto yii wa fawọn to ti fi ipo oselu silẹ
Kwara:
Lọdun 2018 ni ijọba ipinlẹ Kwara mu ayipada ba ofin to de sisan owo ifẹyinti fawọn to ti jẹ Gomina tabi igbakeji wọn ni ipinlẹ naa.
Wọn gbe igbesẹ yii lẹyin ti ariwo pọ lori bi awọn Gomina tele ri kan nipinlẹ ọhun, ti n gba owo laaye wọn gẹgẹ bi Sẹnẹtọ ati lakoto ijọba ipinlẹ bakanna.
Bukola Saraki ati Shaba Lafiaji wa lara awọn to jẹ Gomina tẹlẹ ri taa n sọ, ti wọn si tun jẹ Sẹnẹtọ to n soju agbegbe wọn.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Toun ti pe ofin tuntun ni ki wọn mase san owo fawọn to di ipo miran mu lẹyin ti wọn fi ipo Gomina tabi igbakeji silẹ, wọn ko wọgile sisan owo yii bi ipinlẹ Zamfara ti ṣe ṣe.
Titi di bi a ti ṣe n sọrọ yii, owo tabua ati ajẹmọnu lofin bu fawọn to dipo mu tẹlẹ yii.
Lara mudunmudun ti ofin yii la kalẹ fun wọn ni pe:
Akwa Ibom:
Akwa Ibom labẹ ofin Pension Act, 2014  maa n na okere tan, miliọnu lọna mẹrinlelaadọjọ o le diẹ naira N174.16 lori awọn Gomina tẹlẹri, ti wọn a si ma na miliọnu lọna mẹtalelaadọrun o le diẹ naira, N93.62 fawọn to jẹ igbakeji gomina tẹlẹri.
Eleyi yatọ si miliọnu mẹẹdọgbọn naira ti wọn ma fi n parọ ọkọ fun wọn ati ẹgbẹrun mẹta milọnu ti wọn fi n kọ ile fawọn Gomina ana silu Abuja.
Senẹtọ Godswill Akpabio ni Gomina to wa lori oye nigba ti wọn gbe ofin yii kalẹ ni 2014.
2015 ni Akpabio pari saa keji rẹ gẹgẹ bii Gomina, ti o si tun bọ si ile aṣofin agba Naijiria gẹgẹ bi Sẹnẹtọ.
A ko le fidi ọrọ mulẹ boya o gba owo ifẹyinti yii lasiko to jẹ Senetọ ṣugbọn ipinlẹ Akwa Ibom ko ti mu ayipada tabi ki o pa ofin yii rẹ, di baa ti ṣe n sọrọ yii.
Eko:
Ofin ti ipinlẹ Eko ti wọn fi lọlẹ lọdun 2007 laa kalẹ pe, awọn Gomina tabi igbakeji wọn ti wọn ko ba yọ nipo laanfani lati gba deede owo oṣu wọn gẹgẹ bi owo ifẹhinti.
Wọn a tun fun wọn ni ile meji, ọkan ni ilu Eko ati omiran nilu Abuja, bi Gomina naa ba ṣe saa kan, ile kan ṣoṣo ni wọn yoo fun wọn.
Yatọ si awọn ohun ti a ka kalẹ yii, wọn tun n gba ọkọ ayọkẹlẹ mẹfa pẹlu awọn ajẹmọnu miran pẹlu oṣiṣẹ ti yoo ma ba wọn ṣiṣẹ.
Gomina mẹrin lo ti jẹ ni ipinlẹ Eko lati igba ti ijọba awarawa ti bẹrẹ. Lateef Jakande, Bola Tinubu, Babatunde Raji Fashola ati Akinwumi Ambode.
Tinubu ati Fashola ṣe saa meji pe perepere, ṣugbọn saa kan ni Jakande ati Ambode ṣe .
Osun:
Ọdun 2011 ni ofin ti wọn fidi mulẹ, deede owo ti wọn n gba lasiko ti wọn wa lori oye si ni owo ifẹhinti Gomina ati igbakeji rẹ.
Fawọn Gomina mẹrin to ti jẹ ni ipinlẹ naa, eeyan kọọkan gẹgẹ bi isiro kan ti iwe iroyin kan gbe jade lọdun 2017, yoo maa gba miliọnu meji naira le diẹ lọdun.
Oríṣun àwòrán, @Akinwumi Ambode
Sẹnẹtọ Isiaka Adeleke to ti doloogbe, Bisi Akande, Olagunsoye Oyinlola ati Rauf Aregbesola lawọn Gomina Osun to n jẹ mula yii.
Awọn ipinlẹ miran tawọn Gomina ati igbakeji wọn ti n jẹ iru anfaani yii
Loju opo Twitter wọn, BudgIT Nigeria fi orukọ awọn ipinlẹ ti ofin ṣe agbekalẹ owo ifẹhinti to yatọ si eleyi ti ajọ to n mojuto sisan owo fawọn oṣiṣẹ lorileede Naijiria gbe kalẹ.
Awọn ipinlẹ naa re e:
Ọrọ owo ọna meji tabi ọna mẹta fawọn to di ipo mu tẹlẹ naa jẹ ohun ti o n kan awọn eeyan lominu.
Loju opo Twitter, n ṣe ni ero ṣe ọtọọtọ lori ofin ọhun
Oyo 2020 Budget: Èyí ni àtúpalẹ̀ abá ìṣúná 2020 tí Seyi Makinde gbé kalẹ̀
Gomina Seyi Makinde gbe aba eto isuna ọdun 2020 kalẹ siwaju awọn asofin lọsan ọjọru eyi ti apapọ rẹ le diẹ ni igba biliọnu naira (208,802,972,878.00bn).
Bi atupalẹ́ eto isuna naa se lọ ree ati ipin owo ti ẹka kọọkan ko ninu aba isuna ọhun.
Gomina Makinde wa fi ọwọ gbaya pe gbogbo owo ti oun ba na, ni oun yoo se atupalẹ rẹ fun araalu, ti eto isuna ọdun 2020 yoo se amusẹ rẹ doju ami
Makinde wa rọ ile asofin lati tete se agbeyẹwo aba isuna naa, ki wọn si fọwọsi, ki amusẹ rẹ lee gberasọ loju ọjọ.
Saaju la ti mu iroyin wa fun yin pe, Gomina ipinlẹ Ọyọ, onimọ ẹrọ Seyi Makinde ti se agbekalẹ aba eto isuna ọdun 2020, tii se akọkọ iru rẹ ti yoo gbe kalẹ lati igba ti ijọba rẹ ti bẹrẹ, eyi to pe ni eto isuna awọn araalu, fun araalu.
Apapọ owo isuna naa si lo le diẹ ni igba biliọnu naira (208,802,972,878.00bn).
Nigba to n sọrọ lori aba isuna ọhun, Makinde ni adinku ida mẹrindinlogoji, 36% lo ba eto isuna naa yatọ si eyi ti ijọba ana gbe kalẹ lọdun to kọja, bakan naa si lo ni ida ogoji lo ba eto isuna ti wọn bu fun ile ijọba ati ẹka asofin nipinlẹ Ọyọ, yatọ si bo se maa n waye tẹlẹ.
Makinde wa fi gbogbo ọwọ sọya pe oun yoo ri daju pe wọn se amusẹ eto isuna naa, o kere tan, ida aadọrin ninu ọgọrun, ki ọdun 2020 to buse, lọna ati ba aini awọn araalu pade.
Makinde tun salaye pe gbogbo isẹ akanse ti ijọ to kogba wọle nipinlẹ Ọyọ se ni asepati ni oun yoo pari, to si tun kede pe oun ti gbe olu ileesẹ to n ri si idagbasoke eto ọgbin OYSADEP pada si ilu Saki ti wọn ti gbe kuro.
Bakan naa lo salaye pe nibamu pklu isẹ titan ina yika ipinlẹ Ọyọ ti oun ti dawọ le, oun yoo tun ri daju pe gbogbo ipinlẹ Ọyọ ni wọn tan ina oju popo si, to fi de awọn aafin awọn ọba alaye bii Olubadan tilẹ Ibadan, Alaafin tilu Ọyọ ati Sọun ti Ogbomọsọ.
Lori eto ẹkọ, Seyi Makinde salaye pe nigba ti esi idanwo WAEC yoo ba fi jade lọdun to n bọ, ipo kẹrindinlọgbọn ti ipinlẹ Ọyọ wa yoo ti sun siwaju nitori ijọba ti n se aayan lati gba awsn olukọ si, to si ti n pese awọn iwe idanwo to ti kọja fun awọn akẹkọ lati fi gbaradi fun idanwo naa.
Sowore: Ilé aṣòfin Amẹrika ní ìwà ìfìyàjẹni tíjọba Nàíjíríà hù ń kọ àwọn lóminú
Oríṣun àwòrán, @YeleSowore
Ile asofin Amẹrika to wa nilu Washinton DC ti koro oju si bijọba Naijiria se n tẹsiwaju lati fi Omoyele Sowore, Jones Abiri ati Kofi Bartels pẹlu Samuel Ogundipẹ si ahamọ ọlọjọ pipẹ.
Bakan naa nile asofin Amẹrika tun fi aidunnu rẹ han si ohun to pe ni iwa titi awọn ileesẹ iroyin ati ayelujara pa ni Naijiria, pẹlu afikun pe igbesẹ ijọba ati tawọn ileesẹ agbofinro rẹ safihan aikọbi ara si ominira araalu.
Ile asofin Amẹrika gbarata bẹẹ ninu iwe ẹhonu kan to kọ ransẹ si ileesẹ asoju ijọba Naijiria pẹlu afikun pe iwa ifiyajẹni ijọba Naijiria ti n kọ ọpọ eeyan lominu, to si n mu ifura lọwọ.
Oríṣun àwòrán, @YeleSowore
Ijọba ti n kọ eti ikun si ọpọ asẹ ileẹjọ lati tu awọn eeyan to wa ni ahamọ silẹ, to si tun n lo agbara apapsẹ waa lati tako awọn eeyan to n fi ẹhonu han lawọn agbegbe kan lorilẹede naa, eyi to n kọ wa lominu pupọ, to si jẹ ẹdun ọkan fun wa.
Iwe naa, ti asofin agba nilẹ Amẹrika, Sẹnetọ Robert Menedez ati ọmọ ile asoju sofin kan, Josh Gottheimer dijọ fọwọsi lo tun bu ẹnu atẹ lu ijọba Naijiria fun bo se n huwa ọyaju, to si tun ti Sowore atawọn eeyan miran mọle, awọn to sọ pe wọn n sewadi, ti wọn si n sọrọ sita lati tako awọn isoro ti wọn kẹẹfin nidi eto isejọba, to fi mọ iwa ajẹbanu ati aisi eto aabo to peye.
Oríṣun àwòrán, @YeleSowore
Ọpọ awọn iroyin ti ko fararọ lo ti de etigbọ wa,nipa bi awọn ileesẹ alaabo se n fiya jẹ awọn akọroyin, ti wọn si tun n ti wọn mọle, ti wọn n lo agbara ati iwa ipa lori awọn oluwọde ti ko huwa idaluru ati awọn igbesẹ miran to lee pagi dina ominira sisọ ero ẹni, eyi to n di awọn ọmọ Naijiria lọwọ lati sọ tẹnu wọn gẹgẹ bi ẹtọ ọmọniyan ti gba wọn laaye.
Ile asofin Amẹrika wa n rọ ijọba Naijiria lati ri daju pe o bọwọ fun ẹtọ ọmọniyan gẹgẹ bo se wa ninu ofin ilẹ wọn fun araalu kọọkan, ki wọn si gbe igbesẹ lati di alaafo to wa laarin wọn ati awọn akọroyin, awọn ọmọ ẹgbẹ oselu alatako, atawọn ọmọ ẹgbẹ ajafẹtọẹni.
O fikun pe, ẹtọ araalu kọọkan ni wọn gbọdọ bọwọ fun laisi idunkooko lọdọ ijọba fun igbẹsan, ta si n foju sọna fun ilọsiwaju nidi awsn ohun to se koko ta mẹnuba naa.
Oṣun State: Gómìnà Oyetola ní 167,000 yàrá ìkàwé ni òun kọ́ sí 32 iléẹ̀kọ́
Oríṣun àwòrán, Facebook/Gboyega Oyetola
Gomina ipinlẹ Oṣun, Gboyega Oyetola ti sọ pe ijọba oun ti mu ileri rẹ ṣẹ lori eto ilera nipinlẹ naa.
Ninu ọrọ to ba awọn eeyan ipinlẹ sun sọ lati fi sami ọdun kan ti o gori aleefa gẹgẹ bi gomina ipinlẹ Oṣun, ni Oyetola ti fidi ọrọ yii mulẹ.
Oyetola ni oun ṣeleri ni ibẹrẹ ijọba oun pe, oun yoo pese eto ilera to peye fawọn eeyan ipinlẹ naa lọna ti ko ni na wọn lowo pọju.
O ni ijọba oun ṣe eleyi nipa agbekalẹ eto ilera fun mutu-muwa eyun-un ni, Osun Health Insurance Scheme (OHIS).
Gomina sọ pe ''ẹgbẹrun un lọna ọgọrin eeyan ti wọn ko rọwọ họri ni wọn ti janfaani eto ilera to peye laisan kọbọ labẹ eto OHIS ni bii ọdun kan sẹyin.''
Oríṣun àwòrán, @GboyegaOyetolaileriOluwa
Eto aabo
Gomina Gboyega Oyetọla ni ijọba ti ṣiṣẹ takuntakun lati rii wi pe ipinlẹ Oṣun ṣi wa lara awọn ipinlẹ ti eto aabo wọn muna doko.
Gomina ni ijọba oun pese awọn ohun eelo fun eto aabo ati ọkọ ayẹta pẹlu awọn ohun elo mii fawọn oṣiṣẹ eleto aabo nipinlẹ Oṣun.
Eto ẹkọ
Gomina ipinlẹ Oṣun ni ijọba oun ti kọ yara ikawe mẹtadinlaadọsan an ni ijọba ibilẹ mejilelọgbọn kaakiri ipinlẹ naa.
O fikun ọrọ rẹ pe, awọn akẹkọọ ati olukọ to le lẹgbẹrin ni wọn n jẹ anfaani awọn yara ikawe ọhun.
Oyetola ṣalaye pe ohun to ku fun ijọba oun bayii ni lati mojuto eto ẹkọ imọ ẹrọ eleyi ti yoo pese iṣẹ fawọn araalu.
Iranlọwọ fun araalu
Gomina Oyetola tun ṣalaye pe, ijọba ipinlẹ Oṣun labẹ ijọba oun laarin ọdun kan sẹyin ti ṣeranwọ owo fawọn ọdọ lati lati rii wi pe airiṣẹ ṣe dinku nipinlẹ naa.
Gomina sọ pe, eto ironilagbara ti orukọ rẹ n jẹ Osun Youth Empowerment Scheme (OYES) ni ijọba fi kan si ọpọ araalu.
Gomina ni ijọba oun gba awọn olounjẹ to le ni ẹgbẹrun un meji lati maa gbe ounjẹ kaakiri ile iwe alakọbẹrẹ kaakiri ipinlẹ ọhun, fun eto ounjẹ ti ijọba n fawọn akẹkọọ.
Iṣẹ ọgbin
''Ohun ti ijọba Oṣun fẹ ṣe ni lati sọ iṣẹ agbẹ di iṣẹ to lowo lori eleyi ti yoo wu ọpọ lati maa ṣe,'' Gomina Oyetola woye bẹẹ.
Gomina Oyetola ni ijọba oun ṣetan lati lo iṣẹ agbẹ pese iṣẹ fawọn eeyan ipinlẹ Oṣun.
New Minimum wage: Ìjọba Eko bẹ̀rẹ̀ sísan N35,000 gẹ́gẹ́ bí owó oṣù tó kéré jùlọ fáwọn òṣìṣẹ́
Oríṣun àwòrán, Twitter/Babajide Sanwo-Olu
Igba ọtun de fawọn oṣiṣẹ ijọba niluu Eko, ijọba ipinlẹ Eko ti ṣetan lati maa san ẹgbẹrun un marun un le lọgbọn naira gẹgẹ bi owo oṣiṣẹ to kere julọ fawọn oṣiṣẹ ipinlẹ naa.
Koda awọn oṣiṣẹ ipinlẹ Eko yo rẹrin lọ ile nipari oṣu kọkanla yii, nitori oṣu gan an ni ijọba yoo bẹrẹ si ni san ẹkunwo owo oṣu oṣiṣẹ tuntun.
Gomina Babajide Sanwo-Olu ti sọ tẹlẹ pe ijọba ipinlẹ Eko yoo san ju ọgbọn ẹgbẹrun un naira ti ijọba apapọ kede gẹgẹ bi owo oṣu oṣiṣẹ to kere julọ lọ.
Olori awọn oṣiṣẹ nipinlẹ Eko, Hakeem Muri-Okunola lo kede ọrọ yii ninu atẹjade kan to fi sita, to si tun fi ṣọwọ sawọn olori ẹka ijọba gbogbo l'Ọjọru
Ọgbẹni Muri-Okunola ni nitori iṣẹ to n lọ lori ẹkunwo owo oṣu oṣiṣẹ tuntun yii ni ko jẹki awọn oṣiṣẹ gba owo oṣu kọkanla yii lọjọ kẹtalelogun ti wọn maa n gba tẹlẹ.
O ni ijọba ipinlẹ pinnu lati san ju owo oṣu ti apapọ gan an n san fawọn oṣiṣẹ rẹ nitori igbayegbadun awọn oṣiṣẹ lo jẹ ijọba ipinlẹ Eko logun.
Olori awọn oṣiṣẹ rọ awọn oṣiṣẹ nipinlẹ Eko lati jara mọ iṣẹ wọn, ki wọn si ṣiṣẹ wọn lai ṣọlẹ.
Bakan naa ni Ọgbẹni Muri-Okunola rọ awọn oṣiṣẹ lati fọwọ ṣowọpọ pẹlu ijọba Gomina Sanwo-Olu fun aṣeyọri ijọba rẹ.
Bukola Saraki: Àìbọ̀wọ̀ f'áṣẹ ilé-ẹjọ́ n'ìgbẹ́sẹ̀ EFCC láti gba ilé mi ní Ilorin
Oríṣun àwòrán, Facebook/Bukola Saraki
Aarẹ ile aṣofin agba l'Abuja ni saa eto ijọba awarawa to kọ ja, Sẹnẹtọ Bukola Saraki ti fẹsun kan ajọ to n gbogun ti iwa ajẹbanu ati ṣiṣe owo ilu kumọkumọ, EFCC.
Saraki ni pe ajọ naa fẹ gbẹsẹ le ile oun to wa niluu Ilorin.
Ninu atẹjade kan to fi sita l'Ọjọru lati ọwọ agbẹnusọ rẹ, Yusuph Olaniyonu, Saraki ni EFCC lọ sile ẹjọ giga nipinlẹ Eko l'Ọjọru nibi ti wọn ti beere fun aṣẹ lati gbẹsẹ le ile rẹ to wa ni Ilorin.
Loṣu kẹwaa ni ile ẹjọ giga ijọba apapọ paṣẹ pe ko jọwọ ile rẹ meji to wa lagbagbe Ikoyi niluu Eko.
Ṣugbọn Saraki sọ ninu atẹjade to fi sita pe owo ifẹyinti ati owo ara oun loun fi kọ ile to wa ni ilu Ilorin, ati wi pe lẹyin toun ṣe gomina tan nipinlẹ Kwara loun kọ ile naa.
Sẹnẹtọ Bukola Saraki ni sisọ fun ile ẹjọ pe ko gbẹsẹ le dukia oun ni Ilorin tumọ si idunkooko mọni ati lilo agbara nilo kulo.
Yorùbá tone mark: Fífi àmì ohùn sí orí ọ̀rọ̀ Yorùbá ṣe pàtàkì
Saraki loun ṣetan lati pade ajọ EFCC nile ẹjọ, nitori oun gbagbọ pe nibẹ loun ti le ri idajọ ododo gba.
Bukọla Saraki lo jẹ iyalẹnu pe ajọ EFCC n tako aṣẹ ile ẹjọ giga l'Abuja eleyi to dena ajọ naa lati gba dukia rẹ.
'Buns ni ọmọ mi jẹ tán ní ṣọ́ọ̀ṣì, ló bá di àwátì'
O ni EFCC tun n tako ọrọ adajọ agba patapata ni Naijiria, Ibrahim Tanko Muhammed to sọ pe gbogbo ẹka ijọba gbọdọ bọwọ fun ofin orilẹ-ede Naijiria.
Kidney Transplant: Ilé ìwòsàn ṣ'àṣìṣe ṣiṣẹ́ abẹ kìndìrín fún aláìṣàn ní New Jersey
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Kidney Transplant: Ilé ìwòsàn ṣ'àṣìṣe ṣiṣẹ́ abẹ kìndìrín fún aláìṣàn ní New Jersey
Eleyi maa gbẹnutan! Ile iwosan kan niluu New Jersey lorilẹ-ede Amẹrika lo ṣaṣiṣe fun ẹnikan kindirin ti kii ṣe tiẹ.
Ẹlomiiran to n jẹ orukọ kan naa ti ọjọ ori wọn ko jina si ara wọn ni wọn fẹ parọ kindirin rẹ kawọn dokita naa to lọ fun ẹni ko ni aarun kindirin.
Nigbẹyin gbẹyin, awọn mejeeji ni ile iwosan Virtua Our Lady of Lourdes ni Camden parọ kindirin wọn, koda ile iwosan ni ara awọn mejeeji ti bọ wa s'ipo bayii.
Lọjọ keji ti wọn ṣiṣẹ abẹ naa tan ni ile iwosan naa ṣẹṣẹ mọ pe aṣiṣe ti waye lori ẹni ti wọn parọ kindirin rẹ.
Awọn alaṣẹ ile iwosan naa ni iru rẹ ko ṣẹlẹ ri lati igba ti wọn ti da ile iwosan naa silẹ.
Igbakeji aarẹ ile iwosan naa to tun jẹ olori awọn dokita nibẹ, Reginald Blaber sọ pe iru aṣiṣe bayii ko wọ pọ rara.
Oríṣun àwòrán, @Virtua Health
Oto leni ti won fe fun ni kindinrin, oto ni eni ti won sise fun
Amọ, Blaber ni o yẹ ki ayẹwo finifini le dena aṣiṣe yii, bo tilẹ jẹ pe iru rẹ ko wọ pọ.
Eeyan bi ẹgbẹrun un mẹtalelaadọfa ni ile iwosan naa fẹ ṣiṣẹ abẹ pipaarọ kindirin fun gẹgẹ bi iroyin ti wọn fi sita lori oju opo itakun agbaye wọn.
Yorùbá tone mark: Fífi àmì ohùn sí orí ọ̀rọ̀ Yorùbá ṣe pàtàkì
Bayii, wọn ti tun iṣẹ abẹ pipaarọ kindinrin fun ẹni ti wọn fẹ ṣee fun gangan lọsẹ to tẹlee.
Adari awọn oniṣegun oyinbo naa ni pe ẹni ti wọn kọkọ fun ni kindinrin tuntun naa nilo kindinrin ṣugbọn ko si lara awọn torukọ wọn wa loke pe asiko ko pọ fun mọ.
Ile iwosan naa kọ lati fi orukọ awọn mejeeji sita.
Ile iwosan Virtua Our Lady of Lourdes yii nikan ni wọn ti n ṣe iṣẹ abẹ paṣipaarọ kindinrin, ọkan ati awọn iṣẹ abẹ bẹẹ miran ni guusu New Jersey.
Cancer: Àṣe ara mi ni iso ti n run gbogbo bí mo ṣe n ṣèrànwọ́ lórí jẹjẹrẹ
Border closure: Ẹ wo iye t'óúnjẹ dà báyìí lọ́jà lẹ́yìn tí ìjọba ti ibodè
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Niṣe lawọn ọmọ Naijiria n pariwo lori ọwọn gogo ounjẹ nitori ibode ori ilẹ ti ijọba apapọ ti pa lati oṣu kẹjọ.
Ounjẹ bi irẹsi, iṣu, ẹran adiẹ tutu ati ohun elo ọbẹ bi timọti lo ti gbowo lori bayii.
Ẹwẹ, ijọba Aarẹ Muhammadu Buhari ti ni lootọ ni pe ibode ti awọn ti lo fa ki owo ọja o gbe pẹẹli soke si Ibodè tí a tì ló fa ọ̀wọ́ngógó owó ọjà- Ìjọba Naijiria.
Minisita fun eto isuna orilẹ-ede Naijiria, Abilekọ Zainab Ahmed lo sọ bẹẹ lẹyin ipade igbimọ alasẹ ti ijọba apapọ, Federal Executive Council ni ilu Abuja.
Eyi ni atupalẹ iye owo ti wọn n ta awọn ọunjẹ kan ki ijọba to ti bọda ati lasiko yii ti wọn ti ṣi ibode.
Irẹsi
Awọn eeyan maa n ra baagi ireṣi kan ki ijọba to ti ibode ni bi ẹgbẹrun mẹtala naira si mẹrindinlogun (eyi nii ṣe pẹlu ti irẹsi naa ba ṣe mọ to ati ibi ti wọn ti n ko o wa).
Ṣugbọn iresi ti gbowo lori lẹyin ti ijọba ti ibode tan, baagi irẹsi kan ti di ẹgbẹrun lọna ogun naira si ẹgbẹrun lọna mejidinlọgbọn bayii, koda awọn irufẹ irẹsi mii maa ju bẹẹ lọ.
Ohun tawọn olutaja n sọ ni pe awọn ko tilẹ ri irẹsi ti wọn n gbin ni Naijiria ra, eyi jẹ ko nira lati mọ iye ti wọn ta gan an.
Oríṣun àwòrán, Others
Eyi ni atupalẹ iye owo ti wọn n ta awọn ọunjẹ kan ki ijọba to ti bọda ati lasiko yii ti wọn ti ṣi ibode.
Ẹran adiẹ
Ki ijọba to ti ibode pa fun apẹrẹ niluu Eko, apo mẹfa naira ni wọn maa n ta ẹran adiẹ (chicken) tutu kilo kan.
Ṣugbọn ni bayii, kilo ẹran adiẹ tutu kan ti di apo mẹjọ naira.
Koda ẹni to ba fẹ ra Tọki gbọdọ mu apo mẹjọ naira lọwọ ko to le ri kilo Tọki kan ra bayii.
Tomato
Tomato naa ko gbẹyin ninu awọn ounjẹ ati ohun elo to ti gbowo lori lẹyin ti ijọba ti ibode pa.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Fun apẹrẹ, ogoji kilo tomato ti wọn n ta ni ẹgbẹrun un mẹfa aabọ naira lọja Bodija niluu Ibadan ti di ẹgbẹrun un mẹjọ le laadọrin naira.
Yorùbá tone mark: Fífi àmì ohùn sí orí ọ̀rọ̀ Yorùbá ṣe pàtàkì
Ororo
Awọn eeyan maa n ri ororo jala mẹẹdọgbọn ni ẹgbẹrun mẹsan an aabọ naira ki ibode to di titi pa ṣugbọn bayii o gbọdọ ni ẹgbẹrun mọkanla si mẹẹdogun lọwọ koo to le ra ororo to tẹ ẹ lọrun.
Koda awọn kan n ra ororo naa ti gbowo lori, ẹgbẹrun mọkanla din igba naira ni wọn ta a nisinyi.
'Buns ni ọmọ mi jẹ tán ní ṣọ́ọ̀ṣì, ló bá di àwátì'
Thai Deer: Pátá awọtẹlẹ, rọba àti ìdọ̀tí kilo méje ṣekú pa Ìgalà
Oríṣun àwòrán, The Protected Area Regional office 13 (Phrae)
Wọn ba orisirisi idọti ninu Igala naa ti wọn ṣokunfa iku rẹ
Igala kan ti wọn ri oku rẹ ni ọgba iko-ẹranko-si kan lariwa orile-ede Thailand ni awọn alaṣẹ ti ba idọti to to iwọn kilo meje ninu rẹ.
Lara awọn nkan ti o wa ninu idọti naa ni awọtẹlẹ ọkunrin, rọba, ọra iyẹfun kọfi ati okun wa lara ohun ti wọn ba ninu rẹ.
Oṣiṣẹ ọgba iko-ẹranko-si naa ni Khun Sathan ational Park sọ pe o ti pẹ ti  Igala naa ti n jẹ rọba ike ki o to wa ṣokunfa iku rẹ.
Laipẹ yi ni ẹranko inu omi kan ti wọn n pe orukọ rẹ ni ''dugong'' ti kọkọ ku lataari idiwọ ti rọba to jẹ n ṣe fun un ninu ikun rẹ.
Earlier this year, a baby dugong in Thailand died after eating plastic.
Ọwọ awọn to ju idọti silẹ la ba nibẹ:
Lọjọ kẹẹdọgbọn, oṣu kọkanla, awọn oṣiṣẹ to n para inu ọgba naa ba oku igala naa ti ọjọ ori rẹ́ to ọdun mẹwaa nibi to ku si.
Ninu awọn nkan ti wọn ba ninu rẹ la ti ri ibọwọ onirọba ati tawẹli inura kekere kan.
Kriangsak Thanompun to jẹ oludari ọgba naa sọ fun BBC News Thai pe ''A ni igbagbọ pe o ti pẹ to ti n jẹ awọn nkan wọn yi ki o to ku''
O ṣalaye pe awọn ro pe awọn nnkan to jẹ lo di ifun rẹ ṣugbọn awọn yoo ṣe iwadii ẹkunrẹrẹ .
Oríṣun àwòrán, The Protected Area Regional office 13 (Phrae)
Kilo meje pantiri ni wọn ba ninu Igala naa
Loju opo ayeluja ni awọn eeyan ti n bẹnu atẹ awọn to n ju idọti silẹ ninu ọgba ọhun.
Eeyan kan sọ si oju opo Facebook pe''Bi  ba lọ si ọgba yi,ti ẹ si ju idọti silẹ, ẹ ri wi pe ẹ ṣa nigba ti  ba n kuro nibẹ.Ẹ ṣe oun to tọ''
Eeyan kan tilẹ sọ pe iṣẹ nla ni wọn yoo ṣe lati le j ki awọn eeyan ṣa idọti ti wọn ba ju silẹ.
"Ẹlomiran naa sọ pe ""Nkan ti o yẹ ki wọn maa kọ awọn eeyan lati kekere ni. Bi ko ba jẹ bẹẹ, bi wọn ba dagba tan, yoo nira ki wọn to le yi iwa pada''"
Gẹgẹ bi ohun ti ọga ọgba naa sọ awọn yoo gbe ilana olopo mta kan kalẹ ti yoo mu ki awn eeyan ma ṣa idọti ati awọn nkan pantiri mi kuro nilẹ ninu ọgba naa.
Cancer: Àṣe ara mi ni iso ti n run gbogbo bí mo ṣe n ṣèrànwọ́ lórí jẹjẹrẹ
Ilana wa naa yoo tun ṣe alakalẹ ọna lati maa ko idọti lọna to yẹ ati kikọ awọn eeyan lẹkọ nipa dida idọti sayika.
Orile-ede Thailand wa lara awọn orile-ede to n lo rọba pupọ.
Oríṣun àwòrán, The Protected Area Regional office 13 (Phrae)
Rọba ati awọn idọti miran ti Igala naa jẹ lo ṣeku pa
Ajọ to n mojuto ayika ẹni, Greenpeace sọ pe o to biliọnu márùndínlọ́gọ́rin rọba ti awọn eeyan n ju silẹ lọdọọdun.
Minisita ayika ti sọ loṣu Kẹsan an pe awọn ontaja nilẹ Thailand yoo dẹkun lilo ọra lati maa fi ta nkan bẹrẹ lati oṣu Kini, ọdun 2020.
Ọmọ Yahoo tú àṣírí ara rẹ̀ fún, bí wọ́n ṣe ń ṣe é BBC Yorùbá
Watchiranot Thongtep ati Smitanan Yongstar ni wọn ṣafikun iroyin yii ka to gbe e wa si eti igbọ yin.
Omí pọ̀ ju ọkà lọ fún Unai Emery, ìfìdírẹ̀mi mí ló bade fún lọ́wọ́ Frankfurt
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Omí pọ̀ ju ọkà lọ fún Unai Emery, ìfìdírẹ̀mi mí ló bade fún lọ́wọ́ Frankfurt
Ninu atẹjade ti Arsenal fi soju opo twitter wọn ni wọn ti kede ipinnu wọn bayii.
Wọn ni àwọn gbe igbesẹ yii lataari gbogbo ijakulẹ ti Unai emery n ri paapaa lori idije awọn bọọlu ti Arsenal n gba ti to gẹ.
Josh Kroenke lasiko to n sọrọ lorukọ igbimọ alaṣẹ ẹgbẹ agbabọọlu Arsenal ati Kroenke Sports and Entertainment so pe:
"A dupẹ lọwọ Unai ati awọn akẹgbẹ rẹ pupọ nitori pe wọn gbiyanju lati da ogo Arsenal pada de ipele to yẹ ti a beere fun.
A gbadura arinna kore fun wọn bi wọn ti n lọ."
Ẹgbe Arsenal ti le Unai Emery leyin osu mejilelogun, to gba ise.
Amo, Freddie Ljungberg to je igbakeji akonimoogba ni yoo ma sakoso fun igba yii naa.
Wòólì Alfred kú lọ́dún 1964, ó tún padà wà sí ìlú Agelu f'ọ́jọ́ mẹ́rìnlá!
Ọrọ boya iṣẹ yoo bọ lọwọ akọnimọọgba ẹgbẹ agbabọọlu Arsenal Unai Emery tun fidi rinlẹ si lọkan awọn onwoye pẹlu bi ikọ rẹ ṣe fidirẹmi lọwọ Frankfurt ninu idije Europa League.
Ayo meji si odo ni ẹgbẹ agbabọọlu naa fi gbewuro soju ikọ Unai Emery.
Oríṣun àwòrán, BBC Sport
Omí pọ̀ ju ọkà lọ fún Unai Emery, ìfìdírẹ̀mi mí ló bade fún lọ́wọ́ Frankfurt
Ninu awọn ifẹsẹwọnsẹ ti wọn gba sẹyin, eyi ni yoo jẹ igba kẹje ti wọn yoo pade ijakulẹ.
Lẹnu lọọlọ yi, ẹnu ti n kun Unai Emery ti ọpọ si ti n reti igba ti wọn yoo fọwọ osi juwe ile fun un.
Oríṣun àwòrán, EPA
Laipẹ yi ni ẹgbẹ Arsenal lawọn ti n fimu-finlẹ si ẹni ti wọn yoo fi paarọ rẹ ni eyi ti ireti si wa pe o ṣeeṣe ko jẹ akọnimọọgba ẹgbẹ Wolves, Nuno Espirito ni yoo gba ipo rẹ.
Oríṣun àwòrán, Reuters
Omí pọ̀ ju ọkà lọ fún Unai Emery, ìfìdírẹ̀mi mí ló bade fún lọ́wọ́ Frankfurt
Niṣe ni igbe ọọbi gba nu awọn alatilẹyin ẹgbẹ naa lẹyin ifẹsẹwọnsẹ pẹlu Frankfurt ti oju opo Twitter si kun fun ikunsinu lori bi o ti ṣe n tukọ ẹgbẹ naa.
Ọpọlọpọ gba pe iṣẹ rẹ ko dara to ni ẹgbẹ agbabọọlu naa ṣe n ri ijakulẹ
Yorùbá tone mark: Fífi àmì ohùn sí orí ọ̀rọ̀ Yorùbá ṣe pàtàkì
Benin: UK ṣetán láti dá Adìyẹ 'Àkùkọ' Nàíjìrìa ti wọ́n gbé padà
Oríṣun àwòrán, PA Media
Adiye 'Akukọ' ti won mo ni egberun odun seyin ni won se setan lati da pada ba yii.
Akukọ gagara ti wọn mọ, ti wọn pe orukọ rẹ ni 'Okukor' ni o da wahala silẹ ni ẹgbẹrun ọdun sẹyin nigba ti wọn ji i gbe lọ kuro lorilẹ-ede Naijiria lọ si Ilẹ Gẹẹsi.
Ile iwe giga, Cambridge University lo kede wi pe awọn yoo da ọkan lara awọn idẹ ti wọn ji ni ẹgbẹrun ọdun ṣẹyin lasiko ti wọn ṣigun bo Naijiria pada.
Ọpọlọpọ ọdun ni o ti wa lowo wọn ko to di wi pe awọn akẹkọọ kan an ni ipa fun wọn lati da a pada si ibi ti wọn ti gbe e wa.
Oríṣun àwòrán, DAPPER FOUNDATION
Benin: UK ṣetán láti dá Adìyẹ 'Àkùkọ' Nàíjìrìa ti wọ́n gbé padà
Ile iwe giga naa ni Ọba ilu Benin lo ni i, ati wi pe ibe ni wọn ti gbee wa, amọ wọn ko sọ igba tabi akoko ti wọn yoo da a pada.
Lara awọn ohun ẹṣọ abalaye ti awọn ara Benin mọ ni ọkan lara aworan adiyẹ ide ti Ilẹ Gẹẹsi fẹ da pada yii.
Lasiko ti Ilẹ Gẹẹsi kọ Naijiria lẹru, ọ le ni ẹgbẹẹgbẹrun awọn ohun abalayẹ ti wọn ko lọ.
Bakan naa ni wọn si sọ wi pe awọn yoo da lara rẹ pada.
Amọ wọn ṣeleri pe awọn yoo ya Ajọ Nigerian Royal Museum ni lara wọn, ti yoo bẹrẹ iṣẹ ni ọdun 2021.
Oríṣun àwòrán, V&A MUSEUM
Bakan naa ni wọn si sọ wi pe awọn yoo da lara rẹ pada.
Igbesẹ Ilẹ Gẹẹsi  yii farapẹ igbesẹ awọn orilẹ-ede miran ni ilẹ Europe ti o ti pinnu lati da awọn ohun abalaye to jẹ ti ilẹ Afrika amọ ti wọn jigbe pada si ibi to yẹ.
Aarẹ ilẹ Faranse, Emmanuel Macron sọ wi pe laarin ọdun mẹrin ni oun yoo da gbogbo rẹ pada fun Afrika.
Ogun Cholera: Ọdọọdún ni àrùn onígbá-méjì máa n ṣọṣẹ́ ní Nàìjíríà-NCDC
Nigerian Traffic Laws: Ohùn tó yẹ ní mímọ nípa òfin ojú pópó
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Lilọ bibọ loju popo jẹ ohun ti a ko le sa fun gẹgẹ bi ọmọ eniyan.
Ati ẹni to n fẹsẹ rin atawọn to n gun ọkọ, awọn ofin wa to de bi eeyan ti ṣe maa n lọ loju ọna.
Bayi ti ọdun lọ si opin ti awọn eeyan si n palẹmọ lati ririn ajo ọdun Keresimesi, o tọ ki a la ara wa lọyẹ nipa awọn ofin to yẹ ni mimọ loju popo.
Awọn ofin wọn yi ṣebi ni pọ diẹ ṣugbọn nitori asiko diẹ ninu wọn la fẹ gbe yẹ wo lonii.
Ẹ wa nkan fidi le ki ẹ fidi le nkan ma bawa fi ọkan ba awọn ofin wọn yi lọ ni ṣiṣẹntẹle.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ẹni ti ko ba wọ bẹliti ọkọ rẹ yoo san owo ijiya
Awọn to ṣe ọkọ fi aaye kalẹ fun wa lati lo bẹliti yi ni kete ti a ba ti ko si inu ọkọ.
Anfaani bẹliti yi pọ ti a si ma dena fifi ori gba ti ijamba ọkọ ba ṣẹlẹ.
O di dandan fun nikẹni to ba wa ninu ọkọ lati wọ bẹliti yi,o wa fun awakọ ati gbogbo ero to ba gbe.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Nigerian Traffic Laws: Ohùn tó yẹ ní mímọ nípa òfin ojú pópó
Ọkọ kọọkan lo ni iye eeyan to le gbe ati iye ẹru ti o yẹ ki o di.
Bi ẹ ba n wa ọkọ ti ẹru tabi ero pọju deede ohun to yẹ, ẹ ti tasẹ agẹrẹ sofin ni yẹn.
Aburu ka ma di ẹru pupọ ni pe e o ni ri ilẹkun ọkọ pade daada ati pe ọkọ naa ko ni gbera bo ti ṣe yẹ
O gbọdo ni iwe aṣẹ awakọ:
Bi eeyan ba fẹ wa ọkọ, o di dandan ko jẹ awakọ to dantọ.
Oríṣun àwòrán, FRSC/Facebook
Bi eeyan ba wa ọkọ lalai ni iwe aṣẹ awakọ, o ti tapa sofin
Ohun taa si fi jẹri si ni pe yoo ti gba iwe aṣẹ awakọ lọdọ awọn alaṣẹ.
Eleyi ni yoo jẹ eri pe o yẹ ni ẹni to le gbe eeyan si inu ọkọ. Aini iwe yi jẹ ọna kan gboogi tawọn eeyan fi n tako ofin irina.
Yara lọ ṣeto tirẹ ki o to bọ sọna fun irinajo.
Yoruba a ma ni oju ni baba ara.Fẹnikẹni to ba n wakọ, ina ọkọ rẹ ṣe pataki.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ki ina ọkọ rẹ mọlẹ kedere jẹ ọna kan lati dena ijamba ọkọ loju popo
Yatọ si pe wọn yoo jẹ ki wiwakọ lalẹ ninu okunkun rọrun, awọn ina ara ọkọ tun jẹ atọna fawọn awakọ mii lati mọ ti eeyan ba n duro tabi to ba fẹ gbera.
Ẹni ti ina ọkọ rẹ ko ba ṣiṣẹ bo ti ṣe yẹ ti tasẹ agẹrẹ sofin irinna.
Njẹ iwọ fẹran ọti mimu?
Oríṣun àwòrán, Sean Gallup
Ẹni tawọn agbofinro ba ri pe o mu ọti lasiko tabi ṣaaju ki o to wa ọkọ yoo jẹ iyan rẹ niṣu.
Bi o ba n wakọ, ma ṣe mu ọti, ti o ba n mu ọti, ma ṣe wakọ.
Ẹni tawọn agbofinro ba ri pe o mu ọti lasiko tabi ṣaaju ki o to wa ọkọ yoo jẹ iyan rẹ niṣu.
Idi ti wọn fi ni ka ma muti lasiko ta ba n wakọ ni pe o le ṣe okunfa ijamba ọkọ ti ẹmi si le ba lọ.
Awọn ofin miran:
Mọ wi pe ijọba ko gbe awọn ofin wọnyi kalẹ lati fi iya jẹ eeyan bi kii ṣe lati daabo bo ẹmi
Ri wi pe o tẹle awọn ofin yi ki o ma ba ri ibinu awọn ajọ ẹsọ aabo oju popo iyẹn 'Federal Road Safety Commission (FRSC)'
Wòólì Alfred kú lọ́dún 1964, ó tún padà wà sí ìlú Agelu f'ọ́jọ́ mẹ́rìnlá!
Ogun Cholera: Ọdọọdún ni àrùn onígbá-méjì máa n ṣọṣẹ́ ní Nàìjíríà-NCDC
Rélùwéè Èkó sí Ìbàdàn: tíkẹ́ẹ̀tì ọ̀fẹ́ lẹ ó lò fún oṣù mẹ́rin gbáko- Amaechi
Oríṣun àwòrán, Rotimi Amaechi
Awọn eeyan Naijiria ti n fi ero ọkan wọn han lẹyin ti ijọba kede irinajo ọfẹ loju opo reluwe laarin ilu Eko si Ibadan.
Minisita feto irinajo ni Naijiria Rotimi Amaechi lo fi ikede yi soju opo Twitter rẹ ti o si ni fun oṣu mẹrin gbako lawọn eeyan yoo fi wọ reluwe ọfẹ.
Kete ti o fi ikede yi sita lawọn eeyan ti n sọ ti ọkan wọn lori ikede yi.
Bi awọn kan ti ṣe n kan sara si ijọba lawọn miran n sọ pe oṣu mẹrin ti pọju lati fi wọ reluwe lọfẹ
Bakannaa lawọn miran n bere bi wọn ti ṣe fẹ ṣeto reluwe ọfẹ ti wọn ko ba ti pari eto to yẹ.
Ikede irinajo ọfẹ lori reluwe ni Naijiria lẹnu igba ti ijọba n gbiyanju lati sọ ka irina yi ji pada kii 'se tuntun.
Ṣaaju ki reluwe laarin ilu Abuja tii ṣe olu ilu Naijiria si Kaduna gbera sọ,ijọba kede irinajo ọfẹ oloṣumẹta.
Bakanna ni wọn ṣe iru ikede yi nigba ti wọn ṣe ayẹwọ irinajo Eko si Abeokuta to jẹ abala kini oju irin to lọ laarin Eko si Ibadan.
Igbakeji aarẹ Yemi Oṣinbajo ni o ṣe ifilọlẹ irinajo ọfẹ lori reluwe loṣu keji ọdun 2019.
Àlàyé rèé bí òṣìṣẹ́ LASTMA ṣé kàn àgbákò ikú lọ̀wọ̀ àwọn jàńdùkú méjì nílu Èkó
Oríṣun àwòrán, Lastma
Ọga agba ajọ to n mojuto igbokegbodo ọkọ nilu Eko ,LASTMA, ti bẹnu atẹ lu bi awọn eeyan ti ṣe n dunkoko mọ awọn oṣiṣẹ ajọ naa.
Ọgbẹni Olajide Oduoye sọ ọrọ yi lyin ti ọkan ninu awọn oṣiṣẹ rẹ di ero ọrun latari ikọlu tawọn janduku kan ṣe si nilu Eko.
Gẹgẹ bi o ti ṣe sọ ninu atẹjade kan ti Filade Olumide to jẹ igbakeji alukoro ajọ naa fi sita,ni nkan bi ago marun un irọlẹ lawọn janduku naa ju ọkuta nla kan lu Ola Oyesina nibi to tin dari lilọ bibọ ọkọ ni agbegbe Iganmu -Sifax ni Apapa.
''Wọn ṣare gbe Oyeshina ati awọn to ju oko lu u lọ  lọ si agọ ọlọpaa Area B.Ọga ọlọpaa Bayo Suleiman ni ki wọnfi awọn janduku naa si ahamọ ti wọn si sare gbe Oyeshina lọ si ile iwosan LUTH.''
''O ṣeni laanu pe arakunrin yi jẹ ọlọrun nipe lowurọ ọjọ Abameta tii ṣe ọgbọn ọjọ Oṣu Kọkanla''
Ọga Lastma naa wa ṣeleri pe awọn to da ẹmi arakunrin naa legbodo yoo foju ba ile ẹjọ.
O ni eleyi yoo jẹ ọna kan gbogi lati jẹ ki awọn to ba n gbero lati kọlu awọn oṣiṣẹ awọn tọwọ ọmọ bọ aṣọ''
Ofi kun ọrọ rẹ pe pẹlu ifilọlẹ igbimọ apapọ awọn oṣiṣẹ aabo lati dẹkun iwa ibajẹ nilu Eko,ko ni si ibi tawọn aṣebi yoo sapamọ si mọ
Gómìnà Kwara: A kò ní w'ojú olóṣèlú kankan to bá pín nínú owó N5bn ní Kwara
Laipẹ yi ni EFCC jú alága ìjọba ibílẹ̀ 16 si àhámọ́ lóríi ẹ̀sùn àjẹbánu ní Kwara
Ijọba ipinlẹ Kwara ti leri lati fi ijiya to tọ jẹ eyikeyi aṣofin ipinlẹ naa  to ba lọwọ ninu apapin owo biliọnu marun un Naira ti aṣiri lu sita pawọn aṣofin ile ana kan pin.
Ninu atẹjade kan ti agbẹnusọ Gomina,Rafiu Ajakaiye fi sita lọjọ Abamẹta, o ni bo ṣe ẹni to ti fi ipo silẹ, tabi eleyi to wa lori oye, ko si ni ti yoo lọ lalai koju ijiya ofin ti wọn ba jẹbi.
Atẹjade naa to n fesi si iroyin kan to tati ọwọ EFCC jade pe awọn ti ṣe iwadi ri bi awọn aṣofin ile aṣofin ipinlẹ ana kan ti ṣe ṣapapin biliọnu marun un naira owo ajọ to n gbowo ori nipinlẹ Kwara.
EFCC darukọ alaga ajọ naa to ti fi ipo silẹ,Ọjọgbọn Muritala Awodu,ọmọ ile aṣofin ipinlẹ naa kan lana,Moshood Bakare ati awọn awọn oṣiṣẹ KWIRS gẹgẹ bi awọn to lewaju nibi apapin owo yi.
Bakanaa ni EFCC sọ pe awọn ile iṣẹ marun un kan ti o jẹ tawọn ilumọọka oloṣelu nipinlẹ naa gba biliọnu mẹrin  ninu owo yi lalai ni iwe adehun iṣẹ agbaṣe pẹlu ijọba.
Laipẹ yi ni EFCC jú alága ìjọba ibílẹ̀ 16 si àhámọ́ lóríi ẹ̀sùn àjẹbánu ní Kwara
Iwaadi EFCC ti wọn lawọn ṣe ọhun tun ṣalaye pe gbogbo awọn awọn ọm ile aṣofin ni ṣaa oṣelu to kọja lo pin ninu owo yi to fi mọ olri ile aṣofin,Ali Ahmad.
Ninu ọrọ to tẹnu ọkan lara awọn oṣiṣẹ KWIRS to jẹwọ fun EFCC,o ni ''Kọmisana eto ọrọ aje tẹlẹ Ademola Banu a ma gba miliọmu Naira loṣooṣu lalai ṣiṣẹ fun''
''Koda emi ni mo ma n gbe owo naa lọ ba nile rẹ,bi a ko ba fun ni owo naa, ko ni buwọlu ohunkohun ta ba gbe lọ ba''
Gomina Kwara wa tẹpẹlẹ mọ ifarajin ijọba rẹ lati ri pe gbogbo awọn to ba n gba ọna ẹburu ji owo ijọba yoo foju wina ofin
Dino vs Adeyemi: Ìyàwó ni Adeyemi lágbo òṣèlú lọ́jọ́kọ́jọ́
Oríṣun àwòrán, Instagram/Dino Melaye
Ìyàwó ni Adeyemi lágbo òṣèlú lọ́jọ́kọ́jọ́
Ọrọ ko tii tan o lori atundi ibo ile igbimọ aṣofin agba l'Abuja ti ẹkun iwọ oorun Kogi ninu eyi ti Smart Adeyemi fi fẹyin Dino Melaye gbalẹ.
Melaye ti n sọrọ loju opo ayelujara rẹ lati igba ti ajọ INEC ti kede Ọgbẹni Adeyemi gẹgẹ bi ẹni to jawe olubori ninu atundi ibo to waye lẹkun naa lẹyin ti Dino ti kọkọ wọle ki ile ẹjọ to wọgile eto idibo naa.
Nigba to n sọrọ loju opo Twitter rẹ, Dino ni iyawo ni Adeyemi jẹ fun oun lagbo oṣelu.
Sẹnẹtọ Melaye ni bi t'ọkunrin t'obinrin ṣe dibo fun oun fihan pe Eleduwa ṣi wa lẹyin oun gbọingbọin.
Ẹwẹ, Sẹnẹtọ Adeyemi naa ṣapejuwe Dino gẹgẹ ọmọ ọdọ ọkunrin rẹ.
Adeyemi ni ''ti ọmọ ọdọ ba ji aṣọ ọga rẹ gbe, aṣọ naa yoo tobi ju lara rẹ, idunnu wi pe oun n wọ aṣọ ọga rẹ lo maa mu un ṣiwa wu sawọn to yẹ ko ṣapọnle fun.''
Sẹnẹtọ Adeyemi ṣalaye pe ''aṣọ alaṣọ ti ko ṣe deedee ti Dino to wọ s'ọrun nigba to wa nile aṣofin agba lo jẹ ko ṣiwawu nibẹ.''
Adeyemi ti ẹgbẹ osẹlu APC ni ibo 88,373 nigba ti Dino to dije labẹ asia ẹgbẹ oṣelu PDP ni ibo 62,133 ninu atundi ibo ọhun.
Melaye ti sọ pe oun yoo gbe ẹjọ idibo naa lọ siwaju igbimọ igbẹjọ to n ri si awuyewuye to jẹyọ ninu eto idibo.
Wòólì Alfred kú lọ́dún 1964, ó tún padà wà sí ìlú Agelu f'ọ́jọ́ mẹ́rìnlá!
Elephants Death: Erin mẹ́fa d'olóògbé níbi tí wọ́n ti fẹ́ dóòlà ẹ̀mí ara wọn
Oríṣun àwòrán, Khao Yai National Park
Erin mẹ́fa d'olóògbé níbi tí wọ́n ti fẹ́ dóòlà ẹ̀mí ara wọn
Erin mẹfa ṣagbako iku lorilẹ-ede Thailand nibi ti wọn ti n gbiyanju lati doola ẹmi ara wọn.
Awọn oṣiṣẹ ọgba ẹranko Khao Yai National Park lorilẹ-ede Thailand ṣalaye pe ọmọ erin kan lo yọ ṣubu nibi ida omi tawọn erin mi ṣi fẹ doola ẹmi rẹ.
Nibi ti wọn ti n gbiyanju lati rii wi pe ọmọ erin naa ko ku lawọn naa gbọjọ iku wọn.
Koda, awọn alaṣẹ ọgba ẹranko naa daabo bo erin meji miiran ti wọn tun fẹ yọ ṣubu lori oke ti ko jina si ibi tawọn erin mẹfa ti ku.
Ida-omi yii ti wọn n pe orukọ ni Haew Narok ni wọn sọ pe iru iṣẹlẹ bayii ti wọpọ ni bẹ.
Ogun Cholera: Ọdọọdún ni àrùn onígbá-méjì máa n ṣọṣẹ́ ní Nàìjíríà-NCDC
Akọsilẹ fihan pe erin mẹjọ lo ku lọdun 1992 nibẹ, eyi to jẹ ki ijọba Thailand jiroro lori ọrọ naa.
Ibẹ maa n yọ awọn ẹranko ti wọn ba n kọja lati igba de igba ni.
Oríṣun àwòrán, Thailand DNP
Erin mẹ́fa d'olóògbé níbi tí wọ́n ti fẹ́ dóòlà ẹ̀mí ara wọn
Awọn oṣiṣẹ ọgba ẹranko lorilẹ-ede Thailand sọ pe awọn kan lo ṣaa deede pe akiyesi awọn lọjọ Abamẹta to kọja si awọn erin ti wọn duro soju ọna to lọ si ibi ida omi ọhun.
Lẹyin wakati mẹta lawọn oṣiṣẹ ọgba ẹranko naa ko oku ọmọ erin kan ati atawọn marun un miiran nitosi ara wọn.
Cosmic Crisp apple: kò le bàjé nínú ẹ̀rọ amóhun tutù fún ọdún kan
Oríṣun àwòrán, PVM
Cosmic Crisp apple: kò le bàjé nínú ẹ̀rọ amóhun tutù fún ọdún kan
Èso Apple tuntun tí wọ́n ṣẹ̀ṣẹ̀ ṣe yìí gba àwọn ónímọ ìjìnlẹ̀ sáyẹnsì ní ogún ọdún láti ṣèwádìí náà yanjú.
Apple náà si le wà nínú ẹ̀rọ amòmítutu fún ọdún kan gbáko ti kò ni bàjẹ, yóò si wọ ilẹ̀ Amerika loníì.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Cosmic Crisp apple: kò le bàjé nínú ẹ̀rọ amúǹkan tutù fún ọdún kan
Apple tuntun ọ̀hún ni wọ́n n pè ni Cosmic Crisp, èyí ti wọ́n fi àdàpọ oyin àti òwò ṣe, pẹ̀lú fasiti Washington ni wọ́n ti bẹ̀rẹ̀ si ni gbìn láti ọdun 1997
Àfilọ́lẹ̀ èso ẹlẹ́rindòddò yi gba mílíọnù mẹ́wàá dọ́là. (£7.9m)
Ní àsìkò yìí, àwọn àgbẹ̀ láti Washington nìkan lo ní ànfàni lati gbìn èso náà títí dí ọdún mẹ́wàá si àsìkò yìí.
Kate Evans tó wà lárá awọn to dari ọ̀gbìn Cosmic Crisp Apple ní olu ilu orilẹ-ede America sàlàyé pé
Crisp apple le koko, o ni ọdiwọ̀n àdun àti ilera, bẹ́ẹ̀ lo ni omí dáradára
Ogun Cholera: Ọdọọdún ni àrùn onígbá-méjì máa n ṣọṣẹ́ ní Nàìjíríà-NCDC
Kate fí kún un pé ara apple náà kìí tètè bàjẹ bákan náà ni gbogbo èròjà rẹ yóò pé si lára ti o ba wà nínú ẹ̀rọ amómitutu fún oṣù mẹwàá sí méjìlá.
Cosmic Crisp apple: kò le bàjé nínú ẹ̀rọ amúǹkan tutù fún ọdún kan
Igi Cosmic Crisp Apple mílíọnu méjilá ni wọ́n ti gbìn ti iwé àṣẹ̀ rẹ̀ si wà fún àwọn níkan, kò si fi ààyè gba ẹlòmíràn láti gbìn ní apá ibi kankan lọ́rílẹ̀-èdè Amerika.
Washington ló ni ibi ti o tóbi jùlọ ti wọ́n ti n pèsè Apple ni Amẹrika lóniruuru, sùgbọ́n àwọn èyí ti wọ́n ń pè ni Golden Delicious àti Red Delicious ti n ri ìpèníjà pẹ̀lú Pink Lady àti Royal Gala.
Apple ni èso tó n tà julọ lẹ́yìn ọgẹdẹ ní orílẹ̀-èdè Amẹrika.
FUTA: Àwọn mẹ́jọ ló ṣíná ìyà fún Bolu ní FUTA
Lagos-Ibadan Express: Ijọba àpàpọ ti ṣí afára Kara lẹyin àtúnṣe rẹ̀.
Oríṣun àwòrán, FRSC
Ijọba àpàpọ ti ṣí afára Kara lẹyin àtúnṣe rẹ̀.
Ijọba àpapọ Naìjíríà ti ṣí òpópónà Lagos -Ibadan Express lẹ́yìn ti wọ́n pari àtúnṣe ẹgbẹ̀tá míta tó bàjẹ lojú ọ̀nà náà.
Ìròyìn sọ pé apá ibikan ní ìhà àfárá Kara àti Oríta Ishẹri ti ènìyàn ba fẹ́ wọ ìlú Eko ni wọ́n tì pa láti ọjọ kejì, oṣù kẹsàn an láti ṣe àtúnṣe.
Ati pe eyi si ló fa a ti wọ́n fi ń dári ọkọ si ọ̀na ibòmiran.
Abẹ̀wò àwọn akọròyìn si àgbègbè náà sàfihàn pé àwọn eléto ààbo àti àwọn oṣìṣẹ́ tó ń moju to ìgbòkègbodo ọkọ, pẹ̀lú àwọn òṣíṣẹ̀ ilé iṣẹ́ ìrìnnà, agbára àti ilé ìgbé wà níkalẹ̀ láti moju to ṣíṣí ọ̀nà náà.
Bakan náà ni àwọn alábojúto igbokedgbodò ọkọ (FRSC) dúro si òpin afára náà láti maa dari àwọn oní móto si ojú ọ̀na tuntun ti wọ́n ṣi.
FUTA: Àwọn mẹ́jọ ló ṣíná ìyà fún Bolu ní FUTA
Igbakeji adari àjo náà, Taofik Iyanda wá fi ìdúnnú rẹ̀ hàn sí irú àtúnse to wáye loju opópóna marosẹ náà, bákan náà lo dupẹ lọ́wọ ijoba apapọ fun atunṣe oju popo ọhun.
Oríṣun àwòrán, FRSC
Ijọba àpàpọ ti ṣí afára Kara lẹyin àtúnṣe rẹ̀.
O rọ àwọn awakọ láti maa rọra ṣe lóju pópó náà, àti pe wọ́n kò gbọ̀dọ kọja ìwọn ìjánu ti wọ́n ni ki wọ́n maa rin loju pópó marosẹ.
Wòólì Alfred kú lọ́dún 1964, ó tún padà wà sí ìlú Agelu f'ọ́jọ́ mẹ́rìnlá!
Ìmúra málegbàgbé ti Sẹnatọ Dino Melaye ti mú níle aṣòfin àgbà l'Abuja
Ní òpin ọ̀sẹ̀ tó kọja ní àtúndi ibo ilé ìgbìmọ àsọfin àgbà wáye láàrin Sẹnatọ Dino Melaye ti ẹgbẹ òṣèlú PDP àti Sẹnatọ Smart Adeyemi ti APC láti sóju ẹkun ìwọ̀-òòrun ìpínlẹ̀ Kogi.
Sùgbọ́n fún ìgbà keji Sẹnatọ Dino Melaye tun fidirẹmi.
Lásìkò tí Dino Melaye fi wà ni ilé ìgbìmọ̀ àṣòfin àgbà l'Abuja, oríṣiríṣi àṣọ àti ìmúra to pani lẹrin ló maa ń wọ wá si ìjòkó ilé.
Oríṣun àwòrán, @Dino
Dino Melaye rèé lẹ́yìn ti ó jábọ nínú mọto ọlọpàá
Oríṣun àwòrán, @Dino
Sẹnatọ Dino Melaye nínú ilé aṣòfin, O kuku mura bii ti àwọn eniyan ilẹ̀ Arewa (Hausa)
Oríṣun àwòrán, @Dino Melaye
Sẹnatọ Dino Melaye wọ aṣọ ìkẹ́kọọ gboye jáde wa si ipade ile igbimọ aṣofin, lásìkò tí wọ́n ni ko gboye jade fasiti
Oríṣun àwòrán, @Dino Melaye
"Sẹnatọ Melaye ló tun ju ẹ̀gbà ọrun ti awọn kan ṣapejuwe pe ""O make sense"" lori ayelujara lọ si ilé aṣòfin"
Oríṣun àwòrán, @Dino
Ìmúra Dino Melaye tun rèé bi Báàlẹ ìlú tabi alade ti ko fẹ mura tan pẹlu irukẹrẹ lọwọ
Oríṣun àwòrán, @Dino
Nínú ilé ìgbìmọ asòfin, àwọn ènìyàn máa n ri Dino Melaye àti Ademola Adeleke bii Amuludun, Bi ẹnikan ṣe jẹ olórin, bẹ́ẹ̀ ni ẹni kan jẹ oníjó
Oríṣun àwòrán, @Dino
Àwọn ǹkan málegbàgbé ti Dino Melaye ti ṣe níle aṣòfin àgbà
FUTA: Àwọn mẹ́jọ ló ṣíná ìyà fún Bolu ní FUTA
Burkina Faso attack: Àwọn agbébọn pa ènìyàn mẹ́rinlá lásìkò ìjọsìn
Oríṣun àwòrán, others
Àwọn agbébọn pa ènìyàn mẹ́rinlá lásìkò ìjọ́sìn
Awọn agbebọn da ibọn bolẹ nile ijọsin onigbagbọ kan ni orilẹ-ede Burkina Faso.
Iroyin naa ni awọn obinrin ni wọn n ṣe ipade adura lọwọ nile ijọsin naa ni ana ọjọ Aiku ni ila oorun Hantoukoura.
Titi di asiko yii, ko sẹni to le sọ nipa awọn oniṣẹ ibi to huwa buruku yii.
Atejade ti ijọba ibilẹ naa fi sita ni ọpọlọpọ awọn eniyan lo farapa nibi iṣẹlẹ naa.
Ijọba Burkina Faso ni oun ko le ṣo nipato ohun to ṣokunfa iṣẹlẹ ibi yii.
Agbofinro kan ti ko fẹ ki wọn darukọ oun sọ fun akọroyin AFP pe awọn agbebọn lo ṣe iwa ika yii.
Wòólì Alfred kú lọ́dún 1964, ó tún padà wà sí ìlú Agelu f'ọ́jọ́ mẹ́rìnlá!
Iroyin naa ni wọn tun yinbọn lu oluṣọaguntan ṣoṣoọṣi naa atawọn ọmọ wẹwẹ to wa nibẹ.
Loṣu kẹwaa ni awọn agbebọn kọlu awọn kan ni mọṣalaṣi ni eyi ti awọn meẹdogun doku.
Lati ọdun 2015 ni ikọlu sile ijọsin ti bẹrẹ ni orilẹ-ede Burkina Faso ni eyi to ti mu ki awọn alaṣẹ ti ọpọlọpọ ile iwe pa.
Phone Battery: Wo bí o ṣe lè jẹ́ kí bátììrì fóònù rẹ pẹ́ síi
Oríṣun àwòrán, @others
Wo bí o ṣe lè jẹ́ kí bátììrì fóònù rẹ pẹ́ síi
Ohunkohun ti ẹda ba n ṣe laye yii, o yẹ ki a fi tọkan tara ṣee ni- Ọjọgbọn
Nigba ti ọjọgbọn Akira Yoshino bẹrẹ iṣẹ iwadii rẹ lori lilo batiri tuntun ti ẹmi rẹ yoo gun sii nibẹrẹ 1980; ko mọ pe pe iwadii naa maa di nla mọ oun lọwọ.
Coronavirus tips: Kìí ṣe gbogbo ìbòmù ló ń dá coronavirus dúró
O ni erongba oun ni ibẹrẹ iwadii naa ni pe kamẹra oni milimita mẹjọ a le maa lo batiri naa fun ọpọ wakati.
Akira ni iyalẹnu lo jẹ nigba ti iṣẹ iwadii naa n di nla ti o fi di itẹwọgba ni gbogbo agbaye bayii.
FUTA: Àwọn mẹ́jọ ló ṣíná ìyà fún Bolu ní FUTA
Iṣẹ iwadii lagbaye ti gbọrẹjẹgijẹ de ibi ti burọọṣi ifọyin, foonu, ati ọpọ nkan idana naa ti n lo batiri bayii.
Lodun 2019 ni wọn fun ọjọgbọn Yoshino ni ami ẹyẹ to ga julọ lagbaye ninu Chemistry to jẹ imọ sayẹnsi.
1) Pa ibi to n sọ ibudo ti o wa ninu foonu rẹ. Pa àwọn aapu bii afihan ibudo ti o wa ati maapu lasiko ti o ko ba lo wọn.
2) Ṣọra fun yiya fọto tabi fidio ni igba gbogbo lojoojumọ. Ọpọ lo maa n tan kamẹra foonu wọn silẹ nitori pe iṣẹju kọọkan ni wọn fi n ya fọto.
3) O ṣeeṣe fun ẹ lati paṣẹ fun foonu rẹ pe ko má lo batiiri pupọ nipa titan ibi ti wọn pe ni 'Low battery mode' ninu foonu rẹ.
4) Yọọ kuro ni pe ko maa gbọ̀n rìrì bíi ẹlẹgun Sango. Eyi maa n jẹ batiri pupọ bo ṣe n gbọn yẹn.
UI graduation: Fasiti Ibadan ló fún mi ni ẹ̀bùn ẹ̀kọ́ ọ̀fẹ́ tí mo fi kàwé síi- Habibat
5) Pa awọn ifitonileti iṣẹju iṣẹju to n sọ nipa awọn atẹjiṣẹ to n wọle bi wọn ṣe n wọle.
6) Pa awọn aṣẹ to ni ṣe ki foonu rẹ maa ṣatunṣe sawọn nkan ti o n wọ ori foonu rẹ bii fidio to maa bọ sinu rẹ ni kete to ba ti de ori ẹrọ ibanisọrọ rẹ.
7) Yọ awọn aapu ti o ko nilo tabi ti o kii lo nigba gbogbo
8) Ṣe adinku si bi oju foonu rẹ ṣe mọlẹ to. Bi foonu ba ṣe n tan ina si ni odiwọn batiiri to maa lo.
9) Fi ara balẹ ṣakiyesi bi batiiri foonu rẹ ṣe n lọ, eyi yoo jẹ ki o maa kiyesi ti o ba ti fẹ ku lainii fi ṣe odiwọn nọmba to gbe soju.
10) Ṣọra fun fifi foonu rẹ si ibi to gbona bii inu oorun tabi ibi to tutu pupọ nitori bi oju ọjọ agbegbe too fi foonu si ṣe ri maa n jẹ ki o tun bajẹ
11) Sọra fun fifi foonu rẹ sinu ina nigba gbogbo, rii pe batiiri rẹ ti fẹ tan ki o to kii bọ inu ina. Eyi tumọ si pe ko  maṣe fi foonu rẹ sinu ina di oru mọju rara.
12) Ma ṣe lo batiri rẹ de ibi pe o maa ku patapata to jẹ ida odo ninu ọgọrun un tabi koo maa fi sina si ida ọgọrun un nigba gbogbo.
Oríṣun àwòrán, Reuters
Ọna abayọ si ki batiri ẹrọ ibanisọrọ rẹ tete maa jo
13) Rii pe ṣájà ti o ba foonu ré wa ni o n lo fun foonu re nitori awọn ṣájà miran maa n ba foonu jẹ. Eyi lo difa fun pe ki o ṣọra fun lilo ṣájà inu mọto ti ko dara to.
14) Maa fi igbagbogbo pa Blutooth ti a fi n fi nkan ranṣẹ ati ayelujara wi-fi ti o ko ba nilo wọn nigba gbogbo tabi ki o fi si ti o ba wa lori afẹfẹ.
15) Ma sọrọ pẹ ju lasiko kan nigba ti o ba n gba ipe lori ẹrọ ibanisọrọ rẹ.
Ọjọgbọn yii gba awọn ọdọ nimọran lati tẹra mọ iṣẹkiṣẹ ti onikaluku yan laayo nitori pe ohunkohun ti o ba dawọle yẹ koo ṣee daadaa de ibi ere.
Ọjọgbọn yii sọrọ lori ibi ti iṣẹ de duro ati iṣẹ iwadii to ṣi n tẹsiwaju kaakiri ki batiri le maa pẹ ko too jo tan lasiko yi.
Ondo disability: Kò sí ẹni tí àkàndá kò lè ya ilé rẹ̀- Ayọdele
University of Transportation Daura: Nǹkan mẹ́wàá tó yẹ ní mímọ̀ nípa fásitì ẹ̀kọ́ ìrìnnà
Oríṣun àwòrán, Buharisallau1
Nǹkan mẹ́wàá tó yẹ ní mímọ̀ nípa fásitì ẹ̀kọ́ ìrìnnà
Aarẹ Muhammadu Buhari ti lọ ṣe ifilọlẹ fasiti onimọ nipa irinna akọkọ iru rẹ ni Naijiria.
Ni ilu aarẹ, Daura nipinlẹ Katsina ni ariwa Naijria ni wọn yoo kọ ọgba ile ẹkọ naa si.
Wọn yi lawọn nkan mẹwaa to yẹ ni mimọ nipa fasiti tuntun yi :
FUTA: Àwọn mẹ́jọ ló ṣíná ìyà fún Bolu ní FUTA
Dino ní ìyàwó ni Adeyemi jẹ́ f'óun lágbo òṣèlú, Adeyemi l'ọ́mọ ọ̀dọ̀ ni Dino jẹ́
Èso Apple tuntun tí ẹ lè fi pamọ́ fún ọdún kan ti wọ ọjà
Kò sí súnkẹrẹ-fàkẹrẹ mọ lópópóna márosẹ̀ Eko si Ibadan
Àwọn agbébọn pa ènìyàn mẹ́rinlá lásìkò ìjọsìn
Lati igba ti ijọba aarẹ Buhari ti de ori aleefa ni ẹka irinna ti jẹ ọkan lara awọn ẹka ti wọn gbajumọ paapa julọ nipa atunṣe awọn papakọ ofurufu kan lorile-ede Naijiria.
Ijọba Buhari ti ya owo pupọ lati ọdọ orile-ede China lati le ṣe akanṣe iṣẹlẹ lori ileeṣẹ ọkọ oju  irin Naijiria.
World Aids Day: Wo bí kòkòrò ààrùn HIV se bẹ̀rẹ̀ lágbàyé!
Ikoyi Prison: Wáyà iná já lu ẹlẹ́wọ̀n márùn ún lọ́gbà ẹ̀wọ̀n l'Eko, ọ̀pọ̀ w'à níléèwòsàn
Wáyà iná já lu ẹlẹ́wọ̀n mẹ́ta lọ́gbà ẹ̀wọ̀n l'Eko, ọ̀pọ̀ w'à níléèwòsàn
O kere tan ẹlẹwọn márùn ún  ni o ti di ero ọrun bayii lẹyin ti ina ẹlẹntiriki gbe wọn lọgba ẹwọn Ikoyi ni owurọ ọjọ Aje.
Iroyin ti a gbọ sọ pe ọpọ awọn ẹlẹwọn miran ni wọn wa lẹsẹkan aye, ẹsẹ kan ọrun bayii nitori iṣẹlẹ naa.
Ohun ti oṣiṣẹ ajọ ẹlẹwọn kan nibẹ ti a fi orukọ bo laṣiri ṣalaye ni pe ina ọba to ṣa dede lagbara lori awọn waya ina kan lọgba ẹwọn naa lo ṣokunfa iṣẹlẹ buruku ọhun.
O fi kun un pe waya ina naa lo ja lori ibusun kan tawọn ẹlẹwọn sun si to fi di pe awọn mẹta jalaisi bo ṣe ṣẹlẹ.
O ni awọn mẹta lo ku loju ẹsẹ ti awọn yooku si ti n gba iwosan nileewosan ọgba ẹwọn naa.
FUTA: Àwọn mẹ́jọ ló ṣíná ìyà fún Bolu ní FUTA
O ni ka ni alẹ ni iṣẹlẹ naa ṣẹlẹ ni, ko ba buru ju bo ti jẹ naa lọ. O ni ọpọ awọn ẹlẹwọn lo ti dide ti wọn si ti n kọri si ile ẹjọ koowa wọn fun igbẹjọ gbogbo to kan wọn lasiko to fi waye.
Minsita feto ọrọ abo abẹle Rauf Aregbesọla naa ti balẹ si ọgba ẹwọn naa.
Ni kete ti o ba ti bawọn akọroyin wa to wa nibẹ sọrọ la o bun yin gbọ.
World Aids Day: Wo bí kòkòrò ààrùn HIV se bẹ̀rẹ̀ lágbàyé!
Samantha Dalton: Lẹyin ọjọ keji igbeyawo mi, mo padanu kindinrin mi
Oríṣun àwòrán, Samantha Dalton
Bàbá mi fún mi kíndìnrín rẹ̀ láti dóòlà ẹ̀mí mi
Ki ni ka ti pe eleyi, lẹyin ọjọ meji to ṣe igbeyawo tan, akọroyin BBC, Samantha Dalton lugbadi aarun kindinrin.
Kẹrẹ kẹrẹ, laarin ọdun kan aarun naa le debi wi pe Samantha yoo nilo kindinrin miiran.
Samantha ṣalaye pe baba oun lo doola ẹmi oun lẹyin to fi kindinrin tiẹ silẹ fun un.
''Baba mi lo fun mi lanfaani lẹẹkeji lati wa laye, pẹlu ipinnu nla lati fun mi ni kindinrin kan ninu tirẹ,'' Samantha lo sọ bẹẹ.
Samantha ni bi ere bi ere lẹyin ọjọ meji igbeyawo oun lọrọ naa bẹrẹ nigba t'oun ati ọkọ oun, Justin n lọ ki ẹnikan.
Oríṣun àwòrán, Samantha Dalton
Samantha ni dokita oun toni ki oun wa fun awọn ayẹwo kan nibi to ti rii pe ifunpa oun lọ soke nitori awọn kindinrin oun ko ṣiṣẹ daadaa mọ.
Mo gbadun diẹ lẹyin ti wọn fun mi loogun lori ifunpa mi to lọ soke, mo si lanfaani lati rinrin ajo ifẹ lọ si orilẹ-ede Australia pẹlu ọkọ mi bo tilẹ jẹ pe ẹru ṣi n bami pe kindinrin le yọ mi lẹmi nigba kuu gba.
Ṣugbọn ninu oṣu karun un, ọdun 2018, aarun kindinrin yii bẹrẹ si ni wọ mi lara, debi wi pe mo bẹrẹ si ni ru gan an.
Samantha ni bayii loun ṣe dero ile iwosan nibi ti wọn ti sọ pe oun nilo kindinrin mii lati gbadun pada.
Oríṣun àwòrán, Samantha Dalton
Baba mi, ọkọ mi ati ẹgbọn mi ṣe ayẹwo lati fun mi ni kindinrin, ṣugbọn baba mi lo ni oun ṣetan lati fun mi ni kindinrin kan ninu tiẹ.
Bayii ni wọn ṣe iṣẹ abẹ fun mi ti mo si wa nile iwosan fun ọsẹ kan, nibi ti mo ti bẹrẹ si ni gbadun diẹdiẹ.
O jẹ ayọ fun mi pe ara baba mi naa ya lẹyin iṣẹ abẹ ti wọn ṣe lati yọ ọkan lara awọn kindinrin fun mi.
Oríṣun àwòrán, Samantha Dalton
Barry, baba Samantha ni oun fi kindinrin kan silẹ fun ọmọ oun nitori oun ko fẹ ki iyawo oun, Mandy ati ọmọ oun mii, Laura tabi Justin ọkọ Samantha fi kindinrin kan silẹ ninu tiwọn nitori wọn si kere lọjọ ori si oun.
Barry ni ko yẹ ki ọkan lara awọn ọmọ oun, iyawo oun tabi ọkọ ọmọ oun maa gbe ile aye pẹlu kindinrin kan nitori wọn ko tii dagba to oun nitori oun ti sun mọ ọgọta ọdun.
Ondo disability: Kò sí ẹni tí àkàndá kò lè ya ilé rẹ̀- Ayọdele
Opay bikes impoundment: Opeifa ní gbogbo ọlọ́kadà lòfin dè láti rìn ní mọ́rosẹ̀ Eko
Oríṣun àwòrán, Twitter/Mr Festus Emeka
Opeifa ní gbogbo ọlọ́kadà lòfin dè láti rìn ní mọ́rosẹ̀ Eko
Irọ ni pe LASTMET lo ko ọkada Opay kuro nilẹ- Ọpẹifa
Ọgbẹni Kayode Opeifa, tó jẹ alaga ajọ to mojuto igbokegbodo ọkọ ati imuṣẹ ofin to de igbokegbodo ọkọ nipinlẹ Eko (Lagos State Traffic Monitoring and Enforcement team) sọ pe ajọ naa kọ lo ko awọn 'ọkada' to jẹ ti ile iṣẹ Opay lọjọ Aje.
Ọgbẹni Opeifa sọ pe ajọ LASTMET kii mu ọlọkada, o ni awọn n ba awọn ajọ to n mu eeyan to ba ru ofin ṣiṣẹ pọ ni.
Ṣugbọn Opeifa ṣalaye pe ajọ yoo wu to ba jẹ pe oun lo ko awọn ọkada lagbara labẹ ofin lati gbe iru igbesẹ bẹẹ.
Opeifa fikun ọrọ rẹ pe ti ile iṣẹ Opay ba forukọ silẹ pẹlu ijọba ipinlẹ Eko, iyẹn ko fun wọn lagbara lati tapa s'ofin ipinlẹ Eko lori gigun alupupu l'Eko.
O ṣalaye siwaju si pe ofin ipinlẹ Eko lodi si ki ọkada maa gba ọna mọrosẹ nipinlẹ Eko.
Alaga ajọ LASTMET ni ko si iyatọ laarin ọkada Opay atawọn ọkada yoku ti wọn ba gba ọna mọrọsẹ niluu Eko.
Oríṣun àwòrán, Twitter/Otunbabakush1
Opeifa ní gbogbo ọlọ́kadà àti Opay lòfin dè láti gba ọ̀nà mọ́rosẹ̀ l'Eko
O ni kii ṣe pe ajọ to n mojuto igbokegbodo ọkọ ati imuṣẹ ofin to de igbokegbodo ọkọ nipinlẹ Eko dojule Opay nikan.
Opeifa tun ni ofin ipinlẹ Eko ko faaye gba fifi ọkada ṣiṣẹ kero lori opopona marosẹ nipinlẹ Eko.
Ẹwẹ, onimọ nipa ọrọ-aje, Bisi Iyaniwura to ba BBC Yoruba sọrọ fidi rẹ mulẹ pe o yẹ ki ijọba ipinlẹ Eko yẹ ara rẹ wo lori mumu awọn ọlọkada Opay lẹyin ti wọn ti forukọ silẹ pẹlu ijọba.
Ọgbẹni Iyaniwura sọ pe ijọba ni lati ṣe pẹlẹpẹlẹ pẹlu ọlọkada Opay atawọn ọlọkada mii niwọn igba ti wọn ko ba tapa s'ofin to de igbokegbodo ọkọ niluu Eko.
Bakan naa ni Iyaniwura sọ pe igbesẹ ijọba yii le da rogbodiyan silẹ nitori o le sọ ọpọlọpọ ọdọ di alainiṣẹ ni eyi to dẹ le tun fa iwa ipa ati ole jija lawujọ.
Ondo disability: Kò sí ẹni tí àkàndá kò lè ya ilé rẹ̀- Ayọdele
Bakan naa lo mẹnuba aiṣiṣẹ bo ti yẹ awọn oṣiṣẹ ijọba to n risi ọrọ lilọ bibọ ọkọ ni eyi to n ṣafikun si iṣorọ sunkẹrẹ-fakẹrẹ loju popo ni eyi ti ọpọ fi n gun ọkada dipo mọto nigba ti oju ba ti n kan wọn..
Akitiyan BBC Yoruba lati gbọ lati ẹnu awọn alaṣẹ ile iṣẹ Opay, ja si pabo titi di asiko ti a fi kọ iroyin yii.
FUTA: Àwọn mẹ́jọ ló ṣíná ìyà fún Bolu ní FUTA
Saraki: Ilé ẹjọ́ ní yóò yanjú ọ̀rọ̀ lórí ilé mí tí Ìjọba gbẹ̀sẹ̀ lé
Oríṣun àwòrán, EFCC
Ilé ẹjọ́ ní yóò yanjú ọ̀rọ̀ lórí ilé mí tí Ìjọba gbẹ̀sẹ̀ lé
Aarẹ ana ni ile aṣofin agba orile-ede Naijiria Sẹnẹtọ Bukola Saraki ti fesi pe ile ẹjọ ni yoo yanju ọrọ laarin oun ati ijọba Naijiria to gbẹsẹ le ile rẹ kan to wa nilu Ilorin.
Lọjọ Aje tii ṣe ọjọ keji, oṣu Kejila ni ẹka ajọ EFCC to wa nilu Ilorin gba idajọ lọdọ adajọ Ridwan Aikawa pe ki Saraki jọwọ ile naa fun ijọba tori pe ọna aitọ lo gba kọ ọ.
Ninu atẹjade kan ti agbẹnusọ Saraki fi sita fawọn oniroyin, o ni igbesẹ EFCC tapa si ofin nitori ile ẹjọ giga lAbuja to ti paṣẹ pe ki wọn ma ṣe gbe igbesẹ lori gbigba ogun Saraki kankan.
Yusuf Olaniyọnu to jẹ agbẹnusọ fun Saraki ṣalaye ninu rẹ pe: ''Irọ pọnbele ni ọrọ ti EFCC sọ pe ọna aitọ ni Saraki fi kọ ile naa.''
''Ohun to ṣẹlẹ ni pe ijọba Kwara da ninu owo ti wọn fi kọ ile naa ni ibamu pẹlu ofin to de sisan owo ifẹyinti fawọn Gomina ati igbakeji wọn ti Saraki si fi owo ara rẹ pari eleyi to ku''
Olaniyonu sọ pe iṣẹ ko bẹrẹ lori ile yi titi di asiko ti Saraki fẹ pari saa rẹ gẹgẹ bi Gomina ti o si fi iwe sọwedowo san owo kikọ ile naa
O wa tẹnumọ pe Saraki yoo tako igbesẹ yi ni ile ẹjọ lati le fi igbagbọ rẹ ninu titẹle ofin ilẹ yi rinlẹ .
Yatọ si ile Ilorin, ajọ EFCC ti n tọ pinpin awọn dukia Saraki ti Iroyin si kan nigba kan pe wọn gbẹsẹ le ile rẹ kan ni adugbo Ikoyi nilu Eko.
FUTA: Àwọn mẹ́jọ ló ṣíná ìyà fún Bolu ní FUTA
Faakinfa laarin Saraki ati Ijọba Naijiria ko ṣẹṣẹ bẹrẹ.
Nigba to wa lori oye gẹgẹ bi Aarẹ ile aṣofin Naijiria,ajọ to n risi igbogun ti awọn to n lu owo ilu ni ponpo ati gbigbogun ti iwa ibajẹ ICPC naa pe lẹjọ.
Oríṣun àwòrán, Google
Ààrẹ Ilé Ìgbìmọ̀ Àsòfin. Bukola Saraki ti sọ fún Àjọ EFCC pé kí wọ́n fi òun sílẹ̀, kí wọ́n yé é dìtẹ̀ mọ́ òun.
World Aids Day: Wo bí kòkòrò ààrùn HIV se bẹ̀rẹ̀ lágbàyé!
NUC: Àjọ tó n rí si ọ̀rọ̀ fásitì kéde ayédèrú kòfésọ̀ tó tó ọgọ́rùn ún
Oríṣun àwòrán, @others
Iwadii ṣi n tẹsiwaju lati foju awọn ayederu olukọ fasiti han sita
A ti ri to ọgọrun unawọn ọjọgbọn ti wọn kii ṣe ootọ ni fasiti NAijiria kakiri- Abubakar
Ajọ to n mojuto ọrọ ile iwe giga ni Naijiria, NUC ti kede pe oun ti ṣawari awọn ayederu ọjọgbọn kaakiri fasiti Naijiria.
Ojọgbọn Abubakar Rasheed to jẹ akọwe agba ajọ naa lo fi ikede yii sita ninu atẹjade ajọ naa to jade fun iṣẹlẹ oṣu kọkanla.
Wọn ni awọn ti forukọ awọn ayederu kofẹsọ wọnyii ranṣẹ si awọn fasiti ti wọn ti n ṣiṣẹ fun igbesẹ to yẹ.
Rasheed ni idi ti awọn ko ṣe kọkọ fi awọn orukọ yii sita ni pe ki ajọ NUC fun fasiti kọọkan laaye lati lọ fidi iwadii NUC mulẹ ki wọn ri otitọ ọrọ naa.
Sex Education: Ẹkọ ibálopọ̀ ko tó l'awọ́n ọ̀dọ́ ṣe n wá a lorí ayélujára
Rasheed sọ pataki ki awọn adari fasiti kọọkan lọ ṣe iwadii to yẹ lori awọn olukọ ti ọrọ kan ni kiakia lasiko ti ajọ NUC n ṣeto apero fawọn adari fasiti ni Naijiria.
O ni to ba ti di gbendeke ipari oṣu kejila ti wọn fun awọn adari fasiti lati gbe igbese to yẹ ajo NUC yoo gbe awón orukọ awọn olukọ ti igba ọrọ yii ṣi mọ lori sita faraye lati ri.
Abubakar Adamu Rasheed ṣalaye pe aṣiri ko deede tu bikoṣe igbesẹ ajọ NUC ti wọn ni ki gbogbo awọn kofẹsọ Naijiria fi awọn iwe ẹri wọn ṣọwọ soju opo ajọ NUC fun ayẹwo.
O ni lasiko yii ni NUC n ṣawari awọn ayederu iwe ẹri ti ko si fasiti to sọ wọn di ọjọgbọn.
Koda, Akọwe agba ajọ NUC yii tun kilọ fawọn adari fasiti ki wọn ṣe ohun ti o tọ lori awọn akẹkọọ to n jade ni fasiti koowa wọn
O ni NUC ti gba iwe ẹsun lọdọ adari ajọ awọn agunbanirọ pe awọn iwe ẹri awọn agunbanirọ fasiti miran mu ifura dani ti wọn ba n bọ wa sin ilẹ babawọn.
Ondo disability: Kò sí ẹni tí àkàndá kò lè ya ilé rẹ̀- Ayọdele
Bakan naa lo kilọ fawọn adari fasiti lati lọ mojuto iṣe ati ọna ikẹkọọ awọn ile iwe giga ti wọn jọ n ṣe ajọṣepọ ikẹkọọ fawọn akẹkọọ, yala ile ikọṣẹ olukọ NCE tabi awọn ile iwe gbogboniṣe tabi awọn eto agbelekawegboye Sandwish.
Bakan naa ni Rasheed ni ko si aaye fun olukọ fasiti kan lati maa ṣiṣẹ olukọ kọja ile iwe giga meji o pọju.
Ati pe wọn gbọdọ maa ṣiṣẹ wakati mẹjọ wọn pe o keere ju.
FUTA: Àwọn mẹ́jọ ló ṣíná ìyà fún Bolu ní FUTA
Akitoshi Okamoto: Òṣìṣẹ́fẹ̀yìntì, wọ gbaga ọlọ́pàá torí pé o pé ní 24,000
Òṣìṣẹ́fẹ̀yìntì, wọ gbaga ọlọ́pàá torí pé o pé ní 24,000 laarin ọjọ mẹjọ
Ọwọ awọn ọlọpaa lorilẹ-ede Japan ti tẹ oṣiṣẹfẹyinti ọmọ ọdun mọkanlelaadọrin kan lagbegbe Saitama.
Wọn ni o n lo oniruuru nọmba ibanisọrọ lati fi daamu ileeṣẹ ibanisọrọ kan lorilẹ-ede naa.
Oṣiṣẹfẹyinti ọhun ti wọn pe orukọ rẹ ni Akitoshi Okamoto ni wọn ni o pe ileeṣẹ ibanisọrọ naa ni igba ẹgbẹrun mẹrinlelogun, 24,000 laarin ọjọ meje lati beere ọpọlọpọ ibeere ati ẹsun pe wọn tẹ oju ofin adehun oun pẹlu wọn mọlẹ.
Gẹgẹ bi ohun ti ileeṣẹ ibanisọrọ naa, (KDDI) sọ, Alagba Okamoto n binu gan an ni pe awọn ariwo ibanisọrọ redio n farahan lori oju opo ibanisọrọ oun, eleyi to mu ko maa pe wọn ni tẹle-n-tẹle lati fi ẹhonu rẹ han.
Lakọkọ, KDDI ko fẹ gbe igbesẹ ofin lori rẹ gẹgẹ bi ọkan lara awọn onibara wọn ṣugbọn nigba ti ipe rẹ di lemọlemọ ti wọn ko si ri imu mi mọ tabi raye gbọ tawọn onibara yoku mọ ni wọn fi gbe ọlọpaa dide.
Awọn ileeṣẹ iroyin kan tilẹ sọ pe o ṣeeṣe ki ipe alagba naa gan an ju ẹgbẹrun mẹrinlelogun lọ.
Wọn ni ọkẹ aimoye ipe miran ni alagba Okamoto tun pe lawọn ibanisọrọ igboro ti wọn tilẹ ni o tun n sọ oriṣiriṣi ọrọ kobakungbe sawọn oṣiṣẹ ileeṣẹ naa.
Ondo disability: Kò sí ẹni tí àkàndá kò lè ya ilé rẹ̀- Ayọdele
Awọn kan tilẹ sọ pe o ni ki awọn oṣiṣẹ ileeṣẹ ibanisọrọ naa o fi ẹsẹ wọn rin wa ba oun nile lati tọrọ aforiji fun titẹ adehun aarin oun ati wọn loju mọlẹ.
Ni kete to ba si ti rii pe oju opo rẹ ba ti wọle ni yoo pa foonu rẹ.
Ẹsun fifi iwa jibiti di iṣẹ ẹlomiran lọwọ lawọn ọlọpaa fi gbe; ofin yii si faaye ijiya ofin silẹ fun ẹnikẹni to ba di awọn ileeṣẹ lọwọ lati ma ṣe ojuṣe wọn.
Ninu ifọrọwanilẹnuwo kan, alagba Okamoto ṣalaye fun ọlọpaa pe oun kan ni ẹni ti wọn fi iya jẹ lori ọrọ naa.
Ikoyi prisons: Lọjọ Aje ni waya ina ja lu awọn ẹlẹwọn kan ti o si ran wọn lọ sọrun
Lọjọ Aje ni waya ina ja lu awọn ẹlẹwọn kan ti o si ran wọn lọ sọrun.
Ileeṣẹ ọgba ẹwọn lorilẹ-ede Naijiria ti ni awọn ko tii kede orukọ awọn ẹlẹwọn to kagbako iku ojiji
Awọn alaṣẹ Ọgba ẹwọn nipinlẹ Eko lo fi ọrọ yii to BBC News Yoruba leti nilu Eko.
Ni ọjọ Aje ni iroyin lu sita nipa iku awọn ẹlẹwọn marun un kan lọgba ẹwọn to wa ni Ikoyi nilu Eko lẹyin ti waya ina ja lu wọn lori ibusun eleyi to ran awọn meje miran lọ si ileewosan.
Awọn alaṣẹ ileeṣẹ ọgba ẹwọn naa ni ohun ti awọn alaṣẹ ọgba ẹwọn lorilẹ-ede Naijiria n ṣe lori ọrọ naa bayii ni lati kọkọ fi ọrọ naa to awọn mọlẹbi awọn to ku naa lọwọ.
Minisita fun ọrọ abẹle, Rauf Arẹgbẹṣọla to wa lara awọn oṣiṣẹ ijọba to kọkọ de ọgba ẹwọn naa lọjọ Aje pẹlu ko ṣai fi da awọn eeyan loju pe gbogbo eto to yẹ nijọba a ṣe.
O ni igbesẹ lati ri i pe wọn tan ina wa idi ohun to fa iṣẹlẹ buruku naa ni wọn yoo ṣe.
Bakan naa lo ni wọn yoo gbe igbimọ iwadii kan kalẹ lati rii pe ilana ofin gbogbo to yẹ waye lori iṣẹlẹ naa.
Ondo disability: Kò sí ẹni tí àkàndá kò lè ya ilé rẹ̀- Ayọdele
Ninu ọrọ tirẹ, Ọga agba patapata fun ileeṣẹ ọgba ẹwọn lorilẹ-ede Naijiria, Ja'afaru Ahmed ni ara ohun to n ba ileeṣẹ ọgba ẹwọn finra naa ni apọju awọn ẹlẹwọn lọgba ẹwọn lorilẹ-ede Naijiria.
FUTA: Àwọn mẹ́jọ ló ṣíná ìyà fún Bolu ní FUTA
Fun apẹrẹ, o ni ẹgbẹrin ẹlẹwọn ni wọn kọ ọgba ẹwọn naa fun lọdun 1955 ti wọn kọ ọ, ṣugbọn lọwọ yii o le ni ẹgbẹrun mẹta awọn eeyan to wa ninu rẹ.
Ati pe ninu ẹgbẹrun mẹta o le naa, o le ni ẹgbẹrun meji nibẹ to jẹ pe wọn n reti idajọ ni.
Pẹlu bi ọrs ti ri yii, ko tii si ẹni lee sọ boya awọn ẹlẹwọn to ti gba idajọ lawọn marun to ku naa abi awọn to n reti igbejọ ati idajs ile ẹjọ wa lara wọn.
Buhari ṣè ìfilọ́lẹ̀ ọkọ̀ ìjagun ológun tiwantiwa ní Kaduna
Oríṣun àwòrán, Twitter/@BashirAhmaad
Buhari ṣèfilọ́lẹ̀ ọkọ̀ ìjagun ológun tiwantiwa ní Kaduna
Aarẹ Muhammadu Buhari ti ṣe ifilọlẹ ọkọ ijagun tiwantiwa lati le sọ agbara awn ọmọ ogun Naijiria di ọtun,
Ni ilu Kaduna lariwa orile-ede nibi ayẹyẹ apero ọlọdọọdun ọga ileeṣẹ ologun Naijiria ni ifilọlẹ yi ti waye lọjọ iṣẹgun.
Ọkọ naa ti o le tẹ ado oloro mọlẹ loju ogun ni wọn pe orukọ rẹ ni Ezugwu MRAP.
Aarẹ Buhari kan saara si awọn ọmọ ogun Naijiria fakitiyan wọn nipa kikoju awọn agbesunmọmi ati didaabo bo orile-ede Naijiria
Oríṣun àwòrán, Twitter/@BashirAhmad
Aarẹ ṣeleri atilẹyin ijọba rẹ fun ileeṣẹ ologun ki wọn baa le ri awọn erongba wọn muṣẹ.
O tun ni alaafia mọlẹbi wọn ṣe pataki si ijọba.
Aarẹ ni: ''Mo ṣakiyesi ajọṣepọ laarin ẹka imọ ẹrọ ileeṣẹ to ṣe ọkọ yi pẹlu awọn ileeṣẹ tiwantiwa lati gbe iṣẹ ọwọ larugẹ ati idagbasoke ileeṣẹ ologun wa''
O tun sọ pe inu oun dun pe ''akitiyan tawọn ologun Naijiria n ṣe ti bẹrẹ si ni yọri si rere pẹlu ọkọ ti wọn ṣe yi''
Ẹwẹ aarẹ Buhari tun kan saara sawọn ọmọ ogun Naijiria fun ifarajin wọn forile-ede Naijiria.
Ọwọ́ palaba kánsẹ́lọ̀ tẹlé rí olórí adigunjalè tó n jí ọkọ̀ ní Kwara segi
Oríṣun àwòrán, EFCC
Kansẹlọ tẹlẹri kan ni ijọba ibilẹ Ekiti ni ipinlẹ Kwara ti ko si panpẹ ajọ to n gbogun ti iwa jẹgudujẹra ni Naijiria, ìyẹn EFCC.
Ẹsun ti wọn fi kan an ni pe o jẹ olori awọn adigunjale to n fi ọna ẹburu ji ọkọ ayọkẹlẹ.
Loju opo ajọ naa ni wọn fi ikede yi si pẹlu alaye pe ọgbẹni Samuel Opeyemi Adeojo ni o jẹ agbatẹru awọn adigunjale kan ti wọn maa n fi ọna ẹburu ji ọkọ awọn onisowo ọkọ.
Gẹgẹ bi ohun ti ajọ naa sọ, wọn ni  o to ọjọ mẹta ti awọn ti n wa Adeojo ki o to wa di pe ọwọ tẹ ẹ.
O kere tan wọn ti fi idi ẹjọ mẹta mulẹ lori ẹsun ti wọn fi kan ikọ adigunjale yii ti wọn si ti gba ninu awọn ọkọ ti wọn ji gbe lọwọ wọn.
Awọn ọkọ naa wa ni ileeṣẹ ajọ EFCC to wa ni ilu Ibadan.
Iwadii EFCC gẹgẹ bi alaye wọn ṣe, ni o jẹ ki wọn mọ ọgbọn tawọn ole naa n lo lati fi ji ọkọ awọn eeyan.
Ondo disability: Kò sí ẹni tí àkàndá kò lè ya ilé rẹ̀- Ayọdele
Fake Pastors: Bunmi àti Rukayat ni agbódegbà àwọn afurasi pasitọ náà
Oríṣun àwòrán, others
Rukayat Folawewo ni òun ri iṣẹ́ ìyànu gba lọ́dọ̀ pasitọ Favour David lẹ́yìn ìjàmba ọkọ tó lágbara
Awọn òṣìṣẹ́ ọ̀tẹlẹ́múyẹ́ to n rí si ìwádìí ọ̀dáran nípinlẹ̀ Eko ti mú àwọn mẹ́rin kan tọ fi mọ olùsọ́aguntan méji.
Wọn fẹ̀sun kan pé wọ́n ń ṣe iṣẹ́ amí ati iṣẹ ìyanu èké ti wọ́n si n purọ gbówó lọ́wọ́ àwọn olùgbé Lekki àti Epe nípínlẹ̀ Eko.
Àwọn pásìtọ tí wọ́n fẹ́sùn kan ní Favour David ati Favour Chimobi pẹ̀lú ìfọwọ́sowọ́pọ̀ Rukayat Folawewo àti Bunmi Joshua, láti maa ṣe ìṣẹ́ jìbìtì wọ́n.
Agbẹ́nusọ ọlọpàá ní ìpínlẹ̀ Eko Bala Elikana, sọ nínú àtẹjáde kan pe àwọn afurasí náà maa n wá ọmọ ìjọ fún ìjọ Wonders Assembly Ministry to waà ni àdojúkọ Lagos Business School ní márosẹ̀ Lekki/Epe  ni Ajah.
"Elkana ni ""a mú afurasí mẹ́rin ti wọ́n maa n fi iṣẹ́ ìyanu òfége lo gbájuẹ̀ fún àwọn ara ilú ti ko fúra, wọ́n ṣe asọtẹlẹ, awọ́n miran a jẹri èké, èyi ni wọn n lò láti gbowó lọ́wọ wọ́n ti wọ́n a sì tún maa lo àwọn ọna miran láti kó ọrọ̀ jo."""
Elkana ni lẹ́yin ti ará ìlú tàwọn lolobó ni àwọn gbé ìgbésẹ̀ ti àwọn si mú àwọn obinrin méji, Rukayat Folawewo àti Bunmi Joshua ti wọ́n n ṣe bi ọmọ ìjọ naa ti wọ́n sì ri iṣẹ́ ìyànú ìwòsàn gbà láti ọwọ pásìtọ lẹ́yìn ìjàmba ọkọ̀.
Ondo disability: Kò sí ẹni tí àkàndá kò lè ya ilé rẹ̀- Ayọdele
"Ní ti Bunmi Joshua nítirẹ, oun jẹ́ri èké fún àwọn ọmọ ìjọ naa pé ọmọ oun to ti kò gbọ́ran ti ko si lè sọrọ ri ìwòsàn gbà.
O tun ni o sì ti n gbọ́ran àti sọ̀rọ̀ báyìí lábẹ́ iṣẹ́ ìránṣẹ́ pásìtọ Favour Chimobi ti ìjọ Elijah Ministry ní Port Harcourt ti oun ati pasitọ David Favour jọ ń ṣiṣẹ́ pọ̀.
Elkana sàlàyé pé ìwádìí fihan pé ìrọ panbele ni gbogbo ẹ̀rí náà, ti wọ́n si mu àwọn afurasi náà lásìkò ìṣọ́ oru.
Mobolaji Johnson: Yàtọ̀ sí Onikan stadium, wo àwọn dúkìá ìlú tí a fi sọ orí àwọn akọni
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Yàtọ̀ sí Onikan stadium, wo àwọn dúkìá ìlú tí a fi sọ orí àwọn akọni
Gẹgẹ bii ara eto ati ṣe iranti iṣẹ ribiribi ati ipa manigbagbe ti oloogbe Mobọlaji Johnson ko nigba aye rẹ, gomina ipinlẹ Eko Sanwo-Olu ti fi orukọ rẹ sọ papa iṣire Onikan nilu Eko.
Eyi kii ṣe akọkọ igbesẹ bayii. Ọpọ igba lawọn ijọba lẹka gbogbo ti maa n fi awọn ohun amayedẹrun ilu sọ orukọ awọn akọni ati akinkanju ọmọ orilẹ-ede Naijiria kan.
Oríṣun àwòrán, others
Eyi ni diẹ lara awọn awọn dukia ilu ti wọn ti fi sọ ori awọn eekan kan lawujọ.
Papakọ ofurufu ilu Eko jẹ ọkan lara awọn papakọ ofurufu ti igbokegbodo baluu ti n waye julọ ni ilẹ Afirika.
Ni asiko ogun agbaye keji ni wọn kọ papakọ ofurufu yii.
Papakọ ofurufu ilu Eko ni orukọ rẹ tẹlẹ ki wọn to yi orukọ rẹ pada si papakọ ofurufu Murtala Muhammed.
Ondo disability: Kò sí ẹni tí àkàndá kò lè ya ilé rẹ̀- Ayọdele
Wọn ṣe eyi ni iranti olori ijọba ologun lorilẹ-ede Naijiria nigbakan ri, Ọgagun agba Murtala Muhammed to ku ni ọdun 1976.
Fasiti Ọbafẹmi Awolọwọ, (Obafemi Awolowo University) OAU, Ile Ifẹ
Oríṣun àwòrán, oau
Orukọ fasiti yii nigba ti wọn daa silẹ ni fasiti Ile Ifẹ, iyẹn University of Ife, nigba ti ijọba ẹkun iwọ oorun Naijiria nigba naa ni ọdun 1961 daa silẹ.
Wọn wa yi orukọ rẹ pada si fasiti Ọbafẹmi Awolọwọ ni ọdun 1987 lẹyin iku Oloye Ọbafẹmi Awolọwọ.
Awolowo ni ọpọ gba pe oun ni baba iṣelu ni eyi ti wọn ṣi n ri aritọkasi iṣẹ to ṣe bii NTA, Liberty Stadium ati bẹẹ bẹẹ lọ.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Papa iṣire apapọ orilẹ-ede Naijiria, iyẹn National Stadium ni orukọ papa iṣere yii tẹlẹ ki wọn to yi orukọ rẹ pada si papa iṣere Moshood Abiọla ni ọdun 2019.
Papa iṣere naa to wa lara awọn papa iṣere aadọta ti owo ti wọn fi kọ wọn wọn julọ lagbaye ni wọn fi sọri Abiọla ẹni ti ọpọ n pe ni akin eto iṣejọba tiwantiwa ni Naijiria.
Abiola naa dije dupo aarẹ Naijiria ninu idibo ọjọ kejila, oṣu kẹfa, ọdun 1993 ni eyi ti ọpọ gba pe o wọle.
Oríṣun àwòrán, others
Papakọ ofurufu Abuja ni orukọ papakọ ofurufu yii ni igba ti wọn kọ ọ ni ọdun 2000.
Orukọ Ọmọwe Nnamdi Azikwe to jẹ aarẹ alagbada akọkọ lorilẹ-ede Naijiria ni wọn fi sọ papakọ ofurufu naa eyi to wa ni olu ilu orilẹ-ede Naijiria.
Oríṣun àwòrán, usman dan fodio university
Ni ọdun 1975 ni wọn da fasiti yii silẹ gẹgẹ bii fasiti ilu Sokoto.
Ọkan lara awọn fasiti mejila ti ijọba apapọ da silẹ lọdun naa ni. Wọn fi sọ orukọ Usman dan Fodio to jẹ oludasilẹ agbegbe Sokoto.
Papa iṣere Mobọlaji Johnson (Mobolaji Johnson Stadium) Ilu Eko
Oríṣun àwòrán, others
Papa iṣere ti wọn kọkọ kọ sibẹ wa saye ni ọdun 1930 nitosi gbagede Tafawa balewa Square.
Lọdun 1936 ni wọn fi sọ orukọ Ọba ilẹ Gẹẹsi nigba kan ri, King George V. Lọdun 1963 si 1973 ni orukọ rẹ yipada di papa iṣere ilu Eko, Lagos City Stadium.
Ni ọjọ Iṣẹgun, ọjọ kẹta, oṣu kejila, ọdun 2019 ni gomina ipinlẹ Eko, Sanwo Olu Babajide, kede iyipada orukọ rẹ si papa iṣire Mobọlaji Johnson.
Eyi jẹ ni iranti Ọgagun Mobọlaji Johnson to fi igbakan ri jẹ gomina ologun ni ipinlẹ Eko laarin ọdun 1966 si 1967.
Sudan: Àwọn olórí Sudan bẹ Amẹrika pé kó yọ ọ́ kúrò nínú àwọn orílẹ́-èdè agbésùnmọ̀mí
Àwọn olórí Sudan bẹ Amẹrika pé kó yọ ọ́ kúrò nínú àwọn orílẹ́-èdè agbésùnmọ̀mí
Awọn olori ilẹ Sudan ti kepe Aarẹ Donald Trump ilẹ Amẹrika pe wi pe ko yọ orukọ orilẹ-ede naa kuro ninu awọn orilẹ-ede to n ṣatilẹyin fun igbesunmọmi.
Awọn eeyan ọhun ti oloṣelu, awọn olukọ ile iwe giga atawọn ajafẹtọ wa lara wọn sọ ninu iwe ti wọn kọ si Aarẹ Trump pe ko bojumu ki gbogbo eeyan orilẹ-ede Sudan maa jiya ẹṣẹ ti aarẹ ana ilẹ naa, Omar Al-Bashir ṣẹ.
Ninu ọdun 2019 yii naa ni wọn gba ijọba lọwọ Al-Bashir lẹyin ti rogbodiyan bẹ silẹ nitori ifẹhonu to waye kaakiri orilẹ-ede naa.
Lọdun 1993 ni ilẹ Amẹrika fi orukọ Sudan si ara awọn orilẹ-ede to n gbaruku ti igbesunmọmi lori ẹsun pe orilẹ-ede Sudan n ṣatilẹyin fun awọn alakatakiti ẹsin.
Bi ìyàwọ mi ṣe n jábọ́ sí kọ́tà ló jẹ́ kí n kọ́ka fura pé kò ríran mọ́- ọkọ Dorcas
Olori ẹgbẹ Al-Qa'eda to ti di oloogbe bayii, Osama Bin Laden atawọn ọmọ ẹgbẹ rẹ wa lorilẹ-ede Sudan lasiko naa.
Awọn to fọwọ siwe naa ni ki America fiye denu nitori pe gbogbo ọmọ Sudan kọ ni alakatakiti ẹsin Islam.
Aarẹ ẹgbẹ awọn oniṣegun oyinbo, Sara Abdigalil, to jẹ ọkan lara eeyan mọkandinlọgọrin to buwọ luwe ti wọn fi ṣọwọ si aarẹ Amẹrika, ṣalaye fun BBC pe ote ti ilẹ Amẹrika fi le Sudan n ṣakoba fun ọrọ aje orilẹ-ede ọhun.
Abdigalil ni nnkan ti yatọ si ti tẹlẹ lorilẹ-ede Sudan bayii lẹyin ti ijọba Al-Bashir ti wo.
Insecurity: Monguno ní àsìkò ti tó láti f'òpin sí Almajiri ní Nàìjíríà
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Oludamọran fun ijọba lori ọrọ aabo, Babagana Monguno ti kepe ijọba lati fopin si eto ẹkọ Almajiri to wọpọ lapa ariwa orilẹede Naijiria.
Nigba to n sọrọ nibi apero kan to da lori ọna lati ṣeto aabo to mọyan lori, Monguno ṣalaye pe lai fopin si Almajiri bayii, yoo pada wa ṣakoba fun orilẹede Naijiria lọjọ iwaju.
Loṣu kẹfa to kọja ni Monguno sọ pe ijọba apapọ n gbero lati fi opin si Almajiri ki iru awọn ọmọ le lanfaani lati lọ si ile iwe.
Ọgbẹni Monguno fifi opin si Almajiri kan gbogbo eeyan kii ṣe ijọba nikan lọrọ naa kan.
Bakan naa lo sọ nibi apero ọhun pe ọrọ eto aabo to mẹhẹ ni Naijiria nii ṣe pẹlu awọn ọta ile ti wọn ṣi ilẹkun fun ti ita.
O ṣalaye siwaju si pe awọn kọlọnbiti ẹda kan ni wọn lẹdi apo pọ pẹlu awọn kan nilẹ okere lati maa da eto alaafia ru ni Naijiria.
Monguno ni ijọba fẹ lo apero lori eto aabo lati wa ojutuu si iṣoro eto aabo to mẹhẹ, eto ẹkọ ti ko munadoko ati awọn idojukọ pẹlu eto ilera ni Naijiria.
Ilé ẹjọ́ ni Uzor Kalu lu 7.65 biliọnu naira owo ilu ni kumọkumọ pẹlu ọ̀pá jìbìtì
Ilé ẹjọ́ ni Uzor Kalu lu 7.65 biliọnu naira owo ilu ni kumọkumọ pẹlu ọ̀pá jìbìtì
Ile ẹjọ giga ni ipinlẹ Eko lo ni ki gomina ipinlẹ Abia tẹle lọ fi ẹwọn ọdun mejila jura.
Ile ẹjọ lo jẹbi ẹsun mọkandinlogoji ti wọn fi kan an.
Wọn ni laarin ọdun 1999 si 2007 to fi tukọ ipinlẹ Abia bii gomina lo lo jibiti owo to din diẹ ni biliọnu mẹjọ din diẹ.
Ile ẹjọ da ẹjọ fun ile iṣẹ rẹ Slok Nigeria Limited ati oludari eto inawo fun ipinlẹ Abia nigba ti Kalu n ṣe ijọba, Ude Udeogu.
Ile ẹjọ tun ni ki Kalu to jẹ senatọ lọwọ nile igbimọ aṣofin ni Abuja fi gbogbo ohun ini rẹ to jẹ ti ileeṣẹ rẹ Slok silẹ fun ijọba.
Adajọ Mohammed Idris to da ẹjọ naa nipinlẹ Eko gẹgẹ bi ajọ EFCC to n gbogun ti iwa ṣiṣe owo ilu mọkumọku ṣe pee.
Ọkan ninu ẹjọ naa ni Kalu fi Slok Nigeria Limited to jẹ ileeṣẹ oun ati awọn mọlẹbi rẹ to ni to N7, 197, 871, 208.7 owo niara ninu.
Yoruba language: Àmì ohùn ṣe pàtàkì nínú èdè Yorùbá
Agbejọrọ Rotimi Jacobs to ṣoju ajọ EFCC to jẹ olupẹjọ, ni Kalu tun gba milionu ọta le ni irinwo owo naira ninu asunwọn ipinlẹ Abia laari oṣu keje si oṣu kọkanla, ọdun 2002.
O ṣalaye pe ọdun 2007 ni wọn ti bẹrẹ ẹjọ to wa so eso rere lonii yii.
Ilé ẹjọ́ ni Uzor Kalu lu 7.65 biliọnu naira owo ilu ni kumọkumọ pẹlu ọ̀pá jìbìtì
Kalu atawọn to ku naa ni awọn ko jẹbi ẹsun naa ti wọn fi kan wọn.
Ẹlẹri mọkandinlogun ni awọn olupẹjọ pe ti wọn jẹri nigba ti awọn Kalu jẹri gbe ara wọn.
Kalu jẹ ọkan lara awọn seneta ẹgbẹ PDP tẹlẹ ti wọn ti ya lọ si ẹgbẹ oṣelu APC nile igbimọ aṣofin agba ni Abuja bayii.
Ilé ẹjọ́ ni Uzor Kalu lu 7.65 biliọnu naira owo ilu ni kumọkumọ pẹlu ọ̀pá jìbìtì
Idajọ ati igbẹjọ to waye lawọn ile ẹjọ ni Naijiria lonii jẹ ara ọtọ.
Bi adajọ kan ṣe ran gomina nigba kan ri to tun jẹ senatọ bayii lẹwọn ọdun mejila bẹẹ naa ni omiran paṣẹ pe ajọ DSS ko le lagbara ju ile ẹjọ Naijiria lọ.
O ni ki wọn tu Soworẹ silẹ laarin wakati merinlelogun ti awọn eeyan ti n ka bayii.
50668243 - Uzor Kalu tó jẹ́ àṣojú láti ìpínlẹ̀ Abia rí ẹ̀wọ̀n ọdún méjìlá he
Lọjọ kẹta, oṣu kẹjọ lajọ DSS mu Ṣowore, ti wọn si fẹsun onikoko meje to nii ṣe pẹlu idoju ijọba bolẹ kan an.
Iroyin to n tẹ wa lọwọ ni yajoyajo sọ pe ile ẹjọ giga ijọba apapọ niluu Abuja ti paṣẹ pe ki ajọ DSS fi Omoyele Ṣowore silẹ.
Oríṣun àwòrán, Facebook/Omoyele Sowore
Adajọ paṣẹ pe ajọ ọtẹlẹmuyẹ DSS fi Ṣowore ati Olawale Bakare silẹ laarin wakati mẹrinlelogun.
Ẹwẹ, aibọwọ fun ofin ijọba ni Naijiria buru julọ labẹ ijọba Aarẹ Muhammadu Buhari, Ọjọgbọn Wole Ṣoyinka lo sọ bẹẹ.
Ọrọ Omoyele Ṣowore to ṣagbatẹru iwọde #RevolutionNow, ti ile ẹjọ paṣẹ idasilẹ rẹ lahamọ ajọ DSS ṣugbọn ti ajọ naa kọ lati fi silẹ lo mu Ọjọgbọn woye bẹẹ.
Lọjọ kẹta, oṣu kẹjọ lajọ DSS mu Ṣowore, ti wọn si fẹsun onikoko meje ti niiṣe pẹlu idoju ijọba bolẹ, jibiti ati sisọrọ kobakungbe si aarẹ.
Oríṣun àwòrán, Facebook/Omoyele Sowore
Ṣoyinka ní ìjọba Buhari ló burú jùlọ nípa àìbọ̀wọ̀ fún àṣẹ ilé-ẹjọ́
Ṣoyinka ni o dabi ẹni pe awọn ijọba ni Naijiria lati ọdun 1999 to fi di akoko yii n ṣe idije lori aibọwọ fun aṣẹ ile ẹjọ ni.
Ọjọgbọn Ṣoyinka ni iwuwasi ajọ DSS lori ọrọ Ṣowore fihan gbangba pe ijọba n lo oriṣiiriṣii lati tako ofin ile ẹjọ.
Ajafẹtọ Ṣoyinka sọ pe laisi ani-ani ẹka eto idajọ ko lẹnu rara ni ijọba Muhammadu Buhari to wa lode.
Ṣoyinka ni ti awọn ajọ eleto aabo ba le maa ju awọn ajafẹtọ si gbaga, a jẹ wi pe idaji awọn eeyan to wa ni Naijiria le wa latimọle.
O ṣalaye siwaju sii pe aibọwọ fun ile ẹjọ ati iwa jagidijagan, ọmọ iya kan naa ni wọn.
Ondo disability: Kò sí ẹni tí àkàndá kò lè ya ilé rẹ̀- Ayọdele
Hot mic moment: Àwọn ìlúmọ̀ọ́ká olórí orílẹ́-èdè tó sọ̀rọ̀ fẹnu kọ pẹ̀lú ẹ̀rọ gbohùngbohùn rèé
Oríṣun àwòrán, Press Association
Àwọn ìlúmọ̀ọ́ká olórí orílẹ́-èdè tó sọ̀rọ̀ fẹnu kọ pẹ̀lú ẹ̀rọ gbohùngbohùn rèé
Aṣiwi ko to aṣisọ, iyẹn lo difa fun awọn aarẹ orilẹ-ede kan lagbaye ti wọn ṣi ọrọ sọ pẹlu gbohungbohun.
Ohun to wọ pọ lagbo oṣelu ni pe ifura lagba oogun, awọn oloṣelu ko gbọdọ maa ro pe gbohungbohun ko si ni titan nigba gbogbo.
Ṣugbọn iyanlẹnu lo jẹ pe ọpọ awọn olori orilẹ-ede lo maa n saaba gbagbe eleyi.
Awọn aṣisọ ọrọ lati ẹnu awọn ilumọọka oloṣelu lagbaaye kan ti fi abuku nla kan wọn.
Lọsẹ yii ni olootu ijọba orilẹ-ede Canada, Justin Trudeau da bi ẹni pe o n fi Aarẹ ilẹ Amẹrika, Donald Trump ṣe yẹyẹ nibi ipade NATO.
Awọn aṣisọ manigbagbe lati ẹnu awọn olori orilẹ-ede marun un ree:
1. Ronald Reagan: 'A o bẹrẹ si ni ju ado oloro ni iṣẹju marun un' (1984)
Aarẹ ilẹ Amẹrika nigba kan ri, Ronald Reagan sọrọ fẹnu kọ nigba ogun 'Cold War' laarin orilẹ-ede Amẹrika ati orilẹ-ede Soviet Union tẹlẹ.
Nigba ti wọn n ṣe ayẹwo gbohungbohun lọwọ ni Aarẹ Reagan ṣeesi sọrọ pe,:
''ẹyin eeyan Amẹrika, inu mi dun lati sọ fun un yin pe mo ti buwọ lu ofin to de Russia laelae, a o bẹrẹ si ni maa ju ado oloro laarin iṣẹju marun un.
2. Jacques Chirac ko fẹran ounjẹ ilẹ Gẹeṣi tabi Finland (2005)
Aarẹ ilẹ Faranse tẹlẹ ri, Jacques Chirac sọrọ to da rugudu silẹ nigba to rinrin ajo lọ si orilẹ-ede Russia.
Aarẹ Chirac ro pe gbohungbohun to wa lọwọ oun ko si ni titan nigba to bẹrẹ si ni sọrọ pe ''awọn eeyan ilẹ Gẹeṣi ko ṣee gbẹkẹle papaa julọ pẹlu bi wọn ko ti ṣe mọ ounjẹ se.
Chirac ni lẹyin ilẹ Gẹeṣi, orilẹ-ede Finland lo tun buru jai pẹlu ounjẹ sise.
Ọrọ naa di aawọ laarin ilẹ Gẹẹsi ati orilẹ-ede Faranse nigba naa.
3. 'Yo Blair!' (2006)
Ninu ipade G8 niluu St Petersburg lorilẹ-ede Russia ni aarẹ ilẹ Amẹrika tẹlẹ ri, George W. Bush ti sọ pe 'Yo Blair!' nigba to ki olootu ijọba ilẹ Gẹẹsi, Tony Blair.
Awọn mejeeji ko mọ pe awọn akọroyin n gbọ ohun ti wọn n sọ nigba ti wọn n ki ara wọn.
Awọn alatako Blair ati Bush fi ọrọ naa ṣe yẹyẹ lagbo oṣelu.
Oríṣun àwòrán, Press Association
Àwọn ìlúmọ̀ọ́ká olórí orílẹ́-èdè tó sọ̀rọ̀ fẹnu kọ pẹ̀lú ẹ̀rọ gbohùngbohùn rèé
4. Gordon Brown's 'alaṣeju obinrin' (2010)
Olootu ijọba ilẹ Gẹẹsi tẹlẹ, Gordon Brown lo pe obinrin kan ni alaṣeju nibi to ti n bawọn eeyan sọrọ ni Rochdale.
Ọgbẹni Brown pada sinu ọkọ rẹ lai mọ pe gbohungbohun si wa lara rẹ, nibẹ ni o ti n ba ọkan lara awọn amugbalẹgbẹ rẹ sọrọ.
Nibẹ lo ti sọrọ pe alaṣeju l'obinrin, Gillian Duffy to beere ibeere lọwọ rẹ.
Amọ, Brown pada tọrọ aforijin lọwọ obinrin naa.
5. 'Ọrọ rẹ ti su mi'- Aṣiṣẹ Obama ati Sarkozy
Awọn akọroyin ni wọn gbọ nigba ti aarẹ ilẹ Faranse nigba kan ri, Nicolas Sarkozy n sọ fun akẹgbẹ rẹ lati Amẹrika, Barack Obama nibi ipade G20 lorilẹ-ede Faranse.
Ọgbẹni Sarkozy lo n sọ fun Obama pe ọrọ olootu ilẹ Israel, Benjamin Netanyahu ti su oun.
Obama fesi pe 'opurọ ni Netanyahu, ọrọ rẹ gan an le mu eeyan ṣe aisan, ohun ti mo n la kọja lojoojumọ niyẹn.''
Aṣiri ọrọ yoo to tu sita ṣakoba fun ibaṣepọ to wa laarin ilẹ Israel ati ilẹ Faranse pẹlu orilẹ-ede Amẹrika.
UI graduation: Fasiti Ibadan ló fún mi ni ẹ̀bùn ẹ̀kọ́ ọ̀fẹ́ tí mo fi kàwé síi- Habibat
Budget 2020: Ilé aṣòfin àgbà buwọ́lu àbá ìṣúná N10.59trn fún ọdún 2020
Oríṣun àwòrán, nigeria Senate
Ile aṣofin agba ti buwọlu abadofin iṣuna orilẹede Naijiria fun ọdun 2020.
Iṣuna oni tiriliọnu mẹwa abọ o le diẹ naira, N10.59trn ni wọn buwọlu lẹyin o rẹyin.
Aba oni triliọnu mẹwa o le ọdunrun biliọnu naira ni aarẹ gbe ka iwaju ile naa ni sjọ kẹjs oṣu kẹwaa ọdun 2019.
Amọṣa lẹyin ijoko ati ifikunluku awọn igbimọ tẹẹkoto gbogbo ni ile aṣofin mejeeji, awọn aṣofin agba fi ọtalelugba o le mẹta bilisnu naira kun un.
Lara afikun yii, awọn aṣofin apapọ fi biliọnu mẹta kun bilisnu marunlelọgọfa bilisnu naira ti wọn ya sọtọ fun wọn tẹlẹ.
Ninu ọrs to sọ lori afikun naa, alaga igbims lori iṣuna ni ile aṣofin agba, Muktar Batera ni afikun ọhun waye lati mojuto awọn eto to nii ṣe pẹlu idagbasoke ilu.
Nigba to n gbe abajade rẹ sita, Sẹnetọ Jibrin barau ṣalaye pe afikun aadọrun bilisnu Naira waye fun amojuto  ipenija abo lorilẹede yii, eto fawọn aṣofin ati iranwọ fun ipinlẹ Zamfara.
EKSU: Fásitì EKSU lé òṣìṣẹ́ tó lé ní 600 lórí ẹ̀sùn ìwé ẹ̀rí, ọjọ́ orí
Oríṣun àwòrán, Vanguard news
Fasiti ipinlẹ Ekiti, EKSU ti le ẹẹdẹgbẹrun oṣiṣẹ rẹ niṣẹ.
Giwa fasiti naa, Ọjọgbọn Eddy ỌỌlanipẹkun ṣalaye pe abajade iwadi ileeṣẹ atọpinpin iṣuna kan lori iṣuna ati oṣiṣẹ ileeṣẹ naa lo mu eyi wa.
O fi kun pe wọn gbe igbesẹ naa lori aba ti igbimọ olubẹwo ti gomina ipinlẹ naa, Kayọde Fayẹmi gbe kalẹ, eyi to tọka si apọju oṣiṣẹ ni gbogbo ẹka fasiti naa gẹgẹ bi ipenija kan ti ileeṣẹ naa ndojukọ.
Iroyin sọ pe, awọn oṣiṣẹ ti wọn gba siṣẹ laarin ọdun 2016 si 2018 lọbẹ igbesẹ naa ba nidi julọ atipe igbasiṣẹ wọn ti mu iye owo sti fasiti naa n na o tubs pọ si ni ilọpo ọgọrun laarin ọdun mwji.
Gẹgẹ bi ọrọ giwa fasiti naa, o le ni igba awọn oṣiṣẹ fasiti naa ti ko lee fi iwe ẹri ileewe alakọbẹẹrẹ wọn han. Bẹẹni aimọye orukọ ni wọn ri to n gba owo oṣu ṣugbọn ti orukọ wọn ko si ninu iwe oṣiṣẹ fasiti naa.
Bakan naa ni giwa fasiti naa tun ṣalaye pe ọpọ ninun wọn ni ọjọ ori wọn ti kọja ọdun ti ofin la kalẹ fun ati ṣiṣẹ ni fasiti.
Sowore: Atiku Abubakar, Oby Ezekwesili, àtawọn ọmọ Nàìjíríà sọ̀rọ̀ órí ohun tójú Sowore rí ní kóòtù
Lọjọ Ẹti ni gbẹgẹdẹ gbina ni gbegede ile ẹjọ giga apapọ kan ni ilu Abuja ti ṣe olu ilu Naijiria nigba ti awọn agbofinro ajọ ọtẹlẹmuyẹ DSS ya wọ ile ẹjọ lati fi tipatipa mu Ọmọyẹle Ṣoworẹ, ajafẹtọ ọmọniyan pada si ahamọ wọn.
Ni alẹ Ọjọbọ, ọjọ karun un oṣu kejila ọdun 2019 ni ileeṣẹ ọtẹlẹmuyẹ DSS tu Soworẹ silẹ lahams wọn lẹyin aṣẹ ile ẹjọ to ni ki wọn ṣe bẹẹ laarin wakati mẹrinlelogun ki wọn si tun san owo gba mabinu ẹlẹgbẹrun lọna ọgọrun naira fun un.
Ki wọn to de ile ẹjọ lowurọ ọjọ Ẹti ni iroyin ti jade pe DSS yoo gbe Soworẹ, ṣugbọn awọn amofin rẹ ni awọn ti mọ si awọn si ti gbe igbesẹ lori rẹ.
Nibayii, awọn eekan ilu nilẹyii ati loke okun ti n bu ẹnu atẹ lu igbesẹ yii.
Aṣiwaju ajafẹts araalu lagbaye, Ọjọgbọn Oby Ezekwesili wa lara awọn to kọkọ gbohun soke tako igbesẹ naa. O ni ko si bi aarẹ Buhari ṣe lee sọ pe oun ko mọnipa eewọ ti awọn ileeṣẹ agbofinro DSS n jẹ lori ewe iṣejọba tiwantiwa Naijiria.
Oby Ezekwesili ni aarẹ ni oludari agba fun ileeṣẹ DSS, afi ko tete yara paṣẹ fun Ọga agba ajọ naa lati tẹle ofin ile ẹjọ ki wọn si tu Soworẹ silẹ
Ẹwẹ, ninu ọrọ tirẹ, igbakeji aarẹ orilẹede Naijiria nigbakan ri to tun jẹ oludije fun ipo aarẹ ninu eto idibo to kọja, Alhaji Abubakar Atiku sọ ọ yanya pe ibanujẹ nla lo jẹ fun oun ohun to ṣẹlẹ ni ile ẹjọ loni nipa ṣoworẹ.
Oríṣun àwòrán, Twitter/Sahara Reporters
Ko si igba kan ninu itan oṣelu Naijiria ti irufẹ ohun to ṣẹlẹ si adajọ kan loni tii ṣẹlẹ."""
Atiku ni gbogbo awọn alagbara orilẹede Naijiria lo gbọdọ mọ pe iṣejọba tiwantiwa lo wa lode ni Naijiria kii ṣe ti afagidijaye.
O wa rọ awọn ọmọ orilẹede Naijiria lati dide ja fun idaabobo eto iṣejọ awarawa rẹ.
Oniruuru ọrọ si lawọn ọmọ Naijiria n sọ lori ayelujara. Bi awọn kan ṣe n pariwo pe ki ijọba bọwọ fun ofin lawọn miran n ke gbare pe, ijọba atawọn ileeṣẹ agbofinro n tigi boju ẹtọ ọmọniyan lorilẹede Naijiria.
Pẹlu tipa ti ikuuku ni awọn oṣiṣẹ ajọ DSS fi fẹ mu Omoyele Ṣowore pada si atimọle wọn lọjọ Ẹti.
Eleyi ṣẹlẹ ninu ile ẹjọ niluu Abuja nibi ti awọn akoroyin ti faake kọri pe awọn ko nii gba ki wọn u Ṣowore pada si gbaga.
Bakan naa ni awọn oṣiṣẹ ajọ DSS tun gbiyanju lati yinbọ fun.
Adajọ Ijeoma Ojukwu ti sun igbẹjọ siwaju si ọjọ kọkanla oṣu keji ọdun 2020 lẹyin ti awọn agbẹjọro Ṣowore ati ajọ DSS beere pe ki ijọba sun igbẹjọ naa siwaju.
Agbẹjọro fun Ṣowore, Femi Falana ṣalaye pe ajọ DSS fi ipa mu Ṣowore nitori pe wọn fẹ fi ẹsun miiran kan an.
Kò lè ṣeéṣe kí DSS tún dá Ṣowore padà sí àtìmọ́lé wọn
Agbẹjọrọ fun Omoyele Ṣowore ati Adebayo Bakare, Femi Falana sọ pe ẹni eegun n le ko maa rọ ju lọrọ awọn ajọ ọtẹlẹmuyẹ DSS, nitori bi o ti n rẹ araaye lo n rẹ ara ọrun.
Nigba to ba BBC Yoruba sọrọ lẹyin ti ajọ tu Ṣowore ati Bakare silẹ tan l'Ọjọbọ, Falana wi pe ko ṣeeṣe ki ajọ DSS tun mu awọn mejeeji pada lọnii ọjọ Ẹti.
Ṣowore ati Bakare gba ominira lẹyin ti ile ẹjọ giga l'Abuja paṣẹ pe ki ajọ DSS fi wọn silẹ laarin wakati mẹrinlelogun, lẹyin naa lawọn n sọ pe o ṣeeṣe ki DSS tun dawọn pada si gbaga lonii ọjọ Ẹti.
Oríṣun àwòrán, Sahara reporters
Amọ, Falana ni ko si ohun to jọ bẹẹ, o ni digbi lawọn n duro de ajọ DSS lori igbesẹ mii ti wọn ba fẹ gbe lori ọrọ Ṣowore.
Falana tun fidi rẹ mulẹ pe adajọ ni ki ajọ DSS san ẹgbẹrun un lọna ọgọrun un naira lori bi wọn ṣe kọ lati paṣẹ ile ẹjọ mọ pe ki wọn fun Ṣoworẹ lominira
Itusilẹ Omoyele Ṣowore waye lẹyin ti o ti lo ọjọ marundilaadoje ni ahamọ awọn DSS.
Oniruuru idajọ lo ti waye eyi ti awọn ile ẹjọ lorilẹede Naijiria ti ni ki wọn fi silẹ ṣugbọn ti awọn alaṣẹ ileeṣẹ DSS kọ jalẹ pẹlu oniruuru awawi.
Amọṣa ni ọjọbọ ni ileẹjọ miran tun pa aṣẹ ki ileeṣẹ Ọtẹlẹmuyẹ DSS o tu u silẹ laarin wakati mẹrinlelogun.
Oríṣun àwòrán, Instagram/Omoyele Sowore
Ireti wa pe yoo tun farahan ni ile ẹjọ ni ọjọ Ẹti ni itẹsiwaju igbẹjọ rẹ.
Ni ọjọ kẹta oṣu kẹjọ ọdun 2019 ni awọn agbofinro DSS lọ gbe Ọmọyẹle Soworẹ lori ẹsun pe o n ṣe agbatẹru awọn iwọde #revolutionnow eleyi to n beere fun iṣejọba rere lorilẹede Naijiria.
Ni ajọ kẹfa oṣu kọkanla ni ọgbẹni Soworẹ kọkọ mu ileri beeli akọkọ ti ile ẹjọ fun ṣẹ ṣugbọn ti ileeṣẹ DSS ko tuu silẹ.
Oríṣun àwòrán, Facebook/Omoyele Sowore
Ọru ifisahamọ Sowore ti mu ọpọlọpọ awọn ajọ ilẹ okeere ati ti Naijiria pẹlu lati kigbe si ijọba apaọ lati bọwọ fun ofin ṣugbọn ti ileeṣẹ DSS kuna lati tu u silẹ gẹgẹ bi awọn aṣẹ iṣaaju lati ile ẹjọ.
Bakan naa ni ileeṣẹ DSS tun da Olawale Bakare naa silẹ.
Awọn mejeeji yi ni ijọba apapọ n fi ẹsun iditẹ gbajọba kan.
Yollywood: Saheed Balogun sìnkú ìyá rẹ̀, Ìròyìn ohun tó ṣẹlẹ̀ lágbo òṣèré lọ́sẹ̀ yìí nìwọ̀nyí
Oríṣun àwòrán, ogogo/instagram
Nnkan kan lagbo awọn oṣere tiata lọsẹ yii.
Latori afihan sinima, de ori ọjọ ibi kan oku arugbo lo waye laarin awọn oṣere tiata Yoruba ti a mọ si Yollywood lọsẹ yii.
O ya ẹ jẹ ki a gbe wọn yẹwo leni eji.
Oríṣun àwòrán, femi adebayo/Instagram
"Gbogbo wa lo fẹrẹ wo sinima apanilẹrin ti Fẹmi Adebayọ ṣe, to pe akọle rẹ ni Jẹlili, nibayii, o ti tun gbe eyi ti a lee pe ni ipadabọ Jẹlili lẹẹkeji jade bayii. Akọle to fun un ni ""Survival of Jelili"""
Laarin ọsẹ yii naa lo ṣe afihan rẹ ni itagbangba fun igba akọkọ. babi si ni ero pe lọ wo o. Lara awsn oṣere to wa ninu sinima yii ni Toyin Abraham, Dele Odule, Desmond Elliot, Seyilaw, Gbenga Adeyinka 1st, Woli Agba, Arole, Papi Luwe, Aisha Lawal, Rachael Okonkwo and Razak Olayiwola aka ojopagogo, and Bolanle Ninalowo.
Ifẹsẹwọnsẹ bọọlu afẹsẹgba lati sọri ọjọ ibi ọgọta ọdun, Ogogo
Oríṣun àwòrán, ogogo/Instagram
Lara awọn eekan oṣere tiata Yoruba to ti ta gbongbo kaakiri agbaye ni Alhaji Taiwo Hassan ti ọpọ eeyan mọ si Ogogo ọmọ kulodo jẹ. Nitori naa ko ya ni lẹnu nigba ti eto loniranran gbode kan fun ayẹyẹ ọjọ ibi ọgọta ọdun to ṣe. Lara awọn eto naa ni ifẹsẹwọnsẹ laarin ikọ ogogo, (Ogogo All stars) ati ikọ to jẹ ti olori ile aṣofin ipinlẹ Eko, ( Obasa All stars).
Nigba ti ifẹsẹwọnsẹ naa yoo fi pari ni papa iṣire agege, goolu meji lawọn ikọ Obasa All Stars fi gbẹyẹ mọ iks Ogogo lọwọ o. BBC ki Ogogo ku ayẹyẹ ọjọ ibi o. Ọdọọdun ni sapo n ruwe o, yoo maa wa bi ẹwa ni. Ojojo kii ṣ'ogun ajinde ara yoo maa jẹ fun Ebony Alhaji ni o.
Oríṣun àwòrán, Saheed Balogun/Instagram
Saheed Balogun gbẹyin iya rẹ Mama Arikẹ Jọlade. Laarin ọsẹ yii naa lo ṣe eto adura fidau ọjọ kẹjọ iya rẹ.
Nibayii, Saheed gangan ti kede pe osu kẹta ọdun to n bọ, iyẹn ọdun 2020 lawọn fi oku Mama si o. Nitori naa, kẹyin ololufẹ rẹ maa mura silẹ. Gbogbo wa la o gbẹyin arugbo wa o.
Oríṣun àwòrán, foluke daramola/instagram
Ọpọ igba ni iroyin ailera, atọpọ ipenija to n koju awọn agba oṣere tiata maa n jade sita ti o si maa n ba awọn ololufẹ wọn ninu jẹ lọpọlọpọ. Ki iru eyi ma baa ṣẹlẹ ms ni ọkan lara awọn oṣere tiata Yoruba, Folukẹ Daramọla fi dide lati gbe eto kan kalẹ eleyii ti yoo maa ri si bi alaafia ati ilera yoo ṣe maa de ba awọn oṣere nigba ti ọjọ alẹ ba de.
O pe akori eto naa ni 'Nolly veteran SOS Project 2019' lara awọn to ti n janfani eto naa bayii ni Sadiq Daba, Barbara Soki, Kareem Adepoju a.k.a Baba Wande, Kayode Odumosu a.k.a Pa Kasumu, Peter Fatomilola, Lanre Hassan (Iya Awero), Idowu Phillips (Iya Rainbow), Lere Paimo a.k.a Eda Onile Ola ati bẹẹbẹẹ lọ.
Laarin ọsẹ yii naa ni wọn ṣe eto idibo fun igbimọ alakoso ẹgbẹ oṣere tiata TAMPAN ni ilu London.
Aarẹ Ẹgbẹ naa kaakiri agbaye, Ọgbẹni Bọlaji Amuṣan ti ọpọ mọ si Mr. Latin wa lara awọn agbaagba ẹgbẹ to lọ ṣe aayan idibo naa.
Rotimi Amaechi: Rotimi Amaechi, mínísítà fétò ìrìnnà ní àwọn ọmọ Nàìjíríà tí kò lóye ló já ọrẹ́ ìyà fún òun nílùú Madrid
Oríṣun àwòrán, Rotimi Amaechi/twitter
Rotimi Ameachi to jẹ minisita fun eto irinna lọwọlọwọ bayii ni ijọba Aarẹ Muhammadu Buhari ti pariwo sita pe lọsan ọjọ Ẹti, awọn ọmọ orilẹede Naijiria kan ni ilu Madrid, Orilẹede Spain ja pankẹrẹ iya fun oun.
Bi o tilẹ jẹ pe iṣẹ ilu ni Amaechi ba lọ si orilẹede Spain, Rotimi Amachi ni ọpọlọpẹ awọn ọlọpaa lo gba ohun silẹ lọwọ awọn ọmọ orilẹede Naijiria naa bi bẹẹ kọ, boya ẹkọ o ba ṣoju mimu fun oun.
Cancer: Àṣe ara mi ni iso ti n run gbogbo bí mo ṣe n ṣèrànwọ́ lórí jẹjẹrẹ
Minisita fun eto irinna ilẹẹwa naa ni oun dupẹ lọwọ ori pe iwọn ni ikọlu naa mọ, oun ko si farapa, bẹẹ lo fi kun un pe awọn ọmọ orilẹede yii ti ọrs ko ye daadaa lo kọlu oun.
Bi ẹ ko ba gbagbe, laipẹ yii ninu ọdun 2019 yii naa ni awọn ọmọ orilẹede Naijiria kan din dundu iya fun igbakeji aarẹ ile aṣofin orilẹede Naijiria tẹlẹ, Sẹnetọ Ike Ekweremadu lorilẹede Germany.
Aisha Buhari-Aya ààrẹ, Aisha Buhari ni ààrẹ gan kó mọ nípa ọ̀rọ̀ ìyàwò tuntun
Oríṣun àwòrán, Aisha Buhari/ twitter
Aya aarẹ orilẹede Naijiria, Aisha Buhari ti sọ wi pedigbi bayii ni ọkan oun duro nigba ti ariwo aarẹ fẹ gbe iyawo tuntun bọ si igboro aye lorilẹede Naijiria.
Aisha Buhari ṣalaye ọrọ yii ninu ọrọ kan to sọ lori ileeṣẹ Mohunmaworan abẹle kan lorilẹede Naijiria.
Aya aarẹ orilẹede Naijiria ṣalaye wi pe, aarẹ Buhari gan ti iroyin n sọ pe o fẹ gbe iyawo tuntun ko mọ ohun to n lọ.
O ni awọn kan ni ileeṣẹ aarẹ lo wa nidi iroyin ọhun lori ayelujara.
Laipẹ yii ni iroyin gbode lori ikanni ayelujara ati iroyin gbogbo pe aarẹ Muhammadu Buhari fẹ gbe ọkan lara awọn minisita rẹ, Sadiya Farouq niyawo.
Bi o tilẹ jẹ wi pe ko si ẹni to ms ibi ti iroyin naa ti ṣẹ wa nitori pe lẹyin o rẹyin igbeyawo naa ko waye, Aisha ni ko si eyikeyi ninu oun ati ọkọ oun to mọ ohunkohun nipa iroyin naa.
Arabinrin Aisha Buhari ni gbogbo eeyan lo mọ pe Naijiria ko ni abo labẹ iṣejọba ọkọ ohun, ṣugbọn o da oun loju pe asiko to lati mu nnkan bọ sipo fun awọn ọmọ orilẹede Naijiria.
O ni ọpọ akoba ni oṣelu oni baba isalẹ n ṣe fun iṣejọba lorilẹede Naijiria, idi ti gbogbo awọn minisita ti ọkọ oun, iyẹn Aarẹ Buhari yan gbọdọ fi ji giri dide si iṣẹ to yẹ.
Ikoyi Prisons: Iléeṣẹ́ Ọgbà ẹ̀wọ̀n ní kí wọ́dà mẹ́jọ lọ rọ́ọ́kún nílé lórí ikú ẹlẹ́wọ́n márùn ún l'Eko
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ileeṣẹ Ọgba ẹwọn lorilẹede Naijiria ni awọn ti ran awọn wọda mẹjọ lọ rọọkun nile Lori iku  ẹlẹwọn marun ti waya ina ja lu lọjọ aje
Ni owurọ ọjọ aje, ọjọ keji oṣu kejila ọdun 2019 ni iroyin iku awọn ẹlẹwọn marun to ku iku ojiji lu si igboro. Ohun ti awọn alaṣẹ Ọgba ẹwọ sọ ni pe waya ina kan lo ja nitori apọju agbara ina ti awọn ileeṣẹ manamana mu de. Rẹgi ori ibusun ti awọn ẹlẹwọn naa wa ni o ja le ti o si pa awọn marun lẹsẹkẹsẹ, ti awọn meje miran si di ero ileewosan.
Lọjọ naa, ni kete ti minisita fun ọrs abẹle, Rauf Arẹgbẹṣọla bẹ ọgba ẹwọn Ikoyi ni ilu Eko, nibi ti ọrs naa ti ṣẹlẹ wo tan lo ti ṣeleri pe iwadii yoo waye lati mọ ohun to ṣẹlẹ gan.
Agbẹnusọ kan fun ileeṣẹ ọgba ẹwọn ṣalaye pe wọn gbe igbesẹ naa lati lee raye ṣe iwadii naa bi o ti tọ ati bi o ti yẹ lai si idiwọ tabi idena kankan.
Reinhard Bonnke: Ajíhìnrere àgbáyé Reinhard Bonnke papòdà lẹ́ni ọdún mọ́kàndínlọ́gọ́rin
Oríṣun àwòrán, Facebook/Reinhard Bonnke
Ajíhìnrere àgbáyé Reinhard Bonnke papòdà lẹ́ni ọdún mọ́kàndínlọ́gọ́rin
Iku doro, iku ṣeka, iku ti mu gbajugba ajiyinrere agbaye, Reinhard Bonnke lọ lẹni ọdun mọkandinlọgọrin.
Ninu atẹjade kan ti iyawo rẹ, Annie Bonnke buwọ lu loju opo Facebook rẹ ni wọn ti kede iku ojiṣẹ Ọlọrun yii.
Wọn sọ ninu atẹjade naa pe pẹlu alaafia ni Ọgbẹni Bonnke fi pada lọ ba Ẹlẹdaa rẹ ni ọrun.
Fun ọgọta ọdun sẹyin, Bonnke ṣiṣẹ ajihinrere kaakiri agbaye papaa julọ nilẹ Afirika, o ṣe eto isọji kaakiri awọn orilẹ-ede.
Idile rẹ ki gbogbo eeyan fun iranwọ ati igbaruku ti wọn fun Bonnke eleyi to jẹ ko ṣe aṣeyọri ninu iṣẹ ipe rẹ.
Èyí ni ìtàn bí ẹni tí mó gbọ́njú mọ̀ bíi bàbà ṣe fipá bá mi lájọṣepọ̀
Mariam kàgbákò ikú lọ́wọ́ ọ̀rẹ́kùnrin rẹ òní Yahoo-yahoo tó dáná sún un lórí ẹsùn àgbèrè
Oríṣun àwòrán, Google
Mariam kàgbákò ikú lọ́wọ́ ọ̀rẹ́kùnrin rẹ òní Yahoo-yahoo tó dáná sún lórí ẹsùn àgbèrè
Arabinrin kan ti ọrékunrin rẹ dana sun nilu Eko lori ẹsun agbere ti gba ibẹ lọ si ọrun alakeji.
Arabinrin naa ti orukọ rẹ n jẹ Mariam Alabi ti a si gbọ pe o jẹ ọmọ ọdun mẹrinlelogun jẹ Ọlọrun nipe lẹyin ti gbogbo igbiyanju lati doola ẹmi rẹ ja si pabo ni ile iwosan ijọba apapọ to wa ni Igando nilu Eko.
Arakunrin Victor Orji to jẹ ọrẹkunrin rẹ ni ile iṣẹ ọlọpaa nilu Eko sọ pe o dana sun Mariam.
Ninu atẹjade kan ti alukoro ọlọpaa nilu Eko Bala Elkana ti ṣaaju fi sita pe iṣẹlẹ bi Victor ti ṣe dana sun Mariam waye ni ọjọ Abamẹta ladugbo Ọjọọ nibi tawọn mejeeji ti jọ n gbe ile pọ.
''Loju opo ayelujara ti awọn eeyan ti n yan ọrẹ ni Ifeanyichukwu ti pade arabinrin naa ni oṣu Keji ọdun yii ti o si ko lọ ba a nile rẹ ni oṣu Kẹta ọdun.
O ti n ṣe iṣẹ Yahoo yahoo lati nnkan bii ọdun mẹta ti o si n fi owo to ba ri nibẹ san owo ile to gba, ki o tun fi gbadun aye rẹ''.
Bi ìyàwọ mi ṣe n jábọ́ sí kọ́tà ló jẹ́ kí n kọ́ka fura pé kò ríran mọ́- ọkọ Dorcas
Elkana fi kun un pe ọrọ ko wọ laarin awọn mejeeji nigba ti Mariam yọlẹ kuro nile lọjọ Ẹti lati lọ pade ọkunrin miran.
''Ni igba ti asiri tu si Ifeanyichukwu lọwọ, lo ba fi ibinu da bẹntiroo si Mariam lara ti o si dana sun un''
Elkana sọ pe awọn ọlọpaa ọtẹlẹmuye yọju sibi iṣẹlẹ naa ti wọn si gbe Mariam lọ si ile iwosan ijọba.
O ni, o ṣeni laanu pe ile iwosan naa lo dakẹ si lowurọ ọjọ Aiku.
Elkana pari ọrọ rẹ pe ọga ọlọpaa nilu Eko, Hakeem Odumosu ti ni ki wọn fi afurasi naa si ahamọ titi ti yoo fi foju ba ile jọ bi ofin ṣe laa kalẹ.
Èyí ni ìtàn bí ẹni tí mó gbọ́njú mọ̀ bíi bàbà ṣe fipá bá mi lájọṣepọ̀
FIRS: Buhari fi orúkọ àwọn ilé ìgbímọ̀ FIRS tuntun ránṣẹ́ sí àwọn aṣòfin
Oríṣun àwòrán, @others
Buhari fi orúkọ àwọn ilé ìgbímọ̀ FIRS tuntun ránṣẹ́ sí àwọn aṣòfin
Aarẹ Buhari to lagbara lati yan ẹnikéni to wuu gẹgẹ bii alaga ajọ FIRS to ba ti gba ifọwọsi awọn aṣofin ti ṣe bẹẹ.
O kede Muhammed Nami to jẹ olugbaninimọran lori ọrọ owo ori gẹgẹ bi alaga tuntun ni kete tile igbimọ aṣofin agba ni abuja ba ti buwọ luu.
O to ọgbọn ọdun bayii ti Muhammed Nami ti n ṣiṣẹ kaakiri ẹka idokowo, iṣakoso owo ori ati ilanilọyẹ lori ọrọ owo ori.
Bakan naa lo tun ti ṣiṣẹ nile ifowopamọ ati ni ẹka ijọba nipa jijẹ olubadamọran ati olugbaniniyanju lori ọrọ okowo ati owo ori.
Nami jẹ akọṣẹmọṣẹ nipa okowo tuntun ati ọna idagbasoke ninu ọna itaja.
Nibo ni Muhammed Nami ti kawe?
Muhammed kawe jade gboye ẹkọ nipa awujọ lọdun 1991 ni fasiti Bayero ni Kano.
O gba oye imọ ijinlẹ keji ni fasiti Ahmadu Bello to wa ni Zaria nibi to ti kẹkọọ nipa okowo lọdun 2004.
O jẹ akọṣẹmọṣẹ nipa iṣakoso nipa owo ori ati igbani niyanju ni Kaduna, Abuja ati ipinlẹ Niger.
Ṣé ọ̀rọ̀ yìí ò wa tóbi jù láti túmọ̀ sí Yorùbá?
Ogbeni Nami jẹ alaga fun ọpọlọpọ ile iṣẹ ati idokowo nlanla.
Wọn yan an ni ọmọ igbimọ ileeṣẹ Aarẹ Lori gbigba awọn ohun ini Naijiria ti awọn kan ti jigbe loṣu kọkanla, ọdun 2017.
Muhammed ni iyawo, o si ṣabiyamọ.
Oríṣun àwòrán, @FIRS
Buhari ti dahun ibeere pe ṣe Fowler maa lọ lẹẹkan sii ni FIRS nigba to ni ki Muhammed gba iṣẹ Fowler ni Abuja
Oun ni Aarẹ Buhari kede pe ko gba iṣẹ lọwọ Babatunde Fowler ti saa rẹ pari lana ọjọ Aiku gẹgẹ bii alaga FIRS.
Kete ti awọn ọmọ ile igbimọ aṣofin ba ti fọwọsi yiyan Muhammed naa lo maa bẹrẹ iṣẹ ni FIRS lẹkunrẹrẹ.
VAT: Kò sí àǹfàní kankan tí ìjọba ti ṣe fún mi sẹ́yìn
Awọn ọmọ igbimọ tuntun naajẹ ti ẹlẹnu pupọ.
Ẹni kọọkan lati ẹya mẹfa agbegbe ti a pin orilẹ-ede Naijiria si, ati aṣoju lati awọn ileeṣe ijọba kọọkan.
Garba Shehu ni ijọba gba pe Babatunde Fowler yoo fi eto gbogbo silẹ fun adari ti ipo rẹ ga julọ lasiko yii ninu ajọ FIRS.
FIRS Babatunde Fowler to jẹ ọ̀rẹ́ Ọṣinbajo nì àwọn èèyàn n bèèrè bóyá Buhari á tún yàn sípò ṣugbọn Ohun to n tan ni ọdun eegun, bo pẹ bo ya ọmọ alagbaa n pada bọ wa tọrọ akara jẹ ẹkọ ni ọrọ naa jasi.
Fowler gbà pé òdiwọ̀n owó ti òun pa wọle si apo ijọba lolori aṣeyọri oun àti pé ìpènija ni ki àwọn eeyan mọ ìdí tí wọn fi gbọdọ san owo ori.
Oríṣun àwòrán, Others
Babatunde Fowler ati igbakeji aarẹ Osinbajo jẹ lọ sile iwe ni lọdun diẹ sẹyin ko to gba ipo alaga ajọ FIRS.
Ọpọ sọrọ lori idagbasoke to ba nomba iye owo to wọle si asunwọn ijọba lasiko ti Fowler wa nibẹ.
Fowler ni ajọ FIRS to n gba owo ori wọle fun ijọba apapọ Naijiria pọ sii lasiko oun.
Sola allyson, olori Ẹmi ni aala gbọdọ wa lori ohun ti awọn ololufẹ̀ olorin lee ṣe si wọn.
Fowler ni owo ti oun pa wọle lọdun 2018 lo pọju ni asunwọn ijọba ninu itan Naijiria, iyẹn lasiko to pa 5.3 tiriliọnu naira wọle.
Bakan naa lo ni sisan owo ori lona igbalode nipa lilo ayelujara wa lara aṣeyọri Fowler nigba to jẹ adari FIRS.
Bakan naa ni Fowler ba awọn ile iṣẹ nlanla kan pòó lori ọrọ owo ori to yẹ ki wọn maa san.
Awọn miran mẹnuba eyi to ṣe pẹlu ileeṣẹ bii ti MTN ti wọn kọkọ kọ̀ lati san owo ori tuntun ti wọn bu fun wọn pe o pọju.
Fowler funra rẹ ṣalaye ninu ifọrọwanilẹnuwo kan pe ihuwasi awọn eniyan lori sisan owó orí jẹ ipenija nla fun ajọ naa lasiko oun.
Bi ìyàwọ mi ṣe n jábọ́ sí kọ́tà ló jẹ́ kí n kọ́ka fura pé kò ríran mọ́- ọkọ Dorcas
Koko ipenija ti awọn eeyan n pariwo lasiko Fowler ni pe o jẹ ki owo ori pọ sii.
Ọpọ gba pe igbagbọ rẹ pe ki ijọba moju kuro ninu epo rọbi lati owo na wa di ajaga sọrun awọn ara ilu ati ileeṣẹ.
Awọn miran ni o dabi pe FIRS n da ṣiṣẹ laisi ifọwọsopọ awọn ileeṣe ijọba miran bii ki wọn ma mọ ni pato iye ti awọn kan n san.
Iṣẹlẹ lori ọrọ IGR ati odiwọn iye owo to wọle ati eyi to jade naa tun kun ara ẹfọri to la kọja
Babatunde Fowler ati igbakeji aarẹ Osinbajo jẹ lọ sile iwe ni lọdun diẹ sẹyin ko to gba ipo alaga ajọ FIRS.
Loni ọjọ Aje, ọjọ kẹsan an, oṣu kejila, ọdun 2019 ni Fowler fi fipo silẹ lẹyin ti iyansipo rẹ pari lanaa, ọjọ Aiku.
Ọpọ eeyan lo ṣi n woye boya aarẹ Buhari maa tun Fowler yan fun saa keji.
Ọdún 2015 ni Babatunde Fowler di alaga àjọ to n risi ọrọ owó orí ni Naijiria FIRS, ṣe aarẹ Buhari fẹ lòó lẹẹkan sii ni ibeere bayii.
Downsyndrome: Dayo ń wa mótò, ó fẹyawọ, o tún lọ ilú òyìnbó
Logunjọ, oṣu kẹjọ, ọdun 2015 ni ijọba Buhari ti yan Babatunde Fowler sipo adari ajọ FIRS to n risi ọrọ owo ori ni Naijiria.
Oríṣun àwòrán, @others
Iṣe saa akọkọ yii pari fun Fowler, kini o ku?
Ọjọ kẹsan an, oṣu kejila, ọdun 2015 ni ile igbimọ aṣojuṣofin fọwọ si yiyan Fowler sipo.
Lọjọ Aiku yii ni saa ọdun mẹrin ti ijọba yan Fowler sipo pari ni eyi ti ileeṣẹ aarẹ Buhari ko tii sọ nkanakn nipa iyansipo rẹ lẹẹkan sii tabi ko yan ẹlomii.
Ajọ FIRS labẹ ofin Naijiria ni awọn gbendeke to rọ mọ yiyan ẹnikẹni lati tukọ ajọ FIRS ni Naijiria.
Ofin to da ajọ FIRS silẹ faaye gba pe ki aarẹ to ba n tukọ Naijiria yan ẹni to wuu sipo naa.
Aarẹ gbọdọ fi orukọ ẹni naa ranṣẹ sile igbimọ aṣofin ki wọn le buwọlu iyansipo iru ẹni bẹẹ.
Ọdun mẹrin ni saa kọọkan fun ẹnikẹni ti a ba yan sipo alaga naa.
Ẹẹmeji pere to jẹ ọdun mẹjọ lapapọ ni ẹnikẹni le di ipo alaga ajọ FIRS mu.
Tọkunrin tobinrin lo le di ipo naa mu ti ile igbimọ ba ti fọwọ si iyansipo naa.
O ṣeeṣe ko jẹ pe Adari eto gbogbo ti wọn fun ni ipo Coordinating Director nile iṣẹ FIRS ni o maa dipo mu bi Fowler ṣe ti pari saa rẹ yii ti aarẹ Buhari ko si kede tabi forukọ Fowler ranṣẹ fun sa keji.
Èyí ni ìtàn bí ẹni tí mó gbọ́njú mọ̀ bíi bàbà ṣe fipá bá mi lájọṣepọ̀
Yobe Lawan: Wọ́n ti ní kí Baalẹ̀ Yobe lọ rọọ́kún nílé torí ẹ̀sùn pé o fipá bá ọmọdé sùn
Oríṣun àwòrán, @others
Gomina ipinlẹ Yobe ti ni ki Lawan Mari ti wọ́n fẹ̀sùn kàn pé ó fipé bá ọmọ ọdún mẹ́fà sùn ni Yobe
Gomina ipinlẹ Yobe, Mai Mala Buni ti kede pe ki Baalẹ ilu Fananami, Lawan lọ rọọkun nile.
Gomina ṣe ikede yii lataari ẹsun ti wọn fi kan Baale Lawan Mari ni Gashua pe o fipa ba ọmọ ọdun mẹfa ọkunrin kan sun ni ilu wọn ni ijọba ibilẹ Bade ni ipinlẹ Yobe.
Kọmiṣọna fun ọrọ ile, eto ifitonileti ati aṣa lo ṣe ikede yii lorukọ Gomina ni Damaturu to jẹ olu ilu ipinlẹ Yobe ni ariwa Naijiria.
Èyí ni ìtàn bí ẹni tí mó gbọ́njú mọ̀ bíi bàbà ṣe fipá bá mi lájọṣepọ̀
Ogbẹni Abdullahi Bego to jẹ kọmiṣọnna yii ṣalaye pe iwa buruku gbaa ni ẹsun ti wọn fi kan odindin Emir ilu naa.
O ni Gomina Buni ti ni ki iwadii bẹrẹ ni kia lai ṣegbe fẹnikan ki ọwọ ofin si mu Baale naa to ba jẹbi ẹsun ọhun lẹyin iwadii kikun.
Kọmiṣonna ni ikede pe ki Baalẹ lọ rọọkun naa wa ni ibamu titi ti wọn yoo fi pari iwadii naa ti yoo fi otitọ ohun to ṣẹlẹ han.
Oríṣun àwòrán, @others
Wọ́n ti ní kí Baalẹ̀ Yobe lọ rọọ́kún nílé torí ẹ̀sùn pé o fipá bá ọmọdé sùn
O ni wọn ti ṣayẹwo to yẹ fun ọdọmọde naa ti ọrọ kan nile iwosan bi o ti yẹ ati pe wọn ti ṣe akọsilẹ ipo ti wọn baa.
Bi ìyàwọ mi ṣe n jábọ́ sí kọ́tà ló jẹ́ kí n kọ́ka fura pé kò ríran mọ́- ọkọ Dorcas
Ile iwosan ijọba apapọ ni Gashua ni wọn ti ṣe itọju to yẹ fun ọmọ ọdun méfa naa.
Pẹtẹsi akọkọ ni Naijiria
Ex-governors’ pension: ilé aṣòfin Èkó láwọn kò ní ṣé bí tàwọn aṣòfin Zamfara
Oríṣun àwòrán, @others
Oriṣii ọna ti ijọba fi n lo owo ori awọn eniyan
Kuforiji: Kò sí ohun tó burú nínú kí Gómìnà máa gbowó gọbọi lẹ́yìn ìfẹ̀yìntì
Olori ile aṣofin ipinlẹ Eko nigbakan ri, Adeyemi Kuforiji ti gbaruku ti awọn aṣofin lori ofin owo ati dukia ifẹyinti fawọn to ti jẹ Gomina ati igbakeji ri nipinlẹ naa.
Kuforiji sọ ọrọ yi di mimọ lasiko to n kopa lori eto kan lori ẹrọ amohunmaworan Naijiria TVC ni ipinlẹ Eko.
O ṣalaye pe ti awọn to wa lori ipo ba ṣe nkan bo ti ṣe yẹ, ara ilu ko ni maa lọgun nipa owo ifẹyinti gọbọi tawọn Gomina n gba.
Kuforiji ni: ''Ti gbogbo eeyan ba ṣiṣẹ bi Jakande ti ṣe ṣiṣẹ, bi Tinubu ṣe ṣiṣẹ nipinlẹ Eko,ko si ẹni ti yoo ma pariwo lori owo ifẹyinti tawọn Gomina n gba''
Kuforiji ni ti a ba wo wahala tawọn to di ipo mu yii ṣe lati fi sin ilu, o yẹ ki ara ilu fi imoore han pẹlu owo ifẹyinti to jọju.
Lẹnu ọjọ mẹta yi, ariwo ti gbode kan pe ki awọn aṣofin ipinlẹ to ku naa tẹle igbesẹ ile aṣofin Zamfara to wọgile owo ifẹyinti gọbọi fawọn to ba ti jẹ Gomina ri.
Ipinlẹ naa ni yatọ si eleyi ti ofin la kalẹ fawọn to ba wa nipo, awọn ko ni le fi ofin kalẹ ni ijọba ipinlẹ lati tun ya owo ati dukia sọtọ fawọn Gomina ati igbakeji wọn ti wọn ti kuro nipo.
Oríṣun àwòrán, Facebook/Hon Adeyemi Ikuforiji
Ilé aṣòfin Èkó láwọn kò ní ṣé bí tàwọn aṣòfin Zamfara
Adeyemi Kuforiji: Nígbà tá gbé òfin owó ìfẹ̀yìntì kalẹ, iṣẹ nlá là ṣé
Ariwo fífopin sowo ifẹyinti awọn oloṣelu lataari igbesẹ ile aṣofin Zamfara to wọgile owo ifẹyinti gọbọi ló gbode kan.
Ajọ SERAP to jẹ ajọ aladani to n ja fun iṣedeede lawujọ ni Naijiria lo n lewaju ninu ipe ki wọn wọgile owo tabua fawọn Gomina to ti kuro nipo.
Adetokunbo Mumeen to jẹ adari ajọ naa kopa ninu eto ori ẹrọ amohunmaworan ti a n sọ yi to si ni owo gbigba lọna meji lawọn tako.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
ilé aṣòfin Èkó láwọn kò ní ṣé bí tàwọn aṣòfin Zamfara
Bi a ko ba gbagbe, ile ẹjọ giga kan nilu Eko gbe idajọ kalẹ pe ki agbẹjọro agba Naijiria gba gbogbo owo ifẹyinti ọna meji tawọn Gomina to di ipo miran mi mu nijọba gba lọwọ wọn.
Ipinlẹ Eko wa lara awọn ipinlẹ to fariga pe awọn ko ni yi ofin yi pada nitori ko tako ilana ofin owo ifẹyinti fawọn to di ipo Gomina mu tẹlẹ ri.
Bi ìyàwọ mi ṣe n jábọ́ sí kọ́tà ló jẹ́ kí n kọ́ka fura pé kò ríran mọ́- ọkọ Dorcas
Nigba to n ba awọn akọroyin sọrọ ni ọjọ Aiku, alaga igbimọ lori ọrọ ibanisọrọ ile aṣofin Eko, Tunde Braimoh ni ''lopin igba ti ofin tawọn ile ba gbe kalẹ ko ba tako ofin Naijria, wọn lẹtọ lati ṣe ofin ti yoo ṣaanfaani fara ilu''
Atupalẹ owo ifẹyinti ati Dukia fawọn Gomina nipinlẹ Eko
Ofin ti ipinlẹ Eko ti wọn fi lọlẹ lọdun 2007 laa kalẹ pe, awọn Gomina tabi igbakeji wọn ti wọn ko ba yọ nipo laanfani lati gba deede owo oṣu wọn gẹgẹ bi owo ifẹhinti eyi to jẹ opọlọpọ miliọnu naira lọdun.
Wọn a tun fun wọn ni ile meji, ọkan ni ilu Eko ati omiran nilu Abuja, bi Gomina naa ba ṣe saa kan, ile kan ṣoṣo ni wọn yoo fun wọn.
Oríṣun àwòrán, Google
Yatọ si awọn ohun ti a ka kalẹ yii, wọn tun n gba ọkọ ayọkẹlẹ mẹfa pẹlu awọn ajẹmọnu miran pẹlu oṣiṣẹ ti yoo ma ba wọn ṣiṣẹ.
Ilera ọfẹ, owo ina ati omi ati awọ ajemọnu bii titun ọkọ ṣe, gbigba alejo ati bẹẹ bẹẹ lọ lo wa nibẹ.
Oríṣun àwòrán, Google
Ilera ọfẹ, owo ina ati omi ati awọ ajemọnu bii titun ọkọ ṣe, gbigba alejo ati bẹẹ bẹẹ lọ lo wa nibẹ.
Gomina mẹrin lo ti jẹ ni ipinlẹ Eko lati igba ti ijọba awarawa ti bẹrẹ. Lateef Jakande, Bola Tinubu, Babatunde Raji Fashola ati Akinwumi Ambode.
Tinubu ati Fashola ṣe saa meji pe perepere, ṣugbọn saa kan ni Jakande ati Ambode ṣe.
Bẹẹ gbogbo ara ilu lo mọ pataki owo ori sisan lati fi gbọ bukata ijọba.
Èyí ni ìtàn bí ẹni tí mó gbọ́njú mọ̀ bíi bàbà ṣe fipá bá mi lájọṣepọ̀
Int'l Anti-Corruption Day: Àwọn kan ní ìwà àjẹbánu ń peléke síi n'íjọba Buhari, àwọn míì ní Buhari ń gbìyànjú
Oríṣun àwòrán, Twitter/Presidency
Àwọn kan ní ìwà àjẹbánu ń peléke síi n'íjọba Buhari, àwọn míì ní Buhari ń gbìyànjú
Oni ni ọjọ Aje, ọjọ kẹsan an, oṣu kejila, ọdun 2019 to jẹ ayajọ igbogun ti iwa ibajẹ ati iwa ajẹbanu kaakiri agbaye.
Ọkan gboogi lara ileri ti Aarẹ Muhammadu Buhari ṣe nigba to wọle ipo aarẹ fun saa akọkọ lọdun 2015 ni pe oun yoo gbogun tiwa ajẹbanu ati iwa ibajẹ lorilẹ-ede Naijiria.
Koda, Aarẹ Buhari ṣeleri lati fi ile ẹjọ ti yoo maa ri si ẹjọ iwa ibajẹ ati ajẹbanu nikan silẹ.
Eyi ni agbeyẹwo bi ijọba Aarẹ Buhari ṣe sọ pe wọn ti gbogunti iwa ibajẹ lati ọdun 2015 to ti dori aleefa gẹgẹ bi aarẹ orilẹ-ede Naijiria.
Gomina mẹta ọtọọtọ lo ti dero ẹwọn lori ẹsun ṣiṣe owo ilu kumọkumọ lawọn ipinlẹ ti wọn ti ṣejọba.
Awọn góminà tẹ̀lẹ̀ ri tó tí wọ ẹ́wọ̀n nítori ẹ̀sùn ìkówó jẹ
Ní inú oṣù kọkanlá, ọdun 2018 ní ilé ẹjọ to ga julọ wọ́n ẹ̀wọn ọdun mejila lẹ́yin to jẹ̀bi ẹ̀sun oníkókó mẹtadinlọ́gbọ̀n ti wọ́n si ni ko lọ ẹwọn ọdun mẹ́rìnla.
Joshua jẹ gomina ìpínlẹ̀ Plateau láti ọdun 1999 si ọdun 2007 to si tun di sẹnatọ tó ń sojú ẹkun aarin gbùngbùn Plateau kí ilé ẹjoọ to dájọ pe ó jẹ̀bi ẹsùn ti àjọ EFCC fi kan an.
Ẹsùn àkọkọ ní pé ó dá ìgbékẹ̀lé ti ará ìlú ni síi ti o si yẹ ko lọ si ẹwọn ọdun mẹwàá nígba ti ẹsún keji ni i ṣe pẹ̀lú owó kọngila fún atunse ayika to jẹ mílíọnu kan lé ọwọ mẹfa (1.162bilion), eyi ni ẹwọn ọdun meji, sùgbọ́n mejeeji le lọ pọ̀ lẹ́ẹ̀kan ṣoṣo.
Ẹ̀wẹ̀, ilé ẹjọ́ kòtẹmilọrun ni Ẹwọn ọdun mẹwàá ni o tọ si i fún ẹsun
Ní ti Jolly Iyame ni tirẹ, ajọ EFCC gbe e lọ si ilé ẹjọ ninu oṣù karun un, ọdun 2018 lori ẹsun oni koko mọkanlélógójì fun dídari owo ilú to to bílíọnù kan ati ọwọ́ mẹ́fa (1.64bilion Naira) si akoto míràn láàrin ọdun mẹ́rin to fi jẹ gómínà.
Wọ́n ran an lọ si ẹwọn ọdun mẹrinla lẹ̀yìn ti àwọn adájọ ẹlẹni mẹta èyi ti adajọ Abdul Aboki, pàdà wá dín ìdájọ rẹ̀ kù sí ọdun mejila.
Lẹ̀yìn èyí ni wọ́n ni ki Iyame san ẹẹdẹ́gbẹ̀ta din diẹ̀ mílíọnu naira gẹ́gẹ́ bi owó ìtanran bo tilẹ jẹ́ pé ẹ̀wọ́n ọdun mẹrinla ni wọ́n kọ́kọ́ ni ki ó lọ.
Jolly Iyame jẹ gomina ìpínlẹ̀ Taraba láti ọdun 1999 si ọdun 2007.
Ní ọsẹ to kọja yìí ni ilé ẹjọ pàda ṣedájọ Orji Kalu lori ẹsun ìkowó jẹ ti wọ́n ti EFCC fi kan-an.
Gomina ìpínlẹ̀ Abia tẹlẹ̀ ri ni ilé ẹjọ ni ko lọ fi ẹ̀wọ́n ọdun mẹjila jura nibi ìdájọ ti Justice Mohmmmed Idris dari.
Ilé Iṣẹ Slok ni wọ́n fẹ̀sun kan pe ò n lò lati ko òwó àwọn ènìyàn ìpínlẹ̀ Abia ti wọ́n ti gba lọwọ ìjọba apapọ
Bakan náà ni wọ́n ko olùrànlọ́wọ́ rẹ̀, Jones Ude ti wọ́n jo ń lu owó ìlú ní pònpò to si duro bi alabojuto owó lati lọ sẹ́wọ̀n ọdun marun un.
Kalu lú owo ilú to lé ni bílíọnu meje naira (7.2bilion) ni ponpo.
Pẹtẹsi akọkọ ni Naijiria
Gomina ipinlẹ Kano, Abdullahi Ganduje
Ọpọ fẹsun kan ijọba Buhari pe ko gbe igbesẹ akin lori ọrọ Gomina ipinlẹ Kano, Abdullahi Ganduje lẹyin ti oriṣiiriṣii fidio ṣafihan bi o ṣe n gba riba lọwọ kọngila lu sita layelujara.
Gomina Ganduje loun ko jẹbi ẹsun iwa ajẹbanu, o ni awọn alatako oun fẹ fi fidio naa ba oun lorukọ jẹ ni.
Aarẹ Buhari sọrọ lori ẹsun ti wọn fi kan Ganduje pe, ko mọwọ, ko mẹsẹ ayafi ti ẹri to daju ba wa loku.
Bi ìyàwọ mi ṣe n jábọ́ sí kọ́tà ló jẹ́ kí n kọ́ka fura pé kò ríran mọ́- ọkọ Dorcas
Godswill Akpabio
Ajọ to n gbogun ti iwa ibajẹ ati iwa ajẹbanu, EFCC n ṣawidii lori Gomina ipinlẹ Akwa Ibom tẹlẹ ri, Godswill Akpabio lori ẹṣun pe o dari ọgọrun un biliọnu naira to jẹ owo ipinlẹ naa sapo ara rẹ.
Ṣugbọn Aarẹ Buhari kan lo kii kaabọ sinu ẹgbẹ oṣelu APC funra rẹ, koda, Akpabio wa lara awọn minisita ti Buhari yan sipo nigba to wọle saa keji.
Downsyndrome: Dayo ń wa mótò, ó fẹyawọ, o tún lọ ilú òyìnbó
Rotimi Amaechi
Mnisita igbokegbodo ọkọ ni Naijiria bayii, Rotimi Amaechi to jẹ Gomina ipinlẹ Rivers tẹlẹ ri ni oludari ipolongo ibo fun Aarẹ Buhari nigba to dije fun ipo aarẹ fun saa keji.
Ẹka idajọ ti gbe igbimọ kan dide ti Adajọ George Omeregi jẹ olori wọn lati ṣewadi Amaechi lori ẹsun pe o ṣe owo ipinlẹ naa to to naira mẹtadinlọgọrun un biliọnu kumọkumọ.
Amọ, ẹsun naa ko di Buhari lọwọ lati jẹ ki Amaechi tẹsiwaju gẹgẹ bi minisita.
Ero awọn eeyan ṣọọtọọ loju opo Facebook BBC News Yoruba lori agbeyẹwo igbogun ti iwa ajẹbanu ti ijọba Buhari gunle.
Ọpọ lo ni Aarẹ Buhari n gbiyanju lati gbogun ti iwa ibajẹ ni Naijiria ṣugbọn omi lo pọ ju ọka lọ.
Ìwà ìbàjẹ́ ń peléke síi níjọba Buhari- èrò àwọn èèyàn ṣọ̀ọ̀tọ̀ọ̀
Ṣugbọn awọn eeyan bi Oludare Paul, Saruni Sola gbagbọ pe Buhari n ṣegbe lẹyin awọn eeyan kan ninu eto igbogun ti iwa ajẹbanu to n ṣe.
Awọn kan tiẹ ni o yẹ ki Buhari ti ṣewadi asiwaju Bola Tinubu, Adams Oshiomole atawọn eekan ninu ẹgbẹ oṣelu APC ti wọn ti ṣe ijọba sẹyin.
Oríṣun àwòrán, Joshua Adetunji
Ìwà ìbàjẹ́ ń peléke síi níjọba Buhari- èrò àwọn èèyàn ṣọ̀ọ̀tọ̀ọ̀
Bakan naa lawọn eeyan kan gbagbọ pe igba ajẹbanu n buru si ni lati igba ti Buhari ti gori aleefa gẹgẹ bi aarẹ orilẹede Naijiria lọdun 2015.
Wọn ni ko si ayipada rere kankan to ṣee tọka si ninu eto igbogun ti iwa ibajẹ ti ijọba Aarẹ Buhari ti gun le lati ọdun mẹrin sẹyin.
Ìwà ìbàjẹ́ ń peléke síi níjọba Buhari- èrò àwọn èèyàn ṣọ̀ọ̀tọ̀ọ̀
Bi ìyàwọ mi ṣe n jábọ́ sí kọ́tà ló jẹ́ kí n kọ́ka fura pé kò ríran mọ́- ọkọ Dorcas
Lagos murder: Ọwọ́ ọlapàá tẹ afurasí òṣìṣẹ́ mọ̀nàmọ́ná tó gún tọkọ taya lọ́bẹ ní Ikoyi
Oríṣun àwòrán, Facebook/Bernadett Kurucz
Ọwọ́ ọlapàá tẹ afurasí òṣìṣẹ́ mọ̀nàmọ́ná tó gún tọkọ taya lọ́bẹ ní Ikoyi
Ọwọ ile iṣẹ ọlọpaa ipinlẹ ti tẹ afurasi meji, Ade Akanbi ati Olamide Adegoke ti wọn fẹsun kan pe wọn gun tọkọ taya lọbe nile wọn ni Ikoyi niluu Eko lọjọ Aiku.
Agbẹnusọ fun ile iṣẹ ọlọpaa ipinlẹ Eko, Bala Elkana ṣalaye pe awọn afurasi yii gun ọkunrin kan, Gildas Tohouo to jẹ oludari ile iṣẹ ọja kiko wọle lori omi ati iyawo rẹ lọbẹ, eleyi to mu ki iyawo rẹ dero ọrun.
Ile iṣẹ ọlọpaa ni nibi aago mọkanla aabọ lalẹ tawọn alejo ti lọọle tan, ni iṣẹlẹ ọhun ṣẹlẹ.
Agbẹnusọ fun ile iṣẹ ọlọpaa, Bala Elkana ni awọn ile iṣẹ mọnamọna lo muna lọ, ni oṣiṣẹ ina mọnamọna kan, Olamide Adegoke wa lati ṣe iranwọn fun wọn lori titan ati titun ẹrọ amunawa wọn ṣe.
Kete ti wọn ṣilẹkun fun oṣiṣẹ mọnamọna naa ati ẹni to tẹ le e lo bẹrẹ si ni gun wọn lọbẹ lati le ja wọn lole.
Oríṣun àwòrán, Facebook/Gildas Tohouo
Olamide jẹwọ fawọn ọlọpaa pe oun ti beere owo lọwọ ọkunrin naa ri ṣugbọn o kọ lati fun oun.
Ile iṣẹ ọlọpaa fidi rẹ mulẹ pe ọmọ orilẹ-ede Cameroon ni Ọgbẹni Tohouo nigba ti iyawo rẹ si jẹ ọmọ ilẹ Hungary.
Awọn agbofinro sọ pe awọn afurasi mejeeji ti jẹwọ fawọn ọlọpaa pe awọn lawọn ṣiṣẹ laabi ọhun.
Koda, Ọgbẹni Bala Elkana ni ile iṣẹ ọlọpaa ti ri ọbẹ ti wọn fi ṣiṣẹ laabi ọhun gba, bakan naa ni wọn gba kaadi igbowo (ATM card) ati pọọsi kan ti owo wa ninu rẹ ti wọn ji nile awọn tọkọ taya naa.
Omoyele Sowore: Falana ní ìjọba fẹ́ fẹ̀sùn ìgbésúnmọ̀mí kan Sowore
Oríṣun àwòrán, Instagram/Sahara Reporters
Falana ní ìjọba fẹ́ fẹ̀sùn ìgbésúnmọ̀mí kan Sowore
Gbajugbaja agbẹjẹro ati ajafẹtọ, Femi Falana ti ke gbajare pe ijọba apapọ n gbero lati fi ẹsun igbesunmọmi kan Omoyele Ṣowore to ṣagbatẹru iwọde #RevolutionNow.
Ajọ DSS ti kọkọ fi Ṣowore silẹ lahamọ lọsẹ to lọ lẹyin aṣẹ Adajọ Ijeoma Ojukwu, amọ lẹyin ọjọ kan ni wọn tun fi mu u pada.
Ọpọ lo koro oju si igbesẹ ajọ DSS lori ọrọ Ṣowore, ti wọn si di ẹbi gbogbo ẹ ru ijọba apapọ pe o huwa bi i ijọiba afipa muni sin.
Amọ, oludamọran agba si Aarẹ Muhammadu Buhari, Garba Shehu ni ijọba apapọ kọ lo ran ajọ DSS ni ohun ti wọn n ṣe.
Shehu ni ohun ti Ṣowore ṣe da bi ohun tawọn ẹgbẹ agbesunmọmi Boko Haram n ṣe nitori wọn n da rogbodiyan silẹ lapa ariwa Naijiria loke ọya.
Ninu atẹjade to fi sita lọjọ Aje, agbẹjọro Ṣowore, Falana ṣalaye pe ijọba fẹ fi ẹsun igbesunmọmi kan Ṣowore lẹyin to ti kuna lati fẹsun idoju ijọba bolẹ ati sisọ ọrọ odi kan an.
O ni eyi ko yatọ si ohun ti ijọba ṣe si Nanamdi Kanu ti Ipob iran Igbo.
Sola allyson, olori Ẹmi ni aala gbọdọ wa lori ohun ti awọn ololufẹ̀ olorin lee ṣe si wọn.
Falana ni fifi Ṣowore we Boko Hram tumọ si pe ijọba fẹ fẹsun igbesunmọmi kan Ṣowore.
Bi ìyàwọ mi ṣe n jábọ́ sí kọ́tà ló jẹ́ kí n kọ́ka fura pé kò ríran mọ́- ọkọ Dorcas
Agbẹjọro Falana ṣalaye siwaju sii pe ijọba mọ pe ile ẹjọ ko ni gba oniduro Ṣowore ti wọn ba le fi ẹsun igbesumọmi kan an.
O kepe ijọba pe ko bẹrẹ igbẹjọ lori ọrọ Ṣowore to ba daa loju pe Ṣowore jẹbi awọn ẹsun ti wọn fi kan an ni tootọọ.
Downsyndrome: Dayo ń wa mótò, ó fẹyawọ, o tún lọ ilú òyìnbó
Open Treasury Portal: APC ní ètò tó ń ṣàmójútó ìnáwó ẹ̀ka ìjọba yóò gbógunti ìwà àjẹbánu
Oríṣun àwòrán, @others
APC ní ètò tó ń ṣàmójútó ìnáwó ẹ̀ka ìjọba yóò gbógunti ìwà àjẹbánu
Ijọba apapọ ti ṣe ifilọlẹ apo eto iṣuna (Open Treasury Portal) eleyi ti yoo fun ijọba lanfaani lati maa ṣalaye bi ijọba ṣe n na wo to wọle sapọ ijọba.
Akọwe agba ajọ to n ṣafihan didari awọn ile isẹ (Nigeria Extractive Industries Transparency Initiative, NEITI), Waziri Adio lo fọrọ naa lede loju opo Twitter rẹ.
Oríṣun àwòrán, Twitter/Presidency
APC ní ètò tó ń ṣàmójútó ìnáwó ẹ̀ka ìjọba yóò gbógunti ìwà àjẹbánu
Adio ṣalaye pe Aarẹ Muhammadu Buhari ni lati akoko yii lọ, gbogbo eeyan ati ile iṣẹ ti wọn ba n ṣiṣẹ fun ijọba gbọdọ mọ pe gbogbo eeyan lo lanfaani lati ri bi ijọba ti n sanwo fun wọn.
Aarẹ Buhari rọ gbogbo ijọba ipinlẹ ati ti ibilẹ lati fi ijọba apapọ ṣe awokọṣe pe kawọn naa bẹrẹ iru eto yii.
Ọgbẹni Adio ni o ti di dandan fun gbogbo ẹka ijọba apapọ lati maa ṣe atẹjade bi wọn ṣe n sanwo sita lojoojumọ bẹrẹ lati miliọnu marun un lọ soke.
Bakan naa, wọn ni lati maa ṣe agbejade eto inawo wọn loṣooṣu ati gbogbo nnkan miiran ti wọn ba ṣe.
Adio fikun ọrọ rẹ pe ọga agba oluṣiro owo ni Naijiria naa gbọdọ maa ṣe atẹjade bi owo ṣe n wọle si apo ijọba ati bi owo ṣe n jade lojoojumọ.
Ẹwẹ, ẹgbẹ oṣelu APC ti gboṣuba kare fun Aarẹ Buhari lori agbekalẹ eto ti yoo maa ṣamojuto bi owo ti n wọle ati bi owo ti n jade lapo ijọba.
Silas Robotic Engineer: Kò sí ǹkan rere tí ọmọ Nàìjíríà kò lè ṣe
Ti o ba fẹ mọ iye to n wọle sapo ijọba ati bi wọn ṣe n na owo naa, kan si oju òpó yii:
https://opentreasury.gov.ng/
Alukoro fẹgbẹ oṣelu naa, Lanre Issa-Onilu sọ pe eto naa yoo gbogun ti iwa ajẹbanu lawọn ile iṣẹ ijọba.
Aàrẹ Buhari yẹ́ aga nidi Muiz Banire,ó yan Edward Adamu lalága AMCON
Oríṣun àwòrán, Muiz Banire
Aàrẹ Buhari yẹ́ aga nidi Muiz Banire,ó yan Edward Adamu lalága AMCON
Lẹyin ọdun kan le diẹ nipo Aarẹ Buhari ti juwe ọna ile fun Muiz Banire to jẹ alaga ileeṣẹ to n ṣe onidurọ fawọn ile ifowopamọ ni Naijiria (AMCON)
Lọsan ọjọ Iṣẹgun ni ikede yi lu sita ninu iwe kan ti ileeṣẹ aarẹ fi ranṣẹ si aarẹ ile aṣofin agba Naijiria.
Ọgbẹni Edward Adamu ni aarẹ fi orukọ rẹ ranṣẹ gẹgẹ bi ẹni ti yoo gba ipo Muiz Banire.
A ko ti i ribi fidiẹ mulẹ idi ti aarẹ fi gbe igbesẹ yi ṣugbọn Banire ko tii pẹ pupọ lori oye naa.
Koda nigba ti aarẹ Buhari fi orukọ rẹ ranṣẹ si ile aṣofin agba, awọn oloṣelu kan ninu ẹgbẹ APC dide lati tako iyansipo rẹ.
Ṣaaju ki o to jẹ alaga AMCON, Banire ni kọmiṣọnna fun eto ayika nipinlẹ Eko ti o si tun fi igba kan jẹ oludamọran lori ọrọ ofin fun ẹgbẹ oṣelu APC.
Yatọ si Banire ti aarẹ gba iṣẹ lọwọ rẹ, Tunde Fowler ti ohun naa jẹ ọkan lara awọn wọlewọde fun igbakeji aarẹ Yemi Osinbajo naa ni aarẹ kọ lati yan sipo pada lẹyin saa rẹ gẹgẹ bi ọga agba FIRSAàrẹ Buhari júwe ilé fún Babatunde Fowler, ó yan Muhammed Nami .
Silas Robotic Engineer: Kò sí ǹkan rere tí ọmọ Nàìjíríà kò lè ṣe
Àwọn abiyamọ fẹ́ kí gómìnà Ondo dásí ọ̀rọ̀ ọmọ ọdún kan tó di àwátì l'Akure
O ti le ni oṣu kan bayii ti ọmọ kekere jojolo kan ,Gold Kolawole, dédé di awati ni ile ijọsin kan ti a mọ si Sotitobire prayer centre, ni ilu Akure.
Gbogbo igbiyanju obi ọmọ naa lati ri lo jasi pabo ti awọn agbofinro ko si ti sọ nkankna bayi nipa ibi ti ọmọ naa wọlẹ si.
Idi eyi lo mu ki agbarijọpọ awọn obinrin kan ni ilu Akure ṣe iwọde lọjọ Iṣẹgun tii ṣe ọjọ Kẹwa oṣu Kejila ọdun 2019.
Awọn obinrin naa ni awọn fi ẹhonu han latari ai kara maasiki awọn Ọlọpa lori ọrọ naa.
Wọn benu ate lu ileeṣẹ  ọlọpaa lori bi won ṣe fọwọ yẹpẹrẹ mu ọrọ naa ti ko si ẹni kan pato ti wọn fi panpe ọba mu lati bi Oṣu kan sẹyin.Jumoke Aborode to je adari àti alaga Àjọ National Council of women Society of Nigeria, tí ẹka Ondo ni o lewaju awọn obinrin naa.
Ninu ọrọ rẹ pẹlu awọn oniroyin, o sọ pe ara abiyamọ lo ta awọn ti o mu ki awọn jade pẹlu iya ọmọ naa ki awọn agbofinro bvaa le wa wọrọkọ fi ṣada lori ọrọ yi.
Ohun to de ba iya Gold, o de ba gbogbo abiyamọ tootọ. Ẹ jọwọ ibikibi  ti Kolawole Gold ba wa, ẹ bawa wa sita''
O rọ Gomina ipinlẹ Ondo ati awọn lọbalọba lati da si ọrọ ọmọọdun kan to sọnu yi.
Kano Chained Man: Ìdáǹdé dé fún bàbá táwọn ẹbí rẹ so mọlẹ fun ọgbọn ọdun
Oríṣun àwòrán, Human Rights Network
Ni ilu Kano lẹẹkan si, itura ti de ba baba ẹni ọdun marundinlọgọta kan, ti wọn fi ẹwọn so mọlẹ fun ọgbọn ọdun.
Gẹgẹ bi ajafẹtọ ilu kan, Shuaibu Sani ti fidi rẹ mulẹ fun BBC, awọn ọlọpaa lo tu ọkunrin naa silẹ, ẹni ti awọn ẹbi rẹ so mọlẹ lori ẹsun pe o ni arun ọpọlọ.
"Shuaibu ni ""Iya jẹ ọkunrin naa fun ọpọlọpọ ọdun, ti wsn so so mọ ara igi pẹlu irin ninu yara kan ti ko ni ilẹkun tabi ferese."""
O ni bi oun se gbọ nipa igbesẹ tawọn ọlọpaa n gbe lati doola ọkunrin naa, ni oun dara pọ mọ wọn lati wa itura fun ninu ile kan to wa nilu Rogo.
Oríṣun àwòrán, Human Rights Network
Wọn lo ni arun ọpọlọ, to si n huwa ipa amọ dipo ki baba rẹ lọ tọju rẹ lati ọdun 1990, se lo pinnu lati ti ọmọ rẹ mọle.
"Shuaibu tẹsiwaju pe ""nigba ti baba rẹ ku lọdun diẹ sẹyin, awọn aburo rẹ ọkunrin meji tun tẹsiwaju lati maa tii mọle sugbọn loni, o ti gba ominira."
"Koda, awọn aladugbo wọn gan mọ nipa isẹlẹ naa, ti wọn si dide lati ran ọkunrin naa lọwọ."""
Rape cases in Nigeria: Ọmọ ọdun 5 àti 14 ni Kalu wà nígbà tí obìnrin fipá ba lòpọ̀
Lọwọlọwọ bayii, o ni ọkunrin naa ti wa nile iwosan ijọba to wa nilu Rodo, nibi to ti n gba itọju, tawọn ọlọpaa si n fi ọrọ wa awọn aburo rẹ lẹnu wo.
Agbẹnusọ fun ileesẹ ọlọpaa nilu Kano, abdullahi Haruna naa fidi idoola ẹmi yii mulẹ fun BBC, to si ni iwadi n lọ lọwọ.
O ni igba kẹta ree tileesẹ ọlspaa ipinlẹ Kano yoo gunle eto idoola ẹmi fun awọn eeyan ti wọn so mọlẹ fun ọjọ pipẹ bii iru eyi.
Yan Daudu lorukọ ti wọn p e awọn ọkunrin to n mura bi ọkunrin ni ilẹ Hausa
Ọwọ ọlọpaa Ṣẹria ti wọn pe ni 'Hisbah Police' ti tẹ awọn ọkunrin mẹrindinlọgbọn kan ti wọn mura bi obinrin ni ilu Kano.
'Yan Daudu' lorukọ tawọn eeyan ma n pe iru awọn ọkunrin bẹẹ ni ilẹ ariwa.
Igbakeji ọga awọn ọlọpaa Sharia ni Kano, Mallam Tasiu sọ pe ọwọ tẹ awọn ọkunrin naa nibi apejẹ ọjọ ibi ọkan ninu wọn ladugbo Badawa ni ilu Kano.
O ṣalaye pe ''Iroyin to tẹ wa lọwọ pe wọn ṣe apejẹ ọjọ ibi ọkan lara wọn lo mu ki awọn eeyan wa tara ṣaṣa lọ si bẹ.
Ohun adojuti ni ki awọn ọkunrin maa hu iru iwa ka maa mura bi obinrin''
"Tasiu fi kun un pe ""Awọn yoo fi wọn si ahamọ titi tawọn obi wn yoo fi yọju siwa. A ti ṣe iwaasu fun wọn ti a si ti parọwa si wọn lati maa kirun.Ti awọn obi wọn ba de, a o tu wọn silẹ''"
Ọkan lara awọn ti wọn mu ṣugbọn ti ko fẹ sọ orukọ rẹ fakọroyin sọ pe ọrẹ oun lo pe oun wa si ibi apejẹ naa ki ọwọ palaba awọn to ṣegi.
"Ọlọjọ ibi kii ṣe ọrẹ mi, ọrẹ mi lo ni ki n sin oun kalọ. Bi mo ba mọ pe iru nkan ti yoo ṣẹlẹ re e, mi o ba ma yọju. Kete ti ẹni to n ṣe ọjọ ibi ri awọn ọlọpaa Hisbah lo fo iganna salọ''
O tun sọ pe ''wọn ti ṣe waasi fun wa, a si ti ki irun Rakaah ogoji lati igba ti wọn ti mu wa. Mo kabamọ ohun to ṣẹlẹ .Mi o si ni ṣe bẹẹ mọ pẹlu ogo Ọlọrun''
MK Adam to jẹ agbẹnusọ awọn ajafẹtọmọniyan ni Kano sọ pe lopin igba tawọn ọkunrin ti wọn mu yi ti tasẹ agẹrẹ sofin, awọn ko le ṣe iranwọ kankan fun wọn.
Awujọ kọọkan ni o ni ofin ti rẹ. Tohun ti pe awọn ọmọ iya wa lawọn ti Hisbah mu yi, ofin Kano lodi si iwa ti wọn hu yi."
Arọwa mi si wọn ni ki ijọba wa ọna lati ṣayipada wọn ki wọn baa le di eeyan daada lawujọ''
Lati ọdun 2001 ni ofin Sharia ti fẹsẹ rinlẹ ni Kano ti awọn ọlọpaa Hisbah si ni agbara lati mu awọn to ba ṣe ohun to tako ofin Islam.
Akure Kidnap: Àwọn abiyamọ fẹ̀hónúhàn lórí ọmọ tí wan jígbé nílé ìjọsìn Akurẹ
Ayo Fayose: Gómìnà àná ìpínlẹ̀ Ekiti tọrọ àforíjìn, ó ní PDP gbọdọ̀ gbapò gómìnà padà
Oríṣun àwòrán, Twitter/Peter Ayodele Fayose
Gómìnà àná ìpínlẹ̀ Ekiti tọrọ àforíjìn, ó ní PDP gbọdọ̀ gbapò gómìnà padà
A kii rin, ki ori maa ma mi.  Eyi lo difa fun gomina ipinlẹ Ekiti tẹlẹ ri, Ayodele Fayoṣe to tọrọ aforijin lọwọ gbogbo awọn ọmọ ẹgbẹ oṣelu PDP nipinlẹ naa.
Fayoṣe sọrọ yii nibi ipade ibara ẹni laja laarin awọn olori atawọn eekan inu ẹgbẹ PDP to waye nile rẹ ni Afao Ekiti lọjọ Iṣẹgun.
Sẹnẹtọ Biodun Olujimi, Duro Faṣeyi to jẹ ọmọ ile igbimọ aṣofin l'Abuja tẹlẹ ati alaga ẹgbẹ PDP nipinlẹ Ekiti, Oloye Gboyega Oguntuwase ti wọn jẹ adari ẹgbẹ naa ni iyapa wa laarin awọn.
Fayoṣe ni ''ẹgbẹ oṣelu PDP nipinlẹ Ekiti nilo atunṣe lọna ti yoo mu ilọsiwaju ba ẹgbẹ wa, ohun to ku fun wa bayii ni lati fọwọsowọpọ lati gbe PDP ga lẹẹkan si l'Ekiti.''
Akure Kidnap: Àwọn abiyamọ fẹ̀hónúhàn lórí ọmọ tí wan jígbé nílé ìjọsìn Akurẹ
''Mi o dije fun ipo kankan mọ, amọ mo fẹ ki PDP jawe olubori ninu ibo gomina pada l'Ekiti. Ojuṣe mi si ni pe ki ẹgbẹ PDP maa kuna nipinlẹ Ekiti,'' Fayoṣe lo woye bẹẹ.
Fayoṣe lo anfaani ipade naa lati bẹ Sẹnẹtọ Olujimi, Faṣeyi ati Oloye Oguntunwaṣe wi pe ki wọn forijin oun ti oun ba ṣẹ wọn.
O ni oun ko figba kankan gbero lati ba awọn olori ẹgbẹ PDP ja, bakan naa lo sọ pe awọn to n mu iyapa wa ẹgbẹ naa n ṣe e fun anfaani ara wọn ni.
Igbakeji Gomina ipinlẹ Ekiti tẹlẹ, Ọjọgbọn Kolapo Olusola, Kọmiṣọnna fun ọrọ ayika tẹlẹ, Oloye Bisi Kolawole ati ọmọ ile igbimọ aṣofin ipinlẹ Ekiti tẹlẹ, Samuel Omotoṣo atawọn mii lo wa nibi ipade naa.
Bi ìyàwọ mi ṣe n jábọ́ sí kọ́tà ló jẹ́ kí n kọ́ka fura pé kò ríran mọ́- ọkọ Dorcas
Kogi murder: Àwọn agbébọn ṣekúpa akẹ́kọ̀ọ́ tó wà nípele àṣekágbá ní fásítì Kogi
Oríṣun àwòrán, Twitter/Kogi State University
Àwọn agbébọn ṣekúpa akẹ́kọ̀ọ́ tó wà nípele àṣekágbá ní fásítì Kogi
Awọn agbebọn ti sẹkupa akẹkọọ fasiti ipinlẹ Kogi kan, Apey Joseph niluu Ayingba.
Ile iṣẹ ọlọpaa nipinlẹ naa ṣalaye pe ipele aṣekagba ni akẹkọọ naa wa lẹka ẹkọ ede Gẹẹsi, ati pe afurasi ọmọ ẹgbẹ okunkun ni.
Agbẹnusọ fun ile iṣẹ ọlọpaa, DSP William Aya fidi rẹ mulẹ pe, akẹkọọ ọhun lo ṣagbatẹru iṣẹlẹ iṣekupani to waye loṣu to lọ ninu ọgba ile iwe naa.
Ile iṣẹ ni ọkan lara awọn ẹṣọ ile iwe naa, Onuche Jibrin lo ta ile iṣẹ ọlọpaa lolobo pe awọn agbebọn meji ti wọn gun ọkada wọ ile iwe naa ti ṣekupa akẹkọọ kan.
Lati ibẹ ni wọn ti gbe akẹkọọ naa digbadigba lọ si ile ẹkọ iwosan fasiti ọhun, ṣugbọn ọwọ ti bọ sori ki wọn to gbe de bẹ.
Agbẹnusọ ile iṣẹ ọlọpaa tun fidi rẹ mulẹ pe wọn ti gbe oku akẹkọọ naa lọ si ile igbokusi fun ayẹwo.
Bi ìyàwọ mi ṣe n jábọ́ sí kọ́tà ló jẹ́ kí n kọ́ka fura pé kò ríran mọ́- ọkọ Dorcas
New Muhammadu Buhari: Ọkùnrin kan ní Kano ṣ'ayẹyẹ ìsọmọlórúkọ lẹ́yìn tó yí orúkọ padà sí Buhari
Oríṣun àwòrán, Twitter/Naijassador
Ọkùnrin kan ní Kano ṣ'ayẹyẹ ìsọmọlórúkọ lẹ́yìn tó yí orúkọ padà sí Buhari
Bo ba ti wu ni laa ti ṣe igbagbọ ẹni.
Ọkunrin kan niluu Kano lo yii orukọ ara rẹ pada si orukọ aarẹ ọrilẹ-ede Naijiria, Muhammadu Buhari.
Ọkunrin naa to jẹ ẹni ọdun mejidinlogoji tilẹ ṣe ayẹyẹ ikomọjade ọtun lati dawọọ idunnu yi yi orukọ rẹ si Muhammadu Buhari.
Oriṣiiriṣii aworan lati ibi ayẹyẹ isọlmọlorukọ ni ọpọlọpọ eeyan ti gbe soju opo ayelujara.
Iroyin to tẹ wa lọwọ fidi rẹ mulẹ pe lopopona to lọ si ọgba iko ẹranko si ni ayẹyẹ naa ti waye ni Zoo road ni olu ilu Kano.
Okunrin naa fiwe pe Aarẹ Buhari ati gomina Abdulahi Ganduje sibi ayẹyẹ isọmọlorukọ naa.
Oríṣun àwòrán, Twitter/Abdulla
Ọkùnrin kan ní Kano ṣ'ayẹyẹ ìsọmọlórúkọ lẹ́yìn tó yí orúkọ padà sí Buhari
Oríṣun àwòrán, Twitter/Informationng
Ọkùnrin kan ní Kano ṣ'ayẹyẹ ìsọmọlórúkọ lẹ́yìn tó yí orúkọ padà sí Buhari
Koda ọkunrin naa pa ẹran agbo lati fi dawọọ isọlmọlorukọ ara rẹ gẹgẹ ilana eṣin musulumi.
Oríṣun àwòrán, Twitter/Officialpetestack
Ọkùnrin kan ní Kano ṣ'ayẹyẹ ìsọmọlórúkọ lẹ́yìn tó yí orúkọ padà sí Buhari
Eleyi le jẹ iyalẹnu fun ọpọ eeyan, paapaa lasiko ti awọn eniyan n sọrọ lori aibọwọ fun ofin ile ẹjọ ti wọn ni pe o wọpọ lasiko aarẹ Buhari yii.
Bẹẹ, awọn eniyan ilu Kano ni ko ri bẹẹ lọdọ ti wọn nitori pe awọn ara ipinlẹ naa tu yaaya tu yaaya dibo fun Aarẹ Buhari ninu idibo gbogbogbo ọdun 2015 ati 2019.
Silas Robotic Engineer: Kò sí ǹkan rere tí ọmọ Nàìjíríà kò lè ṣe
Uber and Bolt airport ban: Àjọ FAAN sọ pé òun kò fi òfin dé wọ́n
Oríṣun àwòrán, Twitter
Àjọ FAAN sọ pé òun kò mọ bí pátákó ìkìlọ̀ naa ṣe dé ibi tó wà.
Àjọ to n mojuto awọn papakọ ofurufu ni Naijiria, FAAN, ti kede pe irọ ni iroyin to sọ pe oun ti fi ofin de awọn oni takisi igbalode Uber ati Bolt lati ma a gbe ero ni awọn papakọ ofurufu.
Olori ẹka ibanisọrọ nileeṣẹ ajọ FAAN, Henrietta Yakubu, sọ fun BBC pe kii ṣe lati ọdọ ajọ naa ni ikede to n lọ lori ayelujara ti wa.
Yakubu sọ eyi lẹyin ti iroyin ti tàn kaakiri pẹlu aworan kan to ṣafihan rẹ pe ajọ naa ti fi ofin de awọn takisi igbalode ọhun.
Gẹgẹ bi o ṣe sọ, Arabinrin Yakubu sọ wi pe, awọn onitakisi to ti wa tẹlẹ ni papakọ ofurufu ni ẹru n ba pe ki awọn takisi igbalode naa ma gba iṣẹ lọwọ wọn.
Silas Robotic Engineer: Kò sí ǹkan rere tí ọmọ Nàìjíríà kò lè ṣe
Eyi lo si mu ki wọn o gbe patako ikede kan sita ni papakọ ofurufu ilu Calabar, nipinlẹ Cross River, pe ẹgbẹrun mẹwaa Naira ni onitakisi Uber tabi Bolt to ba gbe eero ni papakọ ofurufu naa yoo san, lai jẹ ki ajọ naa o mọ si i.
Awọn eniyan ni ẹtọ lati lo takisi to ba wu wọn lai si ibẹru.
Bakan naa ni ajọ FAAN sọ lori ayelujara pe oun ti gbe patako ikede naa kuro.
Amọ ṣa, ko to o di pe ajọ FAAN sọ eero rẹ lori ọrọ naa ni awọn ọmọ Naijiria kan ti n sọrọ tako 'igbesẹ aja naa'.
Akure Kidnap: Àwọn abiyamọ fẹ̀hónúhàn lórí ọmọ tí wan jígbé nílé ìjọsìn Akurẹ
"Ninu ọrọ ti ẹ naa, Ọga ni ẹka ibanisọrọ ileeṣẹ Uber West Africa, Efosa Aiyevbomwan sọ fun BBC pe ""Uber yoo tẹsiwaju lati maa ṣiṣẹ pọ pẹlu awọn to ba yẹ lasiko."
"O ni Uber a ri i daju pe awọn ko ru ofin kankan, ati lati ṣi ilẹkun anfaani fun awọn to ni ọkọ, awọn awakọ, to fi mọ awọn to n wọ awọn takisi naa."""
Silas Robotic Engineer: Kò sí ǹkan rere tí ọmọ Nàìjíríà kò lè ṣe
Àjọ FRSC, NYSC, kìlọ̀ fún àwọn àgùnbánirọ̀ lórí ìrìnàjò òpin ọdún.
Oríṣun àwòrán, @officialnyscng
Àjọ FRSC, NYSC, kìlọ̀ fún àwọn àgùnbánirọ̀ lórí ìrìnàjò òpin ọdún
Ọga agba ajọ alaabo loju popo ni Naijiria, Boboye Oyeyemi ti rọ awọn agunbanirọ lati ma wọ ọkọ sọọlẹ lasiko ọdun.
Bakan naa lo kilọ fun awọn ọmọ ẹgbẹ awakọ eero pe wọn ko gbọdọ gbe agunbanirọ kankan mọ lati aago mẹfa irọlẹ lasiko ọdun.
Boboye fi ikilọ naa sita nibi ipade opin ọdun ti ajọ naa ṣe pẹlu awọn olori ẹgbẹ awakọ eero nilu Abuja lọjọ Iṣẹgun.
Gẹgẹ bi ajọ akoroyin jọ orilẹ-ede Naijiria ṣe sọ, Boboye sọ pe awakọ ti ọwọ ba tẹ pe o fi ọkọ rẹ gbe agunbanirọ kankan lẹyin aago mẹfa irọlẹ yoo jẹ iya to pọ.
Bi ìyàwọ mi ṣe n jábọ́ sí kọ́tà ló jẹ́ kí n kọ́ka fura pé kò ríran mọ́- ọkọ Dorcas
Boboye ni igbesẹ yi n waye nitori pe aabo ẹmi awọn agunbanirọ naa jẹ ajọ FRSC l'ogun, ati paapa lati dena awọn ijamba opin ọdun jakejado orilẹ-ede Naijiria.
Bakan naa ni Oludari-agba fun ajọ isinru ilu, NYSC, Ọgagun Shuaibu Ibrahim kilọ fun awọn agunbanirọ lati ma wọ ọkọ tabi rinrinajo l'alẹ nitori ọwọn owo ọkọ lasiko ọdun Keresi ati Ọdun titun.
FUTA: Àwọn mẹ́jọ ló ṣíná ìyà fún Bolu ní FUTA
Ẹwẹ, Akọwe Gbogboogbo fun ẹgbẹ awọn to n gba awakọ siṣẹ ni Naijiria, Ọgbẹni Yusuf Adeniyi, sọ pe wọn yoo fi to awọn awakọ leti lati din owo skọ ku fun awsn agunbanirọ to ba n rinrinajo lasiko ọdun.
Silas Robotic Engineer: Kò sí ǹkan rere tí ọmọ Nàìjíríà kò lè ṣe
Punch Newspapaer: Ìjọba Nàìjíríà ní kò burú tí ẹ bá pe Ààrẹ Buhari ni 'Major General'
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ìjọba Nàìjíríà ní kò burú tí ẹ bá pe Ààrẹ Buhari ni 'Major General'
Ileesẹ Aarẹ orilẹ-ede Naijiria ti fesi pe ko si nkan to buru nibẹ ti ẹnikẹni ba pe aarẹ Buhari ni Ọgagun, nitori pe o ṣiṣẹ gba oye naa ni.
Ileeṣẹ aarẹ sọ eyi lẹyin ti ileeṣẹ iwe iroyin Punch kede sita pe lati asiko yi lọ, Ọgagun dipo aarẹ alagbada ni oun yoo maa pe aarẹ Buhari, gẹgẹ bi ọna lati fi ibinu han lori iru iṣejọba to n ṣe.
Olubadamọran pataki fun Aarẹ Muhammadu Buhari lori eto iroyin ati ipolongo, Femi Adesina lo sọ loju opo Twitter pe kii ṣe nkan to buru ni ti ẹnikẹni ba pinnu lati pe aarẹ ni Ọgagun.
Iwe iroyin naa fi ikede yii sita ni oju ewe akọkọ iwe iroyin rẹ, nibi to ti tọka si awọn ọrọ bi fifi ti ijọba fi Omoyele Sowore si atimọle, ati awọn ọrọ miran.
"Ninu ikede ti Adesina fi sita, o sọ pe:""Iwe iroyin kan sọ pe oun yoo bẹrẹ si ni i fi orukọ ipo ọgagun ti Buhari ni gẹgẹ bi ọmọ ogun pe e."
"Ko s'ohun to buru nibẹ. Iṣẹ takun-takun ni aarẹ ṣe ko to o gba oye Ọgagun ko to o fẹhinti.
Bakan naa si ni ofin orilẹ-ede Naijiria pe ipo aarẹ alagbada to wa gẹgẹ bi Apaṣẹ Agba fun awọn ọmọ ogun.
Adesina sọ pe pipe aarẹ ni Ọgagun jẹ ẹri pe ijọba fi aaye silẹ fun ominira awọn oniroyin."
"Bakan naa, amugbalẹgbẹ pataki fun aarẹ lori eto iroyin igbalode, Bashir Ahmed naa sọ lori Twitter pe ""titi lai ni oye Ọgagun yoo maa wa lara orukọ aarẹ."""
Akure Kidnap: Àwọn abiyamọ fẹ̀hónúhàn lórí ọmọ tí wan jígbé nílé ìjọsìn Akurẹ
Ati wi pe ara ọna lati pọn aarẹ le ni orukọ naa.
Koda, o fi kun un pe orukọ naa ko yi i pada pe Muhammadu Buhari ni aarẹ Naijiria titi di ọdun 2023.
Silas Robotic Engineer: Kò sí ǹkan rere tí ọmọ Nàìjíríà kò lè ṣe
Kìnìhún fa èèyàn kan ya ní Nairobi, àdúgbò dàrú
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Kìnìhún fa èèyàn kan ya ní Nairobi, àdúgbò dàrú
Lati inu ọgba ẹranko ni guusu Nairobi to jẹ olu ilu orilẹ-ede Kenya ni Kinihun naa ti jade sita.
Bo ṣe jade naa ni ọkunrin kan to n lọ si igboro ni guusu Nairobi ṣe kongẹ rẹ to si fa a ya pẹrẹpẹrẹ.
Ko pẹ ti wọn doola ẹmi arakunrin yi ti wọn gbe e de ile iwosan tan lo jẹ Ọlọrun nipe.
Arakunrin naa ku lataari awọn ipalara to ri lẹyin to jabọ lẹnu kinhun na.
Ijọba Kenya ni iru iṣẹlẹ bayii ko wọpọ pe ki ẹranko sa jade lati inu ọgba ti wọn fi si wa maa ṣe ara ilu leṣe ni igboro.
Ijọba nipe o san kawọn eniyan gbe ile wọn dipo ki wọn maa sa kiri pẹlu ibẹrubojo lọ lasiko yii.
Ó di dandan kí ará India yìí sọ ìdí tó fi ń sìn kìnìhún- Egbeyemi
Ṣugbọn awọn akọṣẹmọṣẹ ni ọpọ igba ti ẹranko ba sa kuro ni ibugbe rẹ bayii le jẹ nitori pe nkan kan bii ninu.
Tabi pe wọn paarọ tabi mu ayipada ba nkankan ni agbegbe ẹranko naa ni. bii ki wọn yaa sọtọ tabi ki wọn gbe awọn ẹranko mii kuro lẹgbẹẹ rẹ.
Wọn ti kilọ fawọn ara ilu lati ṣọra bi wọn ṣe n rin nigboro.
Ati pe to ba ṣẹeṣe ni ẹkun guusu yii ki awọn eniyan duro sile wọn titi ijọba a fi ri kinihun naa.
Akure Kidnap: Àwọn abiyamọ fẹ̀hónúhàn lórí ọmọ tí wan jígbé nílé ìjọsìn Akurẹ
Aisha Buhari tutọ sókè fojú gbà à, ó ní kí Garba Sheu kọ́we fipolẹ́
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Aisha Buhari tutọ sókè fojú gbà à, ó ní kí Garba Sheu kọ́we fipolẹ́
Orukọ iyawo aarẹ orile-ede Naijiria, Aisha Buhari lawọn eeyan n lọgun tantan loju opo Twitter lataari ọrọ to sọ pe ki agbẹnusọ aarẹ Buhari Garba Sheu kọwe fipo silẹ.
Ninu ọrọ ti Aisha Buhari sọ ninu atẹjade kan loju opo Twitter rẹ, o ni Garba Sheu ti gba abọde ti o si tọ ki o kọwe fiposilẹ.
Aisha Buhari sọ pe nkan ti wọn ni ki ẹlẹmọṣọ Garba Sheu sọ kọ ni o gbaju mọ ti o si yapa adehun to ṣe lati ba aarẹ Naijiria ṣiṣẹ tọkantọkan.
Yatọ si ẹsun yi, Aisha Buhari tun fi awọn ẹsun miran kan Garba Sheu ṣugbọn koko nkan to jẹ yọ ni pe Garba Sheu nikan kọ ni Aisha n sọko ọrọ ba.
Ninu atẹjade naa o sọ pe:
Akure Kidnap: Àwọn abiyamọ fẹ̀hónúhàn lórí ọmọ tí wan jígbé nílé ìjọsìn Akurẹ
Ọkùnrin tó yí orúkọ padà sí Muhammadu Buhari ṣ'ayẹyẹ ìsọmọlórúkọ ní Kano
Kìnìhún fa èèyàn kan ya ní Nairobi, àdúgbò dàrú
Má ṣe fi ọkọ̀ rẹ gbé àgùnbánirọ̀ lẹ́yìn aago mẹ́fà ìrọ̀lẹ́- FRSC
Àwọn agbébọn ṣekúpa akẹ́kọ̀ọ́ tó wà nípele àṣekágbá ní fásítì Kogi
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí:
Ileeṣẹ iroyin BBC  Hausa gbiyanju lati ba Garba Sheu sọrọ lori nkan ti iyawo aarẹ sọ ṣugbọn ko gbe ipe rẹ.
Ni kete ti a ba ti ri esi tirẹ gba lori ọrọ yi la o fi to yin leti.
Lẹnu lọọlọ yi, ǹkan ko ṣẹnu re laarin iyawo Aarẹ Naijiria atiwọn kan to n naka si pe wọn ko jẹ ki aarẹ ṣe ijọba fun ra rẹ.
Google Top Search 2019: Naira Marley na Atiku pa nínú àwọn orúkọ tàwọn èèyàn ń wá jùlọ ní 2019
Oríṣun àwòrán, Instagram/nairamarley
Orukọ Naira Marley gbode kan lọdun yii lẹyin ti ajọ EFCC fi pampẹ ofin mu lori ẹsun jibiti
Ileeṣẹ atẹ imọ oju opo ayelujara Google ti ṣe agbejade orukọ ati awọn nkan tawọn eeyan n wa iroyin nipa rẹ  julo loju opo rẹ fọdun 2019.
Wọn sọ nipa awọn nkan to ni ṣe pẹlu ibeere, awọn gbajugbaja eeyan, olorin, ere fiimu ati iroyin tawọn eeyan n wa nipa rẹ.
Ni isọri isọri, ni wọn ṣe agbekalẹ yi ṣugbọn eleyi to kan wa ni Naijiria la ni ki a ṣe atupalẹ rẹ fun ara wa.
Oríṣun àwòrán, OTHER
Gbajugbaja olorin Naijiria Afeez Fashola ti gbogbo eeyan mọ si Naira Marley ni orukọ rẹ leke ninu orukọ awọn ilumọọka ni Naijria tawọn eeyan n bere ọrọ nipa wọn.
Atiku Abubakar to du ipo aarẹ ninu idibo aarẹ Naijiria lọdun 2019  naa tẹlẹ ti  agbabọọlu nii Neymar ati  alaga awọn awakọ ipinlẹ Eko, MC Oluomo naa ko gbẹyin.
Oríṣun àwòrán, Instagram/mcoluomo
Ni abala ibeere nipa iroyin, iyanṣẹlodi awọn olukọ fasiti Naijiria ti o gbẹnu tolori tẹlẹmu wa lara awọn iroyin tawọn eeyan bere nipa rẹ julọ ni 2019 ni Naijiria.
Idije bọọlu afẹsẹgba ilẹ adulawọ AFCON 2019 naa wa lara awọn to lewaju ti Naira Marley tun ja wọ abala yi to fi mọ ibeere nipa  Women's World Cup 2019 ati Xenophobia.
Oríṣun àwòrán, GIUSEPPE CACACE
Ẹni a ba laba ni baba
Labala awọn olorin ti awọn eeyan n wadi iroyin nipa wọn julọ ni Naijiria lọdun 2019, Zlatan, Burna Boy,Naira Marley,Teni ati Kizz Daniel wa lara wọn.
Ninu awọn kan  miran tawọn eeyan nwadi loju opo Google la ti ri :
Lọdọọdun ni ile iṣẹ Google ma n gbe orukọ ati awọn ọrọ tawọn eeyan n bere nipa rẹ julọ  loju opo rẹ jade .
Naira Marley: Wo àwọn ìṣẹ̀lẹ̀ tó mú Naira Marley di òrìṣà àkúnlẹ̀bọ lọ́dún 2019
Oríṣun àwòrán, NAira Marley/ instagram
Azeez Fashola ti ọpọ mọ si Naira Marley jẹ gbajugbaja akọrin taka sufe lorilẹede Naijiria.
Lọwọ ti a wa yii, Naira Marley ti fẹ di oriṣa akunlẹbọ fun ọpọlọpọ awọn ọdọ.
Akure Kidnap: Àwọn abiyamọ fẹ̀hónúhàn lórí ọmọ tí wan jígbé nílé ìjọsìn Akurẹ
Bẹẹni pẹlu iroyin ti o jadi laipẹ yii, oun ni ọmọ orilẹede Naijiria ti awọn eeyan ṣe afẹri rẹ juls lori oju opo google lọdun 2019. Koda, igbakeji aarẹ tẹlẹ Atiku Abubakar pẹlu gbajugbaja agbabọọlu ni Neymar ko lee duro lẹgbẹ rẹ.
Eyi ni awọn diẹ lara iṣẹlẹ to sọ gbajugbaja akọrin naa di oriṣa akunlẹbọ lọdun 2019.
Oríṣun àwòrán, NAira marley/instagram
Ni oṣu karun ọdun 2019 ni akọrin ara, Simi pariwo sita lori ikanni ayelujara lati koro oju si bi awọn ọdọ ṣe n kan si agbami iwa jibiti ori ayelujara.
Eyi lo si fa itahunsira laarin oun ati Naira Marley.
Kii ṣe Simi nikan ni Naira Marley ba wọ iya ija lori ọrọ boya jibiti ori ayelujara, yahooyahoo tọna paapaa julọ lẹyin orin 'Am I a yahoo boy?' to gbe sita. Ọkan lara awọn odu asọrọdorin lorilẹede Naijiria, Ruggedman pẹlu sọ si ọrọ naa ninu eyi to ti ni ko dara ki awọn olorin, gẹgẹ bi awokọṣe lawujọ o maa gbe lẹyin awọn oni yahooyahoo. Eyi ko dun mọ Naira Marley ninu, o si fi esi ọrọ kobakungbe ranṣẹ sii lori ayelujara. Koda awọn ololufẹ Naira Marley kan tilẹ kọlu Ruggedman ni ilu Gẹẹsi lori ọrs yii gẹgẹ bi iroyin ṣe sọ.
Oríṣun àwòrán, NAira marley/instagram
Ni ọjọ kẹwa oṣu karun un ọdun 2019 lawọn oṣiṣẹ ajọ EFCC mu Naira Marley niluu Eko. Ẹsun mọkanla ni wọn fi kan an eyi to da lori gbigbimọ pọ lati huwa ibi, ninu ayederu kaadi igbawo lọwọ pẹlu iwa jibiti.
Oniruuru iọọrọ odi si ni Naira Marley dojukọ fun ṣiṣe atilẹyin fun iwa jibiti ori ayelujara ti ọpọ mọ si yahoo-yahoo.
Lẹyin to lo ọpọlọpọ ọsẹ ni ọdọ awọn ajọ EFCC ni ile ẹjọ gba oniduro rẹ.
Lati igba ti ọrọ igbẹjọ rẹ naa ti bẹrẹ lo si ti di gbajugbaja ni aarin awọn ọdọ, paapaa julọ awọn to rii gẹgẹ bii ẹni to n ja fun awọn ọdọ nitori aarin awọn ọdọ ni yahoo-yahoo pọ si julọ.
Ariwo Marlian! Marlian !! lo gbode kan bayii.
Blackout: Ẹ wo ohun tí àwọn ọmọ Nàìjíríà ń sọ lẹ́yìn ìyanṣẹ́lódì ilẹeṣẹ́ mọ̀nàmọ́ná
Oríṣun àwòrán, Twitter/RoryPetzer
Ẹnikan ni ileeṣẹ mọnamọna lo n ṣokunfa bi awọn ọdọbirin ṣe n gboyun ojiji
Ni kete ti ẹgbẹ oṣiṣẹ ileeṣẹ mọnamọna Naijiria gunle iyanṣẹlodi ni ọpọ ọmọ Naijiria ti bẹrẹ si n fi eroungba wọn lede lori ipinu ọhun.
Bo tilẹ jẹ pe ẹgbẹ naa ti dawọ iyanṣẹlodi ọhun duro fun igba diẹ, awọn ọmọ Naijiria ko dawọ ọrọ ti wọn sọ duro.
Bi awọn kan ṣe n bu ẹnu atẹ lu ileeṣẹ amunawa, ni awọn mii n sọ pe ko kan wọn, bẹẹ ni awọn miran n fi epe ransẹ si ileeṣẹ ọhun.
Awọn kan tilẹ sọ pe ko si iyatọ laarin igba ti wọn gunle iyansẹlodi ati igba ti wọn n ṣeṣẹ.
@Official_imo ni ileeṣẹ mọnamọna lo n ṣokunfa bi awọn ọdọbirin ṣe n gboyun, latari bi wọn ṣe n gba ina sara ẹrọ ibanisọrọ wọn nile okunrin.
Black Abraham Lincoln ni tirẹ sọ pe oun ti fun ara oun ni isinmi lẹnu iṣẹ titi di igba ti ijọba yoo wa ojutu si ọrọ ina ọhun.
Oxlade Junior bu ẹnu ẹtẹ lu ijọba apappọ latari bi ko ṣe le pese ina gẹgẹ bi ileri to ṣe ṣaaju idibo.
Silas Robotic Engineer: Kò sí ǹkan rere tí ọmọ Nàìjíríà kò lè ṣe
Ẹ wo awọn ohun miran ti awọn ọmọ Naijiria n sọ.
Ki lo ti ṣẹlẹ sẹyin?
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ṣaaju ni kutukutu owurọ oni ni ẹgbẹ ọhun dawọ iyanṣelodi ti wọn gunle tẹlẹ duro fun saa diẹ
Ẹgbẹ awọn oṣiṣẹ ileeṣẹ apinnaka lorilẹ-ede yii NUEE , ti sọ pe oun yoo gunle iyanṣẹlodi miiran ti ijọba ko ba ṣe ohun ti wọn n fẹ.
Akowe apappọ fun ẹgbẹ naa, Joe Ajaero sọ fun BBC pe, idi iyanṣẹlodi ọhun ko ṣẹyin bi ijọba ṣe kọ lati mu adehun to wa laarin rẹ ati ẹgbẹ naa ṣẹ.
Ati pe bi ijọba ṣe n yọ owo ifẹyinti awọn oṣiṣẹ ọhun, to si kọ lati fi owo naa si apo to yẹ ko wa, ati awọn idi miran.
Akure Kidnap: Àwọn abiyamọ fẹ̀hónúhàn lórí ọmọ tí wan jígbé nílé ìjọsìn Akurẹ
Ṣaaju ni kutukutu owurọ oni, ọjọbọ ni ẹgbẹ ọhun dawọ iyanṣelodi ti wọn gun le tẹlẹ duro fun saa diẹ.
O ni wọn da iyaṣẹlodi ọhun duro di oṣu kini, ọdun 2020.
Joe ṣalaye pe o ṣeeṣe ki ẹgbẹ NUEE gunle iyanṣẹlodi miiran lọdun 2020 ti ijọba ko ba ṣe ohun ti wọn n fẹ.
O ni ẹgbẹ NUEE ko bere ohun miran lọwọ ijọba, bikoṣe pe ki ijọba mu adehun to wa laarin wọn tẹlẹ ṣẹ.
Ni kete ti ẹgbẹ naa ti fi ọrọ lede pe oun yoo gunle iyanṣẹlodi ni ọpọ agbegbe lorilẹ-ede yii fara kaasa okunkun birimu.
Àrà méèrírí lórí òkè táwọn ará ìlú Idanre l'Ondo ń gbé láyé gbọ́ngan sẹ́yìn
Ìtàn Mánigbàgbé: Diipọ Fagunwa ní a le è pe bàbá òun ní ‘osó’ ìtàn àkọsílẹ̀
Oríṣun àwòrán, D.O Fagunwa
Ọpọ awọn itan adiitu ti Orowọle kọ, lo n mu ki ọpọ eeyan maa ro pe Iwin tabi ẹmi airi kan ni
Bi ina ba ke, a fi eeru boju, bi ọgẹdẹ ba ku, yoo fi ọmọ rẹ rọpo, bi oloye ba ku, yoo fi oloye silẹ ni, bi eeyan ba si ku, ọmọ ẹni ni selede ni.
Ọmọ Oloogbe D.O Fagunwa, eyiun Diipọ Fagunwa ti n selede lẹyin baba rẹ to si n sọ awọn ohun meremere ti agba onkọwe naa ti gbe ile aye se lasiko to wa loke eepẹ.
Ọjọ Keje osu Kejila ọdun 1963 ni Daniel Ọlọrunfẹmi Fagunwa, ti gbogbo eeyan mmọ si D.O Fagunwa, ẹni to jẹ ilumọọka onkọwe silẹ bora nilu Bida nipinlẹ Niger lẹni ọdun ọgọta ọdun.
'Ó ṣojú mi kòró, ẹ wọ bí ìgbà ayé Bàbá Fagunwa ṣe rí'
Lara awọn iwe manigbagbe ti Fagunwa kọ ni Ogboju Ọdẹ ninu igbo Irunmọlẹ eyi to gbe jade lọdun 1938, Igbo Olodumare to tẹle lọdun 1949, Adiitu Olodumare, Ireke Onibudo 1949 lo gbe ohun naa jade baka naa ati bẹẹ bẹẹ lọ.
Orowọle Jaaniini Fagunwa ni orukọ akọni onpitan yii, amọ orukọ ti ọpọ eeyan mọ si ni Daniel Ọlọrunfẹmi (D.O) Fagunwa, gẹgẹ bii Diipọ ti se alaye, awọn ohun ti awọn eeyan ko mọ̀ nipa oloogbe naa ree:
Ọlọrunfẹmi Fagunwa maa n kọ itan bii ẹni pe o n waasu ni, awọn iwe rẹ lo kun fun ọgbọn, oye ati ẹkọ nipa bi a ti lee se aye rere.
'Fagunwa Mimọ' si lo yẹ ka maa pe nitori awọn itan ti awọn iwe rẹ kọ wa da bii ti awọn iwe mimọ mi, to si yẹ ka fi se iwe ipari awọn iwe mimọ wa fun awọn ẹlẹsin.
TANPAN Conference: Àwọn ilúmọ̀ọ́káá kalẹ̀ sí Ibadan
Oríṣun àwòrán, Realyomifabiyi
Mo le gbe ọ, O ju bayi lọ ni Yomi Fabiyi s fun Mide Martins
Oríṣun àwòrán, odunomoadekola
Ọdunlade Adekọla ati Fausat Balogun ni wọn dijọ maa n kopa iya ati ọmọ ninu ọpọ ere tiata.
Oríṣun àwòrán, odunomoadekola
A ku ọdun , ẹmi wa yoo se pupọ ọdun laye ni Ogogo ati Ọdunlade n sọ fun ara wọn.
Oríṣun àwòrán, odunomoadekola
Mo tẹ ara mi lọrun pẹlu omi yii, ongbẹ ko dara lara ni Ọdunlade Adekọla n sọ.
Oríṣun àwòrán, odunomoadekola
Ta lo dagba ju laarin wa, ẹ ba wa da si? ni Mr Latin n beere.
Oríṣun àwòrán, odunomoadekola
Ọsan to ri gbajumọ ti ko bọ ni awọn mẹẹtẹta yii, odu si ni wọn, wọn kii se aimọ fun oloko lagbo tiata.
Oríṣun àwòrán, odunomoadekola
Ọdunlade Adekọla ni jo ya, ijo ree, jẹ ka jo
Oríṣun àwòrán, Sanyeri02
"Sanyeri ni ""Ọrẹ jọ mi, mo jọ ọrẹ mi."""
Oríṣun àwòrán, Sanyeri02
Awa la wa ri ara wa, bi ologinni ti n ri ọmọ Ẹkun...
Oríṣun àwòrán, Sanyeri02
Ọdunlade Adekọla ni melo ni gbogbo ara Sanyẹri, ti oun ko lee gbe soke.
Oríṣun àwòrán, Antarthywill
Awa agba aja, ti kii ba awo jẹ naa peju sibi ipade Tanpan
Oríṣun àwòrán, Iteledicon01
Ọrẹ law n se, a ko ja rara ni awọn agba osere yii sọ
Oríṣun àwòrán, Realyomifabiyi
Gbogbo wa la peju
Oríṣun àwòrán, odunomoadekola
Ẹrin keke lẹnu awọn osere tiata meji, Ọdunlade Adekọla ati Bọlaji Amusan, ta mọ si Mr Latin.
Election fraud: Òṣìṣẹ́ INEC méjì yóò ṣẹ̀wọ̀n ọdún mọ́kànlélógún fún gbígba rìbá N362m
Oríṣun àwòrán, InEC
Eto idibo ọdun 2015 ti waye o ti lọ, koda eto idibo miran ti waye lẹyin rẹ ni ọdun 2019; ṣugbọn fun awọn oṣiṣẹ ajọ eleto idibo INEC meji kan, iya wọn ṣẹṣẹ bẹrẹ ni o.
Oṣiṣẹ ajọ INEC ni Ibrahim Mohammed ati SahaboIya-Hamman lasiko idibo ọdun 2015, amọṣa awọn mejeeji ti ri ẹwọn ọdun mọkanlelogun he bayii fun gbigba riba ti owo rẹ to ọdunrun o le ọgọta ati meji miliọnu  naira (N362m) lasiko idibo naa.
Àwọn ọ̀jọ̀gbọ́n Yorùbá foríkorí gbé ìwé tó lè sọ ẹ̀yà ara yín lédè Yorùbá.
Ajọ to n gbogun ti iwa ijẹkujẹ lorilẹede Naijiria, EFCC lo gbe awọn mejeeji yii lọ si ile ẹjọ pẹlu minisita fun ọrọ epo rọbi tẹlẹ lorilẹede Naijiria, Arabinrin Diezani Alison-Maduekwe lasiko idibo ọdun mẹrin sẹyin lori owo ti iroyin sọ pe wọn gba lọwọ rẹ.
Amọṣa, wọn ko tii ri arabinrin Diezani mu bayii.
Ninu idajọ rẹ to gbe kalẹ ni ile ẹjọ giga kan ni ilu Yola, ipinlẹ Adamawa, Onidajọ Nathan Musa ni pẹlu ẹri awọn ẹlẹri marundinlogun to yọju niwaju ile ẹjọ naa ati esi awọn olujẹjọ naa, o fihan pe wọn jẹbi ẹsun naa.
Naira Marley: Adọ́jọ́ ṣún ìgbẹ́jọ́ síwájú di oṣù kejì ọdún 20202
O ni o daju gbangba pe wọn gba owo riba naa, ida marun ninu ọgọrun inu rẹ ni wọn pin fun awọn oṣiṣẹ yoku ti wọn ko si lee sọ bi wọn ṣe na iyoku.
O ni ẹwọn ọdun meje-meje ni wọn yoo fara gba lori ọkọọkan ẹsun mẹtẹẹta ti wọn fi kan wọn bẹẹni ọwọ kan naa ni wọn yoo maa ṣe ẹwọn gbogbo ẹsun naa si. Iyẹn tums si pe, lẹyin-o-rẹyin ọdun meje ni wọn yoo lo lẹwọn, ṣugbọn ọdun mọkanlelogun ni yoo ka fun wọn ninu akọsilẹ.
EKIFEST: kí làwọn ohun tó fakọyọ níbi àjọ̀dún àṣà nípínlẹ̀ Ekiti, EKIFEST tọdún 2019
Ijo awọn ẹgbẹ alaṣa ni Ekiti
Ipinlẹ Ekiti ni aṣa ati iṣe ilẹ Yoruba paapaa awọn to nii ṣe pẹlu awọn eeyan ilẹ Ekiti ko ni parun. Idi niyi ti ayẹyẹ ajọdun aṣa fi waye nibẹ.
Ayẹyẹ ajọdun aṣa ipinlẹ Ekiti ti wọn da pe ni EKIFEST n waye lọwọlọwọ bayii ni ilu Ado Ekiti tii ṣe olu ilu Ipìnlẹ Ekiti. Awọn ẹgbẹjẹgbẹ ati ọgba ni wọn ti peju sibẹ lati Ọjọru ti ayẹyẹ naa ti bẹrẹ.
Àwọn ọ̀jọ̀gbọ́n Yorùbá foríkorí gbé ìwé tó lè sọ ẹ̀yà ara yín lédè Yorùbá.
Lara awọn manigbagbe ohun to waye lasiko iṣide ayẹyẹ ajọdun aṣa naa lọjọru ni ayẹyẹ afihan awọn ẹgbẹ aṣa gbogbo lati gbogbo ijọba ibilẹ mẹrindinlogun to wa nibi ayẹyẹ naa. Bakan naa lawọn oṣere tiata Yoruba ati ede oyinbo ko gbẹyin nibẹ.
Oríṣun àwòrán, Sunkanmi
Ẹwẹ awọn ẹgbẹ gbogbo lati awọn ẹya ede miran pẹlu wa nibẹ ti awọn olorin si n fi alujo to ba igba mu da awọn to wa nibẹ laraya.
Ninu ọrọ rẹ, Gomina Kayọde Fayẹmi to ṣide ajọdun ọhun tẹnumọ ipinnu iṣejọba rẹ lati tubọ ya owo sọts fun igbelekeẹka  aṣa ati iṣe fun idagbasoke ọrọ aje awọn eeyan ipinlẹ Ekiti.
Ni ọjọ Ẹti ni aṣekagba ajọdun naa yoo balẹ ni ilu Ado Ekiti.
Yoruba Culture: ọjọ́ méje ni wọ́n fí n rẹ ẹ̀kú Danafojura kó tó jáde
Nigeria Presidency: Kí ló ń fa wàhálà ojojúmọ́ ní ilé Ààrẹ l'Abuja
Oríṣun àwòrán, @NGRPresident
Fun awọn asiko diẹ, alaafia jọba ni ile aarẹ nilu Abuja nitori ọpọ awuyewuye ti o maa n waye nibẹ ni ko dede waye mọ. Nigba naa ọpọ woye pe boya tori idibo to waye ni.
Amọṣa, o dabi ẹni pe bi ọdun ṣe n lọ sopin bayii ni ariwo tuntun n sọ ni ile nla l'Abuja.
Ni ọjọ kẹtala oṣu kẹwaa ọdun 2019 ni iyawo aarẹ Buhari de si orilẹede Naijiria lẹyin to ti lo ọpọ ọjọ loke okun. Laarin asiko yii ni iroyin iyawo tuntun fun aarẹ jade. 'Kìí ṣe ojúṣe mi láti sọ bóyá òótọ́ ni Buhari fẹ́ gbéyàwó tàbí irọ́'
Ìròyìn nípa ìyàwó túntún fún ọkọ mi kò mì mí lọ́kàn rárá-Aisha Buhari
Bó tilẹ̀ jẹ́ pé ìròyìn òfegè ni pé Buhari fẹ fẹ́ Sadiya, síbẹ̀ àwọn ọmọ Nàìjíríà ń ṣètò ìyàwò náà lórí ayélujára
"Rugudu ọrọ yii ṣẹṣẹ fẹ maa dawọ duro ni aya aarẹ, Aisha Buhari de ti o si tun ju akaṣu ọrọ silẹ lori bi ọmọ baba ọkọ rẹ, Daura, iyẹn Fatima ṣe n fi oun ṣe yẹyẹ lori igbesẹ ati fidi aṣẹ ti aarẹ pa pe ki oun atawọn ẹbi rẹ kuro ni ọkan ninu awọn ile to wa ni ile aarẹ fun Yusuf ọmọ ọkunrin aarẹ lati gbe. ""Ọmọ Daura ti tàpá sí òfin ààbò Nàíjíríà, ó sì yẹ kí Buhari le è to ilé rẹ̀"""
Taló ya fídíò ibi tí Aisha Buhari ti ń bínú ní Aso Rock?
Oríṣun àwòrán, @NGRPresident
Ariwo eyii naa pọ.
Ko pẹ lẹyin eyi ni aya aarẹ ba tun pariwo sita pe awọn minisita atawọn gomina ko ṣe ojuṣe wọn fun alaafia araalu. Nibi eto kan eyi ti igbakeji aarẹ funrarẹ wa lo ti sọ eyi.
Mo sọ̀rọ̀ tako ọkọ mi torí òtítọ́ - aya Bùhárí
Oríṣun àwòrán, @NGRPresident
Bi ẹ ko ba ni gbagbe, lasiko ti gbogbo eyi ti n ṣẹlẹ ni ina iroyin kan naa n ja ranyinranyin pe awọn eeyan kan n gbimọ pọ lati yọ igbakeji aarẹ nipo. Oniruuru ọrọ lawọn eeyan sọ nigba naa.
Ariwo to n waye yii ni ile aarẹ ko fi ọkan ọpọ balẹ nitori afihan pe nnkan o rọgbọ nile aarẹ ni.
Laipẹ yii ni ajọ DSS ya bo kootu kan nilu Abuja ti wọn si da jinijini bolẹ. Nigba ti ileeṣẹ aarẹ yoo sọrọ, o ni ko soun to bajẹ ninu ohun to ṣẹlẹ naa nitori ojuṣe ajọ DSS lo n ṣe. Amọṣa, Yẹmi Osinbajo to jẹ igbakeji larinlọọdu ni ile aarẹ ni tirẹ ṣe akawe rẹ gẹgẹ bii idojuti nla gbaa eleyi to ni o mu ki oun maa lee gba ami ẹyẹ kan ti wọn fẹ fun oun.
Àgbẹdọ̀! Má kọ̀wé fipò sílẹ̀, àwọn àgbààgbà Yorùbá sọ fún Osinbajo
Oríṣun àwòrán, @NGRPresident
Eyi mu ki ọpọ maa beere pe, ki gan lo n ṣẹlẹ debi pe ohun igbakeji baba onile ko ṣọkan pẹlu ileeṣẹ aarẹ.
Iyanu ọrọ yii ko tii balẹ lara awọn ọmọ orilẹede Naijiria nigba ti iyawo aarẹ ni tirẹ ba tun pariwo sita pe amugbalẹgbẹ fun aarẹ lori ọrọ iroyin Garba Sheu tí gbàbọde, Aisha Buhari figbe ta fun ọkọ oun o ati pe iṣẹ ti wọn ko ran an lo n jẹ kaakiri.
Ibeere nla wa ni ọrọ naa n ko jade fun ọpọ pe, ki lo ṣe iṣọkan ni ile aarẹ labẹ aarẹ Buhari?
Sowore: Mínísítà fétò ìdájọ́ gba ìwé ẹjọ́ Sowore kúrò lọ́wọ́ àjọ DSS
Lẹyin gbogbo awuyewuye to waye lori bi ileeṣẹ DSS ṣe ya bo ile ẹjọ lati mu Soworẹ laipẹ yii, agbẹjọro  agba lorilẹede Naijiria, Abubakar Malami, SAN ti gba ẹjọ naa lọwọ ajọ ọhun.
"Ninu atẹjade kan ti  agbẹnusọ rẹ, Umar Gwandu fi sita lọjọ Ẹti, akọwe agba nileeṣẹ eto idajọ nijọba apapọ, Ọgbẹni Dayọ Apata, SAN kọwọ si ọga agba ileeṣẹ DSS pe ko tete ""ko awọn iwe ẹjọ naa ṣọwọ si ọfiisi agbẹjọro agba ni kiakia."""
Àwọn ọ̀jọ̀gbọ́n Yorùbá foríkorí gbé ìwé tó lè sọ ẹ̀yà ara yín lédè Yorùbá.
O ni minisita feto idajọ ti paṣẹ pe ki ileeṣẹ eto idajọ o gba akoso ẹjọ naa ni ibamu pẹlu abala aadọjọ ati ikẹrinlelaadọsan iwe ofin orilẹede Naijiria ti ọdun 1999.
Atẹjade naa tun ṣalaye wi pe ki igbẹjọ lee ya ni igbesẹ ati gba a kuro lọwọ ajọ DSS ṣe waye.
Naira Marley: Adọ́jọ́ ṣún ìgbẹ́jọ́ síwájú di oṣù kejì ọdún 20202
Bi ẹ ko ba gbagbe, ni Ọjọru ni minisita feto idajọ, Abubakar Malami ṣalaye fawọn oniroyin pe ijọba apapọ yoo ṣewadi bi awọn oṣiṣẹ DSS ṣe ya wọ kootu kan ni ilu Abuja lati fi tipatipa mu Soworẹ pada si ahamọ.
EKIFEST 2019: Ẹkẹ mímù, ayò títa, àfihàn iṣẹ́ ọnà wáyé níbi àjọ̀dún àṣà
Ẹni ba laya, ko wa wọọ, maa lu ẹ bolẹ- Ta ni yoo bori laarin awọn mejeeji?
Ọna wo ni maa gba fi ẹyin ọkunrin yii janlẹ ni ikọọkan awọn amuẹkẹ yii n sọ.
Alaye ree lori bi idije ẹkẹ mimu naa yoo ti waye.
Orin ‘ ẹ jade, kẹ wa wo wa lawọn ọmọde onijo ibilẹ yii n kọ.
Asọ oke ni asọ ibilẹ wa nil Yoruba, awọn ọna ti a n gba hun asọ oke ree
Ounjẹ lọrẹ awọ, ounjẹ to dara lo n se ara loore
Ebi kii wọnu, ki ọrọ miran wọọ. Awọn oniruuru eroja ounjẹ ati awọn ikoko abalaye ta fi n dana ree.
Awọn afihan isẹ ọna to jẹ oju ni gbese ree nibi ajọdun asa ni Ekiti.
Ẹ jẹ ka gbedi fun awọn onisẹ ọna yii fun isẹ ribiribi ti wọn se, aworan gomina Kayode Fayemi ati iyawo rẹ ree.
Ero maa wa, ero maa bọ, ajọdun asa lo n lọ lọwọ yii, ero maa wa.
Lizzy Anjorin: Kò sí òṣèré tíátà lóbìnrin tó ní dúkìá jù mí lọ
Oríṣun àwòrán, lizzyanjorin_original
Ilumọọka osere tiata lobinrin, Lizzy Anjorin, ti kede faraye pe ọpọ eeyan ni ko mọ pe awọn ọkunrin kii fẹ nawo ọfẹ fun iru obinrin bii toun, to n sisẹ kara loju mejeeji
Lizzy Anjorin, lasiko to n takurọsọ pẹlu iwe iroyin adanilaraya kan salaye pe, oun ko setan lati gbara le ọkunrin kankan fun owo nina, idi si ree ti oun se n se laala lori okoowo katakara ti oun n se.
Elo ni ọkunrin kan fẹ fun iru obinrin bi emi, ti yoo ka lẹnu? Owo osu ti mo n san fun awọn osisẹ mi gan losoosu lasan sun mọ miliọnu kan naira, elo wa ni ọkunrin kan fẹ fi fa mi loju mọra?
Oríṣun àwòrán, lizzyanjorin_original
Lizzy salaye siwaju si pe ọmọ sisẹ sisẹ ni oun, ti oun si maa n lọ soke okun lati lọ ra awọn asọ ati ẹsọ ara ti oun n ta ninu ile itaja oun to wa ni adugbo Ikọta nilu Eko.
Tẹ ba ri awọn fidio ti mo n se lati polowo ọja mi, ẹ ri pe ojoojumọ ni mo maa n jo lati polowo awọn ọja naa. Ki n to lee ta asọ bubu kan soso, maa jo jo jo, ko si lee si akẹẹgbẹ mi kankan to lee sọ pe oun n sisẹ aje ju mi lọ.
Bakan naa ni Lizzy fẹ ki araye mọ pe oun si ni obinrin osere tiata to lowo julọ ni Naijiria nitori pe kii fi bo rara pe ko si akẹẹgbẹ oun kankan ti o ni dukia ti oun ni, tabi ti Ọba oke kẹ ju oun lọ.
Taa gan ló ń jí orin àti ohùn ara wọn lò nínú Adewale Ayuba àti Ajebori
Oríṣun àwòrán, lizzyanjorin_original
Iya mi lo sọ mi di eeyan ti mo da loni, oun si ni igi lẹẹyin ọgba fun ohun ti mo da loni, iya mi le pupọ, nitori emi nikan lo bi, o yẹ ko kẹ mi ra ni, amọ ko ri bẹẹ rara. Ti mo ba fẹ ohunkohun lati kekere, mo gbọdọ sisẹ fun ni, eleyi si lo ran mi lọwọ lati sisẹ kara fun owo.
Nigba ti wọn bi Lizzy leere nipa ohun to jẹ atọna fun, o dahun pe ipamọra ni ati oore ọfẹ Ọlọrun, pẹlu afikun pe eeyan gbọdọ le diẹ ko to lee se aseyọri okoowo nilẹ Naijiria nitori irora pọ ninu sise isẹ aje nilẹ yii.
Oríṣun àwòrán, lizzyanjorin_original
Mo nifẹ oge sise, mo si n sisẹ kara, Mo maa n ra awọn ọja asọ ati goolu to yatọ, ti ko si wọpọ. Idi ree ti awọn ọja ti mo n ta kii fi se iru wa, ogiri wa, wọn kii se gbarọ-gbudu. Ẹnikẹni to ba si ra ọja mi, to wọ ọ, yoo duro re nilẹ, ti yoo si dun wo.
Bakan naa ni Lizzy fikun pe oun nifẹ goolu pupọ, ti oun si maa n de orilẹede meje lati wa goolu to yatọ, eyi to si dara ni oun maa n wa lọ lati ra.
Kwara Commissioners: Àgùnbánirọ̀ obìnrin, ẹni ọdún mẹ́rìndínlọ́gbọ̀n di kọmíṣọ́nnà ní Kwara
Oríṣun àwòrán, Facebook/Abdulrahaman Abdulrasaq
Gomina ipinlẹ Kwara, Alhaji Adulrahman Abdulrazaq kede awọn kọmiṣọnna tuntun lẹyin oṣu mẹfa ati aabọ ti wọn ṣe ibura fun un gẹgẹ bi gomina ipinlẹ naa.
Eyi ni awọn kọmiṣọnna ati ile iṣẹ wọn ti Gomina Abdulrazaq kede lonii ọjọ Ẹti.
Ile iṣẹ ijọba idagbasoke ọdọ ati ere idaraya
Agunbanirọ obinrin, Joana Kolo ni Gomina ipinlẹ Kwara yan gẹgẹ bi kọmiṣọnna ile iṣẹ ijọba to n ri si ọrọ idagbasoke ati ere idaraya.
Joana to jẹ ọmọ ọdun mẹrindinlọgbọn ni kọmiṣọnna ti ọjọ ori rẹ kere julọ kaakiri orilẹede Naijiria bayii.
Kọmiṣọnna fun iṣẹ ṣiṣe
Amoju ẹrọ Rotimi Suleiman ni kọmiṣọnna fun ile iṣẹ to n ri si ọrọ iṣẹ ṣisẹ ni ipinlẹ Kwara.
Kọmiṣọnna fun iṣẹ ṣiṣe
Dokota Raji Abdulrasaq ni yoo maa tukọ ile iṣẹ ijọba to n ri si eto ilera nipinlẹ Kwara.
Kọmiṣọnna fun ọrọ oye jijẹ ati ijọba ibilẹ
Arabinrin Aisha Patigi ni oludari tuntun fun ile iṣẹ ijọba to n ri si ọrọ oye jijẹ ati ọrọ ijọba ibilẹ ni ipinlẹ Kwara bayii.Kọmiṣọnna fun eto ọgbinHeriat Adenike ni kọmiṣọnna fun ile iṣẹ ijọba to n ṣakoso eto iṣẹ agbẹ.
Kọmiṣọnna fun ile iṣẹ idagbasoke awujọ
Deborah Bose Aremu ni gomina yan kọmiṣọnna fun ile iṣẹ to n ri si idagbasoke awujọ ni ipinlẹ Kwara.
Kọmiṣọnna fun ayika
Aliyu Mohammed ni kọmiṣọnna ti yoo maa tukọ ile iṣẹ ijọba to n mojuto ọrọ ayika nipinlẹ Kwara.
Kọmiṣọnna fun eto ẹkọ
Arabinrin Fatimah Bisola ni kọmiṣọnna tuntun fun ile iṣẹ ijọba to n ri si eto ẹkọ.
Kọmiṣọnna fun eto ẹkọ ile iwe giga
Saadat Modibbo Kawu ni kọmiṣọnna fun ile iṣẹ ijọba ti yoo maa ṣamojuto ọrọ eto ẹkọ ile iwe giga ni Kwara.Kọmiṣọnna eto iṣuna
Olasunbo Florence ni kọmiṣọnna tuntun eto inawo
Kọmiṣọnna eto idajọ
Amofin Ayinla Jawondo ni kọmiṣọnna eto idajọ nipinlẹ Kwara.
Kọmiṣọnna ohun amuṣagbara
Aliyu Moro Sabi ni Gomina ipinlẹ Kwara yan gẹgẹ bi kọmoṣọnna ohun amiṣagbara.Kọmiṣọnna oko-owoỌgbẹni Agbaje wahab lo jẹ kọmiṣọnna fun ile iṣẹ ijọba to n ri si ọrọ oko owo.
Kọmiṣọnna eto ibaraẹnisọrọMurtala Olarenwaju ni kọmiṣọnna tuntun fun ile iṣẹ ijọba to n ṣamojuto ibaraẹnisọrọ.
Kọmiṣọnna ohun elo omi
Arinola Lawal lo jẹ kọmiṣọnna fun ile iṣẹ ijọba to n ṣamojuto ohun elo omi mimu nipinlẹ Kwara.
Kọmiṣọnna iṣẹ akanṣe
Arabinrin Funke oyedun Juliana ni kọmiṣọnna tuntnun fun ile iṣẹ ijọba to n ṣakoso akansẹ iṣẹ.
Bàbá ìyàwó ní ìfẹ́ wà láàrin ọmọ́ òun àti ọkọ rẹ̀, inú àwọn sì dùn sí ìgbeyàwó náà
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ọdọmọbinrin ọmọ ọdun mẹrindinlogun kan, Fatima Abubakar ti padanu ẹmi rẹ lẹyin to re sinu kanga omi nigba ti igbeyawo rẹ ku ọla.
Iṣẹlẹ naa la gbọ wi pe o waye ni ilu Gajaja, ijọba ibilẹ Danbatta, nipinlẹ Kano.
Baba Fatima, Ọgbẹni Abubakar sọ fun BBC pe, iṣẹlẹ buruku naa waye lasiko ti ọmọbinrin naa ati awọn ọrẹ rẹ nlọ fun ayẹyẹ alẹ omidan nile anti rẹ kan l'ọjọru.
"Niṣe lo duro l'ẹgbẹ kanga naa, ko to o di wi pe o fi ẹsẹ kọ, to si ṣubu sinu kanga.
Ọjọ keji, to jẹ Ọjọbọ lo yẹ ki ayẹyẹ igbeyawo laarin oun ati ọkọ afẹsọna rẹ o waye.
Baba Fatima ṣalaye pe, inu ọmọ oun dun si igbeyawo naa, ati pe ifẹ wa laarin oun ati ọkọ afẹsọna rẹ.
O sọ pe amọ o ṣeni laanu pe inu ibanujẹ ni awọn alejo to yẹ ko wa ba oun yọ ayọ igbeyawo ọmọ oun wa bayii.
Inu ibanujẹ ni ọkọ afẹsọna naa wa, ti ko si le ba ẹnikẹni sọrọ lori ẹrọ ibaraẹnisọrọ.
Dino Melaye ni àbímọ́ ni iṣẹ́ tíátà àti òṣèlú jẹ́ fún òun
Oríṣun àwòrán, dinomelaye
Sẹnetọ orilẹede Naijiria nigbakan ri, Dino Melaye ti ṣalaye pe ayanmọ oun latọrun wa ni lati ṣe ere tiata ati lati jẹ oloṣelu.
Lasiko to fi n ba awọn oniroyin sọrọ nibi afihan sinima kan to kopa ninu rẹ eyi ti wọn pe akori rẹ ni 'Lemonade' lo ti sọ bẹẹ.
Oríṣun àwòrán, dinomelaye
Ṣe ẹ si mọ pe ọmọ ti yoo ba jẹ aṣamu, ati kekere ni iru wọn ti n ṣẹnu ṣamuṣamu.
Sẹnetọ Melaye tun ṣalaye pe idi ti oun fi kopa ninu ere sinima naa ni lati jẹ ko di mims fawọn ọmọ orilẹede Naijiria pe asiko to ki wọn bọ kuro ninu iṣoro wọn.
Taa gan ló ń jí orin àti ohùn ara wọn lò nínú Adewale Ayuba àti Ajebori
O wa ke si ijọba lati gbe awọn ofin kalẹ ti yoo ṣe agbedide ẹka amuludun  lorilẹede Naijiria.
Melaye ni wọn bi mi mọ ere tiata ati oṣelu ni"" ati pe ẹka to lamilaaka ni ẹka amuludun lorilẹede Naijiria eleyi to ni o fẹ loju ju ẹka epo rọbi lọ."
Christmas: Ọlọ́pàá gbẹ́sẹ̀ lé yínyin ohun ìṣiré ọdún ní ìpínlẹ̀ Ondo
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ileeṣẹ ọlọpaa ti sọ pe ẹnikẹni to ba yin ohun iṣire ọdun ti a mọ si banga nipinlẹ Ondo lasiko pọpọsinsin ọdun keresimesi ati ọdun tuntun to n bọ lọna yoo rugi oyin.
Kọmiṣọna ọlọpaa nipinlẹ Ondo, Adie Udie lo gbe ofin yii kalẹ.
Akure Kidnap: Àwọn abiyamọ fẹ̀hónúhàn lórí ọmọ tí wan jígbé nílé ìjọsìn Akurẹ
Ileeṣẹ ọlọpaa ni ipinlẹ Ondo ni ẹnikẹni to ba ta felefele to si tapa si aṣẹ yii yoo fi ẹnu fẹra bi abẹbẹ.
Bakan naa lo ni gbogbo awọn to ba ṣowo ohun iṣire naa lasiko ọdun ti ọwọ ba tẹ ko ni ṣai jo lamba ofin.
Taa gan ló ń jí orin àti ohùn ara wọn lò nínú Adewale Ayuba àti Ajebori
Ileeṣẹ ọlọpaa nipinlẹ Ondo ṣalaye pe agbepolaja nikan kọ lole, ẹni gba a silẹ gan an ole ni.
Ileeṣẹ ọlọpaa nipinlẹ Ondo wa fi kun un pe awọn ṣe tan lati pese abo to peye lasiko ọdun to wọle de naa.
Pa Kasumu: Òṣèré tíátà Yorùbá ní àìsàn tó ń bá òun fínra kìí ṣojú lásán
Oríṣun àwòrán, Twitter/Joba Bamiro
Gbajugbaja osẹre tiatia, Kayode Odumosu ti ọpọ mọ si Pa Kasumu ti ke gbajare pe adura awọn eeyan loun nilo bayii nitori aisan to n ṣe oun, ejo lọwọ ninu ni.
Fọnran kan to jade laipẹ yii nibi eto ti Foluke Daramola ṣe lo ṣafihan bi Pa Kasumu ti ri nitori aisan to ti n ba a finra lati ọjọ pipẹ.
Amọ nigba to n ba awọn akọroyin sọrọ, Pa Kasumu ni oun ko nilo owo lati ọdọ awọn ololufẹ oun bi ko ṣe adura nitori aisan to n da agọ ara oun laamu ti kọja ọrọ oogun oyinbo lilo.
Pa Kasumu ni oun wa ni ipagọ adura ile ijọsin kan nibi t'oun ti n gbadura fun iwosan agọ ara oun, o ni oun si maa wa nibẹ ti eto naa yoo fi pari.
Ọgbẹni Odumosu to ti n ṣaisan lati bi ọdun mẹwaa sẹyin ṣalaye pe ijọ RCCG ni ṣọọṣi akọkọ ti oun yoo lọ fun ẹbẹ adura lati igba ti aisan naa bẹrẹ.
Oríṣun àwòrán, Twitter/Funso Dove
O ni ṣọọṣi ti oun n lọ ni Sabo, Yaba naa n gbadura fun oun.
Pa Kasuma tun fi kun ọrọ rẹ pe irọ ni iroyin tawọn eeyan kan n gbe kiri pe oun ti ni ipenija pẹlu oju oun.
O ṣalaye pe awọn dokita sọ f'oun pe oun ni aarun rọpa rọsẹ eleyi to ṣakoba fun apa kan ara oun, ti o si tun ba oju oun.
O ni iyawo oun atawọn ọmọ ni wọn n ṣe itọju oun lati igba ti aisan yii ti bẹrẹ.
Oríṣun àwòrán, Twitter/Ridwanullah
Ọkan lara awọn ọmọkunrin Pa Kasumu, Bode Odumosu naa sọ pe adura ni baba oun nilo bayii pẹlu ipo to wa.
Lọdun 2017 ni iroyin kan jade pe aisan to n ṣe Pa Kasumu tun n le sii lẹyin to pada si Naijiria lati orilẹede India nibi to ti lọ gba itọju.
Muhammadu Buhari: Olubunmi-Okogie ní Nàìjíríà ti padà s'áyé ìjọba ológun
Oríṣun àwòrán, Twitter/Anthony Ehilebo
Aarẹ ajọ ẹgbẹ ọmọlẹyin Kristi, CAN tẹlẹ ri, Cardinal Anthony Olubunmi-Okogie sọ pe orilẹede ti n pada si aye ijọba ologun diẹdiẹ labẹ iṣejọba aarẹ Muhammadu Buhari.
Cardinal Olubunmi-Okogie bu ẹnu atẹ lu aibọwọ fun aṣẹ ile ẹjọ labẹ ijọba Aarẹ Buhari.
Ojiṣẹ Ọlọrun Olubunmi-Okogie sọrọ yii ninu atẹjade kan to fi sita, eleyi to pe akori rẹ ni ''Iwa ibajẹ ati ifagbaratẹtọẹnimọlẹ.''
'Ohun to ṣeni laanu ni pe lorilẹede Naijiria ni pe awọn olori jina si awọn eeyan ti wọn n ṣejọba le lori,' Cardinal Olubunmi-Okogie lo woye bẹẹ.
O ṣalaye pe awọn araalu lo dibo yan awọn to n ṣejọba, o ni idi niyii ti wọn fi gbọdọ maa tẹti gbọ ohun tawọn araalu n sọ.
Ojiṣẹ Ọlọrun Olubunmi-Okogie ni ti ijọba ba kọ lati paṣẹ ile ẹjọ mọ, ti o si n dunkoko mọ ẹka eto idajọ, ajẹ wi pe Naijiria ti pada si aye ijọba ologun niyẹn nigba tawọn ologun n ṣe ohun to wu wọn.
O ni laye ologun ni ijọba kan le ṣadeede ju awọn eeyan satimọle lainidi kan pato.
Cardinal Olubunmi-Okogie ni ọmọ Naijiria ko fẹ ijọba ologun mọ nitori o ti ṣakoba nla fun orilẹede yii.
Olubunmi-Okogie ni iru awọn iwa oloṣelu to fa ogun abẹle ni Naijiria bi aadọta ọdun sẹyin ni ijọba to wa lode n wu.
O ni ijọba awarawa Naijiria wa ninu ewu nitori iwa ibajẹ ati tani yoo mu mi.
UFC245: Kamaru Usman, f'ẹ̀ṣẹ́ borí ààyò Trump, Colby Covington ní ìjà UFC
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Bii bara ni abẹṣẹkubiojo ọmọ orilẹede Naijiria, kamaru Usman lu Colby Covington ti wọn jọ koju ija lowurọ ọjọ aiku lati ṣi wa nipo to ni akọle rẹ, welterwwight ni idje UFC 245.
Ija naa waye ni gbagede T-Mobile Arena ni Las Vegas, orilẹede Amẹrika.
Laarin idije ija naa, bi Colby ṣe n ta a ni Kamaru n gbakuru mọ ọ koda o tun fi ẹṣẹ fọ Colby leyin isalẹ ti gbogbo oju rẹ si kun fun ẹjẹ.
Sekinat Quadri ọmọ ọdun meje ajẹsẹ to fẹ dabi Anthony Joshua
Lati idaji ni gbogbo eniyan lori ayelujara ti n reti ohun ti ija yii yoo bi.
Ni bayii, Kamaru náà ni yóò tún jẹ́ ọmọ Afíríkà àkọ́kọ́ tó fẹ̀ṣẹ́kùbíòjò gbaigbanu ẹyẹ idije Ultimate Fighting Championship.
Ni kete ti
Covington could barely stand to listen to Usman's victory speech, charging out of the Octagon to the back as soon as the Nigerian's hand was raised.
"But even in defeat, ""Chaos"" established himself as one of the greatest fighters on the planet with an excellent display that will surely still see his stock rise."
It was an extremely close fight that could have gone either way had it gone the distance, as both men met in the middle of the Octagon and traded blows from start to finish, eschewing their world-class wrestling abilities in favour of an all-out brawl.
But Covington's fortunes changed when Usman broke his jaw at the end of the third round with a hard right.
Electricity: Ìjọba àpapọ̀ f'ẹ́ já iná mànàmáná orílẹ̀èdè Togo àti Benin Republic nítorí gbèsè $7m
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ẹ lọ sanwo ina yin o! Ẹ lọ sanwo ina yin o!!
Ariwo tijọba apapọ Naijiria n pa le awọn to jẹ ẹ ni gbese owo ina niyi bayii o.
Amọṣa lọtẹ yii kii ṣe awọn ọmọ orilẹede Naijiria nijọba apapọ n ba wi, bikoṣe awọn ijọba orilẹede meji kan lẹkun iwọ oorun ilẹ Afirika.
Bẹẹni, ijọba apaps Naijiria ti jawe ikilọ ranṣẹ s'orilẹede Togo ati Benin Republic pe ki ijọba ibẹ tete san gbese ina ẹlẹntiriki ti wọn jẹ orilẹede Naijiria.
Hmmm... alaga ajọ apapọ ina manamana lẹkun iwọ oorun ilẹ Afirika, Usman Gur Mohammed ni orilẹede mejeeji yi jẹ Naijiria lowo ina to to miliọnu meje dọla owo ilẹ Amẹrika, ($7m).
Ọgbẹni Miohammed ni oun o le joye akotileta ti yoo maa yan awọn ọmọ Naijiria jẹ lori ọrọ ina ọba.
"Gẹgẹ bi o ṣe sọ, 'Ọgọrun miliọnu dọla owo ilẹ amẹrika, ($100m) ni orilẹede Benin ati Togo n jẹ ni gbese owo ina nigba ti mo de ipo alaga ajọ apinna ọba Naijiria, TCN. Nibayii mo ti gba owo naa ku miliọnu meje dọla owo ilẹ Amẹrika, ($7m)."""
"Owo ina ti orilẹede Niger republic ni tirẹ n jẹ din diẹ ni miliọnu meji dọla owo ilẹ Amẹrika, ($2m). A o si ni fi wọn silẹ. A maa ja ina wọn gẹgẹ bi a ṣe n ja ina awọn eeyan ni Naijiria nibi ni."""
O ni ko soju aanu lọrọ ina ọba lilo ati pe ko ni si aaye fun awọn eeyan lati maa lo ina ẹlẹntiriki orilẹede Naijiria lai san owo rẹ.
Ki ni awọn ọmọ Naijiria n sọ lori rẹ?
Ni kete tawọn ọmọ Naijiria gbọ ọrọ yii, oniruuru esi ni wọn ti n fọ lori rẹ.
Awọn ọmọ Naijiria kan n tara ni pe inu awọn ko dun si iroyin naa nitori pe o ni ohun ti oju awọn ọmọ Naijiria to jẹ owo diẹ lasan n ri lọwọ awọn oṣiṣẹ amunawa eleyi to fihan pe ijọba apapọ kii ṣe iru rẹ fun awọn ilẹ okeere to jẹ ẹ ni gbese owo ina.
Bakan naa lawọn kan kọminu pe orilẹede Naijiria ko lee pese ina to duro deede fun awọn eeyan rẹ to jẹ oninkan, ṣugbọn o lee maa pese ina ologeere fawọn ti ilẹ miran to si jẹ pe lẹyin o rẹyin wọn ko ni san owo ina naa.
Nigeria-Ghana trade war: Ààrẹ Ghana pàṣẹ kò sáàyè òwò fọ́mọ China tàbí Nàìjíríà mọ́ ní Ghana
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ààrẹ Ghana pàṣẹ kò sáàyè òwò fọ́mọ China tàbí Nàìjíríà mọ́ ní Ghana
Aarẹ orilẹ-ede Ghana ti kede pe ko si aṣiwi tabi aṣitumọ ninu itumọ ti ẹgbẹ awọn ọlọja Ghana fun ofin kan eleyi to gbẹsẹ le ifarahan awọn ọlọja lawọn ọja abẹle gbogbo.
O ni titi di igba ti ayipada yoo fi de ba ofin naa, ẹṣẹ nla ni fun awọn ajeji lati maa ta ọja worobo lorilẹede Ghana.
Aarẹ Akufo Ado ni ẹnikẹni ti kii ba n ṣe ọmọ orilẹ-ede Ghana ko gbọdọ ta ohunkohun lọja Wana.
Lasiko ti o fi n ba awọn akọroyin sọrọ ni Aarẹ Akufo-Addo ṣalaye ọrọ yii.
Bi ìyàwọ mi ṣe n jábọ́ sí kọ́tà ló jẹ́ kí n kọ́ka fura pé kò ríran mọ́- ọkọ Dorcas
Akufo Addo ni ohun ko fẹ mọ irufẹ ajeji tabi orilẹ-ede ti onitọhun lee ti wa, yala China tabi Naijiria, gbogbo wọn ni ofin orilẹ-ede Ghana ti paṣẹ pe ko gbọdọ ta ọja Ghana.
Bakan naa ni aarẹ Ghana tun fapa janu lori bi orilẹ-ede Naijiria ṣe ti ẹnu ibode rẹ nitori fayawọ irẹsi.
Àrà méèrírí lórí òkè táwọn ará ìlú Idanre l'Ondo ń gbé láyé gbọ́ngan sẹ́yìn
O ni ko din ni ọọdunrun ọkọ akẹru latori orilẹ-ede Ghana to fara ko ọwọja ẹnubode ti Naijiria ti naa.
O ni awọn yoo wa ojutu si eto karakata abẹle lorilẹ-ede to bẹẹ ti titi ẹnu ibode ko fi ni nipa awọn eeyan rẹ lara mọ.
Ọrọ ede aiyede laarin awọn ontaja ọmọ orilẹ-ede Naijiria ati akẹgbẹ wọn ni Ghana ti bẹrẹ kaakiri gbogbo ọdun 2019.
Igba marun  un ọtọọtọ si ni awọn ontaja ọmọ orilẹ-ede Ghana ti sọ agadangodo si ṣọọbu awọn ọmọ Naijiria to n taja lawọn ọjọ abẹle gbogbo nibẹ.
Ija owo yii si ti fa ọpọlọpọ ikayasoke laarin orilẹ-ede mejeeji.
Èèyàn méjì kù, ọlọ́pàá mú afunrasí 75 nínú làásìgbò tó bẹ́ sílẹ̀ ní àdúgbò Pákó-Aguda
Oríṣun àwòrán, Twitter/rrslagos767
Làásígbó bẹ̀ẹ̀ sílẹ ní àdúgbo Pákó-Aguda
Eeyan meji lo ku ninu laasigbo to waye ladugbo Pako Aguda Surulere nilu Eko lọjọ Aje.
Alukoro ileeṣẹ ọlọpaa nilu Eko Bala Elkanna to fidi ọrọ yi mulẹ sọ pe ọwọ ọlọpaa ti tẹ awọn afunrasi àádọ́rin to kopa ninu ija to waye naa.
Niṣe ni ọrọ di boolọ ọ yago mi ni adugbo Pako Aguda lagbegbe Ijẹṣa Tẹdo, Surulere nilu Eko nigba tawọn janduku ṣe ikọlu ara wọn.
Ikọ awọn janduku ti wọn n fi ada ṣọṣẹ tawọn miiran si n yinbọn soke la gbọ pe wọn da adugbo ru ti onikaluku si n sa asala ẹmi rẹ.
Akọroyin wa, to ṣabẹwo sadugbo naa lẹyin ti gbogbo nkan ti rọlẹ sọ pe ija emi lọga iwọ kọ lo wa nidi ikọlu naa.
Africa Eye: Ohun tí ọ̀rẹ́ mi fí sórí 'Social Media'ló wọ̀ mí lójú- Grace
Akọroyin BBC sọ pe ijokoo mẹrinla lo n dari awọn agbero ni ipinlẹ Eko tẹlẹ ki wọn to fẹ sọọ di mẹrin.
Wọn yan agbegbe Palo Aguda lati fa ẹni kan kalẹ gẹgẹ bii olori ninu awọn mẹrin ti wọn fẹ yan ni eyi ti awọn kan ninu awọn agbero naa ko fẹ ẹni naa.
Abey to jẹ ọkan ninu awọn agbero naa ni ibọn kọkọ ṣeeṣi ba bakan naa, iroyin sọ pe awọn eeyan mẹta padanu ẹmi wọn tawọn janduku naa si ba ọpọlọpọ dukia jẹ nibẹ.
Ikọ ọlọpaa ayarabiaṣa nilu Eko ti a mọ si Rapid Response Squad loju opo Twitter wọn sọ pe awọn ti dẹwọ aawọ naa tawọn afurasi kan si ti wa lahamọ.
Oríṣun àwòrán, Twitter/rrslagos767
Ija laarin awọn janduku nilu Eko kii ṣe nkna ajoji.
Ninu ọrọ ti wọn fi sita yi, wọn fidi ọrọ mulẹ pawọn janduku lo n ṣe ikọlu si ara wọn ṣugbọn wọn ko sọ boya eeyan kankan padanu ẹmi rẹ ninu ija naa.
Ija laarin awọn janduku nilu Eko kii ṣe nkan ajoji.
Bi awọn awakọ ero ti a mọ si NURTW ko ba maa ṣe ikọlu si ara wọn, awọn ọmọ onilẹ naa a maa da wahala silẹ laarin adugbo.
Pupọ ninu awọn ikọlu wọnyi lo maa n ko ara adugbo laya soke ti ẹmi a si maa bọ nigba miran.
Silas Robotic Engineer: Kò sí ǹkan rere tí ọmọ Nàìjíríà kò lè ṣe
Naira Marley ní àwọn tí kò fẹ́ kí òun di ààrẹ lẹ́yìn Buhari ló ń parọ́ ọkọ̀ jíjí mọ́ òun
Oríṣun àwòrán, NAira Marley/Instagram
Naira Marley ní àwọn tí kò fẹ́ kí òun di ààrẹ lẹ́yìn Buhari ló ń parọ́ ọkọ̀ jíjí mọ́ òun
Gbajugbaja olorin takasufe to n na igboro lọwọ, Azeez Adeyẹmi Fashọla ti ọpọ mọ si, Naira marley, ti ni bi o ti wu ki awọn alatako oun o ba oun lorukọ jẹ to, oun ni yoo jẹ aarẹ orilẹ-ede Naijiria lẹyin ti Buhari ba lo saa rẹ tan.
Naira Marley sọ eyi nigba to n fesi lori ẹsun ti wọn fi kan an pe o ji mọto gbe gẹgẹ bi o ṣe n ja ranyinranyin kaakiri.
Ile ẹjọ Magistrate ipinlẹ Eko kan lo paṣẹ pe ki awọn agbofinro lọ fi gbaga ofin gbe Naira Marley wa siwaju ile ẹjọ fun ẹsun jiji ọkọ.
Adajọ Majisreeti Tajudeen Elias lo gbe aṣẹ yii kalẹ fun ọlọpaa to n ṣe iwadii ẹjọ naa, Sajẹnti Sunday Idoko.,
O ni pe ni wiwọ ni dide o, oun fẹ ri Naira Marley nile ẹjọ nigba ti igbẹjọ miran baa waye.
Amọṣa, Naira Marley funra rẹ ti sọ pe ko si oun to jọọ o.
Oríṣun àwòrán, NAira marley/ instagram
Ninu ọrọ to fi soju opo twitter rẹ @officialnairam1, Naira Marley ni ki nla, ọwọn epo ni tabi airowo ra a.
O ni boya ki oun ṣe afihan fọto awọn ọkọ olowo iyebiye bii Bentley, Porsche tabi Benzo ranṣẹ ki wọn lee mọ pe ti ọrs ba di ti ọkọ oun ksja ẹni ti wọn lee ma fi ẹsun ọkọ jiji lọ.
Naira Marley: Adọ́jọ́ ṣún ìgbẹ́jọ́ síwájú di oṣù kejì ọdún 20202
O ni ko si ẹni to lee ba oun lorukọ jẹ ti oun ko fi ni di aarẹ to kan lorilẹede Naijiria.
Bi ẹ ko ba gbagbe, Naira Marley ṣi n kawọ pọnyin jẹjọ niwaju ile ẹjọ giga apapọ kan nilu Eko lori ẹsun jibiti ori ayelujara ati ayederu ike iṣuna ti ajọ EFCC n fi kan an.
Iná PHCN tó dé lójijì ṣàkóbá ńlá ní Ibadan
Oluwo Divorce: Yàtọ̀ sí Olúwó, wo àwọn Ọba alayé tó ti kọ ìyàwó láìpẹ́
Oríṣun àwòrán, oonirisa - ooni of ife adeyeye enitan ogunwusi oja
Yàtọ̀ sí Olúwó, wo àwọn Ọba alayé tó ti kọ ìyàwó láìpẹ́
Ni ọjọ Aiku ni iroyin kan to ba ọpọ lẹjafuu jade lati akata oluwo ti ilu iwo.
Ko fẹrẹ sii ọmọ Yoruba nile loko ti ko tii gbọ ohun kan tabi omiran nipa Ọbalaye ilu Iwo, Alayeluwa Abdulrasheed Akanbi yala ni daadaa tabi idakeji rẹ iyẹn bo ba ṣe kọju si wọnỌ̀rọ̀ èmi àti Olorì Chanel Chin kò yé ara wa mọ́ nínú ilé- Oluwo .
Lootọ, ohun ti kii saaba waye ni ilẹ Yoruba ni ki Ọbalaye kọ iyawo rẹ silẹ Èèwọ! Ọba aláde o gbọdọ kọ iyàwó rẹ̀ sílẹ̀- Bakare, Iba àṣà Yorùbá.
Idi ni pe ọla ati iyi ti Yoruba so pọ mọ awọn Ọba kii ṣe kekere rara. Ọpọ tilẹ tun rii pe ko si ọkunrin miran to lee sàba le obinrin ti Kabiyesi ba ti gun ori rẹ kọja ni ilẹ Yoruba.
Amọṣa, Kabiyesi Oluwo kọ ni Ọba akọkọ ti yoo ni wahala pẹlu Iyawo rẹ.
Ni ọdun 2015 ni Ọọni Adeyẹye Ogunwusi de ori oye,
Ko si si ẹni to ri i ni igba naa pẹlu ti kii kan sara si Eleduwa fun ẹwa ti Oba Oke fun un.
Ọ̀rọ̀ Imam yìí ṣe kòńgẹ́ bó ti ń rí láàrin lọ́kọ láya
Ọpọ obinrin ni yoo si maa gbadura pé bí ele yii o tilẹ jọkọ ẹni ko jale ẹni.
Lẹyin o rẹyin, Wuraola Zaynab Otiti Obanor ni Ọọni Adeyẹye ja mọ lọwọ lọjọ naa lọhun loṣu kẹta, ọdun 2016 nigba ti awọn igbimọ Ọba Ile ifẹ gba ilu Benin lọ lati lọ tọrọ Wuraọla gẹgẹ bii olori tuntun fun Ọọni ile ifẹ.
Iná PHCN tó dé lójijì ṣàkóbá ńlá ní Ibadan
Nnkan n dun fun awọn mejeeji ti ọpọlọpọ si n woye pe gbogbo nnkan bii ẹwa, iyi ati ẹyẹ ni awọn mejeeji fi yẹ ara wọn.
Ati pe ayọ lo ku ki o to di pe iroyin asọ nihin lọhun lagbo ile Kabiyesi naa to bẹrẹ sii jade sita faraye gbọn.
Ni oṣu kẹjọ, ọdun 2017 ni ipinya de laarin Kabiyesi Ọọni ati olori Wuraọla.
Yàtọ̀ sí Olúwó, wo àwọn Ọba alayé tó ti kọ ìyàwó láìpẹ́
Iroyin ikọsilẹ iyawo rẹ, Chanel Chin jẹ eyi ti ọpọ awọn eeyan ko tilẹ lero rara paapaa bi a ba ni ka wo bi awọn mejeeji ṣe maa n ṣe ni gbangba.
Ọmọ ilẹ Jamaika ni Chanel Chin, Kabiyesi Oluwo kii sii fi ifẹ to ni sii pamọ nigbakugba ti awọn mejeeji ba wa ni gbangba .
Oluwo Divorce: ko si ẹni ti kò mọ pé ọmọ ilẹ̀ òkèrè ni mó fi ṣe aya
Eyii gan an lo jẹ ki iroyin ipinya wọn o jẹ iyalẹnu fun ọpọ eeyan.
Oluwo ni aawọ ti ko ṣee yanju lo ṣokunfa ikọsilẹ wọn.
Amọṣa, Kabiyesi Oluwo kọ ni Ọba akọkọ ti yoo ni wahala pẹlu Iyawo rẹ.
Oríṣun àwòrán, OláShùpò Mábínúorí
Ọba Oluwadare Adepọju ni kabiyesi Deji ti ilu Akurẹ ti ijọba ipinlẹ naa rọ loye lọdun 2010 lẹyin to ko awọn eeyan kan sodi lọ lu olori rẹ, Bọlanle Adesina to ko ẹru kuro nile lọ si ọdọ baba rẹ.
'Bí aya bá kọ ọkọ rẹ̀ silẹ̀, kó wà láì lọ́kọ̀'
Bakan naa ni iroyin sọ ọ ni igba naa pe wọn tun da eroja abanilawọjẹ kan si Olori naa lara to n mu ki ara rẹ maa ṣi bi epo.
Koda, ọga ọlọpaa nigba naa, Ogbonna Onovo pẹlu tilẹ ṣeleri niwaju ile aṣofin apapọ pe Kabiyesi naa yoo jẹjọ.
Ìwà ipá nínú ìdílé máa ń bí ìgè àti àdùbí ni tó lè já sí ikú
2020 budget: Inú mi dùn láti buwọ́lu owó ìṣúná Nàìjíríà l'ọ́jọ́ ìbí mi - Buhari
Oríṣun àwòrán, Facebook/professoryemiosinbajo
Aarẹ orileede Naijiria, Muhammadu Buhari ti buwọlu owo isuna ọdun 2020.
Bashir Ahmad to jẹ oluranlọwọ aarẹ lori ọrọ iroyin ayelujara fi fidio bi aarẹ ti ṣe buwọlu owo isuna naa soju opo Twitter rẹ.
Mike Ifabunmi: Òrìṣà ló gbè wà jù ni Brazil
Ṣaaju ni Aarẹ Buhari ti kede pe ojuṣe to dun mọ oun ninu ni lati bu ọwọ lu owo iṣuna ọdun 2020 ni ayajọ ọjọ ibi ọdun kẹtadinlọgọrin oun.
Pẹlu igbesẹ yii, orilẹede Naijiria ti pada si lilo eto imurasilẹ ati amulo owo isuna laarin oṣu kini ọdun titi di oṣu kejila ọdun.
'500 level'' ni mo wà nígbà tí mo di adélé Ọba'
Oṣu Kẹwa ọdun 2019 ni aarẹ Buhari fi aba isuna owo naa ranṣẹ si ile aṣofin Naijiria.
Triliọnu mẹwa Naira ni iye owo isuna naa, ti awọn ile aṣofin Naijiria ti ṣaaju fi ọwọ si lẹyin ayẹwo.
Catholic Church: A kò ní bó àṣírí àlùfáà tó bá bá ọmọdé lòpọ̀ mọ́
Oríṣun àwòrán, Reuters
Poopu Francis ti wọgile dida aṣọ aṣiri  bo alufaa ti wọn ba fi ẹsun ibalopọ kotọọ kan ninu ijọ Aguda.
Lati le mu iyatọ ba bi ijọ Aguda ti ṣe n fọwọ mu awọn ẹjọ to ni ṣe pẹlu ibalopo ọmọde ni wọn ṣe mu iyipada ofin yi wa.
Poopu mimọ sọ pe awọn ko ni ṣe amulo ofin yi mọ, paapa julọ fawọn ẹsun to niiṣe pẹlu nini ibalopọ pẹlu ọmọde ki idajọ to dara ba le waye lori rẹ.
Ohun ti igbesẹ yi tumọ si ni pe awọn to ba ke gbajare ẹsun ibanilopo yoo ni aanfaani lati sọrọ sita.
Loṣu keji ọdun ni awọn olori ijọ Aguda pe fun iyipada ofin yi lasiko ipade apero wọn.
Poopu sọ pe awọn ko ni i fi aṣiri gbogbo akọsilẹ ti wọn ba gbọ nipa ifipabanilopọ naa, ti wọn yoo si gbe igbesẹ otitọ, ati aabo fun awọn ti wọn ba balopọ.
Bakan naa ni Poopu sọ pe ''pe awọn ọmọ igbimọ ijọ naa gbọdọ tẹle ofin ilu, wọn si gbọdọ ran awọn oṣiṣẹ ile ẹjọ lọwọ lati ṣe iwadii ti iṣẹlẹ yii ba waye.
Ofin daṣọ aṣiri bomi yi jẹ eyi to maa n daabo bo bi wọn ti ṣe n ṣe iṣakoso ijọ Aguda.
Iwe iroyin ijọ Aguda ṣe apejuwe ofin naa bi eyi ti tawọn ileeṣẹ n lo lati fi daabo bo ara wọn tabi eyi ti awọn to di ipo ijọba mu naa n lo.
Buhari: Baba 'Go slo' ní ìṣèjọba alágbádá ti ń falẹ̀ jù fún ipinnu òun gbogbo
Oríṣun àwòrán, @MBuhari
Aarẹ Muhammadu Buhari ti ṣalaye pe sunkẹrẹ-fakẹrẹ eto iṣejọba tiwantiwa ti pọ ju fun oun.
Lasiko ti awọn eeyan kan fi wa ba a ṣe ayẹyẹ ọjọ ibi rẹ to ti pe ẹni ọdun mẹtadinlọgọrin ni ile aarẹ l'Abuja lo sọ bẹẹ.
Aarẹ Buhari ṣakawe eto igbogun ti iwa ijẹkujẹ to gbe dide lasiko iṣejọba rẹ gẹgẹ bii olori ologun lọdun 1983 si 1985 pẹlu ti asiko to wa yii gẹgẹ bii aarẹ alagbada, lẹyi to ni oun ti kẹkọọ pe iyatọ nla gbaa lo wa nibẹ.
Ọpọ awọn oloṣelu ni Ọgagun agba Buhari sọ sinu ẹwọn lẹyin oṣu diẹ to ditẹ gbajọba gẹgẹ bi ologun lọwọ ijọba alagbada nigba naa labẹ aarẹ Shehu Shagari.
Aarẹ Buhari ni oun ranti pe ni waranṣeṣa ni oun ko awọn oloṣelu ti oun funrasi pe igbe aye wọn pọ ju iṣẹ ọwọ wọn nigba naa sẹwọn nipasẹ awọn igbimọ gbogbo ti oun gbe kalẹ.
Oluwo Divorce: ko si ẹni ti kò mọ pé ọmọ ilẹ̀ òkèrè ni mó fi ṣe aya
Amọṣa, o ni oun naa gba ẹsan eyi nigba ti wọn yẹ aga mọ oun naa nidi nitori wọn fi panpẹ ofin mu oun naa wọn si sọ oun sinu ẹwọn.
Buhari ni ireti oun ni pe iṣejọba tiwantiwa yẹ ko tubọ jafafa ju ti ologun lọ amọṣa oun gan an lo wa falẹ ju.
Oríṣun àwòrán, @MBuhari
Budget 2020: Wo àwọn kókó tí àwọn ọmọ Nàìjíríà ń sọ nípa àbá ìṣúná 2020 tí Buhari buwọ́lu
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ile aṣofin Naijiria ti sọ pe ko si nkan to buru lati naa biliọnu mẹtadinlogoji ti Aarẹ Muhammadu Buhari fi ọwọ si pe ki wọn o fi tun ile aṣofin ṣe.
Agbẹnusọ fun ile asọfin, Rawlings Agada sọ fun BBC Pidgin pe, wọn ko tun ile naa ṣe lati ogun ọdun ti wọn ti kọ ọ. O fi kun un pe àjà ile naa ti n jo, ti ko si jẹ ki o ṣeeṣe fun awọn eniyan lati maa duro nibẹ.
O ko le sọ pe nitori pe ko fi bẹ ẹsi owó, ko fi ile rẹ silẹ ko wo.
BBC fi ọrọ wa a l'ẹnu wo nitori iha ti awọn eniyan kọ si ikede naa, pe owo ti wsn fẹ ẹ na ti pọ ju.
Ni ọjọ Iṣẹgun ni Aarẹ Muhammadu Buhari buwọlu abadofin eto iṣuna orilẹede Naijiria funọdun 2020.
Oríṣun àwòrán, @NGRPresident
Wo àwọn kókó tí àwọn ọmọ Nàìjíríà ń sọ nípa àbá ìṣúná 2020 tí Buhari buwọ́lu
Ni oṣu Kẹwaa ni Aarẹ Buhari gbe aba iṣuna naa to jẹ oni tiriliọnu mẹwaa ati ọọdunrun miliọnu o le diẹ naira, N10.33trn ka iwaju apapọ ijọko ile aṣofin apapọ.
O ṣe eyi lẹyin ti ẹka ile aṣofin mejeeji si joko jiroro lee lori ki wọn to fi abajade aba iṣuna oni tiriliọnu mẹwaa o le ẹẹdẹgbẹta miliọnu ati diẹ N10.59trn ranṣẹ pada si ọdọ aarẹ lẹyin ti wọn buwọlu ni ọjọ karun un, oṣu kejila, ọdun 2019.
Oríṣun àwòrán, Budgit
Wo àwọn kókó tí àwọn ọmọ Nàìjíríà ń sọ nípa àbá ìṣúná 2020 tí Buhari buwọ́lu
Lati igba ti Aarẹ ti buwọlu abadofin yii, ohun kan pataki ti awọn ọmọ orilẹ-ede Naijiria nile ati loke okun ko yee pariwo le lori ni biliọnu mẹtadinlogoji naira, N37bn ti awọn aṣofin apapọ ya sọtọ fun atunṣe ileegbimọ asofin apapọ.
Ohun ti ọpọ n sọ ni pe iye owo naa ti pọju niwọn igba ti kii ṣe pe wọn fẹ tun ileegbimọ naa kọ.
Koda, ọpọ lo fi n ṣe akawe pẹlu bilisnu mejidinlogun naira, N48bn ti wọn ya sọtọ fun ipese awọn ohun elo to tọ lẹka eto Ẹkọ.
Oríṣun àwòrán, @NigeriaGov
Aba iṣuna oni tiriliọnu mẹwaa o le ẹẹdẹgbẹta miliọnu ati diẹ N10.59trn ni aarẹ gbe ka iwaju awọn aṣofin apapọ, ṣugbọn aba iṣuna oni tiriliọnu mẹwaa o le ẹẹdẹgbẹta miliọnu ati diẹ N10.59trn.
Afikun igba o le ọgọta ati mẹta biliọnu naira, N263.946 lo gun owo naa. Ki ni awọn nnkan ti awọn aṣofin bu owo le lori?
Sola allyson, olori Ẹmi ni aala gbọdọ wa lori ohun ti awọn ololufẹ̀ olorin lee ṣe si wọn.
Owoona atigbadegba ti ko si fun sisan gbese Recurrent (Non-Debt expenditure) gba afikun to to irinwo miliọnu naira lati tiriliọnu mẹrin naira o le ẹgbẹrin miliọnu naira si tiriliọnu mẹrin o le ẹgbẹrin miliọnu ati irinwo miliọnu naira.
Owoona fun gbese sisan, (Debt servicing) gba afikun lati tiriliọnu meji o le irinwo biliọnu ati ẹẹdẹgbẹta miliọnu naira, N2.45trn si tiriliọnu meji o le ẹẹdẹgbẹrin biliọnu ati igba miliọnu naira, N2.72trn.
Ondo disability day: Ijọba ẹ gbà wá ní ariwo tí àkàndá ẹ̀dá ń pa
Owoona fun ipese ohun elo amayedẹrun (Capital expenditure) naa gba afikun lati tiriliọnu meji o le ọgọrun biliọnu ati irinwo miliọnu naira, N2.14trn si tiriliọnu meji o le irinwo biliọnu ati ẹgbẹta miliọnu naira, N2.46trn.
Ọpọ igba ti ọrọ gbese ba ti yọ ninu iṣuna Naijiria ni ariyanjiyan maa n waye ṣugbọn lọdun yii ohun ti awọn eeyan n jẹ lẹnu ni pe ṣe o yẹ ki ijọba apapọ tun maa gbimọran ati ya owo to to biliọnu mejidinlọgbọn Dọla owo ilẹ Amẹrika nigba ti iye to fẹ fi san lara gbese ti orilẹ-ede yii jẹ lọwọ gan an fun ọdun 2020 ti n pọju owo to ya sọtọ fun idagbasoke ilu lọ.
Mike Ifabunmi: Òrìṣà ló gbè wà jù ni Brazil
Ninu iṣuna ọdun 2020, tiriliọnu meji o le ẹẹdẹgbẹrin biliọnu ati igba miliọnu naira, N2.72trn lo wa fun owoona sisan gbese ati Owoona fun ipese ohun eelo amayedẹrun (Capital expenditure) si jẹ tiriliọnu meji o le irinwo biliọnu ati ẹgbẹta miliọnu naira, N2.46trn.
'500 level'' ni mo wà nígbà tí mo di adélé Ọba'
Oyo: Ilé ẹjọ́ tó ga jù dá Seyi Makinde láre gẹ́gẹ́ bíi gómìnà ìpínlẹ̀ Ọyọ
Oríṣun àwòrán, Akinlade/Abiodun/twitter
Ile ẹjọ to ga julọ ni Naijiria joko lori ẹjọ kotẹmilọrun ti oludije fun ipo gomina ipinlẹ Ogun latinu ẹgbẹ oṣelu Allied People's Movement, APM, Abdulkabir Adekunle Akinlade pe tako alatako rẹ lati inu ẹgbẹ oṣelu All Progressives Congress, APC, Dapo Abiodun.
Akinlade ti ẹgbẹ oṣelu APM lo pe ẹjọ n kotẹmilọrun tako Dapo Abiodun to jawe olubori ninu idibo sipo gomina loṣu Kẹta ọdun yii.
Akinlade ati ẹgbẹ rẹ, APM, n fẹ ki ile ẹjọ fagile idajọ igbimọ to gbọ ẹsun to ṣuyọ lori idibo naa, ati ti ile ẹjọ kotẹmilọrun, to fi idi rẹ mulẹ pe Dapọ Abiọdun lo wọle.
Kini o n ṣẹlẹ lori igbẹjọ eto idibo ipinlẹ Ọyọ?
Ile ẹjọ to ga julọ lorilẹ-ede Naijiria ti fi idi iyansipo Seyi Makinde, gẹgẹ bi pe Gomina ipinlẹ Ọyọ mulẹÌjọba Ọyọ yàtọ̀ sí ti Ọṣun àbí Ekiti tí APC leè fi àṣẹ iléẹjọ́ lé dànù - Seyi Makinde
Eyi waye lẹyin ti oludije fun ipo gomina ninu ẹgbẹ oṣelu ÀPC, Adebayo Adelabu pe ẹjọ nile ẹjọ naa pe, ki wọn o fagile idajọ igbimọ to gbọ ẹsun to ṣuyọ lori eto idibo gomina, ati idajọ ile ẹjọ kotẹmilọrun.
Awọn mejeeji lo dajọ pe Makinde ni gomina to wọle nipinlẹ ỌyọAjimọbi kí Seyi Makinde kú oríire .
Oríṣun àwòrán, @pdpoyostate
Awọn miran ti ile ẹjọ giga julọ tun ni ki wọn tẹsiwaju ninu iṣẹ ilu ti wọn n ṣe ni ipinlẹ wọn ni:
Gomina El Rufai ti ipinlẹ Kaduna, Gomina Masari ti ipinlẹ Katsina ati Gomina Sanwo Olu ti ipinlẹ Eko ati Gomina ipinlẹ Nasarawa.
Sola allyson, olori Ẹmi ni aala gbọdọ wa lori ohun ti awọn ololufẹ̀ olorin lee ṣe si wọn.
Kano couple: Bí ìyàwó mi ẹni ọdún 84 bá bí ìbejì, Hussaina ati Hassana la ó sọ wọ́n
''Bí ìyàwó mi ẹni ọdún 84 bá bí ìbejì, Hussaina ati Hassana la ó sọ wọ́n''
Ọrọ ifẹ ti ẹ ri yẹn, ko yọ ọmọde ko yọ agba silẹ.
Ohun lo difa fun Baba arugbo ẹni ọdun mẹ́rìnléláàdọ́rin kan ti o ṣalabapade iya ẹni ọdun mẹrinlelọgọrin tawọn mejeeji si fẹra wọn sile.
Bii kayeefi lọrọ naa n ṣe ọpọ awọn eeyan ilu Kano ti iṣẹlẹ naa ti waye, amọ lọkan awọn ololufẹ mejeeji, awo ti rawo lọrọ ifẹ wọn ti wọn si ni ko si onya kan ti yoo ya awọn.
Igbeyawo Muhammadu Liti ati Fatsuma ti pe ọsẹ meji ti wọn si wa ni ipele faaji tọkọtaya ti oloyinbo n pe ni ''Honey moon''
Nigba ti wọn bere lọwọ Fatsuma bi o ti ṣe yofẹ fun Muhammadu, pẹlu ẹrin lẹnu, o sọ pe ''O maa n mu ẹbun orisirisi wa bami nibi ti mo ti n ta akara''
Ondo disability day: Ijọba ẹ gbà wá ní ariwo tí àkàndá ẹ̀dá ń pa
''Awa mejeeji a maa ṣaaba ba ara wa jiyan ṣugbọn nigba ti ifẹ wọ inu ọrọ yi, niṣe la gbagbe gbogbo iwọn yẹn''
Muhammadu ni iyawo mẹta nile ṣugbọn ọkan ninu wọn ti ṣalaisi ti Fatsuma si ti gba ipo rẹ
Fatsuma sọ pe nigba tawọn pinnu lati jẹ tọkọ taya, niṣe lawọn eeyan bẹrẹ si ni gbin erokero sawọn ọmọ wọn lọkan ni ireti pe wọn yoo tako ifẹ wọn.
''Ori ba wa ṣe wi pe ọmọ mi obinrin to dagba julọ, Maimuna gbaruku tiwa bẹẹ naa si ni abikẹyin mi, Aminat''
Lọpọ igba, Muhammadu yoo ṣabẹwo si Fatsuma ti yoo si maa kọ orin ifẹ sii niṣoju awọn ọmọ rẹ.
Koda, asiko abẹwo rẹ a maa ṣe deede igba ti afẹsọna ọmọ Fatsuma naa ba wa wo o.
Nigba takọroyin wa beere lọwọ Muhammad boya awọn ọmọ rẹ tako ajọṣepọ ohun ati Fatsuma, o ni ''koda awọn ọkunrin inu wọn dawo fun oun lasiko tawọn fẹ ṣe iyawo''
Fifẹ iyawo to ju ẹyọ kan lọ kii ṣe nkan ajoji lagbegbe ariwa Naijiria paapaa ni ẹsin Islam ti awọn mejeeji jọ n sin.
Mike Ifabunmi: Òrìṣà ló gbè wà jù ni Brazil
Wọn beere lọwọ Fatsuma pe ṣe yoo wu u ki o bi ọmọ. Niṣe lo fi tayọtayọ dahun pe yoo dun mọ ohun ninu ti 'oun o si kọ lati bimọ pupọ.'
Muhammadu ninu esi ti rẹ si ibeere naa sọ pe bi Ọlọrun ba fi ọmọ ibeji ta oun lọrẹ, Husaaina ati Hassana loun yoo sọ wọn.
'500 level'' ni mo wà nígbà tí mo di adélé Ọba'
Trump Impeachment: Ààrẹ Trump n fẹ́ kí ilé aṣòfin gbọ́ ẹjọ́ rẹ̀ ní kíákíá
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Aarẹ orilẹ Amẹrika ti wọn yọ nipo, Donald Trump ti sọ pe oun fẹ ki ile aṣofin agba orilẹ-ede naa ṣe igbẹjọ oun ni kiakia.
L'Ọjọru ni wọn fi ọwọ osi juwe ile fun Trump, ṣugbọn ẹgbẹ oṣelu Democrat kọ lati bẹrẹ  igbẹjọ rẹ nile aṣofin agba.
Ẹgbẹ oṣelu Democrat  gbe igbeṣẹ yii lẹyin ti wọn ni ile aṣofin agba naa ko ni ṣe igbẹjọ to ye kooro, nitori pe awọn ọmọ ẹgbẹ oṣelu Republican ti Trump jẹ ọkan lara wọn lo pọju nibẹ.
Awọn ọmọ ẹgbẹ oṣelu Republican nile aṣofin naa pọ to de bi pe o ṣeeṣe ki wọn dibo gbe Trump lẹyin.
Iyọnipo aarẹ ọhun ti da awuyewuye silẹ ni ilu Washington.
Ẹsun ti wọn fi kan Trump ni pe pe o gbiyanju lati fi dandan mu orilẹ-ede Ukraine ko lee kede iwadii ọkan lara awọn alatako rẹ lẹgbẹ oṣelu Democrats, Joe Biden ati ọmọ rẹ Hunter.
Wọn ni o tun di ile aṣofin lọwọ iṣẹ nipa kikuna lati fọwọsowọpọ pẹlu ile naa nigba ti wọn ṣewaadi ọrọ naa.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Awọn oluwọde ni New York n lọgun ki wọn yọ Trump nipo loru ọjọ idibo lati yọ Trump
Awọn to n fọkan ba iyọni nipo aarẹ Trump ti n beere ọrọ nipa ohun to le tẹyin iṣẹlẹ yi wa.
Njẹ ẹyin naa ti n ronu nipa kini o le ṣẹlẹ si Trump lẹyin ti wọn ba ribi yọ nipo abi?
Ẹ jẹ ki a jijọ ṣagbeyẹwo diẹ́ lara  awọn ibeere to jẹyọ.
Nigba wo ni wọn yoo gbẹjọ rẹ nile aṣofin agba?
Wọn ko sọ pe dandan igba kan ni yoo jẹ amọ eleyi to fẹ sumọ igba ti yoo jẹ ni asiko tawọn aṣofin ba wole pada lẹyin isinmi loṣẹ keji inu oṣu kini ọdun to n bọ.
Asiko yi ni olori ọmọ ile to kere ju labẹ ẹgbẹ Democrat Chuck Scumer beere fun.
Bi o ti lẹ jẹ pe akẹgbẹ rẹ ninu ẹgbẹ Republican to jẹ olori ile aṣofin agba Mitch McConnel ko fi taratara gba ti asiko yi gẹgẹ bi igba ti wọn yoo bẹrẹ igbẹjọ Trump,o ṣeeṣe ki o pada faramọ.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ibeere nla re e ti ko si si ẹni to mọ esi rẹ bayi.
Awọn ọmọ ẹgbẹ Republican ni igbẹjọ yi jẹ anfaani fawọn lati le gbaruku ti aarẹ to si tun jẹ kawọn  pawọpọ da owo jọ fun ipolongo aarẹ Trump .
Ṣugbọn ni tawọn Democrats wọn ni abawọn leleyi yoo jẹ lasiko tawọn eeyan ba fẹ dibo fun Trump gẹgẹ bi aarẹ.
Oríṣun àwòrán, Reuters
The start of a key day in the House of Representatives
Esi awọn ibo abẹle kan ṣafihan pe ero ṣe ọtọọtọ laarin awọn to fẹ Trump ati awọn alatako r.
Ohun ta le sọ ni pe  ko si ẹni to le sọ ibi ti idibo aarẹ yoo fi si ṣaaju igba ti wọn yọ Trump.
Bayi ti wọn yọ, ko sẹni to le sọ ibi ti yoo ja si.
Ko si nkan to tako igbesẹ yi ninu iwe ofin Amẹrika, fun idi eyi, o ṣeeṣe bẹ.
Amọ ipenija akọkọ ti Pence yoo koju ki o to le yan Trump sipo igbakeji ni pe awọn ọmọ ile aṣojuṣofin yoo ni lati buwọlu iyansipo yi.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ti a ba woye pe awọn ọmọ ile aṣojuṣofin yi naa ni wọn fẹ ya Trump ni po,ko daju pe wọn yoo buwọlu iyansipo rẹ gẹgẹ bi igbakeji aarẹ lẹyin ti wọn ba yọ tan.
Nkan mii to ṣeeṣe ki o waye ni pe awọn ọmọ ile aṣofin agba le daba lasiko ti wọn ba n dibo ki Trump fipo silẹ pe ki o ma le di ipo miran mu lọjọ iwaju.
Bi ọrọ ba rii bẹ,Trump o ni ribi pada sipo koda ti Pence ba yan ni igbakeji.
Amọ ti wọn ko ba daba pe ko ma di ipo miran mu lọjọ iwaju,ko le si nkankanti yoo di lọwọ lati du ipo aarẹ lọdun 2020 ti o si le pada sile ijọba White House.
Ti eeyan ba gbọrọ tawọn Democrats n sọ,wọn ni lootọ ni pe awọn le ma ri Trump yọ ṣugbọn ohun to ṣe koko fawọn ni pe ki o kawọ pẹyin rojo ẹsun ti wọn fi kan.
Wọn ri iwa ti aarẹ Trump hu pẹlu bi o ti ṣe beere iranwọ lọdọ aarẹ Ukraine gẹgẹ bi aṣilo ipo fun imọtaraẹni nikan.
Bẹẹ naa si ni ọrọ tawọn eeyan n sọ pe lati ibẹrẹ ijọba Trump lawọn Democrats ti n pariwo ki wọn yẹ aga nidi rẹ.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí:
Wọn ti yọ Donhald Trump nipo gẹgẹ bi aarẹ orilẹ-ede Amẹrika ṣugbọn, ọrọ ko tii tan sibẹ.
Eredi ni pe iyọnipo ọhun si ku abala kan, leyi to wa lọwọ ile aṣofin agba orilẹ-ede ọhun nitori ọna meji ni yiyọ aarẹ nipo lorilẹ-ede Amẹrika pin si.
Orumọju ni wọn pari abala kinni, ni ibi ti wọn ti fi ẹsun kan an pe, o ṣi ipo rẹ lo gẹgẹ bi aarẹ ti wọn si fi ọwọ osi juwe ile fun un.
Abala keji yoo waye losu kinni, ọdun 2020, nibi ti ile aṣofin agba ni Washington yoo ti ṣe igbẹjọ rẹ boya o jẹbi ẹsun ti wọn fi yọọ nipo.
Ninu abala keji yii, ida meji ninu mẹta ni yoo ṣafihan boya wọn yoo le Trump kuro lori alefa patapata.
Ṣugbọ lọwọ yii, awọn ọmọ ẹgbẹ oṣelu Republican ti Trump jẹ ọkan lara wọn lo n dari ile aṣofin agba ilẹ Amẹrika, leyi ti yoo mu ki yiyọ aarẹ Trump ṣoro diẹ.
Ibi ti ọrọ de duro bayii ni pe, boti lẹ jẹ pe wọn ti yọ Trump nipo, oun si ni aarẹ titi di igba ti ile aṣofin agba yoo ṣe idibo tiwọn.
Wọ́n ti yọ Donald Trump nípò gẹ́gẹ́ bí ààrẹ orílẹ̀-èdè Amẹ́ríkà ṣùgbọ́n ọ̀rọ̀ kò tíì tán síbẹ̀.
Mobile App: Àsìkò tó wu àwọn akẹ́kọ̀ọ́ ni olùkọ́ máa jáde wa kọ́ wọn láti inú fóònù wọn
Wọn ti yọ Aarẹ orilẹ-ede Amẹrika, Donald Trump nipo.
Donald Trump ni Aarẹ orilẹ-ede Amẹrika kẹta ninu itan ti ọbẹ yoo maa ba nidi lati ọdọ awọn ile aṣoju-ṣofin lorilẹ-ede naa.
Igbesẹ yii ti wa sọ ọ di ọrọ kannakanna na ọmọ ẹga bayii nigba ti ijiroro lati buwọlu iyọnipo naa ba waye ni ile aṣofin agba nibẹ.
Ẹsun meji to da lori aṣilo ipo, ati ṣiṣe idiwo fun iṣẹ ile aṣofin-ni wọn fi kan Aarẹ Donald Trump .
Idibo lori ẹsun meji yii ko ṣai ba ilana ẹgbẹ oṣelu lọ.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Idibo yii yoo fidi mulẹ bi awọn aṣofin agba ba dibo sapa kan naa lori rẹ.
Gbogbo awọn ọmọ ẹgbẹ oṣelu Democrats yatọ si meji lo dibo fun yiyọ Trump nipo, bẹẹni awọn Republicans to jẹ ẹgbẹ oṣelu Trump dibo tako o.
Wakati mẹwaa gbako ni ijiroro lori ọna ti ilana iyọnipo naa yoo gba fi waye laarin awọn aṣofin naa gba ni Amerika.
Ni nnkan bii agogo meji abọ oru oni to jẹ agogo mẹjọ abọ alẹ lorilẹ-ede Amẹrika ni wọn bẹrẹ idibo naa.
Ondo disability day: Ijọba ẹ gbà wá ní ariwo tí àkàndá ẹ̀dá ń pa
Ẹsun aṣilo ipo ti wọn fi kan aarẹ Trump da lori ẹsun pe o gbiyanju ati fun orilẹ-ede Ukraine lokun lọrun ki o lee kede iwadii ọkan lara awọn alatako rẹ lẹgbẹ oṣelu Democrats, alagba Joe Biden.
Ẹsun keji to kọ Trump lẹsẹ ni pe o di ile aṣofin lọwọ iṣẹ nipa kikuna lati fọwọ sowọpọ pẹlu ile naa lori eto iwadii ati yọ aarẹ naa nipo pẹlu pipaṣẹ pe awọn eeyan kan ko maṣe farahan lati jẹri niwaju ile naa.
Igba o le ọgbọn, 230 awọn aṣofin lo dibo ki wọn yọ ọ lori ẹsun aṣilo ipo ti awọn mẹtadin ni igba, 197 si ta ko o.
Igba o le mọkandinlọgbọn lo dibo fun yiyọ Trump labẹ ẹsun pe o di ile aṣofin lọwọ ti awọn mejidin ni igba si ta ko o.
Mobile App: Àsìkò tó wu àwọn akẹ́kọ̀ọ́ ni olùkọ́ máa jáde wa kọ́ wọn láti inú fóònù wọn
Pẹlu iyọkuro nipo rẹ yii, Donal Trump ti di sawawu kan naa pẹlu awọn aarẹ meji miran to ti jẹ ri nilẹ Amẹrika ninu itan orilẹede ọhun.
Andrew Johnson ati Bill Clinton ni wọn ti dibo yiyọ nipo ri fun.
Eyi ti fa ijiroro ati igbẹjọ gbogbo di iwaju awọn aṣofin agba lorilẹ-ede naa lati mọ boya lootọ, Trump yoo fi ipo silẹ.
'500 level'' ni mo wà nígbà tí mo di adélé Ọba'
Ikorodu muder: Awọn ọlọpaa ni awọn yoo bẹrẹ iwadii lori iku rẹ
Oríṣun àwòrán, Mutiu Agbọnṣaṣa/facebook
Awọn ọlọpaa ni awọn yoo bẹrẹ iwadii lori iku rẹ
Lẹyin ọdun marundinlaadọta to lo loke okun gẹgẹ bii agba oluṣiro owo ni ilu New York lorilẹ-ede Amẹrika, alagba Mutiu Agboṣaṣa dari wale lati wa sinmi iṣẹ ki o lee gbadun oogun rẹ.
Amọṣa awọn ẹni ibi bẹẹ wo pẹlu iku lẹyin bii oṣu mẹta to gunlẹ si ilu Ikorodu nibi to n gbe.
Iroyin sọ pe ile igbafẹ Island club ni alagba naa ti de nibi to ti lọ ba awọn ọrẹ rẹ ṣe faaji lawọn eeyan kan ti wọn fura si gẹgẹ bi agbenipa kọ luu.
Wọn ṣaa si wẹlẹwẹlẹ lẹyin ti wọn yinbọn fun un,  wọn si gbe oku rẹ sọ sinu ọkọ kan ki wọn to dana sun un.
Mobile App: Àsìkò tó wu àwọn akẹ́kọ̀ọ́ ni olùkọ́ máa jáde wa kọ́ wọn láti inú fóònù wọn
Ileeṣẹ ọlọpaa ni awọn ti mu ẹṣọ ile oloogbe naa to wa ni Ginti Estate, lagbegbe Ijede, ni Ikorodu.
Atẹjade kan ti ileeṣẹ ọlọpaa fi sita ṣalaye pe Kọmiṣọnna ọlọpaa ni ipinlẹ Eko, Hakeem Odumoṣu ti paṣẹ iwadii to jinlẹ si iṣẹlẹ naa.
Africa Eye: Ohun tí ọ̀rẹ́ mi fí sórí 'Social Media'ló wọ̀ mí lójú- Grace
Gẹgẹ bi atẹjade ọlọpaa ṣe sọ, nnkan bii agogo meji abọ oru ni ọjọ Aiku, ni ẹṣọ naa ti orukọ rẹ n jẹ Rohis Adamu Dana de agọ ọlọpaa lati fi iṣẹlẹ naa to wọn leti.
Oríṣun àwòrán, Mutiu Agbosasa/facebook
Gẹgẹ bi  atẹjade ọhun tun ṣe fi sita, ẹṣọ oloogbe Agboṣaṣa ni nnkan bii agogo mẹwaa abọ ọjọ Satide, ọjọ kẹrinla, oṣu kejila toun ṣi geeti fun ọga oun lati wa ọkọ wọle ni awọn ọkunrin mẹrin kan ṣa deede ya wọ ọgba bi oun ti ṣe fẹ maa tii.
Ondo disability day: Ijọba ẹ gbà wá ní ariwo tí àkàndá ẹ̀dá ń pa
O ni pe ṣa deede ni oun gbọ ti ọga oun n pariwo si oun pe ki oun lọ pe awọn ọlọpaa.
Mike Ifabunmi: Òrìṣà ló gbè wà jù ni Brazil
LASEPA: Wo àwọn ohun tí o le ṣe tí yóò mú ọ rugi oyin òfin ariwo pípa l'Eko
Oríṣun àwòrán, @LasepaInfo
Wo àwọn ohun tí o le ṣe tí yóò mú ọ rugi oyin òfin ariwo pípa l'Eko
Ajọ to n mojuto ọrọ ayika ni ipinlẹ Eko, LASEPA ti ṣi ile ijọsin ati ile itura mẹrindinlọgbọn kan ti wọn ti pa tẹlẹ fun titapa si ofin to de eto ayika, paapaa julọ ariwo apọju layika ni Eko.
Bakan naa ni LASEPA tun paṣẹ fun awọn ṣọọṣi meji miran pe ki wọn ko ijọsin wọn kuro lagbegbe ti wọn wa lọwọlọwọ nitori apọju ariwo to n ṣe akoba fun adugbo ti wọn wa.
Ọga agba ajọ LASEPA, Ọmọwe Dọlapọ Faṣawẹ ṣalaye pe ajọ naa yoo maa mojuto bi awọn eeyan ati ileeṣẹ fi n tẹle ofin to de ayika ni ipinlẹ Eko.
O ni paapaa lasiko pọpọṣinṣin ọdun yii, ohun ti ijọba n fẹ ni ayika to gbadun fun araalu. Nitori naa ni ajọ naa yoo fi tubọ tẹpa mọ iṣẹ.
Mobile App: Àsìkò tó wu àwọn akẹ́kọ̀ọ́ ni olùkọ́ máa jáde wa kọ́ wọn láti inú fóònù wọn
Bakan naa lo sọrọ nipa awọn igbesẹ ti ile ati ajọ gbọdọ gbe lati bọ lọwọ paṣan ajọ LASEPA.
Ofin to de ariwo pipa ni ilu ti ipinlẹ Eko la awọn igbesẹ to yẹ kalẹ ni ọkọọkan awọn abala rẹ.
Ondo disability day: Ijọba ẹ gbà wá ní ariwo tí àkàndá ẹ̀dá ń pa
Diẹ lara awọn igbesẹ to yẹ ni gbigbe niyi:
Gbogbo eto, ilee igbafẹ bii hotẹẹli, ile ijo ati awọn ile ijọsin gbọdọ gba iwe aṣẹ ariwo.
Ẹṣẹ si ofin ni ki ẹnikẹni maa tan orin ni ita gbangba tabi lilo awo orin tabi ohun eelo orin ati ẹrọ gbohungbohun ni gbangba.
Ẹṣẹ si ofin ni lati lo ẹrọ gbohungbohun fi kede tabi polowo ohunkohun ni itagbangba lawọn agbegbe ti araalu n gbe.
Ẹṣẹ si ofin ni lati lo ẹrọ gbohungbohun fi  pe ero sọkọ ni awọn ibudokọ ero, ọja ati ita gbangba.
Ẹgbẹ tabi ajọ kankan ko gbọdọ lo ẹrọ gbohungbohun ti ko ni jẹ ki raalu ri eti gbọran lati tan iroyin, ẹsin tawọn ariwo miran lai gba aṣẹ lọwọ ajọ to yẹ.
Oríṣun àwòrán, @LasepaInfo
Mohammed Adoke: EFCC dájọ́ wíwà láhàmọ́ ọjọ́ mẹ́rìnlá fún Mínísítà ètò ìdájọ tẹ́lẹ̀
Oríṣun àwòrán, OTHER
Adajọ agba orilẹede Naijiria, Mike Ozhekome to tun jẹ agbẹjọro fun Agbẹjọro -Agba Naijiria tẹlẹ ri Mohammmed Adoke ti ta abuku ajọ EFCC lori pe wn fi panpẹ mu onibara rẹ.
O jẹ ko di mim pe wn ti kọkọ gbe Adoke l si ile ẹjọ lẹyin rẹ gan iyẹn nigba to n kawe lati gboye Masters ni Netherlands.
Ninu iwe to fọwọ si lọjọ ẹti, o ni gbigba aṣẹ ile ẹjọ lati fi Ọgbẹni Adoke si ahamọ fun odidi ọsẹ meji gbako ko tọ rara.
"O ni ""ki wa ni wọn fẹ fi kiko o ni papamọra yii ṣe, ṣe lati fi tẹ ẹ ri ni, fi iya jẹ ẹ, da a laamu ninu ọpọlọ tabi lara""? O sọ eyi nitori ailera rẹ."
Nitori naa adajọ agba fun pe si EFCC lati gba beeli agbẹjọro agba tẹlẹ ri ko le lọ tọju ara rẹ tori o ni ohun to gbe e lọ si ilu Dubai naa ni ọrọ ilera.
Ẹwẹ o ni bi wọ́n ba kọ ti wọn o ba gbọ, wọn yoo mu awọn lọranyan lati fi ọna ofin kọ aṣẹ wọn o.
Ile ẹjọ giga ijọba apapọ to wa nilu Abuja lo fun ajọ to n gbogun ti iwa ibajẹ ni Naijiria, EFCC, ni aṣẹ lati fi Agbẹjọro -Agba Naijiria, to tun jẹ Minisita fun eto idajọ, Mohammed Adoke si ihamọ fun ọjọ mẹrinla.
Onidajọ Othman Musa lo fun EFCC ni aṣẹ yii nitori iwe ẹbẹ ajọ naa ti agbẹjọro rẹ, Fatima Mustapha fun ile ẹjọ l'ọjọ Ẹti.
Mustapha sọ pe erongba lati fi Adoke si ihamọ yoo fun wsn ni asiko lati pari iwadii wọn lori ẹsun ti wọn fi kan an.
Adoke n koju ẹsun pe e o mọ nipa kiko owo kan to ni i ṣe pẹlu iwe asẹ fun ileeṣẹ epo Shell ati ENI lọdun 2011. Owo naa le ni biliọnu kan Dọla (1.3bn).
Ilu Abuja ni wọn ti mu u Adoke l'Ọjọbọ to pada si Naijiria lẹyin to ti salọ si ilẹ okeere fun ọdun mẹẹrin ni EFCC mu.
Loṣu Kẹwa ọdun ni ileeṣẹ ọlọpaa agbaye, Interpol gba Adoke mu u ni Dubai lori ipa to ko ninu apapin owo epo rọbi ti a mọ si Malabu Oil Deal.
'Mo fara da ìsòro gan láwùjọ́ torí àwọn òbí mi di létí'
Ajọ EFCC sọ pe ọga ileeṣẹ awọn, Ibrahim Magu ati awọn alaṣẹ Dubai ti ṣe ọpọlọpọ ipade lori agbẹjọro agba Naijiria tẹlẹ naa.
Lati ọjọ kọkanla oṣu Kọkanla ni Adoke ti wa ni ahamọ ni Dubai nigba ti agbẹjọro rẹ Mike Ozekhome sọ fawọn akọroyin pe o lọ gba itọju.
O sọ pe ile ẹjọ Naijiria ti ṣaaju ni Adoke ko jẹbi ẹsun ti wọn fi kan an ati pe dide to pada de si Naijiria yii, yoo lọ yanju ara rẹ lọdọ awọn to yẹ.
Mohammed Bello Adoke ni Minisita feto idajọ labẹ ijọba Goodluck Jonathan laarin ọdun 2010 si 2015.
Wòlíì bá obìnrin 300 lò pọ́, ó gba ìdájọ́ ẹ̀wọ̀n ọ́dún 19
Oríṣun àwòrán, AFN/GETTY IMAGES
Palaba wolii eke kan to pe ara rẹ ni Johannu inu bibeli 'John of God' ti ṣegi ti adajọ si ti dajọ ẹwọn ọdun mọkandilogun fun un lori ẹsun ibalopọ pẹlu awọn obinrin to le ni ọọdunrun lọna aitọ.
Idajọ yii ko ṣẹyin bi awọn obinrin kan to fi mọ ayaworan ọmọ orileede Zahira Leeneke Maus ṣe fẹsun kan pe o fi ọna aitọ ba wọn laṣepọ.
"Joao Teixeira de Faria, tawọn eeyan mọ si  ""John of God"", ni adajọ sọ pe o jẹbi ifipabalopo awọn obinrin meji ti o si laṣepọ lọna aitọ pẹlu awọn meji miran ni ile iwosan rẹ to wa ni Abadiania."
Agbẹjọro ọgbẹni Texeiria sọ pe awọn yoo tako idajọ yi toun ti pe awọn ẹsun miran ṣi wa nilẹ́ ti wọn fi kan an.
Yatọ si awọn ti a ka kalẹ, awọn obinrin ọmọ Brazil mẹsan kan ti wọn ni ki  wọn fi orukọ bo awọn laṣiri naa naka si i pe o fi ọna eburu ba wọn laṣepọ.
Ni kete ti iroyin lu sita ni ibẹrẹ oṣu Kejila ni awọn agbofinro ti kede pe awọn n wa Teixeria.
Iwe iroyin O Globo ni Brazil naa sọ pe awọn alaṣẹ fura si ipe o fẹ na papa bora nigba ti o gba owo to to miliọnu dọla mẹjọ lakoto owo rẹ meloo kan.
Aṣẹyinwa aṣẹyinbọ, Joao Teixeira de Faria jọwọ ara rẹ fawọn agbofinro to si sọ ninu fọnran fidio kan pe ''mo jọwọ ara mi fun idajọ agbara to gajulọ ti mo si mu ileri ṣẹ lati fi ara mi fun awọn to n ṣe idajọ orilẹ aye.''
Ọgbẹni Teixeria ti kii ṣe onimọ iṣegun ni wọn ti ṣaaju ni ko san owo itanran ti o si ṣẹwọn tori pe o n ṣe itọju awọn eeyan lai ni iwe aṣẹ.
Lọdun 2013, Oprah Winfrey ṣabẹwo si ile iwosan rẹ nibi to ti ri to n ṣe iṣẹ abẹ lai lo irinṣẹ abẹ.
Gẹgẹ bi ohun ti ileeṣẹ iroyin ABC News sọ, Ọgbẹni Faria sọ pe ẹmi Dokita ọgbọn ati awọn ẹmi miiran lo ma n wọ inu ara ohun ti a si maa fun oun lagbara lati ṣe iwosan fawọn eeyan.
Fayose: Mí ò ní èsìí fọ̀ f'áwọn tó ní mo dánìkàn ta ilẹ̀ ẹgbẹ́ PDP ní Ekiti
Oríṣun àwòrán, Facebook/Lere Olayinka
Gomina ana nipinlẹ Ekiti Ayodele Fayose ti fesi si ẹsun ti alaga ẹgbẹ nipinlẹ naa fi kan an pe o danikan ta ilẹ̀ ẹgbẹ fọkan lara awọn wọlewọde rẹ.
Ninu ifọrọwanilẹnuwo ti BBC ni pẹlu agbẹnusọ rẹ Lere Olayinka, Fayose sọ pe ija lo de lorin dowe lo mu ki awọn to n ba oun lorukọ jẹ fẹsun bẹẹ kan oun.
Olayinka sọ pe agba ẹgbẹ PDP ni Fayose nitori naa ko si iru ọrọ ti ara rẹ kọ.
''Ninu oṣelu Naijiria, agba ọjẹ ni Fayose jẹ. Agba kii si ya ẹnu. Nitori naa a ko ni ba awọn to n tabuku ba wa takurọsọ''
Olayinka tẹsiwaju pe lati fi iwe ẹri ibi ti Alaga ẹgbẹ ati akọwe ẹgbẹ ti buwọlu iwe pe awọn gba owo ilẹ ti ẹni to ra lọwọ ẹgbẹ da a pada si akoto owo ẹgbẹ PDP ni ilu Ekiti.
Oríṣun àwòrán, Lere Olayinka
Oríṣun àwòrán, Lere Olayinka
Lere Olayinka fi kun ọrọ rẹ pe ti ina ko ba ti lawo, kii jo kọja odo eleyi to tumọ si pe awọn kan ni wọn n ru ina si bi ọrọ yii ṣe di fa kin fa.
Ninu ọrọ tirẹ, alaga ẹgbẹ PDP ni ipinlẹ Ekiti ti a ri pe o buwọlu iwe ti Lere Olayinka fi sọwọ si wa sọ pe ayederu iwe ni Fayose n gbe ka ati pe ohun ko buwọlu iwe kankan.
O ni Fayose nikan lo da ta ilẹ naa fun wọlẹwọde rẹ ti igbimọ amuṣẹya ẹgbẹ ko si mọ nipa rẹ.
''Lootọ ni Fayose wa ba mi ki n buwọlu iwe kan ṣugbọn mo sọ pe mi o le buwọlu nitori yoo dabi pe mo n fi ọbẹ ẹyin jẹ ẹgbẹ PDP niṣu ni''
O tẹsiwaju pe ''A ko tii ta olu ileeṣẹ ẹgbẹ wa. Eyikeyi iwe ti Fayose ba ni to ṣafihan pe a jijọ ta a ni, irọ pọnbele ni''
Laipẹ yii ni Gomina Fayose sọ pe ohun gba iyọnda awọn igbimọ amuṣẹya ẹgbẹ ki ohun to ta olu ileeṣẹ ẹgbẹ PDP
Oyo PDP: Olórí ọ̀dọ́ farapa ni, ẹni tó wa ọ̀kọ́ ló kú
Oríṣun àwòrán, PolyIbada/Facebook
Ọkọ to gbe awọn ọmọ ẹgbẹ oṣelu Peoples Democratic Party ipinlẹ Ọyọ to n bọ lati ibi idajọ ile ẹjọ giga julọ nilu Abuja eyi to gbe gomina Seyi Makinde leke ni ijamba, o mu ẹmi ọmọ ẹgbẹ kan lọ awọn mẹta mii si fara pa.
Nigba ti BBC Yoruba kan si alaga ẹgbẹ oṣelu PDP nipinlẹ Ọyọ Alhaji Yemi Mustapha, o jẹ ko di mimọ lodi si awọn iroyin mii to sọ pe olori ọdọ ẹgbẹ lo ku pe irọ ni.
Ọrọ rè láti ẹnu àwọn Agbẹjọ́rò Makinde àti Adelabu nípa ìdájọ ọ́rọ́ ìdìbò Gómìnà Oyo
Asiwaju Adekola Adeoye ni olori ọdọ ẹgbẹ to jẹ kan lara awọn to farapa ninu ijamba kọ naa to si ti n gba itọju nile iwosan.
Yemi Mustapha ṣalaye pe arakunrin naa, Yemi Adeniran lo wa ọkọ ti wọn wa ninu rẹ ti wọn n gbe bọ lati Abuja wọn si ti baba wọ inu ilu Ibadan nigba ti iṣẹlẹ naa ṣẹ.
O ni ko sẹni to ku ninu awn adari ẹgbẹ ẹni to si ku yii kii ṣe ọkan lara awọn adari ẹgbẹ PDP ni ipinlẹ Oyo.
Ankara Design: Ai ri oníbara ló jẹ́ kí n wá ọ̀gbọ́n àtinúdá tèmi.
Alaga ẹgbẹ ni oun tabi gomina ko si ni ilu Ibadan nigba ti o ṣẹlẹ ṣugbọn nkan ti wn ṣalaye fun oun ni pe taya ọkọ lo fọ lori ere, arakunrin naa lo si n wa ọkọ to wa jẹ pe ẹgbẹ ọdọ rẹ ni taya ti fọ.
Ẹwẹ, Yemi Mustapha ni kete ti awọn de ti wọn si n ṣe eto ati ki gomina ku abọ ati ku oriire ni awọn tun lọ si ile ẹbi oloogbe naa lati bẹ wọn wo.
Gẹgẹ bi wọn ṣe maa n ṣe, ẹgbẹ ni igbimọ eleto ilera tiwọn to ti sare ṣe asúgbàá awọn to farapa lọ si ile iwosan.
Oloogbe Yemi Adeniran ti gbogbo eeyan mọ si Likedat ti fi igba kan jẹ olori ẹgbẹ awọn akẹkọọ Naijiria (NANS) to si lorukọ laarin awọn ọdọ oloṣelu ni ilu Ibadan.
Mikel Arteta: Wọ́n ti kéde Mikel Arteta gẹ́gẹ́ bí akọ́nimọ̀ọ́gbá ikọ̀ Arsenal tuntun
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Arteta ti sẹṣẹ gẹgẹ bi adari labẹ Pep Guardiola ni Manchester City
Ẹgbẹ agbabọọlu Arsenal ti kede Mikel Arteta gẹgẹ bi akọnimọgba rẹ tuntun.
Ninu adehun iṣẹ naa, Arteta yoo dari ikọ Arsenal fun ọdun mẹta ati aabọ.
"Idunu ati ayọ ni Arteta fi gba iṣẹ naa to si sọ pe ""O jẹ iyi nla fun mi lati dara pọ mọ ikọ Arsenal."""
"O tẹ siwaju pe ""Inu mi dun nitori Arsenal jẹ ọkan lara awọn ẹgbẹ agbabọọlu to tobi ju lagbaye."""
Arteta ti n ṣe iṣẹ tẹlẹ gẹgẹ bi adari labẹ Pep Guardiola ni Manchester City lẹyin to darapọ mọ ikọ ọhun lọdun 2016.
Ọmọ ọdun mẹtadinlogoji naa ti fi igba kan ṣe iṣẹ ni ikọ Arsenal yii ati ikọ Everton ri.
Awọn adari ẹgbẹ agbabọọlu Arsenal ko tii kede awọn ti yoo ba Arteta ṣeṣẹ.
Ankara Design: Ai ri oníbara ló jẹ́ kí n wá ọ̀gbọ́n àtinúdá tèmi.
Infibulation: Wo ọ̀nà tí obìnrin tó ti ní ìbálòpọ̀ tẹ́lẹ̀, ṣe le sọ ara rẹ̀ di ‘Virgin' lẹ́ẹ̀kejì
Oríṣun àwòrán, María Conejo/BBC
Asa adayeba ni ọpọ ilu ni pe o yẹ ki ọkọ iyawo tuntun ba aya rẹ nile, lai tii mọ ọkunrin kankan.
Amọ eyi ko ri bẹẹ mọ nitori ọdaju to de ile aye, ti awọn takọ tabo ti ko tii ni iyawo tabi ọkọ si maa n fi adun ifẹ da ara wọn lara ya.
Idi si ree ni ọpọ igba, ti ironu ati ipaya fi maa n ba ọpọ ọlọmọge to ti mọ ọkunrin amọ to n gbero lati lọ sile ẹkọ ni awọn ilu kan ti asa ibale ti gbinlẹ.
Ọpọ iru awọn obinrin yii si lo maa n wa ọna ti wọn yoo fi sọ ara wọn di ọmọge ti ko tii mọ ọkunrin lẹẹkeji lati gba ara wọn lọwọ itiju, idẹyẹsi ati ẹgan.
Koda, awọn ọmọge to ti jaye sẹyin, ti wọn si n fẹ ki ọk wọn gbagbọ pe awọn ko tii mọ ọkunrin, naa maa n dọgbọn si.
Èyí ni ìtàn bí ẹni tí mó gbọ́njú mọ̀ bíi bàbà ṣe fipá bá mi lájọṣepọ̀
Awon obinrin kan n lọ fun iṣẹ abẹ lati da abẹ fun'ra wọn, ti igbeyawo wọn ba ti ku oṣu kan tabi meji, ki wọn o le ro wi pe wundia ti ko ti i ni ibalopọ ri ni wọn.
Eyi n waye bo tilẹ jẹ wi pe ọpọ ninu wọn ni wọn ti dabẹ fun nigba ti wọn wa l'ọmọde.
Ni awọn orilẹede kan, nigba ti awọn ikoko ba wa ni ọsẹ kan si ọmọ ọdun mẹrin si mẹwa ni wọn maa n ṣe e.
Wọn maa n ṣe eyi nipa gige idọ ati labia kuro. Ti wọn si ṣa ba maa n ran an pada lati le mu ki iho oju ara o kere si. Igbesẹ yii ni wọn n pe ni infibulation.
Awọn agbẹbi lo si maa n ṣe isẹ abẹ yii amọ awọn owu ti wọn fi ran oju ara naa yoo tu u ti obinrin ba ti ni ibalopọ.
Ọkan lara awọn obinrin to ṣe e, Maha sọ fun BBC pe inira pupọ ni igbesẹ naa fa fun oun.
Maha ti a fi orukọ bo ni aṣiri ti le ni ogun ọdun, o si jẹ akẹkọọjade ni fasiti kan, bi o tilẹ jẹ pe ni ọpọ orilẹede lagbaye lonii, ofin ko fi aaye gba abẹ dida fun awọn ọmọbinrin.
"Isẹ abẹ naa dun mi pupọ, debi pe mo ni lati lọ duro si ọdọ ọrẹ mi kan fun ọpọlọpọ ọjọ titi ti ara mi fi ya nitori pe mi o fẹ ki iya mi o mọ pe mo ṣe e.
O nira fun mi lati tọ. Bakan naa ni mi o le rin daada fun ọjọ diẹ."""
Maha lọ fun iṣẹ abẹ naa nigbati o ku oṣu meji ti yoo ṣe igbeyawo pẹlu ọkunrin to ju u lọ diẹ.
"Maha sọ pe ""Ko ni i fi inu tan mi to ba fi mọ pe mo ti ni ibalopọ, ka to o ṣe igbeyawo wa."""
Niṣe ni yoo fi ofin de mi pe mi pe n ko gbọdọ maa jade tabi lo ẹrọ ibaraẹnisọrọ.
Tóò bá fún ọkùnrinn lóúnjẹ́ tóo tẹ́ kiní yẹn sílẹ̀ fún un dáadáa... - Yinka TNT
Ọpọlọpọ aṣa lo n polongo pe ibale obinrin ṣe pataki ṣaaju igbeyawo, eyi si lo maa n mu ki awọn obinrin kan tun pada lọ tun awọ fẹlẹfẹlẹ to bo ẹnu iho oju ara wọn ṣe.
Ṣugbọn, kọọrọ ni wọn ti maa n ṣe iṣẹ abẹ 'oju ara tuntun yii', nitori pe ẹgbẹ awọn onimọ iṣegun oyinbo lawọn orilẹede kan tako o.
Ọkan lara awọn agbẹbi to maa n ṣe e sọ pe lootọ ni oun korira isẹ abẹ naa, ṣugbọn oun maa n ṣe ti oun ba nilo owo fun itọju awọn ọmọ ọmọ oun ti iya wọn ti ku.
Bo tilẹ jẹ wi pe ọlaju ti de, awọn obinrin kan si n ṣe e, nitori pe awọn ọkunrin kan maa n fẹ ki iyawo ti wọn yoo fẹ ẹ, jẹ omidan ti ko ni ibalopọ ri.
Osun Politics: Aregbesola ní irọ́ n'ìròyìn tó ń sọ pé aáwọ̀ wà láàrín òun àti gómìnà Oyetola
Oríṣun àwòrán, @raufaregbesola
Gomina ana ni ipinlẹ Ọṣun to ti di minisita fọrọ abẹle bayii, Ọgbẹni Rauf Arẹgbẹṣọla ti ṣalaye pe ko si ija tabi aawọ kankan laarin oun ati gomina to wa nipo nibẹ bayii,  Gboyega Oyetọla.
Arẹgbẹṣọla yannana ọrọ naa lasiko ti wọn n fi jẹ oye Amirul Wazirul Muminina fawọn musulumi ni ipinlẹ Ọṣun.
O ti pẹ diẹ bayii ti gbọyi-sọyi lẹnu awọn eeyan ti n lọ kaakiri, paapaa julọ laarin awọn ololufẹ oloṣelu mejeeji yii loju opo ayelujara pe tirela ti gba aarin awọn mejeeji lọ.
Aisi gomina Oyetọla nibi ayẹyẹ wiwe lawani naa lo tubọ mu ki ọpọ tun maa woye pe abi lootọ ni ọrọ ọhun ni.
Amọ ni kete ti asiko to fun un lati sọrọ ni Ọgbẹni Arẹgbẹṣọla ti ti kọngọ bọ ilu ọrọ to si lu u laluye pe, aifara han Oyetọla nibi ayẹyẹ naa kii ṣe ti ija, bi ko ṣe irinajo rẹ si ilu Mẹka lati lọ ree tuuba fun Ọlọrun.
Arẹgbẹṣọla ni oun ati Gomina Oyetọla ṣi sọrọ ni owurọ ọjọ ayẹyẹ naa ati pe, ẹjẹ to ba Ọlọrun jẹ lasiko ti o fi n sare igbẹjọ idibo rẹ nile ẹjọ to ga julọ lorilẹede yii pe bi oun ba lee bori oun yoo lọ dupẹ nilẹ mimọ Mecca lo faa ti ko fi fara han nibẹ.
'Mo fara da ìsòro gan láwùjọ́ torí àwọn òbí mi di létí'
Lati igba ti igbesẹ ati yan oludije fun ipo gomina labẹ aṣia ẹgbẹ oṣelu APC fun eto idibo sipo gomina l'Ọṣun to waye lọdun 2018 ni gbọyi-sọyi ti n waye lori boya omi ọrọ laarin awọn mejeeji yii ṣi toro.
Gomina Oyetọla ni olori awọn oṣiṣẹ to ba Arẹgbẹṣọla ṣiṣẹ lasiko to fi wa ni ipo gomina ni ipinlẹ Ọṣun.
Immigration: Akẹ́kọ̀ọ́ méjì tó há sí ibùdó àtìpó ní Bosnia ti gúnlẹ̀ padà sí Nàìjíríà
Oríṣun àwòrán, @nidcom_gov
Awọn akẹkọọ ọmọ orilẹede Naijiria tawọn agbofinro fi si ahamọ ni ibode Bosnia ti gunlẹ sorilẹede Naijiria.
Awọn akẹkọ meji ọhun ti orukọ wọn n jẹ Abia Uchenna, Eboh Chinedu atawọn mẹta miran ti wọn jẹ akẹkọ fasiti imọ ẹrọ FUTO to wa nilu Owerri nipinlẹ Anambra ni wọn lọ silu Zagreb tii ṣe olu ilu Croatia lati kopa ninu idije ere idaraya ẹyin ori tabili kan to wa laarin awọn akẹkọ Fasiti lagbaye.
Ọjọ kejila oṣu kọkanla ọdun 2019 ni wọn de ibẹ ṣugbọn ọjọ kejidinlogun oṣu kọkanla kan naa ni awọn ọlọpaa gbe wọn nigba ti wọn ko lee mu iwe aṣẹ gbogbo to yẹ jade.
Eyi lo mu ki awọn ọlọpaa naa taare si ibudo ti wọn n ko awọn atipo to fẹ faya wọ wọ orilẹede naa si ni ẹnu ibode Bosnia-Herzegovina.
Ninu alaye to ṣe lori iṣẹlẹ naa, alaga ajọ to n mojuto awọn ọmọ Naijiria loke okun, NIDCOM, Abikẹ Dabiri Erewa ni awọn akẹkọ naa ko fi irinajo wọn to ajọ ere idaraya ẹyinori tabili lorilẹede Naijiria, NTTF leti ki wọn to lọ.
O ni ninu awọn marun un to rinrin ajo ọhun, meji ninu wọn ti pada sile lọsẹ meji sẹyin, awọn meji ninu wọn tẹẹ pa sọhun lati beere fun iwe igbelu fawọn atipo, nibẹ ni wahala ti bẹrẹ.
Lẹyin ọpọlọpọ ijiroro ati ifikuluku laarin awọn alaṣẹ orilẹede Naijiria ati Croatia awọn akẹkọ mejeeji ti gba itusilẹ.
ECOWAS: Buhari nàka àbùkù s'orílẹ̀èdè Libya látàrí aàbò tó mẹ́hẹ l'Afrika
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Buhari ni alafi awọn ara ilu lo yẹ ko jẹ awọn aarẹ ilẹ Afirika logun
Aarẹ Muhammadu Buhari ti bu ẹnu atẹ lu orilẹ orilẹede Lybia fun eto aabo to mẹhẹ ni awọn agbegbe iha ilẹ Afirika.
Buhari lo sọ ọrọ yii l'Abuja nibi ipade ti awọn aarẹ ati minisita to wa ni iwọ orun Afirika ṣe, lati wa ojutu si idojukọ awọn alakatakiti ẹsin.
Nibi ipade ọhun ni Buhari tun ti sọ pe iṣẹ ibi awọn alakatakiti ẹsin ni isọro gboogi to n koju iwọ orun Africa.
O ni akoko ti to ni Afirika lati fọwọsowọpọ lọna ati wa ojutu si wahala awọn alakatakiti ẹsin naa.
Buhari mẹnu ba bi awọn onija ẹsin ọhun ṣe pa awọn ọmọ ogun mẹtalelọgbọn ni ipakupa lorilẹede Niger laipẹ yii.
Trump impeachment: Trump kò fìdí janlẹ̀ tán, àmọ́ níbo ni yóò jásì?
Lẹyin naa lo ni orilẹede Naijiria ti ṣe tan lati ṣafẹhinti fun awọn orilẹ-ede mii nilẹ Afririka lati gbogun ti awọn alakatakitii ẹsin ọhun.
Buhari ni alafia awọn ara ilu lo yẹ ko jẹ awọn aarẹ ilẹ Afirika logun.
NIS: Ẹgbẹ́ dókítà làwọn kò mọ sí ìrìnàjò dókítà 58 tí NIS dènà mọ́ láti lọ sí London
Oríṣun àwòrán, Others
Ẹgbẹ́ dókítà làwọn kò mọ sí ìrìnàjò dókítà 58 tí NIS dènà mọ́ láti lọ sí London
Ẹgbẹ awọn dokita oniṣegun oyinbo ni Naijiria, NMA, lawọn ko mọ si irinajo awọn dokita mejidinlọgọta to n rinrin ajo.
Awọn ni awọn dokita kan eyi ti ileeṣẹ to n sọ iwọlewọde si orile-ede Naijiria, (NIS) dena mọ ni papakọ ofurufu ilu Eko.
Aarẹ ẹgbẹ naa lo fesi bẹẹ lẹyin ti NIS sọ pe awọn da awọn dokita wọnyi to fẹ lọ si London pada nitori pe wọn ko ni iwe aṣẹ irinna, fisa.
Koda, wọn ni awọn dokita naa ko ni lẹta lati ọdọ ileeṣẹ ilera tabi lati ọdọ ẹgbẹ onimọ iṣegun Naijiria.
Amọ ṣa, Dokita Innocent Ujah to jẹ aarẹ ẹgbẹ NMA ṣalaye fun BBC pe kii ṣe dandan ki awọn dokita gba iyọnda lọdọ ẹgbẹ naa lati rin irinajo kuro ni Naijiria.
BBC beere pe ṣe iru irinajo yi ko dẹru ba NMA pẹlu ewu to wa lasiko yi ti arun Covid-19 n ja ranyin-ranyin lagbaye.
Ninu idahun Ujah, o ni pe ''gbogbo Naijiria lo yẹ ki ọrọ yi ka laya, kii ṣe NMA nikan.''
O fi kun ọrọ rẹ pe: '' Mi o mọ nipa pe awọn ikọ dokita kankan fẹ ṣe irinajo lọ si ilẹ Gẹẹsi.
Amọ bi wọn ba fẹ lọ si ilẹ okeere, o yẹ ki a beere pe ki lo de ti awọn ọmọ Naijiria fi n sa kuro nilẹ wọn lọ si ilẹ ibomiran.
Bi ilu wọn ba gba wọn laaye daadaa ni, wọn ko ni kuro.''
Ileeṣẹ to n sọ iwọlewọde awọn eeyan si orile-ede Naijiria, Nigeria Immigration Service (NIS) ti kọdi ki awọn dokita ọmọ Naijiria mejidinlọgbọn yi ṣe irinajo lọ si ilẹ Gẹẹsi.
Bawo lo ṣe ṣẹlẹ?
Ni papakọ ofurufu Murtala Muhammed nilu Eko ni wọn ti da awọn dokita naa pada nibi ti wọn ti fẹ wọ baalu kan to wa lati London to fẹ gbe ero pada.
Alukoro ileeṣẹ naa, Sunday James ni meji pere ninu awọn dokita wọnyi lo ni iwe aṣẹ irinna iyẹn fisa.
Ati pe ti awọn mẹrindinlọgọta to ku ko si ni iwe yi.
Ninu ifọrọwanilẹnuwo pẹlu BBC, Sunday  ni ''awọn ko jẹ ki awọn dokita naa tẹsiwaju irinajo wọn nitori pe bi wọn ba fi le lọ, niṣe ni awọn alaṣẹ ilẹ Gẹẹsi yoo da wọn pada.''
O ṣalaye pe ''ọkọ baalu ti wọn fẹ ba lọ ti gba aṣẹ lati ko awọn dokita mejilelogoji lọ si ilẹ Gẹẹsi fun eto idanilẹkọ kan ṣugbọn meji pere ninu awọn mejidinlọgbọn to n lọ lo ni iwe aṣẹ irinna.
Fun idi eyi la ṣe da wọn pada''
O ni o jẹ ohun to tabuku ba awọn pe ko si iwe kankan tawọn ile iṣẹ ilera tabi ẹgbẹ awọn onimọ iṣẹgun kọ lati fi han pe wọn mọ si irinajo awọn dokita wọnyi.
Ati ọga patapata ati ọmọ iṣẹ tabi oṣiṣẹ to kere ju ni ileeṣẹ to n ri si iwọlewọde ajoji ni Naijiria ni yoo ṣe ayẹwo oogun oloro.
Oludari agba ileeṣẹ naa, Mohammad Babandede ati gbogbo oṣiṣẹ ileeṣẹ naa ni yoo ṣe ayẹwo naa.
Gẹgẹ bi alukoro ileeṣẹ naa ṣe sọ ọ, Ọgagun Babandede fi ọrọ yii lede nibi akanṣe eto ayipada ilana ẹkọ ni ile ẹkọ akọkọ ti ileeṣẹ to n ri si iwọle wọde ajoji ni ipinlẹ Kano.
Babandede ṣalaye pe eredi fun ayẹwo yii ni lati jẹ ki awọn oṣiṣẹ ṣ iṣẹ wọn daadaa gẹgẹ bi akọṣẹmọṣẹ.
O tẹnu mọ ọ pe ki wọn ṣọra nipa bi wọn ṣe n gbé ohun ija lẹnu iṣẹ wọn o si fi aridaju han pe ẹni ti ayẹwo naa ba mu, wn o ni kọkọ yọ ọ niṣẹ.
"O ni ""a o ni kọkọ le ẹni ti ayẹwo ba mu, dipo bẹẹ, a o ko wọn jọ fun ikọni."
Bi ẹnikẹni ko ba wa yiwa pada, awọn alaṣẹ yoo gbe igbesẹ lati ṣe ijiya to ba tọ.
Ǹkan tí ẹ̀mí mímọ́ fi hàn mí kí n tó bẹ̀rẹ̀ orin ìfèdèfọ̀ rèé- Testimony Jaga
Gbogbo oṣiṣẹ pata ni yoo ṣe ayẹwo naa bẹrẹ latori emi, lohun ti Babandede sọ.
"Bakan naa lori ọrọ yiyẹ aṣẹ irinna wo kete ti eeyan ba ti de orilẹ-ede Naijiria eyi ti wọn pe ni ""Visa on Arrival"","
O ni yoo jẹ anfani nla fun awọn oniṣowo ọmọ Afirika to ba n bọ lati wa ṣe owo lọna to tọ ki wn le gberu sii.
Bakan naa fun ibaṣepọ to danmọran ti yoo fọ gbogbo ohun idiwọ ẹtọ irina laarin awọn ọmọ Afirika mii.
Ẹwẹ, Babandede ni iforukọsilẹ yóò tẹsiwaju lati lee fun awọn arinrinajo lanfani ati forukọ silẹ ki wọn si le gbe ilu wọn.
Yoruba Film: Ẹ wo ohun táwọn òṣèré tíàtà ń sọ nípa Alabi Yellow tó d'olóògbé
Oríṣun àwòrán, Google
Alabi Yellow ati Kunle Afolayan ninu ere Mọkaliki
Lẹyin ti gbajugbaja oṣere Samuel Akinpelu ti ọpọ awọn ololufẹ rẹ mọ si Alabi Yellow jade lade laye, ọpọ awọn oṣere ẹgbẹ rẹ lo ti n ṣedaro rẹ.
Kunle Afolayan sọrọ loju opo Instagam rẹ pe, iku Alabi Yellow dun oun gan ni, ṣugbọn oun gbagbọ pe o gbe igbe aye to dara.
"Olorin ẹmi Tope Alabi naa ko gbẹyin ninu awọn to n ṣedaro gbajugbaja oṣere yii nigba to fi sita pe ""Sun re o."""
"Fathia Balogun naa dagbere fun Samuel Akinpelu pe ""Sun re o, Alabi Yellow."""
Yomi Fabiyi ko gbẹyin nigba to fi si sita lati ki Alabi Yellow pe o di gbere.
"Oju opo Instagram rẹ ni Yomi ti sọ pe  ""Sun re o Pa Alabi Yellow, ẹ ti sa ipa tiyin."""
Ǹkan tí ẹ̀mí mímọ́ fi hàn mí kí n tó bẹ̀rẹ̀ orin ìfèdèfọ̀ rèé- Testimony Jaga
"Lara awọn to n ṣedaro ẹni ire to lọ naa ni Damilola Ogunsi, ti wọn jọ kopa ninu ere ""Mokalik,"" o ni eeyan daadaa ni Alabi Yellow."
Yatọ si awọn oṣere tiata atawọn olorin ẹmi bi Tope Alabi, ọpọ awọn ololufẹ Alabi Yellow lo n kii pe odigbose lori itakun agbaye.
Ailera ti n ba Alabi Yellow finra fun igba diẹ ki o to wa di pe ọlọjọ de.
Ikede jade pe gbajugbaja oṣere Samuel Akinpelu ti gbogbo eniyan mọ si alabi Yellow ti jẹ eleduwa nipe.
Akinpelu jẹ oṣere ti awọn eeyan ko lee gbagbe fun iru ipa to maa n ko ninu ere sinima agbelewo lorileede Naijiria.
Nigba ti BBC Yoruba kan si Aarẹ ẹgbẹ awọn oṣere,TAMPAN, Bolaji Amusan, Mr Latin lo fidi ọrọ naa mulẹ to si ni adanu nla ni iku Alabi Yellow jẹ lagbo oṣere
Nile rẹ to wa ni  Ikorodu ni Alabi Yellow dakẹ si lowurọ ọjọ Aiku lẹyin aisan to ti fi igba diẹ de mọlẹ.
Oríṣun àwòrán, Instagram/alabiyellow
Latin ṣalaye pe oun ti ni ki Alaga ẹgbẹ TAMPAN to wa  ni Ikorodu lọ yọju si mọlẹbi oloogbe.
Sinima to kopa kẹyin ninu rẹ ni mọkaliki ti Kunle Afolayan dari rẹ.
Ailera ti n ba Alabi Yellow finra fun igba diẹ ki o to wa di pe ọlọjọ de lowurọ ọjọ Aiku.
Nigeria Police: Iléeṣẹ́ ọlọ́pàá pàrọ̀ àwọn kọmíṣọ́nà rẹ̀ láti ìpínlẹ̀ kan sí òmíràn
Oríṣun àwòrán, @gboyegaakosile
Ọga agba ileeṣẹ ọlọpaa ni Naijiria, Mohammed Adamu ti paṣẹ pe ki wọn ṣi awọn kọmiṣọna ọlọpaa kan nipo lati ipinlẹ ti wọn ti n ṣiṣẹ si omiran.
Agbẹnusọ ileeṣẹ ọlọpaa, Frank Mba lo fi ọrọ naa lede ni olu ileeṣẹ naa to wa ni ilu Abuja.
Awọn kọmiṣọna ọhun ati awọn ipinlẹ tuntun ti wọ yoo ti maa ṣiṣẹ ree.
Ipinlẹ Osun -  CP Undie J. Adie
Ipinlẹ Edo -  CP Johnson Babatunde Kokumo
Ipinlẹ Bauchi  -  CP Lawal Jimeta Tanko
Ipinlẹ Ebonyi - CP Philip Sule Maku, fdc
Ipinlẹ Gombe - CP Ahmed Maikudi Shehu
Ipinlẹ  Ondo - CP Bolaji Amidu Salami
Ipinlẹ Oyo - CP Joe Nwachukwu Enwonwu
Eastern Port - CP Evelyn T. Peterside
EOD  - CP Okon Etim Ene, fdc
Ileeṣẹ ọlọpaa ni papakọ ofurufu  -  CP Bello Maikwashi
Ẹka to n gbogun ti iwa jẹgudujẹra ni ipinlẹ Eko - CP Olukolu Tairu Shina
Ọga agba ileeṣẹ naa wa rọ awọn kọmiṣọjna tuntun ọhun lati ri daju pe wọn dabo bo awọn agbegbe tuntun ti wọn n lọ ju ti awọn to ti ṣiṣẹ ṣaaju wọn nibẹ lọ.
Lẹyin naa lo rọ awọn ara ilu lati fọwọsowopọ pẹlu ileeṣẹ ọlọpaa ki iṣẹ wọn le yọri si rere.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ọga ọlọpaa ọhun jade lati inu ọfiisi lati bere ohun to ṣẹlẹ, lo ba tun yin ọga naa nibọn
Rogbodiyan bẹ silẹ nilu Abuja nigba ti ọlọpaa kan, John Markus yinbọn pa akẹgbẹ rẹ, to si tun yinbọn pa ara rẹ lẹyin naa.
Iṣẹlẹ naa waye ni kutukutu ni agọ ọlọpaa to wa ni agbegbe Dutse, ti ọlọpaa mii si ṣeṣe.
Kọmiṣona ajọ ọlọpaa nilu Abuja, ọgbẹni Bala Ciroma fi di ọrọ naa mulẹ fun awọn oniroyin.
O ṣalaye pe iṣẹlẹ ọhun waye ni igba ti Marcus wa lẹnu iṣẹ gẹgẹ bi adena agọ ọhun yinbọn soke.
Wọn ni akẹgbẹ re, kọpura Mathew Akubo bawi, lẹyin eyi lo yin nibọn fun lagbari lẹsẹ kan naa.
Ko pẹ si ni ọkan lara awọn ọga rẹ, Abdullahi Ovanu jade lati inu ọfiisi lati bere ohun to ṣẹlẹ, lo ba tun yin ọga naa nibọn.
Lẹyin iṣẹju diẹ sii ni o ki ibọn ọhun sẹnu, to si dana si ara rẹ.
Ọga rẹ n gba itoju lọwọ nile iwosan, ṣugbọn wọn ti gbe oku rẹ lọ si ile igbokupamọsi to wa ni ile iwosan Kubwa, ni Abuja.
Ǹkan tí ẹ̀mí mímọ́ fi hàn mí kí n tó bẹ̀rẹ̀ orin ìfèdèfọ̀ rèé- Testimony Jaga
#China_kills_Muslims: Àwọn èèyàn bọ́ sórí Twitter lórí ìfìyàjẹ musulumi lọ́wọ́ọ China
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Lẹnu ọjọ mẹta yii, ẹnu ti n kun orileede China lori ẹsun pe wọn n fiya jẹ awọn ẹya orileede rẹ kan ti ọpọ wọn jẹ musulumi.
Ni agbegbe Xinjiang ni iwaadi igbimọ ajọ isọkan agbaye ti ni o fẹẹ to miliọnu kan musulumi ẹya Uyghur ti ijọba China sọ si ahamọ nibi ti wọn ti n fipa yi wọn lọkan pada.
Iroyin yii ati awọn fọnran fidio to fi mọ bawọn eekan lawujọ ti ṣe n bẹnu atẹ lu China ti mu kawọn eeyan gba oju opo Twitter kan lati fi ẹhonu han si iwa ti China n hu yii.
#China_kills_Muslims ni o n leke ninu ọrọ to n ja rain-rain ni Naijiria loju opo Twitter.
Laipẹ yi ni gbajugbaja agbabọọlu ẹgbẹ Arsenal Mesut Ozil fi ọrọ sita loju opo Twitter rẹ nibi to ti ba awọn Musulumi Uyghur China kẹdun ijiya ti wọn fi  n jẹ wọn.
Ọrọ rẹ yi mu ki ileeṣẹ amohunmaworan China fagile ṣiṣe afihan ifẹsẹwọnṣẹ ẹgbẹ Arsenal ni China.
Amọ ṣa, ọrọ Ozil ṣafikun bi awọn eeyan ti ṣe mọ si nipa ijiya awọn musulumi Uyghur tawọn kan si kan sara si fun bi o ti ṣe bawọn kẹdun.
Toun ti gbogbo nkan tawọn eeyan n sọ yii, orileede China faake kọri ni pe ko si ootọ ninu ẹsun pe awọn n fi iya jẹ awọn ẹya musulumi Uyghur.
Awọn ajafẹtọmọniyan ti n ke gbajare si ajọ isọkan agbaye lati gbe igbeṣẹ ijiya to tọ lori China ki wọn ba le dẹkun ijiya awọn Uyghur wọnyii.
Lara awọn ti o wọde fawọn Uyghur la ti ri awọn oluwọde Hong Kong ti wọn ṣapejuwe ijiya tawọn n ri lọwọ ijọba China gẹgẹ bi iru eleyi ti China fi n jẹ awọn musulumi Uyghur.
Aworan ree to ṣe afihan ibi tawọn eeyan ti n ṣe iwọde idaro pẹlu awọn musulumi Uyghur China.
CBN mu adínku ba iye owó sísan lór''i lílo ATM ni Nàíjìrìà
Oríṣun àwòrán, Central Bank of Nigeria
Banki apapọ orilẹede Naijiria lo n se isakoso eto ọrọ owo Naijiria
Ile ifowopamọ apapọ Naijiria CBN ti kede iyipada iye tawọn eeyan yoo ma san lori ifoworanṣẹ tabi gbigba owo lakoto wọn lẹnu ẹrọ ATM.
Naira marundinlogoji ni awọn ile ifowopamọ n gba tẹlẹ amọ bayi wọn yoo ma gba naira márùndínláàdọ́rin lọwọ awọn eeyan.
Ikede iyipada yi ti banki agba fi sita lọjọ Aiku loju opo Twitter wọn ṣalaye iye tawọn eeyan yoo san lati ṣe idunadura lori ẹrọ ATM tabi lohu opo ayelujara taa mọ si Internet Banking.
Nipataki ninu iyipada yi, bi eeyan ba ti fi kaadi ATM rẹ gba owo niule ifowopamọ mi ju ẹmẹẹta lọ loṣu eleyi to ba tẹle yoo san naira marundinlogoji dipo naira arundinlaadọrin ti wọn n san tẹlẹ.
Bi o ba jẹ loju opo ayelujara ni,iye owo ti eeyan yoo san lọ bayi:
Bi awọn eeyan kan ṣe n kan sara siwọn fun igbesẹ yi, lawọn mii ni ki CBN wa nkan ṣe si owo  ẹrọ POS tawọn ile epo ma n gba lori lilo POS lọdọ wọn.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí:
CAN: Ẹgbẹ́ ọmọlẹ́yìn Krístì ni ó dáa bí Amẹ́ríkà ṣé ń ṣọ́ Nàìjíríà lọ́wọ́ lẹ́sẹ̀
Oríṣun àwòrán, Dan Kitwood
Ẹgbẹ ọmọlẹyin Kristi lorileede Naijiria CAN ti kan sara si orileede Amẹrika pẹlu bo ti ṣe gb'orukọ Naijiria jade lara awọn orileede to n tẹ ẹtọ ẹsin eeyan mọlẹ.
Ninu atẹjade kan ti Pasitọ Adebayo Oladeji fi sita lorukọ aarẹ ẹgbẹ naa lọjọ Aiku, CAN ni wọn ti sọrọ yii.
CAN ni toun ti bi ko ṣe dun mọ awọn ninu pe Naijiria n gba orukọ ti ko daa, igbesẹ yii ṣafihan pe awọn ara ita naa mọ ohun toju awọn Kristẹni n ri ni Naijiria.
Ṣaaju ni Minisita feto Iroyin Naijiria Lai Mohammed ti fi atẹjade tirẹ sita to fi tako oun ti Amẹrika sọ.
Lai Mohammed ni awọn oloṣelu alatako lo n gbiyanju lati sọ Naijiria lẹnu pẹlu bi wọn ti ṣe n wọ aṣọ ẹsin fun gbogbo aawọ to n ṣẹlẹ ni Naijiria.
Ninu ọrọ CAN wọn tọka si bi aarẹ Buhari ti ṣe n fa ori apa kan da apa ka si paapa julọ pẹlu iyansipo awọn to n dari eto aabo Naijiria.
Bakanna ni CAN sọ pe awọn Kristẹni n koju inira lọwọ awọn Boko Haram ati darandaran Fulani ni awọn ipinlẹ bii Kaduna, Benue, Plateau Adama ati Taraba.
Wọn wa rọ aarẹ Buhari lati ṣe atunṣe to yẹ lati ṣe deede ati dọgba n dọgba laarin awọn eeyan Naijiria lai fi ti ẹya tabi ẹsin ṣe.
Christmas: Nkan márùn ún tóo lè fi jàjà bọ́ lọ́wọ́ ìjákulẹ̀ téélọ̀ rẹ
Nkan márùn ún tóo lè fi jàjà bọ́ lọ́wọ́ ìjákulẹ̀ téélọ̀ rẹ
Asiko ọdun Keresimesi ku dẹdẹ ti ipalẹmọ si ti n lọ ni yanturu.
Pupọ eeyan lo ti ra adiyẹ ti yoo pa, wọn ti ṣe ra epo sọkọ fun irinajo, wọn ti ra ẹbun ti wọn yoo fun ẹbi ara ati ọrẹ.
Koda, eronja jọlọọfu ti wọn yoo se lọjọ ọdun ti wa ni ṣẹpẹ. Gbogbo nkan lo ti wa ayafi nkan ẹyọkan ti o ku aṣọ ti wọn yoo fi ṣe ọdun.
Oríṣun àwòrán, @EarlJoey_.
Nkan márùn ún tóo lè fi jàjà bọ́ lọ́wọ́ ìjákulẹ̀ téélọ̀ rẹ
Ẹ pe ransọ-ransọ, o kọ, ko gbe ipe, wọn ti de sọọbu rẹ laimọye igba ṣugbọn aṣọ to loun yoo pari ni ijọ keji ko tii pari.
Ṣe ẹ ti ni iriri iru ijakulẹ yi lọwọ teeọ yin ri abi?
Bawo lo ṣe ri lara, ki si ni ohun to yẹ ki ẹ ṣe lati dena irufẹ iṣẹlẹ bẹẹ.
Alaye awọn nkan marun un tẹ le ṣe lati fi kọ ijakule lọwọ telọ yin ree.
Ohun mẹ́jọ tóo ní láti mọ̀ bí o bá fẹ́ lọ ilé ọdun
Ootọ ọrọ a ma jọ isọkusọ ṣugbọn ohun ti Idris Oluwaṣeun to ti ni iru iriri yi sọ fun BBC ni pe ki eeyan ma ran aṣọ ọdun lo ṣe ogun pe awọn telọ ko ni ja ireti rẹ kulẹ.
O ṣalaye pe o ṣoro ki ransọ-ranṣọ to ja ireti eeyan kulẹ ti ko ba ni aṣọ ti eeyan gbe fun un.
Ohun ti eleyi tumọ si ni ṣoki ni pe ki eeyan ra aṣọ ti wọn ba ti ran kalẹ tabi ki o kuku ma gbe aṣọ fun telọ rara.
Ko yẹ ki o tun ri ijakulẹ Teelọ lọdun yii
Tete  gbe aṣọ lọ ile teelọ
Bo tilẹ jẹ wi pe awọn teelọ ko mọ pe eeyan tete gbe aṣọ wa, o san ki eeyan tete gbe e lọ si ọdọ wọn ju ki eeyan pẹ gbee lọ.
Abdulwaheed Kareem to jẹ ransọ ransọ sọ fun BBC Yoruba pe lọpọ igba kii ṣe ẹbi awọn ni pe awọn kii le pari aṣọ ọdun awọn onibara awọn lasiko.
Kii ṣe gbogbo igba la fi ma n jẹbi aitete ran aṣọ ọdun awọn eeyan
O ni pupọ ''eeyan ni kii tete gbe aṣọ wa ti wọn a si ma reti pe ki a pitu pari aṣọ ti wọn ko tete gbe wa''
Ni igba wo wa lasiko to ya lati gbne aṣọ dun lọ fun ranṣọ-ranṣọ?
Abdulwaheed ni ''Bi ẹ ba yara gbe aṣọ yin lọ bi oṣu kan tabi meji ki ọdun to de,o ṣeeṣe ki ijakulẹ ma waye.''
Rii wi pe o ni aṣọ miiran kalẹ ti ijakulẹ ba waye
Teelọ ti ṣe bi o ti ṣe wu u pẹlu pe ko pari aṣọ ti o fẹ wọ lọjọ ọdun. Ko si ṣiṣe, ko si aiṣe, ohun to ku ni ki o wa aṣọ miiran lati wọ.
Ki ọrọ to di bayii, rii wi pe o ti fi aṣọ too ni niile tẹlẹ pamọ de ijakulẹ.
Fọ aṣọ rẹ, fi ẹgẹ si i, lọ ọ ko jọju ki o si ka a pamọ. Bi ijakulẹ ba waye, ṣa asọ rẹ sara ki o si maa ba faaji ọdun rẹ lọ.
Oríṣun àwòrán, @AMAAWARDS
Bẹẹni o. Ko si ohun ti adura ko le ṣe. Koda teelọ to fẹ ran aṣọ ọdun, ọrọ rẹ gba adura.
Kete ti o ba ti gbe aṣọ fun un ni ko ti ko si adura ni kikankikan.
Oríṣun àwòrán, Ahmed Ambali
Ọlamide
Tẹnumọ ninu adura rẹ pe ki ẹmi idaniduro ma ṣe ko si teelọ rẹ ninu.
Bi adura rẹ ba gba, ọrọ bu ṣe.
Ti telọ rẹ ba bere owo''ẹxpress'' waa fun un ki o to bẹrẹ si ni sọ awawi
Lọpọ igba awọn telọ ma n sọ pe iṣẹ pọ lọwọ awọn ṣugbọn wọn ko ni tori rẹ ma gba iṣẹ sii lasiko ọdun.
Ṣe o ri awọn aṣọ ti wọn gba lọdun ku la ti wọn si pari rẹ fawọn to nii, wọn san owo ju tirẹ lọ ni.
Nitori eyi, bi telọ rẹ ba ni ki o mu owo ẹxpress wa ki ohun ba le tete pari aṣọ rẹ, ti o ba ni owo naa, yara fun un.
Ọna kan ree lati fi dena ijakulẹ lọwọ telọ lasiko ọdun.
Gbogbo awọn nkan ti a ka kalẹ yi kii ṣe aridaju ọna kan gboogi lati le dena ijakulẹ.
Imọran ni wọn jẹ ti omii ninu wọn le ṣiṣẹ ti omiran si le ma kopa kankan lara teelọ rẹ.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ọdọọdun ni gbogbo ẹlẹsin Kristẹni lagbaye ma n parapọ lati se ayẹyẹ Ọjọ ibi Jesu Kristi.
Bi o ba ni ajọsepọ to ti pọ pẹlu telọ rẹ bi yoo ba ja ọ kulẹ, ko ni ro o wo lẹẹmeji.
Ayọ ati aṣọ ọdun wa la o fi ṣe keresi yio o!
Christmas:Ṣé ẹ ti ra fìlà ọdún?
Akure Kidnap: Ilé ẹjọ́ fi Wòlíì Alfa sí ẹ̀wọn ọjọ́ mọ́kànlelógún
Sotitobire Church: Ilé ẹjọ́ fi Wòlíì Alfa sí ẹ̀wọn ọjọ́ mọ́kànlelógún
Bayii awọn agbofinro ipinlẹ Ondo ti foju awọn ara ìlú ti wọn kọlu ile ijọsin naa hanỌlọ́pàá Akurẹ kó àwọn ará ìlú tí wọ́n ni wọ́n jí ẹrù Pásítọ̀ Sọ titobi rẹ kó lọ sílé ẹjọ́
Wọn ko wọn wa sile ẹjọ ni Oke Ẹda ni Akurẹ nibi ti wọn ti fẹsun kan awọn mẹtala naa pe wọn pa ọlopaa, wọn ji ohun ini Wolii Sotitobire ko nile ijọsin ti wọn dana sun ati awọn ẹsun miran Ọlọ́pàá Akurẹ kó àwọn ará ìlú tí wọ́n ni wọ́n jí ẹrù Pásítọ̀ Sọ titobi rẹ kó lọ sílé ẹjọ́
Lowurọ oni ni ijọba ipinlẹ Ondo gbe Pasitọ Alfa Babatunde tii ṣe oludasilẹ ijọ Sotitobire ni Ondo lọ si ile ẹjọ.
Lẹyin ọ̀pọ̀lọpọ̀ ohun to waye nile ẹjọ, adajọ ni ki wọn sọ Pasitọ naa si ẹwọn ọjọ mọkanlelogun gbako titi wọn yoo fi pari iwadii.
Fun idi eyi, ile ẹjọ ti sun igbẹjọ si ọjọ kẹtadinlogun oṣu kinni ọdun 2020.
Ẹsẹ̀ ko gbero ninu ile ati ita ọgba ile ẹjọ Oke Eda niluu Akurẹ nibi ti ijọba gbe e lọ.
Ṣe ni awn ero to wa woran kawọ mori nigba ti wọn ri i to jade sita lati inu ile ẹjọ tori nigba ti wọn gbe e wọle, awọn oṣiṣẹ DSS yi i ka wọn ko si jẹ ki ẹnikẹni ribi sunmọ ọ.
Ọkan lara awọn agbẹjọro to wa nibi igbẹjọ naa sọ pe ni ilana ofin, ko tii si aridaju kankan ti wọn fi lelẹ pe o jẹbi ẹsun ti wn fi kan an.
Ijọba ipinlẹ Ondo lo gbe pasitọ ijọ Sọtitobire Miracle Centre, Woli Alfa Babatunde lọ ile ẹjọ fun ẹsun ijọmọgbe.
Alfa Babatunde wa nile ẹjọ Oke Eda, to wa nilu Akure lọwọ bi a ṣe n kọ iroyin yii.
Pasitọ naa ati awọn meje miiran ni ijọba lo foju bale ẹjọ lonii.
Lara ẹsun ti wọn fi kan woli naa ati awọn eeyan rẹ ni iditẹ lati ji ọmọ gbe ati ẹsun jiji ọmọ gbe.
Gẹgẹ bi iwe ẹsun naa ṣe sọ ọ, lara awọn eeyan ti ijọba pe lẹjọ ọhun ti na papa bora.
Nigba ti akọroyin wa fi ọrọ wa agbẹjọro rẹ lẹnu wo, o ṣalaye pe bi onibara oun ko ba ṣ si ofin, wọn yoo fi silẹ. Ṣugbọn bi wọ́n ba rii pe o jẹbi, oun gan gba pe ki wọn fi jofin.
Awa gan n fẹ idajọ to tọ, lọrọ ti agbẹjọro rẹ sọ.
Akure Kidnap: Àwọn abiyamọ fẹ̀hónúhàn lórí ọmọ tí wan jígbé nílé ìjọsìn Akurẹ
Quilox: Ìjọba ìpínlẹ̀ Èkó ti Quilox, ilé ijó Shina Peller pa nítorí ariwo
Oríṣun àwòrán, @Mr_JAGs
Ijọba ipinlẹ Eko ni awọn ti sọ agadagodo si ẹnu ọna gbajumọ ile ijo Quilox lori ẹsun pe o n da ariwo pa ilu ati sunkẹrẹ fakẹrẹ ọkọ.
Amugbalẹgbẹ fun gomina ipinlẹ Eko lori ọrọ ayelujara, Jubril Gawat kede loju opo twitter pe ajọ idaboobo bo ayika lo ti ile ijo Quilox to wa lagbegbe Victoria island.
Ni ọsan ọjọ aje ni iroyin bọ sita pe Ileeṣẹ ọlọpaa ti fi panpẹ ọba mu Aṣofin Shina Abiọla to ni ile ijo naa.
Aṣofin Shina Abiọla lo n ṣoju fun ẹkun apapọ Iseyin/Itesiwaju/Kajola/Iwajowa nile aṣofin apapọ.
Ileeṣẹ ọlọpaa ni ọwọ ofin baa pẹlu awọn eeyan marun ti wọn funra si pe wọn jẹ janduku
Aṣofin Abiọla ti ọpọ mọ si Shina Peller to tun ni ile igbafẹ kan nilu Eko lawọn ọlọpaa ni mimu ti wọn mu u ko ṣẹyin rugudu kan to waye nile ijo naa lẹyin ọjọ diẹ to kede nile aṣofin pe oun ti yọwọ ninu akoso ile ijo yii.
Ileeṣẹ ọlọpaa fi ẹsun kan an pe o ko awọn janduku bii aadọta jọ lati kọlu agọ ọẹọpaa kan ni Maroko lẹyin tawọn ọlọpaa lati agọ naa lọ palẹ sunkẹrẹ fakẹrẹ ọkọ tawọn onibara ile ijo rẹ da silẹ mọ.
Ohun mẹ́jọ tóo ní láti mọ̀ bí o bá fẹ́ lọ ilé ọdun
Alukoro ileeṣẹ ọẹọpaa ipinlẹ Eko, Elkana Bala ni awọn ni lati ko ọlọpaa kun awọn to wa ni agọ naa ni ki wọn to lee ja ajabọ lọwọ awọn tọọgi ti wọn ni Shina Peller ko lọ sibẹ lati fi tipatipa ko awọn ọkọ to wa lagọ naa kuro.
Amọṣa, atẹjade kan lati ọdọ agbẹnusọ fun aṣofin Shina Abiọla ni ṣe ni aṣofin naa lọ si agọ ọlọpaa lati beeli awọn onibara ile ijo rẹ kan to wa nibẹ ti wọn ni wọn gbe ọkọ di oju popo lasiko eto kan ni ile ijo naa
Sowore: Nítorí ìròyìn Sahara Reporters, Adájọ́ ní òun kò leè gbọ́ ẹjọ́ Sowore
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Adajọ kan ni ile ẹjọ giga apapọ nilu Abuja ti ys ọwọ rẹ kuro ninu ẹjọ Ọmọyẹele Soworẹ to wa lahamọ ajọ agbofinro DSS bayii.
Ko si si idi meji ti adajọ  Mohammed la kalẹ ju wi pe, ni igba kan ri sẹyin, Ọmọyẹele Soworẹ to ni ileeṣẹ itẹwe iroyin Sahara Reporters ti fi ẹsun kan oun ri nigba meji ọtọọtọ pe  oun gba owo lori awọn nnkankan lati da kẹkẹ ẹjọ nu.
Soworẹ tọ ile ẹjọ giga apapọ lọ lati gba aṣẹ pe ki ajọ DSS ye tẹ ẹtọ ọmọniyan oun mọlẹ ati pe ki ile ẹjọ paṣẹ ki DSS san ẹẹdẹgbẹta miliọnu naira gẹgẹ bii owo gba maa binu fun oun.
Adajọ naa ni ọpọlọpẹ awọn agbẹjọro agba meji kan lo yọ oun ninu ọfin ẹsun naa.
Oluwo Divorce: ko si ẹni ti kò mọ pé ọmọ ilẹ̀ òkèrè ni mó fi ṣe aya
Onidajọ Mohammed ni idajọ ẹjọ naa lee fi si ibikibi. O ni ti idajọ oun ko ba gbe Soworẹ, o lee ro wi pe oun fi gba ẹsan iroyin ti iwe iroyin rẹ gbe jade nipa oun ni.
Amọṣa agbẹjọro fun Soworẹ, Amofin Fẹmi Falana, SAN ṣalaye pe oun ko mọ si iroyin ti adajọ n sọrọ rẹ naa. O ni nigba to ti ri bayii, ko si oun meji ju pe ki adajọ yọ ọwọ rẹ kuro ninu ẹjọ naa ni.
Agbẹjọro fun DSS, Godwin Agbadua si faramọ eyi.
Deji Adeyanju: Àwọn olólùfẹ́ Ààrẹ Buhari kọlu Deji Adeyanju àtàwọn ajàfẹ́tọ̀ọ́ tó wọ́de l'Abuja
Oríṣun àwòrán, @SaharaReporters
Awọn ololufẹ ijọba aarẹ Buhari kan to n wọde lorilẹede Naijiria ti kọlu awọn aṣiwaju ẹgbẹ ajafẹtọ nibi ti wọn ti n ṣe iwọde lati pe fun itusilẹ awọn ti ijọba fi si ahamọ 'lọna aitọ'
Ọkan lara awọn aṣaaju ẹgbẹ naa ti di ero ileewosan nilu Abuja nibiti o ti n gba itọju fun ọgbẹ ara rẹ.
Ni iwaju ileṣẹ ajafẹtọ araalu lorilẹede Naijiria, NHRC korajọ pọ si lati ke si ijsba orilẹede Naijiria lati maa bọwọ fun ofin ki wọn si tu awọn ajafẹtọ ti wọn de si igbekun silẹ.
Eyi ni igba akọkọ ti awọn ẹgbẹ to n ṣatilẹyin fun ijọba yoo gbe ina woju awọn oluwọde to n tako ijọba ni gbangba.
Oríṣun àwòrán, @SaharaReporters
Awọn eeyan ọhun ti wọn to bii ọgọta niye gbe patako ti wọn kọ oriṣiriṣi ọrọ oriyin fun aarẹ Buhari si.
Nṣe lawọn agbofinro si ko oju sẹgbẹ l;asiko ti awọn eeyan naa fi sare si Ọgbẹni Deji Adeyanju to jẹ ọkan lara awọn aṣiwaju ẹgbẹ to n tako ijọba naa.
Oríṣun àwòrán, @SaharaReporters
Lilu bii bara ni wọn luu pẹlu okuta ati igi ki awọn ọẹọpaa to ronupiwada wa gbaa silẹ. Ileewosan lo gba Ọgbẹni Deji Adeyanju silẹ .
Ohun ti awọn ẹgbẹ ajafẹtọ naa n ja fun ni itusilẹ awọn ti ijọba gbe sọ si ẹwọn lsna ti ko bofinmu ati 'didawọ awọn eeyan ti wọn fina mọ nitori iha oṣelu wọn' duro
Falana àti Garba Shehu takurọ́sọ lórí ẹsùn pé Buhari fẹ́ dupò fún sáà kẹta
Falana àti Garba Shehu takurọ́sọ lórí ẹsùn pé Buhari fẹ́ dupò fún sáà kẹta
Agbẹnusọ aarẹ Buhari, Garba Shehu ati ilumọọka agbẹjọro Femi Falana ti n gbe'na woju ara wọn lori ọrọ pe aarẹ Muhammadu Buhari yoo ṣe tabi ko ni ṣe saa kẹta.
Itakurọsọ naa to waye loju opo Twitter ti mu ki awọn eeyan bẹrẹ si ni yan ẹni ti wọn yoo gbe lẹyin ninu awọn mejeeji.
Lọjọ Aje ni Garba Shehu fi ọrọ kan sita to fi tako ọrọ to ni awọn kan n gbee kaakiri ori ayelujara pe aarẹ Buhari fẹ ṣe saa kẹta.
Ninu awọn ti Garba darukọ pe o n gbe iroyin ofege yi ka ni Femi Falana ti o ṣe apejuwe rẹ gẹgẹ bi oludije alatako to fidirẹmi ninu idibo gomina l'Ekiti lọdun diẹ sẹyin.
Laipẹ yi ni Femi Falana sọ ninu ifọrọwero kan pẹlu BBC pe oun ni ẹri pe Aarẹ Buhari ni erongba lati dije sipo aarẹ fun igba kẹta.
Garba sọ pe ko si ohun to le ṣẹlẹ ti yoo mu ki Aarẹ Buhari du ipo fun saa kẹta.
Shehu tẹnumọ ọ pe Aarẹ Buhari ko ran ẹnikẹni lati gbe igba ipolongo saa kẹta fun oun rara.
Femi Falana ko ti i fesi si ọrọ ti Garba Shehu sọ yi ṣugbọn awọn alatilẹyin Falana kan ti n fun Shehu lesi pada loju opo Twitter.
Ondo disability day: Ijọba ẹ gbà wá ní ariwo tí àkàndá ẹ̀dá ń pa
Bẹẹ lawọn to n gbe lẹyin Garba Shehu naa n dawọn lohun lori ayelujara pe:
Mobile App: Àsìkò tó wu àwọn akẹ́kọ̀ọ́ ni olùkọ́ máa jáde wa kọ́ wọn láti inú fóònù wọn
Bi adẹrinpoṣonu Stephen Sotonwa ṣé kàgbákò ikú nínú ìjàmbá ọkọ̀ ní Ondo nìyìí
Oríṣun àwòrán, Google
Bi adẹrinpoṣonu Stephen Sotonwa ṣé kàgbákò ikú nínú ìjàmbá ọkọ̀ ní Ondo nìyìí
Kaakiri loju opo ayelujara ọrọ idaro lawọn ẹbi ati ọrẹ fi n ranti rẹ.
Ta ni 'Sweet Steve' adẹ́rìnpòṣònú tí àwọn èèyàn n ṣé ìdárò rẹ̀?
Olufemi Stephen Sotonwa ti inagijẹ rẹ a si ma jẹ 'Sweet Steve' dagbere faye lọjọ Aiku ninu ijamba ọkọ kan to waye ni oju ọna Akure si Ile Oluji ni ipinlẹ Ondo
Yatọ si pe o jẹ adẹrinposonu, Sweet Steve a si tun maa ṣe atọkun eto ati adari ayẹyẹ eleyi ti oloyinbo n pe ni MC.
O ṣiṣẹ pẹlu Orange FM 94.5 ni Akure nibi to ti ṣe atọkun eto.
Iku rẹ ba awọn ti wọn mọ lojiji paapaa julọ laarin awọn akẹgbẹ rẹ lagbo sọrọsọrọ .
Woli Arole, Gbenga Adeyinka ati Omo Baba wa lara awọn to ba mọlẹbi rẹ kẹdun.
Christmas:Ṣé ẹ ti ra fìlà ọdún?
Koda Kọmiṣọnna feto ibaraẹnisọrọ nipinlẹ Ondo Donald Ojogo fi ọrọ ikẹdun sita to si ṣapejuwe Stephen gẹgẹ bi ọdọ to jẹ awokọṣe fawọn akẹgbẹ rẹ.
Ohun mẹ́jọ tóo ní láti mọ̀ bí o bá fẹ́ lọ ilé ọdun
Bánkì tó bá kọ láti tẹlé ìlànà CBN tuntun, ₦2m ní yóò fí gbára
Oríṣun àwòrán, @CBN
Ile ifowopamọ apapọ lorile-ede Naijiria CBN ti fi ikilọ sita fawọn ile ifowopamọ to ba kọti ikun si ilana tuntun ti wọn gbe jade.
Ilana yii da lori owo ti ara ilu yoo ma san ti wọn ba fi owo ranṣẹ tabi gba owo ni banki.
Ikede yi ti wọn fi sita loju opo Twitter wọn waye lẹyin eleyi ti wn sọ saaju pe iyipada ti de ba iye owo ti banki yoo ma gba lọwọ ẹni to ba gba owo nidi ATM ati loju opo ayelujara.
CBN lawọn n kede awọn ilana tuntun yi gẹgẹ bi ọna lati daabo bo awọn onibara ile ifowopamọ Naijiria
Àwọn aránṣọ yarí pé gbogbo ẹ̀bi kìí ṣe tàwọn, díẹ̀ wà lọ́wọ́ àwọn oníìbárà náà
Bakan naa ni ile ifowopamọ agba naa sọ pe awọn ile ifowopamọ ni lati ṣe akọsilẹ aroye tawọn onibara wọn ba mu wa bi bẹẹkọ wọn yoo fara gba owo itanra miliọnu naira kan.
Wọn tun ni aadọta naira ti awọn onibara n san lori rira ọja pẹlu kaadi POS ni ko yẹ ko ri bẹẹ.
CBN awọn olokowo ati ileeṣẹ to n gba owo naa lọwọ onibara lo yẹ ki wọn maa san owo naa.
Gbogbo awọn igbesẹ yii ni wọn ni yoo mu ki awọn onibara le gbadun idunadura pẹlu ile ifowopamọ wọn.
Christmas:Ṣé ẹ ti ra fìlà ọdún?
Ẹwẹ, CBN ti ṣalaye pe owo aadọta Naira tawọn ile itaja paapa julọ ile epo n gba lọwọ alabara wọn to ba lo ẹrọ isanwo POS ko tọna.
Wọn ni ile ontaja to n ta ọja falabara lo yẹ ki wọn san owo naa.
Lori eto kan to waye lori ile iṣẹ amohunmaworan Channels TV ni ẹkunrẹrẹ alaye yi ti waye.
Alaye naa ko ṣẹyin ibeere tawọn eeyan n beere latari ikede iyipada awọn owo to yẹ ni sisan fẹni to ba lo ẹrọ ATM.
Musa Jimoh to jẹ adari ni ẹka to n mojuto sisan owo ni CBN sọ pe''iwe ta gbe sita nipa pe kawọn oniṣowo ma san owo ko tumọ si pe ki onibara wọn ma san.''
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Musa tẹsiwaju pe''ti iye owo ọja ti ẹ ta ba ti kọja ẹgbẹrun kan naira,ẹyin ti ẹ n taja lẹgbọdọ san''
O ni ohun tawọn ṣalaye fawọn ile ifowopamọ ni pe awọn fẹ ki awọn olutaja tẹle aṣẹ yi ṣugbọn pupọ ninu wọn n pọn dandan fawọn onibara lati san owo naa fun wọn.
Otuoke attack: Ààrẹ Buhari ní àbò wà fún ẹ̀mí ààrẹ́ àná, Goodluck Jonathan
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Aarẹ Buhari ti pe Aarẹ ana, Goodluck Jonatha lori ẹrọ ibanisọrọ lati baa kẹdun lori ikọlu awọn agbebọn to waye ni Otuoke tii ṣe ilu ibinibi rẹ nipinlẹ Bayelsa.
Christmas & Border Closure: ìrẹsì dí góòlù fún Kérésì 2019
Ninu ọrọ ori foonu naa, aarẹ Buhari ko fi bi iṣẹlẹ naa ṣe ba oun ninu jẹ pamọ. O ṣe akawe rẹ gẹgẹ bi iṣẹlẹ ibanujẹ nla ti o si ku diẹ kaa to.
Aarẹ tun kan sara sawọn ṣọja to n ṣọ ile aarẹ Jonathan fun bi wọn ṣe koju ija naa gẹgẹ bi akin. O wa ba awọn ẹbi ọmọ ogun to ṣubu loju ija naa daro.
Parental Guidance: Ọdún méjì ni kí ẹ ti bẹ̀rẹ̀ kíkọ́ ọmọ nípa ìbálòpọ̀
Aarẹ Buhari wa fi da awọn ọmọ orilẹede Naijiria loju pe abo to yẹ n bẹ fun ẹmi aarẹ ana naa ati gbogbo awọn ọmọ orilẹede Naijiria lai yọ ẹni kan silẹ ati pe abo ni yoo tubọ maa jẹ iṣejọba oun logun.
Christmas:Ṣé ẹ ti ra fìlà ọdún?
Ni Ọjọ Iṣẹgun ni iroyin jade sita pe awọn agbebọn kan kọlu ilu Otuoke to jẹ ilu aarẹ ana, Ọmọwe Goodluck Jonathan ti wọn si pa ṣọja kan nibẹ.
Ohun mẹ́jọ tóo ní láti mọ̀ bí o bá fẹ́ lọ ilé ọdun
FRSC: Ọkọ̀ agbépo tó da epo sílẹ̀ fa súnkẹrẹ-fàkẹrẹ ní Eko sí Ibadan
Ọkọ̀ agbépo tó da epo sílẹ̀ fa súnkẹrẹ-fàkẹrẹ ní Eko sí Ibadan
Bi ẹ ba n ririn ajo lowurọ ọjọ ọdun Keresi jade kuro nilu Eko, iroyin yi yẹ ki o ṣeyin lanfaani.
Ajọ ẹṣọ alaabo oju popo ti kede pe ọkọ agbepo kan ti o danu ti ṣe okunfa idiwọ lilọ bibọ ọkọ loju ọna marosẹ Eko si Ibadan.
Ninu atẹjade kan ti Florence Okpe fi sita lorukọ ọga ajọ naa tẹka ipinlẹ Ogun, sọ pe awọn ti bẹrẹ si ni da epo inu rẹ kuro sinu ọkọ mii.
O ni fun idi eyi, awọn arinrinajo ti n koju idiwọ lataari pe sunkẹrẹ fakerẹ ọkọ ti de ba ẹgbẹ opopona mejeeji marose naa.
Ohun mẹ́jọ tóo ní láti mọ̀ bí o bá fẹ́ lọ ilé ọdun
Florence sọ pe ''Ni nkan bi aago marun un kọja iṣẹju mẹwaa ni ọkọ agbepo naa danu lẹba Mowe ''
Ajọ naa wa rọ awọn arinrinajo lati ṣe amulo ọna miran bi i ti Victoria Island- Ajah- Ijebu Ode, ati  oju ọna to gba marosẹ Lagos - Ota- Itori - Abeokuta.
Àwọn aránṣọ yarí pé gbogbo ẹ̀bi kìí ṣe tàwọn, díẹ̀ wà lọ́wọ́ àwọn oníìbárà náà
Ninu alaye rẹ ajọ naa ni yoo gba awọn ni asiko diẹ ki wọn to ribi pari eto dida epo inu ọkọ naa pada ati gbigbe kuro ninu koto to ja si.
Christmas:Ṣé ẹ ti ra fìlà ọdún?
Wizkid: 'Ọfẹ ní hug'; Ṣé Wizkid yóò fẹ padà wá kọrin ní Ilorin mọ pẹlú òun tí ojú rẹ rí
Wizkid: 'Ọfẹ ní hug
Ilorin Ilu Alimi lo gbori Twitter laarọ yi faa!
Ṣugbọn kii ṣe nitori awọn alufaa onilawani lawọn eeyan ṣe n sọrọ rẹ.
Nitori gbajugbaja olorin takasufẹ Naijiria nii, Wizkid to wa ṣere lọjọ ọdun Keresi, ni wọn ṣe n mu orukọ Ilorin bọ ẹnu
Bi o ko ba si ni agbo ariya naa to waye nile itura Kwara Hotel, jẹ ki a ṣe ofofo ara ọtọ to waye nibẹ fun ọ.
Akọkọ ohun manigbagbe to waye nibẹ ni bi awọn ololufẹ Wizkid kan ti ṣe ja wọ oju agbo ti wọn si  n dimọ gidigidi.
Kakiri ori ayelujara ni fọnran fidio ibi tawọn ololufẹ rẹ ti ja wọ oju agbo yi wa.
Ninu fidio naa, a gbọ ti Wizkid sọ fun awọn to n sọọ pe ''ọfẹ ni hug'' ti awọn ololufẹ rẹ si n dimọ bi ẹni pe o fẹ sa mọ wọn lọwọ.
Ǹkan tí ẹ̀mí mímọ́ fi hàn mí kí n tó bẹ̀rẹ̀ orin ìfèdèfọ̀ rèé- Testimony Jaga
Ko jọ bi ija ni wọn fi fa arabinrin kan kuro lọdọ Wizkid tawọn mi si n gbiyanju lati dimọ ọ.
Yatọ si ọrọ bi wọn ti ṣe gun ori itage lọ ba yi, awọn miran ti n ta si Ilorin pe wọn tabuku ba Wizkid nitori wọn gbe aga onike fun un pe ko jọko si.
Lẹnu awọn wọnyii, bi igba pe wọn o yẹ Wizkid si to ni iru iwa yi jẹ
Ohun mẹ́jọ tóo ní láti mọ̀ bí o bá fẹ́ lọ ilé ọdun
Esi tawọn to wa si agbo Wizkid naa ṣebi ẹni mu ibinu wa ti wọn si ni inu awọn dun lo jẹ awọn fi ifẹ han si Wizkid.
Wọn ni awọn o ṣẹṣẹ ma gba alejo awọn eeyan jankan jankan bi Jose Mourinho, Jayz, Falz ati pe ṣebi Wizkid gba owo ki o to wa kọrin nilu Ilorin.
Christmas:Ṣé ẹ ti ra fìlà ọdún?
Wọn ni ki ẹlẹmọṣọ awọn to n bẹnu atẹ lu Ilorin lọ ṣọ ohun ti wọn gbe sọdọ rẹ ki wọn si ma ba ariya jẹ fawọn.
Àwọn aránṣọ yarí pé gbogbo ẹ̀bi kìí ṣe tàwọn, díẹ̀ wà lọ́wọ́ àwọn oníìbárà náà
Wizkid ko sọrọ laburu nipa iṣẹlẹ to waye ni Ilorin amọ o fi ọrọ sita loju opo rẹ lati fi ifẹ han sawọn eeyan to jade wa wo o.
Igba akọkọ re e ti Wizkid yoo wa kọrin nilu Ilorin.
Ṣe yoo fẹ wa nigba miran? ni ibeere ti ọpọ n beere.
Ǹjẹ́ o mọ pàtàkì igi tó wà ní àyíká rẹ bí?
Christmas: Ìdí rè é tí Gómìnà Sanwo-Olu ṣe buwọ́lùú kí wọn tú ẹléwòn sílẹ
Oríṣun àwòrán, @jimidisu
Awọn mẹta mìí ni wọn yi idajọ iku wọn pada si ẹwọn gbeere.
Gomina Babajide Sanwo Olu ti buwọlu iwe ofin meji eleyi to faṣẹ si itusilẹ awọn ẹlẹwọn mẹfa ati iyipada idajọ iku si ẹwọn gbere fawọn mẹta miran.
Sanwo- Olu sọ pe igbesẹ yi jẹ ọna kan gboogi lati fi ẹmi imoore han lasiko ọdun Keresimesi.
Lasiko to n kopa nibi ijọsin Keresimesi ni ṣọọsi Cathedral Church of Christ, ni Marina nilu Eko lo ti lede ọrọ yii.
Agbẹnusọ rẹ, Gboyega Akọsile naa fidi ọrọ yi mulẹ fun BBC ninu ifọrọwanilẹnuwo pẹlu rẹ.
Christmas: Ẹni ti ọdun ba ti bá láyé yẹ kó dúpẹ́
Akọṣile ni: ''Ohun to yẹ gẹgẹ bi orile-ede ni ki a fi ẹmi imoore han ki a si woye nkan to ṣẹlẹ kọja ninu ọdun yi.
O ni ki a si wo ọna taa fi ṣatunṣe ki a ba le jẹ ọmọ orile-ede to dara ju ti tẹlẹ lọ''
Ohun mẹ́jọ tóo ní láti mọ̀ bí o bá fẹ́ lọ ilé ọdun
Akọsile sọ pe Gomina Sanwo- Olu ti tẹlẹ ohun ti ofin gbaa laaye lati ṣe ati pe ọwọ awọn to n dari eto idajọ nipinlẹ Eko ni itẹsiwajuọrọ naa kan tofi de ori adari awọn ẹlẹwọn naa.
Ninu awọn ẹlẹwọn to gba idande lati ri Bestman Dennar; Wasiu Jimoh; Augustine Opara; Folakemi Osin; Rebecca Danladi ati Njoku Ogechi.
Police Brutality: Ojú mi rí tó lọ́wọ́ ọlapàá nítorí Múrí màrùn ún- Adebayo Olaide
Lara awọn ti wọn yi idajọ iku pada si ti ẹwọn gbere fun ni Muhammed Abdulkadir; Moses Akpan ati Sunday Okondo.
Mo n wa'yawo - Falz
El-zakzaky: Ìjọba Nàìjíríà sọ ìdí tí kò fi tú El-Zakzaky sílẹ̀ pẹ̀lú Sowore àti Dasuki
Iléèṣẹ́ ìjọba Nàìjíríà ṣàlàyé ìdí tí kò fi tú olórí ìjọ Shia tó wà ní ìhámọ́ sílẹ̀.
Ọpọlọpọ eniyan lo ti n beere wi pe ṣe ijọba Naijiria ko fi da olori ijọ Shia Islamic Movement, Sheikh Ibrahim El-Zakzaky silẹ pẹlu Omoyele Sowore ati Sambo Dasuki.
Amọ, Minisita fun eto idajọ ni Naijiria ti sọ wi pe ko si agbara lọwọ ijọba Naijiria lati da El-Zakzaky silẹ.
O sọ wi pe ijọba apapọ ko ni ẹtọ lati da si ọrọ naa nitori wi pe ijọba ipinlẹ Kaduna lo gbe e lọ sile ẹjọ.
Ọjọ Iṣẹgun to kọja ni ijọba paṣẹ pe ki ileeṣẹ alaabo DSS o tu Sowore ati Dasuki silẹ, ti ko si ka lai si El-Zakzaky laarin wọn.
"O fi kun ọrọ rẹ pe: ""Ijọba apapọ ko le dasi eto igbẹjọ ti ipinlẹ, nitori ẹtọ ijọba ipinlẹ ni lati ṣamojuto ẹjọ to ba pe sile ẹjọ bo ba ṣe wu u."
Kílò fa èdè àìyedè láàrin ìjọba àti àwọn ọmọ lẹ́yìn El-Zakzaky?
Ọpọlọpọ igba ni ijọba apapọ ti sọ pe oun kọ l'oun fi ofin gbe El-Zakzaky, ati wi pe ijọba ipinlẹ Kaduna lo pe e l'ẹjọ.
Ṣaaju asiko yii ni ile ẹjọ ti pasẹ pe ki wọn o yọnda El-Zakzaky ati iyawo rẹ, Zinatu, amọ ti ijọba ko mu aṣẹ ile ẹjs ṣẹ.
Shiite: Ẹ̀mí àti ara wa kọ ohun tí ìjọba ń ṣe sìwa láti 2015
Lori iru awọn nkan bayii ni ijọba orilẹ-ede Amẹrika ṣe fi ikede sita ni ọjọ kejilelogun, oṣu Kejila wi pe orilẹ-ede Naijiria wa lara awọn orilẹ-ede ti ko faaye gba ẹnikẹni lati lo ẹtọ to faaye gba wọn lati ṣe ẹsin to wu u laisi idasi ijọba.
Police Brutality: Ojú mi rí tó lọ́wọ́ ọlapàá nítorí Múrí màrùn ún- Adebayo Olaide
Akọwe ijọba Amẹrika, Mike Pompeo lo kede eyi sita.
Ikede ti Amẹrika fi sita n tọka si wahala to yọri si mimu ti wọn mu Sheikh El-Zakzaky si ihamọ.
O tun ṣalaye wi pe ileeṣẹ ologun Naijiria ati awọn oṣiṣẹ alaabo to ku n fi ẹtọ ominira lati ṣe ẹsin to wu wọn dun awọn ọmọ ijọ Shia.
Ohun mẹ́jọ tóo ní láti mọ̀ bí o bá fẹ́ lọ ilé ọdun
Oṣu Kejila, ọdun 2015 ni awọn ọmọ ijọ Shia di ọna mọ awọn ọkọ to kọwọrin pẹlu Olori ileeṣẹ ologun Naijiria nigba naa, Ọgagun Tukur Buratai, nilu Zaria.
Àwọn aránṣọ yarí pé gbogbo ẹ̀bi kìí ṣe tàwọn, díẹ̀ wà lọ́wọ́ àwọn oníìbárà náà
Fidio kan si jade si gbangba, eyi to fihan bi awọn ọmọ ogun ati Shia ṣe kọlu ara wọn lasiko ti awọn ọmọ ogun fẹ ẹ kọja ni ọna naa.
Christmas: Ẹni ti ọdun ba ti bá láyé yẹ kó dúpẹ́
Wahala to waye laarin awọn ọmọ ogun nitori iṣẹlẹ naa yọri si iku ọpọlọpọ.
Lati igba naa si ni awọn alaṣẹ ti mu Zakzaky ati iyawo rẹ, Zinatu si ihamọ.
Ǹjẹ́ o mọ pàtàkì igi tó wà ní àyíká rẹ bí?
Premiership: Arsenal ta ọ̀mì 1-1 pẹ̀lú Bournemouth ní ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ àkọ́kọ́ Arteta
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Arsenal ta ọ̀mì 1-1 pẹ̀lú Bournemouth ní ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ àkọ́kọ́ Arteta
Ọmi goolu kọọkan ni Bournemouth ati Arsenal gba ni idije premiership to waye lale Ọjọbọ yii.
Ifẹsẹwọnsẹ akọkọ wọn labẹ olukọni tuntun, Mikel Arteta kii ṣe eyi to mu iyatọ pupọ wa si ti atẹyinwa.
Bournemouth lo kọkọ gba goolu wọle nigba ti ifẹsẹwọnsẹ naa wọ iṣẹju karundinlogoji pẹlu Dan Gosling.
Balogun ikọ Arsenal, Pierre-Emerick Aubameyang lo ra ọmi fun Arsenal nigba to gba goolu wọle ni iṣẹju kẹtalelọgọta ifẹsẹwọnsẹ naa.
Christmas & Border Closure: ìrẹsì dí góòlù fún Kérésì 2019
Pẹlu abajade ifẹsẹwọnsẹ yii, o fihan pe ifẹsẹwọnsẹ kan ṣoṣo ni Arsenal tii bori ninu mẹrindinlogun ti wọn gba sẹyin.
Mo n wa'yawo - Falz
Èkìtì Chieftancy: Àgbéga dé bá Ọba aláde mẹ́rìndínlógún ní Èkìtì
Oríṣun àwòrán, @ekitistategov
Ijọba ipinlẹ Ekiti ti kede agbega awọn ọba alade mẹrindinlogun ni ipinlẹ naa.
Koda, wọn tun gbe awọn agbegbe sabẹ iṣakoso ara wọn eyi ti oloyinbo n pe ni 'autonomous status'.
Igbesẹ yii ko ṣẹyin aba ti igbimọ to n ṣe agbeyẹwo ipo awọn ọba eyi ti Adajọ J.K.B Aladejana dari rẹ gbe jade.
Kọmiṣọnna fun eto ibaraẹnisọrọ ni ipinlẹ Ekiti, Muyiwa Olumilua lo fidi ọrọ yii mulẹ fun BBC Yoruba.
Olumide ṣalaye pe lẹyin ipade igbimọ alaṣẹ to waye lọsẹ to kọja ni wọn buwọlu ki wọn ṣe agbega awọn ọba.
Ninu awọn ti wọn ṣe agbega wọn si ipele to ga ju ninu ipo lọbalọba gẹgẹ bi Olumilua ti ṣe sọ lati ri:
Àlùfáà ìjọ Redeem àti ọmọ rẹ̀ méjì kú sílé ìgbafẹ́ kan lásìkò Kérésì
Ó kéré tán, ènìyàn mẹ́rìnlá tí kú nínú àjálù ọkọ̀ òfurufú tó já
Ìjọba yóò ti Afára Sagamu pa nítorí ìjàmbá iná- FRSC
Chelsea kò rọ́wọ̀ mú lẹ́yìn tí Southampton dáná sun Stamford Bridge
Akure Kidnap: E túbọ̀ ní sùúrù, a máa wá ọmọ náà rí- Alukoro ọlọ́pàá
Funke Akindele, Toyin Abraham, Bimbo Oshin ṣe Kérésìmesì lọ́nà àrà
Ilorin gbàlejò Wizkid, àwọn olólùfẹ́ rẹ̀ fẹ́ ẹ̀ gbée lójú agbo
Bi àwọn kan ṣé n jẹ àsun ní àwọn míì n ṣeré lórí omí láti gbádùn Kérésì àná
Èyí ni ìdí tí a kò fi yọ̀nda El-Zakzaky pẹ̀lúù Sowore àti Dasuki- Malami
Awọn ti wọn ṣagbega si ipo to tẹlẹ ni awọn marun un wọn yi:
Police Brutality: Ojú mi rí tó lọ́wọ́ ọlapàá nítorí Múrí màrùn ún- Adebayo Olaide
Bakan naa ni Olumilua sọ pe wọn gbe awọn ileto kan si ipo iṣakosa farawọn ti oloyinbo n pe ni 'autonomous status'.
Awọn ileto naa ni :
Mo n wa'yawo - Falz
O pari ọrọ rẹ pe eto agbega naa ṣi n tẹsiwaju ati pe awọn yoo ṣe ikede miran bi nnkan ba ti ṣe n lọ.
Larisa: Má jẹ́ kí ọjọ́ orí rẹ dí ẹ lọ́wọ́ láti bẹ̀rẹ̀ ohunkóhun to wù ọ
Ìdí tí mo fi gún olólùfẹ́ mi tẹ́lẹ̀ pa - Jacinta Igbke
Oríṣun àwòrán, Others
Idí ti mo fi gún olólùfẹ́ mi tẹ́lẹ̀ pa- Jacinta Igboke
Olùkọ́binrin nilé ẹkọ alákọbẹrẹ kan nílú Eko tó gún ololufẹ rẹ nigbakan ri lọ́bẹ pa nigba ti igbéyàwó rẹ̀ ku ọjọ díẹ̀ lo ti wà ni gbaga àwọn ọlọpàá bayii.
Lówurọ̀ ọjọ iṣẹ́gun ni Jacinta Igboke gun Arinze Ani pa ni ṣọọbu rẹ̀ lọ́na opopona Ojo ni agbegbe Satellite Town lẹ́yin ti wọ́n ni gbolohun asọ kan.
Iroyin sọ pé Ani to n Kẹmika ni ọjà ọhun ń ṣètò ìgbéyàwó pẹ̀lú obinrin mìíràn ní ọjọ kẹrin oṣù kíní ọdun 2020, lẹ́yìn ti ìná òun àti Ogboke o wọ̀ mọ́ botilẹ̀ jẹ́ pé ìbásepọ náà mu ọmọkunrin ọdun kan abọ dáni.
Akure Kidnap: E túbọ̀ ní sùúrù, a máa wá ọmọ náà rí- Alukoro ọlọ́pàá
Ìwádìí fi han pé ọ̀rọ̀ wọ́n bẹ̀rẹ̀ bi ifẹ́ òtítọ ni ọdun 2016, ṣùgbọ́n ọ̀rọ̀ dojuru ni kéte ti Igboke lóyún.
Sùgbọ́n ọ̀rọ̀ bẹ́yìn yọ lọ́jọ́ Iṣẹ́gun nígbà ti Igboke lọ si sọọbu Ani láti lọ gba owo ti yóò fi tóju ọmọ rẹ̀, èyi to si mu gbọnmi-si-omi-otó dáni ti Igboke si fi ọbẹ gun láyà.
Ẹni ọdun mọkàndinlógbọ̀n náà to jẹ́ ọmọ bíbí ìpínlẹ̀ Ebonyi sàlàye fun akọroyin iwé ìròyìn Punch ki àwọn ọlọpàá agbegbe Satellite Town eyi ti Chike Oti saju rẹ̀ to mú u gbogbo ǹkan to fa sábàbi to fi wá ja si ǹkan to ṣẹlẹ̀ yìí.
O ni àwọn òbi Ani ko faramọ ìbáṣepọ̀ àwọn nítori òun dàgbà jù ú lọ, o sì yẹ kó fẹ́ ìyàwó kan ni abule wọ́n ni ìpínlẹ̀ Ebonyi.
"O ní "" olukọ ilé ẹkọ alákọbẹ̀rẹ̀ ni mi nígbà tí èmi àti Arinze bẹ̀rẹ̀ eré ìfẹ́ wa ni ọdun 2016. Mo lóyun fun un nígbà náà ni àwọn obi rẹ̀ ni mí o le fẹ́ ẹ nitori mo dàgbà jù ú lọ àti pé dàndàn ni ki ó fẹ́ ìyàwó láti abúlé wọ́n."
"Wọ́n bi i ni ọjọ kọkandinlógun, oṣù kọkànlá ọdun 1990 wọ́n si bi èmi ni ọjọ kọkàndinlọ́gbọ̀n oṣù kẹwàá ọdun 1990.
Awọn mọlẹbi rẹ sọ pe ọmọ nìkan ni àwọn yóò gbà"
Igboke ni bótilẹ jẹ́ pé lẹ́yìn ọ̀rọ̀ náà ti orisiri ija ti n ṣẹlẹ̀, àwọn ọlọpàá ni ki Arinze maa san ẹgbẹ̀run mẹ́wàá, pali Indomie kan ati irẹsi fun òun lóṣooṣu, sùgbọ́n Arinze ko ṣe bẹẹ yala óún  pinu lati ṣe Igbeyawo, sibẹ̀ yoo maa sọ pé ko si owo.
Igboke ni òun lọ si sọọbu Arinze lojọ ti iṣẹ̀lẹ̀ yìí ṣẹ̀ láti bẹ̀ ẹ́ pe ki o fun òun lówó lati ra bàtà ọdún fún ọmọ lẹ́yin ti òun ti lọ ra aṣọ pé ṣùgbọ́n kàkà bẹ́ẹ̀ ṣe ni o ti òun ti o si ku díẹ̀ ki òun ko si ẹnu ọkada o ni ìbinu yìí ni òun fi mu ọ̀bẹ láti dààbo bo ara òun ṣùgbọn òun kò mọ ìgbà ti òun gun pa.
O rọ̀ àwọn ọlọpàá láti gbé ọmọ oun lọ si ilé ọmọ alaini iya titi àwọn ẹbi òun yóò fi wá gbé e àti pé òun kò fẹ́ kí ọmọ náà wà lọ́dọ̀ ẹbi Arinze nítori wọn o fi ìya jẹ ẹ́.
"Jacinta ni"" mo mọ̀ pé mi o lé ri ọmọ mi mọ nítori èmi gan ko ṣe tán láti wà láàye, ṣùgbọ́n àwọn ẹbi Arinze yóò fiya jẹ ọmọ mi nítori wọ́n korira mi."
Nínú ọ̀rọ̀ tirẹ̀ Agbénusọ ọlọpàá ìpinlẹ̀ Eko DSP Bala Elkana sọ pé àwọn yóò gbé afurasí náà lo si ẹka to n ṣe iwadii ọdaran fún itẹsiwáju ìwádìí.
APC vs PDP: Àwọn ọmọ Nàìjíríà ò rí ti APC rò mọ́
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ẹgbẹ oṣelu Peoples Democratic Party ti ni lorilẹede Naijiria o, ko sẹni to n ronu ti ẹgbẹ oẹlu APC mọ.
Wakati melo kan sẹyin ni wọn fi sita gẹgẹ bii pipe akiyesi ẹgbẹ oṣelu to wa lori alefa lọwọlọwọ ni Naijiria, All Progressives Congress si ikede wọn pe awọn ti n ro ẹni ti yoo jẹ oludije to n bọ.
Ẹgbẹ oṣelu PDP ni awọn n fi to aarẹ Buhari atawọn adari ẹgbẹ oṣelu APC leti wi pe awọn Naijiria ti tẹsiwaju ninu irinajo wọn kọja ki wọn maa ronu ọrọ APC.
Awọn si ti n pinu ẹni ti yoo gba eku ida iṣejọba ni ọdun 2020 fun ẹgbẹ oṣelu PDP lati mu apapọ ireti wọn ṣẹ gẹgẹ bi ẹgbẹ lati tun orilẹede yii kọ.
Oríṣun àwòrán, OfficialPDPNig
Mo funra sí 'Swimming Pool' tí ọkọ àti àwọn ọmọ mi rì sí  - Olubunmi Diya
Àlùfáà ìjọ Redeem àti ọmọ rẹ̀ méjì kú sílé ìgbafẹ́ kan lásìkò Kérésì
Ìdí tí mo fi gún olólùfẹ́ mi tẹ́lẹ̀ pa - Jacinta Igboke
Ìjọba korò ojú sí bí Islamic State ṣe bẹ́ àwọn Kristiẹni mẹ́wàá lórí ní Bornu
Orí yọ èèyàn mẹ́ta nínú ilé tí ọkọ̀ bàálù dédé já wọ̀
Wọn jẹ ko di mimọ pe dajudaju itan ti fi han pe ati APC ati iṣejọba rẹ, ko ṣee ma ni ni wọn ṣugbọn pe wọn ti de opin irinajo wọn bayii.
Wọn ta abuku ba iṣejọba ẹgbẹ oṣelu APC pe pẹlu iroyin ti oniruuru ẹgbẹ ilẹ okere to fi mọ United States Department of State kọ ṣafihan iwa ipa lasiko idibo, dida ibo ru, didi awọn araalu lọwọ ẹtọ wọn ati bẹẹ bẹẹ lọ.
Wọn fi ọpọlọpọ nkan to ṣẹlẹ lasiko idibo ipinlẹ Bayelsa ati Kogi ṣe apẹẹrẹ.
Yàjóyàjó: Èsì ìdìbò Kogi tó gbé Yahaya Bello wọlé rèé
Ẹgbẹ́ òṣèlú AA kò gbọdọ̀ kópa nínú ìdìbò gómìnà ní Kogi, Bayelsa - Ilé ẹjọ́
Ohun tawọn eeyan Kogi n sọ saaju idibo Gomina
Ẹwẹ, bi PDP ṣe fi igboya kọ ikede wọn yii sita ni awọn ọmọ Naijiria ti ya bo wọn lati fesi.
Bi awọn kan ṣe ni paaga, ki PDP da ọrọ ti wọn sọ pada pe ki wọn ye yin ara wọn tabi tabuku ba ẹgbẹ APC bẹẹ lawọn to fọwọ si ohun ti wọn sọ naa n kan sara si wọn.
Oríṣun àwòrán, OTHER
Kogi vs Bayelsa: Primate Ayodele sọ àsọtẹ́lẹ̀
Oluwo, ó yẹ kí o bọ̀wọ̀ fún ara rẹ - Olorì àná, Chanel Chin
Oríṣun àwòrán, Queen Cha/instagram
Kii ṣe tuntun mọ pe kabiyesi Oluwo ti ilu Iwo, Ọba Rasheed Akanbi ati olori rẹ, Chanel Chin ti kọ ara wọn silẹ. Bi o tilẹ jẹ pe kabiyesi funrarẹ lo kede iyapa laarin wọn, olori Chanel ko fọhun lori ọrọ ana ayafi bayii lori oju opo Instagram rẹ.
Ninu ọrọ to fi sita loju opo naa, Olori ana, Chanel Chin ṣalaye pe lati igba ti Oluwo ti n fọnrere ọrọ naa lori ayelujara, oun mọọmọ dakẹ ni. o fẹsun kan kabiyesi pe oniruuru ọrọ ibanilorukọ jẹ ni kabiyesi ti sọ nipa oun ṣugbọn ọbẹ kii mi nikun agba loun fi ṣe.
O ni ọ̀wọ̀ ti oun ni fun itẹ Oluwo ni ko jẹ ki oun sọrọ si gbogbo oun ti Kabiyesi Oluwo to jẹ ọkọ oun ana n fi sita.
Amọṣa, bi kabiyesi ko ba bọwọ fun ara rẹ tabi ori itẹ to joko si ...ta ni yoo bọwọ fun un
Akure Kidnap: E túbọ̀ ní sùúrù, a máa wá ọmọ náà rí- Alukoro ọlọ́pàá
O ni igba akọkọ kọ niyii ti Oluwo yoo maa ba awọn eeyan lorukọ jẹ tabi hun irọ jọ nipa eniyan.
Amọṣa kabiyesi naa ti fesi, oluwo ni bo ba wu olori ana lati duro si Orilẹede naijiria, dede ara rẹ ni o, ṣugbọn gbogbo ẹtọ to yẹ fun irinajo rẹ pada si Canada tii ṣe orilẹede rẹ loun ti ṣe.
Texas Shooting: Ìsìn dàrú lẹ́yìn t'ágbébọn pàyàn méjì ní ṣọ́ọ̀ṣì
Isin n lọ lọwọ ni ile ijọsin West Freeway Church of Christ
Ọrọ di bo o lọ, o yaa mi lẹyin ti ọkunrin kan da'bọn bo'lẹ nile ijọsin West Freeway Church of Christ ni Texas lorilẹede Amẹrika nigba ti isin n lọ lọwọ.
Ọkunrin naa lo ṣadeedee dide to si yinbọn fun eeyan meji, amọ ọwọ palaba rẹ segi nigba olujọsin kan yinbọn fun oun naa, to si gba ibẹ dero ọrun.
Ni kete ti olujọsin naa yinbọn fun agbebọn ọhun tan lawọn olujọsin mii naa fa ibọn yọ, bẹẹ ni wọn doju ibọn kọ ọkunrin agbebọn naa.
Ile iṣẹ ọlọpaa ṣalaye pe awọn meji ti agbẹbọn naa yinbọn fun ti jẹ Ọlọrun ni'pe nile iwosan ti wọn gbe wọn lọ.
Awọn agbofinro ni iwadii ṣi n lọ lọwọ lati mọ ohun ti agbebọn naa ni lọkan gan an to fi dabọn bo lẹ nigba ti ijọsin n lọ lọwọ.
Fọnran iṣẹlẹ ọhun lori ayelujara ṣafihan bi awọn to wa nile ijọsin ṣe n sa si abẹ aga lati rii pe ibọn ko ba wọn nibi ti wọn wa.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Alufaa ijọ naa, Jack Cummings sọ fawọn akọroyin pe ọkunrin naa ko ba ṣekupa ọpọ eeyan ti kii ba ṣe pe awọn olujọsin to ni iwe ibọn wa ninu ṣọọṣi naa.
Ẹwẹ, Gomina ipinlẹ Texas, Greg Abbott ti bu ẹnu ẹtẹ lu iṣẹlẹ naa, o ni iwa ipa to buru julọ ni.
Eeyan mejilelogun lawọn agbebọn ṣekupa ninu oṣu kẹjọ ọdun 2019 ni El Paso nipinlẹ Texas bakanna.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Awọn olujọsin
Ninu oṣu kẹjọ kan naa ni agbebọn mii tun yinbọn pa meje ni Odessa-Midland ni Texas.
Lọdun 2017, agbebọn kan tun yinbọn pa olujọsin mẹrindinlọgbọn ninu ijọ Onitẹbọmi kan ni Sutherland Springs lasiko ti isin n lọ lọwọ.
Eleyi lo mu ki ipinlẹ Texas ṣe agbekalẹ ofin to fun awọn eeyan to ba ni iwe ẹri lanfaani lati maa gbe ibọn lọ si ile ijọsin.
Drunk driving: Mu pàrágá wakọ̀ l'Oyo, kóo kó sí gbaga ìjọba
Oríṣun àwòrán, Other
Omi tuntun ti ru, ẹja tuntun ti wọ ọ ni ipinlẹ Oyo. Awakọ mẹẹdọgbọn ni ọwọ ofin ti tẹ nipinlẹ naa lori ẹsun pe wọn n muti nigba ti wọn tun n wa ọkọ.
Kọmiṣọna fun eto iroyin nipinlẹ naa, Wasiu Olatubosun to ba BBC Yoruba sọrọ ṣalaye pe igbesẹ yii yoo jẹ ẹkọ fawọn awakọ mii ti wọn ba tun fẹ hu iru iwa bẹẹ.
Lopin ọsẹ to lọ ni ajọ to n ri si idari ọkọ ni ipinlẹ Oyo, OYRTMA mu awọn awakọ naa pẹlu iranlọwọ ẹrọ igbalode to le ṣafihan bi eeyan ba mu ọti.
Kọmiṣọnna Olatubọsun sọ pe gbogbo awọn awakọ mẹẹdọgbọn naa ni yoo foju ba ile ẹjọ.
Kọmiṣọnna ni ile ẹjọ si ni yoo sọ pato ijiya to tọ si wọn.
Ọgbẹni Olatubosun tun fi kun ọrọ rẹ pe mimu awọn awakọ to n mu ọti kii ṣe ninu asiko pọpọsinsin nikan.
Oríṣun àwòrán, Facebook/Inside Oyo
Kọmiṣọnna fun eto iroyin nipinlẹ ni eto naa yoo tẹsiwaju ninu ọdun 2020 nitori ẹmi awọn eeyan ipinlẹ jẹ ijọba Gomina Ṣeyi Makinde logun.
Ẹwẹ, alaga OYRTMA, Dokita Akin Fagbemi ṣalaye pe igbesẹ ajọ wọn lati mu awọn ọmuti awakọ wa ni ibamu pẹlu iṣẹ ajọ naa lati dẹkun ijamba ọkọ tawọn ọmuti awakọ n ṣe okunfa rẹ nipinlẹ Oyo.
O fi kun ọrọ rẹ pe ni opopona Ring-Road, Iwo-Road, ati Moniya si Ogbomoso ni wọn ti mu awọn awakọ ọhun.
Oluwo: Ohun tó ṣẹlẹ̀ sí mi ni yóò ṣẹlẹ̀ sí ẹni tó bá sọ̀rọ̀ takò mí
Oríṣun àwòrán, Instagram
Ojú òpó Instagram rẹ̀ ni Oluwo ti Ìlú Iwo ti bu ẹnu àtẹ́ lu bí àwọn kan se da lẹ́bi lórí ìtúká ìgbéyàwó rẹ̀.
Oluwo ti Ilu Iwo, Ọba Rasheed Akanbi ti bu epe lu ẹnikẹni to ba da a lẹbi lori bi igbeyawo rẹ ati olori tẹlẹri, Chanel Chin.
Ojú òpó Instagram ni Oluwo ti Ìlú Iwo ti bu ẹnu àtẹ́ lu bí àwọn kan ṣe dá a lẹ́bi lórí bí  ìgbéyàwó rẹ̀ pẹlu olori naa ṣe túká.
Eyi ko sẹyin bi awọn kan ṣe n bu ẹnu atẹ lu ọba naa lori ẹrọ ayelujara lori bi o ṣe tu igbeyawo naa ka pẹlu Chanel Chin.
Oluwo ni oun gbiyanju titi oun ninu igbeyawo naa, ati wi pe ki iya to jẹ oun jẹ ẹnikẹni to ba da oun lẹbi. O ni bi oun ba ṣe ibi ninu idapọ to ṣẹṣẹ tu ka yii, ki Ọlrun da oun lẹjọ ṣugbọn bi oun ba jẹ olododo ki Ọlọrun jẹ ki oun pẹ titi lae.
Laipẹ yii Oluwo ti Ilu Iwo, Ọba Rasheed Akanbi jajatuka pẹlu iyawo rẹ ti awọn mejeeji si taun si ara wọn lori ẹrọ ayelujara.
2019 in Retrospect: Wo àwọn èèkàn tí ikú mú lọ lọ́dún 2019
Oríṣun àwòrán, OTHER
Wọn ni iku doro, iku naa ni ko jẹ keyi to gbo keke o jobi to gbo kẹkẹ.
Kii ṣe ọrọ abẹnu mọ pe kii ṣe gbogbo eeyan to ba wọnu ọdun kan nii jade nibẹ. Iku nii koju ẹbi jọ iku naa nii mu ki ogun ọmọde ma lee ṣere fun ogun ọdun.
Laarin ọmọ Yoruba, o ja, o mu awọn to fẹ mu lọ kọdun to kasẹ nlẹ. Kii ṣe pe agbo Yoruba nikan lo ti ṣẹlẹ kaakiri ẹya agbaye lo ti ṣ'ọṣẹ ṣugbọn a kan mu wa si iranti yin, awọn to ṣẹlẹ nigimu Yoruba.
'Àṣà wa l'Ekiti ló dára jú lórílẹ̀èdè Nàìjíríà'
Lagbo oṣere tiata Yoruba lorilẹede Naijiria, iku naa da bira diẹ lọdun 2019 ti o n pari lọ yii. Diẹ lara awọn eekan oṣere tiata to jade laye lọdun 2019 ree.
Oríṣun àwòrán, Instagram
Ko ṣee rọ sẹyin ni alagba Fasasi Ọlabankẹwin ti ọpọ mọ si Dagunro ninu sinima ede Yoruba.
Ilu Oṣogbo lo dakẹ si ni ọjọ kẹtala oṣu kẹfa ọdun 2019.
Aisan ranpẹ ni iroyin sọ pe o ṣe agba oṣere naa ki o to dagbere faye.
Ọmọ aadọrin ọdun ni baba Dagunro nigba ti iku de.
Oríṣun àwòrán, Instagram
Arabibnrin Funmilayọ Ogunṣọla ti ọpọ mọ si Ijẹwuru ku ni ọjọ Aje, ọjọ kẹrin oṣu keji ọdun 2019 ni ilu Ibadan.
Ọmọ ọdun mejidinlọgọta ni Ijẹwuru ki o to jade laye.
Gbajugbaja oṣere ni, ọkan lara awọn iyawo agba oṣere to ti wọ kaa ilẹ lọ, Ishọla 'I show pepper'Ogunṣọla lo jẹ.
Bi a ba taju kan diẹ wo ita kuro lagbo awọn oṣere Tiata, lara awọn ti iku alumuntu nawọ mu niyii.
Oríṣun àwòrán, Instagram
Ọjọgbọn ati onkọwe to gbayi kaakiri agbye ni Pius Adesanmi.
Oun si ni oludari ẹka ẹkọ nipa ilẹ Afirika ni fasiti Carleton lorilẹede Canada.
Inu baluu Ethiopian Airlines to ja ni ọjọ kẹwa oṣu kẹta ọdun 2019 ni Pius ti jẹ ipe ọlọjọ.
Oríṣun àwòrán, Instagram
Ni Ọjọbọ ọjọ kẹta oṣu kini ọdun 2019 ni Gbenga 'Burger'Akintunde jade laye.
Gẹgẹ bi a ṣe gbọ, Ọgbẹni Akintunde funrarẹ gan lo lọ si ileewosan lati sọrọ nipa aisan iba to n ṣe e. Ohun ti yoo ṣẹlẹ lẹyin rẹ ni iroyin iku rẹ.
Ọmọ ọdun mẹtadinlaadọta ni ki ọlọjọ to de.
Oríṣun àwòrán, Instagram
Gbajugba aforindabira nibi ayẹyẹ ti oyinbo n pe ni DJ ni DJ Xgee.
Ni ọjọ kini ọdun 2019 ni iroyin iku rẹ gbode lẹyin to lọ kopa ni ode ayẹyẹ kan.
Iroyin sọ pe oun funra rẹ gan gbẹmi ara rẹ lẹyin to kọ iwe ibanilọkanjẹ kan sori oju opo Instagram rẹ.
Oríṣun àwòrán, Instagram
Ṣe ẹ ranti Danfo Drivers, iyẹn awọn akọrin meji kan to lu alujo orin sawọn ọmọ alafẹ lorilẹede yii ati loke okun lọdun diẹ sẹyin.
Oghenemaro Emeofa, ti ọpọ mọ ni Mad Melon, ọkan lara awọn meji to da ẹgbẹ naa silẹ jade laye ni ọjọ kẹrindinlọgbọn oṣu kẹsan ọdun 2019.
Ọkọ danfo to n na Ọjọọ si Mile 2 l'Eko lawọn mejeeji yi n wa ki ileeṣẹ orin kan to gbe wọn jade faye ri.
Oríṣun àwòrán, yabaleftonline.ng
Ẹnu o ni pa ọ bii ti Alabi Yẹllow' ni gbajugbaja ọrọ tawọn eeyan maa n sọ laye igba kan. Ko si si idi meji ju ipa ti gbajugbaja oṣere tiata, Samuel Akinpẹlu ti ọpọ mọ si Alabi Yellow maa n ko ninu ere sinima lọ.
Aisan ọlọjọ pipẹ kan lo ṣokunfa iku rẹ. Aisan ẹjẹ riru lo da a dubulẹ lẹyin ti iyawo rẹ ku ni oṣu kẹta ọdun 2019 kan naa.
Bi o tilẹ jẹ pe o ri iranwọ owo miliọnu mẹwa naira latọwọ Wolii Esther Ajayi ti ọpọ mọ si iya adura ni oṣu kẹrin.
Amọṣa ni ọjọ kejilelogun ọdun, oṣu kejila 2019 ni Alabi Yellow jade laye.
Oloye Akin Alabi: Ìdí tí a fí takò lílo N37b láti fi tún Ilé Aṣòfin Àpapọ ṣe
Oríṣun àwòrán, @others
Wọn ni iba dara ki ijọba fi owo naa ran awọn olokowo kekeke lọwọ
Asojusofin mẹta lo ti bu ẹnu atẹ lu igbeṣẹ ijọba lati lo biliọnu mẹtadinlogoji lati fi se atunse Ile Igbimọ Asofin apapọ ni ilu Abuja .
Eyi ko ṣẹyin bi Ile Igbimọ Asofin se gbe jade ninu eto isuna fun ọdun 2020 wi pe wọn yoo nilo owo yii lati tọ̀'ju Ile Igbimọ Asofin.
Ni oju opo Twitter ni Asojusofin Oloye Akin Alabi, Ochilegor Idagbo ati Bamidele Salam ti sọrọ tako igbeṣẹ wọn yii.
Wọn fikun wi pe ki wọn lo owo naa lati fi pese ile iwosan fun awọn eniyan, idokowo kekeeke ati ohun amayedẹrun miran fun awọn ọmọ Naijiria.
Oloye Akin Alabi sọ pe o dara ki ijọba apappọ na owo naa lati fi ṣe atunsẹ awọn ile iwosan ati ile wa ju ki wọn na owo naa fun atunsẹ Ile Igbimọ Asofin apapọ.
Bamidele Salami naa ko gbẹyin ni bi o ṣe bu ẹnu atẹ lu eto iṣuna ọhun.
"O sọ pe ""Gẹgẹ bi ọmọ ile Igbimọ Asojusofin, mi o lero pe a nilo biliọnu mẹtadinlogoji fun atunṣe ile naa bayii."""
Salam ṣalaye pe kaka ki ijọba na owo yii si  Ile Igbimọ Asofin apapọ, iba dara ko fi owo naa ran awọn olokowo kekeke lọwọ.
O ni oun yoo gbe igebsẹ lati tako abadofin naa ni igab ti ile ọhun ba bẹrẹ iṣẹ loṣu kinni ọdun 2020.
'Àṣà wa l'Ekiti ló dára jú lórílẹ̀èdè Nàìjíríà'
Buhari mú ayé dẹrun fún àwọn ọmọ Nàìjíríà ju àwọn ìjọba àtẹ̀yìnwá lọ- Lai Mohammed
Oríṣun àwòrán, @Shakapostng
Ọgbẹni Lai ni ko si ijọba kankan ti yoo la oju rẹ silẹ ki ilu bajẹ mọọ lori
Minisita eto ibanisọrọ ati iroyin, Lai Mohammed ti gboriyin fun ijọba aarẹ Muhammadu Buhari lẹyin to ni ijọba ọhun pese awọn ohun amayedẹrun fun awọn ọmọ Naijiria.
Bo tilẹ jẹ pe awọn ọmọ Naijiria kan koro oju si ina ijọba ti ko ṣe dede ati ọna to ti mẹhẹ, ọgbẹni Lai sọ pe ijọba Buhari pegede bo ṣe pese awọn ohun amayedẹrun.
O ni ijọba Buhari pegede ju gbogbo ijọba to ti ṣaaju lọ ni pipese awọn ohun amayedẹrun fun awọn Naijiria.
Agbẹnusọ ijọba lo sọ ọrọ yii nibi ifọrọwerọ pẹlu awọn oniroyin, nibi to ti n ṣe alakalẹ aṣeyọri ijọba Buhari lọdun 2019.
"Lai sọ pe ""Bi a ṣe n sọrọ yii, awọn ohun amayedẹrun bii opopona, ọna oju irin, ina mọnamọna, ati awọn ouhn miran ni ijọba yii n ṣe lọwọ."""
"O tẹsiwaju pe ""Ko tii si ijọba kankan to gunle iru iṣe bayii, papa julọ ni igabti ọrọ aje dẹnu kọlẹ."""
Ọgbẹni Lai ni ko si ijọba kankan ti yoo la oju rẹ silẹ ki ilu bajẹ mọọ lori.
O ni owo ti ijọba apapọ n ya jẹ lati fi pese awọn amayedẹrun mii ti yoo mu ki ọrọ aje orilẹ-ede Naijiria gberu sii.
'Àṣà wa l'Ekiti ló dára jú lórílẹ̀èdè Nàìjíríà'
End of a decade: Àwọn ìròyìn mẹ́wàá tó mí ilẹ̀ titi láàrin ọdún 2010-2019
Oríṣun àwòrán, Other
Ọdun mẹwaa ninu igbe aye ẹdamọniyan kii ṣe awada.
Idi re e ti BBC Yoruba ṣe ni ki a jijọ ṣe iranti awọn iroyin to mi igboro titi laarin ọdun 2010-2019.
"Ọpọ nkan lo ṣẹlẹ, nibẹ la ti ri eleyi to fọwọkan aw""n eeyan lẹmi ati awọn ti o ṣe awọn eeyan ni kayeefi."
Ni meni meji, diẹ ninu awọn eleyi ti a ri ka re.
Iku Gadaffi lọdun 2011
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ogunjọ Oṣu Kẹwa ni awọn ajijagbara mu olori orileede Libya Muammar Gaddafi, ti wọn si pa.
Iku Gaddafi  milẹ jiji latari bi ọpọ eeyan ti ṣe n fi oju olori ti ko dara wo.
Iku rẹ lo ṣebi ẹni ṣina oṣelu awarawa lorileede rẹ nigba naa.
Amọ loni ta n sọrọ yi, Libya ti di ilẹ ti kosi ifọkanbalẹ ti awọn ọmọ ilẹ naa ko si ti ribi ṣakoso ilẹ wọn bi o ti ṣe wu wọn lọkan.
Poopu Benedict XVI loun ko ṣe poopu mọ ni 2013
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ko ṣẹlẹ ri lawọn eeyan n sọ nigba ti Poopu mimọ Benedict XVI kede pe o to gẹ, oun ko ṣe poopu mọ loṣu keji ọdun 2013.
Igba akọkọ ni yoo jẹ ti Poopu yoo fiṣẹ silẹ ni ẹgbẹ̀ta ọdun ti Poopo ti n jẹ.
Ṣugbọn lẹyin ikede rẹ lawọn eeyan ba tun bẹrẹ si ni ṣe pọpọṣinṣin ẹni ti yoo jẹ Poopu lẹyin rẹ.
Lẹyin o rẹyin, Poopu fi ikede sita pe ailera lo mu ki oun kọwe fi ipo silẹ
Iku Nelson Mandela, 2013
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ilumọọka oloṣelu
Aarẹ South Afrika tẹlẹ Jacob Zuma lo kede iku aarẹ alawọdudu akọkọ South Afrika Nelson Mandela lori ileeṣẹ ẹrọ amounmaworan ilẹ naa.
Ohun ibanujẹ ni iku rẹ jẹ fawọn ọmọ ile naa ati awọn eeyan mii kakiri agbaye.
Zuma ṣapejuwe Nelson Mandela gẹgẹ bi Baba fun awọn eeyan South Afrika. Awọn eeyan gbe orin, fiimu ati eto orisirisi jade ti wọn fi yẹ Mandela si.
Ipolongo #BringBackOurGirls,2014
Oríṣun àwòrán, Twitter
Ipolongo yi lawọn eeyan mu ni ọkunkundun lati ṣe awari awọn akẹkọbirin ile ẹkọ nilu Chibok tawọn ikọ Boko Haram ji gbe.
To fi mọ iyawo aarẹ Amẹrika nigba naa, Michelle Obama, jakejado agbaye lawọn eeyan n ṣe ipolongo pe ki wọn tu awọn akẹkọbinrin yi silẹ.
Wọn le ni igba ti Boko Haram ji gbe.
Loju opo ayelujara lawọn ilumọọka ati olori orileede ti n lọgun ki ijọba Naijiria wa wọrọkọ fi ṣada lori awọn ọmọ wọn yi.
Idibo aarẹ Naijiria,2015
Oríṣun àwòrán, EPA
Buhari lo jaweolubori gẹgẹ bi aarẹ ninu idibo to waye ni ọdun 2015
Lọdun 2015, ọgagun Muhammadu Buhari to ti fi igba kan jẹ olori orileede Naijiria yẹ aga nidi Aarẹ Goodluck Jonathan ninu idibo aarẹ to waye.
o le ni miliọnu meji le diẹ ibo ti Buhari fi jaweolubori ti o si di ọmọ ẹgbẹ alatako akọkọ ti yoo yẹgi nidi aarẹ to wa nipo .
Lẹyin ọdun mẹrindinlogun ti ẹgbẹ oṣelu PDP ti wa lori alefa, APC gba ijọba lọwọ wọn.
Donald Trump di aarẹ Amẹrika , 2016
Oríṣun àwòrán, AFP
Donald Trump jẹ onisowo saaju ki o to di aarẹ Amẹrika
Bi igba ti ilẹ mi ni iroyin pe Donald J. Trump ti ẹgbẹ oṣelu Republican l'Amerika di aarẹ ti ṣe ri lara awọn eeyan lagbaye.
Pupọ eeyan ni ko ni igbagbọ pe o le di aarẹ, ṣugbọn o fi idi  alatako rẹ Hilary Clinton ti ẹgbẹ oṣelu Democrat janlẹ ninu idibo to waye.
Iroyin gbajugbaja oniṣowo to pada wa di aarẹ yi lo gba ori afẹfẹ kaakiri agbaye lọdun 2016
Leicester gba ife ẹyẹ Premier League lọdun 2016
Igba akọkọ re ti Leicester yoo gba ife ẹyẹ Premiership
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Igba akọkọ re ti Leicester yoo gba ife ẹyẹ Premiership
Ọkan gbogi iroyin to mi igboro titi ni ti ẹgbẹ agbabọọlu Leicester ti wọn gba ife ẹyẹ Premiership ni oṣu kaarun un ọdun 2016.
Ọpọ eeyan ni ko tilẹ ro wi pe Leicester le pagọ ṣugbọn ẹgbẹ yi ṣe bẹ wọn kọ ile alarinrin.
Igbeyawo Meghan Markle 'Royal Wedding' 2018
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Igba akọkọ re ti obinrin alawọdudu yoo jẹ oye ayaba Sussex.
Igbeyawo arabinrin Meghan Markle ati ọmọ ọba Harry milẹ titi.
Ni ọjọ igbeyawo wọn tii ṣe ọjọ kọkandinlogun oṣu kaarun, ogunlọgọ awọn eeyan lo n wo iran igbeyawo yi jakejado agbaye.
Loju opo ayelujara, o le ni milọnu mẹta eeyan to n fi ọrọ sita nipa rẹ lori Twitter.
Igbeyawo yi jẹ ọkan lara awọn iṣẹlẹ tawọn eeyan fi tidunu tayọ wo kaakiri agbaye.
Fiimu BlackPanther, 2018
Oríṣun àwòrán, Marvel Studios
''Wakanda Forever'' ni igbe to gbori atẹgun kaakiri agbaye lẹyin ti fiimu Black Panther jade sita lọdun 2018.
Ninu fiimu yi, awọn eeyan alawọdudu ni wọn kopa ninu rẹ pupọ, koda ẹni to dari fiimu naa alawọdudu nii.
Fiimu naa gba ami idanimọ Oscar lorisirisi ti o si jẹ fiimu ti eeyan alawọdudu dari rẹ to pawo julọ lagbaye.
Oríṣun àwòrán, GHANA PRESIDENCY
Ọdun ipadabọ ni 2019 lorileede Ghana naa jẹ iṣẹlẹ kan to lamilaaka .
Awọn ọmọ ilẹ Afrika to wa nilẹ Amerika ti wọn si pada wa si ile ni eto yi yannana.
Pupọ awọn to ti n gbe lẹyin odi yi pada wa sile ni ayajọ irinwo ọdun ti wọn ko awọn eeyan lẹru lọ si ilẹ okere ti wọn si balẹ si ilu Jamestown ni Virginia l'Amẹrika.
Olaronke Alo lo ṣe akojọpọ iroyin yi.
Ritual Murder: Bàbá akẹ́kọ̀ọ́bìnrin LASU tí ọ̀rẹ́kùnrin rẹ̀ fi ṣ'òògùn owó ń bèèrè fún ìdájọ́ òdodo
Oríṣun àwòrán, Nigeria Police
Bàbá akẹ́kọ̀ọ́bìnrin LASU tí ọ̀rẹ́kùnrin rẹ̀ fi ṣ'òògùn owó ń bèèrè fún ìdájọ́ òdodo
Ohun kan ti baba akẹkọọbinrin fasiti ipinlẹ Eko, LASU to n mura fun eto agunbanirọ, Favour Daley-Oladele n beere fun ni idajọ ododo.
O ni ki ijọba da ẹjọ to yẹ fun awọn to fi ọmọ oun ṣe oogun owo.
Pasito ijọ alaṣọ funfun kan, Segun Philip ati Adeeko Owolabi to jẹ ọrẹkunrin Favour pẹlu iya rẹ, Bola Oladele ni ile iṣẹ ọlọpaa ipinlẹ Ogun ṣafihan wọn lọjọ Aje niluu Abeokuta lori ẹsun pe wọn jọ gbimọ pọ ni.
Awọn ọlọpaa ni wọn fi akẹkọọbinrin naa ṣe oogun owo.
Favour ni iroyin sọ pe o kuro nile lọjọ kẹjọ oṣu kejila ọdun 2019, to si di awati, lẹyin naa ni wọn ri oku rẹ ninu eyi ti awọn ẹya ara rẹ kan ko si nibẹ mọ.
Nigba ti awọn ọlọpaa ṣewadii ni wn gbọ pe irina arabinrin yii jọ mọ lilọ si ijọ alaṣọ funfun kan ni niyan niyan Ikoyi-Ile nipinlẹ Osun.
Ninu ifọrọwanilẹnuwo wọn pẹlu Adeeko lo ti ṣalaye pe pasitọ fun oun ni ọmọ odo lati fi lu u lori ti pasit si sare fi ọbẹ yọ ọkan rẹ eyi to fi se asejẹ fun Adeeko ati iya rẹ.
Ile iṣẹ ọlọpaa to wa ni Mowe lawọn obi rẹ fi ọrọ naa to leti ki ọwọ ofin to tẹ awọn to ṣiṣẹ ibi ọhun.
Pasitọ Philip jẹwọ niwaju awọn ọlọpaa wi pe lootọ loun gbimọ pọ pẹlu Owolabi lati fi Favour ṣe oogun owo, amọ iya Owolabi ko mọ nipa ero awọn mejeeji.
Philip ni ohun tawọn gbero lati ṣe ni lati jo awọn ẹya ara akẹkọọbinrin kan pọ fi ṣe agbo fun iya Owolabi ki o le maa ri iṣẹ nla nla ti yoo maa mu owo wọle gba.
2020: Oloye Awurela Ifaleke ti wúré ọdún ìgbéga fún kóówá
Amọ o ni ẹlẹda Favour ko jẹ ni oogun owo, eyi ni ko jẹ ki oogun naa ṣiṣẹ.
Owolabi ẹni ọdun mẹtalelogun naa sọ pe oun kabamọọ ohun ti oun ṣe pẹlu Philip, o ni iṣẹ to bọ lọwọ baba ati mama oun lo sun oun debi fifi ọrẹbinrin oun ṣe oogun owo.
'Mí ò ya wèrè, mí ò burú, ọ̀nà àtijẹ là ń wá'
Ẹwẹ, baba oloogbe akẹkọọbinrin naa ṣapejuwe Favour gẹgẹ bi wura ninu idile oun.
''A woju Ọlọrun fun ọdun diẹ ki a to bi Favour, o si lọ fasiti eyi to mu inu wa dun pe yoo kẹkọọ gboye laipẹ ṣugbọn eeyan kan gbimọ pọ lati ṣekupa a,'' baba lo sọ bẹẹ.
Baba oloogbe naa ni iku Favour jẹ ibanujẹ nla fun idile oun.
Larisa: Má jẹ́ kí ọjọ́ orí rẹ dí ẹ lọ́wọ́ láti bẹ̀rẹ̀ ohunkóhun to wù ọ
Ibadan High Chiefs: Àwọn Olóyè Ibadan mọ́kànlélógún tó ń pe ara wọn lọ́ba ń fi ẹ̀wọ̀n run imú
Oríṣun àwòrán, Facebook/Abiola Ajimobi
Ọrọ ko tii tan lori awọn oloye mọkanlelogun ti ile ẹjọ sọ pe ki wọn lọ rọọkun nile niluu Ibadan.
Kọmiṣọnna eto idajọ tẹlẹ ri nipinlẹ Oyo, Ọgbẹni Michael Lana lo ṣe ikilọ fun wọn pe ki wọn ye pe ara wọn ni ọba kaakiri, bi bẹẹ kọ, wọn n fi ẹwọn run imu ni.
Ninu atẹjade kan ti Ọgbẹni Lana fi sita lọjọ Aje, o sọ wi pe bi awọn oloye naa ti n pe ara wọn ti wọn si n gbe ara wọn gẹgẹ bi ọba lodi si aṣẹ ile ẹjọ.
''Igbesẹ ijọba ana nipinlẹ Oyo to fun awọn oloye mọkanlelogun lati maa de ade ilẹkẹ, ati lati maa pe ara wọn ni ọba lodi si ofin,'' Ọgbẹni Lana lo woye bẹẹ.
O ṣalaye siwaju sii pe idajọ ile ẹjọ giga ipinlẹ Oyo to waye lọjọ kọkandinlogun oṣu kọkanla ọdun 2019 ti gbe igbesẹ ijọba ana lori awọn oloye Ibadan sẹgbẹ kan.
Ọgbẹni Lana sọ pe iyanlẹnu lo jẹ pe awọn kan si tun n wọ ade ilẹkẹ ti wọn si n pe ara wọn ni ọba ilu Ibadan.
O ni ijọba koni bẹṣubẹgba lati gbe igbesẹ lori bi awọn oloye mọkanlelogun naa ṣe n pe ara wọn ni ọba kaakiri.
Ọgbẹni Lana wa kepe Kọmiṣọnna ọlọpaa ipinlẹ Oyo pe ko paṣẹ fawọn agbofinro lati fi ọwọ ofin mu ẹnikẹni ninu awọn oloye naa to ba n pe ara rẹ lọba.
N37b for NASS: 'Ilé aṣòfin àgbà l'Abuja le dà wó lulẹ̀ láì ṣe àtúnṣe rẹ̀ ní kíákíá'
Oríṣun àwòrán, Twitter/Nigerian The Senate
Awuyewuye lori igbeṣẹ ijọba lati lo biliọnu mẹtadinlogoji lati fi se atunse Ile Igbimọ Asofin apapọ ni ilu Abuja ko tii tan nilẹ.
Lẹyin tawọn ajọ SERAP atawọn ajọ ajafẹtọ miiran ti tako igbesẹ ijọba naa, awọn aṣoju-ṣofin kan naa ni owo ọhun pọ ju fun atunṣe gbọngan ile aṣofin.
Koda wọn ni o san ki ijọba apapọ lo owo naa fun ipese ohun amayedẹrun fawọn ọmọ Naijria.
Amọ agbẹnusọ fun ile igbimọ aṣofin agba l'Abuja, sẹnẹtọ Godiya Akwashiki  ti tutọ soke foju gba a lori ọrọ naa lẹyin to sọ wi pe, kii kuku ṣe pe ile aṣofin ni yoo gbowo naa ṣọwọ.
O ni ajọ to n mojuto olu-ilu orilẹede Naijiria, FCDA ni yoo ṣagbatẹru iṣẹ atunṣe ile naa.
Sẹnẹtọ Akwashiki ojuṣe ile aṣofin ni lati fi to ijọba leti ipo ti ile aṣofin wa, eleyi to ni o le da wo bi iṣẹ atunṣe ko ba waye lori rẹ ni kiakia.
Aṣofin Akwashiki fikun ọrọ rẹ pe ajọ FCDA lo mọ ohun to ri ko to sọ pe biliọnu mẹtadinlogoji lohun ma nilo lati ṣatunṣe ile.
O ni to ba wu Aarẹ Muhammadu Buhari, o le ranṣẹ pe awọn kọngila ti FCDA fẹ gbe iṣẹ naa fun lati wa ṣalaye bi wọn ti fẹ nanwo naa.
Àwọn aṣòfin mẹ́ta takò lílo N37b f'àtúnṣe Ilé Aṣòfin Àpapọ Nàìjíríà
Asojusofin mẹta lo ti bu ẹnu atẹ lu igbeṣẹ ijọba lati lo biliọnu mẹtadinlogoji lati fi se atunse Ile Igbimọ Asofin apapọ ni ilu Abuja .
Asojusofin mẹta lo ti bu ẹnu atẹ lu igbeṣẹ ijọba lati lo biliọnu mẹtadinlogoji lati fi se atunse Ile Igbimọ Asofin apapọ ni ilu Abuja .
Oríṣun àwòrán, @others
Wọn ni iba dara ki ijọba fi owo naa ran awọn olokowo kekeke lọwọ
Eyi ko ṣẹyin bi Ile Igbimọ Asofin se gbe jade ninu eto isuna fun ọdun 2020 wi pe wọn yoo nilo owo yii lati tọ̀'ju Ile Igbimọ Asofin.
Ni oju opo Twitter ni Asojusofin Oloye Akin Alabi, Ochilegor Idagbo ati Bamidele Salam ti sọrọ tako igbeṣẹ wọn yii.
Wọn fikun wi pe ki wọn lo owo naa lati fi pese ile iwosan fun awọn eniyan, idokowo kekeeke ati ohun amayedẹrun miran fun awọn ọmọ Naijiria.
Oloye Akin Alabi sọ pe o dara ki ijọba apappọ na owo naa lati fi ṣe atunsẹ awọn ile iwosan ati ile wa ju ki wọn na owo naa fun atunsẹ Ile Igbimọ Asofin apapọ.
Bamidele Salami naa ko gbẹyin ni bi o ṣe bu ẹnu atẹ lu eto iṣuna ọhun.
"O sọ pe ""Gẹgẹ bi ọmọ ile Igbimọ Asojusofin, mi o lero pe a nilo biliọnu mẹtadinlogoji fun atunṣe ile naa bayii."""
Salam ṣalaye pe kaka ki ijọba na owo yii si  Ile Igbimọ Asofin apapọ, iba dara ko fi owo naa ran awọn olokowo kekeke lọwọ.
O ni oun yoo gbe igebsẹ lati tako abadofin naa ni igab ti ile ọhun ba bẹrẹ iṣẹ loṣu kinni ọdun 2020.
'Àṣà wa l'Ekiti ló dára jú lórílẹ̀èdè Nàìjíríà'
Eyi ko ṣẹyin bi Ile Igbimọ Asofin se gbe jade ninu eto isuna fun ọdun 2020 wi pe wọn yoo nilo owo yii lati tọ̀'ju Ile Igbimọ Asofin.
Ni oju opo Twitter ni Asojusofin Oloye Akin Alabi, Ochilegor Idagbo ati Bamidele Salam ti sọrọ tako igbeṣẹ wọn yii.
2019 in Retrospect: Wo àwọn èèyàn jáńkán tí yóò rékọjá sí 2020 nínú ọgbà ẹ̀wọ̀n
Oríṣun àwòrán, @others
Oriṣiriṣi ohun lo ṣẹlẹ lọdun 2019, ọpọ lo ṣe igbeyawo, awọn kan kọle, awọn mii ra ilẹ, awọn kan dero oke okun, bẹẹ lawọn miran dero ẹwọn.
Ninu awọn ti yoo ṣe ọdun tuntun ninu ẹwọn lati ri awọn eeyan jankan bii oloṣelu, pasitọ, oṣere tiata, ati bẹbẹ lọ.
Ẹ jẹ ka wo diẹ lara awọn eeyan ọhun.
Ọpọ ni ko mọ ijọ kan torukọ rẹ n jẹ Sotitibire Miracle Centre nilu Akure tẹlẹ, ṣugbọn okiki ile ijọsin ọhun kan lẹyin ti ọmọ ọdun kan o le diẹ dede poora nile ijọsin naa.
Bi rere bi awada, ọrọ naa di ti agọ ọlọpaa, eyi mu ki Alfa Babatunde Sotitobire dero agọ ajọ ọtẹmuyẹ DSS.
Ṣugbọn lọjọ kẹtalelogun, oṣu Kejila ọdun yii ni ile ẹjọ to wa ni Oke Eda nilu Akure paṣẹ pe ki wọn fi pasitọ  ọhun si ọgba ẹwọn Olokuta nilu Akure, ki igbẹjọ rẹ to tẹsiwaju.
Ṣé lóòtọ́, báwọn wọ̀nyìí ṣe sọ ọ́ ló rí fún gbogbo yín lọ́dún 2019?
Gomina ipinlẹ Abia tẹlẹ, Orji Uzor Kalu jẹ ọkan lara awọn oloṣelu ti orukọ rẹ tan lọdun 2019 lori ẹsun ṣisọwo ilu baṣubaṣu.
Ṣaaju ni ajọ to n gbogun ti iwa jẹgudujẹra, EFCC ti fẹsun kan pe o ko owo ilu sapo nigba iṣejọba rẹ gẹgẹ bi gomina laarin ọdun 199 si 2007.
Lẹyinorẹyin, ile ẹjọ giga kan nilu Eko ran lẹwọn ọdun mejila lọjọ karun un oṣu Kejila ọdun 2019.
To n tumọ si pe, inu ọgba ẹwọn ni gomina ana ọhun yoo ṣe ọdun tuntun.
Gbajumọ laarin awọn oṣere tiata Yoruba ni Olajide Kareeem, ti ọpọ eeyan mọ si  Seun Egbegbe jẹ, koda o gbajumọ to bẹ ti awọn olorin kan ma n kan sara ninu awo wọn.
Wọn ni o lu awọn to ma n ṣẹ owo ilẹ okeere to le ni ogoji ni jibiti, lẹyin to parọ fun wọn pe oun ni owo lati ṣe laarin ọdun 2015 si 2017.
'Àṣà wa l'Ekiti ló dára jú lórílẹ̀èdè Nàìjíríà'
Oṣu Keji ọdun 2017 ni adajọ Oluremi Oguntoyinbo ni ki wọn gba oniduro Egbegbe pẹlu  miliọnu marun un naira, ṣugbọn o ni ko wa lọgba lọgba ẹwọn titi ti yoo fi ri owo itanran ọhun.
Lati igba naa ni Egbegb ti dero ẹwon latari pe ko sẹni to le san  owo ọhun.
Olori ẹlẹsin Musulumi Shia ni Ibrahim El-Zakzaky, oun si ni adari awọn Islamic Movement of Nigeria to da silẹ lọdun 1970.
Ọdun 2018 ni ijọba ipinlẹ Kaduna fẹsun ipaniyan kan oun ati iyawo rẹ, Zeenah Ibrahim ti wọn si gbe wọn lọ ile ẹjọ lẹyin ti awọn ọmọ lẹyin rẹ dena olori ologun Naijiria ni Kaduna.
Akure Kidnap: E túbọ̀ ní sùúrù, a máa wá ọmọ náà rí- Alukoro ọlọ́pàá
Lati ọdun naa ni El-Zakzaky ti bẹrẹ si ni foju wina ijọba Naijiria.
Bo tilẹ jẹ pe wọn ṣejọ rẹ, ile ẹjọ si ti ni ki wọn tu silẹ, o ṣeni laanu pe inu ẹwọn ni ọdun tuntun yoo ba  okunrin ọhun.
Ọjọ kejidinlọgbọn oṣu Kejila ọdun 2015 ni ajọ EFCC  fi iwe pe Mohammed Bello Adoke lori ẹsun magomago epo Malabu ti owo rẹ le ni biliọnu mẹfa naira.
Christmas: Jesu ni ọjọ́ ọ̀la àti ibi ìyanu mi- Jaga
Ṣugbọn ọjọ kẹtadinlogun oṣu Kẹrin ọdunn 2019 ni ile ẹjọ giga kan nilu Abuja ni ki wọn fi pampẹ ofin gbe ati awọn mii lori ọrọ owo naa.
Ni kete to pada wa lati ilu Dubai ni awọn agbofinro nọwọ gan.
Lẹyinorẹyin, inu ahamọ ni Adoke wa bayii ti awọn agborinro si sọ pe o n fọwọsowọpọ pẹlu wọn ninu iwaadi ti wọn ṣe.
2020 Countdown: Àwọn orílẹ̀-èdè tó ti ṣáájú Nàìjíríà wọ ọdún 2020
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Bi ọdun 2020 ti ṣe ku wakati diẹ́ lọdọ tiwa ni Naijiria ati awọn apa ibomiran lagbaye, awọn kan ti n ki ara wọn ku ọdun tuntun.
O yayi lẹnu abi? Bẹẹ lo ri nitori pe lawọn orile-ede kan,oju ọjọ ko ri bi ti ọdọ tiwa ti wọn a si ma fi wakati meloo kan ṣaaju wa lojumọ kọọkan.
Lawọn orile-ede ta n sọ yi, orun n mu ti o si n wọ bi tiwa ṣugbọn iyatọ pe awọn lewaju wa ni ounka wakati lo jẹ ki wọn ti ki ọdun tuntun kaabọ ṣaaju wa.
Diẹ lara awọn orile-ede naa re ati aworan bi wọn ti ṣe ki ọdun 2020 kaabọ lọdọ wọn.
Ni nkan bi aago mọkanla kọja iṣẹju mẹẹdogun, ọjọ Iṣẹgun tii ṣe ọjọ Kọkanlelọgbọn, oṣu Kejila, 2019 lọdọ ti wa ni wọn kii 2020 kaabọ ni Australia.
Yatọ si Sydney,awọn eeyan Alice Springs,Cairns,Adelaide wa lara awọn ilu to ti n ṣe pọpọṣinṣin ọdun 2020.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Wellington,Auckland ati Chatam Island wa lara awọn ilu ti wọn ti dagbere fun 2019 ti wọn si ti ṣe kaabọ si 2020.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
2020: Oloye Awurela Ifaleke ti wúré ọdún ìgbéga fún kóówá
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Lawọn apa kan lorileede Russia bi Pevek, Srednelolymsk, Anadyr, Magadan wọn ti wọ ọdun 2020 lati nkan bi ago kan abọ ọsan ni orile-ede wa Naijiria.
Ṣugbọn lọdọ wọn, lasiko ta n ṣe akojọpọ iroyin yi, ago kan oru ni wọn wa.
Awọn orile-ede miran ti wọn ti ki 2020 kaabọ ni:
'Mí ò ya wèrè, mí ò burú, ọ̀nà àtijẹ là ń wá'
Saraki vs Abdulrazaq: Àwọn arúgbó ní kí ìjọba máà ṣe wó ilé arúgbó m'áwọn lórí
Àwọn arúgbó ní kí ìjọba máà ṣe wó ilé arúgbó m'áwọn lórí
Ọrọ lori ile arugbo ti Ijọba ipinlẹ Kwara lawọn fẹ gba ilẹ naa pada lọwọ aarẹ ile aṣofin agba tẹlẹ Bukola Saraki ti gba ọna mi yọ.
Eyi ko ṣẹyin bi awọn iya arugbo kan nilu Ilorin ti ṣe ṣe iwọde ladugbo Iloffa Road ti ile Baba Saraki ''Oloye'' kalẹ si.
Ninu ifọrọwerọ pẹlu awọn akọroyin awọn Iya arugbọ naa parọwa si  Gomina ipinlẹ Kwara  lati ma ṣe wo ile to wa lori ilẹ naa nitori pe ibẹ lawọn ti n ri jijẹ mimu.
Ọkan ninu wọn to sọrọ pẹlu awọn akọroyin sọ pe ''Eeyan ki ṣe nkan ti eeyan ko to lati ṣe .A n bẹ Gomina ko ma wo ile arugbo''
Bi a ko ba gbagbe, fakinfa kan n waye lẹnu ọjọ mẹta yi laarin Ijọba Kwara ati aarẹ ile aṣofin agba tẹlẹ Bukola Saraki lori ilẹ ti Baba Saraki,Olusola Saraki kọ ile to pe ni ile arugbo le lori.
Ninu ikede ti Ijọba fi sita soju opoTwitter, wọn sọ pe awọn gbẹsẹ le ilẹ naa nitori pe ko ni iwe aṣẹ to yẹ.
Wọn tẹsiwaju pe ọna eru ni Saraki fi gba ilẹ naa fun Baba rẹ lasiko to wa lori alefa nitori ọtọ ni nkan ti ijọba fẹ fi ilẹ naa ṣe.
'Mí ò ya wèrè, mí ò burú, ọ̀nà àtijẹ là ń wá'
Dokita Bukola Saraki naa ko jẹ ki ọrọ yi balẹ ki o to fi esi sita pe oun ko ṣarifin si baba ẹnikẹni nigba ti ohun wa lori oye nitori naa oun ko ni gba ki ijọba Gomina Abdulrahaman Abdulrazaq ṣarifin si baba oun.
Saraki tẹsiwaju pe gbogbo nkan to ba gba lohun yoo fi ba ijọba Kwara fa lori ilẹ to sọ pe Baba oun gba iwe aṣẹ ki o to kọ ile si ori rẹ.
Ni ilu Ilorin ati kaakiri ipinlẹ Kwara, ọrọ yi ti n mu iriwisi ọtọọtọ wa ti awọn kan si ni ki wọn fi ẹlẹ yanju ọrọ naa ki o ba ma da wahala silẹ nilu.
Akure Kidnap: E túbọ̀ ní sùúrù, a máa wá ọmọ náà rí- Alukoro ọlọ́pàá
Naira Marley: Ilé ẹjọ́ ní Naira Marley ń rìn ní bèbè ẹ̀wọ̀n lọ́dún 2020 bí kò bá fara hàn lórí ẹ̀sùn ìjọ́kọ̀gbé
Oríṣun àwòrán, NAira Marley/instagram
Afaimọ ki Naira Marley, gbajugbaja olorin takasufe ti irawọ rẹ n tan lọwọ bayii o maa bẹrẹ ọdun 2020 pẹlu ẹwọn.
Ile ẹjọ Majisireeti agba kan lagbagbe Tinubu nipinlẹ Eko lo paṣẹ pe bi Naira Marley ti orukọ abisọ rẹ n jẹ Azeez Fashọla, ko ba fi ara han niwaju kootu naa ni ọjọ kẹrinla oṣu kini ọdun 2020, ẹwọn lo fi n ṣere.
Naira Marley n jẹjọ ijọkọgbe niwaju adajọ majisireeti Tajudeen Elias pẹlu awọn mọlẹbi rẹ, Idris Fashola, babatunde Fashola ati Kunle Obere.
Adajọ naa kilọ fun gbajugbaja olorin naa lati fara han  ni ọjọ naa aṣẹ ẹ lọ gbe wa ni wiwọ ni dide (Bench warrant) loun yoo pa fawọn agbofinro lori rẹ.
Ni ọjọ Iṣẹgun ni ile ẹjọ paṣẹ naa nibi itẹsiwaju igbẹjọ ẹsun jiji ọkọ gbe ti wọn fi kan an.
Ni ọjọ kẹrindinlogun oṣu kejila ọdun 2019 ni wọn kọkọ gbe wọn lọ siwaju ile ẹjọ naa, ṣugbọn Naira Marley ko ysju sile ẹjọ.
Ni ọjọ naa, awọn afunrasi mẹta toku ni awọn ko jẹbi ọrọ ẹsun naa.
Prophecy 2020: Primate Ayodele, Baba Adeboye àti Father Mbaka sọ àsọtẹ́lẹ̀ nípa 2020!
Prophecy 2020: Adeboye àti Ayọdele sọ nípa ọjọ́ ìwájú 2020
Primate Ayodel kilọ lori ohun to le ṣẹlẹ ninu idibo ipinlẹ Edo ati Ondo.
Bakan naa lo sọrọ lori awọn Boko Haram ati pe 2021 ni ọwọ maa tẹ Shekau olori wọn.
Primate Ayodele ti ijọ INRI evangelical sọrọ yii lasiko eto ti ijọ naa fi n pese iranlọwọ ohun ini fawọn opo ati alaini ni awujọ nile ijọsin wọn ni Eko.
Iyipada ijọba, ilẹ riri yoo waye ni ọpọlọpọ orilẹ-ede lagbaye- Pasitọ Adeboye
Bakan naa ni Baba Adeboye ti ijọ Redeemed Christian Church of God naa pe fun adura ki ọrọ iṣipo pada to maa waye ni 2020 ati ilẹ riri ma ga ju ara lọ.
Oludari Agba fun ijọ irapada, Redeemed Christian Church of God (RCCG), Pasito Enoch Adeboye ti ni ọpọlọpọ iṣẹlẹ ni yoo waye kaakiri agbaye ni ọdun 2020.
Pasitọ Adeboye ni iyipada yoo deba isejoba lagbaye, eleyii ti yoo mu irọun dani ni awọn agbegbe kan, nigba ti ti awọn miran yoo mu rogbodiyan lọwọ.
Ṣé lóòtọ́, báwọn wọ̀nyìí ṣe sọ ọ́ ló rí fún gbogbo yín lọ́dún 2019?
Ògo tuntun yóò sọ ní ọdún 2020!- Olukoya ti ìjọ MFM
Oludasilẹ ijọ Mountain of Fire and Miracles Ministries, MFM, Daniel Odukoya ti fi ọpọlọpọ aṣọtẹlẹ silẹ fun ọdun 2020.
Oríṣun àwòrán, Others
Ohun tí ó wọ́pọ̀ ni orilẹ̀-èdè Naijiria ni kí àwọn olórí Ilé Ijọsìn kọ̀ọ̀kan sọ àsọtẹ́lẹ̀ nípa ọdún tuntun ní ìbẹ̀rẹ̀ ọdún.
"Olukoya to pe ọdun 2020 ni ""ọdun isọji ati ogo tuntun"", rọ awọn ọmọ Naijiria lati gbadura ki ohun gbogbo ma dojuru ni 2020."
Ninu ọrọ rẹ, awọn adari ni iye wọn yoo di ẹni ana.
O fikun un wi pe ẹni to ba tapa si ofin Olorun yoo ru igi oyin ti adura itusilẹ ko ni le e gba a silẹ.
Ohun tí ó wọ́pọ̀ ni orilẹ̀-èdè Naijiria ni kí àwọn olórí Ilé Ijọsìn kọ̀ọ̀kan sọ àsọtẹ́lẹ̀ nípa ọdún tuntun ní ìbẹ̀rẹ̀ ọdún.
Oludasilẹ Ijọ INRI Evangelical Spiritual Church, Oke-Afa, ni Ejigbo ni ipinlẹ Eko, Primate Babatunde Elijah Ayodele ti sọ asọtẹlẹ nipa ọdun 2020.
Oríṣun àwòrán, Others
Primate Ayodele, Baba Adeboye àti Father Mbaka sọ àsọtẹ́lẹ̀ nípa ọdún 2020!
Ayodele sọ eyi lasiko ọdun tuntun nigba to n sọrọ nipa Aarẹ Muhammadu Buhari; Igbakeji aarẹ, Yemi Osinbajo ati adari ẹgbẹ oṣelu APC, Bola Tinubu pẹlu ẹka ijọba miran.
O ni ija, asọ ati ipaniyan yoo pọsi lorilẹede Naijiria, bẹẹ ni rogbodiyan yoo peleke si kaakiri agbaye.
2020: Oloye Awurela Ifaleke ti wúré ọdún ìgbéga fún kóówá
Oludasilẹ ijo INRI tun fikun un wi pe ọrọ aje yoo tubọ dẹnukọlẹ si nii.
O ni ki Tinubu ṣọra ki o rii pe oun n ṣe ohun to tọ fun awọn eniyan Naijiria, ko fi t'Olorun ṣe ninu ilepa rẹ.
APC yoo dide lodi si ijọba laipẹ nitori pe Osinbajọ àti Buhari yoo ri wahala
Primate Ayodele wa kesi awọn ọmọ Niajiria lati gbohun adura soke fun orilẹ-ede naa, ki ijamba, ikọlu ati ibugbamu oloro ma ba a peleke si lorilẹ-ede Naijiria.
Ọbẹ Ẹgusi sise ati jijẹ
Bakan naa ni Baba Adeboye ni adura nikan lo le e ṣẹgun ilẹ riri ati awọn ijamba miran ti yoo waye ni ọdun 2020.
Baba Adeboye ni ilẹ yoo lanu, bi iru eleyii ti ko i tii ṣẹlẹ ri lọdun 2020.
'Òṣìṣẹ́ Bánkì ni mí l'Amẹ́ríkà kí n tó bẹ̀rẹ̀ Tíátà'
Bakan naa ni Fada Ejike Mbaka to ti ijọ Adoration Ministry ti ni iyipada yoo deba ijọba Naijiria ni ipinlẹ ati ni ijọba apapọ.
O ni ayipada nla maa deba iṣelu ipinlẹ Imo ni guusu Naijiria ni 2020.
O tun pin agbara ti ẹmi fun awọn kan ninu ẹgbẹ oṣelu kan to ni pe ki wọn gba agbara lati bẹrẹ iṣẹ
Aare Buhari tilẹ sọ wi pe igba ọtun lo de ni Naijiria, ati wi pe gbogbo ileri ti awọn ti ṣe ni awọn yoo mu ṣẹ.
O tun menuba awọn iṣẹ akanṣe ti ijọba rẹ fẹ ṣe ni 2020 pe Ó ti tán fún mí lọ́dún 2023- Ààrẹ Muhammadu Buhari
#Queen Dihya: Obinrin tó gbógun tàwọn agbésùnmọ̀mí ni Algeria
Operation Amotẹkun: Ẹ̀ṣọ́ ilẹ̀ Yorùbá 'Àmọ̀tẹ́kùn' ṣetán láti bẹ̀rẹ̀ iṣẹ́ káàkiri ilẹ̀ káàrọ́ọ̀ oò jíire
Oríṣun àwòrán, Facebook/Dr Kayode Fayemi
Ẹ̀ṣọ́ ilẹ̀ Yorùbá 'Àmọ̀tẹ́kùn' ṣetán láti bẹ̀rẹ̀ iṣẹ́ káàkiri ilẹ̀ káàrọ́ọ̀ oò jíire
Gomina ipinlẹ Ekiti, Kayode Fayemi ti kede pe gbogbo eto ti to bayii fun ile iṣẹ eto aabo ilẹ Yoruba ''Amọtẹkun'' lati bẹrẹ.
Fayemi ni ọjọ kẹsan an, oṣu kinni, ọdun 2020 ni eto naa tawọn gomina mẹfa apa gusu orilẹ-ede Naijiria iwọ oorun ṣe agbakalẹ rẹ yoo bẹrẹ kaakiri ilẹ Yoruba.
Gomina Fayemi fi ọrọ ọhun lede ninu ọrọ ọdun tuntun to bawọn eeyan ipinlẹ Ekiti sọ l'Ọjọru, ọjọ kinni, oṣu kinni, ọdun 2020.
Fayemi ṣalaye pe awọn ẹṣọ 'Amọtẹkun' yoo maa ṣe iranwọ fun awọn agbofinro ni gbogbo ipinlẹ mẹfa nilẹ Yoruba.
Gomina Ekiti ni ijọba ti ṣetan lati rii wi pe eto daabo gbopọn sii nilẹ Yoruba.
O ni lootọọ ni pe iwa ọdaran ko le tan nilẹ patapata, amọ awọn gomina mẹfẹẹfa ti fẹnu ko lati rii wi pe iwa ọdaran dinku kaakiri ilẹ kaarọ o jiire.
2020: Ọdun 2020 yii ko nìí nira fún àwọn tó bá bẹ̀rù Olorun
Ẹwẹ, ẹgbẹ OPC atawọn ẹgbẹ ajijagbara mii nilẹ Yoruba ti kepe awọn gomina yii tẹlẹ pe ki wọn fawọn laṣẹ lati ṣiṣẹ pọ pẹlu awọn agbofinro lati gbogun ti awọn janduku to n da rogbodiyan silẹ nilẹ Yoruba.
Ilé Arúgbó Saraki: Èyí ni ìdí tí ìjọba ìpínlẹ̀ Kwara fí wó ìlè arúgbó ní ìdàjí
Oríṣun àwòrán, Facebook/RealAARahman
Ijọba ipinlẹ Kwara ti ṣalaye idi tawọn fi gbe igbesẹ wiwo ile arugbo nilu Ilorin.
Kọmisana feto iroyin nipinlẹ naa Murtala Olanrewaju sọ pe awọn ko fẹ ki ikọlu waye lawọn fi wo ile naa loruganjọ.
Ninu atẹjade kan ti o fi sọwọ sawọn akọroyin o sọ pe lasuba ọjọbọ lawọn bẹrẹ si ni wo ile naa tawọn agbofinro si duro wamu lalai doju ija kọ awọn to n tawọn laya.
Olanrewaju tun sọ ninu ọrọ rẹ pe ko si ootọ ninu ọrọ tawọn alatilẹyin Saraki n gbe ka pe ile ẹjọ ti paṣẹ kawọn ma fọwọ kan ile naa
''A ko ri iwe kankan gba lati ọdọ ile ẹjọ ṣaaju asiko ta fi bẹrẹ si ni wo ile naa''
O wa parọwa sawọn ara ilu lati bọwọ fofin ki wọn si ma ṣe gbọ ọrọ ahesọ to le ṣakoba fun alaafia ipinlẹ naa.
Bi a ko ba gbagbe awọn alatilẹyin Saraki to wa si ile arugbo naa ti wọn si ba akọroyin wa sọrọ sọ pe ijọba keti ikun si aṣẹ ile ẹjọ to ni ki wọn ma fọwọ kan ile arugbo Olusola Saraki
Ẹgbẹ oṣelu PDP ti sọrọ lori bi ijọba ipinlẹ Kwara ṣe wo Ile Arugbo lulẹ.
Ninu ifọrọwerọ pẹlu ileeṣẹ BBC, Alaga ẹgbẹ oṣelu PDP,Ọgbẹni Kola Shittu ṣalaye pe wiwo ti ijọba wo Ile Arugbo ko le mu ifẹ awọn arugbo kuro lọkan Saraki.
Shittu ni bẹẹ si ni awọn ọmọ ẹgbẹ PDP naa ko ni jakan ninu ifẹ ti wọn ni si Saraki nitori ile ti wọn wo yi.
O ṣalaye pe Bukola Saraki gan an ni ọrọ naa kan julọ, amọ ohun to ba ti ba oju, o ti ba imu.
''Ko si ohun ti ẹgbẹ PDP fẹ ṣe lori ọrọ Ile Arugbo ti ijọba wo, PDP ko ni tori rẹ lọ si ile ẹjọ,'' Ọgbẹni Shittu lo woye bẹẹ.
O ni ohun ribiribi ti Oloye ṣe si ipinlẹ Kwara ati orilẹede Naijiria lapaapọ ju ki wọn maa gba ilẹ rẹ lọ.
Alaga PDP naa sọ  pe  ohun to yẹ ki ijọba Gomina AbdulRahman AbdulRazaq sẹ ni pe ko paṣẹ ki ijọba gba owo ilẹ naa lọwọ awọn ẹbi Oloye to ba tiẹ jẹ pe Oloye ko sanwo ilẹ ọhun nigba naa.
O fikun ọrọ rẹ pe ẹka ijọba to n ri si ọrọ ilẹ naa lo kọwọ bọ iwe to sọ ilẹ naa di dukia Oloye nigba naa.
Ìjọba AbdulRazaq ti wólé aláànúú wa ní Ilorin
Awọn eeyan to jẹ awọn alatilẹyin Bukola Saraki tu itọ soke foju gba a lori bi ijọba ipinlẹ Kwara ṣe wo ile Arugbo lulẹ laarọ Ọjọbọ niluu Ilorin.
Awọn eeyan naa ti wọn ba BBC Yoruba sọrọ ṣalaye pe ijọba Gomina AbdulRahman AbdulRazaq ko laṣẹ lati wo ile ọhun nitori ọrọ ile naa wa nile ẹjọ.
Amọ ijọba sọ pe ọna aitọ ni Oloye Olusola Saraki fi gba ilẹ naa nigba naa nitori ko si akọsilẹ kankan to ṣafihan pe o sanwo fun ijọba.
Wọn ni ijọba to wa lode nipinlẹ Kwara n fi ibi su oloore pẹlu bi o ṣe wo ile arugbo lulẹ.
Wọ́n ti ti ilé ìjọba Kwara pa ní Ilọrin nítorí ọ̀rọ̀ ilé Arúgbó!
Iroyin to n tẹ wa lọwọ lasiko yii ni pe wọn ti ile ijọba pa ni GRA ni Ilorin ni Kwara.
Wọn ni ijọba paṣẹ pe ki onikaluku oṣiṣẹ ile ijọba gbe ile rẹ lasiko yii nitori wahala.
Ko sẹni to le wọle tabi jade bayii nile ijọba ipinlẹ Kwara
Akọroyin BBC to wa ni Ilorin bayii ṣalaye pe ko si ẹni to le wọle tabi jade lasiko yii nile ijọba ni Ilorin.
O ni wọn ko jẹ ki ẹnikẹni sunmọ tosi ẹnu ọna ibẹ rara nitori pe ẹru n ba wọn pe ki iwọde tabi biba nkan jẹ ma lọ ṣẹlẹ lataari ile Arugbo ti wọn wo ni idaji oni.
2020: Ọdun 2020 yii ko nìí nira fún àwọn tó bá bẹ̀rù Olorun
Lẹ́yìn ọ rẹyìn, ìjọba Kwara wó Ilé Arugbó Saraki lulẹ̀ ní Ilorin
Lẹyin ọ rẹyin, ijọba ipinlẹ Kwara ti pada wo 'Ile Arugbo' to wa ni ilu Ilorin.
Oloye Olusọla Saraki kọ fun ra rẹ, eleyi ti wọn maa n fi n ṣe iranwọ fun awọn eeyan ti ko ri ọwọ họri.
Ile yii ni agbaọjẹ oloṣelu to ti di oloogbe, Oloye Olusọla Saraki kọ fun ra rẹ, eleyi ti wọn maa n fi n ṣe iranwọ fun awọn eeyan ti ko ri ọwọ họri.
Iroyin ti tan kalẹ kaakiri lati bi ọjọ melo kan pe ijọba ti ko katakata debi ile naa lati daa wo, amọ, laarọ oni Ọjọbọ ni ijọba pada wo ile naa.
Atẹjade kan ti olori ajọ to n ri si ọrọ ilẹ nipinlẹ Kwara, Ibrahim Salman fi sita ṣalaye pe ijọba ti ra ilẹ ti ile ọhun wa lori rẹ lati ọpọlọpọ ọdun sẹyin lati kọ olu ile iṣẹ ijọba si ori rẹ.
Ọgbẹni Salman ṣalaye pe ijọba yi ero rẹ pada lori ilẹ naa lọdun 1980 pẹlu erongba lati kọ ile iwosan fawọn oṣiṣẹ ijọba sori ilẹ naa.
Oríṣun àwòrán, Kwara State Bureau of Lands
Oloye Olusọla Saraki kọ ile naa fun ra rẹ, eleyi ti wọn maa n fi n ṣe iranwọ fun awọn eeyan ti ko ri ọwọ họri.
O ni ọdun 1982 gan an ni ijọbakọ ile iwosan sori ilẹ naa pẹlu erongba lati fi ilẹ to ku kọ ile iwosan nla lọjọ iwaju.
Ọgbẹni Salman sọ siwaju sii ninu atẹjade naa pe lojiji ni ile iṣẹ Asa Investment ṣaa deedee bu ninu ilẹ ilẹ naa lati lo fun okowo lọna aitọ.
Ṣugbọn o ṣalaye ninu atẹjade naa pe ko si akọsilẹ wi pe wọn sanwo fun ilẹ ti wọn gba ọhun.
O ni bayii ni ile iṣẹ naa tẹsiwaju ti wọn si kọ Ile Arugbo si ori ilẹ naa nibi ti ijọba ya sọtọ fun garaaji igbekọ si ati ibi ti ijọba tun fẹ kọ ile iwosan nla si lọjọ iwaju.
Olori ajọ to n ri si ọrọ ilẹ nipinlẹ Kwara idi niyii ti ijọba ṣe wo ile naa lẹyin ti Gomina AbdulRahman AbdulRazaq ti gbaṣẹ lati gba ilẹ naa pada.
Ọbẹ Ẹgusi sise ati jijẹ
Nigeria Army: Bàbá Adamu tó jẹ́ ọmọ ogun Nàìjíríà tó dàgbà jùlọ jáláìsí
Oríṣun àwòrán, @Nig Army
Bàbá Adamu tó jẹ́ ọmọ ogun Nàìjíríà tó dàgbà jùlọ jáláìsí
Lọdun 1918 ni wọn bi Adama Aduku labule Abejukolo-Ife ni ijọba ibilẹ Omaha ni ipinlẹ Kogi ni aarin gbungubn Naijiria.
Odun 1945 ni Aduku darapọ mọ iṣẹ ologun ni Naijiria to si ja ọpọlọpọ ogun ati ipese iṣẹ aabo gẹgẹ bii ọmọ ogun ilẹ Naijiria tootọ.
Lọjọ kọkanlelọgbọn, oṣu kejila, ọdun 2018 ni igbakeji aarẹ daa lọla.
Ojọgbọn Yemi Osinbajo ni o gbe ami ẹyẹ ti ileeṣẹ ologun Naijiria fi daa lọla fun un nibi ayẹyẹ Nigeria Army Day Celebration (NADCEL).
Ileeṣẹ ologun ati alaabo ilu lo kede iku akinkanju Aduku naa lori ayelujara lọjọ kinni, oṣu kinni, ọdun 2020.
Lasiko ti Baba Aduku sọrọ lẹyin to gba ami ẹyẹ o kare ti ileeṣẹ ologun fun un lo sọ pe ara oun ṣi le daadaa koda lori ibusun paapaa ni eyi to pa ọpọ lérin in nigba naa.
Oríṣun àwòrán, @HQArmy
Bàbá Adamu tó jẹ́ ọmọ ogun Nàìjíríà tó dàgbà jùlọ jáláìsí
Aduku nigba aye rẹ sọ fawọn akọroyin pe oun ko deede darapọ mọ awọn ologun Naijiria.
O ni oun fẹ maa gbeja awọn eeyan ni nitori pe ọkunrin kan oloye kan ni abule ohun nigba naa.
O ṣalaye pe bi oun ṣe n bọ lati oko nirọlẹ ọjọ kan ni ọmọkunrin kan ti ko to mi ṣin aiya fun olori abule wa.
Aduku ni ọmọkunrin naa ni iwadii fihan pe ọmọ ogun ni ati pe Salikawa lorukọ rẹ.
2020: Ọdun 2020 yii ko nìí nira fún àwọn tó bá bẹ̀rù Olorun
O ni o na olori abule nitori pe ko baa gbe ẹru rẹ lọ sile to to maili mẹwaa sira wọn.
2020: Oloye Awurela Ifaleke ti wúré ọdún ìgbéga fún kóówá
Eyi lo jẹ ki oun pinnu lati di ọmọ ogun nitori aṣaaju ijóba labule wọn ni ko si nkan ti ẹnikéni le ṣe fun sọja naa nitori pe aye ajẹrọrun ni awọn ọmọ ogun n jẹ nigba naa.
'Òṣìṣẹ́ Bánkì ni mí l'Amẹ́ríkà kí n tó bẹ̀rẹ̀ Tíátà'
Baba Aduku ni koko to mu ohun foriti gbogbo ẹkọ ati ijiya lẹnu ikọṣẹ ṣọja ni ireti pe ti oun ba ṣetan, oun a gbẹsan ni abule.
#Queen Dihya: Obinrin tó gbógun tàwọn agbésùnmọ̀mí ni Algeria
O ni oun nii lọkan lati pada si abule ti ṣọja Salikawa n gbe nigba naa lati da seri aiya fun un nitori pe o yẹyẹ olori abule oun.
Ọbẹ Ẹgusi sise ati jijẹ
Anti-grazing law: Awon Fulani Darandaran Oyo ti gbe Gomina Makinde lo si ile ejo
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Awọn ẹgbẹ́ Fulani Darandaran ní ìpínlẹ̀ Oyo fi léde pé ijọba ìpínlẹ̀ Oyo ń tẹ ojú ẹ̀tọ́ wọn mọ́lẹ̀ pẹ̀lú òfin darandaran.
Ijọba ipinlẹ Oyo ti ni awọn ko gbọ pe ẹgbẹ fulani darandaran kankan ni ipinle naa gbe awọn lọ si ile ẹjọ.
Eyi ko ṣẹyin iroyin to tan kalẹ pe awọn ẹgbẹ Fulani Darandaran, Gan Allah Fulani Development Association of Nigeria,ti gbe ijọba lọ si ile ẹjọ lori ẹsun pe wọn fi ofin tuntun de kiko maluu jẹ kaakiri ilu, eleyii ti wọn ni o tẹ oju ẹtọ awọn mọlẹ.
2020: Ọdun 2020 yii ko nìí nira fún àwọn tó bá bẹ̀rù Olorun
Adari eto iroyin fun Gomina Makinde, Taiwo Adisa lo fi lede bẹẹ pe ohun ti awọn gbọ ni wi pe awọn ẹgbẹ darandaran kan n fapa janu lori ofi tuntun ti awon ṣe lori eto ọgbin ni ipinlẹ naa.
Adisa fikun un wi pe ofin naa ko tẹ ẹtọ wọn loju mọlẹ, bi kii ṣe ki eto ọgbin le gbooro si ni awọn ṣe ṣe ofin naa ti Ile Asofin ipinlẹ si gbe e yẹ wo, ki wọn to wa buwọ lu u.
Oríṣun àwòrán, Seyi Makinde
Ninu ọrọ rẹ, O ni awọn ti tọ awọn fulani darandaran lọ lati gbe ofin tuntun naa yẹwọ, ti wọn si wo o finifini, ki o to di wi pe wọn fi ontẹ lu ofin naa.
Ọpọlọpọ ijọba ipinlẹ lo ti gbe ofin dide dida ẹran kaakiri yẹ wo nitori eto aabo to dẹnukọlẹ ati ijamba to n ṣe fun eto ọgbin ni awọn agbegbe kan lorilẹ-ede Naijiria.
2020: Oloye Awurela Ifaleke ti wúré ọdún ìgbéga fún kóówá
Abuja Bank Robbery: Ọwọ́ sìkún ọlọ́pàá tẹ Ernest tí wọ́n ń wá.
Oríṣun àwòrán, Guardian newspaper
Ọwọ́ ti tẹ ọ̀gbẹ́ni adigunjalẹ̀
Ọwọ sinku ọlọpaa ti tẹ arakunrin kan, Ernest, to jẹ igi lẹyin ọgba fawọn adigunjale to lọ ṣọṣẹ ni ile ifowopamọ kan laipẹ yi ni ilu Abuja, to jẹ olu ilu Naijiria.
Iroyin ni Ernest  ọhun to n  ṣiṣẹ ni ile igbafẹ ni o jẹ adari fun awọn adigunjalẹ mẹrin ti o lọ ṣọṣẹ ni First Bank to wa ni agbeegbe Mpape ni ilu Abuja.
Komisọnna Ọlọpaa ni ilu Abuja, Bala Ciroma lọ sọ bẹ fun awọn oniroyin pe ọwọ ti tẹ arakunrin naa.
Alukoro ọlọpaa nilu Abuja Manza Anjuguri fidi ọrọ yi mulẹ tio si ni awọn ṣi n fọrọ wa afunrasi naa lẹnu wo.
Oríṣun àwòrán, Buharist Reporter/Facebook
Kete  ti ọwọ awọn ọlọpaa tẹ awọn adigunjale naa ni wọnti jẹwọ pe Ernest gaan ni firindiọkẹrẹ to ṣalude apade ati ja banki naa lole.
Ninu ọrọ tawọn iyoku rẹ sọ fọlọpaa wọ ni  miliọnu meje naira ni awọn gbọkanle lati ji ko to di wi pe awọn ọlọpaa sigun bo ibẹ.
Larry Ehizo to jẹ osisẹ Banki naa wa lara awọn adigunjalẹ naa pẹlu arakunrin Timothy Joe, Princewill Obinna ati Elijah David to jẹ ọmọ ọdun jmọkandinlogun.
Yoruba Film: Ṣé ẹ máa wá ní Pasuma ni mo bí àwọn ọmọ mi tó ń jẹ́ Kuti fún - Jaiye
Oríṣun àwòrán, jayeola_monje
Lori ọrọ ti awọn eniyan ma n sọ pe awọn ọga ọkunrin ninu iṣẹ tiata ma n bere ibalopọ ki wọn to fun wọn ni isẹ, Jaye Kuti ni ko si otitọ kankan nibẹ.
Amọ o fi kun un wi pe, ẹni to ba n wa ifa, ti oun yọju si oun ti ko kan an ni wọn ma n fi ilọkulọ lọ.
Gbajúgbajà òsèré Nollywood, Jaye Kuti wa parọwa si awọn eniyan papa awọn to fẹran iṣẹ tiata lati ni suuru ni idi iṣẹ wọn, ti wọn si mu iṣẹ wọn ni ọkunkundun.
'Ohun tóo gbúdọ ṣe lọ́dún yìí bí o bá fẹ́ kí Ọlọ́run bá ọ rìn'
Gbajúgbajà òsèré Nollywood, Jaiye Kuti ti ke si awọn ololufẹ rẹ lati jawọ ninu ahẹs pe Pasuma to jẹ gbajugbaja olorin fuji ni ọkọ oun. Pasuma kìí ṣe ọkọ mi o! Lanre Kuti ni mo fẹ́ - Jaiye Kuti
Kuti ni baale ile oun ni Lanre Kuti fun ogun ọdun bayii ti awọn ti ṣe igbeyawo, ti awọn si ti ni awọn ọmọ ninu igbeyawo naa.
Ninu ọrọ rẹ, O ni oun ati Pasuma jọ ṣe fiimu bi ọkọ ati iyawo, ti awọn si wọ asọ igbeyawo, ko to wa di wi pe awọn eniyan bẹrẹ si ni sọ ahẹsọ pe oun fẹ Pasuma.
"Emi ni mo kọ fiimu, Jaiyeola lorukọ mi ninu ẹ ti Pasuma si ṣe ọkọ taa ya fọtọ. Lawọn eeyan ba n ki mi lowurọ ọjọ keji pe mo ku inawo ana.
Jaiye Kuti ẹwẹ fesi pe ọkọ oun jẹ ẹni to ni suuru gan to si mọ wi pe inu ile rẹ ni oun ṣi wa pẹlu awọn ọmọ rẹ to bi fun Kuti.
Gbajugbaja osere tiata naa ni ko tun si otitọ ninu ahẹsọ pe oun fẹ Yinka Quadri, wi pe irọ lasan ni.
Oríṣun àwòrán, INSTAGRAM
Aláboyún oṣù mẹ́jọ kú lẹ́yìn tí ejò bù ú jẹ nílé ìyàgbẹ́ ilé rẹ̀
Oríṣun àwòrán, Usman Ahmad Nuraini
Zainab Aliyu Balarabe padanu ẹmi rẹ lẹyin ti ejo bu u jẹ nile iyagbẹ to wa nile rẹ.
Arabinrin alaboyun kan, Zainab Aliyu Balarabe  ti ku lẹyin ti ejo bu u jẹ nile iyagbẹ kan to wa nile rẹ nilu Kaduna.
Iṣẹlẹ naa lo waye lọjọ keji oṣu kini nile oloogbe to wa ni adugbo Kinkinau nipinlẹ Kaduna.
Oyun oṣu mẹjọ lo wa ninu obinrin naa.
Aburo ọkọ oloogbe to fi idi iṣẹlẹ naa mulẹ fun BBC Yoruba, Usman Ahmad Nuraini, sọ pe oloogbe Zainab lọ si ile iyagbẹ ni owurọ kutu ọjọbọ lati tura, lo ṣakiyesi pe nkankan ge e jẹ ni idi bo ṣe joko sori awo iyagbẹ.
Ṣugbọn ko kọbi ara si i, nitori pe ko mọ pe ejo ni. Lẹyin naa lo lọ ọ ṣaluwala, to si kirun.
Snake Market: Àwọn òńtàjà ẹran ejò ní ẹran ejò dùn ju ẹran adìẹ lọ
Koda, o ti pada sori ibusun lati sun ko to o di pe oju ibẹ bẹrẹ si ni dun un gan, to si wú.
Asiko yii lo to o mọ lọran, to si pe ọkọ rẹ, to si paṣẹ pe ki awakọ wọn o gbe e lọ sileewosan. Orogun rẹ sare gbe e lọ silewosan lasiko ti wọn n duro de awakọ, amọ o ni ẹpa ko boro."""
"Wọn sare gbe e lọ sile iwosan, amọ gbogbo ileewosan ti wọn gbe e de lo sọ pe awọn ko ni aporo ejo lati lo fun un, nitori pe awọn eniyan kii ṣaba wa gba a.
Ati pe gbese lo maa n ja si fun awọn gẹgẹ bi ileewosan.
Ko to o di pe oloogbe ku, o sọ fun ọkọ rẹ lori ẹrọ ibaraẹnisọrọ pe oun ko gbọran mọ, bẹẹni oun ko riran mọ, eyi ti ko ribẹ ki ejo to o bu jẹ.
Ọgbẹni Usman sọ pe igbo wa ni agbegbe ti iṣẹlẹ yi ti waye, ti idile naa si ti gbe awọn igbesẹ kan, to fi mọ ni ilana abalaye lati dena ki ejo o maa ba wọ ile wọn.
Ejo abami to n mu owo ni ajọ Jambu
Bakan naa ni wọn ko ri oyun oṣu mẹjọ to wa ninu rẹ doola.
Lẹyin ti wọn gbe oku obinrin naa pada sile ni wọn ranṣẹ pe awọn to n lo ilana ibilẹ lati mu ejo. Awọn wọnyii lo si ba wọn 'pe ejo naa jade' ninu awo iyagbẹ naa to wa.
Eyi ni fidio ti Ọgbẹni Usman ya lẹyin ti wọn gbe ejo naa jade kuro nile iyagbẹ.
Obinrin naa fi ọmọ ọdun meji saye lọ.
Wọn ti sin obinrin naa ni ilana ẹsin Islam ni ana.
Yemi My Lover: Ìdí rèé tí orin kíkọ fi máa ń pò nínú sinimá mi...
Bi ẹ ba jẹ ẹni to n fi ọkan ba ere sinima lorileede Naijiria bọ daadaa, kete ti wọn ba ti darukọ Yemi My Lover, ko ni ṣe yin ni kayeefi.
Gbajugbaja elere sinima yii, Yemi Ayebo ni BBC Yoruba gba lalejo lori eto wa loju opo Facebook.
Ninu ifọrọwero naa ti pupọ awọn ololufẹ rẹ ti darapọ mọ wa Yemi My Lover tu kẹkẹ ọrọ silẹ nipa awọn nkankan.
Lara ohun to sọ fawọn ololufẹ rẹ ni ipa to ko ninu ere sinima Naijiria paapaa julọ nipa ṣiṣe atọna fawọn elere sinima to ti wa gun oke agba loni.
O sọ pe Afees Ọwọ ti o wa di ilumọọka loni jẹ ọkan lara awọn to kọṣẹ sinima lọdọ ohun.
Koda o ni orukọ inagijẹ rẹ''Ọwọ'' to n jẹ ''emi ni mo fun un.''
Ọmọ bibi ikarẹ ni Ilu Ondo,Yemi Ayebo wa lara awọn to kọkọ tan irawọ ere sinima agbelewo lede Yoruba pèlu awọn sinima bi Yemi My Lover, Joke Onibudo ati Ọdẹ Aperin.
Nigba ti BBC Yoruba beere lọwọ rẹ boya o ṣi n ṣe ere sinima,Yemi Ayebọ sọ pe ''oun ko fi igba kan fi sinima lọrun silẹ'
Oríṣun àwòrán, Yemi Ajebo
''Ninu igbagbọ temi,ki eeyan ma han ninu sinima ni gbogbo igba ko tumọ si pe ere to n gbe jade ni ẹkọ tawn eeyan le kọ''
O tẹsiwaju pe ''bi eniyan ba ni sinima kan laarin ọdun mẹta awọn eeyan ko ni gbagbe rẹ''
O tun ṣalaye idi ti orin fi maa n pọ ninu awọn ere sinima rẹ nipe oun feran orin kiko gan an ni.
''Ẹni ti o ba ṣe fiimu ti ko fi orin sinu rẹ, ko ti ṣisẹ ere sinima.
Eyi ni ẹkọ taa kọ lati ọdọ Ade Love ati Hubert Ogunde''
O ni sọ nipa pataki orin kikọ ninu aṣa ati igbelarugẹ ede Yoruba
Kogi attack: èèyàn mọ́kàndínlógún pàdánù ẹmi wọ́n ninu ikọlù náà
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ìgbà àkọ́kọ́ kọ́ nìyí tí irú ìṣẹ̀lẹ̀ bẹ̀ yòó wáyé
Ileeṣẹ ọlọpaa nipinlẹ Kogi sọ pe awọn agbebọn ti pa eeyan mọkandinlogun ni ilu Twari ni ijọba ibilẹ Kogi ni ipinlẹ Kogi.
Alukoro ọlọpaa ASP William Aya lo fidi ọrọ yi mulẹ fun BBC .
William Aya sọ pe yatọ si awọn eeyan to padanu ẹmi wọn,awọn agbebọn naa tun sọ ina sawọn ile ti awọn oniroyin kan si sọ pe wọn dana sun ile baalẹ kan nibẹ
Lowurọ kutu ọjọ Ẹti lawọn alaburu yi yabo Tawari ti alukoro ọlọpaa si sọ pe awọn ko le sọ pato awọn to ṣe iṣẹ aburu yi.
''Kọmisan ọlọpaa ni Kogi ti ṣabẹwo sibẹ ti o si ti ni ki iwaadi bẹrẹ ni pẹrẹwu.Bẹẹ naa ni o sọ pe alaafia ti pada si agbegbe naa bayi''
William Aya tẹsiwaju ninu alaye rẹ pe awọn ọlọpaa kogberegbe to fi mọ awọn to n ṣiṣẹ ọtẹlẹmuye n pawọ pọ pẹlu awọn ọmọ ileeṣẹ ologun lati tọ pinpin awọn to wa nidi iṣẹlẹ yi.
Awọn oṣojumikoro kan sọ fawọn akọroyin Naijiria pe ikọlu naa j eleyi tawọn darandaran fi gbẹsan bi wọn ṣe pa awọn ajinigbe kan ti wọn fura si pe wọn jẹ Fulani lopopona Lokoja Abuja.
O sọ pe awọn eeyan ilu Tawari lo ta awọn agbofinro lolobo nipa awọn ajinigbe yi .
Alukoro ọlọpaa sọ pe ohun ko le fidi ọrọ yi mulẹ ṣugbọn iwadi ṣi n lọ lọwọ.
Saraki Ile Arugbo: Ipò àpọ́nlé ni mo fi Gómìnà Abdulrahman sí ṣugbọn kò hùwa àpọ́nlé
Oríṣun àwòrán, FACEBOOK/GBEMI SARAKI/ABDULRAHAMAN ABDULRAZAQ
Sẹnẹtọ Gbemisola Saraki ti tutọ soke foju gba a lori bi ijọba ipinlẹ Kwara ṣe wo ile Arugbo eleyi ti Baba rẹ Dokita Olusola Saraki kọ nigba aye rẹ.
Ninu atẹjade kan ti o fi sita loju opo ayelujara, Saraki ni iwa aibọwọ fun eeyan ni ijọba hu pẹlu bi wọn ti ṣe ko awọn agbofinro lọ gba ilẹ naa lagidi.
O ṣalaye pe oun ko ba ma sọrọ lori iṣẹlẹ yii ki o ma baa dabi ẹni pe oun n wọ iya ija pẹlu Gomina ṣugbọn bi awọn agbofinro ṣe fi agidi gba ilẹ naa lo mu oun wa sọrọ.
Gbemi Saraki ni toun ti pe oun jẹ ọmọ ẹgbẹ APC nipinlẹ Kwara ti oun si gba awọn miran wọ inu ẹgbẹ tọwọ tẹsẹ to fi mọ Gomina Abdulrazaq o yẹ ki Gomina bun oun gbọ ki wọn to yabo ile Arugbo.
''Oju ẹgbọn ni mo fi n wo Gomina Abdulrazaq ti a si ti mọra tipe. Mi o si fi igba kan ma ṣe apọnle fun un  ṣugbọn ko fi ọwọ mi wọ mi ''
Gbemi Saraki ti o jẹ Minisita abẹle feto irina lorileede Naijiria labẹ ẹgbẹ oṣelu APC bẹnu atẹ lu bi awọn agbofinro ti ṣe yabo ile Arugbo laago mẹta oru ti wọn si yin afẹfẹ tajutaju lu awọn iya arugbo nibẹ.
O wa kesi ọga ọlọpaa patapata lati fa Kọmisan ọlọpaa leti pe ki o ti ọwọ ọmọ rẹ baṣọ ki o si ma jẹ ki awọnm oloṣelu lo lati tẹ ifẹ inu wọn.
Saraki pari ọrọ rẹ pe ki awọn ọmọ ẹgbẹ oṣelu APC ma ṣe fa wahala koda bi wọn ba n ti ika bọ wọn lẹnu.
Ninu atẹjade ti Gbemi Saraki fi sita yi,ko sọ boya Baba oun niiwe aṣẹ lori ilẹ naa tabi boya mọlẹbi yoo gbe ijọba lọ ile ẹjọ
Ṣé ẹ ti rí kí èèyàn ní àwọ̀ ara tó ń ṣí bíi ìpẹ́pẹ́ ẹja rí?
Ìròyìn tó mi ọ̀sẹ̀ àkọ́kọ́ 2020: Amẹ́ríkà dojú ìjà kọ Iran, Ìjọba Kwara wò ilé arúgbó Saraki
Satide ti yoo ba da ati ọjọ Jimọ laa tii mọ.
Bi a ba ni ka fi ti awọn iroyin to mi igboro lọsẹ kini Oṣu kini ọdun 2020 yi wo o, nkan yoo ṣẹnu 're lagbami iroyin lọdun ti a ṣẹṣẹ mu yii.
O dabi ana ti a dagbere fun ọdun 2019 ti pupọ wa si n ki ara wa pe a ku ipalẹmọ 2020.
2020 ti de ti o si ti n so eso iroyin lorisirisi.
Ẹ jẹ ki a fi diẹ to ara wa leti ninu wọn ki ọrọ naa ma baa di ariyanjiyan.
2020: Ọdun 2020 yii ko nìí nira fún àwọn tó bá bẹ̀rù Olorun
Ojoro la fẹ fi bẹrẹ tori ẹ le fẹ sọ pe ha ha, ọsẹ to kọja ni ọ̀rọ̀ yii bẹrẹ, ṣugbọn ẹyin yoo ri pe ko baa le daa la fi ṣe bẹ tori o ṣi wa lori igba iroyin titi di ọsẹ yii.
Iroyin awọn adigunjale to lọ fọ banki nilu Abuja tọwọ ọlọpaa tẹ wọn la kọkọ fẹ mu.
Oríṣun àwòrán, Guardian Newspaper
Lootọ ni pe lọjọ Kejidinlọgbọn oṣu to pari 2019 ni ọwọ tẹ wọn ṣugbọn ẹni tawọn ọlọpaa sọ pe o jẹ ogunagbongbo iṣẹlẹ naa, laarin ọsẹ kini 2020 ni ọwọ palaba rẹ segi.
Abuja Bank Robbery: Ọwọ́ sìkún ọlọ́pàá tẹ Ernest tí wọ́n ń wá wa lara awọn iroyin tawọn eeyan n ka iroyin rẹ nipa iṣẹlẹ yii.
Ni bayi ti ọwọ ọlọpaa ti tẹ Earnest, iye awọn tọwọ tẹ lori iṣẹlẹ naa ti di marun un.
Oríṣun àwòrán, @GovAyoFayose
Ẹ̀yin ọ̀tá mi, ẹ lọ dì mọ́ òpò ina lọ́dún 2020- Ayodele Fayose
Nise ti ọdun tuntun bẹrẹ, Gomina ipinlẹ Ekiti tẹlẹ ri, Ayodele Fayose fi eebu ọrọ ransẹ si awọn to n pẹgan rẹ.
Ọrọ ko ṣẹyin bi awọn kan ṣe bu ẹnu atẹ lu u lẹyin ti fidio jade nibi ti o ti n jo pẹlu oyinbo lode kan ni ilẹ okeere.
Oríṣun àwòrán, @GovAyoFayose
Wọn ni ṣebi itọju lo loun fẹ lọ gba nilu okeere to fi gba  beeli rẹ lọdọ adajọ.
Fayose da wọn lohun pe ayẹwọ ara ni oun lo se, oun ko dubulẹ aisan, nitori naa oun laṣẹ lati jo ati yọ ninu ọdun tuntun.
Ẹkunrẹrẹ iroyin yi wa loju opo wa nibi yii Ẹ̀yin ọ̀tá mi, ẹ lọ dì mọ́ òpò ina lọ́dún 2020- Ayodele Fayose
Bi ere bi ere ni ọrọ naa bẹrẹ a mọ ki a to diju ka to la, a ijọba ipinlẹ Kwara ti wo ile Arugbo eleyi to jẹ ti Dokita Olusola Saraki, baba adari ile aṣofin agba Naijiria tẹlẹ ri.
Eemọ kileyi lawọn alatilẹyin Saraki n ke ti awọn iya arugbo naa ṣi n ṣemo pe Gomina Abdulrahaman ti gba ijẹ lẹnu awọn.
Ninu fọnran fidio to wa nisalẹ yii, wọn ti ṣaaju ke gbajare si ki o ma wo ile naa ṣugbọn pabo ni igbiyanju wọn ja si.
Àwọn arúgbó ní kí ìjọba máà ṣe wó ilé arúgbó m'áwọn lórí
Nigba ti osẹ yoo fi wa si opin, Bukola Saraki to jẹ ọmọ Dokita Olusola Saraki ati Gbemisola Saraki naa ti tutọ soke foju gba a lori igbesẹ ijọba yii.
Iroyin yi ko ti jọ bi ẹni loju tu,ẹ  tubọ maa tẹle wa fun atupalẹ bi ọrọ naa ba ti ṣe n lọ si.
Ṣaaju igba naa, ẹ ka sii nipa rẹ loju awọn opo wọnyii:
Jẹjẹ lo jọ bi pe ọṣẹ akọkọ 2020 n palẹmọ lati pari ki iroyin bi ilẹ Amerika ti ṣe ṣekupa ọgagun ọmọ orileede Iran kan ni Iraq.
Kete ti iroyin yii lu sita ni gbogbo oju opo iroyin lagbaye gbanajẹ ti awọn eeyan si n pariwo WWIII loju opo Twitter.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ẹkunrẹrẹ iroyin nipa iṣẹlẹ yii ree to ba jẹ pe ẹ ko tii maa fọkan ba a bọ tẹlẹ:
Ààrẹ Donald Trump: Qasem Soleimani ń gbìmọ̀ràn láti kọ lù wá l'Amerika la ṣe kọ́kọ́ yára pa á - Trump Ààrẹ
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Aarẹ ilẹ Amẹrika, Donald Trump ti ni kii ṣe lati bẹ̀rẹ̀ ogun lawọn ṣe pa olori ọmọ ogun alagbara nni lorilẹede Iran bi ko ṣe lati pa ina ogun ko to bẹrẹ.
Ọgbẹni trump sọ pe ijọba idunkukulaja mọ ni ti Soleimani n dari ti wa sopin pẹlu ikọlu to waye ni papakọ ofurufu Iraq lọjọ ẹti.
Soleimani lo dari awọn ikọlu to waye ni aarin gbungbun orilẹede Iran gẹgẹ bi adari ẹgbẹ ọmọ ogun kan to n jẹ Quds Force.
Ẹwẹ, orilẹede Iran ti leri pe afi ki awọn gba ẹsan iku rẹ.  Ẹ̀jẹ̀ yóò sàn pẹ̀lú bí Amerika se pa Ọ̀gáagún wa - Iran
Oṣù Kínní ọdún 2020 ti pẹ́ jù, ẹ ṣe ìgbẹ́jọ́ mi kíákíaá - Donald Trump
Trump impeachment: Trump kò fìdí janlẹ̀ tán, àmọ́ níbo ni yóò jásì?
Bi wọn ṣe pa a yii ti ru ọpọlọpọ ibinu soke laarin orilẹede Iran ati orilẹede Amẹrika.
Bakan naa ni ilẹ Amẹrika ni awọn yoo tun fi ẹgbẹrun mẹta kun ikọ ọmọ ogun ti wọn yoo ran lọ si aarin gbungbun iha Guusu gẹgẹ bi ikọ olu lalakan fi n ṣọri.
Ko da, ile iṣẹ mohunmaworan Iraq royin pe ikọlu inu afẹfẹ kan ti waye lorilẹede naa lẹyin wakati mẹrinlelogun ti wọn pa Soleimani.
Aarẹ Trump ni awọn ọmọ ogun ilẹ Amẹrika ṣe iṣẹ iṣekupani ọhun lai labawọn kankan eyi to si fa iku adunkoko mọni to lagbara ju lagbaye, Qassem Seleimani."
Soleimani n gbimọran ọtẹ lati kọlu awọn eekan ati ologun Amẹrika a si gba a mu lọrun ọwọ eyi la si ṣe pari ẹmi rẹ.
"Ninu ọrọ ti wn fi sita lẹyin iku Soleimani, adari Ayatollah Ali Khamenei sọ pe "" wi pe o faye silẹ lọ ba Ọlọrun kii ṣe opin ọna rẹ tabi iṣẹ ti a fi ran an, ṣugbn ẹsan a ke kikan kikan lroi awọn to lọwọ ninu ẹjẹ rẹ atawọn akinkanju mii ti wọn pa lana."
Ṣé ẹ ti rí kí èèyàn ní àwọ̀ ara tó ń ṣí bíi ìpẹ́pẹ́ ẹja rí?
Otedola Bridge accident: Èèyàn méjì bá ìjàmbá ọ̀kọ̀ tó ṣẹlẹ̀ lórí afárá Otedola lọ
Oríṣun àwòrán, LASEMA
Eeyan meji ti dero ọrun ninu ijamba ọkọ to ṣẹlẹ lori afara Otedola lopopona marosẹ ilu Eko si Ibadan lọjọ Satide.
Ijamba ọkọ naa ṣẹlẹ lẹyin ti ọkọ nla kan to ko okuta ikọle kọlu ọkọ Lexus agbera pa lori afara ọhun.
Ọga ajọ LASEMA to n ri si iṣẹlẹ pajawiri niluu Eko, Ọmọwe Oluwafemi Oke-Osanyintolu ṣalaye pe awakọ nla naa fi ọkọ rẹ kọlu odi to wa laarin ọna.
Ọgbẹni Oke-Osanyintolu sọ pe ọkọ to ko okuta ikọle ọhun ja si meji lẹyin to kọlu odi to wa laarin ọna, ti ori ọkọ naa si jabọ lati ori afara.
Oríṣun àwòrán, LASEMA
O ṣalaye pe awọn meji to mori bọ ninu iṣẹlẹ naa gba itọju lẹsẹkẹsẹ, nigba ti ẹni to farapa ju ti lọ si ile iwosan fun itọju to peye.
Oríṣun àwòrán, LASEMA
Ọga LASEMA ni ajọ naa ṣiṣẹ takuntakun lati rii pe ijamba ọkọ ọhun ko da sunkẹrẹ fakẹrẹ silẹ lopopona Eko si Ibadan.
Ọbẹ Ẹgusi sise ati jijẹ
Ritual Murder: Ọlọ́pàá hú òkú akẹ́kọ̀ọ́ fásítì LASU tí ọ̀rẹ́kùnrin rẹ̀ àti pásítọ̀ ṣekúpa
Oríṣun àwòrán, Nigeria Police
Bàbá akẹ́kọ̀ọ́bìnrin LASU tí ọ̀rẹ́kùnrin rẹ̀ fi ṣ'òògùn owó ń bèèrè fún ìdájọ́ òdodo
Ile iṣẹ ọlọpaa ipinlẹ Oṣun ti hu oku akẹkọọbinrin fasiti ipinlẹ Eko LASU.
Omobinrin naa, Favour Daley-Oladele n mura fun eto agunbanirọ, ki ọrẹkunrin rẹ ati pasitọ kan to jọ gbimọ pọ ṣekupa ni Ikoyi-Ile, ni ipinlẹ Oṣun.
Ọga ọlọpaa ipinlẹ Oṣun to siwaju awọn to hu oku naa, Babatunde Kokumo ṣalaye pe hihu oku naa ṣe pataki fawọn ọlọpaa lati pari iṣẹ iwadii wọn lori iṣẹlẹ naa.
Pasito ijọ alaṣọ funfun kan, Segun Philip ati Adeeko Owolabi to jẹ ọrẹkunrin Favour pẹlu iya rẹ, Bola Oladele ni wọn ti wa ni gbaga ile iṣẹ ọlọpaa lori ẹsun pe wọn jọ gbimọ pọ ni.
Pasitọ Philip ati Owolabi jẹwọ pe lootọ lawọn pa Favour lati fi ṣe oogun owo, amọ ẹlẹda ọmọbinrin naa ko jẹ ni ni oogun owo.
2020: Oloye Awurela Ifaleke ti wúré ọdún ìgbéga fún kóówá
Ninu ifọrọwanilẹnuwo wọn pẹlu Adeeko lo ti ṣalaye pe pasitọ fun oun ni ọmọ odo lati fi lu u lori ti pasitọ si sare fi ọbẹ yọ ọkan rẹ eyi to fi se asejẹ fun Adeeko ati iya rẹ.
#Queen Dihya: Obinrin tó gbógun tàwọn agbésùnmọ̀mí ni Algeria
Owolabi ẹni ọdun mẹtalelogun naa sọ pe oun kabamọọ ohun ti oun ṣe pẹlu Philip, o ni iṣẹ to bọ lọwọ baba ati mama oun lo sun oun debi fifi ọrẹbinrin oun ṣe oogun owo.
Ẹwẹ, baba oloogbe akẹkọọbinrin naa ṣapejuwe Favour gẹgẹ bi wura ninu idile oun.
'Òṣìṣẹ́ Bánkì ni mí l'Amẹ́ríkà kí n tó bẹ̀rẹ̀ Tíátà'
Babab Favour ni: ''A woju Ọlọrun fun ọdun diẹ ki a to bi Favour.
O si lọ fasiti eyi to mu inu wa dun pe yoo kẹkọọ gboye laipẹ ṣugbọn eeyan kan gbimọ pọ lati ṣekupa a,''
Baba oloogbe naa ni iku Favour jẹ ibanujẹ nla fun idile oun ati pe idajọ odod nikan lo ku ti oun n reti.
Ọbẹ Ẹgusi sise ati jijẹ
Gas Explosion: Ẹ̀mí kan bọ́, èèyàn mẹ́ta fara pa nínú ìṣẹ̀lẹ̀ ìbúgbàmù gáàsì tó wáyé l‘Eko
Oríṣun àwòrán, @followlasema
Ọkunrin kan ti wọn ko ti dárúkọ rẹ ti padanu ẹmi rẹ lasiko ti ibugbamu afẹfẹ gaasi to waye ni agbegbe Palmgrove nilu Eko.
Iroyin sọ pe agolo gaasi kan ti wọn fi n tun ẹ̀rọ amule tutu kan ṣe ninu ile alaja kan naa lo bu gbamu, nitori pe ó ń jò.
Yatọ si ọkunrin to kú, ọkunrin mẹta miran tun farapa, ti wọn si ti n gba itọju nileewosan.
Alaga ajọ to n mojuto iṣẹlẹ pajawiri nipinlẹ Eko, Olufemi Oke-Osanyintolu, to fidi iṣẹlẹ naa mulẹ, sọ pe wọn ti ko gbogbo eeyan to n gbe ninu ile naa kuro.
Osanyintolu ni agbegbe Cappa Avenue, Palmgrove nilu Eko ni ibugbamu naa ti waye.
Oríṣun àwòrán, @followlasema
Ó fi kún un pe wọn ti ti ile naa pa, lati dena ijamba miran.
Eyi ko sẹyin bi awọn ibi kan lara ògiri ati òpó ile naa, ṣe ti sán, nitori ibugbamu to waye.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Gas Explosion: Afẹ́fẹ́ gáàsì ṣekúpa ọ̀pọ̀ èèyàn ní Kaduna
Awọn agbofinro ipinlẹ Kaduna ti fi ninu orukọ awọn to ba iṣẹlẹ naa rin sita.
Ijamba ina afẹfẹ gaasi to ṣẹlẹ ni agbegbe Sabon Tasha ni Kaduna ni wọn ni o ti mu ẹmi Ojọgbọn Simon Mallam lọ.
Ojọgbọn Simon Mallam ni adari ajọ Nigeria Atomic Energy Commission to n mojuto ọrọ ado oloro ni Naijiria.
Awọn ọlọpaa ipinlẹ Kaduna fidi ẹ mulẹ pe eniyan mẹfa lo ti jalaisi bayii ninu iṣẹlẹ naa ti awọn miran ṣi wa nile iwosan.
Opọlọpọ ile itaja lo jona mọ ile itaja afẹfẹ gaasi ti iṣẹlẹ naa ti ṣẹlẹ bayii.
Agbenusọ ajọ Nigeria Atomic Energy Commission fidi ẹ mulẹ fun akọroyin BBC pe, nigba ti Ojọgbọn Simon lọ gẹ irun ori rẹ ni ọkan lara awọn ile igẹrun lẹgbẹ ile itaja gaasi naa ni iṣẹlẹ naa waye.
O ni lasiko ti Ọjọgbọn Simon ṣe n gẹ irun lọwọ ni afẹfẹ gaasi naa gbina ṣugbọn gbogbo igbiyanju lati doola ẹmi rẹ ja si pabo ni eyi to ti mu ẹmi Ọjọgbọn naa lọ.
Yoruba language: Ọdún 2020 to wọlẹ́ dé yìí á tu gbogbo wa lára
Ọpa afẹfẹ gaasi to bu gbamu ti ṣekupa ọpọ eeyan niluu Kaduna lọjọ Satide.
Kọmiṣọnna eto aabo ni Kaduna, Samuel Aruwan gboṣuba fawọn oṣiṣẹ iṣẹlẹ pajawiri pé wọ́n tètè dìde si iṣẹlẹ naa.
Awọn ti iṣẹlẹ naa ṣoju wọn ni ṣaa deede ni ṣọọbu naa deede gab ina ni agbegbe Sabon Tasha ni Kaduna.
Oríṣun àwòrán, Twitter/Nasir El Rufai
Iṣẹlẹ ọhun jẹ iyalẹnu fawọn araalu ni Kaduna eleyi ti iroyin sọ pe afẹfẹ gaasi to n jo lo ṣe okunfa rẹ.
Kọmiṣọnna fun eto aabo ni Kaduna, Samuel Aruwan gboṣuba fawọn oṣiṣẹ iṣẹlẹ pajawiri ninu iṣẹ ibanikẹdun to fi ṣọwọ si ẹbi awọn ti iṣẹlẹ naa mu ẹmi wọn lọ.
Iṣẹlẹ ọhun ni kọmisọnna sọ loju opo Twitter rẹ pe o ṣẹlẹ lopopona Kachia ni ijọba ibilẹ Chikun.
'Òṣìṣẹ́ Bánkì ni mí l'Amẹ́ríkà kí n tó bẹ̀rẹ̀ Tíátà'
Ninu ọrọ ibanikẹdun tirẹ, Sẹnẹtọ to n ṣoju ẹkun aringbungbun Kaduna, Uba Sani tọrọ aforiji fawọn to ba iṣẹlẹ naa lọ.
Bakan naa lo ki awọn oṣiṣẹ iṣẹlẹ pajawiri ninu iṣẹ ibanikẹdun to fi ṣọwọ si ẹbi awọn ti iṣẹlẹ naa mu ẹmi wọn lọ.
2020: Oloye Awurela Ifaleke ti wúré ọdún ìgbéga fún kóówá
IranWar:Tump ní ní kíákíá lAmẹ́ríkà yóò kọlù Iran tí wọ́n bá ṣé ikọlù nkán ìní àwọn
Oríṣun àwòrán, Reuters
Aarẹ Amẹrika Donald Trump ti fi ikilọ ranṣẹ si orileede Iran pe bi wọn ba doju ija kọ awọn,ọna mejileelaadọta ni awọn yoo gba kọlu wọn pada.
Ikilọ yi ti Donald Trump fi sita loju opo Twitter ko sẹyin bi Iran ti ṣe ni awọn yoo gbẹsan iku ọgagun awọn ti Amẹrika pa.
Ọgbẹni Trump sọ pe niṣe ni Iran n leri tantan pe awọn yoo kọlu awọn nkan ini Amẹrika kan lati fi gbẹsan iku Soleimani ṣugbọn bi wọn ba dan wo pẹnrẹ,awọn nkan ini to jẹ Iran logun lawọn yoo ṣe ikọlu si.
Ninu ọrọ rẹ o ni iye awọn nkan ini Iran tawọn yoo doju ija kọ yi ṣe deede iye ọmọ Amẹrika ti wọn fi si igbekun ni Iran nigba kan ri.
Yoruba language: Ọdún 2020 to wọlẹ́ dé yìí á tu gbogbo wa lára
Trump ni awọn ko ni jafara lati kọlu Iran ti wọn ba fi le doju ija kọ awọn eeyan Amẹrika tabi nkan ini wọn.
Oríṣun àwòrán, @realDonaldTrump
Trump ni America ṣẹṣẹ ra awọn ohun eelo ogun didara tuntun ni,
O ni awọn ko nii roo lẹẹmeji ki wọn to yẹ iṣẹ awọn ohun eelo ogun tuntun yii wo lara Iran.
Ẹwẹ, oku ọgagun agba Iran  ti Amẹrika pa Qasem Soleiman ti balẹ lorileede naa ṣaju isinku rẹ.
Ijọba Iran kede eto isinku ọlọjọ mẹta lati daro ọgagun yi ti wọn ṣapejuwe rẹ gẹgẹ bi akọni nla loju ija.
Oyo Fire: Dukia ṣófo, ọmọ ọdún mẹ́rìnlá faragbọta níbí iná tó jó ọjà Akesan
Oríṣun àwòrán, Google
Ọpọ dukia lo ti ṣofo ti ọmọkunrin, ọmọ ọdun mẹrinla kan si padanu ẹmi rẹ ninu iṣẹlẹ ina to jo ni ọja Akesan nilu Oyo.
Oríṣun àwòrán, Google
mọjumọ ọjọ Aiku tii ṣe ọjọ karun un, oṣu kini ọdun 2020 ni iṣẹlẹ yi waye.
Oríṣun àwòrán, Google
Alukoro ọlọpaa nipinlẹ Oyo, SP Fadeyi Olugbenga sọ pe nnkan bi aago meji oru ni ina naa bẹrẹ.
Oríṣun àwòrán, Google
O ṣalaye pe kete ti awọn ọlọpaa gbọ iro nkan to n ṣẹlẹ ni ọga ọlọpaa lagbegbe naa atawọn ọlọpaa ti lọ sibẹ.
Oríṣun àwòrán, Google
Ọgbẹni Olugbenga sọ bakan naa pe awọn agbofinro gbiyanju lati gbogun ti awọn to le fẹ ji nkan gbe nibi iṣẹlẹ naa.
Oríṣun àwòrán, Google
Bo tilẹ jẹ wi pe Olugbenga ni awọn eeyan kan duro lati doju ija kọ awọn panapana ti wọn ni wọn ko tete de lati pa ina naa.
Oríṣun àwòrán, Google
Ọlọpaa ni ko si ootọ ninu iroyin pe awọn ọlọpaa yinbon pa eeyan nibi iṣẹlẹ naa.
Oríṣun àwòrán, Google
Gomina Ipinlẹ Oyo, Seyi Makinde ti sọ wi pe iwadii ti bẹrẹ ni pẹrẹwu lori ina to jo ni Ọja Akẹsan ni ilu Oyo.
Oríṣun àwòrán, Google
Gomina ipinlẹ Oyo naa wa rọ awọn eniyan lati ṣe pẹlẹ nitori iwadii ti bẹrẹ ni ẹkun rẹrẹ lori ohun to fa iṣẹlẹ naa.
Gomina Ipinlẹ Oyo, Seyi Makinde ti sọ wi pe iwadii ti bẹrẹ ni pẹrẹwu lori ina to jo ni Ọja Akẹsan ni ilu Oyo.
Gomina Makinde lo sọ ọrọ yii ni oju opo ikansiraẹni Facebook rẹ lati kẹdun pẹlu awọn to sọ dukia ati ohun ini wọn nu ninu iṣẹlẹ ina to jo naa.
Oríṣun àwòrán, Google
Ipenija ina ni ìpínlẹ̀ Oyo lẹnu ọjọ mẹta yi jẹ eleyi to n kan awọn ara ilu lominu.
Ninu ọrọ rẹ, o ni inu oun bajẹ gidigidi bi oun ṣe gbo iroyin naa, ti o si rọ awọn ti wọn sọ ohun ini wọn nu lati ṣe kan akin lasiko yii.
Gomina ipinlẹ Oyo naa wa rọ awọn eniyan lati ṣe pẹlẹ nitori iwadii ti bẹrẹ ni ẹkun rẹrẹ lori ohun to fa iṣẹlẹ naa.
Ọpọ dukia lo ti ṣofo ninu ijamba ina to sọ ni afẹmọjumọ Ọjọ Aiku, Ọjọ Karun un, Oṣu Kini ọdun 2020 ti iṣẹlẹ naa waye.Ẹ wo àwòrán bí ọjà Akẹsan ṣe jóná ràùràù ní ìlú Oyo!
Ọpọ dukia lo ti ṣofo ti ọmọkunrin, ọmọ ọdun mẹrinla kan si padanu ẹmi rẹ ninu iṣẹlẹ ina to jo ni ọja Akesan nilu Oyo.
Mojumọ ọjọ Aiku tii ṣe ọjọ karun un, oṣu kini ọdun 2020 ni iṣẹlẹ yi waye.
Oríṣun àwòrán, Reuters
Dukia ṣófo, ọmọ ọdún mẹ́rìnlá faragbọta níbí iná tó jó ọjà Akesan
Nigba ti o n fi idi ọrọ yi mulẹ fun ileeṣẹ BBC, alukoro ọlọpaa nipinlẹ Oyo, SP Fadeyi Olugbenga sọ pe ni nkan bi aago meji oru ni ina naa bẹrẹ.
O ṣalaye pe kete ti awọn gbọ iro nkan to n ṣẹlẹ ni ọga ọlọpaa lagbegbe naa tawọn lọ sibẹ.
O ni: Ni iroyin to tẹmi lọwọ kẹyin, ina naa ti lọ silẹ ṣugbọn wọn ko ti ribi pana rẹ patapata.
Ogbẹni Olugbenga sọ bakan naa pe awọn agbofinro gbiyanju lati gbogun ti awọn to le fẹ ji nkan gbe nibi iṣẹlẹ naa.
Bo tilẹ jẹ wi pe Olugbenga ni awọn eeyan kan duro lati doju ija kọ awọn panapana ti wọn ni wọn ko tete de lati pa ina naa.
Ṣugbọn awọn agbofinro ti pana ifẹhonuhan naa.
Mo fẹ fi to yin leti pe ko si ootọ ninu iroyin pe awọn ọlọpaa yinbon pa eeyan nibi iṣẹlẹ naa.
Yoruba language: Ọdún 2020 to wọlẹ́ dé yìí á tu gbogbo wa lára
Nkan to ṣẹlẹ ni pe awọn ọdọ kan n dana sun taya nitori pe awọn panapana ko tete de.
Awọn wọnyi ati awọn to fẹ yabo agọ ọlọpa la kọdi si, ti ko gba laaye. A ko yinbọn mọ ẹnikankan''
Nigba ti BBC beere lọwọ rẹ boya ẹnikankan ku ninu iṣẹlẹ naa, o sọ pe awọn naa gbọ iroyin pe ọta ibọn ba ọmọkunrin ọdun mẹrinla kan ṣugbọn kii ṣe ọlọpaa lo yinbọn lu u.
O ni awọn ṣi n tẹsiwaju pẹlu iwadii.
Fadele: Dán an wò, lóbí ìyá ọ̀kẹ́rẹ́ ni a fi ọ̀rọ̀ ọ̀kadà náà ṣe
Lẹnu ọjọ mẹta yii, ọwọja ina ni ipinlẹ Ọyọ fẹ peleke ti o si ṣe afihan pe ipenija yi fẹ kọja ipa ileeṣẹ panapana.
Ipenija yi jẹ nkan ti Gomina ipinlẹ Oyo Seyi Makinde naa mẹnuba loju opo Twitter rẹ pe:
Ṣé ẹ ti rí kí èèyàn ní àwọ̀ ara tó ń ṣí bíi ìpẹ́pẹ́ ẹja rí?
Àwọn aworan yii wa lati ọwọ Google, Facebook ati Twitter
Asset declaration: Àjọ SERAP ń fẹ́ kí Buhari, Osinbajo, àtàwọn gómìnà kéde dúkìá wọn kọ́jọ́ méje tó pé
Oríṣun àwòrán, @NGRPresident
Ajọ ajafẹtọ kan to n fọnrere igbogun ti iwa ijẹkujẹ, SERAP ti fun Aarẹ Buhari, Igbakeji rẹ, Ọjọgbọn Yẹmi Oṣinbajo atawọn gomina pẹlu igbakeji wọn ni gbendeke ọjọ meje lati kede dukia wọn fun araye gbọ.
Ajọ SERAP ni awọn fẹ ki aarẹ ati gbogbo awọn gomina to fi mọ igbakeji wọn o kede iye dukia ti wọn ni, iye owo to n wọle fun wọn lẹkunrẹrẹ gẹgẹ bi wọn ṣe kọọ sinu fọọmu ikede dukia ẹni ti ajọ Code of Conduct Bureau.
Ajọ naa ni kikede dukia awọn to di ipo iṣejọba mu gẹgẹ bi wọn ṣe kọọ silẹ ninu fọọmu dukia ti wọn tọwọ bọ ṣe pataki.
Fadele: Dán an wò, lóbí ìyá ọ̀kẹ́rẹ́ ni a fi ọ̀rọ̀ ọ̀kadà náà ṣe
Wọn ni bi wọn ṣe sọ nigba ti wọn fẹ gba ipo naa jẹ eyi ti yoo ran ilu lọwọ lati ṣi aṣọ loju awọn iwa kotọ to ba n waye lori iye dukia tawọn eeyan naa n kede.
Yoruba language: Ọdún 2020 to wọlẹ́ dé yìí á tu gbogbo wa lára
Lara awọn dukia ti SERAP n fẹ ki aarẹ atawọn ẹmẹwaa rẹ to dipo ijọba mu ni apapọ ati ipinlẹ o kede ni owo wọn atawọn dukia bi ile, ilẹ ohun ini miran pẹlu ipin idokoowo lawọn ileeṣẹ aladani ati ti ajọni gbogbo.
Oríṣun àwòrán, @NGRPresident
Ajọ SERAP gbe gbedeke naa kalẹ labẹ ẹtọ ofin ọranyan niroyin faraalu, FOI eleyi to ni o kan aarẹ, igbakeji rẹ ati awọn gomina ipinlẹ mẹrindinlogoji ati igbakeji wọn.
Ajọ naa ni ibeere wọn ọhun labẹ ofin FOI ko tako ẹtọ wọn si aṣiri igbe aye wọn nitorina, gbede ọjọ meje ni wọn nilo lati ṣe ikede naa.
'Inu mi bàjẹ́ nígbà tí mo bí i, odidi oṣù mẹ́ta, mi ò lè gbàdúrà s'Ọ́lọ́run'
Electricity tariff hike: SERAP ní aráàlú kò lè máa jìyà, káwọn tó dipò òṣèlú mú máa gbádùn
Ajọ ajafeto-ọmọniyan kan ni Naijiria, SERAP ati awọn eeyan mejilelọọdunrun mii, ti pe aarẹ Buhari ati ile aṣofin lẹjọ lori afikun owo epo bentiroo ati owó ina ọba.
"SERAP ati awọn ti wọn jijọ pe ẹjọ yii ni awọn fẹ ki ile ẹjọ ""f'ọwọ rọ afikun owo epo ati ina ọba sẹyin."
"Alaye wọn ni pe awọn eeyan to dipo nla mu ninu ijọba ko le maa gbadun, ki wọn wà ni k'ara ilu maa ṣe ifarada."""
Ninu awọn ti wọn pe lẹjọ yii la ti ri igbakeji aarẹ, Yemi Osinbajo, aarẹ ile aṣofin agba Ahmad Lawan ,Olori ile aṣoju-ṣofin, Femi Gbajabiamila ati awọn mii.
Oríṣun àwòrán, NERC
SERAP tun n beere pe ki ile ẹjọ kéde pe aarẹ  Buhari lo agbara to ni labẹ ofin, lati le fi owo kun owo epo ati ina ni ilokulo ati lọnà to tako ẹjẹ to jẹ labẹ ofin yi kan naa.
Agbẹjọro SERAP Kolawole Oluwadare ati Opeyemi Owolabi to pe ẹjọ yii ni:
Ṣiṣe iṣẹ tọ ilu tumọ sí pe kí eeyan fi awokọṣe daada le'lẹ to fi mọ ki awọn to di ipo mu gan mu adinku ba owo gọbọi ti wọn n gba, ko le wa ni ibamu pẹlu t'awọn ara ilu to pe wọn lẹjọ
Blind Couples: Pẹ̀lú ìpèníjà ojú, tọkọtaya bímọ mẹ́ta, tí wọn sì tún ń ṣiṣẹ́ olùkọ́
Won tun ni ki ile ẹjọ f'asẹ sí pe owo t'awọn eekan ninu ijọba n gba, toun ti bi ilu ko ṣe rọgbọ, ko bofin mu.
Awọn alaṣẹ ti wọn darukọ ni aarẹ ile aṣofin agba,aare Buhari ati igbakeji rẹ tó fi mọ olori ile aṣojuṣofin.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Aadota odun ree ti e ti n paro atunse ise yin fawon omo Naijiria lero awon kan
Jìbìti ni àfikún owó iná mọ̀nàmọ́ná tí ìjọba kéde rẹ̀- Egbẹ oṣiṣẹ
Ẹgbẹ oṣiṣẹ lapaapọ atawọn ẹgbẹ ajafẹtọ ti koro oju si afikun owo ina mọnmọna ti ijọba apapọ kede rẹ.
Wọn ni jibiti ni ki ijọba fikun owo tawọn araalu n san fun ina mọnamọna nigba ti ina ọhun n ṣe ṣegeṣege ni gbogbo igba.
Ajọ to n ri si okowo ati ile iṣẹ nipinlẹ Eko ni tirẹ bu ẹnu ẹtẹ lu bi ijọba ko ṣe wa nnkan ṣe si bi ile iṣẹ mọnamọna ti n bu owo tawọn eeyan n san lai lo ẹrọ mita.
Ogbeni Usman Arabi, to jẹ ọga agba ẹka ọrọ ara ilu nile iṣẹ mọnamọna NERC kede ninu atẹjade kan pe irọ to jina si ootọ ni iropyin naa.
Loju opo ileeṣẹ iroyin Naijiria, ati itakun agbaye wọn ni Arabi ti ṣalaye lọjọ Aiku pe afikun owo ina mọnamọna to gbode kan kii ṣe tuntun.
O ni o ti wa lati atunṣẹ ti wọn gba aṣẹ lati ṣe ninu agbeyẹwo todun 2016 si 2018 ni.
O ni igbesẹ naa kan ti ọdun 2016, 2017 ati 2018.
Arabi kede pe fun idi eyi ko si alekun owow ori ina mọnamọna rara.
O ni iru igbesẹ bẹẹ ko le deede waye laisi pe ijọba pe ijoko ijiroro pẹlu gbogbo awọn ara ilu ti ọrọ kan ṣaaju fifi owo kun owo ina mọnamọna.
Yoruba language: Ọdún 2020 to wọlẹ́ dé yìí á tu gbogbo wa lára
Lọjọ Satide ọsẹ to kọja ni iroyin ni ajọ to n ṣamojuto ina ọba paṣẹ fawọn ile iṣẹ to pin ina mọnamọna mọkanla to wa ni orilẹ-ede Naijiria pe ki wọn fikun owo ina bẹrẹ lati oṣu kẹrin ọdun 2020.
Igbesẹ yii fihan pe o ti di igba mẹta ọtọọtọ bayii ti ijọba ti ṣe afikun owo ina laarin ọdun marun un sẹyin ni Naijiria.
Olaitan Olamide: mò lè má nílò ìwé ẹ̀rí mi tí mo bá parí ní LASU
Alaga igbimọ to n dundura pẹlu ijọba atawọn oṣiṣẹ, Abdulrafiu Adeniji ni o ṣeni laanu pe ijọba le sare kede afikun owo ina  nigba ti ko ti yawo kan dejo lori ẹkunwo owo oṣu oṣiṣẹ kaakiri Naijiria.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
ọpọ ero gba pe ko tọ si awọn EKEDC lati sọrọ lori ina bayii
O kere tan ijọba ipinlẹ mẹẹdogun ni ko tii fẹnu ko lori ẹkunwo owo oṣu tuntun fawọn oṣiṣẹ, bi o tilẹ jẹ pe ọjọ kọkanlelọgbọn, oṣu kejila, ọdun 2019 ni gbendeke ti ẹgbẹ oṣiṣẹ fawọn gomina.
Ọgbẹni Adeniji ṣalaye pe afikun owo ina ọba dabi jija awọn ọmọ Naijiria lole.
Bakan naa ni akowe ati alukoro ẹgbẹ oṣelu PDP, Kola Ologbondiyan sọ pe igbesẹ ijọba lati fowo kun owo ina yoo dakun iṣoro awọn araalu.
'Ohun tóo gbúdọ ṣe lọ́dún yìí bí o bá fẹ́ kí Ọlọ́run bá ọ rìn'
Ọgbẹni Ologbondiyan ni ijọba ko ni ifẹ araalu ninu pẹlu igbesẹ yii lẹyin owo ori gọbọi tawọn eeyan n san ati ọwọ gogo ọja.
Ṣé ẹ ti rí kí èèyàn ní àwọ̀ ara tó ń ṣí bíi ìpẹ́pẹ́ ẹja rí?
Iran:: Ẹ má fi taratara dúró níbì kan nítorí àwọn tó fẹ́ gbẹ̀san ikú Soleimani
Ẹ má fi taratara dúró níbì kan nítorí àwọn tó fẹ́ gbẹ̀san ikú Soleimani
Oju ni alakan fi n ṣọri lọrọ eto aabo gba bayii lorilẹ-ede Naijiria- Olatunbosun Abolarinwa.
Imọran yii waye lẹyin ti ọga ọlọpaa, Mohammed Adamu ti kesi gbogbo ileeṣẹ ọlọpaa kaakiri lati wa ni igbaradi ki wọn le koju ipenija to ba yọju.
Onimọ nipa ọrọ aabo, Olatubosun Abolarinwa to ba BBC Yoruba sọrọ lo fidi ọrọ yii mulẹ pe ifura loogun agba.
Eyi ko si ṣẹyin bi ile iṣẹ ọlọpaa ṣe sọ pe o ṣeeṣe ki awọn ọlọlufẹ ọgagun orilẹ-ede Iran, Qassem Soleimani ti ilẹ Amẹrika ṣekupa fẹ da rogbodiyan silẹ ni Naijiria.
Loju opo ikansiraẹni Twitter lọga ọlọpaa ti fi ọrọ naa lede.
Ninu ọrọ rẹ, Ọgbẹni Abolarinwa gba awọn ọmọ Naijiria ni imọran lori igbesẹ ti wọn le gbe ki wọn maa baa fara kaasa ti rogbodiyan ba bẹ ṣẹlẹ.
Olaitan Olamide: mò lè má nílò ìwé ẹ̀rí mi tí mo bá parí ní LASU
Ọgbẹni Abolarinwa to jẹ akọṣẹmọṣẹ lori eto aabo ni:
1. Toju tiyẹ laparo fi n riran, ki awọn eeyan ma fi taratara duro nibi kibi ti wọn ba wa.
Eyi ko ṣeyin pe awọn agbesunmọmi fẹran lati maa ṣekọlu si ibi tawọn eeyan ba pejọ pọ bi ṣọọṣi, mọṣalaaṣi, ile itaja, ibudokọ ati bẹẹbẹẹ lọ.
Oríṣun àwòrán, @abolarinwa
Ifura ṣe pataki, tete sa kuro nibi ti ẹru ba ti fẹ maa ba ẹ.
2. Awọn eeyan ni lati ṣora fun irin alẹ nitori awọn oniwa ijamba ti wọn maa n fẹran lati fi okunkun bora.
Oríṣun àwòrán, OTHERS
Ọga ọlọpaa lọrilẹede Naijiria, Mohammed Adamu ti kesi ẹnikẹni to ba fẹ fa ijọngbọn lati ti ọwọ ọmọ wọn bọ asọ.
Ati pe jakunmọ kii rinde ọsan, ẹni a bii re kii rinrin oru ni awọn agba maa n wi.
Alapinni Oosa ṣàdúrà fún gogbo ọmọ kúoótù, oò jíire bí?
3. Ti ẹnikẹni ba ri alejo ti irin rẹ jọ ti afurasi, ki iru ẹni bẹẹ tete kansi ile iṣẹ ọlọpaa lapapọ lori aago 112, bakan naa awọn olugbe ilu Eko le pe 727.
4. Awọn obi ni lati maa ṣamojuto awọn ọmọ wọn nile iwe ti wọn fi wọn si.
Yoruba language: Ọdún 2020 to wọlẹ́ dé yìí á tu gbogbo wa lára
Awọn obi gbọdọ pe akiyesi awọn olukọ si ajeji kankan ti ihuwasi rẹ ba mu ifura dani ni ayika ile iwe awọn ọmọ wọn.
Opin ọsẹ to kọja yii ni orilẹ-ede Amerika fi ibugbamu oloro pa Ọgbẹni Soleimani lori ẹsun pe o ti pẹ ti ọgagun naa ti n wa nidi iṣekupani awọn ọmọ ilẹ Amerika.
'Ohun tóo gbúdọ ṣe lọ́dún yìí bí o bá fẹ́ kí Ọlọ́run bá ọ rìn'
Alcohol: Ó ṣeésẹ kí àwọn ọkùnrin tó maa n mu àmujù ọtí ó maa lo ìwà ipá pẹ̀lú ìyàwó wọn
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ó ṣeésẹ kí àwọn ọkùnrin tó maa n mu àmujù ọtí ó maa lo ìwà ipá pẹ̀lú ìyàwó wọn
Iwadii kan ti fihan wi pe awọn ọkunrin to maa n mu ọti amuju tabi ọti lile tabi oogun oloro l'oṣeeṣe ko maa lo iwa ipa pẹlu awọn ololufẹ wọn.
Abajade iwadii naa ti wọn fi sita ninu iwe ori ayelujara kan, PLOS-Medicine, tan ina se wadii ọpọlọpọ ẹsun nile iṣẹ ọlọpaa.
Bakan naa ni wọn ṣe ayẹwo ileewosan l'orilẹ-ede Sweden fun ọdun mẹrindinlogun ki wọn to gbe abajade iwadii naa sita.
Awọn oluwadii naa tun ri i pe o ṣeesẹ ki awọn ọkunrin to ni aisan ọpọlọ ati iwa kebe-kebe le maa lu ololufẹ wọn
Sugbọn ti wọn ko to ti awọn to n mu ọti amupara ati oogun oloro.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Amupara ọti a maa fa wahala ti ko dara fun eniyan
Ọjọgbọn Fasiti Oxford, Seena Fazel, to lewaju iwadii naa sọ pe aabọ iwadii awọn fihan pe wọn le din iwa ipa ninu igbeyawo ku, ti wọn ba ri itọju to peye kuro ninu amuju ọti ati oogun oloro.
Yoruba language: Ọdún 2020 to wọlẹ́ dé yìí á tu gbogbo wa lára
Iwadii naa ti agbarijọpọ awọn akọṣẹmọṣẹ lati orilẹ-ede America, Sweden, ati ileewe Kings College, London, tọ pinpin ẹgbẹrun lọna ogoje ọkunrin to maa n mu ọti amupara, ati oogun oloro laarin oṣu Kinni, ọdun 1998 si oṣu Kejila, ọdun 2013.
Olaitan Olamide: mò lè má nílò ìwé ẹ̀rí mi tí mo bá parí ní LASU
Awọn akọṣẹmọṣẹ ọhun tun ṣayẹwo iye eniyan ti awọn ọlọpaa ti mu nitori pe wọn kọlu, dẹruba, tabi fi ipa ba iyawo, ọrẹbinrin tabi ololufẹ wọn obinrin tẹlẹ lo pọ.
Gẹgẹ bi ohun ti alamojuto awọn to fara gba ẹgba iwa ipani England ati Wales, Same Vera Baird, ṣe sọ pe gbogbo wọn jẹ ọmọ iya.
Alapinni Oosa ṣàdúrà fún gogbo ọmọ kúoótù, oò jíire bí?
Ati pe, bo tilẹ jẹ pe ibaṣepọ wa laarin ọti lile, oogun oloro ati iwa ipa laarin ololufẹ, o ṣe pataki lati wo abajade iwadii yii daadaa.
'Ohun tóo gbúdọ ṣe lọ́dún yìí bí o bá fẹ́ kí Ọlọ́run bá ọ rìn'
"O sọ pe ""ọpọlọpọ to maa n lo iwa ipa pẹlu ololufẹ wọn ti wọn ba mu ọti yo, yoo tun ṣe bẹ ẹ ti ọti ba da l'oju wọn."
Fadele: Dán an wò, lóbí ìyá ọ̀kẹ́rẹ́ ni a fi ọ̀rọ̀ ọ̀kadà náà ṣe
Ẹ̀ṣẹ̀ ni fún ọ láti dá fi ọmọ rẹ̀ sílẹ̀ nílé láì ní àmójútó - Child Protection Network
Oríṣun àwòrán, other
Lopin ọsẹ to kọja ni iroyin iku awọn ọmọde mẹta to jona mọle nilu Ibadan, olu ilu ipinlẹ Ọyọ gba igboro kan.
Awọn ọmọ mẹtẹẹta ọhun, la gbọ wi pe wọn jona mọle laarin oru lasiko ti iya ati baba wọn ko si nile, to si jẹ pe awọn nikan lo da sun sinu ile.
Iroyin ti a gbọ ni pe awọn ọmọ naa ko raaye sa jade lasiko ti ina naa bẹrẹ nitori pe awọn obi wọn ti ti ilẹkun mọ wọn sinu ile lati ita.
Awọn ọmọ ọhun ti ọjọ ori wọn jẹ ọdun mẹrinla, mẹjọ, ati mẹta kagbako iṣẹlẹ buruku naa ni ile wọn to wa ni adugbo Eyin Grammar, nilu Ibadan.
Akọwe agba nigba kan fun ajọ awọn obinrin musulumi to wa fun itọju awọn ọmọ ti ko l'obi lorilẹede Naijiria, FOMWAN, Alhaja Surura Ayero, sọ fun BBC Yoruba pe ko tọ lati da fi ọmọ ti ko tii pe ọdun mejidinlogun silẹ lai si alamojuto kankan.
Nitori pe ni ti ọjọ ori yii, wọn o ti gbaradi lati mojuto ara wọn.
"Kinni ọmọde le ṣe lati ran ara a rẹ lọwọ lasiko ti iru iṣẹlẹ yii ba waye? To ba tilẹ wa jẹ pe obi ko ni si nile, o yẹ ko wa ẹnikan bi mọlẹbi tabi alabagbele to le fi awọn ọmọ naa ti.
Nigba t'oun naa n sọrọ, igbakeji alaga ajọ to n ja fun ẹtọ awọn ọmọ nipinlẹ Oyo, Alhaja Ogungbenro Hairat Omowumi, sọ pe ko lẹtọ fun obi lati fi ọmọ silẹ lai ni amojuto. O ṣalaye pe nkan to ṣe pataki obi ti ko ba le raaye mojuto ọmọ rẹ lati wa ẹnikan tabi ile itọju ọmọde to le ko wọn lọ.
Alhaja Ogungbenro tẹsiwaju ninu ọrọ rẹ pe ijiya wa l'abẹ ofin orilẹede Naijiria fun obi to ba fi ọmọ rẹ silẹ lai mojuto o, ti nkan buruku ba ṣẹlẹ si ọmọ naa.
Obi to ba fi ọmọ silẹ bẹẹ, ijiya wa fun un, nitori pe awọn ọmọde ni ẹtọ si amojuto obi wọn."""
Niru iṣẹlẹ yii, ti ijọba ba ri i pe awọn obi awọn ọmọ naa jẹbi lẹyin iwadii, ijiya nla ni fun wọn.
Balogun market fire: Olubadamọran gomina sọrọ lori ina náà
Ri i daju wi pe o pa gbogbo nkan eelo to n lo ina ninu ile ki o to jade, ki o si pa orisun ti ina ti wọ ara wọn ki ina ma baa sọ lara wọn.
Lilo orisun ina kan fun ọpọlọpọ ohun elo to n lo ina le fa ijamba.
Ma ṣe ko eroja bẹtiro pamọ sinu ile lasiko ọyẹ, ki o si ri i daju pe o ko rọ epo si ẹrọ amuna wa rẹ nigba to n ṣiṣẹ lọwọ.
Amojúẹ̀rọ tó ń nu bàtà fi wá oúnjẹ òòjọ́
Chekole Menberu to ti di ẹni ọdun mẹtadinlọgbọn bayii ni ọpọlọpọ ireti giga nigba ti kawe ja pẹlu oye fasiti onipele kinni ninu imọ chemical Engineering lọdun meji sẹyin ni orilẹede Ethiopia.
O jẹ asiko idunnu fun un pẹlu bi o ba boju wo iye ọdun to ti fi ṣe laalaa ati gbogbo iṣoro to ti la kọja lati de ipo yii.
Fun ọpọlọpọ ọdun lo ti fi nu bata fun awọn eeyan lẹgbẹ ọna lati fi tọju ara rẹ, lati kekere ni Ọgbẹni Chekole ti fi wa iṣẹ kiri loju titi.
Lati igba to ti jẹ ọmọde ni baba rẹ ti ku to si ti n gbe pẹlu awọn obi baba rẹ ni agbegbe Fogera ni ẹkun Amhara. Iya rẹ si ti fẹ ọkọ mii.
O wu Chekole gan ko kawe ṣugbọn awọn baba baba rẹ ko lowo ati tọ ọ.
Lo ba kọri si ile ẹgbọn baba rẹ lati maa ṣe aṣọ́ ẹran ọ̀sìn. Ṣugbọn o si tun n ni ireti pe awọn obi baba oun yoo le ran oun lọwọ.
Gbogbo igba ni mo maa n fi ikanra sọ pe awọn obi baba mi ko le ran mi nilewe, o sọ fun BBC.
'Ǹkan tó jẹ́ kí iṣẹ́ ọ̀nà tèmi yàtọ̀ lágbàáyé ni ǹkan tí mò ń lò'
Nigba to ya, baba baba rẹ gbọ si ẹbẹ rẹ o si mu u lọ forukọ silẹ ni ileewe alakọbẹrẹ kan ni ilu to n jẹ Woreta.
Ṣugbọn iranwọ baba baba rẹ wa sopin nigba to de ipele keji.
Mo ni lati jade sita lati wa ọna ati ran ara mi lọwọ
Pẹlu iranlọwọ ọrẹ rẹ kan to maa n kun bata, Whekole bẹrẹ si ni nu bata fawọn eeyan.
"Chekole ni ""Mo ro wi pe ninu baba lee ran mi lọwọ. Odidi idaji ọjọ kanni mo fi n ṣiṣẹ lojọ ti maa si fi idaji to ku ka iwe""."
Aye le mọ mi. Ṣugbọn itan awọn eeyan to n ronu bii temi ṣugbọn ti wọn di dokita ati imọ ẹrọ gba mi niyanju.
'Ohun gbogbo ka mi lara gan'
Gbogbo saa ẹkọ rẹ nileewe lo fun un ni wahala tori o ni lati ra aṣọ ileewe eyi ti ko si lowo rẹ.
Ẹkọ na mi lowo gaan, eyi lo sọ.
Ọpọlọpọ igba ipọnju ni mo la kọja ṣugbọn mi o ni gbagbe bi o ṣe ka mi lara gan nigba ti mo fi de ipele ẹkọ kẹjọ ati ikẹwa atii lọdun ti mo wọ ile iwe fasiti.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Pẹlu gbogbo nkan to foju ri, o ṣaa tiraka wọ ile iwe fasiti Bahir Dar ni olu ilu Amhara nibi to ti kawe gboye imọ Chemical Engineering.
Idi ti mo fi lọ fun imọ ẹkọ yii ni wi pe awuyewuye wa pe orilẹede wa nilo ọpọlọpọ amojuẹrọ. Mo si nireti pe mo maa ri iṣẹ ni kete ti mo ba kawe ja.
O ri iranwọ diẹ nigba ti lẹta kan wa si ileewe rẹ lati ilu ibi rẹ pe ko ni oluranlọwọ kankan. Fasiti rẹ ba bẹrẹ si ni san 200 birr ($10) loṣu.
Mo tun maa n ri iranwọ latd awọn alabagbe mi atawọn ọrẹ mi ṣugbọn nigba ti ọjọ ikọkgboye mi n sunmọ etile, ẹru bẹrẹ si ni ba mi boya mo maa ri iṣẹ.
Òbí àwọn ọmọ tó j'óná mọ́lé n'Ibadan leè dáràn ìjọba o!-  Àjọ ajàfẹ́tọ̀ọ́ ọmọdé
Olaitan Olamide: mò lè má nílò ìwé ẹ̀rí mi tí mo bá parí ní LASU
'Mi o lori iṣẹ'
Lọdun 2017 ni Ọgbẹni Chekole kẹkọọ gboye to si fẹ gun le wiwa iṣẹ loju ẹsẹ.
Ṣugbọn ori ko gbe e.
"Oṣu mẹta ni mo fi n wa iṣẹ ni Addis Ababa. Mo rin kaakiri ilu fun iṣẹ ṣugbn mi o lori rẹ.
Koda o rinrinajo kaakiri ati kọja ilu rẹ, mo tun wa iṣẹ lai lo iwe ẹri fasiti rẹ ṣugbọn ọpọlọpọ igba ni wọn n kọ iwe iwaṣẹ mi."
Lẹyin ọpọlọpọ oṣu wiwa iṣẹ ti iwẹ ẹri rẹ ko si so eso rere, o pada si ilu Bahir Dar - lati bẹrẹ iṣẹ ti ko lero pe o le pada si.
Nigba ti ko sohun ti mo le ṣe mọ, mo pada si ẹsẹ aarọ ki n maa nu bata.
Taa ba wa beere boya o kabamọ pe o tilẹ ka iwe, o ni inu ko ba ma bi oun to bayii bi ko ba ka iwe.
"Ẹkọ yii na mi lowo gan, mi o si jere kankan nibẹ, mi o ba ma ti ṣe laalaa to bẹẹ lori rẹ.
Bi awọn oluko mi to mọ mi ni fasiti ba ri mi, ara wọn a ka ti wọn a si ka oju kuro. Ṣugbọn awọn mii a gba mi niyanju wọn a si fun mi lowo."
Awọn ọrẹ mi nileewe gan maa n mọọmọ wa nu bata bi bata wọn gan ko tilẹ dọti tori ki wn le fun mi lowo.
"Ẹwẹ, o ni ireti, ninu ohun gbogbo pe yoo ri iṣẹ to dara. Mo ṣi maa n lọ wo awọn patako ti wọn ti n polowo iṣẹ,"" Chekole sọ."
Pásítọ̀ Bakare kéde orúkọ àwọn ọ̀tá tó ń da Nàìjíríà láàmú
Oríṣun àwòrán, Tunde Bakare/twitter
Pasitọ ijọ Latter Rain Assembly to tun ti figba kan ri du ipo igbakeji aarẹ lorilẹ-ede Naijiria, Tunde Bakare ti pariwo sita pe ọta mọkanla ni orilẹ-ede Naijiria ni.
Ninu ọrọ kan to sọ fawọn ọmọ ijọ rẹ lo ti ṣalaye ọrọ yii.
Pasitọ Bakare ni pẹlu bi ọrọ ṣe ri yii, asiko to fun awọn ọmọ orilẹ-ede Naijiria lati dẹkun kikan sara sawọn ọta orilẹ-ede naa bayii.
O ni ijọba pẹlu gbọdọ ṣetan lati doju ija kọ awọn ọta orilẹ-ede Naijiria gangan ki wọn lee gba awọn ọmọ Naijiria lọwọ wọbia awọn amunisin to n jẹ gaba lori wọn.
Olaitan Olamide: mò lè má nílò ìwé ẹ̀rí mi tí mo bá parí ní LASU
1.Gbogbo awọn ọta orilẹ-ede Naijiria wa lẹka ijọba gbogbo, ni opopona, ile ati ọja gbogbo atawọn to n ta orilẹ-ede wọn lati ni ọrọ
2.Awọn eeyan to gba lati maa woran nigba ti irawọ orilẹ-ede yii fẹ maa wọmi loju wọn.
3.Awọn ayederu iranṣẹ Ọlọrun to n fi iṣẹ Ọlọrun boju ṣiṣẹ ibi lati yan araalu jẹ.
Fadele: Dán an wò, lóbí ìyá ọ̀kẹ́rẹ́ ni a fi ọ̀rọ̀ ọ̀kadà náà ṣe
4.Gbogbo awọn n kopa ninu jijẹ aṣuwọn orilẹ-ede Naijiria lajẹrun pẹlu awọn ti wọn n ṣe baba rere, baba kẹ fawọn to n ko owo ilu jẹ nitori pe wọn jẹ ọmọ ẹya kan naa tabi ẹsin kan naa.
5.Gbogbo awọn to n gbe ẹru owo ori to wuwo le awọn ọmọ orilẹ-ede yii lori.
6.Awọn ijọba ipinlẹ ti wọn n na owo to yẹ fun eto abo fun ara wọn.
'Inu mi bàjẹ́ nígbà tí mo bí i, odidi oṣù mẹ́ta, mi ò lè gbàdúrà s'Ọ́lọ́run'
7.Gbogbo awọn to n lo irinṣẹ ilu lati fi tipatipa gba awọn to ba tako wọn wọlẹ.
8.Gbogbo awọn to yi irinṣẹ ilu ati ipinlẹ wọn di ogun wọn
9.Gbogbo awọn oloṣelu to n ṣe magomago lati fi ibo gbe ẹni tiwọn sori ipo ki wọn lee ko ọrọ ilu ati ipinlẹ si apo ara wọn.
Dambe fight: ìdíje ìjà láàrin àwọn akóni tó n ja ẹ̀ṣẹ̀
10.Gbogbo awọn to n ta ibo wọn ti wọn si tun n da wahala ati rogbodiyan oṣelu silẹ
11.Awọn adajọ to n fi ipo iṣedajọ yan alailagbara jẹ tabi ti wọn sọ iṣedajọ di owo ree idajọ ree.
12.Awọn aṣofin ti wọn n ja orilẹ-ede naijiria lole labẹ iboju iṣẹ idagbasoke ilu ti wọn si n ṣe ofin to n dena ominira araalu ti wọn si  n ti ipasẹ bẹẹ da omi alaafia ru.
Pẹsẹ́ ní Ọlọ́pàá Nàìjíríà wà látàrí ìṣekúpani Ọ̀gágun Iran- Ọ̀gá Ọlọ́pàá
Ẹ wo àwòrán bí ọjà Akẹsan ṣe jóná ràùràù ní ìlú Oyo!
Bauchi State: Okú 596 ló ṣì ń gba owó oṣù
Kí ni Buhari sọ nípa ààrẹ tó kàn lọ́dún 2023?
Pasitọ Bakare wa koro oju si ofin ti awọn aṣofin fẹ ṣe lati de ọrọ lori ayelujara.
Amọṣa ajọ ajafẹtọ kan to n gbogun ti ijẹkujẹ, SERAP ti ni awọn mẹrin kan ni ọta orilẹ-ede Naijiria.
Oyo Fire: Dukia ṣófo, ọmọ ọdún mẹ́rìnlá faragbọta níbí iná tó jó ọjà Akesan
1.Awọn aṣofin to n gọ si abẹ iṣẹ akanṣe idagbasoke ilu lati ja orilẹ-ede Naijiria lole owo gọbọi
2.Awọn adajọ to n da oju ẹjọ ru
Baṣọ̀run Gáà: Ó yan ọba mẹ́rin, tó sì pa ọba mẹ́rẹ̀ẹ̀rin àmọ́ ọba karùn-ún ló pa á
Irọ́ ni pé a fẹ́ fowó kún owó iná mọ̀nàmọ̀nà- NERC
Al Shabab ṣe ìkọlù sí ibùdó ogun America ní Kenya, ẹ̀mí mẹ́ta lọ síi
Ó ṣeésẹ kí ọkùnrin tó n mu àmujù ọtí ó maa lo ìwà ipá pẹ̀lú ìyàwó rẹ̀
3.Awọn gomina to n ji owo eto abo ti wọn si n jẹ gaba lori araalu
4.Awọn to n sọ ipinlẹ wọn di ogun ẹbi wọn
Alapinni Oosa ṣàdúrà fún gogbo ọmọ kúoótù, oò jíire bí?
C. Ronaldo: C. Ronaldo fi góòlù mẹ́ta bẹ̀rẹ̀ ọdún 2020 pẹ̀lú Cagliari
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ogbontagi agbabọọlu ọmọ orilẹede Portugal, Christiano Ronaldo ti fi goolu mẹta ṣẹwọ ninu ọdun tuntun.
Ronaldo tun rọjo goolu gẹgẹ bi iṣe rẹ pẹlu goolu mẹta nibi ifẹsẹwọnsẹ ẹgbẹ agbabọọlu Juventus pẹlu Cagliari ni liigi Serie A.
Igba akọkọ niyi ti Ronaldo yoo gba goolu mẹta wọle ni ifẹsẹwọnsẹ kan naa lati igba to ti dara pọ mọ Juventus lọdun 2018.
Oun ni agbabọọlu akọkọ ti yoo gba goolu mẹta wọle ninu ifẹsẹwọnsẹ kan ṣoṣo ni liigi mẹta ọtọọtọ lagbaye, iyẹn liigi ilẹ Gẹẹsi (Premier league), liigi orilẹede Spain (la liga) ati liigi ilẹ Aguda, orilẹede Italy (Serie A).
oun yii kan naa si tun ni agbabọọlu to gba goolu mẹta wọle ninu ifẹsẹwọnsẹ kan naa julọ lagbaye. ifẹsẹwọnsẹ mẹrindinlọgọta ọtọtọ ni Ronaldo ti gba goolu mẹta wọle, eleyii ti ko si agbabọọlu miran to tii dan iru bẹbẹ bẹ wo.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Kii ṣe tuntun mọ pe ifigagbaga wa laarin Ronaldo ati Messi toun pẹlu jẹ odu agbabọọlu lagbaye.
Ni kete ti ifẹsẹwọnsẹ naa pari si ni awọn ololufẹ awọn mejeeji ti n waako lori ikanni ayelujara gbogbo.
Bi awọn ti Ronaldo ko ṣe fẹ wọn ọn kun, lawọn ti Messi naa ko fẹ gba a laabọ.
Kano: À ti fa àwọn oníbalòpọ̀ akọsákọ tí a mú le òbi wọ́n lọ́wọ́- Ọlọpàá Hisbah
Oríṣun àwòrán, Other
Kano: Àti fa àwọn oníbalòpọ̀ akọsákọ ti mú le òbi wọ́n lọ́wọ́- Ọlọpàá Hisbah
Àwọn ọlọpàá Hisbah ni ìpínlẹ Kano ni àwọn ti mú àwọn kò sakọ kò sabo àti àwọn ọkunrin to maa n wọ àṣọ bi obinrin mẹẹdogun ni agbegbe Sabuwar Gandu ni ìpínlẹ̀ Kano.
Igbakeji ọgá Hisbah ni ipinlẹ Kano Shehu Tasi'u ní kété ti wọ́n ta awọn lólobó pé ayẹyẹ kan yóò wáye ti àwọn oníbalopọ̀ akọsákọ tabi Amúra bii obinrin ni Sabujwar Gandu ni wọ́n ti gba ibẹ̀ lọ ti wọ́n si mú àwọn to péjú si ibi ayẹyẹ náà nítori pe ìjọba n gbìyànjú láti kò irú iwà bẹ́ẹ̀ kúrò nilẹ̀.
Ilé iṣẹ́ ọlọpáà Hisbah ṣàlàyé pé àwọn bá àwọn ènìyàn wọ́nyi sọ̀rọ̀ pẹ̀lú ìgbàníyànju lẹ́yin náà ni wọ́n ko wọ́n lọ si ilé àwọn òbi wọ́n.
Alapinni Oosa ṣàdúrà fún gogbo ọmọ kúoótù, oò jíire bí?
Gẹ́gẹ́ bí ó ṣe sọ fún akọroyìn BBC pé kété ti wọ́n dé ilé àwọn òbi wọ́n, ó jẹ́ ìyàlẹ́nu fún àwọn òbi wọ́n nitori pé wọ́n kò mọ pé ǹkan ti àwọn ọmọ wọ́n n dánwò niyẹn.
Fadele: Dán an wò, lóbí ìyá ọ̀kẹ́rẹ́ ni a fi ọ̀rọ̀ ọ̀kadà náà ṣe
Ìgbákeji ọ̀gá àgbà náà wá sàlàyé pé àwọn ti fa wọ́n le àwọn òbí wọn lọ́wọ́, ti awọn sì fi lée pé wọ́n gbọdọ̀ máa pèsè wọ́n nígbàkúùgbà ti àwọn bá nílo láti ri wọ́n.
'Inu mi bàjẹ́ nígbà tí mo bí i, odidi oṣù mẹ́ta, mi ò lè gbàdúrà s'Ọ́lọ́run'
Tẹ ò bá gbàgbé, wọ́n mu àwọn ènìyàn náà ni ọjọbọ níbi ayẹyẹ ti àwọn akẹkọọjáde  Fasiti Bayero ní Kano pé láti ṣe ayẹyẹ àṣeyọri ètò ẹkọ́ wọ́n.
Dambe fight: ìdíje ìjà láàrin àwọn akóni tó n ja ẹ̀ṣẹ̀
Iran war: Ẹgbẹ́ Shiites wọ́de l'Abuja, wọ́n jó Àsìá Amẹ́ríkà
Soleimani Killing: Àwọn Shiites wọ́dé l'Abuja, jó Asia Amẹrika
Àwọ́n ọmọ ẹgbẹ́ Islamic Movement of Naigeria (IMN) ti gbogbo ènìyàn mọ si Shi'ites lọ́jọ́ Ajé ti ya si ìgboro lágbègbè ilé ìtajà Bannex ni Wuse nílú Abuja.
Won n ṣe iwọde nítori Olóri ọmọ ogun Iran Quasm Soleimani ti àwọn ọmọ ogun ilẹ̀ Amẹrika pa lọ́jọ́ Ẹtì to kọja.
Bákan náà ni wọ́n pè fún ìtúsilẹ̀ adari wọ́n Sheikh Ibraheem El-Zakzeky àti ìyàwó rẹ̀ Zeenat ti wọ́n wà ni àhámọ lọ́wọ́lọ́wọ́.
"Awọ́n olùfẹhonuhan náà bọ́ si ìgbòro Abuja ti wọ́n sì n pariwo àwọn òrin ọ̀tẹ bí "" Iku ni fún Amerika"""
Bakan náà ni wọ́n dána sun àsìá orílẹ́-èdè Amerika tí wọ́n sì gbé àwọn àkọle to bẹnu àtẹ lu pípa ti Amerika pa olóri ọmọ ogun Iran sọ́wọ́.
Soleimani Killing: Àwọn Shiites wọ́dé l'Abuja, jó Asia Amẹrika
Olaitan Olamide: mò lè má nílò ìwé ẹ̀rí mi tí mo bá parí ní LASU
CAN rọ ìjọba àpapọ láti tú àwọn òǹdè Boko Haram silẹ̀
Oríṣun àwòrán, Ayokunle
CAN rọ ìjọba àpapọ lati tú àwọn òunde Boko Haram silẹ̀
Ẹgbẹ́ tó n ri sí ọ̀rọ̀ tó kan àwọn ọmọ lẹ́yìn Krísti lórílẹ̀-èdè Naijiria (CAN) ti rọ ìjọba àpapọ láti lo gbogbo ǹkan to ba wà ni ìkáwọ wọ́n láti tu àwọn Kristẹni to wà ni àhámọ Boko Haram àti ISWAP silẹ̀.
Wọn ni o ṣe pataki nítori pé àwọn ti wọ́n pa laipẹ yìí fi han pé, àwọn onígbàgbọ́ lorilẹ̀-èdè Naijiria n kojú inúnibini.
Nínú àtẹjáde kan láti ọ̀dọ̀ ààrẹ ẹgbẹ́ náà, Ọmọwe Samson Ayokunle, èyí ti olùrànlọ́wọ́ pàtàkì lori ibanisọrọ, Adebayo Oladeji fọwọ si nílu Abuja, LO TI SỌRỌ NAA.
O ṣàlàyé pé alága ẹgbẹ́ CAN ti Michika ni ìpínlẹ̀ Adamawa, Lawan Andimi ti wà ní àhámọ Boko Haram láti ọ̀ṣẹ̀ to kọja nígba ti wọ́n yabo ilú náà to jẹ́ pé Kristẹni lo pọ̀ níbẹ̀.
"O fí kún un pé "" bó tilẹ̀ jẹ́ pé àwọn ọmọ ogun jà fitafita, ki wọ́n to fi tipa gbé Andimi lọ pẹ̀lú ọkọ Hilujx wọ́n, nínú fọ́nran ti wọ́n fi si ta."
Olaitan Olamide: mò lè má nílò ìwé ẹ̀rí mi tí mo bá parí ní LASU
"O ní oníwàásù náà ti n bẹ ìjọba àpapọ, gómìnà Adamawa àti àwọn adari CAN láti ran òun lọ́wọ́."""
Yoruba language: Ọdún 2020 to wọlẹ́ dé yìí á tu gbogbo wa lára
Ààrẹ CAN tún fi ẹdun ọkàn rẹ̀ hàn pé, àfi bi ẹni pe èyí kò tó ni àwọn alọkolohun kígbe tun yabo ilú ti àwọn Kritẹni to n gbé ni Ijọba ibilẹ̀ Chikun ni ìpínlẹ̀ Kaduna ní déEdé ààgo mẹ́fà ààbọ lọ́jọ́ Ajé.
Nibẹ ni wọn ti kó èníyàn mọkànlélógún to fi mọ olùṣọagùntàn, Joshua Samaila ti ko si si ẹni to mọ ǹkankan nípa wọ́n titi di àsìkò yìí.
Bakan náà ni wọ́n ke si àjọ ìsọkan àgbáyé (UN) ilẹ̀ Amerika, àti ilẹ̀ Gẹẹsi to fi mọ àwọn orilẹ̀-ede míràn láti dide ìrànwọ, pẹ̀lú ìfọwọ́sowọ́pọ̀ pẹ̀lú ìjọba Naijiria láti dóòlà ẹmi àwọn ènìyàn wọ̀nyi ko to pẹ́ jù.
Fadele: Dán an wò, lóbí ìyá ọ̀kẹ́rẹ́ ni a fi ọ̀rọ̀ ọ̀kadà náà ṣe
CAN àti gbogbo àwọn ọmọ Naijiria wá fi da àwọn to wà nínú ìgbèkùn lásìkò yìí lójú pé àwọn ǹ gbà àdúra fun wọ́n àti pe Ọlọrun yóò tú wọ́n sílẹ̀ nínú ìgbèkùn ti wọ́n wà gẹ́gẹ́ bi o ṣe gbà àwọn ọmọ Isrẹli silẹ̀ lọ́jọ́si.
'Inu mi bàjẹ́ nígbà tí mo bí i, odidi oṣù mẹ́ta, mi ò lè gbàdúrà s'Ọ́lọ́run'
2023 presidency: Ààrẹ Buhari ní òun kò leè dá sí ètò yíyan ààrẹ tuntun lọ́dún 2023
Oríṣun àwòrán, @NGRPresident
Ààrẹ Buhari ní òun kò leè dá sí ètò yíyan ààrẹ tuntun lọ́dún 2023
Ileeṣẹ aarẹ lorilẹ-ede Naijiria ti sọ wi pe Aarẹ Mohammadu Buhari mọ ohun ti yoo ṣe lori ẹni ti yoo joko sori aga aarẹ lẹyin to ba fi ipo silẹ ṣugbọn ko ni fi tipatipa yan eeyan kan lori Naijiria.
Agbẹnusọ fun aarẹ, Ọgbẹni Fẹmi Adeṣina ṣalaye pe ohun ti aarẹ gbagbọ ni pe ẹni to ba wu araalu ni ko wọle kii ṣe lati yan eeyan le awọn ọmọ Naijiria lọwọ.
O ni aarẹ Buhari lee ni ero to ga lori irufẹ eeyan to fẹ ko rọpo oun lati tẹsiwaju pẹlu awọn iṣẹ rẹ gbogbo ṣugbọn oun kọ ni yoo yan le araalu lọwọ.
Ọrọ yii jẹ bii esi si ọrọ kan ti pasitọ agba ni ijọ Latter Rain Assembly, Tunde Bakare sọ ninu ọrọ akọsọ rẹ fun ọdun 2020 lọjọ Ẹti Wo àwọn ọ̀tá tó ń da orílẹ̀èdè Nàìjíríà láàmú  pe Aarẹ Buhari ko gbọdọ kawọ gbera tabi kọ iha kokan mi si igbesẹ ati yan aarẹ ti yoo rọpo rẹ bi o ba kuro lori ipo.
Oyo Fire: Dukia ṣófo, ọmọ ọdún mẹ́rìnlá faragbọta níbí iná tó jó ọjà Akesan
Fẹmi Adeṣina ni aarẹ ko nilo ẹnikẹni lati ran an leti pe loṣu karun un, ọdun 2023 ni yoo fi ipo silẹ.
Lootọ gẹgẹ bi Pasitọ Bakare ṣe sọ aarẹ fẹ mọ irufẹ ẹni ti yoo gba ipo lọwọ oun ṣugbọn ko ni tọwọ bọ omi igbesẹ ati yan onitọun.
Dambe fight: ìdíje ìjà láàrin àwọn akóni tó n ja ẹ̀ṣẹ̀
Bakan naa lo ṣalaye pe Aarẹ Buhari yoo rii daju pe ẹni to ba gun ori itẹ aarẹ lẹyin oun tẹle ilana ti oun fi silẹ, ati pe o mọ le ipinlẹ to ti gbe kalẹ.
Fadele: Dán an wò, lóbí ìyá ọ̀kẹ́rẹ́ ni a fi ọ̀rọ̀ ọ̀kadà náà ṣe
Oluwo: Oluwo fárígá pẹ̀lú ìjọba àpapọ̀ lórí àgbékalẹ̀ iléèwé ẹ̀kọ́ṣẹ́ olùkọ́ni
Oríṣun àwòrán, Emperor Abdulrasheed Adewale Akanbi Telu 1
Oluwo fárígá pẹ̀lú ìjọba àpapọ̀ lórí àgbékalẹ̀ iléèwé ẹ̀kọ́ṣẹ́ olùkọ́ni
Kabiyesi Oluwo ti ilu Iwo, Ọba Abdulrasheed Akanbi ti kebosi sita pe bi ijọba apapọ ko ba gbe ileẹkọ olukọni onipo kinni to fẹ da silẹ ni ipinlẹ Ọṣun si ilu Iwo, nnkan yoo yan.
O ni pe iwa ọdalẹ leyi yoo jẹ fun atilẹyin ribiribi ti awọn eeyan ilu Iwo ṣe fun ijọba ẹgbẹ Oṣelu APC.
Ọba Akanbi ni ti ileewe giga naa ba ja mọ ilu miran lọwọ nipinlẹ Ọṣun, a jẹ wi pe oun yoo darapọ mọ awọn alatako ijọba apapọ lorilẹ-ede Naijiria ni.
Oluwo ṣalaye pe lara awọn Ọbalaye to duro ti Aarẹ Buhari ni gbangba lasiko ipenija rẹ, ọkan gboogi loun jẹ ninu eyi ti oun ti ṣeto awọn ipade adura itagbangba lorukọ aarẹ ki ilera rẹ lee tubọ gbe ẹnu soke.
'Inu mi bàjẹ́ nígbà tí mo bí i, odidi oṣù mẹ́ta, mi ò lè gbàdúrà s'Ọ́lọ́run'
Oluwo tun sọ ọ laifọtape wi pe ni ojumọ to mọ loni yii, oun loun lee dari omi atilẹyin oṣelu awọn eeyan ilu Iwo si ibi to ba wu oun.
Dambe fight: ìdíje ìjà láàrin àwọn akóni tó n ja ẹ̀ṣẹ̀
O wa rọ aṣaaju ẹgbẹ oṣelu APC, Bọla Tinubu; Igbakeji Aarẹ Yẹmi Oṣinbajo, Oloye Bisi Akande, Rauf Arẹgbẹṣọla pẹlu Gomina Gboyega Oyetọla lati rii daju pe wọn gbe ileewe naa kalẹ si ilu Iwo.
Fadele: Dán an wò, lóbí ìyá ọ̀kẹ́rẹ́ ni a fi ọ̀rọ̀ ọ̀kadà náà ṣe
LASU Murder: Àwọn ẹbí ní ìwádìí ọlọ́pàá ṣì ń tẹ̀síwájú ni wọn kò ṣe rí òkú gbà
Oríṣun àwòrán, @femiadi
Eto isinku Favour Daley-Oladele, ti iya, ọmọ pẹlu Pasitọ sekupa lati fi se oogun owo, to yẹ ko waye lọsan ọjọ Isẹgun, ni wọn ti sun siwaju.
Gẹgẹ bi akọroyin BBC to wa nibi isẹlẹ naa ti salaye, ọpọ ero ti pejọ fun isinku naa nitẹ oku Atan to wa ladugbo Yaba nilu Eko, ki iroyin to de pe eto isinku naa ko ni lee waye mọ.
Gẹgẹ bi a ti gbọ lati ẹnu awọn ẹbi oloogbe to ti de sitẹ oku naa, awọn alasẹ ileesẹ eto ilera nipinlẹ Eko lo pasẹ pe kawọn ẹbi naa ma ti gba oku akẹkọbinrin naa lọ sin.
Awọn osisẹ ileesẹ eto ilera sọ fun wa pe ijọba pẹlu ileesẹ ọlọpa fẹ tanna wadi isẹlẹ naa siwaju ki wọn to fun awa ẹbi lasẹ lati lọ sin oku ọmọ wa pada. Koda, a ti fi ọwọ si gbogbo iwe to yẹ lati gba oku naa sita fun sinsin, ki wọn tun to sọ fun wa pe asẹ kan to wa lati oke ni wọn ko gbọdọ gbe oku naa fun wa.
Awọn eeyan to peju sibi eto isinku naa, ti iroyin ọhun ba lojiji, si ti n pada lọ sile lọọkọkan.
Laipẹ yii la mu iroyin wa fun yin pe, awọn ẹbi, ọrẹ ati akẹẹgbẹ akẹkọbinrin ileeẹkọ fasiti Eko, LASU, Favour Daley-Oladele, ti iya ati ọmọ kan fi se ọbẹ alata fun oogun owo laipẹ yii, ni wọn ti n de si itẹ oku Atan ladugbo Yaba, nilu Eko.
Akọroyin BBC Yoruba to wa nibi eto isinku naa jabọ pe se ni oju awọn eeyan naa, to peju sibi eto isinku yii faro, ti wọn si n kẹdun iku ojiji to mu arabinrin naa lọ.
Bẹẹ ba gbagbe, Pasito ijọ alaṣọ funfun kan, Segun Philip ati Adeeko Owolabi to jẹ ọrẹkunrin Favour pẹlu iya rẹ, Bola Oladele ni akara tu sepo pe wọn fi ọmọbinrin naa se oogun owo.
Pasitọ Philip ati Owolabi jẹwọ pe lootọ lawọn pa Favour lati fi ṣe oogun owo, amọ ẹlẹda ọmọbinrin naa ko jẹ ni ni oogun owo.
Lọwọlọwọ bayii, Ile iṣẹ ọlọpaa ipinlẹ Oṣun ti hu oku akẹkọọbinrin fasiti ipinlẹ Eko LASU, ti awọn afurasi naa si ti wa ni gbaga ile iṣẹ ọlọpaa lori ẹsun pe wọn jọ gbimọ pọ pa ọmọbinrin naa ni
Dambe fight: ìdíje ìjà láàrin àwọn akóni tó n ja ẹ̀ṣẹ̀
Bi eto isinku naa ba se n lọ, la maa mu wa fun yin.
Calabar Killing: Àwọn ará ilú dáná sún èèyàn méji tí wọ́n furasí bíi olè
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Calabar Killing: Àwọn ará ilú dáná sú èèyàn méji
Àwọn ènìyàn méjì kan ti wọ́n fura si gẹ́gẹ́ bi olè, ni wọ́n ti dáná sun nilu Calabar, tii ṣe olú ilú Cross River.
Ìṣẹ̀lẹ̀ náà wáyé ni agbègbè Akai Effa, tawọ́n si fi tipa fun àwọn afurasi náà ni fóònù láti pe àwọn ẹbí wọ́n láti sọ fún wọ́n pé, wọ́n ti fẹ́ dána sun àwọn nítorí àwọn jalè ki wọ́n to dána sun wọ́n.
Ìròyìn sọ pé, àwọn ará àdúgbò ọhun pà imọ̀ pọ̀ láti dána sún àwọ́n afurasi adigunjale naa nítori bi àwọn olè ṣe n já ládúgbò láti ìgbà díẹ̀ sẹ́yìn.
Ní ọjọ ọdún kérésìmesi, afurasi ọ̀daran kan lẹ́yìn to jalè tán, tún fipa bá ẹni to kamọle lòpọ̀ ni àgbègbè Okoro Agbor ní Calabar.
Olaitan Olamide: mò lè má nílò ìwé ẹ̀rí mi tí mo bá parí ní LASU
Amọ o papa bọ si ọwọ àwọn ara ilú, wọ́n lùú, bó tilẹ̀ jẹ́ pé àwọn ọlọpàá gbìyànjú láti gba silẹ̀ sùgbọ́n ẹmi ti bọ lára rẹ̀ ki wọ́n to gbé de ilé ìwòsàn.
Alapinni Oosa ṣàdúrà fún gogbo ọmọ kúoótù, oò jíire bí?
Alukoro ọlọpàá ipinlẹ Cross Rivers, DSP Irene Ugbo, fìdi ọ̀rọ̀ náà múlẹ̀ pé lootọ ni isẹlẹ naa waye, bi ko tilẹ̀ sọ ọ̀rọ̀ míràn kún alaye rẹ mọ.
'Inu mi bàjẹ́ nígbà tí mo bí i, odidi oṣù mẹ́ta, mi ò lè gbàdúrà s'Ọ́lọ́run'
Naira Marley: Pásítọ̀ Omatsola tún kìlọ̀ fáwọn ọ̀dọ́ láti yé pe ara wọn ní Marlians
Gbajugbaja olorin takasufe, Afeez Fashola ti ọpọ eeyan mọ si Naira Marley, ti fesi si ọrọ Pasitọ Chris Omashola to pe ni ẹlẹmi Eṣu.
Ojiṣẹ Ọlọrun naa ti sọ tẹlẹ pe, Ọlọrun lo fi iran han oun pe ẹlẹmi Eṣu ni Naira Marley.
Ọkunrin kan ti orukọ rẹ n jẹ @omo_billionaire loju opo Twitter, lo bi awọn eeyan leere pe kin ni idajọ lori ọrọ pasitọ Omashola ati Naira Marley.
Lẹyin naa ni Naira Marley funra rẹ fi ọrọ kan naa lede loju opo Twitter tiẹ naa.
Ṣugbọn orin ni Naira Marley fi fesi si ọrọ yii lẹyin to sọ pe ''Se bi omo jesu niwo, gbese ko Tesumole 🎶.''
Ero ọpọlọpọ awọn ololufẹ Naira Marley lo jọra wọn lori ọrọ naa, n ṣe ni awọn naa fi orin ''Se bi omo jesu niwo, gbese ko Tesumole 🎶'' bọ ẹnu ni idahun wọn si esi Naira Marley.
Amọ, ero awọn kan ṣọtọọtọ lori ọrọ naa, fun apẹrẹ, @funshi ni oniyẹyẹ ni pasitọ Omashola, o ni pasitọ naa ko riran pe Fashola Azeez lẹmi Eṣu.
Ẹlomiran, @mubaraq_a tun kin ọrọ @funshi lẹyin, o ni Naira Marley nikan ni Ọlọrun fihan ojiṣẹ Ọlọrun naa.
Epe rabandẹ lawọn kan tiẹ n fi ranṣẹ si pasitọ Omashola, wọn ni ko mọ ohun to n sọ.
Laipẹ yii ni Pasitọ Omashola sọrọ loju opo Twitter rẹ, nibi ti o ti kọ orukọ awọn eeyan to ro pe wọn ko le wọ ijọba ọrun ninu eyi ti Naira Marley wa loke tente.
Pasitọ Omoshola fikun ọrọ rẹ pe Naira Marley ni lati ronu piwada ni kiakia ko too pẹ fun un.
O ni awọn orin ti Naira Marley n kọ ni imisi Eṣu ninu, eyi to le ṣakoba fun ọjọ iwaju ati ayanmọ awọn ọdọ ni Naijira.
Bakan naa ni ojiṣẹ Ọlọrun Omoshola kilọ fawọn ọdọ wi pe, ki wọn ye pe ara wọn ni ''Marlians.''
Tinubu: Buhari kò leè du ipò fún sáà kẹta láéláé
Oríṣun àwòrán, Presidency
Aarẹ Muhammadu Buhari ati Asiwaju Bola Ahmed Tinubu sepade pọ nilu Abuja lọjọ Isẹgun.
Lẹyin ipade bonkẹlẹ to waye laarin awọn mejeeji, Tinubu sọ fun awọn ọmọ Naijiria pe asaaju Naijiria naa jẹ oniwa rere ati onigboya eniyan, ti ko si lee fẹ se saa kẹta lori aleefa laelae.
Amọ Naijiria ti ori rẹ ba pe, to ba si ti ba aarẹ Muhammadu Buhari sisẹ ri yoo mọ pe kii se ẹni to lee ti ọwọ bọ ofin ilẹ wa Naijiria.
Olaitan Olamide: mò lè má nílò ìwé ẹ̀rí mi tí mo bá parí ní LASU
Awọn eeyan ti ko fẹ ko gbajumọ isẹ to n se lori ipo aarẹ, lo n fura kiri, ti wọn si n fi awọn ẹsun ti ko tọ kan Buhari, sugbọn emi ni mo ti n ja fun ifẹsẹmulẹ ijọba awa ara wa.
Oríṣun àwòrán, Presidency
Alatako ni mo jẹ tẹlẹ fun Buhari ko to di pe erongba sise saa kẹta de, eyi ti asaaju kan tẹlẹ nilẹ yii kuna lati gbe kalẹ. Mo mọ Buhari pe ko lee gbinyanju iru rẹ laelae.
'Inu mi bàjẹ́ nígbà tí mo bí i, odidi oṣù mẹ́ta, mi ò lè gbàdúrà s'Ọ́lọ́run'
Presidency: Kí ló dé tí Ààrẹ Buhari tún ń dá àwọn tó fúnrarẹ̀ yọ nípò pàdà
Oríṣun àwòrán, @NGRPresident
Aarẹ Muhammadu Buhari ti fa iwe aṣẹ gbele ẹ ti wọn fun oludari agba ajọ ipese ina igberika lorilẹ-ede Naijiria, REA, Arabinrin Damilọla Ogunbiyi ya.
Igbesẹ yii waye lẹyin ti minisita fun ọrọ ohun amuṣagbara, Sale Mamman ti paṣẹ pe ko lọ rọọkun nile.
Amọṣa, ileeṣẹ aarẹ ṣalaye lori pe wọn fa iwe naa ya lati lee fun laaye lati funra rẹ kọwe fipo silẹ ki o lee lọ gba ipo tuntun to ṣi silẹ fun un ni ajọ iṣọkan agbaye.
Igbesẹ yii mu ki ọpọlọpọ eeyan lorilẹ-ede Naijiria ati loke okun o bẹrẹ si ni kun lori aṣa rin siwaju yọdi-sẹyin ti ijọba yii ti gbe lori awọn iyannisipo awọn eeyan kan lati igba to ti de aleefa.
Diẹ ree lara awọn eeyan ti aarẹ ti da pada lẹyin ti wọn ti rọ wọn loye lati igba ti aarẹ Buhari ti de ipo ni ọdun 2015:
Oríṣun àwòrán, Tetfund
Kí ló dé tí Ààrẹ Buhari tún ń dá àwọn tó fúnrarẹ̀ yọ nípò pàdà
Ọjọgbọn Suleiman Bogoro, akọwe agba ajọ iṣuna eto ẹkọ giga ni Naijiria, TETFUND:
Ni ọdun 2014 ni aarẹ ana, Goodluck Jonathan kọkọ yan an sipo ṣugbọn oṣu keji, ọdun 2016 ni ijọba aarẹ Buhari yọọ kuro nipo.
Trump picture: ọjọ́ tí Trump kí mi kú iṣẹ́ lórí 'twitter' ní inú mi dùn jù- Oyedele
Ẹsun ti wọn fi kan Bogoro ti wọn fi yọ ọ nigba naa ni pe ọwọ rẹ ko mọ lori igba biliọnu naira kan ti ajọ naa gbe sita fun akanṣẹ iṣẹ ṣugbọn tawọn kan ṣe baṣubaṣu.
Ṣugbọn oṣu kinni, ọdun 2019 ni wọn to tun daa pada sipo naa.
Oríṣun àwòrán, @NhisNg
Kí ló dé tí Ààrẹ Buhari tún ń dá àwọn tó fúnrarẹ̀ yọ nípò pàdà
Lẹyin ọpọlọpọ iwadii si awọn ẹsun iwa aṣemaṣe ti wọn fi kan an ni minisita feto ilera nigba naa, Ọjọgbọn Isaac Adewọle yọ Usman Yusuf nipo gẹgẹ bii akọwe agba ileeṣẹ adojutofo ilera, NHIS.
Alapinni Oosa ṣàdúrà fún gogbo ọmọ kúoótù, oò jíire bí?
Amọṣa, lẹyin asiko diẹ ni ikede tun waye pe ijọba apapọ ti da a pada si ipo rẹ.
Oríṣun àwòrán, @abdulrashid_mai
Kí ló dé tí Ààrẹ Buhari tún ń dá àwọn tó fúnrarẹ̀ yọ nípò pàdà
Ni ọdun 2013 ni ajọ iṣẹ ijọba apapọ le Maina kuro nipo lẹyin aṣẹ ofiisi olori ẹka oṣiṣẹ ijọba lorilẹ-ede Naijiria.
Lara ẹsun ti wọn fi kan an nigba naa ni pe o sa lẹnu iṣẹ.
Dambe fight: ìdíje ìjà láàrin àwọn akóni tó n ja ẹ̀ṣẹ̀
Ẹsun ti wọn fi kan Maina nigba naa ni pe ọwọ rẹ ko mọ lori bi wọn ṣe lu biliọnu meji naira, owo ifẹyinti awọn oṣiṣẹ ọlọpaa ni ponpo.
Lẹyin iwadii ile aṣofin agba, pa aṣẹ iwe aṣẹ fun awọn agbofinro lati mu u jade ṣugbọn o na papa bora.
LASU Ritual: Àwọn akẹẹgbẹ́ akẹ́kọ̀ọ́ LASU tí wọn fi ṣowó sọ̀rọ̀ lórí ìgbé ayé olóògbé
Ni ọdun 2017 ni Maina ba tun wọle pada sẹnu iṣẹ ọba, koda ipo oludari kan ni ileeṣẹ ọrọ abẹle ni wọn da a pada si ki ariwo to sọ.
Ipada sipo rẹ gan an fa olori awọn oṣiṣẹ nileeṣẹ aarẹ ati olori ẹka oṣiṣẹ nigba naa, Winifred Oyo-Ita gbe'na woju ara wọn.
Lẹyin ọpọlọpọ ariwo ni aarẹ Buhari to ni ki wọn le e nipo ki wọn le ṣe iwadii rẹ bi o ti yẹ.
Cardiac Attack: Wo ọ̀nà méje bí o ṣe lè dẹ́kun ikú òjijì
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Alága ẹgbẹ́ òṣèlú PDP ní ìpínlẹ̀ Kogi, Taiwo Kola-Ojo papòdà lẹ́yìn tí ó fò sánlẹ̀ kú níbí tó tí ń gbá bọ́ọ̀lù ẹ́lẹyin.
Ọpọlọpọ eniyan lai yọ ọmọde tabi agbalagba silẹ lo ti ku iku ojiji nitori aiṣe akiyesi ara wọn.
Koda, ni irọlẹ Ọjọ Isẹgun ni iroyin gbalẹ pe gba Alagba ẹgbẹ oṣelu PDP ni ipinlẹ Kogi, Agbẹjọrọ Taiwo Kola-Ojo subu lulẹ, ni ibi ti o ti n gba bọọlu ẹlẹyin, lawn Tennis to si ku.
Bakan naa ni Osu Kẹwa, ọdun 2019 ni arakunrin kan fo sanlẹ to si ku, nibi to ti n sare ni agbeegbe WEMCO, ni Ogba, nipinlẹ Eko.
Tunwẹ, Ọdun 2018 ni Alaga Ajọ Ere Idaraya, Deji Tinubu naa fọ sanlẹ ku lasiko to n ṣe ere idaraya bọọlu alafẹsẹgba ni agbeegbe Epe ni Ilu Eko.
Ta ba wa ni ka beere, ki lo de tawọn eeyan fi n se agbako iku ojiji bayii, paapa lasiko ere idaraya atawọn ọna ta lee gba dena rẹ.
Nigba to n dahun awọn ibeere yii fun BBC Yoruba, Onimọ kan nipa eto ilera ara, Chidinma sọ awọn nkan to n fa iku ojiji lawujọ ati ọna abayọ.
Wo ọ̀nà méje bí o ṣe lè dẹ́kun ikú òjijì:
Dokita Chidinma wa rọ awọn eniyan lati ma a se ayẹwo ara wọn ni ẹẹkan laarin oṣu mẹfa, ki wọn ba le mọ ipo ti ẹya ara wọn wa.
Bakan naa lo parọwa fun awọn eniyan lati ma a jẹ ounjẹ to n ṣe ara loore pẹlu eso jijẹ lasiko.
Ìtàn mánigbàgbé: J.F Odunjo kó ipa ribiribi sí àgbéga èdè Yorùbá
Oríṣun àwòrán, JF Odunjo
Ta ba n sọrọ nipa awọn onkọwe nilẹ Yoruba, a ko lee ka orukọ wọn lai ma fi orukọ Joseph Folahan Odunjo si aarin wọn nitori odu ni, kii se aimọ laarin awọn oloko onkọwe.
Ta ba si ni ka maa darukọ awọn to jẹ sawawu oloogbe Odunjọ, a o mẹnuba Daniel Olorunfẹmi Fagunwa, taa mọ si D.O Fagunwa, ẹni ti oun naa se gudugudu meje ati ya ya ya mẹfa ninu isẹ iwe itan arokọ.
Ọpọ wa lo ka iwe onkọwe yii lasiko taa wa nile iwe, bẹẹ si ni bi onirese J.F Odunjo ko ba fingba mọ, awọn eyi to ti fin silẹ ko lee parun laelae.
Idi si ree ti BBC Yoruba fi fẹ ka mọ nipa itan igbe aye akọni onkọtan naa.
ITAN IGBE AYE J.F ODUNJO GẸGẸ BO ṢE WA LOJU OPO ITAKUN AGBAYE:
Wo itan omi gbigbona ati tutu ni Ikọgosi Ekiti
Trump picture: ọjọ́ tí Trump kí mi kú iṣẹ́ lórí 'twitter' ní inú mi dùn jù- Oyedele
Oloogbe Oloye Joseph Folahan Odunjo jẹ eeyan nla, ẹni takuntakun to ko ipa tiẹ, ti kii se keremi si ilọsiwaju ede Yoruba ati isẹ olukọ nilẹ Yoruba.
Titi laelae si la o maa ranti akọni onkọwe naa fun ipa ribiribi to ko si ede Yoruba, bi o tilẹ jẹ pe J.F Odunjo ti ku, amọ isẹ ọwọ rẹ si n fọhun sibẹ, ti iran Yoruba ko si le gbagbe rẹ titi aye.
A wa n gbadura pe ki Ọba oke tẹ Joseph Folahan Odunjo si afẹfẹ rere.
Seyi Makinde: Ẹ ṣe àkójọpọ̀ orúkọ àwọn òǹtàjà tí àjálù bá lọ́jà Akẹ̀sán fétì ìrànwọ́
Oríṣun àwòrán, Seyi Makinde
Idunnu ti n subu lu ayọ bọ fun awọn osisẹ ipinlẹ Ọyọ nitori gomina Seyi Makinde ti kede pe ko ni si osisẹ kankan nipinlẹ Ọyọ ti owo rẹ yoo kere si ẹgbẹrun lọna ọgbọn naira, tii se owo osu to kere julọ tijọba apapọ kede rẹ.
Gomina Seyi Makinde seleri bẹẹ lasiko isin alajumọse akọkọ lati ki ọdun tuntun 2020 kaabọ, eyi ti ijọba ipinlẹ Ọyọ seto pẹlu awọn osisẹ, to waye lọgba Secretariat milu Ibadan.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí:
Gomina ni ijọba oun ti sefilọlẹ igbimọ kan ti yoo dunadura pẹlu awọn osisẹ lori agbekalẹ owo osu tuntun naa pẹlu afikun pe oju opo kanna ni ijọba ati awọn ẹgbẹ osisẹ n tọ lori ọrọ yii.
Oríṣun àwòrán, Seyi Makinde
Bakan naa ni Makinde fọwọ idaniloju sọya pe ijọba oun ko ni mẹẹri nidi ipese eto idẹrun to yanranti fun awọn osisẹ ipinlẹ Ọyọ, eyi ti yoo mu igbe aye wọn bẹsuẹ si.
Oríṣun àwòrán, Seyi Makinde
Ẹwẹ, gomina Seyi Makinde ti se abẹwo si ọja akẹsan nilu Ọyọ to jona lọjọ Aiku lati se abẹwo si awọn ohun to jona nibẹ.
Gomina Makinde, ẹni to ba awọn eeyan to padanu ẹmi ati dukia ninu isẹlẹ ijamba ina naa, wa seleri pe oun yoo kọ ọja igbalode pada fun wọn, ti isẹlẹ naa yoo si di ile ọba to jo, ẹwa lo bu kun.
Oríṣun àwòrán, Seyi Makinde
Mo gba gbogbo ẹbi mọra lori bi awọn osisẹ panpana se kuna lati tete bomi pa ina ọhun ko to bọwọ sori, ijsba mi yoo si se atunse to yẹ nipa isẹlẹ naa.
Makinde wa kesi alaga afunsọ ijọba ibilẹ ila oorun Ọyọ, ti ọja Akẹsan wa labẹ rẹ lati se akojọpọ orukọ awọn ontaja ti ajalu naa ba, lọna ti seto iranwọ to yẹ fun wọn.
Supreme Court: Okowa, Ishaku, Bello àti Ikpeazu yege àtakò ìbò
Oríṣun àwòrán, Empics
Gómìnà mẹ́rin jáwé olúborí nilé ẹjọ́ to gajù lọ
Ilé ẹjọ to ga jùlọ lórílẹ̀-èdè Najiria ti dájọ pé àwọn gómína mẹrin ti ẹjọ wọ́n wà níwáju òun, ni wọ́n n jáwé olúbori nínú ìdìbò to gbé wọ́n wọlé.
Àwọn gómínà náà ni Okezie Ikpeazu (ipinlẹ Abia) Dairus Ishaku (Ipinlẹ Taraba), Ifeanyi Okowa (ipinlẹ Delta) àti Abubakar Bello (Ipinlẹ Niger).
Ní ìpínlẹ̀ Abia, Alex Otti to dije lábẹ́ àsíà ẹgbẹ́ òṣèlú All Progressive Grand Alliance (APGA), kàn si ilé ẹjọ to ga jùlọ láti da ìdìbò Ikpeazu nu, ti ilé ẹjọ to n gbẹ́sun awuyewuye to jẹyọ nídi ìdìbò ti dá láré.
Lateef Fagbemi to jẹ́ agbẹjọrò Otti rọ ilé ẹjọ láti dá ijáwe olúbori ikpeazu sigbo, ki wọ́n si gbe fun onibara oun.
Sùgbọ́n John Galinje to dájọ náà lorukọ igbimọ ẹlẹni meje to jokó lori ẹjọ náa ni àwọn afinisu náà ko lee mu ẹ̀ri to dáju wá si iwájú ilé ẹjọ.
Gómìnà mẹ́rin jáwé olúborí nilé ẹjọ́ to gajù lọ
Ní ti gomina Taraba, ẹgbẹ́ òṣèlú All Progressive Congress (APC) ti ké gbàjare pé, Dairus Ishaku to jẹ́ gómínà kò wọle ìdìbò náà lọna to tọ, bákan náà ni ẹgbẹ́ tún sọ pé, kò tèlé ìlànà to yẹ gẹ́gẹ́ bi ofin ẹgbẹ́ (2010)ṣe sọ.
Kanu Agabi to sojú Ishaku ati People's Democratic Party (PDP) rọ ilé ẹjọ láti da ẹjo APC nù nítori pé ẹ̀sù wọ́n o mọyan lórí.
Ní ìdáhun Agabi,  Ishiaku Dikko to jẹ́ agbẹ́jọrò APC nigba ti ó ń fìdí ẹ mulẹ̀ pe, lóòtọ ni wọ́n fagile asoju APC lati dije dìbò pé o tọ si ẹni to ṣe ipò keji láti dupo.
Nínú ìdájọ rẹ̀, adájọ naa gba pé ẹgbẹ́ òṣèlú APC ko ni ọmọ ẹgbẹ́ to pegede nínú idibo náà.
Gómìnà mẹ́rin jáwé olúborí nilé ẹjọ́ to gajù lọ
Ní ìpínlẹ̀ Delta, Great Ogboru àti ẹgbẹ òṣèlú APC rọ ilé ẹjọ láti da ìbò Ifeanyi Okowa nu nítori ẹ̀sun ségeṣègé to wáye nínu ètò ìdíbò.
Yunus Usman, to sojú ẹgbẹ oselu alátakò sàlàyé pe, gbogbo ìbò ti Okowa ni kọja iye ènìyàn to forúkọ silẹ̀ fún ìdìbò gómìnà to wáye ní ọjọ kẹsan oṣù kẹta, 2019.
Ẹ̀wẹ̀, Damian Dodo to jẹ́ agbẹ́jọrò Okowa rọ ilé ẹjọ láti dẹjọ olupẹjọ nù nitori kò si ẹ̀ri to dájú.
O ní àwọn olùpẹjọ ko ri ẹri mu jáde yála nile ẹjọ to n gbẹjọ ẹsun ìdìbò àti nílé ẹjọ kò tẹmilọrun.
Adájọ Centus Nweze ni, Ogboru àti APC pé wọn o le fi ẹri to dáju han pe èrò to dibo pọ ju àwọn to forúkọ silẹ̀ lọ.
Gómìnà mẹ́rin jáwé olúborí nilé ẹjọ́ to gajù lọ
Bakan náà ni ilé ẹjọ dá ẹjọ olùpẹjọ to fẹ̀sun kan gómìnà Niger nú.
Ẹjọ kòtẹ́milọrun ti Umar Mohammed Nasko to jẹ́ ọmọ ẹgbẹ́ PDP pè ni adájọ tun dànu
Mohammed fi ẹsun kan Bello pe iwé ẹri èké lo gbe kalẹ̀ to si jẹri irọ sinú iwé to to fọwọ́ si lọ́ds àjọ ẹleto ìdìbò.
Bákan náà lo ni ilé ẹjọ to n gbẹsun ìdìbò ko dá jọ láàrin ọgọsan ọjọ gẹ́gẹ́ bi òfin se sọ
Mary Abaji to jẹ adajọ nio pe ilé ẹjọ ti se nkan ti ó to fún ẹjọ ti wọ́n dá .
O ni ilé ẹjọ to ga jùlọ ko lágbara láti tu gbé ẹjọ ti ilé ẹjọ kòtẹmilọrun ti dá tẹ́lẹ̀
Operation Amọtẹkun: Ilé iṣẹ́ ààrẹ ránṣẹ́ pe àwọn gómìnà ilẹ̀ Yorùbá lórí ọ̀rọ̀ Àmọ̀tẹ́kùn
Oríṣun àwòrán, Facebook/SEyi Makinde
Ile iṣẹ aarẹ ti ranṣẹ pe awọn gomina marun un to wa nilẹ Yoruba lori agbekalẹ eto aabo ''Amọtẹkun'' ti wọn fẹ ṣe ifilọlẹ rẹ l'Ọjọbọ.
Gbogbo eto lo ti to fun ifilọlẹ eto naa eleyi ti Gomina ipinlẹ Ondo, Oluwarotimi Akeredolu jẹ alaga rẹ.
Iroyin to n tẹ wa lọwọ sọ pe, ile iṣẹ aarẹ yoo ṣepade nirọlẹ oni Ọjọru pẹlu awọn gomina mẹfẹẹfa lati beere idi ti wọn fi fẹ fi eto naa lọlẹ nilẹ Yoruba.
Nibi apero kan to waye lori eto aabo loṣu keje ọdun 2019, lawọn gomina mẹfẹẹfa ti pinnu lati gbe eto Amọtẹkun kalẹ lẹyin ti iṣẹlẹ ijinigbe pọ kaakiri ilẹ Yoruba lọdun to kọja
Awọn eeyan to n ṣe fijilante, awọn onimọ lori ọrọ eto aabo atawọn ọlọpaa yoo wa ninu ẹṣọ Amọtẹkun naa.
Iṣẹ wọn ni lati maa ṣe iwadii lori ọrọ to niṣe pẹlu aabo kaakiri ilẹ Yoruba, bakan naa ni wọn le mu awọn ọdanran.
Illegal Orphanage: Ìjọba ti ayédèrú ilé ọmọ aláìlóbìí pa, ọmọdé mẹ́tàdínlọ́gbọ̀n gbòmìnira
Awọn alaṣẹ tọrọ kan lorilẹede Naijiria ti ko agadagodo silẹkun ile ọmọ alailobi kan ti ko niwe ofin ni ipinlẹ Kaduna, ti wọn si tu ọmọde mẹtadinlọgbọn silẹ.
Ọjọ ori awọn ọmọ naa wa laarin ọdun mẹta si mejila.
Agbẹnusọ ile iṣẹ Ọlọpaa ipinlẹ Kano, DSP Abdullahi Haruna sọ fun BBC pe, o to ọmọde mọkandinlogun tawọn tu silẹ nile awọn ọmọ alailobi Du Merci niluu Kano.
Bakan naa ni Abdullahi sọ pe, ile iṣẹ ọlọpaa tun tu awọn mẹjọ miiran silẹ nile awọn ọmọ alailobi Du Merci to wa niluu Kaduna.
Ile iṣẹ ọlọpaa sọ pe, eleyi ṣeeṣe pẹlu iranlọwọ ajọ NAPTIP to n gbogun ti fifi eeyan ṣe owo ẹru lorilẹede Naijiria.
Agbẹnusọ fun ile iṣẹ ọlọpaa ni, ayederu ile ọmọ alailobi nibi tawọn ti tu awọn ọmọde naa silẹ.
Oludamọran fun Gomina ipinlẹ Kano, Fatima Abdullahi Dala, to ba BBC sọrọ ṣalaye pe Du Merci ti wa fun bi ọdun mẹẹdọgbọn lai niwe ofin.
O wa rọ awọn eeyan Kano lati fi to ijọba leti, ti wọn ba ṣakiyesi iru ile ọmọ alailobi bẹẹ lagbegbe wọn.
Amotekun: APC ń fẹ́ káwọn ẹkùn yókù wàwòkọ́ṣe Ikọ̀ àbò àmọ̀tẹ́kùn fún àbò ẹkùn wọn
Oríṣun àwòrán, @PoliceNG
Ẹgbẹ oṣelu APC ti rọ awọn ẹkun miran lorilẹede Naijiria lati ya omi ọgbọn bu mu lori eto abo tuntun 'Operation Amọtẹkun' tawọn ijọba lẹkun iwọ orun gusu orilẹede Naijiria ṣẹṣẹ fẹ gbe sita eyi ti wọn yoo fi lọọlẹ lonii.
Igbakeji alaga apapọ ẹgbẹ oṣelu APC fun ẹkun iwọ orun gusu Naijiria, Bankọle Oluwajana lo sọ bẹẹ.
O ni bi oun ṣe n wo o, ọwọja ikọ alaabo naa yo rinlẹ daadaa paapaa julọ bi awọn ẹkun yoku ba lee wo awokọṣe rẹ.
O ni awọn ẹkun bii aringbungbun gusu orilẹede Naijiria, ila oorun gusu ati aringbungbun ariwa orilẹede Naijiria naa yoo nilo lati tun ya a lo nitori ikọ alaabo tuntun naa yoo gba ẹkun Yoruba pada lọwọ awọn janduku ati ọdaran to n ṣọṣẹ nibẹ.
Ni Ọjọbọ, ọjọ kẹsan oṣu kinni ọdun 2020 ni awọn gomina ipinlẹ mẹfẹẹfa to wa nilẹ Yoruba yoo ṣefilọlẹ ikọ abo Amọtẹkun nilu Ibadan.
Carabao cup: Iheanacho gba góòlù wọlé láti ra Leicester city padà lọ́wọ́ ìfìdírẹmi
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ipele to kangun si aṣekagba ni idije Carabao cup waye ni ilẹ Gẹẹsi ṣugbọn ori lo ko ikọ agbabọọlu Leicester city yọ lọwọ idojuti ni kọọrọ iyara wọn ni papa iṣere Kings power.
Bi o tilẹ jẹ pe ọpọ lo ti wo o pe irọrun ni ifẹsẹwọnsẹ ọhun yoo ba de fun ikọ naa amọṣa omi fẹrẹ t'ẹyin wọ igbin wọn lẹnu.
Ọpẹlọpẹ goolu kan ti Kelechi Iheanacho gba wọle ni ko jẹ ki Aston villa na Leicester city mọle lẹyin ti Frederic Guilbert ti kọkọ fi ori gbe goolu wọle fun Villa nigba ti ifẹsẹwọnsẹ naa wọ iṣẹju kejidinlogun.
Abala keji ifẹsẹwọnsẹ naa ni wọn gbe Iheanacho wọle ti o si jẹ goolu naa.
Ninu ọrọ rẹ, olukọ ẹgbẹ agbabọọlu Leicester city, Brendan Rodgers ṣapejuwe Kelechi gẹgẹ bii agbabọọlu ti ẹbun rẹ ko ṣee fọwọ rọ sẹyin. O ni lootọ ni pe Iheanacho kii fi bẹẹ ri aye gba bọọlu ki oun to de gẹgẹ bi olori ikọ naa ṣugbọn lati igba ti oun ti de loun ti bẹrẹ si nii fun un ni aye lati maa dabira lori papa, eleyi to ni o si ti n so eso rere.
Bakan naa lo ni agbabọọlu ọmọ Naijiria naa a maa ṣe iṣẹ takuntakun ni gbogbo igba to si jẹ pe eyi ti n fara han ninu ayo to n gba bayii.
Siji Ọlamiju: Paracetamol àti ìyẹ̀fun bleach tí àwọn ọlọ́jà ń lo láti ṣe GààríÌ ti mú kí ijọba pariwo síta
Awọn agba bọ wọn ni ọna ọfun ni ọna ọrun.
Amọṣa ki ọpọ ma baa gba ọna ati jẹ Gaari di ero ọrun lo mu ki ijọba ipinlẹ Ọṣun maa pariwo tantan si eti awọn araalu paapaa awọn to n ṣe Gaari ni ipinlẹ naa.
Ijọba ipinlẹ Ọṣun ti ke sawọn olounjẹ nipinlẹ ọhun lati dẹkun aṣa lilo ogun paracetamol lati fi se ẹran rọ tabi lilo eroja ifọṣọ 'bleach' fun ṣiṣe Gaari lati mu ki Gaari ati fufu tubọ funfun sii.
Amugbalẹgbẹ fun gomina ipinlẹ Ọṣun lori ọrọ ilera, apoogun Siji Ọlamiju pẹlu kọmiṣọna fun iroyin ati itaniji, Funkẹ Ẹgbemode lo pe ipe yii lati ṣalaye awọn ijamba ti irufẹ igbesẹ bẹẹ lee ko ba ẹya ara bi ifun, ẹdọ, kidirin ati ọkan.
Ọlamiju ni ijọba ṣẹṣẹ ṣawari aṣa naa ni nipasẹ awọn oṣiṣẹ ilera ti wọn yan lati ṣe abẹwo sawọn ileewosan ilera alabọde kaakiri ipinlẹ naa.
Oríṣun àwòrán, others
Wọn ni iwa ọdaran paraku ni aṣa naa leyi ti awọn to n ṣe e gbọdọ dẹkun rẹ ki ọwọ palaba wọn to segi.
O ni erooja ifọṣọ ni Hypo ti ko si yẹ ko maa kan ara ki a to ma sọ inu ikun.
kọmiṣọna fun iroyin ati itaniji, Funkẹ Ẹgbemode ni ijọba ipinlẹ Ọṣun yoo bẹrẹ eto itaniji jakejado ipinlẹ naa lori rẹ.
O ni ijọba ti ṣakiyesi pe awọn eeyan kan n lo ogun ara riro paracetamol lati se ẹran rọ ati lati se ẹsẹ maluu to ba le lati din inawo ati akoko wọn ku.
Amotekun: Fayemi ni ikọ̀ àláàbò yìí ni yóò máa ṣe àkóso ìpínlẹ̀ kọ̀ọ̀kan
Gomina Kayọde Fayẹmi ti ipinlẹ Ekiti, to tun jẹ alaga agbarijọpọ awọn gomina orilẹede Naijiria ṣe alaye wi pe, lojoojumọ ni a n koju ipenija wahala awọn adigunjale, darandaran ati bẹẹbẹẹ lọ ni ẹkun iwọ oorun Naijiria.
O ni bo tilẹ jẹ wi pe awọn ileeṣẹ agbofinro sa ipa wọn, sibẹ, omi pọ ju ọka lọ nitori ọkan lara awọn adari ẹya Yoruba, Reuben Faṣọranti naa padanu ọmọ rẹ sinu laasigbo to n ba ilẹ Yoruba finra ọhun.
Fayẹmi tẹsiwaju wi pe, eyii lo ta awọn gomina ilẹ Yoruba nidi kan lati pe ipade pajawiri lori eto aabo ilẹ Yoruba ni bii oṣu mẹfa sẹyin, abajade apero naa si ni Amọtẹkun ti wọn n ṣiṣọ loju ẹ lonii.
O ni Amọtẹkun ko waye lati rọpo awọn ileeṣẹ aabo to n bẹ nilẹ tẹlẹ, ṣugbọn yoo ṣiṣẹ papọ pẹlu awọn ẹṣọ aabo to ku, ki eto naa le kẹsẹjari.
O ṣe afikun ọrọ wi pe, gbogbo awọn aṣoju Amọtẹkun ni yoo maa ṣe amojuto awọn agbegbe kọọkan pẹlu oye ede ati aṣa awọn agbegbe naa.
Fayẹmi ṣe alaye wi pe, Amọtẹkun ipinlẹ kọọkan ni yoo maa mojuto ipinlẹ ti wọn pin wọn si lai rekọja lọ si ipinlẹ mii, ayafi ti iṣẹlẹ pajawiri ba waye.
Igbakẹji gomina Ipinlẹ Ọṣun, Gboyega Alabi to soju gomina Gboyega Oyetola nibi akanṣe eto naa ni, agbekalẹ Amọtẹkun jẹ ojuṣe awọn gomina nitori ikawọ wọn ni aabo ẹmi ati dukia awọn eeyan ilu wa.
O dupẹ lọwọ ileeṣẹ ologun ati awọn agbofinro to ku, fun bi wọn ṣe ji giri si ojuṣe wọn lasiko ti ipenija eto bẹrẹ ni ẹkun iwọ oorun Naijiria.
O wa parọwa si awọn aṣoju Amọtẹkun lati ṣiṣẹ wọn pẹlu otitọ inu pẹlu alaye wi pe, ijọba ipinlẹ Ọṣun ti ya ikorita Ọlajokun silẹ ni opopona maroṣẹ Gbọngan, ti yoo maa jẹ olu ileeṣẹ Amọtẹkun nipinlẹ Ọṣun.
Ninu ọrọ ti ẹ, gomina ipinlẹ Ondo ti o tun jẹ alaga agbarijọpọ awọn gomina ilẹ Yoruba, Rotimi Akeredolu ni ifilọlẹ Amọtẹkun jẹ nnkan ayọ fun gbogbo awọn gomina ẹkun iwọ oorun guusu Naijiria.
O ni eto aabo ilẹ Yoruba ṣe pataki si awọn gomina naa, eyi lo si ṣe atiwaye ifilọlẹ Amọtẹkun.
Akeredolu ni ko si ipinlẹ kankan ti o bọriyọ lọwọ awọn ipenija eto aabo lorilẹede yii, eyii lo si mu ki awọn ọmọ orilẹede yii to n bẹ loke okun maa bẹru lati wa si ilẹ baba wọn.
Gomina ipinlẹ Ondo tẹsiwaju wi pe, agbekalẹ Amọtẹkun yoo mu opin de ba wahala awọn adigunjale, darandaran ati ijinigbe.
O ni awọn gomina ilẹ Oodua ko ni tẹti ninu ojuṣe wọn titi ti ipenija eto aabo yoo fi di ohun igbagbe ni ẹkun iwọ oorun guusu Naijiria, eyii lo si mu ki gbogbo awọn gomina naa fi orikori lati ṣe ifilọlẹ Amọtẹkun.
Lẹyin eyi ni gomina ipinlẹ Ondo ti o tun jẹ alaga awọn gomina ilẹ Yoruba, Rotimi Akeredolu ti ṣiṣọ loju awọn ọkọ iwọde fun Amọtẹkun.
O ṣe alaye wi pe alupupu bii ọgọrun mii tun wa kaakiri awọn ipinlẹ to n bẹ ni iwọoorun guusu fun iwọde Amọtẹkun.
Lẹ́yin o rẹyin, eto ifilọlẹ Amotekun to yẹ ko ti bẹrẹ lati aago mẹsan aarọ, ti gberasọ bayii, tawọn eeyan jankan-jankan, to fi mọ awọn gomina mẹfẹẹfa nilẹ Yoruba, si ti de sibi eto naa.
Bakan naa ni awọ̀n oriade nilẹ́ Yoruba bii Ọ́ọni tilu Ile Ifẹ, Ọba Adeyẹye Ẹnitan Ogunwusi, Olugbọn tile Igbọn ti peju sibi ayẹyẹ naa.
Ninu ọrọ ikini kaabọ rẹ, olugbalejo pataki nibi ayẹyẹ ifilọlẹ ọhun, gomina Ṣeyi Makinde ti ipinlẹ Ọyọ ni, asiko ti to fun ilẹ Yooba lati dẹruba ẹru gangan funra rẹ.
Makinde tẹsiwaju pe agbẹkale Amọtẹkun waye fun igbaye-gbadun ati eto aabo to nipọn fun gbogbo ọmọ Oodua.  O ni gbogbo gomina lo bura lati bọwọ fun ofin nipa ṣiṣe agbekale eto aabo ti yoo rẹsẹwalẹ fun gbogbo awọn araalu.
Gomina ipinlẹ Ọyọ fikun pe akanṣe eto yii si jẹ imuṣẹ ileri ti awọn gomina ṣe lasiko iburawọle, pẹlu alaye pe inu oun dun lati jẹ olukopa ninu agbekalẹ eto ti yoo fẹ oju eto aabo ati igbayegbadun awọn eeyan ilu.
O tẹsiwaju wi pe, ipinlẹ Ọyọ tun ti gba oye tuntun gẹgẹ bii ipinlẹ ti agbekalẹ eto aabo ẹlẹkunjẹkun akọkọ iru ẹ ti gbinaya.
"Ifilọlẹ eto aabo alajumọse ti awọn gomina ẹkun iwọ oorun guusu Naijiria se agbatẹru rẹ, ti wọn pe ni ""Amọtẹkun"" ti gbinaya bayii.Agbekalẹ naa waye lati bomirin eto aabo nilẹ Yoruba, paapaa julọ lori ikọlu awọn darandaran to n gogo lẹnu lọọlọ yii.Gomina ipinlẹ Ondo, Rotimi Akereolu ti o jẹ alaga awọn gomina ilẹ Yoruba ni ireti wa wi pe yoo ṣi'ṣọ loju eto naa, ti yoo waye lọọfisi gomina nilu Ibadan."
Ireti si wa pe gomina Seyi Makinde ni yoo jẹ olugbalejo nibi ayẹyẹ naa.
Akọroyin BBC Yoruba to wa nibi ifilọlẹ eto aabo naa fi to wa leti pe, aago mẹsan ni eto naa yẹ ko bẹrẹ, ti wọn si n reti awọn alejo pataki lọwọlọwọ.
Awọn ẹṣọ aabo igberiko ati diẹ lara awọn alejo ti wọn fi iwe pe nikan lo wa nikalẹ, ti wọn si ti gbe awọn ọkọ isẹ ti wọn fẹ pin fun awọn osisẹ alaabo kalẹ.
Bẹẹ ba gbagbe, ana Ọjọru ni ileeṣẹ aarẹ kesi awọn gomina mẹfẹẹfa to n bẹ nilẹ Yoruba lati wa wi tẹnu wọn lori agbẹkalẹ eto aabo Amọtẹkun naa, amọ titi di akoko yii, a ko tii mọ ohun ti wọn ba bọ lati ileesẹ aarẹ.
Iroyin kan to n ja rainrain labẹlẹ ni wi pe, o ṣeeṣe ki ileeṣẹ aarẹ pagidina agbekalẹ eto aabo Amọtẹkun lẹkun iwọ oorun guusu Naijiria.
Ohun mii ti awọn eeyan tun un sọ ni wi pe o ṣeeṣe ki ileeṣẹ aarẹ maa bẹru wi pe, ilẹ Yoruba ti fẹ ya ara wọn kuro ni Naijiria nipasẹ agbekalẹ naa.
Àrìnfẹsẹ̀sí - Ìbéèrè ni a bèrè lọ́wọ́ àwọn èèyàn, ika òṣì ni wọ́n ń ta dànù
Bi isẹlẹ naa ba se n lọ, a maa mu wa fun yin.
Nkechi Blessing: Ọ̀rọ̀ ìfẹ́ wa dàbí ti Romeo àti Juliet
Oríṣun àwòrán, Nkechi Blessing
Ọrọ ifẹ, awamaridi ni, ko si si ẹni to lee mọ ibẹrẹ abi opin rẹ, koda, awọn eeyan miran tun maa n se apejuwe ifẹ bii adanwo.
Bẹẹni ọrọ ifẹ laarin ilumọọka osere tiata lobinrin kan, Nkechi Blessing Sunday, to jẹ ọmọ ẹya Ibo, amọ to n sere ere Yoruba jẹ.
Lasiko to n salaye bi ọrọ ifẹ oun ati ọkọ rẹ, Mike Adeyẹmi se bẹrẹ loju opo Instagram rẹ, lasiko ti wọn n bawọn ololufẹ wọn jẹwọ loju koroju, Nkechi ni ọrọ naa dabi ti Romeo ati Juliet ni.
Ẹ gbe ẹni wa lati sun sibi kẹ wa gbọ itan bi ifẹ emi ati ọkọ mi se bẹrẹ nitori diẹ ni mo fi han yin nipa mi, ẹ wa ka nipa igbe aye obinrin to yo ifẹ.
Oríṣun àwòrán, Nkechi Blessing
Nkechi, ẹni to wa nilẹ Amẹrika bayii lati lọ se afihan sinima rẹ, lo tun lo anfaani irinajo naa lati ri ọkọ rẹ, ẹni to n gbe nilẹ Amẹrika.
Igba akọkọ si ree ti osere tiata naa yoo sisọ loju ololufẹ rẹ ọhun, Michael, ti gbogbo eeyan ms si Razor Ray, ti oun naa jẹ osere tiata to fi orilẹede Amẹrika se ibujoko.
Nkechi ni ifẹ awọn mejeeji bẹrẹ ni kete ti awọn fi oju kan ara awọn, to si ti n gbinlẹ si lati igba naa wa.
"Mike adeyẹmi, nigba ti oun naa da si ọrs ọhun ni ""inu agbekalẹ sinima mi kan, ti mo pe akọle rẹ ni 'Bad Market' ni a ti kọkọ pade, bi o tilẹ jẹ pe a foju kanra fun igba akọkọ lasiko ta lọ pade rẹ ni ibudokọ reluwe, ti ifẹ si ru bo wa loju lọgan."""
Oríṣun àwòrán, Nkechi Blessing
Ninu sinima naa, a jẹ ete ara wa, bi ifẹ wa si se bẹrẹ ree. Aaro rẹ maa n sọ mi gidigidi nitori ọdun 2018 ni a ti foju kan gbẹyin, inu mi si dun lati gbaa ni alejo lẹẹkan si lorilẹede Amẹrika.
'Ìgbésí ayé tí kò pariwo ló dára'
A jẹ wipe ko si ibi ti ifẹ kii ti gbilẹ, a ki Michael Adeyemi ati Nkechi Blessing pe wọn ku oju to tun tura ri.
Olusegun Runsewe rí ẹ̀wọ̀n he torí pé ó tàpá sí àṣẹ iléẹjọ́
Oríṣun àwòrán, NCAC
Runsewe àti Bobrisky ní ìjà tì tẹ́lẹ̀ lohun tí ọ̀pọ̀ mọ̀ tí wọ́n sì ń tàn káàkiri.
Lẹyin ti ko ju bii wakati mẹrinlelogun eyi tii ṣe ọjọ kan ti ile ẹjọ paṣẹ pe ki oludari agba ileeṣẹ to n risi ọrọ aṣa ati iṣe na ni Naijiria, Oluṣẹgun Runsewe lọ sẹwọn, o ti ni oun loun mọ idi.
O ni idi ti wọn fi n fun ogun mọ oun ni tori pe oun ti ilu aṣa ati iṣẹ ọna to wa niluu abuja pa.
Awọn oniroyin ni oludari agba ileeṣẹ to n risi ọrọ aṣa ati iṣe sọ ọ̀rọ̀ yii fun niluu Abuja.
O ni idi ti awọn si fi ti ilu naa pa ni wi pe o ti n di ibi isapamọ si fun awọn ọmọ amugbo ati ọdaran.
Ẹwẹ, o ni awọn ọlọpaa Naijiria si ti paṣẹ pe ki wọ́n ṣi i pada.
O ni lẹyin eyi oun ko le tun ṣẹṣẹ maa fi alaye dahun ibeere kankan lori ọrọ na.
Bí àwọn ọ̀tá mi bá jẹ ilá àti ẹ̀bà tán, itẹ́ òkú ní wọn yóò ti fọwọ́ - Bobrisky
‘Ìwádìí ti bẹ̀rẹ̀ lórí ọlọ́pàa'tó lo ‘POS’ fi gba rìbá lọ́wọ́ aráàlú’
Èyí ni fídíò bí wọ́n ṣe ní Iran ló kọlu bàálù Ukraine tó já ní Tehran
"'A rí wàhálà táwọn èèyàn ń kojú nilẹ̀ẹ̀ Yorùbá la ṣe fi ""Amotekun"" fi ọkàn wọn balẹ̀'"
Ṣáájú, ìròyìn sọ pẹ́yìn ìjà pẹ̀lú Bobrisky, Runsewe rẹ́wọ̀n he torí ó tàpá sí àṣẹ iléẹjọ́
Ileẹjọ giga kan to kalẹ sadugbo Maitama nilu Abuja ti pasẹ lọjọbọ pe ki wọn sọ ọga agba fun ibudo asa ati isẹ ọna nilẹ wa, Olusẹgun Runsewe sọgba ẹwọn tori hihu iwa ọyaju sile ẹjọ.
Adajọ Jude Okeke, lasiko to n gbe idajọ rẹ kalẹ pasẹ fun ọga agba ọlspa pe ko ls mu Runsewe, ko si fi sinu ọgba ẹwọn Kuje nilu Abuja titi ti yoo fi bọ asọ ọyaju sile ẹjọ silẹ.
Ohun to fa sababi ni pe Runsewe se orikunkun si asẹ ileẹjọ to pa lọjọ Kẹẹdogun osu Kejila ọdun 2017, pe igun mejeeji to ni nkan se pẹlu ẹjọ kan nipa abule isẹ ọna gbọdọ jẹ ki ohun gbogbo wa bo se wa.
Àrìnfẹsẹ̀sí - Ìbéèrè ni a bèrè lọ́wọ́ àwọn èèyàn, ika òṣì ni wọ́n ń ta dànù
Ileẹjọ ni Runsewe ko gbọdọ ti amule isẹ ọna naa pa amọ to kẹyin si asẹ naa, ti adajọ Okeke si ni ki wọn gbe asọ ẹwọ wọọ lọrun, ko lee jẹ ẹkọ fun awọn eeyan miran to maa n tapa si asẹ ileẹjọ.
Ibadan Fire: Iná míràn tún ṣẹyọ nilú Ibadan
Oríṣun àwòrán, Magik
Iná míràn tún ṣẹyọ nilú Ibadan
Ilé ìwòsàn kàn ti wọ́n n pe ni Sanwo ni oríta Challenge ni Ibadan ló sàdédé gbina lọ́sàn òní.
Ìròyìn sọ pé iná mọ̀nàmọnána ti wọ́n múlọmúbọ̀ ló fa iná náà, ti wọ́n si ru ẹbi náà ru àwọn ilé iṣẹ́ mọ̀nàmọ̀ná
Ẹni ti ọ̀rọ̀ náà sojú rẹ̀ sàlàyé pé wọ́n ránṣẹ́ pe panápana, sùgbọ́n wọ́n ni ko sí omi ti wọ́n yóò fi pa iná nígbà ti wọ́n de wọ́n ní kò si.
Ibadan Fire: Iná míràn tún ṣẹyọ nilú Ibadan
A sì ń ko iròyìn yìí jọ lọ́wọ́
Nigeria Police: Ọlọpàá f'ọ̀bẹ la ará ilú nífun nílùú Eko.
Oríṣun àwòrán, @Bala
Ọlọpàá f'ọ̀bẹ la ará ilú nífun nílùú Eko.
Okùnrin kan ti àwọn ènìyàn mọ si Olalekan Ogunsanya ni iròyìn sọ pé ASP Francis fi ọ̀bẹ là nífun nígbàtí gbólóhùn aṣọ ṣẹlẹ̀ láàrin wọ́n lágbègbè Itire nílùú Eko.
Samuel Agbolajo ti ọ̀rọ̀ náà sojú rẹ̀ ló gbé ìṣẹ̀lẹ̀ yìí sórí ayelujara Facebook rẹ̀ pé, ọlọpàá Francis ṣe Ogunsanya lọ́sẹ lásìkò ti ìjà dú wọ́n.
Bakan náà ni Agbalajo fẹ̀sùn kan pé ilé iṣẹ́ ọlọpàá Itire ti wọ́n mú ẹjọ́ lọ ń gbìyànjú láti bo ẹsùn náà mọ́lẹ̀ ti wọ́n si ti tú Francis silẹ̀.
Ọ̀pọ̀ àwọn ọmọ Naijiria tó ló ti bu énú àtẹ lu ìwà ti Francis wù lẹ́yin ti wọ́n ri foto adẹ́rù bani náà lori Facebook.
Bo tilẹ̀ jẹ́ pé Ogunsanya la wàhálà náà já, sibẹ̀ o ní òun n fẹ ki igbésẹ̀ to gbópọ̀n lati ọ̀dọ̀ ọlọpàá
Iwádìí fi han pé Francis jẹ ọkàn lára àwọn ẹka ọlọpàá FCIID ni agbègbè Alagbọ̀n, Ikoyi.
Wàhálà bẹ́ sílẹ nígbà ti Francis n gbé àwọn ẹbi rẹ̀ lọ si ilé ìwòsàn ti o sì gbá òun pẹ̀lú ọkọ tirẹ̀, Ogunsanya ni gbogbo ǹkan ti òun fẹ́ lọ́wọ́ rẹ̀ lásìkò náà ni pe ki o tọ̀rọ̀ aforiji, ṣùgbọ́n kàkà bẹ́ẹ̀ ẹ̀ṣẹ̀ ni ọlọpàá náà fi pàdé òun.
 Inú bi mi, botilẹ jẹ́ pe mo fẹ kó bẹ̀ mi sùgbọ́n ṣe lo n pariwo 'ṣe o mọ irú ènìyàn ti mo jẹ́ ni?' Bẹẹ lo mú búlálà àti ọ̀bẹ jáde to si jáde kúrò nínú ọ̀kọ rẹ̀ wá si ọ̀dọ̀ mi, bẹ́ẹ̀ ni emi náà sáre lọ mu irinṣẹ́ ti àwọn kafinta fi n gé igi ti mo ri láti dáàbò bo ara mi.
O ní lẹ́yin náà ni Francis tún lọ sínú motorẹ̀ nígba ti àwọn èrò di lọ́wọ́ láti súnmọ òun, sùgbọ́n o tu gbìyànju síi.
"Lẹ́yin ti o fi fi ọbẹ làmi lọ́fun, mí o tilẹ̀ mọ àwọn èèyàn lo pé àkíyèsí mi sii ti mo fi ri ẹ̀jẹ̀ to sàn, mó wá pe òní fóto kan láti yà mi ki wọ́n to gbé mi lọ si ilé ìwòsàn.
Nínú ọ̀rọ̀ tirẹ̀, alukoro ọlọ́pàá ni ìpínlẹ̀ Eko, bala Elkana ni ìjà bẹ silẹ̀ láàrin ọlọ́pàá àti Ogunsanya, ilé iṣẹ́ ọlọ́pàá sì ti bẹ̀rẹ̀ ìwádìí lóri ọ̀rọ̀ náà láti fi ìdí òkodoro ọ̀rọ̀ múlẹ̀.
Nigeria Police: Ìwádìí ti bẹ̀rẹ̀ lórí ọlọ́pàa'tó lo ‘POS’ fi gba rìbá’
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Láìpẹ́ yìí ni fídíò jáde ní bí tí ọlápàá ti ń bèrè ATM lọ́wọ́ aráàlú, tí ó sì gbé POS dání láti gba owó.
Ile iṣẹ ọlọpaa lorilẹede Naijria ti fi lede wi pe awọn ti bẹrẹ iwadii lori ọlọpaa to n lo ẹrọ igbalode ti wọn n lo lati fi owo ranṣẹ POS fi gba owo lọwọ eniyan.
Eyi ko ṣẹyin bi fidio kan sẹ jade lori ẹrọ ayelujara nibi ti ọlọpaa to wa loju popo ti n paṣẹ fun ẹni ti wọn da duro lati mu ẹrọ ATM ti wọn fi n gba owo rẹ jade lati san owo.
Arakunrin naa ti ọlọpaa fẹ gba owo lọwọ rẹ wa kọjalẹ wi pe oun ko ni fi ATM oun silẹ fun ọlọpaa lati yọ owo pẹlu rẹ.
'A rí wàhálà táwọn èèyàn ń kojú nilẹ̀ẹ̀ Yorùbá la ṣe fi Amotekun"" fi ọkàn wọn balẹ̀'"
Ileeṣẹ ọlọpaa to ni iwadii naa ti bẹrẹ fi lede ninu atẹjade ti wọn fi lede ni Ọjọbọ.
Ninu atẹjade ọhun, Ọga Agba Ọlọpaa, Mohammed Abubakar Adamu ni awọn korira iwa ibajẹ ni gbogbo ọna, ati pe awọn ṣisẹ lati ri i wi pe iwa ajẹbanu di awati ni ajọ ọlọpaa lorilẹede Naijiria.
Wọn ni iwadii ti bẹrẹ lati mọ boya fidio naa jẹ ootọ, ibi ti iṣẹlẹ naa ti waye ati iye awọn ọlọpaa to kopà ninu iṣẹlẹ ọhun.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Láìpẹ́ yìí ni fídíò jáde ní bí tí ọlápàá ti ń bèrè ATM lọ́wọ́ aráàlú, tí ó sì gbé POS dání láti gba owó.
Bakan naa ni wọn sọ wi pe, ti fidio naa ba jẹ otitọ, awọn yoo ri i wi pe wọn fi iya to tọ jẹ gbogbo ẹni to ba lọwọ ninu iwa ibajẹ naa.
Amọ ajọ ọlọpaa wa rọ awọn eniyan lati ri i wi pe wọn ṣeranwọ fun wọn lati fi oju awọn ẹni ibi lede ati ki wọn fi iroyin lede nipa ẹni ọhun ti wọn mọ nipa iṣẹlẹ naa.
Ọbẹ̀ ni, ẹran ni o, irú oúnjẹ wo lẹ́ fẹ́, ká báa yín sè é wá sílé yín?
Coffin Business: Àwọn aláṣẹ ilé ìwòsàn fẹ́ kó oníṣòwò pósí lọ sí itẹ́ okú
Oríṣun àwòrán, Fellipe Abreu
Oniruuru awọn posi alarabara ree, eyi to ba wu eeyan kan ni yoo mu nibẹ.
Ijọba apapọ ti pasẹ fun awọn onisowo to yan isẹ posi tita ni aayo, lati tete ko aasa wọn kuro lẹnu ọna ile iwosan apapọ, bibẹẹkọ, wọn yoo ba ara wọn ni itẹ oku.
Awọn alaisan lo n fi ẹjọ sun nipa awọn onisowo posi naa, ti wọn fi abawọle ile iwosan ẹkọsẹ isegun to wa ni olu ilu orilẹede Zambia, Lusaka se isọ wọn.
Awọn alaisan naa ni, bawọn se n fi oju kan awọn posi to wa lẹnu ọna ile iwosan naa, lo n mu ki irẹwẹsi ọkan ba awọn, eyi to nira lati le tete san ninu aisan to n se awọn.
Ilẹ si ti ta si ti awọn eeyan kan, paapa awọn ọdọ ti patẹ posi siwaju ile iwosan naa, lati maa pawo wọle, paapa lasiko yii ti ilu le nilẹ Zambia.
Ibudo posi yii si ni awọn eeyan to ba padanu ẹbi wọn maa n ya lati ra posi, eyi ti ko jinna si ibudo igbokusi ile iwosan naa.
Oríṣun àwòrán, AFP
Nibayii, awọn alasẹ ile iwosan ọhun ti wa fun awọn onisowo posi ọhun ni osu mẹta pere lati ko aasa wọn kuro nibudo ti wọn wa yii, bibẹẹkọ, wọn yoo le wọn si itẹ oku to sunmọ tosi lati lọ ta ọja wọn.
Wọn ni asa tita posi niwaju ile iwosan ko ni fun awọn alaisan ni ireti ati ri iwosan, ti yoo si da kun aisan to n se wọn, eyi to lee tete jẹ ki wọn dagbere faye.
Covid-19 in Ondo: Dókítá mìí dágbére fáyé lẹ́yìn tó lùgbàdì àrùn Covid-19 ní Ondo
Oríṣun àwòrán, Others
Arun Covid-19 tun ti mu Dokita miran lọ nilu Akure.
Dokita Michael Adeyeri, to jẹ oludari ile iwosan Shekinah Hospital ladugbo Alagbaka nilu Akure, la gbọ pe o padanu ẹmi rẹ lọwọ arun yii .
Gẹgẹ bi ohun ti akọwe ẹgbẹ awọn dokita oniṣegun oyinbo nipinlẹ Ondo, Dokita Olasakinju Tunde ṣe fidi rẹ mulẹ fun BBC, mọjumọ Ọjọbọ ni onimọ iṣegun yii dagbere faye.
''O ṣeni laanu pe a tun ti padanu dokita mii sọwọ arun Covid-19, mojumọ oni ni a gbọ pe wọn ṣe alaisi''
Dokita Adeyeri ti fi igba kan jẹ dokita to n tọju alakoso ologun fun ipinlẹ Ondo tẹlẹ ri, oloogbe Ibe Onyearugbulem.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ọwọja iku awọn oṣiṣẹ ilera lati ọwọ arun Covid- 19 lẹnu ọjọ mẹta yii n peleke si ni Ondo.
Laipẹ yi ni Covid-19 mu Kọmisana feto ilera ipinlẹ Ondo, Dokita Wahab Adegbenro lọ.
Nigba ti BBC Yoruba kan sile oloogbe Adeyeri nilu Akure, a ri awọn olubanikẹdun ti wọn ti ya bo ile naa lati daro ẹni re to lọ.
Aya, awọn ọmọ ati ọpọ ẹbi oloogbe naa lo ti de sibẹ, ti gbogbo agbegbe naa si kan gogo.
Ọkan ninu awọn ẹbi oloogbe to ba wa sọrọ salaye pe, Ọjọbọ ni dokita naa sọ fun iyawo rẹ pe o dabi ẹni pe oun ti ko arun Coronavirus.
Kia kia lo si gba ile iwosan FMC ti wọn ti n tọju awọn alarun naa lọ, amọ ẹpa ko boro mọ, lẹ yin wakati diẹ to debẹ ni ẹlẹmi gbaa.
Mama Arsenal: Màmá àgbà yìí máa ń lọ sí ìbùdó tí wọ́n ti ń wo bọ́ọ́lù láti wòran
Lọwọ lọwọ ta n sọrọ yii, awọn dokita ti daṣẹ silẹ lawọn ile iwosan ijọba nitori pe, aini asọ aabo to peye (PPE) lati fi koju arun Covid -19.
Yatọ si ile iwosan ti wọn ti n tọju ajakalẹ arun IDH nilu Akure, awọn dokita ko tọju alaisan lawọn ile iwosan ijọba.
Akọwe ẹgbẹ awọn dokita onisegun ni Ondo, Dokita Olasakinju fi to BBC leti wi pe, awọn ko ti ribi yanju ọrọ pẹlu ijọba lori iyanṣẹlodi to n waye yi.
Nigba ti BBC beere lọwọ rẹ nipa iroyin to gbode pe awọn dokita ko tọju awọn alarun Covid-19 ni IDH mọ, o sọ pe ''ohun ko le dahun ibeere yi nitori ohun ko mọ nkan to n ṣẹlẹ nibẹ bayi''
Awọn dokita onisegun oyinbo to n sisẹ nile iwosan ti wọn ti n tọju ajakalẹ arun, IDH nilu Akure, nipinlẹ Ondo to n wo isẹ wọn niran.
Ile iwosan IDH yii si ni wọn ti n tọju awọn alarun Coronavirus, ti wsn si ni igbesẹ awọn naa ko sẹyin bi ọwọja itankalẹ arun Covid-19 se n gbilẹ si nipinlẹ naa.
Lọwọ-lọwọ bayii, awọn dokita ọhun ko se itọju kankan fun awọn eeyan to ni arun Coronavirus mọ nile iwosan naa.
Awọn dokita naa wa n fi ika gun gomina Rotimi Akeredolu nimu lori ọwọ yẹpẹrẹ ti wọn lo fi mu itankalẹ arun naa.
Lara ohun ti ẹgbẹ awọn dokita nipinlẹ Ondo si mẹnuba ti wọn fi n yan isẹ lodi naa ni pe titi di akoko yii, wọn ko tii fi ẹnu ọrọ jona lori owo osu to kere julọ ati atunse rẹ, eyi tawọn ti kii se dokita nile iwosan ti n jẹ anfaani rẹ.
Wọn ni awọn ti sọ fawọn dokita naa nipinlẹ Ondo lati mọ isẹ loju bẹrẹ lati ọjọ Aje, ọjọ Kẹfa osu Keje nitori aisi omi aanu loju ijọba gomina Akeredolu.
Kemi Dairo: Iṣẹ́ abẹ nínú ọpọlọ àti ẹ̀rọ ni mo fi ń gbọ́ ọ̀rọ̀ báyìí
Awọn dokita ile iwosan ẹkọsẹ isegun to n yansẹ lodi ti n fẹhonu han ninu ọgba ile iwosan naa to wa nilu Akure, tii se olu ilu ipinlẹ.
Deede aago mẹsan aarọ lawọn dokita ti oju wọn ko rẹrin naa ti pejọ sibẹ, ti wọn si gbe oniruuru akọle lọwọ, ninu eyi ti wọn kọ awọn ohun to n jẹ wọn lọkan si.
"Lara awọn ẹdun ọkan wọn ti wọn kọ sara awọn akọle naa ni pe "" A n beere fun ohun ti a sisẹ fun, Inu fifo la fi n sisẹ, ti a ko si mọ igba ti ounjẹ miran yoo wa, Dokita ti ebi n wa jẹ ewu fun awujọ, ẹtọ wa ni owo osu wa, kii se ẹbun, ẹ jọwọ, ẹ san owo osu ti ẹ jẹ wa, ki lo de tile iwosan tiwa yatọ , ati bẹẹ bẹẹ lọ."""
Nigba to n bawọn akọroyin sọrọ, Alaga fun igbimọ to wa feto iroyin labẹ ẹgbẹ awọn dokita, ẹka tile iwosan naa, Taiwo Olagbe salaye pe, wọn jẹ awọn dokita naa ni owo to to osu mẹfa, marun, mẹrin ati mẹta, eyi to wa lọwọ igba ti onitọun ba wọ isẹ.
Dokita Olagbe fikun pe lẹyin spọ ẹbẹ si awọn alasẹ ati iwọde lọ si ọọfisi gomina, gbogbo ileri ti akọwe ijọba ipinlẹ naa, Ifedayo Abegunde ati oludamọran gomina feto ilera se, lo ja si pabo.
Awọn dokita naa wa n rawọ ẹbẹ sijọba ipinlẹ Ondo labẹ gomina Rotimi Akeredolu, to fi ms gbogbo ọmọ Naijiria lati bawọn kesi awọn alasẹ ile iwosan naa pe ki wọn jẹ owo ti wọn jẹ wọn.
"'A rí wàhálà táwọn èèyàn ń kojú nilẹ̀ẹ̀ Yorùbá la ṣe fi ""Amotekun"" fi ọkàn wọn balẹ̀'"
Wayi o, Kọmisana feto ilera nipinlẹ Ondo, Dokita Wahab Adegbenro ti wa fi ọwọ idaniloju sọya fawọn dokita naa pe, wọn yoo maa ri alaati gba lati ile ifowopamọ wọn pe owo osu ti wọ apo asunwọn owo wọn.
LASU student killing: Ilé ẹjọ́ pàṣẹ kí wọ́n fi àwọn tó pa àkẹ́kọ̀ọ́ LASU sí ẹ̀wọ̀n
Oríṣun àwòrán, Nigeria Police
Bàbá akẹ́kọ̀ọ́bìnrin LASU tí ọ̀rẹ́kùnrin rẹ̀ fi ṣ'òògùn owó ń bèèrè fún ìdájọ́ òdodo
Ile ẹjọ ti ni ki wọn o fi awọn ti wọn fi ẹsun kan pe o pa akẹkọbinrin Fasiti ipinlẹ Eko, Favour Oladele.
Awọn afurasi mẹtẹẹta, Philip Segun, Owolabi Adeeko, to jẹ ọrẹkunrin oloogbe, ati iya rẹ, Bola, ni wọn gbe lọ sile ẹjọ magistreti.
Onidajọ Olukunle Idowu, ti ile ẹjọ Majistreti naa gẹgẹ bi iwe iroyin Vanguard ṣe sọ, dajọ pe ki wọn o fi wọn pamọ si ọgba ẹwọn Ileṣa titi di ọjọ kẹẹdọgbọn, oṣu Kẹta, ọdun 2020, ti igbẹjọ yoo waye nile ẹjọ giga lori ẹsun ti wọn fi kan wọn.
LASU Ritual: Àwọn akẹẹgbẹ́ akẹ́kọ̀ọ́ LASU tí wọn fi ṣowó sọ̀rọ̀ lórí ìgbé ayé olóògbé
Favour, ni iroyin sọ pe o kuro nile l'ọjọ kẹjọ, oṣu Kejila, ọdun 2019, to si di awati. Lẹyin naa ni wọn ri oku rẹ, ṣugbọn ti awọn ẹya ara rẹ kan ko si nibẹ mọ.
Iwadii awọn ọlọpaa lo si fihan pe, irinajo arabinrin yii jọ mọ lilọ si ile ijọsin Segun to wa ni ilu Ikoyi-Ile nipinlẹ Osun.
Olaitan Olamide: mò lè má nílò ìwé ẹ̀rí mi tí mo bá parí ní LASU
Ninu ifọrọwanilẹnuwo wọn pẹlu Adeeko lo ti ṣalaye pe, pasitọ fun oun ni ọmọ odo lati fi lu u lori, ki oun pasitọ to o fi ọbẹ yọ ọkan rẹ, eyi to fi se asejẹ fun Adeeko ati iya rẹ.
Nigeria Police: Èsì àwọn ọmọ Nàìjíríà tó tẹ̀lé bí iléèṣẹ́ ọlọ́pàá ṣe yin ara rẹ̀
Lori kaadi ti wọn fi sita loju opo ayelujara Twitter wọn, ileesẹ ọlọpaa sọ pe kaadi naa jẹ afihan akojọpọ awọn aṣeyọri wọn laarin ọjọ kẹrindinlogun, oṣu Kinni, ọdun 2019 si ọjọ kẹrindinlogun, oṣu Kinni, ọdun 2020.
Wọn tọka si awọn 'ẹka' bi awọn afurasi, ọmọ ẹlẹgbẹ okunkun, ti ọwọ tẹ, to fi mọ iye ọkọ ti wọn jigbe, ṣugbọn ti ọlọpaa gba pada, awọn afurasi ajinigbe ati adigunjale, to fi mọ iye nkan ija oloro ti wọn ri gba.
Ṣugbọn ṣa, bi awọn ọmọ Naijiria kan ṣe n gboriyin fun awọn ọlọpaa ni awọn kan n sọ pe awọn ọmọ Naijiria lo yẹ ko fi iru kaadi igbelewọn naa sita, kiiṣe ileeṣẹ ọlọpaa.
Bakan naa ni awọn kan tun n sọ, paapa labẹ ikede ileeṣẹ ọlọpaa ọhun pe, o yẹ ki wọn o kọ iye aṣita ibọn ọlọpaa to pa araalu, riba gbigba, iye awọn ọdọ ti ọlọpaa fiya jẹ lọna aitọ, ati awọn ẹsun miiran ti araalu fi n kan awọn ọlọpaa si ori kaadi naa.
Yatọ si eyi, awọn kan sọ pe o yẹ ki wọn kọ iye afurasi ti ọrọ wọn wa nile ẹjọ, ati awọn to ti gba idajọ sori kaadi igbelewọn naa.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Awọn kan tilẹ sọ pe ko dara bi wọn ṣe gbe kaadi igbelewọn naa, to ṣafihan ọjọ kẹrindinlogun oṣu Kinni, ọdun 2019 si ọjọ kẹrindinlogun oṣu Kinni, ọdun 2020, jade ni ọjọ kẹsan an, oṣu Kinni, 2020.
Titi di akoko yii, ileeṣẹ ọlọpaa ko tii f'esi si ọkankan ninu awọn esi araalu naa.
"'A rí wàhálà táwọn èèyàn ń kojú nilẹ̀ẹ̀ Yorùbá la ṣe fi ""Amotekun"" fi ọkàn wọn balẹ̀'"
Yollywood: Tóyìn Abraham kẹ̀yìn sí àgbo títà, Ṣọlá ọmọ Jídé Kòsọ́kọ́ ṣe ọjọ́ ìbí
Oríṣun àwòrán, Kunle Afolayan
Bẹbẹ lọ lagbo awọn oṣere tiata Yoruba lọsẹ yii. Bi ọlọjọ ibi ṣe n ṣe ọjọ ibi ni alayọ n yọ. Idunnu ṣubu layọ fawọn oṣere tiata Yoruba lọsẹ yii.
Diẹ lara bẹbẹ to lọ niyi.
Oríṣun àwòrán, Kunle Afolayan
Odu ni Kunle Afọlayan ni ti ka gbe sinima kalẹ ni orilẹede Naijiria ati lagbaye. Ọpọ l o n sọ pe ọrs rẹ ko lee maa ribẹ nitori ogbontagi oṣere ni baba rẹ Adelove, nitori ọmọ ti ẹya ba bi ẹya naa ni yoo jọ.
Trump picture: ọjọ́ tí Trump kí mi kú iṣẹ́ lórí 'twitter' ní inú mi dùn jù- Oyedele
Nibayii, iroyin to n jade ni pe, 'Citation'sinima tuntun ti Kunle Afọlayan yoo gbe jade laipẹ yoo tun le kenka nitori ọmọ baba olowo nla, Ọtẹdọla, iyẹn Temi yoo farahan ninu sinima naa.
Temi to jẹ abigbẹyin baba olowo Fẹmi Ọtẹdọla yoo ma dara pọ mọ awọn eekan oṣere biiJimi Jean Loius to jẹ ọmọ ilẹ Haiti, Sadiq Daba, Gabriel Afọlayan atawọn miran.
Eduardo: Mo ń jí mọ́tò pẹ̀lú àwọn ọ̀rẹ́ mi nítorí pé mo fẹ́ di 'Big boy'
Oríṣun àwòrán, Toyin abraham
Gbajugbaja oṣere tiata, Toyin Abraham ti ti ileeṣẹ alagbo to ṣi silẹ loṣu kẹwa ọdun 2019 pa.
Toyin ti iroyin sọ pe agbo ibilẹ lo fi bi ọmọ rẹ lẹyin ọpọ ijakadi pẹlu airọmọbi bẹrẹ owo naa loṣu diẹ sẹyin.
Amọṣa funra rẹ lo bọ soju opo ayelujara instagram rẹ lati kede pe, oun ti fi owo agbo naa kọ sibikan naa nitori edeaiyede pẹlu awọn ti wọn jẹ alabadowo pọ rẹ.
Oríṣun àwòrán, Sola Kosoko
Sọla Kosọkọ, gbajugbaja oṣere, to tun jẹ ọmọ eekan oṣere tiata ni Naijiria, Jide Kosọkọ ṣe ayẹyẹ ọjọ ibi ogoji ọdun rẹ.  Okiki kan.
Ọbẹ̀ ni, ẹran ni o, irú oúnjẹ wo lẹ́ fẹ́, ká báa yín sè é wá sílé yín?
Manigbagbe nibi ayẹyẹ ọjọ ibi rẹ naa ni eto ikini ku ọjọ ibi ti awọn mọlẹbi rẹ ṣe fun. Lowurọ kutu hai  ni awọn mọlẹbi rẹ kaa mọle pẹlu orin, fere, ijo, ẹrin.
Iyalẹnu nla lo jẹ fun Sọla to ni oun ko rokan rẹ rara. Baba rẹ Jide, aburo rẹ Bidemi pẹlu ko gbẹyin nibi ayẹyẹ naa.
'Mo fọ́ lójú ṣùgbọ́n mo mọ gbogbo irinṣẹ́ tí mo fi ń ṣe mọkalíìkì'
Human traffiking: Òyìnbó kòráà, amòfin kan wọ gbaga òfin fún títa obìnrin kan sóko ẹrú
Oríṣun àwòrán, Omolola Ajayi
Òyìnbó kòráà, amòfin kan wọ gbaga òfin fún títa obìnrin kan sóko ẹrú
Ọwọ ofin ti tẹ ọmọ orilẹede Lẹbanon kan torukọ rẹ jẹ Wasit Muhammad pẹlu awọn eeyan meji miran ti wọn lo lọwọ ninu tita arabinrin kan, torukọ rẹ n jẹ Ọmọlọla Ajayi si oko ẹru ni orilẹede Lebanon.
Fidio kan ti arabinrin Ajayi Ọmọlọla fi sita laipẹ yii lo di alatagba lori ayelujara nibi ti o ti n ṣalaye pẹlu omije loju pe, awọn eeyan kan ta oun si orilẹ-ede naa labẹ pe oun yoo ri iṣẹ aje se.
Amọ o ni ọrọ ọhun yi pada nigba ti oun de ọhun nitori nibẹ ni o ti lu si oun leti pe, wọn ti gba owo oku ati aye oun.
Ọlatunji Sanusi to jẹ agbẹjọro ati ẹlomiran ti orukọ rẹ n jẹ Tunde, ni awọn meji ti ọwọ ba pẹlu Oyinbo koraa naa.
Oríṣun àwòrán, Naptip
Gẹgẹ bi iroyin ṣe sọ, iwadii ileeṣẹ abo ara ẹni labo ilu fi kun un pe, yatọ si arabinrin Ajayi, eeyan mejidinlọgbọn ni awọn eeyan mẹta yii ti ran lọ soko ẹru loke okun labẹ pe wọn fẹ lọ ṣiṣẹ kore oko dele.
Fidio alaye ti arabinrin Ọmọlọla se ree, eyi to gba ori ayelujara kan:
Ninu atẹjade kan ti Gomina ipinlẹ Kwara, Abdulrazaq fi sita, ijọba ipinlẹ Kwara ni oun ko ni gba iwa bẹẹ laaye mọ rara.
Ẹtan pe yoo lọ di olukọ ede oyinbo ni wọn fi mu Ọmọlọla Ajayi lọ sorilẹ-ede Lẹbanon, ki ọrọ to di baa mii nigba to de ibẹ tan.
Trump picture: ọjọ́ tí Trump kí mi kú iṣẹ́ lórí 'twitter' ní inú mi dùn jù- Oyedele
Boko Haram: Ilé iṣẹ́ ọmọogun kò sọ fún mi pé ọkọ mi kú fún ọdún kan- Iyawo soja
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Boko Haram:Ilé iṣẹ́ ọmọogun kò sọ fún mi pé ọkọmi kú fún ọdún kan- Iyawo soja
Ilé àwọn Abdulaziz Musa to jẹ ọmọogun orilẹ̀ede Naijíríà ro pẹlu ọfọ ní àisùn ọdún tuntun ti gbogbo ènìyàn n dúnnu láti wọ ọdun 2020 ní ilu Ilorin.
Ní ọjọ́ yìí gan ni ilé iṣẹ́ ọmọogun Naijiria lọ túfọ fún ẹbí Abdulaziz ẹni ọdun márundinlogojì ti àwọn ọmọ ikọ̀ Boko Haram pa ní ìpínlẹ̀ Borno.
Ìròyìn sọ pé Musa to ni Nọmba idanimọ ọmọogun 14NA/71/1222 wà ni ẹ̀ka ìpèsè àti ìrìnà fún ilé iṣẹ́ ọmọogun Naijiria.
Sááju ni ìròyìn ti sọ pé àwọn ẹbi ko tii ri Musa bá sọ̀rọ̀ láti inú oṣù kejìlá ọdun 2018, eyi ti o sì ti da ìyàwó àti ọmọ ọdun mẹrin ti wọ́n ni láàmú.
Ikọlù to ṣẹ̀lẹ̀ si àwọn soja ni Metele ninu oṣù kọkànlá ọdún 2018 níbi ti ọ̀pọ̀ sójà ti padánù ẹ̀mi wọ́n tun mu ki ẹbi rẹ má ni ìfọ̀kànbalẹ̀, síbẹ̀ ilé iṣẹ́ ọmọogun ko bùn ẹbi gbọ́.
Ilé iṣẹ́ ọmọogun ni irọ́ ni pé ọmọogun to to ọgọ́run kú nínú ìṣẹ̀lẹ̀ náà àti pé ènìyàn mẹ́tàlélógun péré lo bá ìṣẹ̀lẹ̀ náà rin.
Lẹ́yìn náà ni ọ̀gágun ilé iṣẹ́ ọmọogun Naijiria Tukur Buratai fi àtẹjáde kan sita ti ọmọogun Sani Usman si buwọlù ú pé sójà mejila ku ni Kukawa, Ngshe, Kareto àti Gajiram ti gbogbo rẹ̀ wà ni ìpínlẹ̀ Borno nigbati àwọn ọmọogun ko sọ́wọ́ Boko Haram ọjọ keji si ọjọ kẹtàdinlogun oṣù kọkanlá ọdun 2018.
Iyàwo Musa Sherifat ni ọjọ́ keji ti ìṣẹ̀lẹ̀ náà wáye ni òun pé láti bèrè lọ́wọ́ ọkọ òun pe ṣe àláfia lo wà, ṣùgbọ́n gbogbo ìgbìyànju òun pàbó ló jásí.
’Awọn sọja Cameroun tu mi sihoho'
‘Sọ́jà méje wọ gàù lórí ẹ̀sùn olè jíjà’
O ní kóda àwọn ẹbi tun ránṣẹ́ si àwọn ọgálọ́ga soja, wọ́n si sọ fún àwọn pé aláfíà lo wà.
O ní inú oṣù kejila ọdun 2018 ni òun ba ọkọ òun sọ̀rọ̀ kéyin. Ní ọ̀pọ ìgbà orí àtẹjisẹ́ WhatsApp ni òun ti maa ba a sọ̀rọ̀ ṣùgbọ́n láti ìgbà náà òun kò lé ba a sọ̀rọ̀ mọ. O ní àwọn pe àwọn ọ̀gá rẹ̀ síbẹ̀ wọ́n ni kò sí wàhálà kankan, pe ti wàhálà ba wà àwọn yóò ti jẹ ki ẹbi mọ ti wọ́n yóò si ti kàn si wọ́n láti Abuja.
 Ọjọ kọkanlélọ́gbọ̀n oṣù kejila ọdún 2019 ni wọ́n kàn si àburo rẹ̀ to jẹ orukọ to fi sílẹ̀ pé òun ló súnmọ òun jù (Next of Kin) pe ó ti kú, wi pe o kú nínú ìṣẹ̀lẹ̀ to wáye nínú oṣù kọkànlá ọdun 2018.
Musa to jẹ́ ọmọ ilọrin ni ìpínlẹ̀ Kwara wọ iṣẹ́ ọmọogun Naijiria lọdun 2014 lẹ́yin ọdun kan to gbé ìyàwó ti ìyàwó si ti wà nínú oyun lásìkò to lọ fun ìgbáradi.
Agẹnusọ ọmọogun Naijiria ti ikọ iroyin kan si Sagir Musa seleri pe oun yóo fesi lẹyin atẹjisẹ pe ki o sọ iha àwọn ọmọ ogun sùgbọn ko tii fèsì di àsìkò yìí.
Oman ń ṣelédè lẹ́yìn Sultan Qaboos bin Said
Oríṣun àwòrán, Reuters
Sultan Qaboos ni adari ilẹ Arab to pẹ ju lagbaye, o si ti wọ kaa ilẹ sun bayii lẹni ọdun mọkandinlọgọrin.
Pẹlu ibinujẹ ni idile ọba ilẹ Gẹẹsi fi kẹdun iku Ọlọlajulọ Sultan Qaboos bin Said, to jẹ Ọlọrun nipe lọjọ ẹti gẹgẹ bi ọrọ ti ile ẹjọ fi sita.
Loṣu to kọja lo pada sile lẹyin to lọ fun ilera ni orilẹede Belgium. Iroyin ti a gb ni pe aisan jẹjẹrẹ lo n ba a ja.
Nibayii, orilẹede naa ti kede ọjọ mẹta lati fi ṣ'ọfọ rẹ.
Ìdájọ́ ikú ń dínkù, àmọ́ orílẹ̀-èdè mélòó ló sì ń pa ẹlẹ́sẹ̀?
'Mo fọ kọ́mú, pátá, ògiri ilé lórí 200,000 láìlèfọhùn lórílẹ̀èdè Oman'
Bakan naa, wọn ti ṣe ibura wọle fun minisita orilede Oman fun ọrọ aṣa, Haitham bin Tariq lati tẹsiwaju ni ipo rẹ.
Ohun taa gbọ ni wi pe Sultan Qaboos ko ni ọmọ tirẹ nitori naa o kọ orukọ ibatan rẹ sinu lẹta to kọ silẹ ti wọn ka jade gẹgẹ bi ẹni ti yoo gba eku ida lọwọ rẹ.
Oríṣun àwòrán, KEYSTONE
Sultan Qaboos ko fẹ́ iyawo bẹẹ si ni ko bimọ kankan tabi ẹni ti yoo gbe ade le lori lẹyin ipapoda rẹ.
Ni ẹni ọdun mkandinlọgbọn ni Sultan yii gbajọba lọwọ baba to bi i lọmọ, Said bin Taimur lasiko itajẹsilẹ buruku kan ti ilẹ Britain ṣatilẹyin fun lọdun 1970.
Pẹlu ọwọ lile ni baba rẹ fi dari orilẹede Oman.
O fi ofin silẹ lati ma jẹ ki awọn eeyan rẹ ni anfani awọn nkankan bii gbigbọ rẹdio tabi wiwọ gilaasi oju koda to fi m yiyan ẹni ti wọn yoo fẹ funrawọn, ọrọ ileewe tabi bi wọn ba fẹ kuro lorilẹede.
Adari yii lo owo epo rọbi orilẹede naa lati fi san na idagbasoke fun Oman.
Nkan bii aadọta dun lo fi ṣejọba, Sultan Qaboos lo wa ni ori akoso igbe aye oṣelu orilẹede Oman nibi ti eeyan to fẹrẹẹ to miliọnu mẹrin abọ o le diẹ (4.6 million) wa.
Sultan Qaboos bin Said ni adari to ṣakoso ijọba orilẹede Oman to pẹ ju lagbaye.
JAMB ṣe ìdádúró lílo nọ́mbà ìdánimọ̀ fún ìdánwò àṣewọlé ọdún 2020
Oríṣun àwòrán, @EyeWitness101
Ajọ JAMB ni wọn yoo nilo nọmba idanimọ naa fun idanwo ọdun 2021
Ajọ to n ri si idanwo aṣewọle iwe giga, JAMB ti ṣe idaduro lilo nọmba idanimọ Naijiria, NIN, fun iforukọ silẹ idanwo aṣewọle ọdun 2020.
Ọga agba ajọ JAMB, Ishaq Oloyede lo fi ọrọ naa lede nigba to n ba awọn oniroyin sọrọ l'Abuja.
Bakan naa ni ajọ ọhun fi ọrọ naa lede loju opo Twitter rẹ, nibi to ti dari awọn oluṣedanwo lati fi orukọ wọn ranṣẹ si 55019 fun iforukọ silẹ idanwo naa.
Ishaq sọ pe, idaduro lilo nọmba idanimọ naa jẹ ọna lati fun awọn to n ṣe idanwo JAMB lanfaani sii, lati lee gba nọmba idanimọ wọn.
O ni igbesẹ naa tun jẹ ọna lati lee wa ojutu si awọn kudiẹkudiẹ to n waye ni awọn ojuko idanwo JAMB kaakiri oriliẹ-ede yii.
Ọga agba ọhun ṣalaye siwaju sii pe, awọn oluṣedanwo ko nilo nọmba idanimọ fun idanwo ọdun 2020, ṣugbọn wọn yoo nilo nọmba naa fun idanwo ọdun 2021.
Ṣaaju lọdun 2019 ni ajọ JAMB sọ pe awọn to ba fẹ ṣe idanwo aṣewọle ọdun yii yoo nilo nọmba idanimọ naa lati lee fopin si bi awọn kan ṣe ma n forukọ silẹ funn idanwo ọhun ju igba kan lọ.
'Mo fọ́ lójú ṣùgbọ́n mo mọ gbogbo irinṣẹ́ tí mo fi ń ṣe mọkalíìkì'
Hanan Buhari: Ìjọba ní Ọmọ Buhari lásẹ láti wọ bàálú Nigeria Air force
Oríṣun àwòrán, Hanan Buhari/Instagram
Hanan Buhari ni àwọn ènìyàn rí tó ń bọ́lẹ̀ nínú ọkọ baalu ní Bauchi níbí tò ti lọ ya fọ́tọ̀.
Orisirisi awuye lo ti ṣẹyọ lẹyin ti abigbẹyin Aarẹ Buhari, Hanan Buhari wọ ọkọ ofurufu, Nigeria Air Force lati lọ ṣe iṣẹ ọwọ rẹ.
Bi awọn kan ṣe n bu ẹnu ẹ̀tẹ́ lu igbeṣẹ naa wi pe arabinrin naa n lo baalu ti awọn ara ilu n san owo ori lẹ lori lati lọ fi sẹ iṣẹ ara rẹ ni ipinlẹ Bauchi ni àwọn miran ni ko buru
Ayẹyẹ ọdun Durbar ni Bauchi ni ọmọ aarẹ Buhari lọ ya fọto rẹ gẹgẹ bi iṣẹ aje rẹ nibi to ti ni anfani lati ya aworan nipa ọdun naa ati awọn nkan miran ni Bauchi.
Amọ, ijọba lasiko ti wọn n fesi si igbeṣẹ naa ni ọmọbinrin naa ni Hanan ni aṣẹ labẹ ofin lati lo ọkọ ofurufu naa gẹgẹ bi ọmọ Aarẹ orilẹ-ede Naijiria.
Oríṣun àwòrán, Other
Olubadamọran pataki fun Aarẹ Buhari, Garba Shehu lọ sọ bẹẹ pe nitori o gba aṣẹ lọwọ Baba rẹ ni o fi lo ọkọ ofurufu naa.
Garba Shehu ni labẹ ofin, eniyan mẹrin lo laṣẹ lati lo ọkọ ofurufu ijọba Naijiria, iyẹn ni Aarẹ, Awọn ẹbi aarẹ, igbakeji Aarẹ ati Aarẹ Ilẹ Igbimọ Asofin agba ati kekere orilẹ-ede Naijiria ati ẹnikẹni ti Aarẹ ba gba laaye pẹlu aṣẹ.
Eduardo: Mo ń jí mọ́tò pẹ̀lú àwọn ọ̀rẹ́ mi nítorí pé mo fẹ́ di 'Big boy'
Bẹẹ, lo tun fikun un pe Aarẹ Buhari sọ fun olubadamọran lori eto aabo orilẹ-ede Naijiria lori bi arabinrin naa ti lọ ṣe iṣẹ ayawòrán ni ayẹyẹ Durban to waye ni Bauchi.
Ọmọbinrin Aarẹ Buhari naa lo gba iṣẹ ati lọ ya fọtọ ni ayẹyẹ naa, lẹyin to gba ipo oni ipele kini (First Class) ninu ẹkọ imọ ayaworan lati Fasiti Ilẹ Gẹẹsi laipẹ yii.
Amọ awọn ọmọ Naijiria ati ẹgbẹ oṣelu PDP ko fi ara irẹ gba ọrọ yii, ti wọn si fikun un wi pe owo goboi ni ijọba n gba lọwọ araalu lati tun awọn ọkọ ofurufu yii ṣẹ.
Wọn tilẹ ran ijọba leti wi pe ko ranti ipinnu rẹ lati ta awọn ọkọ baalu yii, ki ijọba le e ri owo fi pese awọn ohun amayedẹrun fun ijọba.
PDP ni ṣe o yẹ ki ọmọ aarẹ maa gun ọkọ ofurufu ijọba nigba ti eyi ti igbakeji aarẹ n gun n dẹnukọlẹ lojoojumọ?
Trump picture: ọjọ́ tí Trump kí mi kú iṣẹ́ lórí 'twitter' ní inú mi dùn jù- Oyedele
Awọn miran sọ ootọ ọrọ funra wọn lati tubọ tẹ ipa mọ iṣẹ aje wọn bayii ti ọmọ aarẹ ba le maa ya aworan kiri.
Bẹẹ ni wọn fikun un pe, iye owo to le ni biliọnu, N8.5bn ti ijọba pinnu lati na ninu eto isuna ọdun 2020 ti pọ ju fun itọju baalu ọkọ ijọba.
Contraband: Ọlọ́pàá Uganda rí ohun ìpara olóró nínú ‘baby’
Oríṣun àwòrán, Dicksons Kateshumbwa
Àwọn aláṣẹ ilẹ̀ Uganda ní ọ̀pọ̀ ìgbà ni àwọn ènìyàn ti ń gbé òògùn olóró àti àwọn ohun tí ìjọba ti wọ́gilé wọ ilẹ̀ náà.
Ile iṣẹ to n gbogun ti iwa gbigbe oogun oloro lọna aitọ wọle ti fi panpẹ ọba mu arakunrin to n gbe ohun ipara oloro si inu ‘baby’ onike.
Ọga Agba aṣọbode lorilẹ-ede Uganda, Dicksons Kateshumbwa lo ni arakunrin naa to gbe 'baby' pọn sẹyin ni ọwọ tẹ ni ibode Democratic Republic of Congo.
Dicksons Kateshumbwa ni oju opo twitter rẹ sọ wi pe awọn to n ṣisẹ fayawọ kii ye pa eniyan lẹrin.
Ifa Priest: ọdún mọ́kànlá ni mo fi ṣe iṣẹ́ agbejọ́rọ̀ kí n tó gbọ́ràn si Ifá lẹ́nu
Dicksons ni arakunrin ti ọwọ ba naa kọ ọpọlọpọ ohun ipara ati ọṣẹ iwe sinu ‘baby’ naa to si gbe e pọn bi ọmọ, ni ọna lati maṣe jẹ ki wọn fura si oun ti wọn gbe naa.
Ọbẹ̀ ni, ẹran ni o, irú oúnjẹ wo lẹ́ fẹ́, ká báa yín sè é wá sílé yín?
Ọga Agba aṣọbode lorilẹede Uganda ni awọn eniyan ma n gbe oṣẹ ati ohun ipara to n mu eniyan pọn fo wọlẹ lati ẹnu ibode DR Congo, eleyii ti awọn ti wọgile ni ọpọ igba.
Bakan naa lo fi lede pe ọdun 2016 ni awọn ti wọgile gbigbe ọṣẹ ipara borabora wọlẹ si orilẹ-ede naa, nitori o ni awọn ohun ipalara bi hydroquinone ati mercury to n ṣe ipalara fun ara.
Eduardo: Mo ń jí mọ́tò pẹ̀lú àwọn ọ̀rẹ́ mi nítorí pé mo fẹ́ di 'Big boy'
Supreme Court: Ilé ẹjọ́ gíga jùlọ sún ìgbẹ́jọ́ ìbò Kano, Imo àti Sokoto
Oríṣun àwòrán, OTHER
Ile ẹjọ to ga ju lọ lorilẹede Naijiria ti sun igbẹjọ to yẹ ko waye lonii lori ibo ipinlẹ mẹfa lorilẹede yii siwaju.
Adajọ agba Naijiria, Adajọ Tanko Muhammad lo pa aṣẹ naa lẹyin ti awọn oniṣẹ aabo ko lee kapa aduru ero to wa nibẹ ati ariwo pupọ ninu ile ẹjọ.
Adajọ Muhammad lo dari igbimọ igbẹjọ ẹlẹni meje to jẹ asan adajọ lati gbọ ẹsun awuyewuye to jẹyọ nibi ibo gomina ipinlẹ Bauchi, Kano, Sokoto, Plateau, Benue ati ipinlẹ Imo.
Ifa Priest: ọdún mọ́kànlá ni mo fi ṣe iṣẹ́ agbejọ́rọ̀ kí n tó gbọ́ràn si Ifá lẹ́nu
Ẹwẹ, lẹyin iṣẹju diẹ ti igbẹjọ bẹrẹ ni ijoko ile ẹjọ dide nigba ti wọn n gbọ ariwo ero to wa ninu ile ẹjọ ti wọn ko si le kapa rẹ ti adajọ si sun un siwaju di ọjọ kẹrinla, oṣu kinni, ọdun 2020.
Lati wa jẹ ki ero dinku, adajọ agba pasẹ pe ki awọn tọ́rọ̀ kan ma mu wa ju agbẹjọrọ marun un lọ.
Ni kete to si ti fun wọn laye lati ṣe ẹlẹri pe ijoko na bẹrẹ ni adajọ Muhammad paṣẹ pe ki wọn so igbẹjọ naa rọ na.
Lẹyin eyi wọn ni ki awọn oloṣelu ti ọrọ kankan o kan ṣugbọn to wa sile ẹjọ jade kuro ninu ile ẹjọ ti awọn ọlọpaa si lo aja lati ran wọ́n lọwọ ki ero le din ku.
Ṣaaju, oni ọjọ Aje lo yẹ ki ile-ẹjọ to ga ju lọ ni Naijiria dajọ awuyewuye to jẹyọ nibi ibo gomina awọn ipinlẹ naa.
Oludije fun ipo gomina labẹ asia ẹgbẹ oṣelu PDP, Abba Kabir Yusuf lo pe oludije ẹgbẹ oṣelu APC, Abdullahi Umar Ganduje to jawe olubori ninu ibo gomina ipinlẹ Kano lẹjọ.
Jide Kosọkọ: Isẹ́ tíátà yóò gòkè tíjọba bá gbówó kalẹ̀ láti seré
Ile ẹjọ kotẹmilọrun ti kọkọ dajọ pe ko si ẹri to daju to fidi rẹ mulẹ pe magomago wa ninu eto idibo to gbe Ganduje wọle.
Rogbodiyan nla bẹ silẹ lasiko idibo ati lẹyin idibo ọhun nipinlẹ Kano lẹyin tawọn ọdọ ti wọn jẹ alatilẹyin oludije ẹgbẹ oṣelu PDP yari pe Kabir Yusuf lo yẹ ko wọle ibo naa.
Ibo gomina Ipinlẹ Sokoto
Oludije ibo gomina fẹgbẹ oṣelu APC nipinlẹ Sokoto, Ahmad Aminu Waziri lo pe gomina Aminu Waziri Tambuwal to jawe olubori ninu ibo gomina ipinlẹ naa.
Amọ, ile ẹjọ kotẹmilọrun nipinlẹ naa ati ipinlẹ Kaduna da ẹjọ naa nun, eyi lo jẹ ki Aliyu mori le ile ẹjọ to ga julọ l'Abuja.
Koda, atundi ibo tiẹ wa nipinlẹ Sokoto ati Kano, amọ ibi pẹlẹbẹ naa ni ọbẹ fi lelẹ.
Eduardo: Mo ń jí mọ́tò pẹ̀lú àwọn ọ̀rẹ́ mi nítorí pé mo fẹ́ di 'Big boy'
Ibo gomina Ipinlẹ Imo
Oludije ibo gomina fẹgbẹ oṣelu APC nipinlẹ Imo, Hope Uzodimma naa yoo mọ lonii bo ya oun lo wọle ibo gomina ipinlẹ Imo.
Ile-ẹjọ kotẹmilọrun ti kọkọ da ẹjọ rẹ lẹyin to tako bi ajọ eleto idibo INEC ti kede gomina Emeka Ihedioha gẹgẹ bi ẹni to jawe olubori ninu eto idibo naa.
Ọbẹ̀ ni, ẹran ni o, irú oúnjẹ wo lẹ́ fẹ́, ká báa yín sè é wá sílé yín?
Ẹwẹ, gbajugbaja ọjiṣẹ Ọlọrun nipinlẹ Enugu, Fada Ejike Mbaka sọ asọtẹlẹ nipari ọdun 2019 pe ki Gomina Ihedioha palẹ ẹru rẹ mọ nitori Uzodimma ẹgbẹ APC yoo di gomina ipinlẹ Imo lọdun yii.
Omolola Ajayi ti bọ́ l'óko ẹrú lẹ́yìn tí ìjọba Nàìjíríà dá sí ọ̀rọ̀ rẹ̀
Oríṣun àwòrán, Abike Dabiri-Erewa
Omolola Ajayi lo wọ aṣọ otutu funfun laari awọn to duro ninu aworan yii.
Orilẹ-ede Naijiria ti doola ọmọbinrin kan, Omolola Ajayi, ti awọn kan ta si oko ẹru l'orilẹ-ede Lebanon.
Oludari ajọ to n ri si ọrọ awọn ọmọ Naijria nilẹ okeere, Abike Dabiri-Erewa lo fi ikede naa sita l'ori opo ayelujara Twitter rẹ nirọlẹ ọjọ aje.
"Ninu ikede naa, Arabinrin Dabiri-Erewa sọ pe ọmọbinrin yii ti wa ni ọdọ aṣoju Naijiria ni Beirut bayii, ti ""inu rẹ si dun lati wa ni ibi aabo""."
Fidio alaye ti arabinrin Ọmọlọla se ree, eyi to gba ori ayelujara kan. Ninu fidio naa, Omolola ṣalaye pe ẹnikan ti oun mọ lo tan oun lọ si orilẹ-ede Lebanon pe oun yoo ma ṣiṣẹ olukọ ede Gẹẹsi. Ṣugbọn, oko ẹru lo ta oun si.
Gomina ipinlẹ Kwara, Abdulrahman Abdulrazak koro oju si iwa fifi eeyan ṣe owo ẹru to n gogo sii lorilẹede yii.
Atẹjade kan ti amugbalẹgbẹ rẹ feto iroyin, Rafiu Ajakaye fi sita lorukọ gomina naa ṣe apejuwe iwa yii gẹgẹ bi ika si ọmọniyan eyi ti ko lee jẹ itẹwọgba rara.
Bakan naa lo tun ṣekilọ pe ẹnikẹni ti ọwọ ba tẹ pe o n san iru asọ yii ṣe oro ko ni lọ laijiya, ti onitọhun yoo si tun fi'mu kata ofin.
Atẹjade naa fi kun un pe inu gomina Abdulrahman ko dun rara si fọnran aworan to gbode nipa arabinrin Ọmọlọla Ajayi.
Oun ni wọn fi sọko lọ ṣe owo ẹru nilu Lebanon, ẹni ti awọn obi rẹ n gbe nilu Ilọrin, tii se olu ilu nipinlẹ Kwara.
Oríṣun àwòrán, @LiberateKwara
Gomina ti wa bu ẹnu atẹ lu iru iwa ika bayii, to si ti pasẹ fun awọn agbofinro lati tu isu de isalẹ ikoko lori isẹlẹ naa, ti ọwọ si ti tẹ awọn afurasi mẹta, ti wọn ni o n sọ nipa isẹlẹ naa.
Ifa Priest: ọdún mọ́kànlá ni mo fi ṣe iṣẹ́ agbejọ́rọ̀ kí n tó gbọ́ràn si Ifá lẹ́nu
Atẹjade naa fikun pe ọwọ ba Wasit Muhammed, tii se ọmọ orilẹ-ede Lebanon, Olatunji Sanusi, tii se agbẹjọro ati ẹnikan ti wọn pe orukọ rẹ ni Tunde.
Sugbọn wọn ni ọkunrin kan to n jẹ Joseph, toun naa mọ nipa bi wọn se fi Ọmọlọla se owo ẹru, lo ti na papa bora.
Ọbẹ̀ ni, ẹran ni o, irú oúnjẹ wo lẹ́ fẹ́, ká báa yín sè é wá sílé yín?
Iroyin ọhun fikun pe Gomina Abdulrahman ti wa n kan si awọn ileesẹ ijọba apapọ ti ọrọ fifi eeyan se owo ẹru kan, to fi mọ ileesẹ to wa fọrọ ilẹ okeere ati ajọ agbaye to n ri si iwa sise atipo loke okun, lati tete mọ bi wọn yoo se gba Ọmọlọla silẹ lọwọ awọn eeyan to mu sigbekun.
Eduardo: Mo ń jí mọ́tò pẹ̀lú àwọn ọ̀rẹ́ mi nítorí pé mo fẹ́ di 'Big boy'
Biafra at 50: Ọ̀nà tí ẹja panla gbà di gbajúgbajà nínú ìṣasùn nìyí
Oríṣun àwòrán, @others
Ẹja Panla to wọ Naijiria bii ounjẹ iranlọwọ nigba ogun Biafra lo ti di ounjẹ tolowo n gbadun bayii.
Ṣe o mọ ẹja Panla? Ṣaṣa lẹni to lee ni oun ko mọ ẹja Panla lorilẹ-ede Naijiria.
Lootọ awọn mẹkunnu ni a mọ ẹja yii mọ ni igba kan ṣugbọn bayii, awọn ọtọkulu paapaa ti n karamasiki ẹja yii bayii.
Bakare Mubarak: ọ̀pọ̀ èèyàn ló máa ń fẹ́ dúró sí ẹgbẹ́ mí tójú si máa n tì mí
Itan sọ wi pe, asiko ogun abẹle to waye laarin ọdun 1967 si 1970 fa ọpọlọpọ iyàn, iyẹn airi ounjẹ jẹ fawọn ọmọde ati agbalagba.
Ogun yii waye nigba ti awọn iran Igbo ni wọn fẹ ya kuro lara orilẹ-ede Naijiria ki awọn lọ da duro.
Bẹẹ, awọn alaṣẹ orilẹ-ede Naijiria lasiko naa yari pe awọn ko ni fi iran Igbo silẹ lati lọ da duro.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ọ̀nà tí ẹja panla gbà di gbajúgbajà nínú ìṣasùn nìyí
Iroyin sọ pe, ẹgbẹrun lọna ẹẹdẹgbẹta o din ogun, 480,000 lawọn ọmọde to fara kaaṣa iyan to mu lasiko naa.
Ida mọkanlelọgbọn ninu ọgọrun un, 31% lọjọ ori wọn ko ju ọdun ọdun marun un lọ.
Ọpọlọpọ obi lo si n foju ara wọn ri iku ọmọ wọn pẹlu ibanujẹ.
Ounjẹ jijẹ jẹ ara ohun to maa n fara gba nigba ogun jija.
Amọṣa, ogun abẹle to waye yii ati awọn wahala ọwọngogo ounjẹ to waye nipasẹ rẹ lo mu ki ọpọ awọn ajọ aṣeranwọ lagbaye o dide iranlọwọ.
Ifa Priest: ọdún mọ́kànlá ni mo fi ṣe iṣẹ́ agbejọ́rọ̀ kí n tó gbọ́ràn si Ifá lẹ́nu
Gẹgẹ bi itan ṣe sọ, lara awọn iranwọ ti ajọ aṣeranwọ lati orilẹ-ede Norway gbe kalẹ fun awọn ọmọde lagbegbe ile Igbo to n jagun Biafra ti aisan Kwaṣọkọ n ba finra nipasẹ airounjẹ jẹ lasiko ogun abẹle naa ni ẹja Panla.
Ẹja jẹ ara ohun amuṣọrọ fawọn eeyan orilẹ-ede Norway.
Ọbẹ̀ ni, ẹran ni o, irú oúnjẹ wo lẹ́ fẹ́, ká báa yín sè é wá sílé yín?
Ọpọ iran Igbo lo dupẹ lọwọ orilẹ-ede Norway fun bi wọn ṣe ko ẹja panla ranṣẹ lasiko ogun yii ki awọn ọmọ Biafra ma lọ ku tan nitori airi ounjẹ aṣaraloore jẹ.
Jide Kosọkọ: Isẹ́ tíátà yóò gòkè tíjọba bá gbówó kalẹ̀ láti seré
Bi o tilẹ jẹ wi pe ẹja Panla ti di wọọ kilu mọ ninu ikoko ọbẹ awọn ọmọ Naijiria, itan to gbee di odu ni iṣasun niyi.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Finance Bill: VAT di 7.5% láti 5% lẹ́yìn tí ààrẹ Buhari buwọ́lu àbá ètò ìnáwó
Oríṣun àwòrán, Twitter/Bashir Ahmad
VAT di 7.5% láti 5% lẹ́yìn tí ààrẹ Buhari buwọ́lu àbá ètò ìnáwó
Lẹyin ọ rẹyin, owo ori VAT ti di 7.5% lati 5% lẹyin ti aarẹ Muhammadu Buhari buwọlu aba eto inawo ọdun 2019 lonii ọjọ Aje.
Aba ọhun ati aba iṣuna ọdun 2020 ni ile aṣofin gbe lọ siwaju aarẹ papọ ki ọdun 2019 to pari.
Amọ, Buhari buwọlu aba eto inawo lẹyin ọjọ mẹtadinlọgbọn to ti kọkọ buwọlu eto iṣuna ọdun 2020.
Buhari sọ loju opo Twitter rẹ pe o jẹ idunnu fun oun lati buwọlu aba eto inawo nitori aba naa yoo ṣatunṣe ọrọ owo ori.
Aarẹ ni aba yii to ti di ofin ni yoo jẹ ki ilana owo ori sisan ni Naijiria wa ni ibamu pẹlu gbogbo agbaye.
Aarẹ Buhari ni eyi nigba akọkọ ti aba eto inawo yoo tẹle aba eto iṣuna lati rii pe gbogbo eto lọ bo to yẹ lati igba ti orilẹede Naijiria ti pada si ijọba awarawa lọdun 1999.
Ofin yii yoo tun mu ayipada ba owo ori epo rọbi, ibode, owo ori ọja tariifu, owo ori ile iṣẹ ati owo ori awọn araalu lapaapọ.
Pẹlu ofin ti aarẹ Buhari buwọlu yii, awọn ile iṣẹ ti ere wọn ko ba to miliọnu mẹẹdọgbọn ko ni maa san owo ori lori ere ti wọn ba jẹ mọ.
Ifa Priest: ọdún mọ́kànlá ni mo fi ṣe iṣẹ́ agbejọ́rọ̀ kí n tó gbọ́ràn si Ifá lẹ́nu
Bakan naa, owo ori tawọn ile iṣẹ ifowopamọ maa n yọ tẹlẹ lori ẹgbẹrun un kan naira yoo bẹrẹ lati ẹgbẹrun un mẹwaa naira bayii.
Eduardo: Mo ń jí mọ́tò pẹ̀lú àwọn ọ̀rẹ́ mi nítorí pé mo fẹ́ di 'Big boy'
Wasiu Ayinde: Ó pọn dandan fún Mayegun láti ri pé àláfíà jọba
Oríṣun àwòrán, Instagram/K1 the ultimate
Ó pọn dandan fún Mayegun láti ri pé àlaáfíà jọba
Ile Ọba Alaafin ti ilu Oyo ti sọ ipa ti Mayegun ti ilẹ Yoruba, Wasiu Ayinde yoo ma a ko ni ilẹ Yoruba.
Ọmọọba Alaafin, Bunmi Labiyi lọ sọ bẹẹ fun BBC Yoruba lasiko ti a n fi ọrọ wa a lẹnu wọ nipa iṣẹ ti ipo naa wa fun ni ilẹ Yoruba.
Labiyi ni ipa gboogi ti Maiyegunyoo ko ni lati ri wi alaafia to niye gbinlẹ ni ilẹ Yoruba.
Ti ija ba waye laarin ileto si ileto, tabi ipinlẹ si ipinlẹ, ẹtọ Maiyegun ni lati ri wi pe wọn wa opin si aawọ naa laarin ilu mejeeji.
Lẹyin naa ni yoo ri daju pe ibasẹpọ to dan mọran wa larin agbeegbe tabi ipinlẹ ti asọ tabi ija naa ti waye.
O fikun pe, Maiyegun naa ma n dunadura laarin awọn ọmọ Yoruba, lọna ati mu idẹru, alaafia, igbeleke asa ati alaafia gbilẹ si ni ilẹ Yoruba.
Oríṣun àwòrán, Instagram/saheedosupa
Alaafin ti Oyo to yan Wasiu Akande amyegun gẹgẹ bi Maiyegun ti ilẹ Yoruba naa lo sọ fun un pe oye ẹni to n gbe asa Yoruba ga,
Bakan naa ni wọn tun fikun pe oye Maiyegun ti Kayode Ajulo gba lọwọ aarẹ ọna kakanfo ni lati fi ṣisé.
Ọpọlọpọ ariyanjiyan lo tẹle Alaafin to yan Maiyegun tuntun sọ pe Wasiu ti ọpọ mọ si KWAM 1 ko ni dọbalẹ f'awọn ọba kan mọ lati oni lọ.
A moye yii jẹ na, iwo nna! Alaafin ti ilu Oyo, Oba Lamidi Olayiwola Adeyemi kẹta ti fi ilumọọka olorin Fuji, Alhaji Wasiu Ayinde jẹ oye Mayegun ilẹ Yoruba.
Oye naa ti kọkọ da ariyanjiyan silẹ lẹyin ti Alaafin sọ pe Wasiu ti ọpọ mọ si KWAM 1 ko ni dọbalẹ f'awọn ọba kan mọ lati oni lọ.
Amọ Alaafin ṣalaye pe awọn kan ti wọn n pe ara wọn lọba loun n sọ nipa awọn kii ṣe awọn ọba laye bi Ọọni Ile Ife, Awujalẹ ti ilẹ Ijẹbu, Owa Obokun Ileṣa, Alake ti ilẹ Ẹgba ati bẹẹ bẹẹ lọ.
Alaafin ni Wasiu ko to bẹẹ lati nawọ si iru awọn ọba nla bayii ti wọn ba pade lode.
Alaafin Oyo ṣalaye siwaju sii pe oun ko le ṣe nnkan to tako aṣa ati iṣe Yoruba laelae, o ni oye Mayegun wa ni ibamu pẹlu aṣa Yoruba.
Oríṣun àwòrán, Instagram/K1 the ultimate
O rọ awọn eeyan wi pe ki wọn ye oju opo ayelujara ni ilokulo, Ọba Alaafin ni ilokuko oju opo ayelujara lo jẹ kawọn kan ṣi oun gbọ lori ọrọ oye Mayegun.
Alaafin ni Wasiu gan lo beere fun oye Mayegun ni bi ọdun mọkanla sẹyin nigba to kan si oun laafin pẹlu awọn ọrẹ rẹ.
Alaafin ni oun kọkọ kọ eti ikun si ọrọ naa, lẹyin igba yii loun ṣe iwadii lẹmi ati lara ki oun to gba lati fi Wasiu jẹ oye naa.
Oríṣun àwòrán, Instagram/K1 the ultimate
Ọpọ olorin atawọn eeyan jankan jankan lo ti n ki K1 ku oriire oye Mayegun to ṣẹṣẹ jẹ.
Ọlọ́pàá Uganda rí ohun ìpara olóró nínú ‘baby’ tí ẹnìkan pọ́n sẹ́yìn bí ọmọ
Àwọn ọjọ́ ìsìnmi tó máa wà nínú ọdún 2020 ní Nàìjíríà
Ìjọba Nàìjíríà ti rí obìnrin tó wà l'óko ẹrú ní Lebanon gbà
Ẹ̀bùn ọdún tuntun tó yááyì ni ikọ̀ Amotekun - Soyinka
Ifa Priest: ọdún mọ́kànlá ni mo fi ṣe iṣẹ́ agbejọ́rọ̀ kí n tó gbọ́ràn si Ifá lẹ́nu
Ariwo kò jẹ́! A ti sún ìgbẹ́jọ́ Ganduje, Tambuwal àti Ihedioha sí ọ̀la
Imam tó fẹ́ ọkùnrin míì níyàwó forí kó ìjìyà òfin
Owó orí VAT di 7.5%  láti 5% lẹ́yìn tí ààrẹ Buhari buwọ́lu àbá ètò ìnáwó
Àwọn sẹ́nétọ̀ Nàìjíríà fa ìbínú yọ 'torí N2Miliọ̀nù owó àjẹmọ́nú Kérésì tí wọ́n fún wọn
Iṣẹ́ bọ lọ́wọ́ Ọgágun àgbà Niger lórí ìkọlù tó ṣékú pá ọmọ ogún 89
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Iṣẹ ti bọ lọwọ ọgagun agba ileeṣẹ ologun lorile-ede Niger lọjọ mẹrin sigba tawọn agbebọn pa eeyan mọ́kàndínláàdọ́rùn ún ni ẹka ileeṣẹ ọmọ ọlogun kan.
Eyi ni iye eeyan to pọju lọ to ku lọjọ kan ninu akọsilẹ ilẹ naa.
Lori redio ni wọn ti kede iyọninipo ọgagun Ahmed Mohammed ati awọn ọgagun mẹta miran lẹyin ipade igbimọ alaṣẹ.
Laarin ọdun meji ti ọgagun Mohammed ti wa nipo, niṣe ni ikọlu ti n waye lemọ lemọ pẹlu awọn ikọ agbesunmọmi alakatakiti ẹsin Islam to ni ajọṣepọ pẹlu al-Qaeda ati Islamic State (IS).
Ọgagun Salifu Modi ni wọn fi rọpọ rẹ bi wọn ṣe yọọ nipo tan.
Bakare Mubarak: ọ̀pọ̀ èèyàn ló máa ń fẹ́ dúró sí ẹgbẹ́ mí tójú si máa n tì mí
Ẹwẹ, orile-ede Niger ti kede idaro ọlọjọmẹta lati fi kẹdun iku awọn ọmọ ogun mọ́kàndínláàdọ́rùn ún to padanu ẹmi wọn ni ilẹeṣẹ ologun Chingedor camp ni iwọ oorun agbgbe Tillaberi.
Loṣu to kọja ọmọ ogun mọkanlelaadọrin ni awọn agbesunmọmi ṣeku pa nileeṣẹ ologun Inates camp lagbegbe kan naa.
Oríṣun àwòrán, Reuters
Lọwọlọwọ bayi, aarẹ ilẹ Niger, Mahamadou Issoufou ati awọn aarẹ agbegbe Sahel wa ni ilẹ Faranse nibi ipade pẹlu aarẹ Macron.
Ni ibẹrẹ ipade naa to n waye ni Pau, aarẹ Macron ati awọn olori orileede wọn yi ṣe ayẹsi fawọn ọmọ ogun to fẹmi wọn lelẹ ni Mali loṣu to kọja.
Ọgbẹni Macron ti beere pe ki awọn aarẹ wọn yi fi atilẹyin wọn hansi ikọ ọmọ ogun ilẹ Faranse ẹlẹgbẹrun mẹrin ti ọpọ n bẹnu atẹ lu tohun ti bi ipenija aabọ ti ṣe n peleke si.
Awọn olori orile-ede Chad, Mali, Niger, Burkina Faso ati Mauritania wa nibi ipade naa.
Ifa Priest: ọdún mọ́kànlá ni mo fi ṣe iṣẹ́ agbejọ́rọ̀ kí n tó gbọ́ràn si Ifá lẹ́nu
Aláàfin Ọyọ: Mí o ní kí Wasiu Ayinde má bọ̀wọ̀ fàwọn ọba ilẹ̀ Yorùbá ayafi...
Oríṣun àwòrán, Facebook/alaafinoyo
Mí o ní kí Wasiu Ayinde má bọ̀wọ̀ fàwọn ọba ilẹ̀ Yorùbá ayafi...
Ikubabayeye, Alaafin Ilu Oyo, Ọba Lamidi Adeyemi sọ pe Ọba ti o ba n mu ọti nita gbangba ko yẹ ni ni aa bọwọ fun .
Ọba Lamidi sọ ọrọ yi lasiko to n fi oye da Wasiu Ayinde Marshal lọla gẹgẹ bii Mayegun ilẹ Yoruba nilu Oyo.
Ninu alaye ọrọ rẹ paapaa lori pe oun ko ni ki ẹnikankan ri awọn Ọba fin, Kabiesi ni ''eyikeyi Ọba ti koba bọwọ fun ipo rẹ ti o si n mu ọti tabi to n jo nile igbafẹ ko yẹ lẹni apọnle''
Bakare Mubarak: ọ̀pọ̀ èèyàn ló máa ń fẹ́ dúró sí ẹgbẹ́ mí tójú si máa n tì mí
Lori ọrọ tawọn kan n sọ pe Alaafin ni ki Wasiu Ayinde ma dọbalẹ ki awọn Ọba kan, Alaafin ṣalaye pe ''Emi o ni ki Wasiu ma bọwọ faṣa Yoruba, yoo ṣe apọnle awọn Ọba ṣugbọn kii ṣe awọn ti ko fi ara wọn si ipo ọba''
Ifa Priest: ọdún mọ́kànlá ni mo fi ṣe iṣẹ́ agbejọ́rọ̀ kí n tó gbọ́ràn si Ifá lẹ́nu
Awọn Ọba wo gan an ni Wasiu ko le dọbalẹ fun?
Alaafin ko darukọ ọba kankan pe Mayegun ko gbọdọ bọwọ fun wọn ṣugbọn gẹgẹ awọn iwe iroyin Naijiria kan ti ṣe sọ, Alaafin ni oun ko sọ fun Wasiu Ayinde ko tabuku si awọn ọba bi Ooni Ife, Orangun Ila, Awujale Ijebu-Ode, Owa Obokun Ilesa, ati  Alake Egba pẹlu awọn miran to fi ara wọn si ipo ọwọ.
Bẹẹ naa ni Alaafin sọ pe Wasiu Ayinde ti beere fun oye Mayegun yii lati nkan bi ọdun mọkanla sẹyin ṣugbọn awọn Oyo Mesi ko faṣẹ si i nigba naa.
Alaafin pari ọrọ rẹ pe ki ẹnikẹni to ba ni ikunsinu pẹlu Wasiu lọ pari rẹ pẹlu rẹ.
''Ki wọn ma fi oju opo ayelujara maa fi doju ija kọ ara wọn''
Supreme Court: Ilé ẹjọ́ tó ga jùlọ ní Nàìjíríà yóò ṣe ìdájọ́ àwọn gómìnà meje lónìí
Kano Governorship: Ilé ẹjọ sún ìgbẹ́jọ Ganduje sí ogunjọ oṣù kíní
Ilé ẹjọ to ga jùlọ lórílẹ̀-èdè Naijiria, ti sún ìdájọ ẹjọ́ kòtẹmilọrun ti o jẹ́yọ láti ibi ètò ìdìbò gomínà ipinlẹ Kano.
Ìgbìmọ̀ ẹlẹni meje to adajọ àgba Nàjíríà Tanko Muhmmmad sojú lo mu ọjọ́ tuntun ọhun lọ́jọ́ iṣẹ́gun nilu Abuja lásìkò ìgbẹ́jọ kòtẹmilọrun ti olùdíje ẹgbk òṣèlú People's Democratic Party  (PDP) Abba Yusuf ninú ìdìbò ọjọ́ kẹsàn Oṣù kéta, ọdun 2019.
ilé ẹjọ ti fẹnukò láti pàdé ni ọjọ ajé Ogunjọ oṣù yiì'láti fẹnu ọ̀rọ̀ jana lóri ìdájọ náà lẹ́yin ti agbẹjọro rẹ̀ ti wijọ nínú ìpẹ̀jọ náà.
Awọn olùjẹ́jọ ni Gomina Gandujè ti ẹgbẹ́ òṣèlú APC àti àjọ elétò ìdìbò Naijiria (INEC).
Supreme Court: Ilé ẹjọ́ tó ga jùlọ ní Nàìjíríà a ṣe ìdájọ́ àwọn gómìnà meje lónìí
Oríṣun àwòrán, @others
Ilé ẹjọ́ tó ga jùlọ ní Nàìjíríà a ṣe ìdájọ́ àwọn gómìnà meje lónìí
Mukhtar Gidado to jẹ oluranlọwọ pataki si Gomina Bala Muhammed to n tukọ ipinlẹ Bauchi bayii lo fi atẹjade sita.
Ninu atẹjade naa ni wọn ti ṣalaye pé o rẹ gomina naa ni eyi ti wọn ti o ṣi n gba itọju lọwọ nile iwosan ni London bayii.
Gomina Bala Mohammed fohun ranṣẹ sawọn eniyan ipinlẹ Bauchi pe nitootọ lo rẹ oun ni London ṣugbọn ọkan oun balẹ pe didun lọsan a so fun oun ninu idajọ to n lọ lọwọ ni Abuja.
Awon agbejoro n pe agbejoro nise ni nile ejo laaro yii ni Abuja
Fọ́fọ́ ní ilé ẹjọ́ kún fún ìdájọ gomina ìpínlẹ̀ Kano, Imo, Sokoto, Benue, Plateau àti Bauchi
Ilé ẹjọ́ tó ga jùlọ ní Nàìjíríà a ṣe ìdájọ́ àwọn gómìnà mẹ́fà lónìí
Lana ni ile ẹjọ to ga julọ ni Naijiria sun idajọ awọn gomina mẹfẹẹfa naa si oni Ariwo kò jẹ́! A ti sún ìgbẹ́jọ́ Ganduje, Tambuwal àti Ihedioha sí ọ̀la
Awọn gomina ti ko wọle lo gbe awọn miran ti ajọ eleto idibo INEC kede lọ sile ẹjọ.
Ilé ẹjọ́ tó ga jùlọ ní Nàìjíríà a ṣe ìdájọ́ àwọn gómìnà mẹ́fà lónìí
Adajọ agba ni wọn so igbẹjọ naa rọ ni ana ọjọ Aje nitori pe ariwo ti pọju ati pe o rẹ ọkan ninu awọn adajọ to maa ṣe idajọ naa.
Loni ni wọn maa dajọ ipinlẹ Kano, Sokoto, Benue, Imo, Plateau , Bauchi ati Adamawa.
Ortum fun ra re naa wa ni ikale lati gbo iidajo boya ko tesiwaju tabi bee ko
Awọn agbẹjọro ti kun ile ẹjọ lati ṣoju awọn gomina mẹfẹẹfa ati awọn to pe wọn lẹjọ.
Adajọ meje ati Adajọ Tanko Mohammed to jẹ olori awọn adajọ Naijiria naa ti wa ni ikalẹ fun idajọ naa.
Awon agbejoro ti wa ni ikale
Wo awon to n soju awon Gomina mẹfẹẹfa nile ẹjọ ni Abuja lonii.
Ero kun fọfọ ni lati mọ ibi ti ọrọ Ganduje, Ihedioha, Tambuwa, Ortom maa ja si lonii
awon agbejoro ti setan
Ẹwẹ, lẹyin iṣẹju diẹ ti igbẹjọ bẹrẹ ni ijoko ile ẹjọ dide nigba ti wọn n gbọ ariwo ero to wa ninu ile ẹjọ ti wọn ko si le kapa rẹ ti adajọ si sun un siwaju di ọjọ kẹrinla, oṣu kinni, ọdun 2020.
Lati wa jẹ ki ero dinku, adajọ agba pasẹ pe ki awọn tọ́rọ̀ kan ma mu wa ju agbẹjọrọ marun un lọ.
Gbogbo eto lo ti to ni sẹpẹ loni nile ẹjọ ni Abuja.
Awon ololufe awon gomina mefeefa na ti wa ni ikale
Awon eniyan onikaluku naa ti wa ni ikale lori idajo toni yii.
Agbejoro n pe agbejoro ran nise ni loni nile ẹjo ni Abuja
Ibo gomina Ipinlẹ Sokoto
Oludije ibo gomina fẹgbẹ oṣelu APC nipinlẹ Sokoto, Ahmad Aminu Waziri lo pe gomina Aminu Waziri Tambuwal to jawe olubori ninu ibo gomina ipinlẹ naa.
Bakare Mubarak: ọ̀pọ̀ èèyàn ló máa ń fẹ́ dúró sí ẹgbẹ́ mí tójú si máa n tì mí
Amọ, ile ẹjọ kotẹmilọrun nipinlẹ naa ati ipinlẹ Kaduna da ẹjọ naa nun, eyi lo jẹ ki Aliyu mori le ile ẹjọ to ga julọ l'Abuja.
Koda, atundi ibo tiẹ wa nipinlẹ Sokoto ati Kano, amọ ibi pẹlẹbẹ naa ni ọbẹ fi lelẹ.
Awon agbejoro gan an po de ibi pe o dabi ajo ironupiwada ni won pe nile ejo Abuja loni ni
Ibo gomina Ipinlẹ Imo
Oludije ibo gomina fẹgbẹ oṣelu APC nipinlẹ Imo, Hope Uzodimma naa yoo mọ lonii bo ya oun lo wọle ibo gomina ipinlẹ Imo.
Kakiri Naijiria ni awon agbejoro wonyii ti jade wa soju awon onibara won lotunlosi
Ile-ẹjọ kotẹmilọrun ti kọkọ da ẹjọ rẹ lẹyin to tako bi ajọ eleto idibo INEC ti kede gomina Emeka Ihedioha gẹgẹ bi ẹni to jawe olubori ninu eto idibo naa.
Ifa Priest: ọdún mọ́kànlá ni mo fi ṣe iṣẹ́ agbejọ́rọ̀ kí n tó gbọ́ràn si Ifá lẹ́nu
EFCC: EFCC mú Ọmọ ọdún 17, afurasí mẹ́jọ tó ń ṣe yahoo-yahoo ní Íbàdàn
Oríṣun àwòrán, @officialEFCC
EFCC mú Ọmọ ọdún 17, afurasí mẹ́jọ tó ń ṣe yahoo-yahoo ní Íbàdàn
Ọwọ ajọ to n gbogun ti iwa ijẹkujẹ lorilẹ-ede Naijiria, EFCC ti tẹ ọmọ ọdun mẹtadinlogun kan ti wọn ni wọn gbamu fun ẹsun lilu jibiti lori ayelujara, iyẹn yahoo-yahoo.
Opin ọsẹ to kọja ni ẹka ajọ naa to wa ni ilu Ibadan mu ọdọmọkunrin naa ti wọn pe orukọ rẹ ni Abdulrahaman Qozeem atawọn mẹjọ miran kaakiri ilu Ibadan.
Gẹgẹ bi ajọ EFCC ṣe ṣalaye, ọwọ tẹ awọn eeyan naa lẹyin ọpọ iwadii lori iwa ọdaran yahoo-yahoo ti wọn yan laayo.
Oríṣun àwòrán, @officialEFCC
EFCC mú Ọmọ ọdún 17, afurasí mẹ́jọ tó ń ṣe yahoo-yahoo ní Íbàdàn
Gẹgẹ bi wọn tun ṣe fi kun un, awọn ohun ini olowo iyebiye bii ọkọ ayọkẹlẹ mẹfa pẹlu oniruuru ẹrọ ibanisọrọ, kọmputa alagbeka, iwe irinna silẹ okeere atawọn iwe miran to jẹ ayederu iroyin ni wọn ba lọwọ awọn afurasi naa nigba ti ilẹ mọ ba oloro wọn nita gbangba.
Bakare Mubarak: ọ̀pọ̀ èèyàn ló máa ń fẹ́ dúró sí ẹgbẹ́ mí tójú si máa n tì mí
Naira Marley: Naira Marley moribọ, ilé ẹjọ́ tú ẹ̀sùn ìjọ́kọ̀gbé tí wọ́n fi kàn án ká
Oríṣun àwòrán, Naira Marley/ instagram
Naira Marley moribọ, ilé ẹjọ́ tú ẹ̀sùn ìjọ́kọ̀gbé tí wọ́n fi kàn án ká
Naira Marley, gbajugbaja olorin taka sufe ni ti bọ lọwọ bebe ẹwọn to n rin fun igba diẹ bayii lori ẹsun jiji ọkọ gbe ti wọn fi kan an.
Arakunrin kan ti orukọ rẹ n jẹ Ademọla Adelekan lo fi ẹsun kan Naira Marley atawọn ọbakan rẹ mẹta pe wọn ji ọkọ oun gbe.
Ni ọjọ Iṣẹgun ni igbẹjọ naa waye lẹyin ti adajọ majisireeti to n gbọ ẹjọ ọhun ti fi aṣẹ lelẹ nigba igbẹjọ to kọja pe ki awọn ọlọpaa waa kan ki wọn si gbe e lọ soko ẹwọn nigba to kuna lati fara han niwaju ile ẹjọ naa.
Bakare Mubarak: ọ̀pọ̀ èèyàn ló máa ń fẹ́ dúró sí ẹgbẹ́ mí tójú si máa n tì mí
Amọṣa ọrọ yi pada nigba ti Agbẹjọro fun Naira Marley, Ayọdeji Awokulẹhin ṣalaye fun ile ẹjọ pe ẹsun ti wọn kan an ko lẹsẹ nilẹ ati pe ọkọ ti wọn n sọrọ rẹ naa ti di titun ṣe.
Nigba to n sọrọ lori idi ti Naira Marley ko fi si nile ẹjọ, amofin Awokulẹhin ni ko si lorilẹ-ede Naijiria lo faa.
'Mo fọ́ lójú ṣùgbọ́n mo mọ gbogbo irinṣẹ́ tí mo fi ń ṣe mọkalíìkì'
Ọgbẹni Ademọla Adelekan to fi ẹsun kan Naira Marley ṣalaye pe Naira Marley atawọn ọbakan rẹ lu oun, wọn si ba ọkọ rẹ jẹ ṣugbọn oun ṣetan lati jawọ ninu ẹjọ naa.
Ifa Priest: ọdún mọ́kànlá ni mo fi ṣe iṣẹ́ agbejọ́rọ̀ kí n tó gbọ́ràn si Ifá lẹ́nu
Ẹsun mẹrin to da lori igbimọpọ huwa ọdaran, ole ati lilu eeyan pẹlu didi ọlọpaa lọwọ mimu Naira Marley ni opopona Eko Hotel ni ọjọ karundinlogun, oṣu kejila, ọdun 2019 ni wọn fi kan an.
Lẹyin ti igbẹjọ naa waye ni adajọ Majisireeti, Tajudeen Elias wọgi le ẹjọ naa, to si ni ki Naira Marley maa lọ ni alaafia.
Toyosi Arigbabuwo: Iṣẹ́ aránṣọ̀ ló ń ṣe níbẹ̀rẹ̀ kó tó yà sí iṣẹ́ tíátà
Oríṣun àwòrán, Toyọsi Arigbabuwo
Bi ọdẹ ba ku, ọdẹ nii soro lẹyin ọdẹ, baa ba si ku laa di ere, eeyan kii sunwọn laaye, bẹẹ ni ọrọ ri pẹlu iku Oloye Toyosi Arigbabuwo to dagbere faye.
Ọpọ awọn ọrẹ rẹ ti wọn dijọ n sisẹ tiata ni wọn ti n salaye nipa iru eeyan ti Arigbabuwo jẹ ati bo se lo igbe aye rẹ nigba to wa loke eepẹ.
Nigba to n ba BBC Yoruba sọrọ, ọkan lara awọn ọrẹ timọtimọ Toyọsi Arigbabuwo ti wọn jọ n sisẹ tiata, Alhaji Musiliu Dasọfunjo salaye pe Arigbabuwo jẹ akikanju eeyan pupọ pupọ.
Oríṣun àwòrán, Toyọsi Arigbabuwo
Isẹ aransọ ni Toyọsi kọkọ kọ nigba aye rẹ ko to ya si idi isẹ tiata, to si n fi ẹsa ẹkun iyawo kewi, eyi ti awọn eeyan mọ si, ko to wa da ẹgbẹ tiata tiẹ silẹ taa mọ Toyọsi Arigbabuwo Theather Group ni adugbo Alekusọ-Oritamẹrin nilu Ibadan.
Oloogbe Sẹgun Olubukun, toun naa jẹ ilumọọka osere ori itage ni ọga to kọ Arigbabuwo ni isẹ tiata.
Lẹyin ti Arigbabuwo si da ẹgbẹ tiata tiẹ silẹ lo bẹrẹ si ni se ere fun ileesẹ mohunmaworan ijọba apapọ lasiko to wa ni WNTV ko to wa di NTA bayii.
O to si tun maa n kewi fun awọn ileesẹ Redio kaakiri, paapa ni Radio Nigeria to wa nilu Ibadan to fi mọ awọn eto miran lorisirisi.
Ti a ba si n sọrọ nipa ihuwasi oloogbe Arigbabuwo, Dasọfunjo ni o jẹ onisuuru pupọ pupọ, ti kii ba eeyan kankan ja, ti ohunkohun kii si bi ninu, paapa ninu isẹ tiata.
Dasọfunjo salaye pe 2018 ni Arigbabuwo kọkọ bẹrẹ aisan, to si se isẹ abẹ nile iwosan UCH, amọ aisan yii tun pada lọdun 2019, to si tun se isẹ abẹ fun igba keji, lẹyin eyi si ni ko lee jade sita mọ titi ti ọlọjọ fi de baa.
Oríṣun àwòrán, Toyosi Arigbabuwo
Nigba to n sọrọ lori ipa ti ẹgbẹ awọn osere tiata ko lati seranwọ fun Arigbabuwo lasiko to wa lori idubulẹ aisan, Dasọfunjo ni ohun ko lee sọ pato ohun ti ẹgbẹ Tanpan abi ANTP se lati ran Arigbabuwo lọwọ.
Amọ o ni ẹnikọọkan gẹgẹ bii ọrẹ Arigbabuwo lo dide lati sa ipa tiẹ fi seranwọ fun oloogbe naa.
Dasọfunjo ni manigbagbe ni Arigbabuwo jẹ ninu isẹ tiata, to si ti kọ ọpọ eeyan nisẹ tiata, koda ọkan lara wọn ti di ọjọgbọn ni ọgba fasiti bayii.
O wa fọwọ gbaya pe awọn ti n seto lati da ajọ alaanu kan silẹ, taa mọ si Foundation loruks oloogbe Toyọsi Arigbabuwo, eyi ti wọn yoo maa fi se iranti rẹ, ko maa ba parun.
Oríṣun àwòrán, Toyosi Arigbabuwo
Bakan naa, ọrẹ minu miran fun Arigbabuwo ninu isẹ tiata, Gbọlagade Akinpẹlu, tawọn eeyan mọ si Ogun Majek naa sọ tẹdun tẹdun fun BBC Yoruba pe, isẹ tiata ye daada, o lee sere, o lee kọrin, to si tun lee kewi.
O ni Arigbabuwo jẹ eeyan jẹjẹ, ti kii fa wahala lẹsẹ abi se ijangbọn ti awsn yoo si maa ranti rẹ fun ọgbọn to maa fi n pari ija laarin ẹgbẹ ati sna alaafia to maa n san laarin awọn eeyan.
Iku doro, iku ti sika, iku tun ti mu ọkan lara awọn ọlọpọlọ pipe, osere ori itage, Toyosi Arigbabuwo lọ.
Iroyin to tẹ wa lọwọ salaye pe irọlẹ ọjọ Aje ni Toyọsi mi kanlẹ lẹyin aisan olosu mẹfa to ti n baa finra, ti okiki si gbalẹ kan lasiko kan pe o wa lori aisan nile iwosan nla UCH nilu Ibadan.
Toyọsi Arigbabuwo, ẹni ti wọn bi soke eepẹ lọjọ kẹta osu Kẹta ọdun 1948, eyiun ọdun mejilelọgọta sẹyin, lasiko to wa loke eepẹ jẹ ilumọọka nidi isẹ tiata, to si maa n fi ẹkun iyawo dabira lasiko ere sise.
Bakare Mubarak: ọ̀pọ̀ èèyàn ló máa ń fẹ́ dúró sí ẹgbẹ́ mí tójú si máa n tì mí
O maa n ke ewi, to si tun jẹ ẹni to gbe ẹsin Islam sori titi to fi tẹri gbasọ, koda oun ni alarina fun ẹgbẹ awọn musulumi to wa lagbegbe Apẹtẹ-Awọtan nilu Ibadan.
Ọsan oni ni wọn yoo fi ara rẹ fun ilẹ nile rẹ to wa ni Awọtan nilu Ibadan
YCE: Ìpínlẹ kọ̀ọ̀kan ní àṣẹ láti dá ààbò bo àwọ̀n ènìyàn wọn
Ìpínlẹ kọ̀ọ̀kan ní àṣẹ láti dá ààbò bo àwọ̀n ènìyàn wọn
Ẹgbẹ to n risi idagbasoke ilẹ Yoruba, Yoruba Council of Elders ti bu ẹnu ẹ̀tẹ́ lu ohun ti agbejọro ijọba sọ lori idasilẹ ikọ Amọtẹkun to wa fun eto aabo ilẹ Yoruba.
Akọwe ẹgbẹ YCE, Dokita Kunle Olajide lọ sọ wi pe o ku diẹ kaatọ lori ọrọ ti agbẹjọro agba fun ijọba apapọ sọ.
Sunday Igboho: Fulani kò leè dúró, táa bá lo ohun ta jogún lọ́dọ̀ àwọ̀n bàbá wa
O ni iwe ofin ilẹ wa faaye gba ipinlẹ kọọkan pẹlu aṣẹ lati da aabo bo awọn ara agbegbe rẹ labẹ iṣejọba alagbada.
Dokita Olajide ni labẹ ofin, ohun ti ijọba sọ ko bojumu nitori ijọba tiwantiwa la n ṣẹ, ti onikaluku si ni ẹt lati da aabo bo ara wọn, igbimọ kọọkan ni ẹtọ lati da abo bo ara wọn.
Malami ní ìjọba àpapọ̀ nìkan ló ni ojúṣe ètò ààbò
Bakan naa ni agbajọwọ eniyan lẹtọ lati daabo bo ara wọn.
O fikun un wi pe awọn Gomina ti awọn eniyan dibo yan lẹtọ lati pejọ, ki wọn wa ọna lati ri i wi pe aabo to daju wa fun awọn eniyan ilẹ ati agbegbe wọn.
Akọwe ẹgbẹ YCE naa ni igbeṣẹ ti awọn yoo gbe yoo waye lẹyin ti awọn ba ṣẹ iwadii finifini lori boya ijọba n takọ ikọ Amọtẹkun patapata ti wọn si n lero pe ki wọn tu wọn ka.
BIAFRA at 50: Ìhàlẹ̀ ológun ni Gowon ni ká kọ́kọ́ fi bẹ̀rẹ̀- Aladejẹbi
O ni ohun to difa fun wi pe ijọba fi aaye gba ikọ Sharia ti o ti wa ni awọn ipinlẹ kọọkan ni Ariwa orilẹ-ede Naijira fun ọpọlọpọ ọduin, ati ọlọpaa Hisbah ti wọn ko si se nkan ti ko tọ si wọn.
Naa lo difa fun awọn Amọtẹkun ti awọn gomina gbe kalẹ lati maa ran awọn ọlọpaa lọwọ.
Abubakar Malami ni kò si Gómìnà, yálà ẹyọ kan tàbi lápapọ̀, to ni ẹ̀tọ láti ṣe ìdásílẹ̀ àjọ kankan to níi ṣe pẹ̀lú èètò ààbo.
Ìjọba orilẹ̀-èdè Naijiria ti ṣe àfiwe ẹgbẹ́ ààbò tuntun ti àwọn gómìnà ẹkun ìwọ̀ òòrun Naijiria dá sílẹ̀ Àmọ̀tẹ́kùn bíi èyí ti wọ́n dá sílẹ̀ lọ́nà ti kò bá òfin mú.
Agbẹjọ́rò àgbà fún ìjọba àpapọ̀ Abubakar Malami (SAN) sàlàyé pé, ọ̀rọ̀ ààbò jẹ ojúṣe ìjọba àpapọ níkàn ni.
Nínú àtẹjáde ti olubadamọ̀ràn pàtàkì lóri igbòhùn sáfẹ́fẹ́ rẹ, Umar Gwandu fọwọ́sí sàlàyé pe, Àmọtẹ́kùn kìí ṣe èyi to ba òfin orilẹ̀-èdè Naijiria mu.
"Àtẹjáde náà ka bayìí pé "" ìwé òfin orílẹ̀-èdè Naijiria ti ọdun 1999 ti fi idí rẹ̀ múlẹ̀ pé, ọmọogun orilẹ̀, ọmọogun ojú omi, àti ọmọ omọogun ojú ofurufu, ọlọpàá àti àwọn to farapẹ́ nìkàn lo wà fún ètò ààbò Naijiria."""
Bakare Mubarak: ọ̀pọ̀ èèyàn ló máa ń fẹ́ dúró sí ẹgbẹ́ mí tójú si máa n tì mí
"Nítori ìdí èyí kò si Gómìnà yálà ẹyọ kan tàbi lápapọ̀ to ni ẹ̀tọ tàbi agbára láti ṣe ìdásílẹ̀ ilé iṣẹ́ tàbí àjọ kankan to níṣe pẹ̀lú èètò ààbo.
Ìpínlẹ kọ̀ọ̀kan ní àṣẹ láti dá ààbò bo àwọ̀n ènìyàn wọn
Amotekun: Igboho ṣe káre fáwọn gómìnà Yorùbá pé wọ́n fi ohùn kan sọ̀rọ̀ fún ìgbà àkọ́kọ́
Akọni ọmọ Oodua kan, Sunday Majasọla Adeyẹmọ, ti gbogbo eeyan mọ si Sunday Igboho ti fọwọ gbaya pe oun yoo se atilẹyin fun eto Amotekun.
Oríṣun àwòrán, Sunday Igboho
Atẹjade kan ti Igboho fisita fun awọn akọroyin nilu Ibadan salaye pe awọn gomina ilẹ Yoruba fi ohun kansoso sọrọ fun igba akọkọ lori agbekalẹ eto Amọtekun, idi si ree ti oun yoo fi sa ipa oun lati sugba eto naa.
Ifa Priest: ọdún mọ́kànlá ni mo fi ṣe iṣẹ́ agbejọ́rọ̀ kí n tó gbọ́ràn si Ifá lẹ́nu
Bakan naa lo fikun pe ohunkohun to ba kan iran Yoruba lapapọ lo kan oun naa, ti eto to wa fun ipese aabo to peye naa yoo si mu ilọsiwaju ati idagbasoke ba awujọ ati gbogbo ọmọ ilẹ Kaarọ oojire lapapọ.
Igboho gbosuba fun awọn gomina to wa lẹkun iwọ oorun guusu Naijiria pe wọn se ara wọn ni osusu ọwọ lori eto yii lai fi oniruuru ẹgbẹ oselu ti wọn wa se, eyi to fihan araye pe wọn nifẹ awọn araalu lọkan.
O wa salaye pe eto Amotekun ko ni ohunkohun se pẹlu ẹgbẹ oselu kankan, bẹẹ lo si kọja agbara ẹda kankan, idi si ree ti gbogbo ọmọ Yoruba fi gbọdọ ri eto naa gẹgẹ bii ipe lati sin ilẹ abinibi wa."""
"'A rí wàhálà táwọn èèyàn ń kojú nilẹ̀ẹ̀ Yorùbá la ṣe fi ""Amotekun"" fi ọkàn wọn balẹ̀'"
Sunday Igboho wa kesi awọn ọmọ ẹgbẹ OPC, Fijilante atawọn eeyan miran to ni nkan se ninu ipese eto aabo labẹ Amotekun lati fi ọpọlọ se e, ki wọn si ri daju pe wọn ko tẹ ẹtọ awọn araalu mọlẹ.
Imo Supreme Court: Fada Mbaka kéde pé ẹ̀mí mímọ́ ti kọ Ihedioha bíi gómìnà Imo
Oríṣun àwòrán, Fada Ejike Mbaka
Fada Mbaka kéde pé ẹ̀mí mímọ́ ti kọ Ihedioha bíi gómìnà Imo
Ọjọ aisun ọdun tuntun, iyẹn ọjọ Kọkanlelọgbọn, osu Kejila, ọdun 2019, lasiko isin ti wọn fi n ki ọdun tuntun kaabọ ninu ijọ Adoration Ministry to wa nilu Enugu, ni asọtẹlẹ nla kan ti waye.
Oludari agba fun ijọ naa, Fada Ejike Mbaka ti tẹnumọ pe asọtẹlẹ ti oun n sọ nipa gomina ipinlẹ Imo, Emeka Ihedioha gbọdọ wa si imusẹ ni, eyi to ti pada wa sẹ bayii Ṣé àsọtẹ́lẹ̀ ìjàmbá iná kò tíì máa ṣe báyìí?.
Mbaka ni ẹmi mimọ lo sọ fun oun pe oludije fun ipo gomina fẹgbẹ oselu APC, Hope Uzodinma ni yoo pada wa yẹ aga mọ gomina to wa nipo naa lọwọ nidi ninu ọdun tuntun.
Fada Mbaka kéde pé ẹ̀mí mímọ́ ti kọ Ihedioha bíi gómìnà Imo
Lasiko ti asọtẹlẹ naa waye, ẹjọ ti Uzodinma pe lati tako esi ibo to gbe Ihedioha wọle si wa nile ẹjọ.
Amọ, ojisẹ Ọlọrun ninu ijọ Katoliki naa n tẹnumọ pe gbogbo awọn eeyan to n yọ suti ete si ohun lori asọtẹlẹ naa, ni yoo pada wa yin oun lawo lẹyin to ba sẹ tan.
Nigba to tun di ọjọ isinmi akọkọ ninu ọdun tuntun ni Mbaka tun ke tantan pe ki gomina Ihedioha maa palẹ ẹru rẹ mọ nile ijọba nitori gomina tuntun maa to de.
Bakare Mubarak: ọ̀pọ̀ èèyàn ló máa ń fẹ́ dúró sí ẹgbẹ́ mí tójú si máa n tì mí
Mbaka ni ẹmi mimọ ti kọ gomina Ihedioha, ti ireti tuntun pẹlu asia ọtun yoo si duro nile ijọba ipinlẹ Imo laipẹ.
"Mbaka ni ""Emi ko mọ bi asọtẹlẹ yii yoo se di mimusẹ, sugbọn ohun kansoso ti mo ri ni ireti, ayọ ati ijọba tuntun nipinlẹ Imo. Koda bi Ihedioha bori nile ẹjọ kekere ati ti ileẹjọ Kotẹmilọrun, eyi ko tumọ si pe yoo bori nile ẹjọ to ga julọ."""
"'A rí wàhálà táwọn èèyàn ń kojú nilẹ̀ẹ̀ Yorùbá la ṣe fi ""Amotekun"" fi ọkàn wọn balẹ̀'"
Asọtẹlẹ naa si ti wa si imusẹ nirọlẹ ọjọ Isẹgun nigba ti ile ẹjọ to ga julọ nilẹ Naijria kede pe gomina Emeka Ihedioha kọ lo moke ninu ibo gomina, Hope Uzodinma ni
Ileẹjọ naa ni ki wọn bura lọgan fun gomina tuntun, Hope Uzodinma, lati gba ipo Ihedioha lọgan.
Ile ẹjọ to ga julọ nilẹ wa ti kede pe ofuutu fẹẹtẹ, aasa ti ko ni kanhun ni ibo to gbe gomina ipinlẹ Imo, Emeka Iheodiha wọle.
Irọlẹ ọjọ Isẹgun ni igbimọ ẹlẹni meje nile ẹjọ to ga julọ nilẹ wa, ti adajọ Tanko Muhammad ko sodi, dijọ panupọ kede pe oludije fun ẹgbẹ iselu APC, Hope Uzodinma lo moke ninu ibo gomina to waye nipinlẹ naa lọjọ kẹsan an, osu Kẹta, ọdun 2019.
Oríṣun àwòrán, Hope Uzodinma
Adajọ Kudirat Kekere Ẹkun to ka idajọ alajumọse naa wa pasẹ pe ki wọn gba iwe ẹri moyege ibo ti wọn fun Ihedioha lọgan.
Bakan naa lo tun pasẹ pe ki wọn gbe iwe ẹri moyege ibo tuntun fun Hope Uzodinma loju ẹsẹ, ki wọn si bura fun un lọgan.
Bẹẹ ba gbagbe, laipẹ yii ni alufa ijọ Aguda kan, Fada Mbaka sọ̀ asọtẹlẹ pe ile ẹjọ to ga julọ yoo yẹ aga mọ gomina Ihedioha nidi.
Ifa Priest: ọdún mọ́kànlá ni mo fi ṣe iṣẹ́ agbejọ́rọ̀ kí n tó gbọ́ràn si Ifá lẹ́nu
Biafra at 50: Ó tó mílíọ̀nù mẹ́ta èèyàn tó bá ogun náà lọ
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ọgagun Odumegwu Ojukwu n sọrọ nibi ipade alaafia laarin Biafra ati Naijiria. Oun lo pe fun Biafra
Ogun abẹle ni Naijiria, ti a tun mọ si ogun Biafra, waye laarin ijọba orilẹ-ede Naijiria ati awọn ípinlẹ Biafra to yapa laarin ọjọ kẹfa, oṣu Keje, ọdun 1967 si ọjọ kẹẹdogun, oṣu Kinni, ọdun 1970.
Oni ọjọ Aje gan si lo pe ọdun mẹtalelaadọta ti ogun abẹle Baifra naa bẹrẹ.
Ogun naa bẹrẹ nitori ikunsinu lori ọrọ oṣelu, ọrọ aje, ẹya, àṣà, ati ẹsin to ti wa nilẹ ṣaaju ki orilẹ-ede Britain to o tu Naijiria silẹ l'oko ẹru lọdun 1960.
Ohun to fa ogun naa ni pato l'ọdun 1966 ni ija ẹlẹyamẹya ati ẹsin to waye ni apa Ariwa Naijiria, iditẹ gbajọba, ati bi awọn kan ṣe gbogun ti awọn ẹya Igbo to n gbe ni apa Ariwa Naijiria.
Bakan naa ni ija lori ẹni ti yoo maa ṣakoso ipese epo-rọbi to wa ni agbegbe Niger Delta, naa ko ipa pataki.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Awọn to fi ara wọn silẹ lati jagun fun orilẹ-ede Biafra
Ni nkan bi ọdun 1940 si 1950, awọn ẹgbẹ oṣelu nilẹ Yoruba ati Igbo lo n lewaju ija fun ominira kuro lọwọ orilẹ-ede Britain. Wọn si tun n fẹ ki Naijiria o jẹ pipin si ipinlẹ kekeeke.
Amọ awọn akọsilẹ kan sọ pe igbesẹ wọn yii ko dun mọ awọn olori apa Ariwa lọrun, ti wọn si n bẹru pe ominira yoo fi agbara fun awọn to wa ni Gusu lati maa dari ọrọ aje ati oṣelu. Eyi mu ki wọn o faramọ iṣejọba orilẹ-ede Britain.
BIAFRA at 50: Ìhàlẹ̀ ológun ni Gowon ni ká kọ́kọ́ fi bẹ̀rẹ̀- Aladejẹbi
Eyi mu ki awọn olori ni Ariwa o sọ pe ki orilẹ-ede Naijiria o wa ni pinpin si ẹkun mẹta nikan lo le mu ki awọn o faramọ ominira, ki Ariwa si ni agbegbe to pọju.
Afojusun awọn olori ẹya Yoruba ati Igbo lati gba ominira, mu ki wọn o faramọ ibeere awọn eniyan Ariwa.
Gomina ologun ni agbegbe Gusu-Ila oorun, Ọgagun Odumegwu Ojukwu, ati ile aṣofin agbegbe naa kede pe agbegbe Guusu-Ila oorun ti yapa kuro lara orilẹ-ede Naijiria, nitori bi wọn ṣe pa awọn eniyan ẹya Igbo ni ipakupa ni agbegbe Ariwa, ati mago-mago eto idibo.
Wọn kede pe Biafra ni awọn yoo maa pe orilẹ-ede tuntun naa; orilẹ-ede olominira, ni ọgbọnjọ, oṣu Karun un, ọdun 1967.
Ọpọlọpọ ipade lo waye laarin ijọba Naijiria ati awọn olori Biafra, paapa eyi to waye ni Aburi, l'orilẹ-ede Ghana (Aburi Accord).
Abajade ati adehun ti wọn fẹnuko le ni ipade alaafia naa f'oriṣanpọn, ogun si bẹrẹ.
Bakare Mubarak: ọ̀pọ̀ èèyàn ló máa ń fẹ́ dúró sí ẹgbẹ́ mí tójú si máa n tì mí
Ijọba Naijiria ko awọn ọlọpaa sita lati gba agbegbe to yapa pada.
Ọjọ kẹfa, oṣu Keje, ọdun 1967, si ni ogun naa bẹrẹ ni pẹrẹwu, nigba ti awọn ọmọ ogun Naijiria gba ọna meji wọ ilẹ Biafra.
Wọn gba Ariwa ilẹ Biafra ati ilu Nsukaa wọle. Ọna meji si ni wọn pin awọn ọmọ ogun si.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Awọn ọmọ ogun Biafra n yẹ awọn ibọn wọn wo ni imura silẹ
Amọ ṣa, awọn ọmọ ogun Biafra naa fi ija da orilẹ-ede Naijiria lohun nigba ti wọn wọ Iwọ-oorun Naijiria lọjọ kẹsan an, oṣu Keje.
Ilu Benin ni wọn gba wọle, ko to o di pe awọn ọmọ ogun da wọn duro ni ilu Ọrẹ lọjọ kọkanlelogun, oṣu Kẹjọ.
Wọn ko fi bẹ ni idojukọ kankan ni awọn agbegbe to yi ilẹ Yoruba ka, nitori naa ni wọn ṣe gba agbegbe naa.
Bo tilẹ jẹ wi pe ijọba Naijiria pada gba ilu Benin pada ni ogunjọ, oṣu Kẹsan an, awọn eniyan Biafra mu ipinnu wọn ṣẹ nipa kikapa awọn ọmọ ogun Naijiria kan.
Laarin ọdun kan ti ogun naa bẹrẹ, ijọba Naijiria fi awọn ọmọ ogun yi agbegbe Biafra ka, ti wọn si gba awọn ileeṣẹ ifọpo wọn, ati ti ilu Port Harcourt.
Ijọba ilẹ Biafra fi ẹsun kan pe Naijiria n lo ebi ati pipa awọn eniyan wọn nipakupa lati fi bori ogun naa, wọn si beere fun iranlọwọ lati ilẹ okeere.
Ni ọdun 1968, aworan awọn ọmọde ti ebi n pa, ti awọ wọn si ri rada-rada gba ori awọn amohunmaworan nilẹ alawọ funfun kan.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ni ọdun 1968, aworan awọn ọmọde ti ebi n pa, ti awọ wọn si ri rada-rada gba ori awọn amohunmaworan nilẹ alawọ funfun.
Wahala airi ounjẹ jẹ yii di nkan ti awọn orilẹ-ede ilẹ okeere n jiroro le lori laarin ara wọn, eyi si mu ki afikun de ba bi wọn ṣe n nawo fun orilẹ-ede miran.
Bakan naa ni awọn ajọ ti kii ṣe tijọba n di gbaju-gbaja.
Ọpọlọpọ awọn ajọ alaanu si bẹrẹ si fi ounjẹ, oogun, ati nkan ijagun (bi awọn kan ṣe sọ) ranṣẹ si Biafra.
Bakan naa ni ijọba Naijiria fi ẹsun kan Biafra pe oun lo awọn ọmọ ogun ilẹ okeere lati le fa ogun naa gun.
Orilẹ-ede United Kingdom ati Soviet Union ni alatilẹyin gboogi fun ijọba Naijiria, nigba ti France, Israel ati awọn orilẹ-ede kan faramọ Biafra.
Wo imọran Fọlọrunṣọ Alakija fun awọn ọdọ adulawọ
Ni oṣu Kẹfa, ọdun 1969, Biafra yawọ Naijiria pẹlu agbara lati le kọlu wọn lojiji.
Awọn ọmọ ogun ilẹ okeere si ran wọn lọwọ nipa ounjẹ, oogun ati nkan ijagun.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Awọn ọmọ ogun Biafra n ṣe ajọyọ pẹlu ibọn wọn lori ọkọ ijagun Naijiria ti wọn bajẹ lọdun 1968
Awọn ọmọ ogun ilẹ okeere yii kọlu ibudo ijagun Naijiria to wa ni Port Harcourt, Enugu, Benin ati Ughelli, ti wọn si ba ọpọ awọn baalu ijagun wọn jẹ.
Bo tilẹjẹ pe ikọlu Biafra naa ba Naijiria lojiji, ko pẹ pupọ ti wọn fi gbẹsan.
Ọjọ kẹtalelogun, oṣu Kejila, ọdun 1969 ni Naijiria tun kọlu wọn. Ọgagun Olusegun Obasanjo, to pada di aarẹ Naijiria lo lewaju awọn ọmọ ogun to kọlu wọn.
"Ọjọ keje, oṣu Kinni, ọdun 1970 si ni wọn ṣe ifilọlẹ ikọlu ikẹhun ti wọn pe ni ""Operation Tail-Wind""."
Ọjọ kẹtala, oṣu Kinni si ni ogun naa pari nigba ti awọn ọmọ ogun Biafra jọwọ ara wọn.
Ọjọ diẹ ṣaaju ọjọ naa ni Ojukwu sa kuro ni ilu; o wa baalu lọ si orilẹ-ede Cote d'Ivoire, to si fi igbakeji rẹ, Philip Effiong, silẹ lati mojuto jijọwọ ara wọn fun ijọba Naijiria.
"'A rí wàhálà táwọn èèyàn ń kojú nilẹ̀ẹ̀ Yorùbá la ṣe fi ""Amotekun"" fi ọkàn wọn balẹ̀'"
Didi ti wọn ti awọn ọna to wọ ilẹ Igbo fa ìyàn kaakiri ilẹ naa, to si jẹ pe awọn akọsilẹ kan sọ pe eniyan to to ẹẹdẹgbẹta ẹgbẹrun (500 thousand) si miliọnu meji l'awọn ọmọ Biafra tó kú nitori airi ounjẹ jẹ.
Eyi ko tun yọ awọn ọmọ ogun bi ọgọrun un ẹgbẹrun silẹ.
Awọn kan tilẹ sọ pe eniyan bi miliọnu mẹta lo ku nitori ogun naa.
#Queen Dihya: Obinrin tó gbógun tàwọn agbésùnmọ̀mí ni Algeria
Omolola Ajayi: Gloria Bright ní ọ̀gá òun kọ̀ láti sanwó oṣù fún òun lẹ́yìn oṣù mẹ́ta
Lebanon: Iṣẹ́ tí kòsí ní Naijiria, la ṣe lọ ṣe ọmọ ọ̀dọ̀ ní Lebanon
Ọ̀gá mi fẹ́ fi tipá bámi lòpọ̀ ní Lebanon àmọ́ ìjọba yọ mí l'óko ẹrú - Ọmọ Nàíjíríà míì
Ẹni ọdún mẹ́tàlélógún kan ti darapọ̀ mọ́ ẹbí rẹ̀ ní ìpínlẹ̀ Kwara lẹ́yìn tórí kóo yọ lóko ẹrú orílẹ̀-èdè Lebanon.
Ori ti ko ọmọ Naijiria mii, Gloria Taye Bright yọ loko ẹru lorilẹ-ede Lebanon, nibi to ti n ṣe iṣẹ ọmọ ọdọ.
Obinrin ẹni ọdun mẹtalelọgbọn ọhun ni ori ko yọ, lẹyin to figbe ta lori itakun agbaye, to si ṣalaye ohun toju rẹ ri lorilẹ-ede ọhun.
Gloria sọ pe, ọga ti oun n ba ṣeṣẹ kọ lati sanwo oṣu oun, bo tilẹ jẹ pe oun ti ṣe iṣẹ fun oṣu mẹta, ati pe ọpọ igba ni ọga naa ma n gbiyanju lati fi ipa ba oun lopọ.
O ṣalaye pe iṣẹ olukọ ede Gẹẹsi ni wọn sọ pe oun yoo lọ se lorilẹ-ede Lebanon, ṣugbọn iṣẹ ẹru ni wọn fi oun ṣe lẹyin to de ọhun.
Ni bayii, obinrin naa ti darapọ pẹlu awọn ẹbi rẹ ni olu ileeṣẹ ajọ aabo ara ẹni labo ilu ti ipinlẹ Kwara, nilu Ilorin.
O sọ fun awọn akọroyin pe, ọpọ awọn ọmọ Naijiria to wa ni Lebanon ni iṣẹ ti wọn n ṣe yatọ si iṣẹ ti wọn lero pe wọn yoo ṣe, ti wọn ba de ọhun.
Bakare Mubarak: ọ̀pọ̀ èèyàn ló máa ń fẹ́ dúró sí ẹgbẹ́ mí tójú si máa n tì mí
Gloria sọ siwaju sii pe, ko si owo dọla lorilẹ-ede Lebanon bayii, nitori naa, o ṣeṣe ki ọpọ awọn Naijiria to n ṣiṣẹ lọhun ma ri owo iṣẹ ti wọn n ṣe gba.
O ni iṣẹ olukọ ede Gẹẹsi ni wọn sọ pe oun yoo lọ ṣe lorilẹ-ede Lebanon
Lẹyin naa lo rọ awọn ọmọ Naijiria to n gbero ati lọ si Lebanon lati tu ero wọn pa, nitori nnkan ko ri bi wọn ṣe ro.
Bi ẹ ko ba gbagbe, inu ọsẹ ti a wa yii ni ori ko Omolola Ajayi yọ l'oko ẹru Lebanon, lẹyin to fi fidio kan lede leyi to gba oju opo Facebook kan.
Ifa Priest: ọdún mọ́kànlá ni mo fi ṣe iṣẹ́ agbejọ́rọ̀ kí n tó gbọ́ràn si Ifá lẹ́nu
Kara Bridge: Ó kéré tán, ọkọ̀ yóò lo wákàtí mẹ́ta kó tó bọ́ lójú ọ̀nà Kara tó dí pa
Ọpọ awọn eeyan to n gba opopona Berger si ori afara Kara nilu Eko lo ti n figbe ta bayii lori isoro sunkẹrẹ-fakẹrẹ ọkọ nla ti wọn n koju lagbegbe naa.
Isoro oju ọna to di pa naa waye nitori bi ileesẹ Berger to n se atunse abala kan ni opopona Marosẹ Ibadan silu Eko, se tun ti abala kan oju ọna naa pa, eyi to lọ si Ibadan lati Eko.
Bẹẹ ba gbagbe, oju awọn araalu ri mabo lopin ọdun 2019 nigba ti ileeẹ to n se oju sna ọhun ti abala kan pa ladugbo Kara si Berger, eyi to nira fun ọpọ eeyan lati gba oju ọna ọhun wọ ilu Eko.
Lọwọlọwọ bayii, wahala naa tun ti peleke si lati Ọjọ Aje, ọjọ Kẹfa osu Kinni ọdun 2020 nigba ti wọn tun ti abala titi naa pa, ti ọpọ awọn eeyan to n gba opopona ọhun si n lo wakati mẹta, o kere tan, ki wọn to ri ọna kọja.
Iroyin to n tẹ wa lọwọ bayii ti wa fidi rẹ mulẹ pe, se ni awọn ọkọ duro lai lee lọ siwaju abi sẹyin lopopona marosẹ to wọ Ibadan si Eko ati eyi to lọ lati Eko si Ibadan nitori ọna ti wọn ti pa naa.
Nigba to n sọrọ lori bi wọn se ti ọna ọhun pa, Ademọla Kuti, tii se oludari feto isẹ ode nileesẹ to wa fọrọ isẹ ode labẹ ijọba apapọ, fi ọwọ gbaya pe isẹ yoo ya kiakia lori atunse opopona naa nitori akoko ẹẹrun ti a wa.
BIAFRA at 50: Ìhàlẹ̀ ológun ni Gowon ni ká kọ́kọ́ fi bẹ̀rẹ̀- Aladejẹbi
Kuti fikun pe ti yoo ba fi di idaji osu Keji shun 2020, o seese ki awọn isẹ atunse oju ọna Ibadan si Eko ti buse ki ojo too bẹrẹ.
Oríṣun àwòrán, @others
Ijamba ọkọ Akẹru naa n fi kun asiko irinajo awọn eniayn
Laarọ ni wọn ni awọn ọkọ akẹru meji kọkọ gba ara wọn ni agbegbe Ikorodu ni ipinlẹ Eko ni Guusu Naijiria.
Iroyin ni ijamba yii fa sunkẹrẹ-fakẹrẹ ọkọ ni eyi to fi kan awọn ọkọ to n rin ni opopona mejeeji awọn to n lọ ati awọn to n bọ pada wọnu Eko.
Ko pẹ ti ijamba yii ṣẹlẹ ni wọn ni awọn ajọ ẹṣọ alaabo oju popo (FRSC) ti de sibẹ lati pese iranwọ to yẹ.
Oríṣun àwòrán, @others
Ìjàmbà ọkọ̀ akẹ́rù ní Ikòròdú fa súnkẹrẹ-fàkẹrẹ ọkọ̀ ní Márosẹ̀
Awọn eniyan ti n gbọ sọ fun ara wọn lati yago fun opopona Ikorodu bayii nitori pe ijamba to ṣẹlẹ nitosi agbegbe Obanikoro naa ko kere
Oríṣun àwòrán, @others
Ìjàmbà ọkọ̀ akẹ́rù ní Ikòròdú fa súnkẹrẹ-fàkẹrẹ ọkọ̀ ní Márosẹ̀
Iroyin to n tẹ wa lọwọ ni pe awọn oṣiṣẹ to n mojuto igbokegbodo ọkọ nipinlẹ Eko, LASTMA ti de sibẹ wọn si ti di ọna naa pa ki wọn le raaye wọ awọn ọkọ akẹru naa kuro.
Oríṣun àwòrán, @others
Ijamba oko akeru ni Obanikoro ti fa sunkere fakere oko
Idásilẹ̀ Amotekun ko ba òfin ọdún 1999 mu- Malami
Ọ̀gá mi fẹ́ fi tipá bámi lòpọ̀ ní Lebanon àmọ́ ìjọba yọ mí l'óko ẹrú - Ọmọ Nàíjíríà míì
Bí ìtàn ayé Toyosi Arigbabuwo ṣe lọ rèé láti ẹnu Musiliu Dasofunjo àti Ogun Majek
Àsọtẹ́lẹ̀ Fada Mbaka, tó yẹ àga mọ́ gómìnà Imo nídìí rèè
BIAFRA at 50: Ìhàlẹ̀ ológun ni Gowon ni ká kọ́kọ́ fi bẹ̀rẹ̀- Aladejẹbi
Ìtàn Mánigbàgbé: Ó pé ọdún mẹ́rìnlélàádọ̀ta tí Akintola kú, ìdí abájọ ìja rẹ̀ pẹ̀lú Awolowo rè é
Oríṣun àwòrán, Other
Ladoke Akintola: Ó pé ọdún mẹ́rìnlélàádọ̀ta tí Akintola kú, ìdí abájọ ìja rẹ̀ pẹ̀lú Awolowo rè é
Iku ogun nii pa Akikanju, iku odo nii pa omuwẹ.
Oni ọjọ Iṣẹgun, ọjọ kẹẹdogun, oṣu kinni, ọdun 2020 lo pe ọdun mẹrinlelaadọrin tawọn ologun ṣekupa Samuel Ladoke Akintola to jẹ Aare Ona Kakanfo kẹtala ilẹ Yoruba.
Akintola to jẹ alakoso ijọba apa iwọ oorun Naijiria nigba naa wa lara awọn gbajugbaja oloṣelu tawọn ologun ti wọn ditẹ gbajọba awarawa lọdun 1966.
Ilu Ibadan tii ṣe olu-ilu ijọba apa iwọ oorun Naijiria ni wọn pa Akintola si ninu iditẹ-gbajọba ti wọn ti pa ọpọ oloṣelu to jẹ ọmọ ẹgbẹ NPC (Northern People's Congress).
BIAFRA at 50: Ìhàlẹ̀ ológun ni Gowon ni ká kọ́kọ́ fi bẹ̀rẹ̀- Aladejẹbi
A bi Akintola lọjọ kefa, oṣu keje, ọdun 1910 si idile Akintola Akinbola and Akanke niluu Ogbomoṣo to wa labẹ ipinlẹ Oyo bayii.
Nigba ti Akintola wa ni kekere ni baba rẹ to jẹ oniṣowo ko ẹbi rẹ lọ si ilu Minna.
Eto ẹkọ Akintola
Akintola bẹrẹ eto ẹkọ rẹ nile iwe Church Missionary Society school niluu Minna to jẹ olu-ilu ipinlẹ Niger lonii.
Akintola pada si ilu Ogbomoṣo lọdun 1922 lati maa gbe pẹlu awọn baba baba rẹ, nibẹ lo ti lọ ile iwe Baptist day school.
Akintọla tẹsiwaju ẹkọ rẹ nile iwe Baptist College lọdun 1925.
Akintola ṣiṣẹ olukọ nile iwe Baptist Academy lati ọdun 1930 si ọdun 1942, ko too lọ ṣiṣẹ ni ile iṣẹ Reluwe.
Oríṣun àwòrán, Other
A bi Akintola lọjọ kefa, oṣu keje, ọdun 1910 si idile Akintola Akinbola and Akanke niluu Ogbomoṣo to wa labẹ ipinlẹ Oyo bayii.
Akintola wọ agbo oṣelu
Lẹyin to kẹkọọ gboye tan nilẹ Gẹẹsi gẹgẹ bi agbẹjọro, Akintola pada si Naijiria lọdun 1949.
Lẹyin naa lo darapọ mọ awọn ti wọn ti kawe gboye mii lapa iwo oorun Naijiria lati da ẹgbẹ oṣelu Action Group (AG) silẹ pẹlu ifari Oloye Obafemi Awolowo.
Akintola kọkọ di ipo oludamọran lori ọrọ ofin ẹgbẹ naa mu ko to di igbakeji adari ẹgbẹ oṣelu AG lọdun 1953 lẹyin iku Bode Thomas.
Oríṣun àwòrán, Other
Lẹyin to kẹkọọ gboye tan nilẹ Gẹẹsi gẹgẹ bi agbẹjọro, Akintola pada si Naijiria lọdun 1949.
Gẹgẹ bi igbakeji adari ẹgbẹ, Akintola ko ṣiṣẹ ninu ijọba apa iwọ oorun Naijiria ti Oloye Awolowo jẹ alakoso rẹ.
Ṣugbọn oun ni adari ẹgbẹ osẹlu AG nile aṣoju-ṣofin Naijiria lapaapọ nibi to ti jẹ olori ẹgbẹ oṣelu alatako.
Bakare Mubarak: ọ̀pọ̀ èèyàn ló máa ń fẹ́ dúró sí ẹgbẹ́ mí tójú si máa n tì mí
Akintọla jẹ minisita eto ilera, ibaraẹnisọrọ ati minisita ọkọ ofurufu.
Ọrọ lori iṣejọba ajumọlo ninu ẹgbẹ oṣelu AG lo mu ki edeaiyede ṣẹlẹ laarin Akintola ati Awolowo.
Akintola tako igbesẹ ẹgbẹ AG pẹlu idari Awolowo lori asopọ pẹlu ẹgbẹ oṣelu mii, Akintola ni awọn ẹya Igbo ni wọn n jẹ anfaani eto ọhun ju.
Edeaiyede laarin Awolowo ati Akintola
Awolowo fẹsun kan Akintola pe o fẹ fi eeru gba ipo olori ẹgbẹ oṣelu AG mọ oun lọwọ.
Rogbodiyan bẹ silẹ nile igbimọ aṣofin ijọba apa iwọ oorun Naijiria lẹyin tawọn aṣofin kan dibo lati yọ Akintola nipo lọdun 1962.
Rogbodiyan ọhun lo jẹ ki ile aṣofin ijọba apa iwọ oorun Naijiria pin si meji.
Rogbodiyan yii lo jẹ ki olootu ijọba Naijiria nigba naa, Sir Abubakar Tafawa Balewa kede ko nile o gbele nilẹ Yoruba.
O si fi Oloye M.A Majekodunmi, to jẹ minisita eto ilera nigba naa gẹgẹ bi alakoso ijọba.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Lẹyin ọ rẹyin, Akintola pada gba ipo rẹ gẹgẹ bi alakoso ijọba apa iwọ oorun Naijiria lọdun 1963.
Akintola tun wọle ibo gbogbogbo ọdun 1965 ṣugbọn o dije ninu eto idibo naa gẹgẹ bi adrari ẹgbẹ oṣelu tuntun Nigerian National Democratic Party (NNDP).
Ẹgbẹ oṣelu NNDP ni ajọsẹpọ pẹlu Northern People's Congress (NPC) to n ṣakoso ijọba apapọ nigba naa.
Idile Akintola
Akintola ṣe igbeyawo pẹlu Oloye Faderera Akintola, Eleduwa si fi ọmọ marun un jinki wọn.
Meji ninu ọmọ rẹ, Oloye Yomi Akintola and Dokita Abimbola Akintola naa jẹ minisita keji fun eto inawo.
Yomi Akintola tun fi igba kan jẹ aṣoju ijọba orilẹ-ede Naijiria ni Hungary, bakan naa ni iyawo ọmọ rẹ kan, Dupe Akintola jẹ aṣoju ijọba Naijiria ni Jamaica.
Amotekun: Ó ju ẹnu Malami lọ láti ní ètò náà kò bófin mu
Oríṣun àwòrán, @oyostategovt
Ki oju ma ribi, ẹsẹ loogun rẹ, eyi lo mu ki gomina ipinlẹ Ọyọ, Seyi Makinde sare tete gba ilu Abẹokuta lọ, lati ls sepade pọ pẹlu Oloye Olusẹgun Ọbasanjọ.
Gẹgẹ bi iwe iroyin kan ti wi, abẹwo Seyi Makinde naa ko sẹyin bi ijọba apapọ se ni agbekalẹ eto alaabo Amotekun ko ba ofin ilẹ wa ọdun 1999 mu.
Deede aago meji kọja isẹju diẹ ni Makinde gunlẹ si ọgba ile iyawe-kawe Ọbasanjọ to wa nilu Abẹokuta, ti awọn mejeeji si jọ se ipade bonkẹlẹ.
Gomina Makinde, ẹni ti Senetọ Hosea Ayoola Agboola ati oludamọran rẹ feto aabo, Fatai Owoseeni kọwọrin pẹlu rẹ, jade sita lẹyin ipade naa ni aago mẹrin aabọ.
Oríṣun àwòrán, @seyimakinde
Nigba to n bawọn akọroyin sọrọ lẹyin ipade naa, Makinde ni ijọba apapọ ko lagbara lati kede pe ikọ Amotekun ko bofin mu.
"Ni iru orilẹede taa wa yii, emi ko ro pe o yẹ ki iru agbẹjọro agba nilẹ wa sadede dide, maa da ofin se lọwọ ara rẹ.'
Kii se oju opo ikansira ẹni lori ayelujara ni eeyan ti n se ijọba, iha ti maa si kọ si ohun ti Malami sọ ko ba yatọ to ba jẹ pe o kọ iwe si wa lori ọrọ naa, amọ ori ayelujara nikan ni mo ti n ka iroyin ohun to sọ"""
BIAFRA at 50: Ìhàlẹ̀ ológun ni Gowon ni ká kọ́kọ́ fi bẹ̀rẹ̀- Aladejẹbi
Makinde fikun pe ojuse agbẹjọro agba nilẹ wa ni lati gba aarẹ nimọran lori awọn ọrọ to nii se pẹlu ofin, amọ emi ko mọ ofin to fun Malami lagbara lati sọ iru ohun to kede yii.
Oríṣun àwòrán, Others
Ijọba ipinlẹ Oyo, ti sọ pe, igbega lẹnu iṣẹ fun awọn olukọ yoo da le bi awọn akẹkọ ti wọn n kọ ba ṣe ṣe daadaa si ninu idanwo.
Alaga ajọ to wa fun akoso ile ẹkọ girama nipinlẹ Oyo, Tescom, Pasitọ Akinade Alamu lo sisọ loju ọrọ yii nibi ifọrọwerọ kan to waye ni ileewe Ansaru Deen, ni Saki.
O ni, omi tuntun ti ru ni ẹka eto ẹkọ nipinlẹ Oyo, nitori naa gomina Seyi Makinde ti pinnu lati maa gbe awọn olukọ ga gẹgẹ bi esi idanwo awọn akẹkọ wọn ba se dangajia si.
Alamu ṣalaye pe ijọba ti gbe igbimọ kan kalẹ, ti yoo wo bi awọn olukọ ṣe n ṣe dede si lẹnu iṣẹ, ti yoo si ṣe ayẹsi ẹni to ba ṣe dede julọ ninu wọn.
Oríṣun àwòrán, @seyimakinde
Omi tuntun ti ru ni ẹka eto ẹkọ nipinlẹ Oyo
O ni owo oṣu awọn olukọ to ma n da awuyewuye silẹ laye ijọba ana, ti di ohun igbagbe.
Gẹgẹ bi ọrọ to sọ, ifọrọwerọ naa to bẹrẹ ni Saki yoo kari gbogbo agbegbe mẹfa to wa ni ipinlẹ Oyo, o si jẹ ọna lati mu ibaṣepọ to gun rege wa laarin awọn oṣiṣẹ ati ajọ ọhun.
Ṣaaju ninu ọrọ ikinni kaabọ rẹ, alaga ajọ Tescom lẹkun Saki, Aderonke Oladoyinbo fi ẹmi imore han si ijọba ipinlẹ Oyo fun akitiyan rẹ lati mu ki eto ẹkọ gberu sii.
Lẹyin naa lo rọ awọn olukọ lati fọwọsowọpọ pẹlu ijọba, ki aba naa lee di mimu ṣẹ.
BIAFRA at 50: Ìhàlẹ̀ ológun ni Gowon ni ká kọ́kọ́ fi bẹ̀rẹ̀- Aladejẹbi
Michael Oluronbi: Ẹranko tó da àṣọ èèyàn bora ní mí, mo jẹ̀bi ohun tó ṣẹlẹ̀
Oríṣun àwòrán, West Midlands Police
Pasitọ kan to ba ọmọ lopọ ni ọpọ igba lẹyin to ba fun wọn ni 'omi mimọ' tan, ti salaye pe ẹmi esu lo n ba oun ja.
Awọn ọmọde meje ni Michael Oluronbi foju sun laarin ogun ọdun, to si n dẹru bawọn pe wọn yoo fidi rẹmi ninu idanwo wọn nileewe tabi ki wọn ya were, ti wọn ko ba setan lati ba oun lopọ.
Ọmọdebinrin mẹrin ni pasitọ yii ti fun loyun, ti iyawo rẹ, Juliana Oluronbi si n bawọn seto bi wọn se n sẹ oyun naa.
Koda ọkan ninu awọn ọmọbinrin naa salaye pe, oun ti sẹ oyun bii marun si mẹfa fun Pasitọ nigba ti oun wa nile ẹkọ girama.
Nibayii, ileejọ kan ni Birmingham nilẹ United Kingdom ti wa ju tọkọ-taya naa si ẹwọn lori ọpọ ẹsun ti wọn fi kan wọn eyi to ni wọn jẹbi rẹ.
Oluronbi jẹ wolii ati akọsẹmọsẹ apoogun (Pharmacist), to si n fi ọwọ lile ati agbara nla mu awọn ọmọ ijọ rẹ, ohunkohun to ba si sọ, ni abẹ ge.
"Kan ninu awọn eeyan to fori sọta lọwọ Pasitọ naa ni ""Ojisẹ Ọlọrun yii buru pupọ, to si n se akoba fun aye gbogbo eeyan."""
Nigba ti ọmọdekunrin kan ati ọmọdebinrin mẹfa wa ni ewe, bii ọmọ ọdun mẹjọ ni Pasitọ Oluronbi ti n lo wọn nilokulo, titi ti wọn fi di agbalagba.
Orilẹede Naijiria ni Pasitọ Oluronbi ti bẹrẹ isẹ Ọlọrun, ninu ijọ Kerubu ati Serafu, to si da ẹka ijọ naa silẹ ninu ile rẹ ni Birmingham.
"Gẹgẹ bi wọn ti sọ fun ileẹjọ, ""Iwẹ mimọ"" yoo waye ninu ọkan lara yara to wa loke ile rẹ, eyi to fi n dibọn lati maa ba awọn eeyan lopọ lọna aitọ, to fi de iwa ifipabanilopọ."
Awọn ọmọde naa ni wọn kan nipa fun lati maa de amure pupa lasiko to ba n ba wọn lopọ.
Oríṣun àwòrán, West Midlands Police
Mẹta si mẹrin ninu awọn ọmọdebinrin naa lo loyun, ti wọn si sẹ oyun fun lọpọ igba, ti awọn ọlọpa si ni eyi seese fun oluronbi lẹyin to ba fi ayederu orukọ wọn silẹ lawọn ile iwosan.
Iwa ika yii lo tẹsiwaju fun ọpọ ọdun titi ti ọkan lara awọn eeyan to n ba lopọ fi tọ awọn ọlọpa lọ, ti ọwọ si tẹ Oluronbi losu karun ọdun 2018 ni papakọ ofurufu Birmingham lasiko to fẹ sa kuro nilẹ UK.
"Ileesẹ ọlọpa ni UK se afihan fidio kan nile ẹjọ ninu eyiti Oluronbi ti sọ fun ọkan lara awọn mọlẹbi awọn eeyan to n fipa ba lopọ pe ""Ẹbi oun ni gbogbo ohun to sẹlẹ naa"", to si se apejuwe ara rẹ bii ẹranko to da asọ eeyan bora."
Oluronbi, tii se ẹni ọgọta ọdun lo n gbe ni agbegbe Orchard Drive, Longbridge, Birmingham, to si rẹwọn ọdun meje he lori pe o jẹbi ẹsun biba eeyan sun lọna to lodi sofin.
Iyawo Oluronbi, tii se ẹni ọdun mejidinlọgọta lo n gbe lopopona Walker, lagbegbe Walsall, to si jẹbi ẹsun mẹta to nii se pẹlu sise onigbọwọ fun iwa ifipabanilopọ.
Wasiu Ayinde: Èmi kìí ṣe Mayegun olórin àmọ́ mo fẹ́ jẹ́ olùlàjà nílẹ̀ Yorùbá
Oríṣun àwòrán, Wasiu Ayinde
Gbajugbaja olorin fuji, Wasiu Ayinde to ṣẹṣẹ jẹ oye mayegun Ilẹ Yoruba ti sọ pe, oye naa kii ṣe lati buga, ṣugbọn o jẹ lati tun ilẹ Yoruba ṣe.
Mayegun lo sọ ọrọ yii nigba to gbalejo BBC Yoruba lori eto ifọrọwerọ loju opo Facebook wa.
O ni oun kii ṣe Mayegun olorin, ṣugbọn ojuṣe oun gẹgẹ bii Mayegun ni lati ṣe iṣẹ olupẹtusaawọ ati olulaja nilẹ Yoruba.
Oluomo ṣalaye pe iṣẹ oun akọkọ gẹgẹ bii Mayegun ni lati ri pe alaafia jọba nilẹ Yoruba.
"Ninu idahuin rẹ si ibeere awọn eeyan lori eto naa, Kwam 1 ni ""Lati kekere ni mo ti n sapa lati ri pe Naijiria tẹsiwaju, bẹrẹ lati adugbo ti mo n gbe titi de ilẹ okeere, idi niyẹn ti mo ṣe n ba awọn oloṣelu ṣepọ, mo n bawọn sọrọ, wọn si n tẹti si imọran mi."""
O ṣalaye pe, ibi ti oun ti jẹ oye naa ko ni nnkan ṣe pẹlu iṣẹ to rọ mọ oye ọhun, nitori gbogbo awọn to ṣe pataki nilẹ Yoruba lo peju sibi ifinijoye naa, leyi to tumọ si pe wọn fọwọ sii.
"Ninu ọrọ rẹ, o sọ pe ""Kabiesi Alaafin Oyo ko dede fi mi jẹ Mayegun, ọpọ ohun ni wọn fi han mi ki wọn to fi mi jẹ Mayegun, kii si n ṣe ohun ti a ṣe ni kọrọ."""
"Nipa awọn iṣẹ ti yoo ṣe gẹge bii Mayegun, o ni ""Ituluṣe ni mo wa fun. Mi o joye lati buga, ṣugbọn oye yii wa lati ṣi awọn eeyan leti."""
Lori ọrọ ikọ Amotekun to ti di ariwo lẹyin ti ijọba apapọ ni ko ba ofin mu, o sọ pe ko sẹni to mọ ọmọ pọn bi ọlọmọ, fun idi naa, ko si eewọ ninu ka ṣọra ẹni, ṣugbọn ki ijọba fi oju ṣunukun wo ọrọ ọhun.
Mi o joye lati buga, ṣugbọn oye yii wa lati ṣi awọn eeyan leti
Ni ti pe Mayegun ko lee dọbalẹ fun elomiran mọ, o ni Alaafin ko ni ki oun ma bọwọ fun awọn to yẹ lati bọwọ fun, gẹgẹ bi ọmọ Yoruba.
Mayegun pari ifọrọwerọ naa pe, ki awọn ọmọ Yoruba kaakiri agbaye ṣe ara wọn ni oṣusu ọwọ, nitori ohun to ba n ṣe Abọyade, gbogbo Ọlọya lo n ṣe.
BIAFRA at 50: Ìhàlẹ̀ ológun ni Gowon ni ká kọ́kọ́ fi bẹ̀rẹ̀- Aladejẹbi
Hope Uzodinma: Gbogbo ẹyìn tí ẹ pète pọ láti jà mí lólè ẹ́tọ̀ọ́ mi, mo foríjì yín
Oríṣun àwòrán, Facebook/SenatorHopeUzodinma
Aaya bẹ silẹ o bẹ saare ni Gomina tuntun ipinlẹ Imo Hope Uzodinma fẹ fi ọrọ ijọba rẹ ṣe pẹlu bi o ṣe ni ki wọn fi iwe eto inawo ipinlẹ naa ranṣẹ si oun laarin ọjọ mẹrin.
Hope Uzodinma fi ọrọ yii sita lẹyin iburasipo rẹ to waye ni ilu Owerri.
Ninu aṣẹ ti o pa, o ni ki oluṣiro owo agba ipinlẹ naa fi ẹkunrẹrẹ gbogbo iwe to ni ṣe pẹlu eto inawo ipinlẹ Imo lati oṣu kaarun ọdun 2010 ranṣẹ si oun laarin ọjọ mẹrin.
Bẹẹ lo tẹsiwaju pe ki wọn dawọ duro lori sisan owo kankan jade ninu akoto ijọba ipinlẹ naa.
''Mo dupẹ lọwọ ẹka idajọ to duro sinsin lati ri i pe ẹtọ mi ko dun mi. Mo si ṣe tan lati ṣiṣẹ pọ pẹlu gbogbo ọmọ ipinlẹ Imo. Gbayawu ni ilẹkun mi wa ni ṣiṣi fun gbogbo yin''
Hope bakanna sọ pe oun foriji gbogbo awọn  ti o gbimọran pọ lati ja oun lole ẹtọ rẹ.
Ọrọ to sọ nipa ayẹwo iwe yii ti n mu iriwisi ọtọọtọ wa.
Bi awọn kan ti ṣe n sọ pe igbesẹ naa daa lati jẹ ki gbogbo owo ilu ṣe anfaani to yẹ fara ilu, awọn miran ni o ti yara ju lati ma tọ ọna yii eleyi to fẹ jọ wi pe yoo ṣe iwaadi awọn to ṣe ijọba ṣaaju rẹ.
Wọn ni ohun to yẹ ki o gbajumọ ni ṣiṣe iṣẹ fun idagbasoke ilu yatọ si ki o ma tọ pinpin awọn to ti ṣe ijọba ṣaaju rẹ.
Nigerian Soldier: Àṣìta ìbọn sọ́já pa ẹgbọn Kamsi láàrin fà kí n fà á ọ̀rọ̀
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ariwo hee sọ ni ile kan to wa ni agbegbe Seaside Estate, Badore Ajah ni ipinlẹ Eko bi ọta ibọn sọja kan ṣe ṣe eṣiṣi ba ẹgbọn arabinrin kan to pe e lati wa ba a na aladugbo rẹ.
Ileeṣẹ Ọlọpa ipinlẹ Eko ti fọrọ sita pe lootọ ni ẹmi arabinrin naa ti ọwọ sọja ti a ko mọ orukọ rẹ bọ.
Iṣẹlẹ yii waye ni agbegbe Ajah ni ipinlẹ Eko nigba ti iroyin sọ pe ẹgbọn oloogbe gan lo lọ pe sọja wa pe ko ba oun na aladugbo rẹ.
Agbẹnusọ ileeṣẹ Ọlọpaa ipinlẹ Eko, Bala Elkana ti fi ọrọ lede pe Ọlọpa ipinlẹ Eko ti mọ nipa iṣẹlẹ naa.
Ninu fidio kan to gba ori ayelujara kan lọjọ iṣẹgun lo ṣi aṣọ loju ọ̀rọ̀ naa.
Iroyin taa gbọ ni pe oloogbe ati ẹgbọn rẹ lo ni gbọnmi sii omi o to pẹlu aladugbo wọn kan ki ọkan lara wọn to lọ pe sọja wa.
Títí d'òní, Bàbá mi dara pọ̀ mọ́ iṣẹ́ ológun kò sí padà wálé - Grandma Biafra
Kamsi lorukọ ẹni to lọ pe sọja. Iroyin ti a gbọ ni pe oun ati ọmọ iya rẹ fẹ ko jade ni ile ti wọn n gbe lai san gbogbo gbese owo ti wọn n jẹ ti aladugbo wọn si.
Eyi si lo mu ki Kamsi lo ẹsẹ gigun  pe o mọ sọja ri lati lọ wa ba a ṣe moyo iya fun aladugbo wọn ọhun.
Ẹwẹ, nigba ti sọja naa de, ẹnu fa ki n fa a ọrọ ni sọja yii ati arakunrin to jẹ aladugbo awọn to pe e wa wa ti ọta ibọn meji fo yọ latẹnu ibọn sọja to si ta ba obinrin naa.
Nigba to ya ni wọn pe Ọlọpaa si ọrọ naa ṣugbọn sọja ti baba na papa bora ki awọn Ọlọpaa to de. Ni wọn ba ko ati Kamsi ati aladugbo rẹ lọ si agọ Ọlọpaa adugbo naa.
Ìtàn Mánigbàgbé: Bode Thomas ní ọpọlọ pípé, ó jẹ́ aṣaájú àmọ́ ó ní inú fùfù
Oríṣun àwòrán, Others
Bode Thomas ní ọpọlọ pípé, ó jẹ́ aṣaájú àmọ́ ó ní inú fùfù
Orukọ Ọmọọba Alfred Olabode Akanni Thomas, ti gbogbo eeyan mọ si Olabode Thomas, lee ma nitumọ mọ niwaju awọn ọdọ iwoyi amọ arugbo rẹ ti se oge ri nilẹ yii, ekisa rẹ si ti lo igba ri.
Lootọ orukọ Olabode Thomas lee ma jẹ ki awọn eeyan ranti adugbo kan ti wọn fi sọri rẹ ni agbegbe Surulere nipinlẹ Eko, amọ ohun ribiribi to se nile aye ko gbọdọ parẹ.
Bi Olabode Thomas ko tilẹ dagba tabi darugbo ko to jade laye, nitori ko lo ju ọdun mẹrinlelọgbọn lọ, to fi tẹri gbasọ, sibẹ a ko gbọdọ gbagbe akanda ọmọ Yoruba yii, tori ipa to ko si idagbasoke iran Yoruba ati Naijiria lapapọ.
Oríṣun àwòrán, Others
Bode Thomas ní ọpọlọ pípé, ó jẹ́ aṣaájú àmọ́ ó ní inú fùfù
Gẹgẹ baa ti ri ka loju opo ikansiraẹni lori ayelujara, Wikipedia, awọn ohun to yẹ ka mọ nipa Olabode Thomas ree, tori bi onirese rẹ ko ba fingba mọ, awọn eyi to ti fin silẹ ko lee parun.
BBC Yorùbá: Temidayọ Ọlọfinsawo ní kò rọrùn láti darí òṣìṣẹ́ ọlọ́pọlọ pípé
Ọja Arena Oshodi ni àwọn èèyàn ti ń r'aja
O ṣójú mí kóró bí wọ́n ṣé fí àdó olóró pa Dele Giwa lọdún 1986- Soyinka
Pius Adesanmi ní kò bá rọ́pò Wole Soyinka tí kò bá kú - ọmọ Naijiríà
Soyinka: Ọ̀pọ̀ ìgbà ni ayédèrú ìròyìn ti pa mí
Wole Soyinka rèé láti kékeré
Wo itan omi gbigbona ati tutu ni Ikọgosi Ekiti
Sogidi Lake: Kòṣẹja-kòṣèèyàn lá bá nínú adágún odò náà -Ojedele
Bakare Mubarak: ọ̀pọ̀ èèyàn ló máa ń fẹ́ dúró sí ẹgbẹ́ mí tójú si máa n tì mí
Ọmọọba Alfred Olabode Akanni Thomas ku togo-togo, ko gbe ile aye lati da awọn ara to wa ninu rẹ nitori ọdun mẹrinlelọgbọn pere lo se nile aye.
Èyí ni bí ogun abẹ́lé Biafra ṣe bẹ̀rẹ̀ ní Nàìjíríà
Ọ̀pọ̀ àwòrán tó ń ṣeni láàánú rèè nípa ogun abẹ́lé Nàíjíríà
Ǹjẹ́ o mọ ipa tí ẹja Panla kó lásìkò ogun abẹ́lé Biafra?
Ọta ìbọn ogun Biafra ṣì wà lọ́rùn mi lẹ́yìn àádọ́ta ọdún tí ogun parí - Umar
BIAFRA at 50: Ìhàlẹ̀ ológun ni Gowon ni ká kọ́kọ́ fi bẹ̀rẹ̀- Aladejẹbi
Títí d'òní, Bàbá mi dara pọ̀ mọ́ iṣẹ́ ológun kò sí padà wálé - Grandma Biafra
A wa gbadura pe Ọba oke tẹ Alfred Olabode Akanni Thomas si afẹfẹ rere nibayii to ti pe ọdun mẹtadinlaadọrin to ti jade laye.
Fire: Ọkùnrin mẹ́fà àti obìnrin mẹrin ni wọ́n rí gbé jáde nínú ọkọ̀ akérò tó jóná
Ọjọ buruku esu gbomi mu ni ọjọbọ oni jẹ fun awọn mọlẹbi idile to jona ninu ọkọ akero kan to jona lagbegbe Ijẹbu Ifẹ, lopopona marosẹ Ọrẹ si  Ijẹbu Ode lọ si Sagamu.
Atẹjade kan ti ajọ FRSC, ẹka tipinlẹ Ogun fisita lo sisọ loju isẹlẹ yii pẹlu afikun pe deede aago mẹta kọja ogun isẹju lọsan oni ni ọkọ akero Toyota kan, ti ero mẹẹdogun wa ninu rẹ sadede gbina.
Ọpẹlọpẹ awọn osisẹ ajọ ẹsọ oju popo FRSC ti wọn lọ sisẹ idoola ẹmi  loju ẹsẹ ti isẹlẹ naa waye, amọ awọn ero kan jona ninu isẹlẹ naa, ti awọn miran si ha sinu ọkọ ọhun.
Oríṣun àwòrán, Others
Atẹjade naa ni ọkunrin mẹfa ati obinrin mẹrin ni wọn ri gbe jade ninu ina naa, nigba ti ọkunrin meji ati obinrin kan ti jona kọja ala, nigba tawọn osisẹ panapana yoo fi de ibi isẹlẹ naa.
Iwadi fihan pe ọkọ akero to jẹ tileesẹ ọlọkọ ero De-Modern Transport Company, to n bọ lati apa ila oorun ilẹ yii, lo ko awọn eroja to lee sadede gbinna.
Wasiu Ayinde: Èmi àti Aláàfin sọ fún Gani Adams nípa oyè Mayegun, a kò jà rárá
Ọkọ naa ni ajọ FRSC fikun pe o bajẹ loju ọna, to si n duro loore koore fun atunse ile epo ati rọba to n fa epo sinu ẹngini ọkọ naa, ti wọn n pe ni Fuel Pump, eyi ti wọn fi okun so pọ mọ ileepo, ti dẹrẹba ọkọ naa si lero pe yoo gbe wọn de Eko, amọ to gbinna loju ọna.
Awọn eroja to lee tete gbinna ti ọkọ naa si ko lo tete mu ki ina ọhun ran, to si ran eeyan mẹsan lọ sọrun ọsan gangan.
Títí d'òní, Bàbá mi dara pọ̀ mọ́ iṣẹ́ ológun kò sí padà wálé - Grandma Biafra
Oludari ajọ ẹsọ oju popo,ẹka tipinlẹ Ogun, Clement Oladele wa kẹdun pẹlu awọn to lugbadi ijamba naa, to si tun n rọ awọn awakọ lati maa tẹle ofin irinna tijọba gbe kalẹ, lati dena ewu.
Oríṣun àwòrán, @roshawn6869
Asa ki awọn eeyan maa duro si ẹgbẹ titi lati wa ọkọ ti wọn yoo wọ ti wa tipẹ tipẹ, bi o tilẹ jẹ pe ọpọ ewu lo so mọ asa yii.
Lọwọlọwọ bayii, awọn eeyan kan nilu Eko lo ti n figbe bọnu, ti wọn si n ka boroboro nipa ohun ti oju wọn ri nidi diduro si ẹgbẹ titi lati wọ ọkọ ero aladani, taa mọ si sọọlẹ.
Ni oju opo Twitter, obinrin kan lo n fi itara sọ ohun ti oju rẹ aburo ri nidi wiwọ ọkọ sọọlẹ nilu Eko, eyi to yẹ ko jẹ arikọgbọn fun gbogbo wa.
Obinrin naa, Omotunde @Funkemyfun salaye pe aburo oun obinrin lo pe oun lojiji ni kete ta se ọdun tuntun 2020 tan, to si n sọkun kikankikan, eyi to mu ki n lọ baa nile rẹ.
Oríṣun àwòrán, @Atren_
Ọmọtunde ni ọkọ Sọọlẹ Sienna ni aburo oun wọ ni deede aago marun idaji ni adugbo Berger, eyi to n lọ si Victoria Island, oun si ni ero keji ti wọn yoo gbe.
"Gẹgẹ bi aburo rẹ ti salaye, ""Ni kete ti mo joko ni awọn ọkunrin mẹrin wọle ti mi bii ero, ti wọn si n da ẹsẹ ati ipa bo mi kikankikan fun wakati kan. Wọn gbe mi lọ si agbegbe Ikeja, wọn se orisirisi pẹlu mi, bẹẹ ni wọn gbe omi oloro asidi sita pe awọn yoo daa si mi lara."""
Bi o tilẹ jẹ pe ori yọ mi pe wọn ko da asidi naa si mi lara, wọn ja mi si agbegbe Opebi lori ere, ti mo si fi ara gbọgbẹ.
"O tẹsiwaju pe ""Igbati-igbarun ni wọn fi n tẹle gbogbo ibeere ti wọn n bi mi, koda, wọn tun gba ẹrọ ibaraẹnisọrọ mi, ti wọn si n ka gbogbo ohun to wa nibẹ, wọn gba nọmba ATM mi, ti wọn si ni ki n maa tẹ owo ransẹ si apo asunwọn awọn ni kiakia ."""
O salaye pe lẹyin o rẹyin, owo to to ẹgbẹrun lọna irinwo naira, ₦400,000 ni wọn gba lọwọ oun, ti gbogbo ara oun si kun fun ọgbẹ lorisirisi.
Ẹlomiran to tun salaye ohun ti oju aburo tiẹ naa ri, Roshawn @ roshawn6869 ni nigba to ku diẹ ka se ọdun Keresi lo wọ ọkọ ero adani de ibudokọ to gbe ọkọ rẹ pamọ si.
Wọn gun mi lọbẹ ni gbogbo ara amọ a dupẹ pe ko ku, o wa laaye, amọ ko tii lee rin, ti ọgbẹ ori rẹ lọwọlọwọ bayii si buru jai.
Ọpọ eeyan miran tun sọ awọn ohun ti wọn koju nidi wiwọ sọọlẹ adani:
Ọpọ awọn eeyan to da si ọrọ yii lo wa gba awọn araalu nimọran lati sọra nidi wiwọ ọkọ sọọlẹ, paapa ọkọ Sienna, nitori ewu n bẹ loko Longẹ.
Blackout: Iléeṣẹ́ amúnáwá ní ìṣẹ́ ti ń lọ láti ṣe àtúnṣe ẹ̀rọ náà
Oríṣun àwòrán, @ayemojubar
Ẹrọ amunawa apapọ fun orilẹede Naijiria dẹnukọlẹ lọjọbọ oni, eyi to ko orilẹede Naijiria sinu okunkun biribiri fun igba akọkọ lọdun 2020.
"Ileesẹ amunawa TCN fidi isẹlẹ naa mulẹ loju opo Twitter rẹ, eyi to wipe ""ni deede aago kan ku isẹju mẹrindinlọgbọn lọsan oni ni aise deede ba ẹrọ amunawa to n pese ina ọba ni Naijiria, eyi to sọ awọn agbegbe kan si okunkun biribiri."""
"Atẹjade ori ayelujara naa ni ""amọ nigba to di ago kan kọja isẹju mẹwa ni ina ọba pada silu Abuja atawsn agbegbe mii to kan. A si n sisẹ lọwọ lori ẹrọ amunawa to dẹnu kọlẹ naa, ki ina ọba lee duro pada yika Naijiria."""
Oríṣun àwòrán, @ayemojubar
Bakan naa ni ileesẹ amunawa to wa ni agbegbe Ikeja nilu Eko sọ loju opo Twitter rẹ pe ẹrọ amunawa ni Naijiria bajẹ ni aago meji kọja isẹju mẹẹdogun lssan oni Ọjọbọ, lẹyin isẹlẹ akọkọ to waye.
Ẹyin onibara wa, aayan ti n lọ lati se atunse ẹrọ naa, ẹ jọwọ, ẹ ba wa fara daa.
Wasiu Ayinde: Èmi àti Aláàfin sọ fún Gani Adams nípa oyè Mayegun, a kò jà rárá
Bẹẹ ba gbagbe, o to igba mẹwa ti ẹrọ amunawa to n pese ina ọba yika orilẹede Naijiria bajẹ lọdun 2019.
Chioma Ikeaza-Uzodinma tí wọ́n ṣẹ̀ṣẹ̀ búra wọlé fún ọkọ rẹ̀ ní Imo
Oríṣun àwòrán, OTHER
Chioma Ikeaza-Uzodinma ni iyawo gomina tuntun ti ipinlẹ Imo ti wọn ṣẹṣẹ bura wọle fun lọjọ kẹẹdogun oṣu kinni ọdun 2020 oun si ni o ti la gbogbo awọn to ku gẹgẹ bii iyawo gomina tọjọ ori rẹ kere ju.
Ẹni ọgbọn ọdun ni bẹẹ si ni agbẹjọro ni pẹlu. O un ni aya gomina Hope Uzodinma to ti kọkọ jẹ sẹnetọ to n ṣoju ẹkun idibo Iwọ Oorun ipinlẹ Imo ni agbegbe Orlu lọdun 2015.
Arabinrin Chioma Uzodinma ni yoo bẹrẹ si ni maa gba kiki ọlọla julọ aya gomina ipinlẹ Imo. Abiyamọ ni nile gomina pẹlu ọmọ mẹta, lara wn ni ibeji lanti lanti wa.
Iroyin taa gbọ ni wipe akinkaju arẹwa ọdọbinrin yii kawe gba oye ninu imọ ofin (LLB) ni fasiti ipinlẹ Imo nibi to ti kẹkọọ jade.
Bakan naa o di agbẹjọro ti wọn bura wọle fun lẹyin to tun kawe siwaju sii nile iwe giga ara ọtọ ti imọ ofin to wa ni ilu Abuja.
Títí d'òní, Bàbá mi dara pọ̀ mọ́ iṣẹ́ ológun kò sí padà wálé - Grandma Biafra
Agbẹjọro ẹni ọgbọn ọdun yii ti ṣiṣẹ gẹgẹ akọsẹ amofin kaakiri awọn ile iṣẹ ni Emeka & Co law office, o ti ṣiṣẹ ni Rickey Tarfa & CO ati ni Chris Uche & Co law office.
Ilu Aba ni ipinlẹ Abia lo ti lo ọpọ igbesi aye rẹ lasiko naa o n jẹ orukọ baba rẹ Ikeaka ko to wa f Hope Uzodinma.
Oun nikan ni ọmọbinrin ti baba rẹ bi pẹlu ọmọ ọkunrin meji.
O jẹ ọmọ bibi ijọba ibilẹ Ideato ni ipinlẹ Imo.
Biafra at 50: Umar ní àwọn tó ń bèèrè fún ogun kò mọ bí ogun ṣe rí ni
Ogun o ri bi iyan, ko si ri bi ẹkọ. Bi ayajọ aadọta ọdun ti ogun abẹle ti ọpọ mọ si ogun Biafra ṣe n lọ lọwọ, ọkan lara awọn soja nigba naa sọ iriri rẹ fun BBC.
Ọgbẹni Ibrahim Umar, ajagunfẹyinti ẹni ọdun mẹtadinlọgọrin sọ fun BBC pe, ọta ibọn ti wọn yin mọ oun loju ogun ṣi tun wa lara oun di oni.
''Ọdun 1968 ni ọta ibọn ba mi ni ọrun nibi ti mo ti n gbe akẹgbẹ mi ti wọn yinbọn fun, ṣadeedee ni mo kan gbọ pau, ọrun mi ni ibọn naa ba,'' Umar lo woye bẹẹ.
Ọkan lara wa yinbọn pada nibẹ ni gbogbo rẹ ti daru, si wọn si gbe mi digbadigba kuro nibẹ.
Umar ni oun wa nile iwosan fun ọpọ oṣu nibi ti oun ti gba itọju, ṣugbọn awọn dokita sọ fun oun pe ọta naa wa lori iṣan ọrun oun.
"Awọn dokita sọ fun mi pe tawọn le yọ ọta ibọn naa lara mi, mo le rọ lapa rọ lẹsẹ, idi ti ọta naa fi wa lara mi di oni niyẹn''
Wasiu Ayinde: Èmi àti Aláàfin sọ fún Gani Adams nípa oyè Mayegun, a kò jà rárá
Nigba ogun Biafra yii naa ni Umar padanu ọrẹ rẹ Tanko Musa lẹyin tawọn omogun alatako dena de wọn.
Umar ni ọpọ ninu awọn ọrẹ oun lo ba ogun lọ, ṣugbọn o ni eyi to dun oun ju ni iku Musa.
Ajagunfẹyinti Umar wa gbadura pe ki orilẹede Naijiria ati ilẹ Afirika lapapọ ma ṣe ri ogun mọ.
Umar ni awọn to n pariwo ogun kaakiri ko mọ ohun ti wọn n pe ni ogun. O ni ninu igbo tawọn ti n jagun loun ti mọ oniruuru eso jẹ nitori ko si ounjẹ gidi kan fawọn lati jẹ.
Ninu ọrọ tiẹ, Anthony Uko jẹ ọkan lara awọn soja to ja ogun Biafra lati ọdun 1969 ti ogun naa pari, ṣalaye pe nnkan ko rọgbọ f'oun lẹyin ogun Biafra, o ni oun n gbiyanju lati ṣe owo gẹgẹ bi afikun si owo ifẹyinti ti ijọba n fawọn.
Uko to jẹ ẹni ọdun mejidinlaadọrin sọ pe, ẹgbẹrun un lọna ogun naira lowo ifẹyinti awọn loṣu.
O wa rọ ijọba lati ṣe alekun owo naa nitori owo naa ko too na pẹlu bi gbogbo nnkan ti gbowo lori ni Naijiria lode oni.
Sotitobire: Ọlọ́pàá ní ₦800,000 ní àfurasí náà ń bèèrè láti fi ọmọ tí wọn ń wá sílẹ̀
Oríṣun àwòrán, Sotitobire
Egbirin ọtẹ, ba ti n pa ọkan ni omiran n ru ni ọrọ ọmọdekunrin Gold Kọlawọle, ọmọ ọdun kan ti wọn ji gbe nilu Akurẹ ninu ile ijọsin Sotitobire.
Idi ni pe laarọ oni yii ni ọwọ ileesẹ ọlọpa ipinlẹ Ondo tẹ ọkunrin kan to pe orukọ ara rẹ ni Elike Chibuzor, to ni oun loun ji Gold Kọlawọle gbe lọ.
Nigba to n fi idi isẹlẹ yii mulẹ fun BBC Yoruba, agbẹnusọ fun ileesẹ ọlọpa nipinlẹ Ondo, Femi Joseph salaye pe, Chibuzor lo pe ileesẹ ọlọpa naa laarọ ọjọ Ẹti pe ọdọ oun ni Gold wa, ti wọn ba si fẹ gbaa pada, ki wọn san ẹgbẹrun lọna ẹgbẹrin naira (₦800,000) fun oun.
Afurasi naa, to ni ilu Akure ni oun ti n pe awọn ọlọpa ọhun, lo tun fi ye wọn pe, awọn eeyan kan lo ni ki oun parọ mọ Alfa Babatunde, ti ojisẹ Ọlọrun naa ko si mọ ohunkohun nipa bi ọmọde naa se sọnu ninu ile ijọsin Sotitobire.
Oríṣun àwòrán, Gold Kolawole
Joseph ni, ni kete ti ọkunrin naa pe awọn lori aago, to si tun fi atẹjisẹ ransẹ lori owo to n beere yii, ni awọn bẹrẹ isẹ, to si foju han pe ilu Portharcourt lo ti n ba ileesẹ ọlọpa sọrọ, kii se ilu Akurẹ, gẹgẹ bo se sọ ninu ọrọ rẹ.
Oríṣun àwòrán, BBC Sport
Eyi lo mu ka bẹrẹ iwadi wa, ta si gbe ọkunrin naa, Chibuzor nilu Portharcourt to wa, amọ nigba to bọ si gbaga wa, lo yi ohun pada pe ọgbọn atijẹ ni oun n da, oun ko mọ ẹnikẹni tabi ohunkohun nipa isẹlẹ naa."""
Chibuzor fikun pe oun fẹ lu jibiti gba owo lọwọ ọlọpa ni, ọmọde ti wọn n wa naa ko si lọdọ oun, bẹẹ ni ẹnikẹni ko ran oun nisẹ lati parọ mọ pasitọ Babatunde.
Oríṣun àwòrán, facebook
Joseph salaye pe, iwadi ileesẹ ọlọpa fihan pe ọkunrin Chibusor naa ti lọ sẹwọn ri nitori iwa lilu jibiti, eyi kii si se igba akọkọ rẹ ti yoo ko si gbaga ofin.
O wa fọwọ gbaya pe ọjọ Aje to n bọ ni wọn yoo fi oju Chibuzor Elike ba ile ẹjọ lori ẹsun lilu jibiti.
Bẹẹ ba gbagbe, ni aarọ oni ọjọ Ẹti oni ni alufa Babatunde, tii se pasitọ ijọ Sotitobirẹ to wa nilu Akure, nibi ti ọmọdekunrin naa ti sọnu, yọju sile ẹjọ, ti adajọ si ni ki wọn da pada sọgba ẹwọn nitẹsiwaju ẹjọ naa.
Wo àwọn ìbejì tó lẹ́ pọ̀ lẹ́yìn àṣeyọrí ìṣẹ́ abẹ dókìtà 70
Fídíò bí ìgbẹ́jọ́ Pásítọ̀ ìjọ Sotitobire ṣe lọ níléẹjọ́ Májísíréètì lónìí rèé
Ile ẹjọ majisireeti to wa ni Oke Eda ni ilu akure, ipinlẹ Ondo ti sun igbẹjọ Pasitọ Alfa Babatunde ti ijọ Sotitobire ilu Akure siwaju di ọjọ karun un oṣu keji ọdun 2020.
Idajọ naa ti kuro nile ẹjọ majisireeti lonii eyi ti yoo waye ninu oṣu keji yoo waye nile ẹjọ giga ipinlẹ Ondo.
Eyi tum si wi pe Pasitọ Babatunde yoo tun lọ lo nkan bii ọsẹ mẹta lọgba ẹwọn ni agbegbe Olokuta.
Akure Kidnap: E túbọ̀ ní sùúrù, a máa wá ọmọ náà rí- Alukoro ọlọ́pàá
Tipatikuku lawọn ọlọpaa kogberegbe ati oṣiṣẹ ileeṣẹ ẹlẹwọn fi tu awọn akọroyin ka lasiko ti wọn gbe Pasitọ Alfa Babatunde wa si ile ẹjọ majistereeti ladugbo Oke Eda nilu Akure.
Ninu fọnran fidio ti o tẹ BBC lọwọ lati ile ẹjọ naa,a ri ti Pasitọ Babatunde sọkalẹ ninu ọkọ akero pẹlu awọn afunrasi mẹfa miran.
Pasitọ Sotitobirẹ wọ aṣọ olomi ewe ti wọn si ti ge irun rẹ.
Bi eeyan ko ba wo daada, o f le ma damọ pe oun lo bọ lẹ ninu ọkọ naa.
Ṣe ni ileẹjọ ti igbẹjọ Pasito Alfa Babatunde ti ile Ijọsin Sotitobirẹ yoo ti waye ti kun fọfọ pẹlu awọn to n reti Pasitọ naa.
Ninu awọn to ti wa ni ikalẹ ni awọn ọmọ ijọ rẹ, awọn mọlẹbi obi ti ọmọ wọn sọnu ati awọn akọroyin.
Akọroyin wa to n jabọ lati ibẹ fi awọn aworan ranṣẹ si wa ti o si ni laipẹ yii ni adajọ ati Pasitọ naa yoo kalẹ si ile ẹjọ.
Diẹ ninu aworan naa ree:
Lonii ọjọ Ẹti ni Alfa Babatunde to jẹ oludasilẹ ijọ Sọtitobirẹ Miracle Centre yoo foju ba ileẹjọ niluu Akure lori ẹsun to da lori bi ọmọ ọdun kan, Gold ṣe di awati ninu ṣọọṣi rẹ lọjọ kẹwaa oṣu kọkanla ọdun 2019.
Ajọ ọtẹlẹmuyẹ lo gbe Alfa Babatunde lẹyin tawọn obi ọmọ naa fẹsun kan an pe o mọ nipa bi ọmọdekunrin naa ṣe di awati.
Loṣu kejila ọdun 2019 ni wọn kọkọ foju ba ileẹjọ Majisireti Oke Eda niluu Akure.
Adajọ paṣẹ pe ki wọn ju pasitọ naa si gbaga fun ọjọ mọkanlelogun, bakan naa ladajọ sọ pe igbẹjọ yoo tẹsiwaju lọjọ kẹtadinlogun oṣu kinni ọdun 2020.
Lonii naa ni adajọ yoo sọ bo ya ileẹjọ yoo gba oniduro Alfa Babatunde.
Alfa Babatunde atawọn ọmọ ijọ rẹ mẹfa ti wọn jẹ oṣiṣẹ nile ijọsin naa ni wọn jọ foju ba ileẹjọ lori ẹsun to da lori koko mẹta ti wọn fi kan wọn.
Arabinrin Modupe Kolawole ni àwọn asọna to wa lẹ́nu iṣẹ́ lọ́jọ́ náà àti igbakeji oludari lo lọ sibl sùgbọ́n oludasilẹ o dasi ọ̀rọ̀ náà.
Ẹwẹ, ileẹjọ paṣẹ l'Ọjọru ọsẹ yii pe ki wọn si fi eeyan mẹrin ti wọn fẹsun kan pe wọn ṣekupa ọlọpaa nigba tawọn eeyan yabo ṣọọṣi naa ṣi atimọle.
Adajọ Charity Adeyanju paṣẹ pe ki wọn ṣi wa latimọle titi di ọjọ Aje ọsẹ to n bọ tii ṣe ogunjọ oṣu kinni ti igbẹjọ wọn yoo tẹsiwaju.
Fuel Price: Ìjọba ń gbèrò láti máa pèsè gáàsì CNG fún ọkọ̀
Ijọba apapọ n gbero lati sọ jala epo bẹntiro di naira mẹtadinlọgọrun-un lati naira marunlelogoje to wa bayii pẹlu ipese afẹfẹ gaasi CNG tawọn ọkọ yoo maa lo gẹgẹ bi epo.
Minisita keji fun ile iṣẹ epo rọbi, Timipre Sylva to fọrọ yii lede l'Ọjọbọ ṣalaye pe afẹfẹ gaasi CNG le gba ipo bentiro ati disu.
Sylva sọ pe ipese gaasi CNG ko nilo ki ijọba ṣẹṣẹ fi owo sori rẹ bi epo bentiro ki araalu le lagbara lati ra a.
O fikun ọrọ rẹ pe ipese afẹfẹ gaasi CNG dinwo ju epo bẹntiro lọ lai fi owo kankan kun un lati apo ijọba.
Minisita o ṣe pataki fun ijọba lati wa nnkan ṣe si owo ribiribi ti ijọba n na lati rii pe awọn ọmọ Naijiria lagbara lati ra epo bẹntiro.
Sylva ṣalaye pe Eleduwa fi afẹfẹ gaasi lọpọ yanturu jinki Naijiria eleyi ti ọpọ rẹ ṣofo danu.
Minisita tun ṣalaye pe o yẹ ki ile aṣofin agba l'Abuja le buwọlu aba lori epo rọbi(PIB) ni Naijiria ko too di oṣu karun un ọdun yii.
O ṣalaye pe ọpọ anfaani lo wa ninu aba naa fun araalu ti o ba di ofin tan.
Grid Collapse: Ajọ TCN ní ìpèsè iná ọba ti padà ní ìlọ́po méjì lọ́jọ́ Ẹtì
Oríṣun àwòrán, Getty Images
ọpọ ero gba pe ko tọ si awọn EKEDC lati sọrọ lori ina bayii
Oju opo ikansiraẹ́ni lori ayelujara n gbona girigiri lẹyin ti ẹrọ amunawa apapọ orilẹede Naijiria dẹnukọlẹ l'Ọjọbọ, eyi to ko orilẹede Naijiria sinu okunkun biribiri fun igba akọkọ lọdun 2020.
L'Ọjọbọ ni ileesẹ amunawa TCN fidi isẹlẹ naa mulẹ loju opo Twitter rẹ pe, ni deede aago kan ku isẹju mẹrindinlọgbọn ọsan Ọjọbọ ni aiṣe deede ba ẹrọ amunawa to n pese ina ọba ni Naijiria, eyi to sọ awọn agbegbe kan si okunkun biribiri.
Bakan naa ni ileesẹ amunawa to wa ni agbegbe Ikeja nilu Eko sọ loju opo Twitter rẹ pe, ẹrọ amunawa ni Naijiria bajẹ ni aago meji kọja isẹju mẹẹdogun ọsan Ọjọbọ, lẹyin isẹlẹ akọkọ to waye.
Nibayii na, iroyin to n tẹ wa lọwọ ti sisọ loju rẹ pe ajọ̀ to n pese ina ọba nilẹ wa ti kede pe oun ti pese ina ọba pada sawọn agbegbe ti ko si ina ọba, ti ipese ina ọba si ti wa ni ilọpo meji.
Sugbọn ọrọ ina mọnamọna yii to n ṣe ṣegesẹge lawọn eeyan n gba, bi ẹni n gba igba ọtọ loju opo Twitter lati Ọjọbọ titi di oni ọjọ Ẹti.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Aadota odun ree ti e ti n paro atunse ise yin fawon omo Naijiria lero awon kan
Ọpọ lori ayelujara ni wọn di ẹbi ina ọba to n ṣe ṣegesẹge naa ru minisita ile iṣẹ mọnamọna tẹlẹri, Babatunde Fashola.
Awọn eeyan yii ni Fashola ko ṣiṣẹ gidi lori ina ọba nigba to fi jẹ minisita.
Oríṣun àwòrán, @ayemojubar
@viknaki sọ ni tiẹ pe ko si ohun tawọn ọmọ Naijiria ko tii ri lorilẹede ti ileeṣẹ amunawa (NEPA) ti n fi ọlọpaa mu ọfiisi ajọ NEPA mii nitori ko tete sanwo.
Ọgbẹni ChuksClassie tiẹ ni, ọrọ ileeṣẹ ina ọba n buru si ni, o ni nṣe ni wọn n jo ajorẹyin lojoojumọ, bi ẹgbẹ agbabọọlu Arsenal ati Manchester United.
Officialyugmiz sọ pe ileeṣẹ to n pese ina ọba gan an ko nina, o ni ohun ti wọn mọ naa ni lati maa pin biili fawọn onibara wọn.
Ajayi Muyiwa ṣalaye pe, ọjọ kan lawọn ni ina lagbegbe oun laarin ọjọ mẹta, oṣiṣẹ NEPA kan si tun laya ''lati sọ fun wa pe ki a maa yọ ọwọ ina ti wọn ba fun wa lo.''
@GallantMichael ni pe, to ba jẹ ina ọba ni ọkọ atọkẹlẹ n lo, ọpọ ọkọ ni ko ba ti dẹnukọlẹ nitori airina lo.
Bẹẹ ẹ o ba gbagbe, o to igba mẹwa ti ẹrọ amunawa to n pese ina ọba yika orilẹede Naijiria bajẹ lọdun 2019.
Naira Marley: Ẹ̀kọ́ rèé fáwọn Marlians tó pa iléẹ̀kọ́ tì, tí wọn ń fa ṣòkòtò sílẹ̀ kiri
Oríṣun àwòrán, NAira Marley/ instagram
Azeez Fasola ti ọpọ eeyan mọ si Naira Marley lo jẹ ilu mọọka olorin taka sufe ti ọpọ eeyan n gbokiki rẹ.
Marley, ẹni ti Twitter kede lọdun 2019 pe oun ni awọn eeyan wadi rẹ julọ, la gbọ pe ọpọ eeyan, paapa awọn ọdọ n fi se awokọse.
Awọn ọdọ naa, ti wọn maa n hu ọpọ iwa ti Naira Marley n hu, ni kii fa sokoto wọn soke, ti awọn eeyan yoo si maa ri pata ti wọn wọ si abẹ sokoto naa.
Awọn miran ninu wọn si lo ti pa ile iwe ti bayii nitori pe wọn jẹ ololufẹ Naira Marley, ti wọn si ro pe akọrin naa ko ka iwe rara.
Koda, awọn ololufẹ Marley miran maa n mu igbo lati se atilẹyin fun asaaju wọn, ti wọn ni ijọba n gbogun ti pe o n mu igbo lojutaye.
Oríṣun àwòrán, Instagram/Naira Marley
Sugbọn fun iyalẹnu ọpọ eeyan, akọsilẹ itan igbesi aye Naira Marley fihan pe kii se alakọpati ẹkọ tori pe, o kawe gba oye imọ ijinlẹ ni fasiti, gẹgẹ bi iroyin isalẹ yii ti fihan wa.
Pẹlu awọn igbiyanju Naira Marley lati mu se ohun to yẹ, to si la ipa fun ara rẹ ni idi orin kikọ, ko yẹ ki ọdọ kankan, to ba fẹ fi akọrin naa se awokọse pinnu, lati pa ileewe ti.
Oríṣun àwòrán, NAira Marley/ instagram
Bakan naa lo yẹ ki awọn ọdọ to pe ara wọn ni ololufẹ Naira Marley jawọ ninu awọn iwa kan, eyi to mu ki ọpọ eeyan maa fi oju abuku wo wọn, ki wọn si maa huwa ọmọluwabi ninu iwa, ise ati ọrọ ẹnu wọn.
Oríṣun àwòrán, @Toyin_Abraham, @lizzyanjorin_original
Gbajugbaja oṣere Yollywood, Lizzy Anjorin tun ti ṣagbejade ọja rẹ tuntuntun yatọ fun ja aṣọ tita.
Lafikun aṣọ tita, agbo tita loriṣiriṣi ni Lizzy ti ko sori atẹ rẹ loju opo ayelujara bayii ti ọpọ awọn ololufẹ rẹ si ti n na ika kare si i.
Ẹwẹ, laipẹ yii ni akẹgbẹ rẹ ninu agbo oṣere kan naa, Toyin Abraham ṣẹṣẹ kede pe oun ti yọ ọwọ ninu ọja agbo tita fun awọn idi kọọkan to ni ṣe pẹlu awọn alajọṣiṣẹ pọ rẹ bo tilẹ jẹ pe o ṣi n ta awọn pẹ pẹ pẹ lẹgbẹ kan.
Oríṣun àwòrán, @Toyin_Abraham
Oríṣun àwòrán, Toyin_abraham
Eyi ko tii to ọsẹ kan rara ti Lizzy Anjorin fi gbe ikede tirẹ sita gẹgẹ bi o ṣe maa n polowo ọja rẹ pẹlu fidio, aworan ati akọle ọja to fi mọ oniruuru agbo to ko le igba.
Lara awọn agbo ibilẹ Yoruba naa to darukọ ni Fodan, Tẹ ẹ kanlẹ, Fọ ọ ko mọ, O n ya bọ, Gbe'dan ro ati bẹẹ bẹẹ lọ.
Oríṣun àwòrán, lizzyanjorin_original
Wo àwọn ìbejì tó lẹ́ pọ̀ lẹ́yìn àṣeyọrí ìṣẹ́ abẹ dókìtà 70
Bi ẹ ko ba gbagbe, lọdun to kọja ni ija nla kan bẹ silẹ laarin Lizzy ati Toyin eyi to bẹrẹ latari pe Toyin bimọ, Lizzy kọ lati ki i ku ewu ọmọ tori o ni kii ba oun naa yọ.
Ija yii fẹ loju to bẹẹ ti awọn agbaagba oṣere atawọn ẹlẹgbẹ wọn ni lati da si ọrọ naa ko to di pe o fa nilẹ.
Ko pẹ rẹ ni Toyin Abraham kede pe agbo tita ni ọna owo ti oun yan laayo to si n polowo rẹ lakọ lakọ ṣugbọn ko ju bii o'su
Collapse Building: Àjọ LASEMA ti gbe ọkùnrin náà lọ sílé ìwòsàn
Oríṣun àwòrán, LASEMA
Ọkunrin kan to ha si abẹ awoku ile to dawo laarọ ọjọ Ẹti ni ori ti ko yọ lọwọ iku ojiji.
Bi o tilẹ jẹ pe ẹsẹ kan aye, ẹsẹ kan ọrun ni ọkunrin naa wa bayii, amọ ajọ LASEMa ti gbe digba-digba lọ sile iwosan fun itọju oju ẹsẹ.
Se ni wọn fi ẹrọ ti eeyan fi n mi, to ni afẹfẹ ninu si imu ọkunrin naa, ki eemi rẹ lee jake, ni kete ti wọn fa yọ tan.
Oríṣun àwòrán, LASEMA
Ko si si ẹni to lee sọ ibi ti ọkunrin naa ti sese, ti eruku ile to wo naa si wa lara rẹ.
Oríṣun àwòrán, LASEMA
Ile alaja mẹta  ti wọn n kọ lọwọ lopopona Alasepe, ladugbo Agọ Ọkọta nilu Eko ti da wo lulẹ.
Atẹjade kan ti oludari agba fun ajọ Lasema nipinlẹ Eko, Oluwafẹmi Oke-Osanyintolu to fi idi isẹlẹ naa mulẹ fun BBC Yoruba salaye pe ọkunrin kan lo ha sabẹ awoku ile naa.
Ọsanyintolu ni isẹ idoola ẹmi ti n lọ lọwọ lati fa ọkunrin naa yọ, ti isẹlẹ naa si ti se akoba fun awsn ile to yii ile awoku naa ka.
Oríṣun àwòrán, LASEMA
Lasema ni ni kete ti wọn ba ti doola ẹmi ẹni to ha sinu ile naa ni awọn yoo wo awoku ile naa kanlẹ, ko maa baa jẹ ewu fun awọn ara adugbo naa.
"Ọsanyintolu ni ""Ni kete ta de sibi isẹlẹ naa, a woye pe ọkunrin kan ti ha sabẹ ile awoku naa, taa si ti bẹrẹ isẹ idoola ẹmi rẹ. Ni kete lẹyin eyi, si la wo ile naa kanlẹ."""
Oríṣun àwòrán, LASEMA
Amotekun: Àwọn ọmọ Nàìjíríà fi iṣẹ́ rán àwọn gómìnà sí Buhari
Oríṣun àwòrán, @others
Ọpọ awọn ọmọ Kaarọ oojire ti n fi ohun ransẹ si awọn gomina to wa lẹkun iwọ oorun guusu Naijiria lori bi ijọba apapọ se kede pe ikọ alaabo naa ko bofin mu.
Awọn ọmọ Yoruba naa ti wọn n fẹ ki awọn gomina wọn fi isẹ wọn jẹ fun aarẹ Muhammadu Buhari lasiko ipade ti yoo waye laarin aarẹ ati awọn gomina naa laipẹ yii.
Awọn gomina naa la gbọ pe wọn n gbero lati kan si aarẹ nilu Abuja, ki wọn si jọ se ipade pọ lati mọ ero rẹ lori ikede ti agbẹjọro agba fun ilẹ wa, Abubakar Malami se pe ikọ alaabo Amotekun ko ba ofin mu.
"Nigba to n fi ero rẹ ransẹ si gomina ipinlẹ Ogun, Ọmọọba Dapọ Abiọdun, Bukky Aweniade Akinbo wa n beere pe ""Ki lo n dẹru ba ijọba apapọ gan lori ọrọ amọtẹkun, ti ọpọ eeyan si n kin lẹyin lori ibeere naa."
Adio Daud Ajidawura naa da si ọrọ ọhun nigba to ni oun fẹ ki wọn sọ fun aarẹ pe awọn gomina ilẹ Yoruba ko da ikọ Amotekun sile lati ṣe atako ẹnikẹni.
"O tẹsiwaju pe ""Nigba ti awọn ajinigbe atawọn Fulani darandaran n pa awon agbẹ ninu oko wọn, nibo ni aarẹ wa. Ilẹ Yoruba ni ẹto lati daabo bo ara wọn pẹlu eyikeyi ọna ti wọn ba mọ."""
Musiliu Alabi Akoriola ni tirẹ sọ pe mi o le wa ku kankan ko lee joye ile baba rẹ, nitori naa, ki ẹya Yoruba ma gba ki awọn kan fi ẹtọ ati daabo bo ara wọn dunwọn.
Ni ti Dotun Bolu, ṣe lo fariga pe, ki wọn kuku pin orilẹ-ede Naijiria, ko si pada si boṣe wa tẹlẹ laye awọn baba Awolowo.
Ẹ wo awọn ohun miran ti awọn eeyan n sọ lori ọrọ ọhun.
Wo àwọn ìbejì tó lẹ́ pọ̀ lẹ́yìn àṣeyọrí ìṣẹ́ abẹ dókìtà 70
NEPA: Ọ̀gá DisCos rọ ọmọ Nàìjíríà kí wọ́n yé pè iléeṣé tó ń p'íná ní NEPA mọ́
Oríṣun àwòrán, Other
Ẹ ye pe wa ni NEPA mọ bi ẹ ba fẹ ina ọba, DisCos ni orukọ ile iṣẹ wa.
Alakoso ẹgbẹ awọn ile iṣẹ to n pin ina ọba, Sunday Oduntan lo sọrọ yii ninu ifọrọwanilẹnuwo lori ẹro amohunmaworan.
O ni tawọn ọmọ Naijiria ba tẹsiwaju lati maa pe ile iṣẹ awọn(DisCos) ni NEPA, a jẹ wi pe wọn ko tii fẹ ina ọba niyẹn.
''Niwọn igba ti ẹ ba si n pe wa ni NEPA, o fihan pe ẹ ko mọ pe ọpọn ti sun lori ọrọ ina mọnamọna ni Naijiria niyẹn,'' Oduntan lo woye bẹẹ.
Ọgbẹni Oduntan ni o tun fihan pe awọn eeyan ko fẹ ayipada ti wọn ba si n pe ile iṣẹ DisCos ni NEPA, ati pe wọn ko fẹ ipese ina mọnamọna ti wọn si n pe awọn NEPA.
O ṣalaye siwaju sii pe ile iṣẹ NEPA lo kọkọ wa ko too di PHCN, ṣugbọn o ti di DisCos bayii bo tilẹ jẹ pe ijo ''DisCos'' kọ lawọn n jo nibẹ.
Ọgbẹni Oduntan omi tuntun ti ru, ẹja tuntun si ti wọọ, ile iṣẹ NEPA ati PHCN ti ohun igbagbe ni Naijiria, DisCos lo wa lode bayii.
O tun sọrọ lori afikun owo ina wi pe igbesẹ ṣe pataki nitori ida marunlelaadọrun un eroja tawọn n lo, oke okun lawọn ti koo wa.
Operation Amotekun: Ẹgbẹ́ kan rọ Tinubu, láti sọ èrò rẹ lórí ọ̀rọ̀ Amọtẹkun
Oríṣun àwòrán, Facebook/Asiwaju Bola Tinubu
Lẹyin ti ọpọ eekan nilẹ Yoruba ti sọrọ akin lati gbaruku ti eto ẹṣọ Amọtẹkun tawọn gomina ipinlẹ Yoruba ṣe ifilọlẹ rẹ, ẹgbẹ kan to n jẹ 'Save Lagos Group' ti ke pe Asiwaju Bola Tinubu pe ki oun naa sọ ero rẹ faye gbọ.
Lootọọ Tinubu ko tii fi ero rẹ han lori ikọ Amọtẹkun ti awọn gomina mẹfẹẹfa ilẹ Yoruba ṣe ifilọlẹ rẹ lọjọ kẹsan oṣu yii niluu Ibadan.
Koda ẹgbẹ naa labẹ oludari rẹ, Ọgbẹni Adeniyi Sulaiman fun Tinubu ni wakati mẹrinlelogun lati sọ ero rẹ lori eto Amọtẹkun.
Ọgbẹni Sulaiman rọ Tinubu pe ko gbọdọ ṣojo lati sọrọ bo tilẹ jẹ pe o n gbero lati dupo aarẹ orilẹede Naijiria.
Oludasilẹ ẹgbẹ 'Save Lagos Group' ni isọkusọ lasan ni ẹgbẹ awọn darandaran, Miyetti Allah Kautal Hore n sọ lẹyin ti sọ pe eto Amọtẹkun le dena ki ọmọ Yoruba jẹ aarẹ ninu ibo gbogbogbo ọdun 2023.
O ni alagagebe ni ijọba apapọ pẹlu bi o ti tako eto Amọtẹkun nigba ti o faye gba ọlọpaa Shariah, Hisbah nipinlẹ to le ni mẹwaa lapa ariwa orilẹede Naijiria.
"Wọn ni ""eto aabo to mọyan lori nilẹ Yoruba san ju erongba ẹnikan lati dije fun ipo aarẹ lọ""."
O leè má mọ̀ bóyá o ní àrùn HIV/AIDS o! Wo àwárí akọ́ṣẹ́mọṣẹ́ yìí
Ẹwẹ, agbẹjọro kan to fi ilu Eko sẹbugbe, Ọgbẹni Malcolm Omirhobo, ti gbe ijọba lọ si ileejọ lori bi o ti tako eto ẹsọ alaabo Amọtẹkun.
O rọ ileẹjọ lati kede pe ijọba apapọ n ṣegbe lẹyin ẹnikan lẹyin to faye gba iru ẹṣọ alaabo bi Amọtẹkun lapa ariwa.
Awọn ọtọkulu bi Ọjọgbọn Wole Soyinka, eekan ẹgbẹ Afenifere, Oloye Ayo Debanjo; agbẹjọro agba ati ajafẹtọ, Femi Falana, Oloye Olu Falae, ati Aarẹ Ọnakakanfo, Iba Gani Adams atawọn mii ni wọn ti sọrọ lati gbaruku ti eto Amọtẹkun.
ECO Currency: Orílẹ̀èdè mẹ́fà bu ẹnu àtẹ́ lu ìgbésẹ̀ Ivory Coast
Oríṣun àwòrán, AFP
Orilẹede Naijira atawọn orilẹede marun un mii ti wọn jọ wa labẹ ajọ ọrẹdẹgbẹ ECOWAS ti bu ẹnu atẹ lu bi orilẹede Ivory Coast ṣe gbe igbesẹ lati yi orukọ owo ilẹ wọn lati CFA si eco.
"Gẹg bi ileeṣẹ iroyin AFP ṣe jabọ, Eco yii gẹlẹ ni orukọ tuntun ti ajọ ECOWAS yan lọdun to kọja ti wọn ṣe ilana eto silẹ lati da owo kan ṣoṣo silẹ fun awọn orilẹede to wa ni ajọ naa ti wọn si gbero lati pe e ni ""eco""."
Lẹyin ipade awọn orilẹede ẹkun Iwọ Oorun Afirika fun eto isuna kan naa - Naijiria, Guinea, Sierra Leone, Ghana, Liberia ati Gambia to waye lọjọbọ sọ pe ko yẹ ki orilẹede Ivory Coast gbe igbesẹ naa.
Ipade yii waye laarin wọn ati awọn Minisita eto isuna, awn gomina ile ifowopamọ giga ju lọ lẹkun Iwọ Oorun Afirika.
Wọn ti wa pe fun ipade pataki laarin awọn adari orilẹede ẹkun Iwọ Oorun Afirika mẹẹdogun lati jokoo fọrọ jomi toro ọrọ naa.
"Siṣe ayipada owo CFA franc ko wa ""ni ibamu pẹlu ipinu awọn alaṣẹ ijọba ajọ ECOWAS lati yan eco fun orukọ owo kan ṣoṣo"", ileeṣẹ iroyin Bloomberg ni ohun ti awọn orilẹede naa sọ niyii."
Wo àwọn ìbejì tó lẹ́ pọ̀ lẹ́yìn àṣeyọrí ìṣẹ́ abẹ dókìtà 70
Lọwọlọwọ, orilẹede mẹjọ lẹkun Iwọ Oorun Afirika ati Aarin gbungbun Afirika ti ọpọlọpọ wọn gbominira kuro lọwọ ilẹ Faranse lo n lo owo CFA Franc.
"Wọn si ti n bu ẹnu atẹ lu owo naa tipẹ pe owo aye atijọ ti igba ijọba amunisin ni CFA. Nitori naa loṣu to kọja, aarẹ Ivory Coast Alassane Ouattara kede pe wọn yoo yi orukọ owo CFA Franc si ""eco"" ti wọn yoo si maa na a mọ euro."
"Pẹlu igbesẹ ti ajọ ECOWAS naa ti baba gbe lori owona kan naa ti orukọ rẹ tun n jẹ ""eco"", bi ko ba si iforikori, eyi yoo da nkan mii silẹ o."
Lẹgbẹ kan, owo Naira ti wọn maa n foju wo bi eyi to ga ju, ko tii ye daju bayii boya ile ifowopamọ to ga ju lọ lorilẹede Naijira yoo yọnda didari owo naira fun awọn alaṣẹ eto ẹnawo Iwọ Oorun Afirika.
Davido: Kí ló fa ariwo lórí ìdọ́rẹ́ òun àti Chioma aya rẹ̀ lójú òpó Instagram?
Oríṣun àwòrán, davido/twitter
Ariwo ta ni owurọ ọjọ Abamẹta lori ayelujara nigba ti awọn eeyan bẹrẹ si ni gba a bi ẹni n gba igba ọti pe gbajugbaja akọrin takasufe, Davido ati iyawo rẹ ti kẹyin sira wọn lori ikanni Instagram.
Iroyin naa ṣalaye wi pe awọn mejeeji ti wọgi le orukọ arawọn loju opo ẹnikeji wọn.
Ohun ti iroyin loju opo ayelujara atawọn ileeṣẹ iroyin abẹle n sọ ni pe, igbesẹ naa waye lẹyin ti Ọga ileeṣẹ agborinjade Golden Boys Record, King Patrick ke gbajare sita pe ibi a foju si ọna o gba bẹ ati pe arakunrin Peruzzi ti ọpọ n wo gẹgẹ bii ẹgbọn Chioma, iyawo Davido kii ṣe ẹgbọn rẹ, ọrẹ ikọkọ rẹ ni.
Nibayii lẹnu wakati melo lọjọ kan naa, Davido ati aya rẹ Chioma tun ti bẹrẹ si ni tẹle ara wọn gẹgẹ bii ọrẹ lori oju opo ayelujara awọn mejeeji.
Amọṣa nigba ti ọrọ yii n ja ranyinranyin, oniruuru ọrọ ni awọn ololufẹ awọn lọkọlaya yii atawọn ọmọ Naijiria kan sọ. Diẹ lara rẹ niwọnyii.
Bakare Mubarak: ọ̀pọ̀ èèyàn ló máa ń fẹ́ dúró sí ẹgbẹ́ mí tójú si máa n tì mí
BIAFRA at 50: Ìhàlẹ̀ ológun ni Gowon ni ká kọ́kọ́ fi bẹ̀rẹ̀- Aladejẹbi
O leè má mọ̀ bóyá o ní àrùn HIV/AIDS o! Wo àwárí akọ́ṣẹ́mọṣẹ́ yìí
Sex for grade: Òkìkí olùkọ́ fásitì OAU míràn tún ti kàn lóríi pé ó fẹ́ bá akẹ́kọ̀ọ́ rẹ̀ lò pọ̀ fún máàkì
Oríṣun àwòrán, @OAUniversity
Òkìkí olùkọ́ fásitì OAU míràn tún ti kàn lóríi pé ó fẹ́ bá akẹ́kọ̀ọ́ rẹ̀ lò pọ̀ fún máàkì
Ariwo kinla! Lo gbaye kan lori ikanni ayelujara bayii lori iroyin olukọ miran ni fasiti Ọbafẹmi Awolọwọ ile ifẹ, OAU ti wọn ni aje tun ṣi mọ lori bayii o lori pe oun naa tun fẹ ba akẹkọọ lajọṣepọ ko to lee fun un ni maaki.
Arakunrin Bisi Babalẹyẹ ni ariwo rẹ gbode pe oun pẹlu fẹ jẹran sunkunsi akẹkọọ abẹ rẹ ni ẹka ẹkọ imọ ọrọ ilẹ Okeere, International Relations lọgba fasiti naa.
Iroyin sọ pe akẹkọọ kan ti orukọ rẹ n jẹ Motunrayọ lo tu aṣiri sita lori ohun to n lọ laarin oun ati olukọ fasiti naa.
Koda akọsilẹ ibanisọrọ lori oju opo Whatsapp ati akasilẹ ohun ajọsọ ọrọ awọn mejeeji lori ẹrọ ibanisọrọ wa lara awọn ẹri maajẹmi niṣo ti wọn ni akẹkọọ naa fi sita.
Lati igba ti iroyin yii si ti jade  ni awọn eeyan ti n pariwo ki awọn alaṣẹ fasiti OAU o gbe igbesẹ to yẹ lori rẹ.
Bi a ko ba ni gbagbe, ni ọdun meji sẹyin ni irufẹ iroyin bayii ṣẹlẹ eyi ti aje rẹ ṣi mọ agba olukọ kan ni fasiti naa, iyẹn ni ẹka imọ iṣiro owo lori.
Bakare Mubarak: ọ̀pọ̀ èèyàn ló máa ń fẹ́ dúró sí ẹgbẹ́ mí tójú si máa n tì mí
Akitiyan lati kan si alukoro ileewe giga naa lati mọ iha awọn alaṣẹ ileewe naa lo ṣi ja si pabo.
Diẹ lara awọn ẹri ti wọn n fi kaakiri ori ayelujara niyi:
BIAFRA at 50: Ìhàlẹ̀ ológun ni Gowon ni ká kọ́kọ́ fi bẹ̀rẹ̀- Aladejẹbi
Ọmọwe Lekan Are jáde láyé lẹ́ni ọdún mẹ́rìndínláàdarún
Oríṣun àwòrán, others
Alagba Lalekan Ayọkunnu ti ọpọ mọ si Lekan Arẹ ti jade laye
Ẹni ọdun mẹrindinlaadọrun ni Ọmọwe Arẹ ko to di ara ilẹ ni ọsan Satide, ọjọ kejidinlogun, ọdun 2020 lẹyin aisan ranpẹ nileewosan nla UCH ni Ibadan.
Eekan ọmọ ilu Ibadan ni oloogbe Arẹ. O si di ipo nlanla mu lawujọ ninu eyi ti ipo ọmọ igbimọ adari ileeṣẹ iwe iroyin Punch wa.
Bakan naa ni o jẹ oludari agba fun ileeṣẹ Kakanfo Inn ati oko nla ti Lekan Arẹ farms.
O leè má mọ̀ bóyá o ní àrùn HIV/AIDS o! Wo àwárí akọ́ṣẹ́mọṣẹ́ yìí
Nigba aye rẹ, pataki laarin awọn onimọ ijinlẹ nipa eto ọgbin ni alagba Arẹ.
Ni ọdun 1933 ni wọn bi oloogbe Ọmọwe Lalekan Arẹ.
Titi di igba to wọ kaa ilẹ sun, Lalekan Arẹ ni Laguna Bọbajiroro ilu Ibadan
Bakare Mubarak: ọ̀pọ̀ èèyàn ló máa ń fẹ́ dúró sí ẹgbẹ́ mí tójú si máa n tì mí
Ààfá mẹ́ta réwọ̀n hé nípa ṣíṣe ìrànlọ́wọ́ òjijì fún obìnrin kan pẹ́lù 36 mílíọ̀nù náìrà
Oríṣun àwòrán, @others
Wọn ti gbe Aafa Sule Shauibu, Wasiu Salami àti Francis Akinola lọ si ilé ẹjọ fún ẹ̀sùn pe wọ́n gbá Olayinka
Awọn ọlọpaa Ibadan nipinlẹ Ọyọ ni guusu Naijiria ti foju awọn aafa ti wọn fẹsun gbajuẹ kan hande ni Iyaganku.
Aafa Sule Shauibu to jẹ ẹni ọdun aadọrin ọdun ni wọn ni o jẹ olori awọn mẹtẹẹta naa.
Awọn amugbalegbẹ rẹ ti wọn fẹsun kan pe  wọn jọ gba arabinrin Olayinka ni Aafa Wasiu Salami ẹni ọdun marundinlọgọta ati Francis Akinọla to jẹ ẹni ọdun marundinlaadọta.
Ẹsun jibiti mẹta ni wọn fi gbe wọn wa sile ẹjọ majisreeti ni Iyaganku ni iluj Ibadan
Super touch: Roller Blader ni mí láti ọdún mẹ́jọ sẹ́yìn
Sajẹnti Olalekan Adegbitẹ to ṣaaju ikọ agbofinro to gbe awọn ti a fẹsun kan wa sile ẹjọ ṣalaye pe awọn mẹtẹẹta gba owo lọwọ arabinrin Olayinka Ishioye lọna aitọ.
O ni wọn gba miliọnu mẹrindinlogoji lọwọ rẹ lọdun 2015 pelu ileri lati baa wa ojutu si ogun aye rẹ ti o nii lara lasiko naa.
O leè má mọ̀ bóyá o ní àrùn HIV/AIDS o! Wo àwárí akọ́ṣẹ́mọṣẹ́ yìí
Wọn ni wọn fẹ fi owo naa seto adura ati awọn aajo miran lati yọ arabinrin Olayinka kuro ninu iṣoro ara níni to de baa lọdun 2015 ni.
Obinrin naa ni wọn ni wọn fẹ pese iranlọwọ ninu ẹ̀mí fun oun ni nigba naa.
Adegbitẹ ni eyi si ṣe lodi siu iwe ofin ati iwa ọdaran ni Naijiria abala 383 ni eyi to tọ si ijiya ni abala 390 (9) ati abala 415 ati ti 516 iwe ofin iwa ọdaran Cap 38; Vol II ti ọdun 2000 ni ipinlẹ Oyo.
Agbẹjọro Hammed N. A ati Adesanya D. S ti wọn n ṣoju awọn olujẹjọ beere fun gbigba oniduro awọn Aafa mẹtẹẹta lẹyin ti wọn ni awọn ko jẹbi ẹsun naa.
Wọn ni kii ṣe pe awọn ṣe gbajuẹ fun Arabinrin Olayinka nigba to gbe iṣoro wa si ọdọ wọn gẹgẹ bii Aafa.
Illegal Rehab Centre: A le ni ogójì tí wan n kó 'sinú ìyará kékeré kan níle Ọlọrẹ
Adajọ Adesina S. A pada gba oniduro awọn mẹtẹẹta ti wọn fẹsun jibiti ninu iṣẹ Ọlorun kan naa pẹlu miliọnu mẹrin naira ari awọn oniduro agba meji.
Wo àwọn ìbejì tó lẹ́ pọ̀ lẹ́yìn àṣeyọrí ìṣẹ́ abẹ dókìtà 70
Adesina sun igbẹjọ naa di ọjọ kẹta. oṣu keji ọdun 2020.
Títí d'òní, Bàbá mi dara pọ̀ mọ́ iṣẹ́ ológun kò sí padà wálé - Grandma Biafra
Harry and Meghan: Mí o ṣààdédé gbé ìgbésẹ̀ láti kúrò nílé Ọba
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ọmọba Harry fi ọrọ yi lede nibi apejẹ kan to kopa nibẹ lọjọ Aiku
"Ọmọọba ilẹ Gẹẹsi ti o si tun jẹ ""Duke ti Sussex"" ti sọ pe igbagbọ loun fi gbe igbẹsẹ lati yẹra kuro nile ọba nitori ko si nkan mii ti oun le ṣe."
Nibi apejẹ kan ti oun ati iyawo rẹ Meghan kopa nibẹ nirọlẹ ọjọ Aiku ni o ti sọ pe o wu awọn lati maa ṣiṣẹ sin yeye Ọba lai gba owo ṣugbọn ''ko le ṣeeṣe''
Eyi ni igba akọkọ ti yoo sọrọ nita gbangba lori ọrọ yii lati igba ti oun ati iyawo rẹ Meghan ti kede pe awọn fẹ yẹra kuro nile ọba.
Ọmọọba naa ni oun ri ayọ ati idunnu ti oun ti n wa pẹlu Meghan ṣugbọn oun fẹ ki o ye awọn eeyan pe awọn ko lọ lai wẹyin wo.
''Ile ni ilẹ Gẹẹsi jẹ fun mi, ko si oun ti yoo si yi i pada''
Oríṣun àwòrán, PA Media
Harry, iyawo rẹ ati ọmọ rẹ Archie ni Victoria lasiko ọdun Keresimesi to kọja
Harry sọ pe ohun to n ṣẹlẹ n ṣafihan iru bi nkan ko ṣe rọrun fun oun eleyi to mu ki oun fi mọlẹbi oun pamọ lati le gbe igbe aye alaafia.
Nibẹrẹ oṣu yii ni ọmọọba Harry ati Meghan sọ pe awọn fẹ yẹra kuro nipo gẹgẹ bi aṣaaju mọlẹbi ọlọba ilẹ Gẹẹsi tawọn si fẹ́ da duro funra awọn.
Lọjọ Abamẹta ni ikede wa lati aafin Buckingham Palace pe wọn o ni maa lo oye ọlọmọọba wọn mọ ti wọn ko si ni kopa ninu awọn iṣẹ to jọ mọ jíjẹ́ ọmọ ọba.
Ọmọọba Harry ati aya rẹ ti a mọ si Duke ati Duchess Sussex lẹyin igbeyawo wọn ni wọn ko ni lo orukọ oye ile ọla to jẹ ile Ọba UK mọ.
Koda, wọn ko ni fọwọ kan owo ilu mọ ni ile Ọba ni Buckingham.
Bakan naa ni wọn pinnu lati da miliọnu meji ati irinwo pọun ile UK ti ile Ọba fi ba wọn tun ile Cottage ti wọn n gbe lẹyin igbeyawo wọn ṣe pada Harry àti Meghan kò ní lo orúkọ oyè wọn mọ́, wọn kò sì lẹ́tọ̀ọ́ sí owó ilú mọ́ ní UK.
Owó ara wọn ni wọn yoo maa na pẹlu ileri lati ma doju ti Ọbabinrin ninu iwa ati iṣe wọn nibikibi ti wọn ba wa.
Oríṣun àwòrán, PA Media
Lódun 2016 ni aafin Kessingtin fi atẹjade sita lati fidiẹ mulẹ pe lootọ ni Ọmọọba Harry ati oṣere binrin Meghan Markle ti n fẹ ara wọn lati oṣu diẹ sẹyin. Toronto ni wọn ti kọkọ fi aworan wọn ti wọn jọ ya papo sita.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ni kete ti wọn ṣe ikede ipinnu wọn lati fẹ ara wọn titi lae ni Meghan sọ fun BBC pe ọna ara to yanilẹnu, to mu ife dani, to tun dùn leti to wa tuni lara ni Harry gba dẹnu ifẹ kọ oun.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Losu keji ọdun 2018, ni awọn tọkọtaya naa kopa ninu eto itagbangba pẹlu ẹgbọn rẹ Duke ati Duchess Cambridge. Nibẹ ni Meghan ti darapọ mọ ẹbi alayọ yii lati kopa ninu eto Royal Foundation Charity. Nibi eto yii ni Harry ti ṣe yẹyẹ pe Awọn mẹrẹẹrin a jọ wa pọ laelae ni.
Oríṣun àwòrán, PA
Lọjọ kọkandinlogun, oṣu karun un, ọdun 2018 ni wọn so awọn mejeeji pọ ni Windsor Castle. ero to le ni igba le ni ẹgbẹrun kan ni wọn fiwe pe sibi igbeyawo naa ti wọn si ṣafihan rẹ kaakiri awọn amohunmaworan ni UK. Ori ẹṣin ni tọkọtaya yii gun fi ki awọn ara ilu pe wọn ku aduroti lẹyin igbeyawo naa.
Oríṣun àwòrán, EPA
O le ni ẹgbẹlẹgbẹ ero to to si oju opopona lati wa ki awọn t\ọkọtaya tuntun ti yoo maa ṣakoso Susex ni UK.
"'A kẹ̀yìn sí Ivory Coast, owó yín ò lè máa jẹ́ ""eco"" táa ti mú fún àjọná owó ECOWAS'"
Ẹgbẹ́ kan fún Tinubu ní wákàtí mẹ́rìnlélógún láti sọ èrò rẹ lórí Amọtẹkun
Lalekan Ayọkunnu Are jáde láyé
Kínla! Ṣé olùkọ́ fásitì OAU míràn tún ti kó sí gbaga ìbálòpọ̀-fún-máàkì ni?
Oríṣun àwòrán, Reuters
Ile ijọsin St George Chapel ni tọkọtaya Harry ati Meghan ti jẹ ẹjẹ ootọ inu sira wọn titi iku yoo fi ya wọn niwaju Obabinrin ati ero to pọ pẹlu ayọ
Wo àwọn ìbejì tó lẹ́ pọ̀ lẹ́yìn àṣeyọrí ìṣẹ́ abẹ dókìtà 70
Oríṣun àwòrán, Reuters
Obabinrin Elizabeth, Duke ti Edinburgh ati awọn eekan mi ninu ile Ọba ni gbogbo wọn fi ayọ han nibi eto igbeyawo Harry ati Meghan pe o ṣoju wọn.Inu Ọbabinrin ati ọkọ rẹ dun pupọ lati ri ọmọmọ wọn ko gbe iyawo to wuu wọnu ile ọla loju aye wọn.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Loṣu kẹfa, ọdun 2018 ni Obabinrin Elizabeth ati Olori Meghan kọkọ jọ fojuhan papọ nita. Awọn mejeeji jọ ṣi Gateway Bridge and Chester's Storyhouse Theatre nilu Ọba. Opọ ni ile Ọba ti t\wọ gab Meghan wọle lẹyin eto yii.
Títí d'òní, Bàbá mi dara pọ̀ mọ́ iṣẹ́ ológun kò sí padà wálé - Grandma Biafra
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Lasiko ọyẹ ni ilé Ọba ni Kessington fi sita pe Meghan ti fẹraku ati pe wọn ko ni pẹ bi \omọọmọọmọ miran fun Ọbabinrin Elizabeth. Kete leyin ikede yii ni Harry ati Meghan bẹrẹ irinajo akọkọ wọn lọ silẹ okeere. Wọn lọ si Australia, New Zealand, Fiji ati Tonga papọ. Eyi ni ọkan lara awọran ti wọn ya ni Bondi Beach ni Sydney ni \Australia pẹlu awọn ololufẹ wọn.
Ìtàn ìgbé ayé Bode Thomas rèé, ó kọ́ wa láti máa kó ẹnu wa ní ìjánu
Ààfá mẹ́ta réwọ̀n hé nípa ṣíṣe ìrànlọ́wọ́ òjijì fún obìnrin kan pẹ́lù 36 mílíọ̀nù náìrà
Harry àti Meghan kò ní lo orúkọ oyè wọn mọ́, wọn kò sì lẹ́tọ̀ọ́ sí owó ilú mọ́ ní UK
Wo àwọn krìstíẹ́nì tó n wẹ̀ nínú odò tó ní yìnyín láti ṣàjọyọ̀ ìrìbọmi Jesu
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Lọjọ kẹfa, oṣu karun un, ọdun 2019, ọdun kan lẹyin igbeyawo wọn ni Meghan bi ọmọkunrin lantilanti sinu ile Ọba. Archie Harrison Mountbatten Windsor ni wọn sọ orukọ ọmọ tuntun o. Oun ni ẹni keje si itẹ Ọba ilẹ Gẹẹsi lẹyin Obabinrin elizabeth. Harry fi idunnu rẹ fawọn akọroyin pe iriri naa ti dara ju lati di baba ikoko.
Oríṣun àwòrán, PA Media
Loṣu kẹfa ọdun 2019 ni tọkọtaya yii ni awọn ko ṣe iṣẹ iranlọwọ papọ mọ pẹlu Duke ati Duschess Cambridge to jẹ égbọn Harry ati aya rẹ. Wọn ni awọn fẹ bẹr ti ara awọn lọtọ
Super touch: Roller Blader ni mí láti ọdún mẹ́jọ sẹ́yìn
Oríṣun àwòrán, Reuters
Lọdun to kọja ni Archie omọ tuntun ti abi kọkọ rinrin ajo lọ silẹ Adulawọ. Wọn gbe e lọ ki Archbishop Desmond Tutu ni orilẹ-ede South Africa lasiko abẹwo wọn akọkọ gẹgẹ bii ẹbi kan.
Oríṣun àwòrán, PA Media
Omọọba Harry ati ọmọ rẹ Archie ni Canada ti wọn kede lati maa gbe lasiko yii
Wo àwọn ìbejì tó lẹ́ pọ̀ lẹ́yìn àṣeyọrí ìṣẹ́ abẹ dókìtà 70
Oríṣun àwòrán, Reuters
Aworan yii ni tọkọtaya Harry ati Meghan ya nile wọn ni Canada ṣaaju bibeere fun iyọkuro ninu iṣẹ ile Ọba ni eyit i Ọbabinrin Elizabeth ti tu wọn silẹ bayii pe o dabọ. Ile Ọba ni Haary ati Meghan ko ni maa lo orukọ oye wọn ati pe wọn ko ni maa na ninu owo ile Ọba mọ
Gbogbo aworan yii lo ni awọn to ni wọn bi a ṣe darukọ wọn.
Ẹ má mu gaarí mọ́ nítorí ìbà Lassa- Dókítà Boniface
Oríṣun àwòrán, @Others
Dokita Okolo ni ọpọ ninu awọn eku to maa n ko arun iba Lassa lo n rin ninu gaari ti awọn eeyan n mu
Adari ẹka eto ilera ni ipinlẹ Enugu, Oniṣegun oyinbo Boniface Okolo ti kilọ fawọn eniyan Naijria.
O ni iwadii ti fihan pe lara gaari ni awọn ekute ile ti maa n tan arun iba Lassa kalẹ.
Okolo fi ikilọ yii sita lasiko to n ni ifọrọwanilẹnuwo pẹlu ileeṣẹ iroyin Naijiria (NAN) nilu Enugu.
O ni o ti di dandan ki eleto ilera kilọ fawọn ara ilu lori ipa ti ekute ile ati gaari n ko ninu itankale Iba Lassa.
Dokita Okolo ni o ṣe pataki lati kilọ nipa mimu gari lasiko yii nitori pe wọn kii fi omi gbigbona muu bi ẹba.
'Owó tí mo ń rí lórí Garri ni mo fi ń ran ọkọ lọ́wọ́'
Dokita Boniface ni omi gbigbona ti wọn n fi si ẹba fi tẹẹ a maa pa kokoro arun lassa ninu gaari ṣugbọn omi tutu ko ni pa kokoro naa ti awọn eeyan ba fi mu gari.
Eku ọlọmu pupọ lo nfa iba Lassa
Dokita ni o san lati fi gari tẹ ẹba ju lati muu lọ nitori itankalẹ arun iba lassa yii.
O ni awọn oṣiṣe eleto ilera n gbiyanju lati gbogun ti itankalẹ arun buruku yii paapaa nipinlẹ Enugu ṣugbọn gbogbo ara ilu gbọdọ fọwọsowọpọ lati ja ija ilera naa yanju ni.
Super touch: Roller Blader ni mí láti ọdún mẹ́jọ sẹ́yìn
Bakan naa lo tun kilọ pe ki awọn eeyan ma fọ eso ati ewebẹ wọn daadaa ki wọn to jẹẹ.
Ni ipari o ni ki onikaluku ṣọra lori ọna ti wọn n gab fi ounjẹ pamọ ki ekute ile ma ti lọ tẹnu bọọ ki wọn si ko arun Lassa sinu ounjẹ naa.
Títí d'òní, Bàbá mi dara pọ̀ mọ́ iṣẹ́ ológun kò sí padà wálé - Grandma Biafra
O ni ki awọn eeyan maa lo ike ọlọmọri to de daadaa ki wọn to fi ounjẹ silẹ ninu ikoko lai dee daadaa.
Wo àwọn ìbejì tó lẹ́ pọ̀ lẹ́yìn àṣeyọrí ìṣẹ́ abẹ dókìtà 70
PDP yóò wọ́de lọ́jọ́ Ajé nítorí ìdájọ́ ìdìbò gómìnà ìpínlẹ̀ Imo
Oríṣun àwòrán, @OfficialPDPNig
Ẹgbẹ oṣelu PDP ti ni lọjọ Aje, ogunjs oṣu kinni ọdun 2020 lawọn yoo fọn sigboro lati fi ẹhonu han lori idajọ ileẹjọ to ga julọ lorilẹede Naijiria eleyi to yi Emeka Ihedioha lagbo da sina gẹgẹ bii gomina ipinlẹ Imo.
Nilu Abuja ni ẹgbẹ oṣelu PDP ti sọ pe iwọde naa yoo ti waye.
Ninu atẹjade kan ti ẹgbẹ oṣelu PDP gbe sita, awọn alaṣẹ ẹgbẹ oṣelu naa bẹrẹ lati ori alaga rẹ, Uche Secondus ti fọwọsi iwọde naa pe ko waye.
Oniruuru awijare ati ariyanjiyan lo ti waye lori idajọ naa to waye lọjọ iṣẹgun eyi to sọ Hope Uzodinma ti ẹgbẹ oṣelu APC di gomina ipinlẹ Imo lẹyin ti ile ẹjọ to gaju lorilẹede Naijiria yẹ aga mọ Ihediora nidi.
Oríṣun àwòrán, @OfficialPDPNig
Ẹgbẹ oṣelu PDP ni iwọde naa yoo lọ nirọwọ rọsẹ ko si ni ni rogbodiyan kankan ninu rara.
Nibayii awọn ọmọ ẹgbẹ oṣelu PDP ti bẹrẹ iwọde lawọn ipinlẹ kọọkan ni ọjọ Aiku ni imura silẹ fun eyi ti yoo waye nilu Abuja lọjọ Aje.
Super touch: Roller Blader ni mí láti ọdún mẹ́jọ sẹ́yìn
Abule Egba Explosion: Ọ̀pọ̀ ẹ̀mí àti dúkìá ṣòfò níbi ọ̀pá epo tó gbiná
Oríṣun àwòrán, @adebolaolu2019
Iroyin to tẹ wa lọwọ lati agbegbe Abule Egba, ipinlẹ Eko ti ọpa epo bẹntiroo ti gbina ni wi pe eeyan marun un lo ba iṣẹlẹ naa rin.
Ninu eeyan marun un ọhun, ọmọdebinrin to jẹ ọmọ ọdun marun un kan wa nibẹ, agbalagba ọkunrin mẹta ati agbalagba obinrin kan.
Bakan naa bii eeyan ogun lo fara pa ṣugbọn ti wọn tọju wọn loju ẹsẹ nibi iṣẹlẹ naa.
Ile bii mẹfa, ile itaja mẹtadinlogun ati ọkọakoyanrin mẹtalelọgbọn, ọkọ ayọkẹlẹ mẹta ati kẹkẹ NAPEP alupupu mẹta.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Lasiko ti ọ̀pá epo bẹ́ntiró naa gbiná l'Eko, ọ̀pọ̀ ẹ̀mí lo lọ síi.
Oluwatoyin Ojo to jẹ ọkan lara awón alafojuri to wa nibi iṣẹlẹ naa ni ori lo ko oun yọ.
O ni ko pẹ ti oun n jade lọ si agbegbe Meiran ni alẹ ana ọjọ Aiku ti oun k'ẹfin ero to pọ ti wọn n gbọn epo bẹntiroo nitosi ile epo nla ti NNPC to wa ni opopona Ekoro.
Oluwatoyin Taiwo Ojo ṣalaye pe bi oun ṣe ri ero to pọ yii to tun ti fa sunkẹrẹ- fakẹrẹ ọkọ ni oun ba ṣeri pada.
Oríṣun àwòrán, LASEMA
Oluwatoyin ni ko pe iṣẹju aaya lẹyin ti ọkọ oun pada ni oun gbọ ariwo nla ti ina ti sọ ti o si dabi ala ti ọpọ ero n sa asala fun ẹmi wọn.
Koko to gba ẹnu awọn eeyan ni owuro yii ni pe asiko ti to lati mọ pe gbigbon epo bentiroo to n danu kọ ni ọna abayọ lasiko yii nitori ewu rẹ pọ ju owo ti o maa ri nibẹ lọ.
Hepatitis: A kò leè kóo nípa dídìmọ́ ara ẹni
Bayi, ajọ LASEMA to n mojuto iṣẹlẹ pajawiri nipinlẹ Eko ni wọn ti ri ina naa pa nitori pe wọn ti ti ọpa epo nla to n gbe epo naa bọ.
Alukoro ajọ naa,  Nosa Okunbor ni igbesẹ ti awọn ajọ ọhun gbe ni kia tete jẹ ki wọn rii pa loru ana.
O ni wọn ti fidiẹ mulẹ pe agbalagba meji ati ọdọmọkunrin kan ti doloogbe bayii pẹlu ọkọ akẹru mọkanla yatọ si ile to kun fun ọpolọpọ dukia.
Títí d'òní, Bàbá mi dara pọ̀ mọ́ iṣẹ́ ológun kò sí padà wálé - Grandma Biafra
Iná sọ, dúkìá parẹ́, níbi ọ̀pá epo tó gbíná l'Eko
Ọpa epo bẹntiro kan tun ti bu gbamu ti ina si sọ lagbegbe Oke odo ni ilu Eko.
Gẹgẹ awọn iroyin to n jade lati agbegbe naa ṣe sọ, ọpọlọpọ dukia ati ohun ini lo n jona lọwọ bayii nibẹ.
Iwadii fihan bayii pe awọn ọkundun ẹda ti n tori owo odi bẹ ọpa epo ijọba lagbegbe naa lati ji epo fa lo ṣokunfa ina ajoranju mọọ naa.
Ni asiko ti a fi n ko iroyin yii jọ, a ko ti fi idi rẹ mulẹ boya ẹmi lọ si iṣẹlẹ naa.
Super touch: Roller Blader ni mí láti ọdún mẹ́jọ sẹ́yìn
Ẹkunrẹrẹ iroyin n bọ wa...
premier league: Liverpool to ọrẹ́ sí ẹ̀yìn Manchester United pẹ̀lú àmì ayò méjì sí òdo
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Itakun Manchester United gbiyanju titi ṣugbọn ko lee da erin Liverpool duro lọna pe ko maa tẹsiwaju ninu ilepa rẹ lati gba liigi Gẹẹsi ti saa yii.
Ni ifẹsẹwọnsẹ to waye lalẹ ọjọ Aiku ni papa iṣire Anfield, ami ayo kan si odo ni Liverpool  fi gbẹyẹ mọ Manchester united lọwọ.
Ni iṣẹju kẹrinla ifẹsẹwọnsẹ naa ni Virgil, agbabọọlu Liverpool gba goolu kan ṣoṣo to pin awọn ẹgbẹ agbabọọlu mejeeji niya wọle.
Bi o tilẹ jẹ wi pe Liverpool gba bọọlu si awọn manchester United ni igba meji miran lasiko ifẹsẹwọnsẹ naa, wọn ko kaa nitori awọn aṣemaṣe ti wọn ṣe ṣaaju rẹ.
Amọṣa nigba ti ifẹsẹwọnsẹ naa wọ iṣẹju kẹtalelaadọrun ti orun n rebi atiwọ ni Mohammed Sallah ba tun fi ọba lee fun Liverpool.
Pẹlu abajade ifẹsẹwọnsẹ naa, Liverpool lo ṣi n lewaju atẹ igbelewọn liigi ilẹ gẹẹsi bayii pẹlu ami ayo mẹrinlelọgọta ninu ifẹsẹwọnsẹ mejilelogun nigba ti  Manchester United ṣi di ipo karun un rẹ mu pẹlu ami ayo mẹrinlelọgbọn ninu ifẹsẹwọnsẹ mẹtalelogun.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ninu ọrọ ti o sọ ṣaaju ifẹsẹwọnsẹ ọhun, olukọni ẹgbẹ agbabọọlu Liverpool, Jurgen Klopp jẹ ko di mimọ pe awọn agbabọọlu oun yoo da ọpọlọpọ wahala silẹ fun Manchester United nitori pe bi awọn agbabọọẹu oun ba gba bọọlu daradara, awọn agbabọọẹu Manchester united yoo maa sa kijokijo lati di oju ile wọn ni o.
Ni tirẹ, olukọni Manchester United, Olu Gunner Solkjaer ni awọn mọ pe aja to wọle ts ẹkun lọrọ awọn nitori ibi to le gidigodo lawọn wa yii, ikọ to si ja fafa lawọn wa koju.
Ni saa kini, Liverpool ta ayo gidigidi, ṣugbọn laifọta pe,
Supreme court judgement: Àwọn ọmọ ẹgbẹ́ PDP fẹ̀hónú hàn nílé ẹjọ́ gíga jùlọ
Oríṣun àwòrán, OTHER
Àwọn ọmọ ẹgbẹ́ PDP fẹ̀hónúhàn nílé ẹjọ́ gíga jùlọ
Lafikun bi ile ẹj to ga julọ lorilẹede Naijiria ṣe dajọ pe Gomina Ganduje ti Kano ati Gomina Tambuwal ti Sokoto lo wọle, ile ẹjọ kan naa ti kede Gomina Simon Lalong gẹgẹ bi ajawe olubori ibo gomina ni ipinlẹ Plateau.
Ọjọ aje ọjọ̀ kẹwaa oṣu kinni ọdun eyi to ṣe gẹlẹ oṣu mẹwaa lẹyin ti ajọ ele5to idibo, INEC da gomina Lalong pada gẹgẹ bi ajawe olubori idibo to waye ninu oṣu kẹta ọdun to kọja.
Jeremiah Useni ti ẹgbẹ oṣelu PDP lo pe ẹjọ naa ni ile ẹjọ giga julọ lati pe ikede ẹgbẹ oṣelu APC nija gẹgẹ bi ẹgbẹ ti ajọ INEC kede.
Ẹwẹ, ile ẹjọ fagi le ipẹjọ rẹ pẹlu ipohun pọ dajọ nile ẹjọ giga julọ labẹ idajọ adajọ Adamu Galinje.
Ile ẹjọ ni olupẹjọ kuna lati fi gbogbo ọna to ni Simon Lalong fi tẹ anfani ati jawe olubori ara rẹ nidi nibi idibo ọjọ kẹsan oṣu kẹta ọdun 2019.
Ọgọọrọ awọn alatilẹyin ẹgbẹ oṣelu PDP lo ṣewọde niluu Abuja lọjọ Aje lẹyin idajọ ileẹjọ giga julọ to f'ountẹ lu Gomina Abdulahi Ganduje gẹgẹ bi ẹni to jawe olubori nipinlẹ Kano.
Awọn adajọ ẹlẹni meje ti Adajọ agba Naijiria, Muhammed Tanko ṣaaju da ẹjọ ti Abba Yusuf to jẹ oludije lẹgbẹ oṣelu PDP pe lati tako wiwọle Gomina Ganduje ti ẹgbẹ oṣelu APC nu.
Eyi lo mu kawọn alatilẹyin ẹgbẹ oṣelu PDP bẹrẹ ifẹhonuhan ninu eyi ti wọn ti n sọ pe awọn ko faramọ idajọ ileẹjọ to giga julọ.
Ilé ẹjọ́ gíga jùlọ fi òǹtẹ̀ lu Tambuwal (PDP) gẹ́gẹ́ bíi gómìnà ìpínlẹ̀ Sokoto
Ile ẹjọ to ga julọ ti fi ontẹ lu Aminu Tambuwal gẹgẹ bi gomina ipinlẹ Sokoto.
Awọn adajọ da ẹjọ oludije fun ipo gomina fẹgbẹ oṣelu APC, Ahmed Aliyu nu lẹyin ti wọn fidi rẹ mulẹ pe Tambuwal lo wọle ibo naa.
Oríṣun àwòrán, Facebook/Aminu Tambuwal
Igbẹjọ ti wa ni idaduro bayii lẹyin ti ile ẹjọ ti yanju awuyewuye to jẹyọ ninu ibo gomina ipinlẹ Sokoto ati Kano.
Ẹwẹ, iroyin ti a gbọ ni pe rogbodiyan bẹ silẹ laarin awọn alatilẹyin ẹgbẹ oṣelu PDP ati APC niwaju ileẹjọ to ga gulọ l'Abuja.
Oríṣun àwòrán, @others
Ile ẹjọ to ga julọ ni Naijiria ti fi ountẹ jan Ganduje gẹgẹ bii gomina ipinlẹ Kano
Ganduje máa bá iṣẹ́ rẹ lọ- ilé ẹjọ́ gíga jùlọ
Awọn adajọ ẹlẹnu meje ti Adajọ agba Naijiria, Muhammed Tanko ṣaaju ti ni ki Gomina Ganduje  maa ba iṣẹ rẹ lọ.
Eyi ni idajọ lori ẹjọ ti Abba Yusuf to jẹ oludije lẹgbẹ oṣelu PDP pe tako wiwọle Gomina Ganduje ti ẹgbẹ oṣelu APC ninu eto idibo to kọja.
Ṣaaju ni wọn ti kọkọ gbọ ẹjọ naa nile ẹjọ kotẹmilọrun ni Kano.
Bayii, Adajọ Sylvester Ngwuta sọ pe ko si idi lati tẹsiwaju pẹlu idajọ naa biko ṣe pe ki Gomina maa ba iṣẹ rẹ lọ titi di 2023 gẹgẹ bi gopmina ipinlẹ Kano.
Bala Muhammed, gómìnà ìpínlẹ̀ Bauchi ti dé sílé ẹjọ́ ní Abuja Kano Governorship: Ilé ẹjọ sún ìgbẹ́jọ Ganduje sí ogunjọ oṣù kíní
Fọ́fọ́ ni ilé ẹjọ́ ti kún báyìí látàri ìgbẹ́jọ́ lórí ìdìbò ìpínlẹ̀ Kano, Sokoto àti Bauchi
Bi ẹ ko ba gbagbe lasiko igbẹjọ idibo ipinlẹ Bauchi ti Bala Muhammed n tukọ re lọsẹ to kọja ni wọn ni ara ré ko ya.
Eyi lo si jẹ ki wọn gbe e lo fun itọju nile iwosan nilẹ okeere.
Hepatitis: A kò leè kóo nípa dídìmọ́ ara ẹni
Lonii, pẹlu inu fuu, aya fuu lori idajọ ipinlẹ Imo ni awọn ero ṣe pe silẹ ẹjọ, Koda awọn gomina ti ọrọ kan paapaa ti de.
Ọpọlọpọ awọn agbẹjọrọ ni ko ri aaye jọko si ninu ile ẹjọ to ga julọ bayii.
Awon agbejoro ko ri aga joko si nile ejo nitori pe ero ti po ju
Fọ́fọ́ ni ilé ẹjọ́ ti kún báyìí látàri ìgbẹ́jọ́ lórí ìdìbò ìpínlẹ̀ Kano, Sokoto àti Bauchi:
Awon ero lorisirisi ni won ti kun ile ẹjọ giiga lati mọ ibi ti ọrọ maa ja si lonii
Loni ni idajọ ile ẹjọ to ga julọ lori igbẹjọ ẹni ti yoo maa tukọ ipinlẹ Kano, sokoto ati Benue.
Ṣaaju ni oni ọjọ Aje lo yẹ ki ile-ẹjọ to ga ju lọ ni Naijiria dajọ awuyewuye to jẹyọ nibi ibo gomina awọn ipinlẹ naa.
Oludije fun ipo gomina labẹ asia ẹgbẹ oṣelu PDP, Abba Kabir Yusuf lo pe oludije ẹgbẹ oṣelu APC, Abdullahi Umar Ganduje to jawe olubori ninu ibo gomina ipinlẹ Kano lẹjọ.
Ṣaaju, oni ọjọ Aje lo yẹ ki ile-ẹjọ to ga ju lọ ni Naijiria dajọ awuyewuye to jẹyọ nibi ibo gomina awọn ipinlẹ naa.
Ibẹru bojo wa ni ọkan awọn eniyan ipinlẹ naa latari ohun to ṣẹlẹ nile ẹjọ lọṣẹ to kọja lori igbẹjọ ipinlẹ Imo Àsọtẹ́lẹ̀ Fada Mbaka, tó yẹ àga mọ́ gómìnà Imo nídìí rèè
Ohun gbogbo ti wa ni ikale lasti bere igbejo naa
Saaju ni Ile ẹjọ to ga ju lọ lorilẹ-ede Naijiria ti sun igbẹjọ to yẹ ko waye lọsẹ to kọja si oni lori idibo ipinlẹ marun un to ku lẹyin ti wọn dajọ ti ipinlẹ Imo.
Adajọ agba Naijiria, Adajọ Tanko Muhammad lo pa aṣẹ naa lẹyin ti awọn oniṣẹ aabo ko lee kapa aduru ero to wa nibẹ ati ariwo pupọ ninu ile ẹjọ.
Adajọ Muhammad lo dari igbimọ igbẹjọ ẹlẹni meje to jẹ asan adajọ lati gbọ ẹsun awuyewuye to jẹyọ nibi ibo gomina ipinlẹ Bauchi, Kano, Sokoto, Plateau, Benue.
'Opọlọpọ awọn agbẹjọro lo n forigbari lati fẹnuko lori ọrọ ikẹyin wọn ti yoo gbe are fun onibara wọn
Fọ́fọ́ ni ilé ẹjọ́ ti kún báyìí látàri ìgbẹ́jọ́ lórí ìdìbò ìpínlẹ̀ Kano, Sokoto àti Bauchi
Awon adajo kookan ti n de sile ejo to ga julọ nilu Abuja
Gbogbo ni awọn agbofinro kun ile ẹjọ f
Isabel dos Santos: Obìnrin tó lówó jùlọ ní Africa 'ja orílẹ̀-èdè rẹ̀, Angola lólè' fi kó ọ̀rọ̀ jọ
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Awọn iwe akọsilẹ kan ti aṣiri rẹ tu sita ti ṣafihan bi obinrin to l'owo julọ nilẹ Africa ṣe ko ọ̀rọ̀ rẹ jọ nipa lilo orilẹ-ede rẹ fun anfaani ara tiẹ, ati nipa iwa ibajẹ.
Isabel dos Santos anfaani si awọn idokowo to jọ oju nigbese bi i ilẹ, eporbi, okuta iyebiye(diamond) ati eto ibaraẹni sọrọ, lasiko ti baba rẹ fi jẹ aarẹ Angola. Orilẹ-ede Angola wa ni Gusu ilẹ Africa, o si kun fun awọn nkan alumọọni.
Awọn iwe akọsilẹ naa fi bi wọn ṣe fi aaye gba oun ati ọkọ rẹ lati ra awọn dukia ijọba to jẹ olowo iyebiye l'ọnna to mu ifurasi dani.
Arabinrin Dos Santos sọ pe irọ patapata ni awọn ẹsun ti wọn fi kan oun, ati wi pe ọtẹ oṣelu ti ijọba orilẹ-ede Angola n ṣe ni.
Orilẹ-ede UK ni ọmọ aarẹ nigba kan ri ọhun n gbe, to si ni ọpọlọpọ dukia olowo iyebiye ni aarin gbungun ilu London.
Lọwọlọwọ, awọn alaṣẹ orilẹ-ede Angola ti n wadii rẹ fun iwa ibajẹ, wọn si ti gbẹsẹ le awọn dukia rẹ to wa ni orilẹ-ede naa.
Ọpọ awọn iwe naa ni ajọ to n daabo bo awọn to n tani lolobo ni Africa; Platform to Protect Whistle-blowers in Africa.
Wọn si ṣe ajọpin awọn iwe naa pẹlu ẹgbẹ awọn akọroyin to n ṣewadi abẹnu l'agbaye.
Ìdá ọgbọ̀n àwọn ọmọ orilẹ-ede Angola lo n gbe ninu òṣì
Ọkan lara awọn okoowo to ṣe to mu ifurasi dani ni ti epo to ṣe nipasẹ ẹka ileeṣẹ eporọbi orilẹ-ede Angola, Sonangol.
Arabinrin Dos Santos ni wọn fi jẹ alamojuto ileeṣẹ Sonangol l'ọdun 2016, ni aṣẹ baba rẹ, Jose Eduardo dos Santos, to lo ọdun mejidinlogoji nipo aarẹ.
Ṣugbọn ẹni to gba ipo aarẹ lẹyin ti baba rẹ fẹhinti lọdun 2017 yọ Arabinrin Dos Santos kuro ni ipo naa.
Awọn iwe akọsilẹ aṣiri wọn tu sita fihan pe bi Santos ṣe n fi ipo naa silẹ, lo buwọlu sisan miliọnu mejidinlọgọta Dọla ($58m) fun ileeṣẹ ọrọ rẹ kan nilu Dubai, Matter Business Solutions.
Ileeṣẹ eporọbi Angola, Sonangol ni ẹka nilu London, nibiti awọn okoowo to mu ifurasi dani ti waye.
Bo tilẹ jẹ pe ileeṣẹ Matter ṣe awọn akanṣe iṣẹ kan fun Sonangol, ko fi bẹ si akọsilẹ pe o yẹ ki o gba to owo ti wọn buwọlu fun un.
Awọn agbẹjọro Dos Santos sọ pe gbogbo owo ti wọn san fun ileeṣẹ Matter lo ba ofin mu, ati pe kii ṣe igba ti wọn le e kuro nipo lo buwọlu u.
Ọkọ Arabinrin Dos Santos, Sindika Dokolo, fi ọwọ si iwe adehun ẹlẹnikan ni ọdun 2012 pẹlu ileeṣẹ orilẹ-ede Angola, Sodiam, to n pese 'diamond'.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Sindika Dokolo, ọkọ Isabel dos Santos, to jẹ ọmọ orilẹ-ede DR Congo jẹ gbaju-gbaja olokoowo
O yẹ ki ọkọ rẹ ati ileeṣẹ naa o pin owo idokoowo ti wọn ṣe ni ileeṣẹ to n ṣe ẹṣọ ara ni Switzerland, De Grisogono dọgba-dọgba ni, ṣugbọn, ileeṣẹ ijọba lo ko owo to pọju silẹ.
Iwe akọsilẹ naa si fihan pe niṣe ni Sodiam ya gbogbo owo to lo ni banki aladani kan, ti Arabinrin Dos Santos ti jẹ oludokowo to tobi julọ.
Mo kabamọ pe Angola yan ipa ọna yii.
Bravo da Rosa, to jẹ ọga agba tuntun fun Sodiam sọ fun Panorama pe awọn eniyan Angola ko ri owo kankan botiwu ko kere mọ lara okoowo naa.
"Nigba ti ao ba fi san gbese naa tan, Sodiam yoo padanu owo to le ni igba miliọnu Dọla ($200m).
Aṣiri tun tu pe Arabinrin Dos Santos ra ilẹ kan to wa ni eti okun Luanda l'oṣu Kẹsan, ọdun 2017, o si san asansilẹ owo kekere.
Ọpọlọpọ awọn eniyan lo si di alainilelori nigba ti wọn le wọn kuro lori ilẹ naa ti wsn fẹ ẹ fi kọ ilu tuntun Futungo.
Awọn araalu sọ iriri wọn nipa gbigbe ni 'tosi ibi ti wọn n da igbọnsẹ si ni Angola
Yatọ si eyi, mọlẹbi bi ẹẹdẹgbẹta ni wọn tun le kuro nibi ti ilẹ naa ṣan de lẹyin ti Dos Santos tun bẹrẹ iṣẹ miran.
Ni bayii, 'tosi ibi ti wọn n da igbẹ si ni awọn mọlẹbi naa n gbe, ti igbẹ si maa n ṣan wọ ile wọn ti riru okun ba pọ.
Obinrin olowo tabua yii tun jẹ eere pupọ ni ẹka ibaraẹnisọrọ ni Angola.
Ìdá mẹẹdọgbọn ni ìpín rẹ ni ileeṣẹ ibaraẹnisọrọ alagbeka to tobi ju ni Angola, Unitel.
O tilẹ lo anfaani naa lati mu ki Unitel o ya ileeṣẹ tuntun kan to da silẹ ni ọtalelọọdunrun miliọnu Pọhun, yatọ si biliọnu kan Dọla ti ileeṣẹ naa ti san fun un.
Hepatitis: A kò leè kóo nípa dídìmọ́ ara ẹni
Orukọ ileeṣẹ naa, Unitel International Holdings, mu ifurasi dani, nitori pe ko ni ibaṣepọ kankan pẹlu Unitel, Arabinrin Dos Santos lo si ni i.
Awọn iwe akọsilẹ naa fihan bi Ms Dos Santos ṣe buwọlu iwe owo yiya gẹgẹ bi ẹni to yawo, ati ẹni to ya wọn ni owo, ti ko si yẹ ko ri bẹ ẹ.
Arabinrin Dos Santos ati awọn agbẹjọro rẹ sọ pe gbogbo awọn to yẹ ko fi ọwọ si owo yiya naa lo mọ si i.
Ati pe awọn ya owo naa lati fi daabo bo Unitel lọwọ bi owo ṣe n ṣe ṣege-ṣege.
Orisun: Forbes magazine ati awọn miran
UK-Africa summit: Àǹfààní wo ló wà nínú Brexit fún Nàìjíríà àtàwọn orílẹ́èdè Afíríkà rèé
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Lẹyin ti eto Brexit ba yanju tan ti UK si kuro lara ajọ EU, ijọba UK n gbero lati jẹ ki ajọsẹpọ rẹ lori idokowo pẹlu Afirika ko gberu sii.
BBC ṣe agbeyẹwo anfaani to le jẹ yọ fun ilẹ adulawọ nigba ti eto Brexit ba kẹsẹ jari nilẹ Gẹeṣi.
Akọroyin BBC, Matthew Davies BBC ṣalaye pe ọrọ le maa ri bi eeyan ti ro nigba miiran.
Ti gbogbo eto ba lọ ni irọwọ rọsẹ, ipari oṣu kinni ọdun 2020 yii ni UK fẹ fi ajọ EU silẹ patapata.
Lẹyin naa ni ilẹ Gẹẹsi yoo ṣe agbalẹ ọna ti wọn yoo fi maa ṣe idokowo pẹlu awọn orilẹede mii ti fi mọ ilẹ Afirika naa.
Hepatitis: A kò leè kóo nípa dídìmọ́ ara ẹni
Ṣugbọn ọna wo gan an ni Afirika yoo fi jẹ anfaani ti ilẹ Gẹẹsi ba fi ajọ EU silẹ tan?
Akọwe ijọba UK lori ọrọ idagbasoke pẹlu ilẹ okere, Alok Sharma sọ pe ijọba ilẹ Gẹẹsi yoo ṣe imugbooro iṣowo ati idokowo pẹlu ilẹ adulawọ kete ti eto Brexit ba ti bẹrẹ.
Oríṣun àwòrán, Cristina Aldehuela/AFP/Getty
O ni lori ọrọ yii gan an ni apero lori idokowo to n lọ lọwọ niluu London laarin ilẹ Gẹẹsi atawọn orilẹede Afirika da le lori.
Ti UK ba ti fi ajọ EU silẹ, anfaani awọn orilẹede Afirika yoo pọ si ọrọ idokowo.
Oríṣun àwòrán, @UKinNigeria/Twitter
Ilẹ Gẹẹsi yoo gbiyanju lati rii pe idokowo rẹ pẹlu ọrilẹede Amẹrika, South Korea ati Australia gberu si lẹyin to ba ti fi EU silẹ.
Ilẹ Adulawọ ni yoo kan ti yoo jẹ iru anfaani bayii lẹyin awọn orilẹede mẹrin yii.
Ni gbogbo igba ni Olootu ijọba ilẹ Gẹẹsi, Boris Johnson atawọn alatilẹyin rẹ maa n sọ pe Brexit yoo fun ilẹ Gẹẹsi lanfaani lati le duna-dura bo ti wu wọn lori ọrọ idokowo.
Wo àwọn ìbejì tó lẹ́ pọ̀ lẹ́yìn àṣeyọrí ìṣẹ́ abẹ dókìtà 70
Operation Amotekun: Atiku ní ẹ̀ṣọ́ alábòò Amọtẹkun yóò ṣ'èrànwọ́ lórí ètò ààbò tó mẹ́hẹ
Oríṣun àwòrán, Twitter/Atiku Abubakar
Atiku ní ẹ̀ṣọ́ aláábòò Amọtẹkun yóò ṣ'èrànwọ́ lórí ètò ààbò tó mẹ́hẹ
Oludije fun ipo aarẹ labẹ asia ẹgbẹ oṣelu PDP ninu ibo gbogboogbo ọdun 2019, Atiku Abubakar naa ti kede atilẹyin rẹ fun ẹṣọ alaabo Amọtẹkun.
Ninu ọrọ rẹ, Atiku ni idasilẹ ọlọpaa ipinlẹ tabi ọlọpaa ẹkunjẹkun yoo ṣe iranwọ lori eto aabo to mẹhẹ lorilẹede Naijiria.
Atiku fọrọ yii lede lọjọ Aiku lẹyin ti minisita fun ọkọ ofurufu tẹlẹ ri, Femi Fani-Kayode sọ pe ata akara ti ko ran ikọ lọrọ ti ijọba apapọ sọ pe idasilẹ Amọtẹkun ko ba ofin mu.
Ninu atẹjade ti Atiku fi sita lati ọwọ oludamọran rẹ lori ọrọ iroyin, Paul Ibe, igbakeji aarẹ orilẹ-ede Naijiria tẹlẹ ni bi eto aabo ṣe ri ni nnkan bi ọdun mẹwaa sẹyin fihan pe ọrọ eto aabo nilo atunṣe ni Naijiria.
Atiku ni ko fẹẹ ma si ipinlẹ kan lorilẹ-ede Naijiria ti ko ni idojukọ tabi ipenija kan tabi omiran lori ọrọ aabo.
Hepatitis: A kò leè kóo nípa dídìmọ́ ara ẹni
Atiku ni: ''Niwọn igba ti ipenija ipinlẹ kọọkan lori eto aabo ti yatọ si ra wọn, o tumọ si pe eto aabo ti ijọba apapọ nikan pese ko le dẹkun iwa ọdaran ati rogbodiyan ni Naijiria,
O ni idi eyi ni idasilẹ ẹṣọ eleto aabo bii Amọtẹkun fi ṣe pataki ni Naijiria.
Ẹwẹ, alaga ẹgbẹ awọn gomina ilẹ Yoruba to tun jẹ gomina ipinlẹ Ondo, Ọgbẹni Rotimi Akeredolu ti sọ pe awọn ko ṣe agbakalẹ Amọtẹkun lati tako iran mii ni Naijiria.
O leè má mọ̀ bóyá o ní àrùn HIV/AIDS o! Wo àwárí akọ́ṣẹ́mọṣẹ́ yìí
Akeredolu kilọ fawọn to n fi oju ẹlẹyamẹya wo Amọtẹkun pe eto aabo to munadoko lo jẹ awọn logun, eyi lo fa sababi ifilọlẹ Amọtẹkun.
Wo àwọn ìbejì tó lẹ́ pọ̀ lẹ́yìn àṣeyọrí ìṣẹ́ abẹ dókìtà 70
Awọn ọtọkulu bi Ọjọgbọn Wole Soyinka, eekan ẹgbẹ Afenifere, Oloye Ayo Debanjo; agbẹjọro agba ati ajafẹtọ, Femi Falana, Oloye Olu Falae, ati Aarẹ Ọnakakanfo, Iba Gani Adams atawọn mii ni wọn ti sọrọ lati gbaruku ti eto Amọtẹkun.
Super touch: Roller Blader ni mí láti ọdún mẹ́jọ sẹ́yìn
Child Abuse: Ọmọ ọdún mẹ́wàá ń ké ìrora lẹ́yìn tí ọ̀gá tì í sínú àrò búrẹ́dì
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Irora nla ni ọmọkunrin ọdun mẹwa kan to jẹ ọmọ ileewe almajiri, Nafiu Usman to ti n jẹ irora lati igba ti wọn ti fi ẹsẹ rẹ mejeji jona nileeṣẹ burẹdi kan lori ẹsun pe o ji burẹdi oni ọgọrin naira (N80).
Lai lai, ko si ẹni to lee ni imọlara iru irora ti o la kọja bi ọga rẹ ṣe n ti ẹsẹ rẹ bọ inu iho ina to n jo hii hii.
Ọpọ awọn ara ipinlẹ Gombe ni ọrọ yii ṣi n ya lẹnu idi ti oludari ileeṣẹ burẹdi naa, Idris Abubakar yoo kan ṣe dede jo ẹsẹ ọmọ ọdun mẹwa nina ninu ina aro ti wọn fi n ṣe burẹdi.
Ẹgbẹ kan to n ja fun ẹtọ araalu Muryar Talaka sọ fun BBC pe ọwọ ti tẹ afurasi naa ṣugbọn ti wọn tun pada da a silẹ nigba ti oku ọmọ naa si wa nile rẹ.
Ahmed Sulaiman to jẹ adari ẹgbẹ Muryar Talaka sọ fun BBC pe oun bẹ ọmọkunrin naa wo ti olukọ ile keu si ti n tọju ara rẹ.
Ni agbegbe Bajoga ni ijọba ibilẹ Funakaye, ipinlẹ Gombe ni Usman wa lati wa kọ ẹkọ keu lati odidi Tafawa Balewa, ipinlẹ Bauchi.
Ahmed ni oun to ṣẹlẹ ni pe ọludari ile iṣẹ burẹdi naa fi ẹsun kan ọmọkunrin ọhun pe o ji burẹdi lo ba ti i sinu iho ina ti wọn fi n yan burẹdi."
Iroyin ti a gbọ ni wi pe ọga ileeṣẹ burẹdi yii ko ẹsẹ Nafiu sinu ina aro ti wọn da si abẹ burẹdi, nigba to yọ ọ jade to ri i pe ko jo o daadaa o tun ju u sinu ina lẹẹkan sii.
Hepatitis: A kò leè kóo nípa dídìmọ́ ara ẹni
Ko pẹ rẹ ni ọlọpaa tu ọga ileeṣẹ burẹdi naa silẹ ṣugbọn ọmọ ti wọn jo ẹsẹ rẹ nina ṣi wa ninu irora kikan.
Nigba to kuro ni atimọle ọlọpaa, o lọ bẹ ọmọ naa wo nile ṣugbọn ọga ile keu kan ti tọju ara ọmọ naa.
Ṣugbọn adari ẹgbẹ Muryar Talaka, sọ pe afurasi ọhun kuro ni atimọle lẹyin ti eekan kan ninu ilu lọ gba beeli rẹ.
Bakan naa o ni lọgan ni wọn ti ṣe iwe ẹri sita pe arun ọpọlọ n da Idris ọga ileeṣẹ burẹdi ọhun laamu.
ẹwẹ, nigba ti ileeṣẹ BBC kan si alukoro ọlọpaaa agbegbe naa o fesi pe oun ko tii gbọ nipa iṣẹlẹ yii ṣugbọn oun yoo kan si BBC pada lori bo ṣe jẹ bi wọn ba ti gbọ iroyin kankan.
Oyo Algon: Ìjọba àpapọ̀ kò gbẹ́sẹ̀lẹ̀ lé owó tó tọ́ sáwọn ìjọba ìbílẹ̀ l‘Ọyọ
Oríṣun àwòrán, @Makinde Instagram
Ìpínlẹ̀ Oyo kò ri lẹ́ta kankan gbà láti ọ̀dọ̀ Malami lóri ọ̀rọ̀ àwọn alága Kansu
Lórí ọ̀rọ̀ kan to gbà gboro kan pé àgbẹjọrò àgbà orilẹ̀-èdè Naijiria, Abubakar Malami ti paṣẹ fún gómìnà ìpínlẹ̀ Oyo láti gba àwọn alága kansu ti wọ́n yọ nípò pada, ijọba Ọyọ ti fesi lori isẹlẹ naa.
BBC Yoruba kan si akọwé ìkéde ìjọba ìpińlẹ̀ Oyo, Ọgbẹ́ni Taiwo Adisa lórí ọ̀rọ̀ náà sùgbọ́n o ni, ìrọ to jìnà si òtítọ ni nítori pé títí di àsìkò ti òun ń ba ilé iṣẹ́ BBC sọrọ, ko ti si lẹ́ta kankan to jọ bẹ́ẹ̀ láti ọ̀dọ̀ Malami.
O fí kun pé ko si ìgbà kankan ti Malami jáde láti sọ pe òun kọ lẹ́tà ránṣẹ́ si ìpínlẹ̀ Oyo, pẹlu afikun pe, o se pàtàki ki àwọn akọroyin máa ṣe ìwádìí wọ́n dáradára, ki wọ́n to maa tan ìròyìn ti ko fi ìdí múlẹ̀ káakiri.
Oríṣun àwòrán, Ayodeji Abass Aleshinloye
Lori àhesọ ọ̀rọ̀ kan to sọ pé, ìjọba ìpinlẹ̀ Oyo ko rí owó gbà láti ọ̀dọ̀ ìjọba àpàpọ fún àwọn ìjọba ìbilẹ̀, nítori pé àwọn alaga fidiẹ ni wọ́n fi si ìjọba Kansu, Adisa ni ofo ọjọ keji ọja ni ọrọ ọhun.
 Ẹni ti wọ́n ba nà ló yẹ ki ara maa ta, tí ìjọba ìpínlẹ̀ Oyo ko ba ri owó gbà, ẹnu ìjọba ìpínlẹ̀ ni ẹ o ti gbọ ki ṣe ẹnu àwọn ìròyìn ẹlẹ́jẹ̀. Nitorinaa, ofuutu fẹẹtẹ ni iroyin to ni awọn ijọba ibilẹ ni Ọyọ ko ri owo to tọ si wọn gba lati ọdọ ijọba apapọ.
Makinde, dá àwọn alága ìjọba ìbilẹ̀ padà sípò- Abubakar Malami
Makinde, dá àwọn alága ìjọba ìbilẹ̀ padà sípò- Abubakar Malami
Agbẹjọ́rò àgbà àti mínísita fun ètò ìdájọ, Abubakar Malami ti pàṣẹ̀ fún gómìnà ìpínlẹ̀ Oyo, Seyi Makinde láti ṣe àyipada ìpinnu rẹ̀ lóri bo ṣe tú àwọn alága ìjọba ìbílẹ̀ ká ni ìpínlẹ̀ Oyo.
Èyí wáyé nínú lẹ́ta ti o fi síta ni ọjọ kẹrinlá, oṣù kínní 2020, ránṣẹ́ sí agbẹjọrò àgbà àti kọmisọna ètò ìdájọ ni ìpínlẹ̀ Oyo.
Lẹ́tà to pe àkọlé rẹ̀ ní yíyọ àwọn Gómìnà ti wọ́n dìbò yan lọ́nà àitọ àti yíyan àwọn ìgbìmọ̀ alábojúto, titẹ̀lé ìdájọ di dandan.
Agbẹjọrò ìjọba àpàpọ ní ìpínnu ilé ẹjọ to gajù lọ ti fofin de gbogbo ìjọba ìpínlẹ̀ mẹ́rìnrìndílógoji.
"O ni: "" Àṣà àwọn gómìnà ni láti maa da àwọn alága ijọba ìbilẹ̀ sílẹ̀ ti wọ́n ba ti de ori òye, èyi ko ba òfin mu rárá."""
Farms to You: Irú ajílẹ̀ wo ló yẹ fún lílò lásìkò yìí- Aisha
"Malami ni: "" Mo bẹ gbogbo àwọn gómìnà ìpińlẹ̀ àti àwọn àbẹnugan ilé ìgbimọ aṣòfin ti wọ́n ń tẹ òfin ọdun 1999 lóju, ti wọn n ṣe àigbọràn si ilé ẹjọ to ga jùlọ."
"O ni pe o ṣe pàtàkì láti ṣe àtúnṣe to tọ ki wọn si dá wọ́n pada si ori oyè lojuna a ti fun àfin láàye ki wọ́n si ràn ìjọba awa ara wa lọ́wọ́."""
Hepatitis: A kò leè kóo nípa dídìmọ́ ara ẹni
" O ṣe pàtàkì láti tú gbogbo ìgbìmọ̀ alabojuto náà ka ki wọ́n sì dá àwọn alága ti wọ́n dìbò yàn pada sori oyè.
Ẹ̀wẹ̀, akọwé ìkéde fún gomina Seyi Makinde, Taiwo Adisa ni àwọn ko ri lẹ́ta kankan láti ọ̀dọ̀ agbẹjọro àgbà Naijiria.
O fí kun pé ti lẹ́ta naa ba ti tẹ àwọn lọ́wọ́, ìjọba yoo gbe ìgbésẹ̀ to ba yẹ.
Supreme court judgement: Ta ni Gómìnà Bala Mohammed?
Oríṣun àwòrán, Others
Ta ni Gómìnà Bala Mohammed?
Wọn bi Bala Abdulkadir Mohammed lọjọ karun un, oṣu Kẹwaa, ọdun 1958 nipinlẹ Bauchi.
O kẹkọọ gboye imọ ijinlẹ ninu ede Gẹẹsi ni Fasiti ilu Maiduguri lọdun 1982.
O ṣiṣẹ akọroyin pẹlu iwe iroyin The Democrat, ko to di oṣiṣẹ ijọba laarin ọdun 1984 si 2000.
O fẹyinti gẹgẹ bi Oludari ẹka amojuto ni ajọ to n wo òye oju ọjọ ni Naijiria.
Lẹyin naa lo di oluranlọwọ pataki fun gomina ipinlẹ Bauchi nigba naa, Isa Yuguda, laarin ọdun 2000 si 2005.
Wọn dibo yan an sipo sẹnetọ ẹkun idibo Guusu Bauchi l'ọdun 2007.
Aarẹ nigba kan fun Naijiria, Goodluck Jonathan yan an ni Minisita olu ilu Naijiria, FCT, lọdun 2010.
O wọle sipo gomina ipinlẹ Bauchi labẹ ẹgbẹ PDP, lẹyin ti atundi ibo waye ninu idibo apapọ ọdun 2019.
Ọjọ Kẹwaa, oṣu Kinni, ọdun 1966 ni wọn bi Tambuwal, nipinlẹ Sokoto
O pari ileewe alakọbẹrẹ l'ọdun 1979, o si darapọ mọ ileewe olukọni, Dogan-Daji Teachers College nibi to ti gba iwe ẹri Teachers Grade 11 l'ọdun 1984.
Farms to You: Irú ajílẹ̀ wo ló yẹ fún lílò lásìkò yìí- Aisha
Lẹyin naa lo darapọ mọ Fasiti Usman Dan Fodio nilu Sokoto, nibi to ti kẹkọọ gboye imọ ofin l'ọdun 1991.
Tambuwal bẹrẹ si ni kọ nipa oṣelu ṣiṣe laarin ọdun 1999 si 2000, nigba to n ṣe amugbalẹgbẹ lori ọrọ ile aṣofin, fun Sẹnetọ Abdullahi Wali, to jẹ olori ile aṣofin agba lasiko naa.
Oríṣun àwòrán, @others
Ta ni Gómìnà Aminu Waziri Tambuwal?
Wọn dibo yan an si ipo aṣoju ẹkun Kebbe / Tambuwal Federal Constituency nipinlẹ Sokoto l'ọdun 2003 labẹ ẹgbẹ oṣelu ANPP.
Tambuwal di awọn ipo kan mu nile aṣofin. bíi lọdun 2005, o di Olori ọmọ ẹgbẹ to kere ju nile aṣofin, ko to o di pe o lọ darapọ mọ ẹgbl PDP.
O tun di Akojanu ile lẹyin to tun pada wọle ibo lọdun 2007.
Bakan naa lo jẹ ọmọ igbimọ oriṣiriṣi nile aṣofin ko too di Tambuwal di Olori ile aṣoju-sofin kẹwaa
Ninu oṣu Kẹfa, ọdun 2011, Aminu Tambuwal di Olori ile aṣoju-ṣofin pẹlu ilana to mu iriwisi dani.
Oun lo gba ipo lọwọ Olori ile tẹlẹ, Dimeji Bankole.
Super touch: Roller Blader ni mí láti ọdún mẹ́jọ sẹ́yìn
Lọdun 2015, Aminu Tambuwal dije dupo gomina ipinlẹ Sokoto, o si wọle labẹ ẹgbẹ oṣelu APC.
L'ọjọ kinni, oṣu Kẹjọ, ọdun 2018, Tambuwal fi ẹgbẹ oṣelu APC silẹ, o si pada si PDP.
Lati inu ẹgbẹ oṣelu PDP lo si ti dupo gomina l'ọdun 2019, to tun fi wọle saa keji.
Oríṣun àwòrán, Twitter/Abdullahi Ganduje
Ta ni Gómìnà Kano Abdullahi Umar Ganduje?
Ọjọ Aje lawọn adajọ ẹlẹni meje nile ẹjọ giga julọ niluu Abuja sọ pe ki Gomina Abdullahi Umar Ganduje maa ba iṣẹ rẹ lọ gẹgẹ ni Gomina ipinlẹ Kano.
Ile ẹjọ da ẹjọ ti Abba Yusuf to jẹ oludije fẹgbẹ oṣelu PDP nu ninu eyi to ti sọ pe eeru wa ninu ibo to gbe Ganduje ti ẹgbẹ oṣelu APC wọle.
Amọ awọn adajọ meje nile ẹjọ to ga julọ dajọ pe awọn agbẹjọro PDP kuna lati fidi rẹ mulẹ pe eeru wa ninu ibo to gbe Ganduje wọle.
Pẹlu iadajọ yii, Gomina Ganduje yoo wa lọfiisi gomina ipinlẹ Kano titi di ọdun 2019.
Igbe aye Ganduje ree:
A bi Abdullahi Umar Ganduje lọdun 1949 labule Ganduje ni ijọba ibilẹ Dawakin Tofa nipinlẹ Kano.
O bẹrẹ si ni kọ Kewu ni kekere labule rẹ ko to lọ si ile iwe alakọbẹrẹ Dawaki Tofa laarin ọdun 1956 si 1963.
Ganduje teṣiwaju ẹkọ rẹ nile iwe girama lọdun 1964 si 1968.
Oríṣun àwòrán, Twitter/Abdullahi Ganduje
Ganduje kẹkọọ nile iwe olukọni bẹrẹ lati ọdun 1969 di ọdun 1972, lẹyin naa lo lọ si fasiti Ahmadu Bello niluu Zaria, ipinlẹ Kaduna nibi to ti kẹkọ gboye lọdun 1975.
Ganduje kẹkọọ gboye keji ni fasiti Ado Bayero lọdun 1979, bakan naa lo tun kẹkọọ gboye keji ninu isakoso ilu.
Bakan naa ni Ganduje tun kẹkọọ gboye ni fasiti ilu Ibadan lọdun 1993.
Ganduje wọ agbo oṣelu
Ganduje darapọ mọ ẹgbẹ oṣelu NPN nibi to to ṣe igbakeji akọwe lọdun 1979 si 1980.
O dije ninu eto idibo sile aṣoju-ṣofin niluu Kano lọdun 1979 labẹ asia ẹgbẹ oṣelu NPN, ṣugbọn o fidi rẹmi.
ọ darapọ mọ ẹgbẹ oṣelu PDP lọdun 1998, o si jẹ igbakeji gomina laarin 1999 si 2003.
Oríṣun àwòrán, Twitter/Abdullahi Ganduje
Ganduje dipo oludamọran fun minisita eto aabo, Rabiu Kwankwaso laarin ọdun 2003 si 2007.
O wọle ibo gomina ipinlẹ Kano lọdun 2015.
Ganduje tun wọle ibo gomina fun saa keji lọdun 2019, amọ ẹgbẹ oṣelu PDP pee lẹjọ pe eeru lo fi wọle.
Ṣugbọn ile ẹjọ giga julọ daa lare lọjọ Aje, ti wọn ko ba yọọ nipo, Ganduje ni yoo ṣe gomina ipinlẹ Kano di ọdun 2023.
Amotekun: Soyinka fèsì padà fún Balarabe Musa pé ó kùnà lóríí ikọ̀ aláàbò náà
Ọjọgbọn Wole Soyinka ti dasi ọrọ Amọtẹkun to n ja rain rain ni Naijiria eyi ti wọn ni gomina tẹlẹ nipinlẹ Kaduna, Balarabe Musa sọ nipa ikọ alaabo Amotekun.
Ninu atẹjade kan to fisita, Soyinka sọ pe Balarabe kuna pẹlu ọrọ to sọ nipa Amọtẹkun, eyi to ni o lee se okunfa iyapa ni orilẹede Naijiria ati agbekalẹ orilẹede Oduduwa.
Soyinka ni oun to ma n da wahala silẹ ni ''ki awọn eeyan kan ma mu ọrọ ibẹru gẹgẹ bi ọrọ ododo tabi ki ijọba ati awọn ẹya kan ma gbe igbesẹ latari ibẹru to gba ọkan wọn''
O ni iru iwa bayi kii labọ nitorinaa o wu oun ki Balarabe yẹra fun iru ọrọ tabi iwa bayi.
Balarabe gẹgẹ bi ohun ti iwe iroyin kan sọ lo ni idasilẹ Amẹtẹkun jẹ ọna kan ti ẹya Yoruba fẹ gba lati mu ipinya Naijiria wa.
O wa rọ aarẹ Buhari lati maṣe faye gba idasilẹ ikọ alaabo Amọtẹkun tawọn Gomina ipinlẹ Kaarọ o jiire dasilẹ.
Yatọ si ọrọ ọjọgbọn Soyinka, pupọ awọn to jẹ olori ẹgbẹ, yala ti Yoruba ati awọn agbẹjọro to fi mọ awọn amofin, lo ti da si ọrọ yii.
Oríṣun àwòrán, Others
Iwọde fun itẹwọgba eto Amotekun to lọ gaaraga lawọn olu ilu ipinlẹ to wa nilẹ Yoruba lọjọ Aje, lo pakasọ nilu Eko.
Idi ni pe ọrọ di boolọ, ko ya fun mi nigba ti awọn agbofinro ya bo ibudo ti wọn kede pe eto iwọde alaafia naa yoo ti gberesọ.
Iwọde naa, ti ẹgbẹ agbarijọpọ awọn ọmọ Yoruba, Yoruba World Congress (YWC) kede pe yoo gbera ni ibudo igbafẹ Gani Fawẹhinmi ladugbo Ọjọta nilu Eko ni awọn ọlọpaa ti pa.
Ni kutu hai owurọ ọjọ Isẹgun si lawọn osisẹ ọlọpaa ti ya bo ibudo naa, ti wọn si ti ẹnu ọna abawọle ibẹ, ki awọn eeyan to n gbero lati se iwọde maa baa ri aaye pejọ.
Koda, ọkọ ọlọpa to wa nikalẹ nibudo ọhun le ni ogun, tawọn agbofinro ti oju wọn ko rẹrin si duro wa wa wa, bi esinsin ba si ta firi nibẹ, wọn yoo wọn.
Amotekun: Ikọ̀ aláàbò yíì kọjá ọ̀rọ̀ ẹ̀sìn, àwọn ọdẹ àti Àgbẹ̀kọ́yà ló pọ̀ nínú rẹ̀
Kaakiri awọn olu ilu ipinlẹ to wa nilẹ Yoruba lawọn eeyan ti jade lọjọ Aje lati se iwọde alaafia fun itẹwọgba ikọ alaabo alajumọse lẹkun iwọ oorun guusu Naijiria, taa mọ si Amotekun.
Nibi iwọde naa, ti agbarijọpọ ẹgbẹ ọmọbibi ilẹ Yoruba, Yoruba World Congress, ni asaaju iwọde naa nilu Ibadan, Kunle Adesọkan ti kede pe ẹnikẹni to ko ba fẹ tẹwọgba eto Amotekun, ni ko fẹran ilẹ Yoruba.
Adesọkan tun fikun pe ẹni to ba n ba eto Amotekun ja, lo n ba iran Yoruba ja, to si kesi awọn gomina ilẹ Yoruba lati mase bẹru nitori digbi ni awọn wa lẹyin wọn.
Bakan naa nilu Akurẹ, awọn eeyan to se iwọde nibẹ kede pe ikọ alajumọse Amotekun kọja ọrọ ẹsin nitori awọn ọdẹ ati awọn Agbẹkọya lo wa nibẹ.
Farms to You: Irú ajílẹ̀ wo ló yẹ fún lílò lásìkò yìí- Aisha
Wọn fikun pe ikọ alaabo Amotekun ko wa lati dojukọ ẹya Fulani abi ẹnikẹni, sugbọn gbogbo ẹni to ba n huwa ọdaran ni Amotekun yoo maa doju ija kọ, onitọun ko baa jẹ ẹya Yoruba.
Agbarijọpọ ẹgbẹ ẹya Yoruba, Yoruba World Congress n bẹrẹ iwọde alaafia lati kede atilẹyin wọn fun ifilọlẹ eto aabo alajumṣe nilẹ Yoruba ti wọn pe ni Operaton AMOTEKUN""."
Eto Amotekun yii naa ni awọn gomina lẹkun iwọ oorun Naijiria pawọpọ gbe kalẹ lai naani ẹgbẹ oselu ti wọn wa se, ilu Ibadan, tii se olu ilu ipinlẹ Ọyọ si ni eto ifilọlẹ naa ti waye.
Alaye awọn to ṣe agbatẹru iwọde naa nipa ohun to mu wọn gunle iwọde ọhun ni wi pe ko bojumu ki ijọba apapọ to n ṣe atilẹyin fun ikọ HISBAH ni ẹkun ariwa orilẹede yii, kede pe ifilọlẹ eto AMỌTEKUN nilẹ Yoruba ko ba ofin Naijiria mu.
Ọpọlọpọ àwọn àgbàlagbà àti àwọn ọdọ ni wọn tú jáde ní witiwiti láti fi ìfẹ́ hàn sí idasile eto Amotekun tí ìjọba káàkiri ilé Yoruba gbé kalẹ.
Adari iwọde Amotekun nilu Akure, Tola Ogunlalaka ṣàlàyé pé, akoko ti tó kí ètò alajumọse naa bẹ̀rẹ̀ àti wí pé, ẹranko tí ó jẹ Amotekun leè ṣọdẹ dáadáa.
Awọn eeyan miran tí ó bá iko BBC Yoruba sọrọ, Ogbeni Jephrey Abidoye ṣàlàyé pé, àsìkò ti to láti mú eto ààbò ilé Yoruba gbòòrò sì.
Lọwọlọwọ bayii, iwọde naa n lọ lọwọ ni ilu Eko, Abeokuta, Ibadan, Osogbo, Akure ati Ado-Ekiti. Àwọn ọdọ àti àwọn ọdẹ náà kò gbeyin nínú iwode naa.
Coronavirus: Àìsàn yíì ti ràn dé Amẹrika, Thialand àti South Korea
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ijọba orilẹ-ede China ti kilọ fawọn eeyan dawọ lilọ-bibọ si ilu Wuhan nibi ti aarun Coronavirusti ti ṣekupa eeyan mẹsan an.
Bakan naa ni ijọba ti sọ fawọn olugbe ilu naa ti wọn miliọnu mọkanla lati yago fun apejọ ti ọpọ eeyan wa.
Aarun naa ti n ran bi ina inu ọyẹ lati ilu Wuhan lọ si awọn ẹkun miiran ni China, ko da o ti ran de ilẹ Amẹrika, orilẹede Thailand ati South Korea.
Oji le lugba eeyan lo ti lugbadi aarun naa eyi to n ran lati ọunjẹ inu okun.
Igbakeji minisita eto ilera, Li Bin ṣalaye pe ijọba n ṣiṣẹ takuntakun lori idena aarun naa lati ma le ran sii mọ.
China ti kọkọ kilọ pe o ṣeeṣe ki aarun naa ran lati ẹnikan si ẹlomiran.
Mobile Wash: iṣẹ́ fífọ́ mọ́tò tà ni mó yàn láààyò- Slay Mama
Àkíyèsí nípa àìsàn 'Coronavirus' tó ń ṣàkóbá fún bí a ṣe ń mí
Arun Coronavirusti, to tun n jẹ 2019-nCoV, to n ja rain ni ilẹ China  lo ti di irawọ ọsan to n ba awọn agba lẹru bayii lorilẹede Najiria nitori ọsẹ to n se.
Ìwádìí fi léde pé tí àìsàn tó ń jà ní ilẹ̀ China yíì bá ran ènìyàn kan, ó le è pa ènìyàn mẹ́rìnlá.
O ti le ni ọọdunrun eeyan to ti jẹ Ọlọrun nipe latipasẹ arun naa, eyi ti ibẹrubojo wa pe ọwọja rẹ lee tan de orilẹede yii.
Yoruba si ni o n bọ, o n bọ awọn laa dẹ de amọ lode oni, oju ni wọn n mu to. Ta ba si fẹ kiyesara nipa arun naa, o yẹ ka mọ ohun kan tabi meji nipa rẹ ati awọ̀n ọna ta lee gba dena rẹ.
Oríṣun àwòrán, Reuters
Olarewaju Bamidele fi 'Screw driver' gún ìyáwo rẹ̀ pa
Ọ̀pọ̀ ẹ̀mí ènìyàn lo ti sọnù nítorí àìsàn Iba Lassa ní Kano àti Ondo
Ọọ̀ni obìnrin, Lúwòó Gbàgídà rèé, akọni tó ń gun ọkùnrin ní ẹṣin rìn
Ìríwísí àwọn aráàlú bí EFCC ṣe kó afurasí ọmọ yahoo 49 ní Ibadan
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Amọ Ajọ Eto Ilera ni Agbaye, WHO ti ni, Ọjọ Kejilelogun, Osu Kini, ọdun 2020 ni awọn yoo ṣe ipade lori boya awọn yoo ka aisan naa si arun bii Ebola ati aisan ẹlẹdẹ ' Swine flu '.
Kini Aisan Coronavirus?
Ẹ̀yin ẹ máà wò ó, ó ṣeéṣe kí APC túká lẹ́yìn ìṣèjọ́ba Buhari!
Ìríwísí àwọn aráàlú bí EFCC ṣe kó afurasí ọmọ yahoo 49 ní Ibadan
Àwa ò ri lẹ́ta kankan gbà láti ọ̀dọ̀ Malami lóri ọ̀rọ̀ àwọn alága Kansu - Makinde
Mí ò le nífẹ̀ẹ́ obìnrin Nàìjíríà kankan mọ lẹ́yìn ti mo ti tọ́ obìnrin òyìnbó wò- Issa
Kini akiyesi ti awọn eniyan gbọdọ mojuto?
Awọn oṣiṣẹ ilera ti kilọ fun awọn eniyan lati ṣe awọn akiyesi wọnyii, titi ti ọna abayọ yoo fi yọju nipa aarun naa.
Ni bayii, ko tii si ọna abayọ si arun naa, amọ iwadii n lọ lọwọ lati ara awọn ti wọn ko arun naa lati wa ọna abayọ si arun Coronavirus naa.
Farms to You: Irú ajílẹ̀ wo ló yẹ fún lílò lásìkò yìí- Aisha
Aguda Ogba Fire: Iná míì tún sọ ní Ọgba, nílùú Eko!
Àwọn tí ìṣẹ̀lẹ̀ iná náà ṣe ojú rẹ̀ ní ó bẹrẹ ní déédé ago márun un ní Ọjọ́ Eti kí àwọn panapana to dé.
Awọn oṣiṣẹ panapana ti wa ni agbeegbe Aguda, Ogba ni ipinlẹ Eko nibi ti ina ti sọ ni irolẹ Ọjọ Eti.
Awọn ti ọrọ naa ṣe oju wọn ni wn n sun ina ni ilẹ kan ni agbeegbe naa, ki o to di wi pe ina naa wa bẹrẹ si ni ran.
Arabinrin Funmilayo Taiwo ti ina naa ran ile itaja rẹ sọ wi pe oun ati awọn ara agbeegbe lo ja ilekun ile naa lati lọ pa ina naa ki awọn panapana to de.
Ni bayii awọn panapana ti dawọ ina naa duro, ti ohun gbogbo si ti pada si ipo.
Ti a ko ba gbagbe, ọmọ ọdún márùn-ún àti àgbà mẹ́rin ló bá ìṣẹ̀lẹ̀ ọ̀pá epo bẹntiróò tó gbiná ní Abule Egba lọ láìpẹ́ yìí.
Gomina ipinlẹ Eko, Babajide Sanwo-Olu ti paṣẹ ipese eto iranwo fun awọn olugbe agbeegbe ijọba ibilẹ Agbado/Oke Odo nilu Eko, lẹyin ti wọn lugbadi ọpa epo bẹntiroolu to gbina.
Oríṣun àwòrán, @adebolaolu2019
Ọmọ ọdún márùn-ún àti àgbà mẹ́rin ló bá ìṣẹ̀lẹ̀ ọ̀pá epo bẹntiróò tó gbiná ní Abule Egba lọ láìpẹ́ yìí.
Ajọ eleto pajawiri ni ipinlẹ Eko, Lasema ni, gomina Sanwo-Olu gbe igbeṣẹ yii lẹyin ti awọn Alaga ijọba ibilẹ naa ke gbajare si fun ipese eto iranwọ.
Lasema ni awọn eniyan ti wọn nilo iranwọ ni agbeegbe naa to ọọdunrun eniyan, ti awọn obinrin ati ọmọde si wa ni ara wọn.
Wọn fikun pe Gomina Sanwo-Olu ti buwọ lu ki wọn fun awọn eniyan to lugbadi iṣẹlẹ naa ni ipagọ to wa ni Igando Relief Camp, Igando ni ipinlẹ Eko, ki wọn maa gbe fun igba diẹ na.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ọmọ ọdún márùn-ún àti àgbà mẹ́rin ló bá ìṣẹ̀lẹ̀ ọ̀pá epo bẹntiróò tó gbiná ní Abule Egba lọ láìpẹ́ yìí.
Bakan naa ni wọn ṣeleri pe awọn yoo ma a fito awọn ara ilu leti bi o ba ṣe n lọ, lori eto iranwọ fun awọn eniyan agbeegbe naa.
Ọmọ ọdún márùn-ún àti àgbà mẹ́rin ló bá ìṣẹ̀lẹ̀ ọ̀pá epo bẹntiróò tó gbiná ní Abule Egba lọ láìpẹ́ yìí.
Bakan naa bii eeyan ogun lo fara pa ṣugbọn ti wọn tọju wọn loju ẹsẹ nibi iṣẹlẹ naa.
Ile bii mẹfa, ile itaja mẹtadinlogun ati ọkọ akoyanrin mẹtalelọgbọn, ọkọ ayọkẹlẹ mẹta ati kẹkẹ NAPEP alupupu mẹta naa ba iṣẹlẹ naa lọ.
Ileesẹ ologun oju omi ti salaye ohun to faa ti wọn fi n fi tipa-tikuuku le awọn olugbe Tarkwa Bay to wa ni erekusu Eko, eyi ti eeyan le gba oju omi nikan wọ ibẹ.
Oríṣun àwòrán, @justempower
Osu Kejila ọdun 2019, paapa lati ọjọ aisun ọdun Keresi ni awọn ologun ti ya bo agbegbe Tarkwa Bay, ti wọn si n le awọn eeyan tipa tikuuku.
Nigba to n bawọn akọroyin sọrọ, agbẹnusọ fun ikọ ologun oju omi to lewaju igbesẹ lile awọn eeyan agbegbe ọhun, Ọgagun Thomas Otuji salaye pe, awọn ọpa epo to n gbe epo wa silu Eko ati awọn etikun lo gba agbegbe ọhun kọja eyi ti wọn maa n fọ lojoojumọ.
"Otuji ni ""Afojusun wa ni lati daabo bo awọn irinsẹ to jẹ ti ajọ elepo rọbi nilẹ wa lọwọ awọn eeyan to n fọ ọpa epo kiri. Wọn ti kọ ile sori awọn ọpa epo naa, ti wọn si n fa epo ta lọna aitọ."""
Oríṣun àwòrán, @justempower
Amọ Otuji ko sai fikun pe bi o tilẹ jẹ pe kii se gbogbo awọn eeyan to n pe ni agbegbe naa lo n ji epo ta, sugbọn ẹni to gbe epo laja ko jale, bi ẹni to gbaa silẹ, nitori ti wọn ko ba tu asiri awọn eeyan to n ji epo fa lọna aitọ ni ayika wọ, gbogbo wọn ni wọn jọ jẹbi.
Nibayi naa, awọn ẹlẹgbẹjẹgbẹ lorisirisi lo ti n bu ẹnu atẹ lu igbesẹ tawọn ologun naa gbe ati igbiyanju wọn lati le awọn olugbe erekusu Tarkwa Bay ni erekusu Eko.
Oríṣun àwòrán, @justempower
Ẹgbẹ kan to pe ara rẹ ni Nigerian Slum/Informal Settlement Federation, ninu atẹjade kan to fisita lọjọ Isẹgun oni, koro oju si igbesẹ ijọba lati le ẹgbẹrun mẹwa eeyan to n gbe ni erekusu ọhun pẹlu ipa.
Gẹgẹ bo se jẹyọ ni oju opo ikansiraaẹni ẹgbẹ ajafẹtọ ẹni kan, @justempower, jei, ẹgbẹ naa ni ọna ipa ti ijọba apapọ n gba le ogunlọgọ ero kuro ninu ile wọn lai bọwọ fun ofin to yẹ.
Iroyin naa ni igbesẹ lile awọn eeyan to wa ni agbegbe Badagry keji pẹlu awọn agbegbe miran to wa ni adugbo Ajegunlẹ lo kọkọ saaju, ti wọn si fi ọba le pẹlu lile awọn olugbe adugbo mẹrinlelogun miran to wa ni erekusu Eko.
Oríṣun àwòrán, @justempower
Pẹlu ibanujẹ la fi n wo ijọba apapọ lati ipasẹ ileesẹ ologun oju omi, ti wọn n le awọn eeyan to n gbe ni adugbo Abagbo, Abule Ẹlẹpa, Abule Glass, Ajakoji, Akaraba, Bobukoji, Ebute Oko, Fashola, Idi Mango, Ilajẹ, Inangbe/Ilado, Kopiamy, Ogunfẹmi, Oko-Kate, Okun Alfa, Okun Babakati, Okun gbogba, Okun Ilasẹ, Okun Kobena, Sankin, Sapo Okun ati Tokunbọ, titi de Tarkwa Bay.
Ẹnu ya wa nipa awijare ileesẹ ologun lori igbesẹ lile awọn eeyan yii, niwọn igba ti wọn mọ pe ko si ofin kankan lorilẹede Naijiria to fi aaye gba igbesẹ wiwo ile awọn araalu tabi fifi iya jẹ wọn lọna to lodi sofin.
Ẹgbẹ Ajafẹtọẹni naa wa n rọ awọn asaaju wa leti pe awọn ilana aatọ wa nilẹ to jẹ itẹwọgba lawujọ agbaye eyi to de sise amojuto agbegbe kọọkan, ti yoo si tun mu agbega ba idagbasoke aabo ati awujọ.
Oríṣun àwòrán, @justempower
Iroyin kan to gba ori ayelujara kan salaye pe awọn ọmọ ologun ti n fi tipa le awọn eeyan to n gbe ni adugbo Tarkwa Bay nilu Eko.
Gẹgẹ bi awọn iroyin to gba oju opo ikansiraẹni Twitter ti wi, awọn ọmọ ologun oju omi, Nigerian Navy lo n le awọn eeyan naa kuro ni agbegbe ọhun to wa ni erekusu ipinlẹ Eko.
Iroyin naa ni lati osu kejila ọdun to kọja, paapa lati ọjọ aisun ọdun Keresi ni awọn ologun ti ya bo agbegbe naa, ti wọn si n le awsn eeyan naa tipa tikuuku.
A gbọ pe pẹlu ọta ibọn, afẹfẹ tajutaju ati ẹrọ katakata ni wọn fi ni ki awọn olugbe agbegbe  ọhun kuro ni ibugbe wọn naa.
Oríṣun àwòrán, @justempower
Iroyin naa fikun pe awọn ọmọ ologun yii lo n yin ibọn soke soju ofurufu, lati fi dẹru ba awọn olugbe erekusu naa, ki wsn lee tete ko aasa wsn kuro lagbegbe naa.
Wọn ni wakati kan pere ni wọn fun awsn eeyan to n gbe ni agbegbe ọhun lati ko ẹru wọn, eyi to mu ki ohun gbogbo dojuru.
Oríṣun àwòrán, @justempower
Lọwọlọwọ bayii, o seese ki erekusu Tarkwa Bay, ti ọpọ eeyan maa n lọ lati gbafẹ lee ma si mọ nitori isẹlẹ to waye yii.
Oríṣun àwòrán, Twitter/drobafemihamzat
Igbakeji Gomina ipinlẹ Eko, Obafemi Hamzat ti ṣe abẹwo sawọn adugbo ti o farakasa iṣẹlẹ ijamba ina lagbegbe'Abule Egba ,nilu Eko.
Lasiko to n ba awọn ara adugbo kẹdun, Hamzat fi ifarajin ijọba han nipa mimu atunṣe ba agbegbe naa ati pipese aabo to peye.
Hamzat to ṣoju fun Gomina ipinlẹ Eko,si wa lara awọn eekan ijọba, to ti ṣe abẹwo si abule Egba lẹyin ijamba ina to ṣakoba fun dukia nibẹ.
Oríṣun àwòrán, Twitter/drobafemihamzat
Ẹwẹ, ọga agba ileeṣẹ to n risi ọrọ epo rọbi ni Naijiria, Mele Kyari, naa ti ṣe abẹwo si Abule Egba ti o si ni ileeṣẹ NNPC ti brẹ si nigbe epo gba inu ọpa to gba Abule Egba kọja .
Kyari ninu ọrọ rẹ nibẹ, rọ awọn ara adugbo lati maa ta awọn agbofinro lolobo, bi wọn ba ti ko firi awọn to n bẹ ọpa epo.
Bakanna ni o tun ṣe abẹwo si Oba ilu Eko, Akiolu Rilwan nibi to ti beere iranwọ lọdọ awọn lọbalọba nipa mimu aabo to peye ba awọn adugbo to wa labẹ wọn.
Oríṣun àwòrán, Twitter/NNPCgroup
Amotekun: Àwọn èèyàn sọko ọ̀rọ̀ sí Tinubu lórí ìkéde rẹ̀ nípa Amotekun
Ṣaaju ki Asiwaju ẹgbẹ oṣelu All Progressives Congress Bola Ahmed Tinubu to sọrọ nipa idasilẹ ikọ alaabo Amọtẹkun, n ṣe lawọn eeyan n dẹti lati gbọ ọrọ rẹ.
Bayi to ti wa fi ọrọ sita, iriwisi ọtọọtọ ti n tẹle ọrọ rẹ tawọn kan si ni o kọ lati soju abẹ niko nipa idasilẹ Amọtẹkun.
Ninu awọn to fi esi sita la ti ri Femi Fani Kayode ti ko pẹ ọrọ sọ rara lati bẹnu atẹ lu Tinubu. Lero tirẹ, Tinubu n gbe lẹyin ijọba apapọ ni:
Fani Kayode nikan kọ ni o lero pe Tinubu ko gbe lẹyin awọn eeyan ilẹ Yoruba.
Dexbrown Civil @Eni_kanda naa sọ pe, Tinubu ko sọ ododo nitori pe o n gbero lati jẹ aarẹ Naijiria.
Ibi kanna ni Òkín Oba Eye@St_michaelalter sun, ti o kọ ori si ibi kanna.
Amọ bi awọn ti ko gba ti ọrọ rẹ ṣe n sọ tiwọn, lawọn miran n kan sara si.
Awọn ta n sọ yi ni agba ki fi gbogbo ẹnu sọrọ ati pe, bi o ti ṣe yẹ ki Tinubu sọrọ lo ṣe sọ.
Ilu ti ko ba si ofin, ẹsẹ ko si nitori naa, ni ilumọọka agba amofin nni, Femi Falana se n ke tantan tan fun awọn gomina lẹkun iwọ oorun guusu Naijiria pe, ki wọn fi ofin gbe idasilẹ eto Amotekun nidi.
Falana, lasiko to n sọrọ lori ifidimulẹ ikọ alaabo ọhun nilẹ Yoruba kede pe, gbogbo awuyewuye to n waye lori agbekalẹ ikọ Amotekun ko ba ti ri bẹẹ, to ba jẹ pe awọn gomina ti kọkọ se ohun to yẹ ki wọn se ni, nipa sise ofin ti yoo ti ikọ naa lẹyin nipinlẹ koowa wọn.
Agba amofin naa wa kesi awọn gomina ilẹ Yoruba pe ko tii pẹ ju bayi, yoo si dara lati tete se awọn ofin naa, lati ipasẹ awọn ile asofin ipinlẹ wọn, ki eto Amotekun lee rẹsẹ walẹ digbin.
Awọn gomina ilẹ Yoruba sefilslẹ eto alaabo kan ti wọn pe ni Amotekun, ti ileesẹ Ọlọpaa si tii lẹyin amọ agbẹjọro agba nilẹ yi, Abubakar Malami ta ko pe ko bofin mu. Bi o tilẹ jẹ pe mo ni nkan ba Malami fa lori ikede rẹ naa, amọ maa kọkọ rọ awọn gomina ilẹ Yoruba naa lati tete lọ fi ẹsẹ ofin ti agbekalẹ naa nidi.
Mobile Wash: iṣẹ́ fífọ́ mọ́tò tà ni mó yàn láààyò- Slay Mama
Nigba ti ko si abala ati ẹsẹ ofin to yẹ fun agbekalẹ eto Amotekun, to fi mọ ilana isọwọsisẹ wọn, ojuse ti wọn yoo se, ilana eto akoso wọn, ipese ati owona, ni ọpọ awọn ẹlẹgbẹjẹgbẹ lorisirisi nilẹ yii se n tẹsiwaju lati maa sọ ero wọn lori awuyewuye ti ko nidi, eyi to n ti agbekalẹ eto Amotekun nidi.
Bakan naa lo fikun pe, o yẹ ki awọn eeyan ilẹ Yoruba to tẹwọgba eto naa mọ nipa ofin to gbe Amotekun royats si awsn eeyan to n tako.
Oríṣun àwòrán, Facebook/Bola Tinubu
Lẹyin o rẹyin, asaaju ẹgbẹ oselu APC ati gomina tẹlẹ nipinlẹ Eko, Oloye Bola Ahmed Tinubu ti sọrọ lori eto alaabo Amotekun tawọn gomina ilẹ Yoruba gbe kalẹ.
Bola Tinubu, ẹni to foju han ninu atẹjade kan to fisita pe o n se atilẹyin fun eto Amotekun, wa fikun pe agbekalẹ eto naa ko dunkoko rara mọ ifẹsẹmulẹ orilẹede Naijiria.
Amọ Tinubu ko sai daba pe ki ipade igbọraẹniye wa laarin awọn gomina ẹkun iwọ oorun guusu orilẹede yii ati agbẹjọro agba ni Naijiria, Abubakar Malami lori agbekalẹ eto Amotekun.
Oríṣun àwòrán, Bola Ahmed Tinubu
"Bakan naa ni gomina ipinlẹ Eko tẹlẹ tun woye pe ""awọn eeyan to ni agbekalẹ eto aabo Amotekun yoo fa isọkan orilẹede Naijiria ya pẹrẹ-pẹrẹ lo jẹ ẹwa ede to lewu lati ẹnu awọn eeyan to yẹ ki oye ye julọ."""
Gbogbo awọn eeyan to n pariwo pe agbekalẹ eto alaabo ti ko mu ewu lọwọ yii , to si tun ni gbedeke ibi to lee sisẹ de lo n dẹru ba isọkan Naijiria ni ko ni arojinlẹ.
Ko tan sibẹ, atẹjade asaaju ẹgbẹ APC naa ni, awọn eeyan to tun n kesi ijọba apapọ lati jẹ gaba, tabi sọ ẹkun guusu Naijiria di akurẹtẹ, lo ti sọnu lai mọ ibi ti wọn n lọ, ti ẹmi ibẹru si ti di oju inu wọn, bẹẹ ni agbara oselu ti kun ọpọlọ wọn ni oorun.
Tinubu afikun pe eyi lewu pupọ, to si lee se orilẹede kan ni ijamba taa ba gba iwa imọtara ẹni nikan laaye lati dagba.
Ko sai tun sọ ero rẹ nipa awọn eeyan to n se atilẹyin fun agbekalẹ eto Amotekun, to si salaye pe ọpọ wọn ni ko ni oye pupọ nipa eto naa, gẹgẹ bi awọn eeyan to jẹ alatako eto naa ko se ni oye nipa rẹ pẹlu.
O ni ọpọ awọn eeyan to jẹ alatako eto Amotekun ni ko tako lori otitọ amọ wọn se bẹẹ nitoripe awọn alatako wọn ninu oselu lo daba eto naa ni, tabi tori pe wọn ko lee ri anfaani kankan jẹ ninu rẹ fun ara wọn ni.
"Ọwọ ti ọpọ eeyan fi mu ọrọ Amotekun yii fihan pe ọna wa si jin ni Naijiria lati mu ki eto iselu ijọba awa ara wa pegede. Ọpọ okun ni awọn eeyan fi sofo lati dabaru eto yii dipo ki wọn wa ọna abayọ si
Sugar: Iléẹjọ́ ní àwọn afurasí mẹ́rin kò mọwọ́-mẹsẹ̀ lórí ikú Sugar
Oríṣun àwòrán, Temitope Sugar
Ileẹjọ giga to wa nilu Ibadan ti da awọn afurasi mẹrin silẹ, awọn ti wọn n jẹjọ lori iku to pa asoju-sofin to n soju ẹkun idibo Lagelu Akinyẹle nipinlẹ Ọyọ, Asofin Temitọpẹ Olatoye, ti gbogbo eeyan mọ si Sugar,
Awọn afurasi naa ni Akinmoyede Olafioye, to jẹ akojanu ile tẹlẹ nile asofin ipinlẹ Ọyọ ati Rafiu Adebayọ, to fi mọ Rasheed Ọladele ati Kazeem Ayinde.
Adajọ Adegbọla Mufutau, lasiko to n gbe idajọ rẹ kalẹ kede pe awọn olujẹjọ naa ko lẹsẹ lọrun nitori ikọ olupẹjọ kuna lati fidi ẹri to daju mulẹ pe awọn olujẹjọ ọhun jẹbi ẹsun ipaniyan.
Bẹẹ ba gbagbe, Asofin Temitope Olatoye Sugar lawọn eeyan kan sekupa lọjọ Satide, ọjọ Kẹsan osu kẹta ọdun 2019 lasiko idibo gomina ati tile asofin ipinlẹ to waye yika orilẹede wa Naijiria.
Àwọn aladugbo ibí tí ìjọba Èkó tí n wole sọ èrò ọkàn wọn
Nigba to n fesi lori idajọ naa, Asofin Akinmoyede ni Ọlọrun ti da oun lare lori awọn ẹsun ipaniyan ti wọn fi kan oun lori iku Sugar, ti otitọ si ti foju han pẹlu idajọ naa pe oun ko mọwọ mẹsẹ ninu awọn ẹsun ti wọn fi kan oun.
Ẹgbọ́n olóògbé Suga: Wọ́n yìnbọn fún Suga lójú mi, n kò sì lè dá wọn dúró
Olafioye wa lo akoko naa lati kẹdun pupọ pẹlu awọn mọlẹbi oloogbe ọhun, pẹlu adura pe Ọlọrun yoo tu wọn ninu lati gba adanu naa mọra.
Transparency International: Ipò 144 ní Nàíjíríà wà nínú orílẹ̀èdè 180 tí wọ́n ṣe ìwádìí rẹ̀
Oríṣun àwòrán, @anticorruption
Ijọba apapọ ti bu ẹnu atẹ lu abọ iwadi ajọ to n tanna wadi bi iwa ajẹbanu se rẹsẹ walẹ si lagbaye, ti wọn n pe ni Transparency International (TI), to si ni ofo, ọjọ keji ọja ni esi to gbe sita nipà orilẹede Naijiria.
Ni aarọ ọjọbọ ni ajọ TI abọ iwadi rẹ sita nilu Abuja, to si kede pe orilẹede Naijiria tun ti ja walẹ pẹlu ipele meji, ninu iwadi to se lori bi Naijiria se n gbogun tiwa ibajẹ si lọdun to kọja.
Naijiria lo gbe ipo kẹrinlelogoje laarin awọn ọgọsan orilẹede ti wọn se iwadi le lori.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ajọ TI ni bi ilana ofin Naijiria se n se ojusaaju nidi awọn eeyan to n lo ida ofin le lori nipa iwa ijẹkujẹ, lo mu ko ja walẹ lori akaba iwa ijẹkujẹ, to si jẹ pe awọn mẹkunnu lo n jiya iwa ajẹbanu, tawọn olowo si n rọna yọ.
Nigba to n fesi lori ọrọ naa, agbẹjọro agba ati Minisita feto idajọ, Abubakar Malami ni ko si ẹri to daju ti ajọ TI fi gbe ara rẹ lẹsẹ lori esi to gbe jade naa.
Ta ba ni ka sọrọ nipa gbigbogun ti iwa ibajẹ, a ti n se ju ti atẹyinwa lọ, ta si tun setan lati se ju bẹẹ lọ yatọ si ohun ti ajọ TI gbe jade. Bẹẹ si ni ko si ohun ti orilẹede yii ko tii se lati sẹ eegun ẹyin iwa ajẹbanu lorilẹede yii"""
Láì rọ lápa rọ lẹ́sẹ̀, ẹ wo ọmọ ọdún mọ́kànlá tó ń lọ́ ara lóríṣi ọ̀nà
Birth tourism: Ẹ̀yin obìnrin tẹ́ẹ fẹ́ wá bímọ ní America, ọ̀nà ti tì pa látònì! - Trump
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ilẹ Amẹrika ti ṣipaya awọn ofin mii lati bẹgi dina irinajo awọn obinrin aboyun lọ si Amẹrika lati lọ bimọ.
"Loni ọjọ ẹti ọjọ kẹrinlelogun ni igbesẹ yii yoo gberasọ yoo si jẹ ohun ti yoo mu opin wa si ohun ti ọpọ eeyan mọ si ""birth tourism"" iyẹn gbigba iwe aṣẹ irina ati lọ bimọ"
Labẹ ofin yii, awọn aboyun to fẹ gba iwe aṣẹ irina olubẹwo si US yoo ni lati sọ idi pataki ti wọn fi fẹ lọ yatọ si pe wn fẹ lọ bimọ sori ilẹ Amẹrika.
Kí lo tíì rí  nípa Amotekun? Ẹ sùnmọ́bí, ẹ wo gbankọgbì!
Eyi ọpọ gbagbọ pe wọn maa n ṣe e ki ọmọ ti wọn bi sọhun lee di ọmọ ilẹ Amẹrika nipa ibi nikan eyi ti ofin fi aye gba tẹlẹ bẹẹ si ni aarẹ Donald Trump bu ẹnu atẹ lu eyi.
Iṣejọba aarẹ Trump ni aato irina tuntun yii ṣe pataki fun abo ati eto ilera ilẹ Amẹrika.
Fun idi eyi aarẹ Trump ti fẹ bẹgi dina irinajo wọ ilẹ Amẹrika, bakan naa o ti pe fun atunṣe iwe ofin eyi to n sọ ni di ọmọ ilu Amẹrika fun gbogbo ọmọ ti wọn ba bi si Amẹrika.
Ofin naa fi kun aato to ti gbigba awọn eeyan laye lati lọ bimọ lẹyin pe yoo boju to iwa ọdaran labẹle tabi tayọ orilẹede.
Bakan naa o ṣe afikun ofin lori awọn to fẹ lati lọ si US fun ilera wọn.
Ọmọ melo ni awọn ara orilẹede mii rinrinajo lọ bi si ilẹ Amẹrika?
Ko si akọsilẹ ọlọdọọdun fun iye ọmọ ti awọn ajoji si ilẹ Amẹrika bi ṣugbọn oniruuru ajọ lo ni iṣiro tiwọn.
Lọdun 2017 nikan, nkan  bii ẹgbẹrun mẹwaa ni ọmọ ti awọn ajoji bi si Amẹrika bẹẹ si ni bi ajọ ilẹ Amẹrika to n ri si idena aisan ni lati ẹgbẹrun mẹjọ din nigba ti ọdun 2007 lo ti goke si ẹgbẹrun mẹwaa.
Ni lọọlọ yii, alaboyun lee wọ ilẹ Amẹrika koda titi di ọjọ ibimọ gẹgẹ bi ajọ aṣọbode ilẹ Amẹrika ṣe sọ ọ ṣugbọn irina ẹni to ti fẹẹ di abiyamọ kan le ri idiwọ ni bi wọn ba ri idi pe o ṣi fẹ duro si Amẹrika kọja iye akoko ti wọn fun un lori iwe aṣẹ irina rẹ tabi igbiyanju lati jẹ ki awọn to n san owo ori ni ilẹ Amẹrika ba a san owo ile iwosan to ti bimọ rẹ.
Serena Williams: Wang tún da àlá Ife ẹ̀yẹ kẹrìnlélógùn fún Serena Williams rú
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ọrọ Serena Williams, agbabọọlu ẹlẹyin ori papa ati ilepa rẹ lati gba ife ẹyẹ idije lawn tennis Grandslam fun igba kẹrinlelogun tun ti dete.
Wang Qiang, ọmọ orilẹede China lo bomi pana ala yii lẹẹkan sii nibi idije Australian Open to n lọ lọwọ.
Serena Williams jẹ ọkan lara awọn odu elere idaraya Lawn Tennis ti itan agbaye ko lee gbagbe laye lẹyin awọn bẹbẹ loriṣiriṣi to ti gbe ṣe lere idaraya naa.
Kí lo tíì rí  nípa Amotekun? Ẹ sùnmọ́bí, ẹ wo gbankọgbì!
Ẹ̀yin obìnrin tẹ́ẹ fẹ́ wá bímọ ní America, ọ̀nà ti tì pa látònì! - Trump
Amọṣa, lẹyin to gba idije Australian open ni ọdun 2017, eyi to mu ki iye ife ẹyẹ grandslam to ti gba o jẹ mẹtalelogun lo ti n lepa ati gba ẹyọkan sii ko lee jẹ mẹrinlelogun ti yoo si sọ  ọ di elere idaraya Lawn tennis to da gba ami ẹyẹ Lawn tennis to pọ julọ ninu itan lagbaye.
Amọṣa, lati igba yii wa ni o ti n ba ijakulẹ pade.
Lẹni ọdun mejidinlogoji, ireti ọpọ nigba ti idije Australian open ti ọdun 2020 bẹrẹ ni pe ilakaka Serena Williams yoo so eso rere ki o to di pe o pade Wang Qiang ọmọ orilẹede China ni ipele kẹta idije naa.
Wang gbo ewuro soju Serena eleyi to jẹ ipele to ya ju ti Serena ti jabọ ni idije Lawn Tennis lati ọdun mẹrinla sẹyin ti o ti ja kulẹ ni ipele yii kan naa nigba to koju Daniela Hantuchova.
Williams ti kọkọ fẹyin Wang gbolẹ ni idije US open ni osu kẹsan ọdun to kọja ki Wang to wa gba ẹsan rẹ bayii
Oko oloyun: Àwọn agbébọn pa gbajúgbajà apòògùn ìbílẹ̀, Àláájì Fàtáì ọkọ olóyún
Oríṣun àwòrán, others
Gbajugbaja, oniṣegun ibilẹ, Alhaji Fatai Yusuf ti ọpọ mọ si ọkọ oloyun lawọn eeyan kan yinbọn pa ni irọlẹ Ọjọbọ ni ipinlẹ Ọyọ.
Gẹgẹbi iroyin ṣe sọ, opopona Eruwa si Igboọra lagbegbe Ibarapa nipinlẹ Ọyọ.
Mercy Aigbe, Lateef Adedimeji, Ayoola Ayolola kó sọ́wọ́ ìbéèrè kàbìtì, ó di gbọin!!!
Alukoro ileeṣẹ ọlọpaa ni ipinlẹ Ọyọ, Gbenga Fadeyi to fi idi rẹ mulẹ fun BBC news Yoruba ṣalaye pe lootọ ni awọn aṣekupani pa Alhaji Fatai Ọkọ Oloyun ṣugbọn  ileeṣẹ ọlọpaa ti bẹrẹ iwadii lori rẹ.
'Aṣẹ ti wa lati ọdọ kọmiṣọna ọlọpaa pe ki ẹka ọtẹlẹmuyẹ ileeṣẹ ọlọpaa, SCID bẹrẹ iwadi lori rẹ lati mọ bi iku rẹ ṣe jẹ'.
Ileeṣẹ ọlọpaa ni awọn ko tii lee sọ ni pato boya igbenipa ni iku rẹ ni abi nnkan miran. Ayafi nigba ti wọn ba pari iwadii.
Wasiu Ayinde: Èmi àti Aláàfin sọ fún Gani Adams nípa oyè Mayegun, a kò jà rárá
Gbajugbaja oniṣegun ibilẹ ni Alhaji Fatai Ọkọoloyun ti o jẹ ilu mọọka pẹlu awọn ọkan-o-jọkan ogun ibilẹ rẹ eleyi ti o gbajugbja.
Alahaji ọkọ oloyun wa lara awọn eekan to mu iṣegun ibilẹ tọ ọna igbalode lọ nipa ṣiṣe ogun ibilẹ si igo gẹgẹ bii olomi ati ni koro bi awọn ogun oyinbo.
Titi di bi a ṣe n sọrọ yii ko tii si ẹni lee sọ bi iku rẹ ṣe jẹ.
Kí lo tíì rí  nípa Amotekun? Ẹ sùnmọ́bí, ẹ wo gbankọgbì!
Amotekun: Omi ṣì ń bẹ làmù fún ìjọba lórí Àmọ̀tẹ́kùn - Amòfin Fẹ́mi Abórìṣàdé
Awọn gomina ipinlẹ iwọ oorun yoo nilo lati tete jawe sobi lori ipenija to n dojukọ ikọ alaabo Amọtẹkun ti wọn gbe kalẹ.
Amofin Fẹmi Aboriṣade to jẹ ajafẹtọ araalu lo ṣalaye bẹẹ nigba to n ba BBC News Yoruba sọrọ lori ọna ofin ti awọn gomina yoo lo lati ti Amọtẹkun lẹyin.
Amofin Aboriṣade ṣalaye pe ko le si wahala lati wa ofin fi gbe Amọtẹkun lẹyin ni toripe yoo kan nilo pe awọn awọn ileegbimọ aṣofin ipinlẹ kọọkan o gbe ofin kalẹ ni eleyi ti adehun nnkan ti wọn fẹ ko wa yoo ti di mimọ laarin wọn.
O ni niwọn igba to jẹ pe ileeṣẹ Oodua tilẹ ti wa tẹlẹ laarin awọn ipinlẹ naa, wiwa eto afẹnuko ofin ko lee jẹ ipenija ati pe nigba ti ofin ilẹẹwa ko tii faye ile aṣofin ẹlẹkunjẹkun kalẹ, awsn ile aṣofin ipinlẹ ni iṣẹ ku si lọwọ.
Nigba ti o n dahun ibeere boya ohun ti alaga ajọ gomina ipinlẹ ẹkun iwọ oorun gusu, Gomina Rotimi Akeredolu sọ pe lasiko ti awọn ba fi n ṣeto ofin naa, mimi kan ko lee mi Amọtẹkun, amofin Aboriṣade ni ootọ ọrọ ni Akeredolu sọ nitori pe niwọn igba ti eto kan ko ba tii di iṣọkan ati itẹsiwaju orilẹede Naijiria, a ko lee sọ pe iru eto bẹẹ  ko bofin mu.
O fi kun un pe eeyan kan kii fi iṣẹ igbọnsẹ ran ọmọ ẹni nitori naa, kii ṣe ẹṣẹ pe awọn gomina naa ko duro gbe ofin kalẹ ki wọn to gbe Amọtẹkun naa kalẹ gan an gan.
O ni itara ati doola ẹmi kọja ironu ofin kan lo ṣeeṣe ko faa ti awọn gomina naa fi kọkọ gbe igbesẹ ki wọn to lọ yanju ọrọ ofin.
Amọṣa o wa fi kun pe bi o ti wu ki eto abo Amọtẹkun o dara to, bi ijọba ko ba ṣe ohun to tọ loriipese iṣẹ, lile iṣẹ danu, ipese awọn ohun elo amayedẹrun, eto ẹkọ ọfẹ ati bẹẹbẹẹlọ fun araalu, faims ki o ma jẹ oju kan naa ni ẹkun Yoruba yoo ba ara rẹ.
Yoruba Films: Àwọn òṣèré tó bímọ s'Amẹrika lọ́dún 2019 rèé kí Trump tó f'òfin dèé
Oríṣun àwòrán, Instagram
Bi awada, bi ere, ọrọ naa ti di otitọ bayii. Ijọba ilẹ Amẹrika ti kede pe ohun ko ni fawọn ara ilẹ okere ni iwe irinna lati wa bimọ si orilẹede naa mọ.
Gẹgẹ bi atẹjade ti akọwe iroyin ijọba Amẹrika White House, Stephanie Grisham fi sita, ofin yii ti mulẹ lati oni ọjọ kẹrinlelogun oṣu kinni ọdun 2020.
Ọgbẹni Grisham ṣalaye pe igbesẹ yii ṣe pataki lati mu eto aabo ba irinrinajo si ilẹ Amẹrika gbopọn sii.
Mercy Aigbe, Lateef Adedimeji, Ayoola Ayolola kó sọ́wọ́ ìbéèrè kàbìtì, ó di gbọin!!!
Ọpọ ọmọ orilẹede Naijiria papaajulọ awọn oṣere ere ori itage lo ti bi ọmọ si ilẹ Amẹrika eleyi to si ti sọ awọn naa ọmọ ilẹ Amẹrika.
Diẹ niyii lara awọn oṣere tiata Yoruba atawọn ilumọọka ọmọ Yoruba miiran ti iyawo wọn bimọ silẹ Amẹrika.
Wunmi Toriola
Ijafara lewu lawọn Yoruba ma n wi. Eyi lo difa fun oṣere tiata Yoruba, Wunmi Toriola bimọ rẹ akọkọ silu Amẹrika lọjọ kẹrinla, oṣu kẹwaa ọdun 2019.
Ọjọ kẹtala oṣu karun un ọdun 2018 ni Wunmi ṣe igbeyawo pẹlu ọkọ rẹ to fi oke okun ṣe ibugbe.
Ọdun kan o le diẹ ni Eleduwa fi ọmọkunrin lanti lanti \ti orukọ rẹ n jẹ Zion jinki idile wọn ti wọn si di ọlọmọ.
Ronke Odusanya
Lọjọ kọkandinlogun oṣu kẹjọ ọdun 2019 ni Ronke Odusanya kede loju opo Intsagram rẹ pe Ọlọrun fi ọmọ jojolo ta oun ati ọkọ oun lọrẹ.
Ilu Amẹrika loun naa bimọ si, kete to kede lori ayelujara lọgọrọ awọn oṣere ẹgbẹ rẹ bẹrẹ si ni fi ikinni ranṣẹ sii.
Ronke sọ lori oju opo Instagram rẹ pe inu oun ko le sọ bi inu oun ṣe dun to lori ọmọ tuntun ti Eleduwa fi ta idile oun lọrẹ.
Tunde Owokoniran
Oṣere tiata Tunde Owokoniran ati iyawo rẹ ki ọmọjojolo kaabọ si ẹbi wọn lọjọ kejidinlogun oṣu kẹjọ ọdun 2019 lorilẹede Amẹrika.
Tunde gangan an lo fi aworan rẹ ati aya rẹ pẹlu ọmọ wọn si ori oju opo Twitter.
World Education Day: Wo ọmọ ogún ọdún tí kò lè ka lẹ́tà ''A'' dé ''Z''
Ọjọ Ẹti, Ọjọ Kẹrinlelogun,  Oṣu kinni lọjọ ti ajọ iṣọkan agbaye ya sọtọ fun ayajọ eto ẹkọ lagbaaye.
Abba Haladu to n ṣiṣẹ pẹlu ajọ to ri si eto mọọkọ mọọka ni Naijiria ṣalaye pe eeyan to to ọgọta miliọnu ni ko mọọkọ mọọka ni Naijiria.
Ọgbẹni Haladu ni orilẹede Naijiria go le goke agba di eto ẹkọ ko ba gbe pẹlẹ si ju bi o ti wa lọ lasiko yii.
Ẹwẹ, Aliyu Mohammed, olugbe ilu Kano to jẹ ọmọ ogun ọdun ni iwadii BBC fihan pe ko le ka ''A'' de ''Z'' ninu lẹta Ede Gẹeṣi.
Mohammed sọ fun BBC pe ko kuku dun mọ oun naa ninu pe oun ko le ka lẹta Gẹẹsi le ka ''A'' de ''Z.''
Nigba ti akọroyin BBC ṣi iwe fun Mohammed ṣugbọn o sọ pe oun ko le ka mọ ohun to wa nibẹ.
Mohammed ni awọn obi oun ko fi oun sile iwe, eleyi to maa n mu oun jowu awọn to lọ si ile iwe.
''Mi o wọ yara ikawe ri lati igba ti wọn ti bi mi, ṣugbọn o maa wu mi ko jẹ pe emi naa le kawe bawọn to lọ si ile iwe ṣe maa n ṣe,''Mohammed lo woye bẹẹ.
Awọn onimọ sọ pe o yẹ ki Mohammed lọ kẹkọọ lawọn ibi ti wọn ti n ṣe idanilẹkọọ agba.
Amọ, Mohammed sọ pe oun ṣetan lati lọ kẹkọọ ti wọn ba le kọ oun lọ fẹẹ.
Amotekun: Àwọn gómìnà ìpínlẹ́ ẹkùn ilẹ̀ Yorùbá yoó ṣì ṣèpàdé pẹ̀lúu Ààrẹ Buhari lórí 'Àmọ̀tẹ́kùn'
Oríṣun àwòrán, Tolu ogunlesi
Ọrọ taa ni ki baba o maa gbọ, baba ni yoo pari rẹ ni ọrọ Amọtẹkun tun kan bayii gẹgẹ bii alaga ajọ awọn gomina ẹkun ilẹ Yoruba, Gomina Rotimi Akeredolu ṣe sọ.
Akeredolu ni awọn yoo ṣi ṣe ipade pẹlu Aarẹ Muhammadu Buhari lori awọn awuyewuye to n waye ati agbekalẹ eto ikọ alaabo ilẹ Yoruba ti wọn pe ni 'Amọtẹkun'.
Akeredolu to jẹ gomina ipinlẹ Ondo ṣalaye pe irinajo aarẹ si ilẹ Gẹẹsi lo jẹ ki wọn sun ipade naa, bibẹẹkọ, ọsẹ to kọja lọ ni o yẹ ko ti waye.
Mercy Aigbe, Lateef Adedimeji, Ayoola Ayolola kó sọ́wọ́ ìbéèrè kàbìtì, ó di gbọin!!!
O fi kun un pe ipade ti awọn ṣe pẹlu Igbakeji aarẹ, Yẹmi oṣinbajo ko ṣaadede waye o. O ni aarẹ Buhari gan gan lawọn kọwe si lati ri ki aarẹ to wi pe oun n lọ si ilẹ okeere lati ṣe awọn ohun kan tabi meji, ṣugbọn ki oun ma baa fi ti oun da wọn duro lo fi ni ki awọn gomina ilẹ Yoruba ọhun lọ ṣepade pẹlu igbakeji oun.
Gomina Akeredolu ni o da oun loju pe aarẹ yoo tẹti gbọ ero ati ẹhonu awọn gomina ẹkun ilẹ Yoruba naa.
O ni Aarẹ Buhari ko fi igba kankan tako agbekalẹ ikọ alaabo Amọtẹkun, ṣugbọn ariwo tawọn kan pa lẹyin ọrọ ti amofin agba Abubakar Malami sọ lomu ko tara kiji pe bawo lo ṣe jẹ.
Ẹ̀yin obìnrin tẹ́ẹ fẹ́ wá bímọ ní America, ọ̀nà ti tì pa látònì! - Trump
Cisse bẹ́ sí Kàǹga nítori fóònù N3,000
Kí lo tíì rí  nípa Amotekun? Ẹ sùnmọ́bí, ẹ wo gbankọgbì!
EKSU: Àwọn òṣìṣẹ́ tí fásitì EKSU lé fún ìgbìmọ̀ aláṣẹ ní gbèdéke ọgbọ̀n ọjọ́ láti dá wọn padà sí ẹnu iṣẹ́
Oríṣun àwòrán, others
Awọn kan lara awọn oṣiṣẹ fasiti ipinlẹ Ekiti, EKSU nilu Ado Ekiti ti iṣẹ bọ mọ lọwọ laipẹ yii ti fariga pe akutupu yoo hu o bi awọn alaṣẹ fasiti naa ko ba da awọn pada sẹnu iṣẹ wọn laarin ọgbọn ọjọ.
Awọn oṣiṣẹ naa wa lara awọn oṣiṣẹ bii ẹẹdẹgbẹrun ti wọn yọ niṣẹ lọgba fasiti ọhun ni oṣu kejila ọdun to kọja.
Lara awọn ẹsun ti wọn fi yọ awọn oṣiṣẹ naa ni ayederu iwe ẹri, aitọ ọna to tọ wọ iṣẹ, kikọja ọjọ ori ti ofin la kalẹ lati ṣiṣẹ ni fasiti atawọn ẹsun miiran eyi to tako ilana igbanisiṣẹ.
Ninu lẹta kan eleyi ti agbẹjọro wọn kọ, awọn oṣiṣẹ naa ni bi wọn ṣe gba iṣẹ lọwọ awọn tako ilana ati ofin iṣẹ ijọba.
Lẹta naa darukọ awọn oṣiṣẹ mẹta...ti wọn ni wọn n gbẹnu awọn oṣiṣẹ mọkandinlọọdunrun miran ti wọn gba siṣẹ ni ọdun 2016 pe ẹjọ ọhun ki wọn to yọ wọn niṣẹ ni ọjọ karun un oṣu kejila ọdun 2019.
Mercy Aigbe, Lateef Adedimeji, Ayoola Ayolola kó sọ́wọ́ ìbéèrè kàbìtì, ó di gbọin!!!
Awọn amofin to n gba ẹjọ wọn ro ṣalaye pe ṣaka lara ilana to gba awọn eeyan ọhun siṣẹ le eleyi to tako ohun ti o n lọ kaakiri.
Bakan naa ni awọn oṣiṣẹ naa tun n beere fun sisan gbogbo owo oṣu, ẹtọ ati ajẹmọnu to tọ si wọn lati igba ti wọn ti yọ wọn kuro niṣẹ titi di asiko yii.
Mushin Amu Market fire: Ibi táa ti ń rí oúnjẹ òòjọ́ wa nìyí o, ẹ gbà wá
Oríṣun àwòrán, Twitter
Ajọ to n ri si iṣẹlẹ pajawiri ni ipinlẹ Eko ti fi aridaju han pe lootọ ni ina burẹkẹ ni isọ pako ni Mushin Amu ṣugbọn wọn ni awọn oṣiṣẹ awọn ti wa nibẹ.
Alukoro ajọ LASEMA, Ọgbẹni Nosa Okunor sọ fun BBC pe nkan bii ago kan kọja lọganjọ oru ni ina yii ti bẹrẹ si ni jo ti awọ́n si ti n gbiyanju lati pa a.
"Ọ̀gbẹ́ni Nosa ni awọn ṣi wa lori igbiyanju lati mu ki ọwọ ina naa rọlẹ ṣugbọn ""nitori pe asiko ẹrun ati ọgbẹlẹ niyii ati pe ọpọlọpọ nkan to lee tete ran ina ni wọn ko sinu awọn ṣọọbu to wa ninu ja naa, a ko tii ri i yanju""."
Oríṣun àwòrán, LASEMA
Inu iroyin ibanujẹ yii ni awọn olugbe agbegbe Mushin ni ipinlẹ Eko ji si ni owurọ yii ni nkan bii ago kan oru kọja iṣẹju marundinlọgbọn ti ọpọlọpọ ipe si ti lọ si ọdọ ajọ LASEMA.
Iroyin ti aj LASEMA fi ranṣẹ ni pe kete ti ipe de ọdọ awọn naa ni wọn ti kan lu iṣẹ. Nigba ti wọn de ibi iṣẹlẹ naa, wọn ri i pe ọgọọrọ ile itaja pako ati awọn ileegbe ni ina naa ti ran mọ.
Nigba ti wọn ṣe iwadii siwaju sii, wọn gbọ pe awọn nkan amuna wa lo fa iṣẹlẹ ọhun.
Bo tilẹ jẹ pe wọn ko tii le sọ pato iye nkan to ti bajẹ bayii titi di igba ti wọn yoo ri aridaju akọsilẹ, wọn fi iwoye ṣiro pe ina yii ti ba ohun ini ati ja to to ọpọlọpọ miliọnu naira jẹ.
Ẹwẹ, ko si iroyin pe ẹmi kankan ba iṣl naa rin ko si si ẹni to fara pa bo tilẹ jẹ pe awn oni jagidijagan kan fẹ maa da wahala silẹ latari iranwọ aibere fun ti wọn fẹ maa ṣe.
Lọwọlọwọ, akitiyan ti n lọ lati pa ina naa patpata pẹlu iṣẹ ẹka panapana ajọ LASEMA pẹlu ọkọ apina meji wọ, ati ẹka panapana ileeṣẹ Julius Berger naa pẹlu ọkọ apina meji ati ọkọ nla olomi.
Bakan naa, wọn ni ileeṣẹ panapana ti ipinlẹ Eko naa wa nibẹ pẹlu ọkọ apina meji ati pe ajọ RRS, LNSC atawọn araalu ni gbogbo wọn n pawọ pọ lati ṣeranwọ.
Oyo Fire: Dukia ṣófo, ọmọ ọdún mẹ́rìnlá faragbọta níbí iná tó jó ọjà Akesan
Ẹwẹ, loju opo ayelujara, awọn eeyan ti gba gbogbo rẹ kan ti wn si n ke gbajare lori anfani ti awọn ati mọlẹbi wọn n ri ni ọja nla yii bẹẹ si lawọn araalu n gbohun adura soke si Ọlọrun.
A ó máa mú ẹ̀kúnrẹ́rẹ́ ìròyìn yìí wá fún un yín.
Lamido Sanusi: Emir Kano ní fífẹ́ ju ìyàwó kan lọ ló mú ìṣẹ́ àti ìfàsẹ́yìn ba àpá àríwá Nàìjíríà
Oríṣun àwòrán, Facebook/Lamido Sanusi
Laisi ani-ani, aṣa fifẹ ju iyawo kan lọ midi abajọ oṣi ati iṣẹ to wọ pọ lapa ariwa orilẹede Naijiria.
Emir ilu Kano, Muhammad Sanusi Keji lo sọrọ yii nibi ayẹyẹ ikẹkọọjade fasiti ijọba apapọ niluu Gusau eyi to jẹ alakọọkọ iru rẹ.
Sanusi fọrọ naa lede nigba to ṣe amojuto iwe apilẹkọ kan ti Ọmọwe Usman Bugaji ka nibi ayẹyẹ ikẹkọọgboye fasiti ọhun nipinlẹ Zamfara.
Emir Kano lai jẹ pe awọn eeyan lapa ariwa Naijiria yipada pẹlu aṣa fifẹ ju iyawo kan lọ, o ni oṣi ati iṣẹ to n ba ọpọ finra ko le tan.
O ṣalaye pe ọpọ ọkunrin ni ko le da iyawo ṣoṣo bọ ṣugbọn o ni iyawo mẹta pẹlu awọn ọmọ bakan naa.
O ni iru wọn ko le pese ounjẹ tawọn ọmọ naa yoo jẹ ka to wa sọ pe wọn lowo lọwọ latyi ran awọn yii lọ si ileewe
Oríṣun àwòrán, Faceboo/Lamidi Sanusi
Sanusi ni lẹyin awọn ẹkun yoku lapa ariwa Naijiria yoo maa wa ayafi ti wọn ba yi aṣa naa pada.
''Ida ọgọrin ninu ọgọrun un awọn eeyan to wa lapa ariwa Naijiria lo n ba iṣẹ finra, nigba ti ida ogun pere wa ni apa gusu,'' Sanusi lo woye bẹẹ.
O fikun ọrọ rẹ pe ọpọ lo bimọ ti wọn ko tọju wọn, iru awọn bẹẹ lo n tọrọ bara kiri lati le jẹun.
Sanusi ni kekere lawọn ohun to n ṣẹlẹ lasiko yii bi ikọlu ẹgbẹ agbesunmọmi, Boko Haram, awọn adigunjale ati airiṣẹṣe nitrori yoo buru si nibi ogun ọdun tabi ọgbọn ọdun lọjọ iwaju.
Lassa Fever: 'Ẹ yé mu gaàrí mọ́, tẹ́ẹ̀ bá fẹ́ lùgbàdì ibà Lassa'
Oríṣun àwòrán, OTHERS
Ọ̀pọ̀ ènìyàn lo ti sọ ẹmi nù nítorí àìsàn Iba Lassa
O dabi ẹni pe alabọrun ti n di ẹwu bọ o pẹlu iba Lassa to ran kaakiri bi ina inju ọyẹ lorilẹede Naijiria.
Oludari ẹka eto ilera nipinlẹ Enugu, Dokita Boniface Okolo ti awọn ọmọ Naijiria pe ki wọn ye mu gaari mọ ti wọn ko ba fẹ lugbadi iba Lassa.
Dokita Okolo sọ pe awọn eku to n fa aarun Lassa ti maa n fara kan ọpọ ounjẹ to wọ pọ ju tawọn eeyan n jẹ ni Naijiria, gaari lọpọ igba.
Okolo ni mimu gaari lewu pupọ nitori kokoro to n fa iba Lassa le wa ninu gaari.
Dokita Okolo ni ewu to wa ninu gaari mimu ni pe lai si omi gbigbona to le pa kokoro iba Lassa, aifaimọ ki eeyan maa lugbadi aarun ọhun.
O ni ko si ewu pẹlu ki eeyan fi gaari tẹ ẹba nitori omi gbigbona ni yoo pa kokoro to le fa iba Lassa ninu gaari.
Ẹwẹ, iroyin to tẹ wa lọwọ lo sọ pe iba Lassa ti wọ ipinlẹ Kaduna bayii.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ekute to n fa iba Lassa pọ ni Iwọ-oorun ilẹ Africa.
Kọmiṣọnna fun eto ilera nipinlẹ naa, Dokita Amina Mohammed-Baloni lo fidi ọrọ naa mulẹ pe ijọba ibilẹ Chikun ni akọsilẹ ti wa ẹni kan ti lugbadi aarun naa.
Dokita Mohammed-Balonim sọ pe ọkunrin to lugbadi aarun naa, ẹni ọdun mẹrindinlogoji ti n gba itọju lọwọ bayii nile iwosan ti ijọba ti ya sọtọ fun itọju awọn to ni iru aarun bẹẹ.
Kọmiṣọnna rọ awọn eeyan ipinlẹ Kaduna lati mu eto imọtoto lọkunkundun lati le dena iba Lassa.
Minimum wage: Ìjọba Ondo gbà láti san #30,000 gẹ́gẹ́ bí owó oṣù òṣìṣẹ́ tó kéré jùlọ
Oríṣun àwòrán, Faceboo/Rotimi Akeredolu Aketi
Ẹrin keekee ti gba ẹnu awọn oṣiṣẹ ipinlẹ Ondo bayii lẹyin ti ijọba ipinlẹ naa gba lati san ẹgbẹrun un lọna ọgbọn naira
gẹgẹ bi owo oṣu oṣiṣẹ to kere julọ fawọn  oṣiṣẹ.
Lẹyin ọpọlọpọ ifọrọwerọ laarin ijọba ipinlẹ Ondo ati ẹgbẹ oṣiṣẹ lapaapọ, ijọba ti kede pe ohun ti ṣetan lati san owo naa.
Ọjọ Satide ọjọ kẹẹdọgbọn oṣu kinni ọdun 2020 ni ijọba atawọn oṣiṣẹ tun jọ ṣepade pọ lati yanju ọrọ naa.
Bakan naa awọn aṣoju ile igbimọ aṣofin ati ẹka eto idajọ nipinlẹ Ondo naa wa nibi ipade ọhun.
Ijọba gba lati san owo oṣu tuntun fawọn oṣiṣẹ to wa ni ipele kẹfa lọ si isalẹ nigba ti awọn oṣiṣẹ to wa lati akasọ keje lọ soke yoo j'anfaani ẹkunwo ti wọn naa.
Ninu ọrọ tiẹ, olori ẹgbẹ oṣiṣẹ nipinlẹ Ondo, Ọgbẹni Oluwadare Aragbaye dupẹ lọwọ awọn olori ẹgbẹ oṣiṣẹ fun ifọwọsowọpọ wọn, o ni ijọba yoo tẹsiwaju latiu mu igbayegbadun awọn oṣiṣẹ lọkunkundun nipinlẹ naa.
Awọn olori ẹgbẹ oṣiṣẹ naa gboriyin fun ijọba Gomina Rotimi Akeredolu lori bi o ṣe n sanwo oṣu awọn oṣiṣẹ ati ajẹmọnu wọn deedee lati ọdun 2017.
Lassa fever outbreak: Ìpínlẹ̀ Ondo, Edo àti Ebonyi ni ibà Lassa ti ń ṣọṣẹ́ jùlọ
Oríṣun àwòrán, @NCDCgov
Ajọ to n mojuto ajakalẹ arun lorilẹede Naijiria, NCDC ti kede pe eeyan mọkandinlogun lo ti di alaisi lori ajakalẹ arun iba Lassa to tun ṣẹṣẹ gbilẹ lawọn ipinlẹ kan lorilẹede Naijiria.
Ipinlẹ mọkanla lo ni arun iba Lassa ti tan kalẹ de lorilẹede Naijiria ti wọn si ti ri igba o din marun un eeyan ti ọwọ aarun naa si ti ba.
Ninu atẹjade kan, ti ọga agba ajọ naa, Dokita Chikwe Ihekweazu fi sita, ipinlẹ Ondo, Edo ati Ebonyi ni ọwọja arun yii pọ si julọ.
O ni ida mọkandinlaadọrun iye awọn ti o ti ko aarun naa ni wọn wa lati ipinlẹ mẹta yii.
Ẹ lee maa wo pe ki lo n fa a ti arun yii tun fi pada wa ni iru akoko bayii? Ajọ NCDC ni bi oju ọjọ ati ayika ṣe ri lasiko yii lo faa ati pe ajs naa n sa gbogbo ipa to yẹ lati kapa rẹ.
Ajọ naa ṣalaye pe ọpọ awọn oṣiṣẹ ni wọn ti fi ṣọwọ sawọn ipinlẹ marun un to n fara ko arun ọhun ni lọwọlọwọ.
Hepatitis: A kò leè kóo nípa dídìmọ́ ara ẹni
Amọṣa, ajọ naa ni adinku ti ba iye ẹmi to ba aisan yii lọ bi a ba wo o ni ifẹgbẹ kẹgbẹ pẹlu ọwọja rẹ lasiko yii kan naa ni ọdun 2019.
Ida mẹtalelogun awọn eeyan to ko aisan iba Lassa lọdun 2019 lo baa lọ sọrun alakeji, ṣugbọn lọdun yii nkọ, ida mẹrinla awọn to ko aisan naa ni wọn jade laye.
Oludari agba Ajọ to n mojuto ajakalẹ arun lorilẹede Naijiria, naa ni ibudo ayẹwo marun ọtọọtọ lo wa lorilẹede Naijiria nibiti wọn ti lee ṣayẹwo iba Lassa.
Yollywood: Odunlade Adekola àtàwọn òṣèré sinimá Yorùbá míràn tó padà lọ sí fásiti lọ kàwé
Oríṣun àwòrán, Muyiwa Ademola/mr. latin
Ọpọ lo n ri awọn eekan ilu, paapaa awọn oṣere sinima gẹ¶gẹ bi awọn to ti ni gbogbo ohun ti wọn n fẹ tan.
Amọṣa, diẹ ninu wọn ni ọwọ awọn ko tii tẹ eku ida eto ẹkọ nitori naa awọn n pada lọ si ile ẹkọ lati lọ kẹkọ.
Diẹ niyi lara awọn oṣere tiata Yoruba to ti pada ls kawe gboye ijinlẹ lẹyin ti wọn bẹrẹ ere sinima ṣiṣe:
Oríṣun àwòrán, odunlade adekola/instagram
Gbajumọ ni Ọdunlade adekọla ninu ka ṣe ere tiata Yoruba, koda o ti gbiyanju ninu awọn sinima miran to jẹ ti ede oyinbo pẹlu. Gbogbo aye lo si n fẹran rẹ eleyi ti o farahan ninu awọn ami ẹyẹ to ti n gba nihin ati lọhun.
Ọmọ ilu Ọtun Ekiti ni ipinlẹ Ekiti ni, ṣugbọn Abẹokuta lo gbe dagba, eyi ti o si maa n fi han ninu ede ẹgbọ ti o maa n saba lo ninu ere rẹ nigba miran.
Ni ọdun 1996 ni ọdunlade Adekọla bẹrẹ ere tiata ṣiṣe, ni ọdun 2018 ni Ọdunlade Adekọla kẹkọ gboye ijinlẹ ninu imọ akoso okoowo, (Business Administration) ni fasiti ilu Eko, Unilag.
O ni igbagbọ oun ninu wiwa imọ kun imọ lo ṣokunfa bi oun ṣe pada si ileewe.
Oríṣun àwòrán, Muyiwa ademola/ instagram
Sinima 'Ori'lo fọnrere Muyiwa Ademọla, ti ọpọ ṣaaju mọ si Muyiwa Authentic, sita.
Ni ọdun 2006 lo pada si fasiti ilu Ibadan lati lọ kẹkọ Diploma nipa imọ ẹkọ agba ati idagbasoke agbegbe, (Diploma in Adult Education and Community Development)
Ọlanrewaju Omiyinka (Baba Ijeṣa)
Oríṣun àwòrán, Olanrewaju Omiyinka/facebook
Baba Ijeṣa kii ṣe alejo ni agbo ere sinima, paapaa julọ sinima ede Yoruba. O si jẹ ọkan lara awọn adẹrinpoṣonu ninu ọpọlọpọ ere.
Fasiti ilu Eko ni baba Ijeṣa pada lọ lati lọ kawe gba ims nipa ere tiata. O ni oun ṣe bẹẹ lati lee tubọ jawe sobi irinajo oun nile aye ni.
Oríṣun àwòrán, Mr.Latin/facebook
Lẹyin ọdun marundinlogoji to pari ẹks girama ni Bọlaji Amusṣan ti ọpọ mọ si Mr. Latin pada si ileewe giga. Faisiti agbelegboye ti orilẹede Naijiria, National Open University lo si lọ lati lọ kọ nipa eto alaafia ati ipẹtu si aawọ
Coronavirus Update in Nigeria: 'Ewu ń bẹ pẹ̀lú bí àwọn ọmọ iléèwé ṣe wọlé padà lásìkò àrùn Coronavirus'
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Dokita Onimọ nipa eto ilẹra lorilẹede Niajiria ti ni ewu nla ni yoo jẹ fun eto ilẹra ni Naijiria ti ijọba apapọ ba paṣẹ ofin konile-o-gbele ọlọjọ gbọọrọ mii, ti arun Coronavirus ba peleke si ni Naijiria.
Alaga ẹka to n risi ajakalẹ arun ni ileewosan ẹkọṣẹ ti ileewe giga fasiti eto ilera ni Naijiria, UNIMED ni ipinlẹ Ondo, Dokita Ayodeji Akinbodewa lọ sọ bẹẹ fun BBC.
Dokita Akinbodewa  n sọrọ lori bi awọn eniyan ṣe kọ lati ma ṣe yoju si ileewosan fun ayẹwo nipa arun Coronavirus.
Dokita Akinbodewa ni ibanujẹ ọkan ni yoo jẹ fun awọn dokita ni ileewosan kaakiri orilẹede Niajiria nitori iṣẹ yoo wọ wọn lọrun.
O ni kii ṣe arun Coronavirus nikan ni Naijiria n koju lọwọlọwọ, awọn aisan bii Lassa Fever, ikọ fere ati arun ti ko gboogun, HIV naa ṣi n ba awọn ọmọ Naijiria finra ju arun Coronavirus lọ.
''Nitori naa ni ijọba, awọn oloṣelu ati awọn adari ijọ gbọdọ fi ọwọ sowọpọ lati rii wi pe awọn eniyan tẹle ofin to rọmọ didẹkun itankalẹ arun Coronavirus ni Naijiria''
''Ti a ba wo awọn orilẹede miiran lagbaye, ohun ti a ri ni pe ti ijọba ba ti dẹ ofin konile o gbele, ti awọn eniyan si pada si igbeaye wọn tẹlẹ, arun naa ni peleke sii ni, ti o si n mu ọpọlọpọ ẹmi lọ.''
''Amọ, yatọ si orilẹede South-Afrika ni ilẹ Afrika, arun yii ko ni ipa lara wa bi akọsilẹ ṣe kọkọ sọ wi pe yoo ri.''
''Bakan naa ni ida aadọrin awọn eniyan to ni arun Coronavirus ni Naijiria ni ko fi ami han lara wọn, ti ko si ṣe wọn ni ijamba.''
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Nitori naa, alaga ẹka to n risi ajakalẹ arun ni ileewosan ẹkọṣẹ ti ileewe giga fasiti eto ilera ni Naijiria, UNIMED, Dokita Ayodeji Akinbodewa naa ni oun ni igbagbọ wi pe bi awọn akẹkọọ ṣe pada si ileewe yii, ko le e ni ipa buburu lori awọn eniyan.
Oríṣun àwòrán, @Osrt school Instagram
Onimọ nipa eto ọrọ aje ni Niajiria, Bisi Iyaniwura ti ni inu oun bajẹ pẹlu bii ijọba ṣe fun awọn ọmọ ileewe alakọbẹrẹ laaye lati pada si ileewe lasiko arun Coronavirus yii.
Iyaniwura ni o lewu nitori wi pe ijọba ko fi ohun gbogbo ti awọn ọmọ naa nilo lati pada si ileewe sibẹ, ki ijọba to paṣẹ ki awọn ọmọ kekeke pada si ileewe.
O ni awọn ọmọ ileewe ti oun ri ni agbegbe kan n di mọ ara wọn lai tẹlẹ ofin ijinasiraẹni nitori wi pe o ti pẹ ti wọn ti ri ara wọn gbẹyin.
Oríṣun àwòrán, osun state government/ twitter
''O ṣi dara ti awọn ọmọ girama ati fasiti ba pada si ileewe, amọ o buru jai fun awọn ọmọ ileewe alakọbẹrẹ nitori wọn ko le e tọju ara wọn.''
Nitori naa, o rọ ijọba lati fun awọn ọmọ naa laaye lati jọkọ sile fun oṣu kan si meji lati woye bi arun naa yoo ṣe lọlẹ si, ki wọn to pada si ileewe.
Bakan naa lo bu ẹnu atẹ lu igbesẹ ijọba to fi owo kun owo epo ati owo ina lasiko arun Coronavirus ti awọn orilẹede miran n ṣe iranwọ fun awọn araalu.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
O rọ ijọba lati mu gbogbo nkan rọrun fun awọn ọmọ Naijiria lasiko yii, ki wọn ba le tọju ara wọn ati ẹbi wọn.
Bakan naa lawọn ile ẹkọ giga nipinlẹ Eko wọle pada.
Oṣu mẹfa gbako ni ijọba fi gbe awọn ileewe tipa lẹyin ti ajakalẹ aarun covid-19 bẹ silẹ lorilẹede Naijiria.
Awọn akẹkọọ to wọle lọjọ Aje lawọn ileewe alakọbẹrẹ ati girama kan niluu Eko ko pọ rara.
Ṣugbọn lawọn ileewe kan, niṣe lawọn akẹkọọ tu yahaya tu yahaya wọle pada sile iwe.
Ohun to jẹ iyalẹnu ni pe awọn ogo-wẹẹrẹ ti a mọ si ''Nursery pupils'' ti ijọba paṣẹ pe ki wọn maa tii wọle rara naa wọle pẹlu awọn akẹkọọ ileewe alakọbẹrẹ lawọn ileewe kan niluu Eko.
Ohun ti a gbọ ni pe ileewe alakọbẹrẹ ẹgbẹrun le ni mẹtadinlogun(1017) to jẹ ti ijọba ipinlẹ Eko ko tii wọle.
Ọpọ ileewe alakọbẹrẹ to jẹ ti aladini naa ko wọle kaakiri ilu Eko.
Akomolede àti Aṣa: Ọ̀rọ̀ Ẹ̀yán ni Bunmi Femi Amao ń kọ́ wa lórí ètò Akọ́mọlédè àti Àṣà lóri BBC Yoruba
Ilé ìjọsìn lè bẹ̀rẹ̀ ìsìn àárín ọ̀sẹ̀ padà, Mọ́sáláṣí àti Ṣọ́ọ̀ṣì lé gba iye èèyàn tó wù wọ́n ṣùgbọ́n...
Ijọba ipinlẹ Eko ti kede pe ki awọn ile ijọsin bẹrẹ isin aarin ọsẹ pada ni ipinlẹ naa.
Bakan naa ni Gomina ipinlẹ Eko, Babajide Sanwo-Olu ti fun awọn Musulumi laaye lati bẹrẹ adura ojoojumọ pada ki iye awọn to fẹ kirun si pọ bi o ba ṣe wu wọn.
Oríṣun àwòrán, Twitter/Sanwo-Olu
Sanwo-Olu sọ ọrọ yii lasiko to n kede awọn igbesẹ tuntun ti wọn gbe lati de awọn ofin to de arun Coronavirus ni ipinlẹ Eko.
Amọ, gomina Sanwo-Olu rọ awọn eniyan lati tẹle ofin ijinasiraẹni ati fifọ ọwọ loore koore, lọna ati dẹkun itankalẹ arun Coronavirus.
Oṣu mẹfa sẹyin ni ijọba ti awọn ileewe, ile ijọsin ati awọn ojuko iṣere to fi mọ sinima lọna ati dẹkun arun Coronavirus.
Bakan naa ni gomina Sanwo-Olu kede awọn ilana tuntun fun awọn akẹkọọ ti o fẹ wọle pada ni Ọjọ Ajẹ, Ọjọ Kọkanlelogun, Oṣu Kẹsan, ọdun 2020.
Iye awọn eniyan to ti lugbadi arun Coronavirus ni Naijiria bayii ti le ni ẹgbẹrun lọna mẹtadinlọgọta.
Nigba ti , iye eniyan to ti ni arun Coronavirus ni ipinlẹ Eko kaakiri ti le ni ẹgbẹrun mejidinlogun.
Ìjọba ìpínlẹ̀ Eko ti kéde ọjọ́ ìwọ́lé ọ̀tọ̀ọ̀tọ̀ fún àwọn ìpele ẹ̀kọ́ ni ìpíńlẹ̀ yìí.
Gómínà ìpínlẹ̀ Eko Babajide Sanwo-Olu kéde ọ̀rọ̀ yìí lọ́sàn ọjọ Abamẹta, nílé ìjọba tó wà ni Marina.
Nínú ọ̀rọ̀ rẹ̀, ó ni àlàálẹ̀ oríṣiríṣi ló ti wà fún àwọn ìpele ẹ̀kọ́ ní ìpińlẹ̀ Eko pàápàá jùlọ èyí to níṣe pẹ́lú sí pípéjú ọgbà ilé iwé.
Oríṣun àwòrán, Sanwol-olu/instagram
Ó ní àwọn àkẹ́kọ̀ọ́ tó wà ni ipele, kẹta àti ìkaarún ní ilé ìwé girama nìkan ni ààyè wà fún láti padà sí ilé ẹ̀kọ́ ni ọjọ́ ajé, ọjọ́ kọkàlélógún, oṣù yìí.
Gónìmà ni èyí rí bẹ́ẹ̀ láti lè jẹ́ ki wọ́n gbáradì fún ìdánwò tó ń bọ̀ lọ́nà àti kí àwọn onípele kààrún nílé ẹ̀kọ́ girama ba à lè múrasílẹ̀ fún ipele kẹfa.
Sùgbọ́n fún gbogbo àwọn ipele ẹ̀kọ́ tó kù láti ilé iwé alákọ́bẹ̀rẹ̀ titi de àwọn onipele kẹrin nílé iwé girama, ìjọba ni òun yóò kéde lẹ́yìn ti arídáju bá ti wa pé gbogbo ìlàna tó yẹ ló ti wà nílẹ̀.
'Búrẹ́dì tí wọn ó fi jẹ ẹ̀wà ni wọ́n lọ rà ni wọ́n pàdé ikú gbígbóná'
Ẹ̀wẹ́, o ní kí olúkúlùkù pada si àwọn ìlàna orí ayelujara tabi rẹdíò ti wọ́n ń lò tẹ́lẹ̀ láti fún àwọn akẹ́kọ̀ọ́ ni ìmọ̀ títí di ìgbà ti ìjọba yóò ṣe ikéde tuntun.
Bakan náà ni ìjọba tún kéde pé gbogbo àwọn ilé ọtí àti gbogbo ibi ìtura gbogbo tó fi mọ́ àwọn ilé ijọ àti sinimá níwọ̀n ìgbà ti wọ́n ba ti tẹ̀lé àwọn ìlànà lati dena ìtàkálẹ̀ ààrùn Covid-19.
Iye ènìyàn tọ gbọ̀dọ̀ péjú lẹ́ẹ̀kan kò gbọdọ jú ìdá ọgbọ́n lọ́, gbogbo àwọn ilé iṣẹ́ yìí si gbọ̀dọ gba iwé ẹ̀rí lọ́dọ̀ ìjọba ìpínlẹ̀ Eko kí wọn to bẹ̀rẹ̀.
Oríṣun àwòrán, Seyi makinde
Ìjọba Oyo kéde pé láàrín Sept. sí Dec. ni abala kínní sáà ètò ẹ̀kọ́ yóò wáyé
Ijọba ipinlẹ Oyo ti kede pe awọn ile ẹkọ rẹ yoo di ṣiṣi pada ni ọjọ kọkanlelogun oṣu kẹsan-an taa wa yii.Atẹjade kan ti kọmisana feto ẹkọ nipinlẹ Oyo, Olasunkanmi Olaleye fi sita lo sisọ loju ọrọ yii.
Atẹjade naa ni ọjọ kọkanlelogun oṣu kẹsan-an si ọjọ kejidinlogun oṣu kẹwaa ọdun 2020 ni abala kinni saa eto ẹkọ ọdun 2020 si 2021 yoo bẹrẹ.
Abala keji saa eto ẹkọ naa yoo bẹrẹ lọjọ kọkanla osu kinni si ọjọ kẹsan-an osu kẹrin ọdun 2021.
Bolaji Faleke ni Olùkọ́ tó ń kọ́ wa ní àṣà oge ṣiṣe lórí BBC Yorùbá
Abala kẹta eto ẹkọ naa yoo bẹrẹ lọjọ Kẹta osu karun, ti yoo si pari ni ọgbọnjọ osu keje ọdun 2021.Ileesẹ eto ẹkọ wa rọ awọn araalu ati awọn eeyan tọrọ naa gberu lati ṣe akiyesi bi saa eto ẹkọ naa yoo ṣe lọ.
Oríṣun àwòrán, osun state government/ twitter
Ijọba ipinlẹ Ogun ti kede igbega si kilaasi to kan lai ṣe idannwo fun awọn ọmọ ile iwe alakọbẹrẹ ati girama ipinlẹ naa ni kete ti wọn ba pada ṣenu ẹkọ wọn.
Bakan naa lo tun kede ọjọ kọkanlelogun, oṣu Kẹsan an, ọdun 2020 gẹgẹ bi ọjọ ti awọn ile iwe rẹ yoo di ṣiṣi pada.
Oríṣun àwòrán, @dabiodunMFR
Agbẹnusọ fun gomina ipinlẹ naa, Kunle Somorin lo kede bẹẹ ninu atẹjade kan to fi sọwọ si awọn akọroyin.
O ni gomina Dapo Abiodun ti buwọlu ṣiṣi gbogbo ile iwe pada bẹrẹ lati ile iwe alakọbẹrẹ titi de awọn ile ẹkọ giga.
Somorin fi kun pe ijọba ti ṣetan lati ṣi awọn ile iwe naa ni ibamu pẹlu ilana to rọmọ Covid-19.
Gẹgẹ bi alakalẹ ṣiṣi ile iwe ọhun ṣe lọ, awọn ọmọ ile iwe alakọbẹrẹ lati ipele kini si ikẹta yoo lọ ile iwe lati aago mẹjọ owurọ si mọkanla, nigba ti awọn to wa ni ipele kẹrin si ikẹfa yoo lọ lati aago mejila ọsan si aago mẹta.
Akomolede ati Aṣa lori BBC: Mọ̀ si nípa oríṣìí ẹ̀ka ìsọ̀rí ọ̀rọ̀ àti ìwúlò wọn
Awọn ti ile iwe girama lati ipele kini si ikẹta akọkọ yoo kẹkọọ lati aago mẹjọ si mọkanla owurọ, nigba ti awọn ti ipele kinni si ikẹta keji yoo lọ ile iwe lati aago mejila ọsan si mẹta.
Somorin ṣalaye pe awọn to n lọ ile iwe ẹkọṣẹ ọwọ yoo maa kẹkọọ bi wọn ṣe n ṣe tẹlẹ, lati aago mẹjọ owurọ si meji ọsan.
Nigba ti awọn akẹkọọ ile iwe giga ni anfani lati ṣi ile iwe pada ni ọjọ kọkanlelogun, oṣu Kẹsan an, ọdun 2020, ṣugbọn igbesẹ naa wa lọwọ awọn adari ile iwe bẹẹ.
Ni ti awọn ọmọ ile iwe lati ọmọ ọdun mẹta si marun un, o ni wọn ko lanfaani lati pada sile iwe lasiko yii.
Bo tilẹ je pe awọn akẹkọọ nile iwe girama to wa ni ipele kẹta akọkọ yoo tẹsiwaju si ipele kinni ẹlẹẹkeji lai ṣe idanwo, wọn yoo ṣe idanwo BECE ninu oṣu Kẹwaa ọdun 2020.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ki lo ti ṣẹlẹ sẹyin?
Ijọba ipinlẹ Kogi ti kede pe awọn akẹkọọ yoo wọle pada ni Ọjọ Kẹrinla, Oṣu Kẹsan an, ọdun 2020 lai yọ ileẹkọ alakọbẹrẹ, girama ati awọn ileewe giga ipìnlẹ naa.
Kọmisọnna fun eto ẹkọ, imọ sayẹnsi ati imọ ẹrọ nipinlẹ naa,Arakunrin Wemi Jones lo kede rẹ ni ilu Lokoja.
Jones ni ijọba ipinlẹ naa kede igbesẹ yii lẹyin ti wọn ṣe ifọrọwerọ pẹlu awọn eniyan ti ọrọ naa kan ni ẹka eto ẹkọ.
Jones fikun un  pe idi ti gomina ipinlẹ Kogi, Yahaya Bello ṣe gbe igbesẹ lati ti ileekọ ni Oṣu Kẹta, ọdun 2020 ni tori arun Coronavirus to n ja ranyinranyin kaakiri agbaye.
"Lẹyin naa ni awọn tẹlẹ aṣẹ ilẹeṣẹ ijọba to n risi ẹka eto ẹkọ ni  Naijiria, wi pe ki wọn ṣi ileewe alakọbẹrẹ fun awọn to wa ni Primary 6, JSS3 ati  SS3 ni Ọjọ Kẹwaa, Oṣu Kẹjọ, Ọdun 2020.
Ati wi pe lẹyin ipade pẹlu awọn ti ọrọ naa kan ni gomina naa gbe igbesẹ naa pe ki gbogbo awọn akẹkọọ pada si ileewe ni Ọjọ Kẹrinla, Osu Kẹsan an, ọdun 2020 ""."
Kọmisọnna fun eto ẹkọ naa fikun wi pe idi ti ijọba ipinlẹ Kogi ṣe ni ki awọn akẹkọọ pada si ileẹkọ ni pe awọn ko kabamọ pẹlu awọn akẹkọọ Primary 6, JSS3 ati  SS3 ti wọn ti kọkọ wọle.
Bakan naa ni ijọba wa rọ awọn adari ileewe lati tẹle ofin ati ilana ti ijọba gbe kalẹ lati le bọ lọwọ arun Coronavirus nipinlẹ naa.
Oríṣun àwòrán, OTHERS
Àwọn ìjọba ìpínlẹ̀ kéde ìwọlé fásitì, ASUU àti ìjọba àpapọ̀ ní kí wọ́n ṣọ́ra!
Awọn alaṣẹ ijọba apapọ ti fi imọran sita gẹgẹ bi awọn ijọba ipinlẹ kọọkan ṣe ti kede ọjọ ti awọn ileewe yoo wọle.
Ipinlẹ Eko ati Osun ni iha Guusu-Iwọ Oorun ti ni awọn ileewe yoo di ṣiṣi lọjọ kẹrinla ati ikọkanlelogun oṣu kẹsan ọdun 2020.
Ijọba apapọ gan ti wa funpe si awọn ijọba ipinlẹ pe ki wọn ṣọra lori bi wọn ṣe fẹ ṣi awọn ileewe tori pe ewu ṣi wa loko longẹ.
Boss Mustapha to jẹ akọwe ijọba apapọ to tun jẹ alaga igbimọ amuṣẹya aarẹ lori ọrọ COVID-19 fi ikilọ yii lede lọjọ Aje ni ilu Abuja nibi ipade ikejilelọgọta igbimọ naa.
Oríṣun àwòrán, osun state government/ twitter
O ni bi orilẹede ṣe n pinu lati ṣi awọn ibi ipejọpọ itagbangba, wọn gbudọ rii pe wọn ṣi n ṣe ohun gbogbo lati bori.Minisita fun eto ilera ni agbara aisan COVID-19 ko re 'bikan o pe o lewu to si n gba ẹmi awọn eniyan.'Ẹwẹ, ẹgbẹ awọn olukọni fasiti ni Naijiria, ASUU ti kilọ fun awọn ijọba ipinlẹ pe ki wọn ma  ṣe ṣi awọn ile ẹkọ giga lasiko yii.
Oríṣun àwòrán, Twitter
Ajọ awọn oṣiṣẹ olukọ ile ẹkọ giga
Ẹgbẹ ASUU n fẹ ki ijọba mu suuru titi di igba ti wọn ba lee ri ọna gboogi lati dinwọ aranka aarun Coronavirus ku.
Ẹgbẹ naa ni bi nkan ṣe wa lasiko yii, o fẹrẹẹ ma le tii si aaye fun awọn ile iwe giga ijọba lati tẹle ofin ijinasiraẹni.
Lọwọlọwọ awọn ọmọ ileewe girama to wa ni kilaasi aṣekagba nikan lo n lọ ileewe kaakiri gbogbo ipinlẹ mẹrindinlogoji Naijiria lati ọjọ kẹrin oṣu kẹjọ ọdun 2020 lati le kọ idanwo wọn bii WAEC ati NECO.Ẹwẹ, minisita abẹle fun eto ẹkọ, Họnọrebu Emeka Nwajiuba sọ pe ijọba apapọ ko tii sọ ọjọ ti awọn ileewe yoo wọle jakejado ṣugbọn ọjọ eyi tawọn ijọba ipinlẹ kede n kọ awọn obi lominu gidi gan.
Oríṣun àwòrán, Adegboyega oyetọla
Ijọba ipinlẹ Ọṣun ti kede eto iwọle tuntun fun ṣiṣi awọn ileewe ni ipinlẹ naa pẹlu mimu ọjọ kọkanlelogun oṣu kẹsan ọdun 2020 fun ṣiṣi awọn ileewe nibẹ.
Ninu atẹjade kan ti kọmiṣọnna feto iroyin ati ilanilọyẹ ni ipinlẹ naa, Arabinrin Funkẹ Ẹgbẹmọde fi sita lẹyin ipade igbimọ iṣakoso ijọba ni ipinlẹ naa, ijọba ipinlẹ Ọṣun ṣalaye pe awọn ilana a a tẹle gbogbo yoo ṣi wa nikalẹ fawọn alẹnulọrọ lẹka eto ẹkọ nibẹ ni ibamu pẹlu ilana ti ijọba apapọ ba gbe kalẹ.
Pẹlu eyi, ijọba ipinlẹ naa ti kede ọjọ kọkanlelogun, oṣu kẹsan an naa lati pari saa kẹta eto ẹkọ to n lọ lọwọ ki ajakalẹ arun COVID-19 loṣu kẹta ọdun 2020.
Ijọba ipinlẹ Ọṣun ni awọn gbe igbesẹ yii lẹyin oniruuru agbeyẹwo lawọn ileewe lati mọ bi igbaradi wọn lati pada si eto ẹkọ kikọ ṣe ja fafa si.
Ni ọgbọn ọjọ, oṣu kẹwaa ni saa kẹta to ku yoo pari fun awọn akẹkọọ lati le e lọ fun isinmi ranpẹ eyi ti yoo pari ni ọjọ kẹsan an, oṣu kọkanla, ọdun 2020.
Wo bí Sunday Orimola ṣe gba ikú ẹranko kú ní Ifon ni Ondo lórí ọ̀nà àtijẹ
Atẹjade naa tun fi kun un pe isinmi ranpẹ miran yoo tun waye bẹrẹ lati ọjọ kẹrinlelogun, oṣu kejila nitori pọpọṣinṣin ọdun ti yoo maa waye nigba naa.
Ṣugbọn awọn akẹkọọ yoo pada si ẹnu ẹkọ wọn ọjọ kẹrin oṣu kinni, ọdun 2021 lati pari saa akọkọ eto ẹkọ ọdun 2020/2021 eyi ti yoo pari ni ọjọ kejilelogun, oṣu kinni, ọdun 2021.
Bolaji Faleke ni Olùkọ́ tó ń kọ́ wa ní àṣà oge ṣiṣe lórí BBC Yorùbá
Amọṣa, ijọba apapọ ti fa awọn ipinlẹ to n gbe igbesẹ lati ṣi awọn ileewe pada leti  pe ẹkọ gbigbona n fẹ suuru.
Boss Mustapha to jẹ alaga ikọ amuṣẹya lori ọrọ ajakalẹ arun COVID-19 ni Naijiria ṣalaye lasiko ijiroro igbimọ naa lọjs Aje nilu Abuja pe nnkan lee da bi ẹni pe o ti n lọlẹ lẹnu lọwọlọwọ yii lori ọwọja ajakalẹ arun naa ṣugbọn O ni ẹyẹ ina gbigbona lọrọ arun naa ni Naijiria bayii, O kan fi eeru tutu boju ni.
Oríṣun àwòrán, others
Ni bayii ti awọn eeyan lorilẹ-ede Naijiria, paapaa julọ awọn obi, alagbatọ ati akẹkọọ n ko aya soke lori ibeere ati mọ igba wo gan an lawọn iloro ileewe yoo di ṣiṣi pada fun ẹkọ lorilẹ-ede Naijiria.
Lati oṣu kẹta ọdun 2020 ni ileewe ti wa ni titi pa lorilẹ-ede Naijiria nitori ọwọja ajakalẹ arun COVID-19 to bẹ silẹ kaakiri agbaye.
Ni ọsẹ to kọja ni ijọba ipinlẹ Eko kede ni tirẹ pe awọn akẹkọọ ileewe giga gbogbo ni ipinlẹ naa yoo wọle pada sẹnu eto ẹkọ ni ọjọ kẹrinla oṣu kẹsan an nigba ti awọn ileewe alakọbẹrẹ ati girama yoo tẹlee ni ọjọ kọkanlelogun, oṣu kẹsan kan naa.
Eyi tubọ mu ki ọpọ akẹkọọ lawọn iipinlẹ yokuu o maa beere pe igba wo ni yoo kan awọn naa pẹlu.
Ninu ifọrọwerọ pẹlu iwe iroyin abẹle kan lorilẹede Naijiria, ipinlẹ Ogun ati Ekiti ti ni awọn ko kanju lati da akẹkọọ pada si ileewe bayii.
Ninu ọrọ ti Remmy Hazzan, olubadamọran fun gomina ipinlẹ Ogun lori ọrọ ibanisọrọ ṣalaye fun ileeṣẹ iroyin naa, pe wọn ko tii le wọle.
Remmy Hazzan ni aṣẹ ijọba apapọ lawọn tẹle ni ipinlẹ Ogun.
Eyi to wa lati ti awọn ileewe pa, o si di igba ti ijọba apapọ ba tun gbe aṣẹ miran jade to tako eyi ki awọn to lee ṣi ileewe pada.
'Oyenusi ló mú mi wọ ẹgbẹ́ adigunjalè kó tó di pé mo b'Ólúwa pàdé'
Bakan naa ni ẹni to n dari igbimọ amuṣẹya lori ọrọ coronavirus ni ipinlẹ Ekiti Ọjọgbọn Bọlaji Aluko pẹlu sọ pe awọn ko ṣetan lati wo aago alaago sare.
O ni awọn yoo kọkọ wo bi nnkan yoo ṣe lọ si lẹyin eto idanwo aṣekagba girama WASSCE ati JSSCE to n lọ lọwọ ba ṣe waye.
Natalia Mufuta ìyá Yakub, Kamil àti Adam sọ̀rọ̀ lórí bí wọ́n ń sọ èdè mẹ́rin pàpọ
Ipinlẹ Ogun ati Ekiti nikan kọ lo ni ero yii lori wiwọle pada awọn akẹkọọ.
Ipinlẹ Enugu, Katsina, Bauchi, Gombe pẹlu ni awọn ko tii lee ṣe ohun to js bẹẹ lọwọ yii.
Wọn ni o di igba ti ọkan ba balẹ lori abo ati alaafia awọn akẹkọọ ki awọn to gbe igbesẹ ati ṣi  ileewe pada.
Oríṣun àwòrán, @Sanwoolu
Gomina ipinlẹ Eko, Babajide Sanwo-Olu ti kede pe ọjọ kẹrinla, oṣu Kẹsan an, ọdun 2020 ni gbogbo ileewe giga to wa ni ipinlẹ naa yoo bẹrẹ pada.
Gomina Sanwo-Olu sọ eyi di mimọ lasiko to n ba araalu sọrọ lori ibi ti nkan de duro lori aarun coronavirus nipinlẹ naa.
Bakan naa ni gomina sọ pe ijọba ti n ṣiṣẹ lori ki awọn ileewe girama, ati alakọbẹrẹ naa le wọle pada, to ba ṣe e ṣe lati ọjọ kọkanlelogun, oṣu Kẹsan-an, ọdun 2020.
Ọjọ kẹrindinlọgbọn, oṣu Kẹta, ni ijọba Naijiria ti gbe gbogbo ileewe ti pa, nitori itankalẹ aarun coronavirus.
"Ṣugbọn ṣa, gomina kilọ fun awọn obi, ati alakoso ileewe pe ""igba kuugba ni wọn le ṣe atunṣe tabi agbeyẹwo si igbesẹ naa."
Bakan naa lo sọ pe awọn ile ti, ile faaji, ati ile ijo yoo ṣi wa ni titi pa.
Coronavirus in Nigeria: Ìpínlẹ̀ Eko bẹ̀rẹ̀ fínfín àyíká nítorí Coronavirus
Ṣaaju ni Minista ileeṣẹ ijọba apapọ to n risi eto ẹkọ ni Naijiria ti fi ilana aatẹle sita ṣaaju ki awọn ile ẹkọ to wọle pada.
O ni awọn ilana yii di dandan ki ile iwe to ku le di ṣiṣi fun awọn akẹkọọ to ku lati bẹrẹ kilaasi wọn pada.
Sugbọn wọn ko tii sọ ọjọ gangan ni pato ti awọn akẹkọọ maa wọle pada sile iwe wọn.
Ṣaaju ni ijọba Naijiria ti ṣi awọn ile ijọsin, eto irinna ọkọ ofurufu nile tai nilẹ okeere ati awọn igbesẹ miran.
Sunday Igboho: Ẹ fi Ògún búra fún wa láti jà fún ilẹ̀ Yorùbá láì gbé Amotekun sábẹ́ ìjọba
Lẹyin ti ajakalẹ arun to n ba gbogbo agbaye finra yii ti di ohun ti ajọ WHO ni ao kọ lati maa baa gbe titi abẹrẹ ajẹsara yoo fi jade ti yoo si gbọ wiwo ni.
Ijọba Naijiria ti fi awọn ilana to le jé ki ajajakalẹ arun Covid 19 naa dinku ni titankalẹ ti awọn akẹkọọ ba pada sile iwe bayii:
1) Ile iwe kọọkan gbọdọ kọ Olukọ nipa eto aabo funra wọn ati akẹkọọ ati awọn oṣiṣẹ nile iwe kọọkan.
2) Wọn gbọdọ ṣe agbekalẹ ilana Covid 19 lati tete de ile iwosan tabi ipese ayẹwo ni kia ti ifura ba wa.
3) Ile iwe kọọkan gbọdọ ṣeto ọkọ to n gbe alaisan nipa iṣẹlẹ apajawiri ki wọn si ni oore ọfẹ lati tete ṣe ayéwo lasiko pẹlu itọju pẹlu ajọ NCDC to n risi itankalẹ ajakalẹ arun ni NAijiria.
4) Wọn gbọdọ ni omi to mọ, ọṣẹ ifọwọ sanitaisa, imọtoto nigba gbogbo fun akẹkọọ ati awọn Olukọ.
5) Ki ile iwe din iye akẹkọọ to n wa ni kilaasi kọọkan ku ati ni ile igbe awọn akẹkọọ ati awọn ibudo ijọsin.
6) Ki wọn maa lo gbagede fun awọn eto kọọkan dipo inu iyara ikawe tabi kilaasi.
Akomolede ati asa Yoruba: Ẹ wá kọ́ nípa àpòtí ìṣura èdè wa lórí BBC Yorùbá
Ki wọn ṣe agbekalẹ igbimọ kan ti yoo maa mojuto ilana aatẹlẹ wọnyii fun ile iwe wọn.
Awọn ile iwe gbọdọ ṣeto iwe kika lọna to rọrun fun awọn akẹkọọ ti wọn ko si ni korajọ pọ soju kan.
Ki wọn rii pe awọn akékọọ ati Olukọ ati awọn osiṣẹ to ku n tẹlẹ awọn ilana ti ijọba ti la kalẹ naa.
Imọtoto fun gbogbo ẹni to ba n wọle to si n jade ninu ile iwe kọọkan.
Oríṣun àwòrán, julischools.com.ng
Awọn ile iwe ti ko ba ni agbra lati pese awọn ilana aatẹle yii ni oore ọfẹ lati ṣi fi awọn akẹkọọ wọn  sile nile obi ati alagbatọ wọn.
Ki wọn si maa kọ wọn ni ẹkọ lati ori ayelujara.
Oríṣun àwòrán, Emmanuel oloye
Ìjọba orílẹẹède Niajiria ti pàṣẹ kí ẹ̀ka ìṣúná má san owó oṣù fún àwọn òṣìṣẹ́ tí kò bá gba ètò IPPIS.
Ki lo ti kọ́kọ́ sẹlẹ̀?
Láì san owó oṣù tẹ jẹ wá, kò sọ́rọ̀ kankan - ASUU sọ fún ìjọba
ASUU Strike: Àwọn olùkọ́ fásitì ní àmúṣẹ àdéhùn ọdún 2019 làwọn dúró lé lórí
Adari ẹgbẹ awọn olukọ nile ẹkọ fasiti nilẹ wa (ASUU), Ọjọgbọn Biodun Ogunyemi ti sọ fun ijọba apapọ ati ti ipinlẹ pe ki wọn san owo oṣu oṣiṣẹ ti wọn gbe ẹsẹ le fun awọn ọmọ ẹgbẹ naa.
ASUU ni bi eyi ba waye, yoo fun awọn ni anfaani lati lee joko sọrọ lori awọn nkan to so pọ mọ iyanṣẹlodi to ti bẹrẹ lati ọjọ kẹtalelogun, Oṣu Kẹta, Ọdun yii.
Ogunyemi ni owo oṣu marun ni awọn olukọ fasiti ko tii ri gba ati pe, awọn ko ni ṣẹwele iyanṣẹlodi naa ti ijọba apapọ ba kọ lati se amuṣẹ adehun to ṣe pẹlu ASUU ni ọdun 2019.
Sunday Igboho: Ẹ fi Ògún búra fún wa láti jà fún ilẹ̀ Yorùbá láì gbé Amotekun sábẹ́ ìjọba
Bakan naa ni ẹgbẹ salaye lọjọ isẹgun pe, ilana sisan owo oṣu awọn oṣiṣẹ fasiti (UTAS) ti wa nilẹ bayii, lati tan imọlẹ si owo oṣu oṣiṣẹ sisan ti ijọba apapọ beere fun.
ASUU lo se agbekalẹ UTAS lati duro gẹgẹ bii IPPIS tiẹ, eyi to da gbọmisi-omi-oto silẹ laarin ASUU ati ijọba apapọ.
Ogunyemi kede pe UTAS ti wa nilẹ lasiko apero kan to waye nilu Abuja, bakan naa lo pe aarẹ Muhammadu Buhari lati da si rogbodiyan to n lọ ni fasiti Eko (UNILAG), ko si se agbekalẹ igbimọ olubẹwo si ile iwe naa.
Alaafin: Olori Aanu Adeyemi ṣàlàyé ìdí tó ṣe gẹ́ Oba Lamidi Adeyemi ti ìlú Oyo
O ni ASUU ko ni sinmi iyanṣẹlodi ti ijọba ko ba ṣe amuṣẹ adehun rẹ ọdun 2019 pẹlu ASUU.
O ni owo oṣu marun gbako ni ijọba gbẹsẹ le laisan fawọn oṣiṣẹ fasiti ni Maiduguri, nigba ti Akowe owo Fasiti Michael Opara, si n di owo awọn olukọ ibẹ, nitori wọn kọ lati fi orukọ silẹ fun IPPIS.
O wa kilọ pe ASUU ko ni ri aaye fun ẹjọ kankan mọ lori wiwọgile iyanṣẹlodi, ti ijọba ba kọ lati san awọn owo ti wọn jẹ.
Ẹgbẹ awọn oṣiṣẹ lorilẹede Naijiria, ASUU ti paṣẹ fun awọn olukọ fasiti lati da iṣẹ silẹ ni igbakugba ti ijọba ba ti kọ, lati san owo oṣu wọn.
Alaga ẹgbẹ awọn oṣiṣẹ ni ile ẹkọ fasiti Abeokuta, Adebayo oti sọ fun ile iṣẹ iroyin Punch pe awọn ti fi aṣẹ naa ranṣẹ si awọn ọmọ ẹgbẹ naa.
Adebayo ni abajade ipade ẹgbẹ ni wi pe ti ijọba ba kọ lati san owo oṣu awọn kan, gbogbo awọn ni awọn yoo da iṣẹ silẹ.
Bakan naa ni wọn fi ẹsun kan awọn oṣiṣẹ ijọba pe wọn lọ gba ẹyin ba ẹbọ jẹ lori eto isanwo oṣiṣẹ eto IPPIS.
Eto IPPIS ni ijọba pese lati ma a san owo oṣu oṣiṣẹ lati inu apo isuna kan naa fun owo gbogbo oṣu oṣiṣẹ ijọba, eleyii ti  Asuu ni eto isanwo yii yoo gba aṣẹ to gbe awọn duro lati le daduro lai si afikun ijọba lori eto isuna awọn.
Oríṣun àwòrán, Twitter
Ajọ awọn oṣiṣẹ olukọ ile ẹkọ giga
Amọ ijọba ni idi ti awọn fi gbe e kalẹ ni lati gbe ogun ti iwa ibajẹ ati jẹgudujẹra to wa ni ẹka oṣiṣẹ ijọba lorilẹede Naijiria.
Lẹyin ọpọlọpọ ipade ati akitiyan lati ọdọ ijọba apapọ ati ẹgbẹ oṣiṣẹ ASUU, wọn gba pe ki wọn gbe ajọ UTAS silẹ ti yoo gbogun ti iwa ibajẹ ni eto isuna ile ẹkọ giga, ẹleyii ti ko nilo eto IPPIS.
Amọ ẹgbẹ oṣiṣẹ ASUU fi ẹsun kan ijọba pe wọn ko duro lori ọrọ wi pe ki wọn gbe ajọ UTAS yẹmọ, amọ ti ijọba paṣẹ pe oṣiṣẹ ti ko ba si lori eto isuna IPPIS ko ni gba owo Oṣu Kini, ti ọdun 2020 ti o n pari ni ọṣẹ yii.
Oríṣun àwòrán, other
Laipẹ yii ni Aarẹ Buhari paṣẹ fun awọn oṣiṣẹ lasiko ti oun ṣe ipade pẹlu wọn lati ri pe wọn yanju ọrọ naa pẹlu minisita fun eto ẹkọ lorilẹede Naijiria, Adamu Adamu.
Amotekun: Aro tó wá láti ilú Ọyọ ló máa ń fi ẹranko náà dojú ìjà kọ àwọn ọ̀tá
Oríṣun àwòrán, Wikipedia
Kii se tuntun  mọ pe awọn gomina lẹkun iwọ oorun guusu Naijiria sefilọlẹ igbimọ alaabo kan ti wọn pe ni Amotekun, eyi ti yoo maa mojuto eto aabo ilẹ Yoruba.
Sugbọn ohun to wa ya ni lẹnu julọ ni wipe iwadi ati itan ti jẹ ko ye wa pe, ikọ alaabo Amotekun kii se tuntun nilẹ Yoruba, o ti wa lati igba ọdun o le diẹ sẹyin.
Itan naa, gẹgẹ baa ti kaa loju opo itakun agbaye Wikipedia, ni nilu Ilaro, to wa ni agbegbe Yewa, taa mọ si Ẹgbado tẹlẹ ni ikọ Amotekun ti gberasọ lati ọdọ ẹnikan to da ilu naa silẹ.
Oríṣun àwòrán, @wunmy5
Gẹgẹ baa ti gbọ, Aro ni orukọ ọkunrin naa, to da ilu Ilaro silẹ, to si ni Amotekun kan to n sin bi ẹran ile, eyi to maa n mu kiri.
Ilu Ọyọ la gbọ pe Aro ti wa, lasiko ti iroyin gbalẹ kan pe awọn agbesunmọmi lati ilẹ okeere n dunkooko mọ awọn ọmọ Oduduwa to wa layika.
Aro si tẹdo si ilu kan ti wọn n pe ni Igbo Aje, eyi to wa lori oke, ti yoo si mu ko rọrun fun oun ati awọn akẹẹgbẹ rẹ lati mọ igba tawọn ọta ba sunmọ tosi, lati wa sisẹ ibi wọn.
Agbẹ gidi ati ọdẹ haun-haun ni Aro, ti awọn eeyan si bẹrẹ si fi orukọ rẹ pe ilu Igbo Aje. Wọn n pe ilu naa ni ilu Aro, eyi to wa pada di Ilaro ni oni.
Amotekun ti Aro si maa n mu kiri lo maa fi n daabo bo ilu naa ati awọn agbegbe ilẹ Yoruba yoku, ti awọn ọta ba si de lati wa fi ogun ko ilu Aro, Amotekun yii ni yoo doju ija kọ wọn, ti yoo si ba wọn ja ni ajasẹgun.
Imoyosola Adetoro: Àwọn èèyàn sọ fún ìyàwó mi pé mo ti jẹ́ẹ̀jẹ́ nínú awo pé ń kò ní bímọ
Nigba ti ogbo de, Aro fẹ fi han awọn eeyan bi agbara oogun rẹ ti pọ to, Aro ati Amotekun rẹ ni wọn dijọ wọ ilẹ lọ ni aaye, ti wọn ko si ri wọn mọ titi di oni.
Oríṣun àwòrán, Oba Adeoye
Agbẹjọro agba nipinlẹ Ekiti, to si tun jẹ kọmisana feto idajọ, Wale Fapohunda ti sọ pe ipinlẹ Eko, Ogun ati Ekiti lo n lewaju lati ṣe agbekalẹ ofin ti yoo ṣe atọna ikọ alaabo Amotekun.
Fapohunda fi ọrọ yi lede fawọn akọroyin lọjọ Aiku, pẹlu afikun pe Amọtẹkun yoo lagbara lati mu awọn to ba tasẹ agẹrẹ sofin.
Ninu alaye rẹ, Fapohunda sọ pe awọn agbẹjọro agba lawọn ipinlẹ ta darukọ ṣaaju, yoo ṣe ipade lọjọ kẹfa oṣu Keji, lati se akojọpọ gbogbo abadofin ti wọn ba kojọ nipa ilana ti Amọtẹkun yoo maa tẹle.
''Ohun ta fẹ ni pe ki a gbe ikọ alaabo eleyi ti yoo ba ofin mu kalẹ, ki awọn eeyan agbegbe ta ti ṣe agbekalẹ rẹ baa le ni igbabọ ninu rẹ. Afojusun wa ni ki a ni ofin ti yoo daabo bo ẹmi awọn ara ilu''
Fapohunda tẹsiwaju pe, abadofin tawọn n ṣeto rẹ ni yoo ṣe agbekalẹ aṣẹ ti awọn yoo gbe le ikọ Amọtẹkun lọwọ.
''Kii ṣe nkan tuntun ni ki awọn ikọ alaabo ni agbara lati mu awọn ọdaran. Gbogbo awọn ikọ alaabo igbalode wa lo ni agbara lati mu ọdaran. Ohun pataki ni pe ki ni yoo ṣẹlẹ lẹyin ti wọn ba mu awọn ọdaran naa tan?''
Bi Amọtẹkun yoo ti ṣe ṣiṣẹ ni pe bi wọn ba ri ọdaran to n tasẹ agẹrẹ sofin, wọn yoo fi to awọn agbofinro leti. Bi eleyi ko ba ṣeeṣe, wọn yoo mu ẹni naa ti wọn yoo si fa le awọn agbofinro lọwọ''
O pari ọrọ rẹ pe, awọn ṣi n ṣiṣẹ pẹlu awọn ọọfisi agbẹjọro agba lawọn ipinlẹ Iwọ oorun to ku, lati ri pe awọn ofin wọnyi ko yatọ sira wọn.
Bi a ko ba gbagbe, laipẹ yi ni awọn Gomina ipinlẹ Iwọ oorun ati ijọba apapọ fẹnuko lori idasilẹ ikọ alaabo Amọtẹkun.
Ninu ipade naa, ti igbakeji aarẹYemi Osinbajo dari rẹ, wọn panupọ pe ki awọn ijọba ipinlẹ pada lọ ile lati fi ofin to yẹ gbe idasilẹ Amọtẹkun lẹyin.
Algon Oyo: Àwọn ọlọ́pàá ẹnu ọ̀nà káńṣù náà ṣetán láti wọ́n eṣinṣin tó bá ta fírí
Oríṣun àwòrán, Others
Olu ileeṣẹ ijọba ibilẹ Ariwa Ibadan, Ibadan North, to n bẹ ni agbegbe Agodi-Gate n'Ibadan, naa jẹ ọkan lara awọn ijọba ibilẹ ti awọn oṣiṣẹ ko ti ni anfani lati wa si ẹnu iṣẹ lonii.
Gboin-gboin ni ẹnu iloro ijọba ibilẹ naa wa ni titi pa lasiko ti ikọ BBC Yoruba se abẹwo sibẹ.
Wamu-wamu si ni awọn agbofinro duro sibẹ, ti esinsin ba si ta firi nibẹ, wọn yoo wọn ni.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí:
Ọkan lara awọn oṣiṣẹ ijọba ibilẹ naa, to ni ki a fi orukọ bo oun laṣiri ṣalaye wi pe, lati opin ọṣẹ ti o kọja ni awọn alakoso ijọba ibilẹ naa ti ranṣẹ si awọn oṣiṣẹ wọn.
Awọn lo si wi pe ki onikaluku osisẹ joko sile lonii titi di ọjọ miran, jọ re, nipasẹ iroyin to n ja rainrain wi pe awọn alaga ibilẹ tẹlẹri ninu ẹgbẹ oṣelu APC ipinlẹ Ọyọ, ti n gbero lati pada sẹnu iṣẹ wọn lonii.
Saaju ni agbẹjọro agba lorilẹede yii, Abubakar Malami ranṣẹ si gomina ipinlẹ Ọyọ, Onimọẹrọ Ṣeyi Makinde lati da awọn alaga ibilẹ tẹlẹri naa pada sẹnu iṣẹ wọn, ti Makinde si fesi wi pe agbẹjọro agba orilẹede yii ko lẹtọ lati fi ọwọ lalẹ nipinlẹ Ọyọ.
Ijọba ipinlẹ Ọyọ ti fesi si awuyewuye ọrọ to n ja rain-rain nilẹ pe o seese ki alaafia ma jọba lawọn ibujoko ijọba ibilẹ to wa jake jado ipinlẹ naa loni ọjọ Aje.
Oríṣun àwòrán, Others
Atẹjade kan ti akọwe iroyin fun gomina Seyi Makinde, Taiwo Adisa fisita kede pe eyikeyi alaga ibilẹ ana labẹ ijọ ẹgbẹ oselu APC, ti ọwọ ba tẹ pe o n da omi alaafia ilu ru, ni yoo jo palongo labẹ ofin.
Bakan naa ni atẹjade naa fikun pe, ijọba Ọyọ yoo se agbeyẹwo ofin ọdun 1999, ti yoo si mu lo gẹgẹ bo se kan awọn alaga ijọba ibilẹ mejidinlaadọrin ti wọn juwe ọna ile fun nijooni.
Atẹjade naa ni eyi se pataki nitori bi awọn alaga ijọba ibilẹ naa se n dunkooko kiri pe awọn yoo gba akoso awọn kansu lonii ati bi ẹgbẹ awọn osisẹ ijọba ibilẹ Nulge se ni kawọn ọmọ ẹgbẹ rẹ joko sile.
Imoyosola Adetoro: Àwọn èèyàn sọ fún ìyàwó mi pé mo ti jẹ́ẹ̀jẹ́ nínú awo pé ń kò ní bímọ
Adisa ni bi o tilẹ jẹ pe ijọba ko ni foju laifi wo ẹgbẹ Nulge pe o niu kawọn osisẹ rẹ joko sile nitori ibẹru ohun to lee sẹlẹ, amọ o rọ awọn osisẹ ijọba nipinlẹ Ọyọ lati kẹyin si idunkooko lati ibikibi pẹlu erongba lati da eto isejọba ru nipinlẹ naa.
Oríṣun àwòrán, Seyi Makinde
O ti n rugbo bọ lori awuyewuye to n waye nipa ta lo tọ lati dari awọn ijọba ibilẹ nipinlẹ Ọyọ, ti ko si sẹni to mọ ibi ti igi ọrọ yoo wo si loni ọjọ Aje.
Oniruuru awọn iroyin ti ko fẹsẹ mulẹ lo ti n gba ori awọn ikanni ayelujara kan pe o seese ki awọn ijọba ibilẹ tijọba ana bura fun wọle pada sẹnu isẹ lonii.
Bẹẹba gbagbe, ni kete ti ijọba gomina Seyi Makinde gba ijọba lo pasẹ pe ki awọn alaga ijọba ibilẹ naa, ti wọn jẹ ọmọ ẹgbẹ oselu alatako APC, lọ rọọkun nile na, to si yan awọn alaga afunsọ rọpo wọn.
Oríṣun àwòrán, Nulge
Lọsẹ to kọja la gbọ pe Agbẹjọro agba ni Naijiria, Abubakar Malami fiwe ransẹ si ijọba ipinlẹ Ọyọ pe ko fawọn alaga ijọba ibilẹ latinu ẹgbẹ APC ọhun laaye lati maa ba isẹ wọn lọ, eyi ti iroyin gbalẹ kan pe wọn yoo wọ isẹ lonii.
Sugbọn lasiko to n ba BBC Yoruba sọrọ, akọwe iroyin si gomina Seyi Makinde, Taiwo Adisa ni ko si ohun to jẹ otitọ ninu iroyin naa nitori ijọba Ọyọ ko ri iwe kankan gba lati ọdọ Malami.
Oríṣun àwòrán, Abiola Ajimobi
Lọwọ-lọwọ bayii, nitori wahala to seese ko bẹ silẹ loni nidi emi ni adari ijọba ibilẹ, iwọ kọ,laarin awọn alaga afunsọ ati alaga latinu ẹgbẹ APC, ẹgbẹ awọn osisẹ si ti faake kọri pe wọn yoo gbe ẹnu ọna awọn ileesẹ ijọba ibilẹ jakejado ipinlẹ Ọyọ tipa.
Oríṣun àwòrán, Nulge
Ninu atẹjade kan ti wọn fisita lọjọ Ẹti, ẹgbẹ awọn osisẹ nijọba ibilẹ, NULGE, ẹka tipinlẹ Ọyọ salaye pe lẹyin ipade igbimọ alasẹ ẹgbẹ naa ni awọn fẹnuko lati gbe ilẹkun awsn ijọba ibilẹ ti pa bẹrẹ lati sjọ Aje, titi di ọjọ miran, ọjọ ree.
Ẹgbẹ Nulge ni erongba awọn lati gbe igbesẹ yii ni lati ri pe alaafia jọba lawọn ijọba ibilẹ to wa nipinlẹ Ọyọ, ti ko si si rogbodiyan kankan rara.
Imoyosola Adetoro: Àwọn èèyàn sọ fún ìyàwó mi pé mo ti jẹ́ẹ̀jẹ́ nínú awo pé ń kò ní bímọ
Ilẹ aanu Oluwa kii su, bẹẹ ni ọrọ ri fun Imoyosola Adetoro ati aya rẹ, Tejumade lasiko ti Ọba oke da wọn lohun, ti wọn si bi ọmọ lẹyin idaduro ọdun mẹjọ.
Imoyosola Adetoro: Àwọn èèyàn sọ fún ìyàwó mi pé mo ti jẹ́ẹ̀jẹ́ nínú awo pé ń kò ní bímọ
Lasiko to n ba BBC Yoruba sọrọ, Imoyosola salaye pe oun ko tiẹ mọ boya ki oun maa sunkun ni tabi maa rẹrin nigba ti oun gbọ pe iyawo oun bimọ saye.
O ni ọpọ eeyan lo ti sọ isọkusọ fun iyawo oun pe oun ko lee bimọ nitori oun ti da majẹmu ninu ẹgbẹ awo ti oun wa pe oun ko ni bimọ.
Maryam Sanda: Àdájọ́ ní kí wọ́n yẹgi fun títí tí ẹ̀mí yóò fi bọ́ lára rẹ̀
Oríṣun àwòrán, Others
Maryam Sanda, ìyàwó tó pa ọkọ rẹ, ri ìdájọ ikú he Ileẹjọ giga kan to kalẹ si opopona Aguiyi Ironsi ladugbo Maitama nilu Abuja ti gbe idajọ kalẹ lonii pe iku lo tọ si iyawo kan to sekupa ọkọ rẹ, Maryam Sanda.
Maryam yii ni wọn lo fi ọbẹ gun ọkọ rẹ, Bilyaminu Bello, eyi to ran sọrun ọsan gangan lọdun 2017.
Fidio ree lori bi Maryam Sanda se foju ba ileẹjọ:
Maryam Sanda: Ṣe ló ń wa ẹkún mu nílé ẹjọ́ lórí ìdájọ́ ikú tí wọn fun
Bi o tilẹ jẹ pe Maryam sọ pe oun ko mọwọ mẹsẹ lori ẹsun ipaniyan ti wọn fi kan oun naa, sibẹ o papa foju ba ileẹjọ.
Maryam ati ibatan rẹ kan, iya ati alabasisẹpọ rẹ kan si ni wọn fi ẹsun kan pe wọn ba ẹri to daju jẹ, eyi to lee fidi rẹ mulẹ pe Maryam jẹbi ẹsun ti wọn fi kan.
Oríṣun àwòrán, Others
Lẹyin atotonu agbẹjọro fun ijọba ati igun olujẹjọ, ni adajọ kede pe Maryam jẹbi ẹsun ipaniyan ti wọn fi kan, to si ni ki wọn lọ yẹgi fun titi ti ẹmi yoo fi bọ ni ẹnu rẹ.
Imoyosola Adetoro: Àwọn èèyàn sọ fún ìyàwó mi pé mo ti jẹ́ẹ̀jẹ́ nínú awo pé ń kò ní bímọ
Maryam, iya rẹ ati awọn ẹbi yoku to wa nile ẹjọ si lo mu igbe bọnu ni kete ti adajọ naa gbe idajọ rẹ kalẹ.
Agric Locust: Àwọn kokoro eṣú ti ba irè oko jẹ nílẹ̀ Afirika
Ai si ojo fun ọpọlọpọ igba ni Ila Oorun Ilẹ Afirika ti fa ki kokoro ajẹnirun ba ere oko awọn agbẹ jẹ ni ẹkun naa.
Wo fidio yii lati mọ oun to se ti kokoro esu ba wọnu oko rẹ:
East Africa: Àwọn kokoro ti ba èrè oko jẹ nílẹ̀ Afirika
Nkan ko ṣe ẹnu ire fun awọn agbẹ lorilẹede Kenya, Ethiopia to fi mọ Yemen nitori esu to n ja ire oko.
Esu kan to miliọnu kokoro, ti o si ba awọn ere oko jẹ fun awọn agbẹ.
Amọ onimọ nipa eto ọgbin ti rọ awọn agbẹ lati ma lọ kuro ni ileto kan si omiran, ti kokoro ba ti ba ire oko wọn jẹ.
Ọyọ: Àwọn Alága APC fàáké kọ́rí fún Seyi Makinde, wọn padà sẹ́nu iṣẹ́
Oríṣun àwòrán, Oladiipo Oyeyemi Deeplomacy
Alaga ijọba ibilẹ ni ipinlẹ Oyo ti ni awọn kọ aṣẹ gomina ipinlẹ Oyo, Seyi Makinde to yọ awọn nipo lai ti pe ọjọ.
Alaga ẹgbẹ agbarijọpọ awọn alaga ijọba ibilẹ, ALGON, ẹka tipinlẹ Ọyọ, Ọmọọba Ayodeji Abass-Alẹshinoye sọ eyi lasiko to ba awọn akẹgbẹ rẹ sọrọ ni ilu Ibadan, ti wọn si panupọ sọ wi pe, awọn yoo pari saa awọn tan, eleyii to ku ọdun kan, ki awọn to kuro ni ipo.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí:
Ijọba ipinlẹ Ọyọ ti yan awọn alaga fidihẹ fun awọn ijọba ibilẹ to wa ni ipinlẹ Oyo, lẹyin ti Gomina naa kọwe lọ gbe ile rẹ fun awọn alaga to wa nibẹ tẹlẹ.
Oríṣun àwòrán, Oladiipo Oyeyemi Deeplomacy
Abass-Aleshinloye ni, alaga ijọba ibilẹ Oluyole ni ipinlẹ Oyo pẹlu aṣẹ ile ẹjọ to gaju lọ lorilẹede Naijiria.
Bakan naa lo paṣẹ fun awọn akẹgbẹ rẹ ti ijọba ti kọwe lọ gbe ile rẹ fun, lati pada si ibi iṣẹ wọn ni waranṣesa, ayafi awọn agbeegbe ti ijọba ti ti ileeṣẹ wọn.
Làáhànmí: Ìwádìí ní èèyàn 219 ni ibà Lassa pa lọ́dún tó lọ́, 29 lọ́dún yìí, tètè dènà rẹ̀
Alaga ijọba ibilẹ ni ipinlẹ Oyo naa fi ẹsun kan Gomina Makinde wi pe, o tẹ oju ofin mọlẹ nipa titapa si aṣẹ ile ẹjọ to ga julọ lorilẹede Naijiria.
O ni oun ti gomina naa n ṣe ni lati bọwọ fun ofin ti o ba a lara mu, ti o si kọ awọn ofin to ku silẹ.
Oríṣun àwòrán, Nulge
Iroyin ni ti ipa, ti ikuuku ni awọn alaga ijọba ti gomina yọ ni ipo fi wọ ileeṣẹ wọn ni Ọjọ Aje.
Laipẹ yii ni Minisita fun eto idajọ, Abubakar Malami kọ lẹta si Kọmisana feto idajọ ni ipinlẹ Oyo lati da awọn alaga ijọba ibilẹ ti gomina ipinlẹ Oyo, Seyi Makinde yọ nipo, pada si ipo wọn.
Lassa Fever: Ìwádìí ní èèyàn 219 ni ibà Lassa pa lọ́dún tó lọ́, 29 lọ́dún yìí, tètè dènà rẹ̀
Lori eto Laahanmi ti BBC Yoruba, a se atupalẹ ohun ti iba Lassa jẹ, ọsẹ to n se lawujọ wa ati awọn ọna ta fi lee dena rẹ.
Làáhànmí: Ìwádìí ní èèyàn 219 ni ibà Lassa pa lọ́dún tó lọ́, 29 lọ́dún yìí, tètè dènà rẹ̀
Iwadi fi ye wa pe awọn ekute ile lo n fa iba yii, eyi to n sekupa ọpọ eeyan lọwọlọwọ bayii.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí:
Ẹ wo fidio yii lati mọ iye eeyan ti arun yii ti pa, awsn ohun to n sokunfa rẹ, ami ta fi mọ pe iba Lassa wa lara eeyan kan ati ọna ta lee gba dena rẹ.
Toyosi Adesanya: Iléeṣẹ́ ọlọ́pàá ní Kwara ní àwọn àti Fijilanté wà nínú igbó láti ṣàwárí ọ̀daràn tó ṣèkọlù náà
Gbajugbaja osere ori itage lobinrin, Toyosi Adesanya Ileyemi ti iroyin gbalẹ kan pe awọn gende agbebọn kọlu ti ba BBC Yoruba sọrọ.
Lasiko ti a kan si Toyosi lori aago ilewọ rẹ fun ifọrọwerọ, obinrin ti ori ko yọ ninu ikọlu naa, ti ko lee sọrọ daada, fi to wa leti pe ojora si n mu oun lọwọ nipa isẹlẹ laabi naa, to si han ninu ohun rẹ pẹlu.
Toyosi Adesanya, ẹni to ni alaafia ni oun wa, seleri pe ni kete ti ara oun ba ti bọ sipo lati sọrọ nipa bi isẹlẹ naa se waye, ni oun yoo dahuin ibeere latọdọ BBC Yoruba.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí:
Nigba to n sọrọ lori isẹlẹ yii, aarẹ fun ẹgbẹ awọn osere ori itage TANPAN, Bolaji Amusan, ti gbogbo eeyan mọ si Mr Latin sọ fun BBC Yoruba pe oun ti ba Toyosi Adesanya sọrọ ni kete ti isẹlẹ naa waye laarọ ọjọ Aje, ti inu oun si dun pe ara rẹ le.
Oríṣun àwòrán, Toyosi Adesanya
Amusan ni isẹlẹ naa ko mu inu oun dun debi pe oun yoo maa sọrọ rẹpẹtẹ lori rẹ amọ lẹyin ti ẹgbẹ awọn ba se ipade tan lori isẹlẹ yii, awọn yoo fi iroyin sita nipa oloogbe to salaisi ninu isẹlẹ naa, ati ohun ti ẹgbẹ fẹ se fun.
Wayi o, ileesẹ ọlọpa nipinlẹ Kwara ti salaye lori ikọlu tawọn agbebọn kan se si osere ori itage obinrin, Toyosi Adesanya Ileyemi.
Nigba to n ba BBC Yoruba sọrọ, Osisẹ alarena fun ileesẹ ọlọpa nipinlẹ Kwara, Geffrey Okasanmi Ajayi salaye pe aarọ ana ni isẹlẹ naa sẹlẹ, nigba ti awọn agbebọn kọlu awọn osere tiata kan, eyi ti awọn kan fi to ileesẹ ọlọpa leti.
Ajayi ni opopona marosẹ Ogbomọsọ si Ilọrin ni isẹlẹ ikọlu naa ti waye, ti Kọmisana ọlọpa nipinlẹ Kwara, Kayode Ẹgbẹtokun si pasẹ pe ki awọn ọlọpa tete dide si isẹlẹ naa.
Oríṣun àwòrán, PoliceNG
A ti gbe oku lọ sibudo igbokusi nile iwosan, awọn to sese lati se itọju fun wọn, ta si ti bẹrẹ iwadi wa, awọn ọlspa ati fijilante ti wa ninu igbo lati se awari awọn eeyan to huwa ibi yii. Ti ọwọ wa yoo si tẹ wọn.
Nigba to n salaye lori ohun tawọn eeyan kan fisita pe awọn gende agbebọn to sọsẹ naa jẹ Fulani, Ajayi ni ohun ti awọn gbọ niyẹn, ko si ọlọpa kankan nibi isẹlẹ naa nigba to waye, amọ iwadi ti n lọ lọwọ lati mọ iru awọn eeyan to sisẹ naa.
Ohun to se koko nipe iwa ti wọn hu yii buru jai, ẹnikẹni to wu ko jẹ, ti ọwọ sinku wa ba fi tẹ wọn, a o fi oju wọn ba ileeẹjọ.
Làáhànmí: Ìwádìí ní èèyàn 219 ni ibà Lassa pa lọ́dún tó lọ́, 29 lọ́dún yìí, tètè dènà rẹ̀
Nigba to n sọrọ lori ipo ilera ti Toyosi Adesanya wa, osisẹ alarena ileesẹ ọlọpa nipinlẹ Kwara ni bi o tilẹ jẹ pe oun ko tii foju kan kan osere ori itage naa, sibẹ oun gbagbọ pe alaafia lo wa.
Oríṣun àwòrán, Toyosi Adesanya Ileyemi
Iroyin kan to gba ori ayelujara kan ti kede pe, ori lo ko osere tiata lobinrin kan yọ, Toyosi Adesanya Ileyemi, lọwọ iku ojiji.
Amọ bi o tilẹ jẹ pe Toyosi moribọ lọwọ isẹlẹ iku naa, awakọ to wa ọkọ to wa ninu rẹ ko ye isẹlẹ naa, to si gba ibẹ lọ si ọrun alakeji.
Gẹgẹ baa se gbọ, oju ọna marosẹ ilu Omu Aran si Ilọrin la gbọ pe awọn mejeeji ti n rekọja lọ, nigba ti awọn eeyan mẹrin kan ya bo wọn, ti wọn si se wọn lọsẹ.
Nigba to n kede isẹlẹ naa loju opo Instagram rẹ, ilumọọka osere tiata mii, Ibrahim Chatta fi tẹdun tẹdun daro awakọ to jẹ Ọlọrun nipe naa, ẹni to pe orukọ rẹ ni Juwọn.
Chatta ni abẹ oun ni Juwọn yii ti n sisẹ nigba to kọkọ de si agbo isẹ tiata gẹgẹ bii alakoso ibi ti ere de duro, to si tun maa n sisẹ awakọ laarin awọn, ki owo lee to na fun.
Agba osere naa wa gbadura pe ki Ọlọrun tẹ ọdọmọkunrin ọhun si afẹfẹ rere.
Titi di asiko yii, a ko tii gbọ ọrọ lẹnu Toyosi Adesanya, ti oun ati Juwọn dijọ rinrinajo , ti a ko si lee sọ iru ipo ti oun gan wa bayii, amọ bo ba se jẹ, a mu ẹkunrẹrẹ iroyin naa wa fun yin.
Maryam Sanda: Toyin Abraham, Femi Adebayo, Tayo Sobola barajẹ́ lórí ìdájọ́ ikú
Idajọ iku ti ileẹjọ giga ilu Abuja da fun Maryam Sanda, to pa ọkọ rẹ ti n mu oniruuru ariwisi dani lati ọdọ awọn osere ori itage Nollywood.
Ọpọ awọn osere tiata yii lo n para poro nipa awọn isẹlẹ iwa ipa to n waye lemọlemọ laarin lọkọ laye, ti wọn si n kilọ fun tọkunrin-tobinrin lati sọrase.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí:
Toyin Abraham, loju opo Instagram rẹ lo n wa ẹkun mu poroporo, to si ni oun ko tii sunkun to bayi ri laye oun, ti idajọ naa si ba oun lọkan jẹ.
Toyin Abraham wa n gba awọn lọkọlaya nimọran pe ti ede wọn ko ba yede mọ, ti igbeyawo wọn si n la ina kọja, yoo kuku dara ki tọkọtaya yago funra wọn, dipo ki wọn sekupa ara wọn.
Mama Ire, ẹni to n gbarata lori ohun ti yoo sẹlẹ si ọmọ ọwọ ti Maryam Sanda gbe dani lasiko ti wọn dajọ iku fun, wa n rawọ ẹbẹ si ọba oke pe ko siju aanu wo obinrin naa.
Bakan naa ni ilumọọka osere tiata miran, Femi Adebayo fi fidio kan to se si oju opo Instagram rẹ, to si n rọ awọn eeyan pe ibasepọ lọkọlaya kii se tipa tikuuku.
Femi naa wa gba awọn tọkọtaya nimọran pe, ti igbeyawo wọn ko ba mu adun lọwọ, yoo dara ki wọn pin gaari, ki olukaluku si ba tirẹ lọ.
"Femi Adebayo, ti gbogbo eeyan mọ si Jẹlili, wa n beere pe ""Bawo la se fẹ sọ fun ọmọ tuntun ẹjẹ ọrun naa pe iya rẹ lo pa baba rẹ, idi si ree ti wọn se yẹgi fun oun naa. Ohun ibanujẹ nla gbaa ni."""
"Femi, ti oju rẹ kọrẹ lọwọ lori isẹlẹ bi wọn se dajọ iku fun Maryam Sanda wa rawọ ẹbẹ sawọn eeyan pe ""Ẹ jọwọ, ẹ dakun, mo rọ yin, ẹ jẹ ka maa sọra fun inufufu ati igbonara, ẹni apọnle ni abuku n wa kiri, adura mi si ni pe Ọlọrun oba yoo maa dari isisẹ wa."""
Ko tan sibẹ, osere tiata obinrin miran, Tayo Sobola, to mura bii ẹni ti ọfọ sẹ loju opo Instagram rẹ ni imura oun lo n se afihan ipo ibanujẹ ti oun wa nitori inu oun bajẹ lori idajọ iku ti wọn se fun Maryam Sanda.
"Tayo ni ""Ile aye! Ibinu jẹ mihuwasi to lagbara pupọ eyi to maa n kesi eeyan lati kọbi ara sii amọ ibeere to yẹ ka bi ara wa ni pe bawo ni a se lee se akoso ibinu wa si?"""
Sotayo salaye pe oun wo bi igbẹjọ Maryam Sanda, ti wọn dajọ iku fun tori pe o pa ọkọ rẹ lọdun 2017, se ti lọ nile ẹjọ, ti oun si rinrin ajo lai kuro loju kan soso.
N ko tiẹ mọ ohun ti eeyan lee sọ, amọ mo kan n jẹrora ninu ọkan mi ni, ti mo si n woye pe bawo ni wọn yoo se yẹgi fun obinrin akẹẹgbẹ mi? Amọ ohun to daju ni pe lootọ lo pa ọkọ rẹ, boya lati ipasẹ asise ni abi o mọọmọ see.
Sobola fikun pe Maryam gba ibinu lati gbakoso ọkan rẹ, ohunkohun si lo lee fa isẹlẹ yii, koda awọn ọkunrin lee ti obinrin debi pe yoo fi gbẹmi eeyan, bakan naa si lawọn obinrin kan ni aseju lọwọ, ti wọn si maa n se idajọ lọwọ ara wọn, eyi to maa n mu ki nkan polukumusu sii.
Amọ ootọ ọrọ to wa nilẹ ni pe a lee yago fun awọn nkan kan nitori ojoojumọ ni ọpọ iroyin n wa nipa awọn ọkunrin to n pa iyawo wọn ati awọn obinrin to n pa ọkọ wọn, tawọn afẹsọna lọkunrin-lobinrin naa si n gbẹmi ara wọn nitori ẹsun sise oju meji.
Osere tiata ọhun wa rawọ ẹbẹ sawọn eeyan pe ki wọn maa tiraka lati rin jinna si ohunkohun to ba lee fa wahala ba aye wọn tabi ge ẹmi wọn kuru, to si tun rọ wọn lati ta kete si ija, ki wọn si tun kẹyin si awọn eeyan to ba lee ru ibinu wọn soke.
Sise idajọ iku fawọn ti ile ẹjọ ba fi idi ẹri mulẹ pe wọn ṣeku pa eeyan akẹẹgbẹ wọn, kii ṣe nkan tuntun.
Oríṣun àwòrán, Others
Ìjọba ìpínlẹ̀ Eko fẹ̀sùn kan Lekan Shonde pé ó lu ìyàwó rẹ̀ pa, lẹ̀yín to fi ẹ̀sùn kan pé iyawo rẹ̀ pé óún yan àlè.
Koda ofin orileede Naijiria fi ofin gbe awọn agbofinro lẹyin, lati se amusẹ idajọ iku tile ẹjọ ba da, lẹyin ti Gomina ipinlẹ tabi Aarẹ ba ti buwọlu aṣẹ yii.
Iroyin idajọ iku fun arabinrin Maryam Sanda to pa ọkọ rẹ nilu Abuja, to waye lọjọ Aje, tun jẹ ohun aritọkasi pe iru idajọ iku bayii ṣi n waye ni Naijiria.
Amọ melo ni iru awọn eeyan to daran ipaniyan, ti ile ẹjọ dajọ iku fun, ti ẹyin ranti?
E jẹ ka ran ara wa leti nipa diẹ ninu wọn:
Ọmọ Ọba Eko Adewale Oyekan:
Ẹni aadọta ọdun ni ọmọọba Eko ana, Adewale Oyekan, ti o si gba idajọ iku lọdọ adajọ ile ẹjọ giga kan nilu Eko lori ẹsun pe o pa oniṣowo kan, Alhaja Sikirat Edun.
Gẹgẹ bi ohun ti a ri akọsilẹ rẹ, ọmọọba Adewale Oyekan fun Lateef Bello, tii se ọmọ ọdọ Alhaja Edun ni ẹgbẹrun lọna ọgọta Naira. lati pa ọga rẹ.
Oríṣun àwòrán, Others
Iwaadi awọn ọlọpaa fihan pe wọn yin oloogbe lọrun pa, ti wọn si ju oku rẹ sinu kanga to wa ninu ile rẹ.
Osere tiata lapa oke ọya, Rabi Ismaila:
Oṣere tiata lapa ariwa ilẹ Naijiria ni Rabi Ismaila, to si fi ilu Kano ṣe ibudo.
Ẹsun ti wọn tori rẹ dajọ iku fun ni pe o pa ọrẹkunrin rẹ, ọgbẹni Auwalu lọdun 2002.
Ile ẹjọ giga ni Kano dajọ ki wọn yegi fun, titi ti ẹmi yoo fi bọ lara rẹ.
Rabi tawọn eeyan mọ si Rabi Cecilia ninu sinima, tan ọrẹkunrin rẹ lọ si adagun omi kan, ti o si fun ni majele jẹ ki o to ju oku rẹ sinu omi.
Pasitọ ijọ Redeem, Akolade Arowolo to pa iyawo rẹ:
Pasitọ awọn ọdọ kan ninu ijọ Redeem naa gba idajọ iku lori pe o pa iyawo rẹ, Titilayo to n ṣiṣẹ ni ile ifowopamọ kan.
Orukọ pasitọ naa ni Kolade Arowolo, ti ile ẹjọ si fidi ẹsun iwa ọdaran naa mulẹ pe oun funra rẹ lo pa iyawo rẹ sinu ile wọn.
Oríṣun àwòrán, Others
Ẹjọ yi mu iriwisi wa ti awn eeyan si n ṣe emo bi ẹni to pe ara rẹ lẹni Ọlọrun ṣele hu iru iwa bayi.
Iwaadi fihan pe igba 76 ni o gun iyawo rẹ lọbẹ ti adajọ si fi wakati mta gbako ka idajọ rẹ.
Khadijat Oluboyo, ti ọrẹkunrin rẹ oniyahoo yahoo ṣeku pa:
Ni oṣu kẹta ọdun 2019 ni ile ẹjọ giga ni ipinlẹ Ondo da ẹjọ iku fun Seidu Adeyemi to pa ọmọ igbakeji gomina ana nipinlẹ Ondo, Khadijat Olubọyọ ni ọdun 2018.
Seidu Adeyemi to jẹ ọrẹkunrin Khadijat Oluboyo ni wọn fẹsun kan wi pe o pa a, ti o si tun rii mọle si inu yara rẹ ni Aratusi, Oke-Aro ni Akure, nipinlẹ Ondo.
Khadijat Oluboyo n mura lati jade fasiti ni ile iwe giga fasiti Adekunle Ajasin ni Akungba Akoko ni ipinlẹ Ondo, ki o to jade laye.
Ọ̀rẹ́kùnrin Khadijat Olubọyo gba ọjọ́ ikú
Lẹyin ọsẹ kan tí wọn ti ń wá Khadijat tó jẹ́ ọmọ igbákeji gómínà tẹ́lẹ̀rí ní ìpínlẹ̀ Ondo, ni wọ́n bá òkú rẹ̀ ní ilé àfẹ́sọ́nà rẹ̀, Adeyemi Alao.
Alukoro fun ile iṣẹ ọlọpaa ipinlẹ Ondo to ba BBC Yoruba sọrọ lasiko ti isẹlẹ naa waye sọ wi pe, ṣe ni Adeyemi gbe oku Khadijat sinu ile fun ọjọ mẹfaki ẹnikẹni maa baa fura si.
Orukọ kanna ni wọn jijọ njẹ ṣugbọn arabirin Stella Gilbert ko wo eyi mọ alabagbe rẹ, Stella Godwin lara, ko to fi ibinu gun lọbẹ pa.
Ile ẹjọ ko ṣe iye meji ki o to dajọ pe o jẹbi ẹsun ipaniyan ti ijọba ipinlẹ Eko fi kan. Ẹṣẹ ipaniyan to hu yii si lo tako ofin ọdaran tipinlẹ Eko, abala okoolerugbao le kan.
Oríṣun àwòrán, Google
Adugbo Ajegunle ni ojule kọkandinlọgọta, Opona Ojora ni iṣẹlẹ naa ti waye ni ọjọ kejilelogun oṣu Kẹfa ọdun 2013.
Stella sọ pe, looto loun gun alabagbele oun lọbẹ laya amọ lẹẹkan ṣoṣo ni.
Eyi si lo mu ki ile ẹjọ dajọ iku fun.
Africa Eye: Ìjìjàgbara fún àwọn ọmọdébìnrin tó wà lọ́wọ́ ewu
Ikọ ọtẹlẹmuyẹ Africa Eye tun de orilẹede Congo nibi to ti finmu finlẹ nipa igbe aye awọn ọdọbinrin ti wọn dagba soju popo.
Fidio naa ree:
Africa Eye: Ìrírí àwọn ọ̀dọ́bìnrin tó dágbà sójú pópó àti ìrètí wọn fún ọjọ́ ọ̀la
Ogun Accident: FRSC ní Sokoto làwọn èrò náà ti ń bọ̀ wá sí Ijẹbú Ode
Oríṣun àwòrán, Abiodun
Iroyin to n tẹ wa lọwọ fi ye ni pe ọpọ oku lo ti sun, ti ọkẹ aimọye si farapa lasiko ti ọks akẹru kan rebọ sinu odo Ogun lopopona Ibadan silu Ijẹbu Ode lọjọ Isẹgun.
Iroyin naa ni ọkọ akẹru ọhun, ti nọnba rẹ jẹ XE331MKA lo ko ero bii mejidinlọgọta, to si n bọ lati ilu Sokoto wa si Ijẹbu Ode lasiko to rebọ sinu odo Ogun ni idaji kutu hai ana.
Gẹgẹ bi oludari fun ajọ ẹsọ oju popo, FRSC, ẹka tipinlẹ Ogun, Clement Oladele yi sọ fun awọn akọroyin, o seese ko jẹ pe o ti rẹ awọn arinrinajo naa dẹnu lo mu ki ijamba naa waye.
Oríṣun àwòrán, Others
Ni kete ti isẹlẹ yii to wa leti, lawọn osisẹ wa lati ẹka ti Ijẹbu Ode ati Ago Iwoye, yara lọ sibi ti isẹlẹ ọhun ti waye, ti wọn si ko awọn oku to fori sọta ijamba naa lọ sile igbokusi, nigba tawọn to farapa wa ni ile iwosan ijọba nilu Ijẹbu Ode.
Africa Eye: Ìrírí àwọn ọ̀dọ́bìnrin tó dágbà sójú pópó àti ìrètí wọn fún ọjọ́ ọ̀la
Oladele wa rọ awọn ero lati maa rinrinajo pẹlu ọkọ ti wọn se fun ẹru kiko nikan nitori awọn ijoko wọn ko wa fun ijoko.
Ban on Okada: Báwọn èèyàn kan ṣe tako òfin kí ọ̀kadà má rìn l‘Eko, làwọn míì faramọ́ọ
Oríṣun àwòrán, LASG
BBC Yoruba bọ sigboro lati gbọ tẹnu awọn araalu lori ofin kan tijọba ipinlẹ Eko kede laipẹ yii eyi to fi ofin de lilo ọkada ati kẹkẹ Marwa lawọn oju popo kan nipinlẹ naa.
Fidio ohun tawọn eeyan sọ lori fifi ofin de ọkada ree:
Ban on Okada: Báwọn èèyàn kan ṣe tako òfin kí ọ̀kadà má rìn l‘Eko, làwọn míì faramọ́ọ
Ọjọ kinni osu keji ọdun 2020 si ni ofin naa yoo ti bẹrẹ si ni fidi mulẹ́, ijọ̀ba ibilẹ mẹẹdogun si ni ọrọ ọhun kan.
Amọ ero awọn ọdọ lori isẹlẹ naa ni pe ole ati awọn onijibiti ọmọ Yahoo yoo pọ si ti ofin naa ba fi fidi mulẹ.
Ero awọ̀n eeyan to ba BBC sọrọ lori isẹlẹ yii si lo yatọ, bi awọn kan se faramọ ofin ọhun, ni awọn miran tako.
Balogun Fire: Ilé ìtajà alájà mẹ́rin ni iná náà ti kọ́kọ́ sẹyọ
Awọn osisẹ ajọ LASEMA ati panapana ti de sibi isẹlẹ ina naa lati bomi pana rẹ.
Ọ̀ga àgbà àjọ LASEMA Femi Osanyitolu, sàlàye pe ni kété ti àwọn de ibi ìṣẹ̀lẹ̀ náà ni àwọn ti ri pé ilé alájà mẹrin kan ni ìnà náà ti bẹ̀rẹ̀.
O sálàyé pé ǹkan to fa ìṣẹ̀lẹ̀ náà ni bi àwọn ènìyàn ṣe n ko epo pamọ lanà ti kò dára lo ṣẹ iná yẹ
Fidio bi ina se jo ọja Balogun ree:
Balogun Fire: Àwọn òǹtàjà figbe ta pé owó alájẹṣẹ́kù làwọn fi ra ọjà tó jóná
O ni láti ibẹ̀ lo ti fò mọ ilé méje míràn sùgbọ́n àjọ LASEMA ní àwọn ti ń kápa rẹ ti àwọn si ti wó ilé méjé ti iṣẹ̀lẹ̀ náà de bá
Gbogbàwọn àjọ to yẹ lo ti wà nilẹ̀, ti Osanyitolu si ti rọ gbogbo àwọn ènìyàn láti lo fi ọkàn wọ́n
Ilé bíi mẹjọ ló ti jóná báyìí ní opópóna Matin ni ọja Balogun
Ó ṣeéṣe kó jẹ́ ọyẹ́ tó ń mú lásìkò yìí ló fa ìjàmbá iná lọ́jà Balogun - LASEMA
Ó ṣeéṣe kó jẹ́ ọyẹ́ tó ń mú lásìkò yìí ló fa ìjàmbá iná lọ́jà Balogun - LASEMA
Isẹlẹ ina to n jo lemọlemọ lẹnu lọọlọ yii tun ti na ọwọja rẹ de gbajugbaja ọja Balogun nilu Eko, to si nawọ gan ibudo itaja mẹrin ọtọọtọ.
Nigba to n ba BBC Yoruba sọrọ akọtun isẹlẹ naa, oludari ajọ to n risi isẹlẹ pajawiri nipnlẹ Eko, LASEMA, Femi Oke Ọsanyintolu, salaye pe oun ko tii le sọ ohun to se okunfa ijamba ina ọhun.
Ọsanyintolu ni o seese ko jẹ asiko ọyẹ taa wa yii lo mu ki isẹlẹ ina ọhun waye, gẹgẹ bo se n sẹlẹ kaakiri agbegbe wa lẹnu lọọlọ yii.
LASEMA ni opopona Martins ti ina ti sọ nijooni, naa tun ni ijamba ina mii ti n waye lọwọlọwọ bayii, ti awọn osisẹ ajọ naa ati awọn panapana si ti de sibi isẹlẹ ọhun lati tete bomi pa ina naa ki ọwọja rẹ to kọja aala.
Oríṣun àwòrán, LASEMA
O fikun pe ko sẹni to lee se odiwọn ọsẹ ti ina naa ti se nitori pe o si n jo lọwọ, amọ ni kete ti ọwọja rẹ ba ti lọ silẹ, ni awọn yoo fi ikede sita lati salaye lẹkunrẹrẹ nipa isẹlẹ naa.
Bẹẹ ba gbagbe, igba meji ọtọọtọ ni awọn ile itaja jona ni ọja Balogun lọdun to kọja, ti ọkẹ aimọye dukia si baana.
Ọ́pọ awọn ontaja si la ri ti wọn n wọ inu ina lati ko ọja wọn jade ko maa baa jona, eyi to lewu pupọ.
Africa Eye: Ìrírí àwọn ọ̀dọ́bìnrin tó dágbà sójú pópó àti ìrètí wọn fún ọjọ́ ọ̀la
Ìròyìn tó ń tẹ̀ wa lọ́wọ́lọ́wọ́ ní wí pé ile itaja mẹrin ni ọja Balogun lo n jona lọwọ lọwọ bayii.
Oríṣun àwòrán, LASEMA
Bi o tilẹ jẹ pe ko si ẹni to tii lee salaye ohun to fa ina ọhun, sibẹ a ko tii kofiri awọn osisẹ panapana nibẹ́.
Ko si si ẹni to lee sọ iye dukia to jona nitori ina ọhun si n jo lọwọ.
A n se akojọpọ ẹkunrẹrẹ iroyin yajoyajo lọwọ, a o maa gbe ẹkunrẹrẹ iroyin naa sori atẹ iroyin wa laipẹ. Ẹ jọwọ, ẹ tun oju opo iroyin yi yẹwo, ki ẹ lee ri ẹkunrẹrẹ iroyin ọtun laipẹ.
EFCC: Ẹ̀wọ̀n ọdún méjìlá ní iléẹjọ́ fún tìyá-tọmọ tó lu òyìnbó ní jìbìtì
Oríṣun àwòrán, EFCC
Yoruba ni owu ti iya ba gbọn, ni ọmọ yoo ran, bẹẹ si ni ọmọ kii ba ipele iya rẹ, ko si asọ da.
Iya kan ree, Alaba Kareem Adeyeri, ti adajọ da ẹjọ ẹwọn ọdun mejila fun oun ati ọmọ rẹ, Damilola Ahmed Adeyeri lori ẹsun pe awọn mejeeji dijọ lẹdi apo pọ lu oyinbo ara Amẹrika kan ni jibiti owo to to ẹgbẹrun lọna mejilelọgọrin ati aabọ naira.
Ẹsun mẹrin ọtọọtọ to nii se pẹlu iwa jibiti lori ayelujara ni ajọ EFCC fi kan tiya-tọmọ, tawọn mejeeji si ni ki adajọ se awọn jẹjẹ, tori pe awọn jẹbi.
Ọlọpa ọtẹlẹmuyẹ fun EFCC, Idi Musa lo salaye pe ajọ ọtẹlẹmuyẹ ilẹ Amẹrika, FBI, lo fi to awọn leti pe awọn onijibiti kan lo tọwọbọ oju opo Email ifiweransẹ ileesẹ Amẹrika naa, ti wọn si ji owo gọbọi naa.
Musa ni ni kete ti Damilola ri pe awọn ọtẹlẹmuyẹ ti n dọdẹ oun, lo ba fi ara soko, to si ni kii iya oun lọ ba oun gba owo tuulu yii, to si ba fi ra ọpọ ile ati dukia lorisilorisi.
Oríṣun àwòrán, EFCC
Ibi ti iya naa ti lọ gba owo nile ifowopamọ lọjọ kan ni ọwọ ti baa, to si mu awọn ọtẹlẹmuyẹ lọ si ibi ti ọmọ rẹ wa, bẹẹ ni wọn ba ọpọ owo ni inu apo asunwọn wọn.
Agbẹjọro fun ajọ EFCC, Bilikisu Buhari sọ fun ileẹjọ pe Alaba ati ọmọ rẹ yii ati ẹnikan ti wọn pe ni Kareem Russel, to ti na papa bora, ni wọn dijọ lu adari ileesẹ kan nilẹ Amẹrika ni jibiti lọdun 2017 amọ ti ọwọ tẹ wọn lọdun 2019.
Oríṣun àwòrán, EFCC
Nigba to n gbe idajọ rẹ kalẹ, Adajọ Aneke salaye pe afihan fidio ti ajọ EFCC se nile ẹjọ fidi rẹ mulẹ pe awọn mejeeji lo jẹbi ẹsun lilu jibiti ti wọn fi kan wọn, to si ni ki wọn lọ fun ẹwọn ọdun mẹta mẹta lori ikọọkan ẹsun mẹrẹẹrin ti wọn fi kan wọn.
Bakan naa lo pasẹ pe gbogbo owo ti wọn ba ninu apo asunwọn owo wọn nile ifowopamọ, ko di ti ijọba
Beard Woman: Irungbọ̀n mi máa ń dójú tì mí láti jáde lọ ra nǹkan ní ọ̀sán gangan
Njẹ ẹyin ti ni iriri eleyi ti awọn agbofinro sọ pe ki ẹ bọra silẹ lati le e ri aridaju pe lootọ obinrin ni yin?
Obinrin kan to n se kọndọ lẹyin ọkọ lorilẹede Kenya to si ni irungbọn bi ọkunrin, ti n sọ ohun ti oju rẹ ri lọwọ awọn ọlọpaa.
Theresia Mumbi sọ fun BBC pe, awọn ọlọpaa to n dari ọkọ ni Nairobi mu oun, ti wọn si ni ki oun bọra silẹ ki awọn ba le mọ boya lootọ obinrin loun.
O ni wọn fi oun si ahamọ pẹlu awọn obinrin miran.
''Awọn ọlọpaa meji wa, ti wọn si ni ki n bọ aṣọ mi. Lẹyin igba naa ni wọn yẹ ara mi wo finifini. Mi o mọ nkan ti wọn ri ṣugban wọn ni ki n pada si ahamọ''
O ṣalaye pe, n ṣe ni oun maa n ranti iṣẹlẹ naa to waye ni ọdun 2018 lori pe wọn fẹ ri iwe ẹri oun. O ni oun fi iwe han wọn, ti wọn si ni ki oun maa lọ.
Iriri yii lo mu ki arabinrin Mumbi di agbẹnusọ ati ajafẹtọ fawọn obinrin, ti wọn ko foju jọ obinrin tabi ti wọn ni aleebu lara.
O ni oun n sọ iriri oun lati pe kiyesi awọn eeyan si ohun to n ṣẹlẹ, ati ki awọn obinrin miran ba le sọrọ sita lori ohun ti wọn koju nigba ti wọn ba dunkoko ma wọn.
Ayẹwọ awọn dokita lo ṣafihan pe, arabinrin Mumbi ni awọn eroja ara homoonu kan lara rẹ, eyi to mu ko ni irungbọn bi ọkunrin.
O ni oun a ma saba fa irungbọn yii, to si maa n mu ki ara maa ja oun jẹ.
''Ni nkan bi ọdun melo kan sẹyin, mo nilati pa asa fifa irungbọn mi ti, nitori pe o ma n yun mi, ti awọn oju irun ti mo fa a si ma di egbo''
Irungbọn naa bẹrẹ si ni hu, ti eleyi si mu ko maa le jade lọsan lati lọ ra nkan, bi kii ṣe lalẹ.
O ni nigba ti atijẹ atimu fẹ ma nira loun ba bẹrẹ si ni ṣe iṣẹ kọndọ.
Nibi iṣẹ rẹ lo ti ṣalabapade awọn obinrin mii, tawọn naa n koju iru ipenija yii, to si ma n gba wọn niyanju.
O jẹ ọkan lara awọn ọmọ ẹgbẹ obinrin to ni irungbọn ni Kenya, ti wọn a si ma ba awọn obinrin sọrọ nibi ipade wọn.
Child Abuse: Amòfin ní ọmọbìnrin náà leè rí ara rẹ̀ bíi ẹni tí kò wúlò
Amofin nipa ẹtọ ọmọde, Taiwo Akinlami sọ pe ọgbẹ ọkan manigbagbe laelae ni ijiya ti baba ọmọdebinrin ọmọ ọdun mẹwaa jẹ fun ọmọ naa, lẹyin ti baba rẹ so mọ aja ti o si tun dana sii labẹ.
O ni ọkan lara ipa ti iru ijiya yii le ni lori ọmọ naa ni pe o le jẹ ki ọmọ yii ri ara rẹ gẹgẹ ẹni ti ko wulo lọjọ iwaju.
Ajọ NSDC lo fọwọ ofin ju baba ọmọ naa, ẹni ọdun mọkanlelogoji pẹlu iyawo rẹ lẹyin ti wọn fẹsun kawọn mejeeji pe wọn pa ọwọ pọ fiya jẹ ọmọdebinrin yii lọna aitọ.
Baba ọmọ naa ṣalaye pe, oun fẹ dẹru ba ọmọ oun ni ko le jẹwọ lẹyin to ji ẹgbẹrun un mẹta naira to jẹ ti obinrin kan, ti orukọ rẹ n jẹ Rukayat Trimisiyu.
Iroyin sọ pe ọmọ naa pada jẹwọ, bẹẹ lo si lọ mu owo ọhun wa nibi to fi pamọ si, lẹyin ti wọn fiya jẹ ẹ tan.
Africa Eye: Ìrírí àwọn ọ̀dọ́bìnrin tó dágbà sójú pópó àti ìrètí wọn fún ọjọ́ ọ̀la
Ọmọdebinrin yii wa nile iwosan bayii nibi ti o ti n gba itọju si apa ti ijiya naa ni ara rẹ.
Amọ agbẹjọro Akinlami ni, ko si ohun to buru ninu ki obi ba ọmọ wi ti ọmọ ba ṣẹ, ṣugbọn kii ṣe ki obi wa sọ ọmọ di alaabọ ara tabi ko lu ọmọ naa pa.
Amofin Akinlami ni, ohun tawọn obi yii ṣe buru jai, bakan naa ni ohun ti wọn se lodi si ofin ẹtọ ọmọde ni Naijiria.
Kí lo tíì rí  nípa Amotekun? Ẹ sùnmọ́bí, ẹ wo gbankọgbì!
O fikun ọrọ rẹ pe, ileejọ nikan lo le sọ iru ijiya to tọ si awọn obi ọmọ yii.
O ni eyi yoo jẹ ẹkọ fawọn obi mii tawọn le fẹ fiya jẹ ọmọ wọn lọna to lodi s'ofin.
Amofin Akinlami sọ pe, o ṣe pataki lati tubọ ṣe ilanilọyẹ sii lori ofin to n ja fẹtọ awọn ọmọde ni Naijiria.
Corona Virus: Àyẹwò fi han pé kìí ṣe àìsàn naa lo ń se àkẹkọọ ti wọ́n fura si
Oríṣun àwòrán, Others
Corona Virus: Àyẹwò fi han pé kìí ṣe àìsàn naa lo ń se àkẹkọọ ti wọ́n fura si
Nínú ìbẹ̀rù bojo àti ìfòyà ni ọ̀pọ̀ ọmọ Naijiria wá lẹ́yìn ti ìròyìn tà kan pé, óṣeeṣ ki àìsàn náà ti wọle si orilẹ̀-èdè Ivory Coast èyi to jẹ ilẹ adúlawọ.
Sùgbọ́n ìdùnú subu lú ayọ fun gbogbo ènìyàn ilẹ Afirika wi pé àbájade àwọn àyẹwò ti wọ́n ṣe fun àkẹkọ̀ọ́ náà fi han pe ko ni àìsàn náà.
Oríṣun àwòrán, Frank hersay Tweet
Corona Virus: Àyẹwò fi han pé kìí ṣe àìsàn naa lo ń se àkẹkọọ ti wọ́n fura si
Iroyin to fi ìdí ọ̀rọ̀ náà múlẹ̀ wáye nínú àtẹjáde kan ti ile iṣẹ́ ètò iléra orílẹ̀-èdè náà gbé jáde ti wọ́n si fi si lóri àtẹjisẹ Facebook
Kokoko lára akẹkọ̀ọ́ náà le ti o sì ti padà si ọ̀dọ̀ àwọn ẹbi rẹ̀.
Buhari Resign: Secondus ní kí Buhari kéde nǹkan ò fararọ lẹ́ka ààbò, bí bẹ́ẹ̀ kọ́ kó kọ̀wé fipò sílẹ̀
Oríṣun àwòrán, Twitter/Bashir Ahamad
Ẹgbẹ oṣelu PDP sọ pe gbọingbọin lawọn wa lẹyin olori ẹgbẹ osẹlu alatako to gbojigan julọ nile aṣofin agba l'Abuja, Ṣẹnẹtọ Enyinnaya Abaribe to sọ pe ki aarẹ Muhammadu Buhari kọwe fipo silẹ.
Alaga gbogbogbo ẹgbẹ oṣelu PDP, Uche Secondus lo sọrọ yii fawọn akọroyin niluu Abuja l'Ọjọbọ.
Sẹnẹtọ Abaribe sọ fun aarẹ pe ko kọwe fi ipo silẹ lori eto aabo to mẹhẹ kaakiri lorilẹede Naijiria.
Ninu ọrọ tiẹ, Secondus ni o ṣe pataki fun Buhari lati kede ilu nnkan o fararọ lẹka eto aabo, o ni ijọba ti ko dara to lo ṣokunfa eto aabo to mẹhẹ.
O fikun ọrọ rẹ pe bi ẹgbẹ oṣelu APC to wa lori aleefa ṣe n ṣejọba lo jẹ ki eto aabo mẹhẹ, ohun naa lo si jẹ ki airiṣẹṣe pọ si ati ọrọ aje to dẹnu kọlẹ.
Amọ Secondus ṣalaye pe ẹgbẹ oṣelu PDP ko fẹ doju ijọba Naijiria bo lẹ, ṣugbọn ohun ti ẹgbẹ naa n sọ ni pe ki Buhari fipo silẹ ti ko ba le wa nnkan ṣe si eto aabo to mẹh
Abaribe, ọ̀rọ̀ agọ̀ lo sọ pé kí Buhari kọ́we fipo sílẹ́ torí ààbò tó mẹ́hẹ - Iléèṣẹ ààrẹ
Ileeṣẹ aarẹ orileede Naijiria ti tutọ soke foju gba lori ọrọ ti ile aṣofin agba sọ pe ki aarẹ Buhari kọwe fiposilẹ lori lori pe ko ri nkankan ṣe lori ipenija aabo to n koju Naijiria.
Lọjọru ni Garba Sheu to jẹ agbẹnusọ ileeṣ aarẹ fi ọrọ yi sita loju opo Twitter ti o si ni iwa agọ ni Sẹnẹtọ Enyinnaya Abaribe hu bo ti ṣe ni ki aarẹ Buhari fiposilẹ.
Oríṣun àwòrán, Enyinaya Abaribe/Facebook
Garba Sheu ni ti aarẹ Buhari ba ni lati fiposilẹ,aimọye eeyan naa lo yẹ ko ṣebẹ ti Abaribe naa yoo si wa lara wọn.
Ọrọ Garba Sheu yi ti mu iriwisi ọtọọtọ wa lati ọdọ awọn ọmọ Naijiria loju opo Twitter.
Bi awọn kan ti ṣe n gbe lẹyin Sheu lawọn miran n sọ pe ọrọ  Abaribe ko buru rara toun ti ipenija aabo to n koju Naijiria
Ki gan ni Abaribe sọ ni ile asofin agba?
Lasiko ti ile aṣofin agba n jiroro lori ọrọ aabo Naijiria ni Sẹnẹtọ Enyinaya Abaribe dide lati sọrọ.
Ọrọ rẹ to da lori pe ipa aarẹ Buhari ko ka ipenija aabo ti Naijiria n koju, mu ki awọn Sẹnẹtọ fẹ ma tahun si ara wọn.
Ṣugbọn kii ṣe ohun nikan lo sọ bẹẹ, tile si pada wa panupọ lori  koko ọrọ mẹta ti o da lori pe:
Bo tilẹ jẹ wi pe orukọ Abaribe lawọn eeyan n mu bọnu paapa julọ loju opo Twitter, Sẹnẹtọ Abdullahi Abubakar to n ṣoju ẹkun ariwa ipinlẹ Kebbi, lo daba ọrọ ti o fẹ ṣebi ẹni da wahala silẹ yii.
Amotekun: Fatomilola ní gaga ọwọ̀ làwọn baba wa fi ń ṣọ́ ilé, òyìnbó ló sọ wá di ọ̀lẹ
Ilumọọka agba osere tiata kan, Peter Fatomilola ti fọwọ gbaya pe agbekalẹ ikọ alaabo Amotekun yaayi lasiko yii tori agbara oogun lawọn baba wa fi n daabo bo ara wọn laye atijọ.
Lasiko to n ba BBC Yoruba sọrọ, Fatomilola ni awọn baba wa kii se ilẹkun si ẹnu ọna ile, amọ gaga ọwọ mẹẹdogun ti to lati koju ole.
Fidio naa ree:
Amotekun: Fatomilola ní gaga ọwọ̀ làwọn baba wa fi ń ṣọ́ ilé, òyìnbó ló sọ wá di ọ̀lẹ
O fikun pe igba tawọn oyinbo de ni awọn sọja ati ọlọpa de, ti a ko si lee fi ilana ibilẹ daabo bo ara wa mọ, ta wa di ọdẹ ati ọlẹ.
Ede Poly Fire: Igbó tí wọn ń ṣun ládùgbóò ló fa ìjàmbá iná
Oríṣun àwòrán, The Federal Polytechnic, Ede
Ijamba ina tun ti waye nilegbe awọn obinrin to wa lọgba ileẹkọ poly tilu Ẹdẹ.
Gẹgẹ bi ileesẹ panapana nipinlẹ Ọsun ti salaye, aarọ ọjọbọ ni isẹlẹ ina ọhun waye nitori igbo kan ti wọn n sun ladugbo Jere ti ilegbe awọn obinrin naa wa.
Wọn fikun pe ina ọhun ni ọwọja rẹ tan lati adugbo wọ inu ọgba ileeẹkọ Poly naa, to si se ọsẹ nla ọhun.
Ilegbe ọhun, ti wọn ko tii kọ pari, ni ina ọhun jo kanlẹ, ti ko si si ẹmi kankan to ba isẹlẹ naa rin.
Oríṣun àwòrán, The Federal Polytechnic, Ede
Nigba to n se akojọ apapọ iye ti awọn dukia to jona yoo to, awọn osisẹ panapan naa ni o kere tan iye dukia to jona ninu isẹlẹ naa yoo wọ miliọnu mẹwa naira.
Nigba to n fidi isẹlẹ yii mulẹ, awọn agba osisẹ kan lọgba Poly Ẹdẹ naa salaye pe awọn eeyan kan to n sun igbo, eyi ti ọwọja rẹ tan de inu ọgba awọn, tawọn si tete ke si ileesẹ panapana.
Amotekun: Fatomilola ní gaga ọwọ̀ làwọn baba wa fi ń ṣọ́ ilé, òyìnbó ló sọ wá di ọ̀lẹ
Wọn  wa  kan saara sileesẹ panpana ipinlẹ Ọsun fun bo se tete dahun si ipe awọn, eyi to mu adinku ba ọwọja itankalẹ ina naa.
Toyosi Adesanya: 'Ọ̀kọ̀ wa wọ'gbó lọ lẹ́yìn táwọn dánàdánà dàbọn bò wá'
Oríṣun àwòrán, Instagram/Toyosi Adesanya
Gbajugbaja osere tiata lobinrin, ti ori ko yọ ninu ijamba ọkọ lọjọ Aje, Toyosi Adesanya Ilesanmi ti salaye lẹkunrẹrẹ nipa bi isẹlẹ to mu ẹmi awakọ rẹ, Juwọn Awẹ, se waye.
Nigba to n ba BBC Yoruba sọrọ laarọ ọjọbọ, Toyosi ni awakọ oun, Juwọn ati awọn eeyan mẹrin miran lawọn jọ wa ninu ọkọ, lati lọ se ere tiata kan nilu Ilọrin.
Kò tíì tó oṣù kan tí èmí àti Favour bẹ̀rẹ̀ sí ní fẹ́ ara wa tí mo pa á ṣe ògùn owó - Kayeefi
"O ni bi awọn se fẹ wọ ilu Ilọrin lawọn n gbọ ""Fulani Herdsmen! Fulani Herds men!"", ti gende agbebọn mẹrin, Fulani mẹta ati Yoruba kan si sadede bọ soju ọna, ti wọn si ni ki awọn duro."
O fikun pe Juwọn to wa ọkọ lo fi aake kọri lati duro, ti oun si n kilọ fun pe ko ma sa fun wọn, amọ ko gbọ, to si sare kọja awọn agbebọn ọhun, eyi to mu ki wọn yinbọn fun awọn.
Oríṣun àwòrán, Toyosi Adesanya
O ni bi mọto awọn se wọnu igbo lọ ree, tawọn agbebọn naa si ja awọn lole, wọn tu gbogbo ẹru awọn, ti wọn si gba owo ati ẹrọ ibaraẹnisọrọ awọn, ti oun ko si lee sọ ipo ti oun wa, bẹẹ ni Juwọn ti dero ọrun.
Nigba to n sọrọ lori bi Juwọn se de ọdọ rẹ, o ni oloogbe naa bẹrẹ isẹ ni ọdọ oun ni ọjọ Keji osu Kinni ọdun 2020, amọ o ti n sisẹ ni ọdọ awọn akẹẹgbẹ oun ninu isẹ tiata tẹlẹ, ti wọn jọ ni ede aiyede eyi ti ko jẹ ki oun fẹ kọkọ gbaa mọra.
Oríṣun àwòrán, Juwon Awe
Se ni Juwọn de ile mi nilu Akurẹ lọjọ keji osu kinni yii, to si n bẹ mi pe ki n se aanu oun. Mo sọ fun pe ko lọ pari ija pẹlu awọn to ni ikunsinu pẹlu rẹ amọ o sa n bẹ mi ni. Niwọn igba to si jẹ pe ara awọn eeyan kan naa ni emi naa ti dide, lo jẹ ki n faa mọra.
Mo sẹsẹ ra ẹrọ ibaraẹnisọrọ tuntun fun ni, to si bẹrẹ idanilẹkọ nipa ere tiata. Igba ta fẹ lọ sisẹ nilu Ilọrin lo ni oun yoo tẹ le wa lọ nitori ilọrin lo ti se kekere, to si fẹ ri awọn eeyan to ti ri tipẹ.
Oríṣun àwòrán, Juwon Awe
Toyosi, nigba to n sọ iru eeyan ti oloogbe ọhun jẹ nigba aye rẹ salaye pe eeyan daada ni, kii bẹru tabi foya, to si ni iwa irẹlẹ pupọ.
Lẹyin to de ọdọ mi tan ni mo wa ri pe oloogbe Juwọn naa fẹran obinrin, igba to ku tan yii ni mo gbọ pe obinrin marun lo ti bimọ fun. Sugbọn lọdọ temi, ọmọ daada ni nitori ko si si ẹni ti ko ni aleebu tiẹ lara.
Ilumọọka osere tiata naa ni oloogbe ọhun maa n ba oun fọ asọ, to si maa n ba gbogbo eeyan sere. Ko si si ibi to de, ti kii fẹ ki awọn eeyan to wa nibẹ sakiyesi oun.
Juwọn ni igboya, ti mo si maa n sọ fun pe igboya rẹ ti pọ ju, gbogbo igba si lo maa n se adura pe asiko ti oun wa lọdọ mi yii ni oun maa jẹ eeyan, ti gbogbo wa yoo si maa rẹrin.
Amotekun: Fatomilola ní gaga ọwọ̀ làwọn baba wa fi ń ṣọ́ ilé, òyìnbó ló sọ wá di ọ̀lẹ
Toyosi wa dupẹ pupọ lọwọ gbogbo eeyan to dide fun iranwọ rẹ lasiko ti isẹlẹ naa waye, paapa awọn asaaju ẹgbẹ osere tiata TANPAN, ti Bolaji Amusan, taa mọ si Mr Latin ko sodi ati Alhaji Abbey Lanre.
Bakan naa lo n dupẹ lọwọ Ọmọọba Jide Kosọkọ, Adebayọ Salami taa mọ si ọga Bello, to pe lati ilu ọba, ati gbogbo ọmọ ẹgbẹ Tanpan, ẹka tipinlẹ Kwara, ti gbogbo wọn ko fi silẹ, lasiko isẹlẹ naa, paapa alaga Tanpan Kwara, ti wọn n pe ni 'Akinkanju ọdẹ Ilọrin'.
Mo ni aarẹ ẹgbẹ to dara ninu ẹgbẹ Tanpan, Bolaji Martins Amusan, mo si jẹ anfaani pe mo n se ẹgbẹ naa, mo mọ koko pe mo n se ẹgbẹ, mo si tẹle asaaju to dara, oun ati Abbey Lanre, isẹlẹ yii si jẹ ki n mọ bi mo se tobi to laarin awọn akẹẹgbẹ mi ati awujọ wa lapapọ.
Awa la se awọn nkan to pọ lati sin oloogbe, ti awọn ẹbi rẹ naa si fọwọsowọpọ pẹlu wa. Awọn eeyan kan gbogun, amọ awọn ẹbi oloogbe dide pe awọn ti ri gbogbo ohun to sẹlẹ ni Ilọrin awọn ko si fa wahala kankan bikose ki gbogbo wa dijọ pawọpọ lati tọ awọn ọmọ to wa nilẹ.
Oríṣun àwòrán, Instagram/Tosin Adesanya
Nigba to n sọrọ lori ẹkọ ti isẹlẹ naa kọ, Toyosi ni ko si ohunkohun nile aye yii, ka ma si se sababi iku.
O yẹ ka maa ronu pe iku lee de nigba kuugba, Ọlọrun lo kan yọ awa naa, tori Fulani kii kọlu eeyan, ko ma ku. Ka maa gbadura.
Bakan naa lo gbadura pe ki Ọlọrun fun wa ni eto aabo Amotekun se nilẹ Yoruba nitori ko si eto aabo tabi olugbeja fun wa rara, Ọlọrun nikan ati awa ara wa la n daabo bo ara wa, yoo si dara ki ijọba saanu wa.
Coronavirus: Nàìjíríà sọ àgádágodo sí ilé ìtajà China l‘Abuja láti dènà ìtànkálẹ̀ Coronavirus
Oríṣun àwòrán, FCCCP/Facebook
Ajọ to n mojuto idaabo bo awọn araalu nipa ọja rira ni Naijiria, Federal Competition and Consumer Protection Commission (FCCPC), ti sọ agadagodo si ile itaja awọn ọmọ orileede China kan nilu Abuja, Panda Supermarket.
Igbesẹ yii, gẹgẹ bi ajọ naa ti ṣe sọ jẹ ọna lati koju itankalẹ aisan Coronavirus.
Loju opo Twitter wọn ni ajọ naa fi ikede yii sita, ti wọn si ṣe afihan awọn ounjẹ ti ile itaja naa n ta, eyiti wọn gbe wọ Naijiria lọna ti ko tọ.
Tunde Irukera, to jẹ ọga agba ajọ naa lo ko awọn ọlọpaa sodi, lati lọ ti ile itaja naa pa lẹyin to ni awọn kan ta oun lolobo pe ayederu ọja wa lara nkan ti wọn n ta nibẹ.
Ninu awọn aworan ọja ti wọn fi si oju opo wọn, a ri wi pe ọjọ ti rekọja lori awọn ohun jijẹ kan ti wọn n ta nibẹ.
Irukera sọ pe awọn yoo gbe awọn ounjẹ wọn yii kuro lori igba lati le fi daabo bo ara ilu.
Oríṣun àwòrán, FCCCP/Facebook
Ẹwẹ, iye eeyan to ti ba iṣẹlẹ ajakalẹ aisan coronavirus ti di 170 bayi, ti wọn si ti kede pe o ti tan kalẹ de gbogbo agbegbe China.
Awọn alaṣẹ ilẹ China ni awọn eeyan to le ni ẹgbẹrun meje ni aisan naa ti n ba finra bayi. Itankalẹ rẹ si ti de awọn orileede mẹrindinlogun lagbaye.
Oríṣun àwòrán, FCCCP/Facebook
Lọjọbọ ni ajọ ilera agbaye yoo ṣe ipade pajawiri, lati jiroro lori ipenija aisan coronavirus.
Coronavirus: Àjọ WHO ní àìsàn pàjáwìrì gbogbo àgbaye ló dé yìí
Corovavirus: Àjọ WHO tí bẹ̀rẹ̀ ètò láti ràn àwọn orílẹ̀-èdè Afrika lọ́wọ́
Àjọ WHO ni ó ti wá ṣe pataki fun gbogbo àyé lati mọ báyìí pe wọ́n gbọdọ gbáradì láti ma jẹ ki àìsàn náà tàn kan, èyi mọ síṣe àmùjútó, ki wọ́n si maa fi afura si pamọ.
Siṣe àwári àwọn ti wọ́n ba fúnra si wọ́n ko ààrùn náà.
WHO ni ki gbogbo àwọn orile-èdè ma fi ọ̀rọ̀ náà sere ki wọ́n sì maa ni àkọsilẹ gbogbo àwọn ìwádìí wọ́n ki wọ́n si rii dáju pe wọ́n n pin ìwádìí náà pẹlu Ajo WHO.
Bí WHO ṣe ni àwọn ti n gbárrùkù ti àwọn orilẹ̀-èdè láti mọ iyé ènìyàn to ti lùgbàdi àìsàn náà àpẹrẹ wà pé ìbáṣepọ hàn láàrin China àti Afirika.
Dokita Matshidiso Moeti, to jẹ adari ẹkun Afirika ti fi ìlànà ránṣẹ́ si gbogbo àwọ ilẹ Afrika ti o ṣeeṣe ki àìsàn náà jẹ wọ.
Ajọ WHO ti tọka si àwọn òrilèdè ti o ṣeeṣe ki Coronavirus wọ ni Algeria, Angola, Cote d'Ivoire, Democratic Republic of Congo, Ethiopia,
Awọn orilẹ̀-èdè miran ni Ghana, Kenya, Mauritius, Nigeria, South Africa, Tanzania, Uganda and Zambia o si ṣe pàtàkì láti maa ṣe àyẹwò ni pápákọ òfùrufu ki àwọn ènìyàn to wọ ilú
Aisan Coronavirus, jẹ èyí to ma koju ija si ìlera ènìyàn to si maa n mu ọ̀fìkìn lọ́wọ́
Gẹ́gẹ́ bii ìwádìí ni ọgbọ̀n ọjọ oṣù kini ọdun 2020, ènìyàn to dín ni ẹgbẹ̀run mẹjọ
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Akọsilẹ tawọn alaṣẹ orilẹede China fi sita ṣalaye pe eeyan to din diẹ lẹgbẹrun mẹjọ lo ti ni aarun ọhun eyi to bẹrẹ niluu Wuhan.
Ilẹ Gẹẹsi ti kede pe eniyan meji ti ni aisan corona virus ni orilẹede wọn.
Adari eto ilera ni orilẹede naa, Ọjọgbọn Chris Whitty kede pe  awọn mejeeji naa wa lati idle kan naa ati wi pe wọn ti bere si ni gba iwosan.
Whitty ni ajọ eleto ilera orilẹede naa wa ni sepẹ lati koju aarun naa, ati lati wa awọn ti awọn mejeeji naa ti farako lati le dẹkun itanka aarun naa.
O fikun pe awọn ti gbaradi fun aarun naa nitori naa ni awọn ṣe tete koju rẹ ki kiakia.
Wọn ko fi ohun miran lede nipa iru eniyan ti wọn jẹ ati ami idanimọ wọn.
Ko tilẹ fi lede ibi ti wọn ti n gba itọju.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ayẹwo fun aarun coronavirus ni papakọ ofurufu niluu Eko
O ti le ni igba eniyan to ti ku latari aarun corona virus ni orilẹede China, ti ẹgbẹẹrun wọn si ti ni aisan naa kaakiri.
Bakan naa ni orilẹede mejidinlogun ti ko aarun naa, ti mejidinlọgọrun si ti ko aarun naa.
Ajọ eleto ilera lagbaye, WHO ti kede aarun coronavirus gẹgẹ bi ajakalẹ aarun gbogbo agbaye.
Eyi ko ṣẹyin bi Ajọ agbaye ṣe ni aisan naa n tankalẹ si kaakiri agbaye, ipaya si wa wi pe o le e ran lọ si awọn agbeegbe ti ko ni eto ilera to daju.
Olori ajọ WHO sọ wi pe kii ṣe nitori nkan to n ṣẹlẹ ni China ni awọn fi kede re, amọ ọna lati dena ki o ma ṣe de awọn orilẹede ti iya ati iṣẹ n koju ni awọn ṣe kede eto pajawiri naa.
Kò tíì tó oṣù kan tí èmí àti Favour bẹ̀rẹ̀ sí ní fẹ́ ara wa tí mo pa á ṣe ògùn owó - Kayeefi
Bakan naa ni orilẹede Amẹrika ti sọ fun awọn eniyan rẹ lati ṣọra lati lọ si orilẹede China.
O lẹ ni igba eniyan lorilẹede China to ti ku nipasẹ aarun naa, ti ẹgbẹrun mẹwa eniyan si ti ni aarun naa.
Ajọ WHO naa fikun pe aarun naa ti wa ni orilẹede mejidinlogun yatọ si China, ti eniyan mejidinlọgọrun si ti ni aarun naa, amọ ti ko si ẹni to ti ku nipasẹ aarun naa.
Iwadii fikun wi pe awọn to ni aarun naa ti lọ si ibi to ti bẹrẹ ni agbeegbe Wuhan, lorilẹede China.
O kere tan bayii, eeyan bi aadọsan ni iroyin sọ pe wọn ti dero ọrun lẹyin ti wọn lugbadi aarun Coronavirus to n ran kiri bi ina inu ọyẹ.
Akọsilẹ tawọn alaṣẹ orilẹede China fi sita ṣalaye pe eeyan to din diẹ lẹgbẹrun mẹjọ lo ti ni aarun ọhun eyi to bẹrẹ niluu Wuhan.
Gbogbo orilẹede lagbaaye ni wọn ti n ṣo ra bayii lẹyin ti aarun naa ti ran de orilẹede mẹrindinlogun.
Orilẹede Naijiria wa lara awọn orilẹede to n kaya soke lori aarun Coronavirus ti bẹrẹ si ni ran kaakiri agbaye.
Idi abajọ ni pe ọpọ ọmọ Naijiria lo wa lorilẹede China ti wọn n kawe atawọn mii ti wọn n rinrin ajo lọ sibẹ fun okoowo ati fawọn nnkan miiran.
Awọn ohun ti Naijiria n ṣe niyii lati gbogun ti aarun Coronavirus
Minisita fun eto ilera, Osagie Ehanire ṣalaye lọjọ Iṣẹgun, ọjọ kejidinlọgbọn oṣu kinni odun 2020 pe Naijiria naa ko ni kawọ gbera lati rii wi pe aarun naa ko wọ Naijiria.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ayẹwo fun aarun coronavirus ni papakọ ofurufu niluu Eko
''Ma ṣe lọ si China bayii''
Minisita eto ilera Osagie Ehanire ti kilọ fawọn ọmọ Naijiria ti wọn fẹ rinrin ajo lọ si orililẹede China lasiko pe ki wọn maa tii lọ bayii.
O ni imọran yii ṣe pataki fawọn ọmọ Naijiria lakoko yii ki wọn maa ba lugbadi aarun naa.
Minisita tun rọ awọn to ṣẹṣẹ de lati orilẹede China atawọn orilẹede ti aarun Coronavirus ti ran de pe ki wọn ya ara wọn sọtọ fun ọsẹ meji koda bi ko ba si apẹrẹ pe wọn ti ko aarun naa.
Iṣọra lawọn abawọle si Naijiria
Minisita eto ilera Osagie Ehanire tun ṣalaye pe ijọba ti ṣeto pe kawọn ẹṣọ wa ni imurasilẹ lawọn abawọle si Naijiria to fi mọ papakọ ofurufu marun un niluu Abuja, Eko, Enugu, Port Harcourt ati ilu Kano.
Ajọ to n ri si igbokegbodo ọkọ ofurufu ni Naijiria naa ti rọ awọn oṣiṣẹ papakọ ofurufu atawọn arinrinajo lati fọwọ sowọpọ pẹlu awọn alakalẹ lati dena aarun Coronavirus ko maa ba wọ Naijiria.
Ifọwọsowọpọ ajọ NCDC ati ajọ eto ilera lagbaaye WHO
Ajọ to n ri si didena ajankalẹ aarun ni Naijiria NCDC ṣalaye pe awọn n ṣiṣẹ pọ pẹlu ajọ eto ilera lagbaaye lori aarun Coronavirus.
Ajọ naa rọ awọn ọmọ Naijiria pe ki wọn maa paya lori aarun ọhun.
Awọn ọmọ Naijiria ni China nkọ?
Oludari ajọ to n ri si ọrọ awọn ọmọ Naijiria ti wọn wa niluu okere, Abike Dabiri-Erewa sọ BBC pe ajọ naa ko gba iroyin pe ọmọ Naijiria kankan ti lugbadi aarun naa lorilẹede China.
Abike sọ pe awọn akẹkọọ to jẹ ọmọ Naijiria ni China ti lọ si olu ile iṣẹ orilẹede Naijiria lorilẹede naa.
O fikun ọrọ rẹ pe ijọba tin gbero lati ko awọn ọmọ Naijiria ti wọn ko tii lanfaani lati lọ si olu ile iṣẹ Naijiria ni China wale.
Favour Oladele: Bó ṣe kàgbákò ikú gbígbóná lọ́wọ́ ọ̀rẹ́kùnrin rẹ̀- Kayeefi
Kò tíì tó oṣù kan tí èmí àti Favour bẹ̀rẹ̀ sí ni fẹ́ ara wa tí mo pa á ṣe ògùn owó
Ninu fidio to wa loke yii, ẹ o ri pabanbari bi Owolabi Adeẹkọ ṣe fi ọrẹbinrin rẹ ṣe oogun owo fun oun ati iya rẹ.
Ṣe ẹ ranti Favour Daley Oladele ni nkan bii ọsẹ diẹ sẹyin ti ọrẹkunrin rẹ Owolabi ati iya rẹ ati Woli rẹ pa ti wọn si ge ẹran ara rẹ fi ṣe asejẹ ki Owolabi ati iya rẹ le di ọlọla laye.
Odidi ilu marun un  ni ọrọ to kan iku Favour rọ mọ kaakiri - Eko, Abeokuta, Mowe, Ikoyi Ile, Osogbo.
Eko ni ile iwe Favour wa, Fasiti ti ipinlẹ Eko (LASU) nibi to ti n kọ nipa imọ ẹkọ Tiata.
Mowe ni Favour n gbe pẹlu awọn obi rẹ, Alagba ati iyaafin Dale David Oladele. Mowe naa ni agọ Ọlọpa ti awọn obi Favour lọ nigba to di pe wọn n wa ọmọ wọn.
Ikoyi Ile  ni ṣọọṣi Wolii Phillips to jẹ Pasitọ ijọ ti Owolabi ọrẹkunrin Favour mu u lọ wa.
Favour dagbere nile pe oun n lọ si ile iwe lati lọ mura ko to bẹrẹ idanwo aṣekagba ni fasiti rẹ, Fasiti ilu Eko ninu imọ ẹkọ Tiata.
Oun ati awọn obi rẹ dagbere lai mọ pe ọtọ ni ibi ti o n lọ gẹgẹ bi ọrẹkunri rẹ ṣe ti sọ fun un pe ko wa ba oun ni ilu Ikoyi Ile.
Àjọ EFCC gbé òtè lé àwọn adélébọ̀ tó ń wá iṣẹ́
Ààrun Coronavirus ti dí àjàkálẹ̀ gbogbo àgbàyé - WHO
Ajọ to n gbogun ti iwa jẹgudujẹra lorilẹede Naijiria EFCC n gba ni si iṣẹ lọwọ wọn si ti fi kun ara awọn ofin to wa labẹ ipolowo iṣẹ naa pe ki awọn to ti lọkọ tabi laya ma dabaa rẹ rara.
Igbesẹ yii ni ọpọ awọn eeyan ti n bu ẹnu atẹ lu to fi mọ ẹgbẹ kan to so mọ ẹgbẹ awọn oṣiṣẹ to n jẹ ẹgbẹ awọn olugbaninimọran nipa igbanisiṣẹ.
"Ninu iwe kan to tan ka gbogbo ori ayelujara lọjọ kẹẹdogun oṣu kinni ọdun 2020 ninu eyi to sọ pe ajọ EFCC fẹ gba oṣiṣẹ si awọn ipo kan lo ti han wi pe "" ẹni to ba ti lọkọ tabi laya ko ma rẹ""."
Kò tíì tó oṣù kan tí èmí àti Favour bẹ̀rẹ̀ sí ní fẹ́ ara wa tí mo pa á ṣe ògùn owó - Kayeefi
Ààrun Coronavirus ti dí àjàkálẹ̀ gbogbo àgbàyé - WHO
'Lórí owó gọbọi 33k,mò lè tún àgùnbánirọ̀ NYSC mi ṣé tí ààyè bá gbà mí'
Bakan naa fun ọkan lara awọn ipo naa, ẹni to ba ti le ni ọdun mọkanlelogun ko gbudọ kọ iwe lati wa iṣẹ naa. Fun omii, ẹni to ba ti le ni ọdun mẹẹdọgbọn ati ikẹta, ẹni to ba ti le ni ọdun mẹtadinlọgbọn.
Lẹyin eyi ni wọn wa fi kun gbogbo rẹ pe ẹni ti yoo ba wa iṣẹ naa ṣi gbudọ jẹ apọn ati omidan.
Ohun ti awọn eeyan n sọ nipa rẹ lori ayelujara ree.
"...ewo tun ni ti ọjọ ori ninu iṣẹ ijọba. O da mi loju gan pe iwọnba ti wọn fẹ gba yẹn, ẹni ba lẹsẹ ni yoo ri i gba...
Ọjọ ori yii ti ja ọpọlọpọ awa ti a nifẹ lati gba iṣẹ naa walẹ... Aparo kan ko ga ju ọkan lọ o. Eyi ko dara rara.
Mi o mọ idi ti eeyan nilo lati lọ fi iwe naa silẹ ni ọfiisi ajọ EFCC. Ori ayelujara lo yẹ ki wọ"
Àgbékalẹ̀ Amotekun dára torí agbára òògùn àwọn baba wa kò dínkù tàbí parẹ́ - Peter Fatomilola
Ẹwẹ nigba ti akọroyin BBC kan si ọkan lara awọn agbẹnusọ ileeṣẹ naa, o kọ lati fọ esi kankan lori rẹ.
Ọkọ̀ wa wọ'gbó lọ lẹ́yìn táwọn dánàdánà dàbọn bò wá- Toyosi Adesanya
NYSC: Àwọn àgùnbánirọ̀ fi orin ọpẹ́ bọ ẹnu lórí owó oṣù tuntun 33k
Alabi Seyifunmi to n sin ilẹ baba rẹ nilu Abuja ti ni idunnu subu layọ fun awọn nigba ti awọn agunbanirọ ri pe ijọba ti n san ẹgbẹrun mẹtalelọgbọn Naira(33,000) owo osu fun awọn.
Agunbanirọ Seyifunmi ni ẹgbẹrun mọkanlelọgbọn ni awọn tilẹ n reti, ko to di wi pe awọn akẹgbẹ rẹ sọ fun un wi pe ẹgbẹrun mẹ̀talelọgbọn ni wọn ri ninu banki wọn.
Arabinrin naa ni bi inu oun ṣe dun mọ oun to, oun ko ni fi ẹsẹ rin mọ ni igboro Abuja, ọkọ ọyọkẹlẹ ni oun yoo ma a wọ bayii.
O fikun pe oun yoo fi afikun owo naa kọ ẹkọ imọ ti yoo ṣe oun ni anfaani, bakan naa ni  oun yoo ra awọn nkan ti o nilo si ara oun.
Ninu ọrọ tirẹ, agunbanirọ Akinlolu Ogunmọlawa ni oun fẹ fi owo naa kọ iṣẹ ọwọ ki oun le dadurọ ti oun ba bari gẹgẹ bi agunbanirọ.
Ogunmọlawa fikun wi pe nibi ti inu awọn dun de, awọn ti wọn ti fi igba kan ṣe agunbanirọ ri n parọwa si ijọba lati fun awọn laaye lati wa ṣe agunbanirọ lẹẹkan si, ati wi pe ki wọn fikun iye ọdun ti awọn yoo ma a fi sin orilẹede Naijiria.
Ẹgbẹrun mọkanlelogun o le ẹgbẹrin naira ni wọn n gba tẹlẹ ni oṣooṣu, ki o to di pe ijọba wa fikun owo oṣu wọn to di ẹgbẹ̀run mẹ̀talelọgbọn.
Alaati ti dun, kii ṣe 'audio money', ijọba ti n san owo agunbanirọ tuntun ẹgbẹrun mẹtalelọgbọn Naira!
Ọrọ ti agunbanirọ kan fi si oju opo Facebook rẹ lati fi jẹri fawọn ọrẹ rẹ pe alekun ti ba owo ti ijọba n san fun wọn.
Idunnu to ṣubu layọ fun agunbanirọ yii jẹ eleyi tawọn ẹlomiran ti kii ṣe agunbanirọ gaan n ba wọn yọ nipa alekun owo naa.
Koda awọn kan sọ pe ti awọn ba ni anfaani, awọn yoo pada lati lọ ṣe agunbanirọ ki wọn baa le jẹ anfaani owo yii.
Loju opo Twitter wọn ko fi ọrọ yi bo rara
Pupọ awọn to ti pari ẹkọ ati agunbanirọ ni Naijiria ni ko tii ri iṣẹ.
Lara awọn to ti ri gan, owo oṣu ti ẹlomiran n gba ko to owo tuntun yii ti ijọba ṣẹṣẹ bẹrẹ si ni san.
Oríṣun àwòrán, PIUS UTOMI EKPEI
Ṣaaju asiko yii, owo oṣu to kere julọ ti ijọba n san fawọn oṣiṣẹ ko kọja ẹgbẹrun mejidinlogun le diẹ ti alawee awọn agunbaniro si jẹ ẹgbẹrun mọkandilogun naira le diẹ.
Idi ree ti awọn ti ko tii ri iṣẹ miiran fi n sọ pe yoo wu awọn lati tun agunbanirọ ṣe lati le fi ma ri owo yii gba.
Tithing: Daddy Freeze àtàwọn ọmọ Nàìjíríà míì ta gbá òjíṣẹ́ Ọlọ́run torí ègún ìdá mẹ́wàá
Oríṣun àwòrán, @DavidOyedepoMin
Ṣe ni ori ayelujara tun n gbona tori ọrọ ida mẹwaa ti olori ìjọ Living Faith, Bisọọbu David Oyedepo sọ ni ọjọ Ẹti.
Bisọọbu Oyedepo, lo sọ loju opo Twitter rẹ pe egun ọda owo yoo ja ẹnikẹni ti ko ba da ida mẹwaa fun ijọ Ọlọrun.
"Oyedepo ni ""Ida mẹwaa jẹ majẹmu pẹlu Ọlọrun ti ko ṣe e yẹ, laisi ida mẹwaa, ko see ṣe lati ṣe rere tabi ni ọrọ, aisan ida mẹwaa si lo n fi ẹ sinu egun ọda owo."
"Bakan naa lo fikun pe"" ọna to n gba ṣe akoso ẹnawo rẹ ni yoo sọ bo ṣe lowo si nitori ọpọ isoro ti ẹda n koju la le e tọ ipasẹ rẹ de idi ibasepọ rẹ pẹlu owo. """
Ṣugbọn ọpọ ọmọ Naijiria to ka ọrọ yii lo faraya, ti wọn si ni irufẹ ọrọ bayii ko dara rara.
Nigba to n fesi lori ọrọ Oyedepo naa, Ifedayo Olarinde, ti ọpọ eeyan mọ si Daddy Freeze ni ọrọ radarada ni ojisẹ Ọlọrun naa kọ, ti ko si bojumu.
Oríṣun àwòrán, Other
"Ṣe o ni ida kan owo ti awọn olowo agbaye bii Jeff Bezos, Bill Gates ati Warren Buffet, ti kii san ida mẹwaa ni bi? Mo ri ọrọ yii bii eyi ti ko ba Bibeli mu, to si jẹ iwa ika si ọmọniyan?
Daddy Freeze ni Jesu tabi awọn ọmọ ẹyin rẹ ko gba ida mẹwaa nigba aye rẹ, ofin atijọ ni sisan ida mẹwaa jẹ, idi si ree ti Kristẹni fi n pe ofin majẹmu laelae ni ofin ẹsẹ ati iku.
Ẹ yé tako ìjọba lórí iléèjọ́sìn títì pa, ẹ jọ̀wọ́ ṣọ́ọ̀ṣì yín fún ìtọ́jú àwọn tó lárùn coronavirus- Tunde Bakare
Oludasilẹ ijọ Latter Rain Assembly, Tunde Bakare ti rọ awọn alufa ijọ bi tiẹ lati jọwọ gbọngan ile ijọsin silẹ fun ijọba lati loo fun ibudo itọju awọn alaisan coronavirus.
Pasitọ Bakare sọrọ yii ninu fidio kan to wa lori ayelujara eleyi tawọn eeyan ti n sọrọ nipa rẹ.
Oríṣun àwòrán, Twitter/Pastor Tunde Bakare
Pasitọ Bakare ni ijọ Latter Rain gan an ti jọwọ gọngan meji to jẹ ti ṣọọṣi naa fun ijọba ipinlẹ Eko lati lo fun ibudo iyasọtọ awọn to ti lugbadi coronavirus.
Bakan naa lo sọ pe ijọ naa tun ti jọwọ ile kan niluu Abẹokuta fun ijọba ipinlẹ Ogun lati lo fun itọju awọn to laarun covid-19.
O bu ẹnu atẹ lu awọn ojiṣẹ Ọlọrun kan ti wọn sọ pe ko yẹ ki ọja wa ni ṣiṣi nigba ile ijọsin wa ni titipa.
Alufaa Bakare nisẹ lo yẹ kawọn ojiṣẹ Ọlọrun ṣiṣẹ pọ pẹlu ijọba lati gbogun ti ajakalẹ aarun coronavirus to n ba gbogbo aye finra lọwọ yii.
O ni o yẹ kawọn ile ijọsin nla jọwọ lo ohun ini wọn lati ran ijọba lọwọ, dipọ kawọn olori wọn maa tako igbesẹ ijọba lori ofin konle-o-gbele.
Oríṣun àwòrán, Twitter/Pastor Tunde Bakare
Pasitọ Bakare ni ṣọọṣi nikan kọ ni ijọba fofin de, o ni o kan mọṣalaaṣi naa.
O ṣalaye pe ijọba ko gbe ọja tipa nitori ki ebi maa ba pa ọgọrọ araalu to jọ pe iṣẹ oojọ ni wọn n ṣe ki wọn to le jẹun.
Alufaa Bakare lu awọn oṣiṣẹ eleto ilera lọgọ ẹnu lori iṣẹ takun takun ti wọn n ṣe lasiko ajakalẹ coronavirus yii, o gbadura fun aabo Ọlọrun lori wọn.
Èrò ọmọ Nàìjíríà ṣ'ọ̀tọ̀ọ̀tọ̀ lórí ọ̀rọ̀ Bíṣọ́ọ́bù Oyedepo pé kò sí ìdí tí iléèjọ́sìn láti wà ní títì pa
Bisọọbu David Oyedepo, nínú ìsìn irọlẹ Ọjọru faraya lórí bí ìjọba àpapọ̀ ṣe ti ilẹkun mọ àwọn sọọsi àmọ́ tó ń sì àwọn ọjà oúnjẹ gbogbo fún wákàtí mẹ́fà gbáko, nibiti àwọn aráàlú kò ti bọ̀wọ̀ fún òfin títa kété síra ẹni.Ọ̀rọ̀ ojisẹ Ọlọ́run náà sì lo tí ń fa awuyewuye làwọn ojú òpó ikansiraẹni lórí itakun àgbáyé , bí àwọn èèyàn kan sì ṣe tako èrò rẹ, ni àwọn míràn fara mọ.Kódà, ọ̀rọ̀ náà kò tíì tán lójú òpó BBC Yoruba, nibiti àwọn èèyàn ti ń gbáà ọrọ náà mọ ara wọn lọ́wọ́, bíi ẹni gba igba ọtí.
Lérò tí Ajayi Solomon, oúnjẹ leè gbé ẹmi ró gẹ́gẹ́ bíi ẹlẹ́ran ara àmọ́ ọ̀rọ̀ Ọlọ́run nìkan ni oúnjẹ ẹ̀mí tí yóò jẹ ká dàgbà nínú ìwà rere, tí yóò sì jẹ ká ye, ó ní ọjà àti sọọsi lo yẹ kí ìjọba sí papọ.
Ṣùgbọ́n ọ̀pọ̀lọpọ̀ èèyàn ló tako èrò rẹ yìí, ní èrò tí Nurudeen Mufc Bamidele, kò sì ibi tí èèyàn kò ti leè gbọ ọrọ Ọlọ́run, tí Dára Dariz Ogunsola náà sì kin lẹ́yìn pé oúnjẹ kii wọnú, kí ọrọ miran wọ ọ, bí àwọn èèyàn kò bá jẹun, ọ̀rọ̀ Ọlọ́run kò leè wọ wọn létí.
Ọ̀pọ̀ èèyàn tó sì dá sí ìjíròrò náà lo fara mọ pe oúnjẹ ní kókó, kódà, Oluwaseun Abiodun ni, niwọn ìgbà tí àwọn ilé ìjọsìn kò ní fún àwọn ni oúnjẹ jẹ, ọjà tí àwọn yoo ti rí oúnjẹ rà ni pàtàkì. Ṣùgbọ́n àwọn èèyàn míràn yí ọ̀rọ̀ náà si ibòmíràn, tí wọ́n sì ni torí owó tí àwọn ìjọ Ọlọ́run kò rí pa wọlé mọ,  ní ojisẹ Ọlọ́run náà ṣe ń pariwo lórí bí ìjọba ṣe tí ilé ìjọsìn pá.
Oríṣun àwòrán, davidoyedepomin
Afolabi Idris Wayforward ń tiẹ̀ ń béèrè pé kí ló dé tí Oyedepo fi fẹ́ kí jọba si sọọsi pẹ̀lú tipátipá, ṣe nítorí owó tí kò wọlé fún àwọn ojisẹ Ọlọ́run mọ ni?
Ìmọ̀ràn tí àwọn èèyàn mìíràn bíi Ojo Omoniyi wá ń gba aráàlú ni pé, bí wọn ṣe gba wọn láàyè láti lọ sí ọjà, ṣe ni kí wọn tẹle òfin títa kété síra ẹni, kí a máa bàa wá jẹbi lẹ́yìn ó rẹyìn.
Oríṣun àwòrán, @DavidOyedepoMin
Oyedepo, ẹni tó pariwo bẹẹ lásìkò ìsìn wákàtí àdúrà tó wáyé ní Ọjọru ni, òun fura pé ejò lọ́wọ́ nínú lórí bí ìjọba kò ṣe tíì pàṣẹ láti ṣílẹ̀kùn ilé Ọlọ́run padà.
Ẹ ní kí wọn máa ṣílẹ̀kùn ọjà gbogbo fún wákàtí mẹ́fà, kí wá lo dé tí ẹ kò fi silẹkun sọọsi fún wákàtí méjì, mo ní ìgbàgbọ́ pé iditẹ mọ ìdàgbàsókè àwọn sọọsi ni Nàìjíríà ni èyí""."
Mo ń fura pupọ lórí ìṣẹ̀lẹ̀ yìí. Ọlọ́run bá mi sọ̀rọ̀ púpọ̀ lórí ìṣẹ̀lẹ̀ naa ni àná, àbí ọ̀nà wo ni wọn tún fẹ́ gbà láti dá sọọsi lọwọkọ kò má baa gbòòrò, oyè èyí kò ye àwọn èèyàn ti ọ̀rọ̀ yìí kan.
Oyedepo ni ohùn òkùnkùn lo fẹ́ ń darí àwọn èèyàn ní gbogbo ẹ̀ka yìí, tó sì dojú kọ ìjọ Ọlọ́run nítorí bí àwọn sọọsi ṣe ń gbòòrò lo ń fọ èṣù lórí, àmọ́ ẹnu ọ̀nà ọrùn àpáàdì kò ní borí,
Èṣù àti àwọn ọmọ ogun rẹ yóò jìyà rẹ.
"Oyedepo tún wà ń béèrè pé"" irú ilé ìwòsàn wo ló ń ṣe àṣeyọrí ìwòsàn bíi èyí táwọn ìjọ Ọlọ́run ńṣe?"
Ó ní ilé ìwòsàn tí àwọn èèyàn ń kú sí wa ni ṣíṣí silẹ àmọ́ wọn ti ilẹ̀kùn ilé Ọlọ́run nítorí ìwà ìjẹgàba Èṣù, èyí tí kò ní ìwòsàn.
Wo àwọn nǹkan mẹ́rin tó yẹ kó wà nínú báàgì rẹ lásìkò Covid-19 yìí
Oríṣun àwòrán, Twitter/US Mission Nigeria
Irọ lasan ni, iroyin ofege lawọn eeyan kan n gbe kaakiri.
Olu ileeṣẹ ilẹ Amẹrika ti fesi si si iroyin to lu oju ayelujara pa laarọ ọjọ Ẹti pe wọn o fun oludasilẹ ijọ Living Faith Church ti ọpọ mọ si Winners, Bisọọbu David Oyedepo.
Iwe iroyin Thisday lo kọkọ gbe iroyin naa pe olu ile iṣẹ ilẹ Amẹrika ni Naijiria kọ lati fun Bisọbu ni fisa.
Amọ olu ileeṣẹ ilẹ Amẹrika ṣalaye loju opo Twitter wọn pe irọ funfun balau ni iroyin naa.
Wọn rọ awọn eeyan ti wọn ti ri iroyin naa lori ayelujara wi pe ki wọ  kọ eti kun sii nitotri kosi otitọ kankan nibẹ.
Olu ileeṣẹ ilẹ Amẹrika sọ loju opo Twitter wọn pe iṣinilọna gbaa ni iroyin naa to jade.
Oríṣun àwòrán, Twitter/Bishop David Oyedepo
Ọpọ eeyan lo ti n sọrọ lori ayelujara lati aarọ ọjọ Ẹti lati igba ti iroyin naa ti jade.
Ìdílé kan gbé ilé iṣẹ́ ọkọ̀ òfurufú lọ ilé ẹjọ́ lẹ́yìn tí wọ́n léwọ̀n dànù nínú ọkọ̀ pé ara wọ́n ń rùn
Oríṣun àwòrán, AFP
Idíle kan gbé ilé iṣẹ́ ọkọ̀ òfurufu lọ ilé ẹjọ lẹ́yin ti wọ́n lẹwọ̀n dànu ninu ọkọ pé ara wọ́n ńrun
Idile kan ni Michigan, ti àwọn ilé iṣẹ ọkọ ofurufu ilẹ Amẹrika kan lé kuro ninu ọkọ ofurufu wọ́n nítori pé wọ́n ni òòru ara (Body Odour) ti gbé ilé iṣk náà lọ ilé ẹjọ.
Ilé iṣẹ́ ọkọ ofurufu náà lé Yehuda Yosef Adler, iyawo rẹ̀ Jennie àti ọmọ wọ́n obinrin kékéré kuro ninu ọkọ ofurufu Detroit ni inú oṣù kini ọdun to kọja.
Wọ́n ni ọkàn nínú àwọn olùrànlọwọ inu ọkọ ofurufu sọ̀rọ̀ nipa ẹsin ìgbà jew ti àwọn ń sìn.
Sùgban àwọn ilé iṣẹ́ ọkọ ofurufu náà ni ìdi ti àwọ̀n fi le wan kuro ni pe kìí ṣe nitori ẹsìn bíkòṣe pé àwọn àlábara wọ́n to ku ń kùn pé wọ́n ni òòrun ara pàápàá jùlọ ọgbẹ́ni Adlers
Ipẹjọ náà ti wọ́n pe ni Texas sàlàye pe ìbanilórukọ jẹ́ ni wọ́n se fun ẹbi ọhùn , ti èyi si fa iréwési ọkàn fun àwọn ẹbi náà to si tàkà àbuku si ẹsìn wọ́n
Oríṣun àwòrán, AFP
Idíle kan gbé ilé iṣẹ́ ọkọ̀ òfurufu lọ ilé ẹjọ lẹ́yin ti wọ́n lẹwọ̀n dànu ninu ọkọ pé ara wọ́n ńrun
Ogẹni Alder ni lẹyin iṣkju marun ti a[wọn ti wa ninu ọkọ ni ọkan ninu àwọn òsìsẹ́ wọ́n wa sọ pe ìṣẹ̀lẹ̀ pajawiri sẹlẹ̀ wọ́n si ni lati sọkalẹ.
Nígbà ti wan sọkalẹ tan ni o wá sọ fun wan pe awako ofurufu lọ yọ orukọ wan kuro ninu irinajo náà.
"Nínú àtẹjade ilé iṣẹ́ náà fi sita la'ti ọdọ Fox News: "" a so fun ọgbẹni Alder àti ẹbi rẹ̀ láti sọkalẹ ninu ọkọ ofurufu náà lẹ́yin ọpọlọpọ àwọn èrò ńkùn nitori wọ́n, ìgbésẹ wa ni ]nkan ti a ro pe o tọna láti ṣe nitori alafia awọn èrò to kù"""
" Ko si eyi to niṣe pẹlu ẹsin ọgbẹ̀ni Adler
Coronavirus: Ọmọ ilẹ̀ China kan ti kú sí orílẹ́èdè míì lẹ́yìn tó lùgbàdì ààrùn náà
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ileeṣẹ to n ri si eto ilera lorilẹede Naijiria ni pẹlu ajọṣepọ ajọ agbaye to n ri si eto ilera WHO, Naijiria ti ni ibudo to lee kapa ṣiṣe ayẹwo ẹni to ba ko aarun aṣekupani Coronavirus eyi to bẹrẹ lorilede China.
Minisita wa lo oju opo itakun Twitter wọn lati fun pe si ẹnikẹni lorilede Naijira to ti lọ si China ni oṣu bii melo sẹyin lati ya ara wọn s'ọ́tọ̀ na fun ọjọ́ mẹ́rìnlá ki wọn si pe ajọ to nṣamojuto kikoju aarun NCDC lori nọmba 07032864444."
Oríṣun àwòrán, @Fmohnigeria
Bakan naa wọn tẹnu mọ ọ pé ẹnikẹni to ba ti ri i pe oun ni iba, ikọ, ọna ọfun n dun un ati inira lati mí, ki o tete lọ si ileewosan to ba wa ni tosi rẹ.
Ehanire gba gbogbo awọn oṣiṣẹ eleto ilera niyanju pe bi wọn ba ṣe n tọju awọn to ba wa, ki wọn maa fun wọn ni iboju, ki wọn si ya wọn sọtọ ki wọn to kan si ajọ NCDC.
O ti le lọdunrun-un eeyan to ti dero ọrun bayii nipasẹ aarun coronavirus eyi ti ọpọ ninu wọn wa lati ẹkun Hubei ni Wuhan.
Ọkunrin kan ti gbẹmi mi lorilẹede Philippines lẹyin to lugbadi aarun Coronavirus to n ran kaakiri agbaye bayii.
Ọmọ orilẹede China ni ọkunrin naa, ẹni ọdun mẹrinlelogoji, ọmọ ilu Wuhan to wa lẹkun Hubei ti aarun Coronavirus ti bẹrẹ ni ọkunrin naa ti wa.
Ajọ to n ri si eto ilera lagbaaye, WHO ṣalaye pe o dabi ẹni pe ọkunrin naa ti lugbadi aarun Coronavirus ko to rinrin ajo lọ si orilẹede Philippines.
O ti le lọdunrun un eeyan to ti dero ọrun bayii nipasẹ aarun coronavirus eyi ti ọpọ ninu wọn wa lati ẹkun Hubei ni Wuhan ti aarun naa ti bẹrẹ.
Eeyan to le lẹgbẹrun un mẹrinla lo ti ni aarun coronavirus bayii kaakiri agbaye.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ẹwẹ, ọrọ di bo o lọ, o ya a mi nile iwosan kan ni Wuse niluu Abuja lọjọ Abamẹta lẹyin tawọn eeyan marun un kan parọ pe awọn ti ko aarun coronavirus.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Akọsilẹ tawọn alaṣẹ orilẹede China fi sita ṣalaye pe eeyan to din diẹ lẹgbẹrun mẹjọ lo ti ni aarun ọhun eyi to bẹrẹ niluu Wuhan.
Awọn eeyan naa ti orukọ wọn jẹ Peggy Shandi, Abayomi Adedoyin, David Enemigin, Priscilla Ajesola ati Jacob Oji ṣe idiwọ fun ilera nile iwosan naa.
Agbẹnusọ fun ile iṣẹ ọlọpaa l'Abuja, DSP Anjuguri Manza ṣalaye pe awọn eeyan naa yoo foju ba ileẹjọ ẹjọ lẹyin tawọn agb ofinro ba pari iṣẹ iwadii wọn tan.
Corovavirus: Àjọ WHO tí bẹ̀rẹ̀ ètò láti ràn àwọn orílẹ̀-èdè Afrika lọ́wọ́
Akọwe iroyin fun minisita olu ilu Naijiria, Ọgbẹni Anthony Ogunleye sọ ninu atẹjade kan pe oludari eto ilera niluu Abuja, Dokita Josephine Okechukwu ti fọkan awọn ara ilu Abuja balẹ pe ko si ohun to jọ aarun coronavirus l'Abuja.
Pastor Adeboye ṣáájú ìwọ́de àdúrà lòdí sí ìpànìyàn ní Nàìjíríà
Oríṣun àwòrán, @rccg_pr
Jakejado orilẹede Naijiria lowurọ yii ni ijọ irapada ti gbogbo eniyan mọ si Redeemed Christian Church of God ṣe iwọde ifẹhonu han lodi si iṣekupani to n di lemolemo lorilede Naijiria.
Laipẹ yii ni awọn ajinigbe ṣekupa alaga ẹgbẹ awọn ọmọlẹyin Kristi ni iha Guusu Naijiria. Eyi ati ọpọlọpọ awọn ọmọ Naijira to n la ijinigbe ati iṣekupani kọja lo mu ki ẹgbẹ ọmọlẹyin Kristi lapapọ lorilede Naijira kede iwọde yii.
Oríṣun àwòrán, Isaac Jeremiah
Ijọ Redeem, Chapel of Life, Abuja
Ijọ Reedeem, Ọgba Eko
"Pasitọ ijọ Redeem, Enoch Adejare Adeboye nibi isin idupẹ oṣu keji ọdun eyi to waye ni iya ijọ Redeem to wa ni Ebute Meta, ipinlẹ Eko sọ wi pe ""gbogbo ẹni ti wọn pa lorilẹede Naijiria yala Kristẹni tabi Musulumi gbudọ ṣe pataki si wa""."
Prophecy 2020: Adeboye àti Ayọdele sọ nípa ọjọ́ ìwájú 2020
Oríṣun àwòrán, @yemility007
Ijọ Redeem, King's Court, Eko
Lẹyin ti Adeboye le adura fun aabo, ipamọ ati alafia fun orilẹede Naijiria ninu isin naa tan lo mẹnu ba ọrọ awọn ti wọn n ṣekupa lorilẹede yii.
"Latari eyi oni ẹgbẹ CAN ti kede pe ki gbogbo Kristẹni ṣe iwọde lodi si i eyi to pe ni ""irin adura(prayer walk)""."
"Ninu iwọde ọhun, Pasitọ Adeboye lo ṣaaju awọn ọmọ ijọ rẹ pẹlu patako ti wọn gbe lọwọ pẹlu akọle to sọ wi pe ""Gbogbo kan se iyebiye si Ọlọrun""."
Oríṣun àwòrán, RCCG Abba Father, Ado Ekiti
Oríṣun àwòrán, Isaac Jeremaih
Ijọ Redeem, Chapel of Life Area 1, Abuja
Oríṣun àwòrán, RCCG Jesus House
Ijọ Redeem, Jesus House Parish, Eko
Oríṣun àwòrán, RCCG TEAP, Abuja
Okada Ban: Iléeṣẹ́ ọlọ́pàá láwọn yóò rún ọ̀kàdà àti kẹ̀kẹ́ Maruwa t'ọ́wọ́ bá tẹ̀ jégéjégé
Oríṣun àwòrán, Other
Oni ọjọ Aiku tii ṣe ọjọ keji oṣu keji ọdun 2020 lo pe ọjọ meji ti ijọba ipinlẹ Eko fi ofin de alapupu ti ọpọ mọ si okada ati kẹkẹ ẹlẹsẹ mẹta(kẹkẹ Maruwa) wiwa lawọn ijọba ibilẹ kan jakejado ilu Eko.
Ọpọ awọn ọlọkada atawọn to n wa kẹkẹ Maruwa ti wọn ṣori kunkun lọwọ awọn ọlọpaa tẹ lọjọ Abamẹta ti ofin naa bẹrẹ si ni mulẹ.
Ọga agba ọlọpaa nipinlẹ Eko, Hakeem Odumosu to ṣaaju awọn ọlọpaa to n ṣe itọpinpin eto naa kaakiri sọ pe awọn ti ọwọ tẹ yoo foju wina ofin.
Ọgbẹni Odumosu ṣalaye pe gbogbo awọn ọkada ati kẹkẹ Maruwa tawọn gba nile iṣẹ ọlọpaa yoo run jegejege.
O ni asiko sissan owo itanran lati gba ọkada pada ti lọ nipinlẹ Eko.
Oríṣun àwòrán, Twitter/Abdulhammed Abiola
Ẹwẹ, Gomina ipinlẹ Eko, Babajide Sanwo-Olu ṣalaye pe ofin to ti wa tẹlẹ ni ijọba ṣe agbekalẹ rẹ pada lẹyin ti ijọba ti kọkọ fofin de wiwa ọkada ati kẹkẹ Maruwa lọdun mẹfa sẹyin.
Sanwo-Olu ni yatọ si wi pe iwakuwa awọn ọlọkada pọ, ijamba ọkada ati kẹkẹ Maruwa ti ran ọpọ lọ si ọrun lairotẹlẹ.
Ọgbẹni Agbator Solomon to fi aworan kan si oju opo rẹ Twitter bu ẹnu ẹtẹ lu igbesẹ ijọba ilu Eko.
O ni o dabi ẹni pe ijọba gba iṣẹ lọwọ awọn eeyan ni lẹyin ti wọn ti kuna lati pese iṣẹ fun wọn.
Bakan naa lọmọ ṣori lagbegbe Sabo Yaba, niṣe lero pọ loju titi biba nibi ti wọn ti n duro de ọkọ fun igba pipẹ.
Ẹwẹ, awọn ọlọkada kan ti wọn wa iṣẹ aje wa silu Eko ti bẹrẹ si ni pada sibi ti wọn ti wa.
Ọkọ tirela lọpọ ninu wọn fi n ko ọkada ti wọn n gun l'Eko pada si ilu wọn lẹyin ti ijọba ile Eko mimu awọn ọlọkada atawọn onikẹkẹ Maruwa nipinlẹ naa.
Ẹru to n ba ọpọ ni bi ilu Eko Eko yoo ṣe ri lọjọ Aje tawọn eeyan yoo pada si ẹnu iṣẹ ṣugbọn lai si ọkada ati kẹkẹ Maruwa ti wọn le wọ mọ.
Nathaniel Samuel: Ìwádìí tí bẹ̀rẹ̀ lórí afurasí tó gbé ado olóró wọ ilé ìjọsìn Winners
Oríṣun àwòrán, Google
Ọwọ palaba arakunrin kan ti wọn fura si pe o fẹ yin ado oloro ni ile ijọsin Living Faith Church ni adugbo Sabo ni Kaduna ti segi.
Awọn aworan ta ri loju opo ayelujara niṣe ni arakunrin naa mu nkan ti o o jọ ado oloro atọwọda lọwọ ti awọn ọlọpaa si rọ yika rẹ.
Ninu ifọrọwanilẹnuwo pẹlu BBC, alukoro ọlọpaa nipinlẹ Kaduna Yakubu Sabo, fidi ọrọ naa mulẹ ti o si ni iwaadi ti bẹrẹ lati mọ ibi tarakunrin naa ti wa ati ero rẹ.
''A mu arakunrin kan ti orukọ rẹ njẹ Nathaniel Samuel ninu ile ijọsin Living Faith lasiko ijọsin pẹlu awọn ohun ta furasi pe o jẹ ado oloro atọwọda''
Nigba ti akọroyin wa bere lọwọ rẹ́ẹ boya ọmọ inu ile ijọsin naa nii ṣe, o ni awọn ko ti le sọ ati pe iwaadi ṣi ntẹsiwaju lati mọ boya ara ita ni tabi ọmọ ile ijọsin naa
Gẹgẹ bi ohun ta ri ninu awọn fọnran fidio to wa loju opo Facebook,a ri arakunrin naa to joko sinu ọkọ pẹlu awọn ọlọpaa.
Okada Ban: Ara mi ò yá mọ́ báyìí tórí pé mo rìn lọ gbogbo ibi tí mò ń lọ - Ará Eko
'Ẹ bá wa sọ fún Sanwoolu kó dárí jì wá o, ìpinú tí wọ́n ṣe l'Eko kò m'ọ́gbọ́n wá rárá'
Ikọ iroyin BBC jade si igboro lati fun awn ara ipinlẹ Eko lanfani lati s iriri wọn lnu ọjọ mẹta ti ijọba ipinlẹ eko bẹrẹ ofin ti wn ṣe lati ko gbogbo ọkada ati kẹkẹ maruwa kuro lawọn adugbo kọọkan.
Ṣaaju eyi ọpọlọpọ iṣẹlẹ la ri nigboro ni idahun si igbesẹ ti ijọba ipinlẹ Eko gbe yii.
Iroyin to n tẹ wa lọwọ ni wi pe awọn to n fi ọkada ati kẹkẹ ṣiṣẹ ni agbegbe Ijora nipinlẹ Eko n wọya ija pẹlu awọn ọlọpaa.
A gbọ pe awọn eniyan naa ni dandan ni ki awọn o maa se iṣẹ aje awọn lọ.
Koda, iroyin sọ pe ibọn ti ba awọn eniyan kan, ti wọn si ti gbe wọn lọ sile iwosan.
Ọjọ kinni, oṣu Keji, ọdun 2020 ni ofin ti ijọba ipinlẹ Eko ṣe lati dena lilo ọkada ati kẹkẹ fun ero gbigbe ni awọn agbegbe kan, gbera sọ.
Bakan naa ni awọn kan n fi ẹhonu han ni agbegbe Ikeja, nitori ofin naa.
Ọkada to le ni aadọwa(188) ati kẹkẹ Maruwa mejidinlọgọrin(78) ni ileeṣẹ ọlọpaa ipinlẹ Eko ti gbẹsẹ le lẹyin ti ijọba ipinlẹ Eko fi ofin de ọkada ati kẹkẹ wiwa lawọn ijọba ibilẹ kan jakejado ilu Eko.
Agbẹnusọ fun ileeṣẹ ọlọpaa, Bala Elkana lo fọrọ yii lede ninu atẹjade to fi sita.
Bakan naa ogoji eeyan ti wọn kọ lati pa ofin naa mọ ni ileeṣẹ ọlọpaa ti fi ọwọ ofin mu kaakiri ilu Eko laarin ọjọ Abamẹta si ọjọ Aiku ti eto naa bẹrẹ.
Oríṣun àwòrán, Other
Ọga agba ọlọpaa ipinlẹ Eko, Hakeem Odumosu to ṣaaju awọn ọlọpaa lati ṣe itọpinpin eto naa kaakiri dunnu si bi awọn araalu sẹ pa ofin naa mọ.
Ọgbẹni Odumosu dupẹ lọwọ awọn olugbe ipinlẹ Eko fun ifọwọsowọpọ wọn pẹlu ijọba ati ileeṣẹ ọlọpaa.
Ileeṣẹ ọlọpaa ni awọn yoo tẹsiwaju itọpinpin lati rii wi pe awọn olugbe ipinlẹ pa ofin ti ijọba fi de ọkada and kẹkẹ Maruwa wiwa mọ.
Ẹwẹ, Gomina ipinlẹ Eko, Babajide Sanwo-Olu ti paṣẹ fun ileeṣẹ to n ri si ọkọ akero lati ko ọkọ bọọsi marunlelọgọta jade lati ṣe iranwọ fawọn eeyan to n lọ sẹnu iṣẹ wọn.
Awọn ọkọ akero naa yoo bẹrẹ iṣẹ lonii ọjọ Aje ọjọ kẹta oṣu keji.
Awọn ọna tuntun ti wọn yoo na niyii pẹlu owo ọkọ tawọn eeyan yoo maa san: Ikeja si Ogba(N100), Berger si Ogba(N100), Ikeja si CMS(N200), Oshodi si Ajah(N500), Obalende si Ajah(N250), CMS si Ajah(N250) ati Inner Marina si Ajah(N250).
Gomina Sanwo-Olu ti kọkọ ṣalaye pe ofin to ti wa tẹlẹ ni ijọba ṣe agbekalẹ rẹ pada lẹyin ti ijọba ti kọkọ fofin de wiwa ọkada ati kẹkẹ Maruwa lọdun mẹfa sẹyin.
Sanwo-Olu ni yatọ si wi pe iwakuwa awọn ọlọkada pọ, ijamba ọkada ati kẹkẹ Maruwa ti ran ọpọ lọ si ọrun lairotẹlẹ.
Coronavirus: Àjọ tó ń rí sí ìwọléwọ̀de ní kò s'áàyè f'ẹ́nikẹ́ni tó láárùn yí láti wọlé sí Nàìjíríà
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ajọ to n ri si wiwọlẹ ati jijade si orilẹede Naijiria sọ pe digbi lawọn wa lati dena aarun Coronavirus to n ran kaakiri agbaaye.
Agbẹnusọ fun ajọ naa to ba BBC Yoruba sọrọ, James Sunday ṣalaye pe ajọ to n ri si wiwọle ati jijade lati Naijiria ko ni gba ẹnikẹni to ba laarun Coronavirus laaye lati wọle.
Ọgbẹni Sunday sọ pe ko si ohun ti ajọ naa n lo ju ofin to wa nilẹ lọ lori jijade ati wiwọle si orilẹede Naijiria.
O fikun ọrọ rẹ pe awọn oṣiṣẹ ajọ naa ko fẹ lugbadi aarun coronavirus, eyi lo jẹ ki wọn wa ni igbaradi.
Agbẹnusọ fun ajọ naa ṣalaye siwaju sii pe ọrọ yii kọja ọrọ Naijiria nikan, o ni gbogbo orilẹede lo yẹ ki wọn maa ṣe ayẹwo awọn arinrinajo finifini ki wọn to jẹ ki wọn wọn ọkọ ofurufu lọ si orilẹede mii.
Ọgbẹni Sunday ni ojutu si ọrọ aarun Coronavirus ni pe ki orilẹede kọọkan sẹ eto ayẹwo to mọyan lori eyi ti yoo dena awọn to laarun naa lati maa le rinrin ajo jade silẹ miiran.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ẹwẹ, ajọ kan ti kii ṣe ti ijọba, Thoracic lọ sọ pe o ṣeeṣe ki ewu aarun Coronavirus wu orilẹede Naijiria.
Ninu atẹjade kan ti ajọ naa fi sita, wọn ni Naijiria le wa ninu ewu nitori ọpọ oniṣowo lo wọ Naijiria lati China ti aarun naa ti bẹrẹ.
Ileeṣẹ to n ri si eto ilera lorilẹede Naijiria ni pẹlu ajọṣepọ ajọ agbaye to n ri si eto ilera WHO, Naijiria ti ni ibudo to lee kapa ṣiṣe ayẹwo ẹni to ba ko aarun aṣekupani Coronavirus eyi to bẹrẹ lorilede China.
"Minisita wa loju opo itakun Twitter wọn lati funpe si ẹnikẹni lorilede Naijira to ti lọ si China ni oṣu bii melo sẹyin lati ""ya ara wọn s'ọ́tọ̀ na fun ọjọ́ mẹ́rìnlá ki wọn si pe ajọ to nṣamojuto kikoju aarun NCDC lori nọmba 07032864444."
Testimony Jaga sọ ohun tójú rẹ rí kó tó lè wo ara rẹ̀ láwòdúpẹ́
Kí n máa kọrin Ọlọ́run láàrín àwọn amugbó pé mi ju ìsọjí ńla lọ - Testimony Jaga
Kí n máa kọrin Ọlọ́run láàrín àwọn amugbó pé mi ju kí wọ́n pè mí sí ìsọjí ńla lọ.
BBc Yoruba ba akọrin ẹ́mi ti ọpọlọpọ mọ si Testimony Jaga lalejo nile orin rẹ.
Jaga kẹnu bọrọ, ko fẹ tan mọ tori itan igbesi aye rẹ ko to de ibi to yanju fọwọ tọ ni lọkan gan.
Ǹkan tí ẹ̀mí mímọ́ fi hàn mí kí n tó bẹ̀rẹ̀ orin ìfèdèfọ̀ rèé- Testimony Jaga
Ìdíle olórógún lórí mi yàn nígbà tí mo dé ayé. Ìyawó mẹ́fa, àwa ọmọ 27, láàrín wọn ni mo ti jáde.
"Jaga ni ipo kejilelogun loun wa ninu awọn ọmọ baba oun. O ni ""ìyá mi kò rí mi bí lásìkò tó yẹ kí ó bi mi, Ọ̀tá mi tún kú lọ́jọ́ ìkómọ fún wákàtí mẹ́jọ""."
Iya Woli: Ẹ̀mí ìjókíjó, Wòó, Ṣọ̀kí, Wojú, Ṣàkùṣákù, One Corner...jáde!
Mo ti kó sọ́wọ́ Ọlọ́pàá lọ́pọ̀ ìgbà, SARS, Area G ...iya mi nikan lo maa n wa lẹyin mi  ni  gbogbo igba titi ti Ọlọrun fi ṣeyanu ko to di pe awọn oniroyin gbe mi saye.
Ohun ti Jaga la kọja lo jẹ ko sọ fun Ọlọrun pe bi o ba le ko oun yọ ninu iṣoro, oun a sin in.
Christmas: Jesu ni ọjọ́ ọ̀la àti ibi ìyanu mi- Jaga
Coronavirus: Akẹ́kọ̀ọ́ ọmọ Afíríkà kan tí lùgbadì ààrùn Coronavirus
Fasiti Yangtze ni China ti kede pe akẹkọọ kan to jẹ ọmọ ilẹ Afirika ní orilẹede China, Kem Senou Pavel Darly ti lugbadi aarun Coronavirus o si ti wa nile iwosan.
Gẹgẹ bi atẹjade ti Fasiti  naa fi sita, wọn ni akẹkọọ naa lọ si ile iwosan lọjọ kkandinlogun oṣu kinni nigba to kuro ni Jingzhou.
Wọn ri i pe akẹkọọ naa ni aisan iba, ikọ, igbẹ gbuuru bẹẹ si ni ẹsẹ rẹ ko lagbara pupọ nigba ti wọn ṣe ayẹwo fun un ni ile iwosan.
Latari eyi ni wọn ṣe gbagbọ ti wọn si kede pe o ni aarun Coronavirus lẹyin ọjọ meji ti fasiti naa si ṣa gbogbo ipa wn lati bu ẹrin sẹkẹ r ati ẹbi rẹ ati ọfiisi orilẹede Cameroon ni China.
Ni bayii, ọmọ ọdun mọkanlelogun naa til le jẹun, ara rẹ si wa ni ipo to dara to si balẹ.
Nigba ti wọn ṣawari aarun yii lara rẹ, ti fasiti naa si kede, wọn kọ lẹta si aarẹ Biya  ti Cameroon pe ko ran wọn lọwọ.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ọwọ Gómìnà Makinde làṣẹ wà bóyá a ó fí òfin dé Okada ní Oyo -OYRTMA
A kò ní jẹ́ k'ẹnikẹ́ni tó láàrùn Coronavirus wọlé sí Nàìjíríà- Àjọ tó ń rí sí ìwọléwọ̀de
Ìyàwó ilé lu ọmọ ọkọ rẹ̀ pa ní ìpínlẹ̀ Ogun
'Ẹ bá wa sọ fún Sanwoolu kó dárí jì wá o, ìpinú tí wọ́n ṣe l'Eko kò m'ọ́gbọ́n wá rárá'
O to ọọdunrun ọmọ Cameroon to jẹ akẹkọọ ati oṣiṣẹ ni China to ti funpe si aarẹ Biya ko naw iranwọ si wọn ni ti jijẹ, iboju, ọṣẹ ati pe ko pese nọmba ti wn le tete pe si.
Idi ti orilẹede Cameroon fi kọ lẹta yii si aarẹ Biya ni pe wọn ni awọn ti gbiyanju titi lati kan si ọfiisi wọn to wa ni Beijing ṣugbn to n bọ si pabo.
Ni bayii, awọn akẹkọọ to wa ni ilu Wuhan-Hubei ni ẹru ọjọ iwaju wọn n ba bayii tori wn ko ribi kan si ọfiisi wọn to wa ni China fun iranwọ.
" O n da omi si wa lọkan bi a ba n ri awọn ọmọ orilẹede mii ti wọn n ri iranwọ gba lati ilu wọn. ni bayii, a n wo o bii pe orilẹede tiwa ti pa wa ti.
Ẹwẹ, ijọba ilẹ Cameroon ti sọrọ pe awọn n foju si awọn eniyan wọn to wa ni China bẹẹ si ni ileeṣẹ to n ri si ọrọ abẹnu ki wọn lee wo ohun ti wọn lee ṣe.
'Street Gospel' tí mò ń kọ, Ọlọ́run ń fi tún ayé àwọn 'Boys' ṣe gan - Testimony Jaga
Gómìnà Makinde ló lè pàṣẹ bóyá kí a gbà okada wọlé tàbí kí a fòfin dè wọ̀n l'Òyó
Oríṣun àwòrán, OYRTMA
Lara ohun ti yoo tẹyin aṣẹ ijọba ipinlẹ Eko lati fofin de lilo okada ati keke Napep lawọn ijọba ibilẹ kan ni pe awọn ọlọkada naa yoo kẹru wọn lọ si awọn ipinlẹ to sumọ Eko.
Ipinlẹ Ogun ati Oyo ni awọn to wa ni tosi Eko ti o si ṣeeṣe ki pupọ wọn ti gunlẹ sibẹ bi a ṣe n sọrọ yii.
O ri bẹẹ ko ri bẹẹ, ajọ to n dari eto irina nipinlẹ Oyo OYRTMA ti tẹnumọ ipinnu wọn lati mojuto apọju awọn kẹkẹ ọkada ati lilo awọn ọkada nipinlẹ naa.
Alaga ajọ naa, Akin Fagbemi ni o fi ọrọ yii to awọn akọroyin leti nilu Ibadan.
Fagbemi ni ajọ naa n fi tọkan tọkan reti igbesẹ ati aṣẹ lati ọdọ Gomina Seyi Makinde boya awọn naa yoo fofin de lilo ọkada tabi ki wọn ma lo ni ipinlẹ ọhun.
''Ko ba wa lojiji pe awọn ọkada yoo ya wọ Oyo lati Eko ṣugbọn digbi la wa lati koju ipenija yii''.
O ni lootọ ni pe awọn a ma gba awọn ajoji lalejo ṣugbọn ti o ba ti di wi pe yoo ṣakoba fun aabo tabi awọn ohun amayedẹrun ilu, awọn ko ni ma ṣalai gbe igbesẹ to yẹ.
Fagbemi tun tẹsiwaju pe awọn ti n ṣe eto lati ni akojọpọ orukọ awọn ọlọkada, oni kẹkẹ Napep ati awọn ọlọkọ ero nipinlẹ naa.
Oríṣun àwòrán, others
Okada Ban: ọjọ kini oṣù keji ni òfin tuńtun yóò bẹ̀rẹ̀
O ni igbesẹ yi yoo jẹ ki o rọrun fawọn lati le mọ awọn ọkọ ti wọn ba jigbe ati lati le ni ounka iye awọn ijamba ọkọ to ba waye.
Báyìí ni akẹ́kòó mẹ́tàlá ṣé kàn àgbákò ikú lásìkò ijáde nílé ẹkọ ní Kenya
Oríṣun àwòrán, NATION MEDIA
Awọn akẹkọọ kan ti ku ti awọn ọgbọn miran si farapa lasiko wọduwọdu to waye nile ẹkọ alakọbẹrẹ kan ni iwọ oorun Kenya.
Iroyin to tẹwa lọwọ sọ pe awọn akẹkọọ naa n sare jade kuro ni kilasi wọn ni igba ti asiko ilọle to laago marun un irọlẹ.
Akọroyin BBC jabọ pe, awọn akẹkọ kan jabọ lati oke kẹta ile ẹkọ alakọbẹrẹ Kakamega Primary School.
Awọn akọroyin lagbegbe naa ṣe afihan bi awọn obi ati mọlẹbi ti ṣe peju si inu ọgba ile iwosan Kakamega lati gbọ iroyin nipa awọn ọmọ wọn.
Iku awọn ọmọ yi tunbọ pe akiyesi ara ilu si bi ko ti ṣe si aabo to peye fun awọn akẹkọọ ni ile ẹkọ Kenya.
Lọdun to kọja ni awọn akẹkọọ mẹjọ padanu ẹmi wọn ti mọkandinlaadọrin si farapa nigba ti ile ti wọn fi n ṣe ile ẹkọ kan wo lulẹ ni Nairobi.
Oyo LG Crisis: Olamiju Akala ní àwọn èèyàn òun sì ń gba ìtọ́jú lọ́wọ́ nílé ìwòsàn lórí wàhálà náà
Oríṣun àwòrán, Adebayo Alao-Akala
Ọlamiju sọ pe oju ọna ibiiṣẹ ni oun wa nigba ti awọn ọmọ ẹgbẹ PDP kọlu awọn alatilẹyin oun.
Irọ ni pe awọn alatilẹyin mi lo kọkọ kọlu awọn ọmọ ẹgbẹ PDP nilu Ogbomọṣọ l'ọjọ Aje."""
Eyi ni ọrọ ti ọkan lara awọn alaga kansu, to tun jẹ ọmọ gomina ipinlẹ naa tẹlẹ, Alao Akala, eyiun Olamiju Akala, ti gomina ipinlẹ Oyo, Seyi Makinde le kuro lori oye, sọ̀,
Olamiju sọ fun BBC Yoruba pe, awọn ọmọ ẹgbẹ PDP lo kọkọ kọlu awọn.
"O sọ pe ""Awọn ni wọn sapamọ sibikan ti wọn si kọlu wa, lasiko ti mo n lọ si ibi iṣẹ gẹgẹ bi alaga nitori pe ile ẹjọ dajọ pe emi ni."
Bí wọ́n ṣe dá mi padà sípò alága kò ní nkan ṣe pẹ̀lú bàbá mi - 'Juwọn Akala
"Oju ọna la wa nigba ti wọn kọlu wa. Koda bi mo ṣe n sọrọ lọwọlọwọ, awọn eniyan wa wa ni ileewosan."""
Oríṣun àwòrán, Others
O tẹsiwaju pe iṣẹlẹ naa jẹ kayeefi fun oun, to si jẹ eyi to yanilẹnu pe, iru nkan bẹẹ le waye ni ipinlẹ Oyo.
"Ni ti ọmọ ẹgbẹ oṣelu Peoples Democratic Party ti gomina yan lati rọpo Akala, Ibrahim Ajagbe, o ni ki akọroyin wa o pe oun pada nitori pe ""oun wa ni ipade""."
Ni kete ti a ba ri Ajagbe ba sọrọ, ni a o mu ẹkunrẹrẹ wa fun yin.
Ọkunrin kan ti orukọ rẹ n jẹ Isah Azeez lo gbẹmi mi nigba tawọn alatilẹyin awọn alaga ti wọn da duro kọlu awọn alatilẹyin awọn alaga afunsọ ti ijọba Gomina Seyi Makinde yan.
Ọgbẹni Azeez ni a gbọ pe wọn yinbọn pa nigba tawọn alatilẹyin awọn alaga ti wọn da duro, fẹ fipa le alaga afunsọ kuro lọfiisi rẹ.
Agbẹnusọ fun ileeṣẹ ọlọpaa ipinlẹ Oyo to fidi iṣẹlẹ naa mulẹ, Gbenga Fadeyi ṣalaye pe, wọn gbe Azeez digbadigba lọ si ile iwosan Bowen l'Ogbomoṣo, amọ ẹpa ko boro mọ.
Oríṣun àwòrán, Others
Ọpọ eeyan to mori bọ ninu iṣẹlẹ naa ni wọn farapa yanna-yannaa nibi ti wọn ti n sa asala fun ẹmi wọn.
Ija bẹ silẹ lẹyin tawọn alaga ẹgbẹ oṣelu APC to lọ si ijọba ibilẹ Surulere lọsẹ to lọ, tun pada si ọfiisi ti wọn si ba alaga PDP ba nibẹ.
Ṣaaju rogbodiyan yii lawọn janduku ti dana sun ọkọ ati alupupu nijọba ibilẹ ariwa, guusu ati aarin gbungbun Ogbomoṣọ.
Agbẹnusọ fun ileeṣẹ ọlọpaa ipinlẹ Oyo, Ọgbẹni Fadeyi ṣalaye pe, awọn eeyan to fara gbọgbẹ si n gbatọju nile iwosan l'Ogbomoso.
Community Policing: Onímọ̀ ètò ààbò ní kìí ṣe ojúṣe ọ̀gá ólọ́pàá láti dá ọlọ́pàá agbègbè sílẹ̀
Oríṣun àwòrán, @NTANewsNow
Ọlọpaa agbegbe, ti ileeṣẹ ọlọpaa Naijiria n gbero lati dasilẹ ko le kẹsẹjari, laijẹ wi pe ijọba ṣetan lati maa fawọn ti wọn fẹ gba ṣiṣẹ lowo.
Onimọ nipa ọrọ eto aabo, Ọgbẹni Richard Amuwa to ba BBC Yoruba sọrọ, lo woye bẹẹ.
Ọgbẹni Amuwa sọ pe awọn ara ilu to ba fẹ ṣiṣẹ ọlọpaa agbegbe, nilo lati gba owo oṣu, bi bẹẹ kọ, wọn ko ni ṣiṣẹ naa tọkantọkan.
Onimọ nipa ọrọ eto aabo tun sọ pe, kii ṣe ojuṣe ọga ọlọpaa lati ṣe eto gbigba ọlọpaa agbegbe.
O ni awọn awọn alaṣẹ ipinlẹ kọọkan lo yẹ ki wọn wa awọn eeyan lawujọ lati ṣiṣẹ ọlọpaa agbegbe, nitori awọn lo mọ awọn eeyan wọn.
Ọga agba ọlọpaa Mohammed Adamu lo paṣẹ fawọn ọga ọlọpaa ipinlẹ kọọkan lati forikori pẹlu awọn ọba alaye atawọn olori awujọ k'eto naa kẹsẹjari.
Ṣugbọn Ọgbẹnu Amuwa ni ọga agba ọlọpaa ko ni ohun kan ṣe pẹlu ọlọpaa agbegbe nitori ko si lọwọ ijọba apapọ.
O fi Gomina ipinlẹ Imo tẹlẹ, Rochas Okorocha ṣe apejuwe ijọba ipinlẹ to ti ṣe agbekalẹ ọlọpaa agbegbe ri.
Ọgbẹni Amuwa ni Rochas forikori pẹlu awọn ọba alaye atawọn olori awujọ lati gba awọn eeyan ṣiṣẹ, bakan ni ijọba rẹ si n fun wọn lowo.
Cancer Survivor: Àìsàn jẹjẹrẹ ọyàn ṣe wò, ta bá tètè ṣe àkíyèsí rẹ̀, ká sì lọ sílé ìwòsàn
O ni ijọba apapọ ati ọga agba ọlọpaa ni Naijiria ko mọ itumọ ọlọpaa agbegbe.
Onimọ nipa ọrọ eto aabo, Ọgbẹni Amuwa ni ko lee si eto aabo to mọyan lori ti ijọba ba kọ lati sanwo fawọn ti wọn fẹ gba gẹgẹ ọlọpaa agbegbe.
Cancer Survivor: Àìsàn jẹjẹrẹ ọyàn ṣe wò, ta bá tètè ṣe àkíyèsí rẹ̀, ká sì lọ sílé ìwòsàn
Cancer Survivor: Àìsàn jẹjẹrẹ ọyàn ṣe wò, ta bá tètè ṣe àkíyèsí rẹ̀, ká sì lọ sílé ìwòsàn
Lẹnu lọọlọ yii, ọpọ obinrin lo n koju aisan jẹjẹrẹ ọyan, ti wọn si n baa lọ.
Amọ obinrin kan ree ti ori ko yọ lọwọ aisan asekupani naa, Arabinrin Bolanle Uwaje, ẹ gbọ alaye rẹ lori ọna to gba to fi bọ lọwọ aisan naa.
Bakan naa lo sọ ohun to yẹ ki awọn obinrin maa se lati bọ lọwọ itiju aisan jẹjẹrẹ ọyan.
Arap Moi: Ọdún mẹ́rìnlélógún ló fi darí Kenya, tó sì di apàṣẹ wàá
Bi itan aye Daniel Arap Moi se lọ ree ninu fidio yii, ẹni to fi ọdun mẹrinlelogun tukọ orilẹede Kenya.
Arap Moi: Ọpọ lo ri ijọba rẹ bii onijẹkujẹ
Orilẹ-ede Kenya ti kede asiko ti ko l'opin fun gbogbo ọmọ orilẹ-ede naa lati ṣọfọ, lẹyin ti aarẹ wọn to pẹ ju lori oye, Daniel arap Moi jade l'aye.
Ileewosan Nairobi lo ku si ni owurọ ọjọ Iṣẹgun, l'oju awọn mọlẹbi rẹ, gẹgẹ bi ikede kan ṣe sọ.
Kenya yoo ṣe ọfọ rẹ lati ọjọ kẹrin, oṣu Keji titi di ọjọ ti wọn yoo sin oku rẹ, botilẹjẹ pe wọn ko ti i kede ọjọ.
Awọn aarẹ ati olori ijọba orilẹ-ede agbaye ti n ba awọn eniyan Kenya kẹdun nitori iku aarẹ wọn tẹlẹ, Daniel arap Moi to jade l'aye ni owurọ kutu ọjọ Iṣẹgun.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Eto isinku lati ọwọ ijọba ni wọn yoo fun aarẹ nigba kan ri ọhun
Aṣoju, Kyle McCarter sọ pe ilẹ America wa pẹlu awọn eniyan Kenya lasiko ti wọn n ṣọfọ.
Aarẹ Uganda, Yoweri Museveni ti kẹdun Daniel arap Moi. O sọ pe Moi jẹ ọ̀kan lara awọn olori ti oun wo ni awokọṣe nigba ti oun wa ni fasiti.
Jane Marriot sọ pe oun ranṣẹ ibanikẹdun atọkan wa si ẹbí ati awọn ọrẹ, ati awọn eniyan Kenya.
Aarẹ tẹlẹ ni orilẹede Kenya, Daniel Arap Moi ti jade laye lẹni ọdun marundin lọgọrun.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Daniel Arap Moi jẹ aarẹ Kenya laarin ọdun 1978 si 2002
Aarẹ Moi lo jẹ aarẹ keji fun orilẹede Kenya lẹyin ti Jomo Kenyata fipo naa silẹ lọdun 1978.
Ọjọ keji, oṣu Kẹsan, ọdun 1924 ni wọn bi Moi.
Ọpọ awọn ti ko gba ti iṣejọba rẹ ri i gẹgẹ bi apaṣẹ wa a, to di ipo agbara mu fun ọdun mẹrinlelogun. Ṣugbọn, awọn to gba tiẹ gbe oṣuba fun un pe o jẹ ki nkan o lọ deede ni orilẹ-ede Kenya.
Ọdun 2002 ni Moi fi ipo silẹ, lẹyin ti ofin de e pe ko tun gbọdọ dije fun ipo aarẹ mọ.
Lasiko to wa ni ipo aarẹ, bi awọn eniyan ṣe bẹru rẹ naa ni wọn gba tiẹ. Bakan naa ni wọn fi ẹsun kan an pe o tẹ ẹtọ ọmọniyan mọlẹ.
Moi lo jẹ ki ẹgbẹ oṣelu o pọ si i ni Kenya l'ọdun 1991, ṣugbọn awọn eto idibo ti wọn ṣe lẹyin naa kun fun mago-mago.
Saheed-Fathia Balogun: Ọjọ́ Karùn-ún oṣù kejì ni wọ̀n bí wọn, tí wọn sì bí ọmọ méjì fúnra wọn
Oríṣun àwòrán, Fathia Balogun
Ọjọ ibi se pataki, o se koko, bẹẹ si ni inu ẹni kii dun ka pa mọra ni ọjọ ibi ẹni.
Bẹẹ ni ọrọ ri lọjọru, ọjọkarun osu keji ọdun 2020 nigba ti tọkọ-taya tẹlẹ, Saheed Balogun ati aya rẹ tẹlẹ, Fathia Balogun dijọ se ọjọ ibi wọn.
Kii wọpọ ki tọkọtaya dijọ maa se ọjọ ibi wọn ni ọjọ kanna, idi si ree ti ọrọ ajọsepọ Saheed ati Fathia fi yatọ pupọ, bi o tilẹ jẹ pe wọn ko jọ gbe papọ mọ.
Oríṣun àwòrán, Saheed Balogun
A wa n ki Saheed ati Fathia Balogun ku oriire ọjọ ibi wọn.
Oríṣun àwòrán, @adedimejilateef
Opin ọsẹ to kọja yii ni gbajumọ oṣere tiata Yoruba, Adedimeji Lateef ṣe ayẹyẹ ọjọ ibi ọdun kẹrinlelọgbọn rẹ loke eepẹ.
Nibi ayẹye naa to waye ladugbo Ikeja, lo ti ṣe ere ori itage ti oun nikan da ṣe, to si danikan ko ipa eeyan mejila ninu ere naa.
Akọle ere ọhun ni  Ọmọ Prime Minister.
Ọpọ awọn akẹẹgbẹ rẹ nidi iṣẹ tiata bii Iyabo Ojo, Femi Adebayo, Bimbo Thomas, Bimbo Oshin ati bẹẹ bẹẹ lọ, lo peju sibi ayẹyẹ ọjọ ibi ọhun, koda, Ọọni Ile Ife wa nibẹ pẹlu.
Oríṣun àwòrán, @adedimejilateef
Ayẹyẹ ọhun dun, gbọngbọn kan si, eyi lo mu omije bọ loju awọn obi rẹ nigba ti wọn pari ajọyọ ọhun.
"Nigba ti Lateef n ṣafihan aworan igba ti awọn obi rẹ domije ayọ loju lori opo Instagram rẹ, o ni ""Iya mi, iya Lati, omije ayọ ni."""
Oríṣun àwòrán, @adedimejilateef
"O tẹ siwaju pe ""Iya mi, iya Oluwasegunfunmi, mo ni ifẹ rẹ mama mi."""
Oríṣun àwòrán, @adedimejilateef
"Lateeef tun kan sara si baba rẹ loju opo Instagram ọhun kan naa, nigba to ni ""Baba mi, baba ti ko gba gbẹrẹ, mo ni ifẹ rẹ gan ni baba mi."""
Bẹẹ naa lo tun kan sara si awọn ibatan rẹ fun aduroti wọn.
ISWAP vs Muric: À kò ni ìbáṣepọ̀ kankan pẹ̀lú àwón agbésùmọ̀mí- Ishaq Akintola
Oríṣun àwòrán, Muric
Ọ̀kan nínú ẹgbẹ́ àwọn Sahara Strategy Group (SSG) ti rọ ìjọba àpapọ láti wádìí àbájáde ẹgbẹ́ Muslim Rights Concern (MURIC)
Wọ́n ní eyí ṣe pàtàkì nítori wọ́n gbá ẹgbẹrun lọ́nà igba dọ́lá lọ́wọ́ àwọn ọmọ ẹgbẹ́ agbésùmọ̀mí  Islamic State For West Africa Province (ISWAP).
San Louis Keita to jẹ olórí ọ̀tẹlẹ̀múyẹ́ ní Mali ló fẹ̀sùn náà kàn lọ́jọ́ Jimọ, ọjọ́ keje, oṣù kẹ̀jọ, ọdún 2020 níbi ìpàdé àwọn oníròyìn kan tó pè ni Abidjan tí i ṣe olúùlú Ivory Coast.
San Louis ní wọ́n gba owó náà láti gba àwọn ọmọ Fulani kéékèké  ti wọ́n n gbé ìhà Ìwọ̀ òòrùn-gúúsù Nàìjíríà.
Ẹ̀wẹ̀, MURIC ti ké gbàjàré pé òun kò mọ ǹkan kan nípa rẹ̀.
Àwọn ẹgbẹ́ ajàfẹ́tọ musulumi náà sàpèjúwe ẹ̀sùn náà bi ìwà ìkà àti irọ́ pọ́nbélé láti inú ọ̀gbùn àìlópin.
Alaafin: Olori Aanu Adeyemi ṣàlàyé ìdí tó ṣe gẹ́ Oba Lamidi Adeyemi ti ìlú Oyo
Èsì MURIC yìí wà nínú àtẹ̀jáde to adári ẹgbẹ́ náà ọjọ̀gbọ́n Ishiaq Akintola fọwọ́ sí lọ́nìí ọjọ́ Isẹgun, ọjọ kọkànlá, osú kẹjọ, 2020.
Àtẹjàdè náà kà báyìí pé:
A ṣe àkíyèsí pé àwọn kan ń ṣe àhesọ ọ̀rọ̀ lórí àwọn ẹ̀rọ àkànsiraẹni káàkiri pe MURIC gbá ẹgbẹ̀rún lọ́nà igba dọ́là lọ́wọ́ ISWAP.
Ìwà ìkà àti ìbanilórúkọ jẹ́ ni, mo sì sọ gbangba-gbàǹgbà pé, a kò tii fi ìgbà kan ké si ISWAP tàbi ẹgbk agbésùmọ̀mí kankan fún ohunkóhun.
Oríṣun àwòrán, MURIC
Ọwọ́ ọlọ́pàá ìpínlẹ̀ Kebbi tẹ bàbá àti ìyàwó rẹ̀ méjì fún pé wọn so ọmọ pọ̀ mọ́ ewúrẹ́ fún ọdún méjì
Ẹgbẹ́ òṣèlú ZLP gbàmí tọwọ́tẹsẹ̀ láti díbò gómínà ní Ondo- Agboola Ajayi
Coronavirus: Ewu wo làwọn òṣìṣẹ́ elétò ìlèra ń kojú ní Nàìjíríà?
Ifẹ̀họ̀núhàn ń lọ lọ́wọ́ ní Belarus lẹ́yìn tí ìdìbò tùn gbé Ààrẹ̀ Lukashenko tó ti wà nípò fún ọdún 26 wọlé
Àjọ JAMB kéde ìlànà ìgbà ni wọlé tuntun fún àwọn ilé ẹ̀kọ́ gíga
Oríṣun àwòrán, @AbujapeopleO
Katsina: Àwọn agbébọn gbẹ̀mí àgbẹ̀ márùndínlógún ní Katsina
Ileeṣẹ ọlọpaa ariwa-iwọ oorun Naijiria ti sọ pe awọn agbebọn ti pa awọn agbẹ marundinlogun labule kan ni ipinlẹ Katsina.
Wọn ni ṣe ni awọn agbebọn naa ti iye wọn to igba bẹrẹ si ni yinbọn awon lu eeyan to n ṣiṣẹ ni oko kan to wa ni abule Yargamiji.
Ko din ni ọgọrun eeyan to ti dero ọrun nipasẹ iru akọlu bẹ ni ipinlẹ ọhun laarin oṣu Kẹrin si oṣu Kẹfa ọdun yii.
Agbẹnusọ ọlọpaa, Gambo Isah sọ fun ileeṣẹ iroyin AFP pe alupupu ni awọn agbebọ ọhun gun lọ ṣe iṣẹ ibi naa.
Iroyin ni ọjọ ti pẹ ti awọn agbebọn ọhun to ṣeṣe ko jẹ darandaran n kọju ija si awọn agbẹ nitori ilẹ ati omi lagbegbe naa.
O ti to nnkan bi ọdun diẹ sẹyin ti ijọba Naijiria ti ni oun yoo wa ojutu si ija laarin awọn darandaran atawọn agbẹ, ṣugbọn kaka k'ewe agbọn ọrọ naa dẹ, lile lo tun n le si.
Oríṣun àwòrán, Other
Obinrin kan, Rabi Rabi'u to gun ọkọ rẹ pa ti ṣalaye pe, ede aiyede to ṣẹlẹ laarin awọn mejeeji lori ta ni yoo kọkọ ti fooni bọ ina lo fa sababi iṣẹlẹ naa.
Rabi, to jẹ iyawo ile sọrọ yii nigba ti ileeṣẹ ọlọpaa ipinlẹ Katsina ṣe afihan rẹ lọjọ Iṣẹgun, pẹlu afikun pe oun ko mọ pe ọkọ oun le gba idi aawọ naa dero ọrun.
O ni iṣẹlẹ naa waye nigba ti ileeṣẹ ina mọnamọna ṣẹṣẹ mu ina de lagbegbe tawọn n gbe, ti esu si lo oun.
Rabi sọ di mimọ pe, ọkọ oun, Shamsu Salisu, ẹni ọdun mẹẹdọgbọn naa fẹ ti foonu tiẹ naa sina nigba kan naa pẹlu oun, eyi to fa aawọ laarin awọn mejeeji.
Amọ obinrin naa ṣalaye pe, Salisu gan lo kọkọ yọ ọbẹ jade, ki oun to gba ọbẹ naa lọwọ rẹ ṣugbọn oun ko mọ pe igbesẹ ọhun ko ni bimọ ire.
Tunde Kelani: Àwa ọmọ Nàíjíríà kò le è bá òyìnbó mọ́ láéláé nínú sinimá ṣíṣe
''Igbeyawo wa ko tii ju ọjọ mọkanlelaadọta lọ, a ṣẹṣẹ n gbero lati bimọ ni, bẹẹ si ni mo nifẹ ọkọ mi,'' Rabi lo woye bẹẹ.
Agbẹnusọ fun ileeṣẹ ọlọpaa ipinlẹ Katsina, Gambo Isah ṣalaye pe, ni bii aago marun un aabọ idaji lawọn gba ipe wi pe, aawọ ti bẹ laarin Salis ati iyawo rẹ labule Almakiyayi.
Isah ni iyawo Salisu gun un lọbẹ kaakiri ara rẹ to fi mọ inu, nigba ti Salisu n sun lọwọ.
Agbẹnusọ fun ileeṣẹ ọlọpaa ni, wọn gbe Salisu digbadigba lọ si ile iwosan nibi to ku si nitori ẹpa ko boro mọ.
Isah ni ileeṣẹ ọlọpaa ri ọbẹ ati aṣọ bẹẹdi ti ẹjẹ wa lara rẹ ninu iṣẹ iwadii wọn.
Coronavirus: Ilé aṣojú-ṣòfin tako kíkó ọmọ Nàìjíríà wálé láti China
Oríṣun àwòrán, Twitter/House of Reps NGR
Ile aṣoju-ṣofin gbona janjan lọjọ Iṣẹgun nigba ti wọn jiroro lori aba lati ko awọn ọmọ Naijiria to wa lorilẹede China wale, nitori aarun coronavirus to n ran kaakiri lorilẹede naa, bi ina inu ọyẹ.
Ṣugbọn lẹyin ọ rẹyin, ile pada fẹnu ko, lati tako aba kiko awọn ọmọ Naijiria to wa ni China wale.
Ohun ti ile sọ ni pe, orilẹede China ni awọn irinṣẹ igbalode nile iwosan ti wọn le fi dena aarun coronavirus ju Naijiria lọ.
Bi adari ile, Femi Gbajabiamila se gbiyanju to lati parọwa fawọn aṣofin pe ki wọn tiẹ gbọ tẹnu aṣofin to mu aba naa wa, Benjamin Okezie, n ṣe ni wọn faake kọri, ti wọn ko si fun un lanfaani lati sọrọ.
Ohun to ya ọpọ lẹnu ni pe, awọn aṣofin meji mii to wa lara awọn to ṣagbatẹru aba naa kọ lati ṣe atilẹyin fun aṣofin Okezie nigba ti ọrọ naa di ede aiyede nile.
Oríṣun àwòrán, Twitter/House of Reps NGR
Ẹwẹ, aṣoju orilẹede China ni Naijiria, Zhou Pingjian sọ pe, ọgọta ọmọ Naijiria lakọsilẹ fihan pe o wa niluu Wuhan ti aarun coronavirus ti bẹrẹ gan.
Ṣugbọn Ọgbẹni Pingjian sọ pe, ko si ọmọ Naijiria kankan to tii lugbadi aarun coronavirus.
Ibadan Fire: Àwọn olùgbé Ibadan,Ṣakí àti Ìséyìn lè bọ sí òkùnkùn biribiri
Oríṣun àwòrán, Other
Ajọ alagbelebu pupa Red Cross ti sọ pe eeyan mẹta to farapa ninu ijamba ina to ṣẹyọ ni ibudo amunawa nilu Ibadan ti n gba itọju.
Akọwe ajọ naa  Ojo Olaleye lo fi ọrọ yi mulẹ fawọn akọroyin nilu Ibadan.
Amọ ṣa o ṣeeṣe ki awọn eeyan agbegbe Ibadan,Saki ati Iṣeyin wa ni okunkun birimu nitori ijamba ina yi to ṣe akoba fẹrọ amunawa ni Ayede.
Oṣiṣẹ ileeṣẹ mọnamọna kan ti ko fẹ ki adarukọ ohun lo ta awọn akọroyin lolobo ọrọ yi.
O ni awọn oṣiṣẹ ileeṣẹ mọnamọna to wa nibiṣẹ lasiko ijamba yi gbiyanju lati pa ina naa ṣugbọn pabo ni igbiyanju wọn ja si.
O ni yatọ si awọn ilu ta darukọ tẹlẹ, Sagamu ati Iwo naa le ma ni ina nitori ẹrọ to n muna wa si adugbo wọn ni ina naa jo.
Lẹyin igbiyanju fun nkan bii wakati mẹta, ni wọn to ribi pana to ṣẹyọ ni ibudo ina mọnamọna nilu Ibadan.
Toun ti bẹẹ, awọn alaṣẹ ko ti ribi fidi ọrọ mulẹ nipa ohun to ṣokunfa ina naa tabi iru akoba ti ṣe.
Alukoro ileeṣẹ to n pin ina ni agbegbe Ibadan, IBEDC, Frank William sọ pe, ibudo amunawa to jona naa kii ṣe tawọn, bi ko ṣe ti ileeṣẹ to n ta ina fawọn to n pin fara ilu,Transmission Copany of Nigeria(TCN).
Ni nkan bi ago meje aarọ ni ina naa ṣẹyọ, ti igbakeji ọga ileeṣẹ panapana nilu Ibadan, Adewumi Moshood  naa si fidi ọrọ mulẹ pe iṣẹlẹ naa waye.
Wọn ko ti sọ boya awọn ara ilu Ibadan ko ni ni ina, nitori ijamba to waye yii.
Ni kete ti a ba ti ri aridaju rẹ, a o ma mu wa si eti igbọ yin.
Oríṣun àwòrán, Other
Ina tun ti ṣeyọ ni ibo ina mọnamọna to wa lagbegbe Ayede ni adugbo Ring Road niluu Ibadan.
Awọn ti ọrọ ṣoju wọn ni, ibugbamu lo kọkọ ṣẹlẹ ni ibudo naa ki ina to tẹ lee.
Ina naa ti da ipaya ọkan silẹ fawọn olugbe agbegbe naa niluu Ibadan bayii.
Ibeere ti wọn si n bi ara wọn ni pe báwo ni wọn ṣe fẹ́ pa iná tó ṣẹ́yọ níbùdó amúnáwá tó wà ní agbegbe Ayede n'Ibadan?
Idi ni pe ọ̀pọ̀ ohun eelo amunawa to wa nibudo naa lo lee maa gbe ẹni to ba sunmọ ibẹ, to si seese ki onitọhun dero ọrun.
Bi o tilẹ jẹ pe awọn osisẹ panapana ti de si ibudo ti ina tii n jo lọwọ naa, sibẹ ko dabi ẹni pe agbara wọn tii ka ina ọhun, lasiko ta n ko iroyin yii jọ.
Tunde Kelani: Àwa ọmọ Nàíjíríà kò le è bá òyìnbó mọ́ láéláé nínú sinimá ṣíṣe
Tunde Kelani: Àwa ọmọ Nàíjíríà kò le è bá òyìnbó mọ́ láéláé nínú sinimá ṣíṣe
Tunde Kelani lasiko to n ba BBC Yoruba sọrọ ninu fidio yii, salaye pe lootọ lo dara kawọn osere tiata maa pa awọn araalu lẹrin, ka da wọn laraya amọ o tun yẹ ki wọn gba ọna miran yọ yatọ si eyi.
Kelani salaye pe oun ati Baba Wande ti pari ija to wa laarin awọn, ti oun si ri baba Wande bii ẹnikan ti Ọlọrun fun lẹbun pupọ lorilẹede yii.
O tun woye pe ko si bi ọmọ Naijiria se lee fi ede elede sọrọ laakaye fun awọn to n wo sinima lai jẹ pe a sọ ede abinibi wọn.
Sotitobire: Ìgbẹ́jọ́ kò le è wáyé mọ́ l‘Ọ́jọ́rùú, wọ́n ṣun síwájú di Ọjọ́bọ̀
Ileejọ ti sun igbẹjọ to waye yẹ ko waye lọjọru siwaju di Ọjọbọ ọla lori ẹsun ijiọmọgbe ti wọn fi kan oludasilẹ ijọ Sotitobire nilu Akurẹ.
Bẹẹ ba gbagbe o ti to ọjọ melo kan ti igbẹjọ naa ti bẹrẹ nipa ẹsun ti wọn fi kan Pasitọ Alfa Babatunde, tii se asaaju ijọ Sotitobi rẹ nilu Akure, lori bi Gold Kolawole, ọmọ ọdun kan se di awati ninu ijọ rẹ.
Nigba ti wọn n se alaye nipa ohun to fa bi wọn se sun ẹjọ ọhun siwaju, awọn osisẹ ileẹjọ sọ fun akọroyin BBC Yoruba to wa nile ẹjọ pe, ijọba ipinlẹ Ondo ti gbe ẹjọ ọhun kuro niwaju ileẹjọ Magistrate lọ sile ẹjọ giga ipinlẹ naa.
Awọn ọmọ ijọ Sotitobirẹ pọ biba nile ẹjọ lati  wa se atilẹyin fun asaaju wọn, ti awọn akọroyin naa ko si gbẹyin pẹlu awọn eeyan miran to wa woran, ti ọpọ ko si mọ pe wọn ti sun ẹjọ naa siwaju.
Sugbọn wọn ko gbe Alfa Babatunde yọju sile ẹjọ rara nitori bi wọn se sun ẹjọ naa siwaju amọ agbẹjọro rẹ, wa nile ẹjọ .
Nigba to n ba BBC Yoruba sọrọ, Olusola Oke, tii se agbẹjọro Babatunde salaye pe, igun olujẹjọ ti sọ saaju lasiko igbẹjọ to kọja pe, awọn ti kọwe ẹbẹ pe ki wọn gbe ẹjọ naa lọ sile ẹjọ giga ipinlẹ naa, idi si ree ti wọn ko fi gbe olujẹjọ wa sile ẹjọ lọjọru.
"Ileasanmi wa fọwọ gbaya pe ""lọjọbọ ni olujẹjọ naa, Alfa Babatunde yoo yọju sile ẹjọ lati tẹsiwaju nidi igbẹjọ rẹ, gbogbo awọn agbẹjọro si ni yoo yọju sile ẹjọ giga naa lọjọbọ naa."""
Tunde Kelani: Àwa ọmọ Nàíjíríà kò le è bá òyìnbó mọ́ láéláé nínú sinimá ṣíṣe
"Ara ilana ileeẹjọ ni bi wọn se gbe ẹjọ naa lọ sile ẹjọ giga nitori oun nikan lo lẹtọ lati gbọ ẹjọ onikoko meji ti wọn fi kan olujẹjọ ọhun, ti igbẹjọ yoo si bẹrẹ ni sansan."""
Charly Boy: Mo faramọ́ bí ìpínlẹ̀ Eko ṣe fòfin de ọ̀kadà!
Oríṣun àwòrán, Instagram
Yanpọn-yanrin naa to bẹ silẹ lọjọru ni ọwọja rẹ tan de Abule Ẹgba, tawọn ọlọpa si n da afẹfẹ tajutaju si awọn eeyan adugbo loju.
Baba isalẹ awọn ọlọkada ni ipinlẹ Eko, Charles Oputa, ti awọn eniyan n pe ni Charly boy ti sọrọ lori bi ijọba ṣe gbẹṣẹlẹ wiwa ọkada ni awọn opopona ati agbeegbe kan ni ipinlẹ Eko.
Charly Boy to bu ẹnu atẹ lu awọn ọlọkada to wa ni ita bayii, sọ wi pe oun faramọ igbeṣẹ ijọba ipinlẹ Eko.
'Area fada’ fi ero rẹ han lori oju opo ikansiraẹni Instagram, lẹyin to sọ wi pe awọn eniyan n woye idi ti oun fi dakẹ lori iṣẹlẹ naa.
Pajawiri ni Charly Boy pe akori ọrọ rẹ oun, wi pe ki awọn eniyan kiyesi ara ni agbeegbe wọn, nitori pe awọn ẹlẹsin jagidijagan ti wọle si ipinlẹ Eko.
O ni iwadii oun pẹlu olori awọn ọlọkada fihan wi pe awọn ti oun ṣe atilẹyin fun tẹlẹ, ti wọn jẹ awọn ti wọn kawe kọ ni wọn wa nibẹ bayii.
Charly Boy ni awọn ọlọkada miran, Shia ni wọn pẹlu awọn miran ti wọn ko tilẹ mọ ẹsin wọn, nitori ọna ti wọn yatọ si ti awọn musulumi miran.
Baba isalẹ awọn ọlọkada naa wa parọwa si awọn eniyan ati ijọba lapapọ lati lo awọn eniyan fun ofintoto fun eto aabo to peye ni ipinlẹ Eko ati Naijiria lapapọ.
Ile iṣẹ ọlọpaa ni ipinlẹ Eko ti ni ọwọ sinkun ọlọpaa ti tẹ awọn ọlọkada mọkanlelogun ti wọn da rogbodiyan silẹ ni agbeegbe Iyana Ipaja ni ipinlẹ Eko.
Oríṣun àwòrán, Others
Agbẹnusọ ileeṣẹ ọlọpaa, Bala Elkana lo sọ ọrọ yii fun BBC Yoruba, lasiko to n sọrọ lori rogbodiyan to sẹlẹ laarin awọn ọlọpaa ati awọn ọlọkada ni agbeegbe naa.
Elkana ni awọn ọlọkada naa lo ṣe ikọlu si awọn ọlọpaa ti wọn n ṣiṣẹ ti ijọba gbe le wọn lọwọ, lati ri pe ko si ọlọkada to n gba awọn opopona ti wọn ti fofin de e ni ipinlẹ Eko, ki awọn ọlọkada ma ṣiṣẹ nibẹ.
Oríṣun àwòrán, Others
O ni igbesẹ awọn ọlọpaa amuṣẹya to ko ọkada wọn ni ibi ti wọn ti n fi ṣiṣẹ naa lo bi wọn ninu, ti wọn fi wa ṣe ikọlu si awọn ọlọpaa to n sọ opopona agbeegbe Iyana Ipaja.
Agbẹnusọ ileesẹ ọlọpaa naa ni ikọlu si awọn ọlọpaa yii ko ba ju bẹẹ lọ, ti ko ba ṣe bi awọn ṣe ran iranwọ si wọn, ti ọwọ ọlọpaa si tẹ awọn mọkanlelogun ninu awọn ọlọkada naa.
Oríṣun àwòrán, Others
Elkana ni awọn n gbe awọn ọlọkada ti ọwọ tẹ naa lọ si ile ẹjọ lati jẹjọ ẹsun ti tapa sofin ijọba, ati ṣiṣe ikọlu si awọn agbofinro ni ẹnu iṣẹ.
Awọn eniyan to fesi loju opo Twitter naa sọ ohun ti oju wọn ri ni agbeegbe naa lasiko ti rogbodiyan yii bẹẹ silẹ.
Amọ awọn ti ọrọ naa soju wọn sọ wi pe awọn ọlọkada naa n fẹhọnu han pe awọn ajọ amuṣẹya naa kọja ibi ti ijọ̀ba ni ki wọn ti mu awọn ọlọkada.
Oríṣun àwòrán, Others
Rògbòdìyàn náà bẹ́ sílẹ̀ lẹ́yìn tí àwọn ọlọ́pàá amúṣẹ́yá gba ọ̀kadà àwọn tí wọ́n rúfin lílo òkadà ní ìpínlẹ̀ Ekó.
Saaju la ti mu iroyin wa pe, rogbodiyan gba agbegbe Iyana Ipaja nilu Eko kan lọsan ọjọru eyi to n waye laarin awọn ọlọpaa ati awọn ọlọkada.
Gẹgẹ bi iroyin naa ti wi, awọn osisẹ ọlọpaa amusẹ nipinlẹ Eko lo n wọ inu ile ladugbo naa lati se awari awọn eeyan to ni ọkada, ti wọn si n gbe ọkada wọn.
Isẹlẹ ọhun to bẹrẹ lopona Raji Rasaki ni Iyana Ipaja lo mu ki wahala naa fọnna soju, tawọn ọdọ si n dana sun taya mọto, bẹẹ ni wsn n gbe idi dina.
Oríṣun àwòrán, Others
Bakan naa lawọn ọdọ ọhun n na igi soke, wọn n ju okuta kaakiri lati fi ẹhonu wọn han, ta si tun n gbọ iro ibọn kikankikan ladugbo naa.
Ọpọ mọto ti okuta ba ni gilaasi wọn fọ, tawọn ero to wa loju popo, paapa awsn to fẹ wọ ọkọ ero ati awọn to ni sọọbu soju titi n sa asala fun ẹmi wọn nigba ti aawọ naa fọnna soju.
Oríṣun àwòrán, Others
Ọkan lara awọn eeyan kan to n gbe ladugbo Iyana Ipaja salaye pe, inu ile lawọn wa lai fi Ọkada awọn sisẹ,  nigba ti wọn osisẹ amusẹya ọhun wọ inu ile kan lọ lati gbe ọkada to wa nibẹ sita.
Oríṣun àwòrán, Others
Yanpọn-yanrin naa si ni ọwọja rẹ tan de awọn agbegbe to mule ti wọn bii Abule Ẹgba, tawọn ọlọpa amusẹya naa si n da afẹfẹ tajutaju si wọn loju.
Tunde Kelani: Àwa ọmọ Nàíjíríà kò le è bá òyìnbó mọ́ láéláé nínú sinimá ṣíṣe
Bẹẹ ba gbagbe, ijọba ipinlẹ Eko ti fofin de fifi ọkada ati kẹkẹ Maruwa se isẹ se lawọn oju popo kan nijọba ibilẹ mọkandinlọgbọn nipinlẹ naa.
Hanged Policeman: Iléeṣẹ́ ọ̀tẹlẹ̀múyẹ́ ní ṣòkòtò ni afurasí ọ̀hún lò láti pa ara rẹ̀
Oríṣun àwòrán, Others
Ọlọpaa kan ti wọn ti mọle lori ẹsun pe o pa eniyan ti fi ọwọ ara rẹ gbẹmi ara rẹ ninu ahamọ.
Iroyin naa ni se ni ọlọpaa ọhun, pokunso ninu ahamọ ti wọn fi si nileesẹ awọn ọlọpa ọtẹlẹmuyẹ CID to wa ni Panti ladugbo Yaba, nilu Eko.
A gbọ pe ọlọpa naa, ti wọn pe orukọ rẹ ni Essien ni wọn gbe wa si ileesẹ ọtẹlẹmuyẹ naa lọjọ Isẹgun to kọja lori ẹsun pe o pa ọkunrin kan nibudo ifọpo Dangote.
Essien, ẹni ti ọwọ tẹ pẹlu awọn eeyan mẹta miran, lawọn ọtẹlẹmuyẹ fọrọ wa lẹnu wo, ti wọn si fi sinu ahamọ fun itẹsiwaju ifọrọwanilẹnuwo wọn.
Amọ, ọtọ ni nkan ti Essien n ro lọkan nitori se lo lo sokoto to wọ sidi lati fi pokun so to si gbẹmi ara rẹ.
Oríṣun àwòrán, PoliceNG
"Ọlọpa kan, lasiko to n gbarata lori isẹlẹ naa ni ""Ọpọ eeyan lo maa n beere pe ki ni idi ti awọn ọlọpa se maa n ni ki afurasi bọ asọ ko to wọ inu ahamọ ti wọn ba fẹ fi pamọ si?"""
Ọkan lara idi ta fi maa n se bẹẹ ree. Afurasi to pa eeyan lee ro pe dipo ki oun la isoro igbẹjọ kọja nile ẹjọ, o kuku san fun oun lati gbẹmi ara oun, idi si ree tawa ọlọpa fi maa n ni ki afurasi bọ asọ, ko to wọ inu ahamọ.
Tunde Kelani: Àwa ọmọ Nàíjíríà kò le è bá òyìnbó mọ́ láéláé nínú sinimá ṣíṣe
Kọmisana ọlọpa nipinlẹ Eko, Hakeem Odumosu, si ti pasẹ pe ki wọn sewadi lẹkunrẹrẹ lori ọrọ naa, ti iwadi nipa isẹlẹ naa si n tẹsiwaju.
Female Genital Mutilation Day: Ọ̀mọ̀wé kan ní obìnrin tí kò bá dá abẹ́ yóò ṣe ìṣekúṣe
Oríṣun àwòrán, María Conejo/BBC
Abẹ dida fun obinrin jẹ aṣa kan ti awọn eeyan ko fi taratara gba tiẹ mọ lawujọ.
Fun ọpọ obinrin ti wọn ti dabẹ fun, pupọ a ma sọ pe bi awọn ba lagbara lati lọ ṣe atunṣe ohun ti wọn ṣe, awọn ko ni gba ki wọn dabẹ fawọn.
Layajọ to n pe ipe si iṣesi yi, BBC Yoruba ba awọn obinrin kan sọrọ ti wọn si sọ irir wọn nipa rẹ.
Arabinrin Adeola(a kan pe wọn ni Adeola lati fi forukọ bo wọn laṣiri) sọ pe iṣẹ abẹ lọdọ tawọn ko mu anfaani kankan ba awọn.
Idi ni pe iṣ abẹ tawọn ṣe ko jẹ ki ọkan awọn maa fa si ibalopọ.
''Mi o ni gba ki eeyan da abẹ fun ọmọ mi obinrin nitori ko da rara.Wọn ṣe fun mi ti mi o si tete mọ pe oun lo n jẹ ki ara mi ma fa si ibalopọ''
''Nigba ti mo beere lọdọ mama mi, wọn ko ri alaye idi ti wọn fi ṣe ṣugbọn atunṣe ko ba mọ.''
Aburu abẹ dida f'ọmọbinrin
Adeola tẹsiwaju pe oun gbiyanju lati mu ki ọkan oun fa si ibalopọ pẹlu lilo awọn ogun ti yoo mu ara oun fa si ibalopọ.
''Mo ti bi ọmọ obinrin meji bayi,akọkọ  ọmọ mi, a ko dabẹ fun. Pẹlu ogo Ọlọrun wọn ko ni dabẹ fun ẹlẹẹkeji naa.''
Ninu iriri ti Iyaafin Modupe tawọn naa sọ fun BBC Yoruba, wọn ni lasiko tawọn fẹ bi ọmọ, idọ ti wọn ge fawọn mu ki asiko ibimọ awọn pẹ.
''Wọn ni lati ge oju ara mi ki igbalaye le wa fun ọmọ mi ni.O mu inira bami ti mi o si ro pe maa jẹ ki wọn dabẹ fun awọn ọmọ temi naa''
Iwaadi fi yewa pe pupọ lawọn awujọ ti aṣa yi ṣi gbalẹ, idi ti wọn fi n dabẹ fawọn obinrin pe orisirisi.
Yala ki wọn ni aṣa ati iṣẹṣe ni tabi kawọn miran ni ko ni jẹ ki obinrin jẹ alagbere ti o ba de ile ọkọ tan.
Imọ ode oni ti fiye wa pe gige adọ obinrin ti wọn ma n ṣe pẹlu abẹ dida yi a ma ṣe ọpọ akoba ju anfaani lọ fawọn obinrin
Se o tọna lati maa da abẹ fun awọn ọmọdebinrin abi bẹẹkọ?
Eyi ni ibeere ti awọn onimọ wa idahun si ninu fidio yii, ti wọn si sọ nipa ohun ti ofin ati asa wi lori dida abẹ fun ọmọbinrin.
Arabinrin Balikis Ọlawọyin tii se olutọju alaisan ni ewu to pọ wa ninu asa dida abẹ fun obinrin loju ẹsẹ ti wsn ba da abẹ fun ati lọjọ iwaju.
Lero ti Ọlalẹyẹ Kayọde, ti ẹka imọ nipa igbagbọ lọgba fasiti Ibadan ni oun fara mọ asa awọn baba wa to ni ọmọbinrin ti wọn ko ba da abẹ fun yoo maa re mọ ọkunrin kiri ni.
Ẹ gbọ ero awọn mejeeji siwaju lati fi idi igbagbọ wọn mulẹ.
Female Genital Mutilation Day: Ọ̀mọ̀wé kan ní obìnrin tí kò bá dá abẹ́ yóò ṣe ìṣekúṣe
Sotitobire: Iléẹjọ́ ṣún ìgbẹ́jọ́ síwájú di ọjọ́ kẹrìndínlógún oṣù Kẹta ọdún 2020
Ile ẹjọ giga tilu Akurẹ ti sun igbẹjọ siwaju lori ẹsun ijọmọgbe ti wọn fi kan olori ijọ Sotitobi rẹ, Alfa Babatunde.
Babatunde, lasiko ti wọn gbe de ọgba ileẹjọ, wọ agbada alawọ eweko, ati obinrin kan ninu ijọ rẹ, ti wọn jọ n jẹjọ, wa laarin awọn osisẹ ọgba ẹwọn to gbe wọn wa sile ẹjọ.
Lasiko igbẹjọ to waye lọjọbọ, adajọ to n gbọ ẹjọ naa faake kọri lati gba oniduro Babatunde, to si ni ki wọn da pada si ọgba ẹwọn.
Ileẹjọ ti wa kede pe oun sun igbẹjọ naa siwaju di ọjọ Aje, ọjọ Kẹrindinlogun osu Kẹta ọdun 2020.
Oríṣun àwòrán, Others
Saaju lati kọ mu iroyin wa fun yin pe, ta ba da ọjọ, ọjọ a pe, ta ba da igba, igba yoo ko, bo si pẹ titi, ogun ọdun n bọ wa ku ọla.
Ọjọbọ tun ni ọjọ ti wọn da pe lati tẹsiwaju ninu igbẹjọ ẹsun ijọmọgbe ti wọn fi kan asaaju ijọ Sotitobire, Alafa Babatunde.
Lọwọ-lọwọ bayii, pitimu nile ẹjọ kun fun awọn akọroyin, ero iworan, awọn agbẹjọro, igun olupẹjọ ati awọn ọmọ ijọ Sotitobire, ti wọn wa se atilẹyin fun asaaju ijọ wọn to n jẹjọ lọwọ, ki wọn si tun foju se mẹrin rẹ lẹẹkan si.
Bẹẹ ba gbagbe, Ọjọru ana ni wọn sun igbẹjọ naa siwaju di Ọjọbọ oni nitori pe ijọba ipinlẹ Ondo gbe ẹjọ ọhun kuro nile ẹjọ Magisireti lọ sile ẹjọ giga.
Olujẹjọ gboogi ninu ẹjọ naa, Alfa Babatunde ko si yọju sile ẹjọ lọjọbọ nitori pe wọn ti sun igbẹjọ naa siwaju amọ awọn agbẹjọro rẹ fọwọ gbaya pe yoo yọju sile ẹjọ loni.
Igba akọkọ si ree ti olujẹjọ naa yoo jọju sile ẹjọ giga nilu Akurẹ nitẹsiwaju ẹjọ naa, bi igbẹjọ naa ba si se waye loni, laa maa mu wa fun yin.
Ẹ ku oju lọna.
Tanker Fire: Eré àṣàpajúdé tí ọkọ́ epo náà sá ló fa ìjàmbá iná ọ̀hún
Oríṣun àwòrán, Lasema
Ọkọ epo miran tun ti gbina ni ibudokọ Abule Ọsun lagbegbe bareke Ọjọọ nilu Eko.
Gẹgẹ bi ajọ to n dide si isẹlẹ pajawiri nilu Eko, LASEMA ti fi idi isẹlẹ naa mulẹ fun BBC Yoruba, ọkọ agbepo naa lo ko eroja disu, ti odiwọn rẹ to ẹgbẹrun mọkanla lita.
Ọkọ agbepo naa, ti wọn ko lee da nọmba rẹ mọ tori o ti jona, ni iwadi fihan pe lasiko ti ọkọ naa n sare asapajude, ni ile epo ẹyin rẹ ja, to si gbina.
Oríṣun àwòrán, Lasema
Ko si ẹmi tabi dukia kankan to fara gba ninu isẹlẹ naa, ti ajọ LASEMA si ti n saayan lati bomi pa ina naa lai jẹ ki ọwọja ina ọhun ran si agbegbe miran.
ALGON Oyo: Àwọn alága káńṣù APC fẹ́ kí ẹjọ́ ọ̀hún tẹ̀síwájú
Oríṣun àwòrán, @MakindeMedia
Ijọba ipinlẹ Oyo ti gbe igbesẹ lati pari rogbodiyan to n waye ni itubi inubi, laarin rẹ ati awọn alaga Kansu, to ni ki wọn lọ rọkun nile.
Agbẹjọro fun ijọba, Akin Onigbinde lo sọ ọrọ naa niwaju adajọ Mashud Abass, nibi igbẹjọ to n lọ lọwọ lori họwuhọwu to bẹ lẹyin idaduro awọn alaga ọhun.
O ni ijọba ti pinnu pe ki wọn lọ yanju ọrọ naa laarin ara wọn, ki alaafia lee jọba nipinlẹ Oyo.
Onigbinde sọ fun adajọ naa pe, wọn yoo pada si ile ẹjọ ti wọn ba kuna lati pari aawọ laarin ara wọn.
Ṣugbọn awọn agbejọro fun awọn alaga ijọba ibilẹ ti wọn da duro, Niyi Akintola ati Kunle Sobolaju sọ pe, igbesẹ yii ko tẹ awọn lọrun.
Wọn ni ile ẹjọ gbọdọ da ẹjọ naa nu, ki wọn to lee pari aawọ naa ni itubi inubi.
Oríṣun àwòrán, Oyo Algon
Lẹyin atotonu awọn agbẹjọro mejeji, adajọ Mashud Abass ki awọn agbẹjọro ku iṣẹ takuntakun, to si ni ki wọn lọ yanju ẹjọ naa laarin ara wọn, ki wọn si tun ri daju pe alafia jọba nipinlẹ Oyo.
Female Genital Mutilation Day: Ọ̀mọ̀wé kan ní obìnrin tí kò bá dá abẹ́ yóò ṣe ìṣekúṣe
Ile ẹjọ ọhun wa sun ẹjọ naa si ọjọ kejila Oṣu Keji ọdun 2020, lati mọ ibi ti ọrọ de duro, bi bẹẹkọ, oun yoo tẹsiwaju lati gbọ ẹjọ naa.
Ọjọ kọkandinlọgbọn oṣu Karun un ọdun 2019 ni gomina Seyi Makinde yọ awọn alaga ijọba ibilẹ naa bi ẹni yọ jiga, to si yan awọn alaga fidihẹ.
Sugbọn awọn alaga naa fẹ fi tipatipa pada ṣẹnu iṣẹ eyi to da rogbodiyan silẹ.
Sim Card Regulation: Amòfin kan ní iye ‘Sim Card’ ta bá ní, kò ní ǹǹkan ṣe pẹ̀lu ìwà ọ̀daràn
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Awọn ọmọ Naijiria kan ti sọ pe, ọrọ iye Kaadi ibaraẹnisọrọ, Sim Card ti eeyan n lo kọ lo yẹ ko jẹ ijọba logun bayii, bikoṣe bi o ṣe maa ṣakoso awọn ileeṣẹ ibanisọrọ.
Ajafẹtọẹni Kunle Wiseman Ajayi lo sọ ọrọ naa fun BBC Yoruba, lẹyin ti minisita fun eto ibaraẹnisọrọ ati ọrọ aje ori itakun agbaye, Isah Pantani sọ pe, ijọba n gbe igbesẹ lati ri dena ki eeyan kan lo ju kaadi ipe mẹta lọ.
Kunle ni oun to yẹ ki ijọba ṣe ni ko ba awọn awọn ileeṣẹ ibanisọrọ wi lori awọn aṣemaṣe ti wọn n ṣe, paapa bi wọn ṣe ma n ja owo awọn onibara wọn ni ijakuja.
Oríṣun àwòrán, Others
O ṣalaye pe, ootọ ni pe awọn eeyan kan n lo ẹrọ ibanisọro lati wu iwa ibajẹ, ṣugbọn ko digba ti ijọba ba gbe gbendeke le oye sim kaadi ti eyan n lo ki eto abo to ṣe dede.
"Ajafẹtọẹni ọhun tẹsiwaju pe ""Awọn eeyan n ṣe oriṣirisi ibajẹ lai lo ẹrọ ibanisọrọ, ko di igba ti wọn ba sọ pe eeyan kan ko gbọdọ lo ju simu mẹta lọ ki eto abo ilẹ wa to ṣenu ire."""
O ni kaka ki ijọba maa fi akoko ṣofo lori iye simu ti eeyan nlo, n ṣe lo yẹ ki ijọba wa nnkan ṣe si iwa jibiti ti awọn ileeṣẹ ibanisọrọ n hu si awọn ọmọ Naijiria.
Ajayi lero pe nnkan to le din iwa ibajẹ ku ni ki ijọba mu aye dẹrun fun awọn eeyan, ki wọn si fi ọrọ siimu silẹ.
Bo tilẹ jẹ pe siimu kan ṣoṣo ni ajafẹtọ ẹni naa n lo, o ni oye owo ti oun n nna lori ẹrọ ibanisọrọ rẹ loṣu le ni ẹgbẹrun un lọna ọgbọn naira.
Oríṣun àwòrán, Others
Amofin agba Dayo Akinlaja ni, labẹ ofin gbogbo ọmọ Naijira ni ẹtọ lati sọrọ bo ṣe wuu, nitori naa, ti eeyan ba ni idi pataki lati ni ju siimu mẹta, ko yẹ ki ijọba sọ pe eeyan ko gbọdọ lo siimu mẹta lọ.
O ni ẹni to ba fẹ wu iwa ọdaran lee huwa ọdaran, bo ba n lo  kaadi ipe kan tabi ju bẹẹ lọ.
Akinlaja sọ pe, iwa ọdaran ko ni nnkan ṣe pẹlu iye siimu ti eeyan n lo.
Female Genital Mutilation Day: Ọ̀mọ̀wé kan ní obìnrin tí kò bá dá abẹ́ yóò ṣe ìṣekúṣe
O ṣalaye pe oun to yẹ ijọba ṣe ni lati maa lo ẹrọ igbalode lati tọpinpin awọn ọdaran, nitori simu kan to eniyan lati ṣe iṣẹ ibi.
"Amofin ọhun pari ọrọ rẹ pe ""Ti eeyan ba ni simu meji tabi mẹta, emi o mọ bi iyẹn ṣe lee din iwa ọdaran ku."""
Nigeria Election: INEC yóò ṣàmúlò ẹ̀rọ ayélujára láti fi gba fọ́ọ̀mù àwọn olùdíje
Oríṣun àwòrán, Facebook/Mahmoud Yakubu
Ajọ eleto idibo lorileede Naijiria, INEC sọ pe awọn yoo se amulo ẹrọ ayelujara lati fi gba fọọmu pada lẹyin tawọn to fẹ ẹ dije dupo ninu eto idibo Gomina ipinlẹ Edo ati Ondo  ba buwọ lu wọn tan.
Ninu iwe asẹ kan ti ajọ naa fi sita lorukọ alaga wọn, Yakubu Mahmood, wọn ni igbesẹ lilo ilana yii lati fi gba fọọmu pada jẹ ọna lati mu adinku ba ewu itankalẹ arun Covid-19.
Bẹẹ naa ni ilana yi yoo kan titọ pinpin iye owo ti awọn ẹgbẹ oselu ba naa fi se ipolongo,  ati iye ti wọn na lati fi orukọ awọn alamojuto eto idibo, ati iwe orukọ awọn asoju ẹgbẹ ransẹ.
Ajọ naa tun sọ pe awọn yoo mu adinku ba iye awọn ti yoo mojuto eto idibo nipasẹ wiwo awọn to sẹ iṣẹ to munadoko ninu eto idibo ti wọn ti se kọja.
''Gbogbo ilana yi wa lati mu adinku ba fifi ara kan ara ẹni, eyi to le mu ki awọn eeyan ko arun Covid-19''
Ba kan naa  ni awọn oludibo ati awọn miran to n kopa ninu idibo naa gbọdọ wọ ibomu ti wọn yoo si ya  ẹnikẹni to ba safihan apẹẹrẹ Covid- 19 sọtọ.
Ẹwẹ, ajọ naa ti la ilana kalẹ fun eto idibo gomina ni ipinlẹ Edo ati Ondo to fi mọ idibo awọn asojuile asofin.
Agbẹnusọ ajọ naa, Aliyu Bello ni idibo awọn ipinlẹ naa yoo waye ni osu Kẹsan ati osu Kẹwa.
''Ki idibo to bẹrẹ awọn eeyan ni lati jinasirawọn lati le fi dẹkun itankalẹ arun naa. Bakan naa ni ajọ wa yoo pese eroja ipawọ 'hand sanitizer', ti ijiya yoo si wa fawọn oludibo to ba tapa si ilana yi.''
Ajọ eleto idibo Naijiria, National Electoral Commission (INEC), ti yọ orukọ ẹgbẹ oṣelu mẹrinlelaadọrin kuro ni Naijiria.
Oríṣun àwòrán, twitter/Inec
Ọga agba INEC ati awọn miran nibi ipade ti ikede naa ti waye.
INEC kede pe marundinlọgọrin ni awọn ẹgbẹ oṣelu ti ko koju oṣuwọn, ṣugbọn ẹyọkan lara wọn, Action People Party (APP) gbe ajọ naa lọ si ile ẹjọ, to si gba aṣẹ to ka INE lọwọ ko lati yọ orukọ rẹ.
Alaga ajọ naa, Mahmood Yakubu to kede igbesẹ naa fun awọn akọroyin nilu Abuja sọ pe yiyọ ti wọn yọ orukọ wọn kuro wa ni ibamu pẹlu ofin Naijiria.
O sọ pe awọn ẹgbẹ oṣelu naa ko koju oṣuwọn to, wọn ko si ni gbogbo nkan ti ajọ naa n beere lọwọ wọn.
Pẹlu igbesẹ ti INEc gbe yii, ẹgbẹ oṣelu mejidinlogun pere lo ku.
Ṣaaju eto idibo gbogboogbo ọdun 2019, ẹgbẹ osẹlu mọkanlelaadọwa (191) lo wa ni Naijiria. Ẹyọkan tun darapọ mọ wọn lẹyin eto idibo na, eyi to sọ ọ di mejilelaadọwa (192).
Ofin Naijiria fun ajọ INEC ni agbara lati yọ orukọ ẹgbẹ oṣelu yoowu kuro l'agbo oṣelu, ti wọn ko ba ni awọn amuyẹ wọnyii:
Ṣugbọn ṣa, idibo sipo gomina ni ipinlẹ Ondo ni INEC kede pe yoo waye ni ọjọ kẹwa, oṣu Kẹwaa, ọdun 2020. Bakan naa ni ti ipinlẹ Edo yoo waye ni ọjọ kọkandinlogun, oṣu Kẹsan, ọdun 2020.
Awọn atundi ibo kan yoo waye ni ẹkun idibo mẹta nitori iku awọn aṣofin kan ni ipinlẹ Niger, Kwara ati Sokoto.
Ọkọ kẹrinla, oṣu Kẹta, ọdun 2020 ni gbogbo atundi ibo naa yoo waye.
Lagos okada ban: Ìwọ́de yóò wáyé pẹ̀lúù àkòrí #OccupyLagos
Oríṣun àwòrán, others
Okada Ban: ọjọ kini oṣù keji ni òfin tuńtun yóò bẹ̀rẹ̀
Oludari #OccupyLagos to n pe fun ifẹhọnu han lori bi ijọba ipinlẹ Eko ṣe gbegile kẹkẹ ati ọkada ti bu ẹnu atẹ lu igbesẹ ijọba.
Ọmọsalewa Badejo ti ni ijọba Eko ko se ohun to dara fun awọn ara ilu nitori iya ati inira lo mu de fun awọn araalu.
'Ẹ bá wa sọ fún Sanwoolu kó dárí jì wá o, ìpinú tí wọ́n ṣe l'Eko kò m'ọ́gbọ́n wá rárá'
Badejọ sọ pe ni ọjọ Satide, ọjọ kẹjọ, oṣu Keji,  ni ifẹhọnu han naa yoo waye ni Eko Atlantic Hotel lasiko ti awọn eniyan ba n ṣe ere sisa maratọọnu to ma n waye ni ipinlẹ Eko l'ọdọọdun.
O ni awọn ti pese eto aabo to peye fun awọn afẹhọnu han ati wi pe ko ni si wahala tabi rogbodiyan lasiko naa nitori awọn yoo sẹ e ni irọwọrọsẹ.
Ọmọsalewa lasiko to n ba BBC sọrọ sọ pe ibanujẹ ọkan lo jẹ fun oun lati ri iya ati ọmọ to n sunkun, nigba ti wọn n fi ẹsẹ rin lọ ni oru nitori ko si ọkọ, bẹẹ ni sunkẹrẹ fakẹrẹ ọkọ peleke si ni ipinlẹ Eko.
Oludari #OccupyLagos ni awọn kọ igbesẹ ijọba nitori o yẹ ki wọn pese ọna miran lati koju aisi ọkada tabi kẹkẹ fun awọn eniyan lati lo, ki wọn to ko wọn kuro nilẹ.
O ni ko bojumu ki ijọba má pese eto irinna to gbooro fun awọn araalu, ki wọn tun fi iya jẹ wọn nitori wọn yoo pẹ de ibi iṣẹ wọn, eleyii ti o le e mu wọn ma ṣe bo ti tọ ni ibi iṣẹ.
Badejo wa rọ ijọba lati tun ero wọn pa, ki wọn si da kẹkẹ ati ọkada pada si igbooro lati mu irọrun ba awọn eniyan ni ipinlẹ Eko.
Lori ọrọ wi pe ọpọlọpọ awọn ọlọkada naa lo n sare asapajude, arabinrin naa ni ijọba lẹtọ lati la wọn lọyẹ lori bi o ṣe yẹ ki wọn ṣe loju popo.
Bakan naa ni o fikun wi pe, nitori sunkẹrẹ fakẹrẹ ọkọ ni ipinlẹ Eko to ti buru si, ijọba gbọdọ tun awọn oju ọna ṣe, ki wọn si pese oju ọna reluwe ti yoo ma a gbe awọn eniyan.
Oludari #OccupyLagos ni ti ijọba ba pese awọn eto yii , igbe aye awọn eniyan  a tunbọ dara si, eleyii ti yoo mu igbeleke ba ipinlẹ Eko.
Operation Amotekun: Amọ̀tẹ́kùn ṣetán láti gbérasọ, fọ́ọ̀mù ìgbaniṣíṣẹ́ ti dé!
Oríṣun àwòrán, @DAWNCommission
Ohun to ba ti ya kan, kii pẹ mọ, fọọmu igbaniṣiṣẹ fun ẹṣọ alaabo lawọn ipinlẹ Yoruba, Amọtẹkun yoo jade lọsẹ to n bọ.
Gomina ipinlẹ Ondo, Rotimi Akeredolu lo fọrọ yii lede lati ẹnu oludamọran rẹ lori ọrọ aabo, Alhaji Jimoh Dojumo.
Gomina Akeredolu ṣalaye pe gbogbo eto lo ti to bayii lati gbe fọọmu naa sita.
''Awọn ọba alaye atawọn olori awujọ ni yoo ṣe oniduro fawọn eeyan wọn to ba fẹ darapọ mọ ẹṣọ alaabo Amọtẹkun,'' Akeredolu lo ṣalaye bẹẹ.
Laipẹ yi ni awọn gomina guusu iwọ oorun ṣepade pẹlu igbakeji aarẹ, Yemi Oṣibajo ati agbẹjọro agba ni Naijiria, Abubakar Malami lati sọ asọyepọ lori eto naa.
Malami ti kọkọ sọ pe, eto Amọtẹkun tawọn gomina ipinlẹ Yoruba gbe kale ko si ninu iwe ofin Naijiria.
Ọpọ awọn ilumọọka agbẹjọro atawọn ajafẹtọ omoniyan lo ti ṣatilẹyin fun eto Amọtẹkun lẹyin ti tako agbekalẹ eto naa.
Ọjọ kẹsan an oṣu kinni lawọn gomina ilẹ Yoruba ṣe agbekalẹ Amọtẹkun ni olu ilu ipinlẹ Oyo, Ibadan.
Ibadan Chieftancy Tussle: 'Ọba Balogun ní Olubadan kò le è lé àwọn kúrò nílùú láéláe
Oríṣun àwòrán, Facebook/High Chief Lekan Balogun
Aawọ to wa laarin Olubadan ti ilẹ Ibadan, Ọba Saliu Adetunji atawọn Ọba ilu Ibadan tun ti gba ọna mii yọ.
Ọjọbọ tii ṣe ọjọ kẹfa oṣu keji ọdun yii ni Olubadan fi atẹjade kan sita, ninu eyi to ti sọ pe n ṣe loun ko ba le awọn Ọba mọkalelogun kuro nilẹ Ibadan, ti oun ba tẹle ohun ti ọpọ ọmọ ilẹ Ibadan n sọ.
Amọ ọkan lara awọn Ọba mọkalelogun, Lekan Balogun to ba BBC Yoruba sọrọ ṣalaye pe, isọkusọ gbaa ni Olubadan n sọ, ko si si ẹni to dan iru rẹ wo ri.
Ọba Balogun ni Olubadan ko lagbara bii ti wulẹ ko mọ, lati le awọn Ọba Ibadan kuro nilẹ Ibadan.
Balogun ni o ti le logoji ọdun ti oun ti wa lori oye niluu Ibadan, bẹẹ ni oun ko ti ri Olubadan to dan iru rẹ wo ri.
''Lati ọdun 1863 lawọn baba nla temi temi ti wa niluu Ibadan, wọn jọ tẹ Ibadan do ni, ẹba ọdan ni wọn n pe nigba naa, nitori naa ko si ẹni to le le mi kuro ni Ibadan,'' Oloye Balogun lo sọ bẹẹ.
O fikun ọrọ rẹ pe, awọn Ọba mọkalelogun gan an lo lagbara lati yọ Olubadan nipo, Olubadan ko lagbara lati yọ awọn Ọba ilu Ibadan.
Oríṣun àwòrán, Facebook/Olubadan of Ibadan
Balogun sọ di mimọ pe, awọn eeyan kan ni wọn n ti Olubadan lati ṣe ọpọ ohun to n ṣe, kii ṣe wi pe Olubadan fun ra rẹ gan lo n daa ṣe awọn ohun to n ṣe.
"O ni ""danwo lo bi iya ọkẹrẹ, ti Olubadan ba sọ pe oun fẹ le awọn Ọba mọkalelogun, a jẹ wi pe o fẹ pin Ibadan si meji niyẹn, oun si lo maa jọba lori eyi to kere ju, ti ilẹ Ibadan ba fi pe meji."
Olubadan sọ ninu atẹjade to fi sita l'Ọjọbọ pe, awọn Ọba mọkalelogun yaju si itẹ oye Olubadan, ninu lẹta ti wọn kọ ranṣẹ si oun lọjọ kẹtadinlọgbọn oṣu kinni ọdun.
Ṣugbọn Oloye Lekan Balogun ni ko si ohun to buru kankan ninu iwe tawọn fi ṣọwọ si Olubadan, o ni awọn kan pe akiyesi rẹ si awọn nnkan kan to ṣe, ti ko dara ni.
UI Bursar: Alákoso owó ní Olùyẹ̀wé owó wò wa fọ́ lójú nígbà tó ń ṣe ìṣirò báa ṣe náwó
Oríṣun àwòrán, @willamazen
Alakoso owo Fasiti ilu Ibadan, Micael Alatise ti sọ nile aṣofin kekere pe Fasiti naa ko fi iwe iṣuna rẹ ransẹ si ile ọhun latari pe oluyewe owo to yẹ ko ṣe iṣẹ naa fọ loju lẹnu iṣẹ.
Alatiṣe lo sọ ọrọ naa niwaju igbimọ to n ri si bi awọn ileeṣẹ ijọba ṣe n na owo, ti aṣojuṣofin Oluwole Oke jẹ alaga rẹ.
O ni idi ti Fasiti Ibadan ṣe kuna lati fi eto bi o ṣe nawo ṣọwọ si oluyẹwe owo wo ijọba ni pe, oluyẹwe owo wo to yẹ ko ṣe iwe naa fọ loju lẹnu iṣẹ, to si ku lẹyin naa.
Esi yii jẹ iyalẹnu fun awọn aṣofin nitori pe oluyẹwe owo wo ti wọn n sọ nipa rẹ ọhun ṣi n gba owo iṣẹ titi di ọdun to kọja.
Ọrọ ọhun kọkọ pa awọn aṣofin lẹrin, ṣugbọn wọn koro oju lẹyinorẹyin lori awijare alakoso owo Fasiti naa.
Awọn aṣofin naa wa n bere pe, ti oluyẹwe owo wo Fasiti ọhun ba fọ loju, ṣe  gbogbo ileeṣẹ rẹ lo fọ loju ni, ti ko ṣe fi iwe bo ṣe nawo ranṣẹ lati nnklan bi ọdun mẹwaa sẹyin.
Wọn ni ti ọga ileeṣẹ to n yẹwe owo wo ba fọ loju, ko yẹ ki iṣẹlẹ naa da iṣẹ ijọba duro.
Alaga igbimọ ọhun, Oluwole Oke wa pe fun iwaadi kikun lori ileeṣẹ naa, ati iwaadi to jinlẹ lori bi iṣu ṣe ku ti ọbẹ si bu lori eto iṣuna Fasiti naa.
Parties Deregulation: Olapade Agoro ní INEC kò fi tó àwọn léti pé ó fẹ́ wọ́gilé 74 ẹgbẹ́ òṣèlú
Oríṣun àwòrán, @InecNews
Lara awọn ẹgbẹ oṣelu ti ajọ  eleto idibo Naijiria, INEC yọwọ wọn kuro lawo eto oṣelu Naijiria ti sọ pe, wọn ko faramọ igbẹsẹ ti INEC gbe.
Alaga ẹgbẹ oṣelu National Action Council, NAC , ọmọwe Olapade Agoro, sọ pe ohun to yẹ ki ajọ INEC ṣe ni ko kọkọ yọ ọwọ ara rẹ kuro lawo iṣakoso ẹgbẹ oṣelu Naijira, nitori ọwọ rẹ gan ko mọ.
O ni ọpọlọpọ awọn oṣiṣẹ ajọ ọhun ma n gba riba lasiko idibo, ki wọn lee gbe are fun ẹlẹbi ninu esi idibo.
Ọjọgbọn ọhun ni o jẹ ohun to yanilẹnu pe, nigba idibo, ẹgbẹ PDP ati APC nikan lo ma n ko ibo to le ni ogoji miliọnu, nigba ti awọn ẹgbẹ yoku bii aadọta, maa ni ibo perete.
"Agoro sọ fun BBC pe, ""Nnkan ti INEC ṣe ko dara rara fun itẹsiwaju ijọba tiwantiwa ni Naijiria."""
O ni ajọ INEC ko fi to ẹgbẹ oṣelu NAC leti pe, o ti yọ orukọ rẹ kuro lara awọn oṣelu titi di igba to kede fun awọn oniroyin.
Oríṣun àwòrán, Olapade Agoro
Olapade Agoro ni o yẹ ki alaga ajọ INEC, Mahmood Yakubu kọwe fipo silẹ
"O ṣalaye pe ""Ṣe ori ẹrọ asọrọmagbesi lo yẹ ki a ti gbọ pe INEC ti yọ orukọ wa ni? Ko si ijọba tiwantiwa lorilẹ-ede yii rara."""
Agoro pari ọrọ rẹ pe, o yẹ ki alaga ajọ INEC, Mahmood Yakubu kọwe fipo silẹ fun iwa aibọwọ fun ẹtọ ọmọniyan to wu, lori igbeṣẹ naa.
Fatai Ibu Owo to jẹ alaga ẹgbẹ oṣelu National Conscience Party , NCP ipinlẹ Eko sọ fun BBC pe, igbeṣẹ ti INEC gbe ki n ṣe igbeṣẹ to ba ofin mu.
Oríṣun àwòrán, Fatai Ibu Owo
O ṣalaye pe, igbeṣẹ naa dabi ẹni to yin agbado ṣeyin awo ni, nitori ṣaaju ni awon ẹgbẹ bii mẹtalelọgbọn ti gbe INEC lọ ile ẹjọ lodi si igbeṣẹ naa.
O fikun pe ṣugbọn INEC gbe igbesẹ yii nigba ti ẹjọ naa ko tii pari.
Fatai sọ pe ko si ẹni to lagbara lati pa ẹgbẹ oṣelu kankan rẹ nitori ofin faaye gba ọmọ Naijiria lati ṣe ẹgbẹ oṣelu.
"O ni ""Ko yẹ ki a maa ni ara wa lara lorilẹ-ede yii, ni ṣe lo yẹ ki ijọba fun onikuluku laaye lati ṣe ẹgbẹ to wuu."""
Dementia: Máṣe pe arúgbó rẹ ní àjẹ́ tàbí wèrè torí pé làákàyè rẹ̀ ń ṣíṣẹ kíṣẹ́ lọ́jọ́ ogbó
Dementia: Máṣe pe arúgbó rẹ ní àjẹ́ tàbí wèrè torí pé làákàyè rẹ̀ ń ṣíṣẹ kíṣẹ́ lọ́jọ́ ogbó
Lorilẹ Afirika, ọpọ idẹyẹsi lawọn ọdọ maa n se sawọn arugbo wọn to ba ni arun to nii se pẹlu ọjọ ogbo eyi to n mu ki ọpọlọ wọn se isẹkisẹ, taa mọ si Dementia.
Ọpọ wọn lo n pe awọn arugbo to n tọ sara, gbagbe nkan, tabi ki ọrọ wọn ma ba taye mu, ni were ati ajẹ, eyi ti ko dara.
Ninu fidio to n lanilọyẹ yii, awọn olutọju arugbo kọ wa ni awọn ohun to yẹ ka se lati setọju awọn arugbo yii, ki ọjọ alẹ wọn lee rọrun fun wa.
Iyabo-Fathia Fracas: Ojo ní ohun tó ń ṣẹlẹ̀ lágbo tíátà wa kọjá àhesọ tẹ́ ń gbé kiri, ó jinlẹ̀, ọ̀rọ̀ ẹ̀mí ni
Oríṣun àwòrán, Instagram/iyaboojofespris
Egbirin ọtẹ lọrọ awọn isẹlẹ to n waye lagbo isẹ tiata lẹnu lọọlọ yii, baa ti n pakan, ni omiran n ru.
Eyi ko sẹyin gbọnmisi omi oto to maa n waye laarin awọn osere tiata, paapa awọn obinrin wọn, to si maa n fa gbodo n rosọ.
Lọdun to kọja, bẹẹ ba gbagbe, aawọ ja ranin-ranin nilẹ laarin Toyin Abraham ati Lizzy Anjorin, to dogun, to dọdẹ, koda ọrọ naa de ọdọ ọlọpa ati awọn asaaju isẹ tiata pẹlu, ki wọn to bomi pana rẹ.
Sugbọn o dabi ẹni pe awọn osere tiata lobinrin miran tun ti n palẹ ogun mọ, ti aawọ miran tun ti n rugbo bọ laarin awọn ilumọọka kan laarin wọn, paapa ta ba wo bi wọn se n sọ oko ati ogulutu ọrọ si ara wọn loju opo Instagram awọn ti ọrọ naa kan.
Oríṣun àwòrán, Iyabo Ojo
Iyabọ Ojo lo kọkọ kọ nkan loju opo Instagram rẹ, eyi to fi n pa asamọ si akẹẹgbẹ rẹ kan lagbo tiata to n se ọjọ ibi lọjọ lọjọru, ọjọ karun osu keji , bi o tilẹ jẹ pe ko darukọ onitọun.
Oríṣun àwòrán,   Iyabo Ojo
Amọ wọn ni olowe lọrọ n ba wi, ẹni to ba si wo atupalẹ ọrọ naa yoo mọ pe Fathia Balogun ni obinrin kansoso to se ọjọ ibi lọjọ naa, bi o tilẹ jẹ pe oun ati ọkọ rẹ, Saheed Balogun ni wọn dijọ see.
Iyabọ Ojo, ẹni to ki gbogbo awọn ọkunrin yoku to se ọjọ ibi lọjọ naa ni ko ki Fathia Balogun amọ dipo bẹẹ, ohun to kọ soju opo Instagram rẹ niyi dabi owe to fi n sọko ọrọ si onitọun.
Dementia: Máṣe pe arúgbó rẹ ní àjẹ́ tàbí wèrè torí pé làákàyè rẹ̀ ń ṣíṣẹ kíṣẹ́ lọ́jọ́ ogbó
 Gbogbo igba lo maa n ba mi lojiji amọ ọrọ rẹ ko ya mi lẹnu nitori pe iwọ ni agbaaya akọkọ ni agbo tiata Nollywood..., o ko bọwọ fun ara rẹ rara, o maa n jowu awọn akẹẹgbẹ rẹ to kere si ọ, to si maa n dibọn bii ẹni pe o nifẹ awọn to n ri anfaani kan abi omiran lara wọn sugbọn lẹyin o rẹyin, o kii jẹ olotitọ si wọn, o si kuku si maa tẹ bọ ni.
"Iyabo tẹsiwaju pe ""Lẹyin gbogbo nkan ti mo se fun ọ lọdun meji sẹyin nigba ti mo se ayẹyẹ ọjọ ibi rẹ fun ọ ni orilẹede Turkey, o tun lọ tẹnu-bọlẹ lẹyin mi fun awọn akọroyin pe mo daku fun ọjọ mẹta! O fẹ ki n ku tori pe o mọ pe mo sisẹ abẹ, mo mọ pe o n reti pe maa ku...idi ree ti o ko fi wa ki mi lẹyin naa sugbọn Ọlọrun mi ju ọ lọ, o lagbara ju ẹ lọ, Ọlọrun mi ja iwọ ati ikọ rẹ kulẹ, mo si wa laaye."""
Oríṣun àwòrán,  Iyabo Ojo
 Ajẹ ni ẹ o, abo kiniun ni mi, to maa n bori ogun lọjọkọjọ, ko si bo se tiraka to lati fa mi walẹ tabi ba orukọ mi jẹ ninu ẹmi... imọlẹ ati okunkun ko le duro sibi kannaa, mo si ni igboya lati sọ fun ẹ pe, eeyan buruku ni ẹ, pada lẹyin mi Ajẹ. Ma gbadun ayẹyẹ ọjọ ibi rẹ ni Islandlounge7, ko si ranti pe, emi ni mo sọ bẹẹ.
Wayi o, oniruuru itumọ ni awọn eeyan ti ba Iyabọ wa si ọrọ rẹ yii, ti ọpọ wọn si ni Fathia Balogun lo n ba wi tori pe oun lo se ayẹyẹ ọjọ ibi ọdun kọkandinlaadọta rẹ ni Turkey lọdun 2018 pẹlu Iyabọ Ojo.
Oríṣun àwòrán, Iyabo Ojo
Ọpọ eeyan lo ti wa n beere pe ki lo faa ti tirela fi gba aarin awọn tẹgbọn-taburo ati ọrẹ yii kọja, amọ awọn eeyan miran ni ija wọn lo seese ko ni nkan se pẹlu pe, wọn gba ọkunrin mọ ara wọn lọwọ.
Sugbọn Iyabọ tun ti kede loju opo Instagram rẹ bayii pe laelae, ohun ti yoo gbẹyin ti ohun lee se ni lati maa du ọkunrin, boya o ti niyawo ni abi bẹẹkọ, mọ obinrin kankan lọwọ, nitori ko jọ rara, ma kan kọti ikun si onitọun ni.
"O fikun pe ""Ohun to n sẹlẹ lagbo tiata wa kọja gbogbo ahesọ ọrọ tẹ n kọ kiri, o si kọja ohun to lee ye yin, huu, o jinlẹ gan ni ooo... o ti n waye lati aye papa Ogunde, yoo si maa wa bẹẹ titi laelae ni, ko si seese ki eeyan mura silẹ de, amọ bo ba se n gbona si, mo ti mura silẹ."""
Too, Ọlọrun nikan lo tun mọ ibi ti eyi to tan de, BBC Yoruba fọwọ lẹran, o n woye ohun to n waye lagbo tiata.
Lagos Okada ban: Àwọn àkàndá ẹ̀dá ní àwìn làwọn gba kẹ̀kẹ́ táwọn fi ń jẹun
Awọn akanda ti fẹhọnu han tako ijọba Eko lori fifi ofin de maruwa ati ọkada.
Ọrọ bi ijọba ipinlẹ Eko se fofin de ọkada ti n bọna miran yọ pẹlu oniruuru ifẹhonu han to n waye lati tako igbesẹ naa.
Ni aarọ ọjọ Aje lawọn akansa ẹda yabo ibujoko ijọba ipinlẹ Eko ni Alausa, ti wọn si n fẹhonu han sijọba lori bo se fofin de ilo ọkada ati kẹkẹ Maruwa lawọn agbegbe kan.
'Ọwọ́ tó bá dilẹ̀ ni èṣù ń bl ní iṣẹ́kíṣẹ́'
Awọn akanda ẹda naa, ti wọn ni oniruuru ipenija ara, gbe ọpọ akọle lorisirisi lọwọ lati pe akiyesi ijọba si wahala ti wọn n koju latipasẹ fifi ofin de ọkada.
Lati ọpọ agbegbe nilu Eko si lawọn akanda ẹda naa, ti ọps wọn jẹ ẹya Hausa, ti wa se ifẹhonu han, koda, wọn tun lẹ awọn akọle wọn si ara kẹkẹ Maruwa ti wọn gbe wa se ẹhonu ọhun.
Nigba to n ba BBC sọrọ, ọkan lara awọn akanda ẹda naa, salaye pe awọn bọ sigboro lati ke gbajare tọ araalu wa, ki wọn lee mọ isoro tawọn akanda ẹda n koju nitori bijọba se fofin de ilo ọkada ati kẹkẹ Maruwa.
"Ijọba sọ fun wa pe a ko gbọdọ jade lọ se agbe loju popo, a gbọ si wọn lẹnu, a si pa owo wa pọ lati ra kẹkẹ Maruwa, ko lee maa mu owo wale fun wa.
A ra kẹkẹ mii ni ẹgbẹrun lọna ẹgbẹrin naira tabi ko din diẹ, koda omiran, a n sanwo rẹ diẹdiẹ ni."
"A n bọ ara wa, ẹbi wa ati awọn eeyan miran lawujọ, ta si tun n se iranwọ fawọn eeyan miran bii awọn ọlspa ta n gbe lọfẹ sinu kẹkẹ Maruwa wa.
Sugbọn ijọba lai ba wa sọ tẹlẹ, lọ fi ofin de lilo kẹkẹ Maruwa"
O fikun pe awọn akanda ẹda yii setan lati fọwọsowọpọ pẹlu ijọba, amọ o wa n beere pe, se ijọba setan lati fun awọn lowo ranpẹ, kawọn fi joko sile tabi kawọn maa gba owo osu lọwọ wọn.
Sugbọn o ni ti eyi ko ba ri bẹẹ, awọn ko ni bọwọ fun ofin yii, ijọba Eko gbọdọ wọgile ofin yii, kawọn lee wulo fun ara awọn ati orilẹede wa.
Ilé ẹjọ́ tó ga jù ní kí gómìnà tẹ́lẹ̀, Jolly Nyame lọ fẹ̀wọ̀n ọdún 12 ṣara rindin
Oríṣun àwòrán, EFCC
Jolly Nyame jẹ gomina ipinlẹ Taraba laarin ọjọ kọkandinlọgbọ̀n, oṣu karun, ọdun 1999 si ọjọ kọkandinlọgbọn, oṣu Karun, dun 2007.
Ile ẹjọ to gajulọ ni Naijiria ti dajọ lọjọ Ẹti pe ki gomina nigba kan, Jolly Nyame o lọ si ẹwọn ọdun mejila.
Ile ẹjọ naa dajọ ẹwọn fun nitori ẹsun iwa ibajẹ, ati mago-mago to ṣe pẹlu owo ilu nigba to fi jẹ gomina. Owo naa to o biliọnu kan aabọ Naira (1.6bn).
Ile ẹjọ ko tẹ mi lọrun ti kọkọ ni ko san owo itanran dipo ẹwọn, ṣugbọn igbimọ ẹni maarun to da ẹjọ naa, ti Onidajọ Mary Odili jẹ olori fun, wọgi le e.
Ile ẹjọ giga nilu Abuja sọ pe ki Nyame, to ti jẹ gomina ipinlẹ Taraba ri jẹbi ẹsun debi pe ko lọ ṣe ẹwọn ọdun mẹrinla fun jija awọn eniyan ipinlẹ rẹ to ni igbagbọ ninu rẹ kulẹ.
Yoo tun ṣe ọdun meji miran fun fun lilo owo ilu nilokulo; ọdun meje miran fun lilo owo ilu fun ifẹkufẹ ara a rẹ; ati ọdun meji miran fun jibiti lilu.
Ajọ to n gbogun ti iwa ibajẹ ni Naijiria, EFCC, lo gbe Nyame lọ sile ẹjọ lori awọn ẹsun naa.
Ọjọ kẹtala, oṣu Keje, ọdun 2007, si ni igbẹjọ bẹrẹ lori ẹsun naa nile ẹjọ giga ijọba apapọ to wa ni Guru. Ẹsun mọkanlelogoji si ni wọn fi kan an.
Ninu oṣu Karun, ọdun 2018, ile ẹjọ giga ti Onidajọ Adebukola Banjoko to dajọ naa sọ pe gomina nigba kan ri naa jẹbi ẹsun mọkandinlọgbọn.
Onidajọ Banjoko dajọ pe Nyame, to tun jẹ pasitọ, ja awọn eniyan to fi ẹmi igbagbọ sinu rẹ kulẹ lasiko to fi jẹ gomina ipinlẹ Taraba, lasiko to na ọtalerugba din mẹwa miliọnu Naira (250m) ni inakuna.
Ajọ EFCC tun sọ loju opo ayelujara Twitter rẹ pe Onidajọ Banjoko tun sọ pe Nyame jẹbi ẹsun pe o lu jibiti miliọnu marundinlaadọsan Naira (165m).
Bi nkan ṣe ri yii, o ṣeeṣe ki Nyame to jẹ ẹni ọdun mẹtalelọgọta bayii o pe ẹni ọdun mọkanlelssdọrun ko to ṣẹwọn tan.
Bola Tinubu 2023: Babachir Lawal sọ pé APC gbọdọ̀ fààye gba Tinubu láti díje fún ipò ààrẹ
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Akọwe ijọba Naijiria nigba kan, Babachir Lawal, ti sọ pe dandan ni fun ẹgbẹ oṣelu All Progressives Congress (APC) lati fi aye gba ẹnikẹni to ba fẹ dije fun ipo aarẹ l'ọdun 2023.
Oṣu Kẹwaa, ọdun 2017, ni wọn yọ Lawal kuro nipo lẹyin ti wọn fi ẹsun kan pe o na N544m ni inakuna lati fi ge koriko.
Lasiko to n ba iwe iroyin abẹle The Punch sọrọ, Lawal sọ pe lootọ ni aṣiwaju ẹgbẹ oṣelu naa, Bola Tinubu, ko ipa pataki ninu bi aarẹ Muhammadu Buhari ṣe wọle ibo si ipo aarẹ l'ọdun 2015.
O ni kii ṣe nkan to pamọ pe igun Tinubu wa ninu ẹgbẹ oṣelu naa.
O fi kun ọrọ rẹ pe nigba ti Tinubu kede atilẹyin rẹ fun Buhari lọdun naa, lo to o fojuhan pe oun ni yoo gba tikẹẹti ẹgbẹ lati dije.
Ìlú Eko ló jẹ gbèsè jù ní Nàìjíríà lẹ́yìn ìjọba àpapọ̀
"Ti kii ba ṣe pe Tinubu jọwọ ara rẹ nigba naa, mo lero pe Kwakwanso ni ko ba gba tikẹẹti ẹgbẹ APC. Nitori idi eyi nikan, o fihan pe Tinubu ni onilu to lu fun iromi Buhari , ati idagbasoke ẹgbẹ APC.
Oríṣun àwòrán, The Guardian
Oṣu Kẹwaa, ọdun 2017, ni wọn yọ Lawal kuro nipo lẹyin ti wọn fi ẹsun kan pe o na N544m ni inakuna lati fi ge koriko.
Bakan naa ni Lawal sọ pe Tinubu lo ko owo jọ fun ipolongo, nigba ti Buhari ko ni owo lọwọ lati gbọ bukata eto idibo. Oun kan naa lo gba ileeṣẹ ilẹ okeere kan lati ilẹ America, fun atunṣe si oju ti awọn eeyan fi n wo Buhari ṣaaju eto idibo.
Oju ti ọpọ eeyan fi n wo Buhari nigba naa ko dara rara, eyi to ṣeeṣe ko ṣe idiwọ fun jijawe olubori rẹ"""
'Ìgbà tí mo máa fi lajú sáyé padà, ọ̀fọ̀ ikú mi ní wọ́n ń kígbe'
Nitori naa, ti a ko ba fẹ pe ibinu Ọlọrun si ori wa, eyi ti a ko fẹ, a gbọdọ fi aaye gba ẹnikẹni to ba fẹ dije, to fi mọ Tinubu.
Ọrọ ti Lawal sọ yii ti n fa ariyanjiyan laarin awọn ọmọ orilẹ-ede Naijiria kan lori ayelujara.
Igba akọkọ kọ niyi ti iroyin ati awuyewuye ti n waye lori pe boya Tinubu fẹ ẹ dije du ipo aarẹ Naijiria ni ọdun 2023. Oun naa si ti sọ laimọye igba pe, oun ko dije.
Oríṣun àwòrán, Twitter/Muhammadu Buhari
Ẹ ṣọra fun iroyin ofege, emi o pe aarẹ Muhammadu Buhari ni alakatakiti ẹsin, eekan ninu ẹgbẹ oṣelu APC, Bola Tinubu lo sọ bẹẹ.
Atẹjade kan lo lu ayelujara pa ninu eyi to fẹsun kan Tinubu pe o ṣapejuwe Buhari bi alakati ẹsun, ẹlẹyemẹta  ati daaru daapọ lọdun 2013.
Atẹjade naa tun sọ pe Tinubu ni ti wọn ba gba Buhari laaye pẹrẹ, afaimọ ko maa pin orilẹede Naijiria, ati pe iwa ẹlẹmyamẹya Buhari le ṣakoba fun iṣọkan fun Naijiria.
Bi ẹ ko ba gbagbe Buhari dije fun ipo aarẹ labẹ asia ẹgbẹ oṣelu ANPP ninu idibo gbogbogbo ọdun 2003 ṣugbọn o fidi rẹmi, nigba ti Olusegun Obasanjo ẹgbẹ oṣelu PDP wọle ibo naa.
Tinubu naa dupo gomina ipinlẹ Eko fun saa keji lọdun naa labẹ asia ẹgbẹ oṣelu AD ninu eyi to ti jawe olubori.
Amọ, oludamọran fun Tinubu lori eto iroyin, Tunde Rahman sọ ninu atẹjade kan to fi sita lọjọ Ẹti pe ayederu iroyin lawọn kan n gbe kiri.
Oríṣun àwòrán, Twitter/Muhammadu Buhari
O ni awọn eeyan kan ti wọn koriira Tinubu lo wa nibi iroyin ofege naa, bakan naa lo beere pe ki ẹnikẹni to ba mọ ibi ti Tinubu ti sọrọ naa wi pe ko wa sọ.
''Asiwaju ko le sọ iru ọrọ bayii nipa Buhari laelae! Ati pe ko si ohun to le mu ki Tinubu sọ iru ọrọ yii nitori oun ati Buhari ko si ninu ẹgbẹ oṣelu kan naa, bẹẹ ni wọn o si nija ara wọn ninu,'' Ọgbẹni Rahman lo woye bẹẹ.
O ṣalaye siwaju sii pe ko ba tiẹ wu Tinubu gan an ki Buhari wọle ibo aarẹ ọdun 2003 nitori oun ti Obasanjo ṣe fun ipinlẹ Eko nigba to gbẹsẹ le owo to n wolẹ lati apo ijọba apapọ.
Tí mo bá rí obìnrin tó kò níṣẹ́ lápá, mó máa ń ní kí wọ́n wò mí ṣe àríkọ́gbọ́n
"Ẹ wo obìnrin ""Bricklayer"" tó  sì ń bọ́ ẹnu èèyàn mẹ́ẹ̀dógún"
Jane Ifeoma ni orukọ rẹ n jẹ, obinrin bi ọkunrin tabi ka tilẹ ni obinrin to ju ọkunrin lọ ni.
Iṣẹ ọwọ rẹ to yan laayo ko doju ti i rara. Ko da o ni ohun ti oun n lo lati fi fun eeyan mẹẹdogun lounjẹ ninu ile oun niyii.
Iṣẹ birikila lo wayan laayo to si maa n yaa lor lati wa iṣẹ lọ ibikibi ti wọn ba ti n kọle.
Ti wọ́n ba sọ fun mi pe kii ṣe iṣẹ obinrin, mo maa n sọ fun wọn pe ko ni ohunkohun ṣe pẹlu pe mo jẹ obinrin.
"Ọp ajalu lo ṣẹlẹ si i. ""Ọmọ méje ni mo bí ṣùgbọ́n gbogbo wọ́n ti ṣaláìsí""."
O mọkan o si gba ọkọ rẹ nimọran fun itẹsiwaju idile wọn.
Ninu owo to n ri lo ti bẹrẹ ile ara rẹ diẹ diẹ titi ti oun fi di onile ara rẹ.
Michael Okhide: Àwọn ọmọ àwọn olóògbé méjèjì kọ̀wé sí aráàlú
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ìròyìn tó ń tẹ̀ wa lọ́wọ́lọ́wọ́ ní wí pé àwọn ọmọ àwọn olóògbé, agbẹjọ́rò Clement Okhide àti ìyàwó rẹ̀, Oluwatoyin Okhide tí ìròyìn ń tàn káàkiri pé ọmọ wọn ọkùnrin gún wọn pa.
"Arabinrin ""A"" to jẹ ọ̀kan lara awọn ọmọ awọn oloogbe ti ko fẹ ki a darukọ rẹ fi omije ba akọroyin BBC sọrọ pe bi awọn ṣe n gbọ iroyin naa kaakiri n ba awọn lọkan jẹ tori awọn ọlọdani oniroyin(Bloggers) ko mọ ohun to ṣẹlẹ gan, wọn kan n kọ gbọ yii sọ yii ni."
O ni itan naa ko fara pamọ mọ pe gigun ati kukuru iroyin naa ni wi pe ọmọ kan gun iya ati baba rẹ pa. Wọn si ti jọ n gbe pẹlu awọn ọmọ wọn ninu ile kan naa fun ọdun mẹtadinlogun bayii lati ọdun 2002 tori ile yii gangan ni ile baba wọn gangan niyẹn ṣugbọn wọn ṣi ni ile mii ti wọn n gbe tẹlẹ.
"Ohun to wa lori awọn iwe iroyin kaakiri eyi ti arabinrin ""A"" naa ni ko si irọ ninu eyi ti awọn iwe iroyin Naijiria tootọ kọ ni wi pe Michael Okhide fi ẹsẹ fẹẹ lẹyin to gun baba ati iya rẹ pa ninu ile wọn to wa ni agbegbe Ejigbo ni ipinlẹ Eko, Naijiria."
Ọmọ ọdun mẹtalelogun naa tun doju kọ arabinrin rẹ to jẹ agunbanirọ nigba to dele ni nkan bii ago marun abọ irọlẹ ṣugbọn arabinrin rẹ ni nigba ti oun wle toun si ti ri ti ẹjẹ fọn kaakiri ile ni ẹru ti n ba oun ati pe o gbọ ohun iya rẹ to n kigbe pe oruk oun lati sọ fun oun pe ko sa lọ.
O kọ lati wọ inu ile gẹgẹ bi Michael arakunrin rẹ ṣe n pe e nitori naa wọn jọ wọya ija ti Michael si ri i gun ni ikun ati ọwọ ṣugbọn ko fi bẹẹ wọ ọ lara tori naa o ri bi sa asala fun ẹmi rẹ.
"Arabinrin ""A"" sọ pe ọrọ naa ti di ọrọ to wa lọwọ Ọlọpaa bayii."
Fun ọpọlọpọ ọdun laye mi la fi jọ gbe inu ile baba wa papọ gẹgẹ bii idile. Ile wa ni lati nkan bii ọdun mẹtadinlogun ki n to rinrinajo kuro ni agbegbe naa tori naa ṣe ẹ ri i pe ti a lee kọ itan nipa rẹ.
O ni to fi mọ ọmọkunrin naa to gun baba awọn pa lawọn jọ dagba ninu ile ti baba awọn ra yii ti awọn obi awọn si tọ daadaa bi Ọlọrun ṣe ran wọn lọwọ.
"Arabinrin ""A"" ni wọn mọ wa ninu ile ọhun. Ile naa ni a ti lọ ile iwe alakọbẹrẹ, girama, fasiti, ibẹ naa ni mo n gba lọ ibi iṣẹ nigba ti mo bẹrẹ iṣẹ. Ohun gbogbo nipa igbe aye wa, inu ile yii lo ti waye""."
"(O bu sẹkun) ""mi o le maa sọ ita n gbogbo ohun to ṣẹlẹ, a maa da bi ofofo iroyin fun un yin nipa idile mii. A maa dabi iṣẹ ẹyin oniroyin""."
"Arabinrin ""A"" ni ""ohun ti mo fẹ ni ki gbogbo titan kalẹ yii dawọ duro, mo fẹ ko duro! Ki awn eeyan jọ ọ. Iwe iroyin tibi ti sọ ọ, t'ọhun ti sọ ọ, awọn ọlọdani oniroyin naa tun wa n gbe e kaakiri. O ti to gẹ!"""
Eeyan ti wọn bọwọ fun lawujọ ni baba mi to jẹ agbẹjọro ati iya mi to jẹ nọọsi. Nitori naa mo fẹ ki eyi daw duro ki awọn eeyan si tẹsiwaju ninu nkan mii. Mi o fẹ maa ri aworan awn obi mi kaakiri.
"Nigba ti akọroyin BBC bere nipa arakunrin rẹ to ṣe iṣẹ ibi yii, Arabinrin ""A"" dahun pe oun ko fẹ sọ nkankan nipa rẹ tabi ibi ti o wa lọwọlọwọ tori oun ko fẹ ki wọn ṣi oun gbọ ati pe a ṣi n ṣ'ọ̀fọ̀."
"Arabinrin ""A"" pada sọ fun akọroyin BBC pe awọn ọrẹ oun gan mọ pe mo maa n sọrọ fun wọn pe mo ni aburo kan to ni iru iwa ipa kan lọwọ ṣugbn a o mọ pe o le ṣe nkan to to eyi. O ti lọ si ile iwosan, a ti gbe e l si ile ti wọn ti n tun iwa ṣe fun oṣu mẹfa ni Abeokuta, wọn si ti da a silẹ pe ara rẹ ti ya; o ti lọ oriṣi fasiti mẹta ọtọtọ..."
Mi o sọ eleyi lati ṣe ẹlẹya ọmọkunrin naa o tori pe... (o bu sẹkun) awọn obi wa gbiyanju, wn kọ wa wọn si fi ifẹ han si gbogbo awa ọmọ wọn tori naa ko tọ si wọn ki awn eeyan maa wa ọrọ si wọn lara. O ti to gẹ!
"Arabinrin ""A"" ni ohun to ṣẹlẹ ti ṣẹlẹ mo ṣi n gbiyanju lati bori rẹ kii ṣe ki n gbe foonu mi ki n tun maa wa ka oniruuru ọrọ ti awọn eeyan n sọ lodi si wa bi awọn kan ti wn a ni ""ko ba san keeyan ma ni ọmọ kankan"". O ti to gẹ!"
O tẹnu mọ ọ pe ọna ati mu iru iwa yii kuro nilẹ lo yẹ ki awn eeyan maa wa kii ṣe ohun ti wọn n san. O ni ijọban gba awọn ọdọ laye lati maa korajọ kaakiri ti wọn si n mu igbo, wọn maa n korajọ ni agbegbe NNPC Junction ni Ejigbo, o yẹ ki ijba lọ ko wọn, dipo rẹ awọn ọmọ Yahoo nikan ni wọn n wa kiri bẹẹ si ni awọn ọdọ n ku kaakiri ti ẹmi wọn si n ṣ'ofo.
Occupy Lagos: A fẹ́ kí ìjọba ìpínlẹ̀ Eko dá Okada àti Maruwa padà - Olùfẹ̀hónúhàn
Oríṣun àwòrán, @ifbnw
Awọn olugbe ipinlẹ Eko kan ti ya bo ojuko ti ere eje-gigun ipinlẹ Eko pari si ni Eko Atlantic lati ṣe iwọde lodi si bi ijọba ipinlẹ ọhun ṣe gbẹsẹ le Okada ati kẹkẹ Maruwa.
"Nibi iwọde naa ti wọn pe ni ""Occupy Lagos"" ni wọn ti sọ fun ijọba ipinlẹ ọhun pe ko tu ero rẹ pa lori bo ṣe fofin de ọkada ati Maruwa naa."
Ọkan gboogi lara awọn to ṣiwaju iwọde naa, Kunle Wiseman Ajayi sọ fun BBC pe iwọde miran ṣi n bọ lọjọ iwaju ti ijọba ba kọ lati yi ipinu rẹ pada lori igbeṣẹ ọhun.
O ni ko yẹ ki ijọba dede gba iṣẹ lọwọ awọn to n fi ọkada ati keke Maruwa jẹun lai ba wọn ṣe ipade ko to fofin de iṣe wọn.
"Ajafẹtọ ẹni naa sọ pe ""Ti ijọba ba fẹ gba iṣẹ lọwọ awọn eeyan, o yẹ ko pe wọn si ijoko lati lee jiroro papọ pẹlu wọn ni."""
Ajayi sọ pe ijọba ipinlẹ Eko ko pese iṣẹ fun awọn eeyan ṣugbọn o n gba iṣẹ lọwọ awọn to pese iṣẹ funra wọn.
Oríṣun àwòrán, @ifbnw
O tẹsiwaju pe ọpọlọpọ awọn ti wọn n wu iwa jagidijagan tẹlẹ ṣugbọn ti wọn n ṣe ọkada ti pada sinu iwa ibajẹ wọn.
O ni oun to yẹ ki ijọba ṣe bayii ni pe ko kọkọ yi ipinlẹ rẹ pada, lẹyin naa ni ko pe ipade pẹlu ẹgbẹ awọn ọlọkada ati kẹkẹ Maruwa lori ohun to kan.
Kunle pari ọrọ rẹ pe ileri ti gomina ipinlẹ Eko, Babajide Sanwo-Olu ṣe fun awọn ọlọkada nigba idibo kọ ni pe yoo gba iṣẹ lọwọ wọn.
Ìdí rèé tí Man U ṣe já Odion Ighalo sílẹ̀ nínú ìgbáradì rẹ̀ tí yóò wáyé ni Spain
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Odion Ighalo ko ni ba awọn akẹgbẹ ni Manchester United kopa ninu igabradi wọn ti yoo waye lorilẹ-ede Spain nitori ibẹru aisan Coronavirus.
Ẹlẹsẹ ayo ọhun darapọ Manchester United lati ẹgbẹ agbabọọlu Shanghai Shenhua lorilẹ-ede China, nibi ti aisan naa ti kọkọ  bẹrẹ.
Wọn ni ti Ighalo ba tẹlẹ awọn akẹgbẹ rẹ lo si Spain, o ṣeṣe ki ileeṣẹ aṣọbode ilẹ Gẹẹsi ma gba  a laaye lati pada si orilẹ-ede naa nitori ibẹru aisan ọhun.
Akọnimọgba Manchester United, Ole Gunnar Solskjaer sọ fun awọn oniroyin pe yoo jẹ didun inu Ighalo lati darapọ mọ awọn akẹgbẹ rẹ.
"O ni ""Nitori bi ọrọ ṣe ri lọwọ yii ni China, ko da wa loju pe wọn yoo gba Igahlo laye lati pada wọ ilẹ Gẹẹsi to ba lee jade."""
Solskjaer tẹsiwaju pe, nitori naa, Ighalo yoo ṣi wa ni ilẹ Gẹẹsi fun akoko yii.
Akọnimọgba naa ni igbesẹ ọhun jẹ fun igba diẹ lati le mọ ibi ti ọrọ aisan Coronavirus naa yoo yọri si.
Aisan coronavirus ọhun to bẹrẹ lorilẹ-ede China ti mu ọpọlọpọ ẹmi lọ, ti awọn onimọ ijinlẹ si ti n wa ojutu sii.
Obìnrin kan dèrò ilé ìwòsàn lẹ́yìn tí ilé ẹru jálé e lórí nílu Eko
Oríṣun àwòrán, LASEMA
Obirin kan ti dero ile iwosan lẹyin ti ile ẹru ja lee lori lagbegbe Iyana Ipaja nipinlẹ Eko.
Ko pẹ ti iṣẹlẹ naa waye ti ajọ to n risi isẹlẹ pajawiri nipinlẹ naa, LASEMA, lọ si ojuko iṣẹlẹ ọhun lati doola ẹmi obirin naa.
Ile ẹru ọhun to ga to iwọn ẹsẹ bata ogoji lo ja le obinrin naa lori lati ori afara, ti obinrin ọhun si ha sabẹ ile ẹru naa.
Oríṣun àwòrán, LASEMA
Ọpọ awọn eeyan agbegbe ti iṣẹlẹ nmaa ti waye lo gbiyanju lati ran awọn oṣiṣẹ LASEMA lọwọ ko lee tete ri obinrin naa yọ labẹ ile ẹru ọhun.
Ọga agba ajọ LASEMA, Olufemi Damilola Oke-Osanyintolu  sọ fun awọn oniroyin ninu atẹjade kan pe, awọn oṣiṣẹ ajọ naa ti doola ẹmi obirin naa.
Lẹyin naa ni wọn gbe obinrin ọhun lo si ile iwosan fun itọju.
Amotekun: Àwọn adájọ́ àgbà ilẹ̀ Yoruba dá àba kí ìkọ̀ Amotẹkun lo ìbọn
Oríṣun àwòrán, @DAWNCommission
Awọn adajọ agba ni ẹkun iwọ oorun Naijiria ti da a laba ki awọn kọọkan ni ikọ Amọtẹkun ma a gbe ibọn.
Arakunrin Seye Oyeleye to jẹ alakoso ikọ Dawn Commission lo fi eyi han fun BBC Yoruba.
O ni awọn adajọ agba da aba yii lasiko ti wọn ṣe ijiroro lori bi ikọ Amọtẹkun yoo ṣe ri ati ọna ti wọn yoo gbe e gba lati ri i pe ikọ naa ri iṣẹ wọn ṣe bi iṣẹ.
Arakunrin Oyeleye ni aba ọhun yoo fun awọn ọga ati awọn kọọkan ninu ikọ amọtẹkun ni anfaani lati le lo ibọn lati koju iwa ọdaran lawujọ.
Amọ, o fi kun un wi pe aba yii ko lee dofin, aya fi ti ile igbimọ asofin ipinlẹ mẹfẹẹfa ba buwọlu, ti ijọba apapọ si fun wọn ni aṣẹ license lati le gbe ibọn dani.
Alakoso ikọ Dawn Commission fi kun un wi pe ko si ẹni ti ko le gbe ibọn ti ijọba ba ti fun wọn ni aṣẹ lati gbe e.
Ile igbimọ Asofin ni iwọ-oorun Naijiria ti ti ṣeleri lati rii wi pe awọn ṣe kanmọ kanmọ ki ikọ amọtẹkun tete bẹrẹ iṣẹ.
Wọn sọ eyi lati fi ran awọn gomina leti ki wọn tete gbe igbesẹ lori eto abadofin naa.
Oríṣun àwòrán, @toluogunlesi
Ọjọ Kẹsan, Osu Kini, ọdun 2020 ni awọn gomina ẹkun iwọ oorun Naijiria parapọ lati ṣe igbekalẹ ikọ ti yoo gbogun ti eto aabo to mẹhẹ ni Naijiria.
Amọ ni ọjọ diẹ sẹyin ti wọn ṣe ifilọlẹ ikọ amọtẹkun ni olotu eto idajọ ijọba ati minisita fun eto idajọ, Abubakar Malami kede wi pe ikọ amọtẹkun ko ba ofin mu.
Kí lo tíì rí  nípa Amotekun? Ẹ sùnmọ́bí, ẹ wo gbankọgbì!
Lati igba naa, ko fibẹẹ tii si ohun pato ti a lee ri gbamu lati sọ pe eto ikọ Amọtẹkun naa ti fẹ gberasọ lẹkun Iwọ Oorun.
Abẹnugan ile igbimọ asofin ipinlẹ Osun, Timothy Owoeye sọ wi pe awọn ti ṣe tan lati ge isinmi awọn kuro ki awọn baa le pada si ẹnu iṣẹ, ki wọn le tete ṣiṣẹ lori abadofin naa.
Bakan naa ni ipinlẹ Oyo sọ wi pe awọn n ṣiṣẹ le abadofin Amọtẹkun lọwọ ki wọn ba le pari rẹ laarin ọsẹ meji.
Oríṣun àwòrán, @toluogunlesi
Ninu ọrọ tirẹ, Abẹnugan ile igbimọ asofin ni ipinlẹ Ogun sọ wi pe awọn naa n sa ipa awọn lati ri wi pe gbogbo rẹ waye ni akoko ti wọn fi si.
Ẹwẹ, ipinlẹ Eko ko le e sọ igba ti awọn yoo le ṣe abadofin naa tan, amọ awọn ti bẹrẹ iṣẹ lori rẹ.
Domestic Violence: Wo ìlú tí wọ́n ti gbàgbọ́ pé bí ọkọ bá nà ẹ, ó nífẹ̀ẹ́ rẹ gan ni
'Lẹ́yìn tó fi ọ̀bẹ halẹ̀, òfin kò gbà kí n sọ̀rọ̀, àfìgbà tí ọkọ mi fi àáké gé mi lọ́wọ́'
Magarita sọ nkan toju rẹ n ri ninu ile fun BBC.
O ni lasdiko ti oun wa yii, o tẹ oun lọrun ki oun ṣi ni ọwọ oun ṣugbọ́n ko lee ri bẹẹ fun un mọ.
Òfin Russia sọ pé àwọn ọ̀daràn fún ìgbà àkọ́kọ́ tí kò dá ọ̀gbẹ́ púpọ̀ sí ẹnìkejì lára kò leè dédé lọ sẹ́wọ̀n.
Eyi lo fa a to fi n ni ifarada gbogbo iwa ti ọkọ rẹ kọkọ n wu si i titi to fi wa di pe o ṣe manigbagbe yii.
Bi o tilẹ jẹ wi pe kii ṣe gbogbo eniyan lo fara mọ iru ofin bayii. Iṣẹlẹ yii ti wa sọ Magarita di gbajugbaja lọdọ awọn oniroyin. Koda o ti ṣe iwe jade lori iriri rẹ
Àrá sán pa aboyún ìnàkí àtàwọn mẹ́ta míì tó jẹ́ àrà ọ̀tọ̀ láyé
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ẹgbẹrun kan pere iru inaki ori apata yii nikan lo wa laye
Inaki mẹrin to fi mọ àwọn abo inaki kan to n gbe lori apata ti ku ni Uganda lẹyin ti mọnamọna ara san pa wọn.
Wọn ri abo agba inaki mẹta ọhun ati akọ ọmọkunrin ni ọgba ti wọn nko ẹranko si, Mgahinga National Park ni Uganda pẹlu ọpọlọpọ ifarapa lara wọn eyi to si tumọ si pe ina gbe wọn.
Apapọ awọn onimọ nipa ranko, Virunga Transboundary Collaboration (GVTC) ṣapejuwe rẹ gẹgẹ bi adanu nla fun ẹya inaki.
Ẹgbẹrun kan pere iru inaki ori apata (Mountain Gorilla) yii nikan lo wa laye.
Awọn ibi ti wọn jẹ ki awọn inaki yii wa ni awọn agbegbe ti abo wa fun ni Democratic Republic of Congo, Rwanda ati Uganda.
"Awọn mẹrin to ku yii wa lara ẹgbẹ ẹlẹni mẹtadinlogun ti wọn n pe wọn ni idile ""Hirwa""."
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Idile awọn inaki Hirwa yii ti wa rekọja ibode lati Rwanda si Uganda lọdun to kọja ti wọn si ti n gbe ọgba ẹranko igbo Mgahinga ni Uganda.
Mgahinga jẹ ọkan lara awọn oke Virunga nla eyi to n pa ala pọ pẹlu awọn ibode Uganda, Rwanda ati DR Congo.
Andrew Seguya to jẹ akọwe agba GVTC sọ fun BBC pe iṣẹlẹ iku awọn inaki yii ba ni lọkan jẹ pupọ.
"O ni ""ipa ti awọn abo inaki mẹta yẹn yoo ko ninu ibisii ko kere rara""."
Ẹwẹ, o fi kun un pe awọn mọlẹbi inaki naa mẹtala to ye iṣẹlẹ ara naa ni wọn ti ri ti wọn si n jẹun daadaa.
Ayẹwo ti n lọ lọwọ lori oku wọn ni ibudo ayẹwo ti wọn si n reti ohun to ṣokunfa iku wọn laarin ọsẹ mẹta si isinsiyii.
Osun Accident: Ọkọ̀ àwọn olùjọ́sìn náà dédé yíwọ́ lọ kọ lu ògiri
Oríṣun àwòrán, Twitter
Iroyin to n tẹ wa lọwọ ni lọọlọ yii ni pe eeyan mẹfa ti ku ninu ijamba ọkọ akero kan lowurọ ọjọ aiku.
Gẹgẹ bi awọn oniroyin ṣe sọ ọ, awọn to ba iṣẹlẹ naa rin n ririnajo bọ lati ipagọ adura awọn Kristẹni kan eyi ti wọn n pe ni Oke Maria Pilgrimage ni agbegbe Otan Ayegbaju ninu ọkọ ijọ Paul Catholic Church, Lagere Ile Ife.
Awọn ti iṣẹlẹ naa ṣoju wọn ni ṣe ni ọkọ to n gbe awọn ero ọhun bọ lati ipagọ adura ti wọn ṣe lọjọ ẹti yiwọ to si lọ rọ lu odi kan lẹba opopona Ire/Eripa/Otan Ayegbaju/Ila eyi to si jẹ ki ọkọ naa da sinu koto.
Oríṣun àwòrán, OTHER
Iroyin sọ pe awọn oṣiṣẹ ajọ ẹṣọ aṣọbode ti de ibi iṣẹlẹ naa ti wọn si ti n gbe awọn to fara pa jade kuro ninu ọkọ naa pẹlu iranlọwọ awọn to n gbe ni agbegbe naa.
Lasiko ti iroyin naa wọle, o ti le ni eeyan mẹwaa ni o ti gbẹmi mi gẹgẹ bi awọn to n kọja lọ ṣe n ke bosi o.
Ọjọ ẹti ọjọ kẹjọ oṣu keji ni ipagọ adura naa waye eyi ti ọgọrọ awọn olujọsin korajọ fun adura ni Oke Maria to wa ni Otan Ayegbaju.
Ọwọ́ ọlọ́pàá Eko tẹ ọmọ ọdún 22 tó jẹ́ olórí 'bambam' f'ẹ́gbẹ́ òkùnkùn Berry Boys
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ọwọ ileeṣẹ ọlọpaa ipinlẹ Eko ti tẹ ọmọkunrin, ẹni ọdun mejilelogun kan, ati awọn miran to jẹ ọmọ ẹgbẹ okunkun.
Ọwọ awọn ọlọpaa lati ẹka agbegbe Itire tẹ Maliki Bello to jẹ olori ẹgbẹ okunkun ti wọn n pe ni Berry Boys.
Ileeṣẹ ọlọpaa sọ ninu atẹjade kan lati ọwọ alukoro ileeṣẹ ọlọpaa Bala Elkana , pe ọjọ ti pẹ ti wọn ti n wa Maliki fun awọn ẹsun jagidijagan ati ija awọn ẹgbẹ okunkun.
Ọwọ tẹ Maliki to jẹ ọmọ ipinlẹ Kwara, ni ọjọ kẹrin, oṣu Keji ọdun 2020.
O jẹwọ pe lootọ, oun ni oun wa nidi awọn ija igboro, ipaniyan, ati idigunjale kan to waye ni adugbo bi i Idi-araba, Dosunmu, Ashimowo, Omo Bola, Mushin, ati Itire.
O sọ fun awọn ọtẹlẹmuyẹ ileeṣẹ ọlọpaa pe ọmọ ọdun mejila ni oun wa nigba ti wọn mu u darapọ mọ ẹgbẹ okunkun.
Lasiko yii, o wa ni kilaasi akọkọ nileewe girama kekere (JSS1). Ko to o di pe o de ipo olori 'bambam'  ninu ẹgbẹ naa.
Bakan naa ni Maliki tun jẹwọ pe oju opo ayelujara Facebook ti wọn pe orukọ rẹ ni 'Bbl Baloteli'ati awọn oju opo ayelujara miran ni awọn ti maa n gba ọmọ ẹgbẹ wọle.
Oju opo ayelujara yii kan naa ni wọn ti maa n ṣe eto bi wọn yoo ṣe ṣe ikọlu.
Lẹyin ti ọwọ tẹ Maliki ni iwadii tun mu ki ọwọ tẹ awọn afurasi mọkanla miran.
Muhammadu Buhari: Falana ní ilé ìwòsàn ti di mọ́ṣúárì ní Nàìjíríà nígbà tí Buhari ń gbàtọ́jú nílẹ̀ òkèrè
Oríṣun àwòrán, Facebook/Femi Falana
Ẹyin ọmọ Naijiria, ẹtọ yin lati beere fun eto ilera to peye lọwọ ijọba aarẹ orilẹede Naijiria, Muhammadu Buhari.
Agbẹjọro ati ajafẹtọ, Femi Falana lo sọrọ yii idanilẹkọ ọdọọdun fun iranti Dokita Beko Ransome-Kuti ẹlẹẹkẹrinla rẹ.
Agbẹjọro Falana sọ pe ijọba ologun Buhari lo ju Dokita Beko si ọgba ẹwọn Kirikiri fun oṣu mẹfa lọdun 1984 nitori o jijagbara lati beere fun eto ilera to peye lọwọ ijọba.
Falana sọ pe ohun to kudiẹ kaato ni pe aarẹ Buhari n rinrin ajo lọ si oke okun fun itọju ara rẹ, nigba ti awọn ọmọ Naijiria n lọ si awọn ile iwosan to ti di mọṣuari bayii.
O ni Buhari fun ra rẹ lo nigba to gori aleefa gẹgẹ bi ọgagun olori orilẹede Naijiria lọjọ kọkanlelọgbọn oṣu kejila ọdun 1983 pe awọn ile iwosan ni Naijiria ti di ibi ti awọn eeyan ti n ri awọn dokita lasan an.
Falana ṣalaye pe Buhari kan naa to sọrọ lọdun 1984 pe awọn ile iwosan to wa ni Naijiria ko ju ibi tawọn eeyan kan ti n ri awọn dokita lasan lọ, oun naa si ni aarẹ Naijiria lonii ti awọn iwosan ti di mọṣuari.
Gbajugbaja agbẹjọro ni Buhari ko lọ si awọn ile iwosan yii, ilu oyinbo lo n lọ fun itọju ara rẹ, owo ilu lo si n na.
Oríṣun àwòrán, Facebook/Femi Falana
''Ẹjọ ti mo pe ijọba wa ni ileẹjọ kotẹmilọrun bayii ninu eyi ti mo ti sọ pe ki ijọba ṣe eto iwosan to peye fun gbogbo eeyan nitori ori ko ju ori,'' Falana lo sọ bẹẹ.
''Ti ẹyin ba n gba ilu oyinbo lọ fun itọju, ẹ gbọdọ ba wa ṣe awọn ile iwosan ti awa naa n lo nile ko dara, ka wa naa le lanfaani si eto ilera to peye,'' Falana lo woye bẹẹ.
Falana tun fi kun ọrọ rẹ pe Buhari naa ni o fa iya to n jẹ ọpọ ara ilu Eko bayii lẹyin ti ijọba f'ofin de ọkada ati kẹkẹ Maruwa nitori o wọgile aba lati ṣe eto igbokegbodo ọkọ ti igbalode oni igba nmiliọnu dọla($200m) eyi ti Gomina Lateef Jakande ṣe agbekalẹ rẹ lasiko to wa lori alefa.
Lassa Fever: Ibà Lassa tún ti rán èèyàn mẹ́rin s'ọ́run ní ìpínlẹ̀ Kogi
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Arábìnrín kan kú látàrí àìsan Lassa ní ìpínlẹ̀ Enugu lẹ́yìn tí wọn kò tètè rí ilé ìwòsàn láti ṣe àyẹ̀wò
Iba Lassa to n ja ran-in ran-in tun ti ṣọṣẹ ni ipinlẹ Kogi, ẹka eto ilera nipinlẹ naa ti ṣalaye pe eeyan mẹrin lo ti jẹ Ọlọrun ni pe ninu awọn mẹsan an to lugbadi aarun naa.
Dokita Austin Ojotule, to n ri si dudena ajakalẹ aarun ni ipinlẹ Kogi lo fọrọ yii lede niluu Lọkọja tii ṣe olu ilu ipinlẹ naa.
Dokita Ojotule ṣalaye pe awọn eeyan mọkanlelọgbọn ni ẹka ilera ṣe ayẹwo fun un lẹyin ti wọn funra pe wọn ti lugbadi iba lassa.
Dokita Ojotule ni mẹtadinlogun ninu wọn ni ko ni aarun naa, ninu awọn mẹsan an ti ayẹwo fi han pe wọn ni aarun ọhun ni eeyan mẹrin ti dero ọrun.
Ijọba ibilẹ Ibaji, Okene, Idah, Okehi ati Igalamela lawọn mẹsan to lugbadi aarun naa ti wa.
Ọrọ di bo lọ ya n mi lori iba lassa ni Gusau
Ojora mu ọpọ araalu Gusau nipinlẹ Zamfara lọjọ Aiku lẹyin ti ayẹwo fihan pe obinrin kan to ku niluu naa laarun iba lassa.
Ọjọ Aiku ni wọn gbe obinrin naa digbadigba lọ si ile iwosan King Fahad Women and Children Hospital nibi to ti jẹ Ọlọrun ni'pe.
Oríṣun àwòrán, OTHERS
Ọ̀pọ̀ ènìyàn lo ti sọ ẹmi nù nítorí àìsàn Iba Lassa
Awọn oniṣẹ eto ilera ṣe ayẹwo fawọn to wa ninu yara wọọdu kan naa pẹlu obinrin yii lati mọ boya awọn naa ti ni aarun Lassa.
Ile iwosan naa gbiyanju lati dena ki awọn eeyan mii wọle lati dena itankalẹ aarun iba lassa.
Wo iye ibùdó ìtójú ibà Lassa tó wà ní Nàìjíríà
Ajọ to n gbogun ti ajakalẹ arun lorilẹede Naijiria, NCDC ti sọ wi pe ile iwosan mẹtadinlogun lo wa fun itọju aisan naa.
Ajọ NCDC sọ eyi latari bi iye awọn eniyan to ti ku nipa aisan iba orẹrẹ Lassa Fever ṣe n pọ si i kaakiri awọn ipinlẹ ni Naijiria.
NCDC lasiko ti wọn n ṣe ipade pẹlu awọn onimọ nipa aisan Lassa n woye boya ki wọn kede eto pajawiri nitori aisan Lassa naa.
Yatọ si awọn ile iṣẹ iwosan yii, awọn ibudo ti wọn ti n ṣe ayẹwo ẹjẹ lati mọ boya eniyan ni aisan naa wa ni ipinlẹ marunlorilẹede Naijiria, awọn si ni:
Cameroon: Àṣírí èèyàn kan tó dìbò ní ìgbà 89 tú, Ọlọ́pàá gbé e jàǹtò!
Bi iroyin ṣe jade tan pe idibo ti pari lawọn ibido idibo kaakiri orilẹede Cameroon lati yan awọn aṣofin atawọn kansilọ ni iroyin mii jade pe ọwọ Ọlọpaa tẹ oludibo kan.
Bi wọn ṣe pari kika ibo lawọn ibudo idibo ti wọn si ti ilẹkun gbọngan ibudo pa to jẹ wi pe awọn oluwoye nikan lo wọle, ṣe lawọn alatilẹyin ẹgbẹ duro sita ti wọn n wo lojuu ferese.
Ka to ni ka maa sinmi lori eto idibo ti ko ni kọnu nkọhọ ninu la gbọ pe ọwọ awọn ọlọpaa tẹ ọkunrin kan to dibo nigba mọkandinlaadọrun ni Kumba to wa ni ẹkun Guusu Iwọ Oorun Cameroon.
Gẹgẹ bi iroyin ṣe sọ ọ, nigba ti wọn de ibudo idibo, eeyan mọkandinlaadọrun ni wọn ba to ti dibo ṣugbọn wọn ko tilẹ ri arakunrin kan nibẹ bẹẹ si ni ko buwọ̀ rẹ luwe idibo.
BBC Africa Eye: Akọroyin fẹ ìdí àwọn oníṣẹ́ ibi ọmọ ogun síta
Oṣiṣẹ ajọ eleto idibo Cameroon kan lo fi aridaju iroyin yii han fun BBC.
Olugbe agbegbe Kumba ọhun kan sọ fun akọroyin BBc pe alaga ibudo idibo naa ti dibo C naa ti wa lọwọ awọn agbofinro.
Iroyin wa sọ pe alaga ẹgbẹ alatako, Social democratic pary ni  Kumba 3 Um Rufus gba afurasi naa mu pẹlu apoti idibo to kun fun iwe itẹka lati igba ti eto idibo ko tilẹ tii gberasọ.
Awọn olugbe adugbo naa sọ fun BBC pe awọn n gbọ iro ibọn latọdọ awọn ologun to wa ni agbegbe naa ti wọn si ni ki gbogbo eeyan doju bo ilẹ.
Ni Kumba nibudo idibo kan, ẹgbẹrun lọna mẹtadinlogun eeyan lo fẹ dibo ṣugbọn bi wọn ṣe bẹrẹ si ni gbọ iro ibọn, wọn o tilẹ ri to eeyan igba rara lati dibo.
Latari eyi, Ọna Kumba ọhun lewu lti gba ti wọn si n ṣe ikọlu si awọn oṣiṣẹ ajọ eleto idibo Cameroon.
Lassa Fever: Àjèjì ààrùn tó ń pani ní Nàìjíríà bàyìí kìí ṣe CoronaVirus, Lassa, tàbí Ebola
Oríṣun àwòrán, Ncdc
Ajọ to n mojuto igbogun ti aarun ni Naijiria, Nigeria Centre for Disease Control (NCDC) sọ pe ohun ti mu erooja lara omi odo ti aisan ajeji kan ti pa awọn eniyan ti ko din ni mẹẹdogun ni ipinlẹ Benue.
Ileeṣẹ eto ilera ipinlẹ Benue sọ pe awọn ti aarun naa fi ọwọ ba julọ n gbe ni ijọba ibilẹ Oye-Obi nipinlẹ naa.
Iku eniyan mẹẹdogun lo ti wa ni akọsilẹ bayii, ti ọgọrun ati mẹrin eniyan si tun ti kagbako aarun naa to bujade lọjọ kọkandinlọgbọn, oṣu Kinni, ọdun 2020.
Nkan to ba ni lẹru ni pe ajeji aarun naa tete n ran kiri ju iba Lassa to ti pa eniyan mẹtadinlaadọta lọdun 2020 nikan lọ.
Ni bayii, awọn alaṣẹ ipinlẹ Benue ti di ọna to lọ si odo naa pa.
Bakan naa ni ajọ NCDC ti sọ pe aarun naa kii ṣe Corona virus, iba Lassa tabi Ebola, nitori pe awọn apẹẹrẹ ti awọn to ni i fihan yatọ.
Awọn onimọ ilera sọ pe o maa n to wakati mejidinlaadọta ki esi ayẹwo to jade.
Minisita fun eto ilera ni Naijiria, Dokita Osagie Ehanire sọ pe awọn onimọ ti n wadii iru aarun to jẹ, ti wọn si n duro de e esi ayẹwo.
Oríṣun àwòrán, TWITTER/@FMOHNIGERIA
Minisita fun eto ilera ni Naijiria, Dokita Osagie Ehanire
Ọmọ ilẹ̀ China tó fìyàjẹ ọmọ Kenya dèèrò ilé ẹjọ́
Oríṣun àwòrán, Twitter/citizentvkenya
Ara me riri,mo ri ori oloogbo latẹ.
Gbolohun eemọ re lo n jade lati ẹnu awọn ọmọ orilẹ-ede Kenya lori bi ọmọ ilẹ China kan ti ṣe to ẹgba sidi ọmọọṣẹ rẹ kan to jẹ ọmọ orilẹ-ede Kenya tori pe o pẹ de ibiiṣẹ.
Ni ile ounjẹ kan ti o jẹ t'awọn ọmọ ilẹ China ọhun, iyẹn Chez Wou Restaurant to ni agbegbe Kileleshwa l'olu ilu Kenya, Nairobi ni iṣẹlẹ naa ti waye.
Niṣe ni oju opo ayelujara gbana lẹyin ti ilẹeṣẹ amohunmaworan kan K24 TV fi fọnran fidio han nibi ti ọkunrin, ọmọ China kan ti n na ọmọ Kenya kan lẹgba.
Lẹyin awuyewuye ti fidio yi mu wa, ileeṣẹ ọlọpaa ni Kenya fi ọrọ sita pe awọn ti mu awọn ọmọ ilẹ China mẹrin ti wọn n ṣiṣẹ ni ile ọunjẹ naa.
Oríṣun àwòrán, KTV
Gẹgẹ bi ohun ti wọn fi sita,eniyan kan pere ninu wọn lo ni iwe aṣẹ to gba laaye lati ma ṣiṣẹ ni Kenya.
Bakan naa ni wọn sọ pe awọn ọmọ Kenya mẹjọ to n ṣiṣẹ nibẹ l'awọn n wadi ọrọ lẹnu wọn.
Wayi o,ileeṣẹ orileede China ni Kenya ti ni digbi lawọn wa lẹyin awọn alaṣẹ nipa wiwadi ẹni to ba tasẹ agẹrẹ sofin.
Orisirisi ọrọ lawọn ọmọ Kenya ti n sọ nipa iṣẹlẹ yi, ti wọn si ni ko da ki eeyan jẹ ẹru ni ilẹ baba rẹ.
@KiplangatLedama ni ti ẹ sọ pe ki wọn mu ẹni to hu iru iwa yi lọ si ilu Wuhan ti Coronavirus ti n ba awọn eeyan finra.
Osun Accident: Àwọn ọmọ ijọ wa tí fí ìgbàgbọ́ gbà ìṣẹlẹ ìjàmbá ọkọ́ - ìjọ Kátólíkì
Iroyin ti bẹrẹ si ni suyọ diẹ diẹ nipa bi ijamba ọkọ to mu eeyan meje lọ ṣe ṣẹlẹ ni ipinlẹ Oṣun.
Alakoso ẹka eto nile iwosan Lady of Fatimah Catholic Hospital Rev Fr Femi Oloyetombi lo na ọrọ naa nibẹ fun ileeṣẹ BBC YORUBA.
Ninu ifọrọwanilẹnuwo, o sọ pe obinrin kan to sọda titi mọ ọkọ lẹnu lo ṣokunfa ijamba naa.
Oloyetombi ni ọna ti ọkọ ọhun gba loun gan naa gba kọja tori oun naa lọ fun ipagọ adura.
O fi kun ọrọ rẹ pe ti a ba fi obinrin naa kun awọn mẹfa to ku ninu ọkọ naa, iye ẹmi to ba iṣẹlẹ naa lọ yoo jẹ meje.
O ni kete ti wọn pe oun lori ẹrọ ibanisọrọ toun si pe awọn akẹgbẹ oun nile iwosan lawọn tete fọwọ kun awọn ajọ ẹṣọ oju popo lati maa ko awọn to ku ati awọn to fara pa lọ si ile iwosan.
"Oloyetombi ṣalaye pe ko si akoko lati maa bere ẹjọ pe ki lo ṣẹlẹ lasiko ati doola ẹmi ṣugbọn ""oun ti mo gbọ ni pe igbiyanju dẹrẹba ọkọ lati yago fun obinrin to fẹ sọda titi ni ko ri ọwọ ara rẹ dari""."
Femi Oloyetombi tubọ ṣalaye pe awọn ọmọ ijọ katoliki ti iṣẹlẹ naa kan lawọn ti fi igbagbọ gba iṣẹlẹ ọhun tawọn si gbadura  pe ki Ọlọrun dawọ le awọn to n gba iwosan ati pe ko fun awọn ti lọ ni isinmi rere.
''Ijọ ti kan si awọn mọlẹbi ti ọrọ yi kan kaakiri lati tu wọn ninu. Gẹgẹ bi ẹlẹran ara, ọrọ yii dun wa ṣugbọn ko si nkan ti a fẹ ba Ọlọrun fa''
Awọn olujọsin ti o fara kasa iṣẹlẹ yii n mbọ lati ipade adura to waye ni  Oke Maria ni agbegbe Lagere, Ile Ife.
Ipade yii jẹ ipade adura apapọ ijọ Katoliki to maa n waye lọdọọdun.
Ọja Arena Oshodi ni àwọn èèyàn ti ń r'aja
BBC Africa Eye: O yẹ kí ìjọba ló ìmọ̀ ẹ̀rọ ìwádìí sátáláìtì láti mú àwọn Boko Haram
Awọn ọmọ Naijiria ti n sọ ero ọkan wọn nipa fidio iwaadi bi awọn agbofinro ṣe n fi iya jẹ awọn afunrasi eleyi ti BBC Africa Eye gbe jade.
Loju opo Facebook ileeṣẹ BBC Yoruba, niṣe ni awọn eeyan bu ẹnu atẹ lu bi awọn agbofinro wọnyi ko ṣe bọwọ fun ofin.
Bawọn kan ṣe n sọ pe ki ijọba kasẹ awọn SARS kuro nilẹ lawọn miiran n sọ pe ki BBC ṣe idayatọ awọn afunrasi ati awọn ti ko mọwọ mẹsẹ ninu iwaadi wọn.
Bẹẹ lawọn miran n beere pe kilode ti ijọba ko ṣe le fi iru ẹrọ iwaadi satalaiti ti wọn lo ninu iwaadi yi lati fi mu awọn ikọ Boko Haram.
Showemimo Victor ti o beere ọrọ yi sọ ọ ni ede Gẹẹsi.
Ninu esi tirẹ, Micheal Alloh naa fẹ ki wọn lo iru imọ yii lati tọ pinpin awọn to jẹ alajẹbanu oloṣelu.
Ni akotan pupọ awọn to ka nipa iroyin naa loju opo BBC lo kan sara si ileeṣẹ iroyin naa ti wọn si ni awọn ni ireti pe ijọba yoo wa nkan ṣe si ọrọ awọn agbofinro to n fi iya jẹ awọn afunrasi.
Revolution Now: Iléẹjọ́ ṣún ìgbẹ̀jọ́ síwájú di ọ̀la Ọjọ́bọ
Oríṣun àwòrán, @YeleSowore
Ileẹjọ giga ilu Abuja ti pasẹ fun agbẹjọro ijọba apapọ ilẹ wa lati san ẹgbẹrun lọna igba naira, owo gba, ma binu fun asaaju ikọ Revolution Now, Omoyele Sowore.
Adajọ Ijeoma, to n gbọ ẹjọ naa kede pe oun pasẹ bẹẹ nitori idaduro ti wọn fun Sowore lori ẹjọ naa.
Idi ni pe ni kete ti adajọ joko lati gbọ ẹjọ ọhun lọjọru ni agbẹjọro ikọ olupẹjọ dide lati sọ fun ile ẹjọ pe agbẹjọro agba nilẹ wa ti gba akoso ẹjọ naa, to si fẹ se atunse si awọn ẹsun ti wọn fi kan Omoyele Sowore.
Oríṣun àwòrán, @YeleSowore
O ni oun ko tii fi igbesẹ naa to agbẹjọro Sowore leti, ti oun si nilo akoko lati se bẹẹ, sugbọn adajọ fọnmu pe lati osu kejila ọdun to kọja, eyi to to ọsẹ meje gbako, ti wọn ti so ẹjọ ọhun rọ lo yẹ ki wọn ti fi ọrọ naa to gbogbo ẹni to yẹ leti.
Oríṣun àwòrán, @YeleSowore
N kò ní òmìnira, ìjọba Buhari ń tẹ ẹ̀tọ́ mi mọ́lẹ̀ - Sowore figbe bọnu
Ọsẹ meje ti kọja ti ikọ olupẹjọ ko si fi igbesẹ tuntun nipa ẹjọ naa to awọn igun to yẹ leti. O dabi ẹni pe ẹ ko setan lati bẹrẹ igbẹjọ, tẹ kan fẹ maa fi akoko sofo nitori ofo lasan ni gbogbo awawi yin.
Oríṣun àwòrán, @YeleSowore
Adajọ Ijeoma fikun pe nitori idi eyi, wọn gbọdọ san ẹgbẹrun lọna igba naira fun igun olujẹjọ nitori gbogbo aaye ti ofin fi silẹ fun wọn lati sun ẹjọ siwaju ni wọn ti lo tan.
Lẹyin eyi ni adajọ naa wa sun ẹjọ ọhun siwaju di Ọjọbọ ọla, ọjọ Kẹtala osu Keji ọdun 2020.
Oríṣun àwòrán, @yeleSowore
Ẹwẹ, loju opo Twitter rẹ, @YeleSowore, asaaju ikọ Revolution Now naa ni oun ti pada de lati ile ẹjọ̀, ti ohun ko si ni ohun toun fẹ jabọ ju iwa ifiyajẹni lọ. Wọn wa sile ẹjọ lai gbaradi, ti wọn si n se atunse si awọn ẹsun .
Saaju lati mu iroyin wa fun yin pe, Omoyele Sowore tii se asaaju ikọ Revolution Now, to n pe fun ijijagbara araalu lorilẹede Naijiria, ti kede pe oun ko tii ni ominira rara.
Soworẹ, ẹni toyọju sile ẹjọ laarọ Ọjọru fun ibẹrẹ igbẹjọ rẹ nile ẹjọ giga ilu Abuja salaye fun BBC Yoruba pe awọn eeyan kan labẹ ijọ apapọ ilẹ wa lo n tẹ ẹjọ oun loju mọlẹ.
Assaju ikọ Revolution Now naa ni se ni wọn n fẹsẹ tẹ ẹtọ oun loju mọlẹ , ti oun si setan lati daabo bo ẹtọ oun.
Nigba toun naa n salaye fun BBC idi to fi tẹle Soworẹ wa sile ẹjọ, Asofin agba kan, to tun jẹ ajafẹtọẹni, Shehu Sani kede pe ọrẹ, arakunrin ati alabasepọ oun ninu isẹ ijija gbara ni Soworẹ.
Sani ni gbogbo iwa ijẹgaba ti Sowore ti n ja fun lati ọjọ pipẹ wa, lo wa n pada jiya labẹ rẹ yii, to si se ni laanu pe o ti ja fun ijọba tiwa n tiwa ju pe ko foju wina ifiyajẹni bii eyi lọ.
Asiko yii lo yẹ ki gbogbo wa sugba Soworẹ, ka duro tii gbagbagba, ka si ba pin ninu isoro to n la kọja lati ọwọ awọn alagbara. O si ti le ni ọgbọn ọdun taa ti jọ n se pọ, mo si wa pẹlu rẹ ninu ẹmi, ọkan ati ara.
Shehu Sani fikun pe wọn sẹsẹ gba oniduro oun tan lọwọ ajọ EFCC ni gẹgẹ bi wọn se gba oniduro Sowore lọwọ ajọ ọtẹlẹmuyẹ DSS, awọn si gbọdọ fi imọ se ọkan.
LaarọỌjọru oni la mu iroyin wa pe igbẹjọ agbatẹru ipolongo #RevolutionNow Omoyele Sowore bẹrẹ ni ile ẹjọ giga apapọ nilu Abuja.
Omoyele Sowore, to fi igba kan du ipo aarẹ Naijiria ati akẹgbẹ rẹ Olawale Bakare, ni ijọba Naijiria dijọ fi ẹsun kan pe, wọn n pe fun ifitẹgbajọba Naijiria.
Yatọ si ẹsun yii, wọn tun ni wọn n fọna ẹburu gba owo, ti wọn si tun n dunkoko mọ awọn eeyan loju opo ayelujara.
Awọn mejeeji ti ni awọn ko jẹbi ẹsun ti wọn fi kan wọn
Yatọ si ẹsun yii, wọn tun ni wọn n fọna ẹburu gba owo, ti wọn si tun n dunkoko mọ awọn eeyan loju opo ayelujara.
Awọn mejeeji ti ni awọn ko jẹbi ẹsun ti wọn fi kan wọn.
Adajọ Ijeoma Ojukwu ni yoo dari ẹjọ naa.
Wahala laarin ijọba ati Sowore bẹrẹ ni oṣu kẹjọ dun 2019, nigba ti ileeṣẹ ọtẹlẹmuyẹ Naijiria mu pe o n ṣagbatẹru iwọde jakejado Naijiria.
Lọjọ keji oṣu Kẹjọ ni Sowore fi ọrọ sita loju opo Twitter pe ''A ni lati ṣe ijijagbara eyi tawọn eeyan ti ara n ni yoo fi mu ọjọ ti wọn yoo fi gba ominira, ti wọn ko si ni gba ki awọn amunisin maa fi iya jẹwọn''
Ọjọ keji ni awọn DSS wa mu pe o fẹ tu ijọba aarẹ Buhari ka.
Wọn fi Sowore si ahamọ titi di oṣu Kẹwa ọdun 2019 ti ile ẹjọ paṣẹ ki wọn gba oniduro rẹ leleyi ti awọn agbofinro si kọ lati tu silẹ.
Ọrọ tun gba ọna miran yọ nigba ti ileeṣẹ ọtẹlẹmuyẹ Naijiria tun gbe ninu ile ẹjọ, lẹyin wakati mẹrinlelogun ti wọn tu silẹ.
Iwa ti awọn DSS hu yi mu ki awọn eeyan bẹnu atẹ lu wọn ni Naijiria ati lẹyin odi.
Lọjọ aisun ọdun Keresi to kọja, agbẹjọro agba Naijiria, Abubakar Malami fi atẹjade sita pe, awọn ṣetan lati tu Sowore ati akẹgbẹ rẹ silẹ ni ibamu pẹlu aṣẹ ile ẹjọ.
Osogbo Photographer:
Yiyọju si ile ẹjọ loni ni igba akọkọ ti wọn yoo bẹrẹ igbẹjọ ẹsun ti wọn fi kan ni pẹrẹwu niwaju adajọ.
Amotekun: Ìjọba ìpínlẹ̀ Oyo, Ogun, Ondo ní ìyókù kù sí ọwọ́ asòfin ìpínlẹ̀
Oríṣun àwòrán, Tolu ogunlesi
Ijọba ipinlẹ Oyo, Ondo ati Ogun ti buwọlu abadofin ọdun 2020 to gbe ikọ amọtẹkun kalẹ ni ipinlẹ naa.
Nibi ipade ajọ amuṣẹya ni awọn ipinlẹ naa ni wọn ti buwọlu abdofin naa, ti yoo wa lo si ile igbimo asofin ibilẹ nibi ti wọn yoo ti jiroro lori rẹ.
Ipade naa to waye ni ilu Ibadan ni wọn ti jiroro lori ohun ti abadofin naa da le lori ati ohun ti wọn gba laaye fun ikọ naa.
Kí lo tíì rí  nípa Amotekun? Ẹ sùnmọ́bí, ẹ wo gbankọgbì!
Kọmisọnna fun eto idajọ ati agbẹjọro agba ni ipinlẹ naa sọ wi pe gomina ipinlẹ ogun sa ipa rẹ lati mu ki eto naa gberu si.
O ni awọn fi aaye gbawọn lati da duro,bakan naa ni awọn fayegba ibaṣepo to dan mọran laarin ẹka naa ati ẹka eleto aabo to ku ni ipinlẹ mẹfa ni iwọ oorun Naijiria.
Oríṣun àwòrán, Facebook/SEyi Makinde
Kọmisọnna fun eto idajọ ati olootu naa sọ wi pe o da awọn loju pe awọn asofin yoo ri daju pe abadofin naa kẹsẹjari, ki gomina naa le fowosi laipẹ.
Ni ipinlẹ Ogun, awọn igbimọ amuṣẹya naa gbe abadofin naa kalẹ lati le wa ọna abayọ so eto aabo to mẹhẹ,ti awọn igbimọ amuṣẹya naa si pa ohun pọ fẹnu ire pe e.
Oríṣun àwòrán, @NGRPresident
Bakan naa ni awọn igbimọ amuṣẹya naa ni ibaṣepọ to danmọran ti wa laarin awọn olootu ijọba mẹfa naa, ti wọn si jọ panupọ lori isoro naa.
Osu Kini, ọdun 2020 ni ipinlẹ mẹfa ni ẹkun iwọ orun Naijiria fowosowọpo lati da eto aabo awarawa silẹ , amọ wọn nilo ofin lati gbe duro daadaa.
Ìkede ti jáde pe ẹnikẹni to ba na tabi kọju ija si osisẹ ikọ Àmọ̀tẹ́kùn lẹ́nu iṣẹ́, yóò fi ẹ̀wọ̀n osù kan jura àti ko san ẹgbẹ̀rún lọna igba naira ati abọ.
Bakan náà, wọ́n ko le fi òfin de ọmọṣẹ Amotẹkun fún òhun kohun to ba ṣe lásìkò tó ba wà lẹ́nu iṣẹ́.
Àṣegbé ni ohunkóhun tí òṣìṣẹ́ aláàbò náà bá ṣe lẹ́nu iṣẹ́
Eyi ni ni ọkàn lára ẹsẹ ofin to wà ninu àbádofin to de isọwọ sisẹ ikọ Amotekun nipinlẹ Ekiti, (Ekiti State Security Agency Bill) ti ọdun 2020, èyi to ti wà niwaju ile igbimọ aṣòfin bayii.
Oríṣun àwòrán, @DAWNCommission
"Gẹ́gẹ́ bi abala kẹrindinlogoji abadofin náà ṣe sọ, ""ẹnikẹni to ba gbiyanju lati di Amọtẹkun lọ́wọ́ láti ṣe ojuṣe wọ́n, lù u tàbi pa a lára lọnà àitọ lẹ́nu iṣẹ́, ti ṣẹ lábẹ́ òfin, yóò si fi ẹwọ̀n àti ẹgbẹrun lọ́na igba àti ààbọ̀ naira jura."
Oríṣun àwòrán, facebook/Amotekun
Ọjọ kẹsan an Oṣu Kinni ọdun yii ni awọn gomina ipinlẹ mẹfa lati ilẹ Yoruba ṣe ifilọlẹ ikọ Amọtẹkun nilu Ibadan
Awọn Gomina ìhà Guusu-Iwọ-òòrun to ku náà ti fi abádòfin wọ́n, siwáju ilé ìgbàmọ àsòfin ìpínlẹ̀ koowa wọ́n.
Bakan náà ni òfin tun sọ pé, olori ilé iṣẹ́ Amotẹkun gbọdọ jẹ́ oṣìṣẹ́ fẹ̀yìnti lẹ́nu iṣẹ́ ologun tabi agbofinro.
Osogbo Photographer:
O gbọdọ ni ìmọ iṣẹ náà, o kere tan ọdun mẹwàá, ti abadofin náà si kan kọmisona ọlọpàá ipinlẹ náà àti adele ilé iṣẹ́ ọmọogun.
Abadofin náà tun fààye gba ìdásílẹ̀ àjọ Amọtẹkun, ti ko si gbọdun din ni sáà ọdun mẹrin.
Ilaro Poly: Ààrẹ ẹgbẹ́ akẹ́kọ̀ọ́ ní ṣọ́ọ́ṣì ni òun ń lọ, àmọ́ òun tó bára òun nínú igbó fún ìbúra ẹgbẹ́ awo
Oríṣun àwòrán, Others
Aarẹ ẹgbẹ awọn akẹkọ nile ẹkọ gbogbonse Poly ti Ilaro, Adegboye Olatunji, ti aṣiri tu nijooni pe o wa ninu ẹgbẹ okunkun ti salaye pe awọn ọmọ ẹgbẹ okunkun kan ni wọn fi oogun mu oun lati darapọ mọ wọn.
Olatunji, lasiko ti olu ileesẹ ọlọpa nipinlẹ Ogun n safihan rẹ pẹlu awọn afurasi bii mẹtadinlọgọrin miran fun oniruuru ẹsun to nii se pẹlu iwa sise ẹgbẹ okunkun, ifiyajẹni, ipaniyan ati idigunjale eyi to waye ni olu ileesẹ ọlọpa ni Eleweran, lo ti sọ bẹẹ.
O fikun pe ni ile ijọsin ni oun nlọ lasiko ti oun ko mọ oun ti oun n se mọ, ti oun si ba ara oun ninu igbo pẹlu awọn ọmọ ẹgbẹ okunkun naa ti wọn n sebura fun oun.
Aarẹ ẹgbẹ awọn akẹkọ naa ni asiko ibura naa ni awọn ọlọpa de, ti wọn si ko oun mọ awọn ọmọ ẹgbẹ okunkun, bẹẹ ni oun kii se ọmọ ẹgbẹ okunkun amọ ko ye oun bi oun se ba ara oun ninu igbo fun ibura imulẹ.
Ọja Arena Oshodi ni àwọn èèyàn ti ń r'aja
Ile ijọsin ni mo n lọ lọjọ Isinmi nilu Ilaro ni deede aago meje aarọ, koda ọga ileewe wa gan n lọ sile ijọsin naa, to si korira ohunkohun to ba jọ mọ iwa sise ẹgbẹ awo.
Bakan naa lo wa kede pe ọwọ tawọn alasẹ ileewe oun gba mu isẹlẹ yii ko dun mọ oun ninu nitori pe wọn ko se iwadi to yẹ lori rẹ.
Osogbo Photographer: Adediran rọ àwọn òbí láti jẹ́ kí ọmọ ṣe iṣẹ́ tó bá wù ú
Osogbo Photographer:
Ori lo mọ isẹ asela, Yooba si ni ori ẹni ki ba ibusun, sebi ko ba tun ibẹ se.
Bẹẹ ni ọrọ ri fun ilumọọka ayaworan kan nilu Osogbo, Beta Adewale Adediran, ẹni to wu awọn obi rẹ ko di dokita onisegun oyinbo amọ to kuna, to si pada di alaseyọri ayaworan.
Lasiko to n ba BBC Yoruba sọrọ, Adediran ni se ni oun n fidi rẹmi ni kilaasi sayẹnsi ti oun wa, titi ti wọn fi le oun kuro nileewe naa, ti oun si lọ sile ẹkọ miran.
Adediran ni ileewe miran ni oun ti bọ si kilaasi isẹ ọna, ti oun si n se daada, titi ti oun fi di ayaworan, to si rọ awọn obi lati maa gba awọn ọmọ wọn laaye lati se ohunkohun to ba wu wọn, dipo ki wsn maa fi agidi mu wọn lati se ohun tawọn ọmọ ko fẹ.
Sunday Igboho: Òǹyẹ̀ kankan kò lè yẹ àgbékalẹ̀ Amotekun nílẹ̀ Yorùbá
Oríṣun àwòrán, Instagram/sunday_igboho
Ilumọọka olokoowo ati ajafẹtọ awujọ, Oloye Sunday Adeyemo, ti ọpọ eeyan mọ si Sunday Igboho, ti woye pe onyẹ kankan ko le yẹ ikọ alaabo Amotekun.
Sunday Igboho woye ọrọ yii nigba to n sọ ero rẹ lori oniruuru atako to n waye nipa agbekalẹ ikọ alaabo ọhun, tawọn gomina mẹfẹẹfa lẹkun iwọ oorun guusu Naijiria da silẹ.
Igboho, nigba to n fesi si ọrọ asaaju ẹgbẹ Miyetti Allah nipinlẹ Bauchi, Alhaji Sadiq Ahmed, to ni ki ijọba wọgile ikọ naa nitori pe, ko si aabo mọ lati gbe nilẹ Yoruba nitori agbekalẹ ikọ Amotekun.
Ahmed ni ikọ Amotekun jẹ idunkooko nla mọ isọkan orilẹede Naijira, lasiko to ba bẹrẹ isẹ aabo ẹmi ati dukia lẹkun naa.
O fikun pe, wọn se agbekalẹ ikọ Amotekun lati ba okoowo awọn ara oke ọya jẹ ni, ko si tun lee da wọn lọwọ kọ lati se ọrọ aje wọn lẹkun iwọ oorun guusu Naijiria.
Amọ nigba to n fun Ahmed lesi ọrọ rẹ, Sunday Igboho se apejuwe ọrọ yii bii iwa anikanjọpọn ati eyi ti ko boju mu.
"Gbogbo eeyan lo mọ awa Yoruba pe a ko ni mọra, ta si tun ni ifarada nipa awọn ara oke ọya, paapaa lasiko ti wọn ba tọ wa nija.
Nitori naa, asisọ ọrọ ni ki eeyan kan ni Amotekun n dunkooko mọ oun tabi jẹ ewu fun aabo ẹmi ati dukia, ọrọ naa ko ye mi."
Obateru Akinruntan: Wíwá ohun tá jẹ títí láé ló gbé wa kúrò nílé Ife
Igboho tẹsiwaju pe, wọn se agbekalẹ ikọ alaabo ọhun lati daabo bo ẹmi ati dukia nilẹ Yoruba ni lai naani ẹya, ẹsin ti ẹni kọọkan n se.
Amọ ki eeyan kan wa woye pe agbekalẹ ikọ alaabo Amotekun to wa lati gbe ijọba nigbọnwọ, ni yoo ba ọrọ aje awọn eeyan kan jẹ, jẹ iwa aimọkan ati ọna lati ba erongba rere agbekalẹ ikọ Amotekun jẹ.
Oríṣun àwòrán, Sunday Igboho
Ọrọ di boo lọ, ko yago fun mi ladugbo Soka nilu Ibadan lasiko ti gende meji to gbe ohun ija oloro lọwọ, ti wọn pe ara wọn ni ọmọ onilẹ ya bo agbegbe naa.
Owurọ ọjọ Isẹgun ana niroyin gba igboro Ibadan kan, tawọn eeyan si n pe sori redio gbogbo nilu naa pe ẹmi awọn eeyan to n gbe ladugbo naa ko de tori awọn gende agbebọn to ya bo wọn.
A gbọ pe se ni iro ibọn n dun lakọ-lakọ, tawọn eeyan si n sa asala fun ẹmi lasiko ti awọn ọmọ onilẹ ọhun ni ki awọn onile gbe ile wọn kuro lori ilẹ awọn.
Se lawọn ọmọde ati agba, alaboyun ati awọn iyalọmọ, to fi mọ awọn arugbo n sa asala fun ẹmi wọn, ti awọn to si laya lati beere pe ki lo fa isẹlẹ naa, jẹ ajẹkun iya.
Oríṣun àwòrán, Sunday Igboho
Ẹnikan ti isẹlẹ naa soju rẹ salaye pe ọpẹlọpẹ asaaju ọmọ Yoruba kan, Oloye Sunday Adeyẹmọ, ti gbogbo eeyan mọ si Sunday Igboho to tete de sadugbo ọhun lasiko ti laasigbo naa gbona janin-jani.
A gbọ pe Igboho ati ọkunrin kan ti wọn pe orukọ rẹ Babatunde Arowolo, ti gbogbo eeyan mọ si Bako, lo de lasiko lati gba awọn eeyan adugbo naa silẹ, ni kete ti aawọn ọmọ onilẹ naa si foju gaani rẹ, ni wọn ba juba ehoro.
Sunday Igboho, lasiko to n ba BBC Yoruba sọrọ salaye pe, lootọ ni oun lọ si adugbo Soka lana lati gba awọn eeyan adugbo naa silẹ lọwọ ijẹgaba awọn ọmọ onilẹ.
Sunday Igboho: Fulani kò leè dúró, táa bá lo ohun ta jogún lọ́dọ̀ àwọ̀n bàbá wa
O ni ni kete tawọn ọmọ onilẹ foju kan oun ati Bako ni wọn fẹsẹ fẹ, eyi to mu kawọn doola ofo ẹmi ati dukia ti ko ba waye latipasẹ isẹlẹ yii.
"Adugbo Soka nilu Ibadan ni mo n gbe, ti awọn agbegbọn kan si ya wọ adugbo mi lati maa dunkoko mọ awọn eeyan mi, n ko si lee la oju mi silẹ, ki n wa larọwọto, kawọn eeyan kan maa se awọn eeyan mi lese tabi pa wọn ni ipakupa.
Osogbo Photographer:
Bakan naa ni Igboho ni o ti to ẹẹmẹfa ti awọn ọmọ onilẹ naa ti ya bo awọ̀n eeyan adugbo naa, ti wọn si n yinbọn ti wọn n pa awọn mẹkunnu, ti ọpọ wọn si ti ku lai jale, to si n beere pe se gbogbo mẹkunnu lo ni owo lọwọ lati tun ilẹ ra.
Awọn ara adugbo naa ti wa rọ ijọba ipinlẹ Ọyọ lati tete da si ọrọ naa tori kii se igba akọkọ ree ti awọn ọmọ onilẹ yoo wa maa dun mahuru-mahuru mọ wọn lori ilẹ ti wọn ti ra lati ọdun gbọọrọ.
Gẹgẹ bi iroyin naa ti wi, nigba ti BBC Yoruba kan si agbẹnusọ fun ileesẹ ọlọpa nipinlẹ Ọyọ, Olugbenga Fadeyi lati gbọ tẹnu rẹ, o ni ka pe oun pada laipẹ.
MMA: Àwọn èrò ní ìwà àjẹbánu ní kò jẹ́ kí Nàíjíríà ní ohun èèlò tó yẹ ní pápákọ̀ òfurufú
Oríṣun àwòrán, Others
Ijamba baalu ti ko waye lorilẹede Naijiria ni ọba oke ko wa yọ ninu rẹ nigba ti wọn dari awọn baalu to n ti oke okun bọ lọsan ọjọbọ oni, gba papakọ ofurufu ilẹ Ghana lọ lojiji, pe ki wọn lọ ba sibẹ.
Iroyin naa ni oju ọjọ ti ko dara ati ohun eelo igbalode kan to se pataki fun baalu lati ba ni papakọ ofurufu Muritala Muhammed tọjọ ti lọ lori rẹ, lo fa sababi bi wọn se dari awọn baalu naa lọ si papakọ ofurufu ilẹ Ghana.
A gbọ pe lara awọn baalu ilẹ okeere ti wọn pasẹ fun lati dori kọ papakọ ofurufu Ghana ni Baalu ilẹ Gẹẹsi, British Airways to n bọ lati London, baalu Delta to n bọ lati orilẹede Amerika ati baalu Emirates to n bọ lati Dubai.
Oríṣun àwòrán, Others
ọkan lara awọn ero to wa ninu baalu ilẹ Gẹẹsi, Olayiwola Zaid ni ko si ohun eelo igbalode tiyoo gbalẹmọ fun baalu lati ba, lo fa sababi, to si nira fun baalu awọn lati ba nitori pe o tobi pupọ, bi o tilẹ jẹ pe awọn baalu miran ba ni Eko laisi ewu.
O ni gbogbo awọn ero to wa ninu baalu naa ni aya awsn ko ja, ti skan awsn si balẹ lasiko tisẹlẹ abanilẹru  naa n waye, ti awọn ko si gbo awakọ baalu tabi awọn osisẹ lẹnu titi to fi balẹ.
Oríṣun àwòrán, Others
Gbogbo ero ti isẹlẹ naa kan ni ẹnu wa n ya pe ki lo de ti papakọ ofurufu bii Muritala Muhammed ko fi ni awọn ẹrọ igbalode to yẹ fun baalu lati gbera ati lati ba silẹ.
 O ya mi lẹnu pe nitori ọyẹ lasan lasan, baalu ko le ba si Naijiria, nigba to jẹ pe awọn orilẹede miran ti oju ọjọ wọn buru jai, ti yinyin si maa n bọ, n faaye gba baalu lati ba. Eyi safihan bi iwa ajẹbanu  se ba ọrọ aje Naijiria jẹ, to si n fa aago idagbasoke wa sẹyin, titi to fi kan papakọ ofurufu ilẹ wa."""
Osogbo Photographer:
Awakọ baalu naa ni o nira fun ohun lati riran daada pẹlu bi oju ọjọ se ri, ti Naijiria ko si ni ẹrọ igbalode to lee seranwọ lati fi balẹ, bẹẹ si ni baalu to balẹ bẹẹ lọjọ Isẹgun ana bajẹ ni.
Victor Olaiya: Ẹni ọdún 89 ni àgbà olórin tó jáde láyé!
Oríṣun àwòrán, Others
Lára àwọn àwo orin tí Baba náà kọ ní Omo Pupa, Mofe Mu Yan, Omolanke tí ó gbé jáde ní ọdún 2018 wà lára àwọ orin rẹ̀.
Victor Abimbola Olaiya ti gbogbo eniyan mọ si Victor Olaiya ti jade laye ni ẹni ọdun mọkandinlọgọrin.
Baba Victor Olaiya jẹ gbajugbaja onifere ti o ma n korin igbalode, iyẹn highlife.
Bi o tilẹ ṣepe Victor Olaiya gbajugbaja ni orilẹede Naijiria gẹgẹ bi ọkan gboogi lara awọn olorin ni Naijiria.
Ọjọ Kejila, Osu Keji, ọdun 2020 ni arakunrin naa jade laye lẹyin aisan ranpẹ ni ile iwosan ikọni ti ipinlẹ Eko.
Ọpọlọpọ awọn ololufẹ agbaọjẹ olorin, Victor Olaiya lo n ba ebi ati ara oloogbe naa kẹdun lẹyin to jade laye.
Lori oju opo ikansiraẹni Twitter ni awn ololufẹ olorin oun ti n ranti gbogbo ipa ribiribi to ko fun igbelaruge asa, ede ati orin ni orilẹede Naijiria ati Ilẹ adunlawọ lapaapọ.
Bakan naa ni awọn ololufẹ rẹ wa gbadura fun ẹbi, ara ati ọrẹ ti o fi silẹ si aye lo.
Joseph Yobo ni igbákejì akọ́nimọ̀ọ́gbá Super Eagles tuntun - NFF
Oríṣun àwòrán, @NGfooty
Ajọ to n ri si ọrọ ere bọọlu ni Naijiria, NFF ti kede Joseph Yobo gẹgẹ bi igbakeji akọnimọgba ikọ naa tuntun.
Yobo bọ si ipo yii lẹyin ti wọn fi ọwọ osi juwe ile fun  Imama Amapakabo to di ipo na mu tẹlẹ.
Ki Yobo to de ipo tuntun yii, o ti fi igba kan jẹ balogun ikọ Super Eagles to si ṣe aṣeyọri ninu idijẹ ifẹ ẹye ti ilẹ Afrika to waye lọdun 2013.
Yobo ni ọpọ iriri gẹgẹ agbabọọlu latari bo ṣe ti gba bọọlu ni oriṣiriṣi ẹgbẹ agbabọọlu kaakiri agbaye.
O gba igbega si ikọ Super Eagles lẹyin to ṣoju orilẹ-ede Naijiria ninu idije ọjẹ wẹwẹ ti ọjọ ori wọn ko ti ju ogun ọdun lọ lọdun 1999.
Ko ti di pe Yobo fẹyinti gẹgẹ agbalọọlu fun ikọ Super Eagles, o ti kopa ninu idioje ife ẹyẹ agbaye nigba mẹta, ati ninu idije ife ẹyẹ ilẹ Afrika nigba mẹfa.
Lara awọn ẹgbẹ agbabọọlu ti Yobo ti ṣeṣẹ tẹle ni ikọ Olympique Marseille, Everton, Norwich City ati Fenerbahçe.
Ọja Arena Oshodi ni àwọn èèyàn ti ń r'aja
Insecurity: Àwọn aráàlú ní ìpànìyàn àti ìgbéṣùnmọ̀mí ni kò jẹ́ kí ẹnu sìn lára Buhari
Oríṣun àwòrán, Others
Nkan ko ṣẹnu re fun aarẹ orileede Naijiria lẹnu ọjọ mẹta yii, pẹlu bi awọn ara ilu ṣe n fi ẹhonu han si iṣejọba rẹ.
Yatọ si awọn ti o n bẹnu atẹ lu loju opo ayelujara, awọn ara ilu tun safihan pe inu awọn ko ṣe dun loju koroju pẹlu aarẹ Muhammadu Buhari nipinlẹ Borno.
Lasiko to ṣe abẹwo ibanikẹdun si awọn eeyan Maiduguri, n ṣe ni awọn ara ilu n pariwo pe awọn ko fẹ ẹ mọ.
Fọnran fidio kan, eleyi to ṣe afihan iṣẹlẹ yii ti gba oju opo Twitter kaakiri, ti awọn ọmọ Naijiria si ti n sọ pe bi aarẹ ko ti ṣe mojuto eto aabo ko jẹ ohun  to dun mọ awọn.
Lẹnu ọjọ mẹta yii, ọwọja ikọlu Boko Haram, paapa julọ ni ipinlẹ Borno, fẹ peleke.
Ni ọjọ Aiku ni ikọ naa dana sun awọn arinrinajo to to ọgbọn, mọ inu ọkọ ni Auno.
Oríṣun àwòrán, @wampa80
Saaju igba naa, wọn ṣe ẹmi awọn ara ilu kanna legbodo ni ilu Gamboru, lẹyin ti wọn yin ado oloro lori afara kan nibẹ.
Awọn iṣẹlẹ yii ati awọn miran to n waye jakejado Naijiria, lo mu ki awọn ara ilu gba oju opo Twitter lati sọ pe, awọn ko fara mọ bi aarẹ Buhari ko ti ṣe mu ọrọ aabo ni koko.
Mo ma gbe igbesẹ lati koju ipenija aabo:
Aarẹ Buhari lasiko abẹwo rẹ ba awọn ara ilu Maiduguri kẹdun, ti o si sọ pe oun yoo tẹramọ igbiyanju lati koju ipenija aabo to n ba wọn.
O rọ awọn olori ilu lati tubọ ma pawọpọ pẹlu awọn ọmọ ogun nipa titawọn lolobo iroyin nipa awọn agbesunmọmi.
Aarẹ Buhari ko yọju si ilu Auno ti iṣẹlẹ ikọlu ti Boko Haram ti pa to eeyan ọgbọn ti waye.
Oríṣun àwòrán, @SegunAde88
Se ni awọn ilu Maiduguri tii se olu ilu ipinlẹ Borno, tu ya ya jade lọjọru lati pade aarẹ ilẹ wa, Muhammadu Buhari to se abẹwo sipinlẹ naa.
Amọ yatọ si ijo ati ọyaya tawọn araalu fi saba maa n pade aarẹ to ba wa bawọn lalejo, se ni awọn eeyan yii fi orin abuku pade aarẹ Buhari, ti wọn si n pariwo pe awọn ko fẹ, awọn ko nifẹ si.
Niwọn igba to si jẹ pe ẹni to moju naa ni aarẹ, oun naa ko si sopo bọ awọn ọba alaye to duro lati kii kaabọ lọwọ, ti ko si tun se abẹwo si awọn agbegbe Auno, ti ikọlu ti waye lọjọ Aiku to kọja.
Oríṣun àwòrán, @SegunAde88
"Nigba to n salaye idi ti eyi fi ri bẹẹ, Garba Shehu tii se oludamọran agba si aarẹ lori eto iroyin ni ""ko si idi fun aarẹ lati lọ si Auno, abẹwo aarẹ si ni lati bawọn eeyan ipinlẹ Borno lapapọ kẹdun nipa ajalu to ba wọn."""
Oríṣun àwòrán, @SegunAde88
Nigba to n bawọn eeyan sọrọ lẹnu abẹwo rẹ naa, aarẹ Muhammadu Buhari ni ole kii ja agba, ko ma se loju firi, nitori naa lai si atilẹyin awọn araalu, ko seese fun ẹnikẹni lati wa kọlu agbegbe kankan.
Oríṣun àwòrán, @SegunAde88
"Ẹyin eeyan Borno, bawo lo se rọrun fun ikọ Boko Haram lati maa rọwọ mu di akoko yii lai ni atilẹyin yin ninu? Mo si n rọ yin lati fọwọowọpọ pẹlu awọn agbofinro, ẹ mase gba ikọ Boko Haram laaye lati de ọdọ awọn araalu, mo si n rọ awọn ti wọn le kuro nile wọn lati pada sile.
World Radio Day: Àwọn òṣìṣẹ́ rédíò ní àwọn ń pa ìsòro àwọn mọ́ra ni láti mú inú aráàlú dùn
Buhari ni oun ti setan lati se agbekalẹ awọn ilana to gbopọn lati sẹ eegun ẹyin ikọ Boko Haram, to si tẹnumọ pe sise alabapin iroyin laarin awọn araalu atawọn agbofinro si ni ọna abayọ si aseyọri.
Insecurity: Ọọ̀ni ni báwọn ọba alayé ṣe lọ́wọ́ nínú àgbékalẹ̀ Amotekun, ni yóò ṣe tọ́jọ́
Oríṣun àwòrán, From The Palace of Ooni of Ife
Yoruba ni agba kii wa lọja kori ọmọ tuntun wọ, bẹẹ si ni agba ti ko ba kẹhun sọrọ, afaimọ ko ma kẹtan sare.
Boya eyi lo mu ki Sultan ilu Sokoto, Alhaji Sa'ad Abubakar Kẹta fi n lọgun too fun awọn ọba alaye pe wọn ti n dakẹ pupọ ju lai sọrọ lori eto aabo to mẹhẹ ni Naijiria, tori bi ara ile ẹni ba n jẹ kokoro buruku, ti a ko ba wi fun, hẹrẹhuru rẹ ko ni jẹ ka sun loru.
Sultan parọwa yii nilu Osogbo lọjọbọ lasiko to n sọrọnibi ipade apero lori eto aabo ati aifararọ ni Naijiria eyi ti ibudo kan to wa fun agbelarugẹ asa ilẹ adulawọ seto.
Oríṣun àwòrán, From The Palace of Ooni of Ife
Sultan, ẹni to n fi ika gun awọn ọlaju lawujọ nimu pe se ni wọn n lo awọn mẹkunnu ti ko ni nkankan lati gba ohun ti wọn n fẹ, tun rawọ ẹbẹ sawọn ọba alaye pe ki wọn maa pariwo sita nipa isoro to n koju orilẹede yii, wọn sa ni igi gogogro ma gun mi loju, ati okeere laa tii lọọ.
Bakan naa, ni ọba alaye ọhun ẹni to tun gbarata lori ebu ẹyin to n ba ipese awọn ohun eelo amayedẹrun lorilẹede yii, wa ran awọn ọba alaye leti pe lati ọdun gbọọrọ wa ni wsn ti n se akoso awujọ wọn, ki ijọba to gba wọn sẹyin lọdun 1914, ti isopọ waye ni Naijiria.
Oríṣun àwòrán, From The Palace of Ooni of Ife
A ko lee ni alaafia ati eto aabo to peye nigba ti a ko ni isejọba rere ati idajọ ododo. Ohun ti awọn baba nla wa se ree, a si gbọdọ dide si ipenija yii, nitori nkan ko sẹnu re rara ni, Tẹ ba si dakẹ, ti ẹ ko dide lati seranwọ fun awọn oloselu lori isẹlẹ yii, a jẹ pe awa gangan jẹ ara isoro naa."""
Sultan tun gba awọn ọba alaye nimọran lati maa sọ otitọ lai bẹru pe gomina abi awọn alaga ijọba ibilẹ yoo dunkoko mọ wọn. O ni to ba da yin loju, ẹ sọ ọrọ sita, kẹ si duro lori rẹ.
World Radio Day: Àwọn òṣìṣẹ́ rédíò ní àwọn ń pa ìsòro àwọn mọ́ra ni láti mú inú aráàlú dùn
Nigba to n sọrọ, Ọọni tilu Ile Ifẹ, Ọba Ẹnitan Adeyeye Ogunwusi, Ọjaja Keji ni nitori pe awọn ọba alaye lọwọ si eto aabo Amotekun, ni yoo se fidi mulẹ, to si rọ ijọba lati maa jẹ kawọn ọba alaye lọwọ ninu agbekalẹ eto aabo lagbegbe wọn.
Revolution Now: Adájọ́ ṣún ìgbẹ́jọ́ sí March 11, 12 àti 13
Ileẹjọ tun ti sun igbẹjọ siwaju lori ẹjọ ẹṣun ete lati ditẹgbajọba ti ijọba apapọ pe asaaju ẹgbẹ ajijagbara Revolution Now, Omoyele Sowore.
Lọjọbọ ni igbẹjọ naa bẹrẹ nile ẹjọ giga to wa nilu Abuja eyi ti Adajọ Ijeoma Ojukwu ko sodi, ti adajọ si pasẹ pe ki ijọba apapọ san owo gba ma binu fun Sowore lori bo se n fi ẹjọ naa falẹ.
Nigba to yọju sile ẹjọ loni, Omoyele Sowore ati ẹnikeji rẹ ti wọn dijọ n jẹjọ, Bakare sọ fun ileẹjọ pe awọn ko jẹbi ẹsun onikoko meji tijọba apapọ fi kan awọn, ti adajọ̀ si fidi rẹ mulẹ pe, ijọba apapọ ti san owo naa.
Lasiko igbẹjọ naa si ni igun olupẹjọ se atunse si awọn ẹsun to fi kan Sowore eyi to nii se pẹlu didi ọtẹ lati gba ijọba ati iditẹ lati gbajọba.
Bamubamu si lawọn agbofinro pe sile ẹjọ lasiko ti igbẹjọ naa bẹrẹ, ti wọn ko si fẹ ki agbofinro ya fọto Soworẹ.
Bakan naa si lawọn ọmọ ẹgbẹ ajijagbara Revolution Now peju sile ẹjọ, ti wọn si gbe oniruuru aksle lọwọ eyi ti wọn fi n sọ nipa ohun ti ẹgbẹ wọn duro le lori.
World Radio Day: Àwọn òṣìṣẹ́ rédíò ní àwọn ń pa ìsòro àwọn mọ́ra ni láti mú inú aráàlú dùn
Adajọ Ojukwu ti wa sun igbẹjọ naa siwaju di ọjọ Kọkanla, ikejila ati ikẹtala osu Kẹta ọdun 2020.
Madam Saje: Lónìí ọjọ́ ìbí mi, mo bẹ Ọlọ́run kí ń má jajé ọmọ mi m‘áyé
Sajẹ: Mo n rọ awọn akẹẹgbẹ mi lati se suuru de asiko Ọlọrun
Ọjọ Kẹtala Osu Keji ọdun ni ọjọ ibi Alhaja Fausat Balogun, ti gbogbo eeyan mọ si Madam Sajẹ ninu ere tiata.
Lọdun 2020 yii si lo pe ọdun mọkanlelọgọta loke eepẹ, to si n dupẹ lọwọ Ọlọrun fun idasi ẹmi.
Lasiko to n ba BBC Yoruba sọrọ, Madam Sajẹ rọ awọn akẹẹgbẹ rẹ ti wọn jẹ osere ori itage lati mase kanju kọja kadara nitori ibukun Oluwa nii mu ni la, laifi laala kun.
Bakan naa lo bẹ Ọlọrun pe ko si bi oun ti se dagba tabi lokiki to, oun ko fẹ jẹ aye ọmọ oun maye.
Sunday Igboho: Alukoro ọlọ́pàá Ọyọ ní àwọn ọlọ́pàá kọ́ ló kọlu aráàlú, iṣẹ́ wọn ni wọ́n ń ṣe
Oríṣun àwòrán, Instagram/Sunday_igboho
Ileesẹ ọlọpa nipinlẹ Ọyọ ti salaye ohun to mọ nipa rogbodiyan to waye ladugbo Soka lọjọ Isẹgun eyi to pagidina alaafia ilu.
Lasiko to n ba BBC Yoruba sọrọ, alukoro fun ileesẹ ọlọpa nipinlẹ Ọyọ, Olugbenga Fadeyi salaye pe ohun to mu ki awọn ọmọ onilẹ lọ si adugbo Soka lọjọ naa ko sẹyin ilakaka wọn lati fidi idajọ ileẹjọ to ga julọ mulẹ.
Fadeyi ni awọn ọlọpa to wa nibi isẹlẹ naa lo tẹle akọwe ileẹjọ to tẹle awọn eeyan ti wọn pe ni awọn ọmọ onilẹ lọ si adugbo naa, lati ri pe asẹ ileẹjọ fidi mulẹ, kii si se pe awọn ọlọpa naa n gbeja awọn ọmọ onilẹ.
Oríṣun àwòrán, Others
Eyi si lo tako iroyin to n ja rainrain nilẹ kiri pe, awọn ọlọpa to le ni ọọdunrun niye, to tẹle awọn ọmọ onilẹ meji naa, to fẹ wa gba ilẹ wọn, lo n fiya jẹ awọn ara adugbo Soka yii, ti wọn fi n sa kijokijo kiri.
Alukoro ileesẹ ọlọpa ni asiko ti akọwe ileẹjọ ati awọn ọmọ onilẹ fẹ se amusẹ idajọ ileẹjọ to da wọn lare, lawọn eeyan kan to pe ni 'Janduku' jade sita si wọn, ti wọn si kọlu wọn, eyi to mu ki laasigbo waye nibẹ.
World Radio Day: Àwọn òṣìṣẹ́ rédíò ní àwọn ń pa ìsòro àwọn mọ́ra ni láti mú inú aráàlú dùn
Fadeyi wa fidi rẹ mulẹ pe Kọmisana ọlọpa nipinlẹ Ọyọ ti pasẹ pe ki  iwadi bẹrẹ lọgan lori ohun to fa rogbodiyan to waye lagbegbe Soka ọhun, ni kete ti iwadi naa ba si ti pari lawọn yoo kede fun araye gbọ.
Bẹẹ ba gbagbe, ọjọ Isẹgun ni iroyin gbalẹ kan pe awọn ọmọ onilẹ meji ti n pagidina omi alaafia lagbegbe Soka, ti awọn ara adugbo ibẹ si n sa kijokijo kiri.
Iroyin naa ni ọpẹlọpẹ asaaju Yoruba kan, Oloye Sunday Adeyẹmọ, ti gbogbo eeyan mọ si Sunday Igbohoati ẹnikeji rẹ, Bako, to gba wọn silẹ lọwọ wahala naa.
Nigba to si n fidi isẹlẹ naa mulẹ fun BBC Yoruba, Igboho ni lootọ loun dide lati gbeja awọn eeyan oun ladugbo Soka,nitori adugbo naa ni oun n gbe, ikọlu awọn ọmọ onilẹ si awọn mẹkunnu to wa nibẹ si ti n di lemọlemọ bayii.
Bayelsa Guber update: Atiku ní àwọn adájọ́ fihàn pé ọwọ́ aráàlú lagbára sì wà
Oríṣun àwòrán, Facebook/Atiku Abubakar
Gbọingbọin lawọn ọmọ orilẹede Naijiria wa lẹyin ile ẹjọ giga julọ, oludije fun ipo aarẹ labẹ aisa ẹgbẹ oṣelu PDP ninu ibo gbogbogbo to lọ, Atiku Abubakar lo sọri lẹyin ti ileẹjọ yẹ aga mọ oludije ẹgbẹ oṣelu APC ninu ibo gomina nipinlẹ Bayelsa nidii, David Lyon.
Ọla ọjọ Ẹti ló yẹ kí wọ́n búra fún David Lyon gẹgẹ bi gomina tuntun ipinlẹ Bayelsa ki ileẹjọ to ga julo to paṣẹ pe olùdíje PDP Sẹnẹtọ Douye Dirini ni yoo gori aga gomina ipinlẹ naa.
Ileẹjọ ni igbakeji oludije ẹgbẹ osélu APC Biobarakuma Degi-Eremienyo to lo ayederu iwe ẹri lo ṣakoba fun Ọgbẹni Lyon ti ajọ INEC kọkọ kede pe oun lo jawe olubori.
Ninu ọrọ rẹ, Atiku ni pẹlu idunnu loun fi gba iroyin idajọ ile ẹjọ to ga julọ pe oludije ẹgbẹ oṣelu PDP ni yoo ṣe gomina ipinlẹ Bayelsa bayii.
''Awọn adajọ tun ti fihan pe ọwọ awọn araalu ni agbara wa, amọ ileẹjọ to ga julọ ni lati maa da ẹjọ lai ṣegbe lẹyin ẹnikan,'' Atiku lo sọ bẹẹ.
Oríṣun àwòrán, @others
Atiku rọ awọn eeyan ipinlẹ Bayelsa lati gba alafia laaye, lẹyin idajọ ileẹjọ to ga julọ l'Ọjọbọ.
Àwọn ọmọ Naijiria sọ̀rọ̀ lẹ́yìn tí ilé ẹjọ́ tó ga jùlọ yẹgi mọ́ Olùdíje gómìnà APC ní Bayelsa nídìí
Ni kete ti ile ẹjọ to ga julọ ni Naijiria da ibo to gbe David Lyon nu ni ipinlẹ Bayelse, awọn ọmọ Naijiria ti bẹrẹ si ni fi eroungba wọn lede lori idajọ ọhun.
Kola Ologbondiyan to jẹ alukoro apapọ fun ẹgbẹ oṣelu Peoples Democratic Party, PDP, ki awọn ọmọ ẹgbẹ naa ku ori ire lori idajọ ọhun.
"Comrade Mayor ni tirẹ sọpe ""Ogo fun Ọlọrun... Awọn eeyan ipinlẹ Bayelsa ti gba ohun to jẹ tiwọn."""
Ni ti Efadi Gold9ja, o sọ pe oun fẹran idajọ naa, ati pe inu oun dun lati wa laye lasiko ti iru idajọ bẹẹ waye.
Bi inu awọn kan ṣe n dun ti wọn si faramọ idajọ naa, awọn mii n sọ pe idajọ ọhun kii ṣe idajọ ododo.
Benin Finest ni ẹgbẹ PDP ni ẹgbẹ ti ko wulo julọ ninu gbogbo oṣelu to wa ni Naijiria.
Oríṣun àwòrán, @AfricResource
Taitos Special ni ojoro ni idajọ to da ibo  David Lyon nu, bi bẹ kọ, o yẹ ki ile ẹjọ kan naa da ẹtọ Ihedioha to ji gbe lọ ni ipinlẹ Imo.
Ẹ wo awọn awọn ohunn mii ti awọn eeyan n sọ.
Iroyin to n tẹ wa lọwọ ni yajoyajo ti kede pe ile ẹjọ to ga julọ nilẹ wa ti wọgile ibo to gbe oludije fun ipo gomina labẹ ẹgbẹ oselu APC wọle nipinlẹ Bayelsa.
Oludije naa, David Lyon ni ajọ eleto idibo INEC kede pe oun lo jawe olubori  ninu ibo gomina to kọja, ti oun ati igbakeji rk si ti n mura feto imura.
Amọ igbimọ oludajọ ẹlẹni marun, ti adajọ Mary Odili ko sodi, ti pasẹ fun ajọ Inec lati gba iwe ẹri moyege kuro lọwọ oludije APC naa.
O fikun pe ko se iwe ẹri tuntun fun oludije fẹgbẹ PDP, pe oun lo jawe olubori ninu ibo ọhun.
Ileẹjọ giga naa ni ki ajọ eleto idibo Inec fun oludije ẹgbẹ oselu to ni ibo to pọ sikeji, to si tun ni ibo to tan iyẹ kaakiri ipinlẹ naa lasiko ibo gomina to kọja.
O ni ki wọn fun wọn ni iwe ẹri moyege ibo tuntun, to si foju han ẹgbẹ oselu PDP lo ba awọn akawe yii mu
Oríṣun àwòrán, Degi-Eremienyo
Adajọ Ejembi Ekwo, to ka idajọ naa sita lorukọ awọn adajọ yoku pasẹ bẹẹ, lẹyin to kede pe oludije fẹgbẹ oselu APC ninu ibo gomina naa, Degi-Eremienyo, ko lẹtọ lati soju ẹgbẹ oselu naa.
A ranti pe ileeẹjọ giga ijọba apapọ nilu Abuja ti fofin de Degi-Eremienyo lati dije fun ipo gomina ọhun tori pe ayederu iwe ẹru lo gbe kalẹ fun ajọ eleto idibo naa.
World Radio Day: Àwọn òṣìṣẹ́ rédíò ní àwọn ń pa ìsòro àwọn mọ́ra ni láti mú inú aráàlú dùn
Ileẹjẹ naa ni idajọ yii ti ko oludije ati igbakeji rẹ papọ nitori tikẹẹti alapapọ lati dije ni awọn mejeeji ni, ti wọn si jọ gbegba ibo papọ lọjọ kẹrindinlogun osu Kọkanla ọdun 2019 to kọja.
Ń ko dúró ṣe ìdánwò WAEC nílé ẹ̀kọ́ gírámà, kí n tó bẹ̀rẹ̀ tíátà - Kamilu Compo
Oríṣun àwòrán, kamilu kompo
Ilumọọka osere tíátà kan, Tijani Adekola, tí ọ̀pọ̀ èèyàn mọ si Kamilu Compo àbí Gọlugọ, tí kesi àwọn olólùfẹ́ rẹ láti má ṣe bá ẹnikẹ́ni dá àṣà pé ko si ohun tó ń jẹ àrùn Coronavirus.
Kamilu Compo, lásìkò to ń kópa lórí ètò BBC Yoruba ṣàlàyé pé, àrùn Covid-19 kii se ohun ti a n fi ọwọ yẹpẹrẹ mú nítorí kò tíì sí òògùn fún ìwòsàn rẹ.
Kamilu, ẹni tó kéde pé òun ti ṣètò iranwọ fáwọn olólùfẹ́ òun lásìkò igbele Covid-19 náà, tún rọ wọn láti máa tẹle àwọn ìlànà tó ń dènà itankalẹ àrùn bíi fífi ọ̀sẹ̀ fọ ọwọ, lilo ìbòjú àti títa kété síra ẹni.
Nígbà tó ń ṣàlàyé nípa ohun tó fi ń pa ọwọ dà lẹ́yìn ere tíátà, Gọlugọ ní òun sì ibùdó kan tí wọn ti ń ta bàbá Ìjẹ̀bú taa mọ si Lotto, àmọ́ ajakalẹ-arun Coronavirus tí mú kí òun gbé ilẹkun ibùdó náà tí pá.
Kamilu, ẹni tó sàlàyé bo se de ìdí ere tíátà, sísọ lójú rẹ pé, ile ẹ̀kọ́ alakọbẹrẹ ni òun ti bẹ̀rẹ̀ si ní ìfẹ́ si eré tíátà, tí òun sì darapọ mọ ẹgbẹ́ osere Seyi Adeoye.
Ọmọ bíbí ìlú Oyo ni mí, bi mo ṣe jáde kúrò nílé ẹ̀kọ́ alakọbẹrẹ, ní mo darapọ mọ ère tíátà ni ọdọ ọga mi n'ilu Oyo, ibẹ sì ni mo ti pàdé Afonja Olaniyi, tá mọ sì Sanyeri.
Oríṣun àwòrán, Sanyeri ati kamilu kompo
Ń kó ṣe idanwo WAEC tí mo fi di òní tíátà, àwọn òbí mi yín mi nù, mo bẹ̀rẹ̀ si gbe ni ọdọ ọga mi, tí mo sì ń lọ nù agolo nileesẹ búrẹ́dì láti rí owó jẹun, ebi pa mi, ìyá jẹ mi àmọ́ mo dúpẹ́ lọ́wọ́ Ọlọ́run lonii
Kamilu wa gbà àwọn èèyàn tó kú díẹ̀ kaato fún ní ìmọ̀ràn pé tí wọn ba ni sùúrù, yóò dára, kí wọn sá ni Ọlọ́run, kí wọn sì mọ ohun tí wọn ń ṣe.
Èmi àti Sanyeri tí tọrọ oúnjẹ jẹ nílé oninawo rí, wọn tí fi ada lè wá lójú agbo ìnáwó rí, tí oro si ti lè wá ni abule kan lẹba Oyo rí, ṣùgbọ́n loni, a dúpẹ́ pé Ọlọ́run gba àdúrà wa.
Kamilu ni ọdún 1996 ni òun kọ́kọ́ kópa nínú eré sinima, tí òun sì ti ṣe fíìmù méjìlá jáde, pẹ̀lú afikún pé gbogbo eka tó nii ṣe pelu fíìmù ṣíṣe ni òun mọ nípa rẹ.
Èmi àti Sanyeri nìkan là dá ṣe fíìmù ni Malaysia, àwa ní osere ati a yàwòrán, kò sì nkankan tó wà nínú ṣíṣe sinima jade, tí ń kó mọ.
Oríṣun àwòrán, kamilu-kompo
O ṣàlàyé pé, ó dára kí èèyàn ni ẹkọ tó ye kooro nínú gbogbo ohunkóhun ta bá fẹ́ ṣe, ẹnikẹ́ni tó bá di fẹ́ lu aluyọ nínú isẹ tíátà gbọ́dọ̀ ni Ọlọ́run, kò ní ìtẹríba àti apọnle àwọn ọga tó bá lẹ́nu isẹ pẹ̀lú ìfaradà àti aforiti.
Kamilu wá rọ awon eeyan tó ń sọ ahesọ ọ̀rọ̀ kiri pé òun ni ìyàwó mẹrin, pé kí wọn dẹkun sísọ ohun tí ojú wọn ko tó nítorí èyí kò rí bẹ́ẹ̀ rárá, ìyàwó kan soso ni òun ni.
Nígbà tó ń sọ̀rọ̀ nípa àjọṣepọ̀ rẹ pẹlu gbajumọ oṣere tíátà míì, Odunlade Adekola, Gọlugọ ni onirẹlẹ ẹ̀dá ni, tí kìí fi ojú pá ẹnikẹni rẹ, tó si máa ń fi ọwọ sọwọ́pọ̀ pẹ̀lú àwọn akẹẹgbẹ rẹ nígbà kuugba.
Oríṣun àwòrán, Instagram/Okunnu
Gbajugbaja adẹrinpoṣonu oṣere tiata, Wale Akorede, ti ọpọ mọ si Okunnu sọ pe ọjọ ti pe tawọn eeyan ti n sọ pe orilẹede Naijiria yoo dara.
Ọgbẹni Akorede ni lori wi pe Naijiria yoo dara naa ni baba to bi oun lọmọ ku si, Naijiria yoo dara naa lo jẹ ki oun ko idile oun lọsi oke okun.
Okunnu ni Eleduwa ti kọ ni kadara fun idile oun pe, oke okun ni wọn yoo fi ṣe ibugbe lo jẹ ki wọn wa loke okun bayii.
Ifọrọwerọ BBC Yoruba ati Akorede Okunnu ree:
Ọgbẹni Akorede ni iṣẹ oun ni ko fun oun naa lanfaani lati maa gbe oke okun pẹlu idile oun.
Oríṣun àwòrán, Instagram/Okunnu
''Lati igba ti mo ti wa nile iwe alakọbẹrẹ ni mo ti bẹrẹ ere tiata ni ṣiṣe, ṣugbọn ko si ọkan ninu baba ati iya mi to fọwọ sii pe ki n ṣiṣẹ tiata,''
Sajẹ: Mo n rọ awọn akẹẹgbẹ mi lati se suuru de asiko Ọlọrun
Ṣugbọn lẹyin ti baba mi papoda tan, mo beere iyọnda lọwọ mama mi pe, ki wọn jẹ ki n ṣe ere tiata.
Okunnu to jẹ ọmọ ile Olokiti, Ijẹru ọja niluu Ogbomoṣo ni, ilu Ibadan ni wọn bi oun si, nibi ti oun ti dagba.
Ọgbẹni Akorede ṣalaye pe, ifẹ ni iyawo oun ni to fi fẹ oun, kii ṣe owo lo wo, to fi duro ti oun di oni.
Oríṣun àwòrán, Instagram/Okunnu_1
Nigba to n sọrọ lori ija to maa n waye laarin awọn oṣere tiata to jẹ obinrin, Okunnu ni abuda awọn awọn obinrin ni lati maa ba ara wọn ja, o ni ko si iru rẹ laarin awọn ọkunrin oṣere.
''Ẹnu Ayinde Barrister ni mo ti gbọ orukọ Okunnu, ṣugbọn okun nu ni itumọ orukọ naa lẹyin ti mo ṣe iwadii lori rẹ,'' Okunnu lo woye bẹẹ.
O ni ti oun naa ba n wo 'Okunnu' ninu ere, emi gan maa n rẹrin arin takiti, amọ Wale Akorede maa n tiju gan an ti ko baa tii ri ẹrọ kamẹra.
World Radio Day: Àwọn òṣìṣẹ́ rédíò ní àwọn ń pa ìsòro àwọn mọ́ra ni láti mú inú aráàlú dùn
Ọdun mẹtala ni Okunnu fi gbe orilẹede Saudi Arabia, amọ o ni isẹ tiata ko gba oun laye lati wọ eyin Mecca, ati pe ọṣọ lasan ni eyin Mecca.
Okunnu ni wọn le sọ pe ki oun ṣe ọmuti tabi ki oun gba obinrin lọ sile itura, eleyi to tako wiwọ eyin Mecca.
Ninu esi rẹ si ọrọ ti minisita fun ọrọ iṣẹ ati ileegbe, Babatunde Fashola sọ pe ohun tawọn ọdọ n wo ninu ere tiata lo jẹ ki wọn maa ṣoogun owo, Okunnu ọrọ ko rii bẹẹ.
Oríṣun àwòrán, Instagram/Okunnu_1
''Ẹni to lọ ṣoogun owo kẹyin to wo ere tiata tan ti fẹ ṣe oogun tẹlẹ ni, kii ṣe pe ninu ere tiata lo ti rii,'' Okunnu lo woye bẹẹ.
O ni lati oun jogun ba awada ṣiṣe lati ọwọ mama oun ni, bakan naa lo sọ pe iwe ere awada lo ṣoro kọ ju laye.
Cabinet reshuffle: Sajid Javid kọ̀wé fipò Káńsélọ̀ sílẹ̀, Rishi Sunak gba ipò rẹ̀
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Wọn ti fi Rishi Sunak rọpo Sajid Javid lẹyin to kọwe fipo silẹ
Ọkan pataki lara awọn adari ijọba ilẹ Gẹẹsi, Sajid Javid ti kọwe fipo silẹ, lẹyin ti olori ijọba Boris Johnson ṣe atunto igbimọ ijọba orilẹ-ede naa.
Ikọwe fiposilẹ yii lo waye lẹyin ti ilẹ Gẹẹsi yapa kuro lara ajọ Iṣọkan ilẹ Yuroopu.
Ọgbẹni Javid kọ lati fọwọ osi juwe ile fun awọn to n ba ṣeṣẹ ni bo ṣe sọ pe kii ṣe ohun dara lati ṣe.
Oṣu keje ọdun 2019 ni Boris Johnson yan Sajid sipo lẹyin to gori alefa gẹgẹ bi olori ijọba ilẹ Gẹẹsi.
Ki Sajid to kọwe fiposilẹ, awọn ahesọ kan ti n waye pe họwuhọwu wa laari rẹ̀ ati ọgbẹni Dominic Cummings, to jẹ olubadamọran pataki si Boris Johnson.
Ni bayii, wọn ti fi Rishi Sunak rọpo rẹ.
Oríṣun àwòrán, @htTweets
Sunak ni minisita fun eto ilegbe tẹlẹ ko to ri igbega sipo akọwe iṣura orilẹ-ede Gẹẹsi.
Rishi Sunak jẹ ẹni ọdun mọkandinlogoji, o si kawe ni Winchester College ati Fasiti Oxford lẹyin naa lo da ileeṣẹ aladani kan silẹ.
Sunak di minisita fun eto ilegbe lọdun 2018 ko to ri igbega sipo akọwe iṣura orilẹ-ede Gẹẹsi.
Operation Amotekun: A ó da ọlọ́pàá agbègbè àti Amotekun papọ̀ - Ọ̀gá ọlọ́pàá Naijiria
Oríṣun àwòrán, @ekitistategov
Ọga agba ajọ ọlọpaa orilẹ-ede Naijira, Muhammed Adamu ti sọ pe ọlọpaa agbegbe tí ijọba apapọ n gbero rẹ yoo ṣiṣẹ papọ pẹlu ikọ Amotekun ilẹ Yoruba.
Adamu lo sọ ọrọ yii nibi ijiroro kan to waye pẹlu awọn gomina ilkẹ Yoruba nilu Eko lori agbekalẹ ọlọpaa agbegbe.
"O sọ fun awọn akọroyin pe ""Ipade keji niyi ti a maa ṣe pẹlu awọn gomina naa lori agbekalẹ ikọ Amotekun."""
"Adamu ṣalaye pe ""Gbogbo ipinlẹ lo ni eto abo ti wọn lati koju iwa ọdaran, ikọ Amotekun ko si yatọ si iru agbekalẹ bẹẹ."
O ni ajọ ọlọpaa ati awọn gomina naa ti fẹnuko lati sọ ọlọpaa agbegeb ati Amotekun di ọkan ṣoṣo ki eto abo ilu lee jẹ lati ọwọ awọn ara ilu.
Oríṣun àwòrán, @followlasg
Adamu sọ pe ajọ ọlọpaa yoo ṣatilẹyin fun awọn eeyan lati ri pe agbegbe wọn wa ni alafia
Ọga agba ajọ ọlọpaa naa tẹsiwaju pe ileeṣẹ ọlọpaa Naijiria yoo lọwọ si igbanisiṣẹ ati idanilẹkọ awọn eeyan ti yoo ṣeṣẹ gẹgẹ bi ikọ Amotekun.
Adamu sọ pe eto abo gbọdọ bẹre lati ọdọ awọn ara ilu, lẹyin naa lo rọ awọn eeyan lati fọwọsowọpọ gbogun ti iwa ibajẹ.
Adamu pari ọrọ rẹ pe ajọ ọlọpaa yoo ṣatilẹyin fun awọn eeyan lati ri pe agbegbe wọn wa ni alafia.
Oyo Land Revocation: Ajimobi gbé Makinde lọ ilé ẹjọ́ lórí ilẹ̀ rẹ̀ tí ìjọba gbẹ́sẹ̀ lé
Gomina ana nipinlẹ Oyo, Sẹnatọ Abiola Ajimobi ti gbe Gomina Seyi Makinde ati awọn eeyan mii ninu ijọba rẹ lọ ile ẹjọ, lẹyin ti wọn gbẹsẹle ilẹ rẹ nilu Ibadan.
Ṣaaju ni iroyin kan jade pe, ijọba ipinlẹ Oyo gbẹsẹ le awọn ilẹ kan lagbegbe Agodi ati Jericho, nilu Ibadan nitori awọn idi kan.
Ọjọ kẹwa oṣu keji ọdun 2020 ni aṣẹ jade pe, ki wọn gbẹsẹ le awọn ilẹ ọhun nitori pe lilo rẹ lodi si anfani awọn ara ilu ati ijọba.
Atẹjade kan lati ọwọ agbẹnusọ Gomina Makinde, Taiwo Adisa ṣalaye pe, gomina kan tẹlẹ nipinlẹ ọhun lo ra ilẹ naa, ti gomina to ṣaaju rẹ si gbẹsẹ le e, to si fi ilẹ naa fun oniṣowo kan ni Ibadan.
Oríṣun àwòrán, Others
O tẹsiwaju pe, oniṣowo ọhun ṣe iforukọsilẹ ilẹ naa pẹlu ileeṣẹ ijọba to n ṣamojuto ọrọ ilẹ, to si sọ pe oun ti bun gomina ana miran nilẹ ọhun.
Ṣugbọn o ni ninu iwe kootu kan to tẹ awọn akọroyin lọwọ, ni wọn ti fiwe pe Gomina Makinde, kọmiṣọna fun ọrọ ilẹ ati ilegbe, to fi mọ adajọ agba ipinlẹ Oyo, lati wa sọ tẹnu wọn lori bi ọrọ ọhun ṣe jẹ.
Iwe ipẹjọ ọhun to jade lọjọ kejila oṣu Keji ọdun 2020 sọ pe, iwa ẹtanu ni bi wọn ṣe gbẹsẹ le ilẹ naa jẹ ati inunibini.
Ile ẹjọ naa tun dena ijọba Oyo lati gbe igbesẹ kankan lori ọrọ ilẹ ọhun, titi ti igbẹjọ yoo fi bẹrẹ.
Amotekun: Ìjọba Eko kéde pé òun ní ẹ̀ṣọ́ aláàbò tẹ́lẹ̀, òun kò sí ní yí orúkọ rẹ̀ padá sí Amotekun
Oríṣun àwòrán, facebook/Amotekun
Kọmiṣọna feto iroyin ni ipinlẹ Eko, Gbenga Omotoso ti sọ pe ipinlẹ naa ko fa sẹyin ninu eto aabo rara, ki awọn gomina ilẹ Yoruba to daba agbekalẹ ikọ alabo Amotekun.
"Omotoso ni ti eto Amotekun ba fẹsẹ mulẹ tan, ẹṣọ alabo ipinlẹ Eko ko ni yi orukọ rẹ pada lati ""Neighborhood watch"" to n lo fun aabo agbegbe pada si Amotekun, nitori iṣẹ kan naa ni wọn n ṣe."
Omotoso, lasiko to n ba BBC Yoruba sọrọ kede pe lẹyin agbekalẹ Neighbourhood Watch, lawọn ipinlẹ yoku bii Oyo, Ogun ati Ondo gbe abadofin Ametekun lọ si ile igbimọ aṣofin ipinlẹ wọn.
"Ni ti pe ipinlẹ Eko n fa sẹyin lati gbe abadofin Amotekun lọ si ile igbimọ aṣofin rẹ, o ṣalaye pe ""Ati ni ofin to ju ti Amotekun lọ, tile igbimọ aṣofin ipinlẹ Eko ti fọwọsi ṣaaju akoko yii, orukọ nikan lo yatọ."""
Ipinlẹ Eko ti ni nnkan to jọ mọ nnkan ti wọn sọ yẹn tipẹtipẹ, ko to di akoko yii.
Kọmiṣọna naa ṣalaye pe, eto aabo ayika ki n ṣe nnkan tuntun nipinlẹ Eko, nitori ipinlẹ ọhun ti ni ẹsọ alabo ayika to dantọ tẹlẹ.
Oríṣun àwòrán, @EKITISTATEGOV
Omotoso ṣalaye pe, ọga agba fun ileesẹ ọlọpaa ti ṣalaye fun awọn gomina ilẹ Yoruba pe, eto Amotekun kii ṣe eto gbogbo ẹkun iwọ oorun guusu Naijiria, ṣugbọn ki olukuluku ṣe amojuto eto abo wọn lọtọtọ.
"Omotoso wa pari ọrọ rẹ pe ""orukọ ti wọn n jẹ naa ni mo ro pe wọn maa jẹ lọ, a ko le yi orukọ wọn pada. Nnkan to ba yẹ ni ṣiṣe lati daabo bo awọn eeyan wa, la o ṣe."""
Bayelsa: Douye Diri di gómìnà Bayelsa lẹ́yìn ìbúrawọlé, iléeṣẹ́ ọlọ́pàá kéde kóńlé ó gbélé
Oríṣun àwòrán, Facebook/Seyi Makinde
Adajọ agba nipinlẹ Bayelsa, Kate Abiri ti ṣe ibura fun oludije ipo gomina fẹgbẹ oṣelu PDP, Douye Diri gẹgẹ bi gomina tuntun ipinlẹ naa.
Ni irọle ọjọ Ẹti ọjọ kẹrinla oṣu lkeji ni ibura naa waye nile iṣẹ ijọba nilu Yenagoa tii ṣe olu ilu ipinlẹ Bayelsa.
Bakan naa ni adajọ agba ipinlẹ Bayelsa ṣe ibura fun Sẹnẹtọ fun Lawrence Ewhrudjakpo gẹgẹ bi igbakeji gomina tuntun ipinlẹ naa.
Ẹwẹ, ile iṣẹ ti kede ofin konile o gbele ti yoo maa bẹrẹ lati irọlẹ di idaji ọjọ keji nipinlẹ Bayelsa lẹyin tawọn olufẹhonu ati awọn janduku kọlu ile gomina tuntun fun ipinlẹ naa, Douye Diri ti wọn si ba nkan jẹ.
Ọga agba ọlọpaa nipinlẹ naa, Uche Anozia lo ṣe ikede naa fawọn akọroyin lọjọ Ẹti.
Oríṣun àwòrán, Twitter/nigeria police
Ọgbẹni Anozia to ṣe ikede naa nibi tawọn ọga ajọ eleto aabo miran naa ti wa nijoko ṣalaye pe alẹ ọjọ Ẹti, ọjọ kẹrinla oṣu Keji yii naa ni eto konle o gbele ọhun yoo bẹrẹ.
Ọga ọlọpaa naa ṣe ikilọ pe ẹnikẹni to ba ta felefele laarin aago mẹjọ alẹ si aago mẹfa aarọ yoo foju wina ofin.
Niṣe ni ile iṣẹ ijọba ipinlẹ Bayelsa kun fọfọ nigba ti ọga ọlọpaa n ṣe ikede naa.
Àwọn jàndùkú kọlu ilé gómìnà ìpínlẹ̀ Bayelsa tuntun, wọ́n ba nkan jẹ́
Iroyin kan to tẹwa lọwọ ni pe awọn olufẹhonu ati awọn janduku kọlu ile gomina tuntun fun ipinlẹ Bayelsa, Douye Diri ti wọn si ba nkan jẹ.
Gẹgẹ bi iwe iroyin The Punch ṣe jabọ iroyin, awọn janduku naa ba awọn ọkọ kan ti wọn gbe sinu ọgba ile naa jẹ, ati abala kan lara ile naa.
Oríṣun àwòrán, Punchng
Eyi waye lẹyin ti ajọ INEC fun Diri ni iwe ẹri moyege gẹgẹ bi gomina ipinlẹ Bayelsa.
Oríṣun àwòrán, Punchng
Ọsan ọjọ Ẹti ni ajọ eleto idibo Nigeria, Inec ti fun oludije gomina fẹgbẹ oselu PDP, Sẹnatọ Douye Diri ati igbakeji ni iwe ẹri moyege ibo gẹgẹ bi gomina ipinlẹ Bayelsa.
Oríṣun àwòrán, Punchng
Eyi waye lọjọ lẹyin ipade ti ajọ Inec ṣe nilu Abuja lati jiroro lori idajọ ileẹjọ to ga julọ ni Naijiria to waye l'Ọjọbọ.
Oríṣun àwòrán, Twitter/OfficialPDPNIg
Ajọ INEc ti fun oludije PDP, Douye Diri ni iwe ẹri moyege
Ile ẹjọ naa wọgile ibo to gbe oludijẹ ẹgbẹ oselu APC wọle nipinlẹ Bayelsa, to si yẹ ki wọn bura fun lonii.
Eyi lo si fidi rẹ mulẹ pe gbogbo igbiyanju oludije fun ipo gomina labẹ ẹgbẹ APC, David Lyon lati sebura wọle bii gomina ipinlẹ Bayelsa l'oni, ọjọ Ẹti lo ti ja si pabo.
Oríṣun àwòrán, Others
Ṣaaju ni ajọ eleto idibo naa ni oun ti setan lati gbe iwe ẹ́ri moyege ibo fun oludije ẹgbẹ oselu PDP, Senator Douye Diri ati igbakeji rẹ, Lawrence Ewhruojakpo, gẹgẹ bi ileẹjọ ti paa lasẹ.
Lati Ọjọbọ ti ile ẹjọ si ti dajọ ni omi nu ti n kọ awọn eniyan ipinlẹ Bayelsa lori taa ni gomina ipinlẹ Bayelsa ti wọn yoo bura fun loni.
Valentine: Ọkùnrin ní kí obìnrin má fún àwọn ní àwọ̀tẹ́lẹ̀ mọ́ bíi ẹ̀bùn ọjọ́ olólùfẹ́
Idi ni pe ẹgbẹ oselu APC ati PDP ti n tutọ si ara wọn loju lori ohun ti idajọ ileẹjọ naa sọ, ti ko si tii foju han, ẹni ti wọn yoo bura fun bii gomina ni Bayelsa.
Lasiko to n bawọn akọroyin sọrọ nilu Abuja, alaga ẹgbẹ oselu APC, Adams Oshiomole leri leka, to si n tọ ilẹ la pe ko si ẹnikẹni ti wọn yoo bura fun bii gomina ni Bayelsa lonii.
Oríṣun àwòrán, David Lyon
"Oshiomole ni ""kii se bonkẹlẹ mọ pe ile ẹjọ to ga julọ ti dajọ pe wọn ko lee bura fun David Lyon, bẹẹ si ni ẹni to ni ibo to pọ julọ sikeji ni ki wọn bura fun. Eyi tumọ si pe lati ọla lọ, ko ni si ijọba kankan mọ ni Bayelsa."""
O fikun pe oludije fẹgbẹ PDP ko ni ida mẹta ibo to yẹ ninu eto idibo gomina ọhun, ti ọwọja ibo rẹ ko si tan ka ida mẹta ijọba ibilẹ to wa nipinlẹ naa.
Oríṣun àwòrán, Adams Oshiomole
Amọ agbẹnusọ fun ẹgbẹ oselu PDP, Kọla Ọlọgbọndiyan ni  ofo lasan ni ihalẹ Oshiomole nitori ofuutu, fẹẹtẹ, aasa ti ko ni kaun ni.
Ẹgbẹ oselu PDP wa n fewe ọmọ mọ Oshiomole leti lati ta kete si ipinlẹ Bayelsa nitori igbinyanju rẹ lati da rogbodiyan silẹ nipinlẹ naa, ti kuna.
Bẹẹ ba gbagbe, a mu iroyin wa fun yin pe ile ẹjọ to ga julọ nilẹ wa ti yẹ aga gomina mọ David Ylon, tii se oludije gomina fẹgbẹ APC nidi, ẹni ti ajọ Inec kede pe oun lo moke ninu ibo gomina to waye nipinlẹ naa losu Kọkanla ọdun 2019.
Idi ni pe ẹni to jẹ igbakeji Lyon naa, Biobarakuma Degi-Eremienyo, ko ayederu iwe ẹri kalẹ fun ajọ eleto idibo, to si mu ki awọn Lyon ati igbakeji rẹ naa kuna lati lee de ipo gomina.
Oni, ọjọ Ẹti lo yẹ ki wọn bura fun Lyon ati igbakeji rẹ naa amọ nibayii, ti ileẹjọ ti kede pe ki wọn gba iwe ẹri moyege ti ajọ Inec fun, ki wọn si kọ iwe ẹri miran fun oludije ẹgbẹ oselu PDP, taa wa ni wọn yoo bura fun bii gomina Bayelsa lonii.
Koda, lọwọ aarọ ana ni Lyon ti n se igbaradi fun bi wọn yoo se bura fun bii gomina lonii, ti ko si mọ pe riro ni teniyan, sise ni ti Ọlọrun, bẹẹ ni igun ijọba ẹgbẹ oselu PDP to n dari Bayelsa gan ti setan lati fa ibi ti akoso de duro le Lyon lọwọ.
Oluwo: Olu ní àwọn ọmọ Iwo kan ti ń bẹ̀ àwọn, àmọ́ ta làwọn mọ̀ ti nínà yóò tún kàn
Oríṣun àwòrán, Oluwo
Ọba Agbaje Abeeb Adetoyese, Olu ti Ile Ogbo, ti kesi gomina Adegboyega Oyetola ti ipinlẹ Ọsun lati tete pasẹ pe ki Oluwo tilu Iwo, Ọba Abdulrasheed Adewale Akanbi lọ rọọkun nile na, ko si kuro ninu igbimọ lọbalọba fun igba diẹ.
Ọba alaye naa ni eyi ni yoo kọkọ jẹ ijiya ẹsẹ Oluwo lori bo se na ọba alaye bii tiẹ, Agbowo tilu Ọgbaagba lasiko ipade alaafia to waye lọọfisi igbakeji ọga ọlọpa lẹkun kọkanla nilu Osogbo.
Lasiko to n ba BBC Yoruba sọrọọ lori isẹlẹ ọhun, Olu tile Ogbo ni oun wa nibi ipade alaafia naa, nibi ti ọga ọlọpa ti n yanju awọn fun awọn ati Oluwo.
Oríṣun àwòrán, Ọba Dikrulahi Ọlaleke Akinrọpo, Ọlabiran Kẹta.
O fikun pe lootọ lawọn ti pe agbẹjọro awọn, sugbọn awọn n rọ ijọba ipinlẹ Ọsun lati le Oluwo kuro lori oye nitori kii se eeyan ti ori rẹ pe lati di iru ipo to wa mu.
Awa ọba pọ nibi ipade naa bii Onigẹgẹ ti Igẹgẹ,Onitara ti Feesu, Onimese ati Olupọ ti Olupọnna, to fi mọ Oluwo Oke, ti ọga ọlọpa si n bawa sọrọ, sadede ni Oluwo dide, to si n na Agbowo ti Ọgbaagba.
"O na a gidi gan ni, debi pe ẹjẹ bẹ loju rẹ ni, ile iwosan si ni gbogbo wa sare gbe digbadigba lọ ni Asubiaro, ijọba ko si gbọdọ wo Oluwo niran lori ọrọ yii, wọn gbọdọ ni ko lọ joko sile na.
Oríṣun àwòrán, Oluwo
Ọba Adetoyese ni ko yẹ ki ọba to n dari ilu to tobi to ilu Iwo maa dọti ilu Iwo kaakiri, o si yẹ ko gba ijiya to yẹ lori bo se hu iru iwa bayii niwaju ijọba.
Nigba to n salaye ohun to fa laasigbo naa, Adetoyese ni Oluwo lo n fọwọ gbaya pe oun loun ni gbogbo ilu wa, oun loun ni Ile Ogbo, Ọgbaagba, Idi Ẹgẹ, Feesu, Ọlọja biire, Onifin, Olupọnna, Iwo Oke ati gbogbo ilẹ, o ni a n ta ilẹ oun, ta si sọ fun pe a ko ta ilẹ rẹ, ilẹ ilu wa la n ta."""
Oríṣun àwòrán, Oluwo
O fikun pe, bi Agbowo Ọgbaagba sọ fun pe ilẹ Ọgbaagba ni oun n ta, bi Oluwo se binu dide niyẹn, to si da igbaju-igbamu boo, lai jẹ pe a sọ ọrọ to ju ẹnu wa lọ si.
Awọn ẹgbẹ ọmọ Iwo kan ti n bẹ wa pe ka ma jẹ ko le fun, amọ ko si bi ko se ni le fun, nitori a ko mọ ẹni ti yoo kan lọla, emi gan lo kọkọ fẹ na, amọ mo jinna sibi to joko si, ni ko jẹ ko na mi.
Iroyin kan to n tẹ wa lọwọ ni ija nla ti bẹ silẹ laarin awọn ọba alaye meji, eyiun Oluwo tilu Iwo, Ọba Abdulrasheed Adewale Akanbi ati Agbowu tilu Ọgbaagba, Ọba Dikrulahi Ọlaleke Akinrọpo, Ọlabiran Kẹta.
Aawọ naa buru to bẹẹ gẹẹ, ti awọn mejeeji tahun sira wọn, eyi to mu ki Oluwo bu igbaju-igbamu lu Agbowu, ti ẹjẹ si n tu jade ni ẹẹkẹ rẹ.
Nigba to n fidi isẹlẹ naa mulẹ fun BBC Yoruba, Ọba Akinrọpo salaye pe, ọjọ ti pẹ ti awọn ti n paara ọdọ ọlọpa, lati saa igbakeji ọga ọlọpa fẹkun keji, Oyebade, nitori bi Oluwo se wọ awọn ọba mẹjọ kan lọ siwaju ọga ọlọpa naa.
O ni Oluwo fẹsun kan awọn ọba mẹjẹẹjọ naa, bii ọba Ọgbaagba, Kuta, Ile'gbo pe awọn n dunkooko mọ ẹmi oun, nitori bi awọn se n ta ilẹ ni agbegbe awọn
Akinrọpo ni awọn sọ fun Oluwo pe awọn ko ta ilẹ nilu Iwo bikose agbegbe awọn, ti wọn si pe ipade alaafia laarin awọn lati yanju aawọ naa, amọ o ni n se ni Oluwo n da ipade naa ru.
Se ni Oluwo n da ijoko naa ru lọdun to kọja, ti wọn si tun pe ipade alaafia miran lọdun yii si ẹkun kọkanla ileesẹ ọlọpa nilu Osogbo, iwaju ọga ọlọpaa naa la wa, nibi to ti n rọ wa lati gba alaafia laaye. Ibi ta ti n salaye pe a ko lọ ta ilẹ nilu Iwo, ilẹ ọdọ wa la n ta, ni Oluwo ti sọ pe, ki lo de ti oun n sọrọ, ti emi naa n sọrọ, abi ori mi daru ni.
Oríṣun àwòrán, Oluwo
BI Oluwo se dide ree, to n lu mi mọlẹ, to ni oun yoo jẹ ki emi mọ pe oun ni ọba ati ọga. Bo se n gba mi loju, gba mi nimu ree, niwaju AIG, Kọmisana fọrọ ijọba ibilẹ ati oye jijẹ, pẹlu Kọmisana fọrọ ilẹ ati ilegbe ati alaga fun ijọba ibilẹ Iwo atawọn ọba miran, to fi mọ Olupọ tilu Olupọnna.
Akinrọpo fikun pe, oun ko sọrọ ibinu rara si Oluwo to fi n na oun, ti ẹjẹ si n da loju oun, koda ọga ọlọpa gan lo n sọrọ lọwọ, to fi dide mọ oun.
Mo kan sọ fun pe ọba ni olukaluku wa, a si n se akoso agbegbe wa, ki wa lo de ti yoo fi maa pasẹ pe awọn ko gbọdọ ta ilẹ to wa ni agbegbe awọn.
Valentine: Ọkùnrin ní kí obìnrin má fún àwọn ní àwọ̀tẹ́lẹ̀ mọ́ bíi ẹ̀bùn ọjọ́ olólùfẹ́
Ọlọgbaagba ni ile iwosan ni oun ti n ba wa sọrọ lati lọ gba itọju, to si pẹ diẹ lẹyin to na oun tan, ki ara oun to balẹ, ti wọn si gbe oun lọ sile iwosan. O ni oun ko mọ ohun to fi gba oun loju, ki ni naa ya oun loju, ti ẹsẹ si n yọ.
O ni awọn ọlọpa ti gba ọrọ silẹ lẹnu awọn nitori oju wọn naa lo ti sẹlẹ, oun si fẹ ki ofin gbe igbesẹ to ba yẹ lori rẹ.
Gbogbo igbiyanju wa lati ba Oluwo sọrọ lori isẹlẹ naa, lo ja si pabo, to si sọ fun wa pe ara oun ko tii bọ sipo lati ba wa sọrọ.
Amọ nigba ta kan si alukoro ileesẹ ọlọpa ipinlẹ Ọsun, Folasade Odoro, o ni awọn ko tii gbọ nipa isẹlẹ naa, yoo si daa ka kan si ẹkun ileesẹ ọlọpa fun alaye.
A mu ẹkunrẹrẹ iroyin naa wa fun yin laipẹ, ti awọn mejeeji ba ti ba wa sọrọ
Buhari visits Borno: Garba Shehu ní ọ̀pọ̀ èèyàn ló jáde kí ààrẹ káábọ̀, wọ́n ló ṣeun ṣeun
Oríṣun àwòrán, others
Ẹgbẹ́ alátakò ló ràn àwọn èèyàn láti pariwo lé ààrẹ Buhari lori.
Ilé iṣẹ́ ààrẹ orilẹ̀èdè Naijiria ti fẹ̀sùn kan àwọn ẹgbẹ alatako pé, awọn lo san owo láti gba àwọn to kígbe le ààrẹ Muhammadu Buhari lori lasiko ìrìnàjò rẹ̀ lọ si ìpínlẹ̀ Borno lọ́jọ́ru ni.
Oluranlọ́wọ́ pàtàkì àgbà lori igbòhun sáfẹ́fẹ́ fún ààrẹ Buhari Garba Shehu, lo fẹ́sun náà kan lásìkò to n ba BBC sọ̀rọ̀.
Awọn olùgbé ìlú Maiduguri ti ṣe olúùlú ìpínlẹ̀ Borno pe bo ọkọ ààrẹ lọ́jọ́ru, ti wọn si kígbe ni ìlòdì si ìrìnàjò ààrẹ Buhari lóri ìṣekupani ti àwọn ọlọsa ṣe si àwọn arinrinajo ọgbọ̀n ni Borno.
"Shehu ni ""Mo wa lára àwọn to rin ìrìnàjo náà láti pápákọ ofurufu titi de ààfin Shehu Borno, àwọn ènìyàn jáde ti wọ́n ki ààrẹ kaabọ, wọn ni o ṣeun fun àbẹ̀wò naa."""
Oríṣun àwòrán, Others
"Sùgbọ́n lójìji ni àwọn kan de ti wọ́n bẹ̀rẹ̀ si ni kígbe pe 'A ò fẹ́, A ò fẹ́'
O ní o ṣeeṣe ki àwọn ọlọṣelu ẹgbẹ́ alátako kó àwọn ènìyàn jọ, ki wọ́n si fún wọ́n ni owó láti lọ yẹ̀yẹ́ ààrẹ Buhari"
Gẹ́gẹ́ bi Garba Shehu ṣe sọ, ẹnikẹni to ba ya fọ́nran ibi ti wọ́n ti n pariwo le ààrẹ, to sì tún pin ká lóri ayélujara kò ṣe e láti ràn àwọn ènìyàn ìpínlẹ̀ Borno lọ́wọ́, bi wọ́n ṣe jẹ́ ẹni ti gbogbo ènìyàn mọ gẹ́gẹ́ bi ìlú to maa n gbà alejò.
Valentine: Ọkùnrin ní kí obìnrin má fún àwọn ní àwọ̀tẹ́lẹ̀ mọ́ bíi ẹ̀bùn ọjọ́ olólùfẹ́
O ní ìjọba to n bẹ lóde ti ṣe gudugudu meje, yaya mẹfa láti koju Boko Haram, ti àwọn si ti tun ń pinnu láti yi ìlànà àtẹyinwá pada.
Sunday Igboho: Bí ń kò bá jẹ́ èèyàn dáadáa, Ọlọ́run kò ní ṣe oun dáadáa fún mi
Oríṣun àwòrán, Instagram sunday_igboho
Ilumọọka agba awujọ kan, Oloye Sunday Adeyemo, ti ọpọ eeyan mọ si Sunday Igboho ti yari kanlẹ pẹlu awọn eeyan to n sọrọ aidaa nipa rẹ.
Igboho gbọnmu lori iwa aidaa ti awọn eeyan naa n hu si loju opo Instagram rẹ ninu fidio kan to ju sibẹ lọjọ Aiku.
Sunday Igboho, ẹni to wa ninu ọkọ ayọkẹlẹ rẹ pẹlu ọrẹ rẹ kan lo n sọrọ naa lowe lowe, lai darukọ awọn to n ba wi.
Amọ o daju pe Igboho ni awọn eeyan kan lọkan to n tahun si ninu fidi o.
Gbajumọ awujọ naa ni oun dupẹ lọwọ Ọlọrun Ọba to se oore daadaa fun oun, bi oun ba si jẹ eeyan radarada ni, Ọlọrun ko se nnkan daadaa fun oun.
Sunday Igboho: Fulani kò leè dúró, táa bá lo ohun ta jogún lọ́dọ̀ àwọ̀n bàbá wa
"Bi eeyan ba lowo laye, yoo lowo lọrun ni, bi eeyan ko ba si jẹ nnkan kan laye, ko lee jẹ nnkan lọrun.
Awọn to maa n bu eeyan, ẹ ri pe awọn talaka ti ko ba nkankan mu ni, awọn ọta Ọlọrun ni wọn nitori awọn ti Ọlọrun ba se daada fun, ọta Ọlọrun nii maa tẹ wọn tabi ba wọn jẹ."
O fikun pe o yẹ kawọn eeyan fura si awọn to ba kundun ki wọn maa pẹgan eeyan ẹlẹgbẹ wọn, o ni awọn ti ko jẹ nnkan kan ni, nitori ẹni to ba jẹ nnkan ko ni bawọn pẹgan eeyan laelae.
Oríṣun àwòrán, Instagram/Sunday Igboho
Awọn olugbe agbegbe Soka niluu Ibadan ṣe alaye fun ikọ BBC Yoruba wi pe, lati nnkan bii ọdun mẹta sẹyin ni wahala awọn ọmọ onilẹ ti n waye ni lemọlemọ ni adugbo naa ki o to di wi pe Sunday Igboho da sii lọdun yii.Ọpọlọpọ awọn ogiri ile ni wọn ṣe ami si wi pe, awọn ọmọ onilẹ ti gbẹsẹ lee pẹlu atilẹyin ile ẹjọ giga, lasiko ti ikọ BBC Yoruba ṣe abẹwo si agbegbe naa lowurọ Ọjọ Ẹti.
Awọn olugbe agbegbe naa to ba wa sọrọ labẹ aṣọ ṣalaye pe, pupọ ninu awọn abulẹṣowo to ta ilẹ fun awọn lo ti di oloogbe.
Awọn ọmọ awọn oloogbe naa lo wa yirapada di ọmọ onilẹ to n ṣoro bi agbọn, pẹlu ẹsun wi pe ọna aitọ ni wọn gba ra awọn ilẹ naa.
Ọkan lara awọn olugbe agbegbe naa, ti o ni ki a fi orukọ bo oun laṣiri ṣe alaye wi pe, igba mẹfa ọtọọtọ ni awọn ọmọ onilẹ ti lọ gba aṣẹ ile ẹjọ lati gbẹsẹ le awọn ilẹ ti awọn eeyan ti kọle si lori, ni agbegbe Soka.
"O tẹsiwaju wi pe, ""ohun to maa n gbẹyin ọrọ lọpọ igba ni ki awọn ọmọ onilẹ naa gba owo ibọbẹ lẹyin idunkukulaja wọn, ṣugbọn airi owo gba lọdun yii lo da gbọmi si omo o to silẹ."""
"Awọn ọmọ onilẹ naa ko ọlọpaa lẹyin, t'oun ti aṣẹ ile ẹjọ gẹgẹ bi iṣe wọn lọsẹ yii. ki ilumọọka ajafẹtọmọniyan Sunday Igboho to gbẹna woju wọn.Lati ọjọ Isẹgun ti isẹlẹ naa ti waye, awọn olugbe agbegbe naa ṣe alaye wi pe, awọn ko tun tii ri ọmọ onilẹ kankan mọ ni agbegbe Soka niluu Ibadan.
Coronavirus: Orílẹ̀-èdè Egypt ti ṣe àkọsílẹ̀ ẹni àkọ́kọ́ tó ní ààrùn Coronavirus
Ẹka eto ilera lorilẹede Egypt ti kede pe eeyan kan ti niaarun coronavirus lorilẹede Egypt.
Eyi ni igba akọkọ ti aarun naa yoo mu ẹnikankan nilẹ Afirika lati igba to ti bẹrẹ niluu Wuhan lorilẹede China.
Awọn alaṣẹ ẹka eto ilera lorilẹede Egypt ko sọ bo ya ọmọ orilẹede Egypt lẹni to naa tabi ajeji ni.
Amọ wọn ti fi to ajọ eleto ilera lagbaaye, WHO, l'eti, bẹẹ ni wọn si fi ẹni naa pamọ si ibi kan fun itọju ati ayẹwo siwaju sii.
Orilẹ-ede Egypt ni orilẹ-ede kejidinlogun ti aarun naa ti tan kalẹ de bayii, ohun si ni akọkọ nilẹ Afirika.
O le ni ẹgbẹfa eeyan to ti di oloogbe lẹyin ti wọn ko aarun coronavirus. Bakan naa ni eniyan to le ni ẹgbẹrun mẹrinlelọgọta ni ayẹwo fihan pe wọn ti ni aarun naa kaakiri agbaye.
Okada Ban: Bàbá ọmọ ni ₦20,000 péré ni àwọn ọlọ́pàá fi lọ òun àmọ́ òun kò gbàá
Stray Bullet: Bàbá ọmọ ni ogún náírà péré ni àwọn ọlọ́pàá fi lọ òun àmọ́ òun kò gbàá
Arinfẹsẹsi  ko kan maili a fi ki ọba oke maa sọ wa.
Baba ọmọdebinrin kan, Mariam Sobukola, ti asita ibọn ba, lasiko iwọde kan to waye lagbegbe Ipaja nilu Eko, lati tako bi ijọba se wọgile wiwa ọkada ati kẹkẹ, ti kigbe tọ BBC Yoruba wa.
Lasiko to n ba wa sọrọ, Mukaila Sobukola ni awọn ọlọpa to yinbọn mọ ọmọ oun ko tiẹ tara nipa isẹlẹ naa rara, oun nikan si ni oun n da gbọ bukata wahala yii.
Sobukọla ni dokita yọ ọta ibọn lara ọmọdebinrin naa, to si fi le oun lọwọ, amọ o ni, lọjọ kẹta ni dokita tun n bẹ oun pe ki oun mu ọta ibọn naa wa pada, ti wọn ko si fun oun mọ.
O fikun pe ọlọpa obinrin kan yọju si awọn sile iwosan, to si na ẹgbẹrun lọna ogun naira si awọn, amọ oun ko gbaa lọwọ rẹ, lati igba naa wa, awọn ko gbọ ohunkohun mọ.
Oluwo: Agbówú wá bẹ̀bẹ̀ fún adé lọ́dọ̀ mi ni, torí náà, abẹ́ mi ló wà
Oríṣun àwòrán, Oluwo
Oluwo tilu Iwo, Aba Abdulrasheed Adewale Akanbi, Telu Kinni, ti fesi si ohun to bi ija agba meji to waye lọjọ Ẹti laarin rẹ ati Agbowu tilu Ọgbaagbaa, Ọba Dikrullai Olaleke Akinropo, Ọlabiran Kẹta.
Oluwo salaye loju opo Instagram rẹ pe lootọ ni ọga ọlọpa pe awọn si ipade alaafia amọ se ni Agbowu n da ọrọ mọ oun lẹnu, to si n pe oun ni orukọ buruku, ti ko se gbọ seti.
Ọba Akanbi ni se ni Agbowu na ọpa asẹ rẹ si oun, to si fẹ kii bọ oun loju, ti oun si fi tipa kọ igbesẹ naa, eyi ti ara Agbowu ko gba rara.
Oluwo wa n beere pe bawo lo ti seese ki Kọsitabu ọlọpa maa yaju si Kọmisana ọlọpa niwaju ọga agba ọlọpa, se eyi seese bi? N jẹ ẹnikẹni lee hu iru iwa yii si Ọọni abi Alaafin?"
Bakan naa lo fi kun pe awọn ẹri to daju wa nilẹ pe jẹjẹ ni oun joko, ti baalẹ ilu Ọgbaagbaa, eyiun ọba Akinrọpo yii kan naa, kọwe si oun pe oun fẹ maa dade, eyi to fihan pe abẹ oun Oluwo ni ilu Ọgbaagba wa, tori wọn wa tẹdo sara ilẹ Iwo ni.
Ta ba wo ohun ti asa ati itan sọ, Oluwo lo fi Ọgbaagba si ibi ti wọn tẹdo si loni, lodi si ahesọ ọrọ ti wọn n gbe kiri. Mo ni iwe ti mo fi gbe ade fun awọn ọba marundinlogoji to wa labẹ mi, ilẹ Iwo si kọja agbegbe Ọgbaagbaa, ojuse mi si ni lati daabo bo awọn ilẹ naa.
Kii se nitori temi abi iran ta wa yii, amọ tori iran to n bọ lẹyin ni, ẹsẹ ti mo sẹ ree o, wọn fẹ ta ilẹ Iwo ni. Gbogbo ilẹ Iwo lo ti fẹẹ lọ tan, to si ti n bọ sọwọ awọn atalẹjẹun nitori ohun ti ko to nkan.
Oríṣun àwòrán, Ọba Dikrulahi Ọlaleke Akinrọpo, Ọlabiran Kẹta.
Oluwo fikun pe, a gbọdọ raga bo ilẹ Iwo, ohun ti oun si n se ree, ti ọjọ ọla yoo si da ohun lare, ẹnikẹni, to fi mọ ọba lo si lee ta dukia rẹ amọ iwa ailaju ni ki ọba maa ta ilẹ ilu lowo idakọmu, lai si ẹni ti yoo yẹ lọwọ wo.
Ọba Akanbi fikun pe, ojoojumọ ni oun n gbọ ariwisi awọn araalu lori igbesẹ naa, ki ọba maa ta ilẹ kan fun eeyan meji-mẹta, lai jẹ ki awọn mọlẹbi to ni ilẹ mọ si.
Oríṣun àwòrán, Oluwo
Ẹ wo iru Agbowu yii to bẹbẹ pe oun fẹ de ade, lo tun wa pada lọ sọ fawọn akọroyin pe oun ko si labẹ Oluwo, to si tun fẹ sọ Oluwo di afọju nipa nina ọpa asẹ si mi loju. Awa ọba alaye kii se alakoso ilẹ, mo si gbọdọ da si iwa iwa tita ilẹ laidaa ti wọn n hu, ki n si pin wọn lọwọ rẹ.
Oluwo ni wọn ri ilẹ tita bi ojulowo ọna ti owo n gba wọle fun wọn, afojusun oun si ni lati tọ wọn sọna pe ko daa, kii se lati gba ohun ti oun ti fun wọn.
Stray Bullet: Bàbá ọmọ ni ogún náírà péré ni àwọn ọlọ́pàá fi lọ òun àmọ́ òun kò gbàá
Gbogbo awọn ọba ti ọrọ yii kan labẹ mi, ko si eyikeyi ninu yin ti yoo maa jẹun lati ara araalu, ti yoo fi ara re lọ, ẹ ko si ni mu jẹ. Aayan si ti n lọ lọwọ lati gba gbogbo awọn ilẹ ti awọn ọba alaye yii ti gba lọna aitọ, tabi ta fawọn atalẹjẹun.
O wa n beere pe anfaani ilẹ tita wo lo wa labẹ asa ati ihuwasi lọjọ ọla fawọn araalu, ti ọba ti ta gbogbo ilẹ wọn jẹun?
Oríṣun àwòrán, Oluwo
Oluwo salaye pe, iwa ọlaju ode oni lo bọwọ fun ilana aatọ ati ẹtọ ẹnikọọkan. Awọn ilu to wa nilẹ Iwo ti fun pọ ju.
Ìjọba Ọyọ: Igba náírà péré làwọn ọlọ́kadà yóò máa san lójúmọ́ fáwọn adarí ibùdókọ̀ tuntun
Oríṣun àwòrán, @transports_NG
Ijọba ipilẹ Ọyọ ti kede pe oun ti yan awọn alakoso ibudokọ lati maa se akoso awọn ibudokọ to wa lawọn gbogbo ijọba ibilẹ to wa jake jado ipinlẹ naa.
Kọmisana fun isẹ ode, Ọjọgbọn Raphael Afọnja, to sisọ ọrọ yii fawọn akọroyin fikun pe ọjọ aje lawọn yoo kede orukọ awọn alakoso ibudokọ ọhun.
Bakan naa lo salaye pe yatọ sawọn alakoso ibudokọ, ijọba tun ti yan awọn igbakeji alakoso ibudokọ, akọwe ati akapo.
Afọnja fikun pe ojuse awọn alakoso ibudokọ naa ni lati maa gba owo ita ati sise akoso awọn akọsẹmọsẹ  lorukọ ijọba, wọn yoo maa gba igba naira lojumọ lọwọ awọn ọlọkada
Oríṣun àwòrán, Seyi Makinde
O wa mẹniba pe ahesọ lasan ni iroyin kan to n ja nilẹ pe ijọba ipinlẹ Ọyọ yan alaga tẹlẹ fẹgbẹ awakọ ero, Mukaila Lamidi, ti gbogbo eeyan mọ si Auxiliary, gẹgẹ bii ọkan lara awọn alakoso ibudokọ.
Saaju lọjọbọ ni ẹgbẹ oselu APC nipinlẹ Ọyọ ki kede loju opo Twitter rẹ pe ijọba Ọyọ ti yan Auxiliary gẹgẹ bii alaga ẹgbẹ ọlọkọ ero.
Kọmisana fun isẹ ode wa tẹnumọ pe, ofin to de ẹgbẹ ọlọkọ ero nipinlẹ Ọyọ si wa nilẹ digbi, ti gbogbo owo tawọn asaaju ẹgbẹ ọlọkọ ero ọhun si n gba ko bofin mu.
"Awọn alakoso ibudokọ tuntun yii ni yoo jẹ asoju ijọba, ti wọn yoo si maa gba owo lorukọ ijọba, bẹẹ ni wọn yoo maa san sapo ijọba lati ipasẹ awọn alamojuto, ti yoo san sapo ijọba.
Afọnja ni eyi yatọ si ohun to maa n waye latẹyinwa, ijọba si ro pe o yẹ ki awọn eeyan kan wa ti yoo lewaju ninu pipa owo wọle fun ijọba, gbogbo awọn alakoso gareji ọkọ ati ti ibudo iwakusa ni yoo maa sanwo fun ijọba.
Stray Bullet: Bàbá ọmọ ni ogún náírà péré ni àwọn ọlọ́pàá fi lọ òun àmọ́ òun kò gbàá
O wa rọ awọn agbofinro lati ri daju pe wọn ko maa gba owo mọ lọwọ awọn ọlọkada, bẹẹ si ni gbogbo awọn asaaju ẹgbẹ onimọto tijọba ti fofin de ko lẹtọ mọ lati maa gba owo lọwọ awọn awakọ ati ọlọkada.
Marriage by Election:Àwọn ọkùnrin méjì kópa nínú ìdìbò láti yan ọkọ fún ọmọ ọdún mẹ́rìnlá
Oríṣun àwòrán, @Mubarack_Umar
Yoruba ni airin jinna ni airi abuke ọkẹrẹ, bi eeyan ba rin jinna, yoo de ibi ti wọn ti n fi odo ibulẹ jẹ.
Bẹẹ lọrọ ri pẹlu omidan kan, ọmọ ọdun mẹrinla,Hajara, ẹni ti iporuru ọkan ba nipa ẹni ti yoo fẹ laarin awọn ọkunrin meji to lawọn fẹ fi ṣe aya.
Nigba ti Hajara ko mọ boya ki oun gba fun Ibrahim tabi Yunusa lo ba ni ki wọn lọ kopa ninu idibo ti o si ni ẹni ba jawe olubori loun yoo fẹ.
Isẹlẹ naa, to waye nilu Giade nipinlẹ Bauchi lo n se ọpọ eeyan ni haa-hii.
Akọroyin wa to ba Hajara ati ẹgbọn rẹ ọkunrin sọrọ sọ pe awọn ọkunrin mejeeji naa, ti ọjọ ori wọn naa ko to ogun ọdun, ni ko setan lati fi Khadijah  silẹ, lọrọ ba di taa ni iyawo ọsingin yoo ja mọ lọwọ.
Oríṣun àwòrán, @Mubarack_Umar
Awọn mejeeji gba lati kopa ninu idibo eleyi ti arakunrin kan Umar Saleh dari rẹ.
Ki wọn to bẹrẹ idibo ni wọn ti yan igbimọ ti yoo gbẹjọ kotẹmilọrun to ba waye latara idibo naa.
Idibo naa waye ni iwajuile Yunusa to jẹ ọkan lara awọn arakunrin to fẹ gbe Hajara ni iyawo.
Hajara ran awọn ọrẹ rẹ lati lọ wo bi idibo naa ti ṣe lọ ti o si pada ja si pe Yunusa bori Ibrahim to jẹ alatako rẹ.
Oríṣun àwòrán, @Mubarack_Umar
Lọjọ ti idibo waye, se ni ero pe pitimu, to fi mọ awọn ọmọde ati agba,koda awọn oṣiṣẹ ajọ orilalakanfisọri naa peju sibẹ.
Lẹyin idibo naa, ti Inusa bori, ni wọn ba ja iwe ajakọ kan, ti wọn si fun niwe ẹri moyege ibo, pe o lasẹ lati fẹ Hajara.
Ọrọ yi gẹgẹ bi akọroyin wa ti ṣe wadi ko dun mọ Ibrahim ninu ti o si fi ẹhona han nitori pe iwaju ile Yunusa ni idibo ti waye.
Ọrọ ti a ni ki baba ma gbọ, baba naa lojọ pe yoo pada ba wọn pari rẹ
Ọrọ ti lọ si ọdọ baalẹ ilu naa ti ṣe Mohammad Sabo Abdulkadir.
Ibi ti baalẹ ba yanju ọrọ si ni yoo sọ ẹni ti yoo pada fẹ Hajara.
Stray Bullet: Bàbá ọmọ ni ogún náírà péré ni àwọn ọlọ́pàá fi lọ òun àmọ́ òun kò gbàá
O ṣeeṣe ki awọn mọlẹbi ti ọrọ kan pada jiroro lati yanju ọrọ yi ni tubinubi tabi ki wọn tun ibo di.
Bi o ba ṣa tiṣe ri, Hajara ti sọ pe ẹni ti wọn ba sọ pe o yege ni oun yoo fẹ.
Eyi si lo mu ki o di ọkọ iyawo, ni oloruka ba gba oruka, ti ọwọ awe keji si gbofo.
Bullion Van: Àwọn ọ̀dọ́ ìlú Akure faraya lẹ́yìn tí ọkọ̀ akówó sálọ lẹ́yìn tó pa okùnrin kan
Oríṣun àwòrán, @YemieFash
Awọn ọdọ kan nilu Akure ti sẹwọde lodi si bi ọkọ agbówórìn Bullion Van"" ile ifowopamọ kan ṣe pa okunrin kan nilu naa."
Ọmọkunrin ọhun, torukọ rẹ n jẹ Ibikunle Abiodun, ni wọn ni ọkọ ọhun gba lagbegbe Fanibi, lopona to lọ si ilu Ondo.
Awọn ti ọrọ naa ṣoju wọn sọ pe, dẹrẹba ọkọ naa ati awọn ọlọpaa to n tẹlẹ ko bikita lati duro mọ alafia okunrin ọhun, lẹyin to gba a tan, ṣugbọn n ṣe lo fẹsẹ fẹ.
Ọpọ awọn eeyan ilu Akure ti bẹrẹ si ni fi eroungba wọn han lori iṣẹlẹ naa loju opo Twitter.
Awọn oluifẹhonuhan ọhun bẹrẹ iwọde wọn lagbegbe Oshinle, ti wọn si n kọ oriṣiriṣi orin aro, ki wọn to forile aafin ọba Deji ti ilu Akure.
Wọn ni wọn fẹ ki ileesẹ ọlọpaa ipinlẹ Ondo foju awako naa han-de.
Ọkan lara awọn oloye pataki ilu Akure, Toyin Aladetoyinbo parọwa si awọn ọdọ naa lati ma ru ofin niroti iṣẹlẹ naa
Oríṣun àwòrán, @YemieFash
Aladetoyinbo wa ṣeleri fun wọn pe, Kabiesi ti ilu Akure Oba Aladelusi Aladetoyinbo yoo ri pe awọn ọlọpaa ṣe iwadi to peye lori iṣẹlẹ ọhun.
Valentine: Wo bí àwọn òṣèré tíátà Yoruba ṣe ṣàyájọ́ olúlùfẹ́ ọdún 2020
Oríṣun àwòrán, I_am_shai
Ọjọ kẹrinla Oṣu Keji ni ayajọ ọjọ ololufẹ lagbaye, ọjọ ọhun si jẹ ọjọ ti ọpọ awọn eeyan ma n fi ifẹ han si ẹbi, ọrẹ ati ni paapaa julọ, awọn ololufẹ wọn.
Oriṣiriṣi ọna lawọn eeyan gba ṣajọyọ ayajọ ololufẹ ọdun yii, awọn oṣere tiata Yoruba naa ko gbẹyin ninu ọdun ololufẹ ọhun.
Bi awọn kan lara wọn ṣe n ki awọn ololufẹ wọn ku ọdun ololufẹ, lawọn mii n sọ pe wọn ko ni ololufẹ, lawọn mii ẹwẹ n ṣapejuwe ohun gangan ti ifẹ jẹ.
Koda, ara ọ́tọ lawọn asọ ti wọn wọ fun ayajọ ololufẹ ọhun , awọn kan se wọ asọ alawọ pupa balau, lawọn kan ko si funfun, ti awọn miran si wọ asọ alarabara miran.
Oríṣun àwòrán, aishalawal1
Alhaja Salawa Abẹ́ni, tii se olorin Waka, naa ko dagba ma labẹ, koda inu asọ pupa ni mama fọ si lati se ayajọ ifẹ, to si n ki awọn ololufẹ rẹ ku ayajọ ọdun falẹntai.
Oríṣun àwòrán, officialsalawaabeni
Awoyemi Bukola Grace, ti awọn ololufẹ rẹ mọ si Arugba ṣeranti ọdun diẹ sẹyin nigba to pade ọkọ rẹ, Damola Olatunji.
"O ni ""Mo ranti ọdun diẹ sẹyin nigba ti mo pade arakunrin yii, mi o lero pe a o di tọkọ taya nitori ibi ti mo foju si, ọna ko gbabẹ."""
Oríṣun àwòrán, damolaolatunji
Ni ti ọkọ rẹ Damole, fidio lo fi fesi pada pe Bukola ni ololufẹ and alabadaro oun ti ko si si elomiran lẹyin rẹ.
Jumoke Odetola ni oun n wa okunrin ti yoo ba oun ṣe ọdun naa.
Bukọla Adeẹyọ gan ko gbẹyin ninu ajọyọ ọjọ ifẹ, asọ pupa lo ko si, to si sun silẹ pẹlu ayọ.
Oríṣun àwòrán, bukola_adeeyo
"Aisha Lawal loju opo Instagram rẹ sọ fun awọn tirẹ pe ""Mo n ki yin ku ọdun ayajọ ololufe Falẹntain, ifẹ ati imọlẹ lo n jade lati ọdọ mi nibi."""
"Ni ti Funke Akindele ati ọkọ rẹ Bello ti ọpọ mọ si JJC Skiilz, ibi ayẹyẹ ""LoveFest"" ni wọn ti ṣe ọdun ololufẹ naa ni ilu Eko."
Oríṣun àwòrán, funkejenifaakindele
Afeez Owo pẹlu iyawo rẹ Mide Funmi-Martins naa ko gbẹyin, bi wọn ṣe ṣe ajọyọ ọdun ololufẹ ọhun papọ.
"Ọgbẹni Owo gbe aworan oun ati iyawo rẹ soju opo Instagram rẹ, to si kọ akọle kan pe ""Ololufẹ mi."""
E wo die lara awon aworan ti awọn oṣerẹ tiata Yoruba miran fi lede lati fi ṣajọyọ ayajọ ololufẹ naa.
Iyabo Ojo.
Oríṣun àwòrán, iyaboojofespris
"O ni ""A de ku odun valentine oni o🤦, ọmọ araye o ni fi kayamata gba ọkọ lọwọ wa. Awa ti a o tii ni, a o ni se asedanu lori ọkọ ọplọkọ o."""
Oríṣun àwòrán, kunleafod
Ni ti Kunle Afod n tiẹ, kaadi lo se sita pẹ́lu aworan rẹ ninu rẹ, to si fi n ki awọn ololufẹ rẹ pe wọn ku ọdun ọjọ ifẹ.
Oríṣun àwòrán, realmercyaigbe
Asẹ alawọ pupa ati funfun ni Mercy Aigbe wọ, to fi ki awọn ololufẹ rẹ ku falẹntai.
Oríṣun àwòrán, Eniola Badmus
Ẹniola Badmus ree, to n ki yin pe ẹ ku falẹntai, ọpọ ẹbun ti awọn ololufẹ rẹ fi ransẹ si bii ẹbun ọjọ ifẹ, si lo patẹ rẹ yii, koda awọ pupa ati funfun lo ko si, to si dun wo.
Oríṣun àwòrán, I_am_shai
Aworan eyi tun ga. Aworan mama kan ree ti Seyi Ẹdun gbe soju opo Instagram rẹ, eyi to n safihan pe ayajọ ololufẹ ko si fun awọn ọdọ nikan, tọmọde tagba lo wa fun.
Oríṣun àwòrán, Kola Ajewole
Baba ati Mama Ire naa ko gbẹyin, Toyin Abraham ati Kolawole Ajewole, awọ̀n se ayajọ ololufẹ ni ranpẹ.
Kola ni bi Toyin ba pẹ laye di ọdun mọkanlerugba, oun naa fẹ ba gbe, to ba wa ku ọjọ kan ki dun naa pe, ki oun re kọja lọ, tori oun ko fẹ gbe ile aye laisi Toyin nibẹ. Ifẹ eyi tun ga ju.
Valentine: Ọkùnrin ní kí obìnrin má fún àwọn ní àwọ̀tẹ́lẹ̀ mọ́ bíi ẹ̀bùn ọjọ́ olólùfẹ́
Lagos Abeokuta Accident: Àwọn ọ̀dọ́ dáná sun tírélà Dangote tó sọ èèyàn méje dèrò ọ̀run
Oríṣun àwòrán, Google
Ijamba ọkọ tirela  Dangote kan ati awọn ọkọ akero meji to waye ni opopona maroṣẹ Eko si Abeoukuta ti mu ẹmi eniyan meje lọ, ti eniyan mewa si farapa.
Fun idi eyi,awọn aradugbọ towa lẹgbẹ ibi ti iṣẹlẹ naa ti waye iyẹn Old Toll Gate ni Ọta ti dana sun ọkọ tirela Dangote naa.
Ọkunrin agbalagba meji,obinrin mẹta, ọmọdekunrin kan ati ọmọdebinrin kan lawọn to ba iṣẹlẹ naa lọ.
Ninu atẹjade kan ti ileeṣẹ BBC ri gba lọdọ ọga ajọ ẹsọ oju popo nipinlẹ Ogun, Clement Oladele,ijamba ọkọ naa waye ni ọjọAbamẹta ni nkan bi ago mọkanla aabọ owurọ.
Oladele ṣalaye pe are asaju lo ṣokunfa ijamba naa ati pe ọpọ ẹmi lo ti lọ ni agbegbe ibi ti ijamba naa ti waye .
Oríṣun àwòrán, FRSC
Oríṣun àwòrán, FRSC
O ni laarin ọdun marun un tokọja, o to eeyan ogoji to ti ko agbako iku nitori ijamba ọkọ ni ibẹ.
O rọ awọn ọlọkọ nla lati ṣe pẹlẹ ki wọn yago lati ma sare apaajude ki iruijamba bayi ma ba waye.
3rd Mainland Bridge: Mo fẹ́ lọ tọ̀ l'ọkùnrin tó bẹ́ sódò so fún awakọ̀
Oríṣun àwòrán, LASEMA
Lẹyin ọpọ wakati wọn ko ribi doola arakunrin to bẹ sodo naa
Igbiyanju lati doola arakunrin to bẹ si ọsa lati ori afara Third Mainland Bridge nilu Eko ti wa si opin.
Ohun ta gbọ ni pe arakunrin naa sọ fun awakọ to gbe wi pe oun fẹ tọ  afi bo ṣe bọ silẹ ninu ọkọ ti o si bẹ sodo.
Gẹgẹ bi ohun ti ileeṣẹ ọlọpaa nilu Eko sọ, iṣẹlẹ naa waye ni nkan bi ago mọkanla owurọ ti gbogbo awọn oṣiṣẹ pajawiri si pawọpọ lati doola ẹmi rẹ.
Gẹgẹ bi ohun tajọ iṣẹlẹ pajawiri nilu Eko,LASEMA sọ, wọn ni orukọ arakunrin naa ni Daibo Toju Davies ti ọjọ ibi rẹ si jẹ ọjọ kejilelogun oṣu Keje ọdun 1998.
Wọn fi kun pe o n gbe ni ojule kẹtadinlogun ni opopona Sosanya,Gbagada Soluyi nilu Eko.
Oríṣun àwòrán, Twitter/RRS Lagos
Lasema sọ pe lati ile iwosan Mercy Hospital ni Gbagada ni arakunrin naa ti wọ ọkọ Uber ki o to de ori afara Third Mainland ti o si bẹ sodo.
Wọn ni iwaadi awọn fi han pe arakunrin naa sọ fun awakọ Uber to gbe pe inu n run oun.
Suicide Prevention: ìwọ́de yìí wáyé láti gbógun ti pípa ara ẹni
Kete ti awakọ duro, lo ba bẹ sodo.
Agbarijọpọ ajọ iṣẹlẹ pajawiri ati ileeṣẹ panapana ilu Eko ni wọn jijọ gbiyanju lati doola ẹmi arakunrin naa.
PDP sí Buhari: Gbájú mọ́ ìṣèjọba rẹ ní, yé dùnkokò mọ́ alátakò àti oníròyìn
Ẹgbẹ alatakọ lorileede Naijiria Peoples Democratic Party ti sọ fun aarẹ Muhammadu Buhari pe ki o duro nibi ti wọn ba fi ẹlẹmọṣọ rẹ sọ ko ye dunkoko mọ alatako.
Ikilọ ti wọn fi sita yi ninu atẹjade kan ko sẹyin bi ileeṣẹ aarẹ ti ṣe ni awọn alatako ati awọn oloṣelu kan n pete lati ṣe iwọde kan lọjọ Aje.
Kola Olongbọdiyan to jẹ akọwe ipolongo ẹgbẹ naa lo fi ọrọ yi sita loju opo Twitter.
Ologbọndiyan sọ pe ọrọ ti d'eti igbọ ẹgbẹ PDP pe ijọba Buhari n wa ọna lati doju ọrọ ru lori ailekoju ipenija agbesunmọmi, awọn janduku ajinigbe ati awọn ikọlu miran to n peleke sii ni Naijiria.
''O ti han si gbogbo eeyan to fi mọ ijọba Buhari pe awọn ọmọ Naijiria n tako ijọba rẹ ti wọn ko si nilo ẹnikẹni lati ko wọn jọ ki wọn to fẹhonu han''.
Akọwe ipolongo ẹgbẹ naa sọ bakanna pe''ọna lati dunkoko mọ wa lati ma ṣe beere pe ki ijọba ji si awọn ojuse rẹ ni wọn n da. A ko si ni gba''
Ológbò gan mọ́ yìnyín, ẹ wo bí aláànú yíì ṣe fi ǹkan gbígbóná yọ wọ́n
Lọjọ Abamẹta ni Garba Shehu to jẹ agbẹnusọ ileeṣẹ aarẹ Naijiria figbe ta pe awọn oloṣelu kan ati awọn to n jẹ nidi ikọlu BokoHaram ti ṣeto awọn ayederu oluwọde to to ẹgbẹrun meji ti yoo fi ẹhonu han tako awọn olori ọmọogun Naijiria lọjọ Aje.
Garba Sheu to darukọ ẹgbẹ PDP ninu ọrọ rẹ sọ pe ọna ati tabuku ba aarẹ Buhari ni wọn da ti wọn si fẹ ki araye ro pe awọn ọmọ Naijiria wa lẹyin wọn.
Oluwo: Ìgbà mẹ́rin rèé tí ọ̀rọ̀ Oluwo ti Iwo dá awuyewuye sílẹ̀
Oríṣun àwòrán, Instagram/emperortelu1
Ninu ọba alade ilẹ Kaarọ ojiire, o fẹẹ ma si eleyi ti o sunmọ ọba ilu Iwo Abdulrasheed Adewale nibi ka jẹ olokiki.
Laye ode oni ti ti ọlaju oju opo ayelujara ti gbilẹ, iroyin orisirisi nipa Ọba yii lawọn eeyan ma n gbe kaakiri.
Pupọ ninu awọn iroyin wọnyi a maa ti ati ọwọ ọba Abdulrasheed wa nitori pe oun gaan ma n fi ọrọ si oju opo Instagram nipa ohun to ba n ṣẹlẹ ni ayika rẹ.
Ẹ jẹ ki a a ran ara wa leti diẹ ninu awọn iroyin to jẹyọ latara ọrọ ti ọba alade yi sti ọ ati awọnnkan to ṣe to mi igboro titi
#Oluwo Divorce
Kabiesi ni idi ti oun fi kọ olori Chanel silẹ ni pe iyatọ n waye laarin awọn ti ko ṣee yanju.
Iroyin yii mi igboro titi ti awọn eeyan si bẹrẹ si ni sọ pe ko yẹ ki ọba Alade kọ iyawo rẹ silẹ.
Oluwo ko sọ ni pato ohun to fa ikọsilẹ naa lasiko yii ju pe ki awọn eeyan dẹkun bibu ọla fun Channel gẹgẹ bii iyawo oun mọ.
Oríṣun àwòrán, @others
Ọmọ kan ni Chanel bí fún Oluwo, orukọ rẹ a si maa jẹ Oduduwa.
"Olori Chanel Chin jẹ ọmọ orilẹ-ede Jamaica, baba rẹ si ni olorin takasufe ti ọpọ eeyan mọ si ""Bobo Zaro."""
'Èmi ni atọ́nà oyè Wàzírì nílẹ̀ Yorùbá'
Ọrọ o ṣe oye Waziri ilẹ Yoruba ko ṣe oye Waziri jẹ ọkan ti o da awuyewuye silẹ nigba ti Oluwo ilu Iwo sọ ọ.
Oluwo tilu Iwo so pe oun fẹ di Ọba onilawani (Emir) ilẹ Yoruba
Ki lo ṣẹlẹ gaan? Oluwo kede pe oun fẹ danikan ṣe ifilọlẹ ẹni ti yoo jẹ Waziri fun gbogbo ilẹ Yoruba lalai fi ti awọn ọba toku tabi awọn onimọ Islam miran ṣe.
Ọrọ ko dun mọ awọn Alfa ilẹ Yoruba ninu ti o si di fa kin fa a laarin wọn ati Oluwo.
Lẹyin o rẹyin, Oluwo fi ẹni to wu u jẹ oye yi ti awọn Alfa si ni igbesẹ rẹ ko tọna nitori awọn onimọ́ ẹsin lo yẹ kio yan Waziri kii ṣe ọba.
Mo ti ṣetán láti daríi ìfẹ̀họ́nú hàn lòdì sí ìpànìyàn - Olúwó
Oluwo ti ilu Iwo, Ọba Abdulrasheed Adewale Akanbi, sọ pe oun ti ṣe tan lati daríi ifẹhonuhan lodi si ipaniyan ati iwa ibajẹ ti o gbode kan lorilẹ-ede Naijiria.
O bu ẹnu atẹ lu iha ti ijọba kọ si ọrọ ipaniyan ṣowo, ati pe pipaniyan fun ṣiṣe oogun owo buru ju iwa ijinigbe lọ.
Oríṣun àwòrán, @BolanleCole
Oseni laanu wipe ijọba apapọ ko kọbi ara si iwa ipanijaye ti o gbode kan lorilẹ-ede wa
Oluwo tẹsiwaju pe, eto aabo ara ilu jẹ ojuṣe akọkọ fun ijọba.
O si bu ẹnu atẹ lu iwa ifẹmiṣofo ti o ti di tọrọ-kọbọ lorilẹ-ede yii.
Lasiko ajọyọ ọdun Egungun to waye nilu Iwo ni Oluwo ti sọ ọrọ.
Ninu ifọrọwanilẹwo pẹlu BBC Yoruba, Oluwo ni ọna ati gbe aṣa larugẹ ni ọdun egungun yii jẹ amọ oun ko ni gba ki egungun kankan rinrin  idọti wọ aafin oun.
Kosi eegun kan ti yoo wọ aafin mi to gbọdọ dọti. Kii ṣe wipe wọn yoo gbe ẹku 1960 wa, to ti dọti, to n run. Mo fẹ ki egungun to ba wa, jẹ nnkan iwuri fun awọn ọmọde ati awọn agba, ki gbogbo eeyan lee fi ọwọ kan awọn eegun yii.Kabiyesi tẹsiwaju wi pe, ọdun egungun kii ṣe fun ibọriṣa, bikoṣe fun igbelaruge aṣa ati ere idaraya.
LASEMA dáwọ́ wíwá ọkùnrin tó bẹ́ s'ódò 3rd Mainland Bridge dúró
Oríṣun àwòrán, @TalktoLaswa
Odo Afara Third mainland l'Eko
Ajọ to n ri si iṣẹlẹ pajawiri ni ipinlẹ Eko, LASEMA ti so wiwa ọkunrin to bẹ sinu odo afara 3rd Mainland Bridge l'Eko rọ na.
Loru ọjọ Satide ni aj LASEMA ṣe ipinu yii ti wọn si ni idi ti awọn fi ṣe bẹẹ ni tori ọwọ iji omi naa.
Awọn adoola sọ pe bi omi naa ṣe n fi sihin sọhun ko jẹ ki awọn le tete ri arakunrin naa lẹyin ọpọlọpọ wakati ti wọn ti wa ninu omi.
Eyi lo mu ki ajọ LASEMA sun wiwa ọkunrin naa siwaju di ọjọ aje.
Iroyin sọ pe ṣe ni ọkunrin ọhun sọ fun dẹrẹba Uber to gbe e pe oun fẹ tọ, afi ti o bọọlẹ ninu ọkọ to si fo sinu alagbalugbu omi.
Ileeṣẹ Ọlọpaa ipinlẹ Eko jẹ ko di mimọ iṣẹlẹ naa waye ni nkan bii agogo mọkanla owurọ ti gbogbo awọn oṣiṣẹ iṣẹlẹ pajawiri atawn adoola si ti ṣe asugba lati tete doola ọkunrin naa.
Daibo Toju Davies ni arakunrin naa n jẹ ti wọn bi i ni ọjọ kejilelogun oṣu keje ọdun 1998 gẹgẹ bi ajọ LASEMA ṣe sọ ọ.
Wn fi kun un pe ojule nọmba ikẹtadinlogun adugbo Sosanya ni Gbagada Soluyi ni o n gbe ni ilu Eko.
Pẹlu iwadii wọn, wọn ri i pe arakunrin hun sọ fun awakọ to gbe e pe inu n lọ oun. Lẹyin ti awakọ duro lo sọkalẹ to si fo afara bọ sinu odo.
Ajọ́ to n ri si iṣẹlẹ pajawiri l'Eko, LASEMA, ile iṣẹ panapana atawọn adoola oju omi lo wa nikalẹ lakoko naa lati doola rẹ̀.
Ológbò gan mọ́ yìnyín, ẹ wo bí aláànú yíì ṣe fi ǹkan gbígbóná yọ wọ́n
Amotekun: Àwọn aṣòfin ilẹ̀ Yoruba yóò ṣe ìjíròrò ìta gbangban lórí àbádòfin lọ́jọ́ Ajé
Oríṣun àwòrán, @ekitistategov
Gbogbo ile igbimọ aṣofin lawọn ipinlẹ Yoruba ni Naijiria ti ṣe tan lati ṣe ijiroro ita gbangba lori eto ikọ alabo Amotekun.
Agbarijọpọ awọn agbẹnusọ ile igbimọ aṣofin ipinlẹ Ondo, Ekiti, Osun, Oyo, Ogun ati ipinlẹ Eko lo fi ọrọ naa lede.
Nibi ipade kan to waye nilu Ibadan lọjọ Kẹrinla Oṣu Keji ọdun 2020 ni wọn ti sọ pe ijiroro ita gbangba naa yoo waye.
Awọn agbẹnusọ ile igbimọ aṣofin naa ṣepade lọjọ keji ti awọn Gomina ipinlẹ wọn ṣepade pẹlu ọga agba ajọ ọlọpaa ni Naijiria nipinlẹ Eko.
Awọn eeyan ọhun fẹnuko lati ṣepade pẹlu awọn adajọ agba nipinlẹ wọn lẹyin ijiroro naa, lati lee ṣayẹwo agbekalẹ abadofin naa.
"Ninu atẹjade ti wọn fi ṣọwọ si awọn akọroyin ni wọn ti sọ pe ""Lẹyin ọpọ ijiroro ni a fẹnuko pe gbogbo ile igbimọ aṣofin nilẹ Yoruba ni lati gbe igbesẹ ati fi Amotekun sinu ofin ipinlẹ wọn."""
Oríṣun àwòrán, @news360info
"Wọn tẹ siwaju pe ""A ti kan nipa fun  gbogbo ilẹ igbimọ aṣofin ilẹ Yoruba lati ṣe ijiroro ita gbangba nigba kan naa ni awon ipinlẹ wọn lọjọ Aje, ọjọ kẹrinlelogun, oṣu Keji ọdun 2020."""
Bẹẹ ni wọn wa rọ awọn ara ilu lati peju sibi ijiroro ita gbangba ọhun lati le dasi ọrọ abo gbegbe wọn.
Wọn ti wa parọwa si ile igbimọ aṣofin ipinlẹ Ondo to wa ni isinmi lati pada sẹnu isẹ, ki wọn le ṣeṣẹ lori ababdofin ọhun.
Aláàfin ìlú Oyo ti bímọ okùnrin tuntun lẹ́ni odún 81
Oríṣun àwòrán, Alimat Bamgbopa
Ọmọ Kabiesi ni kii jẹ ijẹkujẹ loje ko nio okun
Alaafin ilu Oyo, Ọba Lamidi Olayiwola Adeyemi kẹta ti bi ọmọ okunrin tuntun.
Ọmọ tuntun ọhun ni iyawo kabiesi to kere ju, Olori Damilola Adeyemi bi fun un.
"Ninu ọrọ ti Olori naa fi soju opo Instagram rẹ lo ti ki ara rẹ ku oriire, to si kọ akọle kan sibẹ pe ""Mo ki ara mi ku ori ire, ọmọ ọba ti de."""
Ọkan lara awọn ọmọ Alaafin, Bunmi Labiyi fi idi ọrọ naa mulẹ fun BBC Yoruba ni aarọ yii ninu ifọrọwerọ kan.
O sọ pe ounjẹ gidi ti Alaafin n jẹ ati awọn ere idaraya to ma n ṣe ṣeeṣe ko jẹ ohun to ṣi n fun baba ni okun bi ọdọmọde.
"Bunmi ni ""Baba mi ki n ṣaye bi awọn eeyan mii ṣe ma n ṣe aye wọn. Kii jẹ ijẹkujẹ."""
Oríṣun àwòrán, Alimat Bamgbopa
"Bunmi tẹ siwaju pe Alaafin mọ irufẹ ounjẹ to yẹ ko jẹ ati iru ounjẹ ti ko yẹ ko jẹ, koda o ni Kabiesi kii mu ẹlẹrindodo ""Coca Cola."""
Bakan naa, o fi hande pe onimọ nipa ounjẹ jijẹ ni Kabiesi to si maa n kilọ fun awọn eeyan nipa iru awọn akanpọ ounjẹ ti wọn n jẹ.
"Ọmọ Ọba ṣalaye pe ""Baba mi jẹ ẹni to mọ nipa ounjẹ gidi. Kii sọ pe nitori o jẹ Ọba Alaye ko wa maa jẹ ijẹkujẹ ki wọn eeyan le ri pe Alaafin lo n jẹun. Boya idi niyẹn ti Baba ṣi fi ni okun."""
O pari ọrọ rẹ pe Kabiesi fẹran ere idaraya to bẹ to fi jẹ pe o loju ọdọmọde to lee figa gbaga pẹlu Alaafin ti wọn ba bẹrẹ si n rin papọ.
Kò sí ǹkan tó  ń jẹ́ ọ̀rọ̀ ìgbàgbọ́ tàbí ìmọ̀le nínú àgbékalẹ̀ Amotekun - Alake ti Egba
Seyi Makinde: Ìjọba Oyo kò fi ti NURTW ṣe, wọ́n ṣe ìfilọ́lẹ̀ olùdarí ìbùdókọ́ tuntun
Oríṣun àwòrán, Tribune
Adari ẹgbẹ awakọ ero NURTW ipinlẹ Oyo ti ijọba ti fofin de, Alhaji Abideen Olajide ti fesi si ifilọlẹ awọn adari ibudoko lati ọwọ ijọba ipinlẹ Oyo.
Abideen ti ọpọ eeyan mọ si Ejiogbe sọ fun ileeṣẹ BBC Yoruba ninu ifọrọwerọ pe ohun ko ni nkankan sọ nipa igbesẹ yi yatọ si eleyi ti awọn agba ẹgbẹ NURTW ni Abuja ba sọ.
Ni ọjọ Aje ni ijọba ipinlẹ Oyo ṣe ifilọlẹ awọn adari ibudo iwọkọ ti yoo ma ṣe akoso gbigba owo si apo ijọba lawọn ibudoko kaakiri ipinlẹ naa. Fun idi eyi, ọwọ ijọba ipinlẹ Oyo ni owo ti wọn ba gba yoo maa lọ bayii.
Ṣaaju ifilọlẹ yi, Ejiogbe ati awọn ọmọ gbẹ rẹ kan ti fohun silẹ ninu fọnran fidio kan pe awọn yoo da wahala silẹ ti ijọba ba tẹsiwaju pẹlu igbesẹ yi lọjọ Aje.
Alhaji Mukaila Lamidi ti awọn eeyan mọ si Auxilliary naa da si ọrọ yi ninu fidio ti ẹ na totini kawọn eeyan sowọ pọ pẹlu ijọba.
Ninu atẹjade tawọn naa fi sita ni idahun si fidio yi, ileeṣẹ ọlọpaa ni Oyo fi ikilọ sita pe ki awọn ọmọ ẹgbẹ naa ti ọwọ ọmọ wọn baṣọ ti wọn ko ba fẹ jẹ iyan wọn niṣu.
Ẹwẹ ifilọlọlẹ awọn adari tuntun yi ti waye gẹgẹ bi ohun ta ri ka ninu iwe iroyin Tribune to fi Ibadan ṣe ibujoko.
Gẹgẹ bi wọn ṣe sọ,Kọmisana fun ohun amayederun ati irinna ni Oyo, Raphael Afonja lo ṣe ifilọlẹ yi.
Yatọ si awọn adari ti wọn yan ati igbakeji wọn fun ibudokọ kọọkan, ijọba tun fi alaga ẹgbẹ awakọ ero tẹlẹ ri ni Ibadan Alahaji Lamidi Mukaila Auxiliary jẹ alaga igbimọ ti yoo ma ṣe akoso awọn adari wọn yi.
Kò sí ǹkan tó  ń jẹ́ ọ̀rọ̀ ìgbàgbọ́ tàbí ìmọ̀le nínú àgbékalẹ̀ Amotekun - Alake ti Egba
Kizito Mihigo: Akọrin tó fẹ́ lọ darapọ̀ mọ́ ìkọ̀ ajìjàgbara gbẹ̀mí ará rẹ̀ làhàmọ́
Oríṣun àwòrán, AFP
Awọn ọlọpaa lorileede Rwanda sọ pe akọrin kan tawọn mu lọsẹ to kọja nigba ti o fẹ sa kuro nilu ti pa ara rẹ ni atimọle.
Gẹgẹ bi ohun ti wọn sọ, Kizito Mihigo n gbiyanju lati lọ darapọ mọ awọn ajijagbara kan ni orileede Burundi.
Akọrin naa ti lo ọdun mẹta lẹwọn latara bi ijọba ṣe fẹsun kan pe o n gbimọran lati ditẹ gbajọba.
Amọ ṣa, awọn ajafẹtọmọniyan lẹyin odi ti fi ọwọ rọ alaye awọn ọlọpaa yi ṣi ẹgbẹ kan.
Wọn ni Kizito ko ni erongba lati darapọ mọ awọn ajijagbara kankan bi kii ṣe pe o fẹ lọ si orileede Belgium nibi to ti fi igba kan gbe ri.
Bẹẹ ni wọn lawọn ko gbagbọ pe o gbẹmi ara rẹ lahamọ ṣugbọn wọn ro pe awọn ọlọpaa pa ni.
Ohun to da wahala silẹ fun Kizito ni orin rẹ to n kọ.
Ninu ọkan lara orin to fi sita, o sọ pe o yẹ ki ijọba ranti gbogbo awọn to ku ninu iṣekupani lasiko ogun to waye ni Rwanda lọdun 1994 yala wọn jẹ ẹya Hutu tabi Tutsi.
Awọn alaṣẹ lawọn ri ipe rẹ ninu orin naa gẹgẹ bi ọna lati tako ohun ti ijọba sọ pe awọn Tutsi ni wọn ku lasiko ogun to waye nilẹ naa.
Eyi lo mu ki awọn alatako ijọba sọ pe wọn doju le e nitori ọrin to kọ yii.
Ẹwẹ, ileeṣẹ ọtẹlẹmuyẹ ni Rwanda lawọn ti bẹrẹ iwaadi lati mọ ohun to ṣokunfa iku Kizito Mihigo.
Agbẹnusọ ileeṣẹ naa, Michelle Umuhoza sọ fun BBC pe wọn ti gbe oku rẹ si ile igbokupamọ si nibi ti wọn yoo ti ṣe ayẹwo ohun to ṣeku pa.
Lassa Fever: Ṣe ẹ rí eku tí ẹ̀ ń pè yẹn, oúnjẹ tó dára ni - ìyá ẹgbẹ́ àwọn eléwé ọmọ̀
'Mo lè jẹ eku mẹ́wàá lọ́jọ́ kan'
"Ṣé ẹ rí ìwádìí tí wọn sọ pé lára eku ni wọ́n ti rí Lassa Fever yẹn, wọn ò tíí mọ ibi tí wọ́n ń lọ."""
Láti inu fídíò tó wà lókè yìí lẹ ó ti gbọ́ ọ̀pọ̀lọ̀pọ̀ ọ̀rọ̀ àgbọ́ ya ẹnu sílẹ̀ lẹ́nu àwọn tí kò léè ju ìgbàgbọ́ wọn nínú ohun tí wọ́n ti ń ṣe tàbí jẹ látayé dáyé nù kí wọ́n wá gba ti òyìnbó tàbí ònímọ̀ ìlera wọlé - Fáàbàdà. Èèwọ̀ ni.
Ọ̀pọ̀lọpọ̀ ìlú lagbaye ni ko mọ pe apa ibi kan ṣi wa lorilẹ aye ti wọn ti n ta eku gbigbẹ iyẹn ni Naijiria
Awọn olutaja kan wa to jẹ pe loju paali, ni beeli, beeli, dọsiini dọsiini ni wọn ko ekute to ti ku sori igba wọn.
"Bẹẹ ba de isọ awọn ti wọn n pe ni ""Lekulẹja tabi Elewe Ọmọ"", ẹ o ki aje ku ikalẹ."
Làáhànmí: Ìwádìí ní èèyàn 219 ni ibà Lassa pa lọ́dún tó lọ́, 29 lọ́dún yìí, tètè dènà rẹ̀
Arabinrin Ṣakirat Jaiyesinmi ni gbogbo awọn ohun tawọn n ta yii ni wọn fi ń ṣe asejẹ fun eeyan to n woju Ọlọrun fun ọmọ, alaboyun ati bẹẹ bẹẹ lọ.
Emi ti mo n baa yin sọrọ yii, mo le jẹ eku mẹwa lojumọ, ti o dẹ ni ṣe mi ni nkankan.
Awọn ọdẹ lo maa n pa awọn eku yii wa fun awọn to n ta a.
"Mama Ṣakirat ti o jẹ iya ẹgbẹ awọn elewe ọmọ ni ọja Ikorodu, ipinlẹ Eko, Naijiria ni ""ṣe ẹ rí eku tí ẹ̀ ń pè yẹn, oúnjẹ tó dára ni"", emi maa n jẹ ẹ daadaa..."
Diẹ to ninu nkan oni nkan, ẹ funra yin wo sii ki ẹ gbọ pabanbari ninu fidio to mbẹ loke iroyin yii.
Oluwo tí sọ̀rọ̀ nípa awuyewuye láàrin rẹ̀ àti Agbowu tìlùu Ogbaagbaa
Oluwo ilu Iwo ba BBC Yoruba sọrọ lori awuyewuye pẹlu awọn Ọba
Oluwo ilu Iwo Ọba Abdulrasheed Adewale Akanbi ti ba BBC Yoruba nipa ohun to ṣẹlẹ laarin rẹ ati Agbowu ilu Ogbaagba.
Ninu ifọrọwanilẹnuwo to waye pẹlu Oluwo, Oba Alade naa ṣalaye pe ko si eleyi ti oun ko bọwọ fun laarin awọn ọba to wa labẹ ohun ṣugbọn iwa arifin awọn kan ti fẹ pọju.
Oluwo ni kii ṣe pe o wu ohun lati ma tahun si awọn ọba wọnyii ṣugbọn nigba ti wọn ba ti n tẹ ẹtọ awọn ara ilu mọlẹ nipa tita ilẹ lọna ti ko tọ, ohun ko ni le dakẹ.
''Ti awọn eeyan ba wa fẹjọ wọn sun mi, mo maa n sọ fun wọn pe ade mi lo wa lori wọn, ẹ ma ba wọn ja. Mo fi aye gba wọn gaan ṣugbọn laarin bii ọdun mẹrin bayii, arifin wọn ti pọju''
Oba Abdulrasheed nigba ti a beere nipa ẹsun ti wọn fi kan wọn pe wọn da apa si ọba Agbowu lara sọ pe ''Iro balawu ni wọn pa mọ mi''
Kii ṣe oni ni wọn ṣẹṣẹ n na ọpa si mi loju. Bẹẹ, eewọ ni ki wọn na ọpa si ọba. Nigba ti wọn fẹ ki ọpa bọ mi loju, ṣe ki n maa wo wọn niran ni?'.
Oluwo tẹsiwaju pe pupọ ninu awọn ọba to n doju ija kọ oun lo ti ta ilẹ awọn baba wọn tan ti wọn wa n wa awọn ilẹ ara ilu ti wọn a ta kun.
O pari ọrọ rẹ pe oun jẹ Oba to ni ifẹ ara ilu lọkan nitorinaa, oun ko ni gba ki ẹni kankan wa maa tẹ ẹtọ ara ilu mọlẹ.
Ibadan Kings: 2,000 si 5,000 ni Oyè Ibadan, àmọ̀ Olubadan ń gba N30m
Oríṣun àwòrán, Others
Otun ti ilu Ibadan, Lekan Balogun ti ni oye ni ilu Ibadan kii ṣe fun tita bi Olubadan ṣe n ta oye fun awọn eniyan.
Balogun ni lati ogoji ọdun sẹyin ti oun ti jẹ ọkan gboogi fun idile ọba ni ko ti si ẹni to n ta oye ni ilu Ibadan.
O ni ẹgbẹrun meji naira si ẹgbẹrun marun naira ni awọn ti wọn ba fi jẹ oye ni ilu Ibadan ma n san, amọ awọn n gbọ pe Olubadan n ta oye fun awọn eniyan ni ọgbọn miliọnu naira.
Otun ni ohun ti wọn ma n ṣe ni Ibadan ni wi pe, wọn ma n fi oye fun awọn ti wọn ba ni orukọ rere ni awujọ, bi wọn ko tilẹ ni owo lọwọ.
Amọ, O ni ohun ti oun gbọ ni wi pe ẹni ti o ba ni owo julọ ni Olubadan n fun ni oye, bi ko tilẹ ni orukọ rere.
Lori ẹsun wi pe wọn fẹ yọ ọba Olubadan ni ipo, Otun ti ilu Ibadan ni awọn ko sọ wi pe awọn fẹ yọ Olubadan.
Oríṣun àwòrán, Others
Ati wi pe ẹṣẹ si awọn afọbajẹ, iyẹn Balogun ati olori ile Olubadan ni ilu Ibadan ko lee sọ wi pe ki wọn yọ ọba bi o tilẹ jẹ pe wọn ni aṣẹ lati yọ Olubadan ni ipo.
O fi kun un wi pe ẹṣẹ si ilu ni awọn fi le yọ Olubadan ni ipo, ati wi pe tita oye ilu Ibadan ja si ẹṣẹ si ilu, amọ awọn ko ni i lọkan lati yọ Olubadan nipo.
Balogun fi kun un wi pe yiyọ Olubadan ni ipo lee ba ilu Ibadan jẹ, eleyii ti awọn ko fẹ ko ṣẹlẹ.
Amọ gbogbo igbiyanju wa lati jẹ ki Olubadan fi ero rẹ lede lori ẹsun ti wọn fi kan an naa lo ja si pabo. Agbẹnusọ fun Olubadan, Adeola Oloko ko gbe ẹrọ ibanisọrọ rẹ, bakan naa ni oluwoye igbesẹ, Yanju Adegboyega naa ko gbe ẹrọ ilewọ rẹ.
Mike Ifabunmi, àwọn òṣèré Yorùbá kí BBC Yorùbá kú ayẹyẹ
Mike Ifabunmi kí BBC Yorùbá kú ayẹyẹ ọdún méjì
Ọpọlọpọ awọn eeyan jankan jankan lo ti n fi ikini ku ayẹyẹ ọdun meji ranṣẹ si ileeṣẹ BBC Yoruba tẹ  o si maa ri gbogbo rẹ loju opo wa bi oni ba ṣe n lọ.
Ka to wi ka to fọ ka to ṣẹju pẹrẹ, ọdun meji ti pe. Ọmọ kekere ana ti wa wa dagba.
Akanṣe eto pataki ti a ṣe fun ayẹyẹ ọdun meji BBC Yoruba loju opo Facebook wa niyii nisalẹ.
Awọn iroyin pataki taa ti mu wa fun un yin ko lonka lati igba ti BBC Yoruba ti bẹrẹ.
Iko BBC Yoruba tuntun
Kẹrẹkẹrẹ nigba ti igbohunsafẹfẹ ileeṣẹ BBC Yoruba ati kiko iroyin sori ẹrọ ayelujara bẹrẹ lọjọ naa lọhun, wẹrẹ wẹrẹ la n wọle si ọkan awọn eeyan.
Eyi ko tii dawọ duro bayii o koda, iroyin wẹrẹwẹrẹ ti di eyi ti wọn n rọ lu witiwiti lati ka bayii to bẹẹ ti okiki BBC Yoruba ti kan tayọ orilẹede Naijiria to si ti de gbgobo agbaye.
Iroyin lori eto oṣelu atawọn eekan Naijiria
Olusegun Obasanjo: Ọmú ìyá mi ti mo fi ń mùkọ ni kekere ló jẹ ki ń lókun
BBC Yoruba taa ṣe ifilọlẹ rẹ ni dede ọjọ oni lọdun meji sẹyin, ọjọ kọkandinlogun, oṣu keji ọdun 2018 ni ifilọlẹ pataki nla naa waye ni ipinlẹ Eko, Naijiria.
Itan ati Aṣa Yoruba
Ṣé ẹ mọ̀ pé olóògbé Ìjàpá tó kú lẹ́ni ọdún 344 yìí kò gba abẹ́rẹ́ rí?
"A gbúdọ̀ wẹ̀ ọmọ tuntun pẹ̀lú epo pupa, kàìnkàìn ìbílẹ̀ àti ọṣẹ dúdú'
Àkójọpọ̀ àwòrán láti ìpàdé ìtagbangba pẹ̀lú àwọn olùdije ní Ọyọ
Sanwo-Olu, Jimi Agbaje yọ kúrò nínú ìfọ̀rọ̀wérọ̀ ìtagbangba BBC ní Eko
Ọ̀rọ̀ LAUTECH gba àpérò f'áwọn Olúdíje Ọṣun
Ọ̀nà tí àwọn olùdíje ipò gómínà ní Ìpínlẹ̀ Ọyọ fẹ̀ gbà yànjú ọ̀rọ̀ ààbò rèé
Kwara yóò gbàlejò BBC Yoruba
2019 Elections: Aago mẹ́sàn-án àárọ̀ ni ìjíròrò Eko yóò bẹ̀rẹ̀
Iriwisi àwọn ará ìlú ṣe ọtọtọ lórí èsì ìdìbò Osun
Lara awọn iroyin manigbagbẹ ti a ti sẹ ni yii nipa eto idibo gbogboogbo to waye lorilẹede Naijiria ni ọdun 2019, eto oṣelu ni Naijiria, asa, iroyin kayeefi to fi mọ iroyin awọn oṣere tiata Yoruba lorilẹede Naijiria.
Akure Kidnap: E túbọ̀ ní sùúrù, a máa wá ọmọ náà rí- Alukoro ọlọ́pàá
Sotitobire church: Àwọn ọ̀dọ́ ilu dáná sun ilé ìjọsìn
Ondo: Dejí sun ọmọ méje àtagbalagba meji mọ́lé nítorí pé ó ń bínú
Lassa fever: ìpínlẹ̀ Èkó kéde èèyàn kan pẹ̀lú ibà Lassa
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Iba Ọrẹrẹ, ti aye mọ si iba Lassa ti wọ ipinlẹ Eko bayii!
Kọmiṣọna feto ilera nipinlẹ Eko, Ọjọgbọn Akin Abayọmi lo ṣalaye eyi ninu atẹjade kan lọjọru.
Ọjọgbọn Abayọmi ni ẹni naa ti wa labẹ itọju nileewosan nla fasiti ilu Eko, LUTH.
Amọṣa kọmiṣọna feto ilera nipinlẹ Eko ko ṣai fi awọn olugbe ipinlẹ naa lọkan balẹ pe ko si idi fun wọn lati foya nitoripe eto gbogbo ti to lati kapa iba naa to ba fẹ gbera sọ nibẹ.
O ni ileeṣẹ eto ilera ti n ṣe iwadii lori awọn eeyan ti ẹni to ko aarun naa ba da nnkan pọ lati mọ awọn to ṣeeṣe ko ti ko aarun ọhun lọwọ yii nipasẹ rẹ.
Bakan naa ni kọmiṣọna fun eto ilera ni ipinlẹ Eko tun ke sawọn eeyan ipinlẹ Eko lati karamasiki ilera wọn ki wọn si yago fun ekute.
O ni awọn agbegbe ayẹwo iyasọtọ ti wa kaakiri lati tọju awọn eeyan to ba lugbadi aisan naa; ti oogun ati itọju to bagbamu pẹlu ilana agbaye si ti wa nikalẹ fun wọn.
Gẹgẹ bii iwadii ajọ to n ṣewadi ati igbogun ti ajakalẹ arun lorilẹede Naijiria, eeyan eedẹgbẹta ati mọkanlelọgbọn ni wọn ti funra aisan iba Lassa si bayii lorilẹede Naijiria; mẹrinlelọgọrun ninu wọn ni wọn si ti fi idi rẹ mulẹ pe wọn ni aisan naa ti eeyan mẹfa si ti jade laye nipasẹ rẹ.
Champions league: Lẹ́yìn tó fìdírẹmi ní Spain, Ṣé Liverpool ṣì leè yí ojú ayò padà ní Anfield?
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ifẹsẹwọnsẹ akọkọ ni ipele komẹsẹ o yọ to kan ni idije Champions league ọdun yii ti bẹrẹ.
Lara eyi to waye ni aṣalẹ ọjọ Iṣẹgun ni itaporogan laarin ẹgbẹ agbabọọlu Athletico Madrid ati Liverpool.
Goolu ti Saul Niguez, agbabọọẹu Ath;etico Madrid gba wọle nigba ti ifẹsẹwọnsẹ naa wọ iṣẹju kẹrin ni o la awọn ikọ mejeeji laarin ni papa iṣire Wanda Metropolitano
Bi o tilẹ jẹ wi pe Athletico Madrid bori ifẹsẹwọnsẹ naa, sibẹ ọrọ ọhun ko tii tan nitori pe awọn ẹgbẹ agbabọọlu mejeeji yii yoo tun fojurinju ni ọsẹ mẹta si asiko yii ni papa iṣire Anfield to jẹ ibuba Liverpool.
Ibeere to wa n gba ẹnu ọpọ bayii ni pe, ṣe yoo ṣeeṣe fun Liverpool lati yi oju ayo pada?
Lootọ, oniruuru ọrọ ni awọn ololufẹ Liverpool ti nsọ lati fi igbagbọ wọn han pe ikọ naa yoo yii pada yoo si bori Athletico lati tẹsiwaju.
Bi a ba ni ka wo o daradara, ikọ agbabọọlu Liverpool kii ṣe ajeji si irufẹ igbesẹ bẹẹ.
Eyi si ni awọn igba ti Liverpool ti yi oju ayo pada fun awọn alatako wọn lẹyin ti wọn ti kọkọ n m'oke.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ni ọdun 2005, Liverpool na Milan pẹlu ami ayo gbe e silẹ ko o gba a si goli, pẹnariti lati gba ife ẹyẹ Champions league ni ọdun naa lọhun.
Eyi waye lẹyin ti  Milan ti kọkọ gba goolu mẹta wọ ile Liverpool ki Liverpool to wa ta kiji da mẹtẹẹta pada.
Bi ti ọdun 2005 ba jina, eyi to waye ni ọdun to kọja, 2019 tun le nilẹ.
Barcelona ti na Liverpool pẹlu ami ayo mẹta si odo ni ifẹssẹwọnsẹ akọkọ to waye ni papa iṣire Camp Nou ni Spain ni ipele to kangun si aṣekagba idije Champions league kan naa. Nigba ti Barcelona yoo fi yọju si papa iṣire Anfield fun apa keji goolu mẹrin si odo ni wọn ba lọ eleyi to gbe Liverpool wọ ipele aṣekagba idije naa eyi ti wọn wa bori lẹyin-o-rẹyin.
National ID: Anthony Joshua gba nọ́mbà ìdánimọ̀ NIN, wo èsì àwọn ọmọ Nàìjíríà
Oríṣun àwòrán, NIMC
Eto iforukọsilẹ fun nọmba idanimọ awọn ọmọ orilẹede yii ki ṣe eyi ti o ṣokunkun si ọpọ mọ bayii paapaa julọ lẹnu lọwọlọwọ yii.
Amọṣa gbigba rẹ lo di wahala nla sawọn ọmọ orilẹede Naijiria lọrun paapaa julọ ilana ati gba a.
Ni aṣalẹ ọjọ Iṣẹgun ni ajọ to n ṣe kokari eto iforukọsilẹ  kaadi idanimọ lorilẹede Naijiria, NIMC kede loju opo Twitter rẹ pe gbajugbaja akanjẹ agbaye ni to jẹ ọmọ Naijiria ṣugbọn to n ja fun orilẹede Gẹẹsi pẹlu ti gba forukọsilẹ fun kaadi idanimọ gẹgẹ bi ọmọ Naijiria, o si ti gba nọmba idanimọ rẹ, NIN.
Oríṣun àwòrán, @nimc
Pa-pa-pa ti eto naa lọ fun Anthony Joshua lo wu ariwo awọn ọmọ orilẹ€de Naijiria sita ti olukuluku si bẹrẹ si nii sọ ohun oju wọn ri lori ilana ati gba.
Bi awọn kan ṣe n faraya pe nitori pe Joshua lorukọ, o tete ri tirẹ gba, ṣugbọn ọpọ ni o ti wa lẹnu igbesẹ ati gba iwe idanimọ ati nọmba naa ṣugbọn ti ko si ohun to jade nibẹ.
Bakan naa ni awọn kan ṣalaye pe oniruuru aṣemaṣe bii jibiti ati riba gbigba lawọn ọmọ Naijiria n dojukọ labẹ eto naa.
Anthony Joshua: Lẹ́yìn ìjà rẹ̀ pẹ̀lú Luiz, Anthony Joshua bẹ Ọba ìlú rẹ̀, Àkárìgbò wò
Oríṣun àwòrán, CockFM Radio
Ṣe awọn agba bọ wọn ni ọmọ ale ni fi ọwọ osi juwe ile baba rẹ.
Gbajugbaja akanṣẹ lagbaye, Anthony Joshua bẹ ile wo lọjọru. Taara ta ilu rẹ ni Ṣagamu lo mori le, nibẹ lo si ti ṣe baba kẹẹ pẹ sawọn ọbalaye ati oriade gbogbo to wa nilu naa.
Eyi ni igba akọkọ ti Anthony Joshua yoo maa yọju si orilẹede Naijiria lẹyin to gba igbanu ẹyẹ agbaye rẹ, WBA, WBO, IBF ati IBO pada lọwọ Andy Ruiz.
Ọmọ orilẹede Mexico naa si lo gba ami ẹyẹ ọhun dani fun bi oṣu diẹ, nibi ija wọn to waye ni gbagede Diriyah Arena lorilẹede Saudi Arabia.
Oríṣun àwòrán, CockFM Radio
Ọkẹ aimoye awọn ololufẹ rẹ ni wọn rọgba yii ka lasiko to fi lọ ki Alafin Ẹlẹpẹ ati Akarigbo ti ilẹ Rẹmọ ni aafin wọn.
Lẹyin to foribalẹ fawọn ọba alade naa tan, ni Anthony Joshua wa ya fọto pẹlu awọn ololufẹ rẹ ti wọn wa foju gaanni rẹ.
Oríṣun àwòrán, CockFM Radio
Ariwo 'ibi ni ile rẹ kii ṣe ilẹ Gẹẹsi' ni ọpọlọpọ awọn eeyan to tu sita wa wo agba ọjẹ akanṣẹ naa n pa, bi gbogbo wọn ṣe n da giiri lati baa ya fọto, ti wọn si tun wọ tọọ lẹyin lati aafin Elepe lọ si aafin Kabiyesi Akarigbo ti ilu Rẹmọ.
Lassa fever: Ìjọba Eko ní akẹ́kọ̀ọ́ fásitì Ebonyi tó wá kẹ́kọ́ ìmọ̀ òfin, ní wọ́n bá Lassa lára rẹ̀
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ọwọ ijọba ipinlẹ Eko ti tẹ awọn eeyan mẹtalelọgọta ti wọn ti ni ajọṣepọ pẹlu eeyan ti o ni aisan iba Lassa ni ipinlẹ Eko.
Ni ọjọ Iṣẹgun, ọjọ kẹtadinlogun oṣu keji ọdun 2020 ni kọmiṣọna feto ilera ni ipinlẹ Eko, Ọjọgbọn Akin Abayọmi gbe atẹjade kan sita pe ijọba ti ri eeyan kan, to ti ko aisan iba naa, ti wọn si ti fi onitọun si abẹ itọju makan nileewosan nla LUTH.
Kọmiṣọna feto ilera wa ṣalaye fawọn akọroyin lasiko to n ṣe ipade pẹlu wọn ni Ikẹja pe, awọn eeyan to ti ni ajọṣepọ pẹlu eeyan ọhun ni wọn ti fi si ahamọ fun itọju ati ayẹwo, lati rii pe wọn ko tii ko aisan naa.
Dokita mẹjọ lo ti ba arun lassa lọ ni Naijiria
O ni akẹkọ fasiti ipinlẹ Ebonyi ni arakunrin ti wọn mu pẹlu arun iba Lassa ati pe, ibudo ikẹkọ agba nipa ofin, to wa ni ilu Eko lo wa lati gba imọ kun imọ nipa ẹkọ imọ ofin, ko to di pe aarẹ muu.
Kọmiṣọna feto ilera fi kun un pe, ileewosan ile ẹkọ naa to lọ lati ṣalaye pe iba n ṣe oun lo fi di ẹ mulẹ pe, nigba ti ko san lẹyin gbogbo itọju aisan iba gbogbo ti wọn fun un, ni wọn yẹ wo fun arun Lassa.
O wa rọ gbogbo awọn olugbe ipinlẹ Eko lati tete fi to ijọba leti, bi wọn ba kẹẹfin ẹnikẹni to n ṣafihan awọn aisan iba ti ko fẹ gbọ ogun ati itọju, ki ijọba lee tete gbe wọn lọ fun ayẹwo ati itọju to ba yẹ.
Female Driver: Sokunbi ni obìnrin àwakọ̀ Dáńfó l‘Eko, tó ń lọ̀ láti ìpínlẹ̀ kan sí òmíì
Bakan naa ni ijọba ipinlẹ Eko tun ya awọn nọmba ibanisọrọ kan silẹ fun ipe pajawiri lori aisan Lassa nipinlẹ naa.
Awọn nọmba ibanisọrọ naa ni 08023169485, 08033565529 ati 08052817243
Stellah Adadevoh: Ẹ̀bí dókítà náà ní ìfẹ́ Nàíjíríà ló ní tó fi fi ẹ̀mí rẹ̀ lélẹ̀
Oríṣun àwòrán, drasatrust
Awọn ẹbi oloogbe Dokita Stellah Adadevoh ti ni, inu awọn dun si igbesẹ ti ijọ́ba apapọ gbe lati fi opopona kan sọ ori dokita naa, lẹyin ọdun marun to doola orilẹede yii lọwọ ajakalẹ nla, to ṣeeṣe ki apa rẹ o maa ka.
Ninu ọrọ to ba BBC News Yoruba sọ, Arabinrin Niniọla Williams ṣalaye pe, bi o tilẹ jẹ wi pe Dokita Adadevoh ko fi ẹmi rẹ lelẹ nitori ati gba ami ẹyẹ kankan, bikoṣe ifẹ nla to ni si orilẹede Naijiria, sibẹ inu awọn mọlẹbi ko ṣai dun si igbesẹ naa.
Ọmọ orilẹede to nifẹ Naijiria tọkantọkan ni oloogbe Adadevoh, idi si niyi to fi ṣe ohun to ṣe"""
Fun ọpọlọpọ ọmọ Naijiria to ranti ohun to ṣẹlẹ ni ọdun marun un sẹyin, wọn ko lee gbagbe orukọ Dokita Ameyo Stellah Adadevoh.
Oríṣun àwòrán, Others
Ohun ti yoo si wa si iranti wọn ni ipa takuntakun ti arabinrin naa ko, lati rii daju pe aisan gbẹmigbẹmi nni, Ebola ko raye ṣọṣẹ lorilẹede Naijiria.
Bi kii ba ṣe ti Dokita yii ni, to fi tipa tikuuku de ọmọ orilẹede Liberia kan, Patrick Sawyer to ko arun naa wọ orilẹede Naijiria mọlẹ ni ileewosan rẹ, First Consultant Hospital, to wa nilu Eko, afaimọ ki ẹmi ti ko ba ba arun naa lọ nigba naa ma di ẹgbẹlẹgbẹ.
Lọna ati sọ orukọ akọni obinrin naa di manigbagbe, lọjọru ni ijọba apapọ fi orukọ Dokita Adadevoh sọ opopona kan ni olu ilu Naijiria, Abuja.
Oríṣun àwòrán, Others
Opopona naa, lo wa lagbegbe opopona Ahmadu Bello nitosi gbọngan ipade nla ti ileeṣẹ ọmọogun ofurufu ilẹ Naijiria, Nigeria Airforce Conference center.
Ni ọjọ kọkandinlogun oṣu kẹjọ ọdun 2014 ni Dokita Adadevoh jade laye, lẹyin to ti ko arun Ebola naa lara Ọgbẹni Sawyer to wa sorilẹede Naijiria lati Liberia.
Oríṣun àwòrán, drasatrust
Awọn kan n woye pe ohun to loorin ju eyi lọ, bii ileewosan to ti ṣiṣẹ nigba aye rẹ, papakọ ofurufu, ibudokọ oju omi, tabi papa iṣere ati ileewosan apapọ orilẹede Naijiria, lo yẹ ki ijọba fi sọ ori dokita Adadevoh.
Bẹẹni awọn miran kan sara si ijọba fun igbesẹ naa ti wọn si tun n woye pe, o ku ni ibọn n ro, ki ijọba o ranti awọn oniṣẹ eto ilera miran to ku lasiko arun naa.
Female Driver: Sokunbi ni obìnrin àwakọ̀ Dáńfó l‘Eko, tó ń lọ̀ láti ìpínlẹ̀ kan sí òmíì
Female Driver: Sokunbi ni obìnrin àwakọ̀ Dáńfó l‘Eko, tó ń lọ̀ láti ìpínlẹ̀ kan sí òmíì
Yoruba ni ohun ti ọkunrin lee se, awọn obinrin gan lee se ju bẹẹ lọ, idi isẹ ẹni si laa ti mọ ni lọlẹ.
Folasade Sokunbi, tii se awakọ danfo akọkọ to n na ipinlẹ kan si omiran salaye fun BBC Yoruba pe, awọn ẹbi, ara ati ọrẹ tako isẹ naa nibẹrẹ, amọ oun ko gba fun wọn.
Sokunbi ni isẹ asejere ni isẹ danfo wiwa, bi o tilẹ jẹ pe ko rọrun rara, sibẹ, oun fẹ di ọga nla.
Royal Tussle: Olúbàdàn ní Lekan Balogun nìkan ló ń bá òun jà, àwọn ìjòyè yókù kò sí lẹ́yìn rẹ̀
Oríṣun àwòrán, Others
Kaka ki ewe agbọn dẹ, ko ko ko lo n le si lọrọ aawọn to wa laarin Olubadan ati awọn ijoye rẹ mọkanlelogun, ti wọn ti di ọba bayii.
Olubadan tilẹ Ibadan, Oba Saliu Adetunji Aje Ogungunnisọ kinni, ti naka aleebu sawọn ijoye rẹ lori bi wọn se n lo awọn ẹsun ti ko lẹsẹ nlẹ lati fi ba oun lorukọ jẹ, ti wọn si tun n tẹnbẹlu ori apeere toun wa.
Atẹjade kan to bọ sọwọ awọn akọroyin lati aafin Olubadan wa n fewe ọmọ mọ awọn araalu leti pe ki wọn yago gede gede fun awọn  iroyin ẹlẹjẹ, eyi to fara pẹ ọrọ ahesọ nile ọti ati eyi to jọ tawọn eeyan ti oogun oloro n da laamu, to lu igboro pa bayii.
Atẹjade naa, eyi to n fesi si iwe kan tawọn ọba mọkanlelogun ọhun fisita lọjọ Aje pe ọgbọn miliọnu naira ni Olubadan n ta oye nilẹ Ibadan, wa n leri leka pe Olubadan ti pinnu lati wẹ ara rẹ mọ lọwọ awọn ọrọ abanilorukọjẹ bii eyi.
Oríṣun àwòrán, Others
Atẹjade naa, ti amugbalẹgbẹ Olubadan feto iroyin, Adeola Oloko fisita, wa n kesi awọn ijoye Olubadan ọhun lati tọkasi eeyan kan pere, to ra oye nilẹ Ibadan pẹlu ọgbọn miliọnu naira.
Ko ba dara ki wọn tu asiri ibi ti wọn ti san owo naa ati akoko ti wọn san, se banki ni wọn san si ni abi sọwedowo ni wọn fi san tabi wọn fi sọwọ lati ori asunwọn owo kan si omiran? Se owo ilẹ okeere ni owo ọhun ni abi Naira ilẹ wa, ati pe iru oye wo ni onitọun fẹ ki Olubadan fi oun jẹ, to fi n san ieu owo banta banta naa.
Oríṣun àwòrán, Others
"Atẹjade naa fikun pe, ""Ọtun Olubadan, Oloye Lekan Balogun to fẹsun kan ọba alade ọhun lo kuna lati jẹ ki awọn araalu mọ nipa owo oye ti Olubadan gba nigba tawọn agba ijoye wa n dirẹbẹ niwaju ọba naa pe ko di awọn alafo to wa ninu igun oye ilẹ Ibadan lati ori Ọtun Olubadan titi de Jagun."""
O ni ẹgbẹrun lọna ọgọrun naira pere ti Olubadan maa n gba naa lo gba amọ ti akasọ oye meji ba wa niwaju ẹnito fẹ joye, a jẹ pe ẹgbẹrun lọna igba naira ni onitọun yoo san, to ba si jẹ alafo oye mẹta ni, a jẹ pe ẹgbẹrun lọna ọọdunrun naira ni yoo san.
Oríṣun àwòrán, Others
Owo yii la maa n san si apo asunwọn igbimọ Olubadan, eyi ti wọn yoo pin si ọna mẹta. Igun kan yoo lọ sọdọ Olubadan, ti igun oye ỌTUN ATI Balogun Olubadan yoo si pin meji to ku.
"Bi awọn ijoye se n parọ kiri naa ree lasiko ti Olubadan fi Ajimobi ati aya rẹ joye, ti wọn ni miliọnu lọna aadọta naira ni Olubadan gba lọwọ gomina ana naa, ayafi igba ti onitọun tan imọlẹ si ọrọ naa pe oun ko san kọbọ fun oye ti wọn fi oun jẹ ọhun.
Oríṣun àwòrán, Others
Ti eeyan ba jẹ ọba lẹnu ọdun mọkanle laadọrun bii Olubadan, iru ọrọ aye wo lo tun ku ti yoo maa ko jọ? Iwa Oloye Lekan si dabi iwa asa, to ro pe gbogbo ẹda yoku naa n jẹ oromọdiẹ. A si fẹ ki Lekan Balogun wa salaye miliọnu mẹfa ati aabọ naira to gba lọwọ Ọmọwe Sunday Ọladiti to ti di oloogbe bayi, lọdun 2017, lori ẹtanjẹ pe oun yoo ba gba oye Jagun lọwọ Olubadan?"""
Lẹyin ti ọkunrin naa ku, Lekan Balogun ko da owo naa pada nitori iyawo ati awọn ọmọ oloogbe ti tọ Olubadan wa pe ko ba awọn dasi ọrọ yii, ki awọn lee ri owo gba pada. Koda, tori atilẹyin owo ti gomina tẹlẹ, Rashidi Ladọja se fun Lekan Balogun laipẹ yii, lo se gbe ẹjọ to pe kuro nile ẹjọ laipẹ yii, to ba si dabi irọ, ẹ bi ajọ EFCC ati ileesẹ ọlọpa nilu Ibadan.
Female Driver: Sokunbi ni obìnrin àwakọ̀ Dáńfó l‘Eko, tó ń lọ̀ láti ìpínlẹ̀ kan sí òmíì
Atẹjade naa tun salaye pe danfo ni Lekan Balogun wa ninu ija to n ba Olubadan ja, ko ni ọmọ ogun lẹyin rara nitori oun naa lo n buwọlu iwe lori awọn oloye yoku, bẹẹ si ni losu kejila ọdun 2019 to kọja ni Lekan Balogun ati awọn oloye yoku wa bẹbẹ fun idarijin lọdọ Olubadan tori bi wọn se fi Baalẹ Alape jẹ lai lọwọ Olubadan ninu.
Auxiliary ní òun yóò lé àwọn ọmọ ẹ̀yìn òun tó ń hùwà tọ́ọ̀gì dànù
Oríṣun àwòrán, The park Management Oyo State
Alaga igbimọ to n ṣe akoso gareeji ọkọ nipinlẹ Oyo, Alhaji Mukaila Lamidi, ti ọpọ eeyan mọ si Auxiliary ti fi ewe ọmọ mọ awọn ọmọ igbimọ rẹ leti, lati yago fun iwa tọọgi ati idaluru.
Bakan naa lo tun dunkooko pe, igbimọ alaṣẹ ti oun n dari ko ni roo ni ẹẹmeji, ko to le ọmọ igbimọ rẹ to ba huwa ọdaran.
Auxiliary leri leka bẹẹ, lasiko ti Ileesẹ ode ati igbokegbodo ọkọ pẹlu ajọ to n ṣe akoso oju popo nipinlẹ Oyo, ṣeto ilanilọyẹ fawọn ọmọ igbimọ alakoso gareeji, lori bi isẹ wọn ko fi ni lọwọ jagidijagan ninu.
"Auxiliary ni ""A ti n gbadun alaafia nipinlẹ Oyo lati igba ti mo ti n dari igbimọ Alakoso gareeji, mo si n rọ awọn ọmọ igbimọ mi lati lati ri daju pe alaafia naa n tẹsiwaju."""
Oríṣun àwòrán, The park Management Oyo State
Auxiliary tun ni oun ko ni faramọ iwakiwa to le ta epo si aṣọ aala awọn, tabi ba iṣẹ rere tawọn ti n tiraka lati ṣe jẹ lati ipasẹ iwa idaluru.
Alaga igbimọ alakoso gareeji ọkọ naa wa gba awọn ọmọ igbimọ rẹ nimọran lati maa kan si awọn ọlọpaa atawọn Ileesẹ agbofinro lagbegbe wọn, ki alaafia lee jọba nibẹ.
Yoruba ni bi ọwọ Bàtá ba ti n le ni aroju, o setan to fẹ ya ni.Asamọ yii ni ijọba ipinlẹ Oyo n pa lowe lowe fun asaaju igbimọ to n ṣe akoso gareeji ọkọ ni ipinlẹ Oyo, Alhaji Mukaila Lamidi, ti ọpọ eeyan mọ si Auxiliary.
Oríṣun àwòrán, The park Management Oyo State
Nigba to n fi ewe ọmọ mọ Auxiliary leti, Kọmisana fun iṣẹ ode ati igboke-gbodo ọkọ nipinlẹ Oyo, Ọjọgbọn Raphael Afonja ni eti ìjọba ipinlẹ Oyo ti kun, lori awọn iwa idaluru ti asaaju igbimọ alakoso gareeji ọkọ ati awọn ọmọlẹyin rẹ n hu nigboro.
Afonja, lasiko to n kopa lori eto ori redio kan nilu Ibadan ni, ko si ẹni ti ijọba ko lee paarọ, yoo si daa ki Auxiliary ati isọmọgbe rẹ so ewe gbejẹ mọ wọ.
Eti ijọba Oyo ti kun nipa iwa ipanle ti awọn ọmọlẹyin Auxiliary n ṣe, mo wa n fi akoko yii kesi oun ati awọn ọmọ ẹyin rẹ lati sinmi agbaja, bi bẹẹ kọ, ìjọba yoo gba ipo naa lọwọ rẹ nitori ko si ẹni to ga ju ofin lọ.Bẹẹ ba gbagbe, ọpọ igba ni ariwo ti sọ nigboro ilu Ibadan nipa bi awọn ọmọlẹyin Auxiliary ṣe n hu iwa ipa ni awọn ibudokọ ti wọn ti n ṣíṣẹ.
Oríṣun àwòrán, Others
Ijọba ipinlẹ ọyọ ti fesi lori idunkoko ẹgbẹ awakọ ero NURTW lẹkun guusu Naijiria to n fẹ kijọba yi ipinnu rẹ pada lori yiyan awọn alakoso gareji ọkọ.
Lasiko to n ba BBC Yoruba sọrọ, akọwe feto iroyin fun gomina, Taiwo Adisa, to gbẹnu Seyi Makinde sọrọ salaye pe, awọn awakọ nipinlẹ Ọyọ nikan lo lasẹ lati sọrọ lori igbesẹ tijọba gbe lati yan awọn awọn adari ọkọ sawọn gareji gbogbo nipinlẹ naa.
Ijọba Ọyọ ni lọdọ awọn, ko sẹni to mọ okolo awọn ẹgbẹ NURTW lẹkun iwọ oorun guusu Naijiria lọyọ, tori wọn ko fi orukọ silẹ lọdọ awọn, oye ohun to si n waye nipinlẹ naa ko ye wọn to.
Oríṣun àwòrán, Others
Ijọba ni ohun ti ko kan awọn asaaju ẹgbẹ awakọ ero naa ni wọn n dasi, bẹẹ si ni igbesẹ ijọba Ọyọ lati maa gba owo ni ẹẹkan lojumọ lo dun mọ awọn awakọ yika ipinlẹ naa ninu, lodi si ohun to n waye tẹlẹ.
Tẹlẹtẹlẹ, awọn awakọ ero nipinlẹ Ọyọ lee sanwo fun irinajo kan ni ọna meji, orita bii mẹta si ni wọn yoo ti sanwo ita naa. Apo awọn eeyan kan si ni owo naa n lọ, eyi ti ko dara to.
O fikun pe, igbesẹ tijọba gbe naa lo n mu ominira ba awọn awakọ gan ni, owo ẹẹkan pere ti wọn ba san wa lati aarọ titi di alẹ, pẹlu afikun pe awọn to n dunkoko mọ ijọba ko mọ ohun ti wọn n sọ ni.
Female Driver: Sokunbi ni obìnrin àwakọ̀ Dáńfó l‘Eko, tó ń lọ̀ láti ìpínlẹ̀ kan sí òmíì
Agbeyẹwo tijọba n se yoo mu ilọsiwaju ba awọn awakọ, ti ijọba yoo si nawo fun atunse awọn gareji ọkọ wa, ti iyatọ yoo si ba wọn laarin ọdun kan, yatọ si bi awọn eeyan kan se maa n da owo gareji si apo ara wọn..
Nigba to n salaye lori idunkooko pe awọn asaaju ọlọkọ naa yoo pasẹ fawọn awakọ lati dasẹ silẹ, ijọba Ọyọ ni ala ti ko lee sẹ ni idunkooko naa, ko si si awakọ kankan nipinlẹ Ọyọ ti yoo tẹle asẹ awọn adari ẹgbẹ NURTW naa.
Igbesẹ ijọba yoo tubọ mu ki owo pọ ni apo awakọ ero kọọkan ni, ti yoo si mu si gba owo kuro lọwọ awọn asaaju ẹgbẹ. Ti igbesẹ naa ko ba si tẹ awọn asaaju ẹgbẹ lọrun, ọkọ tiwọn nikan, to jẹ ẹtahoro ni wọn yoo gbe kuro loju popo, tori ko si awakọ to ya owo ra ọkọ ara rẹ, ti yoo gbọrọ si wọn lẹnu.
Oríṣun àwòrán, Others
Ijọba Ọyọ ni oun ko di isẹ awakọ lọwọ rara, o si rọ awọn awakọ ero lati maa ba isẹ wọn lọ, ki wọn si gbọn eti wọn si ohun ti awọn olori ẹgbẹ to n gba owo lọwọ wọn n sọ.
Bẹẹ ba gbagbe, laipẹ yii ni ẹgbẹ NURTW lẹkun iwọ oorun guusu Naijiria ni oun ko faramọ iyansipo alaga tẹlẹ fẹgbẹ awakọ ero nipinlẹ Ọyọ, Mukaila Lamidi, ti gbogbo eeyan mọ si Auviliary gẹgẹ bii oludari awọn alakoso gareji tijọba sẹsẹ yan.
Oríṣun àwòrán, Seyi Makinde
Awọn asaaju ẹgbẹ ọlọkọ ero naa, ninu eyi taa ti ri MC Oluomo tun n dunkooko pe awọn yoo ni kawọn awakọ ero dasẹ tilẹ tijọba Ọyọ ko ba tẹle ohun tawọn n fẹ laarin ọjọ meje.
Chloroquine: Àwọn oníṣègùn òyìnbò ní China sọ pé Coronavirus o le duro wo tan
Oríṣun àwòrán, Other
Ọrọ yii da bi ọrọ iwe mimọ to sọ pe ''okuta tawọn ọmọle kọ silẹ, lo di pataki igun ile.
Oogun iba to wọpọ nilẹ Afirika, papaa julọ lorilẹede Naijiria ni bi ogun ọdun si ọgbọn sẹyin, Chloroquine phosphate ni awọn onimọ iṣegun ti sọ pe, oogun naa ṣiṣẹ fun itọju aarun Coronavirus to n tan kalẹ kaakiri.
Ẹka ijọba imọ ijinlẹ ati imọ ẹrọ lorilẹede China lo sọ pe, oogun Chloroquine ṣiṣẹ daadaa lara awọn to ni aarun naa tawọn ti danwo lara wọn.
Awọn onimọ iṣegun oyinbo lo Chloroquine fun itọju iba fun ọpọlọpọ ọdun, ki o to di pe oogun naa ko ran awọn kokoro to maa n fa aisan iba mọ.
Loju opo Twitter COVID-19 ti wọn ti n dawọn eeyan lohun lori aarun coronavirus, wọn sọ nipa oogun Chloroquine pe o n dena aarun coronavirus.
Oríṣun àwòrán, Reuters
Iroyin to tẹ wa lọwọ lati orilẹede China fidi rẹ mulẹ pe, awọn dokita onimọ iṣegun ti dan oogun naa wo lara awọn to laarun coronavirus nile iwosan mẹwaa, wọn si ri pe o ṣiṣẹ daadaa.
Ẹwẹ, onimọ kan nipa oogun oyinbo to ba BBC sọrọ ṣalaye pe bo ya oogun Chloroquine le ṣiṣẹ fun aarun coronavirus tabi bẹẹ kọ, ajọ eto ilera lagbaye(WHO) ati ajọ ilẹ Amẹrika to n ṣakoso ounjẹ lo le sọ.
Ohun ti ajọ ilera lagbaaye sọ ni pe o ṣeesẹ ki oogun aarun coronavirus jade ni bii ọdun kan aabọ si akoko yii.
Nibayii, oju opo Twitter ti n yeruku lala lori iroyin pe oogun Chloroquine dara fun itọju aarun coronavirus.
Ọpọ lo dunnu si iroyin naa, bakan naa ni wọn ṣe iranti bi wọn ti maa n loogun ọhun fun itọju aarun iba lati ọjọ to ti pẹ.
Harry Obi ni tiẹ sọ pe, ta lo lo ro pe oogun Chloroquine le ṣe itọju coronavirus, o ni o daju pe, awọn dokita oniṣegun oyinbo yoo tun ni oogun naa nitori wọn ti lo ọpọ rẹ fun itọju aarun iba tẹlẹ.
Ọgbẹni Adekunle ni ta lo mọ boya oogun Flagyl gan le ṣe itọju aarun HIV lẹyin tawọn onimọ iṣegun ti sọ pe, Chloroquine dara lati koju corona virus.
Seyi Makinde: Ìjọba Ọyọ ṣetán láti pèsè káàdì ìdánimọ̀ fáwọn ọlọ́kadà
Ijọba ipinlẹ Ọyọ ti setan lati gunle ipese kaadi idanimọ fawọn ọlọkada jakejado ipinlẹ naa lọna ati dena iwa ọdaran ati apsju awọn ọlọkada nipinlẹ naa.
Bakan naa, gomina ipinlẹ Ọyọ, Seyi Makinde ti pasẹ pe ki adinku ba igba naira owo ojumọ ti awọn ọlọkada yẹ ko san si ọgọrun naira.
Kọmisana feto isẹ ode, ipese awọn ohun eelo amayedẹrun ati igbokegbodo ọkọ nipinlẹ Ọyọ, Raphael Afọnja lo sisọ loju ọrọ yii lasiko to n bawọn akọroyin sọrọ.
Oríṣun àwòrán, Seyi Makinde
Bakan naa lo fikun pe gomina Makinde ko fẹ di kun ajaga awọn araalu lo se mu adinku ba owo tawọn ọlọkada n san, ti yoo si tun pese kaadi idanimọ fun gbogbo ojulowo ọlọkada pata to n sisẹ aje nipinlẹ naa.
Gẹgẹ bi Afọnja ti wi, ijọba fẹ gbe igbesẹ naa ka lee mọ ojulowo ọlọkada yatọ si awọn to jẹ asawọ laarin wọn nitori gbogbo alaamu lo da ikun delẹ, a ko mọ eyi ti inu n run ninu wọn.
Oríṣun àwòrán, Seyi Makinde
"Ta ba wo bi ijọba se fofin de awọn ọlọkada ati oni kẹkẹ Maruwa nipinlẹ Eko, ọpọ wọn lo ya wa sipinlẹ Ọyọ, a si ti pinnu pe a seto kaadi idanimọ fawọn ọlọkada naa, ka lee mọ ẹni ninu ẹni.
Bakan naa ni kọmisana fun isẹ ode fikun pe ijọba Ọyọ yoo sisẹ pọ nifọwọkọwọ pẹlu awọn osisẹ ajọ ẹsọ oju popo FRSC pẹlu awọn ẹka to n pawo wọle labẹle lati se akojọpọ orukọ nipa awọn ọlọkada ero ati aladani, eyi ti yoo tun wulo fun awọn agbofinro pẹlu.
Afọnja ni Asigbọ kan lo waye laarin wa pẹlu ajọ to n pawo wọle ati ileesẹ eto isuna, ohun ta gbọ ni pe igba naira lawọn ọlọkada yoo maa san lojumọ, nigba ti gomina Makinde gbọ, ko ba lara mu rara, to si ni ka mu adinku ba owo ojumọ ti awọn ọlọkada n san lati igba si ọgọrun naira."""
Mother Language Day: Bàbá míì ní àìkọ́ ọmọ òun ní Yorùbá ló mú kò pàdánù iṣẹ́ olówó ńlá
Kọmisana ni gareji ọkọ kọọkan ni wọn yoo ti maa gba owo yii bẹrẹ lati oni, ọjọ Ẹti lọ, to si n rọ awọn ọlọkada lati fọwọsowọpọ pẹlu ijọba ipinlẹ Ọyọ.
Mother Language Day: Àwòráń àwọn ohun ìṣẹ̀ǹbáyé tí kò leè parun rèé
Oluwo: Ọ̀pọ̀ ọ̀dọ́ láwọn aṣíwájú orílẹ̀èdè Nàìjíríà ti fi ìwà àjẹbánu àti ìjẹkújẹ lé dànù sí òkè òkun
Oríṣun àwòrán, oluwo of iwo
Oluwo ti ilu Iwo, Ọba Abdulrasheed Akanbi ni lootọ loun sa kuro lorilẹede Naijiria lọpọ ọdun, ṣugbọn iwa ijẹkujẹ to gogo lorilẹede Naijiria lo sọ oun di alarinkiri ni ilẹ okeere.
Oluwo ti ilu Iwo ni ko si idi meji ti ọpọ awọn ọdọ fi n digba di agbsn wọn gba oke okun lọ bikoṣe iwa ajẹbanu to gogo laarin awsn to di ipo oslu ati iṣejọba mu lorilẹede Naijiria.
Ọbalaye naa sọ eyi lasiko to fi n gba alejo kọmiṣọna feto Ẹkọ ni ipinlẹ Ọṣun, Ọgbẹni Ọlayinka Ọladoyin Fọlọrunshọ ati igbimọ rẹ ti wọn wa ṣe abẹwo si ibudo ileẹkọ giga fun ẹkọṣẹ olukọ apapọ ni ilu Iwo.
Kabiyesi Oluwo ni oun ni lati fi orilẹede Naijiria silẹ lọpọlọpọ ọdun sẹyin lati wa papa oko tutu fun ọjọ ọla oun nitori iwa ijẹkujẹ ati ajẹbanu to n waye laarin awsn atuks ijọba orilẹede Naijiria nigba naa.
Gẹgẹ bi iroyin ṣe sọ ilu Canada ni kabiyesi Oluwo wa nigba ti ipe ati wa gun ori apere awsn babanla rẹ jade sii lọdun mẹrin sẹyin.
iyonipo
Oluwo tilẹ Iwo, Ọba Abdulrasheed Akanbi ti fesi lori ipinnu igbimọ lọbalọba nipinlẹ Ọsun to ni ko lọ rọọkun nile fun osu mẹfa.
Nigba to n ba BBC Yoruba sọrọ, Oluwo ni lootọ ni awọn se ipade lọbalọba lootọ ti Ọọni ko si ni asẹ lati ni ki oun lọ rọọkun nile na.
O ni gomina ipinlẹ Ọsun nikan lo ni asẹ lati ni ki oun lọ rọọkun nile na, to si dabi ẹnipe wọn ti ni nkan ninu si oun.
O dabi ẹni pe inu wọn ko dun bi mo se maa n sakọ, ti wọn si n binu mi. Gbogbo wọn ni wọn kan oro mi sinu, o si dabi ẹni pe ọta pọ, Ọlọrun yoo si gbe mi jẹri wọn.
Oríṣun àwòrán, Instagram
Nigba to n sọrọ lori bi wọn se ni o yaju si Alaafin ati Ọọni, Oluwo ni oun ko gba ade ni Ọyọ, oun si ni oun lasẹ lati fi ọba miran jẹ nilẹ Iwo, kii se Alaafin, gẹgẹ bo se waye ni Ikoyi.
Oríṣun àwòrán, Oluwo
Ile ifẹ ni mo ti gbade lọdọ iya mi, tori ọmọ alade ni mi nile Ifẹ, emi ko gba ade ni Ọyọ,  ipinlẹ Ọyọ ni Alaafin wa, ko si lee maa gbe ade le Onikoyi to wa labẹ mi lori. Alaafin sọrọ si mi tori pe n ko jẹ ko gbe ade le Onikoyi lori, amọ ibi to ba kan onikaluku ni ko duro si bii ọba.
Mother Language Day: Bàbá míì ní àìkọ́ ọmọ òun ní Yorùbá ló mú kò pàdánù iṣẹ́ olówó ńlá
Oluwo ni oun si ni Ọba alade nilẹ Iwo,  Oluwo ti Iwo, Alase lori orisa, ọba miran ko si lee ni ki oun lọ rọọkun nile na, wọn kan le ni ki oun ma wa si ipade wọn mọ ni.
Iroyin to n tẹ wa lọwọ ti kede pe igbimọ lọbalọba nipinlẹ Ọsun ti ni ki Oluwo tilu Iwo, Aba Abdulrasheed Akanbi lọ rọọkun nile fun osu mẹfa gbako.
Oríṣun àwòrán, Oluwo
Igbimọ kan ti igbimọ lọbalọba naa gbe kalẹ, eyi ti Ọrangun ile Ila, Ọba Wahab Adedọtun ko sodi, lati sewadi awọn isẹlẹ to nii se pẹlu Oluwo, gbe abọ wọn kalẹ lọjọ Ẹti.
Lẹyin abọ igbimọ naa, ni igbimọ lọbalọba ọhun ba pe ipade pajawiri, eyi to waye nibujoko ijọba ipinlẹ Ọsun to wa ni Abẹrẹ.
Ipade naa, ti Ọọni tilu Ile Ifẹ, Ọba Adeyeye Ẹnitan Ogunwusi lewaju rẹ, wa fohun sọkan pe ki Oluwo lọ rọọkun nile na fun osu mẹfa.
Oríṣun àwòrán, Ọba Dikrulahi Ọlaleke Akinrọpo, Ọlabiran Kẹta.
Igbesẹ yii si lo waye lẹyin ọsẹ kan pere ti Oluwo lu Agbowu tilu Ọgbaagba nibi ipade alaafia kan ti igbakeji sga agba ọlspa pe nilu Osogbo.
Nigba to n bawọn akọroyin sọrọ lẹyin ipade pajawiri naa, Ọrangun Ile Ila ni asẹ ti igbimọ naa pa pe ki Oluwo lọ rọọkun nile na ko ni ohunkohun se pẹlu ija to waye laarin rẹ ati Oluwo.
Amọ o ni wọn se ipinnu ọhun lẹyin iwadi wọn nipa isesi Oluwo si awọn ọba alaye yoku nilẹ Yoruba.
Oríṣun àwòrán, Oluwo
Ọrangun ni Oluwo ti yaju tẹlẹ si Alaafin tilu Ọyọ, Ọba Lamidi Ọlayiwọla Adeyemi Kẹta ati Ọọni tilu Ile Ifẹ, Ọba Adeyẹye Ẹnitan Ogunwusi.
Fayose: APC Ekiti ní àwọn olóṣèlú tó ti fìdírẹmi kò le è ráyè láàrin àwọn
Oríṣun àwòrán, Ayodele fayose
Ẹni ba mọ gomina ana ni ipinlẹ Ekiti, Ayọdele ọmọ Fayoṣe, ko yara sọ fun un pe bo ba n gbero ati dara pọ mọ ẹgbẹ oṣelu APC lọwọ yii, ko tun ero naa ro o, nitori ko daju pe ọna wa nibẹ fun un.
Gẹgẹ bi ẹgbẹ oṣelu APC ni ipinlẹ Ekiti ṣe sọ, bi Fayoṣe ba n gbero ati fi ẹgbẹ oṣelu PDP to wa silẹ, wa dara pọ mọ APC, awọn ko ni tẹwọ gba a.
Ọpọ eeyan ni yoo wi pe, awọn ko ri idi ti gomina ipinlẹ Ekiti tẹlẹ naa yoo fi gbe igbesẹ ati fi ẹgbẹ oṣelu PDP silẹ lọ si APC, paapaa bi o ṣe jẹ wi pe odu ni Fayoṣe jẹ lara awọn ọmọ ẹgbẹ oṣelu alatako.
Oríṣun àwòrán, Ttribune online
Bẹẹ ba gbagbe, Fayose lo n fi gbogbo igba gbe ohun dide tako Aarẹ Buhari pẹlu ẹgbẹ oṣelu rẹ, iyẹn APC, eyi si lo mu ki awọn eekan ẹgbẹ oṣelu APC ni awọn fẹ ki o mọ pe, aye rẹ ko ṣi silẹ laarin awọn.
Alukoro fun ẹgbẹ oṣelu APC ni ipinlẹ Ekiti, Ọgbẹni Ade Ajayi ṣalaye nilu Ado Ekiti pe, Ẹgbẹ oṣelu naa ko si fun awọn oloṣelu to ti jakulẹ pẹlu afikun pe, ilẹkun ẹgbẹ oṣelu APC ko si silẹ fun Fayose.
Mother Language Day: Bàbá míì ní àìkọ́ ọmọ òun ní Yorùbá ló mú kò pàdánù iṣẹ́ olówó ńlá
"Gẹgẹbi ọrọ rẹ, "" Fayoṣe ko ni amuyẹ lati di ọmọ ẹgbẹ APC ni ipinlẹ naa"""
Electricity Tariffs: DISCOs ní oko gbèsè ni ìjọba ń rán àwọn pẹ̀lú owó tó ń kéde fún iná
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Adari ajọ to n ri si itankalẹ ina ọba ní Naijiria, TCN, Usman Mohammed mu iroyin kan tọ araalu wa lọjọbọ pe, laipẹ laijina, iye ti wọn n ta ina ọba lorilẹede Naijiria yoo gbẹnu soke sii.
O ni ko si idi meji fun eyi naa ju pe, ki araalu lee tubọ maa janfani to sodo sinu ilana sisọ ipese ina di ti aladani.
Amọ ṣa, ibeere tawọn eeyan wa n beere ni pe, ṣe iyatọ yoo de ba ijafafa ipese ina manamana faraalu bi owo naa ba goke, awọn agba bi eeyan ba fowo ra ooyi, o yẹ ko kọọ loju.
Nigba ti o n ba BBC News sọrọ lori iroyin naa, agbẹnusọ fun awọn ileeṣẹ to n pin ina manamana lorilẹede Naijiria, DISCOs, Amofin Sunday Ọduntan ṣalaye pe, ohun to sọnu lẹka ipese ina ọba kọja ikede afikun owo ina ti alaga ajọ TCN ṣe naa.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Amọfin Ọduntan ni, awọn igbesẹ jọmọ o ṣowo, maa jọmọ o kowo dele ti ijọba apapọ n gbe kalẹ ni ẹka naa, n ṣe ọpọ akoba fun bi araalu ṣe n gbadun ina si.
Ninu ọrọ rẹ o ni, bi iye ti ijọba fẹ kede ba kere si owo ti awọn ileeṣẹ apinna, DISCOs n san lati fi ra ina lọwọ ijọba, ofo ọjọ keji ọja ni igbesẹ naa yoo jasi.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Agbẹnusọ fun awọn ileeṣẹ to n pin ina manamana, DISCOs naa ṣalaye pe, ọgọrin naira o le kọbọ diẹ ni awọn ileeṣẹ DISCOs n san lati ra ina lọdọ ileeṣẹ itankalẹ ina ọba, TCN.
Sugbọn, o ni ijọba fi ofin kan an nipa fun wọn lati maa ta ina bẹẹ ni naira mọkanlelọgbọn ati kọbọ diẹ, eyi to tumọ si pe adanu nla lawọn ileeṣẹ apinna DISCOs n pa lori owo wọn.
"O di igba ti ijọba ba to jẹ ki iye owo ti eto karakata n gbe jade loju ọja, ki ọrọ to lee yanju lẹka ipinsẹ́ ina ọba lorilẹede Naijiria.'
Oríṣun àwòrán, Others
Ọduntan ni oju opo ina pinpin jakejado Naijiria ti di alapa, eleyi ti ko lee gbe agbara ina pupọ, leyi to ni o n fa bi ina manamana ṣe maa n ku pii jakejado Naijiria.
O ni bi orilẹede Naijiria ṣe tobi to, ko si igba kankan ti ina ọba ti orilẹede yii n gbe jade de ẹgbẹrun mẹfa kilowaati, gẹgẹ bi ijọba ṣe maa n pariwo kiri lọpọ igba.
Mother Language Day: Bàbá míì ní àìkọ́ ọmọ òun ní Yorùbá ló mú kò pàdánù iṣẹ́ olówó ńlá
Agbara ina to ga ju ti orilẹede Naijiria de ri jẹ ẹgbẹrun marun abọ o le diẹ mẹgawaati ina, eyi ko si ju aarin wakati mẹrinlelogun lọ ti o tun fi pada si ẹsẹ aarọ rẹ"""
Boko Haram: CAN àti àwọn ará Chibok ní kò sí orílẹ̀èdè tó yege nínú yíyí ọkàn aṣẹ̀rùbálú padà
Oríṣun àwòrán, @ElvisChinedu12
Ile igbimọ aṣofin nilu Abuja ti gunle abadofin ti yoo ṣedasilẹ ileeṣẹ ijọba, ti yoo ma ṣetọju awọn ọmọ ẹgbẹ Boko Haram to ba ronupiwada.
Abadofin ọhun ni Sẹnatọ to n ṣoju Ila-oorun ipinlẹ Yobe, to tun jẹ gomina ana nipinlẹ ọhun, Ibrahim Gaidam n ṣagbatẹru rẹ.
Gẹgẹ bi agbekalẹ abadofin naa ṣe sọ, ileeṣẹ ọhun yoo pese anfani fun awọn agbesunmọmi to ba jọwọ ohun ija wọn, lati lọ si ile iwe.
Lẹyin eyi, yoo ṣe atunkọ ohun ti wọn gbagbọ, iyipada ọkan wọn, ti yoo si tun da awọn eeyan naa pada si awujọ gẹgẹ bi ẹni to ti ni iyipada ọkan ati ẹdun tuntun.
Ko tan sibẹ, ileeṣẹ naa yoo tun kọ awọn eeyan naa ni iṣẹ ọwọ bii gbẹnagbẹna, iṣe amọkoko, ati bẹẹ bẹẹ lọ.
Igbimọ to ga julọ fun ọrọ ẹsin Musulumi, eyi ni Supreme Council for Islamic Affairs ti ṣe atilẹyin fun abadofin naa.
Oríṣun àwòrán, @thesignalng
Ṣugbọn lẹyin wakati diẹ ti abadofin naa kọja kika akọkọ, ni awọn olugbe ilu Chibok, ti Boko Haram ṣakọlu si lọdun 2014 ati CAN tako abadofin naa.
Bẹẹ naa ni adari ajọ ọmọlẹyin Kristi, CAN lori ọrọ ofin, Kwamkar Samuel sọ fun awọn akọroyin pe, oun ko tii ri orilẹ-ede kankan lagbaye to ṣaṣeyọri ninu yiyi ọkan ẹgbẹ aṣẹrubalu pada.
Mother Language Day: Bàbá míì ní àìkọ́ ọmọ òun ní Yorùbá ló mú kò pàdánù iṣẹ́ olówó ńlá
Yatọ si ẹgbẹ CAN ati awọn ara ilu Chibok, ogunlọgọ awọn Naijiria lo n bu ẹnu ẹtẹ lu awọn asofin naa pe, abadofin ọhun kii ṣe ọna abayọ si ọrọ ikọ Boko Haram.
Agbẹnusọ fun ilu Chibok ni tirẹ sọ pe, abadofin ọhun jẹ ohun ti ko ni ọgbọn ninu.
Ti ẹ ko ba gbagbe, ọjọ kẹrinla Oṣu Kẹrin ọdun 2014 ni ikọ Boko Haram ṣakọlu si ilu Chibok, to si ji awọn ọdọbinrin to le ni igba gbe lọ.
Ìlú Eko ló jẹ gbèsè jù ní Nàìjíríà lẹ́yìn ìjọba àpapọ̀
Pete Edoche: Elebuibon ní tá bá ṣọ́ra, àṣà àjèjì yóò sọ wá dẹrú òyìnbó
Oríṣun àwòrán, @theknot
Araba awo ilu Oshogbo, Oloye Ifayemi Elebuibon ti sọ pe, ki ọkunrin maa kunlẹ lati beere lọwọ ọrẹbinrin rẹ pe ko fẹ oun, kii ṣe aṣa ilẹ Yoruba,o ni iwa ajeji naa ni asa ọhun.
Elebuibon lo sọ ọrọ yii ninu ifọrọwerọ rẹ pẹlu BBC Yoruba, lori ọrọ ti ọkan lara awọn agba ọjẹ oṣere tiata lorilẹ-ede yii, Pete Edoche sọ pe, oponu ati ọdẹ ni ọkunrin to ba n kunlẹ fun obinrin lati beere pe, ko gba ki oun lee fi ṣaya.
Oloye Elebuibon ni awọn oyinbo alawọ funfun lo ma n ṣe iru nnkan bẹẹ, ati pe ko si ninu aṣa ilẹ Yoruba.
O ni awọn oyinbo lo ma n ṣe bẹẹ, kii ṣẹ aṣa tiwa pẹlu afikun pe, ti ọkunrin ba fẹ gbeyawo laye ijọun nilẹ Yoruba, n ṣe lo maa n kọkọ ṣe iwaadi iru ile ti obinrin bẹẹ ti jade wa.
Oríṣun àwòrán, others
Lẹyin naa alarena yoo tọ ẹbi obinrin ọhun lọ, kii ṣe pe ki ọkunrin mu oruka lọwọ, ko si kunlẹ lati beere pe ki obinrin fẹ ọhun.
Elebuibon tẹsiwaju pe, awọn obi obinrin lo yẹ ki ọkunrin dọbalẹ fun lati beere pe ,oun fẹ fi ọmọ wọn ṣaya, kii ṣe obinrin naa.
"Ni ti aye to daye ọlaju, Elebuibon ni ""Kii ṣe gbogbo nnkan ni a gbọdọ maa tẹle pẹlu ọlaju, a ko le sọ pe aye ti daye ọlaju, ka foju ẹgbo tẹ ilẹ."""
Mother Language Day: Bàbá míì ní àìkọ́ ọmọ òun ní Yorùbá ló mú kò pàdánù iṣẹ́ olówó ńlá
Elebuibọn pari ọrọ pe, iwa ọlaju maa n koba eeyan ni, ti ko si n jẹ ki eeyan ni ami idanimọ gẹgẹ bi ọmọ ilẹ Yoruba atata.
Yollywood: Bákan náà ni àwòrán Sikiratu Sindodo tó ń ṣọjọ́ ìbi, gba orí ayélujára
Oríṣun àwòrán, ourlovefrotoyinabraham
Eyi ni agbeyẹwo awọn nnkan tawọn oṣere tiata Yoruba, Yollywood ṣe lọsẹ yii.
Toyin Abraham
Awọn ololufẹ oṣere Toyin Abraham ati ọkọ rẹ Kola Ajeyemi fi oriṣiiriṣii fọto awọn mejeeji pẹlu ọmọ wọn, Ire, soju opo Instagram, nibi ti wọn ti di kaka di kuuku niluu London.
Awọn olololufẹ wọn ni, ẹni ti ko ba ti ba idile Toyin Abraham pade, ko gbiyanju lati ṣe bẹẹ nitori idile ti o dara ni.
Wọn ni ifẹ awọn si Toyin ati Kola ko le tan laelae, nitori ọmọluabi ni wọn.
Sindodotayo
Inu ẹni kii dun ki a pa mọ ra. Bẹẹ gẹgẹ lọrọ ri pẹlu oṣere tiata, Tayo Odueke ti ọpọ mọ si Sikiratu Sindodo, to n ṣopẹ fun Eleduwa to mu ri ọjọ ibi rẹ mii.
Ọ sọ loju opo Instagram rẹ pe ẹrin keke lo gba ẹni oun lonii ọjọ Ẹti tii ṣe ọjọ ibi oun.
Tayo sọ pe oun ko le tori bi ilu ṣe ri ki oun maa dunnu lọjọ ibi oun, bẹẹ lo gbadura pe ki Ọlọrun tubọ maa fi ere si iṣẹ ọwọ oun.
Odunlade Adekola
Gbajugbaja oṣere Odunlade Adekola fi fọto ara rẹ ati ti olootu rẹ, Mercy Aigbe sori oju opo Instagram nibi tawọn mejeeji ti rẹrin muṣẹ.
Odunlade sọ pe Mercy ni olootu ere tiata ti oun kopa ninu rẹ, eyi ti akọle rẹ n jẹ ''DARA.''
Femi Adebayo Salami
Aṣọ to gbajugbaja ni oṣere Femi Adebayo Salami fi dawọ idunnu opin ọsẹ.
Awọ pupa ni aṣọ ọhun pẹlu fila pipa naa lori rẹ, bata alawọ funfun ni Femi Adebayo fi wọ si ori aṣọ naa.
O sọ loju opo Instagram rẹ pe ara ọjọ Ẹti ọsẹ yii ni imura oun duro fun eyi to pe ni ''Friday swag.''
Domestic Violence: Ìyá ọlọ́mọ méji náà fẹ̀ṣùn kan ọkọ pé ó ń yan àlè ló ṣe tìí bọ́
Oríṣun àwòrán, Dailytrust
Ìyàwò kejì tó fi owú ré ọkọ bọ́ láti òkè pẹ̀tẹ́sì gba ìdájọ́ ikú
Ilé ẹjọ gíga kan ní ilú Abuja ti dájọ ikú fún obinrin kan to ti ọkọ rẹ bo lati ilé ori okè to si kú.
Lónìí ọjọ jimọ ni adajọ AT Badamosi dájọ fún ẹni ọmọ ọdun mọ́kanlélọ́gbọ̀n kan Rashida Saidu nitori pe o jẹbi ẹsùn ìpànìyàn ikú ọkọ rẹ Adamu Ali nitori pe o ti wọ́n láti ori ilé alaja.
Ogunjọ oṣù keji ọdun 2019 ni iṣẹ̀lẹ̀ náà ti ṣẹ̀lẹ̀ ni àgbègbè Dorayi ni Kano lásìkò ti òun ati ọkọ rẹ̀ ni gbolohun asọ.
Ìjà bẹ́ silẹ̀ nígbà to gbọ́ pe ọkọ oun ń bá obinrin ti o fẹ̀sun kan pe o jẹ ọ̀rẹ́binrin rẹ̀ sọ̀rọ̀ lóri foonu
Lẹ́yin to ti jabọ lo ti wà ni ẹsẹ̀ kan aye ẹsẹ̀ kan ọ̀run, eyi si lo bá kú.
Gẹ́gẹ́ ìròyìn ṣe sọ, ọmọ meji ni Rashida bi òun lo ni ilé ti wọ́n gbé, bákan náà oun ni ìyàwò ẹlẹ́kiji Adamu lásìkò ìṣẹ̀lẹ̀ náà.
Kí wọ́n to ṣe igbéyawò, wọ́n pàdé ni Federal College of Technology ni Kano nibi ti wọ́n ti pada fẹ́ àra wọ́n.
Sáájú kii Rashida to pa ọkọ rẹ̀ ni o ti sọ fun ọ̀rẹ rẹ̀ ti wọ́n jọ n gbe pe ki o dúró náà sùgbọ̀n ko gbọ́ osi gba ilé lọ ti iṣẹ̀lẹ̀ aburu náà fi ṣẹlẹ̀.
Fire Eater: Azonto ní àfojúṣùn òun ni láti lọ fi idán iná yìí pa owó lókè òkun
Fire Eater: Azonto ní àfojúṣùn òun ni láti lọ fi idán iná yìí pa owó lókè òkun
Ara ko ni tan nile alara ni Yoruba n sọ, airin jinna si ni airi abuke ọkẹrẹ.
Ina ti ọpọ eeyan maa n sa fun tori ọsẹ to lee ni se ni ọkunrin kan to n jẹ Timi, n jẹ bii ounjẹ, o fi n pa ara, to si tun n fi sere.
Lasiko to n ba BBC Yoruba sọrọ, ọkunrin naa ti inagijẹ rẹ tun n jẹ Azonto fikun pe oun lee fi omi lasan tan ina, bi o tilẹ jẹ pe awọn eeyan gba pe ina ati omi kii se ọrẹ.
Azonto ni lasiko ti oun n sere itage ni oun kọ isẹ naa nipinlẹ Ogun, ti gbogbo eeyan si maa n pe oun ni Sango lai wa lati idile onisango tabi jẹ ọmọ ilẹ Yoruba.
Timi wa rọ yin kẹ mase fi ina sere nitori a kii dagba kọja ohun ti a ko ba mọ, ina si lewu.
Credit Joshua Akinyemi
Abacha Loot: Amẹ́ríkà ní gómìnà Kebbi ló bá Abacha kó ọ̀pọ̀ bílíọnù dọ́là wá, tó sì lo oṣù mẹ́fà ní àhámọ́ òun
Oríṣun àwòrán, @FRNcitizens
Laipẹ yii ni iroyin kan awọn ọmọ Naijiria pe ijọba ilẹ Amẹrika tun ti sawari owo kan ti olori tẹlẹ fun ijọba ologun ni Naijiria, oloogbe ọgagun Sani Abacha ko pamọ sorilẹede naa, ti wọn si setan lati daa pada fun wa.
Inu gbogbo ọmọ ilẹ yii lo n dun, taa si n fo fayọ pe owo tun de amọ iroyin to wa gbalẹ kan bayi ni pe ileesẹ eleto idajọ lorilẹ ede Amẹrika ti n dena mọ bi owo yii yoo se tẹ ijọba Naijiria lọwọ.
Niwọn igba to jẹ pe ti ko ba si ẹsẹ, ẹsẹ kii dede sẹ, ohun ti wọn lo fa sababi ni bi ijọba ilẹ Naijiria se n gbero lati yọ miliọnu lọna ọgọrun ninu owo naa fun gomina Atiku Bagudu, tipinlẹ Bauchi.
Ninu iwe ipẹjọ kan ti ẹka eto idajọ gbe siwaju ileẹjọ District Colombia ti Washinton, ni akara ọrọ naa ti tu sepo, gẹgẹ bi iwe iroyin ilẹ Amẹrika kan ti gbe jade, ti ijọba apapọ ko si ti fesi le lori.
Oríṣun àwòrán, @cbngov_akin1
Ileesẹ ilẹ Amẹrika naa ni, ijọba orilẹede Naijiria lo n dina gbogbo igbiyanju wọn lati ri owo Abacha gba pada, eyi ti wọn tọpasẹ rẹ de ọdọ alaga ẹgbẹ awọn gomina fẹgbẹ oselu APC, tii tun se gomina ipinlẹ Bauchi ọhun.
Wọn ni Bagudu, tii se korikosun Buhari ati eekan kan ninu ẹgbẹ oselu APC, nijọba ilẹ Amẹrika ti fẹsun kan saaju pe oun lo seranwọ fun Abacha lati fẹyin pọn aimọye biliọnu dọla jade kuro ni Naijiria nidaji saa ọdun 90s.
Oríṣun àwòrán, @AnasAda04084492
Iwe naa ni osu mẹfa gbako ni Bagudu lo ni atimọle awọn nilu Texas nigba ti wọn fẹ di lapanyaka lọ si erekusu kan ni Jersey amọ se lo yara tete gba lati da miliọnu lọna mẹtalelọgọjọ dọla pada si Naijiria, ti wọn si fa le ilẹ Naijiria lọwọ pe ko lọ foju wina ẹsun kiko owo tuulu lọ soke okun.
Amẹrika ni fun iyalẹnu, bi Bagudu se de silẹ Naijiria, ni wọn wẹ ẹ mọ kuro ninu awọn ẹsun naa, to si n du ipo oselu lọ, lati ile asofin agba de ipo gomina, to si n gbadun ofin mafọwọ kan mi lọ.
Bakan naa ni ileesẹ eto idajọ Amẹrika fikun pe ijọba Naijiria ni ko jẹ ki aayan ilẹ Amẹrika so eso rere lati gba owo to tọpasẹ rẹ de ọdọ Bagudu pada, o ni ijọba Buhari ni adehun ọlọdun mẹtadinlogun ti wa nilẹ, eyi to fun Bagudu lẹtọ si owo naa, ti ko si ni jẹ kijọba seranwọ fun Amẹrika lati gba owo ọhun.
Fire Eater: Azonto ní àfojúṣùn òun ni láti lọ fi idán iná yìí pa owó lókè òkun
Iwe naa wa n salaye pe awọn isẹlẹ yii lee sokunfa ede aiyede ti yoo sediwọ fun ifọwọsowọpọ laarin Naijiria ati Amẹrika lati gba owo ti Abacha ko wa soke okun, eyi ti ajọ Transpartency International ni o to biliọnu marun dọla.
Amotekun: Miyetti Allah ní òun yóò péjú síbi ìpàdé ìta gbangba lọ́jọ́ Ajé láti sọ tẹnu òun
Bi wọn ba n ke gbe gbe gbe, ti a ko ba bawọn gbe, afaimọ ki wọn ma gbe si ẹyinkule wa.
Idi ree ti ẹgbẹ Miyetti Allah to jẹ awọn olusin maalu lorilẹede Naijiria, ti wọn jẹ ẹya Fulani, naa fi n kede faraye pe awọn ko ni gbẹyin nibi ipade ita gbangba lori agbekalẹ ẹsẹ alaabo Amotekun ti yoo waye lọjọ Aje.
Miyetti Allah ni awọn fẹ lọ sibi ipade ita gbangba ọhun lati fi ero awọn han lori ifilọlẹ ikọ alaabo ọhun lẹkun iwọ oorun guusu Naijiria.
Oríṣun àwòrán, @tosinsammy_s
Alaga ẹgbẹ Miyetti Allah nipinlẹ Ogun, Abdulmumin Ibrahim sọ fawọn akọroyin pe ko yẹ ko jẹ ẹya Yoruba nikan ni yoo wa ninu ẹsẹ alaabo Amotẹkun niwọn igba ti yoo dojukọ aawọ to maa n waye laarin awọn agbẹ ati darandaran.
Ibrahim ni awọn ko fẹ ki wọn sọ ẹsọ alaabo Amotekun di ẹgbẹ ọmọbibi ilẹ Oodua, OPC, o si yẹ ki wọn gba awọn ọmọ ẹgbẹ Miyetti Allah sinu ikọ Amọtẹkun naa, ko lee fidi mulẹ bo se yẹ.
Ko tan sibẹ, akẹẹgbẹ rẹ lati ipinlẹ Ondo, Alhaji Garuba Bello naa ni awọn ọmọ ẹgbẹ Miyetti Allah yoo bawọn peju sibi ipade gbangba lori Amotekun lọjọ Aje, to si fikun pe oun tijọba ba ni ki awọn se, lawọn yoo se.
Bẹẹ ba si gbagbe, ẹgbẹ Miyetti Allah yi lo ti n tako agbekalẹ eto alaabo Amotekun latẹyinwa, ti wọn si ni afojusun eto naa ni lati le ẹya Fulani jinna rere si ẹkun iwọ oorun guusu Naijiria.
Fire Eater: Azonto ní àfojúṣùn òun ni láti lọ fi idán iná yìí pa owó lókè òkun
Amọ awọn gomina to wa nilẹ Yoruba ti wa sọ fawọn Fulani pe ibẹru wọn yii ko lẹsẹ nilẹ, ko si tọ, bẹẹ ni ko pọn dandan.
Mother Language Day: Ẹgbẹ́ Akọ́mọlédè l‘Eko ṣe káre sí BBC Yorùbá fún àgbéga àṣà
Yinni Yinni, kẹni lee se omiran ni, bẹẹ si ni ku isẹ lo n mu ki ori onisẹ ya.
Eyi lo mu ki ẹgbẹ Akọmọlede ati asa Yoruba, ẹka tipinlẹ Eko fi n fẹmi imoore wọn han si ileesẹ akọroyin BBC Yoruba fun isẹ takuntakun ti wọn n se lati se agbega asa, ede isesi ati awọn ohun ajogunba iran Yoruba.
Ẹgbẹ Akọmọlede naa fi ami ẹyẹ da BBC Yoruba lọla lasiko ayẹyẹ aadọta ọdun ti wọn da silẹ, eyi ti wọn fi sọri ayajọ agbelarugẹ ede abinibi to waye lọjọ Ẹti.
Ileẹkọ girama Ikeja, to wa ni Bọlade-Osodi nilu Eko si ni ayẹyẹ naa ti waye, akori ajọdun naa si ni ‘Isamulo ede abinibi fun idagbasoke, ibomirin, alaafia ati ibalaja.
Nigba to n ki awọn alejo to peju sibi ayẹyẹ ọhun kaabọ, alaga ẹgbẹ Akọmọlede ati Asa nipinlẹ Eko, Zainab Ọlaide aya Ọlaitan mọ riri ipa takuntakun tijọba ipinlẹ Eko n ko si idagbasoke eto ẹkọ.
Bakan naa, aya Ọlaitan tun dupẹ lọwọ awọn akọroyin lọkanojọkan, to fi mọ ileesẹ BBC Yoruba, lori ilakaka wọn lati ri pe ede Yoruba tẹ siwaju, to si gba adura pe ọba oke yoo pin wọn lere.
A mọ riri ileesẹ BBC News Yoruba fun ipolongo ede, aṣa ati ise Yoruba. A si n fi asiko yii dupẹ lọwọ yin fun isẹ takuntakun alailẹgbẹ ti ileesẹ yin n se laarin wa.
Nigba to n tẹwọgba ami ẹyẹ naa lorukọ ileesẹ iroyin BBC Yoruba ati BBC lagbaye, Olootu ileesẹ iroyin BBC Yoruba, Ọgbẹni Temidayọ Ọlọfinsawo mẹnuba ọpọ isẹ ribiribi tileesẹ wa n se nidi agbega asa ati ede Yoruba, eyi ti ko fi ni jẹ ki awọn ohun ajogunba wa parun.
"Ọlọfinsawo ni "" Ohun itiju gbaa ni ki ọmọ ilẹ Kaarọ ooojire ma lee sọ ede Yoruba to dangajia lẹnu. Kekere si lo yẹ ka ti pẹkan iroko awọn ọmọ wa, nipa sisọ ede abinibi si wọn ninu ile nitori ọpọ adanu lo wa lọjọ iwaju, ti ọmọ ko ba mọ ede Yoruba sọ."""
Fire Eater: Azonto ní àfojúṣùn òun ni láti lọ fi idán iná yìí pa owó lókè òkun
Ọpọ awọn eeyan jankajankan miran to n se agbeaga fun asa ati ede ilẹ wa ni wsn tun fun lami ẹyẹ nibi ayẹyẹ naa, to fi mọ afihan awọn ohun isẹmbaye wa, to jẹ manigbagbe.
BBC Yorùbá: Temidayọ Ọlọfinsawo ní kò rọrùn láti darí òṣìṣẹ́ ọlọ́pọlọ pípé
Oluwo: Ọ̀ràngún ní táwọn kò bá ní kí Oluwo sinmi nílé, kò ní ṣíwọ́ ìwà àbùkù tó ń ṣe
Orangun ṣàlàyé ìdádúró Oluwo ní ìgbìmọ̀ lọ́balọ́ba
Ọrọ ti n foju han bayii lori idi ti igbimọ lọbalọba nipinlẹ Ọsun fi pasẹ fun Oluwo ti Iwo, Ọba Abdulroshid Adewale Akanbi, Telu Kinni, lati lọ sinmi nile fun osu mẹfa gbako.
Nigba to n ba BBC Yoruba sọrọ, Ọrangun ile Ila, Ọba Wahab Kayode Oyedọtun, Bibire Kinni salaye pe, ko si ẹni to kanro Oluwo sinu tabi korira rẹ tori pe o n se akọ, asa ilẹ wa naa lo n gbe ga, eyi si kọ lo jẹ kawọn juwe ọna ile fun.
Ọba Oyedọtun ni, Ọọni tilu Ile Ifẹ lo pe ipade pajawiri awọn lọbalọba pe kawọn wa jiroro, lori ohun to lee faa aawọ laarin Oluwo ati Agbowu, gẹgẹ bo se waye lọsẹ kan sẹyin, bẹẹ si ni ọjọ naa kii se ọjọ ipade awọn.
Oríṣun àwòrán, Instagram
O ni ipade naa kun gan, ti awọn ọba to wa nibẹ si le ni ọgọrin, nigba ti Ọọni si n fi ẹdun ọkan rẹ han lori isẹlẹ naa, lo ti salaye pe oun ko si nile, Abuja ni oun wa, amọ oun sare wale ni, inu awọn ọba Arẹwa ati ila oorun ilẹ yii ko dun sawọn ni Ọsun, ti wọn si n rọ oun lati wa nkan se si bi ọba se n na ọba nilẹ Yoruba.
Oríṣun àwòrán, Ọrangun ile Ila
Kabiyesi ni awọn pe igbakeji ọga agba ọlọpa, AIG, ni Ọsun pẹlu awọn lọgalọga osisẹ ọba miran sibi ipade yii, Agbowu si lo kọkọ sọrọ nipa bi Oluwo se na oun lalubolẹ ni iwaju ọga ọlọpa, to si fi ọrun rẹ ti wọn we bandeji mọ, han awọn.
A ni ki Oluwo naa ba wa sọrọ amọ ohun ta ri dimu ninu ọrọ rẹ ni pe, oun ko na Agbowu, oun kan kilọ fun pe ko ma na ọpa ọwọ rẹ si oun mọ ni. O ni wọn n ta ilẹ Iwo, oun si ni oun fi awọn ọba abẹ oun sipo, koda awọn ọba to wa laarin oun ati Agbowu lọjọ naa to mẹrin, ti wọn ko si jẹ ki ọwọ oun to o.
iyonipo
Sugbọn sibẹ Agbowu ni Oluwo na oun lalubolẹ, koda o ni igbakeji ọga agba ọlọpa lo wa gbe Oluwo dide lori oun, nigba ta si bi AIG, o ni oun ko fi ọwọ kan wọn, amọ ẹri to daju han pe lootọ ni Oluwo na Agbowu.
Ọrangun fikun pe, ti isẹlẹ naa ko ba tiẹ to awọn loju, amọ mọ igba ti Oluwo lọ fi abuku kan Alake nilu Abẹokuta, nibi eto kan ti onitọun pe si, to si ni ori aga ti wọn pese silẹ fun Ọọni, ni oun fẹ joko le lori nitori Ọọni ko ju oun lọ.
Oríṣun àwòrán, Oluwo
A ri igba to tabuku Alaafin naa nipinlẹ Ọsun, a si mọ bo se maa n wọ Ọọni nilẹ loju wa lasiko ipade awa ọba, awọn eleyi si ti to lati sọ fun Oluwo pe ko lọ sinmi laarin wa, to ba tiẹ ni oun ko na Agbowu, ta si mọ pe eleyi kii se ootọ, a kan bẹ Agbowu ni pe ko mu suuru, ara iya ọba naa niyẹn. Ọlọrun ko si ni fi iya jẹ.
Fire Eater: Azonto ní àfojúṣùn òun ni láti lọ fi idán iná yìí pa owó lókè òkun
Igba ta wa wo ọrọ yii si ọtun ati osi, a ri pe ta ba fun Oluwo ni ewe dẹkun, o le e ma siwọ ohun to n se yii, ijoko wa ko si fun wa lasẹ lati yọ ọba kankan, awa ko tiẹ fẹ ki wọn yọ ọba, tori idile to ti wa ati ati abuku to maa jẹ fun ori ade kaakiri nilẹ Yoruba.
Ọba Oyedọtun ni, awọn lee kilọ fun ara awọn, lawọn se ni ki Oluwo lọ sinmi laarin awọn naa ninu igbimọ lọbalọba fun osu mẹfa, awọn ko si yọ Oluwo gẹgẹ bii ọba tori ileẹjọ nikan lo lasẹ lati yọ ọba.
Lasiko ti Oluwo ba fi n sinmi nile, a sọ fun pe ko gbọdọ ba awọn akọroyin sọrọ, tori to ba sọrọ, yoo tun maa ba ẹjọ ara rẹ jẹ ni, ko gbọdọ kọrin owe abi eebu, o gbọdọ maa lọ jẹẹjẹ, ko si maa ba isẹ rẹ lọ, amọ ko gbọdọ wa si ipade awa lọbalọba tipinlẹ Ọsun.
Oríṣun àwòrán, @asiwaju_ayobami
O ni lẹyin eyi, awọn maa se atunse laarin awọn ọba ti Oluwo ti huwa abuku si kaakiri Naijiria, awọn yoo lọ ri wọn, pe ki wọn fiye denu, Oluwo naa ko si ni se bẹẹ mọ.
Kabiyesi ni inu awọn lọbalọba ni Ọsun ko dun rara, paapa awọn ọba to wa lati ilẹ Iwo ati ilu Ọgbaagba, awọn kan n fi ọgbọn-gbọn  tu wọn ninu ni, ti Oluwo ba si dakẹ, to rọra n ba isẹ rẹ lọ, awọn yoo ri aaye tọwọbọ ọrọ naa, ti alaafia yoo fi jọba laarin wọn.
Oríṣun àwòrán, Oluwo
Nigba to n fesi lori ọrọ ti Oluwo sọ pe, awọn ọba kan lo kan oro oun sinu, ti wọn n binu oun nitori pe oun n sakọ, Ọrangun ni se Oluwo nikan lo n wọ asọ ni tawọn yoo fi maa binu rẹ, abi ọba wo lo ri to n rin ihooho, bo ba si se wu, lo se lee lo owo rẹ.
Adesuwa Etomi Wellington ní ìranù pátápátá ni ọbẹ̀ gbẹ̀gìrì
Oríṣun àwòrán, others
Gbajugbaja oṣere sinima, Adeṣẹwa Etomi Wellignton to tun jẹ iyawo fun ilumọọka akọrin takasufe, BankyW ti bu ẹnu atẹ lu ọbẹ gbẹgiri.
Ninu ọrọ kan to sọ loju opo twitter rẹ, Adeṣẹwa ni oun ti pinnu lọkan oun pe iranu patapata gbaa ni ọbẹ gbẹgiri ti ọpọlọpọ ọmọ Yoruba kundun lati maa fi jẹ Amala.
ẹ̀fọ́ rírò jẹ́ alábárìn iyán, fùfú, ẹ̀bà, àmàlà àti ìrẹsi funfun
O ni awọn ọrẹ oun lo fi tipatipa mu oun jẹ ọbẹ Amala oun pẹlu gbẹgiri; ṣugbọn nisinyii ti oun ti dagba, to ojuubọ, oun ti wa rii pe 'amala pẹlu ọbẹ ewedu ati ọbẹ ata dindin ni ọkan mi gbadun julọ lati fi jẹ amala'.
Gbẹgiri jẹ ọbẹ kan pataki ti awọn ọmọ Yoruba kii fi ṣere bi wọn ba fẹ jẹ Amala.
Gbajugbaja oṣere sinima naa ni abupọ ọbẹ gbẹgiri ati ewedu ti ọpọ n pe ni abula lawọn agbegbe bii Ibadan, Ọyọ, Osogbo ati bẹẹbẹẹ ls bi wọn ba fẹ jẹ amala ni ajẹgbadun.
Amọṣa, ọpọ awọn ọmọ Naijiria ni wọn ti ya bo oṣere sinima yii lori ayelujara, paapaajulọ loju opo Twitter rẹ ti wọn si ni ọrọ to sọ nipa ọbẹ gbẹgiri jina si ootọ.
Ọbẹ egusi dun gaani, o ni orisirisi eroja
Ni iwoye tirẹ, Theophilous-Truth-hurts(omo iya calabar) @theonce001 salaye pe Amala ti Adesuwa n sọ pe oun gbadun ju amala pẹlu gbẹgiri kii ṣe amala gidi ti gbogbo aye mọ.
Ni tirẹ, Ọgbẹni ni ẹkọ ẹlẹkọ ni ẹgba ẹlẹgba ati pe ki Adesuwa dẹkun sisọ ọrọ odi si amala nitori oun gẹgẹ bi ọmọ Ogbomoṣọ ko ni tẹwọ gba irufẹ ọrọ odi bẹẹ.
Bakan naa ni Ṣèyí Pàtàkì, @seyi_ro naa ko fi oju rere wo ọrọ ti Adesuwa sọ yii.
Bẹẹ lawọn miran n juwe agbegbe ti awọn ti jẹ ọbẹ gbẹgiri ati amala ti ko lẹgbẹ kaakiri.
Bakan naa la ri awọn ọm naijiria miran ti wn kin Adesuwa lẹyin pe lootọ ni ọbẹ gbẹgiri kii ṣe ọbẹ to ṣee pọnle.
Yoruba Foods: Ọ́pọ́ àwọn oúnjẹ wọ̀nyí ló ti ń di ìgbàgbé, táa sì gbọdọ̀ pè padà
Oríṣun àwòrán, Others
Ẹya Yoruba yaayi, wọn gbafẹ, wọn ni aṣa, ede ati ọpọ ohun ajogunba to jẹ manigbagbe, eyi ti ko ṣee fi ọwọ rọ sẹyin.
Ki awọn oyinbo alawọ funfun to de ni Yoruba ti n ṣe aye, wọn n wọṣọ, wọn n jẹun, ti awọn ounjẹ wọn kii si ṣe aṣadanu.
Awọn ounjẹ Yoruba gbajumọ pupọ, ti awọn ẹya miran gan ṣi kundun lati maa jẹ ounjẹ yii nitori adun rẹ ati bo ṣe n ṣe ara loore.
Fun apẹẹrẹ, amala, ẹba ati iyan jẹ ounjẹ abalaye iran Yoruba ṣugbọn o ti di itẹwọgba bayii lọdọ awọn ẹya miran lorilẹede Naijiria.
Ṣugbọn fun iyalẹnu ọpọ eeyan, diẹ lara awọn ounjẹ ati ọbẹ abalaye wa ti n lọ sokun igbagbe, idi si ree to fi yẹ ka pe akiyesi wa sawọn ounjẹ naa, ki wọn maa baa di igbagbe patapata.
Ẹwa Agọnyin:
Arimalelọ ni ẹwa Agọnyin, awopadasẹyin si ni pẹlu, paapa ọbẹ alata ti wọn maa n bu le e lori.
Oríṣun àwòrán, Others
Ẹwa Agọnyin yatọ si ẹwa alasepọ to wọpọ, eyi ti wọn maa n ro epo ati ata papọ, ṣugbọn ọtọ la n din ata ori ẹwa Agọnyin.
Ẹwa pupa ni wọn maa fi n se ẹwa yii, ti wọn si maa n din ata rẹ, ti yoo gbẹ titi yoo fi din di dudu ki wọn to bu u le ẹwa naa lori.
'Mo fẹ́ ìdájọ́ òtítọ́ àti òdodo lóríi ikú àìmọ̀dí tí wọ́n fi pa ọmọ mi'
Isu Ewura ni a fi n se Ikọkọrẹ, ẹlẹmi meje ni, tori ọpọ eroja ti wọn fi n se e, to si wọpọ laarin awọn ẹya Ijẹbu.
Oríṣun àwòrán, Others
Lara awọn eroja taa nilo taa ba fẹ se Ikọkọrẹ ni Isu ewura, alubọsa, epo pupa, awọn eroja amuọbẹdun, ẹja gbigbẹ, pọnmọ, inu ẹran ati bẹẹbẹẹ lọ.
Ko si ẹni ti o foju kan Ikọkọrẹ ti ebi ko ni pa lati jẹ nitori ẹlẹmi ọgbọn ni ounjẹ ọhun.
Mọin-mọin ẹlẹmi meje:
Asọdun ni pe ounjẹ kan ni ẹmi meje amọ taa ba se mọin-mọin naa, amọ pe ko si irọ ninu orukọ ti wọn n pe.
Oríṣun àwòrán, Others
Mọin-mọin tabi ọọlẹ ni wọn n fi ẹwa se, pẹlu eroja ata, ewe, epo abi ororo, ti wọn si maa n fi ẹja, ede, ẹyin ati ẹran wẹwẹ sinu ounjẹ yii.
Owo nla lo pa mọin-mọin ẹlẹmi meje tori ko wa fun ẹniti ko lowo lọwọ tori ọpọ eroja to nilo, to si n se ara loore pupọ pẹlu.
Ẹgbo ati ẹwa jẹ ounjẹ abalaye to ti n lọ sokun igbagbe bayii, to si yẹ ka pe akiyesi wa si.
Oríṣun àwòrán, Others
Agbado gbigbẹ ti wọn ti bo, ni wọn fi n ṣe egbo, wọn yoo fẹ idọti ara rẹ kuro, ki wọn to da sori ina lati see, titi ti yoo fi rọ
Lẹyin eyi ni wọn yoo wa bu ẹwa sise le lori, eyiun ẹwa fifọ bii ẹwa Aganyin, ti wọn yoo si bu ata dindin le lori pẹlu.
Adun ẹwa Aganyin ko se fẹnu sọ nitori onibeji to jẹ, to si n fun ni lokun, agbara ati eroja asara loore.
Bi o tilẹ jẹ pe awọn oyinbo alawọ funfun lo ko irẹsi wa silẹ yii, sibẹ, awa naa ni irẹsi tiwa n tiwa to wọpọ laarin wa ni bii adọọta ọdun sẹyin.
Oríṣun àwòrán, Others
Irẹsi Ọfada jẹ eyi to lee wu lorilẹede yii, yatọ sawọn ẹya irẹsi miran, to si ni adun ti ko ni afiwe.
Lootọ ni irẹsi ọfada ni okuta, ams ta ba fi ara balẹ see, a gbadun rẹ ti adun rẹ ko si ni tete di ohun igbagbe.
Ọbẹ ata dindin pẹlu inu ẹran, ede, pọnmọ, inu ẹran ati iru lo mu ki ọbẹ ọfada yatọ si awọn ọbẹ ounjẹ miran, arimalelọ si ni pẹlu.
Yoruba ni iyan ni ounjẹ, ọka ni oogun, eyi to n sọ bi ounjẹ naa ti se pataki si lawujọ wa.
Oríṣun àwòrán, Others
Alejo ti wọn ba gun iyan fun, ọba ni, nitori adun rẹ, paapa ta ba fi adiẹ se ọbẹ ata taa fi jẹ.
Isu ti wọn se lori ina, ti wọn si gun lodo lẹyin ti isu jinna tan la n pe ni iyan, ọbẹ ẹfọ riro si la saba maa n fi jẹ.
Orisirisi ẹfọ riro lo wa bii sọkọ, tẹtẹ, igbo, ati bẹbẹ bẹẹ lọ ta lee fi jẹ iyan, ti a si fi awọn eroja ẹlẹmi meje bii pọnmọ, ede, ẹja gbigbẹ, panla, igbin ati bẹẹ bẹẹ lọ se.
Ẹwa ti a ti lọ kun pẹlu awọn eroja bii ọpọ alubọsa ati asa, ta wa din ninu ororo tabi epo pupa la n pe ni akara.
Oríṣun àwòrán, Others
Akara kọja nkan ipanu nitori ounjẹ asaraloore gidi ni, to si tun maa n mu ki ara fuyẹ.
A lee fi epo tabi ororo din akara, o si wa lọwọ ta ba se fẹ si.
Akara ba ba fi ororo din la n pe ni Sẹẹkẹ, aye ode oni si lo ti wọpọ nigbati awọn oyinbo n se ororo.
Oríṣun àwòrán, Others
Amọ laye atijọ, akara taa fi epo din, ta n pe ni kengbe lo wọpọ, ki sẹẹkẹ to de.
A le fi ede ati ẹja sinu akara ta fẹ din lati mu ko ladun, bakan naa si la lee fi ata wẹwẹ sinu rẹ ko lee ta lẹnu.
Eroja ounjẹ miran ti awọn ọdọ ode iwoyi ko saba kundun, to si ti n di manigbagbe lọ ni Asaro abi Ẹbẹ jẹ.
Isu taa se pẹlu ata ati epo pupa ni a n pe ni asaro, to si tun lee ni eroja amounjẹ dun bii ede, ẹjọ, inu ẹran ati bẹẹ bẹẹ lọ
Oríṣun àwòrán, Others
Bi isu ba ti jinna tan, la fọ si wẹwẹ, ti a si fi ata ati epo si eyi to mu ki wọn maa pe ni asaro elede abi elepo rẹbẹ-rẹbẹ.
Asaro rọrun lati jẹ ju isu lasan lọ nitori ọpọ eroja asaraloore miran ta se pẹlu rẹ.
A lee pe Ekuru ni onibeji nitori Ekuru aro ati funfun maa n lọ papọ ni.
Ẹwa taa ti bo, ta si fi ẹrọ lọ lai fi ata tabi epo si la n pe ni ekuru.
Oríṣun àwòrán, Others
Ekuru ta ba fi kaun diẹ sinu rẹ la n pe ni aro, tori kaun inu rẹ yoo jẹ ko dudu bii aro, ekuru ti a ko si fi kaun si ni wsn n pe ni ekuru funfun.
A maa n jẹ ekuru mejeeji yii papọ ni pẹlu ata dindin bii ata ẹwa aganyin, ti ata rẹ ọhun naa si maa n ni awọn eroja ẹlẹmi pupọ bii ede, ẹjọ, ẹran wẹwẹ ati inu ẹran.
Oríṣun àwòrán, Others
Yoruba gbagbọ pe ekuru ni ounjẹ ibeji, ti wọn si maa n se fun wọn.
Salawa Abeni: Ìpolówó ọjà ni àwòrán tí èmi àti Kolington ti dì mọ́ra, ìfẹ́ kọ́
Oríṣun àwòrán, other
Kii ṣe pe emi ati Alhaji Kollinghton Ayinla ti pada di tọkọtaya o! Eyi ariwo ti Ọbabirin orin Waka, Salawa Abẹni fi bọnu.
Laipẹ yii ni aworan kan jade kaakiri ninu, eyi ti Kolinghton Ayinla ati Salawa Abẹni ti di mọ ara wọn pẹki-pẹki.
Eleyi si ti n mu ki ọgọọrọ awọn eeyan maa beere pe, abi Ọba Waka ti pada sile Ọba Fuji bayii ni?
Tọkọ tiyawo ni Alaaji Kolington Ayinla ati Salawatu Abẹni tẹlẹ, ki tirela to gba aarin wọn kọja lọpọ ọdun sẹyin.
Amọṣa, ninu ifọrọwerọ pẹlu ileeṣẹ iroyin abẹle kan, Alhaja Salawatu Abẹni ṣalaye pe, ko si ohunkohun to jọ fifẹra laarin oun ati Kebe-n-kwara o, ipolowo ọja lasan ni.
Ipolowo ọja lasan ni. Emi o raye awọn nnkan bẹyẹn.
Oríṣun àwòrán, other
Bakan naa ni Salawatu Abẹni wa gba awọn olorin ode oni niyanju, lati maa kọ ọrin to ni itumọ seti araye. Gẹgẹ bi o ṣe sọ, ni igba ti awọn to ṣaaju n kọ orin tiwọn, gbogbo ohun to n lọ lawujọ ni wọn fi n kọrin lati ṣi araalu leti.
Fire Eater: Azonto ní àfojúṣùn òun ni láti lọ fi idán iná yìí pa owó lókè òkun
Bẹẹ lo tun rọ wọn lati maa tẹriba fun agba.
ALGON Oyo: Ìjọba ní àlá lásán tí kò le è dòhun ni ìlàkàkà àwọn alága APC láti padà sí káńṣù
Oyo local government: ALGON, Makinde sọ ọ̀rọ̀ ọ̀tọ̀ọ̀tọ̀ lórí ọ̀nà àti
Awọn alaga kansu nipinlẹ Ọyọ ti sọ pe, igbesẹ ti ijọba ipinlẹ Ọyọ n gbe lori ọrọ aawọ laarin awọn ati ijọba, kii ṣe eyi to lee mu alaafia waye bọrọ.
Awọn alaga naa ni, ijọba Seyi Makinde setan lati san gbogbo owo oṣu ati ajẹmọnu awọn fun iye ọdun to ku, to yẹ kawọn fi pari saa awọn gẹgẹ bii alaga kansu, eyi tii se ara ilana ati pana aawọ naa, ṣugbọn awọn ko fẹ bẹẹ.
Lọjọ Ẹti ni iwe kan n fẹ kiri loju awọn opo ikansiraẹni lori ayelujara pe ijọba ipinlẹ Ọ́yọ ti fi iwe ransẹ si agbẹjọro awọn alaga kansu naa, Algon, pe oun setan lati san gbogbo owo osu ati ajẹmọnu wọn, ki wọn si maa ba tiwọn lọ.
Oríṣun àwòrán, Algon Oyo
Alaga ẹgbẹ awọn alaga kansu, ALGON naa, Ọmọọba Abass Alẹṣinlọyẹ, to ba BBC News Yoruba sọrọ ṣalaye pe, kii ṣe owo ni awọn n fẹ bikoṣe titẹle ilana ofin nipa pipari saa awọn to ku, gẹgẹ bii alaga kansu nipinlẹ Ọyọ.
Amọ ninu ọrọ to ba ileeṣẹ BBC news Yoruba sọ, agbẹnusọ fun gomina ipinlẹ Ọyọ, Ọgbẹni Taiwo Adisa ni, gẹgẹ bii ijọba ti ko fẹ wahala, to si fi oju woo pe ati tọtun, ati tosi, ọmọ ipinlẹ Ọyọ ni gbogbo wọn, lo mu ki ijọba gbe aba alaafia naa kalẹ.
Oríṣun àwòrán, Ayodeji Abass Alesinloye
O ni ninu aba naa nijọba ti gba lati san awọn nnkan kan fun awọn alaga kansu naa, nitori ala ti ko lee sẹ ni igbiyanju wọn lati pada si ọọfisi bii alaga kansu, to si ni ki wọn tu itọ rẹ danu pe eyi yoo ri bẹẹ.
Bẹẹ ba gbagbe, lọdun 2019 ni ijọba ipinlẹ Ọyọ fa awọn alaga kansu latinu ẹgbẹ oselu APC, labẹ saa ijọba ana lọ sile ẹjọ pe, ki ile ẹjọ ka wọn lapa ko, ki wọn si maa pada si ipo alaga mọ.
Fire Eater: Azonto ní àfojúṣùn òun ni láti lọ fi idán iná yìí pa owó lókè òkun
Ijọba ipinlẹ Ọyọ ni, eto idibo to gbe awọn alaga kansu naa wọle tako ofin, niwọn igba ti ile ẹjọ ti ni ki wọn nisuuru ki wọn gbọ ẹjọ wọn tan, ki wọn to ṣe idibo ọhun nigba naa.
Eleyi ni wọn fa titi, ki ile ẹjọ to gba wọn laye lati lọ yanju ọrọ naa ni tubi inubi laarin ara wọn.
Ireti ọpọ ni pe, igbesẹ naa yoo tete mu ki alaafia waye lori ọrọ naa; amọṣa ọrọ ko fẹ jọ bẹẹ bayii, kaka ki ewe agbọn aawọ ọhun si dẹ, ko ko ko lo n le si.
Oríṣun àwòrán, Ayodeji Abass Alesinloye
Ko si idi meji fun eyi, ju iroyin kan to n lọ kaakiri pe ijọba ipinlẹ Ọyọ ti na ọwọ alaafia si ẹgbẹ awọn alaga kansu naa, ALGON.
Ni ọjọ Ẹti lawọn alaga kansu ọhun kọkọ gba ile ẹjọ lọ, lati fi to ile ẹjọ giga ipinlẹ Ọyọ leti pe awọn ti tẹwọgba eto ti ijọba fi silẹ fun yiyanju aawọ naa, ṣugbọn awọn ko tii yiri rẹ wo.
Kò sí ǹkan tó  ń jẹ́ ọ̀rọ̀ ìgbàgbọ́ tàbí ìmọ̀le nínú àgbékalẹ̀ Amotekun - Alake ti Egba
Togo Elections: Ààrẹ Gnassingbe díje fún sáà kẹ́rin, òun àti bàbá rẹ̀ ti ṣèjọba Togo fún àádọ́ta ọdún lé
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Awọn ọmọ orilẹede Togo jade lonii ọjọ Abamẹta lati dibo yan aarẹ tuntun ti yoo tukọ ilẹ naa fun saa miiran
Aarẹ Faure Gnassingbe to wa lori aleefa lọwọlọwọ n dije fun saa kẹrin lẹyin to di aarẹ ilẹ Togo lọdun 2005 nigba ti baba rẹ, Eyadema Gnassingbe aarẹ orilẹede naa tẹlẹ papoda.
Eyadema fipa gbajọba lorilẹede Togo lọdun 1967, o si jẹ aarẹ ilẹ naa to fi di ọdun 2005 to ku.
Ọmọ rẹ, Faure  to ti ṣe ijọba fun saa mẹta ọtọọtọ, n gbegba ibo aarẹ fun saa kẹrin lati tẹsiwaju ijọba ẹbi Gnassingbe lorilẹede Togo.
O ti le ni aadọta ọdun bayii ti ẹbi Gnassingbe ti n ṣe ijọba orilẹede Togo.
Lati le dẹkun awọn alatako rẹ, aarẹ Gnassingbe ṣe agbekalẹ ofin kan eyi to sọ pe aarẹ ilẹ Togo ko le lo ju saa meji ọlọdun marun un marun un lọ.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Eleyi tumọ si pe Gnassingbe si le jẹ aarẹ orilẹede naa di ọdun 2030 to ba wọle idibo gbogbogbo toni ati to ba tun ṣe saa kan sii.
Gnassingbe ṣeleri pe oun ṣetan lati tun ọrọ aje orilẹede Togo ṣe ti oun ba wọle.
Iṣẹ ati oṣi n ba awọn eeyan Togo finra, akọsilẹ ajọ IMF tiẹ sọ pe orilẹede naa lo tosi ju sikẹjọ lagbaye.
Awọn oludije alatako mẹfa ni yoo figa gbaga pẹlu Faure ninu ibi gbogbogbo ọjọ Abamẹta.
SARS: Ẹgbẹ́ agbábọ́ọ̀lù Remo Stars ní ikọ̀ SARS ló pa agbábọ́ọ́lú òun
Oríṣun àwòrán, @RemoStarsSC
Ẹgbẹ agbabọọlu Remo Stars ti fẹsun ipaniyan kan ikọ ọlọpa to n gbogun ti iwa idigunjale, Special Anti-Robbery Squad, SARS, nipinlẹ Ogun. pe ikọ naa lo pa Tiyamiyu Kazeem, to jẹ ọkan lara ọmọ ikọ ọhun.
Alukoro ẹgbẹ agbabọọlu naa, Dimeji Oshode sọ ninu atẹjade kan pe, iṣẹlẹ naa waye lopopona Sagamu nigba ti ologbe ọhun ati akẹgbẹ rẹ, Sanni Abubakar n rinrin ajo.
O ni awọn ikọ SARS da Kazeem duro, ti wọn si fi ẹsun kan pe o jẹ ọmọ Yahoo, oni jibiti ori ayelujara, nitori imura rẹ, ṣugbọn o ṣalaye fun wọn pe iṣẹ bọọlu gbigba ni oun n ṣe.
Ẹni ti ọrọ naa ṣoju rẹ sọ pe, Kazeem fi kaadi idanimọ rẹ han awọn agbofinro naa gẹgẹ bi agbabọọlu, ṣugbọn wọn kọti ikun sii.
Lẹyin-o-rẹyin, wọn fi panpẹ ofin mu, o si gba lati tẹle wọn lọ si agọ wọn.
Ṣugbọn lẹyin ti wọn n gbe lọ loju ọna marosẹ Sagamu si Abeokuta, lo ba beere ibi ti wọn n gbe oun lọ, nitori ibi ti wọn dorikọ yatọ si ọna agọ awọn ọtẹlẹmuyẹ ọhun.
Oríṣun àwòrán, Tiyamiyu Kazeem
Gẹgẹ bi atẹjade naa ṣe sọ, lẹyin eyii ni awọn ọlọpaa naa duro, ti wọn si tii jade ninu ọkọ wọn, eyi to mu ki ọkọ mii to n bọ kọlu, to si gba ibẹ jẹ Ọlọrun nipe.
Ẹwẹ, ajọ ọlọpaa ipinlẹ Ogun ti sọ pe, ikọ SARS ipinlẹ naa ko mọwọ mẹsẹ ninu iṣẹlẹ ọhun.
Oríṣun àwòrán, @RemoStarsSC
Agbẹnusọ fun ileesẹ ọlọpaa ipinlẹ Ogun, Abimbola Oyeyemi sọ fun awọn akọroyin pe, ikọ SARS kọ lo pa Kazeem, o ni lootọ ni ikọ naa kan fi pampẹ ofin mu pe o wọ aṣọ ṣọja.
O ni lẹyin ti wọn n gbe lọ ni ọkọ wọn taku loju ọna, ṣugbọn nigba ti ologbe naa gbiyanju ati sọda loju popo, ni ọkọ miran kọlu.
Ọpọ awọn ọmọ Naijiria ti bẹrẹ si ni n fi ero wọn lede, lẹyin iroyin iku agbabọọlu naa, ti wọn si n bu atẹ lu ikọ SARs naa.
Fury vs Wilder: Ìbínú ni Wilder fi kúrò níbí ìjà, tó sì ní síbẹ̀-síbẹ̀, akọni ni òun
Oríṣun àwòrán, @peluu_lovers
Tyson Fury ti fagba han Deontay Wilder lẹyin to na jati-jati ninu idije ẹṣẹ kikan to waye laarọ ọjọ Aiku, ni gbọgan MGM, to wa ni Las Vegas.
Alubami ni Fury, to jẹ ọmọ orilẹ-ede Gẹẹsi lu Deontay, to jẹ ọmọ ilẹ Amẹrika ninu idije ife agabaye ọhun.
Fury ni ẹni ti ọwọ rẹ moke ju ninu ija naa, igba keji si ree ti wọn yoo pade lori papa, ṣugbọn ninu abala keje ija ọhun lo ti fọ Wilder lẹnu tan patapata, ti onitọun ko si lee ta putu.
Nnkan bi ọdun kan o le diẹ sẹyin ni wọn kọkọ pade, ṣugbọn awọn to n ri si ija naa ni ọmi ni wọn ta lọjọ naa lọhun.
Eyi si mu ki wọn mu ọjọ ija mii, ti awọn afẹṣẹku bi ojo mejeji si ti n leri tantan mọra wọn lọpọ igba ti wọn ba pade.
Lẹyin ija ọhun, ti wọn si kede Fury bi ẹni to moke julọ, lo gba igbanu gẹgẹ bi ẹni to le ja ẹṣẹ ju ninu idije WBC lagbaye, eyi ni WBC World Heavyweight.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
"Ibanujẹ ni Wilder fi kuro ni gbọgan MGM ti ija naa ti waye nigba to sọ pe ""Ẹni to lee ja ju lo bori, jagunjagun ni mi, ṣugbọn ko si awawi."""
"Ni ti Fury ni tirẹ, o sọ fun awọn oniroyin lẹyin ija naa pe ""Ọba ti pada bọ sori itẹ,"" lẹyin naa lo gboriyin fun Wilder pe iṣe lo ṣe."
Cerebral Palsy: Ìyá Najeebah ní oyún oṣù mẹ́rin ààbọ ni wọn gbe jáde kúrò nínú òun
"O ni ""Mo fẹ gboriyin fun Deontay Wilder fun iṣe takuntakun to ṣe, o ja fitafita titi di abala keje ija ọhun, ṣugbọn ọba ti pada sori itẹ rẹ."""
Ọpọlọpọ awọn ololufẹ ẹṣẹ jija ti bẹrẹ si ni fi erongba wọn lede lori ija naa, ti wọn si ti n ki Tyson Fury ku ori ire.
Cerebral Palsy: Ìyá Najeebah ní oyún oṣù mẹ́rin ààbọ ni wọn gbe jáde kúrò nínú òun tó di ọmọ
Cerebral Palsy: Ìyá Najeebah ní oyún oṣù mẹ́rin ààbọ ni wọn gbe jáde kúrò nínú òun
Isẹ kekere kọ ni ki eeyan tọju ọmọ to dape ninu ẹmi, ara ati ọpọlọ, ka ma sẹsẹ sọ eyi ti ko pe rara.
Lasiko to n ba BBC sọrọ iya Najeebah ni igba ti oyun inu oun n mu ewu dani ni wọn gbe jade losu mẹrin aabọ, to si wa ninu igo fun osu mẹsan, bẹẹ lo wa lẹsẹ kan aye, ẹsẹ kan ọrun fun osu mẹfa gbako.
Najeebah ti pe ọdun mẹrindinlogun bayii, to si ni isẹ ayaworan lo wu oun lati se.
Ọrọ pọ ninu fidi yii, o ya, ẹ woo.
Boko Haram: Ikọ̀ afẹ̀jẹ̀wẹ̀ náà kó òògùn òyìnbó, oúnjẹ́ tí wọ́n sì tún pa ọmọogun mẹ́ta
Oríṣun àwòrán, @jorowasinda
Ilu Garkida to wa nijọba ibilẹ Gombi nipinlẹ Adamawa gbona jain-jain lalẹ ọjọ Ẹti nigba ti ikọ aṣẹrubalu Boko Haram kọlu ilu naa, to si ti si ti fọwọ gbaya pe oun gan loun wa nidi ikọlu ọhun.
Iroyin naa ni, bi eeyan ba jẹ ori ahun, yoo papa bu sẹkun to ba ri ọwọja ikọlu ọhun bo se lagbara si, nitori awọn agọ ọlọpa ati baraki wọn, ọpọ ile ijọsin, ilegbe, to fi mọ ile ajagunfẹyinti Paul Tarfa, ni wọn jo kanlẹ.
Gbọnmọ-gbọnmọ awọn ikọlu awọn ikọ afẹjẹwẹ wọnyi lo ti wa n legba kan ju ọrin lọ nilẹ Naijiria lẹnu lọọlọ yii, kaka ki ewe agbọn wọn si dẹ, koko lo n le si.
Oríṣun àwòrán, @jorowasinda
A gbọ pe wakati mẹfa gbako ni wọn fi da ilu Garkida naa, to wa loju ọna Damaturu laamu, eyi ti ko jinna si guusu Borno ati igbo Sambisa.
Ikọ asẹrubalu Boko Haram naa ni ọmọ ogun mẹta ni oun gbẹmi wọn, toun si ti mu awọn olujọsin tọwọ oun ba lawọn ile ijọsin ni igbekun, to fi mọ awọn olugbe abule naa.
Oríṣun àwòrán, @jorowasinda
Ileesẹ ọmọogun Naijiria ni awọn se bi akin, tawọn si wọya ija pẹlu awọn ikọ afẹjẹsofo naa, ti ibọn n dun lakọlakọ, amọ awọn olugbe ilu naa ni awọn ti tete kofiri awọn awọn ọmọ ikọ asẹrubalu naa lati okeere, tawọn si ta awọn ọmọ ogun lolobo.
Oríṣun àwòrán, @jorowasinda
Amọ dipo ki wọn se isẹlẹ naa ni ogun ti yoo ka ni mọle, okeere laa tii ko, se ni wọn, eyi ko ri bẹẹ, tawọn ikọ naa fi wọle ti awọn lọpọ yanturu, ti wọn si bẹrẹ si ni ja ilu naa lole loju ibọn.
Cerebral Palsy: Ìyá Najeebah ní oyún oṣù mẹ́rin ààbọ ni wọn gbe jáde kúrò nínú òun
Bi wọn se n ko oogun oyinbo ninu ọpọ sọọbu, ni wọn n fọ ilegbe ati ibudo itaja fun eroja ounjẹ lai si ẹni ti yoo yẹ wọn lọwọ wo. Wọn pa ọpọ eeyan, ti wọn si tun ba ọkẹ aimọye dukia jẹ, to fi mọ ile ajagunfẹyinti Paul Tarfa.
Mathematics Education: Fasiti Ibadan f'orin tàkasúfèé wá ojúùtú si ìṣòro ẹ̀kọ́ ìṣirò
Oríṣun àwòrán, UI
Fasiti UI forin tàkasúfèé wá ojúùtú si ìṣòro ẹ̀kọ́ iṣirò
Lójúnà ati wá ojúútú si bi àwọn ènìyàn ṣe maa n fìdírẹmi nínú ẹkọ ìsirò yála nilé ìwé alákọbẹ́rẹ̀ tàbi ni girama lásìkò ìdánwò, olùkọ́ni kan láti ẹka ẹkọ àwọn ọmọde ni Fasiti Ibadan, Omowe Ishola Salami ti ṣe àgbekalẹ̀ orin tàkasúfèé láti mu ẹkọ náà rọrùn.
Salami to ni pàtàkì ǹkan to jẹ òun lógun ni ìmọ ẹ̀kọ́ àwọn ọmọ wẹ́wẹ́, sàláyé pe orin tàkasúfèé náà ni ọ̀nà láti mu ki ọpọlọ àwọn ọmọ ilé-ìwé alákọbẹ́rẹ́ ẹkọ ìmọ isirò ṣí kíákíá.
"Salami ni ""ẹníkẹni to ba lé wá ojúutu si ẹkọ ìṣìrò lé wá ojúutu si ìsòrò tó bá ń ṣẹlẹ̀ láwujọ rẹ̀."""
Lasìkò to n sàlàyé lóri ìmọ tuntun tó gbékalẹ̀, ó ṣàlàyé pé orin tàkasúfèé tí òun pè ní MATMusic, ni àwọn orin tó ni àwọn ìmọ̀ ìṣìrò ti jẹ ki ó rorùn nínú.
Idanwò WAEC ni ọdun 2019 fi han pé nínú àwọn ọmọ to dín díẹ̀ ńi ẹgbẹ̀run mejilà to kọ ìdánwo náà, agbara káká ni a fi ri eniyan ẹgbẹ̀run mẹta to gba àmì Krediiti marun to si ni Isiro àti èdè Gẹẹsi nínú.
Kíkọ ìmọ̀ ìṣìrò ti jẹ̀ ìṣòrò fun ọ̀pọ̀ láti ìgbà to ti pẹ́ láti ilé ìwé alákọbẹ̀rẹ̀ jákèjádò gbogbo àgbàyé, ǹkan to si fa irú iṣòro yii ni pé ìmọ ẹkọ náà ni ọ̀pọ̀ àwọn ofin ti a ko le foju ri ṣùgbọ́n ti a gbọ̀dọ fi pamọ sinu ọpọlọ ní.
Bákan náà ni ìwádìí fi hàn pé ti awọn ọmọde ba fẹ́ràn orin ti wọ́n gbọ́, wọ́n maa n ranti àwọ́n ọ̀rọ̀ inú orin náà, nítori náà ti gbogbo àwọn ìlàna àti òfin inu ìsìrò ba di orin, èyi yóò ràn wọ́n lọ́wọ́ láti mọ̀ ọ́.
Tori ìdí èyi gàn ni mo ṣe ṣe àkojọ àwọn orin to ni ṣe pẹlu imọ ìṣiro fun àwọn ọmọ ilé-iwé alakọbẹ̀rẹ̀.
Mo si ní ìgbagbọ́ pé àwọn ìjọba gúúsù-ìwọ̀-òòrun Naijiria yoo gba ìmọ̀ tuntun yìi wọ́le ti wọ́n yoo si ma lò ó láwọ́n ilé ẹkọ lakọbẹ̀rẹ̀
Nigeria border closure: Ìdí tí Ààrẹ Buhari kò ṣe tíì ṣí ibodè tó tì pa rèé
Oríṣun àwòrán, @alabiopeyemiola
Buhari parọwa si awọn orilẹ-ede ti ọrọ naa kan lati ni suuru
"Aarẹ Muhammadu Buhari ti sọ pe oun n duro de esi igbimọ to n ri si ọrọ ibode to di titi pa, eyi ni ""Tripartite Committee"" ko to gbe igbeṣẹ to kan lori ibode ọhun."
Buhari lo sọ orọ yii nibi ipade kan to ṣe pẹlu aarẹ orilẹ-ede Burkina Faso, Roch Marc Christian Kabore, to si ṣeleri pe atunṣe yoo waye lori ọrọ ibode naa to di titi pa laipẹ.
O ni oun ṣe tan lati ṣe ohun to yẹ lai fi akoko ṣofo ni kete ti igbimọ naa ba ti fi esi wọn ranṣe.
Awọn to wa ninu igbiimọ naa ni; ijọba Naijiria, ijọba Benin ati ijọba Niger Republic.
"Buhari sọ pe ""ootọ ni pe orilẹ-ede Naijira mọ erongba awọn orilẹede to yi wa ka ati ajọ ECOWAS lori ibode ti a gbe agadagodo si, ṣugbọn a o wa ojutu si ọrọ naa laipẹ."""
Oríṣun àwòrán, @Buharisallau1
Awọn to wa ninu igbiimọ naa ni; ijọba Naijiria, ijọba Benin ati ijọba Niger Republic.
O ṣalaye pe idi kan gboogi ti awọn ibode ọhun ṣe di titi pa ni eto aabo to mẹhẹ, paapaa julọ nitori bi awọn kan ṣe n ko ohun ija ogun ati egboogi oloro wọ orilẹede yii.
Lẹyin naa ni aarẹ Buhari wa parọwa si awọn orilẹede ti ọrọ naa kan lati ni suuru.
Ẹwẹ, alaga igbimọ alaṣẹ ẹgbẹ oṣelu PDP, Sẹnatọ Walid Jibrin ti sọ pe ibukun nla ni igbesẹ ijọba Buhari lati gbe agadagodo sẹnu ibode Naijiria.
Jibri sọ ọrọ naa gẹgẹ bi alatilẹyin ẹgbẹ awọn oniṣowo aṣọ ni Naijiiria, lẹyin to ti ṣe iṣẹ gẹgẹ bi oniṣowo aṣọ fun ọdun marundinlaadọta.
Àwọn olúlùfẹ́ fí ìbòjú fi ẹnu ko ara wọn ní  Philippine
O ṣalaye pe bi ijọba ṣe ti awọn ibode naa ti ṣe adikun si bi awọn kọlọransi kan ṣe n ko aṣọ wọle si Naijiria lọna ti ko ba ofin mu.
Jibri sọ pe igbesẹ lati ti ibode naa jẹ ọkan gboogi lara aṣeyọri aarẹ Buhari lati ri pe awọn ileeṣẹ to n ṣe aṣọ lorilẹ-ede yii gbera sọ.
Mother Language Day: Bàbá míì ní àìkọ́ ọmọ òun ní Yorùbá ló mú kò pàdánù iṣẹ́ olówó ńlá
Tiamiyu Kazeem: Ọlọ́páà kò lẹ́tọ̀ọ́ láti fìyà jẹ ará ìlú tó bá wọ aṣọ ológun - Amofin
Oríṣun àwòrán, @others
Amofin kan, Banjo Ayenakin ti sọ pe ọlọpaa ko lẹtọ labẹ ofin lati fiya jẹ ẹnikẹni ti wọn ba gbamu pe o wọ aṣọ ologun ti kii si n ṣẹ ọmọ ologun.
Ayenakin lo sọ ọrọ naa fun BBC Yoruba lẹyin iku Tiamiyu Kazeem to ṣagbako iku lati ọwọ ẹka ileeṣẹ ọlọpaa SARS, ti wọn ni wọn fofin mu latari pe o wọ aṣọ ologun lai jẹ ọmọ ogun.
"O ni ""Ti ọlọpaa ba mu ẹnikẹni pẹlu aṣọ ologun, wọn ko laṣẹ lati fi iya jẹ iru ẹni bẹẹ tabi ki wọn lu."""
Amofin ọhun tẹsiwaju pe o yẹ ki wọn fi pampẹ ofin mu ọlọpaa to ba lu eeyan nitori pe o wọ aṣọ ologun.
Ṣugbọn amofin naa ṣalaye pe , gẹgẹ bi ofin ṣe gbe kalẹ, ẹni ti kii ba n ṣe ọmọ ologun ko ni aṣẹ lati wọ asọ ologun lorilẹ-ede Naijiria.
"O ni ""O lodi si ofin ati pe ijiya n bẹ fun ẹnikẹni ti ọwọ ofin ba tẹ pe o wọ aṣọ ologun ti ko si jẹ ọkan lara ọmọ ogun Naijiria."
"Ayenakin ṣalaye fun BBC Yoruba, ẹsẹ ofin to ni ṣe pẹlu iwa ọdaran, iyẹn ""Criminal code"" to sọ ijiya to wa fun ẹni to ba wọ aṣọ ologun."
O ni ijiya to wa fun ẹni to ba wọ aṣọ ọmọ ogun laarin igboro ni pe yoo san owo itanran ẹgbẹrun meji tabi ko ṣewọn oṣu kan.
Ṣugbọn ẹni to ba wọ aṣọ ọmọ ogun lati fi tan ara ilu jẹ pe ologunn ni oun ti ko si ri bẹẹ, yoo lọ si ẹwọn oṣu mẹfa.
Fire Eater: Azonto ní àfojúṣùn òun ni láti lọ fi idán iná yìí pa owó lókè òkun
Ẹwẹ, amofin naa sọ siwaju sii pe ẹni to ba wọ aṣọ ologun lati fi ṣe ere ori itage, tabi ẹni ti gomina tabi aarẹ ba fun ni aṣẹ lati wọ aṣọ naa ko lẹtọ si ijiya kankan labẹ ofin.
Ayenakin pari ọrọ rẹ pe ofin ko faye gba ọlọpaa kankan lati fiya jẹ ara ilu nitori pe o wuwa ọdaran.
O ni ofin faye gba ara ilu lati foju ba ile ẹjọ, ko si sọ tẹnu rẹ lori ohun ti wọn ba ka mọ lọwọ kaka ki ọlọpaa fi iya jẹ iru ẹni bẹẹ.
Oríṣun àwòrán, @Official3SC
Gomina ipinlẹ Ogun, Dapo Abiodun ti sọ pe gbogbo awọn to lọwọ ninu iku Tiamiyu Kazeem, to jẹ ọmọ ẹgbẹ agbabọọlu Remo Stars ti ipinlẹ Ogun ko ni lọ lai foju wina ofin.
Kazeem di oloogbe lopin ọsẹ to kọja yii, lẹyin ti wọn ni awọn ọtẹlẹmuyẹ Special Anti-Robbery Squad, SARS lo fa ṣababi iku rẹ lopopona Sagamu si Abeokuta.
Bo tilẹ jẹ pe ileeṣẹ ọlọpaa sọ pe wọn ko lọwọ ninu iku arakunrin ọhun, ṣugbọn wọn ni wọn fi pampẹ ofin mu u nitori o wọ aṣọ ologun, ti kii sii ṣẹ ọmọ ogun Naijiria.
Ṣugbọn ẹni ti ọrọ ọhun ṣoju rẹ sọ pe, awọn SARS mu Kazeem lẹyin ti wọn fẹsun jibiti ori ayelujara kan an, to si sọ fun wọn pe iṣẹ bọọlu gbigba ni oun n ṣe, ṣugbọn awọn ọlọpaa kọti ikun si aroye rẹ.
Wọn ni igba ti wọn n gbe e lọ ninu ọkọ wọn ni wọn ti ti i lati inu ọkọ naa, to si ko sẹnu ọkọ mii to n bọ, leyi to mu ko jẹ Ọlọrun nipe.
Oríṣun àwòrán, @dabiodunMFR
Gomina Abiodun ti wa parọwa si awọn awọn ọmọ ikọ Remo Stars atawọn ọmọ ipinlẹ Ogun lati ma tẹ oju ofin mọlẹ nitori wọn n fẹ idajọ ododo fun arakunrin wọn to d'ologbe.
Ninu atẹjade kan lati ọwọ agbẹnusọ rẹ, Kunle Somorin, Abidoun sọ pe ẹnikẹni lara awọn agbofinro ti aje ọrọ ọhun ba ṣi mọ lori yoo jẹ iyan rẹ niṣu.
Gomina ọhun sọ pe ijọba yoo ṣe iwaadi finifini lori ọrọ naa lati mọ pato ọhun to ṣẹlẹ gan latari bi ọrọ ẹni ti ọrọ naa ṣoju rẹ ati ọrọ awọn ọlọpaa ṣe yatọ.
Abiodun wa kẹdun iku ologbe naa, to si sọ pe ijọba rẹ ko ni fọwọ yẹpẹrẹ mu eto abo ẹmi ati dukia awọn eeyan ipinlẹ Ogun.
Mother Language Day: Bàbá míì ní àìkọ́ ọmọ òun ní Yorùbá ló mú kò pàdánù iṣẹ́ olówó ńlá
BBC Africa Eye: Ìyá mi, bí mo bá rántí ikú rẹ lásìkò ìrọbí, àìbímọ tèmí ń pa mí kú díẹ̀díẹ̀
Akọ ìbẹ́pẹ ni Yorùbá yóò pè é, ẹ wo bí òṣèré yìí ṣe ń ní ọgbẹ́ ọkàn pé kò tíì r'ọ́mọ bí
Ìyá mi, lórí pé o fẹ́ pe ọmọ wáyé, o sọ ẹ̀mí tìrẹ nù, torí emi gan ò lè bímọ, mo tí ń kú díẹ̀ díẹ̀ báyìí.
Ninu fidio yii to jẹ akanṣe fọnran ẹka ileeṣẹ BBC to maa n tu aṣiri aidaa lawujọ, BBC Africa Eye, arabinrin kan to jẹ akọroyin ati aṣefiimu lọ sinu yara ibimọ nile iwosan kan lati lọ ya fiimu bi obinrin naa ṣe n bimọ lọwọ lọwọ.
Àwọn olúlùfẹ́ fí ìbòjú fi ẹnu ko ara wọn ní  Philippine
O fi eyi ran ara rẹ leti ohun ti iya rẹ la kọja.
O ni ṣe ni ohun n ranti bi iya ti oun ṣe ku lasiko to n rọbi lati bimọ. Bo tilẹ jẹ pe iya rẹ bi ọmọ naa saye, o gba ibẹ lọ.
Aicha wa lọmọ ọdun marun nigba ti iṣẹlẹ yii ṣẹlẹ ti eeyan lee ni ọmọde o mọ nkankan ṣugbọn lati igba ti oun gan ti wọ ile ọkọ bayii, ti ko gbọ pa tabi gbọ po, ni omije ti bẹrẹ si ni bọ ni oju rẹ́ ti irẹwẹsi si n wọ ọ lọkan.
67 year old mother: Mo kojú ọ̀pọ̀lọpọ̀ àìsàn fún ọdún 35 lẹ̀yín ìgbéyàwò
Komla Dumor Award 2020: BBC ń wá ìràwọ̀ akọ̀ròyìn tí yóò sọ ìtàn Áfíríkà
Ami ẹyẹ Komla Dumor jẹ fún iranti akọni to lọ
Lonii ọjọ aje, ileeṣẹ BBc n ṣe ifilọlẹ ọdun kẹfa ami ẹyẹ pataki kan fun iṣ iroyin ni iranti oloogbe akọroyin ọmọ orilẹede Ghana kan, Komla Dumor to ṣaadede ku ldun 2014 lni dun mọkanlelogoji.
Erongba ami yẹ naa ni lati ṣawari  ati lati ṣe agbende awọn irawọ Afirika to ṣẹṣẹ n dide ninu iṣẹ iroyin ti yoo si tubọ ṣe afihan ẹbun rẹ bii ti oloogbe Komla Dumor to n sọ itan Afirika lọna to jinlẹ to si tun n gbe ogo ati idayatọ ilẹ adulawọ jade pẹlu gbogbo agbara rẹ ati ifarajin.
BBC ṣe'filọlẹ ami ẹyẹ Komlar Dumor
Awọn to ti jawe olubori gba ami ẹyẹ Komlar Dumor ti ileeṣẹ BBC ri ni Nancy Kacungira ati Solomon Serwanjja ti orilede Uganda, didi Akinyelure ati Amna Yuguda ti orilẹede Naijiria to fi mọ Waihiga Mwaura ti Kenya.
Ilu Johannesburg lorilẹede South Africa ni ifilọlẹ ti ọdun yii yoo ti waye pẹlu eto ipade itagbangba BBC kan ti wọn yoo ṣafihan ati agbejade rẹ lori eto ori rẹdio Focus on Africa ati BBC World Service .
Ẹni to ba gbegba oroke ninu idije yii yoo lo oṣu mẹfa ni ile igbohunsafẹfẹ ti BBC to wa niluu London ti yoo si ba awọn oniroyin to moye ju lagbaye ṣiṣẹ pọ lati kọ ẹkọ ati imọ kun imọ.
Oju opo ti wa ṣi silẹ bayii fun awọn to ba fẹ kopa ninu idije lati gba ami ẹyẹ Komla Dumor ti BBc fun ọdun yii, 2020 titi di oru ọjọ kẹrindinlogun oṣu kẹta ọdun 2020 nipasẹ lilọ si oju opo itakun agbaye www.bbc.com/komladumor.
"EndSARS: Ìgbé ""a kò fẹ́ SARS mọ́"" lára ìlú gbé lọ bá Akarigbo ìlú Remo"
Oríṣun àwòrán, Ogun Today
Ikọlu ti waye laarin awọn ileeṣẹ ọlọpaa nilu Sagamu ati awọn ara ilu to n ṣe iwọde ifẹhonu han nitori agbabọọlu ti wn ni oṣiṣẹ SARS kan pa.
Kaakiri oju opo Twitter ni aworan ati fọnranfidio to ṣe afihan bi awọn oluwọde ti ṣe n ṣe ikọlu pẹlu ọlọpaa.
Ninu ọrọ tawọn eeyan fi sita loju opo Twitter naa lati ri i ka pe eeyan mẹta lara awọn oluwọde ni o ti f'ara gb'ọta.
Oríṣun àwòrán, Twitter/Ekwulu
Ileeṣẹ ọlọpaa ni ipinlẹ Ogun fidi ọrọ mulẹ pe lootọ lawọn kan n ṣe iwọde lori iku agbabọọlu ti oṣiṣẹ SARS kan ṣeku pa.
Alukoro ọlọpaa, Abimbola Oyeyemi ni oun ko ni iroyin nipa pe ọlọpaa yinbọn pa ẹnikankan ṣugbọn oun mọ pe iwọde n waye ni Sagamu.
Oríṣun àwòrán, Twitter/Okeydegeneral
Abimbola ni iroyin tẹ oun lọwọ pe awọn eeyan kan fẹ lọ kogun ba awọn ọga ọlọpaa to wa ni agọ ọlọpaa Sagamu lati dana sun ibẹ.
''Kọmisana ọlọpaa ati awọn ọga wa miiran wa nibẹ. Wọn lọ si Sagamu lati lọ ba mọlẹbi ẹni to ku ati Akarigbo ilu Rẹmọ kẹdun iku Tiamiyu''
''Mi o mọ idi tawọn kan yoo fi wa bọ sita lati ni awọn fẹ dana sun agọ ọlọpaa''
Lọwọlọwọ bayi, orukọ Sagamu lo le tente loju opo Twitter gẹ́gẹ́ bi eleyi tawọn eeyan n ran lẹnu.
Ninu awọn aworan ati fidio taa ri, awọn ara ilu lọkunrin ati lobinrin n kọrin pe awọn ko fẹ SARS nilu mọ.
Koda wọn gbe iwọde wọn de iwaju ile Akarigbo ilu Remọ pẹlu.
Yatọ si fidio yii, awọn aworan ati fidio mii ti a ko le fidi rẹ mulẹ ṣe afihan awọn eeyan to n gbe arakunrin kan wọ ile iwosan lọ ti wọn si ni awọn ọlọpaa lo yinbọn pa a.
Heatwave: Ìyàtọ̀ ojú ọjọ́ ló fa ooru gbígbóná lásìkò yìí
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ọ̀pọ̀lọpọ̀ àwọn ènìyàn ló ń ké ìrọra ooru gbígbóná lasiko yii pẹ̀lú àwòrán lórí ayélujára láti ṣe àfihàn bí oru náà ṣe n báwọn fínra.
Onimọ nipa eto isegun kan ti parọwa si awọn eniyan lati ma wọ aṣo ti yoo gba atẹgun laye lasiko ooru gbigbona yii.
Dokita Ikubese Wilson lo  ṣe agbekalẹ awọn ọna ti eeyan le fi koju oru gbigbona to n ja rain kaakiri orilẹede Naijiria.
Dokita naa lasiko to n ba BBC Yoruba sọrọ ni ayipada oju ọjọ, eleyii ti awọn oloyinbo n pe ni climate change lo ṣokunfa bi ayika ti ṣe gbona jainjain yi.
Awọn eniyan tilẹ n fi aworan si ori ẹrọ ayelujara lati le ṣe afiwe bi o ṣe ri ni ara wọn lasiko ooru gbigbona yii, paapaa ni alẹ.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Bakan naa ni dokita naa sọ pe awọn aisan to wọpọ ni asiko yii ni aisan to n ba ẹyin oju ja, aisan yirun yirun, ti awọn oyinbo n pe ni meningitis, CMS ati aisan igbona(measles), aisan onigba meji, ikọ ati awọn aisan to ma n ṣe awọn eniyan ni ọnafun.
Ìpínlẹ̀ Osun yóò mú àyípadà bá àwọn ilànà ìṣèjọba Rauf Aregbesola
Oríṣun àwòrán, others
Ipinlẹ Osun yóò mu àyípada ba àwọn ilànà ìṣejọba Aregbesola
Gómìnà ìpínlẹ̀ Osun Gboyega Oyetola ni gbogbo ètò ti tò láti fi òpin si ọ́rọ́ àṣọ ilé iwé fun gbogbo àkẹkọọ ìpínlẹ̀ Osun eyi to ti n da awuyewuye silẹ láti ọdun 2013, nígba ti Ọgbẹ́ni Rauf Aregbesola ti wà lóri oye bíi gómìnà.
Lára ìgbésl yìí, tí tún àwọn ilé iwé kọ àti ìdáduro ilé iwe ọkùnrin níkàn tàbi ilé iwé obinrin nikan ti wọ́n fi òpin sí tẹ́lẹ̀ wà lári koko mẹ́rindinlọgbọ̀n ti ìjọba Gomina Oyetola yóò múgbọ̀.
Àwọn ǹkan agbéyẹwò míràn ni Ọpọ́n ìmọ, gbigba iwe eri ile iwe alakọbẹrẹ, yiyi orukọ Fasiti Ladoke Akintola (LAUTECH) pada lara awọn akanṣe eto ti Ọgbẹni Rauf gbe kalẹ nigba naa lọhun.
Kò sí ìjà láàrín èmi àti gómìnà Ọ̀ṣun - Aregbesola
Oluwo yí ìpinnu padà,Telu lóun yóò tẹlé àṣẹ lọ rọọ́kún nílé ṣùgbọ́n...
''Láìpẹ́, ìjọba ìpínlẹ̀ Eko yóò fi ǹkan tó dára míì rọ́pò Kẹ̀kẹ́ àti ọ̀kadà''
Àwọn oṣiṣẹ feyinti ni Osun ṣé iwọde
Oríṣun àwòrán, others
Ipinlẹ Osun yóò mu àyípada ba àwọn ilànà ìṣejọba Aregbesola
Ọ̀pọ̀ àwọn atunṣe yìí ni àwọn ènìyan ni o wáye nitori pé ọ̀pọ̀ ara ilú, awon ọjọgbọ́n ati àwọn to ni ilé iwé lo n pariwo lori àwọn eto ijọba to wa nilẹ̀ tẹ́lẹ̀ lori bi ko ṣe bara mu.
Tí ẹ o ba gbàgbé ni ọjọ karun oṣu kẹwàá ọdunn 2013 ni Aregbẹsola to jẹ gomina ipnll Osuin nígbà náà farahan nibi idasilẹ ile iwe alakọbẹrẹ Salvation Army Osogbo ninu asọ ilé iwé tuntun to si ni awokọṣe ni oun ati igbakeji òun jẹ fun àwọn ilé Eko jakejado ipinlẹ Osun
Harvey Weinstein: Àwọn olùfisùn rẹ̀ faramọ ìdájọ ifipabanilopọ tí wọ́n dá fún un
Àwọn olùfisùn Harvey Weinstein faramọ ìdájọ ifipabanilopọ
Gbogbo àwọn olùfisun, Harvey Weistein lo faramọ idájọ ilé ẹjọ pe o jẹbi ifipabanilopọ ati iwa ipa ti o lo pẹ̀lú gbajugbaja òṣèré tẹlẹ̀ri .
"MaGowan sọ fun BBC pe ""ǹkan ti o dùn mọ oun ninu ni"", nítori pe irú idájọ náà fun àwọn eeyan lásan ni ohùn àti ireti ní ààrin àwùjọ"
Weinstein, ẹni ọdún mẹ́tàdinláàdọrin ni wọ́n dájọ fun ni New York fun ibalopọ̀ àti ìwà ọdaran.
Ẹwọ̀n ọdun márùnlélógun ni wọ́n da fún Weinstein lori idajọ ilé ẹjọ fun ibalopọ pẹẹ̀ú obinrin meji, sùgbọ́n agbẹ́jọrò ré ni yóò pe ẹjọ kòtẹmilọrun
Sááju ní wọ́n ti fi ẹsun kan Weinstein ni Los Angeles nitori o lọ ìwà ipá pẹlu àwọn obinrin meji kan lọdun 2013
Lẹ́yìn náà ni àwọn kan dide pẹlu akọle #MeToo lati ri idajọ ododo gbà nitori pe alágbara ni ẹni ti wan n ba koju.
#SagamuOnFire: Àwọn ẹbí Tiamiyu bèrè fún ìwádìí tòótó lórí ikú ọmọ wọn
Oríṣun àwòrán, Twitter
Gomina ipinlẹ Ogun, Dapo Abiodun ṣe àbẹwò ìbánikẹ́dùn sí àwọn òbí Tiamiyu Kazeem tí àwọn ọlọ́pàá pa.
Awọn obi agbabọọlu ikọ Remọ Stars, Tiamiyu ti bere fun iwadii otitọ lori iku to pa ọmọ wọn nipasẹ awọn ọlọpaa.
Mama Tiamiyu sọ ọrọ yii lasiko ti gomina Dapo Abiọdun ṣe abẹwo si awọn obi Tiamiyu ni ile wọn.
Iya ọmọ naa ni ọmọ awọn, ọdun mẹtadinlọgbọn kii si ṣe yahoo yahoo.
O bere fun idajọ ododo ati iya to tọ fun awọn to pa ọmọ rẹ, nitori olu ọmọ ni ọmọ naa, ati wi pe iya naa ko gbọdọ jẹ oun gbe.
Oríṣun àwòrán, Twitter
Gomina ipinlẹ Ogun, Dapo Abiodun nigba to n fesi nibi to ti lọ ba awọn obi naa kẹdun, ṣeleri pe iwadii ti bẹrẹ lẹkunrẹrẹ lori iṣẹlẹ naa.
Abiodun ni awọn ọlọpaa to pa ọmọ naa kii ṣe ọlọpaa ipinlẹ Ogun lati ọdọ adari zone ni wọn ti wa.
O fikun un wi pe Kọmisọna ọlọpaa ni ipinlẹ Ogun ti fi panpẹ ọba mu gbogbo awọn ọlọpaa ti ọrọ naa kan.
Gomina Dapo Abiodun fikun un wi pe Igbakeji Aarẹ Orilẹede Naijiria, Yemi Osinbajo naa ti fi ẹdun rẹ ranṣẹ si awọn eniyan ipinlẹ ọhun.
Nitori naa ni gomina ṣe rọ awọn ẹbi ati ara Tiamiyu lati mu ọkan le, ati wi pe awọn yoo ṣe iranlọwọ fun wọn ni gbogbo ọna ti awọn lee gba.
Ninu ọrọ tirẹ, Igbakeji ọga agba ọlọpaa to wa ni ẹka iwadii iwa ọdaran, Peter Ogunyonwo to ṣoju ọga agba ọlọpaa, Mohammed Adamu naa ba ẹbi ati ara kẹdun.
Oríṣun àwòrán, Twitter
Ogunyonwo ni ọga agba ọlọpaa ti gba iṣẹ lọwọ awọn ikọ Zonal Intervention Squad, Obada-Oko ni ipinlẹ Ogun to wa ni idi iṣẹlẹ iṣekupani naa.
Tiamiyu Kazeem ni ọkọ oju popo pa lẹyin ti awọn ọlọpaa SARS ti i jabọ kuro ninu ọkọ wọn ni ọna Abeokuta-Sagamu ni ọjọ Satide.
Kazeem ki o to ku ni igbakeji balogun ikọ agbabọọlu Remo Stars.
Ọga ọlọpaa patapata lorilẹede Naijiria, Mohammed Adamu ti paṣẹ fun ọga ọlọpaa to wa lẹka iṣewaadi iwa ọdaran, Anthony Ogbizi lati ṣewadi ohun to fa iku Tiamiyu Kazeem to d'oloogbe nipinlẹ Ogun.
Adamu lo sọ ọrọ naa ninu atẹjade kan ti agbẹnusọ ileeṣẹ ọlọpaa, Frank Mba fi ṣọwọ si awọn akọroyin.
Oríṣun àwòrán, @policeng
Igbesẹ yii lo n waye lẹyin ti rogbodiyan to bẹ silẹ nilu Sagamu lẹyin iku arakunrin naa to jẹ ọmọ ẹgbẹ agbabọọlu Remo Stars.
Ọga ọlọpaa patapata ti ba awọn ẹbi ologbe naa kẹdun, to si fi da wọn loju pe  wọn yoo ri idajọ ododo gba lori iṣẹlẹ naa.
Tiamiyu Kazeem gbẹmi mi lọjọ kejilelogun, Oṣu keji ọdun 2020 lẹyin ti wọn sọ pe ọkan lara awọn oṣiṣẹ SARS ti lati inu ọkọ, ti ọkọ mii to n bọ si kọluu, leyi to mu ko njẹ Ọlọrun nipe.
Bo tilẹ jẹ pe ileeṣẹ ọlọpaa kọkọ ṣe pe oun ko lọwọ ninu iku okunrin naa, ṣugbọn awuyewuye to tẹlẹ iṣẹlẹ ọhun ko kere rara.
Oríṣun àwòrán, @RemoStarsSC
Ọpọ awọn Naijriia lo ti bẹrẹ si n fi eroungba wọn lede loju opo Twitter lori iṣẹlẹ naa pẹlu ami #End SARS, pe ki ijọba gbẹsẹle ẹka ileeṣẹ ọlọpa to n risi ọrọ awọn adigunjale, iyẹn SARS.
Yatọ si Tiamiyu Kazeem to dologbe yii, ọpọ igba lawọn eeyan ti fẹsun kan awọn oṣiṣẹ SARS yii pe wọn n tẹ oju ẹtọ awọn ọmọ Naijiria mọlẹ.
Ìlú Eko ló jẹ gbèsè jù ní Nàìjíríà lẹ́yìn ìjọba àpapọ̀
Dele: 'Oṣù mẹ́jọ ni wọ́n tí yọ ina wa ló jẹ́ kí Dele lọ ṣe iṣẹ́ àmúrelé nídìí ẹ̀rọ ATM
Dele, ọmọdé tó ń fi iná ẹ̀rọ ATM ṣe iṣẹ́ àmurelé sọ ìdí tó fi kára mọ́ ẹ̀kọ́ rẹ̀ fún BBC Yorùbá
Rasheed Fathia Dele ni iṣẹ nọọsi ni oun fẹ ṣe lọjọ waju lo jẹ ki oun mura si ẹkọ oun.
Bi ẹ ko ba gbagbe, lọjọ diẹ sẹyin ni okiki ọmọdebinrin yii kan kaakiri agbaye lori ayelujara pẹlu aworan rẹ ti eeyan kan fi sori ayelujara.
Aworan naa ṣafihan Dele to n fi itanna ẹrọ ipọwo ATM ṣe iṣẹ amurele rẹ lalẹ ọjọ kan.
Bada Maruf Mathew, ẹni to fi aworan Dele sori Twitter to si gbilẹ kaakiri ni nini imọlara ohun ti ọmọde yii n la kọja gẹgẹ bi baba ẹlomiran lo wu oun lori.
O ṣalaye bo ṣe ṣẹlẹ gan to ṣe kongẹ mọde yii ni ipo to wa to bẹrẹ sidi ẹrọ ATM to si n kọ iwe.
"O ni nigba ti ọmọde yii ri oun, ""o sun sẹyin, o jẹ ki n gba owo tan, o tun wa pada wa, ..."
Samuel Veronica to jẹ iya iya Dele kẹnu bọ ọrọ pe ai ri owo ina san ti iya onile awọn si yọ ina awọn
"O ti tó oṣù mẹ́jọ tí wọ́n ti yọ ina wa ló jẹ́ kí ọmọ yẹn lọ ṣe iṣẹ́ àmúrelé nídìí ẹ̀rọ ATM.
Ọgbẹni Bada wa bu ẹnu atẹ lu iroyin kan to n ja rainrain pe ile ifowopamọ kan ti fun ọmọdebinrin ọjọ naa lẹ́bun owo
Ọga ileewe Dele gba awọ́n ọmọ ile to ku ni imọran ki wọn gbiyanju lati maa ṣe gẹgẹ bi Dele ṣe ṣe to lo anfani to ni
Ọ̀ọ̀ni kò láṣẹ láti yọ mí nípò, mi ò sì ní ááwọ̀ mọ́ pẹ́lú Aláàfin-Oluwo
Ìlú Eko ló jẹ gbèsè jù ní Nàìjíríà lẹ́yìn ìjọba àpapọ̀
Hosni Mubarak: Ààrẹ́ Egypt tẹ́lẹ̀ jáde láyé
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Aarẹ orilẹede Egypt tẹlẹ, Hosni Mubarak ti awọn ologun le kuro niluu lọdun 2011 ti dagbere faye ni Cairo lẹni ọdun mọkanlelaadọrun.
Mubarak lo ọgbọn ọdun nipo gẹgẹ bi aarẹ Egypt ki wahala nla kan to suyọ nilẹ Egypt.
Wọn ri i pe o jẹbi ẹsun ipaniyan awọn afẹhonu han lasiko iwọde kan. Ọrọ pada yi pada ti wọn si da a silẹ ninu oṣu kẹta ọdun 2017.
Ile iṣẹ iroyin ilẹ Egypt lo kede ipapoda rẹ lọjọ aje. Ṣaaju eyi, o ti kọkọ jade loju opo itakun agbaye Al-Watan pe o ku ni ile iwosan awọn ologun ni Cairo.
Mubarak ṣe iṣẹ abẹ ni ipari oṣu kinni ọdun yii ti ọmọ rẹ, Alaa si sọ ni ọjọ abamẹta pe o wa ni ibudo awn to nilo itọju pataki.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ologun ni Hosni Mubarak; ṣugbọn iru ologun tirẹ, ẹni to gbe opo ifarajin orilede rẹ si alafia agbaye.
Labẹ iṣejọba rẹ, orilede Egypt ko ipa adari lati ri i pe ibadowo pọ wa laarin orilede Israel ati Palestine.
Ọgbọn ọdun to lo lori alefa wa sopin lọdun 2011 nigba ti wahala nla kan ṣẹlẹ to si ko o ni papa mra kuro lori itẹ.
O doju kọ iṣoro gan pe o lo aṣẹ konile o gbele lati doju kọ awọn alatako oloṣelu; si eyi igbẹyin aye rẹ, gbigbogun ti iwa ibajẹ lo fi ṣe.
Muhammed Hosni sọ wi pe ọjọ kẹrin oṣu karun ọdun 1928 ni wọn bi Mubarak ni Kafr-El Meselha ni iha ariwa Egypt.
Bi o tilẹ jẹ pe atapata dide ni, o kawe gboye ni ileewe awọn ọmọ ogun il Egypt ldun 1949 ko to rekọja lọ si ileeṣẹ awọn ọmọ ogun ofurufu nibi ti wọn ti fi ẹsẹ rẹ mulẹ lọdun 1950.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ọdun meji lo lo to n wa ọkọ ofurufu awn ologun. Asiko ti wọn pa ọgagun Gamal Abdel Nasser lọdun 1952.
Mubarak fẹ Suzanne, ọmọ ọdun mtadinlogun to tun jẹ ọmọ dokita. Mubarak goke lẹnu iṣẹ rẹ titi to fi di ọga ileewe awọn ọmọ ogun oju ofurufu ati ọga patapata awọn ọmọ ogun oju ofurufu lọdun 1972.
Ẹwẹ, lori ipo rẹ to kan lo ti ni orukọ to di gbajugbaja gẹgẹ bi olori ọmọ ogun oju ofurufu ilẹ Egypt ati minisita fun eto abo.
Mubarak wulo gan ninu pipilẹ ikọlu ojiji ti wọn ṣe si ikọ ogun Israel ninu ogun Arab ati Isreal ni ibẹrẹ ọdun 1973.
Orilẹede Russia ati ilẹ Amẹrica wa wọya ija gidi gan gẹgẹ bi wọn ṣe n yara ko awọn ikọ ogun wọn sita. Orilẹede Israel yẹ ikọlu ṣugbọn ti ilẹ Sinai pada ko sọwọ Egypt.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ere Mubarak wa lẹyin ọdun meji, nigba aarẹ Anwar Sadat fi i ṣe igbakeji rẹ.
Mubarak gbajumọ ọrọ abẹle ṣugbn nigba naa o bẹrẹ si ni so okun irẹpọ yi pẹlu awọn adari ilẹ Arab paapaa ju lọ ọmọ ọba Saudi, Fahd.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ija nla kan ṣẹlẹ lọdun 1981 ti awọn sọja to n gbaruku ti ọkan larra awọn ẹgbẹ apani kan ṣekupa aarẹ Sadat lasiko yiyan bi ologun ti wọn fi ṣe ayẹyẹ iṣẹgun rẹ nigba ogun Arab ati Isreal lọdun 1973.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Mubarak jawe olubori gẹgẹ bi aarẹ pẹlu ida mejidinlọgọrun gbogbo ibo to jẹ pe oun nikan ni oludije.
Ipa pataki to ko ninu ilana alafia ilẹ Palestine ati Isreal fẹsẹ ibaṣepọ rẹ mulẹ pẹlu awn aarẹ to jẹ lorilẹede America ti wọn si n fun un ọpọlọpọ biliọnu dollar owo iranwọ.
Awọn mii tilẹ n bu u pe gọngọsu to n tẹle America ni.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Lẹyin igba diẹ, wọn pe Mubarak to ti n ṣe daadaa lẹ́jọ́[. Lori akete aisan, o doju kọ ẹsun to ni ṣe pẹlu iwa ibajẹ ati ipaniyan.
Ikọ alatilẹyin rẹ n fọwọ sọya pe oun ṣi ni aarẹ Egypt tori naa ko si labẹ ile ẹjọ.
Lẹyin oṣu mẹfa, wọn yi ipẹjọda. Wọn si fi si atimle ileegbe ni ileewosan awọn ologun ni Cairo.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ninu oniruuru idajọ, wọn wẹ mubarak mọ ninu awn ẹsun iwa ibajẹ ṣugbn fi ti ikowojẹ kan an.
Lọdun 2017, Ile ẹjọ giga ilẹ Egypt fi ẹsun kan an pe o pa awọn afẹhonu han wọn si tu u silẹ.
Hosni Mubarak si jẹjẹ lati maa sin il Egypt titi di igba ti ẹlẹmi gba ẹmi lọwọ rẹ.
Ààrẹ Buhari ṣí ilé iṣẹ́ àti afára ní ìpínlẹ̀ Ondo
Oríṣun àwòrán, Twitter
Aarẹ orilẹede Naijiria, Muhammadu Buihari ati Gomina ipinlẹ Ondo, Oluwarotimi Akeredolu ti ṣe ifilọlẹ akanṣe iṣẹ ni ipinlẹ Ondo.
Gomina Akeredolu to gbalẹjọ aarẹ Buhari ni ipinlẹ naa ṣi ile itaja nla ni ilu ọrẹ ati afara to la ilu naa kọ ja ni ọjọ kẹẹdọgbọn, Osu Keji, ọdun 2020.
Akeredolu ni igbalejo aarẹ naa pẹlu ayẹyẹ ọdun kẹta ti oun bẹrẹ iṣejọba ni ipinlẹ Ondo.
Oríṣun àwòrán, Twitter
Gomina ipinlẹ Ondo to paṣẹ ọjọ isinmi lo ni fun awọn ara ilu lati gbalejo aarẹ Muhammadu Buhari, rọ awọn araalu lati lo ile itaja naa fun idagbasoke ipinlẹ Ondo ati Naijiria lapapọ.
Bakan naa ni Gomina Akeredolu ta aarẹ Buhari lọrẹ pẹlu aṣọ ibilẹ ti wọn ṣẹ ni ipinlẹ naa fun igbelaruge ọrọ aje labẹle lorilẹede Naijiria.
Awọn lọbalọba ni ipinlẹ naa ko gbẹyin nibi ayẹyẹ ifilọlẹ iṣẹ akanṣe naa.
Gomina ìpinlẹ Ondo, Arakunrin Oluwarotimi Akeredolu fi àṣọ ìbílẹ̀ tí wọn ṣe ní ìpínlẹ̀ Ondo ta ààrẹ lọ́rẹ.
Oríṣun àwòrán, @Bashir Ahmad
Aarẹ Buhari wa gboriyin fun gomina Akeredolu fun iṣẹ akanṣẹ naa ti o gbe ṣe ni ipinlẹ naa, bẹẹ lo si ki ku oriire fun ayẹyẹ ọdun kẹta lori oye.
Sagamu: Ògo ọjọ́ iwájú ìdílé wa ni Kazeem tí àwọn SARS ṣekúpa - Iya Kazeem Tiamiyu
Oríṣun àwòrán, @dabiodunMFR
O ṣalaye pe ọmọ ọhun kii ṣe onijọgbọn, bẹẹ ni ki i ṣe ọmọ  Yahoo."""
Iya Tiamiyu Kazeem ti oṣiṣẹ ileeṣẹ SARS fa ṣababi iku rẹ nilu Sagamu ti sọ pe ogo ọjọ iwaju idile wọn ni ọmọ naa jẹ ko to di pe awọn ọlọpaa dẹmi rẹ legbodo.
Arabinrin naa sọ fun ik iroyin BBC Yoruba to ṣebẹwo si ile wọn ni ilu Sagamu pe ọmọ rẹ ọhun ti ṣeleri oke okun fun oun ki iṣẹlẹ iku ojiji to de ba a.
"O ni ""Kazeem ti sọ fun mi pe ti oun ba ti ri ṣe daadaa nidi iṣẹ bọọlu pe oun maa mu mi lọ si oke okun."""
'Mo fẹ́ ìdájọ́ òtítọ́ àti òdodo lóríi ikú àìmọ̀dí tí wọ́n fi pa ọmọ mi'
Iyaafin Tiamiyu sọ fun BBC pe ibanujẹ nla ati iṣẹlẹ manigbagbe ni iku ọmọ naa jẹ fun gbogbo ẹbi wọn lapapọ.
"O ṣalaye pe ọmọ ọhun kii ṣe onijọgbọn, kii ba eeyan ja ati pe kii ṣe oni jibiti ori ẹrọ ayelujara ti ọpọ mọ si ""Yahoo boy gẹgẹ bi awọn Ọlọpaa ọhun ṣe fi ẹsun kan an."""
Oríṣun àwòrán, @Official3SC
Iya ọmọ naa sọ siwaju sii pe Kazeem ni afojusun lati di araba nidi iṣẹ bọọlu gbigba to n ṣe ki awọn oṣiṣẹ SARS ọhun to ge ẹmi rẹ kuru.
Mi ò kí ń ṣèèyàn burúkú tàbí Babalawo bí ẹ ṣe mọ̀ mí nínú eré - Fadeyi Oloro
"O ni ""ti Kazeem ba n wo ifẹsẹwọnsẹ bọọlu lori tẹlifisan, o ma n woye ọjọ iwaju rẹ, to si ma n sọ pe ibi giga ti oun n lọ niyẹn."""
"Iya Kazeem tẹsiwaju pe ""Gbogbo igba ti ọmọ mi ba lọ gba bọọlu ni mo ma n lọ wo ti papa iṣere naa ko ba jina ju, nitori o ma n jẹ iwuri funmi ti mo ba n wo o, ṣugbọn wọn ti gba ọmọ naa lọwọ mi."""
Tiamiyu Kazeem ni ọkọ oju popo kọlu, leyi to yọri si iku rẹ lẹyin ti iroyin ni awọn ọlọpaa SARS ti i jabọ kuro ninu ọkọ wọn ni ọna Abeokuta-Sagamu lọjọ Satide.
Ko to di oloogbe, Kazeem ni igbakeji balogun ikọ agbabọọlu Remo Stars to wa nipinlẹ Ogun.
#Okadaban: Ìjọba fi páńpẹ́ ọba mú àwọn àkàndá tó fẹ̀họ́nú hàn ní Eko
Oríṣun àwòrán, JEI
Awọn akanda eniyan naa n pe fun ijọba lati da kẹkẹ maruwa pada nitori atijẹ ti nira fun wọn ni ipinlẹ Eko.
Awọn akanda eniyan to n wa kẹkẹ ni ipinlẹ Eko ti fẹsun kan ijọba Eko wi pe wọn ti awọn adari wọn mọle nitori wọn ṣe ifẹhọnu han.
Ileeṣẹ ajafẹtọ awọn akanda, JEI lọ fi ọrọ naa lede lasiko ti wọn n ba BBC Yoruba sọrọ lori ifẹhọnu han to waye ni ipinlẹ Eko naa.
JEI ni awọn akanda naa ṣe ifẹhọnu han nitori wiwa kẹkẹ naa da iṣoro silẹ fun lati rin ati iṣẹ ajẹ wọn.
Oríṣun àwòrán, FEI
Wọn ni igbakeji niyii ti wọn n ṣe ifẹhọnu lori igbesẹ ijọba , amọ ti wọn kọ eti ikun si wọn.
Gbogbo igbiyanju wọn lati ba ijọba sọrọ to jasi pabo lo jẹ ki wọn pinnu lati sun si iwaju ile iṣẹ gomina ipinlẹ Eko ni ọjọ ajẹ.
Asalẹ naa ni awọn ọlọpaa wa ko wọn, ti wọn si lọ sọ wọn si atimọle.
Oríṣun àwòrán, FEI
JEI ni awọn ọga awọn akanda naa, Siriki Abubakar ni ijọba ipinlẹ Eko ti gbe lọ si ileejọ fun ẹsun irinkunrin ati awọn iwa ipa.
Oríṣun àwòrán, FEI
Ileeṣẹ ajafẹtọ naa wa fikun pe ijọba tẹ oju ofin awọn akanda to n pe fun ifọrọwerọ pẹlu ijọba mọlẹ lori bi wọn ṣẹ gbegile wiwa kẹkẹ ni ipinlẹ Eko.
Awọn alabọ ara ipinlẹ Eko ti ṣewọde lodi si bi ijọba ipinlẹ naa ṣe gbẹsẹle keke maruwa ati okada nipinlẹ naa.
Ogunlọgọ awọn eeyan naa ṣewọde lọ si ọfisi gomina ipinla ọhun, Babajide Sanwo-Olu  ti wọn si n bere pe ko jade lati ba wọn sọrọ lori ọna abayọ si igbesẹ naa.
Awọn eeyan ọhun gbe awọn kaadi lọwọ ti wọn si n kọrin pe pe ki Sawo-Olu fun wọn ni ẹtọ wọn gẹgẹ bu olugbe ilu Eko.
Wọn ni igbesẹ ijọba lati gbẹsẹ le keke ati maruwa ti mu ki wọn di alairijẹ, ati pe o ti ṣoro fun awọn kan lara wọn lati rin lati ibi kan si omiran nipinlẹ naa.
Ifẹhonuhan yii ni igba keji ti awọn alabo ara nilu Eko yoo ṣe iwọde lodi si bi ijọba ṣe ni ki keke ati  okada kogba kuro ni igboro.
Lara awọn alabo ara to n ṣe iwọde naa jẹ awọn to n ṣeṣẹ awakọ keke maruwa.
Ẹwẹ,  awọn alabọ ara maa n lo okada lati lọ lati ibi kan si omiran nilu Eko, nitori o ṣeeṣe fun okada lati lọ gbe wọn lẹnu ọna ile wọn.
Mi ò kí ń ṣèèyàn burúkú tàbí Babalawo bí ẹ ṣe mọ̀ mí nínú eré - Fadeyi Oloro
Lagos Business: Ológun kan àtàwọn ọlọ́jà kojú ìjà sí àwọn òṣìṣẹ́ Káńsù
Oríṣun àwòrán, Punch
Ọmọ ologun àti àwọn ọlọja koju ija si àwọn oṣiṣẹ́ Kansu ni Eko
Ọmọ ologun kan koju ìjà si àwọn ọmọ ìgbìmọ̀ alabójutó to n ri si ìmọtótó àgbègbè Ikoyi/ Victioria Island lábẹ̀ ìjọba ìpínlẹ̀ Eko lásìkò ti wọ́n gba ọjà lóri àwọn to n tajà ni etí títí ni àgbàgbè Bonny Camp.
Ṣááju ni ìjọba ti fi atẹjade kan sita tẹ́lẹ̀ pé wọn yoo maa yide kiri ni àdugbò náà láti rii dáju pe gbogbo ayika ọhun dùn wò.
Bakan náà ni ni àwọn ìgbìmọ ọhun ti lọ kakiri àwọn ibi ti wọn yoo ti ṣiṣẹ ni ọjọ iṣẹ́gun ni abẹ afara to kọju si Bonny Camp, ibi yii gan ni àwọn to n ta ǹkan lẹ́gbẹ̀ẹ́ titi náà yàn láàyo gẹgẹ bi olu ilé iṣẹ́ wọn nibi ti wọ́n ti n pín ọja ti wọ́n ba fẹ́ tà.
'Mo fẹ́ ìdájọ́ òtítọ́ àti òdodo lóríi ikú àìmọ̀dí tí wọ́n fi pa ọmọ mi'
Atẹjade náà ni kété ti wọ́n pari abẹwò wọn ni àwọn ọmọ ologun kan ti wọ́n o wọ asọ de wọ́n lọ́wọ́ láti ma gba ọja náà lọ́wọ́ àwọn ti wọ́n n ta.
Àwọn ọmọ ogun ọhun ti àwọn kan wọsọ soja ti awon kan ko si wọ́n ń bere pe àṣẹ wo ni ijọba ni láti maa sọ ǹkan ti yóò sẹlẹ ni àgbègbè àwọn ọmọ ologun ti wọ́n si bẹ̀rl si ni lú gbogbo àwọn òṣìṣẹ́ ìgbìmọ náà ti wọ́n ri.
Èyí si lo fun àwọn to n t ọja náà ni ànfani láti maa lẹ òkò àti àwọn ǹkan to le panilára mọ àwọn òsìsẹ́ ìjọba náà lanu iṣẹ́ wọ́n.
Oríṣun àwòrán, Others
Ọmọ ologun àti àwọn ọlọja koju ija si àwọn oṣiṣẹ́ Kansu ni Eko
" Iroyin ni wan gb]iyànju láti gba ẹrọ ìyàwòràn oniroyin ti o tẹle àwọn ò[sìsẹ́ náà ti wọ́n si lu ọkàn lára àwọn oloye ìgbìmọ náà ti ẹ̀rọ il'éwọ rẹ̀ si tun bàjẹ pẹ̀lú
Alaga ìgbìmọ̀ náà Ọgbẹ́ni Tunji Bello, fi ìbànujẹ rẹ̀ han lori ìgbésẹ̀ àwọn ọmọ ologun náà.
Ọgbẹ́ni Bello to jẹ kọmisọna fun ọ̀rọ̀ ayika àti àlumọni ilẹ̀, sàlàye pe àwọ́n ti se gbogbo ǹkan to le fa èdè aiyede mọlu tẹ́lẹ̀ nitori ìdí èyi si ní àwọn ṣe fi àwé ránṣẹ́ si gbogbo àwọn ẹka ilé iṣẹ́ ọmọ ologun ti ọ̀rọ̀ náà yóò kan. lágbègbè Ikoyi àti V.I.
Mi ò kí ń ṣèèyàn burúkú tàbí Babalawo bí ẹ ṣe mọ̀ mí nínú eré - Fadeyi Oloro
Boko Haram: Ìjọba ń ṣètọ́jú àwọn Boko Haram tó rónúpìwàdà, àwọn àgbààgbà Yorùbá fà ìjọba létí
Oríṣun àwòrán, PremiumTimes
Awọn agbaagba ilẹ Yoruba ti fesi si igbesẹ ijọba lati da awọn ọmọ ẹgbẹ Boko Haram kan pada saarin ilu wọn.
BBC Yoruba kan si agba ilẹ Yoruba ati eekan ninu oṣelu, Oloye Olu Falae to sọ wi pe lootọ o yẹ ki a tọju awọn agbesunmọmi to ba ronupiwada ṣugbọn ka ri i daju pe wọn ti ronupiwada ni tootọ.
O ni ṣugbọn o ṣeeṣe ki awọn akọluni nigba mii dibọn bii pe wọn ronupiwada ki wọn le wọ eeyan lara daadaa ṣugbọn awa gbudọ da ara wa loju pe wọn ti jẹwọ wọn si kọ ohun gbogbo to kọkọ ti wọn si didara pọ mọ Boko Haram patapata.
Ọmọ ẹgbẹ Boko Haram marunlelogun to yipada naa ti gunlẹ si ilu Maiduguri tii ṣe olu ilu ipinlẹ Borno lẹyin ti ijọba Naijiria da wọn silẹ lalafia.
'Mo fẹ́ ìdájọ́ òtítọ́ àti òdodo lóríi ikú àìmọ̀dí tí wọ́n fi pa ọmọ mi'
Iroyin sọ wi pe lara awọn ọmọ ẹgbẹ Boko Haram ti wọn da silẹ naa ni ọkunrin, obinrin atawọn ọmọde wa ti wọn da tọwọ wọn silẹ fun awọn ikọ ogun Niger Republic.
Awọn agbesunmọmi tẹlẹri yii gunlẹ si ilu Maiduguri ninu ọkọ baalu awọn ologun ti awọn ologun si sin wọn wa lati ko wọn lọ ibudo itọju ti ijọba pese fun wọn fun itọju, jijẹ mimu ati ẹkọṣẹ ki wọn to lee ko wọn lọ ba awọn mọlẹbi wọn.
O yẹ ki awọn onimọ nipa aabo, imọ nipa ọpọlọ eeyan ba wọn sọrọ ki wọn si fun wa ni idaniloju pe wọn ti wẹ yan kainkain lati dara pọ mọ ilu ko ma lọ jẹ wipe bi ẹ ṣe n di mọ wọn gbagi, ọbẹ n bẹ lẹyin ṣokoto, ẹni bẹẹ dero ọrun niyẹn""."
"Falae ni ""mo mọ tori mo ti b sọwọ awọn ajinigbe ri fun oṣu mẹrin mo si mọ ohun ti oju mi ri, ọpẹlọpẹ Ọlọrun to ko mi yọ tori eyi, a ni lati ṣọra gidi gan""."
O tẹnu mọ ọ pe dida wọn pada saarin ilu gbudọ jẹ ni pẹlẹ kutu ni ko gbudọ jẹ asare ṣe.
Bakan naa, Ọmọwe Olajide ni ao lee faaye gba eleyii nibi ti aye le de lode oni yii. Oun naa mu ọrọ lati ibi ti Oloye Falae duro si.
Koda bi wọn ba ṣẹṣẹ de, o yẹ ki  kọ ibudo kan to jina tefetefe si ilu fun wọn na ki wọn tilẹ lo bi aadọta si ọgọrun ọdun titi a o fi bori awọn to ku wọn tori lana alana wọn ṣi kọlu ilu kan.
Olajide ni o ti ya ijọba ju lati ni awọn fẹ tete da wọn pada sinu ilu eyi yoo si maa ṣe moriya fun awọn ọdọ alainiṣẹ lati maa dara pọ mọ Boko Haram, wn tun pada wale pe awọn ronupiwada ki wọn lee tun jẹ owo lara ijọba.
"O ni bi o tilẹ jẹ pe ootọ ni pe ara wa ni wọn tẹlẹ gẹgẹ bii ọmọ, ẹgbọn , aburo ""hmmmn ṣugbọn a gbudọ ṣọra tori wọn lee pada di alami fun awọn Boko Haram ẹgbẹ wọn to ku nita""."
Ambode probe: Ambode m'òfo nílé ẹjọ́ lóríi pé k'áwọn aṣòfin yéé tojú bọ ọ̀rọ̀ ọkọ̀ bọ́ọ̀sì 820 tó rà
Oríṣun àwòrán, Google
Ile ẹjọ giga ni ipinlẹ Eko ti fagile ipẹjọ kan ti gomina ana ti ipinlẹ Eko, Akinwumi Ambode to n pe fun ki awọn aṣofin ipinlẹ ma ki oju bọ ọrọ pe o ra bọ́ọ̀sì ojilelẹgbẹrin fun akanṣe iṣẹ atunṣe to ṣe ni saa rẹ gẹgẹ bii gomina.
Lọdun to kọja ni iroyin tan ka pe ile aṣofin ipinlẹ Eko ti tutọ soke pe awọn yoo fi ọlọpaa mu Gomina ana ipinlẹ naa, Akinwumi Ambode lori ẹsun ṣiṣe owo ọba kumọkumọ.
Ile iṣẹ iroyin News Agency of Nigeria (NAN) fabọ jẹni pe adajọ Yetunde Adesanya fagile e wi pe igbimọ ti yoo wa ojulowo ọrọ ni igbimọ ti wọn gbe kalẹ.
Bi iroyin ṣe sọ, alaga igbimọ iwadii naa, aṣoju Fatai Mojeed lawọn rii wi pe Gomina Ambode ko tẹle ilana to yẹ ki wọn to ra awọn ọkọ akero 820
Gẹgẹ bi adajọ naa ṣe sọ ọ, iwadii yatọ fun fifi ẹsun kan eeyan.
"O ni ""ko tii di pe ẹsun ni wọn fi kan olupẹjọ naa (Ambode). Bi ileeṣẹ ijọba kan ba fiwe pe 'ni ko lee tumọ si pe wọn n dun mọhurumọhuru mọ ẹtọ olupẹjọ""."
"Tori naa mo sọ wi pe igbesẹ olupẹjọ naa ni iwe ipe si ile ẹjọ lati ka agbara igbesẹ awọn ile igbimọ aṣofin ipinlẹ Eko ko eyi to ni ṣe pẹlu abala 128, 129 ninu iwe ofin Naijiria ti ọdun 1999.
Adajọ ni eyi kii ṣe ojuṣe ile ẹjọ bẹẹ si ni ile ẹjọ kankan ko gbudọ gba iru ipe bẹẹ rara. Fun idi eyi, a fagile iwe ipe olupẹjọ naa""."
Awọn mii ti ọrọ yii kan ni Ọgbni Fatai Mojeed, alaga igbimọ sarenbaja atawọn ọmọ igbimọ ọhun mẹjọ mii ti ile aṣofin Eko gbe silẹ lati bojuwo rira awọn bọ́ọ̀sì naa.
'Mo fẹ́ ìdájọ́ òtítọ́ àti òdodo lóríi ikú àìmọ̀dí tí wọ́n fi pa ọmọ mi'
Coronavirus in Nigeria: Sanwo-Olu ní ètò wà nílẹ̀ láti káwọ́ Coronavirus l'Eko
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Lẹyin ti ijọba apapọ orilẹede Naijiria ti kede pe ọmọ orilẹede Italy kan ti ko aarun gbẹmigbẹmi Corona virus wọ orilẹede Naijiria, ijọba ipinlẹ Eko nibi ti wọn ti kẹẹfin arakunrin naa ni awọn ti gbe igbesẹ lati dojukọ arun naa ni kiakia.
Ninu atẹjade kan to fi sita loju opo twitter rẹ, gomina ipinlẹ Eko, Babajide Sanwo-Olu ni kete ti awọn kẹẹfin pe eeyan kan ti ko arun naa ni wọn fi to ijọba apapọ leti.
O ni iṣejọba oun ti bẹrẹ si ni tẹmpẹlẹ mọ igbesẹ lati rii pe arun naa ko di tọrọ fọnka le ni ipinlẹ Eko.
O ni igbesẹ yii wa nikalẹ ni ifọwọsowọpọ pẹlu igbimọ ojulalakan fii ṣọri onisọri-isọri ti wọn gbe kalẹ labẹ akoso ajọ to n gbogun ti ajakalẹ arun lorilẹede Naijiria, NCDC.
O ni ijọba ti tan ina ibudo eto pajawiri silẹ bayii lẹyẹ-o-ṣọka lati moju to ọrọ naa ki wọn si mu iṣẹ ṣe lori igbesẹ to ba yẹ ni didena rẹ.
O wa rọ awọn eeyan ipinlẹ Eko lati maṣe ko ọkan soke. Ki wọn maa ba iṣẹ oojọ wọn lọ ki wọn si maa ṣamulo awọn eto imọtoto gbogbo to yẹ.
Ileeṣẹ ijọba apapọ to n ri si iṣakoso arun ti sọ pe arun Coronavirus ti apẹle rẹ n jẹ COVID-19 ti tan de Naijiria.
"Gẹgẹ bi ọrọ to fi lede loju opo Twitter rẹ, o ni ""Minisita fun eto ilera ti fi idi rẹ mulẹ pe arun Coronaviorus ti ṣeyọ nilu Eko."""
Atẹjade ọhun tẹsiwaju pe, wọn fidi arun ọhun mulẹ lọjọ kẹtadinlọgbọn Oṣu Keji ọdun 2020, leyi to  jẹ akọkọ iru rẹ ni Naijiria lati igba ti arun na ti ṣeyọ loṣu Kinni ọdun lorilẹ-ede China.
Ẹni to ni arun naa jẹ ọmọ orilẹ-ede Italy to n ṣe iṣẹ aje ni Naijiria.
Okunrin naa rinrin ajo wa si ilu Eko lati ilu Milan lọjọ karundinlọgbọn Oṣu Keji, ki wọn to ṣayẹwo rẹ nile ẹkọṣẹ iṣegun to wa ni Fasiti ipinlẹ Eko.
Eyii ni igabkeji ti awọn eleto ilera yoo fidi arun naa mulẹ nilẹ adanlawọ lẹyin ti wọn ti ṣaaju fidi rẹ mulẹ ni lorilẹ-ede Algeria ati iha Ariwa Afrika.
Omidan jáde láyé lẹ́yìn tí ìlú lù ú, jáa sí ìhòhò lórí ẹ̀ṣẹ̀ tí kò ṣẹ̀
Ni bayii, ajakalẹ arun Coronavirus ọhun ti tan de orilẹ-ede ti ko din ni ogun kaakiri agbaye lagbegbe Asia, Yuroopu, ati Afrika.
Ṣaaju ni ijọba ipinlẹ Eko ti kọkọ sọ ko si aarun coronavirus ni ipinlẹ naa, lẹyin ti ayẹwo fihan pe ọmọ orilẹ-ede China kan ko ni aarun COVID-19 ọhun.
Ẹwẹ, minisita fun eto ilera Naijiria, Osagie Ehanire ti sọ ninu atẹjade kan pe ijọba apapọ n ṣe isẹ takuntakun lati ri pe arun naa ko tan kalẹ ju boṣe lọ ni Naijiria.
Osagie ni iṣe n lọ lọwọ lati ṣawari gbogbo awọn ti okunrin ọhun ba pade ninu irinajo rẹ lati ilẹ Italy si ilu Eko.
O wa rọ awọn ara ilu lati ma lo oju opo ikansiraẹni lori itakun agbaye lati maa pin awọn iroyin ofege nipa arun naa, leyi to lee fa ibẹru sọkan awọn eeyan.
'Mo fẹ́ ìdájọ́ òtítọ́ àti òdodo lóríi ikú àìmọ̀dí tí wọ́n fi pa ọmọ mi'
Coronavirus in Nigeria: Ọmọ Italy tó kọ́kọ́ kó Coronavirus wọ Eko tún lọ́ sí ìpínlẹ̀ Ogun nàá
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ileewosan Mainland Hospital ti wọn ti n tọju ajakalẹ aarun ni adugbo Yaba nilu Eko ni ọmọ orilẹ-ede Italy to ko aarun Coronavirus wọ ipinlẹ Eko ti n gba itọju lọwọlọwọ.
Dokita Abimbola Bowale to gba ẹnu ileewosan naa sọrọ sọ diẹ lara nkan to yẹ lati mọ nipa ọkunrin naa fun BBC:
Ọmọ orilẹ-ede Italy to kọkọ gbe aarun Coronavirus wọ ipinlẹ Eko, l'orilẹ-ede Naijiria tun lọ si ipinlẹ Ogun ni kete to de lati ilu Milan to jẹ olu ilu Italy ko to o di pe wọn fidirẹmulẹ pe o ni aarun naa.
Àwọn olúlùfẹ́ fí ìbòjú fi ẹnu ko ara wọn ní  Philippine
Eyi ni nkan ti kọmisana fun eto iroyin nipinlẹ Eko, Gbenga Omotoso sọ fun BBC lọjọ Ẹti.
Minisita fun eto ilera ni Naijiria, Osagie Ehanire naa si ti sọ pe awọn ti ran dokita to le ni ọgọta lọ si papakọ ofurufu Murtala Muhammad to wa l'Eko, lati ṣeranwọ ninu ayẹwo awọn arinrinajo to n wọle.
Minisita sọ pe awọn ti wa ni igbaradi lati doju ogun kọ aarun naa.
O sọ pe awọn ti ajọ to n mojuto aarun ni Naijiria, NCDC n ṣiṣẹ pẹlu ti ṣe idasilẹ ibudo itọju pajawiri kan, wọn o si maa ṣiṣẹ pọ pẹlu ijọba ipinlẹ Eko lati ka a lapa ko.
Minisita gba awọn ọmọ Naijiria ni imọran pe ki wọn o ma bẹru, ṣugbọn ki wọn o mu ilera wọn ni pataki.
O sọ pe awọn kan wa to jẹ pe aisan diẹ ni yoo ṣe wọn ti wọn ba ni aarun naa, ti ara wọn yoo si ya.
Ṣugbọn awọn to ba ti darugbo, ati awọn to ba ti n ṣaiṣan ko to o mu wọn ni yoo le koko.
Naijiria si ni o ni akọsilẹ ẹni akọkọ to ni aarun Coronavirus lagbegbe ilẹ olooru Afirika.
Awọn alaṣẹ ṣalaye pe ọmọ orilẹ-ede Italy kan to gunlẹ sorilẹede Naijiria lọjọ mẹta sẹyin ti ko aarun naa.
Ati wi pe ayẹwo ti wọn ṣe fun ọkunrin naa ni papakọ ofurufu ilu Eko ko fihan pe o ni aarun naa nitori pe aarun naa kii tete fi apẹẹrẹ han lara.
Bakan naa ni wọn sọ pe awọn ti ṣe agbeyẹwo akọsilẹ orukọ awọn to wọ baalu pẹlu rẹ, ti wọn si ti n wa wọn.
Botilẹjẹ pe iṣẹlẹ yii ti da ibẹru silẹ, ijọba sọ pe oun ko ni i titori eyi da awọn baalu to n wọle lati okeere duro. tabi fi awọn arinrinajo si ipamọ.
"Atẹjade kan lati ọdọ minisita feto ilera, Dokita Osagie Ehanire, eyi tawọn ileeṣẹ iroyin abẹle gbe sita ṣalaye pe, ""Ọmọ orilẹede Italy kan to n ṣiṣẹ lorilẹede Naijiria lo ko aarun naa wọle nigba to pada de si Naijiria lati ilu Milan ni ọjọ karundinlọgbọn oṣu keji ọdun."
"Alaisan naa wa labẹ itọju ni ileewosan fun wiwo ajakalẹ aarun to wa ni Yaba, nilu Eko, """
Wọn ti kọkọ fura aarun yii lorilẹ-ede Egypt ati Algeria, ṣugbọn ko tii yọju ni agbegbe ilẹ olooru .
Pupọ awọn orilẹede Afirika lo ni ajọṣepọ okoowo ati ọrọ aje pẹlu orilẹede China.
Omidan jáde láyé lẹ́yìn tí ìlú lù ú, jáa sí ìhòhò lórí ẹ̀ṣẹ̀ tí kò ṣẹ̀
Ni Ọjọbọ ni igbakeji olori ọmọ ẹgbẹ to pọ julọ ni ile aṣofin agba orilẹede Naijiria, Sẹnetọ Ajayi Borrofice ti bẹnu atẹ lu eto ti awọn alaṣẹ gbe kalẹ fun didena aarun Coronavirus.
Ni opin ọsẹ to kọja ni ajọ ilera agbaye, WHO ṣekilọ pe ọpọ awọn ilana eto ilera lawọn orilẹede Afirika ni ko duro deede lati koju ajakalẹ arun Coronavirus yii.
Coronavirus in Nigeria: Wo àwọn ohun tó yẹ kí o mọ̀ nípa ọ̀nà láti dáàbò bo ara rẹ lọ́wọ́ Coronavirus
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Aarun Coronavirus ti wọ orilẹede Naijiria bayii, eyi kii sii ṣe iroyin tuntun mọ bayii.
Amọ, bi ọrọ ti ṣe jẹ bayii, awọn ọna wo ni o lee fi daabo bo ara rẹ lọwọ arun yii.
Gẹgẹ bi atẹjade ajọ ilera agbaye, WHO, lootọ orilẹ€de China ni arun yii ti gbera ṣugbọn awọn orilẹede to ti ran de ti pọ, leyi ti orilẹede Naijiria naa si ti wa darapọ mọ wọn bayii.
Pupọ awọn to ba kọlu aarun yii maa n ni ailera diẹ, wọn o si tun pada bọ sipo ilera wọn pada, ṣugbọn bẹẹ kọ lọrọ ri fun fun awọn miran.
Eyi ni ọna ti o lee gba daabo bo ara rẹ atawọn miran lọwọ arun Coronavirus:
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Rii daju pe o n fọ ọwọ rẹ loorekoore pẹlu ọṣẹ ifọwọ ati omi to mọ.
Ki ni idi? Fifọ ọwọ rẹ pẹlu ọṣẹ ati omi mimọ yoo pa awọn kokoro arun to n gbe ni ọwọ rẹ.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Rii daju pe o rin jina fun bi iwọ ẹsẹ bata mẹta si ẹnikẹni ti o ba kẹẹfin pe o n wukọ tabi ṣe ọfinkin.
Ki ni idi? Bi eniyan ba n wuks tabi sin, iwọn omi diẹ to ba n jade ni imu tabi ẹnu wọn lee ni koko arun yii. Bi o ba wa sunmọ wọn ju bi o ti yẹ lọ, iwọ naa lee koo simu pẹlu kokoro arun yii bi o ba jẹ pe onitọun ni kokoro arun COVID-19.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ọwọ rẹ ti o ti fi kan oniruuru nnkan lee ti kan kokoro arun yii. Bi ọwọ ba si ti kan an , o lee taare rẹ si oju rẹ, imu tabi ẹnu rẹ. Nipasẹ bẹẹ kokoro arun yii lee wọ ara rẹ ki o si sọ ọ di alailera.
Duro si ile rẹ bi o ba ṣakiyesi pe ara rẹ ko ya. Bi o ba ni iba, ikọ ati iṣoro lati mi, tete tọ awọn oniṣegun oyinbo lọ fun ayẹwo ati itọju. Pe wọn ni ile iwosan naa silẹ, ki wọn lee ti gbaradi de ọ.
Omidan jáde láyé lẹ́yìn tí ìlú lù ú, jáa sí ìhòhò lórí ẹ̀ṣẹ̀ tí kò ṣẹ̀
Oniruuru iroyin lo n lọ kaakiri lori ọna ti o lee gba dena arun yii ati ohun gbogbo ti o nilo lati mọ nipa COVID-19 ti a mọ si coronavirus.
Ma si ṣe gbagbe lati maa tẹle awọnilana eto ilera tawọn alaṣẹ ijọba lagbegbe rẹ ba fi sita.
Awọn
Lóòtọ́ la mú ọkùnrin kan pẹ̀lú agbárí èèyan, ṣùgbọ́n kìí ṣe pásítọ̀-Ọlọ́pàá Ondo
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ileeṣẹ ọlọpaa ni ipinlẹ Ondo ti ṣalaye wi pe lootọ ni ọwọ awọn tẹ arakunrin kan pẹlu agbari eniyan ati apa meji ni ikawọ rẹ.
Iroyin kan n ja rayinranyin lori ayelujara pe pasitọ kan ti bọ si panpẹ awọn ọlọpaa nigba ti wọn muu pẹlu ika ọwọ mẹtadinlogun ati oniruuru ẹya ara eniyan miran l'agbegbe Alagbaka ni ilu Akurẹ.
Iroyin naa fi kun pe awọn ọlọpaa ikọ SARS kan tun kọlu agbabọọẹu kan nibẹ, ati pe pasitọ ni ọkunrin ti wọn ba ẹya ara eniyan lọwọ rẹ.
Ṣugbọn nigba to n ba BBC Yoruba sọrọ, alukoro ileeṣẹ ọlọpaa nipinlẹ Ondo, Ọgbẹni Fẹmi Joseph ṣalaye pe irọ funfun balau ni iroyin naa ati pe ko si igba kankan ti awọn ọlọpaa ni ipinlẹ naa mu pasitọ kankan pẹlu ẹya ara eniyan.
O ni ọwọ awọn ọlọpaa ipinlẹ naa tẹ arakunrin, ẹni aadọta ọdun kan ni owurọ oni ni ilu Idoani pẹlu agbari eeyan kan ati apa meji ti wọn ti dana sun guruguru.
Omidan jáde láyé lẹ́yìn tí ìlú lù ú, jáa sí ìhòhò lórí ẹ̀ṣẹ̀ tí kò ṣẹ̀
Ọgbẹni Joseph tun sọ pe afunrasi naa ṣalaye pe ẹnikan ti orukọ rẹ n jẹ Alhassan lo ran oun, ti ileeṣẹ ọlọpaa si ti mu awọn mejeeji bayii.
O wa rọ awọn araalu lati jinna sawọn to n gbe iroyin ofege to lee da họwuhọwu silẹ lawujọ.
Coronavirus in Nigeria: A ti rań ọgọ́ta dókítà sí pápákọ̀ òfúrufú láti ṣàyẹ̀wò àwọn tó ń wọlé - Ìjọba Eko, kwara
Coronavirus in Nigeria: A ti rań ọgọ́ta dókítà sí pápákọ̀ òfúrufú láti ṣàyẹ̀wò à
Awọn ijọba ipinlẹ Iwọ oorun guusu  Naijiria ti sọ pe gbogbo eto lo ti wa nilẹ ki arun Coronavirus ma ba tan kalẹ ju boṣeyẹ lọ.
Kọmiṣọna fun ọrọ to n lọ nipinlẹ nipinlẹ Eko, Gbenga Omotoso sọ fun BBC pe pe ijọba ipinlẹ Eko ti mura silẹ lati koju arun naa ko to di pe arun ọhun de Naijiria.
Ni kete ti ileeṣẹ ijọba apapọ to n ri si eto ilera fi lede pe arun naa ti tan de ipinlẹ Eko ni ijọba ipinlẹ naa pe apero awọn oniroyin lati sọ ibi ọrọ de duro lori arun naa.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Omotoso sọ pe ki awọn eeyan ipinlẹ Eko ma bẹru lori arun naa nitori ijọba ko sun lati ri pe arun ọhun ko di tọrọ kọbọ.
O ni ipinlẹ Eko ti ran awọn dokita ọgọta si papakọ ofurufu Eko fun ayẹwo gbogbo awọn eeyan to n wọle sorilẹ-ede Naijiria.
Ni ti Kwara, kọmiṣọna eto ilera nipinlẹ ọhun, Raji Razak sọ fun BBC Yoruba pe ijọba ti ta gbogbo  awọn eleto ilera ipinle naa ti n ṣamojuto gbogbo ibode to wọ ipinlẹ ọhun.
Omidan jáde láyé lẹ́yìn tí ìlú lù ú, jáa sí ìhòhò lórí ẹ̀ṣẹ̀ tí kò ṣẹ̀
"O ni ""Gbogbo ọna abawọle si ipinlẹ Kwara ni ijọba ti ran awọn eleto ilera si kin wọn lee ma ṣayẹwo gbogbo awọn eeyan to ba n wọle lati ibẹ."""
O tẹsiwaju pe ijọba tun ti fiwe ranṣẹ si ileeṣẹ to n ri si eto ẹkọ lati da awọn ileewe lẹkọ nipa ṣiṣe itọju ara ẹni, bii fifọ ọwọ pẹlu ọṣẹ, lilo igbọnwọ lati bo ẹnu bi eeyan ba fẹ wukọ, ati bẹbẹ lọ.
Saani: Gbogbo egungun Tiamiyu ló kán lẹ́yìn tí wọ́n tì í jábọ́ nínú ọkọ̀
Raji sọ pe ipìnlẹ Kwara ti ni awọn ibudo ti wọn lee ko awọn eeyan to ba n ṣaarẹ si fun itọju ni imurasilẹ fun arun naa nipinlẹ ọhun.
Ni kuktukutu owurọ ọjọ kejidinlọgbọn, oṣu Keji ọdun 2020 ni iroyin jade pe arun Coronavirus ti tan de ilu Eko, leyi ti wọn ni ọmọ orilẹ-ede Italy kan lo mu wa.
Coronavirus: Báyìí ni nkan ṣe n lọ ní pápákọ̀ ọkọ̀ òfurufú l'Eko lẹ́yìn tí Coronavirus wọ́lé
Gbogbo awọn to n wọle, tabi jade kuro ni papakọ ofurufu Murtala Muhammed lo n gba abẹ ayẹwo kọja
Yatọ si irinṣẹ ti wọn n mu dani, ẹrọ kan tun wa bi kamẹra to n ṣe ayẹwo awọn eero baalu fun apẹẹrẹ aarun Coronavirus
Oriṣiriṣi awọn oṣiṣẹ eto ilera lo wa ni ikalẹ ni papakọ ofurufu ilu Eko fun ayẹwo awọn arinrinajo
Koda, wọn gbe omi aporo kokoro aifojuri 'sanitizer' silẹ fun awọn arinrinajo
Ati oṣiṣẹ ati eero baalu lo n lo iboju lati ba ara wọn sọrọ nitori Coronavirus
Kii ṣe ita papakọ ofurufu nikan ni ikiyesara ti n waye, gbagbaagba ni kaluku n boju-bomu ninu ọfiisi.
Ẹrọ ayaworan wa tun gbe oṣiṣẹ eto ilera kan to wa lẹnu iṣẹ t'oun ti iboju ati ìbọ̀wọ́
Ṣugbọn o, Coronavirus ko da wiwọle ati jijade ni Naijiria duro ni papakọ ofurufu naa. Kẹti-kẹti ni eero n ya lati wọ baalu.
Igbesẹ oju lalakan fi n sọri ọhun ko yọ awọn oṣiṣẹ ajọ to n risi iwọle-wọde (Immigration) silẹ. Iboju lawọn naa fi ṣe koju o ma ri ibi.
Leap Year: Jedidiah ní òun jẹ́ ọmọ ọdún mẹ́rin, ìgbà àkọ́kọ́ rèé tí ọjọ́ ìbí òun yóò wáyé
Leap Year: Jedidiah ní òun jẹ́ ọmọ ọdún mẹ́rin, ìgbà àkọ́kọ́ rèé tí ọjọ́ ìbí òun yóò wáyé
Ọjọ ibi se pataki, o se koko, idi si ree ti ọpọ eeyan fi maa n se ayẹyẹ rẹ ni ọdọọdun.
Amọ eyi ko ri bẹẹ fun awọn eeyan ti wọn bi ni ọjọ kọkandinlọgbọn osu keji ọdun, nitori wọn ko ni anfaani lati yayọ ọjọ ibi lọdọọdun.
Idi ni pe ọdun mẹrin-mẹrin lo maa n waye, eyi ta n pe ni Leap Year.
Koda, ọmọdekunrin kan ọmọ ọdun mẹrin, Jedidiah Adetunji  salaye pe oun ti pe ọmọ ọdun mẹrin amọ ti oun ko tii fi oju kan ọjọ ibi oun ri loke eepẹ.
Coronavirus: Ọ̀pọ̀ àwọn arìnrìnàjò wá sí Nàíjíríà ló kọjá àbẹ̀wò tó lágbára
Coronavirus: Ọ̀pọ̀ àwọn arìnrìnàjò wá sí Nàíjíríà ló kọjá àbẹ̀wò tó lágbára
Nibayii ti arun Coronavirus ti wọ orilẹede Naijiria, ijọba wa ko sun rara, lati dena itankalẹ arun naa.
Amọ ijọba wa ti n gbe igbesẹ lati dena itankalẹ arun naa bayi bẹrẹ lati awọn papakọ ofurufu ilẹ wa.
BBC Yoruba ṣe abẹwo si papakọ ofurufu wa, ta si ri itu meje ti awọn osisẹ ibẹ n pa lati ri pe wọn se ayẹwo fun awọn eeyan naa.
Ẹ wo fidio yii lati mọ bo se n lọ nibẹ.
Ìtàn Mánigbàgbé: Samuel Taiwo Oredein, àgbà òṣèlú tó fi ẹ̀wọ̀n jura lárúgbó ara
Oríṣun àwòrán, Others
Ìtàn Mánigbàgbé: Ìgbé ayé Samuel Taiwo Oredein kọ́ wa láti máa ni ìtẹ́lọ́rùn
Aye n yi, a n tọọ lẹyin, aye ko tọ lọ bii orere, igba ko tọ lọ bii ọpa ibọn, bẹẹ si ni arugbo ti soge ri, akisa si ti lo igba ri.
Baba oloselu kan wa, to gbajumọ lorilẹ-ede Naijiria, oun si la ba maa pe ni afọbajẹ, oun gan ni baba isalẹ oselu.
Bi o ṣe jẹ ọga patapata nidi ọrọ oselu Naijiria, bẹẹ lo tun jẹ ọwọ ọtun Oloye Ọbafẹmi Awolọwọ nigba naa.
Orukọ agba oloselu naa ni Samuel Taiwo Ọrẹdẹin, o si wa lara awọn eekan oloselu to da ẹgbẹ oselu Ọlọpẹ, Action Group silẹ pẹlu Awolọwọ, ẹgbẹ yii si lo fa olootu ijọba akọkọ silẹ lẹkun iwọ oorun guusu Naijiria lọdun 1955.
Lara awọn sawawu baba naa ti wọn jọ jẹ eegun sonso tii pari ike lagbo oselu ninu ẹgbẹ ọlọpẹ nigba naa ni Abiọdun Akerele, Ade Akinsanya, J.O Adigun, S.O Shonibarẹ, Ayọ Akinsanya ati Ọlatunji Dosunmu.
Bi o tilẹ jẹ pe Ọrẹdẹin ko du ipo oselu kankan nigba naa sibẹ, o lagbara ju awọn to wa nipo asẹ lọ.
Ohun to ba si sọ ni abẹ ge nigba naa nitori oun ni akọwe aato ẹgbẹ Ọlọpẹ, to si ni asẹ lati ni ki awọn to wa nipo asẹ wa kawọ pọnyin ro ẹjọ, ti ohun ti wọn se ko ba dara.
Oríṣun àwòrán, Others
Amọ isẹlẹ kan waye lọdun 1971 eyi to milẹ titi, eyi to sọ ile ọla Ọrẹdẹin di ahoro.
Iṣẹlẹ ọhun mu ki ọlọla ati ẹni ẹyẹ di ẹni abuku, o si yẹ kawọn ọdọ ati ewe iwoyi, to fi mọ awọn eeyan to n lo igba lọwọ lagbo oselu wa fi kọgbọn.
Ẹ jẹ ka fi itan igbe aye Samuel Taiwo Ọrẹdẹin kọgbọn, ka maa sọra se.
Taye Currency ní ọmọ ibàdàn tí Saheed Oṣupa jẹ́ kò lè já òun gbà lẹ́yìn Pasuma
Oríṣun àwòrán, Taye currency
Ṣe ẹ mọ wi pe ọmọ ilu kan naa ni Saheed Osupa ati Taiwo Akande Adebisi ti ọpọ mọ si Taye Currency?
Ilu Ibadan ni awọn mejeeji, eyi ti o fi han pe a lee pe wọn ni tẹgbọn taburo.
Amọṣa Taye kọrẹnsi ti sọ pe lootọ ọmọ ilu kan naa ni awọn mejeeji, sibẹ Pasuma Ọganla loun yoo ba lọ lọjọkọjọ.
Ninu ifọrọwerọ rẹ pẹlu BBC News Yoruba, Taye Kọrẹnsi ni lasiko ti aawọ wa laarin Alaaji Alabi Pasumọ Ọganla ati King Saheed Oṣupa, oun o da si aawọ aarin wọn nitori bi Saheed Oṣupa ṣe jẹ ọmọ ilu oun ti o si dara si oun naa ni Pasuma jẹ awokọṣe fun oun to si jẹ pe ati maa ṣe bọ wọn ti le ni ni ogun ọdun.
O ni bi o tilẹ jẹ wi pe awọn eeyan kan n reti ki oun gbe lẹyin Oṣupa nitori awọn jọ jẹ ọmọ ilu kan naa, sibẹ, wọn tun gbọdọ roo pe oun ati Paso ni awọn jumọ jọ wa lati aye alalumọlẹ.
Omidan jáde láyé lẹ́yìn tí ìlú lù ú, jáa sí ìhòhò lórí ẹ̀ṣẹ̀ tí kò ṣẹ̀
O ni idi niyi ti oun ko fi da si ija aarin awọn mejeeji.
Amọṣa o fi kun un o pe lootọ oninufufu ni Oṣupa Saheed sibẹ o dara si oun ko si si idi kan fun aawọ lati wa laarin oun ati Oṣupa.
Bakan naa ni Alaaji Taiwo Akande Adebisi Taye Kọrẹnsi naa tun sọrọ lori bi o ṣe wakọ wọ agbami oṣelu, ọmọ rẹ, Yusuf Adebisi to jẹ ọkan lara awọn aṣofin ipinlẹ Ọyọ ati oniruuru iṣẹlẹ nipa igbesi aye rẹ.
Wasiu Ayinde: Èmi àti Aláàfin sọ fún Gani Adams nípa oyè Mayegun, a kò jà rárá
Gbogbo eyi ni ẹ lee wo ni oju opo facebook BBCNewsYoruba tabi ki ẹ tẹ adirẹsi ayelujara to wa ni isalẹ yii:
Premier league: Àdúra Arsenal gbà, Watford ja Liverpool bọ́ ní ìlépa àkọsílẹ̀ 'Invincibles' pẹ̀lú góòlù mẹ́ta
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Iyalẹnu nla lo jẹ fun ọpọlọpọ onwoye ere bọọlu lagbaye, paapaajulọ awọn ololufẹ idije liigi ilẹ Gẹẹsi loni nigba ti ifẹsẹwọnsẹ laarin Watford and Liverpool pari loni.
Esi ifẹsẹwọnsẹ ọhun kii ṣe ohun ti ọpọ lero ṣugbọn lẹyin o rẹyin goolu mẹta si odo ni Watford fi na Liverpool.
Sagamu: Ìkọlù wáyé bí ará ìlú ṣe gbéná wòjú ọlọ́pàá torí ikú agbábọ́ọ̀lù
Ẹ̀ṣẹ́ ju ẹ̀ṣẹ́ lọ! Tyson Fury d'ẹ̀ṣẹ́ bo Deontay Wilder lórí, ó gbadé WBC mọ́ ọ lọ́wọ́
Ṣé Liverpool ṣì leè tẹ̀síwájú ní ìdíje Champions league?
Onínúfùfù ni Saheed Oṣupa, ṣùgbọ́n èèyàn dáradára ni-Taye Currency
Igba akọkọ niyi ti Liverpool yoo maa fidirẹmi ni idije liigi ilẹ gẹẹsi lati ọjọ mejilelogun o le irinwo sẹyin
Ọpọ lo ti n woye pe Liverpool yoo pa akọsilẹ ti ẹgbẹ agbabọọlu Arsena fi lelẹ ni saa liigi ọdun 2004 si 2005 nigba ti wọn gba ifẹsẹwọnsẹ mọkandinlaadọta lai fidirẹmi.
Omidan jáde láyé lẹ́yìn tí ìlú lù ú, jáa sí ìhòhò lórí ẹ̀ṣẹ̀ tí kò ṣẹ̀
Ifẹsẹwọnsẹ mẹrinlelogoji ni Liverpool ti gba laifidirẹmi ṣaaju ifẹsẹwọnsẹ pẹlu Watford loni eyi to fihan pe wọn yoo ni lati duro fun saa liigi miran ki wọn to lee pa akọsilẹ naa rẹ.
Yatọ si eyi, ifẹsẹwọnsẹ mejidinlogun ni Liverpool ti gba ti wọn si ti bori ni ṣisẹntẹle lẹyin ti wọn ti ta ọmi pẹlu Manchester city.
Bakan naa, oni yi gan naa lo pe ọdun kan o din ọjọ mẹta ti Liverpool ti gba ifẹsẹwọnsẹ liigi lai gba goolu wọle.
Ismaila Sarr lo kọkọ gba goolu wọle ni igba ti ifẹsẹwọnsẹ naa wọ iṣẹju kẹrinlelaadọta ati ọgọta, ki Troy Deeney to fọba lee ni igba ti o wọ iṣẹju kejilelaadọrin
Restructuring: Obasanjo gbóṣùbà fáwọn gómìnà ilẹ̀ Yorùbá lórí àgbékalẹ̀ Amotekun
Oríṣun àwòrán, Olusegun Obasanjo
Aarẹ ana ni Naijiria, Oloye Olusegun Obasanjo ti kesi awọn asaaju lati tete tẹti si igbe ọpọ ọmọ Naijiria to n pe fun eto atunto orilẹede yii, ko to di pe wọn n se amusẹ rẹ funra wọn.
Oloye Olusegun Obasanjọ pe ipe atunse yii nilu Eko lasiko akanse eto idanilẹkọ kan ti wọn se niranti asaaju ẹgbẹ agbarijọpọ ọmọ bibi Oodua, Oloye Frederick Fasheun.
Obasanjọ wa fi ewe ọmọ mọ awọn ọmọ aarẹ Naijiria, Muhammadu Buhari leti pe to ba kọti ikun si atunse ati atunto orilẹede wa lasiko yii, afaimọ ki omi ma ti ẹyin wọ igbin lẹnu, tori yoo lẹyin, bii oku iya jọjọ.
Bakan naa ni Obasanjo n fika hanu lori ipo to mẹhẹ ti eto aabo Naijiria wa bayii, pẹlu afikun pe se ni eegun ẹyin ikọ afẹjẹwẹ Boko Haram n le si lati ọdun mejila sẹyin, kaka ki ewe agbọn wọn si dẹ, ko ko ko lo n le si.
O ni orilẹede yii ko tun lee bọ sinu ogun abẹle miran lasiko yii nitori pe ko ni lee bọ ninu rẹ bii ti akọkọ, ina eesi ko si tun yẹ ko jo Naijiria lẹẹkeji nidi ogun abẹle.
Hero Tortoise: Ìjàpá 14 ni wọn yà sọ́tọ̀ láti bí Ìrère 2000, kí ìran wọn má baà parun
Obasanjọ wa se kare, mo gba fun yin si awọn gomina to wa nilẹ Yoruba fun agbekalẹ eto alaabo Amotekun, pẹlu afikun pe ko si ẹkun kankan ni Naijiria ti yoo lagbara lati da ẹkun miran to ba fẹ yapa duro, tijọba ko ba tete wa nkan se nidi eto atunto orilẹede yii.
Coronavirus: Adeboye ní àsìkò yìí lá mọ ẹni tó ń sin Ọlọ́run ní òtítọ́ àti òdodo
Oríṣun àwòrán, pastoreaadeboyeofficial
Olusọagutan fun ijọ Redeem, RCCG, Pasitọ Enoch Adejare Adeboye ti fọwọ gbaya pe arun Coronavirus ko lee ran awọn ọmọ ijọ oun to ba sin Ọlọrun deede.
Olusọagutan Adeboye fọwọ idaniloju naa sọya ninu fidio kan to fi soju opo Instagram rẹ, pastoreaadeboyeofficial, eyi to fi n ba awọn ọmọ ijọ rẹ sọrọ lori idi ti wọn fi gbọdọ sun mọ Ọlọrun lasiko yii.
Alufa ijọ RCCG naa wa tọkasi ẹsẹ bibeli kan, Orin Dafidi ori kọkanlelaadọrun, ẹsẹ ikinni to ni, ẹni to n joko nibi ikọkọ ọga ogo, yoo maa gbe abẹ ojiji Olodumare, to si ni eyi ni yoo jẹ ipin awọn ọmọ ijọ oun.
Adeboye, ẹni to rọ awọn ọmọ ijọ naa  pe, ki wọn sin Ọlọrun ju ti tẹlẹ lọ, ki wọn maa jere ọkan, ki wọn si maa da ijọ silẹ si , wa salaye pe, asiko yii ni Ọlọrun yoo se iyatọ laarin awọn to n sin-in lotitọ ati lododo, yatọ si awọn ti ko sin.
Oríṣun àwòrán, pastoreaadeboyeofficial
Bakan naa lo sọ fun wọn pe gbogbo adura wọn lasiko yii ti ijọ naa wa ninu aawọ ati adura, ni Ọlọrun yoo gba, ti yoo si fun wọn ni ẹri to pọ, yoo maa gbe wọn ga latinu ogo bọ sinu ogo nitori oun ti ke pe Ọlọrun nitori wọn.
Mo fẹ fi da yin loju pe ko si kokoro arun kankan ti yoo sun mọ sakani yin. Mo gbagbọ pe asiko yii ni Ọlọrun yoo fihan wa gbangba pe iyatọ wa laarin awọn to ba n sin-in tọkantọkan ati awọn to kẹyin si.
Dan Price: Mò ta ilé méjì, dín owó oṣù mi kù pẹ̀lú $1m láti leè sanwó oṣù gọbọi fáwọn òṣìṣẹ́ mi
Oríṣun àwòrán, Gravity
Ohun to kọju s'ẹnikan, Yoruba bọ wọn ni ẹyin lo kọ si ẹlomiran.
Eyi lo difa fun arakunrin kan lorilẹede Amẹrika to jẹ oludari ileeṣẹ kaadi isanwo Gravity Payments, to buwọlu sisan owo oṣu to kere ju, tii ẹgbẹrun lọna aadoje dọla, gẹgẹ bi owo oṣu to kere julọ fawọn osiṣẹ rẹ.
Lọdun 2015 lo gbe igbesẹ yii lori ọgọfa osisẹ to n ṣiṣẹ labẹ rẹ, ti oun gan alara si yọ miliọnu kan dọla kuro ninu iye owo oṣu rẹ.
Lẹyin ọdun marun to gbe igbesẹ yii, o ṣi n san owo yii fawọn oṣiṣẹ rẹ lai yẹ kuro lori rẹ.
Ohun to mu Dan Price ṣe bẹẹ ni igba to mọ pe ọkan lara awọn oṣiṣẹ rẹ, Valerie ko ri owo ile rẹ san, ọkunrin naa si jẹ alakikanju oṣiṣẹ labẹ rẹ.
Iṣẹlẹ yii mu inu bi Dan Price, to si bẹnu atẹ lu bi ile aye ko ṣe rọrun fawọn eeyan kan. Lẹyin to kọminu lori ọrọ yii, o ri pe oun gan wa lara awọn ti ko mayedẹrun fawọn eeyan.
Toun ti pe Dan jẹ olowo tabua, ohun to ṣẹlẹ si oṣiṣẹ rẹ Valerie yii lo ṣe okunfa bo ti ṣe mọ pe awọn ti nkan ko dẹrun fun pọ lawujọ.
Idi re e ti Price fi pinnu lati mu alekun ba iye owo oṣu awọn to n ṣiṣẹ labẹ rẹ, ni ileeṣẹ Gravity Payments.
Lẹyin to ṣe atupalẹ iye owo ti yoo mu eeyan gbe igbe aye igbadun l'Amẹ́rika, Dan pa ọkan pọ pe ẹgbẹrun lọna aadọrin ni yoo to lowo oṣu to kere julọ fawọn osisẹ oun.
O ni eleyi mu adinku ba owo oṣu oun gan funra ara oun, ti oun si ta ile oun mejeeji. Igba to ṣe awọn eto wọn yii tan, lo ba fi ọrọ to awọn oṣiṣẹ rẹ leti.
Lati igba to si ti gbe igbesẹ yii, ida mẹwa ninu ida ọgọrun awọn oṣiṣẹ rẹ lo ti nile lori, yatọ si ida kan wọn to nile lori tẹlẹ, ki o to fi owo kun owo osu wọn.
Ni bayii, Price ti di ajafẹtọ ẹni to n polongo nipa ibadọgba igbe aye laarin awọn eeyan nilẹ Amẹrika.
PDP: Buhari, O ṣeé dá pẹlú bí ko ṣé sọ̀rọ̀ nípa Coronavirus
Oríṣun àwòrán, Pius Utomi Ekpei
Ẹgbẹ oṣelu alatako lorileede Naijiria Peoples Democratic Party ti bẹnu atẹ lu aarẹ Muhamadu Buhari pẹlu bi ko tiṣe ti sọrọ nipa aisan Corona Virus to wọ Naijiria.
Akọwe ipolongo ẹgbẹ naa, Kola Olongbondiyan ni aifini peni, aifeeyan peeyan ni iwa yi jẹ bi aarẹ ko ti ṣe ti ba awọn ọmọ Naijiria sọrọ.
Ninu atẹjade to fi sita loju opo Twitter ẹgbẹ naa, Ologbondiyan ni ijakulẹ lọwọ aṣaaju gba ni o jẹ bi aarẹ ti ṣe dakẹ lori ọrọ yi.
''Ẹgbẹ PDP parọwa si aarẹ lati taji ki o si mu ọrọ CoronaVirus yi bo ti ṣe yẹ nitori ewu nla lo n bọ yi to gba ki aarẹ doju ija kọ''
Ologbondiyan fi kun ọrọ rẹ pe ti aarẹ ba ba awọn ọmọ Naijiria sọrọ, yoo fi ọkan ọpọ eeyan balẹ.
Loju opo Twitter aarẹ Buhari lootọ, ko ti si ọrọ to ni ṣe pẹlu aisan Corona Virus yi ṣugbọnagbẹnusọ ileeṣẹ aarẹ Garba Shehu ni tiẹ da si ọrọ yi.
Ninu ọrọ rẹ, Garba Shehu ṣemọ bi awọn iwe iroyin Naijiria ti ṣe mu ọrọ Coronavirus nikan bẹnu nigba ti aisan iba n gbẹmi ọpọ eeyan lojumọ ni Naijiria.
Ọrọ rẹ yi mu esi orisirisi wa lati ọdọ awọn ọmọ Naijiria
Pa Kasunmu: Kayode Odumosu,papòdà lẹ́ni ọdún mẹ́tàdínláàdọ́rin
Oríṣun àwòrán, Twitter
Gbajugbaja oṣere tiata  Kayode Odumosu ti gbogbo eeyan mọ si Pa Kasumu ti dagbere faye.
Lọjọ Aiku ni aarẹ awọn oṣere tiata Yoruba Naijiria Bolaji Amusan Mr Latin fidi ọrọ naa mulẹ fun ileeṣẹ BBC Yoruba.
O ti to ọjọ mẹta ti aisan  ti n ba Pa Kasunmu finra.
''Eeyan daada ni wọn yatọ si pe wọn jẹ oṣere tiata.Iku wọn jẹ eleyi to fi ọwọ kan wa lẹmi''
Yatọ si Mr Latin awọn oṣere miran bi Foluke Daramola ti fi ikede iku Pa Kasumu i oju opo wọn ni Instagram pẹlu ọrọ ikẹdun iku rẹ.
Ọjọ kẹrindinlogun oṣu Kẹta ọdun 1953 ni wọn bi Kayode Odumosu ni ilu Ibadan.
Ọmọ Odogbolu ni  ipinlẹ Ogun ni a gbọ pe Baba rẹ jẹ ti iya rẹ si jẹ ọmọ Abeokuta.
O ti kopa ninu ọpọ ere sinima ti awọn eeyan si mọ gẹgẹ bi ogbontarigi ninu awọn adẹrinposonu ere tiata lede Yoruba ati Gẹẹsi.
Oman Returnees: Ọ̀kan lára àwọn obìnrin méjì náà ní òun ṣiṣẹ́ ọdún kan láì mú ₦5 padà wálé
Oman Returnees: Ọ̀kan lára àwọn obìnrin méjì náà ní òun ṣiṣẹ́ ọdún kan láì mú ₦5 padà wálé
Awọn obinrin meji ree ti wọn lọ fi wọn sọfa ni orilẹede Oman, nibi ti oju wọn ti ri mabo.
Damilola Falodun ati Oyinlola Solanke ni ko rọrun lati ni ominira ni Oman lai jẹ pe obinrin ba ọga rẹ sun, ti awọn mejeeji si salaye itu ti awọn ọga wọn fi wọn pa lọhun.
Bakan naa ni wọn fẹsun kan ọpọ awọn osisẹ asọbode to wa ni papakọ ofurufu Naijiria pe, wọn n lẹdi apo pọ mọ awọn to n ko awọn obinrin lọ sowo ẹrun lawọn orilẹede Larubawa.
Ẹkunrẹrẹ ohun ti oju awọn obinrin mejeeji naa ri ni orilẹede Oman ree.
Producer: Yemisi Oyedepo àti Bayo Odukoya
Anthony Olatunfe: Ọlọ́pàá ní Pásítọ̀ náà ta fóónù ẹni tí wọn ń wá ní ₦1,500
Oríṣun àwòrán, @PoliceNG
Akẹkọ ileẹkọ fasiti agbele-gboye (Open University) kan, Anthony Olatunfe di awati logunjọ osu kejila ọdun 2019, lasiko ti wọn ran nisẹ lọ si Ilupeju.
Kọmisana ọlọpa nipinlẹ Eko, Hakeem Odumosu si ti pasẹ pe ki wọn tanna wadi isẹlẹ naa, to si ti fa iwadii ọhun le ẹka to n gbogun ti iwa idigunjale labẹ ileesẹ ọlọpa, SARS lọwọ.
Baba Anthony, Augustine Olatunfe, lo ke gbajare lọ si ọdọ amugbalẹgbẹ gomina ipinlẹ Eko kan, ti ọmọ naa n ba sisẹ pe, oun ko ri ọmọ oun nile, ti onitọun si fi ọrọ yii to awọn ọlọpa leti.
Atẹjade kan ti osisẹ alarena ileesẹ ọlọpa nipinlẹ Eko fisita lọjọ Aiku ti salaye pe, gbogbo aayan awọn lati se awari Anthony lo ja si pabo amọ awọn ti tọpinpin ẹrọ ibaraẹnisọrọ rẹ lati mọ ibi to wa.
Oríṣun àwòrán, @sportingshina
Eyi si lo mu ki wọn sawari pe, foonu naa wa lọwọ obinrin kan, Monsurat Gbadegẹsin, ẹni ọdun mẹtalelogun. Lasiko to n salaye fawọn ọlọpa, ni obinrin naa ti jẹwọ pe ọkọ afẹsọna oun, Abiodun Abiola lo fun oun ni foonu naa, ti wọn si lọ gbe Abiola pẹlu.
Abiola ni ọkunrin kan, Tolu Olurotimi lo ta foonu naa fun oun, ti wọn si gbe ọkunrin ọhun, ẹni to jẹwọ pe ọwọ Pasitọ ijọ Sẹlẹ kan, Ejiro Ologonla loun ti ra foonu naa. Idi si ree tawọn ọlọpa fi gbe pasitọ yii.
Atẹjade naa ni, lasiko ti wọn n fọrọ wa Ologonla lẹnu wo lo ti n ka pe, lootọ ni oun pade Anthony to sọnu yii leti okun, to si ti yo fun ọti lile, to si n le awọn eeyan kiri eti okun naa.
Oríṣun àwòrán, Others
Lẹyin naa lo ni oun ri Anthony yii, to n bọ asọ to wa lọrun rẹ, bata ẹsẹ rẹ, ati foonu ọwọ rẹ silẹ, ko to gun ọkọ oju omi awọn apẹja kan, to si lọ sori agbami okun, nibi to ti bẹ sinu okun.
Ologonla ni wọn lo sọ pe, oun fi ọrọ naa to awọn agbofinro to wa leti okun leti, toun si tun pe awọn ọlọpa lori aago lati fi isẹlẹ naa to wọn leti.
Amọ sa, lẹyin o rẹyin ni oun ko asọ, bata ati foonu Anthony lọ sile, ti oun si ta foonu rẹ fun Tolu Olurotimi ni ẹẹdẹgbẹjọ (₦1,500) naira.
Oríṣun àwòrán, @PoliceNG
Ileesẹ ọlọpa sọ pe, gbogbo awọn eeyan ti pasitọ naa darukọ pe oun sọ fun nipa Anthony to wọ okun lọ, ni wọn ko ri ohun kankan to giriki sọ nipa isẹlẹ naa, tawọn agbofinro to wa leti okun si ni ọkunrin naa ko fi isẹlẹ ọhun to awọn leti rara.
Oman Returnees: Ọ̀kan lára àwọn obìnrin méjì náà ní òun ṣiṣẹ́ ọdún kan láì mú ₦5 padà wálé
Awọn asọ ati bata ẹni to sọnu naa la ri nile Pasitọ. Lootọ si ni a fidi rẹ mulẹ pe Anthony lọ si eti okun Oniru, ko to di pe o di awati, Pasitọ Ologonla si ni ẹni to ri i kẹyin, bẹẹ ni a ko lee sọ boya ọkunrin ta n wa yii wa laaye abi o ti ku, ti gbogbo ẹri to wa niwaju wa si n fihan pe, Pasitọ naa mọ nkan nipa bi Anthony se di awati.
Coronavirus: Mínísítà ní àwọn èèyàn tí wọ́n kó pamọ́ ní Eko àti Plateau kò ní àrùn náà
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Minisita fun eto ilera, Osagie Ehanire ti sọ pe, awọn ọmọ orilẹ-ede China mẹrin ti wọn  ko pamọ fun itọju arun Coronavirus nipinlẹ Plateau, ko ni arun naa.
Osagie sọ fun awọn akọroyin nibi ipade ita gbangba  kan to waye n ilu Abuja pe, ko si ẹnikẹni lara awọn eeyan naa to ni arun ọhun, lẹyin ti wọn ṣayẹwo wọn ni ileeṣẹ ijọba to n ṣetọju arun, NCDC.
Ṣaaju ni ijọba ipinlẹ Plateau ti kede pe, o ṣeṣe ki awọn eeyan naa ni arun Coronavirus lẹyin ti wọn de si Naijiiria lati China, to si fi wọn si apamọ fun ayẹwo.
O tẹsiwaju pe, ipinlẹ naa ti fi awọn ọmọ orilẹ-ede China ọhun sabẹ itọju, nibi ti awọn eleto ilera yoo ti bojuto wọn fun ọjọ mẹrinla fun ayẹwo siwaju sii.
Ẹwẹ, Osagie ni ko tii si ẹni kankan to tii lugbadi Coronavirus ninu gbogbo awọn eeyan to ṣabapade okunrin ọmọ orilẹ-ede Italy, to ko arun ọhun wọ Naijiria nilu Eko.
"O ni ""Gbogbo awọn eeyan to pade ẹni naa ni ipinlẹ Eko ati Ogun ni wọn ti n gba itọju lọwọ, ṣugbọn ko tii si ẹnikẹni lara awọn eeyan naa to tii lugbadi arun naa."""
Oríṣun àwòrán, @InsideOjodu
Minisita ọhun wa rọ awọn ọmọ Naijiria lati mase bẹru lakoko yii, nitori ijọba apapọ n ṣe gbogbo ohun to yẹ lati ri pe arun naa ko tan kalẹ ju bo ṣe yẹ lọ.
Lẹyin naa lo rọ awọn ọmọ Naijira lati mu imọtoto ni pataki, lati maa fọ ọwọ wọn pẹlu ọsẹ, ati lati jina rere ni nnkan bii iwọn eṣẹ bata marun, si ẹni to ba nsin tabi wukọ layika wọn.
Oman Returnees: Ọ̀kan lára àwọn obìnrin méjì náà ní òun ṣiṣẹ́ ọdún kan láì mú ₦5 padà wálé
Osagie pari ọrọ rẹ pe, ki awọn eeyan maa bo imu ati ẹnu wọn pẹlu igbọnwọ, ki wọn si rọ awọn eeyan to ba sun mọ wọn lati ṣe bẹẹ pẹlu.
Gómìnà Oyetọla tí yi ìlànà ètò ẹ̀kọ Rauf Aregbesola pada
Oríṣun àwòrán, Others
Gómìnà Oyetọla tí yi ìlànà ètò ẹ̀kọ Rauf Aregbesola pada
Lọ́sẹ to kọja ni àwọn ọmọ igbimọ ti gomina ìpinlẹ̀ Osun Gboyega Oyetola gbékalẹ̀ láti ṣe àyẹwo àwọn ìlànà èto ẹkọ gomina àná Rauf Aregbẹsọla, gbé àbájade ìwádìí wọ́n wá.
Abájáde náà nàka si àwọn koko mẹ́rìnlélógun gbòógi to nílò sàgbéyẹwò eyi to fi mọ mímú àyípada ba wíwọ aṣọ ilé iwé kan náà jákejádo gbogbo ìpínlẹ̀ Osun.
Ẹ̀wẹ̀, lọ́nìí ọjọ keji, oṣù kẹta ọdun yìí ni gómìnà lásìkò ìpàdé ìgbìmọ aláṣẹ́ ìjọba ni wọ́n ti pa ohùn pọ láti gba aba ìgbìmọ ìwádìí wọ́n wọlé, paàpàá jùlọ lóri èyi to jẹ mọ ìlàna ẹkọ ni ìpinlẹ̀ Osun.
Ti ẹ o bá gbàgbé ìgbìmọ ìwádiìí ti Gomina Gboyega Oyetola gbe kalẹ̀ ni ọjọgbọ́n Olu Aina jábọ rẹ̀ fun Gomina ni ọ̀ṣẹ̀ to kọja ti wọ́n si gba ìjọba ni ìmọ̀ràn láti dá ìwọ̀sọ àwọn akẹkọọ pada si bi wọ́n se wà tẹ́lẹ̀.
Wọ́n fi kun pe o ṣe pataki ki wan pada si ìlàna ẹkọ 9-3-4 gẹ́gẹ́ bi àwọn onímọ ètò ẹkọ ṣe gbé kalẹ̀.
Pa Kasumu: Lere Paimo ní àìrìríjẹ́, àìrímú tàbí ìrònú má a ń jẹ́ kí ọjọ́ ogbó dagun
Coronavirus: Ètò Làá hàn mí yìí ló ń kìlọ̀ fún wa láti mú ìmọ́tótó ní pàtàkì, ká le è dènà Coronavirus
Làá hàn mí: Ètò yìí ló ń kìlọ̀ fún wa láti mú ìmọ́tótó ní pàtàkì láti dènà Coronavirus
Yoruba ni igi gogoro ma gun mi loju, ati okeere laa ti lọ̀, bẹ́ẹ́ si ni ati okeere ni oloju jinjin ti n mu ẹ́kun sun.
Idi ree ti BBC Yoruba, lori eto Laa han mi se n la wa lọyẹ lori awọn ohun to yẹ́ ka se lati dena itankalẹ arun Coronavirus.
Eto naa gba wa nimọran lati yẹra fun ọpọ ero, ka mu imọtoto ni pataki, ka maa se ounjẹ wa jinna daadaa, ka si joko sile, ti ara wa ko ba da.
Ẹ wo fidio yii lati mọ si nipa arun asekupani Coronavirus ati ba se lee bọ lọwọ rẹ.
UCH: Olùdarí ilé ìwòsàn náà ń bẹ̀bẹ̀ fún ìrànwọ́ àwọn ẹlẹ́yinjú àànú láti borí ìṣòro owónàá
Oríṣun àwòrán, UCH
Awọn alasẹ ile iwosan ẹkọsẹ isegun fasiti Ibadan, UCH ti figbe bọnu pe ara ko rọ okun, bẹẹ ni ko rọ adiẹ nile iwosan naa, nitori ẹrọ amunawa to to marundinlọgọrin ni wọn n lo lati sisẹ isegun.
Oludari eto isegun nile iwosan naa, Ọjọgbọn Jesse Abiọdun Ọtẹgbayọ lo sisọ loju ọrọ yii nibi eto kan ti wọn fi n sami ayẹyẹ ọdun kan rẹ lọọfisi.
Ọtẹgbayọ ni isoro nla kan gboogi to n ba ibudo ẹkọsẹ isegun Oritamẹfa naa finra ni aisi ina ọba to duro re, bẹẹ si ni ipenija nla ni eyi jẹ fun iwadi imọ isegun, idanilẹkọ ati ipese iwosan to ye kooro.
Oríṣun àwòrán, UCH
A maa n pa owo to to igba miliọnu naira wọle losoosu, ko si yẹ ka foju fo eyi pẹlu iye ta n na lori epo disu, atunse awọn ẹya ara jẹnẹratọ ta n lo ati owona lori awọn eroja miran ta nilo fun isẹ wa. Mo si lee ni owo yii ko to na rara, o si se ni laanu pe a ni awọn ẹlẹyinju aanu lawujọ to lee fun wa lẹbun owo lati fi kun owo ta n pa wọle.
Oríṣun àwòrán, UCH
Bakan naa ni oludari eto isegun ni UCH salaye pe ipese ina ọba jẹ pataki si awọn nitori bo ti se pataki to fun ipese eto ilera ti wọn n se, paapa fun isẹ fawọn abẹ alaisan.
Afojusun wa ni lati pese awọn imọ ẹrọ to lee se awari ọpọ arun to n tan kalẹ lorilẹede Naijiria, ka si se agbende iwosan aisan ọkan ta n se tẹlẹ, eyi ta ti pa ti tẹlẹ, pada. Bakan naa la fẹ ri daju pe iwosan aisan kidinrin taa yọ lati ara ẹnikan fun ẹlomiran, eyi taa se laipẹ yii, n tẹ siwaju.
Làá hàn mí: Ètò yìí ló ń kìlọ̀ fún wa láti mú ìmọ́tótó ní pàtàkì láti dènà Coronavirus
Amọ o wa fi ika hanu pe laisi ipese ina ọba to jiire, wahala lee de, tabi ki ohun gbogbo dẹnu kọlẹ ti awọn ẹrọ amunawa tawọn n lo ba bajẹ, nitori aisi ipese ina ọba to ye kooro.
Amotekun: Àwọn aṣòfin Oyo fí aṣọ́ Amotekun, ìfúnpá àti gbérí ọdẹ́ buwọ́lu àbádòfin Amotekun
Bi iṣẹ ko ba pẹni ẹnikan kii pẹ'ṣẹ, ni awọn ile asofin ipinlẹ Oyo ati Ogun fi bibuwọlu abadofin idasilẹ Amọtẹkun ṣe.
Lọjọ iṣẹgun yii ni awọn mejeeji joko jiroro lori abadofin naa, ti wọn si buwọlu ofin to gbe idasilẹ ikọ alaabo naa silẹ nipinlẹ wọn.
Ṣaaju asiko yii ni awọn ijọba ilẹ kaarọ o jiire ati ijọba apapọ ti fẹnu ko si pe, ki awọn ipinlẹ kọọkan pada lọ fi ofin gbe idasilẹ Amọtẹkun silẹ ni ipinlẹ wọn.
Yatọ si ipinlẹ Eko ti o mu atunṣe ba ofin to ṣe idasilẹ ikọ alaabo Neighbourhood Watch, ti o ti wa nilẹ tẹlẹ, awọn ipinlẹ to ku ṣẹṣẹ bẹrẹ igbesẹ lati fi ofin de idasilẹ Amọtẹkun lagbegbe  wọn ni.
N ṣe ni awọn aṣofin ile aaṣofin Oyo ko anko wọ aṣọ to jọ awọ Amọtẹkun, wa si ile lati le fi ifarajin wọn han lori sisọ abadofin yii di ofin.
Bẹrẹ lati olori ile to fi dori awọn aṣofin to ku, bi wọn ti ṣe n wọ dansiki, lawọn miran de gberi ọdẹ sori.
Koda agbọpa ile gan ko gbẹyin, ti oun naa si fi asọ amọtẹkun gbe ọpa ile lọwọ, ti wọn si tun wọ ifunpa si apa wọn.
Strongest Teeth: Tajudeen ní èèyàn ló kù tí òun fẹ́ máa fi eyín gbé
Strongest Teeth: Tajudeen ní èèyàn ló kù tí òun fẹ́ máa fi eyín gbé
Ara kii tan nile alara, bẹẹ si ni ẹni ti ko ba de oko baba ẹlomiran ri, ni yoo ni oko baba oun lo tobi ju.
Ọkunrin kan ree, Tajudeen Olisa, ti wọ̀n n pe ni Taju Eleyin idan, to n lo eyin rẹ lati maa gbe awọn ẹru to wuwo bii apo irẹsi nla, ẹrọ amunawa jẹnẹratọ, tabili meji papọ, ati simẹnti, to si tun n fi eyin rẹ yii si agolo nla bii ọbẹ.
Lasiko to n ba BBC Yoruba sọrọ, Tajudeen, ẹni to ni eeyan lo ku fun oun bayii lati gbe, tun fikun pe, oun ko lo oogun ibilẹ rara, lati mu ki eyin oun lee ni agbara lati gbe ẹru to ba wuwo.
Producer Yemisi Oyedepo ati Bayo Odukoya
Gbajabiamila: Mò ń ṣe ọjọ́ ìbí fún màmá mi ní Dubai àmọ́ kìí ṣe owó ìlú ní mo ń ná
Oríṣun àwòrán, @femigbaja
Olori ile asoju-sofin, Femi Gbajabiamila ti mu igbe bọnu pe kii se owo ilu ni oun fi lọ silu Dubai lati se ọjọ ibi fun iya oun.
Atẹjade kan ti amugbalẹgbẹ Gbajabiamila feto iroyin, Lanre Lasisi fisita wa salaye pe, kikida awọn mọlẹbi ati ọrẹ timọtimọ nikan ni wọn ko lọ sibi ayẹyẹ naa, ti wọn ko si to ọọdunrun niye, gẹgẹ bi iroyin kan ti sọ.
Lootọ ni olori ile asofin ati awọn mọlẹbi rẹ wa ni Dubai lati se ayẹyẹ ọjọ ibi mama agba, Alhaja Lateefat Olufunkẹ Gbajabiamila to pe ẹni aadọrun ọdun loke eepẹ, mama naa si ni iya lori ile asoju-sofin nilẹ wa.
"A si fẹ fi da yin loju pe ko si oloselu tabi asofin kankan nilẹ wa to peju sibi ayẹyẹ naa, kikida awọn mọlẹbi ati ọrẹ timọtimọ lo wa nibẹ, ti a ko si lo owo ilu kankan.
Strongest Teeth: Tajudeen ní èèyàn ló kù tí òun fẹ́ máa fi eyín gbé
Laipẹ yii ni iroyin naa gbalẹ pe tijo tilu ni olori ile asoju-sofin fi se ayẹyẹ ọjọ ibi mama rẹ nilu Dubai, eyi ti wọn lo bẹrẹ ni ọjọ keji osu kẹta ọdun yii, ti yoo si pari ni ọjọ kẹwa osu kẹta yii kanna.
Iroyin naa ni, o seese ki Gbajabiamila na to miliọnu lọna ẹẹdẹgbẹta naira lori ayẹyẹ naa, ta ba wo iye awọn eeyan to ko lẹyin lọ sibẹ.
APC: A kò ní takò ìdájọ ilé ẹjọ lórí àṣẹ lọ rọọ́kún nílé Oshiomole
Oríṣun àwòrán, Google
Ọrọ aṣẹ lọrọọkun nile ti ile ẹjọ pa fun alaga ẹgbẹ oṣelu APC ma tun ti gba ọna mi yọ pẹlu bi Adams Oshiomole ti ṣe sọ pe ohun ṣi ni alaga ẹgbẹ naa.
Ninu ọrọ atẹjiṣẹ ti agbẹnusọ Oshiomole Simon Egbegbulem fi ranṣẹ si akọroyin wa, o ni awọn ti kọwe kotẹmilọrun lati tako idajọ naa.
O ni toun ti bi gbogbo igbeṣẹ ti ṣe n lọ ni iwaju ile ẹjọ kotẹmilọrun, Adams Oshiomole ṣi ni alaga ẹgbẹ naa.
Ẹwẹ, ẹgbẹ oṣelu All Progressives Congress APC ti fesi si aṣẹ ile ẹjọ giga Abuja to ni ki alaga ẹgbẹ naa Adams Oshiomole lọ rọọkun nile.
Adele akọwe ẹgbẹ naa Victor Giadom lo fidi ọrọ yi mulẹ ninu ifọrọwerọ pẹlu BBC.
Giadom ni ẹgbẹ awọn yoo bọwọ fun aṣẹ ti ile ẹjọ pa pe ki Oshiomole yẹba ṣẹgbẹ kan titi ti wọn yoo fi gbẹjọ lori yiyọ nipo.
Oríṣun àwòrán, Jubril A. Gawat
Ọpọ onwoye gbagbọ pe omi n bẹ lamu fun Oshiomole lori iṣọkan ẹgbẹ oṣelu naa
Nigba ti akọroyin wa beere lọwọ Giadom nipa iroyin to n ja rain pe awọn agbofinro ti wa ọkọ gunlẹ niwaju oluileeṣẹ ẹgbẹ naa ni Abuja, o ni ko si ohun to jọ bẹ.
''Ko si iyatọ ninu nkan to n ṣẹlẹ niwaju ile ẹgbẹ.Bi ibẹ ti ṣe ma n ri ni gbogbo igba ni yẹn''
Ni ọjọru kannna ti awuyewuye lori aṣẹ lọ rọọkun nile Oshiomole n waye, akọwe ipolongo ẹgbẹ Lanre Issa Onilu ti fi atẹjade sita pe ẹgbẹ ti fontẹ lu awọn oloye apapọ ẹgbẹ mẹta tuntun.
Ninu wọn la ti ri Gomina ipinlẹ Oyo tẹlẹ ri Senatọ Abiola Ajimobi ti wọn yan si ipo igbakeji alaga ẹgbẹ fun Iwọ oorun Guusu.
Oríṣun àwòrán, @AAAjimobi
Abiola Ajimobi
Bẹẹ naa ni wọn ni Arch Waziri Bulama ni yoo jẹ akọwe ẹgbẹ ti Paul Chukwuma yoo si jẹ oluyẹweowowo ẹgbẹ.
Ile ẹjọ giga kan to fi ilu Abuja ṣe ibujoko ti paṣẹ pe ki alaga ẹgbẹ oṣelu All Progressives Congress, APC,Adams Oshiomole lọ rọọkun nile.
Adajọ Danalami Senchi to fi idajọ yii mulẹ ni ki Oshiomole fi ipo alaga silẹ fun igba diẹ, titi ti awọn yoo fi yanju ẹjọ tawọn kan pe lati yọ ni ipo alaga ẹgbẹ naa.
Adajọ niigbẹjọ ọrọ yi yoo waye lọjọ keje ati ikẹjọ oṣu Kẹrin ọdun 2020.
Lẹnu ọjọ mẹta yii, awuyewuye ti n waye lori iṣakoso Oshiomole gẹgẹ bi alaga ẹgbẹ naa ni Naijiria.
Bi a ko ba gbagbe awọn alaga ẹgbẹ naa ni ipinlẹ Edo, ti o jẹ ipinlẹ Oshiomole ti sọ pe, awọn ko ni igbagbọ ninu iṣakoso Oshiomole gẹgẹ bi alaga ẹgbẹ.
Yatọ si aawọ pẹlu awọn alaga wọn yii, awọn Gomina kan ninu ẹgbẹ APC naa ko yọnu si Oshiomole gẹgẹ bi alaga.
#Oshimole: Àwọn aṣáájú APC kò mọ ohun ti wọ́n n ṣe lásìkò yí
Titi di bi a ti ṣe n ṣe akojọ iroyin yi, ẹgbẹ APC ko ti fesi si idajọ ti ile ẹjọ yi gbe kalẹ.
Boko Haram: Afurasí agbébọn tó lè ní 300 ní àríwá Nàìjíríà gbà itusilẹ lọ́wọ́ ológun
Oríṣun àwòrán, Nigeria army/Facebook
Iko ologun
Awọn ọmọde okoolenigba ati mẹta ti mẹwa ninu wọn jẹ obinrin lo ti gba itusilẹ kuro lọgba ẹwọn Maiduguri lati ọdọ ileeṣẹ ologun Naijiria.
Igbesẹ yi waye lẹyin ti wọn ri aridaju pe wọn ko ni ohunkohun niṣe pẹlu awọn ẹgbẹ agbesunmọmi lagbegbe naa.
Ninu atẹjade kan ti BBC ri gba lati ọwọ ajọ to n risi eto ẹkọ awọn ọmọde labẹ ajọ isọkan agbaye,UNICEF, ileeṣẹ ologun fa awọn to gba itusilẹ yi le ileeṣẹ to n risi ọrọ obinrin ati idagbasoke ni Maiduguri ati awọn oṣiṣẹ UNICEF lọwọ.
Lara awọn ọmọ wọn yi la ti ri awọn ti o ti sọnu to bi ọdun mẹrin si marun un tawọn mọlẹbi si rope wọn ti ku ti pẹ.
''Itusilẹ awọn ọmọ yi gẹgẹ bi ohun ti Peter Hawkins aṣoju  UNICEF sọ jẹ ''igbesẹ nla to dun mọ wa ti o si yẹ ki a dunnu si''
O tẹsiwaju pe '' o y ki awọn ọmọde wọn yi ni igbeaye ti ko ni wahala ninu ati pe bayi o yẹ ki a fun wọn ni itọju to peye lẹyin ti ikọlu to waye mu idiwọ ba igbe aye wọn''
O ti pe ọdun mẹwa bayi ti ikọlu Boko Haram ti n waye lariwa Naijiria ti eleyi si ti mu inira ba igbe aye ọgọrọ awọn eeyan lagbegbe naa.
Pupọ ninu awọn to ba kuro lọwọ ologun bayi a ma gba idanilẹkọ ni ile atọnisọna Bulumkutu Rehabilitation Center ni Maiduguri ti wọn a si pada ronupiwada ki wọn to  daramọ awọn mọlẹbi wọn.
Lati ọdun 2016, eeyan to le ni gbẹrun mẹta ti a ri ọmọde to fẹ sunmọ ẹgbẹrun meji ninu wọn (Ọkunrin 1,125,obinrin 618)
Coronavirus: Gbogbo ilé ẹ̀kọ́ alákọ̀ọ́bẹ̀rẹ̀ àti girama yóò wá ní titipá ní Italy
Oríṣun àwòrán, Reuters
Orileede Italy lawọn n gbero lati ti gbogbo ile ẹkọ ati fasiti lorileede naa pa nitori ajakalẹ aisan Coronavirus.
Erongba lati gbe igbesẹ yi waye nibi ipade kan tawọn alaṣẹ ijọba ṣe eleyi to n gbero pe ki wọn ti awọn ile ẹkọ pa titi di aarin oṣu Kẹta.
Wọn ni eleyi jẹ ọna pajawiri lati koju aisan Coronavirus to n ja kaakiri ilẹ naa.
Minisita feto ẹkọ nilẹ naa Lucia Azzolina nigba to n fesi si iroyin yi ti ọpọ ileeṣẹ iroyin ti gbe sọ pe awọn ko ti fẹnuko lori igbesẹ yi ṣugbọn awọn yoo bun wọn gbọ laipẹ.
Ẹwẹ, orileede Faranse ti ti awọn ileẹkọ to wa ni agbegbe Paris pa.
Ọgọfa ileewe ni yoo wa ni titi pa lawọn agbegbe ti ajakalẹ aisan yi ti peleke.
Oríṣun àwòrán, AFP
Ileewe alakọbẹrẹ ati awn ileewe girama lọrọ yi kan ni ariwa Paris nibi ti eeyan meji to padanu mi wọn lọwọ aisan yi n gbe.
Yatọ si Paris, orileede Saudi naa ti kede pe awọn ko ni gba nikẹni laye yala ọmọ ilu tabi alejo lati kopa ninu Umrah gẹgẹ bi ọna lati koju itankalẹ Coronavirus.
Lọsẹ to kọja ni wọn wọgile Umrah fawọn ara ita.
Lọjọ  Aje ni Saudi kede pe eeyan kan to jẹ ọmọ Saudi ni ẹni akọkọ ti yoo ko aisan naa.Arakunrin naa ririn ajo lọ si Iran nibiti ajakalẹ naa peleke julọ nilẹ larubawa.
Oshiomhole: ilé ẹjọ́ gíga míì ti tako àṣẹ ilé ẹjọ́ tó ní kí Oshiomhole lọ rọọ́kún nílé
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ile ẹjọ giga kan ni ipinlẹ Kano ti fọwọ rọ idajọ ile ẹjọ giga Abuja  to ni ki alaga ẹgbẹ APC Adams Oshiomole yẹba ṣẹgbẹ kan gẹgẹ bi alaga ẹgbẹ naa.
Bẹẹ ni adajọ Lewis Allagoa to gbe idajọ yi kalẹ paṣẹ ki ileeṣẹ ọtẹlẹmuyẹ Naijiria pese awọn ẹṣọ alaabo ti yoo tẹle Adams Oshiomole lọ si ọfiisi rẹ pada.
Lọjọbọ ni aṣẹ yi waye nilu Kano.
Wahala edeaiyede abẹle to n waye ni ẹgbẹ oṣelu to n ṣe ijọba orilẹede Naijiria, APC gbinaya gba oju opo ibomiran yọ ni Ọjọbọ nigba ti ile ẹjọ giga kan ni ilu Abuja gbe idajọ kalẹ pe ki alaga apapọ ẹgbẹ oṣelu naa, Adams Oshiomhole o yẹba naa atipe ko gbọdọ pe ara rẹ ni alaga apapọ ẹgbẹ oṣelu naa lọwọ yii titi di igba ti ẹjọ lori boya o lẹtọ lati jẹ alaga ẹgbẹ oṣelu naa yoo fi yọri.
Amọṣa Ọgbẹni Issa Onilu to jẹ alukoro apapọ fun ẹgbẹ oṣelu APC naa ṣalaye pe ki ẹnikẹni maṣe sọ pe wahala abẹle n bẹ laarin ẹgbẹ oṣelu APC.
Ninu ifọrọwerọ rẹ pẹlu BBC News Yoruba lori idajọ to yẹ aga mọ alaga apapọ ẹgbẹ oṣelu naa, Ọgbẹni Issa Onilu ṣalaye pe lootọ o lee jẹ ọmọ ẹgbẹ oṣelu naa lo gbe alaga, iyẹn Adams Oshiomhole ati ẹgbẹ oṣelu naa lọ si ile ẹjọ, sibẹ kii ṣe ọmọ igbimọ majẹobajẹ tabi igbimọ iṣakoso to ga julọ ni ẹgbẹ oṣelu naa.
O ni nipasẹ bẹẹ, a ko lee pe e ni edeaiyede abẹle lẹgbẹ oṣelu naa.
Aremu: Eré ìtàn nípa ìbí, àti jéèyàn pẹ̀lú ìpèníjà Olusegun Aremu Obasanjo
Lootọ, alaga apapọ ẹgbẹ oṣelu APC , Adams Oshiomhole ni oun ti gba ile ẹjọ kotẹmilọrun lọ, bẹẹ ni agbẹnusọ rẹ, Simon Egbegbulem yọju rẹ sita ninu atẹjade kan to fi ranṣẹ si akọroyin BBC news pe awọn ti kọwe kotẹmilọrun lati tako idajọ naa.
Amọṣa, ẹgbẹ oṣelu naa ti ni awọn yoo tẹle ilana ofin lori ọrọ naa.
Òfin tí yóò mú àtúnṣe bá ìlànà ìsìnkú ọba ní ìpínlẹ̀ Ògùn ń bọ̀ lọ́nà
Oríṣun àwòrán, Twitter/dabiodunMFR
Abadofin ti yoo mu atunto ba ilana isinku awọn lọbalọba ni ipinlẹ Ogun ko ni pe dofin.
Nile aṣofin ti wọn ti n ṣe ijiroro lori ofin naa, awọn aṣofin ti ka abadofin naa ni igba ẹlẹẹkeji.
Ohun ti ofin naa n gbero ni lati jẹ ki awọn ọba to ba waja ni anfaani isinku ni ilana ẹsin to wu wọn yala ti Kristẹni tabi ti Islam.
Ofin yi ti wọn pe orukọ rẹ ni 'Ogun State Traditional Rulers (Installation and Burial Rites) Bill 2020' ṣebi ẹni ri atẹwọgba lọdọ awọn aṣofin naa.
Ninu ọrọ tirẹ, aṣoju Balogun Akeem Agbolade to jẹ agbatẹru aba naa ni ofin ọhun ṣe pataki lati dena awọn aṣa ti koba igba mu nipa sisin awọn ọba tabi nipa awọn eto ifinijoye wọn.
Olori ile ni tiẹ sọ pe o di dandan lati daabo bo awọn lọbalọba lọwọ awọn aṣa to tabuku ba ijẹọmọniyan .
Lọpọ aaye ni awọn ilana isinku ti wọn a ma ṣe ni bonkẹlẹ ti gbode kan.
Ninu awọn aṣa isinku lati gbọ pe awọn kan a ma ni ki wọn sin eeyan pẹlu ọba to ba ku iyẹn ta mọ si abọbaku.
Oluwo ilu Iwo nipinlẹ Osun tio gboṣuba kare fawọn aṣofin ipinlẹ Ogun pẹlu igbesẹ wọn eleyi ti yoo mu atunto ba ilana isinku awọn Ọba lagbegbe wọn.
Oba Abdulrasheed Akanbi kan saara si Awujale ilu Ijẹbu Ọba Sikiru Adetona pe iru idagbasoke yi n waye lasiko rẹ lori apere.
Olúwòó ní  àwọn Ọba ń se ẹgbẹ́ òkùnkùn
Ti ofin yi ba kẹsẹjari,eyikeyi Ọba to ba ku yoo ni anfaani isinku ni ilana ẹsin to ba yan laayo yatọ si aṣa tẹlẹ pe wọn yoo sin nilana iṣẹmbaye.
Nollywood: Ìdá 90% nínú àwọn olówó Naijiria lo n lọ ilé babaláwo
Oríṣun àwòrán, Bolaji Amusan
Ìdá 90% nínú àwọn olówó Naijiria lo n lọ ilé babaláwo- Mr Latin
Àgbà òṣèré to tún jẹ́ gbájúgba nínú eré tíátà àti alaga ẹgbẹ́ òṣèré ẹ̀ka ti Tanpan ní Nàìjíría, ọ̀gbẹ́ni  Bolaji Amusan, ti gbogbo ènìyàn mọ sí Mr Latin"" sọ ìhà tirẹ̀ lórí ẹsùn ti mínísita Raji Fasola fi kan Nollywood"
Mr Latin to jẹ́ alejo pataki lóri ètò àkànṣẹ́ ìfọ̀rọ̀wérọ ti ilé iṣẹ́ BBC lọ́sàn òni ọjọbọ to si fẹsì sí ọ̀rọ̀ kan ti o tẹnu mínísita orilẹ̀-èdè Naijira jáde wípe, àwọn òṣèré tíata ló kọ ara ilú bi wọ́n ṣe n ṣe òògùn owó kiri.
Ọgbẹ́ni Bolaji Amusan ní ọ̀rọ̀ náà ko ribẹ̀ rara, nítori gbogbo orilẹ̀-ède aye ní ènìyàn máa ń mọ iṣe àti àsà wọn láti ara awọn òṣèré wọ́n, Amusan sàlaye àwọn àmúyẹ to wà lára àwọn orilẹ̀-èdè àti àwọn eré ti wọ́n máa ń ṣe bi àpẹrẹ Amẹrika fiimu, India fíimu, to fi mọ fíìmù àwọn korea .
O ní ìdá àadọrùn nínú àwọn olówó orilẹ̀-èdè Naijiria lo máa nlọ si ilé Baba Alawo, nítori pe àrà àṣà abíni bi ni lórilẹ̀-èdè Naijiria àti pe tí ọ̀pọ̀ bá bẹ̀rẹ̀ si ni wo fíímu, wọ́n kii biki ta láti wòó pari ti wọ́n maa sọ pe àwọn ti mọ ibi ti yóò pari si èyi si maa n mú wọ̀n pàdánù láti mọ ẹkọ ti o wà níbẹ̀, ni ọ̀pọ̀ ìgbà àwọn fíímu náà maa n naka àbùkù si àwọn to hu irú ìwà síse oògun owo ni.
Oríṣun àwòrán, Bolaji Amusan
Ìdá 90% nínú àwọn olówó Naijiria lo n lọ ilé babaláwo- Mr Latin
O ní lẹ́yìn iṣẹ́ soja, iṣẹ́ ere ori ìtàgé tún ni o ni àṣà ìbáwi jùlọ, nítori náà gbogbo ǹkan ti àwọn ń ṣe, ìdánilẹkọ̀ọ́ lo wà fún.
Lóri ọ̀rọ̀ àwọn àgbà nínú òṣèrè ti wọ́n ku ti ọ̀pọ̀ wọ́n si n ṣe àìsàn, Mr Latin ní, ẹgbẹ́ ń ṣe ìwọ̀n to lè ṣe, sùgbọ́n ìhà ti ẹgbẹ́ yóò ko si irú ẹni bẹẹ ti wà lori irú ìhà ti ẹni náà kọ si ẹgbẹ́ nígbà ti ara rẹ̀ ji pépé.
to ba jẹ́ pe ẹni ti kìí peju dédé lásiko ipade ẹgbẹ́ ni, o ṣeeṣe ki ẹgbẹ́ náà ma kọ ibi ara sii
"Ní ti Kayode Odumosu ti gbogbo ènìyàn mọ si ""Pa Kasumu"" Alaga Tanpan ni ẹgbẹ́ ṣe gudugudu méje àti yàyà mẹfa lati ìgbà to ti bẹ̀rẹ̀ si n ṣe àisan, eyi si de ọ̀dọ̀ gómìnà àná ní ìpinlẹ̀ Ogun Ibikunle Amosun, owo to to mílíọnu meji ni gomina fún láti fi wo ara rẹ."
O ní nítori àwọn ìṣèlẹ̀ yìí ni ẹgbẹ́ ṣe fi orúkọ silẹ̀ ni àwọn ilé iṣẹ́ adójutofò kan láti le jẹ ki àwọn òsèré le maa fi tọ́rọ́kọ́bọ̀ wọ́n síbẹ̀ titi di ọjọ́ ogbó ti wọn kò ni le ṣe iṣẹ́ mọ.
Eyi o sàlàye pe yóò ma ràn wan lọ́wọ́ láti moju to ọjọ iwáju wọ́n, ti a ba si ri ẹni to ṣe àisan, o le gba nínú owó náà láti toju ara rẹ.
Nigeria housing: Ilé orí omi ni mo n gbé ní Eko
Lẹyin ti iwaadi ajọ isọkan agbaye kan jade eyi to bẹnu atẹ lu ipo to buru ti ipese ile igbe wa ni Naijiria, akọroyin wa ni BBC Mayeni Jones ṣe abẹwo si adugbo kan tawọn eeyan ti n gbe ninu ilé ìgbé ti kò bojúmu ni Eko akete.
Bi eeyan ba n wo Oko-Agbon to wa ni Makoko latI okeere, niṣe ni yoo dabi ẹni pe wọn ya aworan rẹ ni.
Ninu aworan ti a o ri yi, awọn  to kọ ile sibẹ fi igi tẹlẹ ile onipakó si ori omi to dudu birikiti.
Bẹẹ leeyan o si ri awọn aradugbo ti wọn kesi ara wọn lati inu ọkọ oju omi.
Awọn ajoji to ri iru nkan bayi ni ilu Venice tawọn eeyan ti n fi ọkọ oju omi rin laarin ile,  a ma ṣapejuwe Makoko gẹgẹ bi Venice tilu Afrika.
Amọ ṣaa, bi eeyan ba sunmọ daada, yoo ri pe ọrọ ko ribẹ tanyanyan.
Orisirisi pantiri lo kun ori omi yi, idọti to fi mọ ẹgbin. Oorun ẹja to ti baje ko ni jẹ ki eeyan rimu mi rara nibẹ.
Oorun naa kọja afẹnusọ.
Dosu Francis ń gbe ni Oko Agbon pẹlu ọmọ àti ìyàwó rẹ̀
Ẹgbẹ̀lẹ́gbẹ̀ àwọn eniyan lo n gbe papọ nibi ti ko si sí ààye la'ti ṣe ǹkan láàye ara ẹni.
Síbẹ, ibi jẹ ibi ààbò fun ọpọlọpọ̀. Dosu to jẹ́ pẹjapẹja kode Makoko ni nkan bi ọdun mẹta ṣẹyin lẹ́yin ti wọn le kúro ni ilé rẹ lẹba omi bakan náà ni àdúgbò Otodo Gbame.
Àwọn aladugbo ibí tí ìjọba Èkó tí n wole sọ èrò ọkàn wọn
Oun, ìyàwó àti ọmọ ni wọ́n jọ n gbe inú yàrá kótópó, ti wọn n l'ò fún ẹja yíyàn.
Igba diẹ lo yẹ ki o fi gbe ile kolobo yi to jẹ ti ọkan lara awọn ọmọ iya rẹ sùgbọ́n ọdun kẹ́ẹ́ta rèé to ti n gbe ibẹ nigba ti ko riibo miran lati gbe.
Pẹlu ohun irẹlẹ Francis sọ fun wa pe ''lati igba ti wọn ti lewa kuro,igbe aye ko dẹrun rara''
''Mo ni awọn ọmọ mẹta to to lọ ileewe ṣugbọn mi o le san owo ileewe wọn. A ti fun wọn lounjẹ jẹ iṣoro tori naa mo ti ni ki meji ninu wọn ma lọ si ọdọ akọbi mi obinrin to wa nile ọkọ ''
O ni ''ọkan ṣoṣo ninu awọn ọmọ mi ọkunrin lo n gbe lọdọ mi bayi''
Ibi ti Dosu Francis n gbe tẹlẹ ni Otodo Gbame ti wọn wo ni nkan bi ọdun mẹta sẹyin
Ogbẹni Francis sọ pe típatikuuku ni wọn fi le àwọn jáde ni Otodo Gbame ni ọdun 2017, nigba ti àwọn ilú to súnmọ wọ́n fẹ́ gba ilẹ wọ́n, ni wọn rán àwọn ọlọpàá láti le àwọn dànù.
 Wọn bẹ̀rẹ̀ si ni le wa díẹ̀ díẹ.A léro pe àwa ati ọlọpàá yoo le dúna dura ni, súgbọ̀n ọjọ kan ni wọ́n kan wá le gbogbo wa dànù
Mo beere lọwọ rẹ boya ijọba san owo gbaa ma binu fun.
''Ko si ẹni to fun wa ni nkankan,wọn ofun wa ni ile, wọn o fun wa ni owo.Wọn o fun wa ni nkankan, wn kan ni ka kẹru wa ki a ma lọ''
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Awon Olugbe Tarkwa Bay lo si ile ẹjo ninu osu keji lati lo pe ijoba lẹjo idi ti wan fi le wan kuro ni ibugbe wọ́n
Kò si ǹkan to jẹ tuntun nínú ọ̀rọ̀ ti ọgbẹ́ni Francis sọ.
Idi ni pé ẹgbẹ̀lẹ́gbẹ̀ èèyàn ni wọn maa n le kúro nilé ni orile-ède Naijiria láisi owo gba mabinu kankan fún wọ́n ti wọ́n ko si ni fi to wọ́n leti tẹ́lẹ̀ tabi fi wọ́n si ile míràn.
Gẹ́gẹ́ bi Amnesty International se sọ pe láàrin 2000 àti 2009 ijọba Naijiria ti le èèyàn miíọnu méji kuro ni ibugbe wọ́n.
Ní ìpínlẹ̀ Eko nikan àimọye àwọn ènìyàn ni wan ti fi tipa le kúro ni ibugbe wọ́n
Ninú osu keji ọdun 2013, o le ni ẹgbẹ̀run mẹsan eniyan ti wọ́n le ni Badia ni ilu Eko, lati mu ki ijọba kọ àwọn ile kan ,nínú osu kẹsan ọdun 2015, ẹniyan ẹgbẹ̀run mẹwàá ni wọ́n le kuro ni àdugbo náà.
Ní ìbẹ̀rẹ̀ ọdun yìí 2020, o to èèyàn ẹgbẹ̀run mẹwàá ti wọ́n fun ni wákàti kan pere láti ko ẹru wọ́n kúro ni Tarkwa Bay, nibi ti ọpọ àwọn ènìyàn ti ma n gbafẹ́ lopin oṣẹ nilu Eko.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Bí àwọn eniyan ṣe kígbe to lori ayelujara, síbẹ ìjọba pada wó ilé wọ́n dànu.
Abẹwo BBC si Tarkwa Bay lati wa idi ti wọ́n fi le àwọn eniyan náà, awon ọmọ ologun ni ki àkoroyin wá kuro ni ẹsẹkẹsẹ,
Wọn ni ko si ǹkan ti àwọn n gbe pamọ súgbọ̀n ki wọ́n lọ gba ọ̀na to tọ láti pada wá
Coronavirus: A kò nílò láti ti àwọn ilé ìwé àti ilé ìjọsin wa pa- Minista ètò ìlera
Oríṣun àwòrán, Getty Images
A kò nílò láti ti àwọn ilé ìwé àti ilé ìjọsin wa pa- Minista ètò ìlera
Komiṣọnna fun eto ilera ni ipinlẹ Eko, Ojọgbọn Akin Abayomi ti kede iyasọtọ awọn mẹta miran lori iṣẹlẹ Coronavirus tuntun.
Lasiko ti Kọmiṣọnna n fidi ọrọ yii mulẹ lo sọ pe ijọba ti ya awọn eeyan yii sọtọ nile ifinipamọ to wa ni adugbo Yaba ni ipinlẹ Eko.
O ni ọkan awọn eniyan mẹta yii gba ipinlẹ Eko wọ Naijiria lọjọ Aje lẹyin ti wọn de lati orilẹ-ede France.
O ṣalaye pe ọkan ninu awọn meji to ku wọle lati England nigba ti ẹni kẹta wọn de lati China nibi ti arun Coronavirus yii pọ si.
Oríṣun àwòrán, @others
Ìpínlẹ̀ Eko kéde afurasí mẹ́ta míràn tó ṣeéṣe kó ni Coronavirus
Kò sí ìdí kankan fún wa láti ti ilé ìwé àti àwọn ilé ìjọsìn wa pa- Minista fun ètò ìlera ní Naijiria
Minista fun eto ilera ni Naijiria, Ọjọgbọn Osagie Ehanire lo fi ọrọ yii sita nilu Abuja pe ko si idi kankan fun Naijiria lati ti ile iwe ai awon ile ijọsin wa gbogbo pa nitori Coronavirus.
Minista ṣalye pe lọwọlọwọ yii, awọn mọkanlelogun ni wọn ti ya sọtọ niyara ifinipamọsi kaakiri ipinlẹ mẹrin ti wọn ti furasi iṣẹlẹ ọhun.
Ipinlẹ Eko, Ogun, Abuja ati Kano ni wọn ti kede pe awọn afurasi naa wa ṣugbọn ko tii si ẹni ti wọn ri to ti ni arun Coronavirus ni pato ni Naijiria.
Ojọgbọn Osagie fidiẹ mulẹ pe awọn eniyan marundinlọgọta o ba arinrinajo ara Italy naa rin ni wọn ti  n ṣe ayẹwo fun laisko yii.
O ni awọn n ṣiṣẹ papọ pẹlu awọn aṣọbode ati ọmọ ogun ori omi lati tubọ maa ṣe ayẹwo ni kikun lori awọn to n wọle si Naijiria bayii.
Ara: Láti kékeré ni mo ti ń lu ìlú pẹ̀lú ayọ̀
Kini o ti ṣẹlẹ ni Ghana nipa Coronavirus?
Ṣé àwọn òṣìṣẹ́ elétò ìlera Ghana yóò ya Aarẹ Akufo-Addo sọ́tọ̀ lẹ́yìn tó dé láti ilẹ́ Yúròòpù?
Coronavirus: Ààrẹ Ghana lọ sílẹ̀ Yúróópò fún ọjọ́ méjìlá níbití àrùn náà wà.
Ras Mubarak tó n ṣojú ẹkùn Kumbungu nílé àṣòfin àgbà ni Ghana n béèrè bóyá wọn yóò fí Aarẹ Akufo-Addo sí àhámọ́ lọ́tọ̀.
Oríṣun àwòrán, Office of the Ghana president
Kini o maa ṣẹlẹ̀ sí Aarẹ Akufo-Addo?
Lori iṣẹlẹ Corona Virus yii naa ni ibeere gbankọgbi ti n jade ni orilẹ-ede Ghana.
Ọgbẹni Mubarak to n ṣoju ẹkun Kumbungu nile aṣofin agba ni Ghana lo ṣide eto ipade naa pẹlu ibeere nla yii.
Mubarak beere lọwọ awọn oṣiṣẹ eleto ilera ilẹ Ghana boya wọn maa gbe igbesẹ lati ya Aarẹ Akufo-Addo to ṣẹṣẹ rin irinajo de lati ilẹ Yuroopu sọtọ ni iyara ahamọ tabi bẹẹ kọ.
O ni Mongila ati Aarẹ Dema naa gbe iru igbesẹ iayraẹnisọtọ yii nitori Arun COVID-19 to gbode kan yii.
Ọjọ mejila ni Aarẹ Akufo-Addo fi rin irinajo abẹwo si ilẹ Yuroopu pẹlu awọn mẹwaa ninu oṣiṣẹ ileeṣẹ Aarẹ Ghana.
Iroyin ni wọn de ọdọ Aarẹ Norway nibi ti eniyan mẹta ti lugbadi arun Coronavirus ti wọn si ti fi eniyan aadọta pamọ fun ayẹwo.
Ibẹru ohun ti arun CoronaVirus yii le bi to ba bẹ silẹ ni Ghana lo n jẹ ki awọn eeyan kan beere pe ki wọn fi Aarẹ Akufo-Addo pamọ bo ti yẹ.
Obasanjo: Àwọn èèyàn ìpínlẹ̀ Ogun ní iṣẹ́ ṣì pọ̀ fún Ọbasanjọ láti ṣe fún mẹ̀kúnù Nàìjírìà
Háà, Coronavirus ba ọjọ́ ìbí mi jẹ́ tán, díẹ̀ ló kù, mo yára ṣàtúnṣe sí i - Obasanjo
Ààrẹ Naijiria àná,  Olusegun Obasanjo ti ní àrun Coronavirus ló jẹ́ kí àtúnṣe débá ètò ayẹyẹ ọjọ́ ìbí rẹ̀ tó wáyé ní Abeokuta.
Aarẹ orilẹ-ede Naijiria tẹlẹ, oloye Olusegun Obasanjo ti sọ pe itankalẹ arun Coronavirus lo mu ki oun ṣe atunṣe si bi oun ṣe fẹ ki ayẹyẹ ọjọ ibi oun waye.
Obasanjo salaye bẹẹ nigba to n ba awọn eeyan sọrọ nibi ayẹyẹ ọdun kẹtalelọgọrin rẹ nilẹ alaye, eyi to waye nilu Abeokuta.
Obasanjo ni awọn eeyan jankan ti oun fiwe pe lati awon orilẹ-ede miran lagbaye wa sibi ayẹyẹ naa, bii aarẹ orilẹ-ede Sierra Leone tẹlẹ, Bai Koroma, aarẹ Liberia ana Ellen Johnson-Sirleaf, atawọn mii ni ko lee wa sibi ayẹyẹ ọhun, nitori ibẹru arun Coronavirus.
"O ṣalaye pe ""Lara awọn eto ti a pinnu lati ṣe ni lati lo ọjọ Isẹgun ati Ọjọru lati ṣagbeyẹwo bi awọn eeyan yii ṣe de ipo giga ti wọn wa, ati awọn ẹkọ ti a lee kọ lara wọn, ṣugbọn a ni lati gbe aba naa ti sẹgbẹ kan nitori ibẹru arun Coronavirus to n ja nilẹ."""
"Baba tẹ siwaju pe ""Mo lero pe to ba di ọjọ iwaju, aye maa wa fun wa lati ṣeto ọhun nitori ọpọ nnkan la lee kọ lati ara wọn nipa awọn aṣeyọri ti wọn ti gbe ṣe, ati bi wọn ṣe ṣe."""
Obasanjọ sọ pe ara eto ayẹyẹ ọjọ ibi naa ni lati ṣapero pẹlu awọn olori lati Asia, lati mọ aṣiri bi wọn ṣe goke agba lawujọ agbaye ati ẹkọ ti ilẹ adulawọ le kọ lara wọn.
O ni ọrọ aje orilẹ-ede Malaysia buru ju ti Naijiria lọ lasiko ta gba ominira lọdun 1960, bẹe naa ni South Korea ati Vietnam, ṣugbọn ni bayii, ọrọ aje awọn orilẹede naa ti ṣenu ire ju ti Naijira lọ, leyi to tumọ si pe, ọpọ nnkan ni Naijiria le kọ lara wọn.
Ninu ọrọ rẹ, Gomina ipinlẹ Ogun, Dapo Abiodun sọ pe, awokọṣe nla ni Obasano jẹ lawujọ awọn oloṣelu ni Naijira ati kaakiri agabye.
O ni ti kii ba ṣe nitori Obasanjo ni, ki ba ma ti si ilu Owu ninu maapu orilẹ-ede Naijira.
Gomina ipinlẹ osun tẹlẹ, Olagunsoye Oyinlola naa sọrọ nipa Obasanjo, o ni baba rere ti eeyan le ṣawokọṣe rẹ gẹgẹ bi aṣaju rere ni Obasanjọ.
Oyinlola ni baba Obasanjo ni oun n wo niwaju, ti oun si mu bii baba ninu oṣelu ni Naijiria.
Lara awọn eeyan jankan to ba oloye Obasanjo ṣayẹyẹ ọjọ ibi rẹ naa ni, gomina ipinlẹ Ogun, Dapo Abiodun, gomina ana nipinlẹ Osun, Olagunsoye Oyinlola, Sẹnatọ ana, Florence Ita Giwa, onimọ nipa ọrọ aje, Nike Akande, atawọn eeyan nla miran.
Xenophobia: Naijiria á kọ́kọ́ pèsè ọ̀nà láti bá ẹbí sọ̀rọ̀ fún wọn
Elebuibon: Àwọn asòfin Ogun yóò ṣe àkóbá fún ilẹ̀ Yoruba pẹ̀lú òfín tó fágilé àsà
Oríṣun àwòrán, @followlasg
Onimọ nipa eto ati asa ilẹ Yoruba, Baba Fayemi Elebuibon ti bu ẹnu atẹ lu igbesẹ awọn asofin ipinlẹ Ogun, ti wọn pe fun ọna igbalode nipa yiyan ọba ati ṣise isinku ọba ni ilẹ Yoruba.
Elebuibon lasiko to n ba BBC News Yoruba sọrọ ni, awọn asofin naa fẹ pa asa ati iṣe ilẹ Yoruba run ni.
O ni ko tilẹ yẹ ko jẹ bi wọn ṣe n yan ọba ni awọn asofin naa yoo jiroro le lori, nitori ki ilu lee tuba, ko tuṣẹ ni wọn se ma n ṣe etutu fun ọba, ni ilẹ Yoruba.
Awọn asofin yii fẹ ba asa Ẹgba jẹ, ti yoo si se akoba fun gbogbo ọmọ ilẹ Yoruba nitori ọba ti ko ba ṣe etutu, kii ṣe ọba. Ẹ ko le yan ọba ilẹ Yoruba bii ti ilẹ Gẹẹsi, bẹẹ naa ni wọn ko le yan ọba ilẹ Gẹẹsi bii ọba ilẹ Yoruba, nitori ọtọọtọ ni Ọlọrun da wa.
Aṣiṣe ti ko dara gba a ni yoo jẹ ti ọba ko ba ṣe etutu ki o to jọba, abi ki wọn ma bọwọ fun asa ti wọn ba fẹ sin ọba
Oríṣun àwòrán, @ObatAkinruntan
Onimọ nipa eto ati asa ilẹ Yoruba naa ni oro ati etutu ti wọn n ṣe fun awọn ọba lo ya ọba sọtọ, nitori ẹlomiran ni owo amọ wọn ko le e pe e ni ọba, nitori ko le e ṣe oun ti ọba n ṣe.
Elebuibon sọ wi pe o ti pe ti wọn ti yii pada ti ọba kii jẹ ọkan ọba mọ ati wi pe wn ti fi ọkan ẹran rọpọ rẹ.
Bakan naa ni o sọ wi pe eto isinku ọba ilẹ Yoruba ti yipada nitori wọn kii sin ẹnikẹni mọ ọba mọ, bẹẹ ni wọn kii yọ ẹya ara kankan lara ọba mọ to ba waja, nitori wọn ti fi ẹran rọpo awọn etutu ti wọn ma n ṣe.
O ni lara asa Yoruba ni ki awọn oni ifa ati awọn agba ṣe irubọ, ki wọn wo ikọṣẹ-jaye ọba ti o fẹ jẹ, kikọ ọba ni bi wọn ṣe n sọrọ lawujọ ati bi ihuwasi to mu ọba yatọ si awọn ẹlomiran, eyi to mu ki wọn ma a pe e ni alaṣẹ ekeji orisa.
Oríṣun àwòrán, Olubadan
Amọ, Elebuibọn faramọ ki wọn mase kọla fun awọn obinrin ni oju ara, amọ ila oju wa fun ẹwa obinrin ati ọkunrin ati lati mọ ibi ti eniyan ti ṣẹ wa.
Onimọ nipa eto ati asa ilẹ Yoruba, naa wa ni ila kikọ tun n pa owe fun awọn ọmọ ilẹ Yoruba pe ki eniyan to le jọrọ, yi o ṣiṣẹ takuntakun.
Oluwo tilu Iwo, Ọba Abdulrosheed Adewale Akanbi, Telu Kinni, ti kede pe o yẹ kawa ọmọ Yoruba se ipade apero lori ọna ta gba pa awọn asa ati ise awujọ wa kan rẹ, ti ko ba igba mu mọ.
Oríṣun àwòrán, emperortelu1
Ọba Akanbi fesi bẹẹ loju opo Instagram rẹ eyi to fi n sọ ero rẹ nipa bi Awujalẹ ilẹ Ijẹbu ati Ọṣilẹ Oke ọna se n beere pe ki wọn se atunse si awọn asa ati ise wa kan to ti di ogbo.
Awọn ọba meejeji naa lo mẹnuba baa pe ilana ibilẹ ti wọn n gba sinku ọba ni ko ba igba mu mọ, o si yẹ ki ayipada de baa.
Oluwo, lero tiẹ ni bi o tilẹ jẹ pe asa wa nilẹ Kaarọ oojire yaayi pupọ amọ awọn abala kan wa ninu rẹ to yẹ ka parẹ, nitori pe wọn ko ba saa taa wa yi mu mọ.
Oríṣun àwòrán, Samuel Ladoke Akintola
Ẹ ko loye lori ohun to n lọ, nitori ẹ kii se ara rẹ. A n gba Oromọdiẹ lọwọ iku, o ni wọn ko jẹ ki oun re akita lọ jẹun ni. Awọn iyipada ta fẹ ninu asa wa ni awọn asa ati ise to n jẹ ka maa huwa bii ẹranko ati  ajẹniyan, awọn abala asa wa ti ẹ ko mọ niyi.
"Oluwo ni ""Awa ti a ni ẹri ọkan yoo wa awọn asa yii jade nitori a ko lee pẹlu ọbọ jẹ oko, lara awọn asa kan gboogi ti ọjọ ti lọ lori wọn ni ila kikọ, asa Yoruba si gbọdọ maa ba igba mu."""
Oríṣun àwòrán, emperortelu1
Oluwo tun tẹsiwaju pe asa Yoruba yaayi lootọ, ko si si ohunkohun taa fẹ gba ninu ka ba asa wa jẹ, amọ ta ba ba aye yi nidi awọn asa to ti di ogbo, a ti kuna niyẹn, iyipada maa n duro titi lae ni.
"Oluwo wa pari ọrọ rẹ pẹlu ibeere pe ""Ta lo fẹ wọ gọmbọ fun ọmọ rẹ lode oni? amọ eyi wa lọwọ ọmọ naa boya o wuu lati kọ ila to ba dagba."""
Coronavirus: Ẹ wo àwọn ìròyìn èké tó gbòde ní Áfíríkà torí àjàkálẹ̀ àrùn
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Yoruba ni ọrọ okeere, bi ko ba le kan, yoo din kan, bẹẹ si lo ri fun arun Coronavirus, nitori oniruuru awọn ayederu iroyin lo n lọ kiri nipa arun naa, tawọn eeyan ko lee fidi rẹ mulẹ nilẹ adulawọ.
Bi o tilẹ jẹ pe Coronavirus ti na ọwọja rẹ de awọn orilẹede kan nilẹ Afrika, sibẹ awọn alasẹ lawọn orilẹede nilẹ adulawọ lo n tiraka lati pana ọpọ ayederu iroyin to rọ mọ Coronavirus.
Eyi ni awọn ọpọ ayederu iroyin tawọn araalu n pin kiri nipa arun Coronavirus to n waye nilẹ Afirika.
Awọn eeyan Afrika lo ti n lo aworan kan lo, eyi ti awọn alasẹ eto ilera nilẹ Amẹrika fisita lori irun to maa n hu loju bii irungbọn, irun imu, irun ẹba eti ati bẹẹ bẹẹ lọ.
Awọn eeyan kan ti wa n gbe iborun kiri pe o yẹ kawọn ọkunrin maa ge irugbọn wọn lati dena arun Coronavirus, eyi ti ko ri bẹẹ rara.
"Fun apẹẹrẹ, akọle kan loju ewe iwe iroyin Punch nilẹ Naijiria lo kede pe ""To ba fẹ bọ lọwọ arun Coronavirus, ge irungbọn rẹ, CDC sekilọ"" Irọ ni."
"Bakan naa ni ọpọ akọle ti n wa lawọn iwe iroyin miran lawọn orilẹede miran eyi tawọn eeyan bẹrẹ si pin kiri. Fun apẹẹrẹ, Iwe iroyin kan nilẹ Australia kọ soju opo Twitter rẹ pe ""Bi irungbọn rẹ se lee jẹ ko wa ninu ewu Coronavirus laimọ."""
Oniwaasu kan to ni oun lee wo arun Coronavirus san naa tun ara awọn iroyin ti ko fidi mulẹ.
Iroyin nipa Davies Kingleo Elijah, ti ijọ Glorious Mount of Possibility lo bẹrẹ si tan kalẹ lori afẹfẹ lẹyin fidio kan to ni oun yoo lọ tẹdo si Ghana lati pa arun Coronavirus run, eyi to gba oju opo YouTube atawọn oju opo ikansira ẹni miran kan.
Maa fi asọtẹlẹ ba arun Coronavirus jẹ. Mo n lọ si China, mo fẹ lọ pa Coronavirus run.
Lẹyin ọjọ diẹ ni iroyin naa wa lawọn opo ayelujara kan pe ojisẹ Ọlọrun naa ti gba china lọ amọ o wa nile iwosan nibẹ to n gba itọju lẹyin tọwọ arun arun Coronavirus gba mu.
Amọ orukọ miran, Elija Emeka Chibuke ni wọn fi kọ iroyin naa nipa oniwaasu ọhun.
Koda, aworan ti wsn lo jẹ aworan osere tiata kan ti ara rẹ ko ya, amọ to ti jalaisi bayii, Adeshina Adesanya, ti ọpọ eeyan mọ si Pasitọ Ajidara.
Iroyin eke nipa awakọ taxi kan:
Iroyin kan nipa awakọ tasi kan ni Naijiria ti wọn lo ko arun Coronavirus lo wa loju opo ayelujara amọ ẹbu ni iroyin naa.
Iroyin naa ni awakọ ọhun ni wọn lo gbe ọkunrin alawọ funfun kan to ni arun Coronavirus, ti wọn si ti yaa sọtọ tori pe o ni arun ọhun.
Wọn ni awakọ naa papa sa kuro nile iwosan ti wọn yaa sọtọ si, to si n dunkoko lati tan arun naa kalẹ ayafi ti awọn mọlẹbi ọkunrin naa ba san milinu lọna ọgọrun naira.
Amọ awọn alasẹ ti sẹ pe irọ ni ọrọ naa, tijọba Ogun si fi ọrọ lede lori Twitter rẹ pe irọ̀ọ ni ọrọ naa.
Lorilẹede Kenya, ijọba fi ikede sita pe pe irọ ni fọnran ohun ti wọn n pin kiri pe arun Coronavirus ti wọ orilẹede naa, eyi to ni awọn eeyan to ni arun naa to mẹtalelọgọta niye.
Ileesẹ eto ilera ni fọnran naa jẹ ohun ti wsn jiroro nibi idanilẹks kan amọ ti ko ye wọn bi fọnran naa se lu sita.
Labẹ ofin ilẹ Kenya, ẹnikẹni to ba pin iroyin eke yoo san ẹgbẹrun lọna aadọta dọla abi ko fi ẹwọn ọdun meji jura.
Nilẹ Naijiria, oniwaasu kan fi fidio ati iwe ikede kan sita, eyi ti wọn n pin loju opo Whatsapp pe, omi ọbẹ alata, taa mọ si Pepper Soup, lee wo arun Coronaviruas san.
Ko tii si iwosan tabi itọju fun arun naa, bẹẹ si ni ẹbu iroyin naa lo n salaye nipa bi omi ọbẹ alata naa se lee se iwosan Coronavirus.
Bakan naa, ileesẹ eto ilera ni Cape Verde ti kilọ fawọn araalu lati mase se alabapin iroyin to n fọnrere pe ewe kan ti wọn fi n se ọbẹ lee wo Coronavirus san.
Ohun kansoso ti ajọ eleto ilera lagbaye kede pe o lee wo Coronavirus san ni ka maa fọ ọwọ wa deede, nitori eyi se pataki lati dena kokoro arun naa.
Odion Ighalo: Ole Gunnar Solskjaer gbóṣùbà káre fún Ighalo lẹ́yìn tó sọ góòlò méjì sáwọ̀n Derby County
Oríṣun àwòrán, @AfricaFactsZone
Ohun ti ẹnikẹni ba sọ ko kan oun, bi ko ṣe ki oun gbaju mọ iṣẹ
Atamatase ikọ Manchester United, Odion Ighalo ti ni, ọrọ ti awọn kan n sọ kiri lori igbeṣẹ oun lati darapọ mọ Manchester United ko tu irun kankan lara oun.
Ighalo sọ pe ohun to ṣe pataki ni ki awọn ojugba oun gbagbọ ninu oun, gẹgẹ bi agbabọọlu to pegede.
"O ni ""Niwọn igba ti awọn akẹgbẹ mi, akọnimọọgba mi ati awọn ololufẹ mi ba lee gbagbọ ninu ipa ti mo le ko lori papa, temi ni lati maa ṣe ohun ti mo mọọ ṣe."""
"Ighalo tẹsiwaju pe ""Ohun ti ẹnikẹni ba sọ ko kan mi, afojusun wa ni Man United ni lati tẹsiwaju ninu saa bọọlu yii."""
Ami ayo mẹta si odo ni Manchester United fi ṣeya fun Derby County ninu ifẹsẹwọnsẹ wọn to waye lọjọ Ọjọbọ, leyii ti Ighalo ti sọ bọọlu meji wọle ninu rẹ.
Ọpọ awọn ololufẹ Manchester United kaakiri agbaye lo ti bẹrẹ si n jẹ ọrọ Ighalo lẹnu bi ẹni jẹ iṣu lẹyin aṣeyọri Manchester United ninu ifẹsẹwọnsẹ naa, papa julọ fun ipa to ko.
Oríṣun àwòrán, @AfricaFactsZone
Ighalo ni aṣẹyọri oun ni Manchester United ti fi han pe, oun kun oju oṣuwọn lati darapọ mọ ẹgbẹ agbabọọlu naa.
Ni bayii, Ighalo ti sọ goolu mẹta sinu awọn ninu ifẹsẹwọnsẹ meji to ti kopa ninu rẹ lati igba to ti darapọ mọ ikọ ọhun ni Oṣu Kini, ọdun 2020.
Ẹwẹ, akọnimọgba Manchester United, Ole Gunnar Solskjaer ti gboṣuba kare fun Odion Ighalo fun iṣe akin to ṣe lati sọ bọọlu sinu awọn Derby County nigba meji ọtọtọ ninu ifẹsẹwọnsẹ FA Cup ọhun.
Aremu: Eré ìtàn nípa ìbí, àti jéèyàn pẹ̀lú ìpèníjà Olusegun Aremu Obasanjo
Oshiomhole Judgement: Ẹ gbọ́ ǹkan ti agbẹ́jọro sọ lórí ìdájọ ti Kano
Idájọ wo ni ẹ ro pe ó jẹ́ ojúlówó nínú ti Kano àti ti Abuja nípa Adams Oshiomhole?
Lóri awuyewiye ìyọnípò alága ẹgbẹ́ òṣèlú All Progressive, Congress APC Adams Oshiomole ni ilé ẹjọ gíga nílu Abuja ní ọjọru
Ìrọ̀lẹ́ ọjọbọ ni ìròyìn tún kan pé, ilé ẹjọ gíga míràn ní ìpínlẹ̀ Kano, tún ni ko ṣeeṣe, a fi ki Oshiomhole pada sáàye rẹ̀ gẹ́gẹ́ bi alága ẹgbẹ́ òṣèlú APC.
Idàrúdapọ ní ọ̀rọ̀ náà wá dá silẹ̀ ti ọ̀pọ̀ si n bere pe irú ìgbésẹ̀ wò ni ọlọpaàá yóò gbé àti pe kíní Oshiomhole gan yóò ṣe, nígba ti ilé ẹjọ méjì ti wọ́n wà ni ipò kan náà n pasẹ ọtọọtọ.
Láti wá ojúútu si ọ̀rọ̀ sunukùn yìí ní BBC Yoruba ṣe képe àmofin ti o fi oju sunukùn wó laáti sàlàye igbésẹ̀ rẹ̀ fún gbogbo àwọn tọ́rọ̀kan
Nínú ọ̀rọ̀ rẹ̀, agbẹjọrò Dayo Akinlaja (SAN) ní ǹkan ti o tini lójú to si bani nínú jẹ́ gbáà ni ọ̀rọ̀ náà bi ilé ẹjọ to jọ ni agbára bákan náà jọ ń dá ẹjọ ọtọọtọ.
''Nkan tí iwé òfin sọ nípa ilé ẹjọ to ni agbára kan náà, ikan ko ni àṣẹ kankan to le pa fún ikèjí, nínú ọ̀rọ̀ ti a si n gbọ lọ́wọ́, ko yẹ ki ipinlẹ Kano gbọ́ ẹjọ yẹn.''
O fikun ọrọ rẹ pe ''o yẹ ki adájọ fi ìyà jẹ agbẹ́jọrò ti ó gbé ẹjọ náà wa.
''Ile ẹjọ giga apapọ ko ni ẹtọ la'ti dá ẹjọ kọọtu ti Abuja nù. Adams Oshiomhole ti wọn dájọ fún lo ni ẹtọ lati lọ si kọọtu láti pe ẹni to pe lẹ́jọ ni ẹjọ.''
Bi nkan tiṣe n lọ bayi, ko si ẹni to mọ idajọ eleyi ti ileeṣẹ ọlọpaa Naijiria yoo tẹle lori idajo boya ki Adams Oshiomole wa loriipo rẹ tabi ki o yẹba ṣẹgbẹ kan naa.
Wahala to de ba Adams Oshiomole jẹ eleyi to niṣe pẹlu bi awọn ọmọ ẹgbẹ APC kan ti ṣe sọ wi pe awọn ko fẹ ri imi rẹ laatan.
Yollywood: Odunlade fẹ́ j'ọba, Bolanle Ninalowo fun ìyàwó rẹ̀ ni ẹ̀bun kanka, Pá Kasumu rebi àgbà ree
Oríṣun àwòrán, toyin_abraham
Ninu awọn iroyin to migboro titi lagbo oṣere tiata Yoruba bawọn kan  ṣe n pawọpọ fi gbe ere sita ni idile awọn oṣere miran n bawọn daawọ idunnu ayọ ọjọ ibi.
Ki a ma deena pẹnu rara, diẹ re lara awọn iṣẹlẹ to jẹyọ nigbesi aye awọn oṣere tiata Yoruba ni Naijiria rèé.
Oya,  jẹ ka ma mu wọn lọọkọọkan.
Bi ere bi ere ni iroyin yi ṣe bẹrẹ ṣugbọn ka to diju ka to ya, o ti di nkan tawọn eeyan n ṣalabapin rẹ kaakiri ayelujara.
Ilumọọka arẹwa oṣerẹ ọkunrin nii Odunlade Adekola jẹ ọmọ bibi ilu Ọtun Ekiti ti a si gbọ pe ile ọba lo ti wa, ọmọ oye si ni pẹ̀lú.
Oríṣun àwòrán, Instagram/odunomoadekola
Ni nkan bi ọjọ meloo kan sẹyin lawọn kan ni awọn afọbajẹ ti kan sipe ko wa jẹ ọba ilu rẹ ṣugbọn oṣere naa ko ti sọ nipa rẹ.
Amọ ṣa ninu ifọrọwerọ kan ti BBC ṣe pẹlu aarẹ oṣere tiata labẹ asia TAMPAN Bolaji Amusan Mr Latin, ni Odunlade fi ọrọ naa lọ ohun lootọ ṣugbọn o ni ohun ko ti mọ boya ki ohun jẹ oba tabi ko ma jẹ.
Ekunrẹrẹ fidio ifọrọwanilẹnuwo pẹlu Mr Latin wa nibi yi.
Loju opo Instagram Bolanle Ninalowo ni ofi ikede ẹbun ile to fi ta iyawo rẹ lọrẹ si.
Ile naa eleyi to ni oun fun Bunmi Ninalowo jẹ eleyi tiileeṣẹ kan fun un.
Oríṣun àwòrán, Bolanle Ninalowo/Instagram
Lọdun 2018 ni Bolanle Ninalowo ati iyawo rẹ ti wọn yara wọn lati nkan bi ọdun mejila pada gẹgẹ bi tọkọtaya.
Orileede Amẹrika ni iyawo rẹ n gbe ni gbogbo igba ti wọn tuka.
Oríṣun àwòrán, Iamnino_b
Odunlade fẹ́ j'ọba, Bolanle Ninalowo fun ìyàwó rẹ̀ ni ẹ̀bun kanka, Pá Kasumu rebi àgbà ree
Gbajugbaja oṣere tiata  Kayode Odumosu ti gbogbo eeyan mọ si Pa Kasumu lọsẹ yi dagbere faye.
Lọjọ Aiku ni aarẹ awọn oṣere tiata Yoruba Naijiria, Bolaji Amusan Mr Latin fidi ọrọ naa mulẹ fun ileeṣẹ BBC Yoruba.
Oríṣun àwòrán, Instagram/folukedaramolasalako
O ti to ọjọ mẹta ti aisan  ti n ba Pa Kasunmu finra.
Ọpọ awọn oṣere lo fi ọrọ ibanikẹdun si oju opo wọn lati fi ṣe iranti agba ọjẹ adẹrinposonu yii.
Pa Kasumu: Lere Paimo ní àìrìríjẹ́, àìrímú tàbí ìrònú má a ń jẹ́ kí ọjọ́ ogbó dagun
Awọn ololufẹ Toyin Abraham ati Broda Shagi to ti n foju sọna sinima Fate of Alakada yoo ni lati ṣe suuru diẹ.
Idi ni pe wọn ti sun ọjọ ti sinima naa yoo jade siwaju .
Toyin Abraham fi ikede yi sojuopo Instagram rẹ to si ni ki awọn ololufẹ ohun ma foya nitori pe ọjọ naa de tan loju ẹlẹmi.
Ọdun 1957 ni wọn bi gbaju-gbaja akọrin Fuji, Olasunkanmi Wasiu Ishola Anifowoshe, ti ọpọ eeyan mọ ọ si Wasiu Ayinde.
Ọdọ oloogbe Sikiru Ayinde Barrister ni Wasiu Ayinde ti bẹrẹ isẹ gẹgẹ bi ẹni to maa n ba ẹgbẹ akọrin rẹ ko irinṣẹ.
Oríṣun àwòrán, Instagram/kwam1-official
O ṣiṣẹ pẹlu ẹgbẹ akọrin Barrister, Supreme Fuji Commander, laarin ọdun 1975 si 1978.
Ọjọ kẹta oṣu Kẹta ọdun 2020 ni o pe ẹni ọdun kẹtalelọgọta.
Michael Oluronbi: Pásítọ̀ r'ẹ́wọ̀n ọdún mẹ́rìnlélọ́gbọ̀n he lórí ẹ̀sùn ìbálòpọ̀
Oríṣun àwòrán, WEST MIDLANDS POLICE
Pasitọ kan, Michael Oluronbi ti rẹwọn ọdun mẹrinlelọgbọn he lẹyin to jẹbi ẹsun ifipa ba awọn ọmọde lo pọ nilẹ Gẹẹsi.
Ẹni ọgọta ọgun ọhun ni wọn fẹsun kan pe o ba awọn ọmọdebinrin mẹfa ati ọmọdekunri kan lo pọ fun ọpọ ọdun labẹ asia pe o un ṣe iwẹ mimọ fun wọn lati lee bawọn le ẹmi ẹsu jinna.
Iyawo rẹ, Juliana Oluronbi naa rẹwọn ọdun mọkanla he lẹyin to jẹbi ṣiṣẹ oyun fun mérin lara awọn ọmọdebinrin mẹrin naa.
Pasitọ ọhun, to jẹ ọmọ Naijiria ṣugbọn to n fi Birmingham ṣebugbẹ nilẹ Gẹẹsi ni wọn sọ pe, o ma n sọ fun awọn to ba ko si lọwọ wa ni ihoho niwaju rẹ, fun iwe mimọ.
Agbẹjọro ijọba sọ fun ile ẹjọ ni Birmingham pe o ma n ṣe eyii lati tan awọn awọn ọmọde naa, lọna ati le ba wọn ni ibalopọ.
Ọwọ palaba pasitọ naa segi loṣu karun un ọdun 2019 nigba to n gbiyanju ati sa kuro nilẹ Gẹẹsi lọ Naijiria, awijare rẹ ni pe iṣe eṣu lo mu oun ṣe aṣemaṣe.
Adajọ to n gbọ ẹsun naa, Sarah Buckingham ni iwa pasitọ yii wa lara awọn iwa ọdaran to buru ju ti wọn tii gbe wa siwaju oun.
Nigba ti wọn sọ iriri wọn fun ile ẹjọ, awọn obinrin ti ọrọ ọhun ṣẹ si so pe, iwa pasitọ naa jẹ eyii ti wọn ko lee gbagbe ni kiakia, koda, ọkan lara ni oun ti dẹkun ati ma lọ ile ijọsin.
"O ni ""Mi o lero mo le fi igabgbọ mi sinu ẹsin kankan mọ. Mo fọkan tan pasitọ yii nitori mo n wo bi Ọlọrunn lorilẹ alaye, ṣugbọn o jami kulẹ."""
Pasitọ Oluronbi to jẹ ọmọ ijọ Kerubi ati Serafu jẹbi ẹsun ifipabanilopọ marundinlogun ti wọn fi kan an atawọn ẹsun mii, lẹyin naa ni adajọ ni ko lọ fi aṣo pempe roko ọba.
Obasanjo: Àwọn èèyàn ìpínlẹ̀ Ogun ní iṣẹ́ ṣì pọ̀ fún Ọbasanjọ láti ṣe fún mẹ̀kúnù Nàìjírìà
Pasuma: Ọ̀gáńlá Fújì ní ominú ń kọ òun lórí ọ̀dá àwọn ìràwọ̀ tuntun lágbo orin Fújì
Oríṣun àwòrán, Wasiu alabi pasuma/instagram
Gbajugbaja akọrin Fuji ni, Alhaji Wasiu Alabi ti ọpọ eeyan mọ si Pasuma Wonder, iba wasi baba baraka ti ṣalaye pe ọrọ iyawo nini fun oun kii ṣe afi waduwadu ṣe o.
Alhaji Pasuma ṣalaye pe idi ti oun ko tii fi ni iyawo lọwọ yii naa ni pe oun fẹ ṣe ohun gbogbo bi o ti yẹ ko le baa ri bose yẹ ko ri.
Paso ni ohun lawọn obinrin to bimọ fun oun o, ṣugbọn ọrọ iyawo afẹsile ko tii yọ fun oun bayii.
Ọganla Fuji ni nigba to ba ya oun yoo niyawo ṣugbọn suuru lo gba.
Ninu ifọrọwerọ rẹ pẹlu BBC News Yoruba ni Ba wasi ti sọ ọrọ yii.
Bakan naa lo sọrọ lori ahesọ ọrọ to n wi pe ọjọṣepọ ifẹ n bẹ laarin oun ati gbajumọ oṣere tiata, Jaiye Kuti.
Pasuma ni ere tiata lo da awọn mejeeji pọ.
Bakan naa lo fi kun un pe ọrẹ lasan loun ati gbajugbaja oṣere tiata, Ronkẹ Ididowo ti ko si si ohun ifẹ ikọkọ kankan to pa wọn pọ.
Bakan naa lo kọminu lori ọda awọn irawọ tuntun lagbo fuji.
O ni ohun to mi oun lọkan ni bi o ṣe jẹ pe awọn ọdọ olorin ko fẹ kọ orin Fuji mọ bi ko ṣe orin takasufe, HipHop.
O fi kun un pe oun yoo sa ipa oun gẹgẹ bii aṣiwaju lati mu idagbasoke ba awọn ọdọ to ba fẹ yan orin Fuji laayo
Coronavirus: Togo di orílẹ̀èdè kẹsàn án tí àrùn Coronavirus dé ní Afíríkà
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Bi aarun Coronavirus ṣe n ran kaakiri bii ina inu ẹrun lagbaye bayii, Orilẹede Togo naa ti darapọ mọ awọn orilẹede ti arun naa ti tan de lagbaye.
Ijọba orilẹede naa ti kede pe awọn ti ri eeyan kan to ni arun naa bayii nibẹ.
Gẹgẹ bi ohun ti ijọba orilẹede naa sọ, arabin ọmọ ọdun mejilelogoji kan to jẹ olugbe ilu Lome tti ṣe olu ilu orilẹede naa lo ko arun naa.
Wọn ni Orilẹede Benin, Germany, France ati Turkey lawọn orilẹede ti arabin naa bẹ wo loṣu keji  ati ikẹta ọdun yii.
Ijsba orilẹede Togo ṣalaye pe awọn ti fi arabinrin naa si abẹ ayẹwo fun itọju to peye; atipe ara rẹ n balẹ.
Orilẹede Togo ni orilẹede kẹsan ti arun Coronavirus yoo ti suyọ lẹyin Algeria to jẹ orilẹede akọkọ l'Afirika ti yoo kede arun ọhun lọjọ karundinlọgbọn oṣu keji ọdun 2020; Egypt, Morocco, Nigeria, Senegal, South africa, Tunisia ati Cameroun.
O ti le ni ẹgbẹrun lọna ọgọrun eeyan bayii to ti ko aarun yii lagbaye, gẹgẹ bii fasiti John Hopkins University ṣe fidi rẹ mulẹ ninu iwadii kan.
Ninu awọn wọnyi, o le ni ẹgbẹrun mẹta ti arun yii ti ran lọ sọrun lorilẹede China nikan.
Awọn orilẹede miran ti arun yii ti n ṣọṣẹ ni Japan, South Korea, France, Ilẹ Gẹẹsi, ati Amẹrika wa lara awọn orilẹede ti arun naa ti n ṣọṣẹ.
Coronavirus: Àjọ bọ́ọ̀lù ní France sún ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ PSG àti Strasbourg síwájú nítorí Coronavirus
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ibanujẹ ba awọn ololufẹ ere bọọlu ni liigi orilẹede France, atawọn ololufẹ Ligue 1 pẹlu bi awọn alaṣẹ
Ere bọọlu lorilẹede naa ṣe sun ifẹsẹwọnsẹ laarin ikọ ẹgbẹ agbabọọlu Paris Saint Germain, PSG ati Strasbourg siwaju nitori ọwọja arun Coronavirus nibẹ.
Eyi ni ifẹsẹwọnsẹ bọọlu akọkọ laarin awọn ikọ odu ẹgbẹ agbabọọlu lorilẹede naa ti wọn yoo maa wọgile nitori arun naa.
Orilẹede France wa laarin awọn orilẹede to n moke lagbo awọn orilẹede ti arun Coronavirus ti n ṣọṣẹ julọ pẹlu bi o ti ṣe jẹ pe ẹgbẹta o le mẹtala eeyan lo ti ko sọwọ arun naa ti eeyan mẹsan ti jade laye nitori rẹ.
Titi di bi a ṣe n kọ iroyin yii wọn ko tii sọ igba ti ifẹsẹwọnsẹ naa yoo wa pada waye.
Orilẹede France kọ ni akọkọ orilẹede tawọn alaṣẹ ere bọọlu yoo ti wọgile ifẹsẹwọnsẹ bọọlu nitori arun Coronavirus.
Orilẹede Italy wọgile ifẹsẹwọnsẹ marun lopin ọsẹ to kọja nitori arun naa ninu eyi ti ifẹsẹwọnsẹ Juventus ati Intermilan wa.
coronavirus: Ìdí tí obìnrin fi leè rù ú là ju ọkùnrin lọ
Oríṣun àwòrán, Getty Images
O n dabi ẹni pe o ṣeeṣe fun ọkunrin lati ku lọwọ arun Coronavirus to n ja nilẹ bayii ju awọn ọkunrin lọ.
Bakan naa si ni ko ṣeeṣe fawọn ọmọde lati ku nipasẹ arun naa to bi awọn agba lọ.
Ọpọlọpọ awọn eeyan lo jẹ wi pe arun yii yoo kan ṣi ni fila lọ ni, ṣugbọn awọn miran a maa tipasẹ arun yii dero ọrun.
Ti o ba ri bẹẹ, ki wa gan an lo n fa iyatọ laarin bi ọṣẹ arun yii ṣe le si laarin ẹya akọ atabo tabi ara awọn ọmọ wẹwẹ ati agbalagba?
Gbogbo awọn iroyin ti a ri kojọ lori eyi wa latawọn iwadii gbankọ gbi tawọn ibudo amojuto ajakalẹ arun lorilẹede China ṣe, Chinese Centers of Disease Control.
ẹgbẹrun mẹrinlelogoji (44,000)  ni iwadii naa gbe yẹwo ninu eyi to ti fihan pe ida mẹta din diẹ ninu ọgọrun (2.8%) awọn ọkunrin to ko arun Coronavirus yii lo jade laye; bẹẹni ida meji o din diẹ ninu ọgọrun (1.7%) awọn obirin to ko arun naa lo jade laye.
Bẹẹni ko tilẹ sun mọ ida kan ninu ọgọrun (0.2%) awọn ọmọde ati ọṣọrọ ọdọ to ko arun yii to jade laye; nigba ti ida marundinlogun (15%) awọn agbalagba ti ọjọ ori wọn ti ju ọgọrin ọdun lọ laisan Coronavirus ti ran lọ sọrun.
Ọna meji ni a le gba ṣalaye abajade iwadii naa lori eyii.
Yala ko jẹ wi pe awọn obirin atọmọde ko lee saba ko arun yii tabi ko jẹ wi pe awọn ẹya ara wọn lagbara lati koju kokoro arun coronavirus ọhun.
"'Koko pataki kan ni wi pe, kokoro arun tuntun yii n tan kalẹ, gbogbo eeyan lo si lee ko o."" Eyi jẹ ọrọ Dokita Bharat Pankhania lati fasiti Exeter sọ."
Idi eyi ni pe ko si ajẹsara kankan ninu agọ ara to lee dena arun yii nitori ko si ẹnu to lugbadi rẹ ṣaaju asiko yii ri.
Lootọ o, lasiko ti arun naa ṣẹṣẹ bẹẹ, o ṣoro diẹ fun awọn ọmọde lati ko kokoro arun naa.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Yoo ya ọ lẹnu pe iyatọ gedegbe wa laarin iye awọn ọkunrin ati obinrin to n ku nipasẹ arun yii?
Ṣugbọn eyi ko ya awọn onimọ sayẹnsi lẹnu o.
Bi a ko ba ni jayopa, bakan naa lọrọ ṣe rilawọn aisan miran bii otutu.
Lara idahun si eyi naa ni pe, igbe aye awọn ọkunrin buru jai ju tawọn obirin lọ lawọn nnkan ti wọn n ṣe bii siga mimu.
Siga n ba ẹdọ jẹ. Iru ẹni bẹẹ ko lee yee rara. Gẹgẹ bi Dokita Nathalie MacDermott lati ile ẹkọ giga Kings College ni ilu London ṣe sọ.
Eyi ṣeeṣe ko fa wahala nla lorilẹede China nibi ti  iwadii ti fihan pe nnkan bi ida mejilelaadọta ninu ọgọrun  awọn ọkunrin wọn lo n ṣana si siga ti o si jẹ pe iwọn perete ida mẹta nini ọgọrun awọn obinrin lo n mu siga nibẹ.
Bakan naa ni iwadii fihan pe iyatọ wa laarin eroja ajẹsara abawaye awọn obinrin ati ti ọkunrin ati ọna ti awọn eroja ajẹsara yii maa fi n gbera sọ nigbakugba ti aisan tabi arun kan ba fẹ dide.
Làá hàn mí dé, ètò tó ń ṣàlàyé ohun tó yẹ ká ṣe láti dènà àrùn Coronavirus
Mi o tíì rí olórí tó fẹ́ràn Naijiria tó Baba Obasanjo- Yoruba  Council of Elders
Idahun awọn ọjọgbọn ni pe 'rara'ṣugbọn awọn akọṣẹmọṣẹ kan ti n sọ ọ wi pe o ṣeeṣe o ki ọrọ maa ri bẹẹ
Oriṣiriṣi nnkan ni oyun nini maa n ṣe fun ara, lara rẹ si ni dindin agbara awọn eroja ajẹsara ara ku. Eyi si maa n mu ki wọn wa larọwọto ọpọlọpọ kokoro arun lasiko oyun yii.
Ijọba ilẹ Gẹẹsi ni 'ko si ami kan gboogi' to fihan pe awọn obirin to ba loyun lee fara kaasa arun coronavirus ju awọn ti ko loyun lọ.
Omidan jáde láyé lẹ́yìn tí ìlú lù ú, jáa sí ìhòhò lórí ẹ̀ṣẹ̀ tí kò ṣẹ̀
Awọn ọmọde lee ko arun Coronavirus. Iroyin tilẹ ti fi idi rẹ mulẹ pe ninu awọn to ti ni arun Ccoronavirus lagbaye bayii, ọmọ kekere jojolo ti wọn ṣẹṣẹ bi wa lara wọn.
Iyatọ nla wa laarin ilana eroja ajẹsara amuwaye (immune system) ọmọde ati ti agbalagba.
Awọn eroja yii lara awọn ọmọde maa n ṣiṣẹ ni kiakia ni; wọn a si maa jẹ iṣẹ kọja ibi ti wọn ba ran wọn de nigba miran. Eleyii lo maa n faa tawọn ọmọde maa fi n saba n ni aisan iba.
Bi awọn eroja yii ba n jẹ iṣẹ kọja ala, wọn le ṣe akoba fun awọn eroja ara yoku, ara idi si niyi ti awọn arun coronavirus lee mu iku dani.
Amọṣa gẹgẹ bi Dokita MacDermott ṣe sọ, eyi kii waye pẹlu arun Coronavirus lara awọn ọmọde o, ko si si ẹni to mọ ohun ti arun naa n ṣe lara awọn ọmọde ti eyi fi ri bẹẹ.
Collapsed building: Ilé tó jẹ́ ti báǹkì wó pa arákùnrin alágbàṣe ọmọ ọdún márùndínlógójì nílùú Èkó
Oríṣun àwòrán, Google Maps
Eeyan kan ti kagbako iku lasiko ti ile kan ti wọn n ṣatunṣe rẹ dawo ladugbo Palmgroove nilu Eko lọjọ Abameta.
Awọn alaṣẹ nilu Eko ajọ iṣẹlẹ pajawiri LASEMA ni arakunrin kan to ba ba iṣẹlẹ naa lọ jẹ ẹni ọdun marundinlogoji.
Alagbaṣe ni arakunrin naa.
Gẹgẹ bi ohun ti ọga LASEMA, Olufemi Damilola Oke-Osanyintolu ti ṣe sọ,Ezekiel Ajibola lorukọ rẹ ati pe ifọwọsowọpọ pẹlu awọn oṣiṣẹ panapana ti mu ki awọn ri oku rẹ yọ tawọn si ti gbe le ọlọpaa lọwọ.
O fikun ọrọ rẹ pe ile to dawo naa jẹ ti ile ifowopamọ Keystone Bank .
Laipẹ yi lọjọ kẹfa oṣu yi ni awọn alẹnulọrọ lara awọn ileeṣẹ ijọba to n f'awọn eeyan ni iwe aṣẹ ki wọn to kọ ile ṣe ipade lori bawọn eeyan ti ṣe n kọ ile lọna ti ko tọ.
Ajọ to n dena didawo ile ni Naijiria ni o kere tan ile to to ẹgbẹrun mẹrindinlọgọta lo wa ninu ewu didawo.
Àwọn aladugbo ibí tí ìjọba Èkó tí n wole sọ èrò ọkàn wọn
Lagosollapsedbuilding: Àwọn èèyàn ìpínlẹ̀ Eko ní ìjọba, aráàlú lọ́wọ́ nínú bí ilé ṣe ń wó
Aarẹ ajọ naa Akinola George sọ fun BBC pe idi ti iru nkan bayi fi n ṣẹlẹ ni pe awọn ti ko mọ nipa ile kikọ ni wọn ma n kọ awọn ile ni Eko.
Lọdun 2029 bakanna ajọ LASEMA naa sọ kin ọrọ yi lẹyin pe lilo ayederu eronja ikọle ati gbigbe iṣẹ fawọn alagbaṣe ti ko dantọ  lo mu ki ile kan wo ladugbo Ikoyi ni Eko.
NCDC: Kò dájú pé láti ilé ni ọmọ Nàìjíríà tó ní Coronavirus ní Washington ti ko
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ajọ to n dẹkun ajakalẹ arun lorileede Naijiria,NCDC, ti fidi ọrọ mulẹ pe ọmọ Naijiria ni  eeyan ẹlẹkeeji to ni aisan Coronavirus ni ilu Washington lorileede Amẹrika.
Loju opo ajọ naa ni Twitter ni wọn ti fidi ọrọ yi mulẹ amọ ṣa wọn ni ko daju pe lati Naijiria ni yoo ti ko lọ si Amẹrika.
Ajọ naa tẹsiwaju pe awọn ati akẹgbẹ wọn lorileede Amẹrika jijọ n fọrọ jomitooro ọrọ nipa iṣẹlẹ yi
Gẹgẹ bi ohun ta ri ka, ọfisi alaga Washington sọ pe ile iwosan kan ni Maryland lo ti n gba itọju.
Wọn ko ti darukọ arakunrin naa ṣugbọn wọn ni awọn alaṣẹ ilera n gbiyanju lati tọ awọn ibi to ti rin de ati awọn to ti ṣalabapade.
Ẹwẹ, NCDC ti sọ pe eeyan mẹtalelogun lawọn fura si pe wọn ni aisan coronavirus ni awọn ipinlẹ marun ni Naijiria.
Ninu awọn wọn yi ti wọn wa lati ipinlẹ Edo Eko,Ogun,Abuja ati Kano, eeyan kan pere layẹwo ti fihan pe o ni aisan naa ti eeyan kankan ko si ku latara aisan ọhun.
Chineme Martins: NFF ní àyẹ̀wò gbogbo irinṣẹ́ ètò ìlera ti di dandan báyìí ṣáájú eré bọ́ọ̀lù kankan
Ajọ to n ri si ere bọọlu ni Naijiriia, NFF ti sọ pe dandan ni ṣiṣayẹwo gbogbo irinṣẹ eto ilera awọn ẹgbẹ agbabọọlu bayi ki ifẹsẹwọnsẹ kankan to le bẹrẹ.
Eyi waye lẹyin iku agbabọọlu Nasarawa United, Chineme Martins to di oloogbe nigba ti ifẹsẹwọnsẹ NPFL n lọ lọwọ pẹlu ẹgbẹ agbabọọlu Katsina United lọjọ Aiku.
Ikọ agbabọọlu Nasarawa ko tii sọrọ lori iku ojiji adilemu wọn to ti ṣoju ikọ agbabọọlu naa nigba mẹrin ọtọtọ ni saa bọọlu yii.
Minisita fun ere idaraya ati ọrọ ọdọ, Sunday Dare fi aidunnnu rẹ han loju opo Twitter rẹ nibi to ti sọ pe o ṣeeṣe ki Martins maa ku tawọn irinṣẹ eto ilera gidi ba wa ni papa iṣere ti iṣẹlẹ naa ti ṣẹlẹ.
Minisita ranṣẹ ibanikẹdun si ẹbi agbabọọlu Martins to di oloogbe.
Igba keji ree ti agbabọọlu yoo gbẹmi mi ni papa isẹre Nasarawa United niluu Lafia.
Oríṣun àwòrán, others
NFF, LMC Kwara United bá Nasarawa United kẹdun ikú Martins
Agbabọọlu Kano Pillars, Dominic Dukudod subu ni papa isere kan naa ninu osu kejila odun 2018.
Àwọn ọmọ Naijiria to ti kú lóri pápá lásìkò ìfẹsẹwọ́nsẹ
Kòsi àniàni, eré ìdáraya bọọlù jẹ́ èyi tó gbàjúmọ jùlọ ni orílẹ-èdè Naijiria àti ní gbogbo àgbàyé, ọ̀pọ́ àwọn ènìyàn lo si máa n lọ wòràn.
Sùgbọ́n o, bi àwọn ènìyàn ṣe n lọ wo bọọlu yìí ọjọ miran wà ti wọ́n maa n ri ohun ti kò dùn mọni nínú.
Ìrú ìṣẹ̀lẹ̀ abaní nínú jẹ yìí lo wáye lána nígbà ti  ọmọ agbábọọlu pẹlu Nasarawa United dédé súbú lulẹ to si gba ibẹ lọ si ọrun alákeji.
Èyí ju ọ̀pọ̀ ọmọ Naijiria , àjọ NFF, LMC, ẹbi, ọ̀rẹ àti àwọn ọmọ ẹgbẹ  àgbá bọọlu jákejádo Naijira sínú ọ̀fọ̀.
Ẹ̀wẹ̀, èyí kìí ṣe ìgbà àkọkọ láàrin àwọn agbábọọlu Nàìjíríà ti agbá bọọlu yóò dédé kú lóri pápá.
Àwọn agbábọ́ọ̀lù Naijiria to ti kú sórí pápá
Samuel Okwaraji: Samuel Okwaraji kú lórí pápá lásìkò to n gbá bọọlu láti fun pegede ife àgbáye pẹlu Angola.
Okwaraji kú ni ọjọ́ kejila, oṣù kẹjọ ọ́dun 1989.
Ọ̀pọ̀ lo si n dáro Okwaraji titi di àsìkò yìí nítori o jẹ olókìkí to si mọ ere orí pápá náà gbá dáadaa.
Oríṣun àwòrán, others
Àwọn ọmọ Naijiria to ti kú lóri pápá lásìkò ìfẹsẹwọ́nsẹ
Michael Umanika: Agbábọọlu Naijiria fún Zagatala PFK lo dójubolẹ lori pápá lásìkò ti wọ́n ṣe ìgbáradi láti lọ fun idíje.
Wọ́n fún ra pe àìsàn ọkan lo pàá, òun náà kú ni ọjọ kẹẹdogun ọdun 2016
Oríṣun àwòrán, other
Àwọn ọmọ Naijiria to ti kú lóri pápá lásìkò ìfẹsẹwọ́nsẹ
Amir Angwe: Agbábọọlu Julus Berger náà kú lóri pápa lọ́dun 1995.
Iròyìn ni pé, àisan ọkàn náà lo pa òun náà.
Orí pápá ló ti subu ti oun náà si gba ibẹ̀ lọ, ọmọ ọdun mọkandinlọgbọ̀n ni lásìkò náà.
Orobosan Adun: Kí wọ́n to lọ fún ìfẹsẹwọ́nsẹ pẹlú Enugu Ranger, àwọn ọmọta kan ti wọ́n fúra si pe o jẹ oloufẹ àwọn ẹgbẹ́ agbábọọlu ti wọ́n fẹ́ lọ bá gbá ti kọkọ ṣe ìkọlu si asọle ẹgbẹ́ agbábọọlu Warri Wolves (Adun).
Asikò ìgbáradi lóri pápá ni Adun kú lẹ́yin ọjọ mẹta ìṣẹ̀lẹ̀ náà.
O kú ni ẹni ọdun méjidinlọgbọ̀n, lọdun 2009.
Azeez Saka: Lọ́dun 2017, okiki irú èyi náà tún kan nígbà ti ọmọ akọnimọọgba bọọlu ori tabili Kasali Lasisi ku.
Saka jẹ ọmọ ẹgbẹ́ agbábọọlu Kwara United, o kú ni ori papa lásìkò ìgbáradi pẹlu àwọn akẹgbẹ́ rẹ ní ilú ìlọrin tii ṣe oluulu ipinlẹ Kwara.
Oríṣun àwòrán, Other
Àwọn ọmọ Naijiria to ti kú lóri pápá lásìkò ìfẹsẹwọ́nsẹ
Emmanuel Ogoli: Ọmọ ẹgbẹ́ agbábọọlu Ocean Boys kan náà kú lori pápá, lásiko idije  league, o si pada jẹ di oloogbe ni ilé iwosan.
O ku ni ọjọ kejila osu kejila ọdub 2010
NFF, LMC Kwara United bá Nasarawa United kẹ́dùn ikú Martins
Oríṣun àwòrán, others
NFF, LMC Kwara United bá Nasarawa United kẹdun ikú Martins
Àjọ NFF  àti LMC ṣì n sọ̀fá ìkú adilé mú ọmọ ẹgbẹ́ agbabọolu Nasarawa United Chineme Martins.
Alaga àjọ LMC, Shehu Dikko, nínú àtẹjáde kan to fi ba Nasarawa United àti ẹbi olóògbé náà kẹ́dun.
Ọgá àgbà èré bọọlu òun ni àwọn yóò ṣe àyẹwò okú náà láti mọ irú ikú to pa Martins ni pàtó.
Oríṣun àwòrán, Others
NFF, LMC Kwara United bá Nasarawa United kẹdun ikú Martins
A ní ìgbàgbọ́ pé tí a ba mọ irú ikú to pa a, ni yóòjẹ ki a lé mọ irú igbésẹ̀ ti a o gbé láti dẹkun irú ìṣẹ̀lẹ̀ bẹ́ẹ̀.
Ẹ̀wẹ̀, àjọ LMC ń wá ọ̀nà láti ni ìbáṣepọ ẹgbẹ́ agbábọọlù olóògbé àti àwọn ẹbi rẹ̀, láti le mọ ọ̀nà ti wọ́n yóò gbà ṣe ìrànwọ́ níru àsìkò aburu yìí
Bákan náà ni àjọ NFF fi ẹdun ọkan rẹ̀ han fún ọmọ agbabọọlu ọ̀un lóri àtẹjiṣẹ́ twitter rẹ.
Bakan náà ni àwọn ẹgbẹ́ agbábọọlu Kwara United náà ti kẹdun pẹlú Nasarawa United lori ikú Martins.
Ìròyìn Yàjóyàjó - Nàìjíríà kéde èèyàn míràn pẹ̀lúu àrùn Coronavirus
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ìròyìn tó ń tẹ̀ wa lọ́wọ́lọ́wọ́ ní wí pé ijọba apapọ orilẹede Naijiria ti kede eeyan keji to to ko aarun Corona virus lorilẹ̀ede Naijiria.
Minisita feto ilera lo kede eyi
Gẹgẹ bi atẹjade kan lori oju opo twitter ajọ to n gbogunti ajakalẹ arun lorilẹede Naijiria, NCDC ṣe sọ, onitọhun wa lara awọn to ni nnkan pọ pẹlu ọmọ orilẹede Italy ti wọn kọkọ kede pẹlu aarun naa ni ọsẹ meji sẹyin.
Ẹni ti wọn ṣẹṣẹ kede naa wa lara awọn ti wọn fi sabẹ ahamọ ayẹwo ni ipinlẹ Ogun.
Ajọ naa ni gbogbo awọn eeyan to ni ajọṣepọ kan abi omiran pẹlu arakunrin ọmọ orilẹede Italy naa ni ipinlẹ Eko ati Ogun ni yoo ṣi wa labẹ ahamọ ayẹwo ajọ naa ati ileeṣẹ eto ilera pajawiri lawọn ipinlẹ mejeeji.
Bakan naa ni minisita feto ilera tun kede rẹ pe awọn onimọ ijinlẹ nipa kokoro aifojuri latawọn ileewosan nla LUTH, ibudo iwadi ajakalẹ arun ni fasiti Redeemers ni Ede ati ibudo iwadi nipa iṣegun oyinbo, NIMR to wa nilu Eko ni wọn pawọ pọ lati ṣawari ilana kan fun itọpinpin arun Coronavirus eyi ti oyinbo n pe ni 'genome sequencing'
O ni nipasẹiwadii tuntun yii, wọn ti fi idi rẹ mulẹ pe irufẹ kokoro arun Coronavirus to n ja kalẹ ni orilẹede Italy ati ilu Wuhan lorilẹede China.
Obasanjọ: Ọbasanjọ ní òhun yóò fi ìyókù ayé òun san oore Ọlọrun ni
Minisita feto ilera ṣalaye ninu ọrọ rẹ fawọn oniroyin pe ogoji eeyan ni wọn ti fi sahamọ ayẹwo lori arun yii nipinlẹ Ogun; ogun miran pẹlu ṣi wa labẹ ayẹwo nipinlẹ Eko.
Eto iwadii ilana fun itọpinpin arun coronavirus tuntun ọhun ni akọkọ nilẹ Afririka, eleyi si fi ẹri si ohun ti ajọ ilera agbaye, WHO sọ pe igbaradi orilẹede Naijiria yanranti ju bo ṣe n lọ lọpọ awọn orilẹede lagbaye.
Chris Oyakhilome: Wọn tí fòfin de iléeṣẹ́ ìròyìn Chris Oyakhilome lẹ́yìn tó sọ pé 5G lọ ṣokùnfà Coronavirus
Oríṣun àwòrán, @lwsat
Ijọba ilẹ gẹẹsi ti fofin de ileeṣẹ igbohunsafẹfẹ oluṣoagutan ijọ Christ Embassy, pasitọ Chris Oyakhilome lẹyin ti wọn fẹsun kan pasitọ naa pe o n waasu tako ilana ofin wọn.
Igbeṣẹ yii lo waye lẹyin ti pasitọ ọhun sọ pe nẹtiwọọki 5G lo ṣokunfa ajakalẹ arun Coronavirus.
Ileeṣẹ to n mojuto igbohunsafẹfẹ nilẹ naa, Ofcom ni iwaasu naa ti awọn eeyan orilẹede Gẹẹsi ni anfani lati tẹti si lee ṣe ijamba fun wọn, nitori naa, o lodi si ofin igbohunsafẹfẹ ilẹ wọn.
Bakan naa, wọn fẹsun kan ileeṣẹ amohunmaworan Loveworld to jẹ ti pasitọ naa pe o sọ pe ogun Hydroxychloroquine lagbara lati ṣegun arun Covid-19 to n ba gbogbo aye finra.
Ninu atẹjade kan ti ileeṣẹ Ofcom fi lede, wọn ni ileeṣẹ amohunmaworan Loveworld ti gba pe wọn ko ni ṣe bẹ mọ.
Ijọba ilẹ Gẹẹsi ni ijiya ileeṣẹ tẹlifiṣọn Loveworld ni pe yoo maa sọ ninu igbohunsafẹfẹ rẹ pe oun kede ọrọ ti ko ni otitọ ninu nipa arun Cpvid-19.
Ṣé òótọ ni pé èèyàn leè kó Coronavirus láti ara aṣọ tàbí bàtà?
Ileeṣẹ naa si ti fesi pe oun yoo ṣe gẹgẹ bi ijọba ti pa laṣẹ fun un.
Ẹwẹ, ijọba UK atawọn onimọ ijinlẹ ti ni ko si ootọ ninu ọrọ ti awọn kan sọ kiri pe nẹtiwọọki 5G naa lee ṣokunfa arun Coronavirus.
Akure okada attack: Ọlọ́kadà tí àwọn afunrasí darandaran ṣá ní
Oríṣun àwòrán, David Oyedepo Ministries International
Biṣọọbu David Oyedepo ti ṣe apejuwe ijọba to wa lorilẹede Naijiria bayii gẹgẹbi egun fun orilẹede Naijiria.
Biṣọọbu Oyedepo sọrọ yii lasiko to fi n waasu ni ijọ rẹ.
O ni ofin tawọn aṣofin n gbero lori kẹlẹnu o ṣẹnu lori ayelujara, (social media bill) iyẹn social media bill jẹ eyi to tako ọpọlọ ati arojinlẹ.
Agba iranṣẹ ọlọrun naa wa ṣalaye pe gbogbo ọmọniyan lo lẹtọ lati sọ ọrọ ẹnu wọn lai si ẹni ti yoo dawọn lẹkun.
"Oyedepo ni ""ni iwoye temi eyi ni ohun to buru juls ti yoo ṣẹlẹ si orilẹede Naijiria, iyẹn ijọba yii. Ohun ni ijọba to buruju, koda bii egun lo ri."""
Africa eye: Fàyàwọ̀ igi gẹdú ló ń wáyé ní Gambia àti Senegal
O ni ijọba to wa lorilẹede Naijiria bayii ko ni pato ibi to n lọ ati pe gbogbo ilana iṣejọba lo ti fẹ sọ orilẹede Naijiria da bi Ọgba ẹranko.
Eyi kọ ni igba akọkọ ti Biṣọbu oyedepo yoo ma sọko ọrọ ranṣẹ si aarẹ Muhammadu Buhari ati ijọba rẹ.
Social Media Bill: Sowore fàáké kọ́rí, ó ní àbádòfin láti ṣàmójútó ayélujára kò lè fẹsẹ̀ múlẹ̀ láéláé
Ajafẹtọ ọmjọniyan, Omoyele Sowore to kuro lahamọ ajọ ọtẹlẹmuyẹ, DSS laipẹ yii, ti faake kọri lori abadofin to yoo maa ṣamojuto ayelujara ni Naijiria to wa niwaju nile aṣofin agba niluu Abuja.
Sowore to ṣagbatẹru iwode ''Revolation Now'' sọrọ yii nibi ijiroro itagbangba lori abadofin naa lọjọ Aje, ọjọ kẹsan an oṣu kẹta ọdun 2020.
Sowore ni  ko si anfaani kankan ti abadofin naa le ṣe fun araalu bi ko ṣe pe ko daabo bo awọn to wa ni ijọba.
Sowore fikun ọrọ rẹ pe abadofin naa ko nibii re, koda o ni abadofin naa ti ku patapata.
Oniruuru ajafẹtọ ọmọniyan, awọn onimọ nipa oju opo ayelujara ati ọpọ eeyan lo peju pesẹ sile aṣofin lọjọ Aje nibi ijiroro itagbangba naa niluu Abuja.
Ẹwẹ, ile aṣofin agba naa fidi rẹ mulẹ pe awọn ṣetan lati ṣe agbeyẹwo ero awọn ọmọ Naijiria lori abadofin ọhun.
Ile ni awọn aṣofin ko ni gbe igbesẹ ti yoo ṣe ipalara fun awọn ọmọ Naijiria lẹyin tawọn ba ṣe agbeyẹwo erongba wọn tan.
Ọpọ awọn ọdọ lo gbe kaadi ilewọ dani nibi ti wọn kọ oriṣiiriṣii nnkan to nii ṣe pẹlu ẹtọ ọmọniyan si.
Sẹnẹtọ Muhammed Sani Musa lati ipinlẹ Niger lo ṣagbatẹru abadofin naa.
Emir of Kano: Gómìnà ìpínlẹ̀ Kaduna fún Sanusi ní ipò tuntun
Oríṣun àwòrán, SANI MAIKATANGA
Gomina ipinlẹ Kaduna ti yan Mahammadu Sanusi keji gẹgẹ bi ọkan lara awọn ajọ to n risi ọrọ karakata ni ipinlẹ Kaduna,(KADIPA).
Ninu atẹjade ti wọn fi lede ni wọn ti fi lede wi pe wọn fẹ fi eyi ṣe atunto ẹka to n risi idagbasoke ọrọ aje ni ipinlẹ naa.
Wọn fikun wi pe awọn gbe igbeṣẹ naa nitori wọn mọ pe ipinlẹ Kaduna yoo fi ohun ribiribi kọ lara ọgbọn ti Sanusi ni ati oye rẹ nipa eto ọrọ aje.
Awọn agbẹjọro Emir ilu Kano ti wọn ṣẹṣẹ rọ l'oye ti sọ pe awọn yoo pe ẹjọ kotẹmilọrun tako igbesẹ ijọba ipinlẹ Kano.
Ninu atẹjade kan ti agbẹjọro agba, Abubakar Balarabe Mahmoud, fi sita l'orukọ igbimọ agbẹjọro fun Emir Sanusi, ni wọn ti sọ pe awọn n ṣiṣẹ niluu Kano ati Abuja lọwọlọwọ lati pe ẹjọ, ayaafi ti wọn ba tu Emir naa silẹ ni ihamọ ni kiakia ni ko ni i jẹ ki awọn o gbe igbesẹ nilan ofin.
Igbimọ naa to ṣapejuwe lile Emir Sanusi  kuro niluu Kano lẹyin ti wọn rọ ọ l'oye, gẹgẹ bi nkan ti ko ba ode oni mu sọ pe ko si ninu ofin Naijiria.
Ati wi pe ile ẹjọ Kotẹmilọrun l'orilẹ-ede Naijiria sọ ọ ni gbangba pe iru igbesẹ bẹ ko ba ofin mu, lasiko ti ijọba ipinlẹ Kebbi rọ Emir ilu Kebbi l'oye.
"Wọn tẹsiwaju lati sọ pe ""ko si igba kankan ti ijọba ipinlẹ Kano fi iwe ranṣẹ tabi pe Emir si akiyesi lori ẹsun aigbọran si awọn alaṣẹ, ati kikuna lati maa lọ fun ipade ati eto ti ijọba ba gbe kalẹ, ti wọn fi kan an."
Bakan naa ni wọn ko fun ni anfaani lati rojọ tabi ṣalaye lori awọn ẹsun ti wọn fi kan an.
Wọn tẹsiwaju lati sọ pe lẹyin ti gomina ba to o ṣepade ati ijiroro pẹlu igbimọ lọbalaba ipinlẹ Kano nikan lo to le gbe igbesẹ lati rọ Emir kankan l'oye.
"Wọn ko fi ọrọ naa lọ igbimọ lọbalọba ipinlẹ Kano, nitori pe Emir Sanusi ni alaga igbimọ naa.
Ko si si bi wọn yoo sẹ fi to igbimọ l'eti, ti ko ni i mọ si."
Yaara yii ni Emir Kano tẹlẹ, Sanusi Lamido sun mọju
Ilu naa lo balẹ si lẹyin ti ijọba ipinlẹ Kano rọ ọ l'oye. Ilu naa lo si sun mọju.
Olori agbegbe Loko, Abubakar Hamed Sabo sọ fun BBC pe wọn gbe Emir Sanusi wa si ilu Loko London, ṣugbọn wọn ti pada gbe e kuro lọ si ilu Awe nipinlẹ Nasarawa bakan naa.
Aafin yii ni wọn kọkọ gbe Sanusi Lamido Sanusi lọ lẹyin ti wọn rọ ọ l'oye
Hamed sọ pe wọn gbe e kuro ni Loko nitori pe agbegbe naa ko tọ si i ni ipo ọlọla to wa.
A ko ni ẹrọ amuletutu, faanu nikan la ni, agbegbe yii si gbona pupọ.
Iroyin kan to tẹwa lọwọ sọ pe wọn ti gbe Emir ilu Kano tẹlẹ, Sanusi Lamido Sanusi kuro ni ipinlẹ Nasarawa lọ si ibi ti ẹnikẹni ko mọ.
Iroyin naa sọ pe baalu ayara fefe ẹlikọpita ni wọn fi gbe kuro ni abule Loko ti wọn fi pamọ si lati ọjọ Aje.
Wọ́n ti gbé Emir Kano tẹ́lẹ̀, Sanusi Lamido kúrò ní Nasarawa lọ síbi tẹ́nìkan kò mọ̀
Ọjọ Aje ni gomina ipinlẹ Kano rọ Emir Sanusi l'oye, ti wọn si tun le kuro nilu Kano lọ si Nasarawa.
Ao ma a mu wa fun yin bi nkan ba tun ṣe n lọ.
Emir ana ilu Kano Sanusi Lamido Sanusi ni oun ti gba kadara iyọnipo to ṣẹlẹ si oun gẹgẹ bi amuwa lati ọdọ Ọlọrun.
Sanusi fi ọrọ yi sita ninu fọnran fidio kan to ṣe ki o to fi afin rẹ nilu Kano silẹ lọjọ Aje.
Ninu fidio naa Sanusi sọ ni ede Hausa pe ''Ọlọrun ti kọ wi pe oun yoo jẹ́ ọba Kano bẹẹ naa si ni akọsilẹ wa wi pe wọn yoo yọ oun.''
O ni ''Inu mi dun mo si dupẹ.Mo ki ẹnikẹni ti wọn ba gbe oye naa fun ku orire.Mo ti sọ fawọn iyawo mi ati mọlẹbi mi pe ki wọn funemir tuntun ni ọwọ to yẹ''
Ni ọjọ Aje ni ijọba Kano yọ Sanusi kuro lori oye ti wọn si paṣẹ pe kio fi ilu silẹ lọ si ipinlẹ Nassarawa.
Lẹyin iyọnipo rẹ, wọngbe ọpa aṣẹ fun Aminu Ado Bayero gẹgẹ bi Emir tuntun ilu Kano.
Ẹwẹ, agbẹjọro Sanusi Abubakar Mahmoud ti sọ pe iyọnipo ati aṣẹ ki Sanusi fi ilu silẹ tako ofin.
Lasiko to n ba ile iṣẹ amounmaworan Naijiria Channels TV sọrọ, Mahmoud ni igbesẹ naa kọdi ẹtọ Sanusi labẹ ofin ati pe ti awọn ba fi le lọ si ile ẹjọ o di dandan ki adajọ yi aṣẹ naa pada.
Oríṣun àwòrán, Legalnaija.com
''Nkan to ku bayi ni ki a ṣe ipade pẹlu Sanusi lori igbesẹ ti a o gbe.Nkan ti o ba sọ fun wa ni a o ṣe ni igbesẹ.A o fun lasiko lati da ọrọ yi wo ki a to gbe igbesẹ''
Ado Bayero: Èyí ni àwọn ohun tó yẹ kí o mọ̀ nípa Emir ìlú Kano tuntun
Oríṣun àwòrán, Aminu Ado Bayero/Instagram
Ijọba ipinlẹ Kano lọjọ Aje gbe igbesẹ meji eleyi ti ọkan ninu rẹ yẹ aga ipo Emir nidi ẹnikan ti o si gbe Emir mi si ori ipo.
Ẹni ti o di Emir ikẹẹdogun ni Kano bayi ti agbara si tiwa ni ikapa rẹ ni Aminu Ado Bayero.
Emir ni ki o to jẹ Emir Kano.Iya to bi jẹ ọmọ Emir ti aburo rẹ naa si jẹ Emir.
Kini awọn nkan miran to yẹ ni mimọ nipa Emir Ado Bayero? Ẹ jẹ ki a sé atupalẹ wọn lọọkọọkan.
Alhaja Adeoti ti awọn eeyan a ma pe ni Iya Aminu ni Iya to bi Emir tuntun yi
Iya yi fun ara rẹ jẹ ọmọ ọba Abdulkadir Dan Bawa to jẹ Emir Kẹjọ nilu Ilorin.
Oríṣun àwòrán, Aminu Ado Bayero/Instagram
Oba Abdulkadir Baba Agba to jẹ oba Kẹẹwa ilu Ilorin si jẹ ẹgbọn Iya Aminu lọkunrin.
Wọn fi iya Aminu fun ọkọ iyẹn Emir Ado Bayero ilu Kano ti o si bi ọpọ ọmọ fun un.
Ọdun kannaa ni wọn bi EmirAminu Ado Bayero ati Lamido Sanusi
Ọdun 1961 ni wọn bi ọba Aminu Ado Bayero eleyi to se rẹgi pẹlu ti Sanusi Lamido Sanusi ti o gba ipo lọwọ rẹ yi.
Fulani to wa lati agbegbe Sullubawa ni Naijiria ni Aminu n ṣe.
Oríṣun àwòrán, Aminu Ado Bayero/Instagram
Ṣaaju ki wọn to fi Aminu Ado Bayero jẹ Emir ilu Kano,oun ni Emir ilu Bichi to jẹ ọkan lara awọn ilu to wa labẹ Emirate ilu Kano.
Yatọ si eleyi, o di ipo to pọ mu bi Dan Majen ilu Kano,ki o to bọ si ori apere gẹgẹ bi Emir tuntun.
Apa ariwa Naijiria ni Bayero ti ka pupọ ninuiwe to ka .sugbọn o tẹsiwaju lọ ilẹ Amẹrika nibi to ti kọ imọ nipa ọkọ ofurufu.
Imọ nipa ibaraẹnisọrọ ti a mọ si Mass Communication lo ka ni fasiti Bayero nilu Kano.
Ko pẹ lẹyin igba to kawe dari nipa imọ ofurufu ni o gba iṣẹ labẹ ile isẹ ọkọ ofurufu Kabo Air gẹgẹ bi alukoro.
Emir Sanusi: Èyí ni ìpa tí àṣẹ àtìpó tí Ganduje pa le è ní lórí ìgbé ayé Emir àná, Sanusi Lamido Sanusi
Sanusi Lamido Sanusi II ati baba-baba rẹ, Muhammadu Sanusi I
Lati igba iwasẹ wa ni a ti mọ daadaa pe bi a ba ti rọ ọ Ọba kan loye, ko lee gbe ninu ilu kan naa pẹlu Ọba tuntun, nitori gẹgẹ bi ọrọ awọn agba, ọba meji ko lee gbe ninu ilu kan naa.
idi niyi ti
nigba tawọn oyinbo amunisin wọ ilu, ko din ni ọba meje si mẹjọ tawọn oyinbo naa rọ loye tiwọn si yọ ran lọ ṣe atipo ni ilu Lọkọja.
Awọn ijọba apa ariwa orilẹede Naijiria naa tẹwọ gba ofin tawọn amunisin lo yii ti wọn si n lo lati fi rọ ọba loye pẹlu.
Wo àwọn ohun márùn ún tó yẹ kí o mọ̀ nípa Sanusi
Sanusi: Ìyọnípò mi kò ṣẹ̀yìn Ọlọ́run
Èyí ni àwọn ìdí tí ìjọba ìpínlẹ̀ Kano ṣe rọ Emir Sanusi Lamido l'óyè
Ìròyìn Yàjóyàjó - Nàìjíríà kéde èèyàn míràn pẹ̀lúu àrùn Coronavirus
Pataki lara awọn Emir ti ọrẹ ofin yii ba ni Emir Muhammadu Sanusi akọkọ to jẹ baba baba Emir Lamido Sanusi ti wọn yọ ni ọjọ iṣẹgun.
Oríṣun àwòrán, KASSIM TURAKI
Emir Sanusi I àti díẹ̀ nínú àwọn ọmọ-ọmọ rẹ̀, tó fi má Emir Muhammadu Sanusi II
Ni ọdun 1963 ni ijọba ariwa Naijiria ni ki Baba baba Lamido Sanusi II, iyẹn Muhammadu Sanusi I o lọ ṣe atipo ni Bauchi.
Ni ọdun 1963 si nnkan bi ọdun 1980 nigba ti gomina alagbada nipinlẹ Kano nigba naa, Abubakar Rimi ni ko pada wa si ipinlẹ Kano, ṣugbọn kii ṣe ilu Kano ki o to jade laye ni ọdun 1984.
Gbogbo awọn ijọba ẹkun ariwa lo ṣi n lo ofin yii.
Facebook love: Ọla àti Folashade ṣègbéyàwó lẹ́yìn ọjọ́ mọ́kànlá tí wọ́n ríra ni Facebook
Awọn Emir miran ti wọn rọ loye ti wọn si le kuro ni ilu niwọnyii:
Sultan Dasuki-Ijọba ologun labẹ olori ijsba naa nigba naa, Sani Abacha lo rọ Sultan Dasuki ti ilu Kano loye lọdun 1996, wọn ni ko lọ ṣatipo ni Taraba ki wọn to gba a laye lati lọ si ilu Kaduna.
Emir Almustapha Jokolo: Emir ilu Gwandu ni Almustapha Jokolo, ọdun 1990 ni wọn rọọ loye ti wọn si lee lọ ṣatipo ni ipinlẹ Nasarawa. Lẹyin to gbe ijsba lọ sile ẹjs ni ile ẹjọ to sọ pe ijọba ko lẹtọ lati ṣe bẹẹ.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ninu ọrọ to ba BBC News Yoruba, Mamhud Jega onimọ nipa aṣa ilu Kano ṣalaye pe pẹlu bi wọn ṣe fun Lamido Sanusi ni aṣẹ gbele rẹ yii, yoo lee ri awọn mọlẹbii rẹ ṣugbọn ko daju boya yoo lee foju ri awọn eeyan miran.
Amọṣa o ni pẹlu bi Emir Almustapha ti ilu Gwandu ti ṣe bori nile ẹjọ lori ibi ti ijọba ti ni ko lọ ṣatipo, o ṣeeṣe ki Sanusi o bori bo ba lọ sile ẹjọ lati tako ibi ti wọn ti ni ko lọ ṣatipo. Amọṣa ko ni lee pada si ilu Kano mọ.
Emir of Kano: Ganduje fún Aminu Ado Bayero ní ìwé ìyannisípò gẹ́gẹ́ bí Emir ìlú Kano
Oríṣun àwòrán, Facebook/Aminu Ado Bayero
Ati moye yii jẹ, iwo n papa, iwo n na! Bayii lọrọ ri fun Emir ilu kano tuntun, Aminu Ado Bayero atawọn alatilẹyin rẹ, lẹyin ti Gomina Abdullahi Ganduje fun ni iwe iyannisipo nirọlẹ Ọjọru niluu Kano.
Aminu ni Emir ẹlẹẹkẹẹdogun ti yoo jẹ niluu Kano lapa ariwa orilẹede Naijiria.
Lọjọ Aje ni akọwe ijọba ipinlẹ Kano, Alhaji Usman Alhaji kede Aminu Ado Bayero gẹgẹ bi Emir tuntun ilu Kano lẹyin ti ijọba rọ Lamido Sanusi loye.
Emir Bichi ni Aminu tẹlẹ ko to di Emir ilu Kano lọjọ Aje, o ti rọpo Emir Kano tẹlẹ, Lamido Sanusi bayii.
'Fáàbàdà! Buhari kò lọ́wọ́ sí ìyọnípọ̀ Sanusi, e yé parọ́ kiri.'
Faabada! Aarẹ Muhammadu Buhari ko lọwọ ninu irọloye Emir ilu kano ana, Lamido Sanusi bii ti wulẹ o mọ.
Oludamọran pataki fun Aarẹ Buhari lori ọrọ iroyin, Garba Shehu lo fọrọ yii lede loju Twitter rẹ.
Oríṣun àwòrán, Facebook/Lamido Sanusi
Shehu ṣalaye pe ko si otitọ kankan ninu ahesọ ọrọ tawọn eeyan kan n gbe kiri pe ati yọ Sanusi nipo ko sẹyin Buhari.
Oludamọran aarẹ ni oṣelu lo wa nidi ọrọ tawọn kan n sọ pe Aarẹ Buhari mọ nipa bi ijọba ipinlẹ Kano ti rọ Sanusi loye.
Garba Shehu ni adura ni Buhari pe ifẹ Eleduwa nikan ni ko maa wa si imuṣẹ nigba gbogbo nipinlẹ Kano, ẹnikẹni ko wu ko wa lori itẹ gẹgẹ bi Emir ilu Kano.
Aarẹ Buhari ki awọn araalu Kano fun ifarabalẹ wọn ati bi wọn ti gba alaafia laaye lati igba ti ijọba Gomina Abdullahi Ganduje ti rọ Sanusi loye gẹgẹ bi Emir ilu Kan
Ààrẹ Buhari mọ̀ nípa ìyọnípò Sanusi Lamido II gẹ́gẹ́ bí Emir Kano-Kwankwaso
Gomina nigba kan ri nipinlẹ  Kano Rabiu Musa Kwankwaso ti di ẹbi iyọninipo Emir Kano,Sanusi Lamido Sanusi, ru aarẹ Muhammadu Buhari.
Olori ẹgbẹ alatako naa sọ pe ijọba ipinlẹ Kano fun ara wọn n sọ pe aṣẹ ti wọn pa fawọn lati ọdọ ijọba apapọ lawọn tẹle lati rọ Sanusi loye.
O ṣalaye pe awọn to sunmọ aarẹ n sọ pe aarẹ Buhari kii da si iru awọn aawọ bayi ṣugbọn ti ọrọ ba kan ipinlẹ Kano,bakanna kọ ni ọmọ ti ṣe sori.
Kwankwaso sọ pe Buhari n da si ọrọ Kano.Nigba to yẹ ko sọrọ,gbogbo wa la ripe o dakẹ.Nigba ti ko ba si yẹ kodakẹ, a ma sọrọ.
Oríṣun àwòrán, @MBuhari
Lati igba ti wọn ti yọ Sanusi ni ọjọ Aje,ijọba Buhari ko ti fesi si iṣẹlẹ yi.
Ṣugbọn ṣaaju asiko yi ni aarẹ ti sọ wi pe oun ko ni dasi ọrọ abẹle to n waye ni ipinlẹ Kano. Ile iṣẹ BBC ko ti ri aridaju lati fi sọ boya lootọ ni awọn nkan ti Sẹnẹtọ Kwankwaso sọ yi.
Sẹnẹtọ Rabi'u Musa Kwankwaso
Lasiko ijọba Kwankwaso ni  Emir Sanusi gun ori oye.
Lọwọlọwọ bayi,Emir Sanusi wa ni ipinlẹ Nasarawa nibi ti wọn le lọ lẹyin iyọnipo rẹ.
Kwankwanso ni ohun ibanujẹ lo jẹ fun ipinlẹ Kano nitori ọba alapọnle nile ati lẹyin odi ni Sanusi jẹ.Gẹgẹ bi ohun to sọ, o ni awọn ri aridaju pe ijọba apapọ  mọ wi wọn gbe igbesẹ lati yẹ aga nidi Sanusi.
O tako ọrọ tawọn kan sọ wi pe lati igba ti Kwankwaso ti wa lori oye ni ijọba ti n kilọ fun Sanusi pẹlu bi o ti ṣe ma n sọ ọrọ ti ko fidimulẹ.
Oríṣun àwòrán, INSTAGRAM/MASARAUTAR KANO
''Mi o fi iwe ikilọ kankan ranṣẹ si Emir Sanusi tabi nkankan to jọ bẹ''
BBC tun beere lọwọ rẹ nipa ẹsun tawọn kan fi kan awọn alatilẹyin Kwankwasiyya pe awọn ni wọn runa si wahala laarin Sanusi ati Gomina Ganduje.
Gẹgẹ bi o ti ṣe sọ,Kwankwanso sọ pe  ohun tawọn eeyan Kano n sọ ni pe inuEmir Sanusi ko dun si Ganduje nitori pe aarẹ ti ni ki wọn jẹ ki awọn to ba jaweolubori ninuidibo ṣe ijọba.
O wa bẹnuatẹ lu bi aibọwọ funEmir yi ti ṣe tabuku ba awọn eeyan ipinlẹ Kano.
Eko bridge: Ìjọba ń ṣe afárá Eko Bridge l'Eko, àwọn ọ̀nà àbùdá tí ẹ lèè gbà nìyí
Oríṣun àwòrán, @jidesanwoolu
Ijọba ipinlẹ Eko ti bẹrẹ atunṣe opoopona afara Eko.
Nitori eyi ijọba ipinlẹ Eko ti wa kede awọn ọna abuja lati yago fun sunkẹrẹ fakẹrẹ ọkọ lagbegbe to yii ka.
Alakoso opopona ijọba apapọ nilu Eko, Ọgbẹni Adedamọla Kuti lo fi idi rẹ mulẹ pe apapkan afara Eko bridge yoo wa ni titi pa ki wọn lee ṣe awọn eto atunṣe gbogbo to ba yẹ nibẹ.
O ni awọn opo afara naa to ti n rẹ sara laarin agbegbe Alaka si Costain titi wọ Apọngbọn ni wọn fẹ tun ṣe.
Oríṣun àwòrán, others
Ninu atẹjade kan ti wọn fi sita lori awọn opopona tawọn awakọ lee maa gba lasiko ti iṣẹ atunṣe yii yoo fi maa waye, ijọba ipinlẹ Eko latẹnu olubadamọran fun gomina ipinlẹ Eko lori ọrọ ohun amayedẹrun ṣalaye pe ijọba ko ṣe eyi lati mu inira ba araalu bikoṣe lati mu abo to peye waye lori awọn ohun amayedẹrun ti wọn n lo.
Eyi ni awọn ọna abuda fun awọn ọlọkọ lasiko ti atunṣe afara Eko bridge naa yoo maa fi waye:
Emir of Kano: Gómìnà Kaduna, El-Rufai fi ipò kejì dá Sanusi lọlá láàrin ọjọ́ méjì
Oríṣun àwòrán, Faceboo/Nasir El-Rufai
Emir ilu Kano tẹlẹ, lamido Sanusi tun ti gba oye miiran lẹyin ti ijọba Gomina Abdullahi Ganduje rọ loye lọjọ Aje.
Lọjọ Iṣẹgun ni Gomina ipinlẹ Kaduna, Mallam Nasir El-Rufai yan an gẹgẹ bi ọkan lara awọn ajọ to n ri si ọrọ karakata ni ipinlẹ Kaduna,(KADIPA).
Lonii Ọjọru. ọjọ kọkanla oṣu kẹta ni Gomina El-Rufai tun fun Sanusi ni ipo mii.
Oludamọran Gomina lori ọrọ iroyin, Ọgbẹni Muyiwa Adekeye ṣalaye pe Sanusi ti di alakoso igbimọ alaṣẹ fasiti ipinlẹ Kaduna.
Sanusi rọpo Oba Alaye, Malam Tagwai Sambo to ti wa nipo naa lati ọdun 2005.
Oríṣun àwòrán, Nasir El-Rufai/Facebook
Adekeye ṣalaye pe Gomina El-Rufai fun Sanusi ni ipo ọhun nitori ipa to ti ko lori eto ẹkọ lorilẹede Naijiria.
Gomina El-Rufai dupẹ lọwọ Malam Sambo fun bi o ti gba pe ki Sanusi di alakoso igbimọ alaṣẹ fasiti ipinlẹ Kaduna tuntun ọhun.
Gómìnà ìpínlẹ̀ Kaduna fún Sanusi ní ipò tuntun
Gomina ipinlẹ Kaduna ti yan Mahammadu Sanusi keji gẹgẹ bi ọkan lara awọn ajọ to n risi ọrọ karakata ni ipinlẹ Kaduna,(KADIPA).
Ninu atẹjade ti wọn fi lede ni wọn ti fi lede wi pe wọn fẹ fi eyi ṣe atunto ẹka to n risi idagbasoke ọrọ aje ni ipinlẹ naa.
Wọn fikun wi pe awọn gbe igbeṣẹ naa nitori wọn mọ pe ipinlẹ Kaduna yoo fi ohun ribiribi kọ lara ọgbọn ti Sanusi ni ati oye rẹ nipa eto ọrọ aje.
Waste to Wealth: Ẹ̀gbin tìrẹ ni èròjà táwọn èèyàn míràn fi n ṣiṣẹ́ ajé, okoòwò ńlá ni
Waste to Wealth: Ẹ̀gbin tìrẹ ni èròjà táwọn èèyàn míràn fi n ṣiṣẹ́ ajé, okoòwò ńlá ni
Ijọba Naijiria ati ajọ eleto ayika lagbaye sefilọlẹ isẹ saatan dọrọ ti owo rẹ to miliọnu mẹẹdogun dọla, ti yoo pese isẹ fun ọpọ ọmọ Naijiria.
Bakan naa ni ọmọ Naijiria kan, Lolade Oresanwo ati ijọba ilẹ Gẹẹsi da ileesẹ kan silẹ, to n sọ aatan di ọrọ, towo rẹ to triliọnu mẹrin ati aabọ Pọun.
Bakan naa ni ileesẹ yii ti gba awọn eeyan to to ẹgbẹrun mẹta sẹnu isẹ, to si tun n wọ́na abayọ̀ si isoro ẹgbin ayika ati ailera to lee mu wa.
Nigba to n ba BBC sọrọ, Oresanwo ni ẹgbin tiwa ni ohun ọ̀rọ aje fun awọn eeyan miran nitori ọpọ eroja la lee fi ẹgbin se lati pawo wọle.
O wa rọ awọn araalu lati mase ri ẹgbin ni ayika wọn mọ amọ ki wọn maa ri eroja ọrọ aje to lee mu owo ati isẹ nla wa fun wọn.
Generator Ban: Àbá ọ̀hún wá yọ àwọn ilé ìwòsàn, pápákọ̀ òfurufú àti àkànṣe iṣẹ́ míì sílẹ̀
Oríṣun àwòrán, Others
Ile asofin agba ilẹ wa ti n se agbeyẹwo aba kan, ti yoo fofin de lilo ẹrọ amunawa jẹnẹratọ lorilẹede Naijiria.
Aba naa, ti Sẹnatọ Bima Enagi to n soju ẹkun idibo guusu ipinlẹ Niger gbe wa siwaju ile, ti wọn si ti ka fun igba akọkọ, lo tun n daba ijiya ẹwọn ọdun mẹwa fun ẹni to ba gbe jẹnẹratọ wọ Naijiria wa tabi to ba n ta a.
Bakan naa ni aba ọhun n kesi awọn araalu pe ki wọn dẹkun lilo ẹrọ amunawa naa eyi to n lo epo disu, pẹtiro abi ebo eebo karosini lọgan lorilẹede Naijiria.
Amọ aba naa wa yọ igbesẹ lilo ẹrọ amunawa fun awọn akanse isẹ to se koko silẹ, ninu eyi ta ti ri ipese iwosan isegun lawọn ile iwosan, papakọ ofurufu ati awọn oju irin reluwe.
Oríṣun àwòrán, Others
Lara awọn akanse isẹ to tun se koko ti wọn daba pe a le lo ẹrọ amunawa fun ni ẹrọ to n gbe ni lọ soke, wa si isalẹ taa mọ si ẹlifetọ, awọn ileesẹ iwadi ati awọn ipese isẹ miran to n waye nisẹ-isẹju lai dawọ duro.
Amọ sa, aba naa ni awọn eeyan to n se akansẹ isẹ pataki wọnyi gbọdọ gba asẹ lọdọ minisita fọrọ ohun amusagbara, ki wọn to lee lo ẹrọ amunawa naa.
Waste to Wealth: Ẹ̀gbin tìrẹ ni èròjà táwọn èèyàn míràn fi n ṣiṣẹ́ ajé, okoòwò ńlá ni
Lọwọ lowọ bayii, ipese ina ọba lorilẹede Naijiria lo n se segesege, ti awọn ọmọ Naijiria si n gbara le ipese ina ọba lati ara awọn ẹrọ amunawa, eyi ti wọn n na owo gege le lori lati fi ra epo sinu wọn.
Coronavirus: Ẹ wo ọ̀nà tí ọrọ̀ ajé Náíjíríà tó dẹnu kọlẹ̀ yóó fi ṣàkóbá fún aráàlú
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Oju ọjọ lẹka ọrọ aje ni Naijiria ṣe bi ẹni ṣokunkun nitori bi ojojo ti n se ogun katakara epo rọbi lagbaye, ti owo agba epo rọbi si ja walẹ.
Eyi ko ṣẹyin ija ọrọ aje to n waye laarin orileede Russia ati Saudi Arabia, to fi mọ airi agba epo ta, ti aisan Coronavirus naa ṣokunfa rẹ.
Bi nkan ṣe ri bayii, ti banki apapọ Naijiria ti ni kawọn eeyan ma mura silẹ de igba ti yoo le diẹ lẹka ọrọ aje, lo mu ki BBC Yoruba fọrọ wa awọn onimọ nipa ọrọ aje lẹnu wo, lati ṣalaye ohun ti awọn ọmọ Naijiria yoo ba pade nigba ti ọrọ aje ba dagun.
Onimọ kan nipa eto ọrọ aje ọmọwe Chijioke Ekechukwu ni iru nkan bayi ko ṣẹṣẹ ma ṣẹlẹ.
Oríṣun àwòrán, @BashirAhmaad
Adura ko ran ọrọ to wa nilẹyi bi kii ṣe ki atunto eto ọrọ aje waye
O ni gbogbo igba ti nkan ba ti deba owo epo rọbi lagbaye yala owo rẹ lọ si oke tabi o walẹ, o di dandan ki Naijiria mọ lara.
Latari iṣẹlẹ eyi ti o mu iye owo epo rọbi walẹ di bi ọgbọn dọla lati ọgọta dọla, Ọmọwe Chijioke sọ pe ajakulẹ ọrọ aje eleyi ti a mọ si Recession lede oyinbo di dandan.
Iduro ko si mọ fawọn to n ṣe ijọba bayii
Ẹlẹẹkeji ipa to ni adinku iye owo epo yii yoo ni lara awọn eeyan Naijiria ni pe, iye owo gbogbo nkan lọja yoo gbowo lori.
''Ati ẹni to n ta ata lọja ati awọn ti ko ni nkan ṣe pẹlu dọla, gbogbo wọn ni yoo gbe owo ọja lọ soke.''
Pẹlu iru nkan bayi, anfaani wa, bẹẹ si ni ipenija wa pẹlu ṣugbọn gbogbo rẹ ku si ọwọ awọn to n ṣe ijọba.
Oríṣun àwòrán, Thinkstock
Fun idi eyi, onimọ Chijioke ni asiko re ti aarẹ Naijiria ati awọn Gomina ni lati ṣan ṣokoto wọn daada ki wọn si mu adinku ba owo inakuna.
Rẹgi ni ọrọ r ṣe pẹlu ọjọgbọn Nazif Abdullahi Darma to ni iIpenija nla ni ọrọ to wa nilẹ yi nitori abaṣepọ to wa laarin ọrọ aje ati ilera kii ṣe kekere.
Darma ni asiko re lati ṣe agbeyẹwo awọn afojusun Naijiria nipa iṣuna ọdun 2020.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Idajọ ileẹjọ lee mu ekuru gba ẹyin ni ifanfa fun ajọ EFCC
Bakanna o ni  agbeyẹwo iye ti a maa n gbe le owo iṣẹ amayedẹrun ni Naijiria ti wa di dandan bayii.
''A ko le ma darukọ owo gọboi pe a fẹ fi ṣe isẹ agbaṣe .Nibo la ti fẹ ri bayi ti owo dọla ti dẹnu kọ ilẹ?''
''O  ti di dandan lati se agbeyewo ibasepọ laarin awọn aladani ati ẹka ijọba ti a mọ si PPP''
Ninu awọn ti Ọjọgbọn Nazifi Abdullahi Darma sọ pe yoo mọ asiko yi lara ju, ni awọn ti wọn maa n na owo dọla, yala lati fi gba itọju nilẹ okere ni tabi fun eto ẹkọ ni oke okun.
O ṣalaye pe, bi eeyan ba ni dọla bayi, ki o ṣọra lati naa. Bi anfaani ba si wa fun lati yanju nkan to n wa lọ si ilẹ okere, ki o yara yanju rẹ nile lai lọ si ita.
Saaju la ti sọ fun yin pe oludari agba fun ajọ elepo rọbi nilẹ wa, NNPC Mele Kiyari ti fi iboosi bọnu pe kawọn ọmọ Naijiria tete gbaradi fun ilu ti yoo le laipẹ, nitori bi owo epo rọbi se n ja wa silẹ lọja agbaye.
Oríṣun àwòrán, Others
Melee, ẹni to ke gbajare yii asiko to n sọrọ lori ipa ti ebu ẹyin to ba owo epo rọbi yoo ni lori ọrọ aje Naijiria, wa n fi ika hanu pe orilẹede yii ko ni ọrọ aje miran to ju epo rọbi lọ, eyi ti ko ta mọ bayii.
O ni arun asekupani Coronavirus to n se ọsẹ kiri yika agbaye lo ko okuta ba epo rọbi lọja, pẹlu orogun owo ti ilẹ Saudi Arabia n ba Russia se nidi okoowo epo rọbi, eyi to mu ki owo epo ja wa silẹ.
Oríṣun àwòrán, Others
Oludari agba fun ajọ NNPC wa n rọ awọn ọmọ Naijiria lati gbaradi fun inira osu mẹta, o kere tan, ki ọja agbaye to bọ lọwọ wahala yii, eyi ti yoo ni ipa ti kii se kekere lori ọrọ aje Naijiria.
O ni ọgọta dọla fun agba epo rọbi kan ni wọn gbe eto isuna ọdun 2020 le lori amọ lọwọ lọwọ bayii, owo agba epo kan ti ja wa silẹ di ọgbọn dọla, to si tun seese ko ja wa silẹ ju bẹẹ lọ.
Oríṣun àwòrán, Others
"Ni bayii, o le ni awọn ile ẹru mejila to wa nilẹ lọja agbaye to kun fun agba epo rọbi, ti ko ri ẹni yọwo rẹ nitori wahala arun Coronavirus to n ja rain nilẹ, eyi ti ọwọja rẹ tun ti tan de awọn ẹya ẹka epo rọbi miran.
Waste to Wealth: Ẹ̀gbin tìrẹ ni èròjà táwọn èèyàn míràn fi n ṣiṣẹ́ ajé, okoòwò ńlá ni
Bakan naa ni olokoowo to gbajumọ julọ ni Afirika, Aliko Dangote, lasiko ipade apero ti banki apapọ ilẹ wa se laipẹ yii ti koro oju si bi orilẹede Naijiria ko see tii waọna miran fun ọrọ aje rẹ yatọ si epo rọbi, to ti di okuta lọja agbaye bayii.
Coronavirus: Uganda ní àwọn arìnrìn àjò láti UK, US àti Yúróòpù lọ̀rọ̀ kàn
Oríṣun àwòrán, AFP
Ijọba orilẹede Uganda ti se agbekalẹ ilana kan ti yoo pọn ni dandan fawọn arinrinajo lati orilẹede mẹrindinlogun lati fi ara wọn pamọ fun ọjọ mẹrinla, ki wọn lee dena itankalẹ arun Coronavirus.
Lara awọn orilẹede ti ọrọ naa kan ni ilẹ United Kingdom, UK, Amẹrika ati awọn orilẹede mii nilẹ Yuroopu
Bakan naa ni awọn alasẹ salaye pe gbogbo awọn arinrinajo to ba n de si papakọ ofurufu Entebbe ni wọn yoo maa fin oogun apakokoro si lara.
Amọ titi di akoko yii, orilẹede Uganda ko tii kofiri alarun Coronavirus kankan bi o tilẹ jẹ pe minisita feto ilera lorilẹede naa ti jẹwọ pe, ọrọ aje ilẹ naa ko lee gbe iwosan arun yii, to ba fi bẹ silẹ lọdọ awọn.
Oṣu kẹwa ọdun 2019 ni arun Coronavirus bẹ silẹ nilu Wuhan, lorilẹ-ede China ti ọpọlọpọ eeyan si ti lugbadi arun naa kaakiri agbaye.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Arun ọhun ko mọ ọmọdẹ tabi agbalagba, bẹẹ ni ko mọ olowo tabi gbajumọ lawujọ, o si ti mu ẹmi ọpọ eeyan lọ.
Iwọnyi ni awọn eeyan jankan lagbaye ti wọn ti fara kaasa arun naa kaakiri orilẹ-ede agbaye.
Owuro kutu Ọjọbọ ọdun yii ni gbajugbaja oṣere ilẹ Amẹrika, Tom Hanks kede loju lopo Instagram rẹ pe, oun ati iyawo oun, Rita Wilson ti lugbadi arun naa.
Hanks ṣalaye pe, awọn mejeeji n ṣe aisan ranpẹ ni wọn ba pinnu lati lọ ile iwosan, esi ayẹwo si fi han pe wọn ti ni arun Coronavirus lara.
Bo tilẹ jẹ pe ọmọ bibi ilẹ Amẹrika ni ẹni ọdun mejilelọgọta ọhun, ṣugbọn orilẹ-ede Australia lo ti lugbadi arun naa.
Nadine Dorries:
Misita fun eto ilera ilẹ Gẹẹsi, Nadine Dorries naa wa lara awọn eeyan jankan lagbaye to fara kasa arun Coronavirus.
Ileeṣẹ eto ilera orilẹ-ede naa sọ pe, minisita ọhun n fi awọn apẹrẹ arun naa han lọjọ kan naa to ṣe ipade ka pẹlu adari ijọba orilẹ-ede ọhun, iyẹn Boris Johnson.
O kere tan, eeyan mẹfa lo ti jẹ Ọlọrun nipe nilẹ Gẹẹsin bayii, ti awọn ti ko din ni ọọdunrun  si n ba arun naa finra.
Claudio Pedrazzini:
Claudio Pedrazzini ni ẹni akọkọ lara awọn to wa ni ile igbimọ aṣofin Italy ti yoo ni arun Coronavirus.
Aṣofin ọhun wa lati agbegbe Lombardy, to jẹ iha ibi ti ọwọja arujn naa ti mulẹ ju lorilẹ-ede ọhun.
Iroyin ni awọn awọn akẹgbẹ rẹ ti wọn n joko ti nile aṣofin ti sẹ ara wọn mọle, ti wọn siti bẹrẹ si n gbe igbesẹ to kan lati mọ boya awọn naa ti ko arunn naa
Làá hàn mí: Ètò yìí ló ń kìlọ̀ fún wa láti mú ìmọ́tótó ní pàtàkì láti dènà Coronavirus
Rudy Gobert:
Ajọ to n risi ere bọọlu alapẹrẹ NBA, niha Ariwa Amẹrika ti kede pe, ọkan lara ọmọ ikọ Utah Jazz, Rudy Gobert ti lugbadi arun Coronavirus.
Wọn ni agbabọọlu alapẹrẹ ọhun ti kọkọ fi ọrọ arun naa ṣere ninu ifọrọwerọ kan pẹlu awọn oniroyin lọjọ Aje, to si fọwọ kan awọn irinṣẹ ti wọn ko wọ inu yara ti wọn ti n parọ aṣọ lọ.
Lẹyin ọjọ meji si lo bẹrẹ si ni ṣaisan ranpẹ, nigba ti ikọ rẹ n gbaradi fun ifẹsẹwọnsẹ pẹlu ikọ Oklahoma City.
Ṣugbọn lẹyin ti ayẹwo fi han pe ọkunrin naa ti ko arun ọhun, ni awọn alaṣẹ ba sun ifẹsẹwọnsẹ naa siwaju.
Daniele Rugani:
Oríṣun àwòrán, @goal
Laipẹ yii ni ikọ agbabọọlu Juventus kede pe, agba-ẹyin fun ikọ ọhun, Daniele Rugani ti ni arun Coronavirus lẹyin ayẹwo kan.
Ikọ naa ti wa sọ pe, oun ti bẹrẹ igbesẹ lati ri pe wọn ko gbogbo awọn to ti ṣalabapade okunrin naa sibi kan fun ayẹwo, ati itọju to peye.
Ko to ni arun naa, Rugani ti kopa ninu ifẹsẹwọn meje fun ikọ na ninu saa yii, eyi to gba gbẹyin ni ifẹsẹwọn wọn pẹlu Spal, leyi ti wọn bori.
Stolen phone: Fóònù mi ni mo lọ́ tún ṣe lọlọ́pàá bá he mí pé mo jí fóònù
Ẹwẹ, bi ọkanjuwa se n dagba lori ọwọja arun Coronavirus to n ja kalẹ bii ọwara ojo yii, naa ni ọgbọn n rewaju nitori awọn onimọ isegun ti se agbekalẹ eroja to n tete sedamọ arun naa lọgan laarin isẹju mẹwa.
Oríṣun àwòrán, Others
Ibudo ayẹwo imọ isegun to wa nilu Dakar lorilẹede Senegal si lo se agbekalẹ awọn eroja ayẹwo ọhun.
Isẹ akanse yii lo jẹ ifọwọsowọpọ ibudo ilera kan nilẹ Gẹẹsi, Mologic ati gbajugbaja ibudo ayẹwo ara kan to wa ni Dakar.
Ireti wa pe awọn ẹrọ to n sayẹwo arun Coronavirus bii miliọnu meji ni wọn yoo maa se jade lọdọọdun, ti wọn yoo si maa pin kaakiri ilẹ Afirika.
Bẹẹ ba gbagbe, ajọ eleto ilera lagbaye ti kede arun asekupani Coronavirus bii ajakalẹ arun lagbaye, to si ti tan ọwọja rẹ de orilẹede bii mẹrinlelaadọfa nigba ti awọn eeyan to to irinwo ati igba ti jẹ Ọlọrun nipe lati ipasẹ arun naa.
Yorùbá Homograph: Àmì èdè ló mú káwọn ọ̀rọ̀ yìí ní ìtumọ̀ ọ̀tọ̀ọ̀tọ̀
Ede Yoruba rẹwa pupọ, ko si si ohun ti a ko lee fi ede naa da lara nitori pe o rọrun lati fi mu ko ba aye yi, bi aye ba se n yi.
Ninu ede Yoruba, gẹgẹ bo se wa pẹlu awọn ede miran lorilẹ aye, awọn ede kan wa ti akọsilẹ wọn jọra, amọ iro wọn ko papọ rara.
Ojulowo ọmọ Yoruba kọọkan si lo yẹ ko mọ akọsilẹ awọn gbolohun ede naa ati iro ti ikọọkan wọn ni, ka ma baa maa fi Ojo pe Aina.
Gẹgẹ baa se mọ pe ede Yoruba jẹ ede to ni ami, ami ori awọn ede kọọkan lo si n jẹ ka mọ iro wọn leti, bẹẹ si lọrọ ri pẹlu awọn ede ti akọsilẹ wọn jọ ara wọn.
Ni ọtẹ yii, iro ede ti a salaye lori rẹ ni gbolohun ogun eyi to pin si orisirisi, ti a si mu itumọ rẹ fun yin ni ẹyọ kọọkan.
Ogún ni awọn oloyinbo n pe ni Twenty, ti ami rẹ si jẹ re mi.
Ogún jẹ ami isiro, ti onka rẹ bẹrẹ lati ookan de ogun, eyi si ni ara onka ni ede Yoruba.
Ògún (do mi) ni orukọ ti wọn fun orisa kan nilẹ Yoruba.
Awọn eeyan to n bọ orisa ogun pọ aja, si ni eroja kan gboogi ti wọn fi n bọ
Awọn eeyan to jẹ olorisa Ogun lo maa n jẹ Ogungbemi, Ogunlana. Ogunrinu ati bẹẹ bẹẹ lọ
Ogún yii naa tun tumọ si dukia tabi imọ ti a ri gba lati ọwọ ẹnikan.
Ami ori rẹ jọ ti onka ogún amọ itumọ rẹ yatọ pupọ.
A saba maa n jẹ ogun awọn eeyan to jẹ ẹjẹ wa bii obi, ẹgbọn tabi ibatan wa, ti a si maa n jẹ ogun imọ lati ọdọ olukọ tabi awọn asaaju ẹsin wa.
Ògùn jẹ orukọ odo kan nilẹ Yoruba, o san lati ipinlẹ Ọyọ lọ si ilu Abẹokuta.
Orukọ odo yii si ni wọn fi n pe ipinlẹ kan nilẹ Yoruba taa mọ si ipinlẹ Ogun, eyi to sunmọ ilu Eko pupọ.
Àrìnfẹsẹ̀sí - Ìbéèrè ni a bèrè lọ́wọ́ àwọn èèyàn, ika òṣì ni wọ́n ń ta dànù
Ogun yii jẹ orukọ ti wọn fun aawọ ati iporogan to ba n waye laarin ilu meji tabi ju bẹẹ lọ.
Ogun yii, (ti ami rẹ jẹ re re) si tun tumọ si rogbodiyan, pakaleke ati aisi alaafia to peye.
Ogun buru jai, to si maa n ba ọpọ dukia jẹ, tabi mu ẹmi eeyan lọ.
Emir of Kano: Soyinka ní ó dun òun pé Ganduje kò ní alámọ̀ran rere
Oríṣun àwòrán, Emir ti Kano
Ọjọgbọn Wole Soyinka ti bu ẹnu atẹ lu bi ijọba ipinlẹ Kano, labẹ iṣakoso Gomina Abdullahi Umar Ganduje, lori bo ṣe rọ Lamido Sanusi loye, gẹgẹ bi Emir ilu Kano.
Nigba to n sọrọ ninu atẹjade kan, Soyinka ni iyọnipo Sanusi tumọ si pe, awọn ara Ariwa Naijiria ko tii ṣetan, lati gba otitọ ati asa igbalode laaye.
Soyinka ni o ṣeni laanu pe Gomina Ganduje ko ni awọn ọrẹ gidi to le gba a silẹ ọwọ ara rẹ, ati pe, Sanusi ti wọn rọ loye jẹ ọkan pataki lara awọn to lee mu ayipada nla ba awọn ara Oke Ọya.
Ẹwẹ, Emir ilu Kano tẹlẹ ti wọn rọ loye, Sanusi Lamido Sanusi ko fi ọwọ yẹpẹrẹ mu ọrọ ọhun rara, tori o ti bẹ awọn agbẹjọro agba mejila lọwẹ lati ja fun ẹtọ rẹ.
Oríṣun àwòrán, DESIGNED BY STUDIO
Sanusi, Emir kẹrinla ilu Kano nibi ayẹyẹ kan
Awọn agbẹjọro agba ti Sanusi bẹ lọwẹ ni; Ọjọgbọn Kanyinsola Ajayi, aarẹ ẹgbẹ awọn agbẹjọro Naijiria tẹlẹ ati Abubakar Mahmoud; aarẹ ẹgbẹ awọn agbẹjọro Naijiria bayii, Paul Osuro.
Awọn to ku ni Ifedayo Adedipe,  Garba Tetengi, Suraj Sa'eda, Funke Aboyade, Nesser Dangiri, Ernest Ojukwu, ati  H.O. Afolabi,  ti gbogbo wọn jẹ agbẹjọro agba (SAN).
Oríṣun àwòrán, Maigaskiya Photography
Ọjọ Ẹti ni Sanusi n gbe ẹjọ naa lọ siwaju ile ẹjọ giga to wa nilu Abuja, to si n beere pe ki wọn tu oun silẹ ni ahamọ to wa, lẹyin ti Gomina ipinlẹ Kano le e kuro lori oye.
Awọn agbẹjọro Sanusi, ti Lateef Fagbemi (SAN) n ṣaaju wọn pe ẹjọ ọhun lodi si bi wọn ko ṣe jẹ ko kuro ni ilu Awe to wa ni, ni ipinlẹ Nasarawa.
Waste to Wealth: Ẹ̀gbin tìrẹ ni èròjà táwọn èèyàn míràn fi n ṣiṣẹ́ ajé, okoòwò ńlá ni
Lara awọn ti Sanusi pe lẹjọ ni; ọga agba ileeṣẹ ọlọpaa, Mohammed Adamu, ọga agba ileeṣẹ ọtẹlẹmuyẹ, DSS, Yusuf Bichi, adajọ agba ipinlẹ Kano Ibrahim Muktar ati adajọ agba Naijiria, Abubakar malami (SAN).
Ọjọ́ Ajé, ọ̀sẹ̀ yìí ní ìjọba ìpínlẹ̀ Kano yọ Sanusi Lamido ní orí oyè gẹ́gẹ́ bí Emir ìpínlẹ̀ Kano.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Emir ipinlẹ Kano tẹlẹ, Lamido Sanusi ti pe ẹjọ ni ile ẹjọ giga ni Abuja lati pe fun itusilẹ oun ni ahamọ.
Sanusi ni wọn gbe lọ si ilu Awe ni ipinlẹ Nasarawa ni ibi ti wọn ti fi si inu ahamọ lẹyin ti ijọba ipinlẹ Kano yọ ọ ni ipo ni Ọjọ Aje.
Adari awọn agbẹjọrọ rẹ, Lateef Fagbemi lọ pẹjọ mọ Ọga agba ọlọpaa, ọga agba ajọ ọtẹmuyẹ, DSS ati olotu eto idajọ ni ipinlẹ Kano naa ni wọn gbe lọ si ile ẹjọ giga ti ilu Abuja.
Sanusi beere ki ile ẹjọ da ẹtọ oun pada gẹgẹ bi ọmọ orilẹede Naijiria.
Oríṣun àwòrán, EMIHD KANO EMIRATE
Ọjọ́ Ajé, ọ̀sẹ̀ tó kọjá ní ìjọba ìpínlẹ̀ Kano yọ Sanusi Lamido ní orí oyè gẹ́gẹ́ bí Emir ìpínlẹ̀ Kano.
Bakan naa ni wọn beere fun aye lati rin lati agbeegbe kan si omiran yatọ si ipinlẹ Kano titi ti ileẹjọ yoo fi gbọ ẹjọ wọn.
Ọkan lara awọn iyawo Sanusi Lamido Sanusi, to jẹ Emir ana nilu Kano, ti ṣabẹwo si ni ilu Awe lẹyin irọloye rẹ.
Iyawo rẹ naa, atawọn ọmọ rẹ mẹta ni wọn bẹ ẹ wo nibi ti gomina ipinlẹ Nasarawa, Abdullahi Ganduje le si ni ipinlẹ nasarawa.
Emir ilu Awe, Umar Isa Abubakar; Kabir Musa Ibrahim ati alaga ijọba ibilẹ ti ilu naa wa, Umar Da-Akanio atawọn eeyan mii ni wọn tun ṣabẹwo si Emir tẹlẹ ri ọhun.
Iroyin ni awọn eeyan ilu ọhun gba Sanusi tọwọ tẹsẹ, bo ti tilẹ jẹ pe inu wọn ko dun si bi ijọba Kano ṣe rọ ọ loye.
Ọkan lara awọn olugbe ilu naa, Mallam Ibrahim Usman Fulani sọ pe Fulani daran daran ni mi, ṣugbọn igba ti mo gbọ iroyin irọloye Sanusi, ni mo pada wa si ilu."
Oríṣun àwòrán, @OfficialPDPNig
"O ni ""O yẹ ki n rinrin ajo kan, ṣugbọn mi o ni lọ titi di ọjọ Jimọ ti mo maa lanfani ati  gbadura papọ ni Mọṣalaṣi kan pẹlu Sanusi."""
Nigba ti Sanusi de ilu naa, ile oni yara meji  kan, ti wọn ni o jẹ ti ọkan lara awọn eeyan ijọba ibilẹ ilu naa lo sun mọju.
Ẹwẹ, ijọba apapọ ti sọ pe oun ko lọwọ ninu bi wọn ṣe rọ Sanusi loye gẹgẹ bi Emir ilu Kano.
Agbẹnusọ fun aarẹ Muhammadu Buhari, Garba Shehu ninu atẹjade kan sọ pe, ki awọn eeyan dẹkun ati maa so iṣẹlẹ naa mọ aarẹ lọrun, nitori ko mọ ohunkohun nipa bi ọrọ naa ṣe ṣẹ.
Waste to Wealth: Ẹ̀gbin tìrẹ ni èròjà táwọn èèyàn míràn fi n ṣiṣẹ́ ajé, okoòwò ńlá ni
LASTMA: Ẹ̀sùn àgbèrè la gbọ́ pé ó fá ìjà, tó já sí ikú náà
Oríṣun àwòrán, Others
Oṣiṣẹ ajọ to n mojuto igbokegbodo ọkọ loju popo nipinlẹ Eko, LASTMA, Emmanuel Mekuri, ti gbẹmi ara rẹ, lẹyin to pa ololufẹ rẹ.
Iroyin sọ pe ija lo waye laarin Emmanuel ati ololufẹ rẹti wọn jọ n gbe, Patricia Ogunshola, ni ile wọn to wa ni Araromi, Morogbo nipinlẹ Eko.
Ẹni ọdun mẹtadinlaadọta ni wọn pe Emmanuel, ti Patricia si jẹ ẹni ọdun mẹtadinlogoji.
Gẹgẹ bi a se gbọ, ede aiyede na da lori iwa agbere, eyi to yọri si kiko ẹṣẹ bo ara ẹni.
A gbọ pe lasiko ija naa ni Emmanuel binu mu ọbẹ, to si fi gun Patricia ni itan, ko to o di pe Patricia raaye sa jade.
Lẹyin naa ni Emmanuel fi ọbẹ naa gun ara rẹ ni ikùn.
Ileeṣẹ ọlọpaa nipinlẹ Eko sọ pe, ariwo ti ọmọ Patricia pa, lo jẹ ki awọn alajọgbele wọn o mọ nipa nkan to ṣẹlẹ.
Oríṣun àwòrán, Others
Oku Emmanuel si ni awọn ọlọpaa ba nilẹ pẹlu ọbẹ naa nigba ti wọn pe wọn sibi isẹlẹ ọhun.
Iroyin ọhun tẹsiwaju pe, wọn gbe Patricia lọ sile iwosan fun itọju, ti wọn si ti gbe oku Emmanuel lọ sile igboku si.
Iru iṣẹlẹ bayii ko ṣẹṣẹ ma a waye l'orilẹ-ede Naijiria laarin ololufẹ.
Saaju la ti sọ fun yin pe irọ ni iroyin kan to sọ pe ọlọpaa kan ti wọn pe orukọ ni Tolulọpe pa iyawọ ati ara rẹ lori ẹsun pe iyawo naa n ṣe agbere.
Ọjọ kejila, oṣu Kẹta, ọdun 2020 ni iṣẹlẹ naa waye nilu Akungba-Akoko.
Alukoro ileeṣẹ ọlọpaa fidi rẹ mulẹ fun BBC Yoruba, Ọgbẹni Tee-Leo Ikolo wi pe pẹlu ayọ ati idunnu ni ọlọpaa naa fi kuro nibi iṣẹ rẹ to wa ni Akungba Akoko, oun pẹlu aya ati awọn ọmọ wọn.
Ọgbẹni Ikolo ni ṣa deedee lawọn lawọn gbọ iro ibọn lati ile ọlọpaa ọun eyi to kọju si ago ọlọpaa to ti n ṣiṣẹ niluu Akungba Akoko
Alukoro ileeṣẹ ọlọpaa ni nigba tawọn de ibẹ lawọn ba oku ọlọpaa naa ati iyawo rẹ nilẹ.
O ṣalaye pe iwadii si n lọ lọwọ lati mọ ohun to ṣe okunfa iku awọn mejeeji gan an.
Ọgbẹni Ikolo ni ileeṣẹ ọlọpaa ti gbe ọmọ ọwọ ati ọmọ ọdun meji ti iyawo naa n gbe lọwọ to fi ku fun mama iyawo naa.
Ileeṣẹ ọlọpaa ni awọn yoo ṣalaye fun araalu ohun to fa iku awọn mejeeji ti iwadii ba ti pari.
Gomina El-Rufai: Èmi àti Sanusi ti wà lọ́nà Abuja
Oríṣun àwòrán, Twitter/Governor Kaduna
Gomina ipinlẹ Kaduna, Nasir El-Rufai ati Emir tẹlẹ, Muhammadu Sanusi ti wa lọna Abuja bayii.
Ijọba ipinlẹ Kaduna lo fi lede bẹẹ loju opoTwitter wọn.
Wọn sọ wi pe awọn mejeeji ti kuro ni Awe bayii lọ si ilu Abuja.
Bakan naa ni wọn kọkọ fi lede wi pe Sanusi ti ko gbogbo ẹru rẹ kuro ni Awe ti wọn si ti n mura irinajo lẹyin ti wọn kirun tan mi Awe.
Ọpọlọpọ eniyan ati ololufẹ Sanusi lo jade lati ki pe o daabọ lẹyin ti wọn ti gbalejo rẹ lasiko ti ijọba ipinlẹ Kano yọ ọ kuro nipo gẹgẹ bi Emir ilu Kano.
Ileẹjọ giga ijọba apapọ to kalẹ silu Abuja ti pasẹ pe ki ajọ ọtẹlẹmuyẹ DSS fi Emir ilu Kano ti wọn yọ nipo, Sanusi Lamido Sanusi silẹ ni ahamọ ti wọn fi si.
Oríṣun àwòrán, Emiri Sanusi
Adajọ Anwuli Chikere lo pasẹ kanmọ n kia naa lọjọ Ẹti lasiko to n gbọ ẹjọ ti agbẹjọro Sanusi, agba amofin Lateef Fagbemi gbe wa siwaju rẹ.
"Nigba to n pasẹ naa, adajọ Chikere ni ""asẹ ileẹjọ yii ni pe ki ọga agba ọlọpaa, oludari ajọ ọtẹlẹmuyẹ ati agbẹjọro agba nipinlẹ Kano ati adajọ agba lorilẹede yii, ti gbogbo wọn jẹ olujẹjọ, lati ri daju pe wọn da ẹtọ ọmọniyan pada fun olupẹjọ naa gẹgẹ bo se n beere fun."""
Bakan naa lo fikun pe ki wọn fi olupẹjọ ọhun silẹ kuro ni ahamọ abi igbele ti wọn fi si, ki wọn si da awọn ẹtọ rẹ bii ọmọniyan pada, eyi to nii se pẹlu ominira, ibakẹgbẹpọ ati lilọ soke-sodo rẹ yika Naijiria, yatọ silu Kano nikan ti ko gbọdọ de, titi ti wọn yoo fi gbọ ẹjọ naa tan.
Adajọ Chikere wa gba Sanusi laaye lati pin iwe asẹ ileeẹjọ naa fun ọga agba ọlọpa ati awọn olujẹjọ yoku.
Akọ́nimọ̀ọ́gbá ikọ̀ agbábọ́ọ̀lù Arsenal, Mikel Arteta náà ti fara káásá àrùn Coronavirus
Oríṣun àwòrán, @Sporf
Awọn alakoso idije Premier League ti wọgile ifẹsẹwọnsẹ to yẹ ko waye laarin ikọ naa ati Brighton lọjọ Abamẹta lẹyin ti akọnimọgba ikọ Arsenal, Mikel Arteta lugbadi arun Coronavirus,
Iṣẹlẹ yi ti mu ki ikọ ọhun gbe kọkọrọ ṣẹnu ilẹkun papa iṣere ti wọn ti n ṣe igbaradi, lẹyin naa ni wọn ya awọn eeyan to ṣalabapade akọnimọgba naa sọtọ fun ayẹwo ati itọju.
Ni bayii, awọn alakoso idije Premier League yoo ṣepade pajawiri lọjọ Ẹti lati jiroro lori ọjọ iwaju idije naa ni saa yi.
"Nigba ti esi ayẹwo rẹ fihan pe o ti Lugbadi arun ọhun, ẹni ọdunn ọdun mẹtadinlọgbọn naa ni ""O ṣeni laanu."""
Arteta sọ pe oun lọ ṣayẹwo lẹyin ara oun rẹwẹsi, leyi to fi han pe Coronavirus lo n ba finra.
Ṣugbọn o ti wa ni oun yoo fẹ lati pada sẹnu iṣe laipe ni kete ti awọn dokita ba ti fun ni aye ati ṣe bẹ.
Oríṣun àwòrán, @BleacherReport
Ọkan lara awọn adari ikọ Arsenal, Vinai Venkatesham sọ fun awọn akọroyin pe ilera awọn oṣiṣẹ ẹgbẹ agbabọọlu naa ati awọn ololufẹ wọn lo jẹ ikọ naa logun.
Ikọ ọhun ti wa ni pupọ awọn ọmọ ẹgbẹ agbabọọlu naa ni wọn yoo fi si apapmọ fun ayẹwo.
Coronavirus: Ẹ̀kọ́ márùn ún tí orílẹ̀-èdè àgbáyé lè kọ́ lára Naijiria lórí ìdènà àjàkálẹ̀ àrùn
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Arun Coronavirus ti tan de orilẹ-ede mẹrinlelaadọfa lagbaye lati igba to ti bẹ silẹ nilu Wuhan, lorilẹ-ede China lọdun 2019.
Lara awọn orilẹ-ede ti arun naa ti ra pala wọ ni Naijiria, eyi to ko ibẹru sọkan ọpọ eeyan, ti ọpọ ọmọ orilẹ-ede yii  si lero pe ijọba kọ ni le kapa rẹ itankalẹ arun naa.
Ṣugbọn o jẹ ohun iyalẹnu pe ijọba ṣe akitiyan ti ko kere lati kapa arun naa to bẹ gẹẹ, ti ajọ eleto ilera agbaye, WHO fi gboṣuba kare fun Naijiria fun akitiyan rẹ.
Iwọnyi si ni awọn ẹkọ marun un ti awọn orilẹ-ede mii lagbaye n kọ lara Naijiria nidi aṣeyọri rẹ lati kapa arun ọhun.
Akitiyan awọn ileeṣẹ iroyin:
Lati igba ti iroyin ti kede pe ọmọ orilẹ-ede Italy kan ko arun naa wọ Naijiria, ni awọn ileeṣẹ iroyin to ṣe e fọkan tan, bii ileeṣẹ BBC atawọn ileeṣẹ iroyin miran ti n ṣe ifitonileti iroyin nipa arun ọhun.
Ojumọ kan ko nii mọ ki ileeṣẹ BBC ma gbe iroyin bo ba ṣe n lọ nipa Coronavirus sita, bẹẹ naa ni wọn n ṣe idanilẹkọ fun awọn eeyan nipa bi wọn ṣe le dabo bo ara wọn, bi wọn ṣe le ṣe imọtoto ara ati bẹ bẹ lọ.
Ohun kan gbogi ti awọn ileeṣẹ iroyin naa n tẹnu mọ, ni bi eeyan ṣe le pa ara rẹ mọ nipa lilo ọṣẹ lati fọwọ ẹni ni igba de igba, atawọn nnkan miran to yẹ fun eeyan lati ṣe, ki arun naa le jinna si wa.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ileeṣẹ ẹrọ ibanisọrọ ṣe ipade lori itakun agbaye:
Ni kete ti arun naa tan de Naijiria ni ọkan gboogi lara awọn ileeṣẹ ẹrọ ibanisọrọ, MTN, ṣe adinku si bi awọn eeyan ti kii ṣe oṣiṣẹ, wọn ṣe n wọle sinu ile iṣẹ wọn, eyi ni Yellow Drome to wa nilu Eko.
Bakan naa, iroyin kan sọ pe awọn alaṣẹ ileeṣẹ naa fiwe ransẹ si awọn ileeṣẹ mii ti wọn n ba ṣiṣẹ pe, idaduro ti de ba ipade ojukoju ti wọn maa n se loore-koore, ti wọn si sun awọn ipade wọn si ori itakun agbaye.
Arakunrin kan, Michael Adeniran sọ pe wọn ko gba oun laye lati wọle sinu ọgba ileeṣẹ naa, to si fi kun pe, wọn ni igbeṣẹ naa ko ṣẹyin ikede nipa arun Covid-19 lati ọdọ ileeṣẹ eto ilera Naijiria.
Làá hàn mí: Ètò yìí ló ń kìlọ̀ fún wa láti mú ìmọ́tótó ní pàtàkì láti dènà Coronavirus
Awari kanmọ n kia nipa awọn to ba ẹni to ko arun ọhun wọ Naijiria:
Ko pẹ ti arun naa de Naijiria ti ijọba ipinlẹ Eko bẹrẹ igbeṣẹ lati ṣawari gbogbo awọn eeyan to wọ ọkọ baalu kan naa pẹlu ọmọ ilẹ Italy, to ko arun naa wọn Naijiria.
Ko pẹ si asiko naa ti kọmiṣọna feto ilera ipinlẹ Eko, Akin Abayomi  kede pe, wọn ti ṣawari awọn meji ti wọn n wa, ti wọn wa ninu ọkọ baalu ilẹ Turkey to gbe ọgbẹni naa wa si papakọ ofurufu ilu Eko.
Koda, wakati mẹrinlelogun si igba ti wọn kede pe wọn n wa awọn eeyan naa ni ijọba Eko ṣawari wọn, ti wọn si fi wọn pamọ fun ayẹwo ati itọju.
Kiko ọgọrun eeyan pamọ fun iyasọtọ ati itọju:
Ko din ni ọgọrun eeyan to ba ọmọ ilẹ Italy to ko arun Coronavirus wọ Naijiria, ti ijọba ko si ipamọ fun ayẹwọ ati itọju.
Waste to Wealth: Ẹ̀gbin tìrẹ ni èròjà táwọn èèyàn míràn fi n ṣiṣẹ́ ajé, okoòwò ńlá ni
Ṣaaju ni ijọba ipinlẹ Eko ti kọ sọ pe o ṣoro lati wa awọn eeyan ọhun ri, nitori pe ọpọ ninu wọn ni ko fi ojulowo adirẹsi ile wọn silẹ.
Ṣugbọn lẹyin iṣẹ takuntakun ti ijọba ilu Eko gunle, pẹlu iranlọwọ lati ọdọ ijọba apapọ, wọn ṣawari awọn eeyan naa.
Gẹgẹ bi ọrọ ti kọmiṣọna feto ilera Eko sọ, awọn eeyan mọkandinlọgọjọ lo wa ninu ọkọ baalu naa, awọn mẹfa si ṣalabapade rẹ nile itura to wọ si, ti awọn marundinlogoji mii tun ṣalabapae rẹ nile iṣẹ to ṣabẹwo si ni ipinlẹ Ogun.
Sise ayẹwo irufẹ́ kokoro Coronavirus to wọ Naijiria:
Orilẹ-ede Naijiria ni orilẹ-ede akọkọ lagbaye ti wọn ti kọkọ ṣe ayẹwo irufẹ kokoro Coronavirus to wa lara ẹni to ko wọ Naijiria, ti wọn si ri pe iru rẹ naa lo kọkọ ṣẹyọ nilu Wuhan, ti arun ọhun ti bẹ silẹ.
Aṣeyọri nla ni eyi jẹ nitori ọpọ lo gbagbọ pe, orilẹ-ede Naijiria ko koju oṣuwọn to nipa iwaadi ijinlẹ nipa eto ilera.
Yoruba Artists: Chatta bímọ tuntun, Toyin ati Davido lẹ̀pọ̀, Sanwo-Olu fún Sola Sobowale lámì ẹ̀yẹ
Oríṣun àwòrán, Instagram
Ẹbun pataki lọmọ bibi, iya aburo ku ewu. Eleduwa ti fi ọmọ tuntun jojolo da idile ọkan lara awọn oṣere tiata kan lọla laarin ọsẹ yii.
Eyi ni akojọpọ awọn ohun to ṣẹlẹ lagbo awọn oṣere tiata Yoruba lọsẹ yii.
Ibrahim Chatta
Eleduwa ti fi ọmọbinrin lantilanti jinki gbajugbaja oṣere tiata, Ibrahim Chatta.
Chatta fi aworan ọmọ naa nibi to ti gbe e dani sori oju opo Instagram rẹ.
Chatta dupẹ lọwọ Ọlọrun bi o ti kede pe ọmọbinrin ni ọmọ naa ti Eleduwa fi ta idile rẹ lọrẹ
Ẹwẹ, kete ti iyawo Chatta bimọ naa tan lawọn akẹgbẹ rẹ bẹrẹ si ni fi ikinni ranṣẹ sii.
Oríṣun àwòrán, Instagram
Wunmi Toriola wa lara awọn oṣere to kọkọ kii ku oriire ọmọ tuntun ti Ọlọrun fi jinki idile Chatta.
O gbadura pe ki Ọlọrun wo ọmọ naa ati awọn ẹgbọn rẹ, koda aworan Chatta ati iyawo rẹ pẹlu ọmọ tuntun naa ni Wunmi fi si oju opo Instagram rẹ lati ki wọn.
Toyin Abraham
Aworan bi Toyin Abraham ti fẹnu ko olorin takasufe, Davido lẹrẹkẹ ni o fi si oju opo Instagram rẹ.
O lo anfaani naa lati polowo fiimu rẹ. ''Fate of Alakada'' ti yoo jade ni sinima lọjọ jẹta oṣu kẹrin ọdun yii.
Adura lo gba pe ki Eleduwa tubọ maa bukun fun olorin Davido.
Mide Martins
Fiimu ''AJULO'' to n bọ lọna ni Mide Martins sọ nipa rẹ lori ẹrọ ayelujara Instagram.
Fọtọ oun ati ilumọọka olorin Fuji, Saheed Osupa lo fi sori ojo opo Instagram rẹ nibi tawọn mejeeji ti jọ joko.
Mide ki awọn ololufẹ rẹ ku oju lọna fiimu ọhun ninu eyi ti Saheed Osupa ko pa ninu rẹ.
Sola Sobowale
Ami ẹyẹ imọriri ẹni ni Gomina ipinlẹ Eko, Babajide Sanwo-Olu fi da oṣere, Sola Sobowale lọla.
Sola Sobowale fi idunnu rẹ han nibi to ti ki Gomina Sanwo-Olu fun imọriri oun.
O ni oun ko niran pe Gomina ipinlẹ Eko ni iru nnkan bayii lọkan lati fun oun ni ami ẹyẹ.
Foluke Daramola
Orin igbe ni Foluke Daramola fi bọnu ninu fidio to fi lede loju opo Instagram rẹ.
Foluke sọ ninu fidio naa pe kawọn eeyan kan to n gbe iroyin ofege kiri pe oun ku ye parọ kiri.
O ni oun ko ni ku iku kiku kan bi ko ṣe yiye, o ni ẹni to ba n ro iku ro oun yoo lọ jẹ Ọlọrun nipe.
Yemi Osinbajo: Osinbajo wọ́gilé ìrìn-àjò rẹ̀ lẹ́yìn tí ọ̀kan lára ẹ̀ṣọ́ rẹ̀ kú lọ́nà pápákọ̀ òfurufú
Oríṣun àwòrán, Twitter/Prof Yemi Osinbajo
Ọkan lara awọn ẹṣọ igbakeji aarẹ, Ọjọgbọn Yemi Osinbajo ṣagbako iku ojiji ninu ijamba alupupu lọjọ Ẹti.
Ali Gomina, to jẹ ọlọpaa insipẹkitọ gbẹmi mi ninu ijamba naa to ṣẹlẹ lọna papakọ ofurufu Nnamdi Azikiwe niluu Abuja.
Gẹgẹ bi ọrọ ti oludamọran igbakeji aarẹ lori ọrọ iroyin, Laolu Akande sọ, Gomina wa lara awọn ẹṣọ to n sin igbakeji aarẹ lọ nigba ti iṣẹlẹ buruku naa ṣẹlẹ.
Ọgbẹni Akande ṣalaye pe igbakeji aarẹ ti wọgile irin-ajo to fẹ rin naa lẹyin iku ọlọpaa ọun to jẹ ẹni ọdun mẹẹdọgbọn.
Oríṣun àwòrán, Twitter/Prof Yemi Osinbajo
Ọjọgbọn Osinbajo ṣapejuwe oloogbe naa gẹgẹ bi ẹni to jara mọ iṣẹ to ṣi ṣe fi ọkan tan an.
Gomina fi iyawo atawọn ọmọ silẹ lọ, oludamọran igbakeji aarẹ gbadura pe ki Eleduwa tẹ ẹ si afẹfẹ rere.
Human Calculator: N kò lo idán àbí àlùpàyídà fún ìṣirò ọpọlọ tí mò ń ṣe
Human Calculator: N kò lo idán àbí àlùpàyídà fún ìṣirò ọpọlọ tí mò ń ṣe
Imọ isiro jẹ ohun ti ko wọpọ, o si maa n le fun ọpọ akẹkọ lati mọ, eyi to n mu ki wọn maa gbe ẹrọ isiro, taa mọ si Calculator kiri.
Amọ eyi ko ri bẹẹ fun akanda ẹda kan, Jolaade Tella, tii se ẹni ọdun mẹtadinlọgbọn, ti ọba oke fi imọ isiro da lọla.
Lasiko to n ba BBC Yoruba sọrọ, Jolaade ni kakuletọ to jẹ eeyan (Human Calculator) ni wọn maa n pe oun, oun lee pin, yọ kuro tabi sọ di pupọ nisẹju aaya.
Jolaade ni oun kii lo idan abi alupayide amọ erongba oun ni lati di onimọ ẹrọ ayarabiasa lagbaye, to maa idasilẹ oniruuru akanse isẹ lori ayelujara.
Emir of Kano: El Rufai ní ó yẹ ká maa bọ̀wọ̀ fún àwọn ọba alayé ní òun ṣe fún Sanusi ní oyè méjì pọ̀
Oríṣun àwòrán, @GovKaduna
Gomina ipinlẹ Kano, Mallam Nasir El Rufai ti fọwọ gbaya pe oun ko lee fi Emir tilu Kano ti wọn rọ loye, Sanusi Lamido Sanusi silẹ lasiko yii nitori kii buru buru, ko ma ku ẹnikan mọni.
El Rufai to kede eyi lasiko to n sọrọ lori bi ileẹjọ se pasẹ pe ki wọn fun Sanusi ni ominira rẹ, tun fikun pe ojo ti n pa igun ati Sanusi bọ, ọjọ ti pẹ, tori lati majesin lawọn mejeeji ti n bara awọn bọ, tawọn ko si fi ara awọn silẹ.
Gomina Kaduna naa, ẹni to yan Sanusi si ipo meji ọtọọtọ ni kete ti wọn rọọ loye, lo tun ti se abẹwo si ọba alaye ana naa nilu Awe, nipinlẹ Nasarrawa tijọba fi pamọ si lọjọ Ẹti.
Oríṣun àwòrán, @GovKaduna
Lati majesin lemi ati Sanusi ti jẹ ọrẹ timọtimọ, ko si ja lẹyin mi lasiko gbogbo wahala ti mo la kọja ati awọn aseyọri mi, emi naa si gbọdọ wa lẹyin rẹ lasiko yii to n la isoro kọja, a ko lee ya ara wa, igba ipọnju sa ni a n mọ ọrẹ.
Sanusi ti ni ominira bayii gẹgẹ bi ileẹjọ ti kede rẹ, o si lee gbe ni ibikibi to ba wu, to fi mọ ilu Kano amọ ilu Abuja la n lọ. O si seese ki Sanusi gba ibẹ lọ si ilu Eko, nibi to wu lati maa gbe lati igba ti wọn ti rọọ loye.
Oríṣun àwòrán, @GovKaduna
Bakan naa ni El Rufai fikun pe, awọn kii tẹ oju ọba mọlẹ nipinlẹ Kaduna n tawọn, awọn si maa n bọwọ fawọn ọba alaye ni nitori awọn ni oludaabo bo asa wa.
Human Calculator: N kò lo idán àbí àlùpàyídà fún ìṣirò ọpọlọ tí mò ń ṣe
Yatọ si pe Sanusi jẹ ọrẹ atigba ewe mi, o yẹ ka maa gbe ọla fun awọn ọba alaye wa, idi si ree ti mo se yan gẹgẹ bii baba isalẹ fasiti ipinlẹ Kaduna.
Ìtàn Mánigbàgbé: Èyí ni àwọn Ọba ilẹ̀ Yorùbá mẹ́jọ tí wọn lé kúrò lórí oyè
Oríṣun àwòrán, Others
Yoruba ni a ko ri iru eyi ri, a fi n dẹru ba ọlọrọ ni nitori ko si ohun ti oju ko ri ri, ẹsin ta ta ta, o ku, eniyan rin, rin, rin, o sọnu.
Ọpọ ọdọ ni ẹnu ya nigba ti wọn kede pe wọn yọ odidi ọba lapa oke ọya, ti wọn si n sọ pe eyi ko le e sẹlẹ nilẹ Kaarọ oojire.
Ọpọ eeyan si lo maa n pa owe pe bi ọba kan ko ba ku, ọba miran ko lee jẹ, eyi to ti n di irọ nla bayii nitori awọn oriade ana kan wa nilẹ Yoruba, to jẹ pe loju aye wọn bayii, ni wọn se fi ọba miran jẹ lati rọpo wọn.
Ààrẹ Buhari àti ìjọba rẹ̀ màá ń làágùn, ìyẹ́ àdiyẹ wọn ni kò jẹ́ kí ẹ mọ̀
Àwọn ìtàn mánigbàgbé tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí:
Idi si ree ti BBC Yoruba fi wọ inu itan lọ, paapa pẹlu awọn akọsilẹ to wa lori itakun agbaye, se itan kii ku, lati selanilọyẹ lori awọn isẹlẹ to ti waye sẹyin nipa ọpọ ọba ti wọn ti rọ loye, ti awọn miran ninu wọn, ko si pada sori oye mọ titi di ọjọ iku wọn.
Ọba Ibikunle Akitoye ati ọba Kosọkọ tilu Eko:
Oríṣun àwòrán, Others
'Èmi gan máa ń béèrè lọ́wọ́ ara mi pé ta ni Wole Soyinka gangan'
Oríṣun àwòrán, Others
Akomolede àti Aṣa: Ọ̀rọ̀ Ẹ̀yán ni Bunmi Femi Amao ń kọ́ wa lórí ètò Akọ́mọlédè àti Àṣà lóri BBC Yoruba
Oríṣun àwòrán, Others
SS3 ní mo wà báyìí, mo sì ti gba àmì ẹ̀yẹ̀ púpò nílé-lóko gẹ́gẹ́ bí onílù - Ayansike
Oríṣun àwòrán, Others
Oríṣun àwòrán, Others
Wo ìtàn ọgọ́ta ọdún Nàíjíríà nínú àwòrán mẹ́fà péré
Ọba Lamidi Adeyẹmi, òṣìṣẹ́ adójútòfò àti Abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò kó tó jọba
Duro Ladipọ, ìlúmọ̀ọ́ká òṣèré tíátà àti ọmọ àlúfà tí kò gbàgbé àṣà ìbílẹ̀
Wo ìmọràn tó lè jẹ kóo gbádùn ṣíṣe iṣẹ láti ilé lásìkò kónílé-ó-gbélé COVID 19 yìí
Oríṣun àwòrán, Others
Oríṣun àwòrán, Others
"Brain Squad: Àwọn ọmọdébìnrin Nàìjíríà ṣe ""App"" ìrànwọ́ owó iléèwè"
Ju gbogbo rẹ lọ, itan manigbagbe yii kọ wa pe akọsilẹ awa ẹda, ko lee tase nitori aye ko lee pa kadara da, wọn kan lee fa ọwọ aago sẹyin ni, ko si si bo se buru fun wa to loni, igba to dara n bọ lọla.
Ronke Oshodi Oke: N kò ṣe mọ́na-mọ̀na púpọ̀ ni ìgbéyàwó mi ṣe tọ́jọ́
Oríṣun àwòrán, Instagram/ronkeoshodioke
Gbajugbaja oṣere tiata, Ibironke Ojo-Anthony, ti gbogbo eniyan mọ si Ronke Oshodi-oke, ti sọ idi ti ọpọ igbeyawo awọn oṣere fi n fori sanpọn.
Ronke Oshodi-Oke lasiko ifọrọwanilẹnuwo pẹlu BBC Yoruba salaye pe, nitori asa to gbode kan bi awọn eniyan ṣe n gbe igbesẹ lati kọ ọkọ tabi aya silẹ.
O ni idi ti igbeyawo oun ṣe wa titi di isinyii ni wi pe, oun kii ṣe mọnamọna pupọ, nitori niwọntun wọnsi ni ọrọ toun, bẹẹ si ni Olorun lo gbe ẹbi oun ro.
Ki igbeyawo to le dan mọran tabi ki o pẹ, ọkọ ati iyawo gbọdọ bọwọ fun ara wọn.
'Ni aye isinyii to jẹ wi pe bi ọkọ ṣe n gbe bukata ẹbi naa ni iyawo n fi owo silẹ, o pọn dandan ki obinrin ni irẹlẹ, ki ọkọ rẹ naa si fẹran rẹ.
Oríṣun àwòrán, Instagram/ronkeoshodioke
Ọmọ bibi ipinlẹ Ondo ni Ronke Oshodi-Oke, amọ ilu Eko lo ti lọ si ileewe alakọbẹrẹ ati girama, to si ni nitori idi kan tabi omiran ni oun ko fi le tẹsiwaju ni idi ẹkọ oun, lọ si ileewe giga.
Lori alaye bi o ṣe bẹrẹ tiata, Ronke oshodi ni iṣẹ karakata ni oun kọkọ n ṣe,lasiko naa ni oun fẹran lati ma a lọ si 'National Theatre' lati lọ wo fiimu, eleyii to mu ki oun ni ifẹ si ere ṣiṣe, ti oun si fẹran lati ma a rẹrin.
O ni ninu fiimu ti oun kọkọ darapọ mọ ti akọle rẹ jẹ 'Oshodi Oke', ni awọn eniyan ti bẹrẹ si ni pe oun bẹẹ, amọ ko ni nkankan ṣe pẹlu ọmu aya oun.
Eld Kabir in Nigeria: Mùṣùlùmí àti Kristiẹni sọ̀rọ̀ nípa àdun oúnjẹ́ àti ẹran ọdún Ileya
Bakan naa ni Oshodi Oke tun sọrọ lori ajọsepọ rẹ pẹlu gbajugbaja olorin takasufe 'Nice' ati alaga ẹgbẹ ọlọkọ ero nipinlẹ Eko, Alhaji Musiliu Akinsanya, ti ọpọ eeyan mọ si MC Oluomo.
Ronke Oshodi Oke ni ọrẹ timọtimọ ni awọn mejeeji jẹ si oun, ti ko si si nnkan ikọkọ laarin awọn, bẹẹ ni awọn ẹbi ati iyawo MC Oluomo mọ oun daadaa ninu ile rẹ.
O fikun pe, oun fẹran orin kikọ, ti oun si ṣetan lati ma a gbe awo orin jade bi iru eleyii ti oun ṣe pẹlu 'Nice', ati eleyii ti oun kọ fun MC Oluomo ni ayajọ ọjọ ibi rẹ.
'Ẹ fi gbogbo ọrọ emi ati MC Oluomo silẹ fun Ọlọrun. Ọrẹ bi ọmọ iya la jẹ.'
Lori ija oun ati Lizzy Anjorin, Ronke Oshodi ni aarin awọn ko fi bẹẹ dan mọran, amọ oun ti kii ku oriire fun ti igbeyawo rẹ.
Oríṣun àwòrán, Instagram/ronkeoshodioke
Lakotan ọrọ rẹ, Gbajugbaja oṣere tiata naa ni oun ṣetan lati mu atunṣe ba gbogbo bi ohun ṣe n ṣe nkan tẹlẹ, nipa afikun imọ nipa lilo ẹrọ ayelujara, eleyii to pe ni 'Rebranding.
Oni ọjọ Abamẹta ni ayẹyẹ ọjọ ibi alaga ẹgbẹ ọlọkọ ero nipinlẹ Eko, Musiliu Akinsanya, ti ọpọ eeyan mọ si MC Oluomo.
Ọpọ awọn ilumọọka lawujọ, awọn osere ori itage ati awọn olorin si lo ti n dawọ idunnu loju opo ibadọrẹpọ lori itakun agbaye pẹlu ọlọjọ ibi naa, fun bi ọba oke se mu ki oju rẹ tun ri ọdun tuntun.
Amọ lara awọn ikinni to ya ni lẹnu julọ ni ti gbajugbaja osere tiata lobinrin kan, Ronkẹ Ojo Anthony, taa mọ si Ronkẹ Oshodi Oke, ẹni to gbe awo orin jade fun MC Oluọmọ.
Oríṣun àwòrán, Ronke Ojo Anthony
Loju opo Instagram rẹ ati lori Facebook ni Ronkẹ gbe awo orin to danikan kọ naa si, to si n fi ohun to rẹ dodo, kọrin fun ọlọjọ ibi naa.
"Nigba to n salaye idi to fi se bẹẹ, Oshodi oke ni "" ọrẹ mi ni ọ MC Oluọmọ, o maa n duro ti mi lọpọ igba, o maa n satilẹyin fun mi, to si maa n fun mi ni iwuri, to ba gbọ ọpọ ohun ti awọn ọrẹ ti se si mi."""
"O tẹsiwaju pe "" Mo jẹ oloriire pe mo jẹ ọrẹ rẹ, mo si nireti pe ọjọ ibi rẹ yii yoo jẹ pataki fun ọ, mo gbadura pe ki gbogbo ala rẹ wa si imusẹ."
Ronkẹ ni MC Oluọmọ seun o, to maa n tẹti si oun, to si tun seun, to jẹ ọrẹ nla si oun.
Oríṣun àwòrán, Ronke Ojo Anthony
Ninu awo naa si lo tun ti n salaye pe igi gbongbo to n so eso fun ẹni ti ebi n pa ni Oluọmọ jẹ, to si ni ni ori gbogbo ti ọlọjọ ibi naa ti da lọla, yoo jẹ ko maa lọ siwaju si, ti Ọlọrun yoo si jẹ ko se ọpọlọpọ ọdun laye.
Coronavirus: Wale Akintade ní ìjọba ń sanwó oṣù fáwọn àmọ́ nǹkan kò rọgbọ
Oríṣun àwòrán, Others
Àìsàn Coronavirus to n jagún káàkiri agbáye ko ti sinmi ìjà rẹ, se lo si n ja rain lọ gẹgẹ bii ajakalẹ arun ti wọn pe e.
Bí gbogbo ènìyàn ṣe n lọgun pe, sebi ilú Wuhan ní China ni arun Coronavirus ti bẹ̀rẹ̀, sùgban báwo lo ṣe wá jẹ pé orilẹ̀-èdè Italy lo n pín ààrùn náà kiri laarin àwọn orilẹ̀-èdè to ko arun ọhun.
Pẹ̀lú gbogbo ìròyìn ajanilaya to n waye lati Italy nipa ọsẹ arun Coronavirus naa, lo mu ki BBC  Yoruba kàn si àwọn ọmọ Naijiria to wà lorilẹede naa, láti mọ irú ipò ti wọ́n wà pẹ̀lú ajakálẹ̀ ààrun yìí.
Oríṣun àwòrán, Others
Ọkan nínú àwọn to bá BBC sọ̀rọ̀, Wale Akintade sàlàye pé, aláfíà ni àwọn wà bo tilẹ̀ jẹ́ pé ààrun náà n bá àwọn ènìyàn Italy fira gidigidi, o ni ko kan àwọn alawọ dúdú to wa nibẹ, àwọn ọmọ ilẹ Italy àti àwọn ọmọ China ni ọ̀rọ̀ náà kan jùlọ.
Oríṣun àwòrán, Others
Coronavirus: Alaye rèé lóri pò ti ni àwọn ọmọ Naijiria wà ní Italy
Akintade ni ìròyìn ti àwọn n gbọ ni pe, àwọn ènìyàn dudu ti Coronavirus mu kò ju bii mẹta lọ, sùgbọ́n yàtọ si ààrun náà, ǹkan ko rọ̀gbọ fun ẹnikẹni nitori wọ́n ti dènà mọ gbogbo ǹkan.
Okúnrin náà fi kún pé, àti ọkọ̀ ofurufu, àti reluwe ni wọn ti tì pà, káràkáta náà ti dẹnu kọlẹ, ko si si ẹni to le wọle láti ilẹ̀ okere rara, konile o gbéle ni gbogbo ènìyàn wà.
O ni adura ti àwọn kan n gbà ni pe, ki arun naa ma ran àwọn ènìyàn dúdú, o ni ilé ìwòsàn, ilé oogun àti ile itaja ìgbàlode nikan ni wọ́n gba láti ṣilẹkun wọn.
Oríṣun àwòrán, Others
Coronavirus: Alaye rèé lóri pò ti ni àwọn ọmọ Naijiria wà ní Italy
Akintade fikun pe bo tilẹ̀ jẹ́ pe àwọn ko ṣiṣẹ́, síbẹ̀ ijọba n san owó fawọn laiyinjẹ ti oṣù bá ti pari, eyi ti ko jọ ohun to n waye nilẹ Afirika to jẹ pe ẹni to sisẹ gan ko ri owo osu rẹ gba.
Ní ojúmọ to mọ lónìí yìí, ènìyàn to lé ni ẹgbẹ̀run lọ́na mẹ́tàdinlógun lo ti ni ààrun náà, èníyan to le ni ẹgbẹ̀fà lo si ti ba iṣẹ̀lẹ̀ náà lọ nígbà ti ènìyàn ẹgbẹ̀run kan o lé márundinláàdọta rú ààrun náà là, ti wọn si pada si ilé wọ́n.
Emir of Kano: Sanusi ní òun mọ ohun tí òun leè ṣe láti gba ipò Emir òun padà
Oríṣun àwòrán, @GovKaduna
Emir ilu Kano tẹlẹ, Lamido Sanusi ti ni oun mọ ohun to yẹ lati ṣe, ti oun ba fẹ pada si ipo Emir ilu Kano.
Sanusi de ilu Eko lọjọ Ẹti lẹyin ti ileẹjọ kan niluu Abuja paṣẹ pe, ki ileesẹ ọtẹlẹmuyẹ DSS fi silẹ lahamọ to wa niluu Awe nipinlẹ Nasarawa, lẹyin irọloye rẹ.
Emir ana naa ṣalaye pe ijọba ipinlẹ Kano ko tẹle ilana to tọ lati rọ oun loye.
Sanusi to jẹ ọga agba banki apapọ orilẹede Naijiria tẹlẹ sọ ninu fidio kan to lu ori ayelujara pa pe, iwe irọniloye oun ti ijọba kọ ku diẹ kaato, o ni o rọrun fun oun lati tako igbesẹ ijọba nileẹjọ.
Amọ, Sanusi ni ọrọ oye Emir ilu Kano ti di afisẹyin ti eegun n fi aṣọ fun oun, o ni oun ti ṣe iṣẹ ti oun fẹ se tan laarin ọdun mẹfa ti oun lo gẹgẹ bi Emir ilu Kano.
Emir ilu Kano tẹlẹ ni ohun ti ileẹjọ yoo beere ni boya ijọba ti ṣe ikilọ fun oun tẹlẹ, ko to yọ oun nipo, tabi ṣe wọn ti gbọ tẹnu oun.
Ṣugbọn Sanusi ṣalaye pe, ipele tuntun lo kan bayii ninu irin-ajo oun, nitorinaa oun ko raye lati maa lọ si ile ẹjọ lori ati pada si ipo Emir ilu Kano.
Tantra: Ìlànà yìí ló ń kọ́ wa láti fi èémí àti ìṣẹ́po ara gbádùn ìbálòpọ̀
O fikun ọrọ rẹ pe, iyọnipo oun kii ṣe ohun to le jọ ki inu oun bajẹ nitori oun ko rii bẹẹ rara.
Alaafin: Ọ̀sán ọjọ́ Àìkú ní Ọba Adeyemi gbalejo Kayode Fayemi
Oríṣun àwòrán, @ekitistategov
Yoruba ni baba ba sẹ ọmọ, ọmọ ni yoo bẹ baba, bi ọmọ si sẹ baba, ọmọ naa ni yoo bẹ baba, nitori agba ni agba yoo maa jẹ.
O si dabi ẹni pe ede aiyede to n waye lori ọrọ lọbalọba nipinlẹ Ekiti, eyi to ti n mu ọpọ awuyewuye dani, ko ni pẹ rodo, lọ ree mumi bayii, ta ba wo isẹlẹ to n waye ni aafin Ọyọ lọsan ọjọ Aiku.
Idi ni pe Gomina ipinlẹ Ekiti, Kayode Fayemi ti lọ se ago laafin sọdọ Alaafin tilu Oyo, Ọba Lamide Ọlayiwọla Adeyemi kẹta lọsan ọjọ Aiku.
Oríṣun àwòrán, @ekitistategov
Gbalaja ni Fayemi fi idọbalẹ bẹ fun Alaafin, eyi to n fihan pe ko si aawọ ma.
Ninu ikede kan ti ijọba ipinlẹ Ekiti fi sori ayelujara Twitter rẹ, ni a ti ri ọpọ aworan to n safihan bi Alaafin se tẹwọ gba Fayemi tọwọ-tẹsẹ.
"Fayemi dọbalẹ gbalaja, Alaafin naa si fọwọ mejeeji gbe e dide pe ""kare, ọmọ daada. Dide nlẹ, ma fọwọ ọla tẹlẹ"""
Oríṣun àwòrán, @ekitistategov
Lẹyin naa ni awọn aworan miran tun fi wọn han nibi ti wọn ti jọ joko, n ka iwe kan to jọ lẹta ti Alaafin ti kọkọ kọ si Fayemi, lori ọrọ kan to sọ pe oun yoo rọ awọn ọba Ekiti l'oye.
"Ko tan si bẹ o, aworan miran tun fi awọn mejeeji han, nibi ti wọn ti n rẹẹrin sira wọn lori ijoko to jọ pe, Alaafin n sọ fun Fayemi pe, ""eeyan o ki n ṣe bayẹn. Ko yẹ ki iwọ naa o sọ pe o maa rọ awọn ọba loye."
Oríṣun àwòrán, @ekitistategov
BBC Yoruba yoo maa mu ẹkunrẹrẹ ijiroro awọn mejeeji wa fun yin laipẹ.
Saaju la ti sọ pe Alawe ti ilu Ilawẹ Ekiti, Ọba Adebanji Ajibade Alabi, Afuntade Kinni, ti ba BBC Yoruba sọrọ lati salaye idi to fi kọ lẹta kan si Gomina ipinlẹ Ọyọ, Seyi Makinde lori ọ̀rọ̀ Alaafin tilu Ọyọ.
Nigba to ba BBC Yoruba, Alawe ṣalaye gbogbo nkan to kọ sinu lẹta ọhun lẹẹkan si, to si ni pe, ọrọ lọbalọba ipinlẹ Ekiti ko le ye Alaafin laelae, nitorinaa ko maa da si ohun ti ko kan an.
''A fẹ ki Gomina Makinde kilọ fun Alaafin wi pe ko maa da aarin awọn lọbalọba ru nipinlẹ Ekiti nitori Ekiti kii ṣe ilẹ Oyo,'' Alawe lo woye bẹẹ.
Kabiyesi Alawe ni awọn lọbalọba Ekiti ko ranṣẹ pe Alaafin lati da si ọrọ to n lọ laarin wọn, nitorinaa ko duro si aye rẹ.
O ni Alaafin ko le duro si Oyo, ki o maa kọ lẹta ranṣẹ si Ekiti nitori Aguda o jẹ labẹ Gẹeṣi ati wi pe kaka ki kiniun ṣe akapo ẹkun, onikaluku a maa ṣọdẹ tiẹ lọtọọtọọ.
Oríṣun àwòrán, Alawe of Ilawe Ekiti
O fikun ọrọ rẹ pe, Ọọni Ile Ife, ni gbogbo lọbalọba gba gẹgẹ bi olori nilẹ Yoruba, kii ṣe Alaafin, yoo si dara ki oriade ilu Ọyọ lọ so ewe gbejẹ mọwọ.
Alawe ni ''asiko ajẹlẹ ti kọja, ati wi pe Ooni Ile Ife ni a gba si baba nilẹ Yoruba, oun ni kokari.''
''Kabiyesi Ọọni ni Arole Oduduwa ti gbogbo wa mọ, Ile Ife si ni gbogbo wa ti san wa, kii ṣe Oyo, bẹẹ si ni Ọọ ni ko lee kọ iru lẹta buruku ti Alaafin kọ yii si gomina Fayemi laelae, arifin gbaa ni oun ti Alaafin se naa'' Kabiyesi Alawe lo sọ bẹẹ.
Tantra: Ìlànà yìí ló ń kọ́ wa láti fi èémí àti ìṣẹ́po ara gbádùn ìbálòpọ̀
Kabiyesi Alawe ni ọgbọn ati imọ ni Kabiyesi Ọọni fi n to ilẹ Yoruba, Ọọni ko le kọ iru iwe ti Alaafin kọ to fi n bu gomina atawọn ọba alaye l'Ekiti.
Lẹta ti Alaafin tilu Ọyọ, Ọba Lamidi Ọlayiwọla Adeyẹmi Kẹta kọ si gomina ipinlẹ Ekiti, Dokita Kayọde Fayemi, ti n bi Ige ati Adubi bayii.
Oríṣun àwòrán, Alaafin Oba Adeyemi III
Idi ni pe ojo lẹta miran tun ti yọju sita eyi ti wọn kọ si gomina Seyi Makinde, amọ to n fun Alaafin lesi pada nipa ọrọ to ba Fayemi sọ lori ọrọ awọn lọbalọba.
Ninu lẹta tuntun naa ni alaga igbimọ lọbalọba nipinlẹ Ekiti, tii tun se Alawẹ tilu Ilawẹ Ekiti, Ọba Adebanji Ajibade Alabi, Afuntade Kinni, ti fesi pada fun Alaafin.
Oríṣun àwòrán, Alawe of Ilawe Ekiti
Ninu iwe oloju ewe marun ọhun, ni Ọba Alabi ti n kesi gomina ipinlẹ Ọyọ pe igbimọ lọbalọba ni Ekiti koro oju si awọn ohun ti Alaafin mẹnuba ninu lẹta rẹ.
Fun alaye, Alawẹ ni alaga igbimọ lọbalọba ni Ekiti, ta gbọ pe awọn ọba yoku kọ lati ba se ipade nitori pe wọn ni o kere si awọn ni ipo, ti ko si lẹtọ lati jẹ alaga le awọn lori.
Alawẹ ni Alaafin ko lee wa jẹ gaba lori awọn ọba Ekiti nitori Ekiti ko si labẹ isejọba Ọyọ ri, bẹẹ ni ko lee si labẹ Alaafin laelae.
Alawẹ wa n rọ Gomina Makinde pe ko da Alaafin lẹkun lori bo se n toju bọ awọn ọrọ abẹle to kan awọn lọbalọba  nipinlẹ Ekiti nitori lẹta ti Alaafin kọ yii, lo kun fun didọwọ bo ootọ loju ati agbekalẹ ti ko tọna nipa isẹlẹ to n waye laarin awọn lọbalọba ati ijọba ipinlẹ Ekiti.
"Lẹta naa fikun pe ""Awọn ọba mẹtadinlogun ni Ekiti lo n tọkasi pe awọn wa lara ilana Pẹlupẹlu ninu igbimọ lọbalọba ni Ekiti, amọ pẹlu akọọlẹ ilana ofin ijọba tọdun 2018, ọba meji pere ni ijọba fọwọsi. Ko si sẹni to tako ijọba gomina Ayodele Fayose nigbanaa, ki wa ni pataki ọba mẹrindinlogun ti Alaafin n tọkasi pe o wa ninu ilana pẹlupẹlu?"""
Mo si n fi gbogbo ẹnu ati asẹ mi sọ pe Alaafin se asise pẹlu bo se ni lati igba iwasẹ ni awọn asaaju ọba ni Ekiti ti jẹ mẹrindinlogun, eyiun awọn ọba ti ko lee darukọ wọn, amọ okan n dibọn pe oun ko mọ pe iye ọba to wa labẹ pẹlupẹlu koo duro si oju kan.
Oríṣun àwòrán, Alaafin Oba Adeyemi III
Alawẹ ni se ni Alaafin kan n feti si gbọyisọyi kiri lai wadi otitọ ko to maa naka aleebu si gomina Fayemi, to si tun kọ lati darukọ awọn ọba to to ni o kere ni ipo, o si n beere pe awọn ọba wo lo n baa wi gan?
Alaawẹ, ninu lẹta naa, lo tun ni ko si aniani pe Alaafin maa n mọọmọ da awuyewuye ati rogbodiyan silẹ ni nibi ti ko si, to si n dasi ọrọ ti ko kan, to n gbe wahala to da silẹ fun igbimọ lọbalọba ni ipinlẹ Ọyọ ijọun wa, eyi to da ija agba meji silẹ laarin Alaafin ati Ọọni, ti wọn ko si lee se ipade mọ titi ti wọn fi yọ ipinlẹ Ọsun lara Ọyọ.
Eyi to wa buru ju nibẹ ni pe igbimọ lọbalọba nipinlẹ Ọyọ ko tii se ipade kankan lati ọdun mẹrin nibiti o ti jẹ alaga wọn, eyi ko si sẹyin bo se nira fun lati jẹ ki alaafia, isọkan ati irẹpọ waye laarin awọn ọba alaye nipinlẹ naa. Bawo lo se fẹ fun wa ni ohun ti iwọ gan ko ni, awa ọba Ekiti kii se Ajẹlẹ Alaafin nitori naa ayọnisọ rẹ si ọrọ abẹle lọbalọba Ekiti ko tọ
Alawẹ ni awọn ọba Ekiti wa n rọ Makinde lati fewe ọmọ mọ Alaafin leti, ko yee da si ọrọ ti ko kan, paapa lori ọrọ to wa nile ẹjọ.
Oríṣun àwòrán, Alaafin Oba Adeyemi III
Saaju la ti sọ fun yin pe Alaafin tilu Ọyọ, Aba Lamidi Ọlayiwọla Adeyemi Kẹta ti salaye pe agba kii wa lọja, ki ori ọmọ tuntun wọ, ni oun  se fi imọran sọwọ si gomina ipinlẹ Ekiti, Kayode Fayemi lori aawọ awọn lọbalọba.
Bẹẹ ba gbagbe, a ti kọkọ mu iroyin wa fun yin nipa lẹta kan ti Alaafin kọ si Fayemi lọjọ kejila osu kẹta, ati awọn koko to wa ninu rẹ.
Nigba to n salaye siwaju lori lẹta naa, Alaafin ni oun ko ni kọnu n kọhọ kankan si gomina naa, koda inu oun ms si amọ oun gbe igbesẹ naa gẹgẹ bii oludaabo bo asa ati ise Yoruba ni.
Alaafin sọ siwaju pe agba ti ko ba kẹhun sọrọ, afaimọ ko ma kẹtan sare, idi si ree ti oun fi n fa Fayemi leti pe ko gbọdọ yi asa ati ise wa pada nipinlẹ Ekiti lọna ti ko bojumu.
Mo kọ lẹta naa gẹgẹ bii Alaafin Ọyọ, ohun mi si ni ohun gbogbo ọmọ Yoruba. Emi ni mo wa nipo to dara julọ lati tọ ijọba sọna, ki n si gba wọn ni imọran lori awọn ọrọ to nii se pẹlu asa ati isẹse Yoruba nitori Alaafin ni oludaabo bo asa to ga julọ.
Oríṣun àwòrán, Alaafin Oba Adeyemi III
Ojuse Alaafin ni lati da si awọn ọrọ to ba nii se pẹlu asa to ba suyọ nilẹ Yoruba. Asa atijọ si ni ilana Pẹlupẹlu to jẹ asa awọn ọba alaye ni Ekiti. Taa ba si wo ipa ti awọn Ekiti ko ninu ogun Kiriji, ko yẹ ka fọwọ rọ wọn sẹyin. Awọn ọba mẹrindinlogun to wa ni Ekiti jẹ akikanju ati alagbara ti Yoruba lee gboju le.
Oríṣun àwòrán, Others
Alaafin tẹsiwaju pe ni gbogbo ọna, ohun amuyangan lawọn Ekiti jẹ fun ilẹ Yoruba, paapa lẹka eto ẹkọ, ko si fẹẹ si agboole kan ti wọn ko ti ni ẹni to kawe de ipo Ọjọgbọn. Iwe ti mo kọ si Fayemi jẹ lẹta baba si ọmọ ni, mo si nigbagbọ pe awọn ohun to wa ninu iwe shun yoo ye yekeyeke.
Amọ titi di akoko yii, ijọba ipinlẹ Ekiti ko tii sọrọ lori lẹta ti Alaafin kọ si naa.
Amotekun: Akeredolu ní àwọn iléeṣẹ́ aláàbò ni yóò ṣèdánilẹ́kọ̀ọ́ fáwọn ẹ̀sọ́ náà
Alaga awọn gomina lẹkun iwọ oorun guusu Naijiria, Rotimi Akeredolu ti kede pe ọsẹ tuntun taa bẹrẹ yii ni wọn yoo gba awọn ẹsọ alaabo fun ikọ Amotekun sisẹ.
Bakan naa lo fikun pe ki osu kẹta taa wa yii to buse, iks alaabo naa yoo gberasọ, ti yoo si bẹrẹ isẹ.
Gomina Akeredolu, ẹni ti olugbani nimọran rẹ feto aabo, Alhaji Jimoh Dojumo gba ẹnu rẹ sọrọ, tun fikun pe gbogbo eto lo ti doju ọgbagade bayii lati ri pe ikọ Amotekun bẹrẹ, eyi ti yoo gbogun ti aifararọ feto aabo nilẹ Yoruba.
Ọjọ mọkanlelogun ni awọn ẹsọ Amotekun yoo fi gba idanilẹkọ amọ loore koore la maa se idanilẹkọ fun wọn lori eto aabo. Awọn ileesẹ alaabo ni yoo maa se idanilẹkọ fun awọn ẹsọ ta ba gba, igbanisisẹ ati idanilẹkọ yoo si maa lọ ni rọgba-rọgba ni.
Tantra: Ìlànà yìí ló ń kọ́ wa láti fi èémí àti ìṣẹ́po ara gbádùn ìbálòpọ̀
Bakan naa ni Dojumo fikun pe awọn n sọrase lati mase se asise lori isọwọ sisẹ ikọ alaabo naa pẹlu afikun pe, o seese ki wọn ma pese asọ isẹ pataki fun ikọ naa bayii, tori ipinnu kankan ko tii waye lori eyi.
Lagos Explosion: Sanwo-Olu rọ olùgbé Eko láti mú ààbò ẹ̀mí ní pàtàkì
Oríṣun àwòrán, Others
Ajọ to n ri si isẹlẹ pajawiri nipinlẹ Eko, Lasema ti kede pe eeyan mẹtadinlogun, to fi mọ ọga agba ileẹkọ kan lo ti jalaisi ninu isẹlẹ naa, nigba ti awọn mẹẹdọgbọn miran n gba itọju nile iwosan, eyi ti iroyin rẹ gbalẹ kan ni aarọ ọjọ Aiku.
Bakan naa, ko din ni aadọta ilegbe, ile ijọsin ati ileẹkọ to bajẹ kọja aala lasiko ti ọrinrin ibugbamu naa waye lagbegbe Abule Ado yii, ti ọwọja rẹ si tan de awọn agbegbe miran pẹlu.
Koda, ọpọ mọto ti wọn gbe kalẹ si adugbo naa lo bajẹ tan pata, ti ọpọ eeyan si di alainile lori.
Sista ijọ katoliki, tii se ọga agba ileẹkọ girama Bethlehem Girls college, Henritta Alokha, to wa ladugbo naa, lo jalaisi lasiko to n gbiyanju ati doola ẹmi awọn ọmọ ileẹkọ naa.
Oríṣun àwòrán, Others
Wayi o, gomina ipinlẹ Eko, Babajide Sanwo-Olu ti se abẹwo si ibudo ti ọpa gaasi naa ti bu gbamu, to si ni ki wọn setọju awọn eeyan to faragba ni kiakia.
Coffee Painter: Adebukola ní kò sí ìrànwọ́ lẹ́yìn ẹ̀kọ́ girama lòun ṣe ń ya àwòrán
Bakan naa lo gba awọn eeyan Eko nimọran lati rin jinna sibi ti isẹlẹ naa ti waye tori ewu, ki wọn si mase mi eefin isẹlẹ naa simu.Arigbamu ti wa bayii nipa iye eeyan to ba isẹlẹ ọpa gaasi to lagbegbe Abule Ado nijọba ibilẹ Amuwo ọdọfin nipinlẹ Eko lọ.
Ijamba ina to sadede bẹ silẹ lọsan ọjọ Aiku lagbegbe Ado Soba, Abule Ado nijọba ibilẹ Amuwo Ọdọfin ti mu ẹmi lọ, to si tun ba ile to le ni aadọta jẹ kanlẹ.
Akọroyin BBC Yoruba to wa nibi isẹlẹ naa jabọ pe deede aago mẹwa aarọ, lasiko ti awọn eeyan kan ti wa nile ijọsin ni ọpa to n pin afẹfẹ gaasi sadede bu gbamu, ti ina si sọ.
Gẹgẹ bi awọn eeyan to  wa ladugbo naa, ti isẹlẹ ọhun si soju wọn ti wi, se ni oorun gaasi kọkọ gba agbegbe naa kan, ti ara si ti n fu awọn pe ewu nbọ, awọn si n wa ọna abayọ lọwọ, ni ina sọ.
Oorun gaasi lo kọkọ ru bo wa ninu ile, ti mo si n sọ fawọn ọmọ pe ki wọn jẹ ka jade sita lati wọna abayọ, ibi ta ti n gbero lati jade, ni mo gbọ gbola lojiji, ti ohun gbogbo si pakasọ.
Bakan naa lo fikun pe ile ti ijamba naa bajẹ to aadọta niye, nigba ti ọpọ eeyan ti wọn ko tii mọ iye wọn, ti jalaisi ninu ijamba ina naa.
Lasiko to n ba BBC Yoruba sọrọ, alaga ijọba ibilẹ Amuwo Ọdọfin, Onimọ-ẹrọ Dotun Valentine salaye pe, awọn ara adugbo naa ni ọpa gaasi naa lo bẹ nitori ẹrọ kan to bajẹ, eyi to mu ki afẹfẹ gaasi maa tu jade, to si sadede gba ina.
Kii se pe awọn eeyan kan lo ba ẹrọ naa jẹ, nitori awọn sọja wa nibudo naa, ti wọn n sọ awọn ọpa afẹfẹ gaasi naa, irinsẹ rẹ kan lo bajẹ, amọ o ti ya ju fun mi lati kede iye ẹmi to ba isẹlẹ naa lọ.
A ti kesi awọn osisẹ ajọ elepo rọbi NNPC lati wa ti ẹrọ to n pin afẹfẹ gaasi wa sidi ọpa naa, ki ina ọhun lee tete jo tan, tawọn osisẹ panapana, Lasema, ọga ọlọpa ati olori ileesẹ ologun lẹkun yii si ti de sibi isẹlẹ naa.
Valentine tun salaye pe ọpọ dukia lo ti sofo nitori isẹlẹ ina ọhun, ti ileẹkọ, ilegba ati awọn ibudo ijọsin loniran nran si dawo lulẹ tabi padanu orule ile wọn.
Eyi to tiẹ se ni laanu julọ ni ti ileẹkọ Bethlehem Girls College, to wa ni gbagede ipatẹ ọja to wa ladugbo naa, tawọn akẹkọ ti n gba idanilẹkọ lọwọ, nigba ti ibugbamu naa waye, to si dawo.
Ẹgbẹ alagbelebu pupa, Red Cross, toun naa ko gbẹyin nibi isẹlẹ ina yii, salaye pe, o ti to eeyan mẹẹdogun ti awọn ti doola ẹmi wọn lọwọ ijamba nileẹks naa, ti wọn si ti gbe wọn lọ sile iwosan.
Lọwọ-lọwọ bayii, ọpọ olugbe adugbo naa lo ti n ko ẹru wọn kuro ni adugbo naa, ta si tun kofiri ọkọ ofurufu to n paraaro adugbo ọhun, aibaamọ, isẹlẹ naa le tun fọn ina soju.
Ajọ Lasema ti wa kede pe ohun ti bẹrẹ isẹ idoola ẹmi nibi isẹlẹ naa, paapa lawọn inu ile to fori sọta ọrinrin ibugbamu ọhun.
Saaju la ti sọ fun yin pe iroyin to n ja rainrain to n tẹ wa lọwọ bayii ti kede pe, ọpa epo miran tun ti bẹ lagbegbe Festac, ti ọrinrin rẹ si gbalẹ yika Eko.
Ariwo ti ibugbamu naa mu lọwọ lo gbalẹ kan, ti awọn eeyan si n sa asala fun ẹmi wọn, a ko si ti lee sọ iye ẹmi to ti ba isẹlẹ naa rin.
Nigba to n fidi isẹlẹ naa mulẹ, oludari ajọ to n ri si isẹlẹ pajawiri nipinlẹ Eko, Lasema, Oke Ọsanyintolu sọ fun BBC Yoruba pe awọn eeyan to n fọ ọpa epo pẹtiroolu lo se okunfa isẹlẹ naa.
Lasema ni oun ti de ibi isẹlẹ naa, ti ọwọ awọn osisẹ ajọ naa si ti n ka ina yii.
Amọ Ọsanyintolu ko tii lee sọ boya ẹmi kankan ba isẹlẹ naa rin abi iye dukia to ti sofo.
A ti de sibi isẹlẹ naa, a n sisẹ lọ lati pa ina yii, ọwọ wa si ti n kaa, amọ a ko tii mọ bii ọsẹ to se ti nipa si. A gbọ wipe awọn eeyan to n fọ ọpa epo lo tun se okunfa akọtun ibugbamu ọpa epo yii. Bo ba se n lọ, a mu to ẹyin akọroyin leti.
Amọ ẹnikan ti isẹlẹ naa soju rẹ, amọ to kọ lati foju han lori aworan BBC Yoruba ni, iye awọn eeyan to ku ninu ijamba yii ko lonka, ti wọn ti ha sinu ina ọhun.
A gbọ pe ọpọ adugbo to sun mọ ibi ti ibugbamu naa ti waye, bii Akọta, Festac ati Abule Ado ni ariwo naa rinlẹ de, ti ilẹ mi titi eyi to se ẹru ba ọpọ eeyan.
Lọwọ-lọwọ bayii, wọn ti n gbe awọn eeyan to sese ninu ijamba ibugbamu naa lọ sile iwosan, ninu eyi ti a ti ri sisita ijọ Katoliki kan ati akẹkọ mta.
Oju opo Twitter ti kun fun ariwo awọn eeyan to gburo ibugbamu naa eyi to se ọsẹ pus fun ọpọ ile.
A gbọ pe awọn dukia kan ti ba isẹlẹ naa rin, tori ibugbamu naa mu ki awọn orule ile kan si, to fi mọ ibudo ijọsin, lasiko ti awọn eeyan n jọsin lọwọ, ti awọn ile kan si ti dawo pẹlu.
Koda, eefin n ru jade lati agbegbe ti ibugbamu naa ti waye, ti oju ọrun si dudu fun eefin.
Akọroyin BBC to sare de ibi isẹlẹ naa ni ileesẹ panapana ijọba ti wa de sibi isẹ́lẹ́ naa, ti wọn si ti n pa ina naa.
A tiẹ tun gbọ pe ileewe kan ti wo lulẹ nitori ariwo ati ilẹ to mi lasiko ti ibugbamu ọpa epo naa waye.
Bi isẹlẹ yii ba si se n tẹsiwaju, nileesẹ BBC Yoruba yoo maa mu wa fun yin.
Coronavirus: Afurasí aláàrùn coronavirus ní ìpínlẹ̀ Enugu ti wà ní ìyàsọ́tọ̀
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ajọ to n risi idena ajakalẹ aarun ni Naijiria, NCDC, ti sọ pe alaisan kan wa ni ipinlẹ Enugu, ni apa ila oorun orilẹ-ede Naijiria ti wọn fura si pe o ni aarun coronavirus.
Gẹgẹ bi ikede kan ti ajọ NCDC fi si ori ayelujara Twitter rẹ lọjọ Aiku, wọn ti fi alaisan naa si iyasọtọ, wọn si ti ṣe ayẹwo ara rẹ, esi yoo si jade lọla, ọjọ Aje.
Ṣugbọn, ikede wọn naa ko sọ boya ọkunrin tabi obinrin ni alaisan naa.
Ọjọ Ẹti to kọja ni Minisita fun eto ilera ni Naijiria, Ọjọgbọn Osagie Ehanire kede pe ọsẹ yii ni wọn yoo yọnda ọmọ orilẹ-ede Italy to ko aarun naa wọn Naijiria kuro nileewosan.
Bakan naa lo sọ pe alaisan keji to ni aarun naa ni ipinlẹ Ogun ko ni aarun naa mọ lẹyin ayẹwo ti wọn pada ṣe fun. Oun naa yoo ma lọ si ile rẹ.
Oṣu Keji ni Naijiria kọkọ ni akọsilẹ aarun coronavirus.
Gẹgẹ bi akọsilẹ onka agbaye kan, Worldometer, eniyan ti ko din ni ẹgbẹrun maarun o le ẹgbẹrin ati marundinlaadọta eniyan ni aarun naa ti ṣekupa.
Awọn papakọ ofurufu ilẹ Amẹrika ti wa ni idarudapọ bayii nitori eto ayẹwo ilera lori arun Coronavirus to bẹrẹ, fun awọn eniyan to n de lati ilẹ Yuroopu.
N ṣe ni awọn eniyan to bẹẹrẹ bẹ fun ọpọlọpọ wakati lati sẹ ayẹwo ara wọn, ki wọn o to kọja lọdọ awọn ẹsọ aṣọbode.
Ṣaaju asiko yii, Igbakeji Aarẹ, Mike Pence sọ pe, ofin ti wọn fi de awọn arinrinajo lati awọn orilẹ-ede to wa ni ilẹ Yuroopu yoo kan ilẹ United Kingdom ati Ireland lọjọ Iṣẹgun.
Oríṣun àwòrán, Ruth Procopi
Awọn alaṣẹ Amerika ti fofin de awọn arinrinajo lati awọn orilẹ-ede mẹrindinlọgbọn to wa ni ilẹ Yuroopu, ṣugbọn ti ki ṣọmọ ilẹ Amerika.
Aaye wa fun awọn ọmọ ilẹ Amerika lati wọle, ṣugbọn wọn yoo ṣayẹwo oju wọn.
Eniyan to le ni ẹgbẹrun meji ati ẹẹdẹgbẹrin lo ti ni aarun Coronavirus nilẹ America, ti awọn mẹrinlelaadọta si ti ku.
Awọn akọroyin n sọ pe idarudapọ lo gbalẹ bayii ni America, pẹlu ibẹru pe o ṣeesẹ ki ibusun alaisan o ma to mọ nileewosan, ati itọju awọn ọmọde ti wọn ti le ọpọlọpọ miliọnu wọn wa sile.
Oshiomole: Ilé ẹjọ́ kòtẹ́milọ́rùn wọ́gilé ìyọnípò Oshiomole gẹ́gẹ́ bíi alága ẹgbẹ́ òṣèlú APC
Oríṣun àwòrán, @marketdigestng
Ile ẹjọ kotẹmilọrunilu Abuja ti ni Adams Oshiomhole si ni alaga gbogbogbop fun ẹgbẹ oṣelu APC.
Igbimọ ẹlẹni mẹta to n gbọ ẹjọ naa, ti adajọ Abubaka Datti Yahaya ko sọdi wọgile ẹjọ ti ile ẹjọ giga ilu Abuja da ṣaaju, leyi to yọ Oshiomole nipo gẹgẹ alaga ẹgbẹ ọhun.
Ṣaaju ni oshiomole ti rọ ile ẹjọ kotẹmilọrun naa lati gbe idajọ iyọnipo rẹ naa ti ṣdegbẹ kan.
Nigba to n gbe idajọ rẹ kalẹ, adajọ naa kilọ fun awọn ti ọrọ ọhun lati ma gbe igbeṣẹ ti yoo tako idajọ to gbe kalẹ.
Lẹyin naa lo rọ awọn ẹgbẹ oṣelu lati maa yanju awọ to ba wa laarin wọn gẹgẹ bi ọmọ iya dipo ki wọn maa yọ ile ẹjọ lẹnu.
Oríṣun àwòrán, Others
Eekan ẹgbẹ oṣelu APC, Bola Tinubu ti sọrọ lori awuyewuye lati yọ alaga apapọ ẹgbẹ naa, Adams Oshiomole nipo.
Ninu atẹjade kan to fi sita lọjọ Aiku, Tinubu ni arun a ti dije fun ipo oṣelu lọdun 2023, lo n ṣe awọn ọmọ ẹgbẹ APC to fẹ yọ Oshiomole nipo alaga.
Tinubu ni igbesẹ yii n ṣakoba fun ẹgbẹ oṣelu APC, bakan naa lo n ṣe ipalara fun iṣejọba Aarẹ Muhammadu Buhari.
''Aarun a ti dupo lọdun 2023 n ṣe ọpọ lagbo oṣelu atawọn alatilẹyin wọn laarin awọn akọroyin'' Tinubu lo woye bẹẹ.
Oríṣun àwòrán, Facebook/Asiwaju Bola Tinubu
Tinubu ni ohun to n ṣe awọn to fẹ yọ Oshiomole nipo ni pe, wọn fẹ ki gbogbo ọrọ lori ibo ọdun 2023 ko yanju tan ninu ẹgbẹ lọdun 2020 yii.
Asiwaju Tinubu fikun ọrọ rẹ pe, Oshiomole ti ṣisẹ takun takun fun ẹgbẹ oṣelu APC papaa julọ, lasiko ibo gbogbo-gbo to kọja.
O ni kii wa ṣe asiko yii lo yẹ ki awọn eeyan kan maa fẹnu tẹnbẹlu rẹ ninu ẹgbẹ.
Oríṣun àwòrán, Others
Tinubu sọ pe iwa aimore ni lati maa mọ riri ipa ti Oshiomole ko ninu ẹgbẹ oṣelu APC papaajulọ lasiko ibo to ja.
Tinubu ni ''ero awọn ti wọn n tako Oshiomole ni pe o maa dina mọ wọn lati dije fun ipo kan tabi omiiran ninu idibo ọdun 2023.''
Coffee Painter: Adebukola ní kò sí ìrànwọ́ lẹ́yìn ẹ̀kọ́ girama lòun ṣe ń ya àwòrán
Tinubu ṣalaye pe akoko ko tii to fun oṣelu ọdun 2023, o rọ awọn ọmọ ẹgbẹ APC lati gbaruku ti Aarẹ Buhari ko le ṣe aṣeyọri ninu ijọba rẹ.
Lagos Explosion: Àwọn akẹ́kọ̀ọ́ iléẹ̀kọ́ Bethlehem ń gbàdúrà òwúrọ̀ lọ́wọ́ ní ìbúgbàmù wáyé
Oríṣun àwòrán, others
Bi awọn dukia kan ṣe wo kanlẹ, ni wọn tun jona
Ẹnikan ti isẹlẹ ile to dawo ladugbo Festac nilu Eko, ti iṣẹlẹ naa ṣoju rẹ sọ fun BBC pe, o ṣoju oun koro nigba ti wọn gbe ọkan lara awọn sista ileewe Bethlehem Girls College jade, lẹyin ti ile iwe ọhun wọ le wọn lori.
Victor Obanor sọ pe oun wa ni nkan bi kilomita meji si ibi ti iṣelẹ naa ti ṣẹ, ṣugbọn iro ibugbamu naa milẹ titi.
Victor ni, ariwo yii lo mu ki oun ati awọn eeyan mii to wa layika sare tete lọ wa ibi ti iṣẹlẹ naa ti ṣẹ lọ, lati le ṣe iranlọwọ fun awọn ti ọrọ naa kan.
Iwaadi ileeṣẹ iroyin BBC fi han pe, wọn ti gbe oku sista Henrietta Alokha, to jẹ alakoso ileewe Bethlehem Girls College ati awọn oṣiṣe ile iwe ọhun meji miran, ti jade laye lẹyin iṣẹlẹ yii,  lọ si ile iwosan awọn omọ ogun ori omi nilu Eko.
Oríṣun àwòrán, others
Ọkan tun re e lara awọn ọkọ ayọkẹlẹ ti ibugbamu fi ọwọ ba, a ko le sọ boya ina tabi ile to wo lo sọ ọkọ yii di rirun jege-jege
A gbọ pe awọn akẹkọ ile iwe naa wa ni adura owuro, lasiko ti ibugbamu naa ṣẹlẹ, leyi to mu ẹmi rẹ lọ.
"Nosa Okunbo, to n gbẹnusọ fun LASEMA sọ fun awọn oniroyin pe igbugbamu miran to waye lẹyin ti ina naa bẹrẹ, lo ba awọn ile to wa layika jẹ, bi ile ijọsin kan ati ibugbe awọn ọmọ ile iwe St Margaret, to wa lagbegbe ọhun.."""
Ẹgbẹ oṣelu Peoples Democratic Party, PDP, ti kesi ijọba apapọ Naijiria, lati fi ami ẹyẹ da Olori ileewe girama Bethlehem, Ẹni ọwọ Henrietta Alokha lọla, to padanu ẹmi rẹ ninu ibugbamu to waye nilu Eko lọjọ Aiku.
Iroyin gbe e pe, arabinrin Alokha ku lẹyin to doola ẹmi awọn akẹẹkọ ileewe naa lasiko ti ibugbamu  waye ladugbo Festac nilu Eko.
Ẹgbẹ PDP, ninu ikede kan ti wọn fi sita loju opo Twitter rẹ sọ pe, oun mọ riri iṣẹ akọni ti arabinrin naa ṣe, ti oun si rọ ijọba apapọ lati fi ami ẹyẹ da a lọla lẹyin iku rẹ.
Gomina ipinlẹ Eko, Babajide Sanwo-Olu ati igbakeji rẹ Obafemi Hamzat ti ṣabẹwo si ibi ti ọpa epo gaasi ti bu gbamu lagbegbe Abule Ado naa.
Gomina Sanwo-Olu ranṣẹ ibanikẹdun si awọn ti ẹbi ati ara ba iṣẹlẹ naa atawọn ti ile wọn ati ọpọ dukia wọn ṣofo ninu iṣẹlẹ naa.
Gomina ipinlẹ Eko ni iwadii n lọ lọwọ lati mọ ohun to ṣe okunfa iṣẹlẹ ibugbamu ọhun gan an.
Sanwo-Olu ni iṣẹlẹ naa ṣeni laanu pupọ, o ni niṣe lo dabi ẹni pe ogun ṣẹṣẹ ja tan nibi ti iṣẹlẹ ti ṣẹlẹ.
Gomina ipinlẹ wa ṣeleri owo iranwọ biliọnu meji naira fawọn ti wọn fara kaasa ninu iṣẹlẹ naa.
O ni ijọba ti ṣetan lati kọkọ fi aadọta miliọnu le lugba silẹ, nigba to rọ awọn ẹlẹyinju aanu ọmọ Naijiria fikun owo naa ko le pe.
Ọga agba ajọ to n ri si ọrọ pajawiri (LASEMA), Olufemi Oke-Osanyintolu, ṣalaye pe eeyan mẹtadinlogun lo padanu ẹmi wọn ninu iṣẹlẹ naa.
Oke-Osanyintolu ni awọn to farapa ninu iṣẹlẹ ọhun si n gba itọju lọwọ nile iwosan.
Coffee Painter: Adebukola ní kò sí ìrànwọ́ lẹ́yìn ẹ̀kọ́ girama lòun ṣe ń ya àwòrán
Coffee Painter: Adebukola ní kò sí ìrànwọ́ lẹ́yìn ẹ̀kọ́ girama lòun ṣe ń ya àwòrán
Yoruba ni ori lo mọ isẹ asela, ki sba oke ma jẹ ka daamu, ka to ja ọna.
Ọdọmọbinrin kan ree, Adedamọla Adebukọla, ti ko ni oluranlọwọ lẹyin eto ẹkọ girama, amọ ti ko setan lati gbe igba nabi abi tọrọ agbe, sugbọn to wa ohun ti yoo se jẹun dọjọ alẹ
Nigba to n ba BBC Yoruba sọrọ, Adebukọla ni osu marun pere ni oun fi kọ isẹ aworan yiya, eroja ohun mimu kọfi, Zobo ati tii elewe Lipton si ni oun fi maa n ya aworan.
O ni owo ti wọn fi n ra ọda lati fi ya aworan ti kọja agbara oun,  ni oun se yan lati maa lo awọn eroja naa, ti owo wọn ko gunpa rara.
Pottery: Àwọn onímọ̀ nípa amọ̀ wúlò púpọ̀ ju ike àbí irin lọ
Ayaworan kọfii naa ni isẹ kekere owo nla ni fifi kọfi ya aworan jẹ nitori owo nla lo n mu wa fun oun.
Sotitotbire: Ilé ẹjọ́ dá Alfa Babatunde padà sí áhàmọ́ọ́ bẹ́ẹ̀ni ó tún sún ìgbẹ́jọ́ si Ọjọ́-Bo̩
Ile ẹjo ti sun igbẹjo si ọjọ Ọjọbo. Agbẹjọro fun ijọba inpinlẹ Ondo, to jẹ olupẹjo, so wi pe, botilẹ̀ jẹ pe ko wu ijọba lati jẹ ki ẹjọ naa pẹ nilẹ, agbẹjọro fun Sotitobire bẹbẹ ki ileẹjọ sun igbẹjọ naa siwaju.
Ọmọ ijọ Sotitobire kan, to wa nile ẹjọ lọjọ Aje, lasiko ti igbẹjọ asaaju ijọ naa n lọ lọwọ lori ẹsun ijọmọgbe ti ba BBC Yoruba sọrọ.
Ninu ifọrọwerọ naa, eyi to da lori ipo ti ijọ ọhun wa lasiko yii ti olori ijọ, Alfa Babatunde wa lọgba ẹwọn, ọmọ ijọ naa, to pe orukọ ara rẹ ni Yetunde salaye pe nkan ko dabi bo se n waye tẹlẹ rara.
Yetunde ni lootọ ni isin n waye nile ijọsin Sotitobire amọ awọn ko lee lu ilu rara nitori gbogbo rẹ ni awọn oluwọde kan ti sun nina, lasiko ti wọn se iwọde wa sile ijọsin naa.
Isìn ń tesiwaju pelu pé kò sí Àlùfáà Babatunde ni itosi, amọ lóòótọ́, kò dabi ìgbà tí bàbá wá nílé, kò sì ìlú lílu nítorí pe gbogbo àwọn èròjà wonyii ni wọn ti jo nina.
Igbẹjọ Alfa Babtunde si n lọ lọwọ, a mu ẹkunrẹrẹ iroyin naa wa fun yin laipẹ.
Ileẹjọ giga ilu Akurẹ tun kun fọfọ lọjọ Aje nitẹsiwaju ẹjọ Asaaju ijọ Sotitobirẹ, Alfa Babatunde, tijọba ipinlẹ Ondo fi ẹsun ajọmọgbe kan.
Bẹẹ ba gbagbe, lati osu kẹjọ ọdun 2019 ni isẹlẹ kan ti waye ninu ijọ Sotitobire nilu Akure pe, ọmọ ọdun kan, Gold Kọlawọle sọnu ninu ijọ naa, ti wọn ko si ri di akoko yii.
Oríṣun àwòrán, Facebook
Eyi lo mu ki ijọba ipinlẹ Ondo fi gbe asaaju ijọ naa ls sile ẹjọ lẹyin ti gbogbo aayan lati ri ọmọdekunrin naa ja si pabo.
Nibi igbẹjọ losu to kọja, ni adajọ ile ẹjọ giga, to gba ẹjọ naa lọwọ ileẹjọ majisireti ti sun igbẹjọ siwaju di ọjọ Aje, ọjọ Kẹrindinlogun, ikẹtadinlogun ati ikejidinlogun osu kẹta ọdun yii.
Ni deede aago mẹsan aarọ si ni awọn osisẹ ọgba ẹwọn ti gbe Alfa Babatunde de sileẹjọ ati awọn afurasi ọmọ ijọ rẹ miran ti wọn fi ẹsun ajọmọgbe kan pẹlu rẹ.
Asọ alawọ eweko, tii se asọ ọgba ẹwọn si ni Babatunde wọ wa sile ẹjọ, ti wsn si fi ọkọ ọgba ẹwọn bọọsi kan gbe wa sibẹ.
Coffee Painter: Adebukola ní kò sí ìrànwọ́ lẹ́yìn ẹ̀kọ́ girama lòun ṣe ń ya àwòrán
Bi igbẹjọ naa ba se lọ, ni BBC Yoruba yoo maa mu wa fun yin.
Ekiti Oba Crisis: Ọọ̀ni ṣalàyé ìdí tí ààwọ̀ àwọn ọba Ekiti fi yàtọ̀ sí ti ẹ̀ẹ̀yà míràn
Oríṣun àwòrán, Ekiti state government
Ni ipo rẹ gẹgẹ bi Arole Oodua nibi ti igi gbogbo ọmọ kootu oo jiire bi ti ṣan jade wa, Ọọni ile ifẹ ti pana aawọ laarin awsn lọbalọba ni ipinlẹ Ekiti.
Ni ọjọ Aje ni Ọọni Adeyẹye Ogunwusi gunlẹ silu Ado Ekiti lati lọ igi alaafia laarin awọn ipele lọbalọba mọkanla ti a mọ si pelupelu ti wọn fariga pe awọn ko fara mọ igbesẹ gomina ipinlẹ naa, iyẹn Kayọde Fayẹmi lati yan Alawẹ ti ilu Ilawẹ Ekiti gẹgẹ bii olori igbimọ lọbalọba ni ipinlẹ naa.
Bakan naa ni Ọọni ile ifẹ tun ṣepade pẹlu gomina ipinlẹ Ekiti, Kayọde Fayẹmi lọna ati wojuutu sii iṣẹlẹ ọhun.
Gẹgẹ bi awọn itakun iroyin abẹle ṣe sọ, nigba ti ipade naa yoo fi pari, ẹrin ayọ lo gba ẹnu awọn ọbalade naa kan.
Oríṣun àwòrán, Ekiti state government
Ninu ọrọ to ba awọn oniroyin sọ lẹyin ipade naa, Ọọni Ogunwusi ṣalaye pe gbun-gbun-gbun gbogbo ti pari.
Ọrọ laarin agboole oduduwa ni, a si ti yanju rẹ
Bakan naa ni Ewi ti ilu Ado Ekiti, Ọba Rufus Adeyẹmọ Adejugbe pẹlu Ajero ti Ijero Ekiti, Ọba Adewọle Adebayọ ti wọn sọrs loruks awọn ọba pelu-pelu mọkanla yooku ni awọn ti panupọ lati fagile gbogbo ẹjọ to wa niwaju ile ẹjọ lori ọrọ naa.
Oríṣun àwòrán, Ekiti state government
O ti to ọjọ mẹta kan bayi ti ọrọ aawọ awọn lọbalọba nipinlẹ Ekiti ti oruyeye ati iṣu ata yan-an yan-an.
Bi alara ti n da sii naa ni Ajero n da sii titi to fi kan Ọwarangun aga.
Ni bayii, awọn Mogaji ilẹ Ibadan naa ti kilọ fun Gomina Kayode Fayemi tipinlẹ Ekiti wi pe ko so ewe agbejẹ mọwọ lori igbesẹ rẹ lati rọ awọn ọba kan loye nipinlẹ ọhun.
Awọn Mogaji ilẹ Ibadan ti wa sọ fun Gomina Fayemi pe ko maa ko aṣa atọhunrinwa de ilẹ Yoruba.
Ninu atẹjade ti Oloye Wale Oladoja fi sita, awọn Mogaji sọ fun Fayemi pe ọdun mẹji nikan lo lanfaani lati lo gẹgẹ bi gomina ipinlẹ Ekiti, ṣugbọn laelae ni ipo awọn lọbalọba.
Oríṣun àwòrán, Ekiti state government
Wọn ni ṣiṣe ayọjuran si ọrọ awọn lọbalọba ko le bimọ ire fun idagbasoke orililẹede Naijiria lapaapọ.
Awọn Mogaji Ibadan ni agba kii wa lọja, ki ọmọ tuntun wọ lọri jẹ fun awọn agbaagba ilẹ Yoruba.
Alaafin tilu Ọyọ, Ọba Lamidi Ọlayiwọla Adeyẹmi ti kọkọ kọ lẹta si gomina ipinlẹ Ekiti lori ọrọ naa pe ko maṣe foju ohun to ṣẹlẹ si Emir Kano wo ọrọ aawọ lọbalọba nipinlẹ Ekiti.
Amọ, Alawe ti ilu Ilawẹ Ekiti, Ọba Adebanji Ajibade Alabi, Afuntade Kinni, to ba BBC Yoruba sọrọ salaye pe ko si ohun to kan Alaafin ninu ọrọ naa, eyi to oun naa kọ lẹta si Gomina ipinlẹ Ọyọ, Seyi Makinde wi pe ko kilọ fun Alaafin lori ọrọ naa.
Laipẹ yii ni wọn fẹsun kan Gomina Fayemi pe o fẹ rọ Ewi of Ado-Ekiti, Oba Rufus Adejugbe loye atawọn ọba alaye mẹwaa mii ti ọpọ mọ si awọn Ọba Pelupelu.
Coronavirus: Ìjọba ní kò sí ìrìn-àjò sílẹ̀ òkèrè mọ́ fáwọn òṣìṣẹ́ ìjọba lásìkò yìí
Oríṣun àwòrán, Twitter/Muhammadu Buhari
Lati akoko yii lọ, oṣiṣẹ ijọba kankan ko gbọdọ riinrin ajo lọ si ile okere mọ, ijọba apapọ lo kede ọrọ nitori ajakalẹ arun coronavirus to tan kalẹ kaakiri agbaye.
Eyi ni igbesẹ igbimọ ti ijọba fi lọlẹ lori itankalẹ arun Covid-19 lẹyin ipade idankọkọ ti wọn ṣe niluu Abuja lọjọ Iṣẹgun.
Akọwe ijọba apapa to tun jẹ akọwe igbimọ naa, Boss Mustapha ṣalaye fawọn akọroyin pe ijọba ti wọgile gbogbo irin-ajo to ti buwọlu tẹlẹ fawọn oṣiṣẹ ijọba.
Ọgbẹni Mustapha ṣalaye pe ijọba ko fẹ ki arun naa tan kalẹ ju eeyan mẹta to ti lugbadi rẹ lọ lorilẹede Naijiria.
Igbimọ naa rọ awọn ọmọ Naijiria pẹlu lati maa rinrin ajo lọ si lọ si oke okun lasiko yii yala fun iṣowo tabi isinmin papaajulọ si awọn orilẹede ti arun coronavirus ti n ṣọṣẹ lọwọlọwọ.
Igbimọ naa ni awọn orilẹede bi China, Iran, South Korea, Germany, Italy, United States, United Kingdom, Switzerland, Norway, Netherlands, Spain, France ati Japan ko ṣee rinrin ajo lọ lasiko yii nitori coronavirus.
Bakan naa ni igbimọ ọhun awọn ọmọ Naijiria to n bọ lati ilẹ okere wi pe ki wọn ya ara wọn sọtọ fun ọjọ mẹrinla nile wọn kete ti wọn ba ti wọ Naijiria pada.
Lọjọ Iṣẹgun ni Ilé ìgbìmọ̀ aṣòfin àgbà l'Abuja ké si ìjọba àpapọ pe ko fi sínú ero rẹ láti fi ofin de àwọn arinrin ajò ti kìí ṣe ọmọ Naijíríà láti àwọn orilẹ̀-èdè ti àrun (COVID-19) náà n bá fíra láti ma wọ Naijiria mọ́.
Coronavirus: Àjọ NYSC ké ètò ìfinimọ̀ fáwọn àgùnbánirọ̀ kúrú nítorí Coronavirus
Wọn ni ki oju maa ribi, ẹsẹ loogun rẹ.
Eyi lo difa fun ajọ agunbanirọ lorilẹede Naijiria, NYSC ti wọn sọ agadangodo si iloro gbogbo ibudo ifinimọle fawọn agunbanirọ kaakiri orilẹede Naijiria; iyẹn lẹyin ti wọn ti ni ki awọn agunbanirọ naa o maa lọ sibi ti wọn yoo ti ṣe isinruulu lẹyẹ o ṣọka.
Ajọ naa kede pe, ohun to fa igbesẹ yii ni arun Coronavirus to ti wa di tọrọ fọnkale yii eleyii to ti mu ki ijọba apapọ paapaa o wọgile idije ere idaraya apapọ orilẹede Naijiria, National Sports festival to yẹ ko waye nipinlẹ Edo lọdun yii.
Oríṣun àwòrán, Nysc Edo State/facebook
Atẹjade to fi igbesẹ naa han sita  jẹyọ loju opo facebook lowurọ Ọjọru.
Atẹjade naa fi kun un pekawọn agunbanirọ o lọ bẹrẹ isinruulu wọn lawọn ibudo ti wọn pin wọn si ati pe nigba ti nnkan ba ṣẹnuure, wọn yoo pe wọn pada.
Coronavirus: Ilé ijó Fẹla Anikulapo, New Africa Shrine gbé ìlẹ̀kùn rẹ̀ tì pa nítorí àrùn Coronavirus
Oríṣun àwòrán, NEW AFRIKA SHRINE
Ni bayii ti olukuluku ileeṣẹ, awujọ ati orilẹede n gbe igbesẹ gbogbo lati dena itankalẹ arun coronavirus, ile ijo ogbontagi olorin ni Fẹla Anikulapo kuti ti gbogbo aye mọ si New Africa Shrine ti gbe ile ijo naa tipa.
Awọn alaṣẹ ile ijo naa ṣalaye pe awọn gbe igbesẹ ọhun lati  dena itankalẹ arun ọhun ni nitori pe agbo ti ọpọlọpọ eeyan lati origun mẹrẹẹrin agbaye ti n pade ni.
Ile ijo naa ni oun yoo tubọ maa bẹju wo bi nnkan ba ṣe n lọ si lori arun naa ki wọn to tun lee sọ igba ti faaji yoo pada bẹrẹ nibẹ.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Minisita feto ilera lorilẹede Naijiria, Dokita Osagie Ehanire ti fi soju gbangba pe ọmọ ikoko kan wa lara awọn eeyan marun un ti wọn ṣẹṣẹ ri wi pe o ni arun Coronavirus lorilẹede Naijiria.
Minisita feto ilera ṣalaye pe, mẹrin ninu awọn eeyan marun un naa ni wọn jẹ ọmọ Naijiria ti ọmọ ikoko naa si jẹ ọkan lara wọn.
O fi kun un pe ọmọ orilẹede Amẹrika ni eeyan kan to ku ninu wọn ati pe kii ṣe ọkọ ofurufu loun ba wọ orilẹede Naijiria ni tirẹ.
O ṣalaye siwaju sii pe gbogbo awọn eeyan to ba ṣẹṣẹ n wọ orilẹede Naijiria lati oke okun gbọdọ fi ara wọn si igbele ọlọjọ mẹrinla, koda bi ohunkohun ko ba ṣe wọn lasiko ti wọn wọ orilẹede Naijiria.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ijọba apapọ ti kede eeyan marun miran pẹlu arun Coronavirus lorilẹede Naijiria.
Eleyi ti sọ iye awọn eeyan to ko aarun naa di mẹjọ.
Minisita feto ilera to kede eyii. O ni awọn maraarun naa ni wọn ti rinrinajo lọ sorilẹede Amẹrika ati ilẹ Gẹẹsi laipẹ yii.
Gẹgẹ bii ara eto lati tete wawọ ọwọja arun Coronavirus wọlẹ, ijọba orilẹede Naijiria ti gbẹsẹle irinajo lati awọn orilẹede Mẹtala kan wọ orilẹede Naijiria.
Ohun ti eyi tumọ si ni pe ko si awọn arinrinajo lati awọn orilẹede mẹtala naa to gbọdọ wọ orilẹede Naijiria.
Elebuibon: Àwọn àṣà àtọ̀húnrìnwá ló fa títa ẹ̀jẹ̀ nítorí ògùn owo
Awọn orilẹede ti ọrọ kan naa ni orilẹede China, Italy, Iran, South Korea, Spain, Japan, Faranse, Germany, Amẹrika, Norway, ilẹ Gẹẹsi, Netherlands ati orilẹede Switzerland.
Ijọba apapọ ni awọn gbe igbesẹ yii lori awọn orilẹede to jẹ wi pe iye awọn eeyan to ti fara ko arun Coronavirus ti ju ẹgbẹrun kan lọ.
Alaga igbimọ amuṣẹya ti ijọba apapọ gbe kalẹ lori pipalẹmọ arun Coronavirus kuro lorilẹede Naijiria (Presidential Task Force on COVlD-19)  ṣalaye fawọn oniroyin ninu Abuja pe ayẹwo to munadoko yoo maa waye fun gbogbo awọn eeyan to ba wọ orilẹede Naijiria lẹyin abẹwo sawọn orilẹede wọnyii; ti wọn yoo si fi wọn sinu ahamọ iyasọtọ ati ayẹwo fun ọjọ mẹrinla.
Bakan naa ni ijọba apapọ tun ṣalaye pe aṣẹ yii  lo bẹrẹ si ni fi ẹsẹ mulẹ bẹrẹ lati ọjọ Satide, ọjọ kọkanlelogun oṣu kẹta ọdun 2020.
Bakan naa ni wọn tun fi idi rẹ mulẹ pe,  lasiko ti aṣẹ yii yoo fi fidi mulẹ, ko ni si aye a n fun ẹnikẹni ni iwe aṣẹ iwọlu-gbelu ti a mọ si visa.
Coronavirus: Ìjọ kò ní tilẹ̀kùn ilé ìjọsìn nítorí Coronavirus - Ondo PFN
Oríṣun àwòrán, RCCG
Alaga ẹgbẹ ọmọlẹyin Kristi ti ijọ igbalode PFN ni ipinlẹ Ondo, Joshua Kolawole Opayinka ti sọ pe, ijọ ko ni gbe kọkọrọ sẹnu ile ijọsin nitori arun Coronavirus.
Biṣọbu ọhun sọ fun BBC Yoruba pe adura nikan ṣoṣo lo le dẹkun arun Coronavirus, kiiṣe titi ile ijọsin pa.
"O ni ""A ko le sọ pe ka ti ile ijọsin nitori Coronavirus, nitori ori bibẹ kọ ni ogun ori fifọ."""
Opayinka sọ pe Ọlọrun mọ si gbogbo ohun to n ṣelẹ patapata, ati pe Ọlọrun nikan lo le yanju gbogbgo iṣorọ ati aisan to ba n ba aye finra lọwọ yii.
Aṣoju PFN naa sọ pe ohun to yẹ ki awọn ọmọlẹyin Kristi ṣe ni pe ki wọn gbohun adura soke ju ti atẹyinwa lọ.
Alufa naa tẹsiwaju pe Ọlọrun lo le aisan Ebola lọ, nitori naa Ọlọrun nikan naa lo le ṣegu arun Coronavirus.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Nipa pe ọna ti ajakalẹ arun fi n tan kalẹ ni kikorajọ ọpọ eeyan, o ni ẹmi eṣu ko le raye laarin awọn ọmọ Ọlọrun.
"Opayinka sọ pe ""Ẹmi eṣu to n kaakiri ninu afẹfẹ ni Coronavirus, ti ẹni to ba ni arun ọhun ba ti n wọle sinu ile ijọsin, ẹmi naa ko ni ba wọle."
Ti eeyan ba wọle sinu ile ijọsin pẹlu ẹmi naa, ẹmi naa ko ba iru ẹni bẹ jade, bẹẹni ko ni ko arun naa ran elomiran.
Nigba to n sọrọ lori pe ti ijọba ba paṣẹ pe ki wọn ti awọn ile ijọsin, Opayinka sọ pe ijọ yoo tẹlẹ aṣẹ ti ijọba ba pa lori arun naa.
Opayinka rọ  ijọba ni ipari ọrọ rẹ pe, ko ma gbe agadagodo ṣenu ọna ile ijọsin latari arun Coronavirus nitori ijọ nikan ṣoṣo ni ọna abayọ si araun naa to n tan kaakiri agabaye.
Elebuibon: Àwọn àṣà àtọ̀húnrìnwá ló fa títa ẹ̀jẹ̀ nítorí ògùn owo
Coronavirus: Àwíjàre ọlọ́pàá ni pé dókítà múra bíi onínàbì láago mẹ́wàá alẹ́
Oríṣun àwòrán, Others
Oniruuru ẹmi ni arun Coronavirus ti gba, boya lati ipasẹ kiko arun naa ni abi ni ọna miran.
Sugbọn eyi to se ni laanu ni  awọn ẹmi to bọ sọwọ awọn agbofinro lasiko ti wọn n se isẹ wọn lati ri daju pe awọn eeyan tẹle ofin fidimọle.
Sugbọn eyi to se laanu ninu gbogbo rẹ ni ti obinrin alaboyun kan ati ọmọ inu re to dero ọrun lasiko to n rọbi lọwọ lọjọ to kẹyin osu kẹjọ ọdun 2020.
Idi ni pe dokita obinrin kan to yẹ ko sare lọ sile iwosan lati sisẹ abẹ fun alaboyun naa lasiko isede nitori Coronavirus, lo bọ sọwọ awọn ọlọpaa to da duro ladugbo Ikeja nilu Eko.
Temitope Akinnusi: Ọ̀pọ̀ iléeṣẹ́ ló takú láti gbà mí síṣẹ́ torí mo ní ojú kan
Gbogbo ẹbẹ dokita naa sawọn ọlọpaa ọhun pe oun fẹ sare lọ dahun ipe pajawiri to le la ẹmi lọ nile iwosan lo ja si pabo.
Bi o tilẹ jẹ pe wọn papa fi dokita naa silẹ lẹyin wakati kan amọ ẹpa ko boro mọ nitori oku alaboyun ati ọmọ inu rẹ lo ba nile iwosan naa.
Gẹgẹ bi iwe akọroyin fun iwe iroyin Punch ti salaye isẹlẹ isẹlẹ naa, se ni dokita obinrin naa bu sẹkun nigba to de ile iwosan, to si gbọ nipa ohun to sẹlẹ si tiya tọmọ.
Oríṣun àwòrán, Others
Ẹnikan ti isẹlẹ naa soju rẹ sọ fun akọroyin naa pe isẹlẹ naa waye ni deede aago mẹwa kọja isẹju mẹẹdogun lalẹ.
O ni awijare awọn agbofinro naa ni pe dokita obinrin yii ko mura bii alakọwe, o si seese ko jẹ pe oninabi ni.
Oríṣun àwòrán, @PastorEAAdeboye
Baba Adeboye, gẹgẹ bi ọpọlọpọ ṣe maa n pe iranṣẹ Ọlọrun naa ṣalaye ninu fidio to gbe jade pe ko si buburu kan ti yoo kan awọn to ba gbagbọ ninu Ọlọrun.
"O ni 'Mo fẹ fi asiko yii fi daa yin loju pe, ko si arun Coronavirus kankan ti yoo de ọdọ yin; nitori pe ẹ n gbe ninu ibi ikọkọ Ọga ogo."""
Eyi gan an lo n fa awuyewuye lori ayelujara lori bi awọn eeyan ṣe n sọrọ pe ohun ti iranṣẹ Ọlọrun yii sọ ninu fidio naa ko tọna.
Amọṣa ohun to wa ninu fidio yii nikan lawọn to n tako iranṣẹ Ọlọrun naa n wo, wọn ko wo ẹsẹ ọrọ rẹ to ti sọ wi pe, yatọ si pe Ọlọrun n ṣọ awọn tirẹ, gbogbo awọn eeyan lo gbọdọ tẹle ilana imọtoto to yanranti nitori imọtoto lo kangun si iwa mimọ.
Ohun ti Pasito Adeboye n gbiyanju lati sọ ni wi pe yatọ si iwa mimọ, gbigbe igbe aye imọtoto ṣe pataki lati bori arun Coronavirus.
Amọṣa ọpọ eeyan lo foju fo amọran rẹ lori ṣiṣe imọtoto ara ẹni ati ayika ẹni, fido ọhun nikan wọn gbajumọ.
Oríṣun àwòrán, @PastorEAAdeboye
"Ninu amọran to tẹlẹ fidio naa ni baba Adeboye ti sọ pe ""Ẹ maṣe gbagbe pe ara gbigbe labẹ ojiji Ọlọrun ni pe ki ẹ maa gbe igbe aye imọtoto."""
Baba tẹsiwaju pe yatọ si jijẹ ọmọ Ọlọrun, o yẹ ki awọn eeyan maa ṣe awọn nnkan bi fifọ ọwọ ẹni pẹlu ọṣẹ ati omi, ati jijẹ ki ayika ẹni wa ni mimọ.
Pasitọ EA Adeboye jẹ ọkan pataki lara awọn iranṣẹ Ọlọrun to lokimi nilẹ Naijiria ti okiki rẹ si kan de oke okun.
Elebuibon: Àwọn àṣà àtọ̀húnrìnwá ló fa títa ẹ̀jẹ̀ nítorí ògùn owo
Coronavirus: Ẹ tilẹ̀kùn ṣọ́ọ̀ṣì àti mọ́ṣáláṣí yín tí èrò bá ju 50 lọ láti dẹ́kun Coronavirus - ìjọba Eko
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ijọba ipinlẹ Eko ti gba awọn olori ẹlẹsin lamọran lati gbẹsẹ le apejọpọ ita gbangba ti awọn eeyan rẹ ba le ni aadọta lawọn ile ijọsin wọn.
Kọmiṣọna fun ọrọ abẹle,  Anofiu Elegushi lo fi ọrọ naa lede lẹyin apero pẹlu awọn olori ẹlẹsin nipinlẹ naa.
Lara awọn to peju sibi ipade naa ni alaga ẹgbẹ ọmọlẹyin Kristi, CAN nipinlẹ Eko, Alexander bamgbola, Imamu agba ipinlẹ Eko Sheikh Suleiman Abou Nolla ati awọn olori ẹlẹ mii kaakiri ipinlẹ ọhun.
Kọmiṣona ọrọ to n lọ, Gbenga Omotoso sọ fun BBC pe bo tilẹ jẹ pe ijọba ipinlẹ Eko ko laṣẹ lati gbẹsẹle ipejọpọ awọn ẹlẹsin, amọran  naa ṣe pataki lasikjo yii.
Lati igba ti arun Coronavirus ti bẹ silẹ nilu Wuhan lorilẹede China lọdun 2019, ọpọ orilẹede lagbaye ni arun naa ti rapala wọ, ilẹ Naijiria ko gbẹyin pẹlu.
Awọn orilẹde bi Kenya ati Somalia ti tilẹkun ibode rẹ mọ awọn eeyan lati ilẹ okere ti arun ọhun ti ṣọṣẹ julọ, bẹẹ lawọn orilẹede kan ti tilẹkun ile iwe atawọn ile ijọsin.
Làá hàn mí: Ètò yìí ló ń kìlọ̀ fún wa láti mú ìmọ́tótó ní pàtàkì láti dènà Coronavirus
Coronavirus treatments: Ọ̀gá àgbà ọlọ́pàá pàṣẹ pé kò gbọdọ̀ sí ìdádúró fún àwọn tí iṣẹ́ wọn ṣe kókó lásíkò ìséde
Oríṣun àwòrán, UNITED STATES AFRICA COMMAND
Ẹgbẹ awọn dokita onimọ iṣegun oyinbo ni Naijiria ti fagile iyanṣẹlodi ti wọn bẹrẹ, nitori bi awọn ọlọpaa ṣe fiyajẹ awọn ọmọ ẹgbẹ wọn kan lasiko isede coronavirus.
Lara oun ti awọn dokita naa tọka si nipe ileeṣẹ ọlọpaa n da awọn ọmọ ẹgbẹ wọn duro, eyi ti ko yọ awọn ọkọ to n gbe alaisan silẹ.
Ninu atẹjade kan ti ẹgbẹ naa fi sita, wọn ni ki awọn dokita o pada si ẹnu'ṣẹ wọn laago mẹfa irọlẹ oni.
Iyanṣẹlodi naa ko pe wakati mejila ti wọn fi kede pe awọn ti fagile.
Ọjọru ni wọn bẹrẹ iyanṣẹlodi naa, ti wọn si s pe yoo wa titi di igba ti ijọba yoo fopin si ifiyajẹni ti awọn ọlọpaa n ṣe si awọn ọmọ ẹgbẹ wọn lasiko ofin Konile-o-gbele.
Ninu atẹjade ti ẹgbẹ ọhun fi sita ni wọn ti fikun pe awọn ọlọpaa tilẹ n ti wọn mọle ni aini idi.
Ṣugbọn ṣa, Ọga Agba Ọlọpaa lorilẹede Naijiria, Muhammed Adamu paapa ti fi aṣẹ tuntun sita nipa ofin konile o-gbele kaakiri orilẹede Naijiria.
Ko din ni aadọta awọn dokita , oniroyin atawọn oṣiṣẹ ẹka to ṣe koko miran lasiko ajakalẹ arun coronavirus yii ni awọn ọlọpaa ni ipinlẹ Eko ti fi panpaẹ ofin mu bayii lọjọ Iṣẹgun ni ibamu pẹlu aṣẹ kan ti ọga ọlọpaa lorilẹede Naijiria pa.
Ni ọjọ kẹtadinlọgbọn oṣu kẹrin ni aarẹ Muhammadu Buhari paṣẹ konile o gbele eleyii to de igbokegbodo ọkọ laarin agogo mẹjọ alẹ si agogo mẹfa owurọ gẹgẹ bi ara ọna lati dena itankalẹ ajakalẹ orun COVID-19.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Amọṣa aarẹ ko ṣai ṣe gafara fun awọn oṣiṣẹ ti iṣẹ wọn jẹ koṣemaani lasiko naa bii awọn oṣiṣẹ eto ilera, akọroyin ati bẹẹbẹl lọ.
Ni ọjọ Iṣẹgun ni ọga ọlọpaa lorilẹede Naijiria ṣe ipade ori ayelujara pẹlu awọn lọgalọga lẹnu iṣẹ ọlọpaa lorilẹ€de Naijiria nibi to ti paṣẹ fun wọn lati tubọ rii pe aṣẹ konile o gbele naa fẹsẹmulẹ sii ti wọn si ni o paṣẹ pe ki wọn maa fi panpẹ ofin mu ẹnikẹni ti irinkerindo rẹ ba ti kọja agogo mẹjọ alẹ.
Lagbegbe Alausa ni ilu Eko, gbogbo awọn dokita ati akọroyin to n bọ lati ibi iṣẹ ni awsn ọlọpaa ko da satimọle ti wọn si gbẹsẹle ọkọ wọn.
Iroyin taa gbọ ni pe awọn ọmọ igbimọ amuṣẹya ti aarẹ gbe kalẹ lori kikoju arun coronavirus, PTF lo wa kan si ọga ọlọpaa lorilẹede Naijiria ki o to paṣẹ ki wọn tu wọn silẹ lẹyin ti wọn ti lo bii wakati meji lagọ ọlọpaa.
Oríṣun àwòrán, Babajide Sanwo-Olu/Twitter
Ijọba ipinlẹ Eko ti n gbeero lati fi opin si isede coronavirus patapata, ṣugbọn diẹdiẹ ni yoo bẹrẹ.
Gomina Babajide Sanwo-Olu lo kede awọn ilana tuntun yii, pẹlu boṣe jẹ pe ipinlẹ Eko ni aarun coronavirus pọ si julọ ni Naijiria.
Ọsẹ keji ti ijọba dẹ isede lo n pari lọ bayii, ṣugbọn gomina sọ pe ọsẹ mẹfa ni yoo gba.
1. Register-to-Open - Eyi tumọ si pe ijọba yoo kọkọ ṣe ayẹwo ile ijọsin, ileeṣẹ, tabi ile itaja to ba fẹ ẹ bẹrẹ iṣẹ pada.
2. Lẹyin ayẹwo naa, ileeṣẹ, ile ijọsin, tabi ile itaja bẹ ẹ yoo gba iwe ẹri pe o pa ilana ati ofin ti ijọba gbe kalẹ lati fi opin si Covid-19.
3. Ijọba ko ti i sọ ọjọ ti awọn eeyan wọn yii yoo pada bẹrẹ iṣẹ wọn, lẹyin ayẹwo naa, ṣugbọn o sọ pe ki awọn to ni ileeṣẹ naa mura silẹ lati tẹle ilana tuntun naa, nitori pe coronavirus ti mu ayipada ba ayika wa.
4. Awọn ti ilana tuntun naa kan ni ṣọọṣi, mọṣalaaṣi, gbọngan ayẹyẹ, ile itaja igbalode nla, gbọngan sinima, ati awọn ibi igbafẹ.
5. Awọn nkan ti ijọba yoo yẹwo kii wọn o to o fun wọn ni iwe ẹri ni, ilana ijina sira ẹni ti wọn ti gbe kalẹ, ati fun imọtoto. Awọn nkan wọnyii ni yoo si sọ boya awọn ṣọọṣi ati mọṣalaaṣi naa yoo ṣi pada.
6. Ijọba yoo paṣẹ fun awọn banki, ati ọja lati maa da awọn onibara to jẹ agbalagba lohun laarin aago mẹsan aarọ si mẹwa aabọ, ki wọn o to da awọn ọdọ lohun.
7. Dandan ni wiwọ ibomu-bo ẹnu nipinlẹ naa. Awọn ọlọkọ eero si gbọdọ tẹle ilana ijina sira ẹni.
Ṣugbọn ṣa, Gomina Sanwo-Olu sọ pe o ṣeeṣe ki isede miran tun waye, ti awọn araalu ko ba tẹle awọn ilana naa.
Yàtọ̀ si aríwo tó ń tàn ká pé gómínà ìpínlẹ̀ Kwara tí paṣẹ pé ki wọ́n fún awakọ̀ tó wà nínú fọ́rán kan to fójú hàn lórí ayélujára níbi ti wọ́n ti n gbé ènìyàn kan sí inú ọkọ pàjáwìrì  aláàrùn Covid-19 níwèé ìdádúro,
Kọmísọ́nà fún ètò ìlera ní ìpínlẹ̀ Kwara Raji Razaq ni ọ̀rọ̀ kò rí bẹ́ẹ̀ rárá.
Raji Razaq ní wọ́n kan yọ awakọ̀ náà kúrò lára àwọn to n mójútó àwọn alárùn coronavirus ni,  nítorí pé ó kùna láti pa àwọn ilànà tóyẹ ki o tẹ̀lé mọ́.
Ó ní ọkùnrin ti wọ́n lọ gbé òun pẹ̀lú kìí ṣe àláàrùn Coronavirus, ó sì ti wà ní àkàtà ìjọba fún ìtọ́jú báyìí.
Kọmísọ́nà ní gbogbo àwọn ọgálọ́gàá ilé iṣẹ́ náà to fi mọ akọwé agba ilé iṣẹ́ iléra to pàṣẹ fun awakọ̀ náà láti lọ gbé ẹni náà ni wọ́n ti gba iwé ìbáwí.
Alhaji Razaq ni ìpàpara ni awakọ̀ náà fi bá iṣẹ́ rẹ̀ jẹ́ nítorí  pé ó yẹ kí ó dúró de àwọn ti yoo gbé aṣọ ìdáàbò tó yẹ kí o wọ̀ wá, súgbọ́n ko fi àrà balẹ̀
Kíni ìlànà tó tọ́ láti gbé aláàrùn Covid-19 nílé wọn
Nínú ọ̀rọ̀ rẹ̀, Kọmísọnà ní tí wọ́n ba ti pé ilé iṣẹ́ ètò ilera bẹ́ẹ̀, ọ̀dọ̀ ọ̀gá àgbà ni ìpè náà yóò dé sí ti yóò si pàsẹ fún àwọn to wà ni ìdí, ètò pàjáwìrì láti lọ́ṣe iṣẹ́ wọn.
Lórí ìtàkùn ayélujára àjọ to n gbógunti ààrùn Coronavirus ni Naijira NCDC náà, wọ́n sàlàyé àwọn ìlànà ti àwọn elétò ààbò àti ará ilú gbọdọ̀ mọ̀ ti wọ́n bá ri ẹni tó ni ààrùn Coronavirus.
* O ṣe pàtàkì láti mọ àwọn ibi ìtọjú to wà ni àyíka ní ìpińlẹ̀ tàbí ni agbègbè wọ́n
* Àwọn elétò ìlera ti gbọdọ̀ kọ́kọ́ lọ fún ìdánilẹ́kọ̀ọ́ bi a ṣe n tọ́jú àjàkálẹ̀ ààrùn ti wọ́n pè ni (Infection, Prevention, And Control IPC).
* Gbogbo òṣìṣẹ́ tí yóò ba kójú àláàrùn Covid-19 gbọdọ̀ wọ aṣọ ìdáàbò (PPE), ìbòmú, ìbọ̀wọ́, awòojú àti fìlà
* Ní kété ti òṣìṣẹ́ ìlera bá ti gbé aláàrùn coronavirus tan, o ṣe pàtàkì láti fi àwọn kẹmika apakòkòrò tọ́jú gbogbo ǹkan ti ẹni náà wọ̀ kí o to kúrò ní ilé ìwòsàn.
Sáájú ní àkọ̀wé gómìnà Kwara Rafiu Ajakaye ti fi àtẹjáde kan síta pé gómìnà ìpínlẹ̀ Kwara Abdulrazaq Abdulraman ti pàṣẹ pé kí wọ́n fún àwakọ̀ náà ni iwé ìdádúró.
Sùgbọ́n nígbà ti BBC padà pèé ló ní, wọ́n kan yọọ́ kúrò ni ẹ̀ka Covid -19 ní kìíṣe pé wọ́n yọọ́ lẹ́nu iṣẹ́
Atẹ́gùn òjò rán ọ̀pọ̀ lóko àdánù nílùú Ìbàdàn, aráàlú gbarata
Ibadan rainstorm: Awọn olugbe ilu Ibadan gbarata lori awọn ile ti atẹgun ojo ṣidanu
Awọn olugbe agbegbe Joyce B ni ilu Ibadan ti bẹrẹ sini ke irora lẹyin ti ojo to fi iṣeju marundinlaadọta rọ lopin ọṣẹ ṣe akoba fun awọn ile kan.
Ninu itakurọsọ pẹlu ikọ BBC Yoruba, ọkan lara awọn ti o fi ara gba iṣẹlẹ naa, arakunrin Kayọde Popoọla ṣe alaya wi pe iru iṣẹlẹ bẹẹ ko ṣẹlẹ ri lati nnkan bii ogun ọdun sẹyin ti oun ati ayarẹ ti ya ile ti wọn fi da ile ẹkọ silẹ fun awọn akẹkọ to n bẹ ni agbegbe naa.
O ni oun n wẹ lọwọ ni nigba ti ipe pajawiri kan wọle wi pe atẹgun ojo ti ṣi paanu ile lọ ti o si rọ lu ile alaja kan to n bẹ ni iwaju ibi ti wọn fi n ṣe ile ẹkọ.
"O ni, ""Inu ile mi ti mo n gbe ni mo wa, mo n wẹ lọwọ ni gbogbo inu ile bẹrẹ sini mi gbugbugbu. Bi mo ṣe jade nile iwẹ mo rii pe yara mi ti n jo."
Yara mi o jo ri, yara awọn ọmọ mi naa bakan naa.
Iyẹn ni a n mojuto lọwọ mo n pe Ọlọrun pe aanu, aanu o.
Lojiji ni ẹrọ ibanisọrọ mi dun, ọkan ni ninu awọn olukọ wa lo pe mo ba gbe ipe rẹ.
"Jọkẹ ki lo ṣe ẹ? Daddy atẹgun ti gbe gbogbo paanu o..."""
Popoọla ni iye owo ti yoo ṣe atunṣe ile ẹkọ naa ko di ni milliọnu meji naira, bẹẹ sini awọn to ya ile igbe lo jẹ gbese nitori baba to ni ile ti darugbo.
O ra ọwọ ẹbẹ si ijọba ati awọn ẹlẹyin ju aanu lati ṣe iranlọwọ fun wọn lasiko yii.
Gbogbo paanu ti atẹgun ojo ṣi danu ni awọn to n gbe awọn ile naa ti n gbiyanju lati kojọpọ si ẹgbẹ kan lasiko ti ikọ iroyin BBC Yoruba ṣe abẹwo si agbegbe kan.Lọkọọkan-ejeeji sini wọn duro gẹgẹ bi wọn ṣe n wo awọn ile naa pẹlu iyalẹnu.
Eeyan ẹrin ọtọọtọ lo padanu ẹmi wọn ti ọgọrọ awọn eeyan mii si fi ara pa ninu ijamba ọkọ to waye nilu Ogbomoṣọ lọsan ọjọ ẹti.Ni agbegbe Apake lopopona marosẹ Ogbomọṣọ si Ilọrin atijọ ni ọkọ akẹru kan ti sa wọ ibi ti awọn ero ọkọ ati ọlọkada korajọpọ si.
O ṣoju mi koro ṣe alaye fun awọn oniroyin pe eeyan mẹrin lo ku loju ẹsẹ gẹgẹ bi wọn ṣe ko awọn ti o fi ara pa lọ si ile iwosan ẹkọṣẹ iṣegun Oyinbo, LAUTECHTH to n bẹ niluu Ogbomọṣọ.Iroyin sọ wi pe ẹkun ariwa ni ọkọ naa n ri irinajo lọ ki o to di wi pe o padanu ijanu ọkọ lasiko to n sa fun awọn ẹṣọ aabo oju popo niluu Ogbọmọṣọ, ṣugbọn adari ẹṣọ aabo oju popo to n bẹ ni agbegbe naa, Bọlade Olugbẹsan sọ wi pe irọ to jina si ọọtọ ni ẹsun naa.
Ìyàtọ̀ láàrín ìgbélé ní Nàìjíríà àti ilẹ̀ òkèèrè
O ni ko si oṣiṣẹ ẹṣọ aabo pupo ni ibi ti ijamba naa ti ṣẹlẹ.O ṣoju mi koro mii ti o ba awọn oniroyin sọrọ ṣe alaye wi pe ọlọkada ni awọn eeyan mẹrẹẹrin to padanu ẹmi wọn sinu ijamba naa.Lasiko ti a ṣe akojọpọ iroyin yii, awọn osiṣẹ aabo duro wamuwamu si ofisi ẹṣọ aabo oju to n bẹ ni agbegbe 'High School' niluu Ogbomọṣọ lati dena akolu awọn ara ilu to n fapajanu nitori ijamba naa.
Gomina Seyi Makinde ni oun ko ni yọnda wọn fun ijọba ipinlẹ Sokoto, ayafi ti wọn ba kọkọ ṣayẹwo Coronavirus
Mẹrin ninu awọn eeyan mọkanla to n ti ipinlẹ Sokoto bọ ṣugbọn ti awọn agbofinro mu lẹnu ibode ipinlẹ Oyo si Osun lo ni arun Coronavirus.
Ẹni to n risi iṣẹlẹ naa, Taiwo Ladipo lo fi ọrọ ọhun lede fun awọn oniroyin lọjọ Iṣẹgun.
O ni awọn mẹrin naa ti wa ni ile iwosan ti wọn ya sọtọ fun awọn to ni arun Covid-19, eyi to wa ni Olodo.
Lẹyin itakurọsọ pẹlu awọn arinrin ajo naa, Gomina ipinlẹ Oyo, Seyi Makinde sọ pe oun ko ni yọnda wọn fun ijọba ipinlẹ Sokoto, ayafi ti wọn ba kọkọ ṣayẹwo arun Coronavirus fun wọn.
Iye awọn to ti lugbadi arun naa nipinlẹ Oyo lọwọ yii jẹ mọkandinlogoji, ti mejidinlọgbọn ninu wọn si n gba itọju lọwọ.
Bo tilẹ jẹ pe awọn mẹsan an ti ri iwosan, awọn kan ti jẹ Ọlọrun nipe nipe nitori arun naa.
Wo bí o ṣe leè ṣe ìjìnàsíraẹni ní ibiṣẹ́ lásìkò Coronavirus yìí
Oríṣun àwòrán, @seyiamakinde
Ijọba ipinlẹ Oyo ti sọ pe ko si ẹni kankan to tii ni arun Coronavirus nipinlẹ naa, ati pe oun ti bẹrẹ  igbesẹ lati ṣawari awọn eeyan to ṣalabapade ẹni ti wọn fura si pe o ṣeṣe ko ti ko arun naa wọ ipinlẹ ọhun.
Kọmiṣọna eto ilera, Bashir Bello ni ijọbaa ti ṣayẹwo ẹni kan to ṣẹṣẹ de lati ilẹ Gẹẹsi, ti wọn si ti fi ayẹwo naa ranṣẹ si yara ayẹwọ to wa ni fasiti ẹkọṣẹ iṣegun to wa ni ilu Eko, LUTH.
O ni lọwọ yii, oun ko tii le fidi rẹ mulẹ pe ẹnikẹni ti lugbadi arun naa nipinlẹ Oyo titi di igba ti esi ayẹwo naa yoo jade.
Bello sọ pe ijọba ipinlẹ naa mọ pe ẹni to ko arun Coronavirus wọ ipinlẹ Ekiti lo akoko diẹ nilu Ibadan.
O ni ileeṣẹ eto ilera ipinlẹ Oyo ti n gbaradi lati koju arun ọhun lati igba to ti ṣẹyọ lorilẹ-ede Naijiria.
"Bello tẹsiwaju pe ""Bo tilẹ jẹ pe arun yii ti n peleke si ni Naijiria, ileeṣẹ eto ilera ipinlẹ wa n ṣiṣẹ takuntakun lati ri pe arun naa ko si ni ipinlẹ Oyo."""
Làá hàn mí: Ètò yìí ló ń kìlọ̀ fún wa láti mú ìmọ́tótó ní pàtàkì láti dènà Coronavirus
Bello wa rọ awọn eeyan ipinlẹ Oyo lati ma foya nitori arun naa, ṣugbọn ki wọn ma ṣe awọn ohun to le mu arun jina si ayika wọn, bii wiwa ni nkan bii iwọn ẹsẹ bata mẹfa si awọn elomiran ati ṣisṣọra fun ibi ti ọpọ eeyan ba korajọpọ si.
Oríṣun àwòrán, Facebook/PDP
Àwọn ọmọ Nàìjíríà ń kán Seyi Makinde níkòó fún ìgbàlejò ìpàdé ìtagbangba PDP níbàdàn lásìkò àjàkálẹ̀ àrùn coronavirus
Ọpọ lo ti n bu ẹnu atẹ lu bi Gomina Seyi Makinde ipinlẹ Oyo ti ṣe ipade itagbangbe oṣelu ẹgbẹ oṣelu PDP niluu Ibadan l'Ọjọru, bo tilẹ jẹ wi pe ibẹrubojo awọn arun coronavirus wa nita.
Nigba to n sọrọ nibi ipade ọhun to waye ni gbọngan Mapo, Makinde ni apẹrẹ wi pe ẹgbẹ oṣelu PDP ti bẹrẹ si ni gbori soke ni bi Gomina ipinlẹ Osun tẹlẹ, Olagunsoye Oyinlola ati awọn alatilẹyin rẹ ṣe pada sinu ẹgbẹ naa.
Igbakeji gomina ipinlẹ Oyo tẹlẹ, Taofeek Arapaja, sẹnẹtọ to n ṣoju ẹkun ariwa Oyo tẹlẹ, Dokita Gbenga Babalola atawọn eekan inu ẹgbẹ oṣelu ADC to fi mọ oludije fun ipo gomina nipinlẹ Osun, Alhaji Fatai Akinbade lo darapọ mọ PDP nibi ipade ọhun.
Bakan naa lawọn eekan inu ẹgbẹ oṣelu ADP ati ZLP darapọ mọ PDP nibi ipadae itagbangba naa ti wọn pe ni ipade iṣọkan ni Ibadan.
''Ipade yii jẹ ibẹrẹ iṣọkan apa iwọ oorun gusu orilẹede Naijiria, ti a ba si ti wa ni iṣọkan lapa iwọ oorun gusu, Naijiria naa ti wa ni iṣọkan niyẹn,'' Gomina Makinde lo sọ bẹẹ.
Makinde ni ''awọn eeyan kan ni ko yẹ ki PDP ṣe iru ipade itagbangba bayii lasiko ti coronavirus n tankalẹ yii, ṣugbọn ọkan lara awọn olori wọn lo sọ pe arun coronavirus ti wọ inu ẹgbẹ wọn, amọ awa mọ pe ko si ninu ẹgbẹ ti wa.''
Ninu ọrọ tiẹ nibi ipade naa, Oyinlola sọ pe asiko ti to lati ṣe atunto orilẹede Naijiria, o ni itanjẹ ẹgbẹ APC ti to gẹẹ.
O rọ awọn ọmọ ẹgbẹ PDP lati fi ọgbọn yanju ọrọ to ba wa laarin wọn ki iṣokan le wa ninu ẹgbẹ.
''Gbogbo ẹ̀yin tí ẹ lọ sí ibi ìpàdé PDP ní Ibadan, ẹ lọ yara yín sọ́tọ̀ fún àyẹ̀wò coronavirus''
Ọgọrọ eeyan lo dẹnu bo Gomina Seyi Makinde lori ayelujara lẹyin to ṣagbatẹru ipade itagbangba ẹgbẹ oṣelu PDP niluu Ibadan l'Ọjọru.
Ohun ti ọpọ n sọ nipe kii ṣe akoko yii ti ibẹru-bojo ajankalẹ arun coronavirus wa nita lo yẹ ki Makinde ṣe iru ipade bẹẹ.
Ibrahim Lawal Esq ṣapejuwe ipade itagbangba PDP bi igbesẹ omugọ ti ko mu ọgbọn wa rara.
Ibeere ni @AbdulMahmud01 n beere ni tirẹ, o ni ''kinni o n ṣe wa gan an? O sọ pe o ṣeni laanu pe ko si ẹnikan to ronu pe iru ipade itagbangba yii le ṣakoba fun eto ilera araalu pẹlu bi arun covid-19 sẹ wa nita bayii.
@Lucasscot_101 ṣalaye ni tiẹ wi pe ẹgbẹ oṣelu APC lo kọkọ bẹrẹ iwa aṣiwere tawọn eeyan si ro pe ko si were to le ju iyẹn lọ.
Amọ o ni o ṣeni laanu pe iwa aṣiwere ti ẹgbẹ oṣelu PDP gan wa ju ti APC lọ. O pari rẹ bayii pe ko si ẹni ti ori rẹ pe ninu awọn ẹgbẹ mejeeji.
Adeola @Harrdehy fi igbe bọnu ni tiẹ, o ni ẹnikẹni to ba kopa ninu ipade itagangba ẹgbẹ osẹlu PDP gbọdọ ya ara rẹ sọtọ fun ayẹwo arun coronavirus.
Ọgọrọ eeyan lo fẹnu ko pe igbesẹ ẹgbẹ osẹlu PDP lati ṣe ipade naa kudiẹ kaato.
Amọ ninu gbogbo eyi, ero Olamide Abimbola yatọ ni tiẹ. O ni aṣiwere ni gbogbo awọn to n ṣatilẹyin fun ẹgbẹ APC ti wọn n sọ oko ọrọ si PDP nitori ipade itagbangba ti wọn ṣe ni Ibadan.
Abimbola ni ẹgbẹ oṣelu PDP ṣe iru ipade itagbangba ti ko waye ri ninu iwe itan. O rọ awọn to n bu ẹgbẹ naa loju opo Twitter pe ki wọn ronu si ọrọ naa daadaa ki wọn to maa sọrọ loju opo Twitter.
Coronavirus: Ushbebe, adẹ́rínpòṣónú ní bí ìjọba ṣe fòfin de ìrìnàjò wọlé láti ilẹ̀ òkèrè mú òun pàdánù owó l
Oríṣun àwòrán, Instagram/ushbebecomedia
Igbesẹ ijọba apapọ orilẹede Naijiria to fofin de irinajọ lọ si awọn orilẹede mẹtala ti arun coronavirus ti n ṣọṣẹ ti ni ipalara fun ọpọ ọmọ Naijiria ti wọn ti rinrin ajo lọ si awọn orilẹede naa tabi ti wọn fẹ ṣẹṣẹ lọ si bẹ.
Awọn orilẹede ti ọrọ kan naa ni orilẹede China, Italy, Iran, South Korea, Spain, Japan, Faranse, Germany, Amẹrika, Norway, ilẹ Gẹẹsi, Netherlands ati orilẹede Switzerland.
Ijọba apapọ ni ohun gbe igbesẹ yii nitori awọn eeyan to ti lugbadi arun Coronavirus ti ju ẹgbẹrun kan lọ lawọn ilẹ naa.
Lara awọn ti wọn ti wa lọhun ki ijọba to kede l'Ọjọru ṣalaye pe ajalu airotẹlẹ ni ikede ijọba apapọ Naijiria jẹ fawọn nitori awọn ni lati maa tete bọ wa si Naijiria ṣaaju ọjọ Satide ti ofin naa yoo di mimuṣẹ.
Adẹrinpoṣonu ọmọ Naijiria to rinrin ajo lọ si ilẹ Gẹẹsi, Justice Nuagbe ti ọpọ mọ si Ushbebe ikede naa ti mu ki wọgile eto ti mo fẹ ṣe lọjọ Aiku to n bọ niluu London ati awọn eto miiran to mu oun rinrin ajo lọ si ilẹ Gẹẹsi.
Oríṣun àwòrán, Instagram/ushbebe comedian
Ko tan sibẹ o, Ushbebe ni igbesẹ ijọba lati fofin de irinajo sawọn orilẹede mẹtala naa na oun owo lowo airotẹlẹ nitori oun ni lati ra tikẹti mii ki oun le pada sile.
Ṣugbọn o ni ilera ara oun ṣe pataki ju owo ti oun padanu lọ nitori igbesẹ ijọba to fofin de irin ajo sawọn orilẹede ilẹ okeere ti arun coronavirus ti ba wọn finra.
Coronavirus: 'Mo sáré padà sí Nàìjíríà láti Uk lẹ́yìn t'íjọba fòfin de ìrìnàjò sílẹ̀ òkèrè'
Ninu ọrọ tiẹ, Arabinrin kan toun naa ṣẹṣẹ de lati ilẹ Gẹẹsi bayii to ba BBC Yoruba sọrọ ṣalaye pe erongba oun tẹlẹ ni lati gba ilẹ Geẹṣi lọ si orilẹede Amẹrika.
Amọ o sọ pe ko le ṣeeṣe mọ foun bayii lẹyin ti ijọba ti fofin de irinajo si awọn orilẹede mejeeji.
O fikun ọrọ rẹ wi pe ohun to f'oun bayii ni lati dari wale ki o di ọjọ Satide.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
O sọ fun BBC Yoruba pe ninu ibẹru lawọn n gbe nilẹ Geẹṣi bayii nitori yala o wa ninu ọkọ, tabi oun n wo ẹrọ amohunmaworan, ọrọ coronavirus lawọn eeyan n sọ.
Arabinrin naa ni ojoojumọ lọpọ eeyan n lugbadi arun coronavirus, debi wi pe coronavirus lẹ maa ri lori foonu tabi lori ẹrọ ayelujara ati ẹrọ agbọrọkaye.
Ṣugbọn ''inu mi dun wi pe mo ti lanfaani lati pada si orilẹede Naijiria, ṣugbọn ibẹrubojo ni mo fi kuro nilẹ Gẹẹsi silẹ.''
O sọ pe oun ṣetan lati ya ara oun sọtọ fun ọjọ mẹrinla bayii gẹgẹ bi alakalẹ ijọba fawọn to ba ṣeṣẹ rinrin ajo de lati awọn orilẹede mẹtala ti ijọba apapọ fofin de.
Coronavirus: Seyi Makinde ní ẹgbẹ̀rún mẹ́wàá ọṣẹ apakòkòrò 'hand sanitiser' lòun fi dènà coronavirus nípàdé ẹgbẹ PDP ní'bàdàn
Oríṣun àwòrán, Twitter/seyi makinde
Lati ọjọbọ ni ori ayelujara ti n ho ruru, ti ọpọ eniyan si n sọ oko ọrọ̀ si gomina ipinlẹ Ọyọ, Seyi Makinde, ati ẹgbẹ oṣelu PDP, lori ipade itangbangba ẹgbẹ naa to waye.
Ọpọ lo gbagbọ pe ko yẹ ki Gomian Makinde le pe iru ipade nla bẹ  lasiko ti arun coronavirus n rin kaakiri ilu.
Ṣugbọn nigba to ba BBC sọrọ, Akọwe ikede fun gomina Makinde, Taiwo Adisa sọ pe gbogbo igbesẹ to yẹ ni awọn gbe nibi ipade naa ni ibamu pẹlu imọran awọn eleto ilera.
Ṣé Makinde kò wá rugi oyin báyìí lórí ìpàdé ìtagbangba PDP tó ṣe níbàdàn Láì náání àjàkálẹ̀ àrùn coronavirus?
Ẹ wo ohun tí baba Adeboye sọ lórí ọ̀rọ̀ Coronavirus
Ìjọ kò ní tilẹ̀kùn ilé ìjọsìn nítorí àrùn Coronavirus - Ondo PFN
Ọkùnrin kan kú lẹ́yìn tí wọ́n lù ú 'fún pé ó ní coronavirus'
Elebuibon: Àwọn àṣà àtọ̀húnrìnwá ló fa títa ẹ̀jẹ̀ nítorí ògùn owo
O ṣalaye pe gbogbo awọn to wa sibi ipade itagbangba naa ni awọn fun ni ọṣẹ apakokoro (hand sanitiser) l'ẹnu ọna abawọle sibi ipade.
"A pa di dandan fun gbogbo olukopa lati fọ ọwọ wọn l'ẹnu ọna, ati lati fi ọṣẹ apakokoro pa ọwọ ki wọn o to o wọle, lai yọ ẹnikẹni silẹ.
Ti mo ba ni kin sọ iye ọṣẹ ti a ra, yoo to ẹgbẹrun mẹwa. Nitori pe iye ti a ra pọ ju iye eniyan to wa si ipade.
O tẹsiwaju lati sọ pe awọn ṣe ayẹwo ilera fun gbogbo awọn to gba papakọ ọkọ ofurufu wọle.
Lori ọrọ ti ijọba ipinlẹ Ekiti sọ pe awọn sọ fun ijọba ipinlẹ Ọyọ nipa ọmọ America to ku si ipinlẹ Ekiti, ati awọn ti wọn jọ wa si Ekiti, ti ọkan lara wọn si ti ni coronavirus, Adisa sọ pe ijọba Ekiti ko sọ fun ijọba Ọyọ tẹlẹ.
Ọjọbọ ti ijọba Ekiti kede faye naa ni wọn sọ fun wa. Ao gbọ si tẹlẹ. Koda, wọn fi atẹjiṣẹ ṣọwọ sori foonu kọmisana eto ilera ipinlẹ Ọyọ."""
O sọ pe ijọba ti lọ si ile ti wọn de si, wọn si ti fin oogun apakokoro sibẹ. Ati pe wọn ti n gbe igbesẹ si n lọ lọwọ lati mọ awọn to ba wọn ṣiṣẹ, bi itọju ile, aṣọ fifọ lasiko ti wọn fi wa nilu ibadan l'agbegbe Bodija.
Sotitobire latest news: Adájọ́ ṣí àṣùwọ̀n ìfowópamọ́sí Wòlíì Sotitobire, ṣùgbọ́n kò fàyè béèlì sílẹ̀ fún un
Ile ẹjọ giga kan ni ilu Akurẹ ti gbẹsẹ kuro lori aṣuwọn ifowopamọsi pasitọ ijọ Sọtitobirẹ Praising Chapel ni ilu Akurẹ, Wolii Alfa Babatunde.
Amọṣa, adajọ to n gbọ ẹjọ ijinigbe ti wọn fi kan Alfa Babatunde atawọn eeyan mẹfa miran, iyẹn Onidajọ Oluṣẹgun Oduṣọla ko faye gba ki wọn gba oniduro rẹ.
Ohun tẹ́ẹ gbúdọ mọ nípa kókó orí ọyàn yín lásìkò fífọ́mọlọ́yàn
Wolii Alfa Babatunde ti ọpọ mọ si Wolii Sọtitobirẹ n jẹjọ ẹsun ijinigbe lori ọmọdekunrin ọmọ ọdun kan to sọnu ni ijọ rẹ loṣu kọkanla ọdun 2019 lasiko ijọsin nibẹ.
Ọmọdekunrin naa, Gold Kọlawọle ni oun ati iya rẹ lọ si ileejọsin naa lọjọ naa ki iṣẹlẹ ọhun to waye.
Ni ọjọ kẹrinlelogun oṣu kẹfa ọdun 2020 ni agbẹjọro fun Wolii Sọtitobirẹ, Amofin Oluṣọla Oke lo pẹjọ fun gbigba beeli wolii naa atawọn mẹfa miran ti wọn jijọ n jẹjọ lori ẹsun naa ti Onidajọ Oduṣọla si sun igbẹjọ lori boya ki wọn gba beeli rẹ tabi rara siwaju.
Ìdílé tí ọkọ da ọmọ síta tóríi ojú Búlùú tí wọ́n ní bá BBC sọ̀rọ̀
Nigba to n gbe idajọ kalẹ lori rẹ, Onidajọ Oduṣọla ṣalaye wi pe oun ko ni fọwọ si gbigba beeli wolii  Sọtitobirẹ atawọn ọmọ ijọ rẹ mẹfa ti wọn n jẹjọ pẹluu rẹ.
Ile ẹjọ ni ọna ti Wolii Sọtitobirẹ n gba beere fun beeli ko si ni ibami pẹlu ofin.
Amọṣa adajọ ni ki wọn gbẹsẹ kuro lori aṣuwọn ifowopamọsi rẹ eyi ti wọn ti sọ agadangodo si lati igba ti igbẹjọ naa ti bẹrẹ.
Eyi fihan pe wolii Alfa Babatunde yoo lee na owo inu aṣuwọn ifowopamọ si rẹ bayii, amọṣa yoo ṣi wa ninu ahamọ ọgba ẹwọn to wa titi di igba ti idajọ yoo fi waye lori ẹsun ti wọn fi kna an.
Oludasilẹ ijọ Sọtitobirẹ ni ilu Akurẹ, Wolii Babatunde Alfa atawọn mẹfa miran ti fi ẹnu ẹjọ wọn jona sibikan bayii ti wọn si n reti bi idajọ ile ẹjọ giga nilu Akurẹ yoo ṣe ri fun wọn.
Gbajugbaja wolii, Babatunde Alfa atawọn mẹfa kan ninu ijọ rẹ n jẹjọ lọwọ lori bi ọmọdekunrin ọmọ ọdun kan ti orukọ rẹ n jẹ Kọlawọle Gold ṣe poora ni ileejọsin naa ni oṣu kọkanla ọdun to kọja.
Adajọ to n gbọ ẹjọ naa ti kede ọjọ kẹrinla, oṣu kẹsan an, ọdun 2020 gẹgẹ bi ọjọ ti awọn agbẹjọro olupẹjọ ati olujẹjọ yoo gbe apilẹkọ awijare wọn kalẹ niwaju ile ẹjọ naa ki Adajọ lee ṣe idajọ to ba yẹ.
Amọṣa Adajọ naa ti laago ikilọ fun awọn agbẹjọro to n lọwọ ninu igbẹjọ naa to ba fẹ gbẹyinbẹbọjẹ lori ẹjọ naa.
Onidajọ Oluṣẹgun Oduṣọla ni idajọ ododo loun wa fun nitori naa agbẹjọro yoowu to ba fẹ daṣọ bo otitọ lori ẹjọ naa lee kan idin ninu iyọ nitori oun ko ni faye gba irufẹ igbesẹ bẹẹ.
Agbẹjọro ijọba lori ọrọ Woli Sotitobire ti ni ọwọ adajọ lo ku si lati sọ bọya Sotitobirẹ jẹbi ẹsun ti wọn fi kan an.
Agbẹjọro naa ni Woli Sotitobirẹ ti sọ wi pe ohun ko mọ nkankan nipa iijnigbe Gold Kọlawole ti wọn jigbe lọ ni Ile Ijọsin rẹ ni Akure.
O ni lasiko ifọrọwanilẹnuwo, Woli Sotitobirẹ sọ wi pe aago mẹta ọsan ni oun to gbọ wi pe wọn n wa ọmọ to sọnu ni ile ijọsin oun.
Agbẹjọrọ ijọba naa fikun pe ijinigbe ọmọ naa ko ni nkankan ṣe pẹlu oun, nitori naa ko kan oun.
Amọ, iya ati baba ọmọ ti wọn jigbe lọ fi ẹsun kan Woli Sotitobirẹ pe ko bikita nipa ọmọ ti wọn jigbe lọ naa ni wọn ṣe fun ra sii.
Sugbọn, Woli Sotitobirẹ ni idi ti oun ko fi kọ ibi ara si ọrọ awọn obi ọmọ ti wọn jilọ naa ni wi pe, awọn obi ọmọ naa bu oun pe oun ko sin Olorun to ni ọmọ naa fi di awati ni ile ijọsin rẹ.
Nínú ìgbẹ́jọ́ tó ń lọ lọ́wọ́ lóri ọmọ tó sọnu nínú ilé ìjọsin Sotitobirẹ nílùú Akure, Alfa Babatude ló léwáju láti sọ tẹnurẹ lórí ǹkan tí ó ṣẹlẹ̀ lọ́jọ́ náà.
Nílé ẹjọ lónìí, Babatunde ni òun kò jẹ̀bi ẹ̀sùn ti wọ́n fi kan òun. Bákan náà ni ni olùrànlọ́wọ́ pàtàkì fún Deji Akure olóyè Taiwo Fagite náà wà lára àwọn to wá jẹ́rìí nilé ẹjọ́ lónìí.
Nínú ọ̀rọ̀ rẹ̀, Fagite ni àwọn òbí ọmọ tó sọnu náà ko ṣe tó bó ti tọ́ àti bó ti yẹ.
O ní lẹ́yin ti wọ́n wá rojọ́ fun kábíyèsí tán, ní àwọn òbi ọmọ náà àti àwọn olùkọ ilé ìjọsìn ọmọdé mẹ́rìnlá wa búra ni ààfìn kábíyèsí
Deji Akure tún pé Alfa Babatunde àti òbi ọmọ náà, ṣùgbọ́n Alfa Babatunde nìkan ló padà yọju
Working religious women: Ẹ̀lẹ́hàá kìí ṣe ọ̀lẹ- Aminat Adegoke
Ẹlẹ́rìí kaarún tó sọ̀rọ̀ nilé ẹjọ́ lónìí Ajíyìnrere Funmilayo Ogunlusi ṣàlàyé pé lẹ́yìn ti wọ́n jí ọmọ náà ní Alfa Babatunde pe fún àdúrà àti ààwẹ ọlọ́jọ́ mẹ́sàn-an pé kí Ọlọ́run ṣàwári ọmọ náà.
Lẹ́yìn tí wọ́n gbà ọ̀rọ̀ lẹ́nu gbogbo ẹlẹ́rìí  bi márùn nínú ìgbẹ́jọ náà ni àdájọ Olusegun Odusola ni nítori àwítúnwi ọ̀rọ̀,  òun kò ni pé ẹlòmíràn mọ́.
Oríṣun àwòrán, facebook
Igbẹjọ lori ẹsun ijọmọgbe ti ijọba n ba Wolii Alfa Babatunde ti ijọ Sotitobire si n tẹsiwaju ni ọjọ Aje to n bọ.
Nigba ti igbẹjọ ọhun waye ni Ọjọbọ, Agbẹjọro agba ati Kọmisana feto idajọ nipinlẹ Ondo, Adekola Olawoye, lo soju ijọba ipinlẹ Ondo lori ẹjọ naa.
Olawoye ni ijọba Ondo ti setan lati ri idi okodoro ọrọ to wa nidi ẹjọ yii, ti igun olupẹjọ ko si ni gba ki wọn fi akoko sofo lori ẹjọ naa rara.
Nigba to bẹrẹ igbẹjọ ọhun, agbẹjọro fun ikọ olujẹjọ, Olusola Oke salaye pe ogun ẹlẹrii ni yoo ma jẹri gbe onibara oun.
'Ẹlẹ́ẹ̀kẹjọ t'óyún máà bàjẹ́ lára mi ni mo tó rí àànú gbà'
Amọ o sọ fun Adajọ Olusegun Odusola to n gbọ ẹjọ naa pe ẹlẹrii mẹta ni olujẹjọ naa yoo ko yọju sile ẹjọ ọhun lana.
Lara awọn olujẹjọ naa si la ti ri aya olori ijọ Sotitobire, Arabinrin Abisola Alfa.
Wayi o, adajọ Odusola ti wa sun ẹjọ naa siwaju di ọjọ Aje, ọjọ kọkandinlọgbọn osu Kẹfa ọdun 2020, eyiun ọsẹ to n bọ.
Ninu awọn ẹlẹri ogun ti yoo jẹri gbe wolii ati olori ijọ Sotitobire, Alfa Babatunde lonii, mẹta ti yọju sile ẹjọ.
Ninu awọn ẹlẹrii mẹtẹẹta naa, ẹlẹri akọkọ ti yoo kọkọ sọrọ ni iyawo Woli Sọtitobirẹ, Ajihinrere Busola Alfa.
Oun si lo n salaye nipa ohun to ṣẹlẹ ni ọjọ ti ọmọ kekere, ọmọ ọdun kan, Kolawole Gold sọnu.
Agbẹjọro agba ati Kọmisọna fun eto idajọ nipinlẹ Ondo, Adekola Olawoye naa ni yoo maa ṣoju ijọba ninu ẹjọ to pe tako olori ijọ Sọtitobirẹ.
Alfa Babatunde ati awọn ẹmẹwa rẹ ni wọn n jẹjọ iwa ajinigbe onikoko mẹta, to fi mọ ẹsun iditẹmọni ati biba ẹri jẹ.
Saaju la ti mu iroyin wa fun yin pe lonii Ọjọru, ọjọ Kẹẹdọgbọn osu kẹfa ọdun 2020, ni igbẹjọ ẹsun ijọmọgbe tun n tẹsiwaju nile ẹjọ pẹlu olori ijọ Sotitobire, Alfa Babatunde.
Ni deede aago mẹwa ku isẹju diẹ ni olujẹjọ naa ati awọn afurasi yoku to n jẹjọ pẹlu rẹ de sile ẹjọ, ninu asọ ọgba ẹwọn alawọ eweko ti wọn maa n wọ.
Nibamu pẹlu akoko yii, awọn olujẹjọ naa fọ ọwọ wọn pẹlu ọṣẹ ati omi ti wọn gbe siwaju abawọle ile ẹjọ, ti wọn si tun fi ibomu-bonu bo imu ati ẹnu wọn.
Ni báyìí, agbẹjọro fún olórí ẹni afẹsunkan, Olusola Oke tí ṣàlàyé fún ilé ẹjọ́ báyìí pé, àwọn ẹlẹri ogun tí dé lati jẹri, ṣùgbọ́n, mẹta péré ni yóò farahàn niwaju adajọ loni.
Igbẹjọ naa ti bẹrẹ nile ẹjọ bayii, bo ba si se n lọ, la maa mu iroyin naa wa fun yin.
Yatọ si ọkan o jọkan awọn ẹlẹri to n jẹri lori ẹjọ, fidio wolii Babatunde Alfa ti ọpọ mọ si Sọtitobirẹ ni wọn tẹ pẹpẹ rẹ sita nile ẹjọ lọsẹ yii gẹgẹ bi ara awọn ẹsibiiti ti olupẹjọ fẹ tẹ siwaju ile ẹjọ.
Bi ẹ ko ba ni gbagbe, Wolii Alfa Sọtitobirẹ n jẹjọ pẹlu awọn mẹfa miran lori ẹsun ijọmọgbe ti wọn fi kan an nipa ọmọdekunrin jojolo Gold Kọlawọle to sọnu ni ile ijọsin rẹ loṣu kọkanla ọdun 2019.
Nibi igbẹjọ to waye l'Ọjọbọ, awọn olupẹjọ pe ẹlẹri lara awọn oṣiṣẹ ajọ DSS atawọn ẹlẹri miran.
ṣaaju ni adajọ to n gbọ ẹjọ naa, Onidajọ Oluṣẹgun Oduṣọla ti kọkọkoro oju si bi awọn oṣiẹ ọgba ẹwọn ṣe pẹ ni gbigbe awọn afunrasi naa wa si ile ẹjọ.
Inu ojo ti ọwọ rẹ le kikankikan ni wọn gbe wolii sọtitobirẹ atawọn afunrasi yooku wọ ile ẹjọ lowurọ ọjọbọ.
Wọn sún igbejo sì ọjọ́ karundinlogbon, ọjọ́ kokandinlogbon àti ọgbọ́n ọjọ́ Oṣù Kẹfà, ọdún yìí.
Pasitọ Babatunde Alfa ti ọpọ mọ si sọtitobirẹ ti gunlẹ si ileẹjọ bayii nibi ti yoo ti tẹsiwaju igbẹjọ ẹsun ijọmọgbe ti wọn fi kan an.
Eyi ni awọn aworan igba ti o gunlẹ si ileẹjọ giga nilu Akurẹ lowurọ ọjọ Aje.
Wolii ijọ Sọtitobirẹ Prayer Minisitry nilu Akurẹ, Alfa Babatunde, ti ọpọ mọ si Wolii Sọtitobirẹ yoo pada si ile ẹjọ loni, ọjọ Aje ọjọ Karundinlogun oṣu kẹfa.
Gbajugbaja iranṣẹ Ọlọrun naa yoo maa fojubale ẹjọ ni itẹsiwaju igbẹjs ẹsun ijọmọgbe ti wọn fi kan an niwaju ile ẹjọ giga kan nilu Akurẹ.
Wolii Alfa Babatunde Sọtitobirẹ atawọn oṣiṣẹ ẹka ileejọsin awọn ọmọde ni ileejọsin naa ni wọn n jẹjọ ti ile ẹjọ si n gbọ awijare awọn olupẹjọ fun ijọba lọwọ bayii.
Ni ọjọ kẹwaa oṣu kẹfa ti ẹjọ naa waye kẹyin niwaju Onidajọ Oluṣẹgun Oduṣọla ni awọn ileeṣẹ Agbofinro DSS n ṣe alaye idi to fi jẹ awọn lo n ṣe iwadii ẹsun naa dipo awọn ọlọpaa to kọkọ bẹrẹ iwadii rẹ.
Pasitọ ijọ Sotitobire, Alfa Babatunde njẹjọ lori ọmọ ọdun kan to poora ninu ile ijọsin rẹ lọdun 2019.
LASTMA Yesufa: Àwọn dókítà gbìyànjú lórí ojú mi ṣùgbọ́n...
Ọpọ eeyan lo ti n beere ibeere lori idi to fi jẹ pe awọn ẹṣọ agbofinro ọtẹlẹmuyẹ apapọ, DSS lo n ṣe ẹjọ ijinigbe ti wọn n fi kan ilumọọka wolii Alfa Babatunde Sọtitobirẹ ni ilu Akurẹ.
Amọṣa ileeṣẹ agbofinro DSS ti bọ si gbangba walia lati ṣalaye idi to fi jẹ awọn gan an lo n ṣe kokaari ẹjọ naa.
Lọjọ Aje ni igbẹjọ miran tun waye nile ẹjọ giga to n gbọ ẹjọ ti ijọba fi kan Wolii Alfa Sọtitobirẹ nilu Akurẹ,
Nibẹ ni ọkan lara awọn oṣiṣẹ ajọ naa ti wọn pe gẹgẹ bii ẹlẹri olupẹjọ nibi igbẹjọ naa ti ṣalaye nipa idi to fi jẹ pe ajọ DSS lo n ṣe ẹjọ naa.
O ni pe iwe ifisun ti awọn eekan ilu ati lajọlajọ bii ileegbimọ aṣofin ipinlẹ Ondo, ajọ ajafẹtọ ọmọniyan, Nigeria Human rights commission, atawọn ajọ miran kọ si ileeṣẹ agbofinro ọtẹlẹmuyẹ DSS lẹyin ti iṣẹlẹ naa ṣẹlẹ loṣu kọkọanla, ọdun 2019 lo le awọn oṣiṣẹ ajọ naa lati ti ẹsẹ bọ iwadii ọrọ ọhun.
Bi a ṣe n sọrọ yii awọn agbofinro ti gbẹsẹ le aṣuwọn ifowopamọsi Wolii Alfa Babatunde Sọtitobirẹ eleyi ti awọn agbẹjọro fun Wolii naa ti kọwe si ile ẹjọ naa lati tako o.
Akure Kidnap: E túbọ̀ ní sùúrù, a máa wá ọmọ náà rí- Alukoro ọlọ́pàá
Bakan naa ni ile ẹjọ tun ti tẹwọ gba iwe iforukọsilẹ awọn ọmọde ni ileejọsin awọn ọmọde to wa ni ileejọsin fasiti Adura, Sọtitobirẹ gẹgẹ bi ọkan lara awọn ẹri niwaju ile ẹjọ naa.
Ninu eyi ni wọn si tun ti fi idi rẹ mulẹ pe orukọ ọmọdekunrin Gold Kọlawọle ti wọn n wa naa wa ni nọmba kẹtadinlaadọrun ninu iwe ọhun.
Onidajọ Oluṣẹgun Oduṣala to n gbọ ẹjọ ọhun wa sun igbẹjọ si ọjọ Aje to n bọ tii ṣe ọjọ karundinlogun osu yii.
Ileẹjọ giga ipinlẹ Ondo to wa niluu Akure ti sun igbẹjọ Pasitọ ijọ Sotitobire, Alfa Babatunde si ọjọ Aje to n bọ tii ṣe ọjọ kẹẹdogun oṣu kẹfa ọdun 2020.
Alfa Babatunde Sotitobire lo mn jẹjọ pẹlu awọn mẹfa mii lori ẹsun igbimpọ lati ji ọmọ ọdun kan, Gold Kolawole gbe lọdun 2019.
Ileẹjọ fidi rẹ mulẹ pe iwe iforukọ silẹ awọn ọmọde eyi ti orukọ Gold wa nibẹ fihan pe lootọọ lọmọ naa wa ni ṣọọṣi lọjọ to di awati.
Adajọ Olusegun odusola kọ eti ikun ẹbẹ agbẹjọro Alfa Babatunde lati ṣi apo ifowopamọ rẹ marun un eleyi ti ajọ ọtẹlẹmuyẹ DSS tipa.
Adajọ tun sun igbẹjọ beeli awọn afurasi naa di ọjọ kẹtalelogun oṣu kẹfa yii kan naa.
Igbẹjọ Pasitọ ijọ Sotitobire n lọ nileẹjọ giga l'Akure
Pasitọ ijọ Sotitobire, Alfa Babatunde ti wa nile ẹjọ giga ilu Akure bayii, ni itẹsiwaju igbẹjọ ọmọ ọdun kan to poora ninu ile ijọsin rẹ lọdun 2019.
Ni dede aago mẹsan an ku iṣẹju mẹwaa owurọ ọjọ Aje ni wọn gbe pasitọ naa atawọn mẹfa mii de lati ọgba ẹwọn Olokuta to wa ni ilu Akure.
Alfa Babatunde Sotitobire tún fojú balé ẹjọ́ lọ́nìí, ni itẹsiwaju igbẹjọ rẹ niwaju ile ẹjọ giga ni ilu Akurẹ lori sun igbimpọ lati ji mọ gbe.
Ilé ẹjọ́ tí sún igbejọ lori ẹsun ijọmọgbe ti wọn fi kan gbajugbaja wolii kan ni ilu Akurẹ, Alfa Babatunde ti p eeyan m si Sọtitobirẹ siwaju di ọjọ́ kẹjọ oṣù kẹfà ọdún yìí láti jẹ ki igbejo náà yà kíákíá.
Leyin ọ̀pọ̀lọpọ̀ atotonu àwọn agbejoro fun wòlíì Babatunde Alfa Sọtitobirẹ ni ile ẹjọ́ àgbà tí ìpínlè Ondo to fikalẹ si ilu Akurẹ lọjọru, ilé ẹjọ́ gba ẹri àwọn agbofinro ọtẹlẹmuyẹ àjọ DSS wọlé pé, wọn fi ẹ̀sùn méjì kan àlùfáà náà tí ó dà lórí ijinigbe àti ifowosowopo láti ṣíṣe láabi náà
Ẹlẹ́rìí àwọn àjọ DSS, Khadijat Oriyomi ṣàlàyé pé, ní ọjọ́ Kejìlá Oṣù Kejìlá Ọdún 2019, ní wón mú ọkàn lára àwọn afunrasi naa, arábìnrin Margaret Oyetola, tí ó sì kọ ìwé sílè pé Lóòótọ́ ni iṣẹlẹ náà ṣẹlẹ̀ ṣùgbọ́n tí kò ye ohun bóyá Lóòótọ́ ni àlùfáà náà jí ọmọ gbé ati pé lóòótọ́ ni ọkàn lára wọn, Peter Anjorin fò fóònù mọ́lẹ̀ èyí tí ó jẹ ti àlùfáà Babatunde níwájú àjọ náà.
Alfa Babatunde Sotitobire tún fojú balé ẹjọ́ lọ́nìí, bàbá ọmọ jẹri níwájú adájọ́
Bàbá ọmọ ọdún kan tí wọ́n jígbé ni ilé ìjọsìn Praising Chapel Akure ní inú oṣù kọkánlá ọdun tókọja, Temitope Kolawole ti jẹri níbi ìgbẹ́jọ tó n lọ lọ́wọ́ láàrín òun àti olórí ìjọ náà wòlí Alfa Babatunde àti àwọn mẹ́fà míràn.
Adájọ́ Olusegun Odusola to gbọ́ ẹjọ́ náà gbà pé ẹ̀rí ni ọ̀rọ̀ Temitope Kolawole  jẹ́ níwájú ilé ẹjọ́ èyí tó ti fi lélẹ̀ lásìkò ti àwọn ẹka ọlọ́pàá tó n rí sí ijínigbé fọ̀rọ̀ wáa lẹ́nuwò.
Ìròyìn  sọ  pé Alfa Babatunde àti àwọn tó kù ti padà sí inú ẹ̀wọ́n Olokuta  ní Ondo  láti tẹ̀síwájú ìgbẹ́jọ lọ́la
Sáájú ni Temitope Kolawole tó jẹ́ bàbá ọmọ tó sọnù sọ fún ilé ẹjọ́ pé àwọn olólùfẹ́ Alfa Babatunde pébò òun ti wọ́n sì fa aṣọ òun ya kí òun tó sá lọ ba Deji Akure láti ṣe àwárí ọmọ òun.
Bákan náà ni àwọn ọgbà ẹ̀wọn ní kí àwọ́n ẹlẹ́wọ̀n tẹlé ìlànà ìmọ́tótó ki wọ́n tó wọ ilé ẹjọ́ tó fi mọ Alfa Babatunde.
Ilé ẹjọ́ dá pásítọ̀ ìjọ Sotitobire àti àwọn tókù padà sọ́gbà ẹ̀wọ̀n, ó sún ẹjọ́ síwájú di ọ̀lá
Ile ẹjọ giga ilu Akure to n gbọ ẹsun ijinigbe ti wọn fi kan pasitọ ijọ Sotitobire, Alfa Babatunde ti sun ẹjọ naa si Ọjọ Kẹfa, oṣu kẹrin ọdun 2020.
Adajọ ile ẹjọ naa, Olusegun Odusola sun ẹjọ naa lẹyin wakati mẹjọ gbako ti wọn ti wa nile ẹjọ ọhun, lati le faye gba awọn ẹlẹri mẹrin ijọba lati wa sọ tẹnu wọn.
Gbọingbọin ni awọn ololufẹ pasitọn naa wa nile ẹjọ titi di igba ti ẹjọ ọhun pari.
Ni bayii, wọn ti da pasitọ naa atawọn mẹfa mii ti wọn fẹsunkan ṣogba ẹwọn Olokuta to wa nilu Akure titi di Oṣu Kẹrin ti igbẹjọ mii yoo waye.
Iroyin lati ile ẹjọ to n gbọ ẹjọ ijinigbe ti wọn fi kan gbajugbaja iranṣẹ Ọlọrun kan niluu Akurẹ ẹni ti ọpọ mọ si Baba Sọtitobirẹ, Wolii Alfa Babatunde n jẹ ko di mimọ pe gbaragada ni iya ọmọ naa, arabinrin Modupẹ Kọlawọle bu s'ẹkun ni ile ẹjọ naa loni nigba to n jẹri lori ẹjọ naa.
Awọn akọwe ile ẹjọ naa ni ṣe aajo rẹ lẹyin to fidijanlẹ sori aga.
Oludasilẹ ijọ Sọtitobirẹ Miracle center nilu Akurẹ, Woli Alfa Babatunde pada si ile ẹjọ lori iṣẹlẹ ọmọdekunrin kan to sọnu ni ileejọsin naa loṣu kọkanla ọdun to kọja.
Awọn oṣiṣẹ ileejọsin naa mẹfa miran n jẹjọ pẹlu woli Babatunde lori ẹsun ijinigbe ati igbimọpọ huwa ijinigbe.
Ireti wa pe iya ati baba Gold Kọlawọle ni yoo ṣiwaju awọn ẹlẹri marun tawọn agbẹjọro ijọba yoo pe jade loni nile ẹjọ.
Nibi ijoko ile ẹjọ naa to waye lọjọ Aje to kọja, iya-iya ọmọ naa ati mọlẹbi rẹ kan wa lara awọn ti wọn pe gẹgẹ bi ẹlẹri nibi igbẹjọ ọjọ naa.
Ni bi a ṣe n sọrọ yii, gba-gba-gba lawọn agbofinro wa nikalẹ lati mojuto eto abo ni ile ẹjọ naa.
Coronavirus: Báwo ni o ṣe le mọ̀ pé o ní àrùn Coronavirus?
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Awọn eeyan ti o n ni awọn apẹrẹ kan ni wọn n gba ikils bayii lati fi ara wọn si isele fun ọjọ mẹrinla gbako lati fi mọ boya arun yii lo n jẹys lara wọn abi oun kọ.
Amọṣa, ṣe gbogbo ailera ni Coronavirsu bayii ni abi bawo?
Bawo ni o ṣe lee mọ boya ailera lasan lo ni tabi boya awọn ifarahan arun coronavirus lo n jẹyọ lara rẹ?
Bawo ni awọn ifarahan arun coronavirus ṣe maa n ri gan an?
Ohun ifarahan meji ti o maa n jẹyọ bi eyan ba ni arun corona virus ni ikọ ahugbẹ ni lemọlemọ ati iba. Bi o ba n ṣe ọfinkin tabi ti o ba ni iba. O ṣeeṣe ko jẹ aarẹ lasan ni, o le maa jẹ arun Coronavirus.
Amọṣa, irufẹ iba wo; tabi bawo ni iba rẹ ṣe lee lagbara to ti a fi lee funra pe boya coronavrus ti rapala wọle;
Atipe, ki gan an ni a lee mu gẹgẹ bii ikọ ahugbẹ ni lemọlemọ?
Eyi ni ki eeyan wukọ ṣugbọn ki o ma ba omi tabi kẹlẹbẹ jade. Eyii kii ṣe irufẹ ikọ ti eeyan n wu lẹẹkọọkan o, bikoṣe eyi ti yoo maa waye ni lemọlemọ laisi idi kan gbogbogi.
O daa o, iru iba wo ni iba to n ṣafihan coronavirus?
Hmmm...bi o ba ni irufẹ iba coronavirus, iwọ naa yoo mọ.
Lọrọ awọn akọṣẹmọṣẹ, bi ara rẹ ba ti gbona ju iwọn onka igbona ara to to metadinlogun celcius tabi ọgọrun Farenheit lọ?
Làá hàn mí: Ètò yìí ló ń kìlọ̀ fún wa láti mú ìmọ́tótó ní pàtàkì láti dènà Coronavirus
Amọṣa bi o ko ba ni ohun elo tamomita ti wọn fi n wọn bi nnkan ṣe gbona si, oo ṣakiyesi pe ara rẹ n gbona,bi eeyan ba si fi ọwọ kan ẹ, aya rẹ ati ẹyin rẹ yoo gbona wa.
Bi o ba wa kẹẹfin pe o ni eyikeyi ninu ifarahan wọnyii, maa jayo pa o, to ba jẹ wi pe iwọ nikan lo n gbe ile, yara duro sile fun ọjọ meje lọ.
Amọṣa to ba jẹ pe o n ba awọn eeyan miran gbe, gbogbo wọn gbọdọ wa ni igbele fun ọjọ mẹrinla
Bi o ba wa di wi pe aisan naa n tubọ burẹkẹ sii lara rẹ, tabi ko tete lọ bọrọ, a dara ki o kan si awọn ileewosan to ba wa nitosi rẹ ki o si ṣalaye fun wọn ni kikun.
Coronavirus: Ọmọ ilẹ̀ Italy tó kó Coronavirus wọ Naijiria kò ní àrùn náà mọ́
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ayẹwo ti fi han pe ọmọ orilẹde Italy to ko arun Coronavirus wọn Naijiria ko ni arun naa mọ.
Ṣaaju ni ọkunrin ọhun to wa si Naijiria lati ilu Milan lọjọ kẹrinlelogun, Oṣu Keji  ọdun yii ti n gba itọju nile iwosan ijọba to wa ni yaba, nilu Eko.
Kọmiṣọna eto ilera ipinlẹ Eko, Akin Abayomi sọ fun awọn akọroyin nibi ifọrọwerọ kan pe ẹni ọdun mẹrinlelogoji naa ko ni arun ọhun lara mọ.
Abayomi tẹsiwaju pe wọn yoo ṣe ayẹwo mii fun ọkunrin naa, ti esi rẹ ba wa bakan naa, wọn yoo da silẹ ko ma lọ ile rẹ layọ ati alafia.
"O ni ""Ọkunrin naa ko ni arun Coronavirus lara mọ, ṣugbọn idi ti a ṣi fi da duro ni pe a fẹ ṣe ayẹwo miran fun ki a to fi silẹ ko maa lọ ile rẹ."""
Ọmọ ilẹ Italy naa wọ sile itura kan to sunmọ papakọ ofurufu ilu Eko ni kete to gunlẹ si Naijiria, ko to lọ si ipinlẹ Ogun fun iṣẹ aje.
Ọjọ kẹta to de si Naijiria ti lo ṣaisan rampẹ, ti ayẹwo si fi han pe arun Coronavirus lo n ba finra.
Làá hàn mí: Ètò yìí ló ń kìlọ̀ fún wa láti mú ìmọ́tótó ní pàtàkì láti dènà Coronavirus
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ẹẹdẹgbeje (1300) awọn eeyan lawọn ileeṣẹ eto ilera n wa bayii lori itankalẹ arun coronavirus ọhun.
Kọmiṣọna feto ilera nipinlẹ Eko, Ọjọgbọn Akin Abayọmi lo ṣalaye eyi lẹyin to kede eeyan mẹrin miran pẹlu arun Coronavirus bayii.
Eyii ti mu ki apapọ awọn eeyan to ni arun naa ni Naijiria pe mejila bayii.
Ọjọgbọn Abayọmi ni ayẹwo mọkandinlogun ni wọn ṣe lori awọn ti wọn funrasi pe wọn ni aarun naa atawọn eeyan to ni nnkan pọ pẹlu awọn awọn marun ti wọn kede pe wọn ni arun naa lọjọru.
Mẹrin ninu ayẹwo ọhun lo ja si tootọ.
O ni akọkọ ninu wọn ni ọmọbinrin ọmọ orilẹede Naijiria kan to wọ orilẹede Naijiria lati orilẹede France pẹlu baluu ilẹ Turkey kan lọjọ kẹrinla oṣu kẹta ọdun 2020.
O fi kun pe ẹni keji ni ọmọkunrin kan ti ọjọ ori rẹ ti le ni aadọta ti ko rinrinajo lọ si ibikibi.
Ẹnikẹta ni arakunrin miran to wọ orilẹede Naijiria ni ọjọ kẹtala oṣu kẹta lati ilu Frankfurt lorilẹede Germany.
O ni ẹẹdẹgbeje awọn eeyan lawọn ileeṣẹ eto ilera n wa bayii lori itankalẹ arun coronavirus ọhun.
Oluwo ti Iwo: N kò ni nkan kan sọ lórí fídíò to gba ayélujára kan pé mo ń we igbó, ẹ mú ẹnu kúrò nibẹ
Oríṣun àwòrán, oluwo of iwo
Oluwo tilu Iwo, Oba Abdul Rasheed Adewale Akanbi, Telu Kínní, tí kéde pé ẹẹmẹta laarin ọ̀sẹ̀ kan ni òun ń fún àwọn ará ìlú Iwo tí ebi ń pá ni oúnjẹ èyí tó bẹ̀rẹ̀ ni ọdún mẹrin sẹ́yìn.Ọba Akanbi, lásìkò to ń bá  BBC Yoruba sọ̀rọ̀ ni òun tún máa ń wọ agboolé lọ n'ilu Iwo láti fún àwọn arúgbó tí kò leè jáde nílé ní oúnjẹ.O ni òun gẹ́gẹ́ bí ọba ìlú, òun kò leè là ojú ṣílẹ̀, kí àwọn ọmọ òun máa kú ní oju òun, ó ní bí èyí bá rí bẹ́ẹ̀, a jẹ pe ìgbà òun kò dára lórí òye nuu.
Ìkórira pé mo jẹ Mayegun ni wọn ṣe parọ́ pé mo ń fẹ́ olorì Aláàfin, kò rí bẹ́ẹ̀ rárá-  Kwam 1
A fẹ́ lo ẹ̀jẹ̀ àwọn èèyàn tó ye àrùn Coronavirus láti fi ṣe ìwòsàn fún àwọn tó wà lórí àárẹ- UK
Ìkórira pé mo jẹ Mayegun ni wọn ṣe parọ́ pé mo ń fẹ́ olorì Aláàfin, kò rí bẹ́ẹ̀ rárá-  Kwam 1
Ọjoọ́ mélòó ni Coronavirus ń lò lára kí ènìyàn tó gba ìwòsàn?
"Ọba Akanbi ni, òun kò gbà nkankan lọ́wọ́ aráàlú n'ilu iwo, àmọ́ òun ń lọ ṣíṣẹ wá fún wọn láti tọju wọn ni, torí òun gan ni ẹrú aráàlú, òun sì máa ń ṣe aráàlú Iwo bíi ọba ní.""Èmi kii pá aago ìbánisọ̀rọ̀  mi, igbakuugba táwọn aráàlú bá sì pé mi, ní wọn máa ń rí mi bá sọ̀rọ̀, mo sì leè fọwọ́ gbaya pé, kò sí aráàlú Iwo tí kò ní nọ́mbà ẹ̀rọ ibaraẹnisọrọ mi lọ́wọ́""Bákan ni Ọba Akanbi ni ìjọba nìkan kò leè dá gbé ẹrù ìpèsè oúnjẹ fún aráàlú, kódà, ìjọba Ìpínlẹ̀ Osun kò leè dá gbé ẹrù oúnjẹ fún àwọn èèyàn ìlú Iwo nìkan, nitori naa, o yẹ ki aráàlú dìde lásìkò yìí, láti ran ìjọba lọ́wọ́.Oluwo fikùn pé òun wà nínú ogún Liberia lọ́dún 1989, tí òun sì ti dé ẹnu ikú ni igba mẹ́jọ, bẹ́ẹ̀ si ni àkókò ogun aifojuri là wá yìí, to jọ tí ogun ìbọn."
"Nígbà ogun, gbogbo aráàlú máa ń kó ohun tí wọ́n bá ní síta ni. Ohun to sí wa de yii, ki awon olowo àti oloro kò owó wọn síta ni lati rán aráàlú lọ́wọ́, gbogbo àwọn èèyàn ti ko si leè lọ sí Mecca lọ́dún yìí, ní kí wọn kò owó wọn
kalẹ fún ìjọba, mo sì ń rọ àwọn aráàlú láti fi idi mọle wọn."
Oluwo wá ṣe sadankata si ìjọba Ìpínlẹ̀ Osun fun bo ṣe kogiri mọ igbogun tí àrùn Covid-19, ó si tún  woye pe, ẹsẹ̀ lo fà ajakalẹ àrùn yìí.
 Ojojumo là ń fi ara wa se oogun owó, a ń fi ojú rí apá àti ẹsẹ, tó fi mọ orí èèyàn nigboro, táwọn ọmọ Badoo sì ń fọ orí àwọn èèyàn kiri, èyí tí kò dun mọ Ọlọ́run nínú.
Oríṣun àwòrán, oluwo of iwo
Ọba Akanbi ni isẹ ti ń lọ láti ṣe agbelaruge àwọn aṣọ ìbílẹ̀ wá, èyí tí yóò fara jọ 'Jeans' oloyinbo, tí yóò sì tún wúlò fún wa lásìkò yìí tí ìlú Oyinbo kò ṣeé lọ fún wa mọ.
Nígbà tó ń dáhùn ìbéèrè lórí fìdío kan tó jáde sórí ayelujara laipẹ  yii, ti ẹnikan tí ojú rẹ jọ tí ọba Akanbi tí ń we igbó, Oluwo ni òun kò ní ohunkóhun sọ lori rẹ, kí wọn mú ẹnu kúrò lórí ọ̀rọ̀ náà ni torí òun kò mọ ohun kohun nípa
rẹ.
Oluwo ni àṣà Yoruba lo dára julọ, àmọ́ àwọn ohun tí kò bá dára, ó yẹ ká mú kuro ninu rẹ. Ó ní fún àpẹẹrẹ ila kíkọ kò bá ìgbà mú mọ, tó fi mọ sise oogun owó àti lilo ẹ̀yà ara èèyàn fún òrìṣà bíbọ nítorí gbogbo ohun tó bá ń mú
ẹ̀mí lọ kò dára, ó yẹ ká mú kúrò nínú àṣà wá.
Oríṣun àwòrán, oluwo
Nígbà tó ń ṣàlàyé ìdí tó fi sọ ọmọ rẹ ni Odùduwà, Oluwo ni kí ló burú nínú kí èèyàn sọ ọmọ rẹ ni orúkọ Baba ńlá rẹ, o ni, ohun tó dára gbaa ni.
Nígbà tó ń fèsì lórí ìbéèrè pé ìgbà wo ni olori tuntun yóò wọ ààfin rẹ lẹ́yìn tí aya rẹ tí kúrò ní ààfin, Oluwo ni àìmọye ọba míì tí wá nílẹ Yoruba ti wọn ṣẹ̀ṣẹ̀ ń wá ìyàwó, nígbà tó  sì yá, wọn si ri ìyàwó, ó fikùn pé, kí àwọn èèyàn
dúró de ìgbà tí Ọlọ́run bá yàn fún òun.
Lórí ibasepọ  to wá laarin Oluwo àti Ọọni tilu ilé Ilé-Ifẹ̀, Oluwo ni ibasepọ  àwọn gùn régé pupọ, to sì tun tọ ipàṣẹ orírun àwọn ìdílé to ń jọba n'ilu Iwo lọ sí Ilé-Ifè nítorí Ooni obìnrin Luwoo Gbagida to wá láti agboolé Lafogido
n'ilu Ilé-Ifè.
Oluwo wá ṣe ikilọ pé arun Coronavirus kò gbọ́dọ̀ gbilẹ ni Nàìjíríà gẹgẹ bo se n pa wọn nílẹ  òkèèrè, tó sì rọ àwọn èèyàn láti mase máa yọjú síta kiri àmọ́ kí wọn joko sílè koowa wọn.
Oluwo tún kesi àwọn ọmọ Naijiria lati fara dà ohun tó ń ṣẹlẹ̀ yìí nítorí kò sí epo rọbi mọ ní Nàìjíríà.
Nígbà tó ń sọ̀rọ̀ lórí ọpọ ọrọ kobakungbe tí àwọn èèyàn kan ń sọ nípa rẹ lórí ayélujára, Oluwo ni òun ń sanwó òkìkí ni ọ̀rọ̀ òun ti wọn n sọ, ẹni tó bá sì wà ipò, ó di dandan kí wọn sọ̀rọ̀ rẹ.
Oluwo wá gba àwọn Mùsùlùmí to bẹ̀rẹ̀ aawẹ Ramadan nímọ̀ràn, láti kó owó síta fún àwọn aláìní, pàápàá àwọn èèyàn tó fẹ́ lọ sí Mecca, tí wọn kò leè lọ mọ.
Oluwo ni òun kò fẹ́ kí àwọn èèyàn kú tàbí máa sunkún, òun sì ń fẹ́ kí Ọlọ́run mú ẹ̀mí oun lati kò Coronavirus kúrò nílẹ nítorí òun kò fẹ́ káwọn aráàlú máa kú báyìí.
Coronavirus: Oluwo ní kò sí ẹ̀bùn òkè òkun tó lée mú òun gbàlejò láàfin
Pẹlu bi ọwọja arun Coronavirus ṣe n gbilẹ kaakiri agbaye bayii, Oluwo ti ilẹ Iwo, Ọba Abdulrasheed Akanbi Telu I ti ke sawọn ọmọ Naijiria lati rii pe wọn tẹle gbogbo ilana to yẹ lati daabo bo ara wọn lọwọ itankalẹ arun naa.
Ninu fidio kan eyi to fi ṣọwọ si BBC News Yoruba, Oluwo ti ilu Iwo rọ gbogbo awọn muslumi lati maṣe lọ si Mọṣalaṣi fun irun Jimọ ni ọjọ Ẹti.
Bakan naa lo tun rọ awọn ọmọlẹyin Kristi lati joko sile wọn lọjọ Aiku ki wọn si jina si ile ijọsin wọn gbogbo.
Ọba Akanbi ṣalaye wi pe koda ilẹ Mẹka nibi ti awọn Musulumi maa n rinrinajo mims lọ pẹlu ti se ilẹkun wọn pa ti wọn si ti ni ko saye lọwọ yii.
Oluwo ni gbogbo ọmọ Naijiria lo ni ojuṣe lati rii pe arun naa ko gbilẹ lorilẹede Naijiria gẹgẹ bi o ti ṣẹ lawọn orilẹede kan lagbaye.
Peter Fatomilola ní àìsí ẹ̀kọ́ ń mú káwọn òṣèré tíátà ó máá ṣe oun tí kò tọ́.
Ninu ọrọ rẹ, ogun ebi lawọn ọmọ orilẹede Naijiria ṣi n ba ja bayii, ko si daju pe orilẹede yii yoo lagbara lati koju ogun arun Coronavirus bi o ba di tọrọ fọnkale.
Bakan naa lo ke ke gbajare sita pe oun ko ṣetan ati gbalejo kankan lasiko yii nitori pe ilana ati daabo bo ara ẹni kan oun naa gẹgẹ bi Ọba.
O ni gbogbo ẹru ẹbun ti ẹnikẹni lee ni lọwọ lati fun oun ki wọn fi sọwọ lọ gbe ile wọn naa titi di igba ti arun naa yoo dẹkun.
Coronavirus: Àwọn onímọ̀ sáyẹ́ǹsì Nàíjíríà ṣe ẹ̀rọ àyẹ̀wò àrùn jáde
Idunnu ti sibu lu ayọ ni orilẹede Naijiria nitori ijọba ti kede pe agbega yoo ba eto ayẹwo awọn eeyan to seese ko ni arun Coronavirus lara.
Aseyori nla si leyi fun ijọba Muhammadu Buhari nidi gbigbe ogun ti itankalẹ arun Coronavirus.
Agbẹnusọ fun aarẹ Buhari lori eto iroyin, Bashir Ahmad lo kede aseyọri nla yii loju opo Twitter rẹ.
"Shehu ni ""Orilẹede Naijiri ti n se ohun eelo ayẹwo arun Coronavirus, ta mọ si Testing Kits funra rẹ, eyi tawọn onimọ isegun oyinbo labẹle se jade."
Shehu fikun pe, ko si aniani pe aseyọri nla naa yoo mu ilọsiwaju ba eto ayẹwo fawọn araalu, lati mọ awọn ti ina arun Coronavirus ti bọ si abẹ asọ wọn.
Coronavirus in Nigeria: Ìwádìí fihàn pé ọ̀pọ̀ aráàlú ni kò gbà pé àrùn Covid-19 wà
Oríṣun àwòrán, Rccg
Saaju la ti sọ fun yin pe ẹgbẹ awọn ọmọlẹyin Kristi ni Naijiria, CAN ti dari awọn ile ijọsin, lati ya ọjọ kejilelogun ati ọjọ kọkandinlọgbọn oṣu kẹta sọtọ fun adura nitori arun Coronavirus.
Alaga CAN, Alufa Samson Ayokunle parọwa si ijọ lati tẹlẹ amọran ti awọn eleto ilera gbe kalẹ lọna ati  dena itankalẹ arun naa ni bi wọn ṣe n gbadura.
O ni ijọba ko tii fi to ẹgbẹ ọhun leti pe o ti wọgile ijọsin ti eeyan rẹ ju aadọta lọ.
Lẹyin naa lo rọ awọn ile ijọsin lati gunle isin olojule ti awọn eeyan ti yoo wa nibẹ ko ni pọ ju boṣeyẹ lọ, tabi ki wọn maa ṣe isin lati ori itakun agbaye ti awọn ọmọ ijọ le darapọ mọ lati ile wọn.
O tẹsiwaju pe ijọ tun le pin isin si isọri ti eeyan ti yoo wa ni isọri kan ko ni pọ ju aadọta lọ.
Ẹgbẹ CAN tun wa rọ awọn ijọ lati pese ọṣẹ  ati omi si ile ijọsin wọn fun imọtoto awọn eeyan, ati pe ki wọn gbiyanju lati jina diẹ si ẹnikẹni to ba n sin, tabi wukọ.
Lati igba ti arun Coronavirus ti bẹ silẹ lorilẹ-ede China lọdun 2019, arun naa ti tan de o orilẹ-ede to le lọgọrun un, eyi si ti mu kin wọn wọgile oriṣiriṣi apero ati ipade kaakiri agabye.
Làá hàn mí: Ètò yìí ló ń kìlọ̀ fún wa láti mú ìmọ́tótó ní pàtàkì láti dènà Coronavirus
Cornavirus: Makinde tọrọ aforiji fun ìpàdé ìta gbangba ẹgbẹ́ PDP tó wáyé nílu Ibadan
Oríṣun àwòrán, @seyiamakinde
Gomina ipinlẹ Oyo, Seyi Makinde titọrọ aforiji lọwọ awọn eeyan ipinlẹ naa fun ipade ita gbangba ẹgbẹ PDP to waye nilu Ibadan laarin awuyeeuye Coronavirus to gbode.
Makinde lo sọ ọrọ naa ninu atẹjade kan to fi soju opo Twitter rẹ.
"O ni ""Mo ti gbọ ẹdun ọkan yin nipa iwọde ti a ṣe lana, mo si fẹ sọ wipe  a pinu lati ṣe miwọde naa lasiko yii nitori awọn iroyin to tẹ wa lọwọ lasiko naa."""
Ko yẹ ki iwọde naa waye, mo gba pe mo ṣe jẹbi lati gunle iwọde naa.
Makinde tẹsiwaju pe ojuṣe oun gẹgẹ bi gomina ni lati dabo bo awọn eeyanb ipinlẹ naa, ati pe ijọba rẹ yoo ṣe gbogboi ohun to yẹ ni ṣiṣe lati dena arun Coronavirus.
Lẹyin naa lo rọ awọn ara ilu lati ma foya lori iroyin itankalẹ arun Coronavirus nitor ale bori arun naa ti a ba fọwọ sowọpọ.
Gomina ọhun tẹsiwaju pe imọtoto ara ẹni ṣe pataki lasiko yii.
"O ni ""Awọn eleto ilera ti fi han pe fifọ ọwọ ẹni pẹlu ọṣẹ ati omi fun ogun aaya ati lilo ipawọ apa kokoro lee jẹ ki arun naa jina si eeyan."
Makinde fi da awọn eeyan ipinlẹ naa loju ijọba ti bẹrẹ igbesẹ lati daabo bo wọn lọwọ ajakalẹ arun naa, leyi ti oun tikalara rẹ n dari.
Gomina ọhun pari ọrọ rẹ nipa fifi nọmba wọyin lede 08038210122, 08023229267, 08073431342.
O si rọ awọn eeyan lati pe eyikeyi ninu awọn nọmba naa ti wọn ba n ri apẹrẹ run naa bii, iba, inu riru, ẹfọri lile, iṣoro lati mi ati bẹbẹ lọ lara wọn tabi lara ẹnikẹni to ba sun mọ wọn.
Peter Fatomilola ní àìsí ẹ̀kọ́ ń mú káwọn òṣèré tíátà ó máá ṣe oun tí kò tọ́.
Coronavirus: Ìjọba àpapọ̀ fi Austria, Sweden kún àwọn orílẹ̀èdè mẹ́tàlá tí kò lè wọ Nàìjíríà
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ijọba orilẹede Naijiria ti fi orukọ orilẹede Sweden ati Austria kun awọn orilẹede mẹtala miran ti wọn se ilẹkun ati wọ orilẹede Naijiria  mọ.
Minisita feto ilera, Dokita Osagie Ehanire lo kede awọn orilẹede meji ti wọn fi kun iye awọn orilẹede to wa nilẹ tẹlẹ.
Ni ọjọru ni ijsba apapọ kede pe ko ni si aye fun awọn arinrinajo lati orilẹede mẹtala kan lati wọ orilẹede Naijiria.
Awọn orilẹede mẹtala naa ni wọn ṣakiyesi pe ọwọja itankalẹ arun coronavirus pọju si lagbaye.
Awọn orilẹede ti ọrọ kan ni China, Iran, South Korea, Germany, Italy, Amẹrika, Ilẹ Gẹẹsi, Switzerland, Norway, Netherlands, Spain, France ati Japan.
Ni bayii ti orilẹede Austria ati Sweden ti kun un, a jẹ wi pe iye orilẹede ti Naijiria ti se ilẹkun rẹ mọ bayii ti di marundinlogun.
Ṣé ẹ̀yin mọ idí ti Abass Akande fi n jẹ Obesere?
Oríṣun àwòrán, Obesere
Ṣé ẹ̀yin mọ idí ti Abass Akande fi n jẹ Obesere?
Lórí ìfọ̀rọ̀wérọ to wáye níle iṣẹ́ BBC News Yoruba lonii pẹlú Abass Akande loti sàlaye oníruuru nipa àra rẹ àti iṣẹ́ orin to yàn láàyò.
Nínú ọ̀rọ̀ rẹ Abass Akande sàlayé ìdí ti oun fi n jẹ Obesere ti gbogbo ènìyàn n pe oun lọ́nìí, o ní èyi kìí ṣe orukọ abísọ ti iyá àti bàbá sọ oun o, sùgbọ́n lásìkò ere ori náà ni oun gba orukọ náà.
Gẹ́gẹ́ bo ṣe sọ oni aluṣẹkẹrẹ oun lágbo ere lo n jẹ orúkọ náà, sùgbọ́n ko nífẹ si orúkọ náà o si maa n bá àwọn èni[yàn ja nítori rẹ.
Peter Fatomilola ní àìsí ẹ̀kọ́ ń mú káwọn òṣèré tíátà ó máá ṣe oun tí kò tọ́.
"Lẹ́yin o rẹyin, ti mo ri pé ọmọ náà ko nifẹ si orukọ ""Obesere"" ni mo ba fi kọrin pe ẹmi ni mo n jẹ bẹẹ, botilẹ̀ jẹ́ pé mo tun fi igba kan gbé orukọ náà jù sílẹ̀ nígba ti o mú awuyewuye dáni pé àwọn obinrin ni mo n fi orin náà bu"""
Ẹ̀yin o rẹyin, gbogbo aye gba orúkọ náà ti o si di ilú mọọka ti gbogbo ènìyàn n pariwo lónìí.
Lori ipo ti Naijira de dúro lonìí, Obesere sàlayhe pe botill jẹ pe ìjọba o ṣe nkan ti ilú n fẹ, o ṣe pataki láti maa fi adura ran wọ́n lọ́wọ́.
O ní ti gbogbo ènìyàn ba le gbáradì láti gbadura ati ààwẹ fun orilẹ̀-èdè yìí, Ọlọrun yóò boju wolẹ̀ láti Ọrun yóò si gbọ ẹbẹ̀ àdura ti yoò mu ki ilú rojú ki o ráye, ti gbogbo nkan yóò si maa lọ dede.
Abasido fi kún pé, gẹ́gẹ́ bi ọlọdan ni o ṣe pataki láti nawọ ìrànwọ si ijọba náà lori àwọn nàkan kan , nítori ijọba nikan ko le dá gbogbo rẹ ṣe.
O ni lai si ìrànlọ́wọ́ ará ilú, ijọba Naijiria ko le ri ilú tò, iranwọ ara ilú ni àwọn oyinbo fi n rọ́wọ́ mú, tori pe to ba jẹ ti ẹsẹ ni, àwọn oyinbo n dẹsẹ ju Naijiria lọ.
O ní ọ̀pọ̀ àwọn oṣere kéèké aye ode oni ni oun ti ba kọ́wọ́ pọ la'ti ṣe àwo orin jáde àti pe àànu ọlọrun ni oun ri gba ti o si fi jẹ ẹni ti aye n fẹ titi di àsìkò yìí láti igbà ti oun ti bẹrẹ orin.
Coronavirus in Nigeria: Àwọn awakọ̀èrò, ọlọ́kadà arìnrìnàjò faragbá nínú ìpa Coronavirus
Oríṣun àwòrán, Ekiti state government
Gẹgẹ bii ara igbesẹ lati dena arun Coronavirus ni ipinlẹ Ekiti, ijsba ipinlẹ naa ti ti gbogbo ileewe to wa nibẹ pa.
Ninu iwe aṣẹ mawobẹ (Executive order) kan to fi sita ni ọjọ Ẹti, gomina Kayọde Fayẹmi ni gbogbo ipesjọpọ to ba ti n ni ọpọ ero to ju ogun eeyan lọ, yala ni ile ijọsin, ile igbafẹ, awujọ oṣelu, ile ijo ati ile ọti ko gbọdọ waye mọ titi di igba ti nnkan ba fi rọgbọ lori arun naa.
Ninu ọrọ to ba awọn eeyan ipinlẹ naa sọ lori ẹrọ maohunmaworan lori iṣẹlẹ arun naa eyi to ti mu eeyan kan bayii ni ipinlẹ ọhun, gomina Kayọde Fayẹmi fi ọkan awọn eeyan ipinlẹ Ekiti balẹ pe wọn ti kapa arun naa nipinlẹ ọhun ṣugbọn sibẹ oju lalakan fii ṣọri.
Oríṣun àwòrán, Ekiti state government
Bakan naa lo paṣẹ pe awọn onimọto nibẹ ko gbọdọ gbe ju eeyan kan ni iwaju ati ero mẹta-mẹta ni ila aga kọọkan ninu ọkọ wọn.
Awọn aṣẹ miran ti ijọba ipinlẹ Ekiti pa lori kikapa arun yii niwọnyii:
Orilẹede Eritrea ti fi lede wi pe awọn ti ni ẹni akọkọ to ni Coronavirus lorilẹede naa.
Ẹni ọdun mọ̀kandinlogoji ni ara ilẹ Eritrean to n gbe ni Norway.
Ọjọ Satide ni arakunrin naa de papkọ ilẹ wọ ni Asmara International Airport, ti wọn si ya a sọtọ fun ayẹwo to fihan pe arakunrin naa ti ni arun Coronavirus.
Bakan naa ni orilẹede Uganda ti paṣẹ ki ọkọ ofurufu kankan maṣe wọle si orilẹede naa lati dẹkun itankalẹ arun naa.
Oríṣun àwòrán, AFP
Gomina ipinlẹ Ekiti, Kayọde Fayẹmi ni gbogbo igbesẹ ni ijọba ipinlẹ naa n gbe lati rii pe ọṣẹ arun Coronavirus nipinlẹ naa mọ leeyan kan to wa lọwọlọwọ.
Amọ orilẹede Democratic Republic of Congo, Gabon, SUDAN ati Burkina Faso ti darapọ awọn orilẹede ni ilẹ Afirika ti awọn to lugbadi arun Coronavirus ti gbẹ ẹmi mi.
Iwe iroyin ilẹ naa fi lede wi pe dokita to n ṣiṣẹ ni ileeṣẹ ijba ni ẹni to ku naa lẹyin to pada si orilẹede DRC lati ilẹ Faranse.
Ọjọ Eti lo gbe ẹmi mi lẹyin aisan ọna ọfun rẹ ko ṣiṣẹ daradara mọ.
Coronavirus in Nigeria: Èèyàn méje l'Eko, mẹ́ta l'Abuja kó àrùn Coronavirus
Ìròyìn tó ń tẹ̀ wa lọ́wọ́lọ́wọ́ ní wí pé Eeyan mẹwaa miran ni wọn tun ti ṣawari bayii pe wọn ni aarun Coronavirus.
Gẹgẹ bi iroyin kan ti minisita fun eto ilera lorilẹede Naijiria Dokita Osagie Ehanire ṣe fi sita loju opo twitter rẹ lọjọ Abamẹta.
Eyi ti mu iye awọn to ni arun yii lorilẹede Naijiria bayii di mejilelogun.
Ninu atẹjade naa, Minisita feto ilera ṣalaye pe mẹsan ninu awọn eeyan mẹwaa tuntun to ni arun naa lo jẹ ọmọ Naijiria ti wọn ṣẹṣẹ de lati orilẹede Canada, France, Netherlands, Spain ati ilẹ Gẹẹsi.
Eeyan kan yooku jẹ ẹni to ti ni ajọṣepọ pẹlu ọkan lara awọn eeyan to ti ni arun naa.
Awọn meje ninu awọn mẹwaa ti wọn ṣẹṣẹ ṣawari naa ni wọn wa lati ilu Eko, mẹta lati ilu Abuja.
O fi kun un pe gbogbo awọn eeyan naa ni wọn n gba itọju to peye lọwọ bayii.
Ni bayii mẹrindinlogun ninu awọn mejilelogun to ti ni arun yii lorilẹede Naijiria ni wọn wa lati ipinlẹ Eko, mẹta lati olu ilu Naijiria, Abuja, meji lati ipinlẹ Ogun, Ẹyọkan lati ipinlẹ Ekiti.
Coronavirus: Àwọn ìlana to tọ̀nà lati tọ ti o ba fún pe o ni ààrun
Dokita Ehanire jẹ ko di mimọ pe, awọn to wa lolu ilu orilẹede Naijiria, iyẹn Abuja ninu awọn eeyan naa ti n gba itọju nileewosan nla fasiti ilu Abuja ni Gwagwalada nigba ti awọn to wa nilu Eko n gba itọju nileewosan fun itọju awọn to ba ni ajakalẹ arun.
Ajọ to n mojuto ajakalẹ arun lorilẹede Naijiria, NCDC ninu atẹjade toun fi sita loju opo twitter tirẹ ṣalaye pe awọn ami aisan naa to farahan lara awọdn eeyan ọhun ṣi mọ niwọnba, wọn si n gba itọju bi o ti tọ ati bo ti yẹ.
Ijọba Eko ti ko ọlọpaa sita lati ri wi pe awọn eniyan ko rin irin gberegbere lasiko arun Coronavirus yii.
Loju opo Twitter ipinlẹ Eko ni wọn ti fi lede pe ki awọn eniyan yago fun ara wọn ni ila mita kọọkan nitori naa ki awọn eniyan yẹra fun ibi ti eniyan to pọ ba wa.
Oríṣun àwòrán, Wikipedia
Minisita Feto ilera lo fi iroyin yii sita ṣalaye pe awọn eeyan naa ṣẹṣẹ de lati awọn orilẹede bii Canada, France ati ilẹ Gẹẹsi ni.
Ijọba Eko ni awọn ọlọpaa ipinlẹ Eko naa yoo ma fi panpẹ mu ẹnikẹni ti wọn ba ri ni ile igbafẹ, ibi ayẹyẹ tabi ibikibi ti ẹro pọsi lati ri wi pe arun coronavirus naa dẹkun.
Bakan naa ni wọn kilọ fun awọn eniyan lati ri pe wọn ko ju ogun eniyan lọ ni ibi ti wọn ba wa, ki eniyan ma pọju bo ṣẹ yẹ lọ ni ibikan.
Wọn rọ awọn eniyan ti wọn ba ni ikọ tabi inira lati mi, ki wọn lọ si ile iwosan fun iwosan to peye.
Awọn nọmba pajawiri ti ẹ le pe ni 08000CORONA, 08023169485,08033565529 tabi 08052817243.
International flights resumption: Bàálù ilẹ̀ òkèèrè bà l'Abuja léyìn ìṣéde oṣù márùn ún coronavirus
Oríṣun àwòrán, others
Lẹyin ti irin ajo ọkọ ofurufu silẹ okeere gberasọ pada ni Naijiria, baalu Ethiopia Airline lo kọkọ ba silu Abuja lati Addis Ababa, Ethiopia.
Oṣu marun un gbako ni ko fi si lilọ bibọ ọkọ ofurufu lati ilẹ okeere sí Naijiria ati lati Naijiria sí oke okun nitori iṣede coronavirus.
Ni deedee aago kan aabọ kọja iṣẹju marun un ni baalu naa ba l'Abuja lọjọ Aje.
Oríṣun àwòrán, others
Aago mejila ọsan ló yẹ ki baalu naa ba ni Abuja tẹlẹ, amọ awọn ero kan ti ko tete sanwo fun ayẹwo coronavirus ti wọn ba ti de Naijiria lo da a duro.
Ẹgbẹrun un mejilelogoji ati aabọ naira(N42,500) lawọn ẹro gbọdọ san gẹgẹ bi owo ayẹwo fun covid-19 ti wọn ba de Naijiria eleyi ti ọpọ wọn koro oju sí.
Akomolede ati Aṣa lori BBC: Mọ̀ si nípa oríṣìí ẹ̀ka ìsọ̀rí ọ̀rọ̀ àti ìwúlò wọn
Ọkunrin kan to de lati UK,  Joe Ogwu bu ẹnu atẹ lu sisan owo naa.
Ọgbẹni Ogwu sọ pe ọfẹ ní ìjọba UK n ṣe iru ayẹwo bẹẹ fawọn arinrinajo.
O ni ohun to buru julọ ni pe ko si ohun kan lati fi ṣe afihan pe awọn ero ti san N42,500 fun ayẹwo naa.
Ẹwẹ, ọga agba ileeṣẹ ọkọ ofurufu ni Naijiria (FAAN), Rabiu Yadudu sọ pe lilọ bibọ baalu silẹ okeere to gberasọ pada ni Naijiria tẹ oun lọrun.
Wo àwọn orilẹ́èdè àgbáyé tó ti sí pápákọ̀ òfurufú wọn fún ìrìnàjò
Àwọn orílẹ̀èdè to le wọ bàálù lọ lókè òkun
Ọpọlọpọ awọn eniyan lo ti n beere igba ti Naijiria yoo si papakọ ofurufu fun irinajo lati orilẹede Naijiria lọ si oke okun.
Amọ ọjọ Kẹjọ, oṣu Keje, ọdun 2020 ni wọn si papakọ ofurufu ti ilu Abuja ati Eko fun irinajo labẹle.
Awọn arinrinajo ni anfaani lati lo papakọ ofurufu naa, lẹyin to ti wa ni titi pa fun oṣu mẹta lati dẹkun itankalẹ arun Coronavirus.
Nipa ti irinajo si okeere, adari ajọ irinna ofurufu ni Naijiria, Sam Adurogboye salaye pe, awọn si n duro de abọ awọn eleto ilera ati ajọ amuṣẹya, ti aarẹ Buhari gbekalẹ, lati koju arun Coronavirus.
Adurogboye fikun pe, awọn ko tii da ọjọ ti wọn yoo si papakọ ofurufu naa, nitori ọpọlọpọ nnkan lo rọ mọ igbesẹ naa.
Adari ajọ irinna ofurufu ni Naijiria, Sam Adurogboye fikun pe, awọn orilẹede miran to si papakọ wọn, lai tẹle ofin to n dẹkun itankalẹ arun Coronavirus, sakiyesi pe arun naa n peleke si.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ọjọ Kini, Oṣu Keje ni wọn ṣi papakọ wọn fun awọn arinrinajo lati orilẹede marundinlogun, eleyii ti Canada, Morocco ati Australia wa lara wọn,
Amọ wọn ko fun orilẹede Naijiria, Amerika, Brazil ati Russia laaye lati wọle sọdọ wọn.
Orilẹede Greece naa si papakọ ofurufu rẹ fun awọn arinrinajo, amọ wọn ko fun orilẹede Amerika, Brazil ati Russia ni anfaani lati wọ ibẹ nitori arun Coronavirus.
Orilẹede mejeeji ṣi ibode wọn lẹyin ọpọlọpọ oṣu nitori arun Coronavirus.
Jamaica ati awọn orilẹede to wa ni agbegbe Caribbean:
Awọn orilẹede bii Antigua, Saint Lucia ati agbegbe U.S. Virgin Island si papakọ ofurufu wọn ni Oṣu Kẹfa.
Egypt to ṣi ni ibẹrẹ Oṣu Keje sọ pe awọn eniyan gbọdọ ni iwe eto ilẹra ti wọn yoo fihan awọn oṣiṣẹ ajọ aṣọbọde ni papakọ ofurufu.
Minisita fun eto igbafẹ lorilẹede naa sọ wi pe, awọn yoo ṣi gbogbo ile iṣẹ eto igbafẹ lorilẹede naa lati Oṣu Keje, amọ awọn arinrinajo lati Germany nikan lo le wọle.
Dubai (UAE) n reti ẹni to ba fẹ wọle si orilẹede wọn lati Ọjọ Keje, Oṣu Keje, lati ri pe wọn mu iwe to fihan pe, wọn ko ni arun Coronavirus dani wa.
Dominican Republic fi lede pe awọn arinrinajo gbọdọ ni kaadi eto ilera ti wọn yoo fihan awọn ẹsọ aṣọbode bi wọn ba ṣe n wọ orilẹede wọn lati Ọjọ Keji, Oṣu Keje.
Haiti ni ti wọn sọ wi pe, awọn arinrinajo naa gbọdọ ni iwe ilera lati wọ orilẹede wọn, eleyii ti wọn yoo fihan awọn ẹṣọ aṣọbode lati Ọgbọnjọ, Oṣu Kẹfa.
Nitori naa ti Naijiria ba fẹ si ibode wọn, wọn gbọdọ ri pe gbogbo eto wa nilẹ lati dẹkun itankalẹ arun Coronavirus.
Nibayii ti awọn papakọ ofurufu ilu Eko ati Abuja ti bẹrẹ si ni gbe ero pada, o tọ ki a fi diẹ lara awọn ilana to de irina lawọn papakọ ofurufu yii to ara wa leti.
Ilana ti a n sọ wọn yi nii se pẹlu bi awọn arinrinajo yoo ti se ma se nibẹ, ṣaaju ki wọn to wọ inu baalu ati nigba ti wọn ba ti wọ inu rẹ.
O kere tan o ni lati de papakọ ofurufu ni wakati mẹta ṣaaju ki baalu rẹ to gbera
O ni lati tẹle ilana ijinasiraẹni nipa diduro lori awọn aaye ti wan ti ṣe ami si ti awọn oṣiṣẹ ilera yoo si yẹ bi ara rẹ ti ṣe gbona si
Ti ara rẹ ko ba gbona pupọ, wọn ma ni ki o tẹsiwaju lati lo ọṣẹ ifọwọ lẹyin ti wa lọ gba iyọnda lati wọ baalu
Ti ara rẹ ba gbona ju bo ti ṣe yẹ lọ, wọn ma da ẹ pada tabi ki wọn fi ọkọ agbe alaarẹ gbe ọ kuro ni kiakia
Oríṣun àwòrán, FAAN
Ri wi pe awọn aaye ti wọn ṣami si ni o duro si
Bi o ba ti wọ inu ọkọ ti yoo gbe yin lọ sinu baalu, joko sọtọ si awọn ti ẹ ba jijọ wọ ọkọ
Ki ẹ to wọ inu baalu,ri wi pe o jina si ẹni to wa ni iwaju rẹ
Ri wi pe ẹni to fẹ wọ baalu ṣaaju rẹ wọle tan ki o to wọle
Ninu baalu wọn ko ni fun yin lounjẹ kankan bi tatẹyinwa
Ri wi pe o fi aaye ijoko to wa laarin kalẹ laarin iwọ ati ẹlomiiran
Wọn yoo fi omi kalẹ si aye ijoko to wa niwaju rẹ ki o ba le muu fun ara rẹ
O gbọdọ wọ ibomu lopin igba to ba wa ninu baalu
Ti baalu ba ti balẹ,ri wi pe o dide lati gbe ẹru rẹ lẹyin ti ẹni to wa niwaju rẹ ba ti gbe ẹru rẹ sọkalẹ
Aaye ibi ti wọn ṣe ami si ni ko gba lati lọ gba ẹru rẹ
Duro si oju ibi ti wọn ṣe ami si lati gbe ẹru rẹ
Ti o ba ti gbe baagi rẹ tan, to sẹyin awọn to wa niwaju rẹ ki awọn oṣiṣẹ ileeṣẹ ọkọ ofurufu baa le ṣe ayẹwo ẹru rẹ boya iwọ lo ni lootọ.
Oni ọjọ kẹjọ, oṣu Keje, ni irinajo oju ofurufu labẹle yoo bẹrẹ pada ni Naijiria.
Awọn papakọ ofurufu bi i ti ilu Eko, ati Abuja ni yoo kọkọ bẹrẹ iṣẹ, ko to o kan awọn ilu yooku.
Ṣugbọn ṣa, abẹwo ti BBC ṣe si papakọ ofurufu ni owurọ kutukutu ọjọ kẹjọ, oṣu Keje, fihan pe, nkan ko lọ leto-leto.
Oríṣun àwòrán, Others
A o gbé pápákọ̀ ofurufu Eko ati Abuja ti laipẹ- Hadi Sirika
Ṣaaju ki awọn papakọ ọkọ ofurufu o to o di ṣiṣi pada, ajọ  to n ṣe amojuto awọn papakọ ni Naijiria, FAAN, kede pe, ki awọn arinrinajo ti pe si papakọ, o kere tan, wakati mẹta ṣaaju akoko ti baalu wọn yoo gbera.
Eyi tumọ si pe, ẹni ti yoo ba rinrinajo laago meje owurọ, ti gbọdọ de si papakọ laago mẹrin idaji.
Aago meje owurọ lo yẹ ki baalu akọkọ o gbera lati ilu Eko si Abuja, ṣugbọn, akọroyin BBC ri i pe, wọn ko ti ẹ ti i ṣe ilẹkun papakọ laago maarun owurọ.
Eyi si tumọ si pe, oju titi to wọ inu papakọ ni awọn arinrinajo duro si. Koda, ko yọ awọn ọkọ silẹ.
Awọn arinrinajo to ba akọroyin BBC Yoruba sọrọ sọ pe, dide si papakọ ọkọ ofurufu ni wakati mẹta ṣaaju irinajo, ko rọrun.
Ọjọ kẹtalelogun, oṣu Kẹta nijọba ti awọn papakọ ọkọ ofurufu ni Naijiria, nitori itankalẹ aarun Covid-19.
Ina ti jo dori koko bayii lori ọrọ ajakalẹ arun coronavirus lorilẹede Naijiria, ajọ to n ri si igbokegbodo ọkọ ofurufu, NCAA ti kede pe papakọ ofurufu ilu Eko ati Abuja yoo di titi pa lọna ọjọ Aje, ọjọ kẹtalelogun oṣu kẹta yii.
Oṣu kan gbakako lawọn papakọ ofurufu mejeeji naa yoo fi wa ni titi pa.
Mínísita fun ọ̀rọ̀ irinajo ofurufu Hadi Sirika, ti kọkọ sọrọ naa tẹlẹ pe ìjọba yóò gbé papakọ ofurufu mejeeji pa.
Ajọ NACAA ni igbesẹ yii jẹ ọkan lara ọna lati dekun itankalẹ arun coronavirus lorilẹede Naijiria.
Amọ ajọ naa sọ pe iṣẹlẹ pajawiri tabi iṣẹ pataki nikan lo le mu ki baalu fo tabi ba lawọn papakọ ofurufu naa.
Lasiko to n ba awọn akọròyìn, ilé ijọba sọ̀rọ̀, lẹ́yìn ìpàdé pẹlú ààrẹ Buhari, Sirika ni, àwọn yóò dẹkun itankalẹ ajakalẹ ààrun Coronavirus.
Oríṣun àwòrán, Other
Sirika jẹ ọkan lara ọmo igbimọ amúṣẹsẹ lori COVID-19 nigba ti Boss Mustapha to jẹ akọwé ijoba apapọ jẹ́ alaga wọ́n.
O ti di eeyan mejilelogun bayii to ti lugbadi arun coronavirus ni Naijiria, amọ ọmọ ilẹ Italy to kọkọ ko arun naa wọ Naijiria ti gbadun bayii, o si ti kuru ni ile iwosan.
Ẹ̀wẹ̀ ìjọba ti fi orilẹ̀-èdè Sweden àti Austgria si àra àwọn orilẹ̀-èdè ti wọ́n ti fi ofin de láti ma wọ Naijiria mọ.
Ní bayìí, orilẹ̀-èdè mẹẹdogun ni wọ́n ti fi ofin de láti ma wọ Naijira mọ
Coronavirus symptoms: Ó ti di Ọgbọ̀n èeyàn báyìí tó ti ní àrùn Coronavirus ní Nàìjíríà
Oríṣun àwòrán, Others
Ẹlòmíràn tún ti lùgbàdì àrùn Corona Virus nílùú Abuja àti Eko
Ìròyìn tó ń tẹ̀ wa lọ́wọ́lọ́wọ́ ní wí pé Ajọ to n gbogun ti ajakalẹ arun lorilẹede Naijiria, NCDC tun ti kede pé ènìyàn mẹta miran tun ti ko arun coronavirus niluu Eko
O ti di eeyan ọgbọn bayii to ti lugbadi arun naa lorilẹede Naijiria.
Ajọ NCDC ṣalaye pe eeyan meji ninu wọn lo ti kuro ni ile iwosan lẹyin ti wọn gba itọju tan.
O ti di eeyan mẹrin to ti lugbadi arun coronavirus bayii, nigba ti ipinlẹ Eko ko mọkandinlogun ninu rẹ, eeyan meji lo karun naa nipinlẹ Ogun, eeyan kọọkan larun naa nipinlẹ Oyo ati Ekiti.
Àrùn coronavirus wọ ìpínlẹ̀ Oyo
Ajọ NCDC ti kede tẹlẹ pe eeyan miran to ni aarun coronavirus lorilẹede Naijiria.
Gẹgẹ bi atẹjade kan ti ajọ naa fi soju opo twitter rẹ lowurọ ọjọ Aiku, eeyan kan naa sọ iye awọn ti wọn kede pe wọn ni arun naa ni ọjọ Aiku nikan di mẹrun bayii.
Oríṣun àwòrán, Seyi makinde
Eeyan mẹta miran tun ti ko arun Coronavirus lorilẹede Naijiria bayii.
Ajọ to n gbogunti ajakalẹ arun lorilẹede Naijiria, NCDC ṣalaye pe o ti di eeyan marundinlọgbọn to ti ni arun naa bayii.
Iroyin naa fi idi rẹ mulẹ pe ipinlẹ Eko ni awọn mẹta tuntun ti wọn ṣẹṣẹ ṣawari naa ti wa.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Bakan naa ni wọn tun fi kun un pe, awọn mẹtẹẹta lo ti rinrinajo lọ sawọn orilẹede ti arun yii ti wọpọ lagbaye laarin ọjọ meje sẹyin.
Ajọ to n gbogun ti ajakalẹ aarun lorilẹede Naijiria, NCDC ko ṣai fi da awọn eeyan loju pe akitiyan n lọ bayii lati ṣawari gbogbo awọn eeyan ti wsn ti ni ajọṣepọ pẹlu awọn eeyan mẹta yii.
Ajọ naa wa n rọ awọn ọmọ Naijiria to rinrinajo pada wa sorilẹede Naijiria laarin ọjọ mẹrinla sẹyin si asiko yii lati fi ara wọn sabẹ igbele fun ọjọ mẹrinla lati mọ boya wọn ni arun naa tabi ara wọn da ṣaka.
Coronavirus: Pásítọ̀ Adeboye ní òun faramọ́ ìmọ́tótó, ṣùgbọ́n àwàdà ni ìgbésẹ̀ àwọn ìjọba lágbáyé láti kojú Coronavirus
Oríṣun àwòrán, PAstor enoch adeboye
Pasitọ Enoch Adejare, oluṣọagutan agbafun ijọ Redeemed Christian Church of God , RCCG lagbaye ti sọ wi pe awọn igbesẹ ti ijọba n gbe lati wawọ arun Coronavirus bọlẹ lagbaye ati paapaa julọ lorilẹede Naijiria jẹ eyi to n pani lẹrin pupọpupọ.
Oluṣọaguntan Adeboye to ṣalaye ninu iwaasu rẹ to ṣe fun awọn ọmọ ijọ naa lagbaye lori ẹrọ ayelujara ati mohunmaworan ṣalaye pe oun ti paṣẹ fun gbogbo ẹka ijs naa lati tẹle aṣẹ ijsba lori pe ko gbọdọ si ipejọpọ ero to ba ju aadọta lọ kaakiri.
Amọṣa o ni nigba ti oun wo awọn igbesẹ ti ijsba gbe kalẹ bii pe ki awọn eeyan to ba ju aadọta lọ o maa korajọ pọ si oju kan naa fun ohunkohun, ẹrin fẹ maa pa oun bi o tilẹ jẹ wi pe ajalu ni nnkan to n ṣẹlẹ.
Baba Adeboye, gẹgẹ bi ọpọ eeyan lagbaye ṣe maa n pee ni ki ni ka ti pe tawọn ibudokọ gbogbo, ati awọn ọja nibi ti ero n pọ si.
Bakan naa lo ni ọgba ileewe wa lara awọn ibudo to dara lati wa julọ lasiko ajakalẹ arun bayii ṣugbọn ijọba ninu ọgbsn wọn le awọn akẹkọ kuro niblẹ wa sile nibi ti arun yi ti n gbilẹ.
Iranṣẹ Ọlọrun naa ni gbogbo eyi lo n mu ki ẹrin o maa pa eniyan lori igbesẹ awọn ijsba gbogbo.
Làá hàn mí: Ètò yìí ló ń kìlọ̀ fún wa láti mú ìmọ́tótó ní pàtàkì láti dènà Coronavirus
Fun apẹrẹ wọn ni ki a maa jinna si ara wa nitori kokoro arun yii, ṣugbọn nibi ti wọn ti n sọ ọ gan ni mo ti n ri awọn minisita ti wọn n joko sun mọ ara wọn pẹkipẹki.
O wa beere pe ki ni ijọba yoo ṣe si awọn ibudo bii ọgba ẹwọn? ṣe wọn yoo ni ki wọn maa lọ si ile bii ti awọn orilẹede kan nii?
O fi kun pe gbogbo agbaye ni yoo gba isinmi lẹnu iṣẹ nitori arun coronavirus yii, nitori naa ki gbogbo awọn smọ ijọ naa o maa gbadun isinmui lẹnu iṣẹ ti Ọlọrun fun wọn.
Coronavirus: Àwọn ìlana to tọ̀nà lati tọ ti o ba fún pe o ni ààrun
Ẹwẹ o ṣalaye pe, bi iku ti arun Coronavirus ti mu wa yii ṣe pọ to ti o si bani ninu jẹ, sibẹ ko to iye ẹmi ti aisan iba ati ijamba mọto ti mu lọ laarin oṣu mẹta akọkọ ninu ọdun 2020.
O ni ohun to jẹ ki orukọ arun coronavirus o gbode kan ni pe, 'aisan alariwo'ni.
O ni arun coronavirus ko lee parẹ mọ laye, o kan lee wawọ lọ silẹ bi awọn aṣiwaju rẹ bii Ebola ni ati pe ẹrin gbaa lawọn wolii kan to n sọ pe ọjọ bayii ni arun naa yoo parẹ n pa oun.
Fuel Price Hike: Onímọ̀ ní oṣooṣù ni owó lítà epò kan yóò máa yàtọ̀, ó le léwó tàbí dínwó
Oríṣun àwòrán, The guradian nigeria
Ẹgbẹ oṣiṣẹ lorilẹede Naijiria ti ni yẹkini kan ko lee yẹ iwọde apapọ jakejado orilẹede Naijiria ti yoo waye lọjọ kẹtalelogun oṣu kẹsan an.
Ẹgbẹ oṣiṣẹ n pe fun iwọde gbankọgbi kaakiri orilẹede Naijiria lati tako igbesẹ ti ijọba gbe laipẹ yii lati fi owo kun owo epo bẹntiro ati ina mọnamọna.
Ninu ọrọ to ba BBC sọ, akọwe agba ẹgbẹ awọn oṣiṣẹ TUC lorilẹede Naijiria, Comrade Musa Lawal ṣalaye pe ijọba apapọ labẹ iṣejọba Muhammadu Buhari ko ṣe bi ẹni to mọ pe ara n ro araalu rara paapaa pẹlu atunbọtan ajakalẹ arun COVID-19 to da ọrọ aje ọpọlọpọ eeyan ati orilẹede ru, ninu eyi ti ọpọ di alainiṣẹ lọwọ.
Ẹgbẹ TUC ni ọna abayọ meji pere ni awọn fun ijọba apapọ ki alaafia to lee jọba. Awọn ọna abayọ naa si ni akọkọ, ki wọn da owo epo pada si iye to wa tẹlẹ, iyẹn naira marundinlaadọjọ N145 lori jala kan; ikeji ki wọn si da owo ina pada si iye to wa tẹlẹ.
Ọmọ méjì ò sọnù nínú àgbàrá òjò o! Ọ̀tọ̀ lọ̀rọ̀ táa ń pè yín sí - Aráa Ketu
Ẹgbẹ naa ni eyi fihan pe bi ijọba ba ti kuna lati ṣe ohun meji yii, ko si ijiroro kankan to lee waye nitori pe o yẹ ki ijọba fi ọrọ naa lọ araalu ki wọn to da iru aṣọ bẹẹ ṣoro.
O fi kun un pe o yẹ ki ijọba o ronu pe ajakalẹ arun COVID-19 ṣe ọpọẹọpọ ijamba fun awọn ọmọ Naijiria, bẹẹni gbogbo awọn ohun itura ti ijọba ṣeleri rẹ , ni araalu o ri, bi o tilẹ jẹ pe ijọba n pariwo pe awọn na ẹgbẹlẹgbẹ owo lori rẹ.
Amofin Lawal ṣalaye pe bi ijọba ba wa kuna lori awọn agbekalẹ rẹ wọnyii ko si ohun to n di awọn lọwọ iwọde awọn niyẹn.
Oríṣun àwòrán, Others
Ijọba orilẹede Naijiria ti ni awọn ti jawọ ninu dida Iye le owo ti awọn elepo yoo ma ta epo bẹntirol lorilẹede Niajiria.
Nibayii, awọn to n ta epo bẹntirol ni yoo ma sọ iye ti wọn ba fẹ ta epo bẹntirol naa loore-koore.
O ti le ni oṣu mẹta bayii ti ijọba ti bẹrẹ si ni yọ ọwọ kuro lori iye ti awọn elepo n ta epo ni Naijiria, ti wọn ko si fi kede iye ti wọn yoo ta epo ni Osu Kẹjọ ati Oṣu Kẹsan an, ọdun 2020.
Adari ileeṣẹ Petroleum Products Pricing Regulatory Agency, PPPRA,  Abdulkadir Saidu ni lati igba yii lọ, bi awọn eniyan ṣe n ta epo sii ati iye ti wọn ta epo rọbi lagbaye, ni yoo ma sọ iye ti awọn elepo yoo ma ta lita epo.
Amọ, o ni ijọba orilẹede Naijiria yoo ri wi pe iye ti wọn ta a, ko kọja agbara awọn ti yoo ra a.
"''Owo bentirol yoo lọ soke si lasiko ti ijọba ni ki awọn elepo maa diye le owo epo."""
Onimọ nipa eto ọrọ aje, Temitọpẹ Kolawole ti salaye ohun ti igbesẹ ijọba tunmọ si fun awọn ọmọ Naijiria.
Kolawọle ni iye ti wọn ba ra a ni yoo ma a sọ iye ti wọn yoo ma a ta, nitori naa iye owo epo bẹntirlo yoo lọ soke si.
Amọ, bi igba ba ṣe n lọ, owo epo yoo walẹ si, ti iye ti wọn yoo ma ta a yio si yatọ si ara wọn bi igba ba ṣe n lọ.
Mayowa Omoniyi: Kò sí orin Obey, Sunny Ade abí tàkasúfèé tí ń kò le ta gìtá sí
O fikun wi pe yiyọ ti ijọba yọ owo iranwọ epo naa, yoo mu ibugbooro ba ọrọ aje ni Naijiria.
'' Íye owo bẹntirol le goke to N250 si N300 lati igba yii lọ''
"‘Apẹẹrẹ ni Sim Card ti a n ra bayii ni ọgọrun naira, amọ nigba ti o kọkọ jade, ẹgbẹrun lọna ọgbọn naira ni wọn n ta."""
Nitori naa, onimọ nipa eto ọrọ aje ni Naijiria, Temitope Kọlawole wa rọ awọn ọmọ Naijiria, lati bẹrẹ si ni ṣe ipesẹ ounjẹ wọn labẹle nitori ọwọngogo ti yoo gori awọn eroja ounjẹ lasiko yii.
Baby abandoned on dunmpsite: Mo ti bímọ mẹ́rin tẹ́lẹ̀ fún bàbá méjì nínú òṣí- Dupe Ogbomos
Kolawole fikun wi pe, asiko ti ijọba gbe igbesẹ naa ni ko rọrun fun awọn ọmọ Naijiria, nitori ọrọ aje to dẹnukọlẹ ati arun Coronavirus to n ba gbogbo agbaye finra.
Ijọba apapọ lorilẹede Naijiria ti sọ wi pe naira mejilelọgọjọ ti wọn n ta lita epo pẹtiro kan lo kere julọ ni ilẹ Afrika.
Minisita fun eto iroyin ati asa, Lai Mohammed lo sọ bẹẹ lasiko to n ba awọn akọroyin sọrọ nilu Abuja.
Lai Mohammed ni, bi o tilẹ jẹpe awọn yọ owo iranwọ to wa lori epo, iye ti awọn n ta lo kere julọ ni iwọ oorun ilẹ Afrika.
Oríṣun àwòrán, Others
O fi iye owo ti wọn n ta a ni awọn orilẹede yii lede bayii;
Minisita naa fikun wi pe, ti a ba kuro ni ẹkun iwọ oorun Afrika lọ si awọn orilẹede bii Egypt ati Saudi Arabia, oye ti wọn n ta a ni N211 ati N168.
Lai Mohammed ni  iye owo epo yii fihan pe, iye owo ti wọn ta epo bẹntirol ni Naijiria lo ṣi kere ju ni ilẹ Afrika, bi o tilẹ jẹ pe awọn ti yọ owo iranwo kuro lori rẹ.
Mohammed ni Naijiria ko ri owo pa wọle mọ bii ti tẹlẹ, nitori naa awọn ko ni le san owo iranwọ lori epo bẹntirol ati mọnamọna mọ.
Bakan naa lo ni ajọ to n bojuto ọrọ epo bẹntirol ni Naijiria, NNPC gbe jade pe, iye owo to le ni triliọnu mẹwaa naira ni awọn ti na lori owo iranwọ epo lati ọdun 2006 si 2019.
Amọ, inú àwọn èèyàn kò dún rárá lásìkò yii tí Ààrẹ Buhari gbé owó lé owó epo àti iná mọ̀nàmọ́ná nigba kannaa, nitori nnkan nira fun awọn eniyan lasiko arun Coronavirus yii.
Ijọba Aarẹ Buhari ti ni o pọn dandan fun oun lati gbe igbesẹ to gbe nipa fifi owo le owo epo bentirol ati ina mọnamọna.
Ijọba ni eyi ri bẹẹ ki idagbasoke nla lee ba ọrọ aje lorilẹede Naijiria ni.
Oríṣun àwòrán, Others
Atẹjade ti oluranlọwọ pataki feto iroyin fun aarẹ Buhari, Mallam Garba Shehu fi lede lo ti salaye idi ti Aarẹ Buhari fi gbe igbesẹ naa.
Ijọba ni awọn yọ owo iranwọ to wa lori epo bẹntirol ati awọn ẹka miran, lọna ati le lo owo ori ti awọn eniyan ba san lọna to tọ, yatọ si sise afikun owo epo.
Atẹjade naa ni yiyọ ti aarẹ yọ owo iranwọ naa yoo fopin si iwa ibajẹ ati iwa jẹgudujẹra, ti awọn kan n ṣe lori owo iranwọ to wa lori epo bẹntirol, ina mọnamọna ati awọn ohun elo to n mu nkan ọgbin gbooro si.
Temitope Akinnusi: Ọ̀pọ̀ iléeṣẹ́ ló takú láti gbà mí síṣẹ́ torí mo ní ojú kan
ijọba ni oun gbe igbesẹ naa, ki awọn ọlọja yii fun ara wọn gbe owo le awọn ọja yii, lọna ti yoo pe awọn ara ilu.
O fikun wi pe awọn ijọba to ti wa tẹlẹ ti gbiyanju lati ṣe eyi, amọ wọn ko ni igboya lati ri wi pe o wa si imuṣẹ.
Oluranlọwọ pataki fun naa ni awọn eniyan yoo ranti aarẹ Buhari si rere ni ọjọ iwaju.
O ni biotilẹjẹpe o lera fun awọn eniyan lasiko yii, awọn igbesẹ naa pọn dandan lati le mu itẹsiwaju ba orilẹede Naijiria, ati lati le mu ilọsiwaju ba ọrọ aje to dẹnu kọlẹ.
Oríṣun àwòrán, Others
Garba Shehu fikun wi pe, nigba ti ẹgbẹ oṣelu APC gba iṣejọba ni ọdun 2015, awọn ṣeleri ati mu igbe aye rọrun fun awọn eniyan, ọdun marun si igba ti awọn wọle, awọn si n n gbe igbesẹ lati mu ohun gbogbo pada si ipo lorilẹede Naijiria.
Bakan naa ni wọn fi lede wi pe, ijọba Aarẹ Buhari nilo ifọwọsowọpọ awọn araalu, ẹgbẹ oṣiṣẹ lorilẹede Naijiria ati awọn ẹgbẹ oṣelu to ku ni Naijiria lati le mu Niajiria de ilẹ ileri.
Fuel Price Increase: Ìjọba Buhari ń fi ara ní àwọn èèyàn púpọ̀ jù
Awọn eeyan ipinlẹ Ọyọ gbarata lori alekun owo epo bẹntiro
Gbogbo awọn eniyan to n lo epo bẹntiro fun iṣẹ oojọ ati igbokegbodo ọkọ ti gbarata lori aleekun ti ijọba mu ba iye ti wọn n ta jala epo kan jakejado orilẹede yii.
BBC Yoruba rin kaakiri ilu Ibadan olu ilu ipinlẹ Ọyọ lati ṣe amojuto awọn ayipada to rọ mọ alekun naa.
Arabinrin kan ti a ba sọrọ ni agbegbe Orita ṣe alaye wi pe epo ẹgbẹrun kan naira ni oun maa n ra sinu ọkọ tẹlẹri ki ijọba to mu alekun ba owo epo.
O tẹsiwaju pe epo ẹgbẹrun kan naira ko le de ibi kankan mọ ninu ọkọ nibayii ti epo ti gbowo lori.
Arọwa arabinrin yii si ijọba ni pe ki wọn ja owo epo pada wa silẹ nitori pe o ti pọ ju.
"O ni, ""gbogbo nnkan lo wọn tẹlẹ, Owo ti wọn fi kun epo yoo kan jẹ ki nnkan tun wọn si i ni ti ara yoo si maa ni gbogbo ara ilu."""
A tun rinrin ajo de agbegbe Tipper Garrage nilu Ibadan:
Awakọ ero kan ti o ba wa sọrọ nibẹ fi ẹhonu han wi pe awọn adari orilẹede yii ko nifẹ ara ilu bo ti n wu ko mọ.
O ni ti wọn ba ni aanu mẹkunu lọkan ni, wọn ko ni fi kun owo epo rara.
O rawọ ẹbẹ wi pe ki ijọba tun ero rẹ pa.
Àṣìṣe ọlọ́pàá àti Adájọ́ sọ mí di ẹni tí wọ́n dájọ́ ikú fún, ọpẹ́lọpẹ́ Fayoṣe tí ko buwọlu
Kini BBC ba bọ ni agbegbe New Garrage?
Alamojuto ile epo kan ni agbegbe New Garrage ṣe alaye fun ikọ BBC News Yoruba wi pe ara ko rọ okun - ara ko rọ adiye ni ọrọ aleekun to de ba owo epo.
O ni bi awọn ṣe n ta epo ni owọngogo naa n kopa buburu lori eto iṣuna awọn nitori yoo kan ẹbi, ara ati ọrẹ awọn to n ta epo naa.
O tẹsiwaju wi pe epo to wọn ki i ṣe ẹbi awọn onile epo bikoṣe awọn alaṣẹ to n be loke.
Baby abandoned on dunmpsite: Mo ti bímọ mẹ́rin tẹ́lẹ̀ fún bàbá méjì nínú òṣí- Dupe Ogbomos
Awọn to n ta epo bẹntiroo naa tun ba akọroyin BBC sọrọ pe:
Ontaja epo mii to ba wa sọrọ ṣe alaye wi pe ọwọ ijọba ni gbogbo rẹ wa nitori ko si ẹni kan to iredi ti ijọba fi gbe igbesẹ naa.
O ni awọn kan ṣa dede ji ni awọn gbọ iroyin wi pe owo epo ti sun lọ soke pe iye bayii ni epo tun un ba jade.
"O ni, ""boya owo dollar lo gbẹnusoke ni o tabi nnkan. Aarin yẹn ko ye wa."
"Ṣugbọn ẹ mọ pe nnkan ti awa ontaja epo aladani ba ra naa ni a maa ta."""
Ki lo kọkọ ṣẹlẹ?
Wo ohun tó ń fa àfikún epo lóòrèkóòrè ní Nàìjíríà
Èyí ni bí ojú ọjà epo lágbáyé ṣe ń fa àfikún epo lóòrèkóòrè ní Nàìjíríà
Kaakiri oju ayelujara ni iroyin ti gbode pe ijọba ti fi owo kun iye owo jala epo bẹntiroo ni Naijiria lọjọru.
Ijọba apapọ nipasẹ ileeṣẹ epo rọbi lorilẹede Naijiria, NNPC ti kede afikun owo epo lorilẹede Naijiria leyi to gbe owo ori epo bẹntiro soke sii.
Eyi si ti fa ọpọlọpọ awuyewuye laarin awọn ẹgbẹ, ọgba, ileeṣẹ lajọlajọ ati mutumuwa.
Amọṣa ki lo n fa afikun epo loorekoore lẹnu ọjọ mẹta yii na?
Idahun si eyi wa ninu atẹjade kan eleyii ti ileeṣẹ ijọba apapọ to n ri si idiyele owo epo rọbi lorilẹede Naijiria, (PPPRA) tẹ jade ni Ọgbọn ọjọ, oṣu kẹta ọdun 2020
"Ṣugbọn ti o bọ si gbangba iwoju araalu ni ọjọ kẹrin, oṣu karunun, ọdun 2020 yii kan naa eleyii ti wọn pe akọle rẹ ni ""Ofin lilo idunadura oju ọja epo lati fi diyele epo bẹntiro t'ọdun 2020""."
Akọwe agba ajọ naa, Abdulkadir Saidu ṣalayekikun ni pa igbeṣe inu fifi owo sori epo.
O ni  wi pe ajọ oludiyele owo epo lorilẹ-ede Naijiria yoo maa boju wo bi nnkan ṣe n lọ si lọja epo rọbi lagbaye lati lee ma fun ajọ elepo rọbi lorilẹede Naijiria, NNPC atawọn ontaja epo ni amọran loṣooṣu lori ibi ti owo ori epo de duro
Baby abandoned on dunmpsite: Mo ti bímọ mẹ́rin tẹ́lẹ̀ fún bàbá méjì nínú òṣí- Dupe Ogbomos
Pẹlu eleyi, o fihan pe awọn alagbata epo ni anfani bayii lati diye le ori epo bẹntiro ki wọn si lee taa ju iye ti ajọ PPPRA ba gbe kalẹ lọ.
Eyi fihan pe ohun ti awọn oniṣowṣo epo ba ra ni ọja epo agbaye ni wọn yoo fi ṣe odiwọn iye ti wọn yoo taa lọja abẹle fun awọn ọmọ orilẹede Naijiria.
Idi niyi ti owo ori epo fi n wa soke-wasilẹ lẹnu ọjọ mẹta yii nitori segesege to n waye lori owo epo lọja agbaye.
Ijọba apapọ n kede afikun owo epo bẹntiro lẹyin ọjọ kan ti wọn kede ẹkunwo owo ina mọnamọna jakejado orilẹede Naijiria.
Lati jọru ti iroyin afikun yii si ti jade lawọn eeyan lẹkajẹka gbogbo lawujọ si ti n fi ero wọn han lori rẹ.
Ninu ọrọ tirẹ, ẹgbẹ awọn oludaleeṣẹ silẹ lorilẹede Naijiria,, MAN ṣalaye pe igbesẹ naa yoo mu inira ba awọn ileeṣẹ kerejekereje to ṣẹṣẹ n gbimọran ati ri ẹsẹ walẹ.
Ijọba apapọ nipasẹ ileeṣẹ epo rọbi lorilẹ-ede Naijiria, NNPC ti kede afikun owo epo ni Naijiria leyi to gbe owo ori epo bẹntiro soke sii.
Bi ọrọ ṣe n lọ bayii, o ṣeeṣe ko jẹ pe naira mejilelọgọta ni wọn yoo pada naa taa nitori ohun ti alaga awọn agbepo lẹkun iwọ oorun guusu Naijiria, Dele Tajudeen sọ fawọn akọroyin kan ni wi pe iye ti awọn yoo maa ta epo niyen niori pe ijọba pẹlu ti gbe owo sisan ni ibdu igbepo gbogbo ti di naira mọkanlelaadọta, (N151.56).
'Oyenusi ló mú mi wọ ẹgbẹ́ adigunjalè kó tó di pé mo b'Ólúwa pàdé'
Awọn MAN ni ohun to yẹ ki ijọba o ṣe ni lati rii pe ina ọba duro deede lati mu ki awọn eeyan o dẹkun rirọgbọku le epo.
Ninu ọrọ tirẹ, ẹgbẹ awọn oṣiṣẹ lorilẹede Naijiria NLC ṣalaye pe n ṣe ni ijọba n mu awọn ọmọ Naijiria ni suẹgbẹ pẹlu igbesẹ naa.
Igba kẹta ree laarin oṣu mẹta. lana ode yii (Ọjọ Iṣẹgun) ni wọn ṣẹṣẹ bu owo le owo ina mọnamọna o.
NLC ni awọn kọ afikun owo epo yii nitori ara n ni awọn ara ilu
Oríṣun àwòrán, others
Ọ̀pọ̀ ọmọ ẹgbẹ́ wa ló n tẹpo níye tó kéré sí iye ti PPPRA fi síta- IPMAN
Ẹgbẹ alagbata epo aladani lorileede Naijiria IPMAN ti paṣẹ ki awọn ọmọ ẹgbẹ wọn jakejado Naijiria maa ta jala epo kan ni naira mejilelọgọjọ.
Afikun ti wọn kede ọhun yoo wa jẹ lati naira márùndínláàdọ́jọ (N145) lita kan ti o wa tẹlẹ si iye tuntun yi.
Ninu alaye rẹ Alhaji Bashir Dan Malam to jẹ alaga IPMAN ni Kano sọ pe iye yi di dandan ki awọn baa le ri owo tawọn naa yọ lẹyin gbogbo isiro to ba iye owo epo de.
Bẹẹ lo ni igbesẹ ijọba to sọ iye owo epo bẹntiroo di Naira mọkanlelaadọjọ lo mu ki awọn naa fi owo kun.
Igba ẹlẹẹkẹta ree ti ijọba Naijiria yoo fi owo kun owo bẹntiroo lẹnu oṣu meloo sẹyin.
Ẹgbẹ oṣelu Peoples Democratic party ti kesi ijọba Naijiria labẹ Aarẹ Muhammadu Buhari lati da owo jala bẹntiroo ati ina mọnamọna ti wọn lekun pada walẹ ni kiakia.
Akọwe ipolongo ẹgbẹ naa Kola Ologbọndiyan lo fi ọrọ yi sita loju opo Twitter lọjọru.
Ologbondiyan ni o jẹ iyalẹnu pe ijọba APC le gbe iru igbesẹ yi lasiko ti ara n ni awọn ọmọ Naijiria to si kesi ile aṣofin Naijiria lati da si ọrọ naa.
Ẹwẹ, Ayodele Fayose to figba kan jẹ Gomina ipinlẹ Ekirti naa ti bẹnu at lu ẹkunwo owo jala epo ti ijọba Naijiria kede.
O sọ ọrọ yi loju opo Twitter rẹ .O ni ohun ti kilọ fawọn ọmọ Naijiria paapa awọn to kopa ninu iwọde lati tako ijọba PDP nigba ti wọn fi owo kun owo epo bẹntiroo
Oríṣun àwòrán, Others
Awọn ọmọ Naijiria ti n ke irora lori bi iroyin ṣe gbode pe alekun ti ba iye owo ti wọn yoo maa san lati fi ra jala epo bẹntiroo.Àìní sí iná mọ̀nàmọ́ná ní Eko ló ń kọ áwọn èèyàn lóminú
Ti iroyin naa ba jẹ́ ootọ, o kere tan ekunwo epo bẹntiroo lati naira marundinlaadọjọ si naira mọkanlelaadọjọ,₦151.56k, ni awọn ọmọ Naijiria yoo bẹrẹ si ni lo nibẹrẹ oṣu Kẹsan an, ọdun 2020.
Ikede yi ti ọpọ ileeṣẹ iroyin ni Naijiria ti gbe lọjọru jẹ eyi ti BBC ko ti ribi fidi rẹ mulẹ.
Ṣugbọn awọn eeyan Naijiria ko tilẹ jẹ ki iroyin naa balẹ ki wọn to ma lọgun pe ẹkunwo yi yoo mu inira ba ara ilu.
Kini iroyin naa sọ ati pe bawo lo ṣe bẹrẹ?
Iwe tawọn akọroyin n lo lati fi kin ọrọ lẹyin nipa alekun yi ni wọn sọ pe o wa lati ọdọ arakunrin kan ti o n ṣiṣẹ pẹlu PPMC ọgbẹni D.O Abalaka.
Gbogbo igbinyanju BBC lati ba awọn alakoso PPMC sọrọ nipa ikede yi ko ti seso re.
Ni kete ti a ba ri aridaju ọrọ yi fi mulẹ, a o jẹ ki ẹ gbọ.
Oríṣun àwòrán, others
Ọ̀pọ̀ ọmọ ẹgbẹ́ wa ló n tẹpo níye tó kéré sí iye ti PPPRA fi síta- IPMAN
Ijọba ti kede ẹkunwo epo bẹntiro lati ọgọrun un nairia le ni naira mọkanlelogun àbọ̀ (N121.50)  si naira mẹtalelogóje  le ni ọgọrin kọ́bọ̀(N 143.80).
Ajọ PPPRA to n ṣamojuto owo epo rọbi lo ṣe ikede naa ninu atẹjade kan to fi sita lọ́sàn Ọjọrun.
"Àjọ náà ni ""lẹ́yìn àgbéyẹ̀wò kíkún àti nǹkan ti ọjà epo bẹtiróò ń sọ lágbàyé nínú oṣù kẹfa, àwọn ṣe àmójútó ìyé tó to gbé epo jáde tí ẹnikẹni kò sì ni pàdánì owó"""
Nítorí náà, a rọ àwọn ilé epo láti máa ta jálá epò bẹtiróò ní ogóje náìrà sí náírà mẹ́tàlélógóje ó lé ọgọ́rin kọ́bọ̀, fún oṣù keje ọdún 2020.
A rọ gbogbo àwọn ilé epo aládani kí wọ́n ta ọjà wọ́n ni gbèdéke iye ti PPPRA pè é.
Ẹgbẹ́ àwọn aladani tó n ta epo bẹtiró ní Nàìjíríà (IPMAN) ti sàlàyé pé, gbogbo ìlànà ti ìjọba là sílẹ̀ ni àwọ́n ń tẹ̀lé nípa títa epo bẹtiró.
Nínú ọ̀rọ̀ rẹ, ààrẹ ẹgbẹ́ IPMAN ní Nàìjíríà Chinedu Okoronkwo sàlàyé pé, ẹ̀dínwó epo látọ̀dọ̀ ìjọba tí kásẹ̀ nílẹ̀, síbẹ̀ àjọ tó n rí si iye owó ti wọ́n n ta epo lábẹle náà n fi gbédéke iye tí ilé epo aladáni gbọdọ̀ ta epo síta.
Ó ní gbogbo ọmọ ẹgbẹ́ ló ń tẹ̀lé àṣẹ́ ijọba nípa títà á ni ìye ti ijọba sọ, tí àwọn míràn tilẹ̀ ń tà á ni ìye tó tún kéré jù bẹ́ẹ̀ lọ.
Okoronkwo ní ọ̀pọ̀ ló ń fi náírà méjì, mẹ́ta tà á nítorí wọ́n fẹ́ padà lọ ra òmíràn lásìkò, kí wọ́n sì pa owó wọ́n kí wọn sì kó èrè wọ́n jọ.
Nígbà ti BBC Yoruba beere lórí ìdí tí àwọn alagbata míràn fí n ta jálá epo kan ní náírà márùndínláàdójé, nígbà tí ìjọba ni kí wọ́n máa tà á ni náírà mọ́kànlélọ́gọ́fà àbọ̀, Okonkwo sọ pé àsìkò péréte náà ló kù tí irú wọ́n kò fì ni lé ṣe bẹ́ẹ̀ mọ nítorí tí ará ìlú bá rí ibi ti epó ti dínwó, wọ́n kò ni lọ sí ibi ti ó ti wọ́n.
Naira mọ́kàndínlọ́gọ́fà ní àwọn ilé epo míràn ń tà á ní ìpínlẹ̀ Porthacourt, sùgbọ́n láìpẹ́ nǹkan ti olúkúlùkù bá rà, ni wọ́n ó tà, ẹni tó bá sì rà ọjà ọ̀wọ́n, náà ni yóò wá bí yóò ṣe tà á.
Kíní ìtúmọ owó ìrànwọ lórí epo (Fuel Subsidy) tí ìjọba yọ báyìí
Ǹkan tí o túmọ sí náà ni pé, ètò ọ̀rọ̀ ajé Nàìjíríà ṣẹ̀ṣẹ̀ bẹ̀rẹ̀ ní, nítóri àsìkò yìí ní àwọn ojúlówó onísòwò epo yóò ṣẹ̀ṣẹ̀ rí tajé ṣe.
Okonkwo sàlàyé pé, sáájú àsìkò yìí, àwọn ti kò ṣòwò epo máa ń gbà owó ìrànwọ́ ìjọba lọ́nà àìtọ́, sùgbọ́n nísìnyí kò ni sí gbogbo ìyẹn  mọ́.
Fuel Price: Ẹ̀dínwó epo bẹntírò ti NNPC kede kò kan ará ilú
O fí kún-un pé, gbogbo àwọn ibi ti wọ́n tí n fọ epo lórílède Nàìjíríà náà yóò le ṣiṣẹ́, èyí yóò sì mú àdíkù báa ìbéèrè fún níná owó dọla nígbàgbogbo, nítórí pé èyí gàn ló n kóba ètò ọ̀rọ̀ ajé Nàìjíríà.
Ó ní tí eyí bá wáye ǹkan yóò túbọ̀ rọrùn ni Nàìjíríà ní.
Sáájú ni àjọ PPPRA ti sọ pé oṣooṣù ni àwọn yóò maa kéde iyé ti wọ́n yóò ma tepo lábẹ́lé ni Naijiria.
Láti inú oṣù kẹta tí owó epo ti jáwálẹ̀ lágbàyé ni PPPRA ti bẹ̀rẹ̀ ìgbésẹ̀ tuntun yìí ti àwọn ilé epo aládàni míràn sì ketí ọ̀gbọin sí ikéde olóṣooṣù náà.
Oríṣun àwòrán, Twitter/PPPRA
Epo bẹntiró ti di N121.50 ní Nàìjíríà báyìí- Àjọ PPPRA
Fuel Price: Àjọ PPPRA epo bẹntiró ti di N121.50 ní Nàìjíríà báyìí
Ijọba ti kede ẹkunwo epo bẹntiro lati ọgọrun un nairia le ni naira mẹtalelogun aabọ(N123.50)  si ọgọrun un nairia le ni naira mókanlelogun aabọ(N121.50).
Ajọ PPPRA to n ṣamojuto owo epo rọbi lo ṣe ikede naa ninu atẹjade kan to fi sita.
Oríṣun àwòrán, OSatuyi
Ẹ̀dínwó epo bẹntírò ti NNPC kede kò kan ará ilú
Ajọ PPPRA ṣalaye ninu atẹjade naa wi ẹdinwo epo bẹntiro naa wa ni ibamu pẹlu idasilẹ ṣiṣe ayẹwo owo epo rọbi oṣu kẹta ọdun yii.
Bi owo epo rọbi ṣe walẹ lọja agbaye lo jẹ ki adinku ba owo tawọn alagbata epo fi n gbepo wọ Naijiria lati oṣu kẹta ọdun 2020 nitori ajakalẹ aarun coronavirus.
Ijọba ti kọkọ ṣe edinwo epo bẹntiro lati naira marunlelogoje si naira marunlelọgọfa lọjọ kejilogun oṣu kẹta.
Lati oṣu kẹta naa ni ijọba ti sọ pe loṣooṣu ni ajọ PPPRA yoo maa ṣe ayẹwo owo epo bẹntiro ni Naijiria.
Ẹ̀dínwó epo bẹntíró tí NNPC kéde kò kan ará ìlú
Ọ̀pọ̀ ọmọ Nàìjíríà ló ti gbàlù gbájó lẹ́yìn ti wọ́n gbọ́ ìkéde pé ilé iṣẹ́ to n rí si epo rọ̀ọ̀bì ni Nàìjíríà (NNPC) tí mú àdínkù bá owó epo rọ̀ọ̀bì.
Sùgbọ́n oo àlàyé láti ẹnu olùdarí ìjáde àti ìwọlé epo nínú ẹgbẹ́  IPMAN to tún jẹ́ akọ̀wé ẹgbẹ́ náà tẹlẹ̀ Mike Osatuyi,  sàlàyé pé, èdinwó náà ko tii sí fún ará ilú.
O ní gẹ́gẹ́ bi àjọ NNPC ṣe ti kéde láti ìgbà tí ọ̀rọ̀ epó bẹntiro tí n já wálẹ̀ l'Ágbàyé pé oṣooṣù ni àwọn yóò ma sọ iye ti àwọn ará ilú yóò maa ra epo.
Osatuyi ni lóòyọ́ ni wọ́n kéde, sùgbọ́n lẹ́yìn ìkéde wọ́n ó yẹ ki àjọ PPMC náà fi ikéde tirẹ̀ sita láti mọ iyé ti o tọ́ fún ará ilú láti maa ràá.
Ọ̀rọ̀ epo kìí ṣe bi iṣu àti ata lọ́ja, wọ́n maa n pé olúkúlúkù láti wá gbé epo ni, iyé ti ẹni náà ba si báa ni yóò ràá, nítori náà iye ti olúkúlúkò yóò si taa yoo yàtọ̀ si ara wọ́n
Ẹkúnrẹ́rẹ́ àlàyé Mike Osatuyi rèé
Ìjọba dín owó epo bẹntiró sí N108
Fuel price: Ìjọba dín owó epo bẹntiró láwọn ibùdó ìjápo (depot) sí N108 láti N113
Oríṣun àwòrán, AFP/Getty Images
Ijọba apapọ orilẹede Naijiria ti kede adinku owo epo bẹntiro kuro ni naira mẹtalelaadọfa naira to wa tẹlẹ si naira mejidinlaadọfa naira gẹgẹ bi iye ti wọn yoo maa ta jala epo lawọn ibudo igbepo gbogbo lorilẹede Naijiria.
Atẹjade kan ti ileeṣẹ to n ri si karakata owo epo lorilẹede Naijiria, PPMC fi sita ṣalaye pe igbesẹ naa wa lati tubọ mu ki ọja rẹ tubọ ta si ni ibamu pẹlu aṣẹ ajs to n ri si idiyele owo epo lorilẹede Naijiria, PPPRA gbe kalẹ lori iye ti wọn yoo maa ta epo lorilẹede Naijiria.
Oríṣun àwòrán, NNPC/Twitter
Iye owo ti awọn alagbata epo n ra awọn epo ni ibudo igbepo (depot) nikan ni adinku yii ba.
Ọgbẹni Musa Lawan, oludari agba ileeṣẹ to n ri si idunadura epo lorilẹede Naijiria, PPMC, ti atẹjade naa kede o fi ọrọ naa sita nio igbesẹ adinku owo epo lawọn ibudo ijapo gbogbo naa yoo mu ki wọn lee tete ta omilẹgbẹ biliọnu jala epo ti waọn ni kaakiri aka wọn sita lowo ti ko ga ju ara rọ fawọn onibara rẹ.
O fi kun pe lẹyin ti wọn fojuwo bi oju ọjọ ṣe ri lọja epo ni wọn fi gbe ẹdinwo naa kalẹ.
Amọṣa, ẹdinwo tuntun yii ko kan epo disu.
ẸNi ti ko ba lo ibomu yoo pada sile rẹ tabi ko jẹ bulala
Iroyin lati Abuja, to jẹ Olu ilu orilẹede Naijiria ti fi han pe sunkẹrẹ fakẹrẹ ọkọ to waye nibẹ ko ṣẹyin iṣẹ takuntakun awọn agbofinro lati ri pe awọn eeyan tẹlẹ ilana ti ijọba gbe kalẹ lasiko yi.
Ọpọ awọn eeyan to n kọja lati ipinlẹ Nasarawa to wa lẹba ilu Abuja ni ko raye kọja, ni bi awọn agbofinro ọhun ṣe n da awọn ti ko ba wọ ibomu pada lẹnu ibode ilu naa.
Oríṣun àwòrán, Osatuyi
Fuel Price: Ẹ̀dínwó epo bẹntírò ti NNPC kede kò kan ará ilú
Iroyin ni wamuwamu ni awọn ọmọ ologun, awọn oṣiṣẹ abo ararẹni labo ilu, NSCDC ati ajọ to n risi igboke gbodo ọkọ, FRSC ro lẹnu ibode ọhun.
Bi wọn ṣe n ṣayẹwo gbogbo awọn to ba fẹ kọja naa ni wọn n da ẹnikẹni ti ko ba wọ ibomu pada, tabi ki irufẹ ẹni bẹ jẹ bulala.
Ni kete ti ijọba apapẹ dẹwọ igbele, ile ifowopamọ lawọn eeyanb kan kọkọ fori le
Ayẹwo ti awọn agbofinro naa n ṣe ti fa sunkẹrẹ fakẹrẹ ọkọ, ti ko si dun mọ awọn eeyan naa ninu nitori wọn ni awọn mii ma n lo wakati mẹrin lojukan.
Ṣaaju ni minisita olu ilu naa ti sọ fun awọn olugbe agbegbe bi Nyanya lati joko sile wọn, ṣugbọn ọpọ ninu awọn eeyan ọhun sọ pe wọn ni lati jade si igboro nitori atijẹ.
Niyi Akinmolayan tó ṣe fíìmu àwòrán-dèèyàn Cartoon nípa COVID-19 tó la ayé já ní N
Lara awọn eeyan ọhun to ba BBC sọrọ ni ti Coronavirus ko ba pa wọn, ebi lo ma pa wọn sile, nitrori naa ko si ohun miran ti wọn le ṣe ju ki wọn jade.
Ni kete ti ijọba apapẹ dẹwọ igbele naa lọjọ Aje, ọjọ kẹrin oṣu karun ọdun 2020, ohun akọkọ tawọn eeyan naa ṣe ni abẹwo sile ifowopamọ ti wọn n lo lati gba owo wọn.
Ẹsẹ̀ bàtà, èso kukumba ni wọ́n fi ń já àbálé àwọn ọmọ Nàìjíríà ní Libya
Ní báyìí tí ìjọba àpapọ̀ tí dẹ okun lọrun àṣẹ kònílé ó gbélé, ó dàbí ẹni pé àwọn aráàlú Èkó àti Abuja tí gbàgbé òfin títa kété síra ẹni.Irinke-rindo ikọ BBC làwọn ojú pópó n'ilu Eko lónìí ọjọ́ Ajé,  ṣàkíyèsí pé, ní agbègbè Ojodu-Berger, ṣe ni àwọn aráàlú ń du ọkọ wọ, tí wọ́n ko si bọ̀wọ̀ fún òfin ìtakété síra ẹni, bẹ́ẹ̀ ni àwọn ọlọkọ èrò ń gbé èrò
kún inú mọto wọn dẹnu.
Ṣáájú sì ni ìjọba Ìpínlẹ̀ Eko ti kede pé ìdá ọgọ́ta nínú ọgọ́rùn-ún èrò táwọn ọlọkọ ń gbé sínú ọkọ wọn tẹ́lẹ̀, ní kí wọ́n máa gbé báyìí, kí àwọn èrò leè ráyè takete síra wọn.Kódà, ní ibùdókọ̀ ọkọ èrò ìjọba, BRT to wá ní Berger, àwọn èrò tó fẹ́ wọnú àwọn ọkọ náà kò bọ̀wọ̀ fún òfin ìtakété síra ẹni lórí ila tí wọn tó sì, láti wọ ọkọ náà.Bi o tilẹ̀ jẹ́ pé àwọn èèyàn yìí ló aṣọ ibomu tó jẹ́ atọwọda, àmọ́ àwọn òṣìṣẹ́ eleto ìlera ti kede tẹ́lẹ̀ pé èyí kò tó láti dáàbò bo ara ẹni lọ́wọ́ Coronavirus.
Ní olú ìlú ilẹ wá, Abuja, ẹwẹ, àwọn òṣìṣẹ́ nibẹ ya bo ojú pópó láti lọ síbi isẹ koowa wọn lọ́jọ́ Aje.Ní agbègbè Nyanya-Mararaba tí ọ̀pọ̀ òṣìṣẹ́ ń gbé, ṣe ni àwọn agbofinro gbé igi dabu ọna, láti tọpinpin lílọ bibọ ọkọ sí Ìpínlẹ̀ Nasarrawa, tíì ṣe Ìpínlẹ̀ miran to mule tí Abuja, tí wọ́n si ń rí dájú pé àwọn èèyàn náà wọ aṣọ ìbòjú.Kódà, àwọn agbófinró ń yẹ ara àwọn èrò àti ọlọkada wo pẹ̀lú ẹ̀rọ, kí wọ́n tó kọjá, tí wọn sì n da àwọn ọlọkọ tó bá lòdì sí òfin pada.
Wàyí o, bi aibọwọ fún òfin ìtakété síra ẹni ṣe ń wáyé n'ilu Eko, naa lo ṣe ri ni Abuja, nítorí báwọn èrò àti ọlọkada ṣe tó fún ayẹwo ọlọ́pàá, lòdì sí òfin ìtakété síra ẹni, ṣe ni wọn to si ẹyin ara wọn lai fi ààyè
kankan silẹ.
Ẹnikan nínú wọn tiẹ̀ sọ fún ikọ ìròyìn BBC pé, àǹfààní ńlá ni ìjáde wọn òní jẹ láti gba atẹgun sára.
Oni ọjọ Aje ni orilẹ-ede Naijiria bẹrẹ si ni dẹ okun ofin konile-o-gbele to fi sita nitori coronavirus nilu Abuja, ipinlẹ Ogun, ati ipinlẹ Eko lati le din ipa buruku ti aarun naa le ni lara ọrọ aje ku.
Lootọ Aarẹ Buhari lo paṣẹ naa, ṣugbọn gomina ipinlẹ Eko, Babajide Sanwo-Olu ti fi awọn ilana ti awọn eeyan gbọdọ tẹle sita.
Lara awọn ilana naa ni pe awọn oṣiṣẹ ijọba to wa ni ipele 'Level 15' soke nikan ni yoo pada sẹnu iṣẹ.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Baby abandoned on dunmpsite: Mo ti bímọ mẹ́rin tẹ́lẹ̀ fún bàbá méjì nínú òṣí- Dupe Ogbomos
Ṣugbọn ṣa, ofin ṣi de ipejọpọ ọpọ eniyan, awọn ile ijọsin ati ileewe.
Awọn to ni aarun coronavirus ni Naijiria pọ si lọsẹ to kọja, pẹlu bi eniyan 2,558 ṣe ni aarun naa bayii, mẹtadinlaadọrun si ti ku.
Gómínà ìpínlẹ̀ Eko Babajide Sanwo-Olu ti kede pé pé kí gbogbo òṣìṣẹ́ ìjọba láti ipile kejila si isàlẹ̀ jòkó silé wọn fún ọsẹ̀ méji.
Sugbọ́n ó ni ikéde yìí yọ àwọn to ṣe àwọn osiṣẹ́ eleto ààbò, awọn panapana àti àwọn onimọ iṣegun.
Bakan náà ni Gomina ni ìjọba ti ṣe àfikún àwọn ilé iwosan ti wọ́n le ko àwọn ènìyàn si.
 a mọ bi ǹkan to wà ni ìwáju wa ṣe toni tó a si ti ṣetan láti koju rẹ, a ti n ba àwọn asoju àwọn ọlọja sọ̀rọ̀ àti àwọn olóri awakọ láti ri dáju pé wọ́n tẹle ìlàna jijina si ẹnikeji.
Ri dájú pe o wà ni ìgbéle fun ọjọ mẹrinla ti o ba ṣẹsẹ tirin ajo dé si Naijiria. Eyi ni ǹkan to tọna láti ṣe.
 A ni láti ji giri si idojukọ wa. A o bori  ti ifọwọsowọpọ ba wa láàrin àwọn olùgbé ìpínlẹ̀ Eko, a ti ri irú idojukọ bayiìí tẹlẹ.
Ẹ̀wẹ̀ ìjọba ìpínlẹ̀ Kwara náà ti ni ki gbogbo oṣiṣẹ tirẹ maa siṣẹ́ láti ilé.
Nínú àtẹjade kan ti Gomina ìpínlẹ̀ Kwara Abdulrahman Abdulrazaq fọwọ́ si lo ti sàlaye pé botill jẹ́ pé ìpínlẹ̀ Kwara ko tii gba nipa ẹnikẹni to ni à[run náà sibẹ̀, iná ko se fi sori orule sùn.
Gomina fi kún pé igbẹ́sẹ̀ ti n lọ lọ́wọ́ lóri eto la'ti mu ki àwọn ilé iwosan ipinlẹ Kwara lé sàmójú to ààrun náà.
Ní báyìí eniyan ọgbsn lo ti ni ààrun náà ni orill èdè Naijira
Nigeria kidnap: Àwọn jàndùkú jí agbábọ́ọ̀lù Nàìjíríà méjì gbé lópòpónà Owo sí Benin
Oríṣun àwòrán, Eniymba FC
Awọn janduku ti ji agbabọọlu ọmọ Naijiria meji, Dayo Ojo ati Benjamin Iluyomade gbe.
Ojo to ti gba bọọlu ri fun ẹgbẹ agbabọọlu Naijiria, Super Eagles n rinrin ajo pẹlu Iluyomade to n gba bọọlu fun ẹgbẹ agbabọọlu Abia Comets lati ilu Akurẹ ki wọn to ko sọwọ awọn ajinigbe lọna ilu Benin.
Akẹgbẹ Ojo ti wọn jọ n gba bọọlu fun Enyimba, Emmanuel James naa wa ninu ọkọ naa ṣugbọn oun mori bọ ni tiẹ.
Ojo ṣoju ẹgbẹ agbabọọlu Sunshine ilu Akure fun igba pipẹ ko to darapọ mọ Enyimba lọdun 2019.
Ojo tun ṣoju Naijiria ninu idije awọn ọjẹwẹwẹ ti ọjọ ori wọn ko ju ọdun mẹtadinlogun lọdun 2010.
Laipẹ yii ni ajọ LMC so idije liigi Naijiria NPFL rọ nitori ajakalẹ arun coronavirus.
Ìbànújẹ́ ńlá ni ikú agbábọ́ọ̀lù Rangers, Ifeanyi George jẹ́ fún wa- Mínísítà àti NFF
Iku agbabọọlu ikọ Rangers International ti ilu Enugu  Ifeanyi George ṣe ni laanu gan na, bayii ni minisita fun ere idaraya ati ọrọ ọdọ, Sunday Dare ṣe n kẹdun
Ifeanyi di oloogbe lẹni ọdun mẹrindinlọgbọn pẹlu awọn akẹgbẹ rẹ meji, Emmanuel Ogbu ati Eteka Gabrielinu ijamba ọkọ to ṣẹlẹ lanaa ọjọ Aiku.
Iroyin ti a gbọ ni pe ọkọ ayọkẹlẹ ti wọn wa ninu rẹ lo lọ fori sọ ọkọ nla akẹru kan nibi ti o duro si .
Lopopona Agbor ni ipinlẹ Edo ni ijamba ọkọ ọhun ti ṣẹlẹ nigba ti George ati awọn akẹgbẹ rẹ n rinrin ajo ni opopona ilu Onitsha si Eko.
Alukoro ẹgbẹ agbabọọlu Rangers ṣalaye pe awọn agbabọọlu naa rinrin ajo lọ si ilu Eko lẹyin ti idije liigi Naijiria(NPFL) ti di siso rọ ki ijamba naa to ṣẹlẹ.
Oríṣun àwòrán, Twitter/NFF
Ajọ ẹṣọ oju popo FRSC sọ pe awọn mẹtẹẹta lo ja laisi lojuna ti ijamba ọkọ naa ṣẹlẹ tan.
Minisita ni o ṣeni laanu pe pe awọn mejeeji ṣagbako iku ojiji lai le jẹ ohun ti wọn fẹ jẹ laye.
Minisita gbadura si Eleduwa pe ko tu awọn ẹbi awọn agbabọọlu mejeeji ninu, o ni oun naa kẹdun awọn agbabọọlu mejeeji.
Ẹwẹ, ajọ to n ri si ere bọọlu afẹsẹgba ni Naijiria, NFF sọ loju opo Twitter rẹ pe ibanujẹ nla ni iku awọn agbabọọlu mejeeji jẹ.
Oríṣun àwòrán, Twitter/NFF
NFF kẹdun pẹlu ẹbi awọn oloogbe naa ati ẹgbẹ agbabọọlu Rangers Intl, ajọ naa gbadura pe ki Eleduwa tẹ wọn si afẹfẹ rere.
Coronavirus in Nigeria: Esì àyẹwò ọmọ ati ìyáwọ ọmọ Atiku ti jáde
Oríṣun àwòrán, Others
Mò n lọ fun ìgbélé nítori mo ṣe alábapàdé ọmọ Atiku- Gomina Bauchi
Ninu atẹjade ti ileeṣẹ ijọba ipinlẹ Bauchi fi sita ni a ti rii pe oun nikan ni aarun naa mu laarin awọn mẹfa ti wọn jọ kọwọrin.
Wọn ṣalaye pe iwadii ti fidiẹmulẹ pe awọn ọmọ ati ẹbi rẹ wa ni alaafia lai ni aarun coronavirus.
Ajọ NCDC si ti gbe igbesẹ to yẹ lati ya gomina Bala muhammed sọtọ bayii ki o ma baa le tan aarun naa kalẹ.
Oríṣun àwòrán, Bauchi
Wọn ṣalaye pe iwadii ti fidiẹmulẹ pe awọn ọmọ ati ẹbi rẹ wa ni alaafia lai ni aarun coronavirus.
Gomina Bala Muhammad yii lo ti figa kan jẹ minista fun olu ilu Naijiria, Abuja ki o= to dije dupo gomina ipinlẹ Bauchi.
Ẹ wo ǹkan to sẹlẹ̀ sí ọmọ àti ìyàwó ọmọ Atikú tó lùgbàdì ààrun Coronavirus
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ẹ wo ǹkan to sẹlẹ̀ sí ọmọ àti ìyàwó ọmọ Atikú ti lùgbàdì ààrun Coronavirus
Ìdúnú subú láyọ fún ẹbi àtikù nígbà ti èsì ayẹwò Coronavirus ìyáwó ọmọ Atiku àti ti àwọn ọmọ jáde ti wan ko si ni ààrun náà.
Ọmọ Atiku Mohammed ti wọ́n fi si ipamọ ni ilé ikwosan ikọni to wà ni Gwagwalad nilú Abuja nítori pé àyẹwo fi han pé o ni ààrun Coronavirus lọ́jọ́ Aiku.
Mohammed fẹ Badriyya to jẹ ọmọ gomina Bauchi Ahmed Muazu to tun jẹ alága ẹgbẹ́ òṣèlú PDP tẹ́lẹ ri.
Lásìkò to n ba àwọn onírolyin sọ̀rọ̀ ọgbẹni Zakari Aliyu to jẹ igbakeji alaga ilé igbé rẹ sàlàyé pé ko si ibẹru bojo nítori pe ẹbi ẹni ti wọ́n n sọrọ gan ko ni ààrun náà.
"Aliyu ni "" ọkunrin ti wan gbé lọ ni dédé àgo kan oru yẹn ni à[run Coronavirus, sùgbọ́n ìyáwó àwti àwọn ọmọ rẹ ko ni, sùgbọ́n o àwọn náà yóò wà ni igbélé fún ọjọ mẹrinla, mo si dúpẹ lọ́wọ́ ìyàwó rẹ pe o fọwọsowọpọ pẹlu wá""."
Àwọn fíìmì òde òní ń kọ́mọ lólè àti ọ̀pọ̀ ìwà burúkú
Ọmọ Atiku ni ìròyìn sọ pé o de láti orilẹ̀-ède Switzerland si orill-èdè naijiria ti o si jẹ ọkàn lára àwọn orilẹ̀-è[de ti o n bààrun Coronavirus fira
Mò n lọ fun ìgbélé nítori mo ṣe alábapàdé ọmọ Atiku- Gomina Bauchi
Gomina ìpínlẹ̀ Bauchi, Bala Muhammed ti kéde pé òun náà yóò lọ fi ara òun si ìgbélé, lẹ́yìn ti ìgbákeji ààrẹ àná lórilẹ̀-èdè Naijiria fi léde pé pé ọmọ oun ti lugbàdi ààrun Coronavirus.
Gómìnà ìpínlẹ̀ Bauchi sàlàyépé òun àti ọmọ Atiku 'sun pàde àra àwọn nínú ọkọ bàlú láti ilú Eko lọ si ilú Abuja ti àwọn si bọ ara àwọn lọ́wọ́
Oludári ilé iṣẹ́ radio naijiria nígbà kan ri Ladan Salihu fi idí èyí mull lori àtẹjiṣẹ́ twitter rẹ̀ pé gbogbo àwọn ti àwọn ba ọmọ náà rin irin ajò ni àwọn ti lọ fi ara àwọn pamọ.
O ní àwọn ti fi ara àwọnnkalẹ fun àyẹwò báyìí ti àwọn si ni ìgbàgbọ́ pé akan ni èsì rẹ yóò jásí.
Nínú àtẹjjáde kan ti Gomina Bauchi fi sita láti ọwọ olùrànlọ́wọ́ pàtàkì rẹ lórí iròyìn Mukhtar Gidado, sàlàye pé àwọn jọ wó ọkọ ofurufu Aero Contractor ní to sì jẹ́ri si pé wọ́n jọ bọ́wọ lọ́ja náa.
Gómina ko fi àmì kankan hàn báyìí, bákan náà losi ti wọ́gile gbogbo àwọn ìpáde to yẹ ki o ní.
Coronaviris in Nigeria: Ọmọ Nàìjíríà kan ẹni ọdún 67 tó kó àrùn COVID-19 ti di olóògbé
Oríṣun àwòrán, Twitter/Federal Ministry of Health
Ọmọ Naijiria kan ẹni ọdun mẹtadinlaadọrin ti jẹ Ọlọrun ni pe lẹyin to lugbadi arun corona virus.
A gbọ wi pe ọkunrin naa ṣẹṣẹ rinrin ajo de lati ilẹ Gẹẹsi ni ki o to tẹri gbaṣọ ni Naijiria.
Ajọ NCDC ṣalaye loju opo Twitter rẹ pe ọkunrin naa ti ni awọn aisan kan lara tẹlẹ bi arun itọ ṣuga ati arun ti oloyinbo n pe ni Myeloma.
O jẹ ọmọ ọdun mẹtadinlaadọrin.
Atẹjade ajọ WHO sọ pe O ṣẹṣẹ de pada lati ilẹ Gẹẹsi laipẹ yii nibi to ti lọ ṣe itọju aisan ara rẹ.
"Wọn ni ko pẹ to gba itọju ""Chemoteraphy"" tan nile iwosan nilẹ Gẹẹsi to fi pada wa sile."
Wọn ni o ti n gba itọju lori awọn aisan naa ki arun COVID-19 to mu lọ.
Ajọ NCDC kẹdun pẹlu idile oloogbe naa.
O ti di eeyan mẹrindinlogoji to ni ni arun naa ni Naijiria bayii ninu eyi ti awọn meji ti jade nile iwosan.
Ọmọkùnrin mi ti kó coronavirus, ẹ bá mi fi sínú àdúrà yín- Atiku
Ẹ fi adura ranmi lọwọ nitori ọmọkunrin mi ti lugbadi arun coronavirus to n tan kalẹ kaakiri agbaaye bi ina inu ọyẹ.
Oríṣun àwòrán, Facebook/Atiku Abubakar
Oludije fun ipo aarẹ fẹgbẹ oṣelu PDP, Atiku Abuabakar lo fọrọ yii lede loju opo Twitter rẹ lalẹ ọjọ Aiku.
Atiku ṣalaye pe oun ti sọ fun ajọ to n gbogun ajakalẹ arun ni Naijiria, NCDC, ati pe ọmọ naa ti n gba itọju nile iwosan olukọni fasiti Abuja to wa ni Gwagwalada.
''Inu mii yoo dun ti ẹ ba le fi ọmọ mi sinu adura yin, ki onikaluku rọra maa ṣe nitori otitọ ni pe arun coronavirus wa nita,'' Atiku lo sọ bẹẹ.
Atiku tun gboriyin fawọn oṣiṣẹ ile iwosan kaakiri orilẹede Naijiria fun iṣẹ takuntakun ti wọn n ṣe lasiko ajakẹlẹ arun covid-19 yii.
''Mo rọ gbogbo ọmọ Naijiria pe ki wọn maa mi kan ti a o fi ṣẹgun arun coronavirus ni Naijiria,'' Atiku lo woye bẹẹ.
Ọgbọn eeyan lajọ NCDC ti kede pe wọn ti ni arun coronavirus ni Naijiria, ninu eyi ti awọn meji ti ri iwosan.
Coronavirus in Africa: Orílẹ̀èdè 11 ni kò tí ì ní àrùn Coronavirus ní ilẹ̀ Afrika
Oríṣun àwòrán, NurPhoto / Getty Images
Àwọn ààrẹ ilẹ̀ Afirika kan ti kéde òfin kónílé ó gbélé nítorí coronavirus
O ti to ẹniyan irinwolelẹgbẹrun (1,400 ) to ti ni arun Coronavirus kaakiri ilẹ Afrika , ti ọpọlọpọ si n gbiyanju lati wa ọna abayọ si ajakalẹ arun naa ni Afrika.
Gẹgẹbi iroyin ti Ajọ Ilera Agbaye, WHO gbe jade, arun Coronavirus ni ilẹ Afrika fi lede pe awọn ilẹ yii ti n peleke si ni awọn orilẹede to ku ni agbeegbe naa.
Orilẹede mẹtalelọgọrin lo ti ni iha ila orun, iwọ orun ati gbungun ilẹ Afrika to fi mọ ariwa ilẹ naa lo ti ni arun Coronavirus naa.
Nikesuliat: Ọ̀dọ́mọdébìnrin akéwì tó n fi ẹ̀ṣà kìlọ̀ ìwá lásìkò yìí
Ijọba orilẹede Senegal, Ivory Coast ati South Africa ti kede ofin konile o gbele, eyi jẹ ọkan lara ọna lati dẹkun itankalẹ arun coronavirus lawọn orilẹede naa.
Aarẹ orilẹede Senegal, Macky Sall ṣalaye pe eto konile o gbele ọhun yoo bẹrẹ laago mẹjila alẹ oni ọjọ Iṣẹgun.
Aarẹ ni ijọba oun tun fofin de rinrin kaakiri ẹnikan lati aago mẹjọ alẹ si aago mẹfa aarọ ọjọ keji.
Ijọba ti ko awọn ologun ati ọlọpaa jade lati maa mu awọn to ba fẹ kọ eti iku si ofin konile o gbele naa.
Oríṣun àwòrán, NurPhoto / Getty Images
Àwọn ààrẹ ilẹ̀ Afirika kan ti kéde òfin kónílé ó gbélé nítorí coronavirus
Eeyan mọkandinlọgọrin ni akọsilẹ sọ pe wọn ti ni arun covid-19 lorilẹ-ede Senegal ninu eyi ti awọn meji ti kuro nile iwosan lẹyin ti wọn gbadun tan.
Ivory Coast
Aarẹ orilẹ-ede Ivory Coast, Alassane Ouattara naa ti sọ pe eto konuile o gbele yoo bẹrẹ lati aago mẹsan alẹ si marun un owuro lati oni ọjọ Iṣẹgun.
Bakan naa ni aarẹ Ouattara kede titipa awọn ile ọti ati rinrin kaakiri ni olu ilu orilẹ-ede naa, Abidjan.
Ijọba gbe igbesẹ yii lẹyin ti awọn to n ni arun naa n pọ si kaakiri Ivory Coast.
Àwọn fíìmì òde òní ń kọ́mọ lólè àti ọ̀pọ̀ ìwà burúkú
South Africa
Aarẹ South Africa, Cyril Ramaphosa ti kede nnkan o fara rọ fun ọjọ mọkanlelogun ni orilẹ-ede naa nitori arun coronavirus.
Nigba to n sọrọ, aarẹ Ramaphosa ni igbesẹ ijọba yoo lagbara lori ọrọ ati dena arun covid-19.
Eeyan meji le ni irinwo lo ti ni arun coronavirus bayii lorilẹ-ede South Africa eleyi to jẹ ilọpo mẹfa awọn to ni arun naa nigba ti aarẹ Ramaphosa bawọn eeyan South Africa sọrọ lori arun covid-19.
Aarẹ Ramaphosa kede pe laago mejila alẹ Ọjọbọ ni ofin konile o gbele naa yoo bẹrẹ kaakiri orilẹ-ede South Africa.
Ramaphosa ni ijọba ko faye gba ẹnikẹni lati kuro nile, bakan naa lawọn ṣọọbu yoo wa ni titi pa ayafi awọn ibi ti wọn ba ti n ṣiṣẹ ko ṣee maa nikan loku.
O fikun ọrọ rẹ pe ijọba yoo kọ ibugbe pajawiri fawọn ti ko nile lori.
Amọ ofin naa yọ awọn oṣiṣẹ eto ilera silẹ nitori iṣe pataki iṣẹ wọn lawujọ.
Coronvirus in Nigeria: Àjọ NCDC ti kede pé ènìyàn méji míran ti ni àrun náà
O ti di ènìyàn Mẹrinlelógóji to ti ni ààrun Coronavirus ni Naijiria
Ní ìròlẹ́ òní ni àjọ to n ri si itankalẹ ajàkálẹ̀ àrun ti tún kéde pé ènìyàn méji míràn tú ti kú àwọn méjilelogoji to wà nilẹ̀ tẹ́lẹ̀ ti o si ti di ẹni mérinlélógójì báyìí to to ti ni ààrun náà ni Naijira.
Awọn méji oun ti rín irin ajò lọ si olrilẹ̀-èdè UK àti Germany, súgbọ̀n kìí se ilú Eko ni wọ́n de si báyìí.
Nikesuliat: Ọ̀dọ́mọdébìnrin akéwì tó n fi ẹ̀ṣà kìlọ̀ ìwá lásìkò yìí
Awọn méjèèjì náà ni wọ́n ri ọkan ni Abuja nígba ti okán wà ni Bauchi
Ní dede ààgo mẹfa kọjá iṣẹju mẹẹdọgbọ̀n ni NCDC kédé ènìyàn méji túntun náà
Oríṣun àwòrán, NCDC
102,000 ènìyàn jàjàbọ́ lọ́wọ́ COVID-19 lágbàáyé
coronvirus world: 102,000 ènìyàn jàjàbọ́ lọ́wọ́ COVID-19 lágbàáyé
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Awọn kan ti n ri iwosan gba lori coronavirus
Fasiti iwadii ti John Hopkins to ni Baltimore ni Maryland lorilẹ-ede America ti fi abajade akọsilẹ iṣẹlẹ corona virus lagbaye ti wọn ṣe sita.
Abọ akọsilẹ naa fihan pe awọn to ti bọ lọwọ aarun coronavirus ti tun pọ sii lagbaye.
Bayii coronavirus ti de orilẹ-ede mẹwaa din ni igba ni gbogbo agbaye.
O ti le ni ẹgbẹrun lọna ọọdunrun awọn eniyan ti wọn ti kagbako Coronavirus yatọ si China nibi to ti kókó bẹ silẹ.
Ninu awọn eniyan 382, 000 to ti lugbadi aarun yii, awọn eniyan 102, 000 ni akọsilẹ fasiti yii fidiẹ mulẹ pe wọn ti gbadun tan patpata bayii.
Awọn eniyan 16, 600 ni wọn ni wọn ti di oloogbe bayii.
Bo tilẹ jẹ pe awọn miran n ku lataari awọn aisan to ti wa lara wọn tẹlẹ.
Nikesuliat: Ọ̀dọ́mọdébìnrin akéwì tó n fi ẹ̀ṣà kìlọ̀ ìwá lásìkò yìí
Abba Kyari lùgbàdì aàrùn coronavirus- Reuters
Coronavirus in Nigeria: Èèyàn mẹ́rin míì kó coronavirus ní Nàìjíríà, ogójì ló ti di níi báyìí
Iroyin ti Reuters fi lede ni Ogbẹni Abba Kyari to jẹ awọn oṣiṣẹ nile ijọba apapọ ni Aso Rock nilu Abuja ti lugbadi aarun coronavirus.
Eni kan to ba wa sọrọ to jẹ ogbontarigi nile ijọba ti ko fẹ ki wọn darukọ oun fidiẹ mulẹ fun BBC pe otitọ ni iroyin naa.
Ṣaaju nigba ti iroyin yii bẹrẹ si ni tan kalẹ ni BBC kan si olubadamọran Aarẹ Buhari lori ọrọ iroyin, Garba Shehu ko le fiidi ọrọ na mulẹ tabi bẹẹkọ.
Oríṣun àwòrán, Presidency
Olori awọn oṣiṣẹ nile ijọba apapọ Naijiria, Abba Kyari ni coronavirus
Gbogbo igbiyanju BBC lati gbọ ohun to n ṣẹlẹ bayii lẹnu Garba Shehu lo ja si pabo.
Reuters ni Abba Kyari rinrin  ajo lọ si orilẹ-ede Germany nibẹrẹ oṣu yii pẹlu ikọ awọn oṣiṣẹ ijọba kan lati ṣe ipade pẹlu Siemes.
Reuters ni awọn ko le sọ igbesẹ ti Abba Kyari tabi ileeṣẹ ijọba apapọ n gbe bayii.
Eni mẹ́rin míì kó coronavirus ní Nàìjíríà, àfàìmọ̀ kó má dàbi ti China, Italy- Mínísítà kìlọ̀
Ajọ NCDC ṣalaye pe mẹta ninu awọn eeyan wa lati ipinlẹ Eko nigba ti ẹyọkan to ku wa lati olu ilu orilẹede Naijiria, Abuja.
Oríṣun àwòrán, Twitter/Muhammadu Buhari
O ti di ogoji eeyan to ti lugbadi arun coronavirus bayii lorilẹ-ede Naijiria, lẹyin ti ajọ to n gbogun ti ajakalẹ arun ni Naijiria, NCDC kede awọn mẹrin mii to ti ni aisan naa lalẹ ọjọ Aje.
Ajọ NCDC ṣalaye pe mẹta ninu awọn eeyan wa lati ipinlẹ Eko nigba ti ẹyọkan to ku wa lati olu ilu orilẹede Naijiria, Abuja.
NCDC ni awọn meji ninu wọn ṣẹṣẹ rinrin ajo de lati oke okun ni.
Gẹgẹ bi alaye ajọ NCDC loju opo Twitter rẹ, eeyan meji ninu awọn ogoji eeyan to lugbadi arun Covid-19 ni Naijiria ti kuro nile iwosan.
Eeyan ti dero ọrun ninu awọn to larun naa ni Naijiria, ọjọ Aje ni ọkunrin naa ẹni ọdun mẹtadinlaadọrin ku.
Oríṣun àwòrán, Twitter/Muhammadu Buhari
Ohun ti a gbọ ni pe ọkunrin ti ni arun itọ ṣuga ati arun jẹjẹrẹ lara tẹlẹ ki o to lugbadi coronavirus.
Ni bayii, eeyan mejidinlọgọn lo wa lati ipinlẹ Eko ninu ogoji to larun naa ni Naijiria, meje lati Abuja.
Eeyan meji wa lati ipinlẹ Ogun, nigba ti ipinlẹ Ekiti, Oyo ati Edo ni ẹyọ kọọkan.
Ẹwẹ, minisita fun eto ilera, Dokita Osagie Ehanire ti sọ pe afaimọ ki ọrọ Naijiria naa ko ma dabi ti orilẹede China ati Italy lori bi ọrọ coronavirus ṣe n lọ yii.
Minisita ọpọ ọmọ Naijiria to ni arun coronavirus ni wọn n deju mọle, dipo ki wọn jade fun itọju ki arun naa maa ba ran awọn mii.
Àwọn fíìmì òde òní ń kọ́mọ lólè àti ọ̀pọ̀ ìwà burúkú
Coronavirus in Nigeria: Ìtànkálẹ̀ coronavirus ṣe ìdíwọ́ fún ìrun Jimọ
Mọṣalaaṣi An-nur nilu Abuja niyii, gbajugbaja ni, ṣugbọn itankalẹ aarun coronavirus sọ ọ di ofo. Irun Jimọ ko waye nibẹ lonii.
Itankalẹ aarun coronavirus ṣe idiwọ fun awọn mọṣalaaṣi pupọ, nitori pe ọpọ wọn ni ko lanfaani lati kirun apapọ lọjọ Jimọ.
Abẹwo akọroyin BBC si mọṣalaaṣi apapọ Naijiria nilu Abuja fihan pe, paro-paro lo da a.
Titipa ni ilẹkun Mọṣalaaṣi apapọ Naijiria nilu Abuja wa. Irun Jimọ ko waye nibẹ.
Bakan naa ni nkan ri ni Mọṣalaaṣi An-nur to jẹ gbaju-gbaja nilu Abuja bakan naa.
Wọn ko ṣi ilẹkun Mọṣalaaṣi An-nur rara, debi ti awọn eniyan o wa a kirun.
Ayipada yii ko yọ ilu Kaduna silẹ.
Botilẹjẹ pe ko ti i si ẹni to ni aarun naa nibẹ, ijọba ipinlẹ naa kede ofin konile-o-gbele, fun gbogbo wakati mẹrinlelogun to wa ninu ọjọ kan.
Koda, awọn aṣoju ijọba duro si oju ọna, ti wọn si n da awọn eniyan duro.
O dabi ẹni pe ofin ijọba ni awọn ibikan pe ki olukulu joko sile rẹ ti n fidimulẹ ni awọn ilu kan ni Naijiria.
Ìjọba ìpínlẹ̀ Oyo kéde pé kí àwọn òṣìṣẹ́ ìjọba dáwọ́ iṣẹ́ dúró nítorí coronavirus
Oríṣun àwòrán, Facebook/Seyi Makinde
Ijọba ipinlẹ Ọyọ ti ti ilẹkun ileeṣẹ ijọba pa fun ọsẹ meji gbako nitori itankalẹ aarun coronavirus nipinlẹ naa.
Gomina ipinlẹ naa, Seyi Makinde lo kede bẹ ẹ ninu atẹjade kan to fi sita loju opo Twitter rẹ lọjọru.
Aṣẹ naa yoo bẹrẹ iṣẹ ni ọjọ Ẹti, ọjọ kẹtadinlọgbọn, oṣu Kẹta, ọdun 2020.
Makinde sọ pe awọn oṣiṣẹ ti iṣẹ wọn jẹ koṣeemani nikan ni yoo ma lọ si ibi isẹ wọn.
Coronavirus: Fífi nkan bó ìmu nìkan kò le dènà kíkó coronavirus
Gomina ìpínlẹ̀ Eko Babajide Sanwo-olu ti kede pe ki gbogbo ọja ní ìpínlẹ̀ Eko wa ni títìpa láti ọjọbọ lọ nítori pe ìbẹru bojo ti wà láàrin ilú.
Ìjọba ìpínlẹ̀ Eko ti ni ki gbogbo ọjà wà ni títì pa, sùgbọ́n...
Gomina ṣe ikéde yìí lósàn oni lásìkò to n ba àwọn oniroyin sọ̀rọ̀, o ní gbogbo àwọn to ba n ta ọjà ti ko niṣe pẹlu Ounjẹ jijẹ àti àwọn to nta òògùn fun ilé ìwòsàn tàbi ọlọdani ki wọ́n jòkó silẹ̀ fun ọṣẹ kan.
O ni èyi ṣe pàtàkì gẹ́gẹ̀ bi ọ̀nà láti da ìtànkalẹ̀ àrun náà dúro nitori oun gbòrò si ni ojoojumọ ni, eyti yoo si ṣe ilu lánfani ti gbogbo ènìyàn ba fi ọwọsọwọpọ.
O ní ki olukuluku dáwọ ipejọpọ duro, yala ìkómọ ni tabi igbeyawo, eyi ni yóò ran ijọba lọ́wa láti tete de ọdọ àwọn to nilo iranlọ́wọ́.
Gmina ni àrun náà ko dá ojú ẹnikẹni mọ, yala, olwo tabi talaka, ẹni to n gbe ilé ijọba tabi ẹni to n gba Mushin, sùgbọ́n títẹle ìlàna ijọba yóò ṣe ànfani to pọ fun gbogbo èniyan.
Gomina fi èrò ìgbàgba han pé, àrun buruku ko ni ya ilé ẹnikẹni.
'Èmi gan máa ń béèrè lọ́wọ́ ara mi pé ta ni Wole Soyinka gangan'
Nǹkan méje tí yóò ṣẹlẹ̀ nìyíí tí ìjọba bá kéde òfin kónílé ó gbélé nítorí coronavirus
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ofin konile o gbele jẹ ọna kan pataki ti ijọba kaakiri agbaye fi gbogun ti itankalẹ arun coronavirus to n ṣọṣẹ lọwọlọwọ.
Lati oṣu kejila ọdun 2019 ti arun naa bẹrẹ lorilẹede China, o ti ran kaakiri ọpọlọpọ orilẹede agbaye bayii.
Orilẹede Rwanda ni orilẹede ilẹ Afirika akọkọ to kede ofun gbele ẹ, ọsẹ meji ni ijọba fi kede ofin konile o gbele naa fi wa nilẹ.
Kinni ofin konile o gbele tumọ si gan an?
Ofin konile o gbele tumọ si wi pe ẹnikẹni gbọdọ joko si ile lai lọ si ibi kan.
Ibi ki bi ti nnkan meje yii ba ti ṣẹlẹ, ki ẹ mọ pe ofin konile o gbele n ṣẹlẹ nibẹ.
Ibode yoo di titi pa:
Oríṣun àwòrán, EMMANUEL OYELEKE
Igbesẹ akọkọ tawọn ijọba orilẹede ti ofin konile o gbele wa yoo ṣe ni titi ibode ori ilẹ, ori omi ati ti ofurufu pa.
O tumọ si pe wọn ko ni jẹ ki awọn eeyan lati awọn orilẹede mii papaajulọ lati awọn orilẹede ti arun covid-19 ba n finra wọ le.
Ṣugbọn wọn le gba ki ẹru maa wọle.
Ko si irin-ajo kaakiri orilẹede:
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Irin-ajo lati ibi kan si ibo miiran ko si nigba ti ofin konile o gbele ba wa lode lorilẹede kan.
Awọn ti iṣẹ wọn ba ṣe pataki nikan bi awọn oṣiṣẹ eto ilera lo le lanfaani ati maa rinrin ajo lasiko ofin konile o gbele.
Coronavirus in Nigeria: Ẹ wo àǹfààní tó wà nínú àrùn Coronavirus
Ẹnikẹni ko gbọdọ jade
Mo n lọ ki ẹnikan ni ibikan ko si nigba ti ofin konile o gbele ba wa nita
Ijọ ko ni fi aye gba ki awọn eeyan maa lọ ki ara wọn.
O ko gbọdọ jade kuro nilu ile ayafi ti o ba fẹ lọ ra ounjẹ tabi o fẹ lọ si ile iwosan tabi ile ifowopamọ loku.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ọpọ
O gbọdọ ṣiṣẹ lati ile
Ijọba maa n sọ fawọn oṣiṣẹ ijọba ati ti adani pe ki wọn maa ṣiṣẹ lati ile wọn lasiko ti iṣede ba wa nilẹ.
Awọn eeyan ti iṣẹ wọn ba ṣe pataki bi awọn oṣiṣẹ eleto ilera, atawọn eeyan to n ṣiṣẹ nile ifowopamọ.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ile iwe di titi pa
Gbogbo ile iwe lo gbọdọ wa ni titi pa lasiko ti ijọba ba kede ofin konile o gbele nitori ki awọn akẹkọọ maa ba lugbadi arun coronavirus to wa nita.
Ijọba maa n rọ awọn ile iwe lati fi eto wọn ranṣẹ sawọn akẹkọọ lori ayelujara.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ko si ipejọpọ lawujọ mọ
Asiko owambẹ ti lọ! Ko si ayẹyẹ igbeyawo, isinku tabi apejọ kankan mọ lasiko konile o gbele.
Ṣọọṣi, mọṣalaaṣi ati gbogbo ile ijọsin ni yoo wa ni titi pa kaakiri orilẹede.
Gbogbo ẹ, gbogbo ẹ lati dẹkun itankalẹ arun naa ni.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Adinku igboke-gbodo ọkọ
Ijọba maa n din igboke-gbodo ọkọ ku lasiko ti fin konile o gbele ba wa nita.
Amọ ijọba maa n faye gba kiko ọunjẹ kaakiri lasiko naa ki awọn eeyan le ri ohun ti wọn maa jẹ nigba ti wọn ba ninu ile.
Ṣugbọn wọn maa saa ba gbawọn eeyan naa ni imọran lati jina si ara wọn ti wọn ba n kẹru si ọkọ.
Ti nnkan meje yii ba n ṣẹlẹ lagbegbe rẹ, ki o tete mọ pe ijọba ti kede ofin konile o gbele niyẹn.
Manu Dibango: Covid-19 ti pa akọni afúnfèrè Sax ilẹ̀ Africa
Oríṣun àwòrán, AFP
Manu Dibango: Covid-19 ti pa akọni afúnfèrè Sax ilẹ̀ Africa
Àgbà ọ̀jẹ afunfere Sax Man Dibango ti ku ni ilú Paris lẹ́yin to he aàrun Coronavirus.
Dibango ti ọ̀pọ̀ ènìyàn mọ fun orin rẹ to pe ni Soul Makossa lọ̀dun 1972 ti jade laye. Oun ni ẹni akọkọ ninu àwọn gbájugbaja àgbáyé ti Covid 19 yóò pa.
Ẹni ọdún mẹ́rìndínláàdọrún to maa n kọrin jazz àti ti ibilẹ papọ jé ọmọ orilẹ-ede Cameroon.
Pẹlú ìbànújẹ ọkàn ni a fi kéde ikú Manu Dibango to jẹ baba amayedun nínú àtẹjáde to jẹyọ lori atẹjisẹ Facebook rẹ.
'A o ni sin òkú rẹ̀ ni ojútaye a si fẹ́ ki àwọn ènìyàn fi ikíní ẹdùn wọ́n ranṣẹ́ si láti ori àtẹ̀jisẹ a o gbé bá wọ́n gbe jáde.
Àwọn olorin ilẹ̀ Afirika to fi mọ Angelique Kidjo àti Youssou N'Dour ti sááju nínú ìkíni.
Lóri àtẹjisẹ́ Twitter, Kidjo pin fọ́nran kan ti wọn gbà kalẹ̀ ni oṣù méji sẹ́yin lásiko ti wọ́n n gbáradi fún orin Makossa pẹlu Dibango.
"Bayii ni olorin ọmọ Benin naa ṣe kọọ sibẹ̀ pé ""iwọ gan an ni erin olorin ilẹ̀ Afirika àti èniyan to rẹwa"""
N'Dour pe ọmọ olorin Cameroon naa ni ọlọgbọ́n inú paápàá jùlọ lori ìlò Saxophone to si sàpejúwe rẹ̀ gẹ́gẹ́ bi ẹgbọ̀n àgbà ati ohun amuyangan fun Cameroon ati ilẹ Africa.
N'Dour àti Kidjo, pẹlú àwọn gbajugbaja olorin míràn bii Salif Keita, Papa Wemba àti King Sunny Ade ni wan jọ ṣe iṣẹ́ pọ lori Dibangu ni ọdun 1992 to pe akọle rẹ̀ ni Wakafrika.
Àwọn fíìmì òde òní ń kọ́mọ lólè àti ọ̀pọ̀ ìwà burúkú
"Lásìkò to n ba BBC sọ̀rọ̀ lọdun 2013 lori bi o ṣe fẹ ki àwọn ènìyàn maa ranti òun, Dibangu sọ pé ti ènìyàn ba ti ku, o ti tan niyẹn, kò si ni ìkáwọ mi mọ lati sọ pe mo fẹ́ nkan bayìí"""
Ilú Doula ni a ti bii lọ́dun 1933, lásìkò ti ilu yii wa lábẹ àwọn Faranse, iṣẹ́ orin Dbango si tan ka fu  bi ọgbsn ọdun.
Nikesuliat: Ọ̀dọ́mọdébìnrin akéwì tó n fi ẹ̀ṣà kìlọ̀ ìwá lásìkò yìí
Coronavirus: Ọ̀ọ̀ni jẹ ọkùnrin Rwanda kan tí kò pa òfin kónílé-ó-gbélé nítorí coronavirus mọ́
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ọkunrin naa fi ile rẹ silẹ, o si lọ si odo lati pa ẹja, ṣugbọn ọọni sọ ọkunrin naa di ounjẹ.
Ọkunrin kan to kọ lati tẹle ofin konile o gbele ti ijọba orilẹ-ede Rwanda fi sita nitori itankalẹ aarun coronavirus ti kagbako iku ojiji.
Ọkunrin naa fi ile rẹ silẹ, o si lọ si odo lati pa ẹja, ṣugbọn ọọni sọ ọkunrin naa di ounjẹ.
Olori agbegbe Gusu Kamonyi ti iṣẹlẹ naa ti waye,  Alice Kayitesi sọ fun BBC pe owurọ Ọjọbọ ni iṣẹlẹ buruku naa ṣẹlẹ ni odo Nyabarongo.
O kọ lati tẹle ofin ijọba pe ki olukulu joko sile rẹ, o wa lara awọn eniyan diẹ ti ko pa ofin naa mọ, lati dena itankalẹ coronavirus.
Ọjọ aiku to kọja ni awọn alaṣẹ ni Rwanda paṣẹ pe ki gbogbo nkan o dawọ duro, nitori bi  awọn to ni arun naa ṣe n pọ si i.
Coronavirus: Fífi nkan bó ìmu nìkan kò le dènà kíkó coronavirus
Ogoji eniyan lo ti ni coronavirus ni Rwanda.
Bi ijọba ṣe f'ofin de eto ọrọ aje ti ṣe akoba nla fun ọpọ eniyan ti ko fi ii bẹ ri taje ṣe.
Bakan naa ninu iroyin miran, a gbọ pe awọn ọlọpaa yinbọn pa ọkunrin meji ni agbegbe Nyanza lẹyin ti wọn kọ lati tẹle ofin naa.
Ṣugbọn, ileeṣẹ ọlọpaa ko ti i sọ nkankan nipa ẹsun naa.
Oríṣun àwòrán, Reuters
Ọmọ ọba ilẹ Gẹẹsi, to tun jẹ ori-ade ilu Wales, Charles naa ti ni aarun coronavirus.
Agbẹnusọ fun aafin ọba ilẹ Gẹẹsi ṣalaye pe ilera Charles ẹni ọdun mọkanlelaadọrin si wa daadaa.
Bakan naa, Ọmọbabinrin to jẹ iyawo rẹ, naa ṣe ayẹwo, amọ ayẹwo fihan pe ko ni aarun naa
Ìgbẹ́tì: Òkè Ìyámàpó ló gba wàá sílẹ̀ lọ́wọ́ ogun
Tí a bá ní káwọn èèyàn jókòó sílé nítorí coronavirus, ebi àti olè jíjà ma pọ̀- Akọ́ṣẹ́mọṣẹ́
Ijọba apapọ orilẹ-ede Naijiria, ijọba ipinlẹ Eko atawọn ijọba ipinlẹ mii ti kede pe kawọn oṣiṣẹ lati ipele kinni si ekejila joko sile wọn nitori aarun coronavirus.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
''Tí a bá ní káwọn èèyàn jókòó sílé nítorí coronavirus, ebi ni yóò pa ọ̀pọ̀lọpọ̀''
Eyi jẹ ọna kan lati dena itankalẹ arun naa eyi to ti mu eeyan mẹrinlelogoji bayii ninu eyi ti ẹnikan ti di oloogbe ti awọn meji si ti kuro nile iwosan lẹyin ti wọn gbadun tan.
Ọpọ awọn ijọba orilẹ-ede agbaye lo ti kede pe ki awọn eeyan joko sile nitori arun naa ṣugbọn ṣe ijọba Naijiria naa le gbe iru igbesẹ yii?
Onimọ nipa ọrọ aje, Bisi Iyaniwura to ba BBC Yoruba sọrọ ṣalaye ofin konile o gbele le ma ṣiṣẹ ni Naijiria nitori iṣẹ oojọ lọpọ ọmọ Naijiria n ṣe.
Iyaniwura ni ọna to dara lati dena itankalẹ arun covid-19 ni kawọn eeyan maa joko sile, ṣugbọn ''ti a ba ni kawọn eeyan joko sile ni tootọọ, kinni wọn o maa jẹ?''
Oríṣun àwòrán, Getty Images
''Tí a bá ní káwọn èèyàn jókòó sílé nítorí coronavirus, ebi ni yóò pa ọ̀pọ̀lọpọ̀''
''Jijoko sile lọrọ coronavirus ba de ṣugbọn ẹni ebi n pa ko gbọ Anago,'' Iyaniwura ni lẹyin ebi to maa pa awọn eeyan, jijoko sile le mu ki ọpọ maa jale.
Ọgbẹni Iyaniwura fikun ọrọ rẹ pe iwadii ti fihan pe ida ọgọrin ninu ọgọrun un awọn ọmọ Naijiria lo n ṣiṣẹ oojọ, eyi tun maa jẹ ki o nira lati sọ fawọn eeyan pe ki wọn joko sile.
O ni ti ọpọ ọmọ Naijiria ko ba lọ si ibi iṣẹ fun ọjọ kan, ko si ohun ti wọn fẹ jẹ.
Nikesuliat: Ọ̀dọ́mọdébìnrin akéwì tó n fi ẹ̀ṣà kìlọ̀ ìwá lásìkò yìí
Iyaniwura ni jijoko sile yoo pa ọrọ aje Naijiria lara nitori owo epo to jẹ ọrọ aje Naijiria ti lọọlẹ.
O sọ pe eyi gan an lo maa jẹ ki ijọba Naijiria naa maa ro daadaa ki wọn to le gbe igbesẹ naa.
Àwọn fíìmì òde òní ń kọ́mọ lólè àti ọ̀pọ̀ ìwà burúkú
Coronavirus in Nigeria: Èèyàn mẹjọ míràn tún ti ní àrùn Coronavirus ní Naijira
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Nibayii, o ti di eeyan mẹtadinlọgọrun un (97) to ti ni aarun naa lorilẹede Naijiria.
Eniyan mẹjọ miran tun ti ni aarun coronavirus ni orilẹ-ede Naijiria.
Ajọ to n risi idena ati amojuto ajakalẹ aarun ni, NCDC lo fi ikede naa sita lalẹ ọjọ Abamẹta loju opo Twitter rẹ.
Meji ninu awọn eeyan ọhun wa ni Abuja, mẹrin ni ipinlẹ Oyo, ẹnikan lati Kaduna ati ẹnikan mii lati ipinlẹ Osun.
"Coronavirus in Nigeria: Ẹ wo bí ẹ ṣe lè ṣe ""hand sanitizer"" nínú ilé yín"
Nibayii, o ti di eeyan mẹtadinlọgọrun un (97) to ti ni aarun naa lorilẹede Naijiria.
Oríṣun àwòrán, davido/instagram
Gbajugbaja olorin takasufe, David Adeleke ti ọpọ awọn ololufẹ rẹ mọ si Davido ti sọ pe afẹsọna oun, Chioma ti ni aarun Coronavirus.
Davido lo fi ọrọ naa sita loju opo Instagram rẹ, nibi to ti ṣalaye pe bi oun ṣe de lati America laip yii, naa ni afẹsọba oun, Chioma de lati ilẹ Gẹẹsi pada si Naijiria.
O ni awọn mejeji ko ṣafihan apẹẹrẹ aarun naa, ṣugbọn wọn lọ fun ayẹwo gẹgẹ bi agbekalẹ ajọ to n dena ajakalẹ arun, NCDC, ti esi ayẹwo naa si fi han pe Chioma ti ni arun naa.
Davido ni ayẹwo ọmọ oun ati Chioma fi han pe ọmọ naa ko ni arun naa lara, ati pe Chioma ko ti ma ṣafihan apẹrẹ aarun ọhun.
Gẹgẹ bo ṣe sọ, o ni oun ti ya ara oun sọtọ  fun ọjọ merinla bayii.
Lẹyin naa lo dupe lọwọawọn ololufẹ rẹ, to si parọwa fun wọn ki wọn duro sile wọn lasiko yii.
Oríṣun àwòrán, Google
Eniyan maarun miran tun ti ni aarun coronavirus ni orilẹ-ede Naijiria.
Eniyan meji lo wa ni ipinlẹ Ọyọ lara wọn, mẹta si wa lati ilu Abuja.
Ajọ to n risi idena ati amojuto ajakalẹ aarun ni Naijiria, NCDC lo fi ikede naa sita lalẹ ọjọ Ẹti loju opo Twitter rẹ.
Nibayii, o ti pe aadọrin eniyan (70) to ti ni aarun naa ni Naijiria.
Ìjọba ìpínlẹ̀ Osun ṣetán láti tilẹ́kùn ibodè rẹ̀ nítorí Coronavirus
Oríṣun àwòrán, @GboyegaOyetola
Ijọba ipinlẹ Osun ti kede igbeṣẹ lati tilẹkun ibode rẹ lọna ati dena itankalẹ arun Coronavirus nipinlẹ ọhun.
Akọwe ijọba, Wole Oyebamiji lo fi ọrọ naa lede nilu Osogbo pe igbeṣẹ naa yoo bẹrẹ lati ọjọ Abamẹta, ọjọ kejidinlọgbọn, oṣu kẹta ọdun 2020.
O ni gbogbo awọn ọja nla ati ọja igbalode ni yoo di titi pa, yatọ si awọn ibi ti wọn ti n ta ogun ati ounjẹ.
Njẹ Chloroquine nipa kankan lati le koju Coronavirus
Oyebamiji tẹsiwaju pe ijọba ipinlẹ ọhun yoo ṣe adinku si iye awọn eeyan ti ọkọ akero le gbe nigbakan ṣoṣo lọna ati dẹkun itankalẹ arun ọhun.
O ni awọn ọlọkada ko ni lanfani ati ma gbe eeyan meji papọ mọ, bẹẹ ni awọn ọkọ korope ko ni ma gbe ju eeyan mẹrin lọ; ẹnikan niwaju, ẹnikan laarin ati meji pere lẹyin.
Oyebamiji wa rọ awọn to ṣẹṣẹ de lati Amẹrika, ilẹ Gẹẹsi atawọn orilẹede mii ti arun ọhunn ti ṣọṣẹ julọ si ipinlẹ Osun lati pe nọmba 293 fun alaye kikun lori bi wọn ṣe le dabo bo ara wọn ati awọn to sun mọ wọn.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ajọ to n gbogun ti itankalẹ aarun ni Naijiria, NCDC ti kede pe eniyan mẹrinla miran tun ti ni coronavirus ni Naijiria.
Eniyan mejila lara awọn ẹni tuntun yii lo wa ni ipinlẹ Eko, ti meji si wa ni ilu Abuja.
Ninu mẹrinla naa, wọn ri awọn mẹfa to ko ẹru wọle lati ori omi, mẹta miran jẹ arinrinajo. Ẹnikan to ku jẹ ẹni to ko o lati ara ẹnikan to ti kọkọ ni i.
Nibayii, eniyan marundinlaadọrin lo ti ni aarun naa ni Naijiria.
Ajọ to n gbogun ti ajakalẹ aarun ni Naijiria, NCDC ti kede pe iye eeyan to ti ni aarun Coronavirus nilẹ yi ti di mọkanlelaadọta bayii.
To n tumọ si pe aarun naa ti rapala wọ ipinlẹ mẹsan an lorilẹ-ede Naijiria.
Awọn eeyan to ni aarun naa nipinlẹ Eko ti di mejilelọgbọn, FCT jẹ mẹwaa, Ogun ni mẹta, eeyan kọọkan lo ni aarun ọhun ni ipinlẹ Ekiti, Oyo, Edo, Bauchi, Osun ati Rivers.
Coronavirus: Fífi nkan bó ìmu nìkan kò le dènà kíkó coronavirus
Ni bayii, eeyan mọkanlelaadọta lo ti lugbadi arun covid-19 ni Naijiria ninu eyi ti ẹnikan ti di oloogbe, ti awọn meji si ti kuro nile iwosan lẹyin ti wọn ri iwosan.
Coronavirus in Nigeria: Covid-19 wọ ìpínlẹ̀ Osun, èèyàn míì tún tí ni l'Eko, ó di èèyàn 46 tó níi ní Nàìjíríà
Oríṣun àwòrán, Pius Utomi Ekpei
Ajọ NCDC ṣalaye pe awọn mejeeji ṣẹṣẹ rinrin ajo de lati ilẹ okeere si Naijiria ni bi ọjọ meje sẹyin ni.
Eeyan meji mii tun ti ni aarun coronavirus lorilẹ-ede Naijiria, ajọ to n gbogun ti ajakalẹ arun ni Naijiria, NCDC to kede ọrọ naa loju opo Twitter rẹ.
Ẹnikan ninu awọn to ṣẹṣẹ larun naa wa lati ipinlẹ Osun, nigba ti ẹnikeji wa lati ipinlẹ Eko.
Ajọ NCDC ṣalaye pe awọn mejeeji ṣẹṣẹ rinrin ajo de lati ilẹ okeere si Naijiria ni bi ọjọ meje sẹyin ni.
Nibayii, eeyan mẹrindinlaadọta lo ti lugbadi arun covid-19 ni Naijiria ninu eyi ti ẹnikan ti di oloogbe ti awọn meji si ti kuro nile iwosan lẹyin ti wọn gbadun tan.
Ọgbọn eeyan ninu awọn mẹrindinlaadọta to ni arun covid-19 ni Naijiria lo wa lati ipinlẹ Eko, nigba ti meji wa lati Abuja.
Ipinlẹ Ogun lo ṣe ipo kẹta pẹlu eeyan mẹta to ni arun naa, eeyan kọọkan lo ni arun ọhun lati ipinlẹ Ekiti ati Oyo.
Ipinlẹ Edo, Bauchi ati Osun naa ni eeyan kọọkan to ni arun coronavirus bayii.
Coronavirus: Gbogbo igbá ti ṣófo láwọn ilé ìtajà káàkiri London
Coronavirus: Odaran tíì kí bá ṣé ọmọ orílẹ̀èdè Ethiopia yóò padà sí ìlú abinibi rẹ
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ẹgbẹrun mẹrin awọn to wa lọgba ẹwọn lorileede Ethiopia ni ijọba ilẹ naa ti ni oun yoo tusilẹ nitori ajakalẹ aarun Coronavirus.
Gẹgẹ bi wọn ti ṣe sọ, wn ni igbesẹ yi yoo jẹ ọna kan gbogi lati dẹkun ajakalẹ aarun naa.
Agbẹjọro agba orileede naa ṣalaye pe awọn ọdaran ti wọn n ṣẹwọn lori ẹsun pẹẹpẹẹpẹ ati awọn obinrin wọn ni ọmọ lọwọ yoo wa lara awọn ti yoo gba itusilẹ.
Awọn ọmọ orileede mìíràn tí wọn mú fún ẹsun ṣiṣe owó ẹrú àti àwọn tí wọn ń ṣe fayawo náà wá lára àwọn tí wọn yóò gbà itusile ti wọn yóò sì dá olúkúlùkù padà sí ìlú abinibi wọn.
Lára àwọn tí yóò tún gba itusile ni àkòroyín kan Fakadu Mahtemework.
Oga agba oniroyin náà padà sí Ethiopia leyin ti asoju ijoba Ahmed Abiy gorí alefa lodun 2018 lásìkò tí wọn tú òpó àwọn tí wọn mu nítorí oselu silẹ.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ṣùgbọ́n wọn ní pe o jẹ owo ori, ejò yìí ni wón ṣe leyin rẹ tí wọn sì ju sì ẹwọn ọdún méje ni inu osu Kẹ̀wá ọdún tó kọjá.
Ilana miran ti ijoba Ethiopia tún gunle ni lati ṣètò àwọn ilé ìtura kan fún àwọn arìnrìn-àjò tí wọn sì ti kan ń pá fún àwọn osise láti maa ṣiṣẹ láti ilé wọn àti pé gbogbo ẹnu ibodè tó wọ orileede náà ni kò wá ní titi pa.
Àwọn ọmọ orileede Ethiopia tí kò bá lè san owó náà, ijoba ni àwọn yóò sanwó wọn.
Ó lè ní irínwó àwọn arìnrìn-àjò lọ sí Ethiopia to tí bẹ̀rẹ̀ igbele túláàsì gẹ́gẹ́ bi atejade tí minisita fún ìlera Ethiopia fi síta.
Ènìyàn méjìlá lọ tí ni aarun Coronavirus ni Ethiopia
Coronavirus: Gbogbo igbá ti ṣófo láwọn ilé ìtajà káàkiri London
Aarẹ orileede Uganda,Yoweri Museveni tí fi ofin de ìgbòkègbodò ọkọ jákèjádò orile náà fún òjò mẹ́rìnlá láti dekun ìtànkalẹ aarun Coronavirus.
Amohunmaworan orileede náà ni Aare tí soro ni Ọjoru, èyí tó sì ni yóò bẹ̀rẹ̀ loni waransesa.
Ni Uganda, Boda-boda ni orukọ ti wọn n pe alupupu akero ọkada.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Kò tán síbẹ̀, ọkọ aladani ni orileede Uganda kò gbogbo kò ju èrò mẹta lọ tó fi mọ awako.
Ènìyàn merinla péré ni àwọn aláṣẹ Uganda ṣẹṣẹ fi idi rẹ mulẹ pé wọn ní aarun náà tó fi mọ ọmọdébìnrin oṣù mejo kan.
Iroyin tún sọ pé àwọn ọmọ orileede Uganda miran ti ko tilè rìn ìrìn-àjò kúrò ní Uganda farakasa aisan naa.
Ẹwẹ àwọn ọja tó máa ń kún fòfò náà yóò kogbasile afi àwọn èyí tí wọn tí ń tà oúnjẹ jíjẹ
Ní ose tó kọjá ní aare ni kí wọn tí gbogbo ilé ìwé, ilé ọtí, àti àwọn ibi igbafe, gbogbo ilé ìworán àti pé ipejopo kò gbọ́dọ̀ ju ènìyàn méjìlélọ́gbọ̀n lọ.
Ijọba orilẹ-ede Australia ti sọ pe oun ko faaye gba ju eeyan marun un pere ti yoo wa nibi ayẹyẹ igbeyawo ati mẹwaa nibi isinku lọna ati dẹkun itankalẹ aarun Coronavirus.
Adari ijọba Scott Morrison lo kede igbeṣẹ yi lẹyin ipade to ṣe pẹlu awọn minisita orilẹ-ede ọhun.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Èèèyàn mẹ́wàá péré ló leè lọ ayẹyẹ ìsinìkú ní Australia báyìí nítorí àrùn Coronavirus
O ni ijọba ilẹ naa yoo wọgile ọpọ lara irin ajo okeere ati pe awọn ibi igbafẹ ita gbangba ni yoo di titi pa.
Ofin tuntun yi ni ijọba Australia sọ pe yoo bẹrẹ lati ago kan ọsan, ọjọ karundinlogun, oṣu kẹta, ọdun 2020 lẹyin ti iye awọn eeyan to ni aarun Coronavirus n peleke sii.
O kere tan, eeyan to fara kaasa aarun naa le ni irinwo laarin wakati mẹrinlelogun, leyi to ti mu ki iye awọn to n ba arun ọhun finra naa le ni ẹgbẹrun meji bayii.
Coronavirus: Gbogbo igbá ti ṣófo láwọn ilé ìtajà káàkiri London
Ni bayii, ijọba ilẹ naa ti gbe agadagodo sẹnu ọna awọn ile ijọsin ati ile ọti, ṣugbọn ko tii gbeṣẹle ile iwe gẹgẹ binawọn orilẹ-ede miran.
Afurasí Boko Haram pa ogójì ọmọ ogun ilẹ̀ Nàìjíríà ní Borno:
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Afurasí Boko Haram pa ogójì ọmọ ogun ilẹ̀ Nàìjíríà ní Borno
Awọn alakatakiti ẹsin Islam, boko Haram ni wọn fura si pe wọn ti ṣeku pa ọmọ ogun ilẹ̀ Naijiria to le ni ogoji nipinlẹ Borno.
Awọn agbesunmọmi yii kọlu ọkọ ọmọ ogun ilẹ̀ Naijiria lasiko ti wọn n wọ aarin igbo Sambisa ni ariwa iwọ oorun Naijiria.
Iroyin ti a kọkọ gbọ sọ pe o le ni aadọrin eniyan lo ku si iṣẹlẹ naa tẹlẹ.
Ogagun Abdulssalam Sani tó jẹ́ alukoro fun ileeṣẹ ọmọ ogun lori iṣẹ akanṣe ṣalaye pe awọn naa pada kọlu awọn oniṣẹ ibi naa.
Iroyin ni awọn miran ninu awọn ọmọ ogun ṣi wa ni ile iwosan fun itọju bayii.
Titi di asiko yii, ko sẹni to tii le sọ nipato boya awọn oniṣẹibi alakatakiti ẹsin Islam, Boko Haram lo ṣiṣẹ naa tabi bẹẹkọ, ṣugbọn awọn ni wọn fura si.
'Èmi gan máa ń béèrè lọ́wọ́ ara mi pé ta ni Wole Soyinka gangan'
Ogagun Abdulssalam Sani ṣalaye fun BBC pe awọn ọmọ ogun ofurufu tete dide iranwọ lasiko ikọlu yii ni kete ti wọn ri ipe pajawiri awọn ọmọ ogun ilẹ̀ Naijria gba.
Bakan naa ni Ogagun Sani sọ fun BBC pe awọn ọmọ ogun ofurufu lo pada gbẹsan lara awọn oniṣẹ ibi naa ninu igbo Sambisa nipinlẹ Borno.
Àwọn fíìmì òde òní ń kọ́mọ lólè àti ọ̀pọ̀ ìwà burúkú
'Ẹ dárí ẹ̀ṣẹ̀ mi jìnmí, àmọ́ èmi nìkan kọ́ ló ṣẹ̀,' Ajimobi bẹ ọmọ ẹgbẹ́ APC l'Oyo
Oyo APC Crisis: Gómìnà Oyo tẹ́lẹ̀, Ajimobi tọrọ àforíjì lọ́wọ́ àwọn ọmọ ẹgbẹ́ APC l'Oyo
Abiola Ajimobi ni ''a kii mọọ rin, k'ori o ma mi,'' o ni oun gba pe oun ṣe awọn aṣiṣe kan ṣugbọn oun tọrọ aforiji lọwọ gbogbo ọmọ ẹgbẹ.
Oríṣun àwòrán, Instagram/abiolaajimobi
Ẹ dari aṣiṣe mi ji mi, amọ emi nikan kọ ni mo ṣe aṣisẹ, awọn miiran naa ṣe aṣiṣe bi temi, gomina ipinlẹ Oyo tẹlẹ, Sẹnẹtọ Abiola Ajimobi lo sọrọ yii nibi ipade igbimọ to n pẹtu si aawọ ninu ẹgbẹ oṣelu APC.
Ajimobi to jẹ igbakeji alaga ẹgbẹ APC lapa gusu orilẹede Naijiria lo ṣe agbekalẹ igbimọ ẹlẹni mẹrindinlogun naa ti gomina ipinlẹ Oyo tẹlẹ, Adebayo Alao Akala jẹ alaga rẹ.
Nigba to n sọrọ nibi ipade naa, Ajimobi ni gbogbo ọmọ ẹgbẹ lo kopa ribiribi ninu aṣeyọri ẹgbẹ APC nipinlẹ Oyo lọdun 2011 ati 2015.
Ṣugbọn Ajimobi ni bakan naa ni gbogbo ọmọ tun kopa ninu ijakulẹ ẹgbẹ APC ninu idibo gbogbogbo ọdun 2019 lọna kan, tabi omiiran.
Ajimobi ni ''a kii mọọ rin, k'ori ma mi,'' o ni oun gba pe oun ṣe awọn aṣiṣe kan ṣugbọn oun tọtọ aforiji lọwọ gbogbo ọmọ ẹgbẹ.
Amọ, o ni loun ti gba ẹbẹ awọn ọmọ mii tawọn naa ti ṣe aṣiṣe kan tabi omiiran.
Oríṣun àwòrán, Instagram/abiolaajimobi
Ajimọbi rọ gbogbo ọmọ ẹgbẹ APC nipinlẹ Oyo lati dariji ara wọn nitori akoko niyii lati ṣe atunṣe ẹgbẹ naa ṣaaju ipenija to le wa lọjọ iwaju.
O ni asiko ti to fun gbogbo ọmọm ẹgbẹ APC lati fi iwa imọtara ẹni nikan silẹ, ki wọn si maa lepa ilọsiwaju ẹgbẹ naa.
Awọn inu ẹgbẹ naa nipinlẹ Oyo bi Ọjọgbọn Prof Dibu Ojerinde, Sẹnẹtọ Teslim Folarin, Họnọrebu Segun Odebunmi, Pa Akin Ojebode, Alhaji Laide Abass, Pa Adeleke atawọn mii.
Coronavirus in Nigeria: Ẹ wo àǹfààní tó wà nínú àrùn Coronavirus
Coronavirus Update: Olóòtú Ilẹ̀ Gẹ̀ẹ́sì, Boris Johnson ti kó àrùn Coronavirus!
Oríṣun àwòrán, Reuters
Ijọba Ilẹ Gẹẹsi ni Olootu ijọba Ilẹ Gẹẹsi, Boris Johnson ti ko arun Coronavirus.
Downing Street to fi lede ni Johnson n fi apẹrẹ diẹdiẹ han pe o ni arun naa lara, ti o si ti wa ni ahamọ ni ile rẹ bayii.
Atẹjade ti wọn fi lede sọ wi pe lẹyin ti Olori ẹka eto iwosan ni Ilẹ Gẹẹsi, Ọjọgbọn Chris Whitty gba a ni imọran lo lọ ṣe ayẹwo ara rẹ naa.
Atẹjade naa fi lede pe Arakunrin Johnson ni yio si ma a ṣẹ akoso ijọba, ati igbogun ti arun Coronavirus.
Ọgbẹni Johnson sọ pe oun ṣafihan apẹrẹ arun naa bii ara gbigbona ati ikọ lati nkan bi wakati mẹrinlelogun ṣeyin.
"Ninu fidio kan to fi lede loju opo Twitter, o ni ""Mo ti bẹrẹ si n ṣiṣẹ lati ile mi bayi, mo si ti ya ara mi sọtọ fun itọju gẹgẹ bi ohun to tọ lati ṣe lasiko yi."""
Njẹ Chloroquine nipa kankan lati le koju Coronavirus
Lalẹ Ọjọbọ ni ọgbẹni Johnso darapọ mọ awọn ara ilu lati fi ẹmi imore han si ileeṣẹ eto ilera ilẹ naa fun iṣẹ takuntakun ti wọn ti ṣẹ fun awọn to ni arun naa.
A ko tii le sọ boya ọgbẹni Johson yo ṣi ma gbe papọ pẹlu afẹsọna rẹ, Carrrie Symond to wa ninu oyun lọwọ yii.
Yatọ si Johsnon, awọn eeyan nla mii to ti fara kaasa arun Coronavirus nilẹ Gẹẹsi ni ọmọ Ọba ilẹ Wales ati ọmọ Ọba ilẹ Gẹẹsi, Charles.
Ni bayii, o le ni ẹgbẹrun mọkanla  awọn eeyan to ti ni Coronavirus nilẹ Gẹẹsi, ti awọn to le ni ẹẹdẹgbẹta si ti jẹ Ọlọrun nipe.
Ilẹ Amẹrika ma ti gba ipo kini gẹgẹ bi orileede ti itankalẹ Coronavirus ti poju lọ lagbaye pẹlu eniyan to le ni ẹgbẹ̀rún lọ́nà márùndínláádọ́rún to ti ni arun naa.
Iye èèyàn tó ní àìsàn náà níbẹ̀ ti kọjá ẹgbẹ̀rún lọ́nà márùndínláádọ́rún, àmọ́ iye èèyàn tó kù níbẹ̀ kò tó ti Italy ati China
Akọsilẹ fihan wi pe orilẹede Amerika ti bori China to ni ẹniyan to le ni ẹgbẹrun lọna ọgọrin (81,782) ati Italy to ni eniyan to le ni ẹgbẹrun lọna ọgọrin(80,589) to ni arun naa.
Amọ iye awọn eniyan to ti ku ni orileede China to le ni ẹgbẹrun lọna mẹta (3,291)ati ti Italy ẹgbẹrun lọna mẹjọ (8,215)pọ ju ti orilẹede Amerika to le ni ẹgbẹrun kan lọ (1,300).
Itankalẹ arun yii peleke si lẹyin ti Aarẹ Donald Trump sọ wi pe o da oun loju pe orilẹede naa yoo pada si ipo laipẹ.
Aarẹ Donald Trump lasiko to n fesi si ọrọ naa ni idi ti nọmba awọn to ni arun naa fi peleke si ni pe awọn n se ayẹwo fun awọn eniyan loju mejeeji lo jẹ ko ri bẹẹ.
Igbakeji aarẹ orilẹede Amerika, Mike Pence sọ wi pe ẹgbẹgbẹrun ile iwosan ayẹwo lo ti wa ni gbogbo ipinlẹ aadọta to wa lorilẹede naa.
Awọn ileeṣẹ ologun lorileede South Afrika ti bẹrẹ si ni fi ofin konileogbele ọlọsẹmẹta  mulẹ lọna ati fopin si itankalẹ arun Coronavirus.
Lilọ bibọ pata ni ofin yi lọdi si, yatọ si awọn to ba n ṣiṣẹ koṣemani ti awọn ọlọpaa ati ọmọ ogun si ti wa ni ṣẹpẹ lati fi ofin na rinlẹ.
Oríṣun àwòrán, AFP
Ṣaaju ki ofin naa to gberasọ ni oru ọjọbọ,niṣe ni awọn ile itaja kun fọfọ ti awọn eeyan si n sare ra ọja witiwiti.
Lorileede South Afrika, eeyan ẹtadinlọgbọnlelẹẹdẹgbẹrun ni o ti ni aisan naa eleyi to pọjulọ ni Afrika.
Ko i ti si eeyan kankan to ku ni ilẹ naa latari aisan naa.
Oríṣun àwòrán, EPA
Lalẹ Ọjọbọ ni a ri aarẹ Cyril Ramaphosa nibi to ti ṣe abẹwo si awọn ọmọ ogun ni ibudo wọn to wa ni Soweto.
Ijọba ti kilọ pe ẹnikẹni to ba tapa si ofin konileogbele yoo fi ẹwọn oṣu mẹfa jura.
Labẹ ofin naa, awọn ile itaja to ba n ta ounjẹ nikan ni wọn yoo ṣi kalẹ ti wọn si ti wọgile tita ọti.
Coronavirus: Fífi nkan bó ìmu nìkan kò le dènà kíkó coronavirus
O sọ fun awọn ọmọ ogun ilẹ naa pe ''mo ran yin jade lati lọ daabo bo awọn eeyan wa lọwọ Coronavirus ni''
''Ohun ti ko ṣẹlẹ ri ni ninu itan ilẹ wa pe ki a deju awọn eeyan mọlẹ fun ọjọ mọkanlelogun lati lọ doju ija kọ ọta ti a ko fi oju ri''
BuhariAddressNigerians:Ààrẹ f'òfin de irina ni Eko,Ogun ati Abuja fọjọ́ mẹ́rìnlá gbako
Oríṣun àwòrán, NTA
Aarẹ orileede Naijiria,Muhammadu Buhari ti kede pe ko ni si wiwọle tabi jijade ọkọ laarin ipinlẹ Eko,Ogun ati Abuja fun ọjọ mẹrinla gbako.
Iṣede yi to paṣẹ rẹ yoo bẹrẹ laago mọkanla lọjọ Aje ti ṣe ọgbọn ọjọ oṣu Kẹta.
Ninu ọrọ to ba awọn ọmọ Naijiria sọ lori ajakalẹ arun Corona Virus lo ti fi aṣẹ yi lelẹ gẹgẹ bi ọna ati dẹkun itankalẹ Coronavirus ni Naijiria
Aarẹ ni gbogbo awọn eeyan agbegbe ti iṣele yi kan ni ki wọn ma se jade rara.
Gbogbo karakata ati ileeṣẹ pata ni yoo wa ni titi pa.
O fi kun pe ọrọ yi ko ni kan awọn oniṣẹ ilera ati awọn ti o n pese irinṣẹ ilera.
Amọ akọroyin kankan ti yoo ba jade sita ni lati fi ẹri han pe oun ko le ṣe iṣẹ lati ile afi ni ọfisi rẹ.
Oríṣun àwòrán, BashirAhmaad
Femi Adeshina to jẹ oluranlọwọ agba aarẹ Buhari ni o fi ọrọ yi sita loju opo Facebook rẹ pe aarẹ yoo ba awọn eeyan Naijiria sọrọ lalẹ ọjọ Aiku.
Ni ọsan ọjọ Abamẹta ni Minisista feto ilera ati ọga agba ajọ ileesẹ to n gbogun ti arun NCDC ṣabẹwo si aarẹ nile ijọba.Lẹyin ipade naa,
Minisita ilera Osagie Ehanire ni awọn wa fi to aarẹ leti iru ipenija to wa niwaju pẹlu arun Coronavirus ati ọna lati le fi koju rẹ.
O ti to ọjọ mẹta ti awọn ọmọ Naijiria ti n reti ki aarẹ Muhammadu Buhari ba wọn sọrọ paapa julọ lori ajakalẹ Coronavirus.
Lori ẹrọ amounmworan orileede Naijiria ni Adeshina ni aarẹ yoo ti ba awọn ọmọ Naijiria sọrọ laago meje alẹ.
Ninu iroyin miran,Ọga agba patapata fun ileeṣẹ ijọba to n risi wọlewọde lorilẹde yii, NIS, Muhammed Babandede ti fara kaasa arun Coronavirus.
Ṣaaju ni Babandede ti kọ ya ara rẹ sọtọ fun ayẹwo lẹyin to tirin ajo de lati ilẹ Gẹẹsi lọjọ kejilellogun oṣu yii.
Oríṣun àwòrán, @chimbiko_jerome
O ni oun ti wa ni apapmọ bayii fun itọju to peye.
"Coronavirus in Nigeria: Ẹ wo bí ẹ ṣe lè ṣe ""hand sanitizer"" nínú ilé yín"
Lẹyin naa lo wa rọ awọn ọmọ Naijria ati awọn alabaṣiṣẹ rẹ ati ranti oun ati awọn ọmọ Naijiria mii to ni arun ọhun ninu adura wọn.
Oríṣun àwòrán, NGRPresident
Aarẹ orileede Naijiria Muhammadu Buhari ti foju han ni igba akọkọ lati igba ti awuyewuye lori ibi to sa pamọ si ti bẹrẹ loju opo ayelujara ni Naijiria pẹlu hashtag #BuhariResign.
Aarẹ Buhari gbalejo Minisita feto ilera ati ọga agba ajọ to n koju aisan ni Naijiria,NCDC nile ijọba lọsan ọjọ Abamẹta.
Ninu awọn fọnran fidio ati aworan ti ileeṣẹ aarẹ Naijiria fi sita, a ri ti aarẹ Buhari joko jina si Minisita Osagie Ehanire ati Dokita Chikwe Ihekweazu.
Oríṣun àwòrán, NGRPresident
Gẹgẹ bi akọle awọn aworan naa ti ṣe ṣalaye, ileeṣẹ aarẹ ni awọn mejeeji wa jabọ fun aarẹ bi nnkan ti ṣe n lọ pẹlu kikoju ajakalẹ Coronavirus.
Lẹnu ọjọ mẹta yi ti iroyin ti lu sita pe olori awọn oṣiṣẹ fun Aarẹ Muhammadu Buhari, Abba Kyari naa ti ni arun Coronavirus ni awọn eeyan ti ni awọn ko ko firi aarẹ Muhammadu Buhari mọ.
Loju opo Twitter, awọn eeyan  n beere pe nibo ni aarẹ wa tawọn kan si ni o ti lọ gba itọju lẹyin odi.
Kete ti fọnran fidio ati aworan aarẹ jade loju opo Twitter lawọn ọmọ Naijiria ti n sọ ero ọkan wọn.
Awọ ọmọ Naijiria kan ko tilẹ gbagbọ pe aarẹ gangan lo wa ninu fọnran fidio naa ti wọn si ni afi dandan nki o ba awọn eeyan Naijiria sọrọ loju koroju
Awọn minisita lorilẹede Naijria ti sẹlẹri lati fi ida aadọta lara owo osu kẹta wọn ṣe iranwọ fun ijọba Naijria lati koju arun Coronavirus.
Oluranlọwọ pataki fun Aarẹ Muhammadu Buhari, Bashir Ahmad lo fi lede loju opo Twitter rẹ ni Ọjọ Satide pe inu atẹjade ti minisita fun ọrọ iroyin, Alhaji Lai Muhammed fi lede ni iroyin naa wa.
Ahmad ni awọn minisita mẹtalelọgọrin lorilẹede Naijria lo ṣetan lati gbe igbeṣẹ ti yio mu atunse ba gbigboju ti ajakalẹ arun naa to n ja nilẹ rain.
Iroyin sọ wi pe awọn minista naa gbe igbesẹ naa lati ṣe moriya fun igbesẹ ijọba lati koju arun naa.
Bakan naa ni awọn minisita naa gboriyin fun Aarẹ Muhammadu Buhari fun iṣẹ takuntakun ti wọn n ṣe lati gbogun ti arun naa.
Ọjọbo, ọsẹ yii ni orilẹede Naijiria gba awọn ohun elo ayẹwo ti gbajugbaja oniṣowo ọmọ China, Jack Ma, to jẹ oludasilẹ ile itaja ayelujara ti a mọ si Alibaba fi ṣe iranwọ fun awọn orilẹede ni ilẹ Afrika lati fi gbogun ti itankalẹ arun Coronavirus ni agbaye.
Ọga agba kan lori ọrọ eto ilera ni Naijiria, Abdulaziz Abdullahi sọ wi pe Jack ma fun Naijiria ni ẹgberun lọna ọgọrun ibomu, ibọwọ ati awọn asọ  to le dena arun Coronavirus to to ẹgbẹrun kan,  ati ẹrọ ayẹwo to le ni ẹgbẹrun lọna ọgun.
Awọn olowo miran lorilẹede Naijiria naa ti n fi owo ati ohun elo se iranwo fun orilẹede Naijiria lati fi koju arun yii.
Ẹ wo àwọn olówó tí wọ́n ti ṣe ìrànwọ́ fún Naijiria láti kojú àrùn Coronavirus:
Oríṣun àwòrán, Google
Igbakeji aarẹ lorilẹede Naijiria tẹlẹri, Atiku Abubaka fi aadọta miliọnu Naira, N50million, se iranwọ fun orilẹede Naijiria lati kapa arun Coronavirus lorilẹede Naijiria.
Atiku ni oun gbagbọ pe owo iranwọ naa yoo fun awọn oṣiṣẹ eto ilera laaye lati dẹkun itankalẹ arun naa ni Naijiria.
Oríṣun àwòrán, Google
Gbajugbaja onisowo lorilẹede Naijiria ati ni ilẹ Afrika, Aliko Dangote ti fi igba miliọnu naira, N200million ṣe iranwọ fun ijọba orilẹede Naijiria lọna ati dẹkun itankalẹ arun Coronavirus ni Naijiria.
Dangote ni ẹni to lowo julọ nilẹ adulawọ.
Oríṣun àwòrán, Google
Alaga ile ifowopamọ United Bank of Africa, UBA  ti fi owo to le ni biliọnu marun un naira, N5billion, ṣe iranwọ fun ijọba Naijiria ati orilẹede mẹtadinlogun ni ilẹ Afrika ki wọn le fi gbogun ti itankalẹ arun naa.
Elumelu ni owo naa yoo ṣe iranwọ fun ilẹ Afrika lati pese ohun elo iranwọ, eto iwosan pajawiri ati owo iranwo fun ijọba.
Bakan naa, o ni wọn yoo pese ileewosan ti yoo ma a se ayẹwo fun awọn eniyan ni ipinlẹ ti arun naa ti de si niNaijiria.
Oríṣun àwòrán, Google
Adari ile ifowopamọ GT, Segun Agbaje ti fi ile iwosan to ni ọgba ibusun ọgọrun un fun ipinlẹ Eko, gẹgẹ bii iranwọ fun ijọba nipa igbogun ti arun Coronavirus.
Agbaje sọ wi pe awọn yoo ri wi pe ile iwosan naa ni ohun elo iwosan ti wọn nilo to fi mọ ẹrọ ti n ṣe iranwọ fun ati mi ‘respirators’ fun awọn to n gba itọju fun arun Coronavirus.
Oríṣun àwòrán, Google
Abdul-Samad Rabiu to jẹ adari ileesẹ BUA Group ti ṣe iranwọ fun orilẹede Naijiria pẹlu biliọnu kan naira, N1billion, lati gbogun ti arun Coronavirus.
O fikun wi pe oniṣowo naa ti bere fun iranwọ awọn ohun elo miran ati ohun elo ilera fun awọn oṣiṣẹ eleto ilera lati le ṣe iṣẹ wọn bi iṣẹ lasiko igbogunti arun Coronavirus yii.
Minisita fun eto ilera, Osagie Ehanire ti ni Naijiria ko mọ pe Coronavirus yoo ri bi o ṣe ri yii nitori wọn ko ṣe igbaradi to peye fun un.
Ehanire ni arun naa ṣe ajoji si gbogbo eniyan to fi mọ awọn orilẹede to ni eto iwosan to peye naa, nitori naa lo ṣe n ja rainrain ni gbogbo agbaye.
Oríṣun àwòrán, TWITTER/@FMOHNIGERIA
O ni orilẹede Naijiria ati gbogbo agbaye to ku ti kọ ẹkọ to peye lati ara arun Coronavirus, ti wọn n pe ni Covid-19.
Ki lo fa Ija lọbalọba ni ilu Iwo
Minisita naa ni to ba ṣe pe wọn gbaradi fun un, wọn ko ni ni iye awọn eniyan to ti ku latari aisan naa.
Bakan naa lo fikun wi pe lootọ ni ọkan gboogi ni ijọba aarẹ Buhari wa n gba itọju lẹyin ti ayẹwo fihan pe o ni arun Coronavirus.
Minisita fun eto ilera, Osagie Ehanire  naa wa ni awọn ṣi n wa awọn ti wọn ti ṣe ipade pẹlu awọn ti o ti ni arun naa.
Àkòjọpọ́ àwọn nkan tó ṣẹ́lẹ̀ lágbo tíátà Yoruba lọ́sẹ̀ yìí
Oríṣun àwòrán, Instagram
Awọn oṣere Yollywood ti dawọ sinima yiya duro bayii nitori itankalẹ aarun coronavirus.
Alaga ẹgbẹ TAMPAN, to jẹ agbarijọpọ awọn oṣere tiata, Alagba Bolaji Amusan, Mr Latin lo fi ikede naa sita lori ayelujara Instagram rẹ.
Mr Latin sọ ninu fidio naa pe ati ẹgbẹ TAMPAN ati ẹgbẹ awọn alagbata sinima fi ẹnu ko nibi ipade kan ti wọn ṣe lọjọ lọsẹ yii pe osere kankan ko gbọdọ ya sinima kankan lati ọjọ kẹtadinlọgbọn, oṣu Kẹta titi di ọjọ kẹtadinlogun, oṣu Kẹrin ọdun 2020.
O sọ pe awọn ṣe bẹ nitori itankalẹ aarun coronavirus.
Bakan naa lo sọ pe ida ẹgbẹ yoo ge oṣere yoowu to ba ru ofin naa.
Ninu iroyin miran, gbaju-gbaja oṣere to tun jẹ olokoowo, Lizzy Anjorin sọ pe itankalẹ aarun coronavirus ko le da ọja tita oun duro.
Ninu fidio kan to fi sita lori Instagram lo ti sọ bẹ, to si tun gba awọn ololufẹ rẹ ni imọran lati ṣe bakan naa nitori ebi.
Koda, o rọ wọn lati ṣe ajọpin ounjẹ de ọdọ awọn alaini.
Lara awọn ti ọjọ ibi wọn ko ọni ọsẹ yii ni:
Regina Chukwu ṣe ọjọ ibi. Arẹwa obinrin naa sọ pe Ọlọrun nikan lo ye bi ọrọ aye oun ṣe n lọ.
Oríṣun àwòrán, Instagram/regina chukwu
Ọjọ kẹtalelogun, oṣu Kẹta ni ọjọ ibi rẹ.
Kii wa a ṣe Regina nikan lo da ni ọjọ naa o.
Bakan naa ni arẹwa obinrin, Oyebade Adebimpe naa pe ọdun miran loke eepẹ. Koda, aarun coronavirus ko da ayẹyẹ duro. Awọn eniyan buta sẹnu nibi ayẹyẹ ọjọ ibi.
Ọjọ naa gan an ni ọjọ ibi agba oṣere, Aina Gold. Ninu fidio kan to fi sita, niṣe ni awọn ọrẹ rẹ fi omi wẹ ẹ lati ṣajọyọ ọjọ naa.
Gbaju-gbaja oludari ere, Adebayo Tijani naa ṣe ayẹyẹ ọjọ ibi. Bakan naa ni arẹwa obinrin, Lola Margaret naa tun dupẹ pe oju oun ri ọdun miran loke eepẹ.
Oríṣun àwòrán, Instagram/lola margaret
Oríṣun àwòrán, Instagram/adebayo tijani
Agba oṣerebinrin, Joke Muyiwa ṣọjọ ibi tiẹ naa lọsẹ yii, ọmọ rẹ tun bimọ tuntun.
Oṣere naa ko le pa idunnu rẹ mọra rara. Ninu ọrọ to fi sita, o sọ pe ẹbun ọjọ ibi to ṣe iyebiye ju ni ọmọ tuntun naa jẹ fun oun.
Coronavirus in Nigeria: Ààrùn Covid-19 ti ran ènìyàn 454 míràn ní Nàìjíríà
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Awọn eeyan mẹrinlelaadọta o le ni irinwo tuntun ni ajọ NCDC to n mojuto itankalẹ ajakalẹ arun ni Naijiria fi sita lalẹ ana ọjọ Ẹti, Ọjọ kẹta, Oṣu keje, ọdun 2020 pe wọn ṣẹṣe lugbadi Covid 19.
Bi akọsilẹ naa ṣe lọ niyii pẹlu ipinlẹ kọọkan ti wọn ti ri awọn eeyan naa
Lagos-87
Edo-63
FCT-60
Ondo-41
Benue-32
Abia-31
Ogun-29
Oyo-19
Kaduna-17
Delta-16
Enugu-15
Borno-14
Plateau-9
Nasarawa-8
Kano-5
Bauchi-4
Gombe-2
Katsina-1
Kogi-1
Titi di oni, ọjọ Abamẹta, ọjọ kẹrin, oṣu keje, ọdun 2020, iye awọn to ti lugbadi Covid 19 ni Naijiria lapapọ jẹ 27,564.
Awọn to ti ri iwosan ti wọn ti pada sile wọn jẹ: 11,069.
Awọn to ti doloogbe si jẹ 628
Àjọ NCDC kéde ènìyàn 626  tó tún ṣẹ̀ṣẹ̀ ní Coronavirus ní Nàìjíríà
Eeyan 626 tuntun mii lo ṣẹṣẹ lugbadi arun Coronavirus ni Naijiria.
Ajọ to n risi idena ati amojuto ajakalẹ arun, NCDC lo fi ikede naa sita loju opo Twitter rẹ.
Apapọ awọn to ti ni arun naa kaaakiri orilẹ-ede Naijiria ti wa di 27,110 bayii.
Eeyan 10,801 lo ti ri iwosan gba, nigba ti awọn 616 ti dero ọrun nitori arun ọhun.
Iye awọn eeyan to ṣẹṣẹ ko arun naa ni ipinlẹ kọọkan ree:
Eko-193
FCT-85
Oyo-41
Edo-38
Kwara-34
Abia-31
Ogun-29
Ondo-28
Rivers-26
Osun-21
Akwa Ibom-18
Delta-18
Enugu-15
Kaduna-13
Plateau-11
Borno-8
Bauchi-7
Adamawa-5
Gombe-4
Sokoto-1
Ajọ to n risi idena ati amojuto ajakalẹ arun, NCDC lo fi ikede naa sita loju opo Twitter rẹ.
Apapọ awọn to ti ni arun naa kaaakiri orilẹ-ede Naijiria ti wa di 26,484 bayii.
Eeyan 9,746 lo ti ri iwosan gba, nigba ti awọn 590 ti dero ọrun nitori arun ọhun.
Iye awọn eeyan to ṣẹṣẹ ko arun naa ni ipinlẹ kọọkan ree:
Delta-166
Eko-120
Enugu-66
FCT-65
Edo-60
Ogun-43
Kano-41
Kaduna-39
Ondo-33
Rivers-32
Bayelsa-29
Katsina-21
Imo-20
Kwara-18
Oyo-11
Abia-10
Benue-6
Gombe-4
Yobe-2
Bauchi-2
Kebbi-2
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ajọ to n risi idena ati amojuto ajakalẹ arun, NCDC lo fi ikede naa sita loju opo Twitter rẹ.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Apapọ awọn to ti ni arun naa kaaakiri orilẹ-ede Naijiria ti wa di 25,694 bayii.
Eeyan 9,746 lo ti ri iwosan gba, nigba ti awọn 590 ti dero ọrun nitori arun ọhun.
Iye awọn eeyan to ṣẹṣẹ ko arun naa ni ipinlẹ kọọkan ree:
Eko-200
Edo-119
Kaduna-52
FCT-52
Niger-32
Ogun-19
Ondo-16
Imo-14
Plateau-11
Abia-8
Oyo-8
Bayelsa-7
Katsina-6
Kano-5
Bauchi-3
Osun-3
Kebbi-3
Borno-2
Jigawa-1
Ajọ to n risi idena ati amojuto ajakalẹ arun, NCDC lo fi ikede naa sita loju opo Twitter rẹ.
Apapọ awọn to ti ni arun naa kaaakiri orilẹ-ede Naijiria ti wa di 25,133 bayii.
Eeyan 9,402 lo ti ri iwosan gba, nigba ti awọn 573 ti dero ọrun nitori arun ọhun.
Iye awọn eeyan to ṣẹṣẹ ko arun naa ni ipinlẹ kọọkan ree:
Eko-166
Oyo-66
Delta-53
Ebonyi-43
Plateau-34
Ondo-32
FCT-26
Ogun-25
Edo-24
Imo-15
Bayelsa-13
Benue-12
Gombe-11
Kano-11
Kaduna-11
Osun-8
Nasarawa-7
Borno-5
Katsina-2
Anambra-2
Ajọ to n risi idena ati amojuto ajakalẹ arun, NCDC lo fi ikede naa sita loju opo Twitter rẹ.
Apapọ awọn to ti ni arun naa kaaakiri orilẹ-ede Naijiria ti wa di 24,567 bayii.
Eeyan 9,007 lo ti ri iwosan gba, nigba ti awọn 565 ti dero ọrun nitori arun ọhun.
Iye awọn eeyan to ṣẹṣẹ ko arun naa ni ipinlẹ kọọkan ree:
Eko-118
Delta-84
Ebonyi-68
FCT-56
Plateau-39
Edo-29
Katsina-21
Imo-13
Ondo-12
Adamawa-11
Osun-8
Ogun-8
Rivers-6
Kano-5
Enugu-3
Bauchi-3
Akwa Ibom-3
Kogi-1
Oyo-1
Bayelsa-1
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ajọ to n risi idena ati amojuto ajakalẹ arun, NCDC lo fi ikede naa sita loju opo Twitter rẹ.
Apapọ awọn to ti ni arun naa kaaakiri orilẹ-ede Naijiria ti wa di 24,077 bayii.
Eeyan 8,253 lo ti ri iwosan gba, nigba ti awọn 554 ti dero ọrun nitori arun ọhun.
Iye awọn eeyan to ṣẹṣẹ ko arun naa ni ipinlẹ kọọkan ree:
Eko-285
Rivers-68
FCT-60
Edo-60
Enugu-56
Delta-47
Ebonyi-42
Oyo-41
Kaduna-19
Ogun-18
Ondo-16
Imo-12
Sokoto-11
Borno-9
Nasarawa-8
Abia-5
Gombe-5
Kebbi-5
Kano-4
Yobe-3
Ekiti-3
Osun-2
Ajọ to n risi idena ati amojuto ajakalẹ arun, NCDC lo fi ikede naa sita loju opo Twitter rẹ.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Apapọ awọn to ti ni arun naa kaaakiri orilẹ-ede Naijiria ti wa di 23,298 bayii.
Eeyan 8,253 lo ti ri iwosan gba, nigba ti awọn 554 ti dero ọrun nitori arun ọhun.
Iye awọn eeyan to ṣẹṣẹ ko arun naa ni ipinlẹ kọọkan ree:
Eko-259
Oyo-76
Katsina-69
Delta-66
Rivers-46
Ogun-23
Edo-22
Osun-22
Ebonyi-21
FCT-20
Kaduna-16
Ondo-10
Imo-9
Abia-9
Gombe-5
Plateau-4
Bauchi-4
Ekiti-2
Anambra-1
Ajọ NCDC to fi ikede naa sita sọ pe eeyan 159 lo ni, nipinlẹ Eko, 106 si ni nipinlẹ Delta.
Esi ayẹwo to ku niyii:
Oríṣun àwòrán, Ncdc
Awọn to ni aarun Covid-19 ni Naijiria ti pe ẹgbẹrun mejilelogun (22,020) bayii.
Eyi ribẹ lẹyin ti ajọ NCDC tun kede eniyan 649 to tun ṣẹṣẹ ni aarun naa.
Ipinlẹ Eko lo ṣiwaju pẹlu 250, Oyo si tẹle pẹlu 100.
jọ to n mojuto ajakalẹ aarun ni Naijiria, NCDC, ti kede eeyan 452 miran to ni aarun coronavirus ni Naijiria.
Eyi si ti mu ki apapọ awọn to ti ràn ni Naijiria o pe 21,371 bayii.
Akojọpọ iye awọn to ni niyii:
Aarun naa ti pa eniyan 533, awọn 7,338 si ti ri iwosan.
Ènìyàn 675 ni èsì àyẹ̀wò sọ pé ó ní Covid-19 ní Nàìjíríà ní 22/06/2020
Ajọ NCDC kede pe eniyan 675 ni esi ayẹwo tun fihan pe o ti ni coronavirus ni Naijiria.
Ipinlẹ Eko ni 288, Oyo si tẹle pẹlu 76.
Awọn to ku ni:
Rivers-56
Delta-31
Ebonyi-30
Gombe-28
Ondo-20
Kaduna-20
Kwara-20
Ogun-17
FCT-16
Edo-13
Abia-10
Nasarawa-9
Imo-9
Bayelsa-8
Borno-8
Katsina-8
Sokoto-3
Bauchi-3
Plateau-2
Lọwọlọwọ, o ti pe eniyan 20,919 to ti ni aarun naa.
Awọn ti ajakalẹ aarun coronavirus ti kọlu ni Naijiria ti pe 20,244 bayii.
Eyi ri bẹ lẹyin ti ajọ NCDC tun kede eniyan 436 to tun ṣẹṣẹ ni i lọjọ Aiku.
Esi ipinlẹ kọọkan re e:
Eniyan 6,879 ti ri iwosan, ti 518 si ti ku.
Esi ayẹwo coronavirsu fun 20/06/2020
Diẹ lo ku ki awọn to ni aarun Covid-19 o pe ẹgbẹrun lọna ogun bayii, lẹyin ti ajọ to n mojuto aarun ni Naijiria, NCDC tun kede eniyan 661 lọjọ Abamẹta.
Lọwọlọwọ, eniyan 19,808 lo ti ni, 6,718 ti ri iwosan, awọn 506 si ti ku.
Bi akojọpọ esi ayẹwo tuntun naa ṣe lọ niyii:
Lagos-230
Rivers-127
Delta-83
FCT-60
Oyo-51
Edo-31
Bayelsa-27
Kaduna-25
Plateau-13
Ondo-6
Nasarawa-3
Ekiti-2
Kano-2
Borno-1
NCDC ni apapọ awọn to ti ni arun naa kaaakiri orilẹ-ede Naijiria ti wa di 19,147bayii.
Eeyan 6,581 lo ti ri iwosan gba, nigba ti awọn 487 ti dero ọrun nitori arun ọhun.
Iye awọn eeyan to ṣẹṣẹ ko arun naa ni ipinlẹ kọọkan ree:
Eko -281
Abia-48
Oyo-45
FCT-38
Ogun-37
Enugu-31
Ondo-23
Plateau-21
Edo-19
Delta-18
Rivers-18
Bayelsa-17
Akwa Ibom-17
Kaduna-14
Kano-12
Bauchi-9
Gombe-4
Osun-3
Benue-3
Nasarawa-3
Kwara-3
Ekiti-2
Borno-1
Oríṣun àwòrán, Others
Ajọ to n risi idena ati amojuto ajakalẹ arun, NCDC lo fi ikede naa sita loju opo Twitter rẹ.
Apapọ awọn to ti ni arun naa kaaakiri orilẹ-ede Naijiria ti wa di 18,480 bayii.
Eeyan 6,307 lo ti ri iwosan gba, nigba ti awọn 475 ti dero ọrun nitori arun ọhun.
Iye awọn eeyan to ṣẹṣẹ ko arun naa ni ipinlẹ kọọkan ree:
Eko-280
Oyo-103
Ebonyi-72
FCT-60
Imo-46
Edo-34
Delta-33
Rivers-25
Kaduna-23
Ondo-16
Katsina-12
Kano-10
Bauchi-8
Borno-7
Kwara-5
Gombe-4
Sokoto-2
Enugu-2
Yobe-1
Osun-1
Nasarawa-1
Oríṣun àwòrán, Others
Akojọpọ esi ayẹwo aarun Covid-19 ni orilẹ-ede Naijiria gẹgẹ bi ajọ NCDC ṣe n kede rẹ.
Ajọ to n risi idena ati amojuto ajakalẹ arun, NCDC lo fi ikede naa sita loju opo Twitter rẹ.
Apapọ awọn to ti ni arun naa kaaakiri orilẹ-ede Naijiria ti wa di 16,658 bayii.
Eeyan 5,967 lo ti ri iwosan gba, nigba ti awọn 469 ti dero ọrun nitori arun ọhun.
Iye awọn eeyan to ṣẹṣẹ ko arun naa ni ipinlẹ kọọkan ree:
Eko-155
Edo-75
FCT-67
Rivers-65
Oyo-56
Delta-50
Bayelsa-25
Plateau-18
Kaduna-18
Enugu-17
Borno-12
Ogun-12
Ondo-7
Kwara-4
Kano-2
Gombe-2
Sokoto-1
Kebbi-1
Ajọ to n risi idena ati amojuto ajakalẹ arun, NCDC lo fi ikede naa sita loju opo Twitter rẹ.
Apapọ awọn to ti ni arun naa kaaakiri orilẹ-ede Naijiria ti wa di 16,658 bayii.
Eeyan 5,623 lo ti ri iwosan gba, nigba ti awọn 455 ti dero ọrun nitori arun ọhun.
Iye awọn eeyan to ṣẹṣẹ ko arun naa ni ipinlẹ kọọkan ree:
Eko-142
FCT-60
Bayelsa-54
Rivers-39
Delta-37
Oyo-30
Kaduna-26
Imo-23
Enugu-19
Kwara-17
Gombe-11
Ondo-10
Bauchi-8
Ogun-7
Borno-6
Benue-1
Eeyan 573 tuntun mii lo ṣẹṣẹ lugbadi arun Coronavirus ni Naijiria.
Ajọ to n risi idena ati amojuto ajakalẹ arun, NCDC lo fi ikede naa sita loju opo Twitter rẹ.
Apapọ awọn to ti ni arun naa kaaakiri orilẹ-ede Naijiria ti wa di 16,658 bayii.
Eeyan 5,349 lo ti ri iwosan gba, nigba ti awọn 424 ti dero ọrun nitori arun ọhun.
Iye awọn eeyan to ṣẹṣẹ ko arun naa ni ipinlẹ kọọkan ree:
Eko-216
Rivers-103
Oyo-68
Edo-40
Kano-21
Gombe-20
FCT-17
Delta-13
Plateau-12
Bauchi-12
Niger-10
Kebbi-9
Ogun-8
Ondo-8
Abia-7
Nasarawa-5
Borno-1
Kwara-1
Benue-1
Anambra-1
Oríṣun àwòrán, Others
Akojọpọ esi ayẹwo aarun Covid-19 ni orilẹ-ede Naijiria gẹgẹ bi ajọ NCDC ṣe n kede rẹ.
Eeyan 403 tuntun mii lo ṣẹṣẹ lugbadi arun Coronavirus ni Naijiria.
Ajọ to n risi idena ati amojuto ajakalẹ arun, NCDC lo fi ikede naa sita loju opo Twitter rẹ.
Apapọ awọn to ti ni arun naa kaaakiri orilẹ-ede Naijiria ti wa di 16,082 bayii.
Eeyan 5220 lo ti ri iwosan gba, nigba ti awọn 420 ti dero ọrun nitori arun ọhun.
Iye awọn eeyan to ṣẹṣẹ ko arun naa ni ipinlẹ kọọkan ree:
Gombe-73
Eko-68
Kano-46
Edo-36
FCT-35
Nasarawa-31
Kaduna-17
Oyo-16
Abia-15
Delta-13
Borno-13
Plateau-8
Niger-7
Rivers-7
Enugu-6
Ogun-6
Kebbi-3
Ondo-1
Anambra-1
Imo-1
Eeyan 501 tuntun mii lo ṣẹṣẹ lugbadi arun Coronavirus ni Naijiria.
Ajọ to n risi idena ati amojuto ajakalẹ arun, NCDC lo fi ikede naa sita loju opo Twitter rẹ.
Apapọ awọn to ti ni arun naa kaaakiri orilẹ-ede Naijiria ti wa di 15,682 bayii.
Eeyan 5101 lo ti ri iwosan gba, nigba ti awọn 407 ti dero ọrun nitori arun ọhun.
Iye awọn eeyan to ṣẹṣẹ ko arun naa ni ipinlẹ kọọkan ree:
Eko-195
FCT-50
Kano-42
Kaduna-27
Edo-26
Oyo-22
Imo-21
Gombe-17
Benue-12
Enugu-12
Delta-11
Anambra-11
Ebonyi-10
Nasarawa-9
Ogun-9
Bauchi-8
Kebbi-4
Akwa Ibom-3
Jigawa-3
Katsina-3
Yobe-2
Borno-2
Kwara-1
Ondo-1
Eeyan 627 tuntun mii lo ṣẹṣẹ lugbadi aarun Coronavirus ni Naijiria.
Oríṣun àwòrán, EPA
Akojọpọ esi ayẹwo aarun Covid-19 ni orilẹ-ede Naijiria gẹgẹ bi ajọ NCDC ṣe n kede rẹ.
Ajọ to n risi idena ati amojuto ajakalẹ arun, NCDC lo fi ikede naa sita loju opo Twitter rẹ.
Apapọ awọn to ti ni arun naa kaaakiri orilẹ-ede Naijiria ti wa di 15,181 bayii.
Eeyan 4,891 lo ti ri iwosan gba, nigba ti awọn 399 ti dero ọrun nitori arun ọhun.
Iye awọn eeyan to ṣẹṣẹ ko arun naa ni ipinlẹ kọọkan ree:
Eko-229
FCT-65
Abia-54
Borno-42
Oyo-35
Rivers-28
Edo-28
Gombe-27
Ogun-21
Plateau-18
Delta-18
Bauchi-10
Kaduna-10
Benue-9
Ondo-8
Kwara-6
Nasarawa-4
Enugu-4
Sokoto-3
Niger-3
Kebbi-3
Yobe-1
Kano-1
Eeyan 681 tuntun mii lo ṣẹṣẹ lugbadi aarun Coronavirus ni Naijiria.
Oríṣun àwòrán, Twitter/todayng
Ajọ to n risi idena ati amojuto ajakalẹ arun, NCDC lo fi ikede naa sita loju opo Twitter rẹ.
Apapọ awọn to ti ni arun naa kaaakiri orilẹ-ede Naijiria ti wa di 14,554 bayii.
Eeyan 4,494 lo ti ri iwosan gba, nigba ti awọn 387 ti dero ọrun nitori arun ọhun.
Iye awọn eeyan to ṣẹṣẹ ko arun naa ni ipinlẹ kọọkan ree:
Eko -345
Rivers-51
Ogun-48
Gombe-47
Oyo-36
Imo-31
Delta-28
Kano-23
Bauchi-18
Edo-12
Katsina-12
Kaduna-9
Anambra-7
Jigawa-5
Kebbi-4
Ondo-4
Nasarawa-1
Oríṣun àwòrán, Twitter/todayng
Ayẹwo ti fi han pe eeyan 409 mii tun ti ni aarun Coronavirus ni Naijiria.
Ajọ to n gbogun ti ajakalẹ arun lorilẹede Naijiria, NCDC lo kede bẹẹ loju opo Twitter rẹ l'Ọjọbọ.
To n tumọ si pe lapapọ, eeyan 13,873 ni ayẹwo ti fihan pe wọn ti ko arun naa ni Naijiria.
Eeyan 4,351 lo ti ri iwosan gba, nigba ti awọn 382 ti papoda nitori arun ọhun.
Iye awọn eeyan to ṣẹṣẹ ko arun naa ni ipinlẹ kọọkan ree:
Eko -201
FCT- 85
Delta- 22
Edo- 16
Nasarawa- 14
Borno- 14
Kaduna- 14
Bauchi-10
Rivers-9
Enugu- 5
Kano- 5
Ogun- 4
Ondo- 4
Bayelsa- 2
Kebbi- 2
Plateau- 2
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ajọ to n gbogun ti ajakalẹ arun ni Naijiria, NCDC ti kede eeyan 663 gẹgẹ bi apapọ awọn tuntun mii to ṣẹṣẹ ni arun Coronavirus ni Naijiria lọjọ Iṣẹgun.
NCDC lo fi ikede naa lede loju opo Twitter rẹ, ti apapọ awọn to ti ni arun naa ni Naijiria ti wa di 13464  bayii.
Eeyan 4206  lo ti ri iwosan gba, nigba ti awọn 365 ti papoda nitori arun ọhun.
Iye awọn eeyan to ṣẹṣẹ ko arun naa ni ipinlẹ kọọkan ree:
Eko -170
Ogun-108
Bauchi-69
Ebonyi-49
Edo-33
Rivers-30
FCT-26
Jigawa-26
Delta-20
Anambra-17
Gombe-16
Kano-16
Imo-15
Abia-14
Borno-11
Oyo-11
Plateau-8
Kebbi-6
Kaduna-6
Ondo-4
Niger-2
Katsina-2
Osun-1
Ekiti-1
Kwara-1
Nasarawa-1
Oríṣun àwòrán, Twitter/todayng
Ajọ NCDC ti kede eniyan 315 gẹgẹ bi apapọ awọn to ni arun Coronavirus lorilẹ-ede Naijiria ni ọjọ Aje.
ANCDC lofi ikede naa si oju opo ikansiraẹni Twitter rẹ, ti apapọ awọn eniyan to ti ni arun naa ti wa da 12801.
Ipinlẹ Eko lo ni eeyan to poju pẹlu eeyan 128 lọjọ Aje nikan soso.
Bi iye awọn eeyan to ṣẹṣẹ ko arun naa ni ipinlẹ kọọkan ṣe lọ ree:
Lagos- 128
FCT-34
Rivers- 32
Edo- 28
Oyo- 22
Kaduna- 20
Gombe- 13
Ogun- 8
Plateau- 5
Delta- 7
Kwara- 7
Kano- 5
Bauchi- 4
Katsina- 2
Oríṣun àwòrán, Twitter
Akojọpọ esi ayẹwo aarun Covid-19 ni orilẹ-ede Naijiria gẹgẹ bi ajọ NCDC ṣe n kede rẹ.
Eeyan 260 tuntun mii lo ṣẹṣẹ lugbadi aarun Coronavirus ni Naijiria.
Ajọ to n risi idena ati amojuto ajakalẹ aarun, NCDC lo fi ikede naa sita lalẹ ọjọ Aiku loju opo Twitter rẹ.
Apapọ awọn to ti ni arun naa kaaakiri orilẹ-ede Naijiria ti wa di 12486 bayii.
Eeyan 3959 lo ti ri iwosan gba, nigba ti awọn 354 ti dero ọrun nitori arun ọhun.
Iye awọn eeyan to ṣẹṣẹ ko arun naa ni ipinlẹ kọọkan ree:
Abia-67
FCT-40
Eko -38
Ogun-19
Gombe-16
Edo-14
Imo-9
Kwara-8
Katsina-8
Nasarawa-8
Borno-8
Kaduna-6
Bauchi-5
Ekiti-4
Niger-2
Ondo-2
Plateau-2
Kano-2
Sokoto-2
Oríṣun àwòrán, Twitter
Ajọ to n gbogun ti ajakalẹ arun ni Naijiria, NCDC ti kede eeyan 389 gẹgẹ bi apapọ awọn tuntun mii to ṣẹṣẹ ni arun Coronavirus ni Naijiria ni Ọjọ Abamẹta.
NCDC lo fi ikede naa lede loju opo ikansiraẹni Twitter rẹ, ti apapọ awọn to ti ni arun naa ti wa di 12233 bayii.
Eeyan 3826 lo ti ri iwosan gba, nigba ti awọn 342 ti papoda nitori arun ọhun.
Iye awọn eeyan to ṣẹṣẹ ko arun naa ni ipinlẹ kọọkan ree:
Eko -66
FCT-50
Delta-32
Oyo-31
Borno-26
Rivers-24
Edo-23
Ebonyi-23
Anambra-17
Gombe-17
Nasarawa-14
Imo-12
Kano-12
Sokoto-12
Jigawa-8
Ogun-7
Bauchi-5
Kebbi-2
Kaduna-2
Katsina-2
Ondo-2
Abia-1
Niger-1
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Akojọpọ esi ayẹwo aarun Covid-19 ni orilẹ-ede Naijiria gẹgẹ bi ajọ NCDC ṣe n kede rẹ.
Ayẹwo ti fi han pe eeyan 328 mii tun ti ni aarun Coronavirus ni Naijiria.
Ajọ to n gbogun ti ajakalẹ arun lorilẹede Naijiria, NCDC lo kede bẹẹ loju opo Twitter rẹ lọjọ Ẹti.
To n tumọ si pe lapapọ, eeyan 11844  ni ayẹwo ti fihan pe wọn ti ko arun naa ni Naijiria.
Eeyan 3696 lo ti ri iwosan gba, nigba ti awọn 333 ti papoda nitori arun ọhun.
Iye awọn eeyan to ṣẹṣẹ ko arun naa ni ipinlẹ kọọkan ree:
Eko -121
FCT-70
Bauchi-25
Rivers-18
Oyo-16
Kaduna-15
Gombe-14
Edo-13
Ogun-13
Jigawa-8
Enugu-6
Kano-5
Osun-2
Ondo-2
Oríṣun àwòrán, Twitter
Eeyan 350 miran ni ayẹwo tun ti fihan pe o laarun Coronavirus lorilẹede Naijiria bayii.
Ninu ikede ti Ajọ to n gbogun ti ajakalẹ arun lorilẹede Naijiria, NCDC fi sita ni oju opò ikansiraẹni Twitter wọn ni wọn ti fi lede bẹẹ.
Lapapapọ bayii eeyan 11516 ni ayẹwo fihan pe wọn ti ko arun yii lorilẹede Naijiria bayii.
Eniyan 3535 lo ti ri iwosan gba, nigba eniyan 323 si ti papoda nitori arun Coronavirus.
Bii awọn ipinlẹ naa ṣe lọ ni yii;
Eko-102
Ogun-34
FCT-29
Borno-26
Kaduna-23
Rivers-21
Ebonyi-17
Kwara -16
Katsina-14
Edo-10
Delta-10
Kano-10
Bauchi-10
Bayelsa-9
Imo-8
Plateau-4
Ondo-3
Nasarawa-2
Gombe-1
Oyo-1
Ajọ NCDC ti kede eniyan 348 gẹgẹ bi apapọ eniyan to ni arun Coronavirus lorilẹede Naijiria ni Ọjọọru nikan lorilẹede Naijiria.
Oríṣun àwòrán, Others
Akojọpọ esi ayẹwo aarun Covid-19 ni orilẹ-ede Naijiria gẹgẹ bi ajọ NCDC ṣe n kede rẹ.
Ajọ NCDC naa fi ikede naa si oju opo ikansiraẹni Twitter wọn, ti apapọ awọn eniyan to ni arun naa ti wa da 11166.
Ipinlẹ Eko lo ni eniyan to poju pẹlu eniyan 163 ni Ojo Iṣẹgun nikan soso.
Iye awọn to ti ri iwosan ti jẹ 3329, ti awọn to si ti ku nitori arun naa lorileede Naijiria ti jẹ 315.
Bi iye awọn to ni ni awọn ipinlẹ to ku ṣe lọ ni yii;
Eko-163
FCT-76
Ebonyi-23
Rivers-21
Delta-8
Nasarawa-8
Niger-8
Enugu-6
Bauchi-5
Edo-5
Ekiti-5
Ondo-5
Gombe-5
Benue-4
Ogun-2
Osun-1
Plateau-1
Kogi-1
Anambra-1
Ajọ NCDC ti kede eniyan 241 gẹgẹ bi apapọ eniyan to ni arun Coronavirus lorilẹede Naijiria ni Ọjọ Iṣẹgun lorilẹede Naijiria.
Oríṣun àwòrán, Twitter
Akojọpọ esi ayẹwo aarun Covid-19 ni orilẹ-ede Naijiria gẹgẹ bi ajọ NCDC ṣe n kede rẹ.
Ajọ NCDC naa fi ikede naa si oju opo ikansiraẹni Twitter wọn, ti apapọ awọn eniyan to ni arun naa ti wa da 10819.
Ipinlẹ Eko lo ni eniyan to poju pẹlu eniyan 142 ni Ojo Iṣẹgun nikan soso.
Iye awọn to ti ri iwosan ti jẹ 3239, ti awọn to si ti ku nitori arun naa lorileede Naijiria ti jẹ 314.
Bi iye awọn to ni ni awọn ipinlẹ to ku ṣe lọ ni yii;
Eko-142
Oyo-15
FCT-13
Kano-12
Edo-11
Delta-10
Kaduna -9
Rivers-9
Borno-8
Jigawa-4
Gombe-3
Plateau-3
Osun-1
Bauchi-1
Ajọ NCDC ti kede eniyan 416 gẹgẹ bi apapọ eniyan to ni arun Coronavirus lorilẹede Naijiria ni Ọjọ Aje lorilẹede Naijiria.
Ajọ NCDC naa fi ikede naa si oju opo ikansiraẹni Twitter wọn, ti apapọ awọn eniyan to ni arun naa ti wa da 10578.
Ipinlẹ Eko lo ni eniyan to poju pẹlu eniyan 192 ni Ojo Aje nikan soso.
Iye awọn to ti ri iwosan ti jẹ 3122, ti awọn to si ti ku nitori arun naa lorileede Naijiria ti jẹ 299. Bi iye awọn to ni ni awọn ipinlẹ to ku ṣe lọ ni yii;
Eko-192
Edo-41
Rivers-33
Kaduna-30
Kwara-23
Nasarawa-18
Borno-17
FCT-14
Oyo-10
Katsina-7
Abia-5
Delta-5
Adamawa-4
Kano-4
Imo-3
Ondo-3
Benue-2
Bauchi-2
Ogun-2
Niger-1
Ajọ NCDC ti kede eniyan 307 gẹgẹ bi apapọ eniyan to ni arun Coronavirus lorilẹede Naijiria ni Ọjọ Aiku lorilẹede Naijiria.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Akojọpọ esi ayẹwo aarun Covid-19 ni orilẹ-ede Naijiria gẹgẹ bi ajọ NCDC ṣe n kede rẹ.
Ajọ NCDC naa fi ikede naa si oju opo ikansiraẹni Twitter wọn, ti apapọ awọn eniyan to ni arun naa ti wa da 10162.
Ipinlẹ Eko lo ni eniyan to poju pẹlu eniyan 188 ni Ojo Aiku nikan soso.
Iye awọn to ti ri iwosan ti jẹ 3007, ti awọn to si ti ku nitori arun naa lorileede Naijiria ti jẹ 287. Bi iye awọn to ni ni awọn ipinlẹ to ku ṣe lọ ni yii;
Eko-188
FCT-44
Ogun-19
Kaduna-14
Oyo-12
Bayelsa-9
Gombe-5
Kano-3
Delta-3
Imo-2
Rivers-2
Niger-2
Bauchi-2
Plateau-1
Kwara-1
Ajọ NCDC ti kede eniyan 553 gẹgẹ bi apapọ eniyan to ni arun Coronavirus lorilẹede Naijiria ni Ọjọ Satide lorilẹede Naijiria.
Oríṣun àwòrán, Others
Ajọ NCDC naa fi ikede naa si oju opo ikansiraẹni Twitter wọn, ti apapọ awọn eniyan to ni arun naa ti wa da 9855.
Ipinlẹ Eko lo ni eniyan to poju pẹlu eniyan 378 ni Ojo Satide nikan soso.
Eko-378
FCT-52
Delta-23
Edo-22
Rivers-14
Ogun-13
Kaduna-12
Kano-9
Borno-7
Katsina-6
Jigawa-5
Oyo-5
Yobe-3
Plateau-3
Osun-1
Iye awọn to ti ri iwosan ti jẹ 2856, ti awọn to si ti ku nitori arun naa lorileede Naijiria ti jẹ 273.
Ajọ to n mojuto ajakalẹ aarun ni Naijiria, NCDC, ti kede pe awọn to ti ni aarun coronavirus ni Naijiria ti pe 9,302 bayii.
Oríṣun àwòrán, Twitter/Sanwo Olu
Akojọpọ esi ayẹwo aarun Covid-19 ni orilẹ-ede Naijiria gẹgẹ bi ajọ NCDC ṣe n kede rẹ.
Ènìyàn 307 ló lùgbàdì àrùn Coronavirus ní Ọjọ́ Aiku
Eniayn 387 tuntun ni akọsilẹ wa pe o ti ni aarun naa, o si ti wọ ipinlẹ marundinlogoji, ati ilu Abuja.
Ni ipinlẹ Eko nikan, eniyan 254 lo ti lugbadi arun naa ni Ọjọ Eti.
May 29: Akala, Aleshinloye sọ̀rọ̀ lórí ọdún kan Seyi Makinde gẹ́gẹ́bíi gómìnà
bayii, eniyan 2697 lo ti ri iwosan gba lọwọ arun Coronavirus, ti eniyan 261 si ti ku nitori arun naa.
Eko-254
Abuja-29
Jigawa-24
Edo-22
Oyo-15
Rivers-14
Kaduna-11
Borno-6
Kano-3
Plateau-2
Yobe-2
Gombe-2
Bauchi-2
Ondo-1
Oríṣun àwòrán, Ncdc
Awọn ti aarun Covid-19 mu l'orilẹ-ede Naijiria ti pọ si, lẹyin ti esi ayẹwo ti ajọ to mojuto ajakalẹ aarun ni Naijiria, NCDC kede fihan pe eeyan 182 lo tun ti ni aarun naa.
Bi esi ayẹwo naa ṣe lọ niyii.
Lagos-111
FCT-16
Akwa Ibom-10
Oyo-8
Kaduna-6
Delta-6
Rivers-5
Ogun-4
Ebonyi-4
Kano-3
Plateau-2
Gombe-2
Kebbi-1
Kwara-2
Bauchi-1
Borno-1
Nibayii, eniyan 8915 lo ti ni, 2592 ti ri iwosan, 259 si ti ku.
Ajọ to n mojuto ajakalẹ aarun ni Naijiria, NCDC, ti kede pe awọn to ti ni aarun coronavirus ni Naijiria ti pe 8,733 bayi.
Eniayn 389 tuntun ni akọsilẹ wa pe o ti ni aarun naa, o si ti wọ ipinlẹ marundinlogoji, ati ilu Abuja.
Ni bayii, ipinlẹ Kogi naa ti darapọ mọ awọn ipinlẹ ti aarun naa ti wọ l''orilẹ-ede Naijiria.
Alaye re e lori ipinlẹ ti awọn ẹni tuntun naa ti wa:
Lagos-256
Katsina-23
Edo-22
Rivers-14
Kano-13
Adamawa-11
Akwa Ibom-11
Kaduna-7
Kwara-6
Nasarawa-6
Gombe-2
Plateau-2
Abia-2
Delta-2
Benue-2
Niger-2
Kogi-2
Oyo-2
Imo-1
Borno-1
Ogun-1
Anambra-1
Ṣugbọn, eeyan 2,501 ti ri iwosan, 254 si ti ku.
AWỌN TO NI AARUN COVID-19 NI NAIJIRIA NI 27/05/2020
Apapọ awọn to ni aarun coronavirus ni Naijiria ti pe ẹgbẹrun mẹjọ ati ojilelọọdunrun le mẹẹrin (8344).
Eyi ri bẹ ẹ lẹyin ti ajọ to n mojuto aarun ni Naijiria, NCDC, tun kede ọrinlerugba din mẹẹrin (276) eeyan to tun ṣẹṣẹ ni lọjọ Iṣẹgun.
Ipinlẹ Eko lo ṣi n lewaju ninu awọn ipinlẹ mẹrinlelọgbọn, ati ilu Abuja, ti aarun naa ti de ni Naijiria.
Ṣugbọn, ẹgbẹrun meji ati ọrinlelọọdunrun le maarun (2385) eeyan lo ti ri iwosan. Eniyan igba ati mọkandinlaadọta (249) si ti ku.
Eeyan to ti ni aarun coronavirus l'orilẹ-ede Naijiria ti pe ẹgbẹrun mẹjọ ati mejidinlaadọrin bayii.
Eyi ri bẹ ẹ lyin ti ajọ  to n gbogun ti aarun ni Naijiria, Nigeria Centre for Disease Control (NCDC) kede esi ayẹwo eeyan igba le mọkandinlọgbọn lọjọ kẹẹdọgbọn, oṣu Karun, ọdun 2020.
Awọn to ni aarun coronavirus ni Naijiria ti pọ si bayii, lẹyin ti ajọ NCDC tun kede okoolelọọdunrun din meje eeyan ti esi ayẹwo wọn ṣẹṣẹ jade.
Ni bayii, eeyan ẹgbẹrun meje, ati ojilelẹgbẹrin din ẹyọkan (7839) ni akọsilẹ wa pa o ti ni aarun naa ni Naijiria.
Akojọpọ awọn ipinlẹ ti esi tuntun naa ti wa niyii.
Ajọ to n mojuto ajakalẹ aarun l'orilẹ-ede Naijiria, NCDC, kede pe eniyan igba ati marundinlaadọrin ni ayẹwo fihan pe o tun ni aarun coronavirus ni Naijiria.
Ninu esi ayẹwo naa, ipinlẹ Eko ni eeyan mẹtalelaadoje, Oyo ni mẹtalelọgbọn, Edo si ni mejidinlọgbọn.
Awọn ipinlẹ to ku ni:
Apapọ awọn to ti ni l'orilẹ-ede Naijiria jẹ ẹgbẹrun meje, ati ẹẹdẹgbẹta le mẹrindinlọgbọn (7526).
Ẹgbẹrun meji ati mẹrinlelaadọsan (2174), ti ri iwosan, okoolerugba le ẹyọkan (221) si ti ku.
Esi ayẹwo aarun coronavirus ti ajọ to n gbogun ti aarun ni Naijiria, NDCD, kede ni alẹ ọjọ Ẹti fihan pe eniyan igba ati marundinlaadọta lo tun ti ni aarun naa ni Naijiria.
Ipinlẹ Eko lo ṣiwaju pẹlu mọkanlelaadoje.
Lọwọlọwọ, eniyan ẹgbẹrun meje ati ọtalerugba le yọkan (7261) lo ti ni Covid-19 ni Naijiria.
Eniyan ọọdunrunlemọkandinlogoji lo tun ṣẹṣẹ ni arun Coronavirus ni Naijiria ni Ọjọọbọ.
Ajo to n koju arun Coronavirus ni Naijiria, NCDC to fi lede ni Ọjọọbọ, ni iye awọn to ti ni arun naa ti di ẹgbẹrun meje ati mẹrindinlogun  (7016).
NCDC fikun pe awọn ipinlẹ ti ọrọ naa kan ni ipinlẹ Eko, Kano, Oyo, Edo, Katsina, Kaduna,  Jigawa, Yobe,  Plateau, Abuja, Gombe, Ogun, Bauchi, Nasarawa, Delta, Ondo, Rivers ati Adamawa.
Nibayii, iye awọn to ti ri iwosan gba ti le ni mejeleẹẹdẹgbẹwa (1907), ti ookanlenigba(211) eniyan si ti ku nitori arun naa.
Eniyan ọrinlenigbalenimẹrin lo tun ṣẹṣẹ ni arun Coronavirus ni Naijiria ni Ọjọọru.
Ajo to n koju arun Coronavirus ni Naijiria, NCDC to fi lede ni Ọjọọru, ni iye awọn to ti ni arun naa ti le ni ẹgbaata ati ọrinlelẹgbẹtadinmẹta (6677).
NCDC fikun pe awọn ipinlẹ ti ọrọ naa kan ni ipinlẹ Eko, Rivers, Oyo, Abuja, Borno, Plateau, Jigawa, Kano, Abia, Ekiti, Delta, Kwara ati Taraba.
Nibayii, iye awọn to ti ri iwosan gba ti le ni ọgọtadinlẹdẹẹgbẹsan(1840), ti igba eniyan si ti ku nitori arun naa.
Eniyan okoolerugbaolemẹfa lo tun ṣẹṣẹ ni arun Coronavirus ni Naijiria ni Ọjọ Iṣẹgun.
Ajo to n koju arun Coronavirus ni Naijiria, NCDC to fi lede ni Ọjọ Iṣẹgun ni iye awọn to ti ni arun naa ti le ni ẹgbẹẹta ati irinwo(6401).
Akojọpọ esi ayẹwo aarun Covid-19 ni orilẹ-ede Naijiria gẹgẹ bi ajọ NCDC ṣe n kede rẹ.
NCDC fikun pe awọn ipinlẹ ti ọrọ naa kan ni ipinlẹ Eko,Ogun, Plateau, Edo,Kaduna,Oyo,Abuja, Adamawa,Jigawa, Ebonyi, Borno, Nasarawa, Bauchi, Gombe, Enugu ati Bayelsa.
Nibayii, iye awọn to ti ri iwosan gba ti le ni ẹẹdẹgbẹsan(1734), ti eniyan mejilelaadọwa si ti ri ku nitori arun naa.
Orilẹede Naijiria ti ni eniyan mẹrindinlogunlenigba lo tun ṣẹṣẹ ni arun Coronavirus ni Naijiria.
Ajo to n koju arun Coronavirus ni Naijiria, NCDC to fi lede ni Ọjọ Aje ni iye awọn to ti ni arun naa ti le ni ẹgbẹẹta(6175).
Akojọpọ esi ayẹwo aarun Covid-19 ni orilẹ-ede Naijiria gẹgẹ bi ajọ NCDC ṣe n kede rẹ.
NCDC fikun pe awọn ipinlẹ ti ọrọ naa kan ni ipinlẹ Eko,Katsina, Oyo, Kano, Edo, Zamfara, Ogun, Gombe, Borno, Bauchi, Kwara, Abuja,Kaduna, Enugu ati ipinlẹ Rivers.
Nibayii, iye awọn to ti ri iwosan gba ti le ni ẹgbẹjọ(1644), ti eniyan mọkanlelaadọwa si ti ri ku nitori arun naa.
Orílẹ̀-èdè Nàìjíríà tí ní àkọsílẹ̀ àwọn ènìyàn ẹ̀tàléláàdọ́wàá to tún ṣẹ̀ṣẹ̀ ní ààrùn covid-19 ti àpapọ̀ gbogbo ibi tí ǹkan dé dúró ní Nàìjíríà báyìí sì ti di ẹgbẹ̀rún márùn-ún àti méjìlélọ́gọ́jọ.
Ìkéde yìí jẹyọ lójú òpó twitter àjọ tó ń gbógun ti àjàkálẹ̀ ààrùn ní Nàìjíríà (NCDC) ní alé ọjọ́bọ.
Ènìyàn 5,162 ló ti ni ààrùn Coronavirus ní Nàìjíríà ti èèyàn 167 si ti bá ààrùn náà rìn.
U.I Language Centre: Yorùbá ló làṣà àti èdè
Gẹ́gẹ́ bí àjọ NCDC ṣe sọ ènìyàn méjílédinlọ́gọ́ta ló ṣẹ̀ṣẹ̀ jẹyọ nípínlẹ̀ Eko, mẹ́rìndíláàdọ́ta ni Kano, márùnlélọ́gbọ̀n ni Jigawa àti méjìlá ni Yobe.
Ènìyàn mẹ́sàn-án ni Abuja, nígbà ti méje wáye ni ìpínlẹ̀ Ogun, Plateau àti Gombe ni márùn-ún, mẹ́rìn ní Imo.
Edo, Kwara àti Borno ni èèyàn mẹ́ta, nígbà ti ẹyọ kọ̀ọ̀kan jẹyọ ni Bauchi, Nasarawa àti Ondo.
Ní ojúmọ́ ọjọ́ ẹti yìí, iye ènìyàn to wà lọ́rí àkéte ààrùn Covid-19 jẹ́ ẹgbẹ̀rún mẹ́ta àti ẹgbẹ̀rin lé mẹ́ẹ̀dógún ènìyàn nígbà ti èèyan ẹgbẹ́run kanlélọ́gọ́san ti wà láàlàfíà.
Ní báyìí enìyàn ọgọ́jọléméje ló ti kú látàrí ààrùn Covid-19
Àjọ NCDC kéde èèyàn 184 míràn tó ni ààrùn Covid-19 lórílẹ̀-èdè Naijíríà
Àjọ NCDC kéde èèyàn 184 míràn tó ni ààrùn Covid-19 lórílẹ̀-èdè Naijíríà
Àjọ tó ń gbógun ti àjàkálẹ̀ ààrùn lórílẹ̀-èdè Nàìjíríà NCDC ti kéde pé ènìyàn mẹ́rinleọgọ́sàn (184) ni àyẹ̀wò tuntun fi hàn pé ó ní ààrùn Covid-19 lórílè-èdè Nàìjíríà ti àpapọ̀ àwọn tó ní  ààrùn náà sì tì di ẹgbẹ̀rúnmẹ́rin àti ọ̀rìlélélẹ́ẹ̀gbẹ̀rún o dín mẹ́sàn-án (4971)
Gẹ́gẹ́ bi àjọ náà ṣe sọ lójú òpó twitter rẹ̀ lálẹ́ ọjọ́ ìṣẹ́gun ènìyàn mẹ́rìlélọ́gọ́jọ ló ti kú nígbà ti ẹgbẹ̀rúnkan lé ni ààdọ́rin ti ri ìwòsàn gbà.
NCDC ní, ìpínlẹ̀ Eko ní ènìyàn mọ́kànléláàdọ́ọ́ta, mẹ́tàlélógun ni Jigawa, Kastsina àti Bauchi ni mẹ́rìndílógún nigbàti Kano ni mẹ́rìnlá.
FCT àti Rivers  ní mẹ́wàá,  nígbà tí ìpínlẹ̀ Kwara ni èèyàn mẹ́sàn-án,  ti Delta ati Kaduna ṣe ni márùn-ún, Sokoto ati Oyo ní mẹ́rin, bákan náà ni Kebbi, Nasarawa àti Osun ni mẹ́ta, Ondo si ni èèyàn mẹ́jì.
Ènìyàn kọ̀ọ̀kan ló lùgbàdì àààrùn náà ní  Ebonyi, Edo, Enugu Anambra Plateau àti Niger
Àjọ NCDC kéde èèyàn 146 míràn tó ni ààrùn Covid-19 lórílẹ̀-èdè Naijíríà
Àjọ NCDC kéde èèyàn 146 míràn tó ni ààrùn Covid-19 lórílẹ̀-èdè Naijíríà
Àjọ tó ń gbógun ti àjàkálẹ̀ ààrùn lórílẹ̀-èdè Nàìjíríà NCDC ti kéde pé ènìyàn mẹ́rìndínláàdọ́jọ ni àyẹ̀wò tuntun fi hàn pé ó ní ààrùn Covid-19 lórílè-èdè Nàìjíríà ti àpapọ̀ àwọn tó ní  ààrùn náà sì tì di ẹgbẹ̀rúnmẹ́rinlé ọ̀rìlélélẹ́ẹ̀gbẹ̀rin àti méje (4787)
Gẹ́gẹ́ bi àjọ náà ṣe sọ lójú òpó twitter rẹ̀ lálẹ́ ọjọ́ ìṣẹ́gun ènìyàn mẹ́jìdílọ́gọ́jọ ló ti kú nígbà ti ọ̀tàdilẹ́ẹ̀dẹ́gbẹ̀rún-ó-dín-kan (959) ti ri ìwòsàn gbà.
NCDC ní, ìpínlẹ̀ Eko ní ènìyàn mẹ́tàdílọ́gọ́ta, mẹ́tàdínlọ́gbọ̀n láti Kano, nígbà tí ìpínlẹ̀ Kwara ni èèyàn mẹ́wàá sí,  èèyàn Mẹ́sàn ni Edo ní lọ́tẹ̀ yìí.
Ènìyàn mẹ́jọ ló lùgbàdì ààrùn náà ni Bauchi, méje ló tún jẹyọ láti Yobe, Oyo àti Kebbi ni mẹrin, Kastsina àti Niger ni mẹ́ta, Plateau, Borno, Sokoto àti Benue ní méjì nígbà ti Gombe, Ebonyi, Ogun, FCT àti Rivers ní èèyàn kọ̀ọ̀kan
Oríṣun àwòrán, NCDC
Àjọ NCDC kéde èèyàn 146 míràn tó ni ààrùn Covid-19 lórílẹ̀-èdè Naijíríà
Àjọ NCDC kéde èèyàn 242 míràn tó ni ààrùn Covid-19 lórílẹ̀-èdè Naijíríà
Àjọ NCDC kéde èèyàn 242 míràn tó ni ààrùn Covid-19 lórílẹ̀-èdè Naijíríà
Àjọ tó ń gbógun ti àjàkálẹ̀ ààrùn lórílẹ̀-èdè Nàìjíríà NCDC ti kéde pé ènìyàn ìgbàléméjìlélógójì ni àyẹ̀wò tún fi hàn pé ó ti ní ààrùn Coronavirus lórílè-èdè yìí ti àpapọ̀ àwọn tó ní  ààrùn náà Nàìjíríà sì ti di ẹgbẹ̀rún mẹ́rin àti ẹgbẹ̀taléméjílèlógójì.
Gẹ́gẹ́ bi àjọ náà ṣe sọ lójú òpó twitter rẹ̀ lálẹ́ ọjọ́ ajé ènìyàn àádóje ló ti kún nígbà ti èjìlélẹ́ẹ̀dẹ́gbẹ̀rún ti ri ìwòsàn gbà.
NCDC ní ìpínlẹ̀ Eko ní ènìyàn mẹ́jìdínláàdọ́rùn, mẹ́rìnlélọ́gọ́ta láti Kano, nígbà tí ìpínlẹ̀ Katsina ni èèyàn mọ́kàndínládọ́ta tí Kaduna si ni mẹ́tàlá
Oríṣun àwòrán, NCDC
Àjọ NCDC kéde èèyàn 242 míràn tó ni ààrùn Covid-19 lórílẹ̀-èdè Naijíríà
Ènìyàn mẹ́sàn ló tún jẹyọ láti Ogun, nígbà ti mẹ́fà wá lati Gombe, mẹ́rin láti Adamawa ti Abuja sì ní mẹ́ta.
Àwọn ìpínlẹ̀ mẹ́fà bi Ondo, Oyo, Rivers, Zamfara, Borno, àti Bauchi ní èèyàn kọ̀ọ̀kan
Àjọ NCDC kéde èèyàn 248 míràn tó ni ààrùn Covid-19 lórílẹ̀-èdè Naijíríà
Àjọ NCDC kéde èèyàn 248 míràn tó ni ààrùn Covid-19 lórílẹ̀-èdè Naijíríà
Àjọ tó ń gbógun ti àjàkálẹ̀ ààrùn lórílẹ̀-èdè Nàìjíríà NCDC lọ́jọ́ àìkù ti kéde pé ènìyàn ìgbàléméjìdíláàdọ́ta ni àyẹ̀wò tún fi hàn pé o ti ní ààrùn Coronavirus lórílè-èdè yìí ti àpapọ̀ àwọn to ni ààrùn náà ni Nàìjíríà sì ti di ẹgbẹ̀rún mẹ́rin àti mọ́kàndínnírinwó.
Gẹ́gẹ́ bi àjọ náà ṣe sọ ènìyàn tó kú ti n peléke sí, bá ààrùn náà ti mú ẹmi èèyàn mẹ́tàdínlógún lọ lóòjọ́ tí àwọn tó kú sì ti di ọgọ́rùn lé mẹ́tàlélógójì nígbà ti àwọn ọgọ̀rún méje àti mẹ́jìdínlọ́gọ́rin ti gba ìwòsàn lọ́wọ́ ààrùn náà..
Mọ́kanlélọ́gọ́rin àwọn tó ṣẹ̀ṣẹ̀ lùgbàdì ààrùn náà wá láti ìpínlẹ̀ Eko, márùndínlógójì láti Jigawa, nígbà tí ìpínlẹ̀ Borno àti Kano ní ènìyàn mẹ́rìndílọ́gbọ̀n.
Ènìyàn ogún ló tún jẹyọ láti Bauchi, nígbà ti mẹ́tàlá wá láti Abuja, méjìla ni ìpínlẹ̀ Edo, mẹ́wàá ní Sokoto àti méje ni Zamfara.
Kwara àti Kebbi ni èèyàn mẹ́rin, Gombe, Taraba, Ogun, àti Ekiti ni èèyàn méji tuntun nígbà ti Osun àti Bayelsa ni ẹnì kọ̀ọ̀kan.
Oríṣun àwòrán, NCDC
Àjọ NCDC kéde èèyàn 248 míràn tó ni ààrùn Covid-19 lórílẹ̀-èdè Naijíríà
Coronavirus ṣekúpa èèyàn mẹrin l'Abuja, méjì ní Kebbi, ẹni márùnlélógójì jàjàbọ́- NCDC
NCDC update on coronavirus: Covid-19 ṣekúpa èèyàn mẹrin l'Abuja, méjì ní Kebbi, ẹni márùnlélógójì jàjàbọ
Oríṣun àwòrán, Twitter/todayng
Aarun coronavirus ti ṣekupa eeyan mẹrin ni olu ilu orilẹede Naijiria, Abuja.
Ajọ to n gbogun ti ajakalẹ aarun lorilẹede Naijiria, NCDC lo fidi ọrọ naa mulẹ loju opo Twitter rẹ.
Ninu akọsilẹ ajọ naa lori ọrọ covid-19 fun ọjọ Abamẹta, eeyan marunlelogoji lo jajabọ lọwọ aarun naa ti wọn si ti pada sile wọn.
O di eeyan mẹjọ ti coronavirus ti pa niluu Abuja bayii.
Kii ṣe ilu Abuja nikan ni coronavirus ṣọṣẹ lọjọ Abamẹta, eeyan meji lo gbẹmi mi ni ipinlẹ Kebbi nigba ti eeyan kọọkan ki nipinlẹ Bornu, Katsina, Kaduna, Kwara ati Nasarawa.
Oríṣun àwòrán, Twitter/NCDC
Lapaapọ, eeyan mọkanla laarun covid-19 pa lọjọ Satide kaakiri Naijiria gẹgẹ bi akọsilẹ.
Ìjọba orílẹ̀-èdè Naijiria tí kéde àwọn ènìyàn tuntun tó tún ṣẹ̀ṣẹ̀ kó ààrùn coronavirus, ní báyìí,  ènìyàn ẹgbẹ̀rún mẹ́rin lé ni ọ̀kànléláàdọ́jọ (4151) to ti ni ààrùn náà ni Nàìjíría.
Àjọ to n gbógun ti àjàkálẹ̀ ààrùn lọ́rílẹ̀-èdè Nàìjíríà (NCDC) kéde lórí àtẹjísẹ́ wọ́n lálẹ́ ọjọ́ sátide lo fi ìkéde náà síta.
Oríṣun àwòrán, NCDC
Àjọ NCDC kéde èèyàn 239 míràn tó ni ààrùn Covid-19 lórílẹ̀-èdè Naijíríà
Gẹ̀gẹ́ bí àjọ náà ṣe sọ, ẹ̀nìyàn mẹ́tàdínlọ́gọ́rùn-ún (97) lo lùgbàdì àarùn náà ni ìpínlẹ̀ Eko, mẹ́rìnlélógójì (44) ni Bauchi, mọ́kàndínlọ́gbọ̀n (29)  ní Kano àti mọ́kàndílógún (19) ni Katsina.
Àjọ NCDC kéde èèyàn 239 míràn tó ni ààrùn Covid-19 lórílẹ̀-èdè Naijíríà
Ìpínlẹ̀ Borno ni mẹ́tàdínlógun (17), Abuja ènìyàn méje (7), Kwara mẹ́fà (6), Oyo márùn-ún (5) nígbà tí Sokoto àti Adamawa ni ènìyàn mẹ́ta-mẹ́ta.
Kebbi, Ogun àti Plateau ni ènìyàn méjì-méjì nígbà tí Ekiti ni ènìyàn kan soso.
Láti ìgbà ti ààrùn náà ti bẹ̀rẹ̀ ní ọjọ kẹtàdílọ́gbọ̀n oṣù keji ẹdún 2020, ni o tí tàn kálẹ̀ si ìpínlẹ̀ mẹ́rìnlélọ́gbọ̀n àti Abuja báyìí.
Ìpínll Eko náà si ni ìpínlẹ̀ to o ni ènìyàn to pọ̀ jù nítórí ibẹ̀ ni a ti rí ẹni àkọ́kọ́, ènìyàn to lé ní ẹgbẹ̀run kan abọ ló ti ni ààrùn náà ni ìpínlẹ̀ Eko, Ipinlẹ Kano lo tèlé, pẹ̀lú ènìyàn ọgọ́rùn márùn lé mẹ́rìndinlọ́gọ́rin, lẹ́yìn náà ni Abuja to ti ni ènìyàn ọ̀ọ̀dúnrún lé mẹ́tàlélógójì.
Oríṣun àwòrán, NCDC
Àjọ NCDC kéde èèyàn 239 míràn tó ni ààrùn Covid-19 lórílẹ̀-èdè Naijíríà
Oríṣun àwòrán, NCDC
Àjọ NCDC kéde èèyàn 386 míràn tó ni ààrùn Covid-19 lórílẹ̀-èdè Naijíríà
Èsì àyẹ̀wò àwọn ènìyàn to ni ààrùn Corornavirus fi hàn pé ènìyàn ọ̀ọ̀dùrún lémẹ́rìdíláàdọrun lo tún ti lùgbàdì àrùn náà.
Alẹ́ ọjọ́ ẹti ni ikéde yìí jáde, tí ìpínlẹ̀ Eko si ní iye èèyàn to pọ̀ jùlọ pẹ̀lúu èèyàn mẹ́ràndín ni ààdọ́san, ]ipínlẹ̀ Kano ṣe ipo keji, pẹ̀lú èèyàn márùndinlọ́gọ́ta.
Kastina ni èèyàn mọkanlelọ́gbọ̀n, Abuja ní Ogun, Borno mẹ́tadinlogun, Bauchi mẹẹdódogún, Nasarawa mẹ́rìnlá, Ogun mẹ́tàlá àti Plateau pẹlú èèyàn mẹ́wàá.
iyé èèyàn túntun to lùgbàdì àrùn náà ni àwọn ìpińlẹ̀ makànlá tókù kò tó márùn-márùn.
Ní bayìí èèyàn ẹgbẹ̀run mẹ́rin din díẹ̀ (3912) lo ti lùgbàdì à[rùn Coronavirus ní Nàìjíríà.
Àjọ NCDC kéde èèyàn 386 míràn tó ni ààrùn Covid-19 lórílẹ̀-èdè Naijíríà
Àjọ NCDC kéde ènìyàn 381 míràn tó ní ààrùn Covid-19 l'órílẹ̀-èdè Nàìjíríà
NCDC update on coronavirus: Àjọ NCDC tún ti kéde ènìyàn 381 tó ní  Covid-19 l'órílẹ̀-èdè Nàìjíríà
Èèyàn 5 mííràn tún ti lùgbàdì ààrùn Coronavirus ní Naijiria
Esi ayẹwo aarun Covid-19 tun ti fihan pe eeyan ọrinlelọọdunrun o le ẹyọkan lo tun ti ni aarun naa l'orilẹ-ede Naijiria.
Alẹ Ọjọbọ ni ajọ to n gbogun ti itankalẹ ajakalẹ aarun ni Naijiria, NCDC, kede eyi lori ayelujara Twitter rẹ.
Lọwọlọwọ, ẹgbẹrun mẹta ati ẹẹdẹgbẹta le mẹẹrindinlọgbọn (3526) eniyan to ti ni aarun naa ni Naijiria.
Oríṣun àwòrán, Ncdc
Ajọ to n gbogun ti ajakalẹ aarun ni Naijiria, NCDC, ti kede pe esi ayẹwo Covid-19 ti fihan pe igba din maarun eeyan lo tun ti ni aarun naa l'orilẹ-ede Naijiria.
Bi esi ayẹwo naa ṣe lọ niyii:
O ti pe ẹgbẹrun mẹta ati marundinlaadọjọ eeyan to ti ni aarun yii ni Naijiria. Ipinlẹ Eko lo ṣi n le waju.
Aworan afikun iroyin nipa ajakalẹ arun coronavirus ni Naijiria
Ni bi a ṣe n sọrọ iye awọn ti ayẹwo ti fihan pe on laarun coronavirus lorilẹede Naijiria ti ẹgbẹrun mẹta o dun aadọta eeyan bayii.
Ajọ NCDC lo ṣalaye ẹkunrẹrẹ eyi ninu ikede alaalẹ ti wọn maa n ṣe lati sọ ibi ti iṣẹ de duro lori ọrọ ajakalẹ arun coronavirus lorilẹede Naijiria.
Aworan afikun iroyin nipa ajakalẹ arun coronavirus ni Naijiria
Atupalẹ onka iye awọn to ti ni aarun naa, iye awọn to n gba itọju lọwọ, iye awọn to ti ri iwosan ati awn ti arun naa ti ran lọ si ọrun niyi ninu atẹ tabili yii.
Aworan afikun iroyin nipa ajakalẹ arun coronavirus ni Naijiria
Ipinlẹ Eko lo n lewaju loke tente ni iye awsn to ti ni arun naa. Bi o tilẹ jẹ wi pe awọn onimọ n jẹ ko di mimọ pe o ṣeeṣe ko jẹ wi pe nitori pe ipinlẹ Eko ni eto ayẹwo rẹ pọ juls lo fa eyi bakan naa ni ipinlẹ Kano naa ti goke tẹlee pẹlu ibẹrẹ eto ayẹwo nibẹ lẹyin ọpọlọpọ awuyewuye to wọ tọ iku ọwọọwọ ati aisi itọju ati amojuto to peye fun ajakalẹ arun naa nibẹ.
Esi ayẹwo aarun Covid-19 tun ti fihan pe eeyan mejidinlaadọjọ lo tun ti ni aarun naa l'orilẹ-ede Naijiria.
Alẹ ọjọ Iṣẹgun ni ajọ to n gbogun ti itankalẹ ajakalẹ aarun ni Naijiria, NCDC, kede eyi lori ayelujara Twitter rẹ.
Ni bayii apapọ eniyan to ti ni aarun naa ni Naijiria jẹ ẹgbẹẹdogun din aadọta.
Akojọpọ rẹ re e:
Ènìyàn 245 míràn tún ti ní Covid-19 ní NàìjíríàÀjọ NCDC kéde èèyàn 184 míràn tó ni ààrùn Covid-19 lórílẹ̀-èdè Naijíríà
Ajọ to n gbogun ti ajakalẹ aarun ni Naijiria, NCDC, ti kede pe esi ayẹwo Covid-19 ti fihan pe ojilerugba le maarun eeyan lo tun ti ni aarun naa l'orilẹ-ede Naijiria.
Bi esi ayẹwo naa ṣe lọ niyii:
Ni bayii, ẹgbẹrun meji ati ẹgbẹrin le meji (2802) eniyan lo ti ni aarun naa ni Naijiria.
Ajọ to n gbogun ti ajakalẹ aarun ni Naijiria ti kede pe esi ayẹwo ti fihan pe aadọsan eeyan lo tun ti ni aarun Covid-19 l'orilẹ-ede Naijiria.
Bi esi ayẹwo naa ṣe lọ niyii:
Ni bayii, ẹgbẹrun meji ati ọtalelẹẹdẹgbẹta (2558) eniyan lo ti ni aarun naa ni Naijiria.
Ajọ to n gbogun ti ajakalẹ aarun ni Naijiria ti kede pe esi ayẹwo ti fihan pe okoolelọdunrun eeyan lo tun ti ni aarun Covid-19 l'orilẹ-ede Naijiria.
Bi esi ayẹwo naa ṣe lọ niyii:
Lagos - 62
FCT - 52
Kaduna 31
Sokoto 13
Kebbi - 10
Yobe - 9
Borno - 6
Edo - 5
Bauchi - 5
Gombe - 4
Enugu - 4
Oyo - 4
Zamfara - 3
Nasarawa - 2
Osun - 2
Ebonyi - 2-
Kwara - 2
Kano -2
Plateau - 2
Lọwọlọwọ, o ti pe ẹgbẹrun meji ati irnwo din mejila (2388) eniyan to ti ni aarun naa ni Naijiria.
Ajọ to n gbogun ti itankalẹ ajakalẹ aarun ni orilẹ-ede Naijiria, NCDC tun ti kede esi ayẹwo ojilerugba din meji eniyan to tun ti ni aarun Covid-19.
Bi esi tuntun naa ṣe lọ niyii:
92-Kano
36-FCT
30-Lagos
16-Gombe
10-Bauchi
8-Delta
6-Oyo
5-Zamfara
5-Sokoto
4-Ondo
4-Nasarawa
3-Kwara
3-Edo
3-Ekiti
3-Borno
3-Yobe
2-Adamawa
1-Niger
1-Imo
1-Ebonyi
1-Rivers
1-Enugu
Lọwọlọwọ, o ti pe ẹgbẹrun meji le aadọsan eniyan to ti ni aarun naa ni Naijiria.
Eeyan mẹrinlenigba miran ni ayẹwo tun ti fihan pe o laarun Coronavirus lorilẹede Naijiria bayii.
Ninu ikede ti ajọ to n gbogun ti ajakalẹ arun lorilẹede Naijiria, NCDC fi sita lọjọru, ọgọrin ninu wọn lo wa lati ipinlẹ Kano, mẹrundinlaadọta ninu wọn wa lati ilu Eko, mejila ninu wọn wa lati ilu Gombe, mẹsan ninu wọn wa lati Bauchi ati Sokoto.
Meje lati Borno ati Edo, mẹfa lati Rivers ati Ogun,mẹrin ni ilu Abuja, Akwa Ibom ati Bayelsa, mẹta ni ilu Kaduna, meji ni ilu Oyo, meji ni Delta ati Nazarawa, ẹyọkan ni Ondo ati Kebbi.
Lapapapọ bayii ẹgbẹwadinmejidinladọrin (1932) eeyan ni ayẹwo fihan pe wọn ti ko arun yii lorilẹede Naijiria bayii.
Eeyan mẹrindinlọgọfa miran ni ayẹwo tun ti fihan pe o laarun Coronavirus lorilẹede Naijiria bayii.
Ninu ikede ti ajọ to n gbogun ti ajakalẹ arun lorilẹede Naijiria, NCDC fi sita lọjọru, mẹtadinlaadọrun ninu wọn lo wa lati ipinlẹ Eko, mẹrinlelogun wa lati ipinlẹ Kano, Gombe ni mejidinlogun, Kaduna mẹtadinlogun bẹẹni olu ilu orilẹede Naijiria, Abuja naani mẹrindinlogun.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Lapapapọ bayii okoolelẹẹdẹgbẹrin ati mẹjọ (1728) eeyan ni ayẹwo fihan pe wọn ti ko arun yii lorilẹede Naijiria bayii.
Katsina mẹwaa, Sokoto mẹjọ, Ẹdo meje, Borno mẹfa, Yobe, Ebọnyi ati Adamawa si ni ẹyọ kọọkan
Eeyan marundinigba miran ni ayẹwo tun ti fihan pe o ni arun Coronavirus bayii lorilẹede Naijiria.
Atẹjade kan ti ajọ to n ri si igbogun ti ajakalẹ arun lorilẹede Naijiria, NCDC fi sita loju opo Twitter rẹ ṣalaye pe, ọgọrin  ninu awọn eeyan naa wa ni ipinlẹ Eko, mejidinlogoji wa lati ilu Kano.
Bakan naa ni mẹẹdogun lati ilu Ogun, mẹẹdogun ni ilu Bauchi, mọkanla ni Borno, mẹwa ni Gombe, mẹsan ni Sokoto, marun un  ni Edo, marun un ni Jigawa, meji ni Zamfara, ẹyọkan ni Rivers, ẹyọkan ni Enugu, ẹyọkan ni Delta, ẹyọkan ni FCT ati ẹyọkan ni Nasarawa.
Eyi ti sun iye awọn to ti lugbadi arun naa siwaju di ẹmejilelaadọtadinlẹgbẹjọ.
Eniyan marundinlọgọtalenigba ninu awọn to ni arun ọhun ni Naijiria ti ri iwosan gba, ṣugbọn mẹrinlelogoji eniyan ti filẹ ṣaṣọ bora.
Eeyan mẹrinlegọta miran ni ayẹwo tun ti fihan pe o ni arun Coronavirus bayii lorilẹede Naijiria.
Atẹjade kan ti ajọ to n ri si igbogun ti ajakalẹ arun lorilẹede Naijiria, NCDC fi sita loju opo Twitter rẹ ṣalaye pe, mẹtalelọgbọn  ninu awọn eeyan naa wa ni ipinlẹ Eko, mẹẹdogun wa lati ilu Abuja, mọkanla lati ilu Borno ati meji ni ilu Gombe.
Eyi ti sun iye awọn to ti lugbadi arun naa siwaju di ẹtalelọgọtadinlẹgbẹfa
Jọwọ ṣe atunṣe ilana ikansi ayelujara rẹ lati ri ẹkunrẹrẹ rẹ
Orisun: Johns Hopkins University atawọn ajọ eto ilera ilu
Igba ti wọn kede iṣiro awọn to nii kẹyin                                              22 Oṣù Bélú 2021 12:46 WAT+3
Eniyan marundindinlọgọtalenigba ninu awọn to ni arun ọhun ni Naijiria ti ri iwosan gba, ṣugbọn ogoji eniyan ti filẹ ṣaṣọ bora.
*Iye awọn to tọwọ aisan ku ni isọri eeyan ẹgbẹrun lọna ọgọrun
Jọwọ ṣe atunṣe ilana ikansi ayelujara rẹ lati ri ẹkunrẹrẹ rẹ
Akọsile imọ yii, da lori akojọpọ iṣẹ iwadi ni Fasisti Johns Hopkins, o si le ma ṣe afihan awọn akọsilẹ iroyin to ba igba mu lati orilẹede kankan.
** Àwọn iyé akọsilẹ̀ to ti wà fún àwọn ti o ṣẹ́ṣẹ̀ ni ààrun náà jẹ́ àkójọpọ̀ ọjọ́ mẹ́ta. Nítori àwọn àtúgbẹ́yẹ̀wò, o níra láti ṣe àkójọpọ fún àwọn ọkọ́ naa
Orisun: Johns Hopkins University atawọn ajọ eto ilera ilu
Iye akọsilẹ to waye gbẹyin 22 Oṣù Bélú 2021 12:46 WAT+3
Eeyan mọkanlelaadọrun miran ni ayẹwo tun ti fihan pe o ni arun Coronavirus bayii lorilẹede Naijiria.
0Atẹjade kan ti ajọ to n ri si igbogun ti ajakalẹ arun lorilẹede Naijiria, NCDC fi sita loju opo Twitter rẹ ṣalaye pe, mẹtalelogoji ninu awọn eeyan naa wa ni ipinlẹ Eko, mẹjọ wa lati Sokoto, mẹfa lati Taraba, marun un ni Kaduna, marun un ni Gombe, mẹta ni Ondo, mẹta ni ilu Abuja.
Bakan naa ni wọn kede pe mẹta wa ni ilu Edo, mẹta ni Oyo, mẹta ni Rivers, mẹji ni Osun, ẹyọkan ni Akwa Ibom, ẹyọkan ni Bayelsa, ẹyọkan ni Ebonyi, ẹyọkan ni Kebbi.
Eyi ti sun iye awọn to ti lugbadi arun naa siwaju di ẹgbẹrunlenigbalemẹtalelaadọrin.
Eniyan mọkanlelogojilenigba ninu awọn to ni arun ọhun ni Naijiria ti ri iwosan gba, ṣugbọn ogoji eniyan ti filẹ ṣaṣọ bora.
Eeyan mejidinlọgọrin miran ni ayẹwo tun ti fihan pe o ni arun Coronavirus bayii lorilẹede Naijiria.
Atẹjade kan ti ajọ to n ri si igbogun ti ajakalẹ arun lorilẹede Naijiria, NCDC fi sita loju opo Twitter rẹ ṣalaye pe, mẹtalelọgbọn ninu awọn eeyan naa wa ni ipinlẹ Eko, mejidinlogun wa lati ilu Borno, mejila ni ilu Osun, mẹsan ni ilu Katsina, mẹrin ni ilu Kano, mẹrin ni ilu Ekiti, mẹta ni ilu Edo, mẹta ni Bauchi, ẹyọkan ni Imo.
Eyi ti sun iye awọn to ti lugbadi arun naa siwaju di ẹgbẹrunleniejilelọgọsan.
Eniyan mejilelokolenigba ninu awọn to ni arun ọhun ni Naijiria ti ri iwosan gba, ṣugbọn marundinlogoji ti filẹ ṣaṣọ bora.
Àjọ NCDC lo fi ikede naa si kita loju opo ikansiraẹni Twitter rẹ.
Eyi ti sun iye awọn to ti lugbadi arun naa siwaju di ẹgbẹrunleọkandinlọgọrun un.
Eniyan mẹjọlenigba ninu awọn to ni arun ọhun ni Naijiria ti ri iwosan gba, ṣugbọn mejilelọgbọn ti filẹ ṣaṣọ bora.
Gomina ipinlẹ Eko, babajide Sanwo-Olu ti kede iroyin ays eleyi to ni eeyan mẹwaa miran ti ruula lọwọ arun Coronavirus l'Eko akete.
Oríṣun àwòrán, Babajide sanwo-olu
Gomina Sanwo-Olu ṣalaye loju opo Twitter rẹ pe mẹta ninu awọn eeyan wọnyii lo jẹ obinrin ti meje yooku si jẹ Ọkunrin.
Mẹẹta ninu ọkunrin atobinrin mẹwaa ti wọn ri iwosan l'Eko yii ni wọn jẹ ọmọ ilẹ okeere.
Gomina Sanwo-Olu ni ko si aniani pe iye awọn to n ni arun naa n peleke sii, sibẹ iroyin aṣeyọri itọju awọn wsnyii n fihan pe iroyin ibanujẹ nikan kọ lo sodo si ọrs arun naa bayii.
Sibẹ o rọ awọn eeyan ipinlẹ Eko lati maṣe jafara pẹlu eto imọtoto wọn o nitori o daju pe iṣẹgun n bọ laipẹ.
Bakan naa lo rọ gbogbo eeyan lati darapọ mọ eto  ikede 'wọ ibomu rẹ l'Eko' iyẹn  '#MaskUpLagos campaign'
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ajọ to n mojuto ajakalẹ aarun ni Naijiria, NCDC tun ti kede pe esi ayẹwo fihan pe eniyan mejidinlaadọfa lo tun ti ni coronavirus ni Naijiria.
Mejidinlọ̀gọ̀rin lara awọn eeyan naa lo wa lati ipinlẹ Eko, mẹrila si wa lati ilu Abuja.
Lọwọlọwọ, o ti pe ẹgbẹrun kan din mẹsan to ti ni aarun naa ni Naijiria.
Atupalẹ awọn to ku niyii:
Ó ti pé ènìyàn 981 tó ní Coronavirus ní Nàìjíríà báyìí
Wọn tun ti ri eniyan mọkanlelaadọrun to ni aarun coronavirus ni Naijiria.
Ajọ NCDC kede eyi lalẹ Ọjọru.
Lọwọlọwọ, o ti pe ọrinlelẹgbẹrin din meje eniyan to ti ni aarun naa ni Naijiria.
Òǹtàjà aṣọ ni mí tẹ́lẹ̀, ọ̀dá owó ló sọ mi di alábárù
Eniyan igba din mẹta ti ri iwosan, mejidinlọgbọn si ti ku.
Atupalẹ awọn ipinlẹ ti wọn ti ri ikọọkan awọn to ṣẹṣẹ ni re e.
Àjọ to n gbógun ti àjàkálẹ̀ ààrùn lórílẹ̀-èdè Naijiria NCDC ti kéde ènìyàn ogún àwọn ènìyàn míràn to ti ni ààrun Corornavirus lórílẹ̀-èdè Naijiria.
Mẹ́tàlá nínú rẹ̀ jẹ láti ìpiínlẹ̀ Eko, méjì wá láti Edo, méjì láti Kano, meji láti ogun nígbà ti ẹyọkan jẹ lati Ondo.
Ní bayii o ti di ènìyàn òjìlélọ́ọ̀dúnrun àti mẹta to ti ni ààrun coronavirus ni Naijiria, ẹniyan mọ́kànléláàdọ́rún ló ti gba ìtúsill lọ́wọ́ ààrun náà ti ènìyàn mẹ́wàá si ti ba ààrun náà lọ
Ipinlẹ mọkandínlogun ni ààsùn náà de dúró.
Coronavirus in Nigeria: Èèyàn 325 ló ti ní àrùn Coronavirus ní Naijiria báyìí
Èèyàn 5 mííràn tún ti lùgbàdì ààrùn Coronavirus ní Naijiria
Ènìyàn márùn míràn ni àyẹwò NCDC fi han pe o tu ti ni ààrun Coronavirus lórílẹ̀-èdè Naijiria bayii.
Nínú márùn-un yìí, méjì nínú wọn  yìí jẹ́ láti ipinlẹ Eko, meji ni ìpínlẹ̀ Kwara, ẹyọkan ni ipinlẹ Katsina
Ajọ to n gbogun ti ajakalẹ arun lorilẹede Naijiria, NCDC lo kede eyi loju opo twitter rẹ lalẹ ọjọ Aikú.
Ní bayíì, ènìyàn marunlélọ́gọ́rin ló ti ri ìwòsàn ti wọ́n si ti lọ ilé wọ́n nígbà ti iye ènìyàn to kú kò tíle ni mẹ́wàá
Ẹ̀wẹ̀, ìpínlẹ̀ makandinlogun lo ti kéde ààrun Coronavirus bayii lórilẹ̀-èèdè Naijiria.
Coronavirus in Nigeria: Èèyàn 318 ló ti ní àrùn Coronavirus ní Naijiria báyìí
Coronavirus in Nigeria: Èèyàn 318 ló ti ní àrùn Coronavirus ní Naijiria báyìí
Ènìyàn mẹ́tàlá míràn ni àyẹwò NCDC fi han pe o tu ti ni ààrun Coronavirus lórílẹ̀-èdè Naijiria bayii.
Nínú mẹ́tàlá yìí, Mọkanla nínú àwọn mẹtala yìí jẹ́ láti ipinlẹ Eko, ẹyọkan ni ìpínlẹ̀ Delta, ẹyọkan ni ipinlẹ Kano
Ajọ to n gbogun ti ajakalẹ arun lorilẹede Naijiria, NCDC lo kede eyi loju opo twitter rẹ lalẹ ọjọ Ẹti.
Ní bayíì, ènìyàn ààdọrin ló ti ri ìwòsàn ti wọ́n si ti lọ ilé wọ́n nígbà ti àwọn mẹ́wàá ti baa ààrun náà lọ
Okòólélọ́dúnrun àti mẹta ènìyàn lo ti ni àrun náà ni Naijiria gẹ́gẹ́ bi NCDC se sọ
Ẹ̀wẹ̀, ìpínlẹ̀ mọ́kandinlogun àti Abuja lo ti kéde ààrun Coronavirus náà bayii lórilẹ̀-èdè Naijiria.
Èèyàn 17 mííràn tún ti lùgbàdì ààrùn Coronavirus ní Naijiria
Eeyan mẹtadinlogun miran ni ayẹwo tun ti fihan pe o ni arun coronavirus bayii.
Ajọ to n gbogun ti ajakalẹ arun lorilẹede Naijiria, NCDC lo kede eyi loju opo twitter rẹ lalẹ ọjọ Ẹti.
Nipa bayii, eeyan marunlelọọdunrun ni iye awọn ti ayẹwo ti fihan pe o ni arun Coronavirus lorilẹede Naijiria.
Mẹjọ ni ilu Eko, Mẹta ni ipinlẹ Katsina, Meji nilu Abuja, ẹyọkan ni ipinlẹ Niger, Kaduna, Anambra, ati Ondo
Iye awọn to ti  ri iwosan kuro lọwọ arun yii ti gbera sọ di mejidinlaadọta, ti eeyan meje miran si ti jade laye.
Ajọ to n risi idẹkun itankalẹ arun lorilẹede Naijiria, NCDC ti kede pe eniyan mẹrinla miran tun ti ni arun Coronavirus lorilẹede Naijiria.
Ajọ NCDC naa fi lede loju opo ikansiraẹni Twitter wọn ni alẹ Ọjọbọ.
Wọn ni eniyan mẹtala miiran tun ti lugbadi aarun naa ni ipinlẹ Eko ati ẹyọkan ni ipinlẹ Delta.
Apapọ gbogbo eeyan to ni aarun covid 19 ni Naijiria bayii jẹ mejidinlaadọrunlenigba.
Ajọ to n risi idẹkun itankalẹ arun lorilẹede Naijiria, NCDC ti kede pe eniyan mejilelogun miran tun ti ni arun Coronavirus lorilẹede Naijiria.
Ajọ NCDC naa fi lede loju opo ikansiraẹni Twitter wọn ni alẹ Ọjọru.
Wọn ni eniyan mẹẹdogun miiran tun ti lugbadi aarun naa ni ipinlẹ Eko, mẹrin ní Abuja, meji ni Bauchi, ẹyọkan ni ipinlẹ Edo.
Apapọ gbogbo eeyan to ni aarun covid 19 ni Naijiria bayii jẹ ọrin le lugba o din mẹrin.
Èèyàn 16 míràn tún ti ní àrùn Coronavirus ní Naijiria
Ajọ to n risi idẹkun itankalẹ arun lorilẹede Naijiria, NCDC ti kede pe eniyan mẹe miran tun ti ni arun Coronavirus lorilẹede Naijiria.
Ajọ NCDC naa fi lede loju opo ikansiraẹni Twitter wọn ni alẹ Ọjọ Iṣẹgun.
Wọn ni eniyan mẹwa ni ipinlẹ Eko, méjì ní Abuja, meji ni Oyo, ẹyọkan ni Delta ati ẹyọkan miran ni Katsina.
Ni apapọ ẹniyan mẹrinlelaadọtalenigba lo ti ni arun Coronavirus ni Naijiria, ti ẹniyan mẹrinlelogoji si ti ri iwosan gba, amọ ti ẹniyan mẹfa si ti ku.
Ajọ to n risi idẹkun itankalẹ arun lorilẹede Naijiria, NCDC ti kede pe eniyan mẹfa miran tun ti ni arun Coronavirus lorilẹede Naijiria.
Ajọ NCDC naa fi lede loju opo ikansiraẹni Twitter wọn ni alẹ Ọjọ Aje.
Wọn ni eniyan meji ni ipinlẹ Kwara, méjì ní Edo, ẹyọ kọ̀ọ̀kan ní ipinlẹ Rivers àti Abuja.
Ni apapọ ẹniyan mejidinlogojilenigba lo ti ni arun Coronavirus ni Naijiria, ti ẹniyan marundinlogoji si ti ri iwosan gba, amọ ti ẹniyan marun si ti ku.
Èèyàn mẹ́jọ míràn tún ti ní àrùn Coronavirus ní Naijiria
Ajọ to n risi idẹkun itankalẹ arun lorilẹede Naijiria, NCDC ti kede pe eniyan mẹjọ miran tun ti ni arun Coronavirus lorilẹede Naijiria.
Ajọ NCDC naa fi lede loju opo ikansiraẹni Twitter wọn ni Ọjọ Isinmi.
Wọn ni eniyan marun un ni ilu Eko, eniyan kan ni ilu Kaduna ati eniyan meji ni olu ilu Naijiria, Abuja.
Ni apapọ ẹniyan mejilelọgbọnlenigba lo ti ni arun Coronavirus ni Naijiria, ti ẹniyan mẹtalelọgbọn si ti ri iwosan gba, amọ ti ẹniyan marun si ti ku.
Ajọ to n risi idẹkun itankalẹ arun lorilẹede Naijiria, NCDC ti kede pe eniyan marun un miran tun ti ni arun Coronavirus lorilẹede Naijiria.
Ajọ NCDC naa fi lede loju opo ikansiraẹni Twitter wọn ni Ọjọ Satide.
Wọn ni eniyan mẹta ni ilu Bauchi ati eniyan meji ni olu ilu Naijiria, Abuja.
Ni apapọ ẹniyan mẹrinlenigba lo ti ni arun Coronavirus ni Naijiria, ti ẹniyan mẹẹdọgbọn ri si ti gba iwosan, amọ ti ẹniyan mẹrin si ti ku.
Eeyan mẹrin miran tun ti ruu la lọwọ arun Coronavirus.
Iroyin ayọ miran ree lori ọwọja arun Coronavirus to n waye bayii.
Ni ipinlẹ Eko, eeyan mẹrin miran tun ti ruu la lọwọ arun Coronavirus.
Commissioner feto ilera, Ọjọgbọn Akin Abayọmi lo kede iroyin ays yii nibi apero pẹlawọn akọroyin to ṣe lọjọ Ẹti.
Ṣaaju ọjọ Ẹti, eeyan mọkandinlogun ti ri iwosan kuro lọwọ arun naa.
Ajọ to n gbogun ti ajakalẹ arun lorilẹede Naijiria, NCDC ti kede pe awọn tun ti ṣawari eeyan mẹfa miran to ni arun Coronavirus ni ipinlẹ Ọṣun.
Ajọ naa fi sita loju opo twitter rẹ pe pẹlu bo ṣe ri yii, o ti di aadọwa eeyan ti wọn ti ṣawari pe o ni arun naa bayii lorilẹede Naijiria.
Ogun eeyan ni wọn ti gba iwosan lọwọ yii ti eeyan meji si ti jade laye.
Ni ipinlẹ Ọṣun nikan, apapọ iye awọn to ti ni arun naa bayii ti di ogun.
Eeyan mẹwa miran ni ayẹwo tun ti fihan pe o ni arun Coronavirus bayii lorilẹede Naijiria.
Atẹjade kan ti ajọ to n ri si igbogun ti ajakalẹ arun lorilẹede Naijiria, NCDC fi sita loju opo twitter rẹ ṣalaye pe, meje ninu awọn eeyan naa wa ni ipinlẹ Eko, ati mẹta ni Abuja.
Eyi ti sun iye awọn to ti lugbadi arun naa siwaju di mẹrinlelọgọsan an.
Ogun ninu awọn to ni arun ọhun ni Naijiria ti ri iwosan gba, ṣugbọn awọn meji ti filẹ ṣaṣọ bora.
Ṣé fífi òrí pa ọwọ́ rẹ leè dáàbò bò ọ́ lọ́wọ́ Coronavirus?
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Eniyan mẹtalelogun miran tun ti ni aarun coronavirus ni orilẹ-ede Naijiria.
Ileeṣẹ ijọba to n risi idena ati amojuto ajakalẹ aarun, NCDC lo fi ikede naa sita loju opo Twitter rẹ lalẹ Ọjọru.
Mẹsan an ninu awọn eeyan ọhun wa ni ipinlẹ Eko, meje wa ni Abuja, marun un ni ipinlẹ Akwa Ibom, ẹnikan ni Kaduna ati ẹnikan yoku ni Bauchi.
Ni bayii, eeyan mẹrinlelaadọsan an (174) lo ti lugbadi arun naa ni Naijria, awọn mẹsan an ti gbawosan, ti eeyan meji lara wọn si ti jẹ Ọlọrun nipe.
Coronavirus: Ṣé ọtí leè dènà tàbí pa àrùn Coronavirus bi?
Coronavirus in Nigeria: Àwọn alárùn òrónà l'Eko gbé fídíò síta láti ṣí aráàlú létí
Awọn eeyan kan ti wọn ti ko arun COVID-19 ti wọn wa ni ibudo iwosan ajakalẹ arun IDH ni Yaba nilu Eko ti gbe fidio kan sita lati ṣe itaniji fun awọn ọmọ orilẹede Naijiria ati lati fi ẹmi imoore han si awọn olutọju wọn nibẹ.
Fidio ọhun ti wọn fi sita loju opo ayelujara lọjọru ṣe afihan awọn to ni arun naa pẹlu akọle lorisirisi lọwọ wọ iboju ninu fidio naa.
"Lara awọn ohun ti wọn kọ sara iwe alakọle ti wọn gbe sọwọ ni ""Ootọ ni arun COVID-19"""
Adupẹ fun awọn eleto ilera to n tọju wa ati bẹẹbẹẹ lọ
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Eeyan mejila miran ni ayẹwo tun ti fihan pe o ni arun Coronavirus bayii lorilẹede Naijiria.
Atẹjade kan eleyii ti ajọ to n ri si igbogun ti ajakalẹ arun lorilẹede Naijiria fi sita loju opo twitter wọn ṣalaye wi pe eeyan mẹsan ninu awsn ti ayẹwo ṣẹṣẹ fi han naa lo wa ni ipinlẹ Ọṣun, meji wa ni ipinlẹ Edo, Ẹyọkan toku si wa lati ipinlẹ Ekiti.
Eyi ti sun iye awọn to ni arun yii siwaju di mọkanlelaadọjọ, 151.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ìròyìn tó ń jáde láti fásitì Johns Hopkins tó wà l'Amerika, fasiti tó  ń ṣe ìwádìí nípa nǹkan tó ń ṣẹlẹ̀ lórií ààrùn Coronavirus, ti fi hàn pé ó kéré jù èèyàn 178,378 tó ní ààrùn Coronavirus tẹ́lẹ̀  ni wọ́n ti rí ìwòsàn .
Báyìí ni ọ̀rọ̀ yìí ṣe rí ní òwúrọ̀ Ọjọ́bọ, ọjọ́ kínní oṣù kẹẹ̀rin , ọdún 2020.
Fásitì náà sọ pé, èèyàn tó kó ààrùn ààrùn Coronavirus lágbáyé ju eeypan 860,000  lọ, nígbà tí ààrùn ná ti pa èèyàn 42,354.
Orílẹ̀èdè mẹ́wàá tí àjàkálẹ̀ ààrùn náà ti pọ̀ ni :
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Akojọpọ esi ayẹwo aarun Covid-19 ni orilẹ-ede Naijiria gẹgẹ bi ajọ NCDC ṣe n kede rẹ.
Ijọba apapọ ti kede pe eeyan mẹrin miran ti ni aarun coronavirus ni Naijiria.
Ajọ to n risi idena ati amojuto ajakalẹ aarun, NCDC lo fi ikede naa sita loju opo Twitter rẹ.
Mẹta ninu awọn eeyan ọhun wa ni Abuja ti ẹnikan to ku si wa ni ipinlẹ Eko.
Nibi ọrọ de duro bayi, eeyan mọkandinlogoje (139) lo ti fara kaasa arun na lorilẹede yii, awọn meji lara wọn ti jẹ Ọlọrun nipe, ti mẹsan an si ti ri iwosan.
Coronavirus: Ǹjẹ́ fífi omi àti iyọ̀ yọnu leè dènà àrùn Coronavirus?
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ajọ to n gbogun ti ajakalẹ arun lorilẹede Naijiria tun ti kede eeyan mẹrin miran pẹlu arun Coronavirus lorilẹede Naijiria.
Mẹta ninu awọn eeyan naa lo wa lati ipinlẹ Ọṣun, eeyan kan yooku si wa lati ipinlẹ Ogun.
Eyi ti sọ iye awsn eeyan ti wọn ti kede pẹlu arun naa bayii di marundinlogoje, (135)
Meji ninu wọn lo si ti jade laye.
Ni alẹ ọjọ aje ni ajọ yii kede ogun eeyan miran to ti ko arun naa.
Mẹtala ninu wọn lo wa lati ipinlẹ Eko, mẹrin lati Abuja, meji lati ipinlẹ Kaduna ti gomina ipinlẹ Ọyọ, Seyi Makinde si kun iye wọn.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Eniyan marun un miran tun ti gba iwosan lẹyin ti wọn gba itọju fun arun coronavirus.
Oluranlọwọ fun aarẹ Muhammadu Buhari, Bashir Ahmad lo fi lede bẹẹ loju opo ikansiraẹni Twitter.
Minisita feto ilera pẹlu ti fi idi rẹ mulẹ nibi ifọrọwerọ to ṣe pẹlu awọn oniroyin ni ọsan oni.
Coronavirus: Ìjọba London ti da ọlọ́pàá sí ìgboro láti mú ẹni tó bá ń rìn gbéregbère
Iye awọn ti wọn ti gba itoju bayii ti di mẹjọ.
Amọ Lọwọlọwọ bayii, o ti le ni ọgọrun un eniyan to ti ni arun Coronavirus naa lorilẹede Naijiria.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Eniyan mẹrinla miran tun ti ni aarun coronavirus ni orilẹ-ede Naijiria.
Ajọ to n risi idena ati amojuto ajakalẹ aarun, NCDC lo fi ikede naa sita lalẹ ọjọ Aiku loju opo Twitter rẹ.
Mẹsan an ninu awọn eeyan ọhun wa ni ipinlẹ Eko, ti awọn marun un to ku si wa ni Abuja.
Nibi ọrọ de duro bayi, eeyan mọkanlelaadọfa (111) lo ti lugbadi arun na lorilẹede yii, ti ẹnikan si ti jẹ Ọlọrun nipe.
"Coronavirus in Nigeria: Ẹ wo bí ẹ ṣe lè ṣe ""hand sanitizer"" nínú ilé yín"
Oríṣun àwòrán, @dabiodunMFR
O nio jẹ ọna lati ṣadinku ba kiko arun Coronavirus wọ ipinlẹ ọhun lati awọn ipinlẹ bi ipinlẹ Eko
Ijọba ipinlẹ Ogun, labẹ iṣakoso Gomina Dapo Abiodun ti pasẹ pe ki wọn ti gbogbo ibode to wọ ipinlẹ naa lati dẹkun itankalẹ arun Coronavirus.
Gomina Abiodun sọ loju opo Twitter rẹ pe igbesẹ naa jẹ lati ṣadinku ba kiko arun Coronavirus wọ ipinlẹ ọhun lati awọn ipinlẹ to yi ka, papa julọ ipinlẹ Eko.
Igbeṣe yii ni yoo bẹrẹ lati aago mejila orun, ọjọ Aiku, ọjọ kọkandinlọgbọn, oṣu kẹta ọdun 2020.
Coronavirus in Nigeria: Ẹ wo àǹfààní tó wà nínú àrùn Coronavirus
Eyi n tumọ si pe ko ni si aye lati wọle tabi jade kuro ni ipinlẹ naa lasiko yii.
"Abiodun sọ pe  ""Mo ti paṣẹ ki wọn ti gbogbo ibode to wọ ipinlẹ yii lati awọn nipinlẹ to yi wa ka ati awọn orilẹ-ede mii."""
Abiodun tẹsiwaju pe ki awọn eeyan ipinlẹ naa fọwọsowọpọ pẹlu ijọba oun lati gbogun ti ajakalẹ arun naa to n ba gbogbo agbaye finra.
O ni ijọba ọun yoo ma ṣatunyẹwo igbesẹ naa ni igba de igba titi ti ọrọ ajakalẹ arun ọhun yoo fi niyanju.
Njẹ Chloroquine nipa kankan lati le koju Coronavirus
Oríṣun àwòrán, @elrufai
Gomina ipinlẹ Kaduna Nasir El Rufai ti kun awọn Gomina to lugbadi arun Coronavirus ni Naijiria.
Loju opo Twitter rẹ ni o fi ikede yi si ninu fọnran fidio kan ti o ti kede fawọn eeyan ipinlẹ rẹ.
O ni irọle ọjọ Abamẹta ni oun fi ara oun silẹ fayẹwo amọ bayi esi ti fi han pe oun ni Coronavirus.
Gomina El Rufai ni igbakeji oun yoo ma dari gbogbo eto nipa kikoju Coronavirus lasiko ti oun ba wa ni ayẹwo.
Ko sọ ibi ti oun ti koarun naa ṣugbọn o ni ki gbogbo awọn eeyan ipinlẹ rẹ duro nile ki wọn si tle ilana didaabo bo araẹni lọwọ Coronavirus
Ipinlẹ Benue ti di ipinlẹ tuntun ti yoo gbalejo arun Coronvirus ni Naijiria pẹlu bi ijọba ti ṣe kede pe eeyan kan ti ni arun naa nibẹ.
Gomina Samuel Ortom sọ ọrọ yi fawọn akọroyin lọjọ Abamẹta.
Oríṣun àwòrán, GovSamuelOrtom
Yatọ si ikede ijọba yi, ajọ to n mojuto itankalẹ arun ni Naijiria NCDC naa fi si oju opo wọn pe eeyan meje miran naa ti ko aisan naa nilu Eko.
Pẹlu iye eeyan tuntun ti wọn kede l'Eko ati Benue, apapọ iye eeyan to ti ni arun naa ni Naijiria ti di mọ́kàndínláàdọ́rùn ún.
Ṣaaju lati fi to yin leti pe eeyan mọkanla miran tun ti ni arun Coronavirus lorilẹede Naijiria, eleyii ti apapọ awọn to ni arun naa fi da mọkanlelọgọrin.
Ajọ to n risi idena ati amojuto ajakalẹ aarun ni Naijiria, NCDC  lo fi iroyin yin lede ni oju opo ikansiraẹni Twitter wọn.
NCDC ni eniyan mẹjọ miran lo lugbadi arun naa ni ipinlẹ Eko, meji ni ipinlẹ Enugu ati ẹyọkan ni ipinlẹ Edo.
Lati igba ti ajakalẹ arun yii ti de orilẹede Naijiria, eniyan kan lo ti ku nitori arun naa, ti ile iwosan si ti fi awọn mẹta silẹ lẹyin ti wọn bori arun naa.
Coronavirus: Kò sí ẹni tí coronavirus kò le mú
Ajọ NCDC tun ṣe atupale awọn ipinlẹ ti arun Coronavirus naa ti tan de.
Nigeria lockdown: Kí ni àwọn kókó tí Ààrẹ Buhari tẹnumọ́ nínú ọ̀rọ̀ tó bá àwọn ọmọ Nàìjíríà sọ lọ́jọ́ Àìkú?
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Lootọ ni Aarẹ orilẹ-ede Naijiria, Muhammadu Buhari ti kede pe ko ni si lilọ bibọ ọkọ ati eniyan nipinlẹ Eko, Ogun ati ilu Abuja, ṣugbọn ofin yii ko de awọn kan.
Eyi ko ṣẹyin bi iṣẹ wọn ṣe ṣe pataki si igbaye-gbadun awọn araalu.
Lara awọn eniyan naa lati ri awọn to n ṣiṣẹ ni awọn ileeṣẹ ẹrọ ibaraẹnisọrọ, awọn ileeṣẹ iroyin radio ati amohunmaworan, awọn oniweeroyin, to si le fi ẹri han pe awọn ko le ṣiṣẹ lati ile wọn.
Bakan naa ni ko yọ awọn ileeṣẹ to n ṣe nkan ti ẹnu njẹ, awọn ileepo bẹtiro, awọn ileeṣẹ eleto aabo ti ijọba ati aladani to fi mọ ileeṣẹ amunawa.
Eyi ko yọ awọn oṣiṣẹ ileewosan, awọn ile itaja ogun silẹ.
Ẹwẹ, iaarẹ sọ pe awọn ọkọ ti yoo lanfaani lati rin loju popo ni awọn ọkọ to ba ko ounjẹ ati ohun eelo itọju alaisan.
Oríṣun àwòrán, The Guardian
Aarẹ Muhammadu Buhari ti kede awọn igbesẹ tuntun lori ọna ati wawọ ajakalẹ arun Coronavirus lorilẹede Naijiria.
Aarẹ Buhari ni awọn igbesẹ naa da lori amọran ileeṣẹ eto ilera nijọba apapọ ati ajọ to n gbogun ti ajakalẹ arun lorilẹede Naijiria
Aarẹ ni lootọ inira pupọ ni igbesẹ yii yoo mu ba awọn ọmọ orilẹede Naijiria ṣugbọn ọrọ arun coronavirus lorilẹede Naijiria bayii ti di tiku-tiye; o ti di ọrọ sunnukun to nilo amojuto pẹlu oju sunnukun.
Aarẹ ni pẹlu bi nnkan ṣe yọri si fun awọn eeyan orilẹede bii Italy ati Faranse, ko si ifarada to pọju fun ati koju aru naa ko to gba aorilẹede Naijiria kan.
Oríṣun àwòrán, Bashir Ahmad
Oríṣun àwòrán, Bashir Ahmad
Oríṣun àwòrán, lasg
Chloroquine for coronavirus: Àjọ NAFDAC fọwọ́ sí pípo ògùn chloroquine fún àyẹ̀wò ìtọ́jú coronavirus ní Nàìjíríà
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ajọ to n mojuto ṣiṣe, lilo ati tita ogun oyinbo ni Naijiria, NAFDAC, ti fun ileeṣẹ apoogun oyinbo kan ni aṣẹ lati ṣe ogun Chloroquine fun itọju coronavirus.
Eyi jẹyọ ninu atẹjade kan ti ọga agba ajọ naa, Ọjọgbọn Christianah Adeyeye fi sita.
Adeyeye sọ pe igbesẹ naa waye lẹyin ayẹwo ti awọn onimọ iṣegun oyinbo ṣe lawọn ileewosan kan ni China, ti esi ayẹwo wọn si fihan pe Chloroquine le kapa otutu aya ti aarun Coronavirus ba fa, ti eyi si le ke ẹmi aarun naa kuru.
O sọ pe lootọ ni ajọ naa ti fi ofin de lilo chloroquine fun itọju aisan iba ni Naijiria, ṣugbọn wọn ti n ṣe agbeyẹwo rẹ pada lati fi koju aarun tuntun, coronavirus.
Sogidi Lake: Kòṣẹja-kòṣèèyàn lá bá nínú adágún odò náà -Ojedele
Nafdac sọ pe wọn yoo dan ogun chloroquine naa wo lara awọn eniyan to ba ni aarun naa lati le mọ boya yoo ṣiṣẹ fun.
Adeyeye tẹsiwaju ninu ọrọ rẹ pe awọn oluwadii ni orilẹ-ede France ati America ti gbiyanju ogun naa fun itọju coronavirus, ti wọn si sọ pe o ṣiṣẹ.
Ipinlẹ Eko yoo bẹrẹ si ni dan chloroquine wo lati mọ bi yoo ṣe ṣiṣẹ si.
Ṣugbọn ṣa, ajọ NAFDAC gba awọn ara ilu ni imọran pe ki wọn o ma lo ogun chloroquine lai gba imọran lọwọ dokita wọn, nitori aṣilo rẹ le fa inu rirun, ki oju o ma a wo baibia, ori fifọ, ati ara yiyun.
Aṣẹ yii ko tumọ si pe wọn ti bẹrẹ si ni i lo chloroquine fun itọju coronavirus, ṣugbọn wọn ti ṣe ọpọlọpọ ogun naa pamọ lati lo, ti awọn ọpọ eeyan ba ko aarun naa.
Nítorí Coronavirus, àjọ Olympics lágbayé kéde ọjọ́ tuntun fún ìdíje Tokyo 2020
Idije ere idaraya Tokyo Olympic games yoo bẹrẹ ni ọjọ kẹtalelogun oṣu keje ọdun 2021 bayii yoo si pari ni ọjs kẹjọ oṣu kẹjọ ọdun kan naa.
Ajọ ere idaraya olympics lagbaye, IOC lo gbe ikede yii jade lẹyin ipade igbimọ iṣakoso rẹ to waye  loni ọjọ Aje, ọgbọn ọjọ oṣu kẹta ọdun 2020.
Wọn sun idije agbaye naa to yẹ ko waye lọdun yii tẹlẹ siwaju nitori ajakalẹ arun Coronavirus to n da agbaye laamu lọwọlọwọ.
Orukọ idije naa ko ni yipada kuro ni Tokyo 2020 to n jẹ tẹlẹ.
Ọjọ karundinlọgbọn oṣu kẹjọ ọdun yii lo yẹ ki idije paralympics to wa fawọn akanda ẹda naa bẹrẹ tẹlẹ, ohun naa yoo wa bẹrẹ ni ọjọ kẹrinlelogun oṣu kẹjọ si ọjọ karun oṣu kẹsan ọdun 2021.
"Aarẹ ajọ IOC lagbaye, Thomas Bach ṣalaye pe, ""Ọmọ eniyan n la afonifoji dudu kọja lọwọ bayii, idije olympics yii si lee jẹ imọlẹ ti yoo tan lẹyin okunkun biribiri naa"""
Ọwọ ijọba ipinlẹ Ọyọ tẹ awọn eeyan mẹjọ kan to sọ ile ẹkọ ijọba di ileeṣẹ bulọku ati ile igbe
Awọn eeyan mẹjọ ọtọọtọ ti bẹrẹ sini fi oju wina ofin ijọba ipinlẹ Ọyọ nipasẹ lilo ayika awọn ile ẹkọ to jẹ ti ijọba lọna aitọ.
L'Ọjọ iṣẹgun kẹlẹ ijọba gbe awọn eeyan mẹjọ naa ni agbegbe Ologunẹru niluu Ibadan nibi ti wọn ri ẹrọ nla to n mọ bulọku si ni ayika ile ẹkọ kan to jẹ ti ijọba ipinlẹ Ọyọ.
Ile ẹkọ igbalode naa ti o di kikọ nipasẹ ajọṣepọ laarin ijọba apapọ ati ẹka eto ẹkọ nipinlẹ Ọyọ lo n bẹ ni ibudo idako Agbopa-Akufo ni ijọba ibilẹ Ido.
Ninu ọrọ rẹ lasiko irinkerindo lati ṣe amojuto awọn dukiya ijọba lasiko ti aarun Corona n ba gbogbo aye finra, alaga ẹka eto ẹkọ kalekako nipinlẹ Ọyọ, SUBEB, Ọmọwe Nureni Adeniran fi aidun inu rẹ han lorii
iwa kotọọ to n waye ni ninu ọgba ile ẹkọ naa gẹgẹ bi o ṣe n bura wi pe awọn to huwa ibajẹ naa ko ni lọ lai fi imu k'ata ofin.
Adeniran ṣe alaye wi pe awọn basejẹ naa ti ṣi ilekun ewu to pọ silẹ fun ile ẹkọ naa pẹlu afikun wi pe awọn yara ikẹkọọ, ile igbọnsẹ ati kọnga igbalode ti wọn kọ si ile ẹkọ naa ni awọn onile iṣẹ bulọku naa ti
bajẹ.
"O ni, ""Kodaa wọn ti sọ awọn yara ikẹkọọ di ibi ti wọn n sun si gẹgẹ bi wọn ṣe fọn gbogbo ohun ini wọn si ayika ile ẹkọ naa""."
"Adeniran tẹsiwaju wi pe, "" ni awọn ikorita kan, awọn basejẹ yii ti sọ awọn dukiya ijọba ti ara wọn pẹluu bi o ṣe jẹ wi pe gbogbo awọn ile ẹkọ yii ni ijọba mọ odi yika.Niṣe ni wọn n fi ipa ṣe akoba fun awọn dukiya ijọba jakejado ipinlẹ Ọyọ""."
Gẹgẹ bi Adeniran ṣe sọ, awọn eeyan mẹjọ to n ta ọjọ lọna aitọ ninu ọgba ile ẹkọ ijọba ni yoo fi oju ba ile ẹjọ ti wọn yoo si jẹjọ nilana ofin.
O ni eleyii yoo mu ki awọn basejẹ ti o ku so ewe agbejẹ mọwọ.
Iṣẹ iwadi fi han wi pe lati igba ti awọn ile ẹkọ ti di titi nitori aarun Corona ni awọn eeyan naa ti sọ ọgba ile ẹkọ ijọba di ile itaja.
Oríṣun àwòrán, Seyi makinde
Ko si ija laarin gomina Seyi Makinde ati aarẹ Buhari.
Ẹgbẹ oṣelu PDP ti ke gbajare sita pe awọn ohun to n waye paapaajulọ lasiko ajakalẹ arun coronavirus to n waye lọwọ ko ni ohunkohun n ṣe eyi to lee tọka si pe gomina Makinde tabi ijọba ipinlẹ Ọyọ n wọ iya ija pẹlu ijọba apapọ atawọn ileeṣẹ rẹ gbogbo.
Wo àwọn bẹbẹ tí Umar Musa Yar'adua ṣe lórí àlééfà
Ẹgbẹ́ àwa dókíta ló ra ìbòmú fúra wa- Alága NMA Ogun
Lóòtọ́ lò n lo ìbomú-bẹnu, ṣùgbọ́n ṣe bóṣeyẹ kí o wọ̀ ọ́ ló ṣe n ṣe?
Ilé aṣòfin àgbà ní ìyàtọ̀ wà láàrín gbèsè ti Buhari àti Jonathan jẹ
Atẹjade kan ti alukoro ẹgbẹ oṣelu PDP ni ipinlẹ Ọyọ, Akeem Ọlatunji fi sita ṣalaye pe irọ ni gbogbo awọn to ba n sọ pe gomina Makinde n fi oju tẹmbẹlu ipo aarẹ n pa.
Ẹgbẹ oṣelu PDP fi kun un pe gbogbo awọn to n sọ ọ kaakiri pe gomina Makinde kii pe aarẹ tabi baa sọrọ ko sọ otitọ nitori ko si ofin to sọ pe ajọṣepọ tabi ajọsọ ọrọ to ba waye laarin Gomina Makinde ati aarẹ gbọdọ di eyi ti a n polongo fun aye ri.
Niyi Akinmolayan tó ṣe fíìmu àwòrán-dèèyàn Cartoon nípa COVID-19 tó la ayé já ní N
O fi kun un pe ọfiisi kii ṣe eyi ti gbogbo awọn gomina ni lati maa fojojumọ kọ lẹta ifẹ ranṣẹ si.
Ẹgbẹ oṣelu APC lo ti kọkọ fi atẹjade sita ninu eyi to ti fẹsun kan gomina Makinde pe o n fi oju tẹmbẹlu ọfiisi aarẹ debi pe kii ni ibanisọrọ kankan pẹlu aarẹ.
Oríṣun àwòrán, Seyi makinde
Ni ọjọ Aje ni gomina ipinlẹ Ọyọ, Onimọẹrọ Ṣeyi Makinde kede pe oun pẹlu ti fara kaasa arun Coronavirus ati pe oun ti fi ara oun si igbele.
Ọkan-o-jọkan awọn ọmọ orilẹede Naijiria, paapaajulọ awọn eeyan ipinlẹ Ọyọ ni wọn si ti n kii.
Pataki lara awọn to ti ki gomina naa ni Sẹnetọ Abiọla Ajimọbi to fi ipo naa silẹ lọdun 2019.
Sẹnetọ Ajimọbi ni inu oun bajẹ gidigidi nigba ti oun gbọ iroyin pe Gomina Seyi Makinde ti ko arun ọhun.
Ninu atẹjade kan eyi to fi sita, Sẹnetọ Ajimọbi ni kete ti oun gbọ iroyin ni oun ti fi iṣẹ ma foya abo Ọlọrun wa pẹlu rẹ ranṣẹ si Gomina Makinde ni kete lẹyin to kede rẹ.
Parental Guidance: Ọdún méjì ni kí ẹ ti bẹ̀rẹ̀ kíkọ́ ọmọ nípa ìbálòpọ̀
Sẹnetọ Ajimọbi kan sara si gomina ipinlẹ Ọyọ fun ọkan akin to ṣe lati kede fun araye pe oun naa ti ko arun ọhun.
Gomina ana nipinlẹ Ọyọ naa wa jẹ ko di mimọ faraalu pe, arun Coronavirus kii ṣe idajọ iku o, bo pẹ, bo ya ilẹ agbaye yoo bori rẹ.
Oríṣun àwòrán, Seyi makinde
Ni ọjọ aje ni gomina ipinlẹ Ọyọ, Ṣeyi Makinde kede rẹ faye gbọ pe oun naa ti dara pọ mọ iye awọn to ti ko arun Coronavirus lorilẹede Naijiria.
Nnkan bii agogo marun abọ irọlẹ ọjọ Aje ni gomina Makinde tẹwọ gba esi ayẹwo rẹ ninu eyi to ti mọ pe oun ti ko arun naa.
Amọṣa nibo ni Makinde ti ko arun yii naa?
Atẹjade kan ti agbẹnusọ fun gomina Makinde, Taiwo Adisa fi sita ṣalaye pe nibi ipade igbimọ ọrs aje lorilẹede Naijiria, NEC ni Makinde ti fẹrẹ ko arun ọhun.
Gomina Makinde wa lara awọn gomina to farahan nibi ipade igbimọ naa, gẹgẹ bi atẹjade ọhun ṣe sọ.
Ọjọ diẹ lẹyin ipade ọhun ni igbimọ awọn gomina lorilẹede Naijiria ba gba gbogbo awọn gomina to wa nibi ipade naa nimọran pe ki wọn lọ ṣe ayẹwo ara wọn nitori iroyin to n jade pe lara awọn to wa nibi ipade naa ti ko arun ọhun.
Ṣẹ́ lóòtọ́ ní ginger àti garlic lè pa àrun Coronavirus?
Iroyin ayẹwo Gomina Makinde yii n waye lẹyin ti wọn da ẹni akọkọ ti wọn kede pe o larun naa ni ipinlẹ Ọyọ silẹ.
Alabọde Amẹrika kan ni ẹni akọkọ ti wọn kede poe o ni arun naa nipinlẹ Ọyọ, wọn si ti daa silẹ pe ki o maa lọ sile bayii lẹyin itọju to peye ni ileewosan ti ayẹwo miran si ti fihan pe arun naa ti kuro ni agọ ara rẹ.
Àrùn Coronavirus àti ìbálòpọ̀ akọ àt'abo: Wo àwọn ohun tó yẹ kí o mọ̀ nípa
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Tí Mo ba ní ìbálòpọ̀ njẹ mo lè kó aarun Koronafairọs? Irú èrò yìí lè wa si yín lọ́kàn sugbon o tini lójú láti béèrè.Kí a yọ epo kúrò nínú àlìkámà, a ti bere ìbéèrè lowo awon onímò.Dókítà Alex George to je oníṣègùn oyinbo àti Alix Fox tó jẹ́ akoroyin nípa ìbálòpọ̀ to sì tún jé sọ̀rọ̀ sọ̀rọ̀ lórí Radio BBC tí ṣàlàyé lórí àwọn ìbéèrè yìí.
Ṣe ko si ewu láti ni ìbálòpọ̀ lásìkò Coronavirus yìí?Dókítà Alex George: Bí ó bá ní olólùfẹ́, tí ẹ jọ ń gbé tí ẹ sì jó ń ṣe pò ni agbègbè kan náà, èyí kò yẹ kí o yí onkohun padà. Èwe tí a bá wà rí pé enikan ń fi àmì hàn èyí túmọ̀ sí pé kí ó fún ẹni náà láàyè tí oloyinbo ń pè ní Social Distancing kí ẹni náà sì wà ní igbele laarin ilé yín náà ni, ní ìlànà tó kofin ja ó yẹ kí olúkúlùkù máa fún ara wọn ní ààyè ìwọ̀n mita méjì sí ara ẹni,sugbon a rí pé èyí lè nira díè.Alix Fox: ó sì pọn dandan kí  a mo pe bí ìwọ bá ní aarun náà tí ó sì àwọn àmì tí kò nira, má ro pe bẹẹ naa ni yoo ri fún enikeji rẹ, bí ó bá ti rí àpẹẹrẹ, yẹra fún olólùfẹ́ rẹ.
Tí Mo ba fi ẹnu kò ẹni tí mo ṣẹ̀ṣẹ̀ pàdé lenu tí ó wà padà rí àpẹẹrẹ aarun náà, kini kí n ṣe?
Doctor Alex: Bí ó bá fi ẹnu kò ènìyàn lenu, tàbí salabapade ẹni tí ó ní aarun náà, ri dájú pé o di ara rẹ sí igbele.Fojú àti ọkàn sí láti mọ bóyá ó ní àpẹẹrẹ, tí ó bá wà tí fi idi rẹ múlè pé ó ní aarun náà, ó jí láti sọra ṣe kí ó sì pe lọ sí orí ayélujára NCDC láti pé àkíyèsí wọn.Alix Fox,: O ṣe pàtàkì láti máa jẹ alábòójútó ẹni kejì wá àti fún àwa arawa, tí ó bá jẹ pe iwọ lọ rí àmì tí ó sì kó pé ó ti fi ẹnu kò àwọn ènìyàn lenu, ó ṣe pàtàkì kí je ki awon eniyan naa mọ, bti bá sì jẹ́ pé ìwọ náà lọ rí àmì lẹ́yìn tí ó fi ẹnu kò enikeni lẹ́nu, ó ṣe pàtàkì kí ó fi ara rẹ pamọ.
Alix Fox: Ìdáhùn yẹ nise pelu ìdí tí ó kii fi lọ roba ifaabobo tẹ́lẹ̀.To óò bá lọ roba idaboobo nítorí pé ìwọ àti enikeji rẹ tí ṣe ayẹwo pé eko ni a aarun tí ń tí ara ìbálòpọ̀ wáyé, tàbí ẹ ń lọ oogun tí kì je ki eniyan ni oyún tí ènìyàn kò fẹ́, ìyẹn dára, sugbon tó bá jẹ́ pé ó kii lọ roba idaabobo ni torí ó fi ọkàn sí pé ẹ ó máa faa yọ tàbí ẹ ń fọkàn sí pé ẹ ó lè ní aarun tó ń tí ara ìbálòpọ̀ mú ènìyàn, ó ṣe pàtàkì kí ẹ bere si lọ roba idaboobo ni asiko yii.
Ǹjẹ́ mo lè ni Coronavirus nípa fífi owó kan nkan obinrjn/ọkùnrin enikeji mi.
Dókítà Alex: Bí ẹ ó bá fi ọwọ kan nkan Obìnrin/Ọkùnrin enikeji rẹ, o ni lati je pe e tí ń fi ẹnu kò ara yín lẹ́nu, èyí sì ni góńgó orí rẹ nítorí ati ara ìtó ni aarun náà ń gba wo àgó ara nítorí náà ayé de fìdí láti gbé aarun náà fún enikeji, sugbon nkan ti ṣe pàtàkì jù ni pé ó ṣe pàtàkì kí olójú fe méjì wá lábé òrùlé kan náà, kí ẹ sì mọ ipò tí olúkúlùkù wa.
Alix Fox: Oro ajakale aarun yìi tí ń mu kí òpó ènìyàn ronú bí wọn ṣe ni ìbálòpọ̀ tó dára ní òpò ìgbà àwọn miran ti wọn wa jí igbele gniyan láti kó leta ololufe sí ara wọn tí wón sì ni ìbálòpọ̀ tó dára lai fi ojú kan ara wọn. Èyí tí ń mú kí ọpọlọ ọgbọ́n atinuda wọn láti mú ìgbádùn bá ara wọn àti ololufe wọn.
Alix Fox: Dókítà Michael Brady ni Terrance Higgins Trust tí fi àwọn imoran kán síta lórí èyí, tí ó bá jẹ pe oun lọ oogun rẹ loore koore nítorí aarun HIV tí sì jí CD4 tó dára èyí  timo sì lè a ó lè ka ó mọ àwọn tí èròjà tó bá àìsàn woyaja rẹ kò lágbára tó, nítorí náà tí ó bá ní aarun HIV, tesiwaju láti máa lọ oogun rẹ  kì o sì tẹ́lẹ̀ àwọn ìlànà tí ó yẹ bí ó bá ti ṣe alabapade ẹni tí ó ní aarun Coronavirus.
Sowore: Ilé ẹjọ́ pàṣẹ kí ìjọba àpapọ̀ san ₦1m owó ẹ̀bẹ̀ fún ẹgbẹ́ ajijagbara Sowore, torí ìwọde wọn tí wọ́n dà rú
Oríṣun àwòrán, omoyele sowore
Ilé ẹjọ́ gíga tí ìjọba àpapọ̀ tó wà n'ilu Eko ti pàṣẹ fún ìjọba láti san mílíọ̀nù kan náírà fún ẹgbẹ́ ajijagbara Revolution Now, lórí bo se da ìwọde ẹgbẹ́ náà ru ni ọjọ́ Kàrún oṣù Kẹjọ ọdún 2019.
Agbẹjọro kan tó kopa ninu ìwọde náà, Olukoya Ogungbeje, ló wọ ìjọba lọ sílè ẹjọ́, lórí ẹ̀sùn pé àwọn òṣìṣẹ́ alaabo yín afẹ́fẹ́ tajú-tajú sì òun àti àwọn èèyàn yókù to ń ṣe ìwọde lójú.
Ilé ẹjọ́, tó ní Ogungbeje jàre ẹjọ́ ọhun, tún pàṣẹ fún ìjọba àpapọ̀ láti tọrọ aforijin lọ́wọ́ olupẹjọ náà, lójú ewé ìwé ìròyìn mẹta nilẹ wá.
"Adajọ Maureen Onyetenu, tún kéde pé bí ijọba àpapọ̀, láti ipasẹ àwọn Ọlọpaa ṣe da ìwọde náà ru  ""kò bófin mú, ìwà ìjẹgàba ni, kò bá ìlànà ìjọba alagbada mú, tó sì tún tako àmúlò òfin ilẹ wa""."
Oríṣun àwòrán, omoyele sowore
Bákan náà ni adajọ Onyetenu gbà pé, ìjọba fi ẹtọ Ogungbeje to pé ẹjọ́ ní orúkọ àwọn Oluwọde yoku dùn wọn, nítorí abala kejidinlogoji, ikokandinlogoji àti ogójì òfin ilẹ̀ wá ti ọdún 1999, tí fun wọn ní àǹfààní
láti ṣe bẹ́ẹ̀.
Adajọ náà tún korò ojú sì bí awọn agbofinro ṣe gbé àwọn oluwode náà lọpọ yanturu, tá àbùkù wọn, fín afẹ́fẹ́ tajú-tajú sì wọn lójú àti fífi wọn sínú túbú.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ọga patapata fun ileeṣẹ ọlọpaa lorilẹ€de Naijiria,  Mohammed Adamu ti ke si araalu pe ẹnikẹni to ba ṣiwọ lu ọlọpaa to wa lẹnu iṣẹ rẹ yoo jẹ iyan rẹ niṣu ni.
Ọga ọlọpaaAdamu sọ ọrọ yii ninu esi rẹ lori arabinrin kan to kọlu ọga ọlọpaa kan ni ilu Eruwa ni ipinlẹ Ọyọ.
Ọga ọlọpaa naa ti wọn pe orukọ rẹ ni ASP Adeyẹmọ Ogunyẹmi lo lọ si agbegbe Gbọlaguntẹ Okeọola ni Eruwa iyẹn nijọba ibilẹ Ibarapa East ni ipinlẹ Ọyọ lati lọ fidi ofin konile o gbele mulẹ nibẹ.
Nibẹ ni arabinrin kan ti orukọ rẹ n jẹ Kẹhinde Afolakẹ ti kọluu to si soo laṣọ mu. Igbaju igbamu ni arabinrin naa fi ṣe ọga ọlọpaa naa lọjọ.
Ẹ wo fidio naa:
Ọga ọlọpaa lorilẹede Naijiria tun ṣalaye siwaju sii pe nigba ti wọn tun ranṣẹ pe arabinrin yii ni ọjọ keji pe ko wa wi tẹnu rẹ lori bi o ṣe kọlu ọga ọlọpaa naa, nṣe lo tun mu awọn ọlọpaa obinrin mejeeji Ripẹtọ Ojola Abiola ati Queen Eguaje ti wọn ran sii lu, koda o tun ge ọkan ninu wọn jẹ pẹlu.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ọga ọlọpaa lorilẹ-ede Naijiria wa ke si kọmiṣọna ọlọpaa lati ṣe iwadii si iṣẹlẹ naa lati lee gbe igbesẹ to ba ts ni ibamu pẹlu ofin.
Bakan naa lo kan sara si ọga ọlọpaa Adeyẹmọ fun iwa ọmọluabi ati ikora-ẹni-ni-ijanu to hu pẹlu bi obinrin yii ṣe n luu to lọjọ naa.
O ni eyi jẹ apẹrẹ oniruru ikọlu ti awọn ọlọpaa n dojukọ lẹnu iṣẹ wọn
Amọṣa ọga ọlọpaa patapata lorilẹ€de Naijiria ni ko si ẹnikẹni to ba tun ṣiwọ lu ọlọpaa to n ṣe iṣẹ rẹ mọ lorilẹede Naijiria ti ko ni jẹ iyan rẹ ni iṣu.
O ni ko din ni ọlọpaa mẹtadinlọgbọn tawọn eeyan bii arabinrin Afọlakẹ ti kọlu lati igba ti ajakalẹ arun COVID-19 yii ti bẹrẹ, ọpọlọpọ ninu wọn lo si ti di ero ileewosan ninu eyi ti wọn ko tii bọ di bi a ṣe n sọrọ yii.
Laarin asiko ti a n sọrọ rẹ yii naa, ọkọ ọlọpaa bii marundinlogun ni awọn eeyan kan ti bajẹ, pẹlu ileeṣẹ ọẹọpaa meji ni Katsina ati Abia ni awọn eeyan kan ti dana sun.
Oríṣun àwòrán, Wolii arole
Ilumọọka adẹrinposonu lórí ayelujara, Oluwatoyin Bayegun, tí ọ̀pọ̀ èèyàn mọ si Wòlíì Arole, tí ṣàlàyé pé ore-ọ̀fẹ́ àti àánú Ọlọ́run ló gbé òun sókè.
O sọ nipa irinajo rẹ láti ilé ẹ̀kọ́ Fáṣítì ti òun ti bẹ̀rẹ̀ awada lórí ayelujara.
Wòlíì Arole, lásìkò to ń bá BBC Yoruba sọ̀rọ̀ ṣàlàyé pé, isẹ awada sise tí gbé òun de ibi gíga, tí òun kò lérò pé òun leè de rí, tí òun ṣi tún mọ àwọn èèyàn ńlá-ńlá pẹ̀lú.
Mo ti lọ sí ilé aarẹ Nàìjíríà, Aso Rock ni ẹẹmeji, ìyàwó Buhari gan tí fun mi ni àmì ẹyẹ rí, mo sì máa ń lọ silu oyinbo loore koore, láti ipasẹ awada yìí náà ni.
"Wòlíì Arole ni ""ọpọ ni kò fẹ́ kọ́kọ́ tẹ́wọ́ gba mi nígbà tí mo bẹ̀rẹ̀, wọn ní èdè Yorùbá ni mo ń sọ àmọ́ nígbà tí kìí se àwọn ni Ọlọ́run, mo rí ọ̀nà àbáyọ."""
Nígbà tó ń sọ̀rọ̀ lórí àwọn ìpènijà tó ti là kọjá sẹ́yìn, Wòlíì Arole ni ọjọ́ kan wà tí wọn gba òun sì ẹgbẹ́ níbi ayẹyẹ kan torí pé òun kò tíì ní òkìkí nígbà náà àmọ́ òun dúpẹ́ fún ibi tí Ọlọ́run mú òun de lónìí.
" Ẹ̀jẹ̀ mi ni Jésù, n kò sì tíì dé ibi tó ń mú mi lọ.
Mo sì ń rọ àwọn èèyàn láti mase ro ara wọn pín, tàbí mú ìrẹ̀wẹ̀sì bá ọkàn wọn nitori ohun tí àwọn ènìyàn ba n sọ.
Ọlọ́run ní kẹ gbé ọkàn yín lé, torí ohun ènìyàn  kọ ni ohùn Ọlọ́run."
Se lootọ ni pe eniyan le ko Coronavirus lara ẹni to ti kú?
"O wa ṣàlàyé pé ""Ọlọ́run ran iya mi sì mi. Òrìṣà ni ìyá mi, kii se ènìyàn. Mo fẹ́ràn ìyá mi gan-an ni,"
Kò sì sí  Wòlíì Arole  lai si ọwọ màmá mi nibẹ.
"Ó mọ mi denudenu, to sì fẹ́ràn mi tọkàntọkàn, tí ọkàn mi bá sì rẹ̀wẹ̀sì, ìyá mi lo máa ń tú mi nínú."""
Wòlíì Arole ni, ẹ̀bùn ni awada òun, tí ayé fi ń ko o jẹ, òun kii sì roo awada ti tẹ́lẹ̀, kí òun tó sọ síta, èyí tó máa ń jẹ ìtẹ́wọ́gbà lọdọ aráyé.
Arole ni òun kò tíì ní ìyàwó nílé, àmọ́ ẹ̀mí Ọlọ́run ni yóò dárí òun lati darí isẹ àti ìdílé òun, lásìkò ti oun bá ní ìdílé.
Oríṣun àwòrán, Wolii arole
"O wu mi kì ń ṣe sinima àti show tèmi, kí n sì ni studio tèmi náà,
Bẹ́ẹ̀ si ni èdè òyìnbó yọ lẹ́nu mi pẹ̀lú, bí mo ṣe leè ṣe awada ni ojúlówó èdè Yoruba náà ni awada tún dùn lẹ́nu mi ni èdè gẹ̀ẹ́sì, mo sì ni eto fún méjèèjì pẹ̀lú ni ọjọ́ iwájú."
Arole wá rọ àwọn olólùfẹ́ rẹ láti jókòó sínú ilé wọn lásìkò igbele Coronavirus yìí, kí wọn sì mú gbogbo ìmọ̀ràn àti arọwa tí ìjọba ń pa fún wọn lọ nítorí ẹ̀mí kò ní ààrọ̀.
Jọwọ ṣe atunṣe ilana ikansi ayelujara rẹ lati ri ẹkunrẹrẹ rẹ
Orisun: Johns Hopkins University atawọn ajọ eto ilera ilu
Igba ti wọn kede iṣiro awọn to nii kẹyin                                              29 Oṣù Bélú 2021 13:33 WAT+3
*Iye awọn to tọwọ aisan ku ni isọri eeyan ẹgbẹrun lọna ọgọrun
Jọwọ ṣe atunṣe ilana ikansi ayelujara rẹ lati ri ẹkunrẹrẹ rẹ
Akọsile imọ yii, da lori akojọpọ iṣẹ iwadi ni Fasisti Johns Hopkins, o si le ma ṣe afihan awọn akọsilẹ iroyin to ba igba mu lati orilẹede kankan.
** Àwọn iyé akọsilẹ̀ to ti wà fún àwọn ti o ṣẹ́ṣẹ̀ ni ààrun náà jẹ́ àkójọpọ̀ ọjọ́ mẹ́ta. Nítori àwọn àtúgbẹ́yẹ̀wò, o níra láti ṣe àkójọpọ fún àwọn ọkọ́ naa
Orisun: Johns Hopkins University atawọn ajọ eto ilera ilu
Iye akọsilẹ to waye gbẹyin 29 Oṣù Bélú 2021 13:33 WAT+3
Gbenga Adeboye: Ó tẹ́ bàbá mi lọ́rùn pé ká mu gàárì nílé ju kí ebi pa ará ìta lọ -
Oluwadamilola Adeboye, tíì ṣe ọmọbìnrin gbajugbaja adẹrinposonu nnì, Gbenga Adeboye, tí sọ àwọn ìrírí tó sì rántí nípa bàbá rẹ̀ tó ti di olóògbé.
Bẹẹ bá gbàgbé, Gbenga Adeboye lo jáde láyé ni ọgbọnjọ oṣù kẹrin ọdún 2003, èyí tó pé ọdún mẹtadinlogun lonii Ọjọ́bọ.
Nígbà tó ń bá BBC Yoruba sọ̀rọ̀  láti sàmì ayajọ ìrántí ikú olóògbé náà, Oluwadamilola ni bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé òun kéré pupọ nígbà tí bàbá òun kú, àmọ́ òun leè ṣe àpèjúwe rẹ bíi ẹni tó gbé aye ṣe rere.
Oluwadamilola ni òun kò mọ ibi tí bàbá òun ti rí ẹ̀bùn tó ni àmọ́ ó fikùn pé, àwọn ẹ̀bùn rẹ náà kasiara, tó sì tún ya ní lẹ́nu pupọ.
O ṣàlàyé pé nígbà tí bàbá òun wà láyé, ojoojumọ ni ile àwọn máa ń kùn,  tí àwọn èèyàn máa ń wa, táwọn yóò sì gba àlejò, tí bàbá òun yóò sì máa ń ṣe awada pẹlu wọn, tí inú àwọn èèyàn yóò sì máa dùn, tí
wọn kò sì ní fẹ́ kúrò nínú ilé àwọn.
Mo sì lee rántí pé Baba mi jẹ́ èèyàn rere, kò si ẹni ti kii se oore fún, kò si mọ bá ṣe ń kọ láti ṣe nkan fún èèyàn, tí onitọun bá nílò iranlọwọ.
Nígbà miran ti bàbà mi bá dé sílè láti ibi tó ti lọ dá ẹrin posonu, tí a kò si ni oúnjẹ nílé, bí màmá mi bá béèrè pé owó tó mú bọ dà, yóò dáhùn pé òun ti pín owó náà fún àwọn tí ebi ń pá, tí yóò sì ní ká lọ mu
"gàárì, òun yóò fún wa lowo lọ́la láti fi ṣe irẹsi."""
'Mo ni baba isalẹ'
Ọmọbìnrin Gbenga Adeboye náà fikùn pé, Baba òun ni ifẹ gbogbo ènìyàn bíi ọmọ àti àbúrò rẹ ni, ó sì tẹ bàbá òun lọrun pé ki awọn ẹbi rẹ mu gàárì kí àwọn ará ìta leè rí oúnjẹ jẹ, tàbí rí owó fún àwọn èèyàn.
"Nígbà tó ń sọ̀rọ̀ nípa ohun tí àwọn ẹbí fẹ́ máa fi ṣe irántí Gbenga Adeboye, Oluwadamilola ni ""èmi àti màmá pẹ̀lú àwọn àbúrò mi ti pinnu láti máa ṣe atilẹyin fún àwọn osere tó ṣẹ̀ṣẹ̀ ń dìde nilẹ láti ìpilẹ̀ṣẹ̀, ní"
"kété tí ajakalẹ àrùn Coronavirus bá ti tan."""
Jọwọ ṣe atunṣe ilana ikansi ayelujara rẹ lati ri ẹkunrẹrẹ rẹ
Orisun: Johns Hopkins University atawọn ajọ eto ilera ilu
Igba ti wọn kede iṣiro awọn to nii kẹyin                                              29 Oṣù Bélú 2021 13:33 WAT+3
*Iye awọn to tọwọ aisan ku ni isọri eeyan ẹgbẹrun lọna ọgọrun
Jọwọ ṣe atunṣe ilana ikansi ayelujara rẹ lati ri ẹkunrẹrẹ rẹ
Akọsile imọ yii, da lori akojọpọ iṣẹ iwadi ni Fasisti Johns Hopkins, o si le ma ṣe afihan awọn akọsilẹ iroyin to ba igba mu lati orilẹede kankan.
** Àwọn iyé akọsilẹ̀ to ti wà fún àwọn ti o ṣẹ́ṣẹ̀ ni ààrun náà jẹ́ àkójọpọ̀ ọjọ́ mẹ́ta. Nítori àwọn àtúgbẹ́yẹ̀wò, o níra láti ṣe àkójọpọ fún àwọn ọkọ́ naa
Orisun: Johns Hopkins University atawọn ajọ eto ilera ilu
Iye akọsilẹ to waye gbẹyin 29 Oṣù Bélú 2021 13:33 WAT+3
O fikùn pé, àwọn yóò ṣe iranwọ fún àwọn osere tíátà lobinrin àti àwọn aláìní pẹ̀lú nítorí ohun tó máa ń mú inú bàbá òun dùn nìyẹn, èyí tíì ṣe fífún àwọn aláìní ni oúnjẹ.Bákan náà lo fikun pé ní ọjọ́ iwájú, tí àwọn bá tún ní erongba miran ti àwọn fẹ́ ṣe fún ìrántí Adeboye, àwọn yóò kéte síta.
Oríṣun àwòrán, davido/instagram
Ilumọọka olorin takasufe Davido ti kọ iwe ifẹ kan ṣọwọ si afẹsọna rẹ ati ọmọ wọn ni ọjọ ibi Chioma to n waye lọjọbọ
Eyi wa loju opo Instagram rẹ.
Mo ki obinrin to lagbara kulọ lara awọn ti mo mọ ku ọjọ ibi. Ka ni ko si ofin konile o gbele ni, awa mejeeji o ba ti jaye ori wa daada kaakiri igboro loni
Iyawo mi tootọ, ayẹyẹ ọjọ ibi rẹ yoo larinrin bi iwọ pẹlu ti ṣe mu ọpọlọpọ ayọ wọ inu aye mi.
O ti le ni ọdun meji bayii ti Davido ati Chioma ti bẹrẹ irinajo ifẹ wọn ti Eleduwa si ti fi ọmọkunrin kan tawọn lọrẹ.
Laipẹ yii ni Chioma bọ lọwọ arun Coronavirus lẹyin ọpọlọpọ ọjọ ti aisan naa fi daa wolẹ.
Jọwọ ṣe atunṣe ilana ikansi ayelujara rẹ lati ri ẹkunrẹrẹ rẹ
Orisun: Johns Hopkins University atawọn ajọ eto ilera ilu
Igba ti wọn kede iṣiro awọn to nii kẹyin                                              29 Oṣù Bélú 2021 13:33 WAT+3
*Iye awọn to tọwọ aisan ku ni isọri eeyan ẹgbẹrun lọna ọgọrun
Jọwọ ṣe atunṣe ilana ikansi ayelujara rẹ lati ri ẹkunrẹrẹ rẹ
Akọsile imọ yii, da lori akojọpọ iṣẹ iwadi ni Fasisti Johns Hopkins, o si le ma ṣe afihan awọn akọsilẹ iroyin to ba igba mu lati orilẹede kankan.
** Àwọn iyé akọsilẹ̀ to ti wà fún àwọn ti o ṣẹ́ṣẹ̀ ni ààrun náà jẹ́ àkójọpọ̀ ọjọ́ mẹ́ta. Nítori àwọn àtúgbẹ́yẹ̀wò, o níra láti ṣe àkójọpọ fún àwọn ọkọ́ naa
Orisun: Johns Hopkins University atawọn ajọ eto ilera ilu
Iye akọsilẹ to waye gbẹyin 29 Oṣù Bélú 2021 13:33 WAT+3
Ẹ̀mí kan náà ló n darí ìrìnàjò wa táa fi jọ kọ́lé papọ̀- Ìbejì
Oríṣun àwòrán, davido
Gbajugbaja akọrin takasufe ni, David Adeleke ti ọpọlọpọ mọ si Davido ti pariwo sita pe nnkan ko rẹrin lori titọju ọmọ ti oun ti iyawo rẹ Chioma bi fun latigba ti iya rẹ ti wa ni igbele iyasọtọ.
Chioma, iyawo Davido ko arun Coronavirus eleyi ti ọkọ rẹ, Davido kede faye ni ọsẹ to kọja.
Ninu ọrọ kan to fi sita loju opo twitter rẹ Davido lọgun pe iṣẹ l'abiyamọ n ṣe.
Lẹyin ti ayẹwo fihan pe Chioma ti ko arun Coronavirus, igba meji ọtọọtọ ni Davido ni oun ti ṣe ayẹwo lati lee mọ boya oun ni arun naa tabi oun ko ni.
Coronavirus in Nigeria: Gómìna Oyetola ní àwọn àbọ̀dé orílẹ̀èdè Côte d'Ivoire ló ń
Gomina ipinlẹ Ọṣun, Alaaji Adegboyega Oyetọla ti ke gbajare sita pe awọn abọde lati orilẹede Côte d'Ivoire ni wọn jẹ ki ajakalẹ arun Coronavirus tubọ gogo sii ni ipinlẹ naa.
Ninu ọrọ to ba BBC News Yoruba sọ lori ẹrọ ibanisọrọ lẹyin ti ajọ to n gbogun ti ajakalẹ arun tun kede eeyan mẹsan miran pẹlu arun Korona ni ipinlẹ Ọṣun lọjọru, Gomina Oyetọla ṣalaye pe arun Korona ki ba ti burẹkẹ to bayii kani ijọba apapọ tete ti gbogbo ẹnuibode ni ki wọn si paṣẹ konileogbele fun gbogbo ọmọ orilẹede Naijiria.
Gomina Oyetọla ṣalaye siwaju sii pe, awọn ọmọ ipinlẹ naa ti wọn n ti orilẹede Côte d'Ivoire bọ wa sile ni wọn ko arun naa dani to fi di pe o tubọ peleke sii nipinlẹ naa.
O wa rọ awsn eeyan ipinlẹ Ọṣun lati fidimọle gẹgẹ bi aṣẹ ti ijọba pa lati lee wagbo dẹkun si wahala yii.
Bakan naa ni o fi to wa leti pe lọna ati lee dẹkun ọwọja ebi ati inira lasiko aṣẹ konileogbele naa, ijọba oun ti gbe awọn igbesẹ ti yoo bu omi tu araalu lara bii sisanwo oṣu fun awọn oṣiṣẹ ki wọn to gbe aṣẹ naa kalẹ ati idasilẹ igbims majẹobajẹ kan lori ọna ati gbogun ti arun naa ati lati mu irọrun ba araalu lasiko ti wọn ba fi n baa wọ iyaaja.
Ẹkunrẹrẹ wa ninu ohun ti a ka silẹ loke yii.
Oríṣun àwòrán, Davido/instagram
Gbajugbaja akọrin takasufe, Divid Adeleke ti ọpọ eeyan mọ si Davido tun ti wẹ yan kainkain lọwọ arun coronavirus.
Ọpọ ẹnu lo ti n kun Davido lẹyin ti iroyin jade pe ọpọ awọn eeyan to sun mọọ lo ti n ni arun yi lara.
Ni ọjọ diẹ sẹyin ni Davido funrarẹ gbe iroyin jade pe iyawo oun, Chioma ti ko arun Coronavirus, bakan naa si ni gomina Seyi Makinde pẹlu kede pe oun pẹlu ti ni arun naa lẹyin ọjọ diẹ to gbalejo Davido ni ile ijọba nilu Ibadan.
Ninu atẹjade kan to fi sita loju opo twitter rẹ ni ọsan ọjọ Ọjọru, Davido ni oun ti tun ayẹwo arun Coronavirus ṣe o, ṣaka bayii si ni ara oun ya.
Oríṣun àwòrán, SEYI MAKINDE
Gomina ipinlẹ Ọyọ, Onimọẹrọ Ṣeyi Makinde kede ni aṣalẹ ọjọ Aje pe oun ti ko arun Coronavirus ti o n ja kale-ka'ko bayii.
O fi si oju opo twitter rẹ pe esi ayẹwo oun ti de ko si si ẹja n bakan kankan lori rẹ nitori ẹja lo ba de.
Lẹyin eyi ni o ṣalaye pe gbogbo awọn to ti ni nnkan n ba oun ṣe laarin asiko ti oun fi lọ sibi ipade igbimọ ọrọ aje orilẹede Naijiria si ọjọ ti oun bẹrẹ igbele ni wọn ti n wa; koda iroyin kan tilẹ ss pe gbogbo awọn to baa da nnkan pọ laarin asiko naa, paapaa awọn kọmiṣọna atawọn amugbalẹgbẹ rẹ gbogbo ni wọn ti wa ni igbele bayii lati lee mọ boya awọn naa ko abi rara.
Oríṣun àwòrán, SEYI MAKINDE
Nibayii, BBC News Yoruba ṣe atupalẹ bi irinajo Gomina Seyi Makinde ṣe lọ laarin akoko naa ati awọn eeyan to ṣeeṣe ki wọn ti ko arun yii lati ara rẹ.
Ẹ maa gbagbe pe eyi ko tumọ si pe gbogbo awọn eeyan to wa nibi eto wọnyii lo ti koo, ṣugbọn iwadi ati ayẹwo to gbọngbọn nikan lo lee fi idi eyi mulẹ.
Fun apẹrẹ, gomina Makinde ṣalaye ninu atẹjade to fi sita pe asiko kan naa ni esi ayẹwo oun ati ti akọwe ijọba ipinlẹ naa, arabinrin Olubamiwo Adeosun de. Esi ti gomina lo jasi bẹẹni ti ti akọwe ijọba ipinlẹ naa si ja si bẹẹkọ.
Idi ti awọn onimọ maa fi n ṣe ato irinajo ẹni to ba ni arun yii ni lati mọ ibi ti wọn lee wa awọn to lee ti koo lati ara wọn si.
Coronavirus lockdown updates in Nigeria: Adeboye ni ọpọ nǹkan ńlá ńlá ni yóò ṣẹlẹ̀ lẹ́yìn ìgbélé Coronavirus
Oríṣun àwòrán, PAstor adeboye
Olusọ agutan agba fun ijọ Redeemed, Pasitọ Enoch Adejare Adeboye ti sọ aṣọtẹlẹ pe ọpọlọpọ nnkan nla nla ni yoo maa ṣẹlẹ tori igbele Coronavirus.
Pasitọ Adeboye woye ọrọ yii lasiko iwaasu isin ọjọ isinmi, eyi to ṣe lori ayelujara.
Coronavirus dé ọ̀dọ̀ ará ọ̀run, ọdún Egúngún di kò ní wáyé nílùú Ibadan nítorí coronavirus
Inú káàdì ìránti tí mo rí he ní mó tí rí fọ́tò ìhòhò Salawa, mó kàn fẹ́ gbà owó díẹ̀ ni- Afurasí
Fájìn ni àbúrò mi ti wọn fipá bálopọ̀ nínú sọ́ọ́sì, tí wọ́n sì tún fọ́ lórí
Jesu Oyingbo rèé, pásítọ̀ tó láṣẹ ìbálòpọ̀ lóri ọmọ ìjọ obìnrin
Adeboye ni ọkan lara awọn nnkan nla nla ti yoo sẹlẹ tori igbele Covid-19 ni afikun yanturu ti yoo ba ọmọ bibi jakejado agbaye.
Mo wa fẹ sin awọn pasitọ ni gbẹrẹ ipakọ pe, ẹ n sinmi bayii, amọ ẹ gbaradi fun eto isọmọ lorukọ lọpọlọpọ ni ibẹrẹ ọdun to n bọ, ẹ si maa ti ojule kan lọ si omiran ni nitori igbele Coronavirus.
Oríṣun àwòrán, Pastor Adeboye/twitter
Gbajugbaja pasitọ naa tun woye pe, iye awọn alarun Coronavirus ti ara wọn n da n ya ni lẹni pupọ, ti iye awọn eeyan ti arun naa n pa si kere si iye awọn ti ara wọn n ya.
Bakan naa lo tun woye pe iye awọn eeyan ti arun Coronavirus pa kere jọjọ si iye awọn eeyan ti ijamba ọkọ ati nkan miran n pa lọ.
Oríṣun àwòrán, Facebook/Pastor E.A. Adeboye
Ṣẹ ẹ fẹ gbọ? Aarun coronavirus ko le tan lori ilẹ aye patapata.
Alakoṣo ijọ Redeem, alufa Enoch Adeboye lo sọ bẹẹ ninu iwaasu rẹ ninu isin ọjọ Aiku to pe akori rẹ ni ''ọna meje lati doju kọ oke.''
Pasitọ Adeboye ni gẹgẹ bi aarun Ebola, covid-19 naa ti di aarun ti yoo ba gbogbo aye gbe laelae.
O ni iyanu nla ni yoo jẹ ti aarun naa ba kuro lori ilẹ aye patapata.
Ṣugbọn alufaa Adeboye awọn ti wọn ba ni ibẹru Ọlọrun ko ni ipin ninu aarun naa mọ.
Oríṣun àwòrán, Facebook/Pastor Enoch Adeboye
Alufaa Adeboye ni o da oun loju pe ọpọ eeyan ni yoo kọ orin iyin si Ọlọrun lẹyin ti coronavirus ba di afisẹyin ti eegun fi aṣọ tan.
Amọ, o rọ awọn eeyan lati ni igbagbọ ninu Ọlọrun to da ọrun ati aye nitori Oun lo ti wa ṣaaju awọn oke gbogbo.
Kí ló pa bàbá Adeboye, bàbá Davido àti Ọ̀ọ̀ni Ifẹ̀ pọ̀ lásìkò ìgbélé l'Ọ́ṣun?
Gbajugbaja pasitọ to jẹ Alamojuto agba fun ijọ RCCG lagbaye, Pasitọ Enoch Adeboye, Ọọni ile Ifẹ, Ọba Adeyẹye Ogunwusi pẹlu gbajugbaja oniṣowo to tun jẹ baba akọrin takasufe ni, Davido, Ọmọwe Deji Adeleke, obinrin to lowo ju nilẹ Afirika Iyaafin Fọlọrunhọ Alakija wa ninu awọn eekan ilu ti ijọba ipinlẹ Ọṣun ṣẹṣẹ ko jọ lati wa ọna ti wọn yoo fi ṣetọ arẹmọlẹkun fawọn eeyan ipinlẹ Ọṣun lasiko igbele coronavirus yii.
Oríṣun àwòrán, PAstorEAAdeboye
Baba Adeboye ni Alaga igbimọ naa eleyi ti awọn gomina tẹlẹ ni ipinlẹ naa atawọn to di di ipo Oṣelu mu pẹlu awọn oludaleeṣẹsilẹ pẹlu wa.
Awọn yoku to jẹ ọmọ igbimọ naa niyi.
Ninu ọrọ to ba BBC News Yoruba sọ lori agbekalẹ igbimọ naa, gomina Gboyega Oyetọla ni ara igbesẹ lati rii pe ebi ko pa awọn olugbe ipinlẹ Ọṣun lasiko ti ofin koniogbele yoo fi wa nikalẹ nipinlẹ ọhun ni wọn
Oríṣun àwòrán, Ooni Enitan Ogunwusi
Gbogbo agbaye ti n damu lori arun yii fun ọpọlọpọlọ oṣu bayii laisi ọna abayọ kan to dan mọran.
Arun Coronavirus ti sọ ara rẹ di ẹrujẹjẹ ni gbogbo ilẹkilẹ, ẹbọra ti n se gbogbo aye mọle porogodo.
Ṣe awọn agba si bọ wọn ni to ba runi loju, aa bi ilẹ leere.
Eyi lo difa fun Ọọni ile Ifẹ, Ọba Adeyẹye Ogunwusi ti ke sawọn alalẹ ilẹ yii lati le arun Coronavirus to gbode kan bayii wọgbo.
Idi niyi ti kabiyesi Ọọni fi kede pe ki gbogbo awọn olugbe ilu ifẹ o wa ninu ile wọn nitori oro fẹ jade lati fọ ilu mọ lọwọ arun Corona.
Atẹjade kan ti Ọọni fi sita latọwọ Oloye Ọyalami Awoyọde ni ẹnikẹni ko gbọdọ yọju sita nitori bi ẹnikẹni foju ba oro yii, oro naa yoo gbe ni o.
Coronavirus in Nigeria: Ìpínlẹ̀ Eko bẹ̀rẹ̀ fínfín àyíká nítorí Coronavirus
Ọọni Ile Ifẹ ṣalaye ninu atẹjade naa pe, lara awọn ibi ti oro naa yoo gba kọja ni iwara ilode, oke atan, iloro, aganhun, arubidi, moremi, ondo road, olurin, omi okun, iyekere, oroto, itaagbon, oke ayetoro, oke soda, otutu,
ajamopo, ita sun, lokore, odoiwara, olumogbe, ijio, ojafe, edena, igbo agbo, obaloogun, onpetu, oduduwa college road, akiile, ilare, saabo, iremo, okerewe, obalejugbe, garage isale, mokuro road, ojaja, ogbingbin, okejan,
iredumi, lagere, fajuyi, gbodo, ita olopo, isale agbara, ogbon agbara, ogbon oya, akui, obalufon, itakogun, oriyangi, ehindi, omisore,olurin, pediro, okemorisa, atawon ibo mii
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ọpọlọpọ ènìyàn ló ti ń sọ iriri wọn bí wọn ṣe ló ojo kini wọn nínú ilé leyin ti ijoba apapo kéde konileogbele ni  ipinle Eko, Ògún àti Ábuja.
Èyí ni àkójọ ìrírí tí àwọn ènìyàn fi sowo sì ilé ose BBC News Yorùbá àwọn ọ̀nà tí wọn gba láti lọ ojo kini igbele wọn.
Leyin ojo kini nìkan àwọn kan ti bere si ni ké gbajare pé kí a bá àwọn bẹ aare Muhammadu Buhari kí  ó tú àwọn sílè nítorí pé ilé tí sú àwọn, wọn ní gbogbo ojo ni àwọn fi sún àti pé ojú ni òun  kò rán àwọn ìṣe mo.
Enikan nínú ìdáhùn re ó ní 'A tẹ fóònù titi fóònù kú, Data Paapaa tán sugbon awon PHCN gbìyànjú díè.
Àwọn ọmọ rí iná wo Cartoon àti pé iṣọwọ jẹun mi, ó lágbára mo sún titi ojú fẹẹ fọ.
Nínú oro tìrẹ Alowonle Olajide ni, oro igbele yìí kò bá òun lára mú rárá, àti pé ó jọ bí ẹni pé ènìyàn wá nínú ewọn ni, ó wá rọ ijọba pé kí wọn dín ọjọ igbele yóò kú tí ó bá ṣeeṣe ọsẹ kan péré tí to kí olúkúlùkù sì padà sí ẹnu isẹ rẹ.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ní ti Kabiru Tunde, igbele fun òun àti àwọn ọmọ oun ni ìṣòro nítorí pé òun dojú kọ wàhálà púpọ bii ariwo pipa lórí àwọn ọmọ wẹ́wẹ́ tó wà nílè.
Ní ìhà míràn igbe kò sì iná mọnamọna ni àwọn miran nke, tí wọn sì ni èyí mú kó nira púpọ fún àwọn láti gbé inú ilé fún ọjo mẹ́rìnlá.
Àwọn miran tilẹ ṣalaye pe ni àdúgbò wọn làwọn agbegbe kan n'ilu Èkó, òfin isèdè yìí kò múlẹ nitori pe olokada àti awọn onimaruwa lọ ń ṣiṣẹ oojọ wọn,
Ó ní n ṣe ní ìta dabi ọjọ lásán tí àwọn ènìyàn ń lọ tí wọn ń bọ̀.
Coronavirus: Ṣé ọtí leè dènà tàbí pa àrùn Coronavirus bi?
Ọpọ lọ n ke si ijọba kí wọn ba awọn tó ń tà ọjà ṣọrọ kí wọn sì ni aṣẹ lori bí wọn ṣe ń gbowó lórí ọjà nitori pe nkan ti àwọn n ra ni eedegbeta Naijiria ti di egbeunnkannabo ládùúgbò báyìí.
Ẹwẹ, àwọn miran ni àwọn sí ń retí oúnjẹ tí ìjọba ń pín nítorí kò tií de àdúgbò wọn rárá.
Coronavirus in Nigeria: Ṣeyi Makinde ní àrùn Coronavirus kò leè borí òun àtará ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́
Oríṣun àwòrán, oyo state government
Iroyin to ba ọpọ lẹjafuu ni iroyin 'Mo ti ni arun Coronavirus'eyi ti Gomina Seyi Makinde gbe jade ni ọjọ Aje loju opo twitter rẹ.
Nibayii ti o ti lo ọjọ meji ni igbele lẹyin ikede yii, gomina ipinlẹ Ọyọ, Ṣeyi Makinde ti ṣalaye pe ko si nnkan ti Coronavirus yoo lee fi oun atawọn eeyan ipinlẹ Ọyọ to ni arun naa ṣe.
Makinde to ni oun dupẹ fun obitibiti ojo adura ti gbogbo eeyan n fi ṣọwọ si oun ṣalaye pe bẹmidije loun, ẹmi oun yii girigiri, eleyi to fi daju pe oun ati gbogbo awọn eeyan ipinlẹ Ọyọ ti ọrọ kan yoo lee ruu la.
Gomina Makinde wa rọ awọn eeyan ipinlẹ naa lati maa tẹle itọni ati ilakalẹ igbimọ amuṣẹya ti ijọba gbe kalẹ lati gbogun ti arun COVID-19 ni ipinlẹ Ọyọ lati lee tete kapa arun naa lọgan ni ipinlẹ ọhun.
Coronavirus: Ṣé ọtí leè dènà tàbí pa àrùn Coronavirus bi?
Nibayii, eeyan mẹjọ lo ti ko arun Coronavirus ni ipinlẹ Ọyọ ninu eyi ti Gomina Seyi Makinde pẹlu wọn.
Bakan naa ni wọn ti tu eeyan kan silẹ lẹyin ti o gba iwosan lọwọ arun ọhun.
Coronavirus in Nigeria: Mohammed, ọmọ Abubakar Atiku sọ̀rọ̀ lórí àrùn Coronavirus tó ń báa finra
Oríṣun àwòrán, Mohammed Atiku Abubakar
E ye gbe iroyin ofege kaakiri papaa julọ lasiko ajakalẹ aarun coronavirus yii.
Mohammed Atiku, ọmọkunrin oludije fun ipo aarẹ ẹgbẹ oṣelu PDP, Atiku Abubakar lo ṣe ikilọ yii lati ibi to ti n gba itọju niluu Abuja, lẹyin to lugbadi aarun covid-19.
Mohammed ni iroyin ofege le ṣakoba nla fun ilera awọn eeyan papaa julọ awọn ti aarun covid-19 n ba finra lọwọ.
Ọmọ Atiku ni o jẹ iyalenu fun oun pe awọn alabaagbe oun n gbe ayederu iroyin kiri nipa oun lẹyin ti oun lugbadi aarun covid-19.
O ni iroyin ofege ko ni ipa kankan lara oun nitori agboole oloṣelu loun ti wa, ṣugbọn akoba nla ni ayederu iroyin n ṣe fun ilera awọn to n ṣaisan lọwọ lasiko yii.
Ẹ jẹki a gbe oṣelu ti sẹgbẹ kan lasiko yii, ki a pawọpọ, ki a si fimọ ṣọ̀kan, eyi ni a fi le bori ajakalẹ aarun coronavirus yii, ọmọ Atiku lo sọ bẹẹ.
Mohammed ni ibẹru-bojo mu oun nigba ti wọn kọkọ gbe oun de ile iwosan, nitori oun ni ẹni akọkọ ti yoo kọkọ ni aarun covid-19 l'Abuja.
O ni oun ni gbagbọ pe laipẹ laijina, oun yoo kuro nile iwosan ti oun yoo si jajabọ lọwọ coronavirus patapata.
Ọmọ Atiku gboriyin fawọn oṣiṣẹ eleto ilera fun iṣẹ takuntakun ti wọn n ṣe papaajulọ lasiko yii.
Oríṣun àwòrán, Tope alabi
Gbajugbaja akọrin ẹmi, Tọpẹ Alabi ti ke sawọn olorin ẹmi lati da si eto igbayegbadun fawọn to ku diẹ kaato fun lasiko igbele ti ijọba lẹka gbogbo n kede lati dena itankalẹ arun COVID-19
Tọpẹ Alabi to fi sita lori ikanni abanidọrẹ, Facebook rẹ ṣalaye pe lootọ igboro le diẹ, sibẹ bi o ti wu ko kere awọn olori ẹmi atawọn to ba nifọn leekanna naa lee ṣe iranwọ fun araalu.
Akọrin ẹmi miran, Tim Godfrey lo gbe eto naa kalẹ leyi ti wọn fẹ fi ko ọgbọn miliọnu naira jọ fun riran awọn ti ko lee ra ounjẹ lasiko igbele yii lọwọ.
Tọpẹ alabi ni ko yẹ ki awọn olorin ẹmi duro de ijọba lasiko yii ki wọn to ran awọn ti ko ni lọwọ. O fi kun un pe niwọnba ohun ti ẹnikọọkan ba ni lo lee fi ran awọn eeyan yii lọwọ.
Iroyin ti alakoso eto naa fi sita ṣalaye pe ẹgbẹrun lọna igba naira ni Tọpẹ Alabi fi silẹ fun aṣuwọn naa.
"Coronavirus in Nigeria: Ẹ wo bí ẹ ṣe lè ṣe ""hand sanitizer"" nínú ilé yín"
Coronavirus tips: Kí ni a ń pè ní fẹntilétọ̀ àtipé kí ni pàtàkì rẹ̀?
Oríṣun àwòrán, dyson
Ìjọba ilẹ̀ Gẹ̀ẹ́sì tí pé fún rírà ẹgbẹ́gbẹ̀run ẹ̀rọ fẹntíletọ̀ láti mú irọ̀rùn bá àwọn ilé ìwòsàn nítorí wàhálà ààrùn Coronavirus tó ń bá àgbáyé fíra.
Fún ẹni tí ààrùn Coronavirus bá bá jà gidi, Fẹntíletọ̀ nìkan lọ́nà àbáyọ láti lè jẹ kí òní anfaani yíyè.
Ní kúkúrú, Fẹntíletọ̀ lọ máa ń gba isẹ́ mímí ṣe nígbà tí àìsàn bá ń bá ẹ̀dọ̀ fòòró ja tí kò sì lè ṣe ojúṣe rẹ̀ mọ́.
Èyí ni yóò fún aláìsàn ni àǹfààní láti bá aarun náà já títí tí ara yóò fi bọ̀ sípò.
1. Ohun elo aṣeranwọ eemi to n lo ẹrọ
2. Ohun elo aṣeranwọ eemi ti ko nilo ati ti bọ inu ara
Gẹ́gẹ́ bí àjọ elétọ̀ àbò àgbáyé (WHO) ṣe sọ ìdá ọgọ́rin àwọn ènìyàn tó ní ààrùn Coronavirus ni kò nílò láti dé ilé ìwòsàn kí ara rẹ̀ tó dá.
Ṣùgbọ́n ẹ̀yán kan nínú mẹ́fà ni yóò ṣe àìsàn gidi ti yoo si nira fún wọn láti mi.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Nínú irú ìṣẹ̀lẹ̀ tó lágbára bayii kòkòrò aifojuri yìí le ba ẹ̀dọ̀ fòòró jẹ́. Ní kété tí èròjà ara tó bá àìsàn ja bá ti rí èyí yóò fi ààyè gba àwọn èròjà tó kú láti kó ọmọ ogun wọlé láti dáàbò bo ara.
Ṣùgbọ́n ìgbésẹ̀ yìí leè kí omi máa wo inú ẹ̀dọ̀ fòòró èyí sì lọ máa ń fà tí èémí yọ fi nira fún irú ẹni bẹ́ẹ̀ tí afẹ́fẹ́ tó ń wọ ara yóò sì dínkù.
Láti wá mú èyí kúrò, ẹ̀rọ Fẹntílàtọ̀ yìí ni wón ń lọ láti gbé afẹ́fẹ́ wọ inú ẹ̀dọ̀ fòòró.
Fẹntílàtọ̀ yìí bákan náà ni afẹ́fẹ́ kosooru-kosotutu tí yóò máa fẹ́ gbígbóná sínú afẹ́fẹ́ ìsẹ̀gùn láti lè bá àgọ́ ara ènìyàn mu.
Oríṣun àwòrán, Intersurgical
Àwọn tí ó bá jẹ pé àmì tiwọn kò nira jú wọn lé máa fi ìbòjú-bomu Fẹntílàtọ̀ mí niti wọn.
Àwọn onímọ̀ ẹ̀rọ London College tí bá wọn onimo miran tó ń ṣe Mercedes ti wọn n se (CPAP) rí wọn pé ní Continuous Positive Airways pressure Device po tí wọn sì ti lọ làwọn ilé ìwòsàn kan tó sì ń ṣe iṣẹ́tó yẹ. Ilé ìṣe náà yoo
bere si ki ṣe egberun kan rẹ ni ojúmọ́ láti ọ̀sẹ̀ tó ń bọ̀ lọ (6 April).
Àjọ tó ń mójú tó ìsẹ̀gùn àti àwọn irinsẹ ìsẹ̀gùn tí jan ẹ̀rọ CPAP lọ́ntẹ̀
Ẹ̀wẹ̀ ọ̀pọ̀ lọ ní  àríwísí lórí lílo Fẹntílàtọ̀ onibòjú-bomu nitoripe tí ihò kan bá si sílẹ̀ tí aláìsàn sì wúkọ́ èyí lè tá sì ọ̀sìsẹ́ ìlera lára kí ó sì kó aarun náà.
Irú Fẹntílàtọ̀ yii ni wọn ń pè ní Non-invasive Ventilation nítorí pé wọn tí nkan kan bọ ẹni náà lọ́fun.
Ẹ̀wẹ̀ àwọn elétò ìlera yóò tètè fún ẹni tó bá nira fún láti mi ni Fẹntílàtọ̀ kí a dinku máa bà bá afẹ́fẹ́ tó ń wo inú ara.
NHS sọpe egberun mejo lè díè ni Fẹntílàtọ̀ to wà sugbon wọn gbìyànjú láti ra kun ni kíákíá.
Ijoba nígbàgbọ́ pé nígbà tí àjàkalẹ̀ ààrùn náà bá dé góńgó àwọn yóò nílò tó ọgbọn ẹgbẹ̀rún Fẹntílàtọ̀, wọn tí pé fún àwọn egberun mewaa tuntun míràn lat ilé ìṣe Dyson.
Dyson sọ fún BBC pé àwọn ń sise lori awon eya tí ó wà nílè ṣùgbọ́n awon yóò ṣẹ̀ṣẹ̀ bẹ̀rẹ̀ si ni gbedi rẹ láti ilẹ̀ ni.
Bákan náà ni wọn ti pé fún rírà lati ọdọ Luton Smith group èyí yóò sí jẹ eya kelebe.
fẹntilétọ̀, ohun èlò aṣèrànwọ́ èémí
Ilé ìṣe ilé Geesi miran Gtech tí ṣe irú rẹ miran ti kí ni nílò afẹ́fẹ́ ile iwosan tí kò sì nílò iná mọ̀nàmọ́ná..
Bákan náà ni ọ̀pọ̀ àwọn àgbáríjọ onímò sáyẹ́nsì àti onímọ̀ ẹ̀rọ láti ilé ìwé Oxford àti King's College London náà tí ṣe àfılọ́lẹ̀ Fẹntílàtọ̀ olówó pọ́ọ́kú tiwọn, èyí tí wọn ní àwọn lè bẹ̀rẹ̀ ṣíṣe rẹ̀ ni kíákíá.
Àwọn àṣẹ wádìí ni Fáṣítì East Angellia náà ń wá onímọ̀ 3D láti ṣe Fẹntílàtọ̀ àti ìbòjú-bomu pelu gbogbo àwọn irinsẹ míràn.
Yoruba Films: Femi Adebayo sọ ẹran àgbò rẹ̀ lórúkọ tuntun, Bukky Wright ṣ'ọjọ ìbí
Oríṣun àwòrán, others
Ajakalẹ aarun coronavirus le wa nita ni tootọọ, amọ aarun naa ko ni kawọn oṣere tiata Yoruba ma ṣe ti wọn.
Wọnyii ni awọn ohun to ṣẹlẹ lagbo awọn oṣere tiata Yoruba, Yollywood lọsẹ yii.Bi awọn kan ṣe n yọ ayọ ọjọ ibi, lawọn kan n palẹmọ fun ti wọn naa, bakan naa lawọn oṣere kan ko sai mẹnu ba ọrọ coronavirus gan an.
1. Bukky Wright
Ọjọ Iṣẹgun ọsẹ yii ni gbajugbaja oṣere, Bukky Wright ṣe ayẹyẹ ọ̀jọ ibi rẹ.Bukky dupẹ lọwọ Eleduwa to jẹ ko ri ọdun miiran laye. Arẹwa oṣere naa ki ara rẹ ku ọjọ ibi loju opo Instagram rẹ.
Ṣé fífi òrí pa ọwọ́ rẹ leè dáàbò bò ọ́ lọ́wọ́ Coronavirus?
2. Lizzy Anjorin
Owo, ọmọ, alaafia ati ẹmi gigun ni mo beere.Orin ti Lizzy Anjorin fi bọnu niyii loju opo Instagram rẹ.Lizzy gbe ọrọ coronavirus si ẹgbẹ kan papaa julọ bi o ti n palẹmọ fun ayẹyẹ ọjọ ibi rẹ.
Ǹjẹ́ oòrùn tàbí oru leè pa àrùn Coronavirus bí?
3. Mercy Aigbe
Awọn oṣiṣẹ eleto ilera ni Mercy Aigbe gboṣuba rabandẹ fun ni tiẹ.Mercy rọ gbogbo eeyan lati lo asiko yii ki wọn fi gboriyin fawọn oṣiṣẹ eleto ilera to n tọju awọn to lugbadi aarun corona virus.O ni oun mọ riri iṣẹ ribiribi ti wọn n ṣe lasiko yii.
Coronavirus: Àwọn èèyàn ìpínlẹ̀ Eko ń sunkún ebi lásìkò ìgbélé
4. Femi Adebayo
Femi Adebayo ni tiẹ sọ pe jijoko sile lasiko coronavirus yii ti su oun.Koda awọn ẹran agbo rẹ lo n ba ṣere nile ti o si fi fidio rẹ sori oju opo Instagram rẹ.Femi Adebayo ni oun tiẹ ti fun awọn ẹran agbo oun lorukọ tittun
Salawa abeni
Coronavirus in Nigeria: Seyi Makinde fojú hàn n'íta fún ìgbà àkọ́kọ́ lẹ́yìn tó ṣẹ́gun Coronavirus
Gomina ipinlẹ Oyo, Ṣeyi Makinde foju han n'ita gbangba fun igba akọkọ lẹyin ti o jaja ṣẹgun aarun Coronavirus.Makinde ṣe abẹwo si ibudo itọju awọn alaarun to n bẹ ni agbegbe Olodo niluu Ibadan lọsan ọjọ Aje.
Nibẹ lo ti ṣe ayewo awọn ohun elo igbalode ti ijọba ipinlẹ Ọyọ ra sibẹ lati dẹkun itankalẹ aarun Coronavirus.
Makinde jẹ ọkan lara awọn gomina mẹta to lugbadi aarun covid-19 ni Naijiria.
Gomina Makinde ni gomina keji ti yoo bo lọwọ aarun coronavirus lẹyin ti gomina ipinlẹ Bauchi, Bala Mohammed naa ti gbadun.
Nasir El-Rufai ni gomina kẹta to laarun covid-19 lorilẹede Naijiria.
Lẹ́yìn ò rẹyìn, Seyi Makinde bori arun Coronavirus
Iroyin ayọ fun gbogbo awọn eeyan ipinlẹ Ọyọ.
Gomina ipinlẹ naa, Onimọẹrọ Ṣeyi Makinde ni oun ti pada lọ ṣe ayẹwo ara oun lẹẹmeji ọtọọtọ lati mọ boyi arun Coronavirus ṣi wa lara oun tabi o ti lọ ati pe ayẹwo mejeeji bayii lo fihan pe ṣaka lara oun le.
Ni ọjọ aje to kọja ni Gomina Makinde gbee jade loju opo twitter rẹ pe ayẹwo ti fihan pe oun ni arun Coronavirus lara to si ṣe bẹẹ wọ igbele iyasọtọ lọ gẹgẹ bi ilana aatẹẹle ti awọn onimọ nipa kokoro arun ati ilera ṣe laa kalẹ fun un.
Ilakalẹ fun ayẹwo ẹni to ba ni arun yii ki o to lee gba iwe ṣaka lara da ni lati ṣe ayẹwo meji ọtọọtọ eyi ti yoo fihan pe ko ni arun naa mọ; mejeeji yii si ni Makinde ṣe bayii.
Oríṣun àwòrán, Seyi makinde
Ninu ọrọ to fi si oju opo Twitter rẹ, Gomina Ṣeyi Makinde ni oun mọ riri adura atilẹyin ati adura awọn eeyan ipinlẹ Ọyọ lasiko ti oun fi wa ni igbele iyasọtọ fun itọju arun naa.
O fi kun un pe oun yoo si pada si ẹnu iṣẹ ni ọjọ Aje.
Ninu ọrọ to ba BBC News Yoruba sọ, Kọmiṣọna fun eto iroyin ati itaniji, Ọgbẹni Wasiu Ọlatubọsun ṣalaye pe aay bẹ silẹ o bẹ are ni gomina Makinde fẹ fi ọrọ ipadabọ rẹ ṣe bayii pẹlu pipada si ẹnu iṣẹ lẹyẹ o ṣọka lati tẹsiwaju pẹlu eto gbogbo lati le arun Coronavirus wọgbẹ ni ipinlẹ Ọyọ.
Coronavirus: Wọ́n ti gbé olóòtú ìjọba ilẹ̀ Gẹẹsi, Boris Johnson lọ sí wọ́ọ̀dù aláísàn tó lágbára
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Iroyin to tẹ wa lọwọ lo sọ pe, wọn ti gbe olootu ijọba ilẹ Gẹẹsi, Boris Johnson lọ si wọọdu itọju aisan to lagbare bayii lẹyin to lugbadi aarun coronavirus.
Boris Johnson laa gbọ pe o sọ fun akọwe ijọba fun ilẹ okeere, Dominic Raab wi pe ko maa ṣoju oun nigba ti oun n gba itọju.
Lati irọlẹ ọjọ Aiku ni Ọgbẹni Johnson ti n gba itọ lẹyin ti covid-19 to wa lara rẹ n ba a finra.
Olotu ijọba ilẹ Gẹẹsi, Boris Johnson ti di ero ileewosan bayii fun awọn ayẹwo gbogbo to yẹ lẹyin ọjọ mẹwaa ti ayẹwo ti kọkọ fihan pe o ti ko arun Coronavirus.
Atẹjade kan lati ileeṣẹ ijọba ilẹ Gẹẹsi ti a mọ si Downing Street ṣalaye pe niaṣalẹ ọjọ Aiku ni wọn gbe lọ si ileewosan kan ni ilu Lọndọn nigba ti o n ṣa afihan aisan naa tofimọ ara gbigbona.
Amọṣa ileeṣẹ ijọba ilẹ Gẹẹsi ṣalaye pe oun ṣi ni akoso ijọba wa ni ikawọ rẹ, bi o tilẹ jẹ wi pe minisita fun ọrọ ilẹ okeere ni ireti wa pe yoo lewaju ipade kan ti yoo waye lori ọrọ arun Coronavirus ni owurọ ọjọ Aje.
Wọn ni igbesẹ itọju lasan ni gẹgẹ bi amọran dokita to n tọju rẹ
Gẹgẹbi akọroyin nipa oṣelu nileeṣẹ BBC,  Laura Kuenssberg ṣe sọ, Ọgbẹni Johnson yoo sun orun alẹ ọjọ kan nibẹ lati lee ṣe awọn ayẹwo gbogbo to ba yẹ.
Lati ile rẹ ni olootu ijọba ilẹ Gẹẹsi naa ti n ṣe iṣẹ rẹ gbogbo lati igba ti ayẹwo ti gbe e jade ni ọjọ kẹtadinlọgbọn oṣu kẹta pe o ni arun naa.
Coronavirus in Nigeria: Wòlíì 'Sọtítóbirẹ̀' fójú ba ilé ẹjọ́, fídíò ohun tójú rẹ̀ rí nílé ẹjọ́ nìyí
Ilé ẹjọ́ kànán nípá fún Wòlíì Sọtítóbirẹ̀ kó tó wọ ilé ẹjọ́
Awọn agba bọ wọn ni, ohun to n ṣe ilemboye kọ lo n ṣe ọmọ rẹ. Ilemboye n wa owo, ọmọ rẹ n wa ọkọ.
Iṣoro ṣe ọtọọtọ bayii fun gbajugbaja ojiṣẹ Ọlọrun ijọ Sọtitobirẹ ni ilu Akurẹ, Wolii Alfa babatunde bayii nitori bi gbogbo aye ṣe n du ori wọn ki wọn maa ko arun coronavirus ni Wolii Sotitobirẹ n du ori rẹ niwaju adajọ ile ẹjọ giga nilu Akurẹ.
Woli Babatunde n jẹjọ ijinigbe ti wọọn fi kan oun atawọn ọmọ ijọ rẹ mẹfa lori ọmọde jojolo kan to poora ni ile ijọsin rẹ ni oṣu kọkanla ọdun 2019.
Wolii Sọtitobirẹ n pada si ile ẹjọ lẹyin ti igbẹjọ ti bẹrẹ ti awọn ẹlẹri gbogbo si ti n wi tẹnu wọn niwaju ile ẹjọ lati mọ boya ọwọ iranṣẹ Ọlọrun naa mọ tabi ko mọ lori ọrọ naa.
Akọroyin ileeṣẹ BBC News Yoruba to wa nibi igbẹjọ naa ṣalaye pe ki awọn afunrasi naa to wọ ile ẹjọ ni wọn ti kọkọ ni ki wọn fọ ọwọ wọn gẹgẹ bi ohun ti o n lọ lode bayii pẹlu ajakalẹ arun Coronavirus.
Bakan naa ni wọn ko jẹ ki akọroyin kankan wọle si yara igbẹjọ naa.
Coronavirus: Ọ̀rá ni àwọn dókítà fi ń dáàbò bo ara wọn nílẹ̀ẹ Gẹ̀ẹ́sì
Bi iye awọn eeyan to ti gbẹmi mi nitori Coronavirus ṣe n peleke sii nilẹ Gẹẹsi, bẹ naa ni awọn ile iwosan atawọn oṣiṣẹ eto ilera n wa ọna lati koju arun ọhun.
Bo tilẹ jẹ pe wọn dẹkun wọn lati ba ileeṣẹ iroyin sọrọ, ọpọ awọn oṣiṣẹ eto ilera nilẹ Gẹẹsi ti sọ ẹdun ọkan wọn fun ileeṣẹ iroyin BBC nipa bi aini irinṣẹ to peye ṣe n jẹ wọn niya.
Ọkan lara awọn dokita ilẹ naa, Roberts sọ pe ile iwosan ti kun fun awọn alaisan Coronavirus.
O ni awọn nọọsi to wa nilẹ ko to fun iye awọn alaisan to nilo itọju, bẹẹ naa ni ko si ogun ati awọn ibusun ti alaisan le fẹyinle. Ṣugbọn o jẹ ohun iyalẹnu pe ọra lasan ni awọn to n ṣeṭoju alaisan fi n dabo bo ara wọn, fun nnkan bi wakati mẹtala ti wọn n lo lẹnu iṣẹ.
Dokita ọhun ni ijọba gba awọn ara ilu lati jinna rere si ẹni ti wọn ba funra sip e o ni arun Coronavirus lara, ṣugbọn awọn to n ṣiṣẹ nile iwosan n fẹgbẹkẹgbẹ pẹlu alarun naa laisi ohun idabo bo ara ẹni to kun oju oṣuwọn.
O tẹsiwaju pe ọpọ oṣiṣẹ ni awọn ẹka ile iwosan rẹ lo wa ninu ibeorubojo nitori wọn ko mọ iru aisan to le kolu wọn lọjọ iwaju.
Roberts fẹsun kan ijọba pe ko pese ohun to yẹ fun awọn  oṣiṣẹ ile iwosan rẹ, idi ree ti wọn ṣe n lo ọra lati fi dabo ara wọn, eyi ti ko bojumu.Ṣaaju ni ijọba ilẹ Gẹẹsi ti sọ pe oun n ni idojukọ pẹlu pinpin awọn ohun elo idabobo ara ẹni ọhun, ṣugbọn iṣẹ n lọ pẹlu ifọwosoẉọpọ awọn ọwọn ọmọ ogun lati ri pe ohun elo naa kari.Ijọba ni iboju ti ko din ni miliọnu kan ni oun ti pin si awọn ile iwosan ni ọjọ kinni oṣu kẹrin ọdun 2020, ṣugbọn dokita Robert sọ pe ọrọ ko ri bẹ nitori ile iwosan ohun ko ri ohunkohun gba.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
"O ni ""Iboju to wa lọdọ wa bayii yẹ ko ti pari iṣẹ lati ọdun 2009, awọn kan yẹ ko ti pari iṣẹ lati 2013, ti awọn toku yoo kọṣẹ lọdun 2021, gẹgẹ bi akọle to wa lara rẹ.""Dikita naa pari ọrọ pe ki awọn ara ilu joko sile wọn lọna ati dabo bo ara wọn ati awọn ololufẹ wọn."
Coronavirus: Àrùn Coronavirus fa'lẹ̀ya láwọn ìletò aláwọ̀dúdú ní Amẹ́ríkà
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Akojọpọ iroyin nipa awọn ti arun Coronavirus n ṣe lati ọdọ awọn oṣiṣẹ eto ilera ni Chicago n jẹ ko di mimọ bayii pe ọpọ awọn eeyan to jẹ ọmọ Amẹrika alawọ dudu lọwọ arun naa ti tẹ.
Awọn ọmọ ipinlẹ Chicago to jẹ alawọ dudu lo ko ida aadọrin ninu ọgọrun awọn eeyan ti ọwọ arun naa ti ba ninu bi o tilẹ jẹ pe ida ọgbọn ninu awọn eeyan to n gbe ilu naa lo jẹ alawọ dudu.
Awọn ilu miran ti awọn eeyan alawọ dudu pọ si bii Detroit, Milwaukee, New Orleans ati New York, lo ti di ibuba fun arun naa.
Ẹgbẹrun lọna ọọdunrun ati ọgọrin eeyan  lo ti ko arun coronavirus lorilẹede Amẹrika, awọn to si ti ran lọ si ọrun din diẹ ni ẹgbẹrun mọkanla.
Lagbaye o le ni miliọnu kan ati ẹgbẹrun lọna ọdunrun eeyan to ti ko arun naa, ẹgbẹrun marundinlọgọrin eeyan lo si ti tipasẹ arun naa ku.
Gẹgẹ bi awọn alaṣẹ ilu Chicago ṣe sọ, titi di ọjọ karun un oṣu kẹrin, ẹgbẹrun mẹrin ati ọrinlelẹgbẹta eeyan ni arun coronavirus ti mu, okoo le lẹgbẹsan ati mẹrin ni iye awọn eeyan to jẹ alawọ dudu laarin wọn.
Bi a ba gbe eyi sẹgbẹ ojilelẹgbẹrin ati meje alawọ funfun, ọrinlenirinwo o din meji ẹya Hispanic ati mẹrindinlaadọfa ẹya Aṣia to n gbe ni Chicago to ni arun naa
Eeyan mejidinlọgọrun larun coronavirus ti ran lọ si ọrun alakeji ni ilu Chicago, ida mejilelaadọrin wọn lo si jẹ alawọ dudu nibẹ.
Iyatọ gedegbe yii n fara han lawọn agbegbe gbogbo ni ipinlẹ nibi ti awọn eeyan alawọ dudu ti n ko ida mọkanlelogoji ninu iku gbogbo to lọwọ arun coronavirus ninu, ti o si jẹ pe ida mẹrinla awọn eeyan to n gbe ni ipinlẹ Illinois lo jẹ alawọ dudu.
Kọmiṣọna fun eto ilera ni ilu Chicago, Dokita Allison Arwady ṣalaye fun awọn akọroyin pe igbelewọn ẹmi awọn alawọ dudu ni ipinlẹ naa ti ja wa silẹ pẹlu ọdun mẹsan din diẹ ju tawọn to jẹ alawọ funfun lọ.
"Olori ilu naa, Mayor Lori Lightfoot ni arun coronavirus ""n ṣe ọṣẹ to lagbara laarin awọn alawọ dudu ilu Chicago""."
O ni wọn yoo ran awọn wolewole ilu naa lọ sawọn ṣọọbu itaja lati rii pe awọn eeyan n tẹle ilana ijinasiraẹni nigba gbogbo.
Bakan naa lo ni o ṣeeṣe ki wọn gbe eto konileogbele yẹwo lawọn agbegbe ti wọn ba rii pe awọn eeyan ti n ko ori js lati mu ọti niwaju awọn ile itaja, gẹgẹ bi iwe iroyin Chicago Sun-Times ṣe gbee jade.
Bi o  tilẹ jẹ pe awọn eeyan n sọ pe arun naa ko mọ oju sibẹ akọsilẹ n fihan pe ọwọja rẹ yatọ ni ileto si ileto.
Ni Michigan ida mẹrinla lawọn to jẹ alawọdudu nibẹ, ṣugbọn awọn gan an lo ko ida mẹtalelọgbọn lara awọn ti arun coronavirus ti kan; bẹẹni ida mọkanlelogoji awọn to ti ku lo jẹ alawọ dudu gẹgẹ bi ileeṣẹ eto ilera nibẹ ti ṣe sọ.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ida mẹtalelogun awọn to nii lo jẹ alalwọ funfun ti ida mejidinlọgbọn awọn to ku ni ipinlẹ Michigan.
Oríṣun àwòrán, Reuters
Mayor Lightfoot n ṣalaye pe aisan itọ ṣuga, aisan ọkan ati aisan to niiṣe pẹlu eroja eemi pọ laarinawọn ileto awọn alawọ dudu nibẹ.
Corornavirus: Kini Gómìnà ìpínlẹ̀ Ekiti ṣe fun baba tọ ni ọmọ òun ko gbọdọ tèlé oun déle nitori o ṣẹ̀ṣẹ̀ de lati Eko?
Oríṣun àwòrán, Fayemi
kini Gómìnà ìpínlẹ̀ Ekiti, Kayode Fayemi ṣe fun baba tó ni ọmọ òun ko gbọdọ tèlé oun déle
Gómìnà ìpínlẹ Ekiti, Kayode Fayemi ni òun ti yan baba ti fọran rẹ tan ka ori ayelujara lásìkò to n ba ọmọ rẹ jà pe ko le tẹ̀lé òun lọ ile lai ṣe ayẹwò Covid-19 lẹ́yìn to ti irin ajo de lati ìpínẹ̀ Eko gẹ́gẹ́ bi asoj;u ìjọba lori ọ̀rọ̀ Covid-19 nipinlẹ Ekiti.
Gomina fi ọ̀rọ́ yìí léde lorí atẹjísẹ́ twitter rẹ̀ lasàn òní pe inú oun dùn fún igbésẹ ọ̀gbẹ́ni Femi Adeoye pẹlu bi o ṣe ṣe pẹlu ọmọ bíbí rẹ̀ nítori pé o ni igboya, o si nifẹ ìpińll Ekiti lọ́kan.
O ní ọ̀gbẹ́ ni Adeoye yoo ran ìjọba lọ́wọ́ láti maa tan àwọn ipolongo lori ààrun corornavirus, yóò si jẹ ọ̀kan lára àwọn ìgbìmọ̀ amúṣẹ́ṣe lori ọ̀rọ̀ coronavirus nípìnlẹ̀ Ekiti
Megabite: Ilé-ìwé ni mo ti bẹ̀rẹ̀ orin kíkọ
Corornavirus: Kini Gómìnà ìpínlẹ̀ Ekiti ṣe fun baba tọ ni ọmọ òun ko gbọdọ tèlé oun déle nitori o ṣẹ̀ṣẹ̀ de lati Eko
O kò leè wọ inú ilé mi lẹ́yìn ìrìnàjò láti Eko, lai ṣe àyẹ̀wò Coronavirus - Bàbá yari fún ọmọ
Coronavirus symptoms vs cold-O kò leè wọ inú ilé mi lẹ́yìn ìrìnàjò láti Eko, lai ṣe àyẹ̀wò Coronavirus - Bàbá yari fún ọmọ
Oríṣun àwòrán, others
Yorùbá ni ọmọ ẹni kii burú títí, ká lè fún ẹkùn pa jẹ àmọ́ èyí kò rí bẹ́ẹ̀ pẹlu bàbá kan ni Ondo, tó le ọmọ rẹ síta nítorí ibẹru àrùn Coronavirus.
Bí ere orí itage si ni ìṣẹ̀lẹ̀ náà ri nigbati bàbá kan, Arákùnrin Babafemi, yari kanlẹ pé ọmọ òun tó ṣẹ̀ṣẹ̀ ti ìlú Èkó de, gbọ́dọ̀ ṣe ayẹwo àrùn Coronavirus, kí òun tó gbà á sínú ilé .
Babafemi, tíì ṣe òṣìṣẹ́ fẹyinti kan nileesẹ àjọ ẹsọ ojú pópó FRSC ṣàlàyé pé, òun ti sọ fún ọmọ òun láti dúró sí Eko, àmọ́ tí kò gbọ .
Mo ti ní kí ọmọ mi má ṣe wá sí Ado Ekiti àmọ́ kò gbọ ọrọ si mi lẹ́nu. Ní báyìí tó sì ti dé sí Ado, ó gbọ́dọ̀ ṣe ayẹwo àrùn Coronavirus ni, kò to dára pọ mọ wa.
Oríṣun àwòrán, other
Babafemi ni kí òun to gba ọmọ òun sínú ilé, yóò kọ́kọ́ lo ọjọ́ mẹ́rìnlá na ni ibùdó iyasọtọ nítorí òun kò leè fi ẹbí òun sínú ewu àrùn Covid-19.
Baba náà ni ó yẹ kí òun fi ọ̀rọ̀ obìnrin oloyun tó wà sì Èkìtì láti ìlú Èkó ṣe arikọgbọn, ẹni tó ko àrùn Coronavirus wá Ekiti láti Eko.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Awọn to ji Komisana eto ọgbin gbe ni ipinlẹ Ekiti ọgbẹni Folorunsho Olabode gbe ti beere ọgbọn miliọnu naira gẹgẹ bi owo tawọn yoo gba ki wọn to tu silẹ.
Ni irọlẹ ọjọ Aiku lawọn ajinigbe yi da ọkọ rẹ lọna ni opopona Isan Iludun ni Ekiti.
Wọn ji Kọmisana naa ati eeyan kan ti wọn jọ wa ninu ọkọ gbe ti wọn si tun yinbọn pa Kansilọ nijọba ibilẹ Ilejemeje kan ti wọn jọ wa ninu ọkọ naa.
Ninu ohun ta ri gbọ ninu awọn iwe iroyin ilẹ Naijiria,eeyan kan ninu  mọlẹbi Kọmisana sọ fun awọn akọroyin ni iAdo Ekiti lọjọ Aje pe awọn ajinigbe naa ti pe awọn lori ago ti wọn si ti beere owo ẹmi ọgbọn miliọnu naira.
Eni ta n wi yi sọ pe ninu ibẹrubojo ni awọn eeyan ilu Kọmisana naa ti se Iye wa ti wọn si n rawọ ẹbẹ si Gomina la ti sa gbogbo agbara lati ri pe wọn doola ẹmi ọmọ awọn.
''A n bẹ Gomina Kayode Fayemi ati awọn agbofinro lati sa gbogbo agbara wọ́n ki wọn ba le doola rẹ''
Ewẹ alukoro ọlọpaa nipinlẹ Ekoto Sunday Abutu to tẹpẹlẹmọ ipinu ajọ naa lati wa Kọmisana naa jade ni awọn ko mọ si owo ẹmi tawọn ajinigbe naa n beere.
Jọwọ ṣe atunṣe ilana ikansi ayelujara rẹ lati ri ẹkunrẹrẹ rẹ
Orisun: Johns Hopkins University atawọn ajọ eto ilera ilu
Igba ti wọn kede iṣiro awọn to nii kẹyin                                              29 Oṣù Bélú 2021 13:33 WAT+3
*Iye awọn to tọwọ aisan ku ni isọri eeyan ẹgbẹrun lọna ọgọrun
Jọwọ ṣe atunṣe ilana ikansi ayelujara rẹ lati ri ẹkunrẹrẹ rẹ
Akọsile imọ yii, da lori akojọpọ iṣẹ iwadi ni Fasisti Johns Hopkins, o si le ma ṣe afihan awọn akọsilẹ iroyin to ba igba mu lati orilẹede kankan.
** Àwọn iyé akọsilẹ̀ to ti wà fún àwọn ti o ṣẹ́ṣẹ̀ ni ààrun náà jẹ́ àkójọpọ̀ ọjọ́ mẹ́ta. Nítori àwọn àtúgbẹ́yẹ̀wò, o níra láti ṣe àkójọpọ fún àwọn ọkọ́ naa
Orisun: Johns Hopkins University atawọn ajọ eto ilera ilu
Iye akọsilẹ to waye gbẹyin 29 Oṣù Bélú 2021 13:33 WAT+3
''A ko mọ si pe awọn ajinigbe naa n beere owo ki wọn to tusilẹ.Wọn o ti sọ fun wa''
Bakanna ni ọkan lara awọn ọmọ ile asofin nipinlẹ Ekiti ti ni ara ohun ti Coronavirus da silẹ ni ijingbe yi jẹ nitori ohun ni ko jẹ ki wọn se ifilọlẹ ikọ alaabo Amọtẹkun lasiko.
Tope Ogunleye to n soju ẹkun idibo Ilejemeje ni ''inu mi ko dun si gbogbo ohun to n sẹlẹ yi.Awọn ọdaran yi ko sẹsẹ ma sọsẹ laaye ibi ti wọn ti ji Kọmisana gbe.Mo mọ wi pe Gomina Fayemi ko fi ọrọ yi sere rara''
Ogunleye ni nigba ti Covid-19 yoo ba fi kasẹ nilẹ, gomina yoo raaye lati se ifilọlẹ ikọ Amọtẹkun.
O sọ pe awọn eeyan awọn to mọ tibu toro agbegbe naa ni yoo wa nibẹ ti wọn yoo si le awọn ọdaran kuro ni ipinlẹ Ekiti.
Ina nla kan tun sọ lọsan oni lagbegbe college Road Road, Abatan Ọgba ni ilu Eko.
Titi di asiko ti a fi n ṣa iroyin yii jọ, ko tii si ẹni lee sọ ohun gan ni pato to fa ijamba ina naa.
Ileepo NNPC to wa ni agbegbe naa ni ina naa ti sọ eyi ti o jo ọpọlọpọ dukia olowo iyebiye.
Oríṣun àwòrán, dele momodu
Gbajumọ akọroyin àti olóṣèlú kan, Dele Momoodu tí woye pe o ṣeé ṣe kí orílẹ̀ èdè Nàìjíríà wo, tí àwọn aráàlú bá fi bínú lórí àfikún igbele àrùn Coronavirus.
Dele Momoodu, lásìkò to ń bá  BBC Yoruba sọ̀rọ̀ ṣàlàyé pé, kí ìjọba tí àwọn èèyàn mọle kọ ní ọ̀nà àbáyọ kan ṣoṣo tó wà láti dènà àrùn Coronavirus.
Tí ẹ bá wo orílẹ̀ èdè Ghana, ó ní ọ̀nà tí ìjọba ń gba láti dènà ifarakinra. Yorùbá si ní ebi kii wọnú, kí ọ̀rọ̀ miran wọ, ebi sì ni ìṣòro ni orílẹ̀ èdè wa.
Ilẹ̀ Nàìjíríà kii se UK, Amẹ́ríkà àti Faranse. Kò sí oúnjẹ, kò sì iná, ẹ wá fẹ tí àwọn èèyàn mọle, kò leè ṣeé ṣe, èmi kò sì mọ bí ijọba wá ṣe fẹ ṣe. 
Bákan náà ni Dele Momoodu koro ojú sì bí ìjọba ṣe kó owó sórí tabili, tí wọn sì ń pín bíi ìgbà tí wọn ń pín àkàrà, èmi kò sì tíì rí èèyàn tó ní òun ti rí owó náà gbà.
A ti pariwo títí fún ìjọba, wọn kò gbọ, Nàìjíríà kò sì ní àkọsílẹ̀ gidi. Kí ló dé tí ìjọba kò ṣe lọ nọ́mbà àsùnwọ̀n owó ni banki láti fi pín owó náà àti pé ọna wo ni wọn gba mọ àwọn aláìní.
Òǹtàjà aṣọ ni mí tẹ́lẹ̀, ọ̀dá owó ló sọ mi di alábárù
Nígbà tó ń sọ̀rọ̀ lórí akojọpọ esi tí ileesẹ tó ń gbógun ti àrùn nilẹ yìí, Momoodu ni Naijiria kò ní àkọsílẹ̀ tó dára lórí iye èèyàn tó ní Coronavirus ni Naijiria, bẹ́ẹ̀ sì ni ọpọ àwọn èèyàn tó wà nibẹ lo ń fẹ́ jẹun láti ara àìsàn náà.
Lórí erongba aṣáájú ẹgbẹ́ APC àti Gómìnà Ìpínlẹ̀ Eko tẹ́lẹ̀, Senato Bola Hammed Tinubu láti di aarẹ Naijiria lọ́dún 2023, Momoodu ni lọ́wọ́ lọ́wọ́ báyìí, Tinubu sì lo kajuẹ julọ láti darí orílẹ̀ èdè yìí.
O ṣàlàyé pé lóòótọ́ ni Tinubu kò fẹ́ lórí bí àwọn èèyàn ṣe ń pariwo rẹ pé kò wá díje nítorí ó ti ìgbésẹ ọhun bíi ìwà ọyaju sì aarẹ Buhari to wa lori aleefa, nígbà tí kò tíì parí ṣáá isejọba rẹ.
Oríṣun àwòrán, dele momodu
"Momoodu ni ""Ọpọlọpọ owó tí awọn eniyan kan ní Tinubu kò yìí, kii na fún ara rẹ nìkan nítorí pé ó ní ojú àánú pupọ, tó sì máa ń rán aráàlú lọ́wọ́,koda tipátipá lọ máa ń fi jẹun."""
Bí APC ba fà Olóye Tinubu silẹ láti díje fún ipò Ààrẹ Naijiria, ó dá mi lójú pé, ó tó gbangba sùn lọyẹ, òun ni yóò mókè laarin awọn oludije yòókù nítorí pé ó kúnjú òṣùwọ̀n, tí yóò sì soro kò tó má di aarẹ Nàìjíríà.
Momoodu tún woye pe ìlànà wiwo ọ̀rọ̀ ẹṣin, ẹ̀yà àti owó láti fà oludije kalẹ ni Naijiria kò bójú mú nítorí ẹni tí kò bá ní owó láti pin tàbí jẹ́ ẹlẹ́ṣin tó kàn láti díje, wọn kò ní ṣe atileyin gùn onitohun.
Oríṣun àwòrán, others
Wo ipinlẹ ti ko tii ni coronavirus ni Naijiria
Titi di ọjọ Kejila, oṣu Kinni, ọdun 2020, orilẹ-ede China nikan lo tii ni awọn to ni aarun coronavirus.
Sugbọn nigba ti yoo fi di ọjọ kẹtala, oṣu Kínní, aarun naa ti di ti gbogbo agbaye, nitori pe orilẹ-ede bi Thailand, Japan, South Korea àti America ṣe bẹ̀rẹ̀ si i ni akọsilẹ ti wọn naa.
Lẹyin naa ni aarun naa bẹ̀rẹ̀ si tàn de awọn orilẹ-ede yooku, to fi mọ Africa.
Lọwọ-lọwọ, o ti to miliọnu meji eniyan to ti ni aarun naa.
Itan Iṣẹlẹ COVID 19 ní Naijiria:
Ọjọ kẹtadinlọgbọn, oṣu Keji, ni Naijiria kọkọ ni akọsilẹ aarun naa, lẹyin ti ọmọ orilẹ-ede Italy kan ni i.Lẹyin naa ni akọsilẹ ẹni keji waye lọjọ kẹsàn-án, oṣu Kẹta. Ọmọ Naijiria ni.Lẹyin eyi ni awọn to ni n pọ si.
libya
Níbo ni ọrọ coronavirus de duro bayii ni Naijiria?
Lọwọ lọwọ, eniyan irinwo ati meje ni ajọ to n dena aarun ni Naijiria, NCDC, sọ pe o ni coronavirus.
Awọn ipinlẹ ti aarun naa ti de ni
Lagos
Abuja
Osun
Edo
Oyo
Bauchi
Akwa Ibom
Kaduna
Ogun
Enugu
Ekiti
Kwara
Rivers
Benue
Ondo
Delta
Katsina
Anambra
Niger
Kano
Apapọ wọn jẹ: mọkandinlogun ati Abuja to jẹ olu ilu Naijiria.
Afeez Agoro: O ṣòro fún mi láti wọ Danfo jáde
Àwọn ipinlẹ ti Covid-19 ko ti i de ni NaijiriaBi aarun yii ṣe n tankalẹ to naa ni a ṣi ni awọn ipinlẹ ti ko tii de ni Naijiria.
Ipinlẹ mẹrindinlogun ni coronavirus ko ti i de ni Naijiria naa niwọnyii:.Gombe
Adamawa
Plateau
Borno
Ebonyi
Cross River
Sokoto
Kebbi
Imo
Bayelsa
Taraba
Kogi
Nasarawa
Zamfara
Yobe
Jigawa
'Èmi gan máa ń béèrè lọ́wọ́ ara mi pé ta ni Wole Soyinka gangan'
Igbesẹ wo ni wọn n gbe lati ri pe ajakalẹ aarun yii ko de ipinlẹ wọn?
Lootọ ni coronavirus ko ti i de awọn ipinlẹ naa, sugbọn lati igba to ti de Naijiria ni diẹ lara wọn ti gbe awọn igbesẹ lati ri i daju pe ko wọ ipinlẹ wọn, àti ọna ti wọn yoo gba koju rẹ to ba ṣèèṣì wọle.
Ipinlẹ Borno gbé igbimọ amusẹya kalẹ lati sisẹ pẹlu awọn ileesẹ aladani, ile ijọsin ati awọn ajọ ti kii se ti jọba lati koju aarun naa, to ba fi le wọ ibẹ.
Lọjọ kọkanlelogun, oṣu Kẹta, ipinlẹ Kebbi kede pe ki gbogbo ileewe o wa ni titi pa.Ipinlẹ Ebonyi naa fi ofin de ipejọpọ ọpọ eniyan, lọjọ kẹtalelogun, ọsu kẹta.
Bakan naa ni ipinlẹ Bayelsa ati Imo kede lọjọ kẹrindinlọgbọn pe ki awọn ileewe di titi pa, wọn si tun fi ofin de ipejọpọ ọpọ eniyan to ba le ni àádọ́ta.
Ni ti ipinlẹ Abia, o ti gbogbo ẹnu ibode ipinlẹ naa pa fun ọsẹ mẹrin, o si tun pasẹ pe ki gbogbo araalu o joko sile. Àwọn ile itaja oúnjẹ àti òògùn nìkan ni ofin naa yọ silẹ.
Ijọba ipinlẹ Cross River fi ofin de ipejọpọ nile ijọsin.Kebbi àti Taraba ko ti ẹ gba ki ẹnikẹni wọle si tabi jade kuro ni ipinlẹ naa.
Niṣe lo yẹ ki onikaluku maa fọwọ wọn loorekoore ki wọn si tẹle gbogbo imọran ajọ WHO lori didẹkun itankalẹ ajakalẹ aarun coronavirus laisko yii.
''O lè kó coronavirus nípa ṣíṣe eré ìdárayá, ẹ gbélé yín lásìkò yìí,''- onímọ̀ ètò ìlera
Coronavirus in Nigeria: ''Èèyàn lè kó coronavirus nípa ṣíṣe eré ìdárayá, ẹ gbélé yín lásìkò yìí,''
Onimọ nipa eto ilera, Dokita Ikubese Wilson ṣe atupalẹ bi eeya ti le ko aarun coronavirus nipasẹ ṣiṣe ere idaraya.
Ilana ijinasiraẹni jẹ ọkan gboogi lara awọn igbesẹ ti ajọ eto ilera agbaye, WHO gbe kalẹ gẹgẹ bi ara ọna ti a le gba dena itankalẹ aarun Coronavirus.
Oríṣun àwòrán, Twitter/globaltimesng
Àwọn Ìpínlẹ̀ tí coronavirus kò tíì dé ní Nàìjíríà, àti ìgbésẹ̀ tí wọ́n ń gbé láti dènà rẹ̀
Nitorinaa, ko jẹ iyalẹnu pe ilana ijinasiraẹni yii wa lara awọn igbesẹ ti ijọba lẹkajẹka gbogbo ni orilẹede Naijiria tẹnpẹlẹ mọ julọ gẹgẹ bi ọna lati din ọwọja aarun naa ku nilẹ yii.
Lati fi idi ilana naa mulẹ, awọn ijọba ipinlẹ bii Eko tilẹ fi ofin gbee lẹyin, ofin yii si wa lara eyi ti wọn gbe kalẹ ni ile ẹjọ lati fi gbajugbaja oṣere sinima, Funkẹ Akindele ati ọkọ rẹ j'ofin ni ọjọ Aje.
Amọṣa, ohun to wa n ṣe ọpọ ni haahinin bayii ni bi awọn eeyan ko ṣe karamasiki ilana yii.
Bi o tilẹ jẹ wi pe ijọba apapọ paṣẹ konile-o-gbele lawọn ipinlẹ kan bii Eko, Ogun ati Abuja, ohun ti o n farahan bayii paapaa lori ayelujara ni pe ọpọ awọn ọmọ Naijiria ti wọn ko fẹ ki jijoko pa sile o sọ awọn di nnkan miran ti wọn si ti bẹrẹ ere idaraya kaakiri lati fi na eegun ati ara wọn.
Amọṣa o, nipasẹ ṣiṣe eyi, ọpọ wọn lo ti n darapọ mọ ibi ti ọpọ ero wa, ti wọn si ti n t'ipasẹ bẹẹ fi ara wọn sinu ewu ati ko arun Coronavirus.
Nibayii ọpọ aworan eyi lo si ti lu ori ayelujara pa.
Ọpọ igba ni igbesẹ ijọba lo ti ba oniruru iha araalu pade.
Arabinrin kan to ni ki a fi orukọ bo oun laṣiri ṣalaye pe ni agbegbe ti oun n gbe ni ilu Eko ni oun ti maa n ṣe ere idaraya lati na eegun ati ara oun.
O ni nigba ti oun yoo fi jade ni ọjọ Aje, 'igboro ti daru' loun lee fi we nitori iye awọn to wa nigboro lati ṣe ere idaraya. O ni eyi lo mu ki oun pinnu lati dawọ duro naa.
Ni aipẹ yii ni awọn olujọsin ni mọṣalaṣi kan ni ilu Eko kọlu awọn oṣiṣẹ ikọ amuṣẹya ti ijọba gbe kalẹ ti wọn wa kan si wọn pe ki wọn pa ofin naa mọ nitori nṣe ni ileejọsin naa kun bamubamu fun awọn to wa kirun.
Njẹ eeyan le ko aarun coronavirus nipa ṣiṣe ere idaraya?
Onimọ nipa eto ilera, Dokita Ikubese Wilson ṣe atupalẹ bi eeya ti le ko aarun coronavirus nipasẹ ṣiṣe ere idaraya.
Dokita Wilson ṣalaye pe o ṣeeṣe ki eeyan ti ipasẹ ere idaraya ko aarun covid-19 nitori sisun mọ ẹni to ni aarun naa lara.
Bakan naa lo sọ pe kokoro aarun covid-19 le wa laaye yala lara ohun elo ere idaraya ti ẹni to ni aarun naa ba ti lo, nitorinaa ''asiko yii ko dara fun ṣiṣe ere idaraya nitori ewu to wa nibẹ pọ.''
Dokita Wilson tun ṣalaye pe ti eeyan ba n ṣe ere idaraya, eemi ẹni naa maa pọ si, bakan naa ni afẹfẹ to n jade lati inu ẹdọ foro naa yoo pọ si.
''Ti ẹni to n ṣe ere idaraya ba mi, eemi naa yoo maa jade leralera, ti ẹni naa ba si ni aarun coronavirus, ẹlomiiran ti wọn jọ n ṣe ere iadaraya le ko aarun naa lara rẹ,'' Dokita Wilson lo woye bẹẹ.
O rọ awọn eeyan lati maa ṣe ere idaraya ninu ile wọn lasiko ti ofin konle-o-gbele wa lode nitori ewu to wa ninu ṣiṣe ere idaraya loju popo tabi ni gbọngan ere idaraya lasiko yii.
O ni fifi ẹmi ẹlomiiran wewu ni ṣiṣe ere idaraya pẹlu awọn mii tumọ sii lasiko yii.
Coronavirus: Báyìí ni àwọn ṣọ́ọ̀ṣì ńlá nlá ní Nàìjíríà ṣe ń bá ìgbà coronavirus yí
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Nṣe ni àwọn sọọsi nlá nlá wà ní òfìfo, tí àwọn ilẹkun wọn naa si wa ni titi pa lasiko yii.
Iru nkan bayii ko dabi pe o ṣẹlẹ ri, aarun coronavirus to n ba gbogbo aaye finra lo fa a.
Ero nipa iwa Abosi ati ọtẹỌkan lara awọn gbaju-gbaja ninu iwa yii ni TB Joshua, to sọ losu keji, odun pe ẹmi ọrun ru oun soke lati sọ aṣọtẹlẹ pe coronavirus yoo ko ẹru rẹ pada sibi to ti wa nigba ti yoo ba fi di ọjọ kẹtadinlogbọn, osu Kẹta.
Eyi jẹ ọjọ diẹ saaju ki ijọba o to kede aṣẹ konile-o-gbele ni Ipinleẹ Eko, Ogun, ati olu-ilu Naijiria, Abuja.
Oríṣun àwòrán, AFP
"Joshua sọ pe 'Nigba ti yoo ba fi di ipari osu yii, boya a fẹ tabi a ko fẹ ẹ, koda ko si oogun oyinbo to wu ki wọn o ṣe, bi coronavirus se wá naa ni yoo se lọ'.Ọrọ yii mu ki awọn ọmọ ijọ rẹ sa a ni atẹwọ pe baba, ọrọ lẹ sọ.Ṣugbọn nigba ti ọjọ kẹtadinlogbọn, osu Kẹta kọja ti coronavirus ko ti i ko ẹrù rẹ pada sibi to ti wá, awọn eniyan fi pasitọ naa ṣe ẹléya.Ṣugbọn o, ọrọ naa ni Pasitọ Joshua tun fi gba ara rẹ silẹ.O ni ""nkan ti mo sọ ni pato lọjọ yẹn ni pe aarun yẹn maa dawọ duro nibi to ti bẹrẹ.Ṣe ẹ dẹ mọ pe o ti dawọ duro niluu Wuhan lootọ.""Wọn ti fi ẹsun kan awọn pasitọ miran pe wọn n pin ayederu iroyin kiri, eyi to n di akitiyan lati kapa aarun naa lọwọ.Ijọ  Christ Embassy, to jẹ ti gbaju-gbaja pasitọ, Chris Oyakhilome, lo fa awuyewuye to mi ìlú julọ.Eyi ko ṣẹyin bi Oyakhilome ṣe sọ ninu fidio kan to kari ori ayelujara pe coronavirus ni nkan ṣe pẹlu idasilẹ irinsẹ ayelujara 5G, ati wi pe ara imọ lati da ilana igbe-aye tuntun 'new world order' silẹ ni.Awọn onimọ sayẹnsi ti sọ pe irọ ni iru iroyin naa.Wọn sọ pe ""ọrọ omugọ lasan ni sisọ pe ayelujara 5G ni nkan ṣe pẹlu COVID-19."
Adura Gbigba lori ayelujaraFun awọn Kristẹni kan, paapa awọn to n lọ si awọn ile ijọsin bi i Anglican ati ijọ Aguda, wọn ni isẹ to pọ lati ṣe ki awọn pasitọ igbalode ma ba a gbá wọn.
"Paapa awọn to n gbá awọn Kristẹni ti ko dakan mọ.""Obinrin kan, Blessing Ugonna sọ fun akọroyin BBC nilu Eko pe"" asiko niyi fun awọn to maa n ta omi iyanu, ororo ati awọn nkan miran fun wa lati jẹwọ agbara wọn"". Itankalẹ coronavirus ti mu ki ọpọlọpọ ninu awọn sọọsi nlanla naa ko tun eero wọn pa.Kiise pe wọn n ṣe isin adura lori ayelujara nikan, wọn tun n fun ijọba ati awọn ọmọ ijọ kọọkan ni owo.Awọn kan sọ pe wọn ṣe eyi lati da omi siwaju ki wọn o ba a le tẹ ilẹ tutu ti coronavirus ba tán nilẹ ni."
Pasitọ Enoch Adeboye - olori ijọ Irapada Kristi, to fẹ ẹ ni sọọsi ni gbogbo adugbo ni Guusu Naijiria ti fun ijọba ipinlẹ Eko ni ẹgbẹrun lọna igba ibọwọ, ẹgbẹrun mẹjọ sanitiser, ati ẹgbẹrun mẹjọ iboju.Bakan naa ni Wooli Chukwuemeka Odumeje, ti ẹnu ti kun lori ayelujara nitori fidio kan to fihan bo ṣe n jijakadi pẹlu ọmọ ijọ rẹ kan to sọ pe o ni ẹmi okunkun ninu - naa ti gba oriyin lori Twitter fun bose fun awọn ti ebi le pa lasiko igbele ọsẹ meji.
Lai fi gbogbo nkan to n ṣẹlẹ ṣe, ongbẹ sọọsi si n gbẹ ọpọlọpọ Kristẹni - ọjọ isinmi to kọja dun wọn pupọ nitori o jẹ ayajọ ọjọ Isinmi Ọpẹ.
Oríṣun àwòrán, AFP
Tẹle, nise ni awọn ojupopo maa n kun fọfọ nilu Eko nitori bi awọn Kristẹni se maa n se iwọde pẹlu ìmọ̀ ọpẹ lọwọ lati fi sami bi Jesu se gun kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ wọ Jerúsálẹ́mù saaju ki wọn o to kan mọ agbelebu.Paroparo ni awọn ojupopo dá lọdun yìí - to si ṣe e ṣe ki wọn o tun ribẹ ni ọjọ Ajinde lopin ọsẹ yii.
"Sugbọn mo se alabapade awọn obinrin mẹta ati ọkunrin kan, wọn n bọ lati ijọsin ti wọn lọ ọ ṣe nile ẹnikan.Nigba ti mo beere idi ti wọn ko fi tẹle ofin pe ki olukuluku gba adura nile rẹ, ọkan lara wọn dahun pe ""Bibeli gan an sọ pe nibi ti eniyan meji tabi mẹta ba pe jọ si, oun wa pẹlu wọn. Bibeli ko sọ pe ẹnikan."""
Mo tun gbera, o di ijọ Mountain of Fire and Miracles Ministry, MFM to wa ni ipinlẹ Ogun.
Gbajugbaja ni ijọ yii jẹ ninu ka gba adura to ni ina ninu .
"Awọn aṣọbode sọ fun mi pe ijọsin ko waye.Mo ba beere pe ṣe ati isin ori ayelujara?Ọkan lara wọn ba tun dahun pe, ""bẹẹni o, isin ko waye lori ayelujara naa"".Bawo wa a ni awọn eniyan ṣe wa n di odi igbagbọ mú? Mo tun beere bẹ ẹ.Lo ba ki ọwọ bọ apo , o si mu iwe pelebe kan jade pe ""nkan ti wọn yoo maa ka niyi ti ofin konile o gbele yoo fi kasẹ nilẹ - ko to o kuro lọdọ mi lati fi 'isan ti geeti gbau.Iwe to fun mi jẹ alawẹ ọgọ́ta, ti wọn si pe akọle rẹ ni Ipagọ adura fun ọgbọn ọjọ.Ṣugbọn ko ni i ya mi l'ẹnu ti awọn ọmọ ijọ naa kan ba pari rẹ laarin ọjọ mẹrinla ti igbele yoo fi wa."
Nigeria: Afunrasí ẹ̀sùn jìbìtì ló ni iléeṣẹ́ tó ń ṣe ìwé àṣẹ wọléwọ̀de ní Nàìjíríà
Iwadii ajumọṣe laarin BBC ati iwe iroyin Premium Times ti fihan pe ẹni to ni ileeṣẹ ti ijọba apapọ lorilẹede Naijiria gbe kalẹ si idi iṣakoso titẹ iwe aṣẹ irinna wọle sorilẹede Naijira lati orilẹede gbogbo lagbaye n jẹ ẹjọ lori ẹsun ikowojẹ ati gbigbọna ẹburu ko owo lọ soke okun.
Ko si ẹri pe ileeṣẹ to n mojuto titẹ iwe aṣẹ iwọle sorilẹede Naijiria naa ni ẹsun iwa ibajẹ kankan tabi boya ẹsun ti wọn fi kan ẹni to nii ni ohunkohun lati ṣe pẹlu iṣẹ iwe aṣẹ irinna ti wọn gbe le wọn lọwọ.
Ajọ to n gbogun ti iwa ijẹkujẹ lorilẹede Naijiria, EFCC gbe Mahmood Ahmadu ati ileeṣẹ rẹ tẹlẹ, Drexel Tech lọ si ile ẹjọ lori ẹsun gbigbọna ẹburu ko owo lọ soke okun.
Ninu awọn mẹta miran to n baa jẹjọ  la ti ri minisita fọrọ abẹle tẹlẹ, Abba Moro ti wọn js n jẹjọ liluni ni jibiti ati titẹ ofin kọngila ọja rira fun ijọba loju mọlẹ.
Gbogbo awọn ti wọn n foju ba ile ẹjọ lori ọrọ naa titi kan Ọgbẹni Moro ati Ahmadu ni wọn sọ fun ile ẹjọ pe awọn ko jẹbi ẹsun naa.
Eeyan iyi ni Ọgbẹni Ahmadu lorilẹede Naijiria, koda ijọba fi ọkan lara awọn ami ẹyẹ to ga ju nilẹ naa daa lọla lasiko iṣejọba aarẹ Goodluck Jonathan lọdun 2014.
Awọn agbejọro rẹ sọ pe ko si igba kankan ti ajọ EFCC tabi awọn alasẹ miran ni Naijiria tabi ibomiran sọ pe awọn n wa a.
Awọn eniyan tẹ ara wọn pa ni Papa isere
Ṣugbọn iwe ti ajọ EFCC fi pe e l'ẹjọ fi ẹsun kan Ọgbẹni Ahmadu, ati awọn miran pe, wọn seto igbani sisẹ to yọri si iku awọn ọmọ Naijiria.
Ileesẹ Ọgbẹni Ahmadu nigba kan, Drexel Tech, ni wọn gbe isẹ fun ni ọdun 2013, lati seto ilana igbani sisẹ fun ẹgbẹrun mẹrin eniyan, fun awọn ipo to ṣófo nileesẹ ajọ to n risi iwọle-wode ni Naijiria.
Oríṣun àwòrán, AFP
Ṣugbọn ajọ naa pada sọ pe ko si eto igbani sisẹ kankan.
Lapapọ, ẹgbẹrun lọna ọrinlelẹgbẹta din mẹrin ati ọrinlelẹgbẹta din maarun (676,675) awọn ọmọ Naijiria lo forúkọ silẹ fun eto igbani sisẹ naa.
Ẹni kọọkan wọn si san ẹgbẹrun kan Naira lati fi orukọ silẹ.
Nigba ti wọn da ọjọ idanwo, ogunlọgọ eniyan lo kú lasiko ti wọn tẹ ara a wọn pa nitori ọpọ eero to wa ni papa isere ilu Abuja, nibi ti idanwo naa ti ileesẹ ìjọba fun ọrọ abẹle seto.
Eto igbani sisẹ naa ya mi l'ẹnu, nitori mi o mọ nipa rẹ, ni ohun ti Ọga Agba ajọ Immigration nigba naa, David Paradang, pada sọ fun ile ẹjọ giga ti jọba àpapọ̀ nilu Abuja.
'O fara pamọ nilẹ Yuroopu'
Ajọ EFCC ti sọ pe Ọgbẹni Ahmadu, iwe ìpéjọ salaye pe o ti ṣa lọ, ati awọn ti wọn jọ fi ẹsun kan, pa ẹgbẹrun lọna ọrinlelẹgbẹta din mẹta milionu (677m) Naira lara eto igbani sisẹ naa.
Iwe ìpéjọ naa pada sọ pe Ọgbẹni Ahmadu ati ileesẹ Drexel Tech Nigeria Ltd, ná lara owo naa lati ra dukia ni ilu Abuja. Ti wọn si tun ṣẹ ọgọrun milionu Naira sì Dọla, fun lilo Ọgbẹni Ahmadu ati ileesẹ naa.
Nigba ti awọn olujẹjo yooku, to fi mọ Ọgbẹni Moro, yọnda ara wọn fun iwadii, ti wọn si ti n jẹ jọ bayii, ajọ EFCC sọ pe Ọgbẹni Ahmadu ko yọju lati sọrọ l'ori ipa to ko ninu eto igbani sisẹ naa.
"Lọdun 2016, agbenusọ ajọ EFCC nigba naa, Wilson Uwajaren, sọ fun iwe iroyin The Nation pe: ""O seese ki a kọwe pe ọlọpaa"
ilẹ okeere ati awọn ajọ miran lati tọ pinpin Mahmood Ahmadu. O ni ileesẹ nigba kan nilẹ Gẹẹsi, ti ko si si ibi to le sapamọ si nitori awọn akọsilẹ nipa rẹ lori ayarabiasa.
"A ti fi orukọ rẹ silẹ gẹgẹ bii ẹni ti a n wa."""
Ni ọsẹ to kọja, agbenusọ ajọ EFCC lọwọ-lọwọ, Tony Orilade, sọ fun BBC pe ẹjọ si wa nilẹ fun Ọgbẹni Ahmadu lati jẹ.
"Iwe ìpéjọ sọ pe o ti ṣa lọ. Bakan naa ni ajọ EFCC si n sọ pe : owo to wọle lati ara igbani sisẹ naa ko ba ofin mú...
 Ajọ EFCC mọ pe ilẹ Yuroopu lo fi ara pamọ si. A ko i ti i ri lati igba ti a ti pe ẹjọ. """
Ileesẹ Ọgbẹni Ahmadu to maa n ṣe eto iwe irinna, Online Integrated Solutions (IOS), sọ loju opo ayelujara rẹ pe oun ṣe asoju ijọba orile-ede Naijiria ni ilu nla mẹẹdọgbọn jakejado agbaye ni Nigeria, China, Lebanon, UAE,
Malaysia, Italy, Netherlands, South Africa, USA, France, Germany, UK, India, ati Canada.
"Ileesẹ naa maa n sapejuwe ara rẹ gẹgẹ bi ""akọṣẹmọṣẹ ninu ka bani seto iwe irinna ati pasipọọti ilẹ okeere ni Naijiria"", pẹlu ajọsepọ awọn ileesẹ aṣoju orilẹ-ede l'agbaye, lati seto irinna silẹ okeere lai mu inira dani rara."
Ọpọlọpọ miliọnu Dọla si ni ileesẹ naa n pa lọdọdun.
Ileesẹ BBC gbiyanju ni ọpọlọpọ igba lati ba ileesẹ ijọba Naijiria to wa fun ọrọ abẹle, ati ileesẹ aṣoju Naijiria nilu London sọrọ, wọn ko fi esi kankan ránsẹ.
Bakan naa ni BBC kan si ileesẹ ilẹ ọrọ abẹle ati eyi to wa fun ọrọ ilẹ okeere nilẹ Gẹẹsi, awọn naa ko setan lati sọ ohunkohun l'ori ọrọ naa .
"Ileesẹ ilẹ Gẹẹsi to wa fun ọrọ okowo, amusagbara ati dida ileesẹ silẹ, sọ pe ""ọmọ orilẹ-ede miran ti wọn fi ẹsun kan ni ilẹ okeere si lanfaani lati da ileesẹ silẹ nilẹ Gẹẹsi, ni wọn igba ti ko ba ti i si iwe lati fi ofin gbe e."
Alaafin of Oyo: Olori Anu dúpẹ́ lọ́wọ́ kábíyèsí Ọba Adeyemi fún ipa ribiribi to kó láyé òun
Oríṣun àwòrán, Olori Anu/ Instagram
Olorì Anu Adeyemi ń ṣe ọjọ ìbí, ẹgbẹ́ ǹkan tò sọ sí Kábíyésì
Ọkan nínú olori lááfìn ọba Oyo, Ọba Lamidi  Olayiwole Atanda Adeyemi III Iku baba yeye, olori Anu.
Nínú ọrọ rẹ  ó gboríyìn fún aláàfin gẹ́gẹ́ bi abẹ ẹsẹ eni ti òun ti n kẹ́kọ̀ọ́, ẹni tó kami lati maa ní afojúsùn
"O ní kábíyèsí ló kọòun pé ẹni ti kò ba ni ìwòye ni wọ́n n pè ń pè ni aláìniwòye ọjọ́ ìwáju '' Kábíyèsí ni ẹni náà dàbí ọkọ ojú omí ti kò sí atukọ níbẹ̀"""
Oríṣun àwòrán, Anu Adeyemi/Instagram
Olorì Anu Adeyemi ń ṣe ọjọ ìbí, ẹgbẹ́ ǹkan tò sọ sí Kábíyésì
"Olorì ní ọ̀na sí aṣeyọrí kò rọgbọ rárá, sùgbọ́n ìpinnu ọkan àti àforítì gangan ni èròjà fún àṣeyọrí"""
Baba kí ẹ pẹ́ lórí itẹ àwọn babanla yín, Ọdún tuntun yìí a sàn wá si ohun rere àti igbé aye ọtun ti yóò tì mi sí ibi gíga.
Ṣé olorì ṣì ni Badirat Ọla láàfin ikú bàbá yèyé?
Alaafin of Oyo: Olori Badirat ti fèsì fún ẹ̀yin tó fẹ́ mọ bóyá ó sì jẹ́ olorì Aláàfin àbí bẹ́ẹ̀kọ́  kọ́
Oríṣun àwòrán, Alaafin of oyo
Yoruba ni lowe lowe la n lu ilu agidigbo, ọlọgbọn lo n jo, ọmọran si nii mọ.
Bẹẹ ni ọrọ ri ni aafin Oyo nigba ti ọkan lara awọn olori Alaafin tilu Oyo, ayaba Badirat Olaitan Adeyemi da awọn eeyan to n sọrọ nipa rẹ lohun lori ayelujara.
Bẹẹ ba gbagbe, laipẹ yii ni iroyin kan tan kalẹ pe olori naa ni ajọṣepọ ikọkọ pẹlu gbajumọ akọrin Fuji nni, Wasiu Ayinde Kwam I, bi o tilẹ jẹ pe awọn mejeeji ti ṣẹ lori ahesọ ọrọ naa.
Ohun ti gbajugbaja olorin Fuji, K1 si sọ̀ nigba naa ni pe, 'ko si idi fun mi lati ni ajọ̀ṣepọ̀ kankan pẹlu awọn ayaba laafin. koda mi o tiẹ gbọdọ roo lọkan depo ki n ṣe nnkan to jọ'
Amọ lati igba ti iṣẹlẹ ọhun ti waye ni awọn eeyan ti n lakaka boya lootọ ni olori Badirat Ola si wa ninu aafin Oyo abi bẹẹ kọ.
Nigba to wa n fi okodoro ọrọ mulẹ pe ayaba si ni oun laafin Oyo, olori Badirat bọ soju opo Instagram rẹ, @queenola2, to si ṣe afihan aworan oun ati ọkọ rẹ, Alaafin papọ.
Sekinat Quadri ọmọ ọdun meje ajẹsẹ to fẹ dabi Anthony Joshua
Ninu aworan naa la ti ri Badirat ati ọba alaye naa, ti wọn wọn aṣọ oke kan naa lori ijokoo, ti wọn si n tẹ sọrọ, ori awọn mejeeji lo fẹẹ sun mọ ara wọn pẹki pẹki.
"Ohun ti Badirat si kọ si abẹ aworan naa ni pe Alaafin n beere pe "" Ṣe o ko ni dẹkun lati maa rẹwa tabi dun wo ni?"
Aworan yii lasan si ti sọ ohun ti awọn araalu fẹ mọ, eyi to n ṣọ pe ọba alaye naa si nifẹ oun bii oju, to si n gbadun pe oun rẹwa pupọ.
Oríṣun àwòrán, Facebook/Alaafin
Awọn onimọ kan ni wọn paṣamọ pe eeyan ti were ba lu iya rẹ pa, bo ba ri mọkaliiki ko ni duro.
Eyi lo ṣebi ẹni difa fun awọn eeyan agbegbe Kosobo ni ilu Ọyọ alaafin ti wọn ni wọn ke gbajare tọ iku baba yeye, Alaafin Lamidi Ọlayiwọla Adeyẹmi kẹta lori ilẹ kan ti wọn ti pati eleyi ti wọn ni o ti di igbo nla saarin ilu ti wọn si ni o ti di ibuba fawọn oniṣẹ ibi gbogbo.
Bi ẹ ko ba si ni gbagbe iṣẹlẹ kan to ṣẹ ni agbegbe Soka ni ilu Ibadan lọdun diẹ sẹyin nibi ti wọn ni awọn agbenipapawo fi ṣe ibuba ti wọn ti n pa awọn eeyan ti wọn si n ṣe karakata ẹya ara eniyan.
Ilẹ naa ti iwọn rẹ to ọgbọn sare ni wọn sọ pe Alaafin Lamidi Adeyẹmi fun eekan oludaleeṣẹsilẹ kan lati fi kọ ileewe girama ti wọn pe oruks rẹ ni Abiọdun Atiba Grammar School ki wọn lee lo iyoku rẹ fun idagbasoke lọjọ iwaju.
Oríṣun àwòrán, oyoinsight.com
Ilẹ apati yii ni wọn lo ti wa di ẹrujẹjẹ to lee pagidina abo awọn olugbe agbegbe naa ti wọn n ni awọn iwa ọdaran bii ifipabanilopọ, idigunjale ati ile fifọ lo n waye lati ibẹ wa.
Ariwo gbajare yii ni wọn ni o de eti Alaafin ti iku baba yeye fi paṣẹ ki wọn wa nnkan ṣe si ilẹ naa.
Damilọla Ajayi: Ọ̀dá owó ló ṣún mi dé ìdí lílo ìyarun bíi fèrè
Aṣẹ alaafin lo ṣokunfa kiko awọn katakata nlanla ls si ilẹ naa lati fa awọn igbo naa kuro.
Pupọ awọn olugbe agbegbe naa ni wọn si ti n kan saara si Alaafin Adeyẹmi fun igbesẹ naa eyi ti wọn ni yoo mu ki ọkan awọn balẹ lọjọyipo ninu ile awọn.
Oríṣun àwòrán, Alaafin
Kii ṣe iroyin tuntun mọ pe Alaafin tilu Oyo, ọba Lamidi Olayiwola Adeyemi Kẹta ni ọpọ olori ni aafin, ti ọjọ ori wọn kere jọjọ si ti baba.
Koda, lọwọ lọwọ, o to awọn ẹlẹyinju ẹgẹ, apọnbeporẹ ati orekelẹwa obinrin bii marun-un ti wọn wa ni aafin ọba alaye naa, ti wọn n ṣe abiyamọ, yatọ si awọn olori agba to wa ni aafin tẹlẹ.
Koda, lara awọn ọdọmọde ayaba naa la ti ri awọn bi ibeji, ibẹta fun ọba Adeyemi, ti ọjọ ori rẹ ti le ni ọgọrin ọdun.
Lara orukọ awọn awẹlẹwa ayaba naa ni Olori Memunat Ọmọwumi àti olori Badirat Olaitan Ajoke,
Eyi ni awọn ohun mẹta ti a mọ nipa Iku Baba yeye atawọn olori rẹ laafin
Ni ọdun diẹ sẹyin ti Kabiyesi alaafin Ọys n dahun ibeere kan lori ọgbọn agba ti baba n lo lati kọnu ifẹ sawọn obinrin, esi ti Baba fọ lọjọ naa lọhun ni pe awọn ko fi igba kọọkan kọ ẹnu si obinrin kankan rii.
Gẹgẹbii itan ti Baba sọ lọjọ naa, wọn ni lati ori Olori agba laafin titi dori awsn olori yooku, awọn ko kọ ẹnu si obinrin kọkan ri.
Oríṣun àwòrán, Alaafin
Bawo ni baba ṣe wa n ṣe e. Ọgbọn wo ni baba n da si kini ọhun?
Ninu ifọrọwerọ kan ti Kabiyesi Alaafin ṣe pẹlu iwe iroyin abẹle kan ni ọdun diẹ sẹyin, Ọba Layiwọla ṣalaye pe 'Emi kọ ni mo dẹnu ifẹ kọ eyikeyi ninu awọn olori mi.
Nigba to n dahun ibeere naa lati ọdọ awọn akọroyin, Iku Baba Yeye ni oun ko figba kankan kọ ẹnu si awọn ọdọ olori ọhun pe oun fẹ fi wọn ṣe aya.
"Ọba Adeyemi ni ""  Ń ko fi igba kankan kọnu ifẹ sawọn ayaba mi ri, ó wu wọn ni wọn pinnu pe awọn yoo duro ti mi tori emi ni mo n ran wọn lọ sile iwe."""
Oríṣun àwòrán, olori memunat adeyemi
Pupọ ninu awọn olori laafin Ọba Lamidi Ọlayiwọla Adeyẹmi kẹta, lo jẹ wi pe alaafin funrarẹ lo ran wọn lọ si fasiti.
Eyi kii ṣe ohun to bo rara. Koda Olori Memuna Adeyẹmi funrarẹ sọ eyi gẹgẹ bi ara ọrọ imoore to kọ ṣọwọ si alaafin loju opo Instagram rẹ. Eyi to ni iwe ẹri HND ninu wọn, kabiyesi ni oun ṣi tun ran an pada lọ sileewe giga fasiti.
Oríṣun àwòrán, Alaafin
Ọba alaye naa fikun pe, lẹyin ti wọn pari ẹkọ fasiti wọn, oun ni ki wọn kuro amọ wọn ni awọn yoo duro ti oun bii ayaba
Oríṣun àwòrán, Alaafin
"Nigba to n dahun ibeere naa lati ọdọ awọn akọroyin ni ọdun diẹ sẹyin, Iku Baba Yeye ni ""Emi kii ṣẹ obinrin tabi yan-an lodi, igbeyawo si jẹ ohun to yẹ ka daabo bo, ẹni kọọkan si lo ni ojuṣe lati ṣe ninu igbeyawo, ọkọọkan awọn ayaba si lo ni ile ti wọn n gbe ni ọtọọtọ."""
"Alaafin tun salaye pe ""Ọlọrun lo fun mi ni abuda ati oore ọfẹ lati ko awọn obinrin jọ, paapaa awọn arẹwa obinrin, emi kii si sọ ọrọ tabi ajọṣepọ emi ati olori kan fun omiran, mo maa n fi ọrọ gbogbo ṣe mẹnumọ laarin ọkọọkan wọn ni."""
Ọba Adeyemi tẹ siwaju pe, oun ti kẹkọọ pe oun gbọdọ ko ipa manigbagbe rere ninu aye awọn eeyan, ki oun si jẹ ki ero wọn nipa òun nigba akọkọ jẹ ero rere.
Oríṣun àwòrán, olori memunat adeyemi
Lẹnu ọjọ mẹta yii oniruuru iroyin lo ti jade lati aafin Kabiyesi Alaafin ti ilu Ọyọ eyi to ti mu ọpọ eti gbọn belebele, ṣugbọn lọtẹ yii iroyin tuntun lo tun ṣẹyọ nibẹ.
Ọkan lara awọn olori kabiyesi iku baba yeye, Adeyẹmi, iyẹn olori Memunat ti fohun ranṣẹ si kabiyesi Ọba Lamidi Adeyẹmi kẹta to si n kii ni mẹsan mẹwaa pe lootọ oun ko pe ṣugbọn Alaafin duro ti oun.
O ni lootọ igbeyawo awọn kii ṣe eyi to pe ni gbogbo ọna ṣugbọn oun ati Ọba Lamidi Adeyẹmi ti fi iṣọkan la awọn ipenija gbogbo to n jẹyọ nibẹ ja.
Bi  ko ba ni gbagbe, laipẹ yii ni iroyin jẹyọ pe ọkan lara awọn olori laafin Kabiyesi Alaafin ti ko jade laafin eleyi ti aafin iku baba yeye ati olori naa ti sẹ jalẹ pe irọ lasan ni iroyin naa.
Amọṣa lọtẹ, olori Mẹmunat Adeyẹmi, to ti bi ọmọ mẹta fun Kabiyesi ṣalaye ninu ọrọ iwuri to kọ soju opo ikanni Instagram rẹ pe eekan sọrọsọrọ, olukọ ati awokọṣe rere to mu  ayipada rere ba igbe aye oun ni kabiyesi Alaafin.
"Ọkọ mi, Alayeluwa Ọba Lamidi Ọlayiwọla Atanda Adeyẹmi kẹta, IKU BABA YEYE. ALAAFIN ILU ỌYỌ. JP CFR LLD SAP
Ọkọ mi, Alaafin Oyo lo ṣe agbatẹru ẹkọ mi nile iwe, to si n tọ mi sọna lati koju ipenija aye ati ile aye laifọtape."","
"mo si n dupẹ fun itọni ati isinileti wọn, ade yoo pẹ lori, bata yoo si pẹ lẹsẹ."""
Olorì Memunat Omowunmi Adeyemi, ṣe sadankata si ọkọ rẹ, Ọba Lamidi Olayiwola Adeyemi Kẹta, pe oun ni ọkọ to dara julọ ni agbaye.
Olori Memunat, ẹni to gbosuba fun Alaafin lasiko ayajọ ọjọ ibi rẹ, loju opo Instagram rẹ ni oun n dupẹ lọwọ Ọlọrun to ṣe oun ni oloriire julọ lagbaye nitori bo ṣe fi ọkọ to dantọ da oun lọla.
Olori Memunat wa ṣe apejuwe Alaafin bii ẹni to jẹ awokọṣe rere, olutọnisọna, ọmọwe ati ọlọrọ apọnle.
"Olori fikun un pe ""Mo tun dupẹ lọwọ ọkọ mi fun ipa to ko lati jẹ ki n bi awọn ọmọ daradara ti Ọlọrun fun mi, mo mọ pe n ko pe, sugbọn wọn duro ti mi digbi lasiko ipenija"""
Olori Alaafin tun tọkasi pe loootọ ni igbeyawo oun ati ọba naa kii ṣe eyi to pe julọ, amọ awọn tiraka lati jẹ ko jẹ igbeyawo alayọ, ọkọ oun si ni nkan to dara julọ, ti yoo sẹlẹ si oun, ti oun si n reti lati lo ọpọ ọdun laye pẹlu rẹ.
Oni ni ọjọ ibi mi, mo si gbadura fun alaafia, ki n bori gbogbo ipenija aye pẹlu irọrun, ki ayọ ati inu didun si jẹ temi.
Kini Yoru[bá ń pe Necklace?
Coronavirus cases in Nigeria: Láì náání awuyewuye tó ń lọ láàfin rẹ̀, Aláàfin dẹ́rìn ín pẹ̀ẹ̀kẹ́ àwọn èèyàn ìlú Ọ̀yọ́
Alaafin pin ounjẹ loriṣiriṣi fun awọn eeyan rẹ.
Oríṣun àwòrán, Alaafi ObaAdeyemi III
Pẹlu bi iroyin nipa ajọṣepọ ohun ati ọkan lara awọn olori rẹ ṣe n ja ranyinranyin lori ayelujara bayii, Kabiyesi iku baba yeye, Alaafin ti ilu Ọyọ ti pin awọn ounjẹ fun idẹrun awọn eeyan ilu Ọyọ lasiko ajakalẹ arun Coronavirus yii.
Alaafin funrarẹ farahan pẹlu ibomu nibi ayẹyẹ naa toun tawọn olori rẹ.
Lara awọn ohun ti wọn pin faraalu ni irẹsi, gaari atawọn ohun jijẹ miran.
Oríṣun àwòrán, Alaafi ObaAdeyemi III
Ṣaaju eyi, awọn ọbalaye bii Ọọni, Oluwo ati Olugbo ni wọn ti gbe igbesẹ lori igbayegbadun awọn eeyan wọn lasiko Coronavirus yii.
Oríṣun àwòrán, Alaafi ObaAdeyemi III
Oríṣun àwòrán, others
Ọba Fuji, Wasiu Ayinde Marshall, tí ọ̀pọ̀ èèyàn mọ si Kwam 1, tí sọ̀rọ̀ lórí ẹ̀sùn tí àwọn èèyàn kan fi kàn-án pé, ó ń ní ajọṣepọ pẹ̀lú ọkàn lára àwọn olórí Aláàfin tilu Ọ̀yọ́.
Kwam 1, lásìkò to ń takurọsọ lójú òpó Instagram pẹ̀lú agba ọjẹ akọroyin kan, Dele Momodu, ṣàlàyé pé, irọ lásán ni wọn pa mọ òun.Wasiu Ayinde ni, ìkórira pé òun jẹ Mayegun ilẹ̀ Yorùbá lo mu ki wọn pa irọ mọ òun, ó ní lérò àwọn èèyàn náà, oyè ọhun kò tó sí òun.
"Kwam 1 sọ síwájú pé ""Nígbà tí wọ́n ko ṣepe fún mi? Èèyàn kan tó jókòó sibi kan ló kan gbé irọ ńlá yìí kalẹ nítorí Ìkórira, kò leè ṣẹlẹ̀ láéláé."""
"Gbogbo àwọn olórí bàbá Aláàfin ni n kò ní àǹfààní láti pàdé wọn tẹ́lẹ̀ ayafi ìgbà tí mo jẹ oyè Mayegun ilẹ̀ Yorùbá.
Ọjọ́ yìí ni ni mo tó fojú rinju pẹ̀lú àwọn olorì, nígbà míràn tí mo tún rí wọn, wọn máa ń wà pẹ̀lú Aláàfin,"
Oríṣun àwòrán, Wasiu Ayinde
"Ìkórira pé mo jẹ Mayegun lo fa wàhálà àti ahesọ ọrọ yìí, tí mo si tún gbọ laipẹ yìí pé, àwọn kan ni òye náà kò tọ́ si mi""."
Kí ni Yorùbá ń pe ọmọ tí wọ́n bí lẹ́yìn Àlàbá?
Bẹ́ẹ̀ bá gbàgbé, laipẹ yìí ni ìròyìn gbalẹ kan pé àwọn ènìyàn kan fi esun kan Kwam 1 pé ó ń fẹ́ ọkàn lára àwọn olorì Aláàfin, Ayaba Badira.Nigba tó ń sọ̀rọ̀ lórí ajọṣepọ rẹ pẹlu olóògbé Sikiru Ayinde Barrister àti Oloye Bola Tinubu lórí eto ohun.
Oríṣun àwòrán, Wasiu Ayinde/instagram
Wasiu Ayinde ní àwọn èèyàn méjèèjì náà lo ṣe àwárí òun, tí òun fi di òhun ti oun da lónìí.
"Ẹ̀gbọ́n àdúgbò ni Asiwaju Tinubu jẹ si mi.
Mo sì tún máa ń tẹle mama mi lọ sí ọdọ mama wọn ní Mọsalasi Jimoh.
Tí àwọn ìyá wá méjèèjì bá sì ń sọ̀rọ̀, Tinubu yóò rán mi láti lọ ra èédú tí yóò fi lọ aṣọ.Kwam 1 ni lẹ́yìn ìgbà tí òun bẹ̀rẹ̀ orin kíkọ, tí òun lọ kọrin ni ilẹ̀ Gẹ̀ẹ́sì, ní Asiwaju tún ṣe àwárí òun, tí òun si dara pọ mọ ijija-gbara kan to ń ṣe nígbà náà."
Kí ló ń ṣẹlẹ̀ láàfin Ọ̀yọ́?
Ṣé lóòtọ́ ni Aláàfin lé Olorì rẹ̀ tàbí àhesọ ọ̀rọ̀?
Ọpọ ọrọ lawọn eeyan ti n sọ lori ayelujara, ṣugbọn ewo lootọ, ewo ni irọ nibẹ?
Oríṣun àwòrán, Queenola2
Ni ẹnu lọwọlọwọ yii ni iroyin kan jade si igboro aye pe nnkan n ṣẹlẹ laafin iku baba yeye, Alaafin ti ilu Ọyọ, Ọba  Lamidi Adeyẹmi III lode Ọyọ.<Story>
Awọn iroyin to suyọ lori ayelujara n sọ pe Iku baba yeye ti da ẹru ọkan lara awọn olori rẹ, Badirat Ajọkẹ, sita.
Ki ree? Ka maa ri o! Ni ohun ti ọpọlọpọ n sọ lori ọrọ naa nigba ti wọn gbọ.
Olori Badirat Adeyẹmi kii ṣe ajeji si ori itakun ayelujara nitori naa nṣe ni iroyin ọhun lalẹ gaaraga.
Iroyin to n lọ kaakiri ni pe Kabiyesi, iku baba yey ti le olori to kere julọ laafin rẹ, iyẹn Olori Badirat Ajọkẹ kuro laafin lori ẹsun pe o n ṣe aṣemaṣe pẹlu gbajugbaja olorin Fuji to tun jẹ Mayegun ilẹ Yoruba, Wasiu Ayinde Marshal, ti ọpọlọpọ mọ si KWAM 1, K1 De Ultimate.
Oríṣun àwòrán, others
Ko si ẹni to lee sọ ni pato ododo ọr yii gan an.
Amọṣa nigba ti BBC News Yoruba gbe ọrọ kalẹ leti iya Olori Badirat Ajọkẹ Adeyẹmi, ohun ti iya sọ fun wa ni pe ko si ohun to jọ bẹẹ ati pe iroyin ahesọ ni awọn eeyan n gbe kiri.
Bakan naa nigba ti BBC News Yoruba gbe ọrọ naa tọ awọn to yẹ ko mọ nipa rẹ laafin, eeyan kan laafin Kabiyesi Alaafin ilu Ọyọ to sun mọ kabiyesi Iku baba yeye ṣalaye pe ko si nnkan to jọ bẹẹ rara.
Koda o fi da BBC News Yoruba loju pe lọwọ yii, ko soun to jọ bi aawọ laarin kabiyesi ati olori rẹ tabi laarin kabiyesi ati Mayegun ileẹ Yoruba, iyẹn KWAM 1
Ninu atẹjade kan eleyii ti agbẹnusọ fun KWAM 1 , Ọgbẹni Kunle Rasheed fi sita lọjọbọ, irọ lasan ni iroyin naa eleyii ti awsn eeyan kan kan n gbe kiiri lati ba awọn eekan kan lorukọ jẹ.
Oríṣun àwòrán, Abiola Ajimobi
Nigba ti a fi koko ọrọ yii sita loju opo Facebook wa pe ẹsẹ wo ni ọkọ tabi aya le sẹ ara wọn to le ju agbere lọ, awọn kan lara wọn sọ pe ẹsẹ agbere yii naa ni kọ́kọ́rọ́ to ba eyin aja jẹ lọdọ ti wọn.Diẹ lara awọn idahun wọn niyii:Yetunde Olatile sọ pe ẹsẹ agbere lagbara pupọ debi pe o le tu igbeyawo ka. O gbagbọ pe obinrin to ba n yan aale le fa iku fun ọkọ rẹ.
Bakan naa ni Idowu Bukunmi ni ti ẹ sọ pe ọrọ owo ni. O sọ pe ti owo ba da ọkọ ati iyawo pọ nigba miran, ija le lagbara ju aale yiyan lọ.Fun Morufudeen Olabanjo, iwa ki ọkọ tabi iyawo gbá òbí ẹnikeji l'eti buru ju aale yiyan lọ.Eero ti Nikks Omotoso Bolarinwa yatọ gedegbe. Oun sọ pe iwa to buru ju ni ki ọkọ tabi iyawo gbiyanju lati fi ẹnikeji ṣe ogun owo.Ẹ le ka gbogbo idahun naa ni
Ọpọlọpọ lo gbagbọ pe ti ọkọ tabi iyawo wọn ba yan aale nikan lo le mu wọn binu tabi tu igbeyawo wọn ka, àmọ́ onimọ sọ pe awọn nkan miran tun buru ju u lọ.
Laipẹ yii ni iyawo gomina ipinlẹ Ọyọ nigba kan, Florence Ajimobi sọ ninu fidio kan pe ọpọ igba ni oun ti dari ji ọkọ oun, Abiola Ajimobi, fun ẹsẹ agbere.
O ni sugbọn, oun naa ti hu awọn iwa kan to buru ju agbere lọ.
Oríṣun àwòrán, Abiola ajimobi
O mẹnu ba kikọ ile lai sọ fun ọkọ rẹ.
Eyi lo mu ki a ba onímọ̀ nipa irinajo ifẹ laarin ọkunrin ati obinrin, pe kini awọn iwa tabi ẹsẹ to tun buru ju agbere lọ ninu igbeyawo tako igbagbọ ọpọlọpọ pe oun lo buru ju.
Oludamọran naa, Arabinrin Temiloluwa Morohunkeji, ti ajọ Temi Love Clinic, sọ pé ọrọ naa dabi ìlù gangan, nitori pe nkan ti Taye le gba mọ́ra, o ṣeé ṣe ki Kehinde o ma le gba a.
O sọ pe fun ẹlomiran, yiyan ale le ma dùn ún.
Awọn nkan miran to tọka si ni pe ki ọkùnrin mọ pe oun ko le ba obinrin ni ajọsepọ, sugbọn ti ko sọ fun iyawo rẹ ki wọn o to o segbeyawo, to jẹ pe inu igbeyawo ni asiri ti tu.
O miran tun ni ki obinrin o ma ni ile ọmọ tabi ko ma le bímọ, ki oun naa o ma sọ fun afẹfẹsọna rẹ saaju igbeyawo.
Fun awọn kan, iwa ipá ninu igbeyawo ni nkan ti wọn ro pe o buru ju. Ifọti ti tu igbeyawo ka ri.
Oríṣun àwòrán, Abiola ajimobi
"Nkan miran ti o tun mẹnuba ni ki ọkunrin ko ba ọmọ rẹ obìnrin ni ajọsepọ, tabi aburo ati ibatan iyawo rẹ ni ibalopọ. ""Iru eyi tun buru pupọ""."
"Ju gbogbo rẹ lọ, ko si nkan ti eeyan ko le foriji, sugbọn eyi ko tumọ si pe irinajo ifẹ naa yoo ri bo ṣe ri tẹlẹ.
Aale yiyan lagbara pupọ, o kan jẹ pe ọpọ ti tẹwọ gba a ni gẹgẹ bi agbelebu.
Obìnrin k'óbìnrin tó bá yan Abiola Ajimọbi l'álè, ajẹ kù mi ló ń jẹ-Florence Ajimọbi
Florence Ajimọbi to jẹ aya gomina ana ni ipinlẹ Ọyọ, Abiọla Ajimọbi ti ṣalaye pe igba meji ọtọọtọ loun ti ka ọkọ oun mọ ale yiyan.
Iyaafin Ajimọbi tu kẹkẹ ọrọ yii sita lasiko to fi n ba ọmọ rẹ obinrin sọrọ lori fidio kan to n ja ranyinranyin bayii lori ayelujara.
Gẹgẹ bi ọrọ ti Florence Ajimọbi sọ, ko si ohun meji ti ọkunrin n ri nidi ale yiyan ju ibalopọ lọ, bi wọn ba si ti ni ibalopọ naa tan, ọrs pari niyẹn ọkan wọn kii si pẹlu ẹni ti wọn n yan lale.
Oríṣun àwòrán, Abiola Ajimobi
Arabinrin Ajimọbi ni, Igba kan si meji ni mo ti ba ọkọ mi to n yan ale, yoo si tọrọ aforiji lọwọ mi, ni kete to ba si ti bẹ mi, o tan niyẹn mi o kii ro arokan lori rẹ tabi fi sọrọ sii mọ. Mi o ṣe bẹẹ ri Bisọla nitoripe mo mọ pe ko si ẹda kan ti kii ṣẹ Ọlọrun lọba alaforiji."
Oríṣun àwòrán, Abiola Ajimobi
Ọrẹ ni wa. Koda gẹgẹ bi iyawo, emi naa maa n ṣe aṣiṣe, lọpọ igba aṣiṣe bẹẹ gan yoo buru ju ki eeyan yan ale lọ.
Nigba ti wọn bii pe iru aṣiṣe wo lo ju ale yiyan lọ, aya gomina ana nipinlẹ Ọyọ Abiọla Ajimọbi naa fesi pe ọpọ awọn obinrin lo n da ile kọ lẹyin ọkọ wọn, eyi buru pupọ. Ki lo de ti waa fi ṣe iru nnkan bẹẹ lai sọ fun un? oniruru nnkan ni a n ṣe ti o buru. Kii ṣe ale yiyan.
Oríṣun àwòrán, Abiola Ajimobi
O wa fi kun un pe bi obinrin ba ka ọkọ rẹ mọ ale yiyan, ko daarijii ko si gbagbe ni o.
O ṣalaye pe bi ọpọ ọkunrin ba nyan ale nitori ati ba obinrin bẹẹ lajọṣepọ ni kii ṣe nitori ifẹ ati pe ibalopọ laarin ọkunrin ati obinrin to ba fẹ sile a maa yatọ
O ni ajẹku ẹba ni obinrin to n ba ọkọ oun sun n jẹ nitori oun gangana lo ti jẹ ogidi ẹran ara rẹ tan.
Coronavirus lockdown: Bí àrùn Coronavirus ṣe dá gbogbo àgbáyé gúnlẹ̀ sójú kan náà nìyí
Aarun coronavirus ti kọlu eniyan to le ni miliọnu kan ni agbaye báyìí, sugbọn ipa to ni to ni kọja ọdọ awọn to ni i.
Bi awọn ijọba orilẹ-ede kaakiri agbaye ti ṣe idasilẹ awọn ilana tuntun lati koju rẹ.
Eyi lo mu ki a ṣe agbeyẹwo ipa to ti ni l'ara awọn eniyan, ati ayika wọn.
Ka ma parọ, orisirisi ọna ni wọn ti fi n koju coronavirus.
Ni Colombia, numba kaadi idanimọ eeyan ni yoo sọ ọjọ ti yoo anfaani lati jade; ni Serbia, wọn ti ya asiko ti o le mu aja rin nigboro sọtọ.
Ni Belarus, aarẹ wọn kọ lati tẹle imọran awọn eleto ilera, to si sọ pe ki awọn eniyan o maa mu ọti vodka ati iwẹ sauna lati daabo bo ara wọn.
Diẹ lara awọn ilana to wọpọ ni ofin ijọba l'ori ijina sira ẹni láwùjọ ni awọn agbegbe kan tabi jakejado orilẹ-ede.
Nigba ti aarun naa kọkọ bu jade ni China ni ipari ọdun 2019, sise ofin konile o gbele dabi aseju.
Sugbọn bi o ṣe n tan kaakiri agbaye, lo n nira lati koju rẹ.
Ọpọ orilẹ-ede lo ti gbe ilana alagbara lati koju rẹ.
Awọn orilẹ-ede ti ko din ni ọgọrun un lo ti kede konile o gbele nigba ti yoo fi di ipari oṣu Kẹta, ọdun 2020, eyi to kan ọpọlọpọ biliọnu eniyan.
O dabi ẹni pe awọn agbegbe kan to ṣẹṣẹ ni akọsilẹ aarun naa laipẹ yii ti n sawokọse awọn akẹgbẹ wọn ní Asia ati Europe.
Awọn ijọba nilẹ Africa naa dabi ẹni ti n jara mọ ọrọ naa.
China ti dẹ ọwọ l'ara awọn ilana rẹ, lẹyin to la asiko ọpọlọpọ iku ati ibujade aarun naa kọja.
Sugbọn igbe aye ko ti i pada bọ sipo.
Ọna si jin paapa fun awa to ku.
Nigba ti aarun naa kọkọ bu jade, ọpọ orilẹ-ede lo fi ofin de baalu lati China, tabi ki wọn o fi awọn to ba rinrinajo de lati orilẹ-ede ti aarun naa pọ si, si ìyà sọtọ.
Lẹyin ti ajọ eleto ilera l'agbaye, WHO kede pe ajakalẹ aarun ni coronavirus lọjọ kọkanla, osu Kẹta, awọn ilana orisirisi tun jẹyọ.
Ààrẹ Trump fi ofin de gbogbo irinajo ti ko ba ṣe koko lati ilẹ Yuroopu si America lọjọ kẹẹdogun, oṣu Kẹta.
Ọjọ kan lẹyin rẹ naa ni ajọ ilẹ Yuroopu naa ṣe bẹ ẹ.
Nigba ti yoo fi di ipari oṣu Kẹta, irinajo si awọn papakọ ọkọ ofurufu to tobi ju ti dinku.
Ni ọsẹ to gbẹyin oṣu Kẹta, irinajo ọkọ ofurufu dinku si ìdá mẹtalelọgọ́ta nitori pe awọn orilẹ-ede kan tun fi ofin de irinajo oju ofurufu.
Kiise lílọ bibọ lati lati ilu kan si òmíràn nikan ni o kan, irinajo laarin awọn ilu nla kaakiri agbaye ti dawọ duro.
Ori ayelujara lo ku ti awọn eniyan ti n gburo ara wọn bayii.
Bakan naa ni akọsilẹ fihan pe saaju ki ijọba to kede konile o gbele ni awọn eniyan ti din irinajo wọn ku.
Koda awọn eniyan ni awọn ilu bi Stockholm ni Sweden, Honk Kong, ati Singapore ti ijọba ko ti ṣe ofin ijina sira ẹni láwùjọ, awọn eniyan n din irinajo wọn ku.
Ṣugbọn olu ilu South Korea, Seoul, ko ti fofin d'ẹnu kọlẹ bi awọn ilu nilẹ Yuroopu.
Bo tilẹj ẹ pe ọpọlọpọ eniyan lo ni coronavirus nibẹ - ilana títọ pinpin awọn to ni nkan ṣe pẹlu ẹni to ba ni aarun naa ni wọn n lo.
Bakan naa ni nkan ṣe ri fun awọn to n rin lojupopo.
Lílọ bibọ eniyan lojupopo ti dinku pupọ ko to o di pe ijoba kede konile o gbele ni awọn ìlú nla kaakiri agbaye.
Aworan ìsàlẹ̀ yii se afiwe asiko ti yoo gba lati lọ lati ibi kan si omiran laarin ilu si igba ti ko si lílọ bibọ.
Igbele wọn ọgọ́ta tumọ si pe irinajo yoo gba ìdá ọgọ́ta ju ti oju ọna ba da paroparo.
Fun àpẹẹrẹ, irinajo to yẹ ko gba ọgbọn isẹju yoo di isẹju marunlelogoji.
Opin ọsẹ ni awọn ibi ti o ti wa silẹ julọ.
Awọn àpẹẹrẹ pe nkan ti n bọ sipo ti n farahan ni China.
Igbokegbodo ọkọ ti pada si ilaji bo se ri ni Beijing ati Shanghai lọdun 2019.
Ni Wuhan ti aarun coronavirus ti bẹrẹ, igbokegbodo ko ti i pada bọ sipo rara ti a ba fi we bọ ṣe ri lọdun to kọja.
Ọkan ninu anfaani ti konile o gbele mu wa ni pe o dabi ẹni pe ijamba si ayika ti dinku ni awọn ibi kan ni agbaye, paapa si ayipada oju ọjọ.
Ni UK, ati awọn ibomiran, akọsilẹ ẹ̀rọ satalaiti ko fihan boya adinku to ba lílọ bibọ lo mu adinku ba titu jade eefin, bo tilẹ jẹ pe awọn kan sọ oun ni.
Bi awọn orilẹ-ede ṣe d'ẹnu kọlẹ, ọpọ oṣiṣẹ ti gbiyanju lati tẹsiwaju pẹlu isẹ wọn lati ile.
Eyi tumọ si pe ìpè oni fidio ati atẹranṣẹ ori ayelujara ti di irin'ṣẹ pataki.
Iye atẹranṣẹ ti awọn eniyan ti fi ránṣẹ lori ayelujara ni New York, Paris, London ati Berlin ti lọ soke si ni ìlọ́po mẹta laarin ọsẹ diẹ.
Sugbọn kii ṣe gbogbo eniyan ni ilana iṣẹ tuntun ti mọ l'ara.
O tun wa a ni ṣe pẹlu ibi ti o ba wa - aaye si le wa lati ṣatunṣe.
Lagos Lockdown: Ìgbésẹ̀ ìjọba lórí Twitter tì mí lójú- Jimi Disu
Oríṣun àwòrán, OTHERS
Lagos Lockdown: Ìgbésẹ̀ ìjọba lórí twitter gbà mí lójú tì- Jimi Disu
Ọ̀pọ̀ àwọn ọmọ orílẹ̀-èdè Nàìjíríà nípìnlẹ̀ Eko tí bu ẹnu àtẹ́ lu ìjọba ìpínlẹ̀ Eko fún ìgbésẹ̀ rẹ̀ bí ó ṣe gbé sorí àtẹ̀jísẹ twitter pé kí àwọn ènìyàn dìbò bóyá kí ijọba kéde ìgbélé míràn tàbí kí wọ́n ma kéde.
Ìjọba ní lẹ́yìn ti àwọn dẹkùn ìgbélé fún ará ilú bí tan, o yáni lẹ́nu pé bi olúkúlùkù ṣe ń hùwà àìbìkítà si àwọn ǹkan ti ìjọba ni kí wọ́n ṣe tàbí kí wọ́n má ṣe kò dára tó, sùgbọ́n àwọ́n fẹ́ mọ ǹkan ti àrá ilú ń fẹ́ bí ọsl méji ìdẹ̀kùn igbẹ́le ṣe fẹ́ parí.
Kàkà kí àwọn ènìyàn sọ ǹkan ti wọ́n fẹ́ ki ìjọba ṣe ọ̀pọ̀lọpọ̀ l'órí twitter ló ni kìí ṣe ibi tí àwọn ènìyàn ti ọ̀rọ̀ náà kan wà ní ìjọba gbé ọ̀rọ̀ lọ àti pé o jọ bí ẹni pé ìjọba kò mọ ìbi ti ọ̀rọ̀ kù sí mọ́.
What causes coronavirus: Akeugbagold sọ àṣírí ohun ti àrùn coronavirus ń dá lárá f
Nínú ọ̀rọ̀ rẹ̀ Jimi Disu to jẹ ìlúmọ̀ọ́ká oníròyìn sàlàyé pé  ìjọba to ba mọ ǹkan tó ń ṣe kò ni fi irú ọ̀rọ̀ bàntàbanta bẹ́ẹ̀ si ọwọ́ àrá ilú, ó ní ọ̀rọ̀ tó níṣe pẹ̀lú ètò ọrọ̀ ajé àti iléra ará ilú kìí ṣe ǹkan àmú ṣeré.
Ó ní ìjọba ló ni ìpinu ti wọ́n fi n lọ ará ìlú, àti pé òun gẹ́gẹ́ bi ẹni kan ko fi ara mọ ìgbélé míràn nítori èyí ti wọ́n ṣe kẹyin kò so èso rere kankan.
Ìjọba kò là ṣe àyẹ̀wò ju ẹgbẹ̀rún márùn-rún lọ nínú iye mílílọ̀nù èèyàn to wà ní ìpínlẹ̀ Eko.
Disu ni ó yẹ kí ìjọba sàlàyé fún ará ilú pé àrùn yìí kìí ṣe ǹkan ti yóò lọ nísin yìí, kí wọ́n si maa tẹ̀lé ìlànà ìmọtótó tó yẹ.
O ní ǹkan ìtìjú ní láti rí irú ǹkan bẹ́ẹ̀ lórí Twitter.
Ẹ̀wẹ̀ nínú ọ̀rọ̀ tirẹ̀, kọmísọna ìròyìn ní ìpínlẹ̀ Eko Gbenga Omotsho ní ìgbésẹ̀ yìí kìí ṣé ǹkan tó burú tàbi ti etí kò gbọ́ rí.
Kọmísọ́na sàlàyé pé, gbogbo ọ̀nà ni ìjọba ìpínlẹ̀ Eko maa n gbà láti bá ará ilú sọ̀rọ̀, àwọn lọ́balọ́ba, àwọn asojú àgbègbè kọ̀ọ̀kàn ló wá ti ìjọba sì n bá wọ́n sọ̀rọ̀ tí wọ́n bá nílò láti fi ọ̀rọ̀ ránṣẹ́ si àwọn ti kò láàfáni láti wà lórí àwọn ojú òpó ìkànsíraẹni.
Omotosho ní ǹkan ti ìjọba ń ṣe yìí kàn jẹ́ ọ̀nà láti fí gbogbo ǹkan to n lọ tó ará ilú léti ni.
O ní àṣẹ̀yìnwá, àṣẹ̀yìn bọ̀ ìjọ̀ba náà ni yóò ṣe ǹkan ti yóò ṣàǹfàní fún gbogbo ènìyàn.
Wò ohun mẹ́ta tí a mọ̀ tí yóò mú ìjọba pàṣẹ kónílé-ó-gbélé lẹ́ẹ̀kejì ní ìpínlẹ̀ Èkó
Is there a lockdown extension in Lagos: Ìdí mẹ́ta tí ó fi ṣeéṣe kí ìjọba pàṣẹ kónílé-ó-gbélé lẹ́ẹ̀ejì ní ìpínlẹ̀ Èkó
Oríṣun àwòrán, Muhammadu Buhari
Lasiko ti a fi n ko iroyin yii jọ, ẹgbẹrun mẹrin o le mọkandinniirinwo eeyan lo ti ni arun COVID-19 lorilẹede Naijiria, ẹgbẹrun kan o le ẹgbẹrin ati marundinlaadọta ninu awọn wọnyii lo wa lati ipinlẹ Eko.
Lati ọjọ aje ọjọ kẹrin oṣu karun ọdun 2020 ni iye awsn eeyan to n ni arun yii ni ipinlẹ Eko ati lorilẹede Naijiria ti n gbẹnu soke.
Lootọ nigba ti ijọba apapọ atawọn ijọba ipinlẹ si ipinlẹ lorilẹede Naijiria kede didẹwọ lori eto igbele, oniruuru eto ni wọn gbe kalẹ lati rii pe lasiko ti wọn dẹwọ igbele naa ajakalẹ naa ko gbẹnu soke.
Amọṣa ko jọ pe eto naa mulẹ rara.
Lara ofin ti ijọba ipinlẹ ati apapọ gbe kalẹ ni pe ibomu facemask di ọranyan fun gbogbo eeyan to ba fẹ jade kuro ninu ile wọn.
Amọṣa, awọn alaṣẹ igbimọ apapọ lori gbigbogun ti arun coronavirus ti ke gbajare sita pe awọn eeyan ko tẹle ofin yii.
Ni ọjọ akọkọ ti wsn dẹkun yii, fọfọfọ lawọn ero kun awọn banki atawọn ile itaja gbogbo kaakiri ilu Abuja ati Eko. Koda ko si ẹnikẹni to tẹle ọrọ ijinna sira ẹni lawọn ibudo ọlọpọ ero naa.
Eyi ti gomina ipinlẹ Eko, Babajide Sanwo-Olu ni o n kọ oun lominu gidigidi.
Gomina Sanwo-Olu ṣalaye pe, o jẹ oun to ba oun ninu jẹ pe pẹlu ọpọ ilanilọyẹ, awọn ero ko dawọ kikun awọn banki atawọn ọja gbogbo lọpọ yanturu .
Lara awọn eto ti ijsba ipinlẹ Eko gbe kalẹ lori eto irinna ni pe awọn awakọ ero to ba ṣiṣẹ gbọdọ mu ibomu lọkunkundun ati pe ida ọgọta lero ti wọn gbọdọ maa gbe.
Ni bi ṣe n sọrọ yii gomina Sanwo-Olu ni ko si titẹle aṣẹ yii latọdọ ọlọkọ ero leyi to mu ki oun tilẹ paṣẹ fawọn agbofinro lati maa fi wọn jofin.
Oríṣun àwòrán, Sanwo-olu/ Twitter
Èrò àwọn èèyàn ṣọ̀tọ̀tọ̀ lẹ̀yìn tí ìjọba kéde pe ó ṣeṣe ki òfin kónílé-ó-gbélé mìí wàyé
"Awọn olùgbé ìpínlè Eko atawọn ọmọ Naijiria mìí ti bẹrẹ sí ń fi èròngbà wọn léde lẹyin ti ìjọba ìpínlẹ̀ náà ní o ṣeṣe ki òfin kónílé-ó-gbélé bẹrẹ lọtun tawọn èèyàn ba tẹsiwaju kikọ etí ikún sí alakalẹ ìjọba.Bi awọn kan n  ṣe n sọ pé kò yẹ kó rí bẹ, láwọn mìí ní bo ṣe yẹ kó rí gán niyẹn.Otunba Olúwaṣeun Solomon ni ""Mo gbagbọ pe ko tii yẹ kí wọn dẹ igbele nigba ti wọn ṣe bẹẹ, nitori awọn èèyàn kò ní tẹle ofin laisepe wọn kan an nípa fún wọn."""
"Ni ti @Ciefbucha, o ni ""Mo kọkọ ro pe ìjọba ni ìṣòro wa nilẹ yi ni, ṣugbọn o ti hàn sí gbàgede pe awa ara ilu gan ni ìṣòro ara wa nitori a ko le tẹle ofin ti wọn là kalẹ fún ànfàní ara wa."""
Ni ṣe ni Roys Akhimie bu ẹnu àtẹ lu gomina, tó sì sọ pé ìpèsè tó yẹ kí ìjọba ṣe fún àwọn èèyàn ìlú ló jẹ oun logun.
Orebanjo Temitope sọ pé ati joko sile kii ṣe ìṣòro, ṣugbọn àti jẹun ni wàhálà.
Èrò àwọn èèyàn ṣọ̀tọ̀tọ̀ lẹ̀yìn tí ìjọba kéde pe ó ṣeṣe ki òfin kónílé-ó-gbélé mìí wàyé
Èrò àwọn èèyàn ṣọ̀tọ̀tọ̀ lẹ̀yìn tí ìjọba kéde pe ó ṣeṣe ki òfin kónílé-ó-gbélé mìí wàyé
Wo àwọn èèkàn ìlú Kano tó kú láàrín ọjọ́ mẹ́rin sí ara wọn
Deaths in Kano Today: Kí ló pa àwọn èèkàn ìlú Kano mọ́kànlá wọ̀nyí láàrín ọjọ́ mẹ́rin
Oríṣun àwòrán, AYAGI'S PROFILE
Lati nnkan bi ọjọ diẹ sẹyin bayii, ọpọ eekan ọmọ ipinlẹ Kano lo ti ba ajakalẹ iku ọwọọwọ to n waye bayi ni ipinlẹ naa lọ.
Awọn ọjọgbọn fasiti, ọmọwe ileewe giga gbogbo, awọn onimọ ẹsin islam atawọn oṣiṣẹ ni wọn ti ba ajalu yii lọ.
Titi di asiko ti a fi n ko iroyin yii jọ, ko tii si ẹni lee sọ ni pato ohun gan to n ṣokunfa iku ọwọọwọ to n waye ni ipinlẹ Kano naa bi o tilẹ jẹ wi pe iku naa n ṣe kongẹ asiko ajakalẹ arun Coronavirus lorilẹede
Naijiria.
Ni ọjọ Abamẹta ati ọjọ Aiku, oniruuru iṣẹlẹ iku ojiji lo waye ni ipinlẹ naa ninu eyi ti awọn eekan ti a ka silẹ wọnyii pẹlu wa.
Ni ọjọ Satide, ọjọ karundinlọgbọn oṣu kẹrin ọdun 2020 ni Ọjọgbọn Ayagi, jade laye. Awọn ẹbi rẹ kede pe aisan ti wọn ko lee sọ bo ṣe jẹ lo gba ẹmi lẹnu rẹni ọdun 1940 ni wọn bii ni ilu Kano to si kẹkọ gba imọ ọjọgbọn ninu imọ eto ọrọ aje.
Oun ni Oludasilẹ ileewe Hassan Ibrahim Gwarzo ni ilu Kano. Ọpọlọpọ ileeṣẹ lo ti ṣiṣẹ, koda kan ileeṣẹ iroyin BBC world service.
Oríṣun àwòrán, dikko's family
Ọmọ ilu Kano ti a bi ni ọdun 1953 ni Ọjọgbọn Dikko.
Ni ọjọ Satide loun pẹlu jade laye lẹni ọdun mẹtadinlaadọrin.
Oun ni ẹni akọkọ ọmọ Ẹya Hausa ti yoo kawe gboye ọjọgbọn ninu imọ ijinlẹ nipa ẹya ara. O fi ọpọlọpọ igba ṣiṣẹ olukọ ni fasiti Bayero ni ilu Kano titi di ọjọ iku rẹ.
O fi igba kan jẹ aarẹ adari ẹka imọ iṣegun ni fasiti Maitama Sule ni ilu Kano ki o to jade laye.
Iyawo ati ọmọ meje pẹlu ọmọọmọ meje lo gbẹyin rẹ.
Ọjọgbọn Maikaba jade laye ni ọjọ Aiku, ọjọ kẹrindinlọgbọn oṣu kẹrin ọdun 2020 lẹyin ti aisan iba daa wolẹ fun ọjọ diẹ, gẹgẹ bi iroyin ti a gbọ ṣe sọ ṣugbọn ni o ni aisan itọ ṣuga tẹlẹ.
Ijọba ibilẹ Fagge ni Ọjọgbọn Maikaba ti ṣẹ. O lọ sileewe alakọbẹrẹ ati girama nilu Kano ki o to lọ kẹkọ gboye ijinlẹ ni iṣẹ iroyin ni fasiti Bayero ni ilu Kano.
Oríṣun àwòrán, Maikaba facebook
O kawe ni fasiti ilu ibadan naa ki o to dori kọ iṣẹ iṣẹ olukọ imọ iroyin ni fasiti Bayero.
Ọmọ mẹrindinlogun ati iyawo mẹrin ni Ọjọgbọn naa fi silẹ saye lọ.
Ọmọwe Sabo Kurawa naa jade laye ni ọjọ Satide, ọjọ kẹrindinlọgbọn lẹyin aisan ọjọ pipẹ gẹgẹ bi awọn mọlẹbi rẹ ṣe sọ.
Ni ọdun 1949 ni wọn bi Ọmọwe Kurawa si kawe titi to fi gboye imọ ijinlẹ ninu imọ iṣe ati ironu ẹda, iyẹn Sociology ati Psychology
Oríṣun àwòrán, kurawa family
Igba meji ọtọọtọ lo ti di ipo igbakeji giwa fasiti Bayero mu lẹyin to bẹrẹ iṣẹ ni fasiti naa lọdun 1978.
Iyawo rẹ Ọjọgbọn Dijeh Kurawa toun pẹlu jẹ olukọ ni ẹka imọ nipa iṣiro owo ni fasiti Bayero atawọn ọmọ mẹfa lo fi silẹ saye lọ.
Oríṣun àwòrán, family
Olukọni ni Ọmọwe Muhammadu Uba Adamu lẹka imọ itan oṣelu ni ileeks gbogboniṣe poly ni ilu Kano ki o to fẹyiti lọdun 1995.
Ọjọ Aje, ọjọ kẹtadinlọgbọn oṣu kẹrin ni iku muu lọ.
Awọn to sun mọọ ṣalaye pe ko fi igba kọọkan rin irinajo lẹnu lọwọlọwọ yii.
Ọga agba fasiti imọ ẹrọ Wudil Technical University to wa nipinlẹ Kano lo kede iku Ọmọwe Ghali Kabeerr Umar to wa lẹka ẹkọ imọ nipa aworan ile yiya.
Ko si alaye to kuna bi alara lori oloogbe naa.
O figba kan ri jẹ adajọ Agba ipinlẹ Kano. Onimọ nipa ẹsin Islam ni. Bi o tilẹ jẹ pe ko ni itan aarẹ kankan, awọn mọlẹbi rẹ sọ pe aisan iba lo paa.
Oríṣun àwòrán, Twitter
Ṣaaju iku rẹ, Abdullahi ni ọga agba ẹka ileefowopamọsi First Bank to wa ni ipinlẹ Kano.
Awọn kan n sọ ahesọ pe arun onigbameji ni awọn eeyan gbagbọ pe o ṣokunfa iku rẹ.
Awọn to sunmọ mọlẹbi rẹ ṣalaye fun BBC News pe ọjọ Satide ni wọn ti gbe edigbadigba lọ sileewosan aladani kanẸni aadọta ọdun ni Abdullahi Lawal nigba to jade laye ni ọjọ Aiku.
Oniroyin ni Oloogbe Musa Ahmad Tijjani to si ti fi igbakan ri jẹ olotu iwe iroyin Leadership Sunday ati Triumph ni Kano.
Ariwo iba ni wọn ni oloogbe naa pa eleyi to sọs di ero ileewosan fun ọsẹ kan gbako ki o to jade laye ni ọjọ karundinlọgbọn oṣu kẹrin ọdun 2020.
Gbajugbaja onimọ nipa ẹsin Islam ni Sheikh Tijjani to si da ileewe Tijjaniya silẹ.
Oun gan ni imaamu agba msṣalaṣi Murtal a ni ilu Kano.
Ni ọjọ Aje, ọjọ kẹtadinlọgbọn oṣu kẹrin ọdun 2020 lo jade laye.
Oríṣun àwòrán, Instagram
Iyawo eekan onimọ nipa Islam, Sheikh Abdulwahab Abdullah ni Halima Shitu jẹ.
O jẹ ọkan lara awọn obinrin to nimọ ti wọn n danilẹkọ nipa Islam ni ilu Kano.
Agbegbe Yakasai ni wọn ti bii ni ọdun 1963 ki o to tẹle Sheikh Abdulwahab lọ tẹdo si Mẹdina lẹyin igbeyawo wọn.
Lasiko naa Sheikh Abdulwahab n kẹkọ nigba naa ni.
Nibẹ ni Hajiya Halima naa ti kẹkọ imọ nipa Qur'an ati Hadith
Awọn mọlẹbi rẹ ṣalaye fun BBC news pe lẹyin ọjọ mẹrin ti aisan ti daa wolẹ lo jade laye.
Ọjọ Aje lo ku to si fi ọmọ mẹfa silẹ saye lọ.
Alaga ẹgbẹ awọn oniṣegun oyinbo ni ipinlẹ Kano ti ni ahesọ lasan ni iroyin ofege to gba igboro kan pe awọn dokita n sa kuro ni ipinlẹ Kano nitori arun to n fa iku ọwọọwọ.
Dokita Sanusi Mohammed Bala ni irọ ni iroyin yii.
Ṣaaju ni wọn ko ti le kọkọ fidi ohun to n fa ajakalẹ arun to n gbẹmi ọpọ eeyan ni Kano mulẹ.
Awọn alaisan kan tun bẹrẹ si nii sọo pe ko si awọn dokita nile iwosan mọ bii ti tẹlẹ.
Ogbeni Sani Adamu to jẹ alaisan kan ṣalaye fun akọroyin BBC pe nigba ti oun joko di aago kan lataarọ ti ko si dokita kankan to yọju si oun ni oun kuro nibẹ
Awọn ẹṣo Federal ministry of health naa tun fidiẹ mulẹ pe ko si oṣiṣẹ kankan nile iṣẹ naa.
Bẹẹ, awọn lo yẹ ki wọn ni imọ kikun lori iṣẹ awọn oṣiṣẹ eleto ilera bii dokita ati nọọsi.
Ṣugbọn dokita Bala ni irọ ni ati pe awọn dokita n ṣiṣẹ takun taklun bayii lati rii pe wọn n gbe igbese lati dẹkun itankalẹ arun coronavirus ni ipinlẹ Kano.
O ni awọn alaisan ti wọn n nio wọn ko ri dokita ko tẹlẹ igbesẹ to yẹ nile iwosan ti w'ọn lọ ki wọn to le ri dokita ni.
Lockdown  the world: Awọn ọmọ Nàìjíríà  káàkiri àgbáyé sọ ìrírí lábẹ́ àṣẹ kónílé-ó-gbélé
Iku ọwọọwọ ni Kano n kọ ọpọ lominu.
Gomina ipinlẹ Kano, Abdullahi Ganduje ni ijọba apapọ gan an lọwọ si bi wahala arun Coronavirus ṣe n gogo sii ni ipinlẹ naa.
Oríṣun àwòrán, Abdullahi Ganduje
Gomina Ganduje ni nṣe ni ikọ amuṣẹya ti ijọba apapọ gbe kalẹ lori gbigbogun ti arun Coronavirus lorilẹ-ede Naijiria, the presidential task force on covid-19 ,dẹyẹsi ipinlẹ Kano lasiko ti arun naa burẹkẹ si bayii.
Ninu ifọrọwanilẹnuwo kan to ṣe pẹlu BBC News, gomina Ganduje ni bi ọrọ ṣe n fojoojumọ buru sii ni ipinlẹ Kano
O ni ko ṣẹyin bi igbimọ amuṣẹya ti ijsba apapọ gbe kalẹ lori arun COVID-19 ṣe kuna lati mojuto ọrọ ipinlẹ Kano.
O ni oun fi ọrọ to awọn alaṣẹ ijọba apapọ titi kan igbakeji aarẹ leti pe ina wahala ajakalẹ arun Coronavirus n jo dorii koko ni ipinlẹ Kano ṣugbọn ko si ohunkohun ti ohun ri gbọ pada lori rẹ.
O ni iyalẹnu nla lo jẹ pewọn ni lati ti ibudo ayẹwo kan ṣoṣo to wa ni ipinlẹ naa fun ayẹwo arun Coronavirus fun ọjọ mẹfa gbako.
Amọṣa, igbimọ amuṣẹya lori gbigbogun ti arun coronavirus lorilẹ-ede Najiria, the presidential task force on covid-19 ni ko sohun to jọọ.
Ati pe akọṣẹmọṣẹ mẹtadinlogun ni wọn fi ranṣẹ si ipinlẹ Kano lati ṣe iranwọ lori gbigbogun ti itankalẹ arun naa.
Oríṣun àwòrán, Dr. Ganduje OFR
Eeyan meji mii tun ti jade laye ni ipinlẹ Kano latari ajakalẹ arun Coronavirus.
Ileeṣẹ eto ilera nijọba ipinlẹ Kano lo kede eyi ni ọsan ọjọ Aje.
Gẹgẹbi ileeṣẹ eto ilera ṣe sọ, eeyan mẹtadinlọgọrin ni ayẹwo ti fihan pe o ni arun naa ti wọn ko si tii ni ẹnikẹni ti ara rẹ tii yaa ninu wọn.
Oríṣun àwòrán, kano state government
Ijọba ipinlẹ Kano ti gba lẹyin o rẹyin bayii pe lootọ ni ọpọlọpọ awọn eeyan n ku ni ipinlẹ naa.ni ọjọ Aiku ni ijọba ipinlẹ naa gbe atẹjade kan jade lori eyi.
Kọmiṣọna feto iroyin nibẹ, Muhammad Garba to fi atẹjade naa sita ṣalaye pe gomina Abdullahi Ganduje ti paṣẹ fun ileeṣẹ ijọba to n mojuto eto ilera nipinlẹ naa lati ṣewadii ohun gan to n ṣẹlẹ.
Ọpọ awọn ọmọ orilẹede Naijiria ni wọn ti n fi ẹhonu han lori ohun to n ṣẹlẹ yii paapaa ọgọrọ awọn eeyan to n ku iku ọwọọwọ nipinlẹ Kano.
Ijọba ipinlẹ Kano ni pẹlu iwadii ranpẹ ti awọn ti ṣe, ohun to n fa iku ọwọọwọ yii ni aisan iba, itọ ṣuga, ẹjẹ ruru ati yinrunyinrun ati pe kii ṣe coronavirus gẹgẹ bi awọn kan ṣe n pariwo kiri.
A ti se gbogbo ẹnubode, titipa gbọingbọin ni ipinlẹ yii wa bayii, bẹẹ lawọn eeyan ipinlẹ wa naa n ṣe imọtoto boti tọ ati bo ṣe yẹ.
Eeyan mejila lo fo ṣanlẹ to ku lowurọ ọjọ Aiku, ọjọ kẹrindinlọgbọn oṣu kẹrin ọdun 2020 nikan eleyi si tun mu ki ohun tawọn eeyan nsọ lori pe boya arun coronavirus lo n ṣokunfa iku naa ga soke sii paapaa julọ pẹlu bi ko ṣe si ayẹwo ni ipinlẹ Kano fun ọjọ mẹta gbako bayii.
Arabinrin kan, Salma Ahmed  sọ ninu ohun agbasilẹ kan to fi sori ikanni Whatsapp eleyii to ti gbalegbako ni ipinlẹ naa pe awọn gbe ọmọ lọ sawọn ileewosan ko si si eyikeyi awọn ileewosan ti wọn de ni ipinlẹ naa to tẹwọn gba ọmọ naa fun itọju, ki wọn si to gbe ọms naa de ileewosan nla Aminu Kano, ọmọ naa ti ku.
Diẹ lara awọn eeyan to baa ileeṣẹ BBC News sọrọ nipa awọn mọlẹbi wọn to ku ṣalaye pe itọ ṣuga tabi aisan ọkan lo ja okun ẹmi wọn.
Ajọ ilera agbaye ti ṣekilọ ṣaaju asiko yii pe awọn to ba ni aisan kan lagọ ara ti wọn n wo wa ninu ewu gidigidi pẹlu arun Coronavirus yii-eyi tums si peo rọrun fun iku lati mu wọn nipasẹ arun COVID-19 yii
Oríṣun àwòrán, others
Ọkùnrin kan, George Bester, lo tí faraya lórí bí ọmọkùnrin rẹ ṣe fi idi rẹmi nínú esi idanwo tó ṣe nile ẹ̀kọ́.
Bester, tíì ṣe ọga agba fún ileesẹ ibaraenisọrọ MTN  ni ẹkun àríwá orílẹ̀ èdè Zambia, lo ń pariwo pe ẹgbẹ̀rún lọ́nà mọ́kànlélógún dọla ($21,000), tíì ṣe mílíọ̀nù mẹ́jọ náírà (N8m) ni oun san bíi owó ilé ẹ̀kọ́ ọmọ náà àmọ́ tó lọ gba
odo wale.
Ìyàn ń bọ̀ ní Nàìjíríà lẹ́yìn coronavirus àyàfi... - Ẹgbẹ́ àgbẹ̀ kìlọ̀
Ìséde ń bọ̀ káàkiri Nàìjíríà, àwọn gómìnà ìpínlẹ̀ fẹ́nukò
Báwo lọ̀rọ̀ Tafsir, ìdanilẹ́kọ̀ọ́ lásìkò Ramadan yóò ṣe jẹ́ pẹ̀lúu Coronavirus tó gbòde yìí?
Epo rọ̀bì ti ṣàkóbá fáwọn olùgbé apá odò l'Ondo
Ilé ẹ̀kọ́  ilẹ̀ Amẹ́ríkà kan tó wà ní orílẹ̀ èdè Zambia sì ni ọmọ náà ń lọ.
Oríṣun àwòrán, others
Fídíò bí Bester ṣe ń fà ìbínú yọ lórí ijakulẹ ọmọ rẹ ọhun, sì lo gba ojú òpó ìkan síra ẹni Twitter kan ni àárọ̀ Ọjọ́bọ, nibiti ọ̀pọ̀ èèyàn ti ń sọ èrò wọn lórí ìṣẹ̀lẹ̀ naa.
Ọkùnrin náà sì lo ń kó igbaju bo ọmọkùnrin rẹ tó kùnà nínú idanwo náà, ó ní kó naani owo ribiribi tí òun na lè lórí nílé ìwé.
Nínú esi idanwo ọmọdékùnrin náà lo tí  jókòó ṣe idanwo fún isẹ mẹ́jọ àmọ́ to kùnà nínú isẹ mẹ́fà, tó sì yege pupọ nínú idanwo imọ nípa  orin taa mọ si Music, bẹ́ẹ̀ lo tún yege díẹ̀ nínú idanwo Georgeraphy
Oríṣun àwòrán, others
Nínú fídíò náà sì ni ìyá ọmọ ọhun tí ń pariwo pé kí bàbà rẹ má gba ni igbaju mọ.Ní báyìí, Iroyin kan ni ẹka ileesẹ ọlọ́pàá tó wà fún ààbò àwọn ọmọdé ni orílẹ̀ èdè Zambia tí ransẹ pé George Bester láti wá sọ ìdí tó fi tẹ́ ẹtọ ọmọ rẹ mọ́lẹ̀.
Àmọ́ ọ̀pọ̀ èèyàn tó dá sí ọ̀rọ̀ yìí lójú òpó Twitter lo ń kan saara si bàbá náà lórí bo se n bá ọmọ rẹ wí.
Lati opin ọsẹ to kọja to jẹ ayajọ isami ọdun ajinde Kristi ni iroyin kan gba oju opo ayelujara kan pe awọn adugunjale ti ya si igboro.
Ileeṣẹ ọlọpaa sọ wi pe awọn oni jagidijagan yii n ṣe ohun gbogbo ti wọn le ṣe lati jẹ ki awọn araalu gbagbọ ninu ọrọ ti wọn sọ.
Awọn araalu bẹrẹ si ni jo taya ọkọ ti wọn ni awọn agbegbe to wa ni ẹnu ibode ipinlẹ Eko ati Ogun, ti wọn si da awọn ẹgbẹ vigilante keekeeke silẹ lati le da aabo bo ara wọn ti awọn adigunjale ba de.
Fun ọpọlọpọ ọjọ, awọn ọdọ wọn yii, kekere ati agba pẹlu ọkunrin ko sun lalẹ
Ada ati ọkọ ni wọn mu dani ti wọn n kaakiri opopona adugbo wọn lati duro de awọn ole ti ko wa si agbeegbe wọn.
Iroyin ofege ti wọn gbo ni pe awọn ọdọ ti wọn to igba n kaakiri lati ja awọn eniyan lo le.
Oríṣun àwòrán, others
Amọ, ileeṣẹ ọlọpaa sọ fun ileeṣẹ iroyin BBC ni ko si otitọ kankan ninu iroyin pe awọn adigunjale n ṣọṣẹ kaakiri,
Iroyin ofege to n kaakiri lori ẹrọ ayelujara lo jẹ ki awọn eniyan gbagbọ ninu iroyin ti kii se otitọ naa.
Ọjọ Aje, ọsẹ yii ni Aarẹ orilẹ-ede Naijiria, Muhammadu Buhari kede pe wọn yoo fi ọsẹ meji kun ofin konile-o-gbele lati koju arun Coronavirus to n tan kalẹ lorilẹ-ede Naijiria.
Bawo ni iroyin pe awọn adigunjale n ja kaakiri ṣe bẹṛẹ?
Aworan ati fidio lo kọkọ jade lori ẹrọ ayelujara nibi ti wọn ti fi lede pẹlu #OgunUnrest ati #LagosUnrest lori ẹrọ ikansiraẹni Twitter, amọ ko si agbegbe kankan ti iru rẹ ti ṣẹlẹ.
Awọn ara agbegbe Agbado, Sango ati Ijoko to wa ni ibode ipinlẹ Ogun ati Eko n sọ lori ẹrọ ayelujara pe awọn n gburo ibọn, ti awọn eniyan si n kọlu awọn eniyan ni inu ile.
Bakan naa ni Agbẹnusọ ileeṣẹ ọlọpaa ni ipinlẹ Ogun, Abimbola Oyeyemi sọ fun ileeṣẹ BBC pe awọn gba ipe to le ni igba lati ọdọ awọn araalu pe o le n ja, ti ko si si otitọ kankan ninu rẹ.
Oríṣun àwòrán, others
Se lootọ ni idigunjale n waye?
Agbẹnusọ fun Ileeṣẹ ọlọpaa ni ipinlẹ Eko, Bala Elkana sọ wi pe ko si idigunjale ni ipinlẹ Eko ati Ogun bi awọn eniyan se n polongo rẹ.
Elkana fikun un pe lootọ ni awọn ti fi panpẹ ọba mu awọn eniyan ọgọrun un ti wọn jẹ ọmọ ẹgbẹ okunkun ti wọn n ja laarin ara wọn.
O tun ṣalaye pe awọn ẹgbẹ okunkun yii lo n fi atẹjise yii sita lati fi da ipaya si ara awọn eniyan.
Ọpọlọpọ igba ni awọn ẹgbẹ okunkun ti ma n ja laarin ara wọn,
Ohun ti o si mu ki awọn eniyan bẹru wọn ni wi pe wọn ma n lo ọna abalaye lati mulẹ ati lati ṣe ohun ti ko tọ laarin ara wọn.
Tikútìyè lọ̀rọ̀ Coronavirus, àdúrà lọ̀rọ̀ gbà lásìkò yìí-Ààrẹ Buhari
Coronavirus pandemic: Ààrẹ Buhari ní àdúrà làsìkò yí gbà pẹ̀lú ìfaradà láti ṣẹ́gun Coronavirus, àrùn tikútìyè tó ń da àgbáyé láàmú
Aarẹ Buhari ki awọn ọmọ Nàijiria ku afarada bi gbogbo nnkan ṣe n lọ lásìkò Coronavirus yìí
Oríṣun àwòrán, Bashir Ahmad
Ààrẹ Buhari ní àdúrà làsìkò yí gbà pẹ̀lú ìfaradà láti ṣẹ́gun Coronavirus, àrùn tikútìyè tó ń da àgbáyé láàmú
Aarẹ Muhammadu Buhari ti ke sawọn ọmọ orilẹede Naijiria pe ki wọn rọju mu gbogbo inira tabi irora ti igbesẹ gbogbo ti ijọba n gbe lati dẹkun itankalẹ arun Coronavirus ba n mu ba wọn.
Ninu ọrọ ikini ku ọdun ajinde to fi ṣọwọ sawọn ọmọ orilẹ-ede Naijiria, paapaajulọ awọn ọmọlẹyin Kirisiti lọrọ naa ti jade.
Aarẹ Buhari ṣalaye pe igbayegbadun awọn ọmọ orilẹ-ede Naijiria kii ṣe oun to ṣee dunadura le lori ṣugbọn igbesẹ aabo ati alaafia araalu ni ijọba lẹkajẹka n le.
Aarẹ Buhari ni tiku tiye lọrọ Coronavirus, gbogbo eeyan orilẹ-ede Naijiria lo si gbọdọ farada awọn igbesẹ gbogbo lati da alaafia ati abo pada sorilẹ-ede Naijiria.
Ilu Ubang, jẹ ilu kan nibiti ede ti awọn ọkunrin wọn n sọ yatọ si ti awọn obinrin wọn.
O wa ke sawọn ọmọlẹyin Kirisiti lati lo anfani ajọdun ajinde Jesu Kiriisiti lati fi wolẹ adura fun orilẹ-ede Naijiria ki orilẹ-ede yii lee la afonifoji to wa lọwọ yii kọja.
Bakan naa ni aarẹ ṣalaye pe ijọba ko ni tori ajakalẹ arun naa gboju kuro lori ilakaka rẹ lati koju ija kọ awọn ikọ agbesunmọmi to n ṣigun si orilẹ-ede Naijiria.
Bí àrùn Coronavirus ṣe dá gbogbo àgbáyé gúnlẹ̀ sójú kan náà nìyí
Kí lo mọ̀ nípa fẹntilétọ̀, ohun èlò aṣèrànwọ́ èémí
Kí làwọn ìdàmú tí Coronavirus n mú bá àgọ́ ara?
Ṣé ìrètí wà pé coronavirus yóò dínkù lásìkò ooru?
'Èmi gan máa ń béèrè lọ́wọ́ ara mi pé ta ni Wole Soyinka gangan'
Mo ti kọkọ sọ fún Toyin Abraham pe mi o le ṣe amúgbálẹ́gbẹ rẹ̀- Sam Olatunji
Oríṣun àwòrán, Toyin/instagram
Ọpẹ ni fún Ọlọ́run lórí ayé Toyin Abraham, láti orí gbèsè jíjẹ, ó di onílé, onimọto àti aya lọ́dọ̀ ọkọ
Gbajúmò osere tíátà lobinrin, tó ń kopa ninu ère tíátà lédè Yorùbá àti oyinbo ní Toyin Abraham.
Ọ̀pọ èèyàn ni kò mọ pe arẹwà obìnrin náà la ọpọ ìṣòro kọjá, ẹni ta sì ro pe kò le è pagọ ni, tó sì di ẹni tó ń kọlé alárrinrin lónìí.Nígbà tó ń mẹnuba diẹ ninu ìṣòro tí Toyin tí là kọjá, alukoro àti Alakoso fún osere-binrin náà, Sam Olatunji kéde pé ọpẹ ló yẹ fún Ọlọ́run.
o ni ti bá wo bó ṣe yí ìgbésí ayé Toyin Abraham padà sí rere báyìí, yàtọ̀ sí ipò aláìní tó wà tẹ́lẹ̀.Nígbà tó ń fi ẹ̀mí imoore rẹ hàn sí Ọlọ́run lójú òpó Instagram rẹ, Olatunji mú ọjọ́ tó kọ́kọ́ pàdé osere-binrin náà wá sí ìrántí, èyí tó bẹ̀rẹ̀ lórí ẹ̀rọ ibaraẹnisọrọ.
"Olatunji ni: ""Toyin lo fi atẹjisẹ kan ránsẹ sí mi lọpọlọpọ ọdún sẹ́yìn lórí ẹ̀rọ ilewọ BBM, pé ki ileesẹ mi wá máa ṣe àkóso àti alarina isẹ rẹ."
"Taa mọ sí Public Relations. Ń ko roo ní ẹẹmeji tí mo fi sọ fun pé owó ìṣẹ wa wọ́n pupọ."""
Ìdí tí mo fi sọ̀rọ̀ bẹẹ ni pé, a kì í ṣiṣẹ́ pọ pẹ̀lú àwọn osere tíátà lédè Yorùbá, ẹnìkan ṣoṣo tó kanka nínú wọn, èyí un Funke Akindele, nikan la ń bá ṣiṣẹ.
Ṣùgbọ́n Olatunji ni, riro ni ti eniyan, àmọ́ sise ni ti Ọlọrun, torí  nígbà tó di ọdún 2017, ní gbajumọ akọroyin orí ayélujára kan, Stella Dimoko-Korkus kesi òun pé, òun ni òun sọ fún Toyin pé kò pé òun, láti máa sisẹ Alarina fun-un, ó ni akoko yii gan an ni àìmọye abawọn si tí tá sì aṣọ ààlà Toyin Abraham.
"Mo wá rí isẹ yìí bíi anfaani fún mi láti ṣe àtúnṣe si ìwà ìgbéraga tí mo hù sí osere-binrin náà ṣáájú nígbà tí mo ní owó isẹ wa wọ́n pupọ.
A pinnu láti fojú rira, ìrísí Toyin lọ́jọ́ taa kọkọ rira dàbí tí gbajumọ osere ti ko sí lójú ọpọn mọ, ẹni tí ipenija ayé àti ibalorukọjẹ lorisirisi tí sọ di idakuda, kódà, kò jọ gbajumọ osere rárá. "
Funke Akindele jẹ àkàndá ẹ̀dá - Adaku
"Olatunji salaye pe: Mo kọ́kọ́ fẹ́ kọ láti bàa ṣiṣẹ́ àmọ́ ẹ̀mí mímọ́ sọ wípé kí n gba, tí ìtọ́ni sì wá fún mi lórí ohun tó yẹ ká ṣe láti mú àyípadà rere bá ayé rẹ. ""Òṣìṣẹ́ alarina Toyin Abraham náà ni, ẹ̀rọ ibaraẹnisọrọ ti osere-binrin náà mú lọ́wọ́ lọ́jọ́ naa sì ku ẹgbẹ̀rún lọ́nà àádọ́jọ náírà, tí yóò fi sanwó fóònù náà tán.Olatunji ni òun sọ fún pé, kò jẹ ki awon ṣe àyípadà pátápátá bá ìtàn ayé rẹ tó bá fẹ́, tó sì gba sí òun lẹ́nu, ó ní bẹ́ẹ̀ lo bọ aṣọ ìgbéraga silẹ, tó sì ń ṣiṣẹ́ náà.""A gbé ìlànà kan kalẹ, a kesi àwọn akọroyin, a mú àyípadà bá ibasepọ rẹ, mo sì dúpẹ́ lọ́wọ́ Ọlọ́run pé làálàá mi lórí rẹ kò já sí asán."""
Ń ko tọrọ agbe fún ìyá Awero, Larry àti bàbà Feyikọgbọn, ẹ má sọ ire di ibi mọ́ mi lọ́wọ́ - Foluke Daramola
Foluke Daramola ṣalaye kikun lórí ahesọ àwọn eeyan lorí pé òun ń tọrọ owó fáwọn Baba Feyikọgbọn àti Iya Awerolásìkò ìgbélé coronavirus.
Oríṣun àwòrán, Foluke/instagram
Ń ko tọrọ agbe fún ìyá Awero, Larry àti bàbà Feyikọgbọn, ẹ má sọ ire di ibi mọ́ mi lọ́wọ́ - Foluke Daramola
Gbajúmò osere orí ìtàgé lobinrin, Foluke Daramola, ẹni tó máa ń béèrè àánú fún àwọn akẹẹgbẹ rẹ tó nílò iranlọwọ, ti ń rawọ ẹ̀bẹ̀ sáwọn aráàlú pé kí wọn má ṣe sọ isẹ àánú tí òun ń ṣe di ibi mọ òun lọ́wọ́.Daramola, ẹni tó kígbe síta bẹẹ lójú òpó Instagram rẹ lọ́jọ́ Ẹti ṣàlàyé pé, àwọn ènìyàn kan ló ń kígbe kiri pé ìyá ńlá lo ń jẹ àwọn àgbààgbà mẹtẹẹta nínú osere tíátà tí òun dárúkọ náà, torí òun ń tọrọ agbe fún wọn.
"Foluke, ẹni tó ní inú òun bàjẹ sí ìṣẹ̀lẹ̀ yìí wá ń béèrè pé, òun kò mọ idi ti àwọn èèyàn ṣe máa ń dori ọ̀rọ̀ kodò, táwọn èèyàn sì ń pe oun nípa àwọn àgbàlagbà mẹtẹẹta náà.""Iya Awero, ọnku Larry àti Baba Feyikọgbọn kò fìgbà kankan tọrọ oúnjẹ àbí iranwọ lọ́nà kọna lọ́wọ́ mi rí, mo kan béèrè iranwọ fún wọn gẹ́gẹ́ bíi ara aáyán mi láti ṣe atilẹyin fún wọn."""
"Foluke Daramola ni: ""Kódà èmi àti ọnku Laary ń jó papọ nínú fídíò tí mo gbé síta ni, tí wọn sì sọ fún mi pé àwọn fẹ́ ṣe filọlẹ ìwé táwọn kọ nígbà tí Ìyá Awero ní àwọn fẹ́ ṣe ọjọ́ ìbí."
Èmi kò wá mọ ìdí táwọn èèyàn fi ń ní iya ń jẹ àwọn èèyàn yìí.
Ẹ jọ̀wọ́ nítorí Ọlọ́run, ẹ má jẹ́ kí oore di ibi mọ mi lọ́wọ́. Mo kan ń tiraka láti ṣe ojúṣe mi ni bí ọmọ ṣe ń satileyin fún òbí, àwọn èèyàn yìí ní àwọn ọmọ gidi tó ń tọju wọn.
Ó ní èyí kò wu etí gbọ rárá, bẹ́ẹ̀ ni kò dára, òun kò sì fẹ́ bẹẹ torí àwọn náà kò tọrọ oúnjẹ àti owó lọ́wọ́ òun rí.
Lásìkò igbele Covid-19 yìí náà ni Foluke Daramola tún lọ kí bàbá Feyikọgbọn nílé láti fun ní ẹ̀bùn owó èyí tó mú káwọn èèyàn kan rò pé ìyà ló ń jẹ bàbá yìí, tí Foluke ṣe lọ fún ní owó.
Bákan náà ni isẹ àánú tó ń ṣe lásìkò igbele Covid-19 yìí tún gbe dé ọdọ Ìyá Awero.
Foluke wá rawọ ẹ̀bẹ̀ pé káwọn ọmọ aráyé má ṣe sọ isẹ àánú di isẹ ibi mọ òun lọ́wọ́.
Funke Akindele tọrọ àforíjì, Lateef Adedimeji d'obìnrin, Bàbá Ire kó ìrẹsì lọ Ogbomoṣo
Yoruba Films: Funke Akindele tọrọ àforíjì, Lateef Adedimeji d'obìnrin, Bàbá Ire kó ìrẹsì lọ Ogbomoṣo
Oríṣun àwòrán, Instagram
Awọn oṣere tiata Yoruba ṣi n dara papaa julọ loju opo Instagram wọn, bo tilẹ jẹ pe konle-o-gbele wa nita.
Bo tilẹ je pe ijọba kede konile-o-gbele nipinlẹ Eko, Ogun ati olu ilu Naijiria, Abuja nitori ajakalẹ aarun coronavirus, ọpọ nnkan lo ṣi ṣẹlẹ lagbo oṣere lọsẹ yii.
Awọn oṣere tiata Yoruba ṣi n dara papaa julọ loju opo Instagram wọn.
Wọnyi ni awọn ohun to ṣẹlẹ lọsẹ yii lagbo awọn oṣere tiata Yoruba lọsẹ yii.
Funke Akindele
Gbajugbaja oṣere ti ọpọ mọ si Jenifa tọrọ aforiji lọwọ awọn ololufẹ rẹ lẹyin to ṣe ayẹyẹ ọjọ ibi ọkọ rẹ, Abdulrasheed Bello ti ọpọ mọ si JC Skillz ti o si tun fi fọnran fidio ayẹyẹ naa to fi si oju opo Instagram rẹ.
Ileeṣẹ ọlọpaa ipinlẹ ti fi ọwọ ofin mu Funke Akindele ati ọkọ rẹ lori ẹsun pe ohun ti wọn ṣe lodi si ofin konile-o-gbele to wa lode.
Wọn gbe wọn lọsi ileẹjọ majisireti nibi ti wọn ti sọ pe awọn jẹbi ẹsun ti wọn fi kan awọn, adajọ ni ki wọn san owo itanran pẹlu tii ṣe ẹgbẹrun un lọna ọgọrun naira fun ẹnikọọkan wọn pẹlu iṣẹ sinsin ilu.
Amọ, Funke Akindele ti rawọ ẹbẹ sawọn eeyan wi pe ki wọn jeburẹ, o ni oun gba pe ohun t'oun ṣe ku diẹ kaato.
Kolawole Ajeyemi
Kolawole Ajewole to jẹ ọkọ gbajugbaja oṣere, Toyin Abraham ti dide iranwọ fawọn ara ilu Ogbomoṣo, tii ṣe ilu abinibi rẹ.
Ajewole ni o ṣe pataki fun oun lati ṣe iran fawọn eeyan ilu oun lasiko ajakalẹ aarun coronavirus yii ti ijọba ni kawọn eeyan maa takete si ara wọn.
O ṣalaye loju opo Instagram rẹ pe oun yoo pin irẹsi, o ni kawọn eeyan maa pe lori eto Gelede to waye lori ile iṣẹ redio Parrot.
Lateef Adedimeji
Gbajugbaja oṣere, Lateef Adedimeji gbarada lẹyin to ro dẹdẹ to kan dudu bi awẹlẹwa obinrin.
Niṣẹ lo tọju to si tọ ẹnu, koda o tun fijo bẹẹ ninu fọnran to fi lede lori oju opo Instagram rẹ.
Bi o ṣe n jo, bẹẹ naa ni awọn eeyan n na lowo ti o si n sọ pe ''Iya Peju ti fẹ jẹ gbese.''
O ki awọn onigbagbọ atawọn musulumi ninu fidio ọhun ku ọdun Ajinde, bakan naa lo ki wọn ku ọjọ Jimọ.
Peju Ogunmola
Gbajugbaja osẹre, Peju Ogunmola dupẹ lọwọ Eleduwa fun anfaani lati wa laaye bi o ti n ṣe ayẹyẹ ọjọ ibi rẹ.
O bẹbẹ pe ki Ọlọrun tubọ maa bukun fun oun bi oun tun ti le ọdun si.
Peju ni ọjọ ibi oun jẹ ọjọ kan to ṣe pataki julọ ninu igbesi aye oun.
Bẹẹ ni o ki ara rẹ ku ọjọ ibi wi pe ẹmi oun yoo ṣe ọpọ rẹ laye ati laaye.
Coronavirus prevention tips: Ọ̀nà àbáyọ fún olóyún lásìkò àjàkálẹ̀ ààrùn Covid-19
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Gbogbo ibi nílẹ̀ káràòjíire ni oyún tí jẹ nkan, oyún jẹ́ àdúrà pàtàkì tí ìyàwó osìngín má ń lẹ́yìn ayẹyẹ ìgbéyàwó.
Ṣùgbọ́n lásìkò àjàkálẹ̀ ààrùn Coronavirus yìí, ọ̀pọ̀ aboyún ni ẹ̀rù ń bà. Ṣáájú ni ààrẹ àwọn agbẹ̀bí Franka Cardee tí ké sí gbogbo àwọn obìnrin tí ó lè máa bẹ̀rù bí wọn yóò ṣe rùú là lásìkò yii, àti ọ̀nà tí yóò gbà láti dáàbò bo ara wọn.
Jọwọ ṣe atunṣe ilana ikansi ayelujara rẹ lati ri ẹkunrẹrẹ rẹ
Orisun: Johns Hopkins University atawọn ajọ eto ilera ilu
Igba ti wọn kede iṣiro awọn to nii kẹyin                                              29 Oṣù Bélú 2021 13:33 WAT+3
*Iye awọn to tọwọ aisan ku ni isọri eeyan ẹgbẹrun lọna ọgọrun
Jọwọ ṣe atunṣe ilana ikansi ayelujara rẹ lati ri ẹkunrẹrẹ rẹ
Akọsile imọ yii, da lori akojọpọ iṣẹ iwadi ni Fasisti Johns Hopkins, o si le ma ṣe afihan awọn akọsilẹ iroyin to ba igba mu lati orilẹede kankan.
** Àwọn iyé akọsilẹ̀ to ti wà fún àwọn ti o ṣẹ́ṣẹ̀ ni ààrun náà jẹ́ àkójọpọ̀ ọjọ́ mẹ́ta. Nítori àwọn àtúgbẹ́yẹ̀wò, o níra láti ṣe àkójọpọ fún àwọn ọkọ́ naa
Orisun: Johns Hopkins University atawọn ajọ eto ilera ilu
Iye akọsilẹ to waye gbẹyin 29 Oṣù Bélú 2021 13:33 WAT+3
Ọ̀pọ̀ àwọn aboyún ni ẹ̀rù ń bà láti láti lọ sí ilé ìwòsàn fún àyẹ̀wò ìgbàdédéìgbà tí ó yẹ kí wọn máa lọ fún nítorí wọn fẹ máa tẹ́lẹ̀ àṣà sún - fúnmi - ń - sún fún ọ.
Bó tilẹ̀ jẹ́ pé ọ̀pọ̀ ǹkan lọ tí yí padà lágbàáyé lẹ́nu lọ́lọ́lọ́ yìí, ọ̀pọ̀ àwọn nọ́ọ̀sì agbẹ̀bí lọ sì ti ń ṣe ìrànwọ́ fún àwọn aboyún lat máa dá wọn lóhùn láti orí aago ìbánisọ̀rọ̀.
Cadée gba àwọn aboyún níyànjú láti wádìí lọ́dọ̀ àwọn olùtọ́jú wọn ọ̀nà tí ó dára jù lásìkò yìí láti ṣe ètò àyẹ̀wò ìgbàdédéìgbà tí alaboyun máa ń ṣe
Bi mo bá láàrùn COVID-19, ṣé mo leè ko ran ọmọ láti inú oyún ?
"Wọn ò tí rí kòkòrò Covid-19 ni ojú ara ìyá, tàbí lára ìwọ́ ọmọ tàbí láti inú omi ọyàn abiyamọ"" , ìwádìí ń lọ lọ́wọ́ lórí èyí ṣùgbọ́n àwọn onímọ̀ kò tíì salábàpàdé Covid-19 nínú olubi ọmọ nínú ẹ̀jẹ̀ .Nkan ti o se pàtàkì jù lọ ní pe ki aboyún sá gbogbo ipá rẹ̀ láti dènà níní ààrùn Coronavirus, àmọ́ óò, tí ó bá lóyún tàbí ó ṣẹ̀ṣẹ̀ bímọ, ó ṣe pàtàkì láti àwọn elétò ìlera kí ó sì tẹ̀lé ìlànà tí wọ́n bá ní kí ó tọ̀"
Mo ń ròó láti bímọ sí ilé ìwòsàn, ṣe ìpinnu tó tọ̀nà ni?
Oríṣun àwòrán, AFP
Ó ṣe pàtàkì láti bèrè lọ́wọ́ àwọn agbẹ̀bí tàbí dókítà wọn ibi tí ó dára jù láti bímọ sí.
Cardee ni èyí dálé ipò tí obìnrin náà wà, irú ìdojúkọ rẹ̀ àti bí ilé ìwòsàn ètò ìlera àgbègbè rẹ̀ bá ṣe rí
Ṣe àwọn ẹbí mi le wà pẹ̀lú mi ti mo bá fẹ́ bímọ?
Fún irú nkan báyìí oríṣiríṣi orílẹ̀-èdè lọ ní àṣà tí wọn. Ṣùgbọ́n Cadée nígbà gbọ́ pé ó ṣe pàtàkì kí aláboyún ni ẹni tí yóò wà ní àyíká rẹ̀ lásìkò ìrọbí níwọ̀n ìgbà tí ẹni náà bá ti dáàbò bo ara rẹ̀, bí àpẹẹrẹ kí ó wọ ìbòjú-bomu ni yàrá
ìgbẹ̀bi kí ó sì máa fọ ọwọ rẹ lóòrè kóòrè pẹ̀lú ọmọ àti ọșẹ
Ṣe eto bí ose  fẹ́ kí gbogbo nkan ó rí, èyí yóò mú àdínkù bá ẹ̀rù. Gba nọ́mbà ìbánisọ̀rọ̀ ẹni tí ó fẹ́ láti bá sọ̀rọ̀ nígbà tí ọmọ bá ti ń mú ọ, mọ ẹni tí fẹ́ kí ó ràn ọ lọ́wọ́ lásìkò ìrọbí, máa ṣe àwọn ǹkan bí eré ìdárayá nínú ilé, èyí yóò
máa mú kí ara rẹ balẹ̀ tí yóò sì mú ọkàn rẹ kúrò níbi ẹ̀rù. Máa ṣe eré ìdárayá èémí, pee nọ́ọ̀sì agbẹ̀bí rẹ tí ó bá kojú ìṣòro kankan. Tọju ara rẹ dáadáa, jẹun dáadáa, mumi dáadáa, feyinti kí inú rẹ sì máa dùn pé ó ní oyún. Irú ìbéèrè wo ni mo le bí àwọn elétò ìlera mi?
Tí àsìkò bá ti tó láti bímọ, ó ṣe pàtàkì kí ó bere àwọn ìbéèrè tí ó bá wù ọ
Kini nkan ti obìnrin tó bá fẹ́ lọ bímọ nílé ìwòsàn yẹ kí o gbé dání? Obìnrin kò nílò láti gbé tí ó pọ̀ ju bó ṣe yẹ lọ, ìwọ̀nba èyí tí àwọn òṣìṣẹ́ ìlera bá ní kí ó mú wá náà ni, ó sì gbọdọ sọra gidi.
Oríṣun àwòrán, Twitter
Ní kété tí mo bá ti bímọ kí ló yẹ kí n ṣe láti dáàbò bo ọmọ mi?
Nkan ti o dára jù ni pé ṣókí ni, ìwọ àti ẹbi rẹ lọ ṣe pàtàkì jù kii se àkókò láti máa jẹ ki àwọn àlejò wò
" Tí ó bá ti ní àwọn ọmọ nílé, má ṣe gba wọn láàyè láti bá àwọn míràn ṣeré. Rí dájú pé ebi rẹ ń fọwọ́ wọn pẹ̀lú omi àti ọṣẹ lóòrèkóòrè. Ìmọ̀ràn Cardee
Ìwádìí tí fi hàn pé, àwọn aláboyún kò sì lára àwọn tí àsìkò yìí ni ewu fún jùlọ láti ni ààrùn Coronavirus ṣùgbọ́n nítorí àwọn àyípadà tó dé bá ara ati èròjà tó ń f'ára lókun tí yóò ti gbọ̀jẹ̀gẹ́, ó ṣe pàtàkì lat ṣọ́ra. Ó gba àwọn obìnrin ni ìyànjú láti máa tẹ́lẹ̀ àwọn ìlànà yìí:
Àwọn òbí ń fún ọmọ wọn lọ́yàn
Ní nkan ti a mọ̀, kò sì ewu nínú kí ọmọ máa mú ọyàn daada, gẹ́gẹ́ bí Cadee ṣe sọ gbogbo ìwádìí tí wọn ti ṣe kó sì àfihàn pé àwọn ọmọ lè kó aarun Coronavirus láti ara ọmú mímú, nítorí náà ìyá leè fún ọmọ lọ́mú"
Ọ̀pọ̀ àwọn obìnrin ni wọn ń gbé ilé tí ó súnmọ́ ara wọn èyí sì mú kí ìsúnfúnraẹni kí ó nira díẹ̀. Ó ní kí àwọn ènìyàn gbìyànjú láti má súmọ́ ẹni tí ó bá ní oyún, tí ó bá sì ṣeé ṣe kí wọn pèsè yàrá ìgbọ̀nsẹ̀ tí ó yàtọ̀ fún aláboyún Bákan náà lọ fi kún pé ó ṣe pàtàkì kí a máa fí omi àti ọṣẹ fọ ọwọ ni gbogbo ìgbà. Orísun: Unicef
Coronavirus tips: Ìlànà ojúlówó márùn ún tó kápá ìtànkálẹ̀ COVID-19
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Arun Coronavirus ti tan kalẹ jakejado agbaye ti o si ti da ipaiya silẹ toun ti bi iye eeyan to n ko arun naa se n pọ tawọn to tọwọ rẹ ku naa ko si din ku.
Pupọ awọn ilu lofin konileogbele ti fẹsẹmulẹ,lilọ bibọ ọkọ ofurufu ni ijọba wọgile tawọn ajọdun ati ayẹyẹ miran naa si ti dẹnukọle.
Ilẹ Yuroopu ni ajakalẹ yi ti gbogo julọ ti o si jẹ wi pe ni Latin Amẹrika orileede Amẹrika ati ilẹ larubawa,iye awọn to n ko arun naa pọ si.
Amọ awọn orileedekan ti ribi dawọ itankalẹ arun naa eleyi ti o ti pa eeyan ẹgbẹrun mẹẹdogun titi di ọjọ kẹtalelogun osu Kẹta  ti o si ti ran eeyan 340,000 lagbaye.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Pupọ awọn orileede to wa ni Asia toun ti pe wọn sunmọ China nibi ti ajakalẹ yi ti bẹrẹ ni wọn ti n ribi mu adinku ba ajakalẹ arun yi.
Onimọ nipa ajakalẹ arun Tolbert Nyenswah to jẹ ọjọgbọn ni fasiti John Hopkins sọ pe'' o ni awọn orileede kan ti wọn gbe igbesẹ lati koju arun yi,mo si lero pe o yẹ ki a kẹkọ lọdọ wọn'' Alamuleti China ti se Taiwan fapẹrẹ ti iye eeyan to wa nilu wọn jẹ miliọnu mẹtalelogun le diẹ ko ni ju iye eeyan marundinlọgọrun to ko aisan naa ti eeyan meji si ku.
Bẹẹ lọmọ sori ni Hong ati Japan ti iye eeyan to ko aisan naa ko pọ to tawọn orileede to jina rere si China lọ.Ki wa lawọn igbesẹ ti wọn gbe.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Awọn onimọ ti BBC ba sọrọ fidi ọrọ yi mulẹ pe sise ayẹwo fawọn eeyan ni ọna kan gbogi la ti mu adinku ba itankalẹ Coronavirus.
Yatọ si nkan ti ọjọgbọn Nyenswah sọ pe a ko le mọ bi arun ba se nipa lara awọn eeyan to lalai se ayẹwọ lati mọ iye eeyan to mu, awọn onimọ mi to fi mọ ọga agba ajọ ilera lagbaye Tedros Ghebreyesus ni sise ayẹwo fun ẹnikẹni to ba ni apẹrẹ arun naa ni ọna ati mu adinku ba itankalẹ kokoro aifojuri yi.
Asiri ibẹ gẹgẹ bi awọn onimọ ti se sọ ni pe awọn orileede to ba n se ayẹwo ni iye awọn eeyan tuntun to n ko arun naa ma n dinku lẹyin wa.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Lara nkan ti South Korea fi se aseyọri nipa mimu adinku ba iye eeyanto ni arun yi ni pe wọn ya awọn to ba ni arun yi sọtọ.
Toju tiyẹ laparo awọn ilẹ yi fi n se ayẹwo bẹẹ si ni wọn n tọpinpin awọn to ba ti niarun yi.
Koda ni Taiwan Singapore ati Hong Kong wọn ya awọn to ba ni arun yi sọtọ niile wọn ti wọn si fi ijiya owo itanran ẹgbẹrun mẹta dọla lelẹ fẹnikẹni to ba tapa si ofin yi
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ojọgbọn Nyenswah, to ti saaju bawọn sisẹ lati koju Ebola nigba to ja ni iwọ oorun Afrika  ni ọna kan pataki lati koju itankalẹ arun ni ki awọn tọrọ kan gbe igbesẹ ni kiakia lati le dena itankalẹ arun yi laarin awọn eeyan.
O ni awọn orileede bi Taiwan ati Singapore ko lọra nipa wiwa awọn to ni arun yi ati yiya wọn sọtọ.
Iwe igbadegba kan lori ilera ti ẹgbẹ awọn onimọ ilera Amẹrika gbe jade sọ pe aseyọri Taiwan nipa kikoju Coronavirus ko sẹyin pe wọn ti n mura kalẹ lati igba ti ajakalẹ SARS ti kọkọ bẹ silẹ nibẹ.
O ni saaju ki wọn ti fidi ọrọ itankalẹ lati ara ẹni kan si omiran ni aarin osu kini ọdun ni Taiwan ti bẹrẹ si ni se ayẹwo awọn arinrinajo to n wọ ilẹ wọn lati ilu Wuhan ti arun yi ti kọkọ sẹyọ.
Iru igbesẹ kiakia yi naa ko jẹ nkan ti Hong Kong naa fi sere ti eleyi si ranwọn lọwọ lati le dẹkun ajakalẹ naa.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Awọn ọna miran ti a le fi dena itankalẹ arun yi ni ki a ri wi pe a tẹle ilana ki awọn eeyan ma talanga sirawọn ti wọn ba wa nita tabi laarin eeyan.
O ni awọn orileede ti o sunmọ China to yẹ ki ajakalẹ arun yi pọ lọdọ wọn ribi fi ilana yi lelẹ ti wọn si tẹlẹ.
Nigba ti yoo fi di ipari osu Kini ọdun yi, Hong Kong gẹgẹ bi apẹrẹ ti ni ki wọn ti gbogbo ile iwe ti wọnsi ti wọgile gbogbo ayẹyẹ eleyi ti yoo u ki awọn eeyan ma darapọ mọ ara wọn.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ni ipari awọn onimọ salaye pe ki a ri pe a moju to ilera ara wa ka si tun gbajumọ imọtọto.
Bi a ko ba gbagbe bi wọn ti se n sọ fun wa, ọwọ fifọ pẹlu omi ati osẹ se pataki.
Pupọ awọn ilẹ Asia lo ti kẹkọ lara ajakalẹ arun SARS ni ọdun 2003.
Wọn ti mọ pe ti awọn ba gbaju mọ imọtotọ awọn ko ni ni arun naa bẹ si ni awọn ko ni le ko ran ẹlomiran.
Bakanna ni ajọ WHO ti se sọ fun wa pe ọwọ fifọ ati imọtoto se koko ti a ba fẹ dena ajakalẹ arun.
Lawọn ikorita kaakiri orileede bi Singapore,Taiwan ati Hong Kong awọn aye wa ti wọn fi omi ati osẹ ifọwọ si fawọn eeyan ti lilo ibomu si jẹ nkan to kari laarin awọn eeyan wọn.
Coronavirus Lockdown: À ń gbáradì láti pàṣẹ òfin kóníléógbélé tó bá dójúẹ̀ tán - Ìjọba ìpínlẹ̀ Ondo
Oríṣun àwòrán, Rotimi akeredolu
Ijọba ipinlẹ Ondo ti sọ pe idi ti oun ko ṣe tii paṣẹ igbele patapata ni awọn iṣoro to rọ mọ igbele ọhun.
Kọmiṣona ọrọ to n lọ ni ipinlẹ naa, Donald Ojogo lo sọ bẹ ninu ifọrọwerọ kan pẹlu BBC.
O ni ijọba n fi akoko yii mura silẹ fun awọn eto lati ran awọn ara ilu lọwọ, ati pe o n fi akoko yii fun wọn laaye lati ra ounjẹ sile.
Amugbalẹgbẹ fun Gomina Akeredolu, Ọmọwe Doyin Ọdẹbọwale koro oju si
Ojogo sọ pe ijọba yoo pasẹ ofin konileogbele patapata to ba jẹ dandan, ṣugbọn o ti gbe agadagodo ṣenu gbogbo ibode to wọ ipinlẹ ọhun bayii.
"O ni "" A ko sọ pe a ko ni paṣẹ konileogbele o, ṣugbọn a n gbadura ki ọrọ naa ma de ipele yẹn ni.""."
Kọmiṣọna ọhun sọ pe ijọba paṣẹ ofin gbele ẹ laarin aago meje alẹ si meje owurọ nitori awọn onifaaji to n gbafẹ lawọn agbegbe kan nilu Akure.
Nipa bi ipinlẹ Ondo ṣe n gbaradi de arun Covid-19, o ni ijọba Ondo n sa ipa rẹ lati gbogun ti arun naa.
Ǹjẹ́ àrùn Coronavirus leè wà lára èèyàn títí láílái?
Ẹwẹ, onimọ eto ilera kan, dokita Wilson Ikubese sọ pe ko yẹ ko ri bẹ.
Ikubese ni kii ṣe oru nikan ni arun Coronavirus n rin, nitori naa ko yẹ ki ijọba paṣẹ konileogbele laago meje alẹ si meje owuro.
Dokita ọhun fi kun pe ti ijọba apapọ ba fẹ kapa arun Coronavirus patapata, niṣẹ lo yẹ ko kede ofin konileogbele kaakiri gbogbo Naijiria.
Ṣé òfin kónílé-ó-gbélé lè mú àdínkù bá ìtànkálẹ̀ Coronavirus?
Ikubese ni ko yẹ ki ijọba kede konileogbele nikan, o yẹ ko ṣe ipese awọn ohun amayedẹrun fun awọn ara ilu.
Lẹyin naa lo rọ awọn eeyan lati ma ṣe imọtoto araẹni gẹgẹ bi ajọ to n gbogun ti ajakalẹ ni Naijiria, NCDC ṣe gbe kalẹ.
Ijọba ipinlẹ Ondo ti fẹsun kan awọn agbofinro pe awọn gan n pẹlu ọbọ jawura lori bi iye awọn to ni aarun Coronavirus ṣe n waye ni ipinlẹ naa.
Eeyan mẹta ni ayẹwo ṣi fihan pe o ni arun yii ni ipinlẹ Ondo, ṣugbọn ijsba ipinlẹ naa n ṣalaye pe awọn to wọ ilu lẹyin igba ti wọn ti iloro ẹnubodu ipinlẹ naa gbogbo lawọn eeyan naa wọle.
Oríṣun àwòrán, Arakunrin akeredolu
Eeyan mẹta ni ajọ to n dena ajakalẹ arun lorilẹede Naijiria, NCDC ṣi kede pe o laarun naa ni ipinlẹ Ondo eleyi ti o n kọ ijọba ipinlẹ naa lominu ni lọwọlọwọ.
Amugbalẹgbẹ fun gomina Rotimi Akeredolu lori akanṣe iṣẹ, Ọmọwe Doyin Ọdẹbọwale ṣalaye fun BBC News Yoruba ninu ifọrọwanilẹnuwo kan pe awọn ọlọpaa ti wọn ko sẹnu ibọde ipinlẹ naa lati maṣe jẹ ki ọkọ kọọkan wọle lati awọn ipinlẹ miran n gbabọde fun ijọba ni.
Gẹgẹ bi o ṣe sọ, owo ẹyin lawọn ọlọpaa naa n gba lọwọ awọn awakọ ti wọn si n jẹ ki wọn wọle.
Oríṣun àwòrán, Arakunrin Akeredolu
Gomina ipinlẹ Ondo, Arakunrin Rotimi Akeredolu ti kede ofin konile-o-gbele kaakiri ipinlẹ Ondo.
Igbele naa yoo maa waye laarin agogo meje irọlẹ si meje aarọ.
gomina Akeredolu ninu ọrọ to ba awọn eeyan ipinlẹ naa sọ lọsan ọjọ Iṣẹgun kminu lori iha kokanmi tawọn eeyan, paapaa awọn ọlọja, awọn onile ọti, awọn onile ijọsin atawọn eeyan kan n kọ si ilakaka gbogbo ti ijọba n sa lati dena itankalẹ arun naa.
Gomina Akeredolu ni bi oun ba tun gbọ pe eeyan kan ni ipinlẹ naa tun ko arun naa, oun yoo ti gbogbo ipinlẹ Ondo pa ni.
Oríṣun àwòrán, Arakunrin Rotimi Akeredolu
Gomina Akeredolu ni o ṣenmi laanu pe pẹlu gbogbo igbesẹ ti ijọba n gbe lati dena ajakalẹ arun naa nibẹ, eeyan kan ṣi lee rapala gbe arun naa wọle.
O ni ijọba yoo gbe igbesẹ to laapọn sii lati dẹkun itankalẹ arun Coronavirus ni ipinlẹ Ondo.
Oríṣun àwòrán, others
Agbẹ kan ni ilu Idanre ni ipinlẹ Ondo ti fi ẹṣẹ lu iyawo rẹ pa.
Baba agbẹ ẹni ọdun mọkanlelaadọrin naa ti wọn pe orukọ rẹ ni Eric Olowokande ni awọn ọlọpaa ṣalaye pe o fi ẹṣẹ lu iyawo rẹ, ti orukọ rẹ n jẹ Mojere.
Gẹgẹ bi ohun ti eeyan kan to ṣoju rẹ sọ ni kete ti ọrọ ja jo alagba Olowokande lọwọ tan lo bẹlugbẹ to si na papa bora lati lee sa mọ panpẹ awọn ọlọpaa lọwọ.
Awọn to ṣoju wọn ṣalaye pe ọrọ lo ṣe bi ọrọ laarin lskọlaya mejeeji yii eleyi to di yanpọnyanrin laarin wọn debi pe baba agbalagba yii ys ẹṣẹ ti iyawo rẹ yii titi ti obinrin naa fi ju ẹmi silẹ
Wọn ni ni kiakia ni wọn gbee digbdigba lọ si ile iwosan nibi ti dokita ti sọọ di mimọ pe arabinrin naa ti gba ekuru jẹ lọwọ ẹbọra.
Ijọba ipinlẹ Ondo gbe agadagodo sẹnu ọna awọn ile ijọsin to tapa sofin konileogbele
Oniruuru ọbẹ nijọ iku erin. Oriṣiriṣi iṣẹlẹ manigbagbe lo ti n waye lati igba ti aṣẹlẹ igbele lati dena itankalẹ arun COVID-19 yii ti bẹrẹ.
Ni ilu Akurẹ tii ṣe olu ilu ipinlẹ Ondo, nṣe ni pasitọ kan gbiyanju lati fo fẹnsi to yi ijọ rẹ ka nibi to ti n gbiyanju ati sa mọ awọn agbofinro ikọ amuṣẹya lori ofin gbele ẹ ti ijọba ipinlẹ Ondo gbe kalẹ lọwọ.
Ijọba ipinlẹ Ondo ati ẹgbẹ ọmọlẹyin kristi nibẹ ti kọkọ fi ẹnu ko pe awsn yoo ṣeto ipade ajọyọ ọdun Ajinde ni ọjọ Aiku ki ijsba to yi ohun pada nitori eeyan kan to tun ni arun naa nipinlẹ ọhun.
Eyi lo mu ki amugbalẹgbẹ fun gomina ipinlẹ Ondo lori ọrọ akanṣe iṣẹ, Ọmọwe Doyin Ọdẹbọwale ati ikọ amuṣẹya ijọba o fọn si igboro lati rii daju pe awọn ileejọsin tẹle aṣẹ yii.
Coronavirus lockdown: Síńimá kòṣewòtán, Pásítọ̀ fo fẹ́ǹsì láti sá mọ́
Bi o tilẹ jẹ pe awọn ileejọsin kan tẹle ofin yii pe kawọn ileejọsin ileejọsin o maa ṣi ilẹkun wọn fun ijọsin, ọpọ awọn ile ijọsin miran lo keti ikun si aṣẹ naa.
Lara awọn ileejọsin yii ni ijọ CAC Okelisa, ijọ TAJEM ni Irese, ijs Assemblies of God lagbegbe olufoam  nibi ti awọn ọmọ ijọ ti tilẹkun mọ ara wọn sinu ijọ naa ki awọn ọmọ ikọ amuṣẹya naa to fi tipatipa ṣi ilẹkun naa.
Amọṣa ọrọ naa di ti sinima awodamiẹnu nigba ti pasitọ ijọ naa gbiyanju ati fo fẹnsi lọna ati sa mọ awọn ikọ amuṣẹya naa lọwọ.
Oríṣun àwòrán, Rotimi akeredolu
Amugbalẹgbẹ fun gomina lori ọrọ akanṣe iṣẹ, ọmọwe Doyin Ọdẹbọwale ṣalaye pe gbogbo awọn Pasitọ tọwọ ba naa nijọba yoo fi jofin lẹyin ti oun ba ti jabs fun gomina lori rẹ.
O ni awọn ileejọsin maraarun ni wọn ti ti pa.
Bakan naa ni ikọ naa tun koro oju si bi awọn ọlọpaa to n ṣọ ibode ipinlẹ naa ṣe n gba owo lọwọ awọn ọlọkọ ero latijẹ ki wọn wọ ipinlẹ Ondo.
Coronavirus update: Àwọn ẹgbẹ́ agbábọ́ọ̀lù ìlẹ̀ Gẹ̀ẹ́sì fẹnukò láti parí líìgì ọdún yìí
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Awọn ẹgbẹ agbabọọlu nilẹ Gẹẹsi ti fohun ṣọkan pe awọn yoo gba awọn ifẹsẹwọnsẹ to ku ninu idije liigi tọdun yii ti arun Coronavirus da duro.
Nibi ipade kan to waye lọjọ Ẹti ni wọn ti gbe afẹnuko yii kalẹ bi o tilẹ jẹ pe wọn ko sọ igba kan ni pato ti wọn yoo pada bẹrẹ gbigba iyoku rẹ.
Ohun ti ọpọ lero ni pe awọn ẹgbẹ agbabọọẹu yoo jiroro lori boya ki wọn pada bẹrẹ ni ọgbọn ọjọ oṣu kẹfa ọdun 2020 ṣugbọn ilana ti wọn yoo fi to idije naa ni wọn jiroro le lori.
Ajọ to n ṣe aayan idije liigi ilẹ Gẹẹsi ṣalaye pe afojusun wọn ni lati pari awọn ifẹsẹwọnsẹ to ku.
Lati ọjọ kẹtala oṣu kẹta ni wọn ti gbe idije liigi ilẹ Gẹẹsi ti si ẹgbẹ kan nitori ajakalẹ arun Coronavirus.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ohun ti agbọ ni pe awọn ẹgbẹ agbabọọẹu naa ni asiko kọ niyi lati jiroro boya ọgbọọjọ oṣu kẹfa ni ki wọn bẹrẹ tabi rara.
Ṣaaju ninu ọoṣu yii ni ajs liigi ilẹ Gẹẹsi ti ṣalaye pe o digba ti alaafia ba ti pada ki awọn to ṣi ilẹkun liigi pada. Lati igba naa titi di asiko yii, iye awọn to ku ni ilẹ Gẹẹsi ti le lẹbẹrun mejila.
Ninu eto idibo kan ti ileeṣẹ iroyin ere idaraya BBC Sport gbe kalẹ lori bi o ṣe yẹ ki wọn pari idije liigi, ida mọkandinlogoji ninu awọn to dibo naa fẹ ki wọn wọgile saa liigi yii, ida mejidinlọgbọn ninu ọgọrun fẹ ki wọn pari rẹ bi o ti wu ko pẹ to.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ajọ ere bọọlu ilẹ Yuroopu ti rọ awọn ajọ to n ṣakoso liigi orilẹede kọọkan lati fun wọn ni asiko diẹ ki wọn fi yanju ọrọ lapa ọdọ tiwọn.
Lọsẹ to n bs ni ajọ UEFA yoo pade lati tubọ jiroro lori rẹ ninu eyi ti wọn fi n gbero ati lo aṣekagba idije Champions league fi pari saa ere bọọlu tọdun yii ni ọjs kọkandinlọgbọn oṣu kẹjọ.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ajọ to n ṣoju awọn eekan liigi ere bọọlu nilẹ Yuroopu sọ pe nigba yoowu ti wọn ba bẹrẹ si ni gba idije liigi kọọkan pada, wọn yoo maa se ilẹkun papa iṣire ni.
Liigi orilẹede Germany: awọn ẹgbẹ agbabọọlu ti pada si papa igbaradi ṣugbọn wọn ṣi gbe liigi orilẹede naa kọ di Ọgbọọjọ oṣu kẹrin.
Liigi orilẹede Spain: ko ni si igbaradi kọkan ayafi igba ti wọn ba gbe ẹsẹ kuro lori awọn eto  to wa nilẹ. Aarẹ ajọ liigi orilẹede Spain, Javier Tebas ni afaimọ ko maa di ọjọ kejidinlọgbọn ki wọn to bẹrẹ liigi pada nibẹ.
Liigi orilẹede Faranse: awọn alaṣẹ liigi lorilẹede Faranse n boju wo aarin ọjọ kẹta si ọjọ kẹtadinlogun oṣu kẹfa gẹgẹ bii ọjs ti wọn yoo bẹrẹ owo bọọlu gbigba pada lorilẹede naa.
Liigi orilẹede Italy: ajọ to n dari ere bọọlu lorilẹede Italy n gbero ati bẹrẹ ayẹwo awọn agbabọọẹu fun mims ẹni to ba ni arun coronavirus ninu wọn ni oṣu karun un ni igbaradi fun bibẹẹrẹ saa ligi wọn pada.
Gbèsè tí Buhari ń jẹ bójúmu, isẹ ìdàgbàsókè ló fi ń ṣe - Agbẹnusọ fún ilé aṣòfin àgbà
Oríṣun àwòrán, Nigeria senate
Ṣenatọ Surajudeen Ajibola Basiru, tí gbogbo ènìyàn mọ si SRJ, tíì se agbẹnusọ fun ilé igbimọ asofin àgbà ilẹ̀ wa ti ṣàlàyé pé, kò seese kí ilé asofin fi òfin de ẹnikẹ́ni, pàápàá àwọn aṣáájú wá, láti lọ gba
itọju lókè òkun.
Agbenuso fún ilé asofin àgbà ní bakan naa ni ọmọ sórí làwọn orile-ede míràn lagbaye, àmọ́ ó wà daba pé, ó yẹ kí ilẹ wa ṣe ìpèsè eto ìlera tó mọyàn lórí ni.
"Ajibola ni ""Kii se àwọn aṣáájú nìkan ló ń lọ sókè òkun, àwọn onísẹ adani, oniroyin àti àwọn èèyàn tó lowo lati lọ sókè òkun lo ń lọ gba itọju sugbọn a gbọ́dọ̀ kọ́kọ́ tọju ilé na, ká tó lọ síta ni."""
Nígbà tó ń sọ̀rọ̀ lórí owoya bilionu lọ́nà ẹgbẹ̀rin àti àbọ̀ náírà tí ìjọba Nàìjíríà ṣẹ̀ṣẹ̀ yá, Ajibola ni irọ tó jinna sooto ni èyí.
"O ni"" ṣáájú ni ile asofin tí buwolu pé kí ìjọba lọ ya owó náà lókè òkun kí àrùn Covid-19 tó dé, àmọ́ nígbà tí àrùn náà dé, ní ìjọba tún padà wá síwájú ilé pé, kí ilé fontẹ lu u pé kí ìjọba lọ yà owó náà ni abẹle dípò"
òkè òkun.
Lórí iyansipo rẹ bíi agbenuso fún ilé, Ajibola ni yiyan tí wọn yàn òun, tòun ṣẹ̀ṣẹ̀ wá sílè asofin àgbà fún ìgbà àkọ́kọ́, lo ṣe àfihàn ìgbẹ́kẹ̀lé tí àwọn asofin náà ni nínú òun ni.
Oríṣun àwòrán, SRJ
O ni òun ń ṣe iṣẹ́ tí wọn kọ́kọ́ fun òun takuntakun, ní wón tún ṣe fún òun ní isẹ akọni mìíràn, tíì ṣe agbenuso fún ilé.
Nígbà tó ń sọ̀rọ̀ lórí bí ìjọba ṣe de òkun lórí àṣẹ konile ó gbélé, ó ní igbese ìjọba náà lo fihan pe, ijọba tó ń gbọ igbe aráàlú lo wà nita, eyi tó fún wọn láǹfààní láti jáde síta lọ wà jíjẹ àti mímú.
Àmọ́ mo wà ń rọ àwọn ènìyàn wá láti tẹle asẹ ìjọba tó nii ṣe pelu òfin ìtakété síra ẹni, fifi aṣọ bo imú, ki wọn maa fi ọ̀sẹ̀ fọ ọwọ, bẹ́ẹ̀ ni kí wọn jìnnà sí ibi tí èrò bá pọ si. 
Oríṣun àwòrán, The nigeria senate
Nígbà tó ń sọ bóyá ijoba ati àwọn ọmọ Nàìjíríà tí kẹ́kọ̀ọ́ lórí àrùn Coronavirus, sẹnatọ Ajibola ni a ti kẹ́kọ̀ọ́ tó pọ̀, pàápàá julọ nípa ṣíṣe isẹ ni ile ati ṣíṣe àtúnṣe òfin ajakalẹ àrùn tó wáyé gbẹyin lọ́dún 1926, fifi
ìwé ipejọ lè èèyàn lọwọ láti ipasẹ ifiweransẹ Email pẹ̀lú sise ìpàdé àti eto ìdájọ́ lójú òpó ayélujára bíi Skype, Zoom àti bẹẹ bẹẹ lọ.
Bí ile asofin àgbà, a yà idà mẹwa ọ̀rọ̀ aje wá ṣílẹ̀ fún idagbasoke eto ìlera, ìdènà ajakalẹ àrùn àti ìmọ̀ ẹ̀rọ, tá sì tún ń ṣe agbeyẹwo àwọn òfin wá ti ọjọ́ tí lọ lórí wọn.
Oríṣun àwòrán, Laureta Onochie
Aarẹ Muhammadu Buhari tun ti yan eeyan kan to ti ku si ipo bayii  eleyi to ti n ṣe ọpọlọpọ eeyan ni haahin.
Aarẹ fi orukọ Oloogbe Tobias Chukwuemeka Okwuru gẹgẹ bii ọkan lara awọn ọmọ igbimọ alakoso fun ajọ ijọba apapọ kan lẹyin oṣu meji to ti jade laye.
Aarẹ Buhari fi iwe kan ṣọwọ si ileegbimọ aṣofin agbalorilẹede Naijiria ni ọjọ Iṣẹgun ninu eyi to kọ orukọ awọn eeyan mẹtadinlogoji to fẹ yan si ipo lai mọ pe Ọgbẹni Okwuru ti jade laye loṣu keji ọdun 2020.
Bi ẹ ko ba gbagbe bi ọdun mẹta sẹyin ni iroyin lu igboro pa pe Aarẹ yan ọpọ awọn eeyan to ti jalaisi sipo akoso loniran-an-ran.
Ninu ọrọ rẹ, ọkan lara awọn amugbalẹgbẹ fun aarẹ, Lauretta Onocjie ṣalaye penigba ti aarẹ kọ yan Okuru, ko tii ku nigba naa koda, 'o funra rẹ mu iwe ẹri rẹ wa ni imurasilẹ fun ifọrọwanilẹnuwo ti yoo waye ni ileegbimọ aṣofin agba.'
Oríṣun àwòrán, Bashir Ahmad
Ní ọjọ́ Isẹgun nílé asofin àpapọ̀ ilẹ̀ wa fi ontẹ lu ọgbọn biliọnu dọla ($30bn) owo tí ijọba àpapọ̀ ilẹ̀ wá fẹ gba lọdọ àjọ ayanilowo lagbaye IMF.
Láti ìgbà tí ìjọba àpapọ̀ si ti tẹ pẹpẹ owoya náà síwájú àwọn asofin àgbà, làwọn ọmọ orílẹ̀ èdè yìí tí ń béèrè pé ṣe ilẹ̀ wá tún nílò owoya kankan lásìkò tí ọrọ aje agbaye ti dagun yìí?
Wọn ní ṣe akọtun ìbéèrè fún owoya yìí, èyí tí yóò mú kí gbèsè tí ilẹ wa jẹ́ láwùjọ agbaye fò fẹrẹ sì biliọnu mẹtadinlọgọrun dọla ($97bn), kò ní ṣe àkóbá ńlá fún igbaye-gbadun àti ọjọ́ ọ̀la àwọn ọmọ orílẹ̀ èdè yìí?
Àmọ́ ṣe ẹni tó béèrè ọrọ, lo fẹ́ ìdí rẹ gbọ, nínú ìwádìí ikọ ìròyìn BBC Yoruba, ìjọba àpapọ̀ ti ṣàlàyé pe, oun fẹ́ gba owó náà lati fi mú kí ọrọ aje Nàìjíríà gbéra lásìkò ajakalẹ àrùn Covid-19 yìí, tí epo rọbi kò ta mọ ni ọjà àgbáyé, ti
ọ̀rọ̀ aje àgbáyé si dẹnu kọlẹ.
Ìjọba ni owo naa ni òun fẹ́ fi ṣe àwọn àkànṣe isẹ tó yà kalẹ ninu eto isuna ọdún 2020.
Jọwọ ṣe atunṣe ilana ikansi ayelujara rẹ lati ri ẹkunrẹrẹ rẹ
Orisun: Johns Hopkins University atawọn ajọ eto ilera ilu
Igba ti wọn kede iṣiro awọn to nii kẹyin                                              29 Oṣù Bélú 2021 13:33 WAT+3
*Iye awọn to tọwọ aisan ku ni isọri eeyan ẹgbẹrun lọna ọgọrun
Jọwọ ṣe atunṣe ilana ikansi ayelujara rẹ lati ri ẹkunrẹrẹ rẹ
Akọsile imọ yii, da lori akojọpọ iṣẹ iwadi ni Fasisti Johns Hopkins, o si le ma ṣe afihan awọn akọsilẹ iroyin to ba igba mu lati orilẹede kankan.
** Àwọn iyé akọsilẹ̀ to ti wà fún àwọn ti o ṣẹ́ṣẹ̀ ni ààrun náà jẹ́ àkójọpọ̀ ọjọ́ mẹ́ta. Nítori àwọn àtúgbẹ́yẹ̀wò, o níra láti ṣe àkójọpọ fún àwọn ọkọ́ naa
Orisun: Johns Hopkins University atawọn ajọ eto ilera ilu
Iye akọsilẹ to waye gbẹyin 29 Oṣù Bélú 2021 13:33 WAT+3
Ìjọba àpapọ̀ ni àkànṣe isẹ mọkandinlọgọrun tó wà káàkiri àwọn ẹkùn idibo tí ń bẹ lorilẹede èdè yìí, làwọn yóò fi owóya náà gbọ bukata rẹ.
Ìjọba sàlàyé pé, lọ́dún tó kọjá àkànṣe isẹ mẹ́rin péré nínú àwọn àkànṣe iṣẹ́ náà, ni ile asofin àgbà tó kogba wọlé fi àṣẹ si láti gbọ bukata rẹ lọ́dún 2016, nígbà tí àwọn àkànṣe isẹ yoku tí wọn kò buwọlu sì ṣe koko fún idagbasoke
Naijiria.
Lára àwọn àkànṣe isẹ ti ijọba si lo ṣe koko náà, tí wọn fẹ gbọ bùkátà wọn nínú owóya ọhun, lo wa ni ẹka eto ìpèsè ohun amusagbara, iwakusa, eto ọgbin, eto ìlera, ìpèsè omi tó ṣeé mú àti eto ẹ̀kọ́.
Ìjọba wá rọ àwọn ọmọ Nàìjíríà láti nigbagbọ nínú ìjọba, nítorí owoya náà ní wọn yóò lo fún àwọn àkànṣe isẹ tó yẹ fún.
Oríṣun àwòrán, Bashir ahmad
Ewu n bẹ loko lọngẹ, longẹ gan an ewu! Aarẹ ẹgbẹ awọn dokita lorilẹede Naijiria(NMA), Dokita Francis Faduyile sọ pe oṣeeṣe kawọn agboku atawọn to wa leti iboji lasiko isinku olori awọn oṣiṣẹ Aarẹ Muhammadu Buhari, Abba Kyari ko aarun coronavirus lati bẹ.
Nigba to n ba BBC Yoruba sọrọ, Dokita Faduyile ni bawọn eeyan ti pejọ leti iboji ati bawọn agboku naa ṣe gbe oku Abba Kyari tako ilana ijina sira ẹni ti ajọ to n gbogun ti ajakalẹ aarun, NDCD la kalẹ.
Aarẹ ẹgbẹ awọn dokita ni Naijiria fikun ọrọ rẹ pe ko yẹ ki ipejọpọ nibi kibi ju ogun eeyan tabi eeyan mẹẹdọgbọn lọ lasiko ti coronavirus wa lode yii.
''Aisan yii le ti ara oku ti wọn sin bọ si ara awọn eeyan to gbe posi tabi awọn eeyan to wa leti iboji,'' Dokita Faduyile lo woye bẹẹ.
O ni bi awọn eeyan ti sun mọ ara wọn nibi isinku Abba Kyari le ṣakoba fun awọn ọmọ Naijiria.
Dokita Faduyille sọ pe o yẹ ki gbogbo eeyan to wa nibi isinku naa yara wọn sọtọ ninu igbele fun ọjọ mẹrinla ki wọn si ṣe ayẹwo lati mọ boya wọn ko ni aarun naa.
Bakan naa lo bu ẹnu atẹ bi awọn oṣiṣẹ eleto ilera ṣe bọ aṣọ idaabo bo ara ẹni lọwọ aarun nibi isinku naa.
Ẹwẹ, lẹyin ọpọlọpọ ọjọ ti ile ẹjọ di da a lẹbi pe o tapa si ofin konile o gbele nipinlẹ Eko, gbaju-gbaja oṣerebinrin, Funke Akindele-Bello ti sọrọ lori iṣẹlẹ naa.
Ninu fidio kan to fi sita lọjọ Aiku, Akindele dupẹ lọwọ awọn ololufẹ rẹ fun atilẹyin ati aduroti wọn lasiko to fi la 'ewu' kọja.
Lẹyin to dupẹ lo ba awọn eniyan sọrọ pe otitọ ni pe aarun coronavirus wa lode.
"Funkẹ sọ pe ""asiko ẹkọ kikọ ni ọsẹ bi i melo sẹyin jẹ fun oun, ṣugbọn ko gbọdọ da itẹsiwaju duro."""
"Ẹyin ọrẹ mi, lootọ ni aarun coronavirus wa. Gbogbo wa lati si gbọdọ tẹsiwaju lati ṣiṣẹ pọ pẹlu ijọba ipinlẹ Eko ati ijọba apapọ nipa diuro nile, fifọwọ loorekoore ati sise iyagosiraẹni.
Ijina sira ẹni yoo ṣe iranlọwọ lati kapa aarun coronavirus. O ba awọn ti eeyan wọn toi ku sọwọ coroanvirus. O ki awọn eleto ilera.
Àṣìṣe ló ṣẹlẹ̀ níbi ètò ìsìnkú Abba Kyari- FCTA
Awa naa gba pe aṣiṣe lo waye nibi eto isinku ati lẹyin isinku olori oṣiṣẹ fun Aarẹ Buhari, Abba Kyari- FCTA
Ileesẹ ijọba apapọ to n mojuto ọrọ Abujato jẹ olu ilu Naijiria ti sọrọ lori ohun to ṣẹlẹ nibi eto isinku Abba Kyari ni iboji Gudu nilu Abuja ni ana.
Wọn dupẹ lọwọ awọn ọmọ Naijiria to ya fọnran naa ati awọn to pin in titi ti ọwọ ijọba fi tẹẹ.
Oríṣun àwòrán, Other
Wọn ni iwa bi arakunrin naa ṣe bọ aṣọ idaabobo to wọ lasiko to n gbe oku Abba Kyari sọnu silẹ naa ku diẹ kaato.
Eyi lo si ti jẹ ki ijọba Abuja gbe igbesẹ to yẹ pe:
Ijọba ni wọn rii pe awọn ohun eelo aabo ara ẹni lọwọ ajakalẹ aarun coronavirus naa wa kaakiri iboju oku naa
Ṣugbọn bayii, wọn ti lọ palẹmọ gbogbo ohun to wa nilẹ kaakiri itẹ oku ni Gudu nilu Abuja.
Ètò ìsìnkú Abba Kyari tako ìlànà ìjìnàsíraẹni lórí ààrùn covid-19- Àwọn ọmọ Nàìjíríà yarí
Bakan naa ni ijọba FCTA ti lọ fin kokoro apako ati apa kokoro aifojuri kaakiri itẹ oku to wa ni agbegbe Gudu nilu Abuja lati dẹkun itankalẹ arun coronavirus.
Ni Afikun, wọn ti n ko awọn eeyan ti ọrọ kan bi awọn oṣiṣẹ ni iboji oku naa si igbele fun ọjọ mẹrinla, lẹyin ti wọn yoo ṣe ayẹwo to yẹ fun wọn.
Ṣe wahala wá ti ọkọ bá kọ̀ láti fún aya tó ti kọ̀ silẹ lára ogún rẹ?
Ni afikun, FCTA tun fi atẹjade sita pe awọn ti da gbogbo awọn ti ọrọ kan mọ, awọn si ti fi ara balẹ wo iṣẹ ti wọn ṣe nibẹ ati ọna abayọ siṣoro to wa bayi
FCTA ṣeleri pe lẹyin isinku Abba Kyari yii, awọn lawọn yoo maa ṣeto oku ẹnikẹni ti coronavirus ba tun pa ni Abuja.
Coronavirus: Àwọn ọ̀nà tí ẹ le fi dun ara yín nínú lásìkò yìí
Wọn fi awọn ara Abuja lọkan balẹ pe ko nii si ewuitankalẹ ajakalẹ arun corona ni Abuja ati agbegbe rẹ.
Awuyewuye lórí nǹkan márùn ún tí ó níí ṣe pẹ̀lú Abba Kyari nígbà ayé rẹ̀ rèé
Abba Kyari: Awuyewuye lórí nǹkan márùn ún tí ó níí ṣe pẹ̀lú olórí òṣìṣẹ́ ààrẹ Buhari tó kú rèé
Bí àwọn ọmọ Nàìjíríà kan ṣe ń daro ikú Abba Kyari pé ẹni re lọ, ní àwọn míràn ń ju oko ọ̀rọ̀ lu àwọn oloselu lori ikú rẹ.
Olori awọn oṣiṣẹ ni ileeṣẹ Aarẹ lorilẹede Naijiria, Abba Kyari ju awa silẹ, o dagbere faye lalẹ ọjọ Ẹti lẹyin to ba arun COVID-19 wọ iyaaja ṣugbọn ti ko lee bori.
Ọpọ lo n foju wo Abba Kyari nigba aye rẹ gẹgẹ bii ẹni to lagbara julọ ni iṣejọba aarẹ Buhari.
Oríṣun àwòrán, Twitter/Bashir Ahmad
Ni ọdun 2015 ni aarẹ Buhari yan Abba Kyari gẹgẹ bii olori awọn oṣiṣẹ ni ọfiisi aarẹ; ipo yii lo si wa di ọdun ọjọ kẹtadinlogun oṣu kẹrin, ọdun 2020.
Nigba aye rẹ oniruuru awuyewuye lo wọ tọọ lẹyin:
Ẹsun pe Abba Kyari gba abẹtẹlẹ lọwọ ileeṣẹ ibanisọrọ MTN
Lọdun 2016 lẹyin ti ajọ to n ṣakoso ẹka ibanisọrs lorilẹede Naijiria, NCC paṣẹ ki ileeṣẹ ibanisọrọ MTN o san owo itanran fun bi o ṣe kuna lati ys gbogbo nọmba ibanisọrọ awọn eeyan ti ko ṣeto iforukọsilẹ awọn nọmba ibanisọrọ wọn gẹgẹ bi ofin ṣe laa kalẹ.
Wọn fi ẹsun kan oloogbe Abba Kyari nigba naa pe o gba owo ẹyin to to ẹẹdẹgbẹta miliọnu naira lọwọ ileeṣẹ naa lati lee din iye owo itanran ti wọn ni ki ileeṣẹ naa san nigba naa.
Ko sẹni to fi idi eyi mulẹ nigba naa nitori Abba Kyari funra rẹ gan ke sawọn oṣiṣẹ agbofinro DSS lati wadii oun.
Ẹsun pe Abba Kyari ni olori awọn igbimọ apaṣẹ wa (Cabal) ni ileeṣẹ aarẹ.
Lati igba ti aarẹ Buhari ti de ori oye ni ariwo pe awọn alagbara kan wa to n paṣẹ ni ijọba rẹ ti bẹrẹ. Awọn alagbara yii ni wọn ni wọn n fi ọla jiyọ ti wọn si ti sọ aarẹ Buhari di aarẹ gbẹwudani. Ọrọ yii di ọrọ ajọsọ kaakiri orilẹede Naijiria paapaa julọ lasiko ti ara aarẹ Buhari ko fi ya to fi lọ gba itọju ni ilu Lọndọn.
Oríṣun àwòrán, others
Gẹgẹ bi iroyin nigba naa,ko si ẹnikẹni to lee ṣe ohunkohun nigba naa bi awọn igbimọ alagbara yii ko ba fọwọ sii.
Aawọ laarin Abba Kyari ati aya aarẹ, Aisha Buhari
Iyawo aarẹ Buhari, Aisha Buhari ni a lee sọ pe o jẹ eeyan akọkọ lara awọn to sun mọ aarẹ Buhari  to kọkọ pariwo sita pe lootọ ni awọn igbimọ alagbara yii wa.
Aisha Buhari pariwo sita nigba naa pe pe awọn eeyan kan n ko aarẹ Buhari ni papa mọra ti wọn si sọ ara wọn di apaṣẹ waa ni ileeṣẹ aarẹ.
Kyari ko iyan ipo igbakeji aarẹ, Oṣinbajo kere.
Bakan naa ni iroyin lọ kaakiri nigba kan naa lorilẹede Naijiria to fẹsun kan Abba Kyari nigba naa pe o n lo anfani bi o ṣe sunmọ aarẹ Muhammadu Buhari  lati maa fi jẹ gaba le igbakeji aarẹ, Yẹmi Oṣinbajo lori.
Ọpọ awọn iwe iroyin abẹle lorilẹede Naijiria nigba naa ni wọn royin bi Abba Kyari ṣe n lo agbara aarẹ Buhari lati ti awọn ohun ti Oṣinbajo ba beere fun inawo si ẹgbẹ kan
Awuyewuye pe Abba Kyari n toju bọ ọrọ to nii ṣe pẹlu abo orilẹede Naijiria.
Laipẹ yii ni awọn iwe iroyin abẹle kan gbee pe iwe ijsba kan wa ti adari eto abo lorilẹede Naijiria, Babagana Monguno ti n fi ẹsun kan Abba Kyari pe o ṣe ayọjuran lọna to lewu si ọrọ eto abo orilẹede Naijiria.
Bakan naa ni Monguna ti fẹsun kan Abba Kyari pe o n paṣẹ fun awọn olori ileeṣẹ alaabo gbogbo lorilẹede Naijiria, eleyi ti aarẹ funrarẹ kii mọ si lọpọ igba.
Ẹ wo àwọn ẹ̀kọ́ tí ikú Abba Kyari kọ olóṣèlú Nàìjíríà - Aráàlú ṣàlàyé
Yoruba ni bàa kú laa dere, èèyàn kò sunwọn ni aaye àmọ́ èyí kò rí bẹ́ẹ̀ pẹ̀lú ikú olórí òṣìṣẹ́ nílé isẹ Ààrẹ, Abba Kyari tó dara ilẹ̀.Lójú opo ikan sira ẹni Twitter àti Facebook, onírúurú ọ̀nà ni awọn ọmọ Nàìjíríà ń gba daro olóògbé náà, bí àwọn kan se kárí bọnu pé ẹni re lọ, ní àwọn miran lọ ikú rẹ láti sọ oko ọ̀rọ̀ sáwọn oloselu Nàìjíríà.
Bẹẹ si ni ọ̀pọ̀ àwọn akẹẹgbẹ rẹ nínú oselu, pàápàá àwọn igun alátakò lo ń ṣe ìdárò rẹ fún ipa tó ko fún ìlọsíwájú orílẹ̀-èdè Nàìjíríà.
Femi Fani-Kayode @realFFK daro pé òun ti pàdánù ọrẹ ogójì ọdún táwọn di jọ lọ sílè ẹ̀kọ́ fasiti Cambridge.
O ṣe àpèjúwe olóògbé náà bíi èèyàn rere àti ẹni apọnle bí ó tilè jẹ́ pé èrò àwọn nínú òṣèlú ṣe ọ̀tọ̀ọ̀tọ̀.
Daddy Freeze @DaddyFRZ lójú òpó tiẹ̀ ni, ẹkọ mẹta ni ikú Abba Kyari kọ àwa ọmọ Nàìjíríà àtàwọn oloselu.
Èkíní ni pé, ikú Kyari fìdí rẹ múlẹ̀ pé, lóòótọ́ ni àrùn Coronavirus wá, to sì ń pá èèyàn.Ẹ̀kọ́ kejì ni pé a nílò abẹrẹ ajẹsara ni kíákíá lórílẹ̀-èdè yìí tí ẹkọ kẹta si n ke si wa pé àwọn ilé ìwòsàn wá nílò àtúnṣe lọgan.
Awọn mii n beere ibeere nla pé bawo la ṣe fẹ mọ pe Abba Kyari ganhan lo ku  lasiko yii pé Ta lo le sọ nipato pe Kyari ni wọn n sin pe o ku?
@CallMeBiola sọ ń tiẹ̀ pé, bóyá Abba Kyari lo kú àbí ẹlòmíràn, inú òun kò dùn rárá pé àrùn Covid-19 ń pá ọmọ Nàìjíríà.
Bákan náà ni àwọn miran ń kesi àwọn aláṣẹ Nàìjíríà pé, kí wọn kọ ẹ̀kọ́ ńlá nípa ohun tí àwọn ọmọ Nàìjíríà ń sọ lẹ́yìn ikú Abba Kyari
Wọn ni ki wọn sì máa rò ohun tí aráyé yóò sọ nípa tiwọn náà, tí wọn ba papoda. Awọn bii: @akeula_trendy
Jù gbogbo rẹ lọ, àwọn oloselu Naijiria ni wọn ń kesi julọ lórí ikú olórí òṣìṣẹ́ fún Ààrẹ Buhari, láti fi ikú rẹ ṣe arikọgbọn.
Ọpọ ni bí onirese wọn kò bá fín igba mọ, èyí tí wọn fín silẹ, kò leè parun láéláé ati pe ariṣe larika; arika ni baba iregun, ohunkohun ti oloṣelu kọọkan ba ṣe laraye a royin lọjọ iku rẹ.
Oríṣun àwòrán, Bashir Ahmad/twitter
Ìfẹ́ orílẹ̀-èdè Nàìjíríà  ló sọkùnfà ikú Kyari - Lai Mohammed
Abba Kyari: Lai Mohammed sọ pé aájò kí Nàìjíríà le dára ló sọkùnfà ikú Kyari
Minisita fun eto iroyin ati aṣa ni Naijiria, Lai Mohammed ti sọ pe aajo Naijiria lo pa Abba Kyari.
Aarun Covid-19 ti ṣekúpa olórí àwọn òṣìṣẹ́ ní ilé ìjọba ní Abuja tó tún jẹ amúgbálẹgbẹ fún Ààrẹ Muhammadu Buhari.
Oríṣun àwòrán, others
Lasiko to n ba BBC Yoruba sọrọ, Lai sọ pe eniyan to fi ara ṣiṣẹ fun Naijiria, to si nifẹ orilẹ-ede naa ni Kyari jẹ nigba aye rẹ, tako bi ọpọlọpọ ṣe maa n bu ẹnu atẹ lu u.
Lai ṣapejuwe Kyari gẹgẹ bi ọkan pataki ninu iṣejọba Aarẹ Muhammadu Buhari, nitori pe ko si nkankan ti aarẹ fẹ ẹ ṣe ti ko ni i fi to o l'eti. Oun ni alamọran aarẹ."""
Oríṣun àwòrán, others
"Lai Mohammed sọ pe Aarẹ Buhari ni iku Kyari maa dùn ju nitori pe o jẹ ẹnikan ti aarẹ gbarale pupọ fun imọran."""
"Gẹgẹ bi Lai ṣe sọ, ọpọlọpọ eniyan ko mọ nipa oloogbe pe o fi tọkantọkan ṣiṣẹ fun ilu wa lati ri pe iṣẹ agbẹ lọ soke, ni pataki julọ, ọrọ irẹsi gbingbin, ati ajilẹ (fertilizer) wa lara awọn nkan to mu lọkunkun dun."""
Lai tẹsiwaju lati sọ pe ọrọ Kyari dabi olootọ ti kii lẹni.
"Germany to lọ to ti kagbako coronavirus, ko lọ fun igbadun ara rẹ. O lọ nitori ilu ni. Ọrọ ina mọna-mọna Naijiria lo ba lọ sibẹ.
Aarẹ ni iku rẹ maa fi pupọ nitori pe o jẹ ẹnikan ti aarẹ gbarale pupọ fun imọran."""
Wọn ti gbe oku olori awọn oṣiṣẹ fun Aarẹ Buhari, Abba Kyari de ilu Abuja fun isinku.
Oluranlọwọ fun Buhari lori ọrọ ayelujara, Bashir Ahmad lo fi ikede naa sita.
Èyí ni àwọn nkan tó yẹ́ kí o mọ̀ nípa Abba Kyari tí coronavirus pa
Abba Kyari ti iku wọlede mu lọ lẹyin ikọlu ajakalẹ arun coronavirus to n gbẹbọ lọwọ gbogbo agbaye yii jẹ odu ti kii ṣe aimọ fun oloko.
Ẹya Kanuri lati ipinlẹ Borno ni olori oṣiṣẹ fun Aarẹ Muhammadu Buhari, Abba Kyari, ti aarun Covid-19 pa.
Ni ọdun 1980, o gba oye imọ ijinlẹ akọkọ ninu imọ nipa ibagbepọ ẹda, Sociology, ni fasiti Warwick. Bakan naa lo gba oye imọ ijinlẹ akọkọ ninu imọ ofin ni Fasiti ilu Cambridge.
Ọdun 1983 ni wọn gba a wọle si iṣẹ aṣofin ni Naijiria, lẹyin to lọ si ileewe imọ ofin Naijiria, Nigeria Law School.
Yatọ si eyi, Kyari tun kẹkọọ lori idagbasoke amojuto ileeṣẹ, ni ileewe eto okoowo, Harvard Business School lọdun 1992 ati 1994.
O fẹ iyawo kan, o si bi ọmọ mẹrin.
Nigba aye rẹ, Kyari ṣiṣẹ amofin pẹlu gbaju-gbaja oloṣelu, oloogbe Fani-Kayode.
Oríṣun àwòrán, Others
O ṣiṣẹ gẹgẹ bi olootu iroyin nileeṣẹ New Africa Holdings Limited nilu Kaduna.
Laarin ọdun 1990 si 1995, Kyari jẹ oye akọwe fun igbimọ oludari African International Bank Limited.
Bakan naa lo jẹ oludari agba fun ẹka awọn alamojuto ni ile ifowopamọ United Bank for Africa, UBA, ko to di pe o di ọga patapata.
Wọ́n fi agídí sé ọmọ Naijiria mọ́lé ní China nítorí àrùn Coronavirus
Lọdun 2002, wọn yan-an gẹgẹ bi oludari igbimọ alakoso fun ileeṣẹ aladani Unilever Nigeria, ko tun to o darapọ mọ igbimọ alakoso ileeṣẹ eporọbi Exxon Mobile Nigeria.
Kyari lo ṣaaju awọn aṣoju ẹkun ariwa Naijiria lọdun 1994 nibi  apero National Constitutional Conference ki wọn to yan an gẹgẹ bii alaga igbimọ to n mojuto ọrọ eto aabo.
Oríṣun àwòrán, others
Abba ti ṣiṣẹ gẹgẹ bii ọkan lara awọn ọmọ igbimọ adari ile ifowopamọ First Bank, Merchant Bank of Commerce ati ile iṣẹ Adojutofo Standard Alliance Insurance ri.
Ọdun 2015 ni wọn yan Kyari gẹgẹ bi Olori awọn oṣiṣẹ fun Aarẹ Muhammadu Buhari.
Kyari jẹ eniyan pataki ninu eto iṣakoso Buhari, debi pe awọn iroyin kan sọ pe oun gan-an ni onílù tó n lu ìlù fún ìròmi Aarẹ Buhari.
Aarun coronavirus ti pa olori awọn oṣiṣẹ lọfiisi Aarẹ Muhammadu Buhari, Abba Kyari.
Agbẹnusọ fun aarẹ Buhari, Femi Adesina lo kede iku rẹ lojo opo twitter ni oru ọjọ Abamẹta.
Gẹgẹ bi Adesina ṣe sọ, ọjọ Ẹti, ọjọ kẹtadinlogun, oṣu Kẹrin ni Kyari ku.
Ọjọ kẹrinlelogun, oṣu Kẹta, ọdun 2020, ni ajọ to n mojuto itankalẹ aarun ni Naijiria, NCDC, kede pe Kyari ni Covid-19.
Ọjọ diẹ ṣaaju ọjọ naa ni Kyari pada si orilẹ-ede Naijiria nibi to ti lọ duna-dura okoowo kan pẹlu ileeṣẹ Siemens AG.
Ilu Abuja ni wọn ti kọkọ n tọju Kyari, ko to o di pe iroyin sọ pe wọn ti gbe e wa si ilu Eko ni ọjọ kọkandinlọgbọn, oṣu Kta, lati maa gba itọju fun aarun naa.
Ọpọlọpọ ọmọ Naijria lo si bu ẹnu atẹ lu igbesẹ naa, pẹlu alaye pe ilu ti ẹni to ni Covid-19 ba n gbe naa ni ki wọn o ti ma a tọju wọn.
Iroyin sọ pe Abba Kyari ni aisan otutu aya, Pneumonia, ati awọn aisan miran ninu agọ ara rẹ, ko to di pe o ko aarun coronavirus.
Awọn onimọ nipa eto ilera si ti sọ pe awọn to ba ni iru awọn aisan bẹ ẹ lara tẹlẹ ni coronavirus yara lati pa.
Coronavirus Vaccine: Ṣé abẹrẹ àjẹsára ti wà fún àrùn COVID-19?
Kyari ni olori ijọba to kọkọ ni Covid-19 ni Naijiria.
Abba Kyari: Àwọn ojúṣe olórí àwọn òṣìṣẹ́ fún ààrẹ Nàìjíríà
Oríṣun àwòrán, Others
Olori awọn oṣiṣẹ fun Aarẹ Naijiria jẹ alarina laarin aarẹ ati ijọba.
Aarẹ lo si maa n yan ẹni ti yoo ba jẹ olori oṣiṣẹ fun, eyi ti ko nilo ontẹ ilẹ aṣofin. Aarẹ Olusegun Obasanjo lo da ipo naa silẹ lasiko iṣejọba rẹ lọdun 1999.
Eyi si ni akọsilẹ awọn Olori Oṣiṣẹ aarẹ to ti jẹ lati igba naa:
Ojuṣe Olori awọn oṣiṣẹ aarẹ yatọ sira wọn lati iṣejọba kan si omiran. Ko si da lori amuyẹ ẹni ti wọn ba yan nikan, o tun ni i ṣe pẹlu afojusun ilana iṣejọba aarẹ to wa lori oye.
Awọn onwoye nipa eto oṣelu ti bẹrẹ si ni woye ẹni ti yoo rọpo olori oṣiṣẹ Aarẹ Buhari, Abba Kyari to d'oloogbe.
Ọjọ Ẹti ni Kyari d'oloogbe ni ipinlẹ Eko lẹyin ọsẹ diẹ toni aarun coronavirus.
Ọkan pataki ninu ijọba Aarẹ Buhari ni Kyari, ti o si tun jẹ ọrẹ timọtimọ si Aarẹ Buhari.
Onimọ nipa eto oṣelu, Dokita Abubakar Kari sọ wi pe awọn eniyan wa ti yoo rọpọ aye ti Abba Kyari fi silẹ.
Ètò ìsìnkú Abba Kyari tako ìlànà ìjìnàsíraẹni lórí ààrùn covid-19- Àwọn ọmọ Nàìjíríà yarí
Lara awọn ti Kari sọ wi pe o le rọpo Kyari ni Asoju ilẹ Naijiria, Babagana Kingibe, Adari ileeṣẹ ẹṣọ ibode lorilẹede Naijiria, Hammed Ali ati Minisita fun eto ẹkọ, Adamu Adamu.
O sọ pe ọrẹ ni Adamu Adamu ati Hammed Ali jẹ si Aarẹ Buhari.
Ko ni i jẹ iyalẹnu, ti aarẹ ba mu ọkan ninu awọn mejeeji.
"O tẹsiwaju lati sọ pe ipo Olori awn oṣiṣẹ fun aarẹ yatọ si ti gomina, nitori naa mi o lero pe Gomina Nasir El-Rufai wa lara awọn ti aarẹ le yan""."
Awọn kan ti ẹ n sọ pe boya Minisita fun ọrọ abẹle tẹlẹ, Abdulrahman Dambazau le gba ipo naa, nitori pe o ti n dafun tolo si tipẹ.
Ṣugbọn, onimọ nipa oṣelu naa sọ pe pẹlu bi Buhari ko ṣe pada yan sipo minisita fun igba keji, o ṣeeṣe ko ma yege lati di olori oṣiṣẹ rẹ.
Babagana Kingibe
Ipinlẹ Borno naa lo ti wa gẹgẹ bi oloogbe Abba Kyari,bẹẹ lo si ti di ipo mu ni awọn ẹka ijọba l'orilẹ-ede Naijiria.
O si tun jẹ ọrẹ si Aarẹ Muhammadu Buhari, amọ awọn miran bu ẹnu atẹ lu ọna ti o  n gba ṣe oṣelu.
Oríṣun àwòrán, Hammed Ali
Hammed Ali
Hammed Ali ni Adari ileeṣẹ aṣọbode lorilẹede Naijiria.
Fun ọpọlọpọ ọdun ni o fi wa pẹlu aarẹ Buhari gẹgẹ bi ọmọ ogun Naijiria.
Ohun ti awọn eniyan mọ Hammed Ali si ni pe kii huwa jẹgudujẹra tabi lu owo ilu ni ponpo, ti o si ma n ṣọra ni ọdọ awọn ọrẹ rẹ.
Oríṣun àwòrán, Adamu adamu/twitter
Adamu Adamu
Lati ibẹẹrẹ iṣejọba Aarẹ Muhammadu Buhari ni ọdun 2015 ni Arakunrin Adamu Adamu ti jẹ minisita fun eto ẹkọ.
Adamu jẹ onkọwe to ti kọ ọpọlọpọ nkan nipa bi o ṣe n lọ l'orilẹ-ede Naijiria.
O jẹ ẹni to ni ọpọlọpọ oye nipa eto oṣelu abẹle Naijiria.
Oríṣun àwòrán, Kaduna Govt
Nasir El-Rufai
Nasir El-Rufai ni Gomina ipinlẹ Kaduna lọwọlọwọ.
Iroyin sọ pe El-Rufai duna duna fun ipo olori awọn oṣiṣẹ ni ọdun to kọja, amọ ileeṣẹ BBC ko ni ẹri to fi idi iroyin yii mulẹ.
Awọ̣n onwoye so wi pe to ba bọ si ipo naa, yoo ṣeeṣe fun lati dije dupo fun aarẹ orilẹede Naijiria ni ọdun 2023.
Amọ, awọn miran tun woye pe o ṣeeṣe ko ma ri aye fun ati du ipo naa.
Richard Akinjide: Ìtàn igbe ayé Richard Akinjide, agbẹjọro àti olóṣèlú tó moye
Yoruba ni awaye ku kò sì, kò sì ẹni tí kò ní kú, kò si ẹni ti oko baba rẹ kò ní di igboro.
Kii se ìròyìn tuntun mọ pe orílẹ̀ èdè Nàìjíríà tún ti padanu ọkàn lára ojúlówó ọmọ orílẹ̀ èdè yìí, èèkàn ìlú àti àgbà amofin, Olóògbé olóyè Richard OSUOLALE Abimbola Akinjide.
Ìdajì kutu òwúrọ̀ ọjọ́ Isẹgun ni ìròyìn tán kalẹ pé erin tí wó, akọni amofin tí lọ, bẹ́ẹ̀ sì lo yẹ ká mọ àkọsílẹ̀ àwọn ohun tó gbé ilé ayé ṣe.
Gẹ́gẹ́ bàa tí ká a lójú òpó itakun agbaye, ọdún mọkandinlaadọrun ni olóògbé Akinjide lo lókè erupẹ, kò tó tẹrí gbasọ, bí ìtàn ayé rẹ sì ṣe lọ ree:
Ìlú Ibadan, tíì ṣe olú ìlú Ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́ ni Osuolale forí sọ ilẹ̀ sì ni ọdún 1930, ní agboolé Aperin, ládùúgbò Orita Aperin n'ilu Ibadan.
Agboolé Aperin jẹ ìdílé àwọn akíkanjú jagunjagun láyé atijọ, a sì leè ni ẹ̀jẹ̀ lọ ro Osuolale, tí òun náà fi jẹ akíkanjú ẹ̀dá lókè eepẹ.
Ilé ẹ̀kọ́ gírámà Odùduwà College nílùú Ilé-Ifẹ̀ ni Osuolale lọ lẹ́yìn tó parí ẹ̀kọ́ alakọbẹrẹ ni Ibadan, tó sì ṣe àṣeyọrí ńlá nibẹ.
Oríṣun àwòrán, Others
Ọmọ ti yoo jẹ́ Ásàmú ni ọrọ Osuolale, kékeré lọ tí ń jẹ ẹnu samu-samu nítorí esi idanwo ipele àkọ́kọ́, taa mọ sì Grade one ni Osuolale mú jáde nínú ìdánwò asejade, gbogbo iṣẹ tó sì jókòó sedanwo rẹ, lo yege pátápátá.
Àṣeyọrí alailẹgbẹ yìí ló ṣe iwuri fáwọn òbí rẹ láti jẹ ko tẹsiwaju lẹ́nu ẹ̀kọ́ rẹ lọ sókè òkun lọ́dún 1951, láti lọ kọ ẹ̀kọ́ ìmọ̀ òfin nílùú Ọba United Kingdom (UK), to sì yege ni ọdun 1955.
Òǹtàjà aṣọ ni mí tẹ́lẹ̀, ọ̀dá owó ló sọ mi di alábárù
Osuolale ni ifẹ ilẹ̀ bàbá rẹ pupọ, ìdí si rèé tó fi pinnu láti má ṣe jókòó silu ọba, àmọ́ ó padà wá sile láti wá da ẹ̀ka isẹ agbẹjọro tiẹ̀ si orílẹ̀ èdè Nàìjíríà èyí tó pe orúkọ rẹ ní Akinjide & Co.
Osuolale ṣe gùdù gùdù meje àti ya ya mẹ́fà nídìí isẹ agbẹjọro ni Nàìjíríà, tí òkìkí rẹ sì kan yíká ilẹ̀ yìí àti lókè òkun, a kò sì lè e gbàgbé inagijẹ Mr two third tí wọn ń pé olóògbé náà.
Osuolale, gẹ́gẹ́ bíi agbẹjọro àgbà fún ẹgbẹ́ òṣèlú NPN, ẹgbẹ́ Onílé nígbà náà, gba inagijẹ Mr two third ọhun, nítorí bo se kéde lórí redio lọ́dún 1979 lẹ́yìn ibo aarẹ tó gbé Alhaji Shehu Shagari wọlé pé,  idà méjì nínú mẹta ìpínlẹ̀ mọkandinlogun tó wà ní Nàìjíríà jẹ́ 12 2/3.
Ọ̀nà kan kò wọ ọjà ni ọrọ Osuolale nítorí bo ti ń ṣe agbẹjọro lọ tún mú oselu mọ isẹ rẹ, tó sì jẹ minisita feto ẹ̀kọ́ ni ṣáá eto ìṣèlú àkọ́kọ́, ni ayé ijọba Tafawa Balewa
Bákan náà lọ tún jẹ́ minisita feto ìdájọ́ ni ṣáá eto iselu alágbada kejì, nígbà tí Alhaji Shehu Shagari jẹ aarẹ Naijiria.
Kí ogbó tó dá ikooko Osuolale lára, ó ṣiṣẹ agbẹjọro débi pé ó gbà òye àgbà amofin taa mọ si SAN, tó sì tún jẹ́ òye n'ilu Ibadan, tíì ṣe ikú abinibi rẹ.
Richard Osuolale Abimbola Akinjide wá sílè ayé, ó ṣe ayé rẹ, o jagun, ó sẹgun, to sì ṣe àṣeyọrí nínú gbogbo ohun tó dá wọ lé.
Osuolale ni ìyàwó, èyí tó ti jẹ́ ìpè Ọlọ́run síwájú rẹ, tó sì bí ọpọ ọmọ pẹ̀lú, nínú èyí taa tí rí Amofin Olajumoke Akinjide, tí òun náà jẹ amofin àti minisita tẹ́lẹ̀ fún olú ìlú ilẹ wá, Abuja.
BBC Yoruba wa ń gba ni àdúrà pé Ọlọ́run Ọba yóò gbà àbọ̀ olóògbé náà, yóò si fi ikú ṣe ìsinmi fún un.
Akọroyin BBC to ṣe abẹwo si ile oloogbe to wa ni adugbo Idi Ishin nilu Ibadan jabọ pe ẹbi, ara, ọrẹ ati awọn olubanikẹdun ti n pejupesẹ si ile oloogbe naa.
Aworan Oloye Akinjide n bẹ lorii tabili pẹluu iwe nla kan ti awọn olubanikẹdun n kọ ikini ati idagbere ikẹyin si.
Ko tii si alaye ni pato lori isinku oloogbe, ṣugbọn iwadi fi idi rẹ mulẹ pe wọn ti tọju oku oloogbe si ileewosan ikọsẹ iṣegun oyinbo, UCH to n bẹ ni Ibadan.
Lara awọn eekan ilu to ti ṣedaro rẹ ni igbakeji aarẹ Naijiria nigba kan, Atiku Abubakar.
Atiku sọ pe Akinjide gbe igbeaye to ni ipa gẹgẹ bi amofin, oloṣelu ati olori ilu.
Bakan naa ni Minisita fun igboke-gbodo ọkọ ofurufu, Femi Fani-Kayode naa sọ pe Akinjide jẹ olori ilu ti ko ṣe fọwọ rọ sẹyin.
Oru ọjọ Iṣẹgun ni iroyin jade pe amofin ati agbẹjọrọ, Oloye Abimbọla Oṣuọlale Richard Akinjide ti ju awa silẹ.
Baba da gbere faye ni nkan bi agogo kan oru lẹni ọdun mejidinlọgọrin ni ile rẹ to wa ni ilu Ibadan lẹyin aisan ranpẹ.
Oloye Richard Akinjide ti figbalan ri jẹ minisita feto idajọ  lasiko  iṣejọba Aarẹ Shehu Shagari.
Bakan naa lo jẹ minisitita feto ẹkọ nigba iṣejọba saa oṣelu akọkọ lorilẹede Naijiria labẹ olootu ijọba naa, Alaaji Tafawa Balẹwa.
Coronavirus Updates: UCH ní èròjà Covid-19 tíjọba fún òun kò tó ₦1m
Oríṣun àwòrán, Others
O ti to ọjọ mẹta bayii ti awuyewuye ti n lọ laarin ijọba ipinlẹ Oyo ati ile iwosan UCH lori ibi ti miliọnu mejidinlọgọfa naira wa.
Ijọba ipinlẹ Oyo lo kede pe biliọnu meji ati miliọnu lsna ẹẹdẹgbẹẹta naira ni oun na fun itọju arun Coronavirus.
Bakan naa lo fikun pe miliọnu lọna mejidinlọgọfa naira ni oun na fun ile iwosan UCH ninu owo yii.
Amọ ile iwosan naa ti figbe bọnu pe irọ to jinna sootọ ni ikede ijọba yii nitori oun ko gba owo naa lọwọ ijọba.
Idi ree ti BBC Yoruba fi n tanna wadi ibi ti owo yii wọlẹ si, abi ejo miran tun ti mi owo ijọba ipinlẹ Oyo ni?
Nigba to n ba BBC Yoruba sọrọ, osisẹ alarina fun ile iwosan UCH, Toye Akinrinola salaye pe eroja ti ko ju miliọnu kan naira ni UCH gba lọwọ ijsba ipinlẹ Oyo.
Oríṣun àwòrán, Facebook/UCH
UCH si wa lori ẹsẹ rẹ pe, ohun ko gba iranwọ owo kankan lati ọdọ ipinlẹ Oyo fun itọju awọn to ni aarun Coronavirus.
Amọ akọwe iroyin fun Gomina Seyi Makinde, Ọgbẹni Taiwo Adisa lasiko to ba BBC Yoruba sọrọ ṣalaye pe, ijọba ṣeranwọ fun UCH pẹlu awọn irinṣẹ atawọn eroja itọju awọn alaarun Covid-19.
Ọgbẹni Adisa ni ijọba ipinlẹ Oyo ti ṣi owo to fi ra gbogbo eroja atawọn irinṣẹ naa, o si jẹ miliọnu mejilelọgbọn
Adisa ni ijọba tun ra eroja ati irinṣẹ to to miliọnu mẹrindinlaadọrun un(N86m) fun ẹka ẹkọṣẹ nipa awọn kokoro aifojuri (Department of Virologyy).
Oríṣun àwòrán, Seyi Makinde Facebook
Ṣugbọn agbẹnusọ fun ile iwosan UCH, Toye Akinrinola sọ fun BBC Yoruba pe, iranwọ aṣọ idaabobo lọwọ arun, (PPE) bii ọtalerugba o din mẹwaa(250) nikan UCH gba lọwọ ijọba.
Amọ Akinrinola ṣalaye pe, gbogbo aṣọ PPE naa ko to miliọnu kan naira lọja.
Agbẹnusọ ile iwosan UCH wa ke pe ijọba lati ṣalaye ohun ti o fi miliọnu mejilelọgbọn ra gan an fun UCH.
Kid boxer: Ọmọọba 'The Buzz' Larbie rèé, ọmọ ọdún méje tó ń fi ẹ̀ṣẹ́ dá bírà
Ọgbẹni Akinrinola fikun ọrọ rẹ pe, gbogbo awọn ileeṣẹ ati eeyan ti wọn ṣeranwọ kan ta bi omiiran fun ile iwosan UCH, ni ile iwosan naa maa n fi lede lori ayelujara.
Kò sí ibùdó ayẹwo àrùn Coronavirus ní UCH, ẹ má wá fún ayẹwo lọ́dọ̀ wa - Ọga àgbà UCH
Ọ̀ga àgbà fún ilé iwosan UCH, Ọjọgbọn Jesse Abiodun Otegbayo lọ sísọ lójú ọ̀rọ̀ yìí lásìkò tó ń gbalejo kọmisana feto ìlera nipinlẹ Ọ̀yọ́, Dókítà Bashir Bello nílé ìwòsàn náà.
Atẹjade kan tí ilé ìwòsàn UCH wá fi síta lẹ́yìn abẹwo naa ni lóòótọ́ nile ìwòsàn náà ń tọju afurasi alárùn Covid-19 kan lọ́wọ́ àmọ́ wọn ṣẹ̀ṣẹ̀ fi ayẹwo rẹ ransẹ sì ikọ ìjọba tó ń ṣe ayẹwo àrùn Coronavirus ni.
Atẹjade náà fikùn pé, ilé ìwòsàn UCH sì ń dúró de èsì ayẹwo náà láti ibùdó ayẹwo níta, táwọn yóò si maa fi ìṣẹ̀lẹ̀ náà tó aráyé létí bo ba ṣe ń lọ.
Coronavirus ti mú kí Rábí elépo pupa ó lówó ju Rábí elépo rọ̀bì lọ́
Ni bi a ṣe n to iroyin yii jọ, agbẹ olowo epo pupa labule kabule lorilẹede Naijiria ma ti di olowo ju baba olowo oniṣowo epo rọbi nibikibi lagbaye.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ara awọn ohun manigbagbe ti ajakalẹ arun Coronavirus lagbaye mu ba aye ree.
Ni ilẹ to mọ loni yii ẹya epo rọbi Brent ti di dọla mọkanlelogun, iyẹn ẹgbẹrun mẹjọ o le bi igba naira lori agba epo rọbi kan nigba ti ẹda epo rọbi WTI ti di dọla mẹrindinlogun iyẹn ẹgbẹrun mẹfa o le ojilelugba ati naira marun lori agba kan.
Amọṣa lori epo pupa, ọtalelẹgbẹta o din mẹta dọla, iyẹn ẹgbẹrun lọna igba o le mẹtadinlogun naira. Eyi tumọ si pe, ẹni to n ṣowo epo pupa lọwọ yii n pawo wọle.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Owo epo ilẹ Amẹrika ti dẹnukọlẹ fun igba akọkọ ninu itan.
Eyi tumọ si peawọn to n ta epo gan lo n sanwo fawo orilẹede to n ra epo lati wa ko epo rọbi naa kuro lori igba wọn.
Idi eyi ko ju ibẹrubojo pe oṣeeṣe ko maa si aye lati ko epo rọbi pams si mọ nigba to oṣu karun ọdun yii ba fi wọle.
Ko si awọn to n beere lati ra epo rọbi lagbaye bayii nitori aṣẹ konileogbele kaakiri agbaye eleyi to ti ti ọpọlọpọ awọn eeyan mọle jakejado agbaye.
Nitori eyi, nṣe lawọn ileeṣẹ apọnpo gbogbo bẹrẹ si ni ya agba ikeposi kaakiri lati ko awọn apọju epo naa si, eyi lo si fa bi owo epo rọbi ilẹ Gẹẹsi ṣe dẹnukọlẹ.
Owo ori ẹya epo rọbi West Texas Intermediate (WTI) to jẹ odinwọn owo epo lorilẹede Amẹrika ti ja lọlẹ si dọla mẹtadinlogoji lori jala kan.
Coronavirus: Ọjoọ́ mélòó ni Coronavirus ń lò lára kí ènìyàn tó gba ìwòsàn?
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Arun Coronavirus bẹrẹ ni ipari ọdun 2019, amọ o le e ṣe diẹ ki awọn eniyan to ba ni arun naa to ri iwosan gba.
Gbigba iwosan niiṣe pẹlu bi eniyan ba ṣe ṣe aisan si nitori arun Coronavirus le ma lagbara lori awọn eniyan kan, amọ ko si ṣọṣẹ lara awọn eniyan miran.
Awọn ohun to niiṣe pẹlu bi eniyan ba tete ri iwosan gba si ni ọjọ ori, ọkunrin tabi obinrin ati boya ẹni naa ni aisan abẹnu tẹlẹ.
Ti eniyan ba tete lọ si ile iwosan, ki o bẹrẹ iwosan naa niiṣe pẹlu bi eniyan yoo ṣe gba iwosan si.
Ọpọlọpọ awọn eniyan to ba ni arun Coronavirus ko ni awọn apẹẹrẹ to koja agbara ju. Wọn le e wukọ tabi ni iba, ara riro, ọfun dundun ati ori fifọ.
Ikọ wiwu naa le ma le lakọkọ, amọ to baya, wọn yoo ba wukọ ti yoo ma tu nkan jade.
Ọna ati gbogun ti arun naa ni ki eniyan sun daadaa, ki eniyan mu omi daadaa ati lilo oogun ara riro tabi ori fifọ bii paracetamol.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Awọn ti apẹẹrẹ wọn ko ba le ju yoo tete ri iwosan gba laarin ọsẹ meji.
Arun yoo le peleke si fun awọn miran, eleyii to le jẹ bi ọjọ mẹwa lẹyin ti wọn ba ti ni arun naa lara.
Ayipada naa le tete ṣẹlẹ, eemi le di iṣoro, ki ọna ọfun sibẹrẹ si ni dun eniyan.
Ohun to ṣẹlẹ ni wi pe awọn eroja ara n tiraka lati gbogun ti arun Coronavirus naa, eleyii le fa ki awọn eroja ara bẹrẹ si ni ṣiṣẹ aṣeju, eleyii to ba ago ara jẹ.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Iwosan fun awọn ti wọn ba ti bẹrẹ si ni lo ẹrọ ventilator lati mi le lo to osu mejila si osu mejidinlogun ni ileewosan, ki ara to bẹrẹ si ni pada si ipo notori ọpọlọpọ eroja ara lo ti sọnu lasiko ti ara n ba arun Coronavirus naa ja.
Ajọ Isokan Agbaye ni ẹnikan ninu ogun eniyan to ba ni arun Coronavirus lo ma n nilo itọju pajawiri, eleyii le jẹ ki wọn kun ẹni naa loorun ni ileewosan tabi ki wọn bẹrẹ si ni lo ẹrọ ventilator lati mi fun ara wọn.
Kí lo mọ̀ nípa fẹntilétọ̀, ohun èlò aṣèrànwọ́ èémí
Kí làwọn ìdàmú tí Coronavirus n mú bá àgọ́ ara?
Ǹjẹ́ ewé dongoyaro lè wo aàrùn coronavirus?
Coronavirus Vaccine: Ṣé abẹrẹ àjẹsára ti wà fún àrùn COVID-19?
Ǹjẹ́ àrùn Coronavirus leè wà lára èèyàn títí lái?
Coronavirus Lockdown: Iléèwé Chrisland ṣetán láti fún ìgbẹ̀kọ́ orí ayélujára lọ́jọ́ Ajé tó ń bọ̀
Oríṣun àwòrán, Other
Ko si ṣiṣe, ko si aisẹ, ile iwe Chrisland niluu Eko yoo wọle saa eto ẹkọ tuntun lọjọ Aje, ọjọ kẹtadinlọgbọn oṣu kẹrin ti a wa yii, bo tilẹ jẹ wi pe ofin konile-o-gbele si wa lode.
Ohun ti awọn alaṣẹ ileewe naa n gbereo lati ṣe ni pe lori ayelujara ni awọn akẹkọọ ile iwe naa yoo ti maa gbẹkọọ.
Amọ ọpọ ninu awọn obin awọn ọmọ ile iwe naa lo tako igbesẹ awọn alaṣẹ ileewe naa.
Ohun to ya ọpọ eeyan lẹnu ni wi pe awọn obi ni lati sanwo ile iwe awọn ọmọ wọn fun saa eto ẹkọ tuntun to maa bẹrẹ lọjọ Aje to n bọ.
Bakan naa ni iroyin sọ pe awọn akẹkọọ tawọn obi wọn ko tii sanwo ileewe wọn ko ni lanfaani lati kopa ninu igbẹkọ naa lori ayeluajra.
Ṣugbọn nigba ti o ba BBC Yoruba sọrọ, Ọgbẹni Jide Onigbogi to jẹ oludari idasoke okowo ileewe Chrisland ṣalaye pe ọpọ ninu awọn obi awọn akẹkọọ ileewe naa lo fọwọ sii pe ki saa igbẹkọọ tuntun bẹrẹ lori ayelujara.
Ọgbẹni Onigbogi sọ pe diẹ lara awọn obi awọn akẹkọọ ileewe naa lo tako ki ileewe Chrisland wọle saa eto ẹkọ tuntun bayii.
O ni awọn alaṣẹ ileewe naa ti pinnu lati ṣe adinku owo ileewe lasiko yii nitori ai lanfaani lati maa kẹkọọ ninu yara ikawe nitori konile-o-gbele to wa nita nitori coronavirus.
Ọgbẹni Onigbogi fikun ọrọ rẹ pe awọn ti ko tii sanwo ileewe fun saa keji igbẹkọ to lọ nikan ni ko ni lanfaani lati kopa ninu igbẹkọ ori ayelujara.
Bakan naa lo sọ pe ofin konile-o-gbele ko mu igbẹkọ lori ayelujara lasiko yii.
Coronavirus pandemic: Ẹgbẹ́ àwọn àgbẹ̀ ní Nàìjíríà ní ìyàn ń bọ̀ lẹ́yìn coronavirus àyàfi...
Oríṣun àwòrán, Twitter/Ministry of Humanitarian Affairs
Ajọ iṣọkan agbaye ti ke gbajare sita pe bi ọrọ ṣe n lọ yii  ajakalẹ iyan yoo waye lagbaye nipasẹ ọwọja arun Coronavirus.
David Beasley to jẹ adari eto ounjẹ lagbaye (WFP) labẹ aṣia ajọ iṣọkan agbaye ni igbesẹ kanmọkanmọn yẹ ko waye lori ọrọ yii lati lee dena ajalu to n rọ dẹdẹ naa.
Abọ iwadii kan fihan pe iye awọn eeyan ti ebi n pa lagbaye lee gbera lati miliọnu marundinlogoje lọ si ọtalelugba o din mẹwaa milọnu eeyan.
Awọn orilẹede mẹwaa ni ajakalẹ ebi yii yoo ṣe ọṣẹ fun julọ, gẹgẹ bi ajọ to n ri si eto ounjẹ lagbaye ṣe sọ.
Abajade iwadii lori wahala ounjẹ ẹlẹẹkẹrin iru ẹ, 'Global Report on Food Crises' tọka si orilẹede Yemen, Democratic Republic of Congo, Afghanistan, Venezuela, Ethiopia, South Sudan, Sudan, Syria, Nigeria ati Haiti.
Nigba ti o BBC Yoruba sọrọ, akọwe agba ẹgbẹ awọn agbẹ to jẹ ọdọ(Young Farmers Association of Nigeria - YFAN), Adeleke Opeyemi jẹri sii pe iyan n bọ lorilẹede Naijiria lẹyin ti aarun coronavirus ba kasẹ nlẹ.
Oríṣun àwòrán, Reuters
Ọgbẹni Opeyemi ni adaimọ ki iyan ma bẹ silẹ lẹyin ti covid-19 ba tan nilẹ, ayafi ti ko ba pẹ ju loku.
O ni lọwọlọwọ bayii, ọpọlọpọ awọn agbẹ lo ko le de oko wọn mọ nitori awọn janduku to n dunkoko mọ wọn lọna.
Akọwe agba ẹgbẹ YFAN ni ko si nnkan koriya fun awọn agbẹ mọ lasiko yii, eyi to ti mu ki ọpọ pa iṣẹ naa ti.
Ọgbẹni Opeyemi tun sọ pe iṣoro to n koju ọpọ awọn agbẹ gan an bayii ni ai ri ibi ti wọn ti le ta nnkan oko wọn.
O ni ọpọ ti wọn fẹ ta ẹyin lọpọ yanturu ni ko ri ọjọ ti wọn ti le taa, bakan lawọn ti wọn fẹ ta nnkan oko mii.
O rọ ijọba lati ṣe agbekalẹ ọja tawọn agbẹ ti le maa ta ọja oko wọn lasiko yii, tabi ki ijọba gan an maa ra lọwọ wọn.
Akọwe agba ẹgbẹ YFAN tun fikun ọrọ rẹ pe o yẹ ki ijọba ṣe eto kiko ere oko awọn agbẹ lọ si ibi ti wọn ba ti fẹ ta ọjọ naa.
Oríṣun àwòrán, Twitter/Ministry of Humanitarian Affairs
Bakan naa lo sọ pe o yẹ ki ijọba ṣeto fawọn agbẹ lati le maa rin lai si ẹni lai ni idiwọ lasiko igbele coronavirus yii.
Lorilẹede South Sudan, ida mọkanlelọgọta awọn olugbe ibẹ lo foju wina ebi ti ko lẹgbẹ lọdun to kọja gẹgẹ bi abajade iwadii naa ṣe fi kalẹ.
Oríṣun àwòrán, Twitter/Ministry of Humanitarian Affairs
Koda, ki ajakalẹ arun yii to wọle de, apa kan ẹkun ila oorun Afirika ati gusu Aṣia lo ti n ba ọwọngogo ounjẹ finra eleyii to waye nipasẹ ọda ojo ati ajalu awọn kokoro ajẹkorun fun ọpọlọpọ ọdun.
Nigba to n ba igbimọ eto abo lajọ iṣọkan agbaye sọrọ, Ọgbẹni Beasley ṣalaye pe gbogbo agbaye gbọdọ ṣe giri pẹlu igbesẹ to yẹ lori ọrọ yii.
O ni afaimọ ki orilẹede agbaye o maa fi oju wina iyan to lagbara bii ti inu Bibeli nigba ti a o ba fi ri oṣu diẹ sasiko yii.
Ramadan 2020: Ṣọ́ọ́ṣì kan sí ìlẹ̀kùn rẹ̀ fún àwọn mùsùlùmí láti kírun Jímọ̀ ní Germany
Oríṣun àwòrán, Reuters
Sọọsi kan nilu Berlin, l'orilẹ-ede Germany, ti silẹkun rẹ fawọn musulumi lati jọsin nibẹ nitori pe mọsalasi wọn ko gba wọn mọ.
Igbesẹ yi ko sẹyin titẹle ilana titaketesiraẹni tuntun ti ijọba gbekalẹ, eleyi ti o mu adinku ba iye eeyan to le jọsin lẹẹkan naa ninu ile ijọsin.
Orileede Germany faye gba ki eto ijọsin yala ni Mọsalasi tabi sọọsi bẹrẹ pada ni ọjọ Kẹrin osu Karun, sugbọn awọn olujọsin gbọdọ takete si ara wọn niwọn ẹsẹ bata marun un.
Nitori eyi, mọsalasiDar Assalamni agbegbe Neukölln ko gba gbogbo awọn to wa jọsin nibẹ.
Ki awọn eeyan ba le ribi jọsin, sọọsi Martha Lutheran ni Kreuzberg nawọ iranwọ pe ki awọn olujọsin to kuwa si ọdọ awọn lati le kirun jimọ to kẹyin ninu osu awẹ Ramadan.
Amọ ni Berlin, bi o ti se ri lawọn orileede to ku l'agbaye, asiko Coronavirus yi sebi ẹni da eto awẹ ru lọdun yi.
Oríṣun àwòrán, Reuters
Imaamu mọsalasi naa sọ fun ileesẹ iroyin Reuters pe ''apẹẹrẹ nla leleyi jẹ, ti o si mu ayọ ati idunnu wa lasiko ifoya yii''.
O ni ''ajakalẹ aarun yii ti mu ki gbogbo wa di ọkan naa.O ti mu ki isọkan wa laarin gbogbo eniyan''.
Jawahir Roble:Hijab tí mò n lò kó jẹ́ kọ́kọ́ jẹ́ ìyàlẹ́nu fún àwọn agbábọ́ọ̀lù mi
Ẹlẹsin musulumi kan, Samer Hamdoun ni ''o kọkọ ri bakan lara nigba ta wa nibẹ nitori awọn ohun eelo orin, ati aworan to yi wa ka. Amọ ti ẹ ba moju kuro lawọn iyatọ diẹ diẹ yi, ẹ o ri pe ile Ọlọrun naa nibi jẹ''
Oríṣun àwòrán, Reuters
Koda pasitọ sọọsi naa, Monika Mathias , n kopa ninu ijọsin ọhun, to si ba wọn sọrọ.
"O sọ pe ""nigba ti wọn si n sadura, mo sa n sọ pe bẹẹni, bẹẹni , bẹẹni nitori pe nkankan na ni ohun to jẹ wa logun, mo si fẹ kẹkọọ lọdọ rẹ. Oun to rẹwa ni lati ri bi ero ọkan wa ti se ri si ara wa""."
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Bi oṣu Ramadan ṣe bẹrẹ lọjọ kẹrinlelogun, oṣu Kẹrin, ọdun 2020, Ramadan ọdun yii yoo yatọ nitori ajakalẹ arun Coronavirus.
Coronavirus yii lo n ba gbogbo agbaye finra leyi to ti mu ki ọpọ orilẹede gbe ofin konile-o-gbele kalẹ.
Eyii si ti mu ki ọpọ awọn Musulumi maa bere pe bawo ni Ramadan ọdun yii yoo ṣe ri.
Sheikh Muhammad Ibn Othman to jẹ Imamu Mọṣalaṣsi Kano ba akọṛoyin ileeṣẹ BBC sọrọ lori bi awọn nkan ti Musulumi le ṣe lasiko Ramadan pẹlu bi arun Coronavirus ṣe wa lode.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Bi Coronavirus yoo ṣe mu ayipada ba Ramadan ọdun 2020
Itakete sira ẹni ti wa ninu ẹsin Imale ṣaaju akoko yii, fun apẹẹrẹ, ti eeyan ba jẹ alubọsa, iru ẹni bẹẹ ko le wọ Mọṣalaṣi nitori oorun rẹ.
Ṣaaju asiko yii, awọn Musulumi ma n korajọ sinu Mọṣalaṣi fun ẹkọ, lati gbadura papọ ati lati ṣinu loṣu Ramadan.
Ṣugbọn bayii nnkan ti yi pada ni Naijiria, ati lawọn orilẹ-ede miran bi Egypt ati Saudi Arabia to jẹ olu ilu awọn Musulumi lagbaye.
Kayeefi: Àkójọpọ̀ ìṣẹ̀lẹ̀ kàyéèfì tó wáyé lásìkò ààrùn coronavirus
Ti isunfunraẹni ba le wa nitori alubọsa, o yẹ ko rọrun fun awọn Musulumi ododo lati takete fun ara wọn ninu Ramadan lasiko arun Covid-19 to wa lode.
Ipa ti imọ ẹrọ lee ko lasiko Ramadan
Oríṣun àwòrán, Getty Images
"Sheikh Othman sọ pe ""Ori ayelujara ni mo ti maa ṣe Tafsir lọjọ Ẹti lati inu iyẹwu mi.""Eyii to n tumọ sipe imọ ẹrọ yoo ko ipa to pọ ninu Ramadan ọdun yii."
Sheikh Othman ni akoko ti to fun awọn adari ẹsin Musulumi lati gbe ero atijọ ti sẹgbẹ kan, ki wọn si bẹrẹ si n lo ẹrọ ayelujara fun isin wọn.
Ẹkọ ti Musulumi le kọ lasiko ajakalẹ arun yii
Ẹkọ kinni, gẹgẹ bi Sheik ọhun ṣe sọ, ni pe Allah nikan lọba lori ohun gbogbo ati lori gbogbo ẹda alaaye.
Ati pe, akoko yi jẹ akoko lati fi ifẹ han si aladugbo ẹni, papa julọ awọn to ku diẹ kaato fun.Sheik ni asiko yi lo yẹ ki awọn eeyan, papa awọn Musulumi ma ro ọjọ atisun, ki wọn si sun mọ Ọlọrun ati awọn ẹbi wọn.
Kí ni Yorùbá ń pe ọmọ tí wọ́n bí lẹ́yìn Àlàbá?
O tun sọ pe ki wọn fi akoko igbele ati Ramadan ọhun gba adura ki wọn si tun fi ṣetọju awọn alaini.
"Sheikh Othman pari ọrọ rẹ pe ""Adura wa ni pe ki Ọlọrun ba wa dawọ iji arun naa duro."""
Oríṣun àwòrán, AFP
Lẹyin to kofiri oṣu tuntun to le , Sultan ti ilu Sokoto, Saad Abubakar ti kede pe awẹ Ramadan fawọn Musulumi yoo bẹrẹ lọjọ Ẹti.
Ninu ikede kan to ṣe lori tẹlifisan ijọba kan lorilẹede Naijiria, Sultan Abubakar to jẹ olori ijọ musulumi lorilẹede Naijiria rọ awọn musulumi lati yago fun ipejọpọ ọlọpọ ero ki wọn si duro si ile wọn.
Bakan naa ni igbimọ to n ṣe akoso ẹsin musulumi lorilẹede Naijiria, NSCIA tun ke sawọn mọṣalaṣi gbogbo lati wọgile gbogbo eto taraweeh, iyẹn adura araarọ lasiko awẹ, idanilẹkọọ Tafsir, atawọn eto miran to js ms asiko awẹ Ramadan.
Wọn wa rọ awọn olori ijọ musulumi gbogbo lati lo ayelujara fun eto iwaasu atawọn nnkan miran ti wọn ba ni lọkan lati ṣe lasiko awẹ yii.
Oríṣun àwòrán, others
Sultan tilu Sokoto, tíì tún ṣe aarẹ àpapọ̀ fàwọn musulumi ni Naijiria, Alhaji Sa'ad Abubakar Kẹta tí kesi àwọn Mùsùlùmí ni Naijiria lati máṣe kí irun àpapọ̀ fún ìbẹ̀rẹ̀ oṣù aawẹ.
"Sultan, ẹni tí akọ̀wé ẹgbẹ́ àpapọ̀ musulumi, Ọmọwe Khalid Abubakar-Aliyu gba ẹnu rẹ sọ̀rọ̀ nílu Kaduna, tun rọ àwọn musulumi lati mase lọ fún Haji kékeré taa mọ si Umurah nílẹ̀ Saudi Arabia nítorí àrùn Coronavirus.""Kò ní sí ìpéjọpọ̀ musulumi fún waasi lásìkò aawẹ, irun isinu àti irun janmọ làwọn mọsalasi gbogbo títí tí ohun gbogbo yóò fi padà bọ sípò."
Sultan wá rọ àwọn musulumi lati maa kan sáwọn ojú òpó ikansira ẹni bíi Facebook, Skype, YouTube, Zoom, Instagram ati bẹẹ bẹẹ lọ, fun waasi aawẹ àti ìtọ́ni àwọn asaaju ẹṣin lásìkò oṣù Alapọnle náà .
The Church of Beer: Ìnira nlá ni òfin tó dé kátà-kárà ọtí líle lásìkò Covid-19 jẹ́ fún ilé ìjọsìn wà
Oríṣun àwòrán, Twitter
Orileede South Africa ti bẹrẹ ifilọlẹ ofin to de ọti tita lasiko Covid -19 fun igba ẹlẹẹkeeji.
Ijọba South Africa ṣe agbekalẹ ofin to de karakata ọti lilẹ lati mu adinku ba iye awọn eeyan to n lọ si ile iwosan.
Agbekalẹ ilana yi ni ipalara awọn ara ilu lọna orisirisi paapa awọn ile itaja to n ta ọti ati awọn ile ounjẹ.
Amọ ṣa ọrọ naa ṣeni ni kayeefi bi awọn ile ijọsin kan ti ṣe n kerora lori ofin to tako tita ọti yi nitori pe awọn ko ni ribi jọsin bo ti ṣe yẹ.
Oríṣun àwòrán, Facebook/Gabola-Church
Ọrọ naa ṣe yin ni haa hun abi?
Ile ijọsin kan ti wọn n pe orukọ rẹ ni Ghabola Church to wa ni guusu olu ilu Johannesburg ni awọn ọmọ ijọ bẹẹ ti ni ki ijọba wa nkan ṣe si ofin ma ta ọti yi.
Nile ijọsin taa n wi yi, igbagbọ wọn ni pe mimu ọti lamupara jẹ ọna kan gbogi tawọn fi le ba Ọlọrun sọrọ .
Gabola ti wọn fi sọri ile ijọsin naa tunmọ si ọti mimu ni ede SeTswana.
Oríṣun àwòrán, Facebook/Gabola-Church
Oludasilẹ ile ijọsin naa Pope Tsietsi Makiti salaye fun akọroyin BBC to ṣabẹwo sile ijọsin naa lati mọ bi nkan ṣe n lọ lasiko yi pe ''awọn ko kọ ki ijọba ti awọn mọle titi di igba ti Jesu yoo fi pada wa.''
Tsietsi to jẹ ẹni ọdun marundinlọgọta ṣalaye pe nkan bi ọdun meji sẹyin lawọn bẹrẹ ile ijọsin awọn.
''Ni ile ijọsin Gabola, o maa gbe ọti rẹ wa ti pasitọ yoo si ba ọ ya si mimọ ki o fi ma ṣe akoba f'ara rẹ''
O ni nigba ti ofin yi si ti bẹrẹ niṣe lawọn ko duro loju kan ṣe ijọsin ki awọn agbofinro ma baa mu awọn.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
'Mo fẹ́ gbé ògo ìdílé ìyá àti bàbá mi ga pẹ̀lú iṣẹ́ Mọkálìíkì'
Òfin tí ìjọba fi dé oko-owo ọtí líle lásìkò igbele Coronavirus ni orílẹ̀ èdè South Africa tí mú kí ọ̀pọ̀ ibùsùn làwọn ilé ìwòsàn ṣófo, mú kí àìmọye oko-owo dojú de, tí làásìgbò oselu sì ń peléke si, èyí tó mú kí àwọn ènìyàn nifẹ báyìí sí ọgbin òyìnbó tá mọ si Pineapple.Ṣáájú kí àrùn Coronavirus tó wọlé sí ilẹ̀ South Africa, ó to àwọn èèyàn bíi ẹgbẹ̀rún lọ́nà mẹrinlelọgbọn, tí wọn máa ń gbé wa sáwọn ílè ìwòsàn ni orílẹ̀ èdè náà ni ọṣẹ kan ṣoṣo, ẹyọ tó lọ́wọ́ ọtí líle ninu.Àmọ́ láti ìgbà tí ìjọba tí ṣe ìkéde konile ó gbele láti dènà itankalẹ àrùn Coronavirus ni osu kẹta ọdún, adinku tí bá ìṣẹ̀lẹ̀ náà sì idà méjì nínú mẹta, èyí tíì ṣe ẹgbẹ̀rún méjìlá péré.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
"Covid-19 yóò nípa burúkú lórí àwọn ọmuti alamupara, bẹ́ẹ̀ si ni nilẹ South Africa, àwọn èèyàn ń gbé ní àgbègbè tó kún fún èrò Nítorí náà, kata-kara ọtí líle leè mú kí itankalẹ àrùn Covid-19 ni agboolé pọ si, nítorí àwọn èèyàn máa ń ṣe awọmu ni, ó si ṣeé ṣe kí ọwọja ìwà ipá sì abo àti ọmọdé pọ sì"" Ọjọgbọn Parry tún ṣe ikilọ.Àmọ́ ń jẹ ó ṣeé ṣe kí wọn tún ṣe àfikún àkókò òfin to de oko-owo ọtí líle, to tí wáyé ṣáájú fún ọ̀sẹ̀ márùn-ún tẹ́lẹ̀, síwájú sí, lẹyin ọgbọnjọ oṣù kẹrin tó yẹ kí òfin náà kasẹ nlẹ?Bẹẹ si ni ọga ọlọ́pàá tí tí ìbínú àwọn èèyàn sókè nígbà tó kéde pé káwọn agbofinro máa lo ọwọ líle àti ọna ti ko bófin mú, fìyà jẹ àwọn èèyàn tó ba tako òfin náà."
Oríṣun àwòrán, Getty Images
"Minisita fún ọrọ ọlọ́pàá, Bheki Cele, tí ọ̀pọ̀ èèyàn mọ fún sísọ ọ̀rọ̀ kobakungbe àti iwanwara rẹ lórí amusẹ òfin to de ọtí tita, lo sí ti fi ikilọ síta laipẹ yìí pé, àwọn ikọ òun ""yóò ba àwọn ohun èlò ti wọn ba fi ń ta ọtí jẹ"".Àmọ́ Apiwe Nxusani-Mawela, tí ṣe obinrin àkọ́kọ́ tí yóò dá ileesẹ ipọnti silẹ, to tún jé alaga ẹgbẹ́ àwọn oloko owó ọtí títa ni South Africa ṣàlàyé pé ""èyí kò dára rárá"", to sì fi ibẹru hàn pé, ó ṣeé ṣe kí oko-owo òun dojú de, tí òfin tó dé kata-kara ọtí líle náà bá tẹsiwaju. O ni ""ọpọ èèyàn ti ko ni isẹ lọ́wọ́ lo ń fi ọtí pa ìrònú rẹ, dípò kí wọn lo oogun oloro, tó sì tún daba pé, tí ìjọba bá fi ààyè gba títa ìwọ̀nba ọtí díẹ̀, èyí kò ní jẹ́ kí oko-owo òun dẹnu kọlẹ."
Oríṣun àwòrán, Getty Images
"Bákan náà ni Nick Smith, tíì ṣe ọmọ ilẹ̀ Amẹ́ríkà tó ní ibùdó ipọnti lẹ́yìn odi ìlú Cape Town sọ pé "" isẹ tán fún wa nìyẹn""O fikùn pé "" òfin tó dé oko-owo ọtí náà tí ṣe àkóbá nla fún àwọn oko-owo alabọde"".Ṣùgbọ́n ní báyìí, àwọn èèyàn ti ń lo ọgbin oyinbo pineapple láti fi ṣe ọtí líle nínú ilé."
Oríṣun àwòrán, Getty Images
"Ọ̀pọ̀ èèyàn sì lo ń wá fídíò kiri lórí ayélujára nípa bí wọn ṣe leè lo pineapple àti ọkà bàbà pẹlu sogomu fi ṣe ọtí líle ni abẹle, tí wọn ń pè ní ""Umqombothi"".Ikilọ sì ti ń lọ káàkiri pé tí wọn kò bá pèsè ọtí ìbílẹ̀ náà pẹ̀lú imọtoto, a jẹ pe ewu ń bẹ ní oko longẹ."
Coronavirus: Àwọn alárùn coronavirus ṣe ìwọ́de ní Gombe, wọ́n ní ìjọba n febi pa wọ́n
Oríṣun àwòrán, Twitter
Nṣe ni awọn alarun coronavirus tu si ita ọkan lara awọn ibudo ti wọn ti n tọju aarun naa nipinlẹ Gombe lati fi ẹhonu han lọjọ Iṣẹgun.
Wọn fi ẹsun kan awọn alaṣẹ pe wọn kofun awọn ni oogun tabi itọju, ati pe ounjẹ paapa ko si ka'nu.
Sugbọn sa, kọmisana eto ilera nipinlẹ naa, Ahmed Gana sọ fun BBC pe awọn eeyan naa ko fi apẹẹrẹ aarun naa han ni wọn ko ṣe nilo oogun.
Bakan naa ni awọn alaṣẹ sọ pe ko si nkan to jọ pe awọn ko fun wọn ni ounjẹ daada.
Wọn pada bẹ awọn eeyan naa lati pada si ibudo naa, ṣugbọn wọn sọ pe ẹru n ba wọn nitori bi awọn alarun naa ṣe darapọ mọ awọn ara abule to jade wa a woran ohun to n ṣẹlẹ.
Oríṣun àwòrán, Twitter
Ijọba Gombe sọ pe aimọkan lo mu ki awọn eeyan naa ṣe iwọde. Wọn si rọawọn to ba jade wa a woran iwọde naa lati ya ara wọn si ọtọ fun ọjọ
mẹrinla.
Àǹfàní ńlá ni àṣẹ ìgbélé jẹ́ fún àyíká ọmọnìyàn pàápàá nílùú Eko
Eeyan bi ọgọrun lo ni aarun naa lọwọlọwọ ni Gombe.
Awọ awọn agbofinro ti tẹ awọn ọmọ orilẹede China mẹtadinlogun kan ti wọn n ji kusa wa ni ipinlẹ Ọṣun
Ikọ alaabo ajumọṣe ti ijọba ipinlẹ Osun ṣẹṣẹ da silẹ lo he awọn eeyan naa lagbegbe Ileṣa ati Ifẹ ni ipinlẹ Ọṣun.
Bakan naa lọwọ awọn agbofin ikọ naa tun tẹ awọn mẹwaa miran pẹluu wọn  ti wọn jẹ ọmọ agbegbe naa.ati  baalẹ agbegbe ọhun.
Ọgbẹni Abdullahi Binuyọ to jẹ igbakeji adari awọn oṣiṣẹ lọfiisi gomina ipinlẹ Ọṣun ṣalaye pe ko si ijọba ti yoo kawọgbera maa woran nigba ti awọn eeyan kan yoo maa ba ọrs ajumọni rẹ jẹ tabi jii ko.
O fi kun pe awọn ajikusa wa naa ti ba odo ọṣun jẹ pẹlu oniruru awọn eroja to jẹ majele fun agọ ara.
Oríṣun àwòrán, osun state government
O ni yat s si pe wọn yoo foju wina ofin, awọn ti wọn mu naa yoo tun san owo gba maa binu fun ijọba.
Ọkan lara awọn ọmọ orilẹede China naa to le sọ ede Oyinbo ṣalaye pe nitoun, oun ko mọ pe wọn n ji kusa wa ni nitori pe ireti oun ni pe wọn ni iwe aṣẹ iwakusa latọdọ ijọba.
Oríṣun àwòrán, Adegboyega oyetola
Eeyan kan ti jẹ Ọlọrun nipe nitori arun Coronavirus ni ipinlẹ Osun, nigba ti ẹni to kọkọ ni arun ọhun ati awọn oṣiṣẹ eto ilera mẹta mii ri iwosan gba.
Kọmiṣọnna eto ilera ni ipinlẹ naa, Rafiu Isamotu sọ pe oloogbe ọhun to jẹ ọmọ aadọrin ọdun din diẹ gbẹmi mi ni ile iwosan ijọba Asubiaro, ni ilu Osogbo.
Isamotu ni ijọba gba esi ayẹwo ẹni akọkọ naa ati awọn oṣiṣẹ eto ilera to ri iwosan lalẹ ọjọ Ẹti.
O ni ilu London ni ẹni akọkọ to ni arun ọhun ni Osun ti wa, ṣugbọn ara rẹ ti da ṣaka bayii lẹyin to lo ọjọ mejidinlogoji nibi to ti gba itọju.
Lọwọ yi, eeyan mẹjọ ni àrùn Covid-19 n ba fínra ni Osun.
Ẹ máà fi Eko wé Ghana lórí dídẹ okùn ìgbélé, ìyàtọ̀ wà níbẹ̀-Hamzat, igbákejì gómìnà Eko
Ìjọba Osun dẹkùn lọrun àṣẹ konile ó gbélé
Koko ohun mẹ́wàá tí Gomina Oyetola báwọn èèyàn Ìpínlẹ̀ Osun sọ
Ìjọba Ìpínlẹ̀ Osun tí dẹkùn àṣẹ konile ó gbé lé ọlọsẹ méjì ni ọrùn àwọn èèyàn jákèjádò Ìpínlẹ̀ náà.
Ìjọba Ìpínlẹ̀ Osun ṣàlàyé pé, àwọn aráàlú yóò ní anfaani lati rin yíká ìpínlẹ̀ náà bẹ̀rẹ̀ láti aago mẹ́fà àárọ̀ si marun irọlẹ, láti ọjọ́ Ajé sì Ọjọ́bọ ọsọọsẹ.
Nígbà tó ń ṣàlàyé ìdí tí ìjọba Ìpínlẹ̀ Osun fi gbé ìgbésẹ náà, gomina Adegboyega Oyetola, nínú ọ̀rọ̀ tó bá àwọn èèyàn Ìpínlẹ̀ náà sọ ṣàlàyé pé, didẹ okun lọrun àṣẹ konile ó gbélé náà yóò mú kó rọrùn fáwọn
aráàlú láti máa ṣíṣẹ oojọ wọn.
Oyetola fikùn pé àṣẹ ọhun, tí yóò bẹ̀rẹ̀ lọ́jọ́ Ajé ọjọ́ kẹrin oṣù karùn-ún, ní yóò tún mú kó rọrùn fún ìjọba láti darí Ìpínlẹ̀ náà bọ ṣe yẹ.
Àmọ́ ó ní kó ni sì lílọ bibọ ọkọ àti èrò láti ìpínlẹ̀ kan si òmíràn lásìkò yii, tí wọn yóò sì gbé àwọn ẹnu bode ìpínlẹ̀ Osun tí pá.
Gomina Ìpínlẹ̀ Osun, Adegboyega Oyetola bá àwọn èèyàn Ìpínlẹ̀ náà sọ̀rọ̀ ni irọlẹ Ọjọ́bọ.
Àkànṣe eto naa si lọ dá lórí igbele àrùn Covid-19 àti akoso Ìpínlẹ̀ Osun.
Oríṣun àwòrán, Unilag
A o le sọ igba ti awọn ileeẹkọ yoo wọle pada ni Naijiria-Ijọba
A ko ti le sọ igba tawọn ileeẹkọ yoo wọle.
Minisista abẹle  feto ẹkọ ni Naijiria, Emeka Nwajiuba, lo sọ ọrọ yi lasiko to n bawọn akọroyin sọrọ nibi ti igbimọ aarẹ to n dari eto gbogbo nipa Covid-19  n jabọ farailu.
O ni toun ti pe aarẹ ni wọn yoo dẹwọ ofin konile o gbele ni Abuja,Eko ati ipiinlẹ Ogun,ileesẹ eto Eko ko ti le sọ ọjọ ti awọn ileeẹkọ yoo bẹrẹ pada jakejado Naijiria.
Ninu ọrọ rẹ, o ni ''aarẹ kuku sọ nipa dida eto ọrọ aje pada diẹ diẹ.Bi a ko ba yanju eyiun naa, a ko le sọ pato ọjọ ti eto ẹkọ yoo gberasọ pada.O gbọdọ wa ni ibamu pẹlu eto to wa nilẹ yi ni.A ko fẹ fi awọn ọmọ wa sinu ewu''
O fi kun pe ''ko si ile ẹkọ kankan to le da isẹ se laifi ti oun sẹlẹ lawujọ se''
Jọwọ ṣe atunṣe ilana ikansi ayelujara rẹ lati ri ẹkunrẹrẹ rẹ
Orisun: Johns Hopkins University atawọn ajọ eto ilera ilu
Igba ti wọn kede iṣiro awọn to nii kẹyin                                              29 Oṣù Bélú 2021 13:33 WAT+3
*Iye awọn to tọwọ aisan ku ni isọri eeyan ẹgbẹrun lọna ọgọrun
Jọwọ ṣe atunṣe ilana ikansi ayelujara rẹ lati ri ẹkunrẹrẹ rẹ
Akọsile imọ yii, da lori akojọpọ iṣẹ iwadi ni Fasisti Johns Hopkins, o si le ma ṣe afihan awọn akọsilẹ iroyin to ba igba mu lati orilẹede kankan.
** Àwọn iyé akọsilẹ̀ to ti wà fún àwọn ti o ṣẹ́ṣẹ̀ ni ààrun náà jẹ́ àkójọpọ̀ ọjọ́ mẹ́ta. Nítori àwọn àtúgbẹ́yẹ̀wò, o níra láti ṣe àkójọpọ fún àwọn ọkọ́ naa
Orisun: Johns Hopkins University atawọn ajọ eto ilera ilu
Iye akọsilẹ to waye gbẹyin 29 Oṣù Bélú 2021 13:33 WAT+3
Nigba ti wọn fi ibeere sọwọ si nipa bi awọn akẹkọ yoo se bọ si ipele mi,o ni ''idanwo ti yoo gbe wọn lọ kilasi mii yoo waye lẹyin tawọn ba ti ri aridaju pe wọn ti kẹkọ to yẹ''
"Fawọn to wa ni kilasi ti wọn yoo ti bọ si abala miran o fi  kun pe awọn n se igbaradi fun wọn.
''Lọwọlọwọ bayi, ajọ Waec to n seto idanwo fawọn to fẹ jade ileewe girama kan sun ọjọ idanwo siwaju ni,wọn ko wọgile.Ki a ba le mu ọjọ ni wọn fi ni awọn sun siwaju titi di igba miran.
Oríṣun àwòrán, unilag
Awọn akẹkọ yoo se idanwọ nigba ti a ab ati ri pe a le mojuto wọn daada''
Orileede Naijiria nikan kọ ni awọn ijọba ti gbe igbesẹ ki awọn ileewe wa ni titi pa lasiko arun Coronavirus yi.
Botilejẹpe awọn orileede kan ti wọn ti n jajabọ lọwọ arun naa ti ni ki awọn ipele eto ẹkọ kan bẹrẹ isẹ pada diẹdiẹ.
Oríṣun àwòrán, unilag
Ẹwẹ, ajọ eto ẹkọ ni Abuja ti kilọ fawọn ileeẹkọ lati ma se bẹrẹ isẹ pada nitori pe awọn ko ti pasẹ eyi to faye gba iru igbesẹ bẹ.
Adele akọwe ajọ naa Umaru Marafa ninu atẹjade kan to fi sita lọjọ Isẹgun ni digbi ni asẹ pe ki awọn ileeẹkọ wa ni titi pa si wa ti yoo si ri bẹ titi di igba ti asẹ mi yoo fi waye.
Oríṣun àwòrán, Bashir ahmad
Aarẹ Muhammadu Buhari gbe ọrọ rẹ kalẹ lori ibi to fẹ gbe ọrọ gba lori eto gbigbogun ti arun Coronavirus lorilẹede Naijiria.
Ọpọlọpọ awọn ọmọ orilẹede Naijiria ni wọn fi ojusọna fun ohun ti aarẹ yoo sọ ninu ọrọ rẹ, ti o si ṣe okunfa bi ọpọ ọmọ Naijiria nile ati loko ṣe sun ti awọn ohun elo gbogbo ti wọn lee fi ṣe alabapade aarẹ lori ohun to fẹ ka.
Amọṣa, lẹyin-o-rẹyin awọn nnkan kan wa eleyi ti aarẹ ko mẹnule, eyi ti ọpọ si ti n reti boya yoo sọrọ lori rẹ.
Lara awọn nnkan yii ni ọrọ iku ọwọọwọ to n waye ni ilu Kano. Ko fẹẹ wọpọ ninu awọn ọmọ orilẹede Naijiria ti ko maa ṣe haahin lori bi iku naa ṣe n waye.
Ọpọ n woo pe boya Aarẹ Buhari yoo lo anfani ọrọ rẹ lati fi ọkan araalu balẹ lori ohun to n ṣẹlẹ gan an ni ipinlẹ Kano, ṣugbọn ninu ohun ti aarẹ ka, yatọ si pe o ni aṣẹ konile-o-gbele ọlọjọyipo yoo wa nikalẹ nibẹ, ko daju pe aarẹ gan an funrarẹ tii mọ ohunkohun nipa okunfa iku ọwọọwọ ni ilu Kano.
Oríṣun àwòrán, Bashir ahmad
Eyi ni awọn ohun miran ti Buhari ko mẹnuba ninu ọrọ rẹ.
1.Nigba wo lawọn akẹkọ yoo pada si ileewe?
2.Eeyan melo ni yoo maa wa ninu ọkọ Danfo atawọn bọọsi akero nigboro lasiko ti wọn ba dẹ ọwọ aṣẹ naa diẹ bẹrẹ lati ọjọ kẹrin oṣu karun un ọdun 2020.
3.Pẹlu bi oniruuru eeyan yoo ṣe maa gbe ibomu tiwọn ran bayii, bawo la ṣe ayederu mọ ati pe ṣe gbogbo awọn ibomu wọnyii ni yoo le ṣiṣẹ idaabobo lọwọ arun yii?
4.Bawọn lawọn ipinlẹ ti ko lee se ẹnubode wọn lasiko ti konile-o-gble- ọlọjọyipo le koko yoo ṣe wa lee se wọn bayii ti konile-o-gbele ti rọlẹ sii?
5.Ṣe titi ipinlẹ Kano pa yoo jẹ ki a lee mọ ohun gan an to n ṣekupa ọgọọrọ awọn eeyan ni ipinlẹ naa?
Awọn ibeere yii ati omilẹgbẹ miran lawọn ọmọ orilẹede Naijiria n beere bayii lori ikanni ayelujara gbogbo lati igba ti aarẹ ti gbe ọrs apilẹkọ rẹ jade.
Oríṣun àwòrán, Bashir Ahmad
Aarẹ Muhammadu Buhari ti buwọlu wiwa ọwọ ofin konile-o-gbele walẹ diẹ ni ipinlẹ Eko, Ogun ati Abuja bẹrẹ lati Ọjọ Aje, ọjọ kẹrin, oṣu karun ọdun 2020.
Aarẹ Orilẹede Naijiria, ni awọn gbe igbesẹ naa lẹyin ti igbimọ amuṣẹya ti ijọba apapọ gbe kalẹ lori ọrs Coronavirus mu aba naa wa ni ifẹgbẹkẹgbẹ pẹluu awọn gomina atawọn igbimọ miran gbogbo ti ijọba gbe kalẹ.
Ninu ọrọ to ba awọn ọmọ Naijiria sọ lalẹ ọjọ Aje ni Arẹ Buhari ti sọ eyi di mimọ.
O ni adinku yoo de ba ọwọ ofin konile-o-gbele ṣugbọn eto ayẹwo ati ṣisawari awọn to ṣeeṣe ko ni arun naa yoo tubọ gbopọn sii.
Corornavirus: Òfin kónílé-ógbélé yoo dínku láti ọjọ kẹrin ọsù tó n bọ̀
Oríṣun àwòrán, others
Ààrẹ Buhari ti fawọ kónile -ogbéle wálẹ díẹ̀ ní Eko, Ogun ati Abuja
Aarẹ Muhammadu Buhari ti kede pé láti ọjọ keji oṣu kaarun ọdun yii adinku yoo ba ofin konileogbele diẹ ni ipinlẹ Eko, Ogun àti Abuja.
Aarẹ ni ìgbesẹ yìí ko ṣẹyin ọna láti ri dáju pé àwọn agbẹ àti awọn oníṣẹ oojọ ko padanu ọna ati jẹ wọn, bákan náà ni ijọba ti ṣepade pọ pẹlu awon to n ri si eto ọ̀rọ̀ aje naijiria ti wọn si ti pese awọn imọran yìí.
Ẹwẹ, aarẹ ni gbigbe ofin yii wálẹ ko tunmọ si pe ki awọn eniyan pa ofin ọwọ fifọ ti, pàápàá jùlọ láti tẹle gbogbo ofin ti àjọ to n gbogun ti àjakalẹ ààrun  lórílẹ̀-èdè Naijiria.
Láti aago mẹsan ọjọ keji osù kaarun, àwọn ọmọ le pada si ilé iwe nígba ti awọn ọlọkọ eero naa le pada si oju popo.
Ààrẹ Muhammadu Buhari ni àwọn alasilẹ ti ijọba yoo gunle ree lasiko yii
a. Ààgo mẹjọ alẹ si si aago mẹfa aarọ, eyi tumọ si pe ko ni si igbokegbodo eniyan ati ọkọ laaarin asiko yii.
b. Ko ni si aaye fun ọkọ ti ko ba ko àwọn ǹkan bii oogun tabi ounjẹ láti kọja ni ilú kan si omiran
kò ni si aaye irin aajo láti ipinlẹ kan si omiran, bakan naa ni gbogbo eniyan gbọdọ maa lo ibomu-bẹnu ni ìgbà gbogbo.
Bakan naa ni aarẹ fi kun pe ìjọba yoo fi alaalẹ sita lori igbesẹ ti awon ile iṣẹ yoo gbe ni asiko yii.
Ẹwẹ, aarẹ ni gbogbo awon alaalẹ yii ko kan ipinlẹ Kano
Aarẹ Muhammadu Buhari rọ àwọn ọmọ Naijiria lati tubọ ni maa fọwọsowọpọ pẹlu ijọba àti àwọn eleto abo láti tubọ tẹsiwaju ninu gbigbogun ti aarun coronavirus
O dupẹ lọwọ awọn osiṣẹ ilera, ajọ NCDC gbogbo ile iṣẹ ati aladani ti wọn nawọ iranwọ si ijọba àti awọn Naijiria
Ààrẹ Buhari yóò bá àwọn ọmọ Nàìjíríà sọ̀rọ̀ lónìí
Buhari to address the nation: Kí ni Ààrẹ Buhari yóò bá àwọn ọmọ Nàìjíríà sọ̀rọ̀ lónìí?
Oríṣun àwòrán, Garba Shehu
Aarẹ Muhammadu Buhari yoo ba awọn ọmọ orilẹede Naijiria sọrọ ni agogo mẹjọ ọjọ Aje.
Atẹjade kan eyi ti olubdamọran agba lori ọrọ iroyin, Fẹmi Adeṣina fi sita leyi ti jẹyọ.
Atẹjade ọhun fi kun un pe  gbogbo awọn ileeṣẹ iroyin, edio, tẹlifiṣan and awọn ileeṣẹ iroyin miran to ba nifẹ sii lee darapọ mọ aarẹ.
Ni ọsẹ meji sẹyin ni aarẹ ba awọn ọmọ orilẹede Naijiria sọ irufẹ ọrọ bayii kẹyin nigba to kede afikun iye ọjọ igbele lati dena arun Coronavirus ni ipinlẹ Ogun, Eko ati Abuja tii ṣe olu ilu orilẹede Naijiria.
Ireti awọn eeyan ni pe aarẹ yoo ṣi aṣọ loju eegun fun araalu lati ms igbesẹ to kan lori aṣẹ konile-o-gbele jakejado orilẹede Naijiria.
Oríṣun àwòrán, Twitter/Muhammadu Buhari
O ṣeeṣe ki aarẹ orilẹede Naijiria o kede itẹsiwaju aṣẹ konileogbele to wa nilẹ ni awọn ipinlẹ bii Ogun, Eko ati Abuja.
Amọṣa iyatọ ti o ṣeeṣe ko de baa ni pe aarẹ Buhari lee fẹ aṣẹ naa loju ko ka gbogbo orilẹede Naijiria lai da ipinlẹ kọkan si.
Kọmiṣọna fun eto ilera ni ipinlẹ Ondo, Dokita Wahab Adegbenro lo sọ eyi di mimọ fun BBC News Yoruba.
Dokita Adegbenro ni awọn gomina ipinlẹ gbogbo lorilẹede Naijiria ti fi ero wọn han fun Aarẹ pe ohun ti wọn fẹ ni ki ijọba apapọ o ti gbogbo ipinlẹ pa lorilẹede Naijiria.
Bakan naa lo ni awọn kọmiṣọna ipinlẹ naa ti fi ọrọ to aarẹ leti gẹgẹ bi awọn onimọ pe ohun ti orilẹede Naijiria nilo bayii lati koju itankalẹ Coronavirus.
Ni aṣalẹ oni ni ireti wa pe Aarẹ Muhammadu Buhari yoo bun awọn ọmọ orilẹede Naijiria sori lori ohun to kan gẹgẹ bi igbesẹ lori aṣẹ konileogbele.
Jọwọ ṣe atunṣe ilana ikansi ayelujara rẹ lati ri ẹkunrẹrẹ rẹ
Orisun: Johns Hopkins University atawọn ajọ eto ilera ilu
Igba ti wọn kede iṣiro awọn to nii kẹyin                                              29 Oṣù Bélú 2021 13:33 WAT+3
*Iye awọn to tọwọ aisan ku ni isọri eeyan ẹgbẹrun lọna ọgọrun
Jọwọ ṣe atunṣe ilana ikansi ayelujara rẹ lati ri ẹkunrẹrẹ rẹ
Akọsile imọ yii, da lori akojọpọ iṣẹ iwadi ni Fasisti Johns Hopkins, o si le ma ṣe afihan awọn akọsilẹ iroyin to ba igba mu lati orilẹede kankan.
** Àwọn iyé akọsilẹ̀ to ti wà fún àwọn ti o ṣẹ́ṣẹ̀ ni ààrun náà jẹ́ àkójọpọ̀ ọjọ́ mẹ́ta. Nítori àwọn àtúgbẹ́yẹ̀wò, o níra láti ṣe àkójọpọ fún àwọn ọkọ́ naa
Orisun: Johns Hopkins University atawọn ajọ eto ilera ilu
Iye akọsilẹ to waye gbẹyin 29 Oṣù Bélú 2021 13:33 WAT+3
Lọwọ yii, iye awọn eeyan to laarun Coronavirus lorilẹede Naijiria ti le ni ẹgbẹrun bayii ti ijọba apapọ ti kede.
Titi di aṣalẹ ọjọ Aiku tii ṣe ọjọ kẹrindinlọgbọn oṣu kẹrin ọdun 2020, ipinlẹ mejilelọgbọn lo ti ni aarun Coronavirus lorilẹede Naijira pẹlu olu ilu ilẹẹwa, Abuja.
Bi iye awọn eeyan to n ko aarun yii ṣe n fojojumọ goke sii, paapaajulọ ni awọn ipinlẹ bii Eko, Kano ati  Abuja, Aarẹ Buhari kede ofin konile-o-gbele ọlọjọ mẹrinla lawọn ipinlẹ bii Eko, Ogun ati Abuja. Nigba ti eyi pari ni aarẹ ba tun kede konile-o-gbele ọlọjọ mẹrinla miran eleyi tii yoo pari ni agogo mọkanla ọjọ Aje, ọjọ kẹtadinlọgbọn oṣu kẹrin ọdun 2020 lati dena itankalẹ arun yii.
Lawọn ipinlẹ bii Ogun, Eko ati Abuja, igbele oṣu kan gbako lawọn araalu ti wa bayii, eleyii to n mu ki ọpọ maa beere nigba wo ni igbele awọn yoo pari?
Ni bi a ṣe n sọrọ yii, ariwo to n ls loju opo ayelujara gbogbo bayii ni ibeere boya aarẹ yoo ṣi tun sun aṣẹ igbele tipatipa naa siwaju sii ni labẹ #lockdownextension
Onimọ nipa ajakalẹ aarun to ba BBC Yoruba ṣalaye pe iṣede kaakiri orilẹede Naijiria yoo ṣe iranwọ nipa gbogbogun ti itankalẹ aarun coronavirus.
Lai jẹ bẹẹ, aarun coronavirus maa ran ni kiakia de awọn ipinlẹ ti ko tii de ti ko ba si iṣede kaakiri orilẹede Naijiria.
O ni otitọ nipe iṣede kaakiri orilẹede Naijiria yoo mu idiwọ ba awọn onimọtọ atawọn mii ti iṣẹ wọn jọ mọ ki wọn maa rinrin ajo.
O rọ awọn ọmọ Naijiria lati fi ara daa fun ọsẹ meji nitori anfaani gbogbo ọmọ Naijiria naa ni.
Ni ipinlẹ Osun, agbẹnusọ gomina, sọ pe  awọn ti di gbogbo ọna to wọ ipinlẹ Osun lati awọn ipinlẹ miran. To si jẹ pe niṣe ni awọn ọlọpaa n da ọkọ ati eero to ba fẹ ẹ wọ ipinlẹ naa pada si ibi ti wọn ba ti n bọ.Ni ti akọwe ikede fun gomina Ondo, sọ fun BBC pe lootọ ni ofin de awọn ọkọ lati ipinlẹ miran si Ondo, aaye gba awọn ọlọkọ eero laarin ipinlẹ Ondo, kiki pe wọn ko gbọdọ gbe ju eero meji lọ.
Lori ẹsun pe awọn oṣiṣẹ alaabo n gba owo lọwọ awọn awakọ lati wọ ipinlẹ naa, o sọ pe lootọ ni iru nkan bẹ ẹ waye, ṣugbọn a ti mojuto, o ti dawọ duro. Gomina ṣepade pẹlu awsn eleto aabo ni kete to mọ pe wọn n ṣe bẹ, ko si si iru ẹ mọ""."
Oríṣun àwòrán, Ekiti state government
Fun ipinlẹ Oyo, Agbẹnusọ Gomina, Taiwo Adisa sọ pe awọn ti fi ofin de ọkọ lati ipinlẹ miran si ipinlẹ Oyo ko tiẹ to o dipe ẹgbẹ awọn gomina ṣe bẹ ẹ.
Ṣugbọn o, o ni awọn kẹẹfin pe awọn ọkọ maa n yọ ọ wọle ni alẹ, awọn si ti dawọ rẹ duro.
Koda, o sọ pe ọwọ tẹ awọn ọkọ ileeṣẹ nla kan mẹfa, to yẹ ko ko ounjẹ, ṣugbọn wsn tun fi ko awọn eeyan lọna aitọ.
Lọwọlọwọ, wọn ti n dawọn pada si ibikibi ti wọn ba wa.
Ìséde ń bọ̀ káàkiri Nàìjíríà, àwọn gómìnà ìpínlẹ̀ fẹ́nukò
Awọn gomina ipinlẹ gbogbo lorilẹede Naijiria ti fẹnu kolori titit gbogbo ẹnubode ipinlẹ si ipinlẹ pa jakejado orilẹede Naijiria fun ọsẹ meji bayii lati pinwọ itankalẹ ajakalẹ arun Coronavirus lorilẹede Naijiria.
Alaga igbims awọn gomina ipinlẹ lorilẹede Naijiria to tun jẹ gomina ipinlẹ Ekiti, Ọmọwe Kayọde Fayẹmi lo sọ eyi di mimọ lẹyin ipade ori ayelujara tawọn gomina naa ṣe lọjọru.
O 'salaye pe awọn eeyan ti iṣẹ wọn jẹ koṣemaani nikan ni aaye yoo wa fun lati maa rin lasiko naa.
O ni wọn fi ọrọ to awọn gomina ipinlẹ gbogbo leti nibi ipade naa lori bi nnkan ṣe n fojojumọ yii sii lori ija gbigbogun tarun COVID-19 pẹlu ipa ti awọn ẹka aladani nko pẹlu idasilẹ eto CACOVID ti wọn gbe kalẹ lati ṣe iranwọ to ba yẹ.
Epo rọ̀bì ti ṣàkóbá fáwọn olùgbé apá odò l'Ondo
O ni pẹlu bi arun naa ti ṣe tan kalẹ de awọn ipinlẹ marundinlọgbọn bayii, awọn gomina ti fọwọ si pinpin eto idojukọ arun COVID-19 kakiri awọn ipinlẹ lorilẹede yii.
Lebanon: Peace Busari àti àwọn 28 míràn ló padà sí Naijiria
Oríṣun àwòrán, Twitter
Arabinrin Peace Busari ti olowo rẹ lorilẹede Lebanon fẹ ta loju opo Facebook ti pada wale si Naijiria.
Alaga Ajọ Nigerians in Diaspora Commission, Abike Dabiri-Erewa,  lo fi lede bẹẹ ni oju opo Twitter rẹ.
Oríṣun àwòrán, Twitter/Dabiri-Erewa
Abike Dabiri-Erewa ni arabinrin Peace Busari pada sile pẹlu awọn mọkandinlọgbọn miran ti wọn wa ni oko ẹru ni Lebanon naa.
'Ó ṣe pàtàkì kí obìnrin gbádùn ìbálòpọ̀ nítorí...'
O saleye pe ki wọn to pada si Naijiria, Busari wa pẹlu ikọ to n bojuto awọn ọmọ Naijiria to wa ni Beirut, Lebanon, lẹyin ti wọn gba pada lọwọ olowo rẹ.
Oríṣun àwòrán, Twitter
Ọgbẹni Wael Jerro polowo Busari Peace pẹlu iwe irina rẹ ọmọ ipinlẹ Oyo loju opo Facebook rẹ ni oṣu diẹ ṣẹyin.
Oríṣun àwòrán, Other
Eleyii lo bi awọn ọmọ Niajiria ninu ti wọn si pe fun itusilẹ Busari ati ki wọn fi panpẹ ọba mu Jerro to polowo rẹ lori ayelujara.
Lẹyin naa ni Dabiri-Erewa kede pe panpẹ ọba ti mu arakunrin naa ti awọn si ti bẹrẹ eto lati mu arabinrin Busari pada sile.
Ọmọ orilẹede Lebanon, Wael Jerro to lu ọmọ Naijiria ni gbanjo loju opo Facebook rẹ ti wa ni gbaga ọlọpaa.
Alaga ajọ to n ri si awọn ọmọ Naijiria ti wọn wa nilẹ okeere, Abike Dabiri-Erewa lo fidi ọrọ yii mulẹ loju opo Twitter rẹ.
Abike ṣalaye pe, ọkunrin naa yoo jẹjọ lẹyin tawọn ọlọpaa ti fi panpẹ ofin mu un.
O ni ijọba ilẹ naa yoo gbe e lọ si ileẹjọ nitori ijọba tako fifi ọmọ eeyan ṣe kata-kara.
Ọgbẹni Jerro polowo Busari Peace pẹlu iwe irina rẹ loju opo Facebook rẹ.
Ẹgbẹrun kan owo dọla($1,000) lo gbe le e lori.
Ọmọ ọgbọn ọdun ni ọmọ Naijiria naa, ipinlẹ Oyo ni o ti wa.
Ọpọ ọmọ Naijiria lo faraya lori ayelujara ti wọn si sọ pe ki ijọba ilẹ Lebanon fi ọwọ ofin mu un.
May Workers day: Ìkáyàsókè bá àwọn òṣìṣẹ́ nítorí àìmọ ọjọ́ ọ̀la lẹ́yìn Coronavirus
Ọjọ kinni oṣu karun ni ayajọ awọn oṣiṣẹ lorilẹede Naijiria ati lagbaye amọṣa yatọ si iṣoro tawọn oṣiṣẹ n fara gba ni atẹyinwa bii ipenija owo oṣu sisan lasiko, aisi igbega lẹnu iṣẹ lasiko ati oniruuru awọn iwa kotọ miran ti wọn n fi oju wina rẹ lẹnu iṣẹ, lọdun yii, ipenija ajakalẹ arun Coronavirus kun ipenija wọnyi koda o ti mu ẹmi ọpọ ninu wọn lọ.
Lasiko Coronavirus yii lagbaye, awọn oṣiṣẹ ẹka ilera naa lo n fara gba ọfa Coronavirus julọ.
Awọn ogo ọla orilẹede Naijiria lẹka eto ilera ni arun yii ti gba lọ tabi da wolẹ lọpọlọpọ igba.
Oríṣun àwòrán, Babajide Sanwo-olu
Dokita Alfa Saidu ti ọpọ n foju wo gẹgẹ bi eekan ati ogo iṣẹ iṣegun oyinbo kaakiri agbaye jade laye ni opin oṣu kẹta nipasẹ ikọlu arun COVID-19 lẹyin to ti fi ogoji ọdun ṣe iṣẹ iṣegun.
Kii ṣe dokita Alfa Saadu nikan ni dokita to jẹ ọmọ orilẹede Naijiria to tii kagbako arun yii lagbye. Lorilẹede Naijiria, gẹgẹ bi iroyin lati ọdọ ẹgbẹ awọn dokita iṣegun lorilẹede Naijiria, NMA, ọtalelugba o le mẹrin awọn dokita iṣegun oyinbo lo ti fara kan awọn eeyan to laarun coronavirus lorilẹede Naijiria ninu eyi ti ogun dokita ti ni arun yii. Meji ninu wọn lo ti pada bọ sipo alaafia ti mẹta si ti ku.
Ẹwẹ, awọn oṣiṣẹ miran lẹka eto ilera to ti fara kaaṣa arun yii jẹ mẹrindinlaadọrin ninu eyi ti mẹrin ninu wọn ti ku.
Bẹẹni minisita feto ilera lorilẹede Naijiria, NCDC, Dokita Osagie Ehanire ṣalaye pe ọrọ ti kuro nibẹ, nitori pe iye awọn oṣiṣẹ eto ilera to ti ko arun coronavirus bayii ti kuro ni ogoji (40), o ti dieeyan mẹtalelaadọfa (113).
Oríṣun àwòrán, Babajide sanwo-olu
Bi awọn dokita atawọn oṣiṣẹ eto ilera miran ṣe n foju wina arun coronavirus lẹnu iṣẹ lawọn oṣiṣẹ miran n foju winna rẹ nipa yala pipadanu iṣẹ ni tabi aimọ igba ti owo oṣu yoo wọle.
ọpọlọpọ awọn oṣiṣẹ ni iroyin jẹ ko di mimọ pe awọn alaṣẹ ileeṣẹ wọn ti sọ sinu isinmi ọlọdọọdun ni tipa.
Bi awọn miran si ṣe n gba ẹdinwo oṣu ni awọn kan n gbadura kiṣẹ maa bọ lọwọ wọn.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ipaya to n ba ọpọ oṣiṣẹ bayii bi pupọ ninu wọn ṣe n pada sẹnu iṣẹ ni pipadanu iṣẹ. Ipaya yii ti dori ẹmi ọpọ oṣiṣẹ to bẹẹ gẹ ti alaga ẹgbẹ oṣelu APC to n ṣejọba lorilẹede Naijiria, Adams Oshiomhole, toun pẹlu ti figbakan ri jẹ aarẹ ẹgbẹ oṣiṣẹ lorilẹede Naijiria fi rawọ ẹbẹ sawọn agbanisisẹ lati maṣe da awọn oṣiṣẹ silẹ tabi dinowo wọn ku.
Amọṣa, ajọ to n mojuto ọrọ awọn oṣiṣẹ lagbaye, ILO ti sọ pe ọgbọn ko digi lọrọ naa bayii nitoripe bi nnkan ṣe n lọ yii, igba o din marun miliọnu (195milion)lawọn eeyan ti yoo padanu iṣẹ wọn lagbaye nipasẹ ajakalẹ arun Coronavirus.
Oríṣun àwòrán, others
Ìgbìmọ̀ amúṣẹ́yá ìpínlẹ̀ Eko lóríi Covid-19 ti mú àwọn aláríyá márùndínláàádọ́rin (65) lóríi ẹ̀sùn ìtàpá sí òfin gbéléẹ láti dẹ́kun àj]akálẹ̀ ààrùn Coronavirus  ní ìpínlẹ̀  náà.
Ìròyìn fi hàn pé ibùdó ìgbáfẹ́ẹ 84 Parks and Gardens ni àwọn ènìyàn náà péjú sí ní àdúgbo Abule Egba fún ayẹyẹ ọjọ́ ìbí náà.
Ìròyín sọ pé ìgbìms náà lọ sí ibi ayẹyẹ náà ni lẹ́yìn ìgbà tí àwọn ará ìlú ta wọ́n lólobó.
Ọ̀gá iléeṣẹ́  LASEPA tó ń mojútó àyíká ní ìpínlẹ̀ Eko, Dolapo Fasawe, sọ wí pé wọ́n ti fi àwọn afurasí náà sọwọ́ sí àwọn ọlọ́pàá, lẹ́yìn tí wan ti ìbùdọ ìgbáfẹ́ náà pa.
Oríṣun àwòrán, others
Ọ̀gá LASEPA náà ṣe àlàyé pé àjàkálẹ̀ ààrùn ti sọ ará ìlú di ọ̀kan tí ó sì gbà wọ́n ní ìyànjú àti máà ìròyìntó àwọn aláṣẹ létí.
Agbẹnússọ ọlọ́pàá ní ìpínlẹ̀ náà, Bala Elkana, tó fi ìdí ọ̀rs náà múlẹ̀ , sọ pé lóríi ẹ̀sùn ìtàpá sí òfin  kí onílé gbé ilé àti lílo ẹfgbò igi olóró ni wọ́n fi mú àwọn afurasí náà.
Jọwọ ṣe atunṣe ilana ikansi ayelujara rẹ lati ri ẹkunrẹrẹ rẹ
Orisun: Johns Hopkins University atawọn ajọ eto ilera ilu
Igba ti wọn kede iṣiro awọn to nii kẹyin                                              29 Oṣù Bélú 2021 13:33 WAT+3
*Iye awọn to tọwọ aisan ku ni isọri eeyan ẹgbẹrun lọna ọgọrun
Jọwọ ṣe atunṣe ilana ikansi ayelujara rẹ lati ri ẹkunrẹrẹ rẹ
Akọsile imọ yii, da lori akojọpọ iṣẹ iwadi ni Fasisti Johns Hopkins, o si le ma ṣe afihan awọn akọsilẹ iroyin to ba igba mu lati orilẹede kankan.
** Àwọn iyé akọsilẹ̀ to ti wà fún àwọn ti o ṣẹ́ṣẹ̀ ni ààrun náà jẹ́ àkójọpọ̀ ọjọ́ mẹ́ta. Nítori àwọn àtúgbẹ́yẹ̀wò, o níra láti ṣe àkójọpọ fún àwọn ọkọ́ naa
Orisun: Johns Hopkins University atawọn ajọ eto ilera ilu
Iye akọsilẹ to waye gbẹyin 29 Oṣù Bélú 2021 13:33 WAT+3
Oríṣun àwòrán, Other
Ilé ẹjọ́ gíga ti Ikeja n'ilu Èkó tí dá ẹjọ́ ikú fún alaga ẹgbẹ́ awakọ èrò NURTW, ẹ̀ka ti Boundary/Ayetoro nipinlẹ Eko, Saheed Arogundade lórí ẹ̀sùn pé ó pa ọlọ́pàá kan.
Ọlọpaa náà, Gbenga Oladipupo  nii ṣe ẹni ọdún méjìlélọ́gbọ̀n, nígbà tó ṣe alabapade ikú òjìji náà.
Nígbà tó ń gbé ìdájọ́ rẹ kalẹ, èyí tó gbà wákàtí mẹta gbáko, adájọ́ Olabisi Akinade pàṣẹ pé, nítorí ìpèsè ààbò tó péye, kí wọn tí gbogbo ọ̀nà tó wọ inú gbọ̀ngàn igbejọ náà, kí wọn sì kó àwọn kọ́kọ́rọ́ rẹ wá fún òun, lọ́nà àti dènà kí idaru-dapọ má bàa wáyé lásìkò tí igbejọ bá ń lọ lọ́wọ́.
Nínú àlàyé rẹ, aṣáájú ikọ olupẹjọ, Arábìnrin C Rotimi-Odutola ṣàlàyé fun ilé ẹjọ́ pé ọ̀daràn náà ṣẹ ẹsẹ ọhun lọ́jọ́ kẹwàá oṣù kẹrin ni ìkòríta Gbara, Ayetoro ládùúgbò Ajegunle nílùú Eko.
Olóògbé náà ń wà ọkada lọ láti ṣe abẹwo si màmá rẹ, Arábìnrin Mojisola Martins ni ile rẹ to wá ní òpópónà Olayinka ni Ajegunle, nígbà tí àwọn gende mẹ́rin ṣẹburu rẹ nikorita Gbàrà, àwọn mẹta nínú wọn mú Ọlọpaa náà mọ́lẹ̀, tí Arogundade sì ń gùn olóògbé náà laimọye ìgbà, kí gbogbo wọn to salọ.
Wọn gbe olóògbé tó fara gba ọgbẹ náà lọ sílè ìwòsàn àmọ́ ẹpa kò boro mọ, Ọlọpaa náà jáde láyé.
Ikọ olupẹjọ náà ni, ẹsẹ kan ṣoṣo tí olóògbé náà ṣẹ àwọn awakọ èrò náà, tí wọ́n fi rán án sọrun ọsan gangan ni pé, ó sewuri fún àwọn onikẹkẹ Maruwa láti máa na Ayetoro, èyí tó ń mú adinku bá owó tí àwọn awakọ èrò ń pá.
Nínú ìdájọ́ rẹ, adájọ́ ni ikọ olupẹjọ fi ẹri tó dájú hàn pé Arogundade lo gbẹmi Ọlọpaa naa, to sì ni kí wọn yẹ igi fún un, títí tí ẹ̀mí yóò fi bọ lára rẹ.
Àmọ́ Adájọ́ Akinlade fún àwọn olujẹjọ márùn-ún yòókù tó ń jẹjọ pẹ̀lú Arogundade ni ìdáǹdè lórí ẹ̀sùn onikoko méjì, tí wọn fi kan wọn.
Ní kété tí adájọ́ gbé ìdájọ́ rẹ kalẹ tán, ní Arogundade ṣubú lulẹ nílé ẹjọ́, táwọn mọlẹbi rẹ náà sì bu sí ẹkún kíkorò.
Awọn agbofinro ti mu afurasi kan lori ẹsun wi pe o fipa ba iyawo rẹ lopọ ti obinrin naa si gba ibẹ dreo ọrun.
Oríṣun àwòrán, Other
Alukoro ileeṣẹ ọlọpaa ipinlẹ Jigawa, Abdu Jinjiri ṣalaye pe abule Kankaleru ni ijọba ibilẹ Ringim ni iṣẹlẹ ọhun ti ṣẹlẹ.
Alukoro ileeṣẹ ọlọpaa ni ọkunrin naa, Alasan Audu fipa ba iyawo rẹ lopọ lẹyin ti obinrin naa kọ lati fun un.
Ọgbẹni Abdu Jinjiri fikun ọrọ rẹ pe awọn tọkọ taya naa ti n ni ede-ai-yede tẹlẹ ti wọn fẹ ara wọn fun ogunjo pere ki ṣaaju iṣẹlẹ naa.
Alukoro ileeṣẹ ọlọpaa ni iyawo naa to di oloogbe, ẹni ọdun metadinlogun ko fẹ fẹ ọkunrin naa lọkọ, ṣugbọn wọn mu ni tipa tipa lati fẹ ẹ.
Oríṣun àwòrán, Other
Iwadii awọn ọlọpaa fihan pe laago mẹrin oru ni ọkunrin naa wọle tọ iyawo rẹ lọ, ṣugbọn obinrin naa ko gba lati jọ ni ajọṣepọ pẹlu ọkọ rẹ nitori oun kọ lo wu u lati fẹ.
Bayii ni atẹjade ileeṣẹ ọlọpaa sọ pe ọkunrin naa fipa ba iyawo rẹ lopọ lati le tan ifẹ inu ara rẹ.
Coronavirus cases in Africa: Ijọba ipinlẹ Oyo ti kọ ẹgbẹsan irẹsi to jẹ iranwọ ti ijọba apapọ fi ransẹ si wọn.
Ijọba ipinlẹ Oyo ti sọ idi ti awọn fi kọ irẹsi to lẹ ti ẹgbẹsan ti ijọba apapọ fi ransẹ si wọn
Awọn alabojuto eto ounjẹ  nipinlẹ Oyo ti wọn fi lede fun awọn ara ipinlẹ Oyo.
Wọn fi lede wi pe kokoro wa ninu irẹsi naa, ti o si fihan gbangba pe awọn ounjẹ naa ti bajẹ.
Bakan naa ni wọn fikun wi pe awọn ko binu si ijọba apapọ amọ ti wọn ba ni irẹsi miran to dara awọn yoo gba lọwọ wọn
Ẹkunrẹrẹ fidio naa ni eyi;
What did Buhari say about the lockdown: Awọn ọmọ Nàìjíríà káàkiri àgbáyé sọ ìrírí lábẹ́ àṣẹ kónílé-ó-gbélé
Kariaye laarun Coronavirus. Gbogbo orilẹede agbye lo fẹẹ tan de tan.
Ni bi a ṣe n sọrọ yii, o ti le ni miliọnu mẹta eeyan to ti ko aarun yii lagbaye.
Gbogbo agbaye lo si ti n gbe igbesẹ lori ọna ti yoo fi pari lọdọ wọn.
Awọn ọmọ Naijiria kaakiri agbaye ṣalaye ohun ti oju wọn ri ati boya inu wọn dun pe wọn ko si ni orilẹede Naijiria ni iru asiko yii.
Corornavirus: Ṣe lilo ìbọ̀wọ́ le dènà ààrùn Coronavirus
O ṣeeṣe ki iwọ naa ti ri tabi gbọ nipa pé bi ènìyà ba ti lo ìbọ̀wọ́ ewu Corornavirus ti fòó.
Èyí kò rí bẹ́ẹ̀ ti ẹni náà kìí bá ti ṣe oṣisẹ ilera tabi awakọ, kóda lilo ìbọwọ́ tun le ṣe akóba fún ọ láti ma huwa aibikita níto ri pé o fi ibọwọ si ọwọ.
Nítori náà o ṣe pàtàkì láti maa fi ọṣẹ fọwọ́ lóòrèkóòrè, lati ri dáju pe o dáàbò bo ilé rẹ lọ́wọ́ ààrun Corornavirus
Ṣe lilo Methtoletom lé koju aarun Corornavirus?
Laipe yii ni ààrẹ Guinea Alpha Condé ni ti eniyan ba lo mentholetom pẹlu ọmi gbigbona yoo bọ lọwọ ààrun Corornavirus.
Ko si ootọ ọrọ nínu ọrọ yìí nitori ko si àridaju imọ sayẹnsi to sọ pe eyi ri bẹẹ.
O se pataki ki tọkọtaya wa ní isọkn niru asiko yii, nítori pé ọna yii nikan ni aabo to yẹ yoo fi wa ninu idile
Gbenga Adeboye: Ó tẹ́ bàbá mi lọ́rùn pé ká mu gàárì nílé ju kí ebi pa ará ìta lọ -
New coronavirus symptoms: Ẹ máà fi Eko wé Ghana lórí dídẹ okùn ìgbélé, ìyàtọ̀ wà níbẹ̀-Hamzat, igbákejì gómìnà Eko
Oman Slave: Ó pe mi kí n máa mu Gari ní Nàìjíríà ju ìlú yẹn lọ o
Ohun taa jẹ, taa mu, taa fi r'ile aye gbe lo mu arabinrin yii ti a ko le fi oju rẹ han kuro ni Naijiria lọ gba iṣẹ ni orilẹede Oman.
Arabinrin yii s fun BBC pe jẹjẹ loun wa nilu wọn ti wọn sọ fun un pe iṣẹ wa ni orilẹede kan ti wọn yoo ti maa san owo to to igba miliọnu naira fun un.
Bi kii ba ti ṣe iṣẹ aṣẹwo, o dara. Ni arabinrin yii fesi fun awọn aburo rẹ to ba a wa iṣẹ. O de 'bẹ tan lorin ba yipada.
Human trafficking in Libya: Ẹsẹ̀ bàtà àti èso kukumba ni wọ́n fi ń já àbálé àwọn ọmọ Nàìjíríà ní Libya-Yetunde, arìnrìnàjò sí Libya
Ohun taa jẹ, taa mu, taa fi r'ile aye gbe lo mu arabinrin yii kuro ni Naijiria lọ orilẹede Libya.
lootọ kii ṣe orilẹede Libya ni wọn sọ fun un pe yoo lọ tẹlẹ, nigba ti ọrọ yoo fi foju han sii, oju ọna Libya lo ti ba ara rẹ.
ohun ti oju rẹ ri lọna nigba to n lọ, a ti mu wa fun iran yin ni abala akọkọ, abala ekeji ree nibi ti arabinrin Yetunde Abrahams ti sọ ohun ti oju rẹ ri ni Libya ati bi irinajo rẹ lati pada si orilẹede NAijiria ṣe jẹ.
Niyi Akinmolayan tó ṣe fíìmu àwòrán-dèèyàn 'Cartoon' nípa COVID-19 tó la ayé já ní Nàìjíríà leè lo sinimá fún ìgbélékè àṣà
Lara awọn iṣoro to yọju fun awọn orilede, lasiko ajakal arun coronavirus yii ni ọna lati ṣalaye rẹ fun awọn ọmọde.
Ọpọlọpọ obi lo si ti ni lati pariwo titi lọna ati ṣalaye fun awọn ọmọ wọn idi ti wọn ko ni lee fi l si ile iwe tabi lba awọn rẹ wọn ṣere, ṣugbọn sibẹ ti ko dabi eyi to w eti awọn ọmọ wọn.
Oríṣun àwòrán, Anthillstudios
Amọṣa, ilumọọka ayaworan sinima kan, Ọgbẹni  Niyi Akinmọlayan ti oun pẹlu ni iriri yii gbe fidio aworan-deeyan kan ti a mọ si Cartoon jade eleyi to ti mu ki alaye naa rọrun fun awn obi lai ni sọ r kan ṣoṣo.
Ọgbẹni Akinmọlayan ba BBC News Yoruba sọrọ lori idi to fi lo ọna yii.
Àǹfàní ńlá ni àṣẹ ìgbélé jẹ́ fún àyíká ọmọnìyàn pàápàá nílùú Eko
Lasiko igbele ti ijba apaps pa gẹgẹ bi ara igbesẹ lati dẹkun itankalẹ arun coronavirus lorilẹede Naijiria, nṣe ni igboro da waiwai, ko si eefin keefin to n ṣe akoba fun afẹfẹ bẹẹni wọlukọlu awọn ero ọna to nlọ  to n bọ ko si pẹlu.
Ipinlẹ Eko jẹ ọkan lara awọn ilu tabi orilẹ lagbaye nibi ti wahala ibajẹ oju afẹfẹ ti gogo si julọ.
Amọṣa lasiko igbele yii ọpọ lo ri ẹwa tuntun ilu Eko eleyi ti ko ni abawọn kankan yala loju ofurufu tabi lori ilẹ.
Eyi ni akojọpọ awọn aworan oju ọjọ bo ṣe ri lasiko igbele ni ilu Eko
Wo àwọn nǹkan mẹ́rin tó yẹ kó wà nínú báàgì rẹ lásìkò Covid-19 yìí
Ajọ to n ri si eto ilera lagbaye, WHO ti sọ pe imọtoto araẹni lee dabo bo eeyan lasiko ajakalẹ arun Covid-19 yi.
Yatọ si fifọ ọwọ pẹlu ọṣẹ, lilo ibomu atawọn nkan mii to yẹ ni ṣiṣe, ki ni awọn nnkan mii ti eeyan tun le ṣẹ lati dabo ara tabi ohun ini rẹ lasiko yi?
BBC Yoruba yannana gbogbo bo ṣe jẹ ninu fidio to wa loke yi.
NFF fi #30,000 kún #10,000 owó ìrànwọ́ oṣooṣù fún ìyá Rashidi Yekini àti Samuel Okwaraji
Oríṣun àwòrán, Others
Ajọ to n ri si ere bọọlu afẹsẹgba ni Naijiria, NFF ti fi ẹgbẹrun un lọna ọgbọn naira kun ẹgbẹrun mẹwaa ti ẹka ijọba to n ri si ere idaraya ṣeto gẹgẹ bi owo iranwọ oṣooṣu fawọn iya oloogbe agbabọọlu Naijiria tẹlẹ, Rashidi Yekini ati Samuel Okwaraji.
L'Ọjọru ni ileeṣẹ ijọba to n ri si ere idaraya ati idagbasoke awọn ọdọ kede eto naa lati maa fun awọn mama oloogbe agbabọọlu Naijiria mejeeji tẹlẹ ni ẹgbẹrun mẹwaa naira loṣooṣu gẹgẹ bi owo iranwọ.
Olaitan Shittu to jẹ aṣoju minisita ere idaraya lo fọrọ naa lede l'Ọjọru nigba to ṣabẹwo si Alhaja Yekini niluu Ijagbo nipinlẹ Kwara.
Oríṣun àwòrán, Others
Rashidi Yekini ṣi ni aṣiwaju atamatase agbabọọlu fun ilẹ Naijiria ninu itan.
Bakan naa ni ijọba tun fun mọmọ Yekini ni ẹgbẹrun lọna aadọta naira gẹgẹ ẹbun fun awẹ Ramadan to n lọ lọwọ.
O ti pe ọdun mẹjọ ti ẹlẹsẹ  ayo, Rashidi to gba goolu sawọn julọ fun Naijiria di oloogbe.
Okwaraji ṣubu lori papa, o si gba ibẹ ku nigba to n kopa ninu ifẹsẹwọnsẹ ati yege fun idije ife ẹyẹ Italian '90 to waye laarin Naijiria ati Angola niluu Eko lọjọ kejila oṣu kẹjọ ọdun 1989.
Ìjọba buwọ́lu ẹgbẹ̀rún mẹ́wàá náírà owó ìrànwọ́ oṣooṣù fún ìyá Rashidi Yekini
Rashidi Yekini: Ìjọba buwọ́lu ẹgbẹ̀rún mẹ́wàá náírà owó ìrànwọ́ oṣooṣù fún ìyá Rashidi Yekini
Ileeṣẹ ijọba to n ri si ere idaraya ati idagbasoke awọn ọdọ ti ṣeto lati maa fun mama oloogbe agbabọọlu Naijiria tẹlẹ, Rashidi Yekini ni ẹgbẹrun mẹwaa naira loṣooṣu gẹgẹ bi owo iranwọ.
Oríṣun àwòrán, others
Olaitan Shittu to jẹ aṣoju minisita ere idaraya lo fọrọ naa lede l'Ọjọru nigba to ṣabẹwo si Alhaja Yekini niluu Ijagbo nipinlẹ Kwara.
Bakan naa ni ijọba tun fun mọmọ Yekini ni ẹgbẹrun lọna aadọta naira gẹgẹ ẹbun fun awẹ Ramadan to n lọ lọwọ.
O ti pe ọdun mẹjọ ti ẹlẹsẹ ayo, Rashidi to gba goolu sawọn julọ fun Naijiria di oloogbe.
Fuel Price: Ẹ̀dínwó epo bẹntírò ti NNPC kede kò kan ará ilú
Coronavirus: Ǹjẹ́ àwọn dókítà tó ń tọ́jú eyín ń ṣisẹ́ lásìkò pàjáwìrì? Àti àwọn ìbéèrè míràn
Ìbéèrè àti ìdáhùn wọn
O ti lé ni mílíọ̀nù mẹ́ta àti ọgọ́rùn ún mẹ́fà (3,600,000) ènìyàn to ni Corornavirus ni gbogbo àgbáyé tí ẹgbẹ̀rún lọ́nà ọtalenigba (251,000) ènìyàn ti kú- ẹgbẹ̀rún lọ́nà mokandinlogbonẹgbẹ̀run (29,000) nínú rẹ̀ ló wá láti UK nìkan.
Coronavirus jẹ ajakalẹ arun ti wọn ri ni China ni oṣu kejila, ọdun 2019 ti wọn n pe ni Covid- 19
O le ni ọgọrọọrun oriṣii coronavirus- ni eyi ti o wọpọ laarin ẹranko bii: ẹlẹdẹ, rakunmi, adan, ati olongbo. Ṣugbọn diẹ lo n nipa lara eeyan bii ti Covid 19 yii
Awọn coronavirus kọọkan maa n fa ailera ti ko lagbara pupọ bii ọfinkin, iba ṣugbọn ti Covid 19 lagbara pupọ lati fa ailera nla bii otutu aya Niumoníà
Awọn to ba ti kagbako rẹ le ni awọn apẹrẹ bii iba, ara riro paapaa tọwọtẹsẹ ati ikọ. Ni eyi to ṣeeṣe lati gbadun lai lọ fun itọju àrà ọtọ kankan
Awọn arugbo ati awọn to ni ailera ni ara wọn tẹlẹ biiaisan ọkan, itọ ṣuga, arun jẹjẹrẹ lo ṣeeṣe ki o pa lára julọ
Nigba ti ara awọn eeyan ba ti ya tán, awọn ohun eelo ija kan a ṣi ṣẹku ni agọ ara wọn lati gbogun ti irufẹ ikọlu naa sii
Awọn eroja igbogun ti ni agọ ara kii ṣe titi aye nitori pe o le dinku ni agbara ti ọjọ ba ṣe n pẹ sii
Ti o ba ti ni coronavirus, ara rẹ yoo maa ja fun ẹ nitootọ ṣugbọn a ko tii mọ odiwọn igba ti agọ ara ẹ le ja fun mọ lẹyin igba akọkọ too ni coronavirus
O kere tan, Ọjọ marun un ni ami coronavirus a bẹrẹ si ni farahan lara eniyan. ṣugbọn awọn onimọ sayẹnsi ni omiran le tete ni apẹrẹ
Ajọ eleto ilera agbaye, (WHO) gba imọran pe o ṣeeṣe ko pe ọjọ mẹrinla lara ni eyi ti iwadii ni o le to ọjọ mẹrinlelogun
O ṣe pataki lati mọ iwọn asiko ti o fi le duro lara ko to fojuhan. Asiko yii lawọn dokita ati eleto ilera fi le gbe igbesẹ ki arun naa ma baa tan kalẹ
Aisan mejeeji jẹ ajakalẹ arun
o kere tan, eeyan meji si mẹta le ko coronavirus lara ẹni to nii nigba ti ẹni kan le ko otutu igba ọginiti lara ẹni to nii
Awọn igbesẹ to rọrun wa too le gbe lati dẹkun itankalẹ coronavirus
Lara awọn eeyan mẹrin ninu marun un awọn to ni Covid- 19 ko ni mọọ lara pupọ, o kan maa dabi otutu lasan lara wọn
Diẹ lara àmì ẹ ni iba, ikọ ẹgbẹ ati ailera fun ọjọ diẹ ti waa si gbadun laarin ọsẹ kan ti awọn apẹẹrẹ yii yoo lọ
Ti o ba ti wọ ẹ lara ni yoo kọle si inu ẹdọ-fooro rẹ nibi ti yoo ti jẹ ki eemi mimi rẹ ko nira pẹlu otutu aya. ẹni kan ninu eniyan meje maa nilo itọju ile iwosan bayii
Imọran Uk fawọn to ni ikọ séèmí-séèmí ni ki wọn tẹsiwaju lati maa lo oogun to yẹ lojoojumọ to n dena ikọlu gẹgẹ bi dokita wọn ṣe sọ fun wọn. Eyi yoo din ikọlu arun nipa eemi ku fun wọn lasiko yii
Maa gbe ohun eelo èémí rẹ rin kaakiri nigba gbogbo paapaa ti o ba kẹfin ikọlu ikọ rẹ nitori ti ikọlu yii ba pọ ju, o ṣeeṣe ki o wa ni ewu nini coronavirus
O ṣeeṣe ki Coronavirus ni ipa to pọ lara awọn arugbo ati awọn to ni ailera miran lara tẹlẹ bii aisan ọkan, aisan ẹdọ-foor ati itọ ṣuga
Ko si ẹri aridaju kankan pe awọn alaabọ ara to ni ilera pipe laini ailera tẹlẹ wa ninu ewu coronavirus ju awọn miran lọ
O ṣeeṣe ki Covid 19 ja si otutu Niumoníà nigba kọọkan lara awọn to ni ailera ẹdọ-fooro tẹlẹ
Sugbọn nitori pe arun tuntun ni coronavirus jẹ, ko si ẹni to le ni ohun eelo igbogun ti ni agọ ara yala Niumonia tabi Sars ti wa lara wọn ri
Iyaraẹnisọtọ ni ilu kọọkan    ati konile-o-gbele nipọn nitootọ ṣugbọn laiṣe eyi, araun naa a maa tankalẹ sii ni
Ko tii si oogun tabi abẹrẹ ajẹsara fun coronavirus  bo ṣe wa fun otutu ọginiti ni eyi to n jẹ ko ni ipa pupọ lara arugbo ati awọn to ni ailera  ara tẹlẹ
Awọn ijọba orilẹ-ede agbaye n ṣatunṣe si ofin wiwọ iboju loorekoore ṣugbọn ajọ WHO gba imọran lati maa wọ iboju nigba gbogbo, yala o ni ami ara gbigbona tabi ikọ tabi pe o n ṣe itọju fun ẹni to ni coronavirus tabi afurasi to ni coronavirus
O ṣeeṣe ki iboju daabo bo ẹ lọwọ ajakalẹ arun yii, ti o ba loo daadaa pẹlu awọn igbesẹ miran bii fifọ ọwọ rẹ nigbagbogbo ki o si gbe ile lai jade sita pupọ
Idi oriṣii ni awọn ijọba kọọkan ṣe n yi ofin lilo iboju wọn pada bii pe ki iboju ma lọ tan ni agbegbe wọn de ibi pe awọn oṣiṣẹ eleto ilera ko ni ri lo mọ. nigba ti awọn miran n ro pe wiwọ iboju maa n jẹ ki awọn eeyan miran ro pe awọn ti ri idaabobo gba kuro lọwọ arun coronavirus
Rii pe o o tẹlẹ ofin to ba wa nita ni ẹkun rẹ bi apẹrẹ ni awọn orilẹ-ede bii Argentina, China, Italy ati Mexico to ti jẹ kan-n-pa fun ẹni to ba fẹ jade
Ti o ba n ba ẹni to n danikanwa gbe, o yẹ ki o din ajọṣepọ ifarakan ara yin ku, koda, to ba ṣeeṣe ki ẹ ma jọ wa ninu iyara kan naa
O yẹ ki ẹni to danikanwa yii wa ni iyara to ni afẹfẹ to pọ pẹlu ferese to ṣeeṣi sita , ki ẹlomiran ma si wọnu iyara naa pẹlu rẹ
Awọn onimọ sayẹnsi n ṣe iwadii lati mọ sii nipa covid 19 ati ipa to le ni lori alaboyun ṣugbọn iṣẹ ṣi n lọ
A ko tii mọ boya o ṣeeṣe ki alaboyun ko arun coronavirus ran ọmọ inu rẹ ninu oyun tabi lasiko irọbi, ṣugbọn titi di asiko yii , a ko tii rii ninu omi ọmu ati omi inu ọlẹ oyun
Ko tii si iwadii to fidi ẹ mulẹ pe ewu nla wa fun oloyun lori coronavirus ju awón eeyan to ku lọ. Ṣugbọn o ṣeeṣẹ ki ipa rẹ pọ pupọ lara oloyun nitori agọ ara wọn ati iyatọ ti oyun n mu ba ara ati awọn ailera nipa eemi mimi
Iya maa n daabo bo ọmọ wọn pẹlu omi ọyan
Ti agọ ara rẹ baa n pese eroja to n gbogunti i yoo ba coronavirus ja ni eyi ti o o le fi sara ọmọ rẹ nipasẹ omi ọyan
Ki abiyamọ to n fun ọmọ lọyan naa tẹle imọran awọn eeyan to ku nipa bibo ẹnu rẹ nigba ti o ba n hukọ tabi sin, sisọ tíṣu ti o lo danu sile ilẹ lẹsẹkẹsẹ, fifọ ọwọ rẹ loorekoore, ma fi ọwọ kan oju, imu ati ẹnu rẹ pẹlu ọwọ to dọti
Akọṣoilẹ China ati awọn orilẹ-ede mii fihan pe coronavirus ko fi bẹẹ ni ipa lori ọmọde
Eyi ṣeeṣe ko jẹ pe awọn ami apẹẹrẹ coronavirus ko han lara wọn tabi nitori pe agọ ara wọn le gbọn ọn danu
Awọn ọmọde ti wọn ba ni ailera ẹdọ-fooro tẹlẹ bii ikọ séèmí-séèmí nilo lati tubọ ṣọ ara wọn
Coronavirus lockdown: Ìyàtọ̀ láàrín ìgbélé ní Nàìjíríà àti ilẹ̀ òkèèrè
Laipẹ yii ni orilẹede Naijiria kede didẹ okun eto konile o gbele lawọn agbegbe kan wa silẹ.
Ọpọ lo ti n kọminu lori ohun to lee ti ẹyin ọrọ naa jade
Arabinrin Sandra to n gbe ni orilẹede Amẹrika ba BBC sọrọ lori bi nnkan ṣe n lọ labẹ eto igbele nibẹ ati iyats to wa ni bo ṣe ri nibẹ ati bo ṣe ri ni Naijiria.
Ṣé o láyà: Ẹ wo àkójọpọ̀ àwọn ǹkan ti o máa n wáyé lẹyin ìtàgé lásiko iṣẹ́ ìfọ̀rọ̀wánilẹ́nu wò
Ọ̀pọ̀ àwọn to ti kópa lórí ètò Ṣe o láyà nnile iṣẹ́ BBC Yoruba lo ṣe bẹbẹ, ni ọ̀ps igba si ni a maa n yọ epò kúrò nínú àlìkámà ki a to mú wa sí ojú ìwòran yìí.
Lónìí a fẹ ki ẹyi náà ni àànfani láti ri àwọn nkan ti o maa n waye lásiko ìfọ̀rọ̀wánilẹnu wò.
Derele Edun àti Jaiye Kuti dán ǹkan wo lẹ́yin ìtàgé Ṣé o láyà
Kogi Coronavirus Status: Kìí ṣe ààrùn Covid-19 ló pa adájọ́ àgba ìpínlẹ̀ Kogi-Kọmísọ́nà ìlera
Oríṣun àwòrán, Othrers
Kọmísọna fún èòì ìlera ní ìpínlẹ̀ Kogi Saka Audu Haruna ní kìí ṣe ààrùn coronavirus lo pa adájọ agbà to jẹ́ Ọlọrun nipe ni ibudó ìtọ́jú àwọn aláàrùn coronavirus ní ìpínlẹ̀ Kogi.
Lásìkò tó n bá BBC news Yoruba sọ̀rọ̀ kọmísọ́nà ètò ìlera náà sàlàyé pé, ibi ètò ìsìnkú rẹ̀ ni àwọn ti n bọ̀ bi òun ṣe n bá BBC sọ̀rọ̀ lọ́wọ́.
Kìí ṣe coronavirus ló paá, sùgbọ́n à ó ṣe ìwádìí ǹkan to n fa ikú tó ń ṣẹlẹ̀.
Haruna ni kò sí ààrùn Coronavirus ni ìpínlẹ̀ Kogi titi di àsìkò yìí gẹ́gẹ́ bi gómínà ìpínlẹ Yahaya Bello ṣe sọ.
Nípa ìjọba ìpínlẹ̀ náà tó ti ìjọba ìbílẹ̀ Kabba Bunnu pa  ní ǹkan bi ọsẹ díẹ̀, ó ni gómínà ṣe èyí láti lé jẹ kí àwọn eletò ìlera ṣe ìwádìí ni, nígbà ti ba abájade ìwádìí náà ba sì jáde àtéjáde tabi ìpàdé oníròyìn yóò wáyé.
A ṣì ń ṣe ìwádìí ikú tó pa adájọ́ àgbà náà lọ́wọ́.
Kíni àwọn ọmọ Naijiria  ń sọ lori ayélujára
Ariwo gomina ipinlẹ Kogi, Yahaya Bello lawọn eeyan n pa bayii lori itakun ayelujara.
Iṣẹlẹ yii lo n waye lẹyin ti adajọ agba ipinlẹ naa, Nasir Ajanah dagbere faye nile itọju awọn to ni arun Coronavirus ni ilu Abuja.
Ṣaaju ni ijọba ipinlẹ ọhun ti ni ko si arun Coronavirus nilẹ oun, ṣugbọn ọrọ bẹyin yọ lẹyin ti àjọ NCDC ni irọ nla ni.
Pupọ lara awọn to fi erongba wọn lede loju opo Twitter lo n bu ẹnu atẹ lu gomina naa lori iha to kọ si ọrọ Coronavirus ni ipinlẹ Kogi.
Lopez Iyke ni gomina ọhun àti pe ipinlẹ Kogi ko ni ilọsiwaju kankan labẹ iṣakoso gomina naa.
Alfred Aji ni tirẹ sọ pe Yahaya Bello ni gomina ti ko ṣe dáadáa ju ninu itan orilẹ-ede Naijiria.
Ni ti Morris Monye, o ni o ṣeni laanu pe awọn eeyan n ku nitori arun Covid-19 ṣugbọn Yahaya Bello ṣe bi pe ko kan oun.
Ẹ wo awọn nnkan miran ti awọn eeyan n sọ:
Oríṣun àwòrán, others
Adajọ agba ipinlẹ Kogi, Nasir Ajanah ti dagbere faye..Iroyin ni Ajanah ku sile itọju awọn alarun Covid-19 to wa ni Gwagwalada, ni ilu Abuja.Iṣẹlẹ yii lo n waye lẹyin nnkan bi ọsẹ meji ti ọkan lara awọn alabaṣiṣẹ gomina ipinlẹ naa, Yahaya Bello ku sile iwosan kan ni Abuja.
Eyi jẹ ọsẹ kan lẹyin ti Ibrahim Shaibu Atadoga to jẹ aarẹ ile ẹjọ magisrati ipinlẹ naa, jade laye.Ṣaaju ni ijọba ipinlẹ Kogi ti sọ pe ko si arun Covid-19 ni ipinlẹ oun, ṣugbọn ajọ NDCD sọ pe irọ patapata ni ọrọ naa.NCDC ni lara awọn eeyan to ni arun ọhun sọ pe ipinlẹ Kogi ni wọn ti wa, eyi to da ariyanjiyan silẹ laarin ijọba ipinlẹ Kogi ati ajọ naa.
Kogi Lockdown: Ǹkan tí a mọ̀ nípa àṣẹ kóníléógbélé níjọba ìbílẹ̀ Kabba-Kunnu
Oríṣun àwòrán, Yahaya Bello
Gómínà Kogi pàṣẹ kóníléógbélé ní ìjọba ìbílẹ̀ kan ní Kogi
Gómínà ìpínlẹ̀ Kogi, Yahaya Bello ti kéde kóníléógbélé ọṣẹ̀ méjì níjọba ìbílẹ̀ Kabba-Kunnu , nípìnlẹ̀ Kogi nítori ààrùn coronavirus.
Èyí wáyé lẹ́yìn tí àjọ tọ gbógun ti àjàkálẹ̀ ààrùn lórílẹ̀-èdè Nàìjíríà (NCDC) fìdí rẹ̀ múlẹ̀ pé ènìyàn méjì tó ni ààrùn coronavirus jẹyọ níjọba ìbílẹ̀ náà, àwọn méjì náà ni Imaamu àgbà ibẹ̀ àti ọmọ rẹ̀.
Nigeria movie industry: Àgbà òṣèré, Lere Paimo ní àìgbọràn ló ń da ọ̀pọ̀lọpọ̀ àwọn
Kóníléógbélé náà yóò bẹ̀rẹ̀ láti aago mẹ́jìlá ọjọ kejì oṣù kẹfa títí di ọjọ kẹẹdógún ọṣù kéfa, bákàn náà ni wọ́n kò gbọdọ rí ẹnikẹni rìn ládùgbọ́n wọn.
Yahaya Bello ni ìgbélé náà yóòràn ìjọba lọ́wọ́ láti lé jẹ ki wọ́n rí àwọn tó ti ní ǹkan ṣe pẹ̀lú imaamu náà ati ọmọ rẹ.
Sùgbọ́n kan tó wà nínú ọ̀rọ̀ yìí ni pé ìròyìn sọ pé gómínà náà kò gbà pé ààrùn coronavirus wà nípínlẹ̀ Kogi.
Nínú àtẹjáde gómìnà Yahaya Bello, ó ní ki gbogbo àwọn to wà ni àyíka àti ni ipinlẹ Kogi maa tẹ̀lé àwọn ìlànà àjọ NCDC bótilẹ̀ jẹ́ pé ko sí ààrùn náà ni ìpínlẹ̀ Kogi
Kogi jẹ́ ọ̀kan lára àwọn ìpínlẹ̀ méjì tí kò tíí ní ààrùn náà ní Naijiria.
Irọ́ lásán ni, ṣe ni NCDC ń fi Coronavirus tan àwọn ọmọ Naijiria jẹ- ìjọba ìpínlẹ̀ Kogi
Coronavirus in Nigeria: Ní ṣe ni NCDC ń fi Coronavirus tan àwọn ọmọ Naijiria jẹ- ìjọba ìpínlẹ̀ Kogi
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ijọba ipinlẹ Kogi ti sọ pe ko si ẹnikẹni to ni arun Coronavirus ni ipinlẹ naa.
Bakan naa lo tun ni ṣe ni ajọ to n gbogun ti itankalẹ ajakalẹ arun ni Naijiria, NCDC n fi ọrọ arun naa ja orilẹ-ede yii lole ni.
Kọmiṣọnna ọrọ to n lọ ni ipinlẹ ọhun, Kingsley Fanwo lo sọ ọrọ naa ninu iforowerọ pẹlu ileeṣẹ amohunmaworan abẹle Channels.
"Fanwo ni ""O yẹ ki ajọ NCDC dẹkun ati maa tan awọn eeyan orilẹ-ede yii jẹ pẹlu Coronavirus nitori mi o gbagbọ pe NCDC n ṣe iranlọwọ kankan fun orilẹede yii."""
"Kọmiṣọnna ọhun tẹsiwaju pe ""Ni erongba temi ni pe, afojusun NCDC ni lati pin arun Covid-19 kaakiri orilẹ-ede yii."""
Fanwo ṣalaye pe ajọ NCDC fẹ fi tipatikuuku jẹ ki ipinlẹ Kogi ni arun Coronavirus ti ko si yẹ ko ri bẹ.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
O ni awọn arun mii wa to n pa awọn eeyan kaakiri Naijiria ju ti Coronavirus lọ bii aisan iba, ṣugbọn Coronavirus ni NCDC joko ti.
Ẹwẹ, adari agba NCDC, Chikwe Ihekweazu ti fesi pe awọn meji kan ti ayẹwo ṣẹṣẹ fihan pe wọn ni arun ọhun sọ pe ipinlẹ Kogi ni wọn ti wa.
Ṣaaju ni NCDC ti sọ pe arun Covid-19 ti rapala wọ ipinlẹ Kogi, ṣugbọn ijọba ipinlẹ naa ni ko si ohun to jọ bẹẹ, eyi si ti n fa họwuhọwu laarin ajọ naa ati ijọba ipinlẹ ọhun.
Oríṣun àwòrán, Twitter
Minisita eto ilera ni Naijiria, Dokita Osagie Ehanire sọ pe ijọba yoo ṣe iwadii ohun to faa gan an ti ipinlẹ Kogi ati Cross River ko fi tii ni akọsilẹ aarun coronavirus.
Dokita Osagie ṣalaye awọn eeyan ti ijọba kọkọ ran lọ si ipinlẹ Kogi kuna nitori ede-ai-yede to ṣẹlẹ laarun awọn eeyan naa ati ijọba ipinlẹ Kogi.
Minisita ni igbesẹ ti ijọba yoo gbe naa ni lati ṣabẹwo si awọn ipinlẹ pada.
Dokita Osagie ni ọsẹ ti o n bọ yii naa ni ijọba yoo ran awọn si ipinlẹ Cross River ati Kogi lati ṣiṣẹ iwadii naa.
Atupalẹ awọn ipinlẹ to ni coronavirus ni Naijiria
Titi di ọjọ kejila osu kini ọdun 2020,orileede China nikan ni o ni eeyan to ni arun coronavirus.
Ṣugbọn nigba ti yoo fi di ọjọ kẹtala, kokoro aifojuri yi di ajakalẹ ti awọn orilẹede bi Thailand, Japan, South Korea ati Amẹrika naa si bẹrẹ si ni kede awọn to kọkọ nii lọdọ wọn.
Laipẹ, arun yi tan kaakiri de agbaye, koda ilẹ Afrika naa ba wọn nipin ninu rẹ.
O le ni miliọnu mẹta eeyan to ti ni Coronavirus lagbaye gẹgẹ bi iroyin to n jade lọdọ ileeṣẹ to n pese iroyin nipa Coronavirus ti fasiti John Hopkins l'Amẹrika.
Ọjọ kẹtadinlọgbọn oṣu keji ni Naijiria kede ẹni akọkọ ti yoo ni arun yii lẹyin ti arakunrin ọmọ orileede Italy kan gbe wọle ti ayẹwo si fihan pe o ni Covid-19.
Lọjọ kẹsan osu kẹta, Naijiria kede ẹni keji iyẹn ọmọ Naijiria to ṣalabapade ọmọ Italy to gbe arun naa wọle.
Lẹhinnaa, awọn to ni arun naa  bẹrẹ si ni pọ si.
Iroyin to n tẹwa lọwọ lati ileesẹ to n gbogun ti idena aisan ni Naijira, NCDC, wọn ni eeyan 3,912 lawọn ti fidi rẹ mulẹ pe wọn ni arun yi,ti ilu Eko si ni iye awọn to pọju tii se 1,667.
Awọn to ti ba Coronavirus lọ ti wọ mẹtadinlọgọfa ti awọn ti ara wọn ya lẹyin itọju si jẹ 679.
Ipinlẹ mẹrinlelogoji pẹlu olu ilu Naijiria, Abuja ni coronavirus ti wọ pẹlu ohun ti a ri gbọ lọdọ wọn lọwọ yi.
Oríṣun àwòrán, Facebook
Ni bayii, ipinlẹ Kogi ati Cross River ni ipinlẹ meji ti aarun covid-19 ko tii wọ lorilẹede Naijiria.
ATUPALE BI NNKAN SE RI PELU CORONAVIRUS NI NAIJIRIA TITI DI ỌJỌ́ KEFA OSU KAARUN 2020
Iye ayẹwo ti wọn ti se - 23,835
Iye awọn to ni arun naa ti wọn fidi rẹ mulẹ- 3,912
Awọn tara wọn ya - 679.
Awọn to gba tọwọ rẹ ku - 117
Ipinlẹ       Iye awọn to laarun covid-19Awọn to wa nibudo iyasọtọ     Awọn to ti gbadun               Awọn to ti ku
Lagos                     1,667                                     1,186                                                 448                              33
Abuja FCT       336                                                      292                                                   40                                 4
Kano                      547                                                      509                                                   20                                18
Gombe                      110                                                      100                                                   10                                 0
Borno                      142                                                      128                                                    0                                  14
Ogun                      113                                                       81                                                     28                                 4
Katsina                       137                                                     120                                                     9                                   8
Edo                       67                                                     51                                                     12                                 4
Osun                       38                                                        4                                                        30                                4
Kaduna                       95                                                     79                                                       14                                 2
Bauchi                       117                                                     110                                        6                                 1
Sokoto                       93                                                     80                                                        4                                   9
Oyo                       59                                                       43                                                      14                                 2
Akwa Ibom        17                                                     5                                                          10                  2
Kwara                       24                                                       15                                                         9                                 0
Ekiti                       12                                                     7                                                           4                                  1
Ondo                       15                                                       9                                                       6                                  0
Taraba                       15                                                    15                                                       0                                0
Delta                       17                                                    11                                                         3                                  3
Rivers                       21                                                      15                                                       4                       2
Jigawa                       83                                                      82                                                          0                               1
Benue                       2                                                    2                                                       0                                 0
Anambra        1                                                    0                                                       1                                 0
Zamfara                      65                                                       62                                                          0                                 3
Abia                       2                                                    1                                                        1                                 0
Enugu                      10                                                       8                                                        2                              0
Niger                      6                                                         4                                                        2                   0
Adamawa       15                                                       15                                                            0                  0
Plateau                      15                                                       14                                                         1                   0
Imo                      3                                                          2                                           1                  0
Bayelsa                      5                                                     5                                                          0                  0
Ebonyi                      7                                                          7                                                           0                  0
Kebbi                     18                                                         18                                                       0                  0
Nasarawa       25                                                        24                                                        0                  1
Yobe                     13                                                     12                                                           0                  1
Bi Coronavirus se n tan kiri Naijiria ti awọn orileede agbaye miranon mii si n ka iye awọn to gba tọwọ rẹ ku to fi mọ awọn miran to n ko lojumọ,ipinlẹ meji kan ni Naijiria wa ti ko ti d'ọdọ wọn.
•Ipinlẹ Cross Rivers
•Ipinlẹ Kogi
Lati igba ti Covid-19 ti bẹrẹ  ni Naijria awọn ipinlẹ mejeeji wọn yi gbe awọn igbesẹ kan lati ma se jẹ ki o wọ ọdọ wọn ti wọn si ti n gbaradi de bi o ba fi le wọ ọdọ wọn.
Ijọba Cross River goment lawọn ti mura de tawọn si ti se ibomu to pọ pẹlu pe wọn pọn dandan lilo rẹ fara ilu.
Gomina ipinlẹ Kogi,Yahaya Bello sọ pe awọn ti se appu kan eleyi ti oo jẹ ki awọn mọ apẹrẹ arun naa.
#justiceforjennifer: Ta ló fipá bá Jennifer lò pọ̀ ní Kaduna?
Ifipabanilopọ jẹ ẹsun to lagbara pupọ labẹ ofin.
Amọṣa yatọ si pe  o lagbara labẹ ofin, kii ṣe iriri to n mu ayọ ba ẹni to ba foju wina rẹ.
Ko sẹni ti wọn ko lee fi ipa ba lopọ, yala akọ tabi abo ṣugbọn lọpọ igba, awọn obinrin lo maa n saba ṣẹlẹ si.
Ni asiko ti iroyin yii jade, iroyin n lọ lori ayelujara nipa ọdọbinrin jojolo kan tawọn ọmọ ọkunrin marun un fi ipa ba lo pọ lọsẹ diẹ sẹyin ni ilu Narayi ni ipinlẹ Kaduna.
Gẹgẹbi ohun ti ọmọ Naijiria kan @Uncle Shemzz fi sita loju opo ayelujara rẹ, ọmọ ọdun mejidinlogun ni ọmọdebinrin naa to pe orukọ rẹ ni Jeniffer.
Ko tii si ẹni lee sọ ohun to pa arabinrin yii atawọn to fipabaalopọ pọ ṣugbọn fidio kan eyi to n lọ kaakiri lori ayelujara ṣafihan ibi ti wọn ti n tọju ọmọdebinrin yii.
Iroyin kan tilẹ tun ṣalaye pe ọwọ ti tẹ meji ninu awọn ọmọkunrin to ṣe iṣẹ laabi naa ṣugbọn wọn ko tii fi wọn jofin
Oniruuru ọrọ lawọn ọmọ orilẹede Naijiria si ti n sọ lori ọrọ yii loju opo twitter.
Diẹ lara wọn niyi:
Iroyin ti a ko tii fi idi rẹ mulẹ tilẹ fi kun un pe awọn obi ọmọdebinrin naa tilẹ ti gba lati gba owo gba maa binu lori ọrọ naa ṣugbọn awọn eeyan kan ti bu ẹnu atẹ lu igbesẹ yii eleyi ti wọn ni ko tọna rara
Coronavirus Cases in Africa: Gomina Makinde gbàlejò àwọn Imam lásìkò àrùn Coronavirus
Oríṣun àwòrán, OTHERS
Ẹgbẹ́ àwọn Imam, the Joint Action Committee for the Preservation of the Rights and Honours of Imams tako àyẹyẹ naa.
Ọpọlọpọ awuyewuye ti tẹle igbesẹ Gomina ipinlẹ Oyo, Seyi Makinde to pe awọn imaamu ni ipinlẹ Ọyọ fun ayẹyẹ Iftar.
Irọlẹ Ọjọru ni ayẹyẹ Iftar naa pẹlu awọn Alfa ati Imaamu waye ni Ile Ijọba Ipinlẹ naa.
Ninu atẹjade ti Adari ikọ Iroyin Gomina Seyi Makinde, Taiwo Adisa fi lede fihan pe kii ṣe igba akọkọ ni yii ti gomina naa n ṣe ayẹyẹ yii.
Adisa fikun wi pe o da oun loju wi pe ayẹyẹ ohun koni tako ofin yiyagofunraẹni ati wi pe ti awọn eniyan naa ba pọju mẹwa lọ, awọn yoo wa n kan ṣe si.
Amọ awọn Ẹgbẹ́ àwọn Imam, the Joint Action Committee for the Preservation of the Rights and Honours of Imams tako àyẹyẹ naa.
Adari ẹgbẹ awọn Imaamu naa, Abu Muhammad ni Gomina naa takọ ofin ijọba apapọ lori yiyago funraẹni ti ijọba apapọ gbe kalẹ lati koju itankalẹ arun Coronavirus to n ja rain lorilẹede Naijiria.
Abu Muhammad si kesi awọn imaamu ati Alfa ti gomina naa pe wi pe ki wọn ma da gomina naa lohun lasiko yii fun anfaani ara wọn.
Oludari agba fun ajọ iṣakoso okoowo ẹkun iwọ oorun gusu Naijiria, DAWN, Ṣẹyẹ Oyelẹyẹ ti jẹ ko di mimọ pe ikọ alaabo ẹkun naa ti ọpọ mọ si Amọtẹkun ko ku o, bẹẹni ina rẹ ko parun.
Oríṣun àwòrán, osun state government
Ọgbẹni Ṣẹyẹ Oyelẹyẹ ṣalaye pe ko sohun meji to n da ibẹrẹ iṣẹ iks naa duro lawọn ipinlẹ ju wahala ajakalẹ arun coronavirus to gba aye kan bayii.
O fi kun un pe ko si ipinlẹ kọkan lara awọn ipinlẹ to wa lẹkun naa to pẹlyinda si afẹnuko lori idasilẹ ikọ ọhun.
Amọtẹkun jẹ ọkan lara awọn eto ti awọn ijọba ipinlẹ lẹkun iwọ oorun gusu Naijiria gbe kalẹ lati koju oniruuru ipenija ọrs to n doju kọ awọn eeyan nibẹ.
Ọkanojọkan ifojusọna lawọn eeyan si ti ni lori ohun ti yoo tẹyin rẹ jade paapaajulọ pẹlu mọhurumọhuru awọn fulani darandaran kan lẹkun naa.
Oríṣun àwòrán, osun state government
Amọṣa lẹyin ti ọrọ ikọ naa ho ṣukuṣuku fun igba diẹ lo ba da wai, eleyi to ti nkọ ọpọ lominu pe ṣe kii ṣe pe ohun naa, gẹgẹ bi ọpọlọpọ eto ijọba miran ti fori ks igbo.
Nibayii naa, ipinlẹ meji lo ti gbe igbimọ isakoso kalẹ fun ikọ naa ni ipinlẹ koowa wọn.
Ipinlẹ Ọṣun ati Ekiti ti gbe igbimọ kalẹ gẹgẹ bi itẹsiwaju igbesẹlẹyin ti gbogbo awọn ipinlẹ naa ti kọkọ buwọlu ofin Amọtẹkun ki wahala ajakalẹ arun coronavirus to wọle de
Ogún ọdún ni mo fi gbáradì fún àjàkálẹ̀ ààrùn coronavirus
Oríṣun àwòrán, Emma Russell
Igbe aye lasiko itankalẹ aarun coronavirus yii le nira pupọ, paapa fun awọn ti ipaya ipa ti aarun naa le ni l'ara wọn. BBC ba Peter Goffin sọrọ l'ori ọna to n gba lo igbesi aye rẹ lasiko yii.
Peter jẹ ẹni to ni ailera ti awọn onimọ n pe ni Obsessive Compulsive Disorder (COD).
Ailera yii tumọ si ki eeyan o deede ni ipaya pe ewu wa fun oun lasiko to tọ, ati asiko ti ko tọ ọ. Iru ẹni bẹ le maa ni ipaya ju bose yẹ lọ nipa kokoro aifojuri, eyi to le mu ki wọn o maa ṣe imọtoto ju bose yẹ lọ.
Ailera ti Peter ni mu ki o rọrun fun-un lati mọ bi o ṣe le gbe igbe aye to ni itumọ lasiko ajakalẹ aarun Covid-19.
"Ilẹ̀ yaara ìdáná mi ni mo joko si, ti mo n fi oogun apakokoro nu ara apo oúnjẹ onihoro kan, ni mo ri ifihan kan: Bi ogun ọdun ni mo n mura silẹ fun ajakalẹ aarun coronavirus.
Nigba ti mo wa ni ọdọ langba, wọn sọ pe mo ni ipenija Obsessive Compulsive Disorder (OCD).
Ìdá meji ninu mẹta asiko ti mo ti lo laye, ni mo fi n wa imọ nipa kokoro aifojuri, bi wọn ṣe le gba ara ẹni kan de ti ẹlomiran, ati bi mo ṣe le kapa wọn.
Oríṣun àwòrán, Emma Russell
Eyi lo si ranmi lọwọ lati tete mọ nkan to yẹ lati ṣe niru asiko ajakalẹ aarun coronavirus, ti gbogbo eniyan ni ilana ti wọn gbọdọ pamọ.
Gbogbo igbesẹ bi i ka jina sira ẹni nibi ti kii ba se ile mi, ọwọ fifọ lẹyin ti mo ba fi ọwọ kan nkan ti ẹlomiran ti fọwọ́ kan, to fi mọ fifi ọsẹ fọ awọn oúnjẹ ti mo ba ra, ni mo ti gbe ni gbogbo ọjọ aye mi. O ti mọ mi lara.
Ko fẹ ẹ si eyi to sajoji si mi ninu gbogbo ilana antẹẹle lori coronavirus.
Eyi to kan ma n jẹ jade ju ni aini ifọkanbalẹ pe aabo wa fun mi lọwọ aarun.
Ẹgbẹẹgbẹ̀rún eniyan kaakiri agbaye lo n bi ara wọn lere bayii pe: Ṣe kii ṣe pe ẹni ti mo pade nile itaja yẹn sunmọ mi ju?"""
"Ha, ṣe mo fọ ọwọ mi daada báyìí?"""
"Ṣe ọsẹ yii ma a pa gbogbo kokoro aifojuri?"""
Lootọ ni a le maa tẹle gbogbo ilana ti wọn ni ki a maa tẹle lasiko yii, lati daabo bo ara wa. Sugbọn iyemeji ati ipaya ko le salai maa waye.
Oríṣun àwòrán, Emma Russell
Eyi ko tumọ si pe eeyan n ro erokero, awọn nkan wọn yii lo mu ki a máa kiyesara.
Sugbọn kan to wa nibẹ ni pe wọn le kọja bose yẹ.
Nigba ti mo n dagba lorilẹ-ede Canada, iṣoro ti mo ni ni bibori ẹ̀rù lati igba ti mo wa ni bi ọmọ ọdún maarun si mẹfa. Nigba ti ma a si fi pe ọdun mejila, o ti dinku si ifoya nípa imọtoto, paapa nipa fifi ara ko àwọn nkan to n jade lara ẹlomiran: bi itọ́ to n jade lẹ́nu wọn ti wọn ba sọrọ, kokoro aifojuri to n tankalẹ ti wọn ko ba fọwọ́ wọn lẹyin ti wọn lo ile ìyàgbẹ́, ati gbogbo awọn kokoro aifojuri ti mo lero pe o yi mi ka.
Awọn ẹbí mi sakiyesi pe mi o ki n fẹ fi ọwọ kan awọn nkankan, ti mo si maa n fọwọ́ kọja bose yẹ.
Wọn ti mi lẹyin, wọn si mu mi lọ ọ ri onímọ̀ nipa ilera ọpọlọ. Lati igba naa ni mo ti n lo oogun fun ìrẹ̀wẹ̀sì ọkan, titi di oni.
Lootọ ni oogun lilo ati OCD ti mọ mi lara, sugbọn o koba igba èwe mi diẹ, nitori pe ọpọ igba ni mo maa n mu ọrọ imototo kọja bose yẹ.
Lati nkan bi ọdun maarun, apá mi ti ka ipaya ti OCD maa n fun mi:mo ti mọ ẹ̀rù to tọ́ ati eyi ti ko yẹ ki n gba laaye.
Ọpọlọpọ eeyan to ri bi i temi lo sọ pe awọn ko fi bẹ ẹ ni ipaya lasiko ajakalẹ aarun yii. Boya nitori pe gbogbo aye lo n ṣe bi i wọn bayii.
Bẹ ẹ lo ri fun emi naa, sugbọn o tun ti da ji awọn ipaya mi kọọkan dide.
Oríṣun àwòrán, Emma Russell
Mo ti pada si iwa ikiyesara ju bose yẹ lọ, fifọ awọn nkan ti mo ba ra ki n to o ko wọn sinu firiiji, fọfọ ọwọ laimọye igba, fifọ bata ti mo ba wọ jade; awọn iwa ti mo ro pe mo ti jawọ ninu rẹ.
Lootọ ni awọn eeyan ti n pe fun ṣíṣí ọrọ aje pada, yoo sọrọ lati ni ifọkanbalẹ. Ko si si igba to wu ki wọn o si awọn ile itaja, ileesẹ ati ileewe, ibẹru ati ipaya ti Covid-19 mu wa ko le lọ kiakia,yoo to ọpọlọpọ oṣu. Sugbọn nkan to damiloju ni pe eeyan le kapa ifoya rẹ.
Emi gẹgẹ bi ẹnikan ti lọ fun idanilẹkọọ lorisirisi bi mo ṣe le bori awọn ipenija mi.
Lootọ lo dara lati ri akọṣẹmọṣẹ nipa ipenija yii, sugbọn o le ṣe diẹ fúnra rẹ : o le kọ awọn nkan to n ja ọ laya si ibi kan, ati idi ti o fi n jaya, ati bi o ṣe ni imọlara si. Eyi ni wọn yoo ṣe agbeyẹwo rẹ lati mọ iru iranlọwọ ti o nilo.
Ko si iru ipaya ti aarun coronavirus le mu ba ọ, boya nípa ilera rẹ, pipanu isẹ, faaji, oun ti o ni lati mọ nipe kii se iwọ nikan lo n laa kọja.
Bakan naa ni awọn imọran awọn eleto ilera to sọ pe ọpọ to ni aarun Covid-19 yoo ru u là, tabi pé fifi omi ati ọsẹ fọ ọwọ rẹ yoo mu ọ mọ tonitoni, to fi mọ fifọ aṣọ rẹ bi i ti tẹlẹ yoo mu kokoro naa kuro lara rẹ, le fi ọ lọkan balẹ.
"Ju gbogbo rẹ lọ, maa ranti pe ọrọ aarun coronavirus yii kii ṣe tẹnikan."""
Coronavirus cure: Akeugbagold sọ àṣírí ohun tí àrùn coronavirus ń dá lárà fáwọn pásítọ̀, àfáà àti ẹlẹ́sìn àbáláyé
Laipẹ yii ni eekan oniwaasi ni, Akeugbagold bọ lọwọ wahala awọn ajinigbepawo kan ti wọn ji awọn ọmọ rẹ gbe.
Amọṣa ninu ifọrọwerọ yii pẹluu, kii ṣe ọrọ awọn ibeji rẹ ti wọn ji gbe lo ba BBC News Yoruba sọ bikoṣe ọwọja arun coronavirus to gbaye kan bayii ninu ilana ẹsin lagbaye.
Gẹgẹbi o ṣe sọ, arun naa ti ṣi aṣọ loju ọpọ lati mọ Ọlọrun wn funrawọn.
Ibrahim Gambari: Olórí àwọn òṣìṣẹ́ lọ́fíìsì Ààrẹ ní oun tí ààrẹ Buhari nílò ni ìjólóòtọ́, ìfọkànsìn pẹ̀lú àtìlẹ́yìn òun
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Olori tuntun fun awọn oṣiṣẹ lọfiisi aarẹ, Ọjọgbọn Ibrahim Gambari ti sọ ọ laifọtape pe oun ati ọmọ Naijiria kii ṣe ọlọrọ o, oun ati aarẹ Buhari lọlọrọ ninu iṣejọba yii.
Ọjọgbọn Gambari ṣalaye eyi lasiko to fi n ba awọn akọroyin sọrọ lẹyin ti wọn kede rẹ lọjsbọ ni ileeṣẹ aarẹ, nilu Abuja.
"Gambari ni oun ko tii lee sọ ibi ti oun yoo ti bẹrẹ si nii mu iṣẹṣe ṣugbọn ohun mọ daju pe, ""oun ko ni abọ kankan n jẹ fun ọmọ Naijiria bi ko ṣe Aarẹ Buhari""."
Ọjọgbọn Ibrahim Agboola Gambari sọ pe oun yoo fi gbogbo agbara oun sin aarẹ Muhammadu Buhari.
Gambari sọrọ yii fawọn akọroyin lẹyin to bẹrẹ iṣẹ nileeṣẹ ijọba l'Ọjọru niluu Abuja.
Gambari ni ifọkansin ati igbarukuti oun ni Aarẹ Buhari nilo lati ṣe ijọba gidi fawọn ọmọ Naijiria.
Olori awọn oṣiṣẹ nileeṣẹ aarẹ tun dupẹ lọwọ Eleduwa fun anfaani lati sin orilẹede Naijiria.
Bakan naa lo dupẹ lọwọ Buhari fun anfaani lati sin in pẹlu ipo tp yan si i.
Ààrẹ Buhari yan Ibrahim Gambari  gẹ́gẹ́ bíi olórí àwọn òṣìṣẹ́ lọ́fíìsì Ààrẹ
Oríṣun àwòrán, Other
Ìròyìn tó ń tẹ̀ wa lọ́wọ́lọ́wọ́ ní wí pé Aarẹ Muhammadu Buhari ti yan Ọjọgbọn Agboọla Ibrahim Gambari gẹgẹbii olori tuntun fawọn oṣiṣẹ lọfiisi aarẹ.
Akọwe ijọba apapọ Boss Mustapha lo kede orukọ Ọjọgbọn Gambari lasiko ti ipade igbimọ iṣejọba apapọ lorilẹede Naijiria fẹ bẹrẹ lọjọru niluu Abuja.
Ọjọgbọn Gambari ni yoo maa gba ipo naa eleyi ti Abba Kyari dimu lati ọdun 2015 ti saa akọkọ iṣejọba aarẹ Buhari bẹrẹ titi di oṣu kẹrin ọdun 2020 ti wọn kede iku rẹ lẹyin to lugbadi arun COVID-19.
Ni ọsan ọjọ Iṣẹgun ni iroyin ti kọkọ lu si igboro pe Ọjọgbọn Ibrahim Gambari ni aarẹ pada fontẹ lu fun ipo naa bi o tilẹ jẹ wi pe ileeṣẹ aarẹ kọkọ sẹ jalẹ pe awọn ko mọ nipa ikede orukọ naa nigba naa.
Ẹkunrẹrẹ iroyin yii n bọ lọna.
Oríṣun àwòrán, Presidency
Ààrẹ Muhammadu Buhari ti yan Ọ̀jọ̀gbọ́n Ibrahim Gambari gẹ́gẹ́ bíi olórí àwọn òṣìṣẹ́ tuntun nílé iṣẹ́ ààrẹ.
Laipẹ yii ni Abba Kyari to jẹ olori awọn oṣiṣẹ nile iṣẹ aarẹ tẹlẹ di oloogbe lẹyin to lugbadi aarun coronavirus.
Ilu Eko ni Kyari ku sii lẹyin ti wọn gbe e wa si ipinlẹ naa fun itọju nigba to lugbadi aarun covid-19 l'Abuja.
Ta ni Ọjọgbọn Ibrahim Gambari gan an?
A bi Ọjọgbọn Ibrahim Agbaoola Gambari niluu Ilorin ipinlẹ Kwara lọjọ kẹrinlelogun, oṣu kọkanla, ọdun 1944.
Ọjọgbọn Gambari lọ si gbajugbaja ileewe King's College nipinlẹ Eko.
O tẹsiwaju ninu ẹkọ rẹ nigba to gboye akọkọ ni fasiti ninu ẹkọ nipa ọrọ aje nileewe London School of Economics lọdun 1968.
Lẹyin naa lo tun gboye keji ni ati ikẹta ni fasiti Columbia niluu New York l'Amẹrika lọdun 1970 ati 1974 ninu ẹkọ nipa sayẹnsi osẹlu ati ibara-ẹni-ṣepọ laarin awọn orilẹede agbaye.
Awọn ipo ti Ọjọgbọn Ibrahim Gambari ti di mu ri
Olori orilẹede Ọgagun Muhammadu Bahuri nigba naa lọhun yan Ọjọgbọn Ibrahim Gambari gẹgẹ minisita fun ọrọ okeere laarin ọdun 1984 si 1985.
Oun ni aṣoju orilẹede Naijiria ni ajọ iṣọkan agbaaye laarin ọdun 1990 si ọdun 1999.
Oríṣun àwòrán, Presidency
Ọjọgbọn Gambari jẹ alaga igbimọ ajọ iṣọkan agbaye to n pẹtu sija laarin ọdun 1990 si ọdun 1999.
Oun ni aarẹ igbimọ alaṣẹ ajọ UNICEF to n ri si ọrọ awọn ọmọde lọdun 1999.
Ọjọgbọn Gambari jẹ oludamọran pataki lori ọrọ ilẹ Afirika labẹ akọwe agba ajọ iṣọkan agbaye, Ban Ki-Moon lọdun 2000 si ọdun 2005.
Bakan naa ni Ọjọgbọn Gambari ṣiṣẹ labẹ akọwe agba ajọ iṣọkan agbaye ninu ọrọ oṣelu laarin ọdun 2005 si ọdun 2007.
Yollywood: Àwọn ayé ló tú èmi àti Iyabo Ojo ká, wọ́n rò pé à ń fẹ́ ara wa ni- Muka Ray
Oríṣun àwòrán, Instagram/Muka Ray
Yoruba ni oju kii ri arẹwa ko ma kii, oju to ba sì rẹwa, o di dandan ko pawo wale.
Idi ree ti ọpọ awọn oṣere tiata lobinrin fi n lo ipara ibora ki wọn lee pupa ni awọ, ti oju wọn yoo si dun wo ninu ere.
Gbajumọ oṣere tiata kan Muka Ray Eyiwunmi lo sisọ loju ọrọ yii lasiko to n kopa lori eto kan loju opo ikanni BBC Yoruba.
Muka, ti ọpọ eeyan tun n pe ni Apasẹ tiata, tun salaye siwaju pe, ọpọ awọn oṣere tiata to dudu bíi koro isin tẹlẹ ni wọn ti bora, ti wọn si pọn roboto, ki awọn oṣere lee maa pe wọn lati kopa ninu ere.
"Ọrọ naa wa lọwọ awọn alagbata sinima, awọn Olootu ere atawọn ololufẹ wa, nitori ọmọ pupa ni wọn n wá ninu fiimu ki wọn to wo o, a si maa n fi wọn ta ọja ni amọ awọn ọmọ dudu naa si wa ninu fiimu wa.
Ọpọ onitiata to dudu si lo di pupa, ki wọn le maa lo wọn ninu ere."
Nigba to n sọrọ lori ajọsepọ rẹ pẹlu gbajugbaja oṣere tiata lobinrin kan, Iyabo Ojo, ti ẹnu n kun awọn mejeeji pe ọrọ ifẹ ikọkọ wa laarin wọn; Muka Ray ni awọn mejeeji dijọ n ṣíṣẹ papọ ni amọ araye ro pe awọn n fẹ ara awọn ni.
Oríṣun àwòrán, Instagram/Muka Ray
 Iyabo Ojo ni iwa irẹlẹ pẹlu oju aanu, yatọ si pe mo jẹ ọga rẹ, ọrẹ mi ni ninu iṣẹ ta dijọ n ṣe. Awọn eeyan ro pe a n fẹ ara wa ni, idi ree taa fi sun sẹyin funra wa, awọn aye lo tu wa ka.
Lori ipo ti iṣẹ tiata wa:
Apasẹ ni gbogbo nkan ti bajẹ patapata nítorí ayelujara ti awọn eeyan ti n wo sinima bayii. Ko si owo ninu iṣẹ tiata mọ,
"Koda, o tun nira lati ni orukọ pẹlu. Akoba ti n wọ iṣẹ tiata bayii, iṣẹ sinima n ku lọ, sinima ti wọn n wo lori ayelujara ko ni jẹ ki ọpọ jade lọ wo sinima."""
Njẹ ọ mọ̀ pé mímí afẹ́fẹ́ tí kò dára lè fa àìsàn?
Gbajugbaja oṣere tiata naa, tii ṣe ọmọ agba ọjẹ oṣere to ti di oloogbe, Ray Eyiwunmi, tun kede fun araye pe, inu ẹjẹ oun ati awọn ẹgbọn oun ni iṣẹ tiata wa, ogun nla tí baba awọn si fi silẹ fun awọn nìyẹn.
O ni oun ati awọn ẹgbọn oun ni awọn dijọ jogun iwe akọsilẹ ere ti baba awọn fi silẹ, owo nla ti awọn ere naa si nilo ni ko tii jẹ ki awọn gbe sinima rẹ jade.
Muka Ray wa rọ ijọba Naijiria lati maa seto iranwọ, nipa amulo awọn dukia ijọba pẹlu owoya, fun awọn oṣere tiata, eyi ti yoo mu ko rọrun fun wọn lati ṣe eré to ni èrè, ti yoo si pawo gidi wọle fun ijọba.
Bakan naa lo tun rọ awọn akẹẹgbẹ rẹ ninu iṣẹ tiata, lati maa pe awọn agba ọjẹ oṣere to ti darugbo si iṣẹ, eyi ti yoo mu ki ẹmi wọn gun, ti gbogbo aye yoo si tun mọ pe wọn wa laaye, ti wọn ko si ni jẹ ohun elo alopati.
Mo kábàámọ̀ pé n kò kàwé, kí n tó bẹ̀rẹ̀ iṣẹ́ tíátà - Sanyeri
Ilumọọka osere tiata, Alhaji Mukaila Olaniyi Afonja, tí gbogbo eeyan mọ sì Sanyeri abi Ambali ti ṣalaye bo ṣe rin irin ajo aye rẹ, ko to di onitiata. Sanyeri, lasiko to n kopa lori eto BBC Yoruba ṣalaye pe, ọjọ pẹ ti oun ti n jẹ Sanyeri, lati igba ti oun ti bẹrẹ ere tiata laarin ọdun 1992 di 1993.
Mo kere diẹ nigba ti mo bẹrẹ ere tiata, bii ẹni ọdun mejidinlogun si mọkandinlogun nigba ti mo wa nile iwe girama, awada ti mo n ṣe lo si mu ki awọn eeyan fi gba mi nimọran pe, ki n lọ ṣe iṣẹ tiata.
Oríṣun àwòrán, Instagram/sanyeri2
"Asiko ijade ounjẹ nile iwe ni ọrẹ mi kan mu mi lọ sibi isẹ tiata lọdọ oga mi tó di oloogbe, mo bẹrẹ tiata ni pẹrẹu nigba ti mo jade ile ẹkọ girama lọdun 1992. Sanyeri tun salaye pe awọn obi òun ko nifẹ si ere ori itage, amọ oun ko sọ fun wọn pe oun ti n ṣe tiata. Ó ni wọn ri aṣọ oogun tawọn fi n ṣe ere lọwọ oun, wọn na oun pupọ, amọ oun ko jawọ lẹyin isẹ tiata.Nigba to n sọrọ lori ajọṣepọ rẹ pẹlu Kamilu Compo, o ni "" Adekola Tijani, wa ba mi lati ṣe tiata, mo si mú lọ sọdọ ọga mi, taa si di ibeji ti ki i ya ara wọn lati igba naa, taa si pinnu láti wá sílu Eko papọ. Sanyeri ni ọdun mẹta ṣe, ki oun to kuro lọdọ ọga oun, tí oju oun si ri mabo nigba ti oun ati Kamilu de Eko, ọdọ ẹgbọn Kamilu Compo si ni awọn n gbe."
Oríṣun àwòrán, Instagram/sanyeri12
"Ere apanilẹrin ni ode inawo ni emi ati Kamilu Compo maa n lọ ṣe nigba ta kọkọ de Eko, ta si n ri owo diẹ-diẹ, kii ṣe agbe taarata amọ a a fi awada tọrọ owo. O ni awon lọ si ode inawo lọjọ kan ni awọn ṣe alapade oloogbe Lekan Lekinson ati Remi Shittabe, ti wọn si gba awọn nimọran lati dara pọ mọ ẹgbẹ tiata kan, ti awọn si dara pọ mọ ẹgbẹ tiata Fadeyi Caucus, ibẹ si ni awọn ti rí oloogbe Alaran, tii ṣe ẹgbọn Kamilu Compo lati ilu Oyo, amọ o ni o kọ lati gba awọn sinu ẹgbẹ naa."""" Nibẹ la ti rí Ajala Jalingo to wa ninu ẹgbẹ osere miran ni Mushin, to si ni oun setan lati gba wa sinu ẹgbẹ amọ o gba wa to oṣu meji ka to ri ẹgbẹrun kan Naira owó iforukọsilẹ ti wọn beere san, tawọn sì lo ọdún mẹta nibẹ, ki awọn to kuro kuro ni ọdun 1998."
Sanyeri tun sọ pe ọjọ ti inu oun julọ lagbaaye lọjọ ti oun gba fisa ilẹ Amẹrika.
O ni ṣaaju asiko naa, oun ko ti ni anfaani lati rinrin ajo kuro ni Naijiria lọ si orilẹede miiran lati Naijiria.
"Sanyeri ni oun maa n kabamọ pe oun ko kawe nitori ti oun ba kawe, oun ko ba ti ju bayii lọ.""Emi gan ko pe mọ pe Ọlọrun ma gbe mi de ipo ti mo wa lonii, o si ma n dun mi pe n ko le kopa ninu ere tiata oloyinbo nitori aikawe mi, ti ero aitẹgbẹ si maa n mu mi."" ""Idi ree ti n ko fi lọ gba ami ẹyẹ nitori oyinbo mi ko dan mọran lati sọrọ imọyi tabi ba awọn akọroyin sọrọ.Mo wa rọ awọn ololufẹ wa pe aikawe kii ṣe arun, ki wọn ye ma yẹyẹ wa tabi fa ila si asise wa ninu oyinbo."" Nigba to n sọrọ lori afojusun rẹ lọjọ iwaju, Sanyeri ni o ti wu oun lati kawe si ki ede oyinbo oun lee dan mọran lati maa ṣe ere tiata ni ede  miran yatọ si Yoruba.Lori ajọṣepọ rẹ pẹlu osere tiata miran Tayọ Amokade, taa mọ si Ijẹbu, Sanyeri ni ""Amugbalẹgbẹẹ mi ni Ijẹbu, koda o gbe inu ile ọdọ mi ri. Oun ati Ẹgbọn rẹ lo ja, to fi wa gbe lọdọ mi."" Sanyeri ni oju Ijẹbu ri diẹ  ko to da duro amọ ọpẹ ni fun Ọlọrun pe oun naa ti jana bayii. O wa gba awọn onitiata akẹẹgbẹ rẹ nimọran lati tẹra mọ ohun tí wọn n ṣe, ti aye fi n nifẹ wọn.Sanyeri ẹni to kọ ila, eyi ti ko wọpọ lode oni sọ pe ""N ko kabamọ pe mo kọla nitori ka ni n ko kọ ila ni, o seese ki n ma de ibi tí mo de loni."" Sanyeri, ẹni to tun sọrọ nipa ajọṣepọ rẹ pẹlu baba ati iya rẹ ni, ""Mo fẹran iya mi, awọn eeyan si iya oun ju iyawo ile oun lọ, oun ko si le ma darukọ rẹ ninu ere nitori o ṣe atilẹyin fun oun nidii isẹ tiata, kí oun to ní orukọ."" Baba mi ko tiẹ gba rara ki n di onitiata. Koda, o mu mi lọ si idi isẹ Telọ nitori o gba pe n ko lee di eeyan gidi nidi isẹ tiata."" Nigba to n sọrọ lori ipenija to koju lẹnu isẹ tiata, Sanyeri ni oun bu sẹkun nigba ti aburo oun sọrọ buruku  si oun nigba ti oun ko ri ọwọ mọlẹbi da, ìyá awọn si lo pari ija naa lẹyin ọdun kan.Sanyeri ni ọjọ ti oun ko leè gbagbe laelae ni ọjọ ti oun gba iwe irinna lọ si ilẹ Amẹrika lẹyin osu mẹta ti oun se fiimu 'Ọ̀pá kan' to sọ oun di olokiki."
Oríṣun àwòrán, Instagram/sanyeri12
UNIOSUN : Ètò ìgbaniwọlé orí ayélujára fáwọn akẹ́kọ̀ọ́ tuntun ní fásitì UNIOSUN kò dín iyì ilé ẹ̀kọ́ gíga kù fáwọn akẹ́kọ̀ọ́ wa- VC UNIOSUN
Oríṣun àwòrán, other
Awọn alakoso fatisi ti ipinlẹ Osun, UNIOSUN ti ni awọn ko mọ igba ti ajakalẹ arun Coronavirus yoo pari ni awọn ṣe ṣe ayẹyẹ igbaniwọlẹ Matriculation fun awọn ọmọ ileewe to ṣẹṣẹ wọ ile iwe giga naa.
Oludari ile iwe giga UNIOSUN, Ọjọgbọn Labode Popoola lo sọ bẹẹ fun BBC News Yoruba lẹyin ti wọn ṣe ayẹyẹ iwọle naa fun awọn ọmọ ileewe.
Ọjọgbọn Popoola ni idi ti awọn fi gbe igbesẹ naa ni wi pe ni ayẹyẹ naa pọn dandan ni awọn ṣe ṣe fun awọn ọmọ ileewe giga naa.
O ni ayẹyẹ naa lọ ni irọwọrọṣẹ pẹlu ẹrọ ayelujara to lọ geere lai si idiwọ idena fun ayẹyẹ naa ti awọn ṣe fun wakati mẹta.
Oludari ileewe UNIOSUN naa ni iyatọ to wa ni bẹ ni wi pe awọn akẹẹkọ naa ko ri asọ ẹ̀ku, Matric Gown ti wọn ma n wọ ni ọjọ ayẹyẹ naa.
Ọjọgbọn Popoola naa wa fikun wi pe ti awọn ba ni anfaani lati ṣe iru rẹ nigba miran, awọn yoo ri wi pe awọn fi asọ ẹku naa sọwọ si wọn ni ibi ti wọn ba wa.
U.I Language Centre: Yorùbá ló làṣà àti èdè
Lori ibeere pe bọya ileewe naa yoo wọle laipẹ, Adari ileewe naa ni awọn akẹẹkọ ti n kẹkọ lori ẹrọ ayelujara fun igba diẹ si isinyii.
Bakan naa ni wọn fikun wi pe ti arun Coronavirus yii ko ba kuro nilẹ laipẹ, awọn yoo ṣe idanwọ fun awọn ọmọ naa.
Ìtànjẹ ti pọ̀jù nínú iṣẹ́ tíátà, a kò rí kọ́bọ̀ nínú fíìmù tó wà lórí YouTube - Yomi Fabiyi
Oríṣun àwòrán, yomi fabiyi
Gbajumọ elere tiata, Yomi Fabiyi ti salaye pe, ọpọ eeyan to fi gbogbo ara ṣiṣẹ tiata, ti wọn ni okiki ati ọrọ, ni akude tí de ba lasiko yii.
Fabiyi salaye bẹẹ lasiko to n kopa lori eto kan ni ikanni BBC Yoruba pẹlu afikun pe, iya n jẹ ọpọ elere tiata lasiko yii.
O ni afihan awọn sinima to n waye lori ayelujara, ti awọn alagbata n gbe sinima silẹ ni gbẹfẹ lai jẹ kò ṣe iyebiye loju araye, n din ifẹ ati ojulowo isẹ tiata ku.
Ọpọ awa ta ni sinima to wa lori YouTube ni a ko ri kọbọ gba lori afihan rẹ. Awọn to n ta sinima wa lo n pa owo sapo ara wọn lai fun ẹni to ni iṣẹ ninu ere ti wọn ba jẹ.
Ẹtan ti pọju ninu iṣẹ tiata, o ti bajẹ , o si ti pin yinkin, ko si le e to ogun ọdun mọ ti ẹka iṣẹ tiata yoo fi dojude.
Bakan naa ni Fabiyi tọka si pe, iya n jẹ awọn eeyan ninu iṣẹ tiata ni oun ṣe n pariwo sita, ẹni to ba si wu, ko fẹran oun, tabi korira oun, osere tiata ti ojuṣe rẹ ba si tọ si sinima kan, lo yẹ ki wọn maa pe sibẹ, lai fi ọrọ ẹbi abi ti ọrẹ ṣe.
" Ẹ jẹ ka ye tan ara wa mọ. Ẹ jẹ ka sootọ pẹlu ara wa, ka ṣe ipade ba ti pin èrè, iya ko ni jẹ wa, tori isẹ ọwọ wa to wa jẹ.
Oríṣun àwòrán, yomi fabiyi
O ni ko si bi awọn ti yoo ṣe onigbọwọ sinima ṣe le e gbe owo kalẹ, nitori ko si ilana to tọ lati ọdọ awọn oni sinima Yoruba."""
Yomi Fabiyi wa gbosuba fun ikọ alaanu ti Foluke Daramola da silẹ, to pe ni para, eyi to n ṣe itọju awọn alaini, pẹlu afikun pe, o seese ki abuku ta ba eeyan nidi ṣiṣe isẹ aanu amọ eyi ko yẹ ko da omi tutu si eeyan lọkan.
 Ọpọ ni ara n ni lori isẹ aanu ti Foluke Daramola n ṣe, ọpẹ iru wa to wa lẹyin rẹ, awọn kan ro pe o n wa okiki, lo ṣe n ṣaanu.
Nigba to n sọrọ lori ẹgbẹ awọn osere ori itage TANPAN ati eto iranwọ to n fun awọn agba ọjẹ ninu ẹgbẹ, Fabiyi ni o ṣe ni laanu pe ko si ọmọ ẹgbẹ naa to n san owo sinu ẹgbẹ, ti wọn ko si pọn omi silẹ de ongbẹ.
 Aarẹ ẹgbẹ wa, Bolaji Amusan, taa mọ si Mr Latin n saayan lati to ẹgbẹ naa, ọmọ ẹgbẹ ti ko ba si ṣe ojuse rẹ ninu ẹgbẹ, yoo da ran isoro to ba baa ni.
Lori ohun ti yoo sẹlẹ si iṣẹ tiata lẹyin ti arun Covid-19 ba kasẹ nilẹ, Fabiyi ni adinku gbọdọ ba awọn sinima oyinbo ti wọn n gbe wa si awọn ile sinima ni Naijiria, ki awọn osere tiata si ni orisun ọrọ aje pupọ, kipo iṣẹ sinima nikan, ti wọn gbajumọ.
Yomi Fabiyi tun koro oju si iwa aibọwọ fofin lati ọdọ awọn alaṣẹ ati agbofinro lasiko igbele Covid-19, ti wọn si n tẹ ẹtọ araalu loju.
O ni ko si ipese ina lati ọdọ ìjọba, ko si nọmbà foonu ipe pajawiri, pẹlu afikun pe, o yẹ ki agbekalẹ ilana wa fun ẹni to ba nilo itọju pajawiri, lọna ti igbele Covid-19 ko fi ni ṣe akoba fun ilera rẹ.
Coronavirus: BBC News Yorùbá ní kí ẹ dúró nílé bí ẹ kò bá ní ìdí láti jáde
Lasiko ti a wa yii, asiko ẹlẹgẹ ati ikiyesara gidi ni.
Bi a ba tẹle awọn imọran gbogbo tawọn onimọ n fi sita a o laa ja.
Idunnu wa ni ileeṣẹ BBC News kaakiri agbaye ni pe ki a ka iye awọn eeyan to laa ja lẹyin ọwọja ajakalẹ arun yii, ki gbogbo ẹyin ololufẹ wa si dahun orukọ yin.
Ẹ wo fidio yii gẹgẹ bi ẹbun kekere ti a ni fun un yin.
Coronavirus cases: Àjọ WHO ní ọ̀rọ̀ àrùn coronavirus ti di èyí tí yóò máa bá ọmọnìyàn gbé láéláé
Oríṣun àwòrán, Who
Onikaluku orilẹ ede lo n sa kijo-kijo kiri lati wa iwosan fun ajakalẹ arun Coronavirus, eyi to n mu ẹmi ọpọ eeyan lọ.
Amọ ajọ eleto ilera ni agbaye, WHO ti wa sin gbogbo agbaye ni gbẹrẹ ipakọ pe, o see ṣe ki arun Covid-19 naa di baraku fun wa, ko ma si kuro laarin wa titi laelae.
Dokita Mike Ryan, tii se oludari iṣẹlẹ pajawiri labẹ ajọ WHO lo ṣe ikilọ naa pẹlu afikun pe, ki awọn eeyan dẹkun sisọ asọtẹlẹ nipa akoko ti ajakalẹ arun Coronavirus yoo kasẹ nilẹ.
O fikun pe, koda gan bi wọn ba ṣe awari abẹrẹ ajẹsara fun Covid-19, iṣẹ nla ni akoso arun naa yoo si tun jẹ.
O le ni eeyan ẹgbẹrun lọna ọọdunrun ti aisan Coronavirus yii si ti mu lọ jakejado agbaye.
Ajọ isọkan orilẹede agbaye, United Nations UN, tun ti sisọ loju rẹ pe, arun Coronavirus ọhun lo ti n mu irẹwẹsi ọkan ati arun ọpọlọ ba awọn eeyan lagbaye, paapaa ni awọn orilẹ ede ti wọn kii ti ja itọju arun ọpọlọ kunra, to si rọ awọn adari ijọba lati ri itọju arun ọpọlọ bii ojuṣe koowa wọn.
Oríṣun àwòrán, Who
O ṣe pataki ka ṣe agbeyẹwo eleyi: Coronavirus yii tun le e di ara awọn ajakalẹ arun miran to wa nilẹ  ni awujọ wa, ti ko si ni lọ mọ laelae. Dokita Ryan sọ bẹẹ nibi ipade awọn akọroyin to waye ni Geneva.
Kokoro arun HIV ko tii kuro nilẹ - a tun ti n ba ajakalẹ arun Coronavirus yi.
"Dokita Ryan ni oun ko gbagbọ pe ""ẹnikẹni le e sọ asọtẹlẹ nipa akoko ti arun yii yoo poora."""
Lọwọ-lọwọ bayii, o le ni ọgọrun-un abẹrẹ ajẹsara ti wọn n dabaa pe yoo wo arun naa san, eyi ti wọn n ṣe lọwọ - sugbọn Dokita Ryan tọka si pe, awọn arun miran bii Ẹyi, ni ko kuro ni ayika wa patapata lai naani pe, aimọye abẹrẹ ajẹsara lo wa fun iwosan rẹ.
Amọ Oludari agba fun ajọ eleto ilera ni agbaye WHO, Tedro Adhanom Ghebreyesus tẹnu mọ pe, o si ṣee ṣe lati mu adinku nla ba ọwọja arun naa, ti a ba ṣe aayan to yẹ.
Ọwọ wa ni ọna abayọ wa, iṣẹ gbogbo wa si ni, gbogbo wa si la gbọdọ ko ipa tiwa si ọna lati dẹkun ajakalẹ arun naa. o ṣalaye.
"Onimọ isegun nipa ajakalẹ arun labẹ ajọ WHO, Maria Van Kerkhove, naa sọ nibi ipade awọn akọroyin naa pe, ""a nilo lati fi sọkan pe, yoo gba akoko diẹ ka to bọ lọwọ ajakalẹ arun Covid-19 ọhun."""
Bá wo ni coronavirus ṣe ń tàn kálẹ̀ ní àyíká wa?
Bi wọn ṣe sọ oju abẹ nikoo naa lo waye lasiko yii, ti ọpọ awọn orilẹ ede agbaye n dẹ okun lọrun ofin konile o gbele, tawọn asaaju orilẹ ede si n gbero lori akoko ati ọna ti wọn yoo gba ṣe agbende ọrọ aje orilẹ ede koowa wọn pada.
Dokita Tedros wa ṣe ikilọ pe, ko si idaniloju kankan to fi idi rẹ mulẹ pe, ọwọja arun Coronavirus yii ko tun ni gbalẹ ni ẹẹkan si bi awọn orilẹ ede ba dẹ okun ofin konile o gbele.
"Ọpọ orilẹede lo fẹ kuro ninu oniruuru ilana to gbe kalẹ lati mu adinku ba ọwọja itankalẹ arun naa, ọga agba fun ajọ WHO salaye ""sugbọn aba ti wa ni pe, ifojusọna ati igbaradi irufẹ awọn orilẹ ede bẹẹ gbọdọ gbepọn pupọ."""
"Dokita Ryan fikun pe ""Ero ajẹbiidan kan tilẹ n lọ pe, ofin konile o gbele n ṣiṣẹ daadaa, ati pe mimu ofin konile o gbele kuro yoo ṣiṣẹ pupọ gan ni. Amọ awọn ero mejeeji naa lo ni ewu ninu."""
How to wear face mask properly : Kìí ṣe gbogbo ìbòmù ló ń dá coronavirus dúró
Coronavirus cure: Olùdásílẹ̀ Yemkem ní ''Olóde'' ni Yorùbá ń pe coronavirus, iléeṣẹ́ Yemkem ti rí òògùn rẹ̀ báyìí
Oríṣun àwòrán, Facebook/Yemkem Int'l
Ileeṣẹ Yemkem International to n fi ewe ati egbo ṣe oogun ati itọju awọn eeyan ti sọ pe awọn ti po ewe ati egbo pọ lati wo aarun coronavirus to n ba gbogbo aye finra lọwọ yii.
Oludasilẹ ileeṣẹ Yemkem International, Akintunde Iṣhola Ayeni to ba BBC Yoruba sọrọ ṣalaye pe awọn ti fi ewe ati egbo tọju awọn alaarun covid-19 kan ti wọn si ti gbadun.
Ọgbẹni Ayeni ṣalaye pe ''olode'' lawọn baba wa laye ọjọun maa n pe coronavirus.
O ni ohun ti wọn fi n pe ni olode ni pe aarun naa maa n gba ode lọwọ olode ni, ko ni jẹ ki oloko lọ soko, ko si ni jẹ ki olodo lọ sodo mọ.
Amọ oludasilẹ ileeṣẹ Yemkem ni ewe ati egbi ni Yoruba fi maa n tọju aarun naa laye igba kan.
Ọgbẹni Ayẹni sọ pe ọrọ covid-19 dabi ọmọ tuntun ti kii ṣe akọpa ajẹ fun ileeṣẹ Yemkem.
O ṣalaye pe ileeṣẹ Yemkem n ṣiṣẹ lori ṣiṣe oogun coronavirus ni koro ati olomi, laipẹ yii ni ileeṣẹ naa yoo fi ṣọwọ si ajọ NAFDAC fun ayẹwo.
Ọgbẹni Ayeni sọ pe awọn nilo ki ajọ NAFDAC fun oogun naa ni nọmba ki awọn to le bẹrẹ si ni taa, bi bẹẹ kọ, oogun naa ko le di tita lori igba.
Ẹwẹ, oludasilẹ ileeṣẹ Yemkem bu ẹnu atẹ bi Aarẹ Muhammadu Buhari ti buwọlu lilo agbo ti orilẹ-ede Madagascar ṣe fun itọju aarun covid-19.
O ni itiju nla ni ki orilẹede Naijiria maa lọ si orilẹ-ede kekere bi Madagascar fun iwosan aarun coronavirus nigba ti awọn elegbo igi wa ni Naijiria.
O ni ijọba ko gbaruku ti awọn to n fi ewe ati egbo ṣe ọmọ araye loore.
Yoruba Films: Mr Latin ní òṣèré tó bá ya sinimá lásìkò Coronavirus yìí, òun ò lọ́wọ́ ń bẹ
Oríṣun àwòrán, Instagram/Mr Latin
Ere Sinima jẹ ara ẹka iṣẹ aayan laayo lawujọ to ṣe pataki, to si tun ma a mu owo wọle fun awọn osere tiata ati ijọba pẹlu.Amọ ajakalẹ arun Coronavirus to gbode kan yii, n pa iṣẹ tiata lara gẹgẹ bo ṣe n waye ni awọn ẹka iṣẹ aayan laayo miran.Ni osu kẹta ọdun ti arun Covid-19 burẹkẹ ni Naijiria, agbarijọpọ ẹgbẹ awọn oṣere tiata ni ede Yoruba, taa mọ si TANPAN, labẹ akoso aarẹ ẹgbẹ Bolaji Amusan, ti ọpọ eeyan mọ si Mr Latin, pasẹ pe ọmọ ẹgbẹ naa kankan ko gbọdọ ya sinima.
Aṣẹ ẹgbẹ TANPAN naa, to wa lati dena itankalẹ arun Coronavirus, ni awọn ọmọ ẹgbẹ naa tẹle, ti koowa wọn si joko sile lai gbe sinima kankan jade.Ṣugbọn lati igba ti aarẹ Muhammadu Buhari ti dẹ okun lọrun ofin konile o gbele, ni awọn oṣere tiata kan ti n gbero lati pada si idi isẹ wọn, ti wọn si n reti igbimọ alakoso ẹgbẹ lati gbe ẹsẹ kuro lori ofin 'ẹ jokoo sile yin' to pa.Amọ aarẹ ẹgbẹ, Mr Latin, ninu alaye to ṣe si oju opo Instagram rẹ ti ni, eyi ko lee ṣee ṣe nitori awọn idi kan to mẹnuba.
Oríṣun àwòrán, Instagram/Mr Latin
"Mr Latin ni loootọ ni oun mọ pe ajakalẹ arun Coronavirus ti ṣe akoba nla fun ọrọ aje awọn osere tiata, sugbọn o san ki eeyan wa laye ninu ilera pipe, ju ko maa jẹ irora aisan lọ.Latin fikun pe ""ifọwọsowọpọ ọpọ eeyan ni sinima ṣiṣe gba, eyi to si le tako awọn ofin to rọ mọ idena arun Covid-19 nitori ogun eeyan tabi ju bẹẹ lọ lo n kopa ninu sinima kan."""
Oríṣun àwòrán, Instagram/Mr Latin
"O wa n rọ awọn ọmọ ẹgbẹ rẹ lati ro gbogbo nkan wọn yii, ki wọn si fara da akoko yii bo ṣe gba.Mr Latin tun woye ninu ọrọ rẹ pe, ni wọn igba ti ijọba ti paṣẹ pe ẹnikẹni ko gbọdọ rin irin ajo lati ipinlẹ kan si omiran yika Naijiria, bawo wa ni yoo ṣe rọrun fun awọn oṣere ori tiata lati rinrin ajo lati ipinlẹ kan si omiran lọ kopa ninu yiya sinima?""Koda, bi oṣere tiata kan ba gba owo lati kopa ninu ere lasiko yii, ti ko si si ọna lati rinrin ajo lọ kopa ninu ere ọhun nipinlẹ ti wọn ti fẹ ya iṣẹ, iru iṣẹlẹ bẹẹ tun le da ede aiyede silẹ, eyi to le da ẹgbẹ ru.Aarẹ ẹgbẹ TANPAN wa sọ oju abẹ niko pe igbimọ amusẹya ẹgbẹ naa ti paṣẹ pe ki awọn oṣere tiata si jokoo sile wọn titi ti ijọba apapọ yoo fi gbe ẹsẹ kuro lori ofin konile o gbele patapata.Amọ ko sai yan pe ""bi Olootu ère kan ba wa le tẹle awọn ofin tijọba la kalẹ lori idena itankalẹ arun Covid-19 ti mo mẹnuba saaju, o le tẹsiwaju lati lọ ya ere amọ ẹgbẹ TANPAN ko lọwọ ninu irufẹ igbesẹ Bẹẹ."""
Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo
Ṣe lootọ ni akudaaya wa?
Ṣe bi eeyan ba ku nibi kan, o leepada lọ di alaaye ni ilu miran?
Igbagbọ Yoruba niyi ṣugbọn pups lo n woye pe ṣe lootọ lo wa tabi ara awọn itan atẹnudẹnu leyi.
Ninu ifọrọwerọ rẹ pẹlu BBC News Yoruba, Araba awo ti ilu Osogbo, Baba Ifayẹmi Ẹlẹbuibọn ṣalaye ipilẹ ọrọ ati bi o ṣe jẹ titi kan ohun to n fa akudaaya.
Ẹwẹ, awọn ẹlẹsin tuntun bii Kiristẹni ati Islam ko fara mọ eyi. Ninu iwoye tiwọn, bi eeeyan ba ti ku, ọrun laala lati koju idajọ Ọlọrun.
Pasitọ kan naa ba BBC Yoruba sọrọ lori iha ti ẹsin Kristẹni kọ si ọrs akudaaya.
Coronavirus symptoms in Nigeria: Pẹ̀lú èròjà olùgbèjà ara 'Antibodies' ṣé ó ṣeéṣe kí ènìyàn tó ní àrùn coronavirus rí lè níi lẹ́ẹ̀kejì
Alaafin of Oyo: Kí ni àjọṣepọ̀ tó wà láàrín Aláàfin, àwọn olorì àti àṣà igbá títí lóde Ọ̀yọ̀?
Oríṣun àwòrán, Alaafin oyo
Yoruba ni 'Ajiṣe bi Ọyọ laa rí, Ọyọ kii ṣe bii baba ẹni kọọkan', eyi to tumọ si pe ilu Ọyọ lo n lewaju ninu agbega aṣa ati iṣe nilẹ Kaarọ o jiire.
Lara iru aṣa bẹẹ to wọpọ nilu Oyo ati ni awọn agbegbe miran nilẹ Yoruba ni Igba Titi jẹ.
Aṣa Igba Titi yii, ti wọn tun maa n pe ni Yúgbá, lo saba maa n waye ni aafin ọba Ọyọ tabi ni aafin awọn ọba alaye miran, to fẹran aṣa ati iṣẹṣe wa.
Awọn aya ọba, ta n pe ni Olori abi Ayaba lo maa n ti igba ni aafin Ọyọ, eyi si jẹ ara ojuse pataki ti wọn gbọdọ ṣe gẹgẹ bi aya ọba.
Oríṣun àwòrán, Alaafin of oyo
Igba orisi meji ni awọn ayaba maa n lo lati tigba. Igba akọkọ lo jẹ eyi to tobi, ti ẹnu rẹ si fẹ, eyi ti wọn yoo doju rẹ bolẹ. Irufẹ igba yii si lee to meji, mẹta tabi ju bẹẹ lọ niwaju awọn ayaba to n tigba.
Igba nla kan si lee wa laarin ayaba meji tabi ju bẹẹ lọ, ti wọn yoo maa gba a bi wọn ṣe n kọrin, tawọn miran laarin wọn yoo si maa gbe orin naa.
Igba keji ni igba to kere, ti ẹnu rẹ ko si fẹ, igba ẹlẹnu kekere yii si ni wọn yoo da ẹnu rẹ kodo sinu omi. Igi gigun meji ni ọkan ninu awọn ayaba yoo fi maa na igba kekere to wa ninu omi yii.
Ayaba to n na igba kekere ọhun ni yoo jẹ onilu fun awọn ayaba to n tigba yoku, oun naa tun ni yoo lewaju orin ti wọn n kọ, nigba ti awọn ayaba yoku yoo maa gbe e.
Ojuse ayaba to jẹ agbalagba ninu aafin ni lati kọ awọn olori kekere ni igba titi.
Oríṣun àwòrán, Alaafin of oyo
Irufẹ agba olori bẹẹ lee jẹ obinrin ti ọba to wa lori oye naa fẹ funra rẹ abi eyi to jogun lati ọwọ awọn ọba to ti waja, to si ba ninu aafin.
Lasiko ti awọn ayaba ba n ti igba, wọn yoo fi igba nla abi kekere siwaju ara wọn, igba nla kan lee wa niwaju ayaba kan abi meji, ayaba kan si le mu igba kan siwaju ara rẹ.
Ayaba to ba si n lewaju awọn olori yoku ni yoo fi igba kekere, to dori kodo sinu omi siwaju.
Irufẹ igba nla to wa niwaju wọn bẹẹ ni wọn yoo doju rẹ de bolẹ,  awọn ayaba yoo si maa kọrin bi wọn ṣe n fi ọwọ ọtun ati osi wọn gba igba naa pẹ pẹ pẹ.
Oniruuru orin to jẹ mọ oriki Alaafin to wa lori aleefa ni awọn ayaba yii yoo maa kọ, bi wọn ṣe n tigba yii, ti wọn yoo si tun maa ki ọba naa mọ awọn baba nla rẹ, tii ṣe Alaafin to ti kọja lọ.
Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo
Lara awọn orin ti wọn n kọ naa yoo dun to bẹẹ gẹ, eyi ti yoo mu ori Alaafin wu, lati dide fẹsẹ rajo.
Igba ti awọn ayaba n ti naa, lo duro fun ilu ti wọn n lu si orin abi oriki Alaafin ti wọn n kọ, bi gbogbo awọn ayaba yii si ṣe da ọwọ bo igba, ti wọn n lu u, ati asaaju wọn to n fi igi gigun meji na igba kekere to wa niwaju rẹ, ni yoo mu kawọn igba ọhun maa ro bii ilu, ni eti awọn to n gbọ.
Bi awọn ayaba naa si ṣe n tigba yii, ti inu Alaafin n dun lati jo, ni inu gbogbo ero to wa ni aafin pẹlu yoo maa dun, ti wọn yoo si maa jo.
Lasiko ti awọn ayaba ba n yungba naa, ti inu Alaafin ati awọn eeyan n dun, wọn yoo nawo fun awọn ayaba naa, ti ori wọn pẹlu yoo si wu siwaju si lati tigba, ati lati ki oriki Alaafin.
Oríṣun àwòrán, Alaafin oyo
Igba titi jẹ ara ọna ti wọn n gba ṣe afẹ ninu aafin, paapaa lasiko ayẹyẹ kan, ọdun ibilẹ tabi ti Alaafin ba gba alejo pataki ti wọn fẹ fi ere da laraya.
Awọn ayaba maa n tigba lati da ọba laraya ninu aafin rẹ lasiko idunnu tabi lati tu ninu.
Igba titi ma n mu irẹpọ ati ibọwọ funra ẹni wa si aarin awọn ayaba.
Igba titi maa n jẹ ki awọn ayaba, paapaa awọn olori kekere to ṣẹṣẹ wọnu aafin, mọ si nipa aṣa ati ise ilẹ Yoruba, to fi mọ oriki Alaafin to wa lori oye ati awọn ọba to ti jẹ siwaju rẹ, eyi ti awọn naa yoo fi kọ iran to n bọ.
Awọn ayaba kii saba yọju sita ni ọjọ lasan, inu káà wọn ni wọn saba maa n wa. Sugbọn aṣa igba titi yii yoo fun wọn ni anfaani lati wọ aṣọ to jẹ oju ni gbese, to si saba maa n jẹ aṣọ ẹgbẹjọda, lati yọju sita fun ọpọ eeyan lati ri wọn
Igba titi tun n fun awọn ayaba ni anfaani lati sọrọ nipa iwa aidaa to n lọ lawujọ, ti wọn yoo si fi ewi, oriki, rara ati orin sọ ero wọn jade.
Oríṣun àwòrán, The Sun Newspaper
Ọba Samuel Afolabi, Onilu ti ilu Ilua ni ijọba ibilẹ Kajola nipinlẹ Oyo ti ku lẹyin aisan ranpẹ.
Ọba Afolabi jẹ ọkan lara awọn ọba ti igbagbọ wa pe o dagba ju ni ipinlẹ Oyo.
Ọjọ Satide, ọjọ kẹtalelogun, oṣu Karun, ni oriade naa darapọ mọ awọn baba nla rẹ ni ipo oku, lẹyin aisan ranpẹ.
Iwe iroyin The Sun sọ pe ọba naa gun ori oye lọdun 1981.
Iroyin sọ pe iṣẹ agbẹ ni ọba naa n ṣe, ni ijọba ibilẹ Itesiwaju, ko to o gun ori itẹ lẹyin Ọba Majaro.
Akure okada attack: Ọlọ́kadà tí àwọn afunrasí darandaran ṣá ní òun mọ ọ̀kan lára àwọn tó ṣa òun ní àdá
Bi a ba n wa ọna atijẹ kiri, afi kaa yara maa gbadura ki a maa pade ohun ti yoo jẹ wa o.
Bẹẹ lọrọ ri fun Ọgbẹni James Daniel, ọlọkada kan ni ilu Akurẹ to jade lọ ibi iṣẹ ọkada rẹ ṣugbọn to ba ara rẹ ni ileewosan.
Idi abajọ ni pe, awọn ọkunrin meji kan, gẹgẹ bi James Daniel ṣe sọ, ni wọn da oun duro gẹgẹ bi onibara loju popo lagbegbe Igbatoro nilu Akurẹ pe ki o gbe awọn lori ọkada rẹ de Ibafo ki o si tun gbe awọn pada.
Ọgbẹni James to ni darandaran Fulani lawọn afunrasi naa, ṣalaye pe nigba ti awsn n lọ lori ere ni awọn afunrasi mejeeji naa ys ada ti oun ti wọn ṣa oun lada yannayanna ki wsn to gbe ọkada oun sa lọ
O ṣalaye fawọn oniroyin pe n ṣe ni wọn fi oun silẹ ninu agbara ẹjẹ ni kete ti wọn rii pe oun ti daku ki oun le gba ibẹ dero ọrun.
O ni alaanu eeyan kan to n kọja lọ lo to gbe oun lọ sileewosan.
Ni bi a ṣe n sọrọ yii, ileewosan kan ni ilu Akurẹ ni Ọgbẹni Daniel wa to ti n gba itọju.
Ẹkunrẹrẹ ajọsọ ọrọ pẹlu BBC News Yoruba lori ẹrọ ayelujara lo wa loke iroyin yii.
Amọṣa, nigba ti BBC News Yoruba kan si ileeṣẹ ọẹọpaa ni ipinlẹ Ondo lati mọ bi ọrọ ti jẹ, alukoro ileeṣẹ ọlọpaa nibẹ, ASP Tee Leo-Ikoro ṣalaye pe lootọ ni awọn gbọ si ikọlu naa ti awọn ọtẹlẹmuyẹ si ti bẹrẹ iṣẹ lori rẹ ni pẹrẹu.
Amọṣa, O ni ni iwoye ọlọpaa, kii ṣe awọn fulani darandaran lo ṣe ọṣẹ naa bikoṣe awọn janduku.
O fi kun un pe ko si ẹri kankan lọdọ ọlọpaa to fidi rẹ mulẹ pe awọn darandaran fulani lo  kọlu James Daniel, ọlọkada naa.
akeugbagold video
Ṣé òótọ ni pé èèyàn leè kó Coronavirus láti ara aṣọ tàbí bàtà?
Ọna kan gboogi ti arun Covid-19 fi n wọ ara eeyan ni lati ẹnu, imu tabi oju.
Awọn kan ti wa n bere pe n jẹ o ṣeṣẹ ki eeyan ko arun ọhun lati ara aṣọ tabi bata ti eeyan ba wọ.
Lootọ ni pe eeyan le ko arun Coronavirus lati ara ohun ti arun naa ba wa, bii ori tabili, aga iojoko tabi nnka mii.
Ṣugbọn ṣe o ṣeṣẹ ki eeyan lugbadi arun Coronavirus lati ara aṣọ tabi bata?
Ẹ wo fidio yii fun alaye ni kikun.
Restructuring: Àgbékalẹ̀ orílẹ̀èdè Nàìjíríà lọ́wọ́ yìí kò lè fàyè ìdàgbàsókè sílẹ̀ fún ẹ̀yàkẹ́yà-Ọ̀jọ̀gbọ́n Banji Akintoye
Ọjọgbọn Banji Akintoye ni aṣiwaju ẹya Yoruba lọwọ yii, nitorinaa obi ọrọ nipa bi idagbasoke ẹya Yoruba yoo ṣe kẹsẹjari gbo ni ẹnu rẹ.
Idi si ni yi ti BBC News Yoruba fi tọọ lọ fun iṣiniye lori awọn igbesẹ to n lọ lọwọ nipa idagbasoke ẹya Yoruba, orilẹ-ede Naijiria ati ajakalẹ arun coronavirus to n fẹju koko kaakiri agbaye bayii.
Inú jìn! Akitiyan ọmọ'ṣẹ́ mi tó wà lára àwọn tó jí ìbejì mi gbé kò kéré níg
House help: Ìgbà márùn ún rèé tí àwọn ọmọ ọ̀dọ̀ ti gé ẹ̀mí ọgá wọn kúrú
Oríṣun àwòrán, others
Lati ayebaye ni awọn eeyan ti maa n gba ọmọ ọdọ, to le jẹ ẹbi tabi ara ita.
Bi ọdun si ṣe n gun ori ọdun, ti ọpọlọpọ iyawo ile si n ṣiṣẹ, ni iwulo awọn ọmọ ọdọ, tabi oṣiṣẹ abani ṣisẹ ile n pọ si.
Wọn maa n ṣe awọn iṣẹ aṣọ fifọ, ounjẹ sise, itọju awọn ọmọ, ọkọ wiwa, oko riro, eto aabo, ati bẹẹbẹ lọ.
Awọn kan lara wọn maa n gba ile wọn wa a ṣiṣẹ, ti awọn miran si maa n gbe pẹlu idile to ba gba wọn siṣẹ.
Ṣugbọn o sẹni laanu pe ole, ajinigbe, ati oriṣiriṣi ọdaran ti n dibọn gẹgẹ bi ọmọ ọdọ tabi abaniṣiṣẹ ile.
To si jẹ pe nigba ti wọn ba gba wọn siṣẹ tan, ni wọn to n fi iwa wọn han.
akeugbagold video
Ọkan lara iru iṣẹlẹ bẹ ẹ to ti waye ni bi ọdun mẹta sẹyin, lasiko ti ọmọ ọdọ kan ji ọmọ mẹta ti awọn ọga rẹ bi lẹyin wakati mẹrinlelogun ti wọn gba a siṣẹ.
Yatọ si pe o parọ orukọ rẹ, o tun parọ ọjọ ori rẹ.
Ọjọ mẹẹrin ni awọn ọmọ naa fi wa ni akata rẹ, ki oun ati ikọ ajinigbe rẹ to gba miliọnu meji Naira, owo itusilẹ.
Ọjọ keji ti wọn tu awọn ọmọ naa silẹ ni ọwọ tẹ wọn.
Ọmọilẹ Cameroon pa ọga rẹ ni Park View Estate
Oríṣun àwòrán, others
Ọkan lara awọn iṣẹlẹ to tun jẹ ibanujẹ ni eyi to waye logunjọ, oṣu Kejila, ọdun 2019 ni Parkview Estate, nilu Eko.
Ọmọ orilẹ-ede Cameroon kan to jẹ ọmọ ọdọ, Leujoe Koyemen Joel, lo gun ọga rẹ pa, nitori pe wọn jẹ ẹ lowo oṣu.
Ọga rẹ, Temidayo Adeleke, ṣẹṣẹ de pada sorilẹ-ede Naijiria ni lati ilẹ okeere to ti lọ kawe, to si n mura silẹ fun igbeyawo rẹ lasiko ti ọmọ ọdọ rẹ pa a.
Koju oṣu meji ti Leujoe bẹrẹ isẹ, lo lọ ba ọga rẹ pe ko fun oun lara owo oṣu oun fun oṣu Kejila. Ṣugbọn ti obinrin naa bẹ ẹ pe ko mu suuru fun oun di ọjọ keji, ki oun fi ṣẹ owo ilẹ okeere to wa lọwọ oun si Naira.
Ṣugbọn niṣe ni Leujoe yari, to si wọ ile idana lọ lati mu ọbẹ to fi gun Temidayo pa.
Ariwo to si pa lo mu ki awọn oṣiṣẹ ile to ku sa wọle, ti ọwọ fi tẹ ẹ. Ṣugbọn, Temidayo pada ku u.
Ile ẹjọ kan nilu Eko si ti dajọ iku fun oun naa.
Tanko Abdullateef pa ọga rẹ ni VGC
Omiran tun ni ti obinrin oniṣowo kan, Mabel Okafor, ti aṣọgba rẹ pa ni adugbo VGC l'Eko.
Oríṣun àwòrán, others
Aṣọgba yii, Tanko Abdullateef nikan ni ọmọ ọdọ ti obinrin ẹni aadọta ọdun naa ni ninu ile rẹ.
Ọrọ owo oṣu naa lo fa wahala laarin wọn. Iroyin sọ pe Tanko n fẹ ẹkunwo owo oṣu lọwọ ọga rẹ ni, ko to o gun-un pa.
Ọjọ meji lẹyin ti iṣẹlẹ naa waye ni awọn ara ṣọọṣi obinrin naa wa wa sile, ti wọn ba ilẹkun ile naa ni titi lati ita.
Aigbe ipe si ori ẹrọ ibaraẹnisọrọ rẹ lo tun mu ifura dani. Eyi lo si mu ki wọn o wọ inu ọgba ile naa, ṣugbọn oorun buruku lo ki wọn kaabọ.
Wọn si ba oku obinrin naa ni ilẹ yaara igbalejo rẹ.
Ọsẹ meji lẹyin naa ni ọwọ tẹ Tanko ni ipinlẹ Taraba.
Ẹni ti ko riran to nlọ'ta ni Mushin
Ọmọ ọdọ Oloye Opeyemi Bademosi dẹmi rẹ legbodo ni Parkview Estate
Ile alakọpọ Parkview Estate naa ni isẹlẹ miran tun ti waye.
Oríṣun àwòrán, others
Oloogbe naa ni Alaga ileeṣẹ Credit Switch Technology.
Ọmọ ọdọ kan lo tun pa ọga rẹ, Oloye Opeyemi Bademosi, ni ọjọ kọkanlelọgbọn, oṣu Kẹwaa, ọdun 2018.
Oloogbe naa ni Alaga ileeṣẹ Credit Switch Technology.
Ọmọ ilu Ondo ni oloogbe naa, nibẹ lo si ti mu ọmọ orilẹ-ede Togo naa wa si Eko, lati maa dana ounjẹ fun idile rẹ.
Ṣugbọn ko pẹ si asiko ti wọn gba a sisẹ ni o pa ọga ọra rẹ laarọ ọjọ kan.
Koda, iroyin sọ pe Sunday Adefonou yi ẹrọ rẹdio inu ile naa soke ki awọn aladugbo ma ba gbo bi o ṣe n gba ẹmi ọga rẹ ọhun.
Ọjọ meji lẹyin iṣẹlẹ naa ni ọwọ ọlọpaa tẹ ọdaran naa ni Yaba, to wa ni ilu Ondo. O kọkọ sẹ pe oun ko mọ ohunkohun nipa iku arakunrin ọhun, ṣugbọn lẹyin ti wọn fi fidio ori ẹrọ CCTV inu ile to ti gba ẹmi ọga rẹ ọhun han, o jẹwọ.
Ile ẹjọ giga kan nipinlẹ Eko ti ran ọdanran naa lẹwọn igbere
Iku ọmọ ogun ori omi ati ololufẹ rẹ ni Port Harcourt
Ọmọ ọdọ mii tun ṣekupa ọga rẹ to jẹ ọmọ ogun ori omi ati ọrẹbinrin kan ni agbegbe Borokini, ni Port Harcourt, ni ipinlẹ Rivers.
Oríṣun àwòrán, others
Iṣẹlẹ naa waye lọjọ kẹrin, oṣu karunnun ọdun 2018.
Nigba ti awọn eeyan kọkọ ri oku ọrẹbinyin ọmọ ologun ọhun, wọn ṣebi ọkunrin naa lo ṣekupa ni lai mọ pe ọmọ ọdọ ọhun ti pa jagunjagun naa ṣaaju.
Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo
Ọmọ ọdọ naa, Thaddaeus Jaja jẹwọ fun awọn ọtẹlẹmuyẹ lẹyin ti ọwọ tẹ tan pe oun dana sun oku oun, lẹyin naa ni oun ta ọkọ rẹ ni miliọnu meji naira dinj diẹ.
Ko tan sibẹ, ọmọ ọdọ ọhun tun fi ẹrọ ibanisọrọ ọga rẹ tẹ atẹjajiṣẹ kan si ọrẹbinrin ọga rẹ ọhun lori ede ayede kan ti wọn ni lọna ati fi ko ba a.
O sọ fun awọn ọtẹlẹmuyẹ pe owo lo fa ede ayede laarin oun ati ọmọ ogun ọhun ti oun fi da ẹmi rẹ legbodo.
O ni oun pa ọrẹbinrin ọga oun nitori obinrin naa lo fa ariyanjiyan laarin awọn memeji lẹyin ti ko jẹ ko  fun oun lowo ti oun bere lọwọ rẹ.
Coronavirus: BBC News Yorùbá ní kí ẹ dúró nílé bí ẹ kò bá ní ìdí láti jáde
Michael Jordan: $560,000 ni wọn lu gbàǹjo bàtà ìlúmọ̀ọ́ká agbábọ́ọ́lùù àlápẹ̀rẹ̀ náà fún ẹ̀ṣọ́ ilé
Oríṣun àwòrán, Sotheby's
Bata ti ilumọọka agbabọọlu alapẹrẹ, Michael Jordan lo ni ọdun 1985, ni wọn ti lu gbanjo rẹ ni ẹgbẹrun lọna ọtalelẹẹdẹgbẹta dọla ($560,000).
Bata olokun buutu naa, ti Ileesẹ Nike ṣe sita, eyi ti Jordan wọ lasiko saa bọọlu alapẹrẹ to fi dojukọ ikọ Chicago Bulls, nireti wa tẹlẹ pe owo tita rẹ yoo wa laarin ẹgbẹrun lọna ọgọrun si ẹgbẹrun lọna aadọjọ dọla nilu Sotheby.
Akọsilẹ to wa nilẹ salaye pe, ojilenirinwo o din meji ati aabọ dọla ($437,500) ni wọn ta ẹsẹ bata Nike yii lọdun 1972.
Awọn ẹsẹ bata buutu ti ko bara dọgba ni Jordan n wọ, ẹsẹ osi rẹ n wọ iwọn bata mẹtala nigba ti ẹsẹ ọtun rẹ n wọ iwọn ẹsẹ bata mẹtala ati aabọ.
Jordan Geller, to da ibudo iṣe nkan iṣẹnbaye lọjọ si silẹ nilu Las Vegas, lo ta bata ti Michael Jordan lo pati lọdun 1985 naa.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Igbesẹ tita bata naa si lo bọ si akoko ti Ileesẹ Netflix gbe akanse ẹkunrẹrẹ fọnran aworan iroyin kan sita, to pe akori rẹ ni - The Last Dance.
Afihan ifiga-gbaga fun idije ami ẹyẹ agbabọọlu alapẹrẹ to fakọyọ julọ, ikẹfa iru rẹ to waye laarin saa idije bọọlu alapẹrẹ fọdun 1997 si 1998 si wa ninu fọnran akojọ aworan fun akanse eto naa.
Coronavirus: Kí ní wọ́n ń pè ní “Herd Immunity?”
Lati igba ti arun Covid-19 ti ṣeyọ ni Wuhan lorilẹede China, oriṣiriṣi aṣayan ọrọ lo ti n jade nitori arun ọhun.
Lara awọn ọrọ naa ni “Herd Immunity” wa.
Herd immunity tumọ si bi ọpọ ero to wa lagbegbe kan naa ba ni eroja to lee gbogun ti arun naa ninu agọ ara wọn.
Ṣugbọn ki ni yoo ṣẹlẹ ti mẹrin ninu awọn eeyan marun un lagbegbe kan naa ba ni eroja ara to lee gbogun arun yii?
Ẹ wo fidi yii fun ẹkunrẹrẹ.
Coronavirus in Nigeria: Ọmọ Nàìjíríà 292 láti Saudi Arabia gúnlẹ̀ sí Abuja
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ọdunrun o din mẹjọ lawọn ọmọ orilẹede Naijiria to gunlẹ si ilu Abuja lati orilẹede Saudi Arabia lalẹ ọjọ Iṣẹgun.
Minisita fọrọ ilẹ okeere lorilẹede Naijiria, Geoffrey Onyeama lo fi idi ọrọ yii mulẹ loju opo twitter rẹ lọjọru.
O ni pupọ lara awọn ọmọ orilẹede Naijiria ti wọn ko wale naa ni wọn jẹ obinrin to n tọ ọmọ lọwọ atawọn ọmọde. O fi kun un pe  wọn ti fi wọn si ipamọ lawọn ileetura labẹ amojuto ajọ to n dena ajakalẹ arun lorilẹede Naijiria, NCDC.
Minisita Geoffery Onyeama  ṣalaye pe ijọba orilẹede Saudi Arabia lo ṣe atọna bi awọn eeyan naa ṣe de orilẹede Naijiria.
Bakan naa lo sọrọ lori awọn ọmọ Naijiria kan to n kẹkọ lorilẹede Malaysia to si ni ijọba apapọ ko tii gbọ iroyin pe wọn fẹ le awọn akẹkọ naa nitori pe iye ọjọ to wa lori iwe igbelu wọn ti pe.
Awọn kan lo kan si ileeṣẹ ọrọ ilẹ okeere lorilẹede Naijiria pe ẹgbẹrun mẹtala lawọn ọmọ orilẹede Naijiria to n kẹkọ ni Malaysia, ṣugbọn ti o ṣeeṣe ki ijọba orilẹede naa o fi tipatipa da pada sile nitori iye ọjọ to wa lori iwe igbelu wọn ti ko.
Foluke Daramola: Ayálégbé wa tó fi tipá já àbálé mi ṣe àkóbá fún ìgbé ayé mi
Oríṣun àwòrán, foluke daramola salako/instagram
Gbajugbaja oṣere tiata lobinrin, Foluke Daramola tun ti sọrọ lori bi ayalegbe baba rẹ ṣe fi tipa ja abale rẹ, nigba to wa ni ọdọ.
Foluke, lasiko to n kopa lori eto kan ni ikanni BBC Yoruba tun sisọ loju rẹ pe, iṣẹlẹ naa ṣe akoba fun igbe aye oun pupọ, ati igbeyawo akọkọ ti oun ṣe.
"Ọrẹ mi kan wa gba mi ni imọran lati lọ ri awọn onimọ nipa arun ọpọlọ.
Mo yari pe ori mi ko daru, n ko si lọ. Amọ nigba ti mo ri onimọ nipa arun ọpọlọ naa, o gba mi nimọran lati maa sọ iṣẹlẹ bi wọn ṣe fi tipa ba mi lo pọ sita, ki ọkan mi le fuyẹ."
O fikun pe onimọ nipa arun ọpọlọ naa tun salaye pe ọpọ eeyan yoo ri ẹkọ kọ ninu iṣẹlẹ naa, ti oun ba n sọrọ sita, eyi to ti to ọdun mẹwa bayii.
 Lati igba naa si ni mo ti n sọ ọrọ naa sita amọ mo ṣe ifọrọwerọ pẹlu awọn akọroyin lọjọ kan, ti ọpọ eeyan si n pariwo le mi lori, ibẹ naa ni mo ri pe ọpọ eeyan lo ni iru isoro yii.
Foluke, ẹni to padanu baba rẹ nigba to wa ni ọmọ ọdun mẹta tẹsiwaju pe, ifọrọwerọ naa lo mu ki awọn oyinbo pe oun fun ipade, ti wọn si gba oun nimọran lati da ajọ alaanu kan silẹ ti oun pe ni PARA, eyi to n ṣe iranwọ fun awọn eeyan ti wọn ba fi tipa ba lọpọ ati awọn ti ebi n pa.
Foluke to ni ọrọ akọmọna ti iya oun fi kọ oun ni ifẹ, otitọ inu ati itẹlọrun wa fikun pe, asiko ti oun ni ajọ alaanu naa ni ọpọ eeyan n tọrọ owo lọwọ oun, to fi mọ awọn oṣere tiata, idi si ree ti oun fi n ṣe aanu fun wọn.
Gbogbo owo ti mo ni nipamọ ni mo fi ṣe PARA tan, amọ ọpọ eeyan lo mọ riri nkan ti mo n ṣe, ti ori mi si n wu nipa rẹ, asiko Covid-19 yii, mo si ri bii ojuṣe mi lati tọju awọn agbaagba ninu iṣẹ tiata.Nigba to n salaye lori idi to fi n gbe oju awọn agbalagba to n ṣe oore fun sita fun araye, Foluke ni ọpọlọpọ eeyan lo n fun oun lowo ti oun n pin, wọn si gbọdọ ri ohun ti oun fi owo wọn ṣe.
Foluke wa tun rawọ ẹbẹ fun eto iranwọ owo fun agba ọjẹ oṣere tiata kan, Oluwasesan Adio, ti gbogbo eeyan n pe ni baba Ojogẹ, to nilo owo lati sanwo ile to n gbe. Foluke, ẹni to salaye pe iya oun koro oju si iṣẹ tiata ni ibẹrẹ pẹpẹ, wa koro oju si awọn eeyan to n kọ iroyin kiri pe oun ku, to si n gbarata lori awọn eeyan to n gbe ẹjọ ẹlẹjọ kiri.
Gbogbo ẹni tó ba huwa ibajẹ nípa ẹnikan, ibajẹ lo maa ba nitori emi ko mọ ohun ti wọn fẹ gba ti mo ba ku.
Nigba to n sọrọ lori ibasepọ laarin ọkunrin si obinrin, Foluke ni awọn to ba n wa okiki kiakia, ti wọn si n wa oju rere ti ko tọ lo n mu ki wọn maa fi ilọkulọ lọ awọn obinrin lagbo tiata.
Iwọ ti iṣẹ ọwọ rẹ ba da ọ loju, o ko ni maa yọju si ibi ti wọn ti n ya ere lai jẹ pe wọn pe  ọ, eyi si lee mu ki wọn fi ilọkulọ lọ eeyan.
O ni isẹ to tii jọ oun loju ni sinima kan, A barber wisdom, ti oun ti gba miliọnu kan ati abọ naira, to si fun oun ni okiki, bẹẹ si ni oun ti ṣe ọpọ sinima miran to gbe oun saye.
O wa sisọ loju rẹ pe, o dara ki eeyan ni igboya funra rẹ, ko si nifẹ ara rẹ, bẹẹ ni ko si bi Ọlọrun ṣe lee ṣe iṣẹda eeyan, yoo ni ipa to lee ko ninu isẹ tiata.
O ni ọjọ iwaju to dara wa fun iṣẹ tiata, ti sinima Naijiria naa si ti n ba ti awujọ agbaye mu, nitori iyipada rere ti n ba awọn sinima ti wọn n gbe jade.
Foluke wa dupẹ lọwọ awọn ololufe rẹ fun atileyin wọn nigba gbogbo, bẹẹ lo tun ro wọn lati fi ọwọ wọnu lori ohunkohun ti oun ba ṣe, ti ko dun mọ wọn ninu.
Ṣe ni oju opo Instagram n yọ eruku lala lori bi agba oṣere nni, Adeniyi Johnson tun ṣe bo aṣọ loju eegun nipa ohun to da igbeyawo rẹ ati gbajumọ oṣere miran, Toyin Abraham ru.
Bẹẹ ba gbagbe, Adeniyi Johnson ati Toyin Abraham dijọ ṣe igbeyawo amọ to fori sanpọn, ti Toyin si ti di aya Kolawole Ajewole, osere tiata miran, nigba ti Adeniyi fẹ Seyi Edun, ti oun naa jẹ osere tiata.
Nigba to n kopa lori eto kan loju opo Instagram pẹlu agba oṣere tiata miran Muka Ray Ejiwunmi, Adeniyi lo anfaani eto naa lati sẹ ahesọ ọrọ kan, ti wọn lo ṣe okunfa bi igbeyawo rẹ pẹlu Toyin Abraham ṣe daru.
"Adeniyi ni ""ọpọ eeyan lo ro pe igbeyawo mi pẹlu Toyin Abraham daru nitori pe mo n ṣe oju meji, ti wọn si ni mo n yan ale pẹlu Seyi Edun nigba naa, ẹni tii ṣe iyawo mi bayii."""
Amọ otitọ ibẹ ni pe lẹyin igba ti igbeyawo emi ati Toyin daru, Seyi Edun lo maa n sin mi lọ sile obinrin mii ti mo n fẹ lẹyin Toyin, ti Seyi gan ko si mọ pe oun ni yoo di iyawo mi lẹyin o rẹyin.
Oríṣun àwòrán, Adeniyi johnson
Ṣugbọn ọpọ awọn ololufẹ Toyin lori ayelujara ti ta gba Adeniyi lori ọrọ to sọ yii, ti wọn si n koro oju si bi Adeniyi ṣe tun bo oju egbo to n jina lọ.
Ọpọ wọn ni o san ki Adeniyi dẹkun sisọ ọrọ nipa igbeyawo rẹ ati Toyin mọ nitori baalu to ti fo, lo n juwọ si.
Wọn ni ọrọ igbeyawo laarin osere tiata mejeeji ọhun ti kuregbe-kuregbe, ti ọkọọkan wọn si ti ni ọkọ ati aya lọọdẹ.
Awọn ololufẹ Toyin Abraham wa n rọ Adeniyi Johnson pe ko fi Toyin lọrun silẹ nitori ohun to kọja, ti kọja lọ.
Ìyàwó ajagunfẹ̀yìntì Oladipo Diya ti jẹ Ọlọ́run nípè
Oríṣun àwòrán, @AledehLive
Ologbe naa tẹri gbaṣọ lọjọ kejidinlogun, oṣu karun un ọdun 2020
Folashade Diya, to jẹ iyawo gomina ologun ipinlẹ Ogun tẹlẹ, ajagunfẹyinti Oladipo Diya ti jẹ Ọlọrun nipe.
Ẹni ọdun mẹrindinlaadọrin naa dagbere faye lẹyin aisan ranpẹ.
Ninu atẹjade kan ti agbẹnusọ aarẹ Muhammadu Buhari, Femi Adesina fi lede, o ni oloogbe naa tẹri gbaṣọ lọjọ kejidinlogun, oṣu karun un ọdun 2020.
"Atẹjade ọhun ka pe ""Pẹlu ibanujẹ ọkan ati ogo fun Ọlọrun ni a fi kede iku Oloye Deborah Folashade Diya, iyawo ajagunfẹyinti Oladipo Diya lẹni ọdun mẹrindinlaadọrin."""
O tẹsiwaju pe ologbe naa fi aye rẹ jin fun igbeleke aye ọmọniyan ati iṣẹ Ọlọrun.
Lẹyin naa lo ni aarẹ Buhari gbadura pe ki Ọlọrun tẹ ologbe ọhun si afẹfẹ rere.
Ajagunfẹyinti Diya ni igbakeji aarẹ ologun ana, ọgagun Sani Abacha ki wọn to fẹsun ifipagbajọba kan an.
Restructuring: Àgbékalẹ̀ orílẹ̀èdè Nàìjíríà lọ́wọ́ yìí kò lè fàyè
Lagos Tanker Accident: Ìjàmbá ọkọ̀ agbépo mú ẹ̀mí èèyàn kàn lọ ní Èkó, awakọ̀ tírélà f'ẹsẹ fẹ́ẹ
Oríṣun àwòrán, LASEMA
Ijamba ọkọ tirela agbepo kan to ṣubu lulẹ nilu Eko ti mu ẹmi eeyan kan lọ ti dirẹba ọkọ naa si ti na papa bora.
Ni iwaju bareke awọn ologun ni adugbo Mile 2 ni iṣẹlẹ yi ti waye lọjọ Ẹti.
Ninu atẹjade ti ajọ to n mojuto iṣẹlẹ pajawiri nilu Eko fi sita lorukọ ọga agba Femi Osanyintolu, wọn ni  epo bẹntiro ni ọkọ naa gbe lasiko to dẹgbẹ lulẹ.
Osanyintolu ṣalaye pe epo naa ti da silẹ lasiko tawọn de ibi iṣẹlẹ naa ati pe awọn ṣi dawọ duro lati da epo naa si ọkọ mi.
Oríṣun àwòrán, LASEMA
O ni idi ni pe awọn fẹ kan si ẹni to ni ọkọ agbepo naa ki awọn to bẹrẹ si ni da epo inu rẹ kuro.
Oríṣun àwòrán, LASEMA
Oríṣun àwòrán, Twitter
Àwọn tó wà nínú ìjàmbá ọkọ̀ órí afára Otedola ń lọ ìpínlẹ̀ míì láti Eko ni - LASTMA
Ileeṣẹ to n risi irinkerinko ọkọ oju popo ni ipinlẹ Eko, LASTMA ti sọ pe arinrin ajo ni awọn eeyan to wa ninu ijamba ọkọ to waye lori afara Otedola ni owurọ Ọjọbọ.
Ọga agba ileeṣẹ naa, Olajide Oduyoye lo fi idi ọrọ naa mulẹ fun BBC.
O ni awọn eeyan to wa ninu ọkọ akero funfun  naa n rin irin ajo lati ipinlẹ Eko lọ ipinlẹ mii ni.
"O fi kun pe ""Awọn eeyan na n kuro ni ilu Eko ni, a ko mọ ibi gan ti wọn lọ, boya ipinlẹ Ogun ni wọn lọ tabi Oyo, a ko lee sọ, ṣugbọn ohun ti a mọ ni pe wọn n rinrin ajo kuro ni Eko ni."""
Ni ti pe awọn eeyan naa tapa sofin to tako irinajo lati ipinlẹ kan si omiran lasiko Coronavirus yii, Oduyoye ni ofin naa yoo ṣoro lati tẹle.
"Nitori ọpọ awọn eeyan lo n ṣiṣẹ ni Eko ti wọn si n fi ipinlẹ Ogun ṣebugbe, papa lawọn agbegbe kan bi Berger, Mowe ati Ibafo.
O ni ọpọ ninu awọn eeeyan to n yọlẹ rin irinajo lati Eko lọ ipinlẹ mii lo ma n parọ pe ile wọn ni wọn n lọ jẹ ko ṣoro lati mọ awọn to n lọ ipinlẹ mii.
Oduyoye pari ọrọ rẹ pe iṣẹ LASTMA ni lati dari ọkọ ni igboro ilu Eko, ti ala iṣẹ iṣẹ wọn si pin si agbegbe Berger, nitori naa o ṣoro lati mu awọn eeyan to ba n lọ ipinlẹ miran.
Oríṣun àwòrán, Twitter
Eniyan kan ti gbe ẹmi mi, ti eniyan meje si faragba ninu ijamba ọkọ to waye lori afara Otedola ni ipinlẹ Eko laarin ọkọ agbepo ati ọkọ igbooro ti eniyan mẹwa.
Ileeṣẹ to n risi irinna ọkọ ni ipinlẹ Eko, LASTMA to fi iroyin naa lede, sọ pe aago mẹjọ aabo ni ijamba ọkọ naa waye laarọ Ọjọọbọ.
Ọkọ Golf naa wa lara awọn ọkọ to lugbadi ijamba ọkọ naa, amọ ajọ LASTMA ni ko si ẹni to farapa ninu ọkọ naa.
LASTMA ni gbogbo awọn oṣiṣẹ ajọ pajawiri lo ti wa nibẹ lati tete bojuto awọn eniyan naa.
Bakan naa ni wọn ti gbe awọn ọkọ to ni ijamba kuro ni oju ọna, ki awọn ọkọ to n lọ, to n bọ ba a le ri ọna kọja.
Ni bayii, wọn ti ṣi ọna silẹ fun awọn eniyan lati kọja, amọ sunkẹrẹ fakẹrẹ wa diẹ ni opopona naa.
Bẹẹ ni Ajọ LASTMA wa kesi awọn eniyan lati ṣe jẹjẹ ni oju popo.
Coronavirus: Bàyíì ní àwọn ọmọbìnrin Afghanistan ṣe fi èròjà ara ọkọ ṣe fẹntilátọ
Oríṣun àwòrán, Reuters
Awọn ọmọbinrin ikọ to n se robọti ni Afghanistan ti doju isẹ wọn kọ́ awọn to ni Coronavirus
Ọhun to ku ti wọn n se bayi ni pe wọn n fi eroja ọkọ se fẹnitilatọ, to jẹ ẹrọ to n mu eemi ja geere sii olowopọọku.
Lọdun 2017 ni wọn di ilumọọka nigba ti wọn gba ami ẹyẹlati lọ kopa ninu idije agbaye kan ni Amẹrika.
Ni bayi, wọn fi gbogbo ara sisẹ la ti le pari fẹntilatọ olowo pọọku yi ki osu karun un to kasẹ nilẹ
Lorile-ede Afghanistan ti ogun ti se akoba fọpọ ọdun, wọn ko ni ju irinwo fẹntilatọ fawọn eeyan to to miliọnu mejidinlogoji le diẹ
Eeyan ẹgbẹrun meje le lo ti ko arun naa ti eeyan mejidinlọgọsan si ti tọwọ rẹ dero ọrun.
Ọkan lara awọn ọmọbinrin naa ti ọjọ ori wọn wa laarin  ọdun mẹrinla si mẹtadinlogun sọ pe '
'O se pataki ki a sa ipa tiwa naa lori ajakalẹ aarun Covid 19, koda bo ba se eeyan kan la le doola ẹmi rẹ pẹlu igbiyanju wa''
Oríṣun àwòrán, Reuters
Agbegbe Herat nibi ti eeyan akọkọ ti safihan arun Covid 19 ni ilẹ ọhun lawọn ọmọbinrin yi ti wa.
Eronja ara ọkọ aloku Toyota Corolla ati eronja seeni ọkọ alupupu Honda kan ni wọn fi se fẹntilatọ wọn.
Wọn sọ pe fẹntilatọ awọn yoo mu ki ara tu awọn ti ko ba le mi daadaa lawọn aaye ibi ti ojulowo fẹntilatọ ko ba si.
Balogun ikọ awọn obinrin yi, Somaya Faruqi ni '' Ori mi wu lati wa lara awọn ikọ to n se ohun to n se iranwọ fawọn osisẹ ilera wa. Awokọse nla ni wọn jẹ fun wa lasiko yi''
Jakejado agbaye ni ọwọngogo fẹntilatọ ti jẹ ipenija.
Pẹlu iye owo ti wọn n ta wọn, bi ẹgbẹrun lọna ọgbọn dọla si ẹgbẹrun lọna aadọta dọla, pupọ orile-ede agbaye ti ko ri taje se ni ipa wọn ko ka rira awọn fẹntilatọ yi.
Sugbọn sa, awọn ọmọbinrin wọnyi lawọn yoo se fẹntilatọ tawọn niye owo ti ko to ẹgbẹta dọla lẹyọ kọọkan.
Bayi ti wọn ti ti awọn ile itaja pa ni Herat, ipenija tawọn ọmọbinrin yi ni ni wi pe wọn ko le jade lati lọ ra awọn eroja ti wọn yoo lo lati fi se fẹntilatọ wọn.
Ọ̀pọ̀lọpọ̀ ìnira lojú àwọn ọ̀dọ́ ilẹ̀ Áfíríkà t''o ń wá ìgbé ayé rere lọ sí Yúróòpù ń rí
Kayode Fayemi: Kìí ṣe torí àti di ààrẹ ni mo ṣe sapá mi fún Àmọ̀tẹ́kùn ṣùgbọ́n tó bá yá, máa sọ̀rọ̀ lórí bóyá a ó jẹ ààrẹ tàbí rárá
Oríṣun àwòrán, Presidency nigeria
Gomina ipinlẹ Ekiti, Dokita Kayode ti sisọ loju rẹ pe ifilọlẹ ikọ alaabo Amotekun lo wa fun ipese eto aabo to jiire fun ilẹ Yoruba, tilẹ jẹ p o fẹ fa ikunsinu laarin awọn gomina ẹkun kaarọ o jiire.
Gomina Fayemi, ẹni to kede bẹẹ lasiko to n kopa lori eto BBC Yoruba kan, wa ṣẹ lori ahesọ ọrọ to n ja rainrain nilẹ pe oun fẹ du ipo aarẹ lodun 2023, ni oun ṣe n ṣe kokari eto Amotekun.
Nigba to n sọrọ lori arun Coronavirus to gbode, ati ipa ti ijọba rẹ n ko lati ṣẹgun arun naa, Fayemi ni ko si ẹni to le sọ pe oun ja ajasẹgun  lori arun Coronavirus.
O ni ohun kan ṣoṣo to si le bori arun ọhun ni igbele ati pe, ko si bi arun naa ṣe le kasẹ nilẹ patapata, yoo si maa wa bii HIV ati  ọfikin ni.
Nigba to n sọrọ lori atilẹyin ti wọn n ṣe fun awọn oloogun ibilẹ lori iwosan arun Covid-19, Fayemi ni o se ni laanu pe oogun oloyinbo la gbajumọ, ko si si ohun to buru nibẹ ti itọju arun naa ba ti ọdọ oogun ibilẹ wa.
O ni aimọkan lo n jẹ ki awọn eeyan kan maa ro pe arumọjẹ ni arun Coronavirus, ijafara si lewu fun agbalagba to ba ni arun miran lara tẹlẹ, to ba tun ni arun Coronavirus.
Fayemi, tii ṣe alaga ẹgbẹ awọn gomina nilẹ Naijiria wa sisọ loju rẹ pe, ni ọpọ ipade ti awọn ti ṣe ni awọn ti fẹnu ko lori awọn igbesẹ kan, to fi mọ ofin pe irinke-rindo ko gbọdọ waye lati ipinlẹ kan si omiran.
O ṣee ṣe ko jẹ pe ọna lati gbadura fun alaafia lori arun Coronavirus lo mu ki awọn gomina kan kede pe ki awọn musulumi lọ kirun ọdun itunu aawẹ, ti wọn si tun fun awọn Kristẹni laaye lati ṣe isin."""
Lori ọjọ ọla Naijiria lẹyin arun Covid-19, Fayemi ni ọjọ ọla orilẹede yii yoo dara nitori ọgbọn tuntun ni arun naa fi n ko wa, to si yẹ ka gbajumọ amulo ayelujara bayii ju ti tẹlẹ lọ.
Igba ipọnju la maa n ronu jinlẹ ju, ara ohun ti yoo si jẹyọ lara arun Covid-19 yoo mu idagbasoke ba wa, bi ilẹkun kan ko ba si ti, omiran kii si.
Coronavirus: BBC News Yorùbá ní kí ẹ dúró nílé bí ẹ kò bá ní ìdí láti jáde
Nigba to n sọrọ lori eto iranwọ ti ijọba rẹ n ṣe, Fayemi ni oun maa n fun awọn arugbo ni ẹgbẹrun marun naira losoosu, ọdọ bii ẹgbẹrun marun si lawọn fun ni ẹgbẹrun lọna ogun ẹni kọọkan, ti oun si tun fun awon akẹkọọ nile ẹkọ giga ni ẹgbẹrun mẹwa owo iranwo eto ẹkọ.
Fayemi, lasiko to n sọrọ lori ajọṣepọ rẹ pẹlu gomina tẹlẹ ni Ekiti, Segun Oni, o ni ko si aawọ laarin oun ati Oni, ti ọpọ awọn to n tẹle gomina ana naa si wa ninu ijọba oun.
₦22.5M ti pọ̀ jù fún owó fọ́ọ̀mù ìdìbò abẹ́lẹ́ sípò gómìnà APC - SERAP
Oríṣun àwòrán, @Pristinenetwor1
Adari agba ajọ SERAP, Adetokunbo Mumuni ti sọ fun BBC pe oṣẹlu ko ni rọrun ti awọn ẹgbẹ oṣẹlu ba n gba owo gọbọi lọwọ awọn to fẹ gbe apoti ibo.
Mummu ni lo sọ ọrọ naa lẹyin ti ẹgbẹ oṣelu APC ni awọn to ba nifẹ lati kopa ninu idibo abẹle gomina ipinlẹ Ondo ati Edo ni lati san miliọnu mejilelogun atabọ naira gẹgẹ bi owo fọọmu.
O ni  owo ti ẹgbẹ APC n bere lọwọ to fẹ gbe apotyi idibo naa ti pọ ju.
Mumuni tẹsiwaju pe ajọ SERAP ko faramọ igbesẹ APC lati sọ fun awọn oludije sipo gomina lati lọ wa owo gọbi fun fọọmu, nitori iru awọn igbeṣẹ bẹẹ lo n fa iwa ajẹbanu ti awọn oloṣelu n wu.
Lẹyin naa lo sọ pe iru igbesẹ bẹẹ yoo mu ko ṣoro fun awọn ọdọ, papa awọn ti ko lowo lati kopa ninu idibo ni Naijiria.
Restructuring: Àgbékalẹ̀ orílẹ̀èdè Nàìjíríà lọ́wọ́ yìí kò lè fàyè
O ni eto oṣelu ni Naijiria ko yẹ ko wa fun awọn to lowo atawọn to ni baba isalẹ nikan.
Ọgbẹni Mumuni wa rọ awọn ọmọ Naijiria lati ke gbajari si ijọba pe ko ṣe atunṣe si ofin to jẹ mọ bi idibo ṣe n waye, ko ma ba di pe olowo nikan ni yoo ma kopa ninu eto oṣẹlu.
Oríṣun àwòrán, @newsacrosscom
Ẹgbẹ oṣelu APC ni Ipinlẹ Edo ti kede pe Ọjọ Aje, ọjọ kejilelogun oṣu kẹfa ọdun 2020 gẹgẹ bii ọjọ ti eto idibo abẹnu fun awọn oludije gomina ninu ẹgbẹ oselu naa ni Ipinlẹ Edo yoo waye.
Bakan naa ni ẹgbẹ APC tun ni idije abẹnu fawọn oludije gomina rẹ ni ipinlẹ Ondo yoo waye ni ọjọ Aje, ogunjọ oṣu Keje ọdun 2020 yii kan náà.
Ẹgbẹ oṣelu APC, lati ipasẹ akọwe Alakoso ẹgbẹ, Emma Ibediro, wa tun kede pe, oludije to ba nifẹ lati kopa ninu idije abẹnu fun ipo gomina naa ni Ipinlẹ mejeeji, yoo san miliọnu mejilelogun ati abọ naira, owo fifi ifẹ lati dije han ati owo fọọmu idije.
Amọ sa, ẹgbẹ APC ni awọn oludije fun igbakeji gomina ko ni san owo kankan fun wọn, ti wọn si tun faaye gba awọn eeyan to ni ipenija ara lati san idaji owo ọhun.
Ese Oruru: Arákùnrin tó jí Ese Oruru gbé gba ìdájọ́ ẹ̀wọ̀n ọdún mẹ́rìndínlọ́gbọ̀n
Oríṣun àwòrán, @HRFKingFGA
Ile ẹjọ giga kan nilu Yenagoa tii ṣe olu ilu ipinlẹ Bayelsa ti dajọ ẹwọn ọdun mẹrindinlọgbọn farakunrin Yunusa Dahiru to ji ọmọbinrin Ese Oruru gbe ti o si tun fipa  fẹ sile.
Lọjọbọ ni idajọ t'awọn eeyan ti n reti yi waye niwaju ile ẹjọ ti adajọ Jane Inyang dari rẹ.
Adajọ tu Yunusa silẹ lori ẹsun kini ti wọn fi kan ṣugbọn o gba idajọ ẹwọn ọdun marun un lori ẹsun keji, meje lori ẹlẹẹkẹta, ẹlẹẹkẹrin ati ẹlẹẹkarun-un.
Gẹgẹ bí adajọ ti se sọ, ni ṣiṣẹ n tẹle ni idajọ naa yóò tẹle ara wọn.
Bi a ko ba gbagbe, ọjọ kejila oṣu kẹjọ, ọdun 2015 ni wọn ji Eseoghene Rita Oruru gbe ni Bayelsa lọ si Kano.
Níbẹ ni Yunusa ti ki mọlẹ to si fun ni oyun, to sọ di iyawo rẹ lalai gba iyọnda awọn obi rẹ.
Ọrọ yi mu iriwisi wa ti ọpọ ọmọ Naijiria si bẹnu àtẹ lu iwa to wu yi.
Koda o mu ki ijọba apapọ pàṣẹ ki ọga agba ọlọpaa nigba naa, Solomon Arase da Eseoghene pada si ipinlẹ Bayelsa lọdọ awọn obi rẹ.
Bẹẹ ni ijọba pàṣẹ ki wọn ṣẹjọ Yunusa ni ibamu pẹlu ofin niwaju ile ẹjọ to kaju osunwọn.
Nollywood: Wo àwọn òṣèré tíátà Yorùbá tó ti kú àmọ́ tí iṣẹ́ wọn ń fọhùn síbẹ̀
Oríṣun àwòrán, OTHERS
Aimọye awọn oṣere tiata ni irawọ wọn n tan lọwọ lọwọ, bẹẹ si ni ọpọ lawọn ti irawọ wọn ti tan sẹyin, amọ to ti wọọkun pada nitori pe wọn ti jade laye.
Ṣugbọn niwọn igba to jẹ pe, ba ku la a dere, eeyan ko sunwọn laaye, idi si ree ti BBC Yoruba fi boju wẹyin lati ṣe akọsilẹ iṣẹ awọn akọni oṣere mẹwaa to ti ku, lati fi ṣe iranti wọn.
Oríṣun àwòrán, others
Baba Oyin Adejobi jẹ agba ọjẹ oṣere tiata nigba aye rẹ, to si dabira ni agbo oṣere tiata pẹlu ọpọ awọn ere akọnilọgbọn.
Bi o tilẹ jẹ pe baba naa ni ipenija ara, ti ko si le da rin, sibẹ eyi ko ṣe idiwọ fun lati fi ipa rere lelẹ, ko to jade laye.
Lara awọn ere manigbagbe ti Oyin Adejobi ṣe ko to dagbere faye ni Orogun Adedigba, Kuyẹ, Kootu Asipa, Ọgba iwosan, Ekurọ ọlọja, Iyekan Sọja ati bẹẹ bẹẹ lọ.
Ọpọ oṣere tiata lo kọ iṣẹ lọdọ oloogbe Oyin Adejobi, lara wọn ni Baba Wande ati oloogbe Alabi Yellow, ti akọni oṣere naa si faye silẹ ni ọdun 2000 lẹni ọdun mẹrinlelaadọrin.
Oríṣun àwòrán, Premium times
Ọdun 1940 ni wọn bi Adeyemi Afolayan, ti ọpọ eeyan mọ si Ade Love, to si jade laye lọdun 1996 lẹni ọdun mẹrindinlọgọta.
Oṣere tiata, Onkọrin, onijo oludari ati Olootu sinima ni Ade Love, to si jẹ ẹni akọkọ to ṣe fiimu jade ni Naijiria yatọ si ere itage to wọpọ nigba naa.
Ade Love to ni awọn ọmọ bii mẹrin to n ṣe ere tiata bayii, Kunle, Aremu, Gabriel ati Moji Afolayan, lo gbe ọpọ sinima jade, ko to jade laye.
Lara awọn sinima ti Ade Love ṣe, ko to silẹ bora ni Ija Ominira, Ajani Ogun, Kadara, Taxi Driver ati Iya ni Wura.
Oríṣun àwòrán, legit.ng
Oṣu Kẹsan ọdun 1963 ni orekelẹwa Funmi Martins dele aye, to si papoda lọdun 2002 lẹni ọdun mọkandinlogoji.
Ọmọ bibi ilu Ilesa nii ṣe, to si ṣe gudu gudu meje ati ya ya mẹfa ninu isẹ tiata, lara awọn ere to ti kopa ni Ija ọmọde, ẹru ẹlẹru, Pẹlumi ati Ẹtọ mi.
Ọmọ rẹ, Mide Martins naa jẹ eekan lagbo tiata bayii, Funmi si ṣẹṣẹ bi ọmọ ti ko ju ogoji ọjọ lọ, nigba to jade laye.
Oríṣun àwòrán, others
Ẹni ọdun marundinlaadọta ni Alade Aromire nigba to jade laye ninu ijamba ọkọ kan lopopona marosẹ Eko si Ibadan ni ọjọ kẹrin oṣu Keje ọdun 2008.
Alade si ni oṣere, oludari ati Olootu ere tiata akọkọ to ṣe ifilọlẹ ere sinima agbelewo.
Lara awọn ere sinima to ṣe nigba aye rẹ ni Ṣoṣo meji, Ọmọ inu oku, Olori, Oro Idile ati bẹẹ bẹẹ lọ.
Oríṣun àwòrán, Premium times
Ọdun 1934 ni Akintola Ogungbe, ti ọpọ eeyan mọ si Baba Ibeji dele aye, oṣere, Onkọrin, onijo, Olootu ati oludari ere nii ṣe ko to jade laye ni ọdun 2012.
Lara awọn ere olokiki taa mọ Akin Ogungbe mọ ni Ireke Onibudo, Asiri Baba Ibeji, Lisabi, Igba Funfun ati Ologbo Jigọlọ.
Oríṣun àwòrán, others
Ọmọwe ati ọlaju ni Zainab Bukola Ajayi nigba aye rẹ, o kawe nilẹ Gẹẹsi, to si tun ṣiṣẹ nileesẹ tẹlifisan NTA bii Olootu eto, ko to dara pọ mọ awọn oṣere tiata.
Bi Bukky Ajayi, to dele aye lọdun 1934, ṣe n sere lede oyinbo naa lo n ṣe ti Yoruba, lara awọn ere to ṣe, ko to jade laye ni Critical Assignments, Diamond Ring, Wiches, Iya mi tootọ, Bolode o ku, Amoye, Orere Aye ati bẹẹ bẹẹ lọ.
Ọjọ kẹfa oṣu Keje ọdun 2016 ni agba ọjẹ oṣere tiata naa jade laye.
Oríṣun àwòrán, others
Ọmọ bibi ilu Osogbo ni Alhaji Yekini Ajileye, ti ọpọ ere rẹ si maa n da lori ihuwasi awọn ajẹ, ati iṣẹ ibi ti wọn n ṣe.
Lara awọn ere to ti ṣe ni Koto Aye, Koto Ọrun, Ide, Ẹran Iya Osogbo, Aye Alaye ati bẹẹ bẹẹ lọ.
Oṣu Kẹwa ọdun 2006 ni agba oṣere naa dagbere faye lasiko aisan oṣu mẹta to ṣe.
Oríṣun àwòrán, others
Adẹrinposonu ati alawada gidi ninu ere tiata ni Lukuluku Bantasi, ẹni to ki aye pe o digbose lọdun 1995.
Lukuluku, ẹni to jẹ irọ̀ awọn alawada bii Baba Suwe lagbo tiata, lo kopa ninu ọpọ ere bii Legal Wife, Ami ọrun, Itunu ati bẹẹ bẹẹ lọ.
Oríṣun àwòrán, others
Agba ọjẹ oṣere tiata ni Olusola Isola Ogunsola, ti ọpọ eeyan mọ si I Show Pepper nigba aye rẹ, o si jẹ ọmọ bibi ilu Abeokuta.
Onkọrin, onilu, onijo, Olootu ati oludari ere ni I Show Pepper, to si ṣe awọn ere bii Iyawo Alalubosa, Efunsetan Aniwura, Alaafin Aganju, Fere bi Ekun, Eru Jẹjẹ, Ko see gbe, Ọmọ laja ati bẹẹ bẹẹ lọ.
Ogunsola dagbere faye lọdun 1992 lẹni aadọta ọdun, to si fi ọpọ iyawo ati ọmọ saye lọ.
Oríṣun àwòrán, dawn commission
Akọni oṣere tiata, Onkọrin ati onijo ni Durodola Ladipo, ti ọpọ eeyan tun n pe ni Sango.
Ọdun 1931 ni Duro dele aye, o ṣe bẹbẹ lagbo tiata, to si gbe ere itage de ilu oyinbo ko to papoda lọdun 1978 lẹni ọdun mẹtadinlaadọta.
Lara awọn ere to ṣe, ko to silẹ bora ni Ọba Koso, Ọba Waja, Ṣango ati bẹẹ bẹẹ lọ.
Diẹ lara awọn oṣere tiata to ti di ara ilẹ ree, ta si n ranti iṣẹ ọwọ wọn, a wa gbadura pe ki Ọlọrun tubọ dẹ ilẹ fun gbogbo awọn oṣere tiata to ti dagbere faye.
Coronavirus treatments: Lẹ́yìn ìgbélé Coronavirus, ọ̀nà wo ni mo lè gbà láti bọ́ l'ọ́wọ́ níní Covid-19.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Irú ewu wo ni eni to dúró tì mí lórí ìlà tí a tò sí láti wọ ọkọ̀ BRT, àbí ṣe mo sì le máa lo si ilé oúnjẹ tàbí ki n máa wọkọ̀ èrò?
Bí àwọn ìjọba orílẹ̀-èdè ṣe n sẹ́wélé òfin ìgbélé, tí àwọn ènìyàn si ti ń padà sí àwùjọ fún onírúurú ìbáraeníse pọ̀, ọ̀pọ̀lọpọ̀ ènìyàn ló tí n fòyà lórí bi wọn ò ṣe ni kó ààrùn Coronavirus, èyí to sì lè mú àjàkálẹ̀ ààrùn ẹlẹ́kejì bẹ́ sílẹ̀.
Ọ̀jọ̀gbọ́n Erin Bromage to jẹ́ onímọ̀ nípa àwọn èròjà tó ń gbógun ti ààrùn lágọ̀ọ́ ara bá wa sọ̀rọ̀ lórí awon ọ̀nà tí a lè gbà láti mú àdínkù bá ewu kíkó ààrùn Coronavirus, o jẹ́ olùkọ́ ìmọ̀ àjàkálẹ̀ ààrùn ni Fásitì Massachusetts Dartmouth ní US, o sì ti bojú tó ààrùn Coronavirus yìí láti ìgbà to ti bẹ̀rẹ̀.
O rí ara rẹ̀ gẹ́gẹ́ bí onímọ̀ nípa bi a ṣe lè lanilọ́yẹ̀ nípa ǹkan ti sáyẹ́nsì sọ ju kí a pèé ní onímọ̀ nípa ààrùn kan ni pàtó lọ, o tí kọ àwọn ǹkan to pọ̀ nípa Coronavirus lórí ayélujára ti àwọn ènìyàn to le ni mílíọ̀nù mẹ́rindínlógún sì ti kà á ní àkà tún kà.
Àwọn ìmọ̀ràn rẹ̀ rèé láti wà ní àlàáfíà bí a ṣe ń padà sí bí a ṣe ń ṣe tẹ́lẹ̀.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Bromage ni ọ̀pọ̀ ló ń lùgbàdì ààrùn Covid-19 nínú ilé wọn nítorí ọ̀kan nínú ẹbí wọn tó ní ló pín fún gbogbo ẹbí lẹ́yìn tó ti rí ààrùn naa he nígboro
Ṣùgbọ́n bi ènìyàn ba kúrò nínú ilé ńkọ́? Șé ewu àti kó ààrùn Coronavirus wà  ti mo bá lo ṣe ère ìdárayá níta pẹ̀lú àwọn tí wọn ò lo ìbòmú? Kò dájú gẹ́gẹ́ bi ọ̀jọ̀gbọ́n náà ṣe sọ.
"Ní ìta gbangba àwọn èròjà míràn wa tí kò ni jẹ́ kí ààrùn naa ràn, ènìyàn máa n mi gúle-gúle sínú àti síta lásìkò eré ìdárayá, àsìkò yìí kéré jọjọ fún kòkòrò yii láti bọ́ sí ọ̀dọ̀ ẹlòmíràn gẹ́gẹ́ bo se sọ fun BBC.
 kí o tó ni ààrùn naa, a jẹ́ pé olúwa rẹ̀ ti koju àwọn kòkòrò tó tó iye èyí tó le fún ènìyàn ni ààrùn náà, pẹ̀lú àwọn ìmọ̀ nípa MERS àti SARS, ìgbàgbọ́ ni pé o gbọ́dọ̀ tó ìwọ̀n ẹgbẹ̀rún kan kòkòrò naa ti yóò wọ àgọ́ ara ki èèyàn to le ni ààrùn naa gẹ́gẹ́ bo se ko sójú òpó ayélujára rẹ̀."
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ọ̀jọ̀gbọ́n náà ṣàlàyé pé bótilẹ̀ jẹ́ pé àríyànjiyàn wà lórí iye kòkòrò àìfojúrí tí èèyàn ti fa símú ki o tó ni ààrùn naa, síbẹ̀ ó ṣeéṣe kí o gba èyí láàrin èémí kan tàbí mẹ́wàá, èyíkéyìí le mú ènìyàn ni ààrùn náà.
Èyí túmọ̀ sí pé iye àsìkò tí a bá lò pẹ̀lú aláàrùn Covid-19 ni yóò sọ bóyá ènìyàn leè kó ààrùn náà, tí a bá lo àsìkò kúkúrú bí ti àwọn to n sáré lójú pópó, o ṣeéṣe ki a máa ni ààrùn náà kódà bi kò sí àlàfo mítà méjì, nítorí náà, àwọn ti ó yẹ kó kàn wá gbọ̀ngbọ̀n ni àwọn tó ti fàmìhàn
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Lóòótọ́ ni ikọ́ àti kàtá máa ṣe ìtànkálẹ̀ ààrùn, ṣùgbọ́n o ní bi èyí ṣe lè wáyé. Ikọ́ ẹ̀ẹ̀kan lè gbé àwọn kòkòrò ẹgbẹ̀rún mẹ́ta síta tó sì le rìn ìwọ̀ Mítà ọgọ́rin láàrín wákàtí kan gẹ́gẹ́ bí Bromage ṣe sọ, ọ̀pọ̀ àwọn kòkòrò yìí si ló tóbi to fi je pé ilẹ̀ ni yóò jábọ́ sí, ṣùgbọ́n àwọn mìíràn fúyẹ́ tí won sì le dúró nínú afẹ́fẹ́ tàbí kí wọn fò wọ yàrá.
Tí o bá wa jẹ́ pé inú àkàsọ̀ ìgbàlódé ní ó ká ọ mọ́ tí ẹni náà ba wá sín, ìlọ́po mẹ́wàá ni ìṣòro tìrẹ.
Tí ènìyàn ba wá sín lẹ́ẹ̀kan ṣoṣo kòkòrò ẹgbẹ̀rún lọ́nà ọgbọ̀n ni yóò jáde tó sì kéré jọjọ, èyí leè rìn kìlómítà tó lé ní ọ̀ọ́dúrún láàrin wákàtí kan, bí Bromage ṣe sọ.
Bí eniyan ba wá ni ààrùn náà, àwọn kòkòrò to ń jáde kọjá milionu méjì to sì ni àwọn èròjà ààrùn naa nínú
"Nítorí náà, tí o bá n ba ènìyàn sọ̀rọ̀ lọ́wọ́ tí ẹni náà sì sín tàbí wúkọ́ sí ọ lójú, òó ríi bóse rọrùn láti gba kòkòrò bíi ẹgbẹ̀rún kan tí ẹni náà ba tún wa ní ààrùn náà.
Tí o ò bá tún wá sí níbẹ̀ lásìkò náà, àwọn kòkòrò àìfojúrí yìí le wà nínú afẹ́fẹ́ fún ìṣẹ́jú péréte ti o sì ṣeéṣe kí o tí fa èyí tó tó sì mú lásìkò péréte náà, tí ààrùn yóò sì wọlé dé.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
A mọ̀ pé lẹ́yìn ọjọ́ márùn-ún ni ààrùn náà tó máa n fàmìhàn tó bá mú ènìyàn, ṣùgbọ́n ki wọn tó bẹ̀rẹ̀ síní fàmìhàn nkọ́, àwọn míràn kò tilẹ̀ ni fàmìhàn rárá.
Èémí wọ́n lásán máa n tí ààrùn Coronavirus jáde sí àyíká.
Èémí ẹ̀ẹ̀kan ṣoṣo le tí láàrin àádọ́ta sí ẹgbẹ̀rún márùn-ún kòkòrò naa síta, ṣùgbọ́n kíá lo sábà máa jábọ́ sílẹ̀
Nítorí naa díẹ̀ nínú kòkòrò yii ni a o ríi tobba jáde láti ara èémí gẹ́gẹ́ bi àlàyé rẹ̀ fún BBC.
Ní ti èémí ko sí eni tó mọ iye kòkòrò Coronavirus yìí to n jáde lẹ́ẹ̀kan náà, Ṣùgbọ́n Bromage sọ pé ìwé ìgbà dé gbà kan sọ pé ẹnikẹ́ni to bá ní ọ̀fìnkìn, ó máa ń ti kòkòrò mẹ́ta sí ogún jáde láàrín ìṣẹ́jú kan.
Bí àlàyé yìí ba wá rí bẹ́ẹ̀, o túmọ̀ sí pé, èèyàn yóò mi èémí naa fún ìṣẹ́jú àádọ́ta láti gba ẹgbẹ̀rún kan kòkòrò náà ti yóò fi ní ààrùn Covid-19 (Atọ́ka ni àlàyé èyí jẹ́).
Nítorí náà a o rí pé ko dájú láti kó ààrùn Coronavirus látàrí pé ènìyàn wà nínú ilé kan náà pẹ̀lú ẹni tó ní ààrùn Coronavirus ṣùgbọ́n tí kò fàmì hàn bí ikọ́ àbí kàtá kò na ṣeé.
Bromage sọ pé Ọ̀rọ̀ sísọ le ṣe àfikún kòkòrò to jáde bíi mẹ́wàá sí igba láàrin ìṣẹ́jú kan, bákan náà ni ariwo pípa tàbí orin kíkọ leè fi kún iye kòkòrò tó ń jáde sínú afẹ́fẹ́.
Àwọn kòkòrò yìí a ma wa láti ibi kọ́lọ́fín ẹ̀dọ̀ fóóró níbi tó jé pé ààrùn náà ti gbilẹ̀ sí nítorí agbára lo fi n jáde nítorí ariwo tí ẹni náà ń pa.
Fún ìdí èyí gbogbo ǹkan tó bá mú ààrùn Coronavirus jáde sínú afẹ́fẹ́ láti inú ẹ̀dọ̀ fóóró yóò pọ̀ gidigidi, bótilẹ̀ jẹ́ pé kíkó ààrùn yìí nínú afẹ́fẹ́ kò tíì fìdí múlẹ̀ dáadáa síbẹ̀ ìtànkálẹ̀ ààrùn yàtọ̀ sí láti inú ilé máa n wáyé latari àwọn ti kò fàmì hàn."
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Láì dénà pẹnu àwọn tó n tọ́jú àwọn alárùn yìí ló léwu fún jù.
Ṣùgbọ́n àwọn àyíká miran náà tún burú jai, bí àpẹẹrẹ àwọn tó wa nínú ọkọ̀ ojú omi, àwọn tí wọ́n wà nínú ọ́fíìsì kan naa, àwọn ti wọ́n péjọ síbi ìnáwó ìyàwó, ọjọ́ ìbí, ìgbáradì akọrin tàbí ìsìnkú, èyí rí bẹ́ẹ̀ nítorí iye àsìkò ti wọ́n lò pẹ̀lú alárùn náà ni.
"kódà ki wọ́n fi àlà mítà àádọ́ta jìnà sírawọn, ìsun téré tó n kan ẹnìkọ̀ọ̀kan tó láti jẹ́ kí wọ́n  ni ààrùn naa, nítorí naa bi a ṣe n padà sẹ́nu iṣẹ́ àwọn ilé iṣẹ́ kan yóò ní láti ṣe àtúnṣe
Àwọn ọ́fíìsì ti kò ní ibi tí atẹ́gùn le gbà wọlé léwu gidigidi, Bromage ṣàpèjúwe pé ìdá mẹ́rìnleláàọ́run ninu òjìlénígba o dín mẹ́rin ọ́fíìsì ló ni ààrùn Coronavirus ni orílè èdè South Korea, ọ̀pọ̀ sì jẹ́ àwọn to wà nínú ọ́fíìsì kàn náà tó tẹ́ gbayawu ṣùgbọ́n tí àtẹ̀gùn rẹ̀ kò to ǹkan.
Àwọn Dókítà eyín náà wà nínú ewu yìí nítorí irú isẹ́ wọn.
Ó ní àwọn olùkọ́ náà yóò wà nínú ewu, àwọn ọ̀jọ̀gbọ́n to ti darúgbó ló pọ̀jù tí wọ́n si ní àwọn akẹ́kọ̀ọ́ tó kún kíláàsì fọ́fọ́, ìrònú jinlẹ̀ gbọ́dọ̀ wà kí irú àwọn yìí tó padà sẹ́nu isẹ́ fún ìgbé ayé àlàáfíà
Bromage ní àwọn to kó ààrùn Coronavirus ní ta ko fi bẹ́ẹ̀ wọ́pọ̀ ṣùgbọ́n àwọn to kóra jọ pò sí inú ibì kan tí won ti ń kọrin, pariwo ló wọ́pọ̀, tí ènìyàn bá ju kòkòrò náà sì àárín ita, afẹ́fẹ́, oòrùn òtútù leè mú àdínkù bá ìtànkálẹ̀ rẹ̀, ẹ̀wẹ̀, ìjìnà sira ẹni àti mímú àdínkù bá ìbáṣpọ̀ elérò yóò rán gbogbo ènìyàn lọ́wọ́ láti fòpin sí ààrùn Coronavirus.

Bákan náà ni àwọn ibi tó jẹ́ pé kò fi bẹ́ẹ̀ sí atẹ́gùn, ti àwọn ènìyàn si maa n gba èémí fúnra ẹni ni, yóò nira díẹ̀ láti máà ni ààrùn náà, àwọn ilé ìtajà ìgbàlódé kò fi bẹ́ẹ̀ léwu, nítorí pé àsìkò péréte ni wọn lò ní àyíká kan.

Bí a bá fẹ́ lọ sóde, a ní láti ṣe àgbéyẹ̀wò irú afẹ́fẹ́ tí ènìyàn yóò máa gbà sì mú níbẹ̀, iye ènìyàn tó ṣeéṣe kí o bá pàdé níbẹ̀ àti iye àsìkò tí óò lò.
To ba jẹ́ ọ́fíìsì gbayawu ni o ti n siṣẹ́ pẹ̀lú àwọn ènìyàn péréte, ewu bíntín ni ṣùgbọ́n ti èrò ba pọ̀ nibẹ̀, o ní láti gbé e yẹ̀wò dáadáa.
Tó bá jẹ́ pé isẹ́ tìrẹ gba kí o maa bâ àwọn oníbàrá rẹ sọ̀rọ̀ lójú kojú ni tàbí èyí tó n mú ariwo dání, o léwu fún ọ
Tó bá jẹ́ pe kí o lọ rajà lásán láwọn ilé ìtajà ni, níwọ̀ba àsìkò tí o n lò níbẹ̀, ewu rẹ̀ kéré jọjọ, ṣùgbọ́n fún àwọn òṣìṣẹ́ ilé ìtajà náà   Ó ṣe pàtàkì ki a maa rántí pe kìí ṣe ṣínsín síni nìkan ni o yẹ ki a máa ṣọ́ra fún, e rántí pé àwọn kòkòrò yìí maa n bàlé àwọn irinsẹ́ tí à ń lò nítorí naa, o se pàtàkì láti máa fọ owọ́ rẹ déédéé kí o si ṣọ́ra láti máa fi owọ́ kan ojú.
Bákan náà, e ṣọ́ra fún fífẹ́ àtẹ̀gùn láti paná àbẹ́là lórí àkàrà oyinbo (cakes) ọjọ́ ìbí.
Coronavirus ti di ara wa, kò le è kúrò mọ láéláé - WHO
Ǹjẹ́ ènìyàn tó ní àrùn coronavirus rí lè níi lẹ́ẹ̀kejì?
Ǹjẹ́ ènìyàn tó ní àrùn coronavirus rí lè níi lẹ́ẹ̀kejì?
Àwọn àràmọ̀ndà ìbomú-bẹnu tó gbòde lásìkò Coronavirus yìí
Coronavirus in Ibadan: Àbẹ̀wò BBC sí iléeṣẹ́ ISON Xperiences"" tí òṣìṣẹ́ 78 ti kó àrùn coronavirus nílùú Ìbàdàn"
Aja ikeji ati ikẹta ile yii to n bẹ ni agbegbe OLD KINGSWAY BUILDING DUGBE, IBADAN ni ijọba ipinlẹ Ọyọ ti ṣe awari oṣiṣẹ bii mejidinlọgọrin to lugbadi aarun Corona.
"Ileeṣẹ ti awọn oṣiṣẹ naa n ṣiṣẹ fun ni wọn pe ni ""ISON Xperiences"" gẹgẹ bi gomina ipinlẹ Ọyọ, Onimọẹrọ Ṣeyi Makinde ṣe kede rẹ lọsẹ yii, aṣoju sini ileeṣẹ naa je fun amojuto awon onibara ileeṣẹ ikansiraẹni bii Airtel ati MTN."
Ikọ BBC Yoruba ṣe abẹwo si ayika ileeṣẹ naa; a si ṣe akiyesi wi pe ẹnu ọna abawọ ileeṣẹ naa ti di titi pa gẹgẹ bi awọn agbofinro ṣe duro wamuwamu ni oriṣiriṣi ikorita.
Ọpọlọpọ ilẹẹṣe ati ile itaja lo yii ileeṣẹ naa ka, pupọ wọn lo si n ba iṣẹ lọ gẹgẹ bi ẹni wi pe ohunkohun ko ṣẹlẹ ni agbegbe naa.
Lara awọn ileeṣẹ ati ile itaja to sunmọ ileeṣẹ naa pẹkipẹki ni ileeṣẹ igbohunsafẹfẹ ijọba Radio Nigeria, Premier Fm 93.5 to dojukọ ileeṣẹ ti wọn ti ri awọn oṣiṣẹ to lugbadi aarun Corona.
Awọn ileeṣẹ mii to n bẹ ni agbegbe naa ni ẹka banki agba ilẹ wa, CBN to n bẹ ni agbegbe Dugbe niluu Ibadan, ile itaja nla Shoprite naa ko gbẹyin ni agbegbe naa.
Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo
Awa aladugbo ti wọn ni ki a fi orukọ bo awọn laṣiri kọminu lori ile itaja Shoprite pẹlu alaye wi pe oṣeeṣe ki awọn oṣiṣẹ to lugbadi aarun naa maa ra nnkan nile itaja naa.
Ẹlomii to ba wa sọrọ ṣe alaye wi pe awọn aṣoju ajọ to n mojuto itankalẹ aarun, NCDC ṣe abẹwo si ileeṣẹ ti aarun naa ti foju han lati fin oogun apakokoro yika ile naa.
Saaju ni awọn olugbe agbegbe na kọ iwe ranṣẹ si ijọba ipinlẹ Ọyọ lati wa ṣe afọmọ gbogbo agbegbe naa nitori ibẹrubojo to rọ mọ awari awọn oṣiṣẹ to lugbadi aarun Corona.
Awọn oṣiṣẹ to ṣiṣẹ ni ileeṣẹ naa ko din ni ẹẹdẹgbẹta, ninu awọn perete ti ijọba ṣe ayẹwo fun sini ni wọn ti ri onka awọn eeyan bii ọgọrin to ti fi ara ko aarun naa.
Alaye ijọba ipinlẹ Ọyọ ni wi pe ayẹwo ṣi n tẹsiwaju.
Coronavirus in Africa: WHO ní ìwádìí ìmọ̀ ìjìnlẹ̀ yóò ṣèrànwọ́ láti pinwọ́ àrùn náà
Adari ajọ to n risi eto ilera lagbaye, WHO, Tedros Adhanom Ghebreyesus ti sọ pe, o ṣeeṣe ki opin de ba kuru-kẹrẹ arun Coronavirus laarin ọdun meji si asiko yii.
"Ghebreyesus sọrọ yii nilu Geneva, nibi to ti ni aarin ọdun meji pere ni ajakalẹ arun ""Spanish flu"" fi ja, ko to kasẹ nilẹ lọdun 1918."
Ṣugbọn o fikun pe, imọ ijinlẹ ti gbinlẹ ju ti ọdun 1918 lọ, nitori naa, o ṣeeṣe ki Coronavirus kogba wọle ki ọdun meji to pe.
"O ni ""Arun naa ni anfani lati maa fẹ loju si bi awọn eeyan ṣe n fara kanra, ṣugbọn a ni imọ ijinlẹ to dantọ lati koju rẹ."""
Oríṣun àwòrán, @BigBadDenis
Ko din ni aadọta miliọnu eeyan to gbẹmi mi nitori arun Spanish to waye ọdun 1918.
Nigba to n fesi si pe awọn kọlọrọsi ẹda kan n fi arun naa kowo sapo ara wọn, paapaa nipa awọn irinṣẹ idaabo ara ẹni, Ghebreyesus ni ohun to buru gba ni.
O ni iwa ọdaran ni ki eeyan maa lo ajakalẹ arun bii Covid-19 lati sọ ara rẹ di ọlọla, ko si bojumu.
Jude Chukwuka: Wọ́n yóò fi ojú ọlọgbọ́n wo akúrí tó bá sọ ojúlówó èdè Yorùbá
"Ghebreyesus ṣalaye pe ""Ni temi o, iwa ipaniyan ni ki eeyan maa ṣe jibiti lori irinṣẹ idabo bo ara ẹni, nitori ti awọn oṣiṣẹ eto ile ilera ko ba ni awọn irinṣẹ naa, a n fi ẹmi wọn ati awọn ti wọn n tọju sinu ewu ni."""
Lati igba ti arun naa ti ṣẹyọ ni ilu Wuhan lorilẹ-ede China lopin ọdun 2019, miliọnu mejilelogun eeyan lo ti fara kasa arun ọhun kaakiri agbaye, ti eeyan ẹgbẹrun lona ẹgbẹrin si ti ku.
Ilẹ Amẹrika ni arun naa tri ṣọṣẹ julọ, lẹyin rẹ ni Brazil ati India.
Oríṣun àwòrán, Others
Ẹ ṣi awọn ileewe yin pada ni kopẹ kọpẹ, ajọ eleto ilera lagbaye, WHO lo rọ awọn orilẹede ilẹ Afirika bẹẹ
Ajọ WHO ni gbigbe ileewe tipa siwaju sii nitori coronavirus yoo ṣakoba fawọn akẹkọọ.
WHO rọ awọn olori orilẹede nilẹ Adulawọ lati ri pe eto to mọyan lori wa nilẹ, lori ilana ati idena itankalẹ arun Coronavirus, tawọn akẹkọọ yoo tẹle  ti wọn ba wọle pada.
Igbimọ ajọ iṣokan agbaye to n ri si ọrọ awọn ọmọde, UNICEF ati WHO sọ pe, diduro sile awọn akẹkọọ ti jẹ ki ọpọ akẹkọọbinrin gboyun, bakan naa lo ti fi ebi pa awọn akẹkọọ.
Rape cases in Nigeria: Ọmọ ọdun 5 àti 14 ni Kalu wà nígbà tí obìnrin fipá ba lòpọ̀
Wọn ni ai lọ si ileewe tun ti jẹ ki ọpọ awọn akẹkọọ maa ṣe kongẹ iwa ipa lawujọ.
Ibi isadi ni ileewe jẹ fawọn akẹkọọ nilẹ Afirika, alakoso ẹlẹkunjẹkun ajọ WHO, Matshidiso Moeti lo sọ bẹẹ.
Moeti ni ''a ko le titori pe a n gbogun ti itankalẹ aarun coronavirus ki a padanu ọjọ iwaju wa pẹlu awọn akẹkọọ.''
Iwadii ti ajọ WHO ati UNICEF ṣe fihan pe orilẹede Afirika mẹfa pere lo ti ṣi gbogbo ileewe wọn pada lẹyin ti wọn ti gbe tipa nitori ajakalẹ aarun covid-19.
Oríṣun àwòrán, Reuters
Awọn orilẹede Afirika kan to ṣi ileewe wọn gbe tipa pada lẹyin ti awọn to n ko aarun coronavirus tun n pọ si.
Awọn orilẹede mii nilẹ Adulawọ ṣi ileewe pada fawọn akẹkọọ to wa ni ipele aṣekagba nikan ki wọn le lanfaani lati ṣe idanwo aṣejade wọn.
Orilẹede Kenya ni tiẹ ti fagile saa eto ẹkọ ọdun 2020 yii.
Ìdí rèé tí ilẹ̀ Afirika fi gbọdọ̀ kópa nínú dídán abẹ́rẹ́ coronavirus wò
Ọpọ iroyin to mu ibẹru dani lo ti jade lori didan abẹrẹ aarun coronavirus wo lara awọn ọmọ ilẹ Adulawọ.
Amọ, awọn onimọ sayẹnsi ti sọ pe o ṣe pataki fawọn ọmọ ilẹ Afirika naa lati kopa ninu didan abẹrẹ naa wo.
Wọn ni aifẹ kopa ninu eto ati dan abẹrẹ covid-19 wo le dena ati ri abẹrẹ ti yoo kapa aarun ọhun lagbaaye.
Loṣu kẹta to lọ ni Ọgbẹni Tedros Adhanom Ghebreyesus to jẹ oludari ajọ eleto ilera lagbaaye, WHO sọ pe gbogbo agbaye gbọdọ fọwọsowọpọ lori ati wa oogun covid-19.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ajọ WHO ni lai tii ri oogun coronavirus, abẹrẹ  yoo ṣe iranwọ fun adinku itankalẹ aarun naa.
Wọn ti bẹrẹ si ni dan abẹrẹ kan wo lori covid-19 lorilẹede South Africa nigba ti omiiran yoo bẹrẹ ni Kenya lẹyin iyọnda ijọba.
Bawo ni wọn ṣe n san gbà-má-bínú fún ẹni ti wọn bá fi dán abẹrẹ tàbí oògùn wò lára rẹ?
Ileeṣẹ Pfizer dan oogun kan wo lara awọn eeyan ni ipinlẹ Kano ni ariwa Naijiria lọdun 1996.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Eyi lo di ọrọ ileejọ ni eyi ti ileeṣẹ naa ni lati san owo gọbọi gẹgẹ bii owo gba mabinu fawọn eeyan
Omode mọkanla lo ṣalaisi nigba ti awọn miran di abirun lẹyin ti wọn lo oogun antibiotics awogba arun naa tan.
Eyi lo bi ọrọ ki ẹ kọkọ maa gba aṣẹ lọwọ obi ọmọde ki ẹ to fi abẹrẹ tabi oogun kankan dan ara wọn wo.
Ni Uganda ni ogun ọdun sẹyin ni oluṣe iwadii Catherine Kyoubutungi  ni o di dandan lati ṣafihan gbogbo igbesẹ inu abẹrẹ tabi oogun ti eeyan ba fẹ dan iṣẹ rẹ wo ki ohun gbogbo si wa letoleto bi o ti yẹ.
Coronavirus: Kí ní wọ́n ń pè ní “Herd Immunity?”
Dokita Kyobutungi to jẹ adari ajọ African Population and Research Center (APHCR) sọ fun BBC pe o di dandan ki ẹnikẹni to ba fẹ dan abẹrẹ tabi oogun kankan wo wa ọna ilepa ilera to peye fun irufẹ ẹni to ba fẹ lo
Ati pe igbesẹ loriṣirisi lo ti wa ti wọn gbọdọ tẹle ki wọn to le dan abẹrẹ tabi oogun naa wo lara enikeni nilẹ Adulawọ
Ọpọ ọdun nilẹ Afrika ti ko si owo iranwọ to tó lati ṣe iṣẹ iwadii
Airi owo to too na lati fi ṣe awọn iṣẹ iwadii ninu eto ilera jẹ ọkan lara awọn nkan to n mu iṣoro ba eto ilera Afirka.
Oríṣun àwòrán, AFP
Lọdun 2001 ni awọn adari ilẹ adulawọ seleri lati maa mu ida meẹdogun ninu ọgọrun un ninu owo isuna wọn lọdọọdun wa fun iwadii nni eyi ti won ko muṣẹ.
Orilẹ-ede marun un pere lo mu u ṣẹ ninu orilẹ-ede ilẹ Adulawọ.
Afrika ni awọn ọlopolọ pipe ọmọ to ti lami laaka ninu iwadii sayensi ṣugbọn orilẹ imiran ni wọn ti lọ n ṣiṣẹ sin nitori ko si owo fun iṣẹ iwadii nilẹ Afirka. To
Awọn to duro lati ṣe iwadii ni Afrika ko ni oluranlọwọ ni eyi ti ko jẹ ki wọn le maa ṣe ayẹwo pupọ lori iwadii.
Child marriage: Ilé ẹjọ́ dá Ààfá dúró láti gbé ọmọ ọdun 16 sílé gẹ̀gẹ́ bí ìyàwó rẹ̀ kẹ́sàn án
Oríṣun àwòrán, @dsw_intl
Ile ẹjọ to n gbọ ọrọ to ni se pelu idile ni ilu Akure ti dẹkun aafa to gbiyanju ati gbe ọmọ ọdun mẹrindilogun sile gẹgẹ bi iyawo rẹ kẹsan an.
Igbimọ ẹlẹni mẹta to ṣedajọ ọrọ naa, ti adajọ Aderemi Adegoroye dari rẹ ti paṣẹ pe ki wọn da ọmọ ọhun pada si ọdọ awọn obi rẹ.
Ọdun 2019 ni Aaafaa naa, Yusuf lateef ti kọ gbiyanju lati fẹ ọmọde ọhun ni igba to ṣi wa ni ile ẹkọ girama, ṣugbọn igbiyanju rẹ fori ṣọpọn.
Ko pẹ si ti ọmọ naa pe ẹni ọdun mẹrindilogun ti aafaa ọhun mu ọjọ igbeyawo pẹlu rẹ.
Ṣugbọn ọmọ ọhun,  ni ifọwọsowọpọ pẹlu ẹgbọn rẹ sa kuro nile ko to di pe igbeyawo naa waye.
Lẹyinorẹyin, ileeṣẹ ijọba ipinblẹ Ondo to n ri si ọrọ awọn obinrin da si ọrọ naa.
Lẹyin eyi ni ileeṣẹ naa pe awọn obi ọmọ naa ati aafaa to fẹ gbe niyawo lẹjọ, ile ẹjọ naa fẹsun kan wọn pe wọ tapa si ofin to n dabo bo ẹtọ awọn ọmọde ti ipinlẹ ọhun gbe kalẹ lọdun 2007.
Lẹyin atotonu awọn olujẹjọ, ile ẹjọ ni ki wọn yanju ọrọ ọhun itubi inubi, o si kan an nipa fun Aljaji Yusuf lati tọwọ bọwe pe ohunkohun ko ni ṣe ọmọdebirin naa, ati pe ko jinna rere sii.
Ni bayii, kọmiṣọna fun ọrọ awọn obinrin ati idagbasoke awujọ ni ipinlẹ Ondo, Titilola Adeyemi ti fa ọmọ naa le awọn ibi rẹ lọwọ.
Akure Kidnap: Àwọn abiyamọ fẹ̀hónúhàn lórí ọmọ tí wan jígbé nílé ìjọsìn Akurẹ
Lágbo tíátà lọ́sẹ̀ yìí, Femi Adebayo di àgbà àáfà òníláwàní, Iyabo Ojo fi sìgá dárà, Allwell Ademola di ọmọdé padà, tí Wazo si bímọ tuntun.
Oríṣun àwòrán, femi adebayo
Yoruba ni oju to ba dilẹ, ohun ni rorẹ n sọ. Bẹẹ lọrọ ri pẹlu awọn oṣere tiata lasiko igbele Coronavirus yii, ti ọpọ wọn ko ri oko ere tiata lọ.
Ni ọsẹ yii, oniruuru àrà ni awọn gbajumọ oṣere tiata ọhun da loju opo Instagram koowa wọn, koda, ọpọ wọn lo pa ni lẹrin, ta si mu diẹ ninu rẹ wa fun yín.
Oríṣun àwòrán, femi adebayo
Femi Adebayo, ti awọn eeyan kan tun n pe ni Jelili oniso, lo di agba aafa musulumi loju opo Instagram rẹ lọsẹ yii, bo si ṣe n ṣe waasi, naa lo n da orin waka lati kilọ iwa.
Femi, ẹni to daju pe o n sin agba aafa kan jẹ ni, lo wọ agbada buluu gbagẹrẹ, to si we lawani sori, nigba ti obinrin kan, ti oun naa jẹ osere tiata rẹ, ṣe bii dadani fun.
Oríṣun àwòrán, others
Gbajugbaja oṣere tiata lọkunrin kan, Owokoniran Razak, ti ọpọ eeyan mọ si Wazo, ni ọba oke fi ọmọkunrin lanti lanti ta lọrẹ ni aarin ọsẹ yii, ti awọn akẹẹgbẹ rẹ si n ki ku oriire.
Wazo funra rẹ si lo kede ayọ ọmọ tuntun ọhun loju opo Instagram rẹ  @wazothefirst, to si fi fọto ọmọ tuntun naa sibẹ pẹlu.
Oríṣun àwòrán, others
Ẹrin arintakiti ni loju opo Instagram pẹlu fidio kan ti Iyabo Ojo ṣe, to fi n sin awọn janduku jẹ.
Iyabo, lo wọ aṣọ bii ọmọ ìsọta, to si kẹ ohun rẹ, o n sọrọ bii janduku, to si n fa siga.
Oríṣun àwòrán, others
Ara ọwọ awọn oṣere tiata to dilẹ, ti sọ awọn gbajugbaja oṣere tiata kan, ninu eyi taa ti ri  Allwell Ademola di ọmọde pada.
Oṣere tiata lobinrin naa lo ṣe amulo ẹrọ igbalode kan lati sọ ara rẹ di ọmọde pada, ẹni tí ko ba si wo daadaa, ko ni mọ pe oun ni, nitori isọrọ ati oju rẹ to jọ ti ọmọde
Oríṣun àwòrán, others
Ọkan lara igbesẹ idanilaraya to n waye lati ọdọ awọn oṣere tiata ni afihan fọto igba kekere ọpọ wọn.
Ninu ọpọ fọto naa la ti mọ bi diẹ lara awọn oṣere tiata naa ṣe ri ni ọdọ, ọpọ wọn si ni ko ni omi lara nigba naa, yatọ si bi wọn ṣe ri bayii.
Koda, awọn fọto igba ewe wọn yii si lo jẹ kí araye mọ pe ọmọ dudu ni wọn amọ ti ọpọ wọn ti di oyinbo bayii.
Yoruba Films: Ọmọba Femi Oyewunmi tí ọ̀pọ̀ mọ̀ sí Laditi ti jáde láyé
Oríṣun àwòrán, Facebook/Prince Kehinde Oyewunmi
Iku n pa ni, ilẹ n jẹ eniyan. Iku tun ti mu gbajugbaja oṣere tiata, Ọmọba Femi Oyewunmi ti ọpọ mọ si Laditi lọ.
Ọrẹ oloogbe naa, Ọgbẹni Sayo Alagbe lo fidi ọrọ naa mulẹ fun ileeṣẹ iroyin BBC Yoruba.
Ọmọba Oyewunmi ni a gbọ pe o ti n ṣaisan fun ọjọ pipẹ, koda Ọgbẹni Alagbe fidi rẹ mulẹ pe o ṣiṣẹ abẹ lori ẹyin rẹ.
O pada jẹ Ọlọrun ni pe lẹni ọdun mẹrinlelọgọta lọjọ Jimọ, ọjọ kejilelogun oṣu karun un ọdun 2020.
Oloogbe Oyewunmi kopa ninu awọn ere tiata bii Aye Toto, Koto Ọrun, Ija Eleye atawọn ere tiata.
O tun kopa ninu ere Ogun O Jalu Ogbomoṣo ki o to dagbere faye.
Ọmọba Femi Oyewumi fi iyawo ati ọmọ meje si aye lọ.
School re-opening: Àwọn orílẹ-èdè tó ti ṣilẹkùn ilé ìwé padà
Oríṣun àwòrán, Heiko Jung
Awọn ileewe jakejado agbaye ti bẹrẹ si ni ṣi ilẹkun wọn pada lẹyin ti awọn ijọba ti n dẹwọ isede to tẹle ajakalẹ arun Covid 19.
O ti kọja osu meji bayi tawọn akẹkọọ ni orile-edeto le ni aadọwa kio ti lọ sile iwe mọ.
Ajọ UNESCO ni awọn ọmọde ati ọdọ to le ni biliọnu kan ni wọn ko ti ribi lọ si ile ẹkọ lati igba ti ajakalẹ arun coronavirus ti di ẹru jẹjẹ ni gbogbo agbaye.
Awuyewuye loriṣiriṣi lo n waye lori ewu to wa nibi ki awọn akẹkọọ pada si ileewe lai se pe wọn ri abẹrẹ ajẹsara atabi oogun to le koju arun Covid-19.
Sugbọn sa, awọn ijọba kan ni igbagbọ pe bi wọn ba tẹle ilana itakete-sira-ẹni eyi le daabo bo awọn akẹkọọ lọwọ arun yi.
Laarin osu Karun un,  nkan bi orile-ede ọgọrun un ni ko tii kede igba tawọn akẹkọọ yoo wọle pada.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Orilẹ-ede marundinlaadọrin ti kede pe awọn yoo si ileewe tabi si wọn laabọ, nigba ti awọn mejilelọgbọn si ni loju opo ayelujara lawọn akẹkọọ yoo ti pari saa eto ẹkọ to ku.
Amọ sa, fawọn akẹkọọ to to miliọnu mẹwaa din ni ọgọrun mẹsan an, eto ẹkọ ko ti i lojutu ba ti se n sọrọ yi.
Wo ninu awọn to ti si ileewe pada ati bi wọn se n daabo bo awọn akẹkọọ:
China
China nibi ti arun yi ti jẹyọ ti da awọn akẹkọọ pada sile iwe lẹyin ti wọn jajabọ lọwọ arun naa.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Awọn ilana bi itakete-sira-ẹni, lilo ibomu, ọkọ ti wọn seto lọtọ ati oju ọna ti wọn la kalẹ si kilaasi kọọkan wa lara nkan ti China n se bayi tawọn akẹkọọ ti pada sile iwe.
Koda , awọn ile ẹkọ kan gbe ẹrọ ti yoo maa sọ bi ara awọn akẹkọọ ba ti se n gbona si kalẹ si ẹnu ọna abawọle ileewe wọn.
Taiwan
Gbogbo awọn ilana ti China fi lelẹ naa ni Taiwan mulo ti wọn si ti si ile ẹkọ wọn pada lati osu Keji nitori bi wọn ti se jajabọ lọwọ ajakalẹ Covid-19.
Eeyan irinwo le ni  mọkandinlogoji lo farako arun naa ti eeyan mẹfa si baa lọ.
Akẹkọọ perete ni wọn n jẹ ki ọkọ ile iwe maa ko lẹẹkan naa.
Wọn ko jẹ ki awọn akẹkọọ to pọ jeun papaọ mọ
Denmark
Awọn naa dẹwọ ilana isede wọn ni aarin osu Kẹrin bi awọn ile ẹkọ ti se bẹrẹ isẹ pada tohun ti bi awọn obi kan se n bẹru pe ajakalẹ naa le tun jẹyọ lẹẹkeeji.
Idi ree tawọn miran ko fi ti i mu ọmọ wọn lọ si ile iwe.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Awọn olukọ gbọdọ tẹle ilana itakete-sira-ẹni lasiko ti wọn ba n kọ awọn ọmọ.
Awọn olukọ kan n kọ awọn ọmọ ni ita kilaasi ti awọn miran si n kọ ọrọ si ilẹẹlẹ dipo oju patako.
Wakati meji meji ni wọn n jẹ ki awọn akẹkọọ lọ fọ ọwọ wọn nigba gbogbo.
Australia
Ni ipinlẹ to tobi ju ni Australia iyẹn South Wales, awọn akẹkọọ pada si ileewe bo tile jẹ pe ọjọ kan laarin ọsẹ ni wọn yoo fi kọ ẹkọ.
Lọjọ Kẹtadinlọgbọn osu yi ni Victoria ipinlẹ to tobi sikeji yoo bẹrẹ kilaasi tawọn akẹkọọ ati olukọ yoo jọ foju kan ara wọn.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ipinlẹ yi pẹlu Melbourne yoo kọkọ gba awọn ọsóọrọmọde lati wọle lẹyin naa lawọn to kere si wọn yoo bẹrẹ ẹkọ pada ni ọjọ kẹsan an, osu Kẹfa.
Akẹkọọ kọọkan mọ iye mita to maa wọn ti ko fi le sunmọ akẹkọọ miran
Germany
Ni ipelenipele ni Germany si awọn ile ẹkọ pada lẹyin ti wọn jajabọ lọwọ arun Covid-19.
Gẹgẹ bi China, Germany fi awọn ilana itakete-sira-ẹni lelẹ lawọn ile ẹkọ to bẹrẹ isẹ pada.
Awọn akẹkọọ n fọ ọwọ wọn loorekoore, wọn ko jẹ ki wọn sunmọ ara wọn rara.
Sweden
Ohun to jọ bi ọwọ yẹpẹrẹ ti Sweden fi mu ọrọ Covid-19 yi ya ọpọ  eeyan lẹnu.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Wọn kọ lati tẹle imọran ajọ isọkan agbaye pe ki wọn ti orile-ede wọn pa.
Awọn akẹkọọ wọn keekeeke si wa ni ile ẹkọ.
Ohun ti wọn sọ ni pe ẹri wa wi pe awọn ọmọde kii  ko tabi tan arun naa kaakiri.
Norway
Lọjọ Kẹtadinlọgbọn, osu Kẹrin ni awọn ileewe alakọbẹrẹ si pada ni Norway ti awọn ileewe jẹle o sinmi si pada ni ogunjọ, osu Kẹrin.
Akẹkọọ mẹẹdogun pere lo le wa ni kilaasi.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Wọn gba awọn eeyan niyanju lati maa fọwọ ati tabili ikọwe wọn loorekoore.
Ilé Gẹẹsi nkọ?
Eto wa nilẹ lori bi awọn ile ẹkọ ni ilẹ Gẹẹsi yoo se bẹrẹ si ni si pada losu to n bọ.
Sugbọn aroye pupọ wa lori boya wọn o yara da awọn ọmọ yi  pada si ile ẹkọ ni tabi bẹẹkọ ati iru aabo ti yoo wa fun wọn nibẹ
Naijiria ati Ghana nkọ ?
Ni Naijiria titi pa ni gbogbo ile ẹkọ yoo wa titi di igba ti wọn yoo fi se agbeyẹwo ẹkunrẹrẹ.
Ohun ti igbimọ to n mojuto ọrọ ajakalẹ arun Covid-19 ni Naijiria sọ ni yi ni Ọjọbọ tii se ọjọ kọkanlelogun, osu Karun un.
Ni Ghana, Minisita feto iroyin, Kojo Oppong Nkrumah sọrọ lori koko yii lasiko tawọn alasẹ n salaye ọrọ nipa ọrọ yi wi pe ijọba ko ni erongba lati si ile ẹkọ pada lasiko yi.
Eid celebrations in Africa: Báyìí láwọn mùsùlùmí ti ṣe ọdun ìtúnu ààwẹ̀ káàkiri ilẹ̀ Afirika lásìkò covid-19 yìí
Awọn musulumi ṣe ayẹyẹ ọdun itunu awẹ, Eid al-Fitr kaakiri ilẹ Afirika, eyi tii ṣe ipari oṣu Ramada.
Oríṣun àwòrán, Reuters
Bayii lawọn musulumi ṣe ki rawọn ni Nairobi...
Oríṣun àwòrán, Reuters
Oríṣun àwòrán, Reuters
Oríṣun àwòrán, Reuters
Ei
Oríṣun àwòrán, AFP
Oríṣun àwòrán, Reuters
Oríṣun àwòrán, AFP
Oríṣun àwòrán, Reuters
Oríṣun àwòrán, AFP
Oríṣun àwòrán, AFP
Oríṣun àwòrán, AFP
Oríṣun àwòrán, AFP
Oríṣun àwòrán, AFP
Oríṣun àwòrán, Reuters
All pictures subject to copyright
Abike Dabiri vs Pantami: Èrò ọmọ Nàìjíríà sọ̀tọ̀tọ̀ lórí fàákájáa láàrin Abike Dabiri-Erewa àti mínísítà ètò ìbárẹ̀nisọrọ̀
Oríṣun àwòrán, Twitter/Signal
Ọ̀rọ̀ sọ̀tọ̀tọ̀ lọ́dọ̀ àwọn ọmọ Nàìjíríà lórí igbésẹ̀ àwọn òṣìṣẹ́ ìjọba àpapọ̀ méjèèjì ti wọ́n léra síta lórí ayélujára lórí ọ̀rọ̀ tó yẹ kí wọ́n yanjú láì jẹ kí etí míràn gbọ́ síi tí wọ́n tahùn síra wọn lórí àtẹ̀jísẹ́ Twitter Fọ́nrán kan ló kọ́kọ́ jẹ yọ níbi tí ile ișẹ́ ìròyìn Sahara ti ṣe ìfọ̀rọ̀wánilẹ́nuwò lórí bí ilé iṣẹ́ to rí sí ọ̀rọ̀ ilẹ̀ òkèèrè ṣe n sojúṣe wọn àti pé àwọn ìpèníjà wo ni wọ́n n  kojú lásìkò yìí
Nínú èsì rẹ̀ alága àjọ tó n rí sí  ọ̀rọ̀ ilẹ̀ òkèèrè Abike Dabiri-Erewa ṣàlàyé pé mínísítà fún ẹ̀rọ ìbárẹ̀nisọrọ̀, Isa Ali Pantami fi ìbọn le òun àti àwọn òṣìṣẹ́ rẹ̀ síta nínú ọ́fíìsì ìjọba, lásìkò tó n rin ìrìn àjò lọ si ilẹ̀ òkèrè.
Ó ní títí di àsìkò yìí àjọ òun kò lọ́fììsì, gbogbo àwọn irinsẹ́ ọlọ́dani tí àwọn sì n lò ló wà ní títì pá títí di àsìkò yìí. Lẹ́yìn wákàtí díẹ̀ tí ọ̀rọ̀ yìí jáde ní mínísítà náà ba fèsì pé irọ́ pọ́nbélé tó jìnà sóòtọ́ ni ọ̀rọ̀ Abike Dabiri. O ni ẹ̀rí wà lorisirisi láti gbé ọ̀rọ̀ yìí lẹ́yìn pe irọ ni Dabiri-Erewa n pa.
Èyí tí wá dọ̀rọ̀ a n gbà bí ẹní n gbagbá otí lórí ẹ̀rọ àtẹ̀jísẹ́ Twitter báyìí, olúkúlùkù sí n sọ èrò tirẹ̀. Àwọn ọmọ Nàìjíríà ní bí ẹni pé ènìyàn n fọṣọ ìdọ̀tí rẹ̀ níta gbangba lọ̀rọ̀ náà rí to sì tini lójú gẹ́gẹ́ bí orílẹ̀-èdè.
Kódà àwọn míràn tí ṣèdájọ́ ojú ẹsẹ̀ tí pé o yẹ kí ààrẹ gbaṣẹ́ lọ́wọ́ Pantami ni fún irú igbésẹ̀ bẹ́ẹ̀.
Àwọn míràn tún fa ẹ̀rí fọ́nrán mìíràn síta pé ìpàdé ri àwọn òṣìṣẹ́ ṣe lẹ́yìn tí wọ́n lé wọn jáde lọ́fììsì lásìkò tí Abike Dabiri ò sí nílé.
Ọ̀pọ̀ tilẹ̀ ni pé isó inú ẹ̀kú ni ọ̀rọ̀ náà, nítorí náà kò to sí Abike Dabiri láti sọ ǹkan tí ojú rẹ̀ bá rí lọ́wọ́ ìjọba yìí.
Isho Pepper: Isola Ogunsola pẹ̀lú àfihàn àwọn ìyàwó tó jẹ́ igi lẹ́yìn ọgbà fun un nínú iṣẹ́ tíátà
Oríṣun àwòrán, Other
Yoruba ni igba ko lọ bi orere, ako o tọ lọ bi ọpa ibọn, nitori saa laa ni, ẹnikan ko lo ile aye gbo.
Bẹẹ ni ọrọ ri pẹlu gbajugbaja oṣere tiata , Olusola Isola Ogunsola, ti ọpọ eeyan mọ si Isho Pepper ati awọn aya rẹ, ti wọn dìjọ mi agbo tiata Yoruba logbo-logbo  laarin ọdun 1965 si 1992.
Ọjọ Aje, ọjọ Kejidinlọgbọn osu Kejila ọdun 1992, eyi to pe ọdun mejidinlọgbọn bayii ni iku pa oju akọni osere naa de, amọ bi onirese rẹ ko ba fin igba mọ, sibẹ awọn eyi to ti fin ko le parun.
Bi o tilẹ jẹ pe Isho Pepper ati meji ninu awọn iyawo marun-un to n ba ṣe ere tiata ti jade laye, sibẹ o yẹ ki awọn ọdọ iwoyi mọ nípa igbe aye ati iku akọni oṣere tiata naa, to fi mọ ipa to ko si idagbasoke iṣẹ tiata nigba aye rẹ.
Ta ni Isho Pepper?
Apetan orukọ gbajumọ oṣere tiata naa ni Olusola Isola Ogunsola, tii ṣe ọmọ bibi ilu Abeokuta, to jẹ olu ilu ipinlẹ Ogun bayii.
Ọjọ Kẹrinla, oṣu Kọkanla, ọdun 1942 ni Samuel ati Abigail Ajike Ogunsola bi akọni oṣere tiata naa sile aye, to si jẹ ọmọ agboole Baala Dasaolu lẹyin mọsalasi Ita Igbẹyin ladugbo Oke Itoku.
Oríṣun àwòrán, Isho Pepper Junior
Olusola ni abigbẹyin ninu ọmọ mẹrin ti awọn obi rẹ bi, abule Olokuta, ni ẹba Alahọ to wa nijọba ibilẹ Oluyole nilu Ibadan si lo ti lo igba kekere rẹ, ibẹ si lo ti lọ sile ẹkọ alakọbẹrẹ Christ School, Olokuta.
Lẹyin to pari iwe mẹfa rẹ lo pada si Abeokuta fun eto ẹkọ girama, to si lọ si Abeokuta Grammar School nibi to ti bẹrẹ afihan ifẹ rẹ si ere tiata lasiko ti ọpọ eeyan korira isẹ naa, ti wọn si n rii awọn osere tiata bii alagbe.
Oríṣun àwòrán, Other
Nitori idi eyi, ọpọ ipenija ni Olusola koju nidi iṣẹ to yan laayo ọhun, tawọn ẹbi ati ọrẹ si kọ ẹyin sii.
Amọ niwọn igba to jẹ pe yeye ọmọ nii gba ọmọ, iya rẹ, Abigail Ajike ṣe atilẹyin alailẹgbẹ fun nidi iṣẹ naa, ti Olusola si dara pọ mọ ẹgbẹ oṣere tiata Akin Ogungbe to wa nilu Abeokuta lọdun 1959, lẹyin to pari ẹkọ girama.
Lara awọn ti wọn dijọ kọ iṣẹ tiata lọdọ Akin Ogungbe lasiko naa ni Jimoh Aliu, Charles Olumo (Agbako), oloogbe Afolabi Afolayan (Jagua), ati Femi Adeyemo (Baba n gba life).
Olusola kuro lọdọ ọga rẹ lọdun 1965 lati da ẹgbẹ tiata tara rẹ silẹ, to si n kọrin, lu ilu, jo ati sere.
O fẹ ọpọ iyawo lati maa ba sere, ti wọn si n tẹle yika gbogbo ilu to ba n lọ.
Mama Rainbow: iṣẹ́ tíátà kò ta sánsán mọ́ bíi ti ayé àtijọ́
O jẹ ọkan lara awọn oṣere tiata to kọkọ ṣe ere itage lori amohumaworan pẹlu awọn gbajumọ oṣere tiata miran bii Hubert Ogunde, Baba Sala, Baba Mero, Kola Ogunmola, Oyin Adejobi, ati Adeyemi Afolayan.
Bakan naa lo ṣe ọpọ ere ninu iwe Atọka, oun naa si tun ni oṣere tiata kẹrin to ya ere sinima lẹyin Hubert Ogunde, eyi to gbe lọ si orilẹ-ede United Kingdom (UK).
Ọpọ eeyan ni Isho Pepper kọ ni iṣẹ tiata, lara wọn ni Samson Eluwole (Jinadu Ewele), oloogbe Adeniyi Orofo (Ewejoko) ati oloogbe Gbolagade Adedeji (Aro onifila gogoro).
Nigeria movie industry: Àgbà òṣèré, Lere Paimo ní àìgbọràn ló ń da ọ̀pọ̀lọpọ̀ àwọn
Olusola jẹ ọkan lara awọn agba ọjẹ oṣere tiata to da ẹgbẹ awọn oṣere taa mọ si ANTP silẹ lọdun 1976, to si jẹ akọwe owo akọkọ fun ẹgbẹ naa laarin ọdun 1976 si 1989, bẹẹ lo tun gbe ọpọ ere jade ni ede Yoruba.
Lara awọn ere naa ni Fere bi Ekun, Alaafin Aganju, Agbalowomeri, Efunsetan Aniwura, Ibu Olokun, Koseegbe, Ajaloleru, Iyawo Alalubosa ati bẹẹ bẹẹ lọ, ko si fẹ ẹ si ilu kan ni Naijiria ti Isho pepper ko gbe ere tiata de.
Oríṣun àwòrán, iSho pepper Junior
Lasiko ti Olusola n dabira lati gbe aṣa, ede ati ìṣe Yoruba larugẹ, ni iku ja ẹmi rẹ gba lairo tẹlẹ lasiko aisan ranpẹ lẹni aadọta ọdun, ni ọjọ kejidinlọgbọn, oṣu Kejila, ọdun 1992.
Mojisola Ogunsola:
Oloogbe Mojisola Ogunsola ti awọn eeyan mọ si Iya Alakara nigba aye rẹ, ni iyale patapata ninu awọn iyawo Isho Pepper, to si maa n tẹle ọkọ rẹ lọ ṣe ere tiata kaakiri.
Oríṣun àwòrán, Other
Ẹni ọgọta ọdun ni oloogbe naa nigba to jade laye lẹyin iku ọkọ rẹ, to si ko ipa manigbagbe ninu iṣẹ tiata pẹlu ọkọ rẹ.
Iyabode Ogunsola
Iyabode Ogunsola ni ọpọ eeyan mọ si Efunsetan Aniwura, to si jẹ gbajumọ oṣere lobinrin lasiko ti ọkọ rẹ wa laye.
Efunsetan si ni gbogbo aye mọ julọ ninu awọn aya oloogbe Isola Ogunsola sugbọn lọwọ lọwọ bayii, o ti dagbere fun iṣẹ tiata, to si di oniwaasu ọrọ Ọlọrun.
Oríṣun àwòrán, Other
Ọpọ ere sinima, fiimu agbelewo ati ere itage ni Efunsetan ti kopa ninu rẹ, ko si si ẹni to ri obinrin naa lori pẹpẹ iwaasu, ti ko ni maa ranti awọn ara manigbagbe to ti da ninu isẹ tiata.
Oríṣun àwòrán, Other
Laipẹ yii si lo ṣe ayẹyẹ ọjọ ibi rẹ loke eepẹ.
Funmilayo OgunsolaIjewuru ni adape orukọ Funmilayo Ogunsola ninu iṣẹ tiata, to si ti silẹ bora lọdun 2019 lati ipasẹ aisan ẹjẹ ruru to ba fínra.
Isẹ kekere kọ ni Funmilayo ko nidi isẹ tiata loju aye ati lẹyin iku ọkọ rẹ, ki iku to yọ ọwọ rẹ lawo lasiko aisan ranpẹ. Orukọ Ijẹwuru to fi silẹ si lo di manigbagbe titi di oni yii, tawọn eeyan fi n ranti rẹ.
Oríṣun àwòrán, Other
Funmilayo ni iyawo kẹta Isho Pepper, toun naa si ko ipa ti ko kere si idagbasoke iṣẹ tiata.
Yetunde Ogunsola
Arẹwa obìnrin, apọnbeporẹ, ni Yetunde Ogunsola nigba to wa lewe, ti Isola Ogunsola fẹ bii aya.
Oríṣun àwòrán, Other
O sa ipa rẹ lati mu agbega ba iṣẹ ọkọ rẹ, tii ṣe ere tiata, ti ọpọ eeyan si mọ gẹgẹ bii Iyawo Alalubosa tabi Ayoni, nitori ipa to ko ninu ere naa Iyawo Alalubosa.
Titi di akoko yii, Yetunde Ogunsola sì n kopa ninu ere tiata lorisirisi, oun naa si ti di Ajihinrere.
Bolatito Ogunsola
Bolatito ni iyawo kekere to gbẹyin ninu awọn iyawo Isho Pepper, Aina Orosun si ni ọpọ eeyan mọ si.
Bolatito ko ipa manigbagbe ninu iṣẹ tiata lasiko ti ọkọ rẹ, Ishola Ogunsola wa loke eepẹ, sugbọn lẹyin ti ọkọ rẹ ku tan, oju obinrin naa ko han mọ ninu ere tiata.
Nibayi to pe ọdun mejidinlọgbọn ti Olusola Isola Ogunsola jade laye, to si fi ọpọ ọmọ silẹ saye lọ, a si n gbadura pe ki ọba oke tẹ si afẹfẹ rere, ko si di idile to fi silẹ saye lọ mu sinsin.
Coronavirus Cases in Africa:Ojú òpó Facebook Live ni mo ti wo ìsìnkú ìbátan mi
Oríṣun àwòrán, Mercy Juma
Iwọn ẹsẹ bata mẹta sira ni wọn  joko  lori aga.Gbogbo eeyan to wa nibẹ lo wọ ibomu.
Gbogbo eeyan lo mọ nipa ilana ijọba Kenya lori isinku lasiko ajakalẹ Coronavirus.
Eeyan mẹẹdogun pere lo kopa ninu isinku ibatan mi, Chris, aago mẹsan owurọ si ni gbogbo eto gbọdọ ti pari.
Nigba ti ago meje yoo fi lu, awa ta ku ti rọ yika ẹrọ alagbeka wa ati ẹrọ kọmputa wa nibi ti a ti n wo isinku naa ti ọrẹ wa kan se alabapin rẹ loju opo Facebook Live.
Ọgọrọ  wa  la ṣetan lati ṣe ẹyẹ ikẹyin fun Chris. Elero eeyan nii se. Lọpọ igba a ma tan imọlẹ sawọn aaye akojọ to ba wa nibẹ.
Bi o ba rẹrin, ko si ẹni ti ko ni gbọ ohun rẹ koda bo ba wa ni jina jina sibi tẹ wa.
Oríṣun àwòrán, Courtesy of Mercy Juma
Bẹẹ si ni Chris naa a ma jẹ ipe awọn eeyan lasiko ti wọn ba nilo rẹ.
Bo ba ṣe ni ibi ayẹyẹ igbeyawo ni tabi isinku, Chris yoo ṣa ri pe oun pe awọn eeyan jọ ni sha.
Nitorinaa lọjọ ta n wi yi, awa naa jẹ ipe rẹ lati ṣe ẹyẹ ikẹyin fun un.
Ṣugbọn kini ọhun ko jọ ara wọn tan nitori pe a ko si nibi isinku bo ti se wu wa.
'A ko le kọ awọn orin rẹ to fẹran ju'
Ibatan mi ni Chris, inu ile kan naa ni wọn ti tọ wa dagba ti o  si sun mọ mi ju ẹgbọn mi lọ.
Ilu Kisumu  lo ku si ni iwọ oorun Kenya ni ọjọ Ajinde lẹyin ti aisan jẹjẹrẹ ẹdọ ti da a lagara fun bi ọsẹ melo kan.
Ijọba sọ ilana isinku rẹ fun wa. A gbọdọ sin in laarin ọjọ mẹta.
Oríṣun àwòrán, Courtesy of Mercy Juma
Sugbọn bi iṣede ti ṣe de pupọ ninu awọn mọlẹbi rẹ mọlẹ ni olu ilu Nairobi, gbogbo wa kọ la le lọ si ibi isinku rẹ.
Ṣoki ni ọrọ iwaasu nibi isinku rẹ, wọn o si kọrin pupọ nibẹ.
Chris fẹran orin kikọ. A maa ba wọn lulu ninu ẹgbẹ akọrin ijọ sọọsi rẹ.
O jẹ ohun to fọwọkan eeyan lẹmi pe ko si ẹni to le kọ awọn orin rẹ to fẹran ju nibi isinku rẹ.
Nise ni mo n wo bi awọn ọrẹ ati alabase rẹ ti ṣe n kọ ọrọ nipa rẹ soju opo Facebook Live isinku rẹ.
Ni oju opo ayelujara nise lawọn eeyan n sọ nipa rẹ ti wọn si n fi ọrọ ikẹdun ransẹ.
Loba wa si mi lọkan wi pe, abi ki n tẹ awọn ọrọ yi jade ni ko ba le jẹ ọrọ ikẹdun nitori ko si iwe ta le kọ si.
Gbogbo nkan to n ṣẹlẹ ko jọ bi ti tẹlẹ. A ko le di mọra wa, ko si ẹni to le ri omije ẹni keji bẹẹ ko si ẹni le bu yẹpẹ si ori posi rẹ bi wọn ti ṣe n gbe e sinu saare rẹ.
''Facebook Live ti wọn n se muna lọ nitori naa mi o laanfaani lati wo irinajo ikẹyin Chris de ipari''
Bi a ba padanu ẹni ta fẹran, a maa n wa ọna lati daro wọn, a maa n wa ki eeyan bawa kẹdun ki a si pa ọkan pọ.Sugbọn lasiko ta dejumọle yi, bawo la ti se le se gbogbo wọnyi?
Inu mi ko dun.
Mi o figba kan lero pe maa sin ẹni ti mo fẹran loju opo ayeujara.
Mi o ro wi pe fifọwọ kan eeyan yoo mu mi lọkan bayi. O dabi ere sinima ni amọ emi gaan wa lara awọn to n kopa nibẹ.
Ibanujẹ lo jẹ pe Facebook Live naa muna lọ lojiji nitori aiṣedede nẹtiwọki.
Mi o laanfaani lati wo irinajo ikẹyin Chris de ipari.
Mi o ri bi wọn ti ṣe gbe posi rẹ sinu saare.Ni ilẹ Afrika lọdọ wa nibi, eto isinku jẹ ohun ti ọpọ ko fi ọwọ yẹpẹrẹ mu.
Awọn agboku lorilẹede Ghana
O dabi iṣipo pada lati alaye lọ si ipo miran ti a ko mọ nipa rẹ.
Torinaa, a mu ọrọ awọn babanla wa to ti lọ ni pataki.
Bi eeyan ba ku lọdọ wa, a kii fi ọrọ ayẹyẹ ati eto isinku wọn sere rara.
Ni aarin awọn eeyan Luo ati Luhya ti mo ti wa ni iwọ oorun Kenya, ohun pataki ni iku eeyan jẹ ati isinku wọn.
Nipele nipe le leto isinku lọdọ wa
Tọwọtọwọ ni a maa fi n ṣeto isinku ẹni ba lọ.
Gbogbo eto ati ilana laa si maa n tẹle ki irinajo wọn lọ si odi keji ma ba kọsẹ rara.
Akọkọ ibẹ ni pe a kii kanju ṣe eto isinku agaga ti o ba jẹ ti agbalagba.
Isinku lọdọ wa  jẹ asiko ayẹyẹ, koda laarin awọn to ba n ṣe idaro ẹni to lọ.
O ma n to ọsẹ kan gbako ti wọn fi n se isinku agbalagba.
Awọn eeyan a ma sunkun, ariwo ma n pọ, awọn eeyan maa n ṣe akojọpọ ti wọn a si ma ba ẹni tọfọ ba ṣe idaro.
Lasiko ta n sọ yii, wọn ma n dana igi tawọn eeyan a si su jọ lati maa sọrọ ẹni to lọ.
Wọn maa n pa ẹran etutu, wọn maa n dana, jijẹ mumu yoo wa rẹpẹtẹ fawọn to wa ba mọlẹbi daro. Akoko ti awọn eeyan maa n se afihan iṣọkan laarin mọlẹbi ati ọrẹ ni isinku maa n  jẹ.
Bi isinku ba ku ọjọ kan tabi meji, wọn maa n tẹ oku sita kawọn eeyan ba le fifẹ han si i t'oun ti pe o ti dero ọrun.
Lọdọ awa eeyan Luo, o kere tan eto isinku mẹwaa la maa n ṣe lati fi dagbere ikẹyin fẹni to lọ.
O ṣeni laanu pe lasiko isinku Chris, a ko ribi dimọra wa, a ko ribi sunkun faraya, ko si apejọ awọn eeyan lati ṣe idagbere ikẹyin, ko si eyi ta ri ṣe nibẹ.
Awọn osisẹ ijọba duro digbi ni lati rii pe isinku naa lọ nibamu pẹlu ilana ti wọn la kalẹ.
Nitori eyi, o dabi ẹni pe idaro mi lori iku Chris ko tii pe.
Boya ti gbogbo nkan ba pada sipo, a o laanfani lati  tun idaro rẹ sii bo ti ṣe tọ ati bo ti se yẹ.
JAMB post UTME screening: UNN, MAPOLY, Auchi poly, AKSU àtàwọn míì ti bẹ̀rẹ̀ ìgbésẹ̀ àtiwọlé ní Naijiria
Oríṣun àwòrán, Others
Awọn ileewe giga kọọkan lorilẹ-ede Naijiria ti bẹrẹ si ni ta fọọmu idanwo Post UTME fun awọn akẹkọọ ṣẹṣẹ fẹ wọ ileewe giga.
Àjọ tó ń ṣètò ìdánwò àṣe wọlé sí ilé ẹ̀kọ́ gíga, JAMB ṣẹṣẹ kéde pe awọn ileewe to ba fẹ ṣe idanwo Post UTME ko gbọdọ bẹrẹ titi di Ọjọ Keje, Oṣu Kẹsan an, ọdun yii.
Ajọ naa ni idi ti awọn fi ṣe alakalẹ naa ni lati ri wi pe awọn akẹkọọ to ṣi n reti esi idanwo asekagba nileewe girama naa oo ni anfaani lati kọ idanwo Post UTME naa.
Awọn ileewe to ti bẹrẹ si ni ta fọọmu re e:
Sextuplet: Àdúrà Ìbùkún ló kú lẹ́yìn ọmọ mẹ́fà yìí- Ifeoma Thelma àti Onyemaechi Chiaka
Oríṣun àwòrán, others
Ajọ to ṣe eto idanwo aṣewọle si awọn ile ẹ̀kọ́ giga ni Naijiria, JAMB, ti pàṣẹ pe ki eto igbani wọle o bẹrẹ ni ọjọ keje, oṣu Kẹsàn-án.
Agbẹnusọ fun ajọ JAMB to ba BBC sọrọ, sọ pe àṣẹ tuntun naa waye lati le fun gbogbo akẹkọọ, to fi mọ awọn to fẹ ẹ lo esi idanwo WAEC tabi NECO ti wọn ko ti i gbà, ni anfaani lati ṣe idanwo Post-UTME, ti
awọn ileewe giga ma n ṣe lẹyin idanwo Jamb.
Oríṣun àwòrán, @JAMB
Ọjọ Aje ni ajọ JAMB fi ẹnu ko si igbesẹ tuntun yii.
Lẹyin ipade ti wọn ṣe pẹlu awọn Ọga Agba Fasiti, Ọga Agba ile ẹ̀kọ́ gbogbo ni ṣe (polytechnic), ati awọn Ọga Agba awọn ile ẹ̀kọ́ gíga to kù.
Alaafin: Olori Aanu Adeyemi ṣàlàyé ìdí tó ṣe gẹ́ Oba Lamidi Adeyemi ti ìlú Oyo
Ọjọ kejilelogun, oṣu Kẹjọ, ọdun 2020 ni ajọ JAMB ti kọkọ dari awọn ile ẹ̀kọ́ giga lati bẹrẹ eto igbani wọle.
"Agbenusọ fún ajọ JAMB sọ pe ""abajade ipade ti a ṣe ni pe eto igbani wọle kankan ko gbọdọ waye ṣaaju ọjọ keje, oṣu Kẹsàn-án si ọjọ kẹrin, oṣu Kẹwàá."""
Bakan naa ni eto igbani wọle miran tun gbọdọ bẹrẹ ni ọjọ kẹjọ, oṣu Kọkanla, nitori awọn ti yoo ṣe idanwo NABTEB.
O fi kun ọrọ rẹ pe nigba ti yoo ba fi to awọn asiko tuntun ti wọn kede, gbogbo akẹ́kọ̀ọ́ yoo ti gba esi idanwo ti wọn ṣe silẹ.
Sugbọn o, awọn ileewe to jẹ pe esi idanwo JAMB nìkan ni wọn fẹ ẹ fi gba awọn akẹ́kọ̀ọ́ wọle si ile ẹ̀kọ́ ti wọn le bẹrẹ igbani wọle, bo tilẹ jẹ pe igbesẹ naa ko ni i pari di oṣu Kọkanla ti ijọba yoo kede pe ki
gbogbo eto igbani wọle wa si opin.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Saaju ni ijọba ti kọkọ sọ eyi ṣugbọn ohun gbogbo ti yipàda, idanwo WAEC di ṣiṣe.
Àwọn akẹ́kọ̀ọ́ bẹ̀ ìjọba láti ṣ'íléèwé fún ìdánwò WAEC, ìpinnu ìjọba ilẹ̀ Yorùbá rèé
Ọrọ ṣiṣi ileewe ni orilẹede Naijiria ti fa ariyanjiyan nitori awọn ijọba ko fi ọjọ ti awọn akẹkọọ yoo pada si ileewe lede.
Lẹyin ti ijọba apapọ kede pe awọn ileewe girama rẹ ko ni le kopa ninu idanwo aṣejade iwe mẹwaa, WAEC eyi ti yoo bẹrẹ ninu oṣu kẹjọ, ọdun 2020 nitori coronavirus, awọn ipinlẹ Yoruba naa ti sọ ero wọn lori igbesẹ ijọba apapọ.
Minisita fun eto ẹkọ ni Niajiria, Mallam Adamu Adamu ṣalye ninu iwe atẹjade kan to sita pe awọn ipinlẹ lominira lati ṣe ohun to ba wu wọn lori ọrọ naa.
Nigba ti o n ba BBC Yoruba sọrọ lori ago, Kọmiṣọnna eto ẹkọ nipinlẹ Osun, Folorunso Oladoyin ṣalaye pe ọrọ ṣiṣi ileewe lasiko yii gba ero nitori ajakalẹ aarun covid-19.
Amọ Ọgbẹni Oladoyin fidi rẹ mulẹ pe ijọba ipinlẹ Osun yoo kọwe si ajọ WAEC lati sun idanwo naa siwaju pẹlu ọsẹ meji ki awọn le gbaradi daadaa fun idanwo naa.
O ni ijọba Osun ṣetan lati tẹle gbogbo awọn ilana ti ijọba apapọ la kalẹ lori ṣiṣi ileewe lasiko yii.
Ninu ọrọ tiẹ, Kọmiṣọnna eto ẹkọ nipinlẹ Ekiti, Ọgbẹni Foluso Daramola, sọ pe ipinlẹ Ekiti yoo gba kawọn akẹkọọ ṣe idanwo WAEC ṣugbọn eyi yoo da lori igbesẹ awọn ijọba ilẹ Yoruba.
Kọmiṣọnna eto ẹkọ l'Ekiti sọ pe gbogbo awọn kọmiṣọnna eto ẹkọ kaakiri ilẹ Yoruba lo ṣepade lọjọ Iṣẹgun lori ọrọ idanwo WAEC.
O fikun ọrọ rẹ ijọba Ekiti yoo pade kede ipinnu rẹ lori ọrọ naa lẹyin ti gbogbo ipinlẹ Yoruba ba ti fẹnuko tan.
Bakan naa lo sọ pe ijọba ti gbaradi lati tẹle gbogbo ilana ti ijọba apapọ la kalẹ lori ṣiṣi ileewe pada lasiko idanwo naa.
Ẹwẹ, Toyosi Kolawole ati Tofunmi Bello ti wọn jẹ akẹkọọ naa sọrọ lori ilana ijọba to da lori kikọ idanwo WAEC loṣu kẹjọ ọdun 2020.
Tofunmi Bello ni tiẹ sọ pe ọrọ naa ti toju su oun, o ni oun ko tiẹ le kawe mọ nitori oun ko mọ igba ti idanwo naa yo ya.
Tofunmi ni o ṣeni laanu pe ijọba n gbaradi fun eto idibo, ṣugbọn ijọba o fẹ kawọn akẹkọọ ṣe idanwo.
O ni idanwo ohun to maa buru jai ni ti ijọba ba le sun idanwo WAEC awọn ti ọdun 2021.
Awọn mejeeji naa panu pọ lati bẹ ijọba pe ko ṣi ileewe pada nitori ọjọ iwaju awọn niyẹn.
Teach your children Yoruba: Wo àwọn òyìnbó tó ń kẹ́kọ̀ọ́ èdè Yorùbá ní Michigan, America
Ìjọba fí ìlànà tuntun lédé lórí àti ṣí iléèwé káàkiri Nàíjíríà láì fí ọjọ́ tí wọn yóò ṣí iléèwé sí bẹ̀
Igbesẹ ijọba lati fi ilana ofin ti awọn olukọ ati akẹkọọ gbọdọ tẹlẹ lai fi ọjọ ti wọn yoo ṣi ileewe lede ti fa ariyanjiyan.
Ilana ofin ati ṣi ileewe naa wa ninu atẹjade ti ijọba fi le de ti wọn pe ni 'Guidelines for schools and learning facilities reopening after COVID-19 pandemic closures: Taking responsibility for safe schools and quality learning.'
Minisita fun eto ẹkọ ni Niajiria, Mallam Adamu Adamu lo buwọlu iwe atẹjade naa.
Ilana ofin naa fi lede pe awọn akẹkọọ gbọdọ tẹle ofin ijinasiraẹni pẹlu mita meji ni gbogbo ileewe kaakiri Naijiria.
Amọ, wọn fikun pe, ti ko ba ṣeeṣe nitori awọn ọmọ to ni ipenija ẹkọ, ki wọn tẹlẹ gbogbo ofin to ku bi lilo oogun apakoko kaakiri agbeegbe naa, ki wọn si maa fọ ọwọ wọn loore-koore.
Wọn fikun wi pe ijọba yoo pese owo fun awọn ileewe lati le fi awọn eto yii lele ni awọn ileewe kaakiri Naijiria lati da abo bo awọn akẹẹkọ lọwọ aarun Coronavirus.
Bakan naa ni Minisita fun eto ẹkọ naa fikun pe lilo eto ẹkọ  lori ẹrọ ayelujara naa yoo ṣeranwọ fun awọn eniyan lati koju ipenija itankalẹ arun Coronavirus.
Yomi Otubela, to jẹ aarẹ ẹgbẹ naa sọ pe igbesẹ ijọba yoo fun awọn ni itura diẹ kuro ninu inira ti itankalẹ aarun Coronavirus mu ba wọn.
Oṣu Kẹta, ọdun 2020, ni ijọba ti ti gbogbo ileewe pa. Otubela sọ ninu atẹjade kan to fi ránṣẹ si BBC pe awọn ileewe aladani naa yoo pin ninu 2.3 biliọnu, owo iranwọ ti ijọba kede lọsẹ to kọja.
'Ẹlẹ́ẹ̀kẹjọ t'óyún máà bàjẹ́ lára mi ni mo tó rí àànú gbà'
Ẹgbẹ NAPS sọ pe awọn fi ọrọ lọ ijọba apapọ, nipasẹ igbimọ to wa fun fifi ẹsẹ eto ọrọ aje mulẹ ni Naijiria, ti igbimọ alasẹ naa si ti buwọlu u.
Igbakeji aare, Yemi Osinbajo, lo n dari igbimọ naa.
Ẹwẹ, ile aṣofin agba Naijiria paapa fi si ori itakun agbaye rẹ pe awọn ileewe aladani wà lara awọn ti ijọba yoo ran lọwọ.
Lori iye oṣu ti ijọba yoo ran wọn lọwọ lati san, Ọgbẹni Otubela sọ pe oun ko ti i le sọ, nitori pe ko si ẹni to mọ igba ti Coronavirus yoo to o wa si opin.
Bakan naa ni ko le sọ igba ti ijọba yoo bẹrẹ si ni san owo naa, nitori pe eto ṣi n lọ.
Ọgbẹ́ni Otubela sọ pe oni ọna ti awọn yoo gba lati mọ àwọn ileewe to jẹ oṣiṣẹ wọn lowo oṣu, nitori pe akọsilẹ wa fun awọn ọmọ ẹgbẹ NAPS.
Minisita kekere fun eto ẹkọ ni Naijiria, Emeka Nwajiuba, sọ pe orilẹ-ede Naijiria ko ṣetan lati fi ilera awọn ọmọde sinu ewu nitori pe wọn fẹ ẹ ṣi ileewe pada.
"Ọgbẹni Nwajiuba ti ko sọ pato ọjọ ti awọn ọmọ yoo wọle pada, sọ pe ""O di igba ti a ba to o ni idaniloju pe awọn ọmọde le lọ sileewe, pada sile laalafia, lai ko aarun Covid-19 pada sile, la to o ṣetan""."
Minisita sọ ọrọ yii lasiko ti igbimọ to n mojuto itankalẹ aarun Covid-19 n ba awọn akọroyin sọrọ lọjọru, ọjọ kẹtadinlọgbọn, oṣu Kẹta.
Ọrọ to sọ yii waye gẹgẹ bi esi fun awọn obi kan ni Naijiria, to n beere pe nigba wo ni ijọba yoo ṣi ileewe pada.
'Mo fẹ́ di ẹni gíga'
Ọgbẹni Nwajiuba sọ pe ileeṣẹ eto ẹkọ yoo gbe ilana jade lori bi nkan yoo ṣe lọ, ti awọn akẹkọọ ba pada sileewe.
"Fun awọn ileewe girama, awọn akẹkọọ wọn le pada sileewe, lati le pari idanwo wọn, ki wọn o si tun pada lọ ọ joko sile.
Bakan naa ni ao mu adinku ba iye akẹkọọ ti yoo wa ni kilaasi kọọkan. Eyi ṣeeṣe ko tumọ si pe eto ẹkọ yoo wa ni owurọ ati ọsan, lati le tẹle ilana titakete siraẹni."""
Minisita tun sọ pe awọn n gbeero lati fin oogun apakokoro si awọn ileewe ṣaaju iwọle pada.
"Ninu ọrọ tiẹ, Alaga igbimọ amuṣẹya fun aarun Covid-19, Boss Mustapha, sọ pe ""ki awọn ipinlẹ, ati ijọba ibilẹ o ṣe gbogbo eto to yẹ"", ki eto ẹkọ le tete bẹrẹ pada ninu ilera pipe."
"O sọ pe ijọba ""ko ṣetan lati fi awọn ọmọ wa tọrẹ fun aarun yii""."
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ilé isẹ́ tó n rí sí ètò ẹ̀kọ́ ni Nàìjíríà ni àwọn kò tíì dá ọjọ́ kankan fún ìwọlé ilé ẹ̀kọ́ jákèjádò orílẹ̀-èdè Nàìjíríà.
Agbenusọ ilé isẹ́ náà, Ben Gong ṣàlàyé fún BBC pé àsìkò tí ilé isẹ́ ètò ìlera ba sọ pé kò séwu mọ ni àwọn ilé  ẹ̀kọ́ yóò tó padà di ṣíṣí.
Gbogbo ilé ẹ̀kọ́ jákèjádò orílẹ̀ èdè yìí ni ìjọba tìpa láti ilé ẹ̀kọ́ alákọ̀bẹ̀rẹ̀, gírámà títí dé Fáṣítì láti ọjọ́ kẹrindinlọ́gbọ̀n oṣù kẹ̀ta ọdún yìí.
"Gong ni ojúṣe ilé iṣẹ́ tó ń rí sí ètò ìlera, àjọ tó ń gbógun ti àjà kálẹ̀ ààrùn ni Nàìjíríà (NCDC) àti ìgbìmọ̀ amúṣẹ́ya Covid-19 tí Ààrẹ yàn ni àti pé àwọn ni ọ̀rọ̀ kù sí lọ́wọ́ nítorí àwọn ni wọ́n ń léwéjú lórí ọ̀rọ̀ Coronavirus àwọn sì ló mọ àsìkò tó yẹ láti ṣí àwọn ilé ẹ̀kọ́."""
Ó ní ní kété ti àwọn ba ti mọ àsìkò tí tí ilé ìwé yóò wọlé padà làwọn yoo ti fi àwọn ìlànà tí àwọn ilé ẹ̀kọ́ yóò maa tẹ̀lé síta.
Ẹ̀wẹ̀ Kọmísọ́nà fún ètò ẹ̀kọ́ ni Ìpínlẹ̀ Kano Muhammad Sansi Sa'ad sọ fún BBC pé kò tíì sí ìfojúsùn ọjọ́ tí àwọn yóò ṣí ilé ẹ̀kọ́ tó ti wà ní títì pa láti oṣù méjì sẹ́yìn.
ìpàdé ní wọ́n ó ti pinnu àsìkò tí ilé ẹ̀kọ́ yóò wọlé padà àti ìlànà ti àwọn olùkọ́ àti àwọn akẹ́kọ̀ọ́ yóò tọ̀ ti wọ́n bá wọlé 
Ọ̀pọ̀ àwọn òbí ni Ìpínlẹ̀ Kano lo tí n káyà sókè pé àwọn ọmọ  ti pẹ́ nílé láì lọ sí ilé ìwé àti pé àwọn ilé ìwé péréte lo ń ṣe ìkẹ́kọ̀ọ́ orí ayélujára fún àwọn akẹ́kọ̀ọ́ wọn.
Nípìnlẹ̀ Rivers Kọmísọ́nà fún ètò ẹ̀kọ́ níbẹ̀ ọ̀jọ̀gbọ́n Kaniye Ebeku sọ fún BBC pé àwọn ò fi ọ̀rọ̀ ẹ̀kọ́ ṣeré rárá ìdí nìyí tí àwọn fi n ṣe ìdánilẹ́kọ̀ọ́ àpapọ̀ lórí redio àti telefísọ̀n fún akẹ́kọ̀ọ́ ipele kẹwàá àti àwọn tó fẹ́ kọ WAEC pẹ̀lú ìgbàgbọ́ pé Covid-19 ò ní pẹ́ kásẹ̀ nílẹ̀.
Ṣùgbọ́n bi ǹkan ṣe ń lọ báyìí à ń wo bí yóò ṣe kan àwọn kíláàsì to ku, èyí sì ni à ń ṣètò lọ́wọ́
Àwọn nkan míràn ti a tún n ṣe ni láti máa fún àwọn olùkọ́ wa ní ìmọ̀ nípa bí a ṣe n kọ́ akẹ́kọ̀ọ́ ní orí ayélujára àti láti mú kí àyíká ilé ẹ̀kọ́ ṣeé lò, ti gbogbo àwọn ǹkan wọ̀nyí bá ti délẹ̀ a ó jẹ́ kí ará ilú mọ̀. 
Ẹ̀wẹ̀, Kọmísọ́nà ṣàlàyé pé àwọn ilé ẹ̀kọ́ gíga n se ìdánilẹ́kọ̀ọ́ orí ayélujára nítorí pé ọ̀pọ̀ kò ní pẹ́ bẹ̀rẹ̀ ìdánwò lórí ayélujára pẹ̀lú.
Bákan náà ni Ìpínlẹ̀ Èkó to jẹ́ orírun ààrùn Coronavirus ni Nàìjíríà náà ń ṣe ìdánilẹ́kọ̀ọ́ orí redio àti telefísọ̀n, ṣùgbọ́n wọn ò sọ àsìkò tí ilé ẹ̀kọ́ yóò wọlé.
Coronavirus cure: Àwọn onímọ̀ ìjìnlẹ̀ ṣetán láti dán abẹ́rẹ́ covid-19 tí fásítì Oxford ṣe wò ní Kenya
Ileeṣẹ kan to n ṣe iwadii nipa eto ilera lorilẹede Kenya ti kede pe ohun yoo dan abẹrẹ aarun coronavirus ti fasiti Oxford nilẹ Gẹẹsi ṣe agbekalẹ rẹ wo niluu Kilifi.
Kemri-Wellcome trust sọ pe ohun yoo nilo irinwo oṣiṣẹ eleto ilera ti wọn yoo fi ara jin fun ẹkọ kikọ, eyi wa lara ohun to pe ''Abẹrẹ kan fun gbogbo eeyan.''
Kaakiri gbogbo aye lawọn onimọ ijinlẹ ti n wa abẹrẹ to le wo aarun coronavirus.
Ẹ gbẹ onimọ ijinlẹ oogun oyinbo kan wa ni fasiti Oxford nibi ti wọn ti n ṣagbeyẹwo abẹrẹ kan ti wọn n pe ni ''ChAdOx1 nCoV-19.''
Wọn ti dan abẹrẹ naa wo lara ẹgbẹrun un kan awọn olugbe ilẹ Gẹẹṣi ti wọn yọnda ara wọn fun idanwo abẹrẹ naa.
Nibayii, ileeṣẹ to n ṣewadi nipa eto ilera ni Kenya ti sọ pe awọn eeyan ti wọn fẹ dan abẹrẹ naa wo lara wọn gbọdọ ju ọmọ ọdun mejidinlogun lọ, wọn si gbọdọ jẹ oṣiṣẹ eleto ilera niluu Kilifi.
Ọpọ lo ti tako didan abẹrẹ coronavirus wo nilẹ Adulawọ, ṣugbọn awọn oniṣẹ iwadii naa ti sọ pe awọn yoo gba iyọnda ko to di pe awọn bẹrẹ iṣẹ.
Wọn o ṣe pataki ki orilẹede Kenya kopa ninu idanwo abẹrẹ naa ki wọn le mọ bo ya abẹrẹ naa yoo ṣiṣẹ nilẹ Afirika.
Coronavirus in Nigeria: Ìjọba àpapọ̀ kéde pé káwọn òṣìṣẹ́ ìpele 12 àti 13 padà s'ẹ́nu iṣẹ́
Oríṣun àwòrán, Twitter/Tolu Ogunlesi
Ijọba apapọ ti kede pe ki awọn oṣiṣẹ rẹ to wa ni ipele kejila ati ẹkẹtala pada si ẹnu iṣẹ.
Bakan naa ni ijọba kede pe ki gbogbo awọn oniṣẹ ko ṣee mani naa pada si ẹnu wọn.
Olori awọn oṣiṣẹ ni Naijiria, Ọmọwe Folashade Yemi-Esan lo sọrọ naa ninu atẹjade kan to fi sita lọjọ kẹwaa oṣu kẹjọ, ọdun 2020 yii.
Ṣaaju akoko yii, awọn oṣiṣẹ lati ipele kẹrinla soke lo ti pada sei ẹnu iṣẹ, igbesẹ naa wa ni nibamu pẹlu akitiyan ijọba lati dena itankalẹ aarun coronavirus.
Ọjọ mẹta pere lawọn oṣiṣẹ naa ṣi fi n ṣiṣẹ laarin ọsẹ.
Ṣugbọn Yemi-Esan ti sọ pe lati igbayi lọ, awọn oṣiṣẹ yoo maa lọ sibi iṣẹ lati ọjọ Aje si ọjọ Ẹti.
Bakan naa lo ṣalaye pe aago mẹjọ lawọn oṣiṣẹ yoo maa wọṣẹ, nigba ti wọn yoo ṣiwọ laago mẹrin irọlẹ.
Igbimọ PTF to n ri si ari dena ajakalẹ aarun covid-19 lo gba ijọba nbi imọran tẹlẹ jẹki awọn oṣiṣẹ ijọba lati ipele kejila pada sẹnu iṣẹ.
June 21 ni pápákọ̀ òfurufú márùn-ún yóò di ṣíṣí padà - Ìjọba àpapọ̀
Ijoba apapọ ti kede pe, papakọ ofurufu marun-un pere ni oun yoo si lati bẹrẹ iṣẹ pada ni ọjọ kọkanlelogun oṣu kẹfa ọdun 2020.
Awọn papakọ ofurufu maraarun ti yoo bẹrẹ iṣẹ ni ti Murtala Muhammed nilu Eko, Nnamdi Azikiwe tilu Abuja, Malam Aminu Kano tilu Kano, Omagwa tilu Portharcourt ati Sam Mbakwe tilu Owerri.
Atẹjade kan ti oludari agba fun Ileesẹ to n ṣe akoso eto irinna ofurufu nilẹ wa, ọgagun Musa Nuhu fọwọsi tun salaye pe awọn papakọ ofurufu yoku labẹle yoo si wa ni titipa nigba ti awọn baalu ilẹ okeere naa ko ni raye ba sawọn papakọ ofurufu wa.
Nuhu fikun pe, lẹyin ọpọ agbeyẹwo ati aato, diẹ diẹ ni ìjọba yoo si awọn papakọ ofurufu yoku labẹle pada.
Oríṣun àwòrán, others
Bẹẹ ba gbagbe, oṣu kẹta ọdun 2020 ni aarẹ Muhammad Buhari pasẹ pe, ki wọn ti awọn papakọ ofurufu ilẹ wa pa, eyi to wa gẹgẹ bii ara ọna lati dẹkun ọwọja itankalẹ arun Coronavirus ni Naijiria.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ajọ to n mojuto igboke-gbodo ọkọ ofurufu ni Naijiria, NCAA, ti gbe ilana ti awọn arinrinajo gbọdọ maa tẹle ti wọn ba ṣi awọn papakọ ofurufu pada
Ajọ NCAA sọ pe nibi ti nkan de duro bayii, awọn oṣiṣẹ inu baalu gbọdọ maa wọ aṣọ idaabo bo ara lọwọ aarun, lasiko ti wọn ba wa ninu baalu.
Ninu atẹjade kan ti Oludari Agba fun ajọ naa, Captain Musa Nuhu fi ọwọ si, NCAA sọ pe dandan ni fun awọn baalu to ba wọ Naijria lati ilẹ okeere, lati pa gbogbo ilana aabo, idena ati amojuto aarun mọ.
Ọjọ kẹtalelogun, oṣu Kẹta, ni ijọba Naijria da eto irinna oju ofurufu duro fun awọn baalu ilẹ okeere, nitori itankalẹ aarun coronavirus.
Lara oun ti ajọ NCCA tun sọ ni pe oun ko ni fi awọn oṣiṣẹ inu baalu si iyasọtọ , ṣugbọn wọn gbọdọ maa ṣe ayẹwo Covid-19 ni ọjọ mẹrinla-mẹrinla.
Awọn ileeṣẹ baalu si ni yoo san owo ayẹwo naa fun awọn oṣiṣẹ rẹ. Eyikeyi oṣiṣẹ to ba ni i yoo si gba itọju.
Ṣaaju ni agbẹnusọ fun ajọ ṣe akoso awọn papakọ ofurufu ni Naijiria, Henrietta Yakubu sọ fun BBC pe awọn arinrinajo gbọdọ maa de papakọ ọkọ ofurufu o keretan, wakati mẹta ṣaaju asiko ti baalu wọn yoo gbera.
Ajọ naa sọ pe oun n ṣiṣẹ kara-kara lati ṣe eto ti yoo daabo bo awọn arinrinajo, ti papakọ ofurufu ba ṣi pada.
Ajọ FAAN ti kọkọ kede pe hun ti fin oogun apakokoro si awọn papakọ ọkọ ofurufu, ṣaaju ki wọn o to o ṣi wọn pada.
Bakan naa lo sọ pe awọn tun ti bẹrẹ si ni fi ami si ilẹ'lẹ papakọ ọkọ ofurufu, lati ṣaami aaye ti eero kọọkan yoo duro si lori ila.
Nigeria At 61: Ìjà Awolowo, Akintola àti ogun 'Wẹtiẹ', ẹ̀kọ́ wo ló kọ́ wa?
Oríṣun àwòrán, other
Ninu eto isejọba alagbada ni orilẹ ede Naijiria, ọpọ ojo lo ti rọ, ti ilẹ ti fi mu nitori awọn hila-hilo to ti la kọja, bẹrẹ lati ṣaa isejọba alagbada akọkọ, eyi to mu ko dojude.
Awọn ami to fa isubu ijọba alagbada akọkọ, naa la si tun ti n kofiri wọn ninu isejọba alagbada kẹrin taa wa yii, adura wa si ni pe ko ma dojude bii ti akọkọ.
Ni bayii ti orilẹ ede Naijiria wa n sami ọdun kọkanlelọgọta to ti gba ominira, BBC Yoruba ri pe akoko to da ree lati gba ara wa niyanju.
Idi ree ta fi ṣe akojọpọ awọn iṣẹlẹ to bi isejọba alagbada akọkọ wo ati ẹkọ ti awọn oloselu aye ode oni lee ri kọ ninu rẹ, nitori ina eesi ko gbọdọ jo ni lẹẹmeji.
Gẹgẹ ba ṣe kaa loju opo itakun agbaye ati ninu awọn iwe itan miran, ẹkun iwọ oorun guusu Naijiria ni ipilẹsẹ ohun to bi ijọba alagbada akọkọ wo ti wa, ẹkunrẹrẹ ohun to si sẹlẹ ree:
Wẹtiẹ ni orukọ ti wọn n pe idarudapọ to waye ni ẹkun ìwọ oorun ijọun, tii ṣe ẹkun ẹya Yoruba, ninu eyi ti awọn oloselu ati araalu ti doju ija kọ ara wọn.
Oríṣun àwòrán, Other
Itumọ Wetiẹ ni 'da epo pẹtiroolu si lara, ko dana sun', eyi ti araalu ati oloselu n ṣe.
Wọn n sun ile ati dukia ara wọn ni ina, ti wọn si n gbe oku si agbala ile ara wọn, lati fi ṣe akoba fun ara wọn.
Ọdun 1962 si ni awọn ohun to fa rogbodiyan naa bẹrẹ, nigba ti aawọ bẹ silẹ laarin Oloye Obafemi Awolowo ati Samuel Ladoke Akintola.
Awọn mejeeji yii si ni wọn jẹ asaaju ẹgbẹ oselu Action Group, AG, ti wọn tun n pe ni ẹgbẹ oselu Ọlọpẹ.
Ede aiyede ati iwa itajẹsilẹ naa si lo bẹrẹ nigba ti Awolowo, tii ṣe asaaju patapata fun ẹgbẹ oselu Ọlọpẹ kọwe fi ipo silẹ gẹgẹ bii Olootu ijọba ẹkun ìwọ oorun Naijiria, lati lọ du ipo Minisita labẹ ijọba apapọ.
Awolowo fidi rẹmi lati gba ipo Minisita náà, amọ o gba ipo olori ẹgbẹ oselu alatako nile asofin apapọ, ti igbakeji rẹ, Ladoke Akintola si gba ipo Olootu ijọba ẹkun ìwọ oorun.
Amọ Awolowo si ni asaaju ẹgbẹ oselu Ọlọpẹ, ti Akintola ko si faramọ igbesẹ naa, eyi to fa aawọ laarin awọn asaaju mejeeji.
Bẹẹ ni ọpọ awọn iyansipo ti Awolowo ṣe, ni Akintola fagile, ti ko si dun mọ Awolowo ninu.
Ni ọjọ kinni osu Kejì ọdun 1962, wọn wọgile ipo igbakeji asaaju ẹgbẹ nibi ipade apapọ ẹgbẹ Ọlọpẹ to waye nilu Jos, eyi to yẹ aga mọ Akintola ati awọn oloye ẹgbẹ miran nidii.
Lara wọn si ni Oloye Ayo Rosiji to jẹ akọwe ẹgbẹ ati Minisita mẹrin miran.
Wọn dibo a nigbẹkẹle ninu rẹ mọ lati yọ Akintola:Nigba to wa di ọjọ kẹrinlelogun oṣu Karun ọdun 1962, ẹgbẹ oselu Ọlọpẹ yan Dauda Adegbenro bii Olootu ijọba tuntun.
Adegbenro si lọ sile asofin pe, ki wọn dibo 'a ko ni igbẹkẹle ninu rẹ mọ' lati yọ Akintola bii Olootu ijọba lẹkun naa, ti wọn si kede pe, awọn ko ni igbẹkẹle ninu Akintola mọ lootọ.
Oríṣun àwòrán, Other
Awọn alatilẹyin Akintola gbọ nipa igbesẹ yii, wọn ya bo ile asofin naa, eyi lo fa wahala nla níbi ijoko ile asofin lọjọ naa lọhun, tawọn asofin si n yọ ọwọ ẹṣẹ sira wọn niwaju ile.
Nigba to ya, gomina ẹkun iwọ oorun Naijiria nigba naa, tii tun ṣe Ọọni tilu Ile Ifẹ, Ọba Ọlọla Adesoji Aderemi yẹ aga ipo Olootu ẹkun ìwọ oorun mọ Akintola nidii.
O wa fi ontẹ lu iyansipo Alhaji Dauda Adegbenro, lati rọpo Akintola bíi Olootu ìjọba tuntun.
Iṣẹlẹ yii lo da idarudapọ silẹ laarin awọn ọmọlẹyin Awolowo ati Akintola ni ẹkun ìwọ oorun guusu Naijiria, tabi ilẹ Yoruba lapapọ, ti eku ko si ke bii eku mọ, bẹẹ ni ẹyẹ ko ke bii ẹyẹ mọ.
Wọn n da epo pẹtiroolu si ara eeyan, ile, mọto ati dukia miran lorisirisi, lati dana sun wọn, ibi ti ọrọ Wẹtiẹ ti jade ree.
Bakan naa ni wọn si tun n gbe oku si ẹyinkule ile ara wọn lati fi ṣe akoba fun ẹni bẹẹ lọdọ ọlọpaa.
Ẹmi ọpọlọpọ eeyan lo bọ lọjọ aipe sinu rogbodiyan itajẹsilẹ naa, ti ọkẹ aimọye dukia si sofo pẹlu, sinu laasigbo naa laarin ọjọ perete.
Idi si ree tijọba apapọ fi kede pe nkan ko fararọ ni ẹkun ìwọ oorun guusu Naijiria, ni ọjọ kọkandinlọgbọn osu Karun ọdun 1962.
Isẹlẹ naa ti pe ọdun Mọkandinlọgọta bayii, boya ọna lati maa ṣe iranti ọjọ nla yii, ọjọ Manigbagbe naa, ni wọn ṣe n bura fun awọn aarẹ ati gomina ni ayajọ ọjọ naa.Ikede nkan ko fararọ ọhun lo mu ki wọn le ọba Adesoji Aderemi gẹgẹ bii gomina ẹkun ìwọ oorun guusu Naijiria.
Wọn si fi Minisita feto ilera labẹ ijọba apapọ, Dokita Moses Majekodunmi rọpo rẹ bii alakoso fidihẹ tabi Alakoso ijọba afunsọ, fun ẹkun ìwọ oorun guusu Naijiria.
Oríṣun àwòrán, Other
Igba akọkọ si ree ninu itan orilẹ ede Naijiria ti wọn yoo ṣe amulo ikede nkan ko fararọ lati yanju rogbodiyan kan tabi omiran, eyi si jẹ ara ọna lati bomi pana wahala kan nigba to ba suyọ.
Amọ nigba to di ọjọ kọkanlelọgbọn oṣu Kejila ọdun 1962 ọhun, Ahmadu Bello, tii ṣe Olootu ijọba ẹkun ariwa Naijiria, ti ọwọ bọ iwe adehun ajọsepọ pẹlu Akintola.
Akintola pada si ipo Olootu ijọba ẹkun ìwọ oorun guusu Naijiria, nigbati Remi Fani-Kayode si jẹ igbakeji rẹ.
Ajọsepọ to wa laarin ẹkun ariwa ati ìwọ oorun guusu yii ko bímọ re fun Awolowo, lẹyin o rẹyìn ni wọn ran Awolowo lọ si ọgba ẹwọn fun ọdun mẹwa lori ẹsun idaluru.
Eyi si lo fun Akintola ati Igbakeji rẹ, Remi Fani-Kayode lanfaani lati fi ọwọ siwe ajọsepọ pẹlu ẹgbẹ oselu awọn eeyan ẹkun ariwa, Northern People's Congress, NPC .
Eyi tun kan awọn ẹlẹgbẹjẹgbẹ oselu kan yika Naijiria, ti gbogbo wọn si yi orukọ wọn pada di ẹgbẹ oselu Nigerian National Alliance, NNA.
Ọ̀pọ̀lọpọ̀ ìnira lojú àwọn ọ̀dọ́ ilẹ̀ Áfíríkà t''o ń wá ìgbé ayé rere lọ sí Yúróòpù ń rí
Amọ ẹgbẹ oselu NCNC to jẹ ti Nnamdi Azikiwe darapọ mọ ẹgbẹ Ọlọpẹ ti Awolowo n dari tẹlẹ ati awọn ẹgbẹ oselu miran yika Naijiria.
Wọn pa orukọ da di ẹgbẹ United Progressive Grand Alliance, UPGA.
Nigba ti idibo sile asofin apapọ de lọdun 1964, ẹgbẹ oselu NNA, ti Akintola jẹ ara wọn, ko ijokoo mejidinlọgọrun ninu ijokoo okoolelọọdunrun o din mẹjọ to wa nile asofin apapọ naa.
Amọ ọpọ akọsilẹ lo fihan pe, magomago rẹpẹtẹ ati eru ibo waye ninu esi ibo naa.
Nigba ti ẹkun ìwọ oorun guusu si tun seto idibo sile asofin tiẹ ni ọjọ kọkanla oṣu kẹwaa ọdun 1965, ti magomago tun waye, ni gbẹgẹdẹ ba gbina, wahala mii tun suyọ.
Rogbodiyan bẹrẹ tori esi ibo, ọpọ oku sun:
Ni kete ti wọn si kede esi ibo ọhun ni gọngọ tun sọ, eruku wahala miran tun sọ lala, rogbodiyan akọtun miran tun gbode ni ẹkun ìwọ oorun guusu Naijiria.
Ọpọ eeyan ni wọn n pa lojoojumọ, ti aimọye dukia si n sofo danu, ogun Wẹtiẹ miran tun de.
Laasigbo ọtun yii si lo mu ki ologun gba ìjọba lọwọ awọn oloselu alagbada ni ọjọ Kẹẹdogun, oṣu Kinni ọdun 1966, eyi to fopin si eto iselu ijọba alagbada akọkọ.
Lasiko ti awọn ologun naa, eyiti ọgagun Chukwuma Kaduna Nzeogwu ati Emmanuel Ifeajuna lewaju wọn, gba ijọba lọwọ awọn oloselu, wọn sekupa Samuel Ladoke Akintola, tii ṣe Olootu ijọba ẹkun ìwọ oorun guusu Naijiria.
Bakanna ni wọn pa akẹẹgbẹ rẹ ni ẹkun ariwa, Ahmad Bello pẹlu Olootu ijọba Naijiria nigba naa, Ọlọla Tafawa Balewa.
Ọpẹlọpẹ pe Awolowo wa lọgba ẹwọn nigba naa ni ori fi ko yọ, bi bẹẹ kọ, o ṣee ṣe ki ẹmi oun gan bọ sinu iṣẹlẹ naa.
Oríṣun àwòrán, Other
Ni bayii ti ilẹ Naijiria n sami ayajọ ọdun Kẹkanlelọgọta ta gba ominira, ọpọ ẹkọ lo yẹ ka kọ lati ara awọn gbongbo to bi isejọba alagbada kinni wo, eyi ti yoo mu ki ijọba alagbada kẹrin taa wa yii ṣe aseye.
Ohun akọkọ to bi ijọba agbada akọkọ wo ni magomago ati ṣiṣe eru ibo, eyi to tun n fi oju han rẹpẹtẹ lasiko isejọba alagbada kẹrin yii.
Osi yẹ ka takete si nitori itakun kan ṣoṣo ko gbọdọ da wa ni epo nu lẹẹkan si.
Iwa afemi-afemi, ẹmi imọ tara ẹni nikan ati ijagudu fun ipo agbara wa lara ohun to bi isejọba alagbada kinni wo, eyi naa si n fi oju han bayii ninu ijọba alagbada kẹrin.
Osi yẹ ka yago fun, ta ba fẹ ṣe aṣeyọri ninu rẹ.
Bakan naa, iwa ipaniyan, dida ina sun ile ati dukia to fa ìjọba ologun wa, eyi to fopin si isejọba alagbada akọkọ, ko tii kasẹ nilẹ ninu ijọba alagbada kẹrin yii, nitori rogbodiyan, itajẹsilẹ ati isekupani to si n waye.
BBC Yoruba wa n gbadura pe ọba oke yoo fi idi ijọba alagbada kẹrin yii mulẹ, ti yoo si tu wa lara.
Nigeria Police Force: Buhari buwọ́lu ẹkùn iléeṣẹ́ ọlọ́pàá márùn ún tuntun káàkiri Nàìjíríà
Oríṣun àwòrán, Twitter/Nigeria Police Force
Ijọba apapọ ti buwọlu ẹkun ileeṣẹ ọlọpaa marun un tuntun ati tuntun ati ẹka ọtẹlẹmuyẹ meji lorilẹede Naijiria.
Ilu Akure ni ẹkun ti yoo maa ṣamojuto ipinlẹ Ekiti ati Ondo wa, ẹkun to n ṣakoso ipinlẹ Enugu, Anambra ati Ebonyi wa niluu Awka.
Ilu Yenagoa ni ibujoko ẹkun to n mojuto ileeṣẹ ọlọpaa ipinlẹ Bayelsa ati Rivers wa,.
Ẹkun ileeṣẹ ọlọpaa Maiduguri ni yoo maa ṣakoso ipinlẹ Borno ati Katsina, nigba ti olu ileeṣẹ ọlọpaa Kaduna ti ṣi lọ si ilu Katsina bayii.
Labẹ atunto yii bakan naa, ẹka FIB to wa labẹ ẹka FCIID tẹlẹ ti da duro bayii.
Ileeṣẹ ọlọpaa orilẹede ti ni ẹka mẹjọ bayii pẹlu afikun ẹka FIB.
Aaarẹ Muhammadu Buhari to tun jẹ alaga ajọ to n ri si ọrọ ileeṣẹ ọlọpaa tun ti pin ẹka ọtẹlẹmuyẹ FCID ṣii.
Iléeṣẹ́ ọlọ́pàá dóòlà ẹ̀mí ọmọ ogun orí omi tí wọ́n jígbé ní ìpínlẹ̀ Ondo
Ileeṣẹ ọlọpaa ipinlẹ Ondo ti doola ẹmi ọmọ ologun ori omi, Ajare Uchegbulah Amadi, ti wọn ji gbe ni opopona Ago Ajayai, to wa ni Oba Akoko ni ipinlẹ naa.
Agbẹnusọ ileeṣẹ ọlọpaa ipilẹ ọhun, Tee-leo Ikoro lo fidi ọrọ naa mulẹ fun BBC.
"Oríṣun àwòrán, ""PoliceNG/Twitter"
Ikoro ni wọn doola ẹmi ọkunrin naa ni nkan bi ago mẹrin afẹmọju Ọjọru, ọjọ kẹtadinlọgbọn, oṣu karun un ọdun 2020.
O ni lẹyin ti awọn ọlọpaa bẹrẹ si n tọpinpin awọn ajinigbe naa, ti awọn ajinigbe ọhun si ri pe ko si ibi ti wọn le foju pamọ si mọ ni wọn fi ọkunrin naa silẹ ninu igbo kiji kan to wa laarin ipinlẹ Ondo ati Kogi.
Ẹwẹ, kọmiṣọna ọlọpaa ipinlẹ Ondo, Undie Adie, ti wa kilọ fun awọn arinrin ajo lati ṣọra lasiko yii, papa bi ijọba apapọ ṣe gbẹsẹle irinajo lati ipinlẹ kan si omiran.
Ninu atẹjade kan to fi lede fun awọn akọroyin, Adie sọ pe awọn ajinigbe ti n lo asiko yii lati ji ọpọ eeyan gbe lọna ati bere owo gọbọi lọwọ awọn ara ile wọn.
Kọmiṣọna ọhun wa fi da awọn eeyan ipinlẹ naa loju pe ileeṣẹ ọlọpa ko ni dẹkun ati maa foju awọn ọdaran lede.
Lẹyin naa lo rọ awọn eeyan ipinlẹ Ondo lati kan si awọn agbofinro ti wọn ba kofiri afurasi tabi iwa ọdaran kankan lagbegbe wọn ko le rọ awọn ọlọpaa lọrun lati dabo bo wọn.
Èèwọ̀ méje tí kò fi ìdí múlẹ̀ nípa nǹkan oṣù obìnrin nílẹ̀ Yorùbá
Oríṣun àwòrán, others
Jakejado agbaye ni igbagbọ ti wa pe eniyan ara ọtọ ni awọn obinrin, akanṣe iṣẹ Olodumare si ni wọn pẹlu nitori iṣẹda wọn.
Lara ohun to si mu ki awọn obinrin jẹ eniyan ọtọ ni ṣíṣe nnkan oṣu, eyi ti yoo mu ki wọn loyun ati bímọ.
Ṣugbọn bi nnkan oṣu obinrin ti ṣe pataki to fun ibisi ẹda yìí, sibẹ oniruuru awọn igbagbọ ti ko fi idi mulẹ lode oni, ni Yoruba so mọ, eyi ta mu lẹsẹ lẹsẹ wa fun yín.
Igbagbọ meje nipa nnkan oṣu obinrin ti ko fi idi mulẹ
Nnkan oṣu n ba oogun ibilẹ jẹ:
Igbagbọ Yoruba ni pe obìnrin to ba n ṣe nnkan oṣu ko mọ rara, ohun ẹgbin si ni. Irufẹ obinrin bẹẹ si ni wọn kii jẹ ko fi ọwọ tabi ara kan oogun ibilẹ nitori igbagbọ pe oogun naa yoo bajẹ ni.
Koda, obinrin to ba n ṣe nnkan oṣu ni wọn kii gba ko jokoo ti ẹni to ni oogun ibilẹ lara nitori igbagbọ pe, oogun naa yoo bajẹ.
Bẹẹ ni irufẹ obinrin bẹẹ ko gbọdọ ja ewe ati egbo tabi fi ọwọ kan wọn, titi ti nnkan oṣu rẹ yoo fi pari.
Ṣugbọn ko si imọ sayẹnsi ati ẹri to daju lati fi idi igbagbọ yii mulẹ.
Oríṣun àwòrán, others
Nnkan oṣu obinrin wulo fun oogun owo:
Igbagbọ kejì ti ko tun fi idi mulẹ nipa nnkan oṣu obinrin ni pe aṣọ, òwú , pata, páàdì abi ohunkohun ti obinrin ba fi ṣe nnkan oṣu lee wulo fun oogun owo lọdọ awọn adahunse tabi onisegun ibilẹ.
Idi si ree ti ọpọ obinrin kii ṣe jafara pẹlu awọn eroja ti wọn fi n ṣe nnkan osu wọn, bi o tilẹ jẹ pe eyi lee ni nnkan ṣe pẹlu iwa imototo.
Bẹẹ si ni ko si iṣẹ iwadii abi arigbamu ẹri kankan to fi idi rẹ mulẹ pe eroja nnkan osu obinrin lee wulo fun oogun owo.
Obinrin to n ṣe nnkan oṣu ko le jọsin fun Ọlọrun:
Igbagbọ kẹta ti ko fi idi mulẹ nipa nnkan oṣu obinrin ni pe obinrin ko ba n ṣe nnkan oṣu ko le jọsin niwaju Oluwa, ko jẹ itẹwọgba.
Bi o tilẹ jẹ pe ẹsẹ Bibeli ni majẹmu laelae ati Kurani tọkasi eyi, ti awọn Kristẹni alaṣọ funfun  atawọn Musulumi si n tẹle, ti awọn ẹlẹṣin abalaye naa si fara mọ igbagbọ yii, sibẹ awọn ọlaju ati imọ sayẹnsi kan tako igbagbọ naa pe ko tọna, ti ọpọ obìnrin miran si maa n jọsin lasiko ti wọn n ṣe nnkan oṣu lọwọ.
Ọkunrin to ba ni ibalopọ pẹlu obinrin to n ṣe nnkan oṣu yoo ku:
Igbagbọ kẹrin nipa nnkan oṣu obinrin ti ko fi idi mulẹ ni pe, ọkunrin to ba ni ibalopọ pẹlu obinrin to n ṣe nnkan oṣu lọwọ yoo ku.
Eyi si maa n mu ki ọpọ ọkọ ninu ile yẹra fun iyawo rẹ to ba n ṣe nnkan osu, yatọ si ero ti wọn tun ni pe iru obinrin bẹẹ ko mọ.
Amọ iwadii imọ ijinlẹ lode oni ti tako igbagbọ naa, to si ni ko si ewu kankan ninu ki obìnrin ni ibalopọ pẹlu ọkunrin lasiko to ba n ṣe eela lọwọ, o kan nilo ko wẹ mọ tonitoni ko to wọle tọ ọkunrin ni.
Obinrin maa n ni arun ọpọlọ diẹ diẹ lasiko nnkan oṣu
Igbagbọ karun nipa nnkan oṣu obinrin ti ko fidi mulẹ ni pe, awọn obinrin to n ṣe nnkan oṣu maa n ṣe gan gan gan fun isẹju diẹ lasiko nnkan oṣu wọn.
"Idi si ree ti awọn ọkunrin fi maa n ba obinrin sere pe ""ṣe nnkan oṣu rẹ tun ti de si ọ ni?"""
Ṣugbọn ko si iwadii imọ ijinlẹ kankan to fara mọ ero yii, iwa abuku si ni wọn lo jẹ fawọn obìnrin.
Coronavirus survivor: Àntí Korona ni wọ́n n pè mí l'ádùúgbò láti ìgbà tí mo ti ní Covid-19
Awọn ounjẹ kan wa ti obìnrin ko le ṣe lasiko nnkan oṣu rẹ
Igbagbọ kẹfa nipa nnkan oṣu obinrin ti ko tun fi idi mulẹ ni pe awọn oriṣi ounjẹ kan wa ti ko ni jinna laelae, ti obinrin to n ṣe nnkan oṣu lọwọ ba se e.
Apẹẹrẹ iru ounjẹ bẹẹ ni mọinmọin tabi ọlẹ, ti igbagbọ wa pe yoo pẹ ko to jinna tabi ko ma jinna laelae ti obinrin to n ṣe nnkan oṣu ba se e.
Amọ ko si iwadii imọ sayẹnsi tabi ẹri to daju, to fi igbagbọ yii mulẹ.
Ọ̀pọ̀lọpọ̀ ìnira lojú àwọn ọ̀dọ́ ilẹ̀ Áfíríkà t''o ń wá ìgbé ayé rere lọ sí Yúróòpù ń rí
Obinrin le loyun to ba ni ibalopọ lasiko to n ṣe nnkan oṣu
Igbagbọ keje nipa nnkan oṣu obinrin ti ko fi idi mulẹ ni pe obinrin to ba ni ibalopọ lasiko to n ṣe nnkan oṣu le loyun.
Igbagbọ yii si ni awọn onimọ ijinlẹ sayẹnsi tako pe ko lee rí bẹẹ laelae.
Coronavirus: Kí ní wọ́n ń pè ní “Herd Immunity?”
Amotekun kò le ṣe èso rere nílẹ̀ Yorùbá àyàfi ni Èkó nìkan - Alao Akala
Oríṣun àwòrán, @NofNews_Nigeria
Gomina tẹlẹ ni ipinlẹ Oyo, Ọtunba Adebayo Alao Akala ti woye pe yoo nira fun ikọ alaabo Amotekun lati ṣe aseyọri ni awọn ipinlẹ to wa nilẹ Yoruba.
Alao Akala, ẹni to sisọ loju ọrọ yii lasiko to n ba awọn akọroyin sọrọ tun fikun pe ipinlẹ Eko ni Amotekun ti lee ṣe aseyọri to yẹ.
Akala ni ko boju mu rara bi awọn gomina yoku nilẹ kaaro oojiire ṣe fi awọn ajagunfẹyinti ṣe olori ikọ alaabo Amotekun ni Ipinlẹ koowa wọn.
Gomina tẹlẹ naa, to fẹyinti bii igbakeji kọmisana lẹnu iṣẹ ọlọpaa tun ni, Ipinlẹ Eko nikan to fi ọga ọlọpaa to ti fẹyin ti nikan lo ṣee ṣe ki ikọ alaabo rẹ yege.
Alao Akala, to n palẹ mọ fun ayẹyẹ aadọrin ọdun rẹ loke eepẹ salaye pe awọn osisẹ ọlọpaa nikan lo le mu ki ikọ alaabo naa yege.
Oríṣun àwòrán, Facebook/Amotekun
Ojuse awọn ọlọpaa ni lati pese eto aabo laarin ilu, ojuse awọn ọmọ ologun ni lati ja ogun, ti ologun si maa n ri ara rẹ bii ọga fun ọlọpaa, bi wọn ba wa fi ologun ṣe olori ikọ Amotekun nipinlẹ kan, wọn ko yan ẹni to tọ lati dari ikọ alaabo bẹẹ.
Ajagunfẹyinti to ba n dari ikọ alaabo nipinlẹ kan, ko ni fẹ tẹriba labẹ kọmisana ọlọpaa to wa nipinlẹ bẹẹ, ti yoo si maa lo iwa ipa, bawo wa ni alaafia yoo ṣe wá, ọlọpaa nikan si tun lo le ba ọdaran ṣe ẹjọ.
May 29: Akala, Aleshinloye sọ̀rọ̀ lórí ọdún kan Seyi Makinde gẹ́gẹ́bíi gómìnà ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́
Ni oni, ọjọ kọkandinlọgbọn oṣu karun un, ọdun 2019 ni wọn bura fun Seyi  Makinde gẹgẹ bi gomina ipinlẹ Ọyọ lẹyin to bori ninu ibo ọdun naa.
Ọdun kan lẹyin eyi, BBC News Yoruba gbe ọrọ tọ awọn eekan oloṣelu ni ipinlẹ naa lọ lati mọ ero wọn lori ijafafa iṣẹ iṣejọba ni ipinlẹ Ọyọ.
Abọ ree.
Coronavirus and Kayeefi: Òtítọ́ àti irọ́ wo ló wà nípa oògun owó àtàwọn ìṣẹ̀lẹ̀ kàyééfì míràn
Ibi gbogbo la n dana alẹ ọbẹ kan n gbe ibi kan dun ju ibi kan lọ ni.
eyi lo tun difa fun akanṣe akojọpọ iroyin Kayeefi BBC News Yoruba tọtẹ yii eyi to kaakiri lati ilu Ibadan de ipinlẹ̀ Cross river, Iwo ni ipinlẹ Ọṣun.
Ẹ gba a kẹ tọọ wo, oyin mọmọ!
Yoruba movies: Portable ní Dec 2018 ni ọ̀rẹ́ gba owó ọkọ̀ lọ́wọ́ òun láì ri mọ́
Oríṣun àwòrán, mrportableharejan/ instagram
Yoruba ni ṣun mọ ni laa mọ ìṣe ẹni, eeyan gbe okeere niyi, inu si jin, o ju ọrun lọ.
Awọn owe yii lo n salaye iru ipo ti gbajumọ oṣere tiata kan, Olu Olowogemo, ti ọpọ eeyan mọ si Portable wa lonii tii ṣe ayajọ ọjọ ibi rẹ.
Nigba to n dupẹ lọwọ Ọlọrun pe o da ẹmi rẹ si lati ri ọdun tuntun loke eepẹ, Portable tun wa n salaye tẹdun tẹdun ọkan nipa awọn ipenija ko n koju rẹ.
Nigba to n salaye yii ni oju opo Instagram rẹ, mrportableharenjan, portable ni o dun oun pe oun ko ni ọkọ nidi, lonii ọjọ ibi oun, ti oun si n fi ẹsẹ rin kiri.
Iji orisirisi lo ja mi, amọ mo sọpẹ. Lara iji naa si ni pe nipari ọdun 2018, ọrẹ mi kan to wa nilu oyinbo pe mi, o ni ki n ta ọkọ kan ṣoṣo to wa nidii mi, ki n si ko owo ransẹ, ki oun ba mi fi owo kun, lati ra mọ́tò tuntun.
O ni maa gba ọkọ naa ni oṣu kinni ọdun 2019, sugbọn lati igba naa, n ko gburo owo pẹlu mọto tuntun, mo ni orukọ, mo gbajumọ sugbọn ẹsẹ ni mo n rin kaakiri, mo tun n gun ọkada kiri.
Oríṣun àwòrán, Portable
Portable ni ti oun ba fẹ lọ ṣíṣe ni ibi kan, oun maa n lọ wọ ọkọ ni gareeji ni, iriri ti oun si n ri nibẹ, ko dara rara,oun si mọ pe inu Ọlọrun ko le dun si ọrẹ oun.
"Nigba to n salaye lori igbesẹ to fẹ gbe lori iṣẹlẹ yii, Portable ni ""Ọjọ ibi mi ọdun yii tun ko lai jẹ ki n ri ọkọ lo, mo wa fun ni ọjọ perete, ti ko to ọjọ mẹwa lati da owo naa pada gẹgẹ bo ti ṣe ileri."""
Bi ko ba wa da owo naa pada, maa fi fọto rẹ sita, pẹlu orukọ rẹ, ibi ti wọn ti bii, orúkọ Baba rẹ ati ibi to n gbe nilu oyinbo, nọmba foonu rẹ, oju opo Facebook rẹ, gbogbo rẹ ni mo fẹ pariwo fun araye.
Portable ni oun yoo jẹ ki gbogbo ololufẹ oun kaakiri agbaye mọ, ki wọn gbeja oun, ti ọrẹ oun naa ko si ni ri ibi rin si, eyi ti yoo jẹ ko mọ pe nnkan ju nnkan lọ.
Portable wa n rọ awọn ololufẹ rẹ jakejado agbaye lati ran oun lọwọ, gba ẹtọ oun fun oun, ni kete ti oun ba pariwo ọrẹ oun naa sita.
Ẹ pèsè 'pad' ọ̀fẹ́ fáwọn obìnrin láti ṣe nǹkan oṣù dípò 'condom' ọ̀fẹ́ - Dókítà
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Onimọ kan nipa isegun oyinbo, Dokita Olufisayo Ogunbayo ti sísọ loju rẹ pe, kii ṣe oju ara nikan ni awọn obinrin ti maa n ṣe nnkan oṣu, amọ awọn obìnrin miran n ṣe e lati imu abi idodo eyi ti ko wọpọ.
Dokita Ogunbayo kede bẹẹ lasiko to n kopa lori eto kan ni ikanni BBC Yoruba eyi to n sami ayajọ imọtoto nnkan oṣu lagbaaye.
Ogunbayo, ẹni to salaye pe lasiko ti obinrin ba n ṣe nnkan oṣu, o ṣee ṣe ko maa kanra, ki ẹjẹ maa ya ni ara rẹ, ki inu si maa run, wa rọ awọn ọkunrin to wa lẹgbẹ wọn lati ni ifarada pẹlu wọn.
Onisegun oyinbo naa tun rọ awọn obinrin lati ni imọtoto lasiko nnkan oṣu, ki wọn si yago fun titi ọwọ bọ oju ara wọn loore koore, ki arun ma baa wọ ibẹ.
Ogunbayo tun gba awọn obinrin nimọran lati maa paarọ iledi wọn ni igba meji ni ọjọ kan, to si tun rọ ijọba lati pese paadi ni ọfẹ fawọn obinrin.
"Ọranyan ni nnkan oṣu ṣíṣe fawọn obìnrin, o si yẹ ki ijọba ṣe ipese paadi ọfẹ fun wọn gẹgẹ bi wọn ṣe n pin rọba idaabobo ta mọ si condom fawọn ọkunrin.
Gbogbo awọn obinrin to kopa lori eto naa si lo kin dokita Ogunbayo lẹyin pẹlu afikun pe ọpọ mẹkunnu ni ko ri owo ra paadi fun nnkan oṣu wọn, ti wọn si n lo awọn eroja ti ko ni imọtoto."
Adeleke: Iléẹjọ́ dá Sẹ́nétọ̀ Adeleke sílẹ̀ lórí ẹ̀sùn màgòmágó ìdánwò tí wọn fi kàn án
Oríṣun àwòrán, Facebook/SEN Ademola Adeleke
Ile ẹjọ giga ijọba apapọ niluu Abuja ti dajọ pe oludije gomina fẹgbẹ oṣelu PDP nipinlẹ Oṣun, Ademola Adeleke ko jẹbi ẹsun magomago lasiko idanwo ti wọn kan an.
Adajọ Inyang Ekwo to dajọ ọhun lọjọ Ẹti lo paṣẹ wi pe ki Sẹnetọ Adeleke maa lọ lalaafia.
Simon Lough tii ṣe agbẹjọro awọn olupẹjọ sọ fun adajọ Ekwo l'Ọjọbọ pe awọn olupẹjọ fẹ ki ẹjọ naa wa sopin nitori bi Adeleke ko ṣe maa yọju nigba kugba ti igbẹjọ ba n lọ lọwọ.
Adeleke ko tii yọju sile ẹjọ lati ọjọ kẹfa oṣu karun un ti ileẹjọ ti fun un laye lati rinrin ajo lọ si orilẹede Amẹrika fun itọju ara rẹ.
Ọga ileewe girama Ojo-Aro ti Adeleke ti ṣedanwo, Sikiru Adeleke, Alhaji Aregbesola Muftau to jẹ akọwe ileewe naa ati olukọ kan nibẹ Dare Samuel Olutope, gbogbo wọn lọ nileẹjọ pe awọn o jẹbi ẹsun ti wọn fi kan awọn.
Agbẹjọro Adeleke. Alex Izinyon (SAN), naa ko tako aba lati wọgile ẹjọ ti wọn pe onibara rẹ.
Ohun ti agbẹjọro agba naa sọ fun adajọ ni pe ko paṣẹ idasilẹ oludije ibo gomina Oṣun, Ademola Adeleke.
Wọ́n nílò ìrànlọ́wọ́ mi láti ṣèmọ́tótó ibi tí wọ́n ti ń tọ́jú àwọn tó ní Coronavirus
Damoah Asare n ṣiṣẹ gẹgẹ bi agbalẹ nile iwosan kan ni London.
O si n ṣiṣẹ ni ẹka ibi ti wọn ti n tọju awọn to ni arun Coronavirus ni ile iwosan Royal Free to wa ni Whitechapel.
Nigba ti o kọkọ bẹrẹ iṣẹ ni ẹka naa, ẹru ma n baa pe o ṣeeṣe ki oun naa lugbadi arun Coronavirus.
Ṣugbọn ni bayii, o ti ṣetan lati maa ba iṣẹ rẹ lọ ati lati koju arun ọrun.
Seyi Makinde: Ọdún 2023 ni màá jíyìn iṣẹ́ ìríjú mi ní ẹ̀kúnrẹ́rẹ́
May 29: Akala, Aleshinloye sọ̀rọ̀ lórí ọdún kan Seyi Makinde gẹ́gẹ́bíi gómìnà
Arise ni arika, arika si ni baba iregun, eyi lo mu ki gomina ipinlẹ Oyo, Onimọ ẹrọ Seyi Makinde fi ṣe alaye aseyọri rẹ ni aarin ọdun kan.
Makinde, nigba to n kopa lori akanse eto to n sami ọdun kan ijọba rẹ lori aleefa, ni ijọba oun ti pari apapọ iṣẹ akanṣe ojilenigba o din ẹyọ kan tijọba ana fi silẹ ni ẹka eto ẹkọ.
Oríṣun àwòrán, Seyi Makinde
Bakan naa lo fikun pe, ijọba oun tun ti da ọwọ le akanṣe iṣẹ miran ni ẹka naa to to mejidinlaadọrin pẹlu afikun pe oun lo ajakalẹ arun Coronavirus lati ṣe agbega ẹka eto ilera nipinlẹ Oyo ni.
Oríṣun àwòrán, Seyi Makinde
O ti pe ọdun kan ti mo gba akoso ipinlẹ Oyo, asiko ka sere yatọ, asiko ijiyin iṣẹ iriju ẹni si yatọ pẹlu, ọdun 2023 si ni maa jiyin iṣẹ iriju mi ni ẹkunrẹrẹ, sugbọn ko to di igba naa, o yẹ ka mọ ibi ti a ti n bọ, ka lee mọ baa ṣe ṣe aseyọri si.
Oríṣun àwòrán, Twitter
Mo ti mu ileri mi ṣẹ lati pari gbogbo iṣẹ asepati ti ijọba to kọja lọ ti ṣe lati ọdun 2011, ti n ko si fi imọ tara ẹni nikan bẹrẹ iṣẹ tuntun miran, ninu ọdun yii nìkan, iṣẹ ojilenigba o din mẹrin la dawọ le.
Oríṣun àwòrán, Seyi Makinde
"Makinde tun salaye pe, ayipada rere ti n ba owo ti ijọba Oyo n pa wọle labẹle, o si ti di irọrun lati gba iwe aṣẹ emi ni mo nilẹ bayii, toun si tun ṣe atunṣe awọn oju popo to ti bajẹ."""
Oríṣun àwòrán, Seyi Makinde
Gomina Makinde ni oun mọ riri atilẹyin ati igbẹkẹle awọn eeyan ipinlẹ Oyo ninu oun, oun si seleri lati ma ṣe ja wọn kulẹ.
Ogun Suicide: Ọlọ́pàá ní iwádìí ṣì ń lọ lórí bóyá ìyàwó ló sokùnfà bí ọkọ rẹ̀ ṣe pokùnso
Baale ile kan ni agbegbe Sango Ota ni ipinlẹ Ogun ti pokunso lẹyin ti oun ati iyawo rẹ tahun si ara wọn, to si wọle lọ.
Ọmọ Oloogbe naa ni oun mura lati lọ gba owo ounjẹ lọwọ Baba oun ni oun ba wọn ni ibi ti wọn pokunso si.
Ọmọ naa ni ọpọlọpọ igba ni baba oun ati iya oun ti maa n ja ati wi pe isẹlẹ naa waye ni ọjọ keji ti wọn de lati agọ ọlọpaa ni ibi ti wọn ti lọ pari ija fun wọn.
Bakan naa ni awọn ará àdúgbò sọ ohun tí wọ́n mọ̀ nípa baalé ilé tó pokùnso nítorí ìjà pẹ̀lú olúlùfẹ́ rẹ̀ naa.
Amọ, Agbẹnusọ fun ọlọpaa ni ipinlẹ Ogun, Abimbola Oyeyemi to fi idi ọrọ naa mulẹ  ni iwadii si n lọ lọwọ lori pe boya iyawo rẹ lo pa a abi kii ṣe oun.
Osun state lockdown update: Ìpínlẹ̀ Osun ṣòfin ẹ̀wọ̀n gbére fún ẹnikẹ́ni tó bá jẹ̀bi ẹ̀sùn ìfipábánilòpọ̀
Oríṣun àwòrán, BBC/others
Ẹwọn gbere ni fun ẹnikẹni to ba ti jẹbi ẹsun ifipabanilopọ bayii  ni ipinlẹ Ọṣun.
Eyi ni atunbọtan  abadofin ti awọn aṣofin ipinlẹ Ọṣun fi ẹnu rẹ jona eyi tiolori ile naa, aṣofin Timothy Owoẹyẹ ṣalaye pe yoo mu adinku ba ọwọja iwa ifipabanilopọ to n fojojumọ gogo sii ni lorilẹede Naijiria bayii.
Ofin yii n waye lẹyin ọkan-o-jọkan iṣẹlẹ awọn omidan ti awọn eeyan kan n ṣekupa lẹyin ti wọn ba ti fipa ba wọn lo pọ tan.
Bakan naa lawọn aṣofin naa tun fi sinu ofin naa pe ẹnikẹni to ba gbimsran rẹ ṣugbọn ti ko ṣaṣeyọri lori rẹ yoo lọ lo ọdun mẹrinla roko ọba.
Asofin Owoẹyẹ rọ awọn ọdọ lati jinna si iwa ọdaran naa tabi iwa ipa yoowu si awọn obinrin.
Justice for Uwa: Ọwọ́ ọlọpàá tí tẹ ọ̀kan nínú àwọn ọ̀daràn tó ṣekú pa Uwaila
Ọwọ́ ọlọpàá tí tẹ ọ̀kan nínú àwọn ọ̀daràn tó ṣekú pa Uwaila
Ọwọ́ sìnkún ọlọ́pàá ti tẹ ọ̀kan nínú àwọn tó pa Uwaila Vera Omozuwa akẹ́kọ̀ọ́ ilé ẹ̀kọ́ Uniben tí wọ́n fipá bálòpọ̀ nínú ṣọ́ọ̀ṣì tí wọ́n sì tún paá síbẹ̀.
Alága àjọ tó n rísí àwọn ọmọ Nàìjíríà lókè òkun Abike Dabiri-Erewa ló fìdí ọ̀rọ̀ náà múlẹ̀ lórí àtẹ̀jíṣẹ́ twitter rẹ̀ @abikedabiri
Ẹ̀wẹ̀ ọ̀pọ̀ àwọn ọmọ Nàìjíríà ló ti ń fèrò wọ́n hàn lórí ìgbẹ́sẹ̀ ilé iṣẹ́ ọlọ́pàáb ní àsìkò yìí
Mo sunkún nígbà tí mo rí ẹ̀jẹ̀ nílẹ̀ ní sọ́ọ̀ṣì tí wọ́n pa ọ̀mọ mi sí- Bàbá Uwa, akẹ́kọ̀ọ́ fásitì tí wọ́n fipábálòpọ̀
Justice for Uwa: Bàbá Uwa, akẹ́kọ̀ọ́ fásitì tí wọ́n fipábálòpọ̀ ní Benin bá BBC sọ̀rọ̀ lórí bí wọ́n ṣe pa mọ rẹ̀
Justice for Uwa: Bàbá Uwa, akẹ́kọ̀ọ́ fásitì tí wọ́n fipábálòpọ̀ ní Benin bá BBC sọ̀rọ̀
Baba arabinrin akẹkọọ ti awọn eeyan kan fipabalop ti wn si tun ṣekupa ni ilu Benin ti ṣalaye fun BBC News pe ibanuj ti ko lẹlgbẹ ni o ba oun pẹlu iku mbinrin naa.
o ṣalaye pe lootọ mọ marun ni oun bi, ṣugbọn Uwa da yatọ laarin gbogbo wọn.
Ọga Agba Ọlọpaa lorilẹede Niajiria, Mohammaed Adamu ti seleri wi pe awọn yoo se awari awọn to sekupa arabinrin Vera Omosuwa ni ipinlẹ Edo.
Adamu ni oun ti fikun awọn ọlọpaa to n sewadii iṣẹlẹ naa lati ri wi pe wọn tete mu awọn to wu iwa ika naa ni kiakia.
Oga ọlọpaa na to bu ẹnu atẹ lu iṣẹlẹ naa, wa ba awọn ẹbi ati ara obinrin naa kẹdun pẹlu ileri pe awọn aṣeka naa ko ni lọ lai jẹya.
Amọ, ileeṣẹ ọlọpaa ni ipinlẹ Edo ti fi panpẹ ọba mu awọn afurasi lori iṣẹlẹ naa.
Ni opin ọsẹ ni iroyin gbe e gbe awọn okunrin mẹrin kan fi ipa ba ọmọbinrin lọpọ ni ibi to ti n kawe ni ile ijọsin, ti wọn si ṣekupa a.
Ọpọlọpọ eniyan lo ti pe fun iwadii finfini lori iṣẹlẹ naa, lẹyin to da awuyewuye silẹ lori ẹrọ ayelujara.
Àwọn ọdọ́ tó wọ́de ìfẹ̀hónúhàn nítori ìwà ìfipá báni lòpọ̀ tí hù sí Uwa, tí wọ́n sì tún gba
ẹmi ọdọ́mọbinrin náà kìí ṣe ìgbà àkọ́kọ́ rèé ní ìpínlẹ̀ Edo.
JusticeforUwa:Awọn àkẹkọ̀ọ́ Uniben wọ́de ìfẹ̀hónú hàn nítórí Uwa tí wọ́n fipa bálòpọ̀
Wọ́n ní ìwà yìí pẹ̀lú kò mọ́ àsọ tí ènìyàn wọ tàbí ọjọ orí oní tọ̀hún.
Ọ kan nínú àwọn olùfẹ̀hónú hàn náà ati ẹgbọ́n ọmọ tí ìṣẹ̀lẹ̀ yìí sẹlẹ̀ sí sàlàyé pé oríṣiríṣi irú ìṣẹ̀lẹ̀ yii ló ti n wáyé látẹyinwá to fi mọ ìyá àgbàlagbà tọ n lọ si ilé rẹ̀ jẹjẹ ti wọ́n sì fi ipá bálòpọ̀ láàrín ọ̀nà
Oríṣun àwòrán, PAstor adeboye/ facebook
Pasitọ agba fun ijọ Redeemed lagbaye, Enoch Adeboye ti ṣeleri ati rii daju pe awọn leṣebi-leṣeka ẹda to ṣekupa akẹkọọ ipele kinni ni fasiti Benin, Uwaila Omozuwa lẹyin ti wọn fipa baalopọ ko sa mọ ofin lọwọ.
Ninu ijọ RCCG miracle Mega Parish ni ilu Benin city lawọn eeyan kan ti lọ fi ipa ba omidan naa lo pọ ni Ọjọru to kọja ki wọn to la agolo panapana, fire extinguisher mọọ lori to si ku; lati igbayi wa si lawọn ọmọ orilẹede Naijiria ti n ke ibosi lori rẹ.
Ninu atẹjade kan eyi to fi sita lọju opo Facebook rẹ, Pasitọ Adeboye ṣalaye pe oun yoo forikori pẹlawọn ajọ agbofinro gbogbo lati rii pe panpẹ ofin tete mu awọn to ṣiṣẹ ibi naa ati pe o digba ti idajọ ododo ba waye lori ọrọ naa ki oun to si lẹyin rẹ.
Bakan naa ni iranṣẹ Ọlọrun naa tun ranṣẹ ibanikẹdun sawọn ẹbi pẹlu adura pe ki Ọlọrun tu wọn ninu.
Bakan naa ni ajs ajafẹts lagbaye, Amnesty Internation pẹlu ti bu ẹnu atẹ lu iṣẹlẹ naa.
Ninu atẹjade kan to fi sita loju opo twitter rẹ,Amnesty International ni ibanujẹ nla lo jẹ pe irufẹ iṣẹlẹ tun lee maa waye ni kopẹkopẹ si asiko ti ọwọ awọn ọlọpaa ṣẹ tẹ awọn ọkunrin mọkanla kan fun fifi ipa ba ọmọ ọdun mejila kan lajọṣepọ ni Limawa ni ilu Dutse ni ipinlẹ Jigawa.
Oríṣun àwòrán, Pastor e.a. adeboye/facebook
Ajọ naa ni bi iwa ifipabanilops ṣe n fojojumọ pọ si lorilẹede Naijiria ko ṣẹyin ijakulẹ awọn agbofinro atipe ọpọ awọn ti wọn hu iwa ifipanilopọ ni wọn maa n bọ ms ofin lọwọ lẹyin o rẹyin.
'Lootọ iwa ọdaran to gogo ni ifipabanilopọ lorilẹede Naijiria, ṣugbọn ọwọ ti ijọba fi n mu u ko wuni lori rara'
Oríṣun àwòrán, Twitter
Ọjọru, ọjọ kẹtadinlọgbọn, oṣu Karùn-ún, ọdun 2020 ni àwọn kan fipá bá ọmọbìnrin ẹni ọdún 22 lopọ̀ nínú sọ́ọ́sì.
Ni owurọ ọjọ Satide ni awuyewuye bẹrẹ lori ayelujara nitori iku to pa ọmọbìnrin, ẹni ọdun mejilelogun kan nipinlẹ Edo.
Iroyin sọ pe ọmọbìnrin náà, Uwaila Omozuwa, ni awọn kan fi ipa balopọ, ti wọn si tun fi agolo afẹ́fẹ́ ti wọn fi n pa ina, 'fire extinguisher' fọ ọ lori, ninu ile ijọsin Redeemed Christian Church of God kan to wa ni adugbo Ikpoba Hill nilu Benin.
Ọmọbinrin naa la gbọ pe ọdun yii ni wọn gba a wọle si Fasiti ilu Benin, lati kẹ́kọ̀ọ́ nipa imọ nípa kokoro aifojuri, Micro Biology.
Ogun: Ọlọ́pàá ní iwádìí ṣì ń lórí bóyá ìyàwó ló sokùnfà bí ọkọ rẹ̀ ṣe pokùnso
Ọjọru, ọjọ kẹtadinlọgbọn, oṣu Karùn-ún, ọdun 2020 ni iṣẹlẹ naa waye, sugbọn ọmọbìnrin Uwa pada ku si ile iwosan to ti n gba itọju lẹyin ọjọ mẹta.
Ẹ̀gbọ́n ọmọbìnrin to ba BBC sọrọ, sọ pe lati bi ọdun meji lo ti maa n lọ ka iwe ninu sọọsi náà. Koda, ko to o di pe wọn gba a wọle si Fasiti ilu Benin.
Oríṣun àwòrán, Twitter
"Bi aago mọkanla si mejila lo maa n lọ, o si maa n pada sile bi aago marun irọlẹ.
Lọjọ ti wọn pa a, oun ati iya wa lo jọ jade nile, ki o to o ya si sọọsi.
Awọn ara sọọsi wa kan ni kọ́kọ́rọ́ maa n wa lọwọ wọn. Ọwọ wọn lo si ti maa n gba kọkọrọ lati si ilẹkun sọọsi, ti yoo si tun da pada to ba kàwé tán.
A n ti n reti rẹ ko pada sile lọjọ naa nitori pe o ti n to bi aago mẹfa irọlẹ. Ibi ti a ti gbiyanju lati pe fóònù rẹ ni awọn ara sọọsi ti pe wa lati wa a wo, nitori awọn o mọ nkan ti wọn ṣe fun.
Ẹ̀gbọ́n ọmọbinrin naa sọ pe, wọn ti gbe e lọ sileewosan ki awọn to de sọọsi.’'
Wọn sọ fun wa pe ninu àgbàrá ẹ̀jẹ̀ ni wọn ti ba aburo mi, ti wọn ti ya pátá rẹ, sikẹẹti rẹ naa wa ni kika soke, ẹwu rẹ si ti kun fun ẹ̀jẹ̀."
Ọkùnrin to máa ń sọ sọọsi wa ni alẹ si owurọ lo de si ibi'ṣẹ ni irọlẹ, to si lọ si ọdọ awọn to maa n tọju kọ́kọ́rọ́.
Wọn sọ fun pé Uwa ko ti i da pada, pe ko lọ wo boya o si n kawe lọwọ tabi o ti mu kọkọrọ lọ sile.
Igba ti ọkunrin naa wọle sinu sọọsi lo ba aburo mi ninu agbara ẹjẹ, ki wọn o to sare gbe lọ sileewosan aladani, sugbọn ileewosan ikọsẹ isegun Fasiti ilu Benin lo pada ku si.
Oríṣun àwòrán, Twitter
" Wúńdíá ni aburo mi lẹni ọdun mejilelogun, ko ni ibalopọ rí.
 Ibanujẹ ni nkan to ṣẹlẹ jẹ fun ẹbi wa, nkan ti a si fẹ ni pe ki awọn to ṣe nkan yii ko má lọ lai jiya."""
Sugbọn, o fi ẹsun kan awọn ọlọpaa pe 'wọn ko bẹrẹ iwadii ni kiakia nitori pe wọn ni baba oun ko fun wọn ni owo lati wu wọn lori'.
Nigba ti BBC kan si alukoro ileesẹ ọlọpaa nipinlẹ Edo, o sọ pe ori ayelujara ni oun naa ti ka nipa iṣẹlẹ naa ni owurọ òní. Eyi lo si mu ki oun pe alamojuto ileesẹ ọlọpaa ni adugbo Ikpoba Hill ti iṣẹlẹ naa ti waye.
Oríṣun àwòrán, Twitter
Alaye to ṣe fun mi ni pe ija lo waye laarin ọmọbìnrin naa ati awọn kan ninu sọọsi. Ọmọbinrin naa farapa, ki wọn o to gbe lọ sileewosan, to ku si.
Alukoro ọlọpaa sọ pe oun ti pàṣẹ fún lati ṣe iwadii oun to ṣẹlẹ ni pato, ko si fun oun ni abọ.
Nigeria movie industry: Àgbà òṣèré, Lere Paimo ní àìgbọràn ló ń da ọ̀pọ̀lọpọ̀ àwọn òṣèrè sinimá láàmú
Agba oṣere lagbo tiata ati sinima ni Oloye Lere Paimọ, MFR tiọpọ mọ si 'Ẹda onile ọla', orukọ rẹ ko si lee parun ninu itan sinima ati tiata ni ilẹ Yoruba.
Lati inu awọn manigbagbe sinima bii 'Ogbori Ẹlẹmọṣọ' de Aṣiri nla' atawọn sinima miran, ni agba oṣere yii ti fi ara rẹ si aaye manigbagbe lọkan awọn ololufẹ sinima ati igbelarugẹ itan, aṣa ati iṣe Yoruba.
Amọṣa, ohun kan wa to n ks agba oṣere yii lominu nipa ipo ti agbo ere sinima ati tiata lorilẹede Naijiria, paapaa julọ ilẹ Yoruba wa bayii.
O ba BBC News Yoruba sọ diẹ nipa ọrọ ọhun. Abọ ree ninu ifọrọwanilẹwo yii o.
Ibadan Masquerades festival: Olóòlù ní bí eégún bá fi aṣọ wọ́lẹ̀ láàrin ìlú ni Coronavirus yóò kúrò
Ibadan Masquerades festival: Olóòlù ní bí eégún bá fi aṣọ wọ́lẹ̀ láàrin ìlú ni C
Wọn ni ẹ jẹ ka ṣe bi wọn tii ṣe, ko lee ri bo ti yẹ ko ri, ko maa ba lẹyin bii oku iya jọjọ.
Eyi ni esi ti ọkan lara awọn eegun ilẹ Ibadan, tii tun ṣe Oloolu baba eegun, Ifasuyi Omotoso Kazeem fi fesi si aṣẹ ti Olubadan pa.
Bẹẹ ba gbagbe, a ti kọkọ mu iroyin wa fun yin pe, Olubadan tilẹ Ibadan, Ọba Saliu Akanmu Adetunji ti paṣẹ pe egungun kankan ko gbọdọ jade fun ọdun eegun, nitori arun Coronavirus.
Amọ nigba to n ba BBC Yoruba sọrọ lori igbesẹ naa, Oloolu ni oun ko gbọ ri rara pe ni ọdun kan, eegun ko ni fi aṣọ wọlẹ nilu Ibadan.
"Oloolu ni ""awọn nnkan to maa n sẹlẹ lẹyin rẹ maa n lagbara, Ọlọrun ma jẹ ka ri ogun igbona, Coronavirus si ree, igbona lo bii,aṣọ eegun si lo maa n ko arun kuro nilu."
Agba eegun naa ni idakureku ojo to n waye laarin ìlú, isoro nla ni, orisirisi arun ni yoo si maa bẹ silẹ, to fi mọ arun ti a ko gbọ ri.
Nigeria movie industry: Àgbà òṣèré, Lere Paimo ní àìgbọràn ló ń da ọ̀pọ̀lọpọ̀ àwọn
Aṣẹ ti ijọba pa fun Olubadan lo sọ sita, oun ti ko si ye ijọba ni pe egungun la fi tẹ Ibadan do, bi eegun ko ba si jade, isoro yoo sẹlẹ, Ọlọrun ma jẹ ki aburu ṣe wa.
Ọrọ bii wahala ni yoo maa sẹlẹ n'Ibadan, ọrọ bii ogun, bii ọtẹ, awọn etutu kan wa ta maa n ṣe fun ọba, bawo wa ni yoo ṣe wa di ọdun yii, ti wọn yoo ni ka ma ṣe etutu ọhun amọ ka jokoo sile.
Oloolu tẹ siwaju pe awọn egungun kan wa to jẹ pe ti wọn ko ba jade, nnkan yoo ṣe awọn to n gbe eegun naa, to si fi eegun kan ti wọn ni ko ma jade ni ọdun kan ṣe apẹẹrẹ, o ni ọmọ ẹni to n gbe eegun naa meji lo ku.
Eyi to ṣẹlẹ yii, bii igba ta kan da wahala sira wa lọrun ni. Ki Ọlọrun ma jẹ ka ri wahala.
Oloolu, ẹni to ni oun ko tii le sọ boya ijọba yoo fun oun lasẹ lati jade ṣe ọdun ni ọdun yii abi bẹẹ kọ wa fi ọwọ gbaya pe bi ijọba ko ba fun oun lasẹ lati jade, oun yoo ṣe iwọnba ohun ti oun ba le ṣe niha toun, amọ ohun ti yoo ti ẹyin rẹ yọ, ni oun ko le sọ,tori mẹwa yoo sẹlẹ.
Oríṣun àwòrán, others
O dabi ẹni pe ko sibi ti ọwọja ajakalẹ arun Coronavirus ko ni de ni orilẹ ede Naijiria, tori o ti de ọdọ awọn ara ọrun pẹlu.
Idi ni pe ọdun egungun ko ni ṣee ṣe fun awọn ara ọrun lọdun yii nitori arun Coronavirus to n ran bii ọwara ojo.
Olubadan tilẹ Ibadan, Ọba Saliu Akanmu Adetunji, Aje Ogungunniso kinni ti paṣẹ fun awọn egungun nilẹ Ibadan lati ṣe etutu ọdun egungun ninu ile wọn, ki wọn si maa ṣe adura fun opin arun Covid-19.
Atẹjade kan to wa lati aafin Olubadan lo sísọ loju ọrọ yii pẹlu afikun pe ko ni si ijade lọpọ yanturu lati ṣe ọdun eegun, titi tawọn alaṣẹ yoo fi si gbogbo eeyan silẹ.
Ọba Adetunji ni oun fi ìpinnu naa síta lẹyin ifikunlukun pẹlu awọn eeyan ti ọrọ ọdun naa gberu, eyi to nii ṣe pẹlu ofin itakete sira ẹni to wa nita, to si tun rọ awọn araalu lati maa fọ ọwọ wọn deede.
Ibadan Masquerades festival: Olóòlù ní bí eégún bá fi aṣọ wọ́lẹ̀ láàrin ìlú ni C
Coronavirus recovery cases: Ìrírí ọkùnrin kan tó ní àrùn coronavirus ní ilẹ̀ Gẹ̀ẹ́sì rèé
Wọn ni iku to ba fẹ pa ni, to ba ṣi ni ni fila, ọpẹ lo yẹ ki ẹda o da si Eleduwa.
Eyi gan ni ni orin ti alagba, ẹni to ru arun coronavirus la lorilẹede Gẹẹsi.
O ni bi ere bi ere larun naa bẹrẹ ati pe awọn egbo ibilẹ bii galiiki ati nnkan miran ti iyawo oun se foun ati ẹbi oun kun ara ohun to mu ki ara oun tete bọ sipo.
Majek Fashek: Mọlẹbí nìkan ló péjú síbi ìsìnkú gbajúgbajà olórin reggae náà ní Amẹ́ríkà
Oríṣun àwòrán, others
Majek Fashek gbajugbaja olorin reggae ọmọ Naijiria ti wọ kaa ilẹ lọ.
Alamojuto ẹgbẹ akọrin rẹ Uzoma Omenka ni eto isinku rẹ waye lorileede Amẹrika nibi tawọn mọlẹbi nikan ti kopa nibẹ.
Uzoma ni ki awọn ọmọ Naijiria paapa julọ awọn ololufẹ rẹ ma ṣe binu nitori pe Covid-19 lo ṣokunfa bi wọn ko ti ṣe le sin ni Naijiria.
Loju opo Instagram rẹ, o fi aworan kan sibẹ ni iranti Majek Fashek
Bi a ko ba gbagbe ọkan lara awọn ọmọ oloogbe naa Randy Fashek ti ṣaaju kede pe isinku ranpẹ lawọn yoo ṣe nitori Covid-19.
Uzoma wa dupẹ lọwọ gbogbo awọn to gbaruku ti mọlẹbi ti o si ni nigba ti gbogbo nkan yoo ba fi lọlẹ awọn yoo ṣeto iranti isinku rẹ lọdun to n bọ
Oríṣun àwòrán, Instagram/official_Majek Fashek
Idile gbajugbaja akọrin Raggae ni, Majek Fashek to ti di oloogbe bayii ti sọ pe orilẹede Amerika ni yoo ti wọ kaa ilẹ lọ.
Ni ọjọ Aje, ọjọ kini, oṣu kẹfa, ọdun 2020 ni Majek Fashek jade laye lẹni ọdun mẹtadinlọgọta.
Gẹgẹ bii alakoso iṣẹ rẹ ṣe sọ, Majek Fashek fọwọ rọri ku ni ni ilu New York lorilẹ-ede Amẹrika.
Alaafin: Olori Aanu Adeyemi ṣàlàyé ìdí tó ṣe gẹ́ Oba Lamidi Adeyemi ti ìlú Oyo
Agbẹnusọ fun ẹbi oloogbe to tun jẹ ọmọkunrin rẹ, Randy Fashek lo kede pe ilẹ Amẹrika ni awọn yoo sin Fashek si.
Ninu fidio kan lori ayelujara ni Randy ti ṣalaye ọrọ yii.
O ṣalaye pe ẹbi Majek Fashek wo awọn nnkan to rọ mọ eto aabo lo jẹ ki wọn gbe igbesẹ lati sin in silu oyinbo.
Randy tun fikun ọrọ rẹ pe ajakalẹ aarun coronavirus naa jẹ ọkan gboogi lara idi ti ẹbi fi pinnu lati sin ogbontarigi olorin to lọ si ilẹ Amerika.
O sọ pe o nira fawọn ẹbi Majek Fashek lati ṣe ipinnu yii, ṣugbọn awọn bi lati ṣe bẹẹ nitori ohun ti o n ṣẹlẹ lọwọ lagbaaye bayii.
Ọmọkunrin Majek Fashek tun fidi rẹ mulẹ pe idile Majek Fashek nikan ni yoo ṣe eto isinku fun un.
Oríṣun àwòrán, Instagram/official_MajekFashek
Bakan naa lo sọ pe awọn ẹbi ko tii mu ọjọ isinku fun Majek.
Randy tọrọ garafara lọwọ awọn ololufẹ Majek Fashek ti wọn fẹ ki gbajugbaja olorin to lọ wọ kaa ilẹ lọ niluu abinibi rẹ ni Naijiria.
O ṣalaye pe awọn ẹbi yoo maa kede ọjọ ti eto isinku naa yoo waye laipẹ.
Ohun mẹ́fà tí àgbáyé kò mọ̀ nípa Majek Fashek tó d'olóògbé nìyí
Ni ọjọ Aje, ọjọ kini, oṣu kẹfa, ọdun 2020 ni gbajugbaja akọrin Raggae ni, Majek Fashek jade laye lẹyin to lo ọdun mẹtadinlọgọta lorilẹ-ede aye.
Gẹgẹ bii alakoso iṣẹ rẹ ṣe sọ, Majek Fashek fọwọ rọri ku ni ni ilu New York lorilẹ-ede Amẹrika.
Lootọ gbajugbaja ni Majek Fashek kaakiri agbaye ṣugbọn awọn ohun mẹfa wọnyii ni awọn eeyan ko mọ nipa rẹ.
Erin wo, ajanaku sun bi oke. Ongbontarigi olorin raggae ni, Majẹkodunmi Fasheke ti ọpọ mọ si 'Majek Fashek' ti re iwalẹ asa nibi ere tii so'kan.
Aṣoju oloogbe Majek Fashek, Omenka Uzoma to ba BBC sọrọ ṣalaye pe ilumọọka olorin fọwọ rọri ku lọjọ kinni oṣu kẹfa niluu New York lorilẹede Amẹrika.
Ọgbẹni Uzoma ṣalaye pe ẹni ọdun mẹtadinlọgọta ni Majek Fashek ki o to dagbere faye.
Ni ilu Benin city ni wọn bi Majek Fashek si. Ọmọ Ilesha ni baba rẹ ti iya rẹ si wa lati Edo.
Ogbontagi olorin raggae to di ilumọọka lẹyin to kọ orin tii akọle rẹ  ''Send down the rain'' ṣiṣẹ pẹlu awọn gbajugbaja olorin bii Jimmy Cliff, Tracy Chapman and Snoop Dogg nigba aye rẹ.
Ninu fidio ti aṣoju fi lede loju opo Instagram rẹ, Uzoma ni asiko ree lati ṣe ayẹyẹ awọn aṣeyọri Majek Fashek ati gbogbo nnkan to ṣe fun Naijiria ati ilẹ Afirika lapapọ.
Oríṣun àwòrán, others
Uzoma ni ko ba dara ki ijọba ranti ohun ipa ribiribi ti Majek Fashek pẹlu orin rẹ ki ijọba ṣi maa ṣe ayẹyẹ ni orukọ rẹ lọjọ keje oṣu kẹta to jẹ ọjọ ibi rẹ.
Itan igbe aye Majek Fashek
Ni ọdun 1988, ni okiki Majek Fashek kọkọ jade to bẹrẹ si ni lo Majek Fashek gẹgẹ bii orukọ apejẹ rẹ ti awo orin rẹ ti o pe akọle rẹ ni 'Prisoner of conscience' jade to si di wọọ ki ilu mọ nigba ti ọkan lara awọn
orin inu awo naa, Send down the rain  di gbajugbaja  to fun ni ami ẹyẹ ti ko din ni mẹfa lọdun 1989 nikan.
Majek Fashek fẹ Rita to si bi ọmọ mẹrin fun un ki wọn to kọ ara wọn silẹ .
Lawọn asiko kan ni igba aye rẹ, irinajo rẹ ṣe bi ẹni wọ diẹ nigba ti iroyin jade pe o n lo ogun oloro.
Amọ ṣa, yatọ si eyi, awọn aisan miran wa to n baa finra eyi to ran an lọ si ileewosan lọpọ igba.
Justice for Uwa: Bàbá Uwa, akẹ́kọ̀ọ́ fásitì tí wọ́n fipábálòpọ̀ ní Benin bá BBC sọ̀rọ̀ lórí bí wọ́n ṣe pa mọ rẹ̀
WAEC: ANCOPSS ní òun àti ẹgbẹ́ olùkọ́ yóò ṣèpàdé lọ́jọ́ Ẹti lórí ìpínu ìjọba àpapọ̀
Oríṣun àwòrán, dnt
Ẹgbẹ agbarijọpọ awọn ọga ileẹkọ girama jakejado Naijiria (ANCOPSS) kede pe, iyalẹnu nla ni ikede ijọba apapọ jẹ pe awọn akẹkọọ ko ni se idanwo asejade WAEC mọ lọdun 2020.
Alaga apapọ ẹgbẹ Ancopss lorilẹede yii, Anselm Izuagie ni haa-hii ni ikede ijọba apapọ naa si jẹ fun awọn, lẹyin ọjọ kan ti minisita feto ẹkọ ti fi ikede ọhun sita.
Ancopss ni oun bawọn peju sibi ipade awọn eeyan ti eto ẹkọ gberu lọjọ Isẹgun to kọja, nibi ti gbogbo awọn ti fẹnu ọrọ jona.
O ni adehun tawọn se ni pe ki eto idanwo WAEC waye, pẹlu sise awọn ilana eto aabo kan.
"Nibi ipade naa la ti se gbogbo agbeyẹwo ati eto aabo fun gbogbo awọn eeyan ti ọrọ kan, ti yoo kopa ninu eto idanwo naa.
A si fẹnu ko pe asise kankan ko gbọdọ waye, amọ ni kete ta pẹyinda tan, ni minisita feto ẹkọ sọ nnkan miran sita."
Izuagie ni ẹgbẹ Ancopss yoo pada se ipade lọjọ Ẹti pẹlu ẹgbẹ awọn olukọ, NUT, lati se agbeyẹwo gbogbo ọrọ naa, ti wọn yoo si fi ikede wọn sita fun araye.
Oríṣun àwòrán, legit
Saaju la ti mu iroyin wa fun yin pe, ijọba apapọ ni awọn ile iwe girama ijọba apapọ, Unity Schools, ko ni kopa ninu idanwo WAEC ọdun yii titi di igba ti o yẹ.
Minisita eto ẹkọ, Adamu Adamu lo kede bẹẹ nibi ipade kan to waye lori ayelujara.
Lẹyin naa lo gba ajọ WAEC atawọn ijọba ipinlẹ ni imọran lati ma ṣi awọn ile iwe lasiko yii nitori o lewu lati ṣe bẹẹ.
Ṣaaju ni alaga igbimọ amuṣẹya to n ri si ọrọ Covid-19 ni Naijiria, PTF, Boss Mustapha ti kọkọ sọ pe ipele awọn akẹkọọ kan yoo pada sẹnu ẹkọ wọn lọna ati gbaradi fun idanwo aṣekagba.
PTF ni o ṣe pataki ki awọn ọmọ ile iwe to wa ni ipele kẹta akọkọ ile iwe girama, JSS 3, ati awọn to wa ni ipele kẹta keji, SSS 3 pada sile iwe.
Wọn ni akoko naa yoo fun awọn akẹkọo ọhun laaye lati gbaradi fun idanwo to n bọ lọna.
Ṣugbọn Adamu ti sọ pe ko yẹ ko ri bẹ nitori bi ẹni fi ẹmi awọn ekẹkọọ wewu ni ọrọ naa yoo ja si.
"Adamu pari ọrọ rẹ pe ""O lewu lati ṣi ile iwe bayii."""
Ki lo ti ṣẹlẹ ṣeyin?
Oríṣun àwòrán, dnt
Ijọba apapọ ti kede pe idanwo aṣepari ni ileewe girama, WAEC, yoo bẹrẹ lọjọ kẹrin oṣun Kẹjọ ọdun 2020.
Minisita eto ẹkọ, Emeka Nwajiuba lo fi ọrọ naa lede nigba ti igbimọ amuṣẹya ijọba apapọ n jabọ ibi iṣẹ de duro lori ọrọ Covid-19 ni Naijiria.
"O ni ""A ti ṣe iwọn ti a le ṣe pẹlu ajọ WAEC, a dẹ n fi akoko yi sọ fun yin pe idanwo naa yoo bẹrẹ lati ọjọ kẹrin oṣu Kẹjọ titi di ọjọ karun un oṣu kẹsan an ọdun 2020."""
Nwajiuba sọ pe aye oṣu kan wa fun awọn ile iwe atawọn ipinlẹ to ba nifẹ si ṣiṣe idanwo naa lati pese awọn ile iwe wọn silẹ fun idanwo ọhun.
Minisita naa sọ pe ileeṣẹ eto ẹkọ yoo pese atẹjade awọn akoko ti idanwo ọhun yoo waye lẹyin ipade pẹlu ajọ NCDC, ẹgbẹ awọn olukọ, NUT, atawọn ajọ miran ti ọrọ kan.
Nwajiuba sọ pe idanwo NECO ati NABTEB yoo bẹrẹ ni kete lẹyin ti wọn ba ti pari idanwo WAEC ọhun.
Ọdun1952  ni wọn gbe idanwo WAEC kalẹ fun awọn akẹkọ lawọn orilẹ-ede iwọ-oorun ilẹ Afirika ti wọn ti n sọ ede Gẹẹsi.
Oríṣun àwòrán, legit
Ajọ to n ṣe kokari idanwo aṣepari ni ileewe girama, WAEC ti ṣalaye wi pe oun ti ṣetan bayii lati ṣeto idanwo fawọn akẹkọs oniwe mẹwaa lorilẹede Naijiria.
Ajọ naa ni oun to wa laarin ajọ naa ati ṣiṣe idanwo fawọn akẹkọọ oniwe mẹwaa lọdun yii ni ilana ti ijọba ba gbe kalẹ ati ṣiṣi awọn ileewe pada.
Ni ọjọ aje ni igbimọ amuṣẹya ti ijọba apapọ gbe kalẹ lori arun coronavirus lorilẹede Naijiria, PTF ṣalaye pe awọn ileewe ati ileeṣẹ eto ẹkọ nijọba apapọ gbọdọ joko lati fẹnuko lori ilana ti eto ẹkọ yoo gba bi wọn yoo ba ṣi ileewe pada; paapaa fun awọn akẹkọọ onidanwo aṣejade bii WAEC, NECO ati bẹẹbẹẹ lọ.
Nigba ti alukoro ajọ onidanwo aṣekagba girama, WAEC, Ọgbẹni Damian ba ileeṣẹ BBC News Yoruba sọrọ, o ni ohun ti awọn n reti bayii naa ni awọn ilana ti ijọba apapọ atawọn ijsba ipinlẹ ba fẹnuko le lori.
O fi kun un pe bi awọn ileewe ba lee di ṣiṣi pada, aaya bẹẹ lẹ o bẹ s'are ni fun awọn nitori awọn ṣetan lati ṣe idanwo naa ni kete ti wọn ba ti ri ilana gba lati ọdọ ijọba lori ọna ti eto ipada si ileewe yoo gba bayii.
Yoruba culture: Adelé Olúbọ̀rọ̀pa ní ọmọ ọdún 16 ni òun jẹ́ Adelé, kó tó lọ sí Fáṣítì
Oríṣun àwòrán, Instagram/officialoluboropa_of_iboropa
Adelé Olúbọ̀rọ̀pa tilu Bọ̀rọ̀pa, Ọmọọba Tinuade Babalola Adejuyigbe ti koro oju si bi ko ṣe si itọju gidi fun awọn ọba alaye ati awọn Adelé.
Adelé Olúbọ̀rọ̀pa woye ọrọ yii lasiko to n kopa lori eto kan ni ikanni BBC Yoruba.
Adelé Adejuyigbe ni ẹgbẹrun lọna marundinlogoji naira ni oun n gba lowo osu eyi ti ko ran nkankan, bẹẹ ni ijọba ko fun oun ni ọkọ ayọkẹlẹ nidii.
Ọpẹlọpẹ awọn araalu to n fun mi lowo, oun ni mo fi n gbọ bukata ara mi, ko si apọnle kankan fun wa.
Adelé, ẹni to ṣẹṣẹ jade nile ẹkọ fasiti, to si n sinru ilu lọwọ, wa mọ riri atilẹyin iya rẹ ati awọn ijoye rẹ, o ni itọni wọn lo mu ko rọrun fun oun lati dari ilu.
Nigba to n sọ iriri rẹ lasiko to wa nile iwe, ọba alaye lobinrin naa to ti lo ọdun marun lori itẹ tun salaye pe, oun kii pa idanwo ati kilaasi jẹ, ti awọn olukọ si da oun mọ pẹlu buba, Sokoto ati ilẹkẹ lọwọ ati lọrun.
Oríṣun àwòrán, Instagram/officialoluboropa_of_iboropa
"Lori ọrọ ifẹ pẹlu ọkunrin, Adele Olúbọ̀rọ̀pa ni ""lootọ ni awọn ọkunrin n wa mi wa amọ n ko gbọdọ ba ara mi jẹ nipa nini ibalopọ gẹgẹ bii Adelé nitori eewọ nla ni, asa wa ko gba ki n lo ifẹ ikọkọ tabi sun mọ ọkùnrin."""
Ọba alaye lobinrin ọhun, to ni oun ko tii ni afẹsọna kankan, wa rọ ijọba lati maa ran awọn ọba alaye ati adele lọwọ.
George Floyd: Àwọn ọlọ́pàá darapọ̀ mọ́ àwọn olùwọ́de lórílẹ̀èdè Amẹ́ríkà
Cultism in Nigeria: Afurasí sọ fúnlé ẹjọ pé ẹgbẹ́ búburú tóun kó ló ṣàkóbá fún òun
Awọn ẹgbẹ okunkun fasiti Naijiria: Buccaneers,Black Axe ati awọn ẹgbẹ ijaiya mìíràn
Ile ẹjọ ti ni kí ọkùnrin, ẹni ọgbọn ọdun, Nwali Kingsley, ma a gbatẹ́gùn ni ọgbà ẹ̀wọ̀n, fun pe o lu ọkunrin kan, Victor Nwafor pa, lasiko to n seto igbaniwọle sinu ẹgbẹ okunkun fun.
Afurasi naa, ni iroyin sọ pe oun ati awọn miran, to ti ṣa lọ bayii, tun ṣe ẹlomiran, Chigbo Ugbala leṣe, nipa fifi igi lu u, ti wọn si tun fi àdá ṣa, nibi eto igbani wọle naa.
Iṣẹlẹ naa la gbọ pe o waye nileewe girama Ekeugwu Azuinyaba, nijọba ibilẹ Ishielu, nipinlẹ Ebonyi, lọjọ kẹwàá, oṣu Keje.
Iroyin ni nibi ti won ti n ju oku Nwafor sinu odo, ni Ugbala si raaye sá lọ, gbogbo igbiyanju lati ri oku oloogbe naa, lo ja si òfo.
Awọn ẹgbẹ okunkun fasiti Naijiria: Buccaneers,Black Axe ati awọn ẹgbẹ ijaiya mìíràn
Ẹsun ipaniyan, igbimọ pọ, ṣíṣe ẹgbẹ okunkun, ati níní nkan ija lai gba iwe àṣẹ, ni wọn fi kan Kingsley.
Afurasi naa, ti ko ní agbẹjọro to ṣoju rẹ nile ẹjọ sọ pe, awọn ọrẹ oun lo fi ọgbọ́n ẹ̀wẹ́ fa oun sinu iwa buruku naa, to si tun bẹbẹ pe ki ile ẹjọ siju aanu wo oun.
"Ọlọpaa to rojọ tako o nile ẹjọ, ASP Eze Nnabuaku, sọ fun ile ẹjọ pe, ""ijiya wa fún awọn ẹsun ti wọn fi kan Kingsley, ninu ofin ọ̀daràn, ti ipinlẹ Ebonyi."
Oronpoto Animation: Akin Alabi ní kò dára bí eré aláwòrán fáwọn ọmọdé ṣe jẹ́ aláwọ̀ funfun
Sugbọn, adajọ ile ẹjọ Majisireti naa, Arabinrin Nnenna Onuoha, ti pàṣẹ pe, ki wọn o taari iwe ẹjọ naa si ọfiisi ikọ agbẹjọro ijọba fun igbesẹ to yẹ,
O ni ile ẹjọ majisireti naa ko ni agbara lati gbọ ẹjọ naa, to si sún igbẹjọ si ọjọ keje, oṣu Kẹjọ ọdun 2020.
Akẹkọọ ọlọdun kini fasiti Naijiria kan ni Roland jẹ nigba to darapọ mọ ẹgbẹ  okunkun Buccaneers.
Laarin oru ni wọn ṣe etutu igbaniwọle ṣẹgbẹ fun un ninu igbo kijikiji.
Awọn to ba ninu ẹgbẹ naa rọ yika wọn, wọn si fi orin, ilu, ijo ati egba to le ki oun ati awọn ọmọ ẹgbẹ tuntun miiran kaabọ bẹrẹ lati oru titi di afẹmọjumọ.
Pataki etutu yi ni ki wọn ba le gbọn gbogbo ojora kuro lara wọn kí wọn si sọ wọn di akin.
"Roland sọ fun BBC pe ""Bi o ba fi le wọ ibẹ ti o si jade, o ti di ẹlomiran ni yen,"""
Awọn ẹgbẹ okunkun yi ni orisirisi orukọ bi Vikings, Black Axe, Eiye ati Buccaneers.
Wọn a ma tẹle ilana ipasẹ eleyi to fara jọ t'awọn ologun.
Wọn  a ma lo ọrọ ti o se pe awo lo le ye, ọgbẹri ko le mọ koda wọn a tun ma lo ami idanimọ to ṣafihan irinṣẹ ijayi wọn fẹran julọ pẹlu awọ ti wọn ṣa lesa.
Wọn a ma fi da ọmọ ẹgbẹ wọn loju pe mimi kan ko le mi wọn lati ọdọ awọn ẹgbẹ to ku.
Agbara ati gbajumọ wa lara nnkan ti wọn fi n tori rẹ ṣẹgbẹ okunkun.
Ijọba  Naijiria tapa si jijẹ ọmọ ẹgbẹ okunkun ti wọn si ti n fi panpẹ ofin mu ogunlọgọ awọn to darapọ mọ awọn ẹgbẹ yi.
Sibẹsibẹ awọn ẹgbẹ wọn yi ko jáwọ nínú iwa buruku yi ti wọn si n pẹka sii paapa julọ lawọn fasiti Naijiria nibi ti wọn ti ko awọn ọmọ ẹgbẹ mii wọle.
'Iroyin ẹlẹjẹ nipa ikọlu awọn ọmọ ẹgbẹ okunkun'
Awọn ti awọn ọmọ ẹgbk okùnkun ti pa nile ekọ
Wọn ti fẹsun kan awọn ọmọ ẹgbẹ okunkun pe awọn ni wọn wa nidi ikọlu lawọn fasiti kaakiri Naijiria ti wọn a si tun ma dunkoko mọ awọn olukọ lati fun wọn ni maaki.
Lawọn ibomiran wọn a ma fi ileri anfaani ipo tabi siso awọn ọmọ ẹgbẹ yi mo awọn ti yoo ran wọn lọwọ tan wọn jẹ.
Ọpọ awọn ẹgbẹ yi lo ti ni ẹka laarin awọn ti ko si ni ọgba fasiti ti awọn wọn yi a si ma gbe igbe aye ole jija ati iwa janduku.
Oríṣun àwòrán, Other
Awọn ẹgbẹ okunkun fasiti Naijiria: Buccaneers,Black Axe ati awọn ẹgbẹ ijaiya mìíràn
Lawọn ilu bi Eko ati Portharcourt awọn ẹgbẹ okunkun yi a ma saba fa awọn ọmọ keekeke wọnu ẹgbẹ janduku ladugbo ti iru awọn wọnyi a si wa pada wa di booran nigba ti wọn ba de fasiti.
Loṣu Kẹrin ọdun yi, awọn ara ipinlẹ Eko ati Ogun ko ara wọn jọ lati ma ṣe fijilante ladugbo kọọkan nitori iroyin to gbode pe awọn ọmọ ẹgbẹ janduku One Million Boys ati Awawa Boys n doju ija kọ awọn eeyan ladugbo wọn. Isede wa lasiko yi nitori Coronavirus.
Awọn eeyan sọ pe eyi lo mu ki awọn janduku wọnyi d'aṣọ okunkun boju lati le fi ja awọn eeyan lole ninu ile wọn.
Ko pẹ ko jina ti iroyin gba oju opo ayelujara nipa bi awọn janduku miran ti ṣe n yabo awon adugbo lati le ṣọṣẹ fawọn eeyan mọ inu ile wọn.
Nṣe lo dabi ẹni pe wọn pe ara wọn jọ lati ṣigun bo awọn araadugbo ni.
Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo
Awọn ọlọpaa sọ pe ko si ohun to jọ bẹ to ṣẹlẹ ti wọn si ni awọn kan mọọmọ tan iroyin ẹlẹjẹ yi ka ni lati le fi d'ẹru ba awọn ara ilu ṣaaju ki wọn to ṣigun wa.
Sibẹsibẹ awọn ọlọpaa ni awọn mu awọn afurasi to le ni igba t'awọn fura sì pe wọn kopa ninu ija to waye laarin awọn ẹgbẹ okunkun meji kan lẹyin iku ọkan ninu awọn olori wọn.
Ipinu Roland lati di ọmọ ẹgbẹ okunkun ko sẹyin pe wọn yoo daaboboo ni fasiti rẹ to wa ni ẹkun ila oorun Naijiria.
Ọrẹ rẹ kan ni ọmọ ẹgbẹ okunkun ja lole ti ọrọ naa si di ranto.
Wọn wọ Roland wọ inu ija yi ti awọn ọmọ ẹgbẹ okunkun si doju ija kọọ leemeji ọtọọtọ.
The Buccaneers have a reputation for living the good life Won mọ awon Bucaneers gẹgẹ bi àwọn to ma n gbegbe aye to dara
O fi ọrọ yi to awọn alaṣẹ fasiti leti ṣugbọn awọn ẹṣọ alaabo fasiti ko ri nkankan ṣe si.
Agbarac awọn ẹṣọ fasiti yi kere jọj si t'awọn ọmọ ẹgbẹ okunkun to n gbe ibọn ati awọn ohun ija oloro mii rin kaakiri.
Ọna ati wa aabo f'ẹmi rẹ lo wa lọ s'ọdọ ẹgbẹ okunkun Buccaneer ṣugbọn ni kete to darapọ mọ wọn, ibẹru bojo awọn ẹgbẹ okunkun to ku lo jọba lọkan rẹ.
Njẹ Wole Soyinka lọwọ si idasilẹ awọn ẹgbẹ okunkun?
Awọn ẹgbẹ okunkun Naijiria ko ri bayi lati ipilẹ.
Lọdun 1952 lasiko ti ijọba amunisin oyinbo n lọ si opin ni awọn ọdọmọdekunrin kan ṣe idasilẹ awọn ẹgbẹ yii.
Ninu wọn la ti ri ilumọọka ọjọgbọn Litireṣọ, Wọle Soyinka t'oun ati awọn miran ni fasiti Ibadan da ẹgbẹ wọn silẹ
Wole Soyinka Salaye abamọ ti wan ko leyin ti Pyrates bere
Awọn akẹkọọ ta n sọ yi pe ẹgbẹ wọn ni  National Association of Seadogs, or Pyrates, ti wọn si gbe  kalẹ lati tako awọn to n fi ipo ọla yan awọn ara toku jẹ.
Awọn meje lo da ẹgbẹ yii silẹ nigba naa.
Wọle Soyinka sọ fun BBC pe ere lawọn kan n se pẹlu ẹgbẹ t'awọn da silẹ yi.
"O ṣàpèjúwe awọn ẹgbẹ okunkun ode oni gẹgẹ bi ""ẹgbẹ kebbe,ẹgbẹ alaburu"""
Mi o fi igba kankan ro pe ẹgbẹ kankan ninu ile iwe fasiti yoo ma ṣamulo awọn iwa buruku bi ijinigbe,ipaniyan,fifi ipa bani lopọ,ajigunjale ati awọn iwa miran bayi
 Mi o lero pe yoo pada da bo ti se ri yi,ki lo si mu di bayi? Nitori pe awọn obi kan,kaka ki wọn foju odaran wo awọn ọmọ buruku wọn yi,nise ni wọn raga bo won
Ẹgbẹ  Pyrates ti Soyinka si yi jẹ ọkan lara wọn gẹgẹ bi o ti ṣe sọ si n ṣe igbelarugẹ awọn iṣẹ oloore f'ẹda moniyan.
Ondo: Dejí sun ọmọ méje àtagbalagba meji mọ́lé nítorí pé ó ń bínú
Wọn ko ẹgbẹ yi kuro lawọn fasiti lọdun  1984 ki awọn obilẹjẹ ma ba bawọn l'orukọ jẹ.
Wọn ko gba ọmọ ẹgbẹ tuntun kankan sí ẹgbẹ naa mọ.
Bi awọn ẹgbẹ okunkun ti ṣe yapa bẹrẹ si ni ju iwa janduku
Ipinya laarin awọn ọmọ ẹgbẹ Pyrates ni igba naa lo mu ki awọn kan yapa lati lọ da ẹgbẹ Buccaneer ati awọn ẹgbẹ mi silẹ.
Ija pẹẹpẹpẹ to waye bẹrẹ si ni mu ki wọn ma bara wọn du obinrin,ipo,ọla,iyi ati atilẹyin awọn oloṣelu to bẹrẹ si ni lo awọn ọmọ ẹgbẹ okunkun lati doju ija kọ awọn alatako wọn.
Awọn ẹgbẹ kan buru ju ara wọn lọ ti kii si ṣe gbogbo ọmọ ẹgbẹ lo ma n wuwa ọdaran.
Toun ti bẹẹ gbogbo awọn ẹgbẹ okunkun lo m an deru ba awọn eeyan bi wọn ba darukọ wọn.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Wole Soyinka gege bi oluko fasiti Ibadan nigba to kere diẹ ni aye 60's
Ninu awọn to buru ninu wọn ni ẹgbẹ Alaake dudu, Black Axe.
Ni nkan bi ọdun diẹ sẹyin ni won bẹrẹ sii ni gberi ti wọn si mọ wọn si Neo Black Movement ni ibẹrẹ.
Awọn to da silẹ ni erongba awọn ni lati tu ẹya alawọdudu silẹ lọwọ igbekun.
Ṣugbọn lode oni, awọn ọmọ ẹgbẹ yi lawọn fasiti ti yi ipinu pada.
Kaka ki wọn ranti ipilẹṣẹ pupo a ma seku pani ti wọn a si ma bani lopo lọna aitọ.
Kayeefi: Facebook ni Wolii Arole Jesu fi tàn an wọ agbo, orí rẹ̀ ni wọ́n fi s'owó
Ni ọdun 1999 wọn pa awọn ọmọ ẹgbẹ igbimọ akẹkọọ fasiti Obafemi Awolowo nilu ile Ife nipinlẹ Osun.
Bẹẹ naa lawọn kan naa seku pa awọn ọmọ ẹgbẹ okunkun Black Axe.
Ni nkan bi ọdun 1990 awọn kan bẹ ori olori ẹgbẹ okunkun ti won si gbe kọ si ori opo lati fi ṣe afihan pe awọn pegede.
Laarin ọdun 1980 siwaju, ija laarin awọn ọmọ ẹgbẹ okunkun peleke.
Ọrọ naa buru pupọ laarin igba t'awọn ologun fi n gba ijọba lorileede Naijiria.
Leralera lawọn eeyan n fẹsun kan awọn ologun pe wọn ṣe iranwọ owo ati nkan ija fawọn ẹgbẹ okunkun lati le doju ija kọ awọn to n pe fun Ijọba alagbada.
Sowore salye bi awon egbe okunkun se gun oun
Akọroyin  Omoyele Sowore mọ awọn ẹgbẹ okunkun yi bi ẹni m'owo nigba to n kẹkọọ ni fasiti ilu Eko, Unilag.
Awọn ọmọ ẹgbẹ okunkun n dunkoko mọ awọn akẹkọọ nigba to jẹ aare ẹgbẹ awọn akẹkọọ fasiti naa.
O ṣe ìpinnu lati koju wọn ṣugbọn igbesẹ yi léwu fún un.
"O so fun BBC pe ""Ẹmi mii fẹ ba lọ"""
Loṣu Kẹta  1994, wọn gbe ibọn si lori ti wọn si gun labẹrẹ ti ko mọ ohun to wa ninu rẹ.
Ọpọ wọn ya bo mi, wọn gun mi lọbẹ lori ati ni ibi ikun mi. Wọn bọ mí sí ihoho
Awọn akẹkọọ akẹgbẹ rẹ lo pada gbaa silẹ lọwọ wọn ti wọn si gbe e lọ si ile iwosan.
Omidan jáde láyé lẹ́yìn tí ìlú lù ú, jáa sí ìhòhò lórí ẹ̀ṣẹ̀ tí kò ṣẹ̀
Iwa to wa lọwọ awọn ẹgbẹ okunkun mi kọja orileede bode orileede Naijiria.
Wọn fẹsun kan ẹgbẹ okunkun Ẹiyẹ pe wọn pẹka de ilẹ okeere.
Awọn ọmọ ẹgbẹ naa wa lara awọn metalelogun t'awọn agbofinro ilẹ Spain mu l'agbegbe Catalonia lọdun 2015 pe wọn n se owo fifi eeyan s'owo ẹru ti wọn a sì tún ma ta oogun oloro to fi mọ ṣíṣe ayederu iwe irina fawọn eeyan.
Ikọ awọn odaran yi ni wọn tun fi ẹsun kan pe wọn n ji epo robi ta lọna aitọ.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Awon ọmọta to n jà ní ori aafara kan nilu Eko
O s'ọwọn ki eeyan to wa ninu ẹgbẹ okunkun ribi já ara rẹ gba kuro ninu ẹgbẹ naa lasiko to wa ni ile ẹkọ.
Awọn to dan wo ninu ki wọn farapa tabi ki wọn padanu ẹmi wọn.
Pupọ akẹkọọ lo pa ẹkọ rẹ ti nigba ti wahala awọn ọmọ ẹgbẹ okunkun ba fẹ yọ ile aye l'ẹmi wọn.
Awọn mi,titi laye ni wọn yoo fi ṣẹgbẹ naa.
Koda a ma fun wọn láánfàní iṣẹ tó da ati ibaṣepọ pẹlu awọn to lẹnu lọrọ láwùjọ.
Yoruba Culture: ọjọ́ méje ni wọ́n fí n rẹ ẹ̀kú Danafojura kó tó jáde
Awọn mi a ma kowo sidi ẹgbẹ okunkun.Won a ma ṣe baba isalẹ fawọn ọmọ ẹgbẹ okunkun.
Awọn wọn yi a si ma wa awọn ọmọ obinrin fun won nigba to ba wu wọn lati ṣe Ibalopọ pẹlu wọn.
Roland ni igbagbọ pe ofo lasan ni ileri ati adehun t'awọn ẹgbẹ okunkun maa n se fawọn ọmọ ẹgbẹ wọn.
Lọpọ igba eeyan yoo wa ninu ibẹrubojo ni.Ko si bi awọn ọmọ ẹgbẹ ṣe le parọ fún e to, gbogbo igba leru ma n ba wọn
* A lo orukọ Roland la ti fi bo ẹni ta ba sọrọ lasiri ki ẹmi rẹ ma ba wa ninu ewu
* Manuella Bonomi ileeṣẹ BBC lo ya gbogbo aworan ta fi ṣe akawe ọrọ
Àwọn ọníṣẹ́ ọwọ́ wọ̀nyí ti gbowó iṣẹ́ àmọ́ Coronavirus ò jẹ́ kí n ṣisé owó tí wọ́n gbà
Lati igba ti ajakalẹ arun COVID-19 ti rapala wọ orilẹede Naijiria, oniruuru ipa lo ti ni.
Lara awọn ipa to ni ni bi awọn eeyan to n ṣe awọn iṣẹ kan ko ṣe lee ṣe iṣẹ mọ nitori ipa ti o ni lori iṣẹ wọn.
Ko si idi meji ju wi pe, arun yii ti jẹ ko di mimọ fun gbogbo mutumuwa pe oun ko ni faramọ aṣepọ awọn eeyan ni fifarakanra, eyi to si jẹ pe akoba ni fun awọn iṣẹ kan nitori aṣepọ bẹẹ lo n mu ọrọ aje ya fun wọn.
Akinyele local government: Iléeṣẹ́ ọlọ́pàá ìpínlẹ̀ Oyo ti mú àwọn afurasí lórí ìpànìyàn tó wáyé
Oríṣun àwòrán, @NSEupdate
Ileeṣẹ ọlọpaa ipinlẹ Ọyo ti fi ṣikun ofin mu awọn afurasi kan ni Ibadan lori iṣekupani Akinyele.
Awọn agbofinro fẹsun kan awọn afurasi yii pe wọn lọwọ ninu ipaniyan to waye lagbegbe Akinyele ni ilu Ibadan.
Olubadamọran pataki fun gomina Seyi Makinde, Fatai Owoseni lo kede ọrọ naa nibi ipade ita gbangba to waye ni Akinyele, eyi ti ileeṣẹ agbohunsafẹfẹ kan gbe kalẹ.
Owoseni sọ pe ileeṣe ọlọpaa yoo fi awọn afurasi naa lede laipẹ.
"Owoseni ni ""Gẹgẹ bi a ṣe mọ pe ko si ilu ti ko si ofin tabi ẹṣẹ, mo fẹ fi da a yin loju pe ọwọ ti tẹ awọpn ọdaran to n gbẹmi eeyan ni Akinyele."""
O tẹsiwaju pe ẹni to wa nidii ọrọ naa ti mu awọn agbofinro lọ si ọdọ awọn to fi eeyan joogun ati pe wọn ti wa ni atimọle.
Oríṣun àwòrán, @247NNU
Ni ti eto aabo ilu, Owoṣeni sọ pe iṣẹ gbogbo eeyan ni eto abo ilu jẹ, lẹyin naa lo sọ fun awọn eeyan naa pe ki wọn mu eto abo ara wọn lọkunkundun nitori oju ni alakan fi n ṣọri.
Ko din ni eeyan marun un ti wọn ti da ẹmi wọn legbodo lagbegbe Akinyele laarin oṣu Karun un si oṣu Kẹje ọdun 2020.
Ṣaaju ni ileeṣẹ BBC Yoruba ti jabọ pe wọn pa alaboyun kan ti wọn fi okuta fọ lori lagbegbe ọhun, yatọ si awọn eeyan miran ti wọn ti pa lagbegbe naa.
Àwọn ọlọ́pàá kò kọbiara si ọ̀rọ̀ ipá lásìkò ìgbéle Covid -19 ni ìwà ipá ṣe pọ̀ - Ajàfẹ́tọ obìnrin
Ṣaaju ni Ajafẹtọ ọmọniyan kan ti fẹsun kan ọlọpaa ipinlẹ Oyo pe wọn ko ṣe to bo ti yẹ.
Àwọn ọlọ́pàá kò kọbiara si ọ̀rọ̀ ìwà ipá lásìkò ìgbéle Covid -19 ni ìwà ipá ṣe pọ̀ - Ajàfẹ́tọ obìnrin
Láti ọ̀sẹ̀ díẹ̀ sẹ́yìn ni ìròyìn aburu nípa ìwà ipá nínú ilé àti ifipábánilòpọ̀ ti n peléke síi lágbàyé tí kò sì yọ orílẹ̀-èdè Nàìjíríà sílẹ̀ pẹ̀lú.
Èyí tó burú jùlọ níbẹ̀ ni pé, ní ọ̀pọ̀ ìgbá tí àwọn oníṣẹ́ nla ibi yìí bá bá àwọn ènìyàn yìí lòpọ̀ tipatipa tán, wọ́n a tún dá ẹ̀mí wọ́n légbodò.
Àwọn ìṣẹ̀lẹ̀ yìí ló mú kí BBC News yoruba ṣe ìwádìí ǹkan ti ó fàá tí àwọn ǹkan wọ̀nyìí fi ń peléke síi lójoojúmọ́.
Iṣẹlẹ to ṣaaju ariwo ifipabanilopọ:
Ojúmọ́ ọjọ́ kan lọ́sẹ̀  bíi méjì sẹ́yìn ni òkìkí kàn pé ọ̀dọ́mọbìnrin ẹni ọdun méjìlélógun kan Vera Omozuwa to jẹ́ akẹ́kọ̀ọ́ ni ilé iwé Uniben  l'àwọn kan fipá bá lòpọ̀.
Ninú ilé ìjọsìn lásìkò tó lọ kàwé níbẹ̀ ni iṣẹlẹ yii ṣẹlẹ ti wọ́n sì tún pa á sibẹ̀.
Lẹ́yìn ìṣẹ̀lẹ̀ yìí, ọ̀pọ̀ àwọn ọdọ́ àti àwọn ajàfẹ́tọ ọmọniyan ló tú sigboro láti fẹ̀hónú hàn lórí ọ̀rọ̀ náà.
Bí eléyìí ṣe n lọ lọ́wọ́ ní òmíràn tún ṣẹlẹ̀ ni ìlú Ibadan to tun di ariwo ikunlẹ abiyamọ.
Nígbà ti àwọn amòokùnṣìkà yìí tún bẹ́ sílé àwọn Barakat Bello tí wọ́n fípa ba ọmọ ọdún méjìdínlógún ọ̀hún lòpọ̀ nínú balùwẹ̀ ilẹ́ wọ́n tí wọ́n sì tún pa a síbẹ̀.
Kemi Dairo: Iṣẹ́ abẹ nínú ọpọlọ àti ẹ̀rọ ni mo fi ń gbọ́ ọ̀rọ̀ báyìí
Èyí ni à n sọ lọ́wọ́ tí omíràn tún sẹ̀lẹ̀ nílùú Ibadan kan náà sí Azizat Somuyiwa eni ọdún makàndínlọ́gbọ̀n lágbàgbè Ijefun ni Moniya.
Ìròyìn sọ pé àwọn oníṣẹ́ ibi náà fọ òkúta mọ ọmọbinrin náà lórí ní idáji ọjọ karùn-ún, oṣù kẹfà bó tilẹ̀ jẹ́ pé, ikú tirẹ jẹ mọ ìfinirúbọ̀ ní gẹ́gẹ bi àwọn ọlọ́pàá ṣe sọ.
Oríṣun àwòrán, others
Àwọn ọlọ́pàá kò kọbiara si ọ̀rọ̀ ìwà ipá lásìkò ìgbéle Covid -19 ni ìwà ipá ṣe pọ̀ - Ajàfẹ́tọ obìnrin
Kò tán síbẹ̀, Nípìnlẹ̀ Ondo, ọkùnrin kan ti wọ́n ń pè ni Oniya lo sá ìyàwó rẹ̀ yánayàna nítori pe ìyàwó rẹ̀ kọ ìbálòpọ̀.
Obìnrin ọ̀hún ti orúkọ rẹ̀ ń jẹ́ Monisola Adeola ní ọkọ òun kò ṣẹ̀ṣẹ̀ má a lu òun lóri àwọn ǹkan ti kò nílárí, sùgbọ́n orí kó Monisola yọ nítóri kò bá ìṣẹ̀lẹ̀ náà rìn kí wọn tó gbà á sílẹ̀
Ọ̀kan nínú àwọn ajàfẹ́tọ̀ọ́ obìnrin tó tún jẹ́ agbẹjọ́rọ̀ Toyin Taiwo Ojo tó bá BBC News Yoruba sọ̀rọ̀ jẹ́rìí sí pé ọ̀rọ̀ ìwà ipá ni àwujọ Nàìjíríà ń peléke síi lásìkò ìgbélé Coronavirus.
Kini a le sọ pe o fa eyi lasiko yii?: Minista fun ọrọ obinrin fesi pe:...
Arabinrin Pauline Tallen to je minista fun ọrọ obinrin ni Naijiria ti ni Isede konile-o-gbele lati dekun itankalẹ ajakalẹ arun Covid 19 lo faa.
O sọ eyi nibi ipade nile ijọba ni Abuja lasiko to n jabọ lori iṣoro ifipabanilopọ to n fẹju kaakiri Naijiria bayii.
O ni ọna abayọ ni ki gbogob ẹka eto idajọ ati agbofinro ati ara ilu dide papọ lati gbogun ti iwa buruku yii.
Loju àwọn agbẹjọro n kọ?
Amòfin Ojo ní ọ̀pọ̀ ǹkan lo fá idí ti èyí bi pọ̀, sùgbọ́n èyí to ga jùlọ níbẹ̀ ni pé, àwọn ọlọ́pàá kò ṣiṣẹ́ lásìkò kónílé-ó-gbéle nínú oṣù kẹrin ki wọ́n tó dẹwọ́ rẹ̀ silẹ̀.
Ajàfẹ́tọ́ obìnrin náà sọrọ lori iriri rẹ ni ọ̀pọ̀ ìgbà gẹ́gẹ́ bi amofin tí ẹjọ́ bá de àgọ́ ọlọ́pàá ti ọ̀rọ̀ náà sì jẹmọ́ ọ̀rọ̀ ipá nínú ilé ati iwa awọn agbofinro lori iru ọrọ bẹẹ.
O ni àwọn ọlọ́pàá maa n sọ fún àwọn ènìyàn wọ́nyìí pé ki wọ́n padà wá lẹ́yìn ti aàrùn Coronavirus ba ti kásẹ̀ nilẹ̀, tábi kí wọ́n lọ yànjú rẹ̀ nílé.
JusticeforBarakat: O lé lọ́mọ ọdún mọ́kànla kí n tó rí abúrò rẹ̀ bí lée
Ẹ lọ yànjú rẹ̀ nílé, ọ̀rọ̀ obìnrin ní, Coronavirus wà níta, a kò le mú ẹnikẹni si agọ wá báyìí, ẹ padà wá ti Coronavirus ba pari.
Amòfin Ojo ní ǹkan tí àwọn ọlọ́pàá ń ṣe yìí ló fún àwọn ènìyàn burúkú yìí lágbára láti maa ṣiṣẹ́ ibi lásìkò Coronavirus.
O fi kún pé, àwọn ilé ẹjọ́ pẹ̀lú kò ṣíṣẹ nítori náà àwọn to yẹ kó kúrò lágọ̀ọ́ ọlọ́pàá lọ silé ẹjọ́ náà ko le kúrò níbẹ̀.
Kíní ǹkan tó wọ́pọ̀ láàrín àwọn tó máa n lo ìwà ipá?
Amòfin Ojo sàlàyé pé láti ọdún díẹ̀ sẹ́yìn ti òun ti ń bá àwọn tí wọ́n kojú ìwà ipá nínú ilé ṣiṣe òun ṣàkíyèsí pé ìtàn wọ́n máa n jọra.
O ní ọ̀pọ̀ awọn tó n lo ìwà ipá sábà máa fi àwọn àmìn yìí hàn:
O ní lẹ́yìn tí o bá ti ṣe àṣeyọri lórí àwọn ǹkan wọ́nyìí ni yóò ṣẹ̀ṣẹ̀ wá yọ́wọ́ ìwà.
Oríṣun àwòrán, Twitter/aduke
A ti bẹ̀rẹ̀ ìwádìí kíkún nípa àwọn tó lọ́wọ́ nínú ikú Barakat Bello -  Iléeṣẹ́ ọlapàá
Ileeṣẹ ọlọpaa ipinlẹ Oyo ti sọ pe oun ti gbe iwadii ọrọ Barakat Bello ti wọn pa lẹyin ti wọn fi ipa ba a lopọ tan lọ si ẹka ọtẹlẹmuyẹ to n ri si iwa ọdaran, CID, ni ilu Ibadan.
Alukoro ileeṣẹ naa, Olugbenga Fadeyi lo fidi ọrọ naa mulẹ fun BBC.
O ni awọn agbofinro ti bẹrẹ iwadii ni kikun lori ohun to fa iṣẹlẹ naa ati idi ti wọn ṣe gba ẹmi ẹni ọdun mẹtadinlogun ọhun.
Agbẹnusọ ọlọpaa naa ni bo tilẹ jẹ pe wọn tete sin oku ọmọbinrin naa ki iwadii to bẹrẹ lẹkunrẹrẹ, awọn agbofinro yoo tu iṣu de isalẹ ikoko bi ọrọ ọhun ṣe jẹ.
Fadeyi tẹsiwaju pe ileeṣẹ ọlọpaa ipinlẹ Oyo ko ni sinmi titi di igba ti yoo fi oju awọn oniṣẹ ibi ọhun lede.
Lẹyin lo rọ awọn eeyan to n gbe lagbegbe ibi ti iṣẹlẹ naa ti waye lati fi to ileeṣẹ ọlọpaa leti nipa ohunkohun ti wọn ba mọ tabi ẹni ti wọn ba fura si lọna ati lee jẹ ki wọn pari iwadii naa lai fi akoko ṣofo.
Ọjọ iṣẹgun, ọjọ keji oṣu kẹfa ni awọn amokun-ṣeka wọle tọ Barakat Bello lagbegbe Akinyele, ni ilu Ibadan, ti wọn si gbẹmi rẹ lẹyin ti wọn fi ipa baa lopọ tan.
Eyín ọ̀ọ́kán mi ni Barakat tí wọ́n pa lẹ́yìn tí wọ́n fipá bá a lòpọ̀- Ìyá Barakat
Ni ọjọ Iṣẹgun ni okiki iroyin kan kaakiri igun mẹrẹẹrin orilẹede Naijiria nipa iku omọdebinrin kan tawọn kan gba ẹmi ẹ lẹyin ti wsn fi ipa baa lo pọ.
Oniruuru iroyin lo si ti waye lori rẹ ti ọpọ awọn eekan si ti n ke sawọn agbofinro lati tete fi oju awọn aṣebi to ṣiṣẹ naa sita.
Amọṣa titi di bi a ṣe n sọrọ yii, diẹ lara awọn ti a mọ nipa iṣẹlẹ iku rẹ niyi:
Eyín ọ̀ọ́kán mi ni Barakat tí wọ́n pa lẹ́yìn tí wọ́n fipá bá a lòpọ̀- Ìyá Barakat
Justice For Barakat: Nítòsí balùwẹ̀ ni wọ́n ti bá Barakat nínú àgbàrá ẹ̀jẹ̀, lẹ́yìn tí wọ́n fipá báa lòpọ̀- Ìyá Barakat
Ati ẹbi ati awọn aladugbo lo pejupesẹ lati kẹdun arabirin Barakat Bello, ọmọ ọdun mejidinlogun ti awọn oniṣẹ ibi kan gba ẹmi rẹ lẹyin ti wọn fi ipa baa lopọ lọjọ Iṣẹgun.
"Lẹyin ti ijọba apapọ paṣẹ wi pe ki awọn ile ẹkọ di titi pa ni Barakat kuro ninu ọgba ile ẹkọ ti a ti n kọ nipa ilera ohun ọsin ati ohun ọgbin, ""Federal College of Animal Health and Production"", ni agbegbe Apata nilu Ibadan gẹgẹ bi akẹkọọ to n bẹ ni ipele akọkọ."
Adugbo Oloro ni agbegbe Akinyẹle nilu Ibadan ni Baraka n gbe pẹlu awọn obi rẹ lati igba naa.
Iya oloogbe Barakat,  Arabinrin Kafayat Bello ba ikọ BBC Yoruba sọrọ lasiko ti a ṣe abẹwo si ile wọn lowurọ Ọjọru.
Arabirin Kafayat ni Baraka ati aburo rẹ ọmọkunrin ẹni ọdun bii meje si mẹjọ ni wọn fi silẹ ni ọjọ ti iṣẹlẹ naa ṣẹlẹ.
`
Wọn ni lẹyin asiko diẹ ni aburo ti o jẹ ọkunrin jade lọ ra nnkan ti o si ku oloogbe nikan sile.
Igba ti aburo to jade lọ yoo fi pada sile ni o dede kan ẹgbọn rẹ ninu agbara ẹjẹ ni itosi baluwẹ wọn to n bẹ ni ẹyinkunle.
Ariwo ọmọkunrin naa lo jẹ ki o han si gbogbo aladugbo wi pe ọfọ ti ṣẹ.
Ike omi meji ti oloogbe pọn lati fi wẹ ṣi wa lẹgbẹ baluwẹ naa titi di asiko yii pẹlu ami agbara ẹjẹ oloogbe.
Lẹyin o rẹyin ni wọn kẹsi ọlọpaa ti ayẹwo iṣegun ṣi fihan nipa iku gbigbona ni oloogbe ku lẹyin ti wọn fi ipa baa lopọ tan.
Iya baraka ṣe apejuwe ọmọ rẹ ti di oloogbe gẹgẹ bii eyin ọọkan ati ogo idile ti oun ati baba rẹ n reti wi pe yoo tọju awọn ati aburo rẹ titi dọjọ alẹ.
O ni oun bẹ Ọlọrun lati fi oju aṣebi han ki o to di ọjọ meje.
Ẹgbọn iya oloogbe ti o ba wa sọrọ, Arakunrin Ọlalẹyẹ Dauda ni Baraka nikan lo le ṣe alaye bi ẹmi ṣe bọ lọrun oun.
Dauda sọ wi pe ọgbẹ ọkan nla ni iku ọmọbinrin naa da silẹ nitori o jẹ daadaa ti gbogbo eeyan fẹran nigba aye rẹ.
Lọjọ ti Baraka ku naa ni wọn sinku rẹ ni ilana ẹsin Islam.
Lọwọlọwọ bayii, ajọ ọlọpaa nipinlẹ Ọyọ ti bẹrẹ iṣẹ iwadii lori awọn olubi ẹda to da idile naa loro.
Oríṣun àwòrán, Twitter/aduke
Iroyin kan to n gbona loju opo ikansiraẹni Twitter ni aarọ Ọjọru lo n beere fun idajọ lori iku to pa omidan Barakat Bello.
Barakat, to jẹ akẹkọọ ile ẹkọ imọ nipa itọju ẹranko (Federal College of Animal Health and Reproduction) la gbọ pe o n gbe lagbegbe Akinyele nilu Ibadan, níbi ti awọn gende kan ti fipa baa lopọ, ki wọn to gbẹmi rẹ.
Barakat, ẹni taa gbọ pe wọn ti sin, ni ọpọ eeyan lori ayelujara wa n beere pe ki awọn agbofinro ṣe awari awọn to fi tipa ba lopọ, ti ẹmi rẹ fi bọ.
Iroyin naa ni ọmọdebinrin naa, tii ṣe ẹni ọdun mejidinlogun, to maa n da aṣọ hijab bori bii musulumi ododo, ni baba rẹ ba oku rẹ ni ayika ile wọn, ti wọn si sawari rẹ pe awọn ọkunrin kan lo fi tipa baa lopọ.
A gbọ pe ẹgbẹ awọn akẹkọọ nile ẹkọ giga nilẹ wa ti n figbe bọnu pe ki ìjọba tan ina wadii iku to pa omidan naa to jẹ ọkan lara wọn.
Bẹẹ ba si gbagbe, irufẹ iṣẹlẹ ifipabanilopọ yii ti waye laarin ọsẹ kan sira wọn fun ọmọbìnrin meji miran eyi to n mu ki awọn araalu figbe bọnu.
Ṣugbọn nigba ti BBC Yoruba kan si Ileesẹ ọlọpaa ipinlẹ Oyo lati fi idi iṣẹlẹ naa mulẹ, alukoro ọlọpaa nipinlẹ Ọyọ, Olugbenga Fadeyi ni iṣẹlẹ naa ko tii de etigbọ awọn agbofinro rara.
Osun state lockdown update: Awọn òṣìṣẹ́ padà sí ẹnu iṣẹ́ ní ìpińlẹ̀ Osun
Oríṣun àwòrán, twitter/Adegbeoyega oyetola
Ijọba ipinlẹ Ọṣun ti dẹ ọwọ aṣẹ konile o gbele to gbe kalẹ lati dẹkun itankalẹ arun coronavirus ni ipinlẹ naa.
Ninu atẹjade kan to fi sita lalẹ ọjọbọ, gomina ipinlẹ Ọṣun, Gboyega Oyetọla ṣalaye pe ofin konile o gbele yoo wa silẹ lati maa waye laarin agogo mẹsan si marun un owurọ.
O ni ki gbogbo awọn oṣiṣẹ ijọba lati akasọ igbega keje soke o pada si ẹnu iṣẹ wọn.
Bakan naa lo ṣalaye pe gbogbo awọn ọja nlanla ni ipinlẹ ọhun ni ko ṣi wa ni titi pa, ṣugbọn awọn ọja yooku ti wọn ṣi, awọn ọlọja nibẹ gbọdọ bọwọ fun awọn ilana idaabobo ara ẹni ti ajọ NCDC ati ileeṣẹ eto ilera apaps gbe kalẹ.
Amọṣa o, ọsẹ meji ni wọn yoo kọkọ fi yiri igbesẹ ilana tuntun yii wo.
Awọn afunrasi ti ọwọ ofin mu lori iku arabinrin Funkẹ Ọlakunrin to jẹ  ọmọbibi aṣiwaju ẹgbẹ afẹnifẹre, Baba Rueben Faṣọranti pada si ile ẹjọ lọjọru nibi ti wọn yoo ti maa farahan niwaju adajọ majisireeti agba ni ilu Akurẹ.
Ni ọjọ kejila oṣu keje ọdun 2019 ni awọn agbebọn kan kọlu ọkọ ti oloogbe Funkẹ Arakunrin wọ ni opopona marosẹ Sagamu si Ọrẹ.
Adajọ majisireeti agba, Victoria Bob-Manuel ti kọkọ gbọ ẹjọ naa ni ọjọ kẹrinlelogun oṣu kẹrin ọdun 2020 to si ni ile ẹjọ ọhun ko laṣẹ labẹ ofin lẹyin to fi buwọlu ẹbẹ olupẹjọ lati fi awọn afunrasi naa si atimọle ki o to sun igbẹjọ wọn si ọjọru ọjọ kẹta oṣu kẹfa.
Awọn afunrasi mẹrin ti wọn pe orukọ wọn ni Auwal Abubakar, Muhammed Shehu Usman, Lawal Mazaje ati Adamu Adamu lawọn agbofinro mu ti wọn si n fi ẹsun igbimọpọ lati paniyan,ipaniyan ati ijinigbe ṣugbọn wọn ko ni agbẹjọro nigba ti ile ẹjọ gbọ ẹjọ naa
Lagos Jumat Mosques: Títì pa ni ìlẹ̀kùn àwọn mọ́ṣáláàṣí kan wà ní ìpínlẹ̀ Eko lásìkò ìrun Jímọ̀
Paroparo ni awọn mọṣalaaṣi kan da nilu Eko, lasiko irun Jimọ to yẹ ko waye.
Eyi yani lẹnu botilẹjẹ pe ijọba ipinlẹ Eko ti kede pe ki awọn ile ijọsin bẹrẹ sini ṣi pada lati ọjọ Jimọ, ọjọ keje, oṣu Kẹjọ, lẹyin oṣu bi i maarun ti wọn ti ti ilẹkun wọn nitori isede aarun coronavirus.
Lasiko ti akọroyin BBC kan de awọn mọṣalaaṣi bi ti Ikoyi ati Lekki lati kirun, titi pa ni awọn ilẹkun ibẹ wa lai si irun Jimọ.
Ṣugbọn ṣa, irun Jimọ waye ni awọn mọṣalaaṣi kan.
Awọn musulumi nipinlẹ Eko yoo laanfani lati kopa ninu irun Jimọ loni lẹyin nkan bi oṣu mẹrin ti ijọba fofin de akojọpọ lawọn ile ijọsin.
Awọn ṣọọṣi naa yoo ṣi pada lọjọ Aiku.
Lati oṣu kẹta ọdun 2020 ni ijọba ti ni ki wọn sọ agadagodo sawọn Mọṣalaṣi ati Ṣọọṣi nitori ajakalẹ arun Covid-19.
Kwara: Fọ́fọ́fọ́ ni mọ́ṣáláṣí kún tí ìlànà ìjìnàsíraẹni 'social distancing' sí forí
Gomina ipinlẹ Eko, Babajide Sanwo-Olu sọ pe igbesẹ ṣiṣi awọn mọṣalaṣi yi jẹ apẹrẹ pe Naijiria n tẹsiwaju ninu idoju ija kọ arun Covid-19.
Ṣugbọn ṣa ijọba ni ida meji awọn to ba yẹ ko wa ni aaye ijọsin naa ni awọn yoo faye gba lati jọsin.
Bẹẹ ni wọn ni awọn olujọsin gbọdọ tẹle ilana bi wiwọ ibomu,fifọ ọwọ ati ijinasiraẹni lasiko ti wọn ba n kirun.
Aarẹ Muhammadu Buhari ti fi ọwọ si afikun ọsẹ mẹrin si abala keji didẹwọ isede coronavirus.
Akọwe ijọba apapọ, to tun jẹ Alaga fun igbimọ to n mojuto itankalẹ aarun Covid-19, Boss Mustapha, lo kede eyi lasiko ti o n ba ara ilu sọrọ l'Ọjọbọ.
O ni isede to n bẹrẹ laago mẹwa alẹ ṣi wa sibẹ.
Mustapha sọ pe igbesẹ yii waye lati le fi idi aṣeyọri ti Naijiria ti n ṣe lori igbogbun ti aarun coronavirus mulẹ.
Ìdílé tí ọkọ da ọmọ síta tóríi ojú Búlùú tí wọ́n ní bá BBC sọ̀rọ̀
Gẹgẹ bi o ṣe sọ, àwọn ayipada ti yoo kan wa ni pe wọn yoo bẹrẹ si ni ṣi papakọ ofurufu fun irinajo si ilẹ okeere diẹdiẹ, ni ibamu pẹlu awọn ilana to yẹ.
Igbimọ amuṣẹya naa sọ pe ki awọn ileeṣẹ baalu to n rinrinajo lọ silẹ okeere, ati awọn alaṣẹ papakọ ọk ofurufu bẹrẹ igbaradi fun ṣiṣi irinajo silẹ okeere.
Bakan na ni irinajo ọkọ oju'rin naa yoo bẹrẹ pada.
Ṣugbọn ko gbọdọ si irinajo laarin ipinlẹ kan si omiran lasiko isede fun awọn arinrinajo loju popo.
Botilẹjẹpe ofin ṣi de awọn ile faaji, ijọba sọ pe oun ti gbẹsẹ kuro lori ofin to de lilọ si awọn ọgba igbafẹ, ṣugbọn ko gbsdọ si ifarakan ara nibẹ.
Ko tan sibẹ o, Ọgbẹni Mustapah tun kede pe awọn eero ọkọ baalu labẹle le ma a de si papakọ ọkọ ofurufu ni wakati kan ataabọ ṣaaju irinajo wọn, dipo wakati mẹta ti ijọba kede tẹlẹ.
Ṣugbọn ṣa, o sọ pe dandan ṣi ni fun gbogbo eniyan lati maa tẹle awọn ilana ti ijọba la kalẹ.
Oríṣun àwòrán, Others
Ìgbìmọ̀ amúṣẹ́ṣe ìjọba àpapọ̀ lórí Covid-19 ti fẹdun ọkan wọn han lori bi itankalẹ aarun Coronavirus ṣe n pọ si laarin awọn to n bẹ nì'jọba.
Eyi si ni wọn lo n mu isoro ba eto isejọba ati didaabo bo ilu lọna to yẹ lorilẹ-ede Naijiria.
Alaga igbimọ ọhun, to tun jẹ akọwe ìjọba apapọ, Boss Mustapha lo salaye ọrọ yii lasiko ijabọ bi nkan ṣe lọ fun ara ilu to ma n waye l'Abuja lojoojumọ.
O sọ ọ di mimọ pe, ṣiṣe ofin konile ogbele tuntun miran le waye lati dẹkun itankalẹ arun yii to n peleke sii.
Akọwe ìjọba wa rọ gbogbo ọmọ Naijiria lati tẹle àwọn ilana to yẹ lati dena aarun Coronavirus nitori pe aarun naa ko mọ olowo tabi talaka.
Kemi Dairo: Iṣẹ́ abẹ nínú ọpọlọ àti ẹ̀rọ ni mo fi ń gbọ́ ọ̀rọ̀ báyìí
Ikilọ alaga yii ko sẹyin bi awọn gomina ipinlẹ lọkan o jọkan, ṣe n lugbadi arun naa ni lọọlọ yii.
Laipẹ yii ni Gomina Ondo, Rotimi Akeredolu, Gomina Ebonyi David Umahi ati awọn miran lugbadi aarun naa.
Mustapha wa kilọ fun awọn to wa nipo aṣẹ lati sọra nitori gbogbo awọn to ti lugbadi arun laipẹ ba ṣe aisan, eyi yoo di isejọba lọwọ lati seto ilu ati lati daabo bo wọn.
Oríṣun àwòrán, Others
A rọ gbogbo ọmọ Naijiria lati maa foju s'ọri bi alakan, yala o jẹ olowo tabi talaka. Aarun yii ko bikita ipo ti ẹnikẹni wa, sugbọn igbimọ amusẹya ìjọba ko ni sinmi, lati maa ṣe ikilọ ni igba gbogbo.
Ẹwẹ, Boss Mustapha ni, awọn nkan to ba jẹyọ ni awọn ọsẹ to n bọ yii, ni yoo sọ inu odo ti igbimọ naa yoo da ọrunla si lori pe, boya ki ìjọba kede igbele gbogboogbo miran..
A o le sọ nkan ti yoo sẹlẹ lọjọ iwaju sugbọn nkan to ṣe pataki julọ ni pe, didaabo bo awọn ọmọ Naijiria lo ṣe pataki julọ.
Mama Arsenal: Màmá àgbà yìí máa ń lọ sí ìbùdó tí wọ́n ti ń wo bọ́ọ́lù láti wòran
"Lati ṣe eyi, to ba jẹ pe kikede konileogbele lọna abayọ, a o ṣe bẹẹ gẹgẹ.
A o gbe abajade iwadi ati ero wa siwaju Aarẹ lati ṣe ipinnu lori aba igbimọ amusẹṣe, nkan to ba sẹlẹ ni ọṣẹ mẹta si asiko yii ni yoo sakawe igbesẹ ti ijọba yoo gbe."
Oríṣun àwòrán, others
Saaju la ti kede pe awọn asaaju ẹgbẹ ọmọlẹyin Kristi (CAN) ti n sọrọ lori aṣẹ ti ìjọba apapọ pa pe, awọn ọmọde ati arugbo ko gbọdọ lọ sile ijọsin.
Nigba ti wọn n ba BBC Yoruba sọrọ lori iṣẹlẹ yii, awọn alaga ẹgbẹ CAN nipinlẹ Oyo ati Ondo, Pasitọ Benjamin Akanmu ati Ayo Oladapo woye pe, ijọba fẹ tete sekupa awọn arugbo ni, ti wọn ko ba ni anfaani lati jade sita.
Lero ti Akanmu, erokero ati iku ojiji ko jinna si arugbo to ba da nikan wa nile, ti aigbọ ọrọ Ọlọrun ni oore koore ko si le ṣe awọn ọmọde loore.
O wa daba pe ki ijọba kesi awọn onimọ ijinlẹ lati tete wa ọna abayọ si arun Coronavirus yii, nitori itọju la nilo, kii ṣe ka gbe ilẹkun ile ijọsin ti pa.
Ohun to n ba ijọba ipinlẹ Oyo lẹru ni pe awọn eeyan to n lugbadi arun Covid-19 n pọ si dipo ki wọn dinku, eyi lo mu ko tilẹkun ile ijọsin, ẹni to si kan lo mọ, amọ gbogbo ọkan lo n pohungbẹ lati wa sile Ọlọrun, ipa ti adura si n ko, kii ṣe ipa kekere.
Oríṣun àwòrán, others
Ninu ọrọ tiẹ, alaga ẹgbẹ CAN ni Ondo salaye pe, ijọba kan n fi ẹtẹ silẹ, maa pa lapalapa ni nitori awọn onimọ isegun ti kede saaju pe, awọn arugbo ni ko sa fun Covid-19, kii ṣe ọmọde.
"Oladapo ni "" Ti awọn obi ba lọ sile ijọsin, nibo ni wọn fẹ fi awọn ọmọ wọn si, ṣe wọn yoo tilẹkun mọ wọn sile ni abi wọn yoo ko wọn da si titi? Ijọba apapọ ko ro ero rẹ daadaa ko to gbe sita."""
O fikun pe o dara bi awọn arugbo ba joko sile, amọ wahala ni wọn fẹ da silẹ pẹlu ọmọde ti wọn ni ko jokoo sile, tori awọn ọmọde ko ni pẹ maa sọnu ladugbo.
Oladapo, to faramọ awọn ilana tijọba Ondo gbe kalẹ lori ijọsin tun ni, ohun to dara ni bi ijọba ṣe kọkọ tilẹkun ile ijọsin pa nitori igbagbọ ninu Kristi ko ni idiwọ, isẹ Ọlọrun si n tẹ siwaju.
Nollywood stars: Àwọn èèkàn òṣèré sinimá ní Nàìjíríà jẹ́wọ́ ara wọn lórí fífi àmì ohùn sí ọ̀rọ̀ Yorùbá
Wọn ni oogun ti a ko ba fi han ọmọ ẹni kii pẹ parun.
Ọpọ lo n kọminu lori ede Yoruba ati bi ti yoo de duro nigba ti a o ba fi ri asiko diẹ si.
Eyi lo mu ki ikọ BBC News Yoruba tọ diẹ lara awọn amuludun ti wọn n fojojumọ gbe sinima Yoruba jade pe, bawo ni lori fifi ami ohun si ọrọ Yoruba. Abọ wa niyi,  Ẹ gbe e yẹwo.
Olumilua: Mimiko ní olóògbé náà kìí ṣe olóṣèlú jẹgúdú-jẹrá, irú rẹ̀ kò sì wọ́pọ̀ mọ́
Oríṣun àwòrán, others
Idi ree ti kọmisana tẹlẹ nigba ti oloogbe Bamidele Olumilua jẹ gomina nipinlẹ Ondo ijọun, toun naa si pada jẹ gomina nipinlẹ naa lẹyin rẹ, Dokita Olusegun Mimiko fi n ṣe idaro ọga rẹ, Olumilua, to papoda ni owurọ Ọjọru lẹni ọgọjọ ọdun.
Nigba to n ba BBC Yoruba sọrọ lori iku Olumilua, Mimiko ni eeyan gidi ati ẹni Ọlọrun ni ọga oun naa, to si jẹ oselu to nifẹ awọn araalu pẹlu ibẹru Ọlọrun.
"Mimiko sọ siwaju pe "" igba ti mo ṣíṣẹ labẹ wọn lọdun 1992 gẹgẹ bii kọmisana, wọn kọ wa bi wọn ṣe n fi ara ati ọkan sin ilu, oselu tiwọn kii si ṣe oselu jẹgudu-jẹra, ki la le ri ko, oselu ti wọn fi sin Ọlọrun ati eniyan ni."""
Inu mi dẹ dun pe titi ti wọn fi papoda, n ko jinna si wọn, awọn naa ko si fi mi silẹ ninu gbogbo ipo akoso ti mo dimu, wọn maa n gba mi niyanju, ko dẹ si gbogbo ayẹyẹ ti mo ṣe nigba ti mo wa ni gomina, ti wọn kii wa.
Gomina tẹlẹ nipinlẹ Ondo naa ni orileẹ-ede Naijiria maa mọ ipapoda Olumilua lara nitori oloselu bii tiwọn ko pọ mọ, to jẹ pe bi wọn ṣe n fi tọkan-tara sin araalu, ni wọn n sin Ọlọrun.
Mimiko wa gbadura pe ogun ti oloogbe Bamidele Olumilua fi silẹ ko ni bajẹ, ti Ọlọrun yoo si tẹ si afẹfẹ rere.
Oríṣun àwòrán, others
Yoruba ni ọjọ taa dele aye ko to ọjọ ta ba ku, nitori iṣẹ ọwọ wa ni yoo sọ nipa ohun ta ba gbe ile aye ṣe.
Bẹẹ ni ọrọ ri fun gomina tẹlẹ nipinlẹ Ondo ijọun, tii tun ṣe agba oselu ati majẹobajẹ ilu, Bamidele Isola Olumilua to jade laye ni aarọ Ọjọru.
Ni wọn igba to jẹ pe arise ni arika, arika si ni baba iregun, ohun ta ba fi oni ṣe, itan ni yoo da lọjọ ọla, idi ree ta fi ṣe akojọpọ itan igbe aye agba oselu to di oloogbe naa.
Oríṣun àwòrán, Others
Iroyin to n tẹ wa lọwọ ni yajoyajo n fi ye wa pe Olumilua jade laye ṣugbọn a ko tii lee fi idi iku to paa mulẹ.
Ọdun 1940 ni wọn bi Bamidele silu Ikere Ekiti, o kawe, o gboye rẹpẹtẹ ni Naijiria ati loke okun, ko to dara pọ mọ eto iselu.
Bamidele dara pọ mọ ẹgbẹ oselu Ẹlẹsin SDP ni saa isejọba alagbada kẹta, to si dupo wọle  gomina nipinlẹ Ondo ijọun ni oṣu Kinni ọdun 1992.
Lasiko ti Olumilua jẹ gomina, Olusegun Agagu ni igbakeji rẹ, nigbati Dokita Olusegun Mimiko jẹ komisana feto ilera, ohun iwuri si lo jẹ pe Agagu ati Mimiko pada jẹ gomina nipinlẹ Ondo, lẹyin Olumilua.
Iroyin to n tẹ wa lọwọ ni yajoyajo n fi yeni pe gomina ipinlẹ Ondo nigbakan ri, Ajihinrere Bamidele Olumilua ti di ara ilẹ.
Baba Olumilua jade laye ni owurọ Ọjọbọ.
Gẹgẹ bi ohun ti ọmọ rẹ ṣe lalaye fun BBC News Yoruba lori ẹrọ ibanisọrọ, ẹni ọgọrin ọdun ni Ajihinrere Bamidele Olumilua ki ọlọjọ to de.
Iroyin to n tẹ wa lọwọ ni yajoyajo n fi ye wa pe Olumilua jade laye ṣugbọn a ko tii lee fi idi iku to paa mulẹ.
Amọ kokoro awọn ologun ko jẹ ki awọn eeyan ipinlẹ Ondo gbadun obi Olumilua to gbo kaka, nitori oṣu Kọkanla ọdun 1993 ni awọn ologun gba ijọba lọwọ awọn oloselu alagbada, eyi ti oloogbe Sani Abacha ṣe agbatẹru rẹ, ti wọn si yẹ aga akoso mọ Olumilua nidii.
Yoruba ni bi ẹṣin ba da ni, a mọ tun gun, idi ree ti Bamidele tun fi dara pọ mọ ẹgbẹ oselu PDP lọdun 1998, ti wọn si yan sipo alaga igbimọ to n seto idẹrun fawọn arinrin-ajo silẹ mimọ Jerusalemu.
Amọ ninu oṣu kẹjọ ọdun 2005, ni ẹgbẹ oselu PDP fi ikede sita pe Bamidele Olumilua kii ṣe ọmọ ẹgbẹ oun mọ, nigba to si di ọdun 2006 ni oloogbe naa dara pọ mọ awọn agba ilu kan lati da ẹgbẹ oselu Action Congress, AC silẹ.
Nollywood stars: Àwọn èèkàn òṣèré sinimá ní Nàìjíríà jẹ́wọ́ ara wọn lórí fífi ohùn àmì
Ni ọdun 2012 tun ni wọn yan Olumilua gẹgẹ bii baba isalẹ fasiti ipinlẹ Ekiti, EKSU.
Nigba to jẹ pe awaye ku ko si, Bamidele Olumilua jẹ ipe Ọlọrun ni owurọ kutu hai Ọjọru, ọjọ Kẹrin oṣu Kẹfa ọdun 2020 lẹni ọgọrin ọdun nilu rẹ, Ikere Ekiti.
BBC Yoruba wa gbadura pe ọba oke yoo dẹ ilẹ fun ẹni re to lọ.
Mercy Aigbe: Àwọn òṣèré tíátà Yorùbá mẹ́wàá tí kìí ṣe Yorùbá
Oríṣun àwòrán, others
Agbo nla ni ẹka awọn oṣere tiata ni ede Yoruba, ti wọn si ni ogunlọgọ awọn oṣere tiata ti ko see fi ọwọ rọ danu.
Bi o tilẹ jẹ pe ọpọlọpọ wọn ni ede Yoruba dantọ ni ẹnu wọn lasiko ti wọn ba n ṣe sinima, sugbọn iyalẹnu lo jẹ pe awọn kan wa ninu wọn, ti kii ṣe ọmọ Yoruba.
Diẹ lara awọn ti kii ṣe ọmọ Yoruba ninu awọn oṣere naa ree:
Oríṣun àwòrán, Rachael Oniga
Bakan naa, agba ọjẹ oṣere tiata ni ede Yoruba ati oyinbo, Racheal Oniga jẹ ọmọ bibi ipinlẹ Delta.
Gbajumọ oṣere yii, ti ede Yoruba yọ lẹnu rẹ lo wa lati ilu Eku ni ẹkun guusu Delta, to si n fi ede Yoruba sisọ jẹun.
Ìròyìn Yàjóyàjó - Ṣé lóòtọ̀ ni gbajúgbajà òṣèré, Racheal Oniga ti jáde láyé?
Oríṣun àwòrán, Faithia Williams
Faithia Williams tawọn eeyan mọ si Faithia Balogun tẹlẹ ni oju rẹ wọpọ ninu ere tiata Yoruba.
Faithia, tii ṣe iyawo gbajumọ oṣere miran, Saheed Balogun, ṣe jẹ agba ọjẹ oṣere to dangajia, naa lo tun jẹ adari ati Olootu ere sinima.
Ọmọ bibi ilu Okpara nijọba ibilẹ ila oorun Ethiope, nipinlẹ Delta si ni akikanju oṣere tiata yii.
Oríṣun àwòrán, Doris Simon
Ilumọọka oṣere bìnrin alawọ pupa yii lo wa lati agbegbe Okpella ni ẹba ilu Benin.
Obìnrin to n sọ ede Yoruba bii ẹni layin naa si lo ti gba ami ẹyẹ lọpọlọpọ lori sinima to ṣe ni ede Yoruba.
Oríṣun àwòrán, Rykardo Agbor
Ọmọ bibi ipinlẹ Delta naa ni Rykardo Agbor amọ to gbe ilu Eko dagba.
Yoruba yọ lẹnu gbajumọ oṣere tiata lọkunrin naa debi pe ko si owe ti ko lee pa ninu sinima, to si tun maa n ṣe tiata lede oyinbo pẹlu.
Oríṣun àwòrán, Kelvin Ikeduba
Ilu Eko ni oṣere tiata yii gbe dagba, ti ede Yoruba si da lẹnu rẹ sugbọn ọmọ bibi ipinlẹ Delta ni oun naa n ṣe.
Agbegbe ẹya Igbo to wa ni Delta lawọn obi Kelvin ti wa, bo si ṣe n sere ni ede Yoruba naa lo n kopa ninu sinima oloyinbo.
Oríṣun àwòrán, Rose Odika
Agba ọjẹ pọnbele ni Rose Odika, to si ti di igi araba ninu sinima lede Yoruba bi o tilẹ jẹ pe ẹya miran lo ti wa.
Rose, ẹni to wa lati agbegbe Igbo nijọba ibilẹ Aniocha nipinlẹ Delta, lo tun jẹ gomina fun gbogbo awọn onitiata lede Yoruba nipinlẹ Oyo.
Oríṣun àwòrán, Liz Da Silva
O loju ẹni to lee gbagbọ pe ọmọbìnrin yii kii ṣe ọmọ Naijiria rara, debi pe yoo jẹ ọmọ Yoruba, ọmọ bibi orilẹ-ede Togo nii ṣe.
Elizabeth Ọmọwunmi Tekovi Da-Silva ni apetan orukọ rẹ, amọ ilu Eko ti wọn bi si lo ṣe iranlọwọ fun lati maa fi ede Yoruba jẹun.
Oríṣun àwòrán, Mercy Aigbe
Odu ni Mercy Aigbe ninu awọn sinima ede Yoruba, kii si ṣe aimọ fun oloko rara nitori ẹwa ati ede Yoruba ẹnu rẹ to dantọ.
Ọmọ bibi ipinlẹ Edo ni gbajumọ oṣere tiata naa, to tun jẹ oludari ere sinima ati gbajugbaja oloko-owo.
Oríṣun àwòrán, Toyin abraham
Toyin Abraham jẹ ẹni taye n fẹ ninu tiata Yoruba, to si ti ṣe ọpọ sinima jade ni ede Yoruba.
Lootọ ni pe ilu Ibadan ti Toyin gbe dagba ṣe iranwọ fun lati gbọ ijinlẹ ede Yoruba amọ ọmọ bibi ilu Auchi nipinlẹ Edo nii ṣe.
Oríṣun àwòrán, Regina chukwu
Orukọ Regina Chukwu lasan ti to lati fihan pe kii ṣe ọmọ Yoruba, sugbọn ede Yoruba lo fi n jẹun ninu ere tiata lede Yoruba.
Ọmọ bibi ipinlẹ Enugu ni Regina sugbọn ilu Eko lo gbe dagba, to si n fi ede Yoruba dabira ninu sinima.
Abiola Ajimobi: APC àti ALGON ti mú àbá tuntun jáde lórí ọ̀rọ̀ gómìnà Ọyọ àná
Oríṣun àwòrán, Abiola Ajimobi
Ẹgbẹ oṣelu All Progressives Congress, APC ni ipinlẹ Oyo ati ẹgbẹ awọn alaga ijọba ibilẹ, ALGON, ẹka tipinlẹ Oyo, ti bẹrẹ eto aawẹ ati adura fun ilera adele alaga ẹgbẹ oselu APC nipinlẹ Oyo, Abiola Ajimobi.
Atẹjade kan ti ẹgbẹ APC fisita nilu Ibadan wa rọ gbogbo ẹmọ ẹgbẹ wọn lati gba awẹ ati adura ẹjọ mẹtanaa, eyi to bẹrẹ ni ọjọ Aje, ọjọ kejilelogun oṣu kẹfa ọdun 2020.
 A rọ gbogbo ọmọ ẹgbẹ APC lati gbadura kikan kikan fun gomina ipinlẹ Oyo tẹlẹ ri, Sẹnetọ Abiola Ajimobi. A gbadura ki ara rẹ ya kia kia.
Ninu atẹjade mii ti alaga ẹgbẹ ALGON, ọmọba Ayodeji Abass Aleshinloye fọwọ si, o jẹ ko di mimọ pe ajọgba ni awẹ ati adura naa ko ba jẹ nita gbangba ṣugbọn nitori akoko ti a wa yii, eyi ti Coronavirus n dari, ni wọn ṣe ni ki onikaluku gba a ni adagba.
"O ni ""yala ẹnikẹni ro iku tabi iye ro o, gbogbo eeyan lo jẹ gbese iku ti wọn si gbudọ san, tori naa, ki lo de taa fẹ kanju tufọ rẹ nigba ti akoko rẹ ko tii to. Eewọ ni koda nile alaye ka maa ro iku ro ọta ẹni""."
Ọlọrun lo n fun ni, to si ngba a, fun idi eyi ko sẹni to lagbra lori aye ẹlomiran.
Kid boxer: Ọmọọba 'The Buzz' Larbie rèé, ọmọ ọdún méje tó ń fi ẹ̀ṣẹ́ dá bírà
Abass ni ọlọyaya eeyan ni sẹnetọ Ajimobi, o si yẹ ki awọn ọmọ Naijiria kọ eti ikun si iru iroyin bẹẹ.
Bi ẹ o ba gbagbe, sẹnetọ Abiola Ajimobi to jẹ wipe ara rẹ ko ya nitori pe o lugbadi COVID-19, ni awọn kan n tan iroyin kalẹ pe o ti ku.
"Ẹgbẹ ALGON Oyo ni ""a fẹ fi yee yin pe, Sẹnetọ wa Abiola Ajimobi, adari wa ko ku, ko si ni ku bi ko ṣe yiye""."
Oríṣun àwòrán, Instagram/ajimobi
"Wọn ni ""Ajimobi ti a mọ si ẹni to kọ Oyo ode oni ṣe iṣẹ ribiribi, o si tun sin ipinlẹ rẹ fun odidi ọdun mẹjọ, ko si wa yẹ ki wọn ro iku ro o, paapaa lasiko yii ti o ti gba igbega lati tukọ ẹgbẹ oṣelu APC ni gbogbo Naijiria."
Ninu igbiyanju wa lati fi idi otitọ mulẹ lori awuyewuye to n lọ ni igboro, ikọ BBC Yoruba ṣe abẹwo si ile gomina tẹlẹri nipinlẹ Ọyọ, Abiọla Ajimọbi.
Ile naa wa ni agbegbe Oluyọle ni ilu Ibadan, ṣugbọn a ko ri ẹnikẹni ti o le ba wa sọrọ nibẹ.
Paroparo ni ayika ile naa da lasiko ti a ṣe abẹwo sibẹ lọsan ọjọ Ẹti.
Lọwọlọwọ, ile iwosan kan lagbegbe Ikoyi ni ilu Eko ni iroyin ni Ajimobi wa lasiko yii.
Ọpọ igba ti gomina tẹlẹ ni ipinlẹ Ọyọ naa ko ba si nile ni Ibadan naa ṣi ni lawọn ololufẹ rẹ kan tabi meji ṣi maa n wa bẹ ile naa wo lati ṣe baba kẹẹ pẹ si 'Akanji' gẹgẹ bi ọpọ tun ṣe maa n pe e.
Nigba ti akọroyin BBC News Yoruba de agbegbe ile rẹ ni Oluyọle Estate gbogbo ọna abawọle mejeeji to wọ adugbo Agbaoye ibadan naa lo da paroparo ti wọn si ti abawọle ile rẹ gba-gba-gba.
Koda, ko si ero ni titi nitori gbogbo adugbo naa da waiwai ni.
Ẹbi Gomina àná ni ipinlẹ Oyo, Senetọ Abiola Ajimọbi ti jade sita wa sọ pé irọ ni pe Ajimọbi ku!
Wọn ni ahesọ lasan ni ọrọ tó n ja ranyinranyin nilẹ pe igbakeji alaga ẹgbe oṣelu APC naa ti jade laye nipasẹ ajakalẹ arun coronavrus.
Fatima Ganduje Ajimọbi to jẹ ọmọ gomina Abdullahi Ganduje to n tukó ipinlẹ Kano to fẹ ọmọkunrin Abiola Ajimobi fi ọrọ naa lede loju opo twitter rẹ pe irọ ni.
Ahesọ yii ko ṣẹyin bi wọn ṣe kọkọ n sọọ kiri pe Ajimọbi ti lugbadi Covid 19 to si n gba itọju nile iwosan aladani kan ni ipinlẹ Eko.
Lọjọ Iṣẹgun, ọjọ kẹrindinlogun, oṣu kéfa yii ni agbẹnusọ fun Senetọ Ajimọbi, Ọgbẹni Bolaji Tunji ti ba BBC Yoruba sọrọ ninu ifọrọwanilenuwo lori ohun to n ṣẹlẹ si Ajimọbi. sọrọ.
O ni Ajimọbi ti ṣelẹri lati yanju aawọ ẹgbẹ oṣelu APC lasiko ipade apapọ ẹgbẹ ti NEC to m bọ lọna.
Ladoja: Àwọn èèyàn Oyo fì ìbò sọ̀rọ̀ pé ìjọba Ajimobi kò dára
Sugbọn Agbẹnusọ Ajimọbi kò sọ nipato lati dahun ibeere boya Ajimọbi ni arun Coronavirus tabi bẹẹkọ rara.
Eyi ko si ṣẹyin awuyewuye to n ṣẹlẹ nipinlẹ Edo lori ọrọ Gomina Obaseki ati Adams Oshiomọlẹ to jẹ alaga ẹgbẹ APC.
Ṣaaju ni ẹgbẹ ti kọkọ kede Ajimobi gẹgẹ bii adele alaga kuro nipo igbakeji alaga to wa tẹlẹ.
Bakan naa ni Fatima tun dupẹ lọwọ awọn eeyan to n pe lati beere nipa Baba wọn Ajimọbi, o pari ọrọ rẹ pe ko si ẹni ti ko ni ku lọjọ kan ṣugbọn ẹbi Ajimobi n dupe pe o ṣi wa laaye.
Oríṣun àwòrán, Instagram/ abiola ajimobi
Ṣé lóòtọ́ ni òjòjò dá Abiola Ajimobi wólẹ̀?
Bi awọn eeyan kan ṣe n sọ pe egungun agba oṣelu naa ṣe bi ẹni jinna si ode ijo fun igba pipẹ lawọn miran n sọ pe o ṣeeṣe ko jẹ pe ọrọ coronavirus yii to jawe joko jẹẹ fun gbogbo mutumuwa naa lo kan baba.
Ni ọsẹ to kọja ni BBC News Yoruba gbe iroyin jade to n beere ibi gan an ti ọkọ Florence wa.
Amọṣa, lọwọ yii iroyin to n lọ kaakiri ni pe o ṣeeṣe ki ojojo maa ṣogun Abiọla Ajimọbi ki ara ogun rẹ o maa le.
Ọpọ lo tilẹ n wi pe o ṣeeṣe ki o jẹ pe aisan rẹ fẹ le diẹ lo jẹ ki baba Abimbọla o lọ fidimọle sibi kan.
Ohun ti awọn iroyin miran to n lọ kaakiri tilẹ tun n sọ ni pe ileewosan kan lagbegbe Ikoyi ni ilu Eko ni wọn gbe agba oṣelu naa lọ bayii fun itọju.
Ohun to wa mu ki gbongbo iroyin yii tun fẹ ṣe bi ẹni gbilẹ sii bayii ni ti atẹjade kan ti ẹka ẹgbẹ oṣelu APC ni ilẹ Gẹẹsi gbe jade loju opo twitter rẹ nibi to ti n ki igbakeji alaga ẹgbẹ oṣelu APC lorilẹ-ede Naijiria naa pe ko ṣara giri, aisan ko ni bori rẹ rẹ.
A o maa gbadura fun ajinde ara ni kiakia fun ọ. Bi ọjọ ti ṣe n gori ọjọ  naa ni ilera pipe n sun mọ ọ. Ero ilera pipe ni kiakia ni a n fi ranṣẹ si ọ-APC UK
Ti wọn si tun fi fidio kan tii nidi.
Ileẹjọ giga l'Abuja ni ohun ti ṣe afikun igba ti Ọgbẹ Giadom yoo nipo adele alaga gbogbogbo APC pẹlu ọsẹ meji.
Victor Giadom: Iléẹjọ́ gíga pàṣẹ pé kí Giadom jẹ adelé alága APC
Victor Giadom gbàṣẹ iléẹjọ́ gíga láti jẹ adelé alága APC
Igbakeji akọwe apapọ agba ẹgbẹ oṣelu APC, Victor Giadom ti gbaṣẹ lati ileẹjọ eyi to fun un lanfaani lati maa tukọ ẹgbẹ naa gẹgẹ bi adele alaga gbogbogbo APC.
Oríṣun àwòrán, Other
Gẹgẹ bi akọsilẹ ileẹjọ giga niluu Abuja ṣe sọ, ileẹjọ ti fikun asiko ti Giadom yoo lo gẹgẹ bi adele alaga gbogbogbo APC.
Ileẹjọ giga l'Abuja ni ohun ti ṣe afikun igba ti Ọgbẹ Giadom yoo nipo adele alaga gbogbogbo APC pẹlu ọsẹ meji.
Ọjọ kẹfa oṣu kẹta ni ileẹjọ kọkọ paṣẹ pe ki Victor Giadom maa ṣe ojuṣe gẹgẹ bi alaga ẹgbẹ oṣelu APC.
L'Ọjọru ni igbimọ amuṣẹya ẹgbẹ APC kede pe Giadom ko si lara awọn oloye ẹgbẹ naa mọ, wọn ni ko si ni ipo to di mu tẹlẹ mọ lati ọdun 2018.
APC ṣalaye pe Giadom kọwe fipo silẹ lọdun 2018 lati dije ipo igbakeji gomina nipinlẹ Rivers.
'Ètò ìdìbò sípò gómìnà Ondo, Edo yóò wọ́lẹ̀ nítorí rògbòdìyàn APC '
O seese ki eto idibo nipinlẹ Edo ati Ondo ki o ma lọ ni ọna ti awọn eniyan foju si nitori rogbodiyan to n waye nibẹ.
Onwoye eto oṣelu lawujọ, Yemisi Fadairo ni ija ati asọ to n ṣẹlẹ ni ẹgbẹ oṣelu le mu ki awọn eniyan dibo fun ẹgbẹ oselu miran to yatọ ẹgbẹ oselu APC ati PDP.
Oríṣun àwòrán, Others
Saaju idibo sipo gomina ni ipinlẹ Edo ati Ondo, ẹgbẹ oṣelu APC n koju rogbodiyan lori tani alaga ẹgbẹ oṣelu naa.
Fadairo ni a ko le sọ ibi ti idibo naa yoo fori sanpọn si nitori Gomina ipinlẹ Edo, Godwin Obaseki ti kuro ni ẹgbẹ oselu APC,
Bakan naa ni wọn ko ni alaga ẹgbẹ oselu ẹyọkan nitori ẹniyan mẹta ni wọn ti kede pe awọn ni alaga ẹgbẹ oṣelu APC.
O fikun un pe ni ipinlẹ Ondo, ẹgbẹ oṣelu APC naa n koju aigbọraẹniye pẹlu bi igbakeji gomina ati gomina ipinlẹ naa ṣe n figagbaga lori ẹni ti yoo dije dupo nibẹ,
Eleyii ti o fihan pe igbakeji gomina naa ti yapa kuro ni ẹgbẹ oṣelu APC, amọ ti ko i tii fi lede ẹgbẹ oṣelu ti o ti fẹ dije dupo gomina.
Bakan naa, Fadairo ni ẹgbẹ oṣelu PDP naa ko i tii na ọwọ ẹnikẹni soke pe oun ni yoo dije dupo gomina labẹ asia ẹgbẹ oṣelu PDP,
Eleyii to ni o fihan pe ile ti wọn naa ko tooro rara.
Oríṣun àwòrán, Other
Victor Giadom
Imọran Onwoye eto oṣelu lawujọ naa ni wi pe ki awọn ẹgbẹ oṣelu yii pari aawọ to wa laarin wọn, ki wọn si tun ile wọn tọ daadaa nitori awọn ara ilu.
Bẹẹ lo kesi Aarẹ orilẹ-ede Niajiria lati maṣe foju kekere wo iṣẹlẹ to n waye ninu ẹgbẹ oṣẹlu APC, amọ ki o pẹẹtu saawọ naa, ki eto iṣejọba tiwantiwa ba le kẹsẹjari.
Victor Giadom ti kede pe oun ko dede darukọ ara oun gẹgẹ bi Alaga ẹgbẹ oselu APC, amọ ile ẹjọ lo na ọwọ soke gẹgẹ bi adele Alaga ẹgbẹ oselu APC.
Eyi ko ṣẹyin gbọnmisi omi oto to n waye ni ẹgbẹ oṣelu lẹyin ti ajọ amuṣẹya ẹgbẹ naa yan eniyan mẹta gẹgẹ bi alaga ẹgbẹ laarin wakati mẹrinlelogun.
Oríṣun àwòrán, Instagram/ abiola ajimobi
Ajọ amuṣẹya APC, NWC tun yan Hilliard Etta lati ma a ṣiṣẹ dele de Abiola Ajimobi to wa ni idubulẹ aisan, amọ Victor Giadom sọ wi pe apo ara wọn ni wọn sọ iyẹn si.
Giadom ni ileejọ to kọkọ yọ Adam Oshiomole kuro nipo, fi lede wi pe oun gẹgẹ bi Akọwe ẹgbẹ ni ki o jẹ adele alaga titi wọn yoo fi yan alaga miran.
O ni igba ti wọn ba to da ẹjọ ileẹjọ giga naa nu ki ẹnikẹni to le yọ oun nipo, amọ o dabi ẹni pe ajọ amuṣẹya APC ko ka idajọ ileejọ giga to fi jẹ adele alaga si, ti wọn si kede ẹni ti o jẹ igbakeji alaga ẹgbẹ na ni Gusuu Naijiria.
Gẹgẹ bi adele Alaga, Giadom ti da gbagbo igbese ti Oshiomọle ru patapata lati Osu Kẹta, to fi mọ ayẹwo awọn oludije fun ipọ gomina ninu idibo sipo gomina nipinlẹ Edo.
Amọ, ti ẹgbẹ oṣelu APC ko ba tete wa wọrọkọ fi sada lori ọrọ ipọ alaga ẹgbẹ oṣelu naa, yoo da wahala silẹ fun idibo sipo gomina ti yoo waye ni ipinlẹ Ondo ati Edo.
Badagry Historical Wells: Omi inú kànga Wawú ló ń kó ọpọlọ àwọn ẹrú lọ
Ọkan gboogi ninu ẹgbẹ oṣelu APC, Sogbogbe Eli lo kọkọ fi idi ẹ mulẹ pe awọn ipo adari ninu ẹgbẹ oṣelu APC ṣofo ni Giadom ṣe di adele alagba.
Sogbogbe ni o asiko ti Adam Oshiomole yọ gbogbo awọn adari nipo ni ileẹjọ wa gbe ọpa aṣẹ le Giadom lọwọ lati tukọ ẹgbẹ naa.
Oríṣun àwòrán, Jubril A. Gawat
Iroyin to n tẹ wa lọwọ bayii ni yajoyajo n fi ye ni pe, igbakeji akọwe apapọ ẹgbẹ oṣelu APC, Victor Giadom ti bọ sori oye gẹgẹ bii adele alaga apapọ ọgbẹ oṣelu naa.
Ọrọ ti di iṣu ata yanan-yanan bayii lẹgbẹ oṣelu APC bayii pẹlu bi ẹgbẹ oṣelu naa ṣe  n ni adele alaga apapọ meji laarin wakati diẹ si ara wọn.
Ni kete ti ile ẹjọ paṣẹ ki Adams Oshiomole o fi ipo silẹ ni ẹgbẹ oṣelu APC ti kede rẹ pe Sẹnetọ Abiola Ajimọbi gẹgẹ bi adele alaga apapọ ẹgbẹ oṣelu naa.
Amọṣa ko pẹ pupọ ni ẹni to jẹ igbakeji akọwe agba ẹgbẹ oṣelu ọhun, Victor Giadom jade sigboro pẹlu iwe idajọ lati ile ẹjọ kan eleyi to ni oun ni o tọ si lati di ipo naa mu.
Ni ọjọru si ni Gaidom gun ori aga naa gẹgẹ bi adele alaga apapọ ẹgbẹ oṣelu APC.
Ni kete ti o si ti wọle ni o ti kede pe oun n gba akoso ni ibamu pẹlu idajọ ile ẹjọ to ni o fun oun lagbara ati ṣe bẹẹ.
Bakan naa lo wọgile eto ayẹwo awọn oldije fun ipo gomina labẹ aṣia ẹgbẹ oṣelu APC ni ipinlẹ Edo.
O fi kun un pe gba-gba-gba lawọn ọmọ igbimọ majẹobajẹ ẹgbẹ oṣelu naa wa lẹyin oun lori igbesẹ naa.
Oríṣun àwòrán, Instagram/abiola ajimobi
APC: Ajimobi di adelé alága àpapọ̀ ẹgbẹ́ òṣèlú
Ajọ Amuṣẹya ẹgbẹ oṣẹlu APC, NWC ti kede Sẹnetọ Abiola Ajimobi gẹgẹ bi Alaga ẹgbẹ tuntun ni Ila Orun orilẹede Naijiria.
Eyi ko seyin idajọ ileejọ kotẹmilọrun ni ilu Abuja to fi ontẹ lu u pe ki wọn yọ Adam Oshiomọlẹ gẹ̀gẹbi Alaga ẹgbẹ oṣelu naa.
NWC fi lede wi pe ni itẹle idajọ Ileejọ Kotẹmilọrun lo mu ki awọn gbe igbesẹ naa lọna to ba ofin ẹgbẹ mu.
Amọ, nibayii ohun ti awọn eniyan n sọ ni wi pe Sẹnetọ Abiola Ajimọbi  wa ni idubulẹ aisan lati bii lóṣu diẹ sẹyin.
Bakan naa, awọn eniyan to n fi ero wọn han lori ẹrọ ikansiraẹni Twitter ni ko ye ki ẹgbẹ oṣelu APC fi ẹni to wa lori idubulẹ aisan ṣe alaga ẹgbẹ lasiko ti idibo n bọ lọna ni ipinlẹ Ondo ati Edo.
Oríṣun àwòrán, Instagram/ abiola ajimobi
Gomina ana ni ipinlẹ Ọyọ ni Sẹnetọ Abiọla Ajimọbi, ko si si bi iru wọn yoo ṣe gbin ti gbogbo ilu ko ni ṣojojo.
Ni aarin ọsẹ yii ni iroyin kan jade si igboro aye pe lori idubulẹ aisan ni gomina ana ni ipinlẹ Ọyọ ọhun wa ni ileewosan nla kan nilu Eko.
Iroyin naa tilẹ fi kun un pe ni ọsẹ to kọja ni wọn gbe Sẹnetọ Ajimọbi digbadigba lọ sileewosan ti a n sọrọ rẹ ọhun nigba ti ọrọ ilera rẹ n ṣebi ẹni fẹ maa mẹhẹ eleyi to si n da aya ja awọn mọlẹbi rẹ.
Wọn ni jiji ti Oloye Ajimọbi ji lọjọ naa lati ṣ'ẹmi ara to si pada ls si inu yara rẹ lo ba ṣubululẹ daku rangbọndan ki awọn ẹṣọ rẹ to gbee digbadigba lọ si ileewosan.
Amọṣa, ninu ilepa ati mọ boya lootọ ni iroyin yii tabi irọ ni BBC News Yoruba ti fi ipe ṣọwọ si ọkan lara awọn eeyan to sun mọ igbakeji alaga ẹgbẹ oṣelu APC naa lati mọ ootọ ọrọ naa.
Ǹjẹ́ o mọ̀ pé orin gbígbọ́ dara fún ọpọlọ ọmọ ìkókó?
Ohun ti onitọhun ti ko fẹ ki a darukọ oun ṣe lalaye ni pe ko si ootọ kan ninu iroyin naa ati pe ṣaka lara baba le.
Fidio kan to fi sita loju opo instagram rẹ lọjọ kini, oṣu karun un ni Sẹnetọ Abiọla Ajimọbi ṣi ti n ki ijọba apapọ atawọn oṣiṣẹ eto ilera ati aabo fun iṣẹ takuntakun ti wọn n gbe ṣe lori igbesẹ ati dẹkun itankalẹ ajakalẹ arun coronavirus lorilẹ-ede Naijiria.
Bakan naa lo farahan nibi eto idanilẹkọ ori afẹfẹ kan eleyi ti ileeṣẹ redio kan ṣe lasiko awẹ Ramadan to waye loṣu karun nibi ti o ti ko ipa gẹgẹ bi alaga eto idanilẹkọ awẹ naa
Pẹlu iroyin to n ja ranyinranyin nilẹ yii ati ohun ti ẹni to sun mọ Sẹnetọ Ajimọbi sọ yii, ibeere to wa gbode lẹnu awọn ololufẹ agba oṣelu yii atawọn onwoye ni pe:
'Nibo gan an ni Sẹnetọ Abiọla Ajimọbi wa lọwọ yii'?
Say no to rape: Ọmọ ọdún 17 tó ń kiri omi inú ọ̀rá fara kásáa ìfipábánilòpọ̀ l'Ekiti
Oríṣun àwòrán, Rolling stone
Ọwọ ọlọpaa ipinlẹ Ekiti ti tẹ awọn afurasi afibanilopọ meji ni ibamu pẹlu ẹsun pe wọn fipa ba ọmọ ọdun mẹtadinlogun kan lo pọ.
Ijọba ipinlẹ Ekiti fi eyi lede loju opo Twitter gẹgẹ bi ọpọlọpọ ṣe n polongo lodi si iwa ifipabanilopọ pẹlu #saynotorape to gba gbogbo ayelujara kan.
Ko tii ju ọsẹ kan lọ rara bayii ti iru iṣẹlẹ yii bẹrẹ si ni gbode kan kaakiri Naijiria. Ọtọ ni ti Uwaila Omozuwa to waye ni ilu Benin, ko pẹ o tun ṣẹlẹ si Barakat ni ilu Ibadan.
Ọwọ sinkun ọba ti tẹ afurasi meji kan to fipa ba ọdọbinrin ọmọ ọdun mẹtadinlogun ni ipinlẹ Ekiti.
Asojukọroyin to wa nibẹ sọ fun BBC Yoruba pe ni ọja'ba tii ṣe gbajugbaja ọja nilu Ado Ekiti ni ọdọbinrin yii ti n ta omi inu ọra ti awọn ọkunrin meji to di kaka di kuku ṣa dede ke e lọna ti wọn si fi tipa tipa ba a lajọṣepọ ni sisẹ n tẹle.
Ṣugbọn ni bayii, ọwọ palaba wọn ti segi bi awọn ọlọpaa ṣe mu wọn.
State of Osun: Pípe ìpínlẹ̀ Osun ni State of State Osun kò bá òfin mu-Adájọ́ Agboola
Awọn eeyan gbe ọmọ naa lọ si ile iwosan lẹyin naa lawọn ọlọpaa bẹrẹ iṣẹ wọn.
Alukoro ileeṣẹ ọlọpaa ipinlẹ Ekiti, Sunday Abutu ti ni awọn yoo ṣe ọfintoto iṣẹlẹ ọhun awọn aṣebi yoo si foju wina ofin.
Bakan naa, ijọba ipinlẹ Ekiti ti ni igbimọ to n ṣiṣẹ lodi si gbogbo iwa aburu si takọ-tabo yoo dawọ iṣẹ le ọrọ ifipabanilopọ yii.
Akinwumi Adesina: Ọdún márùn ún ní Adesina yóò lò ní sáà kejì ipò adarí Báńkì AFDB
Oríṣun àwòrán, OTHERS
Ọmọwe Akinwunmi Adesina ti da Aarẹ Banki Ilẹ Afrika, AfDB lẹyin ti wọn bura wọle fun un ni Ọjọ Kinni, Oṣu Kẹsan an, ọdun 2020.
Ori ẹrọ ayelujara ni iburawọle naa ti waye ni Ọjọ Iṣẹgun.
Ọdun marun un ni Adesina yoo lo lori oye gẹgẹ bi aarẹ Banki ilẹ Afrika, AFDB lẹyin iburawọle fun saa keji naa.
Laipẹ yii ni Adesina jawe olubori ninu iwadii ẹsun magomago ti wọn fi kan an.
Ni Abidjan ni orilẹ-ede Cote D'Ivore ni eto ibura naa ti waye.
Oṣu Kinni, ọdun 2020 ni wọn fi ẹsun ibajẹ onigun mẹrindinlogun kan Adesina, amọ awọn alakoso banki naa fi ọwọ osi da ẹjọ naa nu wi pe ko si otitọ kankan nibẹ.
Akinwumi Adeṣina ti jẹ minisita eto ọgbin fun orilẹ-ede Naijiria ri.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Iroyin to n tẹ wa lọwọ ni wipe wọn ti tun Akinwumi Adeshina yan gẹgẹ bii adari Banki Idagbasoke ilẹ Afrika, AFDB.
Oun ni yoo maa tukọ idari banki naa fun saa ọlọdun marun miran lẹyin ti iwadii ti fihan pe ko si kọnu n kọhọ kankan  ninu saa iṣejọba rẹ akọkọ.
Akinwumi Adeṣina ti jẹ minisita eto ọgbin fun orilẹede Naijiria ri.
Atunyan rẹ kan jẹ ko ma da bii pe wọn ko tẹle ilana ni tori oun nikan ṣoṣo naa ni oludije to wa nibi eto idibo naa eyi to waye lori ayelujara nibi ipade banki naa to waye lọjọbọ.
Ninu ọrọ rẹ to sọ lati pe fun ki wọn dibo yan an fun saa keji, Adesina ni oun n lo oun gbogbo ti oun ni lati sin ilẹ Afirika lai lẹ́ja n bákàn ninu.
Ẹni ọgọta ọdun ni Akinwumi Adesina.
Iwadii tuntun ti Banki Idagbasoke ilẹ Afrika, AFDB gbe kalẹ ti ni adari Banki naa, Akinwunmi Adesina ko jẹbi ẹsun jẹgudujẹra ti wọn fi kan an.
Aarẹ ilẹ Ireland tẹlẹri, Mary Robinson to fi mọ agbẹjọrọ agba lorilẹede Gambia, Hassan Jallow ati Leonard McCarthy to jẹ igbakeji aarẹ Banki apapọ lagbaye, wa lara igbimọ to ṣe iwadii Adesina finifini.
Ajọ naa ni Adesina ko jẹbi kankan ninu gbogbo ẹsun iwa ajẹbanu ti wọn fi kan an.
Lara ẹsun ti wọn fi kan Adesina, to jẹ minisita fun eto ọrọ aje lorilẹede Naijiria ni lilo ipo rẹ lọna aitọ, lilu owo banki ni ponpo ati ṣiṣe oju-saaju.
Amọ, ni gbogbo igba ni Adesina ma n sọ wi pe, oun ko jẹbi ẹsun ti wọn fi kan oun.
Ko to di akoko yii, ni iwadii abẹle ti kọkọ fi lede pe, Adesina ko wu iwa ibajẹ kankan, amọ orilẹede Amerika kọ iwadii naa, ti wọn si gbe omiran kalẹ.
Orilẹede Amerika wa lara awọn orilẹede mẹtadinlọgbọn to wa ninu igbimọ banki AFDB naa, ti wọn si jẹ orilẹede keji to ni ipin idokowo to pọ julọ ni banki ọhun.
Nibayii, orilẹede Amerika ni awọn faramọ abajade tuntun yii pẹlu igbagbọ pe, otitọ ni wi pe Akinwunmi Adesina ko jẹbi ẹsun iwa ibajẹ ati magomago ti wọn fi kan an.
Banki to wa fun idagbasoke ilẹ Afrika, The African Development Bank, sọ pe oun ti ṣe agbekalẹ igbimọ oluwadii aladani lati wadii awọn ẹsun iwa ibajẹ ti wọn fi kan Oludari banki naa, Akinwumi Adesina.
Adesina to ti fi igba kan ri jẹ Minisita fun iṣẹ agbẹ n f'ojusọna lati tun jẹ olori banki naa ninu eto idibo ti yoo waye l'oṣu Kẹjọ.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Sugbọn ilẹ America lo n ṣe agbatẹru ipolongo fun wiwadii rẹ, nitori pe wọn fura si pe o n kowo jẹ, o tun n yan awọn ọmọ Naijiria nikan si awọn ipo nlanla ni banki naa. Wọn tun sọ pe awọn ti wọn ti fi ẹsun jibiti ati iwa ibajẹ kàn ni Adesina n gbega l'ẹnu isẹ.Ọgbẹni Adesina sọ pe oun ko jẹbi ẹsun kankan. Koda, iwadii abẹle ti wọn kọkọ ṣe lori rẹ sọ pe ko jẹbi.
State of Osun: Pípe ìpínlẹ̀ Osun ni State of State Osun kò bá òfin mu-Adájọ́ Agboola
#JusticeforTina: Ọmọ mi ṣèlérí pé òun yóò tọ́jú mi tó bá parí ẹ̀kọ́ rẹ̀, ṣùgbọ́n wọ́n ti pá - ìyá Tina
Awọn ẹbi Tina Ezekwe to di ologbe lẹyin ti ọlọpaa kan yinbọn lu lagbegbe Iyana Oworo ni ipinlẹ Eko ti bẹ ijọba lati ṣewadii bi ọmọ wọn ṣe ku laipe ọjọ.
Tina jẹ Ọlọrun nipe ni ọjọ kejidinlọgbọn, oṣu karun un, ọdun 2020 lẹyin ti ọlọpaa ọhun to ni oun ti mu ọti yo yibọn lu u ni igba to n gbiyanju lati fi panpẹ ofin mu awakọ kan to tapa sofin igbele to wa nita lasiko naa nitori itankale ajakale arun Coronavirus to n ba agbaye finra.
Iṣẹlẹ naa da họwuhọwu silẹ lori itakun ayelujara ti ọpọ ọmọ Naijiria si n bere fun iwadii kikun ati idajọ ododo pẹlu ami #JusticeforTina.
Inu ibanujẹ ọkan ni iya Tina wa nigba ti ikọ ileeṣẹ iroyin BBC ṣe abẹwo sile awọn obi rẹ.
Koda, iya Tina kọ lati jẹun, ni ṣe lo ṣa n pariwo Tina mi o, Tina mi o.
Ẹ wo fido yii fun ẹkunrẹrẹ.
Nigeria rape cases: Ìyá àgbà ní ọkùnrin tó mutí yó náà fipá lòpọ̀ pẹ̀lú òun lójú oorun
Oríṣun àwòrán, @SpeakerOwoeye
Iya onile kan to n gbe ni Ijoko nipinlẹ Ogun ti salaye bi awakọ ọkọ akẹru kan to ti mu ọti yo, ṣe fipa ba a lopọ.
Nigba to n ba akọroyin sọrọ, iya arugbo naa, ti a fi orúkọ bo ni asiri ni, ko si ẹnikẹni ninu ile, gbogbo ayalegbe oun to ti jade lọ, wọn ko si tii wọle pada, ti ọkùnrin to muti yo naa si fi tipa wọnu yara oun.
Aladugbo mi ti mo mọ ni ọkùnrin, ẹni ọdun mẹẹdọgbọn naa, o fi tipa-tipa wọ yara mi lasiko to mu ọti yo ni aago mọkanla alẹ, o bo mi ni ẹnu, ki n ma baa pariwo, o si fi ipa ba mi ni ajọsepọ.
Mo ja fita-fita amọ apa mi ko ka, o ṣe nnkan to fẹ ṣe, nigba to ya, mo raye pariwo sita, awọn aladugbo de, ti wọn si ko ẹgba bo o lẹyin, ko to fi mi silẹ.
Mama agba ni wọn ti fi iṣẹlẹ yii to agọ ọlọpaa to wa ni Agbado leti, tawọn ọlọpaa si ti mu afurasi ọhun, bakan naa ni wọn ba aṣọ ati ina tọọsi to fi silẹ ni yara iya agba naa.
#JusticeforTina: Àwọn obi Tina Ezekwe ń bèrè fún ìdájọ́ òdodo pẹ̀lú omijé lójú
Chris Okotie: Ìlànà tí ìjọba Eko gbé kalẹ̀ fún ìjọsìn lásìkò Covid-19 kò bá wa lára mu
Oríṣun àwòrán, @churchtimesng
Oludasilẹ ile ijọsin Household of God Church, Chris Okotie ti tako awọn ilana ti ijọba ipinlẹ Eko gbe kalẹ ki wọn to le si awọn ile ijọsin pada.
O fi ọrọ yi sita ninu atẹjade kan to si sọ pe, imusẹ asọtẹlẹ inu bibẹli ti n waye bayi ati pe sise atunto ilana ijọsin sọọsi dabi ki eeyan kọdi iwọ ijọsin f'Ọlọrun.
Lọjọbọ ni ijọba Eko kede pe awọn eto ijọsin yoo bẹrẹ lawọn ile ijọsin pada.
Wọn ni awọn Musulumi yoo le ma jọsin pada lawọn mọsalasi lati ọjọ Kọkandinlogun osu Kẹfa, nigba ti awọn Kristẹni yoo bẹrẹ ti wọn ni ọjọ Kọkanlelogun osu kan naa.
Ba kan naa ni wọn gbe awọn ilana kan kalẹ ti yoo mu ki sisi awọn ile ijọsin yi lọ ni irọwọrọsẹ nipa didẹkun itankalẹ arun Covid-19.
Ninu rẹ ni wọn ti sọ pe wiwọ ibomu di dandan ati pe awọn ti ọjọ ori wọn ko ba to ọdun mẹẹdogun tabi  ti  o kọja ọdun marundinlaadọrin ko ni le ba wọn kopa ninu ijọsin.
Oríṣun àwòrán, HouseHold of God Church
Okotie sọ pe bi iparun ti se ba Dagoni to jẹ ọlọrun awọn Philistini ni Coronavirus naa yoo ti se parẹ
Bẹẹ naa ni wọn laa kalẹ pe akojọpọ ijọsin ko gbọdo ju wakati kan lọ.
Nigba to n se itọka lati inu bibeli, Okotie sọ pe bi iparun ti se ba Dagoni to jẹ ọlọrun awọn Philistini ni Coronavirus naa yoo ti se parẹ.
O ni toun ti bi ile ijọsin oun ti se n duro de ki arun yi parẹ awọn ko ni ti ilẹkun ile ijọsin awọn pa ''titi ti ọba ọrun yoo fi pa gbogbo awọn ẹsẹ aye yi rẹ''
#JusticeforTina: Àwọn obi Tina Ezekwe ń bèrè fún ìdájọ́ òdodo pẹ̀lú omijé lójú
Coronavirus in Lagos: 'Bí Covid19 bá peléke síi l'Eko, ilé la ó ti máa tọ́jú àwọn kan'
Oríṣun àwòrán, @Rasheethe
Ijọba ipinlẹ ti jẹ ko hande pe bi wọn ba n ni iye awọn to lugbadi arun Covid19 to n le ni igba si ọọdunrun lojoojumọ gẹgẹ bo ṣe n sunmọ ọ lẹnu ọjọ mẹta yii, awọn ibudo iyaraẹnisọtọ wọn ko ni to fun itọju mọ.
Wọn fi kun un wi pe bi o ṣe tun n peleke si i bayii nipinlẹ naa, awọn alaisan ti ipo wọn le atawọn to sunmọ ọ nikan ni wọn yoo maa tọju nibudo iyaraẹni sọtọ nigba ti wọn yoo ma tọju awọn ti ko safihan ami Covid19 tabi ti tiwọn ko fibẹẹ pọ nile wọn.
Nigba to n ba awọn oniroyin sọrọ nilu Eko lọjọ ẹti, kọmisọna eto ilera nipinlẹ Eko, Ọjọgbọn Akin Abayomi tẹnu mọ ọ pe alaye kikun yoo wa lori itọju alaisan nile ki awọn eeyan le mọ ẹni to tọ si gan lati gba itọju nile tabi nibudo iyaraẹnisọtọ.
Kọmisọna tọka si wi pe tori ọda ibudo iyaraẹnisọtọ yii wọn nilo lati bẹrẹ itọju alaisan nile laarin ọsẹ kan si meji ti wọn yoo si yọnda ibudo iyaraẹnisọtọ fun awọn ti ailera wọn lagbara gan.Lara ohun ti wọn le fi wa tọju alaisan nile ni pe ṣe ile naa wa ni ipo to dara fun itọju?
Ṣe ẹni ti ara rẹ ko ya yii ni iṣoro èémí?Idahun si eyi atawọn nkan mii ni yoo sọ ibi ti wọn yoo ti tọju ẹni bẹẹ fun aisan Covid19.
Kọmisọna sọ pe bi o tilẹ jẹ pe wọn gbero lati tunbọ gba oṣiṣẹ si i, awọn kan wa to ti yọnda ti wọn si ti ṣe idanilẹkọ fun wọn lati lọ maa ṣe itọju awọn alaisan nile laarin ọsẹ kan si meji.
"Ilana itọju alaisan nile""Fun awọn ti ailera wọn ko le ti wọn yoo maa tọju nile, a maa pe wọn lori ẹrọ ibanisọrọ, oṣiṣẹ wa yoo lọ bẹ wọn wo, a o ri i daju pe wọn gba ilana itọju ara ẹni lori ẹrọ ibanisọrọ wa, a o si ma mojuto ayipada wọn."
Bakan naa, wọn yoo gba ẹru itọju ati ogun eyi ti ogun apa irora ati aṣaraloore wa nibẹ.Lafikun, a o ṣe ilanilọyẹ fun awọn araalu lori didaabo bo ara wọn ati ẹbi ati aladugbo wọn lasiko itọju alaisan nile yii.
O fi kun un wipe wọn tun ti ṣeto lati jawo ayẹwo ojoojumọ soke sii lati ẹgbẹrun kan si ẹgbẹrun mẹta loojọ.
O ni ipinlẹ Eko ti ṣe ayẹwo to le ni ẹgbẹrun mejilelogun bẹẹ si ni wọn n tẹsiwaju tori eyi ni wọn ṣe gbudọ mura silẹ de afikun iye awọn to lugbadi arun yii.
Wole Soyinka: Buhari kọ́ ló ń darí wa ni ipo òṣèlú ṣe fì sí apá kan
Oríṣun àwòrán, Instagram/wolesoyinka
Gbajugbaja onkọwe nni, ọjọgbọn Wole Soyinka ti koro oju si bi wọn ṣe pin ipo oselu ni Naijiria, to fi fi si apa kan ju ọkan lọ.Soyinka wa n beere pe ki wọn fi iya to pọ jẹ awọn eeyan to wa nidii ṣíṣe iyansipo oselu naa ninu ijọba Buhari nitori iwa ọdaran ni wọn hu.Ọjọgbọn Soyinka fajuro bẹẹ, nigba to n fesi lori lẹta kan ti gomina ologun tẹlẹ nipinlẹ Kaduna, Umar Dangiwa fisita, to si n daba pe ki wọn pin orilẹ-ede Naijiria si ẹlẹkunjẹkun.
"Okodoro ọrọ ni Umar sọ kalẹ yii lai si iwa imọtaraẹni nìkan nibẹ, ti ẹnu si ya mi pe iru iwa bayii n sẹlẹ.""Iru asiri to tu sita yii mi ilu titi, to si le pin orile-ede si yẹlẹ yẹlẹ, amọ ohun ti ijọba lee ṣe ni ko ṣẹ pe irọ ni ọrọ naa pẹlu ẹri to daju, tabi ko ṣe eto atunto.Ọjọgbọn naa wa woye pe kii ṣe aarẹ Buhari lo n dari Naijiria, to si n rọ ọ lati mase fi ọwọ yẹpẹrẹ mu ọrọ lẹta naa."" N ko ro pe ẹnikẹni wa ni ile ijọba Aso Rock to n dari Naijiria, mo ti n woye bi nnkan ṣe n lọ lati ọdun kan aabọ, mo si gbagbọ pe aarẹ yii kọ lo n ṣe akoso Naijiria ni gbogbo ọna.""Soyinka fikun pe, bi ijọba ṣe dakẹ lai fọhun lori ọrọ naa bi oun ninu, amọ ọpọ awọn ti inu n bi bii ti oun, ni ko fẹ sọrọ to le da nnkan ru."
Ajikanle ní òun ti ta ọ̀pọ̀ dúkìá lórí apá àti ẹsẹ̀ tó rọ láti ọdún kẹta náà
Oríṣun àwòrán, Instagram/murphyafolabi20
Yoruba ni ẹni ti ija ko ba, nii pe ara rẹ ni ọkunrin, bi ere ba si ba ẹdun nilẹ, yoo di ọlẹ ni.Bẹẹ ni ọrọ ri fun gbajumọ oṣere tiata kan, Mufutau Ajikanle, ẹni ti apa ati ẹsẹ rẹ ti rọ lati ọdun mẹta sẹyin.Nigba to n salaye ohun ti oṣere tiata naa n la kọja faraye, gbajugbaja oṣere tiata miran, Murphy Afolabi sọ loju opo Instagram rẹ pe, ọkunrin naa nilo iranwọ araalu kiakia.
Ninu fidio to gbe jade ọhun ni Ajikanle, ẹni to ko ipa ribiribi ninu sinima Mufu Olosha Oko ati Olosha Molete, ti n bẹbẹ si araalu pe ki wọn saanu oun pẹlu iranwọ owo.
"Mufutai, to jokoo lori ibusun pẹlu ọpa lọwọ ni ""ibi ti wọn ti n tọju mi ni mo wa, n ko ni alaafia rara, awọn ẹgbẹ ti mo n ṣe ati awọn ọrẹ ti gbinyanju, ti mo si ti ta dukia mi tan.""O wa bẹbẹ pe ""ẹ saanu mi, Ọlọrun ko ni fi aarẹ ṣe yin, a ti nawo sẹyin lai ri iwosan, amọ mo sẹṣẹ wa ri ibi ti wọn yoo ti tọju mi daadaa bayii ni, sugbọn ko si owo mọ."""
Say no to rape: Ìdájọ́ ikú ni a fẹ́ fún àwọn afipábánilòpọ̀ - Ẹgbẹ́ ajàfẹ́tọmọnìyàn
Agbarijọpọ awọn ẹgbẹ ajafẹtọmọniyan bii mẹrinla ọtọọtọ ti koro oju si iwa ifipabanilopọ ati iṣekupani ti awọn obinrin n koju lawujọ.
Ninu ipade awọn oniroyin to waye lopin ọsẹ yii niluu Ibadan, awọn ẹgbẹ naa gbarata lori iwa ọdaran ti awọn amokunṣeka kan n hu si ọmọde ati awọn agba to jẹ obinrin, paapa julọ lori ọrọ iṣekupani ati ifipabanilopọ.
Ọkan lara awọn aṣoju ẹgbẹ naa, Arabinrin Grace Oluwatoye kesi ijọba ati awọn agbofinro lati bojuto wahala ti awọn ọmọbinrin n dojukọ lasiko yii.
O ni awọn ọmọbinrin bii mẹta ọtọọtọ to padanu ẹmi wọn nitori ifipabanilopọ ati iwa ipa laarin ọsẹ kan ti fa aibalẹ ọkan fun gbogbo abiyamọ pata.
Oluwatoye ni ohun to n kọnilominu ni wi pe awọn obinrin ti o jẹ wi pe lati ara wọn ni gbogbo eniyan ti jade naa lotun wa n koju iru wahala bayii. Gbogbo eleyii ko si sẹyin eto aabo to mẹhẹ lawujọ.
O ni aifi ẹnikankan jofin lo faa ti awọn olubi ẹda naa fi n tẹsiwaju ninu iwa ọdaran. Igbagbọ ẹgba naa ni wi pe igbẹsẹ lati dẹkun iwa ibajẹ naa yoo yan kankan ti ijọba ba bẹrẹ sini ṣe idajọ iku fun ẹnikẹni ti wọn ba gbamu.
"Awọn ẹgbẹ naa tun fi ẹsun kan awọn obinrin to n ta oti lile ati paraga wi pe awọn naa lọwọ si ọrọ ifipabanilopọ yii nitori pe gbogbo nnkan buruku ti awọn ọdaran naa n mu lo n fun wọn ni igboya lati ṣiṣẹ ibi. Wọn ni ""ẹni ti ko mu ọti lile ko ni ba ọmọ ọdun mẹrin si mẹjọ sun""."
Wọn ke si ijọba lati ri si ọrọ awọn obinrin to n ta paraga lawọju ki adinku le de ba ipa buburu ti imukumu n ko laarin wa.
Lara ohun ti wọn tun kesi ijọba lati ṣe ki iwa ọdaran naa le kasẹ nilẹ ni agbekalẹ ofin ti yoo maa da sẹria fun awọn afiabanilopọ, ati ibawi to peye fun gbogbo ẹni ti aje iwa ibajẹ ba ṣi mọ lori.
Arabinrin Oluwatoye tun rọ awọn onile iṣẹ igbohun safẹfẹ lati maa fi aye ilanilọyẹ silẹ lori awọn eto ti wọn n ṣe oye tun bọ le ye awọn ara il sii lori awọn ewu to rọ mọ ifipabanilopọ  ati iṣekupani lawujọ wa.
#JusticeforTina: Àwọn obi Tina Ezekwe ń bèrè fún ìdájọ́ òdodo pẹ̀lú omijé lójú
Ọkan lara awọn ọkunrin to jẹ aṣoju ẹgbẹ naa, Arakunrin Hamzat Kọlawọle so wi pe iwa ti ko bojumu t ko si yẹ awujọ ni iwa ifipabanilopọ.
O ni ọkunrin to ba fi ipa ọmọde tabi agbalagba to jẹ obinrin lopọ ti ṣe ohun buruku.Kọlawọle ni ko yẹ ki a bi iru awọn ẹda bẹẹ si aye rara de ibi wi pe a o maa pe wọn ni ọkunrin.
O ni iru awọn ọkunrin to n hu iru iwa ọdaran bẹẹ lo yẹ ki gbogbo awọn ọkunrin to ku pawọpọ lati bawi nitori wọn ba gbogbo ti ko mọwọmẹsẹ loju jẹ.
A kò tíì lè sọ ti ìfipabánilòpọ̀ àmọ́ òkúta ni wọ́n fi fọ́ orí Azeezat - Ọlọ́pàá Oyo
Agbarijọpọ awọn ẹgbẹ ajafẹtọmọniyan bii mẹrinla ọtọọtọ ti koro oju si iwa ifipabanilopọ ati iṣekupani ti awọn obinrin n koju lawujọ.
Ninu ipade awọn oniroyin to waye lopin ọsẹ yii niluu Ibadan, awọn ẹgbẹ naa gbarata lori iwa ọdaran ti awọn amokunṣeka kan n hu si ọmọde ati awọn agba to jẹ obinrin, paapa julọ lori ọrọ iṣekupani ati ifipabanilopọ.Ọkan lara awọn aṣoju ẹgbẹ naa, Arabinrin Grace Oluwatoye kesi ijọba ati awọn agbofinro lati bojuto wahala ti awọn ọmọbinrin n dojukọ lasiko yii.
O ni awọn ọmọbinrin bii mẹta ọtọọtọ to padanu ẹmi wọn nitori ifipabanilopọ ati iwa ipa laarin ọsẹ kan ti fa aibalẹ ọkan fun gbogbo abiyamọ pata.
Oluwatoye ni ohun to n kọnilominu ni wi pe awọn obinrin ti o jẹ wi pe lati ara wọn ni gbogbo eniyan ti jade naa lotun wa n koju iru wahala bayii. Gbogbo eleyii ko si sẹyin eto aabo to mẹhẹ lawujọ.
O ni aifi ẹnikankan jofin lo faa ti awọn olubi ẹda naa fi n tẹsiwaju ninu iwa ọdaran. Igbagbọ ẹgba naa ni wi pe igbẹsẹ lati dẹkun iwa ibajẹ naa yoo yan kankan ti ijọba ba bẹrẹ sini ṣe idajọ iku fun ẹnikẹni ti wọn ba gbamu.
"Awọn ẹgbẹ naa tun fi ẹsun kan awọn obinrin to n ta oti lile ati paraga wi pe awọn naa lọwọ si ọrọ ifipabanilopọ yii nitori pe gbogbo nnkan buruku ti awọn ọdaran naa n mu lo n fun wọn ni igboya lati ṣiṣẹ ibi. Wọn ni ""ẹni ti ko mu ọti lile ko ni ba ọmọ ọdun mẹrin si mẹjọ sun""."
Wọn ke si ijọba lati ri si ọrọ awọn obinrin to n ta paraga lawọju ki adinku le de ba ipa buburu ti imukumu n ko laarin wa.Lara ohun ti wọn tun kesi ijọba lati ṣe ki iwa ọdaran naa le kasẹ nilẹ ni agbekalẹ ofin ti yoo maa da sẹria fun awọn afiabanilopọ, ati ibawi to peye fun gbogbo ẹni ti aje iwa ibajẹ ba ṣi mọ lori.
Arabinrin Oluwatoye tun rọ awọn onile iṣẹ igbohun safẹfẹ lati maa fi aye ilanilọyẹ silẹ lori awọn eto ti wọn n ṣe oye tun bọ le ye awọn ara il sii lori awọn ewu to rọ mọ ifipabanilopọ  ati iṣekupani lawujọ wa.Ọkan lara awọn ọkunrin to jẹ aṣoju ẹgbẹ naa, Arakunrin Hamzat Kọlawọle so wi pe iwa ti ko bojumu t ko si yẹ awujọ ni iwa ifipabanilopọ.
O ni ọkunrin to ba fi ipa ọmọde tabi agbalagba to jẹ obinrin lopọ ti ṣe ohun buruku.Kọlawọle ni ko yẹ ki a bi iru awọn ẹda bẹẹ si aye rara de ibi wi pe a o maa pe wọn ni ọkunrin.O ni iru awọn ọkunrin to n hu iru iwa ọdaran bẹẹ lo yẹ ki gbogbo awọn ọkunrin to ku pawọpọ lati bawi nitori wọn ba gbogbo ti ko mọwọmẹsẹ loju jẹ.
Oríṣun àwòrán, Other
A kò tíì lè sọ ti ìfipabánilòpọ̀ àmọ́ òkúta ni wọ́n fi fọ́ orí Azeezat - Ọlọ́pàá Oyo
Mẹwaa n ṣẹlẹ ni duniyan, kayefi nla mii tun ṣẹlẹ. Abilekọ ẹni ọdun mọkandinlogun kan, Azeezat Dhikirullahi to jẹ oloyun oṣu meje ni wọn ṣaa dede ba oku rẹ nilẹ ninu yara rẹ ti wọn ti fọ ori rẹ.
Iṣẹlẹ yii waye niluu Ijedun, abule kan lẹbaa Ojoo, Ibadan nipinlẹ Oyo. Ohun taa gbọ ni wi pe awọn to ṣe ọṣẹ yii fẹ fi obinrin naa ṣe ogun owo ni.
Ọjọ mẹrin ṣaaju iṣẹlẹ eleyi ni iroyin ti ọmọ ọdun mọkandinlogun kan, Barakat ti wọn fipa ba lo pọ ti wọn tun pa a ṣẹlẹ ni agbegbe Akinyele nilu Ibadan kan naa.
Ni ti Azeezat, iroyin sọ pe alaga ẹgbẹ awọn onile ni Ijefun, Alhaji Taiwo Adeyemo ṣalaye pe okuta nla ni wọn fi fọ ori rẹ ninu yara rẹ. O fi kun un wi pe oloogbe ṣẹṣẹ rinrinajo de lati ipinlẹ Kano ninu oṣu keji ni nibi ti ọkọ rẹ, Dhikirullahi ti ṣẹṣẹ ri iṣẹ lẹyin ọdun kan eto agunbanirọ rẹ.
Nigba ti BBC Yoruba kan si alukoro Ọlọpaa ipinlẹ Oyo, Olugbenga Fadeyi sọ pe ootọ ni wọn fi okuta fọ ọ lori. Nigba ti ikọ ọlọpaa debẹ, wọn ri i pe ko si ẹmi kankan lara rẹ mọ wọn si gbe e lọ si ile igboku si.
Lẹyin eyi ni kọmisọna ọlọpaa ipinlẹ Oyo, Nwachukwu Enwonu atawọn lọga lọga ọlọpaa ni ipinlẹ naa kọwọ rin pẹlu awọn aṣoju gomina lọ ba idile oloogbe kẹdun ti wọn si ṣeleri pe gbogbo awọn to lọwọ ninu iṣẹlẹ yii ni yoo bọ sọwọ ofin.
Loju ẹsẹ ni wọn si bẹrẹ igbesẹ iwadi lori ọrọ naa gẹgẹ bi ọga awọn ọtẹlẹmuyẹ ṣe ti gun le iṣewadii.
Bi o tilẹ jẹ wipe ọpọlọpọ ileeṣẹ iroyin lo n gbe e safẹfẹ pe yatọ fun okuta ti wọn fi fọ ọ lori, wọn tun fipa ba a lo pọ, alukoro ọlọpaa sọ fun BBC Yoruba pe, awọn ko le fi idi eleyii mulẹ ṣugbọn iwadi ti wọn n ṣe ni yoo boya lootọ ni tabi irọ ni pe wọn tun fipa ba oloogbe aboyun yii lajọṣepọ.
Coronavirus updates: 'Kòkòrò covid-19 kékeré ti mọ́ṣálááṣí pa, há àwọn èèyàn mọ́lé'
Aarun coronavirus ti ṣakoba fun wa lọpọlọpọ, bayii lawọn ọmọ orilẹde Kenya to ba BBC Yoruba sọrọ ṣe sọ.
Awọn to jẹ ẹlẹsin musulumi ninu wọn sọ pe coronavirus ko jẹ kawọn lanfaani mọ lati lọ kirun ni mọṣalaaṣi.
Bakan naa lawọn mii n ṣaroye pe iṣede covid-19 ti ṣe ipalara fun okowo awọn.
Rape cases in Nigeria: Báyìí ni ẹgbẹ́ ajàfẹ́tọmọnìyàn ṣe pè fún ìdájọ́ ikú fún àwọn afipábánilòpọ̀
Agbarijọpọ awọn ẹgbẹ ajafẹtọmọniyan bii mẹrinla ti koro oju si iwa ifipabanilopọ ati iṣekupani ti awọn obinrin n koju lawujọ.
Ninu ipade ni ilu Ibadan, awọn ẹgbẹ naa gbarata lori iwa ọdaran ti awọn amokunṣeka kan n hu si ọmọde ati awọn agba to jẹ obinrin.
Ohun to jẹ ẹgbẹ ajafẹtọmọniyan na logun julọ ni ọrọ iṣekupani ati ifipabanilopọ.
Ọkan lara awọn aṣoju ẹgbẹ naa, Arabinrin Grace Oluwatoye kesi ijọba ati awọn agbofinro lati bojuto wahala ti awọn ọmọbinrin n dojukọ lasiko yii.
Ẹ wo fidio yii fun ẹkunrẹrẹ.
Oniru of Iru land: Onírù tuntun Oba Abdulwasiu Gbolahan Lawal gba ọ̀pá àṣẹ
Oríṣun àwòrán, Twitter/Babajide Sanwo-Olu
Oniru ti Iru nipinlẹ Eko, Oba Abdulwasiu Omogbolahan Lawal, Abisogun ll ti gba ọpa aṣẹ gẹgẹ bi Oniru ikẹẹdogun.
Ko tii ju ọjọ mẹta lọ ti awọn afọbajẹ atawọn agbaagba ilu Iru yan an laarin awọn arẹmọ ọba to n du itẹ naa.
Lọjọ keje oṣu kẹfa ọdun 2020 ni gomina Babajide Sanwo-Olu gbe ọpa aṣẹ le e lọwọ gẹgẹ bii Oniru kẹẹdogun ti ilu Iru nipinlẹ Eko.
Gomina gba Oniru tuntun nimọran lati jẹ ki alafia tẹsiwaju ni ilu naa.
Sanwo-Olu ni pẹlu Ọlọlajulọ Ọba Abdulwasiu Ọmọgbọlahan ati Olori rẹ ni ko si ani ani, ọjọ iwaju ilu Iru yoo dara o si nireti at pe gigun ori itẹ Oniru tuntun yii yoo jẹ ibẹrẹ irinajo lọ sinu ọjọ iwaju naa.''
O ṣapejuwe ipo ọba gẹgẹ bi ibi akọkọ ninu ijọba o si ni yoo maa jẹ ọna si ibi nkan ini Naijiria ni gbogbo igba.
Bi ẹ ko ba gbagbe, ọdun to kọja ni ipo Oniru ṣofo nigba ti Oniru ikẹrinla, Ọba Idowu Oniru filẹ bora bi aṣọ.
Say no to rape: Àwọn òṣèrébìrin Yollywood sọ tiwọn lórí ìfipábánilòpọ̀ tó gbòde
Oríṣun àwòrán, Instagram
Awọn obinrin to jẹ oṣere ni Naijiria ko lee pa ero ti wọn mọra rara pẹlu iwa aburu ifipabanilopọ to gbode kan to si n waye kaakiri orilẹede Naijiria.
Isẹlẹ yii bẹrẹ ko tii to ọsẹ meji rara bẹẹ si ni laarin ọsẹ meji yii nikan, yatọ fun iye awọn obinrin ti wọn ti fipabalopọ lawọn ipinlẹ kọọkan, kayefi ni iroyin to yi awọn iṣẹlẹ ọhun ka eyi to n kọ awọn araalu lominu.
Aidawọ iṣẹlẹ yii duro lo mu ki awọn eniyan maa figbe sita lati sọ ẹdun ọkan wọn, bi awọn kan ṣe n dabaa ijiya iku, lawọn mii n fi epe ranṣẹ si awọn to n ṣe iru iṣẹ laabi yii kaakiri.
Ẹwẹ, sisa ipa ara ẹni ko yọ awọn oṣerebinrin Yollywood silẹ gẹgẹ bi wọn ṣe tu sita loju opo ayelujara wọn lọkọọkan pẹlu fidio, ọrọ, aworan ati bẹẹ bẹẹ lọ lati lodi si iwa ipa naa.
Iyabo Ojo
Lasiko isede yii, ọpọ awọn ololufẹ awọn oṣere lo tun n wọ lọ si oju opo ayelujara oṣerebinrin Iyabo Ojo pẹlu ọna to n gba da awọn eeyan lara ya ṣugbọn nigba tọrọ ifipabanilopọ bẹrẹ si ni gbode, ọna mii ni Iyabo gba yọ pẹlu fọnran to fi sita ninu aṣọ dudu ati omije loju pe oun to ba ni lọkan jẹ ni ki awọn to yẹ ko maa da abo awọn ọmọde sọ ara wọn di eṣu to n fipabaniopọ.
O ni ta la ba gbẹkẹle nigba ti wọn tun n na ika afurasi i ẹni ti wọn fipa ba lo pọ.
Jaiye Kuti
Lara awọn agba oṣerebinrin ni Jaiye Kuti.
O fi iporuru ọkan sọrọ pe bi obinrin ba niwa rere ko ni ki wọn ma fipa ba a lo pọ, kii ṣe tori obinrin n mu ọti tabi gbe ogun oloro ni wọn fi n fipa ba wọn lo pọ kii si i ṣe tori wọn ko ṣọra ni obinrin fi n ṣagbako ifipabanilopọ.
Ẹwẹ, Jaiye ni iwa aidaa yii ko tọ niwaju eniyan ati Ọlọrun.
Mercy Aigbe
Gbajugbaja oṣerebinrin fi ọpọlọpọ ọrọ ati aworan sita ni ipa tirẹ lati waasu didẹkun iwa ifipabanilopọ.
"Ninu ọkan, Mercy fi aworan sita to sọ pe ""o lee jẹ iṣẹju marun un fun iwọ (afipabanilopọ) ṣugbọn ayeraiye ni fun oun (ẹni ti wọn fipa ba lo pọ)."
Torinaa o ni ọdaran lawọn afipabanilopọ bi ọdaran si ni ki wọn ṣe fiya jẹ wọn.
Funke Akindele (Jenifa)
Oṣere apanilẹrin nni Jenifa kọ ọ si oju opo instagram rẹ pe gbogbo bo ṣe n lọ yii kan ṣaa su oun.
Ipaniyan! idarudapọ ati iruniloju! iwa ibajẹ! airiṣẹ! gbigbe ninu ibẹrubojo!
O ni ko sẹni to mo ohun to tun kan lẹyin gbogbo eleyii.
Ninu ọrọ mii, adura ni Funke Akindele gba to sọ asọtẹlẹ si oṣu ikẹfa pe ko bi ibukun ko si wẹ gbogbo ọgbẹ wa danu.
Ko mu idajọ wa sori gbogbo awọn aṣebi ko si jẹ ki alafia wa niluu.
Toyin Abraham
Ilumọka oṣere ni Toyin Abraham. O sọrọ gẹgẹ bi iya ati abiyamọ pe oun ko le koju kuro lara iṣẹlẹ yii.
O ni ọmọbinrin nilo aabo gbogbo wa torinaa ki gbogbo eeyan dide fun ootọ tori pe iṣẹlẹ yii ti su gbogbo obinrin.
Toyin Abraham tun fi nọmba ti awọn obinrin le pe lati fẹjọ ifipabanilopọ sun.
Opeyemi Aiyeola
"Aworan ọmọdebinrin ti ẹyin aṣọ rẹ kun fun ẹjẹ ni Opeyemi fi sita lati sọ pe ""ọmọdebinrin ni wa, ọdọbinrin ni wa, agba obinrin ni wa, iya ni wa, a nilo idajọ fun awọn ọmọbinrin wa."
"To ba ṣe ọmọbinrin tirẹ n kọ?"""
Say no to rape: Àwọn òṣèré tíátà Yorùbá pariwo síta lórí wàhálà ìfipábánilòpọ̀
Lootọ iwa ifipabanilopọ ko ṣẹṣẹ maa waye, koda awọn kan tilẹ n sọ wi pe atigba iwaṣẹ lo ti n ṣẹlẹ.
Amọṣa awọn iran de iran gbogbo lo ti bẹnu atẹ lu u.
Titi di bi a ṣe n sọrọ yii ko tii dẹkun, koda ti ẹnu lọwọlọwọ yii wa peleke sii paapaajulọ lorilẹede Naijiria.
Laarin oṣu kan sẹyin ko din ni omidan mẹrin ti awọn oniṣẹ ibi kan ti fipabalopọ ti wọn si tun gbẹmi wọn eleyii to mu ki ohun awọn eeyan tun goke sii lori ipe fun wiwojuutu si wahala ifipabanilopọ lawujọ wa.
Ooni Ile Ife: Màmá tó bí ìyá Ọọ̀ni ilé Ifẹ̀ ju awà sílẹ̀ lẹ́ni ọdún 103
Oríṣun àwòrán, MOses olafare
Ọọni ile Ifẹ, Ọba Adeyẹye Ogunwusi, Ọjaja keji ti padanu Iya-iya rẹ, iyaafin Comfort Faramọbi Ajọkẹ Ọlasọji Sọji-Ọpa.
Agbẹnusọ fun Aafin ile Oodua, Moses Ọlafare to fidi eyi mulẹ ni aṣalẹ ọjọ Aiku ṣalaye pe ẹni ọdun mẹtalelọgọrun ni iya naa ki ọlọjọ to de.
Iya-iya Ọọni Ogunwusi, ti ọpọ mọ si 'Mama Agba'nigba aye rẹ ni wọn ṣalaye pe o jẹ gbajums oniṣowo ti wọn bi ni ọdun 1907 si idile Oloye Aina Akinyẹmi ni agboole Ajigbayin ni ilu Ile Ifẹ.
Awọn ohun jijẹ ni ilu mọ iya naa fun nigba ṣango ode rẹ ti ko si si ẹni ti ko fẹrẹ maa mọọ ni ọja Itaakọgun, Ọja titun atawọn ọja miran ni ilu Ile Ifẹ ati agbegbe rẹ.
Sani Abacha: Olórí ológun tí ìjọba rẹ̀ ga ju ilé ẹjọ́ lọ
Oríṣun àwòrán, others
Ọjọ nla ni ọjọ kẹjọ osu kẹfa ọdun 1998, nigba ti iroyin gba ilẹ kan pe, olori ijọba ologun ni Naijiria, ọgagun Sani Abacha ti silẹ bora
Iku ojiji to pa olori wa nigba naa, eyi to pe ọdun mejilelogun bayii, si lo n ṣe ọpọ eeyan ni haa-hii.
Ti a ba si ni ka kọ itan orilẹ-ede Naijiria, abala diẹ kọ ni oloogbe ọgagun Sani Abacha yoo ko nitori ipa manigbagbe to ko ninu isejọba Naijiria.
Idi ree ti BBC Yoruba fi ṣe akojọpọ igbe aye akọni ologun naa ati ọpọ iṣẹlẹ manigbagbe to gbe ile aye ṣe, lati la awọn ọdọ lọyẹ.
Ogunjọ oṣu kẹsan-an ọdun 1943 ni Sani Abacha dele aye nipinlẹ Borno, to si jẹ ẹya Kanuri amọ ilu Kano lo ti dagba, to si lọ sile ẹkọ nibẹ.
Ọdun 1963 ni wọn gba Sani sagbo iṣẹ ologun lẹyin to kawe nípa iṣẹ ologun nilu Kaduna lọdun 1969 ati nilẹ Gẹẹsi, to si ja fitafita ninu ogun abẹle Naijiria.
Say no to rape: Àwọn òṣèré tíátà Yorùbá pariwo síta lórí wàhálà ìfipábánilòpọ̀
A kaa pe ọpọ iṣẹlẹ iditẹ gbajọba to waye ni Naijiria lo n lọwọ Abacha ninu nigba to si wa ni ipo 'second lieutenant' lasan, ibẹrẹ pẹpẹ si lo ti bawọn kopa ninu iditẹ gbajọba to waye losu keje ọdun 1966, to fi mọ eyi to waye lọdun 1983, to gbe ọgagun Ibrahim Babangida sori aga akoso.
Ọdun 1985 ti ọgagun Babangida si gba oye aarẹ ati Kọmanda awọn ologun ni Naijiria, naa ni Abacha gba oye olori Ileesẹ ọmọ-ogun ori ilẹ, to si tun di Minisita feto aabo lọdun 1990.
Lẹyin ti Babangida da ibo ọjọ Kejila osu kẹfa ọdun 1993 nu, ti gbogbo agbaye gba pe oloogbe Moshood Abiola lo jawe olubori ninu rẹ, ni rogbodiyan gbode, eyi to mu ki Babangida yẹba lori aleefa, ti wọn si fi Ernest Sonekan jẹ aarẹ fidihẹ ni Naijiria.
Oríṣun àwòrán, others
Amọ ọjọ Kẹtadinlogun oṣu kọkanla ọdun 1993 ni Abacha yẹ aga mọ Sonekan nidi, toun gangan si di aarẹ ologun ni Naijiria.
Isẹlẹ manigbagbe ti Abacha ṣe lori oye:
Coronavirus treatments Nigeria : Gómìnà ìpínlẹ̀ Abia, Okezie Ikpeazu ti fara kásá àrùn Covid-19
Oríṣun àwòrán, Abia state Government
Ijọba ipinlẹ Abia ti kede pe Gomina ipinlẹ naa, Okezie Ikpeazu, ti lugbadi arun Coronavirus.
Gomina ọhun ni gomina kẹrin ti yoo fara kasa arun naa lati igba ti arun naa ti wọ orilẹ-ede Naijiria loṣu keji ọdun 2020.
Agbẹnuṣo Gomina ọhun, Onyebuchi Ememanka to fidi iroyin naa mulẹ fun BBC sọ pe gomina ọhun ti wa ni igbele, ati pe awọn akọṣẹmọṣẹ dọkita ti n ṣe itọju rẹ.
Ememanka ni ki awọn eeyan ipinlẹ naa ma foya, nitori gomina naa kii ṣe gomina akọkọ ti yoo ko arun Coronavirus ni Naijiria.
Ṣaaju ni kọmiṣọna ọrọ to n lọ ni ipinlẹ ọhun, John Okiyi Kalu ti kọ sọ ninu atẹjade kan pe gomina naa ti fun igabkeji rẹ ni aṣẹ lati dele dee ki esi ayẹwo arun naa to ja
Ọgbọn ọjọ, oṣu karun un ọdun 2020 ni gomina ọhun gba lati ṣe ayẹwo, to si paṣẹ pe ki gbogbo awọn to n ba ṣe ijọba ṣe bẹ.
Ọjọ keji oṣu Kẹfa ni esi ayẹwo naa jade ṣugbọn ko ni arun ọhun.
Ni ọjọ Kẹrin kan naa ni o tun ayẹwo naa ṣe ti esi si fi han pe o ti ni arun Coronavirus.
Say no to rape: Àwọn òṣèré tíátà Yorùbá pariwo síta lórí wàhálà ìfipábánilòpọ̀
Òtítọ ní Obasanjo sọ, Buhari n fí agbára fún ẹlẹ́yàmẹ̀yà ní Nàìjíríà-Soyinka
Oríṣun àwòrán, CHARLES IGBINIDU/Twitter
Onkowe Ọjọgbọn Wole Soyinka ti ṣe atilẹyin fun ọrọ ti  aarẹ ana Olusegun Obasanjo sọ wi pe ogun ẹlẹyamẹya gbinlẹ si labẹ ijọba Aarẹ Buhari.
"Soyinka sọ ọrọ yii ninu atẹjade to fi lede to pe akọle rẹ ni ""Between 'Dividers-in-chief' and Dividers-in-law,"" ni ile rẹ ni Ijegba, Idi-Aba Estate, Abeokuta."
Ilumọọka ọjọgbọn yi ni botilẹ jẹ pe oun ko gba ti Obasanjo nitori o pẹlu awọn adari to ba Naijiria de ibi to wa bayii, lori ọrọ to sọ, oun gbe lẹyin rẹ.
O ni gbogbo ọrọ ikilọ ti Obasanjo ti n fi lede labẹ iṣejọba aarẹ Buhari lo tọna ti o si yẹ ki wọn kiyesi, ṣugbọn ijọba keti ikun si nitori Obasanjo lọ sọ ọrọ yii.
O ṣalaye pe ''iyẹn o ni wi pe mọ yi ohun pada lori iwa buruku ti Aarẹ ana, Olusegun Obasanjo wu nigba ti o wa ni ipo.'
'Amọ, a gbọdọ wo ọrọ ti oun sọ fun itẹsiwaju orilẹede Naijiria ati awọn ikilọ rẹ lai bikita ibi ti ọrọ naa ti wa.'
Soyinka fi kun pe 'Orilẹede Naijiria ti n lọ si okun igbagbe nitori ko si ifẹ tabi ajọṣepọ to le e mu isọkan gbinlẹ mọ lorilẹede Naijiria.'
Oríṣun àwòrán, Getty Images
O ni kaka ki wọn gbọ imọran Obasanjo, radarada ni ijọba aarẹ Buhari n ba kaakiri.
'Ẹlẹyamẹya ti ohun waye labẹ iṣejọba aarẹ Buhari ko ṣẹyin ihuwasi aarẹ fun ara rẹ, ati awọn igbesẹ ati eto ti aarẹ n ṣe ti ko mu itẹsiwaju ba orilẹede Naijiria.'
Ọjọgbọn Wole Soyinka ṣe iranti asiko ti awọn darandaran pa awọn eniyan lọgọọrọ, sugbon kaka ki aarẹ Buhari gbe igbesẹ lati da abo bo awọn eniyan, ohun ti aarẹ Buhari sọ ni pe ki awọn eniyan naa wa ọna lati gbe ni alaafia.
Bakan naa ni o sapejuwe ẹka eto idajọ ni Naijiria ti wọn ko naani ẹtọ awọn araalu afi awọn oṣelu ati awọn alagbara ti wọn le lo ọna magomago lati ri wi pe idajọ naa lo bi wọn ṣe fẹ.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Awọn ọmọ Naijiria ti bẹrẹ si ni da si ọrọ ti Aarẹ tẹlẹri lorilẹede Naijiria, Olusegun Obasanjo sọ ati esi ti Aarẹ Muhammadu Buhari fun Obasanjo.
Ko pẹ ti Minisita to n ri si iroyin ati aṣa, Lai Muhammed naa tẹnu bọ ọ̀rọ̀ yii lawọn ọmọ Naijiria naa tu kẹkẹ ọrọ silẹ.
Alhaji Lai Muhammed fi sita pe bi kii ba ṣe ti aarẹ Buhari ni, orilẹede Naijiria o ba ti fori sanpọn.
Ni Ọjọbọ, ọsẹ to kọja ni Baba Obasanjo sọ wipe orilẹede Naijiria ti n lọ sokun igbagbe nitori oun gbogbo ti n dẹnukọlẹ lasiko iṣejọba Aarẹ Muhammadu Buhari.
Ileeṣẹ Aarẹ nigba ti wọn n fesi sọ wi pe Obasanjo gan an ni mọndaru to n pin orilẹede Naijiria, ti o si n sọrọ ẹlẹyamẹya lati igba de igba.
Amọ, awọn ẹgbẹ ọmọ Yoruba ati ẹgbẹ miran lapapọ ti n fesi si ọrọ gbọn mi si omi o to to n waye laarin awọn mejeeji.
Ayo Fayose, Afẹnifẹre, Ndigbo, Arewa dasi ọrọ Buhari ati Obasanjo
Lara awọn to kọkọ fesi ni Gomina ipinlẹ Ekiti tẹleri, Ayo Fayose ni bi o tilẹ jẹ pe oun ko fi igba kan gba ti Obasanjo, otitọ ọrọ gbaa ni Baba Obasanjo sọ.
Lasiko ti Fayose n ṣe ifọrọwanilẹnuwo pẹlu Dele Momodu lo sọ bẹẹ.
Bakan naa ni ẹgbẹ Afẹnifẹre naa ni awọn faramọ ohun ti Obasanjo sọ nitori Aarẹ Buhari ti kuna lati jẹ ki isọkan o jọba lorilẹede Naijiria.
Ninu ọrọ ti wọn, ẹgbẹ awọn ọmọ Igbo, Ohanaeze Ndigbo sọ wi pe otitọ ọrọ ni Obasanjo sọ nitori o mọ ibi ti bata ti n ta orilẹede Naijiria lẹsẹ, amọ o ṣeni laanu wipe ijọba to wa lode yii ko gbọ ọrọ si awọn eniyan lẹnu.
'Aràrá bíi tèmi, kó má rò pé kò sì ǹkan tó lè ṣe láyé ju iṣẹ́ agbe lọ'
Amọ ninu ọrọ ti wọn, ẹgbẹ Arewa Consultative Forun ni Aarẹ Buhari ni awọn ṣe atilẹyin fun pẹlu ẹgbẹ oselu APC, ati wi pe ọrọ Obasanjo gan an lo n da idarudapọ silẹ lorilẹede Naijiria.
Alaga ẹgbẹ Arewa naa, Audu Ogbeh ni ọrọ agọ ni  Obasanjo sọ, eleyii ti ko mu ọpọlọ dani rara, ti o si le e da wahala silẹ lorilẹede Naijiria.
O fikun wi pe nigba ti Obasanjo wa lori oye, ọpọlọpọ nkan ni ko fararọ fun awọn ọmọ orilẹede Naijiria.
Awọn ọmọ Naijiria naa dasi ni ori ẹrọ ayelujara
Bakan naa ni awọn ọmọ Naijiria kan to n sọrọ lori ẹrọ ayelujara naa n sọ wi pe ohun ti Obasanjo sọ dara.
Amọ, awọn miran ni awọn agbalagba bii Baba Obasanjo gan lo wa nidi iṣoro to ba orilẹede Naijiria, pe kii ṣe Buhari nikan ni o ba Naijiria de ibi ti o wa.
Ileeṣẹ aarẹ orileede Naijiria ti sọko ọrọ pada si aarẹ ana, Olusegun Obasanjo pe ohun gan an lo n gbe igbesẹ lati mu ipinya ba Naijiria.
Garba Shehu to jẹ oludamọran aarẹ lori ọrọ iroyin ni o fesi yi ni idahun si ọrọ ti Obasanjo sọ pe Naijiria ti pin yẹlẹyẹlẹ labẹ ijọba Buhari.
Shehu sọ pe Buhari n tun Naijiria ṣe ni ati pe Obasanjo lo n mu ipinya ba orilẹede naa.
Eyi kii ṣe igba akọkọ ti ileeṣẹ aarẹ labẹ ijọba Buhari yoo maa tako ọrọ aarẹ ana Obasanjo .
Ninu atẹjade tuntun yii, Shehu ni ohun to yẹ Obasanjo gẹgẹ bi agba ilu ni ko daba ọna ati yanju ipenija to n ba Naijiria finra dipo bo ti ṣe n ru ina si ipinya labẹ ẹsin ati ẹya.
Garba tun mẹnu ba bi aarẹ Buhari ṣe mu ọkan akin lati yọ owo afikun epo rọbi taa mọ si ''subsidy'' eleyi ti ijọba Obasanjo da laba ṣugbọn ti wọn ko ṣọkan akin lati sọ di mimuṣẹ.
O tun mẹnu ba idagbasoke ti ijọba Buhari ti mu ba Naijiria nipa pipese ayika to faye gba karakata ati idunadura pẹlu awọn ilẹ okeere.
O sọ pe pẹlu bi Buhari ti ṣe ṣe aṣeyọri to yi, ko jẹ iyalẹnu pe awọn oloṣelu ti ko ni aseyọri lasiko wọn yoo maa  jowu aarẹ Buhari.
Obasanjọ: Ọbasanjọ ní òhun yóò fi ìyókù ayé òun san oore Ọlọrun ni
Yoruba ni agba kii wa lọja ki ori ọmọ tuntun wọ, bẹẹ si ni agba ti ko ba kẹhun sọrọ, afaimọ ko ma kẹ itan sare to ba ya.
Idi ree ti aarẹ tẹlẹ ni Naijiria, Olusegun Obasanjo fi n figbe bọnu pe Naijiria ma ti n kuna lọ laye isejọba Buhari, eyi to yẹ ka tete doola rẹ.
"Ilu Abuja ni Obasanjo fi kede bẹẹ ninu ọrọ apilẹkọ rẹ to pe akori rk ni ""Ẹ jẹ ka rin jinna si isubu"", to gbe kalẹ nibi ipade apero kan."
Awọn oniruuru ẹlẹgbẹjẹgbẹ to jẹ ti ẹya kọọkan lawọn ẹkun gbogbo to wa ni Naijiria , bii Afenifere, Middle Belt, Agbaagba lẹkun ariwa, Ohanese Ndi Igbo ati Pan Niger Delta Forum.
Oríṣun àwòrán, Others
Obasanjo ni aile se akoso oniruuru ẹya to wa nilẹ yii lo mu ki orilẹede yii pin yẹlẹyẹlẹ, eyi to jẹ isoro kan gboogi to n ba wa finra.
Aarẹ tẹlẹ naa wa fewe ọmọ mọ awọn eeyan to n lu ilu ogun, ti wọn si ni awọn yoo ya kuro lara Naijiria ni lati sọra se.
Bi ẹya kọskan ba pin kuro lara Naijiria, ẹ ma gbagbe pe a si tun jẹ alamuleti ara wa, tawọn araalu yoo si nilo lati maa ba ara wọn se.
O wa gbe imọran kalẹ pe ti yoo ba se rere, o gbọdọ kọkọ wa ojutu sawọn isoro to nii se pẹlu irẹpọ to sọnu laarin ẹya kọọkan.
Mistura Oseni Akintunde: Ara múmú kìí ṣe oríṣun ìfipábánilòpọ̀, ìran àwòjù ló ń fà á
Bakan naa lo woye pe igbesẹ sise ipade apero miran tile asofin apapọ ilẹ wa n gbero kan wa lati fi akoko sofo ni.
O wa gbe oriyin fawọn ẹgbẹ ibilẹ to ti tako igbesẹ naa, eyi to se apejuwe bii ọna lati baana owo miran.
Oríṣun àwòrán, Other
Aarẹ tẹlẹri lorilẹede Naijiria, Olusegun Obasanjo ti sọ idi ti oun fi ti ilẹkun ile ijọsin mọ awọn oṣiṣẹ rẹ ati ojulumọ, to wa si ibi ayẹyẹ oku iya iyawo rẹ ni Ọjọ Ẹti.
Baba Obasanjo ninu atẹjade to fi lede sọ wi pe, nitori arun Coronavirus ni oun ṣe gbe igbesẹ naa.
Obasanjo salaye pe, bi eto isinku ọhun ṣe bẹrẹ ni agogo mẹwa owurọ ni ijọ Saint Peters Anglican Church to wa ni Isara-Remo, ni ipinlẹ Ogun, ni oun funra oun ti ilẹkun ile ijọsin ọhun, ki awọn eniyan ma ba raye wọle.
'Ó ṣe pàtàkì kí obìnrin gbádùn ìbálòpọ̀ nítorí...'
O fikun pe oun tẹle aṣẹ ijọba to tako ipejọpọ awọn eniyan ọlọgọrọ lasiko ajakalẹ arun Coronavirus yii.
Oríṣun àwòrán, Others
N ṣe ni awọn oṣiṣẹ ati ojulumọ naa duro sita lẹyin igbesẹ Baba Obasanjo, ti wọn si lọ sin oku ohun lẹyin isin.
O ku diẹ ki Mama Florence Adenekan pe ẹni aadọrun ọdun lo jade laye.
Oríṣun àwòrán, Others
Mama Adenekan ni iya Bola Obasanjo to jẹ ọkan lara iyawo Baba Obasanjo.
Oríṣun àwòrán, Others
Iroyin gbe pe, iyawo Obasanjo ko si nibi eto isinku naa, tori o wa ni Ilẹ Gẹẹsi lasiko isinku iya rẹ, ti Baba Obasanjọ si ṣe oju rẹ ni ibi isinku ohun.
Oríṣun àwòrán, Others
Lẹyin isinku naa ni Baba Obasanjo wa tẹsiwaju lọ ki awọn lọbalọba to wa ni agbegbe naa.
Yoruba ni ati okeere ni oloju jinjin ti n mu ẹkun sun, bẹẹ si ni igi gogoro ma gun mi loju, ati okeere la ti n lọ ọ.
Idi ree ti aarẹ tẹlẹ ni Naijiria, Oloye Olusegun Obasanjo fi gunle ọsin ẹja bii ẹgbẹrun lọna aadọta lati dena iyan to le waye lẹyin arun Coronavirus.
Bakan naa ni Obasanjo tun laago ikilọ fun awọn olori orilẹ-ede ede ni ilẹ Afirika pe, ki wọn tete dawọle ọgbin oúnjẹ lọpọ yanturu lẹyin arun Coronavirus.
Oloye Obasanjo woye bẹẹ lasiko to n sọrọ níbi ifilọlẹ ọgbin ẹja naa eyi to waye nibudo iyawe kawe rẹ (OOPL) to wa nilu Abeokuta.
Obasanjo, ẹni tí inu rẹ dun jọjọ lori ọgbin ẹja naa ni, ironu jinlẹ lori iyan to lee sẹlẹ lẹyin ti arun Covid-19 ba kasẹ nilẹ lagbaye, lo mu ki oun gunle ọgbin ẹja naa.
Mo ro pe o yẹ ka mu ọrọ ohun tí yoo sẹlẹ lẹyin arun Coronavirus ni ibaada, mo si gbagbọ pe awọn ijoba ilẹ Afirika yẹ ki wọn ronu bi wọn yoo ṣe ni oúnjẹ ni anisẹku, ki ọwọ ebi ma ba ka awọn eeyan wọn.
Awọn ẹgbẹrun lọna aadọta ẹja to wa ni oko Obasanjo naa lo jẹ ẹja alaran ati ọbọkun ti wọn tu da sinu odo ẹja lati dagba.
Olusegun Obasanjo wá rọ àwọn ìjọba Áfíríkà láti bẹ̀rẹ̀ ọ̀gbìn oúnjẹ lọ́pọ̀ yanturu gẹ́gẹ́ bíi ọ̀nà láti dènà ebi lẹ́yìn àrùn Covid-19.
Azeezat Shomuyiwa : Oyún oṣù méje ló wà nínú Azeezat, kí wọ́n tó f'òkúta fọ́ ọ lórí pa
Lẹyin igbeyawo nilana Musulumi ti wọn n pe ni Nikkah, ireti Alfa Ridwan ati Iyawo rẹ Azeezat ni pe lẹyin oṣu mẹsan ki wọn wa ba wọn ṣe isọmọlorukọ, iyẹn  'suna'.
Asiko imuṣẹ ala rere yii n sun mọ dẹdẹ ni Alfa Ridwan ba ni ki iyawo rẹ o maa bọ nile wa bimọ sọdọ awọn obi oun lo ba di wi pe iroyin iku aya rẹ ni wọn fi ranṣẹ sii pada ni ilu Kano.
Hmmm...Eduwa ko ni jẹ ka kagbako o, ẹkunrẹrẹ itan awodamiloju yii la mu wa fun yin loni, ẹ wo fidio rẹ loke yii.
MC Oluomo: Agbálẹ̀ títì ni ìyá mi, ọmọ ọdún 13 ni mo sì ti sá nílé lọ bẹ̀rẹ̀ iṣẹ́ kọ̀ǹdọ́
Oríṣun àwòrán, InSTAGRAM/MCOLUOMO
Alaga ẹgbẹ onimọto NURTW nipinlẹ Eko, Alhaji Musiliu Ayinde Akinsanya, ti ọpọ eeyan mọ si MC Oluomo, ti salaye bo ṣe bẹrẹ igbe aye rẹ ati bo ṣe di gbajumọ lọjọ oni.
MC Oluomo, lasiko to n kopa lori eto kan ni ikanni BBC Yoruba salaye pe, ọmọ ọdun meje ni baba oun jade laye, atijẹ atimu di ọran, iṣẹ agbalẹ oju popo ni iya oun si n ṣe.
"Oluomo fikun pe ""ọdọ ẹni to ku ni iya fun mama mi nilu Abeokuta la n gbe lọdọ rẹ, Mama mi n gbalẹ titi ni Eko, n ko ri itọju to, ni mo ṣe sa kuro nile lọmọ ọdun mẹtala, ti mo si n ṣe kọndọ lati Abeokuta wa si Eko."""
Oluomo tun sisọ loju rẹ pe, ko si ẹnikẹni to kọ oun ni ọkọ wiwa, oun kan n sun ọkọ siwaju diẹ-diẹ ni ori tọọnu ni gareeji bii kọndọ, ni oun fi mọ ọkọ wa.
Oríṣun àwòrán, InSTAGRAM/MCOLUOMO
Alaga ẹgbẹ ọlọkọ ero ni Eko tun fikun pe, inu iya oun ko dun pe oun n ṣe kọndọ, ti wọn si fẹ mu oun lọ sile ọmọ alaigbọran, ti wọn n pe ni welfare, amọ oun sa mọ wọn lọwọ, ti oun si n sun ita.
O wa yan pe, lootọ ni oun n sun ita tabi inu ọkọ mọju, sugbọn oun ko huwa ọmọ buruku ri, oun kii jale, mu igbo, mu siga tabi ọti, ti oun kii si ṣe ipanle.
"Nigba to n sọ idi ti wọn ṣe n pe ni Oluomo, MC ni ""Oju popo ni mo gbe dagba, a ko ara wa jọ lati dẹkun iwa ole jija ni Oshodi, ni ọba mẹrinla ṣe fi mi jẹ oye Oluomo ni Isọlọ, orúkọ yii si lo ro mi, ti mo fi de ibi giga."""
Oríṣun àwòrán, InSTAGRAM/MCOLUOMO
"Oluomo wa leri leka pe bi Ọlọrun ba bo oun ni asiri, awọn ọmọ ita ni oun yoo ran lọwọ julọ nitori ọmọ ita ni oun naa, idile ti ko si toro lo mu ki ọpọ awọn ọmọ yii di ọmọ ita."""
"Nigba to n sọrọ lori ibasepọ rẹ pẹlu awọn oṣere tiata, Oluomo ni ""iyọ̀ aye ati amuludun ni awọn oṣere tiata,  iwọnba ti mo le ṣe, ni mo fi n ran wọn lọwọ, ohunkohun to ba sì wu awọn eeyan ni ki wọn sọ nipa ibasepọ wa."""
"MC Oluomo, ẹni to ni ẹgbẹ awakọ ero kii lọwọ ninu eto iselu, wa rọ awọn ọmọ ita lati mase ro ara wọn pin, kí wọn mase jale amọ ki wọn lo ọpọlọ wọn lati ṣíṣẹ, ki wọn si fi igbe aye toun ṣe arikọgbọn."""
Violence against women: Oniya ṣá ìyàwó rẹ̀ ládá yánnayànna nítorí ìbálòpọ̀ ló bá ń pariwo pé iṣẹ́ èṣù ni
Ariwo eemọ re, ẹ maa woo niran lawọn eeyan lawọn aladugbo n pa ni ilu Ibulẹ nitosi Akurẹ nigba ti bilisi bẹ silẹ laarin lọkọ laya kan ti ọkọ si tipasẹ bẹẹ yọ ada si iyawo rẹ to ṣa yannayanna.
Abilekọ ni arabinrin Monisola Adeọla ti oun ati ọkọ rẹ si n gbe pọ ki wahala to bẹ silẹ lọjọ buruku , eṣu gbomimu naa, ṣugbọn nigba ti iji wahala naa yoo fi rọlẹ, oju ọgbẹ ada lo kun ara arabinrin naa lati ọwọ ọkọ rẹ pẹlu bi ọkọ rẹ ṣe ṣaa lada yannayanna
Monisola ni òun àti ọkọ rẹ tí jọ ń gbé pọ fún bíi ọdún mẹ́tàdínlógún ṣáájú àkókò tí ìṣẹ̀lẹ̀ yìí ṣẹlẹ̀.
Nígbà tí ó un ṣàlàyé fún BBC Yoruba, arabinrin Monisọla ní àwọn nkan ti o to nkan lo máà ń ná òun lé lórí bíi owó ilé ìwé àwọn ọmọ.
O fi kun un ninu àlàyé rẹ pé, nígbà tí òun kò gbà fún ún láti ni ajosepo pelu òun, ìbínú náà lo mú ṣá gbogbo ara òun báyìí.
Ọgbẹni Oniya Adeola tí ó jẹ ọkọ ọmọ obìnrin náà ṣàlàyé pé kò ye òun bi ọrọ naa ṣe jẹ ati pe bi eedi lọrọ ọhun fẹ jọ loju oun.
Nigeria movie industry: Àgbà òṣèré, Lere Paimo ní àìgbọràn ló ń da ọ̀pọ̀lọpọ̀ àwọn
O ni òun kò mọ ìgbà tí ada de ọwọ òun ti oun si fi ṣá ìyàwó òun.
Oni ìṣe èṣù ni ati pe inú burúkú lo bí òun
Oniya, ẹni tí ó jẹ ọlọkada láàárín ìlú náà sì ìlú Àkúré, ní o ti tọrọ aforiji lọ́wọ́ ìyàwó rè pé ìṣe èṣù ni.
Burundi president: Wo àwọn ohun tó yẹ kí o mọ̀ nípa Pierre Nkurunziza, ààrẹ orílẹ̀-èdè Burundi tó dolóògbé
Pierre Nkurunziza ni Aarẹ ti idibo wọle rẹ fun saa kẹta da fa ki n fa a silẹ. O fẹrẹẹ to ọdun mẹwaa to ti jẹ aarẹ orilẹede Burundi.
Laarin igboro lawọn ilu nla nla, awọn alatako oloogbe Nkurunziza ẹni ọdun mọkanlelaadọta ni afi la, ko gbudọ lọ fun saa kẹta tori pe o lodi si ofin.
Ni idakeji ẹwẹ, awọn alatilẹyin tirẹ ni o jare tori ile aṣofin lo kọkọ yan an sipo lọdun 2005 kii ṣe awọn oludibo gẹgẹ bi ile ẹjọ Burundi ṣe sọ ọ.
Adari awọn agbẹsan ni Nkurunziza jẹ tẹlẹ, o ni idunu si bi o ṣe ti mu alafia de ba Burundi to si nkọ orilẹede to jẹ ọkan lara awọn ti ko lọrọ lagbaye.
Iroyin kan tilẹ sọ wi pe wọn gbe awọn akọṣẹmọṣẹ kan to wa ba Nkurunziza ṣepade lọ si igberiko lati igboro ti wọn si ba aarẹ t n kọ ebe pẹlu awọn agbẹ ilu Bujumbura.
Iwọde ti waye ri ni olu ilu orilẹede naa lodi si saa kẹta ti Nkurunziza n ja fun.
Bakan naa, iwa irẹlẹ arakunrin yii kọja sisọ pẹlu bo ṣe maa n ba awọn ara abule jẹ̀ lawọn ilu igberiko to ti maa n lo akoko rẹ ju.
Iwa yii ti sọ ọ di mọlumọka lawọ abule ṣugbọn ko ri bẹẹ nigboro nibi ti ọpọlọpọ awọn alatako rẹ n gbe.
Onigbagbọ Ododo ati  Kristẹni
Ṣaaju ogun abẹle, Ọgbẹni Nkurunziza lẹyin to kẹkọọ gboye ninu imọ ikọni ere idaraya, o ṣe iṣẹ olukọni ni fasiti Burundi.
O tun ṣe akọnimọọgba ẹgbẹ agbabọọlu awọn ologun Muzinga ati ti Union Sporting nibẹrẹ 1990s.
Baba rẹ, gomina tẹlẹri ti wọn pa lọdun 1972 jẹ ọmọ ijọ Katoliki ti iya rẹ si jẹ ọmọ ijọ Angilika. Ọmọ marun un ni Nkurunziza funrarẹ bi.
Nibayii to ti di atunbi Kristẹni, ko le rinrinajo lai ko ikọ agbabọọlu tara rẹ, Hallaluya FC ati ẹgbẹ akọrin rẹ dani fun anfani gbigbabọọlu pẹlu awọn agbẹbọọlu igberiko ati ṣiṣe ipolongo ihinrere pẹlu eto adura gẹgẹ bi ileeṣẹ iroyin AFP ṣe sọ ọ.
Say no to rape: Àwọn òṣèré tíátà Yorùbá pariwo síta lórí wàhálà ìfipábánilòpọ̀
Koda iroyin ti sọ ọ ri pe oun ati iyawo ti wẹ ẹsẹ awọn eeyan laarin ero pupọ ri eyi si jẹ ki awọn eniyan nigbagbọ ninu rẹ.
Aarẹ Nkurunziza gbagbọ pe atọrun wa ni ipo aarẹ oun o si n fi eyi ṣe atọna igbe aye rẹ ati iṣejọba rẹ. Eyi ni agbẹnusọ rẹ Willy Nyamitwe sọ.
Wọn fi ẹsun ijọba ẹni ti ko fẹ gbe agbara silẹ kan an nigba to fẹ gbe igba saa kẹta.
Ibadan Murder: Oyún oṣù méje ló ń bẹ nínú Azeezat, kí wọ́n tó f'òkúta fọ́ ọ lórí
Ọgbẹni Nkurunziza mori bọ lọwọ igbiyanju awọn kan lati pa a ninu oṣu karun eyi ti ologun kan fẹ fi gba ijọba lọwọ rẹ. Ṣe ni awọn ọmọ ogun tirẹ ba iṣẹ naa jẹ.
Idajọ iku
Ọpọlọpọ igba ni wọn gbiyanju lati pa a, igba mii loju popo ti ẹmi awọn mii lọ si i.
Lẹyin rẹ, ile ẹjọ Burundi kan dajọ iku fun aarẹ Nkurunziza lọdun 1998 ṣugbọn o tun gba idalare eyi to mu ki ija dopin.
Ẹwẹ nigba ti ọlọjọ yan lati wa mu u, aarẹ Nkurunziza jẹ Ọlọrun nipe lọjọ kẹsan oṣu kẹfa ọdun 2020.
#JusticeforTina: Àwọn obi Tina Ezekwe ń bèrè fún ìdájọ́ òdodo pẹ̀lú omijé lójú
Aarẹ orilẹede Burundi, Pierre Nkurunziza ti jade laye.
Aisan ọkan ni iroyin ti a gbọ ṣọ pe o gbẹmi rẹ.
Ijọba orilẹede Burundi fi iroyin iku aarẹ naa sita loju opo twitter rẹ.
Wọn ni ni ọjọ Aje ni aarẹ Nkurunziza jade laye.
Ọdun marundinlọgọta ni aarẹ Nkurunziza ko to jade laye.
Ọjọ Abamẹta ni wọn gbe e lọ si ileewosan Karusi ẹyin to n wo idije ere idaraya kan nitosi ile rẹ.
Say no to rape: Àwọn òṣèré tíátà Yorùbá pariwo síta lórí wàhálà ìfipábánilòpọ̀
Ijọba orilẹede naa ti wa kede eto idaro ọlọjọ meje, bẹrẹ lati ọjọ Iṣẹgun jakejado orilẹ€de naa ni iranti rẹ.
Lati ọdun 2005 ni Pierre Nkurunziza ti di aarẹ orilẹede Burundi, o si n mura lati fa aṣẹ ipo aarẹ le ẹni ti wọn ṣẹṣẹ dibo yan sipo aarẹ nibẹ, Evariste Ndayinshimiye ni ogunjọ oṣu kẹjọ ọdun 2020.
Ni ọjọ kejidinlogun oṣu kejila ọdun 1963 ni wọn bi aarẹ Burundi tẹlẹ to jade laye, Pierre Nkurunziza.
Ọdun 2005 lo gori aleefa gẹgẹ bi aarẹ ilẹ Burundi, ipo aarẹ yii naa lo si dimu titi to fi jade laye.
Oríṣun àwòrán, others
Lọdun 2015 ni ẹgbẹ rẹ tun fa a kalẹ lati dije fun ipo aarẹ fun saa kẹta eleyi ti ọpọ awọn ẹgbẹ alatako koro oju si.
Awọn ẹgbẹ alatako ni o lodi si ofin ilẹ naa fun ẹnikẹni lati lọ fun saa kẹta ni orilẹede naa.
Wọn ditẹ lati gbajọba rẹ lọdun lọjọ kẹtala oṣu karun un ọdun 2015 nigba ko si nile.
Lagos lockdown update: Ayodeji Tinubu ní àìsí àǹfàní ẹ̀kọ́ ayélujára t'íjọba ń pariwo fáwọn ọmọdé agbègbè òun lòun fi di olùkọ́ fún wọn
Lasiko igbele to waye nipasẹ ajakalẹ arun coronavirus, oniruuru eto lo yipada lawujọ ninu eyi ti eto ẹkọ wa.
Gẹgẹ bi ara ọna lati mojuto awọn iyipada yii lo mu ki ijọba ni ipinlẹ Eko o gbe eto ẹkọ ayelujara ati ti ori afẹfẹ jade.
Amọṣa, bi eto naa ṣe loriyin to, ọpọ akẹkọ ni ko lọtọ si nitori aisi anfani ayelujara ati idakureku ina ọba.
Eyi lo mu ki Ọgbẹni Tinubu Ayọdeji, ninu itara rẹ lati rii pe awọn ewe agbegbe rẹ ko padanu nitori airi anfani ayelujara naa lo fi da eto ẹkọ jẹle o sinmi silẹ eleyi ti awọn eeyan ti n kan sara si bayii.
Ọkọ mi kò kú, ó ń palẹ̀ ọjọ́ ìbí 78 rẹ̀ mọ́ lọ́wọ́ - Joke Jacobs
Oríṣun àwòrán,  Instagram/olujacobs
Irọlẹ Ọjọru ni ariwo ta pe gbajugbaja osere tiata kan ni ede Yoruba ati oyinbo, Olu Jacobs, ti jáde laye.
Igba keji ree ni aarin osu kan ti ikede yoo waye pe ilumọọka osere tiata naa papoda, bẹẹ ni ọpọ eeyan to si gbọ ikede yii lo ka ọwọ sori pe ẹni re lọ.
Ṣugbọn iwadii BBC Yoruba ti fihan pe ahesọ ọrọ ati irọ nla to jinna si ootọ ni ikede naa, nitori Olu Jacobs si wa laaye, to n mi loke eepẹ.
Nigba to n fidi otitọ ọrọ mulẹ nipa ipo ti ọkọ rẹ wa, Joke Silva, to tun n jẹ Joke Jacobs, tii ṣe aya oṣere tiata naa ni ko ko ko bii okuta ni ara ọkọ oun le, ko si si iku kankan loju rẹ.
Ko si ohun to ṣe ọkọ mi, koda, ó ń palẹ mọ lọwọ bayii lati ṣe ayẹyẹ ọjọ ibi ọdun kejidinlọgọrin to de ile aye losu keje to n bọ, bẹẹ ni ẹnu ya awọn nigba ti ọpọ eeyan n beere pe ki lo ṣe ọkọ òun.
Joke Jacobs wa fi ọkan awọn ololufẹ wọn balẹ pe ko si ewu rara fun ọkọ oun.
Esabod: Esther Aboderin tí ọ̀pọ̀ mọ̀ sí Esabod ní ẹ̀sín pọ̀ fún òun lọ́jọ́ tí wọn parọ́ pé mo mu sìgá lórí Facebook
Oríṣun àwòrán, others
Oloye Esther Aboderin tii ṣe ilumọọka sọrọ-sọrọ lori ayelujara ati elegbogi ibilẹ to n lo ewe ati egbo ti salaye pe ọrọ aje ati ọna atijẹ lo sọ oun di were lori ayelujara.
Aboderin, ti ọpọ eeyan mọ si Esabod abi iya ewe, lasiko to n kopa lori akanse eto loju opo BBC Yoruba dahun ọpọ ibeere awọn ololufẹ BBC Yoruba.
O salaye pe, bi oun ko ba fi were diẹ diẹ kun ọja ti oun n ta lori ayelujara, ko ni ta bo ṣe yẹ.
Esabod, ẹni to bẹrẹ lilo ori ayelujara lati ọdun 2012, táwọn eeyan si ni o maa n si pata silẹ lori Facebook tun kede pe, oun ko kabamọ awọn iwa ti oun n hu loju opo Facebook.
O ni bo tilẹ jẹ pe igba ti oun bẹrẹ ọja tita ni eebu maa n dun oun, amọ nibayii, o ti mọra, tori ara ipolowo   ọja ni.
"Esabod ni: ""N ko lee gbagbe ọjọ ti wọn n sọ kiri pe mo mu siga lori Facebook, oju ti mi, ẹṣin pọ ju fun mi."
"Idi si ree ti mo kuku fi mu siga naa han wọn lori Facebook, pe bi wọn yoo ba pa mi, ki wọn kuku pa mi."""
Nigba to n sọrọ lori ija lorisirisi to n waye laarin rẹ ati awọn eeyan miran lori Facebook, eyi to mu ki wọn maa sọrọ kobakungbe ṣi ara wọn, ti ẹnu si saaba maa n kun-un, Esabod ni ọpọ awọn eeyan to n bu oun ni oun kii da lohun afi awọn ti aseju wọn ba pọ ju.
"Ogun aye lo ti mi de ori Facebook, ibẹ si ni mo ti ṣe oriire.
Mo dupẹ pe ẹnu n kun mi bayii tori nigba ti iya n jẹ mi, n ko ni ọrẹ, bi ogo ba si ṣe pọ si, naa ni ọta yoo pọ, orúkọ mi si lo gbayi ti wọn ṣe n pariwo mi mo ri oju rere Ọlọrun gba ni."
Ibadan Murder: Oyún oṣù méje ló ń bẹ nínú Azeezat, kí wọ́n tó f'òkúta fọ́ ọ lórí
Kini Esabod sọ nipa iwa ipa ninu idile?
Iya Ewe, tun mu ẹnu ba iwa ipa sáwọn obinrin ninu idile tun mẹnuba ọpọlọpọ idi ti iyawo fi maa n duro sinu idile bẹẹ yatọ si itọju ọmọ.
" Oju kokoro ati ẹtan owo, ifẹ ori ayelujara ati ifẹ afẹju si ọkùnrin wa lara idi ti awọn obinrin fi n fi ara da iya lati ọwọ ọkùnrin.
Amọ mo n rọ awọn obinrin ti ọkọ ba n na wọn  lati ko kuro nibẹ, ko ma baa pa a nitori ọmọ wọn ní ọkọ wọn."
Wo ohun ti Esabod sọ nipa ọrọ alufanṣa to n sọ si awọn Ọba alaye kan:-
Esabod, ẹni ti ọpọ eeyan mọ pe o maa n fi ede abuku sọrọ nipa awọn Ọba alaye nilẹ Yoruba, awọn agba oselu, olorin, oṣere tiata atawọn eekan ilu miran lori ayelujara, wa salaye pe, oun kii woju ẹnikẹni bii sọrọ-sọrọ, ti oun ba wa lẹnu iṣẹ oun
"O ni: "" Ni ẹnu iṣẹ mi, n ko fẹ mọ iru ẹni to jẹ, amọ laisi lẹ́nu iṣẹ, maa kunlẹ fun Ọba; amọ, ki ni Ọba wa de ibi iroyin?"
"Ẹtọ ilu ni mo n ṣe, ija ilu ni mo n ja awọn araalu si lo n fun mi ni ẹri ti mo n lo, ti mo ba si sọrọ Ọba, mo ní ẹri to daju lọwọ."""
Joke Silva: Olu, ó tó gẹ́ pẹ̀lú obìnrin yìí níkan tó ń ba ẹ ṣeré ìfẹ́ nínú sinimá
Imọran Esher Abọdẹrin fun awọn ọdọ Naijiria ni pe:
Iya ewe, to ti le ni ọgbọn ọdun to ti wa loke okun, wa gba awọn ọdọ to n lakaka lati wa iṣẹ aje lọ soke okun nimọran pe, ki wọn ni suuru nitori nnkan ko fi bẹẹ dara mọ lọhun.
"O ni: "" Ewe, tii ṣe iṣẹ idọti lo sọ mi di ọlọla, ogun lo si le mi de idi ewe tita, ki Ọlọrun tete fi ọna han ẹda."
"Ki awọn ọdọ mase fi akoko wọn sofo nipa diduro de ijọba, ki wọn ma si tiju iṣẹ ti wọn ba n ṣe."""
O ni ọlẹ ati ole lo n da awọn ọdọ iwoyii laamu ni wọn ko ṣe fẹ ṣíṣẹ ni Naijiria, bẹẹ si ni oke okun ko dabi ti tẹlẹ mọ, wọn kan n wa fi ara wọn jiya ni.
Coronavirus symptoms : Wo ìdí tí ìdí tí ìjọba ìpínlẹ́ Ekiti ṣe fẹ́ kéde Kónílé-ó-gbélé tuntun
Oríṣun àwòrán, @ng_phenomenal
Ijọba ipinlẹ Ekiti ti sọ pe oun yoo kede ofin konile-o-gbele tuntun mii laipẹ ti awọn eeyan ipinlẹ naa ba tẹsiwaju pẹlu kikọ eti ikun si ilana to gbe kalẹ lati dẹkun itankalẹ arun Coronavirus.
Kọmiṣọna ọrọ to n lọ ni ipinlẹ ọhun, Muyiwa Olumilua lọ sọ bẹẹ ninu ifọrọwerọ kan pẹlu BBC.
"Olumilua sọ pe ""Ti awọn eeyan to ni arun naa ba n pọ si, o di dandan ki a pada si ofin konile-o-gbele."""
Kọmiṣọna ọhun tẹsiwaju pe ojuṣẹ ijọba ni lati daabo bo awọn ara ilu ati pe ki wọn lee wa ni ilera pipe ati alafia.
"O ni ""Ti awọn eeyan ba kọ lati tẹle ilana ti ijọba gbe kalẹ fun ilera awọn eeyan, ko si nnkan mii ti a maa ṣe ju pe ka ti gbogbo ibode wa, ki a si paṣẹ konile-o-gbele."""
Oríṣun àwòrán, @ng_phenomenal
Olumilua sọ pe ijọba Ekiti ko tii mu ọjọ ti yoo kede igbele tuntun ọhun, ṣugbọn ijọba n fi akoko yii kilọ fun awọn eeyan lati tẹle inala to gbe kalẹ.
Lẹyin naa lo rọ awọn olugbe ipinlẹ Ekiti lati tẹle gbogbo ilana ti ajọ NCDC gbe kalẹ, bii fifọ ọwọ ẹni dede, itaketesiraẹni lawujo ati lilu ibomu.
Lagos lockdown update: Ayodeji Tinubu ní àìsí àǹfàní ẹ̀kọ́ ayélujára t'íjọba ń pariwo
Nigeria Senate: Àwọn àbádòfin pàtàkì márùn ún áti ipa wọn nílùú láàrin ọdún kan tí wó̩n fi ṣiṣẹ́
Oríṣun àwòrán, Nigeria senate
Ka to ṣiju pẹẹ, ọdun kan ti yaa pe ti wọn ṣe ifilọọlẹ ile igbimọ aṣofin Naijiria ikẹsan lọjọ kọkanla oṣu kẹfa ọdun 2019 ti yoo si kasẹ nlẹ lọjọ kọkanla oṣu kẹfa ọdun 2023.
Ile igbimọ aṣofin to ni aṣofin mọkandinlaadọfa to jẹ aṣofin agba ati ọgọta le ọọdunrun to jẹ aṣojuṣofin wa ni olu ilu orilẹede yii, Abuja nibi ti wọn ti n ṣe ofin eyi to yẹ ko ni ṣe pẹlu gbogbo araalu eyi ti wọn n ṣoju.
Ẹwẹ lati ọdun to kọja ti awọn aṣofin yii ti bẹrẹ iṣẹ, ọpọ igbesẹ ni wọn ti gbe ọpọ aba ofin si ni wọn ti da ṣugbọn ibeere to n jẹyọ ni wi pe bawo ni awọn aba ọhun ṣe kan ara ilu to si ṣe wọn loore. Lara wọn niyii:
Wọn ti ka abadofin yii ti Sẹnetọ Muhammed Musa mu aba rẹ wa ni ipele kika meji bayii.
Idi pataki fun abadofin naa ni lati lodi si awọn ọrọ ti ko ri bo ṣe tọ ati lati ṣe ofin ti yoo lodi si agbejade iru iroyin bẹẹ lori ayelujara.
Bakan naa lati rii daju pe igbesẹ wa fun idamọ, bibojuto ati didaabo bo eeyan lori awọn iwa tabi ọrọ irọ lawọn oju opo ayelujara. Pari pari ẹ lati fi awọn ọdaran ti wọn ba gbamu jofin...
Ibeere: Njẹ eyi ti ṣe anfani fun awọn araalu?
Idahun ranpẹ: Ile igbimọ aṣofin ko tii gba aba naa wọle, wọn kan ti fọrọjomitoro ọrọ lori rẹ ni ni ipele kika meji.
Abadofin yii ti Sẹnetọ Ibrahim Oloriegbe dabaa rẹ ni lati da abo bo awọn to ni iṣoro ọpọlọ. Abadofin ọhun tilẹ pe fun ki wọn da ajọ kan silẹ lati maa mojuto o.
Idi pataki fun aba yii ni lati pese aaye fun idahun si ọrọ eto ilera fun aisan ọpọlọ. Lati daabo bo ẹtọ awọn to ni idamu ọpọlọ. Lati jẹ ki wọn ri itọju to peye, ki ofin si tun wa ti yoo gbe e lẹyin ati didaabo bo wọn lọwọ idẹyẹsi, ati ki awọn agbanisiṣẹ maṣe fọwọ rọ wọn sẹyin bi wọn ba yege fun iṣẹ naa.
Ibeere: Ki ni abadofin yii ti ṣe fun araalu?
Idahun ranpẹ: Wọn ti ka a fun igba akọkọ nile igbimọ aṣofin.
Aṣofin Wilfred Onyema lo dada ofin yii latari pipese ọna ati maa ṣe idahun kanmọ kanmọ si atunto ofin to ni ṣe pẹlu owo ori ati imuṣẹ rẹ.
Ibeere: Ọna wo ni aba ofin yii yoo fi ṣeranwọ fun araalu nipa owo ori sisan?
Idahun: Wọn ko tii ka a ni ipele kika akọkọ.
Abadofin yii ti aṣofin Wilfred Onyema da laba da lori ṣiṣe agbekalẹ Fasiti ti orukọ rẹ wa loke yii lati pese ohun to tọ fun awọn alaṣẹ rẹ.
Ibeere: Ki ni abadofin yii da fun araalu?
Idahun ranpẹ: Wọn ko tii ka a ni ipele kika akọkọ.
Latọwọ aṣofin Wilfred Onyema ni abadofin yii naa  ti wa eyi to pe fun ọrọ agbekalẹ Fasiti torukọ rẹ wa loke yii ati aridaju pe idọgba wa fun imọ ẹkọ ile iwe giga kaakiri Naijiria.
Awọn ẹkọ kika ri wọn n kọ ni fasiti yii ko pọ bẹẹ si ni awọn ẹka ẹkọ naa ko pọ.
Ibeere: Ọna wo ni abadofin yii ti ṣe anfani fawọn akẹkọọ ni ẹkun ti wọn ti n bere fun igbesẹ?
Idahun ranpẹ: Wọn ko tii ka abadofin naa ni ipele kika akọkọ.
Ẹwẹ, iwadi fi han wipe laarin ọdun kan ti awọn aṣofin agba ati awọn aṣojuṣofin ti bẹrẹ iṣẹ ni wọn ti n da aba, ṣe ijiroro ati ṣe amuṣẹ awọn iṣẹ akanṣe to nilo amojuto lawọn ẹkun ti wọn n ṣoju kaakiri Naijiria.
Bakan naa, aarẹ Muhammadu Buhari ti fi ikini ku oriire iṣẹ takun takun ti wọn n ṣe ranṣẹ si wọn fun ayẹyẹ ọdun kan ti wọn pe.
Alaafin: Kabiyesi ẹ má bínú, àìmọ̀ lo fa ìgbésẹ̀ mi, n kò takò yín - Makinde bẹ Alaafin
Oríṣun àwòrán, others
Bi wọn ba n sọ nipa awọn ọba alade ti ko ṣee maa fi ọwọ rọ sẹyin nilẹ Yoruba, orilẹede Naijiria ati agbaye, ọkan gboogi ni alaafin ilu Ọyọ jẹ ko si si ijọba kan to n ko iyan rẹ kere.
Eyi gan lo faa ti ahesọ iroyin nipa aawọ laarin oun ati gomina ipinlẹ Ọyọ lori idasilẹ ọwọ ẹka ọlọpaa kogberegbe Police Mobile Squadron si ilu Agọ Arẹ fi jẹ eyi ti ọpọ ko lee fi oju fo da.
Amọṣa Ọbalaye naa, iyẹn Kabiyesi Iku baba yeye, Ọba Adeyẹmi Alaafin ti ṣalaye ọrọ pe ko si ija laarin oun ati gomina Makinde lori iṣẹlẹ naa.
Alaafin sọ ọrọ yii nigba ti gomina Makinde bẹẹ wo laafin Ọyọ lasiko irinajo rẹ si ilu Iṣẹmbaye naa lati ṣi awọn akanṣe iṣẹ ti wọn fi n sọri ọdun kan iṣejọba Makinde gẹgẹ bii gomina ipinlẹ Ọyọ.
Alaafin Ọyọ ni imulẹ nla lo n bẹ laarin oun ati Gomina Seyi Makinde, nitori naa ko si ohun to lee fa ikunsinu laarin oun ati gomina naa.
O fi kun un pe oun kuro lara awọn ọba ti yoo maa ba awọn to ba wa nipo iṣejọba ta kangbọn nitoripe oun ko si lati maa tabuku tabi fi ẹrẹ yi awọn to ba wa nipo aṣẹ lara.
Oríṣun àwòrán, Twitter/seyi makinde
Ko si aawọ laarin emi ati gomina. Bi eeyan ba ni ọgbọn ti o si kawe, iru eeyan bẹẹ yoo ms bi a ti n ba awọn to ba wa nipo alaṣẹ ṣe pọ
Iku Baba yeye, Ọba Lamidi Adeyẹmi kẹta ṣalaye lori ohun to ṣẹlẹ nipa ti ọrọ idasilẹ ọwọ ileeṣẹ ọlọpaa kogberegbe naa. O ni oun ko ni ikunsinu kankan si gomina Makinde lori bi o ṣe ni ki ọga ọlọpaa lorilẹede Naijiria o gbe ọwọ naa lọ si Agọ arẹ dipo ilu Ọyọ ti alaafin n ja fun.
Saaju si ni Alaafin ti kọ orisirisi lẹta bii mẹta si ọga agba patapata fun Ileesẹ ọlọpaa nilẹ wa, to si n beere pe oun n fẹ ẹka ibudo ọlọpaa kogberegbe (MOP 73) nilu Oyo, eyi ti aarẹ Muhammad Buhari ti fi ontẹ lu.
Oríṣun àwòrán, oyo insight
Esi lẹta fun agbekalẹ Ileesẹ ọlọpaa kogberegbe naa silu Oyo lo de ni ọjọ kẹtala osu kinni ọdun 2020 pe ijọba ti fọwọsi pe ki wọn gbe Ileesẹ ọlọpaa kogberegbe naa silu Oyo ati ilu mẹfa miran ni Naijiria.
Alaafin si tun kọ lẹta miran ni ọjọ kẹrinla osu keji ọdun 2020 lati dupẹ lọwọ ijọba, ni pe o seun lori bibuwọlu agbekalẹ Ileesẹ ọlọpaa naa.
Amọ lasiko ayẹyẹ ọdun kan rẹ lori aleefa ni Gomina Makinde lọ si Ileesẹ ọlọpaa kogberegbe naa nilu Agọ Arẹ to wa ni agbegbe Oke Ogun, eyi to bi awọn ọmọ Oyo, Alaafin ati Oyomesi ninu.
Ki lo fa Ija lọbalọba ni ilu Iwo
Nigba to fi atẹjade sita lori ọrọ yii, akọwe eto iroyin si gomina, Taiwo Adisa ni irọ gbuu ni pe ilu Oyo lo yẹ ki Ileesẹ ọlọpaa naa wa nitori Makinde lo kọ lẹta lati beere fun Ileesẹ ọlọpaa naa, ti ọga agba ọlọpaa si fi ontẹ lu u pe ko wa nilu Agọ Arẹ, ti wọn si lo Ileesẹ asesiga ìjọun lati bẹrẹ Ileesẹ ọlọpaa naa.
Yoruba ni bi ẹlẹjọ ba ti mọ ẹjọ rẹ ni ẹbi kii pẹ lori ikunlẹ, idi ree ti gomina Seyi Makinde fi n rawọ ẹbẹ si Alaafin pe ko ma binu, ko fi ọwọ wọnu.
Oríṣun àwòrán, oyoinsight
Gomina Seyi Makinde rawọ ẹbẹ naa lasiko to lọ silu Oyo lati si ibudo ilera alabọde kan nilu Oyo, ti Alaafin tilu Oyo, ọba Lamidi Olayiwola Adeyemi kẹta si gbalejo rẹ .
Ninu ọrọ rẹ si ni Gomina Makinde ti rawọ ẹbẹ si Alaafin pe ko jẹ eburẹ lori bi oun ṣe gbe ibudo Ọlọpa kan lọ si agbegbe Oke Ogun dipo ko wa nilu Oyo gẹgẹ bi Alaafin ti n fẹ.
Oríṣun àwòrán, oyo insight
Gomina Makinde sọ fun Alaafin pe ko ma binu nipa ọrọ naa, oun ko mọ rara pe ọba naa ti gbe igbesẹ saaju nípa kíkọ lẹta lori ọrọ yii.
"Kabiyesi, n ko mọ pe ẹ ti kọ lẹta kankan nitori lati oṣù kẹsan-an ọdun 2019 ni ọga agba olopaa ti pàṣẹ pe ki wọn gbe Ileesẹ ọlọpaa kogberegbe  ọhun wa si agbegbe Oke Ogun lati pinwọ iwa ijinigbe atawọn iwa ọdaran miran.
Aisha Buhari: Ìyawó ààrẹ padà délé láyọ̀ láti Dubai
Oríṣun àwòrán, @AishaBuhari
Ọkọ̀ Bàálù mi rí ìdámú nínú afẹ́fẹ́ ṣùgbọ́n...
Iyawo aarẹ orilẹede Naijiria ti ṣalaye bo ṣe mori bọ lọwọ ọkọ baalu to ri idamu loju ofurufu lasiko to n rinrinajo pada bọ wale lati ilẹ United Arab Emirates (UAE).
Arabinrin Aisha Buhari ni oun rinrinajo lọ si orilẹede naa lati lọ fun itọju to so pada wale pẹlu ọkọ ofurufu ileeṣẹ ogun ofurufu Naijiria.
Mo fi asiko yii dupẹ lọwọ gbogbo ọmọ Naijiria fun adura ati ọrọ ikini wọn nigba ti mo lọ fun itọju. Ara mi ti ya bayii mo si ti pada bọ sipo bẹẹni mo ti dari wale si Naijiria"""
Ko ye iru aisan pato to ba aya aarẹ kuro ni Naijiria ṣugbọn ko ba a pada wale gẹgẹ bo ṣe sọ.
"Ẹwẹ, o ni ""loju na wa pada, ọkọ baalu awọn ọmọ ogun ofurufu ri idamu nla ninu ofurufu ṣugbọn awakọ atawọn oṣiṣẹ inu baalu naa ṣe iṣẹ takun takun lati da a pada sọna rẹ""."
Oríṣun àwòrán, @AishaBuhari
Aisha gboriyin fun igboya ti awakọ naa atawọn oṣiṣẹ toku ni si iṣẹ wọn.
Iroyin to n ja rayin-rayin lori ayelujara ni wi pe iyawo aarẹ orilẹede Naijiria ti rinrinajo lọ si Dubai ni orilẹede United Arab Emirate fun idi pato ti a ko mọ.
Awọn iroyin kan tilẹ n sọ pe bi awọn ṣe gbọ ọ, ọrun lo n dun arabinrin Aisha ṣugbọn iroyin naa sọ pe awọn apẹrẹ ṣaa han pe tori ilera rẹ ni.
Ọpọlọpọ ọmọ Naijiria lo ti fọn si oju opo Twitter lati sọ ero wọn nipa irinajo ti a gbọ pe iyawo aarẹ lọ yii.
Igba ti a ri iyawo aarẹ kẹyin ni ita gbangba ni asiko adura ọdun Eid-el-Kabir pẹlu awọn idile rẹ nile Aso Villa nilu Abuja.
Awọn iroyin mii ni lẹyin ọdun Sallah lọsẹ to kọja ni wọn gbe iyawo aarẹ kuro ni Naijiria lẹyin to n kerora ọrun didun lati bi ọsẹ meji to bere fun ki wọn gbe oun lọ oke okun.
Èèyàn mẹ́tàdínláàdọ́fà ló móríbọ́ lọ́wọ́ Covid-19, 443 míì tún lùgbàdì rẹ̀ lọ́jọ́ Ẹtì
Èèyàn 16 kú lẹ́yìn tí bàálù Air India já lulẹ̀ , tó sì kán sí méjì ní Kerala
Ìtàn ayé Shina Rambo, adigunjale tó fi oyún 27 gún ọṣẹ
Ohun tẹ́ẹ gbúdọ mọ nípa kókó orí ọyàn yín lásìkò fífọ́mọlọ́yàn
Ọrọ miran tun ti n rugbo bọ nidile aarẹ orileede Naijiria Muhammadu Buhari pẹlu bi iyawo aarẹ Aisha Buhari  ti se ke gbajare si ọga ọlọpaa lati tu awọn ẹsọ oun silẹ ki wọn ma ba lugbadi Covid-19 lọdọ wọn.
Aisha fi ọrọ yi sita lọjọ Eti si oju opo Twitter nibi to ti sọ awọn ọrọ  pe ko yẹ ki ẹnikankan kọja ofin ti ijọba gbe kalẹ nipa irina lasiko Covid-19 .
Aisha ni ẹnikẹni to ba tasẹ agẹrẹ si ofin yii gbọdọ lọ si iyasọtọ ọlọjọ mẹrinla lati le mọ boya o ko arun naa tabi ko ni.
O pari ọrọ rẹ pe ki  ọga ọlọpaa tu awọn ẹsọ oun ti wọn mu sọdọ silẹ ki wọn ma ba ko Covid-19.
Ìdílé tí ọkọ da ọmọ síta tóríi ojú Búlùú tí wọ́n ní bá BBC sọ̀rọ̀
Ninu ọrọ ti Aisha Buhari sọ, ko darukọ ẹni kankan pe o tapa si ofin ma rina lasiko Covid 19.
Oríṣun àwòrán, Twitter/Aisha Buhari
Sugbọn o jọ gate ko jọ gate, awọn ileesẹ iroyin Naijiria kan sọ pe ọrọ yii ko sẹyin bi ọkan lara awọn amugbalẹgbẹ aarẹ Buhari kan ti se dari si Aso Rock lati irinajo si ipinlẹ miran ni Naijiria.
Gẹgẹ bi wọn ti se sọ, awọn ẹsọ Aisha Buhari ko jẹ ki amugbalẹgbẹ yi wọ Aso Rock nitori pe wọn ni o seese ki o ti ko Covid-19 lati ibi to ti n bọ.
Amugbalẹgbẹ yii la gbọ pe o fi ibinu pe olori awọn alaabo iyẹn CSO ti o si ni ko fi awọn ẹsọ iyawo aarẹ to da lọna si ahamọ.
O seese ki o jẹ idi ree ti Aisha Buhari fi n lọgun sugbọn a ko ti ridi ọrọ yi fi mulẹ.
June 12:Àwọn tó wà ní ìjọba Baba mi ní kò lu owó ìlú ní póńpó- Ọmọ Abacha
Oríṣun àwòrán, Twitter/Aisha Buhari
Ileesẹ ọlọpaa Naijiria naa ko ti fesi boya lootọ lawọn ẹsọ iyawo aarẹ wọn wa lahamọ.
Kete ti Aisha Buhari fi ọrọ yi sita loju opo Twitter lawọn eeyan yabo oju opo rẹ ti wọn si bẹrẹ si ni fesi.
Ọpọ ko tilẹ beere ohun ti o mu ki Aisha Buhari ke gbajare si ọga ọlọpaa.
Ninu ero wọn, Aisha Buhari ko tori awọn eeyan sọrọ nipa titẹle ilana ijọba lasiko Covid-19 yi bi kii se pe eeyan kan tun ti fọwọ tẹ ẹtọ rẹ mọle ni
Awọn kan tilẹ n beere pe se ko ni nọmba ọga ọlọpaa ni abi ki lo wa de to fi n damu awọn loju opo Twitter
Ninu ero awọn ẹlomiran, wọn ni se ko yẹ ki iyawo aarẹ da si awọn ọrọ miran to n jẹ Naijiria logun lasiko yi bi ipaniyan ati ijingbe  to n waye lawọn ipinlẹ kaakiri Naijiria.
Oríṣun àwòrán, Facebook/muhammadubuhari
Aarẹ orillẹede Naijiria, Muhammadu Buhari yoo bawọn eeyan sọrọ lọjọ Ẹti, ọjọ kejila oṣu to ti di ayajọ ijọba awarawa bayii.
Gẹgẹ bi atẹjade ti oludamọran pataki si aarẹ, Femi Adesina fi sita, aago meje aarọ ọjọ Ẹti ni Buhari yoo bawọn ọmọ Naijiria sọrọ.
Ijọba rọ awọn ileeṣẹ redio ati amohunmaworan to fi mọ awọn ileeṣẹ iroyin mii pe ki wọn darapọ mọ ileeṣẹ tẹlifisan ijọba apapọ, NTA lati le ṣafihan ọrọ fawọn eeyan.
Ọjọ kejila oṣu kẹfa ọdun 1993 lawọn ọmọ Naijiria dibo aarẹ ninu eyi ti MKO Abiola ti ẹgbẹ SDP ti waako pẹlu Alhaji Bashir Tofa ti ẹgbẹ NRC.
Abiola lo jawe olubori ibo naa, ṣugbọn Ọgagun fẹyinti Ibrahim Babangida wọgile esi idibo naa eleyi to da rogbodiyan silẹ kaakiri Naijiria nigba naa.
Ti ẹ ko ba gbagbe, lọdun 2018 ni Aarẹ Buhari kede ''June 12'' gẹgẹ ayajọ ọjọ ijọba awarawa dipo ọjọ kọkandinlọgbọn oṣu karun ti ijọba ologun gbejọba fun alagbada ti ijọba kede tẹlẹ.
Ogun state lockdown update: 'Èèyàn 104 tó kó covid-19 ní ílééṣẹ́ kan ní Sagamu fihàn pé ààrùn náà ti wà láwùjọ'
Oríṣun àwòrán, Twitter/Prince Dapo Abiodun
Bi awọn eeyan mẹrinlelọgọrun un ṣe lugbadi aarun coronavirus ni ileeṣẹ kan niluu Sagamu nipinlẹ Ogun fihan pe aarun naa ti wa lawujọ.
Nigba ti Kọmiṣọnna eto ilera ipinlẹ Ogun, Dokita Tomi Coker ba BBBC Yoruba sọrọ lo fidi ọrọ naa mulẹ.
Kọmiṣọnna eto ilera ṣalaye pe ko si ẹni ti o ni apẹẹrẹ pe o ni aarun covid-19 ninu awọn oṣiṣẹ naa ti wọn lugbadi coronavirus.
Kọmiṣọnna ni gbogbo awọn to laarun yii atawọn eeyan ti wọn ni ajọṣepọ lo n gbe ninu ọgbọn ileeṣẹ naa.
O ni ọpọ eeyan lo n rin kiri pẹlu aarun coronavirus lai mọ.
Dokita Tomi fikun ọrọ rẹ pe ewu to wa bayii ni wi pe awọn eeyan ko tẹle ilana wiwọ ibomu lati dena itankalẹ coronavirus.
Kọmiṣọnna ni aarun yii ko le ṣalai maa maa tan kalẹ si nitori awọn eeyan ko tẹ le ilana itakete si ara ẹni.
O ni otitọ ni pe awọn ọlọpaa n gbiyanju lati maa mawọn eeyan ti wọn ko tẹ le ilana ti ijọba la kalẹ lori at i dena itankalẹ aarun covid-19.
Ṣugbọn kọmiṣọnna sọ pe o yẹ kawọn eeyan mu ọrọ ilera ara wọn lọkunkun lai jẹ wi pe wọn n fipa mu wọn.
Lori erongba ijọba ipinlẹ Ogun lati ṣi ile ijọsin ati mọṣalaaṣi, kọmisọnna ni ijọba ti ṣepade pẹlu awọn olori ẹsin lori awọn ilana eto aabo lati dena covid-19 ti ile ijọsin ba di ṣiṣi pada.
June 12: Ìtàn bí Alhaja Kudirat Abiola ṣe dojúkọ ohun t'ọ́kùnrin ń sá fún torí ìjọba àwaarawa
Oríṣun àwòrán, @niwexnigeria
Kudirat Abiola jẹ opo nla gidi nidi agbekalẹ eto isejọba alagbadada, a ko sile sọrọ June 12, ka yọ ipa to ko sẹyin nitori o fi ẹmi rẹ lelẹ fun ijọba alagbada ni.
Wọn bi Kudirat Olayinka Adeyemi ni ilu Zaria lọdun 1951, lati igba ọdọ rẹ lo ti n fi apẹrẹ akinkanju han.
Ijẹri ohun to ṣe ni ileewe girama. Muslim Girls High School lo soo di odidi alagbara obinrin pẹlu iṣẹ takuntakun to fi jẹ adari gbogbo ọmọ ile iwe ni kilaasi aṣekagba rẹ.
Àwọn ìtàn mánigbàgbé tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí:
Gbajugbaja ni Kudirat, orukọ rẹ kari aye, o si jẹ apẹrẹ ara ọtọ aronilagbara ẹda to n ja fun idọgba ati ijọba awa ara wa jakejado Afirika
Ọmọ ọdun mọkanlelogun lo fẹ Oloye Moshood Abiola.
Alhaja Kudirat ni iyawo keji ti Abiola fẹ ṣugbọn oun ni iyale ninu awọn iyawo rẹ lasiko ti wọn pa a.
Ọmọ meje ni Kudirat bi fun ọkọ MKO Abiola - Yisau Olalekan, Hafsat Olaronke, Abdul Mumuni Khafila, Hadi, Moriam, Jamiu Abiodun ati Olalekan Yisau Abiola.
Oríṣun àwòrán, @OgbeniOlaide
Gẹgẹ bi o ṣe wa ni akọsilẹ,  odindi gende ọkunrin mẹfa ni wọn gbe iṣẹ iku rẹ fun.
Ninu ọkọ rẹ ni wọn pa a si pẹlu iru ibọn ti awọn sọja n lo.
Koda, dẹrẹba rẹ gan an ku,  Oluranlọwọ rẹ ti wọn fẹsun kan pe o mọ nipa iku rẹ naa wa ninu ọkọ ṣugbọn oun o farapa rara.
"Ọkọ rẹ, oloogbe MKO Abiola sọ lọjọ kan nigba aye rẹ pe : ""mo n lọ sile lọjọ kan lati lọ bẹ iyawo mi ati ọmọ wa ọkunrin wo, nigba ti mo ri ọkọ ayọkẹlẹ iyawo mi loju ọna, o ni oun ti n gbadura ki n pade oun lọna ile tori pe awọn ọkunrin kan ti wa ta oun lolobo pe ọlọpaa n bọ wa mu mi lati fẹsun kan mi."
Àwọn ará ìlú Abiola ní Abẹokuta bá BBC sọ̀rọ̀
"Kia ni mo sa pada si ibi ti mo n fara pamọ si lati lọ ṣe ọna bi n o ṣe sa kuro ni Naijiria""."
Lẹyin ti Abiola ri ibi salọ si ilu London, iyawo ati ọmọ rẹ naa pada ri ọna salọ ba a lọhun nibi ti wọn ti jọ n yi i mọra wọn ninu ile kolobo kan pẹlu idile awọn Olunloyo.
Ninu eyi ni Kudirat n ba Abiola jiya. Ati ri owo na nira fun wọn ṣugbọn wọn n ri iranwọ lẹẹkọọkan latọdọ awọn mọlẹbi ati ọrẹ Abiola.
Alaṣeyọri oniṣowo ni Alhaja Kudirat.
Oríṣun àwòrán, @deji_of_lagos
Ki ni a le sọ nipa June 12 ni soki?
Ohun ti awọn eniyan maa n saaba ranti ti wọn ban sọ itan jija fun ijọba tiwa n tiwa ni ọna aburu ati ailaanu ti wọn gba pa arẹwa akinkanju obinrin to jẹ iyawo Abiola.
Alhaja Kudirat Abiola di ajafẹtọmọniyan nigba ti ijọba Naijiria bẹrẹ sii doju le e.
Lati igba ti wọn ti gbe Moshood Abiola ti mọle, pẹlu igboya ni Kudirat fi lọ pe fun itusilẹ ọkọ rẹ pẹlu bi ijọba ṣe n dunkooko mọ ẹbi ati awọn alatilẹyin rẹ to.
Alhaja Kudirat Abiola ba ọpọlọpọ ileeṣẹ iroyin sọrọ kaakiri to si n pe fun itusilẹ ọkọ rẹ ati pe o n fi ẹsun kan ijọba pe wọn n run isuna idile oun.
Lọjọ kẹjọ, oṣu karun un, odun 1996, ile ẹjọ giga ipinlẹ Eko da a lẹjọ ẹsun igbimo idite ti ijọba ati ọpọlọpọ irọ.
Bakan naa, lọjọ kejidinlọgbọn, oṣu ati ọdun kan naa, ile ẹjọ tun fi ẹsun yii kan naa kan an.
Ile ẹjọ da a silẹ pẹlu beeli wọn si tun sun ẹjọ rẹ siwaju di ọjọ kẹtadinlogun, oṣu keje.
Pẹlu gbogbo idunkooko mọ ọ yii, Kudirat Abiola tẹsiwaju pẹlu ipolongo lorukọ ọkọ rẹ.
Pẹlu bi o ṣe han gbangba gbangba pe ewu n bẹ lori orule,  Kudirat ṣi huwa adari lasiko yii ti gbogbo ẹ doju ru.
O bọ siwaju lati fi igboya rẹ han pe igbesẹ awọn ologun tẹ oju ofin ẹtọ awọn ọmọ Naijiria mọlẹ lati dibo yan ijọba ti wọn fẹ.
Oríṣun àwòrán, @abdulakeemibra8
Kudirat Abiola tun ṣaaju igbesẹ kan lọdun 1994 eyi to bi iyanṣẹlodi ọlọsẹ mejila ti awọn oṣiṣẹ ileepo.
Ṣe ni iyanṣẹlodi yii ka ijọba niṣan ko tori o jẹ ọkan lara awọn iyanṣẹlodi awọn oṣiṣẹ ileeṣẹ epo bẹntiroo to gun ju ninu itan Afirika.
Ki lo fa sababi iku Kudirat gan an?
Wọn pa Kudirat lasiko ti ijọba orilẹ-ede Naijiria labẹ iṣejọba ologun to fi ọkọ rẹ sẹwọn.
Kashimaawo Abiola lo n jawe olubori ninu idibo to waye ni Naijiria nigba naa lọhun lọdun 1993.
Ko pẹ ni wọn fi ọlọpaa mu Abiola lẹyin ti ijọba to wa lori oye da ibo naa ru lasiko Ibrahim Babangida.
Lẹyin iku Kudirat, wọn ko ṣi tu ọkọ rẹ silẹ kuro lẹwọn.
Bo ṣe ku ki wọn tu u silẹ lọjọ keje, oṣu keje, ọdun 1998 ni Moshood Kashimawo Abiola jade laye.
Lẹyin iku rẹ lọdun 1996, nigba to di oṣu kẹwaa, ọdun 1998, Hamza Al-Mustapha ati ọmọ aarẹ ana, Abacha Mohammed farahan nile ẹjọ pẹlu ẹsun pe awọn ni wọn pa Kudirat Abiola.
Nibi igbẹjọ, ẹni to pa a gangan to fẹnu ara rẹ jẹwọ, Barnabas Jabila ni oun tẹle aṣẹ latọdọ ọga oun Al-Mustapha ni.
Oríṣun àwòrán, @HistoryVille
Ni ọgbọnjọ oṣu kẹfa, ọdun 2012 ni wọn to dajọ iku nipa yiyẹgi fun Hamza Al- Mustapha ati Alhaji Lateef Shofolahan fun iku Kudirat Abiola.
Al-Mustapha yii ti jẹ adari awọn oṣiṣẹ alaabo fun ijoba to wa lori aleefa nigba ti Shofolahan ti jẹ oluranlọwọ pataki fun oloogbe.
Nigba to ya ni wọn gbọ ẹjọ ẹbẹ ti wọn pada tu awọn mejeeji silẹ nile ẹjọ kan ni Eko.
Kudirat Abiola jẹ apẹrẹ ajijangbara fun ijọba awarawa Naijiria to bẹẹ to jẹ pe ọdun mọkandinlogun, wọn ṣi n ṣe iranti igbesẹ yii eti iboji rẹ.
Ibadan Murder: Oyún oṣù méje ló ń bẹ nínú Azeezat, kí wọ́n tó f'òkúta fọ́ ọ lórí
Ninu gbogbo iwadii, a o rẹni to sọrọ lodi si Alhaja Kudirat Abiola ri dipo bẹẹ kiki awọn to n kan sara si igbesẹ rẹ ati iṣẹ takuntakun to ṣe gẹgẹ bi akọni obinrin fun orilẹ-ede Naijiria ni.
Won ni o duro gbọingbọin lẹyin ọkọ rẹ.
"Lapapọ awọn eeyan ni ""lootọ, Kudirat Abiola ni akinkanju ọjọ kejila, oṣu kẹfa (June 12)."
Lọjọ kẹrin, oṣu kẹfa to ku ọjọ perete ti awọn ọmọ Naijiria yan lati dibo yọ ijọba ologun kuro lori oye ni ẹmi Kudirat kuro loke eepẹ pẹlu ọpọlọpọ ọta ibọn. awọn aṣekupani.
Gbàrà, ṣe ni iku Alhaja Kudirat Abiola ṣe agbende akinkanju obinrin mii ni idile Abiola, iyẹn Hafsat Costello ọmọbinrin ti wọn bi lọdun 1974 ẹni to pinnu lati tẹsiwaju lati maa gbe opo ijangbara ti iya rẹ ja ro
Alhaja Kudirat Abiola ku ṣugbọn iṣẹ akinkanju rẹ ṣi n gbe aye lọkan awọn ọmọ Naijiria.
Barrakat Bello: Sábàbí ire ní ikú Barakat padà já sí fún wa- Ẹ̀bí fẹ̀mí ìmoore hàn sí àwọn ọmọ Nàíjíríà
Barrakat Bello: Iya rẹ̀ ní báwọn èèyàn ṣe ń fún òun lówó, làwọn míì ń tún ilé ṣe
Arabinrin Kafayat Bello, Iya Barakat Bello, ti dupẹ lọwọ awọn ẹlẹyinju aanu ti o dide iranlọwọ lẹyin iku ọmọ rẹ.
Baraakat Bello ni ọmọbinrin ẹni ọdun mejidinlogun, ti awọn olubi ẹda kan ṣekupa, lẹyin ti wọn fi ipa baa lopọ tan l'oṣu kẹfa ọdun yii, ni agbegbe Akinyẹle,
"Ninu ọrọ ti o ba ikọ BBC Yoruba sọ l'Ọjọ Aje, iya Baraka ni, ""A dupẹ lọwọ ọmọ Naijiria nilẹ yii ati ni oke okun. Iṣẹ ẹni kankan ko ni di iṣẹ o."
"Mi o ni fi iru eleyii san an fun onikaluku o. Ẹ ṣee, ẹ ku idide, ẹ ku iranlọwọ. Irinajo onikaluku yin naa ko ni dojuru o""."
Arabinrin Kafayat fi to wa leti wi pe, iku Barakat mu ayipada nla de ba ile ti wọn n gbe, nipasẹ awọn alaanu to dide si wọn.
O ni iranlọwọ dide loriṣiriṣi nitori bi awọn kan ṣee n gbe owo silẹ, ni awọn ẹlomii tun un pese awọn ohun elo ti yoo mu ayipada ba ile naa.
O tun fi kun ọrẹ rẹ wi pe, gbogbo ferese ile naa ati ilẹkun lo ti di piparọ, bẹẹ si ni iṣẹ n lọ lọwọ lati kọ ile naa pari.
Arabinrin Bello fikun pe, ko si ohun mii ti wọn n fi owo ti wọn ri gba ṣe yatọ si amojuto ile ti wọn ko tii kọ tan.
O ni bakan naa ni wọn fi katakata ro gbogbo igbo to kun di ile naa tẹlẹri, bẹẹ si ni imọlẹ ti yii ile naa ka.
Baluwẹ atijọ ti wọn pa oloogbe Barakat si naa ti di wiwo, bẹẹ si ni iṣẹ ti n lọ lọwọ lorii ile iwẹ ati ile igbọnsẹ igbalode ti wọn kọ mọ ile naa.
Egbọn iya Baraka ti o ba wa sọrọ, Arakunrin Ọlalẹyẹ Daud ni, sababi ire ni iku Baraka pada jasi.
"O ni, ""Mo ri iyatọ gidi gan ni ayika yii nitori nigba ti iṣẹlẹ yẹn ṣẹlẹ, gbogbo ibi kun fun igbo ni."
Laarin bii ọjọ kẹta, wọn ti wa fi katakata hu gbogbo igbo yẹn.
Lẹyin igba yẹn, a ti ri iyatọ lara gbogbo ile, awọn ọmọ Naijiria dide iranlọwọ inu mi ti ẹ dun.
"Amọ gbogbo nnkan pẹluu sababi ni, bi Ọlọrun ṣe sọ wi pe yoo ṣe ri niyii, a si ti gba fun Ọlọrun."""
"Arakunrin Daud wa dupẹ lọwọ gbogbo ọmọ orilẹede Naijiria pẹluu adura wi pe ""a o ni fi iruẹ gbaa""."
L'ọjọ kẹta oṣu kẹfa ọdun 2020 ni awọn olubi ẹda kan ṣekupa Arabinrin Barakat Bello, lẹyin ti wọn fi ipa baa lopọ tan ni agbegbe Akinyẹle niluu Ibadan.
Awọn olubi ẹda naa si tun da ẹmi awọn obinrin marun un mii legbodo ni ijọba ibilẹ kan naa niluu Ibadan, laarin oṣu kan ti Barakat di oloogbe.
Bo tilẹ jẹ wi pe ileeṣẹ ọlọpaa nipinlẹ Ọyọ ṣe afihan awọn ọdaran ti wọn mu lorii iku Barakat ninu oṣu keje ọdun yii, awọn olugbe agbegbe Akinyẹle ti o ba wa sọrọ labẹ aṣọ, fi idi ọrọ mulẹ wi pe, awọn to n ṣiṣẹ ibi ni agbegbe naa kọ ni ọlọpaa ri mu.
Idi ni pe wọn tun dede ri oku ọmọbinrin ẹni ọdun mẹrindinlogun mii ninu igbo kan ni agbegbe Akinyẹle, lẹyin ti ileeṣẹ ọlọpaa ipinlẹ Ọyọ kede pe awọn ti mu awọn afurasi ọdaran naa to n paayan ni Akinyele.
Yoruba ni a tori ọkan se ọkan ni Ọlọrun Ọba, ti ọpọ eeyan si maa n gbadura pe, ko ma fi ọkan gba ọkan lọwọ wa.
Ẹ ranti iroyin kan nibi ti awọn onisẹ ibi ti da ẹmi ọmọbinrin kan, Barakat Bello legbodo lọjọ aipe, ladugbo Akinyele nilu Ibadan, to si fi tipa ba lopọ, ko to gba ẹmi rẹ.
Bẹẹ ba gbagbe, lasiko ti iya Barrakat, Kafayat Bello n ba BBC Yoruba sọrọ lori bi isẹlẹ naa se waye, o ni ko ba nira fun awọn onisẹ ibi naa lati raye wọnu ile wọn, to ba jẹ pe wọn ni ferese ati ilẹkun gidi ninu ile naa ni.
Oríṣun àwòrán, BBC Sport
Abẹwo BBC si ile naa si fihan pe, wọn ko tii pari ile ọhun, asọ ati ọra ni wọn ta si awọn oju ferese ati ẹnu ọna ile, ti wọn ko si rẹ ara ile ọhun rara.
JusticeforBarakat: O lé lọ́mọ ọdún mọ́kànla kí n tó rí abúrò rẹ̀ bí lée
Wayi o, orire oloogbe Barakat naa ti gbe alawore pade awọn ẹbi rẹ.
Idi ni pe alaga ajọ alaanu kan, HANHF, Asofin Abayomi Fagbenro to se abẹwo si ọdọ iya Barakat lati baa kẹdun, ti pasẹ pe ki wọn bẹrẹ si se atunse ilegbe mọlẹbi naa.
Oríṣun àwòrán, Others
Asofin Fagbenro ni awọn mọlẹbi Barakat nilo atilẹyin to yẹ ati eto idẹrun ti yoo din ironu wọn ku lasiko yii ti wọn n sọfọ iku ọmọ wọn.
Bakan naa lo tun kesi ijọba atawọn araalu lati tete wa ojutu si ọrọ ifipanilopọ to n fi ojoojumọ peleke si, ti ijiya iku si tọ si awọn onisẹ ibi naa.
Saaju la ti mu iroyin wa fun yin pe ileesẹ ọlọpaa nipinlẹ Oyo ti kede pe oun ko sinmi nidi ṣíṣe awari awọn to pa Barakat Bello ati Azeezat Somuyiwa.
Oṣiṣẹ alarena fun Ileesẹ ọlọpaa nipinlẹ Oyo, Olugbenga Fadeyi, lo sísọ loju ọrọ yii lasiko itakurọsọ pẹlu ikọ iroyin BBC Yoruba lori iwa ifipabanilopọ ati ipaniyan nipinlẹ Oyo.
Fadeyi ni ọwọ awọn ti tẹ afurasi kan to ni ohun ṣe pẹlu bi wọn ṣe fi tipa ba obinrin kan to ni ipenija ọrọ sisọ ati gbigbọ lopọ ni agbegbe Ibarapa.
Bakan naa lo ni ọwọ ti tẹ afurasi miran lori iku to pa Azeezat Somuyiwa, ẹni to ni oyun osu meje ti wọn fọ okuta mọ lori ninu yara rẹ.
Amọ oṣiṣẹ alarina ọlọpaa nipinlẹ Oyo naa ni ọwọ ọlọpaa ko tii tẹ afurasi kankan lori iku Barakat Bello ti wọn fi tipa ba lopọ, ki wọn to pa ninu baluwẹ lagbegbe Akinyele.
Fadeyi wa fi ọwọ gbaya pe Ileesẹ Ọlọpa ko ni rẹwẹsi titi ti yoo fi ṣe awari awọn onisẹ ibi yika ipinlẹ Oyo.
Sola Kosoko: Ẹ tẹ ọkùnrin tó bá fipá bá obìnrin lòpọ̀ ní ọ̀dá, ìwà ìkà ni
Oríṣun àwòrán, Instagram/officialsholakosoko
Sola Kosoko ní kò sí ẹ̀sìn tí òun kò le ṣe nítorí Kristẹni ni òun, ọkọ òun sì jẹ́ Mùsùlùmí.
Gbajumọ oṣere tiata lobinrin, Sola Kosoko Abina ti sọ fun araye pe, baba oun, Jide Kosoko, ti oun naa jẹ agba ọjẹ osere tiata, lo ṣe agbatẹru bi oun ṣe de idi isẹ naa.
Sola Kosoko, ẹni to sísọ loju ọrọ yii lasiko to n kopa lori eto BBC Yoruba, tun fikun un pe ọla abata tii mu odo san ni ọrọ oun ninu isẹ tiata.
"O ni ""agbẹjọro abi agbohunsafẹfẹ ni n ko ba jẹ, ka ni n ko ba baba mi ṣe iṣẹ tiata, nitori lẹyin ile ẹkọ girama ni wọn ti ṣe iwuri fun mi lati maa kopa ninu ere ."""
Gbajumọ oṣere tiata naa tun salaye pe lootọ ni wọn maa n kọ ẹnu ifẹ si obìnrin ninu iṣẹ tiata bi awọn akẹẹgbẹ oun kan ti n sọ amọ kii ṣe tipatipa.
Amọ ko sai yan pe kii ṣe inu iṣẹ tiata nìkan ni wọn ti n kọ ẹnu ifẹ si obìnrin nitori o wa kaakiri, ti awọn obinrin miran si maa n pa irọ nigba mii.
Nigba to n sọ ero rẹ lori iwa ifipa bani lopọ to n gogo nilẹ wa lẹnu lọ lọọ yii, Sola ni ẹni ti ori rẹ ko pe lo n fi tipa ba obìnrin lopọ, tori wọn ni agbara lati kọ ẹnu si obìnrin to ba wu wọn.
Oríṣun àwòrán, Instagram/officialsholakosoko
Sola Kosoko ní kò sí ẹ̀sìn tí òun kò le ṣe nítorí Kristẹni ni òun, ọkọ òun sì jẹ́ Mùsùlùmí.
"Sola Kosoko ni: ""Ṣe lo yẹ ki ijọba maa tẹ awọn ọkunrin to ba fipa ba obinrin lopọ ni ọda lọna ati fi wọn jofin, eyi ti yoo mu wọn dẹkun iwa ika ati ipaniyan naa,"
"O ni eyi dara nitori iwa ifipa bani lopọ kii kuro ni ọpọlọ obinrin laelae, bi o tilẹ jẹ pe awọn obinrin agbaaya kan naa wa, to n fi tipa ba awọn ọmọdekunrin sun."""
Sola Kosoko wa kadi ọrọ rẹ nilẹ pe, ko si ẹṣin ti oun ko le ṣin nitori ẹlẹṣin.
Kristẹni ni oun, ọkọ oun jẹ musulumi, iya oun naa jẹ musulumi, baba oun jẹ Kristẹni, ti iya baba oun si jẹ musulumi, nigba ti baba baba oun si jẹ Kristẹni.
George Floyd: Ẹ̀rọ ayàwòrán ara ọlọ́pàá ṣàfihàn bí George Floyd ṣe ni òun kò le mí mọ́
Oríṣun àwòrán, Twitter/Ruty Richardson
Iwadii tuntun ti fihan pe, ọlọpaa ti wọn fẹsun kan pe o pa George Floyd sọ fun un pe, ko gbẹnu dakẹ ni gbogbo igba to fi n pariwo pe oun ko le mi mọ.
Fidio kan to jade sita ṣe afihan George Floyd, to n pariwo fitafita fun iya rẹ to ṣẹṣẹ doloogbe, ati awọn ọmọ rẹ pe awọn ọlọpaa naa yoo pa oun.
Iwadii naa si lo tan imọlẹ si bi Floyd ṣe ja fitafita fun ẹmi rẹ.
Ọpọlọpọ ifẹhọnu han lo waye ni Oṣu Karun, ọdun 2020 lẹyin iku George Floyd.
Awọn ọlọpaa mẹrin ti wọn fi panpẹ ọba mu, nipa iku George Floyd ni wọn ti gba iṣẹ ni ọwọ wọn, ti wọn si ti fi wọn si panpẹ ọlọpaa.
Derek Chauvin to gbe orunkun le ọrun rẹ lo n jẹjọ iwa ipaniyan pẹlu awọn to ku.
Orukọ ọlọpaa mẹta yoku ni - Thomas Lane, J Alexander Kueng ati Tou Thao - wọn fẹsun kan wọn pe, wọn ṣe iranwọ fun ẹni ti wọn fẹsun ipaniyan kan.
George Floyd: Àwọn ọlọ́pàá darapọ̀ mọ́ àwọn olùwọ́de lórílẹ̀èdè Amẹ́ríkà
Ọkan lara awọn agbẹjọrọ to fi fidio iwadii tuntun naa lede, lo n pe fun ki ijọba da ẹjọ ti wọn pe mọ Thomas Lane nu, nitori ko kopa ninu iṣekupani naa.
Ọkan lara awọn agbẹjọro fawọn ọlọpaa mẹrin naa lo fi lede pe, ẹrọ ayaworan to wa lara awọn ọlọpaa fihan pe, ọkan lara awọn ọlọpaa naa lo ni ki Floyd gbẹnu dakẹ.
Black lives Matter: Ọmọ Naijiria sọ ìrírí rẹ̀ lọ́wọ́ àwọn ọlọ́pàá nílẹ̀ Amerika.
Ẹrọ ayaworan naa fihan pe, o le ni igba ogun ti George Floyd fi pariwo pe, oun ko le e mi mọ, lẹyin ti wọn fi orunkun fun lọrun, amọ ti ọlọpaa Chauvin jagbe mọ wi pe, ko gbe ẹnu rẹ soun, ko dakẹ ariwo to n pa.
Amọ, awọn agbẹjoro Chauvin ko i tii fesi si iwadii tuntun naa, lati igba ti o ti wa ni ikawọ awọn eniyan lawujọ.
Oríṣun àwòrán, Reuters
Ẹgbẹẹgbẹrun un awọn olufẹhonuhan lo tu jade laarin gbungbun ilu London lọjọ Satide, bo tilẹ jẹ pe awọn ọlọpaa ti kilọ fun wọn lori iwọde naa.
Ọpọ ninu wọn lo n ju igo sawọn ọlọpaa nigba ti wọn kọlu ara wọn.
Ohun ti wọn sọ ni pe awọn fẹ daabo bo awọn ere tawọn eeyan kan n wo lulẹ notori wọn nii ṣe pẹlu ẹlẹyamẹya.
Ileeṣẹ ọlọpaa Met ti fote le iwọde ṣiṣe nitori ohun to ṣẹlẹ nigba tawọn eeyan kan n fẹhonuhan lopin ọsẹ to lọ.
Bakan naa lawọn ẹgbẹ ''Black Lives Matter'' naa ti ṣewọde kaakiri UK to fi mọ ilu London.
Oríṣun àwòrán, AFP
Awọn to ṣagbatẹru iwọde ti ọjọ Satide ti rọ awọn eeyan lati maa darapọ mawọn ti wọn fẹ ṣe ifẹhonuhan lati tako iwa ẹlẹyamẹya.
Ṣugbọn awọn olufẹhonuhan kan to ko ara wọn jọ nibi ere ti wọn fi n ṣe iranti ogun ni Whitehall ti wọn si gun ere Winston Churchill ni Parliament Square.
Niṣe ni wọn raga bo ere Churchill lati rii wi pe awọn olufẹhonuhan mii ko woo lulẹ.
Coronavirus in South Africa: Ẹ̀kọ́ mẹ́jọ tó yẹ kí ilẹ̀ Afirika kọ́ lára àjàkálẹ̀ ààrùn coronavirus
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Se awọn agba bọ wọn ni ẹṣin iwaju ni tẹyin n wo sare.
Gẹgẹ bi orilẹ-ede South Africa ṣe ń lewaju loriṣiriṣi ọna nilẹ Afirika bẹẹ si ni lọwọlọwọ, wọn tun ti ṣe tan lati dari Afirika lọ si ipele to lewu lasiko Coronavirus yii ọna igbogunti Covid 19 ti wọn gunle.
Eyi lawọn koko ẹkọ mẹjọ pataki to lee kọ awọn orilẹ-ede Afirika:
1.Ẹ tọju iyara ijẹun ninu awon ile iwosan ko mọ toni toni.
Ibi to lewu ju nileewosan ni yara ijẹun.
Ni South Africa, ọpọ ile iwosan ni wọn ti fi dandan ti pa tori pe o ti di ibi ijẹsi fun aisan Covid19.
Ọpọ dokita lo n fa awọn oṣiṣẹ ile iwosan leti pe ki wọn ye korajọ mọ ninu yara ijẹun.
Nibẹ, wọn a yọ ibomu-boju wọn silẹ, wọn a maa parọ foonu, wọn a ti gbagbe iṣẹ ti wọn n ṣe ninu wọọdu.
2.Kikanju ṣe ayẹwo - tabi aiṣe e rara lẹyin ileri lati ṣe e.
Lọwọ lọwọ, ofo ni South Africa n mu ninu ṣiṣe ayẹwo o si ti pọwọ lera wọn gan an ni gẹgẹ bi awọn akoroyin ṣe sọ
Won ni eyi si ti ba iwulo gbogbo ilana ti wọn n gba ṣe ayẹwo jẹ tori igbe aisowo ti ijọba n pa.
Se lawọn dokita ni afi dandan ki wọn maa gbe esi ayẹwo jade laarin wakati mẹrinlelogun.
Eyi lee mu ki aisan naa ti rin jina ni titankale mọ awọn mii ti wọn ko le tọpasẹ rẹ tabi ko ti kọja afẹnusọ lara wọn.
Nibayii, Coronavirus ti ran kọja aala ohun tawọn oṣiṣẹ ilera lee kapa ni South Africa.
4.Sisanra ju ati aisan ẹjẹ riru naa ti n ṣakoba
Iwadii kaakiri awọn ileewosan South Africa di han pe ara sisan ju to fi mọ ẹjẹ riru ati itọ ṣuga lara awọn ọdọ to ni arun Coronavirus ni i ṣe pọlu ọpọ to gba ibẹ ku.
Ọpọ ọdọ South Africa to ni aisan ni ko ṣe ayẹwo ohun to n ṣe wọn pato.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
5.Sisunmọ ibi ti alaisan Covid 19 wa ko tumọ si ohun tawọn eeyan n ro nigba mii.
Fun apẹẹrẹ, ileewosan fun awọn aboyun kan ni Johannesburg di titi pa tori iroyin pe wọn ni oṣiṣẹ wọn kan lọ sunmọ alaisan Coronavirus.
Se ni wọn ran nọọsi mejila lọ sile ki wọn lọ ya ara wọn sọtọ.
Awọn dokita kan bu ẹnu atẹ lu igbesẹ yii pe ibẹru ti koi to lo n ko wọn laya soke nitori naa ilanilọyẹ kikun ṣe pataki nipa ohun to n jẹ sisunmọ alaisan.
6. O ti n ni owo kan oloselu ninu
Awon kan ni pe esu mo si ohun to n sele
Laipe yii ni ijọba South Africa kede pe awọn ile ijọsin lee bẹrẹ isin pada ṣugbọn ki wọn ma ju aadọta lọ.
Igbesẹ yii jẹ imọ awọn oloṣelu kan tara n ta lati dẹ okun isede to wa tẹlẹ.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Hmmmmn, igbesẹ yii ẹwẹ gbe ewu ru sori pupọ nitori pe awọn arugbo ni yoo pọ ju awọn si lo wa ni bebe kiko arun yii ju.
Bi wọn ba wa yan lati pa koko yii ti, o lewu.
Awọn kan tilẹ ni ko yẹ ki ijọba gba awọn to ba ti le ni ọdun marunlelọgọta laaye lati lọ jọsin.
Ṣugbọn ibeere ni pe ṣe wọn yoo gbọ?
6.Ọrọ Covid 19 ti n mu ọwọ kan oṣelu da ni ni South Africa
Ẹgbẹ oṣelu alatako ni South Africa, Democratic Alliance (DA) ti n lo anfani yii lati fa oju awọn araalu mọra lasiko yii nitori naa wọn n kẹnu bọ ọrọ awọn alakalẹ ti ijọba gbe silẹ gẹgẹ bi ofin.
Awuyewuye yii laarin awọn oloṣelu ṣeeṣe ko ta ba ọrọ aje orilẹ-ede naa.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
7.Nibo ni ọrọ ofin ọti mimu ati tita de duro?
Nigba ti South Africa fofin de ọti mimu lasiko isede ti wọn paṣẹ, ọpọ lo ri i bi eyi to le ṣugbọn wọn gba a mọra gẹgẹ bi ọna to tọ lati dinwọ iwa ipa ninu ile ku.
O tun je ki wọn si lee da awọn ibusun ile iwosan si fawọn alaisan Coronavirus nikan.
"Ẹwẹ nibayii isede ti su awọn eeyan wọn si ti dẹ okun ""ma muti"" diẹ."
Ọpọ eeyan kọ lati gbagbọ ninu aridaju imọ sayẹnsi ti ijọba fi n ṣẹlẹri gbogbo ohun ti wọn n sọ nitori naa wọn n sọ pe ọna ati kowo jẹ ni awọn oṣiṣẹ ijọba n lo.
"Bakan naa ni isede ọhun tun faaye gba awọn ọdaran to n ko siga wọle labẹlẹ nitori awọn to n mu u koro oju si ofin ""ma u siga""."
Oríṣun àwòrán, Getty Images
8.Ẹ ṣe e ni soki lọbẹ oge laarin ọsẹ melo kan.
Iriri awọn dokita kan ni Capetown ti fihan pe awọn irinṣẹ kan wa to jẹ olowo pọọku ti yoo si ṣiṣẹ daradara ju awọn fẹntiletọ jaanran ti awọn alaṣẹ ni ki wọn maa rọ owo ra.
Ọjọgbọn Madhi tẹnumọ ọ pe o ti to ọsẹ mẹfa ti oun ti n sọ pe o yẹ ki wọn ra awọn ohun eelo eemi ṣugbọn pabo lo ja si.
O ni aba yii kan naa lo yẹ fun gbigba oṣiṣẹ eleto ilera eyi to mu ki awọn dokita gba ijọba nimọran pe ki wọn gba awọn akẹkọọ dokita tabi awọn to ti fẹyin ti ju ki wọn lọ maa ko awọn dokita ilẹ okeere wa ati orilẹede bii Cuba.
June 12: Àwọn tó ṣojú wọn kòró sọ irírí ọjọ́ náà
Ọlọ́run ló ní kí Abacha kú, àwọn àgbà Yorùbá púpò kò bá ṣòfò- Dele Momodu
Awọn ti iṣẹlẹ June 12 ṣoju wọn ti bu ẹnu atẹ lu bi ijọba ologun to wa nigba naa lọhun ṣe fi ẹtọ ọpọ ọmọ Naijiria dun wọn.
BBC Yoruba lo gbe wọn wa sori akanṣe eto fun ayajọ June 12 eyi ti ijọba apapọ labẹ akoso aarẹ Muhammadu Buhari ti kede ti wọn si sọ ọ di ayajọ eto iṣejọba tiwa n tiwa lorilẹ-ede Naijiria.
Wọn bẹrẹ si ni ṣe eyi ni iranti awọn to ja fitafita fun ijọba awaarawa ni Naijiria.
Awọn alejo mẹtẹẹta to wa lori eto jẹ awọn ti iṣẹlẹ June 12 ṣoju wọn koro.
Oloye Dele Momodu ati akọbi ọmọ oloogbe ajafẹtọ ọmọniyan, Oloye Gani Fawehinmi, Mohammed kẹnu bọ ọrọ o si da bii ki eto naa ma tan mọ.
Dele Momodu ni ọrọ pọ ninu iwe kọbọ pẹlu ọrọ June 12.
O sọ idi ti Oloye MKO Abiola fi fẹ jẹ aarẹ Naijiria nigba naa lọhun.
Abiola ni bi oun ṣe maa n tọju awọn araalu, owo ti oun ni ko lee gbe e tan. lo se pinnu lati lo owo ilu fun ara ilu nipasẹ ijọba, eyi gan an ni gbigbe apoti ibo fun ipo aarẹ ṣe wu Abiola.
"Lasiko idibo ọdun 1993, ""Alhaji Bashir Tofa ati Oloye MKO Abiola lo jọ figagbaga lọjọ naa."
"Ko sija, ko si ikunsinu, gbogbo ẹ lọ ni irọwọrọsẹ ṣugbọn a o wa mọ bi ọrọ ṣe dẹnu akayin ti akara fi wa di egungun""."
O ṣafiwe ohun tawọn ologun ṣe nigba yẹn pe bii igba ti obinrin bi ọmọ tan ti wọn si bẹ ori ọmọ to ṣẹṣẹ yọri sita ni.
Ọgagun Ibrahim Babangida lo wa lori alefa lasiko ti wọn n sọ ọ yii.
Abiola ran Dele lọ ilu Oyinbo, Austria fun ayẹyẹ ami ẹyẹ kan ti Oloye Fawehinmi n gba nibẹ.
BBC gbalejo ọmọ Ibadan
Dele pe awọn oniwe iroyin atawọn mii ni Naijiria wọn si fi da a loju pe pẹlu ohun ti awọn n ri, Abiola ni yoo wọle gẹgẹ bi aarẹ afigba to pe eeyan kan to ni nkan ti ologun fẹ ṣe ree o
"O ni oun ti n wa mi, o ji ọrẹ rẹ Abiola lo mọ da bii pe yo wọle ṣugbọn awọn ologun ko ni gbe ijọba fun un.
Ọọ kẹrindinlogun oṣu kẹfa ni Dele Momodu ati Oloye Gani Fawehinmi tẹkọ ofurufu leti wa si Naijiria.
Ni papakọ ofurufu ni wọn ti gba ipe pe awọn ologun ti da ibo ru o. Eyi gaan ni ibẹrẹ bi ohun gbogbo ṣe doju ru.
Nigba ti Amofin Mohammed Fawehinmi yoo kan lu agbami ọrọ, abuubu tan ni ọrọ ti ọmọ Oloye da walẹ.
Gẹgẹ bi ẹni tọrọ tun ṣoju oun naa, o ni ere lawọn pe e nigba tawọn naa gbọ iroyin nkan tawọn ologun n sọ nigba naa toun wa nileewe loke okun afi ti wọn ni Abiola ko ni wọle.
Ṣaaju si ni Abiola ti sọ fun wọn awọn to fẹ yan sipo minisita atawọn ipo mii lo ba di pe awọn kan lọ si Abuja lọ ki Abacha ku oriire.
Ṣe lo ni igbakuugba ti awọn ologun ba tun ti wa gbe baba Gani Fawehinmi nile inu awọn kii dun ṣugbọn kia iya oun yoo ti gba ọdọ awọn agbẹjọro lọ ti yoo ran oun naa lọ gbe igbesẹ mii.
Koda wọn ti ṣe gbogbo eto bi Abiola yoo ṣe ko lọ si Aso Rock ni Abuja ti eeyan kan dedee wa sọ fun Oloye Abiola pe ko ma lọ sibẹ lọjọ to gbero lati lọ o.
June 12:Àwọn tó wà ní ìjọba Baba mi ní kò lu owó ìlú ní póńpó- Ọmọ Abacha
Bi wọn ṣe wa gbe oloye Abiola lọ si atimọle niyẹn ti Abacha bẹrẹ si ni ṣejọba lọ.
Dele Momodu mu ni ranti pe nigba ologun wọn ko ki n fẹ ki ẹnikẹni maa gbo wọ lẹnu ẹni ba dan an wo gbigbe tabi pipa ni.
Nigba naa ni wọn ṣe agbekalẹ NADECO ti awọn ologun  fi n ṣọ ibi gbogbo lorilẹ-ede Naijiria ṣugbọn Dele Momodu pa owe pe mo n ree mugi wa, mo n ree mugi wa, ọgbọọgbọn lagba fi n sa fun ejo"" ni awọn fi yọlẹ sa kuroni Naijiria"
O ni eyi sele nitori ijọba ologun to mu ohun gbogbo le koko lo mu oun atawọn ọdọ mii sa kuro nile gba ọna ẹnu ibode Sẹmẹ.
O ni bi awọn eeyan nbere ki lode ti awọn fi bẹru. Wọn pa eeyan wọn tun pa obinrinbinrin, Kudirat Abiola ni ita gbangba, o tọ ki awọn fi ibẹru sa lọ.
Bakan naa, ọkan lara awọn ọdọ to ti dagba bayii ṣugbọn to jẹ ọmọde nileewe girama nigba June 12 ṣugbọn to nifẹ si ọrọ oṣelu ati kika iwe iroyin,
Kini Kehinde Oyetunji só?
"Ọgbẹni Kehinde Oyetunji  sọ iriri tirẹ nigba naa lori eto BBC Yoruba pe koda lọjọ naa gbogbo oju popo ni wọn dana si. ""Lọjọ ti wọn fagile ibo, a wọ ọkọ lọ si ilu Oṣogbo ṣugbọn ẹsẹ ni a rin pada lọ si ilu Ire"" tori rogbodiyan ti bẹrẹ nigba naa."
Mohammed Fawehinmi ni iyi ni to fi mu ki Aarẹ Buhari sọrọ pe oun mọ riri June 12, o tun yẹ Abiola si pẹlu oye GCFR lẹyin to ti  doloogbe.
Ni ìdáhùn si ibeere  pé awọn igbesẹ wo lo ti waye to ba nkan ti awọn eeyan ja fun nigba naa:
Ogbeni Kehinde Oyè Tunji ni lati ọdun 1979 si 1993, ijọba ologun lo wa ṣugbọn nigba ti Abiola fẹ dije, awọn agbekalẹ rẹ fara pẹ jẹ fun imayerọrun gbogbo eeyan bíi eto ẹkọ ọfẹ, ìlera ọ̀fẹ́ ati bẹẹ  bẹẹ lọ.
Amọ ó ni ṣe tori pe o kan jẹ Abiola ni wọn ṣe pada yẹ ẹ sì.
Kehinde ni o yẹ ki ijọba ṣe awọn nkan ti Abiola ku fun si ilu.
Bakan ni Amofin Mohammed Fawehinmi naa yi i mọ.
"O ni ""Yoruba ni lati ronu, a o ni olori mọ afi awọn akowojẹ"". O fun pe si awọn to wa ni ijọba pe ""ẹ bẹrẹ ẹkọ ọfẹ, ilera ọfẹ, owo ẹ wa bayii""."
Mohammed ni ko yẹ ki ọmọ Yoruba tun maa san owo ileewe titi di fasiti mọ.
Awọn alejo fẹnu ko pe niwọn igba ti Naijiria ba le mọ riri ayajọ June 12, ki wọn ṣe oun ti yoo maye araalu dẹrun.
Police brutality during lockdown: Nínú Ọlọ́pàá àti Coronavirus, èwo gan an laráàlú ń bẹ̀rù jùlọ?
Kaakiri agbaye ni wahala awọn ọlọpaa ti n waye koda eyi ko ys awọn orilẹ€de ti aye n fi oju wo pe wọn ti goke agba silẹ.
Gẹgẹ bi iwadii kan eyi ti Journal of Epidemiology and community health gbe jade lọdun 2018, eeyan ẹgbẹrun kan ati mẹrindinlaaọjọ (1,146) ni ẹmi wọn ti ọwọ ọlọpaa bọ lọdun 2015 ti ẹgbẹrun kan o le mejidinlaadọfa (1, 092) miran si tun ku lọwọ ọlọpaa lagbaye lọdun 2016.
Eyi ni fidio wahala awọn ọlọpaa lasiko coronavirus eleyi to mu ẹmi ọpọ lọ pẹlu.
'Ọlọ́pàá ló ń pa wá, kìí ṣe coronavirus'
Akure fire: Àwọn tó fara káásá ìjàmbá iná nílùú Akure d'ẹ̀bi ru panápaná
Awọn aladugbo ni agbegbe Ọbanla ni ilu Akurẹ ti di ẹbi bi ọṣẹ ti ijamba ina to waye lagbegbe naa ṣe se pọ ru bi awọn oṣiṣẹ panapana ṣe pẹ de ibi ti ijamba ina naa ti waye lalẹ ọjọ Aiku.
Ina nla kan tun sọ lagbegbe Ọba nla ni ilu Akurẹ eleyii to run ọpọlọpọ dukia olowo iyebiye, ọọbu ati ileegbe.
Awọn eeyan kan ti iṣẹlẹ naa ṣoju wọn ṣalaye pe ijamba ina naa ko ba ti jo ajopadukia run bẹẹ kani awọn oṣiṣẹ panapana naa tete de.
Lowurọ ọjọ Aje ni ọpọlọpọ awọn oniṣowo to ni ṣọọbu si agbegbe naa ṣẹṣẹ n mọ ina to jo dukia wọn ti wọn si n gbiyanju ati ṣaa nnkan ti wọn lee ri ko jọ.
Dukia ẹgbẹlẹgbẹ owo lo tun parun lasiko ti ina nla kan tun sọ lagbegbe Ọba nla ni ilu Akurẹ, olu ilu ipinlẹ Ondo.
Gẹgẹ bi iroyin to tẹ BBC News Yoruba lọwọ ṣe sọ, ileeṣẹ to n ta afẹfẹ idana gaasi kan to wa lagbegbe naa ni ina ọhun ti sọ ni aṣalẹ ọjọ Aiku.
Titi di afẹmọjumọ ọjọ Aje, ọpọ awọn ọlọja to ni ṣọọbu lagbegbe naa ni ko tii mọ bi ina aje ṣe jo wọn to ninu ijamba ina naa nitori ofin konile o gbele eyi ti ijọba ipinlẹ naa gbe kalẹ.
Ọkan lara awọn eeyan ti ile itaja rẹ faragba ninu ijamba ina naa, Ọgbẹni Oluwadare Ọlawale to ba BBC News Yoruba sọrs lori ẹrọ ibanisọrọ ṣalaye pe gbogbo ẹru ati ile oun lo jona raurau. O ṣalaye pe iṣẹlẹ naa ko nii ṣe pẹlu idakureku ina ọba tabi kudiẹkudiẹ ajọ naa nitori ko wulẹ si ina lagbegbe naa tẹlẹtẹlẹ ṣaaju, lasiko ati lẹyin ijamba ina naa.
Bakan naa lọgbẹni Ọlawale jẹ ko di mimọ pe ile ti oun fi ọwọ, owo ati oogun oun kọ wa lara awọn ile to jona ninu ijamba ina naa.
Ile marun un pẹlu ṣọọbu ti ko din ni marundinlọgbọn lo jona lasiko ijamba ina naa.
Tope Alabi, Ron Kenolly àtàwọn míì yóò kọrin níbi ọjọ́ ìbí àṣẹ̀yìndè fún olóògbé Ighodalo lónìí
Oríṣun àwòrán, Topealabi
"Olorin kan lo kọrin pe ""bi a ba n jẹ, bi a ba n mu, bi a ba n fitan ewurẹ jẹ'ka o, ka ma gbagbe pe atipo o la jẹ laye o."
Ọrọ orin naa rinlẹ, to bẹ to mu ni ranti iku oloogbe Ibidunni Ighodalo arẹwa obinrin aya Pasitọ ijọ Trinity House to jẹ Ọlọrun nipe ninu oṣu kẹfa nigba to ku jọ di ko pe ogoji ọdun.
Yoo wa pe ogoji ọdun ọhun lọla ṣugbọn kii ṣe lorilẹ aye.
Ẹwẹ, awọn gbajugbaja olorin ti pọ rẹpẹtẹ ti yoo ṣe isin orin nibi ọjọ ibi aṣẹyinde oloogbe naa lonii lati ago mẹjọ alẹ wọ mejila oru ti yoo ti bọ si ọjọ ibi rẹ.
Awn olorin ẹmi ni Naijira ati lati awọn orilẹede mii -  Tope Alabi, Ron Kenolly, Sammy Okposo, Yetunde Are, TY Bello, Muyiwa Olanrewaju, BJ SAx, Ibiayo Jeje, Polmira, USA, Alabi Oke, Psalmos, Efe Nathan, Seyi Ajayi, Tosin Alao, Mike Aremu ati bẹẹ bẹẹ lọ.
Amọ iṣọ oru ni wọn yoo fi ṣe eyi ti yoo bẹrẹ lati ago mẹjọ alẹ si mejila oru gẹgẹ bi ijọ Trinity House ati ọkọ oloogbe to jẹ pasit ijọ naa ṣe fi si ori ayelujara wọn.
Oríṣun àwòrán, Topealabi
Oríṣun àwòrán, Topealabi
Gẹgẹ bi a ṣe gbọ, lara eto ti wọn tun la kalẹ fun ayyẹ naa ni pe ajọ ti Ibidunni da silẹ ko to lọ iyẹn Ibidunni Ighodalo Foundation yoo ṣe onigbọwọ fun lọkọlaya ogoji tii ṣe dede iye ọdun to pe, lati lọ ṣe ayẹwo ati itọju iṣoro ibimọ.
Wọn ko awọn olorin iyin jọ lati gbe ohun iyin soke si Ọlọrun nitori oloogbe aya pasitọ Ituah Igbhodalo.
Oríṣun àwòrán, Topealabi
Bi ẹ o ba gbagbe, owurọ ọjọ aiku ọjọ kẹrinla oṣu kẹfa ni oloogbe Ibidun Ighodalo ku ninu yara rẹ nile igbafẹ kan ni ilu PortHarcourt latari ikọlu inu ọkan gẹgẹ bi wọn ṣe sọ ọ.
Bo tilẹ jẹ pe idile, awọn ọrẹ atawọn ololufẹ rẹ ti n ṣeto bi ayẹyẹ ọjọ ibi ọdun ogoji rẹ yoo ṣe ri ṣugbọn ọlọjọ de ko to di ọjọ kọkandinlogun oṣu keje ọdun 2020.
Oríṣun àwòrán, topealabi
Oríṣun àwòrán, Instagram/trinityhouseng
Iku o dọjọ, aarun ko doṣu. Ọjọ Abamẹta tii ṣe ogunjọ oṣu kẹfa ọdun 2020 ni arẹwa Ibidunni Ighodalo wọ kaa ilẹ lọ niluu Eko.
Ti eeyan ba jẹ ori ahun, to ba ba de ibi isinku Ibidunni, omi gbọdọ bọ loju rẹ.
Ọgọrọ eeyan lo peju pesẹ sibi eto isinku naa lati ṣe ẹyẹ ikẹyin fun un.
Awọn eeyan jankanjankan lo wa nibi isinku naa, ninu wọn ni Gomina Rotimi Akeredolu ipinlẹ ONdo.
Pasitọ Idowu Oluyomade to jẹ amugbalẹgbẹ alufaa Enoch Adeboye ijọ Redeem naa wa nibi eto isinku ọhun.
Alufaa Adeboye ti kọkọ sọ siwaju pe oun mọ pe Ibidunni ti wa nibi to dara bayii.
Daju daju, gbogbo agbaye lo n ṣelede lẹyin ẹniire to lọ, arẹwa obinrin, aya pasitọ ijọ Trinity House lorilẹede Naijiria, Ibidunni Ighodalo.
Eyi lo mu ki igbakeji aarẹ orilẹede Liberia, arainrin Jewel Howard Taylor fi ọrọ ibanikẹdun ranṣẹ ati adura fun idile to fi silẹ lọ.
"Arabinrin Jewel fi ọrọ sita loju opo instgram rẹ bii ewi pe "" aye wa ṣe ri firi to da bi eyi ti ko pẹ rara koda bi a ba ṣi wa laaye."
Lọsẹ yii a ti padanu arabinrin wa, ẹni daradara ati arẹwa obinrin, Ibidunni.
O wa gbadura pe ki Ọlọrun ko tu ọkọ, ọmọ, ẹbi ati ọrẹ oloogbe ninu.
Oríṣun àwòrán, Instagram/ibidunni_ighodalo
Igbakeki aarẹ Liberia ni iba wu oun ki awọn lee fa a pada lẹẹkan sii ṣugbọn o ti di alaarira tori o ni o daju daju, Ọlọrun ti nilo ko wa si ajule ọrun ni.
Ọjọ kẹrinla oṣu kẹfa, ọdun 2020 ni arabinrin Ibidunni dagbere faye lẹni ọdun mọkandilogoji to ku oṣu kan pere ko ṣe ayẹyẹ ọjọ ibi ogoji ọdun.
Ètò ìsìnkú Ibidunni Ighodalo wáyé lórí ẹ̀rọ amóhùnmáwòrán
Ijọ Trinity House ti sọ pe eto isinkun aya oludasilẹ rẹ to doloogbe, Ibidunni Ighodalo yoo waye lori ẹrọ amohunmaworan bo ba ṣe n lọ lọwọ.
Isinku ọhun yoo waye lọjọ Abamẹta, ogunjọ oṣu kẹfa ọdun 2020.
Oríṣun àwòrán, others
Ibidun Ituah Ighodalo fayé silẹ̀ ìlúmọ̀ọ́ká arẹwà tí fáyésilẹ̀
Iroyin ni awọn eeyan kereje atawọn eeyan diẹ to sun mọ oloogbe naa ni wọn fiwe pe sibi isinkun naa.
Ijọ Trinity House sọ pe eto isinku ọhun yoo waye lori ẹrọ ileeṣẹ Arise TV lori itakun DSTV channel 416 ni aago mẹrin irọlẹ.
Bẹẹ naa ni awọn eeyan tun lee wo bo ba ṣe n lọ loju opo Facebook, Twitter, Instagram ati YouTube.
Wọn tun sọ pe idagbere ikẹyin yoo waye lori ẹrọ amohunmaworan AIT, lori ikanni DSTV channel 253.
Ọjọru ọjọ kẹtadinlogun oṣu kẹfa ọdun 2020 ni wọn ṣe eto aṣalẹ orin onigbagbọ fun oloogbe naa.
Lara awọn kọ orin nibẹ ni ọmọ rẹ obinrin, ọkọ rẹ, pasitọ Ituah Ighodalo ati gbajugbaja olorin ẹmi, Tope Alabi.
Ọjọ kẹrinla oṣu kẹfa ọdun 2020 ni obinrin naa dagbere faye.
Oríṣun àwòrán, Instagram/ibidunnuighodalo
Pasitọ agba ijọ Redeem, Enoch Adeboye ti sọ pe ibi to dara ni oloogbe orekelẹwa Ibidunni Ighodalo wa.
Pasitọ Adeboye fọrọ yii lede loju opo Twitter nigba ti o n daro arẹwa to dagbere faye.
Alufaa Adeboye ni iroyin to ba ni ninu jẹ ju iroyin iku Ibidunni Ighodalo.
Adeboye gbadura pe ki Eleduwa tu ẹbi Pasitọ Ituah Ighodalo to fi silẹ lọ ninu.
Ẹni ogoji ọdun ni Ibidunnu i ṣe nigba ti ọlọjọ de.
Báyìí ni orin ìsìn ìkẹyin olóògbé Ibiduni Ighodalo ṣe lọ
Báyìí ni orin ìsìn ìkẹyin olóògbé Ibiduni Ighodalo ṣe lọ
Olórin ìgbàgbọ́ Tope Alabi náà péjú sibi ìsìn òrin to wáye
Awọn ènìyàn to n sọ̀rọ̀ nípa olóògbé
Olùsọagutan Ituah Ighodalo nínú ìṣìn orin ìkẹ́yìn
Báyìí ni orin ìsìn ìkẹyin olóògbé Ibiduni Ighodalo ṣe lọ
Awọn ebi oloogbe Ighodalo ti gbe oku rẹ lọ si ileewosan kan ni agbegbe Lagos Island ni ilu Eko.
Alamojuto ileeṣẹ rẹ, lo fi ọrs sita faraye gbọ.
O ni ọjọ Aiku ni ọkọ oloogbe naa atawọn mọlẹbi gbe oku rẹ
Nigba ti ikọ BBC news de ile oloogbe naa lagbagbe Bourdilourn ni ilu Eko lowurọ ọjọ Aje nibi ti awọn eeyan leni ejeeji ti n wọle ba wọn daro.
Paroparo ni agbegbe naa da ti iwọnba awọn eeyan melookan to n wọle si n ks ọrọ idaro wọn si iwe ibanikẹkun ti wọn ṣi pẹlu aworan oloogbe naa.
Oríṣun àwòrán, Others
Ọpọlọpọ awuye lo n lọ lori iku to pa Ibidun Ighodalo to jẹ́ ọbinrin tó rẹ̀wà jùlọ nígbàkan rí, tó sì tún jẹ́ ìyàwó adarí àti olùdásílẹ̀ ìjọ Trinity House.
Bi o tilẹ jẹ pẹ ọ̀pọ̀ àwọn ọmọ Nàìjíríà ló tí n fi èrò wọ̀n hàn lórí ikú tó pa Ibídun.Ìròyìn sọ pé, arẹwa náà kú ní ìdájí òní Ọjọ́ àìkú ní ìlú Port Harcourt, nípìnlẹ̀ Rivers.
Olùdásílẹ̀ ilé iṣẹ́ tó máa ń báni ṣètò ayẹyẹ Elizabeth R ní, àti pé ó ti wà ní ìpínlẹ̀ Bayelsa àti Rivers láti ṣèrànwọ́ kíkọ́ ibudó ti wan yóò ti maa tójú àwọn aláàrùn Covid-19 sí.
Nurudeen Lawal  adarí Elizabeth R tó jẹ́ ilé iṣẹ́ olóògbé sàlàyé fún  BBC pé àwọn kò mọ ǹkan to ṣe ku paa nítori lẹ́yìn ti àwọn pari iṣẹ́ ní alẹ́ àná, olúkúlùkù wọ yàrá rẹ̀ lọ láti sù, sùgbọ́n nígbà ti ilẹ̀ mọ́ ni owúrọ̀ yìí ni kò jí mọ.
"Ó lọ sùn lánàá sùgbọ́n nígbà ti olúkúlùkù jí láàrọ̀ òní ni kò jí mọ́
Ọkùnrin náà kò dárúkọ ilé ìtura tàbi àdúgbò ti ìṣẹ̀lẹ̀ náà ti wáyé sùgbọ́n ìlú Port Harcourt lo ti ṣẹlẹ̀.
Bákan náà ni ẹni tó sún mọ́ ọkọ olóògbé náà fìdi ìṣẹ̀lẹ̀ aburu náà múlẹ̀ fún ìwé ìròyìn The Nation"", sùgbọ́n kò sọ bóyá o ti ṣe àìsàn tẹ́lẹ̀."
Ibídùn fí ọkọ àti ìbejì rẹ̀ silẹ̀ sáyé lọ
Ọjọ́ kọkàdínlógún Oṣù tó ń bọ̀ ló pinu láti ṣe ayẹyẹ ọjọ́ ìbí ojójì ọdún rẹ̀.
Oríṣun àwòrán, oyo insight
Ọga ọlọpaa ni ileeṣẹ ọlọpaa t'awọn Adigunjale ti ṣọṣẹ ni ipinlẹ Kogi ti wọ kaa ilẹ sun ni ilu Ibadan
Agbegbe Olunde ni ilu Ibadan ni wọn gbe sin Ọgbẹni Adebọla Tajudeen si.
Ni ọjọ Ẹti ti kọja l'awọn igara ọlọṣa kan ya wọ ilu Isanlu ni ipinlẹ Kogi nibi ti wọn ti pa awọn ọlọpaa ataraalu nibẹ l'asiko ti wọn lọ digun ja banki kan lole nibẹ
Oríṣun àwòrán, Others
Ǹkan tí a mọ̀ nípa Ibidunni Ighodalo tó kú
Ọ̀pọ̀ àwọn ènìyàn ló ń bèrè pé taa ni Ibídunni Ighodalo, nítori náà ni aṣe ṣe àkójọpọ̀ àwọn ǹkan ti a ti mọ nígbà ayé rẹ̀
Ẹ̀wẹ̀, ọkọ rẹ̀ Ituah Ighodalo lẹ́yìn tó gba ipè pé ọkọ rẹ̀ kú lótún ṣe ètò ìsìnkú fún ẹnikan lówòrọ̀ òní ojọ́ àìkú.
Ìsìnkú Deji Okoya ọmọ-ọmọ ilúmọ̀ọ́ka onísòwò Rasak Okoya ni olùsáàgùntàn náà ṣe, tgí ó sì sọ níbẹ̀ pé gbogbo àyé fẹ́ẹ̀ dojúdé pẹ̀lú ìròyìn ikú ìyàwó òun, sùgbọ́n ènìyàn gbọdọ tẹ̀síwájú ìgbé ayé rẹ̀.
Ituah ní láti ǹkan bí wákàtí díẹ̀ sẹyìn, gbogbo ǹkan lo daru papọ.
Tí wọ́n bá sọ fún wá ni ọjọ́ àìkú tó kọjá wipe àó wá sòkú Ayodeji ènìyàn yóò jiya
Ọdún kẹtalá rẹ̀ẹ́ tí Ituah àti Ibidunni ti wà bíi tọkọtaya kí ó to dédé dolóògbé ní ilú Port harcourt láàrọ̀ kùtù ọjọ́ àìkí
Oríṣun àwòrán, others
Ibidun Ituah Ighodalo fayé silẹ̀ ìlúmọ̀ọ́ká arẹwà tí fáyésilẹ̀
Oríṣun àwòrán, @prettypearl
Kwara: Fọ́fọ́fọ́ ni mọ́ṣáláṣí kún tí ìlànà ìjìnàsíraẹni sí forí ṣánpọ́n lẹ́yìn tí ìrun Jímọ̀ bẹ̀rẹ̀ padà ni Ilorin
Kwara: Fọ́fọ́fọ́ ni mọ́ṣáláṣí kún tí ìlànà ìjìnàsíraẹni 'social distancing' sí forí
Witiwiti lawọn olujosin ẹlẹsin Musulumi ṣi bo awọn Mosalasi nilu Ilorin pẹlu bi ijọba ti ṣe faaye gba ijọsin lawọn Mọsalasi ati ile ijọsin Kristẹni pada.
Akọroyin wa to jabọ lati awọn Mosalasi to wa ladugbo Pakata ni aarin gbungbun Ilorin so pe ọpọ àwọn olujosin ni wọn ni inú awọn dun lati ki Irun pada ni mosalasi Jimọ.
Ni Mosalasi Jimọ Government Girls Day Sec school ni Pakata, mosalasi naa kun fọfọ ni ti ko si si apẹrẹ pe awon eeyan n tẹle ilana ijinasiraẹn lasiko ti arun Covid-19 n ja kalẹ.
Diẹ ninu awọn olujọsin lo  lo ibomu ti o sí je pe ati omode ati agbalagba lo wa se ijọsin.
Alfa Ibrahim Igboho to jẹ ọkan ninu awọn alaṣẹ mosalasi naa sọ pe awọn salaye fawọn olujosin gẹgẹ bí ilana ijoba pe ki wọn lo ibomu wá sí mosalasi ṣugbọn kìí ṣe gbogbo eeyan lo tẹle ilana yi.
Laipẹ yi ni ijọba ipinlẹ Kwara dẹwọ ofin to de akojọpọ fun ijọsin.
Bẹrẹ lati ọjọ kokandinlogun awọn sọọsi ati mosalasi láánfàní lati maa ṣe ijosin lalai yọ ẹnikẹni silẹ.
Ṣugbọn to wa nibe ni pe awọn oludari ile ijọsin yi gbọdọ ri pe awọn eeyan tẹle ilana ijinasiraẹni ati ìmọtótó lasiko ijọsin ti won ko si gbọdọ jẹ kí ọrọ iwaasu wọn pẹ pupọ.
Oríṣun àwòrán, Others
Àwọn ti ọrọ naa ṣe oju wọn ni ojo arọrọda lo fa bi afara naa ṣe ja ni Ọjọ Abamẹta.
Eniyan kan ti ku, ti won si n wa eniyan meji lẹyin ti afara kan ja ni Oko-Erin, Ilorin ni ipinlẹ Kwara.
Àwọn ti ọrọ naa ṣe oju wọn ni ojo arọọrọda lo fa bi afara naa ṣe ja ni alẹ́ Ọjọ Abamẹta.
Wọn fikun un pe ọkọ ayọkẹlẹ kan n gbe eniyan mẹta lori afara naa nigba ti o ja, ti wọn si ni awakọ ati awọn eniyan naa ja si koto, ti wọn ko si le doola ẹmi wọn.
Oríṣun àwòrán, Others
Loju opo ikansiraẹni ipinlẹ naa ni ijọba ti ni awọn ti bẹrẹ igbesẹ lati wa awọn eniyan meji ti wọn n wa naa lawari.
Wọn fikun wi pe igbese ti bẹrẹ lati ri wi pe wọn dẹkun bi awọn eniyan ṣe n da idọti si oju omi, eleyii to ti fa ki oju odo o kun ni akunfaya.
Oríṣun àwòrán, Others
Bakan naa ni wọn rọ awọn eniyan lati sọra  nipa kikọ ile si oju omi nipinlẹ naa, eleyii ti wọn ni o sokunfa bi afara naa ṣe ja.
Oríṣun àwòrán, Others
Nibayii, awọn oṣiṣẹ pajawari n ṣiṣẹ lati ri wi pe wọn tete ri awọn to sọnu naa.
Rape: Ó kéré tán wọ́n ń fipá bá obìnrin kan lòpò láàrín wákàtí márùn ún ní Naijiria
Oríṣun àwòrán, Twitter/nigeria police
Iye eniyan to to 717 ni wọn ti fipa ba lọpọ lorilẹede Naijiria laaarin Osu Kini si Osu karun un ọdun yii, ti osi fihan pe laarin wakati marun, won fi ipabaobinrin lọpọ.
Ọga Agba Ọlọpaa lorilẹede Naijiria, Mohammed Adamu lo fi eleyii lede lasiko to n ba awọn oniroyin sọrọ lasiko to lọ ṣẹ ipade pẹlu aarẹ Buhari lori ọr ifipabanilọpọ to n ṣẹlẹ kaakiri ni Naijiria.
Adamu ni ohun to buru jai ni nkan to ṣẹlẹ, to si koju ọrọ si awọn aṣebi wọn yii.
Bakan naa o fikun pe eniyan 799 ni o wa ni panpẹ ọlọpaa lori ẹsun ifipabamilopo, ti 631 ninu wọn si ti fi oju ba ile ẹjọ.
Oríṣun àwòrán, AEPA
Bakan naa ni Ọga Ọlọpaa naa fikun pe awọn sisẹpẹlu awon eto aabo kaakiri Naijira lati ri pe ifipabaniopo
Ojoojumọ ni akọtun iṣẹlẹ iwa ifipa bani lopọ ati isekupani n waye yika Naijiria, eyi to n mu omi loju ọpọ eeyan.
Awọn ọmọbinrin ti wọn n ku iku aitọjọ yii si lo jẹ akẹkọọ, ti ọjọ ọla rere wa fun, to si ṣee ṣe ki wọn gbe ogo Naijiria ga lọjọ ọla.
Kẹ ba le mọ bi igbe aye awọn ọmọbinrin ti wọn da ẹmi wọn legbodo lọjọ aipe yii ṣe ri, ni BBC Yoruba fi ṣe akojọpọ itan ranpẹ nipa aye wọn.
Oríṣun àwòrán, others
Oríṣun àwòrán, Tribuneonline
Oríṣun àwòrán, others
Grace Oshiagwu: Gómìnà Makinde ké sáwọn ọlọ́pàá, àwọn lọ́balọ́ba lágbègbè Akinyele
Rwanda Genocide: Òbí ni mi - sùgbọ́n mo pa òbí àwọn ọmọ ọlọ́mọ
Oríṣun àwòrán, Natalia Ojewska
Ruwanda Genocide: Obi ni mi - mo pa obi awọn ọmọ wẹwẹ
Ẹgbẹlẹgbẹ awọn obinrin lo kopa ninu ipaniyan abẹle to waye  ni Ruwanda lọdun 1994 subgọn ko si ẹni to sọrọ nipa wọn ati bi wọn ṣe n ṣe atunṣe pẹlu ẹbi wọn.
Akọròyìn Natalia Ojewska ti n ba awọn obinrin kan to kopa ninu isẹlẹ naa sọrọ ni ọgba ẹwọn.
Irinajo lati lọ pọnmi  fun ina dida ounjẹ aarọ lasan wa di ǹkan ti Fortunate Mukankuranga daran ipaniyan si.
Ninu asọ ọgba ẹwọn alawọ omi ọsan lowa to ti n sọrọ bi iṣẹlẹ naa ṣe waye lowurọ kutu ọjọ kẹwa oṣu kẹrin ọdun 1994.
Grace Oshiagwu: Gómìnà Makinde ké sáwọn ọlọ́pàá, àwọn lọ́balọ́ba lágbègbè Akinyele
Bí o ṣe n lọ lori ti awọn kan bẹrẹ si ni lu awọn ọkunrin meji kan laarin ọna.
" Nigba ti awọn meji naa subu lulẹ. Mo mu igi mo wa so pe Iku lo tọ si Tutsis!'.
Mo fi igi gba ọkan ninu wọn ati ikeji... mo wa lara awọn apaniya,  ẹni ọdun aadọrin ọun lo sọ bẹ."
Meji niyi ninu awọn ẹgbẹrun lọna ẹgbẹrin awọn ẹya Tutsis àti diẹ ninu awon Hutus ti wahala naa si waye fun ọgọrun ọjọ.
Lẹyin ikopa rẹ ninu ipaniyan yii  Mukankuranga to jẹ ẹya Hutus pada sile lọdọ awọn ọmọ rẹ meje pẹlu irobinujẹ ọkan, tí ọkan rẹ ba tun lọ si bi iṣẹlẹ naa ṣe waye, oun jẹ lọkan gidi.
 Abiyamọ ni mi , mo si pa obi awọn ọmọ kan, bẹẹ lo sọ.
Lẹyi ọjọ meji ti iṣẹlẹ yii ṣe ni awọn ọmọ ẹya Tutsis meji ti wọn ti pa obi wọn yọju de lẹnu ọnà mi pe ki n jẹ ki a ti awọn fara pamọ sọdọ mi.
Igbekun itiju
Ko roo lẹẹmeji to fi fiwọn pamọ, bayii ni iku si ṣe fori awọn ọmọ naa.
" Botilẹ jẹ pe mo doola ẹmi awọn ọmọ naa, mo kuna lori awọ ọkunrin meji akọkọ. Iranwọ ti mo ṣe ko le fd ọwọ ago pada sẹyin gẹgẹ bi Mukankuranga ṣe sọ
Oríṣun àwòrán, Natalia Ojewska
Ruwanda Genocide: Obi ni mi - mo pa obi awọn ọmọ wẹwẹ
O jẹ ọkan lara awọn obinrin ẹgbẹrun mẹrindinlọgọrun ti ijọba ju sẹwọn fun ipa wọn ninu ipaniyan abẹle Ruwanda- awọn miran pa agbalagba bi ti Mukankuranga awọn miran p ọmọ wẹwẹ, nigba ti awọn kan fi anfani naa fipa bawọn eniyan lopọ ti wọn si tun gbẹmi wọn.
Ní alẹ ọjọ kẹfa oṣu kẹrin ọdun 1994, ni àwọn kan yin baa lu to n gbe aarẹ Rwanda to jẹ ẹya Hutu nibọn Juvental Habyarimana bi o ṣe n fẹ ba ni papakọ ofurufu ni Kigali.
Botile jẹpe ko si ẹni to mọ ẹni to se iṣẹ nla ibi naa bayii ni awọn ajajagbara Hutu bẹrẹ si ni naka alebu si àwọn alatako ijọba Hutsi ti wahala si bẹrẹ, laarin wakati diẹ ẹgbẹlẹgbẹ awọn ọmọ Hutus ti wọn ti n lodi si ẹya hutsi fun ọpọ ọdun darapọ ti wọn si bẹrẹ ipaniyan.
Awọn obinrin naa kopa ti wọn pe ara wọn ni obinrin Rwanda ti wọn si n saabo fun awọn obinrin.
O nira ki oye rẹ to ye ni pe bawo ni iya to nifẹ ọmọ rẹ yoo ṣe wa lo si ile aladugbo rẹ lati pa ọmọ rẹ bi Regine Abanyuze ṣe sọ,  òṣìṣẹ ""Never again"" ile iṣẹ ti kii se ti ijọba ti wọn si wà fún ipese alaafia ati ipẹtu sawọ."
Ní kete ti ija ọhun bẹrẹ bayii, ẹgbẹgbẹrun obinrin lo sọ ara wọn di agabatẹru iwa ipa pẹlu awọn obinrin.
Martha Mukamushinzimana ọlọmọ marun, ti oun nikan da ẹru ẹṣẹ gbe fun ọdun marundinlogun, ki o to lọ salaye ara rẹ fun ile ẹjọ lọdun 2009 nigba ti ko le koju isoro ẹdun ọkan yii.
Oríṣun àwòrán, Natalia Ojewska
Ruwanda Genocide: Obi ni mi - mo pa obi awọn ọmọ wẹwẹ
Ọpọ awọn obinrin yii ni eri ọkan ipaniyan yii n da laamu nitori wọn kuna ojuṣe wọn gẹgẹ bi abiyamọ.
" Asiko ni eroja idapadabọsipo ti a n lo julọ, a n fun wọn ni aaye yii bi o ti tọ ati bo tiyẹ titi ti wọn yoo fi wa jẹwọ nkan ti wọn ti ṣe  gẹgẹ bi Grace Ndawanyi adari ọgba ẹwọn awọn obinrin ni Ngoma ni Rwanda.
 Nitori ile mi sun mọ ẹgbẹ titi mọ maa n gbọ fere awọn Tutsi bi wọn se n ko awọn eniyan lo si ileijọsin gẹgé bi Mukamushinzimana ṣe sọ nibi to joko si ni kọrọ ọgba ẹwọn pẹlu omije lọwọ."
Ẹgbẹgbẹrun awọn Tutsis ni wọn n rọpọ si ẹgbẹ kan  ni ijọ Aguda ẹka Nyamasheke, ti wọn si jijadu ẹmi wọn fun ọṣẹ kan gbako, bi afoju ri Stanislus Kayitera to ti pe ọdun mẹtaleláàdọta bayii jẹ ọkan lara awọn to ru iṣẹlẹ naa la pẹlu awọn oniruuru apa lara .
" Mo ranti awọn obinrin ti wọn n gba okuta ti wọn si n fun ọkunrin ti wọn si n lẹẹ mọ wa. Bakna naa ni awọn ọkunrin naa n yinbọn ti wọn sin da epo sawọn eniyan lara ti wọn n sun wọn nina.
Oríṣun àwòrán, Natalia Ojewska
Ipinu wa ni ki a da awon odanran pada si aarin awujọ
 Wọn wọ sọọsi ti wọn bẹrẹ si ni sa wa ni ada ti wọn si n pa awọn eniyan, eri ọgbẹni Kayitera ti oun naa bọ lọwọ ogun naa ree nítori o sa pamọ saarin awọn oku."
" Mo gbe ọmọ mi ọmọ ọṣẹ meji meji sẹyin mo darapọ mọ àwọn obinrin to n fun awọn ọkunrin ni okuta lati pa awọn eniyan, eyi ni alaye Mukamushinzimana nitori pe o ni wọn paa lasẹ fun-un ni.
Nigba ti wọn juu sẹwọn lọdun  2009 ko si ẹbi rẹ kan to bẹẹ wo bakan naa ko ṣẹni to ba tọ awọn ọmọ rẹ mararun.
Fortunate Mukankuranga ni igboya lati jẹwọ ẹsẹ rẹ lẹyin ọdun mẹrin ti wọn ti dajọ rẹ lọdun 2007.
O oun ranti pe ninu ibẹru bojo ni oun wa ti oun fi pe ọkan ninu awọn ọmọ ẹni ti o pa to si jẹwọ fun pe ki o fori ji oun.
Lodi si ero mi,  inu rẹ dun ọkan rẹ si balẹ nigba to ri mi mi o si le pa omije oju mi mọra bi mo se di mọọ"
Mukankuranga wa n wo ọjọ iwaju pẹlu ironu ọtun pe o ṣeeṣe\ki oun le ri atunse si ibasepọ pẹlu ẹbi rẹ.
" Ti mo ba pada dele ma maa gbe igbe aye alafia pẹlu awọn ẹbi mi, n o nifẹ wọn ju ti atẹyinwaa lọ bakan naa ni maa bikita nipa awọn eniyan. Mo n jiya ẹsẹ ti mo ṣẹ ni, ko yẹ ki n wa lẹwọn bi mo ṣe jẹ abiyamọ, o fi kun
Oyo Corornavirus: Gbogbo ìgbìmọ́ aláṣẹ ìjọba ìpínlẹ̀ Oyo ló ṣe àyẹwò àrùn Covid-19 Sùgbọ́n...
Oríṣun àwòrán, Makinde
Gómìnà ìpínlẹ̀ Oyo, Seyi Makinde tí fi léde lórí ojú òpó ìkànsíraẹni Facebook rẹ̀ pé, mẹ́ta nínú àwọn ìgbìmọ̀ aláṣe ìjọba ìpínlẹ̀ Oyo ló ti ni ààrùn Coronavirus bayìí.
Gómìnà ní sáájú àsìkò yìí ní gbogbo ọmọ ìgbìmọ̀ aláṣẹ ti ṣe àyẹ̀wò ààrùn coronavirus súgbọ̀n mẹta nínú wọ́n ni ayẹwò fi idí rẹ̀ múlẹ̀ pé ó ti ni ààrùn náà nígbà tí àyẹ̀wò àwọn méjì kò sì dájú bóyá wọ́n ni tàbi wọ́n kò ni ààrùn.
Seyi Makinde ni ìjọba ti ránṣẹ́ si àwọn ti ọ̀rọ̀ náà kan, títọpasẹ ibi ti wọ́n ti rìn sí náà ti bẹ̀rẹ̀, bákan náà ni ọfíìsì wọ́n tí wà ni títìpa fún àtúṣe tó yẹ.
Gómìnà Makinde ní  Ààrùn náà sì wà pẹ̀lú wa dájúdájú, pé à n gbìyajú láti dá ọrọ̀ ajé padà bọ̀ sípò kò túnmọ̀ si pé ààrùn náà ti di oun ìgbàgbé"""
 Ó ṣe pàtàkì kí a máa mójú tó ara wa nípa wfífọ ọwọ́ wa déédé pẹ̀lú omi aàti ọṣẹ , kí a sì maa wọ ìbòmú ti a bá ti wà pẹ̀lú àwọn eníyà, ìjìnà síra ẹni náà si ṣe pàtàkì pẹ̀lú.
Oríṣun àwòrán, twitter/Seyi makinde
Update on Coronavirus ní Nigeria: Bí a ṣe fi N2.7 bilìọ̀nù kojúu àrùn Coro réé- Ìjọba ìpínlẹ̀ Oyo
Ipinlẹ Oyo ni awọn ti na owo to to N2,779,000,000 lati koju arun COVID-19 nipinlẹ naa.
Ijọba ipinlẹ Oyo fi sita loju opo Twitter wọn pẹlu alaye ni sisẹ n tẹle lori bi wọn ṣe na owo naa.
Nigba to n ṣalaye alakalẹ gbogbo ibi ti wọn na owo yii si kaakiri iṣọri iṣọri, kọmiṣọnna eto isuna ipinlẹ Oyo, Akinola Ojo sọ ipinnu ijọba ni pato.
O sọ eyi nibi ipade igbimọ alaṣẹ ipinlẹ Oyo pe N900.5 miliọnu ni awọn fi ra awọn nkan iranwọ, ounjẹ ati irugbin fun araalu.
Wọn ni awọn na N370.6 miliọnu lati ṣatunṣe ibudo itọju ajakalẹ arun to wa ni Olodo.
Bakan naa, wọn na N453.7 miliọnu lori amojuto ibode ipinlẹ, ọkọ iṣẹ awọn oṣiṣẹ alaabo ati itọju awọn oṣiṣẹ gangan.
N118 miliọnu ni wọn na lori iranwọ ileewosan ijọba to wa ni kọlẹẹji fasiti Ibadan fun ṣiṣe awọn ayẹwo arun COVID-19.
Lafikun, wọn ni fun ayẹwo gangan, N614.7 miliọnu ni wọn na lori ayẹwo, ohun eelo fun ayẹwo atawọn nkan jijẹ fun ilera
Nigba ti wọn na N321.2 miliọnu lati ra ọkọ awọn eleto ilera Ambulansi.
Ojo jẹ ko di mimọ siwaju sii pe N156 miliọnu ni wọn ya sọtọ fun awọn to n ṣiṣẹ iyọnda
Pẹlu N15,000 ajẹmonu owo pe wọn n fẹmi ara wọn wewu ti wọn ti n jẹ wọn latinu oṣu kẹta.
O wa pe gbogbo ẹbun owo to wọle latọdọ awọn Aladani, ileeṣẹ ati ajọ pọ soju kan pe o jẹ N1.2 biliọnu.
Genotype: Kí làwọn àǹfàni àti ewu tí ẹ̀yà jínótáìpù rẹ le mú bá ìgbé ayé rẹ̀
Ijọba ipinlẹ Oyo ti kede ayipada lori ọjọ ti ile iwe yoo di ṣiṣi pada kaakiri ipinlẹ naa.
Ọjọ Aje tii ṣe ọjọ kọkandinlọgbọn oṣu kẹfa ni ijọba Seyi Makinde n gbero tẹlẹ lati ṣi ileewe pada, amọ ijọba ti so o rọ bayii nitori bi awọn eeyan to n karun coronavirus ṣe pọ si nipinlẹ naa.
Akọwe iroyin fun Gomina ipinlẹ, Taiwo Adisa lo fi idi ọrọ naa mulẹ fawọn akọroyin lọjọ Iṣẹgun.
Ni bayii, awọn olukọ nikan yoo wọle pada lọjọ kọkandinlọgbọn oṣu kẹfa nigba tawọn akẹẹkọ kan yoo wọlẹ pada lẹyin ọṣẹ kan tawọn olukọ wọn ba ti wọle tan.
Ẹwẹ, ijọba apapọ ti kọkọ tako ṣiṣi ileewe pada lasiko yii ti aarun coronavirus si n pọ si ni Naijiria, ijọba aika ilera awọn eeyan si ni.
Amọ ijọba ipinlẹ Oyo sọ pe ohun ti gbaradi fun ṣiṣi ileewe pada nipa riran awọn akọṣẹmọṣẹ ninu eto ilera ati ọrọ ayika lọ si awọn ileewe lati sọ bi eto ṣe le kẹsẹjari.
Ijọba ipinlẹ Oyo ni gbogbo eto lo ti to lati rii pe awọn olukọ atawọn akẹkọọ n tele ilana ti ijọba la kalẹ lati dena itankalẹ aarun covid-1
Àìmọ̀kan ló ń ṣe ìjọba Oyo tó fẹ́ ṣí iléèwé, gbogbo ìpínlẹ̀ ló ní àrùn COVID 19- Ijọba àpapọ̀
Ajọ NCDC ti ni ko si ipinlẹ kankan ni Naijiria to dantọ lọwọ arun Coronavirus.
Ọga agba ajọ naa, Chikwe Ihekweazu lo fi eyi lede lọjọ aje lasiko ti wọn n ṣepade pẹlu igbimọ amuṣẹya ti aarẹ gbekalẹ lori arun yii ni ilu Abuja.
Ohun to mu ọrọ yii jade gan ni bi ajọ NCDC ko ṣe tii jabọ boya eeyan lugbadi COVID -19 ni ipinlẹ Cross River lọsan ọjọ aje yẹn.
Oríṣun àwòrán, Twitter/seyi makinde
Ọgbẹni Ihekweazu n sọrọ nigba ti ibeere kan jade lori pe awọn ipinlẹ kan naa to ti da awọn alaisan yii silẹ nileewosan n kede ara wọn pe awọn bọ lọwọ COVID-19.
"Ko si ipinlẹ kankan to ti bọ yanyan lọwọ arun COVID-19, ko si nkankan. Ko da ilu Zealand gan to da wa nibi to wa pada ni lẹyin igba diẹ ti wọn o ni tẹlẹ.
O ni a o le ya ara wa kuro lara orilẹede wa. Tori naa lọwọlọwọ, ko sẹni to bọ, tori eyi lao fi tẹsiwaju ni ṣiṣe ayẹwo lati mọ awọn to ni."
Ẹwẹ, igbimọ amuṣẹya COVID-19 gba awọn ọmọ Naijiria niyanju lati ma bẹru ṣiṣe ayẹwo paapaa julọ tori arun naa kii kuku ṣe idajọ iku.
Oríṣun àwòrán, Twitter/seyi makinde
A lee dena pipadanu ọmọ Naijiria bi a ba pe fun iranwọ. Alaga igbimọ naa, Boss Mustapha sọ eyi o si tun pe akiyesi si ọrọ awọn ara orilẹede meji kan ti wọn gbamu to yọ wọ Naijiria o si gboriyin fun ileeṣẹ to n ri si iwọle wode ni Naijiria fun iṣẹ takun takun. O ni awọn ṣi tun gbọ pe awọn kan n ko ounjẹ wọle lọna aitọ ṣugbọn o ni ileeṣẹ to n ri si iwọle-wọde n ṣe iṣẹ wọn bii iṣẹ.
Ipade yii tun mẹnu ba bi awọn eeyan ko ṣe tẹle awọn ofin ti ijọba la kalẹ lati dena arun yii. O ni ọsẹ meji akọkọ lawọn eeyanfi ṣe boju boju amọ lẹyin rẹ, wọn ti rẹwẹsi.
Mustapha tọka si wipe awọn ṣe iwadii kan to fihan awọn ibi kan wa ni Naijiria ti wọn o ṣi gbagbọ pe COVID 19 wa lootọ ti wọn si n fọwọ yẹpẹrẹ mu u.
Kid boxer: Ọmọọba 'The Buzz' Larbie rèé, ọmọ ọdún méje tó ń fi ẹ̀ṣẹ́ dá bírà
"Dokita Aliyu ni ""o lee ko Coronavirus bi o ba jade lai tẹle awọn ofin ti a ṣe"". Ẹwẹ,  o gboriyin fawọnipinlẹ to n jabọ deedee nipa iye awọn to ti lugbadi arun naa. O jẹ ko di mimọ pe "" ko si itiju ninu sisọ iye awọn to ni i nipinlẹ yin. Bi a o ba mọ otitọ nipa ipo ti ipinlẹ yin wa ni ti arun yoo, ẹ n fi ẹmi awọn araalu yin wewu ni""."
Oríṣun àwòrán, Twitter
Ijọba ipinlẹ Oyo ti sọ pe ipinnu oun lati ṣi awọn ile iwe pada lọjọ kọkandilọgbọn oṣu kẹfa ọdun 2020 ṣi wa ni digbi.
Agbẹnusọ Gomina ipinlẹ naa, Taiwo Adisa sọ fun BBC pe kii ṣe gbogbo ile iwe ni yoo di ṣiṣi
O ni ayafi awọn ile iwe to ba tẹlẹ ilana ti ajọ eleto ilera gbe kalẹ lati dabo bo awọn akẹkọ.
Adisa ni awọn aṣoju ileeṣẹ to n ri si eto ẹkọ ni ipinlẹ Oyo yoo ma kaakiri awọn ile iwe lati ri pe wọn ni gbogbo oun to yẹ
O ni eyi ko ṣẹyin ki wọn baa le ni lọna ati dena itankalẹ arun Covid-19 laarin awọn ọmọ ile iwe.
"Adisa tun  ni ""Ile iwe to ba ṣe awọn nnkan to yẹ nikan lo maa koju osuwọn lati wa ni ṣiṣi."""
Ṣugbọn awọn ile iwe ti ko ba ṣe awọn ohun to tọ bii ibi ti awọn ọmọ ile iwe yoo ti maa fọ ọwọ wọn pẹlu aridaju pe awọn akẹkọọ naa yoo ma lo ibomu, ko tii ṣetan lati di ṣiṣi.
Adisa ṣalaye pe awọn to wa ni ipele kẹfa ile iwe alakọbẹrẹ, awọn to wa ni ipele kẹta akọkọ ati ipele kẹta keji ni ile iwe girama nikan ni ijọba lero pe yoo pada sẹnu ẹkọ wọn.
Oríṣun àwòrán, Seyi Makinde/Twitter
Ni ti pe awọn to ni arun Coronavirus n pọ si ipinlẹ Oyo, Adisa ni ko ṣẹyin ayẹwo ojule si ojule ti ijọba ipinlẹ ọhun gunle.
O ni ojuko ti ijọba Oyo ti n gba nnkan ayẹwo coronavirus le ni mẹwaa kaakiri ipinlẹ naa, ati pe ida mẹwaa ninu ọgọrun awọn to ṣayẹwo arun naa lo ni ni ipinlẹ ọhun.
Adisa pari ọrọ rẹ pe ijọba ti kọwe ranṣẹ si awọn olori ile iwe lori igbesẹ to yẹ ki wọn gbe, ṣugbọn ti wọn ba kọ lati tẹle awọn igbesẹ yii, ko ni si aye lati ṣi irufẹ ile iwe bẹẹ.
Oríṣun àwòrán, Seyi Makinde/Twitter
Ijọba ipinlẹ Ọyọ ti paṣẹ ki awọn ileewe gbogbo ni ipinlẹ naa o di ṣiṣi pada ni ọjọ Aje, ọjọ kọkandinlọgbọn oṣu yii, amọ ijọba ipinlẹ Cross River ti fi ọsẹ meji kun iwọle awọn akẹẹkọ.
Igbimọ amuṣẹya ti ijọba ipinlẹ Ọyọ gbe kalẹ lori kikoju ajakalẹ arun coronavirus lo kede igbesẹ ijọba ipinlẹ naa lọjọ Aje.
Ninu ọrọ ti wọn fi lede, ijọba ipinlẹ Cross River ni awọn fẹ fi ọsẹ meji naa se ayẹwo gbogbo awn ileewe naa lati le gbaradi fun iwọlẹ awọn akẹkọ naa.
Oríṣun àwòrán, Others
Ti ijọba ipinlẹ Cross River ko ba yi ẹnu pada, awọn ni ko ba jẹ ipinlẹ akọkọ ti yoo ṣi ileewe pada lorilẹede Naijiria.
Ninu ọrọ ti wọn, Ijọba ipinlẹ Ọyọ ni awọn akẹkọọ iwe kẹfa nileewe alakọbẹrẹ (Primary Six), iwe kẹta ileewe girama (JSS 3) ati kilasi aṣekagba nileewe girama (SSS 3) nikan ni yoo wọle ikẹkọọ ni ọjọ naa.
Ati pe wọn si gbọdọ maa tẹle awọn ilana ti igbims amuṣẹya naa ba fi silẹ.
Oríṣun àwòrán, twitter/Seyi makinde
Bakan naa lo tun fi kun un pe awọn ileejọsin pẹlu lee pada si nii ṣi ilẹkun wọn silẹ fun ijọsin lati ọjọ Aje kan naa
Sugbọn ida kan ninu mẹrin awọn eeyan to n wa si ileejọsin naa tẹlẹ ni aye gba lati maa jọsin fun asiko yii na ti wọn ko si gbọdọ maa tẹle ofin ati ilana igbimọ amuṣẹya naa.
Bakan naa ni ijọba ipinlẹ Ọyọ tun paṣẹ fun awọn oṣiṣẹ ijọba ipinlẹ naa lati ọjọ Aje to n bọ.
Amọ, ipinlẹ Cross river nikan ni ko i tii kede pe awọn ni arun Coronavirus ninu gbogbo awọn ipinlẹ to wa lorilẹ-ede Naijiria.
Oríṣun àwòrán, Twitter
Adams Oshiomole: Idí tí mo fi faramọ́ ìpinu NEC- Oshiomole
Oríṣun àwòrán, Other
Alága ẹgbẹ́ òṣèlú All Progressives Congress tẹ́lẹ̀rí, Adams Oshiomhole sàlàyé lọ́sàn òní pé òun ti faramọ́ ìpinnu ìgbìmọ ẹgbẹ́ (NEC).
Èyí ni ìgbà àkọ́kọ tí Oshiomhole yóò sọ̀rọ̀ láti ìgbà ti gbogbo ǹkan ti n rú gùdùgùdù nínú ẹgbẹ òṣèlú APC, eyi ti wọ́n sì fi yọ Oshiomhole kúrò nípò gẹ́gẹ́ bi alága.
Oshiomhole ní, òun kò kábàmọ́ gbogbo ìgbésẹ̀ ti òun ti gbé sẹyin.
O ni gbogbo nkan ti oun ṣe lásìkò ti òun jẹ alága ẹgbẹ́ APC lo tẹ oun lọrun ati pe, òun sì wà lẹ́yìn ìjọba ààrẹ Muhammadu Buhari lọ́jọ́kọ́jọ́.
Ibadan Death: Àwọn ará àdúgbò Akinyele ké sita lórí iṣékúpani  tó ń wáyé ní ìlú Ibadan.
Adams Oshiomole ní ààrẹ Buhari pe òun sínú ẹgbẹ́ APC gẹ́gẹ́ bi alága láti ṣe àtúntò ẹgbẹ́ ní, àti pé ààrẹ Buhari kan náà ló lo oyé rẹ̀ láti gbárúkù ti bi wọn ṣe tú ìgbìmọ̀ amúṣẹ́ṣe náà ká.
O mẹnuba pataki titẹ̀lé àṣẹ́ ẹgbẹ́ boya o tẹ eeyan lọrun tabi bẹẹkọ nitori pe ifẹ ẹgbẹ lo ṣe pataki julọ.
Oríṣun àwòrán, Others
Ilé ẹjọ́ kòtẹ́mílọ́rùn yọ alága ẹgbẹ́ òṣèlú APC Adams Oshiomhole nípò
Adams Oshiomhole: Ilé ẹjọ́ kòtẹ́mílọ́rùn  yọ alága ẹgbẹ́ òṣèlú APC Adams Oshiomhole nípò
Ilé ẹjọ́ kòtẹ́milọ́rùn ti ilú Abuja ti yẹ àga mọ alága ẹgbẹ́ òṣèlú APC, Adams Oshiomhole nídìí
Ìgbìmọ̀ ẹlẹ́ni mẹ́tà ti adájọ́ Eunice Onyemanam sójú fún ni wọ́n fẹnu kò láti jan idájọ́ tí ilé ẹjọ́ ti kọ́kọ́ dá tẹ́lẹ̀ lóntẹ̀.
Sáájú ni Oshiomhole ti pe ẹjọ́ kòtẹ́milọ́rùn lórí ìdájọ́ tí àdájọ Abubakar Yahaya sì dájọ pé kí ìdájọ́ náà dúró náà kí ó ṣì maa ṣe alága lọ́  títí ìdájọ́ ilé ẹjọ́ kòtẹ́milọ́rùn yóò ṣe fìdímúlẹ̀.
Port harcourt Bole: Mi kò mọ́ pé bọ̀ọ̀lì títà lè gbé mi dé ipò yìí láyé mi!
Adajọ Onyemanam to dárí ẹjọ́ to wáyé lónìí ọjọ́ iṣẹgún lo dá ẹjọ́ náà ló fídí rẹ̀ múlẹ pé ìdájọ́ ilé ẹjọ́ kekere to yọ Adams Oshiohmole gẹ́gẹ́ bi alágá ni inú ọṣù kẹta ọdún yìí ṣe ǹkan to yẹ ati pé, ẹjọ́ kòtẹ́mílọ́rùn ti Oshiomhole pè kò fìdì múlẹ̀.
Oríṣun àwòrán, Twitter/Godwin Obaseki
Gomina ipinlẹ Edo, Godwin Obaseki ti fi ẹgbẹ oṣelu APC silẹ lẹyin ọpọlọpọ awuyewuye lori yiyọ ti wọn yọ ọwọ rẹ kuro lawo idije fun ipo gomina labẹ aṣia ẹgbẹ oṣelu APC ni ipinlẹ Edo.
Godwin Obaseki ti kọwe fipo silẹ gẹgẹ bi ọmọ ẹgbẹ oṣelu APC lẹyin ipade rẹ pẹlu Aarẹ Muhammadu Buhari ni ilu Abuja ni ọjọ Iṣẹgun.
O ti to ọjọ mẹta bayii ti wahala ti bẹ silẹ laarin gomina Obaseki ati alaga apapọ ẹgbẹ oṣelu APC lorilẹede Naijiria, Adams Oshiomhole.
Atunbọtan itaporogan laarin awọn mejeeji yii gẹgẹ bi igbagbọ ọpọ onwoye ọrs oṣelu ni bi igbimọ ayẹwo fun awọn oludije idibo abẹle lati yan oludije fun ipo gomina labẹ aṣia ẹgbẹ oṣelu APC fi paṣẹ pe ko ni lee kopa nitori ohun ti wọn pe ni aidọgba lori awọn iwe ẹri rẹ.
Bi o tilẹ jẹ wi pe ileewe giga fasiti ibadan ti bọ sita lati kede pe akẹkọjade ileewe naa ni, sibẹ igbimọ kotẹmilọrun ti ẹgbẹ oṣelu AOC gbe kalẹ lori eto ayẹwo naa pẹlu fọwọ si igbesẹ igbimọ ayẹwo naa.
Ibadan Death: Àwọn ará àdúgbò Akinyele ké sita lórí iṣékúpani  tó ń wáyé ní ìlú Ibadan.
Nibayii, ibeere to wa lẹnu ọpọlọpọlọ awọn eeyan ni pe nibo lo kan fun gomina obaseki abi ṣe o ti gba fun Ọlọrun naa niyẹn.
Amọṣa gẹgẹ bi ọpọlọpọ ṣe mọ nipa awọn oloṣelu Naijiria, ko ṣeeṣe ko gba f'Ọlọrun bẹẹ.
Ohun ti ọpọ n woye rẹ lọwọ bayii ni pe boya yoo ko ẹru oṣelu rẹ lọ ba ẹgbẹ oṣelu PDP pẹlu bi o ti ṣe n rin irinajo kaakiri ọdọ awọn gomina ipinlẹ to jẹ ọmọ ẹgbẹ oṣelu PDP bii Wike ti Rivers ati Udom ti ipinlẹ Akwa Ibom.
Mobile Wash: iṣẹ́ fífọ́ mọ́tò tà ni mó yàn láààyò- Slay Mama
Angel Gomes: Angel Gomes, agbábọ́ọ̀lù Manchester United ṣàlàyé ohun gan tó gbé e dé ṣọ́ọ̀ṣì T. B Joshua
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Mo sàbẹwò sí T.B Joshua nítori ìṣòro ẹsẹ tí mo ní-Angel Gomes
Ọmọ agbábọ̀ọ̀lù Manchester United Angel Gomes ti fèsì fún àwọn olólùfẹ́ rẹ̀ lórí ayélujára ìdí tó fi sàbẹ̀wò sí ìjọ T.B Joshua lorílẹ̀-èdè Nàìjíríà.
Gomes bẹ̀rẹ̀ ìrìnàjò bọ́ọ̀lù gbígbá nígbà tó ti wà ni ọmọ ọdún mẹ́fà, wọ́n yan láti gbáradà ní ilé ẹ̀kọ́ ọmọ wẹ́wẹ́ Manchester United tí ó sì lo ọdún mọ́kanlá gbáko kí o tó lé darapọ̀ mọ ẹgbẹ́ agbábọ́ọ̀lù náà lọ́dun 2017.
Láti ìgbà náà, ó ti farahàn tó ìgbà mẹ́wàá nínú ẹgbẹ́ agbábọ̀ọ̀lù Red Devils tí ó sì ti n pinu láti búwọ́ lùwé láti fikún àsìkò rẹ̀ nínú ẹgbẹ́ agbábọ̀ọ̀lù Manchester United.
Ẹ̀wẹ̀, fónrán iṣẹ́jú meji kan ṣẹ́yọ lórí ayélujára, èyí tó sàfihàn ìtiràka rẹ̀ lórí bi yóò ṣe gba ìwòsàn lórí ìṣòro ẹsẹ̀ tó n bá fíra lásìkò  ọ̀ún.
Fọ́nran náà sàfihàn Gomes nibi to ti n ṣi ojú egbò rẹ̀ nínú ìjọ T.B Joshua, Synagouge Church of All Nation.
"Ọ̀dọ́mọkùnrin náà sàlàyé pé òun gbé ìgbésẹ̀ náà lẹ́yìn ti àwọn òbí òun gbà òun nímọ̀ràn láti gbìyànjú rẹ̀ wò gẹ́gẹ́ bi o ṣe sọ nínú fídíò náà': ""Orúkọ mi ni Angel Gomes, mó wá láti Manchester, ọmọ ọdun mẹ́rìndílógún ni mi."
Àlàyé tó fí síta rèé
O ní àwọn isòrò ẹṣẹ̀ tó ń yojú yìí ń kan òun lóminú lásìkò tí ó yẹ ki òun maa gbádún ayé òun nínú eré bọ́ọ̀lù
Mó n gbá bọ́ọ̀lù fún Manchester United, mo sì ń sojú ẹgbẹ́ agbábọ́ọ̀lù England gẹ́gẹ́ bíi balọ́gun ikọ̀ agbábọ́ọ̀lù náà, mo sì ti mọ ijọ synagogue láti kékeré.
Àwọn obí mi fẹ́ràn T.B Joshua púpọ̀ à sì maa n wòó fídíò rẹ lóòrèkóòrè.
"Gomes fèsì lójú òpó Twitter rẹ, tó sì tẹpẹlẹ mọọ pé ẹsìn òun kìí ṣe ǹkan ti ó yẹ kí àwọn ènìyàn máa fọ̀rọ̀ jomitoro ọ̀rọ̀ lé lórí, pàápàá jùlọ nínú ìṣòrò ààùn Corornavirus yìí ati ìfẹhónúhàn ""ayé ènìyàn dúdú ṣe pàtàkì""(BLM) tó n jà ká gbogbo àgbáyé."
O ní: Ni ti fọ́nrán to jẹyọ láti ọdún 2016. Ìdílé onígbàgbọ́ ni mo ti wá, ni àsìkò náà olólùfẹ́ pásítọ ọ̀un ni maami jẹ́, ó sì fẹ́ ki n lọ nítórí àwọn ìṣòrò ti mo ní.
 Mó kéré lásìkò  náà àwọn òbí mi ǹkan yìí dára fún mi láti ṣe, ìṣòro pọ̀ gàn ni lágbàyé báyìí tó yẹ kí a mójú tó
Oluwatoyin Salau: Òkú Toyin làwọn ọlọ́pàáTallahassee ni àwọn rí lẹ́yìn ìpè rẹ̀ lórí twitter
Oríṣun àwòrán, Virgintoyin/twitter
Toyin poora lẹyin to figbe ta nipa ifipabanilopo loju opo Twitter - ka ohun ta mọ nipa iku rẹ
Ileesẹ ọlọpaa gẹgẹ bi ohun ti BBC ri fidi rẹ mulẹ ti sọ pe awọn ti ri oku arabinrin Oluwatoyin Salau lẹyin ọjọ meloo kan ti wọn fi se awati.
Toyin,Ọmọ ọdun mọkandinlogun ajafẹtọmọniyan ọmọ Naijiria ọhun to fi ilẹ Amẹrika se ibugbe bawọn se iwọde Black Lives Matter to waye ni Florida ni Amẹrika.
BBC pidgin lẹyin iwaadi ri wi pe ileesẹ ọlọpaa Tallahassee kede pe o di awati ni ọjọ Kẹsan osu Kẹfa 2020, sugbọn lẹyin ọjọ diẹ ni wọn kede pe awọn ri oku rẹ ni irọlẹ ọjọ Kẹẹdogun osu Kẹfa.
Ìtàn Olaniyi Balogun, ọ̀jọ̀gbọ́n tó fi Nàìjíríà sílẹ̀ lọ gba iṣẹ̀ àgbẹ̀ l'Ámẹ́ríkà
Ohun ta gbọ ni pe ajafẹtọmọniyan naa poora lẹyin to gbe ọrọ sita loju opo Twitter pe eeyan kan gbiyanju lati fipa ba ohun lopọ ni adugbo Park Avenue and Richview Road ni Tallahassee, Florida.
Ninu ọrọ to fi sita, o ni ọkunrin naa sọ pe ohun yoo fi ọkọ gbe  oun pada lọ si sọọsi kan tohun fori pamọ si.
Ọrọ ti Oluwatoyin fi sita kẹhin re ki o to di pe awọn ọlọpaa ri oku rẹ
Gẹgẹ bi ohun ti awọn ọlọpaa sọ ni nkan bi ago mẹsan alẹ kọja isẹju mẹẹdogun lọjọ kẹtala osu Kẹfa ni awọn oluwadi de si ile ibugbe 2100 block to wa ni Monday Road lati se iwaadi to ni se pẹlu eeyan kan ti wọn ni o di awati, iyẹn Oluwatoyin Salau.
Lasiko iwaadi wọn ri oku meji ni  agbegbe naa.
Wọn ni awọn ri oku rẹ pẹlu ti iya agbalagba kan ẹni ọdun marundinlọgọrin lẹgbẹ Wahnish Way and Orange Avenue, Tallahassee..
Oríṣun àwòrán, Screenshot/twitter
Toyin poora lẹyin to figbe ta nipa ifipabanilopo loju opo Twitter - ka ohun ta mọ nipa iku rẹ
Oluwatoyin Salau jẹ ọkan gbogi ninu awọn to n fẹhonu han lori iwa ifiyajẹni si ara ilu lati ọwọ awọn ọlọpaa.
Bi iwaadi naa se n tẹsiwaju awọn ọlọpaa ni awọn ti ri afurasi kan to wa ni ahamọ bayi ti awọn ko si ni iroyin kankan lati fi to ara ilu leti lọwọ yi nipa isẹlẹ naa.
Awọn ọlọpaa ni oju ẹsun  isekupani lawọn fi n wo iku Oluwatoyin ati ti Iya arugbo ẹni ọdun marundinlọgọrin ti wọn jijọri oku wọn.
Wọn ni awọn ti gbe ọrọ naa le ẹka ileesẹ ọlọpaa to n sewadi awọn iwa ọdaran to le lọwọ.
Awọn oluwaadi ti kesei ẹnikẹni to ba ni iroyin to le mu ki awọn ri awọn to hu iwa yi lati kan si awọn lori ago 850-891-4200 tabi  Crime Stoppers lori ago 850-574-TIPS.
Oríṣun àwòrán, others
Toyin poora lẹyin to figbe ta nipa ifipabanilopo loju opo Twitter - ka ohun ta mọ nipa iku rẹ
Oríṣun àwòrán, @virgingrltoyin/twitter
Toyin poora lẹyin to figbe ta nipa ifipabanilopo loju opo Twitter - ka ohun ta mọ nipa iku rẹ
Awọn alasẹ Naijiria ko foju kere isẹlẹ iku Toyin yi.
Ọga ileesẹ Naijiria to n boju to awọn ọmọ ilẹ yi nilẹ okere(NIDCOM)
iyẹn Abike Dabiri-Erewa sọ pe iku ọmọ ọdun mọkandinlogun Oluwatoyin yi jẹ iwa ika to buru to si tun bani lọkan jẹ.
Abike Dabiri-Erewa,alaga ajọ NIDCOM ti wa kesi ijọba Amẹrika lati se iwaadi to peye lati le tu isu de isalẹ koko nipa ohun to sokunfa iku arabinrin Slau.
Bẹẹ naa lo fi ọrọ ibanikẹdun ransẹ si awọn mọlẹbi arabinrin Salau to padanu ẹmi rẹ lasiko to n ja fẹtọmọniyan lọwọ ifiyajẹni ati  aisedeede.
Ìtàn Mánigbàgbé: Ìdílé Mobee, Abass, Aniwura àtàwọn míràn rí owó tabua nínú òwò ẹrú
Owo ẹru jẹ oko-owo to gbajumọ yika agbaye ninu eyi ti wọn ti n ko awọn ọmọ adulawọ lọ ta bíi ẹru soke okun.
Aarin ṣaa onka ẹgbẹrun ọdun kẹrindinlogun si ikọkandinlogun (16th-19th century) si ni owo ẹru gbilẹ nilẹ Afirika
Lasiko yii ni wọn si ta adulawọ bii miliọnu mejila soko ẹru loke okun nigba naa.
Yoruba si ni bi iku ile ko ba pa ni, ti ode ko le pa ni, akọsilẹ si fihan pe, awọn ọmọ Adulawọ kan pẹlu idile wọn lo n ta awọn Adulawọ ẹgbẹ wọn fawọn oyinbo alawọ funfun, ti owo ẹru fi gbilẹ.
Bi o tilẹ jẹ pe ọjọ pẹ ti owo ẹru ti kasẹ nilẹ, sibẹ iyan ogun ọdun tun jo awọn idile to kopa ninu owo ẹru lọwọ,
Paapaa lasiko yii ti ibinu araalu si tun dìde si wọn lẹẹkan si nitori adulawọ kan, George Floyd, ti Ọlọpa kan sekupa ni Amẹrika.
Idi ree ti BBC Yoruba tun ṣe woju wo ẹyin lati ṣe akojọpọ idile marun nilẹ  Yoruba, ti wọn kopa ninu owo ẹru ṣíṣe nigba atijọ.
Sogidi Lake: Kòṣẹja-kòṣèèyàn lá bá nínú adágún odò náà -Ojedele
Ilu Badagry, taa tun mọ si Agbadarigi to wa nipinlẹ Eko, jẹ ilu to gbajumọ fun oko-owo ẹru laye ijọhun nitori bo ṣe sunmọ eti okun ti wọn n gba ko awọn ẹru sọda soke okun.
Lara awọn idile to gbajumọ fun owo ẹru sise nigba naa ni idile Ọba Sunbu Mobee,
Idile yii to ni gbọngan nla nilu Badagry ti wọn n ko ọpọlọpọ ẹru pamọ si, ki wọn to ko wọn lọ soke okun.
Lati ilu Oyo, Ibadan, Abeokuta, Osogbo ati bẹẹ bẹẹ lọ, ni wọn ti n ko ẹru wa fun idile ọba Mobee,
Ti ọja Belekete naa si wa nilu Badagry, ti wọn ti n ta ẹru fun awọn oyinbo ati adulawọ.
Ni kete ti awọn oyinbo naa ba si ti ra awọn ẹru yii, ni wọn yoo fi irin gbigbona kọ orukọ wọn siwaju ẹru wọn,
Wọn yoo sọ ẹwọn irin si wọn lọwọ ati ọrun, fun ọjọ pipẹ, ki wọn to ko wọn lọ silu oyinbo.
Koda wọn tun maa n fi agadagodo pa ete mejeeji ẹnu ẹru de mọra wọn, ki wọn ma baa sọrọ si ara wọn,
Gbogbo awọn eroja ìnira ti wọn si n lo fawọn ẹru yii lo wa ninu ibudo ise nnkan isẹnbaye lọjọ si ni iranti owo ẹrú, eyi to wa lagbo ile Mobee nilu Badagry, titi di oni oloni.
Idile Oba Seriki William Abass:
Gbajugbaja olowo ẹru ni Oba Seriki Williams Ifaremilekun Abass tilu Badagry laarin saa onka ọdun kọkandinlogun (19th century).
Ilu Ilaro, tii ṣe ilu abinibi rẹ ni wọn ti ko Seriki Abass ni ẹru lasiko ogun Ẹ̀gbá ati Dahomey, ti wọn si ta a fun Williams, tii ṣe oyinbo olowo ẹru lati Brazil.
Abass lọ ṣe ẹrú ni Brazil, nibi to ti gbọ ede oyinbo, to si tun mọọ kọ, mọọ ka, ki wọn to da a pada sile lati wa maa ṣe Alakoso owo ẹrú fun ọga rẹ, Williams nilu Badagry.
Seriki Abass jẹ Oba nilu Badagry, lẹyin ti owo ẹrú dopin amọ o ti lowo, o lọla, to si laami laaka saaju nidi owo ẹrú ṣíṣe,
Bẹẹ ni ibudo kan wa nilu Badagry bayii, ti wọn ya sọtọ bii ìṣe nnkan isẹnbaye lọjọ si, fun iranti ọba Seriki Williams Ifaremilekun Abass.
Oríṣun àwòrán, others
Idile Obìnrin takuntakun miran nidi kata-kara owo ẹru ni idile Oloye Efunsetan Aniwura, tii ṣe Iyalode keji nilẹ Ibadan.
Idi owo ẹrú si ni akọni obinrin naa ti ri taje ṣe bii Efunroye Tinubu, oun naa lowo, o lọla, o gbajumọ, to si n dari ọpọlọpọ ọkùnrin labẹ rẹ.
Ọmọ bibi ilu Abeokuta ni Efunsetan pẹlu, oko-owo si lo gbe de ilu Ibadan nibi to ti gbọrẹgẹ-jigẹ ninu owo ẹrú ṣíṣe, to si di ara awọn alagbara to n dari ilu Ibadan.
Akọsilẹ si fi ye ni pe, Efunsetan maa n ni to ẹgbẹrun meji ẹru to maa n ko lọ ta nilu Badagry loore koore,
To si tun ni awọn ẹru to n ṣíṣẹ fun ninu ile, ti ẹru-binrin rẹ kankan ko si lori laya lati loyun, kiku ni onitọun yoo ku, lati ipasẹ ida.
Oríṣun àwòrán, others
Idile miran to tun gbajumọ fun owo ẹrú ṣíṣe ni idile oloye arabinrin Efunporoye Osuntinubu, ti adape rẹ n jẹ Efunroye Tinubu.
Obìnrin takuntakun, obinrin to ju ọkùnrin lọ, obinrin to si n fi ọba jẹ tabi rọ ọba loye ni arábìnrin Tinubu nigba aye rẹ, ẹni to yan kata-kara owo ẹrú laayo nigba aye rẹ.
Ọmọ ilu Abeokuta ni Tinubu, o fẹ ọpọ ọkọ nigba aye rẹ, lara wọn si ni Oba Adele Ajosun tilu Eko, to fẹ lọdun 1833 nilu Abeokuta nigba ti wọn rọ Oba naa loye, to si sa lọ silu Egba.
Ọba Adele ati Tinubu tun ko lọ silu Badagry, ti ọba naa si ran Tinubu lọwọ lati gbọrẹgẹ-jigẹ ninu owo ẹru ṣíṣe nilu ọhun,
Nibe ni obìnrin takuntakun naa si ti ni awọn ọmọ ogun to maa n ran nisẹ lati lọ jagun, ko ẹrú wa fun lati ta fun awọn oyinbo.
Oríṣun àwòrán, others
Idile ọba Kosoko tilu Eko naa wa lara idile to gbaju-gbaja nilẹ Yoruba fun owo ẹru ṣiṣe,
Kosoko si jọba nilu Eko laarin ọdun 1845 si 1851, ki wọn to le kuro lori itẹ.
Ọba Kosoko gbajumọ bii isana ẹlẹẹta fun owo ẹru ṣiṣe, ọpọ igba si ni awọn oyinbo ti ṣipẹ fun un ko pinwọ owo ẹru,
Amọ ti ko dahun pẹlu awijare lọdun 1851 pe ayafi ti Oba Benin ba sinmi owo ẹru, ni oun naa yoo jami lori rẹ.
Eyi si wa lara ẹsun tawọn oyinbo amunisin ka si Oba Kosoko lọrun, ki wọn to rọ ọ loye, to si sa lọ silu Badagry pẹlu Balogun rẹ, Oshodi Tapa, níbi ti owo ẹru rẹ tun ti buyaari.
APC: Mí ò tíí ní ìpinnu lóri ìdíje ààrẹ ọdún 2023-Tinubu
Oríṣun àwòrán, Tinubu instagram
Asáájú ẹgbẹ́ òṣelú ẹgbẹ́ APC, Sẹnatọ Bola Ahmed Tinubu ní òun kò ti ṣe ìpinnu láti díje dupò ààrẹ orílẹ̀-èdè Naijiria lọ́dun 2023
Èyí lòdì sí àwọn oníruuru ọ̀rọ̀ tó ti n lọ nígboro tẹ́lẹ̀, yálà Asiwáju ní ǹkan to jẹ òun lógun jùlọ ni bi ọrọ ajé tó n dẹnu kọle yìí yóò ṣe gbéra sọ pada àti bi eto iléra yóò ṣe pada bọ̀ sípò ní Naijiria.
Tinubu sọ eyi di mímọ nínú àtẹ̀jáde kan tó fọwọ́ sí lọ́sàn òní sátide, èyí sì ni ìgbà àkọ́kọ́ tí yóò fọhùn láti ìgbà tí wọ́n ti yọ ọwọ́ Adams Oshiomhole láwọ gẹ́gẹ́ bi alága ẹgbẹ́ náà tí wan sì tú ìgbìmọ amúṣẹ́ṣe ká lọ́jọ́rú ọ̀ṣẹ̀ yìí.
"Nínú ọ̀rọ̀ rẹ̀ ó ní : Sí gbogbo ẹyin ti ẹ ti n kù pé ìgbésẹ̀ ààrẹ Buhari àti ìpáde àwọn ìgbìmọ tuntun nínú ẹgbẹ́ òṣèlú APC ṣe ṣe fi òpin sí ìpínnu mí láti di ààrẹ lọ́dún 2023, ó ṣe mi láànú fún yín"""
"Ènìyan ẹlẹ́ràn ara lásán ni mí tí kò sì ni oye ọjọ́ iwájú tàbí ọgbọ́n òṣèlú tí ẹ ń fi ẹnu jẹ́ pé ní, ẹ tí n yọ ayọ lórí ikú ìpínnu ìjákulẹ oyé ààrẹ tí kò ti wáye rárá.
Tinubu ní kìí ṣe irú àsìkò ti ààrun Covid-19 ń da ètò ọrọ ajé láàmú yìí, mí ò rí ọjọ́ ìwájú tó bi éyin 'se rii"" Mí ò sì tíì ṣe ìpinnu kankan láti dupò ààrẹ lọ́dún 2023 nítori pé àwọn ǹkan to n kojú wa ní àsìkò yìí tí lágbára tó."
Ní àsìkò tí a wà yìí, mí ò jẹ́ kí ọ̀rọ̀ òṣèlú nípa ọdún 2023 jẹ mí lógún, mó rí eyi bi ǹkan ti kò bójú mu rárá, ó sì jẹ́ ìwà àìní ìmọ̀lára lásìkò ti ọ̀pọ̀ ń koju ìṣòro oníhà méjì, ètò ọ̀rs ajé tó nira àti ààrùn tó n kó ìpaya bá gbogbo ayé.
Láti bi oṣù díẹ̀ sẹyìn ni mo ti n ro àwọn ìlànà ìjọba ti a lè gbé silẹ̀ tí yóò ràn ìjọba lọ́wọ́ níhìn àti lọ́hùn.
Ààrẹ tí sọ̀rọ̀, ọ̀rọ̀ tó sì sọ ní náà ni abẹ́ gé
Nítori idí èyí mo rọ gbogbo àwọn ìgbìmọ̀ amúṣẹ́yá tí wọ́n túka àti gbogbo ọmọ ẹgbẹ́ tókù láti fíyedénu kí wọ́n sì máá wo ọjọ́ iwáju rere tó wà níwájú
Mó ti fara ṣiṣẹ́ fún ẹgbẹ́ bí àwọn ọmọ ẹgbẹ́ tó kù tàbi jù ẹlòmíràn lọ, sùgbọ́n síbẹ̀ kò nimi lára láti túbọ̀ faraji gẹ́gẹ́ bi ọlọ́dani, kò sì si ẹni to yẹ ko ní ìṣoro kankan lòdì si eyi.
Oríṣun àwòrán, Bola Tinubu
Minisita tẹlẹ ni Naijiria Femi Fani Kayode, ti kọ lẹta ranṣẹ si asaaju ẹgbẹ oselu APC, Asiwaju Bola Ahmed Tinubu, lẹyin ti Aarẹ Muhammadu Buhari yan Alaga fidiẹ tuntun fun ẹgbẹ oṣelu APC.
Fani Kayode ninu lẹta naa ni, bi oun ṣe fẹran Tinubu to amọ iwa rẹ lo mu ki oun sa fun un, nitori imọtara ẹni nikan n ba ja.
O ni Aarẹ Buhari to fi ṣe ọrẹ ti sọ di ọta, ti gbogbo ero rẹ lori ẹgbẹ oṣelu APC si ti jasi pabo.
Femi Fani Kayode ni bi o tilẹ jẹ pe Asiwaju ti gbekele ara rẹ wi pe oun ko le e ṣi ṣe, ọrọ yii ti ba ẹyin yọ pẹlu bu Aarẹ Buhari ṣe pada lẹyin rẹ, ti wọn si ri pe ko ni ipo kankan mọ ninu ẹgbẹ oṣelu APC.
Oríṣun àwòrán, Bola Tinubu
'Tinubu ta ẹmi rẹ, ta ọkan rẹ, to si ta gbogbo ilẹ Yoruba, to fi mọ Guusu ati Ariwa orilẹede Naijiria lati le ri wi pe oun mu gbogbo ero ọkan rẹ to kun fun  ibi ṣẹ.
O fikun wi pe gbogbo ilakaka rẹ lati jẹ aarẹ orilẹede Naijiria ni ọdun 2015, 2019 ati 2023 lo ti ja si pabo bayii.
Bakan naa lo ni kaka ki Tinubu o ba aarẹ Buhari sọrọ lati wuwa rẹrẹ si awọn ọmọ Naijiria, ki iya ma ba jẹ wọn, niṣe ni Asiwaju n gbe lẹyin Buhari, ẹni to wa jakulẹ bayii.
Ọrọ ipari rẹ ninu lẹta naa ni wi pe o ti tan fun Tinubu ninu oṣelu orilẹede Naijiria, oun ti o ku ni ki o lọ rọkun nile, ki o si ma a sinmi.
O gba ni adura pe lasiko ifẹyinti Tinubu, ohun gbogbo to ti bajẹ lorilẹede Naijiria yoo gba atunṣe.
Oyè adelé alága APC kúrò ní gúúṣù Nàíjíríà, ó bọ́ sẹ́kùn àríwá
Oríṣun àwòrán, APCng
Gomina ipinlẹ Yobe, Mai Mala Buni ti di Alaga ẹgbẹ oṣelu APC tuntun ni Naijiria.
Eyi ko ṣẹyin bi Aarẹ Muhammadu Buhari ṣe tu igbimọ amuṣẹya ẹgbẹ oselu APC ka, ti o si fi igbimọ fidiẹ sibẹ.
Oríṣun àwòrán, Twitter
INEC ní ìwé ìfitónilétí ti ó tẹ òun lọ́wọ́ ní ọjọ́ kejìdínlógún oṣù kẹfà ọdún yìí kò ni àbuwọ́lù àlága àpapọ̀ ẹgbẹ́ náà.
Ẹgbẹ oṣelu APC ni ipinlẹ Ondo ti ni lootọ ni pe, ajọ INEC da lẹta ifitonileti nipa eto idibo abẹle ẹgbẹ naa nipinlẹ Ondo nu.
Akọwe ẹgbẹ oṣelu APC ni ipinlẹ Ondo, Alex Kalejaiye lo fi idi ọrọ naa mulẹ fun BBC Yoruba.
Kalejaiye ni abajade ipade awọn igbimọ alaṣẹ, NWC lori yiyan alaga ẹgbẹ oṣelu APC tuntun ni yio sọ ibi ti ẹgbẹ oṣelu APC ni ipinlẹ Ondo n lọ.
O fikun pe awọn adari wọn ni Abuja lo ni ọrọ ikẹyin lori bi idibo abẹlẹ APC yoo ṣe ri.
Nibayii, Aarẹ Buhari ti tu Igbimọ Amuṣẹya ẹgbẹ oselu APC ka ni bi ipade to waye ni ile Aarẹ ni Abuja.
Wọn si ti yan gomina ipinlẹ Yobe, Mai Mala Buni gẹgẹ bi Alaga ẹ́gbẹ́ oṣelu APC fidiẹ ni Naijiria.
Oríṣun àwòrán, APCng
Bí wàhálà tó n rú nínú ẹgbẹ́ òṣèlú All Progressives Congress ṣe n fi ojoojúmọ́ gbóná janjan ní ìpińlẹ̀ Edo, bakan naa ló jọ bi ẹni pé ẹgbẹ́ náà kò tún rójúùtú ètò ìdìbò abẹ́nú láti yàn oludíje gómìnà lábẹ́ àsíá ẹgbẹ́ náà nípìnlẹ̀ Ondo náà.
Lọ́sàn yìí ni àjọ tó rí sí ètò ìdìbò ní Naijiria (INEC) fi àtẹjáde kan síta pé, ìwé ìfitóniléti tí ẹgbẹ́ APC nípìnlẹ̀ Ondo kọ sí olú ilé iṣẹ́ ẹgbẹ́ náà l'Abuja  láti pè òun fún ìdìbò àbẹ́nu wọ́n, kò kójú òṣùwọ̀n tó nítorí pé adelé akọwé àpapọ̀ ẹgbẹ́ APC ní Nìgeria níkan ló buwọ́ lu lẹ́tà náà.
Gẹ́gẹ́ bí àtẹjáde náà ṣe sọ, ìwé ìfitónilétí ti ó tẹ ilé ẹgbẹ́ lọ́wọ́ ní ọjọ́ kejìdínlógún oṣù kẹfà ọdún yìí kò ni àbuwọ́lù àlága àpapọ̀ ẹgbẹ́ náà.
Oríṣun àwòrán, Inec
Àtẹjáde tí Rose Oriaran-Anthony, tó jẹ́ akọwé àjọ tó n rí sí ètò ìdìbò ní Naijiria (INEC) buwọlù sàlàyé pé, ìdìbò abẹ́nú tó yẹ kó wáyé ní ogúnjọ́ oṣù kèje ọdún yìí, le ma ṣee ṣe nítori pé àlága apapọ ẹgbẹ́ àwọn akọ̀wé apapọ̀ ẹgbẹ́ ló yẹ kí wọ́n jọ buwọ́lùú.
APC: Àlààyé rèé lórí ìdí ta fi gbé ìlẹ̀kùn olú iléeṣẹ́ APC tì pa l'Abuja
Oríṣun àwòrán, APCng
Ilé iṣẹ́ ọlọ́pàá tí gbé olú ilé ẹgbẹ́ òṣèlú All Progressive Congress (APC) tì pa nílùú Abuja nibamu pẹlu àṣẹ ọgá àgbá ọlọ́pàá ní Naijiria, Mohammed Adamu.
Gẹ́gẹ́ bí ìròyìn tó tẹ wá lọ́wọ́, agádágodo ló wà ni gbogbo ẹnu ọ̀nà ilé ẹgbẹ́ náà l'Abuja.
Iroyin naa ni wọn kò fààyè gba àwọn ọmọ ìgbìmọ̀ amúṣẹ́ṣe fún ẹgbẹ́ náà láti wọlé sùgbọ́n wọ́n gba àwọn òṣìṣẹ́ àti awọn akọ̀ròyìn láti wọlẹ́ láì gbé mótò wọ́n wọlé.
Ìṣẹ̀lẹ̀ yìí súyọ lẹ́yìn tí gbogbo àwọn olórí ẹgbẹ́ òṣèlú APC kò le fẹnu kò lórí ẹni ti yóò dí àdelé alága ẹgbk òṣèlú APC lẹ́ypin ti ilé ẹjọ́ fún Adams Oshiomhole ni ìeé lọ rọ́kún nílé.
Kid boxer: Ọmọọba 'The Buzz' Larbie rèé, ọmọ ọdún méje tó ń fi ẹ̀ṣẹ́ dá bírà
Ize-Iyamu borí ìbò abẹ́nú fún idíje gómìnà l'Edo
Oríṣun àwòrán, others
Iroyin to n tẹ wa lọwọ n fiyeni pe Ize-Iyamu ti jawe olubori gẹgẹ bii oludije ti yoo gbe aṣia ẹgbẹ oṣelu APC ni idibo sipo gomina ni ipinlẹ Edo.
Ẹkunrẹrẹ iroyin n bọ laipẹ.
Oríṣun àwòrán, Twitter/@idowu553
Awọn aṣoju ti bẹrẹ idibo lati yan awọn Oludije ti yoo gbe aṣia ẹgbẹ oṣelu naa nibi idibo gomina ti yoo waye ni ipinlẹ Edo laipẹ.
Bi ẹ ko ba gbagbe, lọsẹ to kọja ni gomina ipinlẹ naa, Godwin Obaseki kọwe fi ẹgbẹ oṣelu naa silẹ lọ darapọ mọ ẹgbẹ oṣelu APC.
Ni ọjọ kẹkandinlogun oṣu kẹsan ni idibo sipo gomina yoo waye ni ipinlẹ Edo gẹgẹ bi ajọ eleto idibo, INEC ṣe ti laa kalẹ.
Oniruuru awuyewuye ati edeaiyede lo ti n wọ ts idibo abẹnu ọhun lẹyin lẹgbẹ oṣelu APC eyi to ti mu ki wọn paṣẹ ki alaga ẹgbẹ oṣelu, Adams Oshiomhole naa lọ rọọkun nile pẹlu.
Akọwe igbimọ to n ṣe aayan idibo abẹnu naa, Ajibọla Bashiru ṣalaye fun ileeṣẹ mohunmaworan abẹle kan lọjọ Aiku pe yẹkini kan ko ni yẹ eto naa.
O ni gbogbo wọọdu mejilelaadọwa to wa kaakiri ijọba ibilẹ mejidinlogun ni ipinlẹ Edo ni eto naa yoo ti waye.
Oríṣun àwòrán, APC
Ni ibi eto idibo naa to ṣi n lọ lọwọ lasiko ti a n ko iroyin yii jọ, gbogbo awọn aṣoju to wa dibo nibẹ ni wọn lo ibomu wọn ni ibamu pẹlu ilana ofin COVID-19 ni ipinlẹ Edo.lawọn wọọdu miran, eeyan marundinlogun lo n wa lori ila lẹẹkanṣoṣo ti awọn ọmọ ẹgbẹ si n ṣe afihan kaadi ọmọ ẹgbẹ wọn lasiko ti wọn fi n reti ati dibo.
Oríṣun àwòrán, Eleta mike
Idibo yii n waye lẹyin ti ẹgbẹ oselu APC ti ys ọwọ gomina Godwin Obaseki atawọn oludije meji miran, Chris Ogiemwonyi ati Mathew Iduoriyekenwen lawo idije naa.
Oríṣun àwòrán, Twitter/@Aroyvinci
Oríṣun àwòrán, @Aroyvinci
Oríṣun àwòrán, @Aroyvinci
Oríṣun àwòrán, Others
Edo state news: Godwin Obaseki ti darapọ̀ mọ́ ẹgbẹ́ òṣèlú PDP
Bi eeyan ba ti n fi ọkan ba awuyewuye to n waye lagbo oselu nipinlẹ Edo lorilee-de Naijiria lẹnu ọjọ mẹta yi, yoo ri pe ara ọtọ ni oselu Naijiria,
Ati pe ọrọ oṣelu yii ti gba ọgbọn ati suuru lasiko yii.
Eyi ko ṣẹyin igba ti aawọ laarin Gomina Godwin Obaseki ati alaga ẹgbẹ oṣelu APC, iyẹn  Adams Oshiomole bẹrẹ yi,
A ti ri itu orisirisi lati ọwọ awọn to n kopa ninu ohun to fẹ jọ ere ori itage yii, sugbọn to se pe awọn oloselu ni oṣere to wa ninu rẹ.
Ki wa lawọn ẹkọ ta le ri dimu ninu ere agbelewo ti gbogbo ọmọ Naijiria n reti ibi ti yoo kangun si yi?
A o  gbiyanju lati se atupalẹ diẹ ninu wọn ni meni meji:
Awọn agba Yoruba lo maa n pa lowe pe ibi ti a ba ti sọ pe o daarọ, a kii pada sibẹ lati  ki wọn pe ẹ kaalẹ sugbọn lagbo oselu Naijiria ọrọ yi ko fẹẹ ri bẹẹ.
Gomina Obaseki ti o jẹ Gomina labẹ ẹgbẹ oṣelu APC la ti ri pe o pada si ẹgbẹ oselu PDP, eyi to ti  bẹnu atẹ lu tẹlẹ ri.
Bakan naa la ri ninu ere ori itage Edo yi pe Adams Oshiomole to ti kọkọ kẹyin si Ize Iyamu to ko ipa ribi ribi nigba ti Oshiomole fi dupo Gomina ti wa pada wa fontẹ lu Iyamu gẹgẹ bi ayanfẹ rẹ bayi.
Ọrọ yi ko jẹ tuntun sawọn to ba mọ isesi awọn oloselu Naijiria.
Ṣugbọn ti o ba se pe o n se ẹyin ni kayeefi, ẹkọ nla kan re fun yin lati kọ - oloselu ko ni ọrẹ tabi ọta titi lailai.
Wọn le ba o se ọrẹ loni, bo si di lọla, wọn a ṣe ipolongo lati tako ọ.
2.Aarẹ Buhari ko ṣe é gbọkanle pe o ni baba ni igbẹjọ tabi pe o máa ṣe iṣe baba isalẹ fun ọ:
Ẹkọ pataki yii la ri kọ lati ara aawọ to waye laarin Adams Oshiomole ati Godwin Obaseki.
Bi eeyan ba jẹ oloselu lode toni tabi to n gbero lati darapọ mọ oselu, o ti wa foju han gbangba bayi pe ko le mu aarẹ Naijiria gẹgẹ bi baba isalẹ ti yoo gba a la lọjọ iṣoro.
Oríṣun àwòrán, @BashirAhmaad
Gbogbo igbiyanju Gomina Obaseki lọ si ile Aarẹ ni Aso Rock lọdọ Aarẹ Buhari  nigba ti ẹgbẹ APC fẹ yọwọ rẹ lawo lati dupo Gomina lo ja si pabo.
Bi o se pe Obaseki  woye ohun to sẹlẹ s'ara waju bii Ambọde àti Kwakwanso ninu ẹgbẹ naa ni, ko ni wulẹ daamu ara rẹ.
Gẹgẹ bi awọn onwoye oselu Naijiria ti se sọ, Aarẹ Buhari kii da si ọrọ aawọ to ba n waye laarin awọn ọmọ ẹgbẹ APC.
Ko sẹsẹ bẹrẹ , eyi si kọ ni yoo jẹ opin. Nitori naa, ẹkọ nla re e f'ẹnikẹni to ba fẹ sa lọ ba  aarẹ lati gbeja rẹ.
3. Paṣan ti a fi na iyale...
Gbogbo nkan ti a n ri ninu awuyewuye oselu ipinlẹ Edo n jẹki ọrọ yi rinlẹ si lọkan gbogbo ẹni to ba n fi ọgbọn ati oye ba a bọ  wi pe awọn oloselu kii ba ara wọn se ọrẹ timọtimọ.
Ki se igba akọkọ re e ta o ri ti baba isalẹ ati ọmọ lẹyin to fa si ipo yoo ma doju ija kọ ara wọn.
Ni ipinlẹ Eko, Gomina Akinwumi Ambode ati agbaọjẹ oloselu ipinlẹ naa Ahmed Bola Tinubu to fa a kalẹ gẹgẹ bi Gomina, pada gbena woju ara wọn.
Ni Kano, iru nkan bayi naa lo sẹlẹ laarin Gomina Abdullahi Ganduje ati ẹni to gbe ipo le lọwọ, Rabiu Kwankwaso.
Ni ipinlẹ Kwara naa ati ri iru rẹ to sẹlẹ ti Abubakar Olusola Saraki to fa Gomina Muhammed Alabi Lawal silẹ wa pada wa doju ija kọ.
Koda, Bukola Saraki to jẹ ọmọ bibi Dokita Olusola Saraki sebi ẹni tako baba rẹ pẹlu bi ko se gbaruku ti aburo rẹ, Sẹnẹtọ Gbemi Saraki ti baba rẹ fẹ ki o jẹ Gomina lẹyin rẹ.
4.   Ipo ti a fẹ du ṣe pataki ju ilana ẹgbẹ lọ
Lawọn orile-ede kan, eeyan a maa da ẹgbẹ oselu mọ pẹlu ilana wọn ati ohun to jẹ afojusun to mu wọn da ẹgbẹ silẹ.
Bi oloselu ba gbe igba ibo, abẹ ilana yiii ni yoo fi gbe eto ati erongba isejọba rẹ kalẹ fun awon ara ilu.
Sugbọn ni agbo oselu Naijiria nilẹ toni to mọ yi, awọn oloselu ko fi tẹgbẹ se. Ibi ti wọn yoo ti ribi du ipo lọkan wọn a maa wa.
Apẹrẹ ti a ri lati fi kin ọrọ yi lẹyin ni bi Gomina Godwin Obaseki ko ti se jẹ ki ọjọ pẹ rara ki o to sare lọ darapọ mọ ẹgbẹ oselu PDP lẹyin ti APC ni pe awọn ko fun un ni tikẹẹti ẹgbẹ mọ.
Labẹ pe awọn oloselu ko bikita fun erongba tabi ilana yi naa la ti ri pe awọn ọmọ ẹgbẹ oselu PDP naa gba Obaseki tọwọ tẹsẹ,
Koda, wọn si tun fi aaye awọn nkankan gba a, ki o ba le jẹ ẹni ti ẹgbẹ fẹ gbe asia le lọwọ lati du ipo.
Ó dára kí obìnrin níṣẹ́ lọ́wọ́ - Toyin Lawani
Sinima to gun ni ọrọ oṣelu Naijiria, ko fẹ ẹ ni opin:
Nibi ti ọrọ de e duro yii, ko si ẹni to le sọ pe ibi kan ni yoo ja si nigbẹyin.
Nigba ti awuyewuye yii bẹrẹ, Adams Oshiomole lo dipo alaga ẹgbẹ APC mu.
Ni ba ti se n sọrọ yi, ile ẹjọ giga ti yẹ aga nidi Oshiomole ti awọn miran si ti n ja witiwiti lati wa ni ipo alaga.
Labẹ pe ibẹrẹ kọ l'onisẹ, afi ẹni ba laa ja, awọn ti o fi ẹgbẹ oselu APC silẹ fun Oshiomole bi Aarẹ ile asofin agba tẹlẹ ri Bukola Saraki ni wọn wa n gba Godwin Obaseki lalejo ninu ẹgbẹ oselu PDP bayi.
Njẹ ajọsepọ awọn to kora jọ lati doju ija kọ ara wọn wọnyi, yoo jẹ ọlọjọ pipẹ tabi awọn naa yoo pada wa tutọ si ara wọn loju?
Oju re e, iran ree lọrọ to wa nilẹ yi.
E jẹ ki a jijọ maa fọkan ba ọrọ yi bọ.
Oríṣun àwòrán, Others
Edo state news: Godwin Obaseki ti darapọ̀ mọ́ ẹgbẹ́ òṣèlú PDP
Godwin Obaseki ti darapọ̀ mọ́ ẹgbẹ́ òṣèlú People's Democratic Party
Gómìnà ìpínlẹ̀ Edo Godwin Obaseki ti kúrò ní ẹgbẹ́ òṣèlú All Progressive Party lọ si ẹgbẹ́ òṣèlú People's Democratic Party.
Akọwé gómìnà Crusoe Osagie lo fìdí ọ̀rọ̀ náà múlẹ̀ fún BBC
Sáájú ni Obaseki ti kéde lọ́jọ́ ìsẹ́gun ọjọ́ kẹrindinlógún, oṣù kẹfa ọdún 2020 pé òún yóò kòwé fi ẹgbẹ́ òṣèlú APC silẹ̀ tẹ́lẹ̀.
Lósàn òní ni Gómìnà ìpínlẹ̀ Edo Godwin Obaseki tìkara rẹ̀ kéde nílé ẹgbẹ́ òṣèlú People's Democratic Party (PDP) nílùú Benin pé òun ti di ọmọ ẹgbẹ́ náà.
"Fọ́nran tó jẹyọ lójú òpó twitter ẹgbẹ́ òṣèlú PDP ni gómínà tí sọ pé ""O ní ni ìpínlẹ̀ Edo àti jákèjádò orílẹ̀ -èdè Naijiria ní òún ti dí ọmọ ẹgbẹ́ náà"""
Osagie fi kun pé Gómìnà ń pinu láti dupò gómìnà lábẹ́ àsìá ẹgbẹ́ òṣèlú PDP.
Oríṣun àwòrán, facebook/godwin obaseki
Ẹgbẹ́ òṣèlú PDP sún ìdìbò abẹ́nú Edo síwájú síi
Obaseki: Ẹgbẹ́ òṣèlú PDP sún ìdìbò abẹ́nú Edo síwájú síi
Ẹgbẹ oṣelu Peoples Democratic Party PDP nipinlẹ Edo to sun ọjọ idibo abẹnu fun awọn to fẹ dipo Gomina ni ipinlẹ naa siwaju.
Idibo ọhun yo yẹ ki o waye lọjọ kokandinlogun ati ogunjọ oṣu Kẹfa  yoo ma waye ni ọjọ kẹtalelogun oṣu Kẹfa bayi.
"Gẹgẹ bi ohun ti a ri ka ninu iwe iroyin Naijiria The Punch,akọwe ipolongo ẹgbẹ naa Kola Ologbondiyan fidi ọrọ yi múlẹ pe"" awọn ti sunjọ idibo naa titi di ọjọ Kẹtalelogun oṣu Kẹfa."""
Ṣaaju ni iwe iroyin naa ti jabọ pe Gomina Obaseki ti ṣe ìpàdé kan pẹlu alaga igbimọ awọn Gomina labẹ ẹgbẹ naa Aminu Tambuwal ati alaga ẹgbẹ Uche Secondus l'#Ojọru.
Bayi ti isunsiwaju yi ti waye, o ṣeeṣe ki ẹgbẹ naa ma palẹmọ gbogbo eto lori gbigbe asia ẹgbẹ fun Obaseki lati dupo Gomina naa labẹ orukọ ẹgbẹ wọn.
Gómìnà Godwin Obaseki yóò d'ọmọ ẹgbẹ́ òṣèlú PDP lọ́sẹ̀ yìí
O daju pe ẹgbẹ oṣelu Peoples Democratic Party, PDP ni Gomina Godwin Obaseki nlọ,
Yoo si darapọ mọ ẹgbẹ naa ki eto idibo abẹle lati yan oludije ipo gomina ipinlẹ Edo lọjọ kọkandinlogun ati ogunjọ oṣu yii.
Alaga ẹgbẹ oṣelu PDP ni ipinlẹ Edo, Tony Aziegbemi lo fi to BBC News leti bẹẹ.
O ni lootọ ko si idaniloju taarata pe oun ni yoo gbe aṣia ẹgbẹ oṣelu naa nitori iwe ofin rẹ ko faaye gba bẹẹ ṣugbọn o daju pe Obaseki yoo darapọ mọ ẹgbẹ oṣelu naa.
"Ọgbẹni Aziegbem ni bayii ohun to mumu lọkan oun gẹgẹ bi alaga ẹgbẹ oṣelu PDP ni ipinlẹ Edo ni ""lati rii daju pe gomina Ọbaseki darapọ mọ ẹgbẹ oṣelu naa."""
Oríṣun àwòrán, facebook/godwin obaseki
"Ni tirẹ, Kọla Ologbondiyan to jẹ agbẹnusọ fun ẹgbẹ oṣelu PDP lapapọ ṣalaye fun BBC pe ""ki gomina Obaseki to lee di ọmọ ẹgbẹ oṣelu PDP ni ṣan an, igbesẹ naa yoo bẹrẹ pẹlu ẹka ẹgbẹ oṣelu naa ni ipinlẹ Edo ki o to kan apapọ ẹgbẹ oṣelu ọhun."""
Bakan naa, igbakeji gomina ipinlẹ Edo, Phillip Shaibu pẹlu ti kọwe fi ẹgbẹ oṣelu APC silẹ.
Koda awọn aworan kan to n jade lori ayelujara ṣe afihan Shaibu nibi to ti n yọ aṣia ẹgbẹ oṣelu naa danu ti o si n pariwo 'o digba fun ẹgbẹ oṣelu APC ni ileejọba ipinlẹ Edo'
Ni ọjọ Iṣẹgun, ọjọ kẹrindinlogun oṣu kẹfa  ni gomina Obaseki kọwe fi ẹgbẹ oṣelu APC silẹ lẹyin ti wọn yọ ọwọ rẹ kuro lawo idije fun aṣia ẹgbẹ oṣelu naa gẹgẹ bi oludije ipo gomina nibẹ.
Period party: Àwọn obìnrin kan ṣe ayẹyẹ nkan oṣù l'órí ayélujára
Manchester City: De Bruyne gba àmì ẹ̀yẹ Premier League mọ́ Henderson lọ́wọ́ lẹ́yìn tí Lyon fi City ṣ'ẹ̀sín
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Lẹyin ti wọn kan abuku oloronbo ninu idije UEFA Champions League lalẹ ọjọ kẹẹdogun oṣu kẹjọ ọdun 2020, ẹlẹsẹ-ayo, Kevin de Bruyne gba ami ẹyẹ agbabọọlu to pegede julọ ninu idije Premier League fun saa bọọlu to ṣẹṣẹ pari.
De Bruyne gba ami ẹyẹ naa mọ Trent Alexander-Arnold, Jordan Henderson ati Sadio Mane lati Liverpool, Danny Ings ti Southampton, ẹlẹsẹ ayo Leicester, Jamie Vardy ati aṣọle Burnley Nick Pope lọwọ.
De Bruyne gba goolu mẹtala sawaọn fun Man City bo tilẹ jẹ pe ipo keji ni wọn gba ti Liverpool si gba ife Premier League.
De Bruyne to jẹ ọmọbibi ilẹ Belgium ṣe okunfa bi Man City ṣe gba ogun goolu sawọn.
Agbabọọlu Arsenal tẹlẹ ri, Thierry Henry nikan lo ti ṣe iru rẹ ri lati igba ti Premier League ti bẹrẹ.
Awọn balogun ẹgbẹ agbabọọlu ogun to wa ni Premier atawọn onimọ nipa ere bọọlu lo dibo lati yan de Bruyne gẹgẹ bi agbabọọlu to dantọ julọ.
De Bruyne ni agbabọọlu ilẹ Belgium ti yoo gbami ẹyẹ naa lẹyin ti Vincent Kompany ati Eden Hazard kọkọ gba a siwaju.
Ẹwẹ, ọjọ Abamẹta ni akọnimọọgba Liverpool, Jurgen Klopp gba ami ẹyẹ akọnimọọgba to pegede julọ ni saa bọọlu 2019/2020.
Premier League gbìnàyá padà, ọ̀gá àti ọmọṣẹ́ fìjà pẹ̀ta
Lati ayebaye lawọn aṣiwaju ti maa n gbadura pe ki ọmọlẹyin wọn o gberi koda ju awọn gan an lọ.
Ni ere bọọlu gbigba atawọn ere idaraya miran, ọpọ igba ni ọga ati ẹni to ti figbakan ri jẹ ọmọṣẹ rẹ ni ere idaraya maa n pada wa figagbaga. Bẹẹni awọn tẹgbọntaburo a maa jọ tẹsẹ bọ ṣokoto kan naa.
Lọjọru ni ifẹsẹwọnsẹ idije Premiership ilẹ Gẹẹsi yoo tun gbinaya lẹyin idaduro oṣu bii mẹta nitori arun coronavirus to bẹ silẹ kaakiri agbaye.
Pataki ninu ifẹsẹwọnsẹ ti yoo waye loni ni laarin Manchester city ati Arsenal.
Yatọ si pe ifigagbaga laarin ẹgbẹ agbabọọẹu mejeeji yii a maa larinrin, ohun kan ti yoo tun tayọ ninu ifẹsẹwọnsẹ wọn tọtẹ yii ni awọn akọnimọọgba mejeeji ti yoo maa leawju awọn ikọ mejeeji; Pep Guardiola ati Mikel Arteta.
Oríṣun àwòrán, Victoria Haydn
Ni iwoyi saa liigi premiership to lọ, ọmọ iṣẹ ni Mikel Arteta jẹ labẹ Pep Guardiola ki wọn to yan an gẹgẹ bi olukọni tuntun fun ẹgbẹ agbabọọlu Arsenal.
Awọn mejeeji yii yoo ba forikori fun igba akọkọ lẹyin ti Arteta fi Manchester city silẹ.
Ireti ọpọ onwoye bọọẹu ni pe ikọ Manchester city yoo fi ajuls han ni ifẹsẹwọnsẹ yii. Awọn ikọ mejeeji lo ni kudiẹkudiẹ lọwọ ẹyin wọn ṣugbọn ko si aniani pe awọn atamatase agbawaju fun ikọ Man city yoo lee ṣe ọpọlọpọ ọṣẹ.
Ni tiwọn, ami mẹta pere lo n dabu Arsenal ninu ilepa wọn lati ri aaye fun idije Europa ni saa to n bọ, gbogbo ipa ni wọn yoo fẹ sa lati lee kopa ninu awọn idije ilẹ Yuroopu ni saa to n bọ.
Coronavirus: Ewu wo làwọn òṣìṣẹ́ elétò ìlèra ń kojú ní Nàìjíríà?
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ṣaaju ni ẹgbẹ oṣiṣẹ awọn dokita oniṣegun oyinbo ti kọkọ gun le iyanṣẹlodi lati fẹhonu han lori aini irinṣẹ to to ati lori owo ti wọn n gba,
ṣugbọn awọn to n ṣiṣẹ lawọn ibudo iyasọtọ fun aarun coronavirus n ṣiṣẹ ni ti wọn.
Ẹwẹ, minisita eto ilera, Dokita Osagie Ehanire ti sọ pe ijọba ti yanju ọrọ aṣọ idaabobo(PPE) tawọn oṣiṣẹ eleto ilera maa n wọ lẹnu iṣẹ.
Iru ewu wo gan an ni o le wu awọn awọn oṣiṣẹ eleto ilera lorilẹede Naijiria?
Ẹgbẹ awọn dokita ile ẹkọ iṣegun(NARD) ti kọminu lori bi awọn oṣiṣẹ eleto ilera ti n ko aarun ti ọpọ si n gba ibẹ ku.
Ẹgbẹ naa ni dokita mẹwaa lo ti ku bayii.
Ajọ eleto ilera lagbaye, WHO ti sọ tẹlẹ pe ọpọ oṣiṣẹ eleto ilera lagbaye lo ti farakasa aarun covid-19.
Ọpọ orillẹede agbaye lo ti kuna lati pese aabo to peye fawọn oṣiṣẹ eleto ilera lẹnu iṣẹ wọn.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ajọ to n to n ri si idagbasoke kaakiri agbaye(CGD) ṣalaye pe o buru jai lawọn orilẹede ti ko rọwọ họri.
Ominu n kọ ọpọ eeyan ni Naijiria tori ọpọ gbagbọ pe ko si ẹni to mọ ohun to ṣẹlẹ dunjudunju lori ajakalẹ aarun covid-19.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Fun apẹẹrẹ, ọpọ eeyan laagbọ pe o ṣeeṣe ko jẹ pe covid-19 lo pa wọn ṣugbọn ko si ayẹwo fun wọn.
Akọsilẹ fihan pe awọn oṣiṣẹ eleto ilera ni Naijiria lo lugbadi aarun coronavirus julọ nilẹ Adulawọ yatọ si orilẹede South Africa.
Ṣugbọn idamẹfa awọn to laarun naa ni iroyin n gbe jade, nigba ti ida mọkandinlogun ni awọn eeyan mọ lorilẹede Niger.
Orilẹede Liberia ati Sierra Leone tun lo kan tawọn oṣiṣẹ eleto ilera tun ti ko aarun covid-19 ju.
Ṣugbọn gbogbo awọn orilẹede apa iwọ oorun Afririka yii ni ko ni awọn eeyan to laarun coronavirus to Naijiria.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ẹka eto ilera ni Naijiria ko ri owo na fun ọjọ pipẹ, loorekoore lawọn oṣiṣẹ maa n gun le iyanṣẹlodi fun ẹkunwo.
Ida mẹrin pere owo eto iṣuna lọdun ni ijọba maa n ya sọtọ fun ẹka ilera ni Naijiria.
Lọdun 2001, awọn orilẹede to jẹ ọmọ ajọ AU ṣeleri lati maa ya idamẹẹdogun owo eto iṣuna sọtọ lọdọọdun fun ẹka eto ilera.
Laipẹ yii ni ijọba orilẹede Naijiria naa ya ida mẹtalelogoji ipin sọtọ fun ẹka eto ilera, papaajulọ nitori ipa ti ajakalẹ aarun covid-19 ni lori ọrọ-aje ati bi ọrọ-aje ebpo rọbi ṣe ri lọja agbaye.
Onimọ nipa eto ilera, Onyeka Onwuegbunam ọmọ Naijiria to n ṣiṣẹ ni Fasiti ilu London sọ pe ''ko si itọju to peye lawọn ile iwosan ijọba nitori ọda owo na.
O ni ile iwosan ko pọ ni Naijiria, awọn eyi to si wa naa, ko dantọ.
Port harcourt Bole: Mi kò mọ́ pé bọ̀ọ̀lì títà lè gbé mi dé ipò yìí láyé mi!
Ajimobi: Obaseki, Ambode àtàwọn gómìnà míràn tí tírélà gba ààrín àwọn àtàwọn bàbá ìsàlẹ̀ wọn kọjá
Oríṣun àwòrán, Twitter/APC
Idibo aarẹ ọdun 2023
Awọn ‘Baba Isalẹ’ ni eto oṣelu Naijiria ni ọpọlọpọ eniyan gbagbọ wi pe wọn kii dije dupo fun ara wọn,
Amọ awọn ni o maa n sọ nipa ẹni ti yoo bori tabi ti yoo kuna ni idibo sipo lagbegbe wọn.
Gẹgẹ bi eto idibo sipo gomina ni ipinlẹ Ondo ati ipinlẹ Edo ṣe ti n sunmọle bayii, awọn Baba Isalẹ yii ni wọn n sọ bi o ṣe maa ri.
Awọn Baba Iṣalẹ yii ni wọn maa n lo owo ati ipọ wọn lati fi gbaruku ti ẹni ti wọn ba tilẹyin ninu ididbo naa.
Awọn eniyan lo gbagbọ pe ẹni to ba ni Baba isalẹ ninu ẹgbẹ oṣelu ni Naijiria ni anfaani lati dije dupo ti wọn yoo si bori, bi wọn ko tilẹ ni ọpọlọpọ imọ nipa oṣelu.
Saaju idibo sipo gomina ni ipinlẹ Edo ni Osu Kẹwaa, Odun 2020, ohun to gba ẹnu awọn eniyan kan ni ija to bẹ silẹ laarin Adams Oshiomọlẹ ati Gomina ipinlẹ Edo, Godwin Obaseki.
Ni ọdun 2016 ni Obaseki deede yoju si gbagede oṣelu Naijiria lẹyin ti Adams Oshiomole gbe e wa lati ilu Eko nibi ti o ti n ṣiṣẹ, ti ọpọ eniyan ko si mọ ọ ni gbagede oṣelu ipinlẹ Edo.
Iroyin gbe e wi pe lasiko idibo sipo gomina ni ọdun 2016 naa ni Gomina Adams Oshiomole gbe ipolongo rẹ kari,
Nibe naa lo si ti n logun rẹ fun awọn eniyan nigba naa lati tako Pasito Osagie Ize-Iyamu to n dije dupo gomina lẹgbẹ oṣelu PDP.
Nibayii, ti ọdun mẹrin miran ti de, ọpọlọpọ nkan ti yi pada, Adams Oshiomọle ti le Obaseki kuro lẹgbẹ Oṣelu APC
Eyi waye lẹyin ti o fi lede wi pe oun naa fẹ dije dupo gomina fun saa keji lẹgbẹ oṣelu APC.
Ibaṣepọ laarin awọn mejeeji ti fori sanpọn, ti Obaseki si ti mura lati darapọ mọ ẹgbẹ oṣẹlu PDP.
Oríṣun àwòrán, Twitter/APC
Idibo aarẹ ọdun 2023
Ohun itiju lo jẹ fun Gomina ipinlẹ Eko, Akinwumi Ambode lasiko idibo sipo gomina ni ipinlẹ Eko lọdun 2019 nibi ipolongo kan.
Eyi sele nigba ti baba isalẹ rẹ, Asiwaju Bola Ahmed Tinubu na ọwọ Babajide Sanwo-Olu sọke gẹgẹ bi oludije sipo gomina ni ipinlẹ Eko lẹyin to ni ki Ambode lo rọọkun nilẹ lẹyin ọdun mẹrin to lo nipo.
Amọ, ohun ti awọn eniyan sọ ni pe, bi Tinubu ṣẹ na ọwọ rẹ soke ni idibo sipo gomina lọdun 2016 lasiko ti ko si ẹni to mọ ọ rara, ti ko tilẹ di ipo ọṣelu kankan mu tẹlẹ ki o to di igba naa.
Nigba naa, gomina to wa nibẹ, Babatunde Fashola fẹ ki kọmisọnna fun eto idajọ nipinlẹ naa, Supo Shasore dije dupo sipo gomina lasiko naa,
Amọ Tinubu kọ jalẹ pe Ambode ni yoo ṣe gomina naa pẹlu gbogbo agbara rẹ.
Ọdun 2019 ni idibo gbogboogbo naa ni Babajide Sanwo-Olu naa fi idi Ambode janlẹ ninu idibo abẹlẹ saaju idibo sipo gomina naa, amọ Ambode si wa ni ẹgbẹ oṣelu APC.
Rashidi Ladoja jẹ gomina ipinlẹ Oyo ni ọdun 2003 si ọdun 2007, ti Adedibu si ṣe agbatẹru fun Ladoja gẹgẹ bi oludije lẹgbẹ oṣelu PDP ni ọdun 2003, ti o si ran an lọwọ lati bori.
Ladọja fun ara rẹ fi idi ẹ mulẹ fun ajọ ajafẹtọ ọmọniyan, Human RIghts Watch pe Adedibu ṣe bẹbẹ lasiko idibo lati jẹ ki o bori idibo naa.
Amọ o ni bi oun ṣe wole ni o gbe igbesẹ lati gba ara rẹ lọwọ Adedibu, ti oun ko si tẹle awọn ilana rẹ mọ.
Ladọja ni oun kọ lati jẹ ki Adedibu lu owo ipinlẹ naa ni ponpo lẹyin ti Adedibu ni ki oun maa fi ida marundinlọgbọn owo Security Vote to to miliọnu marundinlogun Naira si apo oun ni oṣoosu.
Bakan naa ni Ladoja kọ lati jẹ ki Baba iṣalẹ rẹ fi orukọ silẹ fun awọn Kọmisọnna ti wọn yoo jọ ṣe ijọba.
Ninu ọrọ tirẹ, Adedibu ni alaamọrẹ ẹda ni Ladọja, ti o si saa gbogbo ipa rẹ lati jẹ ki o kuro nipo gomina nipinlẹ naa, amọ o lo saa rẹ tan, idibo miran ni ko bori ninu rẹ mọ.
Supporters of Rabiu Kwankwaso wear red hats
Gomina ipinlẹ Kano, Abdullahi Ganduje naa ti pin gaari pẹlu baba isalẹ rẹ, Rabiu Kwankwaso to ṣe agbatẹru fun un lasiko idibo sipo gomina ni ọdun 2016.
Ganduje sọ wi pe idi ti oun fi yapa kuro labẹ Kwankwaso ni pe o jẹ ẹni ti imọtara ẹni nikan n da laamu.
O fẹsun kan an wi pe nitori o jẹ baba isalẹ fun awọn, o fẹ gaba lẹ wọn lori, ki o si sakoso gbogbo nkan to n wọlẹ si ipinlẹ naa fun ara rẹ nikan.
Amọ, Kwankwanso naa lo fa ọwọ rẹ soke ni idibọ ọdun 2016.
Ọpọlọ̀pọ eniyan lo gbagbọ wi pe Godswill Akpabio ni baba isalẹ fun wọn ni ipinlẹ Akwa Ibom.
Amọ ija to de lorin di owe laarin Gomina ipinlẹ naa, Udom Gabriel ati Akpabio lẹyin to kuro ni ẹgbẹ oselu PDP lọ si ẹgbẹ oṣelu APC.
Ohun to han gbangba ni si awọn eniyan pe Udom di gomina ipinlẹ Akwa Ibom nitori ibaṣepọ rẹ pẹlu Baba isalẹ Akpabio ti o gbe le ejika lati dije dupo gomina ni ọdun 2015 to si yege.
Amọ ni bayii wọn ko foju rinju mọ lẹyin ti Udom yẹba fun Akpabio, eleyii to fa gbọnmi si omi o to laaarin wọn , ki wọn to pin gari, ti Akpabio si fi PDP silẹ lọ si APC.
Toyin Ibietan: Àlòkù táyà ọkọ̀ ló mú mi rí nǹkan ṣe lásìkò ìgbélé COVID-19
Dan Foster: Gbajúgbajà sọ̀rọ̀sọ̀rọ̀ orí rédíò Dan Foster ti dágbére fáyé
Oríṣun àwòrán, Facebook/Dan Foser
Amẹrika ni Dan Foster wà tẹ́lẹ̀ kó tó wá sí Nàìjíríà
Gbajugbaja sọrọsọrọ ori redio, Dan ti dagbere faye.
Lọsan Ọjọru ni iroyin tan ka ori ayelujara pe sọrọsọrọ naa ti papoda.
Lasiko ti a n ko iroyin yii jọ, a ko tii mọ ohun to ṣe okunfa iku rẹ.
A o maa mu ẹkunrẹrẹ wa fun yin laipẹ.
Daniel Foster ti wọn maa n pe ni Dan Foster jẹ sọrọ-sọrọ lori redio to jẹ ọmọ orilẹedẹ Amerika to n gbe ni Nijiria.
O si jẹ ẹni to maa n po orin pọ (DJ) to si jẹ olootu ẹto lorii redio.
Iwe iroyin City People ti fun ni ami ẹyẹ ri gẹgẹ bii ẹni to ṣe daadaa fun awọn ara ilu.
Dan Foster jẹ atọkun redio to dantọ tó si ṣi ọna fun ọpọ sọrọ-sọrọ lori redio ni Naijiria.
"O jẹ ọkan lara awọn ti wọn ṣe adari eto ""Idol West Africa"" nigba kan ri."
O ti ṣiṣẹ ni ileeṣẹ redio bii Hughes Radio One, Virgin Island and Mix 106.5 FM ni Naijiria àti ni oke okun.
Ni ọdun 2000 lo wa si Naijiria nigba to darapọpọ mọ Cool FM ti o si di ẹni ti ọpọ awọn ọmọ Naijiria ti wọn gbo redio gba tiẹ.
O gba ami ẹyẹ Nigeria Media Merit Awards gẹgẹ bii sọrṣo-sọrọ ori redio to dantọ ju ni ọdun 2003, 2004 ati 2005.
"Oun ni oludari ati oludasilẹ eto orin ""Cool FM Praise Jam"" ti wọn ṣe ni ọdun 2004."
Brighton vs Arsenal: Ọmọ Otedola bú sẹ́kún lẹ́yìn tí Brighton tún d'ẹrù ìyà lé Arsenal lórí
Oríṣun àwòrán, Instagram/cuppymusic
Ẹgbẹ agbabọọlu Arsenal ti ba ọpọlọpọ ololufẹ wọn ninu jẹ lẹyin ti Brighton ti ẹyin gbe ru wọn ninu idije liigi Premier League ti wọn gba lọjọ Abamẹta.
L'Ọjọru ni Arsenal kọkọ fi iya ṣide idije naa lẹyin ti Premier League bẹrẹ lẹyin isinmi ọlọjọ gbọọrọ nitori coronavirus.
Manchester City lo kọkọ ki bẹbdẹ si Arsenal ninu, ami ayo mẹta si odo ni wọn fi lu wọn bi aṣọ ofi.
Ọpọ awọn ololufẹ wọn lo ti n sọ pe o yẹ ki Arsenal le na Brighton nigba ti wọn ba pade.
Ṣugbọn ọrọ bẹyin yọ nigba ti Brighton fi pọnmọ kun pọnmọ pọnmọ ete awọn Gunners pẹlu ayo meji si ẹyọkan.
Koda aifakọyọ naa ti gbomi loju ọkan lara awọn ololufẹ Arsenal Florence Otedola ti ọpọ mọ si DJ Cuppy.
Cuppy fi sori oju opo Twitter ati Instagram rẹ pe oun ti jawee fun Arsenal lẹyin ọdun mẹfa to ti n tẹle ikọ agbabọọlu naa.
O ni oun ko tii mọ ẹgbẹ agbabọọlu tuntun ti oun yoo maa tẹ le bayii, ṣugbọn o ti tan laarin oun ati Arsenal.
Brighton vs Arsenal: Dákúdájí Arsenal tún paná pii lẹ́ẹ̀kan síi nílé Brighton
Ajẹkun iya ni ẹgbẹ agbabọọlu Arsenal tun jẹ ninu idije Premier League lẹyin ti Brighton din dodo iya fun wọn ninu ifẹsẹwọnsẹ keji ti wọn gba lati igba ti Premier League ti bẹrẹ pada.
Manchester City lo kọkọ lu Gunners ni alubami lẹyin ti wọn lu wọn pẹlu goolu mẹta eyi ti Arsenal ko si lee ta putu.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ọpọ lo ti kọkọ ro pe Arsenal yoo jẹri ara wọn lọjọ Abamẹta nigba ti wọn ba koju Brighton, ṣugbọn ọrọ bẹyin yọ ninu ere bọọlu ọhun.
Manchester city kọ lẹ́tà ìyà, Arsenal ló tẹ́wọ́ gbàá ní Etihad
Iya o to 'ya afada pakun, ikun salọ ada tun sọnu ni ọrọ jẹ fun ẹgbẹ agbabọọlu Arsenal laṣalẹ ọjọru nigba ti wọn pada sori papa ni itẹsiwaju idije liigi premiership ilẹ Gẹẹsi ti wọn so rọ fun nnkan bii ọgọrun ọjọ nitori ajakalẹ arun coronavirus lagbaye.
Ikọ Manchester city ni Arsenal koju, goolu mẹta ti ko ṣee bomi la ni wọn si fi bori Arsenal.
Esi ifẹsẹwọnsẹ yii ko jẹ iyalẹnu fun ọpọ onwoye ere bọọẹu lagbaye, paapaa idije liigi Premiership.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Amọṣa, ọrọ  agbabọọlu ọwọ ẹyin fun Arsenal, iyẹn David Luiz ni ọpọlọpọ mu bs ẹnu lẹyin ifẹsẹwọnsẹ naa.
Yatọ si pe oun lo ṣokunfa meji ninu goolu mẹta ti Manchester city fi gbẹyẹ mọ Arsenal lọwọ, oun naa ni agbabọọlu Arsenal to gba kaadi pupa eyi to tums si pe rẹfiri ni ko wabigba kuro lori papa.
Ni ipele kini ifẹsẹwọnsẹ naa ni aṣiṣe David Luiz ti kọkọ ṣakoba fun Arsena nigba to fara gbe bọọlu to yẹ ko gba danu sọwọ Raheem Sterling agbabọọlu Manchester city ti tọun si kanra gba bọọlu naa sawọn.
Ni abala keji ifẹsẹwọnsẹ naa lo tun ti fa aṣọ Riyadh Mahrez to jẹ agbabọọlu Mancity ti rẹfiri si fọn fere fun pẹnariti ti o si tun fun un ni kaadi pupa pe ko jade kuro lori papa.
Luiz kii ṣe ajeji si irufẹ awsn aṣiṣẹ epo n biyọ bayii to si ti mu ki ọpọlọpọ onwoye bọọlu o maa pe fun ori rẹ.
Pẹlu jijawe olubori yii, O tunmọ si pe  ami mẹfa lo n dabu ẹgbẹ agbabọọẹu Liverpool bayii lojuna ati gba ife ẹyẹ Premiership ti saa yii.
Toyin Ibietan: Àlòkù táyà ọkọ̀ ló mú mi rí nǹkan ṣe lásìkò ìgbélé COVID-19
Ọpọ ni wahala COVID-19 sọ di alairikanṣekan lasiko igbele ti ijọba kede lati dena ajakalẹ arun naa, ṣugbọn bẹẹ kọ lọrọ ri fun arabinrin Toyin Ibietan.
Flooding in Lagos: Ojú àwọn ará Èkó rí màbo pẹ̀lú òjò àrọ̀ọ̀rọ̀dá dá wàhálà sílẹ̀ ní Eko
Lagos: Ojú àwọn ará Èkó rí màbo pẹ̀lú òjò àrọ̀ọ̀rọ̀dá dá wàhálà sílẹ̀ ní Eko
Ko si ẹni ti kii gbadura fun ojo paapaajulọ fun itura bi oju ọjọ ba ṣe bi ẹni mooru.
Amọṣa fun awọn olugbe ipinlẹ Eko, ohun ti oju wọn ri, paapaajulọ awọn  osiṣẹ to n lọ si ẹnu iẹ oojọ wọn, kọja sisọ.
Diẹ lara bi oju ọjọ ṣe ri kaakiri ree pẹlu aworan.
World War III: Wo ohun tó yẹ kí o mọ̀ nípa awuyewuye tó ń wáyé láàárín India àti China
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ariwo World war 3 lawọn eeyan n pa bayii lori ayelujara lẹyin awuyewuye to waye laarin ilẹ India ati China lori ala ilẹ Himalayas, eyi  to ti mu ẹmi awọn eeyan kan lọ.
Awọn ohun to yẹ ki o mọ nipa iṣẹlẹ naa ree.
Ko din ni ogun lara awọn ọmọ ogun ilẹ India to jẹ Ọlọrun nipe ninu ikọlu to waye ni erekusu Galwan, ni agbegbe Ladakh.
Oríṣun àwòrán, AFP
Ṣaaju ni China ti fẹsun kan India pe awọn ọmọ ogun rẹ rekọja ala wọn nigba meji ọtọtọ, ati pe wọn tun ṣakọlu si ẹgbẹgun oun.
Bo tilẹ jẹ pe awọn mejeji ni ko si ninu ọmọ ogun wọn to yi ibọn, ilẹ India sọ pe ̣ ọwọ lasan, okuta, irin ati igi ni awọn awọn ọmọ ogun rẹ fi ja ija naa.
Lẹyin ti China sọ pe oun ti padanu lara awọn ọmọ ogun ohun ni awọn ọgagun lati orilẹ-ede meji naa pe ipade alaafia.
Oríṣun àwòrán, Press information bureau
O ti to nnkan bi ọdun diẹ sẹyin ti fa ki n fa ti n waye laarin orilẹ-ede meji ọhun nitori ilẹ kan ti awọn eeyan ki n gbe.
Ṣugbọn wahala bẹ silẹ lẹyin ti India ṣe opopona si agbegbe Ladakh, lẹba ilẹ kan naa to pin awọn mejeji ti wọn n ja si.Igbesẹ ọhun bi China ninu to bẹ ti oun naa fi lọ kọ ile kan sẹba ọna ti India ṣe, eyi to mu ki orilẹ-ede meji ọhun ko ọmọ ogun lọ sojuko naa.
Oríṣun àwòrán, AFP
Awọn orilẹ-ede mejeji sọ pe ilẹ naa ṣe pataki si wọn nipa ọrọ aje ati eto abo.
Ewu to wa ninu fa ki n fa yii ni pe  i awọn mejeji ba kọ lati pari ọrọ naa ni itubi inubi, o le da ogun silẹ lagbegbe ọhun.
Lati nnkan bi ọjọ diẹ sẹyin ni awọn ọgagun lati orile¬-ede meji naa ti n ṣepade lati yanju awọ yii, ṣugbọn igbiyanju lati pari iru awọ bayii latẹyinwa ko so eso rere.
Ọdun 1962 ni ogun ti waye gbẹyin laarin ilẹ mejeji, ṣugbọn ajẹkunniya ni India jẹ lọwọ China lọdun naa lọhun.
Major US Twitter accounts hacked: Ẹ wo bí àwọn gbájúẹ̀ ṣe ṣọṣẹ́ ní Amerika
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Awọn ọlọla lorilẹede Amerika ti lugbadi awọn gbajuẹ lori ẹrọ ikansiraẹni Twitter pẹlu imọ ẹrọ ayederu Bitcoin.
Oju opo Barack Obama, Bill Gates, Elon Musk, Jeff Bezos ati Joe Biden to fi mọ Kanye West lo lugbadi awọn gbajuẹ naa.
Oríṣun àwòrán, Twitter
Ni oju opo ikansiraẹni Gates Bill, nkan ti wọn ko si bẹ ni pe ti o ba fi $1000 sọwọ si mi, ma a fun yin pada ni $2,000.
Oríṣun àwòrán, Twitter
Oju ọpọ ikansiraẹni Apple naa ko gbẹyin ni bẹ. Ohun ti wọn ko si bẹ ni pe ki o fi owo ṣeranwọ fun Bitcoin.
Oríṣun àwòrán, Instagram
Ninu ọrọ wọn, awọn alaṣẹ oju ọpọ Twitter ni ibanujẹ ọkan lo jẹ fun awọn pẹlu bi awọn gbajuẹ ṣe gba owo lọwọ awọn eniyan.
Wọn fikun pe iwadii ti bẹrẹ lori iṣẹlẹ naa.
Awọn eeyan ti n pariwo lori ayelujara atawọn opo ikansiraẹni gbogbo lẹyin ti ileeṣẹ Twitter kede pe awọn ti gbe eroja kan dide loju opo wọn eyi to lee mu ki awọn eeyan maa ka ohun wọn lati fi ranṣẹ pẹlu akọsilẹ wọn gbogbo lori Twitter.
Gẹgẹ bi wọn ṣe sọ, awọn foonu to ni eroja iOS nikan lanfani naa ṣi silẹ fun.
Eyi si tunmọ si pe awọn to ba n lo foonu to ni eroja Android ko tii le lanfani ati loo.
Ileeṣẹ naa ṣalaye pe, idi ti wọn fi gbe sita ko yẹ lẹyin bi awọn ọrọ kan kii ṣe n duro bi awọn to kọ wọn ṣe fẹ loju opo twitter, ṣugbọn bi wọn ba fi ẹnu wọn sọ ọ yoo tubs gbe pẹẹli sii.
Bawo wa ni eroja aka ohun silẹ yii yoo ṣe maa ṣiṣẹ?
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ogoje iṣẹju nikan lo lanfani ati gba.
ṣe ẹ ranti pe nigba ti twitter kọkọ bẹrẹ, iwọnba ogoje ọrọ pere nikan lo lee gba ni atẹjade kan. O dabi ẹni pe irufẹ ara yii naa ni wọn fẹ fi bẹrẹ pẹlu eroja aka ohun silẹ naa. O ko nilo lati tẹ bọtini idaduro nitori, gẹgẹ bi ileeṣẹ twitter ṣe sọ eroja naa ni yoo funra rẹ daa duro ti yoo si tun bẹrẹ omiran lẹsẹkẹsẹ.
Ko saye ati lo o fi da eeyan lohun
Ẹ ko ni lee lo ohun ti o ba ka silẹ pẹlu eroja naa lati fi da eeyan lohun tabi taare atẹjiṣẹ eeyan kan si ẹlomiran.
O lee maa gbọ ọ bi o ba n ṣe nnkan miran.
Twitter ko fẹ ki ọrọ a n ka ohun silẹ tabi gbọ ohun ti a ka silẹ di eyi ti ko ni jẹ kawọn onibara wọn o ma lee ṣe awsn nnkan miran to ba yẹ ki wọn ṣe.
Ko si fun ikansiraẹni
Bi o ba n gbọ ohun ti a ka silẹ ohun ti yoo kọkọ wa si ọ lọkan ni oju opo ikansiraẹni Whatsapp nibi tawọn eeyan ti maa n lo ohun ti wọn ka silẹ fi ba ara wọn sọrọ.
Amọṣa ọrọ ko ni ri bẹẹ fun ti twitter yii. Ohun ti wọn fẹ ṣe ni pe oju ila itagbangba (public forum) wọn nikan ni ohun ti araalu ba ka yoo maa wa.
Burundi: Wọ́n búra fún Evariste Ndayishimiye bii Ààrẹ Burundi
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Gẹgẹ bii aarẹ to jẹ saaju rẹ, eyiun Ọgbẹni Nkurunziza, Ọgagun Ndayishimiye bori ikọlu ti wọn ṣe sawọn akẹkọọ to jẹ ẹya Hutu ninu ọgba ile ẹkọ fasiti naa, to wa ni olu ilu tẹlẹ fun orilẹ-ede Burundi, Bujumbura.
Idi ree to fi sa kuro ni orilẹ-ede naa, lọ dara pọ mọ igun ọmọ-ogun ọlọtẹ, ti wọn kan-an nipa fun lati doju ija kọ ìjọba ilẹ Burundi, ti ẹya Tutsi n lewaju rẹ.
Ọgagun Ndayishimiye ṣíṣẹ pọ timọ timọ pẹlu Ọgbẹni Nkurunziza lasiko ipade alaafia to waye nilu Arusha laarin ìjọba Burundi ati igun ọlọtẹ FDD.
Nitori abajade ipade alaafia to waye lọdun 2003 eyi to mu ki igun ọlọtẹ pin agbara pẹlu ijọba, Ọgagun Ndayishimiye de ile de olori ọmọ ogun ilẹ Burundi nigba naa.
Nigba to di ọdun 2006, wọn yan sipo Minisita fun ọrọ abẹle, ko to wa di olugbani nimọran si aarẹ ologun ati akọwe apapọ fun ijọba ẹgbẹ CNDD-FDD to n dari orilẹ-ede naa.
Toyin Ibietan: Àlòkù táyà ọkọ̀ ló mú mi rí nǹkan ṣe lásìkò ìgbélé COVID-19
Ọgagun Ndayishimiye, to bi ọmọ mẹfa, lo jẹ olujọsin gidi ninu ijọ Katoliki, gẹgẹ bii aarẹ to ṣe ijọba saaju rẹ, oun naa n tẹnumọ ojuse Ọlọrun ninu iselu.
Aarẹ tuntun yii lo n gba akoso orilẹ-ede ti awujọ agbaye ti dẹyẹ si, ti adehun rẹ pẹlu awọn to n saanu fun si buru jai.
Aarẹ to wa nipo saaju rẹ si ni wọn fi ẹsun kan pe o n dari ijọba to n tẹ ẹtọ ọmọniyan loju pupọ, to si tun n kọju oro sawọn alatako, akọroyin atawọn ajafẹtọ ẹni.
Bakan naa ni orilẹ-ede ọhun to n wọya ija pẹlu ajakalẹ arun Coronavirus, eyi ti aarẹ to jẹ saaju, foju tẹnbẹlu rẹ.
Nitori ete iditẹ gba ijọba to fori ṣanpọn lọdun 2015, ogunlọgọ awọn ọmọ orilẹede Burundi lo sa kuro nilẹ naa lọ sawọn ibudo atipo ni awọn orilẹede to mule ti wọn.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ẹni ọdun mejilelaadọta ni Evariste Ndayishimiye, aarẹ tuntun ti wọn yan ni Burundi ti ireti si wa pe wọn yoo bura wọle fun un lonii ọjọbọ ọsẹ.
Gbogbo eniyan ri i gẹgẹ bii onirẹlẹ eniyan ati olusin Ọlọrun.
O jẹ ọkan lara awọn gbajugbaja ọgagun lati ọdun 2005 nigba ti awọn ọrẹ timọ timọ ati akẹgbẹ rẹ ditẹ mọ ọ, Pierre Nkurunziza gbajọba.
Ọgagun Evariste Ndayishimiye jẹ akẹkọ imọ ofin ni ile iwe giga fasiti Burundi nigba ti ogun abẹle dide lọdun 1993 lẹyin ti wọn pa aarẹ ijọba awaarawa akọkọ ti Burundi ni, Melchior Ndadaye.
Bii ti ẹni to gba eku ida lọwọ rẹ, Pierre Nkurunziza lọdun 1995, Ọgbẹni Ndayishimiye mori bọ lọwọ iku ti wọn o ba pa a nigba ti wọn n pa awọn akẹkọ ẹya Hutu nileewe rẹ ni olu ilu orilẹede naa, Bujumbura.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Nigba naa lo sa kuro lorilẹede to si dara pọ mọ ikọ awọn olugbẹsan lati koju ija si ijọba ti ẹya Tutsi n dari nigba naa.
"Ọgbẹni Ndayishimiye gbaruku ti Pierre Nkurunziza o si ba a ṣiṣẹ papọ lasiko akanṣe ijiroro fun alafia ti wọn pe ni ""Arusha peace talks"" laarin ijọba atawọn FDD rebels."
Fun apẹrẹ, lọdun 1993 nigba ti FDD rebels pin agbara pẹlu ijọba Ọgbẹni Ndayishimiye ṣe igbakeji ọga awọn ọmọ ogun Burundi nigba naa, akẹgbẹ rẹ, Nkurunziza to jẹ minisita ọrọ abẹle.
Diẹ lasan ni apẹrẹ eleyii ninu ọpọlọpọ ajọṣepọ ti wọn ṣe.
Badagry Historical Wells: Omi inú kànga Wawú ló ń kó ọpọlọ àwọn ẹrú lọ
"Ọgbẹni Ndayishimiye jẹ baba ọlọmọ marun o si jẹ ọmọ ijọ katoliki tọkan tọkan to tun tẹle ọgbọn amulo ẹni to gbesẹ le e lọwọ nipa ""titẹnumọ ohun tii ṣe ti Ọlọrun"" ninu oṣelu."
Aarẹ tuntun yii n gbajọba orilẹede ti wọn fi ẹsun kan ẹni to gbaṣẹ lọwọ ẹ pe ijọba to dari tapa si ofin ẹtọ ọmọniyan ati ainaani ẹgbẹ alatako, awọn oniroyin atawọn ajafẹtọ.
Bakan naa, orilẹede yii n koju Coronavirus eyi ti aṣaju rẹ foju kere.
Latari ifipagbajọba eyi to kuna lọdun 2015, ẹgbẹgbẹrun ara Burundi lo ti sa kuro niluu lati lọ ṣatipo lawọn orilẹede ẹgbẹ wọn.
Ẹwẹ, aarẹ tuntun yoo ni lati bẹrẹ ijọba tirẹ lakọtun ni ti yoo si ṣẹṣẹ tun ṣagbejade ilana adari tuntun ni Burundi.
Abiola Ajimobi: Iku Ajimọbi jẹ́ ǹkan ìjayà nítori kò só sí ẹnìkan tó ń reti irúẹ̀ lásìkò yii
Abiola Ajimobi: Àwọn aṣòfin Naijiria ṣọ̀rọ̀ ìwúrí nípa Ajimobi
"Ṣẹnetọ to ṣoju aringbungbun Ọyọ, ""Oyo Central Senatorial District"", Teslim Folarin lo ko awọn akẹgbẹ rẹ marun un mii ṣodi lati lọ ba wọn kẹdun nile gomina tẹlẹri nipinlẹ Ọyọ, Ṣẹnetọ Abiọla Ajimọbi to di oloogbe.Ni ọsan ọjọ Abamẹta ni awọn aṣofin naa abẹwo si ile Ajimọbi to n bẹ ni agbegbe Oluyọle niluu Ibadan.Lara awọn aṣofin naa ni Sẹnetọ Abdulfatai Buhari to n ṣoju ẹkun ariwa ipinlẹ Ọyọ,"
Oríṣun àwòrán, @Ajimobiinstagram
Oyo North senatorial district nile igbimọ aṣofin agba, Họnọrebu Shina Abiola Peller, Họnọrebu Akeem Adeniyi Adeyemi ati Otunba Akin Alabi.
Wọn ti ọwọ bọ iwe lati ṣe idagbere ikẹyin fun goimina Ọyọ tẹlẹri bẹẹ sini wọn ba awọn ẹbi rẹ kẹdun.Ninu ọrọ ti o ba awọn oniroyin sọ nile oloogbe, Sẹnetọ Tẹslim Fọlarin ṣe alaye iku Ajimọbi je nnkan ijaya nitori ko si ẹnikan ti o ni ireti pe iru ẹni to o da pe bẹẹ le dede jade laye, ṣugbọn o fi ọpẹ fun Ọlọrun fun igbe aye rere ti oloogbe gbe.
Oríṣun àwòrán, Instagram/ abiola ajimobi
O ṣe apejuwe Ajimọbi gẹgẹ bi ẹnikan ti o da yatọ laarin awọn akẹgbẹ rẹ ti o si ni igboya. Fọlarin tẹsiwaju wi pe yoo nira lati di alafo ni iku Ajimọbi ṣi silẹ ninu ẹgbẹ oṣelu APC l'apapọ.Ninu ọrọ tiẹ, Sẹnetọ Abdulfatai Buhari ni gbogbo nnkan patapata ni Ọlọrun fun oloogbe, Ṣẹnetọ Abiọla Ajimọbi ni igbesi aye rẹ.O ni ko si ẹni ti ko ni aleebu tiẹ lara, ṣugbọn daadaa Ajimọbi tayọ ohun ti awọn eeyan le maa wo lara rẹ gẹgẹ bii aleebu.
Oríṣun àwòrán, Ajimobi
"O tẹsiwaju wi pe, "" Emi ṣiṣẹ labẹ wọn gẹgẹ bii Kọmisana n'igba ti wọn ṣe ni ti alakọkọ. A dupẹ fun Ọlọrun loriii awọn nnkan pupọ ti Ọlọrun loo fun oun naa ni awa naa n jẹ loni.Ki Ọlọrun Ọba alaanu ki o ba wa ṣe iku ni isinmi fun un.""Họnọrebu Shina peller, Họnọrebu Akeem Adeniyi Adeyemi ati Alhaji Kunle Sanni ti o jẹ alaga awujọ awọn Musulumi ni fasiti ilẹ Ibadan naa ko gbẹyin ninu ipejọpọ awọn abanikẹdun ti o fi irobinujẹ wọn han lorii ipapoda gomina tẹlẹri nipinlẹ Ọyọ, Ishaq Abiọla Ajimọbi.Awọn ṣoju ijọba, oloṣelu ati lẹgbẹlẹgbẹ naa pẹlu awọn fi o fi ara han lati t'ọwọ bọ iwe idagbere ikẹhin fun oloogbe."
Abiola Ajimobi: Gómìnà kòṣẹlẹ̀rí àkọ́kọ́ tó fi ọba 21 jẹ lọ́jọ́ kan ṣoṣo nílẹ̀ Ibadan
Oríṣun àwòrán, Instagram/ abiola ajimobi
Abiola Ajimobi, Gómìnà tí ọ̀rọ̀ kìí kú mọ lára, à fi kó fèsì
Iku pa Abírí, Abírí ku, iku pa Abìrì, Abìrì rọrun, iku pa akọ̀kọ́, omi akọ̀kọ́ danu, ko si ẹni ti ko ni ku, ko si ẹni ti oko baba rẹ ko ni di igboro.
Bẹẹ ni ọrọ ri pẹlu adele alaga ẹgbẹ oselu APC, tii tun ṣe gomina ana nipinlẹ Oyo, Ṣẹnetọ Isiaka Abiola Akanji Ajimobi to dagbere faye lasiko aisan ranpẹ.
Ajimobi, ẹni tii ṣe onimọ nipa oko-owo epo rọbi ati oloselu to dantọ ṣe gudu gudu meje ati ya ya mẹfa nigba aye rẹ,
Idi si ree ti BBC fi ṣe akojọpọ igbe aye agba oselu naa ati awọn ohun ribiribi to gbe ile aye ṣe.
Oríṣun àwòrán, Instagram/ajimobi
Ọjọ nla ni ọjọ kẹrindinlogun, oṣu Kejila, ọdun 1949 ti alagba Ganiyu Ajimobi ati aya rẹ, Sikiratu Abeje bi Isiaka Abiola Akanji sile aye.
Agboole Ajimobi ni adugbo Ọja Ọba nilu Ibadan, tii ṣe olu ilu ipinlẹ Oyo, ni Abiola ti jade wá.
O lọ sile ẹkọ alakọbẹrẹ Patrick Mimọ ladugbo Oke Paadi nilu Ibadan amọ O pari ẹkọ alakọbẹrẹ rẹ ni ile ẹkọ Ibadan City Council, ICC Orita Aperin nilu Ibadan.
APC: òfin NYSC ti APC fi mú mi ni wọ́n kò lò fi mú Ajimọbi tí a kò jọ sìnrú ìlú
Bakan naa ni Abiola morile ile ẹkọ girama Lagelu ladugbo Agugu nilu Ibadan feto ẹkọ oniwe mẹwa rẹ, to si gbajumọ bii isana ẹlẹẹta ninu ere idaraya,
Idije bọọlu ẹlẹyin ori tabili, bọọlu afẹsẹgba, to si jẹ adari akẹkọọ feto ere idaraya.
Ẹkọ iwe lo tun sọ Abiola silẹ Amẹrika, to si lọ gba oye imọ ijinlẹ nipa akoso okoowo nile ẹkọ fasiti New York to wa ni Buffalo, níbi to ti gba oye imọ ijinlẹ ninu imọ sayẹnsi.
Abiola ko duro lori eyi, o tun tẹsiwaju lati gba oye imọ ijinlẹ keji ninu iṣẹ iwadii ati kata-kara ni Governors state University to wa ni University Park, Illinois nilẹ Amẹrika.
Oríṣun àwòrán, Instagram/abiola ajimobi
Yoruba ni ajo ko dabi ile nitori ile labọ sinmi oko, idi ree ti Abiola Ajimobi fi pada wa sile, to si ri iṣẹ pẹlu Ileesẹ elepo rọbi kan National Oil eyi to wa labẹ Ileesẹ elepo rọbi Shell,
Nibẹ, to si sun kẹrẹ-kẹrẹ de ipo oludari agba fun Ileesẹ naa.
Lẹyin to sin Ileesẹ National Oil fun ọdun mẹrindinlọgbọn gbako, Abiola fẹyinti nileesẹ naa, to si dara pọ mọ eto iselu to wa ninu ẹjẹ rẹ nitori ile lo ba a.
Oríṣun àwòrán, Instagram/Abiola Ajimobi
Baba Abiola, Ganiyu jẹ oloselu to gbajugbaja, to si dibo wọle sile asofin ẹkun ìwọ oorun Naijiria ijọhun laye saa isejọba alagbada kinni,
Ti aburo baba rẹ naa si jẹ Minisita fun isẹ ode ati igbokegbodo ọkọ nigba naa.
Lọdun 2003 ni Abiola dibo sile asofin agba labẹ ẹgbẹ oselu Alliance for Democracy AD, to si wọle lati soju ẹkun idibo guusu ipinlẹ Oyo, to si ṣe ọdun mẹrin gbako nibẹ.
Lẹyin naa lo tun gbinyanju lati du ipo gomina ipinlẹ Oyo lọdun 2007 labẹ ẹgbẹ oselu ANPP, amọ, to fidi rẹmi,
Ṣugbọn wọn ni ẹṣin kii da ni, ka ma tun un gun, Abiola tun gbinyanju lẹẹkan si lati du ipo gomina losu kẹrin, ọdun 2011, to si yege.
Oríṣun àwòrán, Instagram/abiola ajimobi
O fi ẹyin gomina to wa lori aleefa nigba naa, Otunba Christopher Adebayo Alao Akala janlẹ lati gbegba oroke, to si fi ibo perete moke ninu ibo naa.
Yoruba ni aidun ọsan la a mu mejila, bi ọsan ba dun, eeyan yoo mu igba.
Eyi lo mu Abiola du ipo gomina ni  ẹẹkan si fun saa keji, to si tun wọle pada bii gomina ipinlẹ Oyo, eyi ti ko sẹlẹ rí ninu itan oselu ipinlẹ naa.
Idi si ree ti ọpọlọpọ eeyan fi n pe e ni Gomina Kosẹlẹri nitori oun ni ẹni akọkọ ti yoo wọle fun ipo gomina ni saa keji ninu itan oselu ipinlẹ Oyo, nitori saa kan pere ni awọn gomina to wa niwaju rẹ ṣe.
Oríṣun àwòrán, Instagram/ Ajimobi
Lasiko ti Abiola Ajimobi wa lori aleefa bii gomina nipinlẹ Oyo fun odindi ọdun mẹjọ gbako, ọpọ aseyọri ati iṣẹ ribiribi lo ṣe lori aleefa,
Eyi je ki  aimọye iṣẹlẹ Kosẹlẹri ni rere si waye nipinlẹ Oyo ni saa isejọba ọlọdun mẹjọ rẹ.
Lara awọn aseyọri rẹ bii gomina ni lila ọpọlọpọ opopona tuntun ati atunse awọn oju popo ti ko dara jakejado ipinlẹ Oyo eyi to to igba,
Ladoja
Atunse ati bibu ẹwa kun ayika ipinlẹ Oyo,
Kíkọ afara abẹyẹfo to wa ni Mokola nilu Ibadan, gbigba awọn ọdọ ti ko niṣẹ lọwọ bii osisẹ Yes-O, rira ọkọ pẹlu kẹkẹ Ajumọse ati bẹẹ bẹẹ lọ.
Lara awọn aseyọri Kosẹlẹri ti Ajimobi ṣe lori aleefa, ni agbekalẹ ofin atunto oye jíjẹ nilẹ Ibadan, to si fi ọba mọkanlelogun jẹ nilẹ Ibadan ni ọjọ kan ṣoṣo,
Eyi ti okiki rẹ gbalẹ kan, ti awuyewuye igbesẹ rẹ yii ko si jẹ ki ilana oye jijẹ nilẹ ni ojutu titi di oni yii.
Oríṣun àwòrán, Instagram/abiola ajimobi
Ajimobi maa n fi ọwọ sọya ni ọpọlọpọ igba pe oun ni Gomina to tii ṣe aseyọri julọ ninu itan ipinlẹ Oyo,
Ati pe oun tun ni gomina ti alaafia to peye ati eto aabo to pegede si jọba nipinlẹ Oyo lasiko isejọba rẹ.
Awọn Awada Ajimobi n kọ?
Ṣugbọn bo ti ṣe aseyọri to lori aleefa, Ajimobi jẹ alawada ọkùnrin, to si maa n fi awada agbekalẹ awọn ọrọ rẹ, eyi ti ọpọlọpọ eeyan maa n si i gbọ, ti  ọrọ rẹ si maa n bọ sapo ibinu wọn.
Fun apẹẹrẹ, Ajimobi gba alejo awọn akẹkọọ fasiti imọ ẹrọ Ladoke Akintola nilu Ogbomoso, ti wọn wa fi ẹhonu han lọgba Secretariat,
"Asiko yii si lo koro oju si akẹkọọ kan lori bo ṣe sọrọ si bii gomina lọna tí ko yẹ, Ajimobi wa beere pe ""Ṣe Aláṣẹ ti ofin gbe kalẹ (Constituted Authority) lo n sọrọ si baun""?"
"Gbolohun naa fa awuyewuye ati ariwisi laarin ilu, ọpọlọpọ eeyan fara, ti wọn si n pe gomina Ajimobi ni ""Mr Constituted Authority"" lati igba naa."
Oríṣun àwòrán, Instagram/abiola ajimobi
Ọpọ eeyan si lo n ṣe apejuwe oloogbe naa bii ẹni ti ọrọ kii ku mọ lara nigba aye rẹ,
"Nitori gbogbo ọrọ lo ni esi lọdọ Abiola Ajimobi, to si maa n sọ pe ""ọmọ Ibadan ni mi, mo si mọ esi ọrọ""."
Ninu idibo ọdun 2019, ti saa keji isejọba Abiola Ajimobi n tẹnu bọ odo lọ, o tun gbinyanju lati dije fun ipo Ṣẹnetọ sile asofin agba,
Amọ ṣe lo fidi rẹmi ninu idije naa, ti Ṣẹnetọ Kola Balogun si jawe olubori.
Lẹyin ti Ajimobi kuro ni ipo gomina, ni ẹgbẹ oselu rẹ, APC tun yan an sipo igbakeji alaga apapọ ẹgbẹ fun ẹkun ìwọ oorun Naijiria,
Ninu eyi to si tun di adele alaga fẹgbẹ oselu naa ni ọjọ kẹrindinlogun oṣu kẹfa ọdun 2020.
Oríṣun àwòrán, Instagram/ajimobi
Amọ o ṣeni laanu pe asiko yii ni agba oselu naa ti wa lori aisan, ti ẹnu si n kun un pe arun Coronavirus lo n ba a finra, bẹẹ ni ko lo ipo naa fun ọjọ kan ṣoṣo, ko to pa ipo da.
Nigba to si jẹ pe aisan lo ṣe e wo, a ri ti ọlọjọ ṣe, Isiaka Abiola Akanji Ajimobi mi kanlẹ nile iwosan kan nilu Eko ni Ọjọbọ, ọjọ Kẹẹdọgbọn, oṣu kẹfa, ọdun 2020, to si ki aye pe o digbose.
Abiola fi aya rẹ, Oloye Florence Ajimobi ati ọmọ marun-un silẹ saye lọ.
Oríṣun àwòrán, Ajimobi
Lara wọn ni Idris Ajimobi, to fẹ ọmọbinrin Gomina Abdullahi Ganduje tipinlẹ Kano ni aya pẹlu Abisola to fẹ ọmọ Oloye Kola Daisi, tii ṣe gbajugbaja olokoowo ni ọkọ.
Bi onirese Abiola Ajimobi ko tiẹ fin igba mọ amọ eyi to ti fin silẹ ko le e parun, ti BBC Yoruba si n gbadura pe, ki Ọba oke tẹ agba oselu ati ojulowo ọmọ bibi ilẹ Ibadan naa si afẹfẹ rere.
Oríṣun àwòrán, Ajimobi
Ajimobi Burial: Ẹbí Abiola Ajimobi kéde bí ètò ìsìnkú rẹ̀ yóò ṣe rí pé...
Oríṣun àwòrán, Abiola Ajimobi
Abiola Ajimobi Central Mosque ni Oke Ado ni ilu Ibadan ni ipinlẹ Oyo ni ile ijọsin kẹyin ti ara Abiola Ajimobi yoo wọ gbẹyin.
Ogbẹni Bolaji Tunji to jẹ oluranlọwọ pataki fun oloogbe Ajimọbi lori eto iroyin nigba aye rẹ lo ṣalaye bi eto isinku naa yoo ṣe waye lorukọ mọlẹbi Ajimọbi.
O ni lẹyin ifikunlukun pẹlu ijọba ipinlẹ Eko ati ti ipinlẹ Oyo lori ọna lati sin oloogbe Ajimọbi bi o ti tọ ati bi o ti yẹ ni wọn fẹnuko lori ọna ti wọn fẹ gba yii.
Aago mejila ọsan ọjọ Aiku, ọjọ kejidinlọgbọn, oṣu kẹfa, ọdun 2020 ni eto isinku Sẹnetọ Abiola Ajimobi yoo waye.
Wọn yoo ṣeto ilana isinku naa pẹlu ilakalẹ to yẹ pẹlu bi gbogbo agbaye ṣe n koju ajakalẹ arun Coronavirus ni.
Ọgbẹni Bolaji tun ṣalaye pe ilana ẹsin Islam ni wọn yoo fi sin Ajimọbi ti wọn yoo si ki irun ikẹyin sii lara ni Mọṣalaṣi rẹ ni Oke Ado.
Bakn naa lo tun ni eto akanṣe miran fun ẹyẹ ikẹyin fun oloogbe Ajimọbi yoo waye lọjọ miran laipẹ.
Ajimobi kìí bá ọ̀lẹ, olè àti ọlọ́pọlọ kúkú ṣe ọ̀rẹ́ - Alaafin
Alaafin Oyo wa kan saara si awọn isẹ ati ipasẹ rere ti Ajimobi fi lelẹ, eyi to ni ko ni parẹ laelae.
Abiola Ajimobi: Ọba Adeyemi daro ikú gómìnà àná ní Oyo
Alaafin Oyo, Ọba Lamidi Olayiwola Adeyemi Kẹta ti kẹdun lori iku Gomina ana nipinlẹ Oyo, Abiola Ajimobi.
Oríṣun àwòrán, Abiola Ajimobi
Ninu ọrọ ibanikẹdun ti agbẹnusọ fun Alaafin, Bode Durojaiye fi sita, Iku Baba Yeye sapejuwe Ajimobi gẹgẹ bi oloselu to ma n mu ileri to ba se fun araalu sẹ lasiko ipolongo ibo rẹ.
Oba Adeyemi fi kun ọrọ pe,  Ajimobi jẹ ọlọkan akin ati olori daada ti kii bẹru lati gbe igbesẹ akinkanju, to si setan lati koju ohunkohun to ba tẹyin igbesẹ naa yọ.
Oríṣun àwòrán, Abiola Ajimobi
Alaafin sọ pe '' Ajimobi mu ipo ogun laarin awọn Gomina ti mo ti ba sisẹ papọ nipinlẹ Oyo.
Mo si ba sisẹ papọ gẹgẹ bi Gomina ati bii baba si ọmọ. To ba jẹ eeyan ti ọpọlọ rẹ pe, ti o jẹ olootọ, ti ẹni naa ko si ya ọlẹ, yoo ba Ajimobi sisẹ pọ.''
Ọba Adeyemi ni  ''Ijọba Ajimobi jẹ tolori tẹlẹmu sugbọn eeyan ko le ri nkan gba lọwọ ijọba rẹ bi ko ba dara pọ mọ afojusun eto atunto, imupadabọsipo ati gbigbe Oyo si ipo to ga, to ni lọkan''
Alaafin Oyo wa kan saara si awọn isẹ ati ipasẹ rere ti Ajimobi fi lelẹ, eyi to ni ko ni parẹ laelae.
Oríṣun àwòrán, Abiola Ajimobi
Ọba Adeyemi wa ba Gomina Seyi Makinde ati ara ilu kẹdun iku Ajimobi, to si sadura pe ki Eledua dẹlẹ fun ẹni rere to lọ.
Lati igba ti wọn ti kede iku Sẹnẹtọ Abiola Ajimọbi lọjọbọ, ni awọn tolori tẹlẹmu ti n sọ ọrọ nipa iku rẹ.
Sẹnẹtọ Ajimọbi dagbere faye lẹni aadọrin ọdun nilu Eko l‘Ọjọbọ.
Saaju la ti kọkọ mu iroyin wa fun yin pe ijọba ipinlẹ Eko ti kede pe arun Coronavirus lo mu ẹmi gomina ana nipinlẹ Oyo, Abiola Ajimobi lọ.
Oríṣun àwòrán, Abiola Ajimobi
Ikede yii lo si jẹ igba akọkọ ti ijọba yoo fi idi rẹ mulẹ pe oloogbe naa ni arun Covid-19, bi o tilẹ jẹ pe ẹnu ti n kun tẹlẹ.
Kọmisana fun eto ilera nipinlẹ Eko, Ọjọgbọn Akin Abayomi lo sisọ loju ọrọ naa ninu atẹjade kan  to fi sita.
Bakan naa lo kede pe ile iwosan First Cardiologist Consultant, to jẹ ileewosan aladani tijọba fọwọsi lati maa tọju arun Covid-19, ni Ajimobi dakẹ si nibi to ti n gba itọju.
"Abayomi tun fikun pe ""Gomina tẹlẹ ri ọhun ni ọpọlọpọ ẹya ara rẹ ti daṣẹ silẹ, nitori oró aarun Covid-19."
Bẹẹ ba gbagbe, ọpọ igba ni ẹnu kun Ajimobi tẹlẹ pe o ni arun Coronavirus amọ  ti amugbalẹgbẹ rẹ, Tunji Bolaji n sẹ pe irọ ni ọrọ naa.
Iroyin to n tẹ wa lọwọ bayii ti fihan pe eto isinku oloogbe Sẹnatọ Abiola Ajimobi to yẹ ko waye loni ni wọn ti sun siwaju.
Ọla ọjọ Satide, ọjọ Kẹtadinlọgbọn osu Kẹfa ọdun 2020 ni eto isinku naa yoo waye .
Oríṣun àwòrán, Abiola Ajimobi
Gẹgẹ bi mọlẹbi oloogbe Ajimobi kan to kọ lati darukọ rẹ ti fi to wa leti, wọn sun eto isinku naa siwaju nitori ki aaye lee wa fun ipalẹmọ isinku naa.
Bakan naa la tun gbọ pe, awọn ikọ to n se amojuto arun Coronavirus ni yoo gbe oku Ajimobi wa lati ilu Eko, lati wa sin.
Iroyin naa tun fikun pe iyawo ati awọn ọmọ oloogbe Ajimobi si wa pẹlu oku rẹ nilu Eko, ọjọ Satide si ni wọn yoo dijọ maa bọ wa silu Ibadan.
Oríṣun àwòrán, Abiola Ajimobi
Akọroyin wa to lọ si mọsalasi Ansarudeen to yẹ ki eto isinku naa ti waye lonii tẹlẹ jabọ pe se ni ibẹ da paro paro.
O fikun pe ni aago mẹjọ si mẹsan owurọ oni to de ibẹ, ko si ẹnikẹni to yọju lati se ipalẹmọ fun eto isinku naa.
A o ranti pe Sẹnatọ Abiola Ajimobi dagbere faye ni ọsan Ọjọbọ nile iwosan kan nilu Eko lasiko to n se aisan ti wọn lo nii se pẹlu Coronavirus.
Bi ọdẹ ba ku, ọdẹ ni soro lẹyin ọdẹ, bẹẹ si ni ba ba ku laa dere, eeyan ko sunwọn laaye.
Bẹẹ ni ọrọ ri pẹlu iku gomina ana nipinlẹ Oyo, Sẹnatọ Abiola Ajimobi to dagbere faye lọjọru.
Oríṣun àwòrán, Abiola Ajimobi
Pọ eeyan ni ara ta pe akikanju ọmọ ibadan naa ti dara ilẹ, ti onikaluku si n sọ ohun to mọ nipa rẹ.
BBC Yoruba kan si gomina tẹlẹ nipinlẹ Oyo, Otunba Adebayo Alao Akala lati mọ bi iku Ajimọbi se ri lara rẹ.
Oríṣun àwòrán, Abiola Ajimobi
Akala, ẹni ti ohun rẹ rẹwẹsi lasiko to n ba wa sọrọ ni ohun ko tii le sọ ohunkohun nipa oloogbe naa.
Iku rẹ ba mi lojiji, jinni-jinni n mu mi lọwọ lori iku Ajimobi, n ko le sọ ohunkohun.
Bakan naa, nigba ta kan si gbajugbaja olorin ẹmi kan nilu Ibadan, Yinka Ayefele, oun naa ni jinni jinni iku Ajimobi si wa lara oun, oun ko si tii setan lati sọrọ.
Oríṣun àwòrán, Abiola Ajimobi
Amọ nigba to n ba BBC Yoruba sọrọ, agba oye kan nilẹ Ibadan, ti oun ati Ajimobi dijọ se ọmọde, Lekan Alabi ni iku oloogbe naa dun oun pupọ.
Oloye Alabi fikun pe ipa ribiribi ni oloogbe Ajimobi ko si idagbasoke ilu Ibadan ati ipinlẹ Oyo lapapọ.
Oríṣun àwòrán, Yinka Ayefele
"Ọdun mẹjọ ti Abiola Ajimobi lo gẹgẹ bii gomina nipinlẹ Oyo lo fi tun ilu se.
O fọ ilu Ibadan to kun fun ẹgbin mọ, Ajimobi fẹ ọpọ́ awọn oju popo to wa nipinlẹ Oyo loju, to si tun kọ afara abẹyẹfo silu Ibadan."
Oloye Alabi tẹsiwaju pe ibatan oun ni Ajimọbi, bẹẹ si ni lati kekere lo ti n fihan pe oun yoo de ibi giga nile aye.
"Ajimọbi ja fafa ninu iwe lati ewe, o jẹ ẹni to nimọ toto, o gbafẹ, to si ni iwa asaaju rere lati igba ta ti wa ni kekere, osu mẹwaa si lo fi ju mi lọ.
Oloye Lekan Alabi wa gbadura pe ki Ọlọrun tẹ akikanju ọmọ Ibadan naa si afẹfẹ rere.
Saaju la ti mu iroyin wa fun yin pe ọjọ Ẹti, ọjọ kẹrinlọgbọn oṣu kẹfa ọdun 2020 ni Gomina ipinlẹ Oyo tẹlẹ, Abiola Ajimobi yoo wọ kaa ilẹ lọ.
L'Ọjọbọ ọjọ kẹẹdọgbọn oṣu kẹfa ni Ajimọbi jade laye lẹni aadọrin ọdun.
Ile iwosan First Cardiology to wa ni Ikoyi niluu Eko ni Ajimobi dakẹ si lẹyin ti o ti n gba itọju nile iwosan.
Nigba ti BBC Yoruba se abẹwo sile oloogbe naa nirọlẹ Ọjọbọ, awọn abanikẹdun ti kora jọpọ sibẹ lati daro ẹni rere to lọ.
Bẹẹ si ni igbe ẹkun ti sọ kikan kikan ni ile Ajimobi to n bẹ ni agbegbe 6th Avenue, Yemoja street, Oluyole Estate nilu Ibadan.
Awọn aṣoju ijọba tẹlẹri, alabaṣiṣẹpọ ati aladugbo ko gbẹyin lara awọn to karibọnu nile Ajimọbi bayii.
Saaju la ti mu iroyin wa fun yin pe ibẹrẹ ọṣẹ yii ni iroyin kan jade pe ayẹwo ti fihan pe Ajimobi ko ni aarun coronavirus.
Ẹwẹ, ẹbi Ajimobi ti sọ pe aago mẹwaa ọjọ Ẹti leto isinku Ajimobi yoo waye ni ilana ẹsin musulumi.
Oríṣun àwòrán, Facebook/Abiola Ajimobi
Abiola Ajimobi jáde láyé!
Lọwọlọwọ, iroyin ti a gbọ ni wi pe, gomina ana ni ipinlẹ Oyo, to tun ti jẹ sẹnetọ tẹlẹ nile igbimọ aṣofin agba Naijiria, Sẹnetọ Isiaka Abiola Ajimobi ti dagbere f'aye.
Ṣaaju iṣẹlẹ yii, ohun ta a mọ ni wi pe iroyin n tan kaakiri pe o n ṣaisan nitori pe o ti lugbadi ajakalẹ arun COVID-19.
Awọn iroyin mii tilẹ sọ wi pe, aisan inu ọkan lo n da a laamu nigba ti awọn kan tun ni itọ ṣuga.
Abiola Ajimobi ni gomina ipinlẹ Oyo laarin ọdun 2011 si ọdun 2019, ko to wa du ipo sẹnetọ lati ṣoju ipinlẹ Oyo nile aṣofin agba lọdun 2019 ṣugbọn ko wọle.
Ṣaaju ko to du ipo gomina to ṣẹṣẹ ṣe saa rẹ tan lọdun 2019, o ti ṣe sẹnetọ fun saa kan laarin ọdun 2004 si 2007.
Ẹni aadọrin ọdun ni sẹnetọ Ajimọbi ko to jade laye.
FRSC thunder strike: Lẹ́yìn ìwádìí ìkú àrà tó sán pa òṣìṣẹ́ FRSC mẹ́ta lọ̀rọ̀ ètùtù kò ṣe ètùtù tó lè wáyé
Oríṣun àwòrán, others
Ajọ to n risi eto irinna oju popo, FRSC ti ni awon ko lee fi idi ẹ mulẹ pe ara lo san pa oṣiṣẹ ajo FRSC mẹta to ku ni ipinlẹ Ogun.
Adari Ajọ FRSC nipinlẹ naa, Ahmed Umar lo sọ bẹ fun BBC lati mọ iru iku to pa awọn oṣiṣẹ naa.
Umar ni oun ti ajọ naa mọ ni wi pe ina lo sokunfa rẹ, bọya ina dede gbe wọn ni tabi ara lo san pa wọn, ati wi pe nitori naa ni awọn ṣe bẹrẹ iwadii lori rẹ.
Amọ, O fikun wi pe ti iwadii ba fidi ẹ mulẹ pe lootọ ara lo san pa wọn, oun ko le e ṣe ẹbo tabi ṣe etutu nitori ẹlẹsin Musulumi ni oun, oun ko si gbagbọ ninu rẹ.
Adari Ajọ FRSC nipinlẹ naa, Ahmed Umar wa fikun pe awọn yoo fi eri iwadii awọn lede lẹyin ti wọn ba ti pari iwadii wọn tan.
Oríṣun àwòrán, Twitter/FRSC Twitter
Ikilọ ni iṣẹlẹ ara to san pa awon ẹṣọ alaabo oju-popo (Federal Road Safety Corps) meta, ti opo si farapa nipinlẹ Ogun.
Ẹlẹsin ibilẹ, Yemi Elebuibọn lo sọ bẹẹ nigba to ba BBC Yoruba sọrọ lori iṣẹlẹ ọhun.
Itele-Ijebu ni Old-gate ni iṣẹlẹ naa ti ṣẹlẹ ni Ọjọru.
A gbọ wi pe bi ara yii ṣe san lo pa awon ẹṣọ meta naa loju ẹsẹ, to si jan awọn mii mọlẹ, ti gbogbo agbegbe naa si di erujeje.
Iroyin to tẹ wa lọwọ tun sọ pe awon oniṣango lọ ṣe etutu to yẹ ko to di pe wọn gbe oku wọn fun ijọba.
Amọ, baba Elubuibọn ni iṣẹ kan kii ṣẹ lasan, ti ko ba si nidi obinrin kii jẹ ikumolu.
Oríṣun àwòrán, Twitter/FRSC Nigeria
Baba Ṣango kii ṣadeedee payan bayẹn ti ko ba jẹ wi pe awọn eeyan naa ti jale tabi ṣe nnkan aitọ kan.
Baba Elebuubọn ni o yẹ ki wọn ṣe etutu lati dena ajalu miiran papaa julọ awọn alabaṣiṣẹ pọ awọn to ku.
Abiola Ajimobi: Àwòrán rèé nípa ìgbé ayé Abiola Ajimobi
Eniyan ti itan igbesi aye rẹ tan kalẹ gẹgẹ bi atapata dide ni Abiola Ajimobi jẹ.
Oríṣun àwòrán, twitter/Ajimobi
Abiola Ajimobi ninu aṣọ ibilẹ nibi eto kan ni ilu Ibadan
Oríṣun àwòrán, Twitter/abiola ajimobi
Sẹnetọ Ajimọbi lasiko to n sọrọ lori koko kan to kaa lara nigba to ṣi jẹ Gomina ipinlẹ Oyo
Oríṣun àwòrán, Twitter/abiola ajimobi
Abiola Ajimobi ati Florence aya rẹ ti ọpọ maa n sọ pe Ajimọbi kii ko iyan rẹ kere ni yii lasiko ipolongo fun ẹgbẹ oṣelu onigbalẹ APC
Oríṣun àwòrán, Twitter/ajimobi
Oloye Ajimobi n jo lọjọ ajọdun aṣa ni ipinlẹ Oyo
Oríṣun àwòrán, Twitter/abiola ajimobi
Ajimobi pelu Aarẹ Muhammadu Buhari to n tukọ Naijiria labẹ ẹgbẹ oṣelu APC
Oríṣun àwòrán, Twitter/ajimobi
Ajimobi pelu gomina ipinlẹ Ekiti tẹlẹ, Ayọdele Fayose, ọrẹ ṣiṣe ko kan iyatọ ninu ẹgbẹ oṣelu ti koowa wa!
Oríṣun àwòrán, Twitter/ajimobi
Ajimobi pelu Emir tilu Kano tẹlẹ, Sanusi Lamido Sanusi lasiko ti wọn jọ n fi ọrọ jomitooro ọrọ
Oríṣun àwòrán, Twitter/ajimobi
Kò ṣẹlẹ rí nilẹ Ibadan, Ajimọbi pẹlu awọn agba oye ilẹ Ibadan to gbe soke di Ọba lọjọ kan ṣoṣo
Oríṣun àwòrán, Twitter/ajimobi
Ajimobi pelu Alaafin Oyo, iku baba yeye Adeyemi kẹta lasiko ti Ajimọbi fi n tukọ ipinlẹ Oyo gẹgẹ bii gomina
Oríṣun àwòrán, twitter/Ajimobi
Ọrẹ la o maa ṣe! Sẹnetọ Ajimobi pẹlu gomina tẹlẹ nipinlẹ Oyo, Alao Akala lasiko ti wọn jọ n ṣe awada
Oríṣun àwòrán, Twitter/ajimobi
Sẹnetọ Ajimọbi lasiko to n gbe opa aṣẹ fun ọkan lara awọn agba oye mọkanlelogun ilẹ Ibadan to gbe soke di Ọba
Oríṣun àwòrán, Twitter/abiola ajimobi
Abiola Ajimobi pẹlu aṣiwaju Bola Ahmed Tinubu, agba ẹgbẹ oṣelu APC. ọrun ma kanju ni awọn agba Yoruba maa n wi! Ilẹ n jẹ eeyan
Oríṣun àwòrán, Twitter/abiola ajimobi
Senato Ajimobi pẹlu gomina Kayode Fayemi ti ipinlẹ Ekiti, ọmọ iya ẹgbẹ oṣelu APc ni awa mejeeji
Oríṣun àwòrán, Twitter/ajimobi
Sẹnetọ Ajimọbi pẹlu awọn eekan agbabọọlu orilẹ-ede Naijiria nigba kan ri, Ikẹ Sorunmu, Mutiu Adepoju Yobo Joseph, Emmanuel Amokachi pẹlu minisita fun ere idaraya,
Oríṣun àwòrán, Twitter/ajimobi
Abiola Ajimobi, Aarẹ Muhammadu Buhari ati Adams Oshiomole ti wọn ṣẹṣẹ yọ kuro nipo alaga ẹgbẹ oṣelu APC. Iku a pa ẹni a n pè, iku a tun pa ẹni to n pe ni! Alumuntu ti kii jẹ ki araye dagbere fun ara pe asiko ti to!
Oríṣun àwòrán, Twitter/ajimobi
Ajimobi pẹlu alaga ẹgbẹ oselu APC ti ile ẹjọ ṣẹṣẹ rọ loye, Adams Oshiomole ati igbakeji aarẹ Yẹmi Osinbajo
Oríṣun àwòrán, Twitter/abiola ajimobi
Ajimobi pẹlu Seyi Makinde to n tukọ ipinlẹ Oyo bayii labẹ akoso ẹgbẹ oṣelu PDP; ọrọ oṣelu ọtọ, ọrọ itẹsiwaju ipinlẹ Oyo ati idagbasoke awọn eeyan ibẹ ọtọ! Eyi ko si nii fi ṣe irufẹ ẹgbẹ oṣelu to ba wa ni ijọba bikoṣe ka ni ifọwọsowọpọ lagba
Hushpuppi: Kíni àwọn nkán tí kò hàn s'awọn èèyàn nípa arákùnrin tí ọlọ̀pàá Dubai fí ẹ̀sùn gbájúẹ̀ kàn?
Oríṣun àwòrán, Instagram/hushpuppi
Hushpuppi lorukọ ti ọpọ mọ si ti o si jẹ pe isọwọ fi ọla rẹ han sọ di ilumọọka loju opo ayelujara.
Ṣugbọn ta ni arakunrin ti awọn ọlọpaa ilẹ Dubai ati ọtẹlẹmuyẹ Amẹrika gbe fun ẹsun gbajuẹ olowo iyebiyẹ yi?
Bí ìjọba bá kọ̀ tí kò ṣèdájọ́, tí Ọlọ́pàá kọ̀ pé àwọn kọ́ ló paá, ẹni tó pa ọmọ mi, náà máa ...
Nibo ni wọn ti bi,ta lawọn obi rẹ ati pe bawo lo ti se di ọlọrọ ti awọn eeyan kan n fi ọla rẹ tọrọ ki awọn naa ri bi tiẹ?
Diẹ ree ninu nkan ti a ri ko jọ nipa Hushpuppi
Ni pato ọjọ ti wọn bi Hushpuppi ti orukọ rẹ gangan n jẹ Ramoni ''Raymond'' Igbalode ko ye wa ṣugbọn bi a ba fi awọn nkan to sọ nipa ara rẹ wo ọrọ yi, ko le ti to ogoji ọdun.
Eyi to sunmọ ootọ ni pe nilu Eko lo dagba si ki o to kuro lorileede Naijiria.
Oríṣun àwòrán, Instagram/hushpuppi
Ninu awọn aworan rẹ nigba to wa ni kekere, a ri  ibi to ti duro lara ọkọ nilu Eko ati awọn omiran to tọka si pe o ti gbe Naijiria daada ki o to lọ si ilu okere.
Loju opo rẹ ni Instagram, o tun sọ nipa ọjọ ori rẹ pe oun ti gun oke agba bọ diẹ diẹ wọ ọmọ ọgbọn ọdun.
Loṣu Kẹwa ọdun 2019 lo fi ọrọ yi sita eyi to jẹ ki a lero pe oṣu Kẹwa ni wọn bi.
Kemi Olunloyo on Sunday Igboho: Mi ò gbè lẹ́yìn Yoruba Nation àmọ́ mo wà lẹ́yìn Sunday Igb
O ti ṣe awọn isẹ ọwọ kan ki o to kuro ni Naijiria ṣugbọn a ko ri aridaju lati fidi ọrọ mulẹ iru iṣẹ to jẹ.
Lẹyin ti awọn ọlọpaa Dubai mu tan la bẹrẹ si ni ri aworan orisirisi to se afihan iru iṣẹ to kọkọ bẹrẹ si ni ṣe ki o to kuro ni Naijiria.
Ọkan ninu iṣẹ ti wọn lo ṣe ni pe o jẹ olootu orin ti a mọ si Music Producer ti o si ba awọn olorin Naijiria kọọkan ṣiṣẹ pọ.
Oríṣun àwòrán, Others
Gẹgẹ bi awọn kan ti se sọ,  wọn tun ni Ramoni ti ta aṣọ bọsikọrọ nigba to wa l'Eko koda wọn tun sọ wi pe o kọ isẹ foonu ati kọmputa tita ni Computer Village nilu Eko kan naa.
Pẹlu gbogbo nkan ti a ka kalẹ yi, eleyi ti ohun gangan kii ye sọ nipa rẹ ni pe awọn obi rẹ kii se olowo ati pe ohun t'apata dide ni ki ẹlẹda to wa kọdi ọla si ọdọ ohun.
Awọn mọlẹbi rẹ ko foju han lẹyin ti ọwọ tẹẹ
Wọn ni ọwọ epo lọmọ araye n ba ni la, wọn kii ba ni la ọwọ ẹjẹ.
Ṣaaju ki ọwọ to tẹ Hushpuppi, kii saba sọrọ nipa awọn mọlẹbi rẹ to bẹ loju opo ayelujara.
Oríṣun àwòrán, Others
Yatọ si aworan ko to fi sita nipa ọmọ iya rẹ obinrin to bimọ lọdun 2019 awọn eeyan ko le tọ ka si pe lagbaja tabi tamẹdun ni ọmọ iya Hushpuppi.
Layajọ iya tabi Baba ti a ma si Father's Day ati Mother's Day, Hushpuppi kii kọ nkankannipa awọn obi rẹ debi ti awọn eeyan yoo fi le sọ pe bi awọn obi rẹ ti se ri ree tabi nibi ni wọn n gbe.
Loju opo ẹni to pe ni ọmọ iya rẹ obinrin@ rawflesh_may_9 ko si nkankan nibẹ ni Instagram lati le fi tọka ẹni to n jẹ bẹ.
Bi a ba sọ pe Hushpuppi nikan lo ri ara rẹ lasiko yi ati pe awọn mọlẹbi ko foju han pe eeyan awọn nii ṣe, a ko kuna rara lati sọ bẹ.
Igi Ọ̀pẹ abàmì tó dá ní orí 42 l'Ekiti rèé o, 'bí mo ṣe ríi l'orí mi ń dìde fììì'
Idahun si ibeere yi pin si ọna meji.
Akọkọ ni pe ti a ba fi orukọ abinibi rẹ wo, tii se Ramoni, idile musulumi lo ṣeese ki o ti jade.
Oríṣun àwòrán, Instagram/Hushpuppi
Ninu awọn ọrọ kan to fi sioju opo Instagram rẹ, o sọ pe oore ti Allah ṣe fun ohun to ga ju lọ ni pe oun jẹ musulumi.
Lọdun 2012  lo fi ọrọ yi sita ti a ko si le sọ boya o ṣi n ṣe ẹsin Islam titi di igba ti wọn fi mu.
Bi a ba tibi orukọ rẹ to yi pada si Raymond wo, o ti le fi ẹsin Islam silẹ ṣugbọn o le jẹ inagijẹ lasan ni Raymond ki o ma se wi pe o pa ẹsin da.
Bakan naa ninu fọnran fidio kan to fi si oju opo Instagram to ti n wẹ ninu omi iluwẹ igbalode, orin iyin ẹsin Kristẹni ni o n kọ ninu rẹ.
Yatọ si eyi, pupọ awọn nkan to ma n kọ soju opo ayelujara, a ma fi adura to jọ ti Kristẹni sinu rẹ. Gbogbo awọn kan wọn yi ni ko jẹ ki a le sọ boya Kristẹni ni Hushpuppi tabi Musulumi.
Eyi to daju ni pe ati ẹlẹsin Kristẹni ati ẹlẹsin musulumi lo wa ninu awọn eeyan to le ni miliọnu meji to n tẹle loju opo Instagram
Wo bí ọwọ́ orílẹ̀-èdè Dubai ṣe tẹ Ramoni Igbalode tí gbogbo ayé ń pè ní Hushpuppi
Oríṣun àwòrán, Screenshot/DUBAI MEDIA OFFIC
Invictus Obi, Hushpuppi, àwọn ọ̀dọ́ Nàìjíríà méjì tí ẹ̀sùn gbájúẹ̀ wà lọ́rùn wọn
Ramoni Igbalode ti ọpọ eeyan mọ si Hushpuppi to fi orilẹ-ede Dubai ṣe ibujoko lasiko yii ni ọwọ awọn agbofinro ilẹ Dubai ti tẹ.
Ninu fọnran fidio 'Fox Hunt 2' ni wọn ti ṣafihan rẹ.
Lọjọbọ ni ileeṣẹ agbofinro dubai fi fidio bi wọn ṣe mu gbajugbaja ori ayelujara Instagram naa sita.
Ọpọlọpọ owo bii owo to wa fun itọju Covid 19 ni Amẹrika ati awọn owo to le ni biliọnu dọla mẹrinlelogun ni wọn ti fi gbajuẹ gba.
Ọlọpaa Dubai ṣalaye bi wọn ṣe mu Hushpuppi ninu atẹjade ti wọn fi sita ti BBC ri.
Wọn ni awọn ti n fura sii ti pe pe o n ṣe awọn 'ọmọ Yahoo'ti wọn n gba awọn eeyan lori ayelujara.
Nibẹ ni wọn ti fi si ori ikanni naa nipa Ramoni Igbalode ati Olalekan Jacb Ponle ti wọn n pe ni 'Woodberry'ati awọn ọmọ ilẹ Adulawọ miran.
Iṣẹ akanṣẹ lati mu awọn ọmọ Yahoo ori ayelujara yii ni awọn agbofinro Dubai pe ni: 'Operation Fox Hunt 2'
Awọn ẹṣẹ bii jiji owo ko lati asuwọn kan si ikeji, jiji owo lori ayelujara, wiwọ akata ayelujara ati eto inawo ẹlomiran lọna aitọ, ṣiṣẹ gbajuẹ fun awọn eeyan ni awujọ ati fun awọn banki ni wọn mu wọn fun.
Ogagun Abdulla Khalifa Al Marri to n tukọ ileeṣẹ ọlọpaa gboriyin fun awọn ọlọpaa Dubai fun iṣẹ takuntakun ti wọn ti fi mu awọn mẹwaa naa.
O ni eyi yoo tun din ole ori ayelujara ati gbajuẹ pẹlu ẹrọ ayarabiaṣa kọmputa ku diẹ lagbaye lasiko yii.
Mobile Wash: iṣẹ́ fífọ́ mọ́tò tà ni mó yàn láààyò- Slay Mama
Ki ni o ti kọkọ ṣẹlẹ lori mimu awọn Invictus àti Hushpuppi
Invictus Obi, Hushpuppi, àwọn ọ̀dọ́ Nàìjíríà méjì tí ẹ̀sùn gbájúẹ̀ wà lọ́rùn wọn
Oríṣun àwòrán, Instagram
Ajọ to n koju iwa jẹgudujẹra lorilẹede Naijiria, EFCC ti ni Ramoni Igbalode, alias Ray hushpuppy ni ẹjọ lati jẹ ni ọdọ wọn.
EFCC to fi eyi lede loju opo ikansiraẹni Twitter wọn ni Hushpuppy is ẹni to gajulọ lorilẹede Naijiria ti wọn n wa bayii fun ẹsun iwa ọdaran lori ẹrọ ayelujara.
Ọjọ kẹ̀wá, Osù Kẹfa ní wọn fí panpẹ́ ọba mú Hushpuppi ní United Arab Emirates lórí ẹ̀sùn lilọ gbajuẹ pẹlu ẹrọ ventilator to le ni $35million.
Ajọ naa ni awọn mọ nipa jibiti owo ati 419 to ṣe ni Niajiria, ti awọn amugbalẹgbẹ rẹ si ti wa ni panpẹ awọn bayii lorilẹede Naijiria.
EFCC fikun wi pe awọn n ṣiṣẹ pẹlu Ajọ Otẹlẹmuyẹ ilẹ Amerika, FBI titi ọwọ palaba rẹ fi segi.
Abiola Ajimobi: Irọ́ ikú làá pa mọ́ àdá, kokoko lara baba wa le, ẹbí Sẹ́nétọ̀ Abiola Ajimobi pariwo síta láàrín ìròyìn ikú rẹ̀
Oríṣun àwòrán, Instagram/abiola ajimobi
Irọkẹkẹ iroyin nipa agba oṣelu, Sẹnetọ Abiọla Ajimọbi lo gba igboro kan lalẹ ọjọbọ nigba ti iroyin dede lu sita pe gomina ana ni ipinlẹ Ọyọ naa ti dagbere faye; bẹẹ lawọn to sun mọọ pẹlu n pariwo irọ iku laa pa mọ ada, kokoko lara ọta le.
Lati bi ọsẹ diẹ sẹyin ni oniruuru ti n jade si oju opo ayelujara gbogbo nipa ipo ilera gomina ana nipinlẹ Ọyọ naa, Oloye Abiọla Ajimọbi.
Oríṣun àwòrán, Instagram/abiola ajimobi
Ni nnkan bii ọsẹ diẹ ni iroyin bẹrẹ si ni tan kalẹ pe sẹnetọ ajimọbi n ṣojojo ati pe ara rẹ ko le. Awọn eeyan kan to ms agba oṣelu ọmọ bibi ilẹ ibadan naa ti wọn si mọ pe kii ṣe ẹni ti a lee pa ohun ms agogo rẹ lẹnu pẹlu n miri pe o ṣeeṣe ko ri bẹẹ nitori o to ọjọ mẹta ti wọn gburo rẹ nita gbangba. Kia ti ikọ iroyin BBC News Yoruba gbọ iroyin yii nigba naa lo tọ awọn to sun mọ agba oṣelu naa bi iṣan ọrun lọ lati mọ ootọ ọrọ nigba naa ti wọn si fi to wa leti pe ko sohun to jọ bẹẹ ati pe ara rẹ ya gaga bi ara akẹkọọ aṣọ.
Ko pẹ pupọ ni ẹka ẹgbẹ oṣelu APC nilẹ Gẹẹsi APC UK chapter gbe iroyin kan jade loju opo ayelujara wọn ti wọn fi n ki agba oṣelu naa pe ko maa faraalẹ o.
Too, a mu ẹnu ro nigba naa, gbogbo aye si ba ko lee daa bọ. Amọṣa ko tun pẹ pupọ ni iroyin miran ba tun lu igboro kan pe aisan to n ṣe agba oṣelu naa tun ti burẹkẹ sii koda wọn ti gbee si ẹka awọn alaisan tọrọ wọn le diẹ nileewosan aladani kan ti a ko ni fẹ darukọ nilu Eko. Lẹẹkan si a tọ agbẹnusọ fun oloye Ajimọbi lọ, ohun pẹlu si ni lootọ ara rẹ ko ya amọ irọ to jinna sootọ ni pe o daku lọ gbọrangandan nileewosan gẹgẹ bi awọn kan ṣe n sọ ọ kaakiri nigba naa.
Ni aṣalẹ Ọjọbọ lawọn kan bẹrẹ lori ayelujara pe agba oṣelu naa ti jade laye. Gboogi lara awọn wọnyii ni Fisayọ Soyọmbọ ti ọpọ mọ si oniroyin lori yaelujara. Ninu atẹjade rẹ kan loju opo twitter lo ti kọkọ kede pe eeyan oun kan 'ti ko ja oun kulẹ ri' sọ pe Abiọla Ajimọbi ti jade laye,
Amọṣa ni kia masa werewere lawọn ẹbi oloogbe naa ti bọ sigboro lati bu omi pa iroyin naa eyi ti wọn ni irọ gbuu lasan ni.
Bakan naa ni wọn tun ṣalaye pe lootọ ara Ajimọbi ko ya, sibẹ o wa laaye ko ku.
Lara awọn to kọkọ jade sọrọ ni iyawo ọmọ rẹ Fatima Ganduje Ajimobi. ṣe ẹ ko gbagbe pe bi ọdun meji sẹyin ni Ajimọbi ko ẹbi ara ati ọrẹ lọ ṣe idana nilu Kano ni ile gomina Ganduje nibiti o ti mu Fatima  ọmọ Ganduje fi ṣe aya fun ọmọ rẹ.
Fatima ọhun lo bọ sita loju opo twitter to kọkọ wi pe, 'Alhamdulilah, baba wa ṣi wa laye'
Bakan naa ni agbẹnusọ fun Abiọla Ajimọbi, Tunji Bọlaji ṣalaye pe ko si ootọ ninu rẹ. O ni gbogbo ohun tawọn kan n gbe kiri nipa ilera rẹ lati bi ọsẹ diẹ sẹyin kii ṣe ootọ.
Bakan naa ni Kẹmi Olunlọyọ ti oun pẹlu sun mọ idile naa naa ṣalaye pe ko si ootọ ninu iroyin naa ati pe lẹyin ti oun ba ọmọ agba oye ilẹ ibadan naa sọrọ, o jẹ ko da oun loju pe aaye ni Abiọla Ajimọbi kii ṣe oku ni bi a ṣe n sọrọ yii.
Police: Mo réèmọ̀ nígboro ayé, adigunjalè dìhámọ́ra lọ ja àgọ́ ọ́lọ́pàá lólè
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Bi ole ba ja eeyan lawujọ, ibi ti eeyan kọkọ n morile naa ni agọ ọlọpaa nitori pe ẹni to ba to nii gba lo yẹ ka fọrọ lọ.
Ki ni ka ti wi ni ti iṣẹlẹ to ṣẹ leyi ti awọn adigunjale ti lọ ja agọ ọlọpaa lole. Ta ni ki wọn wa sa di o?
Ni orilẹede Ghana lọjọbọ, nṣe lawọn adigunjale kan ya bo agọ ọlọpaa kan lolu ilu orilẹede naa.
Awọn ọlọṣa naa wọ agọ awọn ọlọpaa naa ti wọn si ko awọn dukia kan to wa nibẹ lọ.
Lara awọn dukia ti awọn adigunjale naa ko ni ags ọlọpaa Nima to wa ni aringbungbun ilu Accra ni ẹrọ kọmputa alagbeka, tẹlifiṣan, awọn iwe atohun elo ikọwe to fi mọ ẹwu awọn ọlọpaa kan.
Nibayii awọn alaṣẹ ileeṣẹ ọlọpaa ti ni iwadii ti bẹrẹ lati mọ hulẹhulẹ iṣẹlẹ manigbagbe naa.
Lockdown in Africa: Nínú Ọlọ́pàá àti Coronavirus, èwo gan an laráàlú ń bẹ̀rù jùlọ?
Iṣẹlẹ idigunjale naa ṣe ọpọ ni kayefi nitori kii si igba kan ti kii si ọlọpaa to n ṣọ agọ ọlọpaa naa. Bi a  o ba si ranti daadaa, wọn kii tilẹkun ileeṣẹ ọlọpaa nitoripe awọn ọlọpaa kii ṣiwọ iṣẹ ọlọjọyipo.
Amọṣa awọn alaṣẹ ṣalaye pe ile iko nnkan ija si ati ibi ti awọn ti wọn timọle ba wa lawọn ọlọpaa maa n ṣọ ju lọ.
Toyin Abraham: Ó dára ká ní àròjinlẹ̀ pé ayé ni Ọlọ́run fi ju ẹ̀dá lọ
Oríṣun àwòrán, Instagram/toyin abraham
Yoruba ni lowe lowe ni a n lu ilu agidigbo, ọlọgbọn lo n jo, ọmọran si lo n mọ ọ.
Bẹẹ ni ọrọ ri pẹlu iwaasu ti gbajumọ oṣere tiata lobinrin, Toyin Abraham ṣe loju opo Instagram rẹ, eyi to fi n pa asamọ lowe lowe nipa awọn iṣẹlẹ agbọsọgbanu to n waye lawujọ wa lẹnu ọjọ mẹta yii.
Bi o tilẹ jẹ pe Toyin ko sọ pato ohun to n kọ ọ lominu to fi kọ awọn ikilọ yii sita.
Sugbon a mọ pe, ayan to mu kọngọ lọwọ, lo mọ ohun to n fi ilu sọ, amọ o ṣee ṣe ki awọn arojinlẹ ọrọ naa da lori iku Ibidunni Ighodalo to jade laye lọsẹ to kọja.
Toyin salaye ninu ọrọ rẹ naa pe awọn iṣẹlẹ ẹnu ọjọ mẹta yii n jẹ ki oun ronu jinlẹ, ki oun si fi oju ọtọ wo ohun ti wọn n pe ni aye taa wa yii.
Oríṣun àwòrán, Instagram/ Toyin Abraham
Toyin ni Mo wo ara mi, mo si ronu nipa aye yii ati ohun gbogbo to wa ninu rẹ,"
"O si han si mi pẹlu ẹdun ọkan pe asan ni aye, omulẹ mofo. Idi si ree to fi rọrun fun wa lati maa gbe aye wa lonii lai ranti ohun to sẹlẹ lanaa."""
"O ni ""Lootọ gbogbo wa la mọ pe aye ko tọ lọ bii orere, binti laye sugbọn ṣe ojoojumọ la n ranti ọrọ yii, taa si n ṣíṣẹ tọ ọ?"
"Oye mi nipa aye yii ti yatọ ni akoko taa wa yii, haa, o ma dara ki eniyan ni arojinlẹ o."""
Gbajugbaja oṣere tiata naa fikun un pe, ti eeyan ba mọ inu ro, oye aye yii yoo han si wa kedere pe igba diẹ ni aye
Amọ, a kan n sare le awọn ohun to wa lonii, ti ko ni si mọ ni ọla, pẹlu ireti pe yoo wa titi laelae.
Toyin, ti ọpọlọpọ eeyan tun n pe ni 'Mama Ire' tẹsiwaju pe aye yii kere ju ki eeyan maa fi ojoojumo ja lọ
Port harcourt Bole: Mi kò mọ́ pé bọ̀ọ̀lì títà lè gbé mi dé ipò yìí láyé mi!
"Toyin ni:  ""A n gbero nipa ohun ti yoo sẹlẹ ni oṣu mẹfa si akoko yii bii ẹni pe ọla gan an daju fun wa,"
Eyin ololufẹ mi, aye ni Adiitu ti Olodumare fi ju ẹda lọ, a n ṣe eto ohun gbogbo amọ, Ọlọrun nikan lo le jẹ ko wa si imusẹ.
"Mo si n bi ara mi leere pe Oluwatoyin ki lo de to n le òjìji aye kiri nigba to jẹ pe Ọlọrun lo ni aye rẹ? ""."
O fikun un pe ohun kan lo ti ye oun bayii pe gbogbo ohun to n dan kọ ní wura,
Orọ̀ kankan ko si ni wa titi aye amọ ohun to daju ni pe ko si ẹni to le ra aye gbe, oun si ti ri alaafia nipa mimọ Ọlọrun.
Toyin ni ohunkohun ti Ọlọrun ba seto rẹ pe yoo jẹ ti oun, yoo wa sọdọ oun lọjọ-kọjọ, Ọlọrun nìkan si lo ni akoso ohun gbogbo.
Gbajumọ oṣere tiata naa wa gba awọn ololufẹ rẹ ni imọran pe aye yii fuyẹ, ofo ni, ọna ta ba si gba lati gbe inu rẹ ni yoo jẹ ko ṣe iyebiye fun wa, nitori naa, ẹ gbe igbe aye to ni itumọ.
Period party: Àwọn obìnrin kan ṣe ayẹyẹ nkan oṣù l'órí ayélujára
Kwara: Fọ́fọ́fọ́ ni mọ́ṣáláṣí kún tí ìlànà ìjìnàsíraẹni 'social distancing' sí forí
Boko Haram n fipá bá mi lòpò ní òpò ìgbà léyìn tí wọn kọlu ìlú wa- Omọbinrin náà
Oríṣun àwòrán, Others
Ọ ṣòro fún mi láti foríjín ìbátan mi ọmọ ikò Boko Haram tó fipá bámi lòpò
Mi o le fori jin ibatan mi ọmọ iko Boko haram to fipa bamilopọ
Loni, ọjọ Kejidinlogun, oṣu Kẹfa, ti se ayajọ ti ajọ iṣọkan agbaye la kalẹ lati mu opin ba iwa ifipabanilopo lasiko ikọlu,
Odomobirin kan ni Naijiria to ni ki BBC forukọ bo oun laṣiri sọrọ lori bi ibatan oun kan to jẹ ọmọ ikọ Boko Haram ati awọn miran ti ṣe fipa ba oun ati awọn ọmọbinrin miran lopọ f'un igba pipẹ ni ariwa Naijiria.
Arabinrin yi ni iṣẹlẹ aburu yi ṣẹlẹ sí òun lẹyin ti awọn ọmọ ikọ boko haram ṣigun bo ilu wọn.
O ni: Won fipa ba mi lopọ, wọn si fi mi fun awọn ọmọ ikọ boko haram gẹgẹ bi iyawo
"Bi Boko Haram ti ṣe wọ ilu wa, wọn pa gbogbo awọn ọkunrin ilu wa sọna si awọn ile wọn si ko gbogbo awa obinrin lọ"""
Ni ọjọ yi ni ibatan mi to jẹ Boko Haram wa sọ fún mi pe lati oni lọ, mo ti di iyawo ohun,dukia ohun .Lọjọ naa lo si ti bẹrẹ si ni fipa bamilopọ
Leyin igba diẹ ti ede aiyede waye laarin oun ati awọn ọmọ ẹgbẹ naa miran ti won si pa a, wọn fi mí fun ẹlomiran gẹgẹ bi iyawo.
Arabinrin ti a n wi yi  sọ pe oun ati awọn ọmọbìnrin mii ribi sa mọ wọn lọwọ nibi ti awọn oniṣẹ ibi yii ko wọn pamọ si lasiko ti wọn n sun ni nkan bi aago kan oru.
O fi kun ọrọ rẹ pe tohun ti pe awon ribi sa asala kuro lọwọ awọn to mu awọn, oju buruku lawọn to ku ni aaye t'awọn atipo fori pamọ si to wa ni Bama ni Iwọ oorun ariwa Naijiria fi n wo awọn.
"Ibikibi ti a ba rin si, wọn a máa na ika aleebu sí wa pe iyawo Boko haram ni wa
Afi bi igba pe ebi wa ni bi wọn ti ṣe mu wa l'ẹru.
Ni temi, mi o ro pe mo le forijin awọn ọmọ ikọ Boko haram fun nkan ti wọn foju mi ri"
Kini Arabinrin yii fẹ di ni ọjọ iwaju rẹ?
Arabinrin yi to ti pada si Ile ẹkọ girama ni o wu oun lati di ọmọ ogun lọjọ iwaju ki oun ba a le dojú ija kọ awọn ọmọ ikọ Boko Haram.
Erongba mi ni lati pari ẹkọ mi kì n si darapọ mọ awọn ọmọ ogun Naijiria, kí n wọ inu baalu kí n sì sọ ado oloro lu awọn olubi yi ki wọn si parẹ tan yanyan ni Naijiria
Ó dára kí obìnrin níṣẹ́ lọ́wọ́ - Toyin Lawani
Yatọ sí eto ẹkọ rẹ, o ni oun fẹ kọ iṣẹ ranṣọ ransọ laaye ikọsẹ to wa ní ibùdó awọn atipo.
O fikun un pe lati igba ti wọn ti ji oun gbe kò sì ọjọ kan toun kii sunkun titi ti awọn ikọ ẹlẹyinju aanu Al Amin wa saanu fun oun.
Ajọ iṣọkan agbaye UN ni awọn ya ọjọ Kọkandinlogun oṣu Kẹfa ọdọọdún sọtọ  lati mu opin ba ifipabanilopo fawọn to wa ninu wahala ati laasigbo bi ti arabinrin yi.
Ronke Ojo àti Toyin Lawani: Ó dára kí obìnrin níṣẹ́ lọ́wọ́
Ronke Ojo, ti ọpọ eeyan mọ si Ronke Oshodi Oke ati Toyin Lawani ba BBC sọrọ lori ipa to yẹ ki obinrin maa ko ninu ile.
Awọn mejeeji fẹnuko pe o dara ki obinrin niṣẹ lọwọ ko ma ba a jẹ ajaga fun ọkọ rẹ.
Ronkẹ ni oun gbagbọ pe okunrin to lee ṣe awọn ojuṣe ti awọn ọkunrin maa n ṣe laye atijọ ṣọwọn laye ode oni.
Bẹẹ na lo tun gba awọn okunrin ni imọran lati maa ni suuru fun awọn iyawo wọn ti iṣẹ wọn gbomi mu.
Ni ti Toyin Lawani, o ni ohun to dara ni ki okunrin ṣe atilẹyin fun iyawo rẹ ninu iṣẹ to ba n ṣe nitori ọjọ iwaju.
Bẹẹ naa lo tun sọ pe kii ṣe ohun to bojumu ki ọkunrin jẹ alapa ma ṣiṣẹ ti yoo maa reti ki iyawo rẹ maa bọ ọ.
Ẹkunrẹrẹ ohun ti awọn mejeji sọ wa ninu fidio yii.
Lai Mohammed: Sọ̀rọ̀sọ̀rọ̀ tí wọ́n fẹ̀sùn kàn pé ó bú Lai Mohammed gbá ìtúsílẹ̀ lẹ̀yìn ọjọ́ 45 látìmọ́lé
Oríṣun àwòrán, Facebook/Akewi Jolayemi
Ileesẹ ọlọpaa lorileede Naijiria ti tu akewi nii Rotimi Jolayemi ti wọn fẹsun kan pe o kọrin ewi bu Minisita feto iroyin Naijiria Lati Mohammed.
Orin to kọ ọhun gbori ẹrọ ayelujara kaakiri ti ọpọ eeyan si ṣe alabapin rẹ.
Ọjọ marundinlaadota  ni o  lo latimole ki wọn to kede itusilẹ rẹ.
Iwe iroyin Naijiria The Punch so pe iyawo rẹ Dorcas so fun awọn pe lọjọ Ẹtì ni awọn ọlọpaa tu silẹ.
"Mo dupẹ pupọ lọwọ ileesẹ iroyin Punch bi wọn ki ti ṣe dakẹ lori ọrọ ọkọ mi ti wọn timọle lọna aitọ.
Wọn pada tu silẹ ki ma lọ ile lọsan ọjọ Ẹtì ṣugbọn wọn ni kó pada wa buwọlu awọn iwe kan kọkọ Ajé"
Ajọ ajafẹtọmọniyan Amnesty International to ṣaaju kesi awọn ọlọpaa lati da Jolayemi silẹ.
O ti lo ọsẹ marun un lahamọ ki wọn to wọ lọ sí iwaju adajọ ni ọjọ kọkànlá oṣu Kẹfa ọdun 2020.
Atọkun eto ni Jolayemi jẹ ti a si ma seto kan yi wọn n pe ni 'Bi aye se ri' lori ikani redio ipinlẹ Osun ati ni Radio Kwara Ilorin.
Ọjọ kaarun oṣu kaarun ni awọn ọlọpaa mu lori ẹsun pe o fi orin ewi bu Minisita Lai Mohammed.
Awọn ọlọpaa  gbe lọ si Abuja ni ojo keje oṣu karun to sí wa níbẹ ki o to foju ba ile ẹjọ nibi ti adajọ ti  so pe ki wọn lọ fi si ahamọ.
Coronavirus updates: Wo àwọn oníròyìn méje tó kú láàrin ọjọ́ méje ní Nàìjíríà
Oríṣun àwòrán, Facebook
Lootọ ni pe alagbra naa a maa subu, awọn oniroyin lo ṣikeji lẹyin awọn dokita ti wọn si n lewaju lasiko ajakalẹ aarun Covid -19 yii.
Sugbọn o seni laanu pe ọwọja iku ja meje oniroyin Naijiia gba laarin ọjọ meje.
Lati ọjọ meje sẹyin, oniroyin ati akọroyin meje lo ti ku iku Coronavirus ati iku ti ku nise pẹlu aarun naa.
Awọn to ku naa ni in:
Nkirukah Udoh
Awọn iṣẹlẹ to n ja kiri awọn ile iṣẹ iroyin yii ko yọ ile iṣẹ oroyin AIT silẹ bi wọn ṣe padanu akọroyin to tun jẹ gbanumọ akaroyin lori mohunmaworn ile iṣẹ naa.
Nkirukan kun nile iwosan aladani kan lẹyin iṣẹ abẹ kan to gbodi
O ti fi igbakan jẹ akọroyin ẹka ilera ati idajọ.
Awọn akọroyin lorilede Naijira n koju oniruuru ipenija gẹgẹ ọkan lara awọn to n lewaju lati koju aarun coronavirus ti wọn si n ṣiṣẹ ni yara ikoroyin jọ lojoojumọ.
Oríṣun àwòrán, Facebook/Dan Foster
Daniel Foster
Dan Foster , Gbajugba sọrọsọrọ lori redio ti gbogbo eeyan mọ si Big Dawg  lokiki rẹ kan pe o ku lọjọ kejidinlogun osu yii pe o ti gbkruje lọwọ ẹbọra.
Oniruuru iroyin lo tẹyin rẹ jade ti a ko si ri aridaju iru iku to paa, bi awọn kan se ni aarun coronavirus  lo paa, ni awọn miran ni o ti ni arun ẹjẹ riru lo sokun fa rẹ.
Sugbọn iyawo oloogbe naa Lovina salaye fun ile isẹ iroyin Channels pe lọjọru pe  ti se ayewo aarun covid -19 ti esi ayẹwo naa si jade lọjọru sugbọn ọsan ọjọ naa lo dagbere f'aye.
Oríṣun àwòrán, Other
Hugo Ifeanyi Odiogor
Lana ode yii niti Odiogor to jẹ ọga agba oniroyin ati alaga nile iṣẹ iroyin Vanguard tẹlẹ ri.
Gẹgẹ bi ẹbi se sọ, Odiogor kulẹyin ọpọlọpọ ọjọ to ti n ṣaisan eyi to si ti mu rinrin ajo lọ si orilede India.
Ooloogbe naa se papoda ni lọsan ana, ọjọ satide ogunjọ, oṣu kẹfa ọdun yii.
Xiavier Ndayongmong
Ko tan sibẹ o, akọroyin nipa iwa ọdaran nile ise iroyin Daily Independent naa dagbere faye lọjọ jimọ, ọjọ kọkandinlogun, oṣu yii.
Aaro ọjọ Jimọ ni wọ sare gbe lọ si ile iwosan kan ni ipinlẹ Ogun ti wọ si daa duro nibẹ, sugbọn ki ilẹ ọjọ naa to su, ọgbẹni Xiavier ti dagbere f'aye.
Gbogbo ẹgb.e awọn akoroyin to niṣe pẹlu ọdaran (CRAN) lo n selede lẹyin akẹgb. Wọn to lọ
Naomi Uzor
Oríṣun àwòrán, Facebook/Naomi Uzor
Naomi Uzor to jẹ akọroyin nipa ọrọ aje nile iṣẹ Vanguard.
Naomi ku laarin osẹ to kọja pẹlu.
Aramide Praise  Oikelome
Aramide Praise ku lana, Ogunjọ  ọsu kẹfa  bakan naa.
Saaju ninu oṣu kẹrin ọdun yii lo n rọ awọ ololufẹ rẹ lju opo iroyin rẹ pe o ti se diẹ ti oun  kọ nkan si oju opo naa nitori pe oun padanu aburo ti wọn bi le oun sọwọ aarun coronavirus.
Kos i ẹni ti ọrọ naa ye boya iku coronavirus lo pa Aramide naa abi bẹẹ kọ.
Praise ni oludasilẹ Girls Arise Initiative.
Ọpọ awọn oloufe Aramide lo ti n selede lẹyin rẹ loju opo facebook.
Azeez ozi Sanni
Iku kan ilẹkun de ile iṣẹ iroyin The Nation pẹlu nigba to wọbẹ lọ mu ayaworan wọn lọ Azeez Sanni
Sanni ku lọjọ aje nilu Ibadan.
O ni gba ami ẹyẹ  NMMA ni ọdun 2008, 2009, 2010 ati ami ẹyẹ Dame ni  lọdun 2009.
Ọmọ Nàìjíríà fárígá lórí olú iléeṣẹ́ Nàìjíríà tí wọ́n wó ní Ghana
Awọn apa ibi kan lara ileeṣẹ aṣoju orilẹede Naijiria ni Ghana ni iroyin taa gbọ sọ fun wa pe o ti wo lulẹ.
Arakunrin ọmọ orilẹ-ede Ghana kan ti iṣẹlẹ naa ṣoju rẹ lo ta BBC Yoruba lolobo iṣẹlẹ naa.
Iroyin sọ pe arakurin oniṣowo kan lo sọ pe ori ilẹ oun ni wọn kọ ileeṣẹ Naijiria yii si ni Ghana. O yọju lọsẹ to kọja pẹlu awọn ẹri kan lati fi ti ọrọ rẹ lẹyin, ko to o di pe o bẹrẹ si ni wo odi ti wọn mọ yi ile naa ka lulẹ.
Gẹgẹ bi a ṣe gbọ, ko sẹni to sọrọ tako nkan ti oniṣowo yii ṣe ṣugbọn nigba ti ileeṣẹ Naijiria pe ijọba Ghana lẹjọ lori rẹ, wọn ko tii fesi.
Violence against women: Ìjọba pàṣẹ lọ rọọ́kún nílé fún òṣìṣẹ́ káńsù tó lú obìnrin kan ní ìpínlẹ̀ Ogun nítorí ìséde
Oríṣun àwòrán, @TeeBaibie
Wọn ti paṣẹ rọọkun nile fun awọn oṣiṣẹ ijọba ibilẹ Ifọ ni ipinlẹ Ogun ti wọn fihan ninu fidio kan to n ja rayinranyin lori ayelujara nibi to ti n lu arabinrin kan lolu ileeṣẹ ijọba ibilẹ naa labẹ awawi pe oun n fi ofin konile o gbele mulẹ nibẹ.
Eeyan kan loju opo twitter, @TeeBaibie lo fi fidio naa sita nibi ti awọn oṣiṣẹ kansu naa ti n gbiyanju ati jo taya ọkọ arabinrin naa lọjọ Satide lagbegbe Ojodu Abiọdun.
Arabinrin naa ni oun ti ṣalaye pe awọn ko mọ pe awọn ti kọja ala ilẹ ipinlẹ Eko wọ ipinlẹ Ogun lasiko naa eleyii to ni awọn oṣiṣẹ kansu naa faake kọri, wọn ko gbọ.
Kii ṣe iroyin mọ pe inira ni fun ọpọ eeyan lati mọ aala laarin ipinlẹ Eko ati Ogun nitori awọn eeyan ti kọle wọnu ara wọn ni ipinlẹ mejeeji.
Bi o tilẹ jẹ wi pe ipinlẹ Eko ti dẹwọ ofin koni o gbele kaakiri gbogbo ọjọ to wa ninu ọsẹ, ofin konile o gbele ṣi n fidi mulẹ ni ipinlẹ Ogun ni ọjọ Abamẹta ati ọjọ Aiku.
Gẹgẹ bi obinrin naa ṣe sọ oun ati ọkọ rẹ ni wọn jumọ jade ni ọjọ naa lati lọ ra awọn nnkan ti wọn yoo lo fun ayẹyẹ ọjọ ibi smọ wọn to n bọ lọna ti wọn fi pade awọn oṣiṣẹ kansu naa.
Amọṣa ọrọ ba ibomiran yọ nigba ti arabinrin naa gbiyanju lati beere ibi ti ileeṣẹ ijọba ibilẹ naa wa lọwọ arakunrin kan ti o pada wa mọ oruks rẹ si Ọgbẹni Peter.
Arakunrin naa lo n tẹle to si n ka nnkan to n ṣẹlẹ silẹ ki o to di wi pe arakunrin Peter naa ṣa dede yii lojiji to si di igbaju ati igbamu fun un.
Ninu atẹjade kan to fi sita, alaga ijọba fidihẹ ni ijọba ibilẹ Ifọ, Họnọrebu Fọla Salami ni iwadii ti bẹrẹ lori ọrọ naa ati pe gbogbo awọn oṣiṣẹ ti ọrọ naa kan lo ti gba aṣẹ lọ rọọkun nile ti wọn ko si ni gba owo oṣu.
Deaf parents and siblings: Láàrín ìdílé ẹlẹ́ni márùn ún yìí, ọmọ kan ṣoṣo ló léè sọ̀rọ̀
Ọdọmọkunrin kan to jẹ ẹnikan ṣoṣo to lee sọrọ laarin idile ẹlẹni marun un ba BBC Yoruba sọrọ lori idojukọ rẹ.
Ọmọ ọdun mẹrindinlogun naa, Ajekigbe Ifeoluwa Martins sọ pe o jẹ iyalẹnu fun oun pe awọn obi oun ko le sọrọ, ati pe o ṣoro lati ba awọn obi oun sọrọ nigba ti oun wa ni kekere.
Ṣugbọn aile sọrọ awọn obi rẹ lo mu ko lọ kọ bi wọn ṣe n ba awọn odi ati aditi sọrọ.
O ni ẹdun ọkan nla lo jẹ fun oun pe awọn obi atawọn aburo oun ko le sọrọ, ṣugbọn itọju ti wọn fun oun jẹ ohun iwuri.
Botilẹjẹ pe awọn obi ati aburo rẹ ko le sọrọ, o ni oun nifẹ ẹbi naa, ati pe oun yoo ṣetọju awọn obi naa ti ọna ba ti la fun oun lọjọ iwaju.
Awọn mọlẹbi obi ọmọdekunrin naa tun ba BBC sọrọ lori ipinlẹ bi wọn ko ṣe le sọrọ.
Ẹ wo fidio yii fun ẹkunrẹrẹ.
Yoruba Films: Adewale Elesho ní àìkàwé ló ṣàkóbá fún òun nínú iṣẹ́ tíátà
Oríṣun àwòrán, Instagram/officialyemielesho
Gudugbẹ ja ninu ifọrọwẹro BBC Yoruba pẹlu gbajumọ oṣere tiata, Adewale Adeoye Elesho ati ọmọ rẹ, Yemi Elesho.
Adewale Elesho ni oju ti ri to ninu irin ajo oun lati ilẹ, o ni oun kewu lẹyin ti oun pari iwe alakọbẹrẹ tan.
Elesho, gẹgẹ bi ọpọ ṣe maa n pe e ninu ere sọ pe, oun pada kọ iṣẹ oogun tita, ti oun si gba iyọnda lọdun 1975, bakan naa loun ṣi ṣọọbu oogun toun ni 1976.
Adewale Elesho ni baba oun fun oun lowo bẹẹdi ati foomu nigba ti oun bẹrẹ si ni ta oogun, tori baba oun ni ko yẹ ki ẹni ti o n ta oogun maa sun sori ẹni.
Awọn ọlọpaa maa n yọ mi lẹnu nibi iṣẹ oogun tita ni ilu Emure ti mo n gbe nipinlẹ Ondo nigba naa, eyi gan an lo jẹ ki n fi iṣẹ oogun tita silẹ, ti mo fi bẹrẹ ere tiata ṣiṣe.
O ni oun ati ọrẹ oun jọ dawo ra danfo ti wọn fi bẹrẹ ere tiata, laye igba naa lọhun.
''Baba mi ko fẹ ki n ṣiṣẹ tiata, o ni iṣẹ tiatia yoo jẹ ki n maa ṣe oogun,'' Elesho lo woye bẹẹ.
Nigba to ya ni Elesho pada de ọdọ oloogbe Adeyemi Afolayan, ti ọpọ mọ si Ade Love.
O sọ pe awọn olootu ere tiata laye igba naa maa n kọ ẹnu ifẹ si awọn arẹwa obinrin laarin awọn oṣere.
Elesho sọ pe nipasẹ Ade Love loun fi mọ Oga Bello, Isho Pepper ati Iya Awero ninu ere ṣiṣe.
Oríṣun àwòrán, Instagram/officialyemielesho
Adewale Elesho ni aikawe oun ṣakoba fun oun ninu ṣugbọn oun dupẹ lọwọ Eleduwa.
O ni kewu ti toun ka ko ta ninu iṣẹ tiata.
Nipa awọn ọmọ rẹ, o ni ihoho ọmọluabi loun maa n ba awọn ọmọ oun wi, o ni gende ọkunrin marun un loun bi.
Elesho ni ''ọmọ obinrin mi nikan ni mi o ja si ihoho ri.''
O ni Bibeli sọ pe paṣan lo tu were to wa laya ọmọde kuro, ṣugbọn o ni ẹgba tẹẹrẹ ko ran awọn ọmọkunrin mọ, igbaju igbamu lo yẹ wọn.
Yemi Omo Elesho
Yemi Elesho to jẹ ọmọ Adewale Elesho ni tiẹ sọ pe, lati kekere loun ti bẹrẹ ere tiata, ''mama mi lo maa n gbe mi kaakiri ori itage.''
''Ati kekere ni mo maa ti n pa awọn agbalagba lẹrin, iwe kẹrin ni girama ni mo ti ko ẹgbẹ osere jọ.''
Oríṣun àwòrán, Instagram/officialwaleelesho
Fiimu meji ti mo ṣe pẹlu awọn akẹgbẹ mi, ko si ẹni to gba lọwọ wa, nigba to ya ni gbogbo awọn ọmọ ẹgbẹ oṣere mi tuka, ti o si ku emi nikan.
Yemi sọ pe lẹyin naa loun bẹrẹ si wa Maruwa nitori oun ti sa kuro nile.
''Mo ti wa Maruwa lẹyin baba mi ri ṣugbọn wọn o mọ pe emi ni.''
''Ọjọ ti baba mi ri mi nibi ti mo ti n wa Maruwa, ni mo fii silẹ ti mo si pada sile.''
O ni lẹyin naa loun ṣẹṣẹ lọ si ile iwe eyi ti baba oun fẹ, ki oun tiẹ to le ṣe ohun kohun.
Coronavirus: updates: ìlú kan rèé l'Abuja tí kò mọ̀ rárá nípa Covid-19
Pẹlu bi ijọba orilẹede Naijiria ṣe ko owo lorii fifi awọn ileeṣẹ iroyin polongo nipa bi ajakalẹ arun Coronavirus ṣe n ran to, awọn ilu kereje kereje kan ṣi wa to wa lokunkun nipa arun aṣekupani naa.
Abule Zokutu ko ju bi irin wakati meji fun ọkọ lati aarin gbungbun ilu Abuja nibi ti ikọ amuṣẹya ti aarẹ yan to n ṣiṣẹ ojoojumọ nipa fifun awọn eeyan niroyin nipa Coronavirus wa.
Ṣugbọn awọn olugbe ilu yii ni awọn ko gbọ iroyin daadaa nipa bi arun naa ṣe n ran ati bo ṣe le ṣakoba fun awọn.
O ti le lọgọrun ọjọ bayii ti Naijiria ti ni ẹni akọkọ to ni arun Coronavirus bayii, koda itanka arun naa ti sun ọpọn de awọn ilu igberiko sibẹ, ṣe ni iye rẹ n goke sii lojojumọ.
Akọsilẹ to wa lọwọlọwọ bayii fi han pe o ti le lẹgbẹrun lọna ogun eeyan to ti lugbadi arun naa ti o si ti le ni ẹẹdẹgbẹta to ti gba ibẹ ku ni Naijiria.
Ọna pataki kan ti ijọba n gba fi ọrọ sita lori arun naa ni nipasẹ ẹrọ mohunmaworan, rẹdio ati lori itakun ayelujara.
Ṣugbọn abule Zokutu ko ni ọna to dara, ko si họsibitu koda ko si itakun agbaye lati wo ori ẹrọ ayelujara fun iroyin. Wọn o tun ni ina ọba lati gbọ rẹdio tabi tẹlifisan nipa Coronavirus ati ọna ti ijọba n polongo pe wọn le gba dena rẹ.
Rose Mishayi ni awọn ko mọ bi coronavirus ṣe ri
Coronavirus yii, awa o mọ nkankan nipa rẹ o ati bo ṣe n ran awọn eeyan. Nibayii a  o mọ ẹni ti yoo ṣalaye fun wa nipa rẹ.
"Ara ilu naa kan, Mishayi sọ pe ""a kan gbọ pe Coronavirus wa ni Naijiria ṣugbọn a o tilẹ mọ ohun to jọ""."
Ṣugbọn bi akọroyin BBC ṣebẹwo si ilu naa, ṣe lawọn araalu n ṣe owo tiwọn lọ ni rẹpẹtẹ lai naani lilo ibomu tabi ṣiṣe ijina sira ẹni.
Agbẹ lo wọpọ ni ilu naa wọn si ni awọn ko mọ ohun to n jẹ COVID-19.
Hajara ni ijọba maa n ṣe bii pe awọn ko ṣe pataki.
Asiko ipolongo idibo nikan. ni ijọba maa n ranti wa bi idibo ba si ti tan, wọn a gbagbe wa. Solomon sọ eyi fun BBC.
Awọn araalu ilu Zokutu ko lanfaani si omi to daa
Solomon fi kun un wipe niwọn igba ti awọn wa lokunkun, igberi aisan yii lawọn le wa.
Ẹwẹ, minisita fun iroyin, Lai Muhammed ni awọn ti nawo le ipolongo pẹlu awọn ileeṣẹ iroyin lati da awọn ọmọ Naijiria lẹkọọ.
O ni ida mọkandinlọgọrun ọmọ Naijiria lo ti gbọ.
Ṣugbọn ikọ amuṣẹya ti aarẹ yan ni iṣẹ ṣi ku lati jẹ ki awọn eeyan mọ sii paapaa lawọn igberiko.
Awọn ara ilu Zokutu ni awọn ko tii ko firi ẹni kankan ti wọn gbeṣẹ le lọwọ lati maa polongo nipa Coronavirus pẹlu bo ṣi ṣe jẹ pe ẹgbẹ Abuja lawọn wa.
Kid boxer: Ọmọọba 'The Buzz' Larbie rèé, ọmọ ọdún méje tó ń fi ẹ̀ṣẹ́ dá bírà tó ju ọjọ́ orí rẹ̀
Awọn agba bọ wọn ni ọmọ to ba maa jẹ aṣamu, kekere lo ti n ṣẹnu ṣamuṣamu; eyi ni itan Ọmọọba 'The Buzz' Larbie to n ti kekere ṣe ohun ti agba ko lee ṣe lagbo ẹṣẹ kikan.
Ìpànìyàn Akinyele: Àwọn ìgbésẹ̀ tí ọlọ́pàá ń gbé lórí ikú Mujeeb tí wọ́n pa nílùú Ibadan
Oríṣun àwòrán, @PoliceNG
Ileesẹ ọlọ́pàá ìpínlẹ́ Oyo ti ké gbàjarè pé, adiyẹ ń làágùn, sùgbọ́n ìyẹ́ ara rẹ̀ ni kò jẹ́ kí ènìyàn mọ̀, pàápàá jùlọ, nidii igbesẹ rẹ láti dẹ́kun ìwà ìbájẹ́ àti fífi ẹ̀mi àwọn ènìyàn sòfò ní ìpínlẹ̀ Oyo.
Nínú ọ̀rọ̀ rẹ̀, alukoro ọlọ́pàá nípìnlẹ̀ náà Olugbenga Fadeyi sàlàyé fún BBC Yoruba pé, gbogbo ìgbèsẹ̀ tó yẹ fun ileesẹ ọlọpaa lati gbé lori isẹlẹ yii ni awọn n gbe.
O ní àwọn ti kan sí àwọn lọ́balọ́ba, àwọn ọ̀dọ́ àdúgbò, àwọn ọlọ́dẹ, àti àwọn àjọ elétò ààbò míràn láti maa fi ìṣẹlẹ to bá n wáye láyìká wọ́n tó ọlọ́pàá létí .
Fadeyi ni ilé ìṣẹ́ ọlọ́pàá ti bẹ̀rẹ̀ ìwádìí lórí ìṣẹ̀lẹ̀ túntun ti Mujeeb ti wọn pa tó ṣẹlẹ̀ yìí, láti rí idí aburú tó n f'ojoojúmọ́ wáyé níjọba ìbílẹ̀ Akinyele nílùú Ibadan.
Alukoro ọlọ́pàá ní òun kò ní le máa sàlàyé àwọn ǹkan míràn tí àjọ náà tí n ṣe nítori pé, gbogbo àwọn ọ̀daran yìì náà ló n tẹtí sí ǹkan tó n lọ lórí ayélujára láti mọ ibi ti ọlọ́pàá báṣẹ́ dé.
"O ní ""kí ìwádìí ba lè já geere, a ò ni le sàlàye lẹkùnrẹ́rẹ́ ibi ti ìwádìí ti dé dúró, sùgbọ́n ti ìwádìí náá ba ti kẹ́sẹ jári tán, ileesẹ ọlọ́pàá yóò le sọ fún ará ilú bi gbogbo rẹ̀ ṣe jẹ́"""
Nípa bóyá àwọn amọkùn ṣeka yìí fí n ṣe ètùtù ni gẹ́gẹ́ bi àwọn kan ṣe sọ, Ọ̀gá ọlọ́pàá ní ìwádìí ṣì ń lọ lọ́wọ́ lórí rẹ̀ náà.
Títí di àsìkò yìí a kò ti rí ẹni kankan lórí ìṣẹ̀lẹ̀ ti Mujeeb sùgbọ́n ọwọ́ ti tẹ ẹnikan nípa ti Azeezat.
Ẹjọ́ náà ti wà ni ẹ̀ka tó ń ri si ìwà ọ̀daran ní ìpínlẹ̀ Oyo.
Ìpànìyàn Akinyele: Ìgbọ̀nsẹ̀ ni Mujeed lọ ṣe l'Akinyele, ni wọ́n bá ṣáa ní àdá pa
Oríṣun àwòrán, others
Ọrọ gbogbo kii fẹ si lẹyin ikeemu agbegbe Akinyẹle bayii ni ipinlẹ Ọyọ paapaa julọ to ba n di ọrọ ka da ẹmi ẹni legbodo.
Awọn oniṣẹ ibi kan ti pa ọmọ ọdun marun un kan ni ijọba ibilẹ Akinyẹle ni ipinlẹ Ọyọ.
Gẹgẹ bi iroyin abẹle ti a gbọ lati ibẹ, ko pẹ pupọ lẹyin ti ọwara ojo to balẹ lowurọ ọjọ Aje ni ilu Ibadan wawọ ro diẹ tan ni ọmọdekunrin naa ti orukọ rẹ n jẹ Mujeeb Trimisiyu pada lọ si ile awọn obi rẹ to wa lagbegbe Tose lagbegbe ijọba ibilẹ Akinyẹle lati lọ ree ṣe igbọnsẹ.
Igbọnṣẹ ikẹyin ti Mujeeb ṣe niyi o ki awọn oniṣẹẹbi naa to kọlu ti wọn si paa ki wọn to bẹ lugbẹ.
Bi ẹ ko ba ni gbagbe, lagbegbe Akinyẹle yii kan naa lawọn oniṣẹ ibi kan ti pa awọn omidan meji, Barakat Bello ati Grace Osiagwu lẹyin ti wọn fipa ba wọn lo pọ tan.
Bakan naa ni lawọn kan naa tun kọlu Azeezat Shomuyiwa ti wọn fọ okuta mọ lori pẹlu oyun oṣu meje ninu rẹ.
Ibadan Murder: Oyún oṣù méje ló ń bẹ nínú Azeezat, kí wọ́n tó f'òkúta fọ́ ọ lórí
Eyi ni iku kẹrin laarin oṣu kan sira wọn lagbegbe yii kan naa.
Gẹgẹ bi a ṣe gbọ, ọmọdekunrin yii pariwo irora sita nigba tawọn oniṣẹẹbi naa n kọluu, ṣugbọn ki iya rẹ to lee ṣawari ibi ti igbe irora naa ti wa, wọn ti ṣaa lada ti o si ti wa ninu agbara ẹjẹ.
Gẹgẹ bi a ṣe gbọ, igbọnsẹ lo sọ fun awọn ẹgbọn rẹ pe oun fẹ lọ ṣe ti wọn si ṣilẹkun to jade si ẹyinkule ile naa fun pe ko lọ gbọnsẹ .
Ileeṣẹ ọẹọpaa ni ipinlẹ Ọyọ ko tii sọ ohunkohun lori iṣẹlẹ yii lasiko ti a fi n ko iroyin yii jọ.
Chris Ndukwe and Olamide Alli: Ọkùnrin kan gún àfẹ́sọ́nà rẹ pa, òun náà gbé ògùn jẹ
Oríṣun àwòrán, others
Ileesẹ ọlọpaa ipinlẹ Eko ti fidi rẹ mulẹ pe, arakunrin kan ti wọn ni orukọ rẹ n jẹ Chris Ndukwe, ẹni ọdun mọkandinlogoji, ni wọn fura si pe o gun obinrin kan, to n jẹ Olamide Alli pa.
Atẹjade ti ileesẹ ọlọpaa ipinlẹ Eko fisita fun awọn akọroyin salaye pe, lẹyin ti Chris gun Olamide to jẹ afẹsọna rẹ pa tan, ẹti tii se ẹni ọdun mẹẹdọgbọn, lo ba gbe ogun oloro jẹ.
Iroyin naa ni iṣẹlẹ naa waye lọjọ aiku, ọjọ kọkanlelogun oṣu kẹfa ni abule Victory Park, agbegbe Ilasan ni Lekki ni ipinlẹ Eko, ti Olamide to jẹ́ alaisi naa, si wa se abẹwo si Chris, to bi ọmọ meji fun lati agbegbe Ọgba.
Iroyin naa ni Chris lo ransẹ pe Olamide pe ko wa sile oun, ti onitọun naa si wa pẹlu aburo rẹ obinrin, ẹni ọdun mejilelogun ati ọmọ rẹ mejeeji to bi fun Chris, ti wọn jẹ ọmọ ọdun meje ati mẹta.
Olamide, aburo rẹ ati awọn ọmọ rẹ mejeeji sun mọju nile Chris, nigba ti ilẹ si mọ ni aburo Olamide gbọ orin kan to lagbara lati inu yara ti Chris ati ẹgbọn rẹ sun si, igba to de ibẹ lo ri pe awọn mejeeji ti ku.
Kid boxer: Ọmọọba 'The Buzz' Larbie rèé, ọmọ ọdún méje tó ń fi ẹ̀ṣẹ́ dá bírà
Ileesẹ ọlọpa Eko ni ni kete ti wọn fi isẹlẹ naa to oun leti, ni oun ran awọn ọlọpa oluwadii lọ sibẹ, ti wọn si ba obinrin naa ninu ẹjẹ ara rẹ pẹlu ọgbẹ to jin lori rẹ, nigba ti ọkunrin naa n pọ nnkan funfun lẹnu, eyi to seese ko jẹ oogun apakokoro Sniper.
Awọn ọlọpaa tun se akiyesi pe ẹjẹ wa lara ọbẹ to wa ninu yara naa, ti wọn si tun ri korofo igo majele meji , agolo igo ohun mimu Red Bull mẹta ati ẹmu ti wọn fi n yọ eso kan.
Eton tọrọ àforíjìn lọ́wọ́ akẹ́kọ̀ọ́ Nàíjíríà lórí ìwà ẹlẹ́yàmẹ̀yà
Oríṣun àwòrán, Dilibe Onyeama
Olukọ agba Ile ẹkọ girama olokiki nii, Eton College to wa nilẹ Gẹẹsi, ti sọ fun BBC pe, ọkan ohun bajẹ pẹlu bi akẹkọọ alawọdudu to kọkọ pari ẹ́kọ rẹ nibẹ, Dilibe Onyeama, se koju idẹyẹsi ati iwa ẹlẹyamẹya nigba to n kẹkọ nibẹ.
Dilibe Onyeama, tii se ilumọọka onkọwe lorilẹede yii, tun jẹ ẹgbọn Minisita fọrọ ilẹ okeere nil wa bayii, Geofrey Onyeama.
Ile ẹkọ Eton si ni Dilibe ti gba iwe ẹri girama jade lọdun 1969.
Dilibe Onyeama si lo kọ iwe kan nipa iwa ẹlẹyamẹya ti oju rẹ ri nileewe naa ati bi ti ile ẹkọ naa ko se gba a laaye lati pada wa sibẹ mọ.
Olukọ agba ile ẹkọ Eton, Simon Henderson ni awọn ti gbe igbesẹ lati dẹkun iru iwa yi sugbọn o ni oun gba pe lootọ ''isẹ si ku tawọn yoo se''
Ogbẹni Henderson tọrọ aforijin yii gẹgẹ bi idahun si ọrọ ti BBC beere lọwọ rẹ, nipa apilẹkọ kan ti akọroyin Adaobi Tricia Nwaubani kọ, lori nnkan ti oju Onyeama ri lori iwa ẹlẹyamẹya ati nipa iwọde Black Lives Matter to n ja rain.
Orisun: Eton College ati  BBC
"Olukọ agba ile ẹkọ naa sọ pe oun yoo fiwe pe Onyeama lati le tọrọ aforijin lọdọ rẹ ""ki oun si jẹ ko mọ pe ko si igba ti ko le pada wa si ile ẹkọ Eton''"
"Gbogbo wa la gbọdọ sọrọ sita, ki a si mọkan pe a fẹ se daada - mo  setan lati samulo anfaani asiko yii lati fi sokunfa iyipada tootọ, tọkan-tọkan''
Oríṣun àwòrán, Dillibe Onyeama
Onyeama sọ fun BBC pe, ko si wahala kankan ati pe isẹlẹ naa ko mu iyipada si bi oun ti se n foju rere wo ile ẹkọ Eton.
O wa fi kun ọrọ rẹ pe, bi wọn ti se tọrọ aforijin yii ''jẹ ki o di mimọ pe idẹyẹsi eeyan yala nitori awọ ẹni naa tabi ẹya rẹ a maa tẹmbẹlu eeyan, ju orisi iwa abuku miran lọ''
O ti saaju sọ fun BBC pe, ojojumọ lawọn akẹẹgbẹ oun maa n fi oun se yẹyẹ.
Wọn a ma bi ni awọn ibeere pe 'Ki lo de ti o fi dudu?' 'Idin meloo lo wa ninu irun rẹ?' ati pe 'Se iya rẹ a ma fi eegun bọ inu imu rẹ?'
Igba kigba ti Onyeama  ko ba se daada ninu ẹkọ rẹ tabi lagbo idaraya, wọn a ma sọ pe nitori to jẹ alawọdudu lo fa ti ko fi se daada.
Nigba ti o jawe olubori ninu idanwo asekagba, o jẹ iyalẹnu fun gbogbo ile ẹkọ naa.
Wọn bẹrẹ si ni sọ pe''N gbọ na, bawo ni o se se?''
Onyeama ninu iwe rẹ to kọ, sọ pe ''Wọn bi mi pe, se kii se pe o se magomago ninu idanwo?''
Lẹyin to pari ẹkọ rẹ nibẹ, gbogbo ohun to sẹlẹ yii ni Onyeama kọ sinu itan iriri aye rẹ to kọ.
Lọdun 1972, ile ẹkọ naa kọwe si pe, awọn ko fẹ ja pẹtẹ ẹsẹ rẹ nileewe awọn mọ.
Gbogbo aforijin ti olukọ agba to wa nibẹ nisinsin yii n se, ko sẹyin bi awọn ileesẹ nlanla nilẹ Gẹẹsi bii Lloyd's of London ati Greene King, ti se n tọrọ aforijin pe ọwọ awọn ko mọ ninu sise owo ẹru.
Iwọde 'Black Lives Matter' to n mi igboro titi, lo mu ki gbogbo wọn ma tọrọ aforijin lọdọ awọn alawọdudu.
Lọdun 1440 ni Ọba Henry VI da ileẹkọ Eton silẹ, ti o si di ilumọọka nitori iru ẹkọ to ye kooro ti wọn n kọ awọn akẹkọọ nibẹ.
Lọwọlọwọ bayi, awọn akẹkọọ  ile ẹkọ naa  n san owo to to ẹgbẹrun lọna  aadọta dọla lọdun kan.
Alaafin: Wo arẹwà mẹ́jọ̀ tó ń ṣìkẹ́ Ọba Adeyemi
Oríṣun àwòrán, Alaafin Oba Lamidi Adeyemi III
Alaafin tilu Ọyọ, ọba Lamidi Ọlayiwola Adeyemi kẹta ni awọn ọpọ ayaba ni iyẹwu, ti wọn rẹwa pupọ, ti wọn si wu oju ri.
Ta ba ni ka ka wọn mi meni, meji, awọn ayaba naa le ni mẹẹdogun , ti awọn to ti dagba laarin wọn si ti ni ọmọ-ọmọ ati arọmọdọmọ pẹlu.
Amọ lara awọn ayaba naa la ti ri awọn olo, ẹlẹjẹ tutu, apọnbeporẹ, orekelẹwa, ẹlẹyinju ẹgẹ, eyinfunjowo ati Ibadi aran, ti wọn jẹ mẹjọ, ti wọn maa n se idije lawọn oju opo ayelujara wọn, lati jẹ ki araye mọ pe ọla Alaafin ni awọn fi n yan.
Bakan naa ni awọn ayaba olo, ẹlẹjẹ tutu yii tun maa n se idije laarin ara wọn pe, ta ni afẹfẹ (Oxygen) ti Alaafin fi n mi laarin awọn?
Ọpọ awọn orukọ si ni wọn maa n pe ara wọn bii 'Ẹlẹ Daddy' abi 'Oxygen' Alaafin, ti ariyanjiyan si tun maa n wa lati mọ ẹni ti oriki naa tọ si.
Sugbọn iwadi BBC Yoruba fihan pe, ni aafin Ọyọ, awọn ayaba orekelẹwa yii le ni mẹjọ to jẹ afẹfẹ ti alaafin fi n mi, ta a si tun le pe wọn ni Ẹlẹ Daddy, gẹgẹ bi wọn se n pe ara wọn.
Diẹ nipa iroyin ọkọọkan wọn ree:
Oríṣun àwòrán, Abbey Adeyemi Facebook
Olori Abiodun yii la lee pe ni iya awọn ewe ni aafin Ọyọ, eyi tums si alakoso awọn ayaba kekere to wa lẹyin rẹ.
Lati ori obinrin yii si ni awọn apọnbeporẹ wa, yatọ si awọn agbaagba olori to siwaju rẹ
Bi o tilẹ jẹ pe Olori Abiodun kii fi bẹẹ na oju opo ayelujara bii ti awọn olori to de lẹyin rẹ, sibẹ ara awọn olo, ẹlẹjẹ tutu ti Alaafin fi n gbe ẹmi ro ni.
Olori Aishat Folasade Adeyemi:
Oríṣun àwòrán, Ayaba Folashade Adeyemi
Ayaba Folasade lo tẹle Olori Abiodun, ti oun naa si wa lara awọn ẹlẹ ẹlẹjẹ tutu, ti Alaafin fi n se afẹfẹ gbẹmiro ni Aafin Ọyọ.
Olori naa si jẹ ara awọn apọnbeporẹ Alaafin to gbajumọ ni aafin Ọyọ, paa paa nitori pe o tun bi ibẹta fun ọba Lamidi Olayiwola Adeyemi Kẹta.
Ọpọ eeyan lo tun maa n pe olori Folasade ni Iya Mẹta abi yeye Iṣẹṣe, to si mọ oriki awọn Alaafin to ti jẹ sẹyin ati ti ọkọ rẹ pẹlu.
Lasiko ti Alaafin ba n se ayẹyẹ, ni yeye iṣẹṣe maa n ki oriki naa lati da awọn alejo laraya.
Oríṣun àwòrán, queenola2 Instagram
Olori Badirat lo kọkọ pe ara rẹ ni afẹfẹ ti Alaafin n mi sinu, ti oloyinbo n pe ni Oxygen, oun naa si lo tun pe ara rẹ ni ẹlẹ Daddy .
A si le ni orukọ yii mọ lara nitori arẹwa ati ọmọde ni laarin awọn ayaba lode Ọyọ, to si jẹ aayo Alaafin laarin awọn ayaba.
Okunrin kan ati ibeji ọkunrin meji ni awọn ọmọ ti olori badirat bi fun ọba Adeyemi, ọdun 2018 si lo bi awọn ibeji naa.
Laipẹ yii ni awuyewuye kan waye pe ọba Fuji, Wasiu Ayinde Mashal n lo ifẹ ikọkọ pẹlu olori naa, amọ ti ayaba Badirat ti sẹ pe ko si ohun to jọ eyi rara.
Oríṣun àwòrán, olori_omoh_one
Olori Memunat yii wa lara awọn ayaba ọba Adeyemi to gbafẹ, o lọyaya, to si ko ni mọra.
Ọrẹ timọ timọ ni olori Memunat ati olori Badirat, ki wọn to wọ aafin Ọyọ, ati lẹyin ti awọn mejeeji di ayaba tan.
Asọ ẹgbẹjọda si ni awọn mejeeji maa n wọ lasiko kan, eyi ti ko yọ awọn ayaba yoku silẹ nigba miran.
Oríṣun àwòrán, Olori Memunat Adeyemi Facebook
Ọrẹ awọn olori mejeeji yii wọ debi pe wọn maa n ki ara wọn ni mẹsan-mẹwa ni lori ayelujara, ti wọn si tun dijọ n ta asọ ni.
Bakan naa, wọn tun se ọrẹ debi pe ọdun 2018 ni Badirat ati Memunat dijọ bi ibeji, tawọn ibeji Memunat si jẹ obinrin, ti oun naa ti bi ọkunrin fun Alaafin saaju awọn ibeji.
Oríṣun àwòrán, queenmoji_gloo Instagram
Mojisola naa wa lara awọn ẹlẹ daddy, atupa palọ ati 'oxygen' ti Alaafin fi n mi lode Ọyọ.
Mojisola bi ọmọbinrin kan ati ọmọkunrin fun ọba Adeyemi, to si tun daju yoo bi si.
Osu kẹta ọdun 2019 lo bi ọmọkunrin kan ti wọn sọ orukọ rẹ ni Khalid, ti ayaba yii kii si na oju opo ayelujara to bẹẹ.
Oríṣun àwòrán, Mariam Jola Adeyemi Facebook
Ọpọ eeyan ni ko fi bẹẹ mọ nipa Ayaba yii  nitori ko si lara awọn ayaba to saba maa n ta kangbọn lori ayelujara.
Sugbọn losu kẹta ọdun 2019, olori Mariam naa bi ọmọkunrin kan lẹyin ọsẹ mẹta ti olori Mojisola bimọ
Oríṣun àwòrán, queenmoji_gloo Instagram
Ẹgan ni hẹẹ, olori Anuoluwapo naa rẹwa lobinrin, ti ko si se fi ọwọ rọ sẹyin laarin awọn ẹlẹ Daddy to wa ni aafin Ọyọ.
Anuoluwapo si ni aayo ati ẹyinju Alaafin ko to gbe iyawo le e.
Asiko kan tiẹ wa to se ọjọ ibi, ti oun ati Alaafin dijọ n gbe ife ọti si ara wọn lẹnu, to si fesi loju opo ayelujara pe Ta ni ẹlẹ daddy ati oxygen ti Alaafin fi n mi bayii?"""
Oríṣun àwòrán, queen_aanu
Ọrọ yii si lo daju pe o fi n fesi pada fun Olori Badirat, to kọkọ pe ara rẹ ni ẹlẹ Daddy  ati oxygen ti ọba Adeyemi fi n mi, eyi to kọ bi akọle sabẹ aworan kan ti oun ati sba naa dijọ ya.
Ọmọkunrin kan ati ọmọbinrin kan si ni olori Anuoluwapo bi fun Alaafin lọwọ lọwọ bayii.
Oríṣun àwòrán, Damilola Adeyemi
Olori Damilola ni iyawo kekere laarin awọn arẹwa Alaafin bayii, oun si ni oju baba ati afẹfẹ tuntun ti Alaafin n mi simu.
Osu keji ọdun 2020 si ni olori Damilola bi ọmọkunrin tuntun fun Alaafin Ọyọ.
Genotype: Kí làwọn àǹfàni àti ewu tí ẹ̀yà jínótáìpù rẹ le mú bá ìgbé ayé rẹ̀?
Ọpọ eniyan lo n gbe igbe aye wahala nitori aimọkan wọn lori jinitaipu wọn. irufẹ igbesẹ bẹẹ tilẹ tun ti fa ipalara fun ọjọ ọla ọmọ wọn.
Eyi ni ohun ti eto laa han mi gbe yẹwo lọtẹ yii.
Àwọn òmùwẹ̀ ń wá èèyàn kan tó pòórá lẹ́yìn ìjàmbá ọkọ̀ ojú omi to dójúdé l'Eko
Oríṣun àwòrán, twitter/LASWA
Lai tii pe ọsẹ kan lẹyin ti ijọba ipinlẹ Eko kede iroyin ayọ pe ko si ijamba ọkọ ojuomi lawọn ojuna agbami ni ipinlẹ naa laarin oṣu mẹfa, eeyan kan ti di wiwa bayii lẹyin ti ọkọ oju omi kan to n rinna lọ loju agbami agbegbe Lekki dojude.
Iroyin fi idi rẹ mulẹ pe mẹta ninu awọn to wa ninu ọkọ oju omi to dojude naa ni wọn doola ẹmi wọn.
Awọn mẹrin lo wa ninu ọkọ oju omi naa lasiko ti ijamba naa fi waye ṣugbọn wọn ṣi n wa ẹni kẹrin wọn bayii.
Iji nla to ja lori omi naa lasiko irinajo wọn ni wọn ni o ṣokunfa idojude ọkọ naa.
Awọn alaṣẹ ajọ to n mojuto igbokegbodo ọkọ oju omi nipinlẹ Eko, LASWA atawọn ajọ miran la gbs pe wọn pawọ pọ ṣe bẹbẹ ni kete ti ijamba naa ṣẹlẹ lati doola awọn to wa ninu ọkọ naa.
Lasiko ti a fi n ko iroyin yii jọ, awọn omuwẹ ṣi n wa eeyan kan to ku ninu ọkọ oju omi naa.
Eji Gbadero: Ó pa Raji Oba nítorí ilẹ̀ nìjọba bá yẹgi fún un
Oríṣun àwòrán, Others
Yoruba ni aye ko tọ lọ bii orere, igba ko si tọ lọ bii ọpa ìbọn, gbogbo alagbara aye si lo yẹ ko rọra ṣe nitori ilẹ n yọ.
Ni ojumọ toni to mọ yii, ọpọ alagbara aye lo wa, ti wọn n jẹ aye familete ki n tutọ, wọn ni awọn lo ni oni, lai mọ ẹni ti yoo ni ọla, ti wọn si n jẹ aye ọlọba.
Boya ọlọkọ ero ni ẹ ni, abi ọmọ onilẹ, baba isalẹ oloselu ni ẹ ni abi agba janduku, ẹ ko ṣe fi igbe aye awọn alagbara aye to ti kọja lọ kọgbọn ati atubọtan wọn.
Ọkan lara awọn ajunilọ, tii fi ọwọ ọla gba ni loju ni ọkunrin kan nilu Eko, ti ọpọ eeyan mọ si Eji Gbadero, o lowo, o lọla, to si gbajumọ ni saa ọdun 1970 wa soke, bi igbe aye ati iku rẹ si ṣe lọ ree, gẹgẹ bi a ṣe ka a ni oju opo itakun agbaye.
Àwọn ìtàn Mánigbàgbé tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí:
Jimoh Isola Adeyemi ni orukọ abisọ ọkunrin ta n sọrọ rẹ yii, ti awọn inagijẹ rẹ si n jẹ Eji Gbadero, Kiniun baba Moradewun ati Kiniun Mushin, ṣe orukọ to ba wu ọmọ nii jẹ lẹyin odi.
Adugbo Ọja Ọba nilu Ibadan, tii ṣe olu ilu ipinlẹ Oyo ni Eji Gbadero, ọdọmọde si lo ti tẹle aburo baba rẹ wa gbe ni Eko, o kọ iṣẹ ọwọ, to si da Ileesẹ tiẹ naa silẹ to n ṣe ésó.
Eji Gbadero lowo, o gbajumọ, ọmọ jaye-jaye ni, laarin ọdun 1960 si 1970 lọ soke, Eko kan, Gbadero kan ni, lọtun losi si ni awọn olorin maa n ki i, koda, Ebenezer Obey ati Yusuf Olatunji gan wa lara awọn olorin to kii, eyi to n sọ bo ṣe jẹ ilumọọka si nigba naa.
Ni wọn igba to jẹ pe ọna kan ko wọ ọja, owo to n ri nidi èsó tita ko to na mọ fun Eji Gbadero, ó bẹrẹ si ta ilẹ, ra ilẹ, o n ta ile, ra ile, ko si si ẹni to lee gbe ina wo oju Kiniun baba Moradewun, ko ma ge ika jẹ ni igbẹyin.
Eji Gbadero ni olugbeja ẹni ti wọn ba gba ilẹ rẹ, tabi ẹni to fẹ fi tipa gba ilẹ lọwọ ẹlomiran, to fi mọ ipese aabo to peye fun awọn ilẹ ti ẹnikẹni ko le e gba, to si di ọrẹ ọlọpaa.
Koda, gbogbo ẹka agbofinro, awọn adajọ ati awọn Agbẹjọro ni ọrẹ Eji Gbadero nitori ojoojumọ ni wọn n gbe lọ sile ẹjọ, to si mọ ẹsẹ ofin ti yoo sọ fun Agbẹjọro rẹ pe ko fi daabo bo oun nile ẹjọ lai lọ sile ẹkọ nipa ofin.
Kiniun baba Moradewun n jaye ọlọba, kii gba ẹbi bọ nile ẹjọ afi are, ọrọ ti owo ba ṣe ti ni ọrọ Gbadero, ilẹ ni yoo gbe, koda, a le e pe Gbadero ni ofin funra rẹ.
Oríṣun àwòrán, Others
Ni ọjọ kan lọdun 1975, Eji Gbadero ati awọn ọmọ ẹyin rẹ lọ san ilẹ nla kan to gbooro ni agbegbe Alumoso, ibẹ ko si tii laju nigba naa, inu abule ni. Ilẹ ti wọn san ọhun kun fun koko ati obi.
Ni kete ti awọn ara abule naa si ri pe ọrọ aje awọn ni awọn kan n bajẹ yii, wọn ba kọju si Gbadero lati beere pe ki lo de, ti oun naa si da wọn lohun pe lati ọdun 1970 ni oun ti ra ilẹ naa pamọ.
Ṣe ni awọn ara abule yii la ẹnu sílẹ lai lee pa de mọ, nitori o han daju pe irọ ni Gbadero n pa.
Bẹẹ ni wọn n beere lọwọ rẹ pe, eelo lo ra ilẹ ọhun, lọwọ ta lo ti ra a, awọn eeyan wo ni ẹlẹri rẹ, ta si lo san owo ilẹ naa fun?
Ṣugbọn kaka ki Eji fun wọn lesi, yiyan lo n yan kiri lori ilẹ naa, ti awọn ara abule naa ko si jẹ ki wọn tẹsiwaju lati san ilẹ ọhun mọ,
Bẹẹ ni Gbadero ati awọn ọmọ ẹyin rẹ yi ẹsẹ pada, wọn kuro nibẹ, ti awọn ara abule si n pariwo le lori, bo ṣe n lọ.
Ṣugbọn agbo to fi ẹyin rin lọ, agbara lo lọ mu wa ni ọrọ Eji Gbadero, bẹẹ ni ko si igi kigi ti igbin rẹ tẹnu mọ, ti ko ni mu gun, ko si si ilẹ ti Gbadero ba nifẹ si, ti ko ni gba ni tipatipa.
Kid boxer: Ọmọọba 'The Buzz' Larbie rèé, ọmọ ọdún méje tó ń fi ẹ̀ṣẹ́ dá bírà
Awọn ara abule yii mọ pe Gbadero yoo pada wa, kiakia ni wọn si lọ fi ẹjọ rẹ sun ni agọ ọlọpaa to wa ni Agege.
Bi wọn si de n de ibẹ, naa ni Gbadero yọ lẹyin wọn, ti oun naa wa fi ẹjọ sun ọlọpaa.
Amọ gbogbo igbiyanju awọn agbofinro lati yanju ọrọ yii ni pẹlẹ putu lo ja si pabo.
Ọkan lara awọn ara abule naa ni arakunrin kan ti wọn n pe ni Raji Oba, o mọ ọrọ sọ, to si laya bii Kinihun, ko bẹru Eji Gbadero rara, to si sọ bẹẹ loju rẹ
Sabitu sare lọ sọ fun ọkọ rẹ pe oun ma kofiri Gbadero ni aarin abule ni alẹ yii, ti ẹnu si ya onitọhun pe ki lo n wa nibẹ lọwọ alẹ.
Amọ bi wọn ṣe dakẹ, ti Sabitu wọle lọ, ni Gbadero yọ si Raji, to si da ìbọn bo o ni orí, bi iyawo Raji si ṣe sare bọ sita, lo ri akọyinsi Eji Gbadero ati awọn ọmọ ẹyin rẹ ti wọn n sa wọnu igbo lọ.
Sabitu ri pe Gbadero wọ sokoto ati ẹwu oloyinbo, to si mu ìbọn dani.
"Oun si lo kẹyin awọn eeyan to n sa lọ naa, ti Sabitu si n pariwo pe ""Eji Gbadero mo ri ẹ o, ara abule, Eji Gbadero ti pa mi lọkọ ó."""
Genotype: Kí làwọn àǹfàni àti ewu tí ẹ̀yà jínótáìpù rẹ le mú bá ìgbé ayé rẹ̀
Eji Gbadero pada soju agbo ayẹyẹ ikomọ rẹ, to si n ba ọpọ eeyan ya fọto loju agbo, asiko yii si ni awọn ara abule lọ sọ fun awọn ọlọpaa Alimoso pe Eji Gbadero ti pa Raji Oba.
Oju agbo si ni awọn ọlọpaa ti lọ mu pe ko yọju si agọ awọn, ti gbogbo alejo to wa nibi ikomọ naa si n gba ẹri Gbadero jẹ pe ko jade lọ sibi kankan lọjọ naa.
Igbẹjọ bẹrẹ, awọn ẹlẹri bii orisi mẹta jade lati abule Alimoso, ti wọn si jẹri pe gbangba ni awọn ri Gbadero lọjọ naa ni abule wọn pẹlu ọkọ Pijo 504 rẹ.
Koda wọn ni oun ati awọn gende to ko so sẹyin wa sibẹ ni, ti meji ninu wọn si ni awọn ri ìbọn lọwọ rẹ.
Ṣugbọn awọn ẹlẹrii Eji Gbadero naa tako wọn pe inu ile ni olujẹjọ naa wa, to n tọju awọn alejo rẹ níbi ayẹyẹ ikomọ jade rẹ.
Amọ bi irọ ba lọ titi fun ogun ọdun, ọjọ kan ṣoṣo ni otitọ yoo ba a.
Bẹẹ ni ọrọ ri pẹlu ẹjọ Eji Gbadero. Ọpẹlọpẹ ọdẹ alẹ kan ni Ileesẹ Gbadero, to wa lara awọn ẹlẹrii, to tan imọlẹ si idi ọrọ yii.
Badagry ní ogún àjogúnbá tó pọ̀ yàtọ̀ sí òwò ẹrú
Kehinde Yekini ni orúkọ ọdẹ alẹ naa, to si jẹri pe Eji Gbadero wa si Ileesẹ rẹ ni alẹ ọjọ kejilelogun, oṣu kẹjọ, ọdun 1975 naa.
Lẹyin naa lo morile Alimoso pẹlu Modina, Osadebey, Isiaka, Bakare, Wahab Oduntan ati Lukman, ti wọn si tun pada si Ileesẹ naa ni aago mẹsan alẹ.
Yekini fikun pe  nigba ti wọn pada de lati Alimoso, Gbadero fa ìbọn yọ lati abẹ sokoto rẹ, to sì sọ fun oun pe oun Eji Gbadero ti pa ọkùnrin ti Kehinde kọ lati pa.
Adajọ ri idi okodoro ọrọ, to si dajọ pe Eji Gbadero jẹbi ẹsun iditẹ lati pa eniyan ati ipaniyan, to si ni ki wọn lọ yẹgi fun, titi ti ẹmi yoo fi bọ lara rẹ.
Gbadero pe ẹjọ kotẹmilọrun, ti awọn adajọ mẹta to gbọ ẹjọ naa si gba pe ko jẹbi ẹsun iditẹ lati pa eeyan amọ o jẹbi ẹsun ipaniyan.
Gbadero tun gba ile ẹjọ to ga julọ ni Naijiria lọ lọdun 1977, ti wọn si fa ẹjọ ọhun wọ ọjọ kẹrindinlọgbọn oṣu Kẹwa ọdun 1978, nigba ti idajọ waye pe lootọ ni Eji Gbadero jẹbi ẹsun ipaniyan.
Nigba to di ọdun 1979, eyiun ọdun mẹrin lẹyin ti Gbadero pa Raji Oba, ijoba yẹ igi fun oun naa, ti Kiniun baba Moradewun si dagbere fun aye pe o digbose.
Toyin Ibietan: Àlòkù táyà ọkọ̀ ló mú mi rí nǹkan ṣe lásìkò ìgbélé COVID-19
Ibadan Murder: Shagbada pa ọ̀rẹ́bìnrin torí kò gbà kó bá a lò pọ̀
Oríṣun àwòrán, Others
Ileeṣẹ ọlọpaa ipinlẹ Oyo ti fi oju ẹni ọdun mẹrinlelogun kan han, lẹyin ti wọn fẹsun kan an pe o pa ọrẹbinrin rẹ Happiness Winfred ni ij̣oba ibilẹ Akinyele ni ilu Ibadan.
Afurasi naa, Shagbada Erigga, jẹwọ pe lootọ ni oun hu iwa ọdanran yii nigba ti wọn fi oju rẹ atawọn afurasi mejilelọgbọn miran han.
Ẹni ọgbọn ọdun ni arabinrin Hapiness ti ọrẹkunrin rẹ pa tori ibalopọ.
Nigba ti awọn akọroyin fi ọrọ wa lẹnu wo, afurasi naa ni lootọ ọrẹbinrin oun ni, ṣugbọn wahala bẹ silẹ laarin wọn nitori ko gba ki o ba a lo pọ.
O ni ibi ti wọn ti n ṣe ariyanjiyan lori idi ti ko ṣe gba ki o ba a ni ṣe pọ ni oun ti fun un ni ẹṣẹ mẹta pere, to si gba'bẹ dagbere faye.
Nigba to n jabọ fun awọn akọroyin lori iṣẹlẹ naa, Kọmiṣọna ọlọpaa nipinlẹ Oyo, Joe Nwachukwu Enwowu sọ pe ọwọ tẹ Erigga lẹyin ti wọn fi ọrọ rẹ sun ni ẹka ileeṣẹ ọhun to wa ni agbegbe ̣Ojoo.
O ni ọkunrin kan, Agu Benson lo fi to awọn ọlọpaa leti ni Ogunjọ, Oṣu Kẹfa, ọdun 2020 pe oun ri oku eeyan ninu kanga ile rẹ.
Kọmiṣọna ọlọpaa naa ṣalaye siwaju sii pe iwadii ati iṣẹ takuntakun ileeṣẹ ọlọpaa lo jẹ ki wọn ri afurasi ọhun mu.
"O ni ""Happiness Winfred kuro ni ile rẹ lọjọ Aiku, Ọjọ Kọkanlelogun, Oṣu Kẹfa, ọdun 2020,"
"Ṣugbọn inu kanga ni wọn ti ri oku rẹ ni Ọjọ Karundinlọgbọn. oṣu kan naa ninu ile kan lagbegbe Oritoke, ni Ojoo, ni ilu Ibadan."""
Ni bayii ti ọdanran naa ti jẹwọ, yoo foju bale ẹjọ laipẹ.
Isẹlẹ ikọlu miran tun ti waye ni agbegbe Akinyele nilu Ibadan ni idaji ọjọ Aiku.
Lọtẹ yii, arabinrin kan, Adeola Bamidele ati ọmọ rẹ obinrin, Dolapo, ni awọn agbebọn kan kọlu ninu ile wọn.
Oríṣun àwòrán, Others
Deede aago kan oru ni isẹlẹ naa waye , tawọn afurasi ọdaran naa si gba ẹrọ ibaraẹnisọrọ alagbeka meji .
Bakan naa ni wọn sa tiya-tọmọ lọgbẹ ni ori, ti awọn mejeeji si wa nile iwosan fun itọju.
Nigba to n salaye bi isẹlẹ naa se waye, arabinrin Adeola, tii se ẹni ọdun marundinlaadọta ni ada ni awọn afurasi ọhun fi sa oun lasiko ti oun n du ẹmi ọmọ oun lọwọ ikọlu, ti oun si ba ara oun ninu agbara ẹjẹ.
Amọ Dolapo, tii se ẹni ọdun mẹtalelogun ko lee sọrọ rara nitori oro ọgbẹ ada ti wọn sa a, eyi to jin wọnu.
'Buns ni ọmọ mi jẹ tán ní ṣọ́ọ̀ṣì, ló bá di àwátì'
Nigba to n fi idi isẹlẹ naa mulẹ fun BBC Yoruba, osisẹ alarena fun ileesẹ ọlọpaa nipinlẹ Ọyọ, Olugbenga Fadeyi salaye pe lootọọ ni ikọlu ọhun waye.
Fadeyi ni ọwọ ti tẹ awọn afurasi kan lori awọn iwa isekupani ati ikọlu to n waye lagbegbe Akinyele naa.
Bakan naa lo fi kun pe lọsan oni ni wọn yoo se afihan awsn afurasi to wa nidi isẹlẹ Akinyele naa ni olu ileesẹ ọlọpaa to wa ni Ẹlẹyẹle nilu Ibadan.
A o ranti pe o ti to obinrin mẹrin ati ọkunrin kan, Mujeeb Tirimisiyu, Barakat Bello, Grace Oshiagwu, Azeezat Shomuyiwa ati Olusayo Fagbemi, ti wọn ti pa ni Akinyele naa.
Iléeṣẹ́ ọlọ́pàá ní aago márùn-ún ìdájí ni wọ́n pa obìnrin náà níwájú ilé rẹ̀
BBC ṣe abẹwo si ile arabinrin Oluṣayọ Fagbemi, abilekọ ẹni ọdun mejilelogoji ti awọn amokunṣeka kan tun ṣekupa l'owurọ Ọjọru ni agbegbe Ṣaṣa, ijọba ibilẹ Akinyẹle niluu Ibadan.
Oṣojumikoro fi idi ọrọ naa mulẹ fun awọn akọroyin wi pe abọ́ ni arabinrin naa n fọ ni iwaju ile ni idaji ọjọ naa ki awọn olubi ẹda to ṣe ikọlu sii.
Ariwo rẹ ni ọkọ rẹ gbọ ti o si sare si ibi ti aya rẹ ti n fọ abọ sugbọn epa ko ba oro mọ.
Inu agbara ẹjẹ lo ti ba aya rẹ pẹlu apa ibi ti wọn ti fi nnkan ṣaa lori ti wọn si salọ.
"Ọkan lara awọn aladugbo ti o ba wa sọrọ, Ọgbẹni Lateef Nurudeen ṣe alaye wi pe ni nnkan bii aago marun un idaji ti wọn maa n lọ kirun n wọn deede gbọ ti ọkọ oloogbe n pariwo ""ẹ gba mi o""."
Wọn ni bẹẹ naa lo tun n pariwo orukọ iyawo rẹ, ṣugbọn ninu agbara ẹjẹ ni wọn ti ba iyawo naa.
Akinyele Murder: Iléeṣẹ́ ọlọ́pàá ní aago márùn-ún ìdájí ni wọ́n pa obìnrin náà níwájú ilé rẹ̀
O tẹsiwaju wi pe o fẹẹ to bii iṣẹju mẹwaa ki wọn to ri arabinrin naa gbe kuro ninu agbara ẹjẹ lọ si ile iwosan, ṣugbọn igbiyanju wọn ja si pabo.
Wọn parọwa si ijọba ati awọn agbofinro lati fi oju ṣebi han.
Obinrin mẹrin ati ọkunrin kan ni wọn ti pa ni adugbo Akinyele
Ọmọ mẹta ni oloogbe fi silẹ saye lọ, mẹji ninu wọn wa laarin ọmọ ọdun mẹrin si mẹfa.
Iroyin si ti fi idi ẹ mulẹ wi pe iya wọn ṣii n pọn abigbẹyin ni.
Obinrin mẹrin ati ọkunrin kan ni wọn ti pa ni adugbo Akinyele
BBC gbiyanju lati ba ọkọ oloogbe sọrọ, ṣugbọn a ko ri wọn ni ayika ile naa lasiko ti abẹwo si ibe.
Akinyele Murder: Iléeṣẹ́ ọlọ́pàá ní aago márùn-ún ìdájí ni wọ́n pa obìnrin náà níwájú ilé rẹ̀
Nibayii, ile iṣe ọlọpaa ni ipinlẹ Ọyọ tun ti jẹjẹ lati ṣawari awọn ọdaran ti o fẹ sọ ijọba ibilẹ Akinyẹle di ibi ẹru fun awọn olugbe ipinlẹ Ọyọ.
Ninu atẹjade ti wọn fun lede gbatọwọ alukoro ile iṣẹ ọlọpaa nipinlẹ Ọyọ, Olugbenga Fadeyi ṣe alaye iṣẹ iwadii ti bẹrẹ ni pẹrẹu.
Akinyele Murder: Iléeṣẹ́ ọlọ́pàá ní aago márùn-ún ìdájí ni wọ́n pa obìnrin náà níwájú ilé rẹ̀
Mùjẹ̀-mùjẹ̀ ní Akinyele tún ti mu ẹ̀jẹ̀ obìnrin míràn lónìí
Kaka ki ewe agbọn dẹ ni adugbo Akinyele nilu Ibadan ti wọn ti n pa awọn eeyan lẹnu ọjọ mẹta yii, ko ko ko lo n le si i.
Akinyele Murder: Iléeṣẹ́ ọlọ́pàá ní aago márùn-ún ìdájí ni wọ́n pa obìnrin náà níwájú ilé rẹ̀
Idi ni pe wọn tun ti pa obinrin miran,Olusayo Fagbemi, ladugbo Akinyele naa yatọ si Mujeed ti wọn pa nibẹ lọjọ Iṣẹgun.
Nigba to n fidi isẹlẹ naa mulẹ, osisẹ alarina fun ileesẹ ọlọpaa ipinlẹ Oyo, Olugbenga Fadeyi ni aago marun idaji Ọjọru ni wọn pa obinrin naa.
Ni deede aago mẹfa ku ogun isẹju ni idaji Ọjọruni wọn kọlu obinrin kan, Olusayo Fagbemi, ẹni ọdun mejilelogoji, lasiko to n fọ abọ niwaju ile rẹ, to si ni ọgbẹ lori.
Fadeyi tẹsiwaju pe ariwo obinrin naa lo mu ki ọkọ rẹ sare jade lati inu ile, to si ba iyawo rẹ ninu agbara ẹjẹ, ti awọn eeyan to sisẹ laabi naa si ti fẹsẹ fẹ ẹ.
O ni wọn gbe obinrin naa lọ sile iwosan amọ ẹpa ko boro mọ nitori obinrin naa ti jade laye.
Genotype: Kí làwọn àǹfàni àti ewu tí ẹ̀yà jínótáìpù rẹ le mú bá ìgbé ayé rẹ̀
Ileesẹ ọlọpaa ni aayan ti n lọ lọwọ lati sawari awọn olubi ẹda naa.
A o ranti pe o ti to obinrin mẹrin ati ọkunrin kan, Mujeeb Tirimisiyu, Barakat Bello, Grace Oshiagwu, Azeezat Shomuyiwa ati Olusayo Fagbemi, ti wọn ti pa ni Akinyele naa, ti awọn ọlọpaa ko si ti mọ awọn eeyan to pa wọn.
Oríṣun àwòrán, Other
Ogun Majek: Ọmọ, ẹbí àti àwọn òṣèré tíátà ló péjú sìnkú olóògbé
Gbajumọ osere tiata to doloogbe ni idaji ọjọru, Gbolagade Majekodunmi ti wọ kaa ilẹ sun ni ọsan oni.
Abule oloogbe naa, ti ọpọ eeyan mọ si Ogun Majek, to wa ni agbegbe Elesude, lọna Ọmi ni ilu Ibadan ni wọn yoo sin wọn si.
Ẹbi, ara awọn ọmọ ati ojulumọ to fi mọ awọn osere tiata lo peju sibi isinku Ogun Majek.
Ilana ẹsin musulumi ni wọn fi sin oku agba osere ọhun, ti awọn ọmọ rẹ si n sọkun pe o digbo se.
Iroyin to n tẹ wa lọwọ ni yajoyajo ti salaye pe, ilumọọka osere tiata Gbolagade Akinpelu, ti ọpọ eeyan mọ si Ogun Majek ti jade laye.
Ọrẹ timọtimọ Ogun Majek ti wọn tun jọ jẹ oṣere tiata, Musiliu Dasofunjo, ti ọpọ eeyan mọ si Esu laalu, lo fi idi isẹlẹ naa mulẹ fun BBC Yoruba.
Dasofunjo ni ibanujẹ ọkan lo jẹ fun oun nigba ti oun gbọ nipa iku ọrẹ oun yii, nitori ko dagba debi to yẹ ko ku lasiko yii.
Dasofunjo ni wọn gbe Majek digbadigba lọ si ileewosan UCH ni Ibadan, nigba ti aisan rẹ fẹ bọwọ sori amọ ẹpa ko boro mọ.
O fikun wi pe, kii se pe agba lo de si ọrẹ oun nitori ọjọ ori rẹ ko tii to nnkan, amọ asiko ti to, ni Majek fi di ero ọrun.
Oríṣun àwòrán, Foluke Daramola Instagram
Aisan kidinrin ati aisan itọ suga ni Majek ti n ba finra fun ọpọlọpọ ọdun ko to jade laye.
Dasọfunjo fikun pe, aago meji ọsan oni ni wọn yoo sin Majek gẹgẹ bi ilana ẹsin musulumi.
Ọrẹ timọtimọ Ogun Majek, Musiliu Dasofunjo ni ilu wọn ni agbegbe Elesude, lọna Ọmi ni ilu Ibadan ni wọn yoo sin wọn si.
Musiliu Dasofunjo ni awọn ẹgbẹ oṣere Yoruba ni yoo ṣeto isinku rẹ.
Musiliu Dasofunjo wa sapejuwe Ogun Majek gẹgẹ bi ẹni to ni suuru, ti kii si fa wahala.
Majek jẹ ẹni ti ko si nkan ti ko ba lara mu, to si tutu ni iwa.
Oríṣun àwòrán, Others
Gbolagade Akinpelu ti ọpọ eeyan mọ si Ogun Majek ti n ṣe àìsàn láti ọjọ́ mẹ́ta kan, kó tó kú ní Ọjọru.
"Dasofunjo tun ni ""laarin ọpọ eniyan, Majek jẹ ẹni to lawọ, ti ko ba ni, o maa n jẹ ibanujẹ ọkan fun un."""
Dasofunjo ni ohun to dun oun ju ni pe, oun ko ni ri mọ, ti wọn ko si ni lee sọrọ lori ẹrọ ilewọ mọ.
Abiola Ajimobi: Àwọn ìgbà tí aráàlú fajúro lórí ìṣèjọba rẹ̀!
Oríṣun àwòrán, Abiola Ajimobi
Yoruba ni ariṣe ni arika, arika si ni baba iregun, ohun ti onikaluku ba se lonii, ọrọ itan ni yoo da bo ba d'ọla.
Bẹẹ ni ọrọ ri pẹlu iku gomina ana nipinlẹ Ọyọ, Sẹnatọ Abiola Ajimobi to papoda l'Ọjọbọ lẹni aadọrin ọdun.
Lasiko ti oloogbe naa ṣi n ṣe saa lori alefa gẹgẹ bii gomina nipinlẹ Ọyọ, oniruuru awuyewuye lo waye lasiko naa nipa awọn igbesẹ kan ti ijọba rẹ gbe.
Idi si ree ti BBC Yoruba fi se akojọpọ awọn awuyewuye meje to waye, eyi to mu ki ẹnu maa kun Ajimobi lasiko to jẹ gomina nipinlẹ Ọyọ.
Oríṣun àwòrán, Abiola Ajimobi
Igba to wo isọ ati ile lulẹ kaakiri ipinlẹ Ọyọ:
Ni saa akọkọ gomina Abiola Ajimobi lo wo awọn sọọbu kan to wa lẹba oju popo yika ipinlẹ Ọyọ, paapa nilu Ibadan.
Awijare gomina ni pe igbesẹ kikọ isọ sẹba titi lewu pupọ, to si lee se ijamba fun ẹmi araalu, ti mọto ba lọ ya ba wọn.
Bakan naa, ni ijọba Ajimobi tun wo awọn ile kan to wa lẹba odo ati awọn to wa lẹba oju popo ki anfaani lee wa lati fẹ oju popo yika ipinlẹ Oyọ.
Awọn igbesẹ naa si lo bi awuyewuye laarin araalu, ti wọn si n pariwo pe ika ni gomina Ajimobi fi igbesẹ naa se.
Idi ree ti wọn fi sọ ni inagijẹ Isiaka wolewole lasiko naa.
Oríṣun àwòrán, Others
Igba keji ti ẹnu tun kun oloogbe Abiola Ajimobi lasiko to wa lori oye gomina ni igba ti isẹlẹ ajaalẹ waye ladugbo Soka nilu Ibadan.
Ajaalẹ yii ni asiri tu pe awọn ajọmọgbe n lo lati maa ta ẹya ara eeyan, eyi ti wọn sọ ni ajaalẹ Soka.
Bi o tilẹ jẹ pe ijọba fi katakata wo ajaalẹ naa mọlẹ, to si run womuwomu, sibẹ ọpọ eeyan lo n fi ẹnu kun ijọba Ajimobi pe ko fi ẹnikẹni jofin lori isẹlẹ naa.
Ni ọpọ igba tun ni ẹnu kun oloogbe Abiola Ajimobi pe o kundun ko maa ja si agba.
Idi ni pe ti gomina ba n sọrọ nipa ẹnikẹni, yoo bẹrẹ si sọrọ nipa ọjọ ori onitọun, ti yoo si ni aburo oun ni tabi pe oun ju wọn lọ.
"Koda, ẹni to ba ju Abiola Ajimobi, yoo tun sọ fun pe ""ọjọ melo gan lẹ fi ju mi lọ""."
Oríṣun àwòrán, Others
Eruku sọ lala lori Abiola Ajimobi lasiko to se atunto ofin ati ilana oye ọba jijẹ nilẹ Ibadan.
Atunto ilana oye ọba naa si lo fun Ajimobi lanfaani lati yan ọba mọkalelogun ni ọjọ kansoso labẹ Olubadan tilẹ Ibadan.
Ọrọ naa di awuyewuye, ti wọn si ri iwa gomina naa bii ọyaju si Olubadan, ti igbesẹ naa si pin igbimọ Olubadan si meji di oni oloni.
Ẹnu tun kun Abiola Ajimobi lasiko ti ko san owo oṣu awọn oṣisẹ ati oṣisẹ fẹyinti.
Bi o tilẹ jẹ pe ọrọ aje Naijiria lo dagun nigba naa ti ijọba rẹ ko fi ri owo oṣu san, amọ eyi ko ni ki ẹnu ma kun Ajimobi.
Awọn oṣisẹ ni awọn ọrọ kobakungbe ti Ajimobi maa n sọ fun awọn lai san owo oṣu lasiko, to si tun n mu awọn oṣisẹ to ba pẹ de ẹnu iṣẹ lo fa eyi.
Oríṣun àwòrán, Others
Asiko yii ni Ajimobi se ayẹwo fawọn osisẹ, to si tun da pupọ wọn duro tori wọn ko ni iwe ẹri to jinna, tawọn osisẹ naa si ni eyi ko ri bẹẹ.
Awọn osisẹ ti ọrọ yii kan lo lee sọ, ti idaduro ojiji yii si ran ọpọ wọn sọrun ọsan gangan, nigba ti awọn miran di alarun, to fi mọ awọn osisẹ fẹyinti.
Koda, Abiola Ajimobi sọ ni ọjọ kan ti awọn osisẹ fẹyinti n beere ajẹsilẹ owo ajẹmọnu wọn pe:
Se wọn ko ni ọmọ to wulo to lee maa tọju wọn lọjọ ogbo ni eyi ti ko ni jẹ ki wọn gbe ara le owo ajẹmọnu ifẹyinti lati ọdọ ijọba.
Ọrọ Ajimobi yii si lo da họhu-họhu silẹ nigba naa.
Oríṣun àwòrán, Abiola Ajimobi
Igba miran ti ẹnu tun kun Abiola Ajimobi ni akoko to ṣeleri pe oun ko ni gbe igba ibo mọ lati bẹbẹ fun ipo oṣelu lọdọ araalu.
Gbogbo eeyan lo n kan saara si nigba naa amọ ko pẹ lẹyin naa ti Ajimobi fi ko ọrọ naa jẹ, to si beere fun ipo Sẹnatọ .
Ọpọ eeyan lo n yọ suti ete si Abiola Ajimobi nigba naa pe ki lo tun n wa lagbo oselu, to se tun jade pe oun fẹ lọ sile asofin agba, se ko ni itẹlọrun ni?
Sugbọn Ajimobi tẹsiwaju lati dije fun ipo Sẹnatọ naa, bi o tilẹ jẹ pe o ti lọ sile aṣofin agba ri , ko to di gomina ipinlẹ Ọyọ.
Lẹyin o rẹyin, Abiola Ajimobi fidi rẹmi ninu ibo naa, ti Sẹnatọ Kola Balogun si jawe olubori lati lọ sile aṣofin agba ni Abuja.
Oríṣun àwòrán, Others
Lasiko ti Abiola Ajimobi wa lori aleefa bii gomina ipinlẹ Ọyọ, ojojoojumọ ni awuyewuye maa n waye ni ẹka eto ẹkọ nitori awọn igbesẹ to n gbe lẹka eto ẹkọ.
Fun apẹẹrẹ, o le ni ọdun kan ti awọn akẹkọọ fasiti imọ ẹrọ Ladoke Akintola, LAUTECH fi joko sile.
Igba ti awọn akẹkọọ naa si se abẹwo si ọdọ rẹ lọgba Secretariat ,lati fi ẹhonu han lori akude to ba eto ẹkọ wọn, ni wọn ba ibinu Ajimọbi pade tori wọn baa sọrọ lọna aitọ.
Oríṣun àwòrán, Others
"Idi ree ti Ajimọbi fi beere pe ""ṣe Constituted Authority lẹ n ba sọrọ bayẹn?"""
"Lati igba naa si ni wọn ti n pe ni ni ""Constituted Authority"" di oni."
Ko tan sibẹ, awọn akẹkọọ girama naa se iwọde tako ilana ijọba Ajimobi ni ẹka eto ẹkọ, eyi to mu ki igboro mi titi, ti awuyewuye si waye lasiko naa lẹka eto ẹkọ.
Oríṣun àwòrán, Yinka Ayefele Instagram
Pabambari awuyewuye to waye lasiko isejọba gomina Abiola Ajimobi ni bo se da ile orin Yinka Ayefele wo, ladugbo Challenge, nilu Ibadan.
Ajimobi ni ile orin naa lo wa lẹba oju popo, ti Ayefele ko si tun ni iwe onilẹ to yẹ nipa ilẹ to kọ ile le lori.
Ayefele ni iwe wa fun ilẹ oun, ti wọn si pe ọrọ naa lowe, amọ to ni araaro ninu.
Ni idaji ọkọ kan, ni ijọba Ajimobi ko ẹrọ katakata lọ bi ile naa wo, eyi to bọ si ibinu ọpọlọpọ eeyan.
Oríṣun àwòrán, Yinka Ayefele
Bi o tilẹ jẹ pe ẹnu kun Abiola Ajimobi lasiko to wa nijọba, sibẹ ọpọ aseyọri lo se lori aleefa, eyi to jẹ manigbagbe.
O ti wa se iwọn to lee se, o si ti dagbere fun aye pe o digbo se, a wa n gbadura pe Ọba oke yoo dẹ ilẹ fun akikanju ọmọ Ibadan to rele.
Oríṣun àwòrán, @seyiamakinde/twitter
Aarẹ Muhammadu Buhari ti ṣapejuwe gomina ipinlẹ Oyo nigba kan, Abiola Ajimobi, gẹgẹ bi ẹni to ko ipa to jọju ninu idagbasoke Naijiria.
Oludamọran Pataki fun aarẹ lori eto iroyin, Femi Adesina to fi ikede ibanikẹdun naa sita lorukọ aarẹ sọ pe:
Ajimọbi kú lasiko ti ẹgbẹ APC, ati orilẹ-ede rẹ nilo imọran tẹ lati gba iwosan ati idagbasoke.
Oríṣun àwòrán, Femi Adesina
Aarẹ Buhari sọ pe titi lai ni ipa ti Ajimobi ko ninu idagbasoke ipinlẹ Oyo yoo wa ni iranti.
Oríṣun àwòrán, @AAAjimobi/Twitter
Gomina ipinlẹ Oyo, Seyi Makinde, ti ranṣẹ ibanikẹdun si ẹbí Abiola Ajimobi to d'oloogbe l'Ọjọbọ.
Ninu ọrọ rẹ, Makinde sọ pe ipapoda rẹ ba oun lọkan jẹ. Ati pe oun ko ti ẹ le fi ori ṣiro ibanujẹ ti iku rẹ jẹ fun ẹbí rẹ.
O gbadura pe ki Ọlọrun fun wọn ni okun lati le gba iku rẹ mọra.
"Bakan naa lo sọ pe ""ilana ti Ajimobi la kalẹ, lo jẹ ipilẹ diẹ lara awọn iṣẹ ti iṣakoso wa n ṣe."
Gbogbo ọ̀wọ̀ to tọ si iru eeyan to jẹ́, ni ao nawọ rẹ si ẹbí rẹ̀.
"Makinde si ti paṣẹ pe ki wọn o sọ asia orilẹ-ede Naijiria kalẹ loni ọjọ Ẹti, lati le ṣe idaro ""arakunrin, ọrẹ, ati eekan ọmọ bibi ipinlẹ Oyo""."
Gomina ipinlẹ Eko tẹlẹ, Akinwumi Ambode naa ko gbẹhin lara awọn eekan ìlú to ti ṣedaro Ajimobi to ku.
Ambode sọ pe ibaṣepọ oun ati Ajimobi nigba aye rẹ ju ti ọmọ iya tabi akẹẹgbẹ lọ.
O jẹ ẹni to kun fun ọrọ ọgbọn, awada, to si maa n ṣetan lati sọ okodoro nipa iṣẹlẹ yoowu ni gbogbo igba.
Ẹgbẹ oṣelu All Progressives Congress, APC, nipinlẹ Eko naa ti darapọ mọ awọn to n daro iku Ajimobi.
Ninu ikede ti agbẹnusọ ẹgbẹ, Seye Oladejo, fi sita, wọn ba ẹbi ati ẹka ẹgbẹ naa nipinlẹ Oyo kẹdun.
Bakan naa ni wọn gboriyin fun pe o fi ipa manigbagbe silẹ ni ẹka iṣẹ aladani, to si tun jẹ ẹni to sin awọn eniyan rẹ tọkan-tọkan.
Hajj 2020: Yàtọ̀ sí covid-19, wo ìgbà mẹ́wàá míì táwọn mùsùlùmí kò lè ṣiṣẹ́ Hajj ní Mecca
Muslims from around di world perform Hajj evri year inside Mecca, Saudi Arabia.
Eyi kọ ni igba akọkọ ti ijọba orilẹ-ede Saudi Arabia ko ni faye gba ọpọ eeyan lati wa ṣiṣẹ Hajj ni Saudi.
Laipẹ yii ni ijọba ilẹ naa kede pe awọn eeyan lati ilẹ mii ko ni lanfaani lati ṣiṣẹ Hajj fun ti ọdun 2020.
O ti ṣẹlẹ lawọn igba kan sẹyin ti ogun tabi ọrọ oṣelu dena mọ awọn eeyan ti wọn fẹ ṣiṣẹ Hajj.
Lilọ Hajj jẹ ọkan pataki ninu opo to di ẹsin Musulumi mu, wọn si mu u ni ibaada fun gbogbo musulumi lati rii wi pe wọn lọ si Mecca, o kere tan lẹẹkan ki wọn to dagbere faye.
Oríṣun àwòrán, Reuters
Eyi ni awọn igba igba miiran tawọn musulumi ko lanfaani lati ṣiṣẹ Hajj:
1) Okuta dena iṣẹ Hajj ni eyi ti ko si Hajj fun odindin ogun ọdun
Lara awọn igba tawọn musulumi ko le ṣiṣẹ Hajj lo ṣẹlẹ 930, A.D.
Eyi jẹ nigba ti ẹgbẹ Shiite musulumi gan an ti wọn pe ara wọn ni Qarmatians yabo ilu Mecca nitori wọn gbagbọ pe awọn keferi lo n ṣiṣẹ Hajj.
Akọsilẹ sọ pe awọn Qarmatians ṣekupa ọpọlọpọ awọn musulumi to lọ fun Hajj lọdun yii, wọn si ji okuta dudu Kaaba lọ eyi tawọn musulumi gbagbọ pe o wa lati ọrun.
Wọn gbe okuta naa lọ si Bahrain, wọn si foote le iṣẹ Hajj fun ogun ọdun, to fi di igba ti ọkunrin alagbara kan, Abbadis san owo itanran ki wọn le da okuta naa pada
2) Ọrọ oṣelu fopin de Hajj fun ọdun mẹjọ
Lọdun 983, A.D. awọn olori ni Baghdada ba Egypt jagun.
Awọn alaṣẹ Fatimid ni Egypt sọ pe awọn ni ojulowo olori ẹsin musulumi, eyi to mu wọn tako ijọba Abbasid lorilẹ-ede Iraq ati Syria.
Aawọ naa ko jẹ kawọn musulumi lati Mecca ati Medina le ṣiṣẹ Hajj fun ọdun mẹjọ to fi di 991, A.D.
Ibadan Death: Àwọn ará àdúgbò Akinyele ké sita lórí iṣékúpani  tó ń wáyé ní ìlú Ibadan.
Nigba ti ijọba Fatimid da wo lọdun 1168,, A.D. awọn ara ilẹ Egypt ko le wọ Hijaz.
Bakan naa ni a gbọ pe awọn ara Baghdad ko le ṣe ṣiṣẹ Hajj fun ọpọlọpọ ọdun.
Ikọlu awọn ologun labẹ alaṣẹ Napoleon eyi to tako ijọba akonilẹru ilẹ Gẹẹsi ni ẹkun naa ko fun ọpọ musulumi laye lati ṣiṣẹ Hajj laarin ọdun 1798 si 1801.
Oríṣun àwòrán, Reuters
Ajakalẹ aarun atawọn nnkan miiran ti ko jẹ kawọn musulumi ṣiṣẹ Hajj fun igba mẹjọ to ku:
Mobile Wash: iṣẹ́ fífọ́ mọ́tò tà ni mó yàn láààyò- Slay Mama
Eeyan to le ni 161,000 lo ti lugbadi aarun Coronavirusnaa nibẹ nigba ti awọn to ti ku ju 1,300 lọ.
Drug Trafficking: Obìnrin méjìlá ló wà lára àwn olóògùn olóró náà
Oríṣun àwòrán, NDLEA
Ọwọ palaba awọn eeyan to le ni aadọjọ to n gbe oogun oloro ti segi bayii, ti wọn si ti wa ni ahamọ ajọ to n dena ilokulo oogun oloro.
Ajọ NDLEA nipinlẹ Ondo lo kede bẹẹ nibi ipade akọroyin kan to se nilu Akure lọjọ Ẹti.
Oludari ajọ NDLEA nipinlẹ naa, Haruna Gagara  ni wọn se ipade akọroyin ọhun lati fi sami ayajọ gbigbogun ti ilokulo oogun ati gbigbe oogun oloro fun tọdun yii ni.
Gagara fikun pe ọwọ tẹ awọn aadọjọ agboogun oloro naa laarin osu kinni si osu kẹfa ọdun 2020.
O ni ninu aadọjọ awọn oloogun oloro naa, mejila ninu wọn lo jẹ obinrin.
Laarin akoko ti wọn mu awọn eeyan naa, iwọn oogun oloro to to kilo ẹgbẹrun lọna mẹjọ o din diẹ, ni wọn ka mọ wọn lọwọ.
Oríṣun àwòrán, NDLEA
Ninu wọn ni  iwọn ẹgbẹrun meje o le diẹ kilo Igbo mimu wa, ti iyoku si jẹ oogun oloro Cocaine.
Gagara tẹsiwaju pe lọjọ Ẹti nikan, apo igbo marundinlaadọrin ni wsn ri gba ni agbegbe Agunla-Ogbese.
O wa rọ awọn eeyan ti ọrs gbigbogun ti ilokulo oogun oloro kan lati maa gbe igbesẹ to yẹ nidi didẹkun asa buburu yii.
Oríṣun àwòrán, NDLEA
To si tun bẹbẹ fun agbekalẹ awọn eto ilanilọye fawọn ọdọ lati dena mimu oogun oloro ati gbigbe rẹ.
Gagara tun mẹnuba pe aisi ọkọ ayọkẹlẹ lati rin pẹlu owona wa lara isoro to n koju ajọ naa lati sisẹ rẹ deede.
BBC and MTN: ọ̀fẹ́ ni ẹ o máa gbọ́ ìròyìn Yorùbá, Pidgin, Igbo àti Hausa lórí 'MyMTN App' yìn!
Oríṣun àwòrán, MTN
Ire déé! MTN àti BBC World Service bẹ̀rẹ̀ àjọṣepọ̀ lórí ìròyìn ìṣẹ́jú kan BBC
Bi o ba jẹ ọkan lara awọn ololufẹ ileesẹ BBC ti o si ti n ronu bi wa a ti se maa gbadun iroyin isẹju kan wa nigbakugba nibi kibi, iroyin ayọ la mu tọ yin wa yi.
Ileesẹ BBC World Service ati ileesẹ MTN ti setan lati maa mu iroyin yi wa si eti igbọ yin lọfẹ lede Yoruba, Pidgin Igbo ati Hausa.Enikẹni to ba ti kan si MyMTN APP ni anfaani nla yi wa fun.
Iroyin Isẹju Kan BBC lawọn ede wọnyi jẹ iroyin ni soki ti a se akojọpọ rẹ fun awọn ololufẹ wa lai fi ti ọjọ ori se.
Wón yoo si maa gbọ nipa iroyin agbaye, ohun to n lọ nigboro, ere idaraya, imọ ẹrọ ati iroyin amuludun nibẹ.
Pẹlu ibasepọ tuntun yi, awọn ololufẹ wa yoo laanfani lati maa gbadun iroyin to ta leti ọhun nigba to ba wu wọn, lalẹ tabi lọsan gangan.
Bẹẹ naa ni yoo jẹ ki awọn eeyan gbọ ojulowo iroyin lawujọ lasiko yii ti o jẹ pe ayederu iroyin ti gbalẹ kaakiri.Ọga agba to n dari ẹka ede ni Iwọ Oorun ilẹ Afirika fun BBC, Toyosi Ogunseye fi idunnu rẹ han lori igbesẹ akọni yii.
Ohun ayo ni iroyin iṣẹju kan BBC yoo jẹ fun awọn ọdọ Naijiria
Toyosi sọ pe:  ''Ajọsepọ yi pẹlu MTN safIhan ifarajin BBC lati mu iroyin de ọdọ awọn eeyan nibikibi ti wọn ba wa ni Naijiria.
Inu BBC si dun pe a ni anfani lati ni ajọsepọ to dan mọran pẹlu awọn ọdọ latari igbesẹ yi''
Ọga agba ẹka ẹrọ ayelujara fun MTN, Srinivas Rao ni:
''Iwuri ni ibasepọ yi jẹ fun MTN ati pe ọna kan gboogi tawọn ọdọ Naijiria yoo maa fi ri iroyin to peye si lo jẹ''
Ninu ọrọ tirẹ, Kolawole Oyeyemi to jẹ oludari eto to n risi igbadun onibara MTN  sọ pe:
''Igbesẹ yi n safihan iru igbadun to gaju lọ ti awọn onibara wa yoo ma ri bi wọn ba ti lo My MTN App''
Mary Lusiba to jẹ olori ẹka idagbasoke eto karakata ileesẹ BBC World Service ni tirẹ sapejuwe ibasepọ yi gẹgẹ bi eleyi ti yoo ''jẹ ki awọn ọdọ mọ si i nipa BBC.
O ni: Igbesẹ yi n sagbega orukọ rere ti BBC ti ni nipa iroyin to gbamuse ti yoo si de ọdọ awọn ọdọ lorile-ede Naijiria''
Mobile Wash: iṣẹ́ fífọ́ mọ́tò tà ni mó yàn láààyò- Slay Mama
774,000 Jobs: Muhammadu Buhari ti paá láṣẹ fún mínísítà fún ètò ìgbanisíṣẹ́ láti tẹ̀síwájú lórí ètò ìṣẹ́ 774,000
Ààrẹ Muhammadu Buhari tí ti paá lásẹ fún mínísítà tó n ri si ọ̀rọ̀ iṣẹ́ àti ìgbanisíṣẹ́ lórílẹ̀- èdè Nàìjíríà láti tẹ̀síwájú lórí ètò ìgbanisíṣẹ́ ènìyàn ẹẹ́dẹ́gbẹ̀rin o lé mẹ́rìnléláàdọ́rin lábẹ́ ètò (SPW) ti àjọ NDE yóò sì máa mójú tó ètò náà.
"Keyamo lásìkò tó ń ba ilé iṣẹ́ ìròyìn ""The Nation""ní ààrẹ ló pé òun laṣẹ́ kí òun tẹ̀síwájú, àti pé ọ̀rọ̀ àwọn ọmọ ilé ìgbmọ̀ aṣòfin kò láṣẹ láti dá ètò náà dúró."
Sááju ni èdè àìyedè ti wáyé lórí ọ̀rọ̀ yìí, ti àwọn ọmọ ilé ìgbìmọ̀ aṣofin àgbà sì ti ni àwọn ti gbẹ́sẹ̀ lé ètò náà nítori mínísítà kọ̀ láti ṣe ni ìlànà tí àwọn ń fẹ́.
'Ẹlẹ́ẹ̀kẹjọ t'óyún máà bàjẹ́ lára mi ni mo tó rí àànú gbà'
Wọ́n ni Keyamo kò fi ọ̀rọ̀ náà tó àwọn léti lórí bi wọ́n ṣe yan ìgbìmọ̀ ti yóò mójútó ètò ìgbanisíṣẹ́ náà nínú oṣù kèje ọdún yìí.
Keyamo ní bayìí, àwọn ìgbìmọ̀ kọ̀ọ̀kàn ti bẹ̀rẹ̀ iṣẹ́ ni àwọn ìpínlẹ̀ wọ́n gẹ́gk bí wan ṣe làá silẹ̀ tẹ́lẹ̀.
Àjọ NDE ni yóò máa dari ètò náà, à ó si ṣíṣẹ́ takuntakun láti rii dájú pé a bá àsìkò tí a pinu fún ètò náà.
Ètò náà yóò gbà ènìyàn ẹgbẹ̀rún kọ̀ọ̀kan láti ìjọba ìbílẹ̀ ẹẹ́dẹ́gbẹ̀rin ó lé mẹ́rìnléláàdọ́rin jákejádò òrílẹ̀-èdè Nàìjíríà.
Bákan náà ni ètò yìí yóò ná ìjọba ni bílíọ́nù méjìléláàdọ́ta náírà gẹ́gẹ́ bí owó oṣù osgún naira fún ẹni kọ̀ọ̀kan
Oríṣun àwòrán, Others
Ilé ìgbìmọ̀ aṣòfin Nàìjíríà ti kéde pé ki ìjóba dá iṣẹ́ ológun náìra oṣoosù ti ìjọba apapọ fẹ́ gbà àwọn èniyàn sí lábẹ́ àjọ tó ń gbani síṣẹ́ (NDE) láti mú ìrọ̀rùn bá ará ìlú nítori àarùn Covid-19 tó gba ayé kan.
Sáájú àsìkò yìí ni ààrẹ Muhammadu Buhari ti buwọ́lu gbígba ènìyàn ẹẹ́dẹ́gbẹ̀rin o lé mẹ́rìnléláàdọ́rin ènìyàn lọ́bẹ́ ètò náà.
Lábẹ́ ètò yìí ẹgbẹ̀rún kan ọmọ Nàìjíríà ti yóò gba ẹgbẹ̀run lọ́nà ogún Naira lósoosù fun oṣù mẹ́ta àwọn ènìyàn yìí  yóò wá láti ìjọba ìbílẹ̀ kọ̀ọ̀kan ní orílẹ̀-èdè  Nàìjíríà.
O yẹ ki ètò náà bẹ̀rẹ̀ nínú oṣù kẹwàá ọdún yìí ṣùgbọ́n èdè àìyedè to wáye láàrin mínísítà fún ètò iṣẹ́  Festus Keyamo àti àwọn ọmọ ilé ìgbìmọ̀ aṣòfin ní àná ọjọ́ iṣẹ́gun jọ bi ẹni pé ó ti pagidinà ètò náà.
Agbẹnúsọ ilé ìgbìmọ̀ asòfin àgbà Ajibola Bashiru to kéde ìdádúró ètò náà lásìkò to n bá àwọn oníròyìn sọ̀rọ̀ nílùú Abuja, ó sọ pé ilé ìgbìmọ̀ asòfin àgbà pé Festus Keyamo láti yọjú sí ilé aṣòfin láti sàlàyé lóri ọ̀nà ti wọ́n fẹ́  gbà láti gba àwọn ènìyàn sísẹ́ lábẹ́ ètò náà.
"Ó ní ""bí ǹkan ṣe ń lọ yìí mímú ètò náà wá sí ìmúṣẹ yóò mọ́wọ́ró díẹ̀ títí di ìgbà ti mínísítà bá le sàlàyé ara rẹ̀ lẹ́kunrẹ́rẹ́ fún àwọn ọmọ ilé ìgbìmọ̀ aṣòfin àgbà."
Iṣẹ ilẹ gbígbá, fifọ gọ́tà, didari ọkọ̀, ati oju ọna sise, wa lara isẹ tawọn ọdọ yoo ṣe fun oṣu mẹta, ₦20,000 si ni owo oṣu wọn.
Oríṣun àwòrán, Lawma Lagos
Ijọba apapọ ti yan Alaafin tilu Oyo, ọba Lamidi Olayiwola Adeyemi kẹta ati alaga ẹgbẹ awakọ ero nipinlẹ Eko, Musiliu Akinsanya, MC Oluomo, sinu igbimọ ti yoo mojuto eto igbani sisẹ nipinlẹ Oyo ati Eko.
Lara awọn ti ijọba tun yan ni Oloye ẹgbẹ oṣelu APC, Alhaji Mutiu Are, ati ọmọ asiwaju ẹgbẹ naa, Folasade Tinubu-Ojo, to fi mọ alaga ẹgbẹ ọmọ lẹyin Kristi nipinlẹ Oyo, Benjamin Akanmu.
Ko tan sibẹ, alaga ẹgbẹ awakọ ero nipinlẹ Oyo tijọba Oyo ti fofin de, Abideen Olajide, ti ọpọ eeyan mọ si Ejiogbe naa wa lara awọn ọmọ igbimọ agbanisisẹ naa.
Oríṣun àwòrán, Lawma Lagos
Igbimọ ẹlẹni ogún ọhun ni yoo mojuto gbigba ọdọ ẹgbẹrun lọna ogún si iṣẹ nipinlẹ Oyo ati Eko, nigba tawọn ọmọ igbimọ mii naa wa kaakiri awọn ipinlẹ yoku yika Naijiria.
Ọjọ Aje ni Minisita fun ọrọ awọn oṣiṣẹ ati igbani sisẹ, Festus Keyamo, ṣe ifilọlẹ igbimọ naa fun ipinlẹ kọọkan lorilẹ-ede Naijiria.
Ẹgbẹrun kan oṣiṣẹ si ni wọn o gba sisẹ ni ijọba ibilẹ kọọkan, eyi tumọ si pe ẹgbẹrun lọna ọrinlelẹẹdẹgbẹrin din mẹfa ni apapọ awọn ọdọ ti ijọba apapọ yoo gba sisẹ.
Flood: Ọ̀pọ́ Dúkìá ló sọnù ní 2019 lásìkò tí ìjọba ṣí ’dáàmù Ọyan’
Iṣẹ ilẹ gbígbá, fifọ gọ́tà, didari ọkọ̀, ati oju ọna sise, ni diẹ lara isẹ ti awọn ọdọ naa yoo ṣe fun oṣu mẹta.
Ẹgbẹrun lọna ogún Naira si ni owo oṣu wọn.
Sugbọn sa, Keyamo sọ lọjọ Iṣẹgun pe awọn oloṣelu kan ti fẹ ẹ gba isakoso eto naa.
Lọjọ Iṣẹgun yii kan naa ni fidio kan jade sori ayelujara, to safihan bi awọn ọmọ ile aṣofin Naijiria ṣe le Minisita naa jade lasiko to farahan niwaju wọn fun ibeere nipa eto igbani sisẹ naa.
Aarẹ Muhammadu Buhari, naa si ti fi ikede sita pe, ki awọn oloṣelu maṣe lo ipo wọn lati fun ẹnikẹni ni isẹ naa.
Oríṣun àwòrán, @NPOWER_NG TWITTER
Aworan awọn ọdọ to n gba idanilẹkọ labẹ N-Power
Iroyin to gbode nilẹ oni to mọ bayi ni pe pupọ awọn eeyan to forukọ silẹ loju opo igbanisiṣẹ ijọba Naijiria N-Power 2020 ni iforukọsilẹ wọn le ma wọle.
Nitori naa ki o to lọ si oju opo wọn lati bẹrẹ eto iforukọsilẹ,wọn yi lawọn nkan to yẹ ni mimọ ti ko ni jẹ ki o kuna .
Awọn alakoso N-Power tii se eto igbanisisẹ fawọn ọdọ lorile-ede Naijiria ti fi ikilọ sita pe ọfẹ ni eto igbanisisẹ naa.
Ikilọ yi ko sẹyin bi awọn eeyan kan ti se n gbiyanju lati forukọ silẹ loju opo N-Power saaju ki wọn to sii laago mejila ku isẹju mẹẹdogun alẹ ọjọ Eti tii se ọjọ Kẹrindinlọgbọn, osu Kẹfa.
Gẹgẹ bi iroyin lati oju opo naa ti se sọ, iforukọsilẹ to ba waye saaju asiko yi jẹ otubantẹ ni yoo ja si fẹni ba se iru rẹ.
Ijọba apapọ Naijiria lo se agbekalẹ eto iranwọ isẹ N-Power labẹ ileesẹ to n risi idagbasoke awujọ ni Naijiria fawọn ọdọ ti ko ba nisẹ lọwọ.
Bi o ti se le forukọsilẹ kopa ninu N-Power 2020  ree
Labẹ eto igbanisisẹ N-Power ipele kẹta to n waye losu Kẹfa, awọn to ba fẹ jẹ anfaani yi yoo lọ si oju opo ayelujara www.npower.fmhds.gov.ng lati forukọ silẹ.
Sugbọn kii se gbogbo eeyan naa lo le kopa.
Lati jẹ anfaani yi, eeyan gbọdọ jẹ ẹni ọdun mejidinlogun si marundinlogoji.
Wo awọn iwe to gbọdọ ni ko to le forukọ silẹ:
•Nọmba idanimọ ile ifowopamọ BVN
•Aworan pelebe
•Oju opo ikansiraẹni e-mail ati nọmba ẹrọ ibanisọrọ ti wọn le fi pe ọ si
•Iwe ẹri ikẹkọ gboye fasiti ati sabuke agunbanirọ NYSC
Kete ti o ba ti de oju opo N-Power, awọn ohun to yẹ ko se ree:
•Fi e-mail rẹ tabi nọmba foonu rẹ si oju aye ti wọn pese.
•Sise bẹẹ yoo mu ki o gbe ọ lọ si ibi ti o ti jẹri pe lootọ iwọ lo ni e-mail
•Bi o ba se eyi tan, o ni lati kọ nọmba idanimọ ile ifowopamọ BVN rẹ ati ọjọ ibi rẹ (dd/mm/yr)
•Abala iroyin nipa rẹ ati oju opo ikansiraẹni:kọ orukọ baba rẹ, orukọ rẹ bo ti se wa lori nọmba BVN rẹ
•Abala iwe ẹri ẹkọ ati eto miran: labala yi, o le kọ ọ sibẹ boya o kawe gboye tabi o lọ si ile ẹkọ rara.Gbogbo eeyan ni eto N-Power wa fun
•Abala Eto N-Tech ati N- Health wa fawọn to kẹkọ gboye ile ẹkọ giga nikan.
Oríṣun àwòrán, @Osinbajo
Etò NPower jẹ́ ọ̀nà tí ìjọba Nàìjíríà fi ń pèsè iṣẹ́ àti ìgúnpá fún ọ̀pọ̀ ọ̀dọ́ tí kò rí iṣẹ́ ṣe.
Awọn to kawe gboye fasiti, ile ẹkọ gbogbonise HND tabi OND lẹka eto ẹkọ imọ ilera, Microbiology, Psychology, Midwifery Public Health tabi eto ẹkọ miran lẹka sayensi lo le kopa nibẹ.
•Awọn to n wasẹ yi ni lati fi ẹda iwe ẹri ikẹkọgboye fasiti wọn ati iwe ẹri agunbanirọ NYSC sọwọ loju opo naa .
•Oju opo Isẹ ati awọn iroyin miran:
Awọn to n wa'sẹ ni lati dahun awọn ibeere kan ti wọn yoo si fi ẹda kaadi idanimọ wọn sọwọ. Iwe ẹri ti ijọba fontẹ lu niwọn yi:
•Iwe irina pasipọti
•Kaadi idanimọ ti ajọ NIMC n fun awọn ara ilu
•Iwe asẹ iwakọ ni Naijiria
•Kaadi idibo ọlọjọ pipẹ,PVC
•Ipele ayẹwo fini fini ka to pari:
•Nibi ni waa ti yẹ gbogbo nkan to kọ daada ti o si fi sọwọ si oju opo naa
•Bi o ba ti fi sọwọ si oju opo naa tan, wọn yoo fi nọmba idanimọ kan ransẹ si ọ,kọ silẹ ki o fi pamọ daada.
Mobile Wash: iṣẹ́ fífọ́ mọ́tò tà ni mó yàn láààyò- Slay Mama
Iru awọn eeyan ti N-Power 2020 n wa?
Gẹgẹ bi awọn alasẹ ti se sọ, eto igbanisisẹ yi yoo gba eeyan ẹgbẹrun lọna irinwo sisẹ lẹka orisirisi bi isẹ ọgbin, ilera, eto ẹkọ, ile kikọ, isẹ ọna ati imọ ẹrọ tẹkinọlọji.
Ọdun 2016 ni ijọba bẹrẹ eto naa ti eeyan to to ẹgbẹrun lọna ẹẹdẹgbẹta si ti jẹ anfaani nibẹ.
Ibadan Death: Àwọn ará àdúgbò Akinyele ké sita lórí iṣékúpani tó ń wáyé ní ìlú Ibadan
Awọn ara adugbo Akinyele ni ilu Ibadan ti kesi ijọba lati pese aabo fun wọn lẹyin ti awọn kan tun sa obinrin kan ni ada pa ni aarọ kutu Ọjọru
Awọn ara adugbọ to sọrọ ni arabinrin Olufisayo Fagbemi ji laarọ kutu bi aagọ marun un lati fọ aṣọ ni iwaju ile, ki wọn to ba a ninu agbara ẹjẹ.
Lẹyin ti wọn sa a ni ada ni iwaju ori ni Ọjọru.
Awọn ara adugbo wi pe ẹni karun un ni yii laarin oṣu kan ti wọn ti da ẹmi wọn legbodo lagbegbe yii.
Bẹẹ ni wọn kesi ijọba lati ṣeranwọ fun wọn, ki oju awọn aṣebi yii tete han sita.
Covid Update: Ṣé orílẹ̀èdè míì wà l'Áfíríkà tó ń lo rọ́bọ́ọ̀tì ní pápákọ̀ òfurufú bíi ti Nàìjíríà?
Oríṣun àwòrán, Nigeria Defence News/Twitter
Naijiria ti di orilẹede akọkọ ni Afirika ti yo maa lo ẹrọ abaniṣiṣẹ rọbọọti ni papakọ ofurufu gẹgẹ bi ẹka iroyin ileeṣẹ ologun Naijiria ṣe sọ ọ.
Nibayi awọn ẹrọ abaniṣiṣẹ rọbọọti yii ti wa nilẹ digbi wọn si ti duro deede lati maa ṣe ayẹwo gbogbo arinrinajo ni papakọ ofurufu Naijiria lati asiko ajakalẹ arun COVID-19 yii.
Gẹgẹ bi ẹka iroyin ileeṣẹ ologun Naijiria ṣe fi sita loju opo Twitter wọn nibi ti wọn ti n ṣe ayẹwo awọn rọbọọti naa pe orilẹede Naijiria ni orilẹede akọkọ nilẹ Afirika ti yoo ra rọbọọti ti o lee gbe gbogbo iroyin nipa arinrinajo jade ti yoo si maa ṣe ayẹwo wọn ẹnu ọna gbọngan abajade papakọ ofurufu.
Oríṣun àwòrán, Nigeria Defence News
"Nibi ti wọn f'ogun awọn irinṣẹ ti Naijiria ra yii gbari de, wọn tun kede pe ""bi orilẹede Afirika kankan ba wa to ti gbe iru igbesẹ lilo rọbọọti fun iṣẹ ni papakọ ofuru wọn, ẹ jẹ ka mọ. A n duro tọkan tọkan."
Kia lawọn ọmọ Naijiria ti han wọn kaun ṣugbọn koko awọn ọrọ ti wọn n sọ ẹka iroyin ileeṣẹ ologun Naijiria fi han pe lootọ bi awọn orilẹede miran l'Afirika tilẹ n lo awọn mọsiini abani ṣiṣẹ yii, kii ṣe ni papakọ ofurufu bii ti Naijiria
Ko pẹ lawọn ọmọ Naijiria mii naa tu sita pẹlu lati mẹnu le ọrọ awọn ohun elo iranwọ tuntun yii.
Ẹwẹ, ileeṣẹ ologun jẹ ko di mimọ pe iyatọ gedegbe wa laarin iṣẹ ni papakọ ofurufu ati ibomiran. Lilo rọbọọti ni gbogbo papakọ ofurufu ti wọn n gba rinrinajo lọ ilẹ okere ni Naijiria ni wọn n sọ tori naa bi awọn eeyan o ba lee kan sara si ijọba Naijiria fun iṣẹ takun takun, ki wọn ma fa ibọn yọ o tọrọ ba ti kan ohun daradara nipa Naijiria.
Abiola Ajimobi: Ikọ̀ ìjọba Oyo sọ pé àwọn ẹ̀ṣọ́ ilé Ajimobi ní ọwọ́ aya olóògbé ni kọ́kọ́rọ́ géètì wà
Oríṣun àwòrán, Others
Ijọba ipinlẹ Oyo ti sọ pe oun ko mọ idi ti wọn ṣe da ikọ asoju oun pada lẹnu ọna ile gomina ana, Abiola Ajimobi, nigba to yọju sibi adura ọjọ kẹjọ lẹyin to papoda.
Oluranlọwọ pataki fun igbakeji gomina lori ọrọ to n lọ, Omoetan Omolere lo sọ bẹẹ ninu ifọrọwerọ kan pẹlu BBC Yoruba.
Omolere ni awọn ẹṣọ ile gomina ana ọhun sọ fun awọn ẹṣọ igbakeji gomina pe, ọwọ iyawo oloogbe naa ni kọkọrọ ẹnu ọna wa, ati pe ki igbakeji gomina ma ṣeyọnu lati jade kuro ninu ọkọ to gbe e wa.
"O ni ""Lara  awọn ẹṣọ to wa lẹnu ọna lo sọ fun awọn eeyan wa pe, ka ma tilẹ jade kuro ninu ọkọ wa nitori wọn ko ni ṣilẹkun fun wa."""
Oríṣun àwòrán, BBC Sport
Ni ti pe boya ede aiyede ti wa laarin iyawo Ajimobi ati igbakeji gomina tẹlẹ, Omoetan ni oun ko le sẹ boya ija wa laarin awọn mejeji ṣaaju iṣẹlẹ naa.
Gẹgẹ bo ṣe sọ, o ni kii ṣe igbakeji gomina nikan ni wọn le pada lẹnu ọna ile oloogbe naa.
O ni wọn tun le awọn kọmiṣọna meji miran, ati iyawo gomina tẹlẹri ni ipinlẹ ọhun, Alhaja Mutiat Ladoja, to jẹ iyawo ṣẹnatọ Lamidi Ladoja pada lẹnu ọna.
"Omolere pari ọrọ rẹ pe ""Kii ṣe Rauf Olaniyan ni wọn da pada lẹnu ọna gomina Abiola Ajimobi, bi ko ṣe ijọba ipinlẹ Oyo."""
Nitori ko lọ sibi adura naa lorukọ ara rẹ, ṣugbọn o lọ lorukọ ijọba ipinlẹ Oyo.
Ẹwẹ, agbẹnusọ fun Abiola Ajimobi, Bolaji Tunji ti sọ ninu atẹjade kan pe kii ṣe pe awọn mọọmọ le igbakeji gomina pada nibi adura ọjọ kẹjọ ọhun, ṣugbọn o wa lasiko ti ko yẹ ni.
Tunji sọ pe igbakeji gomina naa de lẹyin ti adura ti bẹrẹ ati pe, awọn ẹbi oloogbe nikan ni adura ọhun wa fun.
O tẹsiwaju pe, wọn gbe kọkọrọ ṣenu ọna ni titẹle ilana ijinasiraẹnu gẹgẹ bi ajọ NCDC ṣe gbe kalẹ lọna ati dẹkun itankalẹ arun Coronavirus.
Tunji sọ pe yatọ si pe ko ṣi ẹnikẹni to mọ pe igbakeji gomina yoo yọju sibi adura naa, wọn gbiyanju lati pe igbakeji gomina naa pada, ṣugbọn o ti kuro nibi ti iṣẹlẹ naa ti waye.
Saaju la ti kọkọ s fun yin pe ikọ ijọba ipinlẹ Oyo to lọ sibi adura Fidau ọjọ mẹjọ fun Gomina ana, Abiola Ajimobi ni wọn ko jẹ ki wọn wọle sile Ajimobi to wa ni Oluyole nilu Ibadan.
Gẹgẹ bi Omolere tii se akọwe feto iroyin fun igbakeji Gomina, onimọ ẹrọ Raufu Olaniyan ti se sọ, Igbakeji Gomina, olori awọn oṣiṣẹ ijọba, Alhaja Amidat Agboola ati Kọmisana fọrọ ilẹ, Abiodun Abdul Raheem wa lara awọn ti wọn ko ribi wọle sibi adura Fidau naa.
Ninu ohun ta ri gbọ, n ṣe ni awọn agbofinro to wa nibi isinku naa da ọkọ wọn pada, ti ọrọ naa si fẹ di fa ki n fa ki wọn to fi ibẹ silẹ.
Bi o tilẹ jẹ pe awọn agbofinro naa ko kede ẹni to paṣẹ pe ki maṣe gba awọn asoju ijọba laye lati wọle, ṣugbọn lẹnu igba ti Ajimobi ti papoda ni aawọ ti n waye laarin mọlẹbi rẹ ati ijọba ipinlẹ Oyo.
Oríṣun àwòrán, Others
Bi awọn mọlẹbi ṣe n naka abuku si ijọba Gomina Seyi Makinde, naa ni ijọba n tako wọn pe awọn ko jẹbi ẹsun ti iyawo oloogbe Florence Ajimobi fi n kan ijọba pe, wọn ko fi apọnle to yẹ fun ọkọ ohun lẹyin iku rẹ.
Oríṣun àwòrán, BBC Sport
Ọrọ ti n ba ọrọ bọ lori iku to mu ẹmi gomina ana nipinlẹ Oyo lọ ati ipa ti ijọba ipinlẹ Oyo ko lasiko ti oloogbe naa wa ni idubulẹ aisan.
Idi ni pe Florence, aya oloogbe Abiola Ajimobi, ti n tahun si ijọba ipinlẹ Oyo lori ọna to gba huwa si ọkọ rẹ lasiko to n ṣe aisan.
Florence tahun si igbakeji gomina ipinlẹ Oyo, Rauf Olaniyan to lewaju igbimọ alasẹ ìjọba ipinlẹ Oyo wa ba kẹdun iku ọkọ rẹ.
Koda, fọnran aworan kan to nii ṣe nipa iṣẹlẹ naa ti gba awọn oju opo ori ayelujara kan.
Florence, ẹni to n sọrọ pẹlu ibinu salaye pe oun ko fi igba kankan kan si gomina Seyi Makinde tabi ẹnikẹni ninu awọn alasẹ ijọba l'Ọyọ lati beere iranwọ lasiko ti ọkọ oun wa lori aisan, eyi to ja si iku.
Bakan naa lo tun ṣẹ pe, idile Ajimobi ko ran ẹnikẹni si ijọba gẹgẹ bi gomina Makinde ti sọ.Aya oloogbe Ajimobi, ẹni to gba pe lootọ ko tii yẹ ki oun maa sọrọ síta bayii lasiko ti oun n kẹdun iku ọkọ oun lọwọ, tun salaye pe,
o di dandan ki oun sọrọ sita nitori aimọye iṣẹlẹ aidaa to n waye lati ọdọ ijọba ipinlẹ Oyo.Nigba to n rọ ijọba Oyo lati yago fun oselu buruku, aya Ajimobi ni ololufẹ alaafia ni ọkọ oun, to si sin ipinlẹ Oyo fun ọdun mẹjọ gbako.
"O ni ""Gomina Ipinlẹ Oyo ko fi igba kankan pe oun lori aago tabi fi ọrọ itunu ransẹ fun osu kan ti ọkọ oun fi wa ni idubulẹ àìsàn, iru oselu wo wa nìyẹn?"" Ile aye yii kere pupọ, o si yẹ ka maa ni ibẹru Ọlọrun ninu ohun gbogbo ta ba n ṣe, Ajimobi ti lọ lonii, iwa to ba si hu si ẹnikẹni ko ni ìtumọ mọ."""
Orin ó digberé gb'ọkàn àwọn èèyàn níbi ìsìnkú Abiola Ajimobi
Oríṣun àwòrán, Oyo insight
Iroyin to n tẹ wa lọwọ ni wipe wọn ti gbe oku gomina ana ipinlẹ Oyo, Sẹnetọ Abiola Ajimobi bọ ilẹ ni inu ọgba ile rẹ ni Oluyole, Ibadan.
Awọn iroyin ti a n gbọ latọdọ awọn oniroyin to wa labẹle lawọn to wa nibi eto isinku ni wi pe wọn ti sin oku rẹ ni bonkẹlẹ lai jẹ ki awọn oniroyin wọle.
Ni nkan bii ago mẹwaa kọja iṣẹju marun owurọ yii ni wọn sin in. Ko ju eeyan ogun pere to wa ni bẹ gẹgẹ bi a ṣe gbọ.
Gẹgẹ bi akọroyin BBC Yoruba to wa nibẹ ṣe sọ ọ, gba gba gba lawọn ọlọpaa duro sẹnu ọna ti awọn eeyan kan wa nita.
Ṣaaju, ijọba ipinlẹ Oyo ati ẹbi oloogbe ti fi sita wi pe ilana Covid 19 gbaa ni awọn yoo tẹle fun eto isinku naa.
Oríṣun àwòrán, Oyo insight
Lara awọn agbaagba aafaa to wa nibi eto isinku Oloogbe ni Alaga gbogbo ẹgbẹ awọn musulumi nipinlẹ Oyo, Alhaji Kunle Saani, Sheikh Muiydeen Bello, Olori awọn Imamu ilu Ibadan, Sheikh Abubakar  AbdulGaniyu Agbotomokekere ati awọn mii.
Ni deede ago mejila ọsan ni adura idagbere fun oloogbe bẹrẹ ni Mọṣalaṣi Sẹnetọ Ishaq Abiola Ajimobi to wa ni Oke Ado, Ibadan.
Lootọ gẹgẹ bi wọn ṣe sọ ọ, ilana Covid-19 ni wọn tẹle. Nibi itẹ gangan, eeyan perete pẹlu iyawo oloogbe, Oloye Florence Ajimobi atawọn ẹbi gangan lo wa nibẹ.
Eyi mu ki ero pọ nita ile rẹ ti wọn si n wọ loju titi.
Oríṣun àwòrán, Ajimobi Lives on
Deede ago mejila ọsan ni wọn yoo ṣe adura idagbere fun un ni Mọṣaaṣi. Sen. Ishaq Abiola Ajimobi to wa ni Oke Ado, Ibadan.
Bakan naa nibi eti adura to waye ni Mọṣalaṣi Sẹnetọ Ishaq Abiola Ajimobi, ori ayelujara ni wọn ti ni ki gbogbo eeyan maa wo o. Awọn aafaa diẹ nikan lo peju sibẹ.
Abiola Ajimobi: Àwọn aṣòfin Naijiria ṣọ̀rọ̀ ìwúrí nípa Ajimobi
Abiola Ajimobi: Ẹ wo àwòrán bí ìsìnkú Abiola Ajimobi ṣe lọ!
Akojọpọ aworan isinku gomina ipinlẹ Oyo tẹlẹri, Abiola Ajimobi
Àna olóògbé Abiola Ajimobi, tó tun jẹ́ gómínà ìpínlẹ̀ Kano, Abdullai Ganduje ni bi tó ti n buwọ́lu ìwé àkọlsilẹ̀ níle olóògbé.
Gómínà ìpínlẹ̀ Eko, Babajide Sanwo-Olu sàbẹ̀wò sílé olóògbé
Gomina ipinlẹ Kano ti o tun jẹ ana oloogbe Abiọla Ajimọbi, Abdullahi Umar Ganduje ati gomina ipinlẹ Jigawa, Mohammed Badaru Abubakar ti de si Mọsalaṣi Abiọla Ajimọbi to n bẹ ni Oke Ado niluu Ibadan, nibi ti eto adura ti n lọ lọwọ fun oloogbe
Oríṣun àwòrán, Ajimobi Lives On
Wọn gbe Sẹnetọ Abiola Ajimobi bọ ilẹ ni inu ọgba ile rẹ ni Oluyole, Ibadan.
Oríṣun àwòrán, Ajimobi Lives on
Iroyin ni pe wọn ti sin oku rẹ ni bonkẹlẹ lai jẹ ki awọn oniroyin wọle.
Ita kun fofo awon olopaa naa si wa ni digbi
Oríṣun àwòrán, Ajimobi Lives on
Orin ó digberé gb'ọkàn àwọn èèyàn níbi ìsìnkú Abiola Ajimobi
Ko ju eeyan ogun pere ti wọn jẹ ko wa ni ibi isinku naa, ni ṣe lawọn eniyan duro sita.
Oríṣun àwòrán, Ajimobi Lives on
Ni nkan bii ago mẹwaa kọja iṣẹju marun owurọ yii ni wọn sin in.
Oríṣun àwòrán, Ajimobi Lives on
Deede ago mejila ọsan ni wọn yoo ṣe adura idagbere fun un ni Mọṣaaṣi. Sen. Ishaq Abiola Ajimobi to wa ni Oke Ado, Ibadan.
Bayii ni gbogbo igboro ti kun nibi isinku gomina Abiola Ajimobi
Oríṣun àwòrán, Ajimobi Lives on
Wọ́n ti sin Abiola Ajimobi! Ó di gberééé
Oríṣun àwòrán, Ajimobi Lives on
Deede ago mejila ọsan ni wọn yoo ṣe adura idagbere fun un ni Mọṣaaṣi. Sen. Ishaq Abiola Ajimobi to wa ni Oke Ado, Ibadan.
Access Bank: Ilé ìfowópamọ́ Access ti gbà láti dá owó àwọn oníbàráà wọ́n padà
Oríṣun àwòrán, Access bank
Lẹ́yìn awuyewuye to waye lori ayélujára ní àna nipa owó ti ilé ìfowópàmọ Access bank náà yọ lọ́nà àìtọ́ gẹ́gẹ́ bi (Stamp Duty) ń yọ lori
àwọn oníbàrá wọn, ilé ìfowopamọ́ náà ti gbà láti dá owó oṣù kejì àti kẹrin padà.
Bakan náà lo ni, àwọn yóò dá eyi ti wọ́n yọ lọ́jọ́ Sátidé àti ọjọ́ àìkú pada fun àwọn oníbara ti ọ̀rọ̀ náà kan.
Nínú àtẹ̀jáde tí ilé ìfowópamọ́ ọ̀hún fi síta lọ́jọ́ Àìkú, sàlàyé pé ó ye òun yékéyéke pé àsìkò yìí kò rọgbọ fún àwọn oníbara òun rárá.
"Àtẹjáde náà lọ báyìí: ""A ti wòye lóri bi àwọn alábara wà ṣe fi ẹdùn ọkàn wọ́n hàn lori àwọn ìkànnì orí ayélujara lóríṣiríṣi lọ́jọ́ sátide àti ọjọ́ Àìkú nípa owó tí a ń yọ ""Stamp Duty""."
A ti gbọ́ ẹdùn ọkàn yín a sì ti ṣetan láti dá awọn owó náà padà
Oríṣun àwòrán, AccessBank
"Sáájú ni ilé ìfowópamọ́ náà ti fi àtẹjáde kan sọ́wọ́ pé àwọn kò yọ ""Stamp Duty"" lórí kátàkárà tó wáyé láàrín ọjọ́ kini oṣù keji àti ọgbọ̀n ọjọ́, oṣù kẹrin ọdun yìí tẹ́lẹ̀."
"Iwé ofin Naijiria ọdun 2019 lóri ìṣúna ti paa lásẹ pé ki ilé ìfowópama máa yọ ààdọ́ta nairia gẹ́gk bi ""Satamp duty lórí gbogbo ẹgbẹ̀run mẹwàá náírà ti ó ba wọ àpò ikówósi nílé ìfowwópamọ́."
Sotitobire church news: Ilé ẹjọ́ sún ìgbẹ́jọ́ pásítọ̀ ìjọ Sotitobire sí ọjọ kẹrinla, oṣu Kẹsàn án
Ile ẹjọ giga to kalẹ si ilu Akure ti sun igbẹjọ pasitọ ijọ Sotitobire Miracle Centre, Alfa Babatunde Sotitobire si ọjọ kẹrinla, oṣu Kẹsan an ọdun 2020.
Igbesẹ yii lo waye lẹyin ti pastitọ naa atawọn mẹfa miran ti wọn fẹsun kan pari awijare wọn niwaju ile ẹjọ ọhun.
Eyii n tumọ si pe o ṣeeṣe ki ile ẹjọ naa fi ọjọ ti yoo ṣe idajọ rẹ lede lọjọ naa.
Lẹyin ti ẹlẹri ikarundinlogun ti olujẹjọ pe sọ tẹnu rẹ tan, adajọ to n gbọ ẹjọ ọhun, Olusola Odusola mu Sotitobire si ọjọ kẹrinla, oṣu Kẹsan an ọdun 2020 gẹgẹ binọjọ to kan ki ọjọ idajọ to de.
O ni oun ko ni gba ki agbẹjọro ijọba tabi agbẹjkọro Sotitobire da oju ẹjọ ọhun ru nitori pe idajọ odo ni ou n fẹ lori ọrọ na.
Wolii Sotitobire atawọn ọmọ ijọ rẹ mẹfa miran dẹni to n kawọ pọn tojọ niwaju adajọ lẹyin ti ọmọ ọdun kan, Kolawole Gold, dede poora ninu ijọ rẹ lopin ọdun 2019.
Sotitobire Latest news: Adájọ́ yarí lórí bí àwọn ẹlẹ́rìí ṣe ń fi ẹjọ́ falẹ̀
Ile ejọ giga tipinlẹ Ondo, to kalẹ si ilu Akure, ti fari ga lori bi igbejọ Alfa Babatunde se n fa nilẹ bii igbin.
Adajọ Olusegun Odusola to n gbọ ẹjọ ẹsun ijọmọgbe ti wọn fi kan wolii ijọ Sotitobire naa, lo woye bẹẹ lasiko igbẹjọ to waye lọjọ Isẹgun.
Adajọ Odusola wa fajuro lori bi agbẹjọro fun olujẹjọ, Alfa Babatunde, se tun beere pe ki wọn sun ẹjọ naa siwaju nitori ailera rẹ.
Adajọ naa ni igbẹjọ ẹsun ijọmọgbe naa gbọdọ wa si òpin kí oṣù keje tó ń bọ̀ ó to parí.
Ikede yii si ni adajọ naa tun fi n sọ ero ọkan rẹ, lori bi awọn ẹlẹrii ti olujẹjọ naa pe, se n mu isunsiwaju ati ifasẹyin ba ẹjọ naa.
Adajọ Odusola wa sun igbẹjọ náà siwaju di ọjọ́ Kẹrìnlá, ikẹẹdogun àti ìkẹrin dínlógún oṣù keje ọdún 2020.
Wọn ti sún igbejo sì ọlá ọgbọ́n ọjọ́ oṣù kẹfà fún ìparí gbígbé jọ àwọn ẹlẹri wòlíì Alfa Babatunde.
Adajọ tí wá ṣàlàyé pé, kí wọn gbìyànjú láti jẹ ki awon Ẹlẹ́rìí náà pọ ni iye bíi bẹẹ kọ, ilé ẹjọ́ yóò pé àwọn ẹni a fẹ̀sùn kan, ní pàtàkì Alfa Babatunde láti jẹ ẹlẹ́rìí ara rẹ nítorí wọn fẹ ki igbejo náà tètè parí.
Sotitobire n jẹjọ nipa Gold Kolawole ọmọ ọdun kan to di awati nile ijọsin rẹ ni ilu Akure.
Ṣáájú ni àwọn eleri méjì tí sọ̀rọ̀ gbé sẹ́yìn Alfa Babatunde dípò àwọn mẹta tí ó yẹ kí o sọ̀rọ̀.
Èyí ló mú kí Adajọ Olusegun Odusola pé àkíyèsí ilé ẹjọ́ pé, tí àwọn Ẹlẹ́rìí kò bá pè dáadáa lọ́nà, olórí ẹni afesunkan ni yóò ṣe ẹlẹ́rìí ara rẹ.
Wolii Babatunde Sotitobire tun de ile ẹjọ giga ipinlẹ Ondo lonii lati jẹjọ nipa Gold Kolawole ọmọ ọdun kan to di awati nile ijọsin rẹ l'Akure.
Gẹgẹ bo ti maa n ṣe ni kete to ba ti de ile ẹjọ nipa fifọ ọwọ ati lilo sanitaisa ko to wọ ile ẹjọ lọ.
Ọjọ pẹ ti ọrọ bi ọmọ ọdun kan to sọnu ni ie ijọsin kan nipinlẹ Ondo eyi ti Wolii Alfa Babatunde Sotitobire n dari ẹ ti n waye.
Lonii, ile ẹjọ giga ipinlẹ Ondo tun ti pe Wolii Sotitobire atawọn to pe ni ẹlẹri rẹ ki wọn wa wi tẹnu wẹnu wọn.
Lọsẹ to kọja, iyawo rẹ ti kun awọn ẹlẹri to si sọ ohun to mọ, bakan naa ni awọn eeyan ogun mii naa ti n jẹri ohun ti wọn mọ.
Nile ẹjọ, wọn wo awọn fọran kọọkan lori ifọrọwanilẹnuwo to waye pẹlu Wolii naa.
Bakan naa lọsẹ to kọja, ijọba ipinlẹ Ondo ti ni A kò ní fara mọ́ fífi àkókò ṣòfò lórí ẹjọ́ Sotitobire - Ìjọba Ondo
Bí ìgbẹ́jọ́ wòlíì Sotitobire ṣe ń lọ lọ́wọ́ nílé ẹjọ́ lónìí rèé
Ẹ tẹti leko lonii lori ikani yii, BBC Yoruba fun ẹkunrẹrẹ bo ba ṣe n lọ nile ẹjọ.
Ajimobi Vs Seyi Makinde: Amòfin ní tí Ajimobi bá jẹ́ mẹ̀kúnnù, ṣé Makinde yóò gbà kí wọ́n sín sí GRA?
Oríṣun àwòrán, Ajimobi lives on
Ọrọ ti n ba ọrọ bọ, eegun alare lori igbesẹ ti gomina Seyi Makinde gbe, nipa fifun ẹbi Abiola Ajimobi laaye lati sin oku si ilẹ ijsba GRA, ti ofin ko faaye gba.
Awọn ọmọ Naijiria kan lo fi oju laifi wo igbesẹ naa lori ayelujara, ti wọn si ni igbesẹ arufin gbaa ni Makinde gbe, pẹlu bo se fi ontẹ lu isinku Ajimobi sori ilẹ GRA.
Idi si ree ti BBC Yoruba fi tọ onimọ kan nipa ofin lọ lati beere pe, se gomina Makinde rufin lootọ abi bẹẹ kọ lori gbigba ki wọn sin Ajimobi si GRA.
Lero ti Amofin Ayodeji Olabiwonninu ni ofin Nigeria Land use act 1978 fun gomina ipinlẹ kọọkan lagbara lati sakoso awọn ilẹ ijọba to wa ni agbegbe rẹ.
O fikun pe, pẹlu ohun gbogbo ti a ri ka ninu iroyin ati ofin ilẹ Naijria, ko yẹ ki Gomina Makinde gba ki wọn sin Ajimobi si GRA Oluyole, to wa ni Ibadan.
Amofin naa ni ''O fihan gbangba pe awọn kan ga ju ofin lọ ati wi pe, ofin orilẹede Naijria ko jọba lori gbogbo eniyan.''
''Ni ọpọlọpọ agbegbe ni Naijiria, awọn eniyan giga ati ọlọla n jọba lori ofin, ti ko si si ẹni ti yoo mu wọn si.''
"Amofin Olabiwonninu wa n beere pe, ""ka ni mẹkunu ni Abiola Ajimobi, n jẹ ijọba le gba ki wọn sin oku rẹ si GRA?"
Ijiya wo lo tosi ẹni to ba ru ofin to lodi si sinsin oku si ilẹ ijọba GRA?
Nigba to n mẹnu ba iru ijiya to tọ si ẹni to ba rufin yii, Olabiwonninu sọ wi pe, ijiya to rọ mọ riru ofin to de bi wọn ṣe n lo ilẹ ijọba yatọ ni agbegbe kan si omiran.
Olabiwonninu ni, gbogbo ofin to ba ti tọka si pe iwa yii ko lẹtọ, naa lo ma n sọ iru ijiya to tọ si ẹni to ba rufin naa ni agbegbe ọhun.
Amọ, o ni ohun to ṣe ni laanu ni wi pe, ijọba lo ma n pe eniyan lẹjọ to ba ru ofin to de lilo ilẹ ijọba.
"Sugbọn nibayii, ""ijọba ipinlẹ Oyo gan an lo rufin, ta ni yoo wa gbe Gomina Seyi Makinde lọ si ile ẹjọ bayii, lẹyin ti wọn fun ẹbi Abiola Ajimobi laaye lati sin oku si GRA, to wa ni ipinlẹ naa?"
Awọn ẹri dabi ẹni ti n farahan lori idi ti iyawo gomina ipinlẹ Ọyọ nigba kan, Florence Ajimobi, fi tahun si ijọba ipinlẹ Ọyọ lọjọ Aiku lẹyin isinku ọkọ rẹ.
Ọjọ Aiku ni fidio kan gba ori ayelujara, eyi to ṣafihan Florence, nibi to ti n tahun si igbakeji gomina ipinlẹ Ọyọ, Rauf Olaniyan, pe wọn ko ba oun kẹ́dùn iku ọkọ oun.
Oríṣun àwòrán, @AAAjimobi
Olaniyan naa han ninu fidio naa, ti wọn ká silẹ ninu yara igbalejo kan nile Ajimobi lẹyin eto isinku rẹ.
Ninu ikede kan ti Akọwe iroyin fún Gomina Seyi Makinde, fi sita lo ti dabi ẹni pe ijọba gbiyanju lati wẹ ara rẹ mọ.
Atẹjade naa sọ pe gbogbo igbiyanju àti igbesẹ oun lati ṣe atilẹyin fun idile Ajimobi, lasiko to fi wa ni i dubulẹ aisan lo jasi pabo. Ati pe iyawo Ajimobi kò tẹle ilana to yẹ lati fi aisan àti ikú ọkọ rẹ to ijọba ipinlẹ Ọyọ l'eti.
Ninu fidio naa, Olaniyan sọ pe gbogbo ipe ti oun pe si ori ẹ̀rọ ibanisọrọ Florence Ajimobi, ni kò gbé.
Iroyin tun sọ pe Makinde pe igbakeji gomina ipinlẹ Eko ni, ki o to o ri nọ́mbà dokita to n tọju rẹ.
Ọna ile ijọba ni dokita naa wa, lẹyin ti mo ránṣẹ pé e láti ba mi sọrọ l'ori aisan Ajimobi, ki ọkọ rẹ to jẹ ọkan lara awọn to di ipo mu ninu ise jọba Ajimobi, to sọ fún un pe ko pada, ko si yọ́ wọ ilu Eko.
Koda, igba ti gbogbo igbiyanju mi lati ba Florence sọrọ ja si asán, ni mo pé gomina ipinlẹ Eko, Babajide Sanwo-olu, pe mo fa ohun gbogbo le e lọwọ, ati pe ko ba ipinlẹ Ọyọ tọju Ajimobi daada, ko si jẹ ki n mọ ti wọn ba nilo iranlọwọ mi.
Iroyin tun sọ pe Makinde pe Arabinrin Florence Ajimobi, nigba to gbọ pe ọkọ rẹ kú, sugbọn ko tun gbe ìpè.Ipinlẹ Edo ni gomina wa nigba to gbọ pe Abiola Ajimobi kú.
Ó pe iyawo rẹ, sugbọn ko gbe ipe. Eyi ko si tun di lọwọ lati ṣe nkan to yẹ.
"Loju ẹsẹ lo pàṣẹ pe ki wọn o sọ asia orilẹ-ede Naijiria kalẹ, lati bu ọlá fun."" Iroyin sọ pe, afi bi Gomina Makinde ṣe gba ipe lati ọdọ agba oloṣelu kan, pe ko yọnda ilẹ bi plot mejidinlaadọta fun idile Ajimobi."
Adugbo ti ijọba ya sọtọ, ni Agodi GRA, ni ilẹ to to pulọọ́ti mejidinlaadọta naa wa.
Koda, iroyin sọ pe awọn agbaagba ninu ẹgbẹ oṣelu APC ati PDP, to fi mọ aarẹ Naijiria nigba kan, lo pé Makinde pe ko yọnda ilẹ naa fun wọn lati sin oku Ajimobi si.
"Taiwo Adisa sọ pe ""ọrọ ilẹ naa wa nile ẹjọ, oun ko si le tapa si àṣẹ ile ẹjọ."
"Koda, gomina Abiola Ajimobi lo gbé ijọba ipinlẹ Ọyọ lọ sile ẹjọ lori ọrọ ilẹ naa."""
Ati pe lootọ ni ofin kò gba ki wọn sin oku si adugbo ti ijọba ya sọtọ, ìyẹn GRA.
Ile Ajimobi to wa ni GRA lagbegbe Ring-Road, nilu Ibadan, ni wọn padà sin in si.
Eyi to tumọ si pe o ṣe e ṣe ki ijọba fun wọn ni àṣẹ láti ṣe bẹẹ. Eyi lo si mu ki ọpọlọpọ máa sọ lori ayelujara pe o ṣee ṣe ko jẹ nkan to n bi iyawo Ajimobi ninu gan-an ni pe Gomina Makinde ko jẹ ko gba ilẹ naa to wa ni Agodi GRA ko di tara rẹ.
Ojú ẹni máa là... ọ̀dọ́mọdé tó padà dí dókítà lẹ́yìn ọ̀pọ̀lọpọ̀ ìgbìyànjú láyé
Oríṣun àwòrán, @others
Omo elepo bentiroo to di onisegun oyinbo
Yorùbá ni bi eeyan ba ni suuru ti ko si tete ku, o di dandan ko jẹ ẹran tó ju erin lọ
Bí ènìyàn ba sì ni àfojúsùn, o di dandan kí o ṣ'ori Ire, ko bọ kuro lọwọ iṣẹ ati oṣi.
Báyìí ni ọ̀rọ̀ irirnajo ọdọmọkunri omo orile-ede South Africa kan ṣe rí, iyẹn Ntando Makhubela.
Oriṣiiriṣi iṣẹ agbara ni Ntando ti ṣe ko to pari ẹ si ko maa ṣíṣe gẹ́gẹ́ bí ọmọ tó n ta epo bentiroolu nílé epo to sì ti àti ibẹ̀ di dókítà oníṣègùn òyìnbó.
Ntando Mkhubela jẹ ẹni odun mẹẹdọgbọn to fi itan aye rẹ gba awọn ọdọ bii tirẹ ni imọran lori bi o ṣe ta epo títí to fi di dókítà
Lati ìgbà to ti sọ itan bí o ṣe rìn irinajo ìgbésí aye rẹ̀ lórí ayélujára ni ọ̀pọ̀ àwọn ènìyàn ti n rii gẹ́gẹ́ awokọse rere láwùjọ.
Oríṣí ìjìyà ní àwọn bíi Gómìnà El Rufai àti Fayemi ń bèèrè f'àwọn afipábánilòpọ̀
Leyin to parí ilé ìwé Gírámà pẹlu awọn maaki to lamilaaka, Makhubela kò ní Ore òfẹ́ láti lọ sí ilé ẹ̀kọ́ Fáṣítì nítorí ìṣòro aisowo.
O lọ ilé ẹ̀kọ́ Cyril Clarke lọ́dún 2014 ro si ni àwọn maaki tó ga ju nínú àwọn imo sáyẹ́nsì bí isiro, Physics, Biology, ṣùgbọ́n ko si owó láti lọ sí Fáṣítì.
'Èmi gan máa ń béèrè lọ́wọ́ ara mi pé ta ni Wole Soyinka gangan'
Ntando bẹ̀rẹ̀ sini ṣíṣe nílé epo, ibẹ ni ẹnìkan ti rii ti o si ri pe ọmọ to ni làákàyè ni.
Ṣe ori to ba maa gbe ẹni lo maa n gbe alawo ire ko ẹni, Oluranlọwọ yii lo ba Ntando wa ọ̀nà ètò ẹ̀kọ́ òfẹ́ sí Fáṣítì, èyí lo sì ran an lowo láti kàwé.
Láìpẹ́ yìí ni Makhubela yóò bẹ̀rẹ̀ si ní gbé ìgbé ayé to wù ú láti ìbẹ̀rẹ̀ aye rẹ̀, nítorí pé díẹ̀ loku kí wọ́n ṣe ayẹyẹ ìgbà ni wọlé fún un gẹ́gẹ́ bí dókítà onímọ̀ ìṣẹ̀gùn òyìnbó.
Nikesuliat: Ọ̀dọ́mọdébìnrin akéwì tó n fi ẹ̀ṣà kìlọ̀ ìwá lásìkò yìí
Osun Police: Ọlọ́pàá gba òògùn ìbílẹ̀, ìbọn, àáké àti àdá lọ́wọ́ egúngún
Oríṣun àwòrán, Others
Ìlúmọ̀ọ́ká egúngún kan ní ìlú Ede, ìpínlẹ̀ Osun ti kó sí panpẹ́ ọlọ́pàá nítorí pé ó ń da ìpayà sílẹ̀ láàrín ìlú.
Ìròyìn sọ pé, awọn ènìyàn n fóri gbárí lásìkò tí eégún náà jáde nílu Ede, tí ọkùnrin kan, Mukaila Ismaila sì fàrapa yánayàna, ti wọn si ti gbe lọ sílé ìwòsàn.
Àwọn tí ọ̀rọ̀ náà sóju wọ́n sàlàyé pé, àwọn tó n tẹ̀lé eégún náà kó onírúurú ǹkan ìjà tó léwu lọ́wọ́, ìdí nìyìí tí wọ́n fi mú ẹjọ́ náà lọ sọ́dọ ọlọ́pàá.
Lẹ́yìn èyí ni ilé iṣẹ́ ọlọ́pàá dá àwọn ẹsọ́ aláàbò sí ibi ìṣẹ̀lẹ̀ náà, sùgbọ́n nígbà ti wọ́n dé bẹ̀, àwon ọmọ lẹ́yìn eégún kọjú ìjà sí àwọn ọlọ́pàá pẹ̀lú ìbọ̀n.
Ọwọ́ sìnkún ọlọ́pàá ba èniyàn mẹ́fà nínú wọ́n, to fi mọ eégún ọ̀ún fúnra rẹ̀.
Oríṣun àwòrán, Others
Kọ́mísọ́nà ọlọ́pàá ní ìpińlẹ̀ Osun Undie Adie fìdí ọ̀rọ̀ náà múlẹ̀, nípa bí wọ́n ṣe mú eégún àti àwọn ìsọmọ̀gbè rẹ̀.
Àwọn nǹkan ti wọ́n gbà lọ́wọ́ wọ́n ni òògùn, ìbọ́n ìgbàlodé kan, ìbọ̀n ọdẹ kan, àdá méjì, ààké àti gángan mẹ́rin.
Seyi Makinde; Ilé iwosan kan ṣoṣo tó wà ní  Idí-Iroko /Adewole tí bàjẹ́ pátápátá.
Ọ̀gá ọlọ́pàá náà sàlàyé pé, àti eégún àti àwọn tókù rẹ̀ kò ni lọ láì jìyà ẹ̀ṣẹ̀ wọ́n.
Ibadan: Olóòlù kò ni kọ́ja agboolé rẹ̀ fún ọdún eégún ìlú Ibadan tọdún yìí
Ọdọọdún ni ayẹyẹ ọdún eégún máa n wáye nílu Ibadan tí ọ̀pọ̀lọpọ̀ elégún oníruurú si má n yọjú lásìkò ayẹyẹ yìí.
Sùgbọ́n látì ìgbà tí ààrùn Coronavirus ti bẹ̀rẹ̀ ni ìjọba ìpínlẹ̀ Oyo ti paa lásẹ pé kò ni sí ipejọpọ̀ elérò, yálà fún ayẹyẹ, iṣílé, ìkọ́mọ jáde àti ìgbéyàwọ.
Èyí kò yọ ẹlẹsìn mùsùlùmí, onígbàgba àti àwọn ẹlẹ́sìn àbáláyé silẹ̀ pẹ̀lú.
Òpin oṣù kaarun ni ayẹyẹ ọdún eégun máa ń bẹ̀rẹ̀ ní ìlú Ibadan sùgbọ́n ìjọba ti kéde pé kò ni sí ààyè fún ayẹyẹ eégún kankan láti wọde nílùú Ibadan lọ́dún yìí, èyí ni láti dẹ́kun ìpéjọpọ̀ elérò púpọ̀ tí ó si lé mú kí ààrùn coronavirus túbọ̀ tànkalẹ̀ síi.
Olubadan tilẹ Ibadan, Ọba Saliu Akanmu Adetunji, Aje Ogungunniso kinni tún  paṣẹ fun awọn egungun nilẹ Ibadan lati ṣe etutu ọdun egungun ninu ile wọn, ki wọn si maa ṣe adura fun opin arun Covid-19.
Bí o ṣe wá ku dẹ̀dẹ̀ tí àyẹyẹ eegun kan pàtàkì nílùú Ibadan egúngún oloolu yóò wáyé, BBC bá olóye Ojegboyega Adepoju to jẹ́ aláàgbàá agúngù àti akọ̀wé gbogbo eléégún nílẹ̀ Ibadan, ó sì tún jẹ́ ìgbákeji ààrẹ gbogbo ẹlẹsin ibílẹ̀ ni ìpínlẹ̀ Oyo sọrọ láti mọ igbẹ́sẹ̀ wọ́n nípa àṣe olubadan àti ìjọba.
Adepoju sàlàyé pé, níwọ̀n ìgbà ti àwọn mùsùlùmí àti onígbàgbọ́ kò lọ sí ilé ìjọsìn lásìkò ọdún wọ́n, kò sí bí ọ̀bọ ṣe sorí ti ìnàkí kò ṣe nítori náà àṣẹ ìjọba ni yóò múlẹ̀.
Nípa ti eégún olóòlù, kò sí ǹka tó fi yàtọ̀ si àwọn eégún tó kù ní Ibadan, nítorí náà, kò ni sí ààyè fún láti jáde.
Láti ìgbà tí ọdún eégú ti bẹ̀rẹ̀ ní ọjọ́kọkanlélọ́gbọ̀n, oṣù karùn-ún ọdún yìí ní gbogbo elégún ti ń ṣe ọdún wọ́n ni ààrín agbo ilé wọ́n.
Èmi gan ṣẹ̀ṣẹ̀ gbé eégún tè mi ni àná ni ààrín agboolé sì ni mó ti gbée, nítori náà gbogbo ẹlẹsìn ìbílẹ̀ ló n gbàdúrà kí ààrùn yìí kúrò nilùú, sùgbọ́n lásìkò yìí, kí gbogbo elégún sàdúrà nígbàlẹ̀ wọ́n.
Nínú ọ̀rọ̀ tirẹ̀ bàbá eégún olóòlù fúnra rẹ Ifasuyi Omotosho Kazeem sọ pé àṣẹ ìjọba àti ti Olúbadan ni abẹ́ gé, èyí lòdì sí ọ̀rọ̀ rẹ̀ to ti bá BBC Yoruba sọ tẹ́lẹ̀ pé ti eégún olóólù kò bá jáde, ǹkan le bàjẹ́ nílùú Ibadan.
Nínú ọ̀rọ̀ rẹ̀ sí BBC , Ifasuyi ní kò sí ǹkan ti yóò ṣẹlẹ̀ ti eégún òun kò bá jáde nítorí gbogbo etùtù tó yẹ ni àwọ́n ti ṣe nígbàlẹ̀, bákan náà ni eégún ọ̀hún kò ni kọ́ja agboolé.
''A ti ṣe gbogbo ètùtu tó yẹ́, asì ti sàdúra tí yóò kó ààrùn Coronavirus kúrò nílùú.''
Ibadan: Bode Akindele, Richard Akinjide àti àwọn èèkàn míì tó kú lọdún 2020
Lẹnu lọọlọ yi, iku awọn eekan ilu, paapa julọ awọn to ti gun oke agba ṣebi ẹni fẹ wọpọ.
Yika Naijiria ni iku ti n mu awọn eeyan lọ, ti a si ri atọkasi pe arun Covid 19 to n ja rainrain nilẹ bayii, ni  ipa to n ko ninu rẹ.
Nilẹ kaarọ o jiire, paapa nilu Ibadan, n se ni iku n pa awọn eeyan jankanjankan bi ẹni pa adiẹ.
Ọrọ yii fọwọ kan Olubadan ilẹ Ibadan, Ọba Saliu Akanmu Adetunji lẹmi debi pe lọjọ Aje, Olubadan lọgun lori iku ọwọwọ awọn ogo ilẹ Ibadan yii.
Ti iroyin iku Parakoyi Ibadan, Oloye Bode Akindele ta tun ṣẹṣẹ gbọ laipẹ yii, si tun da omi tutu si ọkan awọn eeyan.
Awọn eekan ilu miran naa si ti lọ ki o to kan gbajugbaja olokoowo yii.
Diẹ ninu awọn eekan Ibadan ti iku mu lọ ree:
Ninu ifọrọwanilẹnuwo kan ti BBC Yoruba ṣe pẹlu aarẹ ẹgbẹ ọmọ Ibadan, Oloye Adeyemi Soladoye, o ni iku Parakoyi Ilẹ Ibadan, Oloye Bode Akindele ni ẹlẹẹkeje iru rẹ ti yoo ṣẹlẹ lati ibẹrẹ ọdun yii.
Bode Akindele jẹ ẹni ti eledua fi ọrọ ta lọrẹ, to si maa n na owo rẹ lati fi ran awọn eeyan lọwọ.
Oríṣun àwòrán, Facebook/Seyi Makinde
Gomina Ipinlẹ Oyo, Seyi Makinde ninu ọrọ ikẹdun iku onisoowo yii sọ pe ''baba to bi mi ma n gbadura pe ki n dabi Oloye Akindele ni, ti mo ba dagba tan''
Makinde sọ pe, Oloye Akindele lẹni to da owo to pọju fun ijọba lati koju ajakalẹ arun Covid 19.
Agbẹjọro agba Richard Akinjide:
Oloye Osuolale Abimbola Richard Akinjide kii ṣe aimọ lagbo awọn ọtọkulu nilẹ Naijiria, paapa ni ẹka imọ nipa ofin.
Agbẹjọro agba yii fi igba kan jẹ minisita feto ẹkọ ni saa iṣejọba alagbada akọkọ, ti o si tun jẹ Minisita feto idajọ ni saa iṣejọba ẹlẹẹkeji ni Naijiria.
Oríṣun àwòrán, Others
Bẹẹ naa lo wa lara awọn to fi ẹgbẹ agbaagba Yoruba, Yoruba Council of Elders lọlẹ ni ọdun 1975.
Ninu awọn to kopa nibi apero atunto ilẹ Naijiria to waye ni 2014, o jẹ ọkan lara awọn agba ọjẹ to kopa nibẹ.
Ọjọ kọkanlelogun oṣu Kẹrin ọdun 2020 ni alagba Richard Akindele dagbere faye pe o digba, lẹni ọdun mọkandinlaadọrun.
Areoye Oyebola:
Olootu agba nigba kan ri fun ileesẹ iroyin Daily Times, alagba Areoye Oyebola kopa ribi ribi lagbo awọn oniroyin ati onkọwe nigba aye rẹ.
Oríṣun àwòrán, The Guardian Nigeria
Ilumọọka onkọwe ni Areoye Oyebola nigba aye rẹ
Bi a ba n darukọ awọn to lalẹ gaara fawọn to n bọ lẹyin wọn nipa iroyin oniwadi, Oyebola jẹ ọkan gbogi.
Nigba aye rẹ, iwe mẹrindinlọgbọn ni Oyebola kọ.
O fi aye silẹ lẹni ọdun mẹrinlelọgọrin lọjọ kẹwa oṣu kẹta  ọdun 2020 yi kan naa.
Lalekan Ayokunnu Are:
Ọmọwe Olalekan Ayokunnu Are jẹ onimọ ati olukọni pataki nilẹ Naijiria.
Ọmọ agbole Are ni Oke Are ni Ibadan nii se, ọmọwe Lalekan si tun jẹ onimọ nipa ọgbin, ti o si jẹ onisowo pataki lawujọ.
Oríṣun àwòrán, Others
Nibi ayẹyẹ isinku rẹ, igbakeji Gomina ipinlẹ Oyo, Rauf Aderemi Olaniyan sapejuwe rẹ gẹgẹ bi awokọse fun oun, ti o si gbadura ki ẹlẹda tẹ si afẹfẹ rere.
Lalekan Are dagbere faye lẹni ọdun marunlelọgọrin.
Sẹnẹtọ Abiola Ajimobi:
Oríṣun àwòrán, @AAAjimobi
Gomina Ajimobi
Gomina nigba kan ri ni ipinlẹ Oyo, Abiola Ajimobi, jẹ ẹnikan ti iroyin iku rẹ milu titi.
Arun Covid 19 lo ṣekupa ogbontarigi oloselu yii lẹni aadọrin ọdun.
Ọjọ kẹẹdọgbọn osu kẹfa ọdun 2020 si ni gomina ana naa dagbere faye nile iwosan aladani kan nilu Eko nibi to ti n gba itọju lori arun Coronavirus.
Oríṣun àwòrán, thisdaylive.com
Oloye Bode Akindele lo si yi fun ijọba ipinlẹ Oyo lowo to pọju lati fi koju arun Covid-19
Saaju la ti mu iroyin wa fun yin pe iku tun ti doro nilẹ Ibadan pẹlu bi iroyin iku Oloye Bode Akindele ṣe gbagboro kan.
Oloye Bode Akindele lasiko aye rẹ jẹ ilumọọka oniṣowo ti o si tun jẹ Parakoyi ti ilu Ibadan.
Ẹni ọdun mẹtadinlaadọrun ni wọn jẹ.
Aarẹ ọmọ ẹgbẹ ilu Ibadan Oloye Adeyemi Soladoye fidi ọrọ yi mulẹ fun ileesẹ BBC Yoruba, to si sọ pe nilu Eko ni agba ọjẹ yi ku si.
Soladoye ṣapejuwe  iku Oloye Bode Akindele gẹgẹ bi eyi to fọwọ kan ni lẹmi nitori o jẹ ọkan lara awọn ogo ilẹ Ibadan ti awọn n foju sun.
''Ni nkan to ti n sẹlẹ lati osu kini ọdun yi, Oloye Bode Akindele ni ẹnikeeje ogo ilẹ Ibadan to jẹ Ọlọrun nipe lọdun yi''
Ninu  apejuwe to se, o sọ pe Oloye Akindele jẹ jagunjagun aye isin lẹka oko owo.
Ẹgbọ́n olóògbé Suga: Wọ́n yìnbọn fún Suga lójú mi, n kò sì lè dá wọn dúró
''Oloye Akindele jẹ akikanju ti a le fi we awọn jagunjagun aye atijọ bi Ogunmọla, Ibikunle, Odẹrinlọ. Awọn ti a n wo mọ Ibadan lara ree laye isin''
Nigba ti BBC beere boya Covid-19 lo sokunfa iku olokoowo yi, Soladoye ni ohun ko le sọ sugbọn o ni arun Covid-19 ko jẹ ki ọpọ awọn agbalagba ko ribi gba itọju to yẹ.
Africa Eye: Ọwọ́ tẹ ayédèrú dókítà Abdallah tó ń tà oògùn Coronavirus
Laipẹ yi ni ilumọọka oniṣowo ọmọ ilẹ Ibadan yi da ọgọrun miliọnu naira fun ijọba apapọ ati ti ipinlẹ Oyo lati fi koju arun Covid-19.
Láàrín ìdílé ẹlẹ́ni márùn ún yìí, ọmọ kan ṣoṣo ló léè sọ̀rọ̀
Lagos School reopening: Ìjóba ìpínlẹ̀ Eko kéde ṣíṣí àwọn ilé ìwé padà
Oríṣun àwòrán, others
Ìjọba ìpínlẹ̀ Eko tí kéde pé kí àwọn ipele ikẹ́kọ̀ọ́ jáde, ipele àkọ́kọ́ girama (JSS3) àti akẹ́kọ̀ọ́ jáde girama (SSS3) kí wọ́n wọlé pade silé ẹ̀ká wọ́n láti ọjọ́ kẹta ọsù kẹjọ ọd'un yìí lọ.
Gómìnà ìpínlẹ̀ Eko Babajide Sanwo-Olu kéde ọ̀rọ̀ yìí pé, lẹ́yìn ti àwọn tí ọ̀rọ̀ kan ti fikùnlukùn ni àwọn pínnu láti ṣilèkùn ilé iwé ní ọjọ kẹta, oṣù kẹjọ, ọdun yii.
O ní ìwọlé yìí wà fún àwọn tọ fẹ́ ṣe ìdánwò àṣe kágbágbá nìkàn ni.
Gómìnà ni àwọn ilé ẹ̀kọ́ fásiti gbogbo yóò sì wà ni títì pa, kí wọ́n tẹ̀síwájú nínú ètò ẹ̀kọ́ orí ayélujara.
Oríṣun àwòrán, FAAN
Airport reopening in Nigeria: Wo ohun tó yẹ kó o mọ̀ tó bá fẹ́ rìnrìnàjò pẹ̀lú ọkọ̀ òfúrufú ní Naijiria
Minisita fun eto irinna ofurufu ni Naijiria, Hadi Sirika ti kede igbẹṣẹ tuntun ti awọn to n rinrinajọ gbọdọ tẹle ti wọn ba de papakọ ofurufu ni Naijiria.
Eyi ko ṣẹyin bi wọn yoo ṣe si papakọ ofufuru fun igbokegbodo ọkọ ofurufu ni Naijiria lati Ọjọ Kẹjọ, Osu Keje yii.
Hadi Sirika ti laa ni ẹṣẹẹsẹ, awọn igbesẹ ti awọn eniyan gbọdọ tẹlẹ ti wọn ba ṣe n de papakọ ofurufu:
Nikesuliat: Ọ̀dọ́mọdébìnrin akéwì tó n fi ẹ̀ṣà kìlọ̀ ìwá lásìkò yìí
Láàrín ìdílé ẹlẹ́ni márùn ún yìí, ọmọ kan ṣoṣo ló léè sọ̀rọ̀
Bakan naa ni Minisita fun irinna ọkọ ofurufu, Hadi Sirika ni ẹnikẹni to ba ni iba tabi to n wu kọ lati ma ṣe wa si papakọ ofurufu, nitori wọn ko ni gba ki ẹnikẹni to ba ni ami to farajọ ti arun Coronavirus wọ ọkọ ofurufu.
Ijọba orilẹ-ede Niajiria ti paṣẹ ki wọn ṣi awọn papakọ ofurufu to wa lorilẹ-ede Naijiria lẹyin oṣu mẹta ti wọn ti i pa nitori ajakalẹ arun Coronavirus.
Minisita fun eto irinna ofurufu ni Naijiria, Hadi Sirika lo kede rẹ loju ọpọ ikansiraẹni Twitter rẹ.
Oríṣun àwòrán, Others
Hadi ni  Ọjọ Kẹjọ, Osu Keje ni papakọ ofurufu ti ilu Eko ati Abuja yoo ṣi pada.
Papakọ ofurufu ti ipinlẹ Kano, Port Harcourt, Owerri ati Maiduguri yoo si ni Ọjọ kọkanla, Osu Kẹjọ,
Nigba ti awọn papakọ ofurufu to ku yoo ṣi ni Ọjọ Karundinlogun, Osu Kẹjọ.
Ni bayii, iye awọn to ti lugbadi arun Coronavirus ni Naijiria ti da 26,484, ti eniyan 603 si ti ku.
Eniyan 10,152 lo ti ri iwosan gba lọwọ arun Coronavirus ni Niajiria.
Oríṣí ìjìyà ní àwọn bíi Gómìnà El Rufai àti Fayemi ń bèèrè f'àwọn afipábánilòpọ̀
Ijọba apapọ lorile-ede Naijiria ti kede pe igbokegbodo ọkọ laarin ipinlẹ kan si omiran le bẹrẹ pada lati ọjọ Kini oṣu Keje.
Amọ to wa nibẹ ni pe laarin wakati ki konileogbele to bẹrẹ ni wọn le fi rinna.
Oríṣun àwòrán, Twitter/Bashirahmad
Alaga igbimọ eleto ijọba lori Covid-19 Boss Mustapha lo lede ọrọ yi lasiko to n jabọ ilana ti yoo de ipele keji idẹwọ isede ti ijọba gbe kalẹ.
Boss sọ pe idẹwọ isede yi yoo waye fun oṣu mẹrin pẹlu iyipada diẹ si eyi to wa nilẹ tẹlẹ.
Ikede yi n waye pẹlu bi iye awọn to lugbadi arun yi ti se kọja ẹgbẹrun mẹrinlelogun.
Uber Lady: Bùkátà pọ̀ lọ́rùn mi ní mo ṣe ń wa taxi akérò
‘Ọ̀pọ̀lọpọ̀ ni inú wọn kò dùn sí bí Hajj kò ṣe ní wáyé lọ́dún yii’
Ìbánújẹ́ gbọkàn àwọn èèyàn nílé abílékọ ọlọ́mọ mẹ́ta tí wọ́n ṣẹ̀ṣẹ̀ pa ní Ibadan
Ẹ wo ìṣẹ̀lẹ̀ nípa ẹ̀sùn ìfipábánilòpọ̀ tí wọ́n fi kan D'banj ní sísẹ̀-n-tẹ̀lé
Eji Gbadero, ọmọ Ibadan àti jayé-jayé ọmọ ónílẹ̀ ti wọn yẹgi fun l'Eko
Bàbá ẹni ọdún 61 bá ọmọ rẹ̀ lopọ̀, ó fún un lóyún l'Eko
'Èmi gan máa ń béèrè lọ́wọ́ ara mi pé ta ni Wole Soyinka gangan'
Lagos Covid-19 Test: N50,400 géérégé lẹ ó san láti ṣe àyẹ̀wò Covid-19
Oríṣun àwòrán, @ProfAkinAbayomi
Lara akitiyan ati tun fogun mọ arun Coronavirus, ijọba ipinlẹ Eko ti fun awọn ileewosan aladani kan ni Eko niwe aṣẹ ṣiṣe ayẹwo Covid-19.
Ọjọ aje ọjọ kọkandilọgbọn oṣu kẹfa ọdun 2020 ni wọn ṣe ifilọlẹ apapọ ẹgbẹ awọn yara ayẹwo ti awọn eeyan ti le maa lọ ṣe ayẹwo arun Covid-19 nipinlẹ Eko.
Ẹwẹ, nigba ti BBC Yoruba kan si ọkan lara awọn laabu ayẹwo naa, wọn fi aridaju han pe irinwo le ẹgbẹrun lọna aadọta Naira (N50,400) n owo ti eeyan kọọkan to ba wa ṣe ayẹwo yoo maa san.
Owo yii kii ṣe ipinu laabu ti a pe nikan o, agbẹnusọ ti a ba sọrọ jẹ ko di mimọ pe iye kan naa ni awọn laabu toku naa yoo maa gba.
Kọmisana eto ilera fun ipinlẹ Eko, Ọjọgbọn Akin Abayomi fi si oju opo Twitter rẹ pe lẹyin ọpọlọpọ ayẹwo ifigagbaga, awọn yara ayẹwo meje ti ijọba Eko yan ni:
·Total Medical Services
·SynLab
·54 Gene
·Medbury medical Services
·Biologix Medical Services
·02 Medical Services
·Clina Lancent Lab
Oríṣun àwòrán, @ProfAkinAbayomi
Agbẹnusọ ọkan lara awọn laabu ti a pe yii lati mọ boya lootọ ni iroyin ti a gbọ pe N50,400 ni ẹni to ba fẹ ṣe ayẹwo yoo maa san ṣalaye pe bẹẹ ni ṣugbọn ijọba Eko ko mu u ni dandan fawọn eeyan.
O ṣalaye pe kii ṣe gbogbo ile iwosan aladani lo n ṣe ayẹwo naa ṣugbọn awọn ni anfani lati wa lara awọn to n ṣe e.
Kẹẹ to lọ fun ayẹwo, ẹ o pe nọmba laabu ọhun wọn yoo si fi atẹjiṣẹ kan ti ijọba pese ranṣẹ sii yin eyi ti ẹ o lo lati forukọ silẹ lọdọ wọn ki wọn to dajọ ayẹwo fun yin.
Seyi Makinde; Ilé iwosan kan ṣoṣo tó wà ní  Idí-Iroko /Adewole tí bàjẹ́ pátápátá.
Nibi eto ifilọlẹ naa, ọjọgbọn Akin Abayomi jẹ ko di mimọ pe awọn laabu ti wọn yan yii ni gbogbo irinṣẹ ati ohun to tọ  lti ṣe ayẹwo Covid-19 tori naa ni wọn ṣe yan wọn.
Ni ipari, aṣoju gbogbo laabu ti wọn yan fọwọ si iwe adehun ni kọọkan pẹlu ijọba ipinlẹ Eko.
Láàrín ìdílé ẹlẹ́ni márùn ún yìí, ọmọ kan ṣoṣo ló léè sọ̀rọ̀
APC news in Ondo State: Yahaya Bello ni alága ìgbìmọ ìdìbò abẹ́lé gónìnà ìpińlẹ̀ Ondo
Egbẹ́ òṣèlú APC  nípìnlẹ̀ Ondo ti yan Gómìnà Kogi Yahaya Bello gẹ́gẹ́ bi alága ìgbìmọ̀ ìdìbò abẹ́lé fún àwọn olùdíje fun ipo gómìnà nípìnlẹ̀ Ondo.
"Èyí jẹyọ nínú àtẹ̀jáde kan ti àkọlé rẹ̀ ni ""Gómìnà Yahaya Bello gẹ́gẹ́ bi alága ìdìbò abẹ́lé ìpínnlẹ̀ Ondo"" tí ìgbákejì akọ̀wé ìpolongo apapọ̀ ẹgbẹ́ buwọ́lù, Yekini Nabena nílùú Abuja lọ́jọ́rú."
Nínú àtẹ̀jáde náà ni wọ́n ti kọọ́ wí pé, ṣaájú ìdìbò abẹ́lé ẹgbẹ́ òṣèlú All Progressives Congress ti yóò wáye ni ìpińlẹ̀ Ondo ní ogúnjọ oṣù kèje, ọdún 2020, lábẹ́ gómìnà ìpínlẹ̀ Yobe Mai Mala Buni tó ń jẹ́ adelé alága ètò àti ìpètù sááwọ̀ ẹgbẹ́.
Gómìnà ìpińlẹ̀ Kogi, Yahaya Bello ni yóò jẹ́ alága ìgbìmọ̀ ìdìbò abẹ́lé, nígbà ti Emperor Chris Baywood Ibe yóò jẹ́ alága ìgbìmọ̀ to ń pètù sí ààwọ̀ ìdìbò abẹ́lé.
Àwọn ọmọ ìgbìmọ̀ ìdìbò abẹ́lé ìpińlẹ̀ Ondo
1. H.E. Yahaya Bello - Alága
2. Olorogun o'tega Emerhor OON - Akọ̀wé
3. Alwan Hassan - Ọmọ ẹgbẹ́
4. Chief Samuel Sambo - Ọmọ ẹgbẹ́
5. Hajiya Binta Salihu - Ọmọ ẹgbẹ́
6. Mr. Emma Andy - Ọmọ ẹgbẹ́
7. Dr. Adebayo Adelabu - Ọmọ ẹgbẹ́
8. Abdullahi Aliyu - Ọmọ ẹgbẹ́
9. Mrs. Margret Ngozi Igwe - Ọmọ ẹgbẹ́
Àtẹ̀jáde ọ̀hún náà tún dárúkọ àwọn ọmọ ìgbìmọ̀ tí yóò pẹ̀tù sááwọ̀ to bá súyọ lẹ́yìn ìdìbò abẹ́lé
1. Emperor Chris Baywood Ibe - Alága
2. Arch. Abdulmimuni Okara - Akọ̀wé
3. Mr. Festus Fientes - Ọmọ ẹgbẹ́
4. Mr. Okon Owoefiak - Ọmọ ẹgbẹ́
5. Mr. ABBA Isah - Ọmọ ẹgbẹ́
6. Alh. Umar Duhu -Ọmọ ẹgbẹ́
7. Hon. Sani El-katuzu - Ọmọ ẹgbẹ́
8. Mrs. Osuere Eunice - Ọmọ ẹgbẹ́
9. Emeka Agaba - Ọmọ ẹgbẹ́
O ní adelé alága APC yóò maa ṣàfilọ́lẹ̀ àwọn ọmọ ìgbìmọ̀ méjèèjì ní olú ilé ]ẹgbẹ́ ni ilú Abuja ní aago mẹta ọ̀sán ọjọ́ Ẹti, ọjọ́ kẹtàdinlógun, oṣù keje, ọdun 2020
Mi ò tíì gba ìwé ìfitónilétí pé wọ́n fẹ́ yọ mí nípò- Igbákejì gómìnà ìpínlẹ̀ Ondo
Oríṣun àwòrán, @RotimiAkeredolu
Igbakeji gomina ipinlẹ Ondo, Agboola Ajayi ti sọ pe oun ko tii gba iwe ifitonileti pe ile igbimọ aṣofin ipinlẹ ọhun fẹ yọ oun nipo.
Ajayi lo fi ọrọ naa lede nigba to ba BBC Yoruba sọrọ lori aago.
"O ni ""Wọn ko tii fun mi ni iwe ifitonileti kankan o, mi o tii gba iwe kankan."""
Ṣaaju ni iroyin kan ti kọkọ jade pe akọwe ile naa, Adeyelu Bode sọ pe ile ọhun ti fun Agboola Ajayi ni iwe ifitonileti naa.
Iroyin naa ṣalaye pe lara ẹsun ti awọn aṣofin naa fi kan igbakeji gomina ọhun ni iwa aṣemaṣe lẹnu iṣẹ, ṣiṣowo ilu baṣubaṣu, aṣilo ipo, eyii to lee da oju ijọba bolẹ, atawọn ẹsun miran.
Oríṣun àwòrán, Olowu Idowu Henry
Ṣugbọn igbakeji gomina naa fidi rẹ mulẹ fun BBC Yoruba pe ọrọ ko ri bẹ nitori ohun ko tii ri iwe kankan gba.
Wahala bẹ silẹ laarin gomina ipinlẹ Ondo, Rotimi Akeredolu ati igbakeji rẹ lẹyin ti Ajayi fi ẹgbẹ oṣelu APC silẹ lọ darapọ mọ ẹgbẹ PDP.
Ko pẹ to gbe igbesẹ yii ti awuyeweuye iyọnipo naa bẹrẹ, ti mẹrinla lara awọn aṣofin ile si gbe igbesẹ lati yọ igbakeji gomina ọhun nipo, ṣugbọn mẹsan an lara wọn ni wọn ko ni lọwọ sii.
Ki lo ti ṣẹlẹ sẹyin?
Oríṣun àwòrán, Ondo Assembly
Ile asofin ipinlẹ Ondo ti bẹrẹ igbesẹ lati yọ igbakeji gomina ipinlẹ naa, Agboola Ajayi nipo rẹ.
Kii  ṣe iroyin tuntun mọ pe aarin Gomina Ipinlẹ Ondo, Oluwarotimi Akeredolu ati Igbakeji rẹ, ko dan mọran mọ.
Eyi ko si sẹyin bi igbakeji rẹ se kuro ni ẹgbẹ oṣelu APC lọ si PDP, lati dije du ipo Gomina ninu eto idibo ti yoo waye ni Oṣu Kẹwa, ọdun yii.
Awọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí:
Lọwọ-lọwọ bayii, awọn aṣofin mẹrinla ninu mẹtalelogun ti buwọlu yiyọ Igbakeji Gomina ipinlẹ Ondo, Agboola Ajayi ni ipo.
Sugbọn ki igbesẹ yii to lee waye, ofin wa ti awọn asofin naa gbọdọ tẹle, nitori wọn ko le dede yọ Igbakeji Gomina ni ipo.
Oyo Schools: Akẹ́kọ̀ọ́ Fásitì, Poly wà nílé, kí ló mú ti alákọ̀ọ́bẹ̀rẹ̀, girama wà níta?
Labẹ ofin orilẹede Naijiria, ẹsun kan ti Ile Igbimọ Aṣofin Ipinlẹ le fi kan Igbakeji Gomina lati yọ ni ipo, ni ti tapa si ofin orilẹede Naijiria.
Nibayii, ẹ jẹ ka wọ awọn igbesẹ ti Ile Aṣofin Ipinlẹ Ondo gbọdọ tẹle lati yọ Agboola Ajayi ni ipo, gẹgẹ bi ofin Naijiria se laa kalẹ.
Ile asofin nipinlẹ Ondo ti pasẹ pe ki wọn fun igbakeji gomina nipinlẹ naa, Agboola Ajayi ni iwe ifitonileti pe awọn fẹ rọ ọ loye.
Olori ile, Bamidele Oleyelogun lo pasẹ bẹẹ lasiko ijoko ile to waye lọsan ọjọ Isẹgun.
Bakan naa lo sisọ loju rẹ pe awọn asofin mẹrinla lo fi ọwọ siwe pe ki wọn rọ igbakeji gomina naa loye, ninu asofin mẹrindinlọgbọn to wa nibẹ.
Ọrọ iyọnipo igbakeji gomina naa si lo lewaju ijiroro ile asofin naa, to pada wọle lẹyin isisnmi ranpẹ ti wọn lọ fun.
Lasiko ijokoo ile naa, asofin mẹsan lo fọwọsi iwe pe awọn ko fara mọ iyọnipo igbakeji gomina naa.
Oríṣun àwòrán, Ondo state House of Assembly
Lẹyin ti ile se agbeyẹwo abala ofin to yẹ nipa igbesẹ rẹ ọhun lo wa pasẹ pe ki wọn lọ fun igbakeji gomina, Agboola Ajayi ni iwe ifitonileti pe wọn fẹ rọ ọ loye.
Nigba to n ba BBC Yoruba sọrọ lẹyin ijoko ile, Asofin Gbenga Omole, tii se alaga igbimọ ile feto iroyin kede pe ile ko tii gba irufẹ iwe ikede bẹẹ.
Omole ni ọla Ọjọru ni wọn yoo mọ bi ohun gbogbo yoo se lọ lori ọrọ iyọnipo naa.
Ẹwẹ, awọn asofin to jẹ ọmọ ẹgbẹ oselu to kere julọ nile asofin naa, ti kọ lati fi ọwọ si iwe iyọnipo igbakeji gomina.
Awọn asofin naa lo n fi apa janu pe ile ko fun awọn ni aaye lati gbọ aroye awọn.
Bẹẹ ba gbagbe, laipẹ yii ni igbakeji gomina nipinlẹ Ondo kuro ninu ẹgbẹ oselu APC, to si dara pọ mọ ẹgbẹ oselu alatako, PDP.
Bi o tilẹ jẹ pe agbẹnusọ fun ijọba ipinlẹ Ondo sọ fun awọn akọroyin pe, wọn ko ni yọ igbakeji gomina naa nipo nitori pe o fi ẹgbẹ oselu APC silẹ.
Amọ aarọ ọjọ Isẹgun ni igbakeji gomina naa lọ sile ẹjọ lati beere pe ki ile ẹjọ da ile asofin ipinlẹ Ondo lọwọ kọ, lati mase yẹ aga mọ oun nidi.
Oríṣun àwòrán, @RotimiAkeredolu
Ọrọ ti n ba ọrọ bọ nipinlẹ Ondo lori bi ajọsepọ to wa laarin gomina Rotimi Akeredolu ati igbakeji rẹ.
Idi ni pe igbakeji gomina, Agboola Ajayi ti kede pe ki Akeredolu tete fa akoso ipinlẹ naa le oun lọwọ laarin ọjọ mọkanlelogun nibayii to to wa ni iyasọtọ nitori arun Coronavirus to lugbadi rẹ.
Bẹẹ ba gbagbe, igbakeji gomina naa lo ti kuro ninu ẹgbẹ oselu APC lọ si PDP, ti ọrọ si ti n lọ kaakiri pe o seese ko gbe igba ibo gomina bii oludije fun ẹgbẹ oselu PDP naa.
Ninu atẹjade kan ti akọwe iroyin igbakeji gomina ọhun, Allen Sowore fisita, Ajayi tọkasi abala ofin ilẹ wa tọdun 1999, ori ọgọsan, ẹsẹ keji, eyi to laa kalẹ pe, o yẹ ki Akeredolu fa akoso ipinlẹ naa le oun lọwọ ni.
Belly Mujinga: Bí iléeṣẹ́ ọlọ́pàá ní UK ṣe parí ẹ̀ṣùn rẹ̀ mú kí àwọn adúláwọ̀ fa ìbínú yọ
"O fikun pe ""Bi gomina ba wa kọ lati fa akoso le emi igbakeji rẹ lọwọ lasiko to wa ni iyasọtọ yii, a jẹ pe o tapa si ofin ilẹ wa ni, to si foju tẹnbẹlu awọn eeyan ati ofin ilẹ wa to jẹjẹ lati tẹle."""
"Bakan naa lo ni ""ipinnu Akeredolu lati mase jẹ ki isejọba tẹsiwaju lasiko to wa ni iyasọtọ yii nitori arun Coronavirus fihan pe, ẹnu lasan lo fi n gbogun ti arun Covid-19 to n ja rain nilẹ."""
Oríṣun àwòrán, others
"Saaju la ti mu iroyin wa fun yin pe gomina ipinlẹ Ondo, Rotimi Akeredolu ti ke gbajari sita pe, oun ko mọ ohunkohun nipa ọti lile kan ti wọn kọ akọle ""Aketi"" si lara."
Akeredolu lo sọ bẹẹ ninu atẹjade ti oluranlọwọ pataki rẹ lori ọrọ to n lọ, Ojo Oyewamide fi lede.
Igbeṣẹ yii lo n waye lẹyin ti fidio kan gbode lori ayelujara, eyi to ṣafihan igo ọti ọhun ti wọn kọ orukọ ipinlẹ ipinlẹ Ondo si lara pẹlu orukọ ti ọpọ eeyan mọ gomina ọhun si, iyẹn Aketi.
Akeredolu ni oun ko nilo lati kọ orukọ oun si ara igo ọti kankan ki awọn eeyan ipinlẹ Ondo to dibo fun oun ninu eto idibo sipo gomina to n bọ.
"O ni ""Awọn to ṣe iru nnkan bayii yii n fẹ ki awọn eeyan ro pe owo ipinlẹ Ondo ni a fi n po ọti"""
"Atẹjade naa tẹsiwaju pe ""Yatọ si eyi, a ṣi n reti ki awọn eeyan to wa nidi igo ọti naa ṣe awọn nnkan miran, ṣugbọn gomina ti gbe igbesẹ lati ṣawari awọn to wa nidi iṣẹlẹ ọhun."""
Lẹyin naa lo ni ki awọn eeyan ma ṣe kọbi ara si fidio ọhun.
Oríṣun àwòrán, Twitter/RotimiAkeredolu
Bi iyawo Gomina Rotomi Akeredolu ba ni Covid-19, wọn yoo kede gẹgẹ bi ọkọ wọn naa se sọ faraye.
Esi ree ti agbẹnusọ Gomina ipinlẹ Ondo, Olusegun Ajiboye fọ nigba ti ileesẹ BBC Yoruba beere lọwọ rẹ pe, se lootọ ni arabinrin Betty Anyanwu iyawo Gomina Akeredolu ti lugbadi Covid-19.
Ajiboye sọ pe ''nigba ti Gomina Akeredolu lugbadi Covid-19, wọn kede fun ara wọn, ti iyawo wọn naa ba ni Coronavirus, ko si awo kankan nibẹ, wọn yoo kede rẹ.''
Oríṣun àwòrán, Twitter/RotimiAkeredolu
Lọjọbọ ni iroyin kan gbode pe, iyawo Gomina ti ko arun Covid -19, ti atẹjisẹ kan ti awọn eeyan n pin kaakiri si sọ pe, ki gbogbo awọn eeyan to kopa nibi eto ti iyawo Gomina se ni Idanre ati Odigbo, tara lọ se ayẹwo.
Ninu ahesọ ọrọ to gbode yii, ni wọn ti sọ pe awọn aṣofin mẹfa, ninu awọn to kọwọrin pẹlu Gomina Akeredolu lati lọ gba fọọmu idibo Gomina, ni wọn ti lugbadi Covid-19.
Lọjọbọ yii kan naa ni awọn agbẹnusọ fawọn asofin ti sọ fun BBC Yoruba pe, awọn yoo mọ boya awọn lugbadi Covid-19 laipẹ.
Amọ Olusegun Ajiboye ni iroyin naa ko ri bẹẹ rara.
Bẹẹ ba gbagbe, laipẹ yii Gomina Akeredolu kede ninu fọnran fidio kan pe, ohun ti lugbadi Covid-19.
O ni ohun ko foju apẹrẹ arun naa han ṣugbọn ohun ti bẹrẹ iyasọtọ ati itọju.
Yatọ si Akeredolu, Gomina Ifeanyi Okowa ipinlẹ Delta atiiyawo rẹ naa kede pe awọn lugbadi arun yi.
Kọmisana feto ilera nipinlẹ Ondo naa, Dokita Wahab Adegbenro la tun gbọ pe o ṣalaisi si ibudo ti wọn ti n tọju awọn alarun Coronavirus nilu Akure.
Oríṣun àwòrán, Akeredolu Twitter
Agbẹnusọ awọn asofin nipinlẹ Ondo, Gbenga Omole lo fi idi ọrọ naa mulẹ fun BBC Yoruba.
Omole ni awọn asofin ogun to tẹlẹ Gomina Akeredolu naa ni yoo lọ ṣe ayẹwo fun aarun Coronavirus ni Ọjọ Keji, Osu Keje, ọdun 2020.
Bakan naa ni agbẹnusọ awọn asofin nipinlẹ Ondo naa ni oun ko ya ara oun sọtọ nitori pe oun ko ni arun Coronavirus.
'Kilo de ti ma a fi ya ara mii sọtọ nigba ti mi o ni arun Coronavirus?'
Oríṣun àwòrán, Twitter
Ọgbọnjọ, Oṣu Kẹfa ni Gomina ipinlẹ Ondo kede pe oun ti ko arun Coronavirus, ti oun si ti ya ara oun sọtọ.
Oríṣun àwòrán, Twitter
Amọ, iroyin fi lede wi pe ọpọlọpọ awọn eniyan ni Gomina Akeredolu ti farakan to fi mọ Aarẹ Buhari, awọn lọbalọba ati awọn aṣofin naa.
Oríṣun àwòrán, Twitter
Awọn asofin to ba Gomina ipinlẹ Ondo, Oluwarotimi Akeredolu lọ si Abuja lati lọ gba sabuke lati dije dupo ninu idibo abẹlẹ saaju idibo sipo gomina ni ipinlẹ Ondo.
Oríṣun àwòrán, Twitter
Gomina Rotimi Akeredolu ti ipinlẹ Ondo ti kede pe oun ti ni arun Coronavirus.
Oríṣun àwòrán, Rotimi Akeredolu Aketi facebook
Gomina Akeredolu ẹni to kede bẹẹ loju opo Facebook rẹ ninu fidio kan to fisita nibẹ fikun pe laarọ ọjọ Isẹgun ni oun gba esi ayẹwo oun.
Gomina ipinlẹ Ondo ni apẹẹrẹ ami Covid-19 na ko jẹ jade lara oun, ti oun ko si saisan lati fihan pe oun ni arun naa.
O wa kede pe oun ti ya ara oun sọtọ bayii fun itọju, ti awọn osisẹ eleto ilera fun arun Coronavirus yoo si maa tọju oun nile.
Akeredolu wa rọ gbogbo eeyan lati ri daju pe wọn wa ni alaafia, ki ara wọn si da.
'Buns ni ọmọ mi jẹ tán ní ṣọ́ọ̀ṣì, ló bá di àwátì'
Bẹẹ ba gbagbe, ọsẹ meji sẹyin ree ti gomina Akeredolu lọ silu Abuja lati lọ kede pe oun fẹ dije fun saa keji lori aleefa, ọpọ eeyan si lo di mọ lati ya aworan.
Akeredolu, Okowa, àtàwọn gómìnà Nàìjíríà míì tó ti kó àrùn Coronavirus
Oríṣun àwòrán, Twitter
Gomina ipinlẹ Delta, Ọmọwe Ifeanyi Arthur Okowa ti di gomina to wa loju ọpọn lọwọlọwọ lara awọn to ṣẹṣẹ lugbadi arun Coronavirus.
Lọjọ kinni oṣu keje ọdun 2020 ni gomina Delta fi si oju opo Twitter rẹ pe Èmi àti ìyàwó mi ti lùgbàdì àrùn CoronaVirus.
Oríṣun àwòrán, Rotimi Akeredolu
Bakan naa, ọjọ kan sira wọn lo wa laarin ikede tirẹ ati ti gomina ipinlẹ Ondo, Rotimi Akeredolu.
Ni tirẹ, oun naa kede loju opo Twitter pe oun ti ya ara oun sọtọ fun itọju bayii bo tilẹ jẹ pe ko fi ami kankan han lara rẹ pe o ni arun Covid-19.
Ọjọ́bọ̀ la ó mọ̀ bóyá a ní Coronavirus - Aṣòfin Ondo
Aisan iba ni gomina Akeredolu kọkọ sọ pe oun ni to si n tọju ni nkan bii ọjọ diẹ sẹyin. Ṣugbọn o ni awọn akẹgbẹ oun lo ni ko lọ ṣe ayẹwo ti esi rẹ si jade lọjọ to gbẹyin ninu oṣu kẹfa eyi to fi han pe o ti lugbadi rẹ.
Bakan naa, gomina ipinlẹ Abia, Okezie Ikpeazu naa wa lara awọn olori ipinlẹ ti esi ayẹwo wọn fi han pe wọn ni arun Coronavirus lorilẹede Naijiria.
Oríṣun àwòrán, Office of the Governor
Gomina Okezie Ikpeazu, Nasir El Rufai , Bala Muhammed ati Seyi Makinde
Esi ti gomina Ikpeazu kọkọ fi han pe ko ni arun naa nigba to lọ ṣe ayẹwo lọgbọn ọjọ oṣu karun ṣugbọn nigba to pada lọ ni ọjọ kẹrin oṣu kẹfa, o pada wale pẹlu esi pe o ni arun naa.
Nibayii, gomina Ikpeazu naa ti bẹrẹ iyasọtọ labẹ akoso awọn eleto ilera akọsẹmọṣẹ o si ni ki igbakeji rẹ maa dele de oun ko to de.
Ko wa tan sori gomina ipinlẹ Abia nikan o, awọn gomina mii to ti lugbadi Coronavirus ree:
Oríṣun àwòrán, Twitter/Bala A. Mohammed
Gomina Bala Mohammed ti ipinlẹ Bauchi ni iha ila oorun ariwa orilẹede naa ti gba esi ayẹwo to fi han pe o lugbadi Covid-19 ninu oṣu kẹta ọdun 2020.
Agbẹnusọ rẹ, Muktar Gidado sọ ọ ninu atẹjade kan lẹyin ti ajọ NCDC ṣe ayẹwo mẹfa lara Ọgbẹni Mohammed to si fihan pe o ni arun naa.
Oríṣun àwòrán, Bauchi
Ninu oṣu kẹrin ni gomina Bala Mohammed wa fi sita loju opo Twitter pe oun ti pada bọ lọwọ arun naa lẹyin to ṣe iyasọtọ to si gba itọju.
Gomina ipinlẹ Kaduna, Nasir El Rufai
Oríṣun àwòrán, Twitter/Nasir Ahmad El-Rufai
Lọjọ kọkandinlọgbọn oṣu kẹta, gomina Nasir El-Rufai ti Kano naa kede pe oun ti ni arun Coronavirus.
O fi kun un pe oun ti ya ara oun sọtọ gẹgẹ bi ilana ajọ NCDC eyi to ni ṣe pẹlu awọn to ko arun naa ṣugbọn ti ko ni ami ifara han rẹ.
Nigba to ya, ninu oṣu kẹrin ni Ọgbẹni El-Rufai tun fi sita ipo ti o ṣi wa koda o tun ṣepade pẹlu awọn lọga ninu iṣejọba rẹ.
Lasiko iyaraẹnisọtọ, ṣe ni Ọgbẹni El-Rufai n fi ọrọ sita loju opo Twitter rẹ ni gbogbo igba nipa ipo ti ilera rẹ wa.
Gomin aipinlẹ Oyo, Seyi Makinde
Oríṣun àwòrán, Twitter/@seyiamakinde
Gomina ipinlẹ Oyo naa kede3 loju opo Twitter rẹ pe oun lugbadi arun Coronavirus ni nkan bii ọgbọnjọ oṣu kẹta.
O ṣalaye pe ami pe o ni i ko fara han lara rẹ to si ni oun yoo tẹle ofin iyaraẹnisọtọ.
Ko pẹ sira, ni oṣu to tẹle e ni gomina Seyi Makinde fi ikede sita pe oun ko ni i mọ, oun ti bọ to si dupẹ lọwọ awọn eeyan atawọn igbimọ to n moju to iṣẹlẹ Covid-19 ti wọn n gbadura fun un.
"Arun ""Coro"" ṣi n dọdẹ gidi gan ni Naijiria bẹẹ si ni lonii, iye awọn to lugbadi arun yii ti le ni ẹgbẹrun marun-din-lọgbọn bayii."
Lazarus Chakwera: Ààrẹ orílẹ̀-èdè Malawi 'tó bá Ọlọ́run jiyàn'
Oríṣun àwòrán, Reuters
Yoruba bọ, wọn ni iwa kii fi oniwa silẹ, bẹẹ gan-an ni ọrọ ri fun aarẹ ti wọn ṣẹṣẹ dibo yan lorilẹ-ede Malawi, Lazarus Chakwera lasiko to ba awọn eeyan orilẹ-ede naa sọrọ nípa isọkan lẹyin ti wọn búra fun tan.
Oṣu mẹtala ni orilẹ-ede naa fi pin yẹlẹ-yẹlẹ, nitori awuyewuye to waye lori esi idibo ọdun 2019, ile ẹjọ fagile esi idibo naa.
O sọ pe ko dara to lati kan ni àlá lai sisẹ to tọ.
"O ni ""asiko ti de fun wa lati ṣe tayọ àlá wa nikan."""
Gbogbo wa gbọdọ jí kuro loju orun, nitori pe asiko niyii lati mu ki àlá wa sẹ.
Iranṣẹ Ọlọrun ni Ọgbẹni Chakwera jẹ ni orilẹ-ede Malawi.
Ọdun 2013 ni ẹni ọdun marundinlaadọrin naa di olori ẹgbẹ oṣelu Malawi Congress Party, lai ni iriri kankan nipa oṣelu.
O di oloṣelu lẹyin ọdun mẹrinlelogun to ti jẹ oludari ijọ Assemblies of God. O jẹwọ pe ko rọrun fun oun nigba ti oun pinnu lati du ipo aarẹ lọdun 2014.
"Mo ni lati ba Ọlọrun jiyàn lori ọna ti mo gba pe o yatọ pupọ.
Sugbọn lẹyin ọpọlọpọ ijiroro, Ọlọrun sọ pe: mo n sọ isẹ ìranṣẹ rẹ di gbigbooroo, ki o le ṣe olùṣọ́ àgùntàn odidi orilẹ-ede."""
O tun sọ ninu ifọrọwanilẹnu kan lọdun 2017 pe, lasiko ijiroro pẹlu Ọlọrun ni oun tun ka iwe Ẹ́ksódù ninu Bibeli, nibi ti Ọlọrun ti farahan Mose, to si sọ fun un pe ko dari awọn ọmọ Ísrẹ́lì jade kuro ni Egypti.
Oludamọran rẹ, Sean Kampondeni sọ fun BBC pe, eyi lo fihan pe adari le mojuto igbe aye ẹ̀mí ati ti ara, awọn eniyan rẹ. Ṣugbọn kii ṣe pe o fẹ ṣe isakoso Malawi ni ilana ẹ̀kọ́ Bibeli.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
"Aarẹ gbagbọ pe isejọba orilẹ-ede jẹ nkan ti Ọlọrun lọwọ si, lati le mu ilọsiwaju ba awujọ, ati ọmọniyan.
Ọgbẹni Kampondeni tun sọ pe O gbagbọ pe isejọba ti wo lulẹ ni Malawi, ti ko si ṣe ojuse yii, lati ọdun mẹẹdọgbọn sẹyin. O si ti yọnda ara rẹ lati ṣe ojuṣe naa."""
Ọmọ oniwaasu ati ajinhinrere ni Ọgbẹni Chakwera. Baba rẹ da ọpọlọpọ sọọsi silẹ.
O sọ fun akọroyin kan, Joab Chakhaza lasiko ifọrọwanilẹnu kan lọdun 2017 pé lootọ lo ni afojusun lati di dokita, nitori o gbagbọ pe oun ko nilo lati ba ipejọpọ ọpọ eniyan sọrọ nípa jíjẹ oṣiṣẹ eto ilera, nitori o jẹ ẹni to maa n tijú.
"O sọ pe ""oun ba Ọlọrun pade nigba to jẹ akẹ́kọ̀ọ́, mo si bẹrẹ si ni dari igbeaye si ilana iṣẹ Oluwa."""
Okun ati imisi naa si lo fẹ ẹ lo fi dari orilẹ-ede bayii.
Mr Kampondeni tun sọ pe aarẹ mọ pe iyatọ nla lo wa laarin jijẹ olori ẹ̀sìn àti oloṣelu.
Sugbọn, o sọ pe ilana ti aarẹ yoo gbe e gba yoo yatọ, ko si ni ṣe e ni ilana bo ba o pa, bo o ba ko bu u lẹsẹ.
Yoo si lo ọgbọn inu rẹ lati da isọkan pada si orilẹ-ede Malawi.
"Ọgbẹni Chakwera sọ fun awọn ọmọ orilẹ-ede naa lasiko to ba wọn sọrọ pe ""ko si ifoya fun awọn ti ko dibo fun""."
Bi aarẹ tuntun naa ṣe fi ẹyin aarẹ to wa nipo, Peter Mutharika janlẹ, jẹ iyalẹnu. Ìdá mọkandinlaadọta ìbò lo ni.
Oríṣun àwòrán, AFP
Akọroyin kan, Chakhaza, sọ fun BBC pe, isẹ nla lo wa nilẹ fun aarẹ tuntun lati ma a fi ẹ̀yà yan ẹnikẹni si ipo, gẹgẹ bi ijọba to kuro nipo to fi ẹlẹyamẹya ṣe e lai fi bò.
Ojú wa lara rẹ pe ko ṣe daada ju isejọba àná lọ, awọn kan si ti n wo o boya yoo le se bẹ ẹ.
Awọn alatilẹhin aarẹ gbagbọ pe o le ṣe e, ati pe yoo ṣe amulo ilana isejọba tuntun to ni ìtọ́ni Ọlọrun ninu, to si wa ni ibamu pẹlu aini awọn ọmọ orilẹ-ede Malawi.
Ko si àní-àní, awọn igbesẹ to lagbara gbọdọ jẹ gbigbe, paapa nipa itankalẹ aarun coronavirus, ati ọna lati gbogun ti iwa ibajẹ, ati mimu idagbasoke ba ọrọ aje.
Awọn nkan wọn yii lo si ṣe e ṣe ko sọ bi isejọba rẹ yoo ṣe jẹ itẹwọgba.
Canada Visa Application: Canada bẹ̀rẹ̀ iṣẹ́ lórí fọ́ọ̀mù àwọn tó fẹ lọ sí orílẹ̀-èdè náà
Oríṣun àwòrán, @truwayofficial
Ijọba ilẹ Canada ti bẹrẹ si n ṣiṣẹ lori fọọmu awọn to nifẹ lati tẹko leti lọ silẹ naa lati Ọjọ Kinni, Oṣu Keje, ọdun 2020.
Ileeṣẹ to n risi eto irinajo ilẹ okere lorlẹ-ede naa, IRCC sọ pe bo tilẹ jẹ pe awọn gbedeke kan yoo wa fun awọn arinrinajo, ṣugbọn o ti bẹrẹ iṣe pada nitori awọn ti yoo bẹrẹ si n rinrinajo lọ ilẹ ọhun laipẹ.
IRCC ni ootọ ni pe awọn kan ko tii le lọ si Canada lọwọ yii nitori arun Coronavirus, ṣugbọn aye wa fun awọn mọlẹbi ti yoo lo ju ọjọ marundinlogun lọ nilẹ naa, atawọn ti iṣẹ wọn ṣe koko lati wọ Canada lasiko yii.
O sọ pe awọn arinrinajo ni lati ṣalaye fun awọn oṣiṣẹ aṣọbode pe iṣẹ wọn ṣe koko ki wọn to le gba wọn laye lati wọ orilẹ-ede ọhun.
IRCC tun ti bẹrẹ iṣe lori fọọmu awọn akẹkọ to fẹ lọ kawe ni Canada, iwe fun awọn to ti ri iṣe nilẹ naa ati iwe awọn to fi orukọ silẹ lati di ọmọ onilu.
Ijọba ilẹ Canada ti ni ọrọyan ni fun ẹnikẹni to ba ṣẹṣẹ wọ ilẹ naa lati wa ni igbele fun ọjọ mẹrinla gbako.
Bakan naa ni awọn arinrinajo ọhun ni lati pese ẹri fun awọn ẹṣọ aṣọbode pe wọn ni alakalẹ bi wọn yóò ṣe wa ni igbele ọhun.
Ṣaaju ni ijọba ilẹ Canada ti sọ pe oun ko ni gba ki ẹnikẹni wọ orilẹ-ede ọhun lati oke okun titi di Ọjọ kọkanlelọgbọn, oṣu Keje ọdun 2020 nitori ajakalẹ arun Coronavirus.
Seyi Makinde; Ilé iwosan kan ṣoṣo tó wà ní  Idí-Iroko /Adewole tí bàjẹ́ pátápátá.
Funsho Adeolu: Ìwọ̀kuwọ̀ àti ìrìnkurìn obìnrin míì ń fa ìfipábánilòpọ̀
Oríṣun àwòrán, Instagram adeolufunso
Funsho Adeolu: Ìwọ̀kuwọ̀ àti ìrìnkurìn obìnrin míì ń fa ìfipábánilòpọ̀
Gbajugbaja oṣere tiata Yoruba, Funsho Adeolu sọ pe, ọpọ awọn obinrin lo n ṣ'okunfa ifipabanilopọ to gogo lawujọ bayii.
Adeolu woye ọrọ yii lasiko to n kopa lori eto ifọrọwerọ kan lori ikanni BBC News Yoruba.
O ni o ṣeeṣe kawọn ọkunrin ti o n fipa bawọn obinrin lopọ larun ọpọlọ, amọ awọn obinrin mii ti wọn n rinrin kurin lo maa ri irikuri.
O fikun ọrọ rẹ pe, gbogbo awọn ọkunrin ti wọn n fipa bawọn obinrin lopọ kiri, ati ilẹ lo ti wọ wa.
Oríṣun àwòrán, Instagram adeolufunso
Funso Adeolu: O ni bi wọn ṣe tọ awọn ọmọkunrin mii lo jẹ ki wọn maa huwa ifipabanilopọ nitori ko si ohun to le mu ọkunrin kan fipa ba obinrin lopọ.
''Koda ko yẹ ki ọkọ fipa mu iyawo rẹ, ko yẹ ki o fi ipa mu un,'' Funsho Adeolu lo woye bẹẹ.
Nigba ti o n sọrọ nipa bi awọn olootu ṣe maa n fun awọn oṣere nipa ti wọn yoo koo ninu ere, Adeolu ni awọn eeyan to ba burẹwa ko le ko ipa to pọ ninu ere.
Oríṣí ìjìyà ní àwọn bíi Gómìnà El Rufai àti Fayemi ń bèèrè f'àwọn afipábánilòpọ̀
O ṣalaye pe, awọn to ba burẹwa lo maa n kopa bi iwin, Eṣu ati ọmọ ọdọ ninu ere.
Adeolu ni ẹsin kan naa lo yẹ ki tọkọ-taya maa ṣe, ki alaafia le jọba ninu idile pẹlu afikun pe adura ati ifarada ṣe pataki ninu ohun to n mu idile duro.
O wa sisọ loju rẹ pe ọdun mẹjọ ni oun ati pẹlu iyawo oun fi fẹ ara awọn, ki awọn to fẹ ara wọn bii tọkọ-taya.
''Igbeyawo wa ti pe ọdun mẹrindinlogun bayii, a kii ṣe ọkọ ati iyawo, ọrẹ lemi ati iyawo mi, mi o ni ọrẹ mii lẹyin rẹ,''
O ni oun maa n fifẹ han si iyawo oun lori ayelujara, lati jẹ ki o jẹ awokọṣe fawọn eeyan.
Oríṣun àwòrán, Instagram adeolufunso
"O si tun kede pe, ""mama ati baba mi jọ ṣere ni wọn fi bi mi, wọn ko fẹ ara wọn, iyẹ lo jẹ ki n pinnu pe iyawo ti mo ba fẹ gbọdọ ba mi kalẹ."
Nigba to n sọrọ lori awọn oṣere kan ti wọn kii le sọ ede Yoruba ninu ere, Adeolu ni itiju nla ni.
O ni awọn ti wọn ro pe ipa ki oun maa le obinrin kiri nikan ninu ere ni oun maa n ṣe, ko mọ pupọ nipa oun.
Adeolu ni oun ti kopa ninu oriṣiriṣii ere to le ni igba, ti oun si ko oniruuru ipa ninu wọn.
Láàrín ìdílé ẹlẹ́ni márùn ún yìí, ọmọ kan ṣoṣo ló léè sọ̀rọ̀
Alaafin Adeyemi: Lára àwọn òrékelẹ́wà ayaba náà ló dẹnu ìfẹ́ kọ Ọba Adeyemi fúnra wọn
Oríṣun àwòrán, Alaafin Oba Adeyemi 111 Facebook
Ni ọjọ mẹta diẹ sẹyin, a mu iroyin kan wa fun un yin, ninu eyi ti Alaafin ti kede pe, oun kii dẹnu kọ obinrin, o wu awọn iyawo oun, ni wọn fẹ oun funra wọn.
Bakan naa, laipẹ yii la tun kọ iroyin miran nipa awọn olo, ẹlẹjẹ tutu mẹjọ ti wọn n gbe ẹmi Alaafin tilu Ọyọ Èyí ni àwọn arẹwà ‘ẹ̀lẹ̀ Daddy’, àfẹ́fẹ́ tí Aláàfin fi ń mí  .
Awọn ẹlẹ wọnyii lo n gbe ẹmi Ọba Lamidi Olayiwola Adeyemi kẹta ro, ni aafin rẹ lọwọlọwọ.
Bawo ni alaafin ṣe n dẹnu ifẹ kọ awọn ọdọmọde arẹwa wọnyii?
Amọ, ọpọ eeyan to ka iroyin naa lo n beere pe, bawo ni Alaafin, ẹni to ti le ni ọdun mọkanlelọgọrin loke eepẹ, se dẹnu ifẹ kọ awọn arẹwa yii?
Wọn ni niwọn igba to se pe Alaafin kọ lo dẹnu kọ awọn obinrin naa, bawo ni awọn ẹlẹ Daddy se n de inu aafin lati di olori?
Ọna lati wa idahun sawọn ibeere yii lo mu ki BBC Yoruba fi imu finlẹ, lati mọ bi ọpọ awọn ayaba naa se di olori laafin.
Oríṣun àwòrán, Alaafin Oba Adeyemi 111 Facebook
Gẹgẹ bi iwadii wa ti safihan rẹ, diẹ lara awọn olori yii lo jẹ akẹkọọ nilu Oyọ, ti ifẹ Ọba Adeyemi si gba ọkan wọn.
A gbọ pe lati ile ẹkọ ni diẹ lara awọn olori naa ti n pohungbẹ lati di ayaba, ti wọn si n sunmọ awọn eeyan to wa ni aafin Ọyọ.
Iroyin naa fi kun un pe, diẹ diẹ imu ẹlẹdẹ wọn wọ ọgba tan, ti wọn raye sunmọ aafin, ti wọn si ni nọmba Kabiyesi lọwọ.
Asiko ti wọn si ri aaye sunmọ Ọba Adeyemi ni wọn n fi ọrọ ransẹ lori aago pe awọn nifẹ rẹ, to si wu awọn lati di olori laafin rẹ.
Niwọn igba to si jẹ pe ọba kii kọ obinrin, agbalagba si maa n gba mọra ni.
Idi ree ti Alaafin fi jẹ hoo fun awọn agunlẹyinju obinrin yii, ti wọn si di ayaba ni Aafin Ọyọ.
Koda, mẹta ninu awọn olori naa la gbọ pe o wa nile ẹkọ olukọni onipo kinni to wa nilu Ọyọ, ( Emmanuel Alayande College of Education, Oyo) lasiko ti wọn fi ifẹ han si Alaafin pe, awọn fẹ jẹ olori rẹ.
Oríṣun àwòrán, Alaafin Oba Adeyemi 111 Facebook
Koda, Alaafin funra rẹ gan an sisọ loju rẹ nigba kan pe, oun maa n ran awọn olori yii lọ sile iwe lẹyin ti wọn ba de ọdọ oun tan, ki wọn le tẹsiwaju lẹnu ẹkọ wọn.
Bẹẹ si ni diẹ lara awọn ọdọmọde arẹwa olori yii lo ti kẹkọọ jade nile ẹkọ fasiti pẹlu oye imọ ijinlẹ akọkọ.
Ati pe wọn kii pa mọra lati jẹ ki araye mọ pe Ọba Adeyemi lo n se atilẹyin fun awọn Olori rẹ.
Flood: Ọ̀pọ́ Dúkìá ló sọnù ní 2019 lásìkò tí ìjọba ṣí ’dáàmù Ọyan’
Nibayi aya ti mọ oju ọkọ, ọkọ naa si ti mọ oju aya, awọn iyawo naa ti bi isun, wọn ti bi iwalẹ fun Alaafin, awọn alarena naa si ti yẹba.
Oríṣí ìjìyà ní àwọn bíi Gómìnà El Rufai àti Fayemi ń bèèrè f'àwọn afipábánilòpọ̀
Rape: Oríṣí ìjìyà ní àwọn bíi Gómìnà El Rufai àti Fayemi ń bèèrè f'àwọn afipábánilòpọ̀
Nibo ni ọrọ ile aye n lọ bayii lori ifipabanilopọ?
BBC Kayeefi oṣu kẹfa yii lọ si Ado Ekiti nibi ti ọmọbinrin kan ti wọn fipa ba lopọ loke ọja ti ṣe iranlọwọ fun awọn agbofinro ti ọwọ si tẹ awọn ọdọmọkunrin oniṣẹ ibi naa.
Kọmiṣọnna ọlọpaa ni ipinlẹ Ekiti, Amba Asuquo kilọ fun awọn obi lati mojuto awọn ọmọ wọn obinrin to n kiri ọja.
Bakan naa ni awọn eeyan ati ajafẹtọ ọmọniyan sọ iriri wọn lori ifipabanilopọ ni eyi ti o yẹ ki gbogbo awujọ fọwọsowọpọ gbogun ti lasiko yii.
Colonial vestiges: Bourdilloun, Victoria Island, Lugard Avenue wà lára àdúgbò tí yóò pa orúkọ dà
Oríṣun àwòrán, Other
Ile igbimọ aṣofin ipinlẹ Eko ke pe Gomina Babajide Sanwo-Olu lati ṣe agbeyẹwo ofin ọdun 2015 to nii ṣe pẹlu orukọ ọna ati agbegbe ni ipinlẹ Eko.
Eyi waye pẹlu erongba lati ṣe ayipada awọn orukọ to nii ṣe pẹlu owo-ẹru ati ikonilẹru laye awọn amunisin.
Igbakeji olori ẹgbẹ oṣelu to pọju nile, Ọgbẹni Noheem Adams lo mu aba naa wa fun gbogbo ile.
Nigba ti o da aba ọhun, aṣofin Adams ranti bi ọlọpaa alawọ funfun kan, Derek Chauvin ṣe pa George Floyd, alawọ dudu to jẹ ọmọ ilẹ Amẹrika.
Wọnyi ni awọn agbegbe ti ijọba oyinbo amunilẹru sọ niluu Eko ati orisun wọn:
Opopona Lugard:
Bi o tilẹ jẹ wi pe ọpọ orukọ agbegbe ati opopona ni ayipada ti ba, ṣugbọn orukọ opopona Lugard ni Ikoyi niluu Eko ko yipada di oni.
Oyinbo ọmọ ilẹ Gẹẹsi, Ọgbẹni Lord Lugard to da apa guusu ati ariwa orilẹ-ede Naijiria papapọ lọdun 1914.
Oun ni Gomina apaṣẹ-waa akọkọ ti o ṣe ijọba orilẹ-ede Naijiria.
Ile kan lo wa ni opopona ọhun ti wọn n pe ni ile Lugard ti o fi di oni niluu Eko.
Oríṣun àwòrán, Other
Opopona Kingsway:
Opopona Kingsway wa laarin gbungbun agbegbe Ikoyi, ọna ọhun lo da Ikoyi si meji.
Agbegbe yii ni awọn oyinbo nikan fi ṣe ibugbe ni Ikoyi laye ijọba amunilẹru ni Naijiria.
Lasiko Gomina Egerton ni ijọba ṣe opopona ọhun niluu Eko.
Ṣugbọn orukọ agbegbe naa ti yi pada bayii si opopona Alfred Rewane.
Wọn yi orukọ opopona ọhun pada ni bi ọgbọn sẹyin din diẹ lẹyin ọpọ rukerudo to ṣẹlẹ lagbo oṣelu ni Naijiria.
Oríṣun àwòrán, Other
Opopona Bourdillon:
Orukọ Gomina apaṣẹ waa, Sir Bernard Henry Bourdillon ni wọn fi sọ ori opopona yii ni Ikoyi.
Ni ọdun 1935 ni Sir Bourdillon di Gomina apaṣẹ waa ni orilẹ-ede Naijiria, o si di ipo naa mu titi di ọdun 1943 ti o fẹyinti ni ipo naa.
Oponopa Bourdillon jẹ opopona gbajugbaja niluu Eko, koda nibẹ ni ile ogbontarigi oloṣelu ti o tun jẹ eekan ninu ẹgbẹ oṣelu APC, Bola Tinubu kọ ile si.
Oríṣun àwòrán, Other
Victoria Island:
Agbegbe awọn ti Eleduwa fi owo jinki ni Victoria Island jẹ nipinlẹ Eko.
Nibẹ si ni oriṣiiriṣii ileeṣẹ ati awọn ọfiisi pọ si niluu Eko.
Agbegbe Victoria Island wa leti alagbalugbu omi okun, eyi to tun mu un rẹwa sii.
Ọbabinrin ilẹ Gẹẹsi, Victoria to jọba ilu oyinbo laarin ọdun 1837 si 1901 ni wọn fi orukọ rẹ sọ Victoria Island.
Oríṣun àwòrán, Other
Race Course:
Race Course ti o ti di Tafawa Balewa Square bayii jẹ papa ti Oba Dosunmu fun awọn oyinbo to ni ijọba akonilẹru ni Naijiria lọdun 1859.
Ibẹ ni wọn maa n lo fun oriṣiiriṣii ere idaraya laye igba naa.
Oríṣun àwòrán, Other
Ọgagun Yakubu Gowon to jẹ olori orilẹ-ede Naijiria lati ọdun 1966 si ọdun 1975 lo paṣẹ pe ki wọn wo o palẹ.
Lẹyin naa ni ijọba Naijiria yi orukọ rẹ pada si Tafawa Balewa Square.
Ibẹ ni wọn lo fun ayẹyẹ ominira Niajiria lọdun 1960.
'Èmi gan máa ń béèrè lọ́wọ́ ara mi pé ta ni Wole Soyinka gangan'
Wahab Adegbenro: Kọmíṣọ́nnà fún ètò ìlera ní ìpínlẹ̀ Ondo jáde láyé
Oríṣun àwòrán, Akintomi Akin
Kọmisọnna fun eto ilẹra ni ipinlẹ Ondo, Wahab Adegbenro ti wọlẹ sun ni Ọjọ Ẹti.
Adegbenrọ ni wọn sin si ile rẹ to wa ni Ilara Mokin ni ijọba ibilẹ Ifẹdore ni deede aago mẹwaa owurọ gẹgẹ bi ẹsin Musulumi ṣe laa kalẹ.
Oríṣun àwòrán, Adetomi Akin
Ile iwosan ijọba to wa ni Owo lo ku si lẹyin to lugbadi arun Coronavirus.
Amọ awọn aworan ti a ri fihan gbangba pe ọpọ awọn eniyan to wa si ibi isinku naa ni wọn ko lo ibomu, ti wọn ko si tẹle ofin yiyagofunraẹni.
Oríṣun àwòrán, Adetomi Akin
Ẹbi, ara ati ọrẹ pẹlu ojulumọ lo peju pese si ibi isinku naa.
Oríṣun àwòrán, Akintomi Akin
Iroyin to n tẹ wa lọwọ ni yajoyajo ti kede pe Kọmiṣọnna feto ilera nipinlẹ Ondo, Dokita Wahab Adegbenro ti jade laye.
Gẹgẹ baa se gbọ ibudo ti wọn ti n tọju awọn alarun Coronavirus nilu Akure ni Kọmiṣọnna naa dakẹ si.
Oríṣun àwòrán, Ondo TV Twitter
Adegbenro, tii se ọmọ bibi ilu Ilaramọkin nipinlẹ Ondo, ni wọn kede iku rẹ lẹyin ọjọ meji ti gomina ipinlẹ naa, Rotimi Akeredolu kede pe oun naa ti lugbadi arun Coronavirus.
Oríṣun àwòrán, Ondo TV Twitter
Mọlẹbi oloogbe naa, Rasheed salaye pe Kọmisana naa se isẹ abẹ fun alaisan kan lọjọ Aje nile iwosan adani rẹ to wa ni Odo Ikoyi.
Amọ sadede lo subu lulẹ, to si daku lọ rangbọndan, ki wọn to gbe digba-digba re ile iwosan.
Oríṣí ìjìyà ní àwọn bíi Gómìnà El Rufai àti Fayemi ń bèèrè f'àwọn afipábánilòpọ̀
"Rasheed fikun pe ""Lati ọjọ Aje naa la ti ri pe ilera wọn ko ji pepe rara titi di ọsan oni to sadede de lati ọọfisi lairoti , ti wọn si gbe lọ sile iwosan FMT, nibi to dakẹ si."""
Ọpọ eeyan lo ti duro go go go sile oloogbe naa lati kẹdun, ti wọn si n sọkun lori iku aitọjọ to mu Kọmisana naa lọ.
Adesoji Aderemi: Ọjọ́ Kẹta, oṣù Keje, ọdún 1980 ni gómìnà Adúláwọ̀ àkọ́kọ́ náà dèrò ọ̀run
Oríṣun àwòrán, Aderemi Royal Family
Ọba Adesoji Tadenikawo Aderemi n se ibura bii gomina adulawọ akọkọ
Ori ti yoo de ade, ko ni se alai de ade naa, ọrun ti yoo wọ ejigbara ilẹkẹ ko ni se alai wọ ọ, ibadi ti yoo lo mọsaji, asọ ọba to jinna koro-koro, yoo lo.
Ọba Adesoji Tadenikawo Aderemi ree ti ori gbe de ipo Ọba, to tun di gomina adulawọ akọkọ losu keje, ọdun 1960, ibura rẹ ree.
Oríṣun àwòrán, Aderemi Royal Family
Ọbabinrin Elizabeth keji ń fi oye Knight da Ọba Adesoji Aderemi lọla ni ọdun 1957 lasiko to se abẹwo wa si Naijiria
Ọbabinrin ilẹ Gẹẹsi, Elizabeth Keji ree to n fi oye Knight da Ọọni Adesoji Aderemi lọla lasiko abẹwo rẹ si Naijiria lọdun 1957.
Oriade meji pade ara wọn, ọkan jẹ alawọ dudu, ekeji si jẹ alawọ funfun, ọkan jẹ obinrin, ti ekeji si jẹ ọkunrin.
Oríṣun àwòrán, Aderemi Royal Family
Ọba Adesoji Tadenikawo Aderemi, Ọọni tilu Ile Ifẹ to tun di gomina Adulawọ akọkọ, aguntasọlo ọdun.
Ko tii si ori ade mọ to ṣe gomina mọ ipo Ọba.
Oríṣun àwòrán, Aderemi Royal Family
Ọba Adesoji Tadenikawo Aderemi n fun Ọba miran ni amiidanilọla ti Ọbabinrin ilu oyinbo
Ọba n da Ọba lọla, oriade n yẹ ori ade si.
Ọba Adesoji Tadenikawo Aderemi ree to n fun Ọba miran ni amiidanilọla ti Ọbabinrin ilu oyinbo.
Oríṣun àwòrán, Aderemi Royal Family
Ọba Adesoji Tadenikawo Aderemi
Ọba Adesoji Tadenikawo Aderemi, ẹni ti obinrin ri, to n yọ ọwọ ọṣẹ, pe temi ni ko gba, temi ni ko mu.
Oriade to dudu bii koro isin, to dùn lati wo lọmọ ọkunrin.
Oríṣun àwòrán, Aderemi Royal Family
Ọba Adesoji Tadenikawo Aderemi ati agba Yoruba miran
Ko si aniani pe Ọba Adesoji Tadenikawo Aderemi ti se gudu-gudu meje ati ya ya mẹfa lati gbe iran Yoruba de ibi giga nigba aye rẹ.
Oriade naa ree pẹlu agba Yoruba miran nibi ipade apero kan.
Oríṣun àwòrán, Aderemi Royal Family
Ọba Adesoji Tadenikawo Aderemi n bọ oyinbo kan lọwọ
Ẹni nla lo n se oun nla. Ọba Adesoji Tadenikawo Aderemi ati awọn eekan ilu miran to n bọ oyinbo lọwọ.
Tolori tẹlẹmu lo n wa ri ti wọn n bu ọla fun Baba nigba aye rẹ
Oríṣun àwòrán, Aderemi Royal Family
Ọba Adesoji Tadenikawo Aderemi n yẹ awọn ologun wo
Ẹ jẹ ka bu ọla fun ẹni ti ọla n se tirẹ. Ọba Adesoji Tadenikawo Aderemi ree to n yẹ awọn ọlọpaa to to lọwọọwọ wo lati yẹ si. Gbosa fun baba.
Kabiesi Aderẹmi jẹ Ọba to mu iṣẹ rẹ ni ọkunkundun.
Oríṣun àwòrán, Aderemi Royal Family
Ọba Adesoji Tadenikawo Aderemi ninu ọkọ ti wọn ti n yẹ si
Ọba Adesoji Tadenikawo Aderemi wa ninu mọto, ti awọn ọlọpaa si gbe ida soke lati yẹ si lasiko to n wọ inu ilu Ile Ife lọ.
Ipo ọla dara lootọ, ki Ọba oke gbe gbogbo wa debẹ.
Oríṣun àwòrán, Aderemi Royal Family
Ọba Adesoji Tadenikawo Aderemi pẹlu Ọgagun Adeyinka Adebayo
Olowo lo n se ọrẹ olowo, otosi lo n se ọrẹ otosi, Adeyinka Adebayo ree to n se ọrẹ oriade.
Ọba Adesoji Tadenikawo Aderemi n tẹti gbọ ohun ti gomina ologun fun ẹkun Iwọ Oorun Guusu Naijiria, Ọgagun Adeyinka Adebayo n sọ
Ibi ipade kan lọdun 1966 ni wọn ti ya aworan naa, ki Ọlọrun fi ọrun kẹ awọn mejeeji.
Oríṣun àwòrán, Aderemi Royal Family
Ọlọla Lyttleton, Oloye Obafemi Awolowo ati Ọba Adesoji Tadenikawo Aderemi lọdun 1950
Aye n lọ, a n tọ ọ, awọn eeyan ti lọ nilẹ yii, ki Ọlọrun ba wa fi ọrun sikẹ wọn.
Ọlọla Lyttleton, eeebo amunisin lati ilẹ Gẹẹsi to dari Naijiria nigba kan ree pẹlu Oloye Obafemi Awolowo ati Ọba Adesoji Tadenikawo Aderemi
Awọn mẹtẹẹlọdun niyi lọdun 1950 ti wọn n takurọsọ.
Oríṣun àwòrán, Aderemi Royal Family
Ọba Adesoji Tadenikawo Aderemi n bọ Ọlọla Winston Churchill lọwọ
Ọba Adesoji Tadenikawo Aderemi n bọ olootu ijọba ilẹ Gẹẹsi nigbakan, Ọlọla Winston Churchill lọwọ ni Blenheim Palace, Woodstock, Oxfordshire, England
Abẹwo naa waye lọjọ kọkanla osu kẹfa ọdun 1953.
Oríṣun àwòrán, Aderemi Royal Family
Ọba Adesoji Tadenikawo Aderemi ati awọn ọmọ Yoruba miran pẹlu U Thant tii se Akọwe agba fun ajọ isọkan orilẹede agbaye, UN
Ọba Adesoji Tadenikawo Aderemi ati awọn ọmọ Yoruba miran pẹlu U Thant tii se Akọwe agba fun ajọ isọkan orilẹ-ede agbaye, UN.
Ọpọlọpọ orilẹ-ede agbaye ni Oba Adesọji Aderẹmi lọ nigba aye rẹ ki ọlọjọ to de.
Oríṣun àwòrán, Aderemi Royal Family
Ọba Adesoji Tadenikawo Aderemi ati Ọba ilu Benin
Ẹ wo Ọba to n ki ỌBA, Ọọni Ile Ifẹ, Ọba Adesoji Tadenikawo Aderemi, Ọba ti ọpọ Ọba n bọwọ fun.
Aderẹmi Adesọji ree lasiko to n gbalejo Ọba ilu Benin, Ọba meji n ki ara ara.
Oríṣun àwòrán, Aderemi Royal Family
Ọba Adesoji Tadenikawo Aderemi
Ọba Adesoji Tadenikawo Aderemi jọba ni ọdun 1930, to si dagba lori itẹ pẹlu ewu lori.
Awọn ọba miran si ti jẹ lẹyin Oba Aderẹmi ni ori apere Ile Ifẹ.
Ọpọlọpọ ẹkọ ni awa iran asiko yii le ri kọ lara Ọba Adesọji Aderẹmi to fi gbogbo ara ṣe iṣẹ ilu lasiko to wa lori oye ipo aṣa ati ipo oṣelu.
Hushpuppi: Ó di ẹlẹ́wọ̀n tó ní nọ́ńbà l‘Amẹrika, orúkọ̀ rẹ̀ wà lórí ayélujára
Oríṣun àwòrán, Hushpuppy/SCREENSHOT/BOP.GOV
Iroyin tuntun ti ileeṣẹ ọgba ẹwọn l'orilẹ-ede Amẹrika, fi sita nipa ọmọ orilẹ-ede Naijiria, Hushpuppi ni pe, o ti wa ni ọgba ẹwọn nilu Chicago, Illinois.
Ọwọ ọlọpaa ilu Dubai tẹ Ramoni Olorunwa Abbas, ti inagijẹ rẹ n jẹ Hushpuppi, laipẹ yii, fun ẹsun lilu jibiti lori ayelujara.
Lẹyin naa ni wọn fi ranṣẹ si orilẹ-ede Amẹrika.
Alẹ ọjọ Aje si ni ileeṣẹ ọgba ẹwọn fi orukọ Hushpuppi si ori itakun agbaye wọn.
Koda, wọn ti fun Hushpuppi ni nọmba idanimọ l'ọgba ẹwọn, 54313-424, eyi ti yoo fun awọn eeyan l'anfaani lati ka nipa rẹ lori itakun agbaye naa.
Awọn nkan miran nipa rẹ to tun wa nibẹ ni, orukọ, ọjọ ori, ati ẹya rẹ.
Ọsẹ bi i melo kan si ni ileeṣẹ eto idajọ ilẹ Amerika yoo gbe ẹni ọdun mẹtadinlogoji ọhun lọ si ilu Los Angeles, lati jẹjọ lori ẹsun lilu jibiti.
Oríṣun àwòrán, BBC/SCREENSHOT/BOP.GOV
Bi ọwọ ọlọpaa ṣe tẹ Hushpuppi, ati Lekan Ponle AKA Woodberry, ti wọn si gbe wọn lọ si orilẹ-ede Amẹrika, fa ariyanjiyan lori ayelujara.
Eeyan mẹwa miran ni awọn ọlọpaa ilu Dubai, ko pọ mọ Hushpuppi ati Woodberry, ninu akanṣe iṣẹ kan ti wọn pe ni 'Fox Hunt 2'.
Ẹsun lilu jibiti, kiko owo pamọ lọna aitọ, jija banki lole, fifi ara ẹni pe ẹlomiran, ni wọn fi kan wọn.
Lasiko ti awọn ọlọpaa mu Hushpuppi, ọwọ wọn tẹ awọn iwe akọsilẹ nipa jibiti kan, ti owo rẹ to ojilenirinwo din maarun miliọnu Dọla, t'oun n murasilẹ fun.
Oríṣun àwòrán, Hushpuppi Instagram
Hushpuppi: APC ní kìí ṣe ojú lásán ni afurasí gbájúẹ̀ náà fi sún mọ́ olóṣèlú
Yoruba ni fi ọrẹ rẹ han mi, ki n le sọ iru eeyan to jẹ nitori agutan to ba n ba aja rin, yoo jẹ igbẹ.
Eyi lo mu ki igbakeji akọwe alukoro fẹgbẹ oselu APC, Yekeen Nabena se fi atẹjade kan sita pe ki ajọ EFCC tete bẹrẹ lori ọrọ Hushpuppi.
Nabena ni ajọsepọ awọn asaaju kan ninu ẹgbẹ oselu alatako, PDP pẹlu ilumọọka afurasi gbajuẹ, Ramon Olorunwa Abass, Hushpuppi mu ifura lọwọ.
Oríṣun àwòrán, @APCUKingdom
Nabena salaye pe ẹsun gbigbe owo ilu lọ sẹyin odi ti wọn fi n kan awọn eekan PDP naa ls silu Dubai lati ipasẹ Hushpuppi lo yẹ ki wọn tanna wadi rẹ.
O fikun pe, saaju eto idibo gbogbo gboo to kọja ni awọn asaaju ẹgbẹ PDP ti sọ Dubai di ibiti wọn n lọ loore koore, bẹẹ si ni bi Hushpuppi se sunmọ awọn oloselu naa kii se oju lasan.
Oríṣun àwòrán, @APCUKingdom
Ni ọpọ igba ni ilumọọka afurasi gbajuẹ naa ti ya aworan pẹlu awọn eekan oloselu ninu ẹgbẹ PDP naa nilu Dubai nibi awọn ipade to waye saaju eto idibo 2019, ko si yẹ ka foju fo iru ajọsepọ to wa laarin wọn ati iru isẹ ti Hushpuppi n se fun wọn.
Bẹẹ ba gbagbe, laipẹ yii ni ọwọ awọn ọlọpaa Dubai tẹ Hushpuppi ati awọn akẹgbẹ rẹ kan ti wọn n lu awọn eeyan ni gbajuẹ lori ẹrọ ayelujara, to si ti farahan nile ẹjọ lorilẹ ede Amerika.
Oríṣun àwòrán, INSTAGRAM/HUSHPUPPI
Amọ aarẹ ana fun ile asofin agba ilẹ wa, Senatọ Bukola Saraki ti foju lai wo ikede ẹgbẹ oselu APC naa.
Akọwe iroyin fun Saraki, Yusuph Olaniyonu, ninu atẹjade kan to fisita salaye pe Bukola Saraki ko mọ Hushpuppi ri, bẹẹ ni ko ni ajọsepọ kankan pẹlu rẹ.
Saraki wa n naka aleebu si ẹgbẹ oselu APC pe oselu ẹtanu ati ibanilorukọ jẹ ni wọn n se pẹlu iwa lilu jibiti lori ayelujara, to si ni aimọye igba ni oun ti pe akiyesi ijọba si ipa ti ọrọ aje ilẹ wa to n se ojojo yoo ni lori awọn mẹkunnu.
Oríṣun àwòrán, HUSHPUPPI/INSTAGRAM
Saaju la ti mu iroyin wa fun yin pe Raymond Abass, ti gbogbo eeyan mọ si Hushpuppi, ti farahan nile ẹjọ nilẹ Amẹrika.
O n jẹjọ lori ẹsun pe o lẹdi apo pọ lati ko obitibiti miliọnu owo Dọla pamọ lọna aitọ.
Ileeṣẹ eto idajọ nilẹ Amẹrika si sọ lọjọ Ẹti pe oun yoo taari ọmọ orilẹ-ede Naijiria naa silu Los Angeles, lati lọ jẹjọ nibẹ.
Oríṣun àwòrán, INSTAGRAM/HUSHPUPPI
Ṣaaju ni ileesẹ ọtẹlẹmuyẹ ilẹ Amẹrika, FBI. sọ pe Ramoni Abbas Igbalode, ti gbogbo eeyan mọ si Hushpuppi gbiyanju lati ji miliọnu mẹrinlelọgọfa Dọla lati ara Premier League.
Inu atẹjade kan ti ajọ FBI fi sita lori ayelujara wọn lọjọ Ẹti ni wọn ti kede rẹ.
Ninu atẹjade naa, FBI sọ pe ẹsun kiko owo pamọ lọna aitọ, ni wọn fi kan an.
Wọn ni obitibiti miliọnu Dọla ni wọn sọ pe o ji lara awọn ileeṣẹ nipaṣẹ emeeli, ati awọn ọna miran.
Awọn eeyan to wa l'Amerika ti juwe iru igbẹjọ ti ileẹjọ a ṣe fun Hushpuppi a
Yetunde Bakare dárà lórí ètò Ṣé o láyà, ẹ ràn án lọ́wọ́ nínú ìbéèrè tó ṣì
Lara jibiti ti Hushpuppi ati awọn isọmọgbe rẹ tun gbiyanju lati ṣe ni jiji ọgọrun un miliọnu Euro (to jẹ miliọnu mẹrinlelọgọfa Dọla), lati ara ẹgbẹ agbabọọlu kan ninu idije Premier League.
Ṣugbọn ajọ naa ko sọ orukọ ẹgbẹ agbabọọlu to jẹ.
FBI sọ pe Abbas jẹ ọkan lara awọn olori ẹgbẹ onijibi ori ayelujara, to pa ẹka kaakiri agbaye, ati kiko owo pamọ lọna aitọ.
Wọn tun sọ ninu atẹjade naa pe Hushpuppi, ati awọn miran tun ja oníbàráà ileeṣẹ amofin kan nilu New York, lole $922,857 loṣu Kẹwa, ọdun 2019.
"Wọn ni: ""Hushpuppi ati awọn yooku rẹ lo ọgbọn ẹwẹ lati tan ẹka kan nilee amofin naa,"
"Wọn ni pe ki wọn o san owo kan ti ọkan lara awọn oníbàráà wọn fẹ ẹ fi ra ile si aṣunwọn banki kan ti oun ati awọn yooku rẹ n mojuto""."
Nikesuliat: Ọ̀dọ́mọdébìnrin akéwì tó n fi ẹ̀ṣà kìlọ̀ ìwá lásìkò yìí
Atẹjade naa tun sọ pe Hushpuppi lẹdi apo pọ mọ awọn kan lati ko $14.7, ti wọn ji lati ori ayelujara pamọ.
Banki kan ni wọn ja lole nilẹ okeere l'oṣu Keji, ọdun 2019.
Niṣe lo pin owo naa kelekele sinu asunwọn banki kaakiri agbaye.
Oríṣun àwòrán, INSTAGRAM/HUSHPUPPI
O si tun sowọpọ mọ ẹnikan to ni asunwọn meji nilẹ Yuroopu, pẹlu ireti pe ẹni kọọkan wọn yoo gba miliọnu marun un Pọun ($5.6 million), lara owo jibiti naa.
Hushpuppi ati awọn iyoku rẹ le lọ si ẹwọn to to ogun ọdun nilẹ Amẹrika, ti wọn ba fi le sọ pe wọn jẹbi awọn ẹsun naa nile ẹjọ.
Ileeṣẹ ọlọpaa nilu Dubai lo kọkọ mu Ramoni Igbalode(Hushpuppi), Olalekan Jacob Ponle (Woodberry), ati awọn miran.
'Èmi gan máa ń béèrè lọ́wọ́ ara mi pé ta ni Wole Soyinka gangan'
Lẹyin naa ni wọn fa wọn le ajọ FBI nilẹ Amẹrika lọwọ, lati lọ koju igbẹjọ lori ẹsun  wọn fi kan wọn.
Ṣaaju ni ijọba United Arab Emirates kede pe oun ti fi afurasi gbajuẹ naa, ranṣẹ si ileesẹ ọtẹlẹmuyẹ ilẹ Amẹrika, FBI.
Ileeṣẹ ọlọpaa Dubai lo fi ikede ọrọ yii sita ninu atẹjade kan to fi si oju opo Twitter rẹ.
Labẹ iṣẹ iwadii akanṣe ọtẹlẹmuyẹ ti wọn pe ni ''Fox Hunt 2'', wọn mu awọn ọdaran kan to n pa awọn eeyan lẹkun jaye loju opo ayelujara, ti wọn si n lu awọn eeyan ni jibiti.
Ajọsepọ awọn ikọ ọlọpaa kogberegbe mẹfa lati ọdọ awọn ọlọpaa Dubai, lo tu asiri awọn ọdaran yii, bi wọn ti ṣe n gbero lati ji owo awọn eeyan kaakiri agbaye.
Oríṣun àwòrán, mrwoodberry/TWITTER
Olalekan Jacob Ponle ti awọn eeyan mọ si Woodberry ati Hushpuppi lọwọ awọn ọlọpaa Dubai tẹ
"Oludari ileesẹ ọtẹlẹmuye FBI Christopher Wray wa kan sara si awọn ọlọpaa ilẹ Dubai, fun iṣẹ ribiribi ti wọn ṣe lati mu Raymond Igbalode Abbas, ti awọn eeyan mọ si ""Hushpuppi"" ati Olalekan Jacob Ponle, ti inagijẹ rẹ n jẹ ""Woodberry""."
Bẹẹ naa ni ọgbẹni Wray fẹmi imoore rẹ han si ileeṣẹ ọlọpaa Dubai, bi wọn ti se gba lati fi awọn ọdaran yii ranṣẹ si ọdọ awọn, ki wọn ba le kawọ pẹyin rojọ ẹṣẹ wọn.
Adari ikọ ọtẹlẹmuyẹ Dubai, ọgagun Jamal Salem Al Jallaf ni, awọn ri ẹri pe awọn ọdaran yii n gbimọran ọtẹ lati lu awọn eeyan ni gbajuẹ, ti iye owo rẹ to miliọnu lọna irinwo le marundinlogoji dọla.
Wọn tun sọ pe, awọn ri ogoji miliọnu dọla le diẹ gba lọwọ wọn pẹlu ọkọ ayọkẹlẹ mẹtala, ti iye owo wọn le ni miliọnu mẹfa dọla.
Bakan naa ni wọn tun gba ẹrọ kọmputa mọkanlelogun, foonu mẹtadinlaadọta ati awọn ẹrọ iko nkan pamọ si 'memory stick' ati 'hard drive', ti o kun fun adirẹsi awọn eeyan ti wọn fẹ lu ni jibiti.
Oríṣí ìjìyà ní àwọn bíi Gómìnà El Rufai àti Fayemi ń bèèrè f'àwọn afipábánilòpọ̀
Yetunde Bakare dárà lórí ètò Ṣé o láyà, ẹ ràn án lọ́wọ́ nínú ìbéèrè tó ṣì
Ikoko dudu fẹyin ti igbo, Ta n mọ o?
Igbin ni idahun rẹ.
Eyi ati awọn ibeere miran ni BBC Yoruba beere lọwọ Yetunde Bakare to jẹ gbajugbaja oṣere Yollywood.
Orukọ miran wo ni Yoruba n pe kokoro èèrùn?
O ya ẹ gbiyanju ẹ wo!
Belly Mujinga: Bí iléeṣẹ́ ọlọ́pàá ní UK ṣe parí ẹ̀ṣùn rẹ̀ mú kí àwọn adúláwọ̀ fa ìbínú yọ
Belly Mujinga jẹ osisẹ kan nileesẹ ọkọ oju irin Reluwe nilẹ UK ti arun Coronavirus gbẹmi rẹ.
Kii se pe tori arun to gbẹmi rẹ lo mu ki ọrọ waye lori iku rẹ bi ko se ọna ti Belly gba ko arun Coronavirus to paa naa.
Ọkunrin alawọ funfun kan to ni arun Coronavirus lo tutọ si Mujinga lara, ti obinrin naa si ko arun yii latipasẹ isẹlẹ naa, eyi to mu ko dero ọrun.
Ileesẹ ọlọpa ilẹ UK se iwadi isẹlẹ naa ti wọn si jabọ pe, ọrọ ko ri bẹẹ eyi ti ko dun mọ awọn adulawọ ninu, ti iwọde si bẹrẹ lori rẹ.
Ọkọ oloogbe, Lusamba Katalay, lasiko to n ba BBC Yoruba salaye pe ibanujẹ ni iku aya oun naa jẹ, paapaa fun iya to bii lọmọ.
Katalay ni oun fẹ ki gbogbo agbaye maa ranti Belly Mujinga bii obinrin takuntakun ati alaanu eniyan, ti kii fi oju pa mẹkunnu rẹ.
Abiola Ajimobi: Ẹbí Kolapo Isola ṣẹ́ pé òun kò gba ₦30m lọ́wọ́ Ajimobi fún ìsìnkú bàbá wọn
Ẹbi ati ara Gomina Ipinlẹ Oyo tẹlẹri, Kolapo Ishola ti bu ẹnu atẹ lu ọrọ ti olori oṣiṣẹ fun Abiola Ajimobi nigba to wa nipo gomina, Gbade Ojo sọ nipa eto isinku rẹ.
Gbade Ojo ni o le ni ọgbọn miliọnu Naira, ti ijọba Abiola Ajimobi fun awọn ẹbi fun isinku gomina tẹlẹri, Kolapo Ishola.
Gbade Ojo sọ ọrọ yii lori ẹrọ redio ni ilu Ibadan, nigba to n ba awọn eniyan fọrọ jomitoro ọrọ lori iku Abiola Ajimobi ati ipa ti ijọba Seyi Makinde ko.
Awọn ẹbi Kolapo Ishola, nigba ti wọn n fesi ninu atẹjade ti wọn fi sita ni, irọ patapata ni olori oṣiṣẹ Ajimobi pa.
Oríṣun àwòrán, TWITTER/AJIMOBI
Wọn fikun wi pe, Ajimobi ko fun wọn ni Kọbọ kan to kereju nitori awọn kọ lati jẹ ki o ti eto oṣelu bọ oku baba awọn, bi o ṣe wu u.
‘Ajimobi ko yọju si ibi isinku naa ti wọn ṣe laarin ọsẹ kan, ti ko si ran ẹnikẹni wa si ibi isinku naa.’
‘Baba wa, Oloye Kolapo jẹ ẹni to ni iwa tutu, to si fẹran awọn ara ipinlẹ Oyo nigba ti o wa laye.’
‘Ko wu wa lati dasi ija to wa laarin Gomina Seyi Makinde ati ẹbi Abiola Ajimobi, amọ ohun to buru ni lati ma pa irọ mọ ẹbi oloogbe Kolapo pe wọn gba owo.’
‘A fi ọrọ yii sita ki awọn araalu le mọ otitọ nipa iṣẹlẹ naa, ki wọn si dẹkun ati ma a wu iwa aitọ.’
Bakan naa ni awọn ẹbi naa wa kesi Gbade Ojo lati sọra nipa ọrọ ẹnu rẹ, nitori pe ko si ẹni ti ko ni ku.
Kolapo Ishola lo wa ni ipo gomina ni ipinle Oyo laarin odun 1992 si odun 1993 labẹ Ijọba Alagbada.
Ọdun 2011 ni gomina tẹlẹri naa jade laye ni ẹni ọdun mẹtadinlọgọrin.
Eto akanse adura Fidau ọjọ kẹjọ fun gomina ana nipinlẹ Ọyọ, Isiaka Abiola Ajimobi ti waye lọjọ Aiku.
Akanse adura Fidau ọjọ mẹjọ naa lo waye nile oloogbe Ajimọbi nilu Ibadan nilana ẹsin Islam.
Oríṣun àwòrán, Ajimobi lives on
Adura Fidau naa, ni awọn ọmọ, aya ati ẹbi oloogbe nikan peju si, ti ikede saaju pe ko si fun gbogbo eniyan nitori ofin itakete sira ẹni to wa lode lori arun Coronavirus.
Ninu waasi rẹ to se ni ede oyinbo nibi adura naa, Imaamu agba fun mọsalasi Oluyole, Sheik Nafiu Atanda Bada mẹnuba pe ọpọ ẹsin to wa laye lo gbagbọ ninu ka gba dura fun oku, eyi ti awọn n se lonii.
Bada ni Abiola Ajimobi ri aye gbe, to si fi aye rẹ sin iran ọmọniyan, to si gbadura pe ki Ọlọrun gba abọ rẹ, ko si dari awọn ẹsẹ rẹ jin.
Bakan naa, Sheik Muideen Ajani Bello, tii se oniwaasi agbaye to se waasi nibi akanse eto adura naa ni ijoko adura naa ti to fun waasi nikan.
Oríṣun àwòrán, Ajimobi lives on
"Bello ni ""ọpọ awọn fọnran aworan ti Ajimobi ti sọrọ silẹ nigba aye rẹ fihan pe, oloogbe naa kii se eeyan lasan, wolii Ọlọrun ni. Gbogbo ohun ti kaluku wa ba n se ni ka yipada, abi, ta a ni sọ."""
O wa gbadura pe ki Ọlọrun kẹ Ajimọbi, ko gẹ ẹ, ko si san gbogbo laada to yẹ ko duro jẹ fun ninu saare.
Iya ni ọpọ eeyan ti ko yin Ajimobi loju aye rẹ, amọ ti wọn n yin lẹyin to ku tan  yoo jẹ niwaju Ọlọrun, nitori igba to wa laye lo yẹ ki wsn sọ daada nipa rẹ.
Oríṣun àwòrán, Ajimobi lives on
Bello, ẹni to sọ pe Ajimobi leri lati kọ mọsalasi nla ti yoo gba gbogbo eeyan, to si mu ileri naa sẹ tun fikun pe, mọsalasi ti Ajimobi kọ silẹ ni iwe ẹri Aljanna to gba laye.
Oniwaasi agbaye naa wa gba aya Ajimobi niyanju lati tẹle ohun ti iwe Alukurani sọ nipa opo sise, eyi to ni o jẹ osu mẹrin ati ọjọ mẹwa, eyiun aadoje ọjọ, ti yoo si jade opo ni ọjọ keji osu Kọkanla ọdun 2020.
Oríṣun àwòrán, Vanguard newspaper
Ikini naa waye lẹyin ti iyawo oloogbe naa, Florence Ajimobi, fi ẹsun kan ijọba ipinlẹ Oyo ti Makinde n dari rẹ pe, wọn ko ki oun ku ara fẹraku ọkọ oun.
Ẹsun to fi kan wọn fa awuyewuye laarin awọn ọmọ Naijria.
Ọjọ isinku ni Florence sọ ọrọ naa, lasiko ti igbakeji Makinde, lọ ọ ki ni ile fun iku ọkọ rẹ.
O ni Makinde n fi ọrọ iku ọkọ oun ṣe ọrọ ati ija oṣelu.
Fidio naa re e:
Ninu lẹta ibanikẹdun naa to wa lori ayelujara, Makinde ṣapejuwe oloogbe Ajimobi, gẹgẹ bi ẹni to fi igbe aye rẹ sin ọmọniyan.
Oríṣun àwòrán, Oyo state Government
"Bakan naa lo sọ pe ""Ajimobi ko ipa ninu idagbasoke ọrọ aje ati awujọ nipinlẹ Oyo, ati Naijiria lapapọ."
Ṣaaju ni Akọwe iroyin fun gomina, Taiwo Adisa, sọ pe ijọba ipinlẹ naa n ṣiṣẹ pọ pẹlu ẹbí Ajimobi, lati fun oloogbe ni eto adura Fidau to bu iyi kun.
Ọjọ karun-un, oṣu Keje, ni adura ọjọ kẹjọ yoo waye fun gomina ipinlẹ Oyo tẹlẹ to di oloogbe, Sẹnetọ Isiaka Abiola Ajimobi.
Eto adura naa, Fidau, wa ni ibamu pẹlu aṣa ati iṣe ẹsin Islam.
Idile oloogbe sọ ninu ikede to fi sita fun eto adura naa pe, ẹbí Ajimobi nikan ni yoo kopa nibi eto adura , nitori ofin to rọ mọ itankalẹ coronavirus.
Oríṣun àwòrán, Twitter/@aaajimobi
Ṣugbọn ṣa, wọn ni awọn araalu yoo ni anfaani lati wo bi eto adura naa ba ṣe n lọ lori amohunmaworan ati lori ayelujara.
Ọjọ kẹẹdọgbọn, oṣu Kẹfa, ọdun 2020, ni Abiola Ajimobi kú, sileewosan First Cardiologist, to wa niluu Eko, lẹyin to ni aarun Covid-19.
Ẹni aadọrin ọdun si ni ko to o kú.
Coronavirus in Nigeria: Ènìyàn 653 ló tún ṣẹ̀ṣẹ̀ lùgbàdì ààrùn Coronavirus ní Nàìjíríà, 129 láti Eko nìkan
Ayẹwo tun fihan pe eeyan ọtalelẹgbẹta o din meje lo ti kun iye awọn to ni arun coronavirus lorilẹede Naijiria lọjọ Abamẹta.
Iye awọn eeyan wọnyi ni ajọ to n gbogun ti ajakalẹ arun lorilẹede Naijiria, NCDC ni awọn ṣawari nipa ayẹwo lati awọn ipinlẹ mejidinlọgbọn kun ẹgbẹrun marundinlogoji o le diẹ to wa nilẹ tẹlẹ.
Ipinlẹ Eko lo moke julọ pẹlu eeyan marundinlọgọfa ti Kwara si tẹle e pẹlu eeyan marundinlaadọrun ti Enugu ati olu ilu ilẹẹwa Abuja si tẹlee pẹlu ọgọrin ati mejidinlọgọrin ni ṣiṣẹ n tẹle.
Bayii ni awọn ipinlẹ yooku ṣe to tẹle ara wọn lori atẹ awọn ayẹwo gbe sita lọjọ Abamẹta:
Ẹgbẹta eeyan ni ayẹwo tun ti fihan pe o tun ti kun iye awọn eeyan to ni arun COVID-19 lorilẹ-ede Naijiria lọjọ kẹtadinlogun, oṣu keje, ọdun 2020.
Ninu ikede olojoojumọ to maa n gbe sita lori bi nnkan ṣe n lọ si pẹlu ajakalẹ arun COVID-19 lorilẹ-ede Naijiria, ajọ to n gbogunti ajakalẹ aarun lorilẹ-ede Naijiria, NCDC ṣalaye pe gẹgẹ bi iṣe rẹ, ipinlẹ Eko lo moke ninu ipinlẹ ogun ti arun naa tun ti ko awọn eeyan mọra ni Naijiria.
NCDC ni eeyan ẹgbẹrun marundinlogoji ati ọtalenirinwo o din mẹfa, (35, 464) ni ayẹwo ti fihan pe o larun naa ni Naijiria.
Ninu eyi ti ẹgbẹrun mẹrinla ati ojilelẹbẹta o din meje eeyan ti ri iwosan, ọrinlelẹẹdẹgbẹrin o din mẹjọ lo ti gba ekuru jẹ lọwọ ẹbọra nipasẹ arun naa.
Eyi ni agbekalẹ awọn ipinlẹ ti ayẹwo fihan lọjọ Ẹti ọjọ kẹtadinlogun, oṣu keje pe o laarun naa:
Oríṣun àwòrán, Others
Àpapọ̀ àwọn tuntun to ṣẹṣẹ lugbadi ààrùn Coronavirus ní Nàìjíríà jẹ 595 ní 1/07/2020
Ninu ikede ti Ajọ NCDC fi sita  fihan pe , awọn to ti ni aarun naa ti pe 34,854 bayii.
Ṣugbọn ṣa, eniyan 14292 ti ri iwosan, awọn 769 si ti ku.
Abajade ipinlẹ kọọkan ninu esi tuntun naa re e:
Ninu ikede ti Ajọ NCDC fi sita ni Ọjọ Ìṣẹgun lo ti fojuhan pe , awọn to ti ni aarun naa ti pe 34,259 bayii.
Oríṣun àwòrán, Others
Ṣugbọn ṣa, eniyan 13,999 ti ri iwosan, awọn 760 si ti ku.
Abajade ipinlẹ kọọkan ninu esi tuntun naa re e:
Ninu ikede ti Ajọ NCDC fi sita ni Ọjọ Ìṣẹgun lo ti fojuhan pe , awọn to ti ni aarun naa ti pe 33,616 bayii.
Ṣugbọn ṣa, eniyan 13,792 ti ri iwosan, awọn 754 si ti ku.
Abajade ipinlẹ kọọkan ninu esi tuntun naa re e:
Àpapọ̀ àwọn tuntun to ṣẹṣẹ lugbadi ààrùn Coronavirus ní Nàìjíríà jẹ 595 ní 13/07/2020
Ninu ikede ti ajọ NCDC fi sita ni Ọjọ Aje lo ti fojuhan pe , awọn to ti ni aarun naa ti pe 33,152 bayii.
Ṣugbọn ṣa, eniyan 13,671 ti ri iwosan, awọn 744 si ti ku.
'Ẹlẹ́ẹ̀kẹjọ t'óyún máà bàjẹ́ lára mi ni mo tó rí àànú gbà'
Abajade ipinlẹ kọọkan ninu esi tuntun naa re e:
Ninu ikede ti ajọ NCDC fi sita ni Ọjọ Aiku lo ti fojuhan pe , awọn to ti ni aarun naa ti pe 32,558 bayii.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ṣugbọn ṣa, eniyan 13,447 ti ri iwosan, awọn 740 si ti ku.
Abajade ipinlẹ kọọkan ninu esi tuntun naa re e:
Àpapọ̀ àwọn tuntun to ṣẹṣẹ lugbadi ààrùn Coronavirus ní Nàìjíríà jẹ 664 ní 11/07/2020
Ninu ikede ti ajọ NCDC fi sita ni Ọjọ Abameta lo ti fojuhan pe , awọn to ti ni aarun naa ti pe 31,987  bayii.
Ṣugbọn ṣa, eniyan 13, 103 ti ri iwosan, awọn 724 si ti ku.
Abajade ipinlẹ kọọkan ninu esi tuntun naa re e:
Ninu ikede ti ajọ NCDC fi sita ni Ọjọ Ẹti  lo ti fojuhan pe , awọn to ti ni aarun naa ti pe 31,323  bayii.
Ṣugbọn ṣa, eniyan 12,795 ti ri iwosan, awọn 709 si ti ku.
Abajade ipinlẹ kọọkan ninu esi tuntun naa re e:
Eyi jẹyọ ninu esi ayẹwo ti ajọ naa fi sita l'Ọjọbọ, fun ipinlẹ mẹtalelogun, ati ilu Abuja.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Apapọ iye eniyan to ti ni aarun naa ni ipinlẹ kọọkan l'orilẹ-ede Naijiria niyii:
Oríṣun àwòrán, Ncdc
Ọtalenirinwo eeyan ni aarun coronavirus tun ṣẹṣẹ ran mọ l'orilẹ-ede Naijiria.
Ninu ikede ti ajọ NCDC fi sita l'Ọjọbọ lo ti fojuhan pe , awọn to ti ni aarun naa ti pe 30,249 bayii.
Ṣugbọn ṣa, eniyan 12,373 ti ri iwosan, awọn 684 si ti ku.
Abajade ipinlẹ kọọkan ninu esi tuntun naa re e:
Awọn ipinlẹ to ku ni:
Awọn to ni aarun Covid-19 ni Naijiria ti pe 29,789, lẹyin ti ajọ NCDC tun kede eeyan 503 to tun ṣẹṣẹ ni i.
Apapọ awọn to ti ri iwosan nipinlẹ kọọkan si ti pe 12,108. Sugbọn eniyan 669 ti ku.
Esi ayẹwo ajakalẹ aarun Coronavirus ti ajọ NCDC fi sita lọ̀jọ̀ Aje fihan pe, ọrinlelẹẹdẹgbta ati maarun (575) eeyan lo tun ti ni aarun naa ni Naijiria.
Awọn ẹni tuntun naa wá lati ìpínlẹ̀ mọkandinlogun, ati olu ilu Naijiria, Abuja.
Lọwọlọwọ, eniyan 29,286 lo ti ni aarun naa, 11828 ti ri iwosan, 654 si ti ku.
Orilẹ-ede Naijiria tun ti ni akọsilẹ ojilelẹẹdẹgbẹta ati mẹrin eeyan to tun ti ni Covid-19.
Ajọ to n mojuto ajakalẹ aarun, NCDC, kede pe ipinlẹ mejidinlogun, ati ilu Abuja ni awọn esi ayẹwo naa ti jade.
Akojọpọ esi naa re e fun ipinlẹ kọọkan.
Ènìyàn 603 ló ní Covid-19 ní Nàìjíríà ní 04/07/2020
Ajọ to n mojuto ajakalẹ aarun ni Naijiria, NCDC, sọ pe esi ayẹwo aarun coronavirus t'oun kede lọjọ Abamẹta fihan pe, eniyan mẹtalelẹgbẹta lo tun ti ni aarun naa.
Esi ayẹwo lati ipinlẹ mọkandinlogun ni wọn gbe jade lọjọ Abamẹta.
Awọn ipinlẹ naa niyii:
Akojọpọ awọn to ti ni ti pe 28,167. Eniyan 11,462 ti ri iwosan, 634 si ti kú.
Kanye West Breakdown: Ìpolongo ìdíje sípò aàrẹ Kanye ti gbéraṣo ní Charleston
Oríṣun àwòrán, @10TampaBay
Ọjọ́ kẹrin, oṣu Keje, ọdún 2020 ni Kanye West fi èròńgbà rẹ̀ léde láti du ipò aàrẹ Amẹrika.
Gbajugbaja olorin ni ilẹ Amerika, Kanye West ti bẹrẹ ipolongo rẹ ni Charleston, ni South Carolina saaju idibo sipo aarẹ lorilẹ-ede naa.
"West to jẹ ẹni ọdun mẹtalelogoji ti bẹrẹ ipolongo rẹ, eyii ti o pe ni ""Birthday Party."""
Ni ibi ipolongo naa ni West ti sọ ero rẹ lori bi o ṣe tako oyun ṣiṣẹ, bi o ti lẹ jẹpẹ awọn eniyan ko gba ipolongo rẹ gbọ.
West ni oun faramọ ki awọn eniyan ni eto labẹ ofin lati ṣẹ oyun, amọ ki ijọba ṣe ipese owo fun awọn oloyun ti ko ba ri owo lati tọju ara wọn.
Oríṣun àwòrán, Reuters
Awọn ololufẹ rẹ ni o ṣeeṣe, ki o fi lede pe oun fẹ dije dupo nitori a ti ta awọn orin tuntun ti o fẹ gbe jade.
Bakan naa ni ipolongo idibo naa ti o ṣe ni Charleston ko fi idi rẹ mulẹ boya lootọ ni o fẹ fi gbogbo ara dije dupo naa tabi ofege ni.
Lockdown updates: Naira Marley gbóríyìn fún Jude Chukwuka pẹ̀lú #1 míliọnù
Ariwo Kanye West gba ori ayelujara kan lọjọ kẹrin oṣu keje ọdun 2020 lẹyin to fi ikede sita pe oun fẹ du ipo aarẹ ilẹ Amẹrika.
Ikede naa jẹ iyalẹnu fun ọpọ eeyan bo tilẹ jẹ pe kii ṣe igba akọkọ rẹ ti yoo sọ pe oun fẹ di aarẹ ni eyii.
Oríṣun àwòrán, Twitter
Kanye West ti fẹ Alexis Phifer ri:
Ko to di pe West gbe Kim Kardashian niyawo, o ti figba kan kọ ẹnu ifẹ si Alexis Phifer, to si sọ pe oun yoo gbe niyawo.
Wọn ti bẹrẹ ere ifẹ wọn lati ọdun 2002 ti wọn si n mura igbeyawo, ṣugbọn ere ifẹ ọhun fori sogi.
Biliọnia ni kanye West
O ti to nnkan bi ọdun diẹ sẹyin ti West ti darapọ mọ awọn abulẹṣowo biliọnia nilẹ Amẹrika.
O tilẹ ti fi igba kan bu ẹnu atẹ lu ajọ to n gboriyin fun awọn eeyan nitori aṣẹyọri wọn, Forbes pe wọn kọ lati fi orukọ oun si ara awọn biliọnia nitori pe oun jẹ alawọ dudu.
Gẹgẹ bi atẹjade ti Forbes fi lede, idiyẹle Kanye West ko din ni biliọnu kan ati ọọdunrun miliọnu dọla, ṣugbọn West yari pe oun niye lori ju bẹ lọ.
Oríṣun àwòrán, PA
Kanye West lo ni ileeṣẹ Yeezy to n ṣe bata
Lati ọdun 2013 ni West ti gbe ileeṣẹ to n ṣe bata tirẹ jade, iyẹn Yeezy, pẹlu ajọṣepọ ileeṣẹ Adidas.
Ileeṣẹ Yeezy ti gbe awọn itẹlẹ kan jade, eyi tawọn eeyan kan sara si pe o dara pupọ.
Ṣugbọn olorin naa ti yi orukọ ileeṣẹ ọhun kuro Yeezy si Ye.
Yetunde Bakare dárà lórí ètò Ṣé o láyà, ẹ ràn án lọ́wọ́ nínú ìbéèrè tó ṣì
Ọmọ meje lo wu Kanye West lati bi
Lọwọ yii, West ti bi ọmọ mẹrin, ṣugbọn o sọ ninu ifọrọwerọ kan lọdun 2019 pe ọmọ meje pere lo wu oun lati bi.
Ko pẹ si akoko yii ti iyawo rẹ, Kim ardashian fidi ọrọ naa mulẹ pe ootọ ni o wu Kanye West lati bi ọmọ meje.
Psalm ni orukọ ti wọn sọ ọmọ wọn kẹrin.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Di American rapper bin visit Trump Tower shortly after Mr Trump win election
O ṣe diẹ ti ọkan Kanye West ti wa nipo aarẹ ilẹ Amẹrika
Ṣaaju ni West ti sọ lọdun 2015 pe o wu oun lati du ipo aarẹ ilẹ Amẹrika.
"Iwadii si fi han pe oludije kan ti orukọ rẹ n jẹ ""Kanye Deez Nutz West"" fi orukọ silẹ lati dije labẹ asia ẹgbẹ oṣẹlu ""Green Party"" lọdun 2015."
Bẹẹ na lo tun sọ lọdun 2019 pe oun yoo du ipo aarẹ ninu idibo ọdun 2020, ṣugbọn o pa ọrọ da pe o di ọdun 2024 ki oun to dije.
Bo tilẹ jẹ pe o ti n bọ sori fun Knaye West lati dije sipo aarẹ lọdun gẹgẹ bi ofin awọn ipinlẹ kan ṣe gbe kalẹ l'Amẹrika, awọn onwoye ohun to n lọ kan ti sọ pe biba lo ba, ko tii bajẹ.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Gbajugbaja akọrin takasufe nilẹ Amẹrika, Kanye West ti kede pe oun naa yoo du ipo aarẹ ilẹ Amẹrika ninu eto idibo ti yoo waye lọdun 2020.
"West to fi ikede naa sita loju opo ayelujara Twitter rẹ lalẹ ọjọ Abamẹta tun sọ pe ""Asiko ti to fun wa lati ranti ileri ilẹ Amẹrika, nipa gbigbẹkẹle Ọlọrun, ka si sowọpọ fun ìran ati kikọ ọjọ ọla wa""."
Sugbọn ko ti i f'ojuhan boya West ti forukọ silẹ lati gbegba ibo, tabi boya o kan n fi ọrọ naa ṣawada ni.
Ọjọ kẹta, oṣu Kọkanla, ọdun 2020 ni eto idibo aarẹ ilẹ Amẹrika yẹ ko waye.
Awọn eeyan kan bi i gbajugbaja onimọ ẹrọ, Elon Musk, ṣe gba pe igbesẹ to dara ni, ti wọn si jẹjẹ atilẹyin fun.
Ṣugbọn awọn miran gbagbọ pe aṣiṣe nla ni yoo jẹ ẹ lati dibo fun Kanye West.
Awọn miran tiẹ gbagbọ pe ipolongo bi West n fi ọgbọn ṣe fun awo orin rẹ tuntun, nitori pe o pẹ ẹ darapọ mọ idije fun idibo naa.
Black women live matters: Ọdún 2015 ní àwọn ọlọ́pàá pa India Kager láìní ìdí- Gina Best
Hushpuppi: Ìròyìn sọ pé ó ṣiṣẹ́ olórin rí, ta àlòkù àṣọ àti Kọ̀ńpútà
Oríṣun àwòrán, Instagram/Hushpuppie
Hushpuppi lorukọ ti ọpọ mọ si ti o si jẹ pe isọwọ fi ọla rẹ han sọ di ilumọọka loju opo ayelujara.
Ṣugbọn ta ni arakunrin ti awọn ọlọpaa ilẹ Dubai ati ọtẹlẹmuyẹ Amẹrika gbe, fun ẹsun gbajuẹ olowo iyebiye yii?
Nibo ni wọn ti bi? Ta lawọn obi rẹ ati pe bawo lo ti se di ọlọrọ ti awọn eeyan kan n fi ọla rẹ tọrọ, pe ki awọn naa ri bi tiẹ?
Diẹ ree ninu nkan ti a ri ko jọ nipa Hushpuppi
Ni pato ọjọ ti wọn bi Hushpuppi ti orukọ rẹ gangan n jẹ Ramoni ''Raymond'' Igbalode ko ye wa ṣugbọn bi a ba fi awọn nkan to sọ nipa ara rẹ wo ọrọ yii, ko le ti to ogoji ọdun.
Eyi to sunmọ ootọ ninu ọrọ aye rẹ ni pe nilu Eko lo dagba si, ki o to kuro lorilẹede Naijiria.
Oríṣun àwòrán, Instagram/hushpuppi
Ninu awọn aworan rẹ nigba to wa ni kekere, a ri  ibi to ti duro lara ọkọ nilu Eko ati awọn omiran to tọka si pe o ti gbe Naijiria daada, ki o to lọ si ilu okere.
Loju opo rẹ ni Instagram, o tun sọ nipa ọjọ ori rẹ pe, oun ti gun oke agba bọ diẹ diẹ wọ ọmọ ọgbọn ọdun.
Loṣu Kẹwa ọdun 2019 lo fi ọrọ yii sita, eyi to jẹ ki a lero pe oṣu Kẹwa ni wọn bi.
O ti ṣe awọn isẹ ọwọ kan ki o to kuro ni Naijiria ṣugbọn a ko ri aridaju lati fidi ọrọ mulẹ iru iṣẹ to jẹ.
Lẹyin ti awọn ọlọpaa Dubai mu tan la bẹrẹ si ni ri aworan orisirisi, to se afihan iru iṣẹ to kọkọ bẹrẹ si ni ṣe ki o to kuro ni Naijiria.
Oríṣun àwòrán, Instagram/hushpuppi
Ọkan ninu iṣẹ ti wọn lo ṣe ni pe, o jẹ olootu orin ti a mọ si Music Producer, ti o si ba awọn olorin Naijiria kọọkan ṣiṣẹ pọ.
Oríṣun àwòrán, Others
Gẹgẹ bi awọn kan ti se sọ,  wọn tun ni Ramoni ti ta aṣọ bọsikọrọ nigba to wa l'Eko, koda wọn tun sọ wi pe o kọ isẹ foonu ati kọmputa tita ni Computer Village nilu Eko kan naa.
Pẹlu gbogbo nkan ti a ka kalẹ yi, eleyi ti ohun gangan kii ye sọ nipa rẹ ni pe, awọn obi rẹ kii se olowo ati pe, ohun t'apata dide ni ki ẹlẹda to wa kọdi ọla si ọdọ ohun.
Wọn ni ọwọ epo lọmọ araye n ba ni la, wọn kii ba ni la ọwọ ẹjẹ.
Ṣaaju ki ọwọ to tẹ Hushpuppi, kii saba sọrọ nipa awọn mọlẹbi rẹ to bẹẹ loju opo ayelujara.
Oríṣun àwòrán, Others
Yatọ si aworan to fi sita nipa ọmọ iya rẹ obinrin to bimọ lọdun 2019, awọn eeyan ko le tọ ka si pe lagbaja tabi tamẹdun ni ọmọ iya Hushpuppi.
Layajọ iya tabi Baba ti a mọ si Father's Day ati Mother's Day, Hushpuppi kii kọ nkankan nipa awọn obi rẹ debi ti awọn eeyan yoo fi le sọ pe, bi awọn obi rẹ ti se ri ree tabi nibi ni wọn n gbe.
Loju opo ẹni to pe ni ọmọ iya rẹ obinrin@ rawflesh_may_9, ko si nkankan nibẹ lori Instagram, lati le fi tọkasi ẹni to n jẹ bẹẹ.
Bi a ba sọ pe Hushpuppi nikan lo ri ara rẹ lasiko yii ati pe awọn mọlẹbi ko foju han pe, eeyan awọn nii ṣe, a ko kuna rara lati sọ bẹẹ.
Idahun si ibeere yii pin si ọna meji.
Akọkọ ni pe ti a ba fi orukọ abinibi rẹ wo, tii se Ramoni, idile musulumi lo ṣeese ki o ti jade.
Oríṣun àwòrán, Instagram/Hushpuppi
Ninu awọn ọrọ kan to fi sioju opo Instagram rẹ, o sọ pe oore ti Allah ṣe fun ohun to ga ju lọ ni pe, oun jẹ musulumi.
Lọdun 2012  lo fi ọrọ yi sita, ti a ko si le sọ boya o ṣi n ṣe ẹsin Islam titi di igba ti wọn fi mu bii afurasi onijibiti.
Bi a ba tibi orukọ rẹ to yi pada si Raymond wo, o ti le fi ẹsin Islam silẹ ṣugbọn o le jẹ inagijẹ lasan ni Raymond, ki o ma se wi pe o pa ẹsin da.
Bakan naa ninu fọnran fidio kan to fi si oju opo Instagram to ti n wẹ ninu omi iluwẹ igbalode, orin iyin ẹsin Kristẹni ni o n kọ ninu rẹ.
Yatọ si eyi, pupọ awọn nnkan to ma n kọ soju opo ayelujara, a ma fi adura to jọ ti Kristẹni sinu rẹ.
Gbogbo awọn kan wọn yii ni ko jẹ ki a le sọ boya Kristẹni ni Hushpuppi tabi Musulumi.
Eyi to daju ni pe, ati ẹlẹsin Kristẹni ati ẹlẹsin musulumi lo wa ninu awọn eeyan to le ni miliọnu meji to n tẹle loju opo Instagram.
Wo bí ọwọ́ orílẹ̀-èdè Dubai ṣe tẹ Ramoni Igbalode tí gbogbo ayé ń pè ní Hushpuppi
Oríṣun àwòrán, Screenshot/DUBAI MEDIA OFFIC
Invictus Obi, Hushpuppi, àwọn ọ̀dọ́ Nàìjíríà méjì tí ẹ̀sùn gbájúẹ̀ wà lọ́rùn wọn
Ramoni Igbalode ti ọpọ eeyan mọ si Hushpuppi to fi orilẹ-ede Dubai ṣe ibujoko lasiko yii ni ọwọ awọn agbofinro ilẹ Dubai ti tẹ.
Ninu fọnran fidio 'Fox Hunt 2' ni wọn ti ṣafihan rẹ.
Lọjọbọ ni ileeṣẹ agbofinro dubai fi fidio bi wọn ṣe mu gbajugbaja ori ayelujara Instagram naa sita.
Ọpọlọpọ owo bii owo to wa fun itọju Covid 19 ni Amẹrika ati awọn owo to le ni biliọnu dọla mẹrinlelogun ni wọn ti fi gbajuẹ gba.
Ọlọpaa Dubai ṣalaye bi wọn ṣe mu Hushpuppi ninu atẹjade ti wọn fi sita ti BBC ri.
Wọn ni awọn ti n fura sii ti pe pe o n ṣe awọn 'ọmọ Yahoo'ti wọn n gba awọn eeyan lori ayelujara.
Nibẹ ni wọn ti fi si ori ikanni naa nipa Ramoni Igbalode ati Olalekan Jacb Ponle ti wọn n pe ni 'Woodberry'ati awọn ọmọ ilẹ Adulawọ miran.
Iṣẹ akanṣẹ lati mu awọn ọmọ Yahoo ori ayelujara yii ni awọn agbofinro Dubai pe ni: 'Operation Fox Hunt 2'
Awọn ẹṣẹ bii jiji owo ko lati asuwọn kan si ikeji, jiji owo lori ayelujara, wiwọ akata ayelujara ati eto inawo ẹlomiran lọna aitọ, ṣiṣẹ gbajuẹ fun awọn eeyan ni awujọ ati fun awọn banki ni wọn mu wọn fun.
Ogagun Abdulla Khalifa Al Marri to n tukọ ileeṣẹ ọlọpaa gboriyin fun awọn ọlọpaa Dubai fun iṣẹ takuntakun ti wọn ti fi mu awọn mẹwaa naa.
O ni eyi yoo tun din ole ori ayelujara ati gbajuẹ pẹlu ẹrọ ayarabiaṣa kọmputa ku diẹ lagbaye lasiko yii.
Mobile Wash: iṣẹ́ fífọ́ mọ́tò tà ni mó yàn láààyò- Slay Mama
Invictus Obi, Hushpuppi, àwọn ọ̀dọ́ Nàìjíríà méjì tí ẹ̀sùn gbájúẹ̀ wà lọ́rùn wọn
Ajọ to n koju iwa jẹgudujẹra lorilẹede Naijiria, EFCC ti ni Ramoni Igbalode, alias Ray hushpuppy ni ẹjọ lati jẹ ni ọdọ wọn.
EFCC to fi eyi lede loju opo ikansiraẹni Twitter wọn ni Hushpuppy is ẹni to gajulọ lorilẹede Naijiria ti wọn n wa bayii fun ẹsun iwa ọdaran lori ẹrọ ayelujara.
Ọjọ kẹ̀wá, Osù Kẹfa ní wọn fí panpẹ́ ọba mú Hushpuppi ní United Arab Emirates lórí ẹ̀sùn lilọ gbajuẹ pẹlu ẹrọ ventilator to le ni $35million.
Ajọ naa ni awọn mọ nipa jibiti owo ati 419 to ṣe ni Niajiria, ti awọn amugbalẹgbẹ rẹ si ti wa ni panpẹ awọn bayii lorilẹede Naijiria.
EFCC fikun wi pe awọn n ṣiṣẹ pẹlu Ajọ Otẹlẹmuyẹ ilẹ Amerika, FBI titi ọwọ palaba rẹ fi segi.
A ti wi pe gbogbo awọn ti wọn j n ṣiṣẹ ni awọn n wa bayii lati ri wi pe ọwọ tẹ wọn ni kiakia.
Oríṣun àwòrán, Instagram
Bakan naa ni iroyin gbe e pe Obinanne Okeke, to jẹ ilumọọka onisowọ ti wọn mu fun ẹsun lilo ẹrọ ayelujara lati ṣe magomago, ti jẹwọ pe lootọ ni oun jẹbi ẹsun naa.
Ọkeke to jẹ ọmọ ọdun mejilelọgbọn ni awọn ajọ ọtẹlẹmuye mu pe, o wuwa ibajẹ lori ẹrọ ayelujara ni ọdun 2015 si ọdun 2019.
Oríṣun àwòrán, Instagram
O ṣeeṣe ki Okeke lọ to ogun ọdun ni ọgba ẹwọn fun ẹsun wiwu iwa ọdaran lori ẹrọ ayelujara.
Ọjọ kejilelogun, Osu Kẹwa ọdun yii ni wọn yoo ma a se idajọ rẹ.
Oríṣun àwòrán, Others
Lati igba ti awọn ọlọpaa ti mu gbajumọ ori ayelujara Instagram, Ramoni Abbas Igbalode, a.k.a Hushpuppi, lori ẹsun pe o lu jibiti lori ayelujara, ni awọn ọmọ Naijiria kan ti n tọka si awọn gbajumọ ti aworan wọn ti jọ han lori ayelujara ri.
"Ọpọ lo bu ẹnu atẹ lu awọn ilumọọka naa, ati awọn oloṣelu, to ba Hushpuppi ya fọto ri, pe o ṣeese ki wọn o mọ pe ""iṣẹ jibiti"" ti wọn fi ẹsun rẹ kan an, lo n ṣe."
Diẹ lara awọn aworan naa ni a ṣe akojọpọ rẹ yii.
Gbajugbaja akọrin Naijiria, David Adeleke da bi ẹni pe ibaṣepọ wa laarin oun ati Hushpuppi.
Koda, Hush lọ sibi ayẹyẹ igbeyawo ẹgbọn Davido, Adewale, to waye nilu Dubai nibẹrẹ ọdun 2020.
Aworan si fihan pe Davido ati Chioma iya ọmọ rẹ, ti ba Hushpuppi ni alejo ri.
Oríṣun àwòrán, Others
Hushpuppi ati Davido nibi igbeyawo ẹgbọn Davido, Adewale, nibẹrẹ ọdun 2020
Gbajugbaja adẹẹrinpoṣonu ori ayelujara, Lasisi Elenu, naa jẹ ọkan lara awọn gbajumọ to ti ni ibaṣepọ pẹlu Hushpuppi.
Awọn iroyin kan ti ẹ sọ pe, Elenu ma n sọrọ iwuri nipa rẹ si afurasi gbajuẹ naa.
Oríṣun àwòrán, Hushpuppi/Instagram
Laipẹ yii ni fidio kan gba ori ayelujara, eyi to ṣafihan agbohunsafẹfẹ, Daddy Freeze, ati ọrẹbinrin rẹ, nibi ti wọn ti kopa nibi ayẹyẹ ọjọ ibi Hushpuppi, nilu Dubai.
"Fidio naa ṣafihan wọn ti wọn jẹ, ti wọn mu, koda, Freeze sọ ninu fidio naa pe ki ""awọn ọdọ to n sọrọ Hushpuppi laida lori ayelujara o bẹ Hushpuppi lati gba baba wọn siṣẹ awakọ rẹ."""
Oríṣun àwòrán, Others
O sọ eyi nitori pe Hush ni N700,00 ni awakọ oun n gba l'oṣu.
Sugbọn Freeze yi ohun pada lẹyin ti ọwọ ọlọpaa tẹ Hushpuppi laipẹ yii.
O sọ ninu fidio kan pe oun o mọ pe gbajuẹ ni Hush n ṣe.
Oríṣun àwòrán, Instagram/hushpuppi
Ilumọọka olorin, Wiskid naa ti ṣe faaji pẹlu Hushpuppi ri, koda awọn mejeeji ti jọ ṣe faaji lori omi ri nilu Dubai.
Oríṣun àwòrán, Twitter
Ọmọ ile aṣofin agba Naijiria nigba kan, Dino Melaye, naa wa lara awọn ti Hush ba ya fọto ri.
O ṣeeṣe ki ibaṣepọ wọn o tayọ fọto yiya, nitori pe Hushpuppi naa lọ sibi ayẹyẹ ọjọ ibi ti Melaye ṣe nilu Dubai lọdun 2019.
Oríṣun àwòrán, Twitter
Ṣugbọn o, Melaye naa ti sọ pe oun ati ẹ kii ṣe ọrẹ, lẹyin ti ọwọ ọlọpaa tẹ Hush.
Oríṣun àwòrán, Instagram/hushpuppi
Ọrẹ timọtimọ ni awọn eeyan maa n pe awọn mejeeji yii. Koda, awọn ololufẹ wọn maa n ṣe afiwe ẹni to lowo lọwọ julọ laarin wọn.
Laipẹ yii naa si ni Mompha koju iru ẹsun lilu jibiti ti wọn fi kan Hushpuppi, lasiko ti ajọ to n gbogun ti iwa ibajẹ ni Naijiria, EFCC, mu.
Mama Arsenal: Ẹgbẹ́ kan ti fún màmá ní ẹ̀bùn owó
Bi a ba ku, iṣe o tan ni Yoruba maa n wi. Bẹẹ gẹlẹ ni ọrọ ri pẹlu mama agba ololufẹ ẹgbẹ agbabọọlu Arsenal, Nosimatu Hassan.
Mama to jẹ ẹni ọdun mẹtadinlọgọrin di ẹni ti ọgọọrọ eeyan n sọ nipa rẹ lori ayelujara lẹyin ti sọ ọpọ ọrọ nipa ẹgbẹ agbabọọlu to yan laayo.
Lati igba naa ọpọ ẹlẹyinju aanu ọmọ Naijiria ti n ṣeleri lati fun mama ni ẹbun kan tabi omiiran.
Ṣugbọn ni bayii, ẹgbẹ ololufẹ awọn ikọ agbabọọlu Naijiria, Authentic Nigeria Supporters' Club ti fun mama ni ẹbun owo rọgun rọgun.
Oríṣun àwòrán, Facebook/ANFASC
Owo ti ẹgbẹ ololufẹ agbabọọlu Naijiria naa fun mama Arsenal ni ṣe ẹgbẹrun un lọna ọta le lugba o din mẹwaa.
Ọlọ́run ló yàn mí ti Arsenal, mi ò lè fi wọ́n sílẹ̀ láéláé- Mama Arsenal yarí
Ara meriri , mo ri ori ologbo lori atẹ ni ọrọ mama agba kan, Nosimatu Hazzan, ti ọpọ eeyan mọ si mama Arsenal.
Mama agba yii, to nifẹ ẹgbẹ agbabọọlu Arsenal bii oju, ti ọjọ ori rẹ yoo si to aadọrin ọdun, lo nifẹ ere bọọlu ju ọmọde tabi awọn ọkunrin miran lọ.
Lasiko ti BBC se abẹwo si ọdọ mama naa, ti ọpọ eeyan mọ si Mama Arsenal nitori bo se nifẹ si ẹgbẹ agbabọslu Arsenal, ẹnu ko gba iroyin.
Ko fẹẹ si agbabọọlu Arsenal tẹlẹ abi lọwọlọwọ bayii ti mama naa ko lee darukọ, to si ni oun maa n wo bọọlu ninu ile oun tabi lọ sawọn ibudo ti wọn ti n wo bọọlu.
Bakan naa lo ni oun maa n lọ sawọn papa isere idaraya nilu Eko lati wo ere bọọlu, ti oun si nifẹ ere sisa, awọn ere idaraya miran lorisirisi, paapaa ẹgbẹ agbabọọlu Arsenal.
Ondo Crisis: Aṣòfin Iroju Ogundeji, Favour Tomowewo àti Williams Adewale ń lọ rọọkún nílé
Oríṣun àwòrán, @Ondo Govt
Ondo
Sinima orita awoowotan ni ọrọ adari ile igbimọ aṣofin ati awọn ọmọ ile igbimọ n di lasiko yii ni ipinlẹ Ondo.
Awọn ile igbimo ti dibo wọn si ti ni ki awọn Họnọrebu mẹta o ko kangara ẹru wọn pada si ile.
Awọn aṣofin méta ti wọn ni ki wọn lọ rọọkun nile ni Họnorebu Irọju Ogundeji to jẹ igbakeji adari ile, Họnọrebu Adewale Williams ati Họnọrebu Favour Tomomewo.
Oríṣun àwòrán, @Ondo House of assembly
Aṣòfin Iroju Ogundeji, Favour Tomowewo àti Williams Adewale ń lọ rọọkún nílé
Ẹsun ti wọn fi kan awọn aṣofin mẹtẹẹta yii ni pe wọn n tapa si ofin ile igbimọ aṣofin.
Bẹẹ, ọrọ lo ko moko-moro wa ni ọrọ ohun to n ṣẹlẹ nile igbimọ aṣofin ati ninu eto oṣelu ipinlẹ Ondo lati bii ọjọ mẹta sẹyin.
Diẹ lara ẹsun ti wọn tun fi kan awọn mẹtẹẹta ni pe:
Wọn ko wa si ipade to igba to yẹ, Gbigba riba tabi ẹbun lọna aitọ lori iṣẹ tabi igbesẹ ile.
Ọmọ ile gbọdọ figba gbogbo maa ṣe ohun to yẹ nigboro ki awọn ara ilu le tubọ nigbagbọ ninu igbimọ ile aṣofin sii.
Aifi ara mọ aba ati awọn ilana ti awọn ọmọ ẹgbẹ fi ẹnu ko le lori.
Oríṣun àwòrán, @Ondo House of assembly
Aṣòfin Iroju Ogundeji, Favour Tomowewo àti Williams Adewale ń lọ rọọkún nílé
Aṣòfin Iroju Ogundeji lo jẹ igbakeji adari ile, oun naa lo n ṣoju ẹkun idibo Odigbo 1;  nigba ti  Favour Semiloore Tomowewo n ṣoju ẹkun idibo Ilajẹ keji;  àti Williams Adewale to n ṣoju Ondo West keji.
Igbakeji awọn ọmọ ile igbimọ aṣofin to pọju lọ, Aṣofin Oladiji Adesanmi lo buwọlu lẹta gbe ile rẹ naa pẹlu ifọwọsi abẹnugan ile.
Wọn ti ni ki awọn Họnọrebu mẹtẹẹta yii má rin ni sakani ile igbimọ aṣofin Ondo mọ ni Akurẹ.
Ati pe ki wọn ko awọn ohun to jẹ ti ilu ati tile igbimọ aṣofin gbogbo to ba wa lọwọ wọn sile.
Oríṣun àwòrán, @Ondo House of assembly
Aṣòfin Iroju Ogundeji, Favour Tomowewo àti Williams Adewale ń lọ rọọkún nílé
Awọn ọmọ ile igbimọ aṣofin to ku ti wọn fọwọ si aṣẹ lọ rọọkun nile awọn akẹgbẹ wọn ni orukọ ati ibuwọlu wọn hande loke yii.
Kemi Dairo: Iṣẹ́ abẹ nínú ọpọlọ àti ẹ̀rọ ni mo fi ń gbọ́ ọ̀rọ̀ báyìí
Kini awọn ẹsun to kọkọ ṣaaju ni ipinlẹ Ondo:
Akeredolu, aya àti ẹbí rẹ̀ ló ń ṣèjọba ni mo ṣe fipò sílẹ̀ - Akọ̀wé ìjọba tẹ́lẹ̀ l'Ondo
Akọ̀wé ìjọba tẹ́lẹ̀ ní irọ́ ni, òun kò sọ pé èrú ìbò ló gbé Akeredolu wọlé
Ọjọ Aje ni awọn ileesẹ iroyin kan gbe iroyin sita pe, akọwe ijọba nipinlẹ Ondo to kọwe fipo silẹ naa, Ifedayo Abegunde, ti kede pe,  gomina ipinlẹ Ondo, Rotimi Akeredolu kọ lo wọle ibo gomina to gbe depo.
O ni awọn ba Akeredolu se magomago ibo, lati jẹ ko moke ninu idibo naa ni.
Eyi si lo mu gomina Akeredolu kesi awọn agbofinro lati gbe akọwe ijọba ana naa, ki wọn lee fi ọrọ wa lẹnu wo lati seranwọ ninu iwadi ẹsun mago mago naa.
Idi si ree ti BBC Yoruba fi kan si akọwe ijọba tẹlẹ nipinlẹ Ondo, Ifedayo Abegunde, lati wadi okodoro ọrọ nipa isẹlẹ naa.
Ninu ifọrọwerọ pẹlu BBC Yoruba, Abegunde ni irọ gedegbe ni ọrọ naa, oun ko si fi igba kankan kede pe magomago abi ayederu ni ibo to gbe gomina Akeredolu wọle lọdun 2016.
"Mo fẹ sọ pe nkan ti awọn oniroyin gbe naa nipa mi kii se otitọ.
Oladapo Adu: Nàíjíríà já mi kulẹ̀ torí wọn kò wá gbé mi
Ohun ti mo sọ ni pe ẹgbẹ APC to jawe olubori ninu ibo taa di lọdun 2016 nipinlẹ Ondo pegede, debi pe awọn ọmọ ẹgbẹ PDP to jẹ alatako gan ko lee lọ sile ẹjọ."
" Mo ni Akeredolu nikan kọ lo bori eto idibo naa, mo ni awa taa jẹ akọni oselu, awọn asoju ẹgbẹ ati araalu la dijọ sisẹ taa fi bori ibo naa.
Kii si se gomina nikan lo da bori ibo yii, idi si niyi ti ko fi yẹ ki oun, iyawo ati awọn ọmọ rẹ maa danikan maa se ijọba, bikose gbogbo awa taa sisẹ to fi moke, lo jẹ ka dijọ se ohun to wa nilẹ yii."
Lori igbesẹ gomina Akeredolu pe ki awọn agbofinro gbe sahamọ lori ẹsun sise magomago ibo to fi kan oun, Abegunde ni ẹni to ba jẹ gbi, ni yoo ku gbi.
Oríṣun àwòrán, APCng
O ni ẹẹmeji ni oun ti lọ soju ipinlẹ Ondo nile asoju-sofin nilu Abuja, ti oun ko si ko owo jẹ, ipo ti Akeredolu si fi oun si, oun ko ri owo kankan nibẹ debi pe oun yoo ko owo jẹ nibẹ, ki wa ni agbofinro fẹ gbẹ oun si?
Akọwe ijọba tẹlẹ nipinlẹ Ondo naa ni, oun kọwe fi ipo naa silẹ nitori oun ko fẹ ba gomina Akeredolu sisẹ mọ ni.
Amọ o ni oun si wa digbi ninu ẹgbẹ oselu APC nitori ẹgbẹ gbogbo awọn ni, ẹgbẹ ti oun nifẹ si ni, kii si se ẹgbẹ Akeredolu nikan.
Mama Arsenal: Màmá àgbà yìí máa ń lọ sí ìbùdó tí wọ́n ti ń wo bọ́ọ́lù láti wòran
Nigba to n salaye boya otitọ wa ninu ọrọ kan to n ja rainrain nilẹ pe, oun naa fẹ fi ẹgbẹ oselu APC silẹ lati lọ dije fun ipo gomina ninu ẹgbẹ oselu miran.
Abegunde ni oun ko dije fun ipo kankan rara nitori awọn to n dije ninu ẹgbẹ APC gan pọ.
"Oluwarotimi Akerdolu ko tọju ẹgbẹ ati awọn ọmọ ẹgbẹ daadaa, o si wu mi pe ki wọn gbe ẹlomiran sita lati rọpo rẹ, ti yoo se daada ju bi Akeredolu ti se lọ.
Ti temi ni pe ki n duro sinu ẹgbẹ APC, ki n si maa tọpinpin awọn ti yoo dije ninu awọn oludije ẹgbẹ wa.
Ti wọn ba si fa ẹlomiran silẹ ko dije ninu ẹgbẹ wa, yatọ si Akeredolu, a jọ maa se e daadaa ti yoo fi wọle, ti yoo si se daadaa ju bi Akeredolu ti se bayii lọ."
Akeredolu lo fi ọrọ naa lede nigba to n jabọ ibi iṣẹ de duro lori bi ipinlẹ naa ṣe n gbogun ti ajakalẹ arun ọhun lọjọ Aje.
"O ni ""Gẹgẹ bi gbogbo yin ṣe mọ, emi naa jẹ ọkan lara awọn eeyan to ni arun Covid-19, ti mi o si ṣafihan apẹrẹ arun naa."""
Lẹyin ti mo lo ọjọ diẹ ni idanikanwa ni mo ṣe ayẹwo miran gẹgẹ bi agbekalẹ ajọ NCDC, iṣẹju diẹ sẹyin ni mo gba esi ayẹwo naa, to si fi han pe mi o ni arun ọhun mọ.
Akeredolu sọ pe ọjọ diẹ ti oun lo ni igbele fun oun laye lati ro arojinlẹ lori awọn ipenija ti Covid-19 mu ba ipinlẹ Ondo.
Lọwọ yii, irinwo le mẹrindinlọgọta  eeyan lo ti ni arun naa ni ipinlẹ Ondo.
Ọgbọn ọjọ oṣu Kẹfa ọdun 2020 ni gomina ọhun kede pe oun ti ti lugbadi arun naa, lẹyin ọjọ diẹ si ni kọmiṣọna eto ilera ipinlẹ ọhun, Wahab Adegbenro dagbere faye.
Ifedayo Abegunde kọ̀wé fipò sílẹ̀ bíi akọ̀wé ìjọba
Oríṣun àwòrán, Temidayo Olofinsawo
Iroyin to n tẹ wa lọwọ ni yajoyajo ti kede pe akowe ijọba ipinlẹ Ondo, Ifedayo Abegunde ti kọwe fi ipo rẹ silẹ.
Abegunde fi eyi lede ninu atẹjade kan to fi si oju opo ikansiraẹni Twitter rẹ.
Abegunde ni ikọwe fi ipo silẹ ọhun yoo bẹrẹ ni Ọjọ Kẹfa, Oṣu Keje, ọdun ti a wa  yii.
Bakan naa lo dupẹ lọwọ gomina ipinlẹ Ondo, Oluwarotimi Akeredolu to fun oun ni ore ọfẹ ati ṣiṣẹ fun ipinlẹ naa.
Abegunde wa gbadura pe ilera pipe yoo jẹ ti gomina ipinlẹ Ondo naa.
Bẹẹ ba gbagbe, o to ọsẹ meji ti igbakeji gomina nipinlẹ Ondo yii kan naa, Agboola Ajayi, kuro ninu ẹgbẹ oselu APC to n se ijọba lọwọ nibẹ, lọ sinu ẹgbẹ alatako PDP.
Bi o tilẹ jẹ pe Agboola si di ipo rẹ mu bii igbakeji gomina, sibẹ iroyin fi ye ni pe, awọn ọgọọrọ oloselu kan ti n ya lọ ba ninu ẹgbẹ oselu alatako naa.
Oyo Schools: Onírúurú ìbòmú ló gbòde, bí àkẹ́kọ̀ọ́ ṣe wọlé padà
Lọjọ Aje ni awọn akẹkọjade ni ipinlẹ Oyo wọle pada si ile ẹkọ kaakiri ipinlẹ naa.
Awọn ileewe pese ike omi ati ọṣẹ ifọwọ fawọn akẹkọọ
Gbe ori rẹ wa ki n wo bi ara rẹ ti se gbona si
Bi eeyan ba ti kọkọ wọle, ọwọ fifọ jẹ dandan
Awọn akẹkọọ jinasirawọn bi wọn ti se joko ni kilaasi ti wọn si wọ ibomu
Gbagada gbagada lawọn ileewe fi ikede sita lori ilana kikoju arun Covid-19
Awọn akẹkọọ to wa ni ipele ikẹkọjade ti bẹrẹ si ni kẹkọ pada
Lati ẹnu ọna abawọle ni wọn ti n se ayẹwo fun olukọ ati akẹkọọ
Ipinlẹ Oyo ni ipinlẹ akọkọ ti awọn akẹkọọ yoo wọle pada sile ẹkọ ni Naijiria
Pupọ awọn obi lo pese awọn ibomu fawọn ọmọ to pada si ileewe.Ijọba ko pese rẹ fun wọn
Awọn obi tẹle awọn ọmọ wọn de ẹnu ọna ileewe lọjọ kini iwọle pada yi
Secret Cults in Nigeria: Iléèṣẹ́ ọlọ́pàá ní kò sí ààyè fún àjọ̀dún 7/7 ní ìpínlẹ̀ Oyo, Ogun
Àdá, àáké, ati fila pupa jẹ́ diẹ lara ami idanimọ awọn ẹgbẹ okunkun ni Naijiria
Ileeṣẹ ọlọpaa ipinlẹ Oyo ati Ogun ti kede pe, aṣiri tu si oun lọwọ pe awọn ẹgbẹ okunkun kan n mura lati ṣe ajọdun nipinlẹ naa.
Atẹjade kan ti alukoro ileeṣẹ ọlọpaa ipinlẹ naa, Olugbenga Fadeyi fi sita, gẹgẹ bi iwe iroyin Punch sẹ sọ, fihan pe ọjọ Aje ni Kọmisanna ọlọpaa nipinlẹ Oyo, Nwachukwu Enwonwu fi ikede naa sita.
Ọgbẹni Enwonwu sọ pe, aṣiri ajọdun ọlọdọọdun ẹgbẹ okunkun Aiye to maa n waye lọjọ keje, oṣu Keje, ti tu si ileeṣẹ ọlọpaa lọwọ.
O ni eyi ko yọ ti ẹgbẹ okunkun Buccaneer naa, to ma n waye ni ọjọ Kẹjọ, oṣu Kẹjọ silẹ.
Kaakiri awọn ipinlẹ to wa ni iwọ oorun Guusu Naijiria, si ni ileeṣẹ ọlọpaa sọ pe ajọdun naa ti ma n waye.
Ẹgbẹ okunkun jẹ nkan to ṣaba wọpọ ni awọn ileewe giga lorilẹ-ede Naijiria, to si ti tàn dé ààrín àwọn tí kìí ṣe akẹkọọ naa, ati ileewe girama.
Oriṣiriṣi ọna ni eto igbani wọle maa n gba ninu awọn ẹgbẹ okunkun.
Oriṣiriṣi ọna ni eto igbani wọle maa n gba ninu awọn ẹgbẹ okunkun
Iwadii kan ti BBC ṣe fihan pe, orin kikọ, ijo, ọti mimu, fifi nkan bo oju awọn to ṣẹṣẹ fẹ ẹ darapọ, tabi lilu wọn ni alubami, lo maa n waye lasiko ajọdun naa.
Awọn eto naa jẹ ọna lati mọ bi awọn ẹni tuntun naa ṣe ni igboya si.
Awọn orukọ ẹgbẹ okunkun bi i Aiye, Eiye, Vikings, Black Axe, ati Buccaneers, jẹ gbajugbaja ni Naijiria.
Ọkan lara amuyẹ ẹgbẹ okunkun Buccaneers ni pe wọn maa n ṣe faaji rẹpẹtẹ
Ọpọ igba si ni ija orogún ma n waye laarin awọn ẹgbẹ okunkun, eyi to ma n mu itajẹ silẹ dani nigba miran.
Ṣugbọn ṣa, Ọgbẹni Enwonwu sọ pe ileeṣẹ ọlọpaa ti wa l'akọ bi ibọn, lati gbogun ti awọn ipejọpọ ti ko ba ofin mu.
Alukoro ileeṣẹ ọlọpaa nipinlẹ Ogun, Abimbola Oyeyemi, sọ ninu ikede kan pe, aṣiri ti tu pe awọn kan n gbero lati ṣeto igbani wọle ṣẹgbẹ okunkun lọjọ keje, oṣu Keje.
"Lẹyin naa ni wọn fẹ ẹ kọju ija si awọn ẹgbẹ alatako wọn.
Nitori naa, awọn ẹka ileeṣẹ ọlọpaa to n gbogun ti ẹgbẹ okunkun, ijinigbe, ati idigunjale si ti wa ni imurasilẹ lati tu ipejọpọ bẹ ẹ ka."
Kemi Remi Dairo: Iṣẹ́ abẹ nínú ọpọlọ àti ẹ̀rọ ni mo fi ń gbọ́ ọ̀rọ̀ báyìí
Igba laye, to ba lo siwaju, a tun lo sẹyin, ko si si ẹni to wa laye, to kọja adanwo.
Bẹẹ ni ọrọ ri pẹlu obinrin kan, Kemi Remi Dairo tii se abani se kokari ayẹyẹ, ti eti rẹ sadede di lẹyin to ti ibi inawo kan de.
Nigba to n ba BBC Yoruba sọrọ, Kemi Dairo ni ariwo nla kan lo jade lati inu speaker nibi inawo naa, ti eti oun si ho, lai mọ pe ijamba ti se oun.
Obinrin naa salaye siwaju pe awọn ọmọ oun maa n kọ ọrọ wọn silẹ fun oun lati ka, ti ọkọ oun si maa n kọ tiẹ sinu foonu, ki oun lee mọ ohun to fẹ.
Ọpẹlọpẹ isẹ abẹ ninu ọpọlọ ati ẹrọ igbalode kan, to gba Kemi silẹ lọwọ ipenija eti didi, eyi to fi n gbọrọ bayi .
MaguEFCC: Omale ni orúkọ tí Magu ń lò. àṣírí míì tú síta
Oríṣun àwòrán, @officialEFCC
Igbimọ ti aarẹ Buhari gbekalẹ fun iṣewadii gbigba awọn owo ilu ti wọn lu ni ponpo pada (PCARA) ti fẹsun kan pe orukọ pasitọ ni alaga ajọ EFCC ti wọn jawe lọ sinmi fun fi na awọn owo ti wọn lọ ẹsun rẹ mọ ọ lẹsẹ loke okun.
Nibayii, Magu n koju ijẹjọ niwaju igbimọ kan ti Amofin Ayo Salami to jẹ adajọ ileẹjọ nigba kan ri kotẹmilọrun n dari.
Ẹsun ti wọn fi kan an ni pe ko fi ọwọ mimọ ṣe eto isuna awọn owo ti ajọ naa ri gba pada lọwọ awọn eeyan.
Ẹwẹ, o jade ninu abọ igbimọ PCARA to n bojuwo owo ijọba ti ajọ EFCC ri gba pada pe laarin oṣu karun ọdun 2015 si oṣu karun ọdun 2020, orukọ Emmanuel Omale to jẹ Pasitọ ijọ kan, Hand of God Prophetic Ministry ni Magu fi n ko owo jẹ.
'Ó ṣe pàtàkì kí obìnrin gbádùn ìbálòpọ̀ nítorí...'
Iroyin jẹ jade pe aṣiri lilo orukọ Omale lu jade lasiko ti ẹka to n lo ọgbn ori fi ṣewadii awọn igbesẹ ajọ EFCC n ṣe iwadii wọn.
Gẹgẹ bi iroyin to jade ṣe sọ ọ, pasitọ naa ra ilẹ to to miliọnu 573 naira ni Dubai lorukọ Magu.
Wọn royin pe pasitọ ọhun rinrinajo lọ si Dubai pẹlu Ibrahim Magu ti wọn si lo orukọ rẹ lati fi ra ilẹ fun Magu ni Dubai.
Gẹgẹ bi pasitọ ti ko gbajugbaja, iroyin fi han pe iye owo ti wọn wọ sinu asuwọn owo rẹ to N573,228,040.41.
Igbimọ PCARA fẹsun kan pe Magu ko fọwọsowọpọ pẹlu awọn alaṣẹ tọrọ kan ni ilu London lati tete bẹrẹ ilana idajọ rẹ.
Bakan naa, kii ṣe ẹsun owo ti wọn lọ mọ ọ lẹsẹ nikan, wọn tun fi ẹsun kan Magu pe o mọọ mọ ma pese aridaju ti wọn nilo lati ṣe ẹjọ minisita fọr epo rọbi nigba kan ri, Diezani Madueke.
Aarẹ Muhammadu Buhari ti kede alakoso tuntun fun ajọ to n gbogun ti iwa ibajẹ nilẹ wa, EFCC.
Oluwa rẹ ni Mohammed Umar, tii se oludari tẹlẹ fun eto akoso isẹ ajọ EFCC, amọ nibayii, oun ni olori patapata fun ajọ ọhun.
Atẹjade kan ti Ọmọwe Umar Jibrilu Gwandu, tii se igbakeji osisẹ alarena, nileesẹ agbẹjọro agba ati Minisita feto idajọ ilẹ wa fọwọ si lo kede iyansipo tuntun naa.
Bakan naa ni atẹjade ọhun tun kede pe, aarẹ orilẹede yii, Muhammadu Buhari ti fọwọ si pe ki adele alaga tẹlẹ fun ajọ EFCC, Ibrahim Magu lọ rọọkun nile na.
Bẹẹ ba gbagbe, ọjọ Aje ni iroyin tan kalẹ pe ileesẹ ọtẹlẹmuyẹ DSS ti gbe Magu, ti wọn si n fi ọrọ wa lẹnu wo.
Igba akọkọ si ree ti awọn alasẹ yoo fidi isẹlẹ naa mulẹ fun awọn akọroyin pẹlu atẹjade.
Oríṣun àwòrán, @officialEFCC
Lati ọjọ Aje ti alaga ajọ EFCC ti wọn ṣẹṣẹ gba iṣẹ lọwọ rẹ, Ibrahim Magu, ti farahan niwaju igbimọ oluwadii, ni ọpọ ọmọ Naijiria ti n fẹ mọ igbesẹ ijọba lori awọn ẹsun ti wọn fi kan an.
Ọjọ Iṣẹgun si ni ijọba kede iyọnipo rẹ
Awọn onimọ kan ni Naijiria ti ẹ sọ pe , ti iwadii ba fi fidirẹmulẹ pe lootọ ni alaga ajọ EFCC, ti wsn ṣkṣẹ gba iṣẹ lọwọ rẹ, Ibrahim Magu, ba fi jẹ ootọ, pe yoo ta ẹrẹ si awọn aṣeyọri ti ijọba sọ pe oun ti ṣe lori igbagun ti iwa ibajẹ.
Aarẹ Muhammadu Buhari lo gbe igbimọ naa kalẹ lati wadii awọn ẹsun iwa ibajẹ, ati afojudi ti wọn fi kan an.
Igbimọ naa, ti Aarẹ nigba kan fun ile ẹjọ kotẹmilọrun, Ayo Salami, jẹ alaga, ranṣẹ pe Magu lati wa a sọ tẹnu rẹ nipa awọn ẹsun naa.
Ṣugbọn nkan ti o si n jẹ kayeefi si awọn ọmọ Naijiria ni pe, Aarẹ Buhari, tabi ijọba apapọ ko ti i sọ nkankan lori ọrọ Magu.
Eyi to si mu ki ọpọ o maa beere pe iha wo gan an ni ijọba Naijiria kọ si ọrọ naa.
Eyi ko ṣẹyin bo ṣe jẹ pe ọkan pataki ni igbogun ti iwa ibajẹ, ninu ilana iṣejọba Buhari.
Bakan naa lo jẹ pe ijọba Aarẹ Buhari naa lo yan Magu si ipo.
Ọpọlọpọ awuyewuye lo si waye lori iyansipo rẹ lati ibẹrẹ pẹpẹ. Koda, ile aṣofin agba Naijiria kọ lati bu ọwọ lu iyansipo rẹ lẹẹmeji ọtọọtọ.
Eyi ti ko ṣẹyin awọn ẹsun kan ti ajọ ọlọpaa ọtẹlẹmuyẹ DSS fi kan an niwaju awọn aṣofin.
Ṣugbọn, Buhari papa yan an sipo.
Lati igba to si tun ti wa ni ipo naa, ni awọn ẹsun iwa ibajẹ ti n jẹyọ lori boṣe n dari ajọ EFCC.
Ariṣe ni arika, arika ni baba iregun.
Oriṣiiriṣii ni awọn eeyan n ka lasiko yii nipa awọn iṣẹ maleegbagbe ti Ibrahim Magu ṣe lasiko to fi tukọ ajọ EFCC to n gbogun ti iwa jẹgudujẹra ni Naijiria.
BBC Yoruba ṣe akojọpọ diẹ lara awọn ẹsun iwa ibajẹ ti ajọ EFCC ṣagbatẹru rẹ lati igba ti Ibrahim Magu jẹ alaga ajọ naa.
EFCC fẹsun jiji owo ilu lọ silẹ okeere kan Diezani Alison-Madueke:
Ara awọn gbajugbaja ẹjọ ti ajọ EFCC ṣe lasiko ti Ibrahim Magu jẹ adele alaga ajọ naa ni ẹjọ minisita epo rọbi tẹlẹ, Diezani Alison-Madueke.
Ẹsun kiko owu ilu lọ si ilẹ okeere ni wọn fi kan Alison-Madueke pẹlu awọn eeyan mii lọdun 2018.
Owo to to aadọjọ miliọnu le mẹta owo dọla ($153m) ni EFCC fẹsun kan minisita epo rọbi tẹlẹ pe o ji ko
Wọn ni o ko owo yii sa lọ ṣaaju idibo gbogboogbo ọdun 2015.
Koda, ajọ EFCC tun gbẹsẹ le ile awo dami ẹnikan to jẹ ti Alison-Madueke to wa niluu Eko.
Ile yii ni wọn pada jọwọ fun ipinlẹ Eko lati maa lo fun ibudo iyasọtọ.
Ẹsun iṣowo ilu kumọkumọ ti EFCC fi kan Gomina ipinlẹ Ekiti tẹlẹ, Ayodele Fayose
Ọkan lara awọn ẹsun iwa ibajẹ ni ijọba ni ti ajọ EFCC ṣagbatẹru nigba ti Ibrahim Magu fi jẹ adele alaga ajọ ni ẹjọ Gomina ipinlẹ Ekiti tẹlẹ. Ayo Fayose.
EFCC fi ẹsun iṣowo ilu to le ni biliọnu kan naira (N1.2b) kumọkumọ kan Gomina ana ipinlẹ Ekiti.
EFCC fẹsun kan Fayose ati ẹnikan pe wọn gbe iye owo naa jade lọna aitọ lati fi ṣe ipolongo ibo gomina.
EFCC fẹsun jiji owo ilu kan Gomina Abia tẹlẹ Orji Uzor Kalu
Ẹjọ miiran ti ajọ EFCC ṣe agbatẹru rẹ lasiko ti Magu fi jẹ alaga ajọ naa ni ẹsun kiko owo bii N7.1bn ilu jẹ ti wọn fi kan Orji Uzor Kalu to jẹ Gomina ipinlẹ Abia tẹlẹ ri.
Wọn tun fi ẹsun kiko owo ilu lọ si ilẹ okeere kan naa kan Kalu.
Ileẹjọ ti kọkọ dajọ ẹwọn ọdun mejila fun Kalu ti o si dero ẹwọn lẹyin naa.
Ṣugbọn ileẹjọ to julọ ni Naijiria tu idajọ ti ileẹjọ kotẹmilọrun da fun un ka.
Ẹwẹ, Ọgbẹni Kalu ti pada sile aṣofin agba l'Abuja nibi o ti n ṣoju ipinlẹ rẹ gẹgẹ bi sẹnẹtọ.
Kemi Dairo: Iṣẹ́ abẹ nínú ọpọlọ àti ẹ̀rọ ni mo fi ń gbọ́ ọ̀rọ̀ báyìí
EFCC fẹsun gbigba N400m lọwọ Sambo Dasuki kan Olisah Metuh:
Ajọ EFCC fi ẹsun kan akọwe ẹgbẹ oṣelu PDP tẹlẹ, Olisa Metuh pe o gba irinwo miliọnu naira lọwọ oludamọran lori ọrọ aabo, Sambo Dasuki.
Ajọ naa ni Metuh gba owo yii lati fi ṣe iṣẹ ijọba kan ni, ṣugbọn ko ṣe nkan kan lẹyin to gba owo naa tan.
Adajọ Okon Abang sọ pe Metuh jẹbi ẹsun onikoko meje ikowo lọ ilu lọ si ilẹ okeere kan Metuh.
Lẹyin ọ rẹyin, ile ẹjọ dajọ ẹwọn ọdun meje fun akọwe ẹgbẹ oṣelu PDP tẹlẹ.
Ẹ̀ṣùn méje gbòógì tí ìjọba àpapọ̀ fi kan Ibrahim Magu rèé
Ibrahim Magu: Lára ẹ̀ṣùn rẹ̀ ni pé ìjọba àpapọ̀ kò mọ ohun tó ń lọ nípa àjọ EFCC
Ana ode yii ni okiki kan lori ayelujara pe awon osisẹ ile ișẹ ọtẹlẹmuyẹ DSS, ti gbe ọga agba ajọ to n gbogun ti iwa ajẹbanu ati lilu owo ilu ni ponpo, EFCC,  Ibrahim Magu fun ifọrọwanilẹnuwò.
Saaju ni Aare Muhammadu Buhari ti gbe igbimọ kan dide, eyi ti Ayo Salami jẹ alaga rẹ.
Igbimọ yii wa lati se iwadii awọn ẹsun oniruuru ti wọn ti fi n kan Magu, lati igba to ti gori oye.
Ti ẹ ko ba gbagbe, ile igbimọ asofin agba kọ lati yan ọga ajọ EFCC gẹgẹ bi ojulowo alaga,.
Wọn ni nitori pe iwadii DSS nigba naa fi han pe, ko yẹ lẹni to le di ipo naa mu.
Lati igba yii ni orisirisi ẹjọ ti n waye lori iṣe si ati ihuwasi rẹ, to fi mọ kikọ olu ile iṣẹ ajọ EFCC naa.
Iroyin sọ pe igbimọ ti Aarẹ yan yii lo pe Magu fun iwadii ninu ile ijọba Aso Rock.
Mama Arsenal: Màmá àgbà yìí máa ń lọ sí ìbùdó tí wọ́n ti ń wo bọ́ọ́lù láti wòran
Iroyin sọ pe, saaju ni Malami ti fi ẹjọ Magu sun Aarẹ Buhari pe, kii jẹ ki ile iṣẹ oun to jẹ ile iṣẹ to n bojuto ajọ EFCC mọ nkankan nipa ohun to n lọ nibẹ.
Paapaa julọ nipa awọn ile ti wọn ba gba lọwọ awọn to lu owo ilu ni ponpo.
Oríṣun àwòrán, @officialEFCC
Malami ni ile iṣẹ oun ko mọ iye ile, owo tabi nkan ini ti won gba lọwọ awọn alajẹbanu oloṣelu, bakan naa ni o rọ Aarẹ pe o ti to ki Magu lọ rọkun nile.
O ti fẹẹ to ọdun marun-un bayii ti Magu ti jẹ adele alaga ajọ EFCC.
Ninu ọrọ rẹ, agbẹjọro ọga agba ajọ EFCC, Oluwatoyin Ojaomo, ninu ifọrọwerọ kan salaye pe nipa idi ti ajọ DSS fi n wa onibara rẹ.
O ni wọn n fọrọ wa onibara oun lẹnuwo nitori awọn kudiẹkudiẹ to wa ninu awọn owo ti ajọ naa gba lọwọ awọn ti wọn mu, iyatọ wa lara iye ti o kede ati iye to wọ apo ìjọba.
O ni owo ti o wọ apo ijọba pọ ju owo ti wọn kede lọ.
Bi aje gbogbo ẹsun yii ba wa si mọ Ibrahim Magu lori, o tumọ si pe, ijọba ti bọs'ọja bayii lati wa elomiran ti yoo rọpo rẹ gẹgẹ bi alaga ajọ EFCC.
Ijọba apapọ orilẹ-ede yii ti pasẹ pe Ibrahim Magu lọ rọọkun nile na gẹgẹ bii alaga ajọ EFCC.
Eekan kan nile ijọba Aso Rock nilu Abuja, ti ko fẹ fara han sita lo fi idi ọrọ naa mulẹ fun BBC lọsan ọjọ Isẹgun.
Ibrahim Magu lo ti kọkọ yọju siwaju igbimọ oluwadii kan ti ileesẹ aarẹ gbe kalẹ lọjọ Aje lati tanna wadi awọn ẹsun aidaa ti wọn fi kan-an.
Igbimọ naa, ti Adajọ-fẹyinti Ayo Salami ko sodi lo ransẹ pe Magu lati gbọ tẹnu rẹ lori awọn ọrọ kan to nii se pẹlu awọn alasẹ ajọ EFCC.
Bakan naa, awọn eekan ilu kan ni Naijiria ti fidi rẹ mulẹ pe ahamọ awọn agbofinro ni Magu sun mọjumọ ọjọ Isẹgun.
Idi ni pe wọn ko lee pari iwadii wọn ni ọjọ Aje.
Eid el Kabir: Àwọn ohun mẹ́sàn án tí Mùsùlùmí gbọdọ̀ ṣe nínú oṣù Dhual rèé
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Anabi Muhammad (SAW) sọ pe ko si ọjọ kankan to ṣe koko julọ ninu ọdun kan ju ọjọ mẹwaa akọkọ ninu oṣu Dhu al- Hijjah.
Awọn onimọ ti rọ awọn Musulumi lati mu ọjọ mẹwaa akọkọ oṣu Dhul Hijjah lẹyin ti wọn ti kede ọjọru gẹgẹ bi ọjọ kinni, oṣu kejila kalẹnda musulumi.
Awọn Musulumi maa ri ọjọ mẹwaa akọkọ oṣu Dhul al- Hijjah gẹgẹ bi eyi to se pataki julọ niwaju Ọlọrun.
Bakan naa ni wọn ni gbogbo adura ati aawẹ ti Musulumi ba se ni ọjọ naa yoo goke arafa lọ ni ibi ti o sunmọ Ọlọrun julọ
Sheikh Aminu Ibrahim Dauraea to jẹ ilumọọka onimọ ẹsin Islam ni orile-ede yii salaye fun BBC nipa gbogbo awọn nkan to rọ mọ Oṣu Dhu al- Hijjah ati awọn nkan ti musulumi gbọdọ ṣe.
Working religious women: Ẹ̀lẹ́hàá kìí ṣe ọ̀lẹ- Aminat Adegoke
Ma  ṣe ge irun tabi fa eekanna rẹ
Nkan akọkọ ni pe ti enikan ba n gbiyanju lati se aluwala, lati ọjọ akọkọ, oṣu Dhu al - Hijjah, ma se ge eekanna rẹ tabi ki o fa irun kankan lara.
Nitori pe Allah (SAWA) yoo se alekun ati ibukun si irun kọọkan ati bi eekanna naa ba ṣe gun to, titi di asiko ti yoo fi ge irun rẹ tabi eekanna.
Gba aawẹ lọjọ Arafa
Gẹgẹ bi Sheikh Daurawa sr sọ, nkan ikeji ni lati gba aawẹ lọjọ Arafa.
Hadiiti sọ pe aawẹ lọjọ Arafa maa n pa gbogbo ẹsẹ ọdun to kọja ati eyi to n bọ rẹ
Irubọ/Itọrẹ
Nkan kẹta, o ṣe pataki lati ṣe itọrẹ aanu, eyi tọ sunnah Anabi Ibrahim  (SAWA) ti Allah pa laṣẹ gẹgẹ bi adanwo lati fi ọmọ rẹ rubọ, o setan lati ṣe ki Ọlọrun to fi Agbo rọpo ọmọ rẹ.
Lọ si Yidi
O ṣe pataki bakan naa ki eniyan lọ fun adua yidi lọjọ ọdun ileya, ki eniyan si wọ asọ tuntun.
Ti oo ba wa ni aṣọ tuntun; o ṣe pataki lati wọ eyi to dara ju ninu awọn aṣọ ti o ni.
O gbọdọ dara si awọn ẹbi rẹ ki o si ra aṣọ tuntun fun wọn ti o ba lagbara rẹ, ki wọn si lọ yidi pẹlu awọn obinrin.
Oṣu aawẹ ni Dhu al- Hijjah
Yatọ si pe o gba aawẹ lọjọ Arafa, o ṣe pataki lati gbawẹ lati ibere lẹẹkan oṣu naa.
Fikun iṣẹ oore ṣiṣe
O ṣe pataki lati maa ṣe saara nigbagbogbo ni oṣu Dhu al-Hijjah
Bi apẹrẹ, ti o ba n sẹ ọrẹ ẹgbẹrun kan Naira, o ni lati fi kun un tabi ki o ṣe ni ilopo
Nkan miran tun ni pe ẹni ti ko ba lọsi Hajj ọdun yii, o yẹ ko fi ilaji owo rẹ ra ounjẹ ati aṣọ fun awọn alaini, iṣẹ oore naa ni.
Ṣe abẹwo si awọn ọrẹ ati ẹbi rẹ
Nkan to yẹ Musulumi ni lati maa ṣe abẹwo si ẹbi ati ọrẹ ninu oṣu yii
Kikọ itẹ oku
O ṣe pataki lati ṣe afikun iye awon itẹ oku ni asiko oṣu ibukun yii.
O se pataki lati kọ awon saare oku ti wọn o kọ akọle bii Allahu Akbar, Allahu Akbar, La'ilaha illalLah Allahu Akbar, Allahu Akbar walillahil hamdu sii
Saudi Arabia Hajj 2020: Alaga Hajj ni Naijiria ni inú wọn kò dùn sí bí Hajj kò ṣe ní wáyé.
Lilọ Hajj
O ṣe pataki lati lọ Hajj tabi Umurah.
Onimọ naa sọ pe awọn iṣesi yii lo ti ṣe akotan gbogbo opo ẹsin musulumi.
Idi niyi ti won ṣe rọ musulumi lati tiraka lati ṣe gbogno nkan wọnyi ninu oṣu mimọ yii.
Oríṣun àwòrán, Manuel Toledo
Ọkan lara awọn ayẹyẹ to ma n waye lasiko ọdun ileya ni Hawan Sallah
Oriṣiriṣi eto amuludun, to fi mọ ẹṣin gigun lo ma n waye lasiko ọdun Ileya nilẹ Hausa.
Arun coronavirus si ni ijọba sọ pe o mu ki wọn o fagile adura Eid l'ọdun yii, lati ri i pe ero ko pọju ki aarun naa ma ba a tun ran si.
Iyalẹnu ni adura Eid ti ko ni i waye jẹ fun awọn kan nilu Kano, nitori pe ko si isede mọ, ati pe ọdun ileya akọkọ niyii ti Emir ilu Kano, Alhaji Aminu Ado Bayero, yoo ṣe lori itẹ.
Kii ṣe ilu Kano nikan ni yoo ṣafẹẹri ọdun adura Eid, ọrọ yii kan awọn ilu nla bi i Rano, Gaya, Karaye, ati Bichi to wa ni ipinlẹ Kano.
Oríṣun àwòrán, NTDC TWITTER
Ṣugbọn ṣa, eyi kọ ni igba akọkọ ti wọn fi ofin de adura agbapọ, nitori awọn idi l'oriṣiriṣi.
Laarin ọdun 1981 si 1983, ayẹyẹ Hawan Sallah ko waye, nitori aawọ to wa laarin gomina igba naa, Abubakar Rimi, ati Emir to wa lori oye.
Ayẹyẹ Hawan Sallah jẹ eto pataki, ninu eyi ti Emir ti ma n gun ẹṣin yipo ilu Kano, ti awọn eeyan yoo si ma a kan saara si.
Bakan naa lọdun 2012, Igbimọ lọbalọba ilu Kano, fi ofin de adura Eid, nitori pe ara Emir ilu Kano nigba naa, Alhaji Ado Bayero ko ya.
Eyi ko ṣẹlẹ ri lati bi igba ọdun ti adura Eid ti n waye nilu Kano.
Amọ ero awọn kan yatọ lori eyi, igbagbọ wọn ni pe irẹpọ ti ko si laarin igbimọ lọbalọba ati ijọba ipinlẹ Kano, lo fa igbesẹ naa.
Eto adura ko tun waye lọdun 2013. Ayẹyẹ kankan ko si waye titi di ọdun 2014, lẹyin iku Emir Ado Bayero.
Oríṣun àwòrán, @KSG
Ọdun 2019 ni ijọba ipinlẹ Kano,tun fi ofin de eto adura, eyi to ba awọn ọdọ ati awọn ọmọbinrin lọkan jẹ pupọ.
Bo tilẹ jẹ pe eto aabo nijọba sọ pe o fa igbesẹ naa, o foju han pe nitori ija to wa laarin igbimọ lọbalọba ati ijọba lo fa a.
Eto adura ko tun waye lasiko itunu awẹ ọdun 2020, nitori itankalẹ coronavirus.
Bakan naa ni ọmọ ṣori ni ipinlẹ Ogun lọdun yii:
Kò ní sí ayẹyẹ ọdún Ojúde Oba lọ́dún yìí- Awujale ilẹ̀ Ijebu
Ọba Sikiru Adetona ti ilẹ̀ Ijebu ti kéde pé ayẹyẹ ọdún Ojude Oba kò ní wáyé lọ́dún yìí.
Ojude Oba festival: Kò ní sí ayẹyẹ Ojúde Oba lọ́dún yìí nítorí Coronavirus- Ọba Sikiru Adetona
Oríṣun àwòrán, @officialpcm
Awujale ati alaṣẹ agba ilẹ Ijebu, Ọba Sikiru Adetona ti kede pe ayẹyẹ ọdun Ojude Oba tọdun 2020 ko ni waye nitori arun Covid-19.
Ajakalẹ arun coronavirus yii lo n gba ẹbọ lọwọ gbogbo agbaye lati oṣu kejila, ọdun 2019 to ti bẹrẹ ni China.
Ohun naa lo si ti mu ayipada ba eto ẹkọ, irin ajo afẹ ati awọn nkan ọlọdọọọdun miran kaakiri agbaye
Oríṣun àwòrán, @folastag
Kò ní sí ayẹyẹ ọdún Ojúde Oba lọ́dún yìí- Awujale ilẹ̀ Ijebu
Oba Adetona lo kede pe Covid 19 yii ko ni jẹ ki ọdun yii waye ninu atẹjade kan ti Ebumawe ti Ago-Iwoye, Oba A.A. Adenugba fọwọ si.
O ni o ṣe pataki ki ayẹyẹ ọdun ọhun ma waye nitori ajakalẹ arun Coronavirus to n ba gbogbo agbaye finra, ti ko si yọ Naijiria sẹyin.
Oba ọhun rọ awọn ara ilu lati tẹle gbogbo ilana ti ajọ NCDC gbe kalẹ bii ọwọ fifọ loorekoore ati ijinasiraẹni lawujọ lọna ati le arun naa lọ.
Lẹyin naa lo parọwa si awọn ọmọ bibi ilẹ Ijebu lati ṣe ọdun ọhun laaye ara wọn lai si ariwo.
Ti ẹ ko ba gbagbe, ọdun Ojude Oba maa n waye lọdọọdun ni ọjọ kẹta ọdun Ileya ti awọn Musulumi maa n ṣe.
Ṣaaju ni Ijọba Kano na ti paṣẹ pe:
Ijọba Kano wọgile ayẹyẹ to maa n waye lẹyin irun ọdun Ileya:
Ko tan sibẹ o, ijọba ipinlẹ naa tun ti wọgile ayẹyẹ ọdun ileya ọdun 2020 nitori Covid-19.
Lojuna ati fopin si itankalẹ aarun Coronavirus ni ipinlẹ Kano, ijọba ti kede lọjọru pe oun wọgile gbogbo ayẹyẹ ọdun Eid-el-Kabir.
Apejọpọ Hawan Daushe ti Emir maa n bẹ gomina wo nile ìjọba l'agbegbe Shettima House laarin awọn ayẹyẹ to ku ko ni waye.
Kọmísọ́nnà fun ọrọ to n lọ ni Kano, Muhammed Garba, sọ pe eyi jẹ ọkan lara igbese ijọba lati tubọ tesiwaju ninu aseyọri rẹ lati gbogun ti aarun Covid-19.
Eid-el-Kabir jẹ ayẹyẹ to mọ julọ ti awon misulumi maa n se lati buyi kun ifẹ Ibrahim to gba lati fi ọmọ rẹ rubọ, ni igbọran si aṣẹ Ọlọrun
Garba ni ipinnu ijọba yii ko sẹyii ifẹnuko igbimọ alaṣẹ leyin ipade to waye.
O ni àwọn igbimọ fẹnuko pe ki awon eniyan kirun janmọ jakejado ipinlẹ Kano, sugbọn ki wọn tẹle ilana ijina sira ẹni ati gbogbo ilana lati dẹkun aarun Covid19 ni agbegbe ibi irun janmọ
Olofa ina: ẹ parí òwe yìí pé ìgbà tí ara bá tu ìgbẹ́ láà ri eṣú....
Garba kede pe ijọba yoo pese gbogbo awon nkan aabo ti won yoo nilo, bii iboju ati 'hand sanitizer' ti won yoo lo.
"O ni:  ""Gbogbo Emir Kano Maraarun ni yoo lọ yidi ni agbegbe wọn ninu mọtọ."""
"Awọn alaṣẹ ijọba kọọkan ni yoo samoju to eto yidi ni agbegbe wọn lati rii daju pe awọn olujọsin  tẹle ilana ijọba lori Covid-19 Alaye Garba ree"""
Bí Coronavirus ṣé jẹ́ kí Awujalẹ wọ́gilé Ojúde Ọba ní Ijẹbu-Ode, bẹ́ẹ̀ náà ló tún ti jẹ́ kí Ganduje wọ́gilé ayẹyẹ 'Hawan Daushe' to máa n waye ninu ọdun Ileya ni Kano.
Oladapo Adu: Nàíjíríà já mi kulẹ̀ torí wọn kò wá gbé mi
Yoruba ni bi eegun ẹni ba joo re, ori a maa ya atọkun amọ eyi ko ri bẹẹ fun Oladapo Adu, to lọ soju Naijiria ninu idije Chess ni Sierra-Leone.
Adu, ẹni to jẹ ọmọ Naijiria to n gbe ni orilẹede Amẹrika salaye pe Naijiria lo mu awọn mẹrin lati soju rẹ ninu idije Chess lai gbe owo kalẹ fi se agbatẹru wọn.
O ni funra oun ni oun ra tikẹẹti alọ ati abọ lati lọ si Sierra Leone, amọ nigba ti idije naa pari logunjọ osu kẹta, arun Coronavirus ti bẹ silẹ.
Coronavirus yii si lo mu ki ọkọ ofurufu oun wọgile eto irinna rẹ, ọkada si ni oun gun lati Freetown lọ si Abidjan ni ọjọ kẹrinlelogun osu kẹta ọdun yii.
Adu ni awọn orilẹede yoku ni iwọ oorun Afirika wa ọna lati gbe awọn asoju wọn nibi idije naa amọ Naijria ko tiẹ ranti oun, tawọn mẹta yoku ti wọn jọ soju Naijiria si ti pada sile.
Schools Resumption: Ohun tó yẹ kí o mọ̀ b'áwọn akẹ́kọ̀ọ́ ṣé fẹ́ wọlé padà ní Ogun,Èkó àtàwọn ìpínlẹ̀ míì
Ipinlẹ Oyo ni ipinlẹ akọkọ ti awọn akẹkọọ yoo wọle pada sile ẹkọ ni Naijiria
Ni ibamu pẹlu aṣẹ ileeṣẹ eto Eko ni ipinlẹ Eko, Ogun ati Kwara awọn akẹkọọ yoo pada sileewe lọjọ Iṣẹgun tii ṣe ọjọ Kẹrin oṣu Kẹjọ ọdun 2020.
Ṣaaju ni ijọba apapọ Naijiria naa ti kede pe ki awọn akẹkọọ ti yoo kọ idanwo aṣekagba jakejado Naijiria pada sile ẹkọ ni igbaradi de idanwo wọn.
Ninu awọn ipinlẹ ti yoo wọle pada ṣẹnu ẹkọ lọjọ Aje ni ipinlẹ Cross Rivers wa.
Ipinlẹ Oyo ti kọkọ fi orukọ silẹ gẹgẹ bi ipinlẹ to bẹrẹ ẹkọ pada loṣu Keje.
Ni ipinlẹ Eko ati ipinlẹ Ogun awọn akẹkọọ ti yoo kọ idanwo aṣekagba SSCE ti wọn n wa lati ile ati awọn eyi to n gbe ni ileewe ni wọn ti ni ki wọn pada sẹnu Eko.
Awọn eleto ẹko ti kede awọn ilana kan kalẹ fawọn akẹkọọ eyi ti yoo mojuto idaabo wọn lọwọ ajakalẹ arun Covid-19.
Yatọ si lilo ibomu ati fifọ ọwọ wọn ki wọn to wọ kilasi, awọn ipinlẹ bi Ogun ti paṣẹ ki gbogbo awọn akẹkọọ mu iwe ẹri ayẹwo wa to ṣafihan pe wọn ko ni arun Covid-19 lara.
Ọrọ owo ayẹwo yi ti n mu iriwisi ọtọọtọ wa paapa ni ipinlẹ Ogun nibi ti awọn obi kan ti n faraya pe owo ayẹwo yi ko rọrun fawọn la ti san.
Ninu atẹjade kan, olubadamọran Gomina lori eto ẹkọ alakọbẹrẹ ati ileewe Girama ni ipinlẹ Ogun, arabinbrin Ronke Soyombo ni awọn gbe igbesẹ ayẹwo yi lati dena itankalẹ arun Covid-19.
O ni awọn ilana to rọ mọ ayewo yi ni pe ijọba ni yoo san owo ayẹwo f'awọn akẹkọọ ileewe ijọba.
Ni tawọn ile ẹkọ to ni akẹkọọ to n gbe ileewe ,o  ni o di dandan ki wọn mu esi ayẹwo yi wa.
Awọn obi tẹle awọn ọmọ wọn de ẹnu ọna ileewe lọjọ kini iwọle pada yi
Soyombo sọ pe ijọba yoo ṣe ẹdinwo fawọn akẹkọọ ileewe aladani lori owo ayẹwo yi sugbọn ẹni to ba fẹ ṣe ayẹwo lọwọ ara rẹ ni lati ṣe lawọn aaye ti ajọ to n gbogun ti arun ni Naijiria NCDC buwọlu.
BBC ko ribi fidi mulẹ iye ti owo ayẹwo yi jẹ gaan ṣugbọn awọn obi kan to ba awọn ile iṣẹ iroyin Naijiria sọrọ lori iṣẹlẹ yi ni awọn ko ni le san ẹgbẹrun mẹẹdọgbọn naira ti ijọba fẹ gba fun ayẹwo yi.
Awọn ipinlẹ miran bi Enugu,Gombe ati Rivers ko ti kede ọjọ tawọn akẹkọọ wọn yoo wọle ti ọpọ awọn onwoye si n beere pe ṣe awọn ileekọ wọn yi ti gbaradi kalẹ pẹlu gbogbo eto to yẹ ṣaaju iwọle awọn akẹkọọ.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí:
Inú wa kò dùn pé Seyi Makinde ṣílẹ̀kùn iléẹ̀kọ́ padà l'Oyo - Àwọn òbí
Awọn obi kan tako bi ijọba Seyi makinde se si ileewe pada nipinlẹ Ọyọ.
Bi o tilẹ jẹ pe awọn akẹkọọ to wa ni kilaasi akẹkọjade nikan lo wọle pada, sibẹ awọn obin to ba BBC Yoruba sọrọ ni akoko ko ti to lati silẹkun ileewe pada.
Awọn obi naa, lasiko ti wọn n ba BBC Yoruba sọrọ ni, ki lo de tawọn akẹkọọ alakọbẹrẹ ati girama fi wọle pada sile iwe, nigba tawọn ẹgbọn wọn to wa ni fasiti ati Poly si wa nile.
Awọn Olukọ to ba ikọ iroyin wa sọrọ naa tun salaye gbogbo awọn igbesẹ ti wọn n gbe, lati ri daju  pe awọn akẹkọọ naa tẹle awọn ofin ati ilana to rọ mọ idena arun Coronavirus.
Satguru Maharaj Ji: Lẹ́yìn tí wọ́n fi kakata hú gbogbo iṣú àti ẹ̀gẹ́ mí, wọ́n tún ṣá àwọn ọmọ mi ládàá
Satguru Maharaj Ji: Awọn ọmọ onílẹ̀ àti ọlọ́pàá jọ gbìmọ̀ pọ̀ láti gba ilẹ̀ mí
Satguru Maharaji ti fẹ̀sùn kan pé àjọ ọlọ́pàá ní ìpińlẹ̀ Oyo pé wọn gbìmọ ọ̀tẹ pẹlú àwọn ọmọ onílẹ̀ láti gba ilẹ̀ òun.
Agbẹnusọ Maharaj, ọgbẹni Ojo Peter lo sọ eyi lasiko to ń ba BBC Yoruba sọ̀rọ̀ lórí bí àwọn ọmọ onílẹ̀ àti àwọn ọlọ́pàá ṣe yabo abúlé Maharaj ti àwọn ọlọ́pàá naa sì dúró tìwọn.
Oríṣun àwòrán, Guru Maharaj
O ní sáájú ni ilẹ̀ náà ti ń dá wàhálà sílẹ̀ láàrin Guru Maharaj àti  Adegoke Amao pẹ̀lú Ṣoara Atere.
Ṣùgbọ́n ilé ẹjọ́ ti fìdí rẹ̀ múlẹ̀ ní ọdún 2016 pé ebí ìyá Aláàdọ́rin, ló nilẹ̀ tí Guru Maharaj sì ti ràá lọ́wọ́ wọ́n.
Lẹ́yìn èyí ni àwọn ọmọ ilẹ̀ Iragbiji tún de pe àwọn gan an ní àwọn nilẹ̀,
Wọn ni o sì di dandan kí Satguru tún ilẹ̀ náà rà, àti ìgbà yìí ni wọ́n ti maa ń wá láti da omí aláafia abúlé Guru Maharaj rú
agbẹnusọ fun Guru, Ojo ni: Sátide, ọjọ́ kẹtàdínlọ́gbọ̀n ní àwọn ọmọ onílẹ̀ kan wa pẹlu awọn  ọlọ́pàá láti wá fi katakata hú gbogbo ǹkan ti wọ́n gbìn sórí ilẹ̀ náà ti wọ́n sì tún ṣe àwọn ọmọlẹ́yìn Maharaj tí wọ́n ń ṣiṣẹ́ lọ́wọ́ níbẹ̀ léṣe yánayàna.
"Ojo ni: ""Nígbà kan ti a lọ fi ẹjọ́ sùn nilé iṣẹ ọlọ́pàá ""Toll gate"" wọ́n padà dá ẹjọ náà nù ni lẹ́yìn tí wọ́n gbà àbẹ̀tẹ́lẹ̀ lọ́wọ́ àwọn ọmọ onílẹ̀."""
Lásìkò yìí bákan náà, àwọn ọmọ onílẹ̀ kó àwọn ọlọ́pàá leyin ni ti wọ́n sì ṣe àwọn tó n ṣiṣẹ́ lóri oko náà léṣe'
Ó rọ ìjọba àpapọ àti ijọba ìpińlẹ̀ Oyo láti dá si ọ̀rọ̀ náà nítori ìdájọ ilé ẹjọ to waye ni 13/07/2016 ti parí ọ̀rọ̀ sùgbọ́n ti àwọn ọmọ onílẹ̀ Iragbiji tún wá lọ ń kó ọlọ́pàá sodí láti wá gba ilẹ̀ náà.
Oríṣun àwòrán, Satguru Maharaj
Kini ile iṣẹ Ọlọpaa ipinlẹ Oyo sọ lori ẹsun Guru yii?
Nigba ti ileṣẹ iroyin BBC kan si ọdọ awọn ọlọpaa ni ipinlẹ Oyo lati fi idi ọrọ yii mulẹ, awọn agbofinro ni ọrọ ko ri bẹẹ.
Agbẹnusọ fun awọn ọlọpaa ni ipinlẹ Oyo, Olugbenga Fadeyi, ṣalaye pe oun gan an ko gbọ iru nkan to jó bẹẹ ri.
Fadeyi ni iru rẹ ko le ṣẹlẹ pe ki awọn agbofinro tẹlẹ awọn ọmọ onilẹ lọ maa ja lẹyin idajọ ile ẹjọ.
Eyi fihan pe, agbọn n ṣe bayii, ikamọdu naa n ṣe, bẹẹ oju oloko ree to wu yii.
Kemi Dairo: Iṣẹ́ abẹ nínú ọpọlọ àti ẹ̀rọ ni mo fi ń gbọ́ ọ̀rọ̀ báyìí
Henry Fajemirokun: Olókoòwò yíká àgbáyé tó bẹ̀rẹ̀ ètò okoòwò lábẹ́ Ecowas
Oríṣun àwòrán, Funeral Programme of Fajemirokun
Bi ẹ ko ba mọ erin, se ẹ ko gbọ ohun erin ni, bi ẹ ko ba si mọ ọsa, se ẹ ko jiyọ lọbẹ, bi ẹ ko ba mọ Henry Oloyede Fajemirokun, ẹ sa mọ awo orin kan.
"Orin naa ni: ""Awọn ẹda kan lo wa, ti wọn n fẹ ki ẹnikeji jẹ, iru wọn ni ti Fajemirokun,"
"To fi owo mọ Oluwa, to tun fi mọ eniyan, ile isẹ rẹ, aimọye eniyan ni wọn n jẹ, ti wọn n mu."""
Ti a ba n sọrọ okoowo ati isẹ aje, bi kanhun se jẹ ọga ni awujọ okuta, naa ni Henry Fajemirokun jẹ ọga lawujọ ọrọ aje lorilẹede Naijiria.
A si lee se apejuwe Henry Fajemirokun bii atapata dide, to de ibi giga, lati ipasẹ okoowo eyi to yẹ kawọn ọdọ fi se awokọse rere.
Gẹgẹ bi a se ka itan igbe aye akọni olokoowo naa loju opo Wikipedia lori itakun agbaye, Fajemirokun ko ipa ribiribi si agbega ọrọ aje lẹkun Iwọ Oorun ilẹ Afirika.
Oríṣun àwòrán, @YorubaHistory
Bi itan igbe aye rẹ si se lọ ree:
Oladapo Adu: Nàíjíríà já mi kulẹ̀ torí wọn kò wá gbé mi
'Báyìí la ṣe rìn ín láti pápákọ̀ òfurufú Abuja sí Eko bí ìrìnà òfurufú abẹ́lé ṣe bẹ̀rẹ̀'
Bí àrùn Coronavirus ṣe dá gbogbo àgbáyé gúnlẹ̀ sójú kan náà nìyí
Fọwọ́ kan obìnrin lọ́nà àìtọ́, kí o rẹ́wọ̀n ọdún mẹ́rìnlá he- Àwọn aṣòfin yarí
Kò ní sí ayẹyẹ ọdún Ojúde Oba lọ́dún yìí- Awujale ilẹ̀ Ijebu
Mama Arsenal: Màmá àgbà yìí máa ń lọ sí ìbùdó tí wọ́n ti ń wo bọ́ọ́lù láti wòran
Cancer: Àṣe ara mi ni iso ti n run gbogbo bí mo ṣe n ṣèrànwọ́ lórí jẹjẹrẹ
Itan Omi Erin
Kemi Dairo: Iṣẹ́ abẹ nínú ọpọlọ àti ẹ̀rọ ni mo fi ń gbọ́ ọ̀rọ̀ báyìí
Ẹ̀mí kan náà ló n darí ìrìnàjò wa táa fi jọ kọ́lé papọ̀- Ìbejì
Oríṣun àwòrán, Others
Baba ọlọla yii fẹ iyawo, oloogbe Comfort Oseboade Fajemirokun, ẹni to papoda lọdun 2019.
Ọlọrun fi awọn ọmọ si aarin awọn mejeeji, lara awọn ọmọ rẹ ni ilumọọka olokoowo kan to kalẹ silu Eko, Dele Fajemirokun.
Dele naa lowo bii baba rẹ, o lọla, to si jogun ileesẹ baba rẹ nilu Eko.
Wo itan omi gbigbona ati tutu ni Ikọgosi Ekiti
Oríṣun àwòrán, Comfort Fajemirokun
Ẹni ọdun mọkanlelaadọta pere ni Henry Oloyede Fajemirokun nigba to lọ sọrun ọsan gangan.
Yoruba ni ka ku ni ọmọde ko yẹ ni san ju ka dagba lai ni adiẹ irana lọ.
Osu Keje, ọdun 2020 yii si ni oloogbe naa ko ba pe ẹni ọdun mẹrinlelaadọrun.
BBC Yoruba wa gbadura pe Ọba oke yoo dẹ ilẹ fun oloore to lọ.
Pẹlu imọran pe ki onikaluku tete ja itanna rẹ to n tan nitori a ko mọ igba ti ọlọjọ maa de.
Awọn Obinrin Dahomey:  Awọn obinrin ilẹ Afirika ti wọn yii itan pada re e
Mohammed Umar: Ta ni ọ̀gá àgbà tuntun fún EFCC?
Oríṣun àwòrán, Others
Mohammed Umar ni ijọba Naijiria yan gẹgẹ bi oludari ti yoo ma ṣakoso gbogbo eto ajọ to n gbogun ti iwa ajẹbanu,EFCC ni Naijiria.
Mohammed Umar jẹ ọga ti o gaju lọ ni ipo to tẹle Ibrahim Magu, ti ijọba ni ko lọ rọọkun nile, lori ẹsun pe o ṣe owo kumọkumọ ati awọn ẹsun miran ti wọn fi kan.
Bayii ti wọn ti ni ki Umar Abba maa dari eto ajọ naa, ibeere tawọn eeyan n beere ni pe ta ni Umar Abba jẹ?
Ṣaaju ki wọn to yan sipo, Umar Abba jẹ igbakeji Kọmisana ọlọpaa to si tun jẹ oludari gbogbo eto ni ajọ EFCC.
Ọmọ ilu Kano ni Umar Abba jẹ ohun si ni yoo ma dari EFCC titi ti Minisita feto idajọ Abubakar Malami yoo fi kede adele alaga ajọ naa
A ko tiribi fidi ọrọ mulẹ lori ọdun ti wọn bi Umar tabi ileẹkọ to ti kẹkọ jade ṣugbọn lọpọ igba lo ti lọ ṣoju adele alaga Magu lawọn aaye to ba ni ko ṣoju ohun.
Oríṣun àwòrán, Others
Lọdun to kọja, oun lo lọ ṣoju Magu nibi ti ajọ EFCC ati ileeṣẹ ọtẹlẹmuyẹ FBI ti n ba awọn akọroyin sọrọ nilu Ekonibi ti wọn ti jabọ iye owo ti wọn ri gba pada lọwọ awọn gbajuẹ.
Bakan naa mi Umar lewaju ninu bi ajọ EFCC ti ṣe n tọ pinpin aarẹ ile aṣofin agba Naijiria tẹlẹ Bukola Saraki.
Ohun lo buwọlu iwe aṣẹ ti wọn fi beere iwe ẹri to fi mọ awọn iwe adehun iṣẹ kọngila gbogbo  ti Bukola Saraki fọwọ si nigba ti o wa ni Gomina.
Saaju la ti mu iroyin wa fun yin pe ijọba apapọ ti kede Mohammed Umar gẹgẹ bi alaga fidi hẹ ajọ to n gbogun ti iwa ibajẹ ni Naijria, EFCC.
Umar ni yoo ma tukọ ajọ ọhun lẹyin ti wọn jawe lọ gbele ẹ fun Ibrahim Magu, to jẹ alaga ajọ naa tẹlẹ.
Gẹgẹ bi eto ajọ naa ṣe ri, ipo Umar to wa ni ipo adari ẹka iṣẹ ninu ajọ ọhun lo tẹle alaga.
Atẹjade kan ti Ọmọwe Umar Jibrilu Gwandu, tii se igbakeji osisẹ alarena, nileesẹ agbẹjọro agba ati Minisita feto idajọ ilẹ wa fọwọ si lo kede iyansipo tuntun naa.
Bakan naa ni atẹjade ọhun tun kede pe, aarẹ orilẹede yii, Muhammadu Buhari ti fọwọ si pe ki adele alaga tẹlẹ fun ajọ EFCC, Ibrahim Magu lọ rọọkun nile na.
Ọjọ Aje, ọjọ Kẹfa oṣu Keje ọdun 2020 ni wọn fi panpẹ ofin mu Magu, ti wọn si gbe e lọ si ile aarẹ ni Abuja nibi ti igbimọ kan ti aarẹ gbe kalẹ ti fọrọ wa lẹnu wo.
Ayo Salami, to ti fi igba kan jẹ aarẹ ile ẹjọ kotẹmilọrun lo dari igbimọ oluwadii naa.
Oríṣun àwòrán, Instagram/officialefcc
Magu wọjọgbọn lẹyin ti adajọ agba Naijiria, Abubakar Malami kọwe mọ ọ lori awọn aṣemaṣe kan.
Wọn fẹsun kan Magu pe na owo ti ajọ ọhun rigba pada lọwọ awọn to lu owo ilu ni ponpo, o si tun lu awọn ohun ini jọba kan ni gbanjo fun awọn eeyan kan to sun mọ ọ.
Wọn tun ni o kọ lati jọwọ ara rẹ sabẹ iṣakoso ọfiisi adajọ agba ilẹ Naijiria.
Ivory Coast: Lẹ́yìn ìpàdé aláṣẹ ìjọba ni wọn gbé lọ sílé ìwòsàn níbi tó kú sí
Oríṣun àwòrán, AFP
Inu ọfọ nla ni ijọba ati awọn eeyan orilẹede Ivory Coast wa bayii nitori iku ojiji to sadede mu olootu ijọba, Amadou Gon Coulibaly  lọ.
Coulibaly, tii se ẹni ọdun mọkanlelọgọta ni ẹgbẹ to n se ijọba lọwọ ni orilẹ naa ti fa kalẹ bii oludije ninu ibo aarẹ to n bọ losu kẹwa ọdun yii.
Igbesẹ naa lo si waye lẹyin ti aarẹ to wa nipo, Allassane Quatara ni oun ko ni lọ fun saa kẹta lori oye.
Coulibaly si sẹsẹ ti ilẹ Faranse de ni, nibi to ti lọ setọju aisan ọkan to n baa finra fun odidi osu meji gbako.
Nigba to n sọrọ nipa ọfọ nla to ja lu orilẹede Ivory Coast yii, aarẹ Quattara ni lootọ ni ara Coulibaly ko ya lasiko ipade igbimọ alaṣẹ ijọba ti wọn se.
Ibi ipade yii si lo ni awọn ti tete gbe digba-digba lọ sile iwosan, sugbọn aisan lo se e wo, ko si ẹni to ri ti ọlọjọ se.
Oríṣun àwòrán, Others
Mo n yonbo aburo mi, ọmọ mi, Amadou Gon Coulibaly, ẹni to ti jẹ alabasisẹ pọ mi fun ọgbọn ọdun gbako, ti mo si tun yin iranti akinkanju ọmọ ilẹ yii naa, fun atilẹyin tootọ rẹ, ifọkansin ati ifẹ si ilẹ baba rẹ.
Iku Coulibaly si ni yoo mu ki ominu wa lori eto idibo to n bọ lọna ni orilẹede naa.
Coulibalylo ti ni aisan ọkan lati ọdun 2012, to si ti lọ silu Paris lọjọ keji osu Karun fun isẹ abẹ.
Funke Akindele: Ajirebi ní Funke Akindele f'óun lówó t'óun fi gba ilé ni, kò ra ilé f'óun
Oríṣun àwòrán, Instagram/kunleafod
Odu, ti kii se aimọ fun oloko ni Kayode Olaseinde lagbo tiata lede Yoruba nitori awọn awada adẹrinposonu to maa n se.
Ọpọ ololufẹ rẹ si lo mọ si Pa Ajirebi nitori orukọ to fun ara rẹ ree ninu ere tiata, ti awọn eeyan si mọ mọ.
Yatọ si awọn ere itage ti Ajirebi ti se, eyi to fun ni okiki, awọn isẹlẹ kan to maa n waye nipa rẹ lasiko ojo lọdọọdun gan tun n mu ki Ajirebi wọnu iroyin.
Isẹlẹ naa ni ti ẹkun omi to maa n wọnu ile rẹ to kọ si adugbo Ikorodu nilu Eko, eyi to maa n daa laamu ni ọdọọdun.
Asiko ojo naa si ni Ajirebi maa n lọgun fun araye pe omi tun ti ya wọnu ile oun, to si ba awọn dukia oun jẹ.
Bi o tilẹ jẹ pe awọn eeyan maa n kaanu rẹ lawọn oju opo ayelujara sugbọn ibẹ lo mọ.
'Ó ṣe pàtàkì kí obìnrin gbádùn ìbálòpọ̀ nítorí...'
Oríṣun àwòrán, Ajirebi1 instagram
Amọ ọrọ yipada ni ọdun 2020 ta wa yii nigba ti oriiire gbe awọn alawo rere ko Ajirebi lasiko ti ọmọ rẹ, Samuel kigbe sori ayelujara pe ẹkun omi tun ti wọnu ile baba oun.
Ni kete ti iroyin naa balẹ ni ọgọọrọ awọn osere tiata lede Yoruba ti dide si ọrọ naa, ti wọn si n bẹbẹ fun awọn ẹlẹyinju aanu ati awọn akẹẹgbẹ wọn to rijẹ sẹku, lati gba ọrọ agba osere naa ro.
Koda, wọn tun fi apo asunwọn ile ifowopamọ Ajirebi soju opo Istagram wọn lati beere iranwọ owo fun osere tiata naa, ko le tete bọ lọwọ ajalu ọhun.
Sugbọn nigba ti yoo fi di ọwọ ọsan ni iroyin miran tun ti gbalẹ kan pe Ọlọrun ti gbe alawore pade Ajirebi, ti onitọun si fun ni ile ti yoo maa gbe.
Kia tun ni awọn osere tiata naa tun ya bo oju opo Instagram wọn lati dupẹ lọwọ awọn alaanu to gba ọrọ ẹdun Ajirebi naa ro.
Koda, osere tiata kan, Kemi Korede kede pe osere tiata lobinrin miran Funke Akindele ti fun Ajirebi ni ile ti yoo maa gbe.
Amọ ninu fidio kan ti Ajirebi se pẹlu osere tiata miran, Kunle Afod, o sẹ lori iroyin naa, to si ni Funke Akindele ko fun oun ni ilegbe rara.
Ajirebi, ẹni to dupẹ pupọ lọwọ awọn ololufẹ rẹ atawọn osere tiata lorisirisi ti wọn dide iranwọ fun wa gbadura pe Ọlọrun yoo wa pẹlu wọn.
Oríṣun àwòrán, Ajirebi1 Instagram
"Mo dupẹ pupọ lọwọ Funke Akindele fun iranwọ owo to fun mi. Mo n salaye fun gbogbo aye pe Funke Akindele ko fun mi ni ile gẹgẹ bi awọn eeyan kan se maa n sọ.
Amọ o fun mi ni owo lati gba ilegbe miran ti maa gbe titi ti ojo yoo fi lọ, mo si n dupẹ pupọ lọwọ rẹ."
Bakan naa lo tun mọ riri Toyin Abraham ati ọkọ rẹ fun iranwọ owo ti wọn fun, to si gbadura pe gbogbo awọn eeyan to se iranwọ owo fun oun, ni ọba oke yoo fi ọpọ rọpo fun.
Nibayi ti gbogbo eeyan n ba Ajirebi yọ pe o ni ibi tuntun ti yoo maa gbe, awa naa n ba dawọ idunnu pe, o ku oriire.
Urine Colour: Fídíò Lahanmi yìí ló ń ṣàlàyé nípa ọ̀pọ̀ àìsàǹ tó rọ̀ mọ́ bí ìtọ̀ wa ṣe rí
Ọpọ aisan ni kii tete fi oju han ninu agọ ara titi ti yoo fi se ipalara.
Amọ itọ jẹ eroja kan pataki ti yoo tete pe akiyesi wa si aisan to ba wọle si agọ ara wa.
Ninu fidio yii ti BBC Yoruba se lati fi seto ilanilọyẹ fun araalu, lo n sọ awọn ohun to yẹ ka se akiyesi rẹ ninu itọ wa.
Eyi yoo si jẹ ka mọ irufẹ awọn aisan to rọ mọ irufẹ ayẹwo ti itọ wa n mu jade.
Ẹ wo fidio naa, lati kọ ọgbọn nipa ohun ti itọ rẹ n sọ nipa ilera rẹ.
Tunde Braimoh: Itẹ́ òkú ní Vault Garden ní wọ́n sin Aṣòfin náà sí ní ìlànà ẹ̀sìn Musulumi
Oríṣun àwòrán, @GiwaMoore
Awaye ku ko sin, ọrun ma kanju, gbogbo wa la n bọ.
Irọlẹ ọjọ ni wọn fi ilẹ bo oku asofin Tunde Braimoh ni asiri nilu Eko ni deedee aago meji ọsan.
Itẹ oku Vault Garden, to wa ni Awoyaya lẹba Mayfair Garden ni adugbo Lekki nilu Eko ni wọn sin asofin Braimoh si.
Bi o tilẹ jẹ pe ọpọ ẹbi, ọrẹ, ojulumọ ati alajọse nidi oselu lo ti peju sile rẹ lati daro iku rẹ, amọ ẹtahoro wọn lo bawọn peju sibi ti wọn ti sin oku rẹ.
Eyi ko si sẹyin ofin tita kete sira ẹni to wa nita, awọn to si peju sin asofin naa ko pe mẹwa niye.
Oríṣun àwòrán, @Toosaino
Awọn abanikẹdun ti yabo ile Tunde Braimoh, aṣofin ipinlẹ Eko to jade laye lowurọ ọjọ Ẹti.
Abẹwo BBC Yoruba sile oloogbe ṣafihan awọn ololufẹ rẹ, to n sọrọ tẹdun-tẹdun pe alaanu kan ṣoṣo to ku fun awọn ni  wọn fi da wọn loro.
Hon Buraimoh:Wọ́n fí ikú rẹ dáwà loro ní-abanikẹdun
Bo tilẹ jẹ pe a ko le fidi iru iku to pa oloogbe ọhun mulẹ, amọ o ta si akọroyin BBC Yoruba l'eti pe, ibudo itọju alarun Coronavirus to wa ni adugbo Yaba, ni Braimoh ku si.
Ko ti i pe oṣu kan ti aṣofin to n ṣoju ẹkun idibo Kosofe, nile aṣofin agba Naijiria, Bayo Osinowo jade laye.
Asofin Braimoh lo n soju ẹkun idibo Kosofe keji nile asofin ipinlẹ Eko.
Bakan naa ni asofin Buraimoh ti se alaga ijọba ibilẹ Kosofe ri, to si tun jẹ aṣoju ṣofin fagbegbe Ketu.
Ni nnkan bi oṣu meji si asiko yii, ni Braimoh ko ba  pe ẹni ọgọta ọdun loke eepẹ.
Koda ninu awọn to ṣeto isinku, to si gbalejo Gomina Eko, Babajide Sanwoolu nile aṣofin agba, Adebayo Osinowo ta mọ si Pepperito, lasiko to jade laye ni Braimoh wa.
Eyi lo mu ki awọn kan ma sọ pe, o ṣeeṣe ki o ti ko arun Covid-19 ṣugbọn a ko ti fidi ọrọ yi mulẹ.
Oríṣun àwòrán, Other
Aworan aṣofin Braimoh lasiko ti Gomina Babajide Sanwoolu ṣabẹwo si mọlẹbi aṣofin agba Adebayo Osinowo to papoda
Gẹgẹ bi mọlẹbi rẹ kan to fi idi isẹlẹ naa mulẹ ti wi, idaji aarọ ọjọ Ẹti oni ni asofin naa tẹri gbasọ, ko si tii si ẹni to lee fi idi ohun to ṣokunfa iku rẹ mulẹ.
Alaga agbegbe idagbasoke Ikosi Isheri nilu Eko, Ọmọọba Samiat Abolade Bada ti wa n daro iku rẹ eyi to n fi idi iku oloogbe naa mulẹ fun ọpọ eeyan.
Hon Buraimoh:Wọ́n fí ikú rẹ dáwà loro ní-abanikẹdun
Chichi Igbo: Ọ̀pọ̀ máa ń rò pé mo ní nǹkan ọkùnrin lábẹ́ torí ìrísí mi jọ ti ọkùnrin
Ọkan lara awọn ọmọ ẹgbẹ agbabọọlu lobinrin fun orilẹede Naijiria, Super Falcons, to ti fẹyin ti ni Chichi Igbo jẹ.
Ọdun mejidinlogun si lo fi gba bọọlu, ko to fẹyin ti
Chichi ni isan, idi ati egungun lile ju awọn ọkunrin miran lọ , ti irisi rẹ ko si yatọ si tawọn ọkunrin amọ obinrin ni.
Nigba to n ba BBC sọrọ lori oju ati ohun ti awọn eeyan awujọ n sọ nipa rẹ, Chichi ni ọpọ eeyan lo ti fi ẹnu pa oun lai tii ku.
O wa koro oju si awọn ọrọ ibajẹ ti ọpọ eeyan maa n sọ nipa rẹ nitori pe irisi rẹ jọ ti ọkunrin.
O si gba awọn eeyan nimọran lati lati ye pa awọn eeyan nipa ọrọ ti wọn ba kọ lawọn oju opo itakun agbaye.
Alaafin Ọyọ Queens: Ǹjẹ́ o mọ àwọn olorì àkọ́fẹ́ Aláàfin Adeyẹmi? Àwọn rèé
Oríṣun àwòrán, Others
Bi Ọba Adeyemi si ti n ṣetọju awọn ẹlẹyinju ẹgẹ, naa ni ko gbagbe awọn aya igba ọdọ rẹ, to si n bu ọla ati iyi fun wọn pẹlu.
Ni ilẹ Yoruba, Ọbaọlọla Olowo, ẹni ti ọba yẹ loye ati eeyan nla ni Alaafin tilu Oyo, Ọba Lamidi Olayiwola Adeyemi Kẹta.
Atọbatẹlẹ si la lee pe Atanda Alowolodu bii iyere, nitori aati igba ewe lo ti n se bi ọba ati eeyan nla.
Oríṣun àwòrán, Mujidat Adeyemi facebook
Bi o tilẹ jẹ pe Kabiyesi ni ọpọ ayaba ninu aafin rẹ, tawọn olo, arẹwa ẹlẹyinju ẹgẹ ati ẹlẹ Daddy si kun inu agbala rẹ babi, sibẹ awọn obinrin miran wa to n gbe ẹmi ọba Adeyemi ro.
Ẹ wo adúrú ǹkan tí Softface ma ń tò pọ̀ láti sín àwọn òṣèré, gbajúgbajà jẹ
Ki o to di pe awọn apọnbeporẹ olori de sinu aye Ọba Adeyemi, awọn obinrin to fẹ nigba ewe rẹ naa wa, ti wọn si jẹ igi lẹyin ọgba fun Alaafin.
Bi oriade yii si ti n ṣetọju awọn ẹlẹyinju ẹgẹ, naa ni ko gbagbe awọn aya igba ọdọ rẹ, to si n bu ọla ati iyi fun wọn pẹlu, bi o tilẹ jẹ pe ọpọ wọn ti dagba, ti wọn si ti ni ọmọ-ọmọ.
Diẹ lara awọn aya igba ọdọ Alaafin ree, ti kii kọ iyan wọn kere rara:
Oríṣun àwòrán, Oba Lamidi Olayiwola Adeyemi kẹta
Olori Abibat Nihinlola ni iyawo akọfẹ Ọba Adeyemi, ti Ọlọrun si fun awọn mejeeji ni ẹmi gigun, alaafia ati ọmọ rere lati ba ara wọn kalẹ.
Olori agba yii, ti ọpọ eeyan ninu aafin n pe ni Iya Adodo ko ni mọra, a si lee ni ori rẹ lo sunwọn, to ran igba awọn ayaba miran ti wọn tẹle lati wa fẹ Ọba Adeyemi.
Oríṣun àwòrán, Olori Abibat Adeyemi
Igba ti Ọba Adeyemi ko si ti ni owo tabi lọla ni olori Abibat ti fẹ, awọn mejeeji si dijọ pilẹ ọla ni gẹgẹ bii tọkọtaya.
Ọjọ ori Olori Abibat ko fi bẹẹ kere si ti Alaafin, koda, a gbọ pe ọjọ ori wọn sunmọ ara wọn nitori mama yii naa ti se ọjọ ibi ọdun kọkanlelọgọrin loke eepẹ.
Oríṣun àwòrán, Olori Abibat Adeyemi
Ọjọ Kẹtalelogun osu Kejila 1939 ni wọn bi Iya Adodo, ti o si ti ri ọmọ-ọmọ ati arọmọdọmọ rẹ, to si ti pe ọgọta ọdun ti oun ati Ọba Adeyemi ti fẹ ara wọn.
Oríṣun àwòrán, Olori Ramat Adedayo Adeyemi
Olori Ramat Adedayo Adeyemi ni ayaba keji to dagba julọ ninu aafin Ọyọ, oun si ni Ọba Adeyemi fẹ sikeji ninu awọn olori rẹ.
Olori Adedayo ati iyale rẹ, Olori Nihinlola ni iyawo meji ti Olayiwola Adeyemi ni lọọdẹ, ko to di Alaafin tilu Ọyọ, awọn mejeeji si ni wọn wa pẹlu rẹ lasiko to n jẹ ọba.
Oríṣun àwòrán, Olori Ramat Adedayo Adeyemi
Ọpọ eeyan lo maa n pe Olori Adedayo ni Iya Ile Koto abi Iya Koto, ojuse rẹ si ni lati maa tọ awọn olori kekeke sọna nipa ise ati ihuwasi to yẹ olori, to fi mọ awọn asa adayeba ilẹ Yoruba.
Gẹ gẹ gẹ si ni awọn ayaba kekere maa n gbe olori agba yii nitori pataki ipo rẹ ninu aafin, ti iya naa si ti pe ẹni ọdun mẹtalelaadọrin loke eepẹ.
Ọgbọnjọ osu Kẹfa ọdun 1943 si lo de ile aye.
Ọba Adeyemi ati Olori Ramat Adedayo Adeyemi
Oríṣun àwòrán, Olori Ramat Adedayo Adeyemi
Olori Adedayo ati Ọba Adeyemi kii fi ifẹ aarin wọn pamọ rara titi di akoko yii, paapaa, ti eeyan ba pade wọn ni ode ariya.
Awọn mejeeji jọ maa n lọ sode daada, ti wọn yoo dijọ fẹsẹ ra ijo, ti awọn ayaba kekeke to ba si wa nibẹ, yoo lọ wa ibi joko si, wọn a ni ọlọkọ lo n lo ọkọ rẹ.
Oríṣun àwòrán, Ayaba Motunrayo Adeyemi
Ọkan lara awọn olori aagba to n sikẹ Ọba Adeyemi ni Ayaba Suliat Motunrayo Abeke Adeyemi.
Olori yii tutu niwa, ti awọn eeyan ko si fẹẹ mọ ohun pupọ nipa rẹ lori ayelujara.
Oríṣun àwòrán, Mujidat Adeyemi facebook
Olori miran ti ko si lara awọn Ẹlẹ Daddy, amọ ti Ọba Adeyemi ko jẹ fi sere ni Olori Mujidat Adeyemi.
Olori Mujidat naa kii pariwo amọ ojuse rẹ ni aafin Ọyọ ko se fi sere rara.
Lagos Collapsed Buildings: Ẹ yọ ilé náà kúrò pátápátá - LASEMA
Oríṣun àwòrán, LASEMA
Eeyan mẹta lo padanu ẹmi ninu iṣẹlẹ ijamba ile alaja mẹta kan to dawo nilu Eko.
Ladugbo Freeman Street ni Isalẹ Eko ni ijamba yi ti waye lowurọ ọjọ Abamẹta.
Oríṣun àwòrán, LASEMA
Ọga ileeṣẹ to n mojuto iṣẹlẹ pajawiri nilu Eko, Femi Osanyintolu fidi ọrọ yi mulẹ fun BBC ti o si sọ pe awọn doola ẹmi eeyan mẹsan nibẹ.
Gẹgẹ bi awọn ileeṣẹ  iroyin Naijiria kan ti ṣe sọ,ni nkan bi ago mẹrin kọja diẹ lowurọ ni ile naa dawo nigba ti awọn olugbe rẹ ṣi n sun lọwọ.
Osanyintolu ni pe ninu awọn to ku ninu iṣẹlẹ naa ni ọmọdekunrin kan ati agbalagba ọkunrin kan.
Oríṣun àwòrán, LASEMA
''A ṣi wa nibi iṣẹlẹ naa bayi ti a ṣi n gbiyanju lati doola ẹmi awọn miran ninu ijamba yi.''
Nigba ti BBC beere pe ki lo ṣe okunfa iṣẹlẹ naa Osanyintolu sọ pe ile yii ti wa lara awọn ile ti wọn ti pinu lati wo teletele.
Lagos building collapse: Àwọn òbí ń kérora lórí ikú àwọn ọmọ wọn nínú ìjàmbá ilé tó wó
Loju opo Twitter awọn eeyan ti n ṣalabapin fidio iṣẹlẹ naa
Ninu fọnran fidio ta ri loju opo ayelujara niṣe lawọn eeyan pe jọ laibikita itankalẹ arun Covid-19.
Lọpọ igba ti ile ba ti wo ni ilu Eko, ipenija nla ni o ma n jẹ fawọn to n ṣeto idoola ẹmi lati ṣiṣẹ wọn nitori ero ti ma n pọju to wa woran nibẹ.
Àlàyé rèé lórí ilé kẹ̀ta tó wó l'Eko
Lagos building collapse: Àwọn òbí ń kérora lórí ikú àwọn ọmọ wọn nínú ìjàmbá ilé tó wó
"Ebila of Ibadan: Ikọ̀ Operation Burst"" ní àwọn ló pa Ebila, olórí àwọn ""One million boys"" n'Ibadan"
Oríṣun àwòrán, others
Ọga agba ikọ agboguntiwa ọdaran ni ipinlẹ Ọyọ eyi taa mọ si Operation Burst, Kọnẹẹli Ọladipọ Ajibọla ti ṣalaye pe ikọ naa lo ṣekupa olori awọn ọmọ ẹgbẹ okunkun One million boys ni ipinlẹ Ọyọ, Abiọla Ebila lọjọ Aiku.
Ọgagunfẹyinti  Ọladipọ Ajibọla ni ara igbesẹ lati dẹkun iwa ọdaran  awọn ẹgbẹ ọdaran abi ẹgbẹ okunkun to n da họwuhọwu silẹ ni ipinlẹ Ọyọ ni o ṣokunfa iku Ebila.
Nigba ti o n ṣalaye bi wọn ṣe pa aṣiwaju ẹgbẹ okunkun naa, Kọnẹẹli Ọladipọ ni, yatọ si pe wọn yinbọn pa Ebila lasiko to fi n gbiyanju lati sa mọ awọn agbofinro lọwọ leti bebe odo Kudẹti, awọn ni ẹri pe ọpọlọpọ awọn ọmọ ẹgbẹ okunkun onemillion boys to wa pẹlu rẹ naa fi ara gbọta ibọn.
O ni awọn agbofinro ikọ Operation Burst fẹ lọ doola eeyan kan tawọn ọmọ ẹgbẹ okunkun naa kan ji gbe ni wọn fi fija pẹẹta ti itaporogan ibọn si waye leyi to ṣeku pa Ebila tawọn miran si tun fara gbọta.
O ni bi o tilẹ jẹ pe awọn ọmọ ẹgbẹ okunkun naa kan gbe oku Ebila lọ, sibẹ awọn lee sọ pe ẹkọ ṣoju mimu nibi ikọlu naa nitori pe awọn ri ẹni ti wọn ji gbe naa gba pada, ti wọn si tun ṣọṣẹ si ẹgbẹ okunkun naa.
'Ó ṣe pàtàkì kí obìnrin gbádùn ìbálòpọ̀ nítorí...'
" Awọn alami kan lo ta wa lolobo pe awọn kan ji eeyan kan gbe pamọ sinu akọku ile kan lagbegbe Kudẹti.
Alami naa ṣalaye fun wa pe mẹta ninu awọn ọmọlẹyin Ebila ji eeyan kan gbe ni ikọ operation Burst ba ko sẹnu i'sẹ lọgan nitori awa pẹlu ti mọ pe awọn ọmọ ẹgbẹ okunkun One million boys ti sọ ara wọn ikan ti n jẹle lagbegbe naa.
Ni kete ti wọn ri wa, awọn ọmọ ẹgbẹ okunkun one million boys ba bẹrẹ si ni yinbọn, nibi ti awa pẹlu naa ti ṣina ibọn bolẹ fun wọn ni a ti pa Abiọla Ebila, ti a si wọ inu akọku ile naa lọ nibi ti a ti ri ẹni ti wọn ji gbe naa ti orukọ n jẹ Olufẹmi Awogboro ti a si doola ẹmi rẹ."
Oríṣun àwòrán, others
Ni tirẹ, kọmiṣọna ọlọpaa ni ipinlẹ Ọyọ, Nwachukwu Enwonwu ṣalaye pe awọn ọlọpaa kọ lo pa Ebila ati pe lati ọjọ kọkanla oṣu kẹrin ọdun yii ni wọn ti n wa Ebila lori iku Moshood Ọladokun ti ọpọ mọ si Ẹkugbemi to jẹ olori ẹgbẹ okunkun miran nilu Ibadan.
Covid19 Benefit: Àsìkò Coronavirus yìí jẹ́ kí n di télọ̀ tó mọṣẹ́ gidi - Favour
Ko tilẹ to pe ọdun mẹwaa rara ni Favour ti maa n lọ ba awọn obi rẹ pe oun fẹ kọ iṣẹ ranṣọranṣọ.
"Ṣe awọn agba maa n sọ pe ""Ọmọ tí yóò bá ti ṣe ṣámú ṣámú, àti kékére la ti ń mọ̀"", Favour Adebayo wa ni ipele keji ileewe girama (JSS 2) ṣugbọn ọgbọn to wa lori rẹ ju ti kilaasi to wa lọ."
Lati kekere ni mo ti maa n ran aṣọ fun bebi mii. Ọjọ́ tí mo sọ fún àwọn òbí mi pé mo fẹ kọ iṣẹ teelọ, wọn ni ki n duro di ọdun mẹwaa.
Nigba to pe ọmọ ọdun mẹwaa, wọn ko si kọ si i lẹnu, wọn jẹ ko bẹrẹ iṣẹ to yan laayo - Ṣebi ori lo mọ iṣ aṣela.
Mo nifẹ iṣẹ ranṣọ ranṣọ gaaan. Favour ni inu oun dun si anfani toun ni lasiko Covid19 yii.
Inú mi dùn pé Coronavirus jẹ́ kí wọn ti iléèwé pa. Lásìkò Coronavirus yìí, mo ti rán aṣọ púpọ̀ mo dẹ̀ ti pawó gan
Ẹwẹ oun naa gbagbọ pe gbogbo nkan ti eeyan ba n ṣe laye, o gbọdọ fi iwe kun un.
Lọ́jọ́ 'wájú, mo fẹ́ di ǹkan mẹ́ta, dókítà, sọ̀rọ̀sọ̀rọ̀, ránṣọ-ránṣọ.
Daniel Lewis Lee, ẹni àkọ́kọ́ tí wọ́n yóò yẹgi fún ní US lẹ́yìn ìdádúró ọdún 17
Oríṣun àwòrán, AFP
Fun igba akọkọ lati ọdun mẹtadinlogun, orilẹ-ede America yoo yẹgi fun awọn ọ̀daràn kan ni Indiana lọjọ Aje.
Eyi ri bẹẹ lẹyin ti ile ẹjọ kotẹmilọrun kan fi àṣẹ sii.
Ijọba fi ẹsun kan Daniel Lewis, ati isọngbe rẹ kan, pe wọn pa eeyan mẹta ninu ìdílé kan naa lọdun 1996.
Kò sí ìfòyà, ọkọ̀ bààlù wà tí ìjọba ba ti afárá 3rd Mainland lósù yìí
Wole Soyinka rèé láti kékeré
Nise lo pa tọkọtaya ati ọmọ wọn kan, to si ju oku wọn sinu odò adágún kan.
Àmọ́, diẹ lara mọlẹbi wọn tako idajọ iku naa, ti wọn si fẹ ki wọn da a duro na, nitori kikopa nibẹ le fi wọn sinu ewu coronavirus.
Ṣugbọn nkan ti idajọ naa tumọ si nipe ijọba le tẹsiwaju lati fa abẹrẹ olóró si ara àwọn ọ̀daràn naa lati sekupa wọn.
Ile ẹjọ kotẹmilọrun lo yi idajọ ile ẹjọ kekere to da pipa Lee duro, danu.
Ile ẹjọ kotẹmilọrun naa sọ pe ko si ofin to faaye gba ẹbí awọn ti wọn pa láti wa nibi ti wọn yoo ti pa awọn ọ̀daràn naa, ati pe awijare ẹbí naa ko fẹṣẹ mulẹ ninu ofin.
Ṣugbọn o, awọn ẹbi tun le pe ẹjọ kotẹmilọrun si ile ẹjọ to gaju lọ, lati da pipa awọn ọ̀daràn naa duro, ti wọn ba le ṣe bẹẹ ki o to di aago mẹrin irọlẹ.
Àṣírí tú! Ẹ̀rọ ayàwòrán ara ọlọ́pàá fihàn pé ìgbà ogún ni George Floyd pariwo, kó tó kú
Àwọn 'ẹ̀bùn' tí ikú George Floyd fún àgbáyé
Kí ló ṣẹlẹ̀ tí àwọn ọmọogun Nàìjíríà tó lé ní 350 fẹ́ kọ̀we fi iṣẹ́ sílẹ̀?
Oṣu Kejila lo yẹ ki wọn o yẹgi fun Lee, ẹni ọdun mẹtadinlaadọta, ṣugbọn wọn da a duro lẹyin ti ile ẹjọ pagidina idajọ iku ti wọn da fun.
Earlene Peterson, ẹni ọdun mọkanlelọgọrin, ti wọn pa ọmọ rẹ obìnrin, ọmọ-ọmọ rẹ, ati ọkọ ọmọ rẹ, lo tako idajọ iku naa.
O ni ẹ̀wọ̀n gbere ni oun n fẹ ki wọn o ju Lee ati ẹnikeji rẹ si i.
"Iya àgbà naa sọ ninu fidio kan lọdun to kọja pe ""Lootọ ni Daniel ba aye mi jẹ, sugbọn mi o gbagbọ pe gbigba ẹ̀mí rẹ yoo mu ayipada ba mi""."
Ki lo mu ki ilẹ America o ṣe ayipada si idajọ ikú?
Isejọba Aarẹ Trump lo sọ lọdun to kọja pe oun yoo bẹrẹ idajọ iku pada lẹyin idaduro ọlọjọ pipẹ.
Nigeria Police recruitment 2020: Bàyìí ni o ṣe leè di ọlọ́pàá Nàìjíríà
Àwọn dókítà Eko bẹ̀rẹ̀ ìyanṣẹ́lódì lórí owó oṣù àti ètò adójútòfò fún ìtọ́jú coronavirus
Ọmọ ọdún méjìlá yìí sọ bó ṣe di téélọ̀ táwọn àgbà ń bẹ́rí fún
Sugbọn awọn kan tako o pe, igbesẹ oṣelu ni, ti wọn si tun sọ pe igbesẹ naa yoo mu ki wọn o ma a fi ikanju ṣe igbẹjọ.
Louis Jones Jr, ẹni ọdun mẹtalelaadọta ni ijọba apapọ ilẹ America pa gbẹhin, fun pe o pa sójà kan to jẹ ẹni ọdun mọkandinlogun, Tracie Joy McBride.
Ọdun 1972 ni ile ẹjọ to gaju lọ l'America fofin de idajọ iku, to si wọgile awọn idajọ iku to wa nilẹ lasiko naa.
Sugbọn nigba to di ọdun 1976, ile ẹjọ yii kan naa lo tun pada fi aaye gba àwọn ijọba ipinlẹ lati maa ṣe idajọ iku.
Ijọba lo sọ ọ di òfin lọdun 1988 pe ki ijọba apapọ naa o bẹrẹ rẹ pada.
Orilẹ-ede America nikan kọ ni wọn ti maa n ṣe idajọ iku fun awọn ọ̀daràn.
O wọpọ ni awọn orilẹ-ede bi Naijiria, Saudi Arabia, ati awọn miran nilẹ Asia ati kaakiri agbaye.
Lagos doctors strike: Ẹgbẹ́ dókítà bẹ̀rẹ̀ ìyanṣẹ́lódì lórí owó oṣù àti ètò adójútòfò fún ìtọ́jú covid-19
Oríṣun àwòrán, Twitter/Prof Akin Abayomi
Nibi a ti n ṣe laa tii jẹ. Eyi lo mu ki awọn dokita to n ṣiṣẹ lawọn ile iwosan ipinlẹ Eko gunle iyanṣẹlodi ọlọjọ mẹta lati ṣe ikilọ fun ijọba.
Awọn dokita labẹ asia ẹgbẹ awọn dokita onisẹgun nipinlẹ Eko, Medical Guild Association sọ pe ijọba n jẹ awọn ni owo oṣu meji.
Bakan naa lawọn dokita n ja fun aabo to peye lẹnu iṣẹ ati eto adojutofo fun wọn.
Ipinlẹ Eko ni aarun coronavirus ti pọ ju lorilẹede Naijiria, eeyan to le lẹgbẹrun mejila lo laarun naa nipinlẹ nikan ninu ẹgbẹrun mejilelọgbọn eeyan to ni covid-19 ni Naijiria.
Alaga awọn dokita naa, to ba BBC sọrọ, Dokita Oluwajimi Sodipo ṣalaye pe ọrọ aabo fawọn dokita to n tọju awọn alaarun covid-19, atawọn ajẹmọnu kan to fi mọ iyatọ to wa laarin awọn dokita to n ṣiṣẹ lawọn ile iwosan ijọba apapọ lawọn fẹ ki ijọba ipinlẹ Eko nkan ṣe si i.
Ọgbẹni Sodipo sọ pe ninu ewu nla ni awọn dokita tọju awọn to laarun coronavirus wa, notori naa, o yẹ ki ijọba wa nkan ṣe si ọrọ aabo wọn lẹnu iṣẹ.
''Awọn dokita fẹ ki ijọba pese aṣọ idaabobo to peye, eto adojutofo ati eto lati maa ṣe ayẹwo deedee fawọn dokita atawọn oṣiṣẹ eleto ilera,'' Dokita Sodipo lo woye bẹẹ.
Ẹwẹ, ijọba ipinlẹ Eko ti sọ pe oun yoo ṣepade pẹlu awọn dokita naa lati wa ojutu si ọrọ wọn.
Ẹru n ba ọpọ eeyan nipinlẹ Eko pe o ṣeeṣe ki iyanṣẹlodi awọn dokita ko pẹ eyi ti yoo ṣakoba fun akitiyan ijọba lati dẹkun itankalẹ coronavirus l'Eko.
Ọmọ ọdún méjìlá yìí sọ bó ṣe di téélọ̀ táwọn àgbà ń bẹ́rí fún
Wunmi Toriola: Ọ̀pọ̀ olólùfẹ́ rẹ̀ kò fẹ́ kó bá Seyi Edun ṣe ọ̀rẹ́ mọ́.
Oríṣun àwòrán, Wumi toriola ati seyi edun
Ni agbo ere tiata Yoruba, odu ni Wunmi Toriola ati Seyi Edun jẹ, wọn kii si ṣe aimọ fun oloko. Bakan naa, ọrẹ timọ-timọ ni awọn eeyan tun mọ awọn osere mejeeji si, nitori bi wọn ṣe maa n ṣe wọle wọde, ti wọn si maa n jọ ya fọto pọ ni ori ayelujara.
'Ẹlẹ́ẹ̀kẹjọ t'óyún máà bàjẹ́ lára mi ni mo tó rí àànú gbà'
"Koda, ninu ifọrọwerọ kan ti Wunmi Toriola ṣe pẹlu BBC Yoruba nigba kan, o sisọ loju rẹ pe, ọrẹ minu oun ni Seyi Edun, tii ṣe iyawo osere tiata miran, Adeniyi Johnson, tii ṣe ọkọ Toyin Abraham tẹlẹ. ""Bi Seyi Edun si ṣe fẹ Adeniyi Johnson lo da aawọ silẹ laarin emi ati Toyin Abraham, nitori o gbagbọ pe lati ipasẹ mi ni Adeniyi Johnson fi fẹ Seyi Edun.""Ọrọ naa di yanpọnyanrin fun ọpọ ọdun, ti ori ayelujara si n gbona fun aawọ wọn ọhun."
Oríṣun àwòrán, Wumi toriola
Amọ laipẹ yii la gbọ pe ija ti tan, ogun si ti dopin laarin Toyin Abraham ati Wunmi Toriola, bẹẹ ni Wunmi gan fi idi ọrọ naa mulẹ ninu ifọrọwerọ kan to ṣe laipẹ yii. Ṣugbọn ipẹyinda iṣẹlẹ yii ni pe, awọn ololufẹ Wunmi Toriola ati Seyi Edun sakiyesi pe aawọ abẹnu ti n waye laarin awọn oṣere tiata mejeeji, eyi to si fi idi mulẹ lasiko ti Seyi Edun ṣe ọjọ ibi.
Oríṣun àwòrán, Wumi toriola
Lootọ ni Wunmi Toriola ki Seyi ku ọjọ ibi amọ ọpọ ololufẹ Seyi ni ikinni naa ko dabi ti tẹlẹ, ti wọn si n fura pe ejo ti gba aarin awọn oṣere mejeeji kọja. Bakan naa, nigba ti Wunmi Toriola ṣe ọjọ ibi ni ọjọ kọkanla osu keje ọdun 2020, Seyi Edun kan ki i ranpẹ ni, eyi to mu ki awọn eeyan kan bẹrẹ ẹjọ lori ayelujara.
Ṣugbọn awọn ọrọ naa pọ to bẹẹ gẹ eyi to mu Wunmi bọ sori ayelujara lati ṣe afihan bi Seyi ṣe ki lasiko ọjọ ibi rẹ, to si ni ohun ko fa wahala mọ rara lori ayelujara nitori oun ti kọgbọn.
Ohun ti Wunmi kọ yii lo fidi rẹ mulẹ pe aarin oun ati ọrẹ rẹ naa, Seyi Edun ko gun rara, ti aawọ si wa laarin wọn gẹgẹ bi ẹnu ṣe n kun wọn. Lọwọ lọwọ bayii, Seyi Edun ko tii fesi si ọrọ Wunmi yii, amọ a lero pe ija naa yoo wa sopin laipẹ laijinna.
BBNaija: Terry Waya sọ oun tó fojú Kiddwaya rí nílé nígbà tó ń bẹ̀bẹ̀ láti lọ BBNaija
Oríṣun àwòrán, @TERRYWAYA/@KIDDWAYA/INSTAGRAM
Baba ọkan lara awọn akopa ninu eto agbelewo Big Brother Naija Kiddwaya ton jẹ Terry Waya ti sọrọ lori bi ọmọ rẹ ṣe n ṣe ninu ilee ẹlẹgbọn agba.
O sọrọ ninu eto ifọrọwanilẹnuwo kan to ṣe pẹlu oludasilẹ Ovation Dele Momodu nibi to ti sọ pe oun ko tilẹ mọ nipa eto agbelewo yii tẹlẹ oun ko si tete fi atilẹyin oun hannigba ti ọmọ oun fẹ lọ kopa.
Tẹlẹ, oun naa lo maa n ṣe ọpọlọpọ nkan nile, oun lo n san owo ileewe awọn aburo rẹ. Ilu London ni mo ran an ko lọ afi ti mo ji ti lọjọ kan ti mo n wa a ni wọn ni o ti lọ si Eko, ọrẹ mi lo ṣeto baalu to gbe e lọ ti mi o si mọ.
Nigba to pada de, mo ni ko lọ ya ara rẹ sọtọ fun ọjọ mẹwaa tabi sẹ meji. Terry Waya ni igba ti Kiddwaya wa ba oun pe o fẹ lọ kopa nilee ẹlẹgbọn agba, oju ti oun fi wo o gan, ṣe lo pa ẹnu mọ.
O ni gbogbo awọn ọrẹ oun wa n pe oun pe nkan to fẹ ṣe niyẹn ṣugbọn ti emi o fẹ ki ẹnikẹni ba mi sọrọ nipa rẹ.
Oríṣun àwòrán, Dele Momodu
Mercy Aigbe ṣá ọmọ rẹ̀ sínúu fíìmù tuntun, wo itú tí ọmọ ọdún mẹ́wàá náà pa
Ọkọ mi kò fẹ́ràn oúnjẹ òyìnbó àfi ti ìbílẹ̀ - Lizzy Anjorin
Daddy Freeze túbá! Wo ìdí tó fi tọrọ àforíjì fún ọ̀rọ̀ ẹ̀gbin tó sọ sí Pásítọ̀ David Oyedepo
Waya ni ṣe ni Kiddwaya bẹrẹ si ni fi ọrọ ran awọn aburo ati ẹgbọn oun lati ibi to ti ya ara rẹ sọtọ ki wọn to wọ ilee Biggie ki wọn ba a bẹ baba rẹ.
Awọn aburo pe mi lori foonu pe o ni ọkan oun daru nibi to ti ya ara rẹ sọtọ to si ni bi oun ko ba gba ibukun lẹnu mi, oun ko ni lọ, ni wọn ba n bẹ mi pe ki n fi aṣẹ sii.
O fi kun un wipe awọn kan n rojọ kiri pe oun n ra ibo fun ọmọ oun ṣugbọn irọ ni wọn n pa. O ni ibo awọn ọmọ Naijiria lo ṣi jẹ ko wa nibẹ.
O ni nkan meji loun mọ pe ọmọ oun nifẹ si gan, ọrọ oun ti awọn obinrin n la kọ́ja atawọn ọdọ ti wọn n fipa ba lopọ.
Mo fẹ ki o jawe olubori ko lee ṣamulo owo to ba ri daadaa. Ṣugbọn bi ko ba si bori, gbogbo atilẹyin ti awọn ọmọ Naijiria n fun un wu mi lori jọjọ.
Bí rere ni àbí búburú, wo ohun tí Covid-19 leè ṣe sí àgọ́ ara rẹ
Nigba ti Dele Momodu bi i nipa Erica, o rẹrin o ni:
Gẹgẹ bi ẹ ṣe mọ mi, ilumọọka ni mi ni Naijiria, gbogbo ibi ti mo ba wọ ni ile mi, ko si si ibi ti mi o ti ni ọrẹ timọtimọ ni Naijiria torinaa ko si ibi ti awọn ọmọ mi ba yan lati tẹdo si ti wọn o ni ri ibukun mi ko si ni fi ṣe ede, ẹya. Ohunkohun to ba yan, ki n kan ṣaa ti fun un ni ibukun baba ni.
Awọn ololufẹ eto ile ẹlẹgbọn agba, BBNaija ti n sọrọ lori ohun to ṣẹlẹ laarin olori ile, Ozo ati igbakeji rẹ, Nengi lalẹ Ọjọru mọju Ọjọbọ.
Awọn kan tiẹ n binu tẹlẹ pe BBNaija ko ri fọnran ohun to ṣẹlẹ laarin Ozo ati Nengi wo.
Ọpọ lo fẹ ri bawọn mejeeji ti jọ sun pọ ninu ile Ozo to jẹ olori ile.
Ṣugbọn ẹrọ ayaworan kamẹra ko ṣafihan ohun to n lọ laarin awọn mejeeji.
Amọ, laarọ Ọjọbọ lawọn eeyan ri fidio kan ninu eyi ti Nengi ti gbagbe irọri rẹ to fi ṣami aye rẹ lori ibusun pẹlu Ozo.
Ki Ozo to di olori ile ati Nengi di igbakeji, awọn mejeeji ko tii jọ sun papọ ri lori ibusun kan naa, bi o tilẹ jẹ pe wọn sun mọ ara wọn.
Ṣugbọn ohun to jẹ ki ọpọ ololufẹ eto BBNaija nipa awọn mejeeji ni pe Ozo nífẹẹ Nengi, amọ Nẹngi ni oun ko fẹ ni ololufẹ ninu ile ẹlẹgbọn agba BBNaija.
'Oyenusi ló mú mi wọ ẹgbẹ́ adigunjalè kó tó di pé mo b'Ólúwa pàdé'
Okun ọrun ko yẹ adiẹ, ohun ti a ba si gbe pamọ lo n niyi.
Idi ree ti Big Brother ninu eto ile ẹlẹgbọn ọn agba ti ṣe ni ki ọkan lara awọn oludije, Dorothy wọle lati lọ paarọ asọ to wọ.
Aṣọ to wọ fi igba aya Dorothy han pupọ ti gbogbo awọn ohun to fi n ṣe oge si n han kedere fawọn oluworan.
Kaakiri oju opo ayelujara paapaa ni Instagram lawọn eeyan ti n ṣe alabapin fidio ibi ti Big Brother ti paṣẹ ki Dorothy lọ parọ aṣọ fun yi.
Iṣẹlẹ yi waye lasiko to pe Dorathy wa si inu iyara ijiroro ''Diary Room''
Akomolede ati asa Yoruba: Ẹ wá kọ́ nípa àpòtí ìṣura èdè wa lórí BBC Yorùbá
Ina kan ṣẹyọ ninu ile ti wọn ti ṣe eto Biggy 237 ni Cameroun, ṣugbọn ẹnikẹni ko ṣeṣe.
Alẹ Ọjọbọ ni ina ọhun deede ṣeyọ ni yara idana, ṣugbọn awọn olukopa ninu eto naa korajọ lati tete pa a.
Adari eto Biggy 237, Cyril Akonteh sọ fun BBC pe ina ọhun bẹrẹ lati inu apoti amu-ounjẹ gbona makirowefu ti wọn lo ni ilokulo.
"O ni ""Ibẹrubojo kọkọ gba ọkan awọn olukopa to wa ninu ile naa, ṣugbọn wọn pa ina ọhun, ohun gbogbo si pada bọ sipo."""
Wo bi ina naa ṣe bẹrẹ:
Orilẹ-ede Cameroun bẹrẹ idije Biggy 237 lọjọ Kejilelogun oṣu Kẹjọ ọdun 2020.
Teach your children Yoruba: Wo àwọn òyìnbó tó ń kẹ́kọ̀ọ́ èdè Yorùbá ní Michigan, America
Eto naa da lori bi awọn ọmọ orilẹ-ede Cameroun to n sọ ede Gẹẹsi ati ede Faranse ṣe le gbe papọ.
Eto Biggy 237 farajọ eto Big Brother Naija to n lọ lọwọ ni Naijiria.
Working religious women: Ẹ̀lẹ́hàá kìí ṣe ọ̀lẹ- Aminat Adegoke
Lilo sọ òtítọ́ fún Ebuka lórí ìbáṣepọ̀ òun àti Eric:
Ọkan lara awọn olukopa ninu idije BBNaija 2020, Boluwatife Aderogba, ti ọpọ eeyan mọ si Lilo ti sọ pe oun kabamọ ibaṣepọ oun ati Eric lori eto agbelewo naa.
Lilo lo sọ bẹẹ ninu ifọrọwerọ kan pẹlu atukọ eto ọhun, Ebuka, lẹyin ti wọn fi ọwọ osi juwe ile fun un lori eto naa.
Oríṣun àwòrán, Lilo Aderogba/Instagram
O ni ifẹ ti oun ni si Eric ti oun ṣalabapade lori eto naa jẹ ki oun sọ afojusun oun nu.
"Ẹni ọdun mẹtelogun ọhun ni ""Ninu iwoye mi, o dabi ẹni pe mo jẹ ki ifẹ ọkan mi bori idi Pataki ti mo fi lọ sori eto naa mọlẹ."""
Ìdílé tí ọkọ da ọmọ síta tóríi ojú Búlùú tí wọ́n ní bá BBC sọ̀rọ̀
Oríṣun àwòrán, BBNaija
O ni oun tete yofẹẹ Eric lori eto, ati pe oun lo kọkọ fi ẹnu ko o lẹnu nigba ti ere ifẹ wọn bẹrẹ.
Bo tilẹ jẹ pe o wu lati wa lori eto naa sibẹ, Lilo ni inu oun dun lati fi ori ọhun silẹ ni kiakia, nitori oun ko mọ oun ti oun n ṣemọ latari ibadọrẹ oun ati arakunrin Eric naa, ọrọ si ti n kọja oju ẹ.
"Nigba ti Ebuka bere lọwọ rẹ boya o kabamọ ere ifẹ rẹ ati Eric, Lilo sọ pe ""ehmm… a ko lee pe ni ikabamọ naa… ṣugbọ mo mọ pe mo ṣu saga."""
Lilo ni oun ko ni ya oun lẹnu ti Eric ba bẹrẹ ere ifẹ pẹlu ẹlomiran lẹyin ti oun kuro lori eto BBNaija 2020, ṣugbọn yoo dun oun.
Lẹyin naa lo ni kii ṣe ohun toju ko ri ri nitori aye n ṣe iru ẹ, o sit un tọrọ aforiji lọwọ awọn ololufẹ rẹ.
Lilo ati Ka3na ni wọn kọkọ le danu lori eto BBNaija 2020 lẹyin ti awọn ololufe eto naa atawọn akẹgbẹ wọn lori eto ọhun fawọn kalẹ gẹgẹ bi awọn ti asiko ti to fun lati pada sile.
'A ò tíì rí omi mu, ẹ ní ká máa fọwọ́ tóríi Coronavirus'
Oríṣun àwòrán, @BBNaija/twitter
Ariwo Erica ati Kiddwaya ni awọn eeyan tun n pa lori ayelujara bayii.
Eyi ko ṣẹyin fidio kan ti awọn ololufẹ eto naa fi sita loru oni mọju, to si ṣafihan awọn 'ololufẹ' mejeeji nibi ti wọn ti n 'fun ara wọn ni eso ifẹ jẹ'.
Lẹyin eto ti wọn ti le Lilo ati Ka3na pada sile lalẹ ọjọ Aiku,  ni iṣẹlẹ naa waye.
Ori aga ijoko ni awọn mejeeji ti kọkọ bẹrẹ, ti wọn si n fi ọwọ pa ara wọn lara. Koda, idi Erica ṣi silẹ ya-n-ya, ti ọwọ Kidd si bu idi naa so.
Lẹyin naa, ti gbogbo awọn olukopa to wa nile wọle lọ ọ sun, ni awọn mejeeji jọ wa pọ lori ibusun kan naa.
Bi awọn kan ṣe n sọ pe niṣe ni Kidd n ki ika si oju ara Erica, ni awọn kan sọ pe ibalopọ taara ni wọn n ni.
Ko tan sibẹ o, ninu fidio naa lo ti han bi Erica paapa n ke ha, yu, bi ẹni n gbadun nkan to dun.
Ṣugbọn ṣa, kii ṣe awọn mejeeji nikan lo ti jẹ ẹran ifẹ ni ori eto Big Brother Naija 2020.
Praise ati Ka3na lo kọkọ jẹ jẹ eso ifẹ.
Ọjọ Ẹti ni eyi waye lẹyin ariya alẹ ti wọn ṣe.
Ninu fidio to gba ori ayelujara, abẹ aṣọ ibora ni awọn mejeeji naa wa, to si jẹ pe bi ara wọn ṣe n lọ si ọtun, ati osi, lo fihan pe 'wọn n dan nkan wo'.
Iyalẹnu lo jẹ fun awọn ololufẹ wọn, nitori pe ko si adehun ifẹ laarin awọn mejeeji.
Ọpọ eeyan to si ti n ro pe 'tọkọtaya' naa yoo tun pada da wọn laraya ti ni ijakulẹ bayii, nitori pe Ka3na ti ja kuro ninu eto naa.
Ọrọ ibalopọ ko ṣẹṣẹ ma a waye laarin awọn olukopa ninu eto naa lati igba to ti bẹrẹ.
Idi ti Aisha Umaru ọmọ Hausa obinrin  kan soso to wa ni BBNaija se fọ sẹkun.
Oríṣun àwòrán, others
Ọkan ninu awọn akopa ninu idijẹ Big Brother tọdun 2020 to n lọ lọwọ̀, Aisha Umaru thi gbogbo eniyan mọ si Kaisha lo fọ sẹkun lasiko ifọrọwerọ pẹ ẹlẹgbọn agba ninu yara.
Fun nkan to da bi ẹni pe akopa yii ko ni le farada iṣẹlẹ to ba gbona janyinnjanyin nile ẹlẹgbọn ọn agba oo, lẹyin ọjọ meji pere Kaisha ni awọn alabosi lo pọ ju ninu ile.
Nigba ti ohun ẹlẹgbọn ọn agba fọ si i pe kini ero rẹ nipa awọn ọmọ ile to ku ati pe bawo lo se n ṣe pẹlu wọn.
"Aisha ni: ""Alabosi ni gbogbo wọn, ẹgbọn agba, lonii awọn kan o ṣe daadaa si ọ, to ba di ọla eni naa a tun maa huwa baami."""
Ọsẹ mẹwaa gbako ni wọn o lo ninu ile Big Brother ẹlẹkaarun yii, se Kaisha yoo le farada lato duro bayii lati gba ife ẹyẹ eto yii.
Oronpoto Animation: Akin Alabi ní kò dára bí eré aláwòrán fáwọn ọmọdé ṣe jẹ́ aláwọ̀ funfun
Tani Kaisha ọmọbìnrin Hausa yii?
Aisha Umar jẹ ẹni ọdun marunlelogun, onisowo ni lati ipinlẹ Sokoto.
O ri ara rẹ bi ajumọ bani ṣiṣẹpọ to se e gbọkanle to si le ba ẹnikẹni ṣe.
O nigbagbọ ninu ki eniyan jẹ ounjẹ to se ara loore.
O ni oun le jẹ ẹni to ni lọwọ sugbọn nkan maa n tete dun oun lọkan.
O fẹran lati maa kọrin, ko maa jade, ko si maa gbadun ara rẹ.
Kini awon eniyan n sọ nipa ẹkun rẹ:
Bi awon kan se n kii, ni awọn mii n buu pe ki lo muu.
Bi awọn kan se n sọ pe o dara bo se jẹ Hausa to jade sita niru eto bẹẹ ni awọn mii ni ko si ninu asa ọmọbinrin Hausa lati kopa ninu iru eto bii BB Naija yii.
Alẹ́ ọjọ́ Aiku ní a o mọ ẹni ti yóò fi ilé ẹlẹ́gbọ́n ọn àgbà sílẹ̀
Oríṣun àwòrán, Bigbrother
Kiddwaya, Lilo, Wathoni, Eric, Tolanibaj ṣe bẹbẹ lásìkò àríyá Sátide àkọ́kọ́ ní Big Brother Naija 2020
Kiddwaya, Lilo, Wathoni, Eric, Tolanibaj jètè àrà awọn lásìkò àríyá àkọ́kọ́
Àwọn akópa nínú Ilé Ẹlẹ́gbọ́n Agbà ti ọdún 2020 ti ṣe ìfẹnukónu fún ìgbà àkọ́kọ́ lásìkò àríyá ti o má n wáye ni alẹ́ ọjọ sátide.
Kiddwaya, Lilo, Wathoni, Eric àti  Tolanibaj ló ń jètè àra wọ́n lásìkò àríya sátide àkọ́kọ́ lórí móghùmáwòràn ti gbogbo ènìyàn si ń ni ànfani láti maa wò wọ́n bí wọ́n ṣe.
Àwon wọnyi ni ẹni àkọ́kọ́ ti yóò maa fi ìfẹ́ han si ara wọ́n láàrin ọjọ́ mẹ́fà ti wọ́n bẹ̀rẹ̀ ètò ọlọ́sẹ̀ mẹ́wàá ni a ti rí Kiddwaya, ọmọ baba olówó Terry Waya àti ìgbákeji olórí ilé Wathoni ti orúkọ rẹ̀ gan n jẹ́ Florence Wathoni Anyansi.
Kìí wá ṣe Wathoni àti Kiddwaya nikan lo fẹnukẹnu, Tolanibaj àti Kiddwaya náà tun ṣe bẹ́ẹ̀ lálẹ́ ọjọ́ kan náà.
Lilo àti Eric náà o gbẹ́yìn, kódà ìfẹnukẹnu ti wọ́n ni ọ̀pọ̀ àwọn olólùfẹ́ wọ́n ń rojọ́ le lórí jùlọ lálẹ́ ọjọ́ sátide, èyí kò ṣẹ̀yìn bi àwọn méjèèjì yìí ṣe ti bẹ̀rẹ̀ eré ìfẹ́ wọ́n ni kété ti wọ́n ti wọ ilé ẹlẹ́gbọ̀n àgbá lọ́sẹ̀ tó kọ́já
Lẹ́yìn àríyá alẹ́ ọjọ́ sátida àwọn ọmọ ilé elẹ́gbọ̀n àgbà ko pari fàájì wọ́n síbẹ̀, sùgbọ́n alẹ́ ọjọ́ Aiku ní a o mọ ẹni àkọ́kọ́ ti yóò fi ilé ẹlẹ́gbọ́n àgbà sílẹ̀.
Oríṣun àwòrán, Others
Ọmọ Terry Waya to jẹ ọkan lara olowo to gbajumọ lorilẹ-ede Naijiria n kopa ninu Big Brother Naija 2020 ti ọtẹ yii ti wọn pe akọle rẹ ni 'Lockdown Season'.
Terseer Kiddwaya ni orukọ rẹ, o si jẹ ẹni ọdun mẹtadinlọgbọn
Kiddwaya to wa lati ipinlẹ Benue jẹ oniṣẹ ara rẹ, to si juwe ara rẹ gẹgẹ bi ẹni to ni igboya, to rẹwa lọkunrin, to si n lakaka lati jẹ eniyan laye.
Amọ, o fikun un pe oun ni igberaga, bẹẹ si ni oun fẹran lati ma a rin irinajo.
Ẹni to ba bori ninu idije Big Brother Naija ti ọdun yii fi biliọnu marundinlaadọrun fi ṣe ara rindin.
Lasiko ifọrọwanilẹnuwo ni Kiddwaya sọ wi pe idaniloju ati ijọraẹniloju lo gbe oun de Big Brother Naija .
Ni bayii to wa ni Big brother Naija naa, afojusun rẹ ni lati gbadun ara rẹ ni ti ọdun 2020 yii.
O ni: 'Eniyan ko mọ igba ti ọlọjọ yoo de, nitori naa ṣe oun to yẹ, nitori ọjọ n lọ'
Working religious women: Ẹ̀lẹ́hàá kìí ṣe ọ̀lẹ- Aminat Adegoke
'Ohun ti mo ṣe to wu mi lori ni bi mọ ṣe ṣe ere idaraya to mu adinku ba bi mo ṣe sanra tẹlẹ.
Eyi dun mọ mi ninu, mo si fẹ ri pe mi o pada si ti tẹlẹ mọ'.
Baba Kidwaya, Terry Waya to jẹ gbajugbaja gbajumọ lawujọ, n gbe ilu London ni Ilẹ Gẹẹsi ni ibi to ti n ṣe kara-kata.
Ẹni ọdun marundinlọgọta ni Baba Kiddwaya, amọ o ti fi igba kan ko si panpẹ awọn agbofinro ni Ilẹ Gẹẹsi, ni ọdun 2006 si 2008.
Terry Waya wa lati ipinlẹ Benue ati ẹya Tiv to wa ni aarin gbungun orilẹ-ede Naijiria.
Oríṣun àwòrán, Bigbrother Naija/Africa Magic
Wo ohun tó yẹ kí o mọ̀ nípa Laycon, akẹ́kọ̀ọ́jáde UNILAG tó ń kópa nínú BBNaija 2020
Laycon BBNaija 2020: Olamilekan ló pegedé jùlọ ni ẹ̀ka ìmọ̀ Phyilosophy ní fásitì UNILAG lọ́dún 2016
Ọkan lara awọn olukopa ninu idije BBNaija 2020, Olamilekan Agbeleshe ti inagijẹ rẹ n jẹ Laycon ni ẹni to pegede julọ ni ẹka imọ Phyilosophy ni fasiti ijọba apapọ to wa ni ipinlẹ Eko, UNILAG, lọdun 2016.
Iṣe orin takasufe ni ẹni ọdun mẹrindinlọgbọn naa yan laayo, ilu Elko lo si fi n ṣe ibugbe.
Laycon sọ pe awọn eeyan ma n ṣi oun tumọ lọpọ igba, ṣugbọn ou kii ni ẹnikẹni ninu nitori oninu ire ni oun jẹ.
"Lara awọn aṣeyọri ti Laycon ti ṣe sẹyin ni orin rẹ ""Fierce,"" eyii to wa loke tente ninu awọn orin mẹwaa to lamilaaka ju lori ikanni MTV BASE fun oṣu mẹfa gbako."
Ọjọ kọkandinlogun oṣu Keje ọdun 2020 ni idije BBNaija 2020 bẹrẹ, ọpọ awọn ololufẹ eto ọhun lo si ti n reti iru awọn sinimna orita ti yoo ṣelẹ ninu ile naa lọdun yii.
Awọn olukopa ogun lo wọ inu ile naa nigba kan naa, ṣugbọn ẹnikan sọṣo ni yoo jaweolubori.
Oríṣun àwòrán, @Dorathy
Ta ni Dorathy Bachor?
Ki lo ti ṣẹlẹ sẹyin?
Eto agbelewo ori amohunmaworan ti a mọ si BBNaija ti gbinaya bayii awọn ọmọ Naijiria si ti n fi ero wọn han lori awọn olukopa kọọkan.
Amọṣa Dorothy Bachor, ọkan lara awọn olukopa eto agbelewo naa laye n jẹ lẹnu bi iṣu bayii.
Oju opo intagram Dorathy ti gbina jẹ bayii pẹlu bi awọn to n tẹ lee loju opo naa ti gbera sọ lati igba to ti wọ inu ile ẹlẹgbọn agba fun eto agbelewo BBNaija.
Ọmọ ipinlẹ Delta ni Dorathy, o si ti jẹ ko di mimọ fun olugbalejo eto agbelewo naa pe, oun wa lati jaye ori oun lori eto naa ni.
Ni bi a ṣe n sọrọ yii, erongba yii ti n ni ipa lori oju opo rẹ to jẹ pe o le ni ẹgbẹrun mẹfa ati ẹgbẹta eeyan lo n tẹlee.
Nigba ti yoo fi di agogo meje alẹ ọjọ Aiku, ọjọ kọkandinlogun, oṣu keje ti Dorathy farahan lori eto agbelewo BBNaija si agogo marun un owurọ Ogunjọ, oṣu keje, iye awọn eeyan to n tẹlee loju opo Instagram rẹ ti le ni ẹgbẹrun mọkandinlogoji.
Oríṣun àwòrán, dorathy bachor
Ọmọ ọdun mẹrinlelogn ni Dorathy Bachor ti o si jẹ agbanisiṣẹ ni ipinlẹ Delta.
O ni ileeṣẹ abaniraja SHOPFORME to da silẹ ni aṣeyọri to ga julọ ti oun ti ṣe.
Oríṣun àwòrán, Instagram/africanmagic
Ogun olukopa lo wọ inu ile ẹlẹgbọn agba fun eto agbelewo BBNaija lalẹ ọjọ kọkandinlogun oṣu keje.
Amọṣa wọn ko ni ijinasiraẹni. idi si ni pe wọn ti ṣe ayẹwo iṣegun fun wọn ti wọn si ti fi han pe wọn wẹ mọ lọwọ arun COVID-19.
Laarin ọsẹ mẹwaa ti wọn yoo lo ni ile naa, ẹgbẹgbọn agba, iyẹn Big Brother yoo maa fun wọn ni iṣẹ kan tabi omiran lati ṣe.
Lara awọn ofin to wa nilẹ fawọn olukopa lati igba ti eto naa ti bẹrẹ wa ni pe wọn ko lee ni ajọṣepọ kankan pẹlu awọn to wa ni ita ile naa.
Lockdown updates: Naira Marley gbóríyìn fún Jude Chukwuka pẹ̀lú #1 míliọnù
Iyẹn ni pe ko saye ipe lori foonu tabi wiwo mohunmaworan.
"Ni saa yii ko ni si aye fun akoko iwẹ apapọ, ti wọn da pe ni ""Shower hour"""
Oríṣun àwòrán, Bigbrother naija/africa magic
Bakan naa ni wọn tun wọgile eto apejọpọ awọn araalu fun iworan ati ifọrọwerọ pẹlawọn olukopa ti wọn ba fẹ gbọn ys kuro lori eto naa.
Ebuka ni yoo ṣi gbalejo eto apejọpọ ọjọ Aiku naa ni ile ẹlẹgbọn agba BBNaija naa
Oríṣun àwòrán, others
Idije BBNaija ọdun 2020 ti gberasọ, oriṣiriṣi oju tuntun ti awọn ololufẹ BBNaija ko tii ri ri ni yoo si pe jọ sinu ile BBNaija lọdun yi.
Lara awọn oju tuntun naa ni:
"Ozoemena ""Ozo"" Chukwu"
Ọmọ ọdun mẹtadinlọgbọn ni Ozo lati ipinlẹ Imo.
Lara awọn aṣeyọri rẹ ni bo ṣe ba ajọ UEFA Federation ṣiṣẹ nilẹ Yuroopu.
Igbagbọ Ozo ni pe ko si ohun ti eeyan ko lee ṣe to ba ti ni igbagbọ.
"Victoria ""Vee"" Adeyele"
Olorin ni Vee, ipinlẹ Eko lo si fi n ṣebugbe ko to darapọ ile BBNaijia ọdun 2020.
Bo tilẹ jẹ pe ilu London ni wọn bi Vee si, ọdun 2019  lo tẹkọ leti lọ si lati tẹpa mọṣẹ orin to yan laayo.
Nelson Enwerem Prince
Oniṣowo ni Prince lati ipinlẹ Abia ilu Eko lo si fi n ṣebugbe.
Lara awọn ohun to n ṣe ni ẹṣọ ile, ṣiṣe iṣẹ ọna sara aṣọ atawọn nnkan miran to jọ mọ ṣiṣe ara lọṣọ.
Ẹni ọdun mẹrinlelogun ni Prince, igbagbọ rẹ si ni pe orukọ rere san ju wura ati fadaka lọ.
Human trafficking: Ààrẹ Buhari, ẹ̀yin gómìnà ìpínlẹ̀ Yorùbá, ẹ rántí wa ní Oman, àwọn ọmọ
Igba kérin ree ti Ebuka Obi-Uchendu yoo gbalejo eto Big Brother Naija.
Ebuka jẹ agbohunsafẹfẹ lori ẹrọ amohunmaworan to ni awọn ololufẹ to pọ pupọ.
Oríṣun àwòrán, @Ebuka
Ta ni Ebuka Obi-Uchendu tó ń gbàlejò BBNaija 2020?
Lọdun 2006 ni Ebuka kọkọ kopa ninu eto BB Naija fun igba akọkọ.
Ọmọ olowo jalumọ biliọnia ni, iyẹn Oloye Vincent Obianodo to ni ileṣẹ Young Shall Grow Transpot ni Ebuka fẹ.
Cynthia Obianodo ti Ebuka gbe sile ni iyawo lo sọ ọ di ana gbajugbaja oniṣowo oloko owo nla naa.
Ọlọpọlọ pipe ni Ebuka jẹ ni eyi to fi ṣe idanwo igbanisile iwe girama lati ipele iwe alakọbẹrẹ kẹrin.
Ebuka ko duro ka iwe alakọbẹrẹ de ipele iwe kẹfa rara ko to bọ si ti girama nitori pe o jafafa pupọ.
Oríṣun àwòrán, @BBNaija
Awon omo inu ile ni season 5 n gbaradi
Agbofinro to dantọ ni Ebuka jẹ. Fasiti Abuja to jẹ ti olu ilu Naijiria ni Ebuka ti kọ ẹkọ nipa amofin to si tun lọ sile iwe awọn akọṣẹmọṣẹ lori ofin ni Bwari ni Abuja kan naa.
Lọdun 2010 ni Ebuka morile Washignton College of Law lati gba ipele oye keji ninu imọ ofin ni America.
Oríṣun àwòrán, BBnaija
BBNaija tọdún 2020 gbéra sọ, wo ohun tó fi yàtọ̀ sí tọdún tó kù!
BBNaija 2020 ń bẹ̀rẹ̀ lónìí, wo gbogbo bí ètò Big Brother Naija yóò ṣe lọ àti ẹ̀bùn #85 mílíọ̀nù tó wà fún jíjẹ
Ẹlẹẹkarun eto Big Brother Naija lo n bẹrẹ lonii, ọjọ kọkandinlogun, oṣu keje, ọdun 2020.
Ebuka Obi- Uchendu naa ni yoo ṣagbatẹru eto naa ṣugbọn lọtẹ yii, Ebuka ati ọkan ninu awọn olukopa miran ni wón yoo jọ dari ẹ.
Odun 2006 ni ebuka funra rẹ kopa ninu eto BB Naijia. ko to di oludari lati ọdun mẹta sẹyin ninu eyi ti wọn pe ni Gobbe, Double Wahala ati Pepper Dem.
Awọn ileeṣẹ Multi choice to n ṣe BBNaija ti ni ninu ifilọlẹ iṣide eto naa ni wọn yoo ti kede orukó ti BBNaija 2020 yoo jẹ .
Lara awọn ohun to sodo sinu ẹbun miliọnu marundinlaadọrin, N85m.
N85m ni olubori eto agbelewo naa yoo ko lọ sile lọdun 2020 yii pẹlu awọn nkan wọnyii.
Kloe: Èmi kìí mu òògùn olóró, àmọ́ mo fẹ́ràn láti máa wà lẹ́bà omi
Bawo lo ṣe le dibo ninu ti eto BB Naija 2020?
O di dandan ki awọn ololufẹ awọn olukopa dibo lasiko ti eto yii n lọ lọwọ.
Eyi yoo fun awọn ololufẹ awọn ero iworan loore ọfẹ lati gbegba oroke ninu ile ẹlẹgbọn agba naa.
Wọn le lo ọna mẹrin yii lati kopa ninu idibo naa:
Ọmọ Yorùbá mẹ́wàá tó jẹ́ àmúlùúdùn ní Amẹ́ríkà àti Yúróòpù
Àwọn alágbára ni mo bá díje ṣùgbọ́n mo ti gbà f'Olọrun- Agboola Ajayi
Ta ni Yusuf Satia ti iku mu lọ?
Èmi Ọba tí wọ́n ń kó jẹ nígboro- Oluwo ti ilú Iwo
Nǹkan mẹ́sàn án tí Mùsùlùmí gbọdọ̀ ṣe nínú oṣù Dhual- Hijjah
Bawo lo ṣe le wo eto BBNaija?
Ori ẹrọ amohunmaworan ati lori ayelujara ni ot i le wo eto naa bo ṣe n bẹrẹ.
DSTV ati GOTv ni wọn yoo maa gbee sita.
Alaalẹ ọjọ Aiku lọsọọsẹ ni wọn yoo si maa yọ ẹni kan kuro ninu ile ẹlẹgbọn agba naa.
Oriṣiriṣi iran fun oju ni yoo ṣẹlẹ ninu eto naa nitori sinima awootunwo ni o maa n ṣẹlẹ nibẹ bii ọrọ ifẹ, ija, asọ, ere, ẹrin pẹlu ayẹyẹ.
Ǹjẹ́ o mọ iye ẹ̀bùn owó tí olúborí BBNaija yóò gbà lọ́dún yìí?
N85mílíọnù àtàwọn ẹ̀bùn míràn ni olúborí BBNaija yóò gbà lọ́dún yìí
Eto agbelewo ile ẹlẹgbọn agba ti a mọ si Bbnaijia ti ọdun 2020 yoo bẹrẹ ni ọjọ Aje to n bọ yii, iyẹn ọjọ kọkandinlogun oṣu keje.
Gẹgẹ bi wọn si ti sọ, ẹbun ti iye owo rẹ to miliọnu marundinlaadọrun naira, N85m ni olubori nibi eto naa yoo fi ṣara rindin.
Amọṣa gẹgẹ bi awọn to n ṣagbatẹeru eto agbelewo BBNaija ṣe sọ, eto ti ọdun yii yoo wa ni ibamu pẹlu gbogbo ilakalẹ ti ijọba ba gbe kalẹ lori gbigbogun ti arun coronavirus eleyi to ti da họwuhọwu silẹ lagbaye.
Eto ayẹwo ọlọjọ mẹwaa ni wọn ti kọkọ ṣe fun awọn olukopa laarin ogunjọ oṣu karun un si ọgbọn ọjọ oṣu karun un kan naa.
Oríṣun àwòrán, Bigbrother
"Ni bi a ṣe n sọrọ yii, wọn ko tii fun saa karun un eto naa ni orukọ apejẹ kankan. Orukọ apejọ ti wọn fun saa ti ọdun to kọja ni Big brother ""perpperdem"".eji"
Ebuka Obi Uchendu to ti n gbalejo eto agbelewo yii fun ọdun diẹ sẹyin naa ni yoo tun gbalejo rẹ lọdun yii.
Black women live matters: Ọdún 2015 ní àwọn ọlọ́pàá pa India Kager láìní ìdí- Gina Best
Corona virus update in Nigeria: Ó lé ní N213 bílíọ̀nù tó wọlé fún ìjọba nípasẹ̀ COVID-19
Oríṣun àwòrán, Babajide sanwo-olu
Ajọ kan to n wadi iṣuna ati inawo ijọba lorilẹede Naijiria ti kede rẹ pe owo to le ni igba o le mẹtala biliọnu naira lawọn ijọba apapọ ati ipinlẹ mẹrẹrindinlọgbọn to wa lorilẹede Naijiria ti tẹwọ gba lori ajakalẹ arun coronavirus  lati fi koju arun naa.
Awọn owo naa lo wa latọwọ awọn lajọlajọ, lẹgbẹlẹgbẹ ati awọn eekan lawujọ fun ọkọọkan awọn ijọba naa eyi ti akojọpọ rẹ ti le ni igba biliọnu naira.
'Ẹlẹ́ẹ̀kẹjọ t'óyún máà bàjẹ́ lára mi ni mo tó rí àànú gbà'
Pupọ lara owo naa lo wa fun ṣiṣeto amayedẹrun fun awọn araalu ṣugbọn to jẹ pe titi di asiko yii, iye ohun taraalu fi oju ri ko tii lee dọgba pẹlu owo naa.
Ninu atẹjade rẹ kan to fi sita ni ọjọ Aje, ajọ BudgIT ni awọn ipinlẹ mẹjọ pere lo tii jẹwọ ilakalẹ lori bi wọn ṣe na owo naa.
O ni awọn ipinlẹ naa ni Ebonyi, Ekiti, Kaduna, Katsina, Eko, Ogun, Ondo ati Oyo.
Ninu ọrọ rẹ, ọga agba ajọ BudgIT ni o yẹ ki awọn ijọba o tubọ ko akoyawọ lori bi wọn ṣe na owo naa ki araalu lee mọ pe ọwọ wọn mọ nipa rẹ.
Kí ló fa ìjà láàrin Wunmi Toriola àti Seyi Edun?
Ọlọ́pàá kọ́ lo pa olórí àwọn ''One Million Boys'' Ebila n'Ibadan- Ọ̀gá ọlọ́pàá Oyo
Ondo 2020: Tani ìgbìmọ̀ tó ń sàyẹ̀wò olùdíjẹ lábẹ́ APC nípínlẹ̀ Ondo yọ kúro gan-an?
Yemi Osinbajo: Ẹgbẹ́ Arewa ní ọ̀rọ̀ ìgbákejì ààrẹ tún dákún ìṣòro Nàíjíríà ni
Oríṣun àwòrán, @ProfOsinbajo
Ẹgbẹ ọmọ Yoruba lorilẹede Naijiria ti satilẹyin fun igbakeji aarẹ lorilẹede, Yemi Osinbajo lori ọrọ to sọ pe, o ṣeeṣe ki Naijiria pin ti awọn adari ko ba kiyesi ara.
Osinbajo, ti akọwe ijọba, Boss Mustapha soju fun, sọ eyi lasiko isin ayẹyẹ ọgọta ọdun ti Naijiria gba ominira, eyi to waye nilu Abuja.
Osinbajo ni ogiri to gbe Naijiria ro n mi titi, eleyii to le fa ki Naijiria wo lulẹ, ti wọn ko ba kiyesi ara.
Ninu ọrọ tirẹ, Akọwe ẹgbẹ afẹnifẹre, Yinka Odumakin ni, ọrọ akọni ni Osinbajo sọ, eleyii to fihan wi pe, ko ṣe magomago pẹlu gbogbo iṣẹlẹ to n waye ni Naijiria.
Obateru Akinruntan: Wíwá ohun tá jẹ títí láé ló gbé wa kúrò nílé Ife
Odumakin fikun wipe, o pọn dandan ki ijọba wa ọna abayọ si iṣoro to n koju awọn ọmọ orilẹede Naijiria.
Bakan naa ni Ẹgbẹ awon ẹya Igbo, Ohanaeze Ndigbo ni o dara bi Osinbajo ṣe sọrọ lori iṣoro to n koju awọn ọmọ Naijiria, ati bi o ṣe le jasi ipinya fun wa.
Ohanaeze ni amọ awọn tako Osinbajo lori ọrọ rẹ wi pe adura ni ọna abayọ.
Ohanaeze ni adura nikan kọ ni ọrọ Naijiria gba bayii, nitori ijọba gbọdọ wa ọna abayọ si iṣoro ipaniyan awọn Fulani darandaran laarin awọn iṣoro ti Naijiria n koju.
Akomolede ati Aṣa lori BBC: Kí ní ìtúmọ̀ Sílébù àti àmi ohun tó ń fún ni?
Ninu ọrọ ti wọn, Ẹgbẹ Pan Niger Delta Forum, PANDEF ni atunto ni ọna abayọ si iṣoro Naijiria, eleyii ti yoo fun awọn ijọba ipinlẹ ni agbara lati mu ilọsiwaju ati idagbasoke ba agbegbe wọn.
Ajọ PANDEF fikun wi pe awọn ẹgbẹ ni Naijiria bi IPOB ati awọn miran to n bere fun ominira ẹya wọn fihan pe ina wa lori orule orilẹede Naijiria.
Amọ, ẹgbẹ awọn ẹya ariwa orilẹede Naijiria, northern socio-political group, the Arewa Consultative Forum, ACF ni ọrọ kubakugba ni Osinbajo sọ, bi o tile jẹ wi pe lootọ ni iṣoro lorisirisi n koju Naijiria.
Oríṣun àwòrán, @ProfOsinbajo
ACF fikun pe, ọrọ Osinbajo tun dakun wahala to wa nlẹ ni nitori awọn ọrọ to sọ lẹnu le fa ẹtanu ati ija.
ACF ni awọn gbagbọ pe laipẹ Naijiria yoo bori gbogbo iṣoro to n la kọja, ni ọna ati mu irọrun ba awọn ọmọ Naijiria.
Oríṣun àwòrán, @ProfOshinbajo
Yoruba ni pẹlẹ ni akọ, to si tun labo, Ọlọrun ma si jẹ ka si ọrọ sọ.
Ṣugbọn eyi ko ri bẹẹ pẹlu ọrọ ti Igbakeji aarẹ Yemi Osinbajo kọ soju opo Twitter rẹ lati ki Ọjọgbọn Wole Soyinka ku ọjọ ibi ọdun kẹrindinlaadọrun loke eepẹ.
"Osinbajo ni ""Ẹ ku ọjọ ibi, Ọjọgbọn!...ẹ pẹ laye lati ri orilẹede Naijiria bẹ ṣe fẹ ko ri"""
Ṣugbọn ṣe ni awọn ọmọ ta gba igbakeji aarẹ lori ikini naa, ti wọn si n sọ oko ọrọ si pe ọrọ to sọ gbẹyin naa lo tabuku ikini rẹ si Soyinka naa.
Awọn kan wa n beere lọwọ aarẹ pe ṣe orilẹede Naijiria ni ala kankan to n fi oju sun ni, ti awọn miran si ni pẹlu ọpọ ẹsun ajẹbanu to wa lọrun awọn asaaju oloselu, ti Naijiria yoo de ibi to yẹ ko de bi?
Ọpọ ọmọ Naijiria ninu ọrọ yii lo si fi oju han pe wọn ti sọ ireti nu nipa orílẹede Naijiria.
Ebila: Ọ̀pọ̀ ẹ̀mí àti dúkìá ni ẹgbẹ́ One Million Boys ṣe lọ́ṣẹ́ ni Ibadan
Oríṣun àwòrán, OTHER
Ẹgbẹ okunkun ti wọn n pe ni one million boys mi ilẹ gidi nitori iṣẹ ole ati ipaniyan ti wọn n ṣe.
Gẹgẹ bi iwadii ti fi ye wa, ogun ọdọ pere lo da ẹgbẹ naa silẹ lati fi jija gbara fun idajọ ododo lagbegbe Ajegunle nilu Eko lọdun mẹfa ṣẹyin.
"Amọ nigba to ya ni awọn ọdọ kan ja ẹgbẹ ọhun gba, ti wọn si bẹrẹ si ni lo fun iwa ipa, idigunjale, ati ipaniyan, bẹẹ ni wọn n da alaafia ilu ru Ohun tí o kò mọ̀ nípa Ebila ""One Million Boys"" àti Ekugbemi, olórí ẹgbẹ́ òkùnkùn méjì tó da ìlú Ibadan rú."
Ni ọjọ kẹsan-an, oṣu kẹwaa, ọdun 2012, awọn ọdọ to to aadoje ni Ileesẹ ọlọpaa ṣe afihan wọn pe wọn jẹ ọmọ ẹgbẹ one million boys ladugbo Apapa ati Ajegunle.
Amọ kaka ki ewe agbọn ẹgbẹ okunkun naa dẹ nidii iṣẹ ibi wọn, ko ko ko lo n le si, ti ọkunrin kan ti orukọ rẹ n jẹ Abiola, ti ọpọ mọ si Ebila si n lewaju wọn nilu Eko lọdun 2014.
Oríṣun àwòrán, OTHER
Ọmọ bibi ilu Ibadan ni Abiola Ebila, ile ẹkọ girama St Lukes to wa ni Molete nilu Ibadan si lo ti kawe, lati ẹni ọdun mejidinlọgbọn si lo ti n dari ẹgbẹ naa.
Ẹgbẹ okunkun miran lo wa ba awọn ọmọ ẹgbẹ one million boys ja, ko si ẹni to laya ninu one million boys lati koju ẹgbẹ okunkun to wa bawọn ja naa afi Abiola Ebila, o jagun, to si segun, lati igba naa si ni wọn ti fi ṣe olori wọn.
Lockdown updates: Naira Marley gbóríyìn fún Jude Chukwuka pẹ̀lú #1 míliọnù
Ilu Eko gbona mọ awọn ọmọ ẹgbẹ one million boys gidi lasiko naa, eyi si lo mu ki Ebiola sa wa silu Ibadan, lati wa fi ori ara rẹ pamọ.
Nitori iwa aburu ti wọn n hu, awọn ara adugbo Ajegunle ta gba wọn, eyi ti ọwọ ba tẹ ninu wọn ni araalu n jo ni ina, ti wọn si n ju oku wọn soju titi fun gbogbo aye lati ri.
Ọpọ wọn sa kuro nilu Eko lọ si agbegbe Ojo ati Badagry, Cotonou nigba ti awọn miran sa wa silu Ibadan, lara awọn to si wa si Ibadan ni Abiola Ebila.
Oríṣun àwòrán, OTHER
Ṣugbọn ọrọ iṣẹlẹ ijinigbe to waye ni adugbo Soka, nilu Ibadan lo jẹ ki okiki Abiola Ebila tan nilu Ibadan nitori ọrẹ rẹ Ọlọkada to sọnu, to n wa kiri lo gbe e de agbegbe Soka, níbi ti akara ti tu sepo nipa iṣẹlẹ ijinigbe to n waye nibẹ.
Lati igba naa ni okiki Abiola Ebila ti kan ni Ibadan, ó si di ọrẹ imulẹ pẹlu awọn agba oselu.
Ọpọ awọn ọdọ to jẹ janduku bẹrẹ si darapọ mọ, ti wọn si n lo ada, ìbọn ati ọbẹ lati da ilu ru.
Black women live matters: Ọdún 2015 ní àwọn ọlọ́pàá pa India Kager láìní ìdí- Gina Best
Oniruuru eto idibo to waye lasiko ti ẹgbẹ one milionu boys n tan kalẹ nilu Ibadan tun mu agbega ba agbara wọn.
Eyi waye nitori atilẹyin ti wọn n ṣe fun awọn oloselu, eyi to mu ko nira fun awọn ọlọpaa ati adari ijọba lati tete ṣẹ eegun ẹyin ẹgbẹ okunkun naa.
Ẹgbẹ one million boys bẹrẹ si gbilẹ nilu Ibadan, lati adugbo Beere, Mapo, Idi Aro, Odinjo, Eleta, Modina de Born Photo ni awọn ọmọ ẹgbẹ okunkun yii ti n ṣe ọṣẹ, wọn n jale, wọn si n pa eeyan.
Okiki ẹgbẹ one million boys yii kan gidi nitori ojoojumọ ni wọn n lowo lọwọ, wọn n fẹ ọmọge to wu wọn, ti awọn ẹgbẹ okunkun miran si n jowu wọn.
Lara awọn ẹgbẹ okunkun ti wọn si jọ n jija ìwọ ko ju mi, emi ko ju ọ ni ẹgbẹ Indomie ati Abẹ-igi aanu nitori wọn siwaju ẹgbẹ one million boys bẹrẹ iṣẹ nilu Ibadan.
Oríṣun àwòrán, OTHER
Ni alẹ Ọjọbọ, ọjọ kọkandinlogun oṣu Kejila ọdun 2019, awọn ọmọ ẹgbẹ one million boys ya bo mọsalasi kan ladugbo Kudeti, pẹlu ọkọ Micra kan, kẹkẹ ẹlẹṣẹ mẹta ati ọkada pupọ.
Lẹyin ikọlu wọn naa, obìnrin kan fara gba ọta, to si ku.
Wọn ge ọwọ ọmọ ẹlẹgbẹ okunkun mii kan, Sikiru Mufutau, to si ku, bẹẹ ni wọn ba ọpọ dukia jẹ.
Oniruuru awọn ikọlu bayii lo ti waye lati igba ti One million boys ti bẹrẹ iwa ika wọn, ti ọpọ ẹmi si ti bọ laarin ẹgbẹ naa ati awọn orogun wọn bii Indomie.
Bakan naa tun ni One million boys maa n fi iwe ransẹ si adugbo ti wọn ba ti fẹ lọ jale.
Koda, wọn yoo si sọ tẹlẹ fawọn aladugbo naa lati pese owo silẹ fun awọn, bi bẹẹ kọ, wọn yoo ge ọwọ wọn.
Ṣe iku Abiola Ebila yoo fopin si ẹgbẹ one million boys bi?
Ni ọjọ mẹta ṣẹyin, ni osu kẹrin, ọdun 2020, ni Abiola Ebila pa orogun rẹ ninu ẹgbẹ okunkun miran, Ekugbemi, lati igba naa si ni awọn agbofinro ti n wa Abiola Abila, ko le e koju igbejọ ẹṣun naa.
Ni irọlẹ ọjọ Aiku, ọjọ Kejila oṣu Keje ọdun 2020 ni ariwo gba ilu kan pe ọwọ ti tẹ olori ọmọ ẹgbẹ one million boys, Abiola Ebila, to si ti jẹ Ọlọrun nipe.
Oríṣun àwòrán, OTHER
Ariwo ayọ gba ilu kan pe eegun ẹyin ẹgbẹ okunkun naa ti ṣẹ, paapaa pẹlu olori rẹ to ku naa, ti awọn ọmọ ẹyin rẹ yoo si fi ẹsẹ fẹ.
Ṣugbọn ibeere ti ọpọ eeyan n beere ni pe, ṣe opin patapata ti de ba ẹgbẹ aseku pani one million boys ni bayii ti olori wọn ti silẹ bora?
Oríṣun àwòrán, OTHER
Ṣugbọn awọn miran n ro ninu ọkan wọn pe, agbo to fi ẹyin rin lọ ni ọrọ ẹgbẹ okunkun one million boys yii lee jẹ, o ṣee ṣe ki wọn lọ tun agbara mu wa.
Seyi Makinde vs ALGON: Àwọn alága káńsù ní ìpínlẹ̀ Oyo fẹ́ pẹjọ́ kòtẹ́milọ́rùn lórí bígómìnà Seyi Makinde ṣe yọ wọ́n nípò
Oríṣun àwòrán, oyoinsight.com
Ni Ọjọru ni ileẹjọ kotẹmilọrun to fikalẹ si ilu Ibadan gbe idajọ rẹ sita lori ẹjọ to n waye lori bi ijọba ipinlẹ Ọyọ labẹ Gomina Makinde ṣe tu awọn igbimọ ijọba ibilẹ ka nibẹ.
Nibayii,  Ẹgbẹ awọn alaga kansu ALGON ni ipinlẹ Ọyọ ti ṣalaye wi pe awọn yoo pe ẹjọ kotẹmilọrun lori idajọ naa niwaju ile ẹjọ to ga julọ lorilẹede Naijiria.
Nigba to n ba BBC News Yoruba sọrọ lori idajs naa, alaga ẹgbẹ awọn alaga Kansu ALGON ni ipinlẹ Ọyọ, Ọmọọba Abass Alẹshinlọyẹ ni bi igba ti eeyan fẹ mọọmọ fi ọwọ ọla gba awọn alaga kansu naa loju lọrs ọhun yii.
O ni asiko to fun awọn gomina lati dẹkun aṣa pe awọn ko lee ba alaga kansu ti ko ba ti wa lati ẹgbẹ oṣẹlu wọn ṣiṣẹ. O fi kun pe ko si ibi ti ile ẹjọ naa ti sọ pe wọn ko dibo yan awọn nitootọ nitori naa ohun to tọna ni ki gomina Makinde fi aye gba awọn alaga kansu naa lati lo saa wọn eleyi ti yoo pari ni ọdun 2021.
Nigba to n dahun ibeere lori ohun to fa akude ba igbesẹ yiyanju aawọ naa ni tubiinubi eleyi to kskọ n waye laarin igun mejeeji, Ọmọọba Alẹshinlọyẹ ṣalaye pe gomina ijọba ipinlẹ Ọyọ n fi iwa jẹgujẹra lọ awọn lo faa ti awọn fi yọwọ-yọsẹ ninu igbesẹ naa nigba naa.
O ni ohun ti ijọba ipinlẹ Ọyọ n gbero lati ṣe nigba naa ni lati san owo fun awọn alaga kansu naa ki wọn si maa lọ eleyi ti wọn ni awọn kọ jalẹ nitori loju awọn bii igba ti awọn gba owo iṣẹ ti awọn ko ṣe ni eyi, iwa jẹgudujẹra si ni.
Oríṣun àwòrán, twitter/Seyi makinde
Ile ẹjọ kotẹmilọrun ni ilu Ibadan ti gbe idajọ kalẹ pe ko sohun to buru ninu igbesẹ Gomina Seyi Makinde lati tu awọn ijọba ibilẹ ka ni ipinlẹ Ọyọ.
Onidajọ Haruna Tsammani to gbe idajọ naa kalẹ gbẹsẹle idajọ ti ile ẹjọ giga ipinlẹ Ọyọ gbe kalẹ ni ilu Ibadan leyi to ti ni Gomina Makinde tasẹ agẹrẹ lori igbesẹ naa, pe ko bofin mu.
Onidajọ Tsammani ṣalaye pe ori ahesọ ati gbọyisọyi ni awọn alaga kansu ti wọn rọ loye naa gbe ipẹjọ wọn naa le.
Ọmọ ọdún méjìlá yìí sọ bó ṣe di téélọ̀ táwọn àgbà ń bẹ́rí fún
Bashorun Bọsun Ajuwọn lo pe ẹjọ ọhun lorukọ awọn alaga kansu naa.
Itaporogan laarin gomina Makinde atawọn alaga kansu labẹ aṣia ALGON ni ipinlẹ Ọyọ bẹrẹ ni kete lẹyin ti wọn bura wọle sipo fun Makinde gẹgẹ bii gomina ipinlẹ Ọyọ.
Gomina Makinde tu awọn igbimọ iṣejọba ibilẹ ni ipinlẹ naa ka lori ẹsun pe ilana ti wọn fi de ipo tako ofin.
Labẹ gomina ana ni ipinlẹ Ọyọ, oloogbe Abiọla Ajimọbi ni wọn ti yan awọn alaga kansu naa ki Gomina Makinde to tu wọn ka ni wakati diẹ lẹyin to gori oye.
Kí ló fa ìjà láàrín ìlú mẹ́ta tó ń jà sí odò Nile?
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ọdun 2011 ni wọm bẹrẹ si ni kọ adagun odo yii, bayii lo ṣe ri lọdun 2019
Ohun to n fa sababii gbọnmi si i omi o to o laarin awọn orilẹ-ede Afirika kan lorii odo Nile ni ẹni ti yoo maa ṣakoso lori odo yii to gun ju ni gbogbo ilẹ Afirika.
Orilẹ-ede mẹta ni Afirika, Ethiopia, Sudan ati Egypt ti fẹnuko bayii lati bẹrẹ ijiroro. lori rẹ lẹyin ti wọn ti baba ṣepade ori ayelujara.
Koko ija to n waye laarin Ethiopia ati Egypt da lori ọjọ iwaju ti odo yii to jẹ ibudo akanṣe iṣẹ ipese agbara eyi to bẹrẹ lọdun 2011.
Ethiopia ni ireti pe odo naa yoo le pese ina fun miliọnu mẹwaa eeyan to n gbe lai ni anfani ina lorilẹ-ede wọn.
Sugbọn ni ti Egypt to jẹ pe ọpọ omi amọlolo ti wọn n o, odo Nile ni wọn ti n ri i, wọn n poruru ọkan pe igbesẹ naa yoo mu wahala ba ipese omi fun orilẹ-ede ti wọn.
Nigba ti wọn ba pari iṣẹ adagun odo nla eyi ti Ethiopia n kọ, ohun ni yoo jẹ ibudo amunawa to tobi ju ni Afirika.
Adagun odo nla yii ti fa ọbitibiti wahala laarin orilẹ-ede Egypt ati Ethiopia,
Yoruba si bọ wọn ni bi erin meji ba n ja, koriko abẹ wọn a jiya - orilẹ-ede Sudan wa laarin awọn mejeji yii
Bẹẹ si ni awọn kan n bẹru pe o lee yọri si ogun bakan naa lorilẹ-ede Amẹrika ti n kẹnu bọ ọrọ naa.
Ki lo fa ija gangan?
Lara ohun to n fa ija ni ọna ti wọn yoo gba lati di inu adagun odo naa ẹru si n ba orilẹ-ede Egypt pe akanṣe iṣẹ yii lee faaye gba ki Ethiopia maa dari odo yii to gun ju nilẹ Adulawọ.
Ọdun mẹfa ni orilẹ-ede Ethiopia fẹ fi ṣe iṣẹ naa.
A ti ni alakalẹ ati aato lati bẹrẹ didi adagun odo yii tori asiko ojo to n bọ a o si bẹrẹ si ni loo lati pese ina ninu oṣu kejila ọdun 2020.
Minisita to n ri si ọrọ omi ni Ethiopia, Seleshi Bekele lo sọ eyi ninu oṣu kẹsan ọdun to kọja.
Ẹwẹ, orilẹ-ede Egypt ti n gbero asiko ti yoo pẹ fun iṣẹ naa tori ki ipele omi naa ma sare wọlẹ paapaa ni ipele akọkọ ti wọn ba n di i.
Lati bii ọdun mẹrin bayii, ina ko tii wọ laarin Sudan ati Ethiopia lorii bi wọn yoo ṣe maa ṣakoso adagun odo naa.
Aarẹ Epypt, Abdul Fattah al-Sisi sọ ninu oṣu kẹsan ọdun to kọja pe bii kii ba ṣe wahala oṣelu to ṣẹlẹ lorilẹ-ede oun ni, Ethiopia ko ba ma lee bẹrẹ iṣẹ ọhun rara.
Ethiopia n fẹ ki wọn so odo naa pọ mọ adagun odo Aswam, Egypt ni lae lae.
Idi ti Ethiopia ṣaa fi fẹ adagun odo yii?
"Àwọn agbófinró ti mú Eji tó jẹ́ ìgbákejì Ebila, olórí ẹgbẹ́ òkùnkùn ""One Million Boys"" sí gbaga"
Ọwọ́ ọlọ́pàá tẹ afurasí ọkùnrin tó gé akẹ́kọ̀ọ́ ọ̀rẹ́bìnrin rẹ̀ wẹ́lẹ́ wẹ́lẹ́ fún òògùn owó ní Ikorodu
Áṣẹyin kìlọ̀ fáwọn adarí olóṣèlú Nàìjíríà láti ṣe ohun tó yẹ nítorí ará ọ̀run ń wò wọ́n!
Trikytee àti Ozo ní wọ́n di ẹrù ilé lé lórí nilé bbnaija lọ́sẹ̀ yìí
Iléeṣẹ́ ọlọ́pàá sọ afurasí ọlọ́pàá tó yìnbọn fún ọ̀dọ́kùnrin tó fún èèyàn lóyún lẹ́sẹ̀ s'átìmọ́lé
Njẹ awọn orilẹ-ede mii yo janfani nibẹ?
Bẹẹ ni. Awọn orilẹ-ede to sun mọ wọn bii Sudan, South Sudan, Kenya, Djibouthi ati Eritrea ṣeeṣe ki wọn jẹ anfani tori ọpọlọpọ wọn ni ko gbadun ina.
Pabanbari ni wi pe bi ọrọ yi ba lee fa ogun, yoo ba okun ajọṣepọ katakara jẹ laarin awọn orilẹ-ede agbaye eyi ti Afirika fi so wọn pọ gẹgẹ bi ileewe giga Washington Institute ṣe sọ ọ.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Minisita fun ọrọ ohun alumọọni inu omi ati ohun amusagbara lorile-ede Ethiopia, Sileshi Bekele, ti kede lori redio ati tẹlifisan orilẹede naa, EBC pe awọn ti n fa omi sinu ibudo iṣe omi lọjọ si, ti wọn kọ si ẹba odo Nile.
Ikede Ọgbẹni Sileshi yii si lo fidi ootọ nipa awọn aworan to jade mulẹ, eyi to ṣe afihan pe odiwọn omi inu ibudo ìṣe omi lọjọ si naa n lọ soke, eyi to n pa lati inu adagun odo.Adagun odo ti wọn fi biliọnu marun-un dọla kọ naa lo n fa aawọ laarin orilẹ ede Ethiopia, Egypt ati Sudan.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Bẹẹ si ni gbogbo ijiroro to waye lọjọ Aje lati yanju aawọ naa lo ja si pabo, ti wọn ko si fẹnu ọrọ jona lori awọn koko ọrọ kan ti orilẹ-ede Egypt ati Sudan n kọminu le lori.Awọn aworan tuntun ti wọn ya lati ori itakun agbaye laarin ọjọ kẹtadinlọgbọn osu kẹfa si ọjọ Kejila osu keje ọdun 2020, lo ṣe afihan bi agbega ṣe n ba odiwọn omi ti adagun odo naa n fa ọwọ rẹ sẹyin.
Ibrahim Magu, Alága àjọ EFCC yóò gbé ìwé àwíjàre rẹ̀ tọ ìgbìmọ̀ olùwádìí Aàrẹ wò lónìí
Oríṣun àwòrán, others
Alaga ajọ EFCC to n rọọkun nile lọwọ bayii, Ibrahim Magu yoo tun farahan niwaju igbimọ oluwadii ti aarẹ gbe kalẹ lati gbe awijare rẹ kalẹ lori awọn ẹsun ti wọn fi kan an.
Aarẹ Buhari gbe igbimọ naa kalẹ labẹ akoso onidajọ Ayọ Salami.
Iṣẹ wọn ni lati wadii iṣẹ ati iṣe Magu gẹgẹ bi alaga ajọ EFCC ati ajọ EFCC gan an pẹlu.
Eyi ko ṣeyin bi agbẹjọro agba fun orilẹ-ede Naijiria to tun jẹ minisita feto idajọ, Abubakar Malami, SAN ṣe kọwe ifisun si Aarẹ.
Amofin agba, Malami fi awọn ẹsun agbọ-gbọnti kan Magu ninu eyi ti a ti ri ẹsun ṣiṣe owo baṣubaṣu, jiji awọn ẹru ti wọn ri gba ko ti wọn si n ta wọn fawọn ọrẹ ati ojulumọ wọn.
Ni Ọjọbọ lo yẹ ko kọkọ ti gbe awijare rẹ kalẹ ṣugbọn ko lee ṣe bẹẹ nitori gẹgẹ bi awọn ileeṣẹ iroyin abẹle ṣe sọ, awọn ọmọ igbimọ naa ko yọju sii rara.
Working religious women: Ẹ̀lẹ́hàá kìí ṣe ọ̀lẹ- Aminat Adegoke
Iroyin to n tẹ wa lọwọ sọ pe, wọn ti da alaga ajọ EFCC, Ibrahim Magu silẹ.
Agbẹjọro rẹ, Toyin Ojaomo fi to ileeṣẹ iroyin abẹle kan leti pe Ọgbẹni Magu ko si ni ahamọ  mọ.
Ibrahim Magu gba idasilẹ rẹ lẹyin to lo ọjọ mẹwaa ni ahamọ igbimọ oluwadi ti aarẹ gbe kalẹ lati wadi ẹsun kotọ ati iwa magomago ti agbẹjọro agba lorilẹede Naijira, Amofin Abubakar Malami fi kan an.
Ileeṣẹ ọlọpaa ti kọkọ ṣalaye wi pe awọn ko mọ ohunkohun nipa ahamọ ti wọn fi alaga ajọ EFCC ti arẹ Buhari yọ nipo naa.
Agbẹnusọ fun aarẹ Buhari, Fẹmi Adesina ṣalaye pe ko si ẹni to tii fi ẹsun ọdaran kan Magu, iwadii lasan lo n waye lori bi nnkan ṣe n lọ si ni ajọ to n gbogun ti iwa jẹgudujẹra lorilẹede Naijiria, EFCC.
Child marriage: Wo ọmọbìnrin ọdún méjìlá tó ṣè'gbéyàwó pẹ̀lú ọkùnrin méjì láàrin oṣù kan
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Eemọ lukutu pẹbẹ. Ọmọdebinrin ẹni ọdun mejila kan lo ṣe igbeyawo tipatipa pẹlu ọkunrin meji laarin oṣu kan ṣoṣo.
Ba wo lo ṣe jẹ? Ilu Nairobi lorilẹede Kenya lo ma ti ṣẹlẹ, baba ọmọ naa to n gbe ni ẹkun Narok lapa iwọ oorun olu ilu Kenya lo kọkọ fi ọmọ naa fun ọkunrin kan ẹni ọdun mọkanlelaadọta.
Ọmọde yii moribọ nibi igbeyawo tipatipa ọhun, lẹyin naa ni baba rẹ tun fi fun ọkunrin mii to jẹ ẹni ọdun marundinlogoji.
Nile ọkunrin keji yii to ṣe igbayawo pẹlu rẹ lo wa ko ti wi pe ajọ ajafẹtọ awọn ọmọde kan gba a silẹ pẹlu atilẹyin awọn oṣiṣẹ ijọba kan.
Gbigbe ọmọbinrin ti ko ba to ọdun mehidinlogun niyawo lodi si ofin lorilẹede Kenya.
Adari ajafẹtọ fawọn ọmọde to doola ọmọdebinrin naa sọ pe ẹnikan lo ta oun lolobo nipa ọrọ ọmọ ọdun mejila naa lasiko ti oun n gbiyuanju lati doola ọmọde miiran.
Ọgbẹni Joshua Kaputah ni iṣẹ ati bi ijọba ti gbe ileewe tipa nitori ajakalẹ aarun coronavirus ti jẹ iṣẹlẹ ṣiṣe igbeyawo tipatipa fawọn ọmọde pọ sii.
''Ọpọ idile ni ebi n pa lasiko yii, ati pe maalu meji si mẹta ti wọn yoo gba gẹgẹ bi owo ori lo n mu ọpọ ṣe igbeyawo tulaasi fawọn ọmọde,'' Kaputah lo woye bẹẹ.
Akọroyin BBC to wa niluu Nairobi sọ pe ṣiṣe igbeyawo tipatipa fawọn ọmọde eyi to wọ pọ laarin awọn ẹya Massai lẹkun Narok n kọ ọpọ lominu lorilẹede Kenya
Ẹwẹ, ileeṣẹ ọlọpaa ti wa awọn baba ọmọdebinrin naa atawọn ọkun mejeeji to fẹ ni tipatipa laarin oṣu kan.
Ṣugbọn iroyin ti a gbọ ni pe awọn ọkunrin ti juba ehoro.
Doctors on Strike: Coro wà Coro ò sí o, èmi á lọ́ sókè òkún bí mo bá ríṣẹ́ - dókítà
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Awọn dokita Naijiria ti figbe ta pe ki ijba apapọ ma wulọ r awn rara lati ma ko l si oke oku lati lọ maa ṣiṣẹ.
Dokita kan ti ko fẹ da orukọ toripe o n ba ijọba ibilẹ ṣiṣẹ ni Naijiria s fun BBC Yoruba pe idi ti ọpọlọpọ dokita Naijiria  ma fi n lọ soke okun ni wipe nkan ti ijba n ṣe ku diẹ kaato.
Laipẹ yii ni minisita fun eto ilera, Osagie Ehanire kil fun awn dokita Naijiria nigba to n sọ̀rọ̀ nibi ipade igbimọ amuṣẹya ti ijọba lori ọrọ Covid-19 pe ki wọn tun ero wọn ro.
O sọ eyi nitori o ni bi wọn ba lọ si ilu London, wọn ko lee ri owo ajẹmọnu ohun toju n ri lẹnu iṣẹ kankan gba lọhun tori naa wọn ko nilo lati lọ sọhun rara.
Dokita oṣiṣẹ ijọba ipinlẹ ti a pe sọ pe tori gbogbo nkan ni koko ti awọn dokita fi maa n sa lọ soke okun latori owo oṣu titi dori gbogbo owo ajẹmọnu to yẹ ki wọn maa san fun wọn.
Ko si nkan ati ṣiṣẹ ni awọn ileewosan wa, a kawe o, a pari agboye o, ṣugbọn ko si nkan ati ṣiṣẹ lawọn ileewosan wa ati pe owo ti ijọba n san kere jọjọtaa ba fi wo gbogbo ọdun ti dokita lo nileewe, lo jẹ ki awn eeyan maa sọ pe ti awọn ba ri ibi to daa, wọn a lọ.
Ogundiya: Àṣìṣe Dókítà ló sọ mi di aláàbọ̀ ara lórí kẹ̀kẹ́
Bakan naa, dokita ni kii ṣe pe ijọba Naijiria ko lee san ju bayii lọ ṣugbọn wọn ko kan fi ọrọ eto ilera ṣe pataki ni. O fi kun un wi pe koda, owo ajẹmọnu ti ijọba Naijiria n sọ yii, ọdọ awọn dokita ijọba apapọ nikan lo n de, bi yoo ba kan awọn oṣiṣẹ ipinlẹ lọwọ rara, o ku sọwọ gomina wọn.
"Nigba taa bi dokita ọhun boya o ti ṣe tan bayi bayi ninu asiko arun Coronavirus yii, o dahun pe lọwọ lọwọ, oun n ṣe awọn nkankan lọwọ ṣugbọn ""bi arun Coronavirus wa o tabi ko si, mo ti ṣe tan lati lọ tori lọhun wọn pese gbogbo eto abo fun dokita ju ọdọ wa nibi yii lọ to bẹẹ ti arun naa ko le ran wọn""."
Ni ti dokita Adewale to n ṣiṣẹ ni ileewosan aladani kan ni Ado Ekiti, ipinlẹ Ekiti, o ni bi oun ba ri anfani ati lọ ṣiṣẹ loke okun, oun yoo ko ẹru oun kia.
Bi wọn ba fun emi niṣẹ ni UK, maa lọ o. Owo ajẹmọnu ti wọn n san ni Naijiria ko difa rara tori iye ti wọn n san fawn dokita ni UK koda bi ko ba si owo ajẹmọnu ohun toju n ri nibẹ ṣi pọ ju iye ti Naijiria n san lọ.
"O ṣalaye pe kii ṣe tori owo nikan lawn dokita fi n sa lọ soke okun ṣugbn ai si irinṣ lawọn ileewosan ijọba gan n da ni lagara tori eyi awn alaisan a kan maa ku iku ti ko yẹ ki wọn ku ni""."
"Dokita Wale ni oun gbagbọ pe eeyan le ṣe oriire lorilẹede rẹ ṣugbọn kii ṣe keeyan kan lọ ibiṣẹ laarọ ko pada sile ni iṣoro ṣugbọn ki inu eeyan tun dun si iṣẹ teeyan nṣe ati agbegbe iṣẹ naa""."
O ni owo oṣu dokita kan ni London lee san owo oṣu dokita Naijiria mẹrin si mẹfa.
Dajudaju, ko ba ti wu awọn dokita Naijiria to lati duro sile ni orilede wọn ṣugbn wọn ni ijọba ko wu awọn lori.
Richard Christoper: Ẹ wo adúrú ǹkan tí Softface ma ń tò pọ̀ láti sín àwọn òṣèré, gbajúgbajà jẹ
Èmi ni mo ni pátá àti kọ́mú tí mo wọ̀ láti sín Regina Daniel jẹ - Softface Ọkùnrin  asínnijẹ́.
Richard Christoper jẹ ọdọkunrin ọmọ Naijiria to n ṣe adamọdi aṣọ wiwọ lati sin awọn gbajugbaja eeyan jẹ ninu fọto.
Ìgbà yẹn ni mo kọkọ 200 laiki laye mi loju opo facebook mi, iyẹ lo wa fun mi ni iwuri latio tẹsiwaju pẹlu eleyii.
Oríṣun àwòrán, @softface_official
Oríṣun àwòrán, @softface_official
O ni oun kan ṣaa ri i pe ẹbun leleyii lati ọdọ Ọlọrun. Nigbakuugba to ba ti ri aworan ti awọn eeyan nla nla ya, a kan mu u a yẹ ẹ wo daadaa a si wo nkan pẹpẹpẹ to le ra lọja lati to pọ mọ ara wọn.
"Mo bẹrẹ, mo n ṣe e lojoojumọ,... bi ẹ ba si wo o daadaa, ẹ o ri i pe o jọ ojulowo gẹlẹ bi oni nkan gan ṣe ya fọto tirẹ""."
Oríṣun àwòrán, @softface_official
Oríṣun àwòrán, @softface_official
Awọn nkan to jẹ wi pe bi ẹyin ti ẹ ya fọto ba ri lara rẹ, ẹ o le ṣe kẹẹ́ ma rẹrin lo maa n to mọra - Bii ko lẹ ewe ọgẹdẹ pọ fi ṣe aṣọ alawọ ewe, pali fi ṣe alawọ eepẹ, abọ ounjẹ fi ṣe kọmu, ata rodo fi ṣe ododo pupa ati bẹẹ bẹẹ lọ.
Ni ibi to ba iṣẹ yii de, o darukọ awọn eeyan jankan jankan lawujọ to ti ran an lọwọ ti wọn si n tun awọn fọto ti o ba ya pin loju opo ayelujara tiwọn gangan fun iṣẹ ọpọlọ to n ṣe lati pa ni lẹrin yii.
Oríṣun àwòrán, @softface_official
Grace Oshiagwu: Afurasí ní abọ́ oúnjẹ kan, ẹ̀ẹ́dẹ́gbẹ̀ta náíra lòun ń gbà lóri àwọn tó pa l'Akinyele
Oríṣun àwòrán, oyo nsight.com
Ọkan lara awọn afunrasi mẹta ti ọwọ ọlọpaa ba fun ipaniyan ọwọọwọ to n waye lagbegbe Akinyẹle nilu Ibadan, ni ipinlẹ Oyo ti sọrọ sita.
O ṣalaye pe abọ ounjẹ kan ati ẹẹdẹgbẹta naira ni oun n gba lori ọkọọkan awọn eeyan mẹfa to pa lagbegbe naa.
Laarin oṣu kan, ko din leeyan marun un, ninu eyi ti alaboyun kan ati awọn akẹkọọ meji wa, ti wọn ti ṣa pa lagbegbe ọhun.
Ni ọjọ Ẹti nileeṣẹ ọlọpaa fi oju awọn afurasi kan han lolu ileeṣẹ ọlọpaa ni ipinlẹ Ọyọ to wa lagbegbe Ẹlẹyẹle.
Arakunrin ẹni ọdun mọkandinlogun naa ṣalaye pe babalawo kan ti o jẹ ẹni aadọta ọdun lo n ran oun ni iṣẹ ibi naa.
O fi kun un pe ni gbogbo igba ti oun ba ti fẹ jade lọ paniyan ni babalawo naa maa n fun oun ni oogun ati ajẹsara ibilẹ gbogbo pẹlu ọfọ ati ayajọ ti oun yoo pe lati di afẹẹri ni ibi ti oun ti fẹ lọ ṣe ọṣẹ naa.
Oríṣun àwòrán, other
"O ni, ""ohun eelo ibulẹ ṣọfẹli ni mo maa fi n pa awọn eeyan ti mo ba fẹ pa, maa si ka ayajọ naa si ori onitọhun ni kete ti mo ba ti rii ti ẹjẹ n jade lara rẹ"""
O ni aṣẹ ti baba fun oun ni lati maa rin yi awọn agbegbe ti oku naa ba wa ka ki oun to kọ ẹyin si wọn.
Ẹ wo adúrú ǹkan tí Softface ma ń tò pọ̀ láti sín àwọn òṣèré, gbajúgbajà jẹ
Afurasi naa ni ẹmi awọn eeyan naa yoo lọ ba babalawo ti o sọ pe o n ran oun yii, ṣugbọn ti baba ko si sọ idi ti o fẹ fi mu ki oun maa pa awọn eeyan naa.
Ati pe a maa ra ounjẹ fun oun yoo si tun fun oun ni ẹẹdẹgbẹta naira pẹlu.
Amọṣa, babalawo to n fẹsun kan naa ṣalaye pe irọ patapata lo n pa mọ oun.
O ni iṣẹ ni wọn mu u wa kọ lọdọ oun ti oun si ti kọkọ kọ ọ silẹ fun awọn iya rẹ to mu u wa ki oun to tun da ọrọ naa ro lati gba a si ẹkọṣẹ ifa ni ọdọ oun lọdun 2016.
Gẹgẹ bii kọmiṣọnna ọlọpaa ni ipinlẹ Ọyọ, Nwachukwu Ewonwu ṣe sọ, awọn afurasi naa ni wọn gbẹmi Barakat Bello ni ọjọ kinni oṣu kẹfa.
Nigba ti wọn pa Grace Oshiagwu ni ọjọ kẹtala, oṣu kẹfa, ti wọn si tun pa ọmọ ọdun marun un kan, Mojeed Tirimisiyu ni ọjọ kejilelogun, oṣu kẹfa ni agbegbe akinyẹle.
Ọmọ Yahoo tú àṣírí ara rẹ̀ fún, bí wọ́n ṣe ń ṣe é BBC Yorùbá
Coronavirus Update: Báwo lo ṣe leè mọ Oogùn apakòkòrò 'Sanitizer' tó jẹ́ ayédèrú?
Oríṣun àwòrán, Getty Images
"Oogun apakokoro lọwọ ti oloyinbo n pe ni ""Hand Sanitizer"" ti di ja pataki lori igba bayii koda o ti di nkan pataki to gbud wa lapo rẹ nibikibi too ba n lọ nitorii arun Coronavirus."
Ṣugbọn ọna ati mọ awọn eyi to jẹ ayederu too ba ri i lori igba ṣe pataki lasiko yii nitori pe ileeṣẹ awọn apoogun orilẹede Naijria to n ṣe iwadii ati idagbasoke (NIPRD) ni ida mẹtalelọgọta oogun apakokoro to wa ni ilu Abuja nikan tii ṣe oluulu orilẹede yii ni kii ṣe ojulowo.
Africa Eye: Ọwọ́ tẹ ayédèrú dókítà Abdallah tó ń tà oògùn Coronavirus
Eyi waye gẹgẹ bi orilẹede Naijiria ṣi ṣe n  ba arun coronavirus finra eyi to ti mu ẹgbẹrun marunlelọgbọn o din diẹ to si ti pa eniyan to din diẹ lẹgbẹrin titii ọjọ Ẹti ọjọ ikẹtadionlogun oṣu keje ọdun 2020.
Ajọ eleto ilera lagbaye, WHO lo fi ontẹ jan lilo oogun apakokoro lati le maa pa awọn kokoro to ba wa lọwọ lasiko ti ko ba si ọṣẹ ati omi larọwọto.
Ṣugbọn lilo oogun apakokoro nikan ko to lati dena arakan arun gẹgẹ bi awọn onim ṣe sọ ọ. Wọn gba awọn eeyan nimọran lati maa tẹle ilana eto ilera eyi to fi mọ lilo iboju-bomu nigboro, fifi ọṣẹ ati omi fọwọ ati jijinasiraẹni.
Ggẹ bi iroyin ti ileeṣẹ to n ri si eto ilera lorilẹede Naijiria fi sita nipa awọn oogun apakokoro, wọn ni beeyan ba bọ sọja lati ra a, o ni lati la oju rẹ daadaa lati wo o boya oogun apakokoro naa ni awọn nkan wọnyii:
"Coronavirus in Nigeria: Ẹ wo bí ẹ ṣe lè ṣe ""hand sanitizer"" nínú ilé yín"
Arsenal vs Liverpool: Arsenal fìyà bẹ̀rẹ̀ sáà bọ́ọ̀lù tuntun fún Liverpool pẹ̀lú Community Shield
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Aṣe igi ti a ba foju rena, lo maa n gun ni loju ni tootọọ. Ẹfọn ja baalu lulẹ ni Wembley lẹyin ti Arsenal fi iya bẹrẹ saa bọọlu tuntun fun Liverpool.Ami ayo marun si mẹrin ni Arsenal fi gbẹyẹ lọwọ Liverpool eyi to mu wọn gba ife ẹyẹ Community Shield.Pierre-Emerick Aubameyang lo kọkọ gbayo wọle Liverpool fun Arsenal ki Takumi Minimano to dayo naa pada.
Ọmi alayo kọọkan ní ifẹsẹwọnsẹ naa pari si ki wọn to fi pẹnariti yanju ẹ.Ife ẹ̀yẹ keji ti ẹgbẹ agbabọọlu Arsenal yoo gba ree labẹ akọnimọọgba tuntun, Mikel Arteta lẹyin ti wọn ti kọkọ gba ife ẹyẹ FA CUP.
Igba keji ree ti Liverpool yoo fidi rẹmi nibi ifẹsẹwọnsẹ pẹnariti lọdun 2020 yii lẹyin ti Manchester City ti kọkọ lu wọn pẹlu pẹnariti.
Mẹsan an mẹwaa ni akọnimọọgba Arsenal, Mikel Arteta n ki ẹlẹsẹ ayo, Aubameyang fun ipa ribiribi to ko ninu ifẹsẹwọnsẹ Community Shield.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Arteta ni o da oun loju pe balogun Arsenal yoo buwọlu iwe adehun tuntun lati wa pẹlu ikọ agbabọọlu naa siwaju sii.
Bi ẹ ko ba gbagbe, Aubameyang lo gba pẹnariti ẹlẹẹkarun un to kẹyin wọle fun Arsenal lẹyin to ti kọkọ mi awọn titi ninu ere bọọlu naa ni papa iṣere Wembley.
Oun kan naa lo gba goolu meji sawọn eyi to mu ki Arsenal gba ife ẹyẹ FA Cup loṣu yii ni Wembley lo ti ṣẹlẹ.
Arteta ko ṣai gboriyin fawọn ọmọ ẹgbẹ agbabọọlu Arsenal yoku, o ni gbogbo wọn patapata lo ṣe gudugudu meje yaya mẹfa bi wọn ti fẹyin Liverpool gbalẹ.
Natalia Mufuta ìyá Yakub, Kamil àti Adam sọ̀rọ̀ lórí bí wọ́n ń sọ èdè mẹ́rin pàpọ
Ohun mẹ́fà tí ọ̀pọ̀ kò mọ̀ nípa ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ Arsenal àti Machester City
Oke ti alagbara gun to mi hẹlẹhẹlẹ ni ikọ Manchester City jẹ fun ọpọlọpọ ẹgbẹ agbabọọlu ni idije premier league, FA Cup lorilẹede Gẹẹsi tabi idije miran kaakiri agbaye.
Eyi si yipada nigba ti ikọ naa koju Arsenal ni alẹ ọjọ Abamẹta.
Ṣaaju ni  ọpọlọpọ ti fi ọkan sii pe ṣokoto yoo ṣo idi Mikel Arteta atawọn agbabọọlu rẹ lẹyin ifẹsẹwọnsẹ ọhun.
Oríṣun àwòrán, Twitter/arsenal
Ohun mẹ́fà tí ọ̀pọ̀ kò mọ̀ nípa ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ Arsenal àti Machester
Amọṣa, ibi aye fojusi ọna ko gba ibẹ lọrọ ja si fun awọn agbabọọlu Arsenal atawọn ololufẹ ikọ naa.
Lẹyin ti alamojuto ifẹsẹwọnsẹ naa fun feere pe ere gbogbo pari, ami ayo meji si odo ni Arsenal fi gbẹyẹ mọ Manchester City lọwọ ninu ifẹsẹwọnsẹ ipele to kangun si a'sekagba idije FA Cup ti ọdun yii ni orilẹ-ede Gẹẹsi.
Victor Agunbiade ni ojú àlá ni Ọlọrun ti yan iṣẹ́ ọmọ ogun ojú omi fún òun ní America
Goolu meji ti atamatase ati Balogun ikọ naa, Pierre-Emerick Aubameyang gba wọ àwọ̀n Manchester City nigba ti ifẹsẹwọnsẹ naa wọ iṣẹju kejidinlogun ati ikọkanlelaadọrin.
Nibayii, Arsenal ti wọ ipele aṣekagba ife ẹyẹ FA cup bayii, eyi si ni igba ikọkanlelogun iru ẹ ti wọn yoo maa ṣe bẹẹ.
Mama Arsenal: Màmá àgbà yìí máa ń lọ sí ìbùdó tí wọ́n ti ń wo bọ́ọ́lù láti wòran
Arsenal yoo maa pade ikọ to ba bori ninu idije Manchester United pẹlu Chelsea
Ninu ọrọ rẹ, Mikel Arteta, olukọni ikọ Arsenal ni iya jẹ awọn pupọ ni ifẹsẹwọnsẹ naa ṣugbọn aato to gun rege ló ko awọn yọ.
Nitirẹ, Pep Guardiola ṣalaye pe nnkan ko ṣẹnure fun awọn agbabọọlu rẹ nitootọ.
Ǹjẹ o yẹ kí èèyàn máa sùn lẹ́nu iṣẹ́?
Ìlú àwọn ‘òmùgò’ gba orúkọ tuntun lẹ́yìn àádọ́rin ọdún!
Ṣé ẹ mọ̀ pé Ẹ̀wà Sóyà, Ẹja Puffer, àti ewébẹ̀ yìí lè ṣekú pa'ni kíákíá?
Àmúwá Ọlọ́run lásán ní ìṣẹ̀lẹ̀ tó wáyé ní Iba-Eburu Iba Oba Okunoye
Ọmọ Yahoo tú àṣírí ara rẹ̀ fún, bí wọ́n ṣe ń ṣe é BBC Yorùbá
Ènìyàn 27 lo ti bá iṣẹ̀lẹ̀ ọkọ̀ ofúrufú tó já rìnrìn ajò
Pasuma kìí ṣe ọkọ mi o! Lanre Kuti ni mo fẹ́ - Jaiye Kuti
Darandaran Fúlàní kankan kò ṣí kúrò l'Ọ́ṣun - olórí Fulani
Unai Emery máa lọ! Àwọn olólùfẹ́ Arsenal ní kí Emery kọ̀wé fipò sílẹ̀
Eji Gbadero, ọmọ Ibadan àti jayé-jayé ọmọ ónílẹ̀ ti wọn yẹgi fun l'Eko
Coronavirus in Nigeria: Nítorí COVID-19, ìjọba ìpínlẹ̀ Kwara kó ọ̀dọ́ 50 tó lọ sí ilé ijó sí gbaga
Oríṣun àwòrán, Bhenji
Nítorí COVID-19, ìjọba ìpínlẹ̀ Kwara kó ọ̀dọ́ 50 tó lọ sí ilé ijó sí gbaga
Aadọta awọn ọdọ ti ọjọ ori wọn ko ju ogun ọdun si ọgbọn ọdun lọ lọwọ ofin tẹ lowurọ ọjọ Abamẹta nile ijo kan nilu Ilọrin
Igbimọ amusẹya lori ajakalẹ arun COVID-19 ni ipinlẹ Kwara lo ko wọn si gbaga.
Igbimọ naa ni wọn tapa si ofin to de ile ijo lasiko COVID-19 yii ni
Atẹjade kan ti igbimọ naa fi sita, eyi ti agbẹnusọ fun gomina ipinlẹ Kwara fi ọwọ si lo yọju ọrọ yii sita.
Gẹgẹ bi atẹjade naa ṣe sọ awọn eeyan kan lo sin igbimọ to n ṣe kokaari eto igbogun ti ajakalẹ arun coronavirus ni ipinlẹ naa ni gbẹrẹ ipakọ.
Oríṣun àwòrán, Bhenji
Nítorí COVID-19, ìjọba ìpínlẹ̀ Kwara kó ọ̀dọ́ 50 tó lọ sí ilé ijó sí gbaga
Eyi lo jẹ ki igbakeji gomina nibẹ fi ọwọ ofin ko awọn awọn ọmọ igbimọ naa sodi lọ sileejo naa.
Dokita Ọladiji to jẹ alaga igbimọ igbaninimọran lori arun naa sọ pe o ṣeeṣe ki wọn ran gbe awọn ọdọ naa lọ sile ẹjọ fun titapa si ofin to wa nilẹ pe ẹnikẹni ko gbọdọ ṣi tabi lọ si ile ijo lasiko yii.
Black women live matters: Ọdún 2015 ní àwọn ọlọ́pàá pa India Kager láìní ìdí- Gina Best
Gbogbo wọn ni wọn si ti ko lọ si ibudo iyasọtọ titi ti esi ayẹwo wọn yoo fi jade
Eeyan marundinlaadọrun lajọ NCDC kede pẹlu arun naa ni ipinlẹ Kwara lọjọ Abamẹta
Nigerians in Oman: Ààrẹ Buhari, ẹ̀yin gómìnà ìpínlẹ̀ Yorùbá, ẹ rántí wa ní Oman, àwọn ọmọ Nàìjíríà
'Ẹ gbà wá o, á ti há sí Oman, ẹ dákun ẹ wá kó wa jáde o'- Awọn ọmọ Naijiria to ha si Oman
Oriṣiiriṣii ọrọ lo ti n jade lati igba ti BBC ti gbe iroyin yii soju opo rẹ pe awọn ọdọbinrin Naijiria n fẹ kuro ni Oman lasiko yii.
Bi awọn kan ṣe ti n gbadura pe ori a ṣọ awọn ọmọ yii de ile pada layọ ni awọn miran n ke si ijọba Naijiria lati tete ran wọn lọwọ.
Bakan naa ni awọn miran n bu ẹnu ẹ̀tẹ́ lu àwọn ọmọbinrin naa pe kini wọn n wa kiri lasiko yii ati pe o yẹ ki tile oge wọn maa to wọn lati jẹ.
Nigba ti awọn miran gba pe ojukokoro lo n fa irinajo ti ko dara lọ silẹ okeere yii.
Ni afikun ijọba ni awọn miran di ẹru naa ru pe ko pese iṣẹ fun awọn ọdọ, bẹẹ ọdọ ni agbara orilẹ-ede.
Awọn ọmọ orilẹ-ede Naijiria kan ti wọn ha si orilẹ-ede Oman ni wọn ti n rawọ ẹbẹ si ijọba apapọ Naijiria.
Koda, wọn n kesi awọn ijọba ipinlẹ ẹkun Iwọ oorun guusu Naijiria lati gba wọn silẹ lọwọ wahala ti wọn wa lorilẹ-ede naa ki wọn si ko awọn wale.
Ki lo ti kọkọ ṣẹlẹ?
Ninu fọran fidio kan ti wọn ṣe ranṣẹ si ileeṣẹ BBC News Yoruba lati fi kan si ijọba ni wọn ti pe fun iranwọ naa.
Awọn eeyan ọhun ni wọn ni iṣẹ aje ni awọn ba de orilẹ- ede Oman ki awọn to ṣeto bi wọn ṣe lọ o to yi idi ọrọ pada.
Wọn ni lẹyin ti awọn de Oman ni awọn fi wa di alarinkiri ni orilẹede naa.
Awọn obinrin naa ṣalaye pe awọn fẹ ki ijọba apapọ o boju wo awọn ọmọ orilẹ-ede Naijiria to wa ni Oman atawọn orilẹ-ede Larubawa miran.
Ati pe ki ijọba dakun gbe igbesẹ lati lee ko wọn pada wa si ile gẹgẹ bi wọn ṣe n ṣe fun awọn to wa lawọn orilẹ-ede miran.
Nigeria COVID-19 cases: Abẹ́rẹ́ àjẹsára kò tíì sí fún COVID-19, síbẹ́ àwọn òṣìṣẹ́ kólẹ̀-kódọ̀tí ń fi ẹ̀mí wọn wéwu
Ọwọja arun coronavirus n fojojumọ peleke sii lorilẹ-ede Naijiria.
Ko tii si abẹrẹ ajẹsara arun naa nitosi, sibẹ omilẹgbẹ awọn ọdọmọkunrin ti wọn n ko idọti lati ojule de ojule ni agbegbe Karu nitosi Abuja lo n fi ọwọ lasan ṣe iṣẹ, laisi ibomu tabi ibọwọ.
Eyi n mu ọpọlọpọ ewu wa fun wọn lati ko arun yii eleyii to ti mu eeyan to le ni ẹgbẹrun mẹrindinlogoji bi a ṣe n sọrọ yii.
Ọmọ ogun ọdun ni Ibrahim, ara awọn kolẹ-kodọti ni oun naa. Ni ọdun mẹta sẹyin lo fi ilu rẹ ni Katsina silẹ wa si ilu Abuja fun igbe aye to larinrin sii.
Amọṣa, iṣẹ kolẹ-kodọti lo ri ṣe eyi ti ko si lee fun un ju aadọta si ọgọrun un naira.
Black women live matters: Ọdún 2015 ní àwọn ọlọ́pàá pa India Kager láìní ìdí- Gina Best
Lojumọ nigbamiran, Ibrahim ni oun a maa pa to ẹgbẹrun meji naira, tabi ẹgbẹrun kan abọ naira nigba ti ọja ko ba ya.
"Lara awọn nnkan ti mo n ri ṣa kiri lati igba ti arun naa ti bẹrẹ ni ibomu, ibọwọ, igo ọṣẹ apakokoro Sanitaisa  atawọn ohun eelo idaabobo ṣugbọn mi o ni idaabobo kankan.
Mi o bẹru coronavirus nitori bi mi o ṣe mi o le e jẹ""- Ibrahim"
Bi ọpọlọpọ awọn ọdọkunrin miran ti wọn ti rinrinajo kuro lawọn ipinlẹ miran lorilẹ-ede Naijiria wa si Abuja ni Ibrahim lati lee ri igbe aye to dara sii.
Lati ojule de ojule ni wọn n lọ lati rii pe imọtoto wa bi o tilẹ jẹ pe eyi naa ri bakan.
Ọkan ninu wọn, Sani ṣalaye pe nigba ti ofin igbele wa nilẹ, ọpọ ile ni wọn ko jẹ ki oun wọ mọ lati ko idọti wọn nitori ibẹru ajakalẹ arun coronavirus.
Awọn oṣiṣẹ kolẹ-kodọti wa lara awọn to n foju wina lasiko ajakalẹ arun yii.
Olutunde Boroffice to jẹ Ọga agba ileeṣẹ Chanja Datti Ltd ati alakoso Waste Africa ṣalaye pe o ṣoro fun ijọba lati kan si awọn eeyan yii nitori pupọ wọn ni ko forukọ silẹ pẹlu ijọba.
O ni, koda, ko si si ẹni to mọ ibi ti wọn n da awọn idọti ohun eelo ilera ti wọn n ko si pẹlu.
Lockdown updates: Naira Marley gbóríyìn fún Jude Chukwuka pẹ̀lú #1 míliọnù
Coronavirus in Nigeria: Èèyàn mẹ́jọ kú, 1,024 míràn tún lùgbàdì ààrùn náà ní Nàìjíria
Oríṣun àwòrán, @Chikwe_I
Arun Coronavirus tun ti mu ẹmi eeyan mẹjọ miran lọ ni Naijiria.
Gẹgẹ bi ọrọ ti ajọ NCDC fi lede loj opo Twitter rẹ lalẹ ọjọ Aiku, eeyan 1,024 tuntun miran lo tun fara kasa arun ọhun bayii.
Esi yii ti sọ apapọ awon to ti ko arun naa ni Naijiria lapapọ di 100,087, awọn 80,030 ti ri iwosan nigba ti awọn 1,358 ti dero ọrun.
Bi iye awọn eeyan to ṣẹṣẹ ko arun naa kaakiri Naijiria ṣe lọ ree:
Lagos-653
Plateau-63
Benue-48
Zamfara-45
FCT-42
Rivers-27
Ondo-26
Adamawa-26
Kaduna-22
Edo-18
Ogun-16
Imo-12
Kano-9
Yobe-6
Ekiti-5
Jigawa-4
Osun-2
Oríṣun àwòrán, Twitter/ncdc
Nilẹ ọjọ Abamẹta to ṣu ni Naijiria, iye eeyan to dagbere faye gba tọwọ aarun Covid-19 ni Naijiria tun ti lekun si.
Iroyin lati ọdọ ajọ to n gbogun ti ajakalẹ aarun ni Naijiria NCDC sọ pe eeyan mẹjọ lo ku ti awọn eeyan ẹgbẹjọ din mẹẹdogun si tun ṣẹṣẹ lugbadi aarun naa.
Ipinlẹ Eko lo ṣi le tenete nipinlẹ ti ọwọja aarun yi ti peleke ti Bauchi si ni iye eeyan to kere julọ.
Ni apapọ awọn to ti ni aarun naa, ajọ naa ni wọn jẹ 99,063.
Eeyan 79,417 lo ti pada sile lẹyin tara wọn ya ti apapọ awọn to ti ku si jẹ 1,350.
1585 new cases of #COVID19Nigeria;
Lagos-573
FCT-182
Plateau-162
Gombe-81
Oyo-75
Rivers-68
Sokoto-58
Ondo-55
Ogun-42
Nasarawa-40
Akwa Ibom-36
Edo-31
Kaduna-27
Anambra-22
Delta-19
Kano-17
Osun-17
Ebonyi-16
Katsina-14
Niger-14
Bayelsa-9
EKiti-8
Borno-7
Jigawa-5
Abia-4
Bauchi-3
Eeyan mọkanla ni ajakalẹ aarun COVID-19 ti ran lọ sọrun lorilede Naijiria laarin ọjọ meji pere ni Naijiria bayii.
Gẹgẹ bi atẹjade kan ti ajọ to n gbogun ti ajakalẹ aarun lorilẹede Naijiria, NCDC fi sita loju opo Twitter rẹ lalẹ Ọjọbọ, eeyan mẹfa miran  lo kun iye awọn eeyan to ku nipaṣẹ aarun naa lẹyin ti o ti kọkọ gbee sita pẹlu ni Ọjọru pe eeyan marun miran ku.
Gẹgẹ bi awọn onwoye ṣe n woo, eyi ko fẹẹ ṣẹyin ọwọja ọwọ keji ajakalẹ aarun COVID-19, eyi to ti gbagboro kan bayii.
Ẹwẹ, eeyan Ẹgbẹrun kan ati ẹẹdẹgbẹta o le marundinlaadọrin, 1565 lo tun kun awọn to ko aarun naa naa bayii.
Eyi si sọ iye awọn to ti lugbadi aarun naa bayii di ẹgbẹrun marundinlọgọrun ati ẹẹdẹgbẹrun o  le mẹrinlelọgbọn, (95, 934).
Iye awọn to ti ku lapapọ ti di ẹgbẹrun kan ati ọọdunrun o le ọgbọn, (1330)
Lagos-807
FCT-236
Kaduna-79
Oyo-57
Plateau-47
Rivers-37
Katsina-35
Edo-30
Sokoto-30
Delta-26
Kebbi-23
Ondo-20
Enugu-18
Abia-17
Ogun-17
Benue-16
Bayelsa-15
Bauchi-14
Niger-13
Kano-10
Borno-6
Imo-5
Ekiti-4
Osun-2
Jigawa-1
Eeyan marun ni ajakalẹ arun COVID-19 tun ti pa bayii lorilẹede Naijiria.
Gẹgẹ bi ohun ti ajọ to n gbogun ti ajakalẹ aarun lorilẹede Naijiria, NCDC sọ loju opo twitter rẹ ẹgbẹrun kan ati ọtalelẹgbẹta o le mẹrin 1664 lawọ ti aarun naa tun ṣẹṣẹ mu bayii
o fi kun pe, eeyan ọrinleldunrun ati mẹj (388) ni ipinl Eko, ọtalelugb o le ẹykan (261) ni Kaduna, mẹtadinlaadọrun (87) ati ogun (20) lo ti ri iwosan bayii.
Lagos-642
FCT-407
Plateau-160
Kaduna-83
Rivers-62
Adamawa-47
Nasarawa-38
Abia-29
Edo-28
Anambra-27
Niger-24
Ogun-24
Imo-15
Oyo-14
Kano-12
Osun-12
Borno-9
Delta-7
Enugu-7
Bauchi-5
Ekiti-5
Sokoto-5
Jigawa-2
Ajọ to n gbogun ti ajakalẹ aarun lorilẹ-ede Naijiria, NCDC ti kede pe Ẹgbẹrun kan o le ọọdunrun ati mẹrinlalaadọta eeyan (1354) miran ti kun iye awọn to ti ni aarun COVID-19 ni Naijiria.
Pẹlu iye awọn eeyan tuntun yii, o ti pe ẹgbẹrun mẹrindinlọgọrin o le mẹrindinni irinwo, (76, 396) eeyan to ti ni arun naa ni orilẹede Naijiria bayii.
Lagos-712
FCT-145
Plateau-117
Kwara-81
Kaduna-54
Sokoto-39
Oyo-38
Rivers-37
Gombe-21
Enugu-20
Akwa Ibom-16
Bauchi-14
Delta-14
Ebonyi-13
Anambra-9
Taraba-8
Edo-8
Kano-3
Osun-2
Ekiti-2
Ogun-1
Ajọ to n gbogun ti ajakalẹ aarun lorilẹ-ede Naijiria, NCDC ti kede pe eeyan 576 miran ti kun iye awọn to ti ni aarun COVID-19 ni Naijiria.
Pẹlu iye awọn eeyan tuntun yii, o ti pe 89,163 eeyan to ti ni arun naa ni orilẹede Naijiria bayii.
Ijọba ipinlẹ Eko ti ni  o le ni ẹgbrun mẹrin( 4,176 )eniyan to n gba itọju arun Coronavirus ni ile, lẹyin ti wọn ṣẹṣẹ lugbadi arun Coronavirus.
Oríṣun àwòrán, Twitter
Kọmisọnna fun eto ilẹra nipìnlẹ Eko, Ọjọgbọn Akin Abayomi lo sọ bẹẹ loju opo ikansiraẹni Twitter rẹ.
Bakan naa lo fikun pe o le ni eniyan marundinlọgọfa lo wa ni ahamọ ni ile iwosan to n tọju arun Coronavirus.
Kọmiṣọnna fun eto ilera naa ni awọn ijọba ibilẹ bii marun un ni Eti-Osa, Ajeromi, Surulere, Amuwo- Odofin ati Mushin ni awn eniyan to lugbadi arun naa ti pọ.
Abayomi ni ipinlẹ Eko lo ti ṣe ayẹwo arun Coronavirus julọ lorilẹede Naijiria pẹlu eniyan  236,212 to ti ṣe ayẹwo ọhun ni ipinlẹ Eko.
O ti fẹrẹ to ọsẹ kan bayii ti iye eniyan to n lugbadi arun Coronavirus ti n le ni 1000 ní ojoojumọ.
Ni Ọjọ Ẹ̀ti, eniyan to le ni ẹgbẹrun (1,074) lo tun ṣẹṣẹ lugbadi arun ohun kaakiri orilẹede Naijiria.
Oríṣun àwòrán, NCDC
Bi a ti ṣe n wọ inu ọdun tuntun loni, Ajọ to n gbogun ti ajakalẹ aarun lorilẹ-ede Naijiria, NCDC ti kede pe eeyan 1,031 miran ti kun iye awọn to ti ni aarun COVID-19 ni Naijiria.
Pẹlu iye awọn eeyan tuntun yii, o ti pe 87,510 eeyan to ti ni arun naa ni orilẹede Naijiria bayii.
Ajọ to n gbogun ti ajakalẹ aarun lorilẹ-ede Naijiria, NCDC ti kede pe eeyan 1,016 miran ti kun iye awọn to ti ni aarun COVID-19 ni Naijiria.
Pẹlu iye awọn eeyan tuntun yii, o ti pe 86,576 eeyan to ti ni arun naa ni orilẹede Naijiria bayii.
Oríṣun àwòrán, Ncdc
Ajọ to n gbogun ti ajakalẹ aarun lorilẹ-ede Naijiria, NCDC ti kede pe eeyan 749 miran ti kun iye awọn to ti ni aarun COVID-19 ni Naijiria.
Pẹlu iye awọn eeyan tuntun yii, o ti pe 85,560 eeyan to ti ni arun naa ni orilẹede Naijiria bayii.
Ajọ to n gbogun ti ajakalẹ aarun lorilẹ-ede Naijiria, NCDC ti kede pe eeyan 397 miran ti kun iye awọn to ti ni aarun COVID-19 ni Naijiria.
Pẹlu iye awọn eeyan tuntun yii, o ti pe 84,414 eeyan to ti ni arun naa ni orilẹede Naijiria bayii.
Ènìyàn 838 míràn ló tún ṣẹ̀ṣẹ̀ lùgbàdì ààrùn Covid-19 ní Nàìjíria
Oríṣun àwòrán, NCDC
Ajọ to n gbogun ti ajakalẹ aarun lorilẹ-ede Naijiria, NCDC ti kede pe eeyan 838 miran ti kun iye awọn to ti ni aarun COVID-19 ni Naijiria.
Pẹlu iye awọn eeyan tuntun yii, o ti pe 84,414 eeyan to ti ni arun naa ni orilẹede Naijiria bayii.
Èsì àyẹ̀wò Coronavirus tuntun to jáde lọ́jọ́ satide lórílẹ̀-èdè Naìjíríà fi han pé ènìyàn ẹgbẹ̀rin àti mọ́kandinlọ́gbọ̀n tún ṣẹ̀ṣẹ̀ lùgbàdì ààrùn  Covid-19 ni Nàìjíríà.
Oríṣun àwòrán, NCDC
Gẹ́gẹ́ bi àtẹ́jáde àjọ tó n gbógun ti àjàkálẹ̀ ààrùn ni Nàìjíríà (NCDC) ṣe fi síta lójú òpó twitter rẹ̀, ìpínlẹ̀ ìpínlẹ̀ Eko, Abuja àti Kaduna lo lé ténté tábìlì.
Nínú àtẹ̀jáde ọ̀hún, ìpínlẹ̀ Eko ni 296 nígbà ti Abuja ni 291, Kadujna ni 79 nígbpa ti Rivers ni 40.
Kano 35 Nasarawa 25, Bauchi 19, Benue 8, nígbà tí Borno, Edo, Oyo àti Sokoto ni 7, Ogun ni 2
Ìpínlẹ̀ mẹ́ẹ̀dógun ni àjọ NDCD kọ sojú òpó wọ́n pé wọ́n ti rí àwọn tó ni ààrùn yìí wọ́n ko fi iye ènìyàn tó ni ààrun náà ní Jigawa soju òpó wọ́n .
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ní báyìí iyed ènìyàn to ti lùgbàdì ààrùn cororvirus ni Nàìjíríà tí lé ni mẹ́tàlélọ́gọ́rin (83,576) nígbà ti àwọn to ti rí ìwòsàn gbà ti lẹ́ ni àádọ́rin (70,495). Ènìyàn tó lé ni ẹgbẹ̀rún kan (1,247) ló ti ba corovirus rin lọ́dun 2020.
Oríṣun àwòrán, NCDC
Èsì àyẹ̀wò Coronavirus to jáde lọ́jọ́ kérésìmesì lórílẹ̀-èdè Nàìjíríà fi hàn pé, ènìyàn ẹ̀ẹ́dẹ́ẹ̀rin àti méjìlá ló tún ṣẹ̀ṣẹ̀ lùgbàdì ààrùn  Covid -19 ni Nàìjíríà.
Gẹ́gẹ́ bi àtẹ́jáde àjọ tó n gbógun ti àjàkálẹ̀ ààrùn ni Nàìjíríà (NCDC) ṣe fi síta lójú òpó twitter rẹ̀, ìpínlẹ̀ ìpínlẹ̀ Eko, Abuja àti Kaduna lo l;e ténté tábìlì.
Nínú àtẹ̀jáde ọ̀hún, ìpínlẹ̀ Eko ni 338  nígbà ti Abuja ni 77, Kwara náà tun ni 39 nígbà ti Katsina ni 35.
Bauchi ni 33 nígbà tí Plateau ni 22, Ogun ni 18, Akwa-Ibom si ni 16, Delta ni 13, sùgbọ́n Kaduna àti Osun jọ ni 12.
Yobe ni 1, Sokoto ni 10, Kebbi ni 8 nígbà tí Enugu ni 6, Edo ní 5 nígbà ti Ondo ni 3 Niger ni 2 sùgbọ́n Kano àti Oyo ni ẹyọ kan péré.
Gbogbo àpapọ̀ àwọn tó ti lùgbàdi ààrùn Coronavirus nni Nàìjíríà ti di ẹgbẹ̀rún méjìlélélọ́gọ́rin ọ le díẹ̀ (82,747) tí àwọn ẹgbẹ̀rún lọ́nà ààdọ́rín ó lé díẹ̀ (70239) sì ti rí ìtọ́jú gbà.
Oríṣun àwòrán, NCDC
Àwọn tó bọ́ lọ́wọ́ Coronavirus ni ìpínlẹ̀ Eko àti Kaduna lé díẹ̀ ni ọ̀ọ́dúnrún
O lé ni ẹgbẹ̀rún ènìyǹ to ti bá ààrùn Covid-19 rìn lọ́dún yìí.
Oríṣun àwòrán, NCDC
Oríṣun àwòrán, @NCDCgov
Esi ayẹwo Coronavirus lati ipinlẹ mejilelogun at Abuja ti ajọ NCDC ṣẹṣẹ fi sita ti fi han pe, eeyan 1,041 tun ti ni aarun naa ni Naijiria.
Ipinlẹ Eko lo le waju, ti Abuja, Kaduna atawọn ipinlẹ to ku n sare tete tẹle wọn lẹyin.
Lagos-316
FCT-210
Kaduna-83
Plateau-70
Gombe-56
Oyo-56
Katsina-47
Nasarawa-35
Kano-33
Ogun-21
Rivers-17
Niger-14
Imo-14
Delta-12
Kwara-12
Edo-12
Benue-9
Anambra-8
Taraba-4
Ekiti-4
Ebonyi-6
Bayelsa-1
Sokoto-1
Oríṣun àwòrán, Twitter/NCDC
Ènìyàn 1,133  lo tun ṣẹṣẹ lugbadi aarun Covid-19 ni Naijiria.
Gẹ́gẹ́ bi àjọ tó n mójú tó ń àjàkálẹ̀ ààrùn ní Nàìjíríà, NCDC, se sọ lójú òpó twitter rẹ̀, ipínlẹ̀ mejidinlogun ni awọn eeyan naa ti wa.
Lọwọlọwọ, apapọ awọn to ti ni aarun naa ti pe 80,922, eyan 69,274ti ri iwosan, 1,236 si ti ku.
Eko -397
FCT-357
Kaduna-81
Plateau-63
Katsina-46
Sokoto-32
Oyo-28
Ogun-21
Kano-19
Rivers-18
Osun-13
Edo-12
Niger-12
Bayelsa-11
Borno-11
Bauchi-8
Jigawa-2
Ondo-2
Ajọ to n gbogun ti ajakalẹ aarun ni Naijiria, NCDC, ti kede pe eeyan 999 miran ti kun iye awọn to ti ni aarun COVID-19 ni Naijiria.
Pẹlu iye awọn eeyan tuntun yii, o ti pe 79,789 eeyan to ti ni arun naa l'orilẹede Naijiria bayii.
68,879 ti gba iwosan nigba ti awọn 1,231 ti ba arun naa lọ.
FCT-416
Eko -324
Kaduna-68
Plateau-42
Kwara-32
Kano-24
Gombe-14
Sokoto-12
Yobe-12
Akwa Ibom-11
Bayelsa-10
Rivers-7
Bauchi-7
Ogun-6
Oyo-5
Edo-4
Taraba-4
Jigawa-1
Oríṣun àwòrán, @NCDCgov
Ajọ to n gbogun ti itankalẹ ajakalẹ arun ni Naijiria, NCDC, ti kede esi ayẹwo ẹrindinlọgọtalelọọdunrun eeyan to tun ṣẹṣẹ lugbadi Coronavirus ni Naijiria.
Ilu Abuja ni awọn to ni i pọ si ju pẹlu eeyan mọkandinlọgọrin, nigba ti eeyan mọ́kàndínlọ́gọ́ta ni ni ipinlẹ Eko, ti Kaduna atawọn ipinlẹ mejila miran si n tẹle lẹyin.
Bi awọn ipinlẹ to ku ṣe lọ ree:
FCT-79
Lagos-59
Kaduna-56
Katsina-37
Nasarawa-30
Kano-25
Edo-18
Gombe-14
Kebbi-12
Akwa Ibom-7
Rivers-7
Sokoto-7
Abia-3
Ogun-1
Cross River -1
Oríṣun àwòrán, @NCDCgov
Ajọ NCDC tun ti kede esi ayẹwo ọkanlelẹẹdẹgbẹta eeyan to tun ṣẹṣẹ ni Coronavirus ni Naijiria.
Ipinlẹ Eko ni awọn to ni i pọ si ju pẹlu eeyan mọkanlenigba, nigba ti eeyan méjìléláàdọ́fà ni ni Abuja, ti Kaduna atawọn ipinlẹ mejila miran si n tẹle lẹyin.
Biu awọn ipinlẹ to ku ṣe lọ ree:
Plateau-24
Katsina-21
Kano-16
Yobe-14
Ondo-10
Ogun-9
Edo-7
Bayelsa-5
Rivers-4
Borno-4
Osun-2
Ekiti-2
Esi ayẹwo Coronavirus lati ipinlẹ mejidinlogun ti ajọ NCDC kede loru ọjọ Abamẹta, ọjọ kọkandinlogun, oṣu Kejila, ọdun 2020, fihan pe, eeyan ẹ̀ẹ́dẹ́gbàárun le ogun tuntun miran lo ṣẹṣẹ ni aarun naa ni Naijiria.
Lọwọlọwọ, apapọ awọn to ti ni aarun naa ni Naijiria bayii ti pe 77,933, eeyan 67,784 ti ri iwosan, nigab ti awọn 1,218 ti dagbere faye.
Bi awọn ipinlẹ naa ṣe lọ ree:
Eko-308
FCT-207
Kaduna-179
Plateau-46
Niger-43
Adamawa-26
Sokoto-18
Rivers-16
Yobe-15
Enugu-13
Kano-13
Ogun-12
Delta-10
Edo-5
Osun-3
Oyo-3
Anambra-2
Ekiti-1
Oríṣun àwòrán, @NCDCgov
Eeyan ẹgbẹrin lẹ mẹfa lo tun ṣẹṣẹ lugbadi aarun Covid-19 ni Naijiria.
Gẹgẹ bi ajọ to n moju to n ajakalẹ aarun ni Naijiria (NCDC) se sọ loju opo twitter rẹ lọjọ Ẹti, ipinlẹ mẹrindinlọgbọn pẹlu olu ilu ilẹẹwa lawọn eeyan tuntun naa ti ṣẹyọ pẹlu arun naa.
Lọwọlọwọ, apapọ awọn to ti ni aarun naa ni Naijiria bayii ti pe 77,013, eeyan 67,484 ti ri iwosan, nigab ti awọn 1,212 ti dagbere faye.
Lagos-287
FCT-255
Kaduna-36
Akwa Ibom-29
Katsina-25
Rivers-25
Kwara-21
Bauchi-19
Kano-15
Ondo-14
Plateau-13
Yobe-12
Nasarawa-11
Ebonyi-9
Gombe-8
Abia-7
Delta-4
Imo-4
Osun-3
Anambra-2
Borno-2
Cross River-1
Edo-1
Ekiti-1
Jigawa-1
Ogun-1
Oríṣun àwòrán, @NCDC
Nigba akọkọ ti arun Covid-19 ti bẹrẹ, iye awọn eeyan to lugbadi arun Covid-19 ni Naijiria ti kọja ẹgbẹrun kan lojumọ.
Lẹnu ọjọ mẹta yi, oke tente ni iye awọn to lugbadi arun naa n lọ bi ọdun Keresimesi ti se n kan lẹkun dẹdẹ.
Loju opo ajọ to n mojuto ajakalẹ aarun ni Naijiria (NCDC) niṣe ni wọn kede pe eeyan ẹgbẹrun kan ati marundinlaadọjọ,1,145 tuntun miran ti lugbadi arun naa lọjọbọ.
Ninu atupalẹ iye awọn to ko arun yi, ipinlẹ Eko lewaju pẹlu eeyan 459 ti Abuja si tẹle pẹlu 145.
Kaduna ati Plateau naa ko gbẹhin bi wọn ti 'ṣe ni eeyab 138 ati 80 eeyan to ko arun naa.
Lọwọlọwọ apapọ iye eeyan to ti ba arun naa lọ ti pe 1201 ti apapọ awọn to lugbadi r ni Naijiria si jẹ 76207 ti ara awọn 67110 si ti ya.
Ẹwẹ awọn ijọba ipinlẹ kọọkan bi Eko ti kede ọjọ ti gbogbo akẹkọọ ile ẹkọ ijọba ati aladani gbọdọ pari eto ẹkọ saa kini ọdun 2020/2021.
Loju opo Twitter wọn ti ikede yi wa, wọn ni kawọn obi ri wi pe wọn tẹle ilana idaabo Covid-19 ṣaaju ki awọn akẹkọọ to pada sile ẹkọ lọjọ Kẹrin oṣu Kini 2021.
Eniyan ẹẹdẹgbẹrun o le ọgbọn lo tun ṣẹṣẹ lugbadi aarun Covid-19 ni Naijiria.
Gẹgẹ bi  ajọ to n mojuto ajakalẹ aarun ni Naijiria (NCDC) se sọ loju opo twitter rẹ l'Ọjọru, ipinlẹ  mọkanlelogun pẹlu olu ilu ilẹẹwa lawọn eeyan tuntun tun ti ṣẹyọ pẹlu arun naa lọjọ kẹrindinlogun oṣu kejila ọdun 2020.
Lọwọlọwọ, apapọ awọn to ti ni aarun naa ti pe 75,062, eeyan 66,775 ti ri iwosan, 1, 200 si ti ku.
Lagos-279
FCT-179
Plateau-62
Kaduna-54
Kano-52
Katsina-52
Imo-42
Jigawa-42
Rivers-38
Kwara-30
Nasarawa-19
Yobe-15
Ogun-13
Borno-10
Oyo-9
Niger-9
Ebonyi-6
Bauchi-6
Edo-5
Taraba-4
Sokoto-2
Cross River-2
Oríṣun àwòrán, Ncdc
Esi ayẹwo coronavirus lati ipinlẹ mọkandinlogun ti ajọ NCDC fi sita ni ọjọ Iṣẹgun, ọjọ karundinlogun oṣu kejila ọdun 2020 fihan pe, eeyan ọtalelẹẹdẹgbẹrin o din meji, 758  lo tun ti ni aarun naa ni Naijiria.
Bakan naa lo fi kun un pe eeyan mẹta larun naa tun ti ran lọ sọrun, eyi si ti mu iye awn to ti ko arun naa di ẹgbẹfa, 1200.
FCT-305
Lagos-152
Kaduna-103
Bauchi-44
Gombe-35
Plateau-31
Rivers-17
Sokoto-15
Kwara-13
Kano-9
Ebonyi-8
Ogun-5
Osun-5
Oyo-4
Edo-4
Anambra-4
Bayelsa-2
Ekiti-1
Taraba-1
Apapọ awọn to ti ni -74,132
Awọn to ti ri iwosan - 66,494
Awọn to ti ku - 1,200
Oríṣun àwòrán, Twitter/ncdc
Covid-19 tún ti ran èèyàn 1,145 míràn ní Nàìjíríà
Esi ayẹwo coronavirus lati ipinlẹ mọkanla ti ajọ NCDC fi sita ni Ọjọru, ọjọ keji, oṣu Kejila dun 2020, (02-12-2020), fihan pe, eeyan marundlaadọjọ tun ti ni aarun naa ni Naijiria.
Lagos-113
FCT-86
Abia-47
Kaduna-39
Rivers-27
Katsina-22
Benue-14
Oyo-13
Kano-12
Enugu-8
Edo-7
Imo-7
Bauchi-6
Ebonyi-6
Ogun-6
Ondo-4
Nasarawa-1
Ẹgbẹrun mẹtalelaadọrin o le marundinlọgọsan (73,175) eeyan lo ti ko aarun naa lorilẹede Naijiria lati igba ti wọn ti kẹẹfin ẹni akọkọ to laarun naa ni Naijiria ni oṣu keji ọdun 2020.
Ẹgbẹrun mẹrindinlaadọrin o le aadọrun (66, 090) lawọn ti ara wọn ti ya nigbati aarun naa si ti gbẹmi awọn ẹgbẹrun kan ati igba o din mẹta (1197) eeyan.
Oríṣun àwòrán, Ncdc
Èèyàn mẹ́ta míràn kú, olú ìlú Nàìjíríà, Eko, Kaduna léwájú ìṣẹ̀lẹ̀ Covid-19 ní Naijiria
Eniyàa mẹrindinlẹgbẹrin lo tun ṣẹṣẹ lugbadi aarun Covid-19 ni Naijiria.
Gẹgẹ bi  ajọ to n moju to n ajakalẹ aarun ni Naijiria (NCDC) se sọ loju opo twitter rẹ lọja Ẹti, ipinlẹ  marundinlogun pẹlu olu ilu ilẹẹwa lawọn eeyan tuntun tun ti ṣẹyọ pẹlu arun naa lọjọ kọkanla oṣu kejila ọdun 2020.
Lọwọlọwọ, apapọ awọn to ti ni aarun naa ti pe 72,140, eeyan 65,722 ti ri iwosan, 1,190 si ti ku.
FCT-258
Lagos-248
Kaduna-117
Katsina-52
Ogun-27
Kwara-23
Gombe-22
Adamawa-17
Plateau-15
Kano-6
Rivers-2
Ondo-2
Ekiti-2
Nasarawa-2
Sokoto-2
Taraba-1
Eeyan ẹgbẹta ati marundinlọgọrin ni esi ayẹwo coronavirus ti ajọ NCDC fi sita ni ọjọ kẹwaa, oṣu Kejila dun 2020 fihan pe o tun ti ni aarun naa ni Naijiria.
Bakan naa ni Covid-19 hun tun ṣekupa eeyan mẹfa.
Ajọ NCDC ti kede eeyan ojilelẹẹdẹgbẹta ati mẹwa to tun ṣẹṣẹ ni Covid-19 ni Naijiria.
Esi ayẹwo ọhun to wa lati ipinlẹ mẹrindinlogun, ati  ilu Abuja, lo ti i pọ ju lati oṣu diẹ sẹyin.
Lagos-219
FCT-168
Kaduna-52
Kwara-19
Kano-15
Rivers-15
Sokoto-10
Enugu-9
Gombe-8
Plateau-7
Osun-7
Anambra-5
Oyo-5
Jigawa-4
Ogun-4
Bauchi-2
Edo-1
Akojọpọ awọn to ti ni aarun naa ni 70,195. Awọn 65,110 ti ri iwosan. O si ti ṣekupa 1,182.
Èèyàn 390 ló tún ti ní covid-19 ní Naijiria
Eeyan irinwo din mẹwa lo tun ṣẹṣẹ ni Covid-19 ni Naijiria.
Esi ayẹwo ti ajọ to n gbogun ti ajakalẹ aarun, NCDC, fi sita ni ọjọ Aje fihan pe ipinlẹ mọkandinlogun, ati ilu Abuja ni awọn esi naa ti wa.
FCT-89
Gombe-89
Kaduna-62
Lagos-35
Kwara-15
Borno-13
Nasarawa-10
Rivers-10
Bauchi-8
Ogun-8
Osun-7
Bayelsa-7
Kano-7
Edo-6
Taraba-6
Ekiti-5
Katsina-5
Akwa Ibom-4
Delta-3
Sokoto-1
Èèyàn 318 tún ti ní COVID-19 ní Nàìjíríà, sùgbọ́n ara ará ilú 60 ló dá
Àjọ tó n gbógun ti ìtàkálẹ̀ ààrùn ní Nàìjíríà (NCDC) ti kéde pé ènìyàn 318 ló tí ni ààrùn coronavirus ní Nàìjíríà.
Nínú àtẹ̀jáde ojoojúmọ́ ilé iṣẹ́ náà lójú òpó twitter rẹ̀ ló lo ti salaye pé, ìpínlẹ̀ méjìlá ni ọwọ́jà ààrùn náà dé dúró ní Nàìjíríà fún tí ọjọ́ kẹrin osù kejìlá ọdún 2020.
Nínú àtẹ́jáde náà, ìpínlẹ̀ Eko ló ń léwájú pẹ̀lú ènìyàn 104, ìpínlẹ̀ Kaduna tẹ̀lée pẹ̀lú 59, Abuja 50 nígbà ti Rivers 17 Ogun 16.
Bákan náà Kano-14, Nasarawa-14, Akwa Ibom-10, Katsina-10,  ńigbà tí Edo-7.
Oyo àti Sokoto ni 5, Plateau ni 4 tí Taraba si ni 3
Àjọ tọ n gbógun ti ìtànkálẹ̀ àjàkálẹ̀ ààrùn ni Nàìjíríà (NCDC) ti kéde pé ènìyàn ọ̀ọ̀dúnrun àti mẹ́w['a ló tun ṣẹ̀sẹ̀ lùgbàdì ààrùn coronavirus lórílẹ̀-èdè Nàìjíríà
Nínú àtẹ̀jáde ojoojúmọ́ ilé iṣẹ́ náà lójú òpó Twitter rẹ̀ ló lo ti salaye pé, ìpínlẹ̀ méjìlá ni ọwọ́jà ààrùn náà dé dúró ní Nàìjíríà fún tí ọjọ́ kẹrin osù kejìlá ọdún 2020.
Nínú àtẹ́jáde rẹ̀, òlúùlú orílẹ̀-èdè Nàìjíríà Abuja  ló ń léwájú pẹ̀lú ènìyàn 128, ìpínlẹ̀ Eko tẹ̀lée pẹ̀lú 86, Kaduna ni 26 nígbà ti Katsina náà ni 20
Àwọn ìpińlẹ̀ tó kù ni Rivers 19, Oyo 7, Benue, Edo, jigawa àti Ogun ní 5 tí Bayelsa ati Kano sì ni 2.
Ní báyìí ènìyàn tó dín díẹ̀ ní ẹgbẹ̀rùn lọ́nà ààdọ́rin ló ti lùgbàdì ààrun Covid-19 ní Nàìjíríà, nígbà ti ènìyàn ẹgbẹ̀rún mẹ́rìnleọgọ́ta ti gba iwòsàn
Bákan náà ní ènìyin tó lé ni ẹgbẹ̀run kan ni ikú ti pa.
Coronavirus in Nigeria: Ìpínlẹ̀ Kaduna ní èèyàn 37 nínú àwọn 122 tí Covid-19 ṣẹ̀ṣẹ̀ ràn ní Naijiria
Esi ayẹwo coronavirus lati ipinlẹ mọkanla ti ajọ NCDC fi sita ni Ọjọru, ọjọ keji, oṣu Kejila dun 2020, (02-12-2020), fihan pe, eeyan marundlaadọjọ tun ti ni aarun naa ni Naijiria.
Kaduna-37
Lagos-29
Plateau-25
Ekiti-9
Rivers-5
Ogun-5
Edo-4
Kwara-4
Bayelsa-2
Bauchi-1
Kano-1
Ẹgbẹrun mẹtadinlaadọrin o le ọtalelẹẹdẹgbẹrun (67,960) eeyan lo ti ko aarun naa lorilẹede Naijiria lati igba ti wọn ti kẹẹfin ẹni akọkọ to laarun naa ni Naijiria ni oṣu keji ọdun 2020.
Ẹgbẹrun mẹtalelọgọta ati ojilelẹgbrin o din ẹykan (63, 839) lawọn ti ara wọn ti ya nigbati aarun naa si ti gbẹmi awọn ẹgbẹrun kan ati mejilelaadọjọ (1173) eeyan.
O dabi ẹni pe coronavirus tun ti n gbilẹ si diẹ diẹ lorilẹede Naijiria. Eeyan eeyan ọrinlelugba o le ẹyọkan lo ko aarun naa lọjọ Iṣẹgun.
Mẹtalelọgọfa ninu wọn lo wa lati ipinlẹ Eko eyi si lo pọju ninu gbogbo ipinlẹ lọjọ Iṣẹgun.
Olu ilu ilẹ Naijiria, FCT lo ṣe ipo keji nibi ti eeyan mẹrinlelọgọta ti lugbadi aarun ọhun.
Eeyan mejidinlogoji lo laarun naa lati Kaduna, marundinlogun lati Imo, mọkanla lati ipinlẹ Rivers nigba ti eeyan mẹjọ ni ni Plateau.
Eeyan marun un lo lugbadi aarun naa lati Ogun nigba ti eeyan mẹrin-mẹrin ni aarun covid-19 lati Bayelsa ati Kwara.
Eeyan mẹta-mẹta lo nii lati Bauchi ati Edo ti eeyan meji si ko aarun naa ni Kano
Eeyan kan ṣoṣo layẹwo fihan pe o ni aarun naa ni ipinlẹ Ọṣun.
Esi ayẹwo coronavirus lati ipinlẹ mẹjọ ti ajọ NCDC fi sita ni Ọjọ Aje, ọjọ kọkandinlọgbọn, oṣu Kọkanla, fihan pe, eeyan marundlaadọjọ tun ti ni aarun naa ni Naijiria.
Lagos-49
FCT-34
Kaduna-34
Plateau-11
Oyo-7
Bayelsa-5
Taraba-4
Sokoto-1
Ẹgbẹrun mẹtadinlaadọrin o le ọtalelẹdẹgbẹta o din mẹta (67,557) eeyan lo ti ko aarun naa lorilẹede Naijiria lati igba ti wọn ti kẹẹfin ẹni akọkọ to laarun naa ni Naijiria ni oṣu keji ọdun 2020.
Ẹgbẹrun mẹtalelọgọta ati ọrinlelugba ati meji (63,282) lawọn ti ara wọn ti ya nigbati aarun naa si ti gbẹmi awọn ẹgbẹrun kan ati mejilelaadọjọ (1173) eeyan.
Èèyàn 82 tún ti ní COVID-19 ní Nàìjíríà lọ́jọ́ Ajé
Esi ayẹwo coronavirus lati ipinlẹ mọkanla ti ajọ NCDC fi sita ni ọjọ Aiku. ọjọ kọ̀kandinlọgbọn, oṣu Kọkanla, fihan pe, eeyan mejilelọgọrin tun ti ni aarun naa ni Naijiria.
Lagos-48
Rivers-8
Kwara-6
Yobe-6
Katsina-5
FCT-3
Nasarawa-2
Plateau-1
Ogun-1
Kano-1
Osun-1
Pẹlu bi nnkan ṣe ri yii, ẹgbẹrun mẹtadinlaadọrin o le irinwo ati mejila (67,412) eeyan lo ti ko aarun naa lorilẹede Naijiria lati igba ti wọn ti kẹẹfin ẹni akọkọ to laarun naa ni Naijiria ni oṣu keji ọdun 2020.
Ẹgbẹrun mẹtalelọgọta o le marundinlgọta (63,055) lawọn ti ara wọn ti ya nigbati aarun naa si ti gbẹmi awọn ẹgbẹrun kan ati mejilelaadọjọ (1173) eeyan.
Eeyan aadọfa lo tun kun iye awọn eeyan to laarun COVID-19 lorilẹede Naijiria bayii.
Gẹgẹ bi ajọ to n gbogun ti ajakalẹ arun lorilẹede Naijiria, NCDC ṣe fi sita, eeyan mẹrindinlọgbọn lo tun ko arun naa ni ipinlẹ Eko, mẹtalelogun fara kaasa rẹ ni olu ilu orilẹede yii, ogun eeyan lati ipinlẹ Kaduna ti mọkanla si wa lati ipinlẹ Katsina.
Ẹwẹ, ni ipinlẹ Ogun, eeyan meje lo tun ko aarun naa bayii, mẹfa lati ipinlẹ Ekiti, marun un lati ipinlẹ Plateau, mẹrin lati ipinlẹ Rivers, Kano ni mẹta, Nasarawa ni mẹta ti Niger si ni meji.
Pẹlu bi nnkan ṣe ri yii, ẹgbẹrun mẹtadinlaadọrin o le ọọdunrun ati ọgbọn (67,330) eeyan lo ti ko aarun naa lorilẹede Naijiria lati igba ti wọn ti kẹẹfin ẹni akọkọ to laarun naa ni Naijiria ni ibẹrẹ ọdun 2020. Ẹgbẹrun mejilelọgọta o le ẹgbẹrin ati mọkandinlogun (62,819) lawọn ti ara wọn ti ya nigbati aarun naa si ti gbẹmi awọn ẹgbẹrun kan ati mọkanlelaadọjọ (1171) eeyan.
Èèyàn 246 ló ní COVID-19 lọ́jọ́ Ẹti ní Nàìjíríà
Alekun eeyan ojilelugba ati mẹfa lo tun ko arun COVID-19 gẹgẹ bi ajọ to n gbogun ti ajakalẹ arun lorilẹede Naijiria, NCDC ṣe gbe e jade lọjọ Ẹti.
Gẹgẹ bi ohun ti ajọ naa fi sita loju opo ẹyẹnkọrin Twitter rẹ, ipinlẹ Eko lo lewaju pẹlu eeyan mọkanlelogoji ti olu ilu ilẹẹwa naa si gba tẹlẹ pẹlu eeyan mẹtalelaadọrin.
Ipinlẹ Plateau-39, Kaduna-25, Ogun-13, Bauchi-5, Rivers-4 Ekiti-2, Taraba-2 ati kano-2 pẹlu ko gbẹyin.
Nibayii iye awọn to ti lugbadi arun naa lorilẹede Naijiria ti le lẹgbẹrun mẹtadinlaadọrin.
Esi ayẹwo coronavirus lati ipinlẹ mejila ti ajọ NCDC fi sita ni Ọjọbọ. ọjọ krindinlọgbọn, oṣu Kọkanla, fihan pe, eeyan mọkandinlaadọsan tun ti ni aarun naa ni Naijiria.
Kaduna-74
FCT-42
Lagos-17
Kano-8
Ogun-6
Oyo-6
Rivers-6
Ekiti-3
Bauchi-3
Katsina-2
Delta-1
Ondo-1
Apapọ awọn to ti ni - 66,974
Awọn to ti ri iwosan - 62,585
Awọn to ti ku - 1,169
Èèyàn 198 ni Covid-19 ṣẹ̀ṣẹ̀ ràn ní Naijiria ní 25/11/2020
Eeyan igba din meji lo tun ti ni aarun Covid-19 ni Naijiria.
Eyi jẹyọ ninu esi ayẹwo ti ajọ NCDC gbe jade, lati ipinlẹ mejila, ati ilu Abuja.
Bi awọn esi ayẹwo naa ṣe lọ niyii:
FCT -53
Lagos-48
Ogun-40
Akwa Ibom-20
Bauchi-9
Plateau-8
Kaduna-5
Kano-4
Benue-3
Jigawa-3
Nasarawa-3
Edo-1
Kwara-1
Àjàkálẹ̀ Coronavirus ran èèyàn 168 ní Naijiria, ó pa ẹnì kan ní 24/11/2020
Ajọ NCDC tun ti kede esi ayẹwo eeyan mejidinlaadọsan. to tun ṣẹṣẹ ni coronavirus.
Ilu Abuja ni awọn to ni i pọ si, pẹlu eeyan mọkanlelọgọta, nigba ti eeyan ọgọta ni nipinlẹ Eko.
Awọn ipinlẹ to ku ni
Kaduna-27
Oyo-12
Rivers-6
Katsina-5
Ogun-3
Kwara-2
Edo-1
Kano-1
Apapọ awọn to ti ni jẹ 66,607, ti 62,311 si ti ri iwosan. Amọ, o ti ṣekupa eeyan 1,169.
Èèyàn 56 ni Covid-19 ṣẹ̀ṣẹ̀ ràn ní Naijiria ní 23/11/2020
Itankalẹ coronavirus ni Naijiria ja walẹ lọjọ Aje, pẹlu bi esi ayẹwo ṣe fihan pe eeyan mẹrindinlọgọta pere lo ṣẹṣẹ ràn.
Ṣugbọn o ṣeni laanu pe, eeyan kan kú.
Kaduna-18
FCT-17
Lagos-6
Plateau-5
Kano-3
Kwara-2
Yobe-2
Ekiti-1
Niger-1
Rivers-1
Apapọ awọn to ti ni jẹ 66,439, ti 62,241 si ti ri iwosan. Amọ, o ti ṣekupa eeyan 1,168.
Covid-19 tún ran èèyàn 56  ní Naijiria, ó ṣekú pa ẹni kan ní 22/11/2020
Eeyan marundinlaadọjọ ni esi ayẹwo fihan pe o tun ti ni aarun Covid-19 ni Naijiria.
Eyi jẹyọ ninu esi ti ajọ NCDC fi sita ni alẹ ọjọ Aiku.
Lagos-60
Katsina-37
Kaduna-35
FCT-6
Ogun-4
Edo-3
Kwara-3
Rivers-2
Kano-2
Jigawa-1
Oyo-1
Taraba-1
Èèyàn 246 tún kó Covid-19 ní Nàìjíríà ní 21/11/2020
Esi ayẹwo ti ajọ to n mojuto ajakalẹ aarun ni Naijiria, NCDC fi sita lọjọ Abamẹta fihan pe eeyan ojilerugba ati mẹfa, 246, eeyan lo ṣẹṣẹ ni Covid-19 ni Naijiria.
Lagos-66
Plateau-63
FCT-48
Kaduna-21
Bayelsa-19
Rivers-12
Niger-9
Ogun-4
Ekiti-2
Bauchi-1
Osun-1
Eyi tumọ si pe awọn to ti ni Covid-19 ni Naijiria ti pe 66,228, nigba ti eeyan 61,884, ti ri iwosan, awọn 1,166 si ti ku.
Ìpínlẹ̀ Eko, Ọyọ ló lékè nínú àwọn tó ṣẹ̀ṣẹ̀ lùgbàdì àrùn Coronavirus ní Naijiria
Apapọ awọn to ni arun Coronavirus ni Naijiria ti pe 65,457 bayii.
Esi ayẹwo naa waye lẹyin ti ajọ to n ṣamojuto ajakalẹ arun, NCDC, kede esi ayẹwo eeyan 152 to tun ṣẹṣẹ ni i.
Eko-61
Oyo-39
FCT-13
Yobe-10
Bauchi-6
Kaduna-5
Kano-4
Kwara-4
Plateau-4
Edo-2
Ogun-2
Rivers-2
Apapọ awọn to ni arun Coronavirus ni Naijiria ti pe 65,148 bayii.
Esi ayẹwo naa waye lẹyin ti ajọ to n ṣamojuto ajakalẹ arun, NCDC, kede esi ayẹwo eeyan 157 to tun ṣẹṣẹ ni i.
Bi awọn esi naa ṣe lọ niyii:
Eko-97
Oyo-37
Kaduna -9
Bayelsa-3
Edo-3
Ekiti-3
Ondo-2
Osun-2
Plateau-1
Apapọ awọn to ni coronavirus ni Naijiria ti pe 65,148 bayii.
Esi ayẹwo naa waye lẹyin ti ajọ to n ṣamojuto ajakalẹ arun, NCDC, kede esi ayẹwo eeyan 152 to tun ṣẹṣẹ ni i.
Bi awọn esi naa ṣe lọ niyii:
Eko-136
Kano-4
Niger-3
Ekiti-2
Kaduna-2
Ogun-2
Taraba-2
FCT-1
Apapọ awọn to ni coronavirus ni Naijiria ti pe 64,996 bayii.
Esi ayẹwo naa waye lẹyin ti ajọ to n ṣamojuto ajakalẹ arun, NCDC, kede esi ayẹwo eeyan 112 to tun ṣẹṣẹ ni i.
Bi awọn esi naa ṣe lọ niyii:
FCT-27
Oyo-27
Bayelsa-9
Rivers-9
Delta-7
Edo-5
Kaduna-5
Ogun-5
Anambra-3
Katsina-3
Ondo-3
Osun-3
Plateau-3
Niger-2
Kano-1
Itankalẹ Covid-19 ni Naijiria tun ṣe bi ẹni l'agbara si, pẹlu esi ayẹwo to fihan pe eeyan 212 tun ti ni, l'Ọjọbọ.
Esi naa ti ajọ NCDC fi sori ayelujara Twitter rẹ fihan pe
Lagos-71
Imo-26
Plateau-26
FCT-19
Ondo-17
Kaduna-14
Rivers-9
Oyo-9
Katsina-6
Osun-4
Bauchi-2
Ekiti-2-
Nasarawa-2
Ogun-2
Kano-1
Kwara-1
Taraba-1
Apapọ awọn to ni coronavirus ni Naijiria ti pe 64,515 bayii. eyi waye lẹyin ti ajọ to n ṣamojuto ajakalẹ arun, NCDC, kede esi ayẹwo ọgọsan eeyan to tun ṣẹṣẹ ni i.
Bi awọn esi naa ṣe lọ niyii:
Lagos-74
Oyo-41
FCT-19
Kaduna-19
Bauchi-12
Ogun-7
Rivers-4
Cross River-2
Edo-2
Esi ayẹwo ti ajọ to n mojuto ajakalẹ arun ni Naijiria, NCDC, fi sita lọjọ Iṣẹgun fihan pe eeyan mejilelaadọjọ lo tun ti ni coronavirus.
Ipinlẹ Eko lo wa ni ipo kinni pẹlu 93, FCT si wa ni ipo keji pẹlu 21.
Awọn ipinlẹ to ku ni:
Oyo-15
Rivers-11
Bauchi-7
Kwara-2
Bayelsa-1
Edo-1
Plateau-1
Bayii ni esi ayẹwo coronavirus ti ajọ NCDC gbe sita lọjọ Aje, ọjọ kẹsan-an, oṣu Kọkanla, ṣe lọ.
Lagos-50
FCT-24
Kwara-9
Edo-4
Kaduna-3
Ondo-2
Plateau-2
Apapọ awọn to ti ni ti pe 64,184, lara si ni 60,069 ti ri iwosan. Awọn 1,158 si ti ku.
Ajakalẹ aarun coronavirus tun ti gbera soke si ni orilẹ-ede Naijiria, pẹlu bo tun ṣe ran ọọdunrun (300) eeyan mii.
Ninu esi ayẹwo to fi sita lọjọ Aiku, ajọ NCDC sọ pe ipinlẹ Eko nikan ní eeyan 255 lara awọn to ni i bayii.
Awọn to ku ni:
FCT-27
Oyo-10
Kaduna-5
Ondo-2
Kano-1
Lati bi ọsẹ kan ni iye esi ti ajọ naa n gbe sita ti n lọ soke diẹdiẹ, eyi to n kọ awọn alaṣẹ eto ilera lomiinu pe o ṣe e ṣe ki aarun naa tun burẹkẹ si lẹẹkeji.
Wọn ni eyi ko ṣẹyin bi awọn eeyan ko ṣe tẹle ilana eto idaabobo mọ, ti onikaluluku si n ṣe nkan to wu u jakejado orilẹ-ede Naijiria.
Fun igba akọkọ  lati ọjọ pipẹ, ipinlẹ Eko ko si lori atẹ esi ayẹwo awọn eeyan to ṣẹṣẹ ni Covid-19 ni Naijiriai.
Eyi jẹyọ ninu esi ayẹwo ti ajọ to n mojuto ajakalẹ aarun ni Naijiria, NCDC. gbe jade ni ọjọ Abamẹta.
Esi lati ipinlẹ mẹjọ pere ni wọn fi sita, ko si si Eko lara wọn. Eeyan mọkandinlọgọta si lo ni i.
Kaduna-28
Rivers-9
Ogun-8
Ondo-8
Kano-2
Niger-2
Kwara-1
Plateau-1
Bi ọrọ Covid 19 se ri ni Naijiria lanaa ree:
Ipinlẹ Eko ni 85
FCT-35
Akwa Ibom-24
Enugu-18
Plateau-13
Rivers-10
Abia-7
Ebonyi-6
Anambra-5
Adamawa-4
Bauchi-3
Imo-3
Ogun-3
Oyo-3
Kwara-2
Osun-1
Taraba-1
Coronavirus kò pa ẹnìkankan lánàá Ọjọ́bọ̀ ní Nàìjíríà, àmọ́ èèyàn ọgọ́sàn án 180 míì ló ṣẹ̀ṣẹ̀ kóo
Ọgọsan ọmọ Naijiria lo tunko arun coronavirus l'Ọjọbọ gẹgẹ bi akọsilẹ ajọ NCDC to n gbogun ti ajakalẹ arun ni Naijiria loju opo Twitter rẹ.
Niṣe ni arun ọhun n fi ojoojumọ pọ si papaa julọ nipinlẹ Eko, eeyan mẹtadinlaadọrun lo lugbadi covid-19 lati ipinlẹ Eko nikan l'Ọjọbọ.
Ti ipinlẹ Oyo naa gberu sii nibi ti eeyan mọkanlelaadọta to ko arun naa.
Mẹwaa lo larun coronavirus lati Plateau, mẹrin l'Edo, eeyan mẹta lo larun naa nipinlẹ Ekiti ati Ogun.
Meji meji lo ko covid-19 l'Ọjọbọ ni Bauchi, Kaduna ati Niger nigba ti ẹni kọọkan lugbadi arun ọhun lati ipinlẹ Kano, Ondo, Osun ati ipinlẹ Rivers.
Eeyan 59,748 lo ti ri iwosan ninu awọn 63,508 ti ayẹwo fihan pe wọn larun coronavirus ni Naijiria.
Ko si ẹni to ku nipasẹ coronavirus l'Ọjọbọ ni Naijiria, eeyan 1,155 to ti ku naa si ni o wa loju Twitter ajọ NCDC.
Coronavirus gbẹ̀mí èèyàn mẹ́rin lánàá Ọjọ́rú ní Nàìjíríà, èèyàn márùndínlọ́gọ́jọ 155 míì tún kóo
Eeyan mẹrin ni coronavirus ṣekupa ni Naijiria l'Ọjọru nigbaa ti eeyan marunlelaadọjọ(155) mii tun lugbadi aarun ọhun lọjọ kẹrin oṣu kọkanla ọdun 2020 yii.
Marunlelọgọrin ninu wọn lo wa lati ipinlẹ Eko nikan nigba ti mẹtalelogun wa lati olu ilu Naijiria, Abuja.
Ẹni mejidinlogun lo ṣe kongẹ arun ọhun nipinlẹ Ondo, eeyan mẹjọ lo ni arun naa lati ipinlẹ Ogun.
Eeyan marun un marun un lo lugbadi covid-19 nipinlẹ Oyo, kaduna, ati Taraba l'Ọjọru ni Naijiria.
Mẹta lo karun coronavirus ni Kano, meji wa lati Rivers, eeyan kan lo larun naa lati Bauchi.
Eeyan 63,328 lo ti lugbadi coronavirus ni Naijiria bayii, ṣugbọn eeyan 59,675 lo ti ri iwosan.
Eeyan 1,155 ni covid-19 ti ṣekupa bayii ni Naijiria.
Èèyàn mẹ́tàdínlógóje 137 ló kó covid-19 lọ́jọ́ Ìṣẹ́gun ọgọ́ta wá láti ìpínlẹ̀ Eko
O dabi ẹni pe coronavirus tun ti n gbilẹ si diẹ diẹ lorilẹede Naijiria. Eeyan eeyan mẹtadinlogoje lo ko aarun naa lọjọ Iṣẹgun.
Ọgọta eeyan lati ipinlẹ Eko lo ni aarun naa eyi to pọju ninugbogbo ipinlẹ lọjọ Iṣẹgun.
Ipinlẹ Abia lo ṣe ipo keji nibi ti eeyan mọkanlelogun ti lugbadi aarun ọhun.
Eeyan mejidinlogun lo laarun naa lati Abuja, mẹtala lati Rivers, marun un lati ipinlẹ Kaduna nigba ti eeyan mẹrin wa lati Oyo.
Eeyan mẹta lo lugbadi aarun naa lati Edo nigba ti eeyan meji meji ni aarun covid-19 lati Delta, Imo, Kano ati ipinlẹ Ogun.
Ẹni kọọkan lo ko aarun coronavirus lọjọ Iṣẹgun lati Bauchi, Gombe, Nasarawa, Niger ati Osun.
O ti di eeyan 63,173 ti ayẹwo ti fihan pe wọn ni coronavirus lapapọ ni Naijiria bayii.
Eeyan 59,634 lo ti jajabọ lọwọ aarun coronavirus bayii.
Èèyàn mọ́kànléláádọta ló wá láti ìpínlẹ̀ Eko nínú èèyàn 72 tó kó ààrùn covid-19 lọ́jọ́ Ajé
Ipinlẹ Eko lawọn to lugbadi aarun coronavirus lọjọ Aje ọjọ kẹta oṣu kọkanla ọdun 2020 ninu awọn mejilelaadọrin ti ajọ NCDC kede.
Eeyan mọkanlelaadọta lawọn to ko aarun naa nipinlẹ Eko nikan.
Olu ilu orilẹede Naijiria, Abuja lo ṣe ipo keji pẹlu eeyan mẹfa, nigba ti ipinlẹ Ogun tẹ le e nibi ti eeyan mẹrin ti fara kaasa aarun naa.
Eeyan mẹta lati Kaduna, meji ni Niger, Ondo ati Plateau lo ni covid-19 lọjọ Aje.
Ẹnikọọkan lo ko aarun ọhun lati ipinlẹ Katsina ati ipinlẹ Oyo.
Lapaapọ eeyan 63,036 ni ayẹwo ti fihan pe wọn ti ko aarun corinavirus lorilẹede Naijiria.
Eeyan 1,147 si ni aarun coronavirus ti ṣekupa lorilẹede Naijiria bayii.
'Aràrá bíi tèmi, kó má rò pé kò sì ǹkan tó lè ṣe láyé ju iṣẹ́ agbe lọ'
Ẹni mọ́kànléláàdọ́fà 111 ló lùgbàdì àrùn covid-19 ní Nàìjíríà lọ́jọ́ Àìkú
Eeyan mọkanlelaadọfa lo ko aarun coronavirus kaakiri orilẹede Naijiria lanaa ọjọ Aiku tii ṣe ọjọ kinni oṣu kọkanla ọdun 2020 yii.
Ipinlẹ Eko ni mọkandinlaadọta ninu awọn eeyan ọhun ti wa.
Olu ilu orilẹede Naijiria, Abuja lo ṣe ipo keji pẹlu ọgbọn eeyan to ṣẹṣẹ fara kaasa aarun naa.
Eni mẹwaa lo ko covid-19 nipinlẹ Plateau lọjọ Aiku nigba ti eeyan mọkanla laarun naa lati ipinlẹ Rivers.
Eeyan merin lo ko aarun naa l'Ogun, mẹta ni Kaduna ati Oyo nigba ti ẹnikan lugbadi aarun naa nipinlẹ Osun.
Lapaapọ eeyan 62,964 ni ayẹwo ti fihan pe wọn ti ko aarun corinavirus lorilẹede Naijiria.
Èèyàn 162 ló kó àrùn Coronavirus ní Nàìjíríà lọ́jọ́ Àbámẹ́tà
Ènìyàn 162 lo tun ṣẹṣẹ lugbadi aarun Covid-19 ni Naijiria.
Gẹ́gẹ́ bi  àjọ tó n mójú tó ń àjàkálẹ̀ ààrùn ní Nàìjíríà (NCDC) se sọ lójú òpó twitter  rẹ̀ lọ́ja àbámẹ́tà. Ìpínlẹ̀  mẹ́rìnlá lo ni ààrun náà.
Lọwọlọwọ, apapọ awọn to ti ni aarun naa ti pe 62,853, eyan 58,675 ti ri iwosan, 1,144 si ti ku.
Gombe-54
FCT-35
Lagos-26
Ogun-12
Plateau-10
Rivers-10
Kaduna-4
Ekiti-3
Edo-2
Osun-2
Bayelsa-1
Imo-1
Ondo-1
Oyo-1
Èèyàn 118 ló kó àrùn Coronavirus ní Nàìjíríà lọ́jọ́ Ajé
Eniyan 118 lo tun ṣẹṣẹ lugbadi aarun Covid-19 ni Naijiria.
Gẹgẹ bi ajọ to n gbodun ti ajakalẹ aarun, NCDC, ṣe sọ ninu ikede to fi sita lalẹ ọjọ Aje, ipinlẹ mẹsan an, ati ilu Abuja ni awọn esi ayẹwo naa ti wa.
Lọwọlọwọ, apapọ awọn to ti ni aarun naa ti pe 61,558, eyan 56,697 ti ri iwosan, 1,125 si ti ku.
Bi apapọ wọn ipinlẹ to ṣẹṣẹ ni arun naa ṣe lọ ree:
Lagos-51
Rivers-26
Imo-12
Osun-8
Plateau-6
FCT-5
Kaduna-4
Ogun-3
Edo-2
Niger-1
Ajọ to n gbogun ti ajakalẹ aarun ni Naijiria, NCDC ti kede pe eeyan 133 miran ti kun iye awọn to ti ni aarun COVID-19 lorilẹ-ede yii.
Pẹlu iye awọn eeyan tuntun yii, o ti pe 61,440 eeyan ti arun ọhun ti kọlu ni Naijiria, awọn 1,125 ti dagbere faye, nigba ti awọn 56,611 ti moribọ.
Bi awọn to ṣẹṣẹ ni arun naa ṣe lọ ree:
Eko-90
Rivers-13
FCT-8
Kaduna-8
Oyo-6
Ondo-3
Katsina-2
Nasarawa-2
Plateau-1
Ajọ to n gbogun ti itankalẹ ajakalẹ arun aijiria,NCDC ti kede pe eeyan 4,161 t bọ lọwọ arun Coronavirus ni ipinlẹ Eko, wọn si ti pada sile wọn layọ ati alaafia, ṣugbọn awọn 113 tuntunmiran tun ni arun ọhun.
Ipinlẹ Eko ati Kaduna lo wa ni ipo kinni, ati ikeji, ninu esi ayẹwo ti ajọ NCDC fi lede nipa awọn to ṣẹṣẹ ni coronavirus.
Ninu esi ayẹwo tuntun naa, ipinlẹ Eko ni apapọ eeyan 37, Abuja ni 16 nigba ti ipinlẹ ogun n sare tete tẹle wọn lẹyin pẹlu eeyan mọkanla.
Awọn ipinlẹ to ku ni:
Plateau-11
Taraba-8
Rivers-7
FCT-6
Enugu-4
Niger-4
Edo-3
Delta-2
Imo-2
Benue-1
Kano-1
Eayan mejila le lugba lo lugbadi aarun coronavirus lorilẹede Naijiria lọjọ Ẹti, ọjọ kẹrindinlogunoṣu kẹwaa ọdun 2020 yii.
Ajọ to n gbogun ti itankalẹ ajakalẹ aarun ni Naijiria, NCDC lo kede rẹ loju opo Twitter rẹ.
Eeyan marundinlaadọrun un ninu wọn lo wa lati ipinlẹ Eko nikan, nigba ti mejilelaadọrin wa lati ipinlẹ Oyo.
Ipinlẹ Ogun leeyan mọkanla nibẹ, eeyan kan ṣoṣo lo wa lati ipinlẹ Oṣun.
Eeyan mọkanla lo kaarun naa lati ipinlẹ Plateau, mẹfa lati Katsina, marun un ni Kaduna nigba ti mọkanlelogun wa lati Abuja.
Lapapọ bayii, eeyan 61,194 lo tu laarun naa ni Naijiria, nigba ti 52,304 ti ri iwosan, eeyan 1,119 lo si ti ba aarun naa lọ.
Èèyàn 179 ló tún ṣẹ̀ṣẹ̀ ní àrùn Coronavirus ní Nàìjíríà
Ajọ to n gbogun ti ajakalẹ aarun lorilẹ-ede Naijiria, NCDC ti kede pe eeyan 179 miran ti darapọ mọ awọn to ti ni aarun COVID-19 ni Naijiria.
Amọ, ko si ẹni ti arun naa pa lọjọru.
Lagos-116
Anambra-20
FCT-9
Oyo-9
Rivers-9
Delta-3
Nasarawa-3
Edo-2
Kaduna-2
Ogun-2
Plateau-2
Ekiti-1
Osun-1
Pẹlu iye awọn eeyan tuntun yii, o ti pe 60,834 eeyan to ti ni arun naa l'orilẹede Naijiria bayii.
Apapọ iye eeyan to ti padanu ẹmi wọn lọwọ Covid-19 jẹ ẹgbẹerun kan le ni mẹrindinlọgọfa,1,116.
Eeyan kan lo padanu ẹmi rẹ lọwọ aarun Covid-19 lorileede Naijira lọjọ Isegun to kọja yi ninu ikede ti ajọ to n gbogun ti  ajakalẹ arun NCDC kede.
Ni bayi awọn eeyan tuntun to lugbadi aarun naa jẹ marundinlọgbọnlenigba,225.
Ipinlẹ Eko lo ṣi le tente pẹlu eeyan marundinlaadọsan,165 ti Abuja si tẹle pẹlu eeyan mẹtadinlogun,17.
Apapọ iye eeyan to ti padanu ẹmi wọn lọwọ Covid-19 jẹ ẹgbẹerun kan le ni mẹrindinlọgọfa,1,116.
Awọn eeyan ti aarun Covid-19 ti ran l'orilẹ-ede Naijiria ti pe ẹgbẹrun lọna ọgọta ati aarundinlọgtalelgbẹta (60,655) bayii.
Ipinlẹ Eko ati Abuja lo wa ni ipo kinni, ati ikeji, ninu esi ayẹwo ti ajọ NCDC gbe sita nipa awọn to ni coronavirus.
Ninu esi ayẹwo tuntun naa, ipinlẹ Eko ni apapọ eeyan 64, Abuja si ni 24.
Awọn ipinlẹ yooku ni :
Enugu-20
Kaduna-11
Oyo-11
Plateau-8
Ondo-7
Anambra-4
Nasarawa-3
Osun-3
Ebonyi-2
Imo-2
Benue-1
Katsina-1
Ogun-1
Ipinlẹ Eko ati Kaduna lo wa ni ipo kinni, ati ikeji, ninu esi ayẹwo ti ajọ NCDC gbe sita nipa awọn to ni coronavirus.
Ninu esi ayẹwo tuntun naa, ipinlẹ Eko ni apapọ eeyan 113, Kaduna si ni 21.
Awọn ipinlẹ yooku ni :
Osun-8
Ondo-5
Oyo-5
Ogun-3
Bayelsa-2
Taraba-2
Edo-1
FCT-1
Katsina-1
Plateau-1
Lọwọlọwọ, o ti pe 60,266 eeyan to ti ni arun naa ni Naijiria. Awọn 51,735 ti ri iwosan, 1,115 si ti ku.
Èèyàn 111 ní àrùn Coronavirus ràn ní Nàìjíríà ní 10/10/2020
Awọn eeyan ti aarun Covid-19 ti ran l'orilẹ-ede Naijiria ti pe ẹgbẹrun lọna ọgọta ati mẹtalelọgọrun (60,103) bayii.
Eyi ribẹ ẹ lẹyin ti eyan mọkanlelaadọfa, 111, ni ni ọjọ Satide, gẹgẹ bi esi ayẹwo ti ajọ to n gbogun ti ajakalẹ aarun, NCDC, ṣe fi ikede sita.
Eeyan 1,115 ni aarun naa ti sẹkupa ni Naijiria, nigba ti 51,711 ti ri iwosan.
Ajọ to n gbogun ti ajakalẹ aarun lorilẹ-ede Naijiria, NCDC ti kede pe eeyan 213 miran tuntun mi ti darapọ mọ awọn to ti ni aarun COVID-19 ni Naijiria ni ọjọ kẹẹdọgbọn, oṣu Kẹsan-an.
Pẹlu iye awọn eeyan tuntun yii, o ti pe 58,062 eeyan to ti ni arun naa l'orilẹede Naijiria bayii.
Iye awọn to ku lọwọ arun naa si ti di 1,103 ti  ara awọn 49,606 si  ti ya lẹyin itọju.
Ninu ikede ti wọn fi soju opoo wọn bakan naa Ajọ NCDC sọ pe awọn ṣeṣi kede pe eeyan kan ku ni Bayelsa lọjọ Kẹtalelogun oṣu Kẹsan.
Wọn ni ọrọ yi ko ri bẹ ati pe  iye apapọ iye awọn ti ara wọn ya  jẹ 364 ti wọn ba fi iye awn to gba itọju nile ni Katsina kun un.
Ajọ to n gbogun ti ajakalẹ aarun lorilẹ-ede Naijiria, NCDC ti kede pe eeyan 125 miran ti kun iye awọn to ti ni aarun COVID-19 ni Naijiria.
Pẹlu iye awọn eeyan tuntun yii, o ti pe  57, 849  eeyan to ti ni arun naa l'orilẹede Naijiria bayii.
Ajọ to n gbogun ti ajakalẹ aarun lorilẹ-ede Naijiria, NCDC ti kede pe eeyan 111 miran ti kun iye awọn to ti ni aarun COVID-19 ni Naijiria.
Pẹlu iye awọn eeyan tuntun yii, o ti pe 57, 724 eeyan to ti ni arun naa l'orilẹede Naijiria bayii.
Ajọ to n gbogun ti ajakalẹ aarun lorilẹ-ede Naijiria, NCDC ti kede pe eeyan 176 miran ti kun iye awọn to ti ni aarun COVID-19 ni Naijiria.
Pẹlu iye awọn eeyan tuntun yii, o ti pe 57, 613 eeyan to ti ni arun naa l'orilẹede Naijiria bayii.
Ajọ to n gbogun ti ajakalẹ aarun lorilẹ-ede Naijiria, NCDC ti kede pe eeyan 195 miran ti kun iye awọn to ti ni aarun COVID-19 ni Naijiria.
Pẹlu iye awọn eeyan tuntun yii, o ti pe 57, 437 eeyan to ti ni arun naa l'orilẹede Naijiria bayii.
Ajọ to n gbogun ti ajakalẹ aarun lorilẹ-ede Naijiria, NCDC ti kede pe eeyan 97 miran ti kun iye awọn to ti ni aarun COVID-19 ni Naijiria.
Pẹlu iye awọn eeyan tuntun yii, o ti pe 57,242 eeyan to ti ni arun naa l'orilẹede Naijiria bayii.
Ajọ to n gbogun ti ajakalẹ aarun lorilẹ-ede Naijiria, NCDC ti kede pe eeyan 189 miran ti kun iye awọn to ti ni aarun COVID-19 ni Naijiria.
Pẹlu iye awọn eeyan tuntun yii, o ti pe 57,145 eeyan to ti ni arun naa l'orilẹede Naijiria bayii.
Ajọ to n gbogun ti ajakalẹ aarun lorilẹ-ede Naijiria, NCDC ti kede pe eeyan 221 miran ti kun iye awọn to ti ni aarun COVID-19 ni Naijiria.
Pẹlu iye awọn eeyan tuntun yii, o ti pe 56,,956 eeyan to ti ni arun naa l'orilẹede Naijiria bayii.
Ninu esi ayẹwo ti ajọ naa fi sita lori Twitter, ipinlẹ mẹtadinlogun, ati ilu Abuja ni esi ayẹwo naa ti wa.
Eeyan 126 ló ní Covid-19 ní Nàìjíríà lọ́jọ́rú
Ajọ to n gbogun ti ajakalẹ aarun lorilẹ-ede Naijiria, NCDC ti kede pe eeyan 126 miran ti kun iye awọn to ti ni aarun COVID-19 ni Naijiria.
Pẹlu iye awọn eeyan tuntun yii, o ti pe 56,604 eeyan to ti ni arun naa l'orilẹede Naijiria bayii.
Eeyan 90 ló ní Covid-19 ní Nàìjíríà lọ́jọ́ Iṣẹ́gun
Awọn to ni aarun coronavirus ni Naijiria tun ti le si bayii, lẹyin ti ajọ NCDC kede esi aadọrun eeyan to tun ṣẹṣẹ ni, lọjọ Iṣẹgun.
Ninu esi ayẹwo ti ajọ naa fi sita lori Twitter, ipinlẹ Eko ni eeyan mẹtalelọgbọn.
Plateau-27
Kaduna-17
Ogun-6
FCT-4
Anambra-1
Ekiti-1
Nasarawa-1
Apapọ awọn to ti ni aarun naa jẹ 56,478
44,430 ti gba iwosan
Awọn to ti ku si jẹ 1,088
Awọn to ni aarun coronavirus ni Naijiria tun ti le si bayii, lẹyin ti ajọ NCDC tun kede esi eeyan mejilelaadoje to tun ṣẹṣẹ ni, lọjọ Aje.
Ipinlẹ Eko, Gombe ati Plateau, lo wa ni ipo kinni si ipo kẹta ninu esi tuntun naa.
Ko ti i ju ọjọ kan lọ ti ajọ naa kede eeyan mọkandinlọgọrin pere to ṣẹṣẹ ni aarun naa, eyi to ti i kere julọ lẹyin ọpọlọpọ oṣu.
Esi ayẹwo tuntun naa niyi:
Lagos-52
Gombe-27
Plateau-17
Kwara-10
Enugu-9
Ogun-9
Katsina-3
Ekiti-2
Bauchi-1
Osun-1
Rivers-1
O dabi ẹni pe itankalẹ aarun coronavirus ti n dinku lorilẹ-ede Naijiria bayii.
Eyi ko sẹyin esi ayẹwo ti ajọ to n mojuto itankalẹ ajakalẹ aarun ni Naijiria, NCDC, fi sita lọjọ Aiku, to safihan pe eeyan mọkandinlọgọrin pere lo ṣẹṣẹ ni.
Numba yii jina pupọ si iye ti wọn ti ma n kede tẹlẹ lati bi oṣu melo kan.
Esi ayẹwo tuntun naa lọ bayii:
Ni bayii, apapọ awọn to ti ni aarun naa ni Naijiria ti pe 56,256. Lara wọn ni eeyan 44,152 ti gba iwosan, ti awọn 1,082 si ti ku.
Eniyan 160 lo tun ṣẹṣẹ ni aarun Covid-19 ni orilẹ-ede Naijiria.
Gẹgẹ bi ajọ to n gbodun ti ajakalẹ aarun, NCDC, ṣe sọ ninu ikede to fi sita lalẹ ọjọ Satide, ipinlẹ mejila, ati ilu Abuja ni awọn esi ayẹwo naa ti wa.
Lọwọlọwọ, apapọ awọn to ti ni aarun naa ti pe 56,177. Eeyan 44,088 ti ri iwosan, 1078 si ti ku.
Eyi ni ibi ti nkan de duro ni ipinlẹ kọọkan fun:
Bí rere ni àbí búburú, wo ohun tí Covid-19 leè ṣe sí àgọ́ ara rẹ
Ajọ to n gbogun ti ajakalẹ arun lorilẹede Naijiria, NCDC ti kede pe eeyan 197 miran ti lugbadi arun Covid-19 ni Naijiria.
NCDC lo kede bẹẹ loju opo Twitter rẹ ni Ọjọ́bọ̀.
Amọ, awọn eniyan 200 lo ri iwosan gba lọwọ arun naa ni Ọjọ́bọ̀ ohun.
Nibayii, eeyan 1,075 lo ti ba ajakalẹ arun naa lọ ni Naijiria.
Eeyan 55,829 ni apapọ ni wọn ti fara ko aarun Coronavirus, ti awọn 43, 610 si ti ri iwosan gba lọwọ ajakalẹ arun ọhun.
Bi awọn ipinlẹ to ni Coronavirus ni Ọjọbọ ṣe lọ ree:
Plateau-83
Eko-48
Kaduna-17
FCT-16
Ogun-11
Katsina-7
Imo-4
Edo-3
Nasarawa-3
Rivers-2
Bayelsa-1
Oyo-1
Osun-1
Ajọ to n gbogun ti ajakalẹ arun lorilẹede Naijiria, NCDC ti kede pe eeyan 176 miran ti lugbadi arun Covid-19 ni Naijiria.
NCDC lo kede bẹẹ loju opo Twitter rẹ ni Ọjọ́ọ̀rú.
Amọ, awọn eniyan 276 lo ri iwosan gba lọwọ arun naa ni Ọjọ́ọ̀rú ohun.
Nibayii, eeyan 1,070 lo ti ba ajakalẹ arun naa lọ ni Naijiria.
Eeyan 55,632 ni apapọ ni wọn ti fara ko aarun Coronavirus, ti awọn 43, 610 si ti ri iwosan gba lọwọ ajakalẹ arun ọhun.
Bi awọn ipinlẹ to ni Coronavirus ni Ọjọ Iṣẹgun ṣe lọ ree:
FCT-40
Eko-34
Plateau-26
Enugu-14
Delta-12
Ogun-12
Ondo-9
Oyo-8
Ekiti-6
Ebonyi-4
Adamawa-2
Nasarawa-2
Kwara-2
Rivers-2
Edo-1
Osun-1
Bauchi-1
Ajọ to n gbogun ti ajakalẹ arun lorilẹede Naijiria, NCDC ti kede pe eeyan 296 miran ti lugbadi arun Covid-19 ni Naijiria.
NCDC lo kede bẹẹ loju opo Twitter rẹ ni Ọjọ Ìṣẹ́gun.
Amọ, awọn eniyan 103 lo ri iwosan gba lọwọ arun naa ni Ọjọ Iṣẹgun ohun.
Nibayii, eeyan 1,067 lo ti ba ajakalẹ arun naa lọ ni Naijiria.
Eeyan 55,456 ni apapọ ni wọn ti fara ko aarun Coronavirus, ti awọn 43, 334 si ti ri iwosan gba lọwọ ajakalẹ arun ọhun.
Bi awọn ipinlẹ to ni Coronavirus ni Ọjọ Iṣẹgun ṣe lọ ree:
Plateau-183
Eko-33
FCT-25
Ogun-16
Oyo-7
Ekiti-6
Kwara-5
Ondo-5
Anambra-3
Imo-3
Nasarawa-3
Rivers-2
Gombe-2
Edo-2
Akwa Ibom-1
Ajọ to n gbogun ti ajakalẹ arun lorilẹede Naijiria, NCDC ti kede pe eeyan 155 miran ti lugbadi arun Covid-19 ni Naijiria.
NCDC lo kede bẹẹ loju opo Twitter rẹ ni Ọjọ Aje.
Amọ, awọn eniyan 309 lo ri iwosan gba lọwọ arun naa ni Ọjọ Aje ohun.
Nibayii, eeyan 1,061 lo ti ba ajakalẹ arun naa lọ ni Naijiria.
Eeyan 55,160 ni apapọ ni wọn ti fara ko aarun Coronavirus, ti awọn 43,231 si ti ri iwosan gba lọwọ ajakalẹ arun ọhun.
Ondo-42
Plateau-25
Rivers-16
Ebonyi-10
Abia-9
Ogun-9
FCT-9
Osun-7
Katsina-6
Kaduna-6
Ekiti-4
Taraba-4
Edo-3
Anambra-2
Akwa Ibom-2
Kano-1
Ajọ to n gbogun ti ajakalẹ arun lorilẹede Naijiria, NCDC ti kede pe eeyan 100 miran ti lugbadi arun Covid-19 ni Naijiria.
NCDC lo kede bẹẹ loju opo Twitter rẹ ni Ọjọ Aiku.
Ipinlẹ Eko si ni iye eeyan to pọ ju to ṣẹṣẹ ni arun ọhun ti wa.
Nibayii, eeyan 1,057 lo ti ba ajakalẹ arun naa lọ ni Naijiria.
Eeyan 55,005 ni apapọ ni wọn ti fara ko aarun Coronavirus, ti awọn 42,922 si ti ri iwosan gba lọwọ ajakalẹ arun ọhun.
Bi awọn ipinlẹ to ni Coronavirus ni Ọjọ Abamẹta ṣe lọ ree:
Eko-39
FCT-22
Kaduna-19
Oyo-7
Ebonyi-6
Edo-3
Katsina-1
Ekiti-1
Bauchi-1
Nasarawa-1
NCDC lo kede bẹẹ loju opo Twitter rẹ loru ọjọ Abameta, ipinlẹ Eko si ni iye eeyan to pọ ju to ṣẹṣẹ ni arun ọhun ti wa.
Nibayii, eeyan 1,054 lo ti ba ajakalẹ arun naa lọ ni Naijiria.
Eeyan 54,905 ni apapọ ni wọn ti fara ko aarun Coronavirus, ti awọn 42,922 si ti ri iwosan gba lọwọ ajakalẹ arun ọhun.
Bi awọn ipinlẹ to ni Coronavirus ni Ọjọ Abamẹta ṣe lọ ree:
Eko-53
Gombe-21
Oyo-19
Delta-12
Ondo-11
Plateau-10
Ebonyi-9
FCT-6
Kwara-6
Kaduna-5
Rivers-3
Ogun-2
Anambra-2
Imo-2
Ekiti-1
Ajọ to n gbogun ti ajakalẹ arun lorilẹede Naijiria, NCDC ti kede pe eeyan 156 miran ti lugbadi arun Covid-19 ni Naijiria.
NCDC lo kede bẹẹ loju opo Twitter rẹ loru ọjọ Ẹti, ipinlẹ Eko si ni iye eeyan to pọ ju to ṣẹṣẹ ni arun ọhun ti wa.
Nibayii, eeyan 1,051 lo ti ba ajakalẹ arun naa lọ ni Naijiria.
Eeyan 54,743 ni apapọ ni arun naa ti fara kan labẹ ayẹwo, ti awọn 42,816 si ti ri iwosan gba lọwọ ajakalẹ arun ọhun.
Bi awọn ipinlẹ to ni Coronavirus ṣe lọ ree:
Eko-36
FCT-35
Oyo-29
Kaduna-10
Abia-9
Osun-5
Ogun-5
Enugu-5
Rivers-4
Nasarawa-3
Ekiti-3
Imo-3
Edo-2
Kwara-2
Katsina-2
Plateau-2
Niger-1
Ajọ to n gbogun ti ajakalẹ arun lorilẹede Naijiria, NCDC ti kede afikun eeyan marundinlaadoje 125 pẹlu arun COVID-19 lorilẹede Naijiria.
Lalẹ Ọjọbọ ni ajọ NCDC kede rẹ loju opo ayelujara Twitter rẹ @NCDCgov.
Ipinlẹ Eko pada sori oke tente tabili ojoojumọ awọn ipinlẹ tawọn eeyan ti ni coronavirus lorilẹede Naijiria lẹyin ti ipinlẹ Plateau ti n ṣiwaju awọn ipinlẹ tawọn eeyan ti n ko arun naa.
Pẹlu afikun tuntun yii, o jasi pe iye awọn ti ayẹwo ti fihan pe o ni aarun yii lorilẹede Naijiria ti di ẹgbẹrun mẹrinlelaadọta ati ẹgbẹta o din mejila, 54, 588.
Eko eeyan mejilelogoji (42), Ilu Abuja eeyan marundinlọgbọn (25), ipinlẹ Katsina eeyan mẹrinla (14), ipinlẹ Kaduna eeyan mọkanla (11), ipinlẹ Kwara eeyan mẹjọ (8), ipinlẹ Ondo eeyan meje (7), ipinlẹ Delta eeyan mẹrin (4), ipinlẹ Anambra eeyan mẹta (3), ipinlẹ Oyo eeyan mẹta (3) ti ipinlẹ Edo, Ogun ati ṣun si ni meji meji. Ipinlẹ Cross river lo kere ju pẹlu eeyan kan ni Ọjọbọ.
Ajọ to n gbogun ti ajakalẹ aarun lorilẹ-ede Naijiria, NCDC ti kede pe eeyan okoolelugba o din mẹrin miran ti kun iye awọn to ti ni aarun COVID-19 lorilẹ-ede Naijiria.
Pẹlu iye awọn eeyan tuntun yii, o ti le ni ẹgbẹrun mẹrinlelaadọta ati ojilelugba ati meje, 54,463 eeyan to ti larun naa lorilẹede Naijiria bayii.
Ipinlẹ Plateau lo tun lewaju iye awọn to laarun naa lọjọru pẹlu eeyan mọkandinlọgọta (59), ipinlẹ Rivers eeyan mẹtadinlọgbọn (27), ipinlẹ Abia eeyan mejilelogun (22), ipinlẹ Eko eeyan ogun (20), ipinlẹ Ọyọ, (18), ipinlẹ Enugu eeyan mẹtadinlogun (17), ipinlẹ Kaduna eeyan mọkanla (11), olu ilu ilẹẹwa Abuja eeyan mọkanla (11), ipinlẹ Ogun eeyan mẹwaa (10), ipinlẹ Ebonyi eeyan mẹrin (4) Ipinlẹ Ekiti mẹrin (4), ipinlẹ Ọṣun eeyan mẹrin (4), Delta eeyan mẹta (3), ipinlẹ Edo eeyan mẹta (3), ipinlẹ Akwa Ibom eeyan meji (2), ipinlẹ Bauchi eeyan kan ṣoṣo (1).
Ajọ to n gbogun ti ajakalẹ aarun lorilẹ-ede Naijiria, NCDC ti kede pe eeyan ojilelugba o din ẹyọ kan miran ti kun iye awọn to ti ni aarun COVID-19 lorilẹ-ede Naijiria.
Pẹlu iye awọn eeyan tuntun yii, o ti le ni ẹgbẹrun mẹrinlelaadọta ati ojilelugba ati meje, 54,247 eeyan to ti larun naa lorilẹede Naijiria bayii.
"Loju opo Twitter ajọ naa ni wọn ti kede eyii lalẹ ọjọ Iṣẹgun pe ""Ni ọjọ kinni. oṣu kẹsan an, ọdun 2020, eeyan eeyan ojilelugba o din ẹyọ kan lo tun ṣẹṣẹ ko aarun naa ti eeyan mẹwaa si jade laye lorilẹede Naijiria."""
Ipinlẹ Plateau lo tun lewaju iye awọn to laarun naa lọjọ Iṣẹgun pẹlu eeyan mẹrindinlọgọfa (116), olu ilu ilẹẹwa Abuja eeyan mẹtalelọgbọn (33), ipinlẹ Eko eeyan mọkandinlogun (19), Ipinlẹ Ekiti mejila (12), ipinlẹ Kaduna eeyan mọkanla (11), ipinlẹ Ogun eeyan mọkanla (11), ipinlẹ Ebonyi eeyan mẹjọ (8)  ipinlẹ Benue eeyan meje (7), ọkọọkan ipinlẹ Abia, ati Delta ni marun un (5), ipinlẹ Ondo mẹrin (4), ipinlẹ Edo eeyan mẹta (3), ipinlẹ Imo eeyan meji (2), ipinlẹ Ọṣun eeyan meji (2) Bauchi eeyan kan ṣoṣo (1).
Ajọ to n gbogun ti ajakalẹ aarun lorilẹ-ede Naijiria, NCDC ti kede eeyan mẹtalelogoje miran to kun iye awọn to ti ni aarun COVID-19 lorilẹ-ede Naijiria.
Pẹlu iye awọn eeyan tuntun yii, o ti le ni ẹgbẹrun mẹrinlelaadọta eeyan to ti larun naa lorilẹede Naijiria bayii.
"Loju opo Twitter ajọ naa ni wọn ti kede eyii lalẹ ọjọ Aje pe ""Ni ọjọ kọkanlelọgbọn oṣu kẹjọ ọdun 2020, eeyan mẹtalelogoje lo tun ṣẹṣẹ ko aarun naa ṣugbọn ko si akọsilẹ iku kankan lorilẹede Naijiria."""
Ipinlẹ Plateau lo tun lewaju iye awọn to laarun naa lojumọ lọjọ Aje pẹlu eeyan marundinlogoji (35), ipinlẹ Kaduna eeyan mọkanlelogun (21), ipinlẹ Eko eeyan mọkandinlogun (19) olu ilu ilẹẹwa Abuja eeyan mẹtala (13), Ebonyi eeyan mẹsan (9), ọkọọkan ipinlẹ Adamawa, Enugu ati Katsina ni meje (7), ipinlẹ Edo mẹfa (6), ipinlẹ Kwara marun un (5), ipinlẹ Osun mẹta (3), ọkọọkan ipinlẹ Anambra, Kano, Benue ni eeyan neji, ipinlẹ Benue, Borno ati Sokoto ni eeyan kọọkan (1).
Ajọ to n gbogun ti ajakalẹ aarun lorilẹ-ede Naijiria, NCDC ti kede eeyam mejidinlogoje miran to kun iye awọn to ti ni aarun COVID-19 lorilẹ-ede Naijiria.
Pẹlu iye awọn eeyan tuntun yii, o ti le ni ẹgbẹrun mẹtalelaadọta eeyan to ti larun naa lorilẹede Naijiria bayii.
Loju opo Twitter ajọ naa ni wọn ti kede eyii lalẹ ọjọ Aiku.
Bakan naa lo fi idi rẹ mulẹ pe eeyan meji miran tun ti jade laye nipasẹ aarun naa.
Pẹlu eyi iye awọn eeyan ti ajakalẹ aarun coronavirus ti ran jade laye ti di ẹgbẹrun kan o le mẹtala.
Ipinlẹ Plateau lo tun lewaju iye awọn to laarun naa lojumọ lọjọ Aiku.
Igba o le aadọta eeyan ni ajọ to n gbogun ti ajakalẹ aarun lorilẹede Naijiria, NCDC tun ti kede pe o ko aarun COVID-19 lọjọ Abamẹta.
Eleyi ti mu ki apapọ iye awọn to ti laarun naa lorilẹede Naijiria o di ẹgbẹrun mẹtalelaadọta ati okoolelẹẹdẹgbẹrin ati meje (53,727)
"Ajọ NCDC ṣalaye loju opo Twitter rẹ pe "" ni ọjọ kọkandinlọgbọn oṣu kẹjọ ọdun 2020, Igba o le aadọta eeyan lo tun kun iye awọn to ni aarun naa bẹẹni ko si ẹni to ku nipasẹ ajakalẹ aarun ọhun."""
Titi di bi a ṣe n sọrọ yii, ẹgbẹrun mọkanlelogoji eeyan o le ọọdunrun ati mẹrinla (41314) ni iye awọn to ti gba iwosan lọwọ aarun naa ti ẹgbẹrun kan o le mọkanla si ti jade laye.
Fun ọjọ kẹta ni ṣisẹ n tẹle, ipinlẹ Plateau lo tun gbegba oroke bayii laarin awọn ipinlẹ ti ọwọja aarun naa n pọ si lọwọlọwọ lorilẹede Naijiria.
Eeyan mọkandinlaadọrin ni wọn tun kede pẹlu aarun naa lọjọ Abamẹta.
Fun ọjọ keji lera bayii, ipinlẹ Plateau ni o n lewaju laarin awọn ipinlẹ ti COVID-19 ti n ṣọṣẹ julọ lorilẹede Naijiria lori onka olojoojumọ awọn to n ni aarun naa eleyii ti ajọ to n gbogun ti ajakalẹ arun lorilẹede Naijiria, NCDC fi sita.
Ninu atẹjade iye awọn to laarun naa, eyi ti ajọ NCDC fi sita lalẹ ọjọ Ẹti, ninu ọgọjọ eeyan to kun iye awọn to laarun coronavirus lorilẹede Naijiria lọjọ Ẹti, mẹrinlelogoji ninu wọn lo wa lati ipinlẹ Plateau.
Gẹgẹ bi atẹjade ọhun ṣe sọ, ipinlẹ Eko lo tẹle e pẹlu eeyan mẹtadinlọgbọn.
Bi atupalẹ awọn ipinlẹ yooku ti awọn eeyan to kun iye awọn to laarun COVID-19 ṣe lọ niyi:
Bi ẹ ko ba gbagbe, ni Ọjọbọ, marundinlaadọrun lawọn to ni aarun naa lati ipinlẹ Plateau.
Eyi to fihan pe l'Ọjọbọ ati Ẹti, ipinlẹ Plateau lo moke pẹlu iye awọn to laarun naa lorilẹede Naijiria.
Ènìyàn mẹ́rìndínlọ́ọ̀dúnrún ló tún lùgbàdì ààrùn Covid-19 lọ́jọ́bọ gẹ́gẹ́ bi atẹjade àjọ tó n gbogun ti ajakalẹ ààrun lórílẹ̀-èdè Naijiria ṣe sọ.
Iye ènìyàn to lùgbàdì ààrùn náà ni ọjọ́bọ yìí tún pọwọ́ lọ sókè díẹ̀ si ju ti ọjọ́rú àti ọjọ́iṣẹgun lọ.
Ẹ̀wẹ̀, o jọ bi ẹni pé ipińlẹ̀ Plateau ń burẹkẹ si ni nítori ojojúmọ́ ni àwọn ènìyàn to n lùgbàdì ààrùn náà ń pọ̀ si níbẹ̀ bi wọ́n  ṣe ti ni ènìyàn marun lélọ́gọ́rín lọ́jọ́bọ.
Ní báyìí ẹgbẹ̀rún mẹ́tàléláàdọ́ta àtí ọọdúnrún le díẹ̀ lo ti lugbadi ààrùn náà.
Ìpínlẹ̀ mẹ́tàdílógún ni àwọn ènìyàn to ṣẹ̀ṣẹ̀ lùgbàdì ààrùn náà ti jẹyọ ni àná
Plateau-85
Enugu-46
Oyo-31
Lagos-21
Rivers-20
FCT-15
Kaduna-13
Bauchi-12
Delta-11
Ekiti-11
Akwa Ibom-7
Ebonyi-6
Kwara-5
Ogun-4
Osun-4
Gombe-3
Niger-2
Ibi ti ìpińlẹ̀ kọ̀ọ̀kan de dúró ni Naijiria rèé
Ikéde àbájáde àyẹ̀wò àwọn tó ṣẹ̀ṣẹ̀ lùgbàdì ààrùn Covid-19 ni Nìàjíríà kò ju igba àti mọ́kànlélógún lọ lọ́jọ́rú.
Ó ti di ọjọ́ mẹ́rin lérawọ́n báyìí ti àbájade ìye ènìyàn to ni ààrùn Covid-19 ti ń já wálẹ̀ lójoojúmọ.
Ibèérè ti ọ̀pọ̀ ń bèèrè ni pé, ṣe à ti bori ààrùn náà ni tàbi kò sí àyẹwò bó ti tọ́ àti bóti yẹ mọ́?
Nínú àbájáde àyẹ̀wò tí ọjọ́rú, ìpínlẹ̀ Plateau náà lo tú wà lókè ténté pẹ̀lú ènìyàn ọgọ́ta, o fi mẹ́wàá pọ̀ ju ti àná lọ.
FCT lo tẹ̀lé pẹ̀lú mẹ́tàlélagbọ̀n, Kaduna náà pọ́wọ́ lèé pẹ̀lú mẹ́rìndinlógu, Rivers ní ènìyàn méjìdínlógún ti Ipinlẹ Eko sì wà ni ipò kaarún pẹ̀lú mẹ́tàdílógún.
Ó ti dí ènìyàn ẹgbẹ̀rúnlọ́nà mẹ́tàléláàdọ́ta àtí makàlelógún to ti lùgbàdì ààrùn náà ni Nàìjíríà
Ènìyàn mẹ́ta tún ti jẹ́ Ọlọ́run nípè, ó sì ti dí ẹgbẹ̀rún kan àti ènìyàn mẹ́wàá to ti bá ìṣẹ̀lẹ̀ náà rìn báyìí.
Plateau-60
FCT-33
Kaduna-26
Rivers-18
Lagos-17
Enugu-9
Kwara-9
Ondo-9
Nasarawa-6
Gombe-5
Anambra-5
Delta-4
Abia-4
Imo-3
Edo-2
Ogun-2
Oyo-2
Osun-2
Bauchi-1
Kano-1
NCDC ní ènìyàn 252 míràn ló tún fara kásá Covid-19 ní Nàìjíríà
Bí ọjọ́ ṣe n gorí ọjọ́ ló dàbí pe ọwọ́jà àjàkálẹ̀ ààrùn coronavirus  ń rọ́lẹ̀ síi ni orílẹ̀-èdè Náìjíríà.
Ènìyàn òjìlélúgbà àti méjìlá ni àwọn to tun ṣẹ̀ṣẹ̀ ní ààrùn náà báyìí.
Ṣùgbọ́n lọ́tẹ̀ yìí ìpò kẹrin ni ìpińlẹ̀ Eko to jẹ́ orírun ààrùn náà ni Nàìjíríà wà ní ipò kẹrin lonìí,  nígbà ti Ipinlẹ Plateau wà lókè ténté pẹ̀lú ààdọ́ta ènìyàn.
Àbájáde èsì ayẹwò to jáde lánáà kan ìpińlẹ̀ méjìdin lógun
Ènìyàn mẹ́ta lo tun bá ààrùn náà rin láná, eyí si ti mú iye ènìyàn tó ti kú wá si ẹgbẹ̀run kan àti méje.
Ní báyìí ẹgbẹ̀rún méjìléláàdọ́ta ó lé ẹgbẹ̀rin ló ti lùgbàdi ààrùn náà ni Naijiria, sùgbọ́n ènìyàn ẹgbẹ̀rún ọgọ́jì dín díẹ̀ ló ti ri ìwòsàn.
Plateau-50
Enugu-35
Rivers-27
Lagos-26
FCT-18
Kaduna-18
Ekiti-10
Kano-10
Taraba-9
Anambra-8
Edo-8
Oyo-8
Delta-7
Ogun-6
Abia-5
Bayelsa-5
Ebonyi-1
Osun-1
Iye ènìyàn to tún lùgbàdì ààrùn Coronavirus tun dín ẹyọkan si ti àná.
Nínú ìkéde ti àjọ tó ń gbógun ti àjàkálẹ̀ ààrùn lórílẹ̀-èdè Nàìjíríà (NCDC) fi síta lónìí, lójú òpó twitter rẹ̀ lo ti ṣe àtúpalẹ̀ àbájade àyèwò àwọn ìpínlẹ̀ kọ̀ọ̀kan ní Naijiria.
Ní ojú tó mọ́ lónìí ènìyàn ojìlélọ́ọ̀dúnrún àti ẹyọkan ló ṣẹ̀ṣẹ̀ lùgbàdi ààrùn Corornavirus ni Naijiria
Àpapọ̀ iye ènìyàn to ti ni ààrùn Covid-19 ni Nàìjíríà ti dí ènìyàn ẹgbẹ̀rún lọ́nà lààdọ́ta le méjì àti ẹ̀ẹ́dẹ́gbẹ̀tààbọ̀ dín méjì.
Ènìyàn méjì tún d'olóògbé lánàá, èyí si ti mú iye ènìyàn ti ààrùn Covid-19 ti ré sí òrun alákeji di ẹgbẹ̀run kan àti mẹ́rin.
Àtúpalẹ̀ ìpínlẹ̀ kọ̀ọ̀kan rèé gẹ́gẹ́ bi o ṣe lọ lánàá
Lagos-98
FCT-34
Bí Coronavirus ṣe n ṣe ni Afrika láti oṣù mẹ́fà sẹ́yìn
Kaduna-30
Nasarawa-25
Benue-21
Plateau-17
Rivers-15
Adamawa-11
Ogun-11
Enugu-9
Edo-8
Delta-7
Ekiti-7
Gombe-5
Ebonyi-4
Bayelsa-3
Kano-3
Ondo-3
Cross River-2
Imo-2
Kebbi-2
Niger-2
Abia-1
Bauchi-1
Ìpínlẹ̀ Eko náà ló si ń léwájú nínú awọn ìpínlẹ̀ to ni ààrùn Coronavirus
Yàtọ̀ sí ìròyìn tó gbòde ni àná ọjọ́ Àìkú lójú òpó Twitter àjọ tó ń gbógun ti àjàkálẹ̀ ààrùn lórílẹ̀-èdè Nàìjírà NCDC nípa bi iye ènìyàn to ni ààrun Covid-19 ṣe gbẹ́nu sókè, ọ̀tọ̀ ló rin nígbà ti iye ènìyàn ti ọjọ́ Àìkú jáde.
Àjọ NCDC kéde pé ènìyàn ojìlélọ́ọ̀dúnrún àti méjì ló ṣẹ̀ṣẹ̀ lùgbàdi ààrùn Corornavirus, èyí jẹ́ ìdajì iye ènìyàn ti wọ́n kédé lọ́jọ́ Satide.
Ní bayìí ènìyàn ẹgbẹ̀rún lọ́nà méjì lé lààdọ́ta àti ọ̀tàlénígba ó din mẹ́ta ló ti ni ààrùn náà lápapọ̀ lórílẹ̀-èdè Nàìjíríà, sùgbọ́n ènìyàn tó dín díẹ̀ lẹ́gbẹ̀rún mọ́kàndílógójì ló ti gba ìwòsàn ti wọ́n sì ti wà ni ilé wọ́n.
Ènìyàn méjìlélẹ́gbẹ̀rún ni ọwajà ààrùn náà ti le lọ sí ọ̀rún alákeji.
Lagos-130
Bauchi-36
FCT-25
Edo-17
Bayelsa-14
Ogun-14
Oyo-14
Anambra-13
Kaduna-12
Ondo-11
Abia-10
Osun-6
Plateau-5
Kwara-5
Kano-4
Ebonyi-3
Sokoto-2
Borno-1
Àjọ tó ń gbogun ti àjàkálẹ̀ ààrùn lórílẹ̀-èdè Nàìjíríà ti kéde pé ènìyàn mọ́kànlélẹ́gbẹ̀ta ènìyàn ló tún ṣẹ̀ṣẹ̀ lùgbàdì ààrùn Covid -19 ni Nàìjíríà, bí ènìyàn to tó lé ni ẹgbẹ̀rún lọ́nà ẹgbẹ̀rin ṣe ti kú lágbàyé báyìí.
NCDC kéde èyí lọ́jọ́ sátidé pé ìpínlẹ̀ Eko to jẹ́ orísun ààrun náà lo gbégba orókè jùlọ pẹ́lù irínwo ènìyàn, nígbà ti Abuja ṣe ipò keji pẹlú ènìyàn mẹ́tàdinlógójì.
Àwọn ìpińlẹ̀  to kù ni orílẹ̀-èdè Nàìjíríà jẹ́ Oyo to ni ènìyàn mọ́kandinlógún, Ondo ènìyàn mẹ́rìnlá, Abia, Enugu àti Kaduna ni ènìyàn mẹ́tàlá.
Jude Chukwuka: Wọ́n yóò fi ojú ọlọgbọ́n wo akúrí tó bá sọ ojúlówó èdè Yorùbá
Edo àti Kano ni méjìlá, Kwara ni mọ́kànlá, Ebonyi ní ènìyàn tuntun mẹ́wàá, Nasarawa, ni méje, Ogun ènìyàn mẹ́fà, Osun, Delta àti Niger ni èǹìyàn márùn.
Ìpínlẹ̀ to kù ni Pleatue àti Bayelsa pẹ̀lú ènìyàn mẹ́rin Kastina mẹ́ta, Ekiti àti Imo ni ènìyàn meji.
Ní orílẹ̀-èdè Nàìjíríà, NCDC fìdí rẹ̀ múlẹ̀ pé ènìyàn kan kú ni ọjọ́ sátide èyí sì ló jẹ́ kí o pé ènìyàn  mẹ́tàdínlẹ́gbẹ̀run kan tó  ti bá ààrùn Covid -19 rin ni Nàìjíríà.
Sùgbọ́n ní báyìí ènìyàn tó díẹ̀ ní ẹgbẹ̀rún mẹ́jiléláàdọ́ta ènìyàn lo ti ni ààrùn náà ní Nàìjíríà tí ènìyàn to dín díẹ̀ ni ẹgbẹ̀rún mọ́kàndínlógójì ló ti gbádun ti wọ́n sì ti pada si ilé wọ́n.
Lagos-404
FCT-37
Oyo-19
Ondo-14
Abia-13
Enugu-13
Kaduna-13
Edo-12
Kano-12
Kwara-11
Ebonyi-10
Nasarawa-7
Ogun-6
Osun-5
Delta-5
Niger-5
Plateau-4
Bayelsa-4
Katsina-3
Ekiti-2
Imo-2
Ajọ to n gbogun ti ajakalẹ arun lorilẹede Naijiria, NCDC ti kede pe eeyan ọọdunrun le ni ogoji miran ti lugbadi arun Covid-19 ni Naijiria.
NCDC lo kede bẹẹ loju opo Twitter rẹ loru ọjọ Ẹti, ipinlẹ Kaduna si ni iye eeyan to pọ ju to ṣẹṣẹ ni arun ọhun ti wa.
Ẹwẹ, awọn eeyan ọọdunrun le ni mẹrindinlogun miran lo ri iwosan ti wọn si ti ni ki wọn maa lọ ile wọn layọ ati alaafia.
Nibayii, eeyan 996 lo ti ba ajakalẹ arun naa lọ ni Naijiria.
Eeyan 51,304 ni apapọ ni arun naa ti fara kan labẹ ayẹwo, ti awọn 37,885 si ti ri iwosan gba lọwọ ajakalẹ arun ọhun.
Bi awọn ipinlẹ to ni Coronavirus ṣe lọ ree:
Kaduna-63
FCT-51
Plateau-38
Eko -33
Delta-25
Gombe-21
Adamawa-21
Edo-20
Katsina-17
Akwa Ibom-11
Ekiti-10
Rivers-9
Ondo-5
Ebonyi-4
Cross River-3
Ogun-3
Sokoto-2
Imo-2
Nasarawa-2
Ọọdunrun ati mọkandinlọgbọn eeyan ni ajọ NCDC tun kede pe o ti ni Covid-19 ni Naijiria.
Esi ayẹwo ti ajọ naa fi sita ni Ọjọbọ lati awọn ipinlẹ mọkanlelogun fihan pe:
Lagos-113
Kaduna-49
FCT-33
Plateau-24
Kano-16
Edo-15
Ogun-14
Delta-13
Osun-10
Oyo-8
Ekiti-6
Bayelsa-6
Akwa Ibom-5
Borno-4
Enugu-4
Ebonyi-3
Rivers-2
Bauchi-1
Nasarawa-1
Gombe-1
Niger-1
Ẹ wo apapọ iye ti ipinlẹ kọọkan ni:
Awọn to ni aarun Covid-19 ni Naijiria pe ẹgbẹrun mejidinlaadọta ati mẹrindinlọgọfa lọjọ kẹtala, oṣu Kẹjọ.
Eyi ri bẹ ẹ lẹyin ti ajọ to n gbogun ti ajakalẹ aarun, NCDC, tun kede ọọdunrun ati mẹtalelaadọrin to tun ṣẹṣẹ ni i.
Ṣugbọn o, ajọ naa ti sọ pe ibudo ayẹwo aarun naa ti pe mẹtalelọgọta jakejado Naijiria, ṣugbọn iṣoro kan to wa nibẹ ni pe awọn to n wa fun ayẹwo ko pọ to o.
Eeyan ọọdunrun le mẹrinlelọgbọn lo gba iwosan lọwọ arun Covid-19 l'Ọjọru, ọjọ kejila, oṣu Kẹjọ, nigba ti awọn irinwo le mẹtalelaadọta miran tun lugbadi rẹ ni Naijiria.
Ajọ to n gbogun ti ajakalẹ arun lorilẹ-ede Naijiria, NCDC lo fidi eyi mulẹ loju opo Twitter rẹ.
Nibayii, eeyan 956 lo ti ba ajakalẹ arun naa lọ ni Naijiria.
Eeyan 47,743 ni apapọ ni arun naa ti fara kan labẹ ayẹwo, ti awọn 33,943 si ti ri iwosan gba lọwọ ajakalẹ arun ọhun.
Bi awọn ipinlẹ to ni Coronavirus ṣe lọ ni yii:
Lagos-113
FCT-72
Plateau-59
Enugu-55
Kaduna-38
Ondo-32
Osun-26
Ebonyi-20
Ogun-9
Delta-8
Borno-7
Akwa Ibom-6
Oyo-5
Bauchi-1
Kano-1
Ekiti-1
Ajọ to n gbogun ti ajakalẹ arun lorilẹ-ede Naijiria, NCDC ti kede irinwo le mẹtalelogun eeyan to ṣẹṣẹ fara kaasa arun Covid-19 ni Naijiria.
Oru ọjọ Iṣẹgun ni ajọ naa kede bẹẹ loju opo Twitter rẹ.
Ajọ ọhun tun kede ọtalenigba le mẹta (263) eeyan to gbawosan, ti wọn si ti ni ki wọn maa lọ sile wọn layọ ati alaafia.
Awọn to ti dero ọrun nipasẹ ajakalẹ arun naa Naijiria ti di 956.
Eeyan 47,290 ni apapọ ni arun naa ti fara kan labẹ ayẹwo, nigba ti eeyan 33,609 lapapọ ti ri iwosan gba.
Bi awọn ipinlẹ to ni Coronavirus ṣe lọ ree:
Lagos-117
FCT-40
Ondo-35
Rivers-28
Osun-24
Benue-21
Abia-19
Ogun-19
Ebonyi-18
Delta-17
Kwara-17
Kaduna-15
Anambra-14
Ekiti-11
Kano-9
Imo-6
Gombe-4
Oyo-3
Taraba-3
Bauchi-1
Edo-1
Nasarawa-1
Bí Coronavirus ṣe n ṣe ni Afrika láti oṣù mẹ́fà sẹ́yìn
Ajọ to n gbogun ti ajakalẹ arun lorilẹ-ede Naijiria, NCDC ti kede eeyan mẹwaa din ni ọọdunrun lo ṣẹṣẹ lugbadi arun Covid-19 ni Naijiria.
NCDC lo kede bẹẹ loju opo Twitter rẹ loru ọjọ Aje, ipinlẹ Eko lo si wa loke tente awọn ipinlẹ ti arun naa tun kọlu lọtun, nigba ti Plateau n tẹle e lẹyin.
Ẹwẹ, ọgọjọ eeyan tuntun miran lo ri iwosan ti wọn si ti ni ki wọn maa lọ ile wọn.
Nibayii, eeyan 950 lo ti dero ọrun nitori ajakalẹ arun ọhun ni Naijiria.
Awọn 46,867 lo to ti fara kasa arun naa, ti awọn 33,346 si ti ri iwosan gba lọwọ ajakalẹ arun ọhun.
Bi awọn ipinlẹ to ni Coronavirus ṣe lọ ree:
Eko-82
Plateau-82
Oyo-19
FCT-18
Edo-16
Kaduna-15
Enugu-9
Ogun-9
Kano-8
Kwara-8
Cross River-5
Ondo-5
Rivers-5
Ekiti-4
Imo-3
Borno-2
Ajọ to n gbogun ti ajakalẹ arun lorilẹede Naijiria, NCDC ti kede pe eeyan irinwo le ni mẹtadinlogoji miran ti lugbadi arun Covid-19 ni Naijiria.
NCDC lo kede bẹẹ loju opo Twitter rẹ, ipinlẹ Eko si ni iye eeyan to pọ ju to ṣẹṣẹ ni arun ọhun ti wa.
Ẹwẹ, awọn eeyan mejilelogoje miran lo ti ri iwosan ti wọn si ti ni ki wọn maa lọ ile wọn layọ ati alaafia.
Nibayii, eeyan 945 lo ti ba ajakalẹ arun naa lọ ni Naijiria.
Eeyan 46,577 ni apapọ ni arun naa ti fara kan labẹ ayẹwo, ti awọn 33,186 si ti ri iwosan gba lọwọ ajakalẹ arun ọhun.
Bi awọn ipinlẹ to ni Coronavirus ṣe lọ ree:
Eko-107
FCT-91
Plateau-81
Kaduna-32
Ogun-30
Kwara-24
Ebonyi-19
Ekiti-17
Oyo-8
Borno-6
Edo-6
Kano-4
Nasarawa-3
Osun-3
Taraba-3
Gombe-2
Bauchi-1
Irinwo le meje eeyan lo gbowosan lọwọ arun Covid-19 lọjọ Abamẹta, nigba ti awọn irinwolelaadọta le mẹta miran tun lugbadi rẹ ni Naijiria.
Ajọ to n gbogun ti ajakalẹ arun lorilẹede Naijiria, NCDC lo fidi eyi mulẹ loju opo Twitter rẹ.
Nibayii, eeyan 942 lo ti ba ajakalẹ arun naa lọ ni Naijiria.
Eeyan 46,140 ni apapọ ni arun naa ti fara kan labẹ ayẹwo, ti awọn 33,044 si ti ri iwosan gba lọwọ ajakalẹ arun ọhun.
Bi awọn ipinlẹ to ni Coronavirus ṣe lọ ni yii:
FCT-75
Eko-71
Benue-53
Delta-39
Borno-30
Enugu-25
Plateau-24
Osun-20
Abia-19
Oyo-17
Kaduna-16
Kano-13
Ebonyi-13
Ogun-9
Kwara-7
Ondo-6
Gombe-3
Ekiti-2
Akwa Ibom-1
Rivers-1
Wọn ti kede eeyan mẹtadinlaadọfa to ṣẹṣẹ jajabọ lọwọ arun Covid-19, bẹẹ naa ni wọn tun kede eeyan 443 miran to ṣẹṣẹ  ni arun ọhun ni Naijiria bayii.
Ajọ to n gbogun ti ajakalẹ arun lorilẹede Naijiria, NCDC lo fidi eyi mulẹ loju opo Twitter rẹ.
Nibayii, eeyan 936 lo ti ṣe alaisi nipasẹ ajakalẹ arun naa ni Naijiria.
Eeyan 45,687 ni apapọ ni arun naa ti fara kan labẹ ayẹwo ti awọn 32,637 si ti ri iwosan gba lọwọ ajakalẹ arun ọhun.
Bi awọn ipinlẹ to ni Coronavirus ṣe lọ ni yii:
Plateau-103
Eko-70
FCT-60
Ondo-35
Edo-27
Rivers-27
Kaduna-20
Osun-19
Borno-18
Oyo-18
Kwara-11
Adamawa-9
Nasarawa-7
Gombe-6
Bayelsa-4
Imo-4
Bauchi-2
Ogun-2
Kano-1
Aarun naa ti tan kalẹ kọja gbogbo awọn ilu nla nla nilẹ Afirika to fi mọ awọn igberiko mii nibi to jẹ wipe awọn irinṣẹ eto ilera perete lo wa nibẹ ti itju alaisan si lee to jọ pupọ.
Ni ọjọbọ ọsẹ, iye awn to lugbadi arun Coronavirus ti rekoja Miliọnu kan ṣugbọn awọn akọṣẹmọṣẹ eleto ilera lagbaye tilẹ ni ootọ awọn to ko arun naa ju iye ti wọn n sọọ yii lọ fiifii tori aisi ọna ati ṣe ayẹwo eyi to wọpọ lawọn orilẹede.
Idaji awọn to lugbadi arun wọn yi wa lati ilẹ South Afrika. O fẹrẹẹ to eeyan ẹgbẹrun mọkanlelogun to ti ku bayii ti awọn aadọrinlelẹgbẹta si ti ti ri iwosan gba.
Ẹwẹ, ni Naijiria ajọ NCDC kede eeyan ọọdurun le mẹrinlelaadọta to ti fori ko ajakalẹ arun naa lọjọbọ.
Lọjọru ọsẹ, gẹgẹ bi ijade nile ati ipejọpọ ṣe ti n bẹrẹ pada lorilede Naijiria, bẹẹ naa ni itankalẹ arun Coronavirus bẹrẹ si ni fi sihin sọhun.
Ikede ajọ NCDC ni nkan bii aago mọkanla kọja lalẹ ọjọru fi han pe ilu ipinlẹ Eko ti gba ipo iwaju pada ti Abuja si to tẹle e lẹyin. Nibayii, ipinlẹ Jos, Plateau naa ti darapọ mọ awọn aṣaaju ninu lilugbadi Covid-19 pẹlu bo ṣe bọ si ipo kẹta lọjọru.
Ẹwẹ̀ lọjọ Iṣegun to jẹ pe lẹyin ọjọ mẹta lera ti iye awọn to ko Covid-19 ni Naijiria ṣẹṣẹ ja wa silẹ, o tun ti gbera sọ pada lọjọ Iṣẹgun.
Ajọ NCDC kede pe awọn to tọwọ arun naa dero ọrun lapapọ ni Naijiria lọjọ Aje ti di ẹẹwalelẹẹdẹgbẹrun.
Olu ilu Naijiria Abuja lo leke pẹlu iye awọn to ṣẹṣẹ lugbadi arun naa pẹlu eeyan 90.
Apapọ awọn to ko Covid-19 tuntun ni Naijiria si jẹ 304
Lapapọ awọn to ti ni Naijiria bayi jẹ 44,433
Awọn tara wọn ti ya lẹyin itọju si jẹ 31,851.
O ma tun ja wa silẹ ju ti tẹlẹ lọọ!
Bẹẹ ni. Iye awọn ti o ṣẹṣẹ lugbadi arun Coronavirus lorileede Naijiria ti dikun sii pẹlu bi ajọ to n mojuto ajakalẹ arun NCDC ṣe kede pe eeyan 288 pere lo ko arun naa lọjọ Aje.
Ikede yi jẹ igba ẹlẹkẹẹta laarin ọsẹ yii ti awọn to ko Coronavirus yoo dinku si tatẹyinwa.
Ni bayi, apapọ awọn to lugbadi arun naa lati igba to ti bẹrẹ ni Naijiria ti di 44,129.
Ni onka awọn to ti gba itọju tara wọn si ti ya, iye wọn ni Naijiria jẹ 20,663 bayi.
NCDC loju opo wọn sọ pe eeyan 896 lo ti baarun naa lọ.
Oyo Schools: Akẹ́kọ̀ọ́ Fásitì, Poly wà nílé, kí ló mú ti alákọ̀ọ́bẹ̀rẹ̀, girama wà níta?
Ikede adinku yi n waye lasiko igba ti ijọba ipinlẹ Eko naa n sọ pe iye awọn to gba itọju nile t'ara wọn si ti ya ti di 10,946 bayi.
Loju opo NCDC ni wọn ti ṣe alabapin iroyin yi eleyi ti wọn ni o wa lati ọwọ ijọba ipinlẹ Eko
O fẹ dabii pe iroyin ayọ ti n ṣẹlẹ lorilede Naijiria lẹnu ọjọ perete yii leyii ti iye awọn to n ko arun Coronavirus dinku si tatẹyinwa.
Koda awọn eekan to ti lugbadi arun naa ti boode lati sọ pe awọn ti bọ.
Lọjọ aiku, ọjọ keji oṣu kẹjọ dun 2020 gẹgẹ bi ajọ NDDC ṣe fi sita, eeyan mẹrinlelọọdunrun pere ni arun naa kora rẹ ran mọ leyi to ṣi kere si iye ti wọn ti n fi sita fun igba pipẹ.
Ọjọ aiku ni igba akọkọ lẹyin oṣu pupọ ti arun Covid-19 ti bẹrẹ si ni ja rain ni Naijiria ti adinku ba iye awọn eeyan tuntun to ṣẹṣẹ ko arun naa.
Lọjọ Ẹti si Abamẹta iye awọn tuntun to ni Covid-19  ja wa silẹ lati 462 si 386.
Yatọ si ilu Abuja to ni eeyan 130 tuntun awọn ipinlẹ bi Imo ati Adamawa ko ni ju eeyan kọọkan lọ.
Iroyin yi jẹ eleyi to dun mọ ọpọ ọmọ Naijiria ninu ti awọn miran si ti bẹrẹ si ni beere pe ṣe Naijiria ti re kọja ewu arun yi ni.
Loju opo ajọ to n gbogun ti ajakalẹ arun ni Naijiria NCDC, ikede yi han lori Twitter
Ni bayi awọn eeyan 43,537 ni arun naa ti fara kan lapapọ ni Naijiria
Awọn to ti ri iwosan gba ti ara wọn si ti ya ti to 20,087 ti awọn to ti ba arun naa lọ si jẹ 883.
Ikede ayipada ninu iye awọn to n ko arun yi ni Naijiria n waye lasiko ti awọn orileede mii ni Afirika bi South Afrika  n ga si.
Nilẹ toni to mọ, awọn to ti ko arun naa ni South Afirika ti kọja ẹgbẹrun lọna ẹẹdẹgbẹta.
Lọjọ Abamẹta Minisita feto ilera wọn kede pe eeyan 10,107 tuntun lo ko arun naa ti awọn to si ti gba tọwọ Covid-19 ku jẹ 8,153
Lọjọ ọdun Ileya,niṣe ni adinku ba iye awọn eeyan to lugbadi arun Covid 19 ni Naijiria.
Ninu ikede ti ajọ to n gbogun ti ajakalẹ́ arun lorileede Naijiria NCDC fi sita lalẹ ọjọ Ẹti, wọn ni eeyan 462 tuntun miran lo lugbadi arun naa.
Wọn fi ikede yi soju opo Twitter wọn.
Nibayi,awọn to ba arun naa lọ ni Naijiria ti wọ  879.
Eyan ti arun naa ti nawọ gan labẹ ayẹwo lapapọ ni Naijiria jẹ 43,151.
Onka awọn to to ti ri iwosan gba ti ara wọn ti ya lẹyin itọju bayi jẹ 19,565.
Bi awọn ipinlẹ to ni Coronavirus ti ṣe lọ ni :
FCT-93
Lagos-78
Plateau-64
Kaduna-54
Oyo-47
Ondo-32
Adamawa-23
Bauchi-19
Rivers-9
Ogun-9
Delta-9
Edo-7
Kano-6
Enugu-6
Nasarawa-5
Osun-1
Ajọ to n gbogun ti ajakalẹ arun lorilẹede Naijiria, NCDC lo fidi eyi mulẹ loju opo Twitter rẹ.
Nibayii, eeyan 878 lo ti ṣe alaisi nipasẹ ajakalẹ arun naa lorilẹede Naijiria.
Eeyan 42,681 ni apapọ ni arun naa ti fara kan labẹ ayẹwo lorilẹede Naijiria.
Ẹwẹ, eeyan 19,270  lo ti ri iwosan gba ti wọn si ti ja ajabọ lọwọ ajakalẹ arun naa.
Bi awọn ipinlẹ to ni Coronavirus ṣe lọ ni yii:
FCT-96
Eko-89
Plateau-68
Ogun-49
Edo-44
Rivers-43
Oyo-25
Osun-23
Delta-15
Enugu-11
Kano-7
Kaduna-7
Bauchi-2
Bayelsa-1
Yobe-1
Eeyan 404 ni wọn  kede pe ayẹwo tun fihan pe o laarun COVID-19 lorilẹede Naijiria bayii.
Ajọ to n gbogun ti ajakalẹ arun lorilẹede Naijiria, NCDC lo fidi eyi mulẹ loju opo Twitter rẹ.
Nibayii, eeyan 873 lo ti ṣe alaisi nipasẹ ajakalẹ arun naa lorilẹede Naijiria.
Eeyan 42,208 ni apapọ ni arun naa ti fara kan labẹ ayẹwo lorilẹede Naijiria.
Ẹwẹ, eeyan 18,203  lo ti ri iwosan gba ti wọn si ti ja ajabọ lọwọ ajakalẹ arun naa.
Bi awọn ipinlẹ to ni Coronavirus ṣe lọ ni yii:
Eko-106
FCT-54
Rivers-48
Plateau-40
Edo-29
Enugu-21
Oyo-20
Kano-18
Ondo-15
Ogun-10
Ebonyi-9
Ekiti-8
Kaduna-6
Cross River-5
Kwara-4
Anambra-3
Delta-3
Imo-2
Nasarawa-2
Borno-1
Eeyan 624 ni wọn  kede pe ayẹwo tun fihan pe o laarun COVID-19 lorilẹede Naijiria bayii.
Ajọ to n gbogun ti ajakalẹ arun lorilẹede Naijiria, NCDC lo fidi eyi mulẹ loju opo Twitter rẹ.
Nibayii eeyan 868 lo ti ṣe alaisi nipasẹ ajakalẹ arun naa lorilẹede Naijiria.
Eeyan 41,804 ni apapọ ni arun naa ti fara kan labẹ ayẹwo lorilẹede Naijiria.
Ẹwẹ, eeyan 18,203  lo ti ri iwosan gba ti wọn si ti ja ajabọ lọwọ ajakalẹ arun naa.
Bi awọn ipinlẹ to ni Coronavirus ṣe lọ ni yii:
Eko-212
Oyo-69
Niger-49
Kano-37
Osun-37
FCT-35
Plateau-34
Gombe-33
Edo-28
Enugu-28
Ebonyi-17
Delta-10
Katsina-9
Ogun-8
Rivers-7
Ondo-5
Kaduna-4
Nasarawa-2
Eeyan 648 ni wọn  kede pe ayẹwo tun fihan pe o laarun COVID-19 lorilẹede Naijiria bayii.
Ajọ to n gbogun ti ajakalẹ arun lorilẹede Naijiria, NCDC lo fidi eyi mulẹ loju opo Twitter rẹ.
Nibayii eeyan 860 lo ti ṣe alaisi nipasẹ ajakalẹ arun naa lorilẹede Naijiria.
Eeyan 41,180 ni apapọ ni arun naa ti fara kan labẹ ayẹwo lorilẹede Naijiria.
Ẹwẹ, eeyan 18,203  lo ti ri iwosan gba ti wọn si ti ja ajabọ lọwọ ajakalẹ arun naa.
Bi awọn ipinlẹ to ni Coronavirus ṣe lọ ni yii:
Eko -180
Plateau-148
FCT- 44
Ondo- 42
Kwara-38
Rivers-32
Oyo-29
Kaduna-21
Osun-20
Edo-17
Ogun-17
Ekiti-11
Kano-9
Benue-9
Delta-9
Abia-9
Niger-7
Gombe-3
Borno-1
Bauchi-1
Imo-1
Eeyan 555 ni wọn tun kede pe ayẹwo tun ti fihan pe o laarun COVID-19 lorilẹede Naijiria bayii.
Ajọ to n gbogun ti ajakalẹ arun lorilẹede Naijiria, NCDC lo fidi eyi mulẹ loju opo Twitter rẹ.
Nibayii eeyan 858 lo ti ṣe alaisi nipasẹ ajakalẹ arun naa lorilẹede Naijiria.
Eeyan 40,532 ni apapọ ni arun naa ti fara kan labẹ ayẹwo lorilẹede Naijiria.
Ẹwẹ, eeyan 17,374 lo ti ri iwosan gba ti wọn si ti ja ajabọ lọwọ ajakalẹ arun naa.
Bi awọn ipinlẹ to ni Coronavirus ṣe lọ ni yii:
Eko-156
Kano-65
Ogun-57
Plateau-54
Oyo-53
Benue-43
FCT-30
Ondo-18
Kaduna-16
Akwa Ibom-13
Gombe-13
Rivers-12
Ekiti-9
Osun-8
Cross River-3
Borno-2
Edo-2
Bayelsa-1
Oríṣun àwòrán, Twitter/NCDC
Eeyan 438 ni wọn tun kede pe ayẹwo tun ti fihan pe o laarun COVID-19 lorilẹede Naijiria bayii.
Ajọ to n gbogun ti ajakalẹ arun lorilẹede Naijiria, NCDC lo fidi eyi mulẹ loju opo Twitter rẹ.
Nibayii eeyan 856 lo ti ṣe alaisi nipasẹ ajakalẹ arun naa lorilẹede Naijiria.
Eeyan 39,977 ni apapọ ni arun naa ti fara kan labẹ ayẹwo lorilẹede Naijiria.
Ẹwẹ, eeyan 16,948 lo ti ri iwosan gba ti wọn si ti ja ajabọ lọwọ ajakalẹ arun naa.
Bi awọn ipinlẹ to ni Coronavirus ṣe lọ ni yii:
Eko-123
Kaduna-50
Rivers-40
Edo-37
Adamawa-25
Oyo-20
Nasarawa-16
Osun-15
Enugu-15
FCT-14
Ekiti-13
Ondo-13
Ebonyi-11
Katsina-10
Abia-9
Delta-8
Kwara-4
Ogun-3
Cross River-3
Kano-3
Bauchi-3
Yobe-2
Sokoto-1
Niger-1
Eeyan 591 ni wọn tun kede pe ayẹwo tun ti fihan pe o laarun COVID-19 lorilẹede Naijiria bayii.
Ajọ to n gbogun ti ajakalẹ arun lorilẹede Naijiria, NCDC lo fidi eyi mulẹ loju opo Twitter rẹ.
Nibayii eeyan 845 lo ti ṣe alaisi nipasẹ ajakalẹ arun naa lorilẹede Naijiria.
Eeyan 39,539 ni apapọ ni arun naa ti fara kan labẹ ayẹwo lorilẹede Naijiria.
Ẹwẹ, eeyan 16,559 lo ti ri iwosan gba ti wọn si ti ja ajabọ lọwọ ajakalẹ arun naa.
Eeyan mẹrinlelẹgbẹta ni wọn tun kede pe ayẹwo tun ti fihan pe o laarun COVID-19 lorilẹede Naijiria bayii.
Ajọ to n gbogun ti ajakalẹ arun lorilẹede Naijiria, NCDC lo fidi eyi mulẹ loju opo Twitter rẹ.
Ajọ NCDC ni ipinlẹ ogun ni wọn ti ri awọn alekun awọn to laarun naa.
Bakan naa lo fi kun un pe eeyan ogun ni aarun naa tun ti pa.
Mibayii iye awọn to ti jalaisi nipasẹ ajakalẹ arun naa lorilẹede Naijiria ti di ẹgbẹrin ati mẹtalelọgbọn.
Apapọ iye awọn ti arun naa ti fara kan labẹ ayẹwo lorilẹede Naijiria ti din diẹ ni ẹgbẹrun mọkandinlogoji.
Ẹwẹ, ẹgbẹrun mẹrindinlogun ati mọkanlelọgọta lawọn eeyan to ti ri iwosan gba ti wọn si ti ja ajabọ lọwọ ajakalẹ arun naa.
Apapọ iye awọn to laarun coronavirus lorilẹede Naijiria bayii ti di ẹgbẹrun mejidinlogoji ati ojilelọọdunrun o le mẹrin, 38,344 lẹyin ti eeyan ojilelẹẹdẹgbẹta ati mẹta, 543 kun wọn l'Ọjọru
Ajs to n gbogun ti ajakalẹ arun lorilẹede Naijiria, NCDC lo kede eyi loju opo twitter rẹ.
Bi atupalẹ afikun awọn to kun iye arun coronavirus ni Naijiria se lọ niyi
Eko-Ọgọsan, Abuja_mẹrindinlaadọrun, Kaduna mẹrindinlọgọta, Ondo-mẹtadinlogoji- Kwara- marundinlogoji, Ogun-19, Rivers-19, Kano-17, Ebonyi-16, Enugu-16, Delta-7, Bayelsa-4, Bauchi-3, Abia- 1
Eeyan Ọrinlelẹẹdẹgbẹta o din mẹrin ni ajọ to n gbogun ti ajakalẹ arun lorilẹede Naijiria, NCDC tun kede ni alẹ ọjọ Iṣẹgun, ọjọ kọkanlelogun oṣu keje pe ayẹwo tun fihan pẹlu arun coronavirus.
Ipinlẹ mọkanlelogun ni awọn eeyan naa ti jẹyọ.
Bakan naa ni ajọ NCDC tun fi kun un pe eeyan mẹrin miran ti padanu ẹmi wọn nipasẹ awọn aisan to peleke tori arun yii lagọ ara wọn.
Nibayii, apapọ iye awọn ti ayẹwo ti fihan pe o laarun naa ni Naijiria bayii ti di ẹgbẹrun mẹtadinlogoji ati mọkanlelẹgbẹrin, 37, 801.
Olu ilu orilẹ-ede Naijiria, Abuja lo lewaju lori atẹ awọn ti ayẹwo fihan gẹgẹ bi ara awọn to kun iye  arun coronavirus lọjọ Aje.
Ipinlẹ Eko lo tẹlee pẹlu ọgọrun eeyan ti ipinlẹ Plateau si ni mejilelaadọta.
Lapapọ eeyan ọtalelẹẹdẹgbẹta ati meji ni ajọ NCDC tun kede pe o kun iye awọn ti ayẹwo ti fihan pe o ni arun coronavirus lorilẹede Naijiria lọjọ Aje, ogunjọ oṣu keje, ọdun 2020.
Pẹlu bo ṣe ri yii, ẹgbẹrun mẹtadinlogoji o le igba ati marundinlọgbọn, 37,227.
Ẹgbẹrun marundinlogun o le ọọdunrun ati mẹtalelọgbọn lo ti ri iwosan, ṣugbọn ẹgbẹrin o le ẹyọkan ẹmi lo ti baa rin.
Eeyan ọtalelẹẹdẹgbẹta o din mẹrin lo tun kun iye awọn to ni aarun coronavirus lorilẹ-ede Naijiria.
Ajọ to n gbogun ti ajakalẹ arun lorilẹ-ede Naijiria, NCDC lo fi eyi sita loju opo Twitter rẹ.
Ajọ NCDC tun ṣalaye pe o ti le ni ẹgbẹrun marundinlogun eeyan to ti ri iwosan lọwọ arun ọhun lorilẹ-ede Naijiria lọwọ bi a ṣe n sọrọ yii.
Bakan naa lo fi kun un pe ọrinlelẹẹdẹgbẹrin o le mẹsan lawọn eeyan to ti jade laye nipasẹ arun yii lorilẹ-ede Naijiria.
Ajọ NCDC tun kede pe awọn ti ayẹwo tun ti fihan pe o ti larun naa ni ọjọ Aiku ni ipinlẹ si ipinlẹ niwọnyii.
Ondo APC Primary: Mo ti bẹ̀rẹ̀ sí ń bá àwọn akẹgbé mi nínú ẹgbẹ́ sọ̀rọ̀ kí àláàfíà léè jọba - Akeredolu
Oríṣun àwòrán, Rotimi Akeredolu Aketi
Gomina ipinlẹ Ondo, Rotimi Akeredolu ti sọ pe oun ti bẹrẹ igbesẹ alaafia laarin rẹ atawọn akẹgbẹ rẹ ninu ẹgbẹ oṣelu APC ni ipinlẹ naa.
Akeredolu lo fi ọrọ naa lede ninu ifọrọwerọ kan pẹlu BBC Yoruba.
"O ni ""Adupẹ fun aṣeyọri ti a ri ninu idibo abẹlẹ ti a ṣe kọja, ṣugbọn oun to wa niwaju wa ṣi ju iṣẹgun ti a ti ni sẹyin lọ."""
Gomina ọhun ṣalaye pe ifọwọsowọpọ nikan lo lee mu itẹsiwaju ba ẹgbẹ oṣelu APC ati ipinlẹ Ondo, nitori naa ni o ṣe gbe igbesẹ ọhun, ki alaafia lee jọba.
Ni bayii, Akeredolu ti lọ ṣabẹwo si awọn ti wọn jọ dije ninu idibo abẹle naa, lara awọn ni Olusola Oke, Salo Iji ati D.I Kekemeke.
Oríṣun àwòrán, Rotimi Akeredolu Aketi
Akeredolu lo jawe olubori ninu abẹle to waye ninu ẹgbẹ oṣelu APC lati yan oludije sipo gomina ninu idibo ti yoo waye loṣu kẹwaa ọdun 2020.
Oríṣun àwòrán, Rotimi Akeredolu Aketi
Ṣaaju idibo abẹle naa ni oriṣiriṣi nnkan ti n ṣelẹ ninu iṣejọba Akeredolu, akọkọ ni pe igabkeji rẹ, Agboola Ajayi fi ẹgbẹ APC silẹ, to si lọ darapọ mọ ẹgbẹ oṣelu PDP.
Ko pẹ si asikọ ọhun ni akọwe ojọba rẹ, Ifedayo Abegunde naa kọ ẹyin si Akeredolu.
Oríṣun àwòrán, others
Olusola Oke ní ìfẹnukò àwọn alátìlẹ́yìn òun ni yóò sọ ìgbésẹ̀ tó kàn lẹ́yìn ìdìbò abẹ́nú APC l'Ondo
Lootọ lawọn aidọgba pọ nipa eto idibo abẹle APC to waye lana nipinlẹ Ondo, ṣugbọn n o tii le sọ igbesẹ to kan fun mi bayii- Olusola Oke.
Amofin Oluṣọla Oke to jẹ ọkan lara awọn oludije nibi idibo naa lo sọ eyi fun BBC News Yoruba.
O ni oun yoo ṣepade pẹlawọn alatilẹyin ohun lati mọ ibi ti awọn yoo gbe ka.
Amofin Oke ni ṣaaju eto idibo naa loun ti pariwo sita pe o ni kudiẹkudiẹ ninu eleyi ti ẹnikẹni ko fi lee tọka si ọrọ oun gẹgẹ bii ẹni to n ṣawawi nigba ti oun fidirẹmi.
Ṣé lootọ ni àwọn Agba ẹgbẹ ṣe atilẹyin fún oludije kan?
Lori boya awọn agbaagba ẹgbẹ naa ṣe atilẹyin fun ọkan ninu awọn oludije naa, amofin Oke sọrọ ni kikun.
O ṣalaye wi pe ni ti oun o, ko si ifarahan awọn agbaagba ẹgbẹ kọkan ni ilu Akurẹ lọjọ ti idibo naa waye.
Awọn aṣoju ẹgbẹ ni ipinlẹ Ondo lo dibo yan ẹni to wọle, nitori naa gẹgẹ bi ọmọ ẹgbẹ oṣelu APC tootọ, ko si idi fun oun lati sọ pe bẹẹni tabi bẹẹkọ lọwọ yii.
Gomina Akeredolu ni wọn kede gẹgẹ bii olubori ibo abẹnu lati mọ ẹni ti yii gbe aṣia ẹgbẹ oṣelu APC ni idibo gomina ipinlẹ Ondo to n bọ lọna ti amofin Oluṣọla Oke si gbe ipo keji.
Olofa ina: ẹ parí òwe yìí pé ìgbà tí ara bá tu ìgbẹ́ láà ri eṣú....
Èsi idibo lati yan ẹni ti yoo dije du ipo gomina fun ipinlẹ Ondo labẹ ẹgbẹ oṣelu APC ti jade. Aketi lo gebgba oroke ju.
Lẹyin gbogbo sinima orita awoo wo tan to ti ṣẹlẹ sẹyin ni ipinlẹ Ondo, Gomina Rotimi Akeredolu to ti tukọ ipinlẹ naa lọdun mẹrin sẹyin ni o tun ri tikẹẹti gba lẹẹkan sii Mo káàbámọ̀ pé mo yan Ajayi gẹ́gẹ́ bíi igbákejì mi- Akeredolu .
Oríṣun àwòrán, others
Bayii ni esi idibo naa ṣe lọ:
Ibrahim Olusegun Michael PHD........ 0Adelami Olayide Owolabi MNI.......4Adetula olubukola Olarogba Okunola.....0Adejutelegan Nathaniel Olumuyiwa DR......4Akeredolu Oluwarotimi Odunayo SAN..........2458Anifowoshe Olajumoke Olubusola......2Awodeyi Akinsheyinwa Akinola Colinus......1Iji Olusola  Joseph...... 9Kekemeke Duerimini Issac.....19Odimayo Okunjimi John......0Oke Olusola Alex SAN......262Oyedele Ifeoluwa Olusola.....1
Bawo ni Idibo APC Ondo ṣe lọ?
Ètò ìdìbò abẹ́lé sípò gómìnà APC ni ipinlẹ Ondo ti bẹ̀rẹ̀ ní pẹrẹwu
Eto idibo abẹle lati mọ ẹni ti yoo gbe apoti ibo sipo gomina ninu ẹgbẹ oṣelu APC ni ipinlẹ Ondo bẹrẹ ni pẹrẹwu.
Bi wọn ṣe n yẹ kaadi idibo awọn olukopa ninu idibo abẹle ọhun wo naa ni wọn n dibo lẹsẹkẹsẹ.
O kere tan, ẹgbẹrun mẹta awọn ọmọ ẹgbẹ oṣelu APC lati ẹkun idibo mẹtalenigba kaakiri ipinlẹ Ondo lop n kopa ninu idibo abẹle naa lati yan ẹni ti yoo gbe apoti ibo sipo gomina ni ipinlẹ Ondo.
Ṣaaju ni mẹta lara awọn to n ba gomina Rotimi Akeredolu dije ti kọkọ sọ pe wọn ko ṣe mọ.
Oríṣun àwòrán, @OndoAPC
Awọn eeyan naa ni Segun Abraham, Ife Oyedele ati Jimi Odimayo.
Ẹwẹ, iroyin ti kọkọ gbode pe ọkan lara awọn oludije ọhun, Nathaniel Adojutelegan ti yọwọ lawo lati dije ninu idibo abẹle naa, ṣugbọn o sọ fun BBC pe irọ pọmbele ni.
Lockdown updates: Naira Marley gbóríyìn fún Jude Chukwuka pẹ̀lú #1 míliọnù
Ki lo ti ṣelẹ sẹyin?
Àwọn olùdíje meji míràn tún ti jọ̀wọ́ àgá fún Akeredolu níbi ètò ìdìbò abẹ́lé APC ìpínlẹ̀ Ondo
Oríṣun àwòrán, @ondoapc
Ni kete to ku wakati diẹ ki eto idibo abẹle lati mọ ẹni ti yoo gbe apoti ibo sipo gomina ninu ẹgbẹ oṣelu APC ni ipinlẹ Ondo bẹrẹ, oludije meji miran tun ti yọnda aga fun gomina Rotimi Akeredolu.
Akeredolu lo fi ọrọ naa ledeloju opo Twitter rẹ lẹyin ti ileeṣẹ iroyin abẹlẹ kan kede rẹ.
Awọn oludije ọhun ni Ife Oyedele, Jimi Odimayo.
Ṣaaju ni Akeredolu ti kede loju opo Twitter rẹ kan naa pe ọkan gboogi lara awọn to n ba du ipo gomina ninu ẹgbẹ oṣẹlu naa, Olusegun Abraham ti yọwọ rẹ kuro lawo idibo ọhun.
Igbesẹ tuntun yii ti mu ki iye awọn to n ba gomina Akeredolu figa-gbaga ninu idibo abẹle naa, ṣugbọn ti wọn jawọ di mẹrin.
Oríṣun àwòrán, others
O le lẹgbẹrun mẹta awọn ọmọ oṣelu APC lati ẹkun idibo mẹtalenigba kaakiri ipinlẹ Ondo ti yoo kopa ninu idibo naa lati yan ẹni ti yoo gbe apoti ibo sipo gomina ni ipinlẹ Ondo.
Ọjọ kẹwaa, oṣu kẹwaa, ọdun 2020 ni idibo sipo gomina ọhun yoo waye.
Ǹjẹ o yẹ kí èèyàn máa sùn lẹ́nu iṣẹ́?
Ènìyàn 653 míràn tún kún iye àwọn tó ní COVID-19 ní Nàìjíríà
Wo ohun tó yẹ kí o mọ̀ nípa Laycon, akẹ́kọ̀ọ́jáde UNILAG tó ń kópa nínú BBNaija 2020
Àwọn àádọ́ta ọ̀dọ́ wọ gàù nítorí ilé ijó ní Ilorin
Bi awọn aṣoju oludibo lẹgbẹ oṣelu APC ṣe n gbaradi lati yan oludije ẹgbẹ oṣelu naa fun ibo gomina to n bọ lọna, oludije miran tun ti dide lori aga fun gomina Rotimi Akeredolu.
Gomina Akeredolu ṣalaye loju opo Twitter rẹ pe Oluṣẹgun Abraham to jẹ okan lara awọn oludije mẹwaa to n ba  a ta kangọn ti gba lati ti oun lẹyin.
Mo ṣẹṣẹ ba ọmọ iya mi, Oluṣẹgun Abraham sọrọ tan lori foonu ni, o si ti jẹ ko di mimọ fun mi peoun ṣetan lati fọwọ si idije mi nigba keji. Ni ifọwọsowọpọ la o js mu ki oorun ipinlẹ Ondo o tubọ maa tan sii.
Ni bi a ṣe n sọrọ yii, eto ti n lọ ni pẹrẹ lawọn ibudo idibo abẹle lẹgbẹ oṣelu APC ni ilu Akurẹ.
Akọroyin BBC News Yoruba to wa nibi idibo naa ṣalaye pe awọn aṣoju ọmọẹgbẹ gbogbo to fẹ dibo ni wọn ti wa nikalẹ ti wọn si n reti ki eto naa bẹrẹ.
Ni Gbongan The Dome, awọn apoti idibo gbogbo ti wa ni ato ni isọri ijọba ibilẹ kọọkan.
Bakan naa lawọn agbofinro naa wa ni sẹpẹsẹpẹ lati rii pe ẹkọ ṣoju mimu lori abo ẹmi ati dukia nibẹ.
Oríṣun àwòrán, twitter/ Arakunrin rotimi akeredolu
Loni ni ireti wa pe awọn aṣoju oludibo lẹgbẹ oṣelu APC nipinlẹ Ondo yoo gbe ipinnu wọn kalẹ lori ẹni gan an ti wọn fẹ ko gbe aṣia ẹgbẹ oṣelu naa ninu eto idibo sipo gomina to n bọ lọna.
Kii ṣe ahesọ ọrọ mọ pe oniruuru awuyewuye lo ti wọ tọ ọrọ tani yoo dije ipo gomina ni ipinlẹ Ondo.
Oríṣun àwòrán, Twitter/rotimi akeredolu
Awọn oludije mọkanla lo n dije fun aṣia ẹgbẹ oṣelu APC naa bayii lẹyin ti iroyin abẹle sọ pe Ifẹ Oyedele, ọkan lara awọn oludije naa to fi pe mejila tẹlẹ ti gba lati jawọ.
Ifẹ Oyedele ni oun gbe igbesẹ naa lati lee ṣe atilẹyin fun gomina Rotimi Akeredolu.
Oyedele kede atilẹyin rẹ fun Akeredolu lẹyin ifikunlukun pẹlu gomina Akeredolu nileejọba ipinlẹ Ondo ni alẹ ọjọ Aiku.
Gomina Yahaya Bello ni alaga igbimọ to n ṣe kokari idibo abẹle naa; oun pẹlu si ṣepade pẹlu gbogbo wọn lalẹ ọjọ Aiku kan naa.
Oríṣun àwòrán, twitter/Arakunrin rotimi akeredolu
Awọn aṣoju lati ẹkun Ariwa Ondo- Gbongan ajọ olomi ẹrọ Water Corporation to wa ni Ijapo Estate,
Awọn aṣoju ẹkun Gusu Ondo- Ileewe girama, St Thomas' Aquinas College nilu Akurẹ
Awọn aṣoju ẹkun Aringbungbun Ondo- Ileegbimọ aṣofin ipinlẹ Ondo, ODHA Complex ni opopona Igbatoro Akurẹ.
Oríṣun àwòrán, thenewstrack.com.ng
Awọn oludije pe fun isunsiwaju idibo abẹle naa
Nibayii, iroyin n sọ pe meje ninu awọn oludije naa ni wọn ti n pe fun isunsiwaju idibo abẹnu naa.
Amọṣa gomina Yahaya Bello ti ṣalaye pe oun gẹgẹ bi alaga igbimọ ibo abẹle naa ko laṣẹ lati sun un siwaju.
Black women live matters: Ọdún 2015 ní àwọn ọlọ́pàá pa India Kager láìní ìdí- Gina Best
"Yahaya Bello ni:  ""A o tẹsiwaju pẹlu idibo abẹle yii."
"Ko si eto idibo to pe nibiki lagbaye, koda titi de orilẹ-ede Amẹrika pẹlu."""
Awọn oludije to n dije fun aṣia ẹgbẹ oṣelu APC lati dupo gomina ipinlẹ Ondo ni Gomina Rotimi Akeredolu, Chief Olusola Oke, Dokita Segun Abraham, Ọgbẹni Olaide Adelami,
Ko yọ Bukola Adetula, Arabinrin Jumoke Anifowose, Ambasadọ Sola Iji, Ọgbẹni Isaac Kekemeke, Jimi Odimayo, Ọgbẹni Nathaniel Adojutelegan ati  Awodeyi Akinsehinwa naa silẹ.
Black women live matters: Ọdún 2015 ní àwọn ọlọ́pàá pa India Kager láìní ìdí- Gina Best
Coronavirus:: Òògùn ìtura dé fún Covid-19! Ọ̀dọ̀ fásitì jànkàn Oxford ló ti jáde
Oríṣun àwòrán, Oxford University
Oogun arun Coronvirus kan ti wọn fiaridaju han pe o n ṣiṣẹ ti jade lati ile iwe giga fasiti Oxford eyi to si fi han pe ko mu ewu dani rara.
Bakan naa wọn jẹ ko di mimọ pe o maa n tọ agọ ara sọna nipa ohun to yẹ ko ṣe ki ara lee ji pepe.
Ayẹwo rẹ ti wọn ṣe lara eeyan ẹgbẹrun kan o le mẹtadinlọgọrin fi han pe abẹrẹ naa gbe awọn ajagun inu ara dide toloyinbo n pe ni 'antibodies' ati eroja ara mii fun ijagun (white blood cell) eyi to lee doju ija kọ arun Coronavirus.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ohun to have iwadii yii jade ni Ireti gidi amọ ṣa, o ti ya ju lati mọ boya eyi nikan ti to lati dajọ pe o nṣiṣẹ lati da abo bo ara bẹẹ si ni awọn oogun ayẹwo mii ṣi wa lọna.
Orilẹede Amẹrika ti beere lati ra miliọnu lọna ọgọrun oogun naa bayii.
Alaafin of Oyo: Wo olorì Aláàfin tí àwọn èèyàn ń pariwo pé ó jọ Bobrisky
Oríṣun àwòrán, Instagram/Olori anu ati Bobrisky
Gbogbo ọmọ Naijiria lo fẹẹ mọ Bobrisky, iyẹn Idrisu Okunẹyẹ, Ọdọkunrin to n ṣe iṣe obinrin, to n mura bii obinrin.
Amọṣa, kii ṣe tori eyi ni iroyin yii ṣe jẹyọ bi ko sẹ ohun to pa Bobrisky ati iyawo Alaafin, Olori Aanu Adeyẹmi pọ.
Ni aipẹ yii ni iroyin kan pe olori Aanu jade si gbangba walia loju opo ayelujara rẹ to si faraya lori awọn ọrọ iwọsi tawọn eeyan kan n sọ sii loju opo ayelujara.
Oríṣun àwòrán, Instagram/Olori anu ati Bobrisky
Koda, Olori tun sọ ọrọ yii debi pe awọn eeyan kan n fi oun we Bobrisky pe awọn mejeeji jọra pupọ.
Lootọ mejimeji l'Eduwa da eniyan, gẹgẹ bi awọn agba ṣe maa n sọ, ṣugbọn ọrọ yii ko pa olori lẹrin rara.
Oríṣun àwòrán, Alamy
kato wi ka to fọ, wọn a maa wi pe o jọ Bobrisky, ṣe Bobrisky kii ṣe eeyan ni. Ẹ jọwọ ẹ wọrọ miran sọ.
Eyi lohun tawọn ileeṣẹ iroyin abẹle kan ka mọ oju opo ayelujara rẹ kan.
Oríṣun àwòrán, Instagram/Olori Anu/Bobrisky
Amọṣa, lati fi idi ọrọ naa mulẹ gan, awa pẹlu lọ soju opo ayelujara Olori laafin Iku Baba yeye naa.
Ko si aniani pe arẹwa ni olori Anu ti n gbe ọla baba, Alaafin yọ. Koda, gbogbo aworan to wa nibẹ ko sẹni ti ko ni rii pe Olori laafin nla niyi, afi ẹni ti oju  ba n dun.
Oríṣun àwòrán, Instagram/Olori Anu/Bobrisky
Oríṣun àwòrán, Instagram/queen anu
Alaafin Oyo kò dàgbà jù fún mi, ohun tó wù mí ní mo ṣe pẹ̀lú ayé mi- Olori Aanu
Ọkan lara awọn olori Iku Baba Yeye, Alaafin ti ilu Ọyọ, Ọba Lamidi Ọlayiwọla III, Olori Anuoluwapọ Adeyẹmi ti kan lu oju opo ayelujara lati fun awọn to n sọrọ nipa igbeyawo oun ati Ọbalaye naa lesi.
Loju opo instagram rẹ lo ti fesi si awọn to n ṣe marimasọ lori igbeyawo rẹ, eyi to ni wọn ni nitori ati lee di olori lo fi lọ fẹ Alaafin.
O ni ohun to ba wu ẹlẹnu ni ko maa fi ẹnu wọn sọ, amọṣa, Kabiyesi Alaafin ko dagba ju fun oun lati fẹ.
"Olori Aanu nu: ""Ọkọ mi ko dagba ju fun mi o, ohun to wu mi ni mo fi igbe aye nmi ṣe"""
Oríṣun àwòrán, Instablog9ja
"O ni awọn kan tilẹ tun n sọrọ si oun pe oun jọ Bobrisky. ""Ṣe Bobrisky kii ṣe eeyan ni?"" ni esi to fi da wọn lohun."
Oríṣun àwòrán, Instagram/queen aanu
O fi kun un pe pupọ awọn to wa n sọrọ yii ni wọn maa n gba ẹyin wa bẹbẹ fun ohun kan tabi omiran lọwọ oun.
Olofa ina: ẹ parí òwe yìí pé ìgbà tí ara bá tu ìgbẹ́ láà ri eṣú....
Ogun TRACE: Ọkùnrin kan pa ara rẹ̀ sínú ọgbà àjọ tó n mójútọ ìrìnnà ọkọ̀ nípìnlẹ̀ Ogun
Oríṣun àwòrán, oguntoday.com
Kayeefi ni ọrọ da ninu ọgba ileeṣẹ ajọ to n mojuto igbokegbodo ọkọ nipinlẹ Ogun, TRACE, lasiko ti ọkunrin kan gbẹmi mi sibẹ.
Iroyin sọ pe ọkunrin naa, Fatai Salami, mu oogun apakokoro nitori pe awọn oṣiṣẹ ajọ TRACE, gba ọkọ rẹ.
A gbọ pe ọwọ awakọ Salami, ni wọn ti gba ọkọ akẹru naa nitori pe o ru ofin to rọ mọ jijade lasiko arun Covid-19.
Ọkọ Salami ti lo ọjọ marun-un ninu ọgba TRACE, nitori pe wọn ni ko san ẹgbẹrun lọna okoolerugba o din marun-un Naira, gẹgẹ bi owo itanran.
Iroyin sọ pe Salami tẹle awakọ rẹ lọ sibẹ lati yanju ọrọ ṣugbọn airi ọkọ naa gba lo mu ki Salami da oogun apakokoro mu.
Ṣugbọn ṣa, awọn alaṣẹ ajọ TRACE, sọ pe awọn ko gba ọkọ lọwọ ọkunrin naa.
Awọn iroyin kan ti ẹ tun sọ pe oludari ileeṣẹ eto irinna kan ni ọkunrin naa, to si jẹ pe ọga rẹ sọ pe iṣẹ yoo bọ lọwọ rẹ ti ko ba ri ọkọ naa gba pada.
Olofa ina: ẹ parí òwe yìí pé ìgbà tí ara bá tu ìgbẹ́ láà ri eṣú....
Gẹgẹ bi alukoro ileeṣẹ ọlọpaa nipinlẹ Ogun, Abimbola Oyeyem, ṣe sọ fun BBC, awọn alaṣẹ TRACE sọ pe awọn deede ri ọkunrin naa to joko sinu ọgba ajọ naa ni.
Ati pe nigba ti wọn si gbiyanju lati sọ fun un pe ko kuro ni ayika naa lo yọ nkankan jade ni apo, to si da a mu.
Wọn gbe e digba-digba lọ sileewosan, ko to o gbẹmi mi nibẹ.
Black women live matters: Ọdún 2015 ní àwọn ọlọ́pàá pa India Kager láìní ìdí- Gina Best
Oyeyemi sọ pe iwadii ṣi n lọ lọwọ lati mọ otitọ ọrọ naa, ati lati mọ awọn ẹbi ọkunrin naa.
Gbogbo igbiyanju BBC lati ba awọn alaṣẹ ajọ TRACE sọrọ lo jasi pabo, nitori pe agbẹnusọ ajọ naa, Babatunde Akinbiyi, ko gbe ipe sori ẹrọ ibanisọrọ rẹ.
Human trafficking: Ààrẹ Buhari, ẹ̀yin gómìnà ìpínlẹ̀ Yorùbá, ẹ rántí wa ní Oman, àwọn ọmọ
Madagascar Covid 19 Update: Àgbo Covid-19 Madagascar kò ṣiṣẹ́, àwọn ènìyàn tí bẹ̀rẹ̀ sí ní kú níbẹ̀
Oríṣun àwòrán, AFP
Ààrẹ orílẹ̀èdè Madagascar, fi ọwọ́ sọ̀yà lórí àgbo nàá, kódà, ó mu lára rẹ̀ lójú gbogbo ayé lórí tẹlifísàn
Ileewosan lorilẹ-ede Madagascar ti n tiraka lati tọju awọn alarun Coronavirus nitori arun naa ti peleke si nibẹ.
Bi o tile jẹ pe Aarẹ orilẹ-ede Madagascar, Andry Rajoelina n lọgun pe agbo awọn n koju arun Coronavirus, Ajo Eto Ilera Lagbaye (WHO) ti ṣekilọ lori lilo agbo naa nitori ko gba ontẹ ayẹwo finifini.
Laarin oṣu kan, iwadii fihan pe iye awọn to ti lugbadi arun naa ti peleke si ni lorilẹ-ede naa.
Eniyan ẹgbẹrun lọna mẹtala lo ti lugbadi arun naa, ti eniyan mejilelọgọjọ si ti ku.
Amọ bi iye eniyan ṣe n peleke si to ni arun Coronavirus naa ni Aarẹ Andry Rajoelina n sọ wi pe agbo Madagascar yii ni ọna abayọ si arun Coronavirus, ti o si ṣe ifilọlẹ rẹ ni Oṣu Kẹrin.
Victor Agunbiade ni ojú àlá ni Ọlọrun ti yan iṣẹ́ ọmọ ogun ojú omi fún òun ní America
Ileeṣẹ Madagascar Institute of Applied Research ni wọn lo egbogi artemisia, to n koju aisan iba ati awọn egbogi miran lati fi ṣe akojọpọ agbo naa.
Orilẹede naa ti polongo oogun ohun gẹgẹ bi oogun to n dena to si n ṣewosan fun arun naa, ti wọn si ti fun awọn akẹkọọ to wa nile iwe mu lati bi oṣu mẹrin ṣẹyin.
Saaju ninu oṣu yii, aarẹ naa ṣi n pin agbo naa kaakiri pẹlu awọn ohun iranwọ miran bii irẹsi, ororo, suga fun awọn eniyan to wa ni igberiko.
Amọ, Ajo Eleto Ilera Lagbaye, WHO ni awọn ṣe agbatẹru fun awọn oogun iwosan ibilẹ, amọ awọn gbọdọ ri ẹri ayẹwo imọ sayẹnsi wi pe awọn agbo yii le e ṣe awotan aarun Coronavirus.
jkkkkk
Kini o ti ṣẹlẹ sẹyin?
Awọn alaṣẹ orilẹ-ede Naijiria ti sọ pe awọn ko ri ẹri tabi aridaju pe àgbo ti orilẹ-ede Madagascar ṣe fun iwosan coronavirus n ṣiṣẹ.
Ajọ to wa fun iwadii ijinlẹ ati idagbasoke nipa oogun ni Naijiria, National Institute of Pharmaceutical Research and Development (NIPRD) lo fi ikede naa sita lẹyin iwadii to ṣe lori agbo naa.
Ṣugbọn awọn alaṣẹ ajọ NIPRD tun sọ pe iwadii ko pin si ibi kan.
Oríṣun àwòrán, AFP
Oṣu Karun ni orilẹ-ede Madagascar fi agbo na, Covid-Organics ranṣẹ si Naijiria, ati awọn orilẹ-ede ilẹ Africa kan, ṣugbọn Aarẹ Muhammadu Buhari sọ pe oun ko ni fi ọwọ si lilo agbo naa ni Naijiria titi di igba ti awọn alaṣẹ eto ilera ba buwọlu u.
Bo tilẹ jẹ pe ọpọ eeyan lo bu ẹnu atẹ lu ijọba nigba naa pe wọn ko fẹ ẹ ṣe atilẹyin fun akẹgbẹ rẹ nilẹ Africa ni.
Ǹjẹ àgbo lè ṣe òògùn coronavirus?
Bakan naa ni ajọ eto ilera l'agbaye, WHO, sọ pe ko si ẹri pe oogun kankan ti wa fun iwosan Covid-19, lẹyin ti
Oríṣun àwòrán, AFP
Ààrẹ orílẹ̀èdè Madagascar, fi ọwọ́ sọ̀yà lórí àgbo nàá, kódà, ó mu lára rẹ̀ lójú gbogbo ayé lórí tẹlifísàn
Ewe Artemisia ni eroja gboogi ti wọn fi ṣe agbo naa, ati awọn ewe miran to wa l'orilẹ-ede Madagascar.
"Olori  ajọ NIPRD, Dokita Obi Adigwe, sọ fun BBC pe ""iwadii ti a ṣe fihan pe agbo naa ni agbara lati mu ki eeyan hu ikọ jade, to si tun din iba ku lara awọn ẹranko ti wọn ti dan-an wo."
Ṣugbọn o ni NIPRD ti gba ijọba Naijiria nimọran pr ko si ẹri pe àgbo naa le dena tabi wo Covid-19 san.
Ti a ba ni akoko ati awọn nkan to yẹ, o ṣeeṣe ki a ṣi ri arigbamu.
O ti le ni ẹgbẹrun mẹtaledinlogoji eeyan ti Covid-19 ti ran ni Naijiria, awọn to le ni ẹgbẹrin si ti ku.
Ṣẹ́ lóòtọ́ ní ginger àti garlic lè pa àrun Coronavirus?
Funmi Adewara: Tele Medicine' ní a fi ń ṣàyẹ̀wò èèyàn ìdá ọgọtá láti dènà ìtànkálẹ̀ Covid 19
Inu ile la ti n tọju àwọn to ni Covid 19 ti itọju wọn ko lagbara ju- Dokita Adewara
Patient Appointment Screen, Tele Medicine, Mobile Health àti àwọn ipede tuntun mii ni arun Coronavirus to n ba gbogbo agbye finra yii ti bi lasiko yii.
Gbogbo ile iṣẹ ni agbaye ni ayipada ti de ba ọna ti koowa n gab ṣiṣẹ oojọ won ni eyi ti awọn kan n daṣa 'New Normal'fun un.
Bayii eto iwosan lati lọ ri dokita naa ti yipada bayii, Dokita Funmi Adeara to jẹ oniṣegun oyinbo lasiko Covid 19 ba BBC sọrọ lori awọn irufẹ ayipada wọnyii.
Bayii, o ti ṣeeṣe fun ọ lati ba dokita rẹ sọrọ lori aisan rẹ lai de ile iwosan rara.
O tun ṣeeṣe lati ṣe ayẹwo boya o ti lugbadi coronavirus tabi bẹẹkọ nipasẹ foonu rẹ
Koda, o le tun gba 'sample' ẹnu itọ ara rẹ fun ayẹwo lai de ile iwosan ki o si ri esi gba laarin ọjọ meji pere.
Ondo 2020 Election: Ọmọlúwàbí ṣọ̀wọ́n láàrín àwọn òlóṣèlú ló jẹ́ kí wọ́n má a lọ láti ẹgbẹ́ òṣèlú kan sí òmìràn - Gbenga Abimbola
Oríṣun àwòrán, Others
Onimọ nipa eto oṣelu lorilẹede Naijiria, ọmọwe Olugbenga Abimbola ti ni aini iwa ọmọluwabi lo n mu ki awọn oloṣelu ma a kuro ni ẹgbẹ oṣelu kan lọ si omiran.
Ọmọwe Abimbola sọ eyi lasiko to n fesi si bi eto oṣelu ṣe n lọ ni ipinlẹ Edo ati Ondo saaju idibo sipo gomina ti yoo waye nibẹ.
O ni iwa ọmọluwabi sọwọn laarin awọn oloṣelu ni wọn ṣe n kaakiri ẹgbẹ oselu ati wi pe awọn ẹgbẹ oṣelu naa ko ni afojusun ohun ti wọn fẹ ṣe fun ilu, eleyii ti wọn ma n pe ni ''party ideology''.
''Íwa inu awọn oloṣelu ni ko dara, kii se pe eto iṣejọba Naijiria ko i tii dagba to lẹyin ọdun mọkanlelogun.''
''Ọpọlọpọ awọn oloṣelu n tan awọn araalu jẹ ni wọn ṣe n kuro ni ẹgbẹ oṣelu kan lọ si omiran.''
O ni Igbakeji gomina ipinlẹ Ondo ni lọkan lati di gomina ni o ṣe lọ darapọ ẹgbẹ oṣelu ZLP ti yoo fun ni anfaani lati dije dupo, eleyii ti o lẹtọ si labẹ ofin.
Oríṣun àwòrán, Others
Onimọ nipa eto oṣelu lorilẹede Naijiria, Dokita Olugbenga Abimbola naa ni awọn oludije mẹta gboogi lo ti suyo ninu idibo ipinlẹ Ondo bayii.
Eleyii to fihan gbangba pe Gomina Akeredolu ti ẹgbẹ Oṣelu APC yoo di ariwa ipinlẹ Ondo mu nibi ti o ti wa, Jegede ti ẹgbẹ oṣelu PDP yoo di gbungun mu ni ibi ti o ti ṣẹ wa, nigba ti Agboola Ajayi ti ẹgbẹ oṣelu ZLP yoo di guusu mu ni ibi ti o ti wa.
Amọ o ni ipolongo ẹlẹkundẹkun ni yoo fihan bi awọn eniyan ṣe fẹran awọn oludije naa si.
Nitori naa ko si ẹni to le e sọ ẹni ti yoo bori eto idibo ipinlẹ Ondo, afi esi idibo ti ko ni magomago ninu ni yoo fi ero awọn eniyan han.
Ṣaaju ni Ogbeni Agboola ti sọrọ lori bi ZLP ṣe tẹwọ gba oun:
Igbakeji gomina ipinlẹ Ondo, Agboola Ajayi ti ni ẹgbẹ oṣelu Zenith Labour Party gba oun tọwọ-tẹsẹ ni oun fi fi ẹgbẹ oṣelu PDP silẹ lati lọ dije dipo gomina ninu idibo sipo gomina ni ipinlẹ Ondo.
Agbẹnusọ fun Agboola Ajayi, Allen Sowore lo sọ bẹẹ fun BBC Yoruba.
Sowore ni awọn oloye ẹgbẹ oṣelu ZLP ni apapọ ti fun Agboola ni anfaani lati dije sipo gomina labẹ ẹgbẹ naa.
O ni awọn eniyan lo paṣẹ fun oun lati lọ si ẹgbẹ miran lati lọ dije dupo fun gomina nitori oun ni awọn fẹ.
Bakan naa ni Sowore ni lilọ kuro lẹgbẹ oṣelu kan lọ si omiran ko le e nipa buburu lori ati debi ipo gomina rẹ, nitori nkan ti awọn eniyan fẹ ni o ṣe.
''Iru ẹ ko ṣẹṣẹ ma a ṣẹlẹ ninu oṣelu Naijiria nitori eto oṣelu ni Naijiria ṣe n dagbasoke ni, nitori naa ni awọn oloṣelu ṣe n kaakiri lati ẹgbẹ kan si omiran.''
'' Oloṣelu ko le e duro si ojukan naa. Bakan naa ni kikuro to kuro lati APC lọ si PDP lọ si ZLP  ko le e ni ipa buburu ninu irinajo naa.''
Agbẹnusọ fun Agboola Ajayi, Allen Sowore ni awọn araalu lo ma a yan ẹni ti wọn fẹ ko ṣe adari fun wọn ninu idibo to n bọ.
Sowore fikun pe awọn nigbagbọ wi pe awọn yoo bori ninu idibo to n bọ ninu awọn ololufẹ rẹ ni APC, PDP ati ZLP yoo dibo fun un.
Alaafin: Olori Aanu Adeyemi ṣàlàyé ìdí tó ṣe gẹ́ Oba Lamidi Adeyemi ti ìlú Oyo
Ti iwaju ko ba ṣe lọ, ẹyi a ṣe e pada si. Igbakeji Gomina ipinlẹ Ondo, Agboola Ajayi tun fi ẹgbẹ oṣelu PDP silẹ.
Oríṣun àwòrán, @Agboola
Ninu atẹjade kan ti oludamọran Ọgbẹni Agboola fi sita, igbakeji Gomina Ondo kọwe fipo rẹ silẹ gẹgẹ bi ọmọ ẹgbẹ PDP lọjọ Aje, ọjọ kẹwaa oṣu kẹjọ ọdun yii(2020).
Ajayi to kuna ninu idibo abele fun ipo gomina ninu eyi ti Eyitayo Jegede ti jawe olubori mu iwe to fi ẹgbẹ naa silẹ lọ si olu ileeṣẹ ẹgbẹ PDP to wa ni wọọdu Apoi keji niluu Kiribo, ijọba ibilẹ Ese Odo.
Nigba to n ki awọn alaṣẹ ẹgbẹ oṣelu PDP fun atilẹyin niwọn igba ranpẹ ti o fi jẹ ọmọ ẹgbẹ naa, Ajayi ni oun gbe igbesẹ lati fi ẹgbẹ naa silẹ nitori awọn eeyan ipinlẹ Ondo fẹ ki oun dije fun ipo gomina ninu ibo to n bọ.
Ẹwẹ, alaga ẹgbẹ oṣelu PDP ni wọọdu Apoi keji, Ọgbẹni Festus Oboro ti tẹwọ gba ikọwefiposilẹ igbakeji gomina Ondo gẹgẹ bi ọmọ ẹgbẹ naa.
Ọjọ kọkanlelogun, oṣu kẹfa, ọdun yii ni Ọgbẹni Ajayi darapọ mọ PDP niluu rẹ, Kiribo nibi to ti dije ninu ibo abẹle fun ipo gomina ipinlẹ Ondo.
Ọgbẹni Ajayi rọ awọn alatilẹyin rẹ pe ki wọn ma ni ọkan, o ni oun yoo kede igbesẹ to kan fun oun laipẹ.
BBC Africa Eye: ìwádìí ìkọ̀ks BBC fihàn pé àwọn kan ń jí ohun èèlò ìdáàbòbò ìjọba tà nígbo
Àwọn alágbára ni mo bá díje ṣùgbọ́n mo ti gbà f'Olọrun- Agboola Ajayi
Igbakeji gomina ipinlẹ Ondo, Agboọla Ajayi ti ṣalaye idi ti o fi fidirẹmi ninu idibo abẹle lati yan oludije fun ipo gomina ni ipinlẹ naa lẹgbẹ oṣelu PDP.
Ninu atẹjade to fi sita lẹyin ibo abẹle naa, Agboọla ni awọn alagbara ti ko lẹgbẹ loun dojukọ lo jẹ ki oun fidirẹmi.
Amọṣa, o ni bi o ti wu ko ri, oun ti gba ohun ti awọn ọmọ ẹgbẹ sọ ati ẹni ti wọn yan.
Peters Ijagbemi dá àrá lórí ètò 'Ṣé o láyà' ti BBC Yorùbá lọ̀sẹ̀ yìí
Bi ẹ ko ba ni gbagbe, laipẹ yii ni  Agboọla fi ọga rẹ tẹlẹ, Rotimi Akeredolu silẹ ti o si ṣi wa si ẹgbẹ oṣelu PDP gẹgẹ bi ara ọna lati dije fun gomina ni ipinlẹ naa.
Kii ṣe iroyin tuntun mọ bayii pe Eyitayọ Jẹgẹdẹ ni wọn dibo yan gẹgẹ bii ẹni ti yoo gbe aṣia ẹgbẹ oṣelu naa lasiko idibo gomina ipinlẹOndo ti yoo waye lọjs Kẹwaa oṣu kẹwaa ọdun 2020.
Ninu awọn aṣoju ọmọ ẹgbẹ ẹgbẹrun meji ati mọlakanlelaadọfa to dibo abẹlẹ naa, Jẹgẹdẹ ni ọrinlelẹgbẹrin o le mẹjọ, 888, Agboọla to tẹlee ni ibo ọtalelẹgbẹta ati meje.
Oríṣun àwòrán, @Eyitayo
Oṣù kẹwàá ọdún 2020 ní INEC à ṣetò ìdìbò míì ní ìpínlẹ̀ Ondo
Ni ìgbẹyin ohun gbogbo ninu ẹgbẹ oṣelu PDP ni ipinlẹ Ondo. Abajade wọn ti dori igba bayii.
Ni ana, ọjọ kejilelogun, oṣu keje ni wọn bẹrẹ eto idibo naa nibi ti awọn Oludije mẹjọ ti pàda wako lati mọ ẹni ti yoo ṣoju ẹgbẹ oṣelu Peoples Democratic Party ninu idibo to m bọ.
Loru mọju oni, ọjọ kẹtalelogun, oṣu keje ni awọn alamojuto idibo abẹlẹ naa kede abajade esi idibo ẹni to maa gba tikẹẹti PDP lati le di gomina Ondo.
Esi naa ree:
Eddy Olafeso - 175Ajayi Agboola - 657Banji Okunomo - 90Ayorinde Olabode - 95Boluwaji Kunlere - 33Ebiseni Olusola - 29Erewa Godday - 14Eyitayo Jegede - 888
Lẹyin ti wọn kede esi idibo yii ni wọn fa Eyitayọ Jegẹde kalẹ lorukọ ẹgbẹ oṣelu PDP pe ko dide giri bi ọmọkunrin lati koju Arakunrin APC ati awọn aṣoju ẹgbẹ to ku ti wọn jọ maa dije idibo to m bọ naa.
Ta ni yóò kojú Akeredolu fún ipò gómìnà Ondo?
Wo bí ètò ìdìbò abẹ́lé ẹgbẹ́ òṣẹ́lú PDP ṣe ń lọ ní ìlú Akure
Idibo ọhun waye lati ori ijọba kan si omiran.
O le lẹgbẹrun meji awọn ọmọ oṣelu PDP to n kopa ninu idibo abéle naa.
Eyitayo Jegede, igabkeji gomina ipinlẹ Ondo, Agboola Ajayi atawọn mii lo n kopa ninu idibo abẹle naa lati le e dupo dije ninu idibo sipo gomina ti yoo waye loṣu kẹwaa ọdun 2020.
Ki lo ti ṣẹlẹ sẹyin?
Awọn ọmọleyin ọkan lara awọn oludije, Eyitayo Jegede, ti sọ pe awọn alatilẹyin rẹ fariga pe, igbakeji gomina, Agboola Ajayi tẹ ayédèrú ìwé idibo wọle.
Wọn ni igbesẹ yii da rugudu silẹ lojuko ti eto idibo abẹle naa ti n waye,  ṣugbon awon ti pana aawọ naa.
Olofa ina: ẹ parí òwe yìí pé ìgbà tí ara bá tu ìgbẹ́ láà ri eṣú....
Ni bayii, iforukọsilẹ awọn oludibo ni wọn n ṣe lọwọ ki idibo gangan to bẹrẹ.
Eto iforukọsilẹ yii wọn n ṣe ni ijọba ibilẹ kọokan.
Ki lo ti nṣelẹ sẹyin?
Akọroyin BBC to wa nibi eto idibo naa to n waye ni Dome ni ilu Akurẹ ni ipinlẹ Ondo ti fidiẹ mulẹ pe edeaiyede bẹ silẹ nibudo idibo naa.
O ṣalaye pe eyi ko ṣẹyin awọn oludibo to jẹ aṣoju kan ti wọn yọ bébà idibo sita lati fi dibo.
Akọrọyin BBC ni awọn to n mojuto eto idibo naa kọ lati gba awọn ti ko ni ojulowo bébà idibo da ni nitori wọn ni ko tọna ni eyi to si fa ariwo nla.
S\ugbọn bayii, o ni awọn agbofinro ti pẹtu si aawọ naa ni eyi ti awọn to ni kaadi idibo si ti lọ gbaojulowo bébà idibo bi o ti yẹ.
Lọwọlọwọ ni awọn to ni ojulowo ohun eelo idibo ti bẹrẹ ayẹwo kaadi awọn ọmọ ẹgbẹ ati aṣoju bo ṣe yẹ
Eto ididbo yii ni yoo yan ẹni ti yoo ṣoju ẹgbẹ PDP ti yoo si koju APC ati awọn oludije ẹgbẹ to ku ninu eto idibo fun ipo gomina to m bọ lọna
Wo bí PDP ṣe fẹ́ yàn olùdíje fún ipò gómìnà l'Ondo
Ta ni yóò kojú Akeredolu fún ipò gómìnà Ondo?
Eto idibo ipinlẹ Ondo yoo waye ni ọjọ kọkandinlogun, oṣu kẹwaa, ọdun 2020.
Oríṣun àwòrán, others
Awọn oludije mẹwaa ni yoo maa dije du aṣia ẹgbẹ oṣelu PDP loni fun idibo sipo gomina nipinlẹ Ondo ti yoo maa waye loṣu kẹwaa, ọdun 2020.
Igbakeji gomina ipinlẹ Ondo, Agboọla Ajayi yoo maa wọ ṣokoto kan naa pẹlu kọmiṣọnna nigba kan ri fun eto idajọ ni ipinlẹ naa, Eyitayọ Jẹgẹdẹ atawọn eekan oludije miran.
Amugbalẹgbẹ fun Gomina Akeredolu, Ọmọwe Doyin Ọdẹbọwale koro oju si
Amọṣa awọn mejeeji yii ni awọn onwoye n foju si lara gẹgẹ bii irin meji ti ikan ko ni fẹ tẹ fun ọkan bọrọ.
Awọn miran to tun n dije fun aṣia ẹgbẹ oṣelu naa ni igbakeji alaga apapọ ẹgbẹ oṣelu PDP fun ẹkun Iwọ Oorun Gusu orilẹede Naijiria, Eddy Olafẹsọ, Sola Ebiseni, Bọde Ayọrinde, Boluwaji Kunlere, Bamidele Akingboye, Banji Okunọmọ ati Godey Erewa.
Funmi Adewara: Tele Medicine' ní a fi ń ṣàyẹ̀wò èèyàn ìdá ọgọtá láti dènà ìtànkálẹ̀ Covid
Ṣaaju idibo naa lawọn kan lara awọn oludije naa ti fi ẹsun kan igbakeji gomina ipinlẹ naa, Agboọla Ajayi pe o ti ọwọ bọ iwe awọn aṣoju ọmọ ẹgbẹ ti yoo dibo ti o si ti rọpo rẹ pẹlu awọn ayederu aṣoju.
Bi ẹ ko ba ni gbagbe, laipẹ yii ni Ajayi kogba kuro lẹgbẹ oṣelu APC lọ si PDP laarin wahala ati ede aiyede laarin oun ati gomina ipinlẹ naa, Rotimi Akeredolu.
Olofa ina: ẹ parí òwe yìí pé ìgbà tí ara bá tu ìgbẹ́ láà ri eṣú....
Yollywood: Ọ̀pọ̀ òṣèré Yorùbá ń ṣelédè lẹ́yìn Yusuf Satia tó d'olóògbé
Oríṣun àwòrán, others
Yusuf Satia, òṣèré Nollywood Yorùbá ti di olóògbé
Ta ni Yusuf Satia ti iku mu lọ?
Oṣere yii kii ṣe ọkan lara awọn oṣere ti wọn maa n saaba gbe nkan jade lori ayelujara nipa ara wọn tabi nipa iṣẹ wọn.
Igba to gbe nkan sori ikansira ẹni facebook gbẹyin ni lọjọ kẹrin, oṣu kẹta, ọdun 2013.
Lasiko yii lo sọ nipa ifojusọna ọjọ ibi rẹ lọdun 2013.
Olofa ina: ẹ parí òwe yìí pé ìgbà tí ara bá tu ìgbẹ́ láà ri eṣú....
A bi Yusuf Ojewale Satia lọjọ kẹsan, an, oṣu kẹta lọdun naa lọhun.
Ipinlẹ Eko ni guusu Iwọ Oorun Naijiria ni Yusuf gbe dagba.
Nibẹ naa lo ti ka iwe alakọbẹrẹ ati iwe ipele girama.
Koda, o ri lọ si Fasiti ijọba apapọ to wa ni Akọka nilu Eko.
O tun gba iwe ẹri jade ni John Curtin College ni Australia.
O doloogbe ni ọjọ kọkanlelogun, oṣu keje, ọdun 2020.
Awọn oṣerẹ bii Toyin Adewale ati Bose alao ati awọn miran ni wọn n ṣe ilede lẹyin rẹ ti wọn si banujẹ nigba ti wọn gbọ iroyin iku Satia Yusuf
Oríṣun àwòrán, Kunle Afod/instagram
Ikú ti yọ́wọ́ òṣèré Nollywood Yorùbá, Yusuf Satia l'áwo
Oṣere Nollywood Yoruba, Yusuf Satia, ti ku.
Ibanujẹ lo jẹ fun agbo ile tiata Yoruba, Lẹyin ti iroyin iku rẹ jade sori ayelujara.
Akẹgbẹ rẹ, Kunle Afod, lo kede iku Satia loju opo Instagram rẹ ni ọjọ Iṣẹgun, ọjọ kọkanlelogun, oṣu Keje, ọdun 2020.
Oríṣun àwòrán, kunle afod/instagram
Afod sọ pe oun gbiyanju lati kàn si Satia ninu ọdun yii, ṣugbọn ko ṣeeṣe.
A ko ti i le sọ nkan to pa oloogbe naa.
Oríṣun àwòrán, Yusuf_satia/instagram
Satia di mimọ fun awọn ololufẹ rẹ fun ipa to ko ninu ere agbelewo Yoruba kan, Ijinlẹ Pam Pam to gbe jade logun ọdun sẹyin.
Awọn kan figba kan n ri Satia lẹyin KWAM 1 agba ọjẹ onifuju n ni lọpọ ọdun sẹyin.
Oríṣun àwòrán, Yusuf_satia/instagram
Oloogbe Yusuf Satia ati gbajugbaja olorin Fuji, Wasiu Ayinde
Awọn oṣere bi i Toyin Adewale, ati Bose Alao naa ti n ṣe idaro rẹ.
Oṣu to kọja ni gbajugbaja oṣere, Ogun Majek naa jade laye lẹyin aisan.
Olofa ina: ẹ parí òwe yìí pé ìgbà tí ara bá tu ìgbẹ́ láà ri eṣú....
Oluwo: Oluwo sọ̀rọ̀ nípa ẹwà rẹ̀ gẹ́gẹ́ bí Ọba alayé tó rẹwà gidigidi
Oríṣun àwòrán, Temperor telu1
Lara awọn gbajugbaja Ọba ti ko ṣee fi ọwọ rọ sẹyin ni ilẹ Yoruba ni Oluwo ti ilu Iwo nibi ti Kabiyesi Adewale Akanbi ti n jọba lọwọlọwọ.
Nibayii Ọba Abdulrasheed Adewale Akanbi ti jẹ ko di mimọ pe yatọ si pe oun jẹ pataki Ọba, oun tun ni ẹwa.
Ninu ọrọ kan to kọ soju opo Instagram rẹ, Oluwo ti ilu Iwo ni ohun to ba wu ẹlẹnu ni ko fi ẹnu rẹ sọ ati pe o da oun loju bi ada pe Ọkunrin to dara loju, dara lẹwa loun jẹ.
"Hmmm mo lero pe ọba to rẹwa ni mi!!! Oun eri ewi oun eri ero Adewale seun epe ko se Oba dara o d'ẹjọ lati ilu Iwo, ilu to rẹwa julọ ni gbogbo agbaye"""
Oríṣun àwòrán, Emperor telu 1
Funmi Adewara: Tele Medicine' ní a fi ń ṣàyẹ̀wò èèyàn ìdá ọgọtá láti dènà ìtànkálẹ̀ Covid
Boko Haram: Ìjọba ṣetán láti ra irinṣẹ́, sanwó oṣù fún adúnkookò mọ́ni tẹ́lẹ̀
Oríṣun àwòrán, Others
Awọn ikọ agbesunmọmi to to mọkanlelẹgbẹta ti wọn jọwọ ara wọn fun ijọba, ti kẹkọọ jade nile iwe.
Ijọba si ti ṣetan lati ma a san owo iranwọ ẹgbẹrun lọna ogun Naira fun wọn ni oṣooṣu, ti wọn yoo si pese irinṣẹ fun wọn.
Kọmiṣọnna fun ọrọ iroyin ni ipinlẹ Borno, Babakura Jatau lo sọ eyi, lasiko ifọrọwanilẹnuwo kan.
Jatau sọ pe, ajọ to n risi idagbasoke ẹkun ariwa Naijiria, (North East Development Commission) ati Ajọ to n risi akoso lilọ-bibọ ero lati agbegbe kan si omiran, (International Organisation for Migration) lo fi iranwọ naa ṣọwọ si awọn ikọ Boko Haram to ronupiwada naa.
Oríṣun àwòrán, Others
O ni ko si otitọ ninu iroyin pe, ijọba n fun ẹni kọọkan ninu wọn ni N100,000, wi pe N20,000 ni awọn n san fun wọn.
Bakan naa ni wọn fikun pe, kii ṣe gbogbo wọn ni ikọ Boko Haram, amọ lara wọn jẹ awọn ti wọn jigbe fun ọpọlọpọ ọdun, ti wọn si kan an nipa fun wọn, lati ma a ba wọn jale.
Hospital Wedding: Oṣù kan péré ni Tash fi ṣe ìgbéyàwó pẹ̀lú Simon kó tó kú
Kọmiṣana fun eto iroyin ni ipinlẹ Borno, Babakura Jatau ni, lati ipinlẹ Gombe ni ijọba yoo ti ko wọn wa si ipinlẹ Borno, ti wọn yoo si ko wọn si ibugbe ti wọn yoo ti ma a gba idanilẹkọ.
‘Won yoo ma lo imọ ekọ ti wọn gba ni ile iwe ti wọn lọ, lati fi ṣiṣẹ.’
Olu ilu ileeṣẹ ikọ alaabọ lorilẹede Naijiria lo fi lede pe, ikọ Boko Haram to le ni ẹgbẹta lo ti jọwọ ara wọn, ti wọn si ti ṣetan lati darapọ mọ awujọ.
Awọn alakatakiti ẹsin Islam ti pa awọn oṣiṣẹ ajọ agbaye marun to wa ṣe iṣẹ iranwọ ni Naijiria. Oṣu to kọja ni wọn kọkọ ji awọn oṣiṣẹ naa ko.
Aarẹ Muhammadu Buhari ti da ẹbi iku awọn eeyan wọnyi le ẹgbẹ Boko Haram.
Oríṣun àwòrán, others
Awọn ajọ adojutebi lo fi lede pe awọn oṣiṣẹ awọn wa lara awọn to ku.
Ipinẹ Borno lawọn alakatakiti naa ti ji awọn ọkunrin marun gbe. Wọn fifọnran kan sita loṣu to kọja eyi to fi oju awọn ti wọn ji gbe ọhun han.
Ẹwẹ, Aarẹ Buhari ti ṣeleri lati fi panpẹ ofin mu awọn apaniyan naa. O ni ijọba oun yoo rii daju pe wọn fa ẹgbẹ naa danu kuro ẹkun Ila Oorun Ariwa Naijiria.
Igbimọ ajọ adojutebi naa ni ibanujẹ ni iku awọn oṣiṣẹ wọn yii jẹ fun wọn pe o si dun wọn pẹlu gbogbo akitiyan wọn lati bere fun itusilẹ wọn.
Alabojuto ẹka itọju ọmọniyan ni ajọ isọkan agbaye, UN lorilẹede Naijiria, Edward Kallon ni ohun to ṣẹlẹ yii ko tọna pe awọn to n gbiyanju ati ṣeranwọ gan ni wọn n ṣe ikọlu si ti wọn si n pa.
"Ẹwẹ, o sọ ninu ọrọ kan pe "" iṣẹlẹ yii ko ni di awọn orilẹede ati ajọ agbaye lọwọ iranwọ ti wọn n ṣe fun ọgọọrọ awọn ọmọ Naijiria to nilo iranwọ ni apa Ila Oorun Ariwa orilẹede Naijiria""."
Bakan naa o bu ẹnu atẹ lu iye orikoo ayẹwo awọn oṣiṣẹ alaabo kaakiri, o ni awọn oriko yii n di iṣẹ iranwọ lọwọ o si ṣi aaye silẹ fun ijinigbe, ipaniyan tabi ṣiṣe awọn eniyan leṣe to fi mọ awọn oniṣẹ iranwọ lorilẹede ti wọn n da ya sọtọ.
Ẹgbẹ agbesunmọmi Boko Haram ti n ṣọṣẹ jiju ado oloro, ipaniyan ati ijinigbe lorilẹede Naijiria lati ọdun 2009.
Umai Emery: Villarael yan akọ́nimọ̀ọ́gbá Arsenal tẹ́lẹ̀, Emery gẹ́gẹ́ bí akọ́nimọ̀ọ́gbá rẹ̀ tuntun
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Unai Emery, akọnimọọgba ẹgbẹ agbabọọlu Arsenal tẹlẹ ni wọn ti yan gẹgẹ bi akọnimọọgba Villareal fun ọdun mẹta.
Emery n gba iṣẹ lọwọ Javi Calleja to fi ẹgbẹ agbabọọlu naa silẹ pẹlupẹlu bi wọn ṣe ṣe ipo karun un lori atẹ liigi Spanish Liga, to si fihan pe wọn yoo lanfani lati kopa ninu idije Liigi Europa ni saa to n bọ.
Ṣẹ ẹkọ ẹlẹkọ kuku ni ẹgba ẹlẹgba ni Yoruba maa n wi
Ni oṣu kọkanla ọdun 2019 ni awọn alaṣẹ Arsenal gba iṣẹ lọwọ rẹ lẹyin to lo ọdun kan abọ gẹgẹ bii akọnimọọgba nibẹ.
Ki o to lọ si Arsenal, Unai Emery ti kọkọ ṣakoso ikọ Sevilla ati Valencia lorilẹede Spain.
Mama Arsenal: Màmá àgbà yìí máa ń lọ sí ìbùdó tí wọ́n ti ń wo bọ́ọ́lù láti wòran
Bakan naa lo tun ṣakoso ẹgbẹ agbabọọlu Paris Saint Germain lorilẹede France.
Emery gba iṣẹ lọwọ Arsene Wenger loṣu karun un ọdun 2018 lẹyin to gba ife ẹyẹ Europa mẹta tẹlera pẹlu Sevilla ati ife ẹyẹ liigi ilẹ France pẹlu PSG.
Lockdown updates: Naira Marley gbóríyìn fún Jude Chukwuka pẹ̀lú #1 míliọnù
Ondo, Edo governorship election: Wo ìdí tí oò fi ní lè wọ Amẹ́ríkà bí o bá lọ́wọ́ sí rírú òfin ìbò
Oríṣun àwòrán, Donald Trump/Instagram
Ijọba  ilẹ Amẹrika  ti ni ko ni si fisa fun awọn kan to lọwọ ninu makaruru idibo inu osu kọkanla  ipinlẹ Kogi ati Bayelsa ati gbogbo rogbodiyan to ti ba imurasilẹ idibo Edo ati Ondo ti yoo waye  lọjọ satide ọsẹ yii ati ti ọjọ kẹwa oṣu kewa to n bọ yii rin.
Botilẹ jẹ pe idibo ko tii waye  ni Edo ati Ondo, akowe agba orile-ede Amẹrika Mike Pompeo fofin fisa Amẹrika de  awọn  ẹniyan kan  nitori ipa ti wọn ko bi eto idibo awọn ipinlẹ mejeeji yii se n bọ lọna.
"Gẹgẹ bi atẹjade ti agbẹnusọ eka Morgan Ortagus fọwọ si lọjọ aje ṣe sọ ""ko ni fisa ilẹ Aměrika gbigba fun wọn."
Wọ́n ti fa Ààrẹ Amẹrika, Donald Trump kalẹ̀ fún àmì ẹ̀yẹ Nobel Peace Prize
Ààwẹ̀ gbẹ̀mí ọmọ Naijiria ní orílẹ̀èdè Amẹ́ríkà
Ìtàn ọ̀rẹ́ tó fi ògùn gba ọkọ ọ̀rẹ́ rẹ̀ ni Akomolede BBC Yorùbá fẹ́ kọ́ wa lònìí
Gẹgẹ bi wọn se ko atẹjade naa:
Ni ọjọ kọkandinlọgbọn, oṣu keje, ọdun 2019, a kede pe a fi ofin de gbigba fisa awọn ọmọ Naijiria kan ti wọn lọwọ si magomago idibo ni inu oṣu keji ati ikẹ̀ta ọdun 2019.
" Loni, akowe agba ilẹ Amerika n fi awọn miran kun awọn ti ofin fisa gbigba de nitori ipa ti wọn ko bi eto idibo inu osu kẹsan ati ikẹwaa ṣe n bọ ni Edo ati Ondo
Awọn eniyan wọnyi  huwa aitọ lai fi ti ipa to ni lara awọn ọmọ Naijiria ṣe ati nkan ti o ṣe fun eto ijọba awa ara wa ni Naijiria."
Botilẹ jẹ pe ijọba ilẹ Amerika ko dárúkọ awọn ti ọrọ naa kan, sugbọn o ni igbesẹ awọn ni lati tubọ mu eto iṣejọba awa ara wa ni Naijiria gbopọn sii
"Ẹwẹ atẹjade naa fi ku pe, awọn eniyan kan ni ifofinde yii n ba wi kii ṣe awọn ọmọ Naijiria lapapọ
Afurasí kan yin Oloruntoba níbọn nítorí èdèàìyedè nílé oní Sharwama
Wọ́n ti ní kí Jolaosho TBlak"" wá káwọ́ pọ̀nyìn r'ojọ́ ìdí tó fi ya ""Blue Film"" nínú igbó Osun Osogbo"
'Aràrá bíi tèmi, kó má rò pé kò sì ǹkan tó lè ṣe láyé ju iṣẹ́ agbe lọ'
Ọga Agba ileeṣẹ ọlọpaa ni Naijiria, Mohammed Adamu, ti kilọ fun awọn oloṣelu ni ipinlẹ Edo ati Ondo, to n kopa ninu idibo si ipo gomina l'oṣu Kẹsan, ati ikẹwa.
Ọjọ kọkandinlogun, oṣu Kẹsan-an, ni idibo yoo waye ni ipinlẹ Edo, ti ipinlẹ Ondo, yoo si waye ni ọjọ kẹwa, oṣu Kẹwaa.
Adamu sọ pe dandan ni fun gbogbo awọn oludije, ati alatilẹyin wọn lati pa ofin orilẹ-ede Naijiria mọ, lai si rogbodiyan kankan.
Oriṣiriṣi iṣẹlẹ lo ti n waye ni agbo oṣelu nipinlẹ Edo, paapa lẹyin ti gomina Godwin Obaseki fi ẹgẹ oṣelu APC silẹ, to si darapọ mọ PDP, nitori pe wọn ko fun ni tikẹẹti ẹgbẹ.
Lara awọn iṣẹlẹ to ti waye ni bi wọn ṣe yọ olori ile aṣofin ipinlẹ naa.tyn
Oríṣun àwòrán, Twitter
Idibo sipo gomina ni ipinlẹ Edo naa yoo waye ni Ọjọ Kọkandinlogun, Oṣu Kẹsan, ọdun 2020.
Bi ere itage lo ri ni Ọjọ Aiku nigba ti Alaga ẹgbẹ oṣelu APC tẹlẹri, Adams Oshiomole ati oludije ẹgbẹ oṣelu APC, Osagie Ize-Iyamu kunlẹ lori ẹsẹ mejeeji fun awọn eniyan ni asiko ti ẹgbẹ oṣelu APC  lo ṣe ipolongo rẹ ni ilu Benin.
Oshiomole ati Osagie Ize-Iyamu naa kunlẹ bẹbẹ fun awọn eniyan lati ṣe agbatẹru fun wọn ni asiko idibo to n bọ nipinlẹ Edo naa.
Aafin ọba Edomwonyi Iduozee Ogiegbean, Enigie ti ilu Egbaen ni ipolongo idibo naa ti waye.
Oríṣun àwòrán, Twitter/Osagie Ize-Iyamu
Idibo sipo gomina ni ipinlẹ Edo naa yoo waye ni Ọjọ Kọkandinlogun, Oṣu Kẹsan, ọdun 2020.
Oludije lẹgbẹ oṣelu APC naa lo asiko naa lati kede ipolongo rẹ ati awọn ohun ti yoo gbeṣe ti oun ba bori ninu idibo to n bọ naa. O pe akọle ipolongo naa ni ‘SIMPLE agenda manifesto’.
Oríṣun àwòrán, Twitter/ Osagie Ize-Iyamu
Lara ohun ti Ize-iyamu ni oun yoo ṣe ni lati jẹ ki eto aabo gbooro si ni ipinlẹ Edo ati lati pese owo iranwọ fun awọn ọdọ fun idokowo.
Oríṣun àwòrán, Twitter
O fikun pe oun yoo ṣiṣẹ pọ pẹlu awọn lọbalọba ni ipinlẹ naa fun ijiroro lori ọna ati mu nkan lọ deede fun awọn to wa ni awọn ilu kereje-kereje.
Oríṣun àwòrán, Twitter/Osagie Ize-Iyamu
Osagie Ize-Iyamu naa dupẹ lọwọ awọn lọbalọba to wa ni bẹ fun atilẹyin wọn, ti o si bẹ wọn lati ṣe atilẹyin fun oun nigba ti asiko idibo ba de ni Osu Kẹsan.
O kere tan eniyan mẹwaa ni wọn wa ni ile iwosan lẹ̀yin ti ija bẹ silẹ, laarin awọn onijagidijagan to n ṣe atilẹyin fun gomina ipinlẹ Edo, Godwin Obaseki ati Pasitọ Osagie Ize-Iyamu to n dije labẹ ẹgbẹ oṣelu PDP.
Gomina Obaseki naa n ṣe iṣide ipolongo rẹ saaju idibo sipo gomina ni ipinlẹ Edo ti yoo waye ni Ọjọ Kọkandinlogun, Oṣu Kẹsan, ọdun 2020.
Oríṣun àwòrán, Others
Nibi ipolongo idibo to waye ni aafin Ọba Benin, Ọba Ewuare 11 ni ija ti bẹ silẹ, ti ọpọlọpọ dukia to fi mọ ọkọ ayọkẹlẹ, awọn asia ipolongo ni wọn bajẹ ni agbegbe naa.
Ikọ ipolongo Obaseki da ẹbi rogbodiyan naa ru ikọ ẹgbẹ oṣelu APC, to jẹ alatako rẹ.
Ninu ọrọ tirẹ, Ọba Ewuare pe fun adura lọwọ awọn alalẹ lati gba fun wọn, ki idibo naa lọ ni irọwọrọsẹ.
Oríṣun àwòrán, @GovWike
Ọba Ewuare ke si awọn oloye rẹ lati bẹrẹ adura ni kankan lati jẹ ki alaafia jọba lasiko idibo to n bọ lọna naa.
Ija naa bẹrẹ nigba ti gomina Obaseki to n dari awọn alatilẹyin rẹ lọ si aafin ọba koju awọn onijagidijagan to di oju ọna ati kọja wọn pẹlu ibọn, igo ati ọpọlọpọ ohun ija oloro.
Bi awọn alatilẹyin Obaseki ṣe n rapala wọ afin ọba naa ni awọn alatilẹyin Osagie Ize-Iyamu  na n bu wọn.
Hospital Wedding: Oṣù kan péré ni Tash fi ṣe ìgbéyàwó pẹ̀lú Simon kó tó kú
Lẹyin eyi ni ija bẹ silẹ, ti Gomina Obaseki si kuro nibẹ lọ si papa iṣere Samuel Ogbemudia to wa ni ilu Benin, ni ipinlẹ Edo.
Obaseki ni ibi ipolongo naa sọ fun awọn alatilẹyin rẹ pe ẹgbẹ oṣelu APC lo fa rogbodiyan naa, ti o si pẹtu si wọn lati maṣe gba ẹsan lara wọn.
Ninu ọrọ ti wọn, ẹgbẹ oṣelu APC daun pe Gomina Obaseki ati awọn ololufẹ rẹ gangan lo n fa wahala ati rogbodiyan ni ipinlẹ naa.
Ibo pataki meji ni awọn oloṣelu Naijiria n gbaradi fun lorilẹede yii bayii lọdun yii.
Oríṣun àwòrán, others
Akskọ ni ibo gomina ni ipinlẹ Edo.
Ekeji si ni ibo gomina ni ipinlẹ Ondo.
Amọṣa ilumọọka wolii kan, Primate Elijah Ayọdele ni oun ti gba asọtẹlẹ idajọ Ọlọrun fun ẹnikẹni to ba gbiyanju ati ṣe eru lasiko idibo to n bọ ni ipinlẹ Edo.
Primate Elijah Ayọdele sọ eyi ninu atẹjade asọtẹlẹ kan to gbe jade.
O ni Ọlọrun ti fi ẹni ti yoo bori idibo naa han oun ati pe ẹnikẹni to ba gbiyanju ati tọwọ bọ idibo naa lati eru yoo fori ko idajọ Ọlọrun.
Prophecy 2020: Adeboye àti Ayọdele sọ nípa ọjọ́ ìwájú 2020
Primate ni Ọlọrun ti fi han oun pe arun coronavirus ni yoo pa ẹnikẹni to ba gbiyanju lati doju ibo ru ni ipinlẹ.
COVID-19 ni yoo pa ẹnikẹni to ba ṣe eru ibo
Ọjọ kọkandinlogun, oṣu kẹsan an, ọdun 2020 ni ibo sipo gomina ni ipinlẹ Edo yoo waye.
Kogi vs Bayelsa: Primate Ayodele sọ àsọtẹ́lẹ̀
Yakubu Dogara: Gómìnà Bauchi da ₦4bn owóyàá ìlú sápò iléeṣẹ́ àdáni kan
Oríṣun àwòrán, Yakubu Dogara Facebook
Olori tẹlẹ fun ile asoju-sofin, Yakubu Dogarati kede fun araye pe, ọna aibofin mu ti ijọba ipinlẹ Bauchi n gba gbe isẹ agbase jade, jẹ ọkan lara ohun to mu oun kuro ninu ẹgbẹ oselu PDP.
Dogara sisọ loju ọrọ yii lasiko to n ba BBC sọrọ lati ipasẹ amugbalẹgbẹ rẹ feto iroyin, Turaki Hassan.
Bakan naa lo tun n kọminu lori aisan owo osu osisẹ lasiko ati bi gomina Bala Muhammed se kuna lati seto idibo ijọba ibilẹ laarin osu mẹfa akọkọ to gori oye, gẹgẹ bo ti seleri.
Oríṣun àwòrán, Femi Adesina Facebook
"Ijọba ya biliọnu mẹrin naira, ti wọn si ba owo naa ninu apo asunwọn banki fun ileesẹ adani kan, bi o tilẹ jẹ pe orukọ ijọba ipinlẹ Bauch ni wsn fi ya owo naa.
Bakan naa ni wọn tun n gbe isẹ agbase sita lai bikita, lai naani owo ilọpo meji ti wọn n na lori rẹ lai tẹle abala ofin to yẹ."
Dogara fikun pe, ọkan lara isoro ti oun ri pẹlu awọn asaaju ẹgbẹ oselu PDP ati ijọba ipinlẹ Bauchi ni bi gomina ko se bọwọ fun agba atawọn ọba alaye, lodi si ileri rẹ.
Africa Eye:  Coronavirus di adákẹ́jà ní Somalia, ikú ọ̀wọ́ọ̀wọ́ ń peléke si
Gbogbo awọn isẹlẹ yii si ni olori ana nile asoju-sofin fi ni o mu ki oun ko aasa oun kuro ninu ẹgbẹ oselu PDP lọ si APC.
Amọ sa, Dogara ti wa sẹ lori ahesọ ọrọ kan to n ja ranin-ranin nilẹ pe, oun fẹ du ipo gomina ipinlẹ Bauchi tabi pada sile asoju-sofin, lo mu ki oun pada sinu ẹgbẹ oselu APC.
Yakubu Dogara padà sí APC, Buhari kí i kú àbọ̀ ní Aso Rock
Oríṣun àwòrán, @BashirAhmaad
Gẹgẹ bi a ṣe gbọ ọ, adari ile igbimọ aṣoju ṣofin tẹlẹ, Yakubu Dogara ti pada si ẹgbẹ oṣelu All Peogresives Congress, APC.
Alaga egbe naa, Mai Mala Buni lo fi lede lẹyin ti ohun ati Dogara kọwọ rin lọ si ile Aarẹ ni Aso Rock ni Abuja.
Ẹgbẹ oṣelu APC ni Yakubu Dogara kọkọ wa ko to ṣi lọ si ẹgbẹ oṣelu PDP lasiko ti oun ati aarẹ ile igbimọ aṣofin tẹlẹ, Bukola Saraki jẹ adari awọn aṣofin.
Oríṣun àwòrán, @BashirAhmaad
Dogara ni adari ile igbimọ aṣoju-ṣofin nigba naa.
Ẹwẹ, Dogara ti ni oun yoo ba awọn oniroyin sọrọ laipẹ ọjọ.
Working religious women: Ẹ̀lẹ́hàá kìí ṣe ọ̀lẹ- Aminat Adegoke
Wyclef Police Ibadan: Kí ni Ọ̀gá Ọlọ́pàá yóò ṣe fàwọn Ọlọ́pàá Ibadan tó ṣe obìnrin bó ṣe wù wọ́n nínúu fídíò?
Oríṣun àwòrán, Getty/Screenshot
Lẹyin ti a ṣewadii iwa aidaa si ọmọniyan ti awọn ọlọpaa kan wu si ọmọbinrin kan ti a ri ninu fọnran to gbalẹ kan lọjọru ọjọ kejilelogun oṣu karun ọdun 2020, ileeṣẹ ọlọpaa Naijiria ti da ọlọpaa mẹta mọ to ṣe e ati araalu kan to ba wọn kopa ninu iwa aibofin mu yii.
Agbẹnusọ ileeṣẹ ọlọpaa, Frank Mba lo fi ọrọ yii lede ninu atẹjade wọn pe iṣẹ ti bẹrẹ lori iṣẹlẹ naa.
Ileeṣẹ ọlọpaa Naijiria si ti ri ọlọpaa mẹta, wọn ti mu meji to ṣe obinrin kan bo ṣe wu wọn ninu fọnran ọhun to gba ori ayelujara kan lẹnu ọjọ melo kan sẹyin.
Atẹjade naa fi kun un pe wọn ti mu afurasi meji bayii. ASP Tijani Olatunji ati Insipẹkitọ Gboyega Oyeniyi.
Igbakeji ọga ọlọpaa Mba sọ pe wọn ti ko wọn si atimọle ọlọpaa to wa ni Panti, Yaba ni ipinlẹ Eko.
Oríṣun àwòrán, others
Bakan naa o ni wọn ti tẹra mọ akitiyan lati mu awọn meji to ku.
Ọga agba patapata awọn ọlọpaa lo paṣẹ pe ki wọn ṣe iwadii lẹyin ti fidio bi awọn ọlọpaa yii ni iha Guusu-Ila Oorun Naijiria ṣe ṣe obinrin kan baṣubaṣu gba ori ayelujara kan to si ni ki wọn fi panpẹ ọba mu awọn oniṣẹ laabi naa.
Ohun to ṣẹlẹ gangan
Ninu fidio naa, wọn ko ṣẹkẹṣẹkẹ si obinrin naa lọwọ ti wọn ba ni ile ti wọn ti fẹ lọ mu afurasi ole kan.
Working religious women: Ẹ̀lẹ́hàá kìí ṣe ọ̀lẹ- Aminat Adegoke
Wọn ko ṣẹkẹṣẹkẹ si obinrin naa ti orukọ rẹ n jẹ Towobola lọwọ, wọn ṣe fidio rẹ bi wọn ṣe n bere ọrọ lọwọ rẹ lori ibalopọ oun ati afurasi ọdaran ti wọn fẹ mu.
Fidio naa si ti mu ki ọpọlọpọ fara ya lori ayelujara.
Itan Ilu gangan
Lagos Building Collapse: Èèyàn méjì tó há sábẹ́ ilé tó wó ní Ebute Meta ti ń gba ìtọ́jú, LASEMA ń ṣàyẹ̀wò ilé náà ló̩wọ́
Oríṣun àwòrán, Said
Ile kan to wa ni ọgangan Ileewosan Comprehensive Health Centre ni agbegbe Ebute Meta nipinlẹ Eko la gbọ pe o ti ṣaa dede wo lulẹ funrarẹ ti eeyan meji si ha sabẹ ile naa.
Ajọ to n ri si iṣẹlẹ pajawiri ni ipinlẹ Eko, LASEMA sọ pe arugbo kan ati ọmọbinrin to ha sabẹ ile naa fara pa diẹ ṣugbọn wọn ri wọn doola ti wọn si ti kọkọ n tọju wọn ninu ọkọ ilera to n jẹ LASAMBUS.
Ile to wo yii ti pe ọdun mẹẹdọgbọn, o wa ni nọmba 95, agbegbe Cemetry Street, lopopona Eko si Abeokuta ni Ebute Metta.
Awọn olugbe agbegbe atawọn to n gbe inu ile naa sọ pe o ti n fi ami han pe agara ti da a fun igba diẹ.
Oríṣun àwòrán, Said
Ẹwẹ, iwadii ti ajọ LASEMA ṣe lori ile naa fi han pe alaja mẹta ni ti o si ni ojule mẹfa oni yara kan, palọ kan to si kun fọfọ pẹlu awọn to gba a lẹyin ti atunlekọ kan ti idile kan gba tun un kọ.
Nibayii, wọn ko tii mọ idi pato to fa ile wiwo naa. Amọ awọn oṣiṣẹ pajawirii ajọ LASEMA atawọn nkan mii fun eto ilera ti wọn gbe lọ sibẹ.
Working religious women: Ẹ̀lẹ́hàá kìí ṣe ọ̀lẹ- Aminat Adegoke
Nollywood Round up: Lizzy Anjọnrin fẹ̀si fáwọn agbọ́yì-sọ̀yí lórí ìgbéyàwó rẹ̀, Madam Sajẹ dasójú ilé iṣẹ́ àti àwọn ǹkan míràn tó ṣẹlẹ̀ lágbo tíátà lọ́sẹ̀ yìí
Oríṣun àwòrán, others
Lara awọn iroyin to migboro titi lagbo oṣere tiata Yoruba lọsẹ yii ni bi awọn kan  ṣe n ṣe ọjọ ibi lawọn mii n ṣe igbeyawo.
Ki a ma deena pẹnu rara, diẹ re lara awọn iṣẹlẹ to jẹyọ nigbesi aye awọn oṣere tiata Yoruba loṣu yii ree.
Gẹgẹ bi ohun to sọ, oun ati ololufẹ rẹ ọhu ti n bara wọn bọ lati nnkan bi ọdun mẹrinla gbako.
Bimbo Oshin
Ọjọ kẹrinlelogun oṣu keje ọdun 1971 ni wọn bi Bimbo Oshin, agbaọjẹ si ni ninu iṣẹ tiata.
Pupọ ninu awọn ojugba rẹ ninu iṣẹ tiata Yoruba lo n kii ni mẹsan an mẹwaa lọjọ to n ṣe ayẹyẹ ọjọ ibi ọhun, koda ọgbẹni kan fi orin aladun kan sọri rẹ.
Oríṣun àwòrán, Bimbo Oshin
Bakan naa ni ileeṣẹ kan yaa lẹnu pẹlu ẹbun bantabanta lọjọ naa.
Doris Simeon
Ọjọ meji ṣaaju ọjọ ibi Bimbọ Oshinn ni gbajugbaja oṣere miran, Doris Simeon ṣe ọjọ ibi.
Oriṣiriṣi aworan to dun n wo loju ni Doris ko si oju opo Instagram rẹ lọjọ naa to pẹ ẹni ọdun mọkanlelọgbọn loke eepẹ.
Pupọ ninu awọn agba ọjẹ ninu awọn oṣere ẹgbẹ rẹ atawọn amuludun miran lo n kii ni mẹsan an mẹwaa.
Oríṣun àwòrán, Doris_Simeon
Working religious women: Ẹ̀lẹ́hàá kìí ṣe ọ̀lẹ- Aminat Adegoke
Lara wọn  ni Dayo Adeneye, Foluke Daramola, atawọn eeyan Kunle Afod, atawọn eeyan jankan jankan miran.
Mide Martins
Oríṣun àwòrán, Mymidemartins
"Laarin ọsẹ yii kan naa ni Mide Funmi Martins tẹsiwaju ninu fiimu kan ti wọn ya lọwọ, ""Enu mi."""
Ọkọ rẹ Afeez Olayiwola Abiodun ti ọpọ eeyan mọ si Afeez owo lo n dari fiimu naa.
Lara awọn to n kopa ninu fiimu ọhun ni Mide Funmi Martins funra rẹ, Omotayo Amokade ti ọpọ mọ si Ijebu, atawọn oṣere n la mii lo kopa ninu ere ọhun.
Adebimpe Oyebade àti Lateef Adedimeji
Bí ọ̀ṣẹ méjì sẹ́yìn ni òkìkí kan nígbà ti àwòràn kan fẹ́ fa orí ayélujára ya lórí pé bóya Adebimpe àti Adedimeji ṣe ìgbéyàwó.
Sùgbọ́n gbogbo ǹkan to wà nínú ìgò náà tó ń jẹ́ jìínì ti fójú hàn báyìí nígbà ti Adebimpe kédé pé, ọbẹ̀ ti àwọn ń se ti jina tan
"O ní àkọlé eré ti àwọn ṣe pọ̀ náà ni ""Resentment''"
Oríṣun àwòrán, Adebimpe
Ọ̀pọ̀ ọmọ Nàìjíríà ló ti ń ṣe sàdánkáta  kare sí wọ́n lóri sinimọ agbélé wò náà.
Fausat Balogun àti Laide Bakare
Nínú ọ̀ṣẹ̀ yìí ìṣẹ̀lẹ̀ mánigbàgbé ni bi Fausat Balogun ti gbogbo ènìyàn mọ si Madam Ṣajẹ náà sé tọwabọ iwé àdéhun pẹ̀lú ilé iṣẹ́ kan.
Madam Ṣajẹ yóò ma sojú wọn ilé iṣẹ kan ti wọ́n ntale talẹ.
Ọ̀pọ̀ àwọn olólufẹ gbájúgbaja eléré tíátà náà ló ti ń baa dáwọ ìdúnu ní gbogbo rí ayélujára
Ẹ̀wẹ́ lọ́jọ́ kan náà ni Laide Bakare náà tọwọ́ bọ ìwé àdéhùn pẹ̀lú ilé iṣẹ́ tó mójútó ilé àti ilẹ̀ rírì nílùú Ibadan láti jẹ asojú ilé iṣẹ́ náà.
Ìdùnnú subú layọ̀ láàrìn àwọn òṣèré tíátà nínú ọṣẹ yìí. Awọn olólùfẹ́ wọ́n nínú eré tíàta àti láwùjọ ló ti n bá àwọn gbájúgbajà òṣèré méjèèjì dáwọ idùnú.
Lizzy Anjorin
Oríṣun àwòrán, Lizzyanjorin/instagram
Tí ẹ o bá gbàgbé Lizzy Anjonrin ṣe ìgbéyawó laipẹ yìí,  to sí fí àwọn fóto ìgbéyàwó náà síta lórí àtẹjíṣẹ rẹ̀ ni ọṣẹ̀ tó kójá òdé yìí.
Sùgbọ́n ó ìyawó ọ̀lẹ̀lé ti pada sórí ìkànsiraẹni Instagram láti fún awọn agbọ́yì sọ̀yí lésì lórí ǹkan ti wọ́n ń sọ nipa ọkọ rẹ̀.
Nínú ọ̀rọ̀ rẹ̀, Lizzy Anjonrin to ti di Abilekọ Lawal ni kí gbogbo àwọn agbọ́yì sọ̀yí lọ gbọ dáada pé ọkọ oun ko fẹ́ ìyàwó mẹrin ko to fi oun ṣaya.
Lizzy sọ èyí di mímọ lójú òpó Twiiter rẹ̀ pé ìdí ti òun fi jáde fẹ̀sì sí ọ̀rọ̀ náà nitóri  ìrú ipò ti òun dìmú  láwùjọ.
Ǹkan to sọ rèé
Peters Ijagbemi dá àrá lórí ètò 'Ṣé o láyà' ti BBC Yorùbá lọ̀sẹ̀ yìí
Orukọ miran wo ni Yoruba n pe Odidẹrẹ?
Agba lo toro lọ......
Awọn ibeere wọnyii ati omiran ni BBC Yoruba beere lọwọ gbajugbaja oṣere ni, Peters Ijagbemi lori eto 'Se o laya'.
Eto yii la maa n fi beere awọn ibeere lede Yoruba lọwọ awọn oju oge ti igba oju mọ lawujọ.
Pataki eto yii ni ki onikaluku le kọ ẹkọ nipa awọn ede ati aṣa Yoruba to ti n wa si igbagbe lasiko yii.
Peters Ijagbemi gbiyanju ipa rẹ ṣugbọn eyin naa le tun ran an lọwọ ninu awọn ibeere to ku diẹ ko gba.
Iya Jogbo Dead: Ọ̀pọ̀ olólùfẹ́ Emmanuella Pobeni Adepoju kẹ́dùn ikú rẹ̀
Oríṣun àwòrán, Twitter
Ọ̀pọ̀ olólùfẹ́ olóògbé gbajúgbajà sọ̀rọ̀sọ̀rọ̀ lóríi rédíò Max FM, Emmanuella Pobeni Adepoju tí gbogbo àwọn olólùfẹ́ rẹ̀ mọ̀ sí iyajogbo  ló ti ń fi ẹ̀dùn ọkàn wọn hàn lórí ìròyìn ikú rẹ̀,
Iyajogbo jẹ́pè Ọlọ́run lẹ́yìn aiasan ranpẹ pẹ̀lú àìsàn ọkàn.
Awọn eniyan fẹran rẹ nitori o ma n dapara lori redio pẹlu Walepowpow ati Obus lori eto 'Wetin Dey show'.
Oríṣun àwòrán, Facebook
Ọpọ ṣapejuwe Iya Jogbo gẹgẹ bi awokọṣe rere fun awọn ọdọ iwoyi
Awọn miran si gabdura fun ẹbi rẹ ati awọn ọmọ rẹ pe ki Olorun tu wọn ninu.
Oríṣun àwòrán, Facebook
Awọn ololufẹ miran tilẹ sọ wi pe oninuure ni Iyajogbo naa, to jẹ irufẹ eniyan ti a le fi yangan.
Awọn miran ni nitori Iyajogbo ni awọn ti ṣe n gbọ eto ‘Wetin Dey Happen’ lati kekere.
Awọn miran royin ipa ribirbi ti eto rẹ n kọ lọkan awọn to n gbọ ọ
Ọ̀pọlọpọ awọn ololufẹ rẹ lo n gbadura kí Edumare tẹ́ẹ sí afẹ́fẹ́ rere.
Working religious women: Ẹ̀lẹ́hàá kìí ṣe ọ̀lẹ- Aminat Adegoke
Emmanuella Pobeni Adepoju dágbere fáyé pé ó dìgbà ó ṣe
Gbajúgbajà sọ̀rọ̀sọ̀rọ̀ lóríi rédíò Max FM Emmanuella Pobeni Adepoju tí gbogbo àwọn olólùfẹ́ rẹ̀ mọ̀ sí iyajogbo ti papòdà.
Gẹ́gẹ́ bí ọ̀gá àgbà Iléesẹ́ TVC, Andrew Hanlon ṣe sọ nínú Ìkéde rẹ̀, iyajogbo jẹ́pè Ọlọ́run lẹ́yìn tó pàdánù ìjà pẹ̀lú àìsàn ọkàn.
Ìyá Jogbo, ẹni tí Hanlon sọ pé ó bá Iléesẹ́ TVC ṣiṣẹ́ fún bíi ọdún mẹ́wàá, gbajúmọ̀ púpọ̀ lórí ètò kan tó máa ń wáyé lórí Max FM èyí tí orúkọ rẹ̀ ń jẹ́ ''wetindey''.
Peters Ijagbemi dá àrá lórí ètò 'Ṣé o láyà' ti BBC Yorùbá lọ̀sẹ̀ yìí
Church of Satan: Báwo ni ìjọ́sìn ṣe n rí nínú ìjọ Sátánì?
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Anton Szandor LaVey, oludasilẹ ijọ Satani. Ọdun 2007 lo kú.
Laipẹ yii ni ile ẹjọ giga ti ijọba apapọ Naijiria, to wa ni ilu Umuahia nipinlẹ Abia, gba oniduro oludasilẹ ijọ Satani, Ifekwe Udo.
Oun ati awọn mẹtadinlogun miran, ni awọn ọlọpaa mu nitori ija igboro to waye ni Ebem Ohafia.
Awọn ara ilu naa fi ẹsun kan Udo ati ijọ rẹ pe, apẹẹrẹ buruku ni wọn jẹ fun ilu naa, ti wọn si ba awọn dukia ijọ naa jẹ.
Oríṣun àwòrán, The sun newspaper
Lara ẹsun ti awọn araalu tun fi kan an ni pe, o n da alaafia ilu naa ru.
Koda, ijọba ibilẹ naa ti sọ pe ko tun gbọdọ ko ijọ rẹ jọ mọ ni ilu naa, nitori pe o n ta epo si aṣọ àlà ilu naa.
Ọgbọnjọ, oṣu Kẹrin, ọdun 1966 ni wọn da ijọ Satani silẹ, lati ọwọ Anton Szandor LaVey, nilu San Francisco l'orilẹ-ede America.
Gẹgẹ bi akọsilẹ to wa ni itakun agbaye ṣọọṣi naa, oun ni ipejọpọ akọkọ to n gbe igbe aye rẹ gẹgẹ bi ẹlẹran ara.
Fun awọn olujọsin, wọn ko sin Satani, ṣugbọn wọn ri i gẹgẹ bi apẹẹrẹ to ba iru eeyan ti wọn jẹ mu nipa ìbí.
Wọn sọ pe esu duro gẹgẹ bi awokọṣe fun igberaga, ominira, ati gbigbe igbe aye ẹni lọna to wu ni - awọn amuyẹ ti awọn kan n pe ni iwa buburu.
Igbagbọ awọn ọmọ ijọ Satani ni pe eniyan, nipa ọgbọn inu rẹ, lo da gbogbo awọn ọlọrun ke ke ke.
Ẹnikẹni to n sin iru awọn ọlọrun bẹ ẹ, ẹni to da a ni wọn n sin.
Oríṣun àwòrán, CHURCH OF SATAN ARCHIVES
Ko tan sibẹ o, awọn ọmọ ijọ Satani sọ pe awọn ni ọlọrun ara wọn.
Ati pe awọn n fi ifẹ han si ẹni to ba tọ si, ati ibinu si ẹni to ba mu inu bi wọn, tabi tapa si igbagbọ wọn.
LaVey gbagbọ pe, Ọlọrun awọn Kristiẹni ko ni òye tabi ni imọ nipa bi ko ṣe rọrun lati jẹ eniyan ẹlẹran ara.
"O si pinnu lati fi opin si ""iye rira, ati abosi, ti awọn ṣọọṣi ẹsin Kristiẹni n polongo""."
Oríṣun àwòrán, GEMMA PURKISS
Awọn ọmọ ijọ naa gbagbọ pe awọn n ja lati ma jẹ ki orilẹ-ede America di ti ẹlẹ́sìn kan ṣoṣo
Ati nnkan ti yoo mu ki awọn eeyan ni ominira lati lo agbara okunkun fun ifẹ ara wọn.
"Oriṣa kan to si farajọ iru nkan to fẹ ni Satani - ""ẹda to n fun ni ni èrè to yẹ."
Ẹni to jẹ pe dipo ki o dá ẹṣẹ, ki ẹri ọkan o le ma a jẹ awọn eeyan, o kuku fi aaye gba titẹ ifẹ ara ẹni lọrun.
"Oun nikan ni oriṣa ti ọrọ wa ye."""
Ibẹrẹ ijọ Satani:
"Lati nkan bi ọdun 1950, ni awọn to faramọ erongba LaVey ti n sun mọ ọ, nipa kikorajọ pọ si ile rẹ ""Black House"" nilu San Francisco."
Oríṣun àwòrán, Others
Ile yii, 'Black House' ni ijọ Satani ti bẹrẹ nilu San Fracisco
Awọn iwadii ti LaVey ṣe nipa ẹmi okunkun, lo pilẹ bi wọn ṣe n lo ẹgba ọrun dudu ati pupa, to ni aworan ẹyẹ àdán.
Ṣọọṣi naa tun sọ pe lẹyin ọdun diẹ, LaVey bẹrẹ si iṣẹ idán okunkun ati agbara irubọ, o n ṣe nipa igbega lẹni iṣẹ, ẹbun ọfẹ, owo, adun ibalopọ, ati pipa tabi yanju awọn ọta rẹ.
Eyi lo tubọ mu ki ọpọ eeyan sun mọ, nitori wọn gbagbọ pe, o ti ni aṣẹ Agbara Okunkun Aye.
Laarin ọdun kan aabọ ti wọn da ijọ Satani silẹ, ẹẹmẹta ni ariwo sọ lori rẹ ninu awọn iwe iroyin.
Igba akọkọ ni ti igbeyawo to waye laarin gbajugbaja akọroyin kan, John Raymond, ati Judith Case, ọmọ gbajugbaja agbẹjọro.
Awọn mejeeji lo jẹ ọmọ ijọ, ti wọn si kesi Olori Alufaa wọn, LaVey lati so wọn pọ ni orukọ Satani.
Gbogbo ileeṣẹ iroyin nilẹ America, to fi de Europe lo fẹ ẹ ni aṣoju nibi eto igbeyawo naa, lati kọ nipa ara meeriri igbeyawo ọhun.
Ipele àṣẹ ninu ijọ Satani:
Ọmọ ijọ to f'orukọ silẹ
Ọmọ ẹgbẹ to n ṣe deede (Oye Akọkọ)
Ajẹ/Oṣo (Oye keji)
Alufaa ọkunrin/obinrin (Oye kẹta)
Magistra/Magister (Oye kẹrin)
Maga/Magus(Oye Karun un)
Ilana Ijọsin wọn:
Oríṣun àwòrán, GEMMA PURKISS
Ijọ naa ma n ṣe isin 'Black Masses', to si ma n jọ ere ori itage
Irubọ wọn akọkọ jẹ iṣọtẹ si ẹsin Kristiẹni. N ṣe ni wọn sẹ pẹpẹ obinrin to wa ni ihoho, pẹlu orin ikọkukọ.
Koda, wọn dori agbelebu kodo, ti wọn si ka Adura Oluwa lati ipari.
'Omi mimọ' ti wọn gbe kalẹ ni wọn sọ di aimọ, nipa kiki nkan si oju ara obinrin.
Ọti wiski ni wọn fi jẹ ounjẹ alẹ Oluwa dipo ẹjẹ Jesu.
Awọn orukọ oriṣa ni wọn si n pe, dipo orukọ Ọlọrun awọn Kristiẹni.
Igbakeji ni asiko ti LaVey ṣe iribọmi fun ọmọ rẹ obinrin ni ilana Satani.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Anton Szandor LaVey, lasiko to n sẹ iribọmi fun ọmọ rẹ, ọmọ ọdun mẹta, Zeena Galatea LaVey
Dipo riri ọmọ naa sinu omi, ẹnu ọna pẹpẹ ijọ ni ọmọ naa joko si, pẹlu oriṣiriṣi nkan ti ẹnu n jẹ.
Bakan naa lo wọ koto to ni aworan Satani si ori, to si ka oriṣiriṣi ọrọ lati jẹjẹ atilẹyin ati ifọkansi fun Satani.
Ọpọlọpọ wọn ko sin Satani:
Iyalẹnu to wa nibẹ ni pe ọpọlọpọ awọn to jẹ olufọkansin ninu ijọ naa kii jọsin fun Satani - wọn ko gbagbọ ninu ọlọrun kankan.
Wọn ko tako ṣiṣe ọdun Keresimesi:
Iyalẹnu nla ni eyi jẹ lati ri i pe wọn faramọ ṣiṣe ajọyọ ọjọ ibi Jesu.
Oríṣun àwòrán, GEMMA PURKISS
Igbagbọ wọn nipe lọwọ awọn ẹlẹsin ibilẹ ni awọn Kristiẹni ti ja akoko ayẹyẹ naa gba.
Ṣugbọn ṣa, Baba Keresi jẹ ọna lati dun ara ẹni ninu, eyi to jẹ ọkan pataki lara afojusun wọn.
Ni asiko yii, a n gbadun adun aye, a si wà pẹlu awọn ti a fẹran.
O ko le ri ijọ Satani kankan ni agbegbe rẹ:
"Gẹgẹ bi o ṣe wa lori itakun agbaye wọn, ijọ Satani ko ni ile ijọsin kankan, nitori pe ""o tako ilana ti ẹnikọọkan wa n gba lo igbeaye wa."
Oríṣun àwòrán, churchofsatan.com
Yatọ si ile oludasilẹ rẹ, ti wọn ti bẹrẹ ijọ naa, wọn ti fi igba kan ni awọn ẹka ile ijọsin , ṣugbọn wọn ti tu wọn ka, nigba ti wọn ro o pe ko ba oju mu.
Koda, Olu ijọ naa ti kuro ni ile LaVey ni San Francisco, o si ti wa ni ilu New York.
Wọn ko si fi  aaye silẹ fun ẹnikẹni lati ṣe abẹwo si ibẹ.
Ida kọnkọ si ni wọn ti maa n ṣe awọn ayẹyẹ wọn.
Ti alejo nile rẹ ba mu inu bi ọ, huwa si i laini aanu
Ma ṣe ni ibalopọ ti ẹni naa ko ba fi ami han pe, oun fẹ ẹ ba ọ lopọ
Ma ṣe pa awọn ọmọde lara
Ma ṣe pa ẹranko, ayafi fun ounjẹ rẹ tabi ti o ba doju ija kọ ọ
Ma ṣe wa ija ẹnikẹni, ṣugbọn o le pa ẹni to ba wa ija rẹ run, lẹyin ti o ba ti kilọ fun.
Awọn nkan ti wọn ka si ẹṣẹ ni jijẹ omugọ, imọ tara ẹni nikan, ki eeyan o ma a dibọn, titan ara ẹni jẹ, aini
Ijọ naa tako lilo, ati katakara oogun oloro.
Wọn gbagbọ pe ọmọ ijọ to ba tako ofin to de oogun oloro ni orilẹ-ede rẹ, ṣe e si iparun ara rẹ.
Ijọ Satani kii ṣe fun talika:
Igba ati marundinlọgbọn Dọla (N81,000) ni ọmọ ẹgbẹ tuntun ma n san lati darapọ.
Eyi si da lori bi ẹni naa ba ṣe le dahun awọn ibeere ti wọn ba bi i.
Igbakuugba si ni wọn le fi opin si jijẹ ọmọ ẹgbẹ fun ẹni naa.
Cancer Marriage: Oṣù kan péré ni Tash fi ṣe ìgbéyàwó pẹ̀lú Simon kó tó kú
Yoruba ni airin jinna ni airi abuke ọkẹrẹ, bii eeyan ba rin jinna, yoo ri ibi ti wọn ti n fi odo ibulẹ jẹun.
Bẹẹ ni ọrọ ri pẹlu tọkọ-taya kan, Tash ati Simon Young, ti wọn se igbeyawo nile iwosan nigba ti dokita ni arun jẹjẹrẹ to n se iyawo, ko ni pẹ mu ẹmi rẹ lọ.
Nigba to n ba BBC srọ, Simon ni osu kan pere ni oun ati aya oun, Tash, fi se igbeyawo ko to dagbere faye, ọjọ mẹrin pere si ni awọn fi palẹmọ fun igbeyawo naa.
Simon ni ọjọ igbeyawo naa ni inu oun dun julọ, paapaa, nigba ti oun n wo aya oun bo se n rin ati bo se n rẹrin musẹ.
Fidio yii, koseemawo ni, ninu rẹ naa lẹ ti gbọ ohun ti awọn dokita atawọn ẹbi iyawo sọ nipa obinrin naa ati ọrọ ifẹ Tash ati Simon Young.
Domestic Chores: Ọ̀pọ̀ àbíkẹ́yìn ń bèèrè pé ṣé ègún ni láti kẹ́yìn nínú mọ̀lẹ́bí?
Oríṣun àwòrán, Others
Se ni oju opo Twitter n gbona fẹlifẹli ni aarọ ọjọ Aiku, nigba ti ọmọbinrin kan fi ọrọ aburo rẹ, tii se abikẹyin ile wọn, to araye leti.
Gẹgẹ bi Mira Jones ti safihan lẹta kan loju opo Twitter rẹ, @mirajones, o ni abikẹyin ile awọn, Mehitabelle Jones Emmanuela lo faraya pe isẹ ile n pa oun lori lọ.
Ninu lẹta naa si ni abikẹyin naa ti gbe awọn ofin tuntun kalẹ, to si n sọ nipa awsn isẹ ile ti yoo maa se ati eyi ti yoo pa ti.
Koda, gbogbo mọlẹbi rẹ ni ọmọbinrin naa darukọ lọkọọkan, to fi mọ aja wọn, to si sọ isẹ to fi silẹ fun ikọọkan wọn.
Oríṣun àwòrán, Others
Ninu lẹta naa ni Mehitabelle ti ni abọ ti oun ati awọn obi oun nikan ba fi jẹun ni oun yoo maa fọ, koda, oun ko ni fọ ikoko ti wọn ba fi se ọbẹ abi ounjẹ rara.
Bakan naa lo ni oun yoo maa wẹ fun aja awọn, Zyron ni ọsọọsẹ, oun yoo si maa ko igbẹ rẹ pẹlu, to fi mọ titun ibugbe rẹ se.
Ọmọbinrin abikẹyin naa ni isẹ oun kọ ni titun yara igbalejo awọn se, amọ oun yoo maa tan ẹrọ amunawa wọn ni alaalẹ, ẹnikẹni ko si gbọdọ wa ji oun lati wa pa, ti oun ba ti lọ sun.
Hospital Wedding: Oṣù kan péré ni Tash fi ṣe ìgbéyàwó pẹ̀lú Simon kó tó kú
O fikun pe oun yoo maa fa omi tabi pọn omi gẹgẹ bi oun ti n se tẹlẹ, ti oun yoo si maa rọ omi sinu ike ti wọn n gbe sinu ẹrọ amomitutu.
Mehitabelle wa n gbarata pe isẹ ile ti wọn gbe le oun lori ti pọ ju, to si n beere pe se egun ni pe kii eeyan jẹ abigbẹyin ninu ile ni?
Koda, o tun fi ẹsun kan awọn ẹgbọn rẹ pe wọn roju debi pe wọn ko lee fa ina tọọṣi kuro lẹnu ina funra wọn, oun ni oun n se e.
Abikẹyin naa ni sinima nikan ni ẹgbọn oun Michelle maa n wo lọpọ igba to ba wa nile, o si kundun ko maa jade lọ.
Koda, o ni ti Ọlọrun ba fi ọwọ tọ lọkan pe ko se ounjẹ fun awọn ni ẹkọọkan, bii igba ti eeyan jẹ majele ni nitori apọju ata.
O ni yoo tun wa fi awọn ikoko to fi dana silẹ fun oun lati fọ.
Lakota, Mehitabelle wa n fewe ọmọ mọ awọn ẹgbọn rẹ leti pe gbogbo awọn lo ni aja to wa ninu ile, ojuse apapọ awọn si ni lati tọju rẹ.
Ọrọ yii si ni awọn eeyan ti n gba bii ẹni gba igba ọti loju opo Twitter, ti ọpọ abikẹyin ti ọrọ naa kan julọ, si n sọ awọn iriri tiwọn naa, eyi to pa ni lẹrin pupọ.
Ghana Witches: Wò bí wọ́n ṣe pa ìyá ẹni ọdún 90 tí wọ́n pè ní àjẹ́
Oríṣun àwòrán, facebook/ AFia pokua
Iya agba ẹni aadọrun ọdun kan, ni iya ooṣa kan atawọn aladugbo kan ti sọ lokuta pa lori ẹsun pe ajẹ ni.
Iya olooṣa yii fi ẹsun kan iya arugbo ọhun, ti orukọ rẹ n jẹ Akua Denteh pe ajẹ mujẹmujẹ ni.
Eyi lo si sun awọn ara adugbo lati dide si iya arugbo naa, wọn fi oniruuru iya jẹ ẹ titi to fi gbe ẹmi mi.
Ni ilu Kafaba, lagbegbe Salaga ni orilẹede Ghana ni iṣẹlẹ yii ti waye.
Fidio kan eyi to gbalẹ bi iso ẹwa lori ayelujara lo ṣafihan bi wọn ṣe yi iya arugbo naa ka, ti wọn si n lo awọn nnkan lati gba a lori.
Africa Eye:  Coronavirus di adákẹ́jà ní Somalia, ikú ọ̀wọ́ọ̀wọ́ ń peléke si
Wọn n digbaju luu, wọn yọ ẹgba ti i fun ọpọlọpọ igba, bi o ṣe joko sori ilẹ titi ti ẹlẹmi fi gba a.
Iroyin sọ pe wọn gbe iya arugbo naa lọ si ile iya olooṣa ọhun.
Iya olooṣa naa pe awọn ayajọ kan, lo ba kede fun gbogbo awọn to wa nibẹ pe ajẹ ni iya arugbo naa.
Lẹyin eyi ni wọn ba din dundun iya fun iya agbalagba naa.
Lẹyin ọpọlọpọ lilu yii ni mama naa daku, ti wọn si fun un ni agbo kan mu ki wọn to gbe e lọ si ile rẹ nibi to ku si.
Peters Ijagbemi dá àrá lórí ètò 'Ṣé o láyà' ti BBC Yorùbá lọ̀sẹ̀ yìí
Awọn ọlọpaa ti gbe oku iya agbalagba naa lọ si ile igboku pamọ si kan, ni ile iwosan nla Tamale Teaching Hospital fun ayẹwo.
Ni bayii, ọga agba ọlọpaa lorilẹede Ghana, James Oppong-Boanuh ti ran awọn agbofinro lọ si ẹkun naa lati lọ ṣawari iya olooṣa ọhun, atawọn araalu to pa obinrin naa.
Gẹgẹ bi ọlọpaa ṣe sọ, wọn n wa iya Hajia Filina to jẹ iya olooṣa naa, eeyan kan torukọ rẹ n jẹ Aliu to jẹ olukọ, Bumaye, Ashley ati Manafo, ti iroyin sọ pe wọn ti juba ehoro.
Ẹgbẹrun meji Cedi owo ilẹ Ghana ni wọn ti kede gẹgẹ bi ẹbun, fun ẹnikẹni to ba lee ran ọlọpaa lọwọ lati ṣawari wọn.
Violence against women: Ilé aṣòfin Kano buwọ́ lu òfin gígé ǹkan ọkùnrin afipabánilòpọ̀
Oríṣun àwòrán, Others
Igbimọ awọn Ulamas nipinlẹ Kano ti kọ abadofin ti ile igbimọ Aṣofin ipinlẹ naa buwọlu, lati ge nnkan ọkunrin ẹnikẹni ti o ba fi ipa ba obinrin lopọ.
Ile igbimọ Aṣofin naa buwọlu abadofin to faaye gba ki wọn ge nnkan ọmọkunrin, lẹyin ti aṣofin Nuraddeen Alhassan gbe abadofin naa kalẹ ni Ọjọ kẹẹdogun, Oṣu Keje, ọdun 2020.
Ninu atẹjade ti awọn Ulamas naa fi lede, ti Alaga igbimọ naa, Sheik Ibrahim Khalil buwọlu sọ pe, awọn kọ ofin naa patapata lẹyin ti awọn ṣe agbeyẹwo rẹ.
Oríṣun àwòrán, Others
Bakan naa ni wọn pe fun atunṣe ofin Sharia ti ọdun 2000 ni ipinlẹ Kano.
Oríṣun àwòrán, Others
Amọ, Khalil fikun pe ipinnu awọn ko tun mọ si pe  awọn gba ifipabanilọpọ laaye, abi awọn n ṣe agbatẹru fun awọn to n wu iwa buruku yii.
Igbimọ awọn Ulamas naa ni awọn yoo ṣe abẹwo si ile igbimọ Aṣofin ipinlẹ naa lati ba awọn aṣofin jiroro lori ọna abayọ si ofin tuntun naa, ni ọna ti yoo tẹlẹ ẹsin Islam.
Gbogbo awọn majẹobajẹ lorilẹede Naijiria ni wọn n ke gbajare lori ọwọja iwa ipa si awọn obinrin, paapaa julọ ifipabanilopọ.
Oríṣun àwòrán, others
Ọrọ naa gba ibi ọtọ tun yọ pẹlu iroyin arakunrin kan ti orukọ rẹ n jẹ Sani Garba ti wọn ni o fipa ba obinrin ẹni ọgọta ọdun lopọ.
Kayefi nla lo jẹ nigba ti Sani ṣalaye idi to fi hu iwa buruku to hu naa.
O ni idi iya naa to maa n ji nigbakugba to ba n rin lo mu ki oun ma lee mu ara duro mọ ti oun si fi lo ipa fi baa lo.
Hmmmm, ọrọ buruku tountẹrin. Ni bi a ṣe n sọrọ yii, ọwọ ọlọpaa ti tẹ Sani Garba ni ipinlẹ Niger.
Iroyin abẹle sọ wi pe nṣe ni afunrasi naa ja wọ yara arabinrin naa ni ọjọ kejidinlogun oṣu keje ni nnkan bi agogo mẹrin abọ irọlẹ to si fi ipa baa lo pọ.
Bakan naa ni afunrasi naa tun ṣalaye fawọn akọroyin pe ko din ni obinrin arugbo mẹta ti oun ti fipa ba lopọ ladugbo naa.
O ni oun ko lowo lati fi fẹ ọmọge loun fi doju kọ awọn abilekọ ati arugbo.
Hydroxychloroquine, Zinc ati Zithromax : Ààrẹ Trump tí sọ̀rọ̀ nípa Dókítà Stella Immanuel,ẹ gbọ́ ohùn tó sọ
Oríṣun àwòrán, Getty/Twitter
Aarẹ orilẹede Amẹrika, Donald Trump ti fesi lori ọrọ Dokita Stella Immanuel to sọrọ pe Hydroxychloroquine (HCQ), Zinc ati Zithromax jẹ oogun to daju lati wo awọn to ba ni arun Covid-19.
Ninu ọrọ rẹ, o gbaruku ti Dokita yi to si sọ pe awọn onimọ iṣegun n tako lilo oogun yi nitori pe ohun ni oun kọkọ sọ pe ki awọn eeyan ma lo.
O fi ọrọ yii sita lẹyin ti oju opo Twitter gbọn ọmọ rẹ agba lọkunrin kuro lori opo wọn nitori pe o ṣe alabapin fidio ti Dokita Stella ti sọ pe ki awọn eeyan ma lo Hydroxychloroquine (HCQ).
Ki gaan ni Aarẹ Trump sọ?
Lasiko to n ba awọn akọroyin sọrọ ni Ile Ijọba Amẹrika, White House ni Aarẹ Trump fesi lori ọrọ yii ni idahun si akọroyin to ni ki lo ri si ọrọ naa.
Aarẹ Trump sọ pe ''Mo le sọ fun yin pe arabinrin naa ati awọn Dokita miran ti wọn faramọ lilo oogun Hydroxychloroquine  ni wọn jijọ sọrọ lori afẹfẹ.
Mo si le ro pe ọrọ rẹ jọju  botilẹjẹ wi pe mi o mọ ibi to ti wa.
Ṣugbọn o sọ pe oun ti ṣe aṣeyọri pupọ lori lilo oogun yi pẹlu awọn alarun Covid-19.Mo lero pe o ṣe apataki ki a tẹti gbọ ọrọ rẹ ṣugbọn mi o mọ nkankan nipa rẹ''
Kete to sọrọ yii tan lo ba wọ inu ọfisi rẹ lọ pada.
Bakan naa ni Aarẹ Trump sọ fun awọn akọroyin ni Ọjọ Iṣẹgun pe: ''Ohun ti o ye mi nipa ọrọ yi ni mo le sọ.
Ti a ba si fi bi mo ti ṣe ka nipa arun yi ati imọ ti mo ni,mo lero pe lilo hydroxychloroquine lati tọju awọn eeyan nibẹrẹ ni anfaani to pọ''
''Mi o lero pe eeyan le padanu nkankan ti o ba lo bi kii ṣe pe lọdọ awọn oloṣelu ọrọ yii ko ta leti wọn''
Trump fi kun pe ''Bi mo ba daba nkan , wọn maa n fẹ lati sọ pe 'ẹ ma tẹlẹ ọrọ rẹ' .''
''Ẹyin ti ẹ lo hydroxychloroquine ti ara yin si ya, ẹ bọsita wa jẹri mi''
Dokita Stella Immanuel ti kesi gbogbo awọn ti  oun ati awọn Dokita miran ti tọju pẹlu  oogun hydroxychloroquine lati yọju lati wa jẹri si iṣẹ rere ti oogun yi ṣe lagọ ara wọn.
O fi ọrọ yii sita ninu fọnran fidio kan lẹyin ti Twitter yọ fidio to kọkọ ti sọrọ nipa lilo oogun yii lati tọju arun Covid-19.
Eeyan to le ni eeyan ọọdunrun ti Dokita Stella ti sọ pe oun tọju pẹlu Hydroxychloroquine ti ara wọn si ti ya.
Oríṣun àwòrán, Twitter
O sọ pe ''ti o ba ti lo hydroxychloroquine ti ara rẹ si ti ya. Asiko rẹ lati jade wa sọrọ. A fara da ewu to pọ lati tọju yin, koda a fi ẹmi awọn mọlẹbi wa sinu ewu lati tọju yin''
Stella fi kun pe ''A ni lati jẹ ki awọn eeyan mọ pe awọn eeyan tia  le foju ri lo ti jẹ anfaani itọju yi''
Ẹgbẹ awọn adari ile iwosan ni Najiria, GMD ti ni ọrọ ti dokita Stella Emmanuel, to jẹ oṣiṣẹ eto ilera nilẹ Amẹrika sọ pe oun lo Hydroxychloroquine (HCQ), Zinc ati Zithromax lati fi ṣetọju arun Covid-19 ko bojumu to.
Ninu atẹjade kan ti aarẹ ẹgbẹ naa, Ọjọgbọn Olufemi Babalola fọwọ si ni ilu Abuja, o ni ko si ẹri aridaju to fidi rẹ mulẹ pe awọn oogun ti dokita naa darukọ lee wo arun Coronavirus.
Ẹgbẹ naa ni dokita Stella ko sọrọ lorukọ apapọ awọn oṣiṣẹ eto ilera, bikoṣe lorukọ ara rẹ.
Ṣaaju ni fidio kan ti jade lori ayelujara, ninu eyii ti dokita naa ti sọ pe oun lo awọn oogun naa lati fi tọju aadọtalelọọdunrun eeyan to ni arun Coronavirus, ti gbogbo wọn si ri iwosan.
Lẹyin naa lo ke pe awọn oṣiṣẹ eto ilera ilẹ Amẹrika lati doola ẹmi awọn ọmọ orilẹede naa to n ku nitori arun ọhun pe, oogun Hydroxychloroquine ni idahun si arun Covid-19.
Hepatitis: A kò leè kóo nípa dídìmọ́ ara ẹni
Aarẹ GMD ni awọn onimọ nipa eto ilera ko tii pari iwaddi wọn lati mọ boya apapọ Hydroxychloroquine, Zinc ati Zithromax lee koju Covid-19.
O ni ki ẹnikẹni ma ṣe gba imọran dokita Stella Emmanuel wọle titi di igba ti imọ ijinlẹ yoo fidi rẹ mulẹ pe lootọ ni awọn oogun naa le wo alarun Coronavirus san
Ẹwẹ, ileeṣẹ atẹsjiṣẹ Twitter ti pa a laṣẹ fun ọmọ aarẹ ilẹ Amẹrika, Donald Trump kekere pe ko yọ ohun to sọ nipa oogun Hydroxychloroquine kuro loju opo rẹ nitrori o le e ṣi awọn eeyan lọna.
Gẹgẹ bi ileeṣẹ iroyin Washington Post ṣe sọ, igbesẹ yii lo waye lẹyin ti ọmọ aarẹ ọhun pin fidio awọn dokita kan to n sọrọ ti wọn ni o le e ṣi awọn eeyan lọna nipa ajakalẹ arun Coronavirus.
Ki lo ti ṣẹlẹ sẹyin?
Oríṣun àwòrán, others
Oju opo ayelujara Facebook, Periscope atawọn oju opo ayelujara miran ti fa fidio obinrin alawọ dudu kan, Dokita Stella Immanuel yọ, eyi to se lati salaye idi ti oogun iba Hydroxychloroquine fi pegede lati wo arun Coronavirus san.
Wọn fa fidio naa yọ lori ayelujara lẹyin ti eeyan miliọnu mẹrinla ti wo o.
Koda, aarẹ Donald Trump tilẹ Amẹrika fi fidio naa soju oò Twitter rẹ.
Ninu fido naa ni Dokita Stella Immanuel, tii se onisegun alabọde nilu Houston kede nibi ipade akọroyin kan pe, oun ti fi oogun Hydroxychloroquine wo alarun Coronavirus to to ọtalelọọdunrun o din mẹwa.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Immanuel ni awọn arugbo lo pọ ju ninu awọn alaisan Coronavirus ti oun wosan, koda, awọn miran ni aisan atọgbẹ ati ikọ semisemi.
Mo fun wọn ni oogun Hydroxychloquine mu pẹlu Zinc ati Zithroma, ti ara gbogbo wọn si da.
Lọwọlọwọ bayii, awọn eeyan to ni arun Coronavirus  le ni miliọnu mẹrindinlogun ni orilẹede mejidinlaadọwa.
Awọn eeyan to to ẹgbẹrun lọna ọtalelẹẹdẹgbẹta lo ti ku lati ipasẹ arun Coronavirus.
Jiji ti awọn ọmọ Naijiria ji lowurọ ọjọ Iṣẹgun ni wọn ṣalabapade fọnran fidio kan, ti o ṣe afihan Dokita obinrin alawọdudu kan lorileede Amẹrika to n sọ fawọn eeyan pe arun Covid-19 ni oogun to daju.
Dokita Stella Immanuel ninu fọnran fidio yii darukọ oogun hydroxychloroquine, zinc ati Zythromax gẹgẹ bi awọn oogun ti ohun ti fi tọju alaisan Covid-19 to le ni ọọdunrun.
Ohun ati awọn agbarijọpọ onimọ iṣegun ti wọn pe ara wọn ni America Frontline Doctors ni wọn ba awọn oniroyin sọrọ ninu fọnran fidio yi ni Washington DC.
Jakejado agbaye lawọn eeyan ti n sọ nipa lilo oogun yi lati  koju ati fun itọju arun Covid-19.
Ajọ eleto ilera agbaye WHO ti sọ pe ki wọn da iwaadi duro lori lilo oogun yi fun itọju Covid 19 nitori pe ko ṣiṣẹ.
Amọ ṣa fọnran fidio yi gbode kan koda eeyan to le ni miliọnu mẹrinla lo ti wo loju opo Facebook  ki wọn to yọ kuro.
Ǹjẹ àgbo lè ṣe òògùn coronavirus?
Fidio yi  ti wa mu ki awọn eeyan ma beere pe ta ni Dokita yi to sọ pe ni Naijiria loun ti kẹkọ nipa eto iṣegun ilera.
Iwaadi ti BBC Yoruba ṣe nipa rẹ tu aṣiri awọn  nkankan nipa Dokita yi. Diẹ ninu ohun ta mọ nipa rẹ ree
Ọpọ awọn to n ṣalabapin fidio yi lo lero wi pe ọmọ Naijiria ni Dokita Stella.
Ninu awọn fọnran fidio to gbe sita Dokita Stella sọ pe ohun kẹkọ gboye ni orileede Naijiria.
Ko sọ ni pato boya ọmọ Naijiria lohun n ṣe ṣugbọn ninu apejuwe to ṣe si oju opo Facebook rẹ, o kọ sibẹ pe fasiti ilu Calabar, ni Naijiria ni ohun ti kẹkọ nipa imọ ilera.
Bakan naa lo kọ sibẹ pe oun lọ si ile ẹkọ Cameroon Protestant College.
Loju opo Amazon nibi to ti polowo iwe kan ti o kọ, apejuwe nipa Dokita Stella sọ pe ọmọ ilẹ Cameroon nii ṣe.
Orukọ rẹ Gwandiku Tita jẹ orukọ tawọn eeyan to wa lati ilu Bali ni orileede Cameroon  n jẹ.
''Dokita nikan kọ ni mi.Mo n fi adura jagun''
Ọrọ ti Dokita Stella fi ṣe apejuwe ara rẹ ree ninu fọnran fidio kan to fi si oju opo ile iwosan rẹ Rehoboth Medical Centre to wa ni ilu Houston Texas lorileede Amẹrika.
Dokita Stella tun ni oju opo ile ijọsin rẹ,Fire Power  Deliverance Ministries nibi ti o ti n ṣe iwaasu loore koore nilana Kristẹni.
Oríṣun àwòrán, @stella_immanuel
Lọpọ awọn fọnran fidio to fi sita, o ma n ṣe iwaasu lori bi awọn eeyan ti ṣe yago kuro lọna Kristi nipa kikopa ninu awọn iwa ẹṣẹ bi ibalopo laarin akọ si akọ ati abo si abo.
Imọ nipa itọju ọmọde lo kọ nipa bawo lo ṣe wa n tọju alarun Covid-19
Oríṣun àwòrán, Twitter
Ibeere yi wa lara ohun tawọn to n tako ọrọ rẹ n beere nipa bi o ti ṣe ni ohun n tọju alarun Covid 19.
Leyi ti BBC ri fidi rẹ mulẹ, Dokita Stella kẹkọ gboye ti o ṣi n ṣe itọju awọn ọmọde nile iwosan Rehoboth Medical Centre to ti n ṣiṣẹ.
Ko daju igba to bẹrẹ si ni tọju awọn agbalagba tabi boya o kẹkọ gboye nipa itọju awọn agbalagba ṣugbọn o sọ pe awọn agbalagba alarun Covid 19  to ni ipenija ilera bi aisan itọ ṣuga ati aisan ọkan wa lara awọn ti ohun ti tọju ti ara wọn si ti ya.
Lara awọn ti ọrọ Dokita Stella  yoo dun mọ ninu ni aarẹ orileede Amẹrika Donald Trump ati awọn alatilẹyin rẹ.
Idi ni pe Aarẹ Trump ko ye tẹnu mọ pe oogun hydroxychloroquine jẹ oogun kan gbogi to ma  n  koju arun Covid 19.
Ninu ọrọ rẹ to fi sita loju opo Twitter, Dokita Stella kesi aarẹ Trump lati gba ohun lalejo ni olu ilu Amẹrika ti ṣe Washington DC nibi ti ohun ati awọn Dokita kan ti n sọrọ nipa lilo  hydroxychloroquine.
Ero ṣe ọtọọtọ lori ohun ti Dokita Stella sọ loju opo Twitter nipa lilo hydroxychloroquine lati koju arun Covid 19.
Bi awọn kan ti ṣe n bẹnu atẹ lu lawọn miran gboṣuba kare fun gẹgẹ bi oniṣegun to dantọ.
Ó lé ni ètò ìgbéyàwó ẹgbẹ̀rún mẹ́rin tí kóòtù ìgbeyawo ìjọba àpapọ̀ tó wà ni Ikoyi ló ti wọ̀gile forúkọsilẹ̀ àwọn tó fẹ́ ṣe ìgbéyàwó níbẹ̀.
Oríṣun àwòrán, others
Ilé iṣẹ́ tó n ri si ọ̀rọ̀ abẹ́le ní Naijria, to sì tún ṣe àmújúto kóòtù to n ṣe ìgbéyàwó ti paa láṣẹ pé kí wọ́n mú ìdádúró ba ètò ìgbéyàwọ́ ti wọ́n forúkọsílẹ̀ láti inú oṣù kẹta nítóri àjàkálẹ̀ ààrùn Coronvirus.
Ìwádìí fi han pé ẹni tó bá fẹ le lọ lo àwọn kóòtù míràn ni àwọn agbègbè míràn kí wọ́n wá sọ, sùgbọ́n ẹni náà yóò san bi ẹgbẹ̀rùn lọ́nà ọgbọ̀n náírà sí ẹgbẹ̀rún lọ́nà ààdọ́ta náírà.
Gẹ́gẹ́ bi ẹni kan ti ọ̀rọ̀ náà kàn ṣe sọ yíyí ibi ti wọ́n yóò ti ṣe ìgbéyàwó pada ní kí wọ́n sọ ìbi tó bá wù wọ̀n lọ́kan, àwọn òṣìsẹ́ kóòtù yóò lọ síbẹ̀ láti ṣe ètò náà.
Ó ní òun ti fi orúkọ sílẹ̀ láti inú oṣù kẹfà ọdún yìí to sì san ẹgbẹ̀rún mẹ́tàlélọ́gbọ̀n náìrà tí wọ́n si fi àtẹ̀jíṣẹ́ ránṣẹ́ pé ètò náà yóò wáyé ní ọjọ́kẹrìnlá, oṣù kẹfà, ọdún 2020.
Sùgbọ́n nígbà ti òun débẹ̀ lọ́jọ́ náà ni wọ́n sàlàyé pé nítori ààrùn Covid-19, àwọn kò ní lé ṣe ètò náà mọ́.
Ẹni náà ni ọkùnrin tó gbé fóònù sọ pé ó lé ni ènìyàn ẹgbẹ̀run mẹ́rin tó ti wà nílẹ̀ láti inú oṣù kẹ̀ta, o ní wọ́n sọ pé tí òn bá le dúro àwọn yóò fi ìpè ránṣk ti àsìkò bá ti tó, sùgban ti kò bá le dúro àwọn lé wá ṣe fun nílé, sùgbọ́n yóò san ẹgbẹ̀rún lọ́nà ààdọ́ta náírà.
Àbẹ̀wò sí kóòtù Ikoyi, lógúnjọ oṣù kéjé fi han pé , ẹni tó bá wù nìkàn ló le mú ibi tó bá wùú ti yóò sì san ẹgbẹ̀rún lọ́nà ààdọ́ta náírà.
Ẹ̀wẹ̀, àgbẹnusọ ilé iṣẹ́ tó ọ̀rọ̀ abẹ́lé, Mohammed Manga sàlàyé pé, owó ayípada ibudó tuntun láti ọ̀ds ìjọba kò ju ẹgbẹ̀rún lọ́nà ọ̀gbọ̀n náírà lọ
Oba Samuel Adeniran Asusumasa Atewogboye II: Alaaye ti Efon Alaaye tí wọ́n yẹgi fún lọ́dún 1949
Oríṣun àwòrán, Others
Yoruba ni ẹni ti a ni ko ki ni lẹyin, ko yẹ ko fi ẹgun sọwọ, bẹẹ ni ẹni ti a ni ko fẹ ni loju, ko gbọdọ fi ata sẹnu.
Amọ eyi ko ri bẹẹ pẹlu Ọba alaye kan nilẹ Yoruba, ti araalu fẹyin ti, to ja wọn lẹyin kulẹ, ti wọn gboju okun le, amọ ti ko jọ ẹni agba.
Gẹgẹ bẹẹ se mọ pe alasẹ ekeji orisa ni awọn Ọ́ba alaye nilẹ Yoruba, awọn si ni araalu ri bi igbakeji orisa, ti wọn gbọkan wọn le.
Sugbọn nilu Efon Alaaye, eyi ko ri bẹẹ o, gẹgẹ bi a se ri ka loju opo itakun agbaye nigba ti Ọba alaye ibẹ ja awọn eeyan rẹ kulẹ, to si ja igbẹkẹle ti wọn ni ninu rẹ si asan.
Ọjọ nla ni ọjọ Kẹwaa, osu Kinni, ọdun 1949 nigba ti isẹlẹ nla kan waye nilu Efon Alaaye, to wa nipinlẹ Ekiti bayii
Ọmọdebinrin kan to n jẹ Adediwura Ojo, tii se ọmọ ọdun kan ati osu mẹta, lo saadede poora ninu agbala baba rẹ to ti n sere.
Ere ni, awada ni, wọn wa ọmọ naa titi, ti ilẹ fi su, amọ wọn ko ri eegun tii jẹ Ajikẹ, iya Adediwura sunkun titi, oju ni oun ko ran-an nisẹ.
Ìdílé tí ọkọ da ọmọ síta tóríi ojú Búlùú tí wọ́n ní bá BBC sọ̀rọ̀
Baba rẹ naa atawọn ọrẹ pẹlu aladugbo gan an gbarata, wọn daamu, ikun imu ọtun wọn bọ si toi si, amọ ofuutu-fẹẹtẹ, aasa ti ko ni kahun ni gbogbo wahala rẹ.
Koda, wọn mu isẹlẹ naa to Ọba Alaaye tilu Efon Alaaye leti nigba ti aayan wọn lati wa ọmọ naa ni gbogbo arọko to sunmọ wọn ja si pabo.
Bakan naa, Ọba Samuel Adeniran Asusumasa Atewogboye keji, Alaaye tilu Efon Alaaye lasiko naa, tun gbe awọn gende dide lati wa Adediwura, sugbọn ẹja ni ọrọ naa, kii se akan rara.
Tóò bá fún ọkùnrinn lóúnjẹ́ tóo tẹ́ kiní yẹn sílẹ̀ fún un dáadáa... - Yinka TNT
Lasiko ti a n sọrọ rẹ yii, awọn eebo amunisin lo n dari akoso ilẹ yii, ko si si ohun to n jẹ orilẹ-ede Naijiria, ti ileesẹ ọlọpaa si wa labẹ akoso wọn.
Abẹ akoso Ọba Gẹẹsi, King George IV la wa, ti ko si si ẹni to ga ju ofin lọ nigba naa, Lloyd Crow si lo n soju awọn eebo fun igbẹjọ.
Wọn fi ọrọ naa to awọn ọlọpa leti, tawọn naa si fi isẹlẹ ọhun to olu ileesẹ wọn leti nitori igba akọkọ ree ti iru isẹlẹ ijọmọgbe bẹẹ yoo waye
Iwadii ti ileesẹ ọlọpaa se lati se awari bi Adediwura se poora:
Ọrọ yii ko lojutu titi di ọjọ Kẹwaa, osu Keji, ọdun 1949, iyẹn nigba to pe osu kan gbako ti Adediwura poora.
Ọjọ naa si ni awọn ikọ ọlọpaa ọtẹlẹmuyẹ mẹrin, ti orukọ wọn n jẹ Insipẹkitọ Aruah, Sajẹnti Olawaiye ati Sule Agbabiaka pẹlu Kọburu Ariyo ya bo ilu Efon Alaaye lati finmu-finlẹ nipa ibi ti Adediwura wọlẹ si.
Laarin ọjọ meji pere, awọn ọlọpaa to dantọ naa fidi rẹ mulẹ pe awọn afọmọ setutu lo gbe ọmọde yii lọ.
Nigba ti yoo si fi di ọjọ Kẹrinla, osu Keji, ọdun 1949, okiki ọrọ naa ti gba ilu kan, tawọn iwe iroyin si ti kede rẹ, bẹẹ ni ijọba eebo tutọ soke, foju gbaa, lori isẹlẹ laabi naa.
Olusegun Obasanjo: Ọmú ìyá mi ti mo fi ń mùkọ ni kekere ló jẹ ki ń lókun
Nigba ti iwadii wọn tẹsiwaju, paapaa lori awọn akinkanju oloogun to wa ninu ilu naa, ọwọ tẹ awọn Babalawo mẹta.
Orukọ awọn onisegun ọhun ni Daniel Ojo, Enoch Falayi ati Gabriel Olabinrinjo, Falayi si lo jẹ babalawo si Alaaye tilu Efon naa.
Nigba to di osu Kẹrin, ọdun 1949, igbimọ olugbẹjọ dide ni gbọngan Obokunbusi to wa nilu Ilesa, eyi ti adajọ Majisireti WO Egbuna ko sodi.
Ọrọ ko pariwo rara nigba ti ọkan lara awọn afurasi to wa ni ahamọ ọlọpaa lori isẹlẹ yii ka boroboro nipa ohun ti wọn se, ti ile fi jona.
Alaye aṣiri tu nipa bi Adediwura se di awati ree:
Bi ọkan lara awọn afurasi naa se tu asiri yii, ni awọn iwadii miran ati ọpọ asiri miran bẹrẹ si ni tu nipa bi ọmọde naa se di awati.
Iwadii fihan pe babalawo Falayi to n kọja lọ, lo ri Adediwura nibi to ti n sere ninu agbala baba rẹ.
Nigba to si wo firi, ti ko ri ẹnikẹni nitosi, lo ba he ọmọ naa lapa, to si gbe e bọ abẹ agbada rẹ lọ sile rẹ.
Falayi pasẹ fun iyawo rẹ nigba to dele pe ko pọn ọmọ naa sẹyin lọ sile ẹnikan to darukọ fun-un.
Badagry ní ogún àjogúnbá tó pọ̀ yàtọ̀ sí òwò ẹrú
Amọ nigba ti wahala wiwa ọmọ naa peleke, Falayi tun gbe Adediwura kuro nibẹ, to si gbe e lọ sile Ọba Asusumasa Atewogboye.
Aafin ọba naa si ni wọn ti kun ọmọde naa bii ẹni kun ẹran, lati fi se etutu fun Ọba Alaaye.
Wọn yọ oju ọmọ naa mejeeji, pẹlu ahọn rẹ, wọn ko o sinu agolo siga, ti wọn si kun iyoku ara ọmọ naa wẹlẹwẹlẹ.
Lẹyin eyi ni ọkọọkan awọn eeyan to sisẹ ibi naa wa bura pe ki ilẹ gbe ẹnikẹni to ba tu asiri awo to wa laarin wọn mi.
Wọn gbe oku ọmọ naa lọ sinu igbo kijikiji to wa lẹba ile ijọsin CMS, ti wọn si sin in nibẹ.
Àyà mi kọ́kọ́ máa ń já nígbà ti mo ṣẹ̀ṣẹ̀ bẹ̀rẹ̀ -Alaga iduro ọkùnrin
Ọkan lara awọn ẹlẹrii ninu igbẹjọ yii ni Aina Ola, ẹni to fọwọ gbaya pe Falayi lo ji Adediwura gbe sabẹ agbada rẹ.
Bakan naa ni ọkan lara awọn ẹlẹrii tọka si Ọba Asusumasa Atewogboye pe, oun lo ran wọn nisẹ ipaniyan naa, ti wọn si lọ mu Ọba si atimọle lọgan.
Wọn gbe ẹjọ naa lọ sile ẹjọ giga tilu Akure labẹ adajọ NS Pollard, ti awọn ẹlẹrii mọkanlelogun si yọju siwaju rẹ.
Bakan naa ni iyawo babalawo yii, Owomobi jẹrii pe inu ile awọn ni ọmọde naa wa titi di aajin, ti ọkọ oun kan an nipa fun oun lati pọn ọmọ naa sẹyin lọ sile afurasi keji, Gabriel Olabirinjo.
Agbẹjọro fun Ọba Asusumasa Atewogboye ni Oloye Obafemi Awolowo nigba ti Bode Thomas jẹ agbẹjọro fun ikọ olujẹjọ yoku, tii se awọn babalawo.
LASTMA Yesufa: Àwọn dókítà gbìyànjú lórí ojú mi ṣùgbọ́n...
Awọn mejeeji ja fitafita lati jẹ ki ẹjọ ọhun gbe awọn onibara wọn, amọ awọn ẹri to wa niwaju ile ẹjọ fihan pe ẹpa ko boro mọ.
Asẹyinwa-asẹyinbọ, ileẹjọ kede pe Kabiyesi Ọba Samuel Adeniran Asusumasa Atewogboye Keji, Alaaye kẹtalelogoji nilu Efon Alaaye ati babalawo rẹ, awọn iransẹ ati Gabriel Olabinrinjo jẹbi ẹsun ijọmọgbe ati ipaniyan.
Ileẹjọ ni ki wọn yẹgi fun gbogbo wọn, titi ti ẹmi yoo fi bọ lara wọn, ọdun 1949 si ni awọn ọdaran naa dagbere faye.
Sogidi Lake: Kòṣẹja-kòṣèèyàn lá bá nínú adágún odò náà -Ojedele
Ẹ́kọ́ wo la ri kọ́ nipa isẹ̀lẹ̀ yii?
Ọ́pọ́ igba lo maa n jẹ pe awọn ti a ba gbọkan le kii gba eeyan duro nitori ibi ti a ba foju si, ọna le ma gba ibẹ lọ.
Igba miran, eni to ba n fẹ eeyan kan le maa se oju aye lasan to jẹ pe o n fi ẹjẹ sinu tu itọ funfun sita ni.
Ifura ni oogun agba titi di aye ode oni, gbogbo igba ni ki a maa gbọ ohun ti ara ba n sọ fun wa.
Asiko ti to ki igbẹjọ maa lọ bi o ti yẹ lai segbe fun ẹnikẹni ni Naijiria mọ́.
Ofin ti a ba tori ẹru se ni a ko gbọdọ de ori ọmọ ki a wa yii pada.
Ati pe ika to ba sẹ̀ ni ki agbara ofin maa ge lai bọwọ fun ẹnikẹni.
Barrakat Bello: Iya rẹ̀ ní báwọn èèyàn ṣe ń fún òun lówó, làwọn míì ń tún ilé ṣe
Lai Mohammed: A ti gba 800 bílíọ̀nù padà lọ́wọ́ àwọn tó jíi kó, àwọn 1,400 ti dèrò ẹ̀wọ̀n
Oríṣun àwòrán, @thebridgenewsng
Ijọba apapọ ti sọ pe oun ti gba owo to le ni ẹgbẹrin bilọnu naira pada lọwọ awọn to jii ko.
Minisita fun eto iroyin at aṣa, Lai Mohammed lo kede bẹẹ nibi ipade awọn akọroyin kan to waye ni ilu Abuja.
O fi kun un pe egbeje eeyan lo ti n faṣọ penpe roko ọba bayii lẹyin ti aje iwa ajẹbanmu ṣi mọ wọn lori.
"O ṣalaye pe ""Gẹgẹ bi mo ṣe sọ tẹlẹ, ijọba to wa lode yii n doju ija kọ iwa jẹgudujẹra, a si ni ẹri lati gbe e lẹsẹ."""
"Minisita ọhun tẹ siwaju pe ""Ijọba yii ni akọsilẹ awọn egbeje eeyan to wa ni ahamọ, bẹẹ ni a si ti gba owo to le ni ẹgbẹrin bilọnu naira pada, yatọ si awọn ohun ini ti agbẹsẹle."""
Oríṣun àwòrán, @ScooperNG
O ni yatọ si gbigba owo ijọba ti awọn eeyan kan lu ni ponpo pada, ijọba to wa lode yii tun n ṣeto iyipada ọkan fun awọn ọmọ Naijiria ki iwa ajẹbanu lee di ohun igbagbe.
Lai pari ọrọ rẹ pe ki awọn to n bu ẹnu atẹ lu akitiyan ijọba to wa lode yii ronupiwada, ki wọn si dojukọ aṣeyọri ti ijọba n ṣe lati pana iwa jẹgudujẹra lorilẹ-ede yii.
Olusegun Obasanjo: Ọmú ìyá mi ti mo fi ń mùkọ ni kekere ló jẹ ki ń lókun
Ajao Estate Gas Explosion: Alága ìjọba ìbílẹ̀ Isolo ní àwọn yóò fi òfin dè títà afẹ́fẹ́ gáàsì létílé
Ijọba ipinlẹ Eko ti ni awọn yoo ṣe agbeyẹwo ofin ti yoo dena ki awọn eeyan maa ta afẹfẹ gaasi lẹba ibi ti awọn eeyan n gbe.
Ọrọ yi waye lataari ibugbamu afẹfẹ gaasi to ṣe akoba fun dukia ati ẹmi awọn eeyan ni adugbo Ajao Estate ni ilu Eko.
Alaga ijọba ibilẹ Isolo, Shamsudeen Abiodun Olaleye lo fidi ọrọ yi mulẹ fun BBC lasiko to ṣe abẹwo si ibi ti ijamba naa ti waye.
Olaleye ni lootọ ni pe koṣeemani ni lilo gaasi f'awọn ara ilu ṣugbọn ohun to ṣẹlẹ yi ti sọ di dandan ki ijọba mu opin ba tita afẹfẹ gaasi lẹgbẹ ibugbe awọn eeyan.
''Ohun to jẹ wa logun kii ṣe awọn to n pa owo nidi tita gaasi, bi ko ṣe didaabo bo ẹmi wọn ati ti awọn eeyan to rọgba yika wọn.''
O ni ijọba yoo gbe igbesẹ lati ri i wi pe iru nkan bayii ko tun waye mọ.
Bakan naa ni aṣoju ẹkun idibo Oshodi/Isolo, Jude Idimogu to kọwọrin pẹlu Alaga naa ni awọn yoo wo ilana ti yoo mojuto bi wọn ko ṣe ni maa ta afẹfẹ gaasi ni itosi ile ibugbe jakejado ipinlẹ Eko.
Ki lo ti ṣelẹ sẹyin?
Ọrọ ibugbamu to n fi ojoojumọ waye nipinlẹ Eko bayii ti wa di ailasọ lọrun paaka bayii, eyi to to apero fun gbogbo ọmọ eriwo.
Idi ni pe isẹlẹ ibugbamu miran tun ti waye nilu Eko lọjọ Isẹgun ninu ibudo itaja kan ti wọn ti n ta afẹfẹ gaasi ati eroja Kanbaadi.
Ajọ to n ri si akoso isẹlẹ pajawiri nipinlẹ Eko, LASEMA to fidi rẹ mulẹ loju opo Twitter rẹ, salaye pe opopona Afariogun ladugbo Ajao Estate nilu Eko ni isẹlẹ naa ti waye.
Lasema ni ibugbamu Kanbaadi ati afẹfẹ gaasi papọ yii si lo se okunfa ijamba ina alagbara kan ninu ile itaja naa.
Oríṣun àwòrán, @followlasema
Ileesẹ o kere tan, ibudo itaja mẹsan miran lo fara gba ninu isẹlẹ ọhun, tii wọn si jona kanlẹ.
Ileesẹ to n se akoso awsn isẹlẹ pajawiri nipinlẹ Eko ni ifọwọsowọpọ isẹ ajọ panapana nipinlẹ Eko ati ajọ naa lo mu ki wọn tete bu omi pa ijamba ina naa.
Oríṣun àwòrán, @followlasema
Ọpọ eroja bii ọpa, silinda gaasi ati awọn nnkan miran to ti jona ni wọn ri nibi isẹlẹ naa, ti ajọ Lasema ko si sọ boya ẹmi kankan sọnu ninu ijamba naa.
Oronpoto Animation: Akin Alabi ní kò dára bí eré aláwòrán fáwọn ọmọdé ṣe jẹ́ aláwọ̀ funfun
Ni ọpọ igba ta ba ri ere alaworan to wa fun awọn ọmọde lori ayelujara tabi mohun maworan, awọn alawọ funfun lo maa n se jade.
Amọ ọmọ Yoruba kan ree, Akin Alabi to n lakaka lati gbe asa Yoruba larugẹ, paapaa nidi ki awọn ọmọde mọ nipa asa, ede, iwọsọ ati itan wa.
Akin Alabi, to sẹsẹ se ere alaworan kan fawọn ọmọde ni ede Yoruba sọ fun BBC pe ko dara to bo se jẹ ere alaworan tawọn alawọ funfun se jade ni ede wọn nikan lawọn ọmọde wa n wo.
Alabi ni ipinnu oun lati fopin si eyi lo mu ki oun se agbejade ere alaworan Orompoto ninu eyi ti awọn alawọ dudu ti kopa, ti wọn si sọ ede wa.
O ni isu mẹrin pere ni oun lee se ni ere alaworan ninu itan naa, to si n kesi awọn onileesẹ nlanla atawọn eeyan to nifẹ agbega asa ati ede Yoruba lati dide, se iranwọ owo fun oun, ki isẹ naa lee pari.
Mamman Daura: Ọmọ Nàíjíríà ní ọgbọ́n àti gbé ààrẹ fún ẹ̀kùn àríwá ni
Oríṣun àwòrán, Others
Awọn eniyan ti bẹrẹ si ni fi ero wọn han lori ayelujara nipa ohun ti ọrẹ timọ-timọ aarẹ Buhari, Mamman Daura sọ.
Ọjọ Isẹgun ni Daura kede pe, ẹni to ba kunju iwọn lo yẹ ko jẹ aarẹ Naijiria, kii ṣe nipa pinpin ipo aarẹ ni ẹlẹkunjẹkun.
Mamman Daura lọ sọ ọrọ yii lasiko to n kopa lori ifọrọwanilẹnuwo kan pẹlu ileeṣẹ iroyin BBC.
Daura ni ọpọlọpọ eniyan n sapejuwe bii ọkan lara awọn to lagbara ju ninu iṣejọba aarẹ Muhammadu Buhari.
Daura ni ẹni to ba kunju iwọn julọ ni wọn gbọdọ gbe ijọba fun ni ọdun 2023, wọn ko gbọdọ fi ṣe ọrọ ẹkun mi lo kan.
Amọ, awọn eniyan ti bẹrẹ si ni fesi loju opo Twitter pe, ọna ati ọgbọn lati jẹ ki ẹya Hausa nikan ma a ṣe ijọba lorilẹede Naijiria ni wọn n wa.
Bakan naa ni awọn kan ni ko tọ si Mamman Daura lẹnu lati sọ iru ọrọ bẹẹ fun awọn ọmọ Naijiria.
Amọ awọn miran faramọ ọrọ ti o sọ, bi o tilẹ jẹ wi pe awọn ko ri ọkan rẹ ati idi ti o fi sọrọ naa.
Awọn miran tilẹ gboriyin fun Mamman Daura wipe, otitọ ọrọ lo sọ nitori sise ipo aarẹ ni ẹlẹkunjẹkun ti sakoba fun wọn, ti ko si mu idagbasoke dani.
Ẹgbẹ afẹnifẹre naa wa lara awọn to bu ẹnu atẹ lu ọrọ ti Mamman Daura sọ, wọn ni bi wọn ṣe n pin ka laarin Ariwa ati Guusu naa ni ko se ma a lọ.
Child Mortality in Nigeria: Ìyanṣẹ́lódì àwọn Nọ́ọ̀sì ṣé àkóbá, ìkókó mẹ́jọ kù níléèwòsàn lalẹ ọjọ́ kàn
Ibanujẹ ti dori awọn abiyamọ kan kodo ni orileede Zimbabwe lẹyin ti awọn ọmọ ikoko mẹjọ ku lalẹ ọjọ kan ni ile iwosan.
Abiyamọ mẹjọ lo wa si ile iwosan lọjọ taa n wi yii, ti wọn si ni lati se iṣẹ abẹ ki wọn ba le bi ọmọ wọn.
Amọ o se ni laanu pe meje ninu awọn ọmọ wọn yii lo ku lalẹ ọjọ kan ṣoṣo.
Ipenija nla ni aisi oṣiṣẹ ilera to to nitori ajakalẹ arun Covid 19 lo ṣokunfa iṣẹlẹ yii.
Gẹgẹ bi awọn Dokita ti ṣe sọ, meji ninu awọn ọmọ yii ni wọn bi ni oku ọmọ nitori pe ko si awọn nọọsi ti yoo gbẹbi awọn awọn nọọsi da iṣẹ silẹ.
Awọn Dokita to ni ki ikọ BBC fi orukọ bo awọn laṣiri sọ pe, mọriwo ni iṣẹlẹ naa jẹ, egungun ṣi n bọ lẹyin nitori pe ko si ipese ohun eelo to yẹ fawọn oṣiṣẹ ilera lati ṣe iṣẹ wọn.
Seyi Makinde; Ilé iwosan kan ṣoṣo tó wà ní  Idí-Iroko /Adewole tí bàjẹ́ pátápátá.
Akọ̀wé àgbà ìgbìmọ̀ ilé ìwòsàn ìpínlẹ̀ Ondo sọ̀rọ̀ lórí ìkọlù ilé ìwòsàn àwọn alárùn ọpọlọ
Wọn ni ọpọ ọjọ lawọn alaboyun yii lo lai ri eeyan kankan ti yoo tọju wọn, ki awọn ọmọ wọn to wa ku lasiko ibi.
Ọpọlọpọ awọn ile iwosan ilera lo ti kogba sile ni Harare, ti ṣe olu ilu Zimbabwe nitori iberubojo ajakalẹ Covid-19.
Akọroyin BBC Andrew Harding jabọ pe, Dokita kan sọ fun oun pe, nkan ko rọgbọ ati pe aisi nkan elo idaabo fawọn dokita, oogun fawọn alaisan  ati bi iṣẹ ti ṣe wọ awọn dokita lọrun jẹ ipenija nla.
Dokita mii sọ fun pe, iṣẹlẹ yii kii ṣe nkan tuntun, ko ṣẹṣẹ ma waye.
Coronavirus updates and palliative: Gomina Dapo Abiodun ti APC kéde àdínkù owó orí nípinlẹ̀ Ogun
Oríṣun àwòrán, others
Gomina Dapo Abiodun to n tukọ ipinlẹ Ogun labẹ akoso ẹgbẹ oṣelu APC ti kede ẹdinku si awọn owo orí kan nibẹ.
O ni oun ti buwọlu awọn igbesẹ kan lori ọrọ owo ori ni eyi ti yoo mu irọrun de sii fun awọn ti oun n dari.
O ni lẹsẹkẹsẹ ni awọn igbesẹ naa di mimuṣẹ lati ileeṣẹ to n ri si ọrọ owo ori nipinlẹ Ogun, iyẹn Ogun state internal revenue services.
Bayii, wọn ti ṣafikun si gbedeke asiko too le san owo ori lai san ele sii fun oṣu mẹfa.
Ko ni si ele idiyele to yẹ ni sisan lori aitete san owo ori ẹni tabi ti ileeṣẹ fun oṣu mẹjọ sẹyin.
Teach your children Yoruba: Wo àwọn òyìnbó tó ń kẹ́kọ̀ọ́ èdè Yorùbá ní Michigan, America
Ko ni si owo ori ọlọsọọsẹ fawọn ileeṣẹ to n te tẹtẹ lati oṣu kẹrin ọdun si oṣu kẹfa.
Dapo Abiodun tun ṣalaye pe o ṣeeṣe lati ṣe ipade pẹlu ileeṣẹ to n mojuto ọrọ owo ori lati ori ayelujara laidaamu wa sileeṣẹ wọn rara.
O tun kede ọna ijiroro ajọsọ lori ọna ti yoo rọrun fawọn to jẹ owo ori tẹlẹ lati tele ọna ti ko ga ju ara lọ.
Iru igbesẹ yii wo ni ipinlẹ Eko gbe ṣaaju asiko yii?
Gomina Sanwo-Olu náà dín  owọ́ orí lórí ilé àti ilẹ̀ kù nítorí Covid 19
Oríṣun àwòrán, @jidesanwoolu/others
Gomina ipinlẹ Eko, Babajide Sanwo-Olu ti bu ọwọ lu yiyọ owo ori ọdun mẹta kuro fun awọn onile ti won ko san owo ori lori ilẹ̀ ati ile wọ́n ni ipinlẹ́ Eko.(LUC Charges)
O si tun yọ ida mẹẹdọ́gbọn ninu ọgọrun un kuro fun awọn to ba tete san ti won lasiko yii.
Sanwo-Olu sọ wi pe owo ti wọn yọ kuro ninu owo naa wa fun riran awọn  onisowo ati awọn to ni dukia  lọwọ lati din inawo wọn  ku  nitori bi  eto ọrọ aje se ri ni akoko corona yii ni Ilu Eko
ati agbaye.
Eld Kabir in Nigeria: Mùṣùlùmí àti Kristiẹni sọ̀rọ̀ nípa àdun oúnjẹ́ àti ẹran ọdún Ileya
Fifi ọ́wọ si adinku owo ori yii wa ye lẹyin osu kan ti Sanwo-Olu ti wọ́n ti n gbe ee yẹ́wo.
Sisan owo adinku ori yii bẹrẹ lati ọdun 2018.
Gomina Sanwo-Olu kede ibuwolu yii ninu ipade pẹlu awọn olori onisowo ati onise Aladani keekeeke (MSMEs) ni Lagos Corporate Assembly to jẹ́ ile okowo ijọba, ni Alausa .
Sanwo-Olu sọ pe oun gbe igbesẹ naa lati le fi ran awọn onisẹ aladani lọwọ ati lati le fi sun ọrọ aje siwaju ni akoko idẹnukọlẹ ọrọ aje ati koni le gbele ti arun Coronavirus yii.
Gomina salaye siwaju si pe wọn sagbekalẹ ofin tuntun yi lati fi dena ija lori ilẹ ati awọ̀n ohun ini to ku.
Gomina sọ wi pe ijoba buwọlu yiyọ owo ori  ọdun mẹta kuro bẹ́rẹ́ lati  ọdun 2017, 2018,  ati 2019.
"Sanwo Olu ni : "" idi ti a fi gbe igbesẹ yii ni ki awọn eniyan ipinle Eko le mo pe a mo riri eto ọrọ́ aje to dẹnukole nitori ajakalẹ arun Coronavirus yii ni gbogbo agbaye."
O tun fi da wọn loju pe didun lọsan a so fun awọn onile ise Aladani nipinlẹ Eko laipẹ
Ipinle Oyo lo kọkọ́ bẹrẹ bayii:
Ìpínlẹ̀ Oyo kéde àdínkù owó orí nítorí Covid 19
Coronavirus Updates in Oyo: Seyi Makinde kéde àdínkù owó orí nítorí Covid 19- Akinola Ojo
Oríṣun àwòrán, Seyi Makinde/Dreamstime
Komisọnna eto ẹnawo ni ipinẹ Oyo lo kede bẹ́ẹ̀ lorukọ Gomina Seyi MAkinde.
Ogbeni Akinola Ojo to jẹ Kọmisọnna fun eto ẹnawo ni ipinlẹ̀ Oyo lo ni ijọba gbe igbesẹ yii ki ara o le tu awọn onile ile isẹ nlanla ati keekeeke ni ipinlẹ Oyo.
Lasiko to n sọrọ lori igbesẹ ijọba lori owo ori nibi apero lori owo ori aladani ati onile isẹ lo sọ eyi di mimọ.
Akinola ni ohun to jẹ gomina Seyi Makinde lọkan ni lati mu igbe aye irọrun ba awọn eeyan ipinlẹ Oyo.
Bakan naa ni Ogbeni Akinola Ojo tun salaye idi ti ijọba fi sun ọjọ fifopin si owo ori sisan sẹyin fun awọn eeyan ati onile isẹ nlanla ati keekeeke.
Lara awọn ọna ti ijọba fi mu nkan dẹrun sii fawọn olugbe ipinlẹ Oyo to tun mẹnuba ni yiyọ́ kuro owo itanran to yẹ ki ẹni to ba lugbadi ofin aitete san owo ori yẹ ko san lasiko yii.
Awọn to ni ileesẹ to nii se pẹlu ohun ọgbin, isẹ́ agbẹ, ọ̀sìn ẹja, eto irinna, iwakusa ati bẹẹ bẹẹ lọ.
Oronpoto Animation: Akin Alabi ní kò dára bí eré aláwòrán fáwọn ọmọdé ṣe jẹ́ aláwọ̀ funfun
Kọmisọnna naa tun fi kun ọrọ rẹ pe ijọba gomina Seyi Makinde ti fọwọ si adinku ida marindinlọgọ́rin ninu ọgọ̀run un fun awọn osisẹ to kuna lati san owo ori tẹ́lẹ̀ nitori wahala Covid 19 ti ko jẹ́ ki agbaye ri isẹ́ se yii.
Awọn ti eyi kan julọ ni awọn osisẹ ile itura, ile iwe, ibudo igbafẹ, ati bẹẹ bẹẹ lọ to yẹ ki wọn ti seto sisan owo ori wọn saaju ọjọ kọkandinlọgbọn, osu kẹjọ, ọdun 2020.
Koda, o tun ni iye osisẹ́ ti koowa ba ni ati iye owo to ba n san fun wọn lasiko Covid 19 yii ni ki wọn san owo ori wọn le lori lai jẹ gbese.
O ni awọn ileesẹ to ba tun tete san owo ori wọn saaju ọgbọn ọjọ, osu kẹsan an a tun ri ẹdinwo ida mẹẹdọgbọn gba sii.
Itan Ilu gangan
O tun ni aaye wa lati pe tabi sọrọ ni kikun lori ayelujara pẹlu awọn osisẹ to n risi ọ̀rọ̀ owo ori lai rinrin ajo wa si ilu Ibadan ni olu ileeesẹ wọn bii ti atijọ
O pari re pe awọn ti kọwe ransẹ si awẹn onile ise kaakiri lori igbesẹ ijọba yii.
Awọn onileesẹ to n se ipese ounje agolo, nkan mimu bii tii, omi inu ike ati omi inu ọ̀rá to ba tete san owo ori saaju ọjọ kọkanlelọgbọn, osu kẹjọ yoo ri ẹbun ida aadọta gba ninu owo ori wọn.
Ayo Fasanmi Afenifere: Ta ni Bàbá Fasanmi tí wọ́n ń gbé lọ sí Iye Ekiti padà lẹ́yìn tó papòdà?
Oríṣun àwòrán, others
Ẹbi Oloogbe Ayo Fasanmi to doloogbe ti kede bi eto isinku rẹ yoo se ri lọjọ Isẹgun, ọjọ kẹrin, osu kẹjọ, ọdun 2020 yii.
Wọn ni ilu abinibi rẹ ni Iye Ekiti ni ipinlẹ Ekiti ni Guusu Iwọ́ Oorun Naiiria ni eto isinku naa yoo ti waye.
Ijọ mimọ St John Anglican Church to wa ni Iye Ekiti ni yoo seto kookari isinku naa.
Koda, ẹbi ti fẹ́nuko pe ninu iboji ti wọn sin ololufẹ Baba si lọ́dun 2014 naa ni itẹ́ oku ti Baba yoo sun si gbẹ̀yin bi o se sọ saaju iku rẹ̀.
Ogbeni Folabi Fasanmi to jẹ ọkan lara awọn ọma baba naa lo salaye fawọn akọroyin bẹẹ nile Baba Fasanmi to wa ni Osogbo nipinlẹ Osun.
O salaye pe ohun to wu Baba ni ki wọn tete sin in ni eyi ti awọn ẹbi si ti pinnu lati mu sẹ pẹlu ajọsepọ awọn Gomina Iwo Oorun Naijiria ati awọn oloselu ti wọ́n ba Baba rin nigba aye rẹ̀..
Ọmọ Baba Fasanmi salaye pe iboju oloke meji ni Baba ati aya re seto silẹ nigba aye wọn ni eyi ti wọ́n jọ fẹnuko pe ẹni to ba kọkọ lọ lo maa wa ni isalẹ ti eni keji ti ọlọjọ ba de fun a wa ni oke ninu iboji naa.
Oloogbe Felicia to jk aya Oloogbe Ayo Fasanmi jade laye ni ọjọ kẹsan an, osu kẹwaa, ọdun 2014.
O ni ni kete ti gbogbo eto ba ti to ni ẹbi a fi to Naijiria leti ti Baba yoo si fi ara rẹ lélẹ̀ ni itẹ́ ikẹyin.
Oronpoto Animation: Akin Alabi ní kò dára bí eré aláwòrán fáwọn ọmọdé ṣe jẹ́ aláwọ̀ funfun
Tani Baba Ayo Fasanmi to doloogbe yii?
A bi Ayo Fasanmi lọjọ kẹtadinlọgbọn, osu kẹsan an, ọdun 1925.
O si jade laye ni irọlẹ ọjọ kọkandinlọgbọn, osu keje, ọdun 2020.
O ku osu meji pere ki Baba pe eni ọdun marundinlọgọ́run un lo dagbere faye pe o digbose.
Ẹkọ apoogun oyinbo ni Baba ka to si gboye to di akọsẹmọsẹ nipa rẹ.
O wa lara awọn ti Baba Awolowo jọ sisẹ papọ nigba aye Baba  iran Yoruba ninu oselu Naijiria.
Fasanmi jẹ senetọ ri to si tun se asojusofin ri nigba aye rẹ.
Oun ni olori agba ẹgbẹ́ Yoruba ti wan pe ni Afenifere titi ti ọlọjọ fi de.
O tun jẹ́ agba ẹgbẹ́ oloye ti APC.
Àwòkọ́ṣe ìwà ìrẹ̀lẹ̀, òtítọ́ àti olùfẹ́ mẹ̀kúnnù ni Ayo Fasanmi - Ìjọba Osun
Ìjọba Osun àti ẹgbẹ́ Afenifere dárò ikú akínkanjú olóṣèlú tó kú
Awọn eeyan ti n sedaro agba ilu, oloselu ati ọkan lara awọn asaaju ẹgbẹ Afẹnifẹre to papoda, Alagba Ayo Fasanmi.
Ninu atẹ́jade kan to fisita, ijọba ipinlẹ Osun ti kẹdun lori iku agba oselu naa, ẹni to sapejuwe bii awokọse fun onirẹlẹ, ẹni ti ko mọtara rẹ nikan ati olootọ eniyan.
Kọmisana feto iroyin ati ilanilọyẹ araalu nipinlẹ naa, Funke Egbemode, ninu atẹjade naa ni ijọba ipinlẹ Osun mọriri gbogbo aseyọri agba oselu naa nigba aye rẹ, paapaa ipo asaaju to dimu ninu oselu.
"Ijọba Osun ni ""Baba Fasanmi jẹ asaaju to maa n safihan ifẹ fun orilẹede wa lawọn ọna to pegede, to si tun maa n gbarata lori ipese eto idẹrun fawọn ọdọ."""
Oríṣun àwòrán, Sogo ọmọ Osun
Atẹjade naa ni ijọba Osun mọriri bi Baba Fasanmi se fẹran ilu Osogbo, ẹni ti isẹ gbe wa silu naa lọdun 1951 gẹgẹ bii osisẹ apoogun amọ to gba lati gbe nilu naa titi di ọjọ iku rẹ.
Ijọba Osun wa gbadura pe ki Ọba oke tẹ oloogbe naa si afẹfẹ rere.
Ọkan gboogi ni Baba Fasanmi ninu ẹgbẹ Afẹnifẹre ki wọn to yapa - Odumakin
Bakan naa, ẹgbẹ ọmọ Yoruba, Afẹnifẹre ti kẹdun ọkan gboogi lara wọn, Baba Ayo Fasanmi to papoda ni ẹni ọdun merinlelaadọrun.
Akọwe ẹgbẹ Afẹnifẹre, Yinka Odumakin, lasiko to n ba BBC Yoruba sọrọ ni Baba Fasanmi jẹ akinkanju eniyan to si ni ifẹ awọn ọmọ kaarọ-ojiire.
Oronpoto Animation: Akin Alabi ní kò dára bí eré aláwòrán fáwọn ọmọdé ṣe jẹ́ aláwọ̀ funfun
Bakan naa lo fi kun pe Fasanmi jẹ ọkan gboogi lara awọn to tẹlẹ Baba Obafemi Awolowo nigba aye rẹ ni, to si ja fun idagbasoke ilẹ Yoruba
'Wọn gbaruku ti Awolowo, to fi mọ igba ti o wa ni atimọle'
Wọn tun jẹ Sẹnetọ ni ipinlẹ Ondo ninu ẹgbẹ oṣelu UPN ni saa ijọba alagba ti ekeji ni Naijiria (2nd Republic), ti wọn si ko ipa ribiribi ninu ẹgbẹ naa.
Odumakin ni, Baba Fasanmi jẹ ọkan ninu awon to di opo ẹgbẹ afẹnifẹre mu, amọ wọn yapa diẹ kuro ninu ẹgbẹ afẹnifẹrẹ nigba to ku diẹ ki wọn ku.
O fikun pe ilẹ Yoruba yoo mọ iku agba oselu naa lara, to si gbadura pe ki Ọlọrun tẹ si afẹfẹ rere.
Oríṣun àwòrán, Others
Iroyin to n tẹ wa lọwọ ni yajoyajo ti kede pe Oloye Ayọ Fasanmi, tii se ọkan lara awọn asaaju ẹgbẹ Afenifere ti jade laye.
Atẹjade kan ti ọmọ oloogbe naa, Folabi Fasanmi fisita lo kede ipapoda ọkan lara asaaju ẹgbẹ Afenifere naa ni alẹ ọjọru
Gẹgẹ bi atẹjade naa ti wi, ọdun mẹrinlelaadọrun lo lo loke eepẹ, ki ọlọjọ to de.
Alagba Fasanmi, nigba aye rẹ, jẹ agba oselu to de ipo Sẹnatọ, oun si ni asaaju fun ẹgbẹ ọmọ bibi ilẹ Yoruba kan, Ilosiwaju Yoruba.
Atẹjade naa ni baba Fasanmi fi ọwọ rọri ku ni nile rẹ to wa nilu Osogbo, ti wọn yoo si maa kede eto isinku rẹ laipẹ.
Richard Gbadebo: Ìjọba ìpínlẹ̀ Oyo yóò ṣe ìwádìí ikú tó pa akẹ́kọ̀ọ́ Fásitì Ibadan
Oríṣun àwòrán, OTHERS
Ijọba ipinlẹ Oyo ti bẹrẹ iwadii lori iku to pa akẹkọọ Fasiti Ibadan, Richard Gbadebo, to ku nile iṣẹ kan ti wọn ti n ṣe ọṣẹ.
Akọwe agba ileeṣẹ ijọba to n ri si ọrọ ayika ati ohun alumọni, Bashir Olanrewaju lo kede bẹẹ nigba to ṣabẹwo si ẹbi oloogbe ọhun.
Gẹgẹ bo ṣe sọ, o ni ijọba ti bẹrẹ eto ayẹwo ti ileeṣẹ naa gbe kalẹ fun oṣiṣẹ rẹ, yoo si fi iya to tọ jẹ ileeṣẹ ọhun lẹyin iwadii rẹ.
Nigba to n fi da ẹbi naa loju pe ijọba yoo fun ẹbi oloogbe naa lowo gba mabinu, o ni ijọba labẹ iṣakoso Seyi Makinde ko ni la oju rẹ silẹ ki iya maa jẹ awọn ara ilu.
"O ni ""A wa nibi yii lati ba mọlẹbi oloogbe kẹdun, ati lati fi da wọn loju pe ijọba ti gbe igbesẹ lati ṣe iwadii ohun to fa iku ọdọmọdekunrin naa."""
Ijọba Seyi Makinde yoo ri pe idajọ ododo waye lọna ati dena iru iṣẹlẹ bayii lọjọ iwaju.
Ẹwẹ, baba ọmọ naa to doloogbe bere pe ki ileeṣẹ ọhun pese fidio ti ẹrọ ayaworan CCTV to n ka ohun ti awọn eeyan n ṣe ni ileeṣẹ naa ki ọrọ lede.
Gẹgẹ bi ohun ti ileeṣẹ naa sọ, Richard dero lẹyin ijamba to waye nile iṣẹ naa nigab to n ṣiṣẹ alẹ loṣu Keje ọdun 2020.
Ohun tẹ́ẹ gbúdọ mọ nípa kókó orí ọyàn yín lásìkò fífọ́mọlọ́yàn
Ki lo ti ṣẹlẹ sẹyin?
Oríṣun àwòrán, others
Ẹgbẹ ajafẹtọ ọmọniyan ti dasi ọrọ iku akẹkọọ fasiti Ibadan, Richard Gbadebo, to ku l'ẹnu iṣẹ ni ileeṣẹ kan ti wọn ti n ṣe ọṣẹ ni ilu Ibadan.
Ẹgbẹ ajafẹtọ ẹni naa ti orukọ wọn n jẹ, 'The Alliance on Surviving Covid-19 and Beyond' ti agbẹjọro agba, Femi Falana ṣe adari fun lo kede bẹẹ.
Femi Falana ni awọn  ti kọ iwe ẹhonu sijọba ipinlẹ Ọyọ lori ọrọ naa, ti awọn yoo si gbe ileeṣẹ Henkel Nigeria limited lọ si ile ẹjọ fun aibikita wọn fun awọn oṣiṣẹ ile isẹ naa.
Gbadebo to jẹ akẹkọọ ọlọdun kẹta ni fasiti Ibadan lo lọ ṣiṣẹ fun igba diẹ ni ileeṣẹ Henkel Nigeria Limited, amọ to kò si inu ẹrọ to n ṣe ọṣẹ, to si gba ibẹ ku.
Ọjọ kejidinlọgbọn, oṣu Keje, ni iṣẹlẹ naa waye ni ilu Ibadan.
Ẹsun ti wọn tun fi kan ileeṣẹ naa ni wi pe, wọn ko pese ohun elo aabo bii PPE fun Richard lo ṣe ku.
Bakan naa ni wọn ni o yẹ ki ileeṣẹ naa ri wi pe, iru awọn ẹrọ to le paniyan bẹẹ  wa ni ibi ti eto aabo to peye wa fun awọn oṣiṣẹ lati le da abo bo wọn.
Wọn fikun wi pe, ileeṣẹ naa tun kọ lati sọ kulẹkulẹ ohun gan an to ṣekupa Richard lẹnu iṣẹ ati bi o ṣe ku.
Awọn ajafẹtọ naa wa kesi ijọba ipinlẹ Oyo lati ri wi pe wọn fi ileeṣẹ naa jofin, ki iru iṣẹlẹ bẹẹ ma baa tun waye mọ.
Wọn fikun wi pe, awọn ijọba orilẹede Naijiria lọpọ igba, ti fi awọn oṣiṣẹ silẹ lati ri daju wi pe wọn wa ni alaafia lẹnu iṣẹ, ti wọn si n fi ẹmi ẉon wewu, eleyii ti ko yẹ ko ri bẹẹ.
Awọn ajafẹtọ ni idajọ otitọ gbọdọ leke lori iku Richard Gbadebo lẹnu iṣẹ, ki awọn ijọba ati awọn ileeṣẹ kaakiri Naijiria ba le kọ ẹkọ wi pe ẹmi awọn oṣiṣẹ ṣe iyebiye.
Ṣaaju ni BBC ti ba awọn obi oloogbe sọrọ, ti wọn si sọ pe ọrọ iku ọmọkunrin naa jẹ kayeefi, ti kii ṣe lasan.
Justice for Richard: Òbí àkẹ́kọ̀ọ́ tó kú síléeṣẹ́ ọṣẹ ń bèèrè fún ìdájọ́ lórí ikú ọmọ wọn
Fidio oke yii ni ọrọ baba ati iya Richard Gbadebo pẹlu BBC yoruba.
Ẹbi Richard Gbadebo, akẹkọọ fasiti Ibadan to ku iku ojiji nileeṣẹ kan to n ṣe ọṣẹ ni Ibadan ti ni irọ ni awọn iwe iroyin kan n gbe jade pe ileeṣẹ ọṣẹ ti ọmọ wọn ku si fun wọn ni ẹbun owo.
Nigba ti akọroyin BBC Yoruba ba ẹgbọn oloogbe sọrọ, Adesewa Gbadebo ni irọ gbaa ni iroyin to n tan kalẹ pe ileeṣẹ naa fun awọn ni owo.
O ni ẹbi awọn ko tilẹ mọ alukoro ileeṣẹ naa rara.
Agbẹjọro wọn pe wa lorii foonu lonii lati ki wa, igba yẹn la n sọ fun un pe ko lọ wo ori iwe iroyin bayi bayi pẹlu ohun ti wọn kọ sita.
O ni lootọ wọn ti wa ki awọn sile, ṣugbọn akẹẹgbẹ aburo rẹ ko tilẹ fun wọn lẹnu ọrọ rara.
Igba keji taa maa rira waye ni agọ ọlọpaa nibi ti wọn ti n sọ fun awa gan fun igba akọkọ pe wọn n ṣe ayẹwo lọwọ lori oku rẹ lati mọ ohun to pa a.
Adesewa ni ọlọpaa gan ko tilẹ gba aṣẹ lọwọ ẹbi ki wọn to bẹrẹ ayẹwo, ṣugbọn awọn ṣaa dakẹ.
Ileeṣẹ ọṣẹ ti akẹkọọ fasiti Ibadan kan, Richard Gbadebo ku si lọjọ aje ọsẹ to kọja Expanded Global Industries Limited ti nawọ ẹ ma binu si idile Richard.
Bakan naa ni ijọba ipinlẹ Oyo ti paṣẹ lọjọ abamẹta pe ki wọn ti ileeṣẹ ọṣẹ ti Richard, akẹkọọ fasiti Ilu Ibadan ku si lọsẹ to kọja.
Lọjọ Satide ọhun ni ijọba paṣẹ fun awọn oṣiṣẹ ileeṣẹ naa ki gbogbo wọn dawọ iṣẹ duro ki wọn si ma lọ sibi iṣẹ mọ.
Ṣaju eyi ni iroyin sọ pe awọn alaṣẹ ileeṣẹ naa ko jẹ ki ikọ ti ijọba ran lọ wọle lọjọbọ ọsẹ.
Ileeṣẹ naa lo ti wa ṣeleri lati san ẹsan ire fun ẹbi oloogbe Richard.
Tóò bá fún ọkùnrinn lóúnjẹ́ tóo tẹ́ kiní yẹn sílẹ̀ fún un dáadáa... - Yinka TNT
Gẹgẹ bi a ṣe gbọ, oloogbe naa kan ṣagbako iku nigba to wa lẹnu iṣẹ rẹ lọjọ buruku eṣu gbomi mu ọhun.
Ileeṣẹ naa ṣapejuwe iku Richard gẹgẹ bi eyi ti wọn kabamọ rẹ gidi gan wn si ti ṣabẹwo si ẹbi oloogbe leyii ti wọn kọwọrin pẹlu ikọ aṣoju awọn akẹkọọ ileewẹ rẹ lọ sile wọn.
Atẹjade ileeṣẹ ọhun fi han pe wn yoo ṣi maa ba ẹbi naa sọrọ lati ṣeranwọ lasiko ikẹdun yii.
Awọn alaṣẹ ileeṣẹ naa wa rawọ ẹbẹ si ileeṣẹ to n ri si ọrọ awọ́n oṣiṣ ni ipinlẹ Oyo lati jọwọ tun ero wọn pa lori titi ileeṣẹ wọn pa tori pe yoo kan tun da kun iṣoro ọrọ aje eyi ti Covid-19  ti da silẹ tẹlẹ ni.
Bakan naa, ileeṣẹ  Expanded Global Industries Limited ti n ṣiṣẹ pọ pẹlu awọn ọlọpaa ati ileeṣ to n ri si ọrọ awọn oṣiṣẹ l'Oyo lati tuṣu de isalẹ koko ohun to fa sababi iku Richard gangan.
Ijọba ipinlẹ Oyo ti paṣẹ ki ileeṣẹ ti akẹkọọ fasiti Ibadan kan ti pade iku ojiji, fi atẹjade sita nipa ohun to ṣẹlẹ si akẹkọọ yii.
Bakan naa ni wọn ni awọn fẹ ri ẹrọ akaworan silẹ CCTV lati ọdọ ileeṣẹ naa, eleyi ti yoo tọka si bi arakunrin naa ti ṣe ṣagbako iku lọjọ Aje.
Oluranlọwọ si Gomina ipinlẹ Oyo lori ọrọ awọn akẹkọọ, Olojede Victor lo fi ọrọ yi soju opo Twitter rẹ.
Olojede ni oun ati oluranlọwọ Gomina lori ọrọ ọdọ ati idaraya, to fi mọ aarẹ awọn akẹkọọ fasiti Ibadan, lawọn kọwọrin lọ ṣabẹwo si mọlẹbi Richard.
Oríṣun àwòrán, Twitter
O ni bakan naa lawọn kan si ileeṣẹ Henkel Nigeria Limited, ti Richard ti lọ ṣisẹ ti awọn si paṣẹ pe ki wọn lọ yọju si mọlẹbi Richard ni kiakia.
Olojede ni awọn tubọ ni ki ileeṣẹ naa se eto iranwọ fawọn mọlẹbi Richard ati pe, awọn ọlọpaa ti bẹrẹ iwaadi lori ohun to ṣokunfa iku Richard.
Ọjọ buruku eṣu gbomi mu lọjọ Iṣẹgun jẹ fawọn mọlẹbi ati ọrẹ Richard Gbadebo, pẹlu bi iroyin iku rẹ ti ṣe kan wọn lara.
Gẹgẹ bi ohun ti a ri ka, Richard padanu ẹmi rẹ nigba to ko si inu ẹrọ to fi n ṣiṣẹ nileeṣẹ, to n ṣe ọṣẹ abufọṣọ nilu Ibadan.
Ninu alaye ti alukoro awọn akẹkọọ fasiti ilu Ibadan, Oladeji Olawunmi Abiodun ṣe fun BBC, o ni onitiju akẹkọọ ti ko ni wahala ni Richard Gbadebo jẹ.
Oríṣun àwòrán, TWITTER
''Richard ni ọmọ ọkunrin kan ṣoṣo ti awọn obi rẹ  bi. O ni ẹgbọn obinrin ati aburo obinrin.Iru iku gbona bayi kọ lo tọ si Richard.''
Oladeji ni awọn akẹkọọ ti ṣaaju yọju si awọn mọlẹbi Richard lati lọ bawọn kẹdun iku rẹ ati pe, nibẹ ni awọn ti gbọ pe ileeṣẹ to ti ṣagbako iku naa ko ti yọju si wọn lati bawọn kẹdun.
''Nigba ti a gbọ ọrọ yii, a ko ara wa jọ lati lọ ba awọn alaṣẹ ileeṣẹ naa.
Wọn ko kọkọ fẹ gba ki gbogbo wa wọle sugbọn lẹyin ọ rẹyin, eeyan mẹrin ninu wa lo ba wọn.''
''Wọn pada ṣalaye fun wa pe nigba ti Richard fẹ du apo lẹnu ẹrọ to n ṣe ọṣẹ ni o ko si ẹnu ẹrọ naa.''
Ibadan Death: Àwọn ará àdúgbò Akinyele ké sita lórí iṣékúpani  tó ń wáyé ní ìlú Ibadan.
O ni wọn tun sọ fawọn pe''awọn meji ti wọn jijọ n ṣiṣẹ ni wọn ri ẹjẹ lẹnu ẹrọ naa ti wọn si pakiyesi awọn eeyan to ku si pe eeyan kan ti ko si ẹnu ẹrọ.''
Loju opo Twitter,niṣe ni awọn eeyan n daro iku Richard.
Akẹkọọ ipele keji ni ẹka imọ nipa ilẹ Yuroopu (Department of European Studies, Faculty of Arts, University of Ibadan) ni Richard ti n kẹkọọ ki ọlọjọ to de.
Awọn oludari ileeṣẹ to ni ibi ti Richard ti ku ni awọn yoo gbe atẹjade sita lori iku Richard ṣugbọn titi di asiko ti a fi n ṣe akojọpọ iroyin yii, wọn ko ti fi sita.
Woman who gave birth in Dubai: Nàìjíríà ní Suliyat Abdulkareem fẹ́ bímọ sí ṣùgbọ́n wọ́n há sí Dubai nítorí Coronavirus
Oríṣun àwòrán, @OvieSheikh/@helpsuliyatuae
Ọmọ Ọba Dubai, Sheikh Hamdan bin Mohammed bin Rashid Al Maktoum ti ni oun yoo san owo itọju ọmọ Naijiria kan to bi ibẹrin si Dubai, ṣugbọn ti wọn ko ri owo ile iwosan san.
Iya ibẹrin ọhun, Suliyat Adulkareem, bi ọkunrin meji ati obinrin meji lọjọ ikunlẹ kan ṣoṣo nile iwosan Latifa ni Dubai lọjọ kinni, oṣu Keje, ọdun 2020.
Iṣẹ abẹ ni wọn fi gbẹbi ẹni ọdun mọkandinlọgbọn naa, bẹẹ ni awọn ọmọ ọhun ko gbo, eyii to mu ki awọn nọọsi gbe wọn sinu igo.
Gẹgẹ bi ọrọ ti ọkọ iya ibẹrin ọhun sọ fun awọn akọroyin, o ni iye owo itọju iya atawọn ọmọ naa le ni miliọnu mọkanlelogoji naira, ti oun ko si ni kobo lọwọ.
Lẹyin naa ni ọkunrin ọhun, Tijani Abdulkareem ke gbajare si awọn eeyan lori ayelujara fun iranlọwọ.
Oríṣun àwòrán, @OvieSheikh
Agbajọwọ awọn ọmọ Naijiria atawọn eeyan orilẹ-ede miran ni Dubai korajọ, wọn ri miliọnu mẹrin din diẹ da fun un, ṣigbọn ko to nnkan.
Lẹyinorẹyin, ọrọ naa to ọmọ Ọba Dubai leti, o si ti ṣeleri lati gbe owo naa san.
Nigba to n ba ileeṣẹ iroyin CNN sọrọ, Abdukareem ni Oore nla ni ọmọ Ọba Dubai ṣe oun atawọn mọlẹbi oun.
Oríṣun àwòrán, helpsuliyatuae
O ni oun yoo sọ ọkan lara obinrin to wa ninu ibẹrin naa ni Latifa, ti n ṣe orukọ ile iwosan ti wọn ti gbẹbi rẹ.
Baba ibẹrin naa ṣalaye pe oriṣiriṣi awọn eeyan ni Naijiria, titi de Portugal ati Brazil lo ti n pe lati fowo ṣowọ si oun, lẹyin naa lo dupẹ lọwọ gbogbo wọn.
Ṣaaju ni tọkọ-taya naa ti gbiyanju lati pada si orilẹ-ede Naijiria lati bi awọn ọmọ naa, ṣuigbọn wọn ha si Dubai nitori isede ti ijọba Dubai kede lẹyin ti ajakalẹ arun Coronavirus burẹkẹ kaakiri agbaye.
Oronpoto Animation: Akin Alabi ní kò dára bí eré aláwòrán fáwọn ọmọdé ṣe jẹ́ aláwọ̀ funfun
Eld Kabir in Nigeria: Mùṣùlùmí àti Kristiẹni sọ̀rọ̀ nípa àdun oúnjẹ́ àti ẹran ọdún Ileya
Loni ọjọ Ẹti ni ayajọ ọdun Ileya fun tọdun yii taa mọ si Eid Kabril.
Gẹgẹ bẹẹ se mọ pe awọn ọmọde ati agba maa n foju sọna fun ọdun alarinrin yii nitori awọn adun kan to wa ninu rẹ.
Idi ree ti BBC Yoruba fi gbe igbimọ kan kalẹ ninu eyi ta ti ri awọn musulumi ati Kristiẹni, ti wọn ti jiroro nipa awọn adun to wa ninu ọdun Ileya.
Lara ohun ti wọn mẹnuba ni ẹran dindin, ounjẹ ọdun, owo ọdun ati asọ ọdun.
Bakan naa ni igbimọ yii tun mẹnuba bi ọdun Ileya se maa n larinrin lasiko igba ti wọn wa ni ewe atawọn ọna ti wsn n gba gbadun rẹ.
Justice for Richard: Òbí àkẹ́kọ̀ọ́ tó kú síléeṣẹ́ ọṣẹ ń bèèrè fún ìdájọ́ lórí ikú ọmọ wọn
Ọlọrun ma jẹ ka foju sunkun ọmọ laye ni adura ti obi maa n gba sugbọn to ba ri bẹẹ, Ọba oke la gbadura si pe ko tu obi ninu.
BBC Yoruba kan si obi Richard Gbadebo ti wọn kede iku rẹ lọjọ Isẹgun pe o ku sẹnu ẹrọ kan to n se ọsẹ nileesẹ kan nilu Ibadan.
Wọn ni Richard nikan soso ni ọkunrin tawọn bi, iku rẹ si ti mu ki orukọ idile parun.
Awọn mejeeji wa n beere pe o se jẹ ifun Richard nikan lo jade sita , ti ko sisi ipa ẹjẹ lara rẹ.
Ninu ọrọ rẹ, baba Richard, Sola Phillips Gbadebo ni ejo lọwọ ninu iku ọmọ oun, ti awọn si n beere fun idajọ ki ọmọ naa ma ku iku sara lasan.
Victor Osimhen Salary: $96m ni wọ́n ra atamátàsé náà láti Lille
Oríṣun àwòrán, @ZachLowy
Ẹgbẹ agbabọọlu Napoli ti tọwọ bọ iwe adehun lati ra ọmọ Naijiria to n gba bọọlu fun ikọ Lille, Victor Osimhen.
Gẹgẹ bi iroyin ti ileeṣẹ L'Equipe gbe jade, iye owo ti wọn ra agbabọọlu naa lati ilẹ France lọ si iha 'Italian Serie A' le ni miliọnu mọkanlelọgọrin pọun.
Eyii to n tumọ si pe Victor ni agbabọọlu lati ilẹ Afrika ti iye owo ti wọn ra a pọ julọ.
Iye owo ti Napoli san lori Osimhen pọ ju iye owo ti Arsenal san fun Lille lati ra ọmọ orilẹ-ede Ivory Coast, Nicolas Pepe ni nkan bii  ọdun kan sẹyin.
Lẹyin ti ẹgbẹ agbabọọlu Lille ta Pepe ni Osimhen darapọ mọ ikọ ọhun lati ikọ Charleroi, to wa lorilẹ-ede Belgium.
Oríṣun àwòrán, @BBCSport
Lẹyin to sọ goolu mejidinlogun ṣawọn fu ikọ Lille ni saa to kọja ni oju ti wa lara rẹ pe o ṣeeṣe ko tẹkọ leti lọ si Napoli laipẹ.
Lẹyin ti idunadura naa pari ni Osimhen sọ loju opo Twitter rẹ pe inu oun dun lati darapọ mọ Napoli, koda o ni niṣe lo dabi pe ki oun ti wa lori papa.
Justice for Richard: Òbí àkẹ́kọ̀ọ́ tó kú síléeṣẹ́ ọṣẹ ń bèèrè fún ìdájọ́ lórí ikú ọmọ wọn
Alaafin: Ọ̀pọ̀ èèyàn ń bèèrè pé kí ló dé tí Olorì Badra kò fi sí nínú fọ́tò ọdún Ileya
Oríṣun àwòrán, Instagram/olori_omoh_one
Ọjọ Ẹti ni ọdun Ileya waye fọdun yii jakejado agbaye ti gbogbo idile si joko sile lati se ayẹyẹ ọdun naa papọ.
Bakan naa si ni ayẹyẹ yii waye ni aafin Ọyọ, nibi ti iku baba yeye, Ọba Lamidi Olayiwola Adeyemi atawọn olori rẹ ti se yata-yoto ọdun.
Asiko ti wọn n se ọdun yii ni Ọba Adeyemi ke si awọn olori rẹ lati wa fara kinra pẹlu oun ni gbọngan igbẹjọ.
Awọn ayaba kekere naa, ti wọn jẹ ẹlẹ Daddy ati afẹfẹ ti Alaafin fi n mi ni wọn rọgba yi baba ka,  to si ya aworan pẹlu wọn.
Ninu aworan naa, ti awọn ayaba ọhun fi soju opo ayelujara wọn, ni apapọ awọn ẹlẹ Daddy naa ti jẹ meje, dipo mẹjọ taa mọ wọn mọ tẹlẹ.
Oríṣun àwòrán, Alaafin Oba Lamidi Adeyemi III
Ẹni to ba si se akiyesi aworan naa finni-finni lati mọ ewo ninu awọn olori ni ko si ninu aworan naa, a ri pe Olori Badrat Olaitan Ajoke Adeyemi ni ko bawọn peju ya fọto lọjọ Ileya.
Ọna lati ba baba laafin se ayẹsi awọn olori naa si lo mu ka fi aworan naa soju opo Facebook wa.
Sugbọn iyalẹnu lo jẹ pe ibeere to gba ẹnu ọpọ ololufẹ Ọba Adeyemi lasiko ti wọn foju kan aworan naa ni pe:
Ki lo mu Olori Badra kuro l'Alaafin Oyo lọjọ Ileya, ti ko fi ba awọn ayaba yoku ya aworan pẹlu ọkọ wọn lọjọ ọdun?
Koda ọpọ ninu awọn eeyan yii lo tun n beere pe, abi tootọ ni iroyin to ja rain-rain nijooni pe, Alaafin ti le Olori Badrat jade kuro ninu aafin rẹ lori ẹsun asemase?
Bẹẹ ba si gbagbe, iroyin naa lo fẹsun kan Olori Badrat Olaitan Ajọke Adeyemi pe o n ni ifẹ ikọkọ pẹlu ọba olorin fuji kan, Alhaji Wasiu Ayinde Kwam 1.
Iroyin naa fikun pe, isẹlẹ ọhun lo mu ki Ọba Adeyemi ja okun ifẹ to wa laarin rẹ ati olori Badrat, to si ni ko jade kuro ninu aafin.
Bi o tilẹ jẹ pe Olori Badrat ati Wasiu Ayinde sẹ pe ahesọ ọrọ lasan ni iroyin naa, ofuutu-fẹẹtẹ, aasa ti ko ni kaun si ni pẹlu.
Oríṣun àwòrán, queenola2 Instagram
Amọ ko si atẹjade kankan to wa lati aafin Oyo lori isẹlẹ naa, ti ko si si ẹni to lee fidi rẹ mulẹ, boya Olori Badrat si wa ninu aafin abi o ti ko kuro.
Sugbọn ohun ti awa sakiyesi ni pe, Olori naa ko fi bẹẹ gbe aworan oun ati ọkọ rẹ, Alaafin soju opo ayelujara rẹ, gẹgẹ bo se maa n se.
Bakan naa, ko si ajọsepọ mọ laarin rẹ ati awọn olori Alaafin to ku loju opo ayelujara, gẹgẹ bi wọn ti maa n se tẹlẹ.
Bẹẹ si ni Olori Memunat Omowunmi Adeyemi ti oun ati Olori Badrat Olaitan dijọ jẹ korikosun ninu aafin gan, ni wọ̀n ko dijọ se bii ti atijọ mọ.
Oríṣun àwòrán, Olori Memunat Adeyemi Facebook
Asa awọn olori Alaafin ni pe ki wọn maa ki ara wọn ku ayẹyẹ ọjọ ibi tara wọn tabi ti ọmọ wọn.
Sugbọn lati igba ti isẹlẹ ọhun ti waye, ko si Olori Alaafin kankan to ki Ayaba Badrat ku ayẹyẹ ọjọ ibi rẹ, ti oun naa ko si ki ẹnikẹni ninu wọn.
Boya lasiko ti ayẹyẹ ọjọ ibi wọn ba ko tabi tawọn ọmọ wọn, eyi to n kọ ọpọ onwoye lominu.
Idi si ree ti ọpọ eeyan tun fi n beere pe 'Nibo ni Olori Badrat Ajoke wa lasiko ọdun Ileya?
Oríṣun àwòrán, Instagram/olori_omoh_one
Yoruba World Congress: Banji Akintoye ní àwọn ọlọ́pàá fẹ́ sọ àwọn ọmọ ẹgbẹ́ òun sá àhámọ́
Oríṣun àwòrán, others
Ọjọgbọn Banji Akintoye to jẹ aṣiwaju igbimọ Yoruba lagbaye, Yoruba World Congress, ti salaye pe Naijiria ko fararọ fun ẹya Yoruba.
Ọjọgbọn Akintoye ni igbimọ Yoruba lagbaye, Yoruba World Congress gba alaafia laaye ninu iṣe rẹ gbogbo, ti ko si fa ijangbọn kẹsẹ rara.
Amọ o ni sibẹ aarẹ Muhammadu Buhari ṣi n lepa lati yọ orukọ igbimọ naa kuro lara awọn ẹgbẹjẹgbẹ to forukọ silẹ labẹ ijọba.
Bakan naa lo fi kun un pe, awọn agbofinro pẹlu ti n gbaradi lati bẹrẹ sifi panpẹ ọba gbe awọn ọmọ ẹgbẹ naa.
Ninu ọrọ to sọ nibi ayẹyẹ ipade igbimọ awọn ẹya ti ko ni aṣoju ninu igbimọ agbaye, aṣiwaju igbimọ Yoruba lagbaye naa sọ pe ohun ti oju ẹya Yoruba n ri nilẹ yii ko dẹrun rara.
O ni awọn oyinbo amunisin Gẹẹsi, pẹlu ibẹru pe ẹya to kawe gidi ni ẹya Yoruba, wọn si sa gbogbo ipa nigba naa lati tẹri rẹ ba.
Owu Water Fall: Ọba Oyewole ni ibùdó ìrìn àjò afẹ́ gidi ni àmọ́ ọ̀nà ibẹ̀ burú jáì
O fi kun n pe, ọṣẹ pupọ ni ijọba ologun gbogbo to wa ni ṣisẹ n tẹle, tun ṣe fun ẹya Yoruba nigba ti wọn gbẹsẹ le gbogbo dukia ajumọni ilẹ Yoruba.
O fikun pe igbesẹ naa jẹ gbogbo eleyi ti wọn ti gbe kalẹ bẹrẹ lati ọdun 1959, pupọ awọn dukia ajumọni ti wọn gbẹsẹ le naa ni wọn ko mojuto daradara, ti ọpọ si tun ti parun.
Eld Kabir in Nigeria: Mùṣùlùmí àti Kristiẹni sọ̀rọ̀ nípa àdun oúnjẹ́ àti ẹran ọdún Ileya
Akintoye ṣalaye fun ipade apapọ igbimọ agbaye naa pe, aisi aabo to peye, ti mu ki awọn iwa ipa bii ijinigbe, ikọlu awọn agbebọn, ikọlu laarin agbẹ ati darandaran ati bẹẹ bẹẹ lọ, di tọrọ fọnkale nilẹ Yoruba.
O wa fi kun pe, pẹlu bi ọrọ ti ṣe ri yii, ijijagbara ẹya Yoruba ti n debi to lapẹrẹ.
Ebenezer Obey fi ìkéde síta pé òun n gbèèrò láti gbé ìyàwó tuntun,
Oríṣun àwòrán, Instagram/ebenezer obey
Eekan olorin ti gbogbo agbaye mọ ni Oloye Ebenezer Obey jẹ.
Iroyin iku rẹ to kaakiri laipẹ yii fihan bi agba olorin Juju naa ṣe lokiki si, nitoripe kaakiri agbaye ni awọn eeyan ti n beere pe ṣe lootọ ni tabi irọ.
Amọṣa, ṣe awọn agba bọ, wọn ni baoku iṣe o tan.
Nibayii lẹyin ti o ti han gbangba pe agba orin yii ko jade laye gẹgẹ bi awọn kan ṣe sọ, baba funrarẹ ti jade sita pe o ṣeeṣe ki iyawo tuntun o wọle laipẹ o.
Ẹyin naa ni haa, baba Ebenezer Obey ṣalaye ọrọ yii ninu ifọrọwerọ rẹ pẹlu iwe iroyin abẹle kan lorilẹede Naijiria.
Ohun to dara ni ki iyawo wa pẹlu eniyan, ko si tako ofin Ọlọrun...obinrin to ti to ọgọta ọdun ni iru emi bayii n wa, nigba ti mo ba si ṣe e laipẹ, gbogbo aye ni yoo ri.
Nigba ti Ebenezer Obey n sọrọ lori irufẹ obinrin to fẹ, o ṣalaye pe oun ko wa obinrin ti yoo tun maa bimọ mọ bayii bikoṣe nitori ati lee jọ maa wa pọ.
Owu Water Fall: Ọba Oyewole ni ibùdó ìrìn àjò afẹ́ gidi ni àmọ́ ọ̀nà ibẹ̀ burú jáì
Mo ti lọmọ, ọmọ-ọmọ ati ọmọ-ọmọ-ọmọ, Ọlọrun ti bukun mi
"O ṣalaye pe ""oponu agbalagba ni yoo ma a gbeero lati fẹ ọdọmọbinrin, nibi ti ọjọ ori mi de bayii""."
Obey sọ pe iru ọdọmọbinrin bẹ ẹ ṣẹṣẹ bẹrẹ aye ni, to si l'agbara ibalopọ ati okun.
Lara awọn amuyẹ ti iyawo ti baba fẹ ẹ fẹ gbọdọ ni, ni pe yoo ti to ẹni ọgọta ọdun tabi ju bẹẹ lọ, kii sii ṣe nitori ọmọ bibi mọ.
Agba akọrin Juju miliki naa ṣalaye siwaju pe ohun kii ye ṣe afẹri iyawo oun to jade laye ti oun si maa n rii loju ala.
Ọjọ kẹtalelogun, oṣu Kẹjọ, ọdun 2011, ni iyawo Ebenezer Obey, Ajinhinrere Juliana Obey-Fabiyi kú lẹni ọdun mẹtadinlaadọrin.
Dúkìá àti ọjà jóná ráúráú lásìkò tí iná sọ ní ọjà Mushin ní ìpínlẹ̀ Eko
Oríṣun àwòrán, lasema
Ina sọ lapakan ọja awọn to n ta ibusun ni agbegbe Ladipo ni Mushin ni ilu Eko lọjọ Abamẹta.
Ajọ to n mojuto iṣẹlẹ ajalu ati pajawiri nipinlẹ Eko, LASEMA ṣalaye pe ṣọọbu ti wọn ti n ta ibusun kan nibẹ ni ina naa ti kọkọ sọ ki o to ran de awọn ṣọọbu itaja miran to sun mọ ọ.
Oríṣun àwòrán, Lasema
Ṣọọbu ti wọn ti n ta ibusun kan nibẹ ni ina naa ti kọkọ sọ ki o to ran de awọn ṣọọbu itaja miran to sun mọ ọ.
Amọṣa ajọ LASEMA ni awọn oṣiṣẹ alaabo ati adoola ẹmi tete de ibẹ lati pana naa ki o to ṣe ọṣẹ ju bo ṣe yẹ lọ.
Oludari agba ajọ LASEMA, Olufẹmi Oke- Ọsanyintolu ṣalaye pe ipenija nla ni ọrọ ilekanle, orule-kan-orule n mu ba ilakaka ati koju ijamba ina ni ipinlẹ Eko.
Ajọ naa fi kun un pe ko si ẹnikẹni to padanu ẹmi sinu ijamba ina naa.
Owu Water Fall: Ọba Oyewole ni ibùdó ìrìn àjò afẹ́ gidi ni àmọ́ ọ̀nà ibẹ̀ burú jáì
Lagos Lockdown: Wo ìlànà tuntun ṣáájú ṣíṣí ilé ìtura, sinimá, gbọ̀ngàn ayẹyẹ ní Eko
Oríṣun àwòrán, @followlasg
Ijọba ipinlẹ Eko ti gbe ilana tuntun jade fun awọn olokoowo to n fi irinajo afẹ, ati faaji ṣiṣẹ nipinlẹ naa.
Ninu atẹjade kan ti Kọmisanna fun irinajo afẹ, iṣẹ ọna, ati aṣa, Arabinrin Uzamat Akinbile-Yussuf, fi sita ni opin ọsẹ, o sọ pe ilana tuntun naa kan awọn ile itura, ile gbigbe alasiko diẹ, ootẹli, gbọngan ayẹyẹ, ile ounjẹ, ile ọti, ati ile sinima.
Arabinrin Akinbile-Yussuf sọ pe awọn ilana tuntun naa, yatọ si eyi to ti wa nilẹ tẹlẹ bii ọwọ fifọ ni gbogbo igba, lilo sanitaisa, titakete sira ẹni, lilo ibomu-b'ẹnu, ṣiṣe ayẹwo bi ara ṣe gbona si, fifin oogun apakokoro si ayika, ati bẹẹ bẹ lọ.
Awọn ilana tuntun naa niyii:
Arabinrin Akinbile-Yussuf  sọ pe miliọnu kan Naira ni ẹnikẹni to ba ru ofin yii yoo san gẹgẹ bi owo itanran.
Oríṣun àwòrán, OTHERS
Fun awọn ile sinima, wọn gbọdọ ri i daju pe eero iworan ko ju ìdá aadọta lọ lẹẹkan naa, ti wọn si gbọdọ fi ọwọ si iwe akọsilẹ nipa Covid-19.
Kọmisanna fi kun pe awọn ile sinima ko gbọdọ ṣi ilẹkun wọn tayọ aago mẹrin idaji si mẹwaa alẹ, ni ibamu pẹlu ofin isede to wa nita.
Laipẹ yii ni ijọba ipinlẹ eko kede pe awọn ile ijọsin le di ṣiṣi pada lẹyin bi oṣu maarun ti wọn ti wa ni titi pa nitori aarun coronavirus.
'Ìgbà tí mo máa fi lajú sáyé padà, ọ̀fọ̀ ikú mi ní wọ́n ń kígbe'
Ijọba ipinlẹ Eko ti gbe ilẹkun ibudo iyasọtọ awọn alarun Covid-19 to wa ni Eti-Osa ti pa.
Gomina Babajide Sanwo-Olu lo sọ igbesẹ naa di mimọ lọjọ Satide, lasiko to n ba awọn araalu sọrọ lori ibi ti nkan de duro nipa aarun naa nipinlẹ Eko.
Gomina fi kun ọrọ rẹ pe laipẹ ni wọn yoo tun ti eyi to wa ni Agidingbi, ti wọn o si ko awọn alaarun naa lọ si ibudo nla tuntun IndoCentre, ti wọn ṣẹṣẹ kọ si adugbo Anthony.
Gẹgẹ bi gomina ipinlẹ Eko, Babajide Sanwo-Olu ṣe sọ ọ lọjọ abamẹta, O ni ki awọn ara ipinlẹ Eko fi sọkan pe aridaju akọsilẹ n wa pe bi eeyan pupọ ba korajọ, o lee dakun aranka arun Covid-19.
Sanwo-Olu ni awọn ile ijọsin yoo di ṣiṣi pada fun awọn Musulumi ati Kristẹni ṣugbọn ida aadọta ninu ọgọrun pere ni wọn faaye gba.
Lafikun o ni awọn ṣọọsi to jẹ pe ọjọ Satide ni wọn maa ṣe isin naa lanfani lati bẹrẹ pada ṣugbọn ni itẹle ofin ti awọn ti ọjọ aiku naa n tẹle ni o.
O ni ẹẹkan lọsẹ nikan ni awọn ile ijọsin lanfani lati pe jọ pọ ti wn si lee ko isin pupọ jọ loojọ bi wọn ba ṣaa ti tẹle ofin aadọta olujọsin.
Ẹwẹ, o ni wọn lee gba awọn eniyan niyanju ti wọn ba nifẹ si wiwo isin naa lori ayelujara lati ṣe bẹẹ.
Tóò bá fún ọkùnrinn lóúnjẹ́ tóo tẹ́ kiní yẹn sílẹ̀ fún un dáadáa... - Yinka TNT
Yatọ si eyi, anfaani ti wa fun ipejọpọ ita gbangba bi ipade, lati gba to aadọta eyan, dipo ogún ti ijọba pa laṣẹ tẹlẹ.
Gomina Sanwo-Olu tun kede pe awọn ile ounjẹ yoo bẹrẹ si ni fi aaye gba awọn onibaara wọn lati joko jẹun.
Awọn ileewe girama ti ijọba ati aladani yoo di ṣiṣi pada fun awọn akẹkọọ to fẹ ẹ ṣe idanwo aṣejade.
Ko ti i si aaye fun awọn ibudo igbafẹ bi i ile ọti, ile iworan bọọlu ati ibudo ti wọn ti n ṣafihan sinima lati bẹrẹ iṣẹ pada.
Mummy calm down: Ìyá Ore sọ pé gbogbo ìgbà tí óun bá n bá a wí ló ma n ṣe àwàdà
Amọ o, gbogbo awọn ti ijọba ti fun ni anfaani lati bẹrẹ iṣẹ wọn pada gbọdọ ma a tẹle awọn ilana bi i titakete siraẹni, lilo ibomu, ati ọwọ fifọ.
Yatọ si awọn ilana tuntun yii, gomina tun kede pe o ti le ni ẹgbẹrun mẹẹdogun eeyan to ti ni coronavirus ni ipinlẹ Eko.
BBNaija 2020: Trikytee àti Ozo ní wọ́n fọ́wọ́ òsì júwe ile fún ni bbnaija lọ́sẹ̀ yìí
Oríṣun àwòrán, Instagram
Gẹ́gẹ́ bí ìṣe ilé ẹlẹ́gbọ̀n àgbà, Laycon mórí ní wan kọ́kọ́ pè jáde sùgbọ́n lẹ́yìn o rẹyin Trikytee ni wọ́n júwe ilé fún.
Trikytee ni olukópa kẹrinla ti yóò kúrò nínú ilé BigBrother
Ebuka ni, ààyà wà fún ẹnikẹni tó bá fẹ́ dìbò fún ẹnikẹ́ni láti jáwe olúbori pẹ̀lú mílíọ̀nu márundìndinláàdọ́run náírà le bẹ̀rẹ̀ láti alẹ́ òní títí di ọjọ́ Eti tọ n bọ̀.
Nínú ọ̀rọ̀ rẹ̀ lẹ́yìn ti Trikytee kúrò nínú ilé, lo sàlàye pé, ìyalẹ́nu ló jẹ́ pé , òun di àsìkò yìí nínú ilé Big Brother nítori pé ọ̀sẹ̀-ọ̀sẹ̀ ni oun ti ma n múra sílẹ̀ láti lọ.
Bákan náà lo sàlàyé pé, kò tẹ̀wọ̀n tọ láti sọ pé òun máá n sábà tèlé ẹni to bá ni àgbára nínú ilé ni òun má n rìn mọ́.
Ní kété ti wọ́n kéde pé ki Ozo máa lọ ilé ni ó gbìyànjú láti f'ẹ́nuko Nengi lẹ́nu bi ikíni ìdágberé
Nínú ìfọ̀rọ̀wánilẹ́nu wò ti Ebuka ṣe fún Ozo, ó ni ìṣesí Nengi àti àwọn ǹkan to ni òun fẹ́ dà láyé wà lára ǹkan tó fi ìfẹ́ rẹ̀ sí.
O ní òun ri àra òun bi omi sùgbọ́n ìna ni Nengi, eni ti àwọn si lé jọ gbé ìdílé ró ni
Nígbà ti Ebuka bèrè lọ́wọ́ Dorathy bóya ó ti ṣetán láti lọ ilé, o ni rárá nítori ko si ibi ti oun fẹ́ lọ bí òun bá kúrò nilé ẹlẹ́gbọ̀n àgbà.
Ó kú ènìyàn márun-ún ti yóò bá ètò náà de ìparí ní sáà BigBrother Naijia yìí.
Àwọn náà ni Vee,
Neo
Nengi
Laycon
Dorothy
Àwọn mẹ́ẹ̀dógun lo tí kó ẹrù wọ́n kúrò níle ẹlẹ́gbọ̀n àgbà láti ìgbà ti ètò náà ti bẹ̀rẹ̀ Lilo, Ka3na, Eric, Tochi, Kaisha, Praise, Wathoni, Tolanibaj, Bighto, Lucy, Prince Kiddwaya, Trickytee àti Ozo,wọ́n lé Erica lọ nírori o rú òfin Bigbrother.
Tani ẹ rò pé yóò lọ nílé ẹlẹ́gbọ̀n ọ́n àgbà BigBrotherNaijia lálẹ́ òní?
Bí ètò ilé ẹlẹ́gbọ̀n àgbà ṣe ń káṣẹ̀ nílẹ̀ wẹ́rẹ́wẹ́rẹ́, àrà ọ̀tọ̀ ni bí wan ṣe fẹ́ yàn àwọn ti yóò lọ kúrò nínu ilé lónìí.
Nínú àwọn méje to ku nínú ilé ni ẹlẹ́gbọ̀n àgbà Trikytee, Vee, Laycon, Neo, Dorathy Ozo ní pín si ẹgbẹ́ méjì láti yàn ènìyàn méjì nínú ẹgbẹ́ méjèèjì tí yóò lọ kúrò nínú ilé ẹlẹ́gbọ̀n àgbà.
Nígbà ti Nengi jẹ́ olórí ilé.
Ẹgbẹ́ aláwọ̀ dúdú àti ẹgbẹ́ aláwọ̀ fúnfun.
Ẹgbẹ́ aláwọ̀ Dudu ni a ti rí
Neo
Dorathy
Ozo
Nígbà ti ẹgbẹ́ aláwọ̀ funfun  ni
Trikytee
Vee
Laycon
Àwọn ẹgbẹ́ méjèèjì yìí yàn Laycon àti Trikyhtee bákan náà wọn mú  Dorathy àti Ozo
Nínú àwọn mẹ́rin yìí a kò tíì kò tii mọ eniyan meji tí yóò lọlé lònìí
Tani ẹyi rò pé yóò lọ ilé nínú àwọn mẹ́rin yìí lálẹ́ òní
Oríṣun àwòrán, Instagram/Nengi
Nengi di olórí tuntun nílé ẹlẹ́gbọ̀n-ọ́n àgbà BBNaija
Nengi ti di olori ile ẹlẹgbọn ọn agba Big Brother Naijia ọjọ Aje ọjọ kẹrinla oṣu kẹsan an.
Igba keji ree ti Nengi yoo gba ipo olori laarin oṣu meji le diẹ.
Awọn mẹfa ni wọn jọ dupo olori ile, TrikyTee nikan ni ko dije nitori oun ni o wa nipo olori ki Nengi to jawe olubori.
Yatọ si awọn olori to ti jẹ tẹlẹ, Nengi ko ni ni igbakeji nile.
Pẹlu ipo olori ti Nengi wa bayii, o ti lanfaani lati wa nile ẹlẹgbọn ọn agba di ọsẹ ti eto naa yoo kasẹ nilẹ.
Prince àti Kiddwaya ní ọpọ́n ilé  sún kàn nílé ẹlẹ́gbọ̀n-ọ́n àgbà BBNaija!
Prince ati Kiddwaya ni olugbe ile ẹlẹgbọn ti wọn ni ko ma kẹru wọn lọ sile lọsẹ yi.
Ninu awọn mẹrin ti orukọ wọn lewaju pe wọn le lọ sile, awọn ni iye ibo ti wọn ri kere ju lọ.
Ni bayi, Prince ati Kiddwaya ni olukopa inu idije Big Brother Naijia ẹlẹẹkejila ati ikẹtala ti wọn yoo ni ko maa lọ sile.
Awọn to ti ṣaaju rẹ lọ ile ni Lilo, Ka3na, Eric, Tochi, Kaisha, Prince, Wathoni, Tolanibaj, Bight O ati Lucy.
Bakan naa ni Erica to wa lara awọn olukopa ogun to bawọn bẹrẹ idije naa ti dero ile lẹyin ti wọn le kuro lọjọ Kẹfa oṣu Kẹsan, 2020.
Oríṣun àwòrán, @BBNaija/Twitter
Ọkan ninu awọn mẹsan an to ku ninu Ile Ẹgbọn Agba, Big Brother Naija n lọ sile loni gẹgẹ bi awọn oluworan ba ṣe dibo fun wọn si.
Ninu awọn mẹsan an to ku naa, awọn mẹrin ti wọn dibo pe wọn le ja kuro ninu BBNaija ni Dorathy Prince, Kiddwaya ati Ozo.
Oríṣun àwòrán, @goji1986
Ohun to ṣẹlẹ ni pe awọn mẹsan an to wa ninu ile naa ni anfaani lati fi orukọ ẹni meji silẹ ti wọn fẹ ko maa lọ sile.
Esi idibo naa fihan pe Prince lo ni ibo mẹfa, Dorothy tẹle pẹlu ibo mẹrin, Kiddwaya pẹlu ibo mẹta, Ozo ati Neo pẹlu ibo meji, nigba ti Nengi ati Vee ni ibo kọọkan.
Amọ, awọn oluworan ni o ṣeeṣe ki Prince jẹ ẹni ti yoo lọ sile, amọ Dorathy ni awọn eniyan wo wi pe ko lee lọ ninu awọn mẹrin naa.
Oríṣun àwòrán, @BBNaija Twitter
Wọn ti fi ọwọ osi juwe ile fun Erica, wọn si ti ni ko kuro ninu ile ẹlẹgbọn-ọn agba Big Brother Naija to n lọ lọwọ.
Ati alẹ ọjọ Abamẹta lo ti dabi pe nnkan ko ni ṣenu ire fun Erica lẹyin iwa to wu ninu ile naa, eyii to jẹ igba kẹta rẹ.
Iwa naa si ti mu ki ọpọ awọn ololufẹ rẹ maa bu ẹnu atẹ lu ṣaaju ki wọn to fi ọwọ osiu juwe ile fun un.
Ṣaaju ni ija kan ti kọkọ waye larin Erica ati Laycon, nibi ti Erica ti sọ awọn ọrọ kobakungbe kan.
Erica wọjọgbọn lẹyin ti Biggie ṣafihan fọrọn rogbodiyan ọhun fun un, to si tun sọ pe o ba ohun ini oun jẹ ni bo ṣe da omi sori ibusun olori ile naa, eyii to ni ko ṣetẹwọgba.
Biggie tun fẹsun kan Erica pe o ru ofin miran lẹyin to kọ lati gba igbakeji olori ile naa, Prince, laaye lati sun si ibi to yẹ ki olori ile ọhun sun si.
Biggie pari ọrọ rẹ pe awọn iwa to wu lodi si ofin to so ile ẹlẹgbọn agba naa ro.
Lẹyin na lo ki Neo nilọ lori iṣẹlẹ naa.
Ki lo ti ṣẹlẹ ṣẹyin?
Oríṣun àwòrán, BBNaija/twitter
Tolanibaj, Wathoni ati Brighto ni wọn le kuro nile Big Brother Naija l'ọsẹ yii.
Awọn mẹtẹẹta ni ẹnikeje, ikẹjọ ati ẹni ksan-an ti wọn le kuro lori eto ori tẹlifisan ọhun.
Tolanibaj, TrickTee, Kiddwaya, Prince, Erica, Lucy, Leo, Wathoni, Dorathy, Vee ati Laycon ni awọn ololufẹ eto naa fi orukọ wọn silẹ pe ko kuro nile ẹlẹgbọn agba.
Ṣugbọn, ibo awọn mẹtẹẹta lo kere julọ.
Oríṣun àwòrán, Twitter
Wathoni
Florence Wathoni Anyansi jẹ ẹni ọdun mọkandinlọgbọn, o si jẹ oniṣẹ adani ni ẹka oge ṣiṣe.
Bakan naa lo tun ma n tẹ akọsilẹ jade lori ayelujara, nipa jijẹ òbí.
Oríṣun àwòrán, Twitter
Tolanibaj
Tolani Shobajo jẹ ẹni ọdun mẹtadinlọgbọn. Ọmọ ipinlẹ Eko ni, o si n ṣiṣẹ agbohunsafẹfẹ.
Oríṣun àwòrán, Twitter
Brighto
Ezekiel Bright 'Brighto' Osemudiame naa jẹ ẹni ọdun mọkandinlọgbọn. Ipinlẹ Edo lo ti wa. O si jẹ awakọ ọkọ oju omi.
Ọsẹ to kọja ni ibanuje sọri agba Praise kodo, wọn ni ko kẹru rẹ kuro ninu ile Big Brother.
Oríṣun àwòrán, BIGBROTHER NAIJA/AFRICA MAGIC
Ṣugbọn Ikede yi to jẹ eyi to maa n waye lọsọọsẹ lẹyin tawọn olukopa ninu ere ile ẹlẹgbọn ba dibo tan kọ lawọn eeyan n ran lẹnu loju opo Twitter.
Ọrọ ti Ebuka atọkun eto sọ nipa Laycon ati Erica ati bi o ti ṣe doju ọrọ kọ Vee.
Ohun taa le sọni pe o kere tan ara ile mẹta lo dibo yan Praise pe oun ni ko maa lọ ile.
'Ìgbà tí mo máa fi lajú sáyé padà, ọ̀fọ̀ ikú mi ní wọ́n ń kígbe'
Ṣaaju, ninu eeyan mẹẹdogun, Trichytee, Wathoni, Praise ati Vee ni ara ile mẹrin ti ibo wọn kere ju lati ita lọsẹ yii.
Ẹwẹ, Tolanibaj, Nengi ati Brighto lo sọ fun Big Brother pe Praise lawọn fẹ ri akẹyinsi rẹ ko maa lọ ile.
Loju opo Twitter niṣe lawọn eeyan kan n gboṣuba kare fun Vee bo ti ṣe da Ebuka lohun tawọn miran si n sọ pe ki awọn eeyan sọra fun Ebuka.
Praise ni olukopa ẹlẹẹkefa ti yoo kogba lọle kuro lori eto BBNaija alagbelewo to n lọ lọwọ.
Oríṣun àwòrán, BIG BROTHER NAIJA
Wọn yọ Kaisha ati lẹyin ti ibo ti awọn ololufẹ eto agbelewo naa to dibo di fun oun atawọ̀n mẹ̀ta miran ko gbewọn to tawọn ẹlẹgbẹ wọn yoku.
Awọn olukopa mẹrin lorukọ wọn wa lori iwe ile ya fun ọsẹ kẹrin.
Awọn naa niwọnyii:
1.Trikytee
2.Kaisha
3.Wathoni
4.Neo
Amọṣa lẹyin eto alalẹ ọjọ Aiku nibi ti wọn ti maa n kede ẹni ti ile ya fun ni olugbalejo eto naa, Ebuka Obi-Uchendukede orukọ Kaisha gẹgẹ bi awọn olukopa ti awọn to n wo eto naa dipbo fun pe ki wọn maa gba ile wọn lọ.
Kaisha yoo maa tẹle, Tochi ati Eric ti wọn yọ bii jiga kuro ni ile naa ni opin ọsẹ kẹta rẹ lọjọ Aiku to kọja ninu awọn mẹjọ torukọ wọn wa ninu iwe ile ya fun ọsẹ naa.
Oríṣun àwòrán,  BBNAIJA
Ninu ọrọ rẹ to sọ lẹyin ti wọn yọọ jade, Kaisha ni ko ya oun lẹnu pe awọn ẹgbẹ ohun dibo yọ oun jade nitoripe oun mọ ninu iwa ati iṣe wọn si oun pe wọn ko nifẹ oun rara.
Nigba ti wọn bii pe ki lo wa laarin oun ati Neo, Kaisha ni oun nifẹ Neo lootọ ni ibẹrẹ.
O ni ni bayi ti oun ti ṣetan ni ile ẹlẹbọn agba BBNaija bayii, oun n lọ gbaju mọ ileeṣẹ itọju ara ti oun da silẹ ni ati pe oun yoo tun mojuto eto ẹkọ ohun.
Natalia Mufuta ìyá Yakub, Kamil àti Adam sọ̀rọ̀ lórí bí wọ́n ń sọ èdè mẹ́rin pàpọ
Saaju ni ẹlẹgbọn agba funrarẹ ti bu omi ikilọ wọn Nengi ati Kaisha larafun wahala to bẹ silẹ laarin lowurọ ọjọ Abamẹta.
O ni irufẹ iwa bẹẹ tako abala kini ofin kejidinlogun to de ihuwasi ninu ile eto ẹlẹgbọn agba BBNaija.
Bakan naa ni ẹlẹgbọn agba ṣalaye pe ikils naa kan gbogbo awọn olukopa nitori ofin igbele naa ko faye gba ija tabi iwa ipa yoowu.
O jẹ ko di mims fun gbogbo wọn pe aparo kan ko ga ju ọkan lọ laarin wọn nitori naa ko si eyi to ju eyi lọ ninu gbogbo wọn.
Láti ìgbà ti ilẹ̀ ti mọ́ lówùrọ òni ni àwọn ọmọ Naijiria tí n fójú sọ́na wípe tani- ẹgban àgbà yóò lé lọ sílé.
Ọ̀pọ̀ ènìyàn ló sì ti ń sọ ẹni ti wan ni lọ́kan pé yóò lọlé, sùgbọ́n bí o ṣe bá àwọn lan lójiji pé Eric àti Tochi ló lọ sílé, àwọn míràn ni kò ya àwọn lẹ́nu pé èyí ṣẹlẹ̀.
Ní kété ti Eric àti Tochi  jáde ni wọ́n ti n dúpẹ lọ́wọ́ àwọn ọmọ Naijria pé wọ́n kú àdúrótì lásìkò ti wọ́n wà nílé ẹlẹ́gbọ̀n àgbà.
Tí ẹ ò bá gbàgbé, Lilo to jẹ́ ọ̀rẹ́bìnrin Eric ni wọ́n lé kúro nílé ẹlẹ́gbọ̀n-ọ̀n àgbà lọ́sẹ̀ tó kọja.
Wọ́n sọ èyí di mímọ̀ lójú òpó Twitter wọ́n.
Ní báyìí o ti ku àwọn akópa mẹ́rìndílógún nínú ilé ẹlẹ́gbọ̀n-ọ́n àgbà.
Ẹ̀wẹ̀, àwọn ọmọ Naijiria gẹ́gẹ́ bi ìṣe wọ́n, wọ́n ti sọ bí ǹkan yóò ṣe ri láàrin Lilo àti Eric nígbà ti wọ́n bá fi ojú kan ara wọ́n.
Díẹ̀ lára àwọn ǹkan ti wọ́n ń sọ lójú òpó Twitter rèé
Big Brother Naija season 5 eviction: Nengi, Kaisha, Laycon, Praise àbí ta ni ilé ń pè?
Oríṣun àwòrán, BBNaija/Twitter
Loni ọjọ Aiku, ọjọ kẹsan an, oṣu kẹjọ yii ni ibeere nla ti gba ọkan awọn ololufẹ eto Big Brother Naija season five yii.
Lẹyin ti Ka3na ati Lilo to bẹrẹ ikopa pẹlu awọn to ku ti dero ile onikaluku ni ọkaa awọn eeyan naa ti gbe soke.
Ojọ kọkandinlogun, oṣu keje, ọdun 2020 ni awọn eeyan yii wọle sile ẹlẹgbọn ọn agba ni eyi to fihan pe irinajo wọn ṣi ku aadọrin ọjọ nibẹ sii.
Oríṣun àwòrán, Others
Ka3na àti Lilo ló kọ́kọ́ dágbére fún ètò Big Brother Naija 2020
Ka3na àti Lilo ló kọ́kọ́ dágbére fún ètò Big Brother Naija 2020
Lilo ati Ka3na ni eeyan meji akọkọ ti wọn le kuro ninu eto Big Brother Naija season 5 lockdown, lẹyin ọsẹ meji ti wọn ti lo.
Orukọ awọn mejeeji, pẹlu Erica ati Praise ni awọn olulufẹ eto naa fi silẹ pe ko pada sile, lẹyin ọsẹ meji ti wọn ti wa ni ile naa.
Ẹnu ti kun Ka3na lopin ọsẹ to kọja, lẹyin ti iroyin jade pe oun ati Praise jọ ni ibalopọ.
Ninu fidio kan lo ti han pe awọn mejeeji jọ n fi ara gbo ara lori ibusun, ti wọn si yi aṣọ bori.
Ọkọọkan lọmọ ọwọ maa n yọ, lo difa fun bi awọn oludije mejeeji ṣe dagbere fun ile ẹlẹgbọn loni tii ṣe ọjọ keji, oṣu Kẹjọ.
Bayii si ni esi ibo naa ṣe lọ
Ìdílé tí ọkọ da ọmọ síta tóríi ojú Búlùú tí wọ́n ní bá BBC sọ̀rọ̀
Lọṣe yii, mejidinlogun ninu awọn eeyan ogun to n kopa ninu eto agbelewo yi ni wọn kọkọ forukọ wọn sita, ti awọn ara ile  si dibo lati yọ awọn ti yoo palẹmọ ẹru lọ sile.
Ẹlẹgbọn agba funra rẹ, Biggie lo mu ayipada yi ba ofin idije naa.
Awọn ọmọ inu ile mẹrindinlogun ni orukọ wọn wa ni bebe lati ko kuro ninu ile:
Oríṣun àwòrán, @bbnaija/twitter
Esi ibo ti awọn ololufẹ eto Big Brother Naija Laockdown di lati mọ ẹni ti yoo kọkọ kuro nibi eto naa.
Wọn ti pari idibo lori awọn olugbe ile ẹlẹgbọn agba ti wọn le dibo lati yọ ninu abala idije naa ti a mọ si Big Brother Naija lockdown Season 5.
Olori ile Lucy ati igbakeji rẹ Prince ni wọn ni 'imuniti' tori naa wọn ko ni si lara awọn ti wọn yoo dibọ lati ran lọ sile.
Ababọ esi idbo yi ni yoo tọka awọn oludije ti yoo kẹru kuro ninu ile ẹlẹgbọn agba.
Oludije ti ibo rẹ ba kere ju lọ ni wọn yoo fọwọ osi juwe ile fun
Tóò bá fún ọkùnrinn lóúnjẹ́ tóo tẹ́ kiní yẹn sílẹ̀ fún un dáadáa... - Yinka TNT
Bawo ni idibo ijuwe ile fawọn oludije yoo ṣe lọ ni ti ọdun yii?
Oríṣun àwòrán, BBNaija/Twitter
Ebuka Obi-Uchendu ni atọkun eto naa
Ni gbogbo ọjọ Aiku lawọn oludije yoo kopa ninu idibo iyọnikuro ninu ile ẹlẹgbọn.
Ọkọọkan ninu awọn oludije yoo lanfaani lati yan awọn  akẹgbẹ wọn mẹrin ti o ni ibo to kere julọ ninu iyara ifọrọwanilẹnuwo,'Diary Room'.
Oludije tawọn akẹgbẹ rẹ ba di ibo to pọju lọ fun ni yoo kẹru rẹ kuro lọsẹ naa.
Igba akọkọ ree ti awọn alakoso ere ile ẹlẹgbọn yoo gbe iru ofin yi kalẹ lati yọ awọn oludije kuro ninu ile ọhun.
Sex: Ìye ìgbà tóo ní ìbálòpọ̀ kọ́ ló ń jẹ́ kí abẹ́ obìnrin fẹ̀
Oríṣun àwòrán, Yinka TNT/Facebook
O lereju abẹ ti ọkunrin maa n fẹ ba le, ti wọn ba ti wọle ti wọn ri i pe awọn ja lu Express, wọn a sa pada.
Bẹẹ ba wo awọn onimọ nipa ibalopọ jakejado agbaye, wọn o ki n fẹ keeyan maa ṣẹnu ku pe awọn ẹya ara to wa fun ilo ibalopọ lakọ labo.
"Ko yọ Yinka Ayanda ti ọpọlọpọ mọ si ""Yinka TNT"" silẹ pẹlu bo ṣe tẹnu mọ ọ pe ""bi ẹ ṣe n pe oju ara yẹn o maa n bi mi ninu, ẹ wa orukọ mii to dun fun un""."
O dabaa awọn orukọ kan bii Agbekẹ, Kabiyesi, Amuniṣiwi, Amunirẹrinmusẹ ati bẹẹ bẹẹ lọ.
Bi ti ọkunrin lo wa n sọ ni tabi ti ara obinrin, awa o le pin in si isọri.
Ohun tẹ́ẹ gbúdọ mọ nípa kókó orí ọyàn yín lásìkò fífọ́mọlọ́yàn
"Ìyá àwọn ọmọ oní ""Blue Eyes"" n'Ilorin t'ọ́kọ dà síta bá BBC Yoruba sọ̀rọ̀"
Ẹ́ wo bí sọ̀rọ̀sọ̀rọ̀ yìí ṣe ń fi ara rẹ̀ kọ́ àwọ́n òbinrin ní ìgbádùn ìbálòpọ̀
Bíbéèrè fún ìbálòpọ̀ gbogbo ìgbà sọ ìyàwó ilé dèrò ilé ìwòsàn
Wò ó bo ṣe mú ara rẹ dé ibi tó ga jùlọ nínú ìbálòpọ̀ pẹ̀lú ìlànà Tantra
Ilu London ni Yinka Ayanda wa to ti n ṣe iṣẹ to yan laayo lati maa ba awn kunrin ati obinrin sọrọ nipa gbigbadun ibalopọ ko da o ni eto lori ayelujara ti ọpọlọpọ maa n rọ bo lati wo olorin si ni pẹlu.
Oríṣun àwòrán, Yinka TNT/Facebook
Koda lasiko ti a n fi ọrọ wa Yinka TNT lẹnu wo, o ni i lara gan lati maa ṣẹnu ku pe awọn ẹya ara yii eyi to ti mọ ọ lara gẹgẹ bi onimọ nipa ibalopọ lakọ labo.
Amọ nitori ofin iṣẹẹ tiwa, kii ṣe gbogbo ọrọ lo ṣee sọ sita tori oniruuru eeyan lo n ka iroyin wa tabi wo fọnran ti a ba fi sita, bẹẹ si ni a gbudọ jẹ ki ohun gbogbo dọgba fun awọn ololufẹẹ wa.
Sibẹ sibẹ lori iru ọr bayii, ani lati fii lẹ bẹẹ ki alejo wa sọ oju abẹ niko nipa awọn ọrọ kọọkan ti ko ṣee tẹnu bọlẹ sọ nipa ibalopọ.
Iwadii fi han pe ọpọlọpọ nkan ti a ṣẹnu ku sọ nipa ibalopọ lo n ko ba ọpọlọpọ igbeyawo to si ti jẹ ọpọlọpọ wọn tuka.
Ẹwẹ, alejo wa ki ẹnu bọ ọrọ lorii bi ẹ ṣe le gbadun ibalopọ, ohun to n jẹ ki ọkunrin wo ita, ohun to n jẹ ki obinrin di ọga ara rẹ tabi sa fun ibalopọ pẹlu ololufẹ rẹ.
Ọrọ pọ ninu iwe kọbọ.
Èmi kọ́ ni mo fi mo fi fídíò ọmọ mi sí ayélujára - Ìyá 'Mummy calm down'
Yoruba Nollywood: Àgbà òṣèré tíátà, Musiliat Arikeusola 'Osuntoun' jáde láyé
Oríṣun àwòrán, OTHER
Iku tun ti mu ọkan gboogi laarin awọn agba oṣere tiata Yoruba lorilẹede Naijiria, Alhaja Musiliat Arikeuọọla ti ọpọ mọ si Ọṣuntoun lọ.
Gẹgẹ bi iroyin ti a gbọ, opin ọsẹ yii naa ni Alaaja Ọṣuntoun jade laye lẹni ọdun mẹtadinlaadọrin.
"Ko si ẹni to ba n wo awọn ere ibilẹ Yoruba to kun fun aṣa, iṣe ati igbagbọ ẹya Yoruba ti ko ni mọ mama, Ọṣuntoun paapaa julọ nitori awọn ipa awọn ""ẹlẹmi agba"" to ko ninu awọn ere oloogbe Yẹkini Ajilẹyẹ."
Ile rẹ lagbegbe Ijẹtu nilu Osogbo ni Mama dakẹ si.
Akọwe fun ẹgbẹ awọn onitiata ni ipinlẹ Ọṣun, Ademọla Adedokun fi idi iroyin iku rẹ mulẹ fun awọn oniroyin.
Lara awọn ere ti oloogbe Osuntoun ti kopa ni Koto Orun, Aye Akamara, Koto Aye, ti gbogbo rẹ jẹ latọwọ oloogbe Ajilẹyẹ.
Oloogbe Ọṣuntoun funrarẹ naa gbe awọn ere kan jade bii 'Omi Ipin,' 'Imi Esin' ati 'Ogun Omo Iya le', to jẹ ere ti o ṣe gbẹyin, gẹgẹ bi ọgbẹni Adedokun ṣe sọ.
Tóò bá fún ọkùnrinn lóúnjẹ́ tóo tẹ́ kiní yẹn sílẹ̀ fún un dáadáa... - Yinka TNT
Abiola Ajimobi: Igbákeji ààrẹ sàbẹwò sí ìyàwó Ajimọbi
Oríṣun àwòrán, others
Ọjọ nii pẹ, ipade kii jinna, ki Ọba oke maṣe jẹ ka jẹ gbese.
O ti pe ogoji ọjọ lonii Ọjọbọ ti gomina ana nipinlẹ Oyo, Sẹnetọ Abiola Ajimobi dagbere faye.
Bẹẹ ba gbagbe, ọjọ kẹẹdọgbọn, oṣu Kẹfa, ọdun 2020 ni opo nla nipinlẹ Oyo naa yẹ, ti erin Ajimobi subu lai le e dide.
Niwọn igba to si jẹ pe ti ọdẹ ba ku, ọdẹ nii soro lẹyin ọdẹ, idi ree ti ẹbi, ara, ojulumọ, atawọn alajọṣepọ rẹ ninu oselu fi korajọpọ sile rẹ l'Ọjọbọ lati sami ogoji ọjọ to dagbere faye.
Oríṣun àwòrán, others
Ninu waasi ti wọn gbe kalẹ lati gba awọn eeyan niyanju níbi eto naa, Sheikh Muideen Ajani Bello atawọn agba Alfa to wa nibẹ gba awọn ololufẹ Ajimobi nimọran lati mase jẹ ki ogun rere to fi silẹ parun.
Bakan naa ni awọn eeyan to peju síbi eto naa yonbo iwa rere oloogbe naa, bẹẹ ni wọn ṣe apejuwe rẹ bii Araba nla to n mi igbo kijikiji lagbo oselu ipinlẹ Oyo ati lorile-ede Naijiria lapapọ.
Lara awọn eekan ilu to peju síbi adura ọjọ mẹjọ to waye nile Ajimobi to wa ni Oluyole nilu Ibadan ni Gomina Ipinlẹ Kano, Abudullahi Ganduje ati aya oloogbe, Florence Ajimobi.
Awọn yoku ni igbakeji gomina Ajimobi, Moses Adeyemo, Sẹnetọ Teslim Folarin, Asofin Segun Odebunmi, Adebayo Adelabu atawon agba Alfa loniruuru.
Ṣugbọn ìjọba ipinlẹ Oyo ko peju tabi fi asoju ransẹ sibi adura ọjọ mẹjọ fun Abiola Ajimobi.
Ni ibẹrẹ ọsẹ yii ni igbakeji gomina ipinlẹ Ọyọ, Onimọẹrọ Rauf Ọlaniyan ṣalaye pe oun ko fi igba kankan binu si iyawo gomina ana ni ipinlẹ naa, Arabinrin Florence Ajimọbi lori awọn iṣẹlẹ gbogbo to ṣẹlẹ lẹyin iku ọkọ rẹ, Sẹnetọ Abiọla Ajimọbi.
Ninu ọrọ kan to ba awọn oniroyin sọ ni ile rẹ ni Onimọẹrọ Ọlaniyan ti sọrọ yii.
O ni oun mọọmọ paṣẹ fun awọn ẹṣọ oun lati maṣe fi ọwọ kan ẹnikẹni ni ni kete ti oun ri bi nnkan ṣe fẹ maa lọ nigba naa.
"Mo mọ iru ipo ibanujẹ ti aya gomina ana naa wa, mi o si binu sii lẹyin iṣẹlẹ ọjọ naa. Iwa ọmọluabi gbọdọ wa lara wa.
Mi o ni ko wa tọrọ aforiji o, nitori pe ko si ẹni to gbadura pe ki oun wa ni iru ipo to wa nigba naa, Ibanujẹ lo ṣokunfa ohun to ṣẹlẹ nigba naa.
Ogun COVID-19 test: Ìjọba kéde ìlànà tuntun fún ìwọlé àwọn akẹ́kọ̀ọ́ tó fẹ́ ṣe ìdánwò àṣejáde
Oríṣun àwòrán, @dabiodunmfr/theencounter.com.ng
Ijọba ipinlẹ Ogun ti kede pe, eto ayẹwo arun Coronavirus ti di ọfẹ fawọn akẹkọọ ile ẹkọ girama to fẹ wọle pada.
Ijọba gbe igbesẹ ọhun lẹyin idarudapọ to waye laarin awọn obi to ni ọmọ nile ẹkọ girama ati ijọba ipinlẹ Ogun lọjọ Aiku.
Bakan naa ni ijọba pasẹ pe ki wọn pin aṣọ iboju ni ọfẹ fun gbogbo akẹkọọ to wa nipinlẹ naa, boya nile ẹkọ ijọba ni tabi ti aladani.
Awọn ọrọ yii lo foju han ninu atẹjade kan ti gomina ipinlẹ Ogun, Dapo Abiodun funra rẹ fọwọsi nirọlẹ ọjọ Aje.
Gomina Abiodun ni oun kabamọ lori gbogbo idarudapọ to waye lori iṣẹlẹ naa.
O ni ipese eto ẹkọ to ye kooro ati igbaye gbadun awọn akẹkọọ ipinlẹ naa lo jẹ ijọba oun l'ogun julọ.O tun han ninu atẹjade naa pe, ayẹwo awọn akẹkọọ lati mọ boya wọn ni arun Coronavirus kii ṣe dandan mọ fawọn akẹkọọjade to fẹ wọle pada sile ẹkọ.
Ni ọjọ Aiku lawọn obi ati alagbatọ ni ipinlẹ Ogun fọn si igboro ilu Abẹokuta lati fi ẹhonu wọn han lori ẹgbẹrun marundinlọgbọn naira ti ijọba ipinlẹ naa kede pe ki awọn akẹkọọ ileewe aladani o san fun ayẹwo kokoro arun COVID-19 ki wọn to lee wọle pada si ileewe.
Lati igba ti iroyin naa ti jade sita lo ti n ṣe ọpọlọpọ ni haa-hin nitori idẹyẹsi naa.
Bi ọpọlọpọ obi ṣe n pariwo pe bawo lọbọ ṣe ṣori ti inaki o ṣe to fi jẹ wi pe awọn akẹkọọ ileewe aladani ni yoo maa sanwo ayẹwo COVID-19 ki wọn to wọle pada sileewe.
Bi o tilẹ jẹ wi pe  ijọba ipinlẹ Ogun ninu atẹjade kan ti olubadamọran fun gomina ipinlẹ Ogun lori ọrọ Ẹkọ alakọbẹrẹ ati girama, arabinrin Ronkẹ Soyọmbọ ṣalaye pe o di dandan fun awọn akẹkọ lati pese iwe ẹri ayẹwo COVID-19 wọn ki wọn to gbawọn si ileewe paapaajulọ awọn to ba wa ni ileegbe lawọn ileewe naa.
Toríi Coro"", ẹ wo bí ètò ìsìn ìgbéyàwó orí ayélujára Zoom ṣe lọ"
Bakan naa ni  ijọba ipinlẹ Ogun ni gbogbo awọn ileewe aladani ni lati rii daju pe awọn akẹkọọ wọn ni iwe ẹri yii.
Amọṣa loju opo Twitter ajọ to n gbogun ti ajakalẹ arun lorilẹede Naijiria, NCDC to jẹ ajọ kan ṣoṣo to laṣẹ lori eto ayẹwo fun kokoro arun naa, ọfẹ ni wọn kọ pe wọn n ṣe ayẹwo fun kokoro arun naa lorilẹede Naijiria.
Ajọ naa ni ko si ibikibi ti wọn ti n fi owo ṣe ayẹwo COVID-19 fun ẹnikẹni lorilẹede Naijiria.
Eyi lo mu ki ọpọ maa beere ibi ti ijọba ipinlẹ Ogun ti wa ri ẹdinwo owo ayẹwo kokoro arun COVID-19 ti wọn ni awọn n ṣe ati pe ẹgbẹrun marundinlọgbọn naira ti wọn fẹ maa gba naa, owo ayẹwo ni ibudo wo ni?
Amọṣa, ijọba ipinlẹ Ogun ni awọn eleto ilera kan lawọn fẹ lo ati pe awọn ti ba awọn eleto ilera naa sọrọ lati pese ayẹwo ọhun fun wọn ni ẹdinwo.
Wayi o, awọn obi ti fariga pe awọn ko ni owo kankan lati san, bakan naa ni awọn ko tilẹ ni iwe ẹri kankan lati fi silẹ.
Ninu ọrọ ti wọn ba BBC News Yoruba sọ, awọn obi kan ni awọn ko ni ẹgbẹrun marundinlọgbọn naira lati san, ati pe awọn ko lee gba ki ọmọ awọn la wahala ti ayẹwo naa lee ko ba ironu awọn akẹkọọ.
Oríṣun àwòrán, theencounter.com.ng
Awọn obi awọn akẹkọ ileewe aladani ni ipinlẹ Ogun ti fariga lori owo ayẹwo fun arun COVID-19 ti ijọba ipinlẹ naa bu fun awọn akẹkọ kọọkan ni sisan ki wọn to lee wọle pada sẹnu ẹkọ wọn ni ọjọ Iṣẹgun ọjọ kẹrin oṣu kẹjọ.
Awọn obi awọn akẹkọọ ileewe aladani ọhun ke gbajare sita lasiko iwọde kan ti wọn ṣe ni ilu Abẹokuta lọjọ Aiku nibi ti wọn ti ni ẹgbẹrun marundinlọgbọn naira ti ijọba ni ki awọn akẹkọọ ileewe aladani o san fun ayẹwo kokoro arun COVID-19 ko rọrun rara.
Awọn obi naa ti wọn ya bo ileewosan MTR Specialist Hospital nibi ti wọn ti ni ayẹwo naa yoo ti maa waye ni awọn ko gbaradi fun irufẹ owo bẹẹ ni sisan ati pe bawo lọbọ ṣe ṣori ti inaki o ṣe to fi jẹ wi pe awọn akẹkọọ ileewe aladani nikan ni yoo maa san owo ayẹwo nigba ti awọn akẹkọọ ileewe ijọba ko ni san kọbọ fun ayẹwo kokoro arun naa.
Wọn tun fi kun un pe ko si idi to fi yẹ ki ijọba kan owo naa ni ipa fun awọn akẹkọọ niwọn igba to jẹ wi pe wọn ti ni ki ileewe kọọkan o maa pese awọn ilana ati ohun elo fun ayẹwo awọn akẹkọọ ṣaaju iwọle wọn.
Mummy calm down: Ìyá Ore sọ pé gbogbo ìgbà tí óun bá n bá a wí ló ma n ṣe àwàdà
Ninu ọrọ to ba awọn oniroyin sọ, igbakeji alaga ẹgbẹ awọn obi ati olukọ PTA ni ipinlẹ Ogun, Alagba Kẹhinde Sanwo ṣalaye fawọn oniroyin pe ko yẹ ki ijọba maa dẹyẹsi awọn akẹkọọ ileewe aladani ati si awọn akẹkọọ ileewe ijọba nitori pe ọmọ ipinlẹ Ogun naa ni gbogbo wọn.
Ninu ọrọ tirẹ, oludari eto ilera ni ipinlẹ Ogun, Dokita Olukayọde Soyinka ṣalaye pe ọrọ sisan ẹgbẹrun marundinlọgbọn owo ayẹwo kokoro COVID-19 ṣe ajeji si oun ati pe titi di asiko ti wọn n sọrọ naa, ọfẹ ni ayẹwo kokoro arun COVID-19 ni ipinlẹ Ogun .
Ati pe, aṣẹ ti oun gba lọwọ kọmiṣọna ni lati wa nibi ayẹwo naa fun idẹra awọn akẹkọọ to ba wa ṣe ayẹwo nibẹ.
Ibadan VC Appointment: Ẹgbẹ́ ọmọ Ibadan fẹ́ kí ààrẹ Buhari yan ọmọ wọ́n gẹ́gẹ́ bí ọgá fásitì Ibadan
Oríṣun àwòrán, UI
Agbarijọpọ awọn ọmọ bibi ilu Ibadan ti ke gbajare si aarẹ Muhammadu Buhari lati foju aanu wo awọn ko fi yan ọmọ bibi ilu Ibadan si ipo ọga agba fasiti ilu Ibadan.
Arọwa yi to wa lati ọdọ aarẹ ẹgbẹ naa ninu ifọrọwerọ pẹlu BBC ko ṣẹyin bi eto iyansipo ẹni ti yoo jẹ ọga fasiti naa lẹyin ti saa Ọjọgbọn Abel Olayinka to jẹ ọmọ ipinlẹ Osun ba pari.
Oloye Adeyemi Soladoye, aarẹ ẹgbẹ ni awọn ọmọ Ibadan ti ṣe suuru to lati igba ti wọn ti da fasiti naa silẹ ati pe aika nkan kun awọn ti to gẹ bayi.
''Awa ọmọ Ibadan kii ṣe oni wahala nii nitori rẹ lo fi dabi ẹni pe a ko tii sọrọ lati nkan bi ọdun mejilelaadọrin ti wọn ti da fasiti Ibadan silẹ pe ki wọn yan ọmọ Ibadan ni ọga fasiti naa.''
''Lọpọ igba ni awọn ọmọ wa ti yẹ ki wọn de ipo yi ṣugbọn niṣe ni wọn maa n doju ọrọ ru ti wọn yoo si yan ẹlomiran sipo.''
Soladoye fi kun un pe ''Nigba to ti wa di pe kii ṣe ẹni to ba gbe igbaoroke ni wọn yoo mu, a fẹ ki aarẹ o mu ọmọ wa ninu awọn ti orukọ wọn ba de ọdọ rẹ''
Oríṣun àwòrán, Premium Times
Aworan ọmọ ẹgbẹ Ibadan lasiko ti wọn n ba awọn akọroyin sọrọ
''Awọn ọmọ wa koju oṣunwọn, o si yẹ ki aarẹ wo nkan mii mọ Ibadan lara lati yan ọmọ wa si ipo ọga fasiti Ibadan.''
Bawo ni iyansipo ọga fasiti ti ṣe maa n waye?
Ọdọ Aarẹ orileede Naijiria ni aṣẹ wa lori ẹni ti wọn yoo yan ni ipo ọga fasiti lẹyin ti awọn igbimọ ayẹwo ti fasiti ba yan ti fi orukọ eeyan mẹta tabi mẹrin ṣọwọ si.
Ni ibamu pẹlu ofin to da awọn fasiti ijọba apapọ silẹ, ẹnikẹni to ba ti kaju oṣunwọn ni ijọba lẹtọ lati yan lai fi ti ibi to ti wa ṣe.
Lọpọ igba awọn fasiti Naijiria a ma ni fakinfa lori yiyan ọmọ ilu gẹgẹ bi ọga fasiti ijọba apapọ.
Bi awọn ara ilu ba ti ṣe n ni ki ijọba yan ọmọ wọn lawọn alakoso yoo ma sọ pe ilana ko yọ ẹnikẹni silẹ.
Yatọ si ipo ọga agba fasiti Ibadan, Oloye Adeyemi sọ pe o wu awọn bakan naa ki aarẹ yan ọmọ Ibadan si ipo ọga agba ile ikọṣẹ iṣegun fasiti Ibadan,UCH.
O lootọ awọn ko ni ikapa kankan lati mu aarẹ ni dandan ṣugbọn o ti wa fẹ di lemọlemọ pe wọn yoo fi ọmọ Ibadan to kaju oṣunwọn silẹ ti wọn yoo si yan ọmọ Ilu mi sipo ọga fasiti Ibadan.
Ibadan Sallah Killing: Ẹbí ọmọ tí wọ́n rí òkú rẹ̀ nínú odò ní Ibadan ní ikú rẹ̀ kìí ṣe ojú lásán
Ẹbí ọmọ ọdún méjì tí wọ́n rí òkú rẹ̀ nínú odò ní Ibadan sọ pé ikú rẹ̀ kìí ṣe ojú lásán
Ẹbi ọmọ ọdun meji to di awati ni ọjọ ọdun Ileya ku ọla, Sukurat Arowolo, ti wọn si pada ri oku rẹ ninu odo kan ni adugbo Olodo ni Ibadan ti kẹdun iku rẹ.
Ẹgbọn baba rẹ to ba BBC sọrọ, Arakunrin Sarafa Arowolo, sọ pe okuta kan ninu odo naa lo da oku ọmọ naa duro lati ibi ti omi ti n gbe bọ.
"Bakan naa ni alagbatọ rẹ, to tun jẹ iyawo ẹgbọn baba rẹ, Arabinrin Arowolo sọ pe, iku ọmọ naa dun oun pupọ, nitori pe ""inu kan ni oun fi gba a lati ma a tọju pẹlu awọn ọmọ oun."""
O ṣalaye pe eroja ọbẹ̀ ọdun ni oun lọ ọ ra, ti ọmọ si ti di awati ki oun o to o de, botilẹjẹ pe oun ati awọn ọmọ miran lo jọ n ṣere niwaju ile.
Ni nkan bi aago mẹjọ alẹ ọgbọnjọ, oṣu Keje, ọdun 2020 ni ọmọ naa di awati, ni ile wọn to wa ni adugbo Ahoyaya ni agbegbe Olodo niluu Ibadan.
Gbogbo awọn aladugbo ati alagbatọ lo fọn sita lati ṣe awari ọmọ naa titi di oru ọdun Ileya ti igbiyanju wọn si ja si pabo.
Ṣugbọn nigba ti yoo fi di owuro ọjọ ọdun ileya ni ariwo sọ lasiko ti ọmọde kan fẹ lọ ṣe igbọnsẹ nibi odo nla kan to n bẹ ni adugbo naa.
Nibẹ lo ti kan oku Sukurat to lefo sinu omi. Igbe ọmọde yii ni awọn ara adugbo gbọ ti wọn si fi mọ pe ọfọ ti ṣẹ.
Ikọ BBC Yoruba ṣe abẹwo si agbegbe naa l'ọjọ Iṣegun, ohun ti a fi oju ri si ba ni lọkan jẹ pupọ.
Ibadan Death: Àwọn ará àdúgbò Akinyele ké sita lórí iṣékúpani  tó ń wáyé ní ìlú Ibadan.
Ohun akọkọ ti a le fi idi ẹ mulẹ ni pe ọmọde naa ko gbe ọdọ awọn obi rẹ.
Ọdọ ẹgbọn baba rẹ lo n gbe ti onitọun si n tọju rẹ pẹluu awọn ọmọ tirẹ naa.
Ohun ti wọn tun sọ fun wa ni pe lati igba ti wọn ti bi ọmọ naa ni iya rẹ ti n ṣaisan, ilu Ondo, Ọrẹ si ni o n gbe. Eyii lo si mu ọmọ naa di ero ile ẹgbọn baba rẹ.
Iyale iya ọmọ naa ti o ba wa sọrọ, Arabinrin Arowolo ṣe alaye wi pe ọmọ naa ati awọn ọmọ oun ni wọn jọ n ṣere ni iwaju ṣọọbu wọn ni ọjọ ọdun ileya ku ọla ki o to di wi pe wọn ko dede rii mọ laarin awọn ọmọ to ku.
O tẹsiwaju wi pe ata ọdun ni ohun lọ ra lasiko ti ọmọ naa ati awọn ọmọ oun jọ n ṣere ni iwaju ita, bẹẹ sini oun sọ fun aburo ọkọ oun kan lati mojuto wọn.
"O ni, "" Ibi ti mo joko si naa niyẹn pe ọla ni ọjọ Aje, gbogbo nnkan le lọju pọ ni ibi alata. Mo wa lọ ba iya ti wọn n ta ata ni adugbo wa, mo ṣaa lọ ra ata ẹgbẹrun meji o le lẹẹdẹgbẹta naira""."
Ki n to wa lọ ra ata yẹn mo mu ọmọ yẹn da ni mo fun ẹni to jẹ aburo ọkọ mi pe ki wọn maa ba mi wo ọmọ yii, kii ṣe oun nikan lo wa nibẹ wọn pọ ati awọn ọmọ temi naa ti gbogbo wọn n jo. Ṣugbọn bi ọmọ yẹn ṣe sọnu o ye Ọlọrun ọba to jọ ṣẹda emi ati ẹ.
Ẹgbọn baba ọmọ naa to ba wa sọrọ, Arakunrin Sarafa Arowolo sọ fun wa pe aṣọ ọdun mẹta ọtọọtọ ni wọn ran fun ọmọ naa lọjọ ọdun ku ọla. Gbogbo rẹ lo si wọ wo.
O ni o jẹ nnkan ibanujẹ wi pe awọn olubi ẹda naa ko jẹ ki Sukura wọn aṣọ ọdun rẹ.
Arowolo fi kun ọrọ rẹ wi pe nigba ti ariwo sọ ni awọn to mọ pe ninu odo kan to n bẹ ni adugbo naa ni wọn sọ oku ọmọ naa si.
O ni awọn ba ẹjẹ lẹnu rẹ nibi ti o lefo si ninu omi.
Leyin ọrẹyin ni wọn sinku ọmọ naa si ẹba ọdọ ti wọn ti ri oku rẹ.
Nibayii ọwọ ileeṣẹ ọlọpaa ipinlẹ Ọyọ ti tẹ afurasi kan, bẹẹ sini iṣe iwadii ti n ọ lọwọ lorii ẹsun naa.
'A ò tíì rí omi mu, ẹ ní ká máa fọwọ́ tóríi Coronavirus'
Coronavirus Update: Omi mímu wọ́n ju owó ilé lọ nílùú yìí
Omi jẹ ọkan pataki lara ohun ti eeyan nilo bi yoo ba duro sile gẹgẹ bi ijọba ṣe n paṣẹ isede, ibomu, fifọwọ, diduro sile lasiko ajakal arun Coronavirus yii.
Bẹẹ si ni ọgọọrọ awọn araa apa Ila-Oorun Ariwa Afirika ti ko si larọwọto riri omi amọloolo lo n koju wahala bi arun naa ṣe n jẹ wọra sii bayii.
Ka to wi ka to fọ, ajọ eleto ilere lagbaaye, WHO yoo ti ni fifọ ọwọ loorekoore jẹ ohun akọkọ ninu gbigbena woju Covid-19.
Inú odò ni wọ́n ti rí òkú ọmọ ọdún méjì tó sọnù l'ọ́jọ́ ọdún Eid nílùú Ibadan
Itan Omi Erin
Itan omi gbigbona ati tutu ni Ikọgosi Ekiti
Ǹjẹ́ fífi omi àti iyọ̀ yọnu leè dènà àrùn Coronavirus?
‘Ìjọba, ẹ ràn wá lọ́wọ́! Kìlómítà márùn là ń rìn ká tó rí omi mu’
Ẹwẹ, ni Naijiria ajọ kan ti ko rọgbọku le ijọba ti n kilọ pe lai si omi to mọ gaara, orilẹede Naijiria ko lee borii Coronavirus.
Eyi lo mu ki awọn ara ilu lẹkun Guusu Iwọ-Oorun, Guusu Iwọ-Oorun ati Ariwa Naijira figbe sita lorii iya ti wọn n jẹ leyii ti ijọba si n kigbe ẹ ma fọwọ loorekoore.
Afẹ́fẹ́ Gáàsì tó rọra ń yọ́ọ́ jò pa Ajibola lẹ́nu iṣẹ́ jórin-jórin
'Irọ́ ni o, àò pinnu láti kógbá Shoprite wọlé ní Nàìjíríà'
Wo ìdí tí àwọn ọmọ ilẹ̀ Amẹ́ríkà kan ṣe ń kó bọ̀ wá fi ilẹ̀ Áfríkà sebùgbé
Coronavirus já wá sílẹ̀ ju ti àt'ẹ̀yìn wá lọ, kò  ju èèyàn 288 tó kó o lọ́jọ́ Ajé
"Toríi ""Coro"", ẹ wo bí ètò ìsìn ìgbéyàwó orí ayélujára Zoom ṣe lọ"
Lagos gas explosion: Afẹ́fẹ́ Gáàsì tó rọra ń yọ́ọ́ jò pa Ajibola lẹ́nu iṣẹ́ jórin-jórin
Oríṣun àwòrán, LASEMA
Ajọ to n ri si iṣẹlẹ pajawiri ni ipinlẹ Eko, LASEMA ti ri oku olukṣẹ kan latarii ibugbamu gaasi to ṣẹlẹ ni agbegbe ibudokọ Alafia ni Orile Iganmu, ipinlẹ Eko.
Ggẹ bi iroyin iwadii ti wọn ṣe ṣe sọ ọ ati ọrọ lẹnu awọn eeyan oṣojumikoro, ohun to fa sababii iṣẹlẹ aburu yii ni afẹfẹ gaasi to rọra n yọọ fiiin jo jade lataraagolo nla gaasi to si fa iku olukọṣ to n lo o lati fi jo irin mọ irin.
Oloogbe naa, Ajibola Olaoye padanu ẹmi rẹ nibẹ naa nigbati awọn mẹrin mii fara gba iṣẹlẹ ọhun ti wọn fara pa gidi amọ wọn ti sare gbe wọn lọ sileewosan kan to wa ni tosi.
'A ò tíì rí omi mu, ẹ ní ká máa fọwọ́ tóríi Coronavirus'
Ohun ti ajọ LASEMA gaan ba nigba ti wọn debẹ ni pe ibugbamu gaasi ọhun ti ṣẹlẹ eyi to n lo lati fi jo irin ninu ọkọ akẹru nla torii pe gaasi naa n yọọ jo jade.
Ẹwẹ, ki awọn ikọ aṣeranwọ gan to de ni iku Ajibola ti waye ati ti wọn si tun ti gbe awọn mẹrin to fara pa nibẹ lọ sile iwosan.
Ajọ LASEMA, awọn ọlọpaa, ileeṣẹ panapana Eko atawọn oṣiṣẹ alaabo mii lo tara ṣaṣa lọ sibi iṣẹlẹ ọhun ti wọn si gbakoso gbogbo adugbo naa ki iṣẹlẹ ọhun ma baa bimọ mii.
Nibayii, wọn ti gbe oku Ajibola fun ẹbi rẹ.
Ondo election 2020: Igbákejì gómìnà Ondo, Agboola Ajayi ní lóòtọ́ lòun fẹ́ f'ẹgbẹ́ PDP sílẹ̀ láti jẹ́'pè aráàlú ṣùgbọ́n...
Oríṣun àwòrán, others
Kii ṣe pe o ṣa dede wu igbakeji gomina ipinlẹ Ondo, awọn eeyan ni wọn n gun un ni kẹṣẹ pe ko fi ẹgbẹ oṣelu naa silẹ.
Igbakeji gomina ipinlẹ Ondo, Agboọla Ajayi ṣalaye pe awọn araalu ni ipinlẹ Ondo ni wọn fẹ ki oun wa oko miran ṣan ki ala rẹ lati di gomina ipinlẹ naa lee ṣẹ.
Ninu ifọrọwerọ pẹlu BBC News Yoruba, agbẹnusọ fun Agboọla Ajayi, ọgbẹni Ọkẹowo ni lẹyin ti esi ibo abẹle ẹgbẹ oṣelu ni ipinlẹ Ondo ti waye ti Jẹgẹdẹ si ti wọle lo ti gba fun Ọlọrun to si ti kii ku orire.
Amọṣa igbe 'awọn eeyan ẹkun gusu ipinlẹ Ondo atawọn majẹobajẹ kan ni ipinlẹ naa ni o mu ki O bẹrẹ ijiroro ati igbesẹ lati kuro ni ẹgbẹ oṣelu PDP'
Gẹgẹ bi o ṣe sọ, igbakeji gomina ipinlẹ Ondo naa ko tii kuro ni ẹgbẹ oṣelu PDP ṣugbọn yoo ṣi kuro titi opin ọsẹ yii.
Ni owurọ ọjọ Iṣẹgun ni iroyin gbode kan pe awọn iwe ipolongo ibo kan to jẹ ti Ọgbẹni Agboọla Ajayi labẹ aṣia ẹgbẹ oṣelu ZLP ti wa kaakiri igboro ilu Akurẹ tii ṣe olu ilu ipinlẹ Ondo.
Igun igbakeji gomina Ondo, Agboọla Ajayi ṣalaye pe eyi ko ṣokunkun si awọn nitoripe ọbẹ to dun ni Agboọla Ajayi gbogbo awọn ẹgbẹ oṣelu lo si fẹ bula nibẹ.
'A ò tíì rí omi mu, ẹ ní ká máa fọwọ́ tóríi Coronavirus'
Agbẹnusọ fun Oloye Agboọla Ajayi, ọgbẹni Ọkẹowo fi kun un pe kii ṣe ẹgbẹ oṣelu ZLP nikan lo ti ṣe iwe pelebe ipolongo idibo pẹlu aworan rẹ, o ni awọn ẹgbẹ oṣelu miran bii ADC, AA pẹlu fẹ gboriwọle.
Amọ o, o ni igbakeji gomina ipinlẹ Ondo ọhun ko ti fẹnuko lori ibi gan an to fẹ lọ nibẹ.
Nigba ti a o ba fi ri opin ọsẹ yii, Agboọla Ajayi yoo kede ibi to fẹ lọ, ṣugbọn o daju pe yoo fi ẹgbẹ oṣelu PDP silẹ
Lebanon Explosion: Ibùdó tí igba èèyàn ti kú lóṣù kẹjọ ní iná míràn ti jó
Isẹlẹ ina naa, ti wọn ko tii sọ ohun to fa a, lo waye lẹyin ina alagbara to sẹlẹ nibẹ lọjọ kẹrin osu Kẹjọ ọdun 2020.
Ikọ alagbelebu pupa tilu Beirut ni ko sẹni to fara pa tabi ku ninu ijamba ina naa amọ awọn eeyan kan, to sun mọ ina naa, ko le mi daadaa.
Ijamba ina ọhun lo tun waye ni ibudo yii kannaa, ti ẹmi to to mọkanlelaadọwa ti bọ losu to kọja nigba ti ibugbamu kan waye ni ibudokọ oju omi naa.
Oríṣun àwòrán, others
Awọn alaṣẹ ijọba Lebanon ti da ọmọ Naijiria marun un pada ki wọn ma lee ririnajo jade pẹlu ọkọ ofurufu ti ijọba Naijiria pese pe ko lọ gbe wọn ni ọjọ kejila, oṣu kẹj,ọ ọdun 2020.
Ọkan lara wọn, Nkiru Obasi to wa lati ipinlẹ Ebonyi nila oorun guusu lorilẹ-ede Naijiria to n ṣiṣẹ ọmọ ọdọ ni Lebanon.
Ibugbamu nla to waye ni Lebanon sọ mi soke janto, mo ri ọpọlọpọ oku nilẹ, ohun ti ọmọ Naijiria kan to moribọ sọ ree.
Ninu ọrọ to fi ranṣẹ si BBC, Nkiru to farapa ninu ibugbamu Beirut eyi to mu ẹmi awọn to le lọgọrun un  lọ sọ pe ṣe ni wọn ti oun atawọn mẹrin mii mọ inu yara kan ti wọn ko jẹ kawọn ba ọkọ baalu wa si Naijiria toripe wọn ni ọga Madaamu awọn wa fi ẹjọ awọn sun.
"Nkiru ni: ""Bi a ṣe de papakọ ofurufu lati lọ wọ baalu ti ijọba ṣeto ni wọn ni awọn ko ni faaye gba wa, awa marun, wọn ni Madaamu wa wa fi ẹjọ wa sun toripe a kuro nile."
"Ni wọn ba ni awọn ko ni gba wa laaye ti wọn si n ju ẹru wa nu."""
"O fi ohun aro ranṣẹ pe:  ""Bi ẹ ko ba gburoo mi mọ ki ẹ mọ pe wọn ti sọ mi sẹwọn, bi ẹ ko ba gburo mi mọ, ki ọ mọ pe wọn ti gba gbogbo nkan lọwọ mi ti wọn si ti ti mi pẹlu gbogbo bi mọ ṣe farapa mọ atimọle""."
Alaafin: Olori Aanu Adeyemi ṣàlàyé ìdí tó ṣe gẹ́ Oba Lamidi Adeyemi ti ìlú Oyo
Nkiru ni oun kuro nilee Madaamu toripe ko san owo oṣu oun latọjọ yii ni.
Ẹwẹ, aṣoju Naijiria ni Lebanon, Goni Modu sọ fun BBC pe awọn mọ nipa iṣẹlẹ naa awọn si n gbiyanju lati yanju ẹ.
Ambasadọ Goni to ni eyi kii ṣe igba akọkọ ti iru iṣẹlẹ ki Ọga Madaamu wọn wa maa fi ẹjọ sun.
Lebanon: Iṣẹ́ tí kòsí ní Naijiria, la ṣe lọ ṣe ọmọ ọ̀dọ̀ ní Lebanon
Iṣẹlẹ Ibugbamu Beirut yii waye lọjọ Iṣẹgun ọsẹ to kogba wọle lọ yii ti o si le leeyan igba to ku ati o le lọgọrun to sọnu to fi mọ ẹgbẹgbẹrun to di alairilegbe.
Awọn onimọ sọ pe ibugbamu yii yoo ṣi fun Lebanon, orilẹede to ṣi n tiraka pẹlu ọrọ aje mọ ẹgbẹ kan ti awọn ọmọ ọdọ yoo si ni lati fara mọ atunbọtan rẹ.
Asojú ìjọba orílẹ̀-èdè Lebanon ti kọ̀wé fipò silẹ̀ nítorí ìbágbàmù tó gbẹ̀mi ènìyàn 200
Asojú ìjọba orílẹ̀-èdè Lebanon ti kọ̀wé fipò silẹ̀ nítorí ìbágbàmù tó gbẹ̀mi ènìyàn 200
Awọn alaṣẹ ijọba orilẹede Lebanon ti kọwe fipo silẹ laarin ọpọlọpọ irunu ati ibinu awọn araalu nitori bugbamu nla to waye lọjọ iṣẹgun ọsẹ to kọja eyi to ba nkan jẹ kọja afẹnusọ ni ilẹ Beirut to si tun mu ẹmi eniyan to le nigba lọ.
Ikede pe wọn fiṣẹ silẹ yii jade lorii tẹlifisan apapọ orilẹede naa nirọlẹ ọjọ aje.
Ọpọlọpọ eniyan lo ti n da ẹbi iṣẹlẹ naa ru awọn adari orilẹede ọhun pe wọn ko kọbiara si ilu ati pe iwa ọbayejẹ wọ wọn lẹwu.Awọn afẹhonu han ti tu sigboro fun odidi ọjọ meji bayii lai simi nitori ibugbamu naa.Aarẹ Lebanon ti ṣaaju sọ pe ohun to fa sababi ibugbamu ọhun ni ibugbamu nkan oloro toonu ammonium nitrate to fẹrẹẹ to ẹgbẹrun mẹta (2,750) ti wọn ko pamọ lọna aitọ fun ọpọlọpọ ọdun.
Oríṣun àwòrán, BBC Sport
Ó lé ní ìgbà ènìyàn lo ti ṣe ódìgbà ó ṣe sí dúníyàn lẹ́yìn ìbúgbàmù Beruit.
Gómìnà Beruit lo fìdí ọ̀rọ̀ yìí múlẹ̀ pé ìbúgbàmù ọjọ́ Iṣẹ́gun tó kọjá ti pa ènìyàn igba.
Marwan Abboud sọ pé ọ̀pọ̀ ènìyàn ni wọ́n ko tilẹ̀ rí mọ́ títí di àsìkò yìí, ti ọ̀pọ̀ sì jẹ́ àwọn àjòjì tó wá ṣiṣẹ́ ni Lebanon.
Alẹ́ ọjọ́ Àìkú ní àwọn ọmọ Lebanon tún bẹ́rẹ̀ ìfẹ̀hhónú hàn míràn ní olúùlùú Beruit tí àwọn àti ọlọ́pàá sì ń kojú ara wọ́n.
Àwọn olùfẹ̀hónúhàn náà ń bínu sí ìhà ti àwọn ìjọba ń kọ sí ìṣẹ̀lẹ̀ to wáyé náà.
Síbẹ̀, bí mínísítà fún ètò ìdájọ tó jẹ́ mínísítà kẹ̀ta ṣe tún kọ̀wé fipò sílẹ̀, kò mú àdínkù bá ìbínú àwọn ará ìlú.
Ní báyìí, wọ́n tún ti kéde pé kí àwọn ènìyàn jáde láti ní ọ̀sán òní ọjọ́ Ajé lásìkò ti aṣojú ìjọba ilọ̀ Lebanon, Hassan Diab yóò máá pe ìpàdè ìgbìmọ̀ aláṣẹ ìjọba Lebanon.
Ọ̀gbẹ́ni Diab ti sàlàyé pé ìbígbàmù náà wáye nítori àwọn èròjà tó dín díẹ̀ ni ẹgbẹ̀rún méjì tóònù ti wọ́n kó pamọ si ibùdókọ̀ ojú omi fún ọdún  mẹ́fàá ló fàá.
Oríṣun àwòrán, Empics
Ìbúgbàmù Beruit wáye lásìkò ìgbéyàwó àwọn lọ́kọláya yìí.
Ìyàlẹ́nu ló jọ́ fún ọ̀pọ̀ ọmọ Lebanon pé ìjọba kó àwọn èròjà olóró sí ìgboro Beruit, bótilẹ̀ jẹ́ pé, o ti pẹ́ ti àwọn ọmọ orílẹ̀-èdè náà ti ń nànka àláebù sí àwọn olóṣèlú, fún ìwà àjẹbánu, àìbìkítà àti síṣẹ́ ǹkan ìlú báṣubàṣu tí wọ́n tí ń ṣe látẹ̀yìn wá.
Oríṣun àwòrán, Reuters
Beirut Port Explosion: Àwọn adarí lágbàyé ṣèpàdé láti ṣèrànwọ́ fún Lebanon lẹ́yìn ìbúgbàmù tó pa ènìyàn 158
Awọn adari lagbaye yoo ṣe ipade loni lati jiroro lori bi wọn yoo ṣe da owo jọ fun orilẹ-ede Lẹbanon ti ibugbamu ba ọpọlọpọ nkan jẹ nibẹ.
Ipade naa ti yoo waye ni aago mejila ọsan oni lori ẹrọ ayelujara ni Ajọ Iṣọkan Agbaye, (UN ) gbe kalẹ.
Aarẹ orilẹ-ede Faranse, Emmanuel Macron lo kọkọ ṣe ipolongo rẹ pe ipade yoo waye lati da owo iranwọ fun orilẹ-ede Lebanon.
Awọn asoju lati Ajọ Isọkan ilẹ Yuroopu EU, China, Russia, Egypt, Jordan ati Ilẹ Gẹẹsi, UK ni yoo darapọ mọ ipade naa.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Aarẹ orilẹ-ede America, Donald Trump ti ṣeleri lati darapọ mọ ipade naa.
Bakan naa ni Aarẹ Trump ni awọn ti ran awọn dokita lati ilẹ America pẹlu iranwọ ounjẹ, omi mimu ati oogun oyinbo lati ran orilẹ-ede Lebanon lọwọ lasiko yii.
Ijọba Lebanon fi lede pe iye nkan ti ibugbamu to waye ni ibi ile ti wọn ko ado oloro ammonium nitrate  naa bajẹ yoo lẹ ni iye owo biliọnu marundinlogun lọ.
Oríṣun àwòrán, Reuters
Eniyan 158 lo ku ninu iṣẹlẹ ibugbamu naa, ti èniyan 5,000 si farapa nigba ti èniyan 3000 ko ri ile gbe nitori  iṣẹlẹ ohun.
Ni Ọjọ Satide lorilẹ-ede Lẹbanon, ẹgbẹlẹgbẹ eniyan lo korajọ lati fẹhonuhan takọ aibikita ijọba si iṣẹlẹ to waye naa.
Oríṣun àwòrán, EPA
Awọn ọlọpaa da ifẹhọnuhan naa ru, ti wọn si fẹ afẹfẹ gaasi tajutaju si awọn eniyan to n fẹhọnuhan naa.
Oríṣun àwòrán, AFP
Ninu ọrọ tirẹ, Olotu Ijọba orilẹ-ede Lebanon, Hassan Diab ti ni oun yoo pe fun eto idibo ni kiakia, gẹgẹ bi ọna abayọ si rogbodiyan ti ibugbamu naa da silẹ.
Oríṣun àwòrán, AFP
Orilẹede Lebanon lo ṣi n koju ọrọ aje to dẹnukọlẹ ati arun Coronavirus to n ba wọn finra ki ibugbamu naa to waye.
Arabinrin Emmanuelle n gbaradi lati bi ọmọ tuntun ni ile iwosan St George's ni ilu Beirut nigba ti ibugbamu naa ṣẹlẹ.
O le ni ọgọrun eniyan to ku ninu iṣẹlẹ naa, ti eniyan to le ni ẹgbẹrun mẹrin si farapa.
Ọkọ arabinrin to n rọbi naa, Edmond sọ iriri rẹ fun Ileeṣẹ Iroyin BBC ati bi o ṣe ṣẹlẹ.
'Wọn n gbe iyawo mi lọ si yara irọbi lọwọ ni, ti awọn dokita ati nọọsi si n pese ibusun rẹ lọwọ ni awọn gbọ irọ igbugbamu to rin ilẹ.'
Ìdílé tí ọkọ da ọmọ síta tóríi ojú Búlùú tí wọ́n ní bá BBC sọ̀rọ̀
'Bi ibugbamu naa ṣe ṣẹlẹ, ti gbogbo gilaasi ferese ati ti orule si fọ, ni mo bẹrẹ si ni wa iyawo mi to n rọbi lọwọ.'
'Ẹru bami, nitori mo ro wi pe iyawo mi ti farapa tabi ọmọ jojolo naa.'
'Ohun gbogbo to wa ni bẹ lo danu ati ohun elo wọn, ko si si ohun kankan to ku mọ.'
'Ohun ti mo kọkọ ṣe ni lati gbe ibusun iyawo mi sita, ti mo si bẹrẹ si ni ran awọn dokita ati nọọsi lọwọ.'
'Iru ba iyawo mi to n rọbi lọwọ, bẹẹ si ni ko si oogun fun un.
'Ọna aye atijọ ni wọn gba lati gbẹbi iyawo mi nitori ko si ohun elo kankan lati lo.'
Ọḳ iyawo naa fikun pe lẹyin wakati kan abo ti ibugbamu naa waye ni iyawo rẹ, Emmanuelle bi ọmọ tuntun, George.
Bẹẹ si ni o dupẹ pẹ iya ati ọmọ tuntun naa wa ni alaafia, ti ara wọn si mokun.
Awọn alaṣẹ ibudo ikẹru si ti ibugbamu ti waye ni Beirut ti wa ni ahamọ.
Gẹgẹ bi ohun ti BBC ri ko jọ, wọn ni ki wọn maa wa ni ahamọ nile wọn titi di igba ti iwadii yoo fi bẹrẹ lori ohun to ṣokunfa ibugbamu ọjọ Iṣẹgun.
O kere tan eeyan marundinlogoje lo ti ku ninu iṣẹlẹ naa ti awọn to le ni ẹgbẹrun mẹrin si ti farapa.
Aarẹ Michel Aoun sọ pe, tọọnu nkan abugbamu ammonium nitrate to le l'ẹgbẹrun meji (2,750), ti wọn ko pamọ lọna ti ko tọ si ibudo ikẹru si, lati bi ọdun mẹfa, lo fa ibugbamu naa.
Ọga agba awọn oṣiṣẹ aṣọbode Badri Daher sọ pe awọn ti ke gbajare ki wọn wa gbe kẹmika to bu gbamu naa kuro laimọye igba ''ṣugbọn wọn ko wa''
O ni awọn  yoo ma reti ababọ awọn onimọ nipa ohun to ṣẹlẹ gaan.
Oríṣun àwòrán, EPA
Lasiko to n dari ipade pajawiri kan lorileede naa, aarẹ Aoun ni ''eeyan ko le ṣe apejuwe iru ajalu nla to rọlu ilu Beirut eyi to ti da ibẹrubojo silẹ nibẹ''
Awọn onimọ ni fasiti Sheffield nilẹ Gẹẹsi sọ pe bi eeyan ba foju sun, ibugbamu Beirut lagbara ni iwọn igba ida mẹwa ninu ọgọrun ibugbamu Atomic Bomb ti orileede Japan ju lu Hiroshima.
Oríṣun àwòrán, EPA
Inu ọfọ nla ni awọn eeyan orilẹ-ede Lebanon wa lẹyin ibugbamu nla to waye ni olu ilu orilẹ-ede naa, Beirut lọjọ Iṣẹgun.
Eeyan bi ọgọrun lo ku, awọn to le ni ẹgbẹrun mẹrin si fi ara pa.
N ṣe ni gbogbo ilu naa mi titi nitori ibugbamu ọhun, to bẹrẹ pẹlu ina ni ebute okun kan.
Oríṣun àwòrán, AFP
Ki i gan ni eroja ammonium nitrate to fa ilẹ ya bẹ ẹ?
Oriṣiriṣi iwulo ni ammonium nitrate ni, ṣugbọn meji to wọpọ julọ ni pe, wọn ma n lo o lati fi ṣe eroja Ajilẹ fun iṣẹ agbẹ, ati bii eroja abugbamu.
Oro inu rẹ l'agbara pupọ, to si ma n bugbamu to ba fi ara kan ina - to ba si ti bugbamu tan, ammonium nitrate ma n fọn afẹfẹ gaasi oloro  nitrogen oxides ati ammonia gas sita.
Oríṣun àwòrán, EPA
Awọn ọkọ to gbina lasiko ibugbamu to waye ni Beirut lọjọ kẹrin, oṣu Kẹjọ
Nitori eyi lo ṣe ni awọn ilana to yẹ ki ẹnikẹni to ba fẹ ẹ ko pamọ tẹle.
Lara awọn ilana naa ni pe, wọn gbọdọ fi eroja ti ko le jona kọ ibi ti wọn ba fẹ ẹ ko si, ko si gbọdọ si nkan to jọ gọta, ọpa to n gbe nkan, tabi awọn ọna miran ti o le ṣan si.
Iroyin sọ pe, ẹgbẹrun meji le díẹ̀ tọọnu ammonium nitrate to gbana yii jẹ ti ẹnikan, to fẹ ẹ ko ranṣẹ si ilẹ okeere lọdun 2014, ṣugbọn tí ijọba gbẹsẹ le e.
Wọn gbe ọrọ naa lọ sile ẹjọ, ẹjọ naa si wa ni kootu titi di asiko ti ibugbamu waye ni nnkan bi aago mẹta ọsan lọjọ Iṣẹgun.
Èèyàn 78 kú ó lé ní 4000 tó farapa níbi ìbúgbàmù tó wáyé ní Beirut, Lebanon
Eniyan to to mejidinlọgọrin ni ijọba Lebanon ti kede pe wọn padanu ẹmi wọn ti awọn to le ni ẹgbẹrun mẹrin si farapa ninu ibugbamu to waye ni Beirut lọjọ Iṣegun.
Orileede naa ti bẹrẹ si ni ṣe ọfọ iku awọn to lọ ti ọpọ eeyan jakejado agbaye naa si ti n bawọn ṣe idaro iṣẹlẹ laabi yi.
Ni aaye iko nkan pamọ si ni ibudoko ọkọ oju omi to wa ni Beirut ni ibugbamu yi ti ṣẹlẹ.
Aaarẹ Michel Aoun sọ pe nkan bi ẹgbẹrun mẹta tọọnu ammonium nitrate ti o ti wa ni ile iko nkan pamọ si yi fun bi odun mẹfa  lawọn funra si pe o ṣokunfa ibugbamu naa.
Bẹrẹ lati ọjọru aarẹ ni awọn yoo la ọjọ mẹta kalẹ lati se idaro lorileede naa.
Oríṣun àwòrán, EPA
Iṣẹlẹ yi n waye saaju abọ igbẹjọ ẹsun pipa Olootu ijọba tẹlẹ, Rafik Hariri lọdun 2005.
Fidio kan to n ja ranin-ranin lori ayelujara ṣe afihan ofurufu to su jọ ati bi ibugbamu ọhun ṣe ba nnkan jẹ si.
Bayii ni nkan ṣe ri lẹyin ibugbamu to waye ni Beirut
Igbimọ olugbejọ kan labẹ ajọ isọkan agbaye ni yoo gbe idajọ kalẹ laipẹ ninu igbẹjọ afurasi mẹrin ti wọn lo lọwọ ninu iwa isekupani lati ipasẹ Ado oloro naa.
'Mo fẹ́ gbé ògo ìdílé ìyá àti bàbá mi ga pẹ̀lú iṣẹ́ Mọkálìíkì'
Kehinde lady mechanic: Láti kékeré níṣẹ́ẹ mọkálíìkì ti wù mí, mo bá ń tẹ̀lé bàbá mi
Iru itan bayii kii ṣe olojoojumọ tẹẹ le ri fidio tabi iroyin nipa rẹ nibi gbogbo ṣugbọn eyi to fọwọ tọ ni lọkan gidi gan ni.
Ibeere to ṣee ṣe ko wa sọkan awọn mii ni wi pe ṣé obìnrin rèé àbí ọkùnrin tó kárà mọ́ṣẹ́ mọkaliiki báyìí?
Ọmọ ọdun mejidinlogun ni Kehinde Popoola to tun jẹ ọmọ ileewe girama ṣugbọn kii ṣe ọmọbinrin bii gbogbo ọmọbinrin ti ẹ mọ.
Iṣẹ mọkaliiki ni Kehinde yan laayo lati kekere ọjọ aye rẹ. Ifẹ to ni si ka maa tu irin kan si omiran, ka maa lo irinṣẹ lo mu kọ lọ bẹrẹ si ni kọṣẹ ni ṣọọbu mọkaliiki kan.
'Ọkọ mi mú ọ̀bẹ jáde lápò, ó sì gé imú mi jábọ́...'
Èèyàn 78 kú ó lé ní 4000 tó farapa níbi ìbúgbàmù tó wáyé ní Beirut
Mo kábàámọ̀ ìbáṣepọ̀ èmi àti Eric nínú ilé Big Brother - Lilo
Ọkọ kọ àwọn ọmọ méjì lé ìyàwó lọ́wọ́ nítorí ìrísí ojú wọn ní Ilorin
Ibeji ni Kehinde, Taye rẹ wa laaye ṣugbọn ibi ori da oun si naa lo i tete n tọpasẹ rẹ bayii.
Lai tii pari ẹkọ rẹ nileewe girama, o ti ni afojusun fun ọjọ iwaju to logo nipa kika imọ ẹkọ Mechanical Engineering nileewe giga fasiti ko baa le di ọga funrarẹ nileeṣẹ imọ ẹrọ tirẹ.
Ọga ẹ to n kọṣẹ lọdọ rẹ gan fọwọ sọya pe o lee dele de oun daadaa fun iṣẹ bi oun ko ba si nile.
Kehinde jẹ ọmọ ilu Omu-Aran ni ipinlẹ Kwara to si wa ni ipele kaarun nileewe girama.
BBC Yoruba ba Kehinde Popoola pade lẹnu iṣẹ rẹ lasiko to n tun ọkọ ṣe lọwọ.
"Bí ìjọba ṣe ń pariwo ""ẹ máa fọwọ́ yín tó"", ẹ wo irú omi tí àwọn ará ìlú yìí fi ń fọwọ́"
WASSCE time table 2020: Àwọn akẹ́kọ̀ọ́ da ìdánwò WAEC rú ni Ghana, wọn gún infijilátọ̀
Oríṣun àwòrán, Other
Ajọ to n ri si idanwo aṣekagba ileewe girama lẹkun Iwọ Oorun Afirika, WAEC, lorilẹ-ede Ghana ti bẹrẹ iwadii lori ohun to mu ki awọn akẹkọọ Bright Senior High, SHS, kọlu awọn to wa ṣakoso idanwo naa nile iwe wọn.
O le ni ẹẹdẹgbẹta awọn ọmọ ile iwe to kọ lati kọ idanwo naa, ṣugbọn ti wọn kọju ija si awọn infijilatọ ti ko jẹ ki wọn gbe iwe wọle si gbọgan idanwo.
Ọkan lara awọn oluṣakoso idanwo ọhun to ba BBC sọrọ, Jerry Alfred sọ pe awọn ọmọ ile iwe naa ṣe mẹrin leṣe ninu awọn mẹfa to lọ ṣakoso idanwo ọhun nile iwe naa.
"Jerry ṣlaaye pe: ""Ọkan lara awọn infijilatọ naa ka ọkan lara awọn akẹkọọ ọhun to gbiyanju lati gbe iwe wọle, o si fi ẹrọ ibanisọrọ rẹ ka a silẹ, ni wahala ba bẹrẹ."""
Alfred ṣalaye pe awọn akẹkọọ ọhun gun lara awọn infijilatọ naa ni 'compass' lẹyin ọrun.
Oríṣun àwòrán, WAEC
Nigba ti ìkọlu naa n waye, awọn akẹkọọ tun fọ ẹrọ ibanisọrọ awọn alakoso naa mọlẹ nitori fidio bi wọn ṣe n gbe iwe wọle to wa lori rẹ.
Alfred fi ẹsun kan adari ile iwe Bright SHS pe o ṣegbe lẹyin awọn ọmọ ile iwe naa lati ṣakọlu si awọn oṣiṣẹ WAEC to wa mojuto idanwo nibẹ.
O ni oun kabamọ pe oun jẹ ọmọ orilẹ-ede Ghana, nitori ni ṣe ni oun n ṣe ojuṣe oun lati rii pe ọjọ ọla awọn akẹkọọ naa dara, ṣugbọn ẹmi oun ti wa ninu ewu.
Ẹwẹ, ajọ WAEC ti sọ pe oun ti bẹrẹ iwadii lati mọ idi ti awọn ọmọ ile iwe naa ṣe ṣakọlu si awọn eeyan ọhun.
Bẹẹ naa lo ni oun yoo gbe igbeṣẹ ti ri pe iru nnka nbẹẹ ko waye mọ.
Ohun tẹ́ẹ gbúdọ mọ nípa kókó orí ọyàn yín lásìkò fífọ́mọlọ́yàn
Ajọ to n ri si idanwo aṣekagba ileewe girama lẹkun Iwọ Oorun Afirika ti gbe atẹ alakalẹ bi idanwo WAEC yoo ṣe lọ fun ọdun 2020 jade.
Ijọba apapọ Naijiria ti ṣaaju kede pe ki awọn akẹkọ to wa ni ipele ikẹkọgboye nileewe girama wọle pada sẹnu ẹkọ wọn lọjọ kẹrin oṣu kẹjọ.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Bakan naa, wọn kede pe idanwo WASSCE yoo bẹrẹ lọjọ kẹtadinlogun oṣu kẹjọ titi di ọjọ kejila oṣu kẹsan ọdun 2020.
Gẹgẹ bi at alakalẹ naa ṣe ri eyi ti ileeṣẹ BBC Yoruba ri, bayii ni gbogbo eto idanwo naa yoo ṣe lọ:
Oríṣun àwòrán, Waec
Oríṣun àwòrán, Waec
Oríṣun àwòrán, Waec
Oríṣun àwòrán, Waec
Oríṣun àwòrán, Waec
Oríṣun àwòrán, Waec
Ajọ WAEC wa gba awọn aṣedanwo nimọran pe ki wọn tẹle ofin ati alakalẹ fun idanwo naa nipa yiyọwọ kuro lawo magomago lasiko idanwo ati pe ki wọn tẹle gbogbo ofin to rọ mọ Covid-19 eyi ti awn ibudo idanwo wọn ti fi silẹ.
Amotekun: Ẹgbẹ́ fijilanté pariwo síta lórí ìlànà ìgbanisíṣẹ́ ikọ̀ Amotekun ní ìpínlẹ̀ Oyo
Oríṣun àwòrán, Western Nigeria security network
Adari ẹka abo oju lalakan fi n ṣọri ni Naijiria, Vigilante Group of Nigeria, VGN, ẹka ti ipinlẹ Ọyọ, Ọgbẹni Ọladeji Olowolafẹ ti ke gbajare sita lori eto abo ẹkun iwọ orun gusu orilẹede Naijiria ti a mọ si Amọtẹkun.
Ọgbẹni Olowolafẹ ṣalaye pe ọrọ Amọtẹkun ni ipinlẹ Ọyọ ti dọwọ ru koda o ti d'ẹsẹ ru bi ẹsẹ telọ.
O ni afaimọ ki iṣẹ ikọ Amọtẹkun ni ipinlẹ Ọyọ maa ja ireti ọpọlọpọ to n foju sọna fun un kulẹ.
O ni ọna ti awọn alaṣẹ ikọ naa ni ipinlẹ Ọyọ fi n gba awọn eeyan si ikọ naa ko bojumu.
O ni oun ti o yani lẹnu ni bi awọn alaṣẹ ikọ naa ni ipinlẹ Ọyọ ṣe n ni ki awọn to fẹ dara pọ mọ ikọ naa o lọ maa forukọ silẹ ni ori ayelujara.
Gẹgẹ bi ọrọ rẹ, ohun kan to le mu ki ajọ naa o kẹsẹ jari lori eto igbaniwọle fawọn to ba fẹ ba a ṣiṣẹ ni lati ko awọn olori ikọ alaabo oju lalakan fi n ṣọri atawọn alaabo ibilẹ gbogbo lẹsẹ kuku mọra.
O ni kiko awọn fijilante, ọdẹ ibilẹ atawọn ọmọ ẹgbẹ OPC mọra fun ikọ naa yoo mu ko so eso rere daadaa.
'Mo fẹ́ gbé ògo ìdílé ìyá àti bàbá mi ga pẹ̀lú iṣẹ́ Mọkálìíkì'
Gẹgẹ bi o ṣe sọ, 'gbogbo awọn to lee ṣe iṣẹ ti a la kalẹ fun ikọ Amọtẹkun kii ṣe awọn to lee ṣe ohunkohun lori ayelujara.'
O ni yiyọ ọwọ awọn ọmọ ẹgbẹ OPC, Agbẹkọya, ọdẹ ibilẹ ati fijilante kuro ninu awo ikọ Amọtẹkun ni ipinlẹ Ọyọ yoo lẹyin.
Oríṣun àwòrán, Western Nigeria security network
Ni ọsẹ diẹ sẹyin ti Oludari fun ikọ Amotekun nipinlẹ Oyo, Ajagunfẹyinti Olayinka Olayanju ba BBC sọrọ lori igbesẹ yii, o ni o di dandan kawọn eeyan to ba fẹ dara pọ mọ ikọ Amotekun fi orukọ silẹ lori ayelujara.
Olayanju ni ko si idi fun awọn ọdẹ ibilẹ to fẹ kopa ninu ikọ Amotekun lati tako igbesẹ fifi orukọ silẹ lori ayelujara.
Mummy calm down: Ìyá Ore sọ pé gbogbo ìgbà tí óun bá n bá a wí ló ma n ṣe àwàdà
Ajagunfẹyinti Olayinka Olayanju ni ko si ohun to nira ninu fifi orukọ silẹ lori ayelujara nitori ko si ibudo itakun agbaye ti wọn ba lọ lati fi orúkọ silẹ, ti wọn ko ni seranwọ lati ba wọn ṣe e.
Fọọmu Amotekun naa ko le rara lati ṣe. Ohun ti wọn n beere ni orukọ wọn, adugbo, ẹkun idibo wọn, iriri nipa sise aabo ilu, ẹgbẹ ọlọdẹ ti wọn wa ati Baalẹ wọn.
Bakan naa ni oludari ikọ Amotekun nipinlẹ Oyo fikun pe awọn to ba fi orukọ silẹ yoo mu fọọmu naa tọ Baalẹ ati asofin to wa lati ẹkun idibo wọn lọ, ti awọn mejeeji yoo si buwọlu u.
Olamide Wonma nurse video: Nọ́ọ̀sì kan ní lóòótọ́ làwọn aláìsàn ń dẹnu ìfẹ́ kọ àwọn
Oríṣun àwòrán, Olamide/Akintayo Blessing
Olutọju alaisan kan to n ṣiṣẹ loke okun ti foju laifi wo oju aṣẹwo ti ọpọ eeyan fi n wo awọn nọọsi.
Akintayo Blessing Christiana safihan ero rẹ naa lasiko to n ba BBC Yoruba sọrọ lori fidio Wonma ti Olamide Baddo ṣẹṣẹ ṣe sita.
Ìdílé tí ọkọ da ọmọ síta tóríi ojú Búlùú tí wọ́n ní bá BBC sọ̀rọ̀
Ninu fidio naa si ni o ti ṣe afihan awọn olutọju alaisan bii oninabi, to n ni ibalopọ lẹnu iṣẹ pẹlu awọn alaisan ti wọn n tọju.
Ninu ọrọ rẹ, Akintayo salaye pe lootọ ni awọn kanda kan wa laarin awọn nọọsi sugbọn eyi ko ni ki wọn tabuku gbogbo olutọju alaissn bii aṣẹwo.
Ibi gbogbo ni awọn kanda inu irẹsi wa, kii ṣe ọdọ  awọn nọọsi nikan ni, koda ko si iṣẹ oojọ ti ko ni iriri bayii.
Ohun tẹ́ẹ gbúdọ mọ nípa kókó orí ọyàn yín lásìkò fífọ́mọlọ́yàn
Ṣugbọn eyi ko tumọ si pe gbogbo awa nọọsi ta n ṣíṣẹ kara lo yẹ ki wọn maa tabuku, bi wọn ba ṣe n bu awọn ti ko ṣe daadaa, lo yẹ ki wọn gboriyin fun awa ta n ṣe daadaa lẹ́nu iṣẹ.
Bakan naa ni oṣiṣẹ nọọsi naa fidi rẹ mulẹ pe lootọ làwọn alaisan maa n nawọ ifẹ sáwọn Nọọsi sugbọn eyi ko sọ gbogbo Nọọsi di aṣẹwo.
Nigba to n salaye iyatọ to wa laarin ṣíṣe isẹ Nọọsi ni Naijiria ati loke okun, Akintayo ni iyatọ nla lo wa laarin awọn oṣiṣẹ mejeeji.
Ilana ta n gba ṣíṣẹ yatọ pupọ, to fi mọ owo osu ati ajẹmonu wa, bakan naa ni ipese irinsẹ fun iṣẹ wa ni Naijiria yatọ si ti oke okun, ti itọju nla si wa fun Nọọsi loke okun.
Akintayo wa gba awọn eeyan nimọran lati dẹkun bíbu ẹnu atẹ lu gbogbo Nọọsi, tori awọn n ṣiṣẹ kara lati doola ẹmi awọn alaisan ni.
Kìí ṣe ọmọbìnrin nìkan ni Ọlọ́run pàṣẹ fún láti pa ìbálé mọ́
Oríṣun àwòrán, @Olamide/Instagram/others
Ẹgbẹ awọn nọọsi l'orilẹ-ede Naijiria ti koro oju si fidio orin ti gbajugbaja olorin takasufe, Olamide Adedeji,  ti awọn eeyan tun mọ si Baddo, gbe sita ninu eyi to ti fihan pe awọn oṣiṣẹ olutọju alaisan maa n ṣere ifẹ pẹlu awọn alaisan ti wọn n tọju.
O pe akọle orin naa ni Wonma.
Ninu fidio orin ọhun to fi bintin ninu rẹ sori ayelujara lọjọ Iṣẹgun, a ri awọn obinrin to wọ aṣọ nọọsi, wọn n jo ninu yara itọju awọn alaisan, ti awọn kan si n fi ọwọ pa awọn alaisan to jẹ ọkunrin lara lọna ati ni ibalopọ pẹlu wọn.
Ọpọlọpọ eniyan ati awọn nọọsi lo bu ẹnu atẹ lu igbesẹ ti Olamide gbe lori ayelujara, ni kete to jade sita, pẹlu #NursesAreNotSexualObjects.
Ṣugbọn awọn kan faramọ fidio orin naa, ti wọn si n kan saara si Olamide.
Ninu ọrọ to ba BBC Yoruba sọ, Aarẹ ẹgbẹ nọọsi, Abdrafiu Adeniji sọ pe isẹ Oluwa ni isẹ awọn olutọju alaisan ati igbẹbi.
Olamide ba wa l'orukọ jẹ ni, o si ta epo si aṣọ ala iṣẹ wa.
O tẹsiwaju ninu ọrọ rẹ pe iru awọn iwa bẹ ẹ jẹ ọkan lara awọn nkan ti ofin iṣẹ nọọsi ko faaye gba.
Mo máa n forin mi kìlọ̀ ìwà ìbàjẹ́ láwùjọ ni -Hameen
Ijiya si wa fun olutọju alaisan kankan to ba lo ipo rẹ gẹgẹ bi olutọju lati gbiyanju tabi ni ibalopọ pẹlu alaisan to n tọju.
Nibi ti nkan de duro bayii, sọ pe awọn agbaagba ẹgbẹ awọn nọọi ti n ṣé ipade lori orin ti Olamide kọ, lati mọ igbesẹ to yẹ lati gbe.
O fi kun pe Olamide yoo f'oju ba ile ẹjọ lori orin naa.
Igba akọkọ kọ niyii ti ẹnu ti kun Olamide Baddo lori awọn orin rẹ.
Lasiko to gbe awọn orin Pata ni Logo Benz jade, ọpọ eeeyan lo bu ẹnu atẹ lu u pe orin rẹ lo fa bi awọn kan ṣe bẹrẹ si ni ji pata obinrin lati fi ṣe aajo owo.
Ẹbí ọmọ ọdún méjì tí wọ́n rí òkú rẹ̀ nínú odò ní Ibadan sọ pé ikú rẹ̀ kìí ṣe ojú lásán
Ẹbi ọmọ ọdun meji to di awati ni ọjọ ọdun Ileya ku ọla, ti wọn si pada ri oku rẹ ninu odo kan ni adugbo Olodo ni Ibadan ti kẹdun iku rẹ.
Ẹgbọn baba rẹ to ba BBC sọrọ, Arakunrin Sarafa Arowolo, sọ pe okuta kan ninu odo naa lo da oku ọmọ naa duro lati ibi ti omi ti n gbe bọ.
Bakan naa ni alagbatọ rẹ, to tun jẹ iyawo ẹgbọn baba rẹ, Arabinrin Arowolo sọ fun BBC pe lati igba ti iya ọmọ naa ti bi i, ni aisan ti n ṣe e, to si jẹ pe ilu abinibi rẹ ni Ondo lo wa to ti n gba itọju.
"Arabinrin Arowolo  sọ pe, iku ọmọ naa dun oun pupọ, nitori pe ""inu kan ni oun fi gba a lati ma a tọju pẹlu awọn ọmọ oun."""
O ṣalaye pe eroja ọbẹ̀ ọdun ni oun lọ ọ ra, ti ọmọ si ti di awati ki oun o to o de, botilẹjẹ pe oun ati awọn ọmọ miran lo jọ n ṣere niwaju ile.
Shina Rambo: Ọmọ Sọ́jà tó di adigunjalè tíí fi ahọn eeyan 100 mu ẹ̀kọ tó wá di Mathew Oluwafemi tó ń gbé Bíbélì
Oríṣun àwòrán, OTHERS
Ìtàn ayé Shina Rambo, adigunjale tó fi oyún 27 gún ọṣẹ
Yoruba ni bi ọmọ ko ba jọ sokoto, yoo jọ kijipa, ẹni to ba bi ni laa jọ.
Bẹẹ ni ọrọ ri pẹlu itan igbe aye arakunrin kan, Matthew Oluwafemi, ti ọpọ eeyan mọ si Shina Rambo.
Shina jẹ ẹda to ga, o to iwọn ẹsẹ bata mẹfa ati aabọ, to si tun ni omi lara, o si dudu lawọ.
Ogboju adigunjale laarin ọdun 1990 si 2000 nii ṣe, ki ọwọ agbofinro to ba a, o lọ ṣe ẹwọn, nibẹ lo si ti ba Ọlọrun pade, o di ajihinrere fun Oluwa.
Bi irinajo aye Apamọlẹkun jaye ẹda naa si ṣe lọ ree, gẹgẹ bi oju opo Wikipedia atawọn oju opo miran lori itakun agbaye ti ṣe akọsilẹ rẹ.
Risikat Moromoke Azeez: Inú èmí àti Òbí mi dùn nígbà ti Risi bí ọmọ olójú búlù- Wasiu
Ọdun 1958 ni wọn bi Shina sile aye, ọmọ bibi ilu Abeokuta nipinlẹ Ogun ni baba rẹ nigba ti iya rẹ jẹ ọmọ ilu Sabongida-Ora nipinlẹ Edo.
Baba rẹ jẹ oṣiṣẹ ologun taa mọ si Sọja, to si ni iyawo to le ni mejidinlogun nitori ọpọ ibi ti iṣẹ gbe lọ, lo ti n fun obinrin loyun.
Gẹgẹ bi Shina Rambo ti salaye, baba oun maa n lo aṣọ ati irinsẹ ologun lati ja awọn eeyan lole, to si maa n ko owo pupọ wa sile.
Lati ọmọ kekere si ni Shina ti n laju ri owo tuulu bayii lọwọ baba rẹ, eyi to maa n wọ ọ loju.
Ni ọjọ kan, nigba ti Shina wa ni ọmọ ọdun meje, baba rẹ gbe apo nla kan to kun fun owo pupọ wa sile.
Awọn owo yii jẹ owo beba ilẹ okeere, ti ẹjẹ si kun ara owo naa, wọn n lo gele obìnrin kan lati nu ẹjẹ kuro lara owo naa.
"Shina ni asiko yii ni oun wa bi baba oun pe ""Ṣe ẹjẹ eeyan niyi ni abi ẹjẹ ẹranko?""."
Ohun tẹ́ẹ gbúdọ mọ nípa kókó orí ọyàn yín lásìkò fífọ́mọlọ́yàn
Ṣugbọn o ni baba oun ko dahun, gbogbo wọn kan n mu ọti ati siga lọ ni, wọn ti wọn si n ṣe faaji pẹrẹu.
Bakan naa, adigunjale yii ni ọpọ igba ni baba oun yoo tu ìbọn Sọja rẹ kalẹ loju oun, ti yoo si tun to o pada, bẹẹ ni oun n fi oju si oun to n ṣe.
Amọ ni ọjọ kan, Shina ni oun wọ yara baba oun lasiko to lọ ṣe igbọnsẹ, oun ri ìbọn rẹ to tu kalẹ, ti oun si joko lati to ìbọn naa pada, eyi ti oun ṣe lai si wahala kankan.
Mr Macaroni sọ nípa eré tí Fraky freaky, Sugar Daddy, You are doing well, freaky spicy fẹ́
Baba rẹ wọle ba nibẹ pẹlu ìbọn to ṣẹṣẹ to tan, o ni inu baba oun bajẹ, to si fẹ pa oun, o yin ìbọn mọ oun nitootọ amọ ori ko oun yọ, ti oun si sa jade.
"Shina ni ""Baba mi duro de mi ni alẹ, o yọ kẹlẹ wọ yara mi, to si fẹ fi ada ge mi lori, mo tiraka lati sa mọ lọwọ sugbọn ada naa ba mi ni ẹsẹ osi, ti apa rẹ si wa lara mi di oni olonii."""
Shina fikun pe ọjọ yii gan ni oun gba pe oun ti gba iyọnda lẹnu isẹ, ohun to ku ni ki oun gbe ìbọn, bi oun si ṣe bẹrẹ iṣẹ adigunjale ree.
Oríṣun àwòrán, OTHERS
Shina Rambo gba pe idi isẹ ẹni laa ti mọ ni ni ọlẹ, to si tiraka lati lu aluyọ nidii isẹ adigunjale.
Niwọn igba to jẹ pe ẹni ti yoo ba jẹun gbọin-gbọin, gbọdọ ti ilẹkun gbọin-gbọin, Shina wa agbara kun agbara, o n ṣe oogun abẹnu gọngọ, ko si si ibi ti ko ṣe oogun de.
Wọn ni ẹni ti yoo ba ba esu jẹun, sibi rẹ yoo gun, Shina ro ara rẹ lagbara ninu oogun debi pe o fi ọmọ odo gun ọlẹ̀ inu alaboyun mẹtadinlọgbọn lati fi ṣe oogun ìṣọ́ra.
Bakan naa, Shina tun ge ahọn ọgọrun eeyan, ó ṣe e jẹ, to si tun gbe ninu igi iroko fun ọpọlọpọ ọjọ, bakan naa lo n sun ni itẹ oku lati sọ ara rẹ di ọkùnrin.
Mummy calm down: Ìyá Ore sọ pé gbogbo ìgbà tí óun bá n bá a wí ló ma n ṣe àwàdà
Ko tan sibẹ o, Shina tun wa agbara lọ silu Ogoja nipinlẹ Cross Rivers, to si setan lati di ilumọọka ogbontagi adigunjale to n dẹru ba araye.
Itẹ oku si ni wọn ti fun ni obìnrin kan bíi aya to maa n tẹle lọ digunjale ti gbogbo aye mọ si Alhaja, awọn eeyan ro pe eeyan ni amọ alujannu ni.
Alhaja maa n bo ori ni, kii si oju silẹ kí asiri rẹ ma ba a tete tu pe abara meji ni, ko si si ẹni to maa n ri oju rẹ rara.
Shina Rambo ni Alhaja yii ni awakọ oun, to si le sare asapajude pẹlu mọto laisi ewu, laarin iṣẹju diẹ, yoo si wa ọkọ lati Naijiria de Cotonou.
Oronpoto Animation: Akin Alabi ní kò dára bí eré aláwòrán fáwọn ọmọdé ṣe jẹ́ aláwọ̀ funfun
"Shina, lasiko to n sọ irinajo rẹ fawọn akọroyin lẹyin ti ọwọ ba a tan, salaye pe ""ọpọ etutu ni mo ti ṣe, ti n ko si le e ka tán."""
Mo di alagbara pupọ, mo lọ sinu igi iroko, to fẹ to odidi ilu kan, ọpọ ile to rẹwa lo wa nibẹ ninu igi Iroko, koda, mo nile temi nibẹ nibi ti ọpọ oloselu atawọn ọlọrọ maa n wa.
Shina Rambo fikùn pe, oun le e gbe orisirisi àwọ̀ eeyan wọ nigba kuugba to ba wu oun, eyi to mu ko nira fawọn ọlọpaa ri oun mu.
"Shina ni: "" Wọn n pa awọn eeyan miran ti ko mọwọ-mẹsẹ ninu iwa idigunjale, wọn ro pe Shina Rambo ni awọn n pa, koda, babalawo mẹsan to ṣe oogun naa fun mi, ọwọ ara mi ni mo fi pa wọn, ki wọn ma baa tu asiri mi."""
Shina ni oun ge ori ọgọrun eeyan, ti oun gbe fun awọn Babalawo naa, wọn si ṣe oogun afẹẹri fun oun, ko si si iru ọta ibọn ti wọn yin mọ oun, bii igba ti wọn sọ ọra omi lu oun ni, ko si si oun ti oun ko le ṣe lati wa agbara.
Bakan naa ni Shina Rambo ni eyi to ba oun ninu jẹ julọ ni pe oun ba iya oun lopọ ri, igbakuugba ti oun ba si foju kan iya arugbo naa, ni ibanujẹ maa n gba ọkan oun.
Oríṣun àwòrán, OTHERS
Lẹyin to gba ọpọ agbara yii, Shina Rambo di ẹru jẹjẹ, ogbontagi adigunjale ati apamọlẹkun jaye, to n ja ilu lole laisi ẹni to to wo o loju.
Lọpọ igba gan lo ti wọ agọ ọlọpaa lọ, ti yoo si pa gbogbo awọn ọlọpaa to ba wa nibẹ lọsan gangan, to si buru ju alujannu oloju kan lọ.
Bo ṣe n na orilẹede Naijiria, lo n pada si ilu Cotonou ni Republic of Benin, ti yoo si fi tipa gba ọkọ ayọ́kẹ́lẹ́ bíi ogoji ni ọjọ kan ṣoṣo, bẹẹ lo di olowo ati ọlọrọ rẹpẹtẹ.
Cancer: Àṣe ara mi ni iso ti n run gbogbo bí mo ṣe n ṣèrànwọ́ lórí jẹjẹrẹ
Shina Rambo ni iyawo ati ọmọ mẹta sugbọn gbogbo rẹ lo padanu ni ọjọ kan naa lasiko tàwọn ọlọpaa bẹ ile rẹ wo nigba to ti jade lọ ṣíṣẹ idigunjale, ṣe atakoro wọ inú Ado, ko le mu ọmọ rẹ wọ ọ.
"Nigba to n sọrọ nipa iyawo rẹ, Rambo ni ""Igi lẹyin ọgba ni iyawo mi jẹ fun mi, mo si maa n pada sile lọ sun ti, lẹyin ti mo ba jale tan."""
O mọ iru isẹ ti mo n ṣe, idi ree ti ọwọ ọlọpaa ko fi tete tẹ mi. Emi kii sun sita ni alẹ, mo maa n pada sile lẹyin ti mo ba jale tan ni ọ̀san gangan.
"O tẹsiwaju pe, ""Mo lowo, mo lọla, mo si n na owo to to aadọta miliọnu loojọ."""
Ọjọ kan tiẹ wa, ti ewe oogun mi fẹ sunko, ọwọ awọn ọlọpaa ati ologun fẹ tẹ mi, a yaa bọ sagbo awọn eeyan to n ṣe inawo, a fọn owo soju agbo, ọpọ eeyan àtàwọn ọlọpaa gan n sa owo, la ṣe ri ọna sa lọ.
Tóò bá fún ọkùnrinn lóúnjẹ́ tóo tẹ́ kiní yẹn sílẹ̀ fún un dáadáa... - Yinka TNT
Lẹyin ti aya, ọmọ ati ohun gbogbo ti Shina Rambo ṣiṣẹ fun tan, ti gbogbo rẹ poora loju aye rẹ, lo ba lọ fi ara rẹ silẹ fawọn ọlọpaa.
Wọn gbe lọ sile ẹjọ, ti adajọ si sọ si ẹwọn ọdun mọkanla ni ọgba ẹwọn Agodi nilu Ibadan.
Oríṣun àwòrán, OTHERS
Asiko to si wa ninu ọgba ẹwọn naa lo ṣe alabapade oloogbe Wolii T.O Obadare lasiko to wa waasu nibẹ.
Shina Rambo fi aye rẹ jin Ọlọrun, Obadare gbadura fun, to si yi orúkọ rẹ pada si Oluwafemi, asiko ti Oloye Olusegun Obasanjo n dari orile-ede Naijiria si lo fun Shina Rambo ni idande kuro lọgba ẹwọn.
Lati igba naa wa ni Shina Rambo ti n waasu ihinrere Ọlọrun, to si dagbere fun iwa idigunjale.
'Mo fẹ́ gbé ògo ìdílé ìyá àti bàbá mi ga pẹ̀lú iṣẹ́ Mọkálìíkì'
Ẹkọ akọkọ ni pe ki obi mase huwa ibajẹ loju awọn ọmọ wọn nítorí obi ni awokose fawọn ọmọ wọn.
Ẹkọ keji ni pe ko yẹ ki awọn òṣìṣẹ́ ti ilu ba gbe ara le ja ilu kulẹ gẹgẹ bi baba Shina Rambo ti ṣe.
Ẹkọ kẹta ni pe o yẹ ka mọ pe bo pẹ, bo ya ewe yoo sunko nitori oogun lo ni ọjọ kan ipọnju, ori ẹni lo ni ọjọ gbogbo.
Oríṣun àwòrán, OTHERS
Bakan naa lo yẹ ka kọgbọn pe ko si ohun gbogbo taa fi ọna eru ko jọ, ti yoo ba ni kalẹ nitori ibukun Oluwa nii mu ni la, laifi laalaa kun.
O tun yẹ ko ye wa pe ko si ẹni ti Ọlọrun ko le mu, asegbe kankan ko si si, asepamọ nikan lo wa.
Lakotan, itan Shina Rambo kọ wa pe ko si ẹda ti Ọlọrun ko le lo fun itankalẹ isẹ rẹ, lai naani bi igbe aye onitọun ti buru to ni ìbẹ̀rẹ̀ pẹpẹ.
Ìdílé tí ọkọ da ọmọ síta tóríi ojú Búlùú tí wọ́n ní bá BBC sọ̀rọ̀
Ondo Election 2020: Olùdíje ẹgbẹ́ òṣèlú PDP, Eyitayo Jegede ti yan Gboluga Ikengboju gẹ́gẹ́ bí ìgbákejì
Oríṣun àwòrán, other
Jegede kéde Gboluga Ikengboju gẹ́gẹ́ bí igbákejì rẹ̀ nínú ètò ìdìbò tó ń bọ́ l'Ondo losu kẹwaa, ọdun yii.
Oludije sipo gomina ninu ẹgbẹ oṣelu PDP ni ipinlẹ Ondo, Eyitayo Jegede ti kede Gboluga Ikengboju gẹgẹ bi igbakeji rẹ ti wọn yoo jọ dije.
Jegede lo kede Ikengboju loju opo Twitter rẹ lọjọ Aje.
"O ni ""Inu mi dun lati kede Gboluga Ikengboju gẹgẹ bi igbakeji mi ti a o jọ ṣiṣẹ papọ lati tukọ ijọba ipinlẹ Ondo ninu idibo to n bọ lọjọ kẹwaa, oṣu Kẹwaa, ọdun 2020."""
Ṣaaju ni ajọ to n ri si eto idibo, INEC, ti kọkọ sọ fun awọn ẹgbẹ oṣelu lati fi orukọ awọn oludije wọn ranṣẹ ko ti di ọjọ kejidinlogun, oṣu Kẹjọ, ọdun 2020 tabi ko gbagbe lati kopa ninu eto idibo ọhun.
Blind DJ: Etu Omotayo kò ríran àmọ́ ó le to irinṣẹ́ eléré pọ̀ láti kọrin láì sí ìrànwọ́
'Àwa ọmọ Nàìjíríà tó farapa fẹ́ wálé láti Lebanon, ìjọba kó wa pamọ́'
Ọlọ́pàá gbọ́dọ̀ wá àwọn tó gbàbọ̀dè láàrín wọn nítorí ẹ̀mí wa ò dè ní Akinyele
Àwọn nkan tó yẹ kí o mọ̀ nípa ṣíṣe ìṣirò àsìkò tí o bá n yé ẹyin
Èèkàn ẹgbẹ́ òṣèlú APC mií Lanre Razak jáde láyé lẹ́yìn àìsàn ráńpẹ́
Ilé ẹjọ́ ní kí ''Yahoo boy'' lọ darí ọkọ̀ f'óṣù mẹ́ta pẹ̀lú N50,000 owó ìtanràn
Oríṣun àwòrán, EPA
Ẹ wo ìkìlọ̀ tí ìjọba America fi léde lórí ìdìbò gómínà Ondo, Edo
Ẹ wo ìkìlọ̀ tí ìjọba America fi léde lórí ìdìbò gómínà ní Ondo àti Edo
Ijọba orilẹede Amerika ti fi aidunnu rẹ han lori bi awọn oṣiṣẹ eleto aabo ṣe n dasi eto oṣelu ni Naijiria, saaju idibo sipo gomina ti yoo waye ni ipinlẹ Ondo ati Edo.
Ileeṣẹ to n soju Amerika ni orilẹede Naijiria lo fi ikilọ naa lede ni oju opo ikansiraẹni Twitter wọn.
Ninu atẹjade ti wọn fi lede naa ni wọn ti sọ aidunnu wọn lori rogbodiyan to bẹ silẹ ni ipinlẹ Edo, eleyii to ti da ipaya silẹ saaju idibo sipo gomina ti yoo waye nibẹ ni osu to n bọ.
Orilẹede Amerika ko ni dẹkun lati ma a ṣe onwoye bi eto idibo ṣe n lọ lorilẹede Naijiria lọna ati ma a gba wọn ni imọran loore-koorẹ.
 A fẹ eto idibo eleyii ti yoo lọ ni irọwọrọsẹ lorilẹede Naijiria, ti ifẹ awọn eniyan lori ẹni ti wọn fẹ ko ṣoju wọn yoo si leke.
Inu wa ko dun rara si bi rogbodiyan ṣe n waye ni ipinlẹ Edo saaju ọjọ idibo
O si ba ninu jẹ pẹlu ẹsun pe awọn eleto aabo n ṣiṣẹ pọ pẹlu awọn oloṣelu lati da awhala silẹ ni ilu.
Ilẹeṣẹ orilẹede Amerika wa kesi gbogbo awọn oloṣelu ati awọn ti ọrọ kan lati ma ṣe jẹ ki eto idibo sipo gomina ti yoo waye ni ipinlẹ Ondo ati Edo da rogbodiyan ni ilu.
Wọn fikun pe ajọ eleto idibo, INEC gbọdọ sa ipa wọn lati ri wi pe idibo ti ko ni magomago ninu lo waye ni ipinlẹ Edo ati Ondo.
Bakan naa ni wọn ni awọn yoo tẹsiwaju lati ma a ri orilẹede Naijiria gẹgẹ bi asaaju ni ile adunlawọ ati orilẹede to bọwọ fun ifẹ araalu lọna ati mu itẹsiwaju ati alaafia ba orilẹede Naijiria.
Ajọ eleto idibo lorilẹede Naijiria, INEC ti gbe ara tuntun yọ bayii lori eto idibo ati wiwo esi idibo lorilẹede Naijiria pẹlu ikede agbekalẹ oju opo ayelujara kan eyi to pe ni IreV, ti yoo wa fun ikede esi ibo.
Ikede naa n waye pẹlu bi ajọ naa ati orilẹede Naijiria ṣe n gbaradi fun eto idibo gomina ni ipinlẹ Edo ati Ondo.
Oríṣun àwòrán, Inec
Ajọ naa kede agbekalẹ oju opo ọhun lẹyin ipade ajọ naa to waye l'Ọjọbọ gẹgẹ bi ara ọna lati  tubs mu ki okun akoso ibo lorilẹede Naijiria o gbopọn sii ki o ma si ni bojuboju kan ninu rara.
Kii ṣe ọrọ irọ mọ pe ọrọ esi idibo a maa fa ọpọlọpọ edeaiyede lorilẹede Naijiria, ajọ INEC ni idi niyi ti awọn fi ṣagbekalẹ oju opo naa.
Eyi ni igbesẹ ti o nilo lati maa wo esi naa bi o ba ṣe n jade loju opo INEC naa:
Igbesẹ akọkọ: Ẹ lọ soju opo https://inecelectionresults.com
"Igbesẹ keji: Tẹ ori akori kan to ni ""Creat new Account?"""
"Igbesẹ kẹta: kọ ohun gbogbo to ba yẹ si inu apoti ọrọ ti igbesẹ keji naa ba gbe sita, lẹyin eyi tẹ akori ibi to kọ ""Sign in"""
"Igbesẹ kẹrin: Kọ orukọ ipinẹ ibinibi rẹ sibẹ ko si tun tẹ ibi ti wọn kọ akori ""Continue"" si."
Igbesẹ karun un: lẹta kan yoo dun ninu apo iwe atẹranṣẹ ori ayelujara rẹ ti a mọ si Email eleyi to o fi silẹ lawọn apoti to ti yọ sita loke ṣaaju.
Igbesẹ Kẹfa: Lọ yẹ apo iwe atẹranṣẹ ori ayelujara rẹ ti a mọ si Email wo ki o si kọ number to ba firanṣẹ sibẹ ti oo lo lori ayelujara naa.
"Igbesẹ keje: Tẹ ori akori ""Activate"" loju opo naa"
Igbesẹ kẹjọ: eleyii ni yoo gbe ọ wọle soju opo ibi ti ẹ o ti yan eyikeyi ibo ti ẹ fẹ yẹ esi ibo to wu yin wo.
Igbesẹ Kẹsan: o lee lo awọn bọtini ayẹwo to wa nibẹ lati fi wa esi idibo ibudo ti o fẹ mọ ni kia masa
werewere.
Igbesẹ kẹwa: Ẹ ma gbagbe lati ti oju opo naa bi ẹ ba ti ṣetan.
Ìdílé tí ọkọ da ọmọ síta tóríi ojú Búlùú tí wọ́n ní bá BBC sọ̀rọ̀
Eto atundi idibo si aga aṣofin ipinlẹ lẹkun aringbungbun Nasarawa ti yoo waye ni ipinlẹ Nasarawa ni wọn yoo ti kọkọ lo oju opo yii.
Breastfeeding week 2020: Bí ọyàn ṣe tóbi tàbí kéré sí kò ní ǹkan ṣe pẹ̀lú ìfọ́mọlọ́yàn
Ọsẹ yii ni ayajọ ọjọ ifọmọlọyan lagbaaye oniruuru alakalẹ si ni ajọ eleto ilera ti la kalẹ.
Awọn iyalọmọ ko ni imọ kikun nipa ifọmọlọyan tori ko si iru imọ ti wọn nilo yii larọwọto wọn.
Eyi lo mu ki BBC Yoruba fi ara ọtọ ọn la ṣe igbelarugẹ ti ọdun yii nipa ṣiṣe akojọ fidio yii pẹlu awọn alabiyamọ toju wọn ti ri too nipa asiko ifọmọlọyan.
Igba ti mo bi ọmọ mi kekere omi kọ, ko jade. Ọpọlọpọ imọran ti wọn gba iya yii, pabo lo ja si.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Abiyamọ́ kan taa ba sọ̀rọ̀ ṣalaye bi ọkan oun ṣe maa n bajẹ bi fifun ọmọ lọyan ko ba lọ deede.
"Ti wọn ba ni lo eleyii maa lo, ti wọn ba ni lo tọhun, ti wọn ba
Ti mo ba fẹ fun ọmọ lọyan ti ọyan yẹn ko ba sẹ, o maa n su mi, igba mi maa sọkun, ara eeyan ko ni balẹ gẹgẹ bii abiyamọ."
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Onimọ eto ilera nipa fifun ọmọ lọyan naa sọ awọn ohun tẹ́ẹ gbúdọ mọ nípa kókó orí ọyàn yín lásìkò fífọ́mọlọ́yàn ati bi ẹ ṣe lee gbe ọmọ si aya.
Bakan naa, o ṣalaye lori ohun to maa n fa ki ọyan obinrin da wa silẹ.
"Àwọn ọmọ iléèwé máa ń pe àwọn ọmọ mi lólójú àjẹ́ toríi ""Blue Eyes"""
Umbilical cord: Àìsàn Màrùndíláàdọ́rùn ni ìwọ́ ọmọ tuntun le wòsàn
Oríṣun àwòrán, Others
Adarí ilé iṣẹ́ ìṣègùn kan Toluwalope Ogunlẹyẹ ti rọ àwọn abiyamọ láti máa yọ̀nda ìwọ́ (Umbilical Cord) ọmọ wọn si àwọn ilé ìkẹjẹ̀ sí jákèjádò Naijiria.
Ó ní èyí ni láti le máa dóòlà ẹ̀mí àwọn ènìyàn to ni ààrùn kan tàbi òmíràn.
Ogunleye sọ èyí nínú ìpàdé orí ayélujára nílùú Eko pé ètò náà wáyá láti pe àkíyèsí àwọn ènìyàn si pàtàkì ìwọ́ ọmọ fún ètò ìwòsàn láwùjọ.
Ohun tẹ́ẹ gbúdọ mọ nípa kókó orí ọyàn yín lásìkò fífọ́mọlọ́yàn
Adarí ilé iṣẹ́ ètò ìlera náà sàlàyé pé, ìwádìí ti fi hàn pé, ìwọ́ ọmọ mii ó wùlò jùlọ fún ìtọ́jú àwọn ààrùn kan ti o sì lé wúlò fun ìtọ́jú àwọn ààrùn márùndínláàdọ́rún kan.
Àwọn ààrùn náà ni ààrùn
O fi kun pé, wọ́n ti lòó láti fi ṣe ìtọ́ju ẹni to ni ààrùn fòníkú, fọ̀la dìde.
Ogunleye ni kíkó ìwọ́ ọmọ wẹ́wẹ́ pamọ́ jẹ̀ ǹkan tó le wáye ni ẹ̀ẹ̀kan lọ́ja ayé ènìyàn láti rí ìwòsàn fún àwọn ààrùn to lágbára púpọ̀, ó fi kún pé, ibi ti wan ti máa n ri irú èròjà yìí tẹ́ẹ̀ ni inú mùdùnmúdùn inú egungun ènìyàn.
"Ó ní ìwòsàn àkọ́ka ti wọ́n lo sítẹ́mú sẹẹ̀lì fún wáye ni ọdún 1988 tí ó sì ni àṣeyọri, ó ni ẹni ti wọ́n ṣe fún ni ọmọkunrin kékere kan to ni ààrun ti wọ́n ń pè ni ""Fanconi's Anemia, ó sì niṣe pẹ̀lú ẹ̀jẹ̀ ti ko já geere. Wọ́n gba ìwọ́ àbúrò rẹ ti wọ́n bi wọ́n sì lòó láti fi ṣe ìwòsàn rẹ̀."
Bákan náà lo ni ìwádìí ti fi ìdí rẹ̀ múlẹ pé ìwọ́ yìí le dí egungun, ẹran ara, ọkan, àti oníruyuru ẹ̀yà ara.
BBC Africa Eye: ìwádìí ìkọ̀kọ̀ BBC fihàn pé àwọn kan ń jí ohun eèlò ìdáàbòbò ìjọba tà nígboro
Se o yẹ ki a maa tun fiya jẹ ara wa nilẹ Adulawọ lori ọrọ Coronavirus?
Ọpọlọpọ ẹmi lo ti sọnu nipasẹ coronavirus ni eyi ti awọn eeyan si ti gba kadara si.
Opọ n fẹsun kan ijọba orilẹ-ede wọn pe wọn ko pese awọn ohun eelo to peye lati koju ajakalẹ arun coronavirus to n gbẹbọ lọwọ gbogbo agbaye yii.
Ṣugbọn iwadii ikọkọ ti BBC Africa Eye ṣe ni orilẹ-ede Ghana fihan pe awọn oṣiṣẹ eleto ilera gan an n ṣe ara wọn ti wọn si n ji ohun eelo ko ta nigboro.
Anas Aremeyaw lo ṣaaju awọn to ṣe iwadii naa nibiti ọwọ si ti tẹ apoogun oyinbo to jé ọga agba nile iwosan nla ni Ghana, Thomas Osei ati Divine Kumordzi to jẹ oṣiṣẹ eleto ilera.
Ṣaaju ni fọnran yii ṣafihan eto isinku dokita akọkọ ti coronavirus pa ni Ghana.
Koda, awọn ẹni ibi tun n ta awọn ohun eelo itọju alaisan Covid 19 nibẹ.
Dokita Hadi Abdallar banujẹ lori iwadii yii lataari ọpọ ẹmi to ti sọnu nipasẹ iwa ika awọn alatẹnujẹ kan nilẹ Adulawọ.
Lẹyin iwadii BBC Africa Eye yii, awọn alaṣẹ ile iwosan ti ọrọ kan ti ni ki awon ti BBC gba mu lọ rọọkun nile na titi wọn o fi pari iwadii ti wọn.
Ileeṣẹ BBC ti ko gbogbo ohun eelo ilera ti a ra lati fi gba awọn oniṣẹ ibi yii mu pada si ile iwosan nlanla gẹgẹ bii ẹbun.
Bauchi woman: Balaraba Ibrahim tó jẹ́ Olùrànlọ́wọ́ pàtàkì fún ọ̀rọ̀ àwọn obìnrin tí a kọ̀ sílẹ̀ jẹ́ kàyééfì ní Nàìjíríà
Oríṣun àwòrán, others
Ṣaaju ni oriṣiriṣi ẹjọ ti jade lori bi gomina ipinlẹ Bauchi to wa ni ariwa Naijiria ṣe yan arabinrin Balarabe Ibrahim sipo oluranlọwọ pataki.
Bo tilẹ jẹ pe awuyewuye waye lori iyansipo naa, ti ọpọ eeyan si n sọ pe oluranlọwọ pataki lori ọrọ awọn ti ko ni ọkọ tabi iyawo ni gomina yan obinrin naa si.
Ṣugbọn bayii,  ijọba ipinlẹ Bauchi ti salaye oun ti ipo naa wa fun.
BBC Africa Eye: ìwádìí ìkọ̀ks BBC fihàn pé àwọn kan ń jí ohun èèlò ìdáàbòbò ìjọba tà nígbo
Gomina Bala, sọ lati ẹnu agbenusọ rẹ pe iyansipo naa kii ṣe babara, nitori pe Balaraba wulẹ̀ ti n ṣe Alaga ẹgbẹ awọn obinrin to ti kọ ọkọ wọn silẹ ni ipinlẹ Bauchi tẹlẹ.
Ati pe, O maa n ṣeto ipade laarin awọn obinrin naa, o si máa n ṣe iṣẹ alarina fún awọn to ba fẹ ẹ pada ni ọkọ.
Tani Balaraba Ibrahim?
Iya n da gbe ni Balaraba fúnra rẹ jẹ, pẹlu awọn ọmọ rẹ.
Iru iyansipo yii kii ṣe nkan ti oju ko riri ni Ariwa orilẹ-ede Naijiria, nitori pe wọn ni i ni ipinlẹ Kano.
Ẹni ti gomina ba yan si ipo naa ni yoo ma a mojuto bi awọn to ti kọ ọkọ tabi iyawo wọn silẹ yoo se pada ni ololufẹ miran, paapaa nitori pe ijọba maa n ṣe ayẹyẹ igbeyawo alasepọ fun wọn.
Ijọba Bauchi ti ẹ sọ pe awokọse ipinlẹ Kano ni oun ṣe.
Ni ipinlẹ Kano bakan naa, wọn ni oye oluranlọwọ pataki lori ibojì òkú.
Oríṣun àwòrán, @Bauchi
Bẹẹni, oju yin ko kuku tan yin jẹ.
Oye yii ni gomina maa n fun eeyan, lati ma a mojuto ọrọ to ba ni i ṣe pẹlu awọn ibi tí wọn n sin oku si nipinlẹ naa.
Oye miran to tun jẹ iyalẹnu ni agbo oṣelu Naijiria ni oye oluranlọwọ pataki lori ọrọ awọn ina ti ijọba n tàn si adugbo, 'street lights'.
Ipinlẹ Kano ni gomina ti fi eeyan kan si ipo yii ni ọdun to kọja.
Oríṣun àwòrán, Others
Gomina Ganduje Abdullahi yan Yakubu Nagoda sipo olubadamọran lori ọrọ iboji oku.
Nagoda kọwe fipo rẹ silẹ lọdun 2018.
Nipinlẹ Imo, awuyewuye waye ni ọdun 2017, nigba ti gomina wọn tẹlẹ, Rochas Okorocha ṣe idasilẹ ileesẹ idunnu, Ministry of Happiness.
Working religious women: Ẹ̀lẹ́hàá kìí ṣe ọ̀lẹ- Aminat Adegoke
Koda, Gomina Rochas yan kọmiṣọnna ti yoo ma a dari rẹ.
O ni ileesẹ naa yoo ma a ran awọn ileesẹ ìjọba yooku lọwọ lati ma a mu inu ara ìlú dùn.
Ìdílé tí ọkọ da ọmọ síta tóríi ojú Búlùú tí wọ́n ní bá BBC sọ̀rọ̀
Diezani gan an ní Hushmummy tó ń bú àwọn Yahoo boys- Àwọn Ọmọ Naijiria lórí Twitter
Oríṣun àwòrán, SAMUEL KUBANI
Awọn ọmọ Naijria ti bu ẹnu atẹ lu ọrọ ti minisita fun ọrọ epo bẹntirolu ni Naijiria tẹlẹri. Diezani Alison-Madueke sọ nipa ihuwasi awọn gbajuẹ ati Yahoo-yahoo ni awujọ.
Diezani Alison-Madueke ni oṣe ni laanu pe awọn oniwa jibiti ni awọn eniyan n gbe larugẹ, ti wọn si n wo gẹgẹ bi awọkọṣe ni Naijiria.
Arabinrin naa sọ eyi ninu fidio kan to n ja ranyinranyin lori ayelujara, nibi ti o ti n sọrọ ni ipade ti wọn ṣe fun awọn ọmọbibi ilu Ijaw lori ayelujara.
Amọ awọn ọmọ Naijiria to fesi si fidio naa lori Twitter ni iru ọrọ bẹẹ ko tọ si ẹnu Madueke nitori oun jẹjọ iwa ibajẹ lọwọ lorilẹ-ede Naijiria.
BBC Africa Eye: ìwádìí ìkọ̀ks BBC fihàn pé àwọn kan ń jí ohun èèlò ìdáàbòbò ìjọba tà nígbo
Wọn ti lẹ pe e ni iya awọn gbajuẹ ati yahoo-yahoo ni Naijiria.
Working religious women: Ẹ̀lẹ́hàá kìí ṣe ọ̀lẹ- Aminat Adegoke
Amọ, awọn eniyan kan gboriyin fun Diezani Alison-Madueke fun ọrọ to sọ tako iwa jibiti lawujọ.
Oluranlọwọ fun Aarẹ Buhari lori ọrọ Iroyin, Bashir Ahmad naa wa lara awọn to ni ọrọ to dara ni Diezani sọ, ati wi pe ki awọn eniyan fi i silẹ.
Peters Ijagbemi dá àrá lórí ètò 'Ṣé o láyà' ti BBC Yorùbá lọ̀sẹ̀ yìí
Ajọ to n gbogun ti iwa ibajẹ lorilẹ-ede Naijiria EFCC n ṣewadii Minisita tẹlẹri naa, Dieziani Alison-Madueke fun ẹsun iwa ibajẹ ati jẹgudujẹra lasiko to wa ni ipo.
Amọ, iroyin ni Olootu ijọba Dominica, Roosevelt Skerrit ti yan Dieziani Alison-Madueke gẹgẹ bi kọmisọnna fun eto oro ajẹ lorilẹ-ede naa, ti wọn si fun un ni iwe igbelu.
Iroyin ni eleyii ti fun Dieziani Alison-Madueke ni anfaani lati le bọ lọwọ ajọ EFCC to n ṣewadii rẹ lati igba to ti wa ni ilu London fun ọdun mẹrin bayii.
Itan Ilu gangan
Beyonce New Album: Ìyá àgbà láti Nàíjíríà ní inú òun dùn láti kọrin pẹlú Beyonce nílẹ̀ Amerika
Oríṣun àwòrán, Others
Iya agba Mojisola Odegbami ti bọ si inu ọla bayii lẹyin to kopa ninu awo orin olorin takasufe ilẹ Amerika, Beyonce.
Iya agba, ẹni ọdun mọkandinlọgọrin, Mojisọla Odegbami ti ṣoju orilẹ-ede Naijiria ati ilẹ Afrika ninu awo orin tuntun ti olorin takasufe ilẹ Amerika, Beyonce ṣẹṣẹ gbe jade, to pe orukọ rẹ ni ‘Black is King’.
Arabinrin Odegbami ni o lọ si orilẹ-ede Amerika fun itoju lai mọ wi pe aye rẹ yoo yipada si rere ni oke okun.
Ọmọde olorin, FJ Akinmurele to jẹ ẹni ọdun meje, lo jẹ ki Beyonce mọ arabinrin naa ati bi o ṣe darapọ mọ ṣiṣe awo orin tuntun ti Beyonce gbe jade.
Beyonce ni awo orin naa fihan gbangba pe awọn alawọ dudu jẹ ẹya eniyan to wunilori, ti itan wọn si bu iyi kun ọmọniyan.
Ninu orin ti o pe akọle rẹ ni ''Bigger'' ni mama agba Mojisọla Odegbami ti safihan ninu fidio naa, gẹgẹ bi ọbabinrin ilẹ Afrika, to si wọ aṣo alaranbara ilẹ Yoruba, pẹlu gele lori rẹ.
Mama Odegbami lasiko to n ba awọn oniroyin sọrọ wi pe ọmọ ọrẹ oun ti oun de si ọdọ wọn ni Amerika lo mu oun mọ Beyonce.
Oríṣun àwòrán, Others
Iya naa ni bi ọrọ ṣe ṣẹlẹ ni wi pe oun ni oun ma n gbe ọmọde olorin naa lọ si ibi to ti n kọ ẹkọ orin kikọ nitori ọmọde olorin naa n kopa ninu awo orin tuntun.
Iya agba, ẹni ọdun mọkandinlọgọrin, Mojisọla Odegbami ni ''iya Moji''  ni awọn oṣiṣẹ Beyonce ma n pe oun, ti iya FJ si fi orukọ oun silẹ pẹlu awọn ileeṣẹ to ma n wa awọn to ni ẹbun.
Victor Agunbiade ni ojú àlá ni Ọlọrun ti yan iṣẹ́ ọmọ ogun ojú omi fún òun ní America
Bi iya ṣe bẹrẹ si ni ya aworan pẹlu Beyonce niyẹn, amọ wọn kilọ fun un pe ko gbọdọ gbe awọn aworan naa sita afi igba ti awọn ba ṣe afilọlẹ awo orin naa.
Akomolede ati asa Yoruba: Ẹ wá kọ́ nípa àpòtí ìṣura èdè wa lórí BBC Yorùbá
Mama Odegbami ni inu awọn dun pupọ lati ṣoju orilẹede Naijiria  ati ilẹ Afrika ni apapọ, ti o si dupẹ lọwọ ọmọ rẹ to jẹ ki oun ṣe alabapade Beyonce.
Mr Macaroni sọ nípa eré tí Fraky freaky, Sugar Daddy, You are doing well, freaky spicy fẹ́
Belarus: Ààrẹ orílẹ̀èdè Lukashenko tún wọlé lẹ́yìn ọdún 25 lórí oyè! Kí ló ń ṣẹlẹ̀ gangan?
Oríṣun àwòrán, EPA
Ọjọ aiku ni aarẹ Alexander Lukashenko jawe olubori fun saa ikẹfa lori ye lẹyin idibo tawọn eeyan n kun yunmu yunmu le lori eyi to si ru ibinu awọn afẹhonuhan soke ti wọn tu si gbogbo igboro jakejado orilẹede naa.Ṣugbọn ki lẹ tun mọ nipa Belarus?Ohun marun niyi ti ẹ le nifẹ lati mọ nipa rẹ.
Belarus ni orilẹede to gbona ju paapaa lasiko ogun agbaye keji.Iṣẹlẹ ogun naa lo da Belarus ru laarin ọdun 1941-1944 to bẹẹ ti wọn padanu ida mẹẹdọgbọn eeyan wọn lasiko ogun agbaye naa ti ilẹ Nazi Germany kogun ja USSR.Ẹẹdẹgbẹjọ miliọnu araalu ati Sọja ẹgbẹta miliọnu lo ku ni Belarus lasiko ogun naa to fi mọ o fẹrẹẹ to iye gbogbo awọn ẹya Juu.Nkan bii ida marundinlaadọrun olu ilu orilẹede naa, Minsk lo bajẹ ninu iṣẹlẹ ibugbamu ado oloro ti wọn si tun un kọ ni 1950s ati 60s.Aarẹ ibẹ ni aarẹ ilẹ Yuroopu to pẹ ju lori oye. Ṣe ni iroyin sọ pe aarẹ Alexander Lukashenko lo tun jawe olubori ninu idibo ọjọ Aiku pẹlu ibo to le ni ida ọgọrin.
"Ẹwẹ, awọn oluwoye idibo ko si nikalẹ, eyi to si fa ibẹru ṣiṣe mago-mago idibo. Ohun si ni iditi oludije alatako gangan, Svetlana Tikhanovskaya ṣe yari pe irọ ni esi idibo naa.Wọn ṣapejuwe aarẹ Lukashenko gẹgẹ bi aarẹ apaṣẹwaa to ṣẹ tun wa nilẹ Yuroopu bayii. O bẹrẹ iṣejọba lọdun 1994.Ọgbẹni Lukashenko ti sọ ọ jade lẹnu ri pe ẹnikẹni to ba dara pọ mọ ifẹhonuhan alatako gẹgẹ bii adunkoko mọni, ""a o yin in lọrun bii ti pẹpẹyẹ ni"".Ọtọ tun ni ajoji kan, Lee Harvey Oswald to pa aarẹ Kennedy tan to wa ko wa si Minsk lati maa gbe nibẹ gẹgẹ bi ẹni tọwọ rẹ mọ.Nitori ọrọ ẹ ba mi sọ fisa igbelu mi dọtun - a o fun ọ, Oswald yii tun daran o ge ọrun ọwọ ọga ileeṣẹ to bẹẹ ṣugbọn ko ma baa si ija ilu si ilu, wọn dari ji i.O fẹ aya, o bimọ nibẹ koda o riṣẹ gidi kaakiri.Bakan naa nigba ti ina nla kan sọ ni ileeṣẹ ipese ina orilẹede ẹgbẹ wọn, Ukraine ati Chernobyl, Belarus fara gba gidi gan.Tori eyi, eeyan miliọnu meji ninu eyi ti ẹgbẹrun lọna ẹẹdẹgbẹta ara orilẹede Belarus pọ ju lo n gbe ni awọn agbegbe to lewu.Ẹwẹ, awọn naa ni ohun amuyangan lagbaye, Azarenka agbabọọlu ẹlẹyin tẹniisi to ṣoriire ju lorilẹede naa. Oun lọmọ Belarus to kọkọ gbe ogo wale to si kọkọ gba ipo akọkọ lagbaye gẹgẹ bi agbabọọlu tẹniisi."
Oríṣun àwòrán, EPA
Oríṣun àwòrán, EPA
Ifẹ̀họ̀núhàn ń lọ lọ́wọ́ ní Belarus lẹ́yìn tí ìdìbò tùn gbé Ààrẹ̀ Lukashenko tó ti wà nípò fún ọdún 26 wọlé
Ifẹhọnuhan ti wọ ọjọ keji bayii lorilẹede Belarus lẹyin ti iroyin fihan pe Aarẹ Lukashenko to ti wa ni ipo fun ọdun mẹrindinlọgbọn tun ti wọle idibo aarẹ.
Awọn ọlọpaa ni olu ilu Belarus, iyẹn Minsk ti fẹ afẹfẹ gaasi tajutaju fun awọn to n fẹhọnu han pe idibo aarẹ naa ni magomago ninu.
Awọn oṣiṣẹ ijọba ni afẹhọnuhan kan ti ku nigba ti ado oloro to mu dani bugbamu mọ ọ lọwọ, to si gba ibẹ lọ.
Oríṣun àwòrán, EPA
Aarẹ Alexander Lukashenko ni esi idibo gbe jade pe, o ti bori ida ọgọrin ninu ọgọrun ida ibo ti awọn oludibo di.
Ọkan gboogi ninu awọn to dije dupo aarẹ naa,  Svetlana Tikhanovskaya kọ lati gba esi idibo naa wọle, to si sọ wi pe oun lo bori idibo naa.
Aisi eto aabo ati awọn onwoye idibo lasiko idibo naa ti fi agbara fun ẹsun magomago lasiko idibo ti wọn fi kan ijọba.
Orilẹ-ede Amerika ati Ajọ Iṣọkan ilẹ Yuroopu, EU ti kọ ẹsi idibo naa.
Aarẹ Lukashenko bori pẹlu ida 80.23%, nigba ti oludije  Svetlana Tikhanovskaya gba ida ibo 9.9% ninu idibo sipo aarẹ naa.
Arabinrin Svetlana Tikhanovskaya lo dije dipo ọkọ rẹ to wa ni atimọle, ti o si dari ifẹhọnuhan ọlọgọọrọ.
Nibayii, Tikhanovskaya ti sa kuro lorilẹede Belarus lọ si Lithuania, ti minisita fun ọrọ ilẹ okeere ni Lithuania si sọ wi pe alaafia ni arabinrin naa wa.
Oríṣun àwòrán, Reuters
Amọ, Aarẹ Lukashenko to ti wa ni ipo lati ọdun 1992 sọ wi pe awọn ijọba lati oke okun lo n ṣe agbatẹru fun awọn alatako oun ati awọn afẹhọnuhan.
Asiko ti ipolongo ibo bẹrẹ ni Arabinrin Tikhanovskaya, ẹni ọdun mẹtadinlogoji, to ti fi igba kan jẹ olukọ, di oloṣelu.
Eyi waye lẹyin to pinnu lati rọ́pò ọkọ rẹ ti wọn mu si atimọle, ti wọn ko si jẹ ko fi orukọ silẹ lati díje.
Sugbọn, ọwọ yẹpẹrẹ ni Aarẹ Lukashenko fi mu ọrọ rẹ, to si fi ṣe awada pé àwọn kan lo n dari rẹ lati ilẹ okeere.
Alaafin: Olori Aanu Adeyemi ṣàlàyé ìdí tó ṣe gẹ́ Oba Lamidi Adeyemi ti ìlú Oyo
Gẹgẹ bi ajọ Viasna ṣe sọ, eeyan to le ni ẹgbẹrun meji, ni wọn ti fi si ahamọ, lati igba ti ipolongo ibo ti bẹrẹ.
Koda, ni alẹ ọjọ ti idibo ku ọ̀la, Arabinrin Tikhanovskaya, sọ pe awọn ọlọpaa mu olori ikọ ipolongo òun.
Oríṣun àwòrán, EPA
Arabinrin Svetlana Tikhanovskaya ni alatako gboogi to koju Aarẹ Lukashenko
Ileesẹ ayelujara NetBlocks tí ẹ sọ pe ayelujara ko ja geere lọjọ Aiku, bí awọn eeyan ṣe n dibo.
Awọn alatako sì sọ pe eyi mu ki o ṣòro lati ko ẹri jọ pé mago-mago ibo waye.
Ọpọlọpọ eeyan ni awọn ọlọpaa mu lasiko iwọde to waye lọjọ Aiku
Bakan naa, ikunsinu ti n waye nitori bi wọn ko ṣe pe awọn oluwoye lati tọ pinpin idibo naa, ìdá bi ogoji ibo si ni wọn ti di saaju ọjọ idibo.
Kii ṣe Tikhanovskaya nikan lo díje tako Aarẹ Lukashenko. Awọn mẹta yooku ni ọmọ ile aṣofin nigba kan, Anna Kanopatskaya, Sergie Cherechen, ati Andrei Dmitriyev.
Lara awọn nkan to fa tí tako ijọba Ọgbẹni Lukashenko, ni bo ṣe fi ọwọ yẹpẹrẹ mu itankalẹ aarun coronavirus.
Oríṣun àwòrán, EPA
Ọgbẹni Lukashenko lasiko to lọ dibo nilu Minsk
Nise ni Aarẹ gba awọn ara ilu ni imọran pe ki wọn o ma a mu ọtí lile vodka, ati ìwẹ̀ saunas, fi gbogun ti aarun naa.
Eeyan bi ẹgbẹrun lọna aadọrin lo ti ni coronavirus ni Belarus, ninu miliọnu mẹsan aabọ to n gbe nibẹ. Ẹgbẹta si ti ku.
Sextuplet: Àdúrà Ìbùkún ló kú lẹ́yìn ọmọ mẹ́fà yìí- Ifeoma Thelma àti Onyemaechi Chiaka
Kini Oluwa ko le ṣe?
Ibeere nla ti idahun rẹ jẹ pe Ko si ohun ti Olorun ko le ṣe ni ifọrọwerọ BBC oni gbe dani loju ọpọn wa.
Ifeoma Thelma ati Onyemaechi ni wọn ṣe igbeyawo lọdun 2014 ti wọn si bẹrẹ si ni woju Oluwa fun ẹbun ọmọ rere to jẹ ìní Oluwa.
Lọdun 2019 ni wọn di iya ati baba Ibẹfa lẹyin gbogbo igbiyanju wọn lori ati di ọlọmọ laye.
Ọmọ ọkunrin mẹrin ati ọmọbinrin meji lanti-lanti ni Oba Oke fi jinki tọkọtaya Chiaka lẹẹkanṣoṣo nigba ti o ṣamin si IVF ti wọn ṣe to si yọ wọn kuro lagan nigba to wu u.
Ifeoma ṣalaye fun BBC pe niṣe ni ẹnu ya gbogbo eeyan nile iwosan ni America ti oun lọ bimọ si nigba ti wọn kọkọ gbe ọmọ mẹrin ti fọto 'Scan' sọ pe o wa nibẹ tẹlẹ sita, ti wọn tun ri mii sii.
Thelma ni awọn mọ pe Olorun to fun awọn ni awọn ọmọ mẹfa yii lẹẹkan ṣoso naa ni yoo pese owo ti awọn yoo fi tọ wọn bi o ṣe yẹ!
BBC gbadura fun gbogbo ololufẹ wa to n woju Oluwa pe, iru ẹbun wọnyii a wọle tọ yin bi o ṣe wu yin laipẹ.
Ọwọ́ ọlọ́pàá ìpínlẹ̀ Kebbi tẹ bàbá àti ìyàwó rẹ̀ méjì fún pé wọn so ọmọ pọ̀ mọ́ ewúrẹ́ fún ọdún méjì
Àmọ̀tẹ́kùn gbéra! Kò séwu nínú ìdìbò tó ń bọ̀ l'Ondo àfi gìrì àparò- Akeredolu
Asojú ìjọba orílẹ̀-èdè Lebanon ti kọ̀wé fipò silẹ̀ nítorí ìbágbàmù tó gbẹ̀mi ènìyàn 200
"Wo ìdí tí Risikat Moromoke Azeez n'Ilorin fi ní ""Blue Eyes"" - Dókítà"
Lagos State Assembly: Ó takò òfin kí àwọn obí jẹ̀yà ti ọmọ ba darapọ̀ mọ́ ẹgbẹ́ òkùnkùn
Oríṣun àwòrán, Others
Awọn ajafẹtọ ọmọniyan ti bu ẹnu atẹ lu igbesẹ Ile Igbimọ Aṣofin ni ipinlẹ Eko lati buwọlu abadofin ti yoo faaye gba ki awọn obi pin ninu iya ti ọmọ wọn to ba n ṣe ẹgbẹ okunkun yẹ ko jẹ.
Eyi ko ṣẹyin bi  abadofin naa ṣe kọja ipele kika kẹta ni ile igbimọ aṣofin ipinlẹ naa.
Agbẹnusọ fun Ile Igbimọ Aṣofin nipinlẹ Eko, Mudashiru Obasa to fi idi ẹ mulẹ wi pe lootọ ni wọn n gbe abadofin naa yẹwo.
Obasa ni ijọba lo kọkọ gbe abadofin naa wa fun wọn, ki ọmọ ile kan to da a laba pe ki awọn obi ni ipin ninu ijiya to tọ si ọmọ, nitori awọn obi naa kọ lati tọ awọn ọmọ wọn daradara.
O ni obi gbọdọ ma a mọ ohun ti ọmọ rẹ ba n ṣe ni gbogbo igba, nitori naa ni wọn gbọdọ pin ninu iya.
Alaafin: Olori Aanu Adeyemi ṣàlàyé ìdí tó ṣe gẹ́ Oba Lamidi Adeyemi ti ìlú Oyo
Kinni ofin sọ lori eyi?
Ṣe awọn obi yoo fi iṣẹ silẹ ati gbogbo ohun ti wọn ba n ṣe lọna ati ri i pe wọn bojuto ọmọ?
Agbẹjọrọ to tun jẹ ajafẹtọ fun awọn ọmọde, Arabinrin Elizabeth Udeh ni ko si ofin kankan to sagbatẹru igbese ti ijọba ipinlẹ Eko fẹ gbe naa.
Udeh ni lọpọ igba, awọn obi kii mọ ohun ti awọn ọmọ wọn n ṣe ni ileewe giga nitori naa wọn ko le e pin ninu iya ẹṣẹ ti ọmọ ba ṣẹ.
‘Awọn ọmọ to wa ni fasiti ti dagba to lati mọ iyatọ laarin iwa rere ati iwa buburu.’
Oríṣun àwòrán, Others
Agbẹjọrọ Elizabeth ni: ‘Ki ni yoo ṣẹlẹ si obi to ba n gbe ni jina rere si ibi ti ọmọ rẹ ti n kẹkọ, ṣe iru awọn obi bẹẹ yoo tun fi oju wina ofin ti awọn ọmọ wọn ba ṣẹ?’.
‘Ṣe awọn obi yoo fi iṣẹ silẹ ati gbogbo ohun ti wọn ba n ṣe lọna ati ri pe wọn bojutọ ọmọ?
Amọ, Agbẹjọrọ to tun jẹ ajafẹtọ fun awọn ọmọde naa, Arabinrin Elizabeth Udeh fikun un pe idi ti awọn obi fi le jẹbi ni ti wọn ba kọ lati bojuto ọmọ wọn,
Abi ti wọn ba fi ẹjọ ọmọ wọn sun pe wọn hu iwa buruku, amọ ti iya gbe lẹyin ọmọ rẹ lai ṣe iwadii to tọ lori ẹsun naa.
Ti iru eleyii ba ṣẹlẹ, wọn le fi iru awọn obi bẹẹ jofin nitori wọn kọ lati sa ipa wọn fun awọn ọmọ wọn.
‘Ijọba yẹ ki wọn kọ awọn obi ni ọna ti wọn yoo fi tọ ọmọluwabi lawujọ’
Bakan naa ni AgbẹjọroTaiwo Akinlami naa bu ẹnu atẹ lu igbeṣẹ ile igbimọ aṣofin ipinlẹ Eko naa to n da a laba lati ma a jẹ ki awọn obi pin ninu iya ti o tọsi ọmọ to ba n ṣe ẹgbẹ okunkun.
Taiwo Akinlami ni ẹnikẹni to ba ti ju ẹni ọdun mejidinlogun lọ lẹtọ labẹ ofin lati jẹjọ ẹsun ni ile ẹjọ.
Oríṣun àwòrán, Others
Akinlami ni ika to ba ṣẹ naa lo yẹ ki ọba ge, nitori naa ti ko ba ti jẹ obi lo wuwa ibajẹ, obi ko gbọdọ jẹya  ẹsẹ ti ko ṣe.
O ni kii ṣe obi nikan lo n tọ ọmọ lawujọ, iṣẹ gbogbo eniyan ni, nitorinaa gbogbo wa lo jẹbi.
Ti wọn ba ti mu awọn obi naa, wọn gbọdọ mu awọn Alfa, pasitọ, olukọ ati imaamu pẹlu awọn alabagbe ọmọ to ba ti wu iwa ibajẹ lawujọ tabi darapọ mọ ẹgbẹ okunkun.
Bakan naa lo fikun pe ijọba yẹ ki wọn sa ipa wọn fun awọn obi nipa lila wọn lọyẹ nipa bi wọn ṣe le tọ ọmọluwabi lawujọ.
O ni jijẹ, mimu, ile ati idagbasoke ọmọ ṣe koko, eleyii ti ijọba kọ lati fi ṣe iranwọ fun awọn obi.
Amọ, Agbejọro naa fikun wi pe ari iru awọn obi bẹẹ ti ko bojuto ọmọ wọn, iru awọn yẹn le gba idajọ lọwọ ijọba.
Unilag VC: Folasade Ogunsola ni obìnrin àkọ́kọ́ tó jẹ ọ̀gá àgbà fún ibùdó ẹ̀kọ́ṣẹ́ ìṣègùn Fáṣítì Eko
Oríṣun àwòrán, @Anisformat
Ọdun 1958 ni wọn bi Ọjọgbọn Folasade Tolulope Ogunsola, ọmọ Mabogunje sile aye.
Kekere si ni Folasade ti nifẹ lati maa ṣe bii dokita, ti yoo si maa tọju bebi to n ṣe aisan.
Laarin ọdun 1974 si 1982, Folasade kẹkọ dokita nile ẹkọ fasiti Ile Ife to si gba oye imọ ijinlẹ akọkọ nigba to gba oye imọ ijinlẹ keji nile ẹkọ fasiti Eko.
Lẹyin naa lo tẹ ọkọ leti lọ si ilẹ Gẹẹsi, to si tun kọ ẹkọ si ni fasiti Wales laarin ọdun 1992 si 1997.
Lẹyin to pada wale, Folasade bẹrẹ iṣẹ ni ile ẹkọ ẹkọṣẹ imọ isegun ni fasiti Eko, to si ni igbega de ipo ọga agba ibudo naa.
Oríṣun àwòrán, @TheICIR
Ọga agba tuntun fun fasiti Eko yii lo ti jẹ oniwadii agba lori kokoro arun HIV, to si tun jẹ alaga igbimọ to n ka ọwọja arun to n ran ko.
Bakan naa ni o jẹ igbakeji ọga agba fasiti Eko lọdun 2017, ẹka iṣẹ idagbasoke, ipo yii si lo wa ti wọn fi kede rẹ bii ọga agba fasiti naa.
Ki lo ti ṣẹlẹ sẹyin?
Oríṣun àwòrán, Others
Iroyin to n tẹ wa lọwọ ni pe awọn alaṣẹ ile iwe giga fasiti Eko, Unilag ti yan giwa tuntun mii lati maa tukọ ile iwe naa.
Ọjọgbọn Folashade Ogunsola lo gbegba oroke ninu gbogbo awọn ti wọn dibo yan eyi to waye larin awọn ile igbimọ aṣofin fasiti naa ti wọn fi yan adele.
Folashade ni igbakeji ẹka idagbasoke fun giwa to wa nibẹ tẹlẹ, Oluwatoyin Ogundipe.
Gẹg bi iroyin ti a gbọ, ninu ibo mẹtadinlaadọsan, Folashade nikan ni ibo marunlelaadoje.
Ẹnikeji ti wọn tun foju sun fun ipo kan naa, Ọjọgbọn Ben Ogbojafor ni tirẹ ni ibo mọkanlelọgbọn.
Nibi ipade ijoko ile igbimọ aṣofin fasiti naa to waye lọjọ Aje ni wọn ti yan Folashade.
'Ìgbà tí mo máa fi lajú sáyé padà, ọ̀fọ̀ ikú mi ní wọ́n ń kígbe'
Ṣaaju, ọga Agba ileewe fasiti ipinlẹ Eko ti wọn yọ nipo, Oluwatoyin Ogundipe ti gba ileẹjọ lọ lẹyin ti Ajọ amuṣẹya fasiti naa yọ ọkuro nipo.
Asiko ipade awọn ajọ amuṣẹya ti wọn ṣe ni ileeṣẹ National Universities Commission ni ilu Abuja ni wọn ti yọ Ọjọgbọn Ogundipe nipo gẹgẹbi ọga agba fasiti ilu Eko.
Nibayii, Ọjọgbọn naa ti gba agbẹjọrọ agba ni Naijiria, Mike Ozekhome lati lọ ṣoju rẹ ni ileẹjọ.
Ninu atẹjade ti Ogundipe kọ si Ozekhome, O ni wọn yọ oun lai tẹlẹ ilana otitọ ati ododo to yẹ ki wọn tẹle lati yọ oun kuro ni ipo.
Ọjọgbọn Ogundipe ni oun ni atilẹyin awọn oṣiṣẹ ati olukọ fasiti naa, nitori wi pe ọna ti wọn gba fi yọ oun tako ofin to de fasiti lorilẹ-ede Naijiria.
Victor Agunbiade ni ojú àlá ni Ọlọrun ti yan iṣẹ́ ọmọ ogun ojú omi fún òun ní America
Ninu ọrọ rẹ, Ozekhome ni iditẹmọni ni ipade pajawiri ti wọn pe lati yọ Ogundipe kuro nipo.
Bakan naa ni Ọjọgbọn Oluwatoyin Ogundipe saaju awọn to n fẹhọnu han lori bi wọn ṣe dede yọ kuro nipo.
Ogundipe ni o farahan pẹlu awọn ẹgbẹ oluko NASU, SSANU àti ASUU nibi ti wọn ti n ṣe ifẹhọnu han lati inu ọgba fasiti naa titi de ẹnu abawọle ileewe giga naa.
Lasiko ti Ọga agba ileewe naa ti wọn yọ nipo n sọrọ, o ni ọgbọn ọdun niyii ti oun ti n sisẹ ni ileewe naa ni ipo kan tabi omiran, nitori naa wọn ko le dede yọ oun bii jiga.
Bakan naa ni alaga ẹgbẹ awọn olukọ fasiti ti ipinlẹ Eko, Dokita Dele Ashiru ni awọn tako bi wọn ṣe yọ Ọjọgbọn Ogundipe nipo, ti awọn si fi igboya tẹle gẹgẹ bi adari wọn.
Sextuplet: Àdúrà Ìbùkún ló kú lẹ́yìn ọmọ mẹ́fà yìí- Ifeoma Thelma àti Onyemaechi Chiaka
Ó ti tó bi ọja mẹ́ta tí awuyewuye ti ń wáye lóri yíyọ giwa Fásitì Eko
Tí ọ̀rọ̀ nááà sì ti dí gbọ́nmísi-omi ò tóo nípa oníruuru ìròyìn tó ń jáde láti ilé iwé ọhun.
Oríṣun àwòrán, Others
Nínú ọ̀rọ̀ rẹ̀, Ọ̀jọ̀gbọ́n Folashade Tolulopẹ Ogunsola sàlàye fún BBC pé, wàhálà yìí kìí ṣe ǹkan ti ó ṣẹ̀ṣẹ̀ bẹ̀rẹ̀ ni àná bíkòṣe láti ọjọ́ tó ti pẹ́.
Ogunṣola ní láti ọdún tó kọjá ní ọ̀rọ̀ náà ti bẹ̀rẹ̀ láti igba ti Omowe Babalakin to jẹ́ alága ìgbìmọ̀ Kánsù tó ń mójútó ọ̀rọ̀ Fásítì náà ]ati Ogundipe ti n ni kudiẹ-kudié.
Koda, eyi wa lara idi ti wọn fi wọgile ṣiṣe eto ayẹyẹ ikẹkọọjade fawọn akẹkọọ ni oṣu kẹta ọdun yii.
Sextuplet: Àdúrà Ìbùkún ló kú lẹ́yìn ọmọ mẹ́fà yìí- Ifeoma Thelma àti Onyemaechi Chiaka
Kini Fasiti UNILAG ri si eto iyọninipo Ogundipe?
Ọ̀jọ̀gbọn Ogunṣola ni ọna iyọni nipo naa kudiẹ kaato nitoripe wọn ko téle ilana ofin bi o ṣe yẹ.
O ni wọn ko fún Ogundipe láàyè láti sọ tẹnu rẹ̀, bákan náà ni wan ko láti tẹ̀lé ìlànà tí o yẹ kí wọ́n tó gbé irú ìgbẹ́sẹ̀ bẹ́ẹ̀ niru iṣẹlẹ fasiti nla bii ti Eko yii.
Ó ní àti yíyọ àti kíkéde ẹlòmíràn kò bá ìlànà tó tọ́ mu.
Ati pe yiyan tabi kikede Ojogbon Soyombo ko tẹle ilana to yẹ gẹgẹ bii adele Giwa fasiti Eko.
Alaafin: Olori Aanu Adeyemi ṣàlàyé ìdí tó ṣe gẹ́ Oba Lamidi Adeyemi ti ìlú Oyo
Kini o wa n ṣẹlẹ bayii ni fasiti Eko UNILAG?
Ní báyìí à ń dúró de ilé iṣẹ ijọba apapọ tó n ri sí ètò ẹ̀ka gíga ni Nàìjíríà lati kede ohun to kan.
Ogunṣola ni Awọn ẹgbẹ olukọ ati awọn ti kii ṣe ti olukọ ti kọwe atilẹyin pe iṣẹ Ogundipọ tẹ awọn lọrun ranṣẹ si oke bi o ṣe yẹ lẹyin ọpọlọpọ ipade lati ana.
Ati pe, ohun to ṣe pataki julọ ni pe:  à ń reti ki ileeṣẹ ijọba apapọ eto ẹkọ ati ẹgbẹ fasiti Naijiria (NUC) sọrọ lori ohun to n kan laiṣegbe fẹnikan bikoṣe pẹlu ootọ inu.
O fi idi ẹ mulẹ pe agbara wa lọwọ awọn mejeeji ati pe awọn nikan lo le sọ ǹkan ti wọ́n fẹ́, àti pé àwọn níkan ló lé pasẹ ibi ti ọ̀rọ̀ yóò dúró lé.
Ní ti NASU àti ASUU, à ti díbo káre máa bá iṣẹ́ rẹ lọ fún gíwá tó wà níbẹ̀ yìí, nítori náà ẹ̀yìn Ogundipe ni a wà.
Adéle gíwá ti wọ́n ṣẹ̀ṣẹ̀ yàn ko ti i bẹ̀rẹ̀ iṣẹ́. títí di isinyi ti iroyin yii n jade
Oríṣun àwòrán, Joshua Adetunji
Kini o kọkọ ṣẹlẹ?
UNILAG VC: Ọ̀jọ̀gbọ́n Ogundipe ní òun sì ni gíwá UNILAG
Giwa fasiti ijọba apapọ to wa niluu Eko, UNILAG, Ọjọgbọn Olawatoyin Ogundipe ti sọ pe iroyin ofege ni iroyin to tan kalẹ kaakiri pe wọn ti yọ oun nipo.
Akọwe agba fasiti naa, Ọgbẹni Oladejo Azeez lo fi atẹjade kan sita pe igbimọ alaṣẹ fasiti UNILAG ti yẹ aga mọ Ọjọgbọn Ogundipe nidi.
Ṣugbọn ninu esi rẹ si atẹjade ọhun, Ọjọgbọn Ogundipe sọ pe Ọgbẹni Azeez lo mọ ibi ti o ti ri iroyin to n gbe kaakiri.
O ni gidigba loun duro ati wi pe mimi kan lo le mi oun.
Ninu atẹjade ti Ọjọgbọn Ogundipe fi ọwọ si fun ra rẹ, o ṣalaye pe ki gbogbo awọn ti ọrọ fasiti UNILAG kan kọ eti ikun si iroyin ofege ọhun.
Ọjọgbọn Ogundipe fikun ọrọ rẹ pe alakalẹ wa lati yọ giwa fasiti nipo eleyi ti igbimọ alaṣẹ UNILAG ko tẹle to ba tiẹ jẹ pe lootọ ni wọn ti yọ ọ nipo.
Oríṣun àwòrán, Other
Ìgbìmọ̀ aláṣẹ UNILAG yọ gíwá iléewé náà nípò
Igbimọ alaṣẹ fasiti ijọba apapọ to wa niluu Eko, UNILAG ti da giwa fasiti naa, Ọjọgbọn Olawatoyin Ogundipe duro lẹnu iṣẹ.
Igbimọ naa kede idaduro Ọjọgbọn Ogundipe nibi ipade wọn to waye ọfiisi igbimọ to n mojuto ọrọ awọn fasiti ni Naijiria, NUC niluu Abuja.
Ọmọ igbimọ meje dibo pe ki wọn yọ Ọjọgbọn Ogundipe nipo, nigba tawọn mẹrin dibo pe ki wọn fi i silẹ.
Ọmọ igbimọ daba ni tirẹ pe ki wọn ja ewe gbele ẹ fun Ọjọgbọn naa fun igba diẹ.
Ninu atẹjade ti akọwe fasiti naa, Ọgbẹni Oladejo Azeez fi sita, ṣalaye pe igbimọ naa  yọ ọ nipo lori ẹsun aṣẹmaṣe ati iṣowo ileewe kumọkumọ.
Oríṣun àwòrán, Facebook/Oluwatoyin Ogundipe
O ni ẹsun aṣilo ọfiisi ni ẹsun mii ti wọn fi kan Ọjọgbọn Ogundipe eyi to jẹ ki wọn da a duro.
Oríṣun àwòrán, Other
Ọgbẹni Azeez ṣalaye siwaju sii pe igbesẹ igbimọ alaṣẹ naa wa ni ibamu pẹlu ofin to gbe e kalẹ.
Alaga igbimọ naa, Ọmọwe Wale Babalakin lo dari ipade ọhun l'Abuja.
Sextuplet: Àdúrà Ìbùkún ló kú lẹ́yìn ọmọ mẹ́fà yìí- Ifeoma Thelma àti Onyemaechi Chiaka
Ooni ile Ife: Iná sọ láàfín Ọọ̀ni Ilé Ifẹ̀, Ọọ̀ni ilé ifẹ̀ ní kò sí ẹ̀mí tó báa lọ
Oríṣun àwòrán, Ile oodua
Ina sọ ni ile Oodua tii ṣe afin Ọọni ile Ifẹ, Ọba Adeyẹye Ogunwusi l'Ọjọbọ.
Atẹjade kan to jade lati  aafin Ọọni Adeyẹye Ogunwusi fi idi iṣẹlẹ ijamba ina naa mulẹ.
Ile to jona ni aafin naa ni wọn sọ wi pe o jẹ ile Saarun Oodua, ẹni to jẹ ẹṣọ iṣẹdalẹ fun Ọọni ile Ifẹ.
Akomolede ati asa Yoruba: Ẹ wá kọ́ nípa àpòtí ìṣura èdè wa lórí BBC Yorùbá
Bakan naa ni akọwe iṣakoso ileeṣẹ panapana ni ipinlẹ Ọṣun , Fatai Arẹmu pẹlu fi idi ijamba naa mulẹ to si tun ṣalaye pe awọn panapana ti bomi pa ina naa.
Amọṣa Ọọni ni ko si giri lori ina to jo naa nitori pe gbogbo nnkan ṣi wa ni sẹpẹ ati pe ko si ẹmi  to ba iṣẹlẹ ijamba ina naa lọ.
Oríṣun àwòrán, Others
Ooni Ifẹ bu ẹnu ẹ̀tẹ́ lú ètò BBNaija nítorí ó tàbùkù àsà YorubaOoni ti Ile Ife, Oba Adeyeye Ogunwusi, Ojaja II ti ni ki ijọba Naijiria gbekile eto Big Brother Naija, ki wọn si fi eto miran rọpọ rẹ.
Ooni sọ eyi lẹyin ti o gbalejo ẹgbẹ ọdọ National Youth Council of Nigeria ni aafin rẹ to wa ni Ile Ifẹ, ni ipinlẹ Osun.
Ooni to bu ẹnu atẹ lu eto Big Brother Naija naa ni eto naa n fihan pe orilẹ-ede Naijiria ko ni awọn ọdọ to jẹ ọmọluwabi ati oninu irẹ.
Oba Ogunwusi wa rọ ijọba lati wa wọrọkọ fi ṣe ada nipa wiwa eto miran ti yoo safihan asa ati iṣe ni orilẹ-ede Naijiria ati awọn ihuwasi to buyi kun eniyan lawujọ.
"O ni ki wọn pe akọle eto tuntun naa ni ""The Big Nigeria Reality Show"""
"''Eto naa yoo ma a ṣe afihan awọn ọdọ lorilẹ-ede Naijiria ti wọn n sisẹ ọwọ, awọn ọdọ akọṣẹmọṣẹ ati awọn oṣiṣẹ to wa ni awọn ẹka iṣejọba ni Naijiria, lọna ati le de ipele to gajulọ ninu iṣẹ ti wọn yan laayo."""
Sextuplet: Àdúrà Ìbùkún ló kú lẹ́yìn ọmọ mẹ́fà yìí- Ifeoma Thelma àti Onyemaechi Chiaka
Ọọni ṣalaye pe: ''Eyi yoo fun awọn oluworan lanfaani lati le ma a ri wọn gẹgẹ bi awokọṣe ni awujọ.''
Ooni ti ile Ife, Oba Adeyeye Ogunwusi, Ojaja II ni o ṣeni laanu pe lasiko idibo gbogboogbo to waye ni Naijiria ni ọdun 2019, eniyan miliọnu mẹtadinlọgbọn lo jade lati dibo, amọ, eniyan ẹgbẹrun lọna aadọrin lo dibo lasiko eto Big Brother Naija ni ọdun 2019.
Ooni ni eleyii fihan pe awọn ọdọ lorilẹede Naijiria fẹran afẹfẹyẹyẹ ati ohun ti ko ni bun iyi kun iṣẹ ọwọ wọn.
Oba Adeyeye Ogunwusi ni pe gbogbo igba ti oun ba ti sọ iru ọrọ yii, awọn eniyan a fi ṣe awada, wọn a si gbagbe nipa ẹ.
Ooni ti ile Ife, Oba Adeyeye Ogunwusi, Ojaja II  ni iṣẹ gbogbo wa ni lati mu idagbasoke ba awọn eniyan, paapaa ọdọ lorilẹ-ede Naijiria.
Immaculate Okochu: Arẹwà orí ìpolówóo Cold Stone Creamery ṣàgbàkò ikú nínú ìjámbá ọkọ̀ nígbèéyàwó ku díẹ̀
Oríṣun àwòrán, @i_amloveday
Ọkọ afẹsọna ọmọbinrin ti ọkọ akẹ́rù tẹ̀ pa nipinlẹ Eko lọjọ kọkanla, oṣu Kẹjọ, Imaaculate Okochu, ti sọrọ lori iku rẹ.
Ninu ọrọ to kọ si ori ayelujara Instagram, arakunrin naa, Loveday, sọ pe o ṣeni laanu pe arẹwa obinrin naa kagbako iku lasiko yii.
O kọ ọ pe ofifo ni igbeaye oun wa, ki Okochu, to fi ayọ ati idunnu kún.
Obinrin to ṣe iyebiye si mi julọ ti fi mi silẹ. Emi ni mo ṣi gbe ẹ de ibudokọ, nigba to n lọ si ibi'ṣẹ lọjọ naa, lai mọ pe igba ikẹyin ti ao rira niyẹn.
Ọgbẹni Loveday to kọ awọn ọrọ to ba ni lọkan jẹ ọhun sọ pe igbeaye ko le ri bakan naa mọ fun oun lẹyin iku arẹwa obinrin naa.
Bakan naa lo daro pe afẹsọna oun ku nigba ti ayẹyẹ igbeyawo wọn ku diẹ ko waye.
Nigba ti Immaculate Okochu n fi ọpọlọpọ fọto rẹ to rẹwa soju opo ayelujara rẹ lọjọ kọkanla oṣu kẹjọ, ko sẹni to mọ pe arimọ rẹ naa niyẹn.
Ẹni ọdun mẹrinlelogun ni arabinrin Okochu, oun si ni oju arẹwa to wa ninu ikede gbajugbaja ohun mimu amunututu Cold Stone Creamery ko to ṣalabapade iku ojiji ninu ijamba ọkọ to waye ninu sunkẹrẹ fakẹrẹ ọkọ ni agbegbe Lagos Island nipinlẹ Eko lọjọ kejila, oṣu Kẹjọ.
"Gẹgẹ bi ọrẹ rẹ kan, Lucy Ibe ṣe sọ, ""opopona Badore ni o wa ti ọlọjọ de. Bi mo ṣe de họsibitu, mo ri i. Wọn kọkọ gbe e lọ si ti aladani ki wọn to wa gbe e lọ si ileewosan ijọba to wa ni CMS Marina""."
Nigba ti ọrẹ rẹ timọ timọ ọhun, to tun jẹ ẹni to n ba a ṣeto igbeyawo rẹ, n ba BBC sọrọ, o ni oun l'ero pe ileewosan naa ni wọn de ti wọn duro toripe bi wọn ṣe debẹ, o ṣi n gba omi ti wọn so mọ ọ lara ninu buutu ọkọ, ti awọn ileewosan ko si ya si i.
Oríṣun àwòrán, Others
Laarin ago mọkanla owurọ si aago kan ọsan ọjọ Iṣẹgun ni iṣẹlẹ yii ṣẹlẹ si Okochu gẹgẹ bi ọrẹ rẹ Lucy ṣe sọ.
Lucy fi kun un pe ẹni to mu foonu rẹ nibi ti iṣẹlẹ yii ti waye lo pe oun lati sọ fun oun koun to sa lọ sileewosan ti Immaculate Okochu ku si.
Bakan naa ni ọkọ afẹsọna rẹ sọ pe oun gbiyanju lati doola rẹ, ṣugbọn ẹpa ko boro mọ.
Immaculate Okochu to jẹ ọmọ ipinlẹ Delta n ṣiṣẹ gẹgẹ bi alamojuto ni ile itaja Cold Stone Creamery ni Apapa, Eko ṣaaju iku rẹ.
Arẹwa obinrin ọmọ Naijiria yii ni a gbọ pe ọkọ akẹru rọ lu to si mu ẹmi rẹ lọ ni ipinlẹ lẹyin wakati diẹ to ṣẹṣẹ to sọ ọrọ kan loju opo Faacebook rẹ.
Koda Immaculate ti fi ikede idana rẹ pẹlu ọkọ afẹsọna rẹ to pe ni OG (Etomi) sita ninu oṣu kẹta ọdun 2020.
Ọmọ ijọ Christ the King Catholic Church ni agbegbe Ajegunle Apapa ni Immaculate to si ṣi ni baba, laye ati aburo/ẹgbọn ọkunrin l'aye. Iya rẹ ti ku lọdun marun sẹyin.
"Ọlọkan ire ni Immaculate Okochu, eleto igbeyawo rẹ sọ fun BBC.
Fọto bi ọkọ akẹru naa ṣe tẹ Immaculate pa jẹ ohun to ba ni ninu jẹ pupọ.
Awọn ọrẹ rẹ ti tu sori ayelujara ti wọn n ṣelede lẹyin rẹ
Burna Boy Twice as Tall: Ǹkan tí ó yẹ ki o mọ̀ nípa Damini Ebunoluwa Ogulu Rex (Burna Boy) ti orin rẹ̀ lu ìgboro pa báyìí
Oríṣun àwòrán, Burna Boygram
Bí ilẹ̀ ṣe mọ́ lónì ni òkìkí kan lórí ayélujára pé Burna Boy bi ọmọ tuntun.
Ayọ̀ abara tíntín, àwo orin tuntun ni ọmọ ti Burna Boy bí, bí àwọn olólùfẹ́ rẹ ṣe ń ki náà ni àwọn ọ̀rẹ́ àti ojúlùmọ̀ náà ń kíi kú oríire.
Sùgbọ́n, Tani Burna Boy?
Damini Ebunoluwa Ogulu Rex tí gbogbo ènìyàn mọ si Burna Boy ni  a bí ni ìlú Port Harcourt ni ọjọ́ kejì, oṣù keje, ọdún 1991.
Bàbá rẹ̀  jẹ́ òṣìṣẹ ilé iṣẹ́ jórin-jórín, nígbà ti ìyá rẹ̀ Bose Ogulu  jẹ́ ń ṣe iṣẹ́ ògbífọ̀.
Burna Boy dàgbà sí ìhà ìlà-oorun Gúúsù Nàìjíríà tí o sì bẹ̀rẹ̀ iṣẹ́ orin ti o pè ni Fruity Loops.
Ìyá rẹ̀ ló dúro gẹ́gẹ́ bí olùdàrí iṣẹ́ orin to yàn láàyò.
Oba Adedokun Abolarin ti Oke Ila: Ó ya ọ̀pọ̀ tó súnmọ́ mi lẹ́nu bí mo ṣe ń kọ́
Ó lọ sí ilé ìwé girama Corona ní Agbara, láti ibẹ̀ ló gbà lọ sí ìlú ọba níbi tó ti tẹ̀síwájú nínú ẹ̀kọ́ rẹ̀.
Ebunoluwa lọ́ si fásitì Sussex láti kan Media Technology, lẹ́yìn náà ló tú lọ sí fásitì Oxford Brooks nibi tó ti ka Media Communication àti Culture.
Àkójọpọ̀ orin àkọ́kọ́ tí Burna Boy gbé jáde ní ilé ìporin pọ̀ ni o pe àkọ́lé rẹ̀ ni L.I.F.E , ó jáde ní ọjọ́ kejìlá, oṣù kẹjọ, ọdún 2013, sùgbọ́n  o ti kọ́kọ́ gbé àwo kan jáde to pe àkọle rẹ̀ ni Mixtape Burn Identity.
Àkọ́jọpọ̀ to gbé jade náà ta ẹgbẹ̀rún lọ́nà ogójì lọ́jọ ti ó kọ́kọ́ jáde.
Nínú agbo olórín lórílẹ̀ -èdè Nàìjíríà lọ́nìí àkjọ́jọpọ orin náà ni ó wà ní ipò kẹwàá tí o si pe àwọn olórin bi 2face Idibia, M.I Timaya, Olamide, Reminisce àti Wizkid.
Orin Fela Kuti ló pọ̀ nínú àkojọpọ̀ orin Burna Boy  tí wọ́n si dibo pé ki o gba àmì ẹ̀yẹ lọ́dun 2014
Ti se akójọpọ̀ awo orin to le ni mẹ́jọ, yàtọ̀ sí àwọn orín ẹlẹ́yọ kọ̀ọ̀kan, àti àwọn eyi to darapọ̀ mọ́ àwọn ènìyàn láti kọ.
Akọ́mọlédè àti Àṣà lórí BBC Yorùbá: Kọ̀ síi nípa iṣẹ́ tí oúnjẹ ń ṣe lára níbí
Àwọn àmìn ẹ̀yẹ ti Burna Boy ti gbà
Burna Boy ti gba àmì ẹ̀yẹ tó le ni ogún  ti wọ́n sì ti yàn-án fún ọ̀kẹ́ àìmọye omíràn ti kò kẹ́sẹjárí.
Ayẹyẹ      Àmì ẹ̀yẹ tó jẹ́
jkkkkk
Peers of Heaven: Ààrẹ ẹgbẹ́ Emèrè ní àwọn ti wà tipẹ́, wọn kò pariwo síta ni
Oríṣun àwòrán, Others
Ẹgbẹ Emere ti wa tipẹ, a ko kan pariwo sita ni, paapa laarin awọn oniṣẹ'ṣe."""
Eyi nikan ti Oloye Oyelola Elebubon sọ fun BBC Yoruba lori ajọdun ẹgbẹ naa to waye laipẹ yii.
"O ni ""Ẹgbẹ yii bẹrẹ lati ara pe awa ti a jẹ ọmọ ẹgbẹ ma n ba ara wa pade ni ode tabi ariya. Ṣugbọn ẹru ma n ba wa lati sọ pe nkan bayii ni a jẹ. A si ma n pe ara wa ni ẹgbẹ ooṣa."""
O ni ọdun mejila sẹyin ni oun gba imisi lọdọ awọn ẹgbẹ pe ki oun ma a polongo nipa awọn ẹlẹgbẹ ọrun.
"O ṣe pataki ki awọn eeyan mọ pe ""a o ki n ṣe ọmọ buruku. Awa naa le ṣe daada."""
Oríṣun àwòrán, others
Elebuibon ni Ọjọbọ ni awọn ma n ṣe ipade ni aago mejila ọsan si lawọn ma n bẹrẹ ipade
Nibi ipade naa, a ma n gba awọn adura to gbona gidigidi. Awọn eeyan ma n mu ẹbẹ adura wa fun awọn ẹbi wọn. Adura naa ma n gba, wọn n jẹri.
"A ma n da ara wa mọ laarin eero. Nkan ti a fi ma n ki ara wa ni pe "" Elére ọmọ! Ẹnikeji yoo si dahun pe, ""Onitẹsiwaju""."
"Ṣugbọn ilẹkẹ ọwọ la fi ma n da ẹni to ba ni ooṣa ẹgbẹ sile. A o ki ẹni naa pe ""A kii ka o! Oun naa yoo dahun pe  ""Aṣẹẹjẹ o. "" A o si jọ sọ papọ pe ""bọlọhun fẹ, oju o ni wa a ti""."
Oríṣun àwòrán, others
Aarẹ ẹgbẹ Emere ni ko dara bi awọn ile ijọsin ṣe ma n fi igbalẹ na awọn elere ọmọ lati le wọn kuro ninu ẹgbẹ.
O ni awọn fẹ ki araye mọ pe ki wọn mase ya ẹgbẹ mọ. O ni ti wọn ba ṣe bẹ ẹ, wọn n le ire, ayọ ati ibukun jinna si ọmọ naa ni.
Lati ọjọ pipẹ ni ọrọ oṣo, ajẹ ati emere ti ma n jẹyọ ni aarin awọn ọmọ Yoruba, ati kaakiri ilẹ adulawọ.
Awọn elede Gẹẹsi si maa n pe wọn ni witches and wizards.
Ṣugbọn, o ṣeeṣe ki ọpọ eeyan ma mọ iyatọ to wa laarin awọn ẹgbẹ mẹtẹẹta.
BBC Yoruba ba Araba ilu Oṣogbo to tun jẹ onimọ nipa aṣa ati ẹsin adayeba nilẹ Yoruba, Oloye Yẹmi Ẹlẹbuibọn, sọrọ lati jẹ ka mọ iyatọ laarin awọn eeyan mẹtẹẹta naa.
Gẹgẹ bi o ṣe sọ, o ni iyatọ wa laarin oṣo, ajẹ, ati emere.
Ni ibẹrẹ pẹpẹ, ọmọ eniyan lo dalẹ, eyi to mu ki awọn ajẹ binu.
Adehun ti awọn ajẹ ṣe nigba ti wọn n bọ si aye ni pe, gbogbo eeyan yoo ma a gbe pọ ni alaafia, ṣugbọn, ọmọ eeyan lo kọkọ yẹ adehun.
Awọn ọmọ eeyan ma n lẹ oko mọ ọmọ ẹyẹ, wọn ma n pa wọn.
Eyi lo mu wọn fi ẹjọ sun Olodumare.
Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo
Éníyán la n pe awọn ìyà mi, ènìyàn ni a n pe ọmọ ènìyàn.
Bi wọn ṣe fi ẹjọ sun yii, mu ki Olodumare ni oun yoo ran ikọ kan lati wo nkan to n ṣẹlẹ.
Awọn ọmọ eniyan mọ pe awọn ti ṣe nkan ti ko tọ ọ,  eyi to mu wọn lọ ke ba awọn ti yoo gba wọn silẹ.
Wọn de ọdọ babalawo kan ti orukọ rẹ n jẹ Abẹ. Oun lo si gba wọn ni imọran lati mu adiyẹ meji to jẹ kan naa wa a.
O la adiyẹ naa si meji, wọn si ki ẹnu wọn bọ ara wọn.
Blind DJ: Etu Omotayo kò ríran àmọ́ ó le to irinṣẹ́ eléré pọ̀ láti kọrin láì sí ìrànwọ́
Wọn gbe sinu awo amọ, wọn si lọ gbe si bebe odo.
Ninu irinajo iranṣẹ olodumare, àpèrè ayọrunbọ ni yoo gun wa si aye, eyi to dabi ẹlikọpita laye ode oni.
Bibalẹ ti àpèrè rẹ balẹ sile aye, bebe odo ti awọn ọmọ eeyan gbe ẹbọ si lo balẹ si i.
Riri to ri ẹyẹ meji ti wọn gbe sibẹ - to ti ku, to ki ẹnu bọ ara wọn l'ẹnu, pẹlu iyẹ wọn to fọn kaakiri ilẹ, o ro ninu ara rẹ pe, a jẹ pe ẹyẹ lo n ba ara wọn ja.
Abọ yii lo jẹ fun Olodumare, pe awọn ẹlẹyẹ naa lo n pa ara wọn.
Eyi mu ki awọn ọmọ eniyan tun ma a ba iwa ọdalẹ wọn lọ.
Osun Osogbo: Ọdọọdún ni Àtáója ń gbàlejò gbogbo arugbá lásìkò ọdún Ọ̀ṣun Òṣogbo
Ni awọn ìyà mi naa ba tun pada si ọdọ Olodurmare lati fi ẹjọ sun. Olodumare sọ fun wọn pe ọtọ ni iroyin ti ikọ oun mu wa.
Lo ba fun wọn ni imọran pe ki awọn naa o ma a na ẹni to ba le wọn, bu ẹni to ba bu wọn, pa ẹni to ba pa wọn.
Bi awọn ìyà mi gba aṣẹ niyi, ti wọn si bẹrẹ si i da ọmọ eeyan laamu - ori ffiọ, inu rirun, iṣẹ ti ko lọ deede, wọn n mu ẹjẹ wọn, ati bẹẹbẹẹ lọ.
Nigba ti ara ni awọn ọmọ eeyan, wọn lọ ọ fi ẹjọ sun olodumare, ṣugbọn o sọ fun wọn pe ko si nkan ti oun le ṣe si, nitori awọn lo kọkọ dalẹ, to yẹ adehun.
Ṣugbọn Olodumare kọ wọn ni ọgbọn pe, etutu ati ẹbọ riru ni ọna abayọ - lilo iyọnu tabi ẹbẹ awọn ajẹ.
Idi niyii ti ọmọ eeyan fi ma n ṣe iyọnu awọn ajẹ, ki wọn o ma ba a da wọn laamu mọ.
Odu ifa to ba jade ni yoo sọ nkan ti yoo wa ninu ẹbọ ajẹ. O le jẹ okete, akika, awọn nnkan inu ẹran bi ifun, ati ẹdọ, o si le jẹ ẹyin adiyẹ.
"Oloye Ẹlẹbuibọn sọ pe ọrọ naa dabi orin Yoruba kan to sọ pe ""iya lo jẹ iya agba, to ko owo lọ ọ ra ajẹ."""
O sọ pe ẹlomiran ma n ti itori pe oun fẹ ẹ gba ẹsan, ko lọ ọ gba ajẹ. Iya ma n fun ọmọ rẹ ni ajẹ, ẹlomii si wa to yẹ pe lati ọrun lo ti gba ajẹ.
Yoruba Culture: ọjọ́ méje ni wọ́n fí n rẹ ẹ̀kú Danafojura kó tó jáde
Yatọ si ti ajẹ, ọrun ni wọn ti ma n ya emere, wọn kii fun yan. Idi si niyii ti ifa fi ṣaba ma n sọ pe ki iru wsn o fẹ babalawo gẹgẹ bi ọkọ, fun amojuto.
Ifa ni olugbala wọn, nitori ẹ si ni wọn ti ma n pe ifa ni Ọdundun, ti i du ori elemere.
Tọkunrin-tobinrin lo ma n jẹ emere, ṣugbọn obinrin lo pọju ninu wọn.
'Àwa Emèrè Onítẹ̀síwájú la ṣèpàdé nílé Elebuibon, kìí ṣe Oṣó àti Àjẹ́'
Oríṣun àwòrán, others
Alaye ni ẹkunrẹrẹ ti n waye lori ipade kan to waye laipẹ yii nile Oloye Ifayemi Elebuibọn ninu eyi ti wọn ni awọn Oso ati Ajẹ peju si.
Bẹẹ ba gbagbe, irọlẹ ọjọ Ẹti la kọkọ mu iroyin wa fun yin pe awọn Oso ati Ajẹ naa se ipade nilu Osogbo nile baba Awo, Elebuibon.
Sugbọn alaye miran to yọju sita lọjọ Aiku lo sisọ loju rẹ pe, ẹgbẹ awọn Emere onitẹsiwaju lo se ipade, kii se ẹgbẹ awọn Oṣo ati Ajẹ, gẹgẹ bi iroyin ti gbe sita.
Ninu alaye rẹ fun BBC Yoruba, alakoso ẹgbẹ awọn Emere Onitẹsiwaju lọrun, ti wọn pe ni Progressive 'Peers of Heaven' Society, Oloye Oyelola aya Elebuibon ni iroyin to ni awọn ajẹ lo se ipade ko ri bẹẹ.
Blind DJ: Etu Omotayo kò ríran àmọ́ ó le to irinṣẹ́ eléré pọ̀ láti kọrin láì sí ìrànwọ́
"O ni "" Awa Emere kii se Ajẹ abi Oṣo amọ ẹlẹgbẹ ọrun ni wa."""
Aya Elebuibon fikun pe, lootọ ni awọn se ipade ajọdun akọkọ nile Araba awo nilu Osogbo, nibi ti Baba Awo Ifayemi Elebuibon to bawọn sọ ọrọ apilẹkọ.
Gẹgẹ bi Oloye aya Elebuibon ti wi, ẹgbẹ Emere Onitẹsiwaju ti n sisẹ kara lati se amulo awọn abuda rere to wa ninu ọmọ ẹgbẹ kọọkan fun isẹ rere.
Oríṣun àwòrán, others
O fikun pe awọn abuda rere naa ni wọn yoo lo fun idagbasoke awujọ wa ati orilẹede Naijiria lapapọ.
Gbajugbaja onimọ nipa iṣegun ibilẹ nilẹ Yoruba, to tun jẹ Araba nipinlẹ Oṣun, Ifayemi Elebuibon, ti gba ipade nla ajọdun ayẹyẹ apapọ ẹgbẹ awọn oṣo ati ajẹ.
Nibi ipade yii ni onimọ iṣegun ibilẹ naa ti fi ọrọ lede pe, itajẹsilẹ lewu pupọ fun idagbasoke orilẹ-ede yii.
Nigba to n ba ipejọpọ naa sọrọ lọjọbọ, eyi to jẹ akọkọ iru ayẹyẹ bẹẹ ti ẹgbẹ itẹsiwaju awọn ajẹ ati oṣo ipinlẹ Oṣun yoo se, Elebuibọn rọ ijọba apapọ lati tete wa wọrọkọ fi ṣada, lori ipaniyan to n waye lorilẹede Naijiria.
O ni ki wọn ṣe eyi ki ibinu Ọlọrun to sọkalẹ sori orilẹede yii.
Gẹgẹ bi baba onifa yii ṣe sọ ọ, wọn gbudọ tọwọ iwa ipaniyan lemọ lemọ to n waye ni iha Ariwa orilẹ-ede yii bọlẹ.
Bakan naa lo ni iwa ipaniyan lati fi eeyan ṣoogun owo ni iha Guusu Naijiria gbọdọ dopin, ki abamọ ma ba a gbẹyin rẹ.
O tun gba awọn onimọ iṣegun ibilẹ nimọran lati mọ daadaa nipa ẹsin wọn, ki wọn ma si faaye gba ọrọ ti ko ba ba ohun ti wọn n ṣe mu.
Elebuibon tun rọ wọn ki wọn wa ni iduro deede ati ṣiṣe ododo pẹlu awọn eeyan lati jẹ eeyan ire lawujọ.
O ni gbogbo ẹda alaaye lo ni ẹgbẹ ọrun kan tabi omiran ti wọn n ṣe, o si tẹnu mọ ọ pe, mimọ ẹgbẹ ẹni daadaa ati ṣiṣe ifẹ inu wọn, maa n ran irinajo ẹda laye lọwọ.
"Iye itajẹsilẹ ati ifiniṣẹṣo owo ni Naijiria n kọ ni lominu.
Ki ijọba ni gboogbo ipele mu opin wa si eyi, ki Eleduwa to rọjo ibinu rẹ le orilẹede lori.
Mo rọ ẹyin ajẹ ati oṣo ki ẹ maa gbe igbe aye ododo, eyi ti wọn mọ awọn oniṣegun ibilẹ fun, ki ẹ si jẹ ki ẹsin awọn baba nla baba wa ṣe atunṣe ọna yin pada tori ohun nikan lo lee daabo bo iru eeyan ti ẹ jẹ lagbaye."
Oríṣun àwòrán, others
Ninu ọrọ rẹ, Oloye Arabinrin Oyelola Elebuibon sọ wi pe pataki ipade naa ni lati fihan gbogbo agbaye pe, jijẹ oṣo tabi ajẹ kii ṣe nkan ibi, gẹgẹ bi awọn ẹlẹsin kan ṣe n wo o.
O ni bi wọn ba lo awọn agbara to wa ninu rẹ daadaa, o lee mu ayipada rere ba imọ ẹrọ orilẹ-ede kan, ko si tun gba ogo wọn pada fun idagbasoke.
O wa parọwa lapapọ pe ki ijọba Naijiria mojuto eto aabo awọn ara ilu lasiko yii nitori bi ọrọ ṣe n lọ yii ko dara to.
The Polytechnic Ibadan: Ẹ̀rọ abẹ́lé tó ń fọ ọwọ́ àti ‘Ventilator’ ló ṣẹ̀ṣẹ̀ gbé jáde
Lafikun, o rọ awọn ọmọ ẹgbẹ Oso ati Ajẹ lati ni ifarajin ninu ilu pẹlu bi ohun gbogbo ṣe le to.
O ni rinrin deede ati ṣiṣe ododo ni ko jẹ koko ọrọ wọn ni gbogbo igba.
Internet Fraud: Iléẹjọ́ ní kí ''Yahoo boy'' lọ darí ọkọ̀ f'óṣù mẹ́ta lẹ́yìn tó tan obìnrin òyìnbó jẹ
Oríṣun àwòrán, Facebook/EFCC
Ileẹjọ giga kan niluu Ilorin nipinlẹ Kwara ti dajọ wi pe ki ọkunrin kan, ọmọ ọdun mẹtalelogun lọ dari igboke-gbodo ọkọ fun oṣu mẹta, lẹyin to jẹ ẹsun ilujibi ori ayelujara.
Adajọ Sikiru Oyinloye tun paṣẹ fun Kolade Emmanuel Balogun pe ki o san ẹgbẹrun un lọna aadọta naira gẹgẹ bi owo itanran lẹyin to jẹbi ẹsun ti ajọ EFCC fi kan an.
Lati ọjọ kẹtadinlogun oṣu kẹjọ ọdun 2020 yii ni ileẹjọ so pe ki Balogun bẹrẹ si ni dari igboke-gbodo ọkọ lẹyin ileeṣẹ ijọba to n ri kikọ ile si ilu.
L'Ọjọbọ, ọjọ kẹtala, oṣu kẹjọ ni EFCC fi ẹsun onikoko kan ọmọkunrin naa pe purọ pe ara rẹ ni Ọgbẹni William Davis ti inagijẹ rẹ n jẹ Behemooth lati tan obinrin alawọfunfun kan jẹ lori ẹrọ ayelujara.
Agbẹjọro fun ajọ EFCC, Aliyu Adebayo ileẹjọ lati fiya to tọ jẹ Balogun nitori ohun to ṣe tako ofin orilẹede Naijiria.
Amọ agbẹjọro ọmọkunrin naa, Rotimi Oyagbola rawọ ẹbọ si ileẹjọ lati fi oju aanu wo ọdọkunrin naa nirori igba akọkọ ree ti yoo ṣe iru nnkan bẹẹ.
Ṣugbọn, Adajọ ni ko si awawi kan fun Balogun nitori ẹri to daju wa wi pe o jẹbi ẹsun ti wọn fi ka an.
Mr Macaroni sọ nípa eré tí Fraky freaky, Sugar Daddy, You are doing well, freaky spicy fẹ́
Adajọ Oyinloye tun paṣẹ pe ki wọn gba ẹrọ ibanisọrọ ati ẹrọ kọmputa ti ọmọkunrin naa n lo lati lu awọn eeyan ni jibiti lori ayelujara, ki wọn si ko fun ijọba apapọ.
jkkkkk
Yoruba Films: Ireoluwa ṣ'ọjọ́-ìbí, Mide àti ọkọ rẹ̀ lẹ̀pọ̀, Iyabo Ojo f'aṣọ ilẹ̀ Afirika dárà
Oríṣun àwòrán, Instagram
Ọjọ nii pẹ, ipade kii jinna. N jẹ ẹ mọ pe ọmọ ti Ọlọrun fi ta idile Toyin Abraham ati ọkọ rẹ lọrẹ ti ṣ'ayẹyẹ ọjọ ibi ọdun kan.
Eyi ni awọn ohun to ṣẹlẹ lagbo awọn oṣere tiata lọsẹ yii.
Toyin Abraham
Bi ọmọde o ku, agba ni i da. Ire Oluwa, ọmọkunrin lanti-lanti ti Eleduwa fi jinki idile gbajugbaja osẹre, Toyin Abraham ati ọkọ rẹ, Kolawole Ajeyemi ti pe ọdun kan.
Ọjọ kẹtala oṣu kẹjọ ọdun 2020 yii naa ni Ire pe ọmọ ọdun kan loke eepẹ, eyi ti awọn obi rẹ fi n dupẹ lọwọ Eleduwa ti O da ọmọ naa si i.
Kolawole pẹlu aya rẹ Toyin lo fi aworan ọmọ naa sori oju opo Instagram wọn nibi ti wọn ti ọrọ iṣiti ati idupẹ lori ọjọ ibi Ire Oluwa.
Mide Martins
Mide Martins ati ọkọ rẹ, Afeez Owo lẹ pọ ninu sinima ti akori rẹ n jẹ ''SALAWA.''
Aworan Mide ati Afeez Owo lo han gbagada lori paali sinima ''SALAWA'' naa.
Sinima naa da lori ọmọbinrin kan, ''SALAWA'' to sọ ara rẹ nu, to gbagbe ile. Ẹkunrẹrẹ wa ninu sinima ọhun.
Wumi Toriola
Yoruba bọ, wọn ni bi ile da bi ko da, awọ ni ẹ wo. Eyi lo mu ki oṣere Wumi Toriola jawe s'obi ninu fọto to fi si oju opo Instagram rẹ.
Wumi ṣalaye pe o ṣe pataki fawọn ọdọmọbinrin lati ni aṣọ to juju n gbese eyi to yoo maa mu wọn ri bi ọmọ kekere ni gbogbo igba.
O fikun ọrọ rẹ pe niwọn igba ti obinrin to ba ti n dagba ko le lanfaani lati di ọdọmọbinrin pada, o ni wiwọ aṣọ to ba igba mu lọna miiran ti obinrin fi le da bi ''ayọngẹ.''
Iyabo Ojo
Aṣa ilẹ Afirika ni Iyabo Ojo gbe larugẹ lọsẹ yii loju opo Instagram rẹ.
Niṣe ni gbajumọ oṣere Iyabo ko sinu aṣọ alaranbara to ni awọ dudu ati funfun ninu eyi to ti n ṣakọ ninu fọto to ya.
Oriṣii ara ni Iyabo da ninu aṣọ to wọ ọhun, bi o ṣe n yanu si atẹgun lo tun duro siwaju ile awo dami ẹnu kan to fi ya fọto.
Lanre Rasak: Èàkàn ẹgbẹ́ òṣèlú APC mií Lanre Rasak dágbére fáyé
Oríṣun àwòrán, Other
Eekan ẹgbẹ oṣelu APC nipinlẹ Eko, Lanre Razak ti jade laye lẹni ọdun mẹrinlelaadọrin.
Iroyin to tẹ wa lọwọ ni pe Ọgbẹni papoda lọjọ Abamẹta ọjọ kẹẹdogun oṣu kẹjọ ọdun 202o yii lẹyin aisan ranpẹ.
Nigba aye rẹ, Ọgbẹni Razak wa ninu igbimọ to n gba gomina ipinlẹ Eko lamọran.
Ọgbẹni Rasak kọkọ fi erongba rẹ rẹ han lati dije fun ipo ṣenẹtọ lẹkun ila oorun ipinlẹ Eko ki o to yọwọ nibẹ ṣaaju ibo abẹle.
Ọjọ Aiku ọjọ kẹrindinlogun oṣu kẹjọ yii ni wọn yoo ṣin Ọgbẹni Rasak ni ilana ẹsin musulumi.
Omotola Jalade Ekeinde: Òjòjò Covid-19 ló mú mi, mò ń gba ìtọ́jú lọ́wọ́
Oríṣun àwòrán, Facebook/Omotola Jalade Ekeinde
Ọrọ arun coronavirus to n ba gbogbo aye finra ko mọ olowo, bẹẹ ni ko mọ talaka, koda ko mọ ọmọde, ko mọ agba.
Arun naa tun ti mu gbajugbaja oṣere tiata, Omotola Jalade Ekeinde, to si kede loju opo Twitter ati Facebook rẹ pe, ojojo arun ọhun ni ko jẹ ki oun yọju sita lati ọjọ yii wa.
Ekeinde ṣalaye pe ohun ti wa ni iyasọtọ lẹyin ti oun lugbadi aarun naa, ara oun si n ti n pada bọ sipo diẹdiẹ bayii.
O ṣeleri lati maa sọ fawọn ololufẹ rẹ, bi ara rẹ ba ti n ṣe sii looree kooree.
Ẹwẹ, ọgọọrọ awọn ololufẹ Ekeinde ni wọn gbadura fun ilera to peye fun un, wọn ni laipẹ lai jina, Eleduwa yoo mu un lara da.
Awọn miiran tun gbadura pe Omotola ni yoo bori coronavirus, wọn covid-19 ko ni rẹyin rẹ.
Omotola ni oun ko ṣai gbọ iroyin bi ọkọ tirela ati apoti ikẹru ti wọn n pe ni ''container'', ti n ṣeku pa awọn ọdọ niluu Eko.
Omotola sọ pe, ohun to buru jai ni iru iṣẹlẹ yii, o wa ke si Gomina Babajide Sanwo-Olu lati wa nnkan ṣe si ọrọ awọn ọkọ tirela to da ẹmi awọn araalu, papaajulọ awọn ọdọ, legbodo.
Gbajumọ oṣere naa ni adura ti onikaluku maa n gba naa ni pe, ki aburu maa ṣẹlẹ si ẹnikọọkan, ṣugbọn o ni ko si ẹni ti iru iṣẹlẹ bẹẹ ko le ṣẹlẹ si i.
Ondo Regent: Adelé Falowo ní òun ń fojú sọ́nà láti ṣe ìyàwó alárédè lẹ́yìn tí òun bá ipò sílẹ̀
Oríṣun àwòrán, Facebook/Moyinoluwa Falowo
Adele Ọba ilu Ibulesoro nipinlẹ Ondo, Regent Moyinolouwa Falowo sọ pe, jijẹ adele ọba ko di ibaṣepọ to wa laarin oun ati ọrẹkunrin lọwọ.
Moyinoluwa ẹni ọdun mẹrindinlọgbọn ṣalaye pe, niwọn igba ti oun si wa lori itẹ baba oun, aṣa ati iṣe ilu Ibulesoro ko gba oun laaye lati lọkọ tabi ṣe abiyamọ.
Amọ, Moyinoluwa sọ pe oun si n foju sọna lati ṣe iyawo alarede, ni kete ti oun ba ti pari iṣẹ oun gẹgẹ bi Adele, ti ọba miiran si gori itẹ.
Adele Ọba Ibulesoro ni, ipo oun ko jẹ iyalẹnu fun afeṣọna oun nitori oun ti ṣalaye fun tẹlẹ pe, oye Adele le yi kan oun ti baba oun ba papoda.
Moyinoluwa fikun ọrọ rẹ pe, oun ko gbọdọ gbe ohunkohun le ori oun tabi ki oun ṣi ori ṣilẹ, koda oun ko gbọdọ kunlẹ niwaju ẹnikankan mọ, niwọn igba t'oun wa lori oye gẹgẹ bi adele.
Oríṣun àwòrán, Facebook/Moyinoluwa Falowo
Adele Oba Falowo ni oye naa ti jẹ ki oun mọ ọpọlọpọ nnkan ti oun ko mọ tẹlẹ, nipa aṣa ati iṣe ilẹ Yoruba.
O ni wiwọ aṣọ ọkunrin ko jẹ nnkan to jọju f'oun nitori ohun to wa ninu aṣa ni wi pe, ọkunrin ni adele tabi ọba to wa lori tẹ gbọdọ jẹẹ.
Amọ, Moyinoluwa sọ pe, bi awọn agbalagba ṣe maa n kunlẹ tabi dọbalẹ fun oun kọkọ ri bakan lara oun, nigba ti oun ṣẹṣẹ jẹ oye naa.
Ṣugbọn bayii, o ni tayọ tayọ loun maa fi n ki awọn to ba n ki oun nitori oun mọ pe, ori ade ni wọn n bọwọ fun un, kii ṣe oun gẹgẹ bi ẹnikan.
The Polytechnic Ibadan: Ẹ̀rọ abẹ́lé tó ń fọ ọwọ́ àti ‘Ventilator’ ló ṣẹ̀ṣẹ̀ gbé jáde
Adele Falowo tun sọ pe, ni ọpọ igba lawọn ojuṣe kan gẹgẹ bi Adele maa n tako igbagbọ oun gẹgẹ bi onigbagbọ ati ọmọlẹyin Kristi.
Amọ, o ni oun maa n yanju rẹ ni itubi inubi pẹlu awọn agbaagba oloye afọbajẹ laisi ikunsinu kankan.
Adele Ọba Ibulesoro ṣalaye pe, sisọ aṣa nu lo n ṣe okunfa iwa ifipabanilopọ to n gogo sii ni Naijiria bayii.
Alaafin: Olori Aanu Adeyemi ṣàlàyé ìdí tó ṣe gẹ́ Oba Lamidi Adeyemi ti ìlú Oyo
O ni ti aṣa ba ti sọnu, yoo jẹ ki rukerudo atawọn iwa ibajẹ maa pọ si lawujọ wa.
The Polytechnic Ibadan: Ẹ̀rọ abẹ́lé tó ń fọ ọwọ́ àti ‘Ventilator’ ló ṣẹ̀ṣẹ̀ gbé jáde
Oriire ti de fun orilẹede Naijiria lati ipasẹ agbekalẹ erọ tuntun meji ti ile ẹkọ gbogbonse Poly Ibadan gbe jade.
Ẹrọ akọkọ ni ẹrọ ifọwọ mẹtadọkan, eyi to n tẹ omi ati ọṣẹ sọwọ eeyan fun ra rẹ, ti yoo si tun tẹ afẹfẹ si ọwọ eeyan lẹyin taa ba fọ ọwọ wa tan.
Ẹrọ keji ni ẹrọ Ventilator, to n seranwọ lati jẹ ki alaisan lee mi jalẹ daadaa.
Nigba to n sọrọ lori idi ti ile ẹkọ Poly Ibadan fi se agbekalẹ awọn ẹrọ mejeeji naa, Alhaji Soladoye Adewole, tii se osisẹ alukoro agba fun ile ẹkọ naa ni ọna lati se ohun ti yoo seranwọ nidi itọju arun Coronavirus lo sokunfa rẹ.
Bakan naa lo ni wọn se tun se awọn ẹrọ ọhun lati seranwọ fun araalu ni lasiko ajakalẹ arun Coronavirus yii.
Ile ẹkọ Poly Ibadan ni oun ti gbe ẹrọ Ventilator fun ayẹwo nile ẹkọ Poly Ibadan, ti wsn si ni o n sisẹ bo se yẹ.
Anthony Obiagbaoso Enukeme: Àkójọpọ̀ àwòrán àràǹbarà nípa ìsìnkú ọlọ́rọ̀ ọmọ Nàíjíríà
Anthony Obiagbaoso Enukeme ni alaṣẹ agba fun ileesẹ elepo rọbi Tonimas oil, ọmọ bibi ipinlẹ Anambra nii se.
Oríṣun àwòrán, ABS
Ijọ aguda James mimọ to wa ni Neni ni wọn ti se isin ikẹyin fun oloogbe Anthony Obiagbaoso Enukeme, awọn Bisọọbu agba meji si lo lewaju isin ikẹyin naa.
Oríṣun àwòrán, ABS
Opin ọsẹ yii ni wọn sin Anthony Obiagbaoso Enukeme nilu rẹ, Neni tilu tifọn pẹlu posi olowo iyebiye ti wọn lo to miliọnu mẹrinlelọgbọn naira
Oríṣun àwòrán, ABS
Ọjọ kẹsan osu Kẹfa ọdun 2020 ni Anthony Obiagbaoso Enukeme jade laye, ti wọn si sin lọjọ Ẹt, ọjọ Kẹrinla osu kẹjọ ọdun 2020 tilu tifọn
Oríṣun àwòrán, ABS
Anthony Obiagbaoso Enukeme ni wọn se ayẹyẹ isisnku ọlọjọ meji fun, eyi to dun, to si larinrin
Oríṣun àwòrán, ABS
Anthony Obiagbaoso Enukeme jade laye lẹni ọdun mẹrindinlọgọrin lawọn ara ilu rẹ fẹran rẹ tori o maa n ko awọn olokoowo wa dale isẹ silẹ milu abinibi rẹ.
Oríṣun àwòrán, ABS
Anthony Obiagbaoso Enukeme wọlẹ lọ pẹlu oriyin nla lati ọdọ awọn eeyan ilu rẹ, atawọn oloselu
Oríṣun àwòrán, ABS
Lara awọn eeyan jankan jankan to peju sibi isinku Anthony Obiagbaoso Enukeme ni gomina ipinlẹ Anambra, Willie Obiano
Oríṣun àwòrán, ABS
Posi awodamiẹ́nu naa ree, to n wọ ẹsẹ mẹfa lọ, eyi ti yoo gbe Anthony Obiagbaoso Enukeme re ile ayeraye
Oríṣun àwòrán, ABS
Iroyin kan ni miliọnu mẹrinlelọgbọn naira ni wọn fi ra posi ti wn sin Anthony Obiagbaoso Enukeme si
Oríṣun àwòrán, ABS
Iyawo ati awọn ọmọ lo n selede tẹyinse fun Anthony Obiagbaoso Enukeme
Oríṣun àwòrán, ABS
Awọn agba bisọọbu ijọ aguda meji lo lewaju isinku fun Anthony Obiagbaoso Enukeme
King of Bahrain robot bodyguard: Wo ohun tó yẹ kí o mọ̀ nípa ‘rọ́bọ́ọ̀tì Ọba Bahrain’
Oríṣun àwòrán, Screenshot
Awọn kan ti sọ ṣaaju pe Ọba Bahrain niyii pẹlu rọbọọti naa
Ẹnu ọjọ mẹta yii ni fidio kan gba ori ayelujara kan, eyi to sọ pe Ọba orilẹ-ede Bahrain ṣabẹwo si Dubai pẹlu rọbọọti kan to jẹ ẹṣọ alaabo rẹ.
"Akọle fidio ọhun sọ pe ""Ọba Bahrain, Hamad bin Isa Al Khalifa wọ orilẹ-ede Dubai pẹlu rọọbi to fi n ṣe ẹṣọ."""
Akọle miran ni, ẹṣọ naa ni ẹrọ ayaworan ọọdunrun le lọgọta lara, to si le e sọ ede mẹfa ọtọọtọ, bẹẹ lo tun ni ibọn ilewọ.
Koda, awọn iroyin kan sọ pe, o ni ohun ija to pọ lara to bẹẹ to fi le e ba ẹgbẹrun le aadọta eeyan ja, ṣugbọn ko si ootọ ninu iroyin naa rara.
Ohun ti a mọ nipa fidio naa ree:
"Ọjọ kẹrinla, oṣu Keji, ọdun 2019 ni wọn fi fidio naa si ori ikanni YouTube, pẹlu akọle pe ""rọbọọti to ga ni iwọn ẹṣẹ bata mẹjọ ki awọn eeyan ni UAE."""
Oríṣun àwòrán, YouTube Screeshot/ Dubai17
ileeṣẹ Cyberstein Robots, nilẹ Gẹẹsi lo si ṣe e
Ninu fidio ọhun ni rọbọọti naa, ti orukọ rẹ n jẹ Titan, ti ki awọn eeyan, to si tun darukọ ara rẹ ni ilu Abu Dhabi.
Lara awọn ileeṣẹ iroyin to lami laaka to ti gbe iroyin nipa rọbọọti ọhun jade lọdun 2019 ni Khaleeji Times ati Gulf News.
Ṣaaju asiko naa, rọbọọti ọhun lọ si ipade ita gbangba awọn to n ri si eto abo ni Abu Dhabi ni oṣu Kẹta ọdun 2018.
Ki ni wọn n fi rọbọọti naa ṣe?
Titan ni rọbọọti akọkọ lagbaye ti wọn fi n da awọn eeyan laraya, ileeṣẹ Cyberstein Robots, nilẹ Gẹẹsi lo si ṣe e.
O ga ni iwọn ẹsẹ bata mẹjọ, oju rẹ si da bii agbari, koda awọn eeyan kan n fi ṣapejuwe rọbọọti Transformer to wa ninu sinima agbelewo kan.
Oríṣun àwòrán, YouTube Screeshot/ Dubai17
Titan ti da awọn eeyan laraya ni oniruru awọn ayẹyẹ kaakiri, bii ere idaraya agbaye Commonwealth.
Ohun pato ti wọn ṣe rọbọọti ọhun fun, ni ko maa da awọn eeyan laraya lodi si iroyin to gbode pe, ẹṣọ alabo Ọba Bahrain lo ni, ati pe o ni ohun ija ogun lara.
Risikat Moromoke Azeez: Inú èmí àti Òbí mi dùn nígbà ti Risi bí ọmọ olójú búlù- Wasiu
Sunday Shodipe: Ilé ẹjọ́ fi Sunday Shodipe, afurasí ìṣekúpani l'Akinyele pamọ́ sí ọgbà ẹ̀wọ̀n
Oríṣun àwòrán, oyo nsight.com
Àwọn aládugbò ṣàlàyé bí Sunday Shodipe ṣe pa Funmilayo tó pa kẹ́yìn l' Akinyele.
Leyin ti ọwọ tẹ Shodipẹ, fun ẹsun ipaniyan ni ṣisẹntẹle ni agbegbe Akinyẹle ni ilu Ibadan, okiki kan nigba ti awọn agbofinro kede pe o tun ti salọ mọ wọn lọwọ.
Ohun to ba ọpọ ninu jẹ julọ ni pe kani ko sa mọ ọlọpaa lọwọ ni, Funmilayọ to pa kẹyin i ba ṣi wa laye.
Ni kete ti o kuro ni agọ ọlọpaa, lo lọ dara pọ mọ awọn ajegbọrọ lọja Elewure lagbegbe Moniya.
Awọn eeyan oja naa ni awọn n rii gegebi ọkan lara awọn to n ba wọn ko agbo ninu ọja naa.
Koda awon kan ni awọn tilẹ ṣi rii ni ọjọ to pa arabinrin naa ṣugbọn ko si ẹni to rokan pe irufẹ ọdaran bẹẹ lee tun bọ mọ ọlọpaa lasiko naa.
Awọn alabagbe Funmilayo ni l'owurọọjọ to pade iku gbigbona lọwọ Sunday Shodipẹ, ohun at'awọneeyan rẹ ni wọn jọ wa ni iyẹwu ki ki o to tọrọ gafara pe oun fẹ lọ tọ.
Leyin iṣẹju diẹ l'awọnọmọde kan to sare wọle pẹlu aruwo pe ejo ti bu u ṣan.
Nigba ti wọn yoo fi de ibẹ ni wọn baa ti wọn ti ṣaa pa.
Abule Ado explosion: Irọ́ ńlá ní NNPC pa lórí ìbúghbàmù Abule Ado níbí tí ẹ̀mí èèyàn 23
Ohun ti ọpọ lagbegbe naa n sọ ni oe, aṣemáṣe olopaa nipa jijẹ ki afunrasi naa o lọ mọ wọn lowo, ti wọn ko si tun fi to ara ilu leti  kun ara oun to ṣokunfa iku to pa Funmilayọ.
Wo ohun tí ilé ẹjọ́ ní kí wọ́n ṣe fún Sunday Shodipe, afurasí ìṣekúpani l'Akinyele
Ile ẹjọ Majisireeti agba kan nilu Ibadan ti ran Sunday Shodipẹ, afurasi tọwọ ọlọpaa tẹ lori iku ọwọọwọ lagbegbe Akinyẹle nilu Ibadan lọ si rimandi ọgba ẹwọn.
Wọn fi  ẹsun pe o ṣekupa arabinrin Funmilayọ Ọladeji kan an.
Adajọ Majisireti agba, Patricia Adetuyibi ko gba ẹbẹ 'o jẹbi tabi o ko jẹbi' lẹnu afurasi naa ki o to ni ki wọn ọs fi si ahamọ ọgba ẹwọn naa titi di igba ti ileeṣẹ eto idajọ ni ijọba ipinlẹ Ọyọ igbẹjọ rẹ yoo fi waye.
Akinyele: Ilé ẹjọ́ fi Sunday Shodipe, afurasí ìṣekúpani l'Akinyele pamọ́ sí ọgbà ẹ̀wọ̀n
Adajọ Majisireeti naa wa sun itẹsiwaju igbẹjọ naa si ọjọ kẹrindinlọgbọn, oṣu kẹwaa, ọdun 2020.
Àṣìṣe ọlọ́pàá àti Adájọ́ sọ mí di ẹni tí wọ́n dájọ́ ikú fún, ọpẹ́lọpẹ́ Fayoṣe tí ko buwọlu
Olupẹjọ jẹ ko di mimọ fun ile ẹjọ naa pe Ọladeji ti Sunday pa lẹyin to sa kuro lahamọ ọlọpaa ni wọn ṣi tori rẹ gbe e wa siwaju ile ẹjọ.
Bi ẹ ko ba gbagbe, Sunday Shodipẹ ti kọkọ jẹwọ pe oun loun pa Barakat, Grace, Azeezat atawọn meji miran ki ọwọ ọlọpaa to tẹẹ to si tun sa lahamọ.
Oríṣun àwòrán, Twitter/femi aladejuyigbe
Iwọde ti n waye baye ni ilu Ibadan lati fi ẹhonu han lori bi afurasi ti wọn mu fun iku awọn eeyan marun kan ni agbegbe Akinyẹle ni ilu Ibadan ṣe salọ ni ahamọ ọlọpaa.
Awọn ọdọ ilu Ibadan tu sita lọpọ yanturu ya bo olu ileeṣẹ ọlọpaa ni Ẹlẹyẹle lati fi ẹhonu wọn han lori iṣẹlẹ naa.
Awọn ọdọ naa ti awọn adari ẹgbẹ akẹkọọ NANS lewaju fun ni wọn bẹrẹ iwọde naa ni iyalẹta Ọjọbọ.
Ile ișẹ ọlọpaa ipinlẹ Oyo ti bẹrẹ ifọrọwanilẹnuwo pẹlu ọlọpaa meji ti Sunday shodipe, ọdaran to n dẹmi awọn ẹniyan legbodo lagbegbe Akinyele, bọ mọ lọwọ.
Alukoro ọlọpaa Fadeyi Olugbenga lo fidi ọrọ naa mulẹ.
Alukoro ọlọpaa ni wọn ti mu awọn ọlọpaa to yẹ ko mojuto ọdaran to salọ lahamọ, bi o tilẹ jẹ pe oun ko le sọ iye awọn ọlọpaa ti ọrọ naa kan.
Ẹwẹ, Kọmisọna ọlọpaa ni ipinlẹ Oyo, Joe Enwonwu lo pada salaye pe, awọn ọlọpaa meji ti aje ọrọ naa ṣi mọ lori, ni awọn n ṣe ifọrọwanilẹnuwo fun lọwọ.
Wayi o, awọn ọmọ ile igbimọ asofin ipinlẹ Oyo naa ti da si ọrọ ọhun, ti wọn si ti pe ọga agba fun ileesẹ ọlọpaa nilẹ wa, Mohammed Adamu lati ṣe iwadii finni-finni lori ọrọ naa.
Awọn ọmọ ile igbimọ asofin naa sọ ọ di mimọ lasiko ti wọn pe ipade awọn akọroyin nile igbimọ asofin ipinlẹ Oyo wipe, iyalẹnu lo jẹ pe iru ọdaran bẹẹ n bọ mọ ọlọpaa lọwọ.
Akomolede ati asa Yoruba: Ẹ wá kọ́ nípa àpòtí ìṣura èdè wa lórí BBC Yorùbá
Ọbalaye agbegbe Akinyẹle nibi ti iṣẹlẹ iṣekupani lọwọọwọ ti n waye ni ipinlẹ Ọyọ lati nnkan bii oṣu mẹta sẹyin.
Alakinyẹle ti ilu Akinyẹle, Ọba James Ọdẹdiran ti pariwo sita pe bi afurasi ti wọn mu fun iṣẹlẹ iṣekupani naa ṣe sa mọ ọlọpaa lọwọ fihan pe ẹmi awọn olugbe agbegbe naa ko de.
Ni ọjọ Aiku ni ileeṣẹ ọlọpaa kede pe Sunday Shodipẹ ti wọn mu fun lilọwọ ninu iku  Barakat Bello, Azeezat Shomuyiwa, atawọn eeyan miran lẹyin ti wọn mu u loṣu keje ọdun yii.
Ọba Ọdẹdiran ni kayeefi pata gbaa ni o jẹ pe afurasi naa lee sa kuro ni ahamọ awọn pẹlupẹlu bi wọn ṣe ni ẹwọn wa lọwọ ati ẹsẹ rẹ nigba gbogbo.
Ọba Alakinyẹle ṣalaye pe iwadii to rinlẹ gbọdọ waye o lati mọ awọn ọlọpaa to gbabọde lori iṣẹlẹ naa.
O ni iṣẹlẹ naa fihan pe bi afunrasi lori ẹsun to le bii ipaniyan ọlọwọọwọ ba lee sa mọ ọlọpaa lọwọ, ko si ẹmi ẹni to de lagbegbe naa niyẹn.
Ile ișẹ ọlọpaa ipinlẹ Oyo ko ti le e salaye titi asiko yii, ọna ti Sunday Shodipe, ẹni ọdun mọkandinlogun gba sa kuro ni ahamọ ọlọpaa ti wọn fi si, titi di asiko ti yoo tun pada foju ba ile ẹjọ.
Lasiko to n ba ile ișẹ BBCYoruba sọrọ, alukoro ile ișẹ ọlọpaa ipinlẹ Oyo, Fadeyi Olugbenga salaye pe, gbogbo nkan to jẹ ile ișẹ wọn logun julọ ni bi wọn yoo se gba afurasi naa mu.
"Nnkan to jẹ wa logun nisin yii ni bi a se maa mu u, gbogbo wa la n gbiyanju lati wa ọna bi a se maa mu.
Gbogbo igbesẹ bi a ṣe maa mú ni a n ṣe lọsan lorun, ti ẹnikẹni ba gbọ nnkan nipa rẹ ati ibi to n rin si, ki wọn tete fi to wa leti "
O ni ile iṣẹ ọlọpaa yoo ba àwọn ara ilu sọrọ laipẹ lori ọrọ naa, pẹlu afikun pe, iwadii n lọ lọwọ lori akọtun isẹlẹ ipaniyan to tun waye ni Akinyele lọjọ Ẹti to kọja.
Lori gbogbo awọn to ku ti ile iṣẹ ọlọpaa foju wọn han pẹlu Sunday nigba naa, alukoro ọlọpaa salaye pe, gbogbo wọn si wa ni ahamọ.
O ni wọn ti n lọ si ile ẹjọ tẹlẹ sugbọn nitori ọrọ Coronavirus lo faa, ti ile ẹjọ fi ni ki wọn lọ fi wọn pamọ si ahamọ ọlọpaa nitori awọn ẹwọn ti kun.
Ile ișẹ ọlọpaa, ninu atẹjade ti kọmisọna ọlọpaa nipinlẹ Oyo, Joe Nwanchukwu fọwọsi, wa rọ ara ilu lati se atilẹyin fun wọn ki wọn le e ri afurasi naa mu nitori iranlọwọ ara ilu ṣe pataki pẹlu.
Blind DJ: Etu Omotayo kò ríran àmọ́ ó le to irinṣẹ́ eléré pọ̀ láti kọrin láì sí ìrànwọ́
Bakan naa lo rọ awọn ọdọ ilu lati maa ni suuru, ki wọn maa si ja fun ara wọn nitori pe gbogbo akitiyan ni ọlọpaa n sa, lati fọ ilu mọ kuro lọwọ awọn onisẹ ibi gbogbo.
Titi di asiko ti a ko iroyin yii jọ, ile ișẹ ọlọpaa ipinlẹ Oyo ko ti se alaye bi Sunday se bọ mọ wọn lọwọ ni ahamọ.
Ṣe ẹ ranti, Sunday Shodipe, afurasi ti ọwọ awọn ọlọpaa tẹ lori awọn iṣekupani to waye lagbegbe Akinyẹle ni ilu Ibadan?
Ileeṣẹ ọlọpaa ni ipinlẹ Ọyọ ti kede pe, arakunrin naa ti sa lọ kuro ni ahamọ awọn ọlọpaa nibẹ.
Ninu atẹjade kan ti ileeṣẹ ọlọpaa fi sita latọdọ alukoro ileeṣẹ ọlọpaa ni ipinlẹ naa, ni eyi ti jẹyọ.
Oríṣun àwòrán, Others
Atẹjade naa fi jẹ ko di mimọ pe, Sunday Shodipẹ ni afurasi ti wọn mu fun ipaniyan ṣisẹ-n-tẹle to waye lagbegbe Akiyẹle ti wọn ṣe afihan rẹ pẹlu awọn meji miran lọjọ kẹtadinlogun, oṣu keje ọdun 2020, ti wọn si gbe lọ si ileẹjọ, ki wọn to da a pada si ahamọ ọlọpaa.
Amọ ṣa, ni ọjọ Iṣẹgun, ọjọ kọkanla oṣu kẹjọ ni afurasi naa sa lọ kuro ninu ahamọ ọlọpaa, ti awọn ọlọpaa si ni awọn ṣi n wa a.
Bi ẹ ko ba ni gbagbe, iku Wasilat Adeola, Barakat Bello, Grace Oshiagwu, Mojeed Tirimisiyu to jẹ ọmọ ọdun marun wa lara awọn ti awọn ọlọpaa ni arakunrin naa jẹwọ pe oun pa.
Ibadan Murder: Oyún oṣù méje ló ń bẹ nínú Azeezat, kí wọ́n tó f'òkúta fọ́ ọ lórí
Bakan naa lo gbiyanju ati pa Adeọla Azeez ati ọmọ rẹ obinrin Dọlapọ Oyeyẹmi ti ori ko yọ.
Nibayii ileeṣẹ ọlọpaa ti jẹ ko di mimọ fun araalu pe ẹnikẹni to ba kofiri rẹ ko fi to ileeṣẹ ọlọpaa to ba wa lagbegbe rẹ leti.
Blind DJ: Etu Omotayo kò ríran àmọ́ ó le to irinṣẹ́ eléré pọ̀ láti kọrin láì sí ìrànwọ́
Yoruba ni ba o ku, ise ko tan, ẹni to ba si ti ku laye, nikan ni tiẹ ti tan, nitori ireti si wa fun igi ti a bẹ lori.
Eyi ni a fi lee se apejuwe igbe aye ọgbẹni Etu Sodiq Omotayo ẹni to ni ipenija oju amọ to n sisẹ gbogbo elere lati wa ounjẹ oojọ jẹ.
Etu ni fasiti Ibadan ni oun wa bii akẹkọọ nigba ti oun ko riran mọ, to si dabi ẹni pe ọna ti pin fun oun sugbọn Ọlọrun la ọna lati ipasẹ isẹ gbogbo elere naa.
Etu ni ọmọ mẹfa ni fasiti, ti ọkan yoku si wa nile ẹkọ girama, idi isẹ gbogbo elere, taa mọ si DJ yii si lo ti n ri owo gbọ bukata wọn.
O wa parọwa si awọn eeyan to wa ni iru ipo to wa yii ati awsn to n la ipenija miran kọja lati di opo Ọlọrun ọba mu.
Douye Diri: Ìgbìmọ̀ olùgbẹ́jọ́ ẹ̀hónú ìbò yẹ àga mọ́ Gómìnà Bayelsa nídìí
Oríṣun àwòrán, Others
Ile ẹjọ to n gbọ ẹhonu ibo gomina nipinlẹ bayelsa ti wọgile ibo to gbe Gomina Douye Diri ati igbakeji rẹ, Lawrence Ewhrudjakpo wọle.
Ninu idajọ ti adajọ Yunusa Musa gbe kalẹ lori ẹhonu ibo gomina ti ẹgbẹ oselu ANDP gbe wa siwaju rẹ, igbimọ olugbẹjọ ẹhonu ibo naa ni ajọ eleto idibo lo yọ orukọ oludije ibo gomina fun ẹgbẹ oselu naa lọna aitọ.
Igbimọ olugbẹjọ naa wa pasẹ fun ajọ Inec lati tun eto idibo gomina mii se nipinlẹ Bayelsa laarin aadọsan ọjọ pere.
Bakan naa lo tun fikun pe, ajọ eleto idibo gbọdọ fi olupẹjọ naa, eyiun ẹgbẹ oselu ANDP sinu eto idibo tuntun.
Blind DJ: Etu Omotayo kò ríran àmọ́ ó le to irinṣẹ́ eléré pọ̀ láti kọrin láì sí ìrànwọ́
Ẹ jọwọ, ẹ tun oju opo iroyin yi yẹwo, ki ẹ lee ri ẹkunrẹrẹ iroyin ọtun laipẹ.
Nigeria international flight resumption: Àwọn ìlànà tuntun ti o gbọdọ tẹlèé rèé ki ó to le wọkọ̀ òfurufú lọ sókè òkun
Oríṣun àwòrán, Others
Bàálù àkọ́kọ́ balẹ̀ si pápákọ̀ òfurufú ìlú Eko lẹ́yìn oṣù márùn gbáko tí ijọba orilẹ̀-èdè Nàìjíríà ti fòfinde ìgbòkègbodo ọkọ̀ òfurufuú ilẹ̀ òkèrè.
Fífòfinde àwọn ọkọ̀ yìí kò ṣẹ̀yìn àjàkálẹ̀ ààrun coronavirus to wọ orílẹ̀ èdè  Naijiria nínú oṣù kẹta ọdún 2020.
Ọkọ̀ òfurufu ọhun to gbéra lati Beirut, lebanon balẹ̀ si pápákọ̀ òfurufú Muritala Muhammed International nílùú Eko ni dede aago méjì kọjá ìṣẹ́jú mẹ́tàdínlógún  lónìí ọjọ́ sátide.
Bákan náà ni ọkọ̀ òfurufú méjì míràn, Delta àti British Airways náà ṣe e ṣe kó bẹ̀rẹ̀ si ni fò láti pápákọ̀ òfurufú náà lónìí.
Ní ọjọ́ Eti ni àwọn ìkọ ìjọba ìpínlẹ̀ Eko ti sàbẹ̀wò sí pápákọ̀ òfururfú NMIA láti mọ̀ bi wọ́n ṣe múra silẹ̀ fún iṣẹ́ ìgbokègbodò to bẹ̀rl lónìí.
Awọn tó sàbẹ̀wò sibẹ̀ ni ìgbákeji gómìnà ìpińlẹ̀ Eko, Obafemi Hamzat Kọmísọnà ètò ìrìnà ìpińlẹ̀ Eko, Frederic Oladeinde àti kọmísọ́nà ètò ìlera, Akin Abayomi àti àwọn èèkan míràn nípìnlẹ̀ Eko.
Àsìkò tí wan sàbẹ̀wò ní ọ̀ga àgbà FAAN ní pápákọ̀ òfurufú náà sàlàyé pé, ọkọ̀furufú kan láti Middle Belt yoo maa bẹ̀rẹ̀ iṣẹ́ fún ìgbà àkakọ́ lónìí..
Sáájú àsikò yìí ni ìjọba àpapọ tí ṣí pápákọ̀ òfurufú fún awọn to n rin ìrìnàjò abẹ́lé ní ọjọ́ kẹjọ oṣù kèje ọdun yii, to si ti sàlàyé pé, ní òní ọja kàrun, ọsù kẹjọ ni àwọn ilẹ̀ òkèrè yóò bẹ́rẹ̀.
Ẹ̀wẹ̀ àwọn aláṣẹ ti fi ìlàna  bi àwọn ọkọ òfúrufú náà yóò ṣe ma rìn  láti òní ọjmọ́ Sátidé, ọja karún, oṣù kẹjọ ọdún 2020.
Nínú àtẹjáde kan ti àwọn aláṣẹ ìrìnà ọkọ̀ òfurufú (NCAA) fi sójú òpó twitter rẹ̀, ló ti sàfihan ìlànà ìrìnà tuntun ti wọ́n fẹ́ gùnlé.
Nínú àtẹ̀jáde náà, wọ́n ni ọkọ̀ òfurufú kankan ko le kó ju igba ènìyàn lọ, wọ́n fi ku pé àwọn fọ́wọ́si iye yìí nitori pe ó le ni ènìyàn ẹgbẹ̀run kan to maa n wa si papakọ òfurufú lọ́ọ̀jọ́.
Oríṣun àwòrán, Ethiopian Airline
Ọ̀la òde yìí ni ìrìnàjò sí ilẹ̀ òkèèrè yóò padà bẹrẹ ní Nàìjíríà
Ijọba apapọ ti kéde ọjọ karun un, oṣu Kẹsan an, ọdún 2020, gẹgẹ bí ọjọ ti irinajo ọkọ ofurufu si ilẹ okeere yoo bẹrẹ pada ni Naijiria.
Ijọba tun kede orukọ Ileeṣẹ ọkọ ofurufu mẹsan an gẹgẹ bi awọn iléeṣẹ́ tó fi ountẹ lu lati maa ko awọn arinrin ajo lọ si oke okun.
Wo àwọn ofin aatẹle ki o to le fo tabi wọle si Naijiria
Èsì ìdánwò òhun tí a ṣé síwájú là n bá fínra báyìí ní Nàìjíríà- Yemi Shodimu
Èèmọ̀! Ọmọbìnrin ọdún 25 gún ọ̀rẹ́kùnrin rẹ̀ pa nítorí ó ní ko lọ ṣẹ́ oyún
Ó tó gẹ́ẹ́! Àwọn ọmọ Nàìjíríà ṣe ìwọ́de l'Osogbo lórí àfikún owó epo bẹntiróò
Wo ohun tí ilé ẹjọ́ ní kí wọ́n ṣe fún Sunday Shodipe, afurasí ìṣekúpani l'Akinyele
Ọwọ́ ọlọ́pàá tẹ afurasí olóògùn owó tó fẹ́ gé ọmú obìnrin kan nílé ìtura
E wo ọmọ Yorùbá àkọ́kọ́ tó jà fún ẹ̀tọ́ àwọn aláwọ̀dúdú ní America!
Ọmọ Nàìjíríà kan gbé Fásitì Oxford lọ sílé ẹjọ́ tàko oríkí ọrọ 'Mortgage' nínú ìwé àtúmọ̀ ọrọ
Ọwọ́ ọlọ́pàá tẹ àwọn olè tó kó góòlù àti ẹgbẹ̀lẹ́gbẹ̀ mílíọ̀nù lọ nílé MKO Abiola l'Eko
Ó sàn kí ẹ pa mí ju kí ẹ ba oko tí mo gbin igbó sí jẹ́ lọ- Afurasi Clement sí NDLEA
A kú oríire! Oró agbọ́n leè wo àìsàn jẹjẹrẹ ọmú sàn, wo ohun tí wàá lò pọ̀ mọ́ra wọn
Isiaka Busari, Mighty Joe tó jẹ́ adigunjalè tó rọ́pò Ọyenusi lẹ́yìn tí wọ́n pa á
Oríṣun àwòrán, Twitter/British_Airways
Kini ikede ti minista kọkọ ṣe tẹlẹ?
Minisita to n ri si eto irinna ọkọ ofurufu, Hadi Sirika lo kéde bẹẹ nigba ti igbimọ ti ìjọba àpapọ gbe kalẹ lori ọrọ Covid-19 n jabọ ni ilu Abuja.
O ni ko sí aye fun awọn iléeṣẹ́ kan lati bẹrẹ sí ni ko ero ni saa yii.
Lara awọn iléeṣẹ́ tó fòfin de ni saa yii ni Air France, KLM, Etihad, RwandAir, Air Namibia, Royal Air Maroc, Lufthansa ati TAAG Angola Airlines.
Minisita naa ni papakọ ofurufu Muritala Muhammed ti ilu Eko ati Nnamdi Azikiwe ti ilu Abuja yoo di ṣiṣi.
Sirika fi kun un pe ìjọba tun fòfin de Ileeṣẹ ọkọ ofurufu Cabo Verde ati South Africa nitori irinajo ofurufu ko tii bẹrẹ lorilẹ-ede wọn.
Àṣìṣe ọlọ́pàá àti Adájọ́ sọ mí di ẹni tí wọ́n dájọ́ ikú fún, ọpẹ́lọpẹ́ Fayoṣe tí ko buwọlu
Bakan naa ni ijọba tun fi ountẹ lu Middle East Airline, British Airways, Delta, Qatar, Ethiopian Airlines, Emirates Airlines, Air Peace, Virgin Atlantic, Asky Airlines, Africa World Airways, Air Cote-d' Ivoire, Kenya Airways, EgyptAir, Turkish Airlines lati bẹrẹ iṣẹ pada ni Naijiria.
Ṣaaju ni ijọba apapọ fòfin de irinajo si ilẹ okeere nitori arun Covid-19 to n mi gbogbo agbaye titi.
Ìjọba Nàìjíríà ti sún ọjọ́ tí ìrìnàjò bàálù sílẹ̀ òkèèrè yóò bẹ̀rẹ̀ padà síwájú
Ìjọba kéde ọjọ́ míràn fún ìbẹ̀rẹ̀ padà ìrìnàjò bàálù sílẹ̀ òkèèrè
Ijọba orilẹ-ede Naijiria ti sun ọjọ ti irinajo ofufuru silẹ okeere yoo bẹrẹ pada kuro ni ọjọ kọkandinlọgbọn, oṣu Kẹjọ, ọdun 2020.
Oludari ajọ to n mojuto irinajo ọkọ ofufuru, Nigeria Civil Aviation Authority (NCAA), Captain Musa Nuhu, lo kede eyi lasiko to n jabọ niwaju igbimọ amuṣẹya to n mojuto ọrọ Covid-19 nilu Abuja lọjọbọ.
Nibayii, ọjọ karun-un, oṣu Kẹsan an, ni irinajo baalu silẹ okeere yoo bẹrẹ pada.
Baby abandoned on dunmpsite: Mo ti bímọ mẹ́rin tẹ́lẹ̀ fún bàbá méjì nínú òṣí- Dupe Ogbomos
Musa ṣalaye pe lootọ ni awọn papakọ baalu , ati awọn ileeṣẹ ọkọ ofurufu ti ṣetan fun iṣẹ, ṣugbọn awọn ẹ̀ka miran ti ko nii ṣe pẹlu ọkọ ofurufu lo fa afikun ọsẹ kan.
O fikun ọrọ rẹ pe dandan ni ọjọ karun-un, oṣu Kẹsan ti wọm kede. Ati pe awọn yoo kede ilana tuntun fun irinajo silẹ okeere.
Oṣu Kẹta ni ijọba Naijiria ti fofin de irinajo oju ofurufu, nitori itankalẹ coronavirus.
Minisita feto ọkọ ofurufu Naijiria Hadi Sirika lo fi ọrọ yi lelẹ lasiko ti igbimọ to n koju arun Covid-19 n jabọ fawọn akọroyin ni Abuja.
O ni ipinnu Naijiria yi ko ṣẹyin bi awọn orile-ede kan ti ṣe kọdi ọkọ ofurufu lati Naijiria si ilẹ wọn paapa julọ awọn ilẹ to wa ni ajọ Yuroopu (EU)
Ipinnu ṣe fun mi ki n ṣe fun ọ yi ko ṣẹṣẹ maa waye laarin Naijiria ati awọn ilẹ miran.
Lọpọ igba Naijiria a maa fi jẹ ki o ye awọn ilẹ wọnyi pe awọn ko gba gberẹ.
Igba mẹta ọtọọtọ ree ti Naijiria ti fi ilana gbigbẹsan yi ba awọn orile-ede miran ṣe papọ latẹyin wa.
Akomolede ati asa Yoruba: Ẹ wá kọ́ nípa àpòtí ìṣura èdè wa lórí BBC Yorùbá
1) Lasiko Ijọba Ologun Buhari / Idiagbon
Eyi to gbajumọ julọ ninu iṣẹlẹ igbẹsan ti ijọba Naijiria ṣe lo waye ni asiko ologun ni ti Umaru Dikko.
Umaru Dikko wa lara awọn ti ijọba Buhari / Idiagbon ni o lu owo ilu ni ponpo.
Oríṣun àwòrán, Twitter/MMMDProvost2
Umaru Dikko gẹgẹ bi ọrọ naa ti ṣe lọ ṣa lọ si ilẹ Gẹẹsi ṣugbọn ijọba ran awọn ọtẹlẹmuyẹ lati lọ ji gbe pada wa sile.
O ku diẹ ki wọn ri i da pada wa sile ṣugbọn ijọba ilẹ Gẹẹsi ni ki baalu ti wọn fẹ fi ji i gbe ma gbera lẹyin ti wọn ri i nibi ti wọn di i sinu paali papọ mọ ẹru.
Blind DJ: Etu Omotayo kò ríran àmọ́ ó le to irinṣẹ́ eléré pọ̀ láti kọrin láì sí ìrànwọ́
Ọrọ yi bi ọgagun Idiagbon ninu ti o si paṣẹ ki baalu ilẹ Gẹẹsi kan to ti gbera kuro ni Naijiria pada si papakọ ofurufu Murtala Muhammed nilu Eko.
Awọn onwoye ni igbesẹ yi ko ṣẹyin bi awọn ọlọpaa ilẹ Gẹẹsi ti ṣe doola ẹmi Umaru Dikko ti ijọba Naijiria fẹ fipa gbe lati pada wale wa jẹjọ ajẹbanu.
2) Abacha ṣe iyipada opopona lati fi gbẹsan ohun ti Amẹrika ṣe
Lasiko ijọba ologun bakan naa a ri i ka ninu itan pe olori orile-ede nigba naa Ọgagun Sani Abacha ni ki wọn yi orukọ opopona kan niwaju ileeṣẹ orile-ede Amẹrika ni Naijiria pada.
Orukọ tuntun ti wọn yi opopona naa pada si ni ti olori ẹgbẹ Nation of Islam, Louis Farrakhan.
Igbesẹ ko ṣẹyin bi Amẹrika naa ti ṣe fi orukọ Kudirat Abiola iyawo MKO Abiola pori opopona kan ni New York.
Lọdun 1998 ni ijọba Naijiri a gbe igbesẹ yi lati fi han Amẹrika pe awọn naa ko gba gbẹrẹ.
Oríṣun àwòrán, AFP
Aisan ọkan ni wọn sọ pe, o pa Ọ̀gágun àgbà Sani Abacha
3) Iṣẹlẹ ifofinde baalu lati ilẹ Yuroopu
Eyi ni iṣẹlẹ to sunmọ ju to ṣẹṣẹ waye lẹyin ti awọn orile-ede Ajọ Yuroopu ka Naijiria kun awọn orile-ede aadọta ti wọn ko faaye gba ki baalu wa lati ilẹ wọn si Yuroopu.
Naijiria wa lara awọn ilẹ ti ọrọ yi kan ti eyi si mu ki ijọba Naijiria tutọ soke foju gba a pe awọn naa ko ni gba ki baalu lati awọn ilẹ Yuroopu yi wọ oju ofurufu Naijiria.
Lọjọbọ ni ijọba orile-ede Naijiria fi ikede sita pe awọn orile-ede to ba gbegi dina irinajo baalu lati Naijiria sọdọ wọn, Naijiria naa ko ni gba ki baalu wọ ilẹ rẹ lati ọdọ wọn.
Oríṣun àwòrán, thecableng
Kini o ti sele sẹyin?
Ni bayi ti awọn ọmọ Naijiria n reti ilana ti wọn yoo tẹle ti wọn ba fẹ rinrin ajo ọkọ ofurufu lọ silẹ okeere lẹnu ijọba, a ni ki a fi to yin leti ohun ti awọn ileeṣẹ ọkọ ofurufu kan ni ẹ gbọdọ ṣe.
Ninu awọn ilana ti wọn gbe kalẹ leleyi to nii ṣe pẹlu ṣiṣe ayẹwo boya eeyan larun Covid-19.
Esi ayẹwo yi ni ẹnikẹni to ba fẹ rinrin ajo yoo mu wa si papakọ ofurufu ki o to le wọ baalu.
Coronavirus: Ọ̀pọ̀ àwọn arìnrìnàjò wá sí Nàíjíríà ló kọjá àbẹ̀wò tó lágbára
Awọn ileeṣẹ ọkọ ofurufu bi i Etihad Airways ti fi ọrọ yi sita loju opo wọn o to ọjọ mẹta.
Lọdọ ileeṣẹ ọkọ ofurufu Qatar afihan iwe ẹri mo moribọ lọwọ arun Covid 19 jẹ nkan ti eeyan gbọdọ mu wa paapa to ba n bọ lati orile-ede miran bi Turkey to si fẹ wọ Qatar.
Akomolede ati asa Yoruba: Ẹ wá kọ́ nípa àpòtí ìṣura èdè wa lórí BBC Yorùbá
Qatar  ti pese aaye ayẹwo ni papakọ ofurufu Hamad International Airport nibi ti wọn yoo ti ṣe ayẹwo yi
Ohun to n kan awọn eeyan lominu bayi ni asiko ti wọn yoo fi ri esi ayẹwo yi gba.
Lọwọ lọwọ ni Naijiria iṣoro nla ni ṣise ayẹwo arun Covid-19 jẹ.
Pupọ awọn eeyan ni ko ribi ṣe ayẹwo yi tawọn to si ti ṣe kii tete ri esi ayẹwo wọn gba
Ijọba apapọ orilẹede Naijiria ti kede pe irinna ọkọ ofurufuru si ilẹ okeere yoo bẹrẹ pada ni ọjọ kọkandinlọgbọn oṣu kẹjọ ọdun 2020.
Minisita feto irinna ofurufu, Hadi Sirika lo fi eyi sita loju opo Twitter rẹ.
O ni igbesẹ yii yoo kọkọ bẹrẹ pẹlu papakọ ofurufu to wa ni ilu Eko ati Abuja.
Bakan naa lo fi kun un pe gbogbo igbesẹ ati ilana to ba yẹ fun idapada irinajo silẹ okeere naa yoo bo si ojutaye laipẹ.
Alaafin Oyo: Alaafin Oyo ní àwọn onílù láàfin ló ń tú ọ̀pọ̀ àṣírí fún òhun láàfin
Oríṣun àwòrán, Alaafin Oyo
Alaafin ilu Oyo, Ọba Lamidi Olayiwola Adeyemi kẹta ti sọ pe, awọn onilu ni afin oun lo maa n ta oun lologbo ti ẹni ibi tabi ọdalẹ ba wọle tọ oun.
Alaafin lo sọ ọrọ naa ninu ifọrọwerọ pẹlu ileeṣẹ iroyin abẹle ede Yoruba kan.
"O ni ""Gbogbo eeyan lo mọ pe aafin yii jẹ ibi aṣa ati iṣe, ti ẹ ba ri ti awọn onilu ba n lu ilu wọn ninu aafin, oriṣiriṣi nnkan ni ilu naa n tumọ si."""
"Kabiesi ni, ""Fun apẹrẹ, ti eeyan buburu kan tabi ọdalẹ ba bami lalejo ni aafin mi, awọn onilu yoo fi ilu wọn ki mi nilọ, bo tilẹ jẹ pe ẹni naa ko ni mọ oun ti ilu naa n sọ, ṣugbọn o ye mi."""
"Ọba Adeyemi ni ""Gẹgẹ bi olori gbogbo awọn Ọba ilẹ Yoruba, mo maa sa ipa mi lati gbe ede, aṣa ati iṣe Yoruba leke, nitori o dabi pe o ti n di ohun igbagbe."""
"Kabiesi tẹsiwaju pe ""Ti ẹ ba ṣakiyesi, ẹ o ri pe mi o fi ọwọ yẹpẹrẹ mu ọrọ aṣọ wiwọ, bi a ṣe n ki ni ati ede Yoruba."""
Akomolede ati asa Yoruba: Ẹ wá kọ́ nípa àpòtí ìṣura èdè wa lórí BBC Yorùbá
Ọba alaye naa pari ọrọ rẹ pe o yẹ ki awọn ọmọ ilẹ Yoruba ṣe ara wọn ni oṣuṣu ọwọ gẹgẹ bi ọmọ iya kan , ki wọn ma si jẹ ki eto oṣelu oin wọn niya.
Lẹyin naa lo ṣeleri pe oun yoo tẹsiwaju lati maa gbe aṣa ati iṣe Yoruba ga, ko ma ba parun.
Oríṣun àwòrán, Alaafin Oyo
Otitọ ni pe ni ilana ati iṣẹṣe Yoruba, lara awọn ti eniyan ko lee fẹ ku laafin Ọba ni awọn onilu wa.
Wọn wa lara awọn ajirọba.
Awọn ni o maa n da ọba lara ya nigba to ba ku oun nikan ṣoṣo laafin rẹ.
Amọṣa lode Ọyọ, iyẹn laafin Kabiyesi Iku baba, yeye, Alaafin ti ilu Ọyọ, Ọba Lamidi Adeyẹmi Kẹta, o fẹ jọ bi ẹni pe adehun kan n bẹ laarin awọn onilu naa ati Iku baba yeye funrarẹ.
Ninu ọrọ ti Baba Alaafin ṣe lalaye fun ileeṣẹ iwe iroyin abẹle kan, aṣiri to wa laarin wọn naa ni pe awọn onilu yii nii maa n ṣe ikilọ fun Alaafin nipa ohun to ba n lọ ni ita afin.
Ninu ifọrọwerọ naa, Kabiyesi Adeyẹmi kẹta
Alaafin Ọyọ ysju rẹ sita pe awọn onilu laafin ni wọn maa n tu aṣiri nipa irufẹ eeyan to n bs wa ri oun laafin fun oun.
O ni bi iru ẹni bẹẹ ba jẹ eeyan buruku, awọn onilu yoo tu aṣiri rẹ fun oun; bi onitọhun ba si tun jẹ eeyan rere, wọn a jẹ ki oun tun mọ pẹlu.
O ni oyun ọrọ n bẹ ninu ilu awọn onilu oun, ilu wọn kii ṣe ilu lasan.  ẹni to ba leti ilu nikan lo le gbs ohun ti wọn n sọ.
Germany football naked protest: Àwọn olùfẹ̀hónúhàn bọ́ra sí ìhòhò lórí pápá lòdì sí sísọ eré bọ́ọ̀lù di jẹunjẹun
Awọn eeyan kan lorilẹ-ede Germany ti lọ sori papa ni ihoho ọmọluabi lọna ati ṣefẹhonuhan lodi si sisọ ere bọọlu di jẹunjẹun.
Ifẹhonuhan naa lo waye nipasẹ ifẹsẹwọnsẹ kan ti ayaworan Gerrit Starczewski gbe kalẹ ni papa iṣere Stimberg ni Ruhr.
Awọn eeyan naa lọ sori papa lai wọ aṣọ kankan, yatọ si ibọsẹ ati bata ti wọn fi n gba bọọlu, bẹẹ ni wọn tun kọ nọmba agbabọọlu si ẹyin wọn.
Starczewski ni igbesẹ naa waye lọna ati fi ẹhonu han lodi si ohun ti wọn sọ ere bọọlu da laye ode oni pẹlu ihoho awọn eeyan naa.
"O ni ""Ere bọọlu ti da idakuda laye ode oni, idi niyii ti a fi wa ni ihoho."""
Blind DJ: Etu Omotayo kò ríran àmọ́ ó le to irinṣẹ́ eléré pọ̀ láti kọrin láì sí ìrànwọ́
Akomolede ati asa Yoruba: Ẹ wá kọ́ nípa àpòtí ìṣura èdè wa lórí BBC Yorùbá
Ede Yoruba ti fẹ di ajeji laarin awọn ọdọ iwoyi, idi si ree ti BBC Yoruba fi se agbekalẹ eto yii lati maa kọ wa ni ede ati asa Yoruba.
Eto naa, ta pe ni Akọmọlede ati Aṣa Yoruba, lo n waye fun igba akọkọ lonii loju opo ikanni BBC Yoruba, ti yoo si maa kọ wa ni ede ati asa wa, ko maa ba parun.
Akori ẹkọ wa fun toni ni Ẹya Litireṣọ ede Yoruba, olukọ wa si ni ọgbẹni Lawanson Olumuyiwa.
Ẹ wa kọ nipa itumọ Litireṣọ, isọri rẹ, abuda rẹ to fi mọ apoti isura ede Yoruba, ẹẹkan lọsẹ si ni eto yii yoo maa gun ori afẹfẹ.
"Bí ẹ ṣe mọ̀wé tó, ẹ wá dánrawò níbí pẹ̀lú ""Àpólà Ọ̀rọ̀ Orúkọ - Noun Phrase"
Alaafin Oyo: Àwọn onílù mí ló ń tú àṣírí ìkà èèyàn tó bá wọ ààfin mi - Aláàfin
Oríṣun àwòrán, Alaafin Oyo
Alaafin ilu Oyo, Ọba Lamidi Olayiwola Adeyemi kẹta ti sọ pe, awọn onilu ni afin oun lo maa n ta oun lologbo ti ẹni ibi tabi ọdalẹ ba wọle tọ oun.
Alaafin lo sọ ọrọ naa ninu ifọrọwerọ pẹlu ileeṣẹ iroyin abẹle ede Yoruba kan.
"O ni ""Gbogbo eeyan lo mọ pe aafin yii jẹ ibi aṣa ati iṣe, ti ẹ ba ri ti awọn onilu ba n lu ilu wọn ninu aafin, oriṣiriṣi nnkan ni ilu naa n tumọ si."""
"Kabiesi ni, ""Fun apẹrẹ, ti eeyan buburu kan tabi ọdalẹ ba bami lalejo ni aafin mi, awọn onilu yoo fi ilu wọn ki mi nilọ, bo tilẹ jẹ pe ẹni naa ko ni mọ oun ti ilu naa n sọ, ṣugbọn o ye mi."""
"Ọba Adeyemi ni ""Gẹgẹ bi olori gbogbo awọn Ọba ilẹ Yoruba, mo maa sa ipa mi lati gbe ede, aṣa ati iṣe Yoruba leke, nitori o dabi pe o ti n di ohun igbagbe."""
"Kabiesi tẹsiwaju pe ""Ti ẹ ba ṣakiyesi, ẹ o ri pe mi o fi ọwọ yẹpẹrẹ mu ọrọ aṣọ wiwọ, bi a ṣe n ki ni ati ede Yoruba."""
Akomolede ati asa Yoruba: Ẹ wá kọ́ nípa àpòtí ìṣura èdè wa lórí BBC Yorùbá
Ọba alaye naa pari ọrọ rẹ pe o yẹ ki awọn ọmọ ilẹ Yoruba ṣe ara wọn ni oṣuṣu ọwọ gẹgẹ bi ọmọ iya kan , ki wọn ma si jẹ ki eto oṣelu oin wọn niya.
Lẹyin naa lo ṣeleri pe oun yoo tẹsiwaju lati maa gbe aṣa ati iṣe Yoruba ga, ko ma ba parun.
Oríṣun àwòrán, Alaafin Oyo
Drums musical instrument: Ka bí o ṣe le mọ èdè Àyàn àti àgbọ́yé ìlù
Oríṣun àwòrán, Others
Ilu dabi ipilẹ lara elo orin ni ilẹ Yoruba, Ko si si ẹni to n kọ iyan rẹ kere to ba ti di asiko orin, bakan naa lo lara idi ti awọn eniyan fi maa n fẹran ayẹyẹ to nise pẹlu Yoruba.
Oniruuru ilu ni a ni ni ilẹ Yoruba ti olukuku si ni isẹ ọtọọtọ ti wọn n ṣe, bi a ṣe ni eyi ti a n lo fun ayẹyẹ bẹni ti orisa wa, bakan naa ni eyi ti a n lo fun ayẹsi ọba laafin.
Oríṣun àwòrán, Others
Gangan lo wọpọ julọ ti Yoruba maa n lo fun ayẹyẹ ọlọkan o jọkan nilẹ Yoruba.
Aaye ọtọ lo wa ninu iṣẹnbaye. Wọn maa n lo lati fi sọrọ ati lati fi sin ẹlomiran jẹ.
Oríṣun àwòrán, Others
Ilu pataki miran nilẹ Yoruba tun ni, ilu oloju meji sugbọn ti oju kan a maa tobi ju ekeji lọ, ni ọpọ igba ibi ayẹyẹ orisa ni wọn ti n lo, bi iwuye, ifọbajẹ tabi ajọdun orisa kan.
Won n lo lati ti fi ohun ranṣẹ si ara ilu lasiko ogun, wọn fi n se ayẹsi, wọn si fi n parako ogun.
Ilu yii si ni orisa Sango yan laayo julọ laarin awọn ilu nilẹ Yoruba.
Oríṣun àwòrán, Others
Omele ni a maa n saba pe eleyi, a mọ si ilu ti a n lu si orin sakara, asiko ayẹyẹ igbeyawo, iwuye, ati ajọdun ni a saba maa n lo.
Gbẹdu/Ogido:
Eyi tumọ si ilu to tobi, boya nítorí eti ni ọpọ se maa n pe orin ati ilu to dun ni 'Gbẹdu'.
Ṣugbọn Gbẹdu ni ilẹ Yoruba ti pẹ ti won ti n lo, ọwọja iṣẹ rẹ si ti tan kọja ilẹ Yoruba nikan, lati bi Senturi  kẹtadinlogun ni Benin ti mu Gbẹdu gẹgẹ bi ami ọmọ alade.
Oríṣun àwòrán, Others
Wọn maa n lo lasiko ayẹyẹ nla, o si ti gbajumọ laarin awọn ọlaju, kii ṣe ohun elo orin abẹle.
Awọn ọba maa n saba jo si orin ti won ba lu  ilu yii si, ẹlomiran ko le ba ọba jo si, o si maa n safihan ami Dansaki nibi kibi to ba ti jẹyọ.
Oríṣun àwòrán, Others|
Ilu miran to tun wọpọ laarin Yoruba ni Ashiko, asiko ajọdun tabi ayẹyẹ orisa ni wọn n lo ohun naa, ori rẹ a maa tobi nigba ti idi rẹ a se roboto.
Awọ ewurẹ ni wọn maa n lo lati ṣe, ọwọ ni wọn n lo lati lu pẹlu, yatọ si gangan ti wọn lo gọngọ fun.
Saworo Idẹ:
Saworo Idẹ dabi ilu gangan sugbọn, wọn ṣe ni ọṣọ pẹlu awọn agogo keekeeke.
Awọn agogo yii a maa dun bi wọn ba ti n lu ilu naa, yatọ didun ilu agogo eti rẹ naa ni adun lọtọ.
Pẹlu gbogbo alaye yii,  o le mọ iru awọn ilu ti Alaafin Oyo, Oba Lamidi Olayiwola Adeyemi kẹta n sọ nigba ti o fi lede pe, awọn onilu lo maa n tu asiri bi awọn ẹni ibi ba fẹ wọ aafin.
Oríṣun àwòrán, Others
Nigba to n ba BBC Yoruba sọrọ, Alhaji Ayanyemi Atokowagbowonle, tii se gbajumọ onilu Juju ati Sẹkẹrẹ nilu Ibadan, salaye pe kii se gbogbo eniyan lo mọ ede ayan, ẹni to ba mọ nikan lo le ye.
O ni asiko ti oju o la ni awọn ayan maa n fi ilu bu eniyan, sugbọn laye ode oni, ko si ẹni to n se bẹẹ mọ.
Oríṣun àwòrán, Others
Ayanyemi ni orisirisi ilu lo si wa laye ode oni, paapa julọ, ni aafin ọba.
Bakan naa lo fi kun pe, ilu ni wọn maa n fi n ji Kabiyesi lori ibusun lowurọ, ati pe oniruuru iṣẹ ni wọn ṣe laafin.
Jumoke Odetola: Ọ́pọ̀ òṣèré koro ojú sí àṣehàn lásán lẹ́yìn ikú akẹẹgbẹ́ wọn, Williams Aanuoluwapo, Kumbalee
Oríṣun àwòrán, https://www.instagram.com/jumokeodetola/
Àwọn òṣèré tíátà Yorùbá kọjú ìjà síra wọn lórí ìdárò akẹẹgbẹ́ wọn tó kú
Awaye ku ko si, Ọba oke mase jẹ ka fi ọjọ ọlọjọ lọ ni.
Ọfọ nla ti sẹ ni agbo ere tiata ni ọjọ Aje, eyi to dori awọn irawọ osere kodo.
Iku tun to wọ agbo awọn oṣere tiata nilẹ yii naa, nigba ti yoo si fi jade, ọkan lara awọn aṣaraloge  (Makeup Artist) lẹka ere tiata Yoruba, lo mu lọ.
Orukọ oloogbe naa ni  Williams Anuoluwapọ, ti ọpọ mọ si Kumbalee.
Iroyin ti a gbọ sọ pe, ijamba ọkada kan to waye lọjọ Aiku lo sọ Kumbalee di ero ọrun.
Idaji kutu hai owurọ ọjọ Isẹgun ni irawọ osere kan, Jumoke Odetola lo tufọ oloogbe naa, ti ọpọ akẹẹgbẹ rẹ lagbo tiata si n tara poro lori iku aitọjọ naa.
Oríṣun àwòrán, others
Sugbọn awọn ọrọ ti awọn osere kan n sọ lori iku ọkunrin naa ati awọn eeyan to n sọfọ rẹ, n kọ ni lominu.
Eyi si lo mu kawọn osere tiata kan fajuro lori ohun tawọn akẹẹgbẹ wọn n kọ nipa iku ọkunrin naa, ti wọn si n gbena woju ara wọn.
Sugbọn ọrọ aro ti ọpọ wọn n kọ soju opo Instagram wọn lo safihan pe, wọn n paroko ọrọ ransẹ saarin ara wọn, to si ni itumọ to jinlẹ.
Oríṣun àwòrán, iamcertified_eyinjueledumare/Instagram
Ọrọ naa lo ni o dara lootọ ki awọn eeyan daro iku ẹni to ba di oloogbe amọ irufẹ idaro bayii gbọdọ ni odiwọn.
O ni ojiji aye lasan ni gbogbo wa n le kiri, ta si n jẹ gaba lori awọn eeyan miran lai mọ ohun ti yoo sẹlẹ ni isẹju meji si asiko yii.
Akomolede ati asa Yoruba: Ẹ wá kọ́ nípa àpòtí ìṣura èdè wa lórí BBC Yorùbá
"Gbogbo wa la n waasu nipa bi aye se jẹ asan, sibẹ awa kan ni orisun isoro ara wa, o n waasu ifẹ, ti ikorira si gba ọkan rẹ kan.
Ọpọ wa ni ko bikita nipa ọjọ ọla wa, oni nikan la n naani rẹ, eyi to sọ wa di ẹni ibi pẹlu ọpọ ibanujẹ, ta si joko si kọrọ ile wa lati maa se idajọ lori awọn asise ẹlomiran."
Oríṣun àwòrán, https://www.instagram.com/iamcertified_eyinjueledu
Ọrọ naa wa kadi nilẹ pe ọjọ kan yoo jọkan, laarin isẹju kan, ti gbogbo rẹ yoo tan, ti yoo si ku wa ati iwa wa ninu saare.
Ọpọ osere tiata lo pin akanse ọrọ yii loju opo Instagram wọn, ti wọn si fi akọle tiwọn sibẹ.
Arike Abiodun Best lo sọrọ pe:
Ti mo ba ku loni, ti o ko si gbe aworan mi soju opo ayelujara rẹ ri tẹlẹ , paapa lajọ ibi mi, ma wulẹ sopo gbe aworan mi lẹyin ti mo ba ku tan nitori maa ri ninu saare mi, ti maa si di igbaju olooyi lu ọ lati inu saare mi.
Oríṣun àwòrán, https://www.instagram.com/iamcertified_eyinjueledu
Bakan naa ni Mustipha Sholagbade gbe ọrọ yii soju opo rẹ, to fi mọ awọn osere tiata miran.
Nigba to ya ni agba osere tiata kan, Yomi Fabiyi bẹrẹ si da awọn akẹẹgbẹ rẹ lẹkun lori ọrọ naa, ati bi wọn se n daro oloogbe lọna to mu ikunsinu lọwọ.
Fabiyi ni ọrọ iku lagbara pupọ, to si wuwo, pẹlu afikun pe tawọn akẹẹgbẹ oun ko ba lee mọ ẹni to nifẹ wọn denu loju aye, bawo ni wọn se fẹ sedamọ rẹ ninu saare.
O ni atako ko wulo rara lasiko yii, yoo si dara ki wọn lo ohun wọn fun nnkan miran to ba wulo fun iran ọmọniyan, eto oselu ibaradọgba ati idajọ ododo.
Oríṣun àwòrán, https://www.instagram.com/realyomifabiyi/
O fikun pe ko dara ki wọn maa pa awọn eeyan kan lẹnu mọ tabi sọ irufẹ ẹni ti yoo daro wọn leti iboji ki araye ba le mọ pe wọn mọ ọrọ sọ.
Eyi n ba ni ninu jẹ, yoo si dara kẹ jẹ kawọn eeyan se idaro oloogbe to ba se wu wọn, ki wọn si fi Ọlọrun silk lati se idamọ awọn eeyan eke ati awọn olootọ ẹda.
Theladyjokelet loju opo tiẹ naa wa n fi ika hanu lori ihuwasi awọn osere tiata Yoruba naa, eyi to ni o n ba oun ninujẹ.Ọfọ sẹ lagbo osere tiata, awọn osere kan n tahun sira wọn tori
Oríṣun àwòrán, https://www.instagram.com/theladyjokelet/
Koda, ilumọọka osere tiata lobinrin, Jumọkẹ Odetola gan bara jẹ pupọ lori iku asaraloge naa, ẹni to salaye pe o papoda lẹyin wakati diẹ ti wọn sọrọ lori aago.
Oríṣun àwòrán, https://www.instagram.com/jumokeodetola/
Ibadan Divorce: Abílékọ Idowu faraya ní kóòtù kọkọ-kọkọ n'Ibadan, Ó ní òun ò leè pín ọkọ òun pẹ̀lú ẹnikẹ́ni
Oríṣun àwòrán, others
Olukọni kan nilu Ibadan, arabinrin Idowu Oluokun ti rọ ile ẹjọ kọkọ-kọkọ kan ni Mapo nilu Ibadan pe ki wọn tu igbeyawo ọlọdun mẹrindinlogun oun ati ọkọ oun ti orukọ rẹ n jẹ Oyetunji ka dipo ki oun maa pin ọkọ naa pẹlu iyawo keji to fẹ.
Arabinrin Idowu ṣalaye fun ile ẹjọ naa pe ọkọ oun ko ṣe e fi ọkan tan ati wi pe ni kete ti oun bi ọmọ ni ọkọ oun ti sọ fun oun pe oun ti fẹ iyawo keji ti awọn ẹbi rẹ fara mọ julọ nitori pe ọmọ ilu kan naa ni wọn.
O tun sọ fun mi pe oun yoo maa sun oorun ni ile emi ati iyawo tuntun to fẹ
"Abilekọ Idowu faraya pe:  Inu bi mi gidigidi nitori eyi ko si ninu adehun ti a jijọ ṣe, itiju nla leyi mu ba mi ladugbo ati ninu ẹbi."""
Mo si sọ fun Oyetunji pe ko di iyawo rẹ mu ko fi emi silẹ
O fi kun un pe ọkọ oun ko ṣe ẹtọ gbogbo to yẹ lori ọmọ kan ṣoṣo ti wọn bi fun ara awọn.
Akomolede ati asa Yoruba: Ẹ wá kọ́ nípa àpòtí ìṣura èdè wa lórí BBC Yorùbá
Oyetunji salaye pe: lẹyin ẹgbẹrun lọna ọgbọn naira to fi ranṣẹ fun owo idanwo aṣekagba girama WAEC rẹ, ko mọ bi ọmọ naa ṣe joko ṣe awọn idanwo gbogbo to ku ati bi o ṣe wọ ile iwe giga fasiti.
Ninu ọrọ tirẹ, Oyetunji ni pe aisi ifẹ, aini igbẹkẹle ati iwa kotọ iyawo oun lo fa ipẹjọ kọkọ-kọkọ naa.
O ni ọdun to kọja loun jawọ ninu fifi owo ranṣẹ fun itọju ọmọ awọn nitori owo kotọ lo maa n fi anfani owo itọju ọmọ ti oun maa n fi ranṣẹ beere fun.
Sunday Igboho: Kò bójúmu bí wọn ṣe ní ká wá fi orúkọ́ sílẹ̀ bíi ọmọ ẹgbẹ́ Àmọ̀tekún lórí ayélujára
Ilumọọka awujọ kan to tun jẹ ajafẹtọlu, Oloye Sunday Adeyemọ, ti ọpọ eeyan mọ si Sunday Igboho ti gbarata lori ilana agbekalẹ ẹgbẹ Amotekun.
Igboho, lasiko to n ba BBC Yoruba sọrọ ni ohun ti awọn daba rẹ kọ ni ijọba n se, ko si tọ bi wọn se gbe Amotekun sabẹ ijọba rara.
O wa fi ọwọ gbaya pe oun funra oun gan setan lati lọ sere ọwọ ninu igbo pẹlu awọn ọdaran, ti wọn ba kan bura fun awọn nikan.
Bakan naa lo tun koro oju si bi wọn se ni kawọn eeyan to ba fẹ se Amotekun wa maa fi orukọ silẹ lori ayelujara, eyi to ni ko bojumu.
Tun wẹ, aarẹ ọdẹ Asọludẹrọ, Nureni Ajijola Anabi naa kin Igboho lẹyin pe ko yẹ ki ẹnikẹni ti ko ba fi ogun bura wa lara awọn Amotekun nitori wọn yoo ba ẹgbẹ naa jẹ.
Seriki Williams Abass: Ọba Badagry tó jẹ́ ẹrú, tó tún padà di olówò ẹrú
Oríṣun àwòrán, Others
Arise ni arika, arika si ni baba iregun, ọpọ ohun ti a ba se ni oni, n bọ wa di itan to ba di ọla.
Idi ree ti iran Yoruba ko fi lee gbagbe ipa manigbagbe ti Ọba Seriki Ifaremilekun Williams Abass Fagbemi se nigba aye rẹ.
O si daju pe bi onirese ko ba fin igba mọ, eyi to ti fin silẹ ko lee parun mọ laelae.
Alaye si ree lori bi Ọba Seriki Abass se lo igbe aye rẹ gẹgẹ baa se ka a loju opo Wikipedia ati awọn oju opo itakun agbaye miran.
Abule Joga-Orile lagbegbe ilu Ilaro nipinlẹ Ogun bayii ni wọn ti bi Ifaremilekun, ti orukọ baba rẹ si n jẹ Fagbemi.
Olowo ẹru kan nilu Dahomey ti orukọ rẹ n jẹ Abass si lo mu lẹru lasiko ogun Dahomey ati Egba nigba to wa ni ọmọ ọdun mẹfa, to si pa orukọ rẹ da si ti ọga rẹ.
Idi si ree to fi n jẹ Ifaremilẹkun Fagbemi Abass.
Oríṣun àwòrán, Others
Lẹyin naa ni wọn ta soko ẹru fun oyinbo Brazil kan to n jẹ Williams, ẹni to gbe Seriki Abass lọ sorilẹede Brazil lati lọ se ọmọ ọdọ rẹ.
Ni kete to si de silẹ Brazil ni ọga rẹ yii tun yi orukọ rẹ pada si Williams nitori ẹru ko ni idamọ kankan to yatọ si ti olowo rẹ.
Brazil ni William Abass ti mọọkọ-mọọka ninu ede Dutch tilẹ Netherlands, bakan naa lo gbọ ede oyinbo, Spanish ati pọtugi.
'Oyenusi ló mú mi wọ ẹgbẹ́ adigunjalè kó tó di pé mo b'Ólúwa pàdé'
Nigba to ya ni Seriki Abass pada sorilẹede Naijiria lẹyin to ti se adehun pẹlu ọga rẹ, Williams pe oun yoo jẹ alabasisẹpọ rẹ ninu owo ẹru.
Agbegbe Ọfin ni isalẹ Eko nilu Eko ni William Abass tẹdo si nigba to ti orilẹede Portugal de, ti ọpọ arọmọdọmọ rẹ to wa nisalẹ Eko lonii si n jẹ Williams, nigba tawọn miran pa orukọ mejeeji pọ, William Abass.
Oríṣun àwòrán, Others
Lẹyin naa lo tun lọ tẹdo silu Badagry laarin ọdun 1830, nibiti owo ẹru ti gbilẹ, to si mọ ilu naa bii atẹlẹwọ rẹ nitori o sunmọ ilu Porto Novo to ti se ẹru tẹlẹ.
William Abass n sisẹ owo ẹru lọ pẹlu ọga rẹ ni Brazil, to si n fi ọpọ ẹrun ransẹ si onitọun, ti oun naa si n ni owo ati ọrọ lati ipasẹ okoowo ẹru naa.
Pẹlu atilẹyin ọga rẹ, William Abass kọ ibudo nla kan silu Badagry ti wọn pe ni Brazillian Barracoon eyi ti wọn kọkọ fi ọparun kọ lọdun 1840.
Sunday Igboho: Ẹ fi Ògún búra fún wa láti jà fún ilẹ̀ Yorùbá láì gbé Amotekun sábẹ́ ìjọba
Lẹyin eyi ni wọn wa fi biriki, iso ati paanu kọ ile naa eyi ti wọn ko wa lati oke okun, nibiti wọn n ko ọpọ ẹru pamọ si, eyi to wa nilu Badagry di oni olonii.
William Abass di eekan ilu nilu Badagry, nigba ti yoo si fi di ọdun 1895, ọla ati owo rẹ ti burẹkẹ debi pe awujọ awọn Musulumi fi jẹ oye Seriki Musulumi fun ilẹ Yoruba lọdun 1895.
"Bí ẹ ṣe mọ̀wé tó, ẹ wá dánrawò níbí pẹ̀lú ""Àpólà Ọ̀rọ̀ Orúkọ - Noun Phrase"
Nigba to ya ni awọn eebo amunisin fi jẹ ọba ilu Badagry lọdun 1913, ẹni to ba si de ile rẹ naa nilu Badagry, yoo ri aloku awọn ohun to fi n se ọla lasiko naa.
Lẹyin eyi ni Ọba Seriki Abass Williams tun da awọn ilu meji miran silẹ nilẹ Yoruba, awọn ilu naa ni Ayetoro ati Idogo, ti wọn wa nipinilẹ Ogun titi di oni.
Ọba Seriki Abass Williams lọla, o lowo, ti akọsilẹ kan si sọ pe o ni aya toto mejidinlaadoje pẹlu ọmọ mẹrinlelogoje.
Alaafin: Olori Aanu Adeyemi ṣàlàyé ìdí tó ṣe gẹ́ Oba Lamidi Adeyemi ti ìlú Oyo
Ọpọ aseyọri ni Ọba Seriki Abass Williams se lasiko to wa lori loke eepẹ, lara wọn si ree:
Badagry: Ojú ọ̀nà àrèmabọ̀ fáwọn ẹrú tó ń lọ sókè òkun
Ọjọ Kọkanla osu Kẹfa ọdun 1919 ni Ọba Seriki Ifaremilekun Abass Williams Fagbemi waja nilu Badagry.
Wọn sin sinu agboole rẹ ti wọn n pe ni Brazillian Barracoon nilana ẹsin Musulumi.
Oríṣun àwòrán, Others
Itan aye Ọba Seriki Abass Williams kọ wa lati lu aluyọ lai naani bi ibẹrẹ aye wa se ri
O tun kọ wa lati jẹ olotitọ si awọn eeyan to jẹ asiwaju wa boya ọga wa lẹnu isẹ abi obi wa
Itan yii tun kọ wa pe ka maa ranti ile ni orilẹede korilẹede taa ba wa.
'Tíátà ọ́mọdé tí wọ́n ń kọ́ wa ní Bariga ti mú mi lọ Germany, Switzerland, Amsterdam...'
Grace Oyin Adejobi: Ẹ̀yin òṣèré tíátà lóbìnrin tẹ́ ǹ bọ́ra sí ìhòhò, ẹ sá fún ìtànjẹ́ ayé
Oríṣun àwòrán, Grace Oyin Adejobi
Gbajugbaja osere tiata lede Yoruba, Grace Owoola Oyin Adejobi ti sọ pe ibi tohun ba iṣẹ ere itage de bayii, ohun ko lero wi pe ohun yoo le ṣe ere mọ.
Arabinrin ẹni aadọrun ọdun naa ṣalaye pe, kii ṣe nitori nkankan bi kii ṣe pe agba ti de.
Ninu ifọrọwerọ Iya Oṣogbo lori eto ori redio kan, iyawo agba-ọjẹ oṣere Oyin Adejobi ni, nnkan bii ọdun mẹtadinlaadọta loun bẹrẹ ere ori itage.
Arabinrin Adejobi wa bẹnu atẹ lu bi awọn oṣere tiata kan paapa awọn obinrin, ti ṣe maa n mura ihoho.
Nigeria movie industry: Àgbà òṣèré, Lere Paimo ní àìgbọràn ló ń da ọ̀pọ̀lọpọ̀ àwọn
O ni ki wọn maṣe jẹ ki yoroyoro aye tan wọn jẹ, ki wọn si gbagbọ pe ogo Ọlọrun nikan lo le gbe wọn de ipo ọla.
Lara alaye ti Iya Oṣogbo ṣe lori eto naa tun ni ere sinima ti akọle rẹ jẹ Eran Iya Oṣogbo, eyi to fi gba orukọ.
''Mo ti fi orukọ mi lelẹ ṣaaju ki ere Eran Iya Oṣogbo to jade. Kii ṣe ootọ pe ere yii lo gbe ogo mi jade''
Gbajúgbajà òsèré tó tún mọ́ ọbẹ̀ sè
Nipa ọjọ manigbagbe nigbesi aye osere yii, Iya Oṣogbo ni ọjọ ti ololufẹ ere awọn kan fẹ ẹ fi ọkọ gba awọn da si gọta nilu Ibadan ni nitori inu rẹ to dun julọ.
''Mi o le gbagbe ọjọ yii nitori pe mo ro pe ọlọjọ lo de ni. Ẹni naa to fẹ ki mi, ki o to ṣeṣi fi ọkọ gba mi wa pada fun mi ẹgbẹrun mẹwa naira to fisi apo iwe''
Oríṣun àwòrán, Grace oyin Adejobi
Lọdun 1953 ni Iya Oṣogbo ni oun bẹrẹ si ni ṣere. Nigba naa lọhun o ni oun a ma ṣere alarinjo kaakiri Naijiria paapa julọ, ni ilu Jebba ni ipinlẹ Kwara.
Kano Woman who killed son: Obìnrin kan dèrò ilé ẹjọ́ lórí ẹ̀sùn pé ó fi ọ̀bẹ rẹ́ ọmọ rẹ̀ lọ́rùn
Oríṣun àwòrán, Other
Obinrin ẹni ọdun mẹtadinlọgbọn kan ti di ẹni to n kawọ pọn rojọ niwaju Adajọ lori ẹsun pe o ṣeku pa ọmọ rẹ ẹni ọdun marun un.
Afurasi ọhun to n gbe labule Sabon Birni, to wa ni ijọba ibilẹ Gwarzo ni ipinlẹ Kano n jẹjọ ẹsun kan ṣoṣo, eyii to ni ṣe pẹlu ipaniyan.
Agbẹjọro ijọba, ọgbẹni Lamido Sorondinki, so fun ile ẹjọ pe afurasi naa hu iwa ọdaran naa lọjọ kejila, oṣu Kẹfa, ọdun.
Sorondinki sọ pe ọbẹ ni obinrin ọhun fi dubu ọmọ rẹ bi ẹni pa ẹran Ileya ni nnkan bi aago mẹjọ owurọ lọjọ naa lọhun.
Eyii to mu ko rọ ile ẹjọ naa pe ki wọn ṣe ayẹwo arun ọpọlọ fun arabinrin ọhun, gẹgẹ bo ṣe wa ninu iwe ofin ọdun 2019.
Gẹgẹ bo ṣe sọ, o ni ẹsun naa tapa si ofin to rọ mọ iwa ọdaran to wa ni abala 225 ninu iwe ofin.
Akomolede ati asa Yoruba: Ẹ wá kọ́ nípa àpòtí ìṣura èdè wa lórí BBC Yorùbá
Nigba ti wọn ni ko wa wi tẹnu rẹ, afurasi ọhun ni oun gba pe oun jẹbi ẹsun ti wọn fi kan oun.
Adajọ to n gbọ ẹjọ ọhun, Ibrahim Karaye, ti ni ki wọn gbe e lọ si ile iwosan awọn alaarun ọpọlọ fun ayẹwo.
Lẹyin naa lo sun igbẹjọ ọhun si ọjọ kẹjọ, ọsu Kẹwaa, ọdun 2020.
Sunday Igboho: Ẹ fi Ògún búra fún wa láti jà fún ilẹ̀ Yorùbá láì gbé Amotekun sábẹ́ ìjọba
Libya shipwreck: Aṣàtìpó lọ sí Yuropu 45 kú sínú òkun ní Libya, 37 m'órí bọ́
Oríṣun àwòrán, Getty Images
O kere tan aṣatipo marundinlaadọta lo dero ọrun, lẹyin ti engini ọkọ oju omi to n gbe wọn lọ si ilẹ Yuropu lati Libya gbina ti wọn si ja sinu okun.
Igbimọ ajọ iṣọkan agbaye to n ri si ọrọ awọn aṣatipo, UNHCR lo fidi ọrọ naa mulẹ.
Awọn mẹtadinlọgbọn tawọn apẹja doola ẹmi wọn ṣalaye pe, awọn ọmọde marun un wa lara awọn to bomi lọ naa.
Ajọ iṣọkan agbaye ati ajọ to n ri si ṣiṣikiri awọn eeyan to n rinrin ajo lori omi okun ti sọ pe awọn to n doola ẹmi awọn arinrin-ajo lori omi gbodọ pọ si.
Wọn lai jẹ bẹẹ, awọn to maa ṣegbe si inu omi okunyoo tubọ maa pọ si.
Akọsilẹ fihan pe awọn aṣikiri to le ni ọdunrun un lo ti ku sinu okun Mediterranean lọna irin ajo wọn lati Libya si ilẹ Yuropu.
Lati ọdun 2011 ti olori orilẹede Libya tẹlẹ, Muammar Gaddafi ti ku ni awọn aṣatipo ti n gba ibẹ lọ sọda si Yuropu.
Ẹwẹ, awọn ti ori iṣẹlẹ ko yọ ninu iṣẹlẹ Ọjọru ti wa lahamọ bayii ni Libya lẹyin ti wọn doola ẹmi wọn tan.
Awọn aṣatipo naa ni a gbọ pe wọn wa lati orilẹede Senegal, Mali, Chad ati Ghana.
Risikat Azeez: Aya gómìnà tún fẹ́ gba sọ́ọ́bù, ra ọjà fún obìnrin olójú búlúù
Oríṣun àwòrán, @Mohammed Jagunma ati Gold Abdulrafiu
Ojo oriire si n rọ siwaju fun idile Risikat Oloju Buluu ati ọkọ rẹ, Abdulwasiu pẹlu awọn ọmọ wọn.
Idi ni pe aya gomina ipinlẹ Kwara, Olufolake Abdulrazaq, to ti tẹwọgba ọrọ wọn lati ilẹ ko tii jawọ nibẹ, to si tun n se wsn loore siwaju lọ.
Nibayii, lẹyin ayẹyẹ yigi ti wọn so lọjọ Satide, aya gomina ti gba ile fun wọn lati maa gbe lọtọ yatọ si ile mọlẹbi.
Nigba to n fidi isẹlẹ naa mulẹ, akọwe iroyin si aya gomina, Yinka Adeniyi sisọ loju rẹ fawọn akọroyin pe, lati ipasẹ ẹgbẹ alaanu ti aya Abdulrazak da silẹ, ni eyi ti see se.
Oríṣun àwòrán, Arewa_ilorin_pple
Ẹgbẹ alaanu naa, to pe ni Ajike Support Grouplo gba ile filaati oniyara meji fun idile naa laarin igboro ilu Ilorin.
O fikun pe ọjọ Ẹti to kọja ni wọn fun tọkọtaya naa ni kọkọrọ ile naa, nigba to ku ọla ti wọn yoo so yigi.
Bakan naa lo ni adugbo tawọn ẹbi ọhun fẹ ni wọn gba ile naa si fun wọn.
Akomolede ati Aṣa lori BBC: Mọ̀ si nípa oríṣìí ẹ̀ka ìsọ̀rí ọ̀rọ̀ àti ìwúlò wọn
Awọn eto ti aya gomina ni fun Risikat ati ọkọ rẹ wa nipele ipele, a tun fẹ gba sọọbu fun obinrin oloju buluu naa lati maa ta oogun to kọ isẹ rẹ.
"A lero lati san owo ile ati owo sọọbu rẹ papọ ni, amọ a gbọ pe ẹlomiran ti gba sọọbu ta fẹ sanwo rẹ naa, idi ree ta fi sanwo ile nikan, ta si ni ki obinrin naa lọ wa sọọbu miran."""
Akọwe iroyin aya gomina tẹsiwaju pe lẹyin eyi ni wọn yoo gba iwe asẹ lati maa ta oogun fun obinrin naa, ti wọn yoo si ra oogun kun inu sọọbu rẹ fun tita.
A wa n ki Risikat ati ọkọ rẹ pe wọn ku oriire ayọ igbeyawo, Ọlọrun yoo se wọn ni ọrẹ ara wọn.
Oríṣun àwòrán, @Mohammed Jagunma ati Gold Abdulrafiu
Loni, ọjọ Satide, ọjọ karun un, oṣu kẹsan an ni Baba Kausara àti Iya Kausara di ara kan naa bii lọkọlaya ninu ẹsin Islam ni Ilorin ni ipinlẹ Kwara.
Se ẹ ranti ọrọ Risikat ati Wasiu ọkọ rẹ nitori oju bulu aya ati ọmọ rẹ meji?
Risikat Moromoke Azeez: Inú èmí àti Òbí mi dùn nígbà ti Risi bí ọmọ olójú búlù- Wasiu
Iroyin ni Ilorin Emirate Dev. Progressive Union lo ṣagbatẹru Nikkah naa laarọ yii.
Ni ọkọ ba ti mọ oju aya tan,
Ki gbogbo alarina yẹba lo ku.
Oríṣun àwòrán, @Mohammed Jagunma ati Gold Abdulrafiu
Oríṣun àwòrán, @Mohammed Jagunma ati Gold Abdulrafiu
Lawọn Aafa nlanla ba kuku so yigi Iya Kausara ati Baba Kausara o
Ni awọn alarinna ba ṣetan ati yẹba fun tọkọ taya.
Oríṣun àwòrán, @Mohammed Jagunma ati Gold Abdulrafiu
Eyi lo tun fidi imọran awọn agba Yoruba mulẹ pe iwọnba leeyan n da si ọrọ lọkọlaya mọ nitori....
Oríṣun àwòrán, @Mohammed Jagunma ati Gold Abdulrafiu
Abi ẹ o riṣẹ Olorun bi?
Ero peju sibẹ lati ba Risikat ati Wasiu yọ ni Ilọrin ni ipinlẹ Kwara ni aarin gbungbun Naijiria.
Oríṣun àwòrán, @Mohammed Jagunma ati Gold Abdulrafiu
Ki lo ti ṣẹlẹ sẹyin?
Ọba Ilorin ló pàṣẹ pé kí ń padà sọ́dọ̀ ọkọ mi - Risikat olójú búlúù
Ilé wa ni mo ṣì wà, èmi kò tíì padà sọ́dọ̀ Bàbá Kaosara
Arabinrin Risikat Azeez ti ọpọ eeyan mọ si oloju buluu, naa ti fesi lori awọn ohun ti ọkọ rẹ ba BBC Yoruba sọ l‘Ọ́jọbọ.
Risikat Azeez: Ilé wa ni mo ṣì wà, èmi kò tíì padà sọ́dọ̀ Bàbá Kaosara
Bẹẹ ba gbagbe, a mu iroyin wa fun yin pe ọkọ Risikat Abdulwasiu Azeez ni oun ati aya oun ti pada sọdọ ara awọn, ti awọn si ti jọ n se mukẹẹkẹ.
Sugbọn ninu ifọrọwerọ rẹ pẹlu wa ni  aarọ ọjọ Ẹti, Risikat ni oun ati baba Kaosara dijọ ya fọto papọ ni, ile awọn si ni oun si wa.
"Rara o, wọn so yigi o, ile wa ni mo wa. Ohun ti mo kan ri nibẹ ni pe aya gomina Kwara ran awọn eeyan wa pe awọn fẹ ka pari aawọ to wa laarin wa, ka si maa sọrọ sira wa.
O tan o, nnkan ti wọn wa fun niyẹn.
Risikat fikun pe, nigba to ya ni wọn tun ni ki eeyan kan wa wọn oun ati ọkọ oun, ti yoo ba awọn ran asọ wa, ti onitọun si gbe ankoo naa wa ni ọjọ keji.
Bí ẹ ṣe mọ̀wé tó, ẹ wá dánrawò níbí pẹ̀lú Àpólà Ọ̀rọ̀ Orúkọ - Noun Phrase"
"Nigba to di Ọjọru, ni wọn ni ka ko asọ wa dani, ti wọn si ni ki wọn se oju mi loge fun mi nibudo ẹkọsẹ asaraloge ti mo ti n kọsẹ.
Ati ibẹ ni ọga mi ti gbe mi lọ si ile ijọba, a debẹ, ni wọn ba n ya fọto fun wa, ohun ta ri naa nuu."
Risikat fikun pe lootọ ni aya gomina n sọ pe ki awọn mejeeji pari ija, ki awọn si maa sọrọ si ara awọn, ti wọn si ya fọto fun awọn.
Nigba ti BBC Yoruba bi iya Kaosara leere pe se lootọ lo ti n lọ sun sile ọkọ rẹ gẹgẹ bi ọkọ rẹ ti sọ fun wa, o dahun pe:
Risikat Azeez: Ìyá àti bàbá ọmọ olójú búlù tí parí ìjà- wọ́n fẹ́ tún yìgì so
Mo fi Ọlọrun Ọba bura, ko si ohun to jọọ, ile wa ni mo wa, n ko si lọ sile ọdọ rẹ
Lori ipalẹmọ lati tun yigi so, Risikat ni ọba Ilọrin ti ran awọn eeyan wa lati ba awọn pari ija, to si ni wọn ti n pari rẹ lọwọ.
A ko tii mu ọjọ iyawo, amọ wọn saa fẹ se, ki wa ni mo fẹ se? Ọba Ilọrin sọ pe ohun ti oun yoo se niyẹn, oun gbẹsẹ le.
Amọ nigba taa bii pe ki lo fẹ ki wọn seto, ko to pada sọdọ ọkọ rẹ, Risikat ni ti wọn ba pari ija tan laarin awọn mejeeji, ko sẹni ti yoo ya si ọdọ awọn mọ.
Ko sẹni to sọrọ lori ọrọ isẹ mi mọ, mo si fẹ ki wọn mojuto ọrọ ile iwe awọn ọmọ mi, isẹ temi naa, bẹẹ ni skọ mi gan ko ni isẹ to duro re.
Oríṣun àwòrán, Arewa_ilorin_pple
Arakunrin Abdulwasiu Ọlọmọyọyọ, tii se ọkọ Risikatu Azeez, arabinrin oloju buluu nilu Ilorin, ti fi idunnu ati ayọ rẹ han fun awọn ọmọ naijiria lori aayan ti wọn ko lati jẹ ki ija to wa laarin oun ati iyawo rẹ pari.
Bakan naa ni Abdulwasiu, ti ọpọ eeyan tun mọ si baba Kaosara tun dupẹ pupọ lọwọ ileesẹ iroyin BBC Yoruba fun atilẹyin wa lori ọrọ naa ati ibi taa ba de, eyi to ni apẹrẹ rere.
Ọkọ Risikat oloju buluu naa ko sai tun se sadankata si aya gomina ipinlẹ Kwara, fun iranwọ to n se lati ri pe idile oun pada toro pẹlu itọju to n se fun wọn.
Amọ sa, Abdulwasiu wa fidi rẹ mulẹ pe laipẹ laijinna, oun ati iyawo oun yoo tun tun yigi so, ti idile oun yoo si pada duro re.
Oríṣun àwòrán, Arewa_ilorin_pple
Saaju la ti mu wa fun yin pe Abdul Wasiu ti sọ fun ileeṣẹ BBC Yoruba pe ni nibayi, ija ti pari laarin oun ati iyawo rẹ.
''Inu mi dun pupọ. Mo dupẹ lọwọ Ọlọrun ati awọn ọmọ Naijiria fun aduroti wọn''
O ṣalaye pe lọdọ Risikatu loun ti kuro laarọ yii ati pe ko ni pẹ ti awọn yoo fi tun ṣe yigi pada''
Ìdílé tí ọkọ da ọmọ síta tóríi ojú Búlùú tí wọ́n ní bá BBC sọ̀rọ̀
Laipẹ yii ni awọn eeyan n beere boya awọn mejeeji yoo pari ija laarin ara wọn.
Koda iyawo Gomina ipinlẹ Kwara sọ wipe, oun yoo gbiyanju lati pari ija laarin awọn mejeeji.
Ninu ohun ta ri gbọ lẹnu Baba Kaosara bakan naa o sọ pe, iyawo Gomina lo ba awọn pari ija naa ,ti o si tun ṣatọkun bi wọn ti ṣe jijọ ya aworan papọ.
Nigba ti BBC Yoruba bi Abdulwasiu pe ki ni yoo sẹlẹ lẹyin ti wọn ba tun yigi se, ti aya rẹ si tun bi ọmọ oloju bulu, baba Kaosara dahun pe ọmọ oloju gan ni oun n tọrọ lọwọ Ọlọrun bayii.
Risikat Moromoke Azeez: Inú èmí àti Òbí mi dùn nígbà ti Risi bí ọmọ olójú búlù- Wasiu
Inu mi yoo dun pupọ ta ba tun bi ọmọ ti oju rẹ yoo bulu, koda, ki ni mo fẹ fi ọmọ olju funfun se mọ, mo tiẹ n gbadura pe gbogbo ọmọ ti Ọlọrun yoo ba fun mi siwaju, ki wọn jẹ oloju bulu.
Abdulwasiu ti wa kesi awọn ọmọ Naijiria lati ṣe iranwọ fun ohun ni[pa ọna iṣẹ lati le fi tọju mọlẹbi rẹ.
O sọ pe ko si iṣẹ kankan lọwọ oun bayii, toun si n beere iranwọ lọdọ awọn araalu lati se atọna bi oun yoo se ri isẹ.
Risikat Azeez: Ìyá àti bàbá ọmọ olójú búlù tí parí ìjà- wọ́n fẹ́ tún yìgì so
Islamic New Year: Ọdún mùsùlùmí Hijiri tuntun bẹ̀rẹ̀ ní Nàìjíríà
Oríṣun àwòrán, Others
Bi awọn musulumi ni Naijiria ṣe n ki ara wọn ku orire ibẹrẹ ọdun tuntun wọn, igbimọ alakoso ẹsin Islam ni Naijiria, NSCIA ti sọ pe, ọjọ Jimọ, ọjọ Kọkanlelogun oṣu Kẹjọ ni onka ọdun tuntun yoo bẹrẹ.
Wọn ni idi ni pe awọn ko ri oṣu Muharram, ti o n tọka pe oṣu naa ti bẹrẹ.
Ikede yii wa loju opo ajọ NSCIA to wa ni Facebook ti wọn fi sita lorukọ Sultan Sokoto, tii ṣe olori awọn musulumi Naijiria.
Ṣugbọn o, ọpọ eeyan ni ko mọ wi pe awọn larubawa ti n ṣe amulo ọdun oloṣu mejila naa, ṣaaju ki Anọbi Muhammad (SAW) to daye.
Oṣu oju ọrun yii ti wa tipẹ ti awọn musulumi si mu lo, lẹyin igba ti Anọbi rinrin ajo lati Makkah lọ si Madinah.
AH, ti wọn n kọ sẹyin ọdun yii tun mọ si lẹyin igba Hijrah.
Risikat Azeez: Ìyá àti bàbá ọmọ olójú búlù tí parí ìjà- wọ́n fẹ́ tún yìgì so
Nitori pe oṣu oju ọrun ni wọn maa n tẹle, ko si kankan ninu awọn oṣu yii ta le sọ pe gerege iye ọjọ bayii lo jẹ.
Lọpọ igba, iyatọ ọjọ mọkanla a maa waye laarin ọdun kan si omiran, bakan naa, iye ọjọ oṣu kọọkan le yatọ si ara wọn.
Bi oṣu mii ba pe mọkandinlọgbọn, omiran le pe ọgbọn tabi ki o si jẹ mejidinlọgbọn.
Alaye ree lori orukọ awọn oṣu kọọkan itumọ ati bi wọn ṣe n pe wọn:
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ọgọrọ awọn musulumi lo maa n kopa ninu isin Hajj ọlọdọọdun
Osu yi tumọ si oṣu eewọ lede larubawa.
Ohun ni osu kini ọdun musulumi, tawọn musulumi si ma n yago fun ogun jija, itajẹsilẹ tabi itahun sira ẹni ninu oṣu yii.
Oṣu keji ọdun ree, o tumọ si ifayegba, nitori oṣu yii lawọn larubawa maa n ṣe ikọlu sawọn ilu to ba wa lagbegbe wọn laye atijọ.
Oṣu Kẹta ree, ohun si ni igba ti irugbin maa n ṣu yọ, to si ṣe deede pẹlu asiko ti irugbin maa n gberi lọdọ wa nibi.
Oṣu yi tumọ si ipari asiko tiirugbin maa n ṣu yọ.Wọn a tun maa pe oṣu yi ni Rabi Al Thani.
Jumada- Al Ula:
Orukọ oṣu yi waye latari bi ọgbẹlẹ ṣe maa n waye .Awọn kan sọ pe wọn fi asiko ti ọgbẹlẹ maa n waye fi sọri oṣu yi.
6 Jumada Al Akhirah- Idakeji oṣu Jumada-Al Ula ni oṣu yi jẹ.Ohun ni asiko ti  ọgbẹlẹ ba wa si opin.
Oríṣun àwòrán, @Aquabi
Ina alarabara loriṣiiriṣi ni wọn fi ṣẹẹsọ si mọṣalaṣi nla yii
Oṣu ọwọ ati eewọ ni oṣu yi jẹ.Awọn larubawa kii jagun loṣu yi rara ati rara
Oṣu Kẹjọ ni Sha'aban.Ninu oṣu yi lawọn larubawa maa n fọnka lori lẹ lati wa omi ati ounjẹ fun nnkan ọsin wọn.
Ramadan tumọ si asiko ti nkan ba gbona. Ninu oṣu yii to gbajumọ ju, lawọn musulumi maa n gbawẹ ọlọdọọdun.
Asiko yii loju ọjọ maa n gbona ju lọdọ awọn agbegbe larubawa.
Aworan awọn musulumi to n kirun
Orukọ oṣu yi wa latari bi awọn rankumi ṣe maa n ru ju ti tẹlẹ lọ ti omi mu wọn a si ma kere ju ti tẹlẹ lọ.
Ninu oṣu yi lawọn larubawa maa n ṣe adehun lati dẹkun ija jija.Wọn kii jagun tabi ba ara wn ja loṣu yi.
Ninu oṣu yi lawọn musulumi maa n ṣe irinajo Hajji lọdọọdun.O wa lara awọn oṣu to gbajumọ laarin awọn larubawa.
Mamman Daura: Ojú òpó ayélujára ń gbóná lórí ìlàkàkà ọmọ Nàíjíríà láti mọ́ ipò tí ìlera rẹ̀ wà
Oríṣun àwòrán, Others
Lowurọ ọjọbọ ni oju opo Twitter n gbona fẹlifẹli pklu ibeere awọn ọmọ ilẹ yii pe, ki ileesẹ aarẹ se alaye lori irinsi Daura.
Yoruba ni ti ko ba si ina, eefin kii ru, ibeere awọn ọmọ Naijiria ko sẹyin iroyin kan to jade laipẹ yii pe ara ibatan aarẹ naa ko da, ti wọn si ti gbe digbadigba lọ sile iwosan.
Idi ree ti BBC fi tiraka lati wa okodoro ọrọ nileesẹ aarẹ lati mọ ibi ti Mamman Daura wa, ati pe se lootọ ni o n se aisan.
Awọn eeyan kan to ba BBC sọrọ nileesẹ aarẹ amọ ti wọn ko fẹ darukọ wọn ni ibatan aarẹ naa rinrinajo lọ silu oyinbo lootọ, amọ kii se oun nikan lo lọ.
Oríṣun àwòrán, Others
Sibẹ, sibẹ, lai naani awọn alaye yii, ẹnu si n kun Mamma Daura loju opo ayelujara nipa ilera rẹ, bo ba si se jẹ, BBC Yoruba yoo maa mu ẹkunrẹrẹ iwadi wa wa fun yin.
Access Bank: Babaláwo ní òun yóò t'ọwọ́ Ifá bọ̀ọ́, tí Access Bank kò bá dá owó ìyá òun pádà
Oríṣun àwòrán, Instagram/Oluwu Jogbodo Orunmila
Ṣe kii ṣe pe ile ifowopamọ Access bank n fi ori ọka họ imu bayii?
Babalawo kan to fi ilu Ibadan ṣe ibugbe, Oluwo Jọgbọdọ Orunmila ti sọ fun ile ifowopamọ naa pe, ti ko ba ẹgbẹrun lọna igba le mẹfa (₦206,000) owo mama oun to yọ pada, titi aago mẹrin irọle ọjọ Ẹti ọjọ kọkanlelogun oṣu kẹjọ yii, oun yoo ti ọwọ Ifa bọ ọ.
Oluwo Jọgbọdọ ni ti wọn ba kọ lati ṣe atunṣe, oun atawọn awo mii yoo lọ fi idan han wọn ni ẹka Access bank ti wọn ti yọ owo mama oun.
O ṣalaye pe, Ifa lo n ka oun lọwọ ko tẹlẹ lori ọrọ naa, bi bẹẹ kọọ, oun mọ ohun ti oun le ṣe lati wa owo naa rii ni kiakia.
L'Ọjọbọ ni Oluwo fun ile ifowopamọ Access Bank ni ọjọ kan pere, lati ṣe awari oṣiṣẹ rẹ to ṣ'okunfa bi ẹgbẹlẹgbẹ owo fi ranṣẹ si mama rẹ ṣe poora, ki wọn si da owo naa pada ni kiakia.
Oluwo ṣalaye pe, ẹgbẹrun lọna ọgọsan owo naira loun kọkọ fi ranṣẹ si mama oun lọjọ ibi rẹ laipẹ yii, ki oun to tun ṣe afikun owo naa pẹlu ẹgbẹrun mẹtadinlọgọta mii.
Jọgbọdọ Orunmila sọ pe, nigba ti mama oun fẹ gba ninu owo ọhun ni ẹka ile ifowopamọ Access Bank kan ni o bẹrẹ si ni awọn idojukọ kan eleyi ti ko jẹ ko ri owo gba.
Oluwo wa gba mọmọ rẹ ni imọran lati lọ sọ ohun to ṣẹlẹ ni ẹka banki naa, mọmọ ko beṣu bẹgba, o lọ sibẹ, nibẹ gan an ni wọn ti sọ fun mama pe kaadi ATM ko ṣiṣẹ daadaa wi pe o nilo omiiran.
Oluwo ni lẹyin ti mọmọ gbiyanju lo kaadi ATM tuntun to ṣẹṣẹ gba fi gba owo ni o bẹrẹ sii ri awọn atẹjiṣẹ ajeji pe o ti gba owo, eleyi ti ko si rii bẹẹ.
''Lẹyin naa ni mo sọ fun mọmọ mi lati lọ si ẹka ile ifowopamọ naa lẹẹkan sii pẹlu aburo mi ki wọn si mu ẹri bi banki naa ṣe jawo ninu apo ikowosi rẹ lọwọ,'' Oluwo lo sọ bẹẹ.
Jọgbọdọ Orunmila ni ''ohun ti a ri nipe ileeṣẹ ifowopamọ Access Bank ti yọ ẹgbẹrun lọna o le mẹfa naira ninu apo ikowosi mama mi lasiko ti wọn fun un ni kaadi ATM mii.''
O fikun ọrọ rẹ pe Banki Access tun sọ fun mama oun pe ki o buwọ luwe pe oun lo gba owo naa, bo tilẹ jẹ ko mọ bi eeyan ṣe le gba owo lori aapu to wa lori foonu.
Oluwo ni lẹyin naa loun pe ile ifowopamọ Access lati ṣalaye ohun to ṣẹlẹ, ṣugbọn o ni wọn ko tii ṣe ohun kan lori rẹ.
Ẹwẹ, ile ifowopamọ Access Bank pada fesi si ọrọ ti Oluwo fi lede loju opo Twitter rẹ, wọn dupẹ lọwọ rẹ wọn si tọrọ aforijin lori ohun ti oju mama rẹ ti ri.
Access Bank beere fun nọmba apo ikowosi mama ati ẹka ileeṣẹ wọn ti iya naa lọ, ki awọn le sẹ iwadii to peye lori ohun to ṣẹlẹ.
Rape cases in Nigeria: Ọmọ ọdun 5 àti 14 ni Kalu wà nígbà tí obìnrin fipá ba lòpọ̀
Ni orilẹede Naijiria ati lawujọ agbaye patapata, isẹlẹ ifipabanilopọ ti di tọrọ fọn kale.
Awọn obinrin si ni isẹlẹ naa maa n kan julọ, ti kii si saba wọpọ pe ki obinrin fipa ba ọkunrin lopọ.
Sugbọn nigba to n ba BBC sọrọ, ọkunrin kan ta fi orukọ ati ohun bo ni aṣiri, amọ ta sọ ni Kalu salaye pe ẹẹmeji ọtọọtọ lawọn obinrin ti fi tipa ba ohun lopọ.
Kalu ni nigba ti oun wa ni ọmọ ọdun marun ati mẹrinla ni isẹlẹ naa waye.
O wa fikun pe, awọn isẹlẹ ifipabanilopọ mejeeji tawọn obinrin to sun mọ oun pupọ se si oun yii, ko jẹ ki oun nigbagbọ mọ ninu ẹnikẹni.
Alaye ree lori bi awọn isẹlẹ ifipabanilopọ naa se waye, ẹ wo o.
Ondo Governorship Election: Ọ̀pọ̀ dúkìá àti mọ́tò bíí 15 làwọn jàǹdùkú bàjẹ́
Oríṣun àwòrán, Others
Ileesẹ slọpaa nipinlẹ Ondo ti fidi rẹ mulẹ pe laasigbo oselu waye lọjọbọnilu Ondo nipnilẹ Ondo
Nigba to n ba BBC Yoruba sọrọ, agbẹnusọ fun ileesẹ ọlọpa nipinlẹ Ondo, Tee-Leo Ikoro ni ninu aawọn naa ni ọpọ eeyan ti fara pa amọ ko si ẹni to ku ninu laasigbo naa.
Ileesẹ ọlọpaa ti n se iwadii nipa oun to fa isẹlẹ naa, ti a ko si lee se alaye awọn ẹgbẹ oselu ti aje ọrọ naa si mọ lori nitori o ti di ija igboro.
Ikoro ni ọwọ ọlọpaa ti ba awọn janduku ẹda kan to lọwọ ninu rogbodiyan ọhun, ti iwadii si tun n lọ lọwọ lati mu awọn afurasi ọdaran miran si.
Iroyin kan fikun pe ọps dukia ni wọn baana lasiko ija igboro to jẹ ti oselu naa, ko si din ni ọkọ ayọkẹlẹ mẹẹdogun to bajẹ.
Rape cases in Nigeria: Ọmọ ọdun 5 àti 14 ni Kalu wà nígbà tí obìnrin fipá ba lòpọ̀
Sugbọn ileesẹ ọlọpa ko tii le sọ ohun to sokunfa isẹlẹ naa.
Wo tuntun tó ṣẹlẹ̀ lágbo àwọn òṣèré Yollywood bíi Femi Adebayo, Odunlade Adekola, Toyin Abraham, Funke Akindele lọ́sè̩ yìí
Oríṣun àwòrán, others
Lọsẹ yii, o da bii pe awọn oṣere Yoruba naa ti n wọle pada sẹnu iṣẹ tiata wọn ni pẹrẹwu gẹgẹ bi ijọba naa ṣe bẹrẹ si ni ṣi awọn ibi kọọkan pada lẹyin isede oṣu gbọọrọ torii arun COVID-19.
Ọpọlọpọ sinima agbelewo lo ti n jade bo tilẹ jẹ wi pe lori ayelujara nikan naa lẹ ṣi ti le ri wọn wo bayii.
Awọn oṣere gangan ti n bọ sori itage pada bayii pẹlu oniruuru sinima to ni akọle awoyanu atawọn eto pataki mii to yatọ si sinima tawọn oṣere gbe ṣe laarin ọsẹ to kogba wọle lọ yii.
Oni gan ni Toyin Abraham, iya Ire pe ẹni ogoji ọdun laye Toyin Abraham pé 40, wo ohun márùn ún tó mú dá yàtọ̀ láàrín ogójì ọdún
Ọpọ eeyan lo ti n kii ku oriire lai yọ baba Ire gan an silẹ to ki Toyin ni oriki to pọ pẹlu adura ọjọ iwaju rere.
Toyin Abraham funra rẹ naa ki ara rẹ ku oriire pẹlu adura pe...
Ọṣẹ yii ninu aye Odunlade Adekọla:
Gbogbo ọsẹ yii ni ilumọọka oṣere, Odunlade Adekola fi n polowo ipadabọọ sinima rẹ, Saamu Alajọ eyi ti gbogbo eeyan n wari fun
Loju opo instagram rẹ, lo ti n fun awọn eeyan ni itọwo kekeke ninu ẹkunrẹrẹ fiimu Saaamu Alajọ to jẹ sinima apanilẹrin.
Nítorí owú jíjẹ, ọkọ Zarka gé imú aya rẹ̀ dànú!
Lọdọ Funke Akindele n kọ lọsẹ yii?
"Lati ọsẹ to kọja ti Funke Akindele ti ṣe nkan ayọ onibẹta iyẹn ayẹyẹ ọdun igbeyawo oun ati ọkọ rẹ, ọjọ ibi rẹ bakan naa lo kede fiimu tuntun rẹ to gbe jade eyi to jẹ ipadabọ fiimu rẹ ""Omo Ghetto""."
Pẹlu awọn aworan to n fi sita lo ti ye ni pe ara ọtọ leyii bẹẹ si ni Funke Akindele gan an ninu sinima naa yatọ si eyi tẹẹ mọ ninu apa kinni Omo Ghetto.
Bẹẹ si ni o da bii pe ipa ti o ko ninu sinima eleyii tun yi lori ju ti akọkọ lọ.
Ninu aye Femi Adebayo, bẹbẹ jade lọsẹ yii:
Odu ni Femi Adebayo ninu agbo awọn oṣere Yoruba toun naa si ti n ṣe itọwo awọn fiimu to fẹ gbe jade.
"Oṣere ọmọ Ilorin yii ti baba rẹ ati aburo rẹ naa jẹ akẹgbẹ fun un ninu iṣẹ fiimu ti n fi oriṣiriṣi aworan sinima ara ọtọ meji kan sita - ""Ẹsin Agbere"" eyi to ṣe lati fi tu aṣiri awọn aafaa to n ṣe lodi si bi o ṣe yẹ ki wọn maa ṣe ẹsin ati ""Sisi""."
Àṣìṣe ọlọ́pàá àti Adájọ́ sọ mí di ẹni tí wọ́n dájọ́ ikú fún, ọpẹ́lọpẹ́ Fayoṣe tí ko buwọlu
Wo ohun tó ṣẹlẹ̀ sí Saka, Sunkanmi Omobolanle àtàwọn òṣèré sinimá míràn lọ́sẹ̀ to kọja
Eyi ni awọn iroyin nipa awọn oṣere sinima to waye laarin ọsẹ to kọja.
"Ṣe ẹ ranti agba oṣere ""Saka I don port"" alawada ninu ọpọ ere agbelewo ṣe ọjọ ibi ni Ọjọbọ, Ogunjọ osu kẹjọ ọdun yii."
Ni ọdun 1963 ni wọn bi alagba Afeez Oyetoro ti ọpọ mọ si Saka ninu ere agbelewo.
Oríṣun àwòrán, Brodashaggi
Ilu isẹyin ni wọn si bii si ni ipinlẹ Ọyọ.
Lọwọ yii, olukọni ni ni ileewe ẹkọṣẹ olukọni agba, Adeniran Ogunsanya College of Education ni ilu Eko.
Ọpọlọpọ awọn eekan oṣere ni wọn ki alagba naa ku oriire ayẹyẹ orikadun.
Yatọ si alagba Saka, eekan oṣere miran, Kelvin Idkeduba pẹlu ṣe ọjọ Ibi rẹ lọsẹ yii.
Ọjọ kọkanlelogun, oṣu kẹjọ ni ọjọ ibi Kelvin ni tirẹ.
Ni ọdun 1976 ni wọn bi Kelvin Ikeduba lagbegbe Ebute Metta ni ilu Eko.
Bi o ṣe n ṣe ere ede Yoruba naa lo n ṣe sinima ede Oyinbo ati Igbo.
Lara awọn eekan to kii ku ayẹyẹ ọjọ ibi rẹ ni Mercy Aigbe, Sunkanmi Ọmọbọlanle
Làásìgbò òṣèlú wáyé nílùú Ondo, ọ̀pọ̀ èèyàn fara pa
Kí ni ọkùnrin yìí ṣe tí bàbá rẹ̀ fi só mọ́lẹ̀ fún ọgbọ̀n ọdún?
Ọba Ilorin ló pàṣẹ pé kí ń padà sọ́dọ̀ ọkọ mi - Risikat olójú búlúù
Ìgbà mẹ́ta ọ̀tọ̀ọ̀tọ̀ tí ìjọba Nàìjíríà ti gbẹsan lára orilẹ-ède mí tó dẹ́yẹsí i
Oríṣun àwòrán, Sunkanmi omobolanle
Eekan oṣere tiata, Sunkanmi Ọmọbọlanle, ọmọ gbajugbaja oṣere, Sunday Ọmọbọlanle ti ọpọ mọ si Pappy Luwẹ ti gbalejo ọmọ tuntun ni aarin ọsẹ yii.
Sunkanmi to fi fọto ati ikede ibi ọmọ rẹ si oju opo Instagram rẹ ni Aderinsọla ni wọn sọ orukọ ọmọ naa.
Oríṣun àwòrán, omotala_jalade
Awọn ololufẹ Omọtọla Ekeinde ti ọpọlọpọ mọ si Ọmọsexy gbadura fun un lẹyin to ko COVID-19
Lati igba ti o kede pe oun ti ko aarun COVID-19 laipẹ yii, awọn ololufẹ agba oṣere sinima naa ti n ki i pẹlu adura pe yoo ye arun naa ati pe piri lolongo rẹ yoo ji lẹyin o rẹyin arun naa.
Awọn ololufẹ rẹ ya bo oju opo Instagram rẹ ti wọn si n fi adura ati ikini ranṣẹ sii.
Oríṣun àwòrán, others
Àwọn òṣèré tíátà Yorùbá kọjú ìjà síra wọn lórí ìdárò akẹẹgbẹ́ wọn tó kú
Awaye ku ko si, Ọba oke mase jẹ ka fi ọjọ ọlọjọ lọ ni.
Ọfọ nla ti sẹ ni agbo ere tiata ni ọjọ Aje, eyi to dori awọn irawọ osere kodo.
Iku tun to wọ agbo awọn oṣere tiata nilẹ yii naa, nigba ti yoo si fi jade, ọkan lara awọn aṣaraloge  (Makeup Artist) lẹka ere tiata Yoruba, lo mu lọ.
Orukọ oloogbe naa ni  Williams Anuoluwapọ, ti ọpọ mọ si Kumbalee.
Sugbọn awọn ọrọ ti awọn osere kan n sọ lori iku ọkunrin naa ati awọn eeyan to n sọfọ rẹ, n kọ ni lominu.
Eyi si lo mu kawọn osere tiata kan fajuro lori ohun tawọn akẹẹgbẹ wọn n kọ nipa iku ọkunrin naa, ti wọn si n gbena woju ara wọn.
Sugbọn ọrọ aro ti ọpọ wọn n kọ soju opo Instagram wọn lo safihan pe, wọn n paroko ọrọ ransẹ saarin ara wọn, to si ni itumọ to jinlẹ.
Akomolede ati asa Yoruba: Ẹ wá kọ́ nípa àpòtí ìṣura èdè wa lórí BBC Yorùbá
Akure: Deji Akure, Oba Aladelusi Ogunlade ti pàṣẹ kí gbogbo ọjà wà ní títì pa fún ọjọ́ méjì nítorí àjọ̀dún ìṣẹ̀mbáyé méjì
Oríṣun àwòrán, DEJI of AKURE Kingdom
Deji ilu Akurẹ, Ọba Aladelusi Ogunlade ti kede pe ki Ọja gbogbo ni ilu Akurẹ o wa ni titi pa fun awọn ọjọ meji kan bayii.
Atẹjade kan lati ọdọ Kabiesi Deji ti ilu Akurẹ, eyi ti agbẹnusọ rẹ, Adeyẹye Michael fi sita fi idi rẹ mulẹ pe ni ọjọ kẹrinlelogun, oṣu kẹjọ ọdun yii ti ṣe ọjọ Aje to n bọ, ko ni si tita rira ni gbogbo ọja to wa ni ilu Akurẹ.
Bakan naa ni ọrọ yoo ṣe ri ni ọjọ kẹsan an, oṣu kẹsan an pẹlu.
Gẹgẹ bi atẹjade naa ṣe sọ, eredi igbesẹ ati ti ọja lawọn ọjọ ti a la kalẹ wọnyii wa lati lee fi sami ayajọ ọdun Aheregbe ati Amole.
Amọṣa o, wọn ni ajọdun naa ko ni di lils bibọ ọkọ ati ẹsẹ lọwọ.
Akomolede ati asa Yoruba: Ẹ wá kọ́ nípa àpòtí ìṣura èdè wa lórí BBC Yorùbá
Jude Chukwuka: Wọ́n yóò fi ojú ọlọgbọ́n wo akúrí tó bá sọ ojúlówó èdè Yorùbá
Yoruba ni ọmọ to ba sọ ile nu, o ti so apo iya kọ, idi si ree ti ọmọbibi ẹya Igbo, Jude Chukwuka, fi n rawọ ẹbẹ sawọn ọmọ Yoruba lati maa sọ ede abinibi wọn.
Jude, tii se osere tiata salaye pe ilẹ Yoruba ni oun gbe dagba, ede wọn si dun gbọ, bẹẹ naa lo dun lati sọ.
O ma ni o se oun laanu fun ọmọbibi ilẹ Yoruba ti ko ba lee sọ ede rẹ doju ami nitori eyi ko bojumu to.
Bakan naa lo fikun pe, ẹni ti ori rẹ ba ku, to ba fi Yoruba to yaayi gbe ọrọ rẹ kalẹ, oju ọlọgbọn lawọn eeyan yoo fi maa wo.
Nigba to n sọrọ lori idi to fi yan isẹ tiata laayo, Chukwuka ni awọn agba osere bii Baba Wande, Lere Paimo ati Lalude, to maa n sọ ede Yoruba ti ko ni abula ninu ere, lo se koriya fun oun lati dara pọ mọ wọn.
A ti gba onírúurú ìgbẹ́ tí a rí lọ́wọ́ Emmanuel Egbu lọ fún àyẹ̀wò -Ọlọ́pàá Oyo
Oríṣun àwòrán, Police
Ilé iṣẹ́ ọlọ́pàá ìpínlẹ̀ Oyo ni ìwádìí ti bẹ̀rẹ̀ ni pẹ̀rẹ̀wu lóri ọkunrin kan ti orukọ́ rẹ̀ ń jẹ́ Emmanuel Egbu ti wọ́n ni o n fi igbẹ jẹ búrẹdi ni ori akintan nilùú Ibadan.
Wọ́n ní awọn kan ni àdúgbò Sango lo ké gbàjare ti wọ́n si fi ọ̀rọ̀ náà tó ilé iṣẹ́ ọlọ́pàá àgbègbè náà léti ki àwọn ará àdúgbò tó ṣe ìdájọ́ fún un láti ọwọ́ ara wọ́n.
Agbẹnusọ ilé iṣẹ́ ọlọ́pàá nípìnlẹ̀ Oyo, Olugbenga Fadeyi ṣàlàye fún BBC News Yoruba pé, ni kété ti wọ́n mú ọkùnrin náà ni wọ́n ti gba ọ̀rọ̀ sílẹ̀ lẹ́nu rẹ̀ ti wọ́n sì gba oníruuru ìgbẹ́ ti wọ́n ri lọ́wọ́ rẹ̀ láti gbe lọ fun àyẹwò.
Yatọ sí ìròyìn kan to sọ pé gbájúgbaja olùtaja àwọn èròjà àṣara àti irun lóge ni ọkùnrin náà to sì ni ṣọ́ọ̀bù ńlá ńlá ni àdúgbo Sango nílùú Ibadan àti pé o ṣẹ̀ṣẹ̀ ra ilé ńla kan ni, ilé iṣẹ́ ọlọ́pàá ni ọjọ́ sátide, ọjọ́ kejìlélógun ni ìṣẹ̀lẹ̀ náà wáye, àjọ ọlọ́pàá si ṣẹ̀ṣẹ̀ bẹ̀rẹ̀ ìwádìí lori ọ̀rọ̀ náà ni.
Fadeyi ni òun kò le fìdí ọ̀rọ̀ náà múlẹ̀ afi ti ìwádìí ba pari ṣùgbọ́n ni òótọ́ ni àwọn bá ìgbẹ́ lọ́wọ́ rẹ̀ ti àwọn si ti kó wọ́n lọ fun àwọn àyẹwò to yẹ́.
Ẹ̀wẹ̀, lọ́wọ́lọ́wọ́ báyìí, ọkùnrin náà wà ni àga ọlọ́pàá agbègbè Sango.
Ǹjẹ́ o leè fẹ́ ẹni tó bá ń jẹ ẹran Ajá?
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ileesẹ ọlọpaa ipinlẹ Oyo ti fi fesi lori ikọlu kan to waye sawọn osisẹ ọlọpaa lagbegbe Ikolaba nilu Ibadan.
Atẹjade kan ti ileesẹ ọlọpaa naa fisita lowurọ ọjọ Satide ni awọn osisẹ awọn to wa lẹba titi nidojukọ agọ ọlọpaa Ikolaba ni awọn agbegbọn naa kọlu.
Atẹjade ọhun ni awọn agbebọn ko ya bo agọ ọlọpa rara, amọ awọn to duro soju popo ni wọn se lọsẹ, ti ẹmi ọlọpaa kan si bọ.
Bakan naa ni wọn sọ pe Insipẹkitọ ọlspaa kan naa fara gbọgbẹ ọta ibọn, ti wọn si ti gbe lọ sile iwosan fun itọju.
Atẹjade ọhun fikun pe aayan ti n lọ lati mu awọn afurasi ọdaran to sisẹ ibi ọhun.
Oríṣun àwòrán, Others
Awọn gende agbebọn kan ti ya bo agọ ọlọpaa to wa ni agbegbe Ikolaba nilu Ibadan nirọlẹ ọjọ Ẹti, ti wọn si mu ẹmi Kọburu ọlọpaa kan lọ.
Osisẹ ọlọpaa yii si lo wa lara awọn ọlọpaa to wa lẹnu isẹ lasiko naa tawọn agbebọn ọhun ba wọn ni alejo.
Iroyin naa ni awọn osisẹ ọlọpaa yoku to wa lẹnu isẹ lo fara gba ọgbẹ ọta ibọn lorisirisi ninu ikọlu naa, eyi to ba wọn lojiji.
Nigba to n fidi isẹlẹ naa mulẹ, Agbẹnusọ fun ileesẹ ọlọpaa nipinlẹ Oyo, Olugbenga Fadeyi ni lootọ ni.
Fadeyi ni oun ko ti gbọ ẹkunrẹrẹ alaye lori bi isẹlẹ naa se waye ati awọn eeyan to huwa ibi yii.
Jude Chukwuka: Wọ́n yóò fi ojú ọlọgbọ́n wo akúrí tó bá sọ ojúlówó èdè Yorùbá
Amọ sa, o ni iwadii si n tẹ siwaju lati mọ ohun to sokunfa isẹlẹ naa, ti BBC Yoruba yoo si mu ẹkunrẹrẹ iroyin wa fun yin.
Lagos-Ibadan Train: Iléeṣẹ́ Rélùwéè ní ìgbà 16 ní àwọn ọkọ̀ ojú irin náà yóò máa rìn lójúmọ́
Oríṣun àwòrán, @Official_NRC
Igba ọtun ati eto idẹrun ti de fun awọn arinrin ajo lati ilu Eko si Ibadan, pẹlu ọkọ oju irin reluwe ti yoo bẹrẹ isẹ losu to n bọ.
Atẹjade kan ti ileesẹ Reluwe nilẹ wa fisita loju opo Twitter rẹ lọjọ Ẹti kede pe ọkọ reluwe mẹrindinlogun lo ti de bayii.
Ileesẹ reluwe ilẹ wa ni awọn ọkọ reluwe naa, ti yoo maa na Eko si Ibadan, ni yoo maa rin ni igba mẹrindinlogun lojoojumọ.
Atẹjade naa fikun pe osu Kẹsan to n bọ ni wọn yoo si eto irinna reluwe lati ilu Eko si Ibadan, ti ara yoo si tu awọn arinrinajo to fẹ lọ silu Ibadan lati Eko.
Bakan naa ni eto irinna oju irin yoo tun bẹrẹ lati ilu Itakpe lọ si Warri de Ore, laipẹ laijinna si ni wsn yoo si eto naa.
Lizzy Anjorin: Ẹ̀yin tẹ bímọ fún ọkọ mi, ẹ kó ọmọ wa ká ṣe àyẹ̀wò DNA fún wọn
Oríṣun àwòrán, lizzyanjorin_original
Ilumọọka osere tiata lobinrin to tun gbajumọ lawọn oju opo ayelujara rẹ, Lizzy Anjorin Lawal ti kede pe igbe aye to dakẹ rọrọ ko wu oun.
Anjorin-Lawal, ẹni to sẹsẹ se igbeyawo laipẹ yii sisọ loju ọrọ yii lasiko to n ba akọroyin kan sọrọ.
Lizzy ni igbe aye alariwo lo n mu owo wọle fun oun, nitori naa, oun ko fẹ lati gbe igbe aye to tutu rọrọ rara.
"Mo nifẹ igbe aye mi bo se n lọ yii, ti emi ati ẹnikan ba si tahun sira wa, amọ ti ipenija ba de ba a, maa pe onitọun, ti maa si tun se iranwọ fun to ba nilo rẹ.
Oríṣun àwòrán, lizzyanjorin_original
Eyi jẹ ọkan lara awọn asiri aseyori mi, nitori ọkan mi mọ si gbogbo eeyan, bẹẹ ni ariwo ọja kii se idiwọ fun ontaja ati onraja, sugbọn bi ariwo ba se pọ si ninu sja ni ọja yoo se maa ya si."
Lizzy fikun pe ibẹrẹ igbe aye oun nira diẹ, ẹni to ba si n se oriire ni awujọ, ko le e jẹ ọrẹ awọn ti ko se daadaa.
O ni ohun kii kọkọ tọ ẹnikẹni amọ ẹni to ba tọ oun rugi oyin, bẹẹ si ni oun ko gbagbe ipilẹ oun, ti oun si maa n ranti akoko toun kiri ọja.
Gbajumọ osere tiata naa ni oun ti gbe ninu ile alapa ri, ti iya oun si tun lo akisa lati fi wo oun, ọpọ eeyan si ni ko lee ye igbe aye ti oun ti la kọja sẹyin.
"Nigba to n sọrọ lori igbeyawo to sẹsẹ se, Lizzy ni ""ọrẹ mi ni mo fẹ lọkọ, awọn obinrin ti wọn si ni awọn ti bimọ fun ọkọ mi, wọn ko ti kan si wa tabi ko ọmọ wọn wa sinu ile wa."
Jude Chukwuka: Wọ́n yóò fi ojú ọlọgbọ́n wo akúrí tó bá sọ ojúlówó èdè Yorùbá
"Mo ti pe wọn nija loju aye,gbogbo wọn kan n lo anfaani pe ọkọ mi jẹ eeyan gidi ni, mo n pe wọn lati ko smọ wọn wa fun ayẹwo DNA."""
Lizzy wa yan pe lootọ ni awọn mejeeji ti bimọ fun ẹlomiran tẹlẹ saaju igbeyawo awọn, amọ ọkọ oun ko se igbeyawo pẹlu ẹnikẹni ninu awọn obinrin to bimọ fun.
Mamman Daura kò rìn ìrìnàjò sí ìbi kánkan,ko ko ko lara le! - Bashir Ahmad
Mamman Daura
Atotonu pọ lori boya Mamman Daura lọ si ilẹ Gẹẹsi lati lọ gba itọju,ṣugbọn bayi ọrọ ti jẹyọ pe ko lọ si ibi kankan.
Oluranlọwọ aarẹ Muhammadu Buhari lori ọrọ ayelujara,Bashir Ahmad lo fi ọrọ sita loju opo Twitter rẹ pe ko lọ si ibi kankan.
Arakunrin Bashir sọ pe ko si ootọ ninu ahesọ pe wọn gbe Mamman Daura lọ si ilẹ Gẹẹsi nitori ko ko ko lara rẹ le.
Bi a ko ba gbagbe lẹnu ọjọ mẹta yi ni iroyin gbode kan pe wọn ti gbe  ibatan aarẹ Buhari Mamman Daura tdigba digba lọ si ilẹ Gẹẹsi lọ gba itọju.
Ninu awọn ti ọmọ Naijiria ni igbagbọ pe o lẹnu lọrọ ninu ijọba aarẹ Muhammadu Buhari ni Mamman Daura wa.
Koda ọrọ bi o ti ṣe lagbara si ni ijọba yi jẹ eleyi to ti n mu fakinfa wa laarin awọn ọmọ rẹ ati iyawo aarẹ Aisha Buhari to ni wọn ko jẹ ki ọkọ ohun ri ijọba ṣe.
South Korean Dogs: Wo bi ọbẹ̀ ẹran ajá ṣe dùn tó
Bẹẹ ni, mo maa n jẹ ẹran aja.
Arabinrin yii to jẹ ọdọ ọmọ orilẹede South Korea ni ki lawọn eeyan n pariwo si lorii keeyan maa gbadun jijẹ ẹran aja.
O ni ni toun ẹran lẹran n jẹ, ẹran lasan si ni aja jẹ
Ko yatọ si ẹran Maalu, Ẹlẹdẹ tabi Pẹpẹyẹ.
'Èèwọ̀! Ẹ kò gbọdọ̀ jẹ ajá mọ́'
Ìwádìí ti fihàn pé Ajá n gbọ́ òórùn àìsàn ibà
Kìnìhún nìkan kọ́ ló burú, àwọn ajá mẹ́wàá yìí náà kò fararọ!
Gẹgẹ bi iye awọn to ni ẹran aja gẹgẹ bi nkan ọsun ṣe n pọ sii lorilẹede South Korea
Jíjẹ́ Vs sínsin ẹ̀ran Ajá Vs fífẹ́ ẹni tó ń jẹ ẹran Ajá? Ẹ wá mú ọ̀kan
Awọn ọmọ South Korea bọ sori gbagede eto kan naa lati tako ara wọn lorii boya o tọ lati maa jẹ ẹran ọsin ti eeyan fẹran gẹgẹ bi ọrẹ.
Awọn mii ni laye atijọ wọn maa n si aja fu  jijẹ nibẹ ni ati pe aṣa ilẹ awọn ni.
Láàrọ̀ kùtùkùtù torí Ọlọ́run
Mo ríi lọ́jà tí àwọn kan sorí Ajá kodò láti tà a fún jíjẹ́, ẹ̀rù bà mí gidi gan
Awọn kan ko foju rere wo o.
Ta ni arẹwà obìnrin yí tí àwọn ọmọ Nàìjíríà fẹ́ kó di àárẹ wọn?
Ariwo ló ń mú owó wọlé fún mi, kò wù mí láti gbé ayé tó dákẹ́ rọ́rọ́ - Lizzy Anjorin
Ó ṣe mí ní àánú fún ọmọ Yorùbá tí kò le sọ èdè abínibí rẹ́ - Ọmọ Igbo Chukwuka
Sunday Shodipe: Iléèṣẹ́ ọlọ́pàá ìpínlẹ̀ Oyo ṣe àfihàn afurásí tó n pààyàn ní Akinyele
Ileeṣẹ ọlọpaa ipinlẹ Ọyọ ti ṣe afihan Sunday Shodipẹ, afurasi ọdaran ti wọn fi ẹsun kan wi pe o n da ẹmi awọn eeyan legbodo ni ijọba Ibilẹ Akinyẹle.
Ni nnkan bi aago mọkanla owurọ Ọjọru ni kọmisana ajọ ọlọpaa nipinlẹ Ọyọ, Joe Nwachukwu Enwonwu fi oju Sunday ati awọn ọdaran mii ti wọn ri mu han fun gbogbo aye ri ninu ipade awọn oniroyin to waye ni olu ileeṣẹ ọlọpaa to n bẹ ni agbegbe Ẹlẹyẹle nilu Ibadan.
Ninu ọrọ to ba awọn oniroyin sọ, afurasi naa sọ pe ni agọ ọlọpaa to n bẹ ni agbegbe Mọkọla ni oun ti salọ nigba ti wọn ṣi oun ati awọn ọdaran mii ti wọn jọ wa ni atimọle silẹ lati lọ wẹ.
O fi ẹsun kan oṣiṣẹ ọlọpaa kan to pe ni Funṣọ, pe oun lo fi aye silẹ fun oun lati sa lọ.
Sunday fi kun ọrọ rẹ pe, bẹẹ ni ko si se lẹyin baba ti oun n ba ṣiṣẹ naa bo tilẹ jẹ wi pe baba naa n bẹ ninu gbaga ọlọpaa.
Lẹyin ti o sa lọ lo tun lọ ṣekupa pa arabinrin kan ni agbegbe Akinyẹle, bẹẹ sini o tun da ọgbẹ si ẹlomii lara.
Ibadan Death: Àwọn ará àdúgbò Akinyele ké sita lórí iṣékúpani  tó ń wáyé ní ìlú Ibadan.
Afurasi naa tẹsiwaju pe ni agbegbe Bodija ni oun ti n ṣiṣẹ alaaru lẹyin to sa kuro ni ahamọ ki o to bọ sọwọ wọn.
Sunday Shodipe sọ pe ibi ti oun ti n ṣe iṣẹ alabaru ni ọja Bodija ni ọkunrin kan ti mu oun.
Bẹẹ si ni o ni oun maa n da fila bo oju ki ẹnikẹni ma baa da a mọ.
Sunday ni kii ṣe ọlọpaa lo mu oun ni Bodija.
O ni arakunrin kan lo ni ki oun ṣe iranlọwọ lati ba oun ti ọkọ lai mọ pe o fẹ mu oun ni.
Arakunrin naa ati awọn ẹlomii lo faa le ọlọpaa lọwọ.
Ninu ọrọ tirẹ, kọmisana ajọ ọlọpaa nipinlẹ Ọyọ, Joe Nwachukwu Enwonwu ṣe alaye fun awọn oniroyin pe aaye ti ko si ni ọgba ẹwọn lo jẹ ki wọn fi Sunday pa mọ si agọ ọlọpaa kan ni Mọkọla.
Ileeṣẹ ọlọpaa ipinlẹ Ọyọ sọ pe oṣiṣẹ ọlọpaa ti Sunday fi ẹsun kan wi pe o ṣi awọn silẹ ti n foju wina ibawi.
O tẹsiwaju pe nibayii ti wọn ti ri i mu pada lẹyin ti o salọ mọ wọn lọwọ, o ti di dandan ki wọn sọ ọ si ọgba ẹwọn nibi ti eto aabo ti fi ẹsẹ mulẹ daadaa.
Ileeṣẹ ọlọpaa ipinlẹ Ọyọ ti ni oṣiṣẹ ọlọpaa ti Sunday fi ẹsun kan wi pe o ṣi awọn silẹ ti n foju wina ibawi.
Awọn ọdaran to fọ ile ifowopamọ First Bank nilu Okeho naa ko gbẹyin ninu awọn ọdaran ti wọn fi oju wọn han, to fi mọ awọn ara ilu kan ti wọn tun ji owo ti wọn ri gba lọwọ awọn ọdaran ọhun.
Oríṣun àwòrán, others
Àwọ́n àṣìrí míràn tún ti jẹyọ lórí bi ọwọ́ ṣe tẹ afunrasí ọ̀daràn Sunday Shodipe tí àwọn ọlọpàá ni àwọn gbé ẹgbẹ̀rún lọ́nà ẹ̀ẹ́dẹ́gbẹ̀ta Naira kalẹ̀ fún ẹnikẹ́ni tó ba ri i mú.
Lọ́sàn àná ni ìròyìn gbòde pé wọ́n ti ri ọ̀dọ́mọde náà mú tí ó sì ti wà ní àhámọ́ ọlọ́pàá gẹ́gẹ́ bi agbẹnusọ ọlọ́pàá ìpínlẹ̀ Oyo Olugbenga Fadeyi ṣe sọ fun ilé iṣẹ́ BBC
Ìbéérè tó tún tèlé e ni pé Báwo ni wọ́n ṣe rii mú gan-an
Ìdí èyí ni ilé iṣẹ BBC fí ṣe ìfòrọ̀wánilẹ́nu wò fún àwọn tó lọ́wọ́ nínú ọ̀nà ti wọ́n fi mú ọmọkùnrin náà.
Ààrẹ ẹgbẹ́ ọdẹ Soludẹrọ nílùú Ibadan Nureeni Ajijolaananbi sàlàye fún BBC Yoruba pé, ní àkọ́kọ́ ti ọlọ́pàá mú Sunday Shodipe náà, iṣẹ́ ọwọ́ àwọn ọdẹ Soludẹrọ ni.
"Bí ẹ ṣe mọ̀wé tó, ẹ wá dánrawò níbí pẹ̀lú ""Àpólà Ọ̀rọ̀ Orúkọ - Noun Phrase"
Ó ní ní kété ti ó sì tún bọ́ lọ́wọ́ ọlọ́pàá padà ni iṣẹ̀ tún bẹ̀rẹ̀ lórí bi wọ́n yóò ṣe ri mu, Ó ní àwọn bẹ̀rẹ̀ sí ni bọ ogún gbígbóna pé gbogbo ibi ti ó bá wa ki èsù tìí síta.
Bótilẹ̀ jẹ́ pé ìròyìn kan sọ pé, ọdọmọkunrin kan ti orúkọ rẹ̀  jẹ́ Isaac Bamidele lo fí ibúdó rẹ̀ sílẹ̀ ni ìlú Akure tí o si wá fi ilú Ibadan ṣe ibùgbé láti ri ọmọkùnrin náà mú.
Sùgbọ́n, ààrẹ Soludẹrọ̀ sọ pé, lóòtọ́ ni sùgbọ́n àwọn jọ fi ọwọ́ sọwọ́pọ̀ ni ti àwọn fi ri ọmọkùnrin náà mú.
Nínú àlàyé Isaac Bamidele to jẹyọ lórí ayélujára, Isaac ni òun fi ilú Akurẹ silẹ̀ láti wa gba òtẹ́lìì sí agbègbè Mọniya ni ilú Ibadan pẹlú àwọn ọ̀rẹ́ òun kọọkan tí àlàyé sì ti wà lórí ǹkan ti ó fẹ́ wá ṣe.
"Nínú ọ̀rọ̀ rẹ̀ ó ní ""Mo sàkíyèsí pé agbègbè Akobọ̀ lo máa n jòkó si to si ti lọ máa n ra igbó, ọ̀rẹ́ mi lo ti maa n ri nibi ojú irin to wa lọ́nà Barack tẹ́lẹ̀ to ti lo ti ma ń ra igbó."
"Nígbà ti a ri mó fẹ́ lọ bá awọn boys mi, agbègbè ibi ti o maa n wà ni,  ni a ri pẹlú ọmọ kekere kan, mo wa dúro si bi móto mi ti tayà rẹ̀ fọ́, mó dọ́gbọ́n bi pe mò n gba ìpè, sùgbọ́n àwọn ọ̀rẹ mi ti n tẹ̀le bọ̀.
Nígbà ti o dé ẹ̀gbẹ́ mi, mo wa bẹ̀ẹ́ ki ó bá mi ti móto mi, o sì bá mi tìí, mo wá ni ki ó jọ̀ọ́ kó bámi tìí díẹ̀ sí pé màá fún ní ǹkan kan."""
Bó ṣe bá mi ti móto yẹn tan, mo wa ni ó jọ bi ẹni pé mọ́tò náà kò ni ṣiṣẹ́ pé o ṣeun àti pé mó fẹ́ lọ pe ẹni ti yoo ba mi tún ṣe.
Mó wá ni kí n dúpẹ́ lọ́wọ́ rẹ̀ pé ó ṣeun tó bá mi ti mótò, bi mọ ṣe mu nìyẹn
Lórí owó ti àjọ ọlọ́pàá fi léde pé àwọn yóò fún ẹni to bá rí ọ̀dọ́mọkùnrin Sunday Shodipe mú
Ààrẹ ẹgbẹ́ ọdẹ Soludẹrọ Ajijọlaanabi ní àwọn ọlọ́pàá ti n ṣeto bi owó náà yóò ṣe tẹ àwọn lọ́wọ́ gẹ́gẹ́ bi ìlérí wọ́n.
Oríṣun àwòrán, Oyo Police
Lọwọlọwọ, oriṣiriṣi ni awọn ileeṣẹ iroyin ti n gbe nipa rẹ. Bi awọn kan ṣe n fi sita pe sisa to salọ ko ṣẹyin ọga ọlọpaa kan, lawọn mii n ni ile iya iya/baba rẹ ni wọn ti pada ri i mu  ṣugbọn a o tii le fidi eleyii mulẹ.
Koda, awọn ikọ alaabo kan niluu naa n sọ pe awọn lawọn ṣokunfaa bi ọwọ ọlọpaa ṣe tẹ ẹ pada.
Ẹwẹ, ọga patapata ileeṣẹ ọlọpaa Naijiria Mohammed Adamu ti dupẹ lọwọ awọn ọmọ orileede Naijiria fun atilẹyin wọn eyi to ja si bi wọn ti ṣe mu Sunday Shodipe.
Arakunrin yii ni afurasi ti o sa mọ ileeṣẹ ọlọpaa ilu Ibadan lọwọ ṣugbọn ti wọn ti ri mu pada ni Bodija lọjọ Aiku.
Ninu atẹjade kan ti Frank Mba fi sita lorukọ ọga agba ọlọpaa, o ni  Sunday Shodipe jẹ afurasi ninu ipaniyan to waye nijọba ibilẹ Akinyele.
Mohammed Adamu wa kilọ fawọn agbofinro lati ma ṣe jẹ ki ina esisi tun jo wọn lori ọrọ yi ki wọn si ṣapa lati yanju ẹjọ to wa nilẹ yi.
'Ìgbà tí mo máa fi lajú sáyé padà, ọ̀fọ̀ ikú mi ní wọ́n ń kígbe'
Iroyin to n tẹwa lọwọ sọ pe ọwọ awọn ọlọpaa  ipinlẹ Oyo ti tẹ arakunrin kan, Sunday Shodipe to sa mọ wọn lọwọ laipẹ yi.
Shodipe jẹ afurasi ti wọn ti kọkọ mu lori iṣẹlẹ iṣekupaniyan to n waye lẹnu lọọlọ yi lagbegbe Akinyele ni ilu Ibadan.
Oríṣun àwòrán, Oyo Police
Ko tii daju ibi ti wọn ti ri i mu ṣugbọn BBC Yoruba ba alukoro ipinlẹ Oyo, Ọgbẹni Fadeyi Olugbenga sọrọ o si fidi ọrọ yii mulẹ.
Mo le fọwọ sọya fun yin bayi bayi pe afurasi ọdaran to sa lọ, Sunday Shodipe ti wa lahamọ Ọlọpaa ipinlẹ Oyo.
"O ni ""ẹ o maa gba iwe atẹjiṣẹ latọdọ mi laipẹ""."
Bi ẹ ko ba gbagbe, iroyin jade rẹpẹtẹ nigba ti ọwọ kọkọ tẹ Shodipe to jẹ ọmọ ọdun mọkandinlogun koda ati igba to tun sa lọ mọ ọlọpaa lọwọ, iroyin ko tii tan nilẹ titi di akoko yii.
Gẹgẹ bi a ṣe gbọ, o ti pẹ diẹ ti iroyin sọ pe afurasi ọdaran yii lo wa nidii iku ọwọwọ to n waye lagbegbe ijọba ibilẹ Akinyele nipinlẹ Oyo.
A n ṣe akojọpọ ẹkunrẹrẹ iroyin yajoyajo lọwọ, a o maa gbe ẹkunrẹrẹ iroyin naa sori atẹ iroyin wa laipẹ.
Ẹ jọwọ, ẹ tun oju opo iroyin yi yẹwo, ki ẹ lee ri ẹkunrẹrẹ iroyin ọtun laipẹ.
Ǹjẹ́ o leè fẹ́ ẹni tó bá ń jẹ ẹran Ajá?
Ikoyi Ile Farmers Herders Clash: Àwọn àgbẹ̀ Ikoyi Ile kérora síjọba ìpínlẹ̀ Oyo!
Oríṣun àwòrán, OTHERS
Awọn agbẹ atawọn olugbe ilu Ikoyi Ile ni ijọba ibil Orire, ipinlẹ Oyo ti ni awọn yoo papa dide iranwọ fun ara awọn ni bi ijọba ipinlẹ Oyo ba kọ lati ṣe iṣẹ didaabo bo awọn.
Wọn figbe yii ta si ijọba latari bi wọn ṣe ni awọn daran daran n dun mọhuru mọhuru mọ wọn ninu ilu wọn.
Awọn agbẹ naa ke gbajare pe pẹlu bi wọn ṣe pa ọkan lara wọn, ti wọn fipa ba awọn ọmọ wẹwẹ wọn lopọ ti wọn si ba oko wọn jẹ, sibẹ sibẹ, awọn daran daran yii ṣi n da ilu awọn laamu eyi to si n gba orun loju wọn.
Akọwe ẹgbẹ awọn agbẹ Idera, Oloye Oyekola Joseph jẹ ko di mimọ pe gbogbo ohun to n ṣẹlẹ yii n kọ awọn lominu lati bii ọdun mẹjọ sẹyin to si n ke si ijọba pe ki wọn tete da si ọrọ naa ko to di nkan mii.
Rúfin kóo san N1M táa bá ṣí òtẹ́ẹ́lì, ilé sinimá, gbọ̀ngàn ayẹyẹ padà - Ijọba Eko
'Bí a kò bá fẹ́ ìbínú Ọlọ́run, a gbọ́dọ̀ jẹ́ kí Tinubu du ipò ààrẹ̀ lábẹ́ àsìá ẹgbẹ́ APC ní 2023'
Àwa la mọ báa ṣe mú Sunday Shodipe táa fà a lé ọlọ́pàá lọ́wọ́ - Ọlọ́dẹ Soludero
"Gẹgẹ bi iroyin ti a gbọ ṣugbọn ta o lee fi aworan rẹ sinu iroyin yii tori o buru jai, wọn fẹsun kan pe ""awọn daran daran ge ọwọ ọkan lara wọn ti wọn si tun ba oko wa jẹ, agbẹ kan ni wọn ṣa oun ni ada lori, awọn mii fara pa koda wọn fipa ba awọ́n ọmọde wa meji lo pọ""."
Awọn agbẹ figbe ta pe wọn ko tii dẹkun kikọlu oko awọn, o ni awọn si ti bẹ wọn tititi ti wọn ko gbọ.
Ẹwẹ, nigba ti a kan si ileeṣẹ Ọlọpaa ati Onikoyi ti Ikoyi Ile, Oba Abdul-Yekeen Atilola Oladipupo ko tii f fesi si ọrọ yii to si sọ fun akọroyin BBC pe oun yoo kan si wọn bo ba ya.
Ilu Ikoyi-Ile jẹ ilu iṣẹmbaye kan ni ijọba ibilẹ Orire ni ipinlẹ Oyo eyi ti ilu to fẹẹ to ẹẹdẹgbẹrin yii ka bii ilu Olode-Elelu, Animashaun, Obamo, Igboayin, Laomi. ati bẹẹ lọ.
Kọmísọ́nà ètò ìlera ìpińlẹ̀ Eko ọjọ̀gbọ́n Akin Abayomi ti lùgbàdì ààrùn Covid-19
'Ìgbà tí mo máa fi lajú sáyé padà, ọ̀fọ̀ ikú mi ní wọ́n ń kígbe'
Zambia Rats Video: Fọ́nrán fídíò èkúté ní ilé ìwòsan jẹ́ ìdójútì fún ìjọba -Mínísítà ìlera
Oríṣun àwòrán, Matthieu Aubry
Fọnran fidio kan to lu sita lori ayelujara ti mu ki awọn alakoso ile iwosan kan ni Zambia wọ gau.
Ninu fidio taa n wi yi, niṣe lawọn ekute n da igba ru ninu lẹda kan ti wọn gbe kalẹ lẹgbẹ ibusun alaisan.
Ile iwosan Kitwe Central Hospital to wa ni agbegbe Copperbelt nilẹ naa jẹ ọkan lara awọn ile iwosan to tobi julọ.
Ọrọ yi to de'ti igbọ Minisita feto ilera, Chilatu Chilufaya, ti mu ki o ṣabẹwo pajawiri sile iwosan naa.
Abalọ ababọ abẹwo yi ni pe o ni ki wọn gbe igbesẹ ijiya to tọ lori oludari ile iwosan ọhun.
Minisita Chilufaya sọ pe idojuti nla ni isẹlẹ yi jẹ si ijọba nitori naa gbogbo awọn ti igba ibajẹ fidio yi ṣi mọ lori ko ni lọ lai jiya.
Loju opo Twitter, niṣe lawọn eeyan orileede naa n bẹnu atẹ lu awọn ijọba ati alakoso ile iwosan naa.
John Blake: Wo ohun tó yẹ kí o mọ̀ nípa ọmọ ọdún 17 tí wọ́n ní ó pa èèyàn méjì níbi ìwọ́de Black Lives Matter ní Kenosha
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Lẹyin ti awọn ọlọpaa alawọ funfun yinbọn lu jacob Blake, to jẹ alawọ dudu ni l'Amẹrika, lawọn eeyan ilẹ naa bẹrẹ si ni tu sita lati ṣe ifẹhonuhan lori iṣẹlẹ naa.
Ni alẹ ọjọ kẹta ti ifẹhonuhan naa bẹrẹ ni iroyin sọ pe ọmọ ọdun mẹtadinlogun kan yinbọn lu awọn olufẹhonuhan, ti meji ninu awọn eeyan ọhun gbẹmi mi, ti ẹnikan si farapa yanayana.
Lẹyin naa ni wọn fi panpẹ ofin mu nile iya rẹ ni Antioch, ni ipinlẹ Illinoi, to jẹ nnkan bi ọgbọn iṣẹju si Kenosha nibi ti iṣẹlẹ naa ti waye.
Ni bayii, wọn ni yoo foju bale ẹjọ lori ẹsun ipaniyan.
Ta ni ọmọkunrin naa gan?
Ayẹwo ti a ṣe si oju opo ikansiraẹni rẹ lori itakun agbaye fi han pe ọmọdekunrin naa, Kyle Rittenhouse fẹran awọn agbofinro.
"Aworan to fi soju opo Facebook rẹ n ṣafihan akọle ""Blue Lives Matter,"" eyii to n ṣapẹrẹ ibadọre pẹlu ileeṣẹ ọlọpaa, to tun jẹ atako si awọn  alatilẹyin ""Black Lives Matter."""
Pupọ ninu awọn akọle to maa n ko sori ikanni facebook rẹ lo maa n fi bu iyi fun awọn ọlọpaa ti wọn ku ṣenu iṣẹ, o si ti fi igba kan jẹ ara ọmọ ikọ ileeṣẹ ọlọpaa abẹle ti ẹka Grayslake ri.
Oríṣun àwòrán, @TalbertSwan
Igba meje ni wọn yinbọn lu Jacob Blake ni Kenosha
O tun fẹran ibọn lọpọlọ nitori bo ṣe maa n fi aworan ibọn soju opo ikansiraẹni rẹ lori ayelujara.
"O sọ pe ara iṣẹ oun ni lati daabo bo awọn eeyan, o ni ""ti eeyan ba ṣeṣe, mo le fi ara mi sinu ewu lati ran wọn lọwọ."""
'Oyenusi ló mú mi wọ ẹgbẹ́ adigunjalè kó tó di pé mo b'Ólúwa pàdé'
Oun to ṣẹlẹ
Lalẹ ọjọ ifẹhonuhan naa, wọn ri Kyle lori aworan CCTV nibi ti awọn eeyan kan ti n le e pẹlu ibọn ti oun naa si yinbọn lu ọkunrin to n le e ni ori.
Lẹyin naa ni awọn eeyan miran tun le e pẹlu ibọn lọwọ ti oun naa si da pada fun wọn.
Ki lo ti ṣẹlẹ sẹyin?
Oríṣun àwòrán, Others
Ọgbẹni John Blake, ọkunrin alawọ dudu tawọn ọlọpaa yinbọn fun ni Kenosha nipinlẹ Wisconsin wa ni wọọdu ICU nibi ti o ti n gba itọju lọwọ Ileeṣẹ ọlọpaa ko tii fi darukọ awọn ọlọpaa ti ọrọ naa kan sita, amọ awọn ọlọpaa naa ti bẹrẹ isinmi lẹnu iṣẹ ni kiakia.Ileeṣẹ ọlọpaa ni awọn ọlọpaa ko ṣ'adeedee lọ si ibi iṣẹlẹ ọhún, wọn ni awọn kan lo ranṣẹ pe wọn pe ki wọn wa pẹtu si ija.
Amọ, ko si ẹni to mọ ohun to da awọn ọlọpaa ati Ọgbẹni Blake pọ.Ẹka idajọ nipinlẹ Wisconsin ti bẹrẹ iwadii lori iṣẹlẹ naa, bakan naa lọgọrọ eeyan ti buwọlu aba lati gbe awọn ọlọpaa ti ọrọ kan sile ẹjọ.
Oríṣun àwòrán, others
Awọn ti ọrọ naa ṣẹlẹ loju wọn ṣalaye pe Blake n pẹtu si ija laarin obinrin meji k'awọn ọlọpaa to bẹrẹ sí ni yin taju taju.Fidio to lu ayelujara pa fihan pe Blake ko gbe ibọn dani, ṣugbọn awọn ọlọpaa tun yinbọn fún un nigba meje lati ẹyin.
Agbẹjọro ati ajafẹtọ, Ben Crump sọ loju opo Twitter rẹ pe loju ọmọdekunrin mẹta Blake lawọn ọlọpaa ti yinbọn fún un.Crump ni titi laelae ni iṣẹlẹ yii yoo maa ṣe iyọnu fawọn ọmọ naa.
Ẹwẹ, oludije ipo aarẹ f'ẹgbẹ oṣelu Democrat l'Amẹrika, Joe Biden ti pe fun Iwadii kikun lori iṣẹlẹ naa.
Oríṣun àwòrán, @BoringMe2Death
Iṣẹlẹ yii waye lẹyin oṣu diẹ ti awọn ọlọpaa tẹ George Floyd to jẹ alawọ dudu
Awọn eeyan orilẹ-ede Amẹrika ti gunle iwọde #BlackLivesMatter lọtun lẹyin ti awọn ọlọpaa alawọ funfu yinbọn lu ọkunrin alawọ dudu kan nigba meje.
Ọkunrin ọhun ti orukọ rẹ n jẹ Jacob Blake ti wa ni ẹsẹ kan aye ẹsẹ kan ọrun bayii nile iwosan.
Iṣẹlẹ naa waye ni ilu Kenosha, to wa ni ipinlẹ Wisconsin lẹyin ti ileeṣẹ ọlọpaa ni wọn gba ipe gbajawiri lori wahala to waye ninu ile kan.
Fidio bi awọn ọlọpaa ṣe yinbọn lu ọkunrin ọhun ti gba ori ayelujara kan, nibi ti ọkunrin naa ti n rin lọ ṣeba ọkọ kan, to si kọyin si awọn ọlọpaa naa ki wọn to yin in nibọn.
Ileeṣẹ to n ri si eto idajọ ni Wsconsin ti ni iwadii ti bẹrẹ lori bi ọrọ naa ṣe ṣẹ, wọn si ti ni ki awọn ọlọpaa to lọwọ ninu iṣẹ ọhun lọ rọkun nile fun igba diẹ na.
Ṣugbọn awọn ara ilu Kenosha ti bẹrẹ ifẹhonuhan lẹyin iṣẹlẹ ọhun, koda wọn dana sun ọpọ ọkọ ti wọn si n pariwo pe o to gẹ.
Oríṣun àwòrán, Reuters
Ko pẹ si akoko naa ti ijọba ipinlẹ ọhun kede igbele pajawiri, o si rọ awọn to n ṣowo oni wakati mẹrinlelogun lati tilẹkun ṣọọbu wọn nitori awọn kọlọrọsi to n lo iṣẹlẹ naa lati ja ṣọọbu, ti wọn si n ji ọja ko lọ.
Ẹwẹ, gomiona ipinlẹ Wisconsin, Tony Evans ti bu ẹnu atẹ lu iṣẹlẹ naa.
Iṣẹlẹ yii waye lẹyin oṣu diẹ ti awọn ọlọpaa tẹ George Floyd to jẹ alawọ dudu lọrun pa l'Amẹrika yii kan naa.
'Ìgbà tí mo máa fi lajú sáyé padà, ọ̀fọ̀ ikú mi ní wọ́n ń kígbe'
Ibadan robbery: Àgbègbè Secretariat ni adigunjalè ti gba ₦446,000 lọ́wọ́ oníbàárà báńki tí wọ́n pa
Oríṣun àwòrán, others
Awọn adigunjale ti yinbọn pa ọkunrin kan, Taoreed Olusola, lagbegbe ọfiisi ijọba to wa ni Agodi, ni ilu Ibadan.
Iṣẹlẹ naa waye ni nnkan bi aago kan abọ ọsan ọjọ Aje.
Ọkan lara awọn ti iṣẹlẹ naa ṣoju rẹ sọ pe, ni ṣe ni awọn adigunjale ọhun ṣọ arakunrin naa lati lori alupupu, ki wọn to ṣakọlu si i.
"Bí ẹ ṣe mọ̀wé tó, ẹ wá dánrawò níbí pẹ̀lú ""Àpólà Ọ̀rọ̀ Orúkọ - Noun Phrase"
O ni lẹyin naa ni wọn gba gbogbo ohun to wa lọwọ rẹ ki wọn yin in nibọn, ti wọn si gbe alupupu rẹ lọ.
Iroyin ni ile ifowopamọ kan ni awọn adigunjale ọhun ti n tọpasẹ ọkunrin naa bọ lẹyin to lọ gba owo tan.
Iwe ile ifowopamọ ti wọn ri lara oloogbe naa fi han pe o ṣẹṣẹ gba owo ti iye rẹ to ₦446,000 nile ifowopamọ kan to wa ni Bodija ni, ki wọn to kọlu.
"Oṣojumi koro miran sọ pe ""Wọn ṣakọlu si Taoreed nigba to n gbiyanju lati ṣa mọ wọn lọwọ pẹlu alupupu rẹ lẹba ile gomina, ṣugbọn wọn da duro wọn si yinbọn lu nigba meji lẹyin ti wọn gba owo naa tan, wọn si salọ."""
"O tẹsiwaju pe ""Inu ọfiisi ni a wa ti a ti gbọ iro ibọn nigba meji, nigba naa ni a sare jade lati wo ohun to n ṣẹlẹ."""
Igba yẹn ni a ri awọn ọkunrin meji lori ọkada, ti wọn n gbe owo ati alupupu rẹ salọ.
Ẹwẹ, agbẹnusọ ileeṣẹ ọlọpaa ipinlẹ Oyo, Olugbenga Fadeyi sọ pe oun ko ti gbọ nipa iṣẹlẹ naa nitori ọwọ oun kun fun iṣẹ igbaniwọle awọn ọlọpaa tuntun to n lọ lọwọ.
'Ìgbà tí mo máa fi lajú sáyé padà, ọ̀fọ̀ ikú mi ní wọ́n ń kígbe'
Sleeping Lawmakers: Àwọn ọmọ ilé ìgbìmọ̀ aṣòfin l'Abuja ti wọ́n ń sùn lásìkò ìjókòó ilé
Oríṣun àwòrán, Others
Ọ̀pọ̀ ọmọ Nàìjíríà ló n gba ọ̀rọ̀ náà bi ẹni gba igbá ọti láti ìgbà ti adájọ́ àgbà ilé ẹjọ́ FCT Ishaq Bello ti ni ojú má a ń gbà òun ti nígbà ti òun bá ri ọmọ ilé ìgbìmọ̀ aṣofin (kékeré tabi àgbà ) tó bá ń sùn lásìkò ìjókó ilé.
Bello ní ó ṣe pàtàkì ki àwọn ọmọ ọ̀dọ́ ayé òde òní gbé ìgbésẹ̀ tó yẹ láti mú àyípadà rere bá orílẹ̀-èdè yìí.
Eyí lo fàá ti BBC Yorùbá ṣe n ṣe àkójọ pọ̀ àwọn ọmọ ilé ìgbìmọ̀ Aṣòfin tó ti ń sùn lásìkò ìjòkó ilé.
Ọ̀pọ̀ ló mi ìgbàgbọ́ pé àwọn asojú ilé ìgbìmọ̀ asoin yiìí kan ń lọ síbẹ̀ láti ná owó ìlú ni kò sí ǹkan pàtó tí wọ́n n ṣe níbẹ̀ ju oorun lọ
Oríṣun àwòrán, Others
Oríṣun àwòrán, Others
Rochas Okorocha bẹ̀rẹ́ iṣẹ́ nile ìgbìmọ̀ asofin kò tii ju oṣù mẹ́ta lọ tó ti bẹ̀rl iṣẹ́ oorun sìsùn
Oríṣun àwòrán, Others
Yoruba bọ̀ wọ́n ni kò si ẹni tó le yan ẹran ara jẹ́, asiko to ba ti ni ki ènìyàn sinmi, o dí dandan ki oluwa rẹ̀ ṣe bẹ́ẹ̀
Oríṣun àwòrán, Others
Ní ọ̀pọ̀ ìgbà ni àwọn ọmọ Naijiria ti maa n gbarata lórí bi àwọn ọmọ ilé igbímọ̀ aṣofin àgbà ṣe ma sùn lásìkò ìjòkó ilé.
Wọ́n ní ọ̀ps wọ́n lo ti sọ ilé ìgbìmọ̀ aṣòfin àgbà di ilé ìfẹ̀yìnti àti ìfọ̀kànbálẹ̀.
Àwọn ọmọ Naijiria ni, èyí n wáye nítori pé Naijira ni ibi ti gbogbo ńkan ti le ṣẹlẹ̀ láìsì ǹkan ti yóò tẹ̀yì rẹ̀ jáde.
Yoruba Language: Akomolede ati Asa Yoruba tọ̀sẹ̀ yí rèé lẹ́nu olùkọ́ wa
Imọ ede Yoruba ko yọ ẹnikẹni silẹ. Atọmọde atagba lo gbudọ maa gbe aṣa Yoruba larugẹ nibikibi ti a ba wa yala nile ni tabi lẹyin odi.
Eto Akọmọlede ati Aṣa Yoruba, ti yoo maa waye lẹẹkan lọsẹ loju opo ikanni BBC Yoruba, yoo maa kọ wa ni ede ati asa wa, ko maa ba parun.
"Akori ọ̀rọ̀ fun agbeyẹwo loni ni ""Apola Ọrọ Orukọ"" eyi ti ẹ mọ loyinbo si ""Noun Phrase"" ati awọn isọri rẹ."
Olukọ wa fun toni ni Iyaafin Idowu Peters lati Ogba Junior Grammar School.
Ẹ o ni le yin in kuro loju fidio to wu ni lori pẹlu ẹkọ ede Yoruba.
Funke Akindele Nollywood: Mi ò gbẹ́kẹ̀lé ènìyàn! Ọlọ́run ni mo gbẹ́kẹ̀ mi lé!
Oríṣun àwòrán, Funke Akindele
JJCSkills to jẹ ọkọ gbajugbaja oṣere fiimu Yoruba to tun jẹ adẹrinpoṣonu, funke Akindele ti gbogbo eniyan mọ si Jenifa ṣe oun iwuri nla fun ololufẹ rẹ.
Isẹ ọpọlọ rẹ maa n da wa lọrun gan, o maa n ṣe ọkan wa pẹlẹ. Lara orin ti awọn olorin kan fi ṣapejuwe patakii Funke Akindele si wọn ree.
Funke Akindele ti di ìyábejì ni ọdun melo kan sẹyin.
Funke Akindele jẹ àkàndá ẹ̀dá - Adaku
Oríṣun àwòrán, Funke Akindele
Kaakiri agbaye ni wọn ti mọ Funke gẹgẹ bii gbajugbaja apanilẹrin laarin awọn oṣere fiimu Yoruba ati ti ede oyinbo koda to fi mọ awọn toke okun kọọkan.
Ko si ani ani pe akọkọ lo jẹ loju ewe awọn apanilẹrin to dantọ ju fun awọn kan.
Fọfọ ni oju opo ayelujara rẹ kun fun oriṣiriṣi ikini latọdọ awọn oṣere ẹgbẹ rẹ, awọn olorin to jẹ ọrẹ rẹ, awọn oṣiṣẹ rẹ koda to fi mọ awọn aladugbo rẹ nibi to n gbe.
Ṣe ni Funke Akindele funrarẹ ṣe ajọyọ pẹlu awọn ololufẹ rẹ pẹlu fidio bo ṣe n ṣe idupẹ lọwọlọwọ ninu ile rẹ tawọn eeyan si n ri i wo loju opo instagram rẹ ti wọn si n fi ọrọ ikini ranṣẹ si i.
Ninu fidio naa lo ti tẹle ofin ijinasiraẹni gẹgẹ bi ko ṣe pe ero ayafi awọn perete ta n gbọ ohun wọn labẹlẹ ati olorin kan to pe ti a ri ninu fidio naa to n kọrin yin Ọlọrun logo nitorii Funke Akindele.
Eyi gaan lo pe ni ayẹyẹ ọjọ ibi rẹ lẹyin eyi to gba foonu lọwọ ẹni to n ṣafihan rẹ to si ṣe adura pupọ fun awọn ololufẹ rẹ pẹlu ede to maa n fi ṣe ere awada rẹ bii ẹni ti ede gẹẹsi ko dan mọnran rara lẹnu rẹ.
"Bí ẹ ṣe mọ̀wé tó, ẹ wá dánrawò níbí pẹ̀lú ""Àpólà Ọ̀rọ̀ Orúkọ - Noun Phrase"
Polio eradication in nigeria: Orísúnmibáre ni àìsàn 'Polio' tó kọlù mí ní kékeré - Fola
Oríṣun àwòrán, folajogun akinlami
Oni, ọjọ kẹẹdọgbọn, oṣu Kẹjọ, ọdun 2020, ni ajọ eto ilera ni agbaye, World Health Organization, kede pe Naijiria ti bọ patapata lọwọ aisan rọmọ lapa-lẹsẹ, polio.
Ẹgbẹẹgbẹrun ọmọ ni aisan naa sọ di arọ ni orilẹ-ede Naijiria, ati kaakiri ilẹ Africa.
BBC ba eeyan meji lara wọn to kagbako aisan yii nigba ti wọn wa ni ọmọde sọrọ lori iriri wsn.
Ọkan lara wọn, Fola sọ pe oun dagba ba ipa aisan naa ninu ayeoun ni.
O sọ pe awọn obi oun sọ fun pe oun ko ju ọmọ ọdun kan lọ nigba ti iṣẹlẹ naa waye.
Oríṣun àwòrán, folajokun akinlami/facebook
"Iya mi sọ fun mi pe laarin oru ọjọ kan ni mo deede bẹrẹ aisan, ti oun si gbe mi lọ sileewosan.
Ara gbigbona ni nọọsi to wa lẹnu iṣẹ ro pe o n ṣe mi, lo ba fun mi ni abẹrẹ laimọ pe aarun rọmọ lapa, rọmọ lẹsẹ lo wa nidi aisan yẹn (polio) ni."
Mo gbọ pe abẹrẹ yẹn gan-an lo da gbogbo nkan ru, ti mo fi di ẹni ti ko le rin mọ.
Arabinrin Fola sọ pe oun dupẹ pe ko gba ju ẹsẹ ọtun oun lọ, nitori pe awọn kan wa ti aarun yii rọ lapa, ẹsẹ, to tun sọ wọn di aditi.
LASTMA Yesufa: Àwọn dókítà gbìyànjú lórí ojú mi ṣùgbọ́n...
Ẹsẹ mi apa ọtun ni mo ti ni ipenija. Awọn dokita tiẹ sọ fun awọn obi mi pe ẹsẹ naa ko nii dagba ju ti ọmọ ọdun kan lọ, to jẹ ọjọ ori mi lasiko to mu mi.
Lori nkan ti aisan naa gba lọwọ rẹ, Arabinrin Fola sọ pe ki oun ṣa dupẹ lọwọ Ọlọrun ti ko fi aaye iyẹn silẹ.
"O ni "" Mo si dupẹ lọwọ awọn obi mi; mo lọ sileewe, mo ni iwe ẹri to dara, mo niṣẹ gidi lọwọ, mo ti rinrinajo kaakiri agbaye, mo tun n fun awọn eeyan ni nkan ni awujọ."
Koda, emi ni Igbakeji Aarẹ  ẹgbẹ Mandela Washington Fellow ni Naijiria, eyi to jẹ pe ileeṣẹ aṣoju America lo n gbọ bukaata wa.
"Ipa ti aisan naa yoo ni lori igbeaye ẹni to ba mu da lori awọn obi, awujọ ati ọlaju."""
Mo le sọ pe orisunmibare ni aisan rọpa-rọsẹ jẹ fun mi.
Idi ni pe, ti kii ba ṣe ti aisan yii,  mi o ni ronu pe mo fẹ ẹ da ajọ alaanu silẹ. Awọn iriri mi lo sọ mi di alaanu, ati ẹni to n polongo fun awọn to tun ni aisan yii lati ni igboya lati koju gbogbo ipenija wọn.
Wòlíì Kasali sọrọ nípa awuyewuye pé o lè ìyàwó rẹ̀ jáde nílé
Nipasẹ ajọ naa ni mo fi ni anfaani lati ma a rinrinajo kaakiri agbaye.
Lori ọrọ ọkọ nini ọkọ tabi aya, ipenija kekere kọ ni awọn ti aisan yii ba mu ma n ni, paapa awọn obinrin.
Nitori naa, nkan ayọ ni bi ajọ WHO, ṣe kede pe aarun polio ko si ni Naijiria mọ, ati gbogbo Africa. Ọpẹ nla ni, nitori emi ni mo mọ nkan ti oju mi ri, ti eeyan ko le gbadura iru rẹ fun ẹnikẹni.
Iṣẹ kekere kọ ni awọn obi ọmọ ti aisan naa ba mu n ṣe.
Ẹlomiran tun ni Arabinrin Yemisi Adeoye, to ti pe ẹni ọdun marundinlaadọta bayii.
O sọ fun BBC Yoruba pe 'measles' ti Yoruba n pe ni tita tabi igbona lo mu oun nigba naa, abajade rẹ ni pe o rọ lẹsẹ.
Ibi ti nkan de duro lori aarun polia ni ilẹ Africa
"Awọn obi mi sọ fun mi pe lasiko naa, awọn ileewosan gan-an ko mọ nipa itọju rẹ, de bi i pe ti wọn ba fun ọmọ ni abẹrẹ, o npa wọn ni.
Eyi kii jẹ ki awọn eeyan gbe ọmọ lọ si ileewosan.
Ondo disability: Kò sí ẹni tí àkàndá kò lè ya ilé rẹ̀- Ayọdele
Kii ṣe pe ko si ileewosan, ṣugbọn awọn ara igba naa kii fẹ ẹ gbe ọmọ lọ, nitori igbagbọ pe ọmọ ti wọn ba fun ni abẹrẹ yoo ku. Ewe ati egbo ni wọn gbẹkẹle."""
O fi kun ọrọ rẹ pe awọn obi oun tun sọ pe oun o ti i ju ọmọ ọdun marun un nigba naa.
"Lootọ, idile onigbagbọ ni mo ti jade, imọran awọn eeyan lo mu wọn lọ si oriṣiriṣi ibi ti wọn juwe fun wọn. Ṣugbọn wọn sọ fun wọn pe o ti pẹ ju.
Ko si ibi ti wọn o gbe mi de."
O wa sọ pe oun ti gba pe bi Ọlọrun ṣe fẹ ki ọrọ aye mi ri niyii.
"Mi o ki n wo ibẹ. Mo ma n kuro laarin awọn to ba n fi mi ṣe yẹẹyẹ.
Mo kọṣẹ, mo si n ṣe iṣẹ mi."
Coronavirus in Kenya: Dípò ìlànà ìkẹ́kọ̀ọ́ àkókò abẹ́rẹ́ adìẹ ló wà lójú pátákó ní kíláàsì
Joseph Maina ti yi kilaasi ikẹkọ rẹ pada di ile adiẹ
IIgbesẹ ijọba Kenya to ti awọn ileẹkọ pa di ọdun to n bọ, ti mu ki ọpọ olukọ di alainiṣẹ lọwọ gẹgẹ bi BBC ti ṣe iwadii rẹ.
Iyara ikẹkọ ileewe Mwea Brethren to ṣe pe ariwo awọn akẹkọ lo maa n gbalẹ nibẹ, ti di ibudo ti igbe awọn adìẹ ti gbalẹ kan.
Kaka ki wọn kọ iṣẹ iṣiro (Maths) si oju patako ikọwe, ohun to wa nibẹ ni alaye asiko tawọn adiyẹ yoo gba abẹrẹ ajẹsara.
Joseph Maina to ni ileẹkọ Central Primary School naa ti sọ kilaasi di ibudo ọsin adìẹ, ko ba le ri owo gbọ bukata to wa nilẹ.
'Ọna ọfun lọna ọrun''
Nkan ko rọgbọ fun Jonathan paapa julọ ni oṣu Kẹta ti wọn paṣẹ ki wọn ti awọn ileewe.
Lasiko taa n sọ yìí, o ni owo kan to ya lọwọ ile ifowopamọ, to si ni lati tun ijoko jokoo pẹlu wọn lori bi yoo ṣe da owo wọn pada.
O kọkọ da bii ẹni pe ko si ireti kankan fun ṣugbọn o pada pinu pe oun gbọdọ wa nkan ṣe pẹlu ileewe to wa nilẹ la ṣe nkankan.
Niṣe ni wọn sun aga ati tabili ijoko sẹgbẹ kan lati le gba nkan ọgbin
Nitori pe awọn ileewe aladani a maa fi owo tawọn obi ba san lati fi san owo oṣu olukọ wọn, bi wọn ṣe ti awọn ileewe pa ṣe akoba fawọn to da iru ileewe bẹ silẹ.
Gẹgẹ bi ẹgbẹ awọn ile ẹkọ aladani ni Kenya ti ṣe sọ, diẹ ninu awọn ileewe aladani lo n gbiyanju lati maa kọ awọn akẹkọ loju ayelujara ṣugbọn owo ti wọn n ri nibẹ ko to lati san owo oṣu awọn oṣiṣẹ.
Nkan bi ida marundinlogorun awọn olukọ bii egberun lọ́nà oodunrun to n ṣiṣẹ pẹlu ileewe aladani ni wọn ti ni ki wọn lọ isinmi nile lai gba owo oṣu.
Peter Ndoro to jẹ alakoso ẹgbẹ yii fikun pe, ileewe metalelaadoje ni wọn sọ agadagodo si, ti wọn ko si mọ igba ti wọn yoo ṣi wọn pada.
'Ko buru to bayi ri'
Ki ọrọ baa ma di pe awọn naa yoo ti ileewe wọn pa, ileẹkọ Roka Preparatory ti tete yi ọgba wọn naa si oko.
James Kung'u to da ileewe naa silẹ ni ọdun mẹtalelogun sẹyin sọ fun BBC pe ''Nkan ko buru to bayi ri fun wa''
Ni ọgbà iṣere awọn akẹkọ ewebẹ ni wọn gbin sibẹ bayi.
O tun n sin adiyẹ nibẹ naa.
''Ọrọ mi ko yatọ si ti ọpọ awọn ileewe mii.Tipa ni mo fi n ri epo ra si ọkọ mi.
Awọn olukọ ati akẹkọ ko si nibi mọ. Ki ni naa ba wa gidi gan''
Oṣiṣẹ meji pere ni Mwea Brethren ati Roka gba ṣiṣẹ ti wọn n ran wọn lọwọ pẹlu iṣẹ oko wọn.
Ogbẹni Kung'u ni ''Ki ṣe lati ko ọrọ jọ. Ara ko ni wa pupọ bẹẹ si ni airikanṣe ko ba wa. O jẹ bi ọna lati ṣe itọju ọkan wa''
Bo tilẹ̀ jẹ pe awọn ileewe meji yii ti ri ọna gbe gba, awọn to ni ileewe naa ni àwọn n jaya lori awọn olukọ ti ko ri owo oṣu gba lati nkan bi oṣu marun un sẹyin.
Ṣugbọn ọrọ ko ri bẹ pẹlu awọn olukọ ileẹkọ ijọba tawọn n ri owo oṣu gba deede.
Ọgbẹni Maina sọ pe awọn olukọ ileewe oun kan ti pe lati beere pe ṣe awọn le ri nkankan ṣe ''O bami lọkan jẹ nitori awa naa n tiraka lati jẹun ni''
Nitori eyi, pupọ awọn olukọ lo ti n wa ọna ijẹ mii.
Baba onile ti le Macrine Otieno to jẹ olukọ fọdun mẹfa ni olu ilu Nairobi kuro nile to n gbe nitori ko ri owo ile san.
O sọ fun BBC pe ''Lati igba ti ajakalẹ yii ti bẹrẹ, ti wọn si ti ti ileewe wa pa, mi o ri iṣẹ kankan ṣe''
'Mo n tiraka lati ma ṣe awọn iṣẹ mii ṣugbọn ko rọrun fun mi.''
NUJ ìpínlẹ Oyo bà àwọn ọmọ ẹgbẹ́ tó lọ ìpàdé tí Femi Fani Kayode pè ní Ibadan wí
Oríṣun àwòrán, others
Ẹgbẹ awọn akọroyin Naijiria, ẹka ipinlẹ Oyo ti pe awọn ọmọ ẹgbẹ to lọ sibi ipade ti Femi Fani Kayọde pe ni ilu Ibadan lati wa wi tẹnuwọn niwaju igbimọ to n ba ni wi ninu ẹgbẹ naa.
Iwaju igbimọ olubaniwi yii ni awọn ọmọ ẹgbẹ naa ti ni anfani lati wa sọ iha ti wọn lori ohun to ṣẹlẹ.
Alaga ẹgbẹ naa, Ogbeni Ademola Babalola ṣapejuwe iṣẹlẹ naa pe ko dara to.
Saaju ni wọn ti ni pe ki gbogbo ọmọ ẹgbẹ ma lọ sibi ipade naa ti Femi Fani Kayode pe latari bo ṣe ṣe si akọroyin Daily Trust ni ipinlẹCross River.
Ademola ni o yanilẹnu pe lẹyin aṣẹ ẹgbẹ yii ni awọn akọroyin miran gbẹyin lọ sibi ipade Femi Fani Kayode naa.
Temitope Akinnusi: Ọ̀pọ̀ iléeṣẹ́ ló takú láti gbà mí síṣẹ́ torí mo ní ojú kan
Ki lo ti ṣẹlẹ sẹyin?
Oríṣun àwòrán, Others
Minisita fun ọrọ irinna ọkọ ofurufu tẹlẹri ni Naijiria, Femi Fani-Kayode ti ni oun yoo gbe ileeṣẹ Iroyin Daily Trust lọ si ileẹjọ nitori wọn ba orukọ oun jẹ ninu iroyin ti wọn gbe jade.
Ija to waye laarin Femi Fani-Kayode ati ileeṣẹ iroyin Daily Trust ko ṣẹyin bi Fani-Kayode ṣe sọ ọrọ odi si akọroyin wọn lasiko ti Fani-Kayode n ba awọn akọroyin sọrọ ni Calabar, ni ipinlẹ Cross River.
Lasiko ti Fani Kayode n ba awọn akọroyin naa sọrọ lori iṣẹ ti gomina ipinlẹ Cross River n ṣe ni akọroyin naa bere lọwọ Fani Kayode wi pe tani o ran an niṣe to n ṣe.
Ibeere yii mu ki Fani Kayode gbana jẹ, to si bẹrẹ si ni sọrọ kubakungbe si akọroyin ileeṣẹ Daily Trust to bere ibeere naa lọwọ rẹ.
"Lẹyin iṣẹlẹ yii ni ileeṣẹ iroyin Daily Trust gbe iroyin kan jade ti wọn pe akọle rẹ ni ""FFK, The Drug Addled Thug In Designer Wears"" lati jẹ ki awọn eniyan mọ iru eniyan ti Femi Fani Kayode jẹ."
Amọ, Femi Fani Kayode lasiko to n fesi si atẹjade naa sọ wi pe iroyin naa tabuku oun, to si ba oun lorukọ jẹ.
Oríṣun àwòrán, others
Agbẹjọro fun Fani-Kayode kesi ileeṣẹ iroyin naa lati gbẹsẹle iroyin naa laarin ọjọ mẹ̀rinla,, ki wọn si san owo gba ma binu biliọnu mẹfa naira.
Agbẹjọrọ naa ni ti ileeṣẹ iroyin Daily Trust ko ba ṣe ifẹ awọn, awọn yoo gbe wọn lọ si ileẹjọ.
Laipẹ yii ni Femi Fani Kayode tọrọ aforijin lọwọ akọroyin ileeṣẹ Daily Trust ti o sọrọ kubakugbe si naa.
Bolaji Faleke ni Olùkọ́ tó ń kọ́ wa ní àṣà oge ṣiṣe lórí BBC Yorùbá
Ki lo ti ṣẹlẹ sẹyin lori ọrọ yii:
Awọn akọroyin ni ipinlẹ Ọyọ naa ti kọ ipakọ si ipade awọn akọroyin ti minisita tẹlẹ lorilẹ-ede Naijiria, Fẹmi Fani Kayọde nilu Ibadan.
Awọn to ṣe eto ipade oniroyin naa ti kọkọ rii daju pe iwọnba aṣayan awọn akọroyin ni wọn pe, wọn si fi kun un pe iwọnba awọn ti wọn fi iwe pe nikan lo yọju nibẹ.
Lẹyin o rẹyin, atawọn ti wọn fi iwe pe, atawọn ti wọn ko fi iwe pe lo kọ lati yọju sibi ipade naa.
Oríṣun àwòrán, Others
Alaga NUJ ni ipinlẹ Oyo, Demola Babalola naa fidi ẹ mulẹ pe awọn pinnu lati ma bu ọla fun iwe ipe ti FFK ti kọkọ fi ranṣẹ si ẹgbẹ wọn
Eyi ko ṣẹyin bi awọn alaṣẹ ẹgbẹ akọroyin ti ṣe paṣẹ fawọn akọroyin pe ko si ẹnikẹni ninu wọn to gbọdọ de ibi idibo naa.
Igbesẹ yii n waye loriọrọ kobakungbe ti Fani Kayọde sọ si akọroyin ileeṣẹ iroyin Daily Trust ni ilu Calabar, ni ipinlẹ Cross Rivers.
Ṣaaju igbesẹ yii naa ni ẹgbẹ akọroyin ni ipinlẹ Akwa Ibom naa ti gbe igbesẹ yii.
Wo bí Sunday Orimola ṣe gba ikú ẹranko kú ní Ifon ni Ondo lórí ọ̀nà àtijẹ
Akọroyin iwe iroyin Daily Trust, Eyo Charles, ti Femi Fani-Kayode, sọ ọrọ kobakungbe si sọ pe oun ti dariji i.
Eyo sọ eyi ninu ọrọ kan to ba BBC sọ pe ni kete ti iṣẹlẹ naa waye ni oun ti gba fun Ọlọrun.
Ọjọ Iṣẹgun ni iṣẹlẹ naa waye nibi ipade oniroyin kan ti Fani-Kayode, ti n ba awọn akọroyin sọrọ nilu Calabar, lori irinke-rindo rẹ ni awọn ipinlẹ to wa ni Gusu-Gusu Naijiria.
FFKVS JORNO:Mi o kabamọ ibeere ti mo beere lọwọ FFK
"Lasiko ipade naa ni Ọgbẹni Eyo Charles ti beere lọwọ minisita tẹlẹ ri ọhun pe ""ta alo n gbọ bukaata irinkiri rẹ""."
"Ibeere naa bi Fani-Kayode ninu, eyi to mu ko pe akọroyin naa ni ""ọdẹ''. To si sọ fun un pe ko ye e beere iru nkan bẹ ẹ mọ."
Tẹ ẹ ba gbagbe, mo sọ ninu fidio to lọ kaakiri ayelujara pe, Olori Alufaa, ati Biṣọpu ni mi ninu ijọ Brotherhood of the Cross and Star , nitori naa ni mo ṣe fa gbogbo nkan le Ọlọrun lọwọ.
'Oyenusi ló mú mi wọ ẹgbẹ́ adigunjalè kó tó di pé mo b'Ólúwa pàdé'
Ọgbẹni Eyo ṣalaye pe kii ṣe nitori ibeere to bi Fani-Kayode ninu ni oun ṣe bẹbẹ.
"O ni ""Mo sọ pe ki o ma binu nitori bi awọn akẹẹgbẹ mi kan ti a jọ wa nibi ipade oniroyin naa ṣe n ba mi wi loju ẹsẹ pe n ko ba ma ti beere ibeere naa. Eyi mu ki ara mi gbọn jinnijinni, ti mi o si mọ nkan ti mo n ṣe mọ."
Mi o reti iru ọrọ lile to jade lẹnu minisita , pẹlu nkan ti awọn akẹẹgbẹ mi sọ.
"Gbogbo ẹ ba mi ni ojiji, eyi si mu ki n ro pe  ọrọ abuku ni mo sọ ni, lo jẹ ki n bẹ ẹ pe ko ma binu.
Ọgbẹni Eyo sọ pe Minisita ti kọkọ sọ pe oun ti lọ si ipinlẹ bi mẹfa tẹlẹ, lati wo awọn iṣẹ akanṣe ti awọn gomina naa n se.
Eyi lo si mu ki oun beere pe ta a lo n gbọ bukaata irinajo naa.
Mo ni  Sir, botilẹ jẹ pe ẹ ko sọ fun wa ẹni to n gbọ bukaata yin, ko jẹ ki n pari ibeere mi, to fi han mi pọnkan."""
Minisita Naijiria nigba kan ri, Femi Fani-Kayode ni oun ko ọrọ pe akọroyin Daily Trust jẹ.
O ni lẹyin ijiroro pẹlu awọn olugbani nimọran oun, oun ti ko gbogob ọrọ ti oun sọ si akọroyin naa nilu Calabar jẹ.
"Mo ni ọpọ awọn ọrẹ to pọ ninu iṣẹ iroyin, ti mo si ti ṣẹ wọn nipa ihuwasi mi nipa lilo awọn ọrọ ti ko ṣe e gbọ seti naa.
Mi o ni ṣe ohunkohun ti yoo pa oniroyin lara, nitori pe mo ti ja fun awọn oniroyin ni ọpọ igba."
"Mo ni igbagbọ pe, eyi yoo rọ ọpọ to ti n binu nitori nkan to ṣẹlẹ naa, lọkan.
 Mo ti fi ṣe afisẹyin, ti eegun n fi aṣọ, mo si ti tẹsiwaju."""
"Ni bayii ti Fani-Kayode ti sọ pe oun ko ọrọ ti oun sọ si akọroyin naa jẹ, Eyo sọ pe bo tilẹ jẹ pe ko ti i pe oun gan-an lati tọrọ aforiji, ""nitori pe emi lo sọ ọrọ kọrọ si, ṣugbọn nitori ipo mi gẹgẹ bi biṣọpu, mo ti dariji."""
"Mo reti pe ko bẹ mi, nitori pe mi o sọ ọrọ kọrọ si, ibeere naa jẹ dandan. Mo n ṣe iṣẹ mi gẹgẹ bi akọroyin ni.
Akọroyin naa sọ fun BBC Yoruba pe ibéèrè òun ko ju pe gbogbo irinajo to n rin lọ si iha Guusu, taa gan lo n ṣe onigbọwọ rẹ tabi gbowoo lẹ.
Ẹwẹ, Fani Kayode ni kii ṣe ibeere rara lo bi oun bi kii ṣe ọrọ lasan to si jẹ eebu.
To ba si wa sọ iru ọ̀rọ̀ eebu yii niwaju aarẹ Trump tabi OBJ, mo mọ iru esi ti wọn yoo fun un""."
Kayode ni oun o kabamọ rara pe oun da akọroyin naa lohun bi oun ṣe sọrọ.
O ni arakunrin naa ni ki oun ma binu lasiko ipade oniroyin ọhun o si tun fi ọrọ ẹbẹ rẹ ranṣẹ lẹyin ipade kan naa mo si ti gba ẹbẹ rẹ pẹlu ọkan kan a si ti n ba igbesi aye lọ pada.
Fani Kayode ni ifura pe awọn ọlọtẹ ọta oun ninu oṣelu lo lee ṣe agbatẹru iru ibeere yii ti wn si fẹ lo arakunrin naa lati doju ti oun ati lati ba daadaa oun jẹ.
"Ṣugbọn o ni ""wọn ri gba ju oun ti wọn gbe wa lọ""."
"O ni ""mo tun un sọ pe ọrọ eebu gbaa ni eleyii, mi o si le gba iru ẹ latọdọ ẹda kankan taa bi ninu obinrin""."
Akọroyin ileeṣẹ iroyin Daily Trust Eyo Charles ti ba BBC Yoruba  sọrọ lori ohun to waye laarin rẹ pẹlu Minisita Naijiria tẹlẹ, Femi Fani Kayode.
Ko ṣẹyin fọnran fidio ti Fani Kayode ti n bu pe ko yẹ ki o beere ibere agọ lọwọ ohun ṣe lawọn eeyan  bẹnu atẹ lu Fani Kayode pe ko yẹ ko bu akọroyin naa to bẹ.
Ninu ọrọ ti Eyo Charles sọ, o ni  ohun kan ṣoṣo ti oun kabamọ ni pe oun tọrọ aforiji lọwọ rẹ lori gbolohun ti oun lo.
''Mo bere lọwọ Minisita tẹlẹri ọhun pe ta ni ni to san owo abẹwo rẹ si awn ipinlẹ ti o n ṣe abẹwo si kaakiri Naijiria.Iyẹn awọn ipinlẹ meje to ni oun lọ''
Ibeere mi ko ju bayi lọ ti Minisita si gbanajẹ to bẹrẹ si ni mu mi bu.
Ipade awọn akọroyin to waye ni nkan bi ago mẹwa owuro lỌjọbọ ni ile itura Gomina Ben Ayade ni Cross River ni iṣẹlẹ naa ti waye.
Akọroyin naa sọ pe Fani Kayode mu ileri rẹ ṣẹ ti o si pe awọn ọga ohun nileeṣẹ iroyin rẹ.
World Press Day: Ọ̀pọ̀ ìgbà ni àwọn jàǹdùkú ká mi mọ́lé nítórí ìròyìn tí mo kà
O ni lẹyin toun ṣalaye ohun to ṣẹlẹ fun ọga oun, wọn ni ki oun ma foya ti wọn ko si kọkọ gbe iroyin iṣẹlẹ naa sita.
Charles sọ pe lẹyin ti ariwo pọ loju opo ayelujara awọn olootu iwe iroyin naa ṣẹṣẹ wa kọ iroyin nipa iṣẹlẹ naa ṣugbọn wọn ko ni i ki Fani Kayode tọrọ aforinjin lọdọ akọroyin wọn.
FFKVS JORNO:Mi o kabamọ ibeere ti mo beere lọwọ FFK
DSTV Price Hike: Ọmọ Nàìjíríà faraya lórí èlé owó DSTV tó ń wáyé ní ẹ̀ẹ̀kan lóṣù mẹ́rin
Oríṣun àwòrán, others
Ileesẹ Multichoice tun ti kede pe, oun yoo tun ṣe afikun owo tawọn ọmọ Naijiria n san fun oju opo iworan DSTV ati GOTV.
Ọjọ kinni osu kesan ọdun 2020 si ni ele owo naa yoo bẹrẹ, eyi tii ṣe afikun ẹẹkeji laarin oṣù mẹrin pere.
Gẹgẹ bi ele owo oju iworan DSTV ati GOTV tuntun yoo ṣe lọ, DSTV Premium yoo kuro ni náírà merindinlogun ati igba (N16,200) bọ si naira mejidinlogun o le irinwo naira (N18, 400) ati bẹẹ bẹẹ lọ.
Ninu alaye to ṣe nipa afikun owo naa, Ileesẹ Multichoice ni owo ọjà to gbowo lori, owo ori ọjà, ati agbara owo naira to dinku lo fa a.
Amọ ikede Ileesẹ Multichoice yii ti bọ sapo ibinu awọn ọmọ Naijiria lori ayelujara ati loju popo.
Ọpọ awọn ọmọ Naijiria si lo n koro oju si ijọba apapọ pe o gba Ileesẹ South Africa laaye, lati maa yan wọn jẹ nilẹ baba awọn.
Ọpọ awọn eniyan naa lo ni lai naani ìnira ti arun Coronavirus ko ba ọrọ aje awọn, ati iṣẹ pẹlu òsì to gogo si lawujọ wa, sibẹ Ileesẹ DSTV si tun n fara ni awọn.
Bákan naa ni wọn tun kesi ile asofin apapọ lati dìde si ọrọ naa, ko to bọ̀wọ sori.
Wọn ni awọn n fẹ ki ìjọba atawon asofin lati pasẹ fun Ileesẹ Multichoice pe iye akoko ti onibara ba fi wo oju opo wọn, ni ko maa sanwo rẹ, eyi ti wọn pe ni Pay As You Go.
'Ní ìjọ wa, ọtí mímú la fi ń pe ẹ̀mí Ọlọ́run sọ̀kalẹ̀'
Gani Adams: Àwọn agbébọn ń jí ọmọdé, àwọn obìnrin, ti wọn sì ń dúnkookò mọ ọrọ̀ aje Oke Ogun
Oríṣun àwòrán, @OnwardNG
Yoruba ni agbalagba to n lu irin loju kan ṣoṣo, o ni ohun to fẹ gba lọwọ irin ni.
Fun igba keji laarin osu kan, Aarẹ Ọna Kakanfo nilẹ Yoruba, Iba Gani Adams tun ti n ke tantan pe awọn agbébọn ti farasin siluu Kishi, lagbegbe Oke Ogun.
O fikun pe bakan naa lawọn agbébọn ọhun tun tẹdo sinu igbo igbafẹ Old Oyo National Park lagbegbe Oke Ogun yii kan naa.
Atẹjade kan ti Kehinde Aderemi, tii ṣe akọwe feto iroyin Gani Adams fisita L'ọjọru lo sísọ loju ọrọ yii.
Gani Adams ni ojuse oun ni lati lọgun faraye nipa awọn ọṣẹ táwọn agbébọn naa n ṣe nilu Kishi ati lagbegbe Oke Ogun lapapọ.
O fikun pe awọn iṣẹlẹ to n waye lagbegbe naa lẹ́nu lọọlọọ yii, jẹ ewu nla feto aabo ilẹ Yoruba lapapọ.
Oríṣun àwòrán, others
"Awọn agbébọn yii n ji eeyan gbe, paapaa awọn ọmọde ati obinrin, ti wọn si n fi tipa ba wọn lopọ.
Eti mi ti kun nipa ọpọ iwa aidaa awọn agbébọn naa ti wọn farasin si agbegbe Oke Ogun ati bi wọn ṣe n dunkooko mọ eto aabo ilẹ Yoruba lapapọ.
Aarẹ Ọna Kakanfo wa n kọminu pe ilẹ Yoruba ti n di ibudo fáwọn afẹjẹwẹ ati adunkooko mọni, to n dibọn bii darandaran.
Atunto Naijiria la n fẹ - Aarẹ Onakakanfo, Gani Adams
Adams wa n kede pe yoo dara kijọba tete wa egbo dẹkun fáwọn eeyan naa ko to pẹ ju, ki eto aabo nilẹ Yoruba ma baa mẹhẹ bii ti Oke Ọya.O wa fikun pe táwọn agbofinro ba gba oun laaye, oun yoo ṣe koriya fáwọn eeyan ti eto aabo gberu labẹle bii awọn ọmọ ẹgbẹ OPC, fijilante, ọdẹ ibilẹ, awọn ọdọ ati Agbekoya.Adams ni pẹlu atilẹyin awọn eniyan naa, yoo rọrun lati le awọn agbebọn ọhun kuro lagbegbe Oke Ogun.
Oríṣun àwòrán, Others
Ilé iṣẹ́ aṣọbode Naijiria (NCS) ti kéde fún àwọn òṣìṣẹ̀ rẹ̀ ní'lú Abuja láti bẹ̀rẹ̀ sí ni fi ojú ṣọ́rí nítorí asiri to tu pe ikọ̀ Boko Haram ti ni ìpagọ́ ni ilú Abuja ati gbogbo agbègbè rẹ̀.
Ìwé ìfilọ kan ti nọ́mba rẹ jẹ NCS/ENF/ABJ/180/S.I/VOL.II, ti ọga agba ilé iṣẹ́ náà fi ọwọ si ni olu ile iṣẹ̀ aṣọ́bodè, ti agbegbe H.A Sabo ni Wuse Zone 3 Abuja, ni asiri ọrọ naa ti tu sita.
Nínú ìwé ìfilọ̀ náà, ti wọ́n pe àkọle rẹ̀ ni ìwádi abẹ́nú lori ọ̀rọ̀ ààbò ìlú"", ileesẹ asọbode ni ìròyìn to ń tẹ̀ òun lọ́wọ́ gẹ́gẹ́ bi ọ̀gá àgba ilé iṣẹ́ yìí fihan pé, àwọn ikọ̀ ọmọ ogun Boko Haram ti wà ní ilu Abuja àti gbogbo agbègbè rẹ̀."
Oríṣun àwòrán, others
Lórí ìwé ìfitóniléti ọ̀hún tó jáde ni ogúnjọ́ oṣù kẹjọ, ọdún 2020, lo ti sọ pé, àwọn ikọ̀ Boko Haram náà ṣètò láti ṣe ìkọ̀lù si àwọn ibì kan nílùú Abuja àti agbàgbè rẹ̀.
Wọ́n ni wọ́n ti ṣetò ibùdó wọ́n sínú igbó Kunyan lópópónà Airport.
Ó fi kun pé, ibùdó míràn tún wà ninú igbó Robochi/Gwagwalada, igbó Kwaku ní Kuje àti igbó Unaisha ní ìjọba ìbílẹ̀ Toto ní ìpińlẹ̀ Nasarawa.
Ẹ̀wẹ́, àgbẹnusọ ilé iṣẹ́ aṣọ́bodè Joseph Attah sọ pé, òun kò mọ ẹni to fún wọ́n ni àwọn aṣírí yìí, sùgbọ́n ìwádìí ń lọ lọ́wọ́.
Oríṣun àwòrán, others
Tí ẹ o bá gbàgbé, irú ìròyìn báyìí náà ti ẹnu olórí ogún nílẹ̀ Yorùbá, Ààrẹ Ọ̀nà Kakanfo, Iba Gani Adams jáde ni ǹkan bi ọ̀sẹ̀ méjì sẹ́yìn.
Gani Adams ni ikọ̀ asẹrubani ISIS ti ni ibùdó si agbègbè Oke Ogun ní ìpińlẹ̀ Oyo, o si yẹ kawọn ọmọ Yoruba fura.
Aarẹ Ọna Kakanfo ilẹ Yoruba Iba Gani Adams ti ke gbàjarè pé awọn ọmọ ẹgbẹ agbesumọmi Islamic State, (IS) wa wọ ipinlẹ Oyo.
Nínú ọ̀rọ̀ rẹ̀ pẹ̀lú BBC lówùrọ̀ òní sàlàyé pé bi ìgbìmọ̀ ààrẹ kò bá ri kò ni sọ.
Ó ní àwọn gómìnà àti àwọn ọba aláde ilẹ̀ Yorùbá ti sùn àsùn píye ti gbogbo àwọn oríṣirisi ṣì n wọle tọ wọ́n wá.
Gẹ́gẹ́ bi ó ṣe sọ, ó ni ìwádìí ti fi han pé àwọn aggbésùmọ̀mi Islamic State ti wà nínú igbó Lùsádà, ilú yìí ló já si ìgbó ọra eyi ti kò sì ju wákàti méji lọ si ìpínlẹ̀ Sokoto.
"Àrídáju wá, a ri àwọn alùpùpù olówó ńla tó lé ẹ̀ẹ́dẹ́gbẹ̀ta tó wọ inú igbó náà, wọ́n di ẹru ìjà olóró àti òunjẹ wọ́n sórí rẹ̀.
Oríṣun àwòrán, Others
O fí kún pé, wọ́n kìí ṣe Boko Haram tàbi Fulani daran-daran ti wọ́n  ti mọ̀ tẹ́lẹ̀, ìmúra wọ́n kò jọ bi àwọn ti a mọ̀ tẹ́lẹ̀"""
Wọ́n ti wọ Ibariba nipìnlẹ̀ Niger, wọ́n ti wọ òkè-ògùn., o ní ọ̀pọ̀ wọ́n wọ asọ sọja, ti wọ́n sì n rìn káàkiri inú igbó náà.
Ó rọ ìjọba àpapọ̀ àti àwọn gómìnà ìpínlẹ̀ Yoruba la'ti gbé ìgbẹ́sẹ nítorí ààrẹ ọ̀nà kò lé ṣe ńkan kan ti ìjọba kò bá lọ́wọ́ síí
Iba Gani Adams mẹnu ba ọ̀rọ̀ MURIC ti wọ́n fẹ̀sùn kan pé ó gbowó lọ́wọ́ ISWAP láti gba awọn Fúlani fún ìgbésùmọmi, sùgbọ́n ó ṣeni laáànu pé, ìjọba kọ̀ láti ṣe ìwádìí nípa pípe adari MURIC, ọjọgbọ́n IShiaq Akintola.À kò gba owó kankan lọ́wọ́ àwọn ẹgbẹ́ agbésùmọ̀mí ISWAP- MURIC
Olóyè Gani Adams ni ìlanilọ́yẹ ni àkọ́kọ báyìí láti ṣe fún àwọn ènìyàn àti àwọn lọ́balọ́ba láwọn agbègbè náà.
Oríṣun àwòrán, @OnwardNG
Igbimọ Aarẹ Ọna Kakanfo ilẹ Yoruba ti sọ pe, awọn ọmọ ẹgbẹ agbesumọmi Islamic State, IS, ti rapala wọ agbegbe Okeogun, ni ipinlẹ Oyo.
Igbimọ naa lo kede bẹẹ ninu atẹjade kan ti Atoloye Aare Ona Kakanfo, oloye Babajide Tanimowo buwọlu
O ni lẹyin ọpọ iwadii ati ifimutolẹ ni Naijiria ati loke okun, igbimọ Aarẹ ọna Kakanfo le e fidi rẹ mulẹ pe, awọn agbesumọmi ati Fulani darandaran ti gunlẹ si agbegbe ọhun.
"Atẹjade naa ni  ""Eyii to kan wa lominu julọ nibẹ ni pe awọn ọmọ ẹgbẹ ISIS ti kora wọn wa si agbegbe Okeogun ni ipinlẹ Oyo."""
Baby abandoned on dunmpsite: Mo ti bímọ mẹ́rin tẹ́lẹ̀ fún bàbá méjì nínú òṣí- Dupe Ogbomos
O tẹsiwaju pe alupupu alagbara bii ẹẹdẹgbẹta ati awọn ohun ija oloro  to jẹ ti awọn ọmọ ẹgbẹ agbesumọmi naa ni wọn ti foju gaani loju ọna Lusada si Sokoto, eyii to jẹ apa kan ọna to gba Igbo-Ora kọja ni ipinlẹ Oyo.
Igbimọ naa wa rọ awọn gomina iha Ariwa Naijria, pẹlu gomina ipinlẹ Kwara ati Kogi lati kẹkọọ lara gomina ipinlẹ Benue, Samuel Otom, to ni ki awọn eeya ipinlẹ rẹ lọ gba aṣẹ lati ni ibọn fun abo ara wọn.
Bakan naa lo rọ ijọba apapọ lati di ala ilẹ Naijiria ti awọn ọmọ ẹgbẹ agbesumọmi naa atawọn Fulani daran daran n gba wọle lati orilẹ-eded miran.
"Bí ẹ ṣe mọ̀wé tó, ẹ wá dánrawò níbí pẹ̀lú ""Àpólà Ọ̀rọ̀ Orúkọ - Noun Phrase"
Spartan in Ogun: Èèyàn márùn-ún ní ọlọ́pàá sọ pé afurasí náà pa léraléra
Oríṣun àwòrán, OTHERS
Afurasi apaayan ati amu oogun oloro to n daomi alaafia ilu Ogere ati Iperu ru ti awọn ọlọpaa ipinlẹ Ogun si ti n wa la gbọ pe wọn ti yinbọn pa bayii.
Ọkunrin naa, Feyisola Dosumu to ti na papa bora fun ọjọ melo kan naa ni wọn ti n wa kiri.
Iroyin taa gbọ ni wipe apapọ ikọ amuṣẹya alaabo ni agbegbe Ogere nipinlẹ naa lọjọ Iṣẹgun ọsẹ.
Ṣaaju, ileesẹ Ọlọpaa ipinlẹ Ogun ti kede pe ọwọ sinkun oun ti ba afurasi apaayan, ọmọ ẹgbẹ okunkun ati amu oogun oloro ti wọn n wa.
Orukọ afurasi naa ni Feyisola Dosumu, ti ọpọ eeyan mọ si Spartan, deede aago kan ọ̀san si ni ọwọ awọn ọlọpaa tẹ ẹ.
Agbenusọ fun Ileesẹ ọlọpaa nipinlẹ Ogun, Abimbola Oyeyemi, ẹni to fidi iṣẹlẹ naa mulẹ tun fikun pe wọn ti gbe afurasi naa lọ si Olu Ileesẹ ọlọpaa nipinlẹ naa to wa ni adugbo Eleweran.
O ti to ọjọ mẹta ti iroyin Spartan ti gbalẹ kan pe awọn ọlọpaa n wa nitori pe wọn fura si pe oun lo n gba ẹmi pupọ nilu Iperu ati Ogeere.
Ọkùnrin kan pa ara rẹ̀ sínú ọgbà àjọ TRACE tó n mójútọ ìrìnnà ọkọ̀ nípìnlẹ̀ Ogun
'Orísúnmibáre ni àìsàn 'Polio' tó kọlù mí ní kékeré'
John Blake wà ní ICU, ọlọ́pàá tó yìnbọn fún un bẹ̀rẹ̀ ìsinmi tipá tipá
"Bí ẹ ṣe mọ̀wé tó, ẹ wá dánrawò níbí pẹ̀lú ""Àpólà Ọ̀rọ̀ Orúkọ - Noun Phrase"
Koda, ọpọ awọn olugbe agbegbe yii ni wọn ti n fi ile wọn silẹ nitori iku ojiji to n pa wọn.
Olugbe kan lagbegbe naa ni lẹyin to ti ran eeyan mẹta sọrun nibẹrẹ ọdun yii, afurasi naa tun pa eeyan meji miran nipari osu keje ọdun yii.
Spartan, to kẹkọ jade nile ẹkọ Gbogbo Nse Poly Moshood Abiola to wa nilu Abeokuta, ni wọn lo jẹ igi wọrọkọ tii da ina ru nilu abinibi rẹ Ogere Remo.
Wọn ní kete to wọ ile ẹkọ Gbogbo Nse tan, lo dara pọ mọ awọn ọmọ ẹgbẹ okunkun, to si tun n mu oogun oloro.
Koda, iroyin naa ni wọn ti gbe afurasi apaayan naa lọ tọju nile iwosan alarun ọpọ to wa ni Aro ri, amọ to sa kuro nibẹ pada silu Ogere, to si n ṣe wọn bi ọsẹ ti n ṣe oju.
Iroyin naa tun fikun pe ṣe ni Dosumu maa n fọnnu kiri pe oun setan lati pa ọpọlọpọ eeyan lagbegbe naa, eyi to n ko ibẹru-bojo ba ọpọ eeyan nibẹ.
'Ìgbà tí mo máa fi lajú sáyé padà, ọ̀fọ̀ ikú mi ní wọ́n ń kígbe'
Lionel Messi: ''Kò sí ohun to lè mú Messi dúró sí Barcelona mọ́''
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Bi gbogbo nnkan ti n lọ yii, afaimọ ki agbaọjẹ agbabọọlu Barcelona, Lionel Messi ma fi ikọ agbabọọlu naa silẹ ni kopẹ kopẹ.
Ileeṣẹ redio kan, Cadena Ser lorilẹede Spain ti sọ pe adehun ọdun meji ni Manchester City fẹ ṣe pẹlu Messi ti wọn ba ti ra a tan lati Barcelona.
Oludari kata-kara awọn agbabọọlu ni Barcelona, Txiki Begiristain ti de si ilu Barcelona lati duna dura lori ati ra Messi lọ si Man City.
Bakan naa ni a gbọ pe baba Messi, Jorge yoo ṣe ipade pẹlu awọn alaṣẹ Barcelona lọsẹ yii lati sọrọ lori bi Messi yoo ti fi ẹgbẹ agbabọọlu silẹ.
Ọpọ lo gbagbọ pe Messi lo le ran Man City lọwọ lati gba ife ẹyẹ UEFA Champions League eyi ti wọn ko tii gba ri ninu itan wọn.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Messi kọ lati ṣe ayẹwo coronavirus lọsẹ to kọja lẹyin ti Barca ni ki gbogbo agbabọọlu lọ fun ayẹwo ki wọn le bẹrẹ igbaradi fun saa bọọlu tuntun.
Koda akọnimọọgba tuntun Ronald Koeman ti ṣe igbaradi akọkọ pẹlu awọn agbabọọlu Barca ṣugbọn Messi ko si nibẹ.
Ẹwẹ, oludije fun ipo aarẹ ẹgbẹ agbabọọlu Barcelona, Toni Freixa ti sọ pe ko si ṣiṣe ko si aiṣe, Messi o le duro mọ ni Barca.
Freixa ni ko si iru adehun ti Barcelona le fẹ fun Messi to le mu duro si Barcelona, o ni aṣọ ko ba ọmọyẹ Messi mọ.
Freixa ni ''ọdun 2015 ti Barcelona ti gba ife ẹyẹ Champions League kẹyin, eyi si lo n kọ Messi lominu nitori o tun fẹ gbade Champions League sii.''
Oludije fun ipo aarẹ ẹgbẹ Barcelona sọ pe o ti han gbangba bayii pe Messi fẹ lọ ba akọnimọọgba rẹ tẹlẹ, Pep Guardiola ni Man City.
Níbo ni Messi fẹ́ mórí lé báyìí lẹ́yìn tó jáwée ó tó gẹ́ fún Barcelona?
Ko si ohun to ni ibẹrẹ ti ko l'opin, lo difa fun gudugbẹ to ja lọjọ Iṣẹgun nigba ti iroyin jade pe elegee ara, Lionel Messi ti kọwe si ẹgbẹ agbabọọlu Barcelona pe oun ṣetan lati dagbere fun ẹgbẹ agbabọọlu naa pe o digba o ṣe.
Ipinnu Messi ko ṣẹyin rukerudo to n ṣẹlẹ lọwọ ni Barcelona papaajulọ lati igba ti Bayern Munich  ti lu wọn laluki pẹlu ami ayo mẹjọ si meji ninu idije UEFA Champions League.
Iṣẹ ti bọ lọwọ akọnimọọgba Quique Setien lẹyin abuku nla naa, koda wọn ti le Eric Abidal naa to n ri sí katakara ati pasiparọ awọn agbabọọlu fun Barca lọ.
Lẹyin ti Ronald Koeman di akọnimọọgba tuntun fun Barcelona, ẹgbẹ agbabọọlu naa ti bẹrẹ awọn atunto kan lati tẹ ikọ naa siwaju.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Lara awọn awọn igbesẹ ọhun ni pe ẹlẹsẹ ayo Luis Suarez at'awọn mii yoo ni lati fi ẹgbẹ agbabọọlu naa silẹ.
Lẹyin naa ni Messi sọ fun  Barca pe asiko ti to lati fi ikọ Barca silẹ.
Awọn ẹgbẹ agbabọọlu bii Manchester City, Manchester United, PSG ati Inter Milan lawọn kan n sọ pe o ṣeeṣe ki Messi mori le.
Iroyin kan tiẹ sọ pe Messi ti kan si akọnimọọgba rẹ tẹle, Pep Guardiola to wa ni Man City bayii.
Ohun to wa ninu adehun ti Messi ṣe pẹlu Barca ni pe oun le fi ẹgbẹ agbabọọlu naa silẹ lọfẹẹ, ṣugbọn Barca ni o gbọdọ jẹ ipari oṣu karun ti saa bọọlu yoo pari.
Awọn alaṣẹ Barcelona ni Messi ko le lọ bayii nitori oṣu karun ti kọja, amọ Messi ni ajakalẹ arun coronavirus ni ko jẹki oun sọrọ lati igba yii wa.
'ìjà ṣẹlẹ̀ láàrín èmi àti ọ̀gá mi ní Lebanon tórí mi ò lè dá N300K padà'
Justice For Uwaila: Ọlọ́pàá ìpínlẹ̀ Edo fojú àwọn aṣebi tó pa Uwaila Omozuwa hàn
Oríṣun àwòrán, Twitter
Ọjọru, ọjọ kẹtadinlọgbọn, oṣu Karùn-ún, ọdun 2020 ni àwọn kan fipá bá ọmọbìnrin ẹni ọdún 22 lopọ̀ nínú sọ́ọ́sì.
Ọkan lara awọn afurasi ti ọwọ ọlọpaa tẹ lori iku ọdọmọbinrin, to jẹ akẹkọọ Fasiti ilu Benin, ti wọn pa laipẹ yii, sọ pe obinrin kan to jẹ ọmọ ijọ kan naa pẹlu rẹ lo ni ki awọn pa a.
Inu ijọ 'Redeemed' kan ni wọn pa Uwaila Vera Omozuwa si, nitosi ile awọn obi rẹ.
"Afurasi naa, Collins Uligbe, sọ lasiko ti ọlọpaa fi oju wọn han ni gbangba pe ""Iya onile oun, Mary Ade, lo fun oun ati awọn isọmọgbe rẹ ni miliọnu kan Naira, lati pa ọmọbinrin naa."
O tun sọ fun wa pe ka fi aṣọ pelebe nu ẹjẹ rẹ, ka si mu u wa fun oun.
O fikun ọrọ rẹ pe Arabinrin Ade sọ fun oun pe gule-gule ọmọ naa ti pọju ninu ṣọọṣi. Uwa lọtun, Uwa l'osi, bi ẹni pe oun nikan ni ọmọ to wa ninu ṣọọṣi.
Kọmiṣọna ipinlẹ Edo, Ọgbẹni Johnson Kokumo lo fi oju awọn afurasi mẹfa naa han lọjọru ọsẹ.
Ṣaaju, ọga agba Ọlọpaa lorilẹede Niajiria, Mohammaed Adamu ti seleri wi pe awọn yoo se awari awọn to sekupa arabinrin Vera Omosuwa ni ipinlẹ Edo.
Ọjọru, ọjọ kẹtadinlọgbọn, oṣu Karùn-ún, ọdun 2020 ni àwọn kan fipá bá ọmọbìnrin ẹni ọdún 22 yii lopọ̀ nínú sọ́ọ́sì.
JusticeforUwa:Awọn àkẹkọ̀ọ́ Uniben wọ́de ìfẹ̀hónú hàn nítórí Uwa tí wọ́n fipa bálòpọ̀
Justice for Uwa: Bàbá Uwa, akẹ́kọ̀ọ́ fásitì tí wọ́n fipábálòpọ̀ ní Benin bá BBC sọ̀rọ̀
Uwaila jẹ akẹkọọ ipele ikini ninu imọ ẹkọ Microbiology ni fasiti Uniben ti awọn obi rẹ si ni ọmọ to da yatọ ni laarin gbogbo ọmọ ti Ọlọrun fun wọn.
Oríṣun àwòrán, others
Awọn afurasi ti wọn foju wọn han naa ni Nelson Ogbebor, Akato Valentine, Arabinrin Tina Samuel, Arabinrin Mary Ade, Nosa Osabohien ati Collins Ulegbe.
"Kọmiṣọna ni '""ọrọ naa jẹ ọrọ to mumu layaa ọga agba awọn ọlọpaa, Muhammed Adamu to si ran ikọ akọṣẹmọṣẹ lọ si ilu Benin lati lọ ṣiṣẹ pẹlu awọn ọlọpaa wa"""
Ohun taa n ri lonii jẹ abajade akitiyan awọn ọlọpaa lati de kulẹkulẹ ọrọ yii.
Kokumo jẹ ko di mimọ pe esi ayẹwo ti wọn ṣe fi han pe lootọ wọn fipa ba Uwaila lo pọ ni.
'Oyenusi ló mú mi wọ ẹgbẹ́ adigunjalè kó tó di pé mo b'Ólúwa pàdé'
Emir Kano tuntun ti balẹ̀ sí ìlú Ilorin fún àyẹ̀wò ọlọ́jọ́ mẹ́ta
Emir tuntun ipinlẹ Kano, Alhaji Aminu Ado Bayero ti gunlẹ si ilu Ilorin fun abẹwo ọlọjọ mẹta.
Nnkan bi aago meji ọsan Ọjọbo ni ọkọ ofurufu to gbe e balẹ bagẹ si papakọ ofurufu ilu Ilorin.
Emir naa ti iya rẹ jẹ ọmọ bibi ilu Ilorin lo gori alefa lẹyin ti gomina ipinlẹ Kano, Ibrahim Ganduje yọ Emir ana to tun jẹ gomina banki apoapọ Naijiria tẹlẹ, Alhaji Lamido Sanusi nipo.
Kẹkẹ ẹlẹṣin ni Emir ọhun yoo gun de Aafin ọba Ilorin.
Ogunlọgọ awọn eeyan ilu Ilorin lo peju si papakọ ofurufu ilu Ilorin lati ki Emir ọhun kaabọ si ilu iya rẹ.
idunu atayọ lawọn eeyan naa fi ki Emir kaabọ
Emir ilu Ilorin ati awọn eeyan ti duro de ọlọla ọba Kano, ti eero si n tu kẹti kẹti lati wa ki ọba naa kaabọ.
Ẹsẹ ko gbero ni papakọ ofurufu ilu Ilorin.
Awọn olorin ibilẹ atawọn oloye ilu miran miran ko gbẹyin nibẹ pẹlu.
Iya Emir ọhun ni ọmọ ọba iIlorin to fẹ Ado Bayero to doloogbe ni Kano.
Pataki àbẹwò yi ni pe ọmọ ọmọ ọba ikejo ní Emir Kano jẹ.
Emir Bawa lo bi iya rẹ ti o si lọ fẹ ọba Kano Ado Bayero
AAUA latest news: Kìí ṣe àkókò yìí ló yẹ kí Akeredolu dín owó ilé ìwé kù, ìbò ló ń fẹ̀ - òbí àti Akẹ́kọ́ọ̀ AAUA
Oríṣun àwòrán, AAUN News Forum
Awọn akẹkọọ AAUA fariga lọdun 2018 lẹyin afikun owo ileewe wọn.
Awọn obi kan ati akẹkọọ fasiti Adekunle Ajasin, AAUA, to wa ni Akungba-Akoko ni ipinlẹ Ondo ti bu ẹnu atẹ lu ijọba ipinlẹ naa lẹyin to ṣadinku iye owo ile iwe ọhun.
Awọn obi ati akẹkọọ ọhun ni kii ṣe pe ijọba, labẹ iṣakoso gomina Oluwarotimi Akeredolu, fẹran ara ilu lo jẹ ko din owo ile iwe naa ku, bi ko ṣe ọgbọn alumọkọrọyi lati jẹ ki awọn eeyan dibo fun un fun saa keji.
Inu atẹjade kan to fi ṣowọ si awọn oṣiṣẹ ati akẹkọọ ni ijọba ipinlẹ Ondo ti sọ pe oun ti ṣadinku si iye owo ile iwe naa lẹyin ti ọrọ aje dẹnu kọlẹ nitori ọwọja ajakalẹ arun Coronavirus.
Ṣugbọn awọn eeyan ti fesi pe eto oṣẹlu ni gbogbo rẹ jẹ, ati pe ko si iyatọ kan gboogi laarin iye owo ti wọn n ṣo tẹlẹ ati eyii ti wọn yọ kuro ninu rẹ.
"Arabinrin Olayinka Olatunji to jẹ obi sọ fun BBC pe ""Ko si obi to fẹ ki ọmọ oun maa jiya lai lọ si ileewe, ṣugbọn iye owo ile iwe ti wọn n san ni AAUA yẹn ti pọ ju."""
"Ni ti iye ti ijọba yọ kuro ninu owo ile ọhun arabinrin naa ni ""Ko si iyatọ ninu iye ti ijọba yọ kuro ninu owo ile iwe naa ati iye ti wọn n san tẹlẹ."
"O tẹsiwaju pe ""Kii ṣe pe Akeredolu fẹran ara ilu to bẹẹ lo jẹ ko din owo ile iwe wọn ku, ṣugbọn o jẹ nitori pe o n fẹ ki wọn dibo gbe oun wọle sipo gomina lẹẹkeji ni."""
Grace Akinbiyi  to jẹ akẹkọọ ni fasiti naa sọ fun BBC pe ijọba ko tilẹ ṣadinku iye owo ti wọn n san ni ẹka ẹkọ oun.
Oríṣun àwòrán, AAUA
"Akinbiyi ni ""ko si iyatọ laarin iye owo ti a n sọ tẹlẹ si iye ti wọn ni wọn yọ kuro, fun apẹrẹ, ₦150,000 ni awọn akẹkọọ imọ ofin n san tẹlẹ, iye kan naa ni wọn ṣi maa san bayii, ki wa ni iyatọ to wa nibẹ?"""
O tẹsiwaju pe ti ijọba ba fẹ ṣadinku iye owo ile iwe ni tootọ, ko yẹ ki adinkun naa din ni ida aadọta.
Akẹkọọ ọhun pari ọrọ rẹ pe oun ko ni igbagbọ ninu gomina Akeredolu nitori akoko to din owo ile iwe ọhun bo si asiko ti eto idibo sunmọ etile.
Ọjọ kẹrindinlọgbọn, oṣu Kẹjọ, ọdun 2020 ni ijọba ipinlẹ Ondo kede adinku owo ile iwe naa pẹlu ẹgbẹrun lọna ogun naira.
'Oyenusi ló mú mi wọ ẹgbẹ́ adigunjalè kó tó di pé mo b'Ólúwa pàdé'
Gbogbo akititayan ileeṣẹ BBC lati ba ijọba sọrọ lori awuyewuye adinku owo ile iwe ọhun lo ja si pabo.
Ọdun 2018 ni ijọba Akeredolu ṣafikun iye owo ile iwe naa, eyii to fa awuyewuye ti awọn akẹkọọ naa si gunle iwọde pe ki ijọba da owo ile iwe naa pada si iye to wa tẹlẹ.
Ṣugbọn lẹyin gbogbo iwọde ọhun, ijọba kọ lati ṣe ohun ti wọn n fẹ.
'ìjà ṣẹlẹ̀ láàrín èmi àti ọ̀gá mi ní Lebanon tórí mi ò lè dá N300K padà'
Ayere Imam's wife murdered: Alayere dá sọ́rọ̀ ìyàwó Ìmáàmù àgbà tí wọ́n pa sínú ilé
Oríṣun àwòrán, Other
Alayere ti ilu Ayere nijọba ibilẹ Ijumu, ipinlẹ Kogi ti sọrọ lori bi awọn afurasi oniṣegun ibilẹ kan ṣe pa iyawo Imaamu agba ilu Ayere, arabinrin Yemisi Baderu.
Iroyin taa gbọ ni wipe inu ile arabinrin naa to jẹ iya to n tọ ọmọ oṣu marun kan lọwọ ni wọn ti pa a loju ọkọ rẹ atawọn ọmọ wọn to dagba pẹlu ada.
Awọn akọroyin n sọ wipe ohun ti awọn ri ko jọ ni pe awọn oniṣegun ibilẹ ọhun ti n fa Imaamu naa leti lori iru awọn waasi to maa n ṣe ṣugbọn Alayere ko lee fidi eyi mulẹ.
"Nigba ti BBC Yoruba ba Ọba ilu naa, Oba Jo Olubo sọ̀rọ̀, o ni ""bi nka ba ṣẹlẹ keeyan fi ro ara rẹ wo, gẹgẹ bi ọba ko tii ṣẹlẹ ri lati bii ọgbọn ọdun, torinaa inu mi ko dun rara""."
'Ìgbà tí mo máa fi lajú sáyé padà, ọ̀fọ̀ ikú mi ní wọ́n ń kígbe'
"O fi kun un wipe ninu itan ilu Ayere ko tii ṣẹlẹ pe ki wọn lọ pa eeyan sinu ile rẹ, "" a o tilẹ layaa rẹ rara""."
Kabiyesi ni lai tilẹ kii ṣe ọba gan, gẹgẹ bii ẹlẹran ara, inu oun ko dun si i rara.
Ẹwẹ, Alayere jẹ ko di mimọ fun BBC Yoruba pe awọn ọlọpaa ti fi ọwọ ofin mu eeyan mẹta ti wọn fura si pe wọn lọwọ ninu iṣẹlẹ naa.
Nigba ti a bi Alayere pe ki ni ilu gaan ti wa ṣe lori ọrọ yii. Ọba Olubo ni ni kete ti oun gbọ ọrọ naa,  ni ilana ibilẹ oun ti pe ipade lọkunrin lobinrin gbogbo awọn ijoye oun ti awọn si ti n gbe igbesẹ.
"Bo tilẹ pe o ni ijọba ti gbe igbesẹ ""ko to le di pe awa naa gbe igbesẹ, a gbudọ jẹ ki ijọba parii titiwọn ṣugbọn awa naa n ṣe eyi ti a lee ṣe laarin ilu""."
Akeredolu ń fẹ́ kí wọ́n dìbò fún òun ló jẹ́ kó ṣàdínkù owó ilé ìwé AAUA - Akẹ́kọ́ọ̀ AAUA
Ta ni Ọmọ ọdún 17 tí wọ́n fẹ̀sùn kàn pé ó pa èèyàn méjì ní Kenosha?
Wo àṣẹ tuntun tí Buhari gbé síta nípa owó iná ọba
'Mi o fọ́wọ́ sí bí ọmọ mi, Kiddwaya ṣe lọ fún BBNaija - Terry Waya
'Oyenusi ló mú mi wọ ẹgbẹ́ adigunjalè kó tó di pé mo b'Ólúwa pàdé'
Kabiyesi ni igbesẹ ti awọn n gbe, oun ko lee sọ ọ sita ṣugbọn o gbagbọ pe ati ti ijọba ati tawọn, gbogbo rẹ lo maa yọri si rere.
Ọba Olubo sọ nipa iru eeyan ti Imaamu ti wn pa iyawo rẹ yii jẹ pe dajudaju ki wọn to lee fi eeyan si iru ipo yẹn, o gbudọ jẹ eeyan daadaa torinaa o ni oun mọ wipe eeyan to dara ni Imaamu agba naa jẹ niluu.
Yinka Ayefele: Aláàánú kan fi kẹ̀kẹ́ tuntun ta akọrin Tungba lọ́rẹ
Oríṣun àwòrán, Screenshot/instagram/yinka ayefele
Gbajugbaja olorin juju nni, Yinka Ayefele ti le e naro bayii lori ẹsẹ rẹ to ba wu u.
Eyi ko si ṣẹyin kẹkẹ igbalode kan to ni awọn eroja irọrun to ṣe e yi si ọtun ati osi, oke ati ilẹ, ibi to ba si wu eeyan, lo le e yi kẹkẹ naa si.
Yinka Ayefele, lo kede pe o ti rọrun fun oun bayii lati rin pẹlu kẹkẹ tuntun naa loju opo Instagram rẹ lọjọ Ẹti.
O fikun pe ẹlẹyinju aanu kan, to pe orukọ rẹ ni Hon Obama Oludare Akande lo fun oun ni kẹkẹ tuntun naa fun oun lati orileede Amẹrika.
Yinka Ayefele: Oṣù àwọn ìbẹ́ta mi kò pé ní kò jẹ́ kí n kọ́kọ́ kéde ìbí wọn
"Ayefele ni ""Mo le duro kọrin nibikibi bayii pẹlu kẹkẹ tuntun naa, 'action' bẹrẹ bayii, mo dupẹ pupọ lọwọ Dare Obama."""
"Akọrin Tungba naa fikun pe ""irọrun de ba mi gidi bayii pẹlu kẹkẹ tuntun naa, Dare Obama tun ti fun mi ni ireti lati rin pada,."""
O wa gbadura fun Alaanu naa pe ko ni mọ inira nile aye rẹ.
Ilé orin wa tí Ajimobi tun kọ́ dára púpọ̀, ṣùgbọ́n a kò ní dẹ́kun òtítọ́
Bẹẹ ba gbagbe, o ti le ni ogun ọdun ti gbajumọ akọrin ẹmi naa ti padanu ọ̀pá ẹyin rẹ, ti ko si lee rin mọ nitori ijamba ọkọ to waye.
Chadwick Boseman wife: Simone Ledward ni ìyàwó Chadwick Boseman, wọ́n sì 'sègbéyàwó kó tó jáde láyé
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Gbajugbaja oṣere sinima ni, Chadwick Boseman to ku laipẹ yii ko ku laapọn o, o ṣe igbeyawo pẹlu iyawo rẹ Taylor Simeone Ledward ki o to jade laye.
Ni osu kẹwaa, ọdun 2019 lawọn mejeeji ṣe eto mọmi n mọ ọ ki wọn to ṣe igbeyawo bonkẹlẹ ki o to jade laye.
Ni ọdun 2015 ni aniyan ifẹ laarin awọn mejeeji yii kọkọ lu sita nigba ti awọn ayaworan kọkọ kofiri wọn pọ ni papakọ ofurufu ilu Los Angeles International Airport.
Ni oṣu kẹta ọdun 2019 ni oloogbe Chadwick Boseman kọkọ sọrọ ni pa ọrọ ifẹ oun ati Ledward ni ibi eto ami ẹyẹ 50th NAACP Image Awards.
Boseman jade laye lẹyin ọdun mẹrin ti aisan jẹjẹrẹ ti n ba a finra, iyawo rẹ naa si wa pẹlu rẹ ni ile rẹ to wa ni Los Angeles nigba to mi eemi ikẹyin.
Akọrin ni Ledward, ileewe giga Carlifornia State lo lọ.
Oríṣun àwòrán, @Chadwick
Iya iya Ledward pẹlu sọ si ọrọ ifẹ aarin awọn mejeeji yii to si ni ifẹ wa laarin wọn, inu awọn mejeeji si dun si ara wọn.
Wọn bọwọ fun ara wọn, inu ọkọ dun, inu iyawo naa si dun pẹlu.
.Ni eyi to fi jẹ ki Boseman fi iyawo ati ẹbi silẹ lọ.
Wo bí Sunday Orimola ṣe gba ikú ẹranko kú ní Ifon ni Ondo lórí ọ̀nà àtijẹ
Ṣe ọmọ ilẹ̀ Afirika ni Boseman Chadwick?
Oṣere Wakanda ti gbogbo aye n pe ni Black Panther le sọ ede isiXhosa to jẹ ede South Africa.
Awọn ibudo itan inu sinima Black Panther to jẹ ibi ala rere naa fi ara pẹ ila oorun Naijiria ninu ere Black Panther to jẹ kikida alawọ dudu lo ṣee lọdun 2018.
Ọpọ ọdọ lo n wo Chadwick gẹgẹ bii awokọṣẹ rere ni gbogbo agbaye nitori pe o fi ifẹ han si awọn alarun jẹjẹrẹ pupọ lai naani pe oun naa n ba aisan naa finra de gongon lọdun mẹrin gbako.
Oríṣun àwòrán, @Chadwick
Gbogbo aye lo ṣedaro iku gbajumọ oṣere tiata to ṣe ere Black Panther, Chadwick Boseman to jade laye lẹni ọdun mẹtalelogoji.
Boseman jade laye lẹyin idojukọ ọdun mẹrin pẹlu aisan jẹjẹrẹ.
Loju opo Twitter rẹ si ni wọn ti tufọ iku rẹ laṣalẹ ọjọ Ẹti.
Atẹjade to waye loju opo twitter rẹ leyi ti wọn fi tufọ rẹ ti di ọrọ ori twitter ti awọn eeyan fi ifẹ han si julọ lagbaye ninu itan idasilẹ oju opo ayelujara Twitter.
Awọn alaṣẹ oju opo ikansiraẹni Twitter lo fi idi eyi mulẹ ninu atẹjade kan ti wọn fi sita ni ọjọ Abamẹta.
Natalia Mufuta ìyá Yakub, Kamil àti Adam sọ̀rọ̀ lórí bí wọ́n ń sọ èdè mẹ́rin pàpọ
Lati igba ti atẹjade ti a n sọrọ rẹ ọhun ti jade loju opo Twitter Chadwick Boseman ni irọlẹ ọjọ Ẹti, o din diẹ ni miliọnu mẹfa eeyan (6.5 million) to ti tẹ eroja ififẹ han (Likes) to wa ni isalẹ oju opo naa.
Ipa ti Boseman ko ninu sinima agbelewo to fọnrere agbara eeyan alawọ dudu ni, Black Panther lo sọ ọ di gbajugbaja.
ọdun 2016 lo bẹrẹ si ni wọ iya ija pẹlu aisan jẹjẹrẹ ki o to kọja afarada, to si gba ẹmi rẹ ni Los Angeles ni ipinlẹ California, Amẹrika.
Aarun Colon cancer lo ṣokunfa iku to pa gbajugbaja oṣere Chadwick Aaron Boseman 'Black Panther'.
Cancer: Àṣe ara mi ni iso ti n run gbogbo bí mo ṣe n ṣèrànwọ́ lórí jẹjẹrẹ
Iyalẹnu ni iku gbajugbaja naa jẹ fun ọpọlọpọ eniyan kaakiri agbaye, nitori pe ko fẹẹ si ẹni to mọ pe iru aisan bẹẹ n ṣe e ko to ku.
Ọdun mẹrin sẹyin ni awọn dokita sọ fun un pe o ni jẹjẹrẹ inu ifun, to si ti wọ ipele kẹta nigba naa. Aisan naa lo pada pa a , lẹyin to wọ ipele kẹrin.
Nitori eyi, ọpọ lo ti n wadii irufẹ jẹjẹrẹ ti wọn n pe ni colon cancer, ati awọn nkan to le fa a.
Gẹgẹ bi akọsilẹ to wa ni ori ayelujara ileeṣẹ eto ilera ilẹ United Kingdom, inu ifun to tobi ju ninu ara, ni jẹjẹrẹ naa ti ma n bẹrẹ.
O si jẹ ọkan lara awọn aisan jẹjẹrẹ to wọpọ julọ. Awọn ti ọjọ ori wọn si ti le ni ọgọta ọdun lo ṣaba ma n ni aisan yii.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Aworan bi jẹjẹrẹ inu ifun 'colon cancer' ṣe ma n ri
Awọn apẹẹrẹ yii le jẹ ti aisan miran, yatọ si colon cancer. Nitori naa lo ṣe gbọdọ ri dokita ti o ba ṣe akiyesi naa to jẹ ajeji ni ara rẹ.
Gẹgẹ bi ileeṣẹ eto ilera ilẹ UK ṣe sọ, ko si ẹni to mọ nkan to n fa jẹjẹrẹ yii ni pato, ṣugbọn awọn nkankan wa to le fi eniyan sinu ewu rẹ bii:
Ọjọ ori - eeyan bi i mẹsan ninu mẹwaa to ni aisan yii lo ti pe tabi le ni ọgọta ọdun
jkkkkk
Ounjẹ - jijẹ ounjẹ to kun fun ẹran bi ti maalu, ewurẹ, agutan tabi ẹran ẹlẹdẹ le ṣokunfa jẹjẹrẹ yii Ko yọ awọn ẹran inu agolo naa silẹ.
Bi ara ba ṣe tobi si - Aisan yii tun wọpọ laarin awọn to ba sanra ju bo ṣe yẹ lọ
Ere idaraya - Ẹni ti kii ba ṣe ere idaraya, tabi fi ara ṣiṣẹ daadaa wa ninu ewu lati ni aisan yii
Oríṣun àwòrán, CHADWICK BOSEMAN
Ọti - mimu ọti le ṣakoba fun ọ, lati ni aisan colon cancer
Ẹni to ba n mu siga, igbo, ati awọn nkan miran naa le ni aisan yii
Ẹbí - ti o ba ni ibatan to sun mọ ọ (iya, baba, ẹgbọn tabi aburo) to ni aisan yii nigba ti ọjọ ori wọn ṣi wa ni abẹ aadọta ọdun, o ṣe e ṣe ki iwọ naa ni .
Oríṣun àwòrán, CHADWICK BOSEMAN
Ẹni ọdun mẹtalelogoji ni Chdwick Boseman ki aisan 'colon cancer' to pa
Yatọ si awọn nkan wọnyii, awọn to ba ni aisan bi ulcerative colitis fun bii ọdun mẹwa, naa le ni jẹjẹrẹ yii.
Oru ọjọ Satide ni ẹbi gbajugbaja oṣere sinima ni orilẹede Amẹrika, Chadwick Boseman ti ọpọ mọ fun ipa Black Panther to ko ninu ere sinima Black Panther, kede pe o ti jade laye.
Aarun jẹjẹrẹ lo ṣokunfa iku Boseman to dagbere faye lẹni ọdun mẹtalelogoji.
Iroyin sọ pe ni ilu Los Angeles lo ku si, iyawo ati awọn mọlẹbi rẹ gbogbo lo si wa lẹba rẹ nigba to mi eemi igbẹyin.
Atẹjade kan loju opo ayelujara rẹ fi sita pe ọdun mẹrin sẹyin ni o ti mọ pe oun laarun naa ṣugbọn o mọọmọ maa fi han sita faraye.
Oríṣun àwòrán, @Chadwick
Iroyin iku Boseman ti domi tutu si agbo ere sinima ti ọpọlọpọ awọn oṣere ati eekan lagbo ere sinima lagbaye si ti n kẹdun iku rẹ.
'Tíátà ọ́mọdé tí wọ́n ń kọ́ wa ní Bariga ti mú mi lọ Germany, Switzerland, Amsterdam...'
Ondo elections: Iroju Ogundeji ní gómìnà Akeredolu ló wà nídí ìgbésẹ̀ yíyọ igbákejì rẹ̀
Oríṣun àwòrán, Sunshinetruth
Igbakeji olori ile aṣofin ipinlẹ Ondo, Họnọrebu Iroju Ogundeji ti ṣalaye pe Gomina Rotimi Akeredolu lo wa ni idi igbesẹ ati yọ igbakeji rẹ ki o to di wi pe iduroṣinṣin awọn aṣofin kan ni ile naa pa okuta si gaari igbesẹ ọhun.
Họnọrebu Iroju sọ ọrọ yii di mimọ ninu ifọrọwerọ rẹ kan pẹlu BBC News Yoruba lori idajọ  ile ẹjọ giga kan nilu Akurẹ lori yiyọ ti ile naa yọ awọn aṣofin mẹta nipo laipẹ yii.
"Iroju ni ipilẹ idojukọ wọn ko ṣẹyin bi ""Gomina (Akeredolu) ṣe ni ki a wa lọ ti ọwọ bọ iwe ka yọ igbakeji oun"" eleyi to ni awọn kọ si nitori awọn ri igbakeji gomina Agboọla Ajayi gẹgẹ bii "" alaiṣẹ"""
"Ṣe o ṣeeṣe ki gomina ati igbakeji rẹ wa lori aleefa ki awọn aṣofin o gbero lati yọ igbakeji gomina kuro nipo lai jẹ pe gomina mọ sii? Ododo ibẹ ni pe gomina ni ko fẹ igbakeji rẹ mọ to si ke gbajare si awọn aṣofin pe awọn ni agbara wa lọwọ wọn ki wọn ba oun yọ ọ"""
Igbakeji olori ile aṣofin naa tun fi kun un pe idi ti awọn fi faake kọri pe awọn ko ni fọwọ si yiys igbakeji gomina nipo ni pe, gomina Akeredolu ko ri ti awọn ro gẹgẹ bi aṣofin, ọdọ igbakeji gomina yii ni awọn aṣofin ti n ri iranlọwọ ti ile naa nilo gba.
Orisunmibare lorukọ tawọn aṣofin mẹta ti wọn fofin lọ rọkun nile de nile aṣofin ipinlẹ Ondo naa yoo maa jẹ bayii pẹlu bii ile ẹjọ ṣe ni ki wọn san miliọnu marundinlogun naira fun wọn.
Ile ẹjọ giga kan ni ilu Akurẹ lo gbe idajọ kalẹ pe ki igbakeji olori ile naa, Ogundeji Iroju, aṣofin Favour Tomomowo ati Wale Williams o pada si ijoko wọn ni ile ki wọn gba owo gba mabinu lọwọ
'Tíátà ọ́mọdé tí wọ́n ń kọ́ wa ní Bariga ti mú mi lọ Germany, Switzerland, Amsterdam...'
Awọn mẹta yii wa lara awọn aṣofin mẹjọ to kuna lati tọwọ bọ iwe ati dibo yọ igbakeji gomina ipinlẹ naa, Họnọrebu Agboọla Ajayi.
Lẹyin to ni ki wọn san owo gba maa binu naa fun awọn aṣofin yii, ile ẹjọ tun ni ki wọn da wọn pada sori ijoko wọn ni ile naa.
Adajọ naa to gbẹjọ naa, Onidajọ Ademọla Bọla ṣakawe yiyọ ti wọn yọ awọn aṣofin naa nipo bi eyi ti ko ba ofin mu ti ko si ribi duro si labẹ iwe ofin orilẹede Naijiria.
Oluwo: Èmi l'ọba lórí òrìṣà, oṣó àti ajẹ́, Olorì tuntun tó ń bọ̀ lẹ́tikẹ
Oríṣun àwòrán, Instagram/Telu_1
Ọba Abdulrasheed Akanbi, Oluwo mti ilẹ Iwo ti ṣalaye ni kikun fun BBC Yoruba idi ti o fi paṣẹ pe ki wọn ko gbogbo oriṣa kuru laafin Iwo.
Oluwo sọ pe oun ni aṣoju Olodumare ni aafin ilẹ Iwo, nitori naa oun ko le maa bọ oriṣa tabi fi ori balẹ fun oriṣa ni aafin.
Ọba Akanbi ni oun ni alaṣẹ lori oriṣa, o ni oun kii ṣe ekeji oriṣa nitori Eledumare loun n ṣoju nisin yii.
''Emi ni ọkọ oṣo, emi ni ọkọ ajẹ, emi ni ọba to ba lori ohun gbogbo ni ilẹ Iwo, nitori naa mi o le tun maa bọ oriṣa laafin,'' Oluwo lo sọ bẹẹ.
Oluwo ni ile isẹnbaye ni o yẹ ki awọn oriṣa wa nitori nnkan ti yatọ si ti aye ọjọun nigba ti wọn bẹrẹ si ni bọ awọn oriṣa naa.
Lori bo ya wọn ṣe etutu ki wọn to ko awọn oriṣa naa kuro laafin, Oluwo ni ko si etutu kankan nitori ṣiṣe etutu tumọ si ibọriṣa eyi t'oun ko le ṣe.
Oluwo ni ''Ọba kii pe meji laafin, mi o le jẹ ọba ki n tun maa fori balẹ fun nnkan mii laafin.''
O ni niwọn igba ti oun ṣi wa lori itẹ gẹgẹ bi Oluwo ti ilẹ Iwo, ko si ẹni ti yoo bọ oriṣa laafin Iwo.
Oluwo ko ṣai sọ nipa Olori mii to n bọ laafin Iwo lẹyin ti o ti kọ Olori tẹlẹ, Chanel Chin silẹ.
Wo bí Sunday Orimola ṣe gba ikú ẹranko kú ní Ifon ni Ondo lórí ọ̀nà àtijẹ
''Olori mii ti yoo rọpo Chanel Chin ti wa ni ṣẹpẹ ṣẹpẹ bayii, eleyi lẹtikẹ,'' Oluwo lo ṣalaye bẹẹ.
Oluwo ni Olori to n bọ lọna ''lẹtikẹ, nla ni eleyi, o ja gbogbo 'scale' patapata.''
Oba Akanbi ni ikan nla ni Olori to n bọ, o ni o lagbara gan an.
Natalia Mufuta ìyá Yakub, Kamil àti Adam sọ̀rọ̀ lórí bí wọ́n ń sọ èdè mẹ́rin pàpọ
Ìdí tí mo fi gbàdúrà ìyàwó bíi Chanel Chin fáwọn tó d'ẹ̀bi ìkọ̀sílẹ̀ rẹ̀ rù mí  rèé - Oluwo
Oluwo ni oun n fẹ olori ti yoo nifẹ awọn eeyan Iwo ni, ti o si ṣetan lati sin wọn gẹgẹ bi oun ti oun jẹ ọba ti n ṣe.
''Olori  temi gbọdọ de ade. Olori to n de ade laafin ko gbọdọ jẹ ọdalẹ,'' Oluwo lo sọ bẹẹ.
Oríṣun àwòrán, Instagram/Telu_1, Chanel Chin
Ọba Akanbi ni nnkan lo wa lọkan Chin to fi n ka gbogbo ohun to n ṣẹlẹ laafin nigba to wa nibẹ.
Oluwo of Iwo, Oba Abdulrasheed Akanbi tun ti sọ oko ọrọ lori iyapa to waye laarin rẹ ati Olori rẹ tẹlẹ, Chanel Chin.
Oríṣun àwòrán, @oluwo
Oluwo ṣalaye idi to fi gbadura iru iyawo bi Chanel Chin fawọn to n bu ẹnu ẹtẹ lu lori ọrọ naa.
Ọba Abdulrasheed Akanbi ni lati ọjọ akọkọ ti Chin to wọ aafin Iwo lo ti bẹrẹ si ni ka gbogbo ohun to n ṣẹlẹ laafin silẹ.
''Ṣe ifẹ niyẹn?'' Oluwo lo beere ibeere yii.
O ni ko yẹ ki iyawo jẹ ko maa ṣe bi ọtẹlẹmuyẹ fun ọkọ rẹ.
"Bí ẹ ṣe mọ̀wé tó, ẹ wá dánrawò níbí pẹ̀lú ""Àpólà Ọ̀rọ̀ Orúkọ - Noun Phrase"
Oluwo ni ''emi ti mu iyẹn kuro ninu aye mi, mo ti kọ ọ silẹ.''
''Adura ti mo n gba fawọn to dami lẹbi lori ọrọ naa ni pe ki Eleduwa fun awọn ati ọmọ wọn ni iru iyawo bii ti Chin.
Oluwo tun sọ pe o lodi ki Ọba alaye maa bọ oriṣa laafin, nitori naa, ko ṣeeṣe fun oun lati maa bọ oriṣa.
O ṣalaye pe ọba alaye n ba Eleduwa jẹ orukọ papọ, idi niyii ti ko fi gbọdọ maa fori balẹ fun oriṣa kankan.
Oluwo ni niṣe lo yẹ ki atunṣe ilana ode oni ba awọn ọdun isẹnbaye nilẹ Yoruba ki o le di ohun tawọn maa fi owo wo.
Ọba Akanbi ni eeyan ko le maa ta epo si ojubọ ki o si maa reti awọn eeyan lati wa woran.
Ninu itan ilẹ Yoruba, aafin Iwo lasiko temi ni awọn ẹleṣin musulumi ati kristẹni wa gbadura laafin fun igba akọkọ.
O ni ko ṣeesẹ ki musulumi wa lọ gbadura nibi ti ko ba jẹ mimọ, bakan naa lawọn ọmọ lẹyin kristẹni.
Oluwo ni eleyi ṣẹlẹ nitori ko si awọn ooṣa kankan mọ laafin.
''Emi ni mo paṣẹ pe ki wọn ko gbogbo oriṣa to wa laafin Iwo kuro nigba ti mo jọba tan,'' Oluwo lo sọ bẹẹ.
Oríṣun àwòrán, @Oluwo
O ni ọba meji ko le wa laafin papọ, ati pe oun jẹ aṣoju Eleduwa to da gbogbo aye.
Oluwo ni Olodumare lo ni aafin, ki ṣe awọn oriṣa nitori naa eeyan ko le sin ọlọrun pẹlu mamoni.
Ọba Akanbi ni lootọọ ni oriṣa bibọ wa ninu itan Yoruba ṣugbọn o yẹ ki wọn ti ko gbogbo awọn oriṣa yii sinu ile iko nnkan iṣẹnbaye si bayii.
Wo ọ̀nà márùn ún tí o lè gbà dáàbò bò ara rẹ lọ́wọ́ ìjàmbá láì gbé ìbọn!
Mi ò ní wọ Uber mọ́ tí wọ́n bá leè fi owó lée nítorí àfikún owó orí tí Sanwo Olu ṣe
Àwọn nkan tó yẹ kí o mọ̀ nípa ṣíṣe ìṣirò àsìkò tí o bá n yé ẹyin
Wo bí o ṣe le fi ẹjọ́ sun àjọ FCCPC tí o bá ra ọjà tó ti 'expire'
'Àwa ọmọ Nàìjíríà tó farapa fẹ́ wálé láti Lebanon, ìjọba kó wa pamọ́'
Victor Agunbiade ni ojú àlá ni Ọlọrun ti yan iṣẹ́ ọmọ ogun ojú omi fún òun ní America
Adebayo Alao-Akala: 'Mo ti dàgbà ọ̀jẹ̀, n kò ní díje fún ipò gómìnà ìpínlẹ̀ Oyo mọ́'
Oríṣun àwòrán, Facebook/Otunba Adebayo Alao-Akala
Gomina ana ipinlẹ Oyo, Otunba Christopher Adebayo Alao-Akala ti kede pe oun ko ni dije fun ipo gomina ipinlẹ naa mọ nibi ti oun ba a de bayii.
Otunba Akala sọrọ yii lori eto kan to waye ni ileeṣẹ redio kan niluu Ibadan lọjọ Abamẹta, ọjọ kọkandinlọgbọn oṣu kẹjọ ọdun 2020 yii.
Bakan naa o fidi ọrọ naa mulẹ fun BBC Yoruba latẹnu agbẹnusọ rẹ, Yusuf Olaniyi pe oun ti fiṣẹ silẹ fawọn to ṣẹṣẹ n dide ninu oṣelu.
Akala ni ohun ti o ku f'oun lati ṣe bayii ni lati rii pe oludije to kun oju oṣuwọn jade ninu ibo abẹle lati ṣoju ẹgbẹ oṣelu APC ninu ibo gomina ọdun 2023 to n bọ.
Otunba Alao-Akala to ṣe ọjọ ibi aadọrin ọdun loke eepẹ laipẹ yii ni igbesẹ oun lati ma dije fun ipo gomina mọ yoo f'oun lanfaani lati ṣiṣẹ ipẹtu si aawọ ti gomina ipinlẹ Oyo tẹlẹ, oloogbe Abiola Ajimobi gbe le oun lọwọ daadaa.
Alao-Akala ni oun ati Ajimọbi sọ ọpọlọpọ ọrọ ninu eyi tawọn ti fẹnu ko pe ki oun pari aawọ to wa laarin gbogbo ọmọ ẹgbẹ to n binu lẹyin idibo gbogbogbo to lọ.
O ni oun ti ba gbogbo awọn ọmọ APC to n binu atawọn to ti kuro sọrọ, wọn si ti gba lati pada sinu ẹgbẹ.
Gomina Oyo tẹlẹ ni oun rawọ ẹbẹ si awọn mii pe ki wọn j'eburẹ ki wọn to gba lati pada sinu ẹgbẹ.
Oríṣun àwòrán, Facebook/Otuba Adebayo Alao-Akala
''Ko si ohun ti n ko mọ nipa oṣelu ipinlẹ Oyo, n o si ni erongba lati fa ẹnikan kalẹ lati dije fun ipo gomina lọdun 2023,'' Alao-Akala lo sọ bẹẹ.
Alao-Akala sọ pe ilẹkun ile oun ṣi silẹ fun gbogbo ọmọ ẹgbẹ APC nipinlẹ bayii.
Nigba ti o n kin ọrọ Akala lẹyin, oluranlọwọ fun gomina ipinlẹ Oyo tẹlẹ, Yusuf Olaniyi sọ fun BBC Yoruba pe Alao-Akala ti di agbaọjẹ ninu oṣelu ipinlẹ, iyẹn lo ṣe ni oun ko ni dije fun ipo gomina mọ.
O ni Akala ti da oun to fẹ da laye papaa julọ lagbo oṣelu, ''eyi gan lo jẹ ko pinnu lati fun awọn to wa lẹyin ninu ẹgbẹ lati dije.''
O ni Alao-Akala ti jẹ oye lemọmu bayii, ko tun le maa du oye Ṣeriki mọ, nitori oun ni alaga apẹtu si aawọ ninu ẹgbẹ oṣelu APC ipinlẹ, ko le maa du ipo gomina mọ to jẹ Ṣeriki.
Bi o lo dagba, bi o loo gbo, bo ba pẹ titi, oju a hun jọ, Olaniyi ni agba naa ti de si Otunba.
Akinyele killings: Ọwọ́ ọlọ́pàá ti tẹ Toheed Ganiyu tí wọ́n ló pa Mary Daramola ẹni ọdún 18 l'Akinyele ní ìlú Ibadan
Oríṣun àwòrán, others
Arabinrin miran ti wọn pe orukọ rẹ ni Mary Daramọla ni awọn oniṣẹ ibi kan tun ti pa lagbegbe Akinyẹle nilu Ibadan, lẹyin ti wọn fi ipa ba a lopọ tan.
Gẹgẹ bi iroyin ṣe sọ, ileto Alabata nitosi Mọniya ni iṣẹlẹ naa ti ṣẹlẹ.
Ọrọ igbenipa lẹyin ifipabanilopọ ti di tọrọfọnkale lagbegbe Akinyẹle ni ilu Ibadan lati osu diẹ sẹyin.
Ọpọ lo si ti woye pe asiko ati fẹdọ lori oronro ti de lẹyin ti ọwọ tẹ Sunday Shodipẹ gẹgẹ bii afurasi ọdaran to wa nidi iṣẹlẹ naa.
Ọmọ ọdun mejidinlogun ni Mary Daramọla ti wọn ṣẹṣẹ tun ṣe lọṣẹ yii.
Awọn eeyan kan n sọ pe arakunrin kan ti orukọ rẹ n jẹToheed Ganiyu lo wa nidi iṣẹlẹ naa, wọn ni ọwọ ba a nigba to n gbiyanju ati ju oku omidan naa danu sinu igbo kan ni ileto ọhun.
Ninu atẹjade to fi ṣọwọ si ileeṣẹ BBC News Yoruba, alukoro fun ileeṣẹ ọlọpaa ni ipinlẹ Ọyọ, SP Gbenga Fadeyi ṣalaye pe ni agogo mẹjọ aṣalẹ ọjọ ti iṣẹlẹ naa ṣẹlẹ, Toheeb Ganiyu tan Mary Daramọla wọ iyara rẹ nibi ti o ti rọ ọ ni ọti yo ki o to fi tipa ba a lopọ.
Natalia Mufuta ìyá Yakub, Kamil àti Adam sọ̀rọ̀ lórí bí wọ́n ń sọ èdè mẹ́rin pàpọ
Oku Mary ni awọn eeyan ri lẹyin eyi pẹlu atọ ọmọ ọkunrin ni oju ara ati ẹnu rẹ.
Fadeyi fi kun un pe ọwọ ọlọpaa ti tẹ afurasi naa, iwadii si ti n lọ lọwọ lẹka iwadii ọtẹlẹmuyẹ ileeṣẹ ọlọpaa to wa ni Iyaganku nilu Ibadan.
Ninu ọrọ tirẹ, Baalẹ Alabata, Oloye Ọlakanmi Ọlaniyan ti rọ awọn ọdọ lagbegbe naa lati bu omi suuru mu ki wọn si ni igbagbọ ninu ọlọpaa ati iwadii wọn.
Oloye Ọlaniyan kọminu lori gbọnmọgbọnmọ iwa ipaniyan ati ifipabanilopọ lagbegbe naa eleyi to fi rọ ijọba atawọn agbofinro lati tete wa ojutu sii.
jkkkkk
Rabiu Yusuf: Ọ̀gá ọlọ́pàá lẹ́kùn kẹrìnlá, Zone 14, AIG Rabiu Yusuf jáde láyé lẹ́yìn àìsàn ráńpẹ́
Oríṣun àwòrán, others
Ọga ọlọpaa lẹkun apapọ kẹrinla ileeṣẹ ọlọpaa, (Zone 14) ni Katsina, AIG Rabiu Yusuf  ti jade laye.
Iroyin nipa iku rẹ ko tii fi bẹẹ han sita, ṣugbọn awọn iwe iroyin abẹle kan lorilẹ-ede Naijiria n sọ pe owurọ ọjọ Abamẹta lo jade laye.
Ni aipẹ yii ni Rabiu Yusuf gba igbega si ipo ọga ọlọpaa AIG ti wọn si yan an gẹgẹ bi ọga agba ọlọpaa tuntun fun ẹkun kẹrinla ti ileeṣẹ ọlọpaa ṣẹṣẹ da silẹ ni ipinlẹ Katsina.
Ṣaaju ipo rẹ tuntun yii lo ti jẹ kọmiṣọnna ọlọpaa fun ipinlẹ Kano.
Natalia Mufuta ìyá Yakub, Kamil àti Adam sọ̀rọ̀ lórí bí wọ́n ń sọ èdè mẹ́rin pàpọ
"Alukoro ileeṣẹ ọlọpaa ni ipinlẹ Kano, Gambo Isah ṣalaye fun awọn ileeṣẹ iroyin abẹle kan pe, AIG Rabiu Yusuf jade laye ""lẹyin aisan ranpẹ."""
O gbadura pe ki Olorun forijin oku naa, ko si fi Aljana rọ ọ lọrun.
Koda, iroyin ni Rabiu ko tii bẹrẹ iṣẹ ni kikun ni ọọfiisi rẹ ni ipo tuntun AIG ẹkun tii ko to di oloogbe.
"Bí ẹ ṣe mọ̀wé tó, ẹ wá dánrawò níbí pẹ̀lú ""Àpólà Ọ̀rọ̀ Orúkọ - Noun Phrase"
Natalia Mufutau ìyá Yakub, Kamil àti Adam sọ̀rọ̀ lórí bí wọ́n ń sọ èdè mẹ́rin pàpọ
Ede Yoruba, Gẹeṣi, Polish ati Finnish ni awon ọmọ mẹtẹẹta n kọ- Adewumi Waliu Mufutau.
Ọpọ àwọn ọmọ Yoruba to wa ni Naijiria ni awọn ọmọ wọn ko gbọ ede Yoruba daadaa ni eyi to ti n kọ awọn onwoye ede lominu lasiko yii.
Ṣugbọn inu BBC Yoruba dun lati ṣawari Adewumi Waliu Mufutau ti o jẹ ọmọ bibi ilu Ṣaki ni ipinlẹ Oyo ṣugbọn to fi orilẹ-ede Finland ṣe ibujoko rẹ to si n kọ awọn ọmọ rẹ ni ede Yoruba.
Natalia Mufutau to jẹ iya awọn ọmọ yii wa lati orilẹ-ede Poland.
O si ṣalaye pe ede mẹrin ni awọn Adam, Kamil ati Yakub ẹgbọn wón le sọ daadaa, iyẹn Yoruba, ede Oyinbo, Polish ati Finish to jẹ ede Finland ti wón n gbe.
O tun sọ nipa pataki ki ọmọ ni idanimọ ninu aye ki o le kọ iwa ọmọluwabi bi o ṣe yẹ.
Natalie wa gba awọn obi Yoruba ni imọran lati dide si iṣẹ iya ni pataki lati kọ ọmọ wọn ni aṣa ati iṣe bii ibówọfagba ti o jẹ Yoruba logun ninu iwa ọmọluwabi.
O sọrọ nipa ibaṣepọ to wa laarin oun ati awọn ẹbi Mufutau ni Saki ni eyi ti o dara pupọ.
Ondo accident: Tírélà méjì tẹ ìyá àti ọmọ pẹ̀lú èèyàn méjì míì pa ní Ikare-Akoko, awakọ̀ sá lọ
Oríṣun àwòrán, Other
Agbẹnusọ ileeṣẹ ọlọpaa ipinlẹ Ondo, Tee-Leo Ikoro sọ fun BBC Yoruba pe awọn eeyan to farapa nibi iṣẹlẹ naa si n gba itọju lọwọ nile iwosan.
ASP Ikoro ṣalaye pe awakọ kan wa ninu awọn eeyan mẹrin to gbẹmi mi ninu iṣẹlẹ naa, nigba ti awakọ keji sa lọ nitori ẹru ba a pe awọn eeyan le lu u pa.
Ọgbẹni Ikoro fikun ọrọ rẹ pe obinrin ati ọmọ rẹ naa wa lara awọn to ku ninu ijamba ọkọ naa.
O ni ileeṣẹ ọlọpaa si n wa awakọ to sa lọ lẹyin ti iṣẹlẹ ọhun ṣẹlẹ tan
Adura nla ni Yoruba maa n gba pe Eleduwa ko ni jẹ ka rin arin fẹsẹ ṣi.
Ijamba ọkọ tirela meji ti ran eeyan mẹfa lọ si ọrun ọsan gan gan niluu Ikare-Akoko nipinlẹ Ondo.
Iṣẹlẹ ọhun waye lọjọ Abamẹta, ọgbọnjọ oṣu kẹjọ, ọdun 2020 nigba ti bireki ọkọ nla meji ọhun ja lori oke.
Oríṣun àwòrán, Other
Nibi tawọn awakọ ti n gbiyanju lati fi jia da awọn tirela naa duro ni ọkọ mejeeji ti lọ fẹnu sọ awọn ṣọọbu to wa lẹba ọna nibi ti eeyan mẹrin ti ṣagbako iku ojiji.
Lati ipinlẹ Ekiti lawọn ọkọ nla ti n bọ, ilu Akure ni wọn n lọ ki ijanu ọkọ wọn to ja ti ko si le mu un mọ.
"Bí ẹ ṣe mọ̀wé tó, ẹ wá dánrawò níbí pẹ̀lú ""Àpólà Ọ̀rọ̀ Orúkọ - Noun Phrase"
Daura varsity: Amaechi ní ọ̀fẹ́ ni China yóò kọ́ fásítì $50M ètò ìrìnnà sí Daura ìlú Ààrẹ Buhari
Oríṣun àwòrán, Twitter/Ministry of Transportation
Minisita eto irinna ọkọ ni Naijiria, Rotimi Amaechi, ti sọ pe ọfẹ ni ijọba orilẹ-ede China yoo kọ fasiti eto irinna ọkọ ti yoo gberasọ niluu Daura, ipinlẹ Katsina loṣu kẹsan an, ọdun 2021.
Aadọta miliọnu owo dọla ni owo ti yoo kọ fasiti naa tan gẹgẹ akọsilẹ ẹka ijọba to n ri si eto irinna ni Naijiria.
Minisita eto irinna to sọrọ yii nigba to lọ ṣe ayẹwo ibi iṣẹ de duro ni fasiti naa ṣalaye pe ọfẹ ni ileeṣẹ onimọ ẹrọ (Technics Engineering Architectural Marketing (TEAM) naa yoo ṣiṣẹ ni fasiti ọhun.
Amaechi ṣalaye ṣiwaju sii pe ni fasiti naa ni wọn yoo ti maa kọ bi wọn yopo ṣe maa ṣe amojuto ọna reluwe ti ileeṣẹ kan lati China n ṣe lọwọ bayii ni Naijiria.
Bakan naa ni minisita sọ fawọn agbaṣẹṣe nibẹ lati kọ ileewe alakọbẹrẹ ati girama si fasiti ọhun.
O ni eyi ni yoo fawọn ọmọ awọn to yoo maa ṣiṣẹ nibẹ lanfaani lati fi ọmọ wọn sile iwe.
Ilu Daura ni ipinlẹ Katsina jẹ ilu abinibi Aarẹ orilẹ-ede Naijiria, Muhammadu Buhari.
Victor Agunbiade ni ojú àlá ni Ọlọrun ti yan iṣẹ́ ọmọ ogun ojú omi fún òun ní America
Coronavirus pandemic update: Wo àwọn orílẹ́-èdè tí kò ní coronavirus lágbàáyé
Oríṣun àwòrán, Palau Hotel
The Palau Hotel, Koror
Ajakalẹ arun coronavirus ti ṣọṣẹ kaakiri orilẹ-ede gbogbo lagbaaye a fi orilẹ-ede mẹwaa kan ti ọwọja rẹ ko de.
Wọn ṣi ile itura lorilẹ-ede Palau lọdun 1982 ki irin-ajọ igbafẹ to fẹsẹ rinlẹ, ṣugbọn lati igba naa, ọrọ-aje Palau ti gberasọ.
Lọdun 2019, ẹgbẹrun lọna aadọrun arinrin-ajo igbafẹ lo ṣabẹwo si Palau, eyi si jẹ ilọpo marun un gbogbo eeyan to wa nilẹ naa.
Koda lọdun 2017, ajọ eleto ẹyawo lagbaaye, IMF sọ pe ẹka eto igbafẹ nikan ko ida ogoji ninu iko ọgunrun un ọrọ-aje orilẹ-ede naa.
Ṣugbọn ki ajakakẹ aarun covid-19 to de ni gbogbo eleyi.
Orilẹ-ede Palau ti ibode rẹ lati oṣu kẹta ọdun 2020. Palau jẹ ọkan lara orilẹede mẹwaa ti ko ni akọsilẹ coronavirus kankan lati igba ti aarun naa ti ba gbogbo aye finra(awọn orilẹede to jẹ ọmọ ẹgbẹ ajọ iṣọkan agbaye, UNO la n sọ nibi yatọ si  North Korea ati Turkmenistan).
Lootọọ ni pe ko si ẹni to laarun covid-19 nibẹ, ṣugbọn ajakalẹ aarun coronavirus si ṣakoba fun wọn lọpọlọpọ.
Gbajugbaja ile itura Palau ti di titi pa lati oṣu kẹta, koda gbogbo ile ounjẹ naa ṣofo
Bolaji Faleke ni Olùkọ́ tó ń kọ́ wa ní àṣà oge ṣiṣe lórí BBC Yorùbá
Awọn orilẹede ti ko ni akọsilẹ coronavirus ree
Natalia Mufuta ìyá Yakub, Kamil àti Adam sọ̀rọ̀ lórí bí wọ́n ń sọ èdè mẹ́rin pàpọ
Palau
Okun to wa ni Palau ko ni afiwe kaakiri agbaye, oludari ile itura Palau, Brian Lee lo sọ bẹẹ.
Okun to lawọ rẹsurẹsu lo maa n da Brian lọrun. Gbogbo yara mẹrinlelaadọta to wa nile itura rẹ lawọn alejo maa fẹ n gba tan.
Ṣugbọn nnkan ko ṣẹnu 're mọ lati igba ti wọn ti ti ibode pa.
Brian ni orilẹede kekere ni Palau, awọn eeyan orilẹede naa kii fẹ gba ile itura Palau.
Ogun oṣiṣẹ lo n ṣiṣẹ nilu itura Palau, ko si ẹni ti wọn da duro ninu wọn.
Brian ni ''gbogbo awọn oṣiṣẹ lo ṣi n wa sibi iṣẹ bo tilẹ jẹ ko si alejo kankan.
O ni ko rọrun lati maa tun ile itura ṣe fun lai si alejo to n gba a. Brian ni ti oun yoo gbiyanju lati ṣe e fun oṣu mẹfa sii lẹyin naa oun le ti ile itura ọhun pa.
Ẹwẹ, aarẹ orilẹede naa kede laipẹ yii pe irin-ajo ọkọ ofurufu yoo bẹrẹ pada lọjọ kinni oṣu kẹsan.
Marshall Island to wa ni erekusu okun Pacific naa ko ni akọsilẹ aarun covid-19, bo tilẹ jẹ pe coronavirus ṣakoba fun ọrọ-aje ti wọn naa.
Awọn arinrin ajo igbafẹ ko lo ṣabẹwo sawọn itura to wa nibẹ lati oṣu kẹta ti wọn ti gbe ibode ti pa.
Ẹẹdẹgbẹrin eeyan lo ṣeeṣe ko padanu iṣẹ wọn nitori ajakalẹ aarun covid-19, ọtale lugba o din meji awọn eeyan yii lo n ṣiṣẹ nile itura atawọn ile ounjẹ.
Oríṣun àwòrán, Mario Tama/Getty Images
Lootọọ ni pe ibode ti wọn ti pe sọ ọpọ di alaini ni Vanautu, ọpọ eeyan ilẹ naa ni ko si fẹ ki wọn ṣi ibode naa pada laipẹ.
Dokita Len Tarivonda to jẹ oludari eto ilera nilẹ naa sọ pe ọpọ ọmọ orilẹede naa tawọn eeyan rẹ ko ju ẹgbẹrun un lọna ọdunrun un lọ ko fẹ ki ijọba ṣi ibode pada.
Dokita Tarivonda ni ''ohun ti wọn sọ nipe awọn ko fẹ ko aarun nitori awọn ko pọ tẹlẹ lorilẹede naa, bi bẹẹ kọọ, gbogbo eeyan le ku tan patapata.
Ọjọ kinni oṣu kẹsan an ọdun 2020 yii ni ijọba orilẹede Vanuata n gbero lati ṣi ibode rẹ pada.
'Superstorm' Harold hits Vanuatu after killing 27
Ki lawọn orilẹ-ede ti ko larun covid-19 le ṣe?
Ọna abayọ ni kiakia ni pe ki ijọba maa sanwo fawọn oṣiṣẹ atawọn oniṣowo.
Ohun miiran ti ijọba tun le ṣe ni ki o ṣeto abẹrẹ ajẹsara fun gbogbo araalu.
'Oyenusi ló mú mi wọ ẹgbẹ́ adigunjalè kó tó di pé mo b'Ólúwa pàdé'
Oṣiṣẹ ile ifowopamọ Asia, Rommel Rabanal lo sọ bẹẹ, o ni ijọba ni lati ṣeto fun ayẹwo awọn eeyan ki o si ṣeto ibudo iyasọtọ aibaamọ aarun covid-19 le bẹ silẹ.
Jonathan Pryke, oludari eto Pacific Island sọ pe oun ko le sọ bo ya kii ṣe titi ibode mawọn alejo lati ilẹ okeere nikan lọna abayọ si ọrọ coronavirus.
Amọ, Pryke ṣalaye pe ti wọn ṣi ibode gan an bayii, awọn ọmọ orilẹede Australia ati New Zealand to n maa ṣabẹwo sawọn orilẹede Pacific ko le wa bayii nitori awọn naa ti ti ibode wọn.
Yahaya Bello: Iléẹjọ́ tó ga jùlọ fòǹtẹ̀ lu Yahaya Bello, wọ́n da ẹjọ́ PDP àti SDP nù
Oríṣun àwòrán, Facebook
Iléẹjọ́ tó ga jùlọ fòǹtẹ̀ lu Yahaya Bello gẹ́gẹ́ bí Gómìnà ìpínlẹ̀ Kogi
Ileẹjọ to ga julọ ni Naijiria ti fi ontẹ lu eto idibo to gbe Yahaya Bello wọle gẹgẹ bi Gomina ipinlẹ Kogi.
Ninu idajọ rẹ lọjọ Aje niluu Abuja, ileẹjọ naa tu ẹjọ ti ẹgbẹ oṣelu PDP pe ẹgbẹ oṣelu APC tii ṣe ẹgbẹ Bello ka.
Lọsẹ to lọ ni igbimọ oludajọ ẹlẹni meje ile ẹjọ to ga julọ ni Naijiria labẹ idari adajọ agba ni Naijiria, Tanko Mohammed gbọ ẹjọ ti oludije ibo gomina fẹgbẹ oṣelu PDP, Musa Wada pe Gomina Yahaya Bello to wọle ibo naa.
Ninu idajọ ti Adajọ Inyang Okoro ka jade lorukọ igbimọ awọn adajọ mejeeje to ṣapero lori ipẹjọ naa, ileẹjọ fi ontẹ lu idajọ ileẹjọ kotẹmilọrun ati ti igbimọ igbẹjọ to n ri si awuyewuye ibo gomina to dajọ pe Bello lo jawe olubori ninu ibo gomina Kogi.
Wo bí Sunday Orimola ṣe gba ikú ẹranko kú ní Ifon ni Ondo lórí ọ̀nà àtijẹ
Lẹyin ti igbimọ oludajọ ṣe agbeyẹwo koko marun un ti ẹgbẹ oṣelu PDP fi gbe Gomina Bello APC lọ si ileẹjọ, ileẹjọ giga ni awọn  ẹsun naa ko lẹsẹ nlẹ.
''Lẹyin ti a wo eṣun ti oludije PDP pe ẹgbẹ oṣelu APC pe kudiẹkudiẹ wa ninu eto idibo to gbe Yahaya Bello gẹgẹ bi gomina ipinlẹ Kogi, o ti han gbangba pe ko si ẹri to dalu lati fi idi ẹsun naa mulẹ, nitori naa, a tu ipẹjọ PDP ka,'' adajọ Okoro lo sọ bẹẹ.
Adajọ agba ni Naijiria, Mohammed, adajọ to ka idajọ ileẹjọ, Okoro ati Abba-Aji atawọn ọmọ igbimọ igbẹjọ mii lo fẹnu ko lori idajọ naa.
Natalia Mufuta ìyá Yakub, Kamil àti Adam sọ̀rọ̀ lórí bí wọ́n ń sọ èdè mẹ́rin pàpọ
Ileẹjọ to ga julọ tun da ẹjọ onikoko meje ti oludije ẹgbẹ oṣelu SPD, Natasha Akpoti naa pe wi pe igbakeji gomina Kogi, Edward Onoja parọ ọjọ ori rẹ ati pe o tun fi ayederu iwe ẹri ranṣẹ si ajọ INEC nu.
Igbimọ oludajọ naa sọ pe ko si ẹri to daju lati fi idi gbogbo ẹsun ti SDP fi kan igbakeji gomina Kogi mulẹ.
Cameroon Atrocity, BBC Africa Eye: Ẹwọ́n ọdún méjìlá ni wọ́n fún àwọn sója mẹ́rin tó pa ìyá àti ọmọ méjì ní Cameroon
Àwọn ọmọ ogun orilẹ̀-èdè Cameroon mẹ́rìn ni wọ́n ti dájọ ẹ̀wọ̀n ọdún méjìlá fún, wọ́n jẹ̀bi ìpànìyàn lásìkò ti wọ́n ń ja ìjà àwọn agbésùmọmí lórílẹ̀-èdè náà.
Wọ́n ní àwọn sójà yìí ló pa obìnrin kan àti àwọn ọmọ rẹ̀ méjì ní orílẹ̀-èdè Cameroon.
BBC Africa Eye: Akọroyin fẹ ìdí àwọn oníṣẹ́ ibi ọmọ ogun síta
Èyí jẹyọ nínú fọ́ran kan tó jẹyọ lórí ayélujara nínú oṣù kéje ọdún 2018 níbi ti àwọn ọmọ ogun kan ti daṣọ bo awọn obinrin meji lójú pẹ̀lú ọmọbinrin lórí ìkúnlẹ̀ ti wọ́n sì pọ ọmọ sẹ́yìn.
Bótilẹ̀ jẹ́ pé ìjọba kọ́kọ́ sọ pé kìí ṣe àwọn sójà ló ṣe iṣẹ́ náà, wọ́n padà mú àwọn ọmọogun méje sùgbọ́n àwọn méjì ninú wọ́n ni wọ́n dásill pé wọ́n kò jẹ̀bi ẹ̀sùn kankan.
Cameroon Atrocity: Àwọn sójà náà ní ìyá àti àwọn ọmọ náà jẹ́ ikọ̀ Boko Haram
Ikọ ọmọ ogun orilẹ-ede Cameroon marun un ni yẹ ki wọn gba idajọ loni lẹyin ti iwadii ile ẹjọ fihan pe wọn jẹbi ẹsun iṣekupani ti wọn fi kan wọn.
Ṣugbọn Adajọ ti sun ọjọ idajọ rẹ di ọjọ kọkanlelogun, oṣu  kẹsan an, ọdun 2020 yii.
Abule Ado explosion: Irọ́ ńlá ní NNPC pa lórí ìbúghbàmù Abule Ado níbí tí ẹ̀mí èèyàn 23
Eyi tumọ si pe idajọ di oṣu to m bọ ko to waye lori awọn  maraarun.
"Aarọ Ọjọ Aje, Ọjọ Kọkandilọgbọn, Oṣu Kẹjọ, ọdun 2020 ni awọn soja naa de ileẹjọ awọn ọmọogun, lẹyin ti wọn rii  wi pe wọn jẹbi ẹsun iwadii ti ''BBC Africa Eye'' ṣe ni ọdun 2018 ti wọn si pe ni ""2018 Anatomy of a killing"" ."
Idajọ naa n waye lẹyin ọsẹ kan ti ileẹjọ dajọ pe awọn ọmọ ogun marun un ninu meje lo jẹbi ẹsun ipaniyan naa, nigba ti awọn meji gba ominira ni Ọjọ Kẹtadinlogun, Oṣu Kẹjọ, ọdun 2020.
Wo bí Sunday Orimola ṣe gba ikú ẹranko kú ní Ifon ni Ondo lórí ọ̀nà àtijẹ
Lẹyin ọdun kan ti iwadii fihan pe awọn soja naa pa iya ati ọmọ rẹ ni agbegbe Zelevet, ni Ariwa orilẹede Cameroon ni igbẹjọ naa bẹrẹ.
Agbẹjọro to ba BBC Yoruba sọrọ ni awọn soja meji ti wọn da silẹ naa, Godwe Mana Didier, Manasse Djakobei Johnathan ko kopa ninu iṣekupani naa, wọn kan tẹle awọn soja to yinbọn pa wọn ni.
Orukọ awọn marun un ti wọn jẹbi ẹsun ipaniyan naa ni Fabassou Etienne, Bitouala Ciriaque, Tchanga Chiengang Jean B, Donassou Gorvo Barnabas, Ntienche Feuroli Ghislain Landry.
Bawo ni awọn ikọ ọmọogun ilẹ Cameroon ṣe pa obinrin kan ati awọn ọmọ rẹ?
Natalia Mufuta ìyá Yakub, Kamil àti Adam sọ̀rọ̀ lórí bí wọ́n ń sọ èdè mẹ́rin pàpọ
Ọba ni mí, mi ò le b'ọ̀rìṣà, Olorì tuntun tó ń bọ̀ já gbogbo ''scale''- Oluwo ti Iwo
Ta ni ìyàwó Chadwick Boseman, tó jẹ́ àwòkọ́ṣe rere f'áwọn ọ̀dọ́ Adúláwọ̀?
Rabiu Yusuf, ìgbákejì ọ̀gá àgbà ọlọ́pàá Nàìjíríà (AIG) lẹ́kùn Katsina jáde láyé
Ọ̀fẹ́ ni China yóò kọ́ fásítì $50M ètò ìrìnnà sí Daura ìlú Ààrẹ Buhari- Amaechi
Ìjọba Ghana ṣí iléeṣẹ́ àwọn ọmọ Nàìjíríà padà. ó fún Nàìjíríà l'èsì àwọn ẹ̀sùn tó fi kàn-án
'Oyenusi ló mú mi wọ ẹgbẹ́ adigunjalè kó tó di pé mo b'Ólúwa pàdé'
Iléẹjọ gíga jùlọ da ẹjọ́ SDP àti PDP nù, wọ́n ní Yahaya Bello ló wọlé ìbò gómìnà Kogi
Ìjà d'ópin, fún ìgbà àkọ́kọ́, bàálù gbéra láti Israel lọ sí UAE
Yàtọ̀ sí Eko, wo ohun t'áwọn ìpínlẹ̀ meje míràn ń sọ nípa ìwọlé àwọn akẹ́kọ̀ọ́
Wo ojú Akeem t'Ọlọ́pàá mú pé ó fipá bá ọ̀dọ́mọbìnrin kan sùn létí odò l'Oṣun
Chief Kanran: Mi ò ṣagbe àmọ́ mo nílò ìrànlọ́wọ́ ọmọ Yorùbá
Oríṣun àwòrán, Others
Ẹ́ wo ìrírí tó mú àgbà òṣèré Chief Kanran dí ẹni tí kò rí ilé gbé mọ́, ti irinṣẹ́ jóná
Afiniṣẹ̀sín ní ọ̀pọ̀lọpọ̀ ọmọ Yorùbá pàápàá àwọn ọ̀rẹ́ àwa òṣèré tíátà- Olusegun Akinremi
Agbaọjẹ oṣere lorilẹede Naijiria, Olusẹgun Akinrẹmi ti gbogbo eniyan mọ si Chief Kanran ti sọ iriri ati ilakọja rẹ fun awọn ọmọ Yoruba.
Chief Kanran sọ awọn ọrọ yii lasiko ifọrọwanilẹnuwo ti BBC News Yoruba ṣe pẹlu wọn ni ile ijọsin ti wọn n gbe.
Kanran sọ iriri rẹ bi oun ṣe di ẹni ti ko ri ile gbe mọ ati bi ohun gbogbo ṣe daru fun oun ni nkan bi ọdun melo ṣẹyin.
"Kanrani ni: ""Lẹyin nkan bu oṣu diẹ ti mọ de lati Canada, ile iṣe ipolowo ọja ati yiya ere amohunmaworan mi jona raurau, ti irinṣe to le ni miliọnu lọna ọgbọn Naira si jọna patapata.''"
Bolaji Faleke ni Olùkọ́ tó ń kọ́ wa ní àṣà oge ṣiṣe lórí BBC Yorùbá
"Ko pẹ diẹ si asiko yii ni awọn adigunjalẹ bẹrẹ si ni koju ija si mi, nitori wọn rọ wi pe emi ni mọ ni ile ti mo n gbe ati awọn ẹru ti wọn n ko wa lati oke okun to jẹ ti onile ti a n gbe naa.''
''Eyi lo mu ki n sakuro ni awọn ile ti mo n gbe naa, ti mo si sa asala fun ẹmi mi nipa sisalọ si ile ijọsin ni ibi ti mọ n gbe lọwọlọwo.''
Wo bí Sunday Orimola ṣe gba ikú ẹranko kú ní Ifon ni Ondo lórí ọ̀nà àtijẹ
Chief Kanran lasiko to n bere iranwọ lọwọ awọn ọmọ Naijiria sọ wi pe gbogbo ohun ini oun ni awọn ti oun ya owo ni ọwọ wọn lati ṣe sinima gba pada, ti oun si da ẹni ti ko ni ọkọ ayọkẹlẹ mọ.
Bí ẹ ṣe mọ̀wé tó, ẹ wá dánrawò níbí pẹ̀lú Àpólà Ọ̀rọ̀ Orúkọ - Noun Phrase"
O fikun wi pe ninu ipọnju yii ni oun wa fun ọpọlọpọ igba, ti iyawo meji ti oun ni si saisan ti wọn si ku.
"Idojukọ ti mo dojukọ ni lo mu mi ke gbajarẹ si awọn ọmọ ile Yoruba lati jọwọ ṣeranwọ fun mi nipa pipese irinṣẹ ti mo nilo lati bẹrẹ si ni ṣe ere oritage pada ati ṣiṣẹ awọn sinima.'
Bakan naa ni Chief Kanran fikun wi pe lọpọ igba ijọba kii ṣe iranwọ fun awọn oṣere bi ko ṣe pe asiko ti wọn ba ṣe aisan tabi ti wọn ba ku , ki wọn to dide iranlọwọ si wọn.
Amọ, agbaọjẹ naa sọ di mimọ pe oun ko tọrọ jẹ, bẹẹ ni oun ko ṣe agbẹ, ohun ti oun nilo lọwọ awọn ọmọ Yoruba ni iranlọwọ lati ra irinṣẹ ti yoo mu ohun pada si ipo.
'Oyenusi ló mú mi wọ ẹgbẹ́ adigunjalè kó tó di pé mo b'Ólúwa pàdé'
Agbaọjẹ oṣere lorilẹede Naijiria, Olusẹgun Akinrẹmi ti  ni awọn oṣere ode oni ti gbagbe awọn agbaojẹ oloṣere, ti wọn ko si naani wọn mọ.
Chief Kanran ni kii ṣe pe mama Ẹfunṣetan Aniwura ko le e kopa ninu ere mọ, amọ awọn eniyan ni ko pe wọn si iṣẹ.
Bakan naa ni wọn fikun pe afiniṣẹsin ni ọpọlọpọ awọn oṣere ni Naijiria, ti wọn si n wa isubu ẹnikeji wọn.
O ni oun ko fẹ iranwọ ẹgbẹ awọn oṣere ni Niajiria ati wi pe awọn ọmọ Yoruba ni oun fẹ ki wọn ran oun lọwọ lori iṣẹ oun.
Chief Kanran wa rọ awọn ọmọ Yoruba lati fi ọwọ sọwọpọ, ki wọn sọra fun gbogbo iwa ibajẹ ki wọn le de ibi aṣeyọri.
Sinimá àwòdamiẹnu, àwọn aṣẹ́wó dín dùǹdú ìyà fún Ẹ̀fáńjẹ́líìsì ní àbẹ́tẹ̀ wọn ní Ejigbo
Oríṣun àwòrán, others
Ẹ wa wo sinima lorita o!
Awọn aṣẹwo ti lu efanjẹliisi daku lÉjigbo nilu Eko o, Wọn ni o kọja aye rẹ nipa wiwaasu ni ile aṣẹwo awọn.
Ẹfanjẹliisi Mathew yii ni wọn ni pe o n pariwo 'ẹ yi pada kuro ninu gbogbo iwa ọwọ yin'
Gẹgẹ bi ọrọ ti ọkan lara awọn ti iṣẹlẹ naa ṣoju rẹ sọ, wahala naa bẹrẹ nigba ti ẹfanjẹliisi naa duro niwaju ilumọọka ile itura kan to wa ni Ejigbo to si bẹrẹ iwaasu fun awọn olowo nọọbi naa atawọn onibara wọn pe ki wọn fi awọn iwa ẹṣẹ ọwọ wọn gbogbo silẹ.
Ẹfanjẹliisi naa ti wọn pe orukọ rẹ ni Mathew wa pẹlu ileejọsin kan ti awọn eeyan fẹran pupọ ni ilu Ejigbo ni eyi ti ko mọ pe irinajo iwaasu ọjọ naa lee di wahala.
Gẹgẹ bi ohun ti awọn iwe iroyin abẹle kan sọ, ọpọ igba atẹyinwa ni wọn ti ṣekilọ fun un pe ko jinna si agbegbe ti wọn ti n na owo wọn nigbakugba to ba ti n waasu.
Bolaji Faleke ni Olùkọ́ tó ń kọ́ wa ní àṣà oge ṣiṣe lórí BBC Yorùbá
Ni ọjọ ti a n wi yii, wọn lu ẹfanjẹliisi naa debi pe o daku.
Aladugbo miran ṣalaye pe kii ṣe igba akọkọ niyi ti yoo waasu wa si ile itura naa,
Ṣugbọn kii sunmọ wọn pupọ to bi o ṣe ṣe lọjọ naa.
Wo bí Sunday Orimola ṣe gba ikú ẹranko kú ní Ifon ni Ondo lórí ọ̀nà àtijẹ
Ọpọ awọn aladugbo lo sọ pe ni iwoye ti wọn, ẹfanjẹliisi yii kọja aye rẹ nitori pe oun funra rẹ mọ pe ibi aimọ ni agbegbe naa"" ni Ejigbo."
Iya to jẹ ẹfanjẹliisi yii o jẹ bẹmbẹ lọna yidi.
Yoruba World Congress: Mi o fi gbogbo ẹnu sọ pé ẹ̀yà Yorùbá yóò tún èrò rẹ̀ pa ní October 1- Akintoye
Oríṣun àwòrán, @thesignalng
Aarẹ ẹgbẹ ọmọ Yoruba l'agbaye, Ọjọgbọn Banji Akintoye ti sọ pe oun ko lọwọ si lilo ipá tabi agidi fi ya kuro lorilẹ-ede Naijiria gẹgẹ bi ẹya Yoruba.
Ninu atẹjade kan to fi sita, Akintoye sọ pe looto ni oun gba pe awọn ọmọ orilẹ-ede Naijiria ni ẹto lati ṣe iwọde lori ipo ti orilẹ-ede wa.
Bakan naa ni wọn tun ni ẹtọ lati sọ pe awọn fẹ ẹ ya kuro lara Naijiria.
O ni ṣugbọn, oun kilọ pe ki awọn ẹya Yoruba ma ṣe fi ipo tyabi jagidijagan ṣe ohunkohun.
O ṣalaye pe iyalẹnu lo jẹ fun oun lati ri i ninu iwe iroyin kan pe oun sọ pe Aarẹ Buhari ni yoo jẹ aarẹ to kẹyin ni Naijiria, tabi pe ọjọ kinni, oṣu Kẹwaa, ni ẹya Yoruba yoo tun ero rẹ pa.
Obateru Akinruntan: Wíwá ohun tá jẹ títí láé ló gbé wa kúrò nílé Ife
"Akintoye ni: ""Mi o fi igba kankan sọrọ lori ayajọ ọjọ ominira Naijiria, October 1, ju pe ki awọn to ba sọ pe dandan ni ki awọn ṣe iwọde ṣe e pẹlu alaafia ati ọwọ."""
Lootọ ni ipo ti Naijiria wa bayii ko dun mọ mi ninu, amọ erongba mi ni pe alaafia nikan ni a le fi mu ki ayipada o wa.
Ọjọgbọn Banji Akintoye ti fi igba kan jẹ senetọ lasiko iṣejọba awaarawa ẹlẹkeji.
Lẹnu ọjọ mẹta yii si ni iroyin ti n lọ lori ayelujara ati laarin ilu pe ẹya Yoruba yoo ya kuro lara orilẹ-ede Naijiria to ba di ọjọ kinni, oṣu Kẹwaa, ọdun 2020. Ti wsn o si da orilẹ-ede ti wọn, Oduduwa Republic silẹ.
Fìdíhẹẹ́ ní Banji Akintoye nínú YWC, lílọ ni yóò lọ - Tola Adeniyi
Ó ti lé ni ọ̀ṣẹ̀ kan báyìí ti awuyewuye ti ń ṣẹ̀lẹ̀ láàrin àwọn ọmọ ẹgbẹ́ Yoruba World Congress (YWC), ti àwọn kan si ti kéde pé ọ̀jọ̀gbọ́n Akintoye kìí ṣe olórí ẹgbẹ́ náà.
Kò pẹ́ sí àsìkò yìí ni àtẹ̀jáde míràn tún jẹ̀yọ láti ọ̀dọ̀ àwọn ẹgbẹ́ YWC pé kò ṣeeṣe kí ènìyàn mẹ́rin yọ ààré YWC kúrò lẹ́gbẹ́.
Ọ̀nà láti mọ òkodoro ọ̀rọ̀ ló mú kí BBC News Yoruba bá olóyè Tola Adeniyi, ọjọ̀gbọ́n Banji Akintoye àti ọ̀túnba Deji Osibogun sọ̀rọ̀, láti tan ìmalẹ̀ sí awuyewuye náà.
Akọgun Tola Adeniyi:
Oríṣun àwòrán, Others
Nínú ọ̀rọ̀ rẹ̀ Akọgun Tola Adeniyi sàlàyé pé, nǹkan to ṣe gbòógi jùlọ ni pé, YWC ko fi ìgba kan yan Akintoye gẹ́gẹ́ bi olórí, fìdí hẹ́ẹ lásan ni.
O ní lọ́pọ̀ ìgbà ti a wọn ba pe ìpàde, àwọn ti ko mọ bi ẹgbẹ́ YWC ṣe wa sáye, ni Akintoye maa n pè láti maa jẹ̀gàba lórí àwọn àgbà ẹgbẹ́.
Ó ni ọ̀pọ̀ ìgbà ni àwọn ti sọ fún Akintoye pé kìí ṣe gbogbo aṣọ ni à n sá lóòrùn, sùgbọ́n gbogbo àṣírí ẹgbẹ́ ni ọjọ̀gbọ́n máá n pe ará ìta sí.
Bolaji Faleke ni Olùkọ́ tó ń kọ́ wa ní àṣà oge ṣiṣe lórí BBC Yorùbá
Adeniyi sàlàyé pe, èyí tó burú jùlọ ni pé, ọjọ́ kan ti o yẹ ki ìpàdé wáyé, ni bàbá lọ ko àwọn ènìyàn bi ogún kan wa, ti wọ́n si da ìpàdé rú, lẹ́yìn náà ni wọ́n gbe abájáde ìpàde lọ fun àwọn oní ìwé ìròyìn.
Adeniyi ní àwọn ẹgbẹ́ bi ọgọ́ta to darapọ̀ mọ́ YWC, sùgbọ́n àwọn olùdásílẹ YWC kìí ṣe olórí ti àwọn mọ́.
Lẹ́yìn àlàyé Akọgun Adeniyi yìí ni BBC tún bá, ọjọ̀gbọ́n Akintoye to jẹ olórí ẹgbẹ́ YWC sọ̀rọ̀.
Ọjọ̀gbọ́n Banji Akintoye:
Oríṣun àwòrán, Others
Nínú ọ̀rọ̀ rẹ̀ Akintoye sọ pé, Yoruba Organization lo se ìpàde ni ọjọ́ kejìlélógun, oṣù kẹjọ, ọdún 2019, tí wọ́n sì ní àwọn fẹ́ yan òun sípò ààrẹ ẹgbẹ́.
Sùgbọ́n òun kọ̀ lati fún wọ́n ni èsì títí di ẹ̀yìn oṣù kan. Lẹyin èyí ni ìpàdé míràn wáyé ní ìlu Ibadan níbi ti wọ́n ti yan òun gẹ́gẹ́ bii ààrẹ ẹgbẹ́.
Ọjọ̀gbọ́n Akintoye ni, ìlànà ti àwọn mẹ́rin náà fẹ́ ki òun tọ́ kìí ṣe ǹka ti òun lè ṣe gẹ́gẹ́ bi àdari.
Ó fi kún pé, irú òṣèlú ti Awolowo ṣe nígbà ayé rẹ̀ ni òun náà ń ṣe, láti fún gbogbo ènìyàn lánfàni kí wọ́n sọ èrò wọ́n fún ìgbéga ìràn Yoruba.
Temitope Akinnusi: Ọ̀pọ̀ iléeṣẹ́ ló takú láti gbà mí síṣẹ́ torí mo ní ojú kan
Akintoye ní àwọn mẹ́rin ti wọ́n kọ lati ba awọn ṣe ìpàdé ti àwọn ṣe kẹ́yin, ti wan kọ̀ láti darapọ̀ mọ́ àwọn kò lágbára láti sọ pé òun kìí ṣe ààrẹ YWC.
Títí di àsìkò yìí, àwọn ti àwọn ènìyàn yìí ń pé ni ọmọde náà ló n sá sóke sódo fun ìlọsíwáju ẹgbẹ́
"Àwá ti di àgbà, ìgbaagba mí si ni láti fún wọ́n lóóre ọ̀fẹ́ láti jẹ́ ki ìtẹ́síwájú wà.
Sáájú àsìkò yìí Tola Adeniyi àti àwọn míràn ti máa ṣe ìpàdé tẹ́lẹ̀.
Bí ẹ ṣe mọ̀wé tó, ẹ wá dánrawò níbí pẹ̀lú Àpólà Ọ̀rọ̀ Orúkọ - Noun Phrase"
Idí ti a fi dá ẹgbẹ́ yìí sílẹ̀ ni, ìròyìn tó ni èdè Yoruba yóò parun láìpọ́ àti pé ètò ààbò ìràn Yoruba mẹ́hẹ.
Sùgbọ́n, nínú ọ̀rọ̀ tirẹ̀, ọmọ ẹgbẹ́ míràn to tún bá BBC Yoruba Otunba Deji Osibogun to tún jẹ́ aṣojú ẹgbẹ́ Yoruba Kọ̀yà, se atilẹyin fun Alintoye.
Ọtunbọ Ayodeji Osibogun:
Oríṣun àwòrán, Others
Osibogun ní kìí ṣe ènìyàn kan ni yóò yọ ọjọgbọ́n Akintoye, oníruuru ẹgbẹ́ ló parapọ̀ lati yan Akintoye sípò nítori náà ti wọ́n yóò ba yọ àwọn náà ni yóò jọ sọ.
Ó ní àdúrà lo ṣe pàtàki ti ìràn Yorùbá nílò láti kẹ́sẹ jári.
Kò sí ewu lóko, àfi gìrì àparò, Ọ̀rẹ̀ ni Akọgun Tola Adeniyi jẹ́ si Akọgun òun si ló mu wọ́n mọ Kila.
Baby abandoned on dunmpsite: Mo ti bímọ mẹ́rin tẹ́lẹ̀ fún bàbá méjì nínú òṣí- Dupe Ogbomos
Kí wọ́n to di ààrẹ, wọ́n jọ máa n jírorò nilé Akintoye ni, nítori náà gbogbo ipò ti Tola Adeniyi kìí baa wà ni YWC, kò ni àkósílẹ̀ nínú iwe òfin YWC.
Osibogun ni ìjà láàrin ọ̀rẹ́ ni, kìí ṣe láàrin ẹgbẹ́ YWC, nítori naa ọ̀rọ̀ tó ṣẹ́lẹ̀ kò lè da ẹgbẹ́ ru nítori kò sí ǹkan ti kò le dìjà láàrin ọ̀rẹ.
Oríṣun àwòrán, @deji_of_lagos
Awuyewuye to n lọ lọwọ ninu ẹgbẹ Yoruba World Congress, YWC, ti gbọna miran yọ, lẹyin ti awọn eekan inu ẹgbẹ naa faake kọri pe dandan ni ki wọn yọ ọjọgbọn Banji Akintoye nipo, gẹgẹ bi Aarẹ ẹgbẹ ọhun.
Ọkan pataki lara awọn to gbe ẹgbẹ naa kalẹ, Akogun Tola Adeniyi sọ fawọn akọroyin pe, lara idi ti wọn ṣe fi ọwọ osi juwe ile fun Akintoye, ko ṣẹyin awọn iwa kan to n wu, eyi to ni ko bojumu to.
"O ni ""A yọ ọ nipo gẹgẹ bi Aarẹ nitori a ri pe ko le e dari wa lọ ibi kankan pẹlu iru igbe aye to n gbe."""
Ṣugbọn oloye Taye Ayorinde to jẹ Baalẹ Ekotedo sọ pe, Akintoye ṣi ni aṣaaju awọn ọmọ kaarọ oojiire gẹgẹ bi awọn ẹgbẹ ọmọ Yoruba to le ni aadọrin ṣe yan an sipo.
Ẹwẹ, Akintoye funra rẹ ninu ifọrọwerọ kan ni eeyan mẹrin pere ko lagbara lati yọ oun nipo Aarẹ, ati pe oun mọ pe inu lo n bi wọn.
Oríṣun àwòrán, @thesignalng
"Akintoye ni ""Ede aiyede maa n waye ninu idile, ṣugbọn o di dandan ki wọn pari iru aawọ bẹẹ."""
"O tẹsiwaju pe ""Mo mọ idi ti wọn ṣe n binu ṣugbọn eeyan mẹrin pere ko lagbara lati yọ adari nipo, o da mi loju pe gbogbo ohun to n run nilẹ maa tan laipẹ jọjọ."""
Ṣugbọn Adeniyi ṣalaye siwaju sii pe, ohun to fa ede aiyede ko ṣẹyin bi awọn kan ṣe n fi aadọrin ẹgbẹ ọmọ Yoruba ti ko kọja ilu Ketu, ni Benin Republic ṣafiwe ẹgbẹ ọmọ Yoruba kakiri agbaye, eyi ti Akintoye jẹ adari fun ki wọn to fi ọwọ osi juwe ile fun un.
Nigba to n sọrọ lori pe awọn oloṣelu ti rapala wọ ẹgbẹ YWC, Adeniyi ni ko ṣeeṣe ki awọn oloṣelu darapọ mọ ẹgbẹ naa nitori awọn oloṣelu lo sọ orilẹ-ede naa di bo ṣe wa loni.
Ọdun 2019 ni wọn yan Akintoye sipo gẹgẹ bi Aarẹ ẹgbẹ YWC lẹyin ti aga naa ti ṣofo fun ọpọ ọdun lẹyin ti oloye Abraham Adesanya jade laye.
Àṣìṣe ọlọ́pàá àti Adájọ́ sọ mí di ẹni tí wọ́n dájọ́ ikú fún, ọpẹ́lọpẹ́ Fayoṣe tí ko buwọlu
Ki lo tin ṣẹlẹ sẹyin?
Oríṣun àwòrán, Other
Eeyan mọkandinlogun ninu ọmọ ẹgbẹ itẹsiwaju Yoruba jakejado agbaye ti tọwọ bọwe pe irọ ni awuyewuye to n lọ lode pe wọn yọ Ọjọgbọn Akintoye to jẹ aarẹ loye.
Wọn sọrọ yi ninu atẹjade pe  awọn adari nkan bii aadọta ẹlẹgbẹjẹgbẹ to parapọ di agbarijọ ẹgbẹ itẹsiwaju Yoruba lagbaye lo yan Ọjọgbọn Banji Akintoye gẹgẹ bi adari ẹgbẹ naa.
"Bẹẹ wọn jẹ ko di mimọ pe oṣuṣu ọwọ kan ṣoṣo ni ẹgbẹ YWC labẹ idari Ọjọgbọn Banji Akintoye ati pe ""a gboriyin fun igboya ati ọkan ire ti Akintoye ni si mimu ayipada ba iran Yoruba lagbaye""."
Atẹjade naa sọ pe ko si idarudapọ kankan laarin ẹgbẹ YWC 'a o si si ninu fa ki n fa a pẹlu ẹnikẹni tabi ẹgbẹ kankan.'
Ọrọ aarin mọlẹbi leleyii to ṣẹlẹ a si ti n yanjuẹ laarin agbo ile.
"A ṣi ni ifarajin si awọn alakalẹ ati afojusun ẹgbẹ YWC gẹgẹ bi Ọjọgbọn Banji Akintoye ṣe ntukọ rẹ fun ayipada iran Yoruba ati lati ni ireti ọjọ iwaju rere fun awọn ọdọ.''
Ruga settlement: YCE ní ìjọba àpapọ̀ ko tó bẹ̀ẹ́ láti kọ́ àgọ́ Fulani sílẹ̀ Yoruba
Wọn tẹnu mọ ọ pe apapọ ẹgbẹ to dibo yan Ọjọgbọn Banji Akintoye gẹgẹ bi adari Yoruba lọdun kan sẹyin naa lo korajọ lati tun sọ pe awọn ni igbagbọ ninu rẹ''"
Awọn mọkandinlogun to tọwọ bọwe ree:1. Chief Taiye Ayorinde2. Comrade Victor Taiwo3. Prof. Kayode Ogundoro4. Sheik Abdulraheem Aduanigba.chief imam YORUBA LAND5. Dr. Tunde Amusat6. Sina Akinpelu7. Evangelist Kunle Adesokan8. Princess Oyeronke Akinlolu9. Dr. Juwon Akinsola10. Engineer Muda Dayo Ogunsola11. Architect George Akinola12. Professor Wale Adeniran13. Princess Tanimowo Okusaga 14. Prince Kola Bamigbade15. Comrade Okunola Kolawole16.  Brief Mrs Patricia Abiodun17. Alhaji Ali Dodo Oyedeji18. Hon. Babatunde Tolase19. Prince Lawal Onikeke Quassim
Awuyewuye lori ẹgbẹ ọmọ Yoruba lagbaaye (Yoruba World Congress), tun ti bẹyin yọ, lẹyin ti aarẹ YWC, Ọjọgbọn Banji Akintoye ti tu igbimọ alaṣẹ ẹgbẹ ọhun ka.
Awọn oludari ati akọwe ti gbogbo wọn jẹ mẹrindinlogun lo wa ninu igbimọ naa.
Ẹgbẹ YWC tun sọ pe ohun yoo gbe igbimọ ẹlẹni mẹrin dide lati ba Aarẹ ẹgbẹ naa Ọjọgbọn Akintoye ṣiṣẹ pọ titi ti wọn yoo yan awọn mii.
Ọmọ ẹgbẹ kan, Ọmọbabinrin Tanimowo Okusaga lo fọrọ yii lede ninu atẹjade kan to gbe sita lorukọ gbogbo ẹgbẹ YWC.
O tun sọ ninu atẹjade naa pe ko si iyapa ninu ẹgbẹ YWC, o ni gbọingbọin ni gbogbo ọmọ ẹgbẹ duro lẹyin aarẹ ẹgbẹ naa, Ọjọgbọn Akintoye.
Bolaji Faleke ni Olùkọ́ tó ń kọ́ wa ní àṣà oge ṣiṣe lórí BBC Yorùbá
Awọn eekan inu ẹgbẹ YWC bii Akin Adejuwon, Ariyike Obet, Nureen Soludero, Bunmi Abidogun, Kunle Adesokan, Muda Ogunsola, Oloye Aduranigba, Imaamu Iyanda Wasiu Abiodun, Paul Bankole, ati Ọmọbabinrin Oyeronke Akinlolu lo wa nibi ipade ti ọrọ naa ti jẹ jade niluu Ibadan.
Amọ, iroyin mii to tun lu ayelujara pa tun sọ pe ẹgbẹ YWC ti yọ Ọjọgbọn Akintoye gẹgẹ bi aarẹ ẹgbẹ naa.
Wo bí Sunday Orimola ṣe gba ikú ẹranko kú ní Ifon ni Ondo lórí ọ̀nà àtijẹ
Iroyin ọhun sọ pe Ọmọwe Amos Akingba, Oloye Tola Adeniyi, Oloye Solagbade Popoola ati Ọjọgbọn Anthony Kila ti wọn da ẹgbẹ YWC silẹ fi atẹjade kan sita ninu eyi ti wọn ti sọ pe iwa tani yoo mu mi, aikoju oṣuwọn ati titapa si ofin ẹgbẹ lo ṣe okunfa yiyọ ọ nipo.
Wọn ni ko ṣeku ko ṣẹyẹ ni Ọjọgbọn Akintoye wi pe bi o ṣe n ṣe ẹgbẹ Afẹnifere, lo n ṣe awọn ẹgbẹ mii nigba ti o si jẹ aarẹ YWC.
'Oyenusi ló mú mi wọ ẹgbẹ́ adigunjalè kó tó di pé mo b'Ólúwa pàdé'
Mike Bamiloye, adarí Mount Zion bèrè bóyá àpaàyàn kọ́ ní ẹni tó ń ṣí ara sílẹ̀ lọ ṣọ́ọ̀ṣì, ṣé apàyàn kọ́ ni ẹ́ báyìí?
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Gbajugbaja oṣere kritẹni, Mike Bamiloye to jẹ oludasilẹ ẹgbẹ oṣere Mount Zion ti ja gudugbẹ ọrọ lulẹ lori aṣọ wiwọ ni ṣọọṣi.
Bamiloye ni ''o n wọ aṣọ to ṣi ara silẹ lọ si ṣọọṣi, o tumọ si pe o ti pinnu lati di apayan ni ṣọọṣi.''
''Iwọ ni tiẹ, ijo ati mu ọmọlakeji ṣubu ni iwọ mọ ọ jo ni tiẹ ti wọn ba n kọ irin ninu isin,'' Bamiloye lo sọ bẹẹ.
Bamiloye ni ''iwọ to sọ pe o n jo lati yin Ọlọrun ni ti o si mọ pe fun ra rẹ pe irọ lo n pa.''
Gbajugbaja oṣere kristẹni naa wa beere pe ''njẹ apayan ni ṣọọṣi kọ niọ bayii.''
Bolaji Faleke ni Olùkọ́ tó ń kọ́ wa ní àṣà oge ṣiṣe lórí BBC Yorùbá
Ọpọ lo ti di ẹbi aṣọ iwọkuwọ ṣọọṣi ru awọn obinrin nikan, ṣugbọn awọn mii sọ pe ki lawọn ọkunrin naa n wo lara obinrin ti wọn kko kọ oju mọ isin ni ṣọọṣi.
Awọn miiran tiẹ ni aṣọ iwọkuwọ lawujọ gan an lo sẹ okunfa iwa ifipabanilopọ to ti pọ si ni Naijiria bayii.
Ikare Monarch: Ọdún méjìdínláàdọ́ta ní Oba Adegbite-Adedoyin ló lókè èèpẹ̀, kó tó mí kanlẹ̀
Lẹyin ti Ọwá Ale Ikarẹ, Oba Adegbite-Adedoyin papòdà lẹ́ni ọdún márùndínláàdọ́rùn ún lánaa, ọjọ Iṣẹgun, ni ọjọ kinni, oṣu kẹsan an , ọdun 2020 ni BBC kan si ilu naa.
Awọn ara ilu sọrọ nipa Kabiesi to waja naa pe o gbiyanju ipa rẹ fun idagbasoke Ikare Akoko.
Ọba Ọwa Ale ilu Ikarẹ, Ọba Samuel Kolapo Adegbite-Adedoyin ti rebi agba n re.
Ori ade yi gẹgẹ bi ohun ta ri gbọ lo ọdun mejidinlaadọta lori apere ki o to dagbere faye lọjọ Iṣẹgun ni aafin rẹ to wa ni agbegbe Okorun.
Lasiko igbe aye rẹ, Oba Adegbite ni aarẹ ẹgbẹ awọn lọbalọba aadoje kan ni ipinlẹ Ondo to si tun jẹ ọmọ ẹgbẹ igbimọ lọbalọba ipinlẹ Ondo.
Ọpọ awọn ara ilu Ikarẹ Akoko lo tu yahaya lọ si aafin lati kọkọ rii pe ṣe lotọ ni Kabiesi waja ki nitori wọn ni awọn ko fẹ gbagbọ pe ki Baba papoda lasiko yii.
Ṣugbọn wọn n fi idaro han lẹyin ti wọn rii pe Kabiesi Adegbitẹ ti re ibi agba n re.
Tọkunrin, tobinrin tọmọde tagba lo n wa si aafin wa ki awọn ẹbi ati Oloye ku ara fẹraku Kabiesi Adegbitẹ to lọ ba awọn baba nla rẹ.
Akọroyin wa to fidi ọrọ yi mulẹ sọ pe niṣe ni gbogbo ilu Ikare n kẹdun Ọba wọn ti ilu si pa lọọlọ.
Ọmọ Oba Adeleke, ọkan ninu awọn ọmọ ti Kabiesi to waja fi silẹ lọ naa ṣalaye iru eeyan ti baba rẹ jẹ fun BBC Yoruba pe oninuure to fẹran ara ilu to n jọba le lori ni.
Ṣugbọn ko le fidi asiko ti wọn yoo tẹ baba si itẹ mulẹ pe ipade ṣi n lọ pẹlu awọn ti ọrọ kan laafin.
Oríṣun àwòrán, The Nation Newspapers
Ta ni Kabiesi Adegbitẹ Adedoyin to waja ni Ikarẹ Akoko?
Lọdun 1935 ni wọn bi Ọba Adegbite Adedoyin ti asiko ibi rẹ si ṣe deede ọdun meji si igba ti wọn bi Moses Orimolade oludasilẹ ijọ mimọ Kristẹni Cherubim and Seraphim Church.
Ọba Adegbite Adedoyin kawe gboye imọ anofin ta si gbọ pe o lọwọ si idasilẹ ile ẹkọ girama to le ni mẹjọ laarin ọsun 1978 si 1982.
Ikede iku ọba naa ko ti waye nitori pe awọn to yẹ ko ṣe ni o ni awọn etutu kan to yẹ ni ṣiṣe k'awọn to kede iku rẹ faraye.
Ọdun 1972 ni Owa Ale gun ori apere awọn babanla rẹ gẹgẹ bi Owa Ale ikẹtadinlogun ilu Ikare.
'Oyenusi ló mú mi wọ ẹgbẹ́ adigunjalè kó tó di pé mo b'Ólúwa pàdé'
Kenya Covid-19 fund: Aàrẹ pàṣẹ pé kí ìwádìí bẹ̀rẹ̀ lórí àwọn tó lu owó ìtọ́jú aláìsàn ní póńpó
Oríṣun àwòrán, Reuters
Aarẹ orile-ede Kenya, Uhuru Kenyatta ti paṣẹ ki ileeṣẹ eto ilera ṣe afihan gbogbo iwe to ni i ṣe pẹlu ohun ti wọn ra nipa kikoju ajakalẹ arun Covid-19 ni Kenya.
Aarẹ Uhuru Kenyatta gbe igbesẹ yi lẹyin ti ọrọ jẹyọ pe awọn alaṣẹ kan ji ọpọ miliọnu dọla to yẹ ki wọn fi ra nkan eelo itọju arun Covid-19.
Lara awọn iwe aṣẹ inawo to ni ki wọn gbe jade leleyi ti ileeṣẹ to n pese eelo itọju alaisan ni Kenya, Kenya Medical Supplies Agency fi ra nkan.
Ileeṣẹ yi gan an ni wọn ni magomago ti waye nipa owo to yẹ ki wọn fi ra nkan eloo itọju alarun Covid-19.
Lasiko to n ba awọn Gomina ipinlẹ sọrọ ni Aarẹ Uhuru kede ọrọ yi.
Uhuru  ni ''Ileeṣẹ ilera gbọdọ ṣe afihan ọna igbowojade ti ko lẹja n bakan ninu jade laarin ọgbọn ọjọ eyi ti gbogbo eeyan yoo ri loju opo ayelujara''
Awọn alaṣẹ ti wọn fi ẹsun yi kan sọ pe awọn ko mọwọ mẹsẹ.
Wo bí Sunday Orimola ṣe gba ikú ẹranko kú ní Ifon ni Ondo lórí ọ̀nà àtijẹ
Edo election 2020: Ọlọ́pàá méjì kú nínú ìjàmbá ọkọ̀ tó ṣẹlẹ̀ sí Adams Oshiomole, APC ní kìí ṣe ojú lásán
Oríṣun àwòrán, others
Ori ko alaga ana lẹgbẹ oṣelu APC, Adams Oshiomhole yọ lọjọ Iṣẹgun, ṣugbọn ọrọ ko ri bẹẹ fun awọn ọẹọpaa meji ti wọn jẹ ẹṣọ rẹ.
Oshiomhole lo lewaju ikọ ipolongo ibo Pasitọ Osagie Ize-Iyamu gẹgẹ bi gomino ipinlẹ naa lọ si Usen nigba ti ọkọ akẹru kan ya lọ kọlu awọn ọkọ to n ba a kọwọrin lọ sibi ipolongo naa lagbegbe Oluku Junction ni ijọba ibilẹ ila oorun Ariwa ipinlẹ naa.
Atẹjade kan ti agbẹnusọ fun Adams Oshiomhole fi sita ṣalaye pe ni nnkan bii agogo mejila ọsan ni iṣẹlẹ naa ṣẹ.
Ọkọ tirela naa kọlu ọkan lara awọn ọkọ Toyota Hilux to n ba a kọwọrin lọ silu Usen nibi ti oun ati Pasitọ Ize-Iyamu to jẹ oludije fun ipo gomina lẹgbẹ oṣelu APC yoo ti ba awọn araalu naa sọrọ lori idi ti wọn fi gbọdọ di ibo wọn fun APC.
Bolaji Faleke ni Olùkọ́ tó ń kọ́ wa ní àṣà oge ṣiṣe lórí BBC Yorùbá
Meji ninu awọn ọlọpaa to wa ninu ọkọ naa jade laye ti awọn miran si wa ni ẹsẹ kan aye, ẹsẹ kan ọrun ni ileewosan.
Awọn ikọ rẹ ti sọ pe, igbagbọ awọn ni pe ọgbọn lati gbẹmi Adams Oshiomhole ni bi o tilẹ jẹ pe awọn ọlọpaa ko tii jade pẹlu iwadii wọn lori iṣẹlẹ naa.
Nibayii igbimọ olupolongo idibo APC ni ipinlẹ Edo ni awọn ti fi eto ipolongo rọ naa lati yẹ awọn to ku ninu iṣẹlẹ ijamba ọkọ naa sii.
Ọba Mohammed bin-Salman ti Saudi yọ ọmọ rẹ̀, Fahad, Abdulaaziz àti àbúrò rẹ̀, Ahmed kúrò nípò nítorí ìwà àjẹbánu
Ọba Saudi Arabiajawe lọ rọọkun nile fun minisita to n ri si eto aabo orile-ede naa.
Ọpọ awọn adari orílẹ̀ ede ati awọn ọmọ oye meji ni Saudi ni wọn ti kọwe gbele ẹ fun ni Saudi.
Ninu iwe ofin Saudi ni Ọba Saudi, Alasẹ Salman ti ni ki ọmọ ọba Fahad bin Turki to jẹ olori ẹṣọ alaabo to tun dari awọn ogun lọ si Yemen pe ko kuro lẹnu iṣẹ rẹ bayii.
Oda, ko yọ ọmọ rẹ silẹ.
Ọmọ rẹ, Abdulaziz bin Fahad, naa jẹ ọkan lara awọn to yọ kuro nipo gẹgẹ bi igbakeji Gomina.
Awọn ọkunrin naa ati awọn mẹrin miran ni wọn n koju iwadii to niṣe pẹlu owo laarin wọn ati ile iṣẹ eto aabo ilu naa.
Ọmọ ọba Mohammed bin Salman, to jẹ ọmọ rẹ ni awọn eniyan maa n fi sọrọ nipa ọba Saudi nitori oun lo n se agbatẹru igbogun ti iwa ibajẹninu ijoba baba rẹ.
Ẹwẹ, awọn alatako sọ pe bi o ṣe n fi panpẹ ọba mu gbogbo awọn eekan ilu, o n dọgbọn san gbogbo igbo didi ti ko jẹ ko de ori oye lọjọ iwaju ni.
Saaju ninu ọdun yii, ni iwe iroyin Wall Street ni, wọn fi panpẹ ọba mu awọn ọmọ ile ọba mẹta, to fi mọ aburo ọba, ọmọ ọba Ahmed bin Abdulaziz ati ati ọmọ oye nigba kan ri, Mohammed bin Nayef.
Bolaji Faleke ni Olùkọ́ tó ń kọ́ wa ní àṣà oge ṣiṣe lórí BBC Yorùbá
Eyi to ga julọ to ṣẹlẹ lọdun 2017, ọpọ awọn ọmọ oye, awọn minisita ati awọn olokoowo lo timole si ile itura  Rittz- Calton ni Riyadh.
Ọpọ wọn lo pada gba ominira sugbọn lẹyin ti won gba lati sa marundinlaasorin bilionu poun sapo ijoba Saudi ni.
Ọmọ ọba Mohammed bin Salman gba oniruuru iyin lọwọ ilẹ okere nigba to jẹjẹ atipade oniruuru ti yoo ba eto ọrọ aje ati igbayegbadun ara ilu nigba to gori oye lọdun 2016.
Ẹwẹ, oniruuru esun ni wọn fi kan an to fi mọ iku akọroyin Jamal Khashoggi ni olu ile ișẹ Saudi ni Istanbul lọdun 2018 ati erongba lati pa ọtėlẹmuyẹ Saudi Lan to wa ni Canada.
Bakan  naa ni wọn ti naka aleebu si ni ọpọ igba lori idarudapọ to n waye ni Yemen, nibi ti ijọba Saudi ti ran ijọba Yemen lọwọ lati maa tẹ ẹtọ awọn obinrin mọlẹ.
Wọ́n rò pé mo ya wèrè ni Saudi lẹ́yìn ikú ọkọ mi
Bo tilẹ jẹ pe Ọba Saudi Arabia n fun awọn obinrin ni awọn ẹtọ kan nigba to de, bi i ki obinrin ni anfani lati maa wa ọkọ.
Ilé ìtura Amazonia ní wọn kó àwọn ọmọ òhun pamọ́ si
Babatunde Olatunji: E wo ọmọ Yorùbá tó kọ́kọ́ jà fún ẹ̀tọ́ àwọn aláwọ̀dúdú ní America!
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ilumọọka onilu nilẹ America ati nilẹ Afrika, Babatunde Olatunji ti tako ofin ẹlẹyamẹya ni ọdun mẹta saaju ki Rosa Park to tako ofin ẹlẹyamẹya ninu ọkọ igboro lorilẹ-ede America.
Akọroyin BBC, Aaron Akinyemi ni ọdun mẹta saaju Rosa Park ni Babatunde Olatunji ti bẹrẹ ijijagbara fun ẹtọ awọn ọmọ ilẹ Afrika gẹgẹ bi eniyan bi i alawọfunfun ni ilẹ America.
Ọdun 1950 si ọdun 1960 ni awọn alawọdudu dide lati ja fun ẹtọ wọn gẹgẹ bi i ọmọniyan.
Ọkan lara wọn ni Babatunde Olatunji, eleyii ti Ajafẹtọ ọmọniyan, Opal Tometi to jẹ adari ikọ ''Black Lives Matter'' sọ wi pe wọn jẹ iwuri fun oun ni aye ode oni lati tako ẹlẹyamẹya ati ifiyajẹni nitori awọ ara eniyan.
Babatunde Olatunji fi orin ati ilu ja fun ẹtọ alawọdudu
Ọlatunji wa nibẹ pẹlu awọn gbajugbaja ajafẹtọ to jẹ ilumọọka bii James Baldin, Harry Belafonte  ni ọdun mẹtadinlọgọta sẹyin nigba ti Martin Luther King Jr sọ ọrọ akinkanju lasiko ifẹhọnuhan to waye nigba naa lati fopin si idẹyẹsini nitori ẹya lorilẹede America.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Babatunde Olatunji pẹlu Martin Luther King (L) ati Malcolm X (R) ni 1964
Ọdun 1927 ni wọn bi Olatunji to jẹ ọmọ Yoruba nipinlẹ Eko, ko to di wi pe Olatunji gba ami ẹyẹ lati lo kawe ọfẹ ni oke okun ni ''Morehouse College'' ni Atlanta, lorilẹede America ni ọdun 1950.
"Olatunji da ilumọọka lẹyin to ṣe awo orin mẹtadinlogun pẹlu awo orin to kọkọ ṣe lọdun 1959, eyi to pe akọle rẹ ni ""Drums of Passion""."
Wọn gbe oriyin fun Olatunji pe orin rẹ ṣe igbalarugẹ asa ati orin ilẹ Afrika, eleyii to gbe awo orin naa wa si gbagede lagbaye.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Babatunde Olatunji ati Malcolm X ni Nigeria ni 1960
Ọdun 1952 ni Olatunji bẹrẹ ifẹhọnuhan tirẹ ni awọn ọkọ igboro ni Guusu ilẹ Amerika.
Lasiko ti Olatunji wa ni ileese Morehouse, ọpọlọpọ nkan to buru jai lo waye nigba naa ti awọn alawọfunfun ṣe si awọn alawodudu nitori ofin ẹlẹyamẹya.
Baby abandoned on dunmpsite: Mo ti bímọ mẹ́rin tẹ́lẹ̀ fún bàbá méjì nínú òṣí- Dupe Ogbomos
Bakan naa ni Olatunji to ma n kọrin ilẹ Afrika ni Amerika ni awọn ile ijọsin ati fasiti ni awọn agbẹgbẹ ilu Atlanta, ni ilẹ Amẹrika.
Ni ọdun 1952 ni Olatunji bẹrẹ ifẹhọnuhan tirẹ ni awọn ọkọ igboro ni Guusu agbegbe naa.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Olatunji ati awọn ọrẹ rẹ tilẹ ma n wọ aṣọ alaranbara ilẹ Yoruba lati wọ awọn ọkọ igboro naa.
Bakan naa ni wọn ma n ṣe ifẹhọnuhan tako ofin ''Jim Crow'' ni Guusu ilẹ Amẹrika.
Oríṣun àwòrán, Olatunji family
Babatunde Olatunji fẹ iyawo rẹ Ammiebelle Bush ni ọdun 1957
Iyawo Olatunji, Iyafin Ammiebelle Olatunji to jẹ ẹni ọdun mọkandinlaadọrun ṣe apejuwe ọkọ rẹ gẹgẹ bi ẹni to gbe igbeaye rẹ lati ṣe igbelarugẹ fun ifimọsọkan awọn ọmọ ilẹ Afrika.
Ni ọdun 1964, Olatunji ṣiṣẹ pọ pẹlu aarẹ akọkọ lorilẹede Tanzania, Julius Nyerere ati Malcolm X lati fopin si ofin ẹlẹyamẹya lorilẹede Amerika.
Awọn ọmọ meji ninu awọn mẹrin ti Olatunji bi, Folasade ati Modupe Olatunji ṣe apejuwe baba rẹ gẹgẹ bi akinkanju eniyan to si kọ awọn ọmọ rẹ ni ṣiṣe iṣẹ takuntakun lọna ati jẹ ki wọn jẹ akinkanju eniyan nibi gbogbo ti wọn ba de.
Ọdun 2003 ni Olatunji sun ti ko ji mọ ni ẹni ọdun mẹrindinlọgọrin.
Iṣẹ takuntakun to ṣe ni ẹka orin kikọ ti jẹ ki Babatunde Olatunji jẹ awokọṣe fun Afrika ati awọn ọmọ ilẹ Afrika ti wọn bi tabi ti wọn n gbe ni Amerika.
Water resources bill: Wo òhun tó yẹ kí o mọ nípa Àbádòfin lórí pínpín àti àmúlò omi ní Nàìjíríà tó bá di ìtẹ̀wọ́gbà
Oríṣun àwòrán, Reuters
Bi eeyan ba ti n fọkan tẹle iṣẹlẹ to n waye nile aṣofin Naijiria lẹnu ọjọ mẹta yi, yoo ri wi pe niṣe ni iriwisi ọtọọtọ n waye nipa abadofin to da lori pipin ati amulo omi ni Naijiria.
Abadofin yii lọdọ awọn kan jẹ ọna ti ijọba yoo fi tubọ fun okun mọ awọn eeyan Naijiria lọrun.
Ṣugbọn lọdọ awọn aṣofin, wọn ni ọrọ ko ri bẹ bi kii ṣe pe awọn yoo fi abadofin naa da aabo bo alumọni omi ti Naijiria ni ko ba le kari ara ilu.
Lọwọlọwọ bayi, ijiroro lori ofin yi ti mu ki  iyapa maa waye laarin awọn aṣaaju ile aṣojuṣofin Naijiria.
Lọjọ Iṣẹgun lawọn iwe iroyin Naijiria kan jabọ pe bi awọn aṣofin kan ti ṣe n sọ pe awọn fẹ joko gba ero ara ilu lori abadofin yi, lawọn aṣofin miran ni wọn ko ni sọrọ nipa rẹ mọ.
Ki gan an labadofin yi ko sinu ati pe awọn wo lo n tako sisọ aba yi dofin?
Orukọ abadofin naa lẹkunrẹrẹ:
Lede Gẹẹsi, orukọ abadofin yi ni National Water Resources Bill 2020 ti ẹka apaṣẹ Naijiria si kọkọ fi sọwọ si ile aṣofin kẹjọ.
Nigba ti wọn fi ṣọwọ, awọn aṣofin tapa si abadofin naa paapaa julọ awọn to wa lati guusu Naijiria lori ẹsun pe o fẹ gba ọna ijẹ lẹnu awọn eeyan to n lo omi ti Eledua fi jinki wọn.
Ero awọn apa kan Naijiria ni pe ijọba fẹ lo ofin yi lati fi gbalẹ ati agbara lilo omi fawọn Fulani darandaran ni.
Bayi ti wọn tun fi abadofin naa sọwọ pada nile aṣofin kẹsan an yi lọjọ Kẹtalelogun, oṣu Keje, ọdun 2020, awọn eeyan ti n beere pe ki lo mu ki ijọba fi abadofin yi ṣọwọ lẹyin tawọn eeyan tako.
Ninu awọn  to gbohunsoke tako abadofin yi la ti ri Ọjọgbọn Wole Soyinka ati Gomina ipinlẹ Benue.
Yatọ si awọn wọn yi, ẹgbẹ oṣiṣẹ Naijiria naa ko gbẹyin ninu awọn to ni abadofin yii fẹ tubọ mu awọn kan lẹru ni Naijiria ni tawọn kan yoo si jẹ gaba le wọn lori.
Oríṣun àwòrán, Benue State Government
Awọn ti o tako abadofin yi naka abuku si ijọba Aarẹ Buhari pe o fẹ fi ofin yi gba iṣakoṣo omi lọna eru ni.
Loju opo Twitter awọn ẹgbẹ ajafẹtọmọniyan ni Naijiria bi SERAP ni awọn yoo tako abadofin yi nile ẹjọ tawọn aṣofin ba fi le buwọlu
Ni ṣoki, ohun ti abadofin yo ko sinu ni pe ijọba Naijiria fẹ ki awọn le ṣe akoso lori lilo ati pipin omi ti Eledua fi ta Naijiria lọrẹ lapapọ.
Labẹ abadofin yi, ijọba apapọ tabi ijọba ipinlẹ yoo lagbara lati paṣẹ bi ara ilu yoo ti ṣe maa lo omi to ba wa ni agbegbe wọn.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Koko miran to wa ninu abadofin yi ni pe eeyan tabi ileeṣẹ kankan to ba fẹ gbẹ omi pẹlu ẹrọ ''bore-hole'' yoo ni lati gba iyọnda lọdọ ijọba.
Bakan naa ni ofin naa yoo ṣe atunto awọn ileeṣẹ ijọba to n ṣe akoso ipese ati lilo omi lọwọlọwọ bayi.
Ni ipari ijọba n gbero pe abadofin yi yoo mu opin ba gbogbo ipenija to n ba Naijiria nipa lilo ati ipese omi.
Baby abandoned on dunmpsite: Mo ti bímọ mẹ́rin tẹ́lẹ̀ fún bàbá méjì nínú òṣí- Dupe Ogbomos
Fuel hike protest: Àwọn akẹ́kọ̀ọ́ ìpínlẹ̀ Oyo, Osun àti Ondo ṣe ìfẹ̀hónúhàn lórí èlé owó iná àti owó epo
Oríṣun àwòrán, @eniola_opeyemi
Awọn akẹkọọ ile iwe giga ni ipinlẹ Oyo, Osun ati Ondo ti gunle ifẹhonuhan nitori ele to gori owo ina ijọba ati epo bẹntiro ni Naijiria.
Awọn akẹkọọ naa korajọ si oriṣiriṣi ojuko ni olu ilu awọn ipinlẹ naa lati fi aidunun wọn han si ijọba lori ibi ti eto ọrọ aje Naijiria n dori kọ.
Wọn ko awọn kaadi ti wọn kọ oririṣiriṣi akọle si, eyii ti wọn fi n bu ẹnu atẹ lu ele ori owo naa.
Nigba to n ba awọn akọroyin sọro, agbẹnusọ awọn akẹkọọ ọhun, Kazeem Israel, sọ pe ele naa jẹ ọna lati mọọmọ ni awọn ara ilu lara.
"O ni ""Lai ṣe aniani, ijọba to wa lode yii ṣe afikun iṣoro awọn ọmọ Naijiria eyii to jugunba lọwọ ijọba  ana ni, koda, ijọba Buhari n ṣapẹrẹ pe awa akẹkọọ ni lati pada si bi aṣe maa n fa 'aluta' laye atijọ."""
Oríṣun àwòrán, Sahara Reporters
Kazeem ni eto ẹkọ ati eto ilera ti dẹnukọlẹ ti awọn to n ṣejọba ko si bikita fun igbeaye awọn ti wọn n ṣejọba le lori.
Akomolede ati Aṣa lori BBC: Mọ̀ si nípa oríṣìí ẹ̀ka ìsọ̀rí ọ̀rọ̀ àti ìwúlò wọn
O fi kun pe ni ṣe lo yẹ ki Aarẹ Muhammadu Buhari kọwe fiposilẹ ti ko ba lee da owo epo bẹntiro pada si naira mẹtadinlọgọrun un.
Aṣoju awọn akẹkọọ naa ni ohun to yẹ ki ijọba ṣe ni ko ṣafikun iye owo to la kalẹ fun eto ẹkọ ni ida marundinlogoji ati iye owo to la kalẹ fun eto ilera, ko maa san owo ajẹmọnu ẹgbẹrun lọgọrun un nairan fun awọn akẹkọọ atawọn nnka miran.
Ṣaaju iwọde naa ti ẹgbẹ awọn ọmọ ile iwe ni Naijiria, NANS. ṣagbatéru rẹ, ni ijọba ti ṣafikun iye owo ina mọnamọna ati owo epo bẹntiro, ti ọpọ awọn ọmọ Naijiria si bu ẹnu atẹ lu igbesẹ naa.
Ṣugbọn Aarẹ Muhammadu Buhari ti fesi oun ko ni yi ipinu oun pada lori ele owo naa nitori bi nnka ṣe ri lasiko yii.
Temitope Akinnusi: Ọ̀pọ̀ iléeṣẹ́ ló takú láti gbà mí síṣẹ́ torí mo ní ojú kan
Oríṣun àwòrán, Kunle Adeleke
Aarẹ Muhammadu Buhari ti fọwọ si yiya ọjọ kan sọtọ lọdun lati maa ṣe ayajọ ọjọ awọ ọdọ jakejado Naijiria.
Eyi waye ninu atẹjade kan ti minisita to n ri si ọrọ awọn ọdọ ati ere idaraya, Sunday Dare fi sita loju opo Twitter rẹ.
Sunday Dare sọ pe ''pẹlu aṣẹ aarẹ, gbogbo ọjọ kini oṣu kọkanla ọdun ni wọn yo maa fi ṣe ayajọ ọjọ awọn ọdọ Naijiria.''
O ni Aarẹ Buhari sọ pe  ọjọ yii ni wọn yo maa fi pe akiyesi ati wiwa ojutuu si awọn ọrọ to ni ṣe pẹlu ọdọ atawọn iṣoro ti wọn n koju.
Minisita ọrọ awọn ọdọ ni eyi tun fihan pe aarẹ Buhari ni ifarajin ati atilẹyin fun awọn aato to ba wa fawọn ọdọ Naijiria.
Pẹlu ikede yi, awọn ọdọ Naijiria yoo dara pọ mọ awọn akẹgb wọn lorileede Ghana ati Cameroon lati ṣe ayajọ ọjọ yi.
Lawọn orileede ti wọn ti n ṣe ayajọ yi, awọn ọdọ a maa ṣe iwọde toun ti pọpọsinsin orin ati ijo.
Amọ lawọn ilẹ mii, niṣe ni wọn maa n fi ọjọ yi ṣe agbeyẹwo awọn ohun to kan ọdọ.
Ko ti daju boya wọn yoo ya ọjọ yi sọtọ lọjọ isinmi lẹnu iṣẹ ni Naijiria.
MKO Abiola: Ọwọ́ ọlọ́pàá tẹ àwọn olè tó kó góòlù àti ẹgbẹ̀lẹ́gbẹ̀ mílíọ̀nù lọ nílé Abiola l'Eko
Oríṣun àwòrán, @mko_abiola
Ileeṣẹ ọlọpaa ti mu awọn afurasi adigunjale to ṣọṣẹ nile oloogbe Oloye Moshood Abiola to wa ni Ikeja niluu Eko nibi ti wọn ti ji nkan to to ẹgbẹlẹgbẹ miliọnu lọ.
Abiola lo jawe olubori ninu ibo aarẹ gbogbogbo to waye lọdun 1993 eyi ọgagun fẹyinti Ibrahim Babangida wọgile nigba naa.
Kọmiṣọnna ọlọpaa nipinlẹ Eko, Hakeem Odumosu lo sọ pe ọwọ awọn agbofinro ti tẹ awọn kọlọnbiti ẹda ọhun ti wọn yabo ile Abiola l'Ọjọru.
Kọmiṣọnna ọlọpaa to ṣabẹwo si ile ọhun fidi rẹ mulẹ pe mẹta lawọn ole ọhun ṣugbọn ọkan lara wọn lo gbe ibọn dani.
Ọgbẹni Odumosu ni ''ẹbi Abiola sọ f'oun pe awọn ole naa ji ọpọlọpọ goolu ati owo lọ.''
''Awọn agbofinro ti wa lojufo bayii legbegbe Ikeja ti ile naa wa to fi de ọdọ awọn ọlọpaa to wa ni ibode Idiroko ati Seme,'' kọmiṣọnna ọlọpaa lo sọ bẹẹ.
Kọmiṣọnna ọlọpaa ipinlẹ Eko ni ko si ẹni to farapa ninu iṣẹlẹ naa ninu iyawo Abiola, Bisi ati ọmọbinrin meji to wa nile.
Ọgbẹni Odumosu fikun ọrọ rẹ pe iwadii ṣi n lọ siwaju lori iṣẹlẹ naa.
Awọn aladugbo to bawọn akọroyin sọrọ ṣalaye pe geeti to wa lẹyin lawọn ole ba wọle, wọn ni laago mẹrin idaji ni iṣẹlẹ naa waye nigba tawọn ẹṣọ to wa nile ile naa ti sun lọ.
Anthony Joshua: Ajagba akẹ̀ṣẹ́ ọmọ Nàìjíríà lóun ṣetán láti f'ẹ̀ṣẹ́ dín dòdò ìyà fún AJ
Oríṣun àwòrán, Instagram
Yoruba bọ, wọn ni o di oni karangida, adiẹ n jẹ ifun ara wọn. Bayii lọrọ ri abẹṣẹ ku bi ojo ọmọ Naijiria, Efe Ajagba to ni oun ṣetan lati fi ẹṣẹ din dodo iya fun ogbontarigi akẹṣẹ Anthony Joshua.
Ilẹ Amẹrika ni Ajagba to ti ṣoju orilẹede Naijiria ri ninu idije ''Olympics'' fi ṣe ibugbe bayii lẹyin to ti wa niluu Eko fun ọpọlọpọ ọdun.
Ọrọ naa da bi ẹni to maa ku pade ẹni to maa pa, nirori Joshua gan an funra rẹ ti sọ tẹlẹ pe o wu oun lati fija pẹta pẹlu akẹṣẹ to jẹ ọmọbibi ilẹ Afirika bi t'oun naa.
Ajagba tiẹ ti bẹrẹ si ni sọ ọna ti o fi le fẹyin AJ gbalẹ ti wọn ba koju ara wọn.
Ajagba sọ fawọn akọroyin pe ko ba wu oun ki Joshua gba lati ba oun ja lorilẹede Naijiria tawọn mejeeji ti wa.
Abẹsẹ ku bi ojo ọmọ Naijiria ṣalaye pe lootọọ ni pe Joshua lagbara, amọ ọgban inu loun maa fi ṣẹ AJ leegun ẹyin tawọn koju ara awọn.
O ni ati oun ati Joshua lawọn jọ lagbara ṣugbọn o ni ọgbọn ju ọgbọn lọ.
Ajagba ni otitọ ni pe Joshua ti gba ami ẹyẹ goolu ninu idije ''Olympics'' ri, oun si tun ni abẹṣẹ ku bi ojo to lami lahaka taye ti aye  n fẹ lọwọ bayii.
Oun oun naa gboṣuba fun AJ fun awọn aṣeyọri rẹ lagbo ẹṣẹ kikan, amọ oun mọ awọn ibi ti Joshua ku si ninu ẹṣẹ kikan.
Joshua gba awọn igbanu rẹ mẹtẹẹta, IBF, WBA ati WBO pada lọwọ Andy Ruiz Jr pada lẹyin ti Ruiz ti kọkọ lu u bi aṣọ ofi nigba ti wọn kọkọ koju ara wọn.
Joshua naa fẹ ṣe bi agbọjẹ ninu ẹṣẹ kikan, oloogbe Muhammad Ali to ba George Foreman ja ni Zaire lọdun 1974.
Amọ Ajagba ti kepe Joshua pe ko jẹ ki awọn ṣe ere ọwọ papọ ni Naijiria, o ni ti o ba ti ya eegun Joshua, o ti ya ọlọrẹ t'oun naa.
Auxiliary: Alága àjọ Park Management System, gbé àwọn tó ń ja ìjọba lólè ní ibùdókọ̀ lọ sí ilèẹjọ́
Oríṣun àwòrán, Oyo Vanguard
Alaga ajọ to n mojuto awọn ibudokọ nipinlẹ Oyo, Park Management System, Alhaji Mukaila Lamidi ti ọpọ mọ si Auxiliary ti gbe eeyan mẹfa to n jawee ayederu fawọn awakọ lọ sile ẹjọ.
Bakan naa lo tun fi ẹsun pe wọn n gba ju owo ti ijọba ipinlẹ Oyo ni ki wọn maa gba lọwọ awọn awakọ lọ.
Auxiliary gan an lo sọrọ yii fawọn akọroyin l'Ọjọru niluu Ibadan.
O ṣalaye pe ọdọmọkunrin ọdun mọkandinlogun kan to ṣẹṣẹ pari ileewe girama wa lara awon mẹfa ọhun ti igba iwa ibajẹ lawọn ibudokọ ti ṣi mọ lori bayii.
Auxiliary sọ pe gbogbo awọn ọbayejẹ ẹda to ba fẹ ma ja ijọba lole nipa gbigba owo lọna aitọ ni yoo foju wina ofin nipinlẹ Oyo.
Akomolede ati Aṣa lori BBC: Mọ̀ si nípa oríṣìí ẹ̀ka ìsọ̀rí ọ̀rọ̀ àti ìwúlò wọn
Bakan naa ni Auxilliary  rọ awọn ẹgbẹ onimọto, RTEAN at'awọn ẹgbẹ ọlọkada lati bọwọ fun ofin ijọba nipa sisanwo wọn deedee ti awọn oṣiṣẹ ajọ PMS ba ti n jawe fun wọn ni ibudokọ.
O ni ọna kan gbogii niyii lati pawo sí apo ijọba ki wọn le pèse ohun amayedẹrun fun araalu
Oríṣun àwòrán, Other
Ejiogbe NURTW ati Auxilliary
Ki lo ti kọkọ ṣẹlẹ laarin NURTW ati Auxilliary funra rẹ ni Ibadan?
Ara ló ń ta àwọn ẹgbẹ́ NURTW tó ń pariwo mi kiri, APC ni wọ́n bá lọ nígbà náà l'Oyo- Auxiliary
NURTW: Auxiliary ní ara ló ń ta àwọn ẹgbẹ́ NURTW tó ń pariwo òun kiri, APC ni wọ́n bá lọ l'Oyo
Ẹgbẹ awakọ NURTW ẹka ti ipinlẹ Oyo ti ke gbajare lori iwa ipa ti wọn ni Alhaji Lamidi Mukaila ti inagijẹ rẹ n jẹ Auxiliary to n hu sawọn ọmọ ẹgbẹ ajọ naa.
Oríṣun àwòrán, others
Auxiliary ni alaga ajọ, Park Management System (PMS) to n ṣe akoso awọn ibudọ kaakiri ipoinlẹ Oyo lati igba ti Gomina Seyi Makinde wọgile ẹgbẹ NURTW nipinlẹ Oyo.
Ajọ NURTW ṣalaye pe niṣe ni Auxiliary n kaakiri gbogbo ọfiisi ajọ naa ti o si n ko ohun ini ẹgbẹ lọ si ibi tawọn ko mọ.
Kini Ejiogbe NURTW sọ?
Eekan inu ẹgbẹ NURTW, Alhaji Abideen Olajide (Ejiogbe) to ba BBC Yoruba sọrọ ṣalaye pe ohun ti ijọba ko ran Auxiliary n ṣe kaakiri ipinlẹ Oyo.
Ejiogbe ni kete ti wọn bura tan fun Alhaji Mukaila lo bẹrẹ si ni pa orukọ NURTW rẹ lara awọn ọfiisi ajọ naa to n si yi pada si PMS.
O ni iṣẹ ti ẹgbẹ NURTW n ṣe ni ijọba gbẹsẹ le l'Oyo kii ṣe ẹgbẹ NURTW.
Ejiogbe ni owo ẹgbẹ NURTW lawọn fi kọ ile ẹgbẹ NURTW ti ti Auxiliary n yi ọrukọ pada si PMS.
O ni ''gbogbo awọn ọmọ ẹgbẹ NURTW to wa ni ipo kan tabi omiiran ni Auxiliary ti yọ nipo tan ti o si fawọn eeyan tiẹ sibẹ.
Alhaji Olajide ni awọn si n rawọ ẹbẹ si ijọba Gomina Makinde lati gbẹsẹ kuro lori ẹgbẹ NURTW nipinlẹ Oyo.
Ejogbe ni ohun ti ijọba ni ki Auxiliary maa ṣe ni pe ko maa pa owo si apo ijọba, ko si maa jawe fawọn awakọ lawọn ibudokọ.
O ni Auxiliary ko mọ iyatọ to wa laarin NURTW ati PMS.
Olusegun Obasanjo: Ọmú ìyá mi ti mo fi ń mùkọ ni kekere ló jẹ ki ń lókun
Kini Auxilliary sọ ni tirẹ?
Ṣugbọn ninu ọrọ ti ẹ, Auxiliary sọ fun BBC Yoruba irọ nla lawọn ọmọ ẹgbẹ NURTW n pa mọ oun pe oun n gbe ohun ini ẹgbẹ naa kaakiri ipinlẹ Oyo.
O ni ''lati ọjọ ki Gomina Makinde ti ti ọfiisi NURTW to wa ni Aduloju pa, oun atawọn ọmọlẹyin ou ko de ibẹ.''
Alhaji Mukaila ni awọn ara awọn ọmọ ẹgbẹ NURTW gan an ti bẹrẹ si ni darapọ mọ awọn ọmọlẹyin oun.
O ni ko si si ohun to jọ ọ pe oun tun n yi orukọ NURTW pada si PMS.
Alhaji Mukaila ni ọwọ to ba ṣẹ ẹkusi lo maa n jẹ ẹ, o ni iyẹn tumọ si pe oun ti ṣiṣẹ silẹ de ongbẹ lasiko yii nitori ẹgbẹ oṣelu PDP loun tẹ le lasiko ibo gbogbogbo to lọ.
''Ẹgbẹ oṣelu APC lawọn to to gba NURTW ipinlẹ Oyo tẹ le, wọn o si ke si mi nigba ti wọn lo ọdun mẹjọ ti wọn naa lasiko ti APC wa ni ijọba,'' Auxiliary lo ṣalaye bẹẹ.
Auxiliary sọ pe ara lo n ta awọn ọmọ ẹgbẹ NURTW ti wọn n pariwo ohun kaakiri.
Alhaji Mukaila ko ṣai fikun ọrọ rẹ pe oun naa lẹtọ si ohun ini ẹgbẹ NURTW nitori ọkan lara ọmọ ẹgbẹ naa loun n ṣe tẹlẹ.
Yollywood Yemi Shodimu sọ̀rọ̀ pé àṣìlò ẹ̀bùn kò jẹ́ kí Nàìjíríà dàgbà sókè mọ́
Oríṣun àwòrán, Facebook/Yemi Shodimu
Odu ni o jẹ lagbo oṣere tiata ni Naijiria kii ṣe aimọ f'oloko.
Bi eeyan ba ti wo awọn ere ileeṣẹ sinima Mainframe ni nkan bi ọdun meloo kan sẹyin, yo ranti arakunrin kan to kopa ribiribi ninu awọn ere ti Tunde Kelani dari wọnyi.
Yemi Shodimu lẹni taa n wi to si  kopa ninu awọn ere sinima bi Ò le kù (1997), Ti oluwa ni ile (1993) ati Kòseégbé (1995).
BBC News Yoruba gba lalejo loju opo Facebook Live ti o si yanana ọrọ lori awọn ohun to ni ṣe pẹlu ere sinima ni Naijiria.
Diẹ lara awọn ohun t ri fayọ ninu ifọrọwerọ naa ree:
Ifarada pọ fawa oṣere nigba ta fi n kopa ninu ere sinima yatọ si tode oni
Gẹgẹ bi agba ọjẹ oṣere sinima yi ti ṣe ṣalaye, o ni tifẹtifẹ, tọkantọkan lawọn fi n se ere sinima lasiko tawọn.
O sọ pe awọn alakoso nigba naa ki ṣe alayaba.
''Inu ọkan wọn ni itan ti wọn ba kọ ti maa n wa ati pe ẹkọ ti wọn kọ nipa gbigbe itan silẹ ni wọn n lo.''
Àṣìṣe ọlọ́pàá àti Adájọ́ sọ mí di ẹni tí wọ́n dájọ́ ikú fún, ọpẹ́lọpẹ́ Fayoṣe tí ko buwọlu
Ẹbun pataki, ẹbun nlanla ni Tunde Kelani jẹ fun orileede Naijiria
Lori gbajugbaja oludari ere sinima yi, Yemi Shodimu ni  o ṣeni laanu pe awọn to yabara ti wa pọ ninu ere sinima.
O ni ṣugbọn kii ṣe lagbo osere tiatia nikan ni wọn wa bii kii se pe wọn pọ ninu oṣelu ati awọn iṣẹ miran ni Naijiria.
Ninu awọn nkan to sọnu ninu ere sinima ode oni, o sọ pe ti a baa n tiraka lati sọ itan oyinbo fun oyinbo, a ko le tẹsiwaju.
O ni aṣeyege pọ, kudiẹkudiẹ naa pọ to fi mọ awọn nkan aṣa wa to pọ ti a ko ti fi han fun araye ninu sinima.
''Ohun to n ṣe oyinbo loyinbo n kojọ ninu fiimu, ki lo de ti a wa naa ko gbe tiwa jade faraye gbọ?
O tẹsiwaju pe ''A ko ti bọ kuro ninu a n fi owo kun owo epo, owo ina, ki laa jẹ, ki laa mu, awọn nkan to n jo wa bi ina labẹ aṣọ pọ ti a gbọdọ fi han agbaye.''
Tunde Kelani; Èmi ò jẹ́ Baba Wande ní owó lórí fíímù Tolúwanilẹ̀
Nipa isọkan Yoruba ati ọrọ iṣelu:
Sodiumu ni Yoruba ni lati pawọpọ ti wọn ba fẹ jana.
Shodimu yabara labẹ akori ọrọ yi lati sọ nipa oselu to n lọ lọwọ ni Naijiria
O sọ pe awọn to dantọ lati se oselu pọ ni Naijiria,bẹẹ lawọn ti ko yẹ ki wọn sunmọ oṣelu naa wa nibẹ.
Baby abandoned on dunmpsite: Mo ti bímọ mẹ́rin tẹ́lẹ̀ fún bàbá méjì nínú òṣí- Dupe Ogbomos
O wa fi kun pe abaabọ  fifi awọn ti ko yẹ sipo ni Naijiria n ba finra bayi.
''A feran lati maa ṣadura lori gbogbo nkan ni Naijiria ṣugbọn ọlọrun ma jẹ ki ọrọ wa ṣu Ọlọrun.
Asilo ẹbun wa ninu nkan to n ṣe wa ni Naijiria ti a ko fi dagbasoke''
Owó oúnjẹ ni mo lọ ọ gbà, oyún ọmọ tí mo jù sí àkìtàn ni mó gbé wálé- Dupe, ìyá Muiz
Ekọ ni ọrọ Iya Muiz jẹ fun awọn ọdọ isiyi
Ti gbogbo obinrin ba loyun, adura wa a bi wẹrẹ, wa ri ọmọ gbejo ni diẹ lara adura ti awọn eeyan ma n gba fun wọn.
Ṣugbọn ni ti Arabinrin Dupe Alabi, ko ri bẹ o. Ori akitan lo ju ọmọ si, lẹyin to ru ẹru oyun fun oṣu mẹsan-an.
Ẹyin naa kọ ha! Ṣugbọn ṣebi ti ko ba nidi, obinrin kii jẹ kumolu.
BBC tẹkọ leti lọ silu Ogbomọsọ, nipinlẹ Oyo, lati ba Dupe sọrọ, nkan to fa igbesẹ rẹ to sọ kọja bẹẹ.
"Dupe ni ""bi mo ṣe bi i tan, mi o tiẹ wo boya ọkunrin ni tabi obinrin. Mo kan gbe ju si ibi ti wọn ti gbe e ni."
Mo wa duro nitosi ibẹ, lati wo boya ẹnikẹni yoo gbe. Ero ọkan mi ni pe ti wọn ba gbe, wọn o ni le mọ pe emi ni mo ju ọmọ sibẹ.
Ọmọ tuntun yii kọ ni akọkọ fun Dupe. O ti bi ọmọ mẹrin tẹlẹ, fun ọkunrin meji.
O sọ fun BBC pe ipọnju ati idaamu lo mu ki oun gbe ọmọ ẹlẹẹkarun sọnu.
Itiju ni oyun ọmọ naa jẹ fun mi, nitori ipo ti mo wa. Mo si fi aṣiri oyun naa pamọ, debi pe ti awọn eeyan ba beere pe ṣe mo loyun, ma a sọ pe rara.
Lati inu oyun ni mo ti pinnu pe, ma wa ibi kan ju u si ti mo ba bi. Nitori naa, ni mi o ṣe ra nkan ọmọ kankan.
Arabinrin Dupe ṣalaye pe ija ati idaamu lo mu oun kuro nile ọkọ oun akọkọ. Ibi to si ti n ṣe ọmọọdọ olounjẹ lo ti pade ọkunrin keji, to bi ọmọ meji fun.
Ile ọkunrin keji yii lo wa, ti baba ọmọ rẹ akọkọ tun fi n fẹ ko pada si ọdọ rẹ.
Ti ọkọ mi akọkọ ba pade mi lọna, yoo ma sọ fun mi pe ki n ko pada si ọdọ rẹ. Ṣugbọn, mo ma n sọ fun pe ko ṣe e ṣe.
Iroyin yii ni ẹnikeji ti mo fẹ n gbọ, to fi ko kuro ninu ile ti a jọ n gbe, to si fẹ obinrin mii. O ni oun gbọ pe ọkọ mi akọkọ sọ pe oun yoo gba mi pada.
Baby abandoned on dunmpsite: Mo ti bímọ mẹ́rin tẹ́lẹ̀ fún bàbá méjì nínú òṣí- Dupe Ogbomos
Dupe ko pada si ile awọn obi rẹ ni Odo Ọba. Ibẹ si lo wa ti ọkọ rẹ akọkọ tun fi n fa oju rẹ mọra.
O tẹsiwaju ninu ọrọ rẹ pe, ọkọ rẹ akọkọ ṣeleri fun lati tọju rẹ pẹlu ọmọ mẹtẹẹta. Eyi si lo mu ki Dupe ko pada si ile rẹ.
Awọn mejeeji jọ n gbe papọ,koda, Dupe tun bimọ kan fun.
"Ṣugbọn ""nigba to ya, o bẹrẹ si ni ba mi ja pe ki n ko awọn ọmọ meji ti mo bi fun ọkunrin keji pada si ọdọ baba wọn."
Àṣìṣe ọlọ́pàá àti Adájọ́ sọ mí di ẹni tí wọ́n dájọ́ ikú fún, ọpẹ́lọpẹ́ Fayoṣe tí ko buwọlu
Ija yii pọ debi i pe, awọn obi mi wa ba mi ko ẹru mi kuro nile rẹ.
Dupe ati ọkọ rẹ yii ko rira fun bi ọdun kan aabọ, nitori pe onitọhun rinrinajo kuro niluuu.
Dide to de pada, o ranṣẹ si Dupe pe ko wa a gba owo ounjẹ fun ọmọ rẹ ọkunrin to bi fun.
Owo ounjẹ ni Dupe lọ ọ gba, oyun ọmọ karun-un lo gbe pada sile.
"Nigba ti mo ri i pe mo loyun, mo gbiyanju lati sọ fun, ṣugbọn mi o ri nitori pe o tun ti kuro niluu.
Iyalẹnu ni pe o ṣọ fun awọn eeyan rẹ to ri i pe oun kọ lo fun mi loyun."""
Bolaji Faleke ni Olùkọ́ tó ń kọ́ wa ní àṣà oge ṣiṣe lórí BBC Yorùbá
Ni ọjọ kọkanla, oṣu Kẹjọ, ọdun 2020, ni ọmọ bẹrẹ sini mu Dupẹ, ko sọ fun ẹnikẹni, nitori pe 'wọn o mọ pe o loyun'.
"Ni nkan bi aago mọkanla alẹ ni ọmọ bẹrẹ si ni i mu mi. Mi o sọ fun ẹnikankan, nitori pe mo ti ma n sọ fun wọn tẹlẹ pe ikun mi kan n wu ni, kii ṣe oyun lo wa nibẹ, ni gba ti wọn ba beere pe ṣe mo loyun.
Mo rọra bọ si inu ile kan to wa ni ẹgbẹ ileewosan Akala, ni Oke Elerin, nilu Ogbomọṣọ."""
Wọn ti maa n wọ inu ile naa tẹlẹ lati ṣe igbọnsẹ.
Bi ọmọ naa ṣe jabọ, mi o ti ẹ wo boya ọkunrin ni, tabi obinrin. Mo kan gbe, mo si ju u si ibi ti awọn oṣiṣẹ ileewosan ti ri.
'Oyenusi ló mú mi wọ ẹgbẹ́ adigunjalè kó tó di pé mo b'Ólúwa pàdé'
"Pipada to pada sinu ile, ni ọkan lara awọn ti wọn jọ n gbele, fi ẹsun kan an pe ""Iya Muiz, ṣe ẹyin kọ lẹ gbe ọmọ ju si akitan ni?"
"Mo tiẹ kọkọ fẹ ẹ ma a sọ pe mi o bi ọmọ kankan, ṣugbọn o sọ fun mi pe awọn obi mi ti wa pẹlu ọmọ ni ileewosan.
Bi mi o ṣe le jiyan mọ niyii, mo si bẹrẹ si ni sunkun."""
Arabinrin Dupe ṣalaye pe oun ni akọbi iya ati baba oun, to si jẹ pe ọmọ mejidinlogun ni baba rẹ bi.
O ni itiju ko fẹ ẹ jẹ ki oun lọ ma a gbe pẹlu iya oun, nitori pe awọn iyawo aburo oun n gbe pẹlu rẹ.
Alaga ijọba ibilẹ idagbasoke Ogbomoso Central, Adeyinka Remi Oluwaseun, sọ fun BBC pe oun ti gba obinrin naa siṣẹ nileeṣẹ ijọba.
"Aanu rẹ ṣe mi, bi mo ṣe ri i pe ọmọ marun lo ti bi, lai si iṣẹ tabi ọkọ ti yoo tọju rẹ.
Awọn oṣiṣẹ wa tọju rẹ nileewosan, mo si tun ti ṣeleri pe ma a tọju ọmọ naa titi de ileewe girama."""
Adeyinka Oluwaseun Moraanugba ni wọn sọ ọmọ tuntun naa.
Health workers Strike: Àwọn òṣìṣẹ́ elétò ìlera lábẹ́ àsìá JOHESU fagilé ìyanṣẹ́lódì káàkiri Nàìjíríà
Oríṣun àwòrán, others
Ẹgbẹ oṣiṣẹ eleto ilẹra lapapọ labẹ ẹgbẹ JOHESU ti kesi awọn oṣiṣẹ wọn lati pada si ẹnu iṣẹ.
Ọjọ meje ṣẹyin ni wọn gunlẹ iyanṣelodi lati pe akiyesi ijọba si awọn ohun to jẹ ẹdun kan fun wọn.
Amọ nibayii, awọn adari ẹgbẹ JOHESU naa ti wa paṣẹ fun wọn lati pada si ẹnu iṣẹ kaakiri orilẹede Niajiria.
JOHESU ni awọn gbegile iyanṣẹlodi naa bi o tilẹ jẹpe ijọba apapọ ko i tii dahun si ibeere wọn.
Ohun ti wọn n bere fun ni ki ijọba san owo oṣu ti wọn jẹ wọn, ki wọn si san owo ajẹmọnu ti ijamba ba ṣẹlẹ si oṣiṣẹ ilera lẹnu iṣẹ.
Amọ, titi di wakati yii ijọba apapọ ko dahun si ibeere wọn, ki wọn to gunlẹ iyanṣẹlodi lati kilo fun ijọba.
Nibayii, ẹgbẹ JOHESU ni awọn ọmọ ẹgbẹ yoo ṣe ipade lati ri wi pe awọn wa wọrọkọ fi sada lori igbesẹ ijọba yii, eleyii ti ko dun mọ wọn ninu.
Ẹgbẹ oṣiṣẹ eleto ilera marun un lo wa labẹ ẹgbẹ oṣiṣẹ JOHESU.
Ọjọ Kẹtala, Oṣu Kẹsan an, ọdun 2020 ni awọn oṣiṣẹ ilera naa gunle iyanṣẹlodi, ki wọn to ṣẹṣẹ pada si ẹnu iṣẹ bayii.
Egberin ọtẹ lọrọ iyanṣẹlodi awọn oṣiṣẹ eleto ilera lorilẹede Naijiria yii o.
Lẹyin ọjọ mẹta pere ti ẹgbẹ awọn dokita da iyanṣẹlodi ti wọn gunle duro, ẹgbẹ gbogbo oṣiṣẹ eleto ilera ni Naijiria, Joint Health Sector Unions, JOHESU naa ti kede iyanṣẹlodi kaakiri orilẹede Naijiria.
Ẹgbẹ JOHESU paṣẹ pe ki awọn oṣiṣẹ eleto ilera da iṣẹ silẹ laago mejila oru ọjọ Aiku ọjọ kẹtala oṣu kẹsan an ọdun 2020.
Ninu atẹjade kan ti ẹgbẹ JOHESU kede iyanṣẹlodi ọhun ninu atẹjade kan to fi sita lọjọ Aiku.
Awọn alaṣẹ ẹgbẹ naa ti kọkọ ṣepade pọ pẹlu ijọba apapọ lọjọ Ẹti lori erongba rẹ lati gunle iyanṣẹlodi.
Ẹgbẹ JOHESU sọ ninu atẹjade naa pe iyanṣẹlodi ọhun yoo tẹsiwaju nitori ijọba ko ṣetan lati ṣe ohun tawọn n fẹ fawọn oṣiṣẹ eleto ilera.
Ẹgbẹ naa ti kọkọ fun ijọba ni ọjọ mẹẹdogun pe awọn yoo gunle iynaṣẹlodi ki wọn to bẹrẹ lọjọ Aiku.
Lara ohun ti wọn n beere lọwọ ijọba atunṣe owo idojutofo fu itọja coronavirus, sisan owo oṣu ti ijọba n jẹ awọn oṣiṣẹ eleto ilera to fi mọ owo oṣu wọn kẹrin ati ẹkarun un ọdun 2018 to wa nilẹ.
Amọ aiṣetan ijọba lati ṣe gbogbo nnkan yii lo mu wọn pada gunle iyanṣẹlodi lọjọ Aiku.
Àwọn dókítà Nàìjíríà ti fòpin sí ìyanṣẹ́lódì wọn
Ẹgbẹ awọn dokita ni Naijiria ti da iyanṣẹlodi ti wọn gunle duro fun saa diẹ.
Aarẹ ẹgbẹ naa, Aliyu Sokunbo sọ fu awọn akọroyin pe ẹgbẹ ọhun ti gunle idunadura miran pẹlu ijọba apapọ lori awọn ohun ti wọn n bere fun.
O ni lẹyin ipade ti wọn ṣe pẹlu ijọba apapọ ni wọn pinnu lati da iyanṣẹlodi ọhu duro fun oṣe meji lati wo ibi ti ọrọ awọn ati ijọba yoo yuọri si.
Ṣaaju ni ijọba apapọ ti sọ oun ti fi biliọnu mẹsan an din diẹ naira kun owo ajẹmọnu owo Covid-19 wọn, eyii to jẹ wọn fun oṣu kẹfa ọdun 2020.
Mayowa Omoniyi: Kò sí orin Obey, Sunny Ade abí tàkasúfèé tí ń kò le ta gìtá sí
Ki lo ti ṣẹlẹ sẹyin?
Oríṣun àwòrán, others
Ijọba apapọ ti paṣẹ fun awọn dokita agba nile iwosan rẹ gbogbo, pe ki wọn fi awọn agunbanirọ to jẹ dokita rọpo awọn dokita to n yanṣẹ lodi.
Ijọba apapọ paṣẹ pe ki wọn fi awọn dokita agunbanirọ to n sinru ilu lọwọ, rọpo awọn dokita iṣegun to n yanṣẹ lodi lawọn ileewosan to jẹ ti ijọba apapọ naa.
Ijọba ni oun n gbe igbesẹ naa ki iṣẹ ipese ilera ati itọju awọn alaisan ma baa dawọ duro nibẹ.
Minisita feto ilera, Dokita Osagie Ehanire lo pa aṣẹ yii lọjọru nilu Abuja lasiko to n sọrọ lori iyanṣẹlodi awọn dokita nile iwosan ijọba, NARD.
Oríṣun àwòrán, others
Iyansẹlodi naa n waye lori sisan owo ajẹmọnu fun ewu ti wọn la kọja lasiko ajakalẹ arun COVID-19 atawọn ẹdun miran.
"Minisita Ehanire ni ""ko si aniani pe, ojuṣe awọn dokita ati gbogbo awọn oṣiṣẹ eleto ilera ni lati doola ẹmi."
"Ko si yẹ ko jẹ pe awọn dokita bẹẹ lo wa n da iṣẹ silẹ niru asiko bayii ti Naijiria n ba ajakalẹ arun finra."""
O ni iru asiko yii lo yẹ ki gbogbo oṣiṣẹ lẹka eto ilera parapọ, wa koju ọta ọmọniyan yii, nitori naa, ohun to ku diẹ ka a to ni idaṣẹsilẹ naa.
Mayowa Omoniyi: Kò sí orin Obey, Sunny Ade abí tàkasúfèé tí ń kò le ta gìtá sí
O fi kun un pe, bi o tilẹ jẹ wi pe ijọba ti mojuto ibeere yii, ti ijiroro lori awọn yooku si ti de ipele to lapẹẹrẹ, suuru ni awọn dokita naa ko ba fi yanju ọrọ naa.
"Ohun to ṣe pataki fun ijọba ni lati wa awọn ọna gbogbo to ba yẹ, lati fi rii daju pe irora iyanṣẹlodi naa ko pọ lapọju fun araalu.
Idi niyi ti ijọba fi paṣẹ pe, ki awọn dokita agba lawọn ile iwosan ijọba apapọ maa lo dokita agunbanirọ, lati maa tọ awọn to n gba itọju pajawiri lọdọ wọn.
Bolaji Faleke ni Olùkọ́ tó ń kọ́ wa ní àṣà oge ṣiṣe lórí BBC Yorùbá
O wa ke s'awọn dokita ti n woṣẹ niran naa lati pada si ẹnu iṣẹ wọn, ki wọn lee tẹnpẹlẹ mọ ijiroro wọn to n lọ lọwọ pẹlu ijọba apapọ, lori awọn ibeere wọn naa.
A n jekuru ọrọ l'agboeto ilera lorilẹede Naijiria ko tan lawo, ṣe ni  wọn tun n gbọn ọwọ rẹ sinu awo.
Lẹyin ti awọn dokita bẹrẹ iyanṣẹlodi wọn lọjọ Aje, ti ọpọ ọmọ orilẹede Naijiria si ti n pariwo, awọn oṣiṣẹ eto ilera yoku naa ti gbe ikilọ sita pe awọn pẹlu yoo gunle iyanselodi bẹrẹ bi ijọba apapọ ba kuna lati sise lori ẹdun wọn.
Ninu ọrọ to ba awon akọroyin sọ nilu Abuja, agbarijọpọ awọn ẹgbẹ oṣiṣẹ lẹka eto ilera lorilẹede Naijiria salaye pe ijoba ti n mu awon lọbọ lori ijiroro won.
Ninu ọrọ to sọ lorukọ awọn ẹgbẹ naa, alaga apapọ, JOHESU, Bio Josiahrọ minisita keji fun ọrọ oṣiṣẹ, Festus Keyamọ SAN lati kewaju ijiroro naa dipi Chris Ngige to n ṣe kokaari rẹ tẹlẹ
Lara awon ẹdun ọkan awọn oṣiṣẹ naa ni sisan aṣẹku owo ajẹmọnu oo asiko ajakalẹ arun COVID-19 fun awọn oṣiṣẹ naa ni ileewosan ijoba apapọ eleyii ti wọn ni o jẹ ida mẹwaa dipo ida ọgọta ninu ọgọrun ti o jẹ adehun ẹgbẹ oṣiṣẹ naa ati ijoba.
Bakan naa lo ke s'awọn ijobaipinlẹ ati ibilẹ ti wọn ko tii bẹrẹ si nii ṣe iṣẹ lori sisan owo ajẹmonu asiko ajakalẹ arun COVID-19 lati bẹrẹ si nii san an lẹyẹ o ṣọka.
Ki lo ti ṣẹlẹ sẹyin?
Oríṣun àwòrán, others
Ẹgbẹ awọn dokita ni Naijiria ti bẹrẹ iyanṣẹlodi loni ọjọ aje.
Ẹgbẹ naa ni igbesẹ yii ko ṣẹyin bi ijọba apapọ ko ṣe mu adehun ṣẹ lori awọn ohun ti wọn jọ fẹnuko le lori.
National Association of Resident Doctors (NARD) ṣalaye pe lati osu kẹfa ni wọn ti ṣepade pẹlu ijọba apapọ lori igbesẹ yii.
Temitope Akinnusi: Ọ̀pọ̀ iléeṣẹ́ ló takú láti gbà mí síṣẹ́ torí mo ní ojú kan
O to ida ogoji dokita Naijiria to wa ninu ẹgbẹ yii ti wọn n beere fun ẹkunwo owo oṣu, itọju to peye lẹnu iṣẹ, atunṣe to yẹ si awọn ile iwosan Naijiria paapaa lasiko Coronavirus yii
Aarẹ ẹgbẹ yii, Dokita Aliyu Sokomba sọ fun ileeṣẹ iroyin AFP pe awọn dokita to n tọju alaisan coronavirus naa yoo darapọ mọ wọn lasiko yii laiyọ ẹnikẹni silẹ
Ki lo ti ṣẹlẹ sẹyin?
Oríṣun àwòrán, others
Ẹgbẹ awọn dokita nileeẹkọṣẹ iṣegun gbogbo lorilẹede Naijiria, NARD ti kede pe awọn yoo bẹrẹ iyanṣẹlodi ọlọjọgbọọrọ bẹrẹ lati ọjọ Aje, ọjọ keje oṣu kẹsan ọdun 2020.
Ninu atẹjade kan ti ẹgbẹ naa fi sita lẹyin ipade igbimọ iṣakoso rẹ lo ti kede yii.
Wọn ni lai jẹ pe ijọba gbe igbesẹ lori awọn ẹdun ọkan wọn ti wọn gbe ka iwaju ijọba awọn yoo tẹsiwaju lori igbesẹ naa.
Lara awọn ohun to fa ẹhonu naa ni sisan owoona fun eto dokita abẹnu nileeṣẹ ẹkọṣẹ iṣegun Residency funding, owo gba ma binu fun ajakalẹ arun COVID-19, sisan owo ewu ẹnu iṣẹ (hazard allowance) pẹlu owo ajẹẹlẹ owo osu ọdun 2014, 2015 ati 2016.
Awọn dokita naa ti kọkọ lọ fun iyanṣẹlodi onikilọ ọlọjọ mẹkanlelogun lati fi fa ijọba leti ṣugbọn ti ko si ọrọ kankan latọdọ ijọba titi di bi a ṣe n sọrọ yii.
Oríṣun àwòrán, others
Èèmọ̀! Ọmọbìnrin ọdún 25 gún ọ̀rẹ́kùnrin rẹ̀ pa nítorí ó ní ko lọ ṣẹ́ oyún
Oríṣun àwòrán, Other
Esio! Kinni ọrọ ifẹ ti wa da bayii?
Ọmọbinrin ọdun mẹẹdọgbọn kan ni iroyin sọ pe o gun ọrẹkunrin rẹ pa lẹyin ti o sọ fun un pe ki o lọ ṣẹ oyun to wa ninu rẹ.
Onyinye Chime tako ọrẹkunrin rẹ Eleyi Azubuike wi pe ko si ohun to jọọ bẹẹ ki ọrọ to bẹyin yọ.
Iṣẹlẹ yii ṣẹlẹ ni Nkpor, lẹba ilu Onitsha, ni ijọba ibilẹ Idemili ipinlẹ Anambra lapa ila oorun orilẹede Naijiria.
Agbẹnusọ fun ileeṣẹ ọlọpaa ipinlẹ Anambra, Haruna Mohammed lo fidi iṣẹlẹ ọhun mulẹ.
Ileeṣẹ ọlọpaa ni iroyin to tẹ awọn lọwọ sọ pe ninu yara ni Oyinye ti gun Azubuike ọrẹkunrin pa.
Ohun ti a gbọ ni pe Azubuike to jẹ ọmọ ọdun mọkandinlọgbọn kọ lati fun Onyinye lowo lati ṣẹ oyun inu rẹ ati fun itọju ara rẹ lo fa aawọ laarin wọn.
Àṣìṣe ọlọ́pàá àti Adájọ́ sọ mí di ẹni tí wọ́n dájọ́ ikú fún, ọpẹ́lọpẹ́ Fayoṣe tí ko buwọlu
Ẹnikan to mọ nipa ọrọ naa sọ fawọn akọroyin pe lootọọ ni Onyinye fi ẹjọ Azubuike sun awọn kan, amọ ko si ẹni to mọ pe o le gun ọrẹkunrin rẹ lọbẹ.
IIeeṣẹ ọlọpaa awọn agbofinro gbiyanju lati gbe Azubuike lọ si ile iwosan amọ ọwọ ti bọ sori ki wọn to de ibẹ.
Baby abandoned on dunmpsite: Mo ti bímọ mẹ́rin tẹ́lẹ̀ fún bàbá méjì nínú òṣí- Dupe Ogbomos
Ileeṣẹ ọlọpaa sọ pe apa oju ọbẹ wa lara oku Azubuike, ati pe wọn ri ọbẹ gba nibi ti iṣẹlẹ ọhun ti ṣẹlẹ.
Agbẹnusọ ileeṣẹ ọlọpaa ni iwadii si n lọ lọwọ lori lori ati mọ wulẹwulẹ iṣẹlẹ naa.
Suspected ritual killer: Ọwọ́ tẹ afurasí olóògùn owó tó fẹ́ gé ọmú obìnrin nílé ìtura
Oríṣun àwòrán, Other
Ọwọ ileeṣẹ ọlọpaa ipinlẹ Anambra ti tẹ ọkunrin afurasi kan to fẹ ge ọmu obinrin kan nile ituru ni ijọba ibilẹ Orumba nipinlẹ̀ Anambra.
Alukoro ileeṣẹ ọlọpaa ipinlẹ Anambra, Haruna Mohammed, to fidi ọrọ naa mulẹ ṣalaye pe kọmiṣọnna ọlọpaa nipinlẹ naa ti ni ki ẹka ileeṣẹ ọlọpaa to n ri si ọrọ ọdaran bẹrẹ iwadii kikun lọri iṣẹlẹ naa.
Mohammed sọ fawọn akọroyin pe ọkunrin kan to wa nile itura ọhun, Ogbonna Nwankwo lo ta ileeṣẹ ọlọpaa lolobo iṣẹlẹ naa.
Alukoro fun ileeṣẹ ọlọpaa ni afurasi ọhun gbiyanju lati pa obinrin naa ninu iyara ti wọn jọ wa lẹyin to gun un lọbẹ ni ikun.
''O gbiyanju lati ge ọmu apa ọtun obinrin naa eyi ti ọpọ gbagbọ pe o fẹ fi ṣe oogun ni, ṣugbọn aṣiri tu lẹyin tawọn to wa nile itura naa gbọ ariwo obinrin ọhun lati inu yara,'' agbẹnusọ ọlọpaa ṣalaye.
Àṣìṣe ọlọ́pàá àti Adájọ́ sọ mí di ẹni tí wọ́n dájọ́ ikú fún, ọpẹ́lọpẹ́ Fayoṣe tí ko buwọlu
Ariwo obinrin yii ni oludari ile itura naa gbọ ki awọn agbofinro to mu un.
Awọn ọlọpaa naa lo gbe obinrin ọhun ti apa wa lara rẹ lọ si ile iwosan fun itọju niluu Nnewi.
Baby abandoned on dunmpsite: Mo ti bímọ mẹ́rin tẹ́lẹ̀ fún bàbá méjì nínú òṣí- Dupe Ogbomos
Bakan naa ni ileeṣẹ ọlọpaa gbe afurasi afiniṣowo naa lọ si ile iwosan lẹyin tawọn eeyan ti lu u ni alubami.
Ileeṣẹ ọlọpaa ni awọn ri ọbẹ nibi ti iṣẹlẹ naa ti ṣẹlẹ.
Petrol Price Hike: Ilé aṣojú-ṣòfin dúró ìṣẹ́jú kan fún Buruji Kashamu àti Rose Okoh
Oríṣun àwòrán, @SpeakerGbaja
Ile igbimọ asoju sofin Naijiria ti rọ ijọba apapọ, lati tẹle adehun ti wọn ṣe pẹlu ẹgbẹ oṣiṣẹ, eyi to mu ki wọn ṣẹwele ipinu lati gunle iyansẹlodi ati ifẹhonu han.
Awọn ọmọ ile igbimọ asoju sofin l'Abuja sọ eyi di mimọ, lẹyin ti wọn wọle pada lẹyin isinmi oloṣu meji ti wọn gunle, fun isinmi ọdọdun ti wọn maa n ṣe.
Ijoko ile naa, ti abẹnugan ile Femi Gbajabiamila dari, salaye pe, o ṣe pataki ki ijọba apapọ tẹle adehun ti awọn ati ẹgbẹ oṣiṣẹ se ti wọn fi wọgile ipinu wọn lati bẹrẹ iyanṣẹlodi to yẹ ko bẹrẹ lọjọ aje.
Oríṣun àwòrán, @SpeakerGbaja
O ni ninu ifọrọwerọ wọn, ijọba apapọ ṣe adehun fawọn ẹgbẹ oṣiṣẹ ati ọmọ Naijiria lapapọ, eyi ti wọn si gbọdọ tẹle.
O fi kun le pe, bi wọn ba ṣe n tẹle adehun yii ko gbọdọ pa gbogbo akitiyan ijọba lara, lati ṣe gbogbo eto amuludun ti wọn ti n pinu lati ṣe tẹlẹ tabi eyi ti wọn n ṣe lọwọ.
Bakan naa ni abẹnugan ile tun ka iwe ẹbẹ aarẹ, to n bere fun ibuwọlu ile lati san idapada owo fun awọn ipinlẹ marun kan, lori awọn opopona ti wọn ṣe lati inu apo ijọba ipinlẹ wọn.
Oríṣun àwòrán, @SpeakerGbaja
Ile igbimọ asofin ninu ijoko ile ṣe idakẹ jẹ iṣẹju kan, fun awọn ọmọ ile igbimo asofin agba meji to papoda, sẹnatọ Rose Okoh ati Buruji Kashamu.
Gbajabiamila ni fun igba akọkọ ninu itan ile igbimọ asofin, ile igbimọ asofin n lo ẹrọ igbalode ti awọn eniyan le ma fi wo ijoko ile loju ẹsẹ.
O ni araalu yoo tun lanfaani lati maa wo bi ijororo ile ati gbogbo idibo yoo se maa waye, bakan naa ni yoo maa lọ si ipamọ fun itan ọjọ iwaju.
Oríṣun àwòrán, @NLCHQ_ABUJA
Saaju la ti mu iroyin wa fun yin pe, ajọ to n se akoso ina ọba ni Naijiria, NERC ti ni, awọn yoo tẹle aṣẹ ijọba apapọ lati da owo ina ọba pada si bo ṣe wa tẹlẹ, ki wọn to fi owo le.
Ajọ NERC fi idi ọrọ naa mulẹ lasiko ti wọn fesi si ikede ijọba to mu ki ẹgbẹ oṣiṣẹ fagile iyanṣẹlodi ti wọn fẹ bẹrẹ ni Ọjọ Aje.
NERC ni awọn ti gbọ gbogbo ohun ti ijọba pa laṣẹ, amọ awọn nilo asiko lati gbeyẹwo, lori bi adinku yoo se ba ina ọba laarin ọsẹ meji.
Ajọ naa fikun pe, gbogbo igbesẹ to ba tọ ni oun yoo gbe, lọna ati tẹle ofin ti ijọba apapọ pa laṣẹ fun wọn.
Ọpọlọpọ ọmọ Naijiria lo fẹhọnu han lẹyin ti ajọ Amunawa lorilẹede Niajiria gbe owo le ina ọba, ti ẹkunwo naa si tun ba owo epo bẹntirol lasiko kan naa.
Obateru Akinruntan: Wíwá ohun tá jẹ títí láé ló gbé wa kúrò nílé Ife
Eyi lo mu ki ẹgbẹ awọn oṣiṣẹ tiraka lati gunle iyanṣẹlodi, amọ wọn gbegile iyanṣẹlodi naa lẹyin ti ijọba paṣẹ pe ki ina ọba pada si bo ṣe wa tẹlẹ ki wọn to fi owo kun un.
Ibanujẹ ọkan lo jẹ fun mi bi ẹgbẹ NLC ṣe wogile iyanṣẹlodi - NLC Eko
Alaga ẹgbẹ oṣiṣẹ nipinlẹ Eko, Comrade Agnes Funmi-Sessi, ti bu ẹnu atẹ lu bi ẹgbẹ oṣiṣẹ lapapọ, NLC, ṣe paṣẹ pe ki wọn gbegile iyanṣẹlodi ti wọn fẹ gunle ni Ọjọ Aje, tako ọwọn gogo epo bẹntirol ati ina ọba.
Comrade Funmi-Sessi lasiko to n ba BBC Yoruba sọrọ ni ohun ti ijọba apapọ n ṣe ni lati pana iyanṣẹlodi naa lasiko yii.
Oríṣun àwòrán, @NLCHQ_ABUJA
O ni ibanujẹ ọkan lo jẹ fun oun wi pe, awọn adari NLC gbọ si ijọba lẹnu nitori awọn eniyan ti mura silẹ lati bẹrẹ iyanṣẹlodi tako ọwọngogo naa.
Amọ, Alaga ẹgbẹ oṣiṣẹ nipinlẹ Eko naa ni, awọn ko le e ṣe ohunkohun lẹyin aṣẹ ti awọn adari oṣiṣẹ pa fun wọn, nitori naa ni awọn ṣe pana iyanṣẹlodi ohun.
Awọn oṣiṣẹ nipinlẹ Eko ti gbaradi lati ṣewode ati iyanṣẹlodi kaakiri ipinlẹ naa loni, amọ awọn adari wa ti gbabọde fun wa""."
Adura wa ni wi pe, ki ẹgbẹ oṣiṣẹ ma doju ti awọn ọmọ Naijiria, pẹlu igbesẹ ijọba lori ọwọn gogo owo epo bẹntirol ati ina mọnamọna.
Ti ọsẹ meji ba pe, ti ko si si aṣeyọri kankan, awọn ọmọ Naijiria ko ni da wa loun mọ, ti a ba pe wọn fun iyanṣẹlodi tabi ifẹhọnu han..
Oríṣun àwòrán, @NLCHQ_ABUJA
Nibayii, Comrade Funmi -Sessi ni awọn ko i tii mọ ohun to kan gẹgẹ bi oṣiṣẹ, amọ awọn n duro de aṣẹ ẹgbẹ NLC, lori ohun to kan lẹyin ti wọn ti wọgile iyanṣẹlodi naa.
Ẹgbẹ awọn oṣiṣẹ lorilẹede Naijiria, Nigeria Labour Congress ati akẹẹgbẹ rẹ, Trade Union Congress, ti fagile iyanṣelodi ọlọjọ gbọọrọ to yẹ ko bẹrẹ loni.
Eyi ko ṣẹyin abajade ipade pajawiri ti ijọba apapọ ati awọn oṣiṣẹ ṣe lati aago mẹjọ alẹ Ọjọ Aiku, titi di afẹmojumo Ọjọ Aje, ti o yẹ ki iyanṣẹlodi naa bẹrẹ.
Oríṣun àwòrán, @NLCHQ_ABUJA
Lẹyin ijiroro fun ọpọlọpọ wakati, ni ijọba paṣẹ ki iye owo ti awọn eniyan n san lori owo ina ọba pada si bo ṣe wa tẹlẹ fun ọsẹ meji.
Minisita fun ọrọ iṣẹ ati igbanisiṣẹ, Chris Ngige to soju ijọba lo ka abajade ipade naa.
Oríṣun àwòrán, @NLCHQ_ABUJA
Ninu ọrọ ti wọn, ẹgbẹ oṣiṣẹ ni awọn gbegi le iyanṣẹlodi naa fun ọṣẹ meji, lati fun ijọba apapọ laaye lati gbe igbesẹ to yẹ fun awọn oṣiṣẹ.
NLC ni awọn igbesẹ ijọba naa gbọdọ fun awọn osisẹ ni igbe aye irọrun, ki wọn si da awọn ohun to wọn gogo pada si bi o ṣe wa tẹlẹ.
"Laarin ọsẹ meji naa ni ajọ to n risi ọrọ ina oba, DISCOs,  yoo fi wọgile owo ina oba ti o ti da owon gogo yii'
Bakan naa ni ijọba fikun pe, wọn n gbe igbesẹ lati ma a ṣe iranwọ fun awọn oṣiṣẹ nipa owo ọkọ, owo ina ọba, owo ile gbigbe, eto ọgbin ati awọn owo iranwọ miran.
Ijọba fikun wi pe, wọn yoo pese ọkọ ti yoo ma gbe awọn eniyan kaakiri ni awọn ilu nla ni orilẹede Naijiria, to fi mọ igberiko, ki ọdun 2021 to pari.
Bakan naa ni awọn oṣiṣẹ ijọba yoo ni anfaani si ida mẹwaa ninu ile igbe ti ijọba apapọ n kọ kaakiri.
Awọn to wa nibi ipade naa ni Aarẹ ẹgbẹ oṣiṣẹ, Ayuba Wabba ati akẹgbẹ rẹ ni ẹgbẹ TUC, Quadri Olaleye.
Bakan naa ni Minisita fun ọrọ oṣiṣẹ, Chris Ngige; Minisita fun ọrọ epo bẹntirol, Timipre Silva; Festus Keyamo (SAN) wa nibi ipade naa.
Obateru Akinruntan: Wíwá ohun tá jẹ títí láé ló gbé wa kúrò nílé Ife
Ko tan sibẹ o, Minisita fun ọrọ iroyin, Lai Mohammed ati akọwe ijọba apapọ, Boss Mustapha naa bawọn peju sibẹ pẹlu.
Yoruba bọ, wọn ni ka wi fun ni ka to da ni, agba ijankadi.
Eyi lo jẹ ki ileeṣẹ ọlọpaa Naijiria kilọ fawọn ẹgbẹ oṣiṣẹ NLC ati TUC to fẹ gunle iyanṣẹlodi lọla ọjọ Aje lori afikun owo ina ọba ati epo bẹntiro.
Alukoro ileeṣẹ ọlọpaa, Frank Mba ti sọ pe, oṣiṣẹ to ba jade lati ṣe iwọde lọjọ yoo foju wina ofin.
O ni wamuwamu lawọn ọlọpaa n duro de awọn oṣiṣẹ to ba fẹ ṣe iwọde, awọn yoo si se ohun to tọ labẹ ofin.
Oríṣun àwòrán, Facebook/Nigeria Police Force
Alukoro ileeṣẹ ọlọpaa sọ fawọn akọroyin pe, ọrọ oun ko ju bayii lọ lori erongba ẹgbẹ awọn oṣiṣẹ lati gunle iyanṣẹlodi lọla.
Ṣugbọn awọn agbẹjọro kan ni ileeṣẹ ọlọpaa ko lagbara labẹ ofin lati da ẹgbẹ awọn oṣiṣẹ duro pẹlu iwọde ti wọn fẹ ṣe.
Agbẹjọro agba, Chino Obiagwu sọ pe, ko lẹtọ labẹ ofin fun ileeṣẹ ọlọpaa lati gba iṣẹ ileẹjọ ṣe, nipa dida awọn oṣiṣẹ duro pẹlu iwọde ti wọn fẹ ṣe.
Amofin Obiagwu ṣalaye pe, lootọọ ni ileẹjọ to n ri si ọrọ osisẹ paṣẹ pe ki ẹgbẹ osisẹ mase gunle iynaṣẹlodi ṣugbọn ileẹjọ ko ni ki wọn maa ṣe iwọde.
Oríṣun àwòrán, @NLCHeadquarters
O ni ọrọ to wa nilẹ kii ṣe ọrọ iwa ọdaran ti ọlọpaa le da si, ọrọ iṣẹ ni.
Agbẹjọro Obiagwu ni, to ba wu ijọba apapọ, o le lọ si ileẹjọ ti o ba ro pe awọn oṣiṣẹ ti tapa si ofin, amọ ọrọ naa ko kan ọlọpaa rara.
Ẹwẹ, olori awọn oṣisẹ lorilẹede Naijiria, Ọmọwe Folasade Yemi-Esan tẹlẹ ti rọ awọn oṣiṣẹ jake jado Naijiria pe ki wọn ma ṣalai lọ sibi iṣẹ lọjọ Aje.
Yemen Water Child: Ọmọdé 44 ni Sọ́jà pa, tí 100 míì sì kú látọwọ́ ohun ìjà olóró
Ẹ̀yin òṣìṣẹ́, ẹ má ṣáì lọ síbi iṣẹ́ lọ́jọ́ Ajé, olórí àwọn òṣìṣẹ́ ní Nàìjíríà tako ìyanṣẹ́lódì
Olori awọn oṣisẹ lorilẹede Naijiria, Ọmọwe Folasade Yemi-Esan ti rọ awọn oṣiṣẹ jake jado Naijiria pe ki wọn ma ṣalai lọ sibi iṣẹ lọjọ Aje.
Amọran yii waye lẹyin ti ẹgbẹ apapọ awọn oṣiṣẹ ni naijiria kede pe iyanṣẹlodi yoo bẹrẹ lọjọ Aje lati fi ẹhonu han lori bi ijọba apapọ ti ṣe afikun owo ina ọba ati epo bẹntiro.
Oríṣun àwòrán, Twitter/@eniola esan
Ọmọwe Yemi-Esan rọ awọn oṣiṣẹ papaa julọ awọn to wa nipele kejila lọ soke atawọn oṣiṣẹ ko ṣee maa ni lati lọ sẹnu iṣẹ wọn lọjọ Aje.
Olori awọn oṣisẹ ni Naijiria ṣalaye pe ijọba apapọ ṣi n jiroro lọwọ pẹlu ẹgbẹ awọn oṣiṣẹ lori ohun ti wọn fẹ ki ijọba ṣe gan an.
Ọmọwe Yemi-Esan tun sọ pe aṣẹ ti ileẹjọ to n ri si ọrọ awọn ile iṣẹ ni Naijiria l'Ọjọbọ ti sọ pe ẹgbẹ oṣiṣẹ ko le gunle iyanṣẹlodi mọ lọjọ Aje.
O wa rọ gbogbo awọn akọwe agba atawọn adari ẹka ileeṣẹ ijọba lati sọ fawọn oṣiṣẹ to wa labẹ wọn pe ki wọn rii pe awọn oṣiṣẹ lọ sibi iṣẹ lọjọ Aje to n bọ.
SS3 ní mo wà báyìí, mo sì ti gba àmì ẹ̀yẹ̀ púpò nílé-lóko gẹ́gẹ́ bí onílù - Ayansike
Kò sí iléẹjọ́ tó le dá wa dúró, ìyanṣẹ́lódì yóò bẹ̀rẹ̀ ní Ọjọ́ Ajé - NLC
Ẹgbẹ oṣiṣẹ lorilẹede Naijiria, NLC ti ni dandan awọn yoo tẹsiwaju ninu iyanṣẹlodi ti awọn fẹ gunle bẹrẹ lati Ọjọ Aje, ọsẹ to n bọ.
Ọkan lara awọn adari ẹgbẹ awọn oṣiṣẹ naa lo sọ fun BBC News Hausa pe awọn ko i tii ri iwe ipẹjọ ileẹjọ kankan to sọ wi pe ki awọn ma gunle iyanṣẹlodi.
Bakan naa ni ẹgbẹ oṣiṣẹ naa fikun wi pe awọn naa ni atilẹyin ileẹjọ lati tẹsiwaju ninu iyanṣẹlodi tako ọwọngogo owo epo bẹnitirol ati ina ọba.
Amọ, ileẹjọ kan ni ilu Abuja ti pasẹ ki ẹgbẹ oṣiṣẹ dawọ iyanṣẹlodi wn duro titi di igba ti awọn ma a gbọ ẹjọ ti ajọ kan pe mọ ẹgbẹ oṣiṣẹ NLC.
Adajọ Ibrahim Galadima gbe igbeṣẹ naa lẹyin ti Ajọ Peace and Unity Ambassadors Association pe fun ki ẹgbẹ NLC jawọ ninu iyanṣẹlodi ti wọn fẹ gunle ni ọjọ Aje.
Bakan naa ni ileẹjọ ohun pàṣẹ ki ẹgbẹ NLC ma di awọn ọmọ Naijiria lọwọ lati ṣe iṣẹ oojọ wọn.
Ileẹjọ naa tun paṣẹ fun Ọga Agba Ọlọpaa ati adari ẹsọ alaabo lati ri wi pe awọn oṣiṣẹ ni aabo to daju lasiko ti wọn ba n ṣiṣẹ wọn tako aṣẹ NLC.
Amọ, ẹgbẹ oṣiṣẹ NLC ti ni gbogbo ọmọ Naijiria ni yoo kopa ninu iyanṣelodi yii nitori gbogbo ọmọ Niajiria lo n jẹ irọra bi wọn ṣe fikun owo epo ati ina ijọba ni Naijiria.
NLC ni owo oṣu oṣiṣẹ ti da radarada nitori ọwọngogo to gun owo epo, ina ọba, ati ounjẹ kaakiri Naijiria.
Ẹgbẹ awọn oṣiṣẹ lorilẹede Naijiria,NLC ti kede wi pe awọn yoo bẹrẹ iyanṣẹlodi ati ifẹhọnuhan kaakiri orilẹede Naijiria bẹrẹ lati Ọjọ Ajẹ, ọsẹ to n bọ.
Adari ileeṣẹ ẹgbẹ awọn oṣiṣẹ NLC ni ipinlẹ Eko, Onyeka Chris lọ sọ bẹẹ fun BBC News Yoruba lasiko to n sọrọ lori igbaradi wọn fun ifẹhọnuhan ọlọgọọrọ naa.
Chris ni awọn oṣiṣẹ darapọ mọ awọn ọmọ Niajiria to ku kaakiri lati tako igbesẹ ijọba to fi owo kun owo epo ati ina ọba naa.
O ni igbesẹ ijọba yii fihan wi pe ko ye wọn ohun ti awọn ọmọ Naijiria n la kọja kaakiri orilẹede Niajiria.
Ẹgbẹ oṣiṣẹ NLC ni awọn tẹlẹ gbogbo igbesẹ to yẹ lati ri wi pe ijọba yi ipinnu wọn pada ko to di asiko yii.
Amọ, ijọba ko fun wọn ni esi lori gbogbo lẹta ati iwe ti awọn fi ranṣẹ si ijọba ko to di wi pe awọn gbe igbesẹ lati ṣe ifẹhọnuhan ati iyanṣẹlodi tako igbesẹ ijọba.
Toyin Atoyebi mechanic: Ẹ wo Toyin, ọmọbinrin ọdún 16 tó ń tún skadà àti gẹnẹrátọ̀ ṣe ní
NLC ni awọn tele ilana ati alakalẹ ti o ṣe koko ki awọn to gunlẹ iyanṣelodi ni ko jẹ ki awọn tete bẹrẹ ifẹhọnuhan di asiko yii.
Gbogbo ẹgbẹ oṣiṣẹ ijọba, awọn oniṣẹ ọwọ, awọn ọdọ, awọn adari ẹgbẹ akẹkọọ lo parapọ sọ wi pe ki iyanṣẹlodi yii tẹsiwaju.
Ẹgbẹ oṣiṣẹ NLC ti ni gbogbo ọmọ Naijiria ni yoo kopa ninu iyanṣelodi yii nitori gbogbo ọmọ Niajiria lo n jẹ irọra bi wọn ṣe fikun owo epo ati ina ijọba ni Naijiria.
NLC ni owo oṣu oṣiṣẹ ti da radarada nitori ọwọngogo to gun owo epo, ina ọba, ati ounjẹ kaakiri Naijiria.
''Owo osu N30,000 ti da N9 nitori owongogo ti ba ounjẹ ti ko si ṣe e ra mọ.''
Akomolede àti Aṣa: Ọ̀rọ̀ Ẹ̀yán ni Bunmi Femi Amao ń kọ́ wa lórí ètò Akọ́mọlédè àti Àṣà lóri BBC Yoruba
''Ohun to buruju ni wi pe awọn oloṣelu to fi owo kun owo epo, ina ọba kii san owo kankan lati ra nkan wọnyii, ọfẹ ni wọn n rii lọ''.
''Mẹkunu ti ko ni iṣẹ, ti oun jẹ iya ni igbesẹ ijọba n fi aye ni lara.''
''Titi da igba ti ijọba ba da owo epo ati ina ọba pada si bo ṣẹ wa tẹlẹ ni awọn yoo to jawọ ninu iyanṣẹlodi naa.''
Bakan naa ni wọn fikun wi pe ileeṣẹ kankan ko ni ṣi, awọn ileepo ko ni ṣi, ojuko iwapo, ileewosan, ileeṣẹ ijọba, ileeṣẹ ofurufu ati bẹẹ lọ ni yoo darapọ.
Ẹgbẹ awọn oṣiṣẹ lorilẹede Niajiria, NLC ti ni awọn ko gbero lati ṣe ifẹhọnuhan tako owongogo bẹntirol ati ina mọnamọna.
Igbakeji adari ẹgbẹ NLC lorilẹede Naijiria, Comrade Joe Ajaero lo fi ọrọ naa lede lasiko to n ba BBC News Yoruba sọrọ lori boya ifẹhọnu han yoo waye ni ọjọ Isẹgun, Ọjọ Kẹjọ, Oṣu Kẹsan, ọdun 2020.
Eyi ko ṣẹyin iroyin to n tan kaakiri pe ẹgbẹ oṣiṣẹ yoo bẹrẹ ifẹhọnuhan tako bi ijọba apapọ ṣe fi owo kun owo epo bẹntirol.
Comrade Joe ni awọn ko i tii fun ọmọ ẹgbẹ awọn ni aṣẹ kankan lati bẹrẹ ifẹhọnu han.
Oríṣun àwòrán, @NLCHQ_ABUJA
O ni ifẹhọnu ti awọn fẹ ṣe ni Ọjọ Iṣẹgun ni lati dẹkun ifiyajẹni to n waye ni ipinlẹ Rivers.
Ẹgbẹ NLC ni ijọba n fi iya jẹ awọn oṣiṣẹ ni ipinlẹ Rivers, ti wọn ti lẹ n na lara wọn nitori wọn n bere fun ẹtọ wọn.
Bakan naa ni wọn fikun wi pe lati igba ti ijọba apapọ ti n gbimọ rẹ ni awọn ti bẹrẹ si ni tako igbeṣẹ naa.
Nibayii, NLC ni awọn ti bẹrẹ ijiroro pẹlu ijọba lati yi igbeṣẹ naa pada.
Amọ, ẹgbẹ oṣiṣẹ NLC fikun pe awọn yoo gunle iyanṣelodi ti ijọba ba kọ lati gba ero wọn ro, abi ti wọn ni dandan awọn yoo tẹsiwaju pẹlu owongogo owo epo bẹntirol ati ina mọnamọna naa.
Ninu ọrọ tirẹ, Aarẹ orilẹede Naijiria, Muhammadu Buhari ni idi ti oun fi gbe igbesẹ naa ni lati fi opin si iwa jẹgudujẹra ni ẹka mejeeji, ki idagbasoke ba a le ba ọrọ ajẹ ni Niajiria.
Yoruba ni awifuni ko to da ni, agba ijakadi ni, bẹẹ si ni ogun awitẹlẹ kii pa arọ, eyiun arọ to ba gbọn.
Agbarijọpọ ẹgbẹ awọn osisẹ ni Naijiria, NLC ati TUC ti n leri leka pe ọjọ isẹgun yoo ro lorilẹede Naijiria.
Idi ni pe awọn ẹgbẹ osisẹ mejeeji yii ti n palẹ ogun mọ lati gbena woju ijọba apapọ lori alekun owo eroja epo rọbi to se.
Awọn ẹgbẹ osisẹ naa ni awọn yoo gun le iwọde lati tako ele owo ori epo naa, bẹẹ ni awọn ti n se koriya ati itaniji fawọn osisẹ lati kopa ninu iwọde naa.
Baby abandoned on dunmpsite: Mo ti bímọ mẹ́rin tẹ́lẹ̀ fún bàbá méjì nínú òṣí- Dupe Ogbomos
Amọ awọn eeyan kan ti n kede loju opo ayelujara pe ileẹjọ kan ti da awọn ẹgbẹ osisẹ ọhun lọwọkọ lati mase gunle iwọde ti wọn n gbero naa.
Nigba to n ba awọn akọroyin sọrọ lori ikede ile ẹjọ naa, igbakeji aarẹ fun ẹgbẹ TUC, Chika Onuegbu sisọ loju rẹ pe, awọn ko tii ri iwe kankan gba lati ile ẹjọ to tako iwọde ti awọn n gbero yii.
Onuegbu ni Lọwọ lọwọ, awa si n ko awọn ọmọ ẹgbẹ wa jọ lati fi ẹhonu han lori owo tijọba fikun owo epo, eyi to n nipa to ko dara lori awọn osisẹ nilẹ yii."
"Bakan naa ni wọn tun fi owo kun owo ina ọba lasiko kannaa, to fi mọ owo ori awọn ọja gbogbo, eyi to nipa buruku lori owo ounjẹ atawọn ohun eelo fun igbaye-gbadun gbogbo osisẹ."""
O fikun pe lasiko ti ọwọn ọja n waye yii, nijọba tun jẹ awọn osisẹ kan lowo osu, owo ifẹyinti ati owo ajẹmọnu ifẹyinti lẹnu isẹ, eyi ti ko wu eti gbọọ rara.
Awọn ẹgbẹ osisẹ naa wa kesi ijọba apapọ lati da owo epo pada si iye to wa tẹlẹ bibẹẹ kọ, awọn yoo korajọ lati fi ẹhonu to lagbara han ni Naijiria.
Awọn eeyan niluu Osogbo tii ṣe olu-ilu ipinlẹ Oṣun ṣe ifẹhonuhan lori afikun owo epo bẹntiroo ti ijọba apapọ ṣẹṣẹ kede rẹ.
Ẹgbẹ kan to n jẹ The Osun Civil Societies Coalition (OCSC) lo ṣagbatẹru ifẹhonahan naa.
Laarọ ọjọ Ẹti lawọn eeyan peju pesẹ si Nelson Mandela Freedom Park, l'Osogbo, lati fi aidunnu wọn han si igbẹsẹ ijọba lati sọ epo jala di naira mọkanlelọgọta.
Ọpọ awọn olufẹhonuhan lo gbe beeba lọwọ eyi ti wọn kọ oriṣiiriṣii ọrọ sii bi ''awa o faramọ afikun owo epo''(NO TO FUEL PRICE INCREMENT), ''O TO GẸẸ''(ENOUGH IS ENOUGH) ati bẹẹ lọ.
Minisita abẹle fun epo rọbi, Timipre Marlin Sylva ti kọkọ ṣalaye pe owo iranwọ ti ijọba ko fi si ori epo mọ lo jẹ ki ayipada maa ba iye tawọn ọmọ Naijiria n ra epo looreekooree.
Russia Covid 19 Vaccine: Nàìjíríà ṣetán àjọṣepọ̀ pẹ̀lú Russia lórí ìpèsè abẹ́rẹ́ àjẹsára
Oríṣun àwòrán, @Fmohnigeria
Ijọba orile-ede Naijiria ti fifẹ han lati ṣe amulo abẹrẹ ajẹsara Sputnik V ti orile-ede Russia n ṣeto lati koju arun Covid -19.
Lasiko ipade kan ti awọn alaṣẹ ileeṣẹ to n mojuto eto ilera Naijiria ṣe pẹlu aṣoju ilẹ Aṣoju Russia si Naijiria ni ọrọ yii ti jẹyọ.
Ninu ipade yi ni Minisita feto ilera Dokita Osagie Ehanire wa pẹlu Alexey L. Shebarshin lati Russia.
Gẹgẹ bi ohun ti ileeṣẹ ilera fi soju opo Twiter wọn, ''Naijiria n wa gbogbo imọ nipa itọju ati abẹrẹ ajesara lati koju arun yii''
Ileeṣẹ naa tun sọ pe awọn nifẹ si ibaṣepọ pẹlu Russia eyi ti yoo mu ajọsepo to gunrege wa.
Adebimpe Adebiyi to jẹ ọga ẹka ile iwosan ileeṣẹ ilera sọ pe  anfaani nla re fun Naijiria lati fikun agbara ipese abẹrẹ ajẹsara wọn.
Ninu awọn ohun ta ri ka loju opo Twitter wọn, ileeṣẹ ilera ko sọ pato boya awọn ti gba abẹrẹ ajẹsara ti wọn n pe orukọ rẹ nui Sputnik lọwọ Russia.
Baby abandoned on dunmpsite: Mo ti bímọ mẹ́rin tẹ́lẹ̀ fún bàbá méjì nínú òṣí- Dupe Ogbomos
Makurdi Church theft: Àga oníke mẹ́wàá ní wọ́n kọ́kọ́ ni Joseph jí tó fi di èrò ẹ̀wọ̀n ní NASME Barracks ní Benue
Oríṣun àwòrán, others
Ọkùnrin ẹni ọdun marunlelogun kan,  Joseph Ada ti NASME Barracks ni Makurdi ti foju bale ẹjọ majisireeti fun ẹsun ole jija, igbimọ iwa ọdaran.
Ọlọpaa to wa nidi ẹjọ naa, Sajẹnti Regina Ishaya sọ fun ile ẹjọ pe, Arabinrin Myina Ifeyunwa lo mu ẹjọ naa wa si agọ ọlọpaa  'D' Division ni Markudi ni ogunjọ, oṣu kẹjọ, ọdun 2020.
Olufisun ọ̀hún ni oun gba ipe lati ọdọ Ebenezer pe ẹnikan ti oun ko mọ ri jalẹkun wọ ile ijọsin Holy Ghost Sanctuary to je ti 'Penticostal' kan ni agbegbe Vita Foam, opopona oja tuntun ni Makurdi.
Akomolede ati Aṣa lori BBC: Mọ̀ si nípa oríṣìí ẹ̀ka ìsọ̀rí ọ̀rọ̀ àti ìwúlò wọn
O ni àwọn mu ẹni ti wọn fẹsun.kan naa pẹlu aga onike mẹwaa to jẹ ti ijọ naa.
Sajẹnti Regina fi kun un pe, ěni ti wọn fẹsun kan naa fẹnu ara rẹ jẹwọ pe lootọ ni oun ji awọn aga naa amọ oun nikan kọ.
O ka Usman Jafaru ati Terdoo Moses naa mọ wọn sugbọn ko si ẹni to mọ ibi ti wọn wa.
Wọ́n tun ka awọn nkan  miran ti wọn ji bi ẹrọ amunawa, faanu, ina lanta igbalode, ati aga onike mẹrinlelogoji ti owo gbogbo rẹ si to ẹgbẹrun lona ọọdunrun naira din diẹ, sugbọn iwadii si n tẹ siwaju.
Ẹwẹ, ẹni a fẹsun kan naa ni oun ko jẹbi ẹsun ohun ti wọ́n fi kan oun tan.
Mayowa Omoniyi: Kò sí orin Obey, Sunny Ade abí tàkasúfèé tí ń kò le ta gìtá sí
Adajọ Erdoo Ter to n dajọ ni majisireei naa wa ni ki wọn gba iduro pẹlu oniduro kan ati ẹgbẹrun lọna ọgọrun naira.
Wọn ti sun igbejọ naa si ọjọ kọkandinlọgbọn, ọsu kesan an, ọdun 2020.
2020 Shiites Ashura day: Àwòráń ọdún Ashura àwọn ẹlẹ́sìn Shiite tí ọ̀pọ̀ ń sọ̀rọ̀ nípa rẹ̀ lórí ayélujára
Kaakiri agbaye ni awọn ẹlẹsin Shiite ti sami ayẹyẹ ọdun Ashura tí wọ́n fi sami ikú Hussein to jẹ́ ọmọ ọmọ Anabi Muhammed (SAW).
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Arakunrin ẹlẹsin Shiite kan ree ni ẹkun Kashmir lalẹ ayajọ Ashura ku ọla ni Budgam ni Iwọ oorun Srinagar
Oríṣun àwòrán, @IHRC
Awọn ijọ El Zakzakky ni Abuja naa sami ayẹyẹ yii lati ranti iku Hussein to jẹ ọmọ ọmọ Anabi Muhammed
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Bayii ni awọn ẹlẹsin Shiite ni Quelta ni Pakistan ṣe sami ayẹyẹ ti wọn pẹlu ẹjẹ ati apa pupọ lati fi ara wọn kẹdun iku Anabi naa
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Awọn Shiite ni Iraq pẹlu ogun awọn Karbala lọjọ Ashura ni ẹkun Suq al-Shuyoukh Dhi Qar
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Awọn obinrin Shiite ni Karbala n tan abẹla lasiko Ashura fun ibanikédun iku Hussein ni Iraq
Oríṣun àwòrán, IMN
Awọn obinrin ẹlẹsin Shiite labẹ Sheikh Ibrahim Zakzaky ni Naijiria n to rin lopopona lọwọọwọ lasiko ọdun Ashura
Oríṣun àwòrán, IMN
Awọn eeyan El Zakzaky ni Shiite n fi ẹjẹ silẹ ni ile iwosan Murital Muhammed ni ipinlẹ Kano lati sami ayẹyẹ ọjọ Ashura
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ogunlọgọ ero ni Kashmir ti wọn n sami iku anabi naa pẹlu ọkan ati ara wọn
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Awọn eeyan Iran kan ree ti wọn ba ina ṣere pọ ati Iraqi ti wọn n sami ayẹyẹ ayajọ Ashura.
Hanan Buhari wedding: 'Cartoon' tí Bulama yà nípa ìgbéyàwó ọmọ mi kò bójúmu tó - Aisha Buhari
Oríṣun àwòrán, Aisha Buhari
Iyawo Aarẹ Naijiria, Aisha Buhari ti sọ pe katun ti gbajugbaja ayaworan, Mustapha Bulama ya, eyii to ṣafihan igbeyawo ọmọ rẹ, Hanan Buhari ti awọn ọmọ Naijiria si n ri sinu odo ko bojumu to.
Agbẹnusọ iyawo Aarẹ, Aliyu Abdulahi lo fi ọrọ naa to BBC leti.
O ni awọn ọmọ olori ilu lẹtọ lati ṣe igbeyawo ni asiko to yẹ, ko si ni nnkan ṣe pẹlu boya awọn eeyan ilu fẹran ijọba awọn obi wọn tabi bẹẹ kọ.
"Aliyu ṣalaye pe ""Katun ti Mustapha Bulama ya ko bojumu rara nitori igbeyawo ọhun kii ṣe ọna aibikita fun awọn ara ilu, idi eyii lo mu ki aya Aarẹ ṣe ipade pẹlu awọn alabaṣiṣẹ rẹ pe oun ko fẹ igbeyawo alariwo ṣaaju ọjọ igbeyawo naa."""
"O tẹsiwaju pe ""Aworan ti aya Aarẹ fi lede lori ayelujara kii ṣe lati fi yọ suti ete si awọn ọmọ Naijiria, ṣugbọn o jẹ ọna lati fi ẹmi imoore han si awọn to ba idile rẹ ṣajọyọ igbeyawo ọhun."""
Oríṣun àwòrán, @Bulamacartoons
Igbeyawo ọmọ Aarẹ Buhari jẹ ọkan gboogi lara awọn igbeyawo onirẹlẹ julọ ti awọn to n tukọ ijọba yoo ṣe ninu itan orilẹ-ede Naijiria.
Ni ti fidio kan to n tan kalẹ lori ayelujara, nibi ti tọkọ-taya ti n jo ti awọn eeyan kan si n na wọn lowo, Aliyu ni kii ṣe ile ijọba ni Abuja ni wọn ti ya fidio ọhun, ṣugbọn iṣẹlẹ naa waye lẹyin ti iyawo dele ọkọ rẹ tan ni Kaduna.
Aliyu ni iyawo Aisha Buhari mọ pe arun Covid-19 ṣi wa lawujọ, nitori naa lo ṣe ri daju pe gbogbo awọn to peju sibi igbeyawo ọmọ rẹ tẹle ilana ijinasiraẹni ti awọn eleto ilera gbe kalẹ.
Temitope Akinnusi: Ọ̀pọ̀ iléeṣẹ́ ló takú láti gbà mí síṣẹ́ torí mo ní ojú kan
Ọjọ kẹrin, oṣu Kẹsan an, ọdun 2020 ni igbeyawo Hanan, to jẹ ọmọ Muhammadu Buhari waye, eyii to jẹ akoko ti ọpọ ọmọ Naijiria n sunkun inira ati ebi nitori bi ounjẹ, ina ijọba ati epo bẹntori ṣe gbowolori.
Onwoye ohun to n lọ lawujọ kan to n fi ilu Kano ṣebugbe, Sani Musa sọ fun BBC pe, ni ṣe lo yẹ ki idile Aarẹ sun ọjọ igbeyawo naa siwaju nitori bi ọrọ aje Naijiria ṣe ri lasiko yii.
Baby abandoned on dunmpsite: Mo ti bímọ mẹ́rin tẹ́lẹ̀ fún bàbá méjì nínú òṣí- Dupe Ogbomos
Ki lo ti ṣẹlẹ sẹyin?
Oríṣun àwòrán, Abdullahi Bashir
Ọrọ ifẹ, bii adanwo ni, bẹẹ si ni oro ọfa ifẹ ju oro ibọn lọ fun ẹni to ba ni iriri rẹ.
Boya eyi lo mu ki ọkunrin kan, Abdullahi Bashir fi n fi ẹsẹ tọ igboro ilu Abuja kiri, lati se alabapade, Hanan, ọmọbinrin aarẹ Muhammadu Buhari.
Bẹẹ ba gbagbe, ọjọ Abamẹta ni ọmọ aarẹ naa se igbeyawo pẹlu ọkọ rẹ nilu Abuja.
Amọ oniruuru awọn ọkunrin lo ti jade sita lati kede ifẹ ti wọn ni si Hanan, ni kete ti wọn gbọ pe o fẹ se igbeyawo,to si wu wọn lati fi se aya wọn.
Oríṣun àwòrán, @MBuhari
Koda, ọkan lara wọn ni Abba Ahmed, ẹni to kede pe oun setan lati pa ara oun ti ọmọ aarẹ ba fi se igbeyawo lẹyin oun.
Ọpẹlọpẹ ileesẹ ọlọpaa to parọwa si ọkunrin naa, ti ko fi se bo se wi.
Nibayii, Abdullahi Bashir, ẹni ọdun mejilelogun to tun ti yọju sita lori itakun agbaye, to si ni aise alabapade ọmọ aarẹ nilu Abuja lati fẹ, da irẹwẹsi si oun lara.
Amọ Bashir, tii se ẹlomiran to tun sẹsẹ kede ifẹ rẹ si Hanan loju opo itakun agbaye, ni to ba jẹ pe ọmọ aarẹ fẹ oun ni, maalu aadọjọ ni oun ko ba fi san owo ori rẹ.
Oríṣun àwòrán, @MBuhari
Sugbọn ọkunrin naa, ni kete to gbọ pe oloruka ti gba oruka, ti Hanan si ti lọ sile ọkọ rẹ, lo ba gba fun Ọlọrun.
Bashir, tii se darandaran nipinlẹ Adamawa lo kede pe oun ti yofẹ pẹlu ọmọ aarẹ ati awọn aworan fọto to n ya.
O ni to ba see se ni, obinrin naa lo wu oun lati fi se aya.
Oríṣun àwòrán, Aishabuhari
Saaju la ti kọkọ mu iroyin wa fun yin pe ileeṣẹ ọlọpaa ni ipinlẹ Kano ni oun ti pẹtu sinu arakunrin kan, Abba Ahmed, to ni oun yoo pa ara oun ti ọmọ aarẹ Buhari, Hanan ko ba fẹ oun.
Ahmed ti fi lede bayii pe oun ti jawọ ninu ero bẹẹ, nitori o ti han gbangba pe iru ero bẹẹ ko dara rara, ati wi pe ko fihan pe oun fẹran Hanan.
Agbẹnusọ ileeṣẹ ọlọpaa, Abdullahi Haruna ni awọn fi iwe pe Ahmed , ti wọn si ba sọrọ iyanju lori ẹrọ ayeluyara ko to di wi pe o jawo ninu ero lati pa ara rẹ.
Ahmed ni oun yi ẹrọ oun pada lori ati pa ara oun nitori ọmọ Buhari nitori ero naa ko dara rara, oun ko si ni ṣe iru rẹ mọ.
Oríṣun àwòrán, Aishabuhari
Amọ, ni Ọjọ Eti opin ọṣẹ yii ni Hanan Buhari ṣe igbeyawo pẹlu Turad Shaban.
Inu ile Aarẹ Buhari ati Aisha Buhari ni Abuja ni ayẹyẹ igbeyawo naa ti waye, ti iyawo aarẹ Buhari si fi si oju opo Instagram rẹ wi pe oun dupẹ lọwọ Olọrun pe o yọri si rere.
Hanan kọ ẹkọ imọ gẹgẹ bi ayaworan ni fasiti  Ravensbourne ni Ilẹ Gẹẹsi, nigba ti ọkọ rẹ jẹ oluranlọwọ pataki si minisita fun ọrọ iṣẹ ati ile gbigbe, Babatunde Fashola.
Baba Turad Sha'aban jẹ aṣofin tẹlẹri ni Ile Igbimọ Aṣofin to ṣoju ẹkun Zaria ni ọdun 2003 si 2007.
Ondo 2020: Afẹnifẹrẹ ní kí Tinubu sọ fún ẹgbẹ́ APC láti ṣe àmúṣẹ́ ilérí rẹ̀ fọ́mọ Nàíjíríà
Oríṣun àwòrán, Twitter
Asiwaju Bola Ahmed Tinubu nibi iside ipolongo idibo gomina ipinlẹ Ondo lo ti pe fun atunto lori bi owo ṣe n wọle fun Naijiria labẹle.
Awọn asaaju kan ninu ẹgbẹ Afenifere ti bu ẹnu atẹ lu asaaju ẹgbẹ oṣelu APC, Bola Tinubu lori bo se pe fun atunto ilana pinpin owo ajọni fawọn ipinlẹ ni Naijiria.
Awọn adari ẹgbẹ Afẹnifẹre to fi ero wọn han ni Oloye Ayọ Adebanjọ ati Yinka Odumakin, to jẹ akọwe ẹgbẹ naa.
Nibi ayẹyẹ iṣide ipolongo idibo APC nipinlẹ Ondo ni Tinubu ti pe fun atunto lori bi ijọba apapọ se n pin owo to n wọle labẹle nilẹ yii.
Tinubu tun kesi awọn gomina nilẹ Yoruba lati ṣiṣẹ papọ, lori bi wọn yoo ṣe ma a ri owo labẹle ni agbegbe naa.
Oríṣun àwòrán, Twitter
O fikun wi pe, ajọṣepọ laarin awọn gomina ni ilẹ Yoruba yoo sọ airiṣẹṣe awọn ọdọ ati iṣẹ, di ohun igbagbe ni ilẹ Yoruba.
Tinubu ni ti atunto ba de ba bi wọn se n pin owo to n wọle nilẹ yii, nipa ṣiṣe amulo awọn ohun alumọọni wa bo se yẹ, ọrọ aje wa yoo tubọ gbooro si.
Ninu ọrọ rẹ, Gomina Rotimi Akeredolu ni ipinlẹ Ondo n ri owo to to N600m si N700m pa wọle si ipinlẹ naa ni oṣooṣu.
Baby abandoned on dunmpsite: Mo ti bímọ mẹ́rin tẹ́lẹ̀ fún bàbá méjì nínú òṣí- Dupe Ogbomos
Akeredolu fikun pe, ni 2018, awọn ri owo to to N1.5bn pa wole ni oṣooṣu.
Amọ, awọn adari ẹgbẹ Afenifẹre ni ki Tinubu ma fi ṣe ọrọ ẹnu nikan, ko bọ si gbagede lati beere fun atunto Naijiria, ki ohun ini ati bi owo ṣe n wọle labẹle ba le kaakiri ọpọlọpọ eniyan.
Wọn fikun pe, gbogbo ẹkun to wa ni Naijiria ni wọn gbọdọ ma a pa owo wọle, paapaa awọn agbegbe to ni ohun alumọni to le mu ibugbooro ba bi owo ṣe n wọle ni abẹle.
BBNaija 2020: Terry Waya ní torí ìfẹ́ tí Erica ní sọ́mọ òun ló fi ní ọ̀pọ̀ ìṣòro
Yàtọ̀ sí owó ti àwọn ọmọ Nàìjíríà ń kó jọ fún Erica nítorí pé wọ́n lé e kúrò nilé ẹlẹ́gbọ̀n àgbà, bàbá Kiddwaya náà ti ṣe ilérí tuntun.
Terry Waya tó jẹ́ ìlúmọ̀ọ́ká olówó, lásìkò tó n sọ̀rọ̀ lórí ayélujára instagram pẹlú olóyè Dele Momodu, sàlàyé nipa ètó tó ni nílẹ̀ fún Erica, tiwọ́n le kúrò nílé lọ́lọ́ ọjọ Aiku.
Mayowa Omoniyi: Kò sí orin Obey, Sunny Ade abí tàkasúfèé tí ń kò le ta gìtá sí
Nínú fọ́nran náà ni Terrywaya ti sàlàyé pé, gbogbo ìṣẹ̀lẹ̀ tó ṣẹlẹ̀ si Erica nínú ilé kò ṣẹ̀yìn ìfẹ́ to ni sí ọmọ òun Kiddwaya, nítori náà, ó yẹ kó ni ìpin nínú owó ẹlẹ́gbọ̀n àgbà.
Nítorí ìdí èyí, Terrywaya ní bi ọmọ òun bá gbégbá orókè nínú idíjẹ to n lọ lọ́wọ́ yìí, òun yóò ri dájú pé ìdajì nínú rẹ̀ lọ sí ọ̀dọ̀ Erica, nígbà ti èyí tó kù yóò padà lọ sí ilé àwọn aláìní.
Oríṣun àwòrán, BB Naija
Ó sàlàyé pé, ọmọ to ṣe e mú yangan ní Erica, tó si lè dúró tí ni lásìkò ìṣòro àti pé, gbogbo nǹkan tó ṣẹlẹ̀ si nínú ilé ẹlẹ́gbọ̀n àgbà, ọ̀pọ̀ wa nítorí Kiddwaya ni.
Gẹ́gẹ́ bi ìṣe àwọn ọmọ Naijiria, àwọ́n kan pé ara wọ́n ní Ellites (àwọn yìí ló wà fún Erica ) nígbà ti àwọn kan pe àra wọ́n ni Icon (àwọn ti Laycon), àwọn ẹ̀ka méjèèjì yìí ti ń gba ọ̀rọ̀ náà bí ẹni gbagbá ọtí.
Onírúurú ọ̀rọ̀ lón tí n lọ lórí ǹkan ti bàbá Kiddwaya sọ. Bí àwọn kan ṣe ń sọ pé, ọrọ ọmọ ni bàbá Kiddwaya ń ṣe, ni àwọn míràn sọ pé, ọgban àti lu àwọn ọmọ Nàìjíríà ni jìbìtì ni.
Wọ́n ni kò si àníàní, Laycon lo ni owó tó wà níle ẹgbọ́n àgbà, àti pé ki Terrywaya lọ wá owó tirẹ̀ síwájú, níwọ̀n ìgbà tó jẹ́ pé olówó ni bàbá òun.
Ètò ìkówó jọ ti wọ́n ń ṣe fún Erica ṣì n lọ lọ́wọ́ títi di àsìkò yìí.
Bobrisky gbé N1m fún Erica torí ẹnu tó ń kùn-ún
Oríṣun àwòrán, Others
Lẹ́yìn awuwuye tó tẹ̀lé bí Erica ṣe hùwà sí Laycon nínú ilé ẹlégbọ́n àgbà lẹ́yìn páti alẹ́ ọjọ́ Satide.
Ọ̀pọ̀ ọmọ Nàìjíríà ló ni ìdájọ́ to yẹ ni láti le Erica kúrò nínú ilé.
Sùgbọ́n lẹ́yìn ti ẹlẹ́gbọ̀n àgbà ṣe ìdájọ rẹ̀ tán tó sì fọ́wọ́ òsì júwé ilé fún Erica ní àwọn ọmọ Naijira bá ń sọ èrò tí wọ́n lóri ọ̀rọ̀ náà lórí ayélujára.
Bí àwọn gbájugbajà òsèré ṣe ń sọ ti wọ́n bẹ́ẹ̀ ni àwọn tó jẹ́ ilúmọ̀ọ̀ká láwùjọ àti àwọn ọmọ Naijira míràn náà ń sọ bí o ṣe yẹ kí o rí.
Lára àwọn tó fi èrò wọ́n sórí ayélujára ni
Gbájúgbajà ọkùnrin to máa ń múra bi obìnrin Olarewaju Idris Okunneye ti gbogbo ènìyǹ mọ̀ si Bobrisky tó fi ìpè síta pé ki wọ́n bá òun fi nọ́mbà ìfówopamọ́ rẹ̀ ranṣẹ́ nítori òun fẹ́ ta lọ́rẹ. mílíọ̀nù kan Naírà.
Ó ní tí a bá fi ọwọ́ ìtún bamọ wi, o di dandan ki a fi ọwọ́ òsì fàá mọ́ra nítori náà òun fẹ́ fún ni mílíọ̀nù kan náírà.
Bakan náà ni ọ̀pọ̀ àwọn ọmọ Naijira lórí àtẹjíṣẹ́ twitter sọ pé àwọn yóò ṣe àkójọpọ̀ ọgọ́rùn mílíọ̀nù náírà láti fi ràn lọ́wọ́.
Lọ́wọ́lọ́wọ́ bi a ṣe n kó ìròyìn yìí jọ àwọn ènìyàn ti ṣe àgbékalẹ̀ mílíọ̀nù mẹ́fà náírà.
Oríṣun àwòrán, Others
Ìyẹn nìkan kọ́ oo, bí ẹlẹkún ṣe ń sunku bẹ́ẹ̀ ni aláyọ̀ ń yọ, ẹyi lo dífa fún ọmọ binrin kan tó wa ẹkún mu bi omi  nítori pe wọ́n le Erica kúrò nile ẹgbọ́n agbà
Ẹkún gidi ni ọmọbìnrin yìí ń sun lẹ́yìn ti wọ́n le Erica kúrò nilé ẹlẹgbọ̀n àgbà
Nínú fọ́nran náà ni ọmọbinrin kan ti n sùnkun tó sì bẹ̀rẹ̀ sí n'ṣépè fún Laycon.
Sùgban ọ̀pọ̀ ni ko gbà pé Laycon ló jẹ̀bi nínú ọ̀rọ̀ yìí, wọ́n ni gbogbo ìkìlọ̀ ti Erica ti gba jẹ́ èyi ti kò bá má wáye, tó ba jẹ́ pé kò ni ìbáṣepọ̀ pẹ̀lú Kiddwaya ni.
Oríṣun àwòrán, BBNaija/ Instagram
Ó jọ́ bi ẹni pé nǹkan o ṣẹnu ire fún Erica nínú ilé BB Naija láti alẹ ọjọ́ Sátidé.
Gbogbo àwọn olólùfẹ́ rẹ̀ pẹ̀lú ló si ti n bẹnu àtẹ lu ìwà tó wu.
Kíló ṣẹlẹ̀ gan tí Erica fi tú bí ejò táa gé nírù?
Lásìkò ti patí alẹ́ ọjọ́ Satíde n lọ lọ́wọ́, ni inú ti bẹ̀rẹ̀ si ni bi Erica nítorí bi Nengi ṣe ń jó pẹ̀lú olólùfẹ́ rẹ̀ Kidwaya.
Erica wa kesi Nengi pé ti o ba nífẹ̀ Kiddwaya, ore-ọ̀fẹ́ wà fún láti sọ ni àsìkò yìí nítori pé, bi ó ṣe ń ṣe ni àyíka rẹ̀, kò tẹ́ òun lọ́rùn rárá.
Nengi fún Erica lésì pé, kìí ṣe pé Kiddwaya fi bẹ́ẹ̀ wu òun lọ́mọ́kùnrin, sùgbọ́n kìí ṣe inú ilé BB Naija ni òun ti ṣẹ̀ṣẹ̀ mọ Kiddwaya, àti pé àwọn ti mọra tipẹ́.
Nítorí owú jíjẹ, ọkọ Zarka gé imú aya rẹ̀ dànú!
Ní kéte ti pati pari, ti olúkúlùkù sì n jíròrò lọ́wọ́ nínú ilé ìdána, ni Erica ba tún ta mọ Laycon, bẹ́ẹ̀ lo ń pariwo fòò pé, ó maa n parọ fún Ebuka pé òun máa ń gbìyànjú láti fẹnukò òun lẹ́nu ní ẹ̀ẹ̀meeji ọ̀tọ̀ọ̀tọ.
Gbogbo bi Kiddwaya àti Trikytee ṣe gbìyànjú tó lati pẹtù si, Erica ò gbọ́ rárá.
Oríṣun àwòrán, Others
Erica ń kígbe pé, Laycon ko si lára ẹni to wu òun rárá, òun ko sì fi ìgbà kankan gbìyànjú lati fẹnu kòó lẹ́nu ri.
"Kò si irú èébu ti ko bu Laycon tan, o tún pe e ni ""Skinny drum Stick"" èyi to tumọ si ki wọ́n pe ènìyàn ni kọ̀ngọ́ ìlù."
Kò tán síbẹ̀ óò, nígbà ti Erica tún de yàrá ti wọ́n ti yà sọ́tọ̀ fún àwọn olórí ilé, ó tún kọjú mọ́ Prince, nítorí pé ó ń gbìyànjú láti pẹ̀tù síi lọ́kàn.
Ó sọ fún Prince náà pé, àṣìṣe gbáà ni fún òun láti yan àn gẹ́gẹ́ bi ìgbákeji olórí ilé.
Baby abandoned on dunmpsite: Mo ti bímọ mẹ́rin tẹ́lẹ̀ fún bàbá méjì nínú òṣí- Dupe Ogbomos
O ní ẹ̀tọ́ rẹ̀ ni gẹ́gẹ́ bi ìgbákejì òun láti dúro ni apá ibi ti òun tò si lásìkò ti òun bá Laycon jà.
Ìbéèrè ni pé, ṣe kìí ṣe àṣemọ Erica rèé ti wọ́n o fi júwe ilé fún kúrò nílé BB Naija.
BB Naija 2020: Erica ní òbùrẹwà, kìkìdá egungun ní Leycon, òun sì fẹ́ pa á
Oríṣun àwòrán, BB Naija
Orisirisi ara lo ti n waye nile BB Naija bayii, eyi to n ya ọpọ eeyan lẹnu.
Lasiko ariya alaalẹ Satide to tun waye lana ati asiko ounjẹ ni aarọ ọjọ isinmi oni, ara miran tun ti sẹlẹ.
Ni aarọ ọjọ isinmi ni awọn ololufẹ meji to gbajumọ bii isana ẹlẹẹta ninu ile naa, Vee ati Neo, tun ti da ara miran tuntun.
Niwaju gbogbo awọn olugbe BB Naijia si ni Neo, ẹni ti ifẹ Vee n pa bii ọti, ti kede pe o di dandan ki oun fun ọmọbinrin naa loyun, ki awọn to setan ninu ile naa.
"Gẹgẹ bo se wi, ""Chai, mo gbọdọ fun ọ loyun."", ti gbogbo awọn eeyan to wa nibẹ si ku silẹ fun ẹrin arintakiti."
Oríṣun àwòrán, BB Naija
Neo, wa sọ fun Nengi, Kiddwaya, Trikytee ati Vee bi inu oun se dun to lati bawọn kopa ninu eto BB Naija tọdun yii.
Inu mi dun lati pade wọn ọrẹ tuntun lori eto yii, ti agbega si ba igbe aye mi, bakan naa ni mo di gbajumọ lawujọ.
Amọ sa, Neo, tii se ẹya Urhobo wa n fi ika hanu pe o seese ki oun sọ awọn ọrẹ oun naa nu, to fi mọ ololufẹ oun, Vee, ti wọn ba le oun lọ sile lonii.
Lalẹ oni si laa mọ ẹni ti yoo jade kuro ninu ile ẹlẹkọ agba.
Wayi o, inu buruku ti bi Erica ninu ile BB Naija to si sọ kobakungbe ọrọ si akẹẹgbẹ rẹ, Laycon, ẹni to se apejuwe bii oburẹwa ẹda.
Oríṣun àwòrán, Erica Leycon Instagram
Erica, tii se olori ile lọwọ lọwọ ni ihuwasi rẹ yii ya awọn akẹẹgbẹ rẹ to wa ninu ile naa lẹnu, paapaa lori ojo eebu ati abuku to n rọ sori Laycon.
Lemọ lemọ si ni Erica, to han pe o ti mu ọti yo, n sọ pe oponu ati oburẹwa to jẹ kikida egungun , ti ko mu agbega kankan ba inu ile naa ni Leycon.
Ọrọ yii ti n mu awuyewuye dani lori ayelujara, ti ọpọ eeyan si koro oju si ihuwasi Erica naa, lẹyin ariya alẹ ọjọ Satide.
Erica lo n binu lori bi ọpọ eeyan se gba pe oun fi ẹnu ko Leycon lẹnu, to si lọ ba ọmọkunrin naa pe ko mu ẹri to ba ni wa lati fi idi rẹ mulẹ pe awọn fi ẹnu konu.
Ọrọ yii si lo bii ninu to bẹẹ, to fi ni oun lee pa Leycon, nitori isẹlẹ to n ja nilẹ naa.
Temitope Akinnusi: Ọ̀pọ̀ iléeṣẹ́ ló takú láti gbà mí síṣẹ́ torí mo ní ojú kan
Ọmọ ọdun mẹwa ati akẹkọọ kilaasi kẹta nile iwe alakọbẹrẹ ni Temitope Akinnusi nigba ti isẹlẹ kan waye eyi to mu oju osi rẹ lọ lọdun 2003.
Lasiko to n ba BBC Yoruba sọrọ, Temitopẹ ni awọn adigunjale to wa sile awọn lasiko ti baba oun ko si nile lo sokunfa ijamba naa.
O ni wọn fẹ fi tipa ba iya oun lopọ, ti oun si tako wọn, ni wọn ba fi idi ibọn fọ oun loju.
Ọkunrin naa, ni oun koju ọpọ ipenija nile iwe lati ọdọ akẹẹgbẹ oun amọ eyi ko di oun lọwọ lati kawe jade titi de ile ẹkọ fasiti.
Amọ idẹyẹsi naa ko tun jẹ ko fi iwe ẹri fasiti rẹ sisẹ lawọn ileesẹ nlanla nitori ọpọ wọn lo taku pe awọn ko le gba oloju kan sẹnu isẹ.
Lọwọ lọwọ bayii, Temitope Akinnusi wa lara awọn akọsẹmọsẹ ati gbajumọ ayaworan nipinlẹ Ondo pẹlu oju kan soso to ni.
O wa n parọwa sawọn eeyan to ni ipenija kan abi omiran lati mase ro ara wọn pin nitori bi ẹmi ba si wa, ireti n bẹ.
Bishop Oyedepo: Ifedayo Olarinde tó ń jẹ́ Daddy Freeze tọrọ àforíjì pé o sọ ọ̀rọ̀ ẹ̀gbin sí David Oyedepo
Oríṣun àwòrán, Others
Oludari ẹgbẹ Free the Sheeple Movement ati Free Nation in Christ, Ifedayo Olarinde, ti awọn ololufẹ rẹ tun mọ si DaddyFreeze, sọ pe oun tọrọ aforiji lori ọrọ kan ti oun sọ si oludasilẹ ijọ Living Faith Church (Winner's Chapel), Biṣọpu David Oyedepo.
Freeze sọ ninu fidio kan to fi si ori Instagram rẹ pe aforiji ti oun tọrọ ko ṣẹyin bi awọn kan ṣe pe akiyesi oun si fidio kan ti oun fi sita ni bi ọdun mẹta sẹyin, lasiko ti oun n sọ ero oun lori awọn iṣẹlẹ kan to waye nigba naa.
"O ni ""mo n bẹbẹ nitori awọn ọrọ ti mo sọ nigba naa ati fun ọrọ abuku to ta ba Biṣọpu David Oyedepo ninu fidio naa""."
Mi o ni i lero lati ri Biṣọpu naa fin, tabi kan an ni abuku, ti mo si kabamọ itumọ ti awọn kan fi n tumọ fidio naa.
Daddy Freeze s'alaye n to faa ti oun fi n tako idamẹwa
"Ninu fidio naa, Freeze sọ pe ọmọ ale ni ẹnikẹni to ba sọ pe Jesu lọwọ nigba aye rẹ. Bo tilẹ jẹ pe ko darukọ pasitọ to  n sọrọ si, o pe ẹni naa ni ""apari adiyẹ"", to si sọrọ bi ẹni naa ṣe ma n sọrọ."
O ṣalaye pe lasiko yii, ọna ti oun n gba sọrọ lori awọn ilana ati eto ẹsin Kristiẹni ti kuro ni ti atako tabi sisọ ọrọ binu. Ti oun si ti n fi ẹsẹ Bibeli ṣe atilẹyin fun nkan ti oun ba sọ.
O ni ṣugbọn oun gbagbọ pe o yẹ ki awọn Kristiẹni o ma a fi aaye gba awọn ilana tabi akiyesi tuntun to ba n jade ni ibamu pẹlu ẹkọ Bibeli yatọ si eyi to ti wa tẹlẹ ti ko si ẹni to le sọrọ tako o.
Ọjọ ti pẹ ti ẹnu ti ma n kun Freeze nitori awọn ọrọ atako to ma n sọ nipa ẹsin Kristiẹni, paapa nipa idamẹwa ati ọrẹ. Eyi ti kii ba awọn Kristiẹni kan lara mu.
Laipẹ yii si ni Pasitọ kan, Pasitọ Paul Enenche sọrọ lori bi Freeze ṣe sọrs abuku si Oyedepo.
Ninu fidio kan to wa lori ayelujara, Pasitọ Enenche ni ko tọ si Freeze lati ma a sọ iru ọrọ bẹ ẹ, nigba ti oun fun'ra rẹ ko ni igbeyawo to duro, tabi iṣẹ lọwọ. Bakan naa lo pe e ni aja digbolugi.
Oríṣun àwòrán, Others
Lẹ́yìn ti orí ayélujara gbóná janjan lọjọ Aje lórí gbómisí-omí-otó láàrin Ifedayo Olarinde tí gbogbo ènìyàn mọ̀ si Daddy Freeze àti Pásítọ̀ Ibiyeomie, Daddy Freeze ti fèsì sí ọ̀rọ̀ pásítọ̀ náà.
Ọ̀pọ̀ tilẹ̀ fẹ́ yọ ẹ̀ṣẹ́ sí ara wọ́n lórí ayelujara lórí bóya, Daddy Freeze lo jẹ̀bi lórí ọ̀rọ̀ to kọ si Bíṣọ̀ọ̀bù David Oyedepo tàbí ọ̀rọ̀ tí Pásítọ̀ Ibiyeomie sọ náà ti pọ̀ju, gẹ́gẹ́ bi ènìyàn Ọlọ́run.
Sùgbọ́n ní lọjọ Isẹgun ni Daddy Freeze náà tún fún òjíṣẹ́ Ọlọrun náà ni èsi nípa ìdúkòkò ikú mọ́ni, ti pásítọ̀ náà gbé sórí ayelujára.
Akomolede ati Aṣa lori BBC: Mọ̀ si nípa oríṣìí ẹ̀ka ìsọ̀rí ọ̀rọ̀ àti ìwúlò wọn
Daddy Freeze ni, ìdúkokò ikú mọ́ni jẹ́ ẹṣẹ̀ si ẹ̀tọ́ ìgbé ayé ọmọnikeji, ti òfin orílẹ̀-èdè Nàìjíríà si takòó gidigidi.
"Ifedayo ni ""Jẹ́ ki o wà nínú àkọsílẹ̀ pé tí òhunkóhun bá ṣẹ̀lẹ̀ sí mi lónìí, ẹ ti mọ̀ ẹni ti ó wà nídi rẹ̀."
"Ó ti tó wákàtì mẹ́rìnlélógun ti Ibiyeomie ti sọ̀rọ̀ ìdúkokò yìí, àwọn ọlọ́pàá Nàìjíríà kò sì ṣe ǹkankan si"""
Temitope Akinnusi: Ọ̀pọ̀ iléeṣẹ́ ló takú láti gbà mí síṣẹ́ torí mo ní ojú kan
"Ó wa pé àwọn ọmọ Naijiria pe, ṣe bi wọ́n yóò kan ṣe maa wò ọ̀rọ̀ yìí ko lọ bẹ́ẹ̀ rèé, nítorí pé Ibiyeomie jẹ́ èèyàn ńla?"""
Ifedayo ni ki olùṣọ́ àguntan náà tọrọ àforijì lọ́wọ́ àwọn oníṣẹ́ ìròyìn to bẹ̀nu àtẹ́ lù, tó si fí iṣẹ́ wọ́n wọ́lẹ̀ tuurutu.
Eruku ìjà sọ lálá lórí ayelujára láàrin Bíṣọ́ọ́bù méjì àti Daddy Freeze
Oríṣun àwòrán, Others
Saaju ni ati mu iroyin wa fun yin wi pe ija ṣẹlẹ lori ayelujara laarin pasitọ ijọ meji ati Daddy Freeze.
Awọn mẹtẹẹta naa ni Bisọọbu David Oyedepo, ti see alakoso agba fun ijọ Winners pẹlu gbajugbaja onwoye awujọ kan, Ifedayo Olarinde ti ọpọ eeyan mọ si Daddy Freeze.
Ẹni kẹta ni gbajumọ Bisọọbu David Ibiyeomie, to ni ọmọ Oyedepo ni oun ninu isẹ Oluwa.
Igba akọkọ si kọ ree ti aawọ n waye laarin Daddy freeze ati David Oyedepo, paapaa lori ọrọ kawọn ọmọlẹyin Kristi maa san idamẹwa.
Ohun to fa aawọ ni iwaasu kan ti Oyedepo ju soju opo Twitter rẹ lori ọrọ igbeyawo lo sọ nipa pataki ki aya maa bọwọ fun ọkọ rẹ.
Oríṣun àwòrán, Others
Oyedepo ni ara ojuse iyawo ni ko tẹriba fun ọkọ patapata, gbogbo ohun to ba si dawọle yoo yọri si rere.
O ni obinrin ti ko ba tẹriba fun ọkọ rẹ lodi si ofin Ọlọrun ọba, iru obinrin bẹẹ ko baa jẹ ojisẹ Ọlọrun.
Amọ nigba to n fesi si abẹ ọrọ ti Oyedepo sọ naa, Daddy Freeze ni itẹriba funra ẹni ko gbọdọ mọ lọdọ obinrin nikan, amọ o wa laarin awọn mejeeji.
O ni tọkọtaya ni wọn gbọdọ dijọ tẹriba fun ara wọn, ti ile yoo ba toro.
Oríṣun àwòrán, daddyfreeze
Amọ ọkunrin kan @jesusemmanuel_ty47, to farahan bii ọmọlẹyin David oyedepo, wa da Daddy Freeze lohun labẹ ọrọ to sọ naa bayii:
Ẹ wo ọkunrin ti igbeyawo rẹ fori sanpọn to n gba ọkunrin ti igbeyawo rẹ ti le ni ọgbọn ọdun nimọran. Ẹyin ọmọ Naijiria maa n pa eeyan lẹrin sa.
Oríṣun àwòrán, @jesusemmanuel_ty47
Ọrọ yii lo bọ si apo ibinu Daddy Freeze, to si fesi pada fun ọkunrin naa pe:
"Ẹ wo ẹni to n ja fun Pasitọ rẹ, o yẹ ko mọ pe ki eeyan lo ọgbọn ọdun ninu igbeyawo ko tumọ si pe igbeyawo naa se aseyọri.
Ọpọ igbeyawo awọn asaaju ẹsin kan n fara da igbeyawo wọn ni, wọn ko gbadun rẹ, tori pe mo si kuna lẹẹkan ko tumọ si pe n ko ni saseyọri lasiko yii, inu mi dun lasiko yii ju ti tẹlẹ lọ."
Oríṣun àwòrán, daddyfreeze
Sugbọn awọn oko ọrọ ti Daddy Freeze fi ransẹ si gbajugbaja ojisẹ Ọlọrun naa lo fa ibinu ojisẹ Ọlọrun miran yọ, eyiun Ibiyeomie.
Ninu fidio kan to lu ori ayelujara pa ni Ibiyeomie ti faraya, to si n ju oko ọrọ pada si Daddy Freeze pe ko ni ẹtọ lati tabuku Oyedepo, tii se baba oun ninu Oluwa.
N ko le gba ko maa tabuku baba mi Oyedepo, se o ni baba bi? To ba ni baba bi, to ba ni, mu baba rẹ jade.
Temitope Akinnusi: Ọ̀pọ̀ iléeṣẹ́ ló takú láti gbà mí síṣẹ́ torí mo ní ojú kan
"Irisi rẹ gan jọ tawọn ara Somalia, iwọ to lee to ile rẹ, o ko niyawo ninu ile, o wa n tabuku baba mi, bi gbogbo eeyan ko ba sọrọ, maa sọrọ, maa si fa onitọun ya pẹrẹpẹrẹ."""
Fidio naa, ti Ibiyeomie se lori pẹpẹ iwaasu lọjọ Aiku ni ọpọ eeyan n pin kiri lori ayelujara, ti wọn si n sọrọ le lori.
Bi awọn eeyan kan se pọn sẹyin oun ti Daddy Freeze sọ, lawọn miran n ta koo, ti wọn si n gbe sẹyin Oyedepo ati Ibiyeomie.
Ondo Election 2020:Lóòtọ́ làwọn tọ́ọ̀gì APC kọlu PDP ní Oba Akoko, ìwádìí ti bẹ̀rẹ̀ - Ọ̀lọ́pàá
Oríṣun àwòrán, Rotimi Akeredolu Facebook
Ileeṣẹ ọlọpaa ni ipinlẹ Ondo ti ṣalaye pe lootọ lawọn janduku lẹyin ẹgbẹ oṣelu APC atawọn ti PDP kọlu ara wọn ni Ọjọru ni ilu Ọba Akoko ṣugbọn iwadii ti bẹrẹ lati mọ ohun pato to fa wahala naa.
Alukoro ileeṣẹ ọlọpaa ni ipinlẹ Ondo, DSP Tee Leo-Ikoro ṣalaye fun BBC pe iṣẹlẹ naa ko dun mọ kọmiṣọna ọlọpaa ni ipinlẹ Ondo to bẹẹ gẹ to fi pe awọn eekan ẹgbẹ oṣelu gbogbo ni ipinlẹ naa fun ijiroro lori rẹ l'Ọjọbọ.
O ni wahala to bẹ silẹ naa tako adehun to wa laarin awọn ẹgbẹ oṣelu mejeeji ati ọlọpaa pe ko gbọdọ si ẹgbẹ oṣelu meji to gbọdọ maa ṣe ipolongo lagbegbe kan naa lasiko kan naa.
O ṣalaye pe awọn ẹgbẹ oṣelu PDP lo n ṣe ipolongo ibo wọn ni ilu Ọba Akoko nigba ti ẹgbẹ oṣelu APC n kọja laarin ilu naa lọ si ilu Ikare Akoko. Nibẹ ni wọn ti kọlu ara wọn.
Ileeṣẹ ọlọpaa ti pe ipade lori iṣẹlẹ naa pẹlu ileri pe irufẹ iṣẹlẹ bẹẹ ko ni ṣẹyọ mọ ṣsaju ati lasiko idibo gomina ni ipinlẹ Ondo to n bọ lọna.
'Búrẹ́dì tí wọn ó fi jẹ ẹ̀wà ni wọ́n lọ rà ni wọ́n pàdé ikú gbígbóná'
Awọn alatilẹyin Gomina Rotimi  Akeredolu ipinlẹ Ondo ati akẹgbẹ rẹ ninu ẹgbẹ PDP Eyitayo Jegede ti n naka abuku sirawọn lori ẹni to jẹbi ikọlu to waye lọjọru.
Ikọlu naa gẹgẹ bi ohun ta ri gbọ waye nigba tawọn ikọ ipolongo mejeeji pade ni ilu Oba Akoko ni ijọba ibilẹ Akoko West.
Lẹyin ti gbogbo nkan walẹ tan, ọpọ ọkọ ni wọn bajẹ ti awọn ẹgbẹ mejeeji si n naka si ara wọn pe ẹnikeji lo kọkọ da wahala silẹ.
Ninu ọrọ ti Eyitayo Jeged sọ fun BBC Yoruba, o ni awọn ti gba iyọnada ṣaaju lọdọ ọlọpaa ki awọn to bẹrẹ ipolongo.
''Iyalẹnu lo jẹ fun wa lati ri ki awọn ọmọ ẹgbẹ APC ya de niwaju aafin  Oba Akoko ti wọn si bẹrẹ si ni ṣe ikọlu awọn eeyan wa''
Eyitayo sọ pe oun wa ni ọdọ Kọmisana ọlọpaa lati lọ fi ẹjọ suin nitori pe awọn janduku ẹgbẹ APC ba ọkọ awọn to to ogun jẹ ninu ikọlu naa.
Oríṣun àwòrán, Rotimi Akeredolu Facebook
O ṣalaye pe oun ti pe Gomina Akeredolu lori ago ti o si ni pe oun ti kọja tan ki iṣẹlẹ naa to waye ati pe oun ko mọ pe iru nkan bẹ waye.
BBC kan si alaga ẹgbẹ APC ni Ondo lati gbọ alaye lẹnu rẹ.
Oríṣun àwòrán, Rotimi Akeredolu Facebook
Alagba Ade Adetimehin sọ pe oun gẹgẹ bi ẹnikan ko mọ igba ti ikọlu naa waye nitori ọkọ ti oun wa ninu rẹ kọja ni Oba Akoko ti wọn ko si kọlu ẹnikankan
''Nigba ti a kọja lọ, a ri pe awọn PDP naa wa nilu Oba  Akoko. Lẹyin igba ti a ti kọja ti Gomina ti kọja a ko ri ẹyin la ti mọ boya awọn eeyan kan ti da awọn eeyan wa lẹyin''
O fi kun pe ''a o ni igbagbọ pe PDP yoo 'se ipolongo wọn loni. A ti gba aaye lati ṣe ipolongo. Nigba ti a de ilu Ikare la gbọ pe wọn ṣe ikọlu si ọkọ wa.''
BBC Yoruba gbiyanju lati ba alukoro ọlọpaa ipinlẹ Ondo arakunrin Tee-Leo Ikoro sọrọ lori iṣẹlẹ yi ṣugbọn ko gbe ago rẹ.
Oríṣun àwòrán, Rotimi Akeredolu Facebook
Awọn janduku oloselu ti gba akoso ile asofin nipinlẹ Ondo, ti wọn si n da idarudapọ silẹ nibẹ
Iroyin to n tẹ wa lọwọ ni o le ni ọgọfa awọn tọọgi naa ti wọn gbarodan siwaju ile asofin ọhun, pẹlu ogunlọgọ ọkọ ayọkẹlẹ wọn.
Bẹẹ ba gbagbe, a ti n mu iroyin wa fun yin tẹlẹ pe nnkan ko fararọ nile asofin ipinlẹ Ondo nitori eto idibo gomina to sunmọ etile.
Laipẹ yii si ni ile asofin naa gbindanwo lati yọ igbakeji gomina, ti omi alaafia ibẹ ko si toro nitori awọn asofin mẹsan to tako igbesẹ naa.
Bi gbogbo ọrọ naa ba se jẹ, BBC Yoruba wa ni sẹpẹ lati mu ẹkunrẹrẹ iroyin wa fun yin.
Baba Legba: Foluke Daramola ní òun kò ní gbàgbé àdúrà òwúrọ̀ tó máa ń gbà fún òun
Gomina ẹgbẹ TAMPAN ni ipinlẹ Ogun, Owolabi Ajasa ti ṣapejuwe Baba Lẹgba to di oloogbe, gẹgẹ bi baba awọn oṣere nigba aye rẹ to ko awọn eniyan mora.
Ajasa ni, baba ni Baba Lẹgba jẹ fun wọn nigba to wa laye, to si tun jẹ awokọṣe iwa ọmọluwabi laarin wọn, to si ma n gba wọn nimọran.
O ni bi o tilẹ jẹ pe oloogbe naa kii ṣe ọmọ ẹgbẹ oṣere TAMPAN nigba aye rẹ, to jẹ wi pe ọmọ ẹgbẹ ANTP ni, sibẹ o sunmọ gbogbo awọn oṣere.
"Gbogbo ohun ti a ba fẹ, lo maa n ṣe fun wa nigba to wa laye, a si ṣe ojuṣe wa fun nigba to dubulẹ aisan, ki o to di wi pe o doloogbe.
Oríṣun àwòrán, Others
Aisan to rọmọ ọjọ ogbo lo ṣe Baba legba to fi papoda, amọ, ede aiyede to ṣẹlẹ laarin ẹgbẹ TAMPAN ati ANTP, lo mu ka maṣe pe oloogbe naa si iṣẹ pẹlu aisan to ṣe wọn."
Owolabi Ajasa fikun pe aisan Baba legba tun peleke si ni ọdun to kọja, sugbọn oun maa n pe oloogbe naa si iṣẹ.
Ninu ọrọ tirẹ, gbajugbaja oṣere Yoruba, Foluke Daramọla Salako ṣe apejuwe Baba Lẹgba gẹgẹ bi ẹni to ni imọ ati oye nipa oṣere, to si kun fun ọgbọn.
Oríṣun àwòrán, Others
Foluke Daramọla ni ohun manigbagbe ti oloogbe naa ṣe fun oun ni adura to maa n gba fun oun ni araarọ, to ba ti pe oun lori aago.
"Itoju ti ẹgbẹ TAMPAN n ṣe fun awọn agbalagba to wa ninu ẹgbẹ oṣere lo mu mi mọ Baba Lẹgba.
Amọ, ọdun to kọja ni aisan asetọ taa mọ si prostate mu, eyi to ṣekupa nitori ọjọ ogbo rẹ."
Akomolede ati Aṣa lori BBC: Mọ̀ si nípa oríṣìí ẹ̀ka ìsọ̀rí ọ̀rọ̀ àti ìwúlò wọn
Bakan naa lo pe oun yoo ṣe idaro Baba Legba nitori ipa ribiribi to n ko ninu fiimu nigba aye rẹ.
Ilumọọka osere tiata lobinrin, Foluke Daramola Salako ti n gbarata lori iku to mu agba ọjẹ osere tiata miran, Alhaji Yekeen Omobolanle lọ.
Ọjọ Aje ni iroyin iku agba ọjẹ ninu isẹ tiata naa gbalẹ kan, ẹni ti ọpọ eeyan mọ si Baba Legba.
Oríṣun àwòrán, Others
Nigba to n kẹdun iku to mu akikanju osere naalọ, Foluke sọ loju opo Instagram rẹ pe kii dun mọ oun ninu lati ri ki awọn agba osere maa jade laye.
Foluke to ni lootọ ni baba naa dagba, ti oun si ba sọrọ lọsẹ to kọja sugbọn ọwọ mi di pupọ nile ounjẹ ti oun da silẹ lati bẹ ẹ wo.
"Ọwọ mi di lati lọ bẹ ẹ wo gẹgẹ bi mo se maa n se nitori o sọ fun mi pe oju ọjọ taa wa yii tutu fun oun.
Oríṣun àwòrán, Others
O dun mi pe n ko le ni anfaani lati juwọ si pe o digbose ko to gbẹmi mi, o si se ni laanu pe a padanu rẹ."
"Foluke fikun pe ""mo da ara mi lẹbi pe n ko lọ bẹ Baba Legba wo nigba to pe mi, ams sa, o dara, Sun re o, Baba."""
Wọn ti sin oloogbe naa nilana ẹsin Musulumi lọjọ Aje.
Akomolede ati Aṣa lori BBC: Mọ̀ si nípa oríṣìí ẹ̀ka ìsọ̀rí ọ̀rọ̀ àti ìwúlò wọn
Ikudoro, iku ti sika, iku ti mu gbajumọ agba ọjẹ ninu isẹ tiata miran lọ.
Oluwa rẹ ni Alhaji Yekeen Omobolanle ti ọpọ eeyan mọ si Baba Lẹgba.
Baba Lẹgba lo maa n sere awada pẹlu baba Sala laye ọjọsi, ki agba to de.
Agba ọjẹ osere tiata naa lo jade laye nile rẹ to wa nilu Abeokuta nipinlẹ Ogun nirọlẹ ọjọ Aiku.
Nigba to n fidi isẹlẹ iku oloogbe naa mulẹ fun BBC Yoruba, gbajumọ osere tiata miran, Ebun Oloyede, ti ọpọ eeyan mọ si Olaiya Igwe ni lootọ ni baba naa ti lọ.
Irọlẹ oni ọjọ Aje si ni wọn yoo fi iyoku ara Baba Legba fun ilẹ nile rẹ nilu Abeokuta nilana ẹsin Musulumi.
Oríṣun àwòrán, Others
Ọdun 1974 ni Baba Legba dara pọ mọ ikọ osere tiata Awada kerikeri labẹ akoso Moses Olaiya, taa mọ si Baba Sala.
Nigba miran, Baba Legba tun maa n ba awọn akẹẹgbẹ rẹ ninu isẹ tiata sere itage, awọn bii Bolaji Amusan taa mọ si Mr Latin ati Segun Ogungbe.
Gẹgẹ bi ọmọ Baba Sala to kede iku oloogbe naa loju opo Facebook rẹ, Adejumọ Boisala Emmanuel ti wi, Baba Lẹgba maa n se babalawo ninu ere tabi ọlọpaa.
Temitope Akinnusi: Ọ̀pọ̀ iléeṣẹ́ ló takú láti gbà mí síṣẹ́ torí mo ní ojú kan
Sugbọn o ni lọpọ igba, alawada ni oloogbe naa ati baba Sala saba maa n se ninu ere.
Adejumọ fikun pe Sunday Omobolanle ni baba naa n jẹ tẹlẹ, ko to lọ si Mecca, to si yi orukọ rẹ pada si Yekeen.
O wa gbadura pe ki Ọlọrun tẹ oloogbe naa safẹfẹ rere.
Akeugbagold Twins: Ilé ẹjọ́ fi afurasí méje pamọ́ sọ́gbà ẹ̀wọ̀n lórí ẹ̀ṣún ìjọmọ́gbe
Oríṣun àwòrán, Akeugbagold/Facebook
Ile ẹjọ Majisireti kan to kalẹ silu Ibadan ti paṣẹ pe, ki awọn afurasi mejeeje ti wọn fẹsun kan pe wọn ji ibeji Aafa Taofeek Akeugbagold gbe lọ fara pamọ sahamọ.
Adajọ ni ki wọn ko awọn afurasi mejeeje naa lọ si ọgba ikọ ọlọpaa to n tako iwa idigunjale, SARS nilu Ibadan.
Awọn mejeeje ni wọn fẹsun kan pe wọn ji awọn ọmọ naa ko ni ọjọ kẹẹdọgbọn, oṣu kẹrin, ọdun 2020.
Orukọ wọn ni Mohammed  Bashir, ẹni ọdun mẹtalelọgbọn, Oyeleye Opeyemi ẹni ọdun mẹẹdọgbọn, Olumide Ajala ẹni ọdun mẹrindinlogoji ati Taiwo Rildwan ẹni ọgbọn ọdun.
Oríṣun àwòrán, Akewugbagola
Ìlànà IVF là fi bí ìbejì tẹ gbé lẹ́yìn idaduro ọdún méjìlá, ẹ jọ̀ọ́, ẹ tú wọn ṣílẹ̀ - Akeugbagold, aya rẹ bẹ̀bẹ̀.
Awọn yoku ni Rafiu Mutiu ẹni ọdun marundinlogoji, Fatai Akanji ẹni ọdun mọkandinlaadọta ati Rafiu Modinat ẹni ọdun mọkandinlọgbọn.
Ọga ọlọpaa Adegboye to ṣafihan awọn ọdaran naa nile ẹjọ majisireeti ọhun ni, wọn gba miliọnu mẹrin owo itanran lọwọ baba awọn ibeji naa, ki wọn to fi awọn ọmọ naa silẹ.
Inú jìn! Akitiyan ọmọ'ṣẹ́ mi tó wà lára àwọn tó jí ìbejì mi gbé kò kéré níg
Ẹsun marun un ni wọn fi kan meji lara awọn afurasi naa, eyiun, Rafiu Mutiu ati Rafiu Modinat, ti wọn gba pe kawọn afurasi ọhun fi awọn ibeji ọhun pamọ sinu ile wọn.
Afurasi kẹfa, Fatai Akanji, nikan ni agbejọrọ wa ṣoju rẹ nilẹ ẹjọ naa, ti awọn to ku ko si ni agbẹjọrọ to n soju wọn.
Igboho, Ajimobi, Makinde àti àwọn ọlọ́pàá ṣe bẹbẹ kí n tó rí ìbejì mi gbà padà
Adajọ Emmanuel  Idowu kọ lati gba oniduro fun gbogbo wọn.
Lẹyin ti ko gba pe wọn ko jẹbi lo ni ki wọn ko gbogbo wọn lọ si ọgba ẹwọn ọlọpaa SARS, ti o si sun igbẹjọ naa si ọjọ kejila, oṣu kẹwaa, ọdun yii.
akeugbagold video
ECOWAS: Aàrẹ Ghana, Nana Akufo-Addo ti di aàrẹ ẹgbẹ́ ìṣọ̀kan ilẹ̀ adúláwọ̀ tuntun
Oríṣun àwòrán, @moigovgh
Ajọ orilẹ-ede iwọ oorun ilẹ Adulawọ, Economic Community of West Afircan State ti yan Aarẹ ilẹ Ghana, Nana Akufo-Addo lati ma tukọ ajọ ECOWAS bayii.
Wọn yan aarẹ yii nibi ipade to n waye ni Niamey to jẹ olu ilu orilẹ-ede Niger loni ọjọ Aje.
Ipade ẹlẹẹkẹtadinlọgọta iru rẹ lo n lọ lọwọ.
Aarẹ Ghana lo n gba a lọwọ aarẹ Muhammadou Issoufou tó jẹ aarẹ ilẹ Niger.
Oríṣun àwòrán, @konkrumah
Awọn ipenija to wa niwaju aarẹ Akufo Addo bayii:
Nipi apero naa ni wọn ti sọrọ nipa ipenija to wa niwaju ajọ yii lasiko yii pe:
Temitope Akinnusi: Ọ̀pọ̀ iléeṣẹ́ ló takú láti gbà mí síṣẹ́ torí mo ní ojú kan
Àṣìṣe ọlọ́pàá àti Adájọ́ sọ mí di ẹni tí wọ́n dájọ́ ikú fún, ọpẹ́lọpẹ́ Fayoṣe tí ko buwọlu
Fìdíhẹẹ́ ní Banji Akintoye nínú YWC, lílọ ni yóò lọ - Tola Adeniyi
Akomolede ati Aṣa lori BBC: Mọ̀ si nípa oríṣìí ẹ̀ka ìsọ̀rí ọ̀rọ̀ àti ìwúlò wọn
BBC Yoruba tun ti de laarọ yii lati la wa lọyẹ nipa ẹkọ ede Yoruba lori eto wa Akọmọlede ati Aṣa.
Lọsẹ yii, aya Adeyemo ni yoo maa kọ wa lẹkọọ nipa Isọri ọrọ ninu gbolohun Yoruba ati itumọ rẹ.
Bakan naa ni yoo sọ fun wa orisi isọri ọrọ to wa, ba se n lo wọn ati anfaani wọn.
Ẹ wa kọ ẹkọ pupọ nipa asa ati ede wa, ko maa baa parun.
Alaafin: Ọmọ ọdún 17 ní Ayaba Abibat Adeyemi nígbà tó fẹ́ ọkọ rẹ̀
Oríṣun àwòrán, Others
Ọba alade nilẹ Yoruba jẹ ẹni ọwọ ati ẹni apọnle, ti awọn araalu si maa n bu ọla to pọ fun wọn.
Lara awọn ohun tawọn ọba yii si maa n fi se ọla ni nini olori tabi ayaba puọ lọọdẹ wọn.
Bẹẹ si ni ọmọ sori ni aafin Ọyọ, nibi ti Ọba Lamidi Olayiwola Adeyemi Kẹta ti ni ayaba to pọ lọọdẹ.
Amọ ko si bi awọn ayaba naa ti pọ to ti ayaba akọkọ ko ni da yatọ, idi si niyi to fi se pataki lati mọ nipa aya akọkọ ti ọba Adeyemi gbe sile.
Abibat Nihinlola Oladele ni orukọ abisọ olori agba laafin Ọyọ lọwọlọwọ bayii, ọjọ kẹtalelogun osu Kejila ọdun 1938 si lo dele aye.
Ọmọ bibi agboole Lagunna ladugbo Agunpopo nilu Ọyọ ni Olori Abibat, kii si se ajeji rara si AafinỌyọ.
Oríṣun àwòrán, Others
Nigba to fẹ Lamidi Olayiwola Adeyemi lo di Abibat Nihinlola Adeyemi.
Iya Adodo ni ọpọ eeyan n pe, gẹgẹ bo se wọpọ lati maa da awọn olori agba pe laafin, eyi to da lori ojuse wọn.
Olori agba naa, to ti le ni ẹni ọgọrin ọdun kii se iyawo mọ fun ọba alade naa, a si lee pe ni iya rẹ nitori aajo ati itọju to ti n se fun lati ọpọ ọdun wa.
Bẹẹ si ni Iya Adodo ni ọpọ ojuse to n se ninu aafin, eyi ti asa Yoruba gbe le lọwọ.
Oríṣun àwòrán, Others
Ọpọ eeyan si lo ri olori agba bii ẹni to ko ni mọra, iya rere ati onifarada ẹda, ti kii kanra mawọn ọdọ ati olori kekere.
Gẹgẹ bi a se gbọ, eeyan nii mu ni mọ eeyan lọrọ ọba Adeyemi ati aya rẹ akọkọ nitori lati ipasẹ aburo rẹ obinrin ni wọn ti pade.
Ile ẹkọ girama kannaa ni Abibat ati aburo Lamidi naa n lọ, ọdun 1956 si ni wọn jọ pade.
Olori Abibat ko si ju ọmọ ọdun mẹtadinlogun lọ nigba ti wọn mọ ara wọn, ti wọn si se igbeyawo lasiko ti obinrin naa wa nile ẹkọ girama.
Ni asiko yii, ọba Adeyemi ko tii gori itẹ awọn baba nla rẹ, ti ko si ti ye rara pe ori ade ni oun bi o tilẹ jẹ pe ọmọ Alaafin ana ni.
Oríṣun àwòrán, Others
Awọn mejeeji ko lee sọ ibi ti ori n ba ẹsẹ wọn re, sugbọn pẹlu ifẹ nla to wa laarin wọn, wọn gba pe ọla yoo dara.
Ọjọ ori ọba Adeyemi ati olori akọkọ rẹ sunmọ ara wọn pupọ, osu lasan si ni wọn gba lọwọ ara wọn.
Osu Kẹwa ọdun 2020 ni Alaafin Adeyemi yoo pe ẹni ọdun mejilelọgọrin, nigba ti Ayaba Abibat yoo pe ẹni ọdun mejilelọgọrin losu Kejila ọdun.
Olori Abibat tẹle ọkọ rẹ silu Eko nibi to ti n sisẹ bii osisẹ nileesẹ adojutofo kan.
Oríṣun àwòrán, Oba Lamidi Olayiwola Adeyemi kẹta
Nibẹ si ni Olori agba yii ti kọ isẹ aransọ taa mọ si Telọ, ilu Eko yii si ni wọn bi ọmọ mẹta si.
Lẹyin ti ọba Adeyemi gori itẹ awọn baba rẹ ni wọn tun bi obinrin meji si, ti apapọ ọmọ ti wọn bi jẹ marun, obinrin mẹta ati ọkunrin meji.
Iya Adodo lo bi ọmọbinrin ati ọmọkunrin akọkọ fun Ọba Adeyemi, eyi ta lee pe ni Bẹẹrẹ ati Arẹmọ laafin Ọyọ.
Gbogbo awọn ọmọ to wa laarin Olori Abibat ni wọn n se daadaa, ti wọn si ti laami laaka ninu isẹ ti wọn yan laayo.
Akomolede ati Aṣa lori BBC: Mọ̀ si nípa oríṣìí ẹ̀ka ìsọ̀rí ọ̀rọ̀ àti ìwúlò wọn
Afihan pe Olori Abibat Nihinlola Adeyemi koni mọra lo farahan pẹlu bo se se koriya fun ọkọ rẹ lati ni ayaba pupọ, ti ko si si ija laarin wọn.
A wa gbadura pe Ọlọrun yoo tubọ lọra ẹmi Alaafin ati Olori rẹ agba, ki wọn le lo ara wọn gbo si.
Oba Olajide Olayode: Ó pe ọlọ́pàá láti yanjú aáwọ̀ ìlú lórí owó orí, bílísì bá dé
Awọn ọba alaye nilẹ Yoruba ni ọwọ nla gidi, tawọn araalu si maa n wa riri fun wọn.
Ojuse awọn ọba si ni lati pa ina aawọ to ba fẹ suyọ laarin ilu, ko to di rogbodiyan.
Amọ wahala nla kan bẹ silẹ lọdun 1969 nilu Ogbomoso to wa nipinlẹ Oyo bayii, eyi to kọja agbara ọba, koda, o tun mu ẹmi rẹ lọ pẹlu.
A si le pe itan yii ni apa keji Ogun Agbekoya nitori ara afikun owo ori tawọn agbẹ n ja fun lo fa sababi iṣẹlẹ yii, gẹgẹ ba ṣe ka a loju opo itakun agbaye.
Oríṣun àwòrán, Others
Ọjọ nla, ọjọ manigbagbe ni ọjọ kinni oṣu Keje ọdun 1969 nilu Ogbomoso lasiko ti ogun abẹle n lọ lọwọ ni Naijiria.
Asiko yii naa tun ni ogun Agbekoya n waye nilu Ibadan eyi to bẹ silẹ nitori afikun owo ori tijọba ṣe fun awọn agbẹ.
Ọba Soun tilẹ Ogbomoso nigba naa ni Ọba Immanuel Olajide Olayode Keji, o si wa laafin rẹ to n dari ilu, bẹẹ lo n fi oye da awọn ọtọkulu ilu lọla.
Gẹgẹ baa se gbọ latẹnu iya agba kan nilu Ogbomoso, Ọba Olayode, lasiko to gori itẹ jẹ ni ti aye n fẹ nitori inu gbogbo ọmọ Ogbomoso lo dun lasiko to jọba lọdun 1967.
Oríṣun àwòrán, Others
"Koda orin ti wọn n kọ nigba naa ni "" Olayode jọba, ilu toro nini..."", ti gbogbo ilu si n tuba tusẹ lasiko rẹ."
Ni ọdun 1969 ni Ọba Olayode fi oye Asipa Ogbomoso da Ajagunfẹyinti Benjamin Adekunle, ti ọpọ eeyan mọ si Black Scorpion lọla, lai mọ pe isẹlẹ manigbagbe kan yoo waye laipẹ sigba naa.
Lẹyin ọjọ diẹ ti ayẹyẹ ifinijoye naa waye, ni awọn agbẹ ati ọdẹ nilu Ogbomoso taku pe awọn ko le san iye owo ori ti wọn bu fun awọn, ti wọn si n bẹ ọba Olayode lati bawọn se adinku rẹ.
Temitope Akinnusi: Ọ̀pọ̀ iléeṣẹ́ ló takú láti gbà mí síṣẹ́ torí mo ní ojú kan
Asiko yii naa si ni irufẹ ibeere yii n waye nilu Ibadan, eyi to papa di Ogun Agbekoya.
A gbọ pe Ọba Olayode da ọjọ fawọn agbẹ lati wa ba se ipade laafin lati dijọ fẹnuko lori iye owo ori ti wọn yoo san.
Nigba ti ọjọ pe, awọn agbẹ ati ọdẹ peju biba si aafin ọba lai mọ pe ọba naa ti ransẹ pe awọn agbofinro, pe ki wọn maa bọ lati koju awọn eeyan naa.
O ni pẹlu ọwọ lile latọdọ awọn agbofinro, eyi yoo jẹ ki wọn gba iye owo ori ti wọn ni ki wọn san tipatipa.
Mayowa Omoniyi: Kò sí orin Obey, Sunny Ade abí tàkasúfèé tí ń kò le ta gìtá sí
Gẹgẹ bi ẹni ti isẹlẹ naa soju rẹ ti sọ fun BBC Yoruba, bi awọn ọlọpaa naa ti n bọ lati Ibadan, oju wọn kọrẹ lọwọ, bi wọn si se wọ ilu Ogbomoso ni wọn kọju oro sawọn araalu ti ko mọwọ mẹsẹ.
Iro ibọn n dun lakọ-lakọ, ti ọpọ ẹmi si n bọ titi ti ilẹ fi su lọjọ naa, koda, iya agba to ba wa sọrọ ni diẹ lo ku ki ibọn ba oun lasiko ti oun n tilẹkun isọ awọn.
Amọ o ni ibọn ba ọmọbinrin kan to n kiri ila lọ loju popo, to se alabapade awọn ọlọpaa naa, ti ibọn si gba ẹmi rẹ.
Ogbologbo ijapa l'aafin Sọun
Ni kete tawọn agbẹ ati ọdẹ gbọ nipa iporogan to n waye laarin ilu, wọn faraya, awọn naa bẹrẹ iwọde lọ saarin ilu, bẹẹ ni wọn n kọrin owe, tawọn ọlọpaa si n koju wọn.
Ọṣẹ ti awọn ọlọpaa ṣe laarin ilu naa gba odi, awọn ọdẹ, agbẹ ati araalu lapapọ fa ibinu yọ, wọn ba ọpọ dukia to wa ninu aafin jẹ, ti wọn si tun sọ ina saafin Ọba Layode naa.
Ṣugbọn lasiko tawọn agbofinro n pitu ọwọ wọn niwaju aafin fawọn agbẹ ati ọdẹ yii, to fi de aarin ilu lapapọ, diẹ lara awọn afẹhonu han yii ti yọ kẹlẹ wọnu aafin Soun, ti wọn si ni o di dandan ki ọba faye silẹ lọjọ naa.
Akomolede ati Aṣa lori BBC: Mọ̀ si nípa oríṣìí ẹ̀ka ìsọ̀rí ọ̀rọ̀ àti ìwúlò wọn
Iya agba ni, Ọba Layode naa kii se ọba yẹpẹrẹ ti wọn kan le pa tuẹ bii ẹni pa adiẹ nitori oun gan le pawọda nilana ti ibilẹ pẹlu oogun abẹnu gọngọ.
Wọn ni ọba yii parada di orisirisi nnkan bii ologbo, okuta ,titi de ori ọmọ tuntun, ti ọkan lara awọn ayaba gbe pọn, nigba tawọn oluwọde yii wọnu iyẹwu rẹ.
Amọ awọn eeyan naa pasẹ fun ayaba lati gbe ọmọ naa kalẹ nitori awọn ko ri gbọ pe ayaba kankan bimọ laafin lasiko igba naa.
Oríṣun àwòrán, Others
Ọba Layode papa parada di eeyan, tawọn afẹhonu han naa si pa a sinu aafin rẹ, wọn la ọfun rẹ, ge e lori, ti wọn si tun yọ nnkan ọmọkunrin rẹ.
"Koda, a gbọ pe wọn pin ẹran ara rẹ yẹlẹ yẹlẹ ni, ti wọn si kun ni ijanja, idi si ree ti wọn se maa n pe awọn ara Ogbomoso nigba miran pe ""Ogbomoso a pọba jẹ."""
"Esi ti awọn naa si maa n fọ pada ni pe, ""o ni ohun ti ọba se, ki wọn to pa a, nitori ti ko ba si ẹsẹ, ẹsẹ kii dede sẹ""."
Baby abandoned on dunmpsite: Mo ti bímọ mẹ́rin tẹ́lẹ̀ fún bàbá méjì nínú òṣí- Dupe Ogbomos
Itan yii ko tii tan sibẹ, a gbọ pe wọn gbe ori ọba Olajide Olayode atawọn ẹya ara rẹ yoku sọwọ, wọn n jo yika ilu pẹlu ẹjẹ bala-bala ati orin eebu, ti gbogbo ilu Ogbomoso si daru lọjọ naa.
Ohun ti wọn fun eṣu, eṣu gba a lọjọ naa, ti ọpọ dukia si bajẹ laarin ilu, o kere ẹmi eeyan to le ni ọgọrun ba iṣẹlẹ naa rin.
Kii si ṣe ọba nikan ni eekan ilu ti ẹmi rẹ bọ sinu laasigbo ọhun, koda ẹmi awọn ijoye kan gan lọ si, ti ẹjẹ nla si san nilu Ogbomoso lọjọ naa.
Nibi ti ọrọ naa buru de, ọgọọrọ ọlọpaa ati ọmọ ologun ti wọn fi ransẹ silu Ogbomoso ko lee dẹkun laasigbo naa, tori ọpọ dukia lo bajẹ sinu iṣẹlẹ naa, ti ọpọlọpọ oku si sùn pẹlu.
'Oyenusi ló mú mi wọ ẹgbẹ́ adigunjalè kó tó di pé mo b'Ólúwa pàdé'
Bẹẹ ni ọwọ ọlọpaa ba lara awọn eeyan ko n gbe ori ọba jo kiri ilu naa, ti wọn si ko wọn wa silu Ibadan fun ẹsun ipaniyan ati idaluru.
A gbọ pe ọpọ lara awọn ti wọn ko si ahamọ nilu Ibadan lori isẹlẹ ọhun ni ko pada mọ silu Ogbomoso, ti awọn ẹbi rẹ ko si mọ boya o ku ni tabi o sọnu.
Amọ lẹyin o rẹyìn, alaafia jọba, ti ilu Ogbomoso si pada tuba tusẹ titi di oni, bi o tilẹ jẹ pe nnkan to dara ti bajẹ saaju.
Owu Water Fall: Ọba Oyewole ni ibùdó ìrìn àjò afẹ́ gidi ni àmọ́ ọ̀nà ibẹ̀ burú jáì
Good luck fish: Ààrẹ Zambia ṣ'èdárò Ẹja akóredé tó papòdà
Oríṣun àwòrán, Facebook/Edgar Lungu
Aarẹ orile-ede Zambia, Edgar Lungu ti darapọ mọ ogunlọgọ ọmọ ilẹ naa ti wọn n ṣe idaro ẹja nla kan to ku ni fasiti Copperbelt to tobi sikeji lorilẹ ede naa.
Ibanujẹ dori agba kodo ni Fasiti Copperbelt nibi t'awọn akẹkọọ ti tan ina abẹla ti wọn si rin kaakiri ile ewe naa lati kẹdun ẹja Mafishi to jẹ Ọlọrun nipe.
Fun bi ogun ọdun sẹyin, awọn akẹkọọ Fasiti Copperbelt gbagbọ pe ẹja Mafishi maa n gbe ire ko wọn ninu idanwo.
Akomolede ati Aṣa lori BBC: Mọ̀ si nípa oríṣìí ẹ̀ka ìsọ̀rí ọ̀rọ̀ àti ìwúlò wọn
Olori awọn akẹkọọ, Lawrence Kasonde ṣalaye pe o to ọdun mejilelogun ki o to jade laye, ati pe ẹja naa ti gbe inu omi lọgba fasiti Copperbelt fun ogun ọdun o kere tan.
Kasonde fikun ọrọ rẹ pe iwadii si n lọ lọwọ lori ohun to ṣekupa ẹja akorede ọhún.
Kasonde sọ fun BBC pe ileewe naa ko tii sin Matfishi, o ni awọn n gbero lati fi oogun ti ko ní jẹ kí oku rẹ bajẹ si ara ẹja naa ki awọn le maa rii wo lọ.
Ninu ọrọ tiẹ, Aarẹ Lungu ṣe ayalo ọrọ ti ajaja ominira ilẹ India, Mahatma Gandhi sọ pe ilọsiwaju ati igoke agba orile-ede kankan da lori iha to kọ si awọn ẹranko rẹ.
Aarẹ Zambia ni titi laelae lorilẹ ede naa yoo maa ṣe iranti Matfishi to lọ.
Ẹwẹ, olori ẹgbẹ alatako ni Zambia, Hakainde Hichilema naa kẹdun pẹlu fasiti Copperbelt lori iku Matfishi.
Tola Ogundipe: Òṣìṣẹ́ mẹ́rin bọ́ sí gbaga ọlọ́pàá lórí ikú ọ̀gá wọn tó rì sómi
Oríṣun àwòrán, talktolaswa/Instagram
Igbakeji Ọga Agba ileeṣẹ to n risi ọrọ owo ori, Price Water Coopers , PwC Nigeria , Tola Ogundipẹ ti jade laye.
Ọjọ Satide ni wọn ti bẹrẹ si ni wa arakunrin naa lẹyin to wọ ọkọ oju omi ni ipinlẹ Eko.
Ọjọ Aiku ni wọn ri ọkọ oju omi naa amọ ti awọn ọlọpaa to n ṣiṣẹ lori omi si ri oku rẹ ni Ọjọ Aje.
Agbẹnusọ fun ileeṣẹ ọlọpaa nipinlẹ Eko, Muyiwa Adejọbi sọ wi pe, lootọ ni iṣẹlẹ naa waye, awọn oṣiṣẹ oloogbe mẹrin ni awọn ti fi ọrọ wa lẹnu wo.
O salaye wi pe, Kọmisọna ọlọpaa nipinlẹ Eko, Hakeem Odumosu ti paṣẹ iwadii idakọnkọ lori iṣẹlẹ naa.
'' A ti gbe iṣẹlẹ naa lọ si ẹka to n risi ọrọ iwa ọdaran ni Yaba, nipinlẹ Eko lati ṣe iwadii naa lẹkunrẹrẹ.''
''Ti iwadii ba pari, ileeṣẹ ọlọpaa yoo fi abajade han si gbangba.''
Ninu ọrọ ti ileeṣẹ Price Waterhouse Coopers fi lede, Ọga agba patapata ni Naijiria, Uyi Akpata sapejuwe Ogundipẹ to doloogbe naa, gẹgẹ bi ẹni to n ṣe iṣẹ rẹ doju ami.
Oríṣun àwòrán, Others
Ko to di oloogbe, Tola Ogundipe ṣiṣẹ gẹgẹ bi adari ẹka PwC Africa Tax , Assurance Leader for PwC Africa ati awọn ipo miran to dimu ninu ilẹeṣẹ PwC.
Ileeṣẹ Price Waterhouse Coopers ni awọn yoo fi ọjọ isinku rẹ lede lẹyin ijiroro pẹlu awọn ẹbi ati ara oloogbe naa.
Mayowa Omoniyi: Olùkọ́ rẹ̀ ní òun ni atagìtá ''Hawaiian guitar'' tó kéré jùlọ lágbàáyé
Omo ti yoo ba jẹ asamu, kekere ni yoo ti maa jẹ ẹnu samu samu.
Bẹẹ ni ọrọ Mayowa Omoniyi jẹ, ọmọ ọdun mẹtala to pegede ju agbalagba miran lọ ninu gita tita.
Nigba to n ba BBC Yoruba sọrọ, Mayowa ni baba oun lo kọ oun bi wọn se n ta jita, bakan naa si ni oun le tẹ duuru pẹlu.
O ni ko si orin Ebenezer Obey, Sunny Ade, takansufe tabi orin ẹmi ti oun ko le tẹ jita si gẹgẹ bii akọsẹmọsẹ atajita.
Nigba tawọn naa n sọrọ nipa bi Mayowa ti dangajia si ninu jita tita, Taiwo Omoniyi, tii se baba Mayowa ati ibeji rẹ, Kehinde fidi rẹ mulẹ pe Mayowa ti kọja ipo tawọn wa ninu jita tita.
Bakan naa ni olukọ to n kọ Mayowa ni ohun elo orin, Samson Akinola ni iwadi oun fihan pe lọwọ lọwọ bayii, Mayowa Omoniyi ni atajita to kere julọ lagbayee.
O ni ko si irufẹ orin ti Mayowa ko le ta jita si.
Penis Captivus: Nǹkan márùn-ún tí obìnrin àti ọkùnrin tó lẹ̀pọ̀ yóò ṣe láti yọ rèé
Oríṣun àwòrán, Others
Laipẹ yii ni iroyin jade nipa ọkunrin ati obinrin kan ti wọn lẹpọ loju ara ni ibi ti wọn ti n ba ara wọn lo pọ, idi ree ti ọpọ ọrọ fi n jade pe ki lo n fa irufẹ eyii.
Bi awọn kan ṣe n pariwo Magun lawọn oloyinbo naa n sọ pe, ko si babara nibẹ.
Ju gbogbo rẹ lọ eyi ni awọn ohun marun ti awọn oniṣegun oyinbo ka silẹ gẹgẹ bi ọna abayọ, bi nnkan ọmọkunrin ati ọmọbinrin ba lẹpọ tabi ha sinu ara wọn, lasiko ibalopọ.
Dokita Ezenwankwo lo fi ilanilọyẹ yii silẹ ninu ifọrọwanilẹnuwo kan to ṣe lori ohun to lee fa wahala yii.
Ohun akọkọ ti awọn ti nnkan yii ba ṣẹlẹ yoo se ni lati ma ṣe ko aya soke, ki wọn fi ọkan balẹ, i wọn si ke si awọn onimọ nipa rẹ fun iranwọ, iyẹn gẹgẹ bi dokita Ezenwankwo ṣe sọ.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ni ọpọ igba la ti gbọ iroyin kaakiri nipa bi nnkan awọn ọkunrin kan se ha soju ara awọn obinrin ti wọn n ba sere ifẹ.
Loju ọpọ ọmọ Yoruba, eyi kii se lasan nitori o lọwọ aye ninu ati oogun abẹnu gọngọ, to si nilo ilana ibilẹ lati tu awọn ololufẹ meji naa silẹ.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Nigba miran awọn eeyan maa n fi oju onisekuse ati alagbere wo awọn ololufẹ ti isẹlẹ naa ba sẹlẹ si, ti wọn ko si mọ pe ko si wahala kankan nibẹ.
Nigba miran, wọn yoo gbe iru awọn eeyan bẹẹ lọ sile iwosan tabi agọ ọlọpaa, ti wọn yoo si pe ero le wọn lori, eyi to tabuku ẹtọ ọmọniyan pupọ
Laipẹ yii si ni fidio kan n ja ranin-ranin lori ayelujara nipa ọkunrin kan to n sere ifẹ pẹlu iyawo ile ẹlomiran, ti nnkan ọkunrin rẹ si ha soju ara obinrin naa.
Iroyin naa ni wọn fa awọn mejeeji le ọlọpaa lọwọ nitori pe oogun abẹnu gọngọ lo mu ki awọn mejeeji lẹpọ.
Sugbọn ninu iwadii awọn onisegun oyinbo, alaye ti wa pe, ko si ohun to buru ninu ki nnkan ọkunrin ha soju ara obinrin.
Wọn ni iti ọgẹdẹ lasan ni, ti ko to ohun ta a yọ ada si.
Gẹgẹ bi Dokita Francis Ezenwankwo se wi, lasiko to n ba BBC sọrọ, bi nnkan ọkunrin ba ha soju ara obinrin, eyi ni oloyinbo n pe ni 'Penis Captivus.'
O ni lasiko ere ifẹ, ẹjẹ lo maa n rọ sinu nnkan ọkunrin, ti yoo fi le gbagidi, ti yoo si maa tobi si to ba wọ oju ara obinrin tan.
Oríṣun àwòrán, Youtube viral
Amọ ogiri oju ara obinrin, to kun fun isan, lee ran lati tobi si tabi kere si lasiko ibalopọ.
O si seese ki irufẹ isan to gbe oju ara obinrin ro yii dasẹ silẹ lasiko ti nnkan ọkunrin ba n sisẹ lọwọ nibẹ.
Nigba miran, o ni o seese ki isan oju ara obinrin naa ran ju bo se yẹ lọ, eyi si lee mu ki abawọle oju ara naa kere si.
Lasiko ti eyi ba waye, yoo mu ko nira fun nnkan ọkunrin lati jade kuro loju ara obinrin, paapaa ti nnkan ọmọkunrin naa ba si le gbagidi sibẹ.
Tóò bá fún ọkùnrinn lóúnjẹ́ tóo tẹ́ kiní yẹn sílẹ̀ fún un dáadáa... - Yinka TNT
Dokita Ezenwankwo ni ko si ohun to jọ Magun tabi oogun abẹnu gọngọ ninu isẹlẹ yii, abuda ara lo n sisẹ tiẹ.
Isẹlẹ yii kii saba waye lasiko ti takọ-tabo ba n sere ifẹ, amọ to ba waye, ko si ohun ijaya rara nipa rẹ.
Ilana isegun oyinbo fi ye wa pe, ti ololufẹ meji ba ha sinu ara wọn lasiko ere ifẹ, wọn ko nilo lati paya rara, ifarabalẹ nikan ni wọn nilo.
Dokita naa ni kii se aarin awọn ti kii se lọkọlaya ni isẹlẹ yii ti maa n waye nikan, amọ o tun maa n waye laarin tọkọ-taya pẹlu.
'Ó ṣe pàtàkì kí obìnrin gbádùn ìbálòpọ̀ nítorí...'
Koda o fikun pe, obinrin kan ti pe oun lori aago ri nigba ti oun ati ọkọ rẹ lẹpọ lasiko ere ifẹ ninu ile, ti oun si gba awọn mejeeji nimọran lati farabalẹ, titi ti ara wọn yoo fi walẹ.
Ti ara wọn ba ti balẹ, yoo rọrun fun nnkan ọkunrin lati jade kuro loju ara obinrin to ha si ni wọọrọwọ, laisi isoro kankan.
Ni ọjọ diẹ sẹyin, fidio kan lu ayelujara pa nibi ti ọkunrin ati obinrin kan ti lẹpọ nibi ibalopọ, ti nnkan ibalopọ wọn ko si lee yọ kuro ninu ara wọn.
Awọn onimọ isegun oyinbo ni awọn iṣẹlẹ bẹẹ maa n waye, ṣugbọn kii saba n wọpọ.
Ṣaaju ni dokita Ezenwakwo Francis ṣalaye fun BBC pe, isẹlẹ naa ko lọwọ aye ninu, kii si se Magun, gẹgẹ bi ẹya Yoruba ti maa n pe e.
Amọ o ni isan oju ara obinrin lo n se ohun to wu, ifarabalẹ laarin ololufẹ mejeeji si ni ẹrọ rẹ lẹyin akoko diẹ, o ni bi wọn ba ti fun won loogun orun tabi sun, ara yoo tu wọn.
Iroyin naa mu awuyewuye lọwọ laarin awọn ọmọ Yoruba, bi awọn kan se tako Dokita to ni bi ololufẹ meji ba lẹpọ, kii se magun, lawọn miran fara mọ.
Mistura Oseni Akintunde: Ara múmú kìí ṣe oríṣun ìfipábánilòpọ̀, ìran àwòjù ló ń fà á
Idi ree ti BBC Yoruba fi tọ awọn onisẹse lọ lati mọ boya wọn nigbagbọ ninu ọrọ dokita yii, bi ko ba si ri bẹẹ, ki lo n fa ki ololufẹ meji lẹpọ lasiko ere ifẹ, ninu igbagbọ awọn baba wa.
Ninu ọrọ to ba BBC News Yoruba, Babalawo Idowu Olukunle, Akoda Awo ṣalaye pe, ko si ootọ ninu ọrọ ti awọn dokita iṣegun Oyinbo sọ naa.
Akoda Awo ṣalaye pe, ti awọn akọ ati abo to ba lẹpọ lasiko ibalopọ, bi awọn agba ko ba ṣe ẹ̀rọ̀ rẹ fun wọn lasiko, afaimọ ki ọkan tabi awọn mejeeji ma jade laye.
O ni lati igba iwaṣẹ ni Magun ti wa, ti awọn agba fi n ṣe iṣọra fun awon iyawo wọn, paapaa julọ, ti wọn ba ti n fura pe iru obinrin bẹẹ n rin awọn irin ti ko tọna.
Oríṣun àwòrán, Others
O fi kun un pe, ẹya gbogbo lo ni agbara ti Eleduwa fun un; lara agbara ti Eleduwa si fun ilẹ Yoruba ni Magun, ma debẹ si lẹrọ rẹ.
Agba awo naa ni ohun to dara ju ni ki awọn eeyan maa duro ti nnkan won, ki wọn maa si ṣe ojukokoro si obinrin olobinrin.
Akoda awo ṣalaye siwaju sii pe, bi ọkunrin ba ni iyawo to si ṣakiyesi pe awọn ọkunrin miran ko jẹ ko sinmi, yoo wa nnkan to ba mọ lati fi ṣọ iyawo rẹ.
Baba Awo Idowu Olukunle ni orisirisi magun pọ pupọ, ko si lopin, ohun ti wọn ba fi se, si ni yoo sọ nipa eewọ rẹ, amọ diẹ lara orisi Magunto mẹnuba ree:
Eyi ni irufẹ Magun ti yoo mu ki ọkunrin ati obinrin  lẹpọ bi wọn ba ti n ṣe ere ifẹ, ti wọn ko si ni lee ya.
Irufẹ Magun yii lo saba n fara han lori ayelujara lode oni.
Mayowa Omoniyi: Kò sí orin Obey, Sunny Ade abí tàkasúfèé tí ń kò le ta gìtá sí
Iru Magun yii ni yoo ma mu ki ọkunrin to ba lu maa pongbẹ fun omi, ni kete ti o ba ti ba obinrin ti wọn ba le ni magun ni aṣepọ.
N ṣe ni ọkunrin bẹẹ yoo maa pongbẹ omi, koda bi wọn gbe odindi odo fun un pe ko mu, ko ni tan oungbẹ naa.
Omi yii ni yoo si mu, titi ti yoo fi gba ọrun alakeji lọ.
Bi ọkunrin ba ti lu Magun yii lara obinrin, ọna bi yoo ṣe takiti ni yoo maa wa, bi o ba si ti le e takiti bayii, ọrun laalaa ni.
Baby abandoned on dunmpsite: Mo ti bímọ mẹ́rin tẹ́lẹ̀ fún bàbá méjì nínú òṣí- Dupe Ogbomos
Bi eeyan ba ti lee lu iru magun yii lara obinrin, yoo maa gun un tabi ṣe e bii ko kọ bi akukọ ni.
Ni kete ti o ba si ti lee kọ fun igba mẹta, ẹlẹkọ ọrun yoo polowo fun un ni.
Bi ọkunrin ba lu Magun yii, yoo maa wa ẹyin kiri ni, to ba si ti rii ni yoo jade laye.
Ọkunrin to ba ba obinrin ti wọn ba le iru Magun yii si lara, ko gbọdọ jẹ ila, ni kete to ba ti le fi ẹnu kan ila, ọrun laala niyẹn.
Baba awo fi kun un pe ohun ti wọn ba le fi pilẹ Magun bẹẹ, ni yoo maa wu ọkunrin bẹẹ lati jẹ tabi se.
Temitope Akinnusi: Ọ̀pọ̀ iléeṣẹ́ ló takú láti gbà mí síṣẹ́ torí mo ní ojú kan
Magun Mafogọta:
Gọta ni yoo ma wu ọkunrin to ba lu Magun yii lati fo, ni kete ti o ba si ti fo o bayii, yoo jade laye ni.
Bi ọkunrin to ba lu iru Magun yii ba ti jẹ kengbe, ọrun laala.
Ọkunrin to ba ba obinrin ti wọn ba le iru Magun yii si lara laṣepọ, yoo maa pongbẹ lati jẹ ibẹpẹ ni. Ni kete to ba si n ti fi ẹnu kan an, ọrun laala o.
Akoda awo wa rọ awọn ọkunrin lati jinna si ṣina, ki wọn tọju obinrin wọn nitori ohun to ba wu ọkọ iyawo lo lee fi sọ iyawo rẹ.
Ifetedo FC: Ọ̀rẹ́ olóògbé ní Damilola kò sàìsàn, ó ń gbá bọ́ọ̀lu lọ́wọ́ ló kú
Oríṣun àwòrán, @bridgeradio987
Ọmọ ẹgbẹ agbábọ́ọ̀lù kan ni ìpińlẹ̀ Osun ti wọ́n pe orúkọ rẹ̀ ni Damilola, ló dédé subu lulẹ̀, tó sì kú ni àsìkò tó wà lórí pápá ni àgbègbè Ido ni ìpínlẹ̀ náà.
Gẹ́gẹ́ bi àwọn ti ọ̀rọ̀ náà sójú wọ́n ṣe sọ, wọ́n lo n gbá bọ́ọ̀lù fún ẹgbẹ́ agbábọ́ọ̀lù rẹ̀, Premier Football Club, Ofetedo lọ́wọ́, ló bá subú.
Ìròyìn sọ pé ni kété ti ọ̀rọ̀ náà ṣẹlẹ̀ ni wọ́n ti gbé ọmọkurin òun lọ si ilé ìwòsàn aládani kan fún ìtọ́jú.
"ilé ìwòsàn náà kò gbà á, bẹ́ẹ̀ ni wọ́n tún rù ú lọ si LAUTECH, ibẹ̀ ni wọ́n ti sọ fún wọ́n pé, ó ti jẹ́ Ọlọrún nípè.
Ipele ifẹsẹwọnsẹ keji lo ti fẹ́ gbá bọ́ọ̀lu wòmí n gbá a-sí -ọ, amọ se lo kan sùbu, ti kò sì dìde mọ́.
Kò fi àmì kankan hàn pé ó ṣe àìsàn rárá. Gbogbo ìgbà ló máa n gbá bọ̀ọ́lu fún ẹgbẹ́ agbábọ̀ọ̀lù rẹ̀,"" gẹ́gẹ́ bi ọ̀rẹ́ rẹ̀ ṣe sọ."
Wọ́n ti sin olóògbé náà nilu Ido Osun lọ́jọ́ ìṣẹ́gun.
Akiyesi Pataki: Àwòrán tí a lo tẹ́lẹ̀ to je ti egbe agbaboolu Knight FC kò ní í ṣe pẹ̀lú ìròyìn yìí.
Akomolede ati Aṣa lori BBC: Mọ̀ si nípa oríṣìí ẹ̀ka ìsọ̀rí ọ̀rọ̀ àti ìwúlò wọn
Donald Trump gbìyànjú nípa ètò àlááfíà ló jẹ́ kí n fàá kalẹ̀ fún àmì ẹ̀yẹ Nobel Peace Prize- Christian Tybring- Gjedde
Oríṣun àwòrán, Reuters
Wọn ti fa Aarẹ ilẹ Amerika, Donald Trump kalẹ fun ami ẹyẹ Nobel Peace Prize ti ọdun 2021.
Ọkunrin kan ti orukọ rẹ n jẹ Christian Tybring- Gjedde, to jẹ ọkan lara awọn ọmọ ile igbimọ aṣofin orilẹ-ede Norway lo fa Trump kalẹ fun ami ẹye naa.
Gjedde sọ fun ileeṣẹ iroyin Fox pe Aarẹ Trump yẹ lẹni to n gba ami ẹyẹ naa fun iṣẹ ribiribi to ti ṣe lati jẹ ki alaafia wa laarin awọn orilẹ-ede kan lagbaye.
"O ni ""ami ẹye ọhun yẹ Trump gan ni nitori o gbiynaju lati jẹ ki alaafia wa laarin awọn orilẹ-ede kan agbaye ju awọn eeyan miran to ti gba ami ẹyẹ naa ṣaaju rẹ."""
Ninu iwe to kọ si awọn igbimọ to n fun eeyan ni ami ẹyẹ ọhun, o sọ pe ijọba Trump gbiyanju lati lati jẹ ki alaafia gbilẹ laarin ijọba ilẹ United Arab Emirates ati Israel.
Oríṣun àwòrán, Reuters
Gjedde sọ fun ileeṣẹ iroyin Fox pe kii ṣe pe oun gba ti Aarẹ Trump to bẹ lo jẹ ki oun faa kalẹ fun ami ẹyẹ naa, ṣugbọn o n gbiyanju tirẹ to ba jẹ ni ti eto alaafia.
"O ni ""O yẹ ki awọn igbimọ to n ri si ami ẹyẹ ọhun wo ti awọn akitiyan Trump gẹgẹ bi ohun amuyẹ fun ami ẹyẹ ọhun, kii ṣe iwa rẹ."""
Aṣofin naa ni pupọ ninu awọn to ti gba ami ẹyẹ naa ṣeyin, bii Aarẹ ana l'Amẹrika, Barack Obama, ko ṣe to ohun ti Trump ti ṣe.
Mayowa Omoniyi: Kò sí orin Obey, Sunny Ade abí tàkasúfèé tí ń kò le ta gìtá sí
Ni Jigawa, àwọn obìnrin dáwó ra ọkọ̀ N1m láti máa fi gbé aláboyún ní iletò kan
Awọn obinrin kan ni ileto Bordo ni ipinlẹ Jigawa, ti da owo jọ fi ra ọkọ ti wọn fẹ maa fi gbe awọn alaboyun lọ sileewosan lasiko isẹlẹ pajawiri.
Awọn obinrin ileto naa ni awon da owo naa, lati lee dẹkuun ipenija ati iṣoro to rọ mọ gbigbe awọn alaboyun lọ si ileewosan, eyi to n koju wọn.
Lati ileto Bordo de ileto to sun mọ ọ ju jẹ kilomita mọkandilọgbọn, yatọ si pe ileto naa da wa, ọna to so o pọ mọ ibi ti ileewosan naa wa ko dara rara.
Arabinrin Halima Adamu to lewaju igbesẹ naa ṣalaye fun BBC pe, wọn bẹrẹ pẹlu eto ẹdawo laarin ọkọọkan awọn obinrin ni ileto naa.
O ni ẹgbẹrun kan Naira ni obinrin kọọkan labule naa fi bẹrẹ ẹdawo ọhun  loṣooṣu.
O ni eyi ni awọn da titi ti owo naa fi wọ miliọnu kan Naira, ti wọn lo ra ọkọ naa.
Adamu fi kun un pe ni bayii, ko si igbakugba ti awon ko lanfani lati maa gbe alaboyun to ba fẹ rọbi tabi ni iṣẹlẹ pajawiri.
O ni nigbakugba ti alaboyun ba ti nilo lati sare lọ fun ilera pipe, ẹgbẹrun meji naira pere ni ọkọ rẹ yoo san, ninu eyi ti won yoo ti yọ ẹgbẹrun kan ati ẹẹdẹgbẹta Naira fi ra epo sinu oko .
Mayowa Omoniyi: Kò sí orin Obey, Sunny Ade abí tàkasúfèé tí ń kò le ta gìtá sí
Obinrin naa ni wọn yoo si mu ẹẹdẹgbẹta naira to ku pamọ fun itọju ọkọ tori ọjọ iwaju.
O tun sọ siwaju sii pe, ọpọ igba l'awọn alaboyun naa maa n bimọ loju ọna.
Olori ileto Bordo, Alhassan Haruna fi to BBC leti pe, pẹlu bi ọkọ naa ṣe wa fun ríran awọn alaboyun lọwọ, sibẹ opopona ko dara.
O ni ọpọlọpọ awon obinrin naa ni yoo ti bimọ, ki wọn to de ileewosan.
Baby abandoned on dunmpsite: Mo ti bímọ mẹ́rin tẹ́lẹ̀ fún bàbá méjì nínú òṣí- Dupe Ogbomos
O wa rọ ijọba lati seranwọ lori atunse ọna naa.
Amọṣa, akọwe ajọ eleto ilera alabọde ni ipinlẹ Jigawa, Dokita Kabir Ibrahim salaye pe, o ti le ni ọgọfa ọkọ ti wọn ni kaakiri ọkan o j'ọkan awọn ileto nibẹ.
Bẹẹ si ni bii ọgọrun lo ti bajẹ ninu wọn.
Tortoise surgery: Àwọn dókítà fi wákàtí mẹ́fà ṣiṣẹ́ abẹ dóòlà ẹ̀mí ìjàpá tí ọkọ̀ gbá
Oríṣun àwòrán, Others
Dokita kan to jẹ onimọ nipa itọju ẹranko, Nura Abubakar to n ṣiṣẹ nile iwosan itọju ẹranko nipinlẹ Sokoto, ti ṣalaye ni kikun bi iṣẹ abẹ ti wọn ṣe fun ijapa ti ọkọ kan tẹ, ti igba ẹyin rẹ si fọ, ṣe lọ.
Dokita Abubakar sọ fun BBC pe, ọmọ ẹni to ni ijapa ọhun, Sadiq Sulaiman n fẹyin rin pẹlu ọkọ, lo fi ṣeeṣi gun ijapa naa lori, eyi to mu ki igba ẹyin rẹ fọ.
O ṣalaye pe kete ti ijamba ọhun ṣẹlẹ ni ọkunrin to ni alabahun naa gbe digba-digba lọ si ile iwosan kan niluu Argungu.
Ṣugbọn nigba ti apa ile iwosan Argungu ko kaa mọ ọ, ni olowo ijapa yii to fẹran ẹranko gbe e lọ sí Sokoto, nibi ti wọn ti ṣiṣẹ abẹ fun un.
Oríṣun àwòrán, Other
Dokita Abubakar ni, awọn dokita onimọ nipa itọju ẹranko mẹfa lo jọ ṣiṣẹ abẹ naa, o ni ohun to jẹ idunnu oun ni pe, ijapa naa ti gbadun bayii, o si ti n ṣere nile olowo rẹ.
Ohun akọkọ ti a ṣe ni lati fun ijapa naa ni itọju ni kiakia, eyi to jẹ ki ara rẹ balẹ di ọjọ keji nitori o ni ipalara to pọ gan an ninu ijamba to ṣe e,
Ẹwẹ, Sulaiman to ṣeesi fi ọkọ tẹ ijapa baba rẹ mọlẹ, wa fi idunnu rẹ han si bi iṣẹ abẹ ti wọn ṣe fun ẹranko naa ṣe yọri si rere.
Oríṣun àwòrán, Other
O ni ẹri ọkan oun ko ba ti jẹ ki oun gbadun, to ba jẹ pe ijapa naa ko ru u la ni.
Fọto ijapa ọhun ti kọkọ lu ori ayelujara pa, lẹyin ijamba ọkọ to ṣẹlẹ si i.
World suicide prevention: Iye àwọn tó ti gbẹ̀mí ara wọn rèé láàrin ọdún mẹ́rin ìjọba Buhari ní Nàìjíríà rèé
Oríṣun àwòrán, others
Mẹwaa n ṣẹlẹ ní duniyan, ẹni to kan lo mọ o. Njẹ o ti ẹ mọ iye awọn ọmọ Naijiria to ti gbẹmi ara wọn nitori bi ilu ti ri ni nkan bi ọdun mẹrin ṣẹyin?
Bi orilẹ-ede Naijiria ti darapọ mọ gbogbo agbaye lati ṣe ayajọ didena gbigba ẹmi ara ẹni, akọsilẹ ti fihan pe ọta le lugba eeyan o le mẹrin ni wọn ti ṣekupa ara wọn lorlẹede yìí lọdun mẹrin ṣẹyin.
Femi Falana: Mẹ̀kúnnù gbọ́dọ̀ ṣetán láti gba ẹ̀tọ́ wọn, ìjọba ti kùnà lórí ẹ̀tọ́ ọmọnìyàn
Nigba ti akori ti ọdun yìí jẹ́ ṣiṣiṣẹ pọ lati dena iwa pipa ara ẹni, eeyan 264  gbẹmi ara wọn laarin oṣu kinni ọdun 2017 sí oṣu kẹjọ ọdun 2020 yii.
Ipinlẹ Eko lo wa loke tente,  eeyan mẹtalelogun lo gbẹmi ara wọn lọdun mẹrin ṣẹyin nibẹ.
Akọsilẹ fihan pe eleyii yatọ si awọn eeyan mii to pa ara wọn ṣugbọn ti awọn akọroyin ko gbe sita.
Bẹẹ si ni iwa gbigba ẹmi ara ẹni lodi si ofin orile-ede Naijiria, koda ẹwọn ọdun kan ni ẹnikẹni to ba gbiyanju lati pa ara rẹ yoo fi gbára.
Adene Oluwabukola Deborah: Bàbá mi kò kọ́kọ́ fọwọ́ sí iṣẹ́ ìlù lílù ṣùgbọ́n....
Ipo kẹwaa ni Naijiria wa nilẹ Afrika ninu awọn orilẹ-ede ti iwa ipara ẹni tí wọ pọ julọ.
"Akọsilẹ fihan pe ogunlọgọ awọn eeyan yii lo mu kẹmika ""sniper"" rọrun nigba t'awọn miiran pokun so."
Suicide Prevention: ìwọ́de yìí wáyé láti gbógun ti pípa ara ẹni
Iwadii tiẹ tun fihan pe niṣe lawọn mii dana sun ara wọn ti wọn sì gba ibẹ dero ọrun.
Dokita Maymunah Yusuf Kadiri to jẹ onimọ nipa aarun ọpọlọ sọ pe ibanujẹ ọkan, ijakulẹ, airiṣẹṣe, ọti mimu ati oogun oloro wa lara awọn idi to n mu ọpọ gba ẹmi ara wọn.
Rashidi Yekini: Ijọba Kwara ti ṣetán látí má ṣèrántí gbajúgbajà agbábọ́ọ̀lù tó ti dolóògbé
Oríṣun àwòrán, Others
Gomina ipinlẹ Kwara, AbdulRahman AbdulRazaq ni eto ti n lọ lọwọ lati yi orukọ papaa iṣere wọn ni Ilorin si orukọ gbajugbaja agbabọọlu Rashidi Yekini to doloogbe.
Gomina Abdurazaq fi eyi lede lasiko ti o lọ ṣe abẹwo ikini si minisita fun ere idaraya ati idagbasoke awọn ọdọ, Sunday Dare ni ofisi rẹ ni ilu Abuja.
Abdulrazaq ni ijiroro awọn da lori ọna ati mu idagbasoke ba awọn ọdọ lawujọ.
O ni ijọba oun yoo fi abadofin ti yoo yi orukọ papa iṣere naa pada si orukọ Yekini, ranṣẹ si Ile Igbimọ Asọfin ni ipinlẹ naa.
Ninu ọrọ idupẹ rẹ, Minisita naa ni ọpọ igba ni awọn kọ lẹta si ipinlẹ Kwara, lati gbe igbesẹ ti ko ni jẹ ki orukọ gbajugbaja elerebọọlu naa parẹ lailai.
Oríṣun àwòrán, Others
Dare rọ ijọba ipinlẹ Kwara lati tẹsiwaju ninu igbiyanju wọn, lati mu idagbasoke ba awọn ọdọ ni agbegbe wọn.
O ni igbelarugẹ ati ipese iṣẹ fun awọn ọdọ lawujọ ni yoo mu ki iwa ibajẹ dinku lorilẹede Niajiria.
Ọjọ Kẹrin, Oṣu Karun un, ọdun 2012 ni agbabọọlu Naijiria naa papoda ni ilu Ibadan ni ẹni ọdun mejidinlaadọta.
O bẹrẹ ere bọọlu pelu UNTL Kaduna ni ọdun 1981, to si tẹsiwaju lọ darapọ mọ ikọ agbabọọlu Naijiria ati Yuroopu.
Nibẹ lo ti gba bọọlu fun ọdun mẹrin pẹlu ẹgbẹ agbabọọlu Vitoria Setubal ni  Portugal, to si tun gba ami ẹyẹ ẹni to gba bọọlu wọ inu awọn julọ ninu idije Primeira Liga ni saa ọdun 1993 si 1994.
Mistura Oseni Akintunde: Ara múmú kìí ṣe oríṣun ìfipábánilòpọ̀, ìran àwòjù ló ń fà á
Gẹgẹ bi agbabọọlu fun ikọ Naijiria, Yẹkini gba bọọlu wọ inu awọn ni igba mẹtadinlogoji, ti o si ṣoju Niajiria ninu idije gboogi marun pẹlu Idije agbaye meji.
Ni ibẹ ni o ti kọkọ jẹ ẹni akọkọ ti yoo gba bọọlu wọ inu awọn fun Naijiria ninu Idije Agbaye.
Ọdun 1993 ni o gba ami ẹyẹ Agbabọọlu Ilẹ Afrika to lamilaaka julọ.
Mistura Oseni Akintunde: Ara múmú kìí ṣe oríṣun ìfipábánilòpọ̀, ìran àwòjù ló ń fà á
Kii saba wọpọ ki eeyan ri obinrin Musulumi nita lati maa sisẹ wolii, gẹgẹ bawọn obinrin ẹlẹsin Kristẹni ti n se.
Amọ ti Wolii obinrin Mistura Oseni Akintunde yatọ, ẹni to n sisẹ wolii nilana ẹsin Islam yatọ.
Nigba to n ba BBC Yoruba sọrọ lori iwa ifipabanilopọ, Wolii Akintunde ni kii se bi obinrin ba se mura lo n fa iwa ifipabanilopọ, gẹgẹ bi awọn eeyan kan se lero.
Amọ o salaye pe bi a ba se wo ara wa loju si, boya ọkunrin ni abi obinrin lo n fa iwa ifipabanilopọ.
Akintunde fikun pe, kii se awọn ọkunrin nikan lo n huwa ifipabanilopọ, gẹgẹ bi awujọ wa se lero, amọ awọn obinrin gan n fipa bani lopọ, ko si yẹ ka maa pariwo awọn ọkunrin nikan.
O wa tako ẹwọn ọdun mejidinlogun ti wọn  n fun awọn eeyan to n fipa bani lopọ, eyi to ni ko to fun ijiya ẹsẹ wọn .
Bakan naa lo rs awọn eeyan lati ye ko awọn ti wọn ba fi tipa ba lopọ laya jẹ lori ayelujara, amọ n se lo yẹ ki wọn sewuri fun wọn lati jade sita sọ tẹnu wọn.
King Millie: Mo mọ ọsàn hó ní ìyàwó mí ṣe bá mi ṣọrẹ ní kékeré, a sì padà fẹra
Oríṣun àwòrán, @iKingMillie
Yoruba ni ọrọ ifẹ, bii adanwo ni, bẹẹ si ni ifẹ ko mọ olowo abi talaka, bẹẹ ni ko mọ abuda ara.
Ibikibi ni afẹfẹ ifẹ ti le fẹ lu ẹda, bẹẹ si ni ọrọ ifẹ kọja agbara ẹda.
Bẹẹ ni ọrọ ri pẹlu ọkunrin ati obinrin kan ti wọn sẹsẹ se igbeyawo amọ ti wọn ti jẹ ọrẹ ati kekere.
Nigba to n salaye bi ọba oke se mu se alabapade aya rẹ lati igba ewe loju opo Twitter rẹ,  ọkunrin kan to n jẹ King Millie ni iyalẹnu lọrọ awọn.
Oríṣun àwòrán, @iKingMillie
Millie ni ọsan ni oun n kiri lọ nigba ti oun wa ni kekere, ti oun si pada ọmọbinrin naa.
O ni obinrin yii lo se akiyesi pe oun mọ ọsan ho daadaa, to si joko ti oun, nibẹ si ni awọn ti di ọrẹ titi di oni.
Loni, inu mi dun pupọ pe mo fẹ ọrẹ mi lati igba ewe.
Oríṣun àwòrán, @iKingMillie
Alaye ọkunrin yii lo mu ki ọpọ eeyan maa ki ku oriire pe, o ba obinrin bii ọkan rẹ pade.
Koda, ẹnikan ni kii ṣe gbogbo obinrin lo le duro lati lo ifẹ pẹlu ọmọ ọlọsan lasan lasan, dipo bẹẹ, wọn yoo maa le awọn eeyan to n lo ọkọ ofurufu kiri ni.
Suicide Prevention Day: Wo àmì márùn-un tí o fi le mọ ẹni tó fẹ́ gbẹ̀mí ara rẹ̀
Oríṣun àwòrán, Science Photo Library
Gbígba ẹ̀mí àra ẹni jẹ́ àrùn tó ni ṣe pẹ̀lú ọpọlọ, tí ó sì le fa ikú àìtọ́jọ́, sùgbọ́n ó ṣeeṣe kó ní àtúnṣe ti àwọn ènìyaǹ bá tètè mọ̀, tí wọ́n si ran irú ẹni bẹ́ẹ̀ lọ́wọ́.
Ní ọ̀pọ̀ ìgbà tí o bá rí ẹnìkan to n lọ lójú pópó, ó maa ròó pé sáká ni àra rẹ̀ dá, pàápàá jùlọ, tó bá ń ṣàwàdà tàbí rẹ́rìn-ín, sùgbọ́n òótọ́ ibẹ̀ ni pé, wọ́n kan ń fí ẹẹrin náà bò ìṣoro wọn mọ́lẹ̀ ni.
Lọ́pọ̀ ìgbà, gbígba ẹ̀mi ara ẹni ni òpin fún ọ̀pọ̀ àwọn tó ni àrun to niṣe pẹ̀lú ọ̀pọ̀, bí 'Bipolar', 'Depression', 'Schiophrenia' tó fi mọ́ 'Anxiety disorder'.
Oríṣun àwòrán, LASEMA
Bẹ́ẹ̀ àwọn ìrònú àròròtán lóri ètò ọ̀rọ̀ ajé àti ìgbéyàwó ló maa n ti ẹlòmíràn láti pa ara rẹ̀.
Dókítà Isah Shaedouw Baka, tó jẹ́ onímọ̀ nípa ààrùn ọpọlọ sàlàyè pé, àwọn ènìyàn tó fẹ́ gba ẹmi ara wọ́n jẹ́ àwọn tí ọ̀rọ̀ ara wọ́n tí sú wọ́n tàbí ti inú wọ́n ba tí dùn jù lórí ǹkankan.
O ni ipele kan náà ni àwọn méjèèjì wà.
Oríṣun àwòrán, Others
Gẹ́gẹ́ bi àjọ WHO ṣe sọ, ipò kẹẹdógún ni Nàìjíríà wà lárá àwọn orílẹ̀-èdè tí wọ́n ti sábà máa ń gba ẹmi ara wọ́n jùlọ.
Nàìjiríà si wà ni ipò keje ní ilẹ̀ Afíríkà, Cameroon ló wà ni ipò kẹrin nígbà tí Ghana kò si ni ipò méjìlá àkọ́kọ́, nínú orílẹ̀-èdè ti àwọn ènìyàn ti n gba ẹ̀mi ara ẹni.
Sùgbọ́n kí wá ni àwọn àmìn tí wọ́n lé fi han gàn, tí ẹbi, ará àti ọ̀rẹ́ fi lè ràn wọ́n lọ́wọ́.
Àwọn àmì tí o fi le mọ ẹni tó fẹ́ pokùnso:
Ẹlẹ́rìí:
Ọ̀pọ̀ àwọn tó fẹ́ gba ẹmi àrà wọ́n sába máá n wa ẹlẹ́rí, láti fi àmì ìkìlọ̀ sílẹ̀, wọ́n ma a ń wá ẹni ti wọ́n yóò sọ fún pé, àwọn fẹ́ gba ẹmi ara wọ́n.
Dókítà Baka sọ pé, ẹni tó bá sọ fún ọ pé, ayé ti sú òun, lé fi ẹrin sọ ọ́ tàbi kí o léjú, sùgbọ́n àmi ńla ni pé, ó ṣeeṣe ki irú ẹni bẹ́ẹ̀ maa rònú láti pa ara rẹ̀.
Oríṣun àwòrán, Others
"Tí o bá ti ń gbọ́ tí ènìyàn ń sọ pé, ""ayé ti sú mi"" tabi Kí òpin ayé tíẹ̀ dá báyìí"", ara àmì pé ẹni náà le gba ẹ̀mi ara ẹni ni."
O ṣe é ki ẹni náà maa sọ̀rọ̀ nípa ikú ṣaa , àwọn àmi rèé láti mọ̀ pé ẹni náà fẹ́ pa ara rẹ̀.
Dr Maynunah Kadiri, tó jẹ́ olùdásílẹ̀  Pinnacle Medical Services, tó má a ń yan amójútó àwọn ìpénija tó ni nnkan ṣe pẹ̀lú ọpọlọ láàyò  salaye pe,
 Ọ̀pọ̀ àwọn tó má n gbèrò láti pa ara wọn, tí o bá rí wọ́n, yóò dàbí ẹni pé wọ́n ń ṣe àwàdà ní, sùgban ti o bá tẹtí láti gbọ́ ìtàn wọn , òyé yóò ye ènìyàn láti mọ́ pé, wọ́n le pa ara wọn,
Ó ní ọ̀pọ̀ tilẹ̀ máá n fi ìwé sílẹ̀ fún àwọn tó sún mọ́ wọ́n, láti sọ ìdí ti wọ́n fi gbé ìgbẹ́sẹ̀ náà, wọ́n le kọ̀ ọ́ pé, asán ni aye yìí, tí wọn yoo si ti fi iwé yìí sílẹ̀.
Mistura Oseni Akintunde: Ara múmú kìí ṣe oríṣun ìfipábánilòpọ̀, ìran àwòjù ló ń fà á
"O ni eyi túmọ̀ si pé ""wọ́n ti ṣetò gbogbo rẹ̀, ki wọ́n to gbé ìgbẹ́sẹ̀."
Àìní ífẹ̀ sí ǹkankan to dára mọ́:
Ní kété ti àwọn ènìyàn kò bá ti ni ìfẹ́ sí àwọn ǹkan to dára mọ́, o seese ki wọn pa ara wọn.
Tí ńkan to n lọ láyìká ẹni náà, kò bá ti ni ìtùmọ̀ si mọ́, tó kàn dà bi ẹni pe ó kàn gbe aye ṣá, o yẹ ka fura siru wọn.
Dokita ni eyi tumọ si pé, o ti ń rònú láti gba ẹ̀mí àrà rẹ̀ ni, Ounjẹ kìí wù jẹ, kò fẹ́ ni ọ̀rẹ́ tàbí alábárò, Dókìtà Baka sọ pé, ọ̀rọ̀ náà ti kọjá bẹ́ẹ̀ nìyẹn.
Àwọn ènìyàn máa n ròó pé, wọ́n sọ èyí nítorí nǹkan tó ṣẹlẹ̀ kan dùn wọ́n ni, wọn ò ni mọ̀ pé wọ́n ti ni àrùn ọpọlọ.
Mayowa Omoniyi: Kò sí orin Obey, Sunny Ade abí tàkasúfèé tí ń kò le ta gìtá sí
Tí ènìyàn bá fẹ́ láti máa dáwà, kí o maa sá fún ọ̀rẹ́ tàbi àéjọ àwọn ènìyàn, èyí jẹ́ ọ̀kan gbòógí pé ìrónú tó n dàmú ọpọlọ ti ṣẹlẹ, tí ènìyàn kò bá tètè fúra, ó lè jásí kí ó gba ẹ̀mi ara rẹ̀.
Ẹlòmíràn kò ni kùrò láàrín ọ̀rẹ́, sùgban ọ̀rọ̀ ti kò tó ǹkan ni wan yóò máa fa ìbínú yọ gidi ti yóò si di ìjà ńla.
Tí ọ̀rọ̀ náà ba ti wá n ri bẹ́ẹ̀ fún ìgbà pípẹ́, ẹ ó gba pé wọ́n tí gba ẹmi ara wọ́n, Dókítà Baka lo sọ bẹ́ẹ̀.
Baby abandoned on dunmpsite: Mo ti bímọ mẹ́rin tẹ́lẹ̀ fún bàbá méjì nínú òṣí- Dupe Ogbomos
Wọ́n a maa hu àwọn ìwà to léwu:
Ìwà àwọn ti ayé bá ti sú máa n yí ìwà pada, yóò maa ṣe àwọn nńkan to le kó o sínú ewu.
O lé má a wa ọkọ̀ ni ìwàkuwa, a gbọdọ mójútó bo ti n sáré tó bá n wakọ̀ ju bi ó ṣe máa n sáré tẹ́lẹ̀ lọ, tàbi kí o maa mú ọtí àmupara tàbi ki o maa ló òògun kọja ǹkan ti wọn fún láti lòo
Ó  le má a sọ̀rọ̀ àsọjù.
Ẹkún sisun
Dókìtà Kadiri ni ẹkún wọn kìí ṣe eyi ti eniyan ń sun, ti yóò simi, ẹkun asu-un-dakẹ ni.
O dá lóri iye ìgbà ti ẹni náà bá fi n sunkun, bí ẹkun naa ṣe pẹ tó, bọ́ya ẹni kan lo mú u bínú tàbi ó kàn dédé sunkún.
Kíni àwọn ǹkan ti o lè ṣe láti ran ẹni tó fẹ́ gba ẹmi ara rẹ̀  lọ́wọ́:
Ọ̀nà àkọ́kọ́ láti déna rẹ̀ láti inu ilé ni
Kọ́kọ́ gbà pé ẹni náà ni ìṣòrò tó ń kojú:
Tí o bá ti gbà pé ẹni náà ni ìṣòro, o le ràn lọ́wọ́, ti ó sì súnmọ ju ti tẹ́lẹ̀ lọ.
Jẹ́ ki wọ́n ni ìgbàgbọ́ nínú rẹ̀, nítorí àwọn tó ni ìṣòrò yìí kìí gbà pé àwọn ni ìṣoro, sugbọ́n ti wọn ba rí ọ bi ọ̀rẹ́ tó súnmọ́ wọn, wọ́n yoo le fi ọkàn tan ẹni náà.
Má dáwọn lẹ́bi, máa tẹti sí wọ́n:
Tétí si ǹkan ti wọ́n ń sọ, má sì dáwọ́n lẹ́bi.
Má bèèrè ìbéèrè tó pọ̀ jù, sáà má tẹti si wọn, ki o sì maa fi oye gbé ǹkan ti wọ́n n kojú.
Má wààsú fún-un:
Má sọ Ara rẹ di pásítọ̀ fún wọn.
Kìí ṣe nítorí pé wọn kìí gbàdúrà ni wọ́n ṣe nísòro, pé wọ́n tilẹ̀ ń sọ̀rọ̀ fún ọ, ǹkan tó dára ni gẹ́gẹ bi Dókítà Kadiri ṣe sọ.
O kìí ṣe akọ́ṣẹ́mọ́ṣẹ́, Nítori náà, ràn wọ́n lọ́wọ́ láti rí akọ́ṣẹ́mọ́ṣẹ̀ onimọ nipa arun ọpọlọ ati ihuwasi ẹda, eyi tí yóò mú ọ̀rọ̀ wọ́n gbọ́.
Tani ẹni to le gba ẹmi ara rẹ?
Dokítà Kadiri sọ pé kò sí ẹni tí kò lè gbìyànjú láti gba ẹmi ara rẹ̀, ọ̀rẹ́, ẹbi, tó fi jẹ́ alájùmọ̀ ṣiṣẹ́ pọ̀ àti ìwọ fúnra rẹ gan.
Ẹni ti èèyàn tó sún mọ́ ṣẹ̀ṣẹ̀ kú fún, ìkọ̀sílẹ̀ nínú ìgbéyàwó, ẹni to ni àìsàn kan to buru, ẹni ti iṣẹ bọ́ lọ́wọ́ rẹ̀, tàbi tó ni ìṣòro owó ńla kan yóò fẹ́ pa ara rẹ̀.
Dókítà Baka ní àwọn to ti le ni ọgọ́ta ọdún tabi jù bẹ́ẹ̀ lọ náà náà le gba ẹmi ara wọn, ti wọn ba ni ìṣòro.
"Láàrin àwọn ọmọ kéékèèké ti wọn n gba ẹmi ara wọn, ọ̀pọ̀ lo ni àrun ti wọ́n n pè ni ""Schizopherenia"""
Schizopherenia jẹ́ àìsàn to maa n jẹ́ ki ènìyàn gba ohùn ti yóò ma dá ẹni náà lẹbi fún ǹkan ti wọ́n ṣe, ohun náà a ma jẹ́ ki aye ṣú wọ́n, yóò si ma sọ pe aye ko já mọ́ ǹkankan.
Iyabo Ojo house: Iyabo Ojo ṣílé tuntun, Eko mì tìtì
Gbajugbaja oṣere tiata Yoruba, Iyabo Ojo ṣi ile tuntun nibi ti ọpọlọpọ awọn ẹbi, ọrẹ ati ojugba rẹ ninu iṣẹ tiata peju si.
Oríṣun àwòrán, iyaboojofespris
Inu ile ọhun ree.
Oríṣun àwòrán, iyaboojofespris
Inu ile naa dun wo loju.
Oríṣun àwòrán, iyaboojofespris
Iyabo Ojo ṣi ile tuntun laarin ọsẹ, nibi ti ọpọlọpọ awọn ẹbi, ọrẹ ati ojugba rẹ ninu iṣẹ tiata peju si.
Oríṣun àwòrán, iyaboojofespris
Ṣaaju ni ọkan lara awọn ọmọ oṣere naa, Priscilla, ti kọkọ kede lori ayelujara pe iya oun ti di onile niluu Eko.
Oríṣun àwòrán, iyaboojofespris
Oṣere naa pẹlu awọn ololufẹ rẹ bii Alhajoi Ajibola Pasuma lo peju sibẹ.
Oríṣun àwòrán, iyaboojofespris
Wẹjẹwẹmu ko gbẹyin nibi ayẹyẹ iṣile naa.
Oríṣun àwòrán, iyaboojofespris
Madam Saje atawọn oṣere miran ko gbẹyin nibẹ.
Oríṣun àwòrán, iyaboojofespris
Gbogbo faaji ni lọjọ́ naa.
Oríṣun àwòrán, iyaboojofespris
Inu ẹni kii dun, ka pa a mọ̀ra ni ihuwasi ati irinsi Iyabo lọjọ isile
Oríṣun àwòrán, iyaboojofespris
Iya rẹ naa ba yọ ayọ ile tuntun.
Oríṣun àwòrán, Iyabo Ojo
Pasuma, MC Oluomo ati awọn eekan ilu miran fi ijoko yẹ Iyabo Ojo si lọjọ isile rẹ
Yoruba films: Gbogbo bó ṣe lọ rèé lágbo òṣéré láàrín ọ̀sẹ̀ yìí
Oríṣun àwòrán, Mercy Aigbe
Gbajugbaja oṣere fiimu Yoruba, Mercy Aigbe to ṣẹṣẹ ṣe agbejade fiimu tuntun kan ti fi oju ọmọ rẹ, Juwon han gẹgẹ bi ọkan lara awọn to kopa.
Igba akọkọ niyi ti Juwon yoo maa kopa ninu ere Tiata gẹgẹ bi iya rẹ ṣe fi sita loju opo Instagram rẹ.
Mercy Aigbe ni iwuri ni eyi jẹ fun oun gẹgẹ bi iya Juwon to ṣẹṣẹ bẹrẹ iṣẹ gẹgẹ bi oṣere.
"Mercy Aigbe ti oun funra rẹ naa kopa ninu fiimu to si tun jẹ igbakeji adari ere ni awoṣifila ni sinima naa to pe akọle rẹ ni ""Kini Igbeyawo"" yoo jẹ."
Lara awọn mii ti wọn tun jọ kopa ninu ere ọhun ni Yemi Blaq, Nkechi Blesssing, Bolanle Ninalowo, Peters Ijagbemi ati awọn mii.
Bọlanle Ninalowo: Ọ̀rẹ́ lásán àti olóore mi ni Mercy Aigbe
Oríṣun àwòrán, others
Bẹbẹ ṣẹlẹ lagbo oṣere laarin ọsẹ yii, bi awọn kan ṣe n ṣi ile awo dami ẹnu, lawọn mii n ṣi ileeṣẹ f'ọmọ, lawọn kan naa jẹpe Eledumare.
Ẹ jẹ ka bẹrẹ lati ọdọ oṣere to si ile tuntun laarin ọsẹ yii.
Iyabo Ojo
Gbajugbaja oṣere tiata Yoruba, Iyabo Ojo ṣi ile tuntun laarin ọsẹ yii, nibi ti ọpọlọpọ awọn ẹbi, ọrẹ ati ojugba rẹ ninu iṣẹ tiata peju si.
Ṣaaju ni ọkan lara awọn ọmọ oṣere naa, Priscilla,  ti kọkọ kede lori ayelujara pe iya oun ti di onile niluu Eko, eyii to mu ki  ọpọ awọn eeyan kii ku ori ire.
Oríṣun àwòrán, Iyabode Omo ladukeade
Awọn oṣere jankan jankan ati awọn eeyan miran bii, Alhaji Alabi Pasuma, MC Oluomo atawọn gbajumọ lawujọ lo peju si ibi ayẹyẹ iṣile naa lati ba ṣọjọyọ.
Toyin Abraham
Lẹyin ọjọ diẹ to ṣe ọjọ ibi, Toyin Abraham kede pe oun, ọkọ oun ati awọn eeyan kan yoo ṣi ileeṣẹ fun ọmọ rẹ, Ire, laipẹ.
Toyin sọ loju opo Instagram rẹ pe ileeṣẹ naa yoo da lori idilẹ ati eto ẹkọ, eyii ti wọn yoo fi sọri ọmọ naa.
Lẹyin naa lo dupẹ lọwọ awọn alatilẹyin rẹ fun ifẹ wọn lori idile rẹ.
Baba Legba
Bo tilẹ jẹ pe o ti ṣe die ti o ti kopa ninu ere agbelewo, aarin oṣẹ yii ni Alhaji Yekini Omobolanle, ti ọpọ mọ si Baba Legba jade laye.
Ebun Oloyede, ti ọpọ mọ si Olaiya Igwe lo kọkọ fidi iroyin naa mulẹ fun BBC Yoruba pe Baba Legba ti papoda.
Mistura Oseni Akintunde: Ara múmú kìí ṣe oríṣun ìfipábánilòpọ̀, ìran àwòjù ló ń fà á
Iroyin ni Baba Legba jade laye lẹyin aisan ranpẹ ni ile rẹ to wa ni Abeokuta.
Ijebuu
Aarin ọsẹ yii kan naa ni Olatayo Amokade, ti ọpọ mi si Ijẹbu polongo loju opo Instagram rẹ pe awọn ololufẹ oun ti le miliọnu kan ati abọ lori ikanni naa.
"O ni ""mo dupẹ lọwọ gbogbo ẹyin milọnu kan ati abọ to n fifẹ han si mi."""
Eniuola Badmus
Eniola Badmus ti ọpọ awọn ololufẹ rẹ mọ si gbogbo Bis girls naa ṣọjọ ibi laarin ọsẹ yii.
Oríṣun àwòrán, ENIOLABADMUS
Oriṣiriṣi aworan ni Eniola ko soju ikanni Instagram rẹ lati fi sami si ọjọ ibi naa.
Ọpọ awọn ololufẹ rẹ lo si n ki ni mẹsan an mẹwaa.
Mayowa Omoniyi: Kò sí orin Obey, Sunny Ade abí tàkasúfèé tí ń kò le ta gìtá sí
Sotitobire: Adájọ́ sọ̀rọ̀ nípa ọjọ́ ìdájọ́ fún Wòlíì Sotitobire Alfa Babatunde
Adajọ to n gbọ ẹjọ ẹsun ijọmọgbe ti wọn fi kan gbajugbaja wolii ijọ Sọtitobirẹ Praising Chapel ni ilu Akurẹ, Alfa Babatunde ti ọpọ mọ si sọtitobirẹ atawọn mẹfa miran ti sọ ọjọ ti yoo gbe idajọ kalẹ.
Wọn n fi ẹsun kan wolii Sọtitobirẹ ati awọn oṣiṣẹ ijọ naa mẹfa pe wọn lọwọ si bi ọmọ ọdun kan, Kọlawọle Gold ṣe poora ni ileejọsin naa ni oṣu kọkanla ọdun 2019.
Adajọ to n gbọ ẹjọ naa kede bi idajọ ẹjọ naa yoo ṣe lọ lẹyin ti gbogbo awọn agbẹjọro fun igun gbogbo ti ọrọ kan ti fi ẹnu awijare ati atotonu wọn lori ẹjọ naa jona sibi kan.
'Búrẹ́dì tí wọn ó fi jẹ ẹ̀wà ni wọ́n lọ rà ni wọ́n pàdé ikú gbígbóná'
Ni oṣu keji ọdun yii ni igbẹjọ bẹrẹ lori ẹsun ijọmọgbe ati igbimọpọ hu iwa ijọmọgbe ti wọn fi kan awọn meje naa.
ẹlẹri mẹsan ni awọn agbẹjọro ijọba pe nigba ti awọn agbẹjọro fun Wolii Sọtitobirẹ atawọn ọmọ ijọ rẹ naa si pe ẹlẹri marundinlogun ati ọpọlọpọ ẹri.
Awọn agbẹjọro, Wolii Sọtitobirẹ Oluṣọla Oke n fẹ ki ile ẹjọ wọgile ẹjọ naa. O fi kun un pe iṣẹ arumọjẹ lasan lawọn agbofinro DSS ṣe lori iwadii wọn.
O ni yatọ si pe wọn fi ọrọ wa Pasitọ naa lẹnu wo, ko si nnkan kan gboogi ti wọn lee mu jade gẹgẹ bi ẹri lẹyin ti wọn yẹ ile ẹjọ naa wo.
Bakan naa lawọn amofin yoku naa gbee nidi lori eyi.
'Ọ̀nà àtijẹ kan ṣoṣo táa ní ni Màálù àwọn Fúlàní ti bàjẹ́'
Amọṣa, agbẹjọro ijọba, ti amofin agba ipinlẹ Ondo, Adekọla Ọlawoye lewaju fun rọ ile ẹjọ naa lati fi iya to ba tọ jẹ wọn nitori awọn ẹri to ṣarajọ lori ẹjọ yii.
Onidajọ Oluṣẹgun Oduṣọla wa ṣalaye fun awọn agbẹjọro naa pe idajọ oun lo kan. O kede pe oun yoo fi ọjọ idajọ ṣọwọ sawọn igun mejeeji laipẹ.
Titi di igba naa, o ni ki wọn da awọn afunrasi ọhun pada si ọgba ẹwọn Olokuta.
Gẹgẹ bi igbejọ ṣi ṣe n lọ lọwọ lori ẹsun ti wọn fi kan oludasilẹ ijọ Sotitobire Praising Chapel l'Ondo, Wolii Alfa Babatunde atawọn ọmọ ijọ rẹ mẹfa tun ti farahan nile ẹjọ lonii lati lọ jẹwọ pe awọn sọ ọrọ ti wọn kọ silẹ.
Ẹwẹ, ko pẹ rara ni adajọ kede pe wan tun ti sun ẹjọ naa siwaju.
Ọsẹ kẹfa ree ti wọn ti gbọ ẹjọ wọn gbẹyin nigba ti wọn pa oju ẹjọ eyi ti agbẹjọrọ afurasi gangan n wi de ni ọjọ kejilelogun oṣu keje, ọdun 2020.
Pásítọ̀ ìjọ Sotitobire padà yọjú sílé ẹjọ́ lónìí, àbọ̀o rèé...
Wo ohun tí Adájọ́ ṣe sí àṣùwọ̀n ìfowópamọ́sí Wòlíì Sotitobire
Akure Kidnap: E túbọ̀ ní sùúrù, a máa wá ọmọ náà rí- Alukoro ọlọ́pàá
Oludari ẹka idajọ ni ileeṣẹ to n ri si ọrọ idajọ, Grace Olowoporoku lo n lewaju ifarahan fun olupẹjọ nigba ti Agbẹjoro Olusola Oke ati Akinyemi Omoware n duro fun olujẹjọ.
Nitori bi ọmọ kekere kan, Gold Kolawole se dede poora ni Sọọṣi Wolii yii ni Akure ninu oṣu kọkanla ọdun 2019 ni ẹjọ ti wọn ṣi wa lori rẹ bayii.
"Ẹwẹ, o yẹ ki awọn olujẹjọ wa sọ pe ""bẹẹ ni a sọ ọrọ ti a sọ ti wọn gba ohun wa kalẹ"" lonii ṣaaju idajọ ti adajọ Olusegun Odusola yoo da ṣugbọn wọn ti ni ko tun ri bẹẹ mọ."
Eyi lo mu ki wọn sun igbẹjọ naa siwaju di ọjọbọ ọjọ kẹtadinlogun oṣu kẹsan yii.
Ọmọ kekere naa, Gold Kolawole yẹ ko ṣe ayẹyẹ ọdun meji lọjọ Abamẹta to kọja.
Ọsán jáá! òṣèré àti ọ̀jọ̀gbọ́n Tiatia, Ayo Akinwale jáde láyé
Ìtàn ọ̀rẹ́ tó fi ògùn gba ọkọ ọ̀rẹ́ rẹ̀ ni Akomolede BBC Yorùbá fẹ́ kọ́ wa lònìí
'Buns ni ọmọ mi jẹ tán ní ṣọ́ọ̀ṣì, ló bá di àwátì'
Kọlọrun jẹ ki abiyamọ o jeere ọmọ.
Ọjọree bi ana yii lọdun meji sẹyin nigba ti ọmọ tuntun jojolo, Gold Kolawole dele aye, lai mọ ohun to n duro de oun.
Oni yii gan-an, ọjọ kejila, oṣu Kẹsan, si ni Gold, ọmọ kekere to sọnu ninu ijọ Sotitobire Miracle Centre nilu Akure, ko ba pe ọdun meji.
Ọjọ kẹwaa, oṣu Kọkanla, ọdun 2019, ni iroyin jade pe, ọmọ naa deede poora ninu ṣọọṣi naa ni ẹka awọn ọmọde ti iya rẹ gbe e lọ, lọjọ isinmi naa.
'Buns ni ọmọ mi jẹ tán ní ṣọ́ọ̀ṣì, ló bá di àwátì'
Gbogbo igbiyanju awọn obi rẹ lati ri lo ja si pabo, koda ọrọ ti di tileeṣẹ ọlọpaa.
Iya ọmọ naa, Modupe Kolawole ṣalaye fun BBC Yoruba pe, inu oṣù kẹfa lawọn ṣẹṣẹ bẹ̀rẹ̀ sí ní lọ sí ṣọọṣi naa, ki iṣẹlẹ yii to o waye.
Iya Gold salaye bi ko ṣe ki n fẹ fi ọmọ rẹ silẹ ati bi awọn ẹṣọ ijọ ṣe ni o yẹ ko maa gbe ọmọ rẹ lọ si yara ti wọn n ko awọn ọmọ wẹwẹ si.
Bakan naa, lo tun sọ nipa bo ṣe pada gbe ọmọ naa lọ si yara awọn ọmọ wẹwẹ, ati bo se wa di ohun to n kọ ni lẹnu lati sọ bi ọmọ ọdun kan ti ko tii le rin tabi sọrọ ṣe poora.
Iṣẹlẹ yii mu ki awọn agbofinro mu Pasitọ ijọ Sotitobire, Alfa Babatunde, ti wọn si fi ẹsun kan oun ati awọn ọmọ ijọ rẹ bi i mẹrin, pe wọn mọ nipa bi ọmọ naa ṣe sọnu.
Sotitobire church: Ẹgbẹ́ CAN ní kí ìjọba ṣe ohun tó yẹ
Lara awọn ẹsun ti awọn obi Gold fi kan Alfa ni pe, ko ja ọrọ ọmọ naa kunra lasiko ti wọn fi to o leti pe o sọnu.
Koda, Deji ti ilu Akurẹ, naa pe awọn obi, pasitọ ati awọn miran lati bura nidi oriṣa nipa nkan ti wọn mọ lori bi ọmọ naa ṣe sọnu.
Lati asiko naa si ni Pasitọ Alfa Babatunde ati awọn ọmọ ijọ rẹ ti wọn mu ti wa ni ọgba ẹwọn Olokuta nilu Akurẹ, nibi ti wọn n gba lọ sile ẹjọ fun igbẹjọ.
"Ko tan sibẹ o, lasiko ti ọrọ bi ọmọ naa ṣe sọnu ṣi n gbona janjan, ni awọn eeyan kan dana sun ṣọọṣi Sotitobire, ""nitori wọn fura pe ori pẹpẹ inu ṣọọṣi naa ni wọn ri Gold Kolawole mọlẹ si""."
'Aràrá bíi tèmi, kó má rò pé kò sì ǹkan tó lè ṣe láyé ju iṣẹ́ agbe lọ'
Ṣugbọn awọn ọlọpaa sọ pe ko si nkan to jọ nkan bẹ ẹ.
Koda, awọn eeyan naa pa ọkan lara awọn ọlọpaa to lọ ọ doola ṣọọṣi naa.
gbogbo bi igbẹjọ pẹlu Alfa Babatunse si se n lọ si lati sawari ọmọ naa ni BBC n mu wa fun yin.
Lizzy Anjorin: Ibadan ní ọkọ mi, ata wíwẹ́ lo fẹ́ràn
Oríṣun àwòrán, Instagram/lizzy Anjorin Lawal
Lẹyin oṣu meji to ṣe igbeyawo, o dabi ẹni pe gbogbo afẹfẹ-yẹyẹ igbeyawo ti dopin bayii fun gbajugbaja oṣere tiata ati eekan ori ayelujara, Lizzy Anjọrin.
Gẹgẹ bi ọrọ kan to fi sita loju opo Instagram rẹ, Lizzy Anjọrin ni oun ti n foju wina ipenija igbeyawo bayii, paapaa julọ igbeyawo pẹlu ọkọ oun to jẹ ọmọ ilu Ibadan.
Awada ni eekan ori ayelujara naa fi ọrọ naa ṣe, amọ otitọ pupọ lo sodo sinu ọrọ naa.
Lizzy ni oju oun ti n ri mabo gẹgẹ bi iyawo Ibadan nitori dipo ki ọkọ oun, Alhaji Lawal maa beere fun burẹdi ati tii gbigbona gẹgẹ bi ounjẹ aarọ, awọn ounjẹ ibilẹ bii Ekuru ati ata ti wọn fi ọwọ lọ, irẹsi ọfada ati ata ṣiṣa ati bẹẹbẹẹ lọ, lo n beere.
Oríṣun àwòrán, Instagram/lizzy Anjorin Lawal
Eyi gan an lo mu ki Lizzy Anjọrin aya Lawal figbe bọnu lori ikanni ayelujara rẹ pe, ẹni ba fẹ ọmọ Ibadan, bi ẹni morile igbo Sambisa nibi ti awọn agbebọn Boko Haram fikalẹ si ni.
O fikun pe ọkọ oun ko mọ awọn ounjẹ alakọwe jẹ ayafi ounjẹ awọn alalẹ.
Ninu ọrọ to kọ soju opo Instagram rẹ naa ni Lizzy tun ti fi imọran sọwọ sawọn omidan ti ko tii lọkọ pe, eyi ti ko ba lee ṣe wahala ina dida fun ọkọ rẹ, to jẹ pe ọkọ burẹdi ati tii lo fẹ fẹ, ko sare lọ fẹ oyinbo ni o, ko maa da laba lati fẹ ọmọ Ibadan rara.
Nigba ti Lizzy yoo pari ọrọ rẹ naa, o ni gbogbo awọn to n pariwo pe ki oun lọ fẹ ọkọ nigba naa, ni isisinyi ti oun n foju ko oro atarodo soju, oun o ri ẹnikẹni ninu wọn mọ o.
Oríṣun àwòrán, Instagram/lizzy Anjorin Lawal
Ẹ jẹ ka wo bi o ṣe kọ ọrọ rẹ naa:
"Ẹyin apọn, ẹ gbiyanju ki ẹ fẹ oyinbo ti yoo maa jẹ burẹdi ati tii lowurọ.
Ẹni ba fẹ ọkọ ni Ibadan bi igba to lọ si igbo Sambisa ni.
Ki le fe je sir ?
Ekuru pẹlu Ata ti won fi owolo,
Ofada pẹlu Ata ṣiṣa
Amala gbegiri Ewedu
Ewa aganyin pẹlu ata dindin
Iyan ti won fi odo gun.
Lọ f'ọka, lọ f'ọkọ emi nikan ni mo n foju wina rẹ pẹlu atarodo loju mi bayii o, kaluku yin wa nibi tẹẹwa bayii ẹ n gbadun aye yin
Tiyin naa fẹrẹ de, ṣe ẹ gbọ"
Afi suuru.
Bí rere ni àbí búburú, wo ohun tí Covid-19 leè ṣe sí àgọ́ ara rẹ
Fulham vs Arsenal: Arsenal lu Fulham ní àlùbami pẹ̀lú 3-0, ṣùgbọ́n ariwo Willian layé ń pa
Oríṣun àwòrán, Premier league
Nnkan o rọgbọ fun ikọ Fulham ni ipadabọ wọn si idije Premier league ilẹ Gẹẹsi lọjọ Satide pẹlu bi Arsenal ti wọn gba lalejo  din dundu iya ni adingbẹ fun wọn ni papa iṣire Craven Cottage to jẹ ibuba wọn.
Goolu mẹta si odo ni Arsenal fi ki ikọ Fulham to ṣẹṣẹ gba igbega wa si premier league lati liigi keji ilẹ Gẹẹsi ti a mọ si Championships kaabọ.
Nigba ti ifẹsẹwọnsẹ naa wọ iṣẹju mẹsan ni atamatase agbabọọlu ikọ Arsenal, Lacazette lo gba goolu akọkọ wọle fun Arsenal eleyi to fun un ni iyi ẹni to gba goolu akọkọ wọle fun saa liigi tọdun 2020/2021 to bẹrẹ lọjọ Abamẹta.
Bakan naa ni goolu ọhun tun sọ Lacazette di agbabọọlu akọkọ ninu itan premier league ti yoo maa gba goolu akọkọ ni saa liigi kan wọle fun saa liigi meji ọtọọtọ.
Oríṣun àwòrán, Premier league
Ni saa liigi ọdun 2017/2018, Lacazette ni agbabọọlu to gba goolu akọkọ wọle lọdun naa ninu ifẹsẹwọnsẹ Arsenal pẹlu Leicester
Agbabọọlu ti Arsenal ṣẹṣẹ ra ni ọsẹ diẹ sẹyin, Gabriel Magalhaesjẹwọ pe Arsenal ko fowo jona pẹlu bi o ṣe gba goolu rẹ akọkọ wọle fun ikọ Arsenal ninu ifẹsẹwọnsẹ naa eleyi to jẹ ifẹsẹwọnsẹ liigi akọkọ ti yoo ti kopa fun Arsenal.
Ni kete ti wọn wọle ni Gabriel ti fori gbe bọọlu gbee silẹ ni igun papa koo gba, iyẹn Corner ti Willian, agbabọọlu tuntun miran ti Arsenal ra lati Chelsea gba soju ile Fulham nigba ti ifẹsẹwọnsẹ naa wọ iṣẹju kọkandinlaadọta.
Gẹgẹ bi iṣe rẹ, balogun ikọ Arsenal, Pierre-Emerick Aubameyang naa da si ojo goolu to rọ fun Arsenal ni papa iṣire Craven Cottage nigba ti oun naa sọ goolu kẹta sawọn fun Arsenal nigba ti ifẹsẹwọnsẹ naa wọ iṣẹju kẹtadinlọgọta.
Oríṣun àwòrán, Premierleague
Pẹlu goolu yii, Aubameyang ti gba goolu mọkanla wọle ninu ifẹsẹwọnsẹ mọkanla ni ṣiṣẹ n tẹle to ti gba fun Arsenal.
Ṣaaju ifẹsẹwọnsẹ ni ni aworan ija laarin agbabọọlu Arsenal meji, Ceballous ati Nketiah ti waye lasiko ti wọn fi n gbaradi fun ifẹsẹwọnsẹ naa ni papa iṣire Craven Cottage ti ifẹsẹwọnsẹ naa ti waye.
Awọn agbabọọlu mejeeji yii wa lara awọn ti akọnimọọgba ikọ naa, Mikel Arteta mu lati rọpo awọn agbabọọlu to ba yọ lori papa bi ifẹsẹwọnsẹ naa ba ṣe n lọ
Secret Cults in Nigeria: Ọwọ́ ọlọ́pàá tẹ àwọn ọmọ ẹgbẹ́ òkùnkùn tó yìnbọn
Oríṣun àwòrán, Nigeria Police Ogun State
Awọn ọmọ ẹgbẹ okunkun Black Axe kan to n ṣe idaro akẹgbẹ wọn ni ọwọ awọn agbofinro ti tẹ nilu Ogijo, nipinlẹ Ogun.
DSP Abimbola Oyeyemi to jẹ alukoro ọlọpaa ni ipinlẹ Ogun, lo fidi ọrọ yii mulẹ ninu atẹjade kan to fi sita fawọn akọroyin.
O ni awọn mu awọn ọmọ ẹgbẹ okunkun naa, lẹyin ti eeyan kan lọ fẹjọ sun lagọ ọlọpaa pe wọn yinbo lu ọmọ ọdun mẹrindinlogun kan ni ikun.
Oyeyemi ni ibọn yinyin naa waye lasiko tawọn ọmọ ẹgbẹ okunkun naa n ṣe iwọde idaro akẹẹgbẹ wọn to ku.
Oriṣiriṣi ọna ni eto igbani wọle maa n gba ninu awọn ẹgbẹ okunkun
Yatọ si pe wọn yinbọn lu ọmọkunrin naa nikun, wọn tun gba foonu ọwọ rẹ, ti wọn si tun soro fawọn aladugbo pẹlu.
Lẹyin ti awọn ọlọpaa doju ija kọ awọn afurasi ọmọ ẹlẹgbẹ okunkun naa tan, ni ọwọ ba tẹ wọn.
Eeyan mẹjọ ni awọn afurasi ti ọlọpaa mu, ti ọjọ ori wọn si wa laarin ogun ọdun si mejilelọgbọn, ọkunrin si ni gbogbo wọn.
Obateru Akinruntan: Wíwá ohun tá jẹ títí láé ló gbé wa kúrò nílé Ife
Kọmisana ọlọpaa ipinlẹ Ogun, Edward Awolowo Ajogun ti wa paṣẹ pe ki wọn ko awọn afurasi naa lọ si ẹka ọtẹlẹmuyẹ ileeṣẹ ọlọpaa.
Ọmọkunrin ti wọn ti wọn yinbọn lu ti n gba itọju nile iwosan.
Oríṣun àwòrán, Others
Ileeṣẹ ọlọpaa ipinlẹ Rivers pawọpọ pẹlu awọn fijilante ibilẹ lati fi mu igara ọlọsa agbenipa kan to jẹ olori ẹgbẹ okunkun Greenlanders, Honest Diigbara ti ọpọ mọ si Bobosky.
Sugbọn ko pẹ si akoko ti wọn gba a mu lo ku si wọn lọwọ lahamọ ọlọpaa ti wọn fi si.
Wọn kede iku igara ọlọsa ajinigbepawo Bobosky ti wọn mu lọjọ Abamẹta.
Alukoro ọlọpaa ipinlẹ Rivers Nnamdi Omoni to fidi ọrọ yi mulẹ fun BBC sọ pe oro ọta ibọn lo ṣokunfa iku rẹ.
Mọjumọ Abamẹta ni wọn lawọn mu ni adugbo Korokoro nibi to sapamọ si pẹlu awọn akẹgbẹ rẹ.
Ninu fọnran fidio kan taa ti ri bawọn ọlọpaa ṣe gba mu, niṣe ni ẹjẹ wa lara Bobosky torukọ rẹ gangan n jẹ Honest Digbara.
Ọwọ palaba igara ọlọṣa ajinigbe kan ti n dẹru ba ara ilu ni ipinlẹ Rivers la gbọ pe o ti segi lẹyin tọwọ awọn agbofinro tẹ ẹ.
Honest Digbara ti inagijẹ rẹ Bobosky fẹ fara pẹ orukọ gbajumọ nii, Bobrisky  la gbọ pe awọn ọlọpaa mu ni nkan bi ago meji abo oru ni adugbo Korokoro Tai ni ijọba ibilẹ Gokana.
Digbara ni ọga awọn ọmọ ẹgbẹ okunkun Greenlander ni ipinlẹ Rivers.
Awọn ileeṣẹ iroyin Naijiria kan naa sọ pe  igbakeji rẹ faragbọta ninu ikọlu pẹlu awọn ọlọpaa.
Ṣaaju asiko yi, Gomina Nyesom Wike ti kede  ọgbọn miliọnu naira gẹgẹ bi ẹbun fẹnikẹni to ba ri Digbara mu.
Agbarijọpọ awọn agbofinro  ti ọga ọlọpaa Gokana  dari wọn ati ọmọ ikọ fijilanti ni wọn jijọ mu ọdaran yi.
Akọroyin kan,Awajis George fi fọnran fidio ibi ti awọn ọlọpaa ti mu afurasi yi sita loju opo Twitter
Coronavirus Update: Ṣe ẹ mọ pe Covid-19 lee yọri si giri tabi ki eeyan daku rọngbọndan?
Ṣebi ẹ mọ pe ọpọ ni kii fi ami han lara pe wọn ni Covid-19 gẹgẹ bi iwadi ṣe fihan?
Koda, ọpọlọpọ ni Naijiria ko tii gbagbọ pe Covid-19 wa ti wọn ko si le gbagbọ titi yoo fi kasẹ nilẹ.
Àwón  Oníbúrẹ́dì ń gbé ìgbésẹ̀ láti fi kún owó Búrẹ̀dí ní Nàìjírià
Ṣé òògùn Chloroquine lè dènà ààrùn Coronavirus bí?
Kére o! Nàíjíríà tún ń wọnú ọrọ̀ ajé tó dagun lọ lẹ́ẹ̀kejì - Ìjọba àpapọ̀ laago ìkìlọ̀
Ṣe o mọ pe o le pin ara rẹ kaakiri agọ ara rẹ pẹlu iranwọ awọn eroja to wa ni ara rẹ?
Ṣe o mọ pe o le ma kọja iba tabi ikọ ati idiwọ eemi fun ẹlomiran? Lo ba tan.
Ẹ wo bí ẹ ṣe lè ṣe àyẹ̀wò Covid 19 yín ní ọ̀fẹ́ lórí fóòònù yin
Nàìjíríà làwọn ní ìfẹ́ sí ìpèsè abẹ́rẹ́ àjẹsára Covid-19 tí Russia ṣe
Mo ti buwọ́lu àdínkù owó orí nítorí ìrọ̀rùn àwọn èèyàn ìpínlẹ̀ Ogun lásìkò Covid 19- Dapo Abiodun
Njẹ ẹ tun gbọ tuntun. Ṣe ẹ mọ pe Covid-19 lee yọri si giri tabi ki eeyan daku rọngbọndan?
Koda ṣe ẹ mọ pe o lee bọ si ọpọlọ ti yoo si yọri si arun rọparọsẹ?
Arakunrin kan to ti bọ lọwọ Covid-19 sọ bi iṣoro eemi ṣe maa n ri fun ẹni ba laisan yii.
Seyi Makinde fún àwọn tó ń tajà lẹ́gbẹ́ títì l'Oyo ní gbèdéke ọjọ́ méje láti wábigbà
Oríṣun àwòrán, Twitter/oyo affairs
Ijọba ipinlẹ Ọyọ ti fun awọn to n taja lẹgbẹ titi lati wa 'bi gba ki wọn to fi imu ko ata ofin.
Kọmiṣọna f'ọrọ ayika ati amojuto ohun alumọni omi, Amofin Idowu Oyeleke lo sọ bẹẹ lasiko to fi n kopa lori eto ori redio kan niluu Ibadan.
Amofin Oyeleke ni ko ni saye fun tita ọja lawọn ọna ti ko ba igba mu mọ ni ipinlẹ Ọyọ paapa julọ tita ọja lẹgbẹ popo.
O ni awọn ti pe gbogbo awọn aṣiwaju awọn ọlọja lati fi ọrọ yii to wọn leti silẹ.
Bí rere ni àbí búburú, wo ohun tí Covid-19 leè ṣe sí àgọ́ ara rẹ
O ni lootọ awọn ọlọja kan ti kọlu awọn oṣiṣẹ ijọba to mu itọni ati igbaniniyanju lori ewu to wa ninu ka maa ta ọja loju popo eleyi to ni o ku diẹ kaa to gidigidi.
Tita ọja lẹgbẹ titi jẹ ọna itaja kan ti awọn ontaja ni ilu Ibadan, ipinlẹ Ọyọ atawọn ilu miran fi n wa ọna ijẹ imu.
Satchet Alcohol ban: Ìjọba àpapọ̀ yóò fòfin de títà àti rírà ọtí inú ọ̀rá bíi 'pẹlẹbẹ', 'pàrágà'
Oríṣun àwòrán, others
Paraga, kainkain, fona gau ati omiran wo lẹyin tun mọ?
Gbogbo awọn ọti inu ọra ati inu igo wọnyii ni ijọba apapọ ti n gbe igbesẹ lati fi ofin de e laipẹ, iyẹn bi ọrọ oludari agba ajọ to n gbogun ti ilokulo ohun jijẹ ati ogun, lorilẹede Naijiria, NAFDAC, Ọjọgbọn Mojisọla Adeyẹye ṣe sọ.
Ajọ NAFDAC ni ijọba apapọ fẹ gbe igbesẹ yii nitori ipa ti mimu ọti lọna ti ko tọ n mu ba ilera ilu pẹlu igbayegbadun araalu.
O ni bi awọn eeyan ṣe n lanfani lati mu ọti wọnyii nigbakugba to ba wu wọn ninu ọra pelebe pelebe ati igo kekeke n ṣe ọpọ akoba fun awujọ paapaa julọ bi iwadii ti ṣe fihan pe awọn eroja yii lo fihan pe ohun lo n ṣokunfa bi awọn eeyan ṣe n mu ọti bi ẹni n mu omi lawujọ.
O ni ijọba ti kọkọ fofin silẹ fun awọn to n pọn ọti inu ọra pelebe ati igo kekeke ni ibẹrẹ ọdun 2020 pe ki wọn din iwọn ti wọn n ṣe jade ku pẹlu ida aadọta ninu ọgọrun, (50%) gẹgẹ bi igbesẹ akọkọ lati dẹkun awọn ọti inu ọra naa.
Ajọ ilera agbaye, WHO ti gbe e sita ninu iwadii kan pe eeyan miliọnu mẹta lo n ku lọdun nitori ọti mimu.
Ọkọ mi kò fẹ́ràn oúnjẹ òyìnbó àfi ti ìbílẹ̀ - Lizzy Anjorin
Mercy Aigbe ṣá ọmọ rẹ̀ sínúu fíìmù tuntun, wo itú tí ọmọ ọdún mẹ́wàá náà pa
Àlàyé rèé lórí bí 'Popular Jingo' ṣé dí inagijẹ akọrin Juju tó bí Wale Thompson 'Lalalẹ Friday'
Oríṣun àwòrán, Popular Jingo
Pupọ awọn to ba dagba saaju igba kọmputa ta wa yii ni yoo ti gbọ ki wọn maa pe ẹni to ba jẹ ilumọọka tabi gbajumọ ni  ''Popular Jingo.''
Inagijẹ yi wọpọ laarin awọn Yoruba ṣugbọn diẹ lawọn ẹni ti yoo ṣi ranti pe eeyan kan to jẹ akọrin Juju ni apejẹ rẹ n jẹ ''Popular Jingo.''
BBC Yoruba ṣe iwadii ọrọ yii nipa biba alagba David Anwo Agbolade ti awọn eeyan mọ si Popular Jingo sọrọ.
Oríṣun àwòrán, Popular Jingo
Ilumọọka  Akọrin Juju ni David Agbolade tawọn eeyan si ni o wa lara awọn to mu ki orin Juju fẹsẹrinlẹ nilẹ kaarọ o jiire.
Lasiko rẹ, eeyan ko le darukọ olorin Juju lagbegbe Ijebu Igbo, Eko ati Ibadan ki wọn ma pe Popular Jingo mọ wọn.
Bi awọn Sunny Ade ati Ebenezer Obey  ti ṣe n fi orin juju da awọn eeyan lara ya nilu Eko ni Popular Jingo naa n migboro titi laaye tiẹ naa.
Ọdun 1943 ni wọn bi alagba David Anwo Agbolade ti o si bẹrẹ ileewe ni Saint Luke's Primary School ni Japara Ijebu Igbo, lọdun 1949.
Alagba David ni ''nigba ti mo wa ni ileewe alakọbẹrẹ ni mo ti bẹrẹ si ni fifẹ han si orin kikọ''
''Koda mi o ti kẹkọ pupọ ki n to mọ lọkan mi pe iṣẹ orin lọna mi''
Oríṣun àwòrán, Popular Jingo
Amọ ṣa baba to bi David iyẹn, alagba Moses Anwoloju Aina ko nifẹ si ki ọmọ rẹ kọrin.
Popular Jingo ni ''Ada ni baba mi yọ si mi nigba ti mo ni mo fẹ bẹrẹ orin. Inu wọn ko kọkọ dun si nigba naa''
Yatọ si pe o jẹ akọrin Juju, Popular Jingo a tun maa gba bọọlu nigba ewe rẹ.
Idi ere boolu gbigba gẹgẹ bi o ti ṣe sọ ni awọn akẹgbẹ rẹ ti fun ni apejẹ rẹ, Popular Jingo.
Oríṣun àwòrán, Populkar JINGO
Ifẹ to ni si orin kikọ yii tun tẹsiwaju si ni igba to wa ni Saint Vincent Catholic Modern School.
Ni igba taa n wi yii, Agbolade a maa ta jita pẹlu 'Mouth Organ' ki o to wa pada wa maa lo 'Accordion'.
''Ni ọdun 1979 ni mo mọ daju lọkan mi pe mo ni ẹbun orin kikọ. Ohun to si ṣẹlẹ ni pe mo kọrin nigba ti eeyan kan ku lagboole wa''
Oríṣun àwòrán, Popular Jingo
Lọjọ naa lọhun Jingo sọ pe niṣe ni gbogbo ile pa lọọlọ ti oun si fi orin da awọn eeyan lara ya.
'Awọn eeyan tẹwọgba orin mi lọjọ naa ti inu mi si dun''
Ninu ifọrọwanilẹnuwo pẹlu BBC,Popular Jingo ni ohun ko ni ọga kan pato.
Amọ o salaye pe ẹnikan ti wọn n pe ni Kolawole Ijaduoye alias 'Kolly Jo' lawọn bẹrẹ orin Mamba lọdọ rẹ ki awọn to yi pada si Juju ṣugbọn ko pe ti awọn lo lọdọ rẹ.
''IK Dairo, Ojoge Daniel, Tunde Nightingale, ati Rosa Adetola ni mo maa n wo lawokọṣe ni igba naa.''
Oríṣun àwòrán, Popular Jingo
Agbolade sọ pe ninu gbogbo wọn, ''Tunde Nightingale ni mo maa n tọ ipasẹ re.''
Nigba naa lọhun, Popular Jingo sọ pe Haruna Ishola olorin Apala to jẹ ọmọ Ijebu Igbo a maa gba oun ni imọran lati maa mu diẹ ninu 'style' Tunde Nightingale.
Royal Brothers Band lorukọ ẹgbẹ akọrin ti Agbolade sọ pe oun da silẹ lọdun 1962.
O si ni nigba naa lọhun irinṣẹ tawọn fi n kọrin ko pọ.
Oríṣun àwòrán, Facebook/Popular Jingo
Tohun ti bẹ awọn eeyan a maa gbadun orin Juju Popular Jingo paapa lagbegbe Ijebu Igbo, ilu Eko ati Ibadan.
Wale Thompson onijuju ọmọ Popular Jingo nii ṣe
Popular Jingo gbe awo orin orisirisi jade to fi mọ 'Oridamilare', 'Ile ẹkọ ni ile ọkọ' ati bẹẹ bẹẹ lọ.
Alagba David fẹ iyawo, o bimọ, o kọ ile koda ninu awọn ọmọ rẹ ati ọmọ ọmọ rẹ, awọn to n kọrin juju wa ninu wọn.
Oríṣun àwòrán, Popular Jingo
Wale Thompson, gbajumọ olorin Juju nii to kọ orin 'Lalalẹ Friday', ni akọbi Popular Jingo to si tẹwọ gba jita lọwọ baba rẹ.
Ẹni ọdun mejidinlọgọrin ni Popular Jingo ti ko si ti maa ṣere ode onijuju mọ.
''Mo dupẹ fun igbe aye mi,inu mi a si maa dun pẹlu ti awọn eeyan ba pade mi ti wọn a si maa sọ pe emi ni mo kọrin nibi ikomọ awọn''
Nilu Ijebu Igbo ni alagba David n gbe titi di asiko yi pẹlu awọn mọlẹbi rẹ.
Ogun Killing: Ọmọ ọdún 23 jẹ́wọ́ bó ṣe pa ẹ̀gbọ́n ìyá rẹ́, ẹni ọdún 60 nípinlẹ̀ Ogun
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Arakunrin kan ẹni ọdun mẹtalelogun ni iroyin sọ pe o jẹwọ pe oun pa ẹgbọn iya oun to jẹ ẹni ọdun ọgọta lẹyin ti iroyin sọ pe Babalawo dẹru ba a pe oun yoo pe oku naa ko wa gbẹsan lara ẹni to pa a.
Ni agbegbe Ipokia ni ipinlẹ Ogun ni a gbọ pe Asogba Dasun ti pa Iyabo Dasun to jẹ ẹgbọn iya rẹ.
Alukoro ileeṣẹ Ọlọpaa ipinlẹ Ogun, Abimbola Oyeyemi lo fi eyi lede fun awọn oniroyin lọjọ Abamẹta.
Gẹgẹ bo ṣe ṣalaye, Oyeyemi ni lẹyin ti arakunrin naa jẹwọ ni awọn fi ọwọ ofin mu u.
Oyeyemi ni awọn ọmọ oloogbe meji wa ta wọn lolobo ni agọ ọlọpaa to wa ni Ipokia.
Wọn wa fẹjọ sun ni agọ wa pe lọjọ kejilelogun oṣu kẹjọ lawọn gbọ iroyin iku iya awọn ti lẹni to jẹ pe ko ṣaisan kankan.
Wọn tẹsiwaju pe tori awọn ko ro ibi si ẹnikẹni, awọn pinu lati sin in lai sọ ohunkohun fun ọlọpaa.
Ṣugbọn lẹyin isinku ni wọn gbọ finrin finrin pe wọn ri afurasi ọhun to jẹ ọmọ aburo iya awọn ninu ile wọn lọjọ ti iṣẹlẹ yii ṣẹlẹ ko si pẹ to kuro ni wọn kede pe arabinrin ọhun ku.
Ọrọ yii ti wu ọpọlọpọ ifura jade laarin ilu ti wọn si leri pe awọn yoo tẹsẹ ile bọ ọ nipa gbigbe ẹbọ ti yoo tu aṣiri ẹni yoo wu ko ṣe iru iṣẹ ọhun.
Kete ti o gbọ ohun ti ilu fẹ ṣe lori ọrọ yii ni afurasi naa, Dansu Asogba jade sita lati jẹwọ pe oun loun wa nidii ọrọ naa.
Oyeyemi ni kete ti awọn gbọ iroyin pe afurasi yii jẹwọ ni ọga ọlọpaa to wa ni ẹkun ti Ipokia, SP Adebayo Hakeem ko awọn ọlọpaa lọ sibẹ lati lọ fi panpẹ ọba mu arakunrin ọhun.
Nigba ti ọwọ ọlọpaa tẹ ẹ, Dansu gba pe oun loun pa oloogbe naa, to si sọ fun ọlọpaa pe idi toun fi ṣe e ni pe oun gbagbọ pe oun lo pa akọbi ọmọ oun ati pe oun lo wa nidii oyun kan to walẹ lara iyawo oun.
Oyeyemi fi kun un pe irin ni Dansu fi gba arabinrin naa lọrun eyi to si la iku lọ.
Ẹwẹ, kọmisọna ọlọpaa ipinlẹ Ogun, Edward Ajogun ti paṣẹ pe ki wọn gbe afurasi naa taara lọ si ẹka awọn ọtẹlẹmuyẹ fun iwadii ati idajọ rẹ.
Ìyàwó ilé lu ọmọ ọkọ rẹ̀ pa ní ìpínlẹ̀ Ogun
Ọkùnrin kan pa ara rẹ̀ sínú ọgbà àjọ TRACE tó n mójútọ ìrìnnà ọkọ̀ nípìnlẹ̀ Ogun
È gbọ òun ti ojú  awọn ara ipinle Ogun rí  lọwọ ìṣẹlẹ omiyale
"Policeman smoking shisha: Iléeṣẹ́ ọlọ́pàá ti bẹ̀rẹ̀ ìwádìí lórí fídíò ọkùnrin kan tó ń mu ""shisha"""
Oríṣun àwòrán, Facebook/Nigeria Police Force
Ileeṣẹ ọlọpaa orilẹede Naijiria ti bẹrẹ iwadii lori fọnran kan to lu ori ayelujara pa ninu eyi ti ọkunrin to wọn aṣọ ọlọpaa ti mu ''shisha.''
Ninu atẹjade kan ti alukoro ileeṣẹ ọlọpaa, DCP Frank Uba fi sita lọjọ Aiku, ileeṣẹ ọlọpaa awọn yoo ṣe agbeyẹwo fidio naa boya ayederu fidio ni.
Bakan naa ni ileeṣẹ ọlọpaa sọ ninu atẹjade naa to fi si oju opo Facebook rẹ pe awọn yoo tun ṣe iwadii ọhun to wa ninu fọnran naa boya ọlọpaa ni ni tootọọ tabi ọdaran to kan wọ aṣọ ọlọpaa lasan.
''Ṣugbọn nigba ti iṣẹ iwadii ṣi n lọ lọwọ, o ṣe pataki lati jẹki awọn araalu mọ pe ohun ti ọkunrin to wa ninu fidio naa n ṣe lodi si ilana ati ofin to de awọn ọlọpaa orilẹede Naijiria,'' Ọgbẹni Uba lo sọ bẹẹ.
O wa rọ awọn araalu ti o ba mọ ohun kan tabi omiiran nipa fidio ọhun lati kan si ileeṣẹ ọlọpaa.
O ni ẹnikẹni to ba ni ohun kan lati fi to ọlọpaa leti le fi ranṣẹ si adirẹsi yii- pressforabuja@police.gov.ng, tabi ki wọn kan si oju opo ileeṣẹ ọlọpaa lori ayelujara.
Lati ọjọ Abamẹta lawọn eeyan ti n sọrọ lori fọnran ọkunrin naa to n fi shishan ṣagbeji ara nibi to joko si.
Ọmọ ọdún 23 jẹ́wọ́ bó ṣe pa ẹ̀gbọ́n ìyá rẹ́, ẹni ọdún 60 nípinlẹ̀ Ogun
Wo nǹkan tí ìjọba àpapọ̀ yóò ṣe fáwọn tó ń ta 'pẹlẹbẹ', 'pàrágà' àti 'fònàgáú'
Professor Ayo Akinwale: Iṣẹ́ rẹ ń tọ̀ ọ́ lẹ́yìn
Oríṣun àwòrán, Etsu Muazu Idris/Facebook
Ayobami Akinwale ọmọ agbo Sasa ọmọ agbo Yaya,
Ọmọ Ibadan nile Oluyole, Omo ajẹgbin jẹ 'karahun ....
Ijagboro loro Ibadan. Ọmọ Ibadan mesiọgọ,
Omo Ibadan Maja Maja ti o fina ara waju leru.......... Hmmmmn!
O yẹ ki ọga mi pe aadọrin dun ninu oṣu kẹrin ọdun to m bọ.
Gẹgẹ bi Abdulrasheed Adeoye to jẹ oludari agba ẹka iṣẹ ọna to si ti jẹ oludari ẹka imọ Tiata ni fasiti Ilorin eyi tii ṣe ipo meji ọtọọtọ ti oloogbe Ayo Akinwale naa ti kuro to gbe eku ida le e lọwọ, wọn bi Ayo Akinwale ni ilu Ibadan, ọmọ bibi ilu Ibadan si ni pẹlu.
Ẹni ti Ọlọrun da ti ko ṣee fara we ni Ọjọgbọn Ayo Akinwale. O mu gbogbo akẹkọọ bi ọmọ rẹ, oloju aanu si ni.
'Aràrá bíi tèmi, kó má rò pé kò sì ǹkan tó lè ṣe láyé ju iṣẹ́ agbe lọ'
Gbogbo agbaye ni Ayo Akinwale ti rin kaakiri lati lọ ṣiṣẹ.
Gbogbo oye to yẹ keeyan gba ninu imọ iṣẹ Tiata lo gba nigba aye rẹ- oye Diploma, Degree, Masters, PhD ni ẹka Tiata fasiti ilu Ibadan.
Abdulrasheed ni gbogbo ohun to wulo fun oniṣẹ Tiata ni rere lawọn atawọn akẹkọ kọ lọdọ Ayo Akinwale.
"Baa ṣe le sọrọ soke,
baa ṣe le rin lori itage,
ṣiṣẹju si eeyan, lilo ọwọ,
iru aṣọ to yẹ ka mọ ni ọga kọ wa. Bo ba wa dari ere kan lonii to di oṣu to m bọ to mu omii, ọtun ọtun lẹ o maa ri ninu iṣẹ rẹ."
Yatọ fun iṣẹ Tiata, ilumọọka ni Ayo Akinwale ninu fiimu lati igba awọn ere atijọ bii:
Afonja
Sango
Ladepo Omo Adanwo
Iranse Aje
"Agbara Obinrin ati bẹẹ bẹẹ lọ pẹlu oniruuru ami ẹyẹ ti Ayo Akinwale gba gẹgẹ bi oṣere, oludari ere, ẹlẹsẹ ijo ati olohun orin - ""gbogbo iha Tiata lo pe lara Ayo Akinwale"". Abdulrasheed sọ fun BBC Yoruba."
Ọmọkùnrin tó ya 'Blue film' nínú igbó Osun Osogbo ti bayé ara rẹ̀ jẹ́ - Yemi Elebuibon
Ó yẹ kí Sotitobire gbọ́ ìdájọ́ lónìí ṣùgbọ́n ẹ wo bí ilé ẹjọ́ ṣe tún ṣe é
Ìbẹ̀rù-bojo dé l'Ado Ekiti! Àwọn agbébọn pa ọ̀gá àjọ tó ń rí sí ọ̀rọ̀ ìjọba ìbílẹ̀
Lai Mohammed, Ayo Fayose, Afẹnifẹre, Ndigbo, Arewa dá sí ọ̀rọ̀ Buhari àti Obasanjo
Gbajugbaja oṣere to tun jẹ ọkan gboogi ọga lọga lagboTiata nile ati lẹyin odi, Ọjọgbọn Ayo Akinwale ti bẹrẹ irinajo rẹ lọ sọrun.
Dajudaju, ẹja nla lo lọ  laarin awọn elere Tiata pẹlu bi ayelujara awọn olukọni ati akẹkọ, to fi mọ awọn ọjọgbọn fasiti atawọn agba oṣere ṣe kun fọfọ pẹlu aworan ati iṣẹ ire ti Ayo Akinwale ṣe.
Oríṣun àwòrán, Abdurasheed Adeoye/Facebook
'Aràrá bíi tèmi, kó má rò pé kò sì ǹkan tó lè ṣe láyé ju iṣẹ́ agbe lọ'
Gẹgẹ bi oludari agba ẹka iṣẹ ọna fasiti Ilorin to gba eku ida ẹka yii kan naa lọwọ Ọjọgbọn Akinwale, Ọjọgbọn Rasheed Adeoye ṣe fi atẹjade sita, gbajugbaja oṣere yii to tun jẹ igi nla lagbo imọ ẹkọ Tiata, Ayo Akinwale jade laye lọjọ kẹtala oṣu kẹsan ọdun 2020 ni ile iwosan fasiti Ilorin.Ayo Akinwale ti jẹ adari patapata ẹka imọ ẹkọ Tiata, Performing Arts ni Fasiti Ilorin ati oludari agba ẹka isẹ ọna ni fasiti kan naa ko to jẹ Ọlọrun nipe.
Osun Osogbo Shrine Porn Video: Wo ìgbà méjì láàrín ọdún méjì tí ojúbọ Osun Osogbo ti mú ìròyìn àìtọ́ lọ́wọ́
Oríṣun àwòrán, @kingtblakhoc/twitter
Tobi Jolaosho 'King Tblak' ni awọn kan gbagbọ pe o pilẹ sinima ibalopọ ni Naijiria
Ni aipẹ yii ni iroyin kan jade pe awọn ọdọ kan lọ ṣe aṣemaṣe ni ojubọ Oṣun oṣogbo ni ilu Osogbo.
Ariwo gbaye kan lori rẹ nitori lara awọn oriṣa to gbajugbaja julọ ni ilẹ Yoruba ni Ọṣun wa koda ilu mẹta ọtọọtọ ni wọn ti n ṣe ọdun ọṣun oṣogbo - ilu Osogbo, ilu Ifẹ ati ilu Ifaki Ekiti.
Njẹ ẹ mọ pe laarin ọdun mej,i igbakeji niyi ti ariwo kotọ yoo maa sọ eleyi ti yoo rọ mọ ojubọ Ọṣun tabi oriṣa naa funrarẹ.
Ni ọdun 2019 ni iroyin jade sita pe ko si oriṣa ọṣun ni ojubọ rẹ mọ atipe awọn kan ti taa fun ẹgbẹlẹgbẹ owo dọla ilẹ Amẹrika.
Ẹni to jẹ Baba Ọṣun tẹlẹ, Alagba Ọlayiwla Adigun ṣalaye pe kabiyesi Ataọja ti ilu Oṣogbo ti ta oriṣa ọṣun fun awọn are kan ati pe igba ti wọn fẹ gbee jade kuro lorilẹede Naijiria ni Ọṣun wa wuwo ti ko ṣe e gbe mọ ti o fi wa yọ si ọkan lara wọn pe ki wọn da oun pada sọdọ awọn to ni oun bi wọn ko ba fẹ ri pipọn oju oun.
Amọṣa nigba ti BBC gbe ọrọ naa tọ Kabiyesi Ataọja nigba naa, baba ni ko soun to jọọ ati pe ija lo de torin dowe.
Kabiyesi Ataọja no oun ko ta oriṣa Ọṣun ṣẹngẹṣẹ, lile ti igbimọ Atasja le Alagba Ọlayiwla Adigun kuro nipo Baba Ọṣun lo mu ki o gbarata sọ ọrọ odi naa jade.
Titi di bi a ṣe n sọrọ yii alagba Ọlayiwla Adigun ṣi n duro lori pe oriṣa Ọṣun ko si ni ojubọ rẹ ms bayii, bẹẹni baba Ataọja pẹlu n faake kọri pe oun ko ta oriṣa Ọṣun.
'Búrẹ́dì tí wọn ó fi jẹ ẹ̀wà ni wọ́n lọ rà ni wọ́n pàdé ikú gbígbóná'
Osun Osogbo: Àtáója ní káwọn èèyàn má a bọ̀ wá bọ Ọ̀ṣun lónìí, torí kò ṣe é jígbé,
Nigba ti awọn araalu ṣẹṣẹ n simi lori awuyewuye yii, ni iroyin kan tun jade lọsẹ yii pe arakunrinkan ti orukọ rẹ n jẹ Tobilọba Jọlaosho lọ ya sinima onibalopọ ti a mọ si 'Blue film' lojubọ naa.
Iroyin yii ka gbogbo aye laya to si mu ki ọpọ o maa ṣe haa hin, ki ree?
Titi di bi a ṣe n sọrọ yii, Tobilọba ti foju ba ile ẹjọ o, koda o ti kawọpọnyin wi fun adajọ pe oun ko jẹbi ẹsun ti wọn fi kan oun rara.
'Ọ̀nà àtijẹ kan ṣoṣo táa ní ni Màálù àwọn Fúlàní ti bàjẹ́'
Oríṣun àwòrán, King Tblak/Twitter
Tobiloba Jolaosho ti ọpọ mọ si King Tblak ti sọ̀rọ̀ niwaju ile ẹjọ pe oun ko jẹbi rara nipa ẹsun ti wọn fi kan an pe o lọ ya fiimu ibalopọ ninu igbo Osun Osogbo.
Ile ẹjọ Majisireeti kan niluu Osogbo tii ṣe olu ilu ipinlẹ Osun ti pe Tobiloba Jolaosho atawọn marun mii ti wọn jọ wa latimọle ọlọpaa ki wọn wa jẹ́jọ́.
"Ẹni ọdun mẹtadinlọgbọn ọhun to gbajugbaja lori ayelujara pẹlu orukọ to n lo, ""TBlak"" ni wọn fi ẹsun kan pe o dan nkan eewọ wo ninu igbo Osun Osogbo nibi to ti lọ ya fiimu ibalopọ pẹlu obinrin kan ni ihoho."
Ọmọ méjì ò sọnù nínú àgbàrá òjò o! Ọ̀tọ̀ lọ̀rọ̀ táa ń pè yín sí - Aráa Ketu
Iroyin fihan pe ọwọ ọlọpaa tẹ Jolaosho nigba ti awọn agbaagba ẹlẹsin ibilẹ fi ọrọ naa to awọn ọlọpaa leti.
Awọn ti wọn jọ kawọ pọnyin rojọ nileẹjọ Majisireeti ni pẹlu Jolaosho ni Ladiva Aije, Juliet Semion, Ahmed Olasunkanmi, Eritosin ati Tunde Jimoh ti wọn si fi ẹsun mẹjọ kan wọn to rọ mọ yiya fiimu ibalopọ ninu igbo Osun Osogbo.
Adajọ olupẹjọ, John Idoko fi ẹsun kan wọn pe wọn lọ yaworan nibẹ pẹlu awọn ọdọbinrin to fẹrẹẹ tu sihoho ti wọn si fi sita lori ayelujara eyi to lodi si igbagbọ ninu ẹsin ibilẹ ti wọn n ṣe ni Osun.
Ẹwẹ, TBlak ati awọn afurasi to ku ni awọn ko jẹbi ẹsun ti wọn fi kan wọn.
Ile ẹjọ si ti sun igbẹjọ naa siwaju di ọjọ kẹtadinlogun oṣu kẹsan ọdun 2020.
Ọmọkunrin kan, Tobiloba Jolaosho, ni awọn ọlọpaa ti mu nitori pe o ya fidio ibalopọ ninu igbo Osun Osogbo, to si tun fi fidio naa sori ayelujara.
Oṣere sinma ibalopọ, ti awọn elede Gẹẹsi n pe ni porn tabi blue film, ni Jolaosho, ti inagijẹ rẹ n jẹ King Tblak HOC.
Iroyin sọ pe ọkan lara awọn ọmọ ẹgbẹ ẹlẹsin ibilẹ nipinlẹ Osun lo fi ọrọ to ileeṣẹ ọlọpaa l'eti pe, oun ri Jolaosho ninu fidio naa to n hu iwa ibajẹ ninu igbo ọhun. Eyi to le da alaafia ilu ru.
Alukoro ileeṣẹ ọlọpaa nipinlẹ Osun, Opalola Yemisi sọ fun BBC pe wọn o gbe Jolaosho lọ sile ẹjọ, ti iwadii ba pari.
Tóò bá fún ọkùnrinn lóúnjẹ́ tóo tẹ́ kiní yẹn sílẹ̀ fún un dáadáa... - Yinka TNT
Wọn fi ẹsun kan pe niṣe lo mura bi abọriṣa Osun, ti oun ati ọmọbinrin kan to wa ni ihoho si jọ ni ibalopọ ninu ojubọ naa, l'oṣu Keje, ọdun 2020.
Oriṣiriṣi fidio ibalopọ naa lo kun ori ayelujara Twitter ọmọkunrin ọhun, to ti ni ololufẹ to le ni ẹgbẹrun mẹrindinlọgbọn to n tẹle e lori ayelujara.
O si tun ni itakun agbaye ti awọn eeyan ti ma n san owo lati wo awọn fidio naa.
Oríṣun àwòrán, @KingTblackhoc/twitter
Nigba to fidi iṣẹlẹ naa mulẹ fun BBC Yoruba, Araba ilu Osogbo, to tun jẹ ọkan lara awọn alamojuto ẹsin ibilẹ nilẹ Yoruba, Oloye Ifayemi Elebuibon, sọ pe niṣe ni ọmọkunrin naa fi kele ati ọpẹlẹ kọrun, to si lọ ba awọn obinrin ṣe aṣemọṣe.
"Ao mọ nkan to kọlu ọmọkunrin naa. Bi igba ti eeyan fẹ ẹ da ẹrẹ si ibi ti a pe ni ibi mimọ ni nkan to ṣe.
Ibi ti gbogbo eeyan ti n wa kaakiri agbaye lati ṣe tutu, lo lọ ọ mu abawọn ba."""
Elebuibon sọ pe ọwọ ileeṣẹ ọlọpaa ti tẹ ọmọkunrin naa.
O ti ba aye ara rẹ jẹ,  ori rẹ ti gbalẹ baun, nitori iwa to hu yii.
Ìtàn ọ̀rẹ́ tó fi ògùn gba ọkọ ọ̀rẹ́ rẹ̀ ni Akomolede BBC Yorùbá fẹ́ kọ́ wa lònìí
Oríṣun àwòrán, @kingtblakhoc/twitter
Tobi Jolaosho 'King Tblak' ni awọn kan gbagbọ pe o pilẹ sinima ibalopọ ni Naijiria
Bakan naa ni o fi kun pe nigba ti ileeṣẹ ọlọpaa ba pari iwadii wọn lori ẹsun ti wọn fi kan Jolaosho, ni awọn ẹlẹsin ibilẹ yoo to o da sẹria to tọ fun.
Oriṣa pataki ni Osun jẹ nilẹ Yoruba, kaakiri agbaye si ni awọn eeyan ti ma n wa fun ayẹyẹ ọdun Osun Osogbo lọdọọdun.
BBC gbiyanju lati ba Jolaosho sọrọ lori foonu nipasẹ numba kan to fi si ori ayelujara Twitter rẹ, ṣugbọn igbiyanju wa ko so eso rere.
Lagos-Ogun Train wreck: Reluwé kọlu ọkọ̀ mẹ́ta l'Eko, èèyàn méjì kú, méje fara pa
Ọkọ mẹta ni reluwe to gbera lati ipinlẹ Ogun wa si ilu Eko ni owurọ ajọ Aje kọlu ninu irinajo rẹ.
Ajọ to n ṣe kokaari iṣẹlẹ pajawiri ni ipinlẹ Eko, LASEMA ṣalaye pe ọkọ Jiipu Highlander ni ọkọ kẹta ti reluwe naa kọlu ti awọn mẹta to wa ninu rẹ fara pa yannayanna ti wọn si gbe wọn lọ si ileewosan nla LUTH fun itọju.
Ọkan ninu wọn lo kọkọ jade laye ti ẹni keji ṣi n gba itọju ni ileewosan naa.
Ṣugbọn ajọ LASEMA ti fidi rẹ mulẹ pe ẹnikeji naa ti pada dagbere faye.
ọkọ akero bọọsi kan ati ọkọ ayọkẹlẹ jiipu miran ni reluwe naa kọkọ kọlu lagbegbe Oshodi.
Eeyan mẹfa lo wa ninu bọọsi funfun naa.
Reluwe naa la gbọ pe o wọ awọn ọkọ mejeeji naa fun ọpọlọpọ irin ko to di pe o duro.
Ọkọ oju irin Reluwee naa kọlu ọkọ bọọsi akero lagbegbe Oshodi ni ilu Eko lowurọ ọjọ Aje.
Ọrọ ọhun di wọlukọlu lagbegbe abẹ bridge ni Osodi.
Ọkọ reluwe ọhun to n gbera lati ipinlẹ Ogun wa si ilu Eko ni irinajo reluwe akọkọ ti yoo waye laarin oṣu marun un ti wọn ti ijọba ti ti irinna ojuirin nitori ajakalẹ arun COVID-19.
Oríṣun àwòrán, Empics
Kii ṣe iroyin mọ pe ọpọ igba lawọn eeyan maa n gbe ọja si oju irin, bẹẹ lawọn ọkọ a maa fo oju opo irin reluwe bi o ṣe wu wọn eyi to si ti mu ẹmi ọpọlọpọ lọ lorilẹede Naijiria.
Ajọ to n ṣe kokaari iṣẹlẹ pajawiri ni ipinlẹ Eko, LASEMA ṣalaye pe ọkọ ti reluwe naa kọlu jẹ bọọsi alawọ funfun kan ti nọmba idamọ rẹ jẹ GGE 972 GE  lagbegbe PWD l'Oshodi.
Ajọ naa ni ko si ẹmi to ba iṣẹlẹ naa lọ ati pe wọn ti kgbe ọkọ naa kuro loju irin bẹẹni reluwe naa ti tẹsiwaju irinajo rẹ.
Ẹwẹ, ọkọ reluwe  naa la tun gbọ pe o kọlu ọkọ ayọkẹlẹ miran ni agbegbe Arena Gate ni Oshodi kan naa.
Ọwọ́ àwọn ọlọ́pàá ti tẹ ọkùnrin kan pẹ̀lú orí ọmọdé nílé aṣòfin àpapọ̀
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Awọn ọlọpaa ti ko mamugarri si ọwọ arakunrin kan ni ẹnu iloro ileegbimọ aṣofin orilẹede naa.
Ileeṣẹ ọlọpaa orilẹede Uganda ka apo kan mọ arakunrin naa lọwọ ninu eyi ti wọn ti ba ori ọmọde kan ti wọn ge nibẹ.
Ko tii si ẹni to lee sọ ni pato ohun gan ti ọkunrin naa fẹ ṣe to fi gbe ori ọmọde wa si ile aṣofin naa, bakan naa ni ko tii si ẹni to mọ ibi to ti ri ori ọhun.
Nibayii, iroyin sọ pe o ti wa ni ahamọ awọn ọlọpaa nibi ti wọn ti n fi ọrọ wa a lẹnu wo.
Eeyan kan ni ẹka ọtẹlẹmuyẹ ileeṣẹ ọlọpaa ni awọn gba ipe pajawiri pe ọmọ kan sọnu lootọ lati agbegbe Masaka, iyẹn apa gusu ilu Kampala to jẹ olu ilu orilẹede naa. Awọn si ri oku ọmọde kan ti wọn ti ge ori rẹ lagbegbe naa ni ọjọ kan naa. Awọn ọtẹlẹmuyẹ ṣi n wadii bi iṣẹlẹ mejeji naa ṣe so pọ mọ ara wọn.
Lawọn ọdun diẹ sẹyin, ọwọja ijinigbe ati iṣekupa awọn ọmọde gogo sii lorilẹede Uganda, ti igbagbọ ọpọ si da lori pe wọn fi wọn ṣetutu ọla ni.
Bakan naa ni iṣẹlẹ awọn ajafẹtọ to n gbe ẹbọ ka iwaju ile aṣofin naa pẹlu ti n waye lati tako iwa ijẹkujẹ ati aisi iṣẹ fun awọn ọdọ.
'Aràrá bíi tèmi, kó má rò pé kò sì ǹkan tó lè ṣe láyé ju iṣẹ́ agbe lọ'
Shan George: Àgbàọ̀jẹ̀ òṣèré Nollywood ṣetán láti ṣègbéyàwó pẹ̀lú ọkọ kẹẹ̀rin lẹ́ni ọdún 50
Oríṣun àwòrán, Instagram/shan george
Lootọọ ni pe ọrọ ifẹ bi adanwo ni. Ati pe ohun to dara ni ifẹ jẹ gẹgẹ bi awọn eeyan ti maa n sọ.
Eyi lo difa fun agbaọjẹ oṣere Nollywood ẹni aadọta ọdun, Shan George to kede pe oun ṣetan lati ṣe igbeyawo fun igba kẹẹrin lẹyin ti igbeyawo rẹ mẹta akọkọ ti fori ṣanpọn.
Ṣebi Yoruba bọ, wọn ni ti ẹṣin ba da ni, aa tun un gun ni.
"Adia fun George to sọ loju opo ayelujara Instagram rẹ pe ""bi o tilẹ jẹ pe ẹru n ba mi, mo ṣi n ṣiyemeji nitori awon iriri mi at'ẹyin wa, ṣugbọn o dabii pe eleyii yoo san, ko yẹ ki n bẹru."""
Nitori naa, mo sọ pe mo gba lati fẹ ọrẹ korikosun mi, ọmọ iya mi, alabaṣiṣẹpọ mi ati ọmọ ipinlẹ Cross River bii temi naa, Shan George lo sọ bẹẹ.
"George ni ""ẹ jẹ ki n gbiyanju rẹ lẹẹkan sii fun igba to kẹyin. Ko tii ju fun mi. Bẹẹ ni, emi naa nifẹ rẹ."""
Awọn ọrọ ifẹ ti gbajugbaja oṣere naa kọ soju opo Instagram rẹ ree koda o tun fi oruka alawọ idẹ sibẹ eyi to ṣafihan pe o ti gba lati ṣegbeyawo pẹlu ọkunrin mii.
Ẹru n bami lati ṣe igbeyawo mii- Shan George
Gbajugbaja oṣere naa ni ti oun ba ti ro ọrọ igbeyawo, niṣe loun maa n gbe pati nitori o maa n mu ẹru ba oun.
''Emi nikan ni awọn obi bi, ni gbogbo aye mi, emi ni mo maa n daabo bo ara mi lọwọ awọn to ba ti fẹ dunkoko mọ mi,'' George lo sọ bẹẹ.
George ni ''nitori naa, ẹni ti o ba fẹ fẹmi sile gẹgẹ bi iyawo gbọdọ mu mi bi ọmọ iya rẹ, bi bẹẹ kọ, n ko le ṣe iyawo pẹlu ẹnikan mọ,
Shan George ni o tẹ oun lọrun ki oun da duro ju ki oun lọ ko si ọwọ ọkunrin kan ti ko ni fun oun ni ibalẹ ọkan lọ.
Nigba to sọrọ lori boya o maa n ronu nigba to ba da wa, o ni iṣẹ ti oun n ṣe gan an ko faye gba pe ki oun maa da wa nikan.
O ni ọpọ igba loun maa n ka iwe ti oun ko ba wa lẹnu iṣẹ tiata ti oun yan laayo.
"Ọmọkunrin meji ti wọn ti dagba bayii, Delnoi ati Jaga ni Eleduwa fi jinki Shan George.Ọjọ kọkanlelogun oṣu kẹẹrin ọdun 1970 ni wọn bi oṣere Shan George.Fasiti ilu Eko, UNILAG lo ti kẹkọọ gboye akọkọ ninu ẹkọ ere ori itage.Lẹyin to kẹkọọ gboye tan lo bẹrẹ si ni ṣee iṣẹ to yan laayo, iṣẹ tiata.Oṣere ni, oludari ati olootu ere tiata si ni pẹlu.  George di ilumọọka lọdun 1997 lẹyin to kopa ribiribi ninu ere ti akọle rẹ n jẹ ""Thorns of Rose."""
Ado Ekiti murder: Ìbẹ̀rù-bojo l'Ado Ekiti lẹ́yìn táwọn agbébọn pa ọ̀gá àjọ tó ń rí sí ọ̀rọ̀ ìjọba ìbílẹ̀
Oríṣun àwòrán, AFP
Ibẹru-bojo ti gbalẹ kan lagbegbe Odo Ado niluu Ado-Ekiti, tii ṣe olu ilu ipinlẹ Ekiti lẹyin ti awọn agbebọn kan yinbọn pa oludari ajọ to n ri si ọrọ ijọba ibilẹ nipinlẹ Ekiti, Ọgbẹni David Jejelowo.
Iṣẹlẹ naa ni a gbọ pe o ṣẹlẹ nile Ọgbẹni Jejelowo lọganjọ oru ọjọ Aje ọkọ kẹrinla oṣu kẹsan an lopopona Umesi, Igirigiri niluu Ado Ekiti.
Alukoro ileeṣẹ ọlọpaa ipinlẹ Ekiti, Sunday Abutu ṣalaye pe wọn ti gbe oku ọkunrin naa sile igboku si nile iwosan ẹkọṣẹ iṣegun fasiti ipinlẹ Ekiti.
Alukoro ileeṣẹ ọlọpaa sọ pe iwadii ṣi n lọ lọwọ lati mọ ohun ti awọn agbebọn naa ni lọkan ti wọn fi ṣekupa Ọgbẹni Jejelowo.
Abutu fidi rẹ mulẹ pe ninu yara Ọgbẹni Jejelowo ni awọn kọlọ nbiti ẹda ọhun ti dabọn bo ọkunrin naa.
O ni iwadii lo maa fihan bo ya adigunjale lawọn agbebọn ọhun tabi agbenipa ni wọn.
Ileeṣẹ ọlọpaa fi da awọn araalu loju pe awọn to wa nidi iṣẹlẹ naa yoo foju wina ofin ti ọwọ ba tẹ wọn tan.
'Aràrá bíi tèmi, kó má rò pé kò sì ǹkan tó lè ṣe láyé ju iṣẹ́ agbe lọ'
Fuel Price Hike: Ìjọba Nàìjíríà rọ aráàlú láti yí ọkọ̀ àti gẹnẹrétọ̀ wọn sí èyí tó ń lo afẹ́fẹ́ gáàsì lọ́fẹ̀ẹ́
Oríṣun àwòrán, Twitter/PPPRA
Minisita fun ọrọ epo rọbi, Timipre Sylva ti kede pe lati oṣu Kẹwaa ọdun 2020 lọ, ijọba apapọ yoo bẹrẹ si yi awọn ọkọ ayọkẹlẹ ati gẹnẹretọ awọn araalu pada si eyi to n lo afẹfẹ gaasi.
Sylva ni wọn yoo ṣe eyi lọfẹẹ fawọn ọmọ Naijiria lọna ati mu adinku ba owo epo petirolu to gbowo lori.
Ori eto kan lori mohunmaworan apapọ ilẹ wa ni Minisita ti kede bẹẹ laarọ ọjọ Aje.
"Sylvia ni awọn ọkọ ayọkẹlẹ ni wọn ṣe lati maa lo gaasi ati epo petirolu papọ, bẹẹ si ni afẹfẹ gaasi dinwo ju epo petirolu lọ."""
"Awọn ọmọ Naijiria yoo lanfaani lati yan eyi to ba wu wọn. Ijọba yoo si bẹrẹ eto naa pẹlu awọn kẹkẹ ẹlẹsẹ mẹta nilu Portharcourt."""
O fikùn pe ilo afẹfẹ gaasi ba oju ọjọ wa mu ni Naijiria, ti eyi ba si dohun tán, Naijiria yoo ri iranwọ gba lati ilẹ okeere.
FRSC: Ajínigbé tó kọlu òṣìṣẹ́ wá, èèyàn méjì kú, mẹ́rin farapa, a kò mọ ibí tàwọn mẹ́wàá wà
Oríṣun àwòrán, AFP
Ìgbà àkọ́kọ́ kọ́ nìyí tí irú ìṣẹ̀lẹ̀ bẹ̀ yòó wáyé
Ọrọ awọn ajinigbe  loju popo Naijiria, kaka ki ewe agbọn wọn dẹ, niṣe lo n le si.
O difa fun bi wọn ṣe ṣe ikọlu sawọn oṣiṣẹ ajọ ẹsọ oju popo Naijiria, FRSC kan ti wọn rin irinajo lati ẹka ajọ naa ni Kebbi ati Sokoto wa si Udi.
A gbọ pe awọn olubi wọn yi ṣina fun awọn ẹsọ alaabo ọhun ni orita Udege loju ọna Mararaban-Udege ni ipinlẹ Nasarawa ti wọn si ji eeyan mẹwaa gbe lọ.
Ìtàn ọ̀rẹ́ tó fi ògùn gba ọkọ ọ̀rẹ́ rẹ̀ ni Akomolede BBC Yorùbá fẹ́ kọ́ wa lònìí
Ọga agba ajọ naa to n risi ọrọ idanilẹkọ ara ilu Bisi Kazeem fidi ọrọ yi mulẹ ninu atẹjade kan to fi sọwọ sawọn oniroyin.
Gẹgẹ bi ohun ti Kazeem sọ, ọkan lara awọn oṣiṣẹ ajọ naa ku ninu ikọlu yi ti omiran si gbẹmi mi ni ile iwosan.
Bẹẹ lo ṣalaye si pe awọn mẹrin mii farapa ti awọn mẹjọ ribi sa asala fun ẹmi wọn ṣugbọn awọn ajinigbepawo naa gbe awọn mẹwa salọ ninu wọn.
Ọga patapata ajọ naa Boboye Oyeyemi sọ pe awọn ti fi ọrọ yi to awọn agbofinro leti ki wọn baa le tete doola ẹmi awọn oṣiṣẹ wọn ti wọn jigbe.
O ni iwadii n tẹsiwaju lati ri pe awọn to wa nidi ọrọ yi foju ba ile ẹjọ. Arakunrin Bisi Kazeem ni ọga ajọ naa ti wa rọ awọn oṣiṣẹ FRSC lati ma ṣe jẹ ki iṣẹlẹ yi mu irẹwẹsi ọkan ba wọn. Ijinigbe lawọn oju popo Naijiria ti wa peleke si lẹnu ọjọ mẹta yi ti ọpọ si ti padanu ẹmi wọn lọwọ awọn alaburu ẹda ajinigbepawo
Akomolede Yoruba: Ìtàn ọ̀rẹ́ tó fi ògùn gba ọkọ ọ̀rẹ́ rẹ̀ nílùú òyìnbó rèé
Arabinrin Olaitan Zainab ni olukọ wa lonii, o ṣalaye iru oju ti ọrẹ meji fi wo ọkunrin kan ti wọn pade ti ọkan fi oju tẹmbẹlu rẹ amọ oun gan lo pada n wa lati fa oju rẹ mọra tori owo
Ṣe ẹ ranti bi inu kilaasi yin ṣe maa n ri lasiko ti ẹ ba fẹ ka awọn iwe ayọka Yoruba nigba ti ẹ ṣi wa nileewe girama?
Bẹẹ gẹlẹ ni Kilaasi Akomolede Yoruba wa yoo ṣe ri lonii ki ẹ lọ wo fidio naa loke fun itan aladun ati akọniloye yii.
"Iwe ti ajọ eleto idanwo aṣekagba WAEC yan fun awọn akẹkọ aṣedanwo ni Akomolede Yoruba gbe yẹwo lonii ti Akọle rẹ jẹ ""Ọ̀rẹ́ mi""."
Ṣe ẹ mọ pe ẹnu awọn olukọ Yoruba maa n dun fun itan sisọ, bẹẹ gẹlẹ ni olukọ wa Zainab Olaitan ko ṣe ja wa kulẹ rara lonii pẹlu awọn ọrọ afiwe, ọrọ apọnle to n jẹyọ.
Koda, ẹkọ ti wọn mu jade nibẹ ko lakawe rara.
Pastor Chris Oyakhilome Rapture Maths: Àlùfáà ìjọ Christ Embassy ṣe ìṣirò ìgbà tí Jesu yóò dé
Oríṣun àwòrán, Screenshot/Loveworld
Oludasilẹ ijọ Loveworld Ministries ti ọpọ mọ si Christ Embassy, Pasitọ Chris Oyakhilome ti ṣalaye bi o ti ṣeeṣe ki ipe dun ti opin aye yoo si de.
Pasitọ Oyakhilome sọ pe gbogbo eeyan ni lati wa ni imura silẹ nitori akoko naa ti sun mọle.
Pasitọ Christ Embassy nigba to waasu ni ṣọọṣi rẹ ṣalaye fawọn ọmọ ijọ rẹ pẹlu ẹkọ iṣiro lorii iye igba to ku ti igbasoke yoo fi de ati idi ti wọn fi gbọdọ mura silẹ.
"Òṣèré méjì yìí ń fi ẹ̀wọ̀n runmú tóríi fíìmù ""Ife"" táwọn obìnrin ń bá ara wọn lòpọ̀"
To ba jẹ pe ẹgbẹrun mẹta ọdun ni Jesu yoo lo ko to pada ni, a jẹ wi pe ẹgbẹrun un kan ọdun lo ku bayii ti yoo fi pada nitori o ti le lẹgbẹrun ọdun meji bayii ti Jesu ti pada lọ si ọrun.
Pasitọ Chris tun ni ''ṣugbọn bawo ni akoko naa ti sun mọ si, ẹ jẹ ki n ṣalaye rẹ fun yin lẹkunrẹrẹ.''
Alufaa Oyakhilome sọ pe igbasoke gan an ko ni apẹẹrẹ kankan ṣugbọn o le ṣẹlẹ nigba kugba.
Pasitọ ijọ Christ Embassy yaworan sori patako lati ṣe iṣiro bi iṣẹlẹ igbasoke naa ti le ṣẹlẹ.
Oríṣun àwòrán, Facebook/Christ Embassy
Ninu aworan naa, o sọ nipa akoko ti Jesu kuro ninu tẹmpili lọdun 30AD ati igba ti wọn bi i laarin ọdun 4BC si ọdun 2BC lati fi mọ igba ti ipe yoo dun.
Oyakhilome ni ''ti a ba wo o lati ọdun 30AD, ki a wo ẹgbẹrun ọdun meji lati igba naa, ọdun 2030 tii ṣe ọdun mẹwaa si asiko yii la n lọ bayẹn.''
O ni ko le ju aarin ọdun mẹwaa yii lọ ti ẹni ti a n reti yoo fi de.
Wo igba mẹta ti Pasitọ Chris ni Jesus le pada de
Alufaa Oyakhilome ṣalaye fawọn ọmọ ijẹ rẹ pe akoko kan ninu mẹta ti oun la kalẹ ni Jesu yoo de.
''Yala ọdun meje siwaju tabi sẹyin tabi laarin, o le wa jẹ ọdun mẹtadinlogun ti Jesu yoo pada de; ọdun meje fun ipọnju ati ọdun mẹwaa ti alatako Kristi yoo fi dide,'' Pasitọ Chris lo ṣalaye bẹẹ.
O ni to ba jẹ pe ọdun meje siwaju ni, o tumọ si pe ọdun mẹta loku ti Jesu yoo fi de, ti o ba jẹ pe laarin in ni, ọdun mẹfa ati aabọ loku ti yoo fi de nitori oṣu mẹfa ti kọja ninu ọdun 2020, Pasitọ Chris ni o tumọ si pe ọdun mẹfa loku niyẹn ti Jesu yoo fi de.
Ni ede kukuru, Alufaa Oyakhilome sọ pe ti Jesu ko ba pada de lọdun mẹta si asiko yii, o le jẹ wi pe ọdun mẹfa ni yoo de, ti dide rẹ ko ba tun ya lọdun mẹfa, ko le ju ọdun mẹwaa lọ si asiko yii.
Ero awọn eeyan ṣọtọọtọ lori alaye ti Pasitọ Chris lori igba ti Jesu yoo pada de.
Alufaa Oyakhilome ṣalaye siwaju sii pe awọn onimọ ijinlẹ naa mọ nipa akoko ti Jesu le de lo jẹ ki wọn maa gbero lati fun gbogbo eeyan to wa laye labẹ ajẹsara lọdun 2030 eyi ti wọn yoo fi ''chip'' si ara gbogbo eeyan.
''Ọdun 2030 lo wa lọkan ajọ GAVI ati MIT to n ri si ọrọ abẹrẹ ajẹsara, koda Eṣu gan an ti n gbiyanju lati mọ bibeli, bakan naa si lo n ti awọn eeyan tiẹ. Wọn ni afojusun wọn,'' Pasitọ Chris lo woye bẹẹ.
Oyo Party Politics: Lanlehin kéde ìparí gbogbo ètò láti darapọ̀ mọ́ ẹgbẹ́ òṣèlú APC
Oríṣun àwòrán, Facebook/Femi Lanlehin
Lẹ́yìn ìpàdé àwọn adari, ololufẹ àti alatilẹyin rẹ̀, Sẹneto Olufemi Lanlehin (SOLAN) ti kéde ìparí gbogbo ètò láti darapọ̀ mọ́ ẹgbẹ́ òṣèlú All Progressives Congress (APC)
O fẹ kuro  láti inú ẹgbẹ́ òṣèlú African Democratic Congress (ADC), ìyẹn ẹgbẹ́ òṣèlú ọlọwọbọwọ, tó wà tẹlẹ.
Lanlehin figba kan jẹ oludije sípò gómìnà nínú ẹgbẹ́ òṣèlú ADC, nínú ìdìbò ọdún 2019.
Bẹ lo tun jẹ  aṣòfin àgbà fún ẹkun Gúúsù Òyó láàrin ọdún 2011 sí 2015.
Nígbà tó n sọrọ nínú ìpàdé tó wáyé nílé rẹ̀ nibadan,Lanlehin sàlàyé gbogbo ìpàdé ipẹtusaawọ tó ti lọ, latari ìgbésẹ rẹ̀ láti darapọ̀ mọ́ ẹgbẹ́ òṣèlú APC.
O fi kun pe oun lọ ṣe ipade  labuja lójóbọ̀, ọjọ Kẹwàá, oṣù Kesan-an, ọdún 2020.
Ladoja: Àwọn èèyàn Oyo fì ìbò sọ̀rọ̀ pé ìjọba Ajimobi kò dára
Nibi ipade yi, o loun sọ  gbogbo ipa tí àwọn aláṣẹ ẹgbẹ́ òṣèlú APC n sa, láti ríi pé gbogbo aawọ dopin nínú ẹgbẹ́ àti láti fa àwọn ọmọ ẹgbẹ́ tó ti lọ, padà wọlé.
Aayan ipẹtusaawọ tí Gómìnà ìpínlẹ̀ Jigawa, Alh. Mohammed Badaru Abubakar n lewaju rẹ̀, pẹlu iranlọwọ lat'ọdọ Gómìnà mẹrin mìíràn, nínú èyí tí Gómìnà Kayode Fayemi tipinlẹ Èkìtì gbé wà, ti n ṣe àṣeyọrí gidi lórí iṣẹ tí ẹgbẹ́ gbé lé wọn lọwọ, Lanlehin ṣàfikún.
Nígbà tó n fi ọkàn àwọn ololufẹ rẹ̀ tó wá láti gbogbo ìjọba ìbílẹ̀ mẹtalelọgbọn ìpínlè Òyó balẹ̀ pé òhun kò níí yẹsẹ kúrò nínú òṣèlú tó nifẹẹ ìlú, Lanlehin sọ fún gbogbo àwọn tó wá sipade náà pé iṣisẹ sinlu ni òpó kan pàtàkì tí òṣèlú ohun dálé lórí, tó sì fi kun-un pé òhun o máa ṣe ohun gbogbo láti ran ọmọnìyàn lọwọ.
Nínú ọrọ tí wọn sọ, Ẹni-ọwọ Ezekiel Adeniran,  Olóyè E. O. Láoyè, Hon. Bili Ajana, Yeye Yetunde Ajibola, Hon. Gaphar Ojetola, Hon. Habib Balogun, Alh. Muraina Kakako, at'awọn mìíràn, kí Sineto Lanlehin ku ọkàn akin àti òṣèlú tó koni móra t'oun ṣe.
Bákannáà, àwọn aṣojú  ìjọba ìbílẹ̀ mẹtalelọgbọn to fèsì  sàlàyé pé pipada sí ẹgbẹ́ òṣèlú APC fun Lanlehin ṣe e fi we ọmọwale, nítorí igun ibè ló ti bẹrẹ òṣèlú.
Nínú ìpàdé ohun, ni àbá ti wá pé kí Lanlehin at'awon alatilẹyin rẹ darapọ̀ mọ́ ẹgbẹ́ òṣèlú APC, ti ẹnikẹni ko sì kọ sí àbá náà.
Lára àwọn tó wà níbi ìpàdé náà ni Olóyè Sunday Ajadi (Abeebo) lati Ogbomoso, Alh. Rafiu Afuku láti Ìséyìn, Alh. Adebayọ Waheed (Adwas) lati Atisbo, Erelu Funkẹ Olayanju láti Ìlà-Oòrùn Ìbàràpá, àti Omowe Akintola láti Àríwá Ìbàràpá.
Àwọn mìíràn ni Hon. Adedokun láti Àríwá Ìbàràpá, Alh. Suara Ogunyemi pelu Hon Adeoye Sobaloju (Lord Moro), àti Otunba Bode Ashiru lati Ìbàdàn, Otunba Kunle Folarin láti Afijio, Alhaja Omotunde Lawal láti Egbeda, Hon. Tiri Olowoake láti Oluyole, Hon. Adekunle Adeolu (Ultimate) láti Ido, pẹlu Hon. Gbenga Aluko àti Hon. Kayode Oladele lati Ìbàdàn.
Hon. Tolani Adigun, Salami Dikko àti Sunday Babatunde náà wà nikale.
Edo Election: Mi ò tíì sọ̀rọ̀ lórí ìdìbò Edo, ẹ di etí yín sí àwọn tó fẹ́ tajà ìròyìn lórí ayélujára - Tinubu
Oríṣun àwòrán, Tinubu Instagram
Aṣiwaju Bola Ahmed Tinubu to jẹ ọkan lara awọn aṣaaju ẹgbẹ oṣelu All Progressives Congress, APC ti fi ọ̀rọ̀ sita pé ki awọn ọmọ Naijiria kọ eti ikun si iroyin to n lọ lori ayelujara.
Iroyin ọhun to sọ pe ẹgbẹ oṣelu APC gba kamu lorii bi PDP ṣe fidi wọn janlẹ ninu idigbo to waye ni ipinlẹ Edo lọjọ kọkandinlogun oṣu kẹsan ọdun 2020.
Tinubu ninu ọrọ ti agbẹnusọ rẹ, Tunde Rahman fọwọ si sọ pe ayederu ni ọrọ naa ti wọn ro pe oun loun n sọ ọ ko si ki n ṣe ọrọ kan to fẹsẹ mulẹ.
Ṣaaju ni atẹjade kan n tan kalẹ lọjọ aje pe Aṣiwaju Tinubu sọ pe:
ẹ jẹ ki inu wa dun ninu gbogbo ijakulẹ wa gẹlẹ bi a ṣe maa n yọ ninu iṣẹgun wa tori pe aduru ohun ti wọn n ṣe lati mu wa balẹ fihan bi a ṣe lagbara to. Ifidirẹmi wa si n fihan pe a o ki n ṣe Ọlọrun bii kii ṣe eniyan....
"Ayederu atẹjade naa tun sọ lorukọ Tinubu pe bi awọn eeyan ẹlẹran ara bii tawọn ba wa ri awọn bii   ti wọn si n ṣajọyọ lori ifidirẹmi awọn bii pe wọn ṣẹgun Ooṣa, ""a jẹ pe a sunmọ jijẹ Ooṣa naa niyẹn""."
Pẹlu bi ọrọ inu atẹjade yii ṣe wuwo to ni awọn eeyan ṣe bẹrẹ si ni gbagbọ pe boya Aṣiwaju lo sọ ọ.
Ṣugbọn ninu ọrọ ti agbẹnusọ Ọgbẹni Tinubu fọwọ si to jade fun awọn oniroyin, Aṣiwaju ni oun o sọ ohun to jọ bẹẹ rara, pe ọgbọn alumọkọrọyi awọn to kan fẹ fi iroyin taja wara wara lori ayelujara ni.
"O ni awọn to mọ Aṣiwaju daadaa mọ pe ko si  ninu  iwa rẹ lati maa ku giri sọrọ sita. ""Tori naa, bi asiko ọrọ ba to, Aṣiwaju yoo fi ọrọ tirẹ sita lori bi eto idibo ipinlẹ Edo ṣe lọ""."
Ẹ má ṣe tẹ́wọ́ gba Godwin Obaseki nínú ìdìbò gómìnà-Tinubu
Àwọn ọmọ Nàìjíríà gbarata lóríi fọ́nrán tí Tinubu fi síta lóríi dídìbò f'ún Obaseki ti Edo
Lẹyin ti gomina ipinlẹ Eko nigbakan ri Oloye Bola Ahmed Tinubu sọrọ ninu fọnran kan to fi sita ni ọjọ Isẹgun lori ẹni ti o fẹ ki awọn eniyan ipinlẹ Edo dibo yan ninu idibo gomina ti yoo waye lọjọ Satide, ọpọ ọmọ Naijiria lo tí ń fi ero wọn han lori ọrọ naa.
Abule Ado explosion: Irọ́ ńlá ní NNPC pa lórí ìbúghbàmù Abule Ado níbí tí ẹ̀mí èèyàn 23
Ni kete ti akọwe fun gomina ipinlẹ Edo Godwin Obaseki fi esi ijọba sita lori ọrọ ti Tinubu sọ ni awọn ọmọ ẹgbẹ ati awọn ọmọ Naijiria ti n sọ ero tiwọn naa, to fi mọ ọkan lara agba ẹgbẹ Peoples Democratic Party (PDP) to tun jẹ igbakeji aarẹ Naijiria Nigba kan ri Atiku Abubakar.
Ninu ọrọ rẹ, Atiku ni ki wọn ma tẹle ọrọ ti Tinubu sọ bikose pe ki wọn tu yaya lọ lati dibo fun ẹgbẹ oselu PDP eyi ti Obaseki n ṣoju fun ni ipinlẹ Edo.
Ọmọ méjì ò sọnù nínú àgbàrá òjò o! Ọ̀tọ̀ lọ̀rọ̀ táa ń pè yín sí - Aráa Ketu
Ni kete ti Tinubu sọrọ naa ni Atiku ti bọ sori atẹjiṣẹ Twitter rẹ nibi to ti salaye pe saa gomina ko tọ si Obaseki nitori naa ki wọn fun ni anfani saa kan si.
Bakan naa ni Atiku rọ àwọn eniyan ipinlẹ Edo lati yago fun iwa jagidijagan lasiko idibo nibẹ.
Ninu ọrọ tirẹ loju opo Twitter bakan naa Femi Fani-Kayode ni awada kẹrikẹri ni gbogbo ọrọ ti Tinubu sọ ninu fọnran naa.
O fi kun-un pe ọrọ Tinubu le ṣe akoba fun Ize Iyamu ninu idibo to n bọ naa.
Ninu awọn miran to tun fi èrò wọn han ni Deji Adeyanju àti awọn ọmọ Naijiria miran.
Lanlehin kéde ìparí gbogbo ètò láti darapọ̀ mọ́ ẹgbẹ́ òṣèlú APC Oyo
Njẹ́ o mọ̀ pé bíi ọdún 700 sẹ́yìn ni wọ́n ti ń bọ Osun-Osogbo? Mọ̀ síi nípa ìtàn ojúbọ̀ nàá
Ǹjẹ́ o mọ̀ pé àwọn tó wá láti ìdílé ẹrú kìí lọ́kọ tàbí aya láyé òde òni ní Nàìjíríà?
Àbájáde ìwádìí ẹlikọ́pítà to já ni Opebi nílùú Eko laipẹ yii ti jáde
Ẹwọ́n ọdún méjìlá ni wọ́n fún àwọn Ṣója mẹ́rin tó pa ìyá àti ọmọ méjì ní Cameroon
Isọrọ ni igbesi, eyi lo mu ki ẹgbẹ oṣelu Peoples Democratic Party, PDP, fesi pada fun Asiwaju Bola Ahmed Tinubu lori fidio to ti ni ki awọn eeyan Edo ma ṣe dibo fun Godwin Obaseki.
Gomina Godwin Obaseki ni oludije ẹgbẹ naa ninu idibo Gomina to n bọ lọna.
Ninu atẹjade ti ẹgbẹ naa fi sita lojuopo Twitter, wọn ni ẹyinkule baba Tinubu ko de Edo, nitorinaa gale gale rẹ to n ṣe ninu fidio ọhun ko le yi ipinu awọn ara ilu Edo pada.
Ẹgbẹ naa sọ pe awọn eeyan Edo ti pinu lọkan wọn ti pẹ lati yan Obaseki si ipo pada nitorinaa ki Tinubu lọ ṣagbejẹ mọwọ.
Yatọ si ọrọ ẹgbẹ yi, Oludamọran  Gomina Obaseki  lori ọrọ iroyin,  Crusoe Osagie sọ pe ki Tinubu da ọrọ rẹ pada.
O ṣalaye pe awọn eeyan Edo ko faye gba baba isalẹ ninu oṣelu ipinlẹ wọn nitori naa ki Tinubu fawọn lọrun silẹ
Godwin Obaseki ko ba wa kopa ninu igbiyanju lati fi oṣelu awarawa rinlẹ, nitori naa ko yẹ lẹni taa dibo fun.
Asiwaju ẹgbẹ oṣelu All Progressives Congress,APC, Bola Ahmed Tinubu lo sọ ọrọ yi ṣaaju idibo Gomina ipinlẹ Edo.
Ninu fọnran fidio  nkan bi iṣẹju mẹrin naa, Tinubu ṣalaye idi ti oun ṣe fẹ ki awọn ara ipinlẹ Edo ma ṣe dibo fun un.
Tinubu mu orisirisi akawe ọna ti Obaseki ko fi ṣe iṣe ẹni to nifẹ oṣelu awarawa to si ni eyi to lati ma ṣe dibo fun Obaseki.
''Gbogbo awọn agbaagba ilẹ yi parọwa si lati bọwọ fun ofin ilẹ wa ṣugbọn o keti ikun si wọn''
O tẹsiwaju pe bẹẹ lo bẹgi dina awọn aṣofin ilẹ Edo lati joko ijiroro ni ile aṣofin.
''Ẹ ma ṣe dibo fun Obaseki, mo parọwa si yin''
Ẹgbẹ oṣelu APC ni Godwin Obaseki ti dije dupo wọle gẹgẹ bi Gomina ipinlẹ Edo.
Oríṣun àwòrán, others
Ija lo de, orin dowe to waye laarin oun ati alaga ẹgbẹ, Adams Oshiomole lo ṣokunfa bi Obaseki ti ṣe kuro ni ẹgbẹ APC lọ si PDP.
Ninu idibo Gomina ipinlẹ Edo to n bọ lọna, Obaseki ati Pasitọ Ize Iyamu ni wọn yoo jijọ du ipo.
Fọnran fidio Tinubu yi jẹ akọkọ iru rẹ nibi ti Tinubu yoo ti jader sita lati parọwa si ara ilu lati ma ṣe dibo fun ẹni to kuro ninu ẹgbẹ APC.
Saaju gbogbo ọrọ ti Tinubu n sọ nipa Obaseki ko ju pe ko sọ loju opo Twitter tabi ninu atẹjade.
Ẹ má ṣe tẹ́wọ́ gba Godwin Obaseki nínú ìdìbò gómìnà-Tinubu
Osogbo JTF vs Youth Protest: Àwọn ẹbí Idris Ajibola bèrè fún ìwádìí tòótó lórí ikú ọmọ wọn
'Búrẹ́dì tí wọn ó fi jẹ ẹ̀wà ni wọ́n lọ rà ni wọ́n pàdé ikú gbígbóná'
Mọlẹbi ọmọkunrin ti o padanu ẹmi rẹ ninu iṣẹlẹ tawọn agbofinro ti le awọn ọdọ kan sẹnu iku ti ba BBC Yoruba sọrọ.
Baba ọmọdekunrin naa arakunrin Kehinde Ajibola sọ pe ọmọ oun kii ṣe oni yahoo yahoo ati pe iwa aibọwọ fofin lawọn agbofinro to ṣeku pa ọmọ naa hu.
Idris Ajibola lorukọ ọmọdekunrin naa gẹgẹ bi baba rẹ ti ṣe sọ ti o si jẹ ọmọ ọdun mọkandinlogun.
Ọgbẹni Kehinde ṣapejuwe Idris gẹgẹ bi ọmọ ti ko laapọn.
''Emi o si nile mo jade mo lọ ra nkan ni. Saadede ni ipe wọle pe ọmọ mi ti ku''
Ọgbẹni Kehinde sọ pe Idris ati ọrẹ rẹ gbe ọkọ jade lati lọ ra nkan ti wọn yoo jẹ ni ''bawọn ọlọpaa ṣe le wọn titi de oju iku niyẹn''
Àwọn ẹbí Idris Ajibola bèrè fún ìwádìí tòótó lórí ikú ọmọ wọn
Oríṣun àwòrán, SCREENSHOT/TWITTER/ NIYI DARAM/OTHERS
Nigba ti BBC beere nipa ọrọ tawọn eeyan n gbe kaakiri pe awọn ọmọ oni yahoo yahoo ni awọn agbofinro lawọn n le ọgbẹni Kehinde ni ọmọ oun kii ṣe oni yahoo yahoo.
''Rara o. Ko si ẹni tẹ le bi leere. Ko si ẹni tii ṣe yahoo ninu wọn.Awọn ọlọpaa kan fẹ fi iyẹn ṣe kini fun wọn ni''
''Iwa ti wọn n hu, iwa pe a ko ni ijọba nilu ni wọn hu. Mo fẹ  ki ọmọ Naijiria gbe mi nija mo si fẹ ki ijọba fi ijiya to tọ jẹ wọn''
Ijọba ipinlẹ Osun ti ṣapejuwe iku ọmọkunrin gẹgẹ bi eleyi to bani ninu jẹ.
Gomina Adegboyega Oyetola si sọ pe awọn yoo ṣe ẹkunrẹrẹ iwadii lati tu aṣiri ohun to ṣẹlẹ si ọmọdekunrin naa.
Awọn mọlẹbi Idris sọ fun BBC pe awọn aṣoju lati ọdọ ijọba ti kan si awọn ṣugbọn awọn ko tii ri ẹnikankan lati ọdọ awọn ọlọpaa.
Isẹlẹ iku awọn ọdọ lati ọwọ awọn agbofinro paapa awọn SARS jẹ nkan ti awọn eeyan Naijiria n bẹnu atẹ lu ijọba si.
Lọpọ igba awọn agbofinro wọnyi a maa fi tipa mu awọn ti wọn ba fura si ti awọn mii a si ma padanu ẹmi wọn lọwọ awọn agbofinro yi.
Alukoro fun ileeṣẹ ọlọpaa nipinlẹ Ọsun, Yemisi Opalola sọ fun BBC pe iwadii ṣi n lọ lati mọ ẹka ileeṣẹ alaabo to wa nidii iṣẹlẹ to mu ẹmi ẹnikan lọ nilu Osogbo.
Ọjọ Iṣẹgun ni iṣẹlẹ naa waye lasiko ti awọn oṣiṣẹ alaabo le awọn ọdọmọkunrin kan ti wọn pe ni afurasi ọmọ 'yahoo-yahoo', titi de oju iku.
Iroyin to n lọ ni pe awọn ọlọpaa lo fa sababi iṣẹlẹ.
Oríṣun àwòrán, NIGERIA POLICE
Ṣugbọn Opalola sọ pe awọn ọmọ ikọ alaabo to jẹ akojọpọ awọn ọmọ ileeṣẹ ologun, ọlọpaa, oṣiṣẹ ajọ civil defence, ati awọn to n risi iwọle-wọde, ti ijọba Ọṣun kojọ fun aabo, lo fa sababi ọrọ.
O ṣalaye pe gbogbo igbiyanju ọlọpaa lati ran pese iranwọ lori iṣẹlẹ naa lo foriṣanpọn, nitori pe okuta ni awọn araalu n sọ lu awọn ọlọpaa.
Ijamba naa mu ki awọn ọdọ kan ṣe iwọde lẹyin iṣẹlẹ naa, ti wọn si ba awọn nkan jẹ laarin ilu.
Olugbe ilu Osogbo kan to ba BBC sọrọ lori iṣẹlẹ naa sọ pe, ile itaja nla kan to wa ni aarin igboro ilu Osogbo ni awọn ọmọkunrin naa ti lọ ra nkan, lati ibẹ si ni awọn ọlọpaa naa ti n fi ọkọ le ọkọ wọn.
Wọn le wọn titi kuro laarin igboro, titi wọn fi de ọna kan ti eeero ko fi bẹ ẹ pọ si lọna ẹyin odi ilu.
"Awọn iroyin kan tilẹ n sọ lori ayelujara pe ọkọ baba ikan lara awsn ọdọmọkunrin naa ni wọn wa ninu rẹ, tako ""ẹsun ti wọn fi kan wọn pe ọmọ yahoo-yahoo ni wọn."
"Òṣèré méjì yìí ń fi ẹ̀wọ̀n runmú tóríi fíìmù ""Ife"" táwọn obìnrin ń bá ara wọn lòpọ̀"
Lanlehin kéde ìparí gbogbo ètò láti darapọ̀ mọ́ ẹgbẹ́ òṣèlú APC Oyo
Àwọn ọmọ Nàìíjíà gbarata lóríi fọ́nrán tí Tinubu fi síta lóríi dídìbò f'ún Obaseki ti Edo
Ọmọ méjì ò sọnù nínú àgbàrá òjò o! Ọ̀tọ̀ lọ̀rọ̀ táa ń pè yín sí - Aráa Ketu
Awọn ti ọrọ naa ṣoju wọn ni awọn ọdọ naa ba ọkọ awọn ẹṣọ alaabo JTF jẹ patapata ni agbegbe Alekuwodo, ni ilu Osogbo.
Iroyin sọ pe ẹnikan lara awọn ọmọkunrin naa ku, ti awọn yooku si farapa, lasiko ti ọkọ wọn kọlu opo ina kan, to si takiti.
Oríṣun àwòrán, TWITTER
Alukoro ọlọpaa ṣalaye pe awọn to ṣe iwọde ko jẹ ki awọn ọlọpaa de ayika ibi ti iṣẹlẹ naa ti waye rara, lati doola ẹmi awọn ọmọkunrin naa.
"Iwadii ṣi n lọ lori iṣẹlẹ naa, a si ti da ọlọpaa si igboro lati le dkun wahala to ba fẹ ẹ waye.
A si ti ko ọlọ́pàá ranṣẹ síbi tí iṣẹlẹ naa ti ń waye lati jẹ ki alaafia jọba padà sibẹ."
Lori ibeere pe nibo ni oku ọmọkunrin naa wa ati awọn to farapa, Opalola sọ pe fun'ra awọn eeyan naa lo gbe wọn, nitori pe wọn o jẹ ki ọlọpaa ran wọn lọwọ.
Ketu Flood: Ọ̀tọ̀ lọ̀rọ̀ táa ń pè ìjọba sí o, ẹ wá wò ó
Ko pẹ ti iroyin tan ka pe agara ojo gbe awọn ọmọde meji kan lọ ni agbegbe Ketu ni ipinlẹ Eko, BBC Yoruba gbiyanju lati lọ ba awọn obi awọn ọmọ naa sọrọ.
Ṣugbọn ọ̀tọ̀ lohun a ba lọ, ọtọ lohun taa ba bọ lati adugbo naa.
Niṣe lariwo n sọ heee pẹlu bi alagbalugbu omi ṣe wọ ni gbogbo adugbo naa.
"Olugbe kan ti BBC Yoruba ba sọrọ, John Okegbola sọ pe ""omi ko gbe ọmọ kankan lọ, ti omi ba gbe ọmọ lọ lati ijẹta, ko si bi ko ṣe ni maa wa ọmọ. Ko si si ohun kankan to n lọ ladugbo yii ti mi o ki n mọ, ko si ẹni kankan to n wa ọmọ""."
John ni. Asọdun awọn eeyan pọ ni pẹlu iroyin ti wn n pe kiri. O ni aduru dukia to n sọnu ni gbogbo igba ti ẹkun omi yii ba bẹrẹ ti ko si si ohun ti ijọba ṣe.
Ariwo pe ijọba fi ẹtẹ silẹ, wọn n pa lapalapa ni awọn ara adugbo n kigbe pẹlu bi wọn ṣe n banujẹ lọwọlọwọ.
Ìtàn ọ̀rẹ́ tó fi òògùn gba ọkọ ọ̀rẹ́ rẹ̀ ni Akomolede BBC Yorùbá fẹ́ kọ́ wa lònìí
Àwọn ẹbí Idris Ajibola bèrè fún ìwádìí tòótó lórí ikú ọmọ wọn
Adunni Oluwole: Akíkanjú obìnrin àkọ́kọ́ to dá ẹgbẹ́ òṣèlú àti tíátà silẹ ṣáájú Ogunde
Oríṣun àwòrán, wikipedia
Yoruba ni ẹni to ba mọ ibi ti ọrọ yoo wo si, ọta ọlọrọ ni.
Bẹẹ lo ri pẹlu akikanju obinrin kan, to rinu rode bii Olodumare, to si mọ bi ọjọ ọla yoo ṣe ri fun orilẹ-ede Naijiria, ka to gba ominira.
Adunni Oluwole, ni akọni obìnrin ọmọ Yoruba to tako ominira fun orile-ede Naijiria nitori igbagbọ rẹ pe awọn ọlaju yoo fi iya nla jẹ awọn mẹkuunu, ti oyinbo ba gbe akoso le wọn lọwọ.
Gẹgẹ ba ṣe ka a loju opo wikipedia atawọn itakun agbaye yoku, obìnrin bii ọkùnrin ni Adunni Oluwole, ajàfẹ́tọ̀ọ́ ẹni ati ajijagbara nla si ni nigba aye rẹ.
Bi itan igbe aye rẹ si ṣe lọ ree pẹlu awọn isẹ akikanju to ṣe lati ja fun mẹkuunu.
Ọdun 1905 ni wọn bi Adunni sile aye, idile awọn jagunjagun nilu Ibadan si ni baba rẹ ti wa.
A si le ni Adunni jogun ba awọn iwa akikanju to ni yii ni, nitori inu ẹjẹ rẹ lo wa, o si laya bii kiniun.
Lasiko ti Adunni wa ni ewe, wahala kan ṣẹlẹ ninu ẹbi rẹ, eyi to mu ki iya rẹ ko ẹru kuro nile, gba ilu Eko lọ.
Agboole Aroloyo nilu Eko, ni iya Adunni n gbe, eyi to mule ti sọọsi Johannu mimọ, St John, ti alufa oyinbo, Adolphus Howells n dari.
Adugbo yii ni wọn ti tọ Adunni dagba, ti alufa Howells si maa n ran ẹbi rẹ lọwọ nípa jijẹ ati mimu.
Nigba to ya, Alufa Howells mu Adunni si ọdọ rẹ lati maa gbe, to si fi sile ẹkọ alakọbẹrẹ St John, Aroloya, amọ Adunni pada sọdọ iya rẹ lẹyin to pari eto ẹkọ alakọbẹrẹ rẹ.
Adugbo Mushin ni Adunni ti lo igba ọdọ rẹ, to si jẹ ọmọ ti ẹnu rẹ mu, ṣe ọmọ ti yoo jẹ asamu, kekere ni yoo ti maa jẹ ẹnu samu samu.
Fun apẹẹrẹ, laarin ọdun 1925 si 1932, nigba ti Adunni wa ni ọdọ, ó kọ ere onise kan fun ẹgbẹ ọdọbinrin Girl's Guild ti ìjọ St John nilu Eko, Ọlọla Herbert Macaulay si lo dari ere naa.
Ere onise yii dun, o larinrin, to si jẹ itẹwọgba ọpọ eeyan, a si le ni Adunni ni obìnrin akọkọ ti yoo da ẹgbẹ akọṣẹmọṣẹ oṣere tiata silẹ ni Naijiria.
Koda, a gbọ pe Adunni da ẹgbẹ oṣere tiata rẹ silẹ siwaju Herbert Ogunde, ti ọpọ mọ bii ọkùnrin akọkọ to da ẹgbẹ oṣere tiata silẹ ni ẹkún ìwọ oorun Afíríkà.
Lati inu ìjọ Ọlọrun ni Adunni ti bẹrẹ iwa ijijagbara rẹ, eyi to papa sọ di ilumọọka ko to jade laye.
Akinkanju obìnrin yii di oniwaasu akin, koda, o tako iwa gbigbe oku wọ inu ìjọ fun isin ikẹyin, o ni oun ri iran lati ọdọ Ọlọrun, to ni Ọlọrun alaaye ni oun, oun kii ṣe Ọlọrun oku.
Ọrọ oye, imọ ati ọlọgbọn to maa n ti ẹnu Adunni jade jẹ ki ọpọ eeyan fẹran rẹ pupọ, ti wọn si maa n tẹle lẹyin bii asaaju wọn.
Iwa ijijagbara akọni obinrin yii si lo mu ko ko awọn obinrin jọ lati ṣe atilẹyin fáwọn oṣiṣẹ reluwe to da isẹ silẹ lọdun 1945.
Koda, Adunni tun gbe owo nla silẹ fun ẹgbẹ awọn oṣiṣẹ naa lati fi tọju ara wọn nigba táwọn ijọba amunisin ko sanwo osu fun wọn tori iyanselodi yii.
Nigba to di ọdun 1954, Adunni da ẹgbẹ oselu silẹ fawọn mẹkuunu, to pe ni Nigerian Commoners Liberal Party (NCLP), ọpọ awọn ọmọ ẹgbẹ oselu naa si lo jẹ ọkùnrin.
Lati jẹ ka mọ bi ẹgbẹ oselu rẹ ṣe gbajumọ laarin ilu si, ko pe osu marun ti wọn da ẹgbẹ NCLP silẹ, lo gba ijoko kan ni ẹkún idibo ariwa Osun, to si fi ẹyin ẹgbẹ alakukọ NCNC ati ọlọpẹ AG janlẹ ninu idibo sile asofin naa.
Lara awọn ọna ti Adunni gba seto ipolongo ibo rẹ, ti araye fi gba ti ẹgbẹ oselu rẹ ni pe, o n mura bii ẹlẹ́wọ̀n lati polongo ibo, ti okiki rẹ ati ti ẹgbẹ oselu rẹ si gbale ẹ kan.
Oludije latinu ẹgbẹ NCLP to moke ni D. L Olateju, to si fi awọn Oludije latinu ẹgbẹ oselu Obafemi Awolowo ati Nnamdi Azikiwe, to lagbara nigba naa gbolẹ.
Amọ nigba to di ọdun 1956, ti wọn kede pe Naijiria yoo gba ominira lọwọ oyinbo amunisin, Adunni yari patapata pe ko ṣeeṣe.
Alaye rẹ ni pe awọn oloselu alawọ dudu yoo fiya jẹ awọn mẹkuunu ni, ti agbara ba bọ sọwọ wọn tan.
Wo ìdílé tí ìyá àti gbogbo ọmọ kara bọ iṣẹ́ ṣíṣe epo tà
Iṣẹ kekere kọ ni Adunni ṣe lati ri daju pe awọn oyinbo amunisin ko fun Naijiria ni ominira lọdun 1960, gẹgẹ bi wọn ti kede rẹ.
Bi awọn eeyan kan si ṣe n fi oju were wo igbesẹ Adunni naa, ni awọn eeyan miran tẹwọ gba a, paapaa awọn mẹkuunu.
Awọn mẹkuunu yii si lo ko ara wọn jọ si abẹ akíkanjú obìnrin naa gẹgẹ bii ẹgbẹ, ti wọn pe orúkọ rẹ ni 'Ẹgbẹ́ Kí Òyìnbó Máì Lọ'.
Amọ ọda owo, awo olokun to n ba ẹgbẹ naa finra ko jẹ ko fi bẹẹ ri ẹsẹ walẹ, to si ku lairotẹlẹ nigba ti owona n da wọn laamu.
Ṣugbọn Yoruba ohun to ba n dun ni, nii pọ lọrọ ẹni, Adunni ko sinmi iwa ijijagbara rẹ, to si lọ saafin Olubadan ni ọjọ kẹẹdọgbọn osu kẹjọ ọdun 1955, lati salaye idi to fi tako ki Naijiria gba ominira, eyi to n atilẹyin Olubadan lori rẹ.
Olubadan ransẹ pe awọn oloye ati eekan ilu wa si aafin rẹ lati wa gbọ ti ẹnu akikanju obinrin, to ni Naijiria ko tii setan lati gba ominira.
Lara awọn to wa ni aafin Olubadan lọjọ ti Adunni wa ni gbajumọ oloselu kan nilu Ibadan, Adegoke Adelabu.
Adelabu pa akọni obinrin yii lẹ́nu mọ, to si pe e ni awọn orukọ abuku bii 'Aṣẹ́wó', koda o tun dunkoko pe oun yoo fi igbalẹ na a jade ni aafin Olubadan.
Ṣugbọn bi wọn ṣe n ge Adunni lọwọ, bẹẹ lo n bọ oruka, kaka ki ewe agbọn Adunni dẹ nidi atako to n ṣe fun gbigba ominira Naijiria, ko ko ko lo n le si.
Adunni ko sun, bẹẹ ni ko wo, koda, o tun morile ilu Akure lati tẹsiwaju nidi ipolongo atako fun ominira Naijiria to n ṣe.
Nilu Akure, Adunni ni ki wọn so okun mọ oun nidii, to si ni ki akọni ọkùnrin meji maa fa okun naa, eyi ti wọn fi n wọ ọ kiri oju popo.
Bi wọn ṣe n wọ kiri, bẹẹ lo n kigbe tako awọn oloselu Naijiria, to ni wọn yoo maa rẹ mẹkuunu, ti oun jẹ ọkan lara wọn jẹ.
Lasiko naa, ọpọ eeyan ni oye ohun ti Adunni n ṣe yii ko ye amọ to bẹrẹ si ye wa lẹyin ta gba ominira ọhun tan, ti oju wa si n ri mabo lọwọ awọn oloselu.
A si le pe Adunni Oluwole ni wolii ti ko niyi nile rẹ laye igba naa, tori ọpọ iwa ijẹgaba, aye familete ki n tutọ, ajẹbanu ati ifiyajẹni táwọn oloselu n hu bayii lo ti sọ asọtẹlẹ rẹ saaju, to si kilọ fun wa.
Ìtàn ọ̀rẹ́ tó fi ògùn gba ọkọ ọ̀rẹ́ rẹ̀ ni Akomolede BBC Yorùbá fẹ́ kọ́ wa lònìí
Ọrọ buruku, kii ba ikun nile ni iku Adunni Oluwole jẹ saaju ki ominira Naijiria lọwọ oyinbo amunisin to waye.
Adunni maa n gbadura pe oun ko fẹ ki oju oun ri rẹdẹ-rẹdẹ lẹyin ti Naijiria ba gba ominira tan, ki awọn oun to ti sọ asọtẹlẹ nipa rẹ, wa maa sẹlẹ loju aye rẹ.
Koda, akọsilẹ ni o sọ nita gbangba pe oun ko fẹ wa laye nigba ti Naijiria ba n gba ominira.
Boya idi ree ti Adunni Oluwole fi jẹ Ọlọrun nipe lọdun 1957, nigba to ku ọdun mẹta ti Naijiria yoo gba ominira.
Gẹgẹ bi akọsilẹ iku rẹ ti wi, akandun lásán-làsàn lo mu Adunni Oluwole ni ika, eyi to ja okun ẹmi rẹ lẹni ọdun mejilelaadọta pere.
Ohun to wa ṣe ni laanu ninu itan aye akọni obìnrin naa ni pe ọjọ ti ọmọ rẹ n ṣe ayẹyẹ igbeyawo, ni oun gan jade laye.
Itan aye Adunni Oluwole kọ wa lati ni ẹmi akin ati igboya, boya a jẹ ọkùnrin ni abi obìnrin.
Itan akọni obinrin naa tun kọ wa lati dide tako iwa ifiyajẹni, ìjẹgaba ati imunilẹru ni gbogbo ọna.
Itan aye Adunni Oluwole tun kọ wa lati jẹ akinkanju ni ipokipo ta ba wa.
Bakan naa la tun kọ ẹkọ pe ka ma fi ẹnu wa sọ ọrọ odi tabi ṣẹ epe nitori o le wa si ìmúṣẹ.
Osogbo JTF vs Youth Protest: Àwọn ẹbí Idris Ajibola ń fẹ́ ìdájọ́ lórí ikú ọmọ wọn
Iku ẹ ko gbọdọ lọ lasan o, gbogbo awọn to wa nidi ẹ, mo fi wọn si ọwọ Ọlọrun.
Temitope, ẹgbọn Idris Ajibola ti ikọ amuṣẹya alaabo niluu Osogbo le oun atawọn ọrẹ rẹ de oju iku faraya.
Ọjọ kẹẹdogun oṣu kẹsan ọdun 2020 ni Idris salabapade iku.
BBC Yoruba ṣe ibẹwo si idile ti ọfọ ṣẹ yii niluu Osogbo nibi ti ẹsẹ ko ti gbero gẹgẹ bi awọn eeyan ṣe n wọ lati lọ bawọn kẹdun iku ọmọ wọn.
Ọ̀rọ̀ gbogbo ṣe wọn maa n ni Ọlọrun lo ye - Ọtọ lọrọ tawọn ọlọpaa sọ ọtọ la ba lẹnu awọn mọlẹbi Idris.
Ṣaaju ni baba ọmọdekunrin naa arakunrin Kehinde Ajibola sọ pe ọmọ oun kii ṣe oni yahoo yahoo ati pe iwa aibọwọ fofin lawọn agbofinro to ṣeku pa ọmọ naa hu.
"Ẹgbọn rẹ ọkunrin to ba BBC Yoruba sọrọ sọ pe ""ọmọ tiwa ko ki n ṣe yahoo boy o, amojuẹrọ ni ọmọ wa to si ti n ṣiṣẹ titun foonu ṣe latigba to ti pari ileewe""."
O ṣalaye pe ṣaadede loun gba ipe lọjọ naa pe wọn ti pa aburo oun ti wọn si ti lọ t oku rẹ siwaju ọfiisi gomina ipinlẹ Osun, Gboyega Oyetola.
Oba Abd-Ganiyu Adekunle Salaueen Oloogunebi Ajinese 1 ti kéde pẹ orò ló kù láti lé àwọn ajínigbé
Oríṣun àwòrán, Oro Festival
A fẹ́ gbé orò láti lé àwọn ajínigbé kùrò ní ìpínlẹ̀ Oyo- Asẹyin
Aseyin ti ilu Iseyin, Oba Abd-Ganiy Adekunle Salaueen Oloogunebi Ajinese 1 ti sọ idi pataki ti ọdun oro yoo fi waye ni ilu Isẹyin ni asiko yii.
Oba  Abd-Ganiy sọ eyi lasiko to n ke gbajare wi pe awọn ajinigbe ti poju lagbegbe naa, lẹyin ti wọn kede orisirisi iṣẹ ijinigbe to ti waye lagbegbe Ibarapa ati Oke-Ogun ni ipinlẹ Oyo.
O rọ ijọba apapọ lati gbiyanju lati ba wọn da si ọrọ naa ni kiakia nitori o ti n da ọrọ ojoojumọ.
Oríṣun àwòrán, Google
Oba  Abd-Ganiy sọ eyi lasiko ti ọdun ọrọ bẹrẹ ni aafin Iṣẹyin ni opin ọsẹ.
Aṣẹyin ni ọdun oro ni ọdun 2020 yii yoo wa fun adura lati le awọn ajinigbe kuro ni ayika wọn, ki ijọba Makinde le ni alaafia.
Bakan naa lo ni wi pe ọjọ keje ati ikarundinlogun ọdun oro naa ni awọn yoo gbe oro naa.
Ni ọjọ ti wọn ba gbe oro naa, awọn obinrin kii jade titi oorun yoo fi wọ ni awọn ọjọ wọnyii.
Asẹyin ni: ''A ti fun awọn ajinigbe ni epe lati ma ṣe rojuraye ni agbegbe wa mọ, nitori o ti pọju ni agbegbe Ibarapa ati Oke-Ogun.''
''Bakan naa ni a kesi ijọba apapọ lati jọwọ ran wa lọwọ lati wa ọna abayọ si ijinigbe yii.''
Ninu atẹjade naa ni wọn ti fikun un wi pe awọn ẹsọ alaabo ti wa ni pesẹ lati ri i wi pe ayẹyẹ naa lọ ni irọwọ-rọsẹ.
Aseyin ti ilu Iseyin, Oba Dr. Abd-Ganiy Adekunle Salaueen Oloogunebi Ajinese 1 fikun un pe igba ati akoko gomina Seyi Makinde yoo rọ wọn lọrun.
O gba awọn adari nimọran lati ṣe ohun to yẹ fun igbadun ati alaafia ara ilu nitori awọn alalẹ ati ara ọrun n wo wọn.
Ṣaaju ni Ifayemi Elebuibọn ti sin awọn Ọba alade ni gbẹrẹ ipakọ lori oro gbigbe gẹgẹ bii aṣa ti ko yẹ ko parun
Ọpọlọpọ awọn ọbalaye ni ilẹ Yoruba ni ko yatọ si eeyan lasan nitori wọn n tapa si iṣẹṣe ati iṣẹmbaye.
Araba ilu Oṣogbo, Oloye Ifayẹmi Ẹlẹbuibọn lo ṣọ ọrọ yii lasiko ajọdun ọdun kẹwaa rẹ lori oye gẹgẹ bi araba awo ilu Oṣogbo.
Oríṣun àwòrán, Crown-art
Oloye Ifayẹmi ni ọpọlọpọ awọn Ọba ni ko karamasiki orò ilu tabi aṣa ati iṣẹṣe mọ.
Ọba ti wọn ko ba ṣoro fun, ti ko tẹfa ti ko ṣe gbogbo nnkan ibilẹ to jẹ ọba le lori, ko yatọ si eeyan lasan.
Baba Araba ni ohun to n da awọn ọba ya sọtọ naa ni awọn oro, ati nnkan ibilẹ ati iṣẹdalẹ ilu rẹ to jẹ ọba le lori.
Ọba ti ko ba ti wa ṣe e, baba Araba ni kii ṣe Ọba, eeyan lasan ni.
'Búrẹ́dì tí wọn ó fi jẹ ẹ̀wà ni wọ́n lọ rà ni wọ́n pàdé ikú gbígbóná'
O ni bi awọn Ọbalaye ba n tẹriba fun iṣẹṣe ati iṣẹdalẹ ilu wọn ni yoo mu ki ilu o toro ki o si tuṣẹ.
O rọ awọn aṣiwaju ni ilẹ Yoruba lati gbe aṣa ati iṣe Yoruba nitori ibi a gbe laa ṣe.
Oríṣun àwòrán, Getty Images / flev
O wa rọ awọn adari lorilẹede Naijiria pe ki wọn ṣee re nitori ohun wọn ba ṣe silẹ n labọwaba.
Ni ọdun 2010 ni wọn fi oloye Ifayẹmi jẹ oye Araba awo ti ilu Osogbo eyi to fihan pe oun ni olori gbogbo onifa ati alawo ni ilu Oṣogbo.
Foluke Daramola: Òfin El-Rufai láti tẹ àfipábánilòpọ̀ ní ọ̀dá gbọ́dọ̀ di mímúṣẹ
Oríṣun àwòrán, Instagram/folukedaramolasalako
Gbajumọ oṣere tiata lobinrin, Foluke Daramola ti kede pe oun fara mọ titẹ awọn afipabanilopọ ni ọda.
Daramola ni  iroyin to tii dun mọ oun ninu julọ ni ikede ofin ti ijọba ipinlẹ Kaduna ṣe, eyi to ni ki wọn maa tẹ awọn afipabanilopọ ni ọda.Lasiko to n ba akọroyin Punch sọrọ ni Foluke Daramola fi ero rẹ yii han sita.
Bakan naa ni oṣere tiata naa ni, oun tun dunnu si abala ofin naa to salaye pe, ki wọn yọ ẹyin ile ọmọ obinrin to ba fipa ba ọkùnrin lopọ.
"Daramola wa n tẹnumọ pe, yoo dara ki ijọba ri daju pe ofin naa di mimuṣẹ, nitori ọtọ ni ki ijọba ṣe ofin, ọtọ ni ki wọn mu ṣẹ."""
Aimọye ofin la ti ṣe ni Naijiria, ti a ko ṣe amusẹ rẹ. Boya wọn kan n ṣe ofin yii fáwọn mẹkuunu ni, ko si fáwọn alagbara.
Amọ tijọba ba ṣe amusẹ ofin titẹ awọn afipabanilopọ ni ọda bo ṣe yẹ, eyi yoo nipa lori ironu awọn eeyan to ba fẹ huwa buruku yii.
"Bẹẹ ba gbagbe, Foluke Daramola ti sọ saaju ninu ifọrọwerọ rẹ pẹlu BBC Yoruba pe, ọdọ ni oun wa nigba ti ayalegbe awọn kan fi tipa ba oun lopọ.
O ni ọpẹlọpẹ awọn ọrẹ oun to gba oun nimọran lati ke gbajare ọrọ naa sita, eyi to mu ki ẹru wiwo aya oun di fifuyẹ.
Oriire Oyo Farmers: Bí àwọn Darandaran ṣe ba okò opó kan jẹ́
Awọn agbẹ ijọba ibilẹ Oriire nipinlẹ Oyo n kigbe sita lorii ikọlu lemọlemọ ti awọn darandaran n ṣe lori awọn oko wọn bẹẹ iṣẹ oko yii nikan ni owo ti wọn n ṣe to wọpọ nibẹ.
Tẹkun tẹkun ni awọn agbẹ naa to fi mọ obinrin, ọkunrin atawọn ọdọ wọn fi ba BBC Yoruba sọrọ ti wọn si n fi awọn ere oko tawọn akọluni darandaran da ẹmi wọn legbodo han.
Koda wọn ni o la iku lọ fun awọn kan lara awọn lasiko ti ọrọ di ogun laarin wọn ti awọn to farapa naa si wa nibẹ.
Gbogbo nkan mi ni wọn ti bajẹ patapata, awọn ọmọ wa si wa nile ẹkọ ti a o ri nkankan fi tọ wọn""."
Ọkan lara wọn ni oun n sọ fun wọn pe oun o pa ara oun ni ti wọn si n bẹ ẹ.
Awọn araalu ni o ti su awọn pẹlu iṣoro awọn Bororo darandaran ti awọn si ti lọ fi ẹjọ sun ọlọpaa lọpọlọpọ igba.
"Baba ka ni ilẹ oko bii aadọta eeka ni oun gbin ẹgẹ nlannla si toun si ro gbogbo aarin poro to mọ tonitoni amọ nigba ti oun fi pada lọ bẹẹ wo gbogbo wew ti mọ feee, ""ẹkun ni mo ba wale."
Ẹwẹ Umar Babuga Yayi Guruma to jẹ Seriki awọn Fulani ni ilu Ogbomoso naa fesi fun BBC Yoruba ni iha titi rẹ toun naa.
Joe Biden: Ṣé ó lè fẹ̀yìn Trump kó di ààrẹ America tó kàn?
Oríṣun àwòrán, Reuters
Joe biden ni ọkunrin naa to ta a tan siwaju aarẹ Donald Trump ati saa ọdun mẹrin kan sii to fẹ lo ni Ile nla funfun White House gẹgẹ bi wọn ṣe n pe e lorilẹede Amẹrika.
Oun ni egungun ẹja to n ha Trump lọrun ninu eto oṣelu Amẹrika lọwọ lọwọ bayii.
Igbakeji aarẹ Barack Obama tẹlẹ ri yii ni wọn yan gẹgẹ bi oludije labẹ asia ẹgbẹ oṣelu Democratic fun idibo inu oṣu kọkanla.
Loju awọn alatilẹyin rẹ, o jẹ akọṣẹmọṣ ninu aatọ ọrọ ilẹ okere pẹlu iriri ọlọdun gbọrọ ni ilu Washington, ẹnu rẹ dun mọran-mọran pẹlu ọrọ sisọ nita gbangba eyi to n fa oju eeyan mọra to fi mọ koda ẹni ti ko rọwọ họri lawujọ o si tun jẹ eeyan kan toun funrarẹ ti jẹya ri laye.
Loju awọn alatako rẹ, o jẹ oni gale gale eniyan to ko maa n sọ ọrọ to lee doju ti ni gidi gan atawọn ọr alufansa si eeyan (koda wọn ni o fẹran ko maa fa oorun ara irun obinrin simu).
Ṣe o wa to gbangbaa sun lọyẹ lati yẹ aga mọ aarẹ Trump nidii ni White House?
Oríṣun àwòrán, Getty
Biden kii ṣe ajoji lawọn ibi ipolongo idibo - o kara bọ eyi niluu Washington lọdun mẹ́tadinlaadọta sẹyin - 1973, ipolongo rẹ akọkọ fun ipo aarẹ lọdun 1987.
Bo ṣe lee ko ifẹ rẹ sori awọn oludibo naa lo ṣe jẹ eeyan to lee ma pẹ da wahala silẹ.
Bi o ṣe gbagbe ara nigba to n sọrọ niwaju ero pupọ lo mu opin de ba ipolongo akọkọ rẹ fun ipo aarẹ (eyi si ni igbakẹta) ki o tilẹ to bẹrẹ.
Oríṣun àwòrán, Reuters
"Nibi awọn iwọde ṣe lo br si nii bọ: ""awọn baba nla baba mi ṣiṣẹ ni ile iṣẹ eedu north-east Pennsylvania"" ati pe inu tun bi i pe wọn ko ri iru anfani to wu wọn jẹ laye."
Ṣugbọn ko si baba nla rẹ kankan to jẹ awa eedu - o kan ji ọrọ yẹn ati ọpọlọpọ mii lo ni latinu ọrọ oloṣelu ilẹ Britain kan, Neil Kinnock, eyi ti awọn mọlẹbi rẹ jẹ awa eedu.
"Iyẹn dẹ lo jẹ akọkọ ninu ọpọlọpọ ti wọn wa n pe ""awọn ado oloro ti Joe""."
"Nigba to fi iriri ara rẹ ninu oṣelu yangan lọdun 2012, o sọ fun awọn ero ti o da bii pe ọrọ ko ye pe ""ẹyin eeyan mi, mo le sọ fun yin pe mo ti mọ aarẹ mẹjọ, mo si mọ mẹta ninu wọn denu denu"", ohun to si n sọ nibi ni pe o ti ba wọn lopọ ri dipo pe wọn kan jọ jẹ ọrẹ."
Oríṣun àwòrán, AFP
Gẹgẹ bi igbakeji aarẹ Obama lọdun 2009, ori kan yan an ni lo fi jẹ eeyan alawọdudu akọkọ to jọ dije dupo gẹgẹ bi aarẹ ati igbakeji pẹlu Obama.
"Lai wo eyi, atilẹyin ti Biden n ri laarin awọn oludibo alawọdudu pọ jọjọ lasiko idibo aarẹ ti o fẹ waye yii ṣugbọn laipẹ yii , tun sọ ọrọ to da ilẹ ru lori eto ori rdio kan to ti sọ pe ""iwọ too ba niṣoro pe o fẹ mọ boya emi ni waa dibo fun tabi Trump, iyẹn nipe oo ki n ṣe alawọdudu."
Oríṣun àwòrán, THE BREAKFAST CLUB ON POWER 105.1/Via Reuters
Ẹwẹ, iha to daa to wu ni lori naa wa ninu ọrọ sisọ rẹ, laarin agbami bi awọn oloṣelu ṣe maa n ka  ọrọ jade ninu iwe, Biden ni iranti igba ewe oun fihan pe oun kii fẹran lati maa ka ọrọ lati inu iwe dipo bẹẹ atinu ọkan loun ti maa n sọrọ.
Oloṣelu to ni ọgbọn alumọkọrọyi pupọ ni, o o lee fi ọrọ ẹnu so ọta pọ di ọrẹ ṣugbọn iru imọlara rẹ si nkan naa lo maa n di iṣoro.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Obinrin mẹjọ lo jade sita lọdun to kọja lati fi ẹsun kan Biden pe o fi ọwọ kan awọn, o di mọ wọn tabi fi ẹnu ko wọn lẹnu bkẹ si ni ileeṣk iroyin ilẹ Amẹrika ṣafihan bi o ṣe maa n ki awọn obinrin timọ timọ nita gbangba eyi to maa n fi han ni ọpọ igba bo ṣe n fi imu fi irun wọn.
Ninu idahun rẹ, Ọgbẹni Biden ṣeleri lati maa fi eyi sọkan ninu iṣesi rẹ sawọn eniyan.
Ẹwẹ, ninu oṣu kẹta, Tara Reade fi ksun kan an pe o fi agiditi oun mọ ara ogiri to si fipa ba a lopọ ni ọgbọn ọdun sẹyin nigba to n ṣiṣẹ gẹgẹ bi oṣiṣẹ oluranlọwọ ni ọfiisi rẹ.
"Biden ti ni irs ni ẹsun naa ti ikọ olupolongo ibo rẹ si ti fi ọrọ sita pe: ""eyi ko ṣẹlẹ rara ati rara""."
"Ninu ifọrọwanilẹnuwo kan to jade laipẹ, Reade sọ pe ""awọn to bimọ fun un ti n sọ ọpọlọpọ ọrọ buruku lori ayelujara."
Bo tilẹ jẹ pe oun funra rẹ ko tii fesi, ṣugbọn o fẹ da bii pe aiṣootọ wa ninu ipolongo rẹ ti wọn n sọ pe ko tii si ewu kankan tabi boya o wa.
Ẹwẹ, ikọ olupolongo rẹ ṣi tun bu ẹnu atẹ lu eyi.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Eleyi fẹ fa iṣoro dani ṣugbọn atẹyin wa lo ti ṣẹlẹ, awọn alatilẹyin Biden n gbero pe iṣọwọ ṣe si rẹ bayii yoo ran an lọwọ lati ma jabọ sinu panpẹ kan naa to ti awọn aarẹ labẹ ijọba awaarawa ko si lọpọ igba.
Biden ti ni ọpọlọpọ iriri ni Washington. O lo ọdun mẹjọ nile aṣoju-ṣofin, mẹjọ nile aṣofin agba, mẹjọ gẹgẹ bii igbakeji aarẹ.
Lọpọ igba, awọn ara Amẹrika ti ni ẹni to ba ni oun kii ṣe ara inu ile nla funfun White House eyi si jẹ ohun to nira fun Biden lati sọ ni ti ara rẹ lẹyin to ti fẹẹ lo aadọtun nipo giga ninu oṣelu wọn si le lo iriri ọlọdun gbọọrọ yi lodi si i.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Biden has a lot of experience on the world stage
Biden ti kopa ninu ọpọlọpọ nkan ro nii ṣe nipa awọn eto pataki ni ọpọlọpọ ọdun sẹyin ti awan ipinu yii si le maa fibẹẹ dun wo ninu oṣelu aye ode oni.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
O ṣe ni laanu fun Biden pe ọkan lara ohun to fi jk ko da bii pe o fẹ jina diẹ si ọpọ oloṣelu ni pe ohun kan to kan gbogbo eeyan ti sun gbọngbọn kan oun naa ri - iku.
Bo ṣe n mura lati ṣe iburawọle ipo sẹnetọ to wọle fun ni iyawo rẹ, Neilla ati ọmọbinrin rẹ, Naomi ku ninu ijamba ọkọ kan eyi to tun pa awọn ọmọkunrin rẹ meji, Beau ati Hunter lara.
Iṣoro inu ọpọlọ lo pada pa Beau lọdun 2015 lẹni ọdun mẹrindinlaadọta.
Torinaa bi o ṣe padanu eeyan pups layika rẹ fihan pe pẹlu gbogbo agbara to ni ninu oṣelu, oun naa ti ni ifọwọkan ajalu to kan awọn eeyan laye oun naa ri.
Ẹwẹ, iroyin nipa idile rẹ nipa ti ọmọ rẹ kan to ku, Hunter yatọ.
Oríṣun àwòrán, Reuters
Hunter pada di agbẹjọro ko to di pe aye rẹ yiwọ.
Iyawo akọkọ rẹ ṣafihan aṣiri pe o n mu oogun oloro, ọti to si n lọ ile ti awọn aṣẹwo ti ma n jo nihoho  ati pe wọn le e danu kuro nileeṣẹ awọn ọmọ ogun ilẹ Amẹrika tori pe o n mu oogun oloro sinu iwe ikọsilẹ wọn
Lọdun to kọja o fẹ iyawo ẹlẹẹkeji lẹyin ọsẹ kan ti o pade rẹ.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Wọn lọ ẹsun kan mọ Biden lẹsẹ to tan kaakiri agbaye gẹgẹ bo ṣe jẹ pe lara iriri to ni ni nipa ọrọ ilẹ okere. Tẹlẹ, o ti jẹ alaga ile igbimọ aṣofin agba nipa ibaṣepọ ilẹ okere to si ti fi eyi yangan gan pe oun ti pade awan adari pataki lagbaye ni gbogbo ọdun marundinlaadọta sẹyin.
Nigba ti eleyi n fun awọn oludibo ni igboya pe o ni iriri lati di aarẹ sibẹ, o nira lati sọ bi itan rẹ lori eyi yoo ṣe baa mu pẹlu awọn oludibo.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ero awọn oludibo ti n gbe Biden ṣaaju Trump pẹlu nkan bii koko marun si mẹwa ninu idije aarẹ yii ṣugbọn idibo ti yoo waye ninu oṣu kọkanla ṣi jina to si jẹ wipe ọpọ ogun lo ṣi wa niwaju.
Awọn oludije mejeji ti baba forigbari lori ọrọ ṣiṣe atilẹyin fun awan afẹhonuhan to n bu ẹnu atk lu awọn ọlọpa nitori awọn alawọdudu ati bi ijọba ṣe n koju ajakalẹ arun Coronavirus.
Koda ọrọ ibomu lasan gan ti di ọrọ oṣelu, pẹlu bi wan ṣe maa n ri Biden ni gbogbo igba to n lo ibomu nigba ti Trump ni tirẹ mu ọna ida keji gba lori eyi.
Ṣugbọn yatọ fun eyi, aimọye ọrọ mii to wa nilẹ to pọ.
"Bi Biden ba jawe olubori, yoo jẹ ewe oye ajẹpẹ amọ to ba fidi janlẹ, yoo pese anfani ọdun mẹrin mii fun ẹni to ro pe ko kun oju osuwọn rara lati jẹ aarẹ Amẹrika - ""ẹni ti ko ṣee gbẹkẹle"" gẹgẹ bo ṣe sọ."
"Ni ọdun diẹ sẹyin nigba ti o n ṣe odiwọn boya yoo kara bọ idije aark lọdun 2016, Biden sọ pe ""mo lee ku gẹgẹ bi eeyan ti inu rẹ dun bi mi o ba jẹ aarẹ""."
Ọrọ ko ri bẹẹ mọ bayii.
Self-certification form: Lẹ́yìn tí ìjọba Nàìjíríà pahùndà lóríi fọ́ọ̀mù tuntun, wo àwọn tọ́rọ̀ kàn
Oríṣun àwòrán, Twitter/government of nigeria
Ajọ agbowoori lorilẹede Naijiria, FIRS ti gbe alaye kalẹ lori bi ọrọ eto iforukọsilẹ fun awọn to ba ni aṣuwọn ifowopamọsi lorilẹede Naijiria.
Lẹyin to ti kọkọ kede pe gbogbo awọn to ba ni akanti ifowopamọsi ni ko lọ gba fọọmu naa, ijọba apapọ jade laarọ ọjọ Ẹti pe oun ko ọrọ naa jẹ ati pe ajọ agbowoori FIRS yoo kede awọn tọrọ naa yoo kan laipẹ.
Wo ìdílé tí ìyá àti gbogbo ọmọ kara bọ iṣẹ́ ṣíṣe epo tà
Nigba ti ajọ agbowoori lorilẹ€de Naijiria, FIRS yoo fi jade pẹlu awọn ti ọrọ naa yoo kan, alaye wọn niyi:
Gẹgẹ bi ajọ FIRS ṣe sọ, kii ṣe gbogbo eeyan ni gbigba fọọmu yii tabi fifi ọwọ si fọọmu yii kan.
Ajọ naa ṣalaye pe awọn eeyan lee gba fọọmu yii lawọn banki ti wọn ba n lo.
Bakan naa lo ni wọn tun lee lọ si oju opo ayelujara ajọ FIRS lati tẹẹ jade nibẹ.
Bi fọọmu iforukọsilẹ awọn iforukọsilẹ tuntun fawọn to ni aṣuwọn ifowopamọsi lorilẹede Naijiria ṣe ri ree.
Irufẹ meji ni fọọmu yii to wa. Ọkan wa fun awọn aladani, omiran si wa fun awọn onileeṣẹ.
Abalaakọkọ ni yoo maa bere awọn iroyin to ba yẹ nipa ẹni to ni aṣuwọn ifowopamọ si naa atawọn iroyin miran to jẹ mọ ọrọ owo ori rẹ.
Abala keji yoo beere iroyin nipa ibi ti ẹni to ni aṣuwọn ifowopamọsi naa n gbe fun anfani owo ori sisan pẹlu nọmba idanimọ fun owo ori sisan iru ẹni bẹẹ, iyẹn, Tax Identification Number, TIN
Abala kẹta yoo rọ eeyan to ni aṣuwọn naa lati jẹri si pe otitọ ni gbogbo awọn iroyin ti o ti fi silẹ lawọn abala akọkọ ati ikeji fọọmu iwe ẹri aṣuwọn banki naa.
Abala akọkọ: iroyin nipa ẹni to ni aṣuwọn naa eyi ti yoo ṣe afihan orukọ ileeṣẹ naa, ẹka ileeṣẹ naa, orilẹede ti wọn ti fi orukọ rẹ sọlẹ si labẹ ofin pẹlu adirẹsi fiweranṣẹ wọn.
Abala keji: ileeṣẹ naa yoo sọ irufẹ aṣuwọn banki tabi irufẹ ileeṣẹ iṣuna ti wọn n lo. (Fun apẹrẹ Investment Entity, Depository Institution, Custodial Institution or specified Insurance Company)
Abala kẹta: Ẹni to ni ileeṣẹ naa tabi ẹni to n ṣe akoso ileeṣẹ bẹẹ.
Abala kẹrin: ileeṣẹ to ni aṣuwọn naa gbọdọ sọ ibi to fikalẹ si to ti n san owo ori ati nọmba to fi n san owo ori, TIN.
Abala karun un:ileeṣẹ to ni aṣuwọn naa yoo jẹri si pe otitọ ni gbogbo awọn iroyin ti o ti fi silẹ lawọn abala akọkọ ati ikeji fọọmu iwe ẹri aṣuwọn banki naa.
Oríṣun àwòrán, TWITTER/@BASHIRAHMAAD
Ijọba apapọ ti tọrọ aforiji fun atẹjade to fi sita nipa fọọmu iforukọsilẹ fun awọn to ni aṣuwọn ifowopamọsi ni banki lọjọ Iṣẹgun.
Ijọba apapọ ṣalaye loju opo Twitter rẹ ni Ọjọ Ẹti pe aṣiṣe nla gbaa ni atẹjade naa.
O wa fi kun un pe ajọ agbowoori lorilẹede Naijiria, FIRS yoo maa gbe alaye to kunna jade lori rẹ laipẹ.
Ijọba apapọ tun ṣalaye pe nigba ti eto iforukọsilẹ naa ba bẹrẹ o loju awọn eeyan ti yoo kan.
Ijọba orilẹ-ede Naijiria ti kede pe ki gbogbo ọmọ Naijiria to ni asunwọn owo nile ifowopamọ, ileeṣẹ adojutofo, ati awọn ileeṣẹ miran to n mojuto ọrọ owó, lọ gba fọọmu ti yoo mu ki wọn o fi aridaju han pe awọn lo ni awọn apo asunwọn naa.
Ọjọbọ ni ijọba kede aṣẹ tuntun yii, loju opo ayelujara Twitter rẹ, pe fọọmu naa ti wọn pe ni 'self-certification' ṣe pataki, fun iranlọwọ awọn ileeṣẹ to wa fun eto ẹnawo lati le tẹle awọn ilana to yẹ lori ofin ti ijọba fi sita loti ọrọ owo ori lọdun 2019.
'Ọ̀nà àtijẹ kan ṣoṣo táa ní ni Màálù àwọn Fúlàní ti bàjẹ́'
Form of entity (eyi wa fun awọn ileeṣẹ)
For controlling Person (eyi wa fun awọn eeyan to ba ni aṣẹ lori asunwọn ẹlomiran)
Form for individual (eyi wa fun ẹni kọọkan to ni apo asunwọn ni banki)
Ijọba sọ pe ẹnikẹni to ba kuna lati tẹle ilana yii yoo jẹ iya to ts labẹ ofin, debi i pe o le padanu owo rẹ to wa ni ile ifowopamọ, tabi ko ma le lo apo asunwọn naa mọ.
Gbogbo ile ifowopamọ, ileeṣẹ adojutofo ati awọn miran ti o ba ni asunwọn si ni wa a ti gba fọọmu naa, ti o si gbọdọ ṣe akọsilẹ rẹ.
Ikede yii ti n fa ariwisi ati ikunsinu laarin awọn ọmọ Naijiria kan, paapa lori ayelujara.
Anambra Killing: Ojú oorun ni ìyá àtàwọn ọmọ méjèèjì wà nígbà tí ọkùnrin náà fi àdá pa wọ́n
Oríṣun àwòrán, Nigeria Police
Orisirisi iwa isekupani lo n waye ni Naijiria to kọja oye ọpọ eeyan.
Laipẹ yii la mu iroyin Kayeefi wa fun yin nipa iya kan to pa ọmọ bibi inu rẹ, to si fi pata sẹnu.
Iroyin kasiara miran to tun wa n tẹ wa lọwọ ni ti ọkùnrin kan, Emeka Ezimadu to sa ọmọ bibi inu rẹ meji ati iya to bi ni ada pa.
Ileesẹ ọlọpaa ẹkun Nnewi nipinlẹ Anambra, nigba to n fìdi iṣẹlẹ naa mulẹ ninu atẹjade kan ti oṣiṣẹ alukoro Haruna Muhammed fisita, salaye pe ọwọ oun ti tẹ ọkùnrin naa, tii ṣe ẹni ọdun mẹtadinlaadọta.
Atẹjade naa ni abule Okpuneze Uruagu nijọba ibilẹ Ariwa Nnewi nipinlẹ Anambra ni iṣẹlẹ laabi ọhun ti waye.
Atẹjade naa ni ko ye ẹnikẹni bi iṣẹlẹ naa ti waye nitori sadede ni ọkùnrin naa fa ada yọ, to si sa ọmọ rẹ meji, Ifechukwu ati Mmeso Ezimadu pa loju oorun.
Ileesẹ ọlọpaa ni ọmọ ọdun mẹsan ni Ifechukwu nigba ti Mmeso jẹ ọmọ ọdun meji.
Bakan naa nileesẹ ọlọpaa fikun pe, ọkùnrin naa tun fi ada sa iya to bi lọmọ, Agnes Ezimadu, tii ṣe ẹni ọdun marundinlaadọwa, ni ada pa lati oju oorun.
Ko tan sibẹ o, Ileesẹ ọlọpaa tun ni ọkùnrin naa tun fi sa ọmọ rẹ mẹta mii ni ada, eyi to da ọgbẹ nla si wọn lara.
Orúkọ awọn ọmọ mẹtẹẹta ti wọn fara gbọgbẹ ni Nonzo, ẹni ọdun mejila, Chinaemerem, ẹni ọdun mọkanla ati Ngozi, ọmọ ọdun mẹjọ.
Ileesẹ ọlọpaa ni oun ti gbe awọn ọmọ to fara gbọgbẹ naa lọ sile iwosan nibi ti wọn ti n gba itọju.
Bakan naa ni wọn ti gbe oku awọn alaisi lọ sibudo igbokusi fun ayẹwo to yẹ.
Edo Election 2020: Obaseki gba ìwé-ẹ̀rí moyege gẹ́gẹ́ bí gómìnà tí wọ́n ṣẹ̀ṣẹ̀ dìbò yàn
Oríṣun àwòrán, Twitter/INEC Nigeria
Ajọ eleto idibo INEC ti fun Gomina Godwin Obaseki ni iwe-ẹri moyege lẹyin to jawe olubori ninu ibo gomina ipinlẹ EDo to waye lọjọ Abamẹta to kọja.
Obaseki fẹyin oludije APC, Osagie Ize-Iyamu gbalẹ ti o si ṣe bẹẹ wọle ibo gomina fun saa keji.
Gomina Obaseki to jẹ oludije ẹgbẹ oṣelu PDP lo ni ibo to pọju ninu idibo naa.
Kọmiṣọnna INEC fun ipinlẹ Edo, Rivers ati Bayelsa, Arabinrin May Agbmuche-Mbu lo fun ni iwe-ẹri ọhun lọjọ Iṣẹgun ni ilu Benin.
Agbmuche-Mbu ko ṣai lu gbogbo awọn ti ọrọ kan lọgọ ẹnu to fi mọ awọn oṣiṣẹ eleto aabo fun aṣeyọri eto idibo ọhun.
Wo ìdí tí ètò ìdìbò gómìnà ìpínlẹ̀ Edo ṣe lọ ní ìrọwọ́-rọsẹ̀
Godwin Obaseki wọle ibo gomina ipinlẹ Edo ninu eto idibo to lọ ni irọwọ-rọsẹ kaakiri ipinlẹ naa lọjọ Abamẹta.
Obaseki to jẹ oludije ẹgbẹ oṣelu PDP fẹyin oludije APC Osagie Ize-Iyamu gbalẹ ninu idibo ọhun ti o si wọle lẹẹkeji.
Oríṣun àwòrán, Facebook/Godwin Obaseki
Ohun to ya ọpọ eeyan lẹnu ni pe edto idibo naa lọ ni wọọrọwọ laisi rogbodiyan papaa julọ pẹlu gbọmisi omi o too to ti waye laarin laarin awọn ẹgbẹ oṣelu APC ati PDP ṣaaju ibo naa.
Onwoye nipa eto idibo, Ọmọwe Dikrullahi Yagboyaju to ba BBC Yoruba sọrọ ṣalaye ohun to ṣe okunfa alaafia to jọba ninu eto idibo gomina ipinlẹ Edo.
Ọmọwe Yagboyaju sọ pe nkan koko mẹta lo mu ki eto idibo Edo kẹsẹjari lai si rogbodiyan.
Ekinni ni pe gbangba laṣa ta ni eto iforukọsilẹ awọn oludibo, eto idibo, akojọpọ ibo ati ikede esi ibo,.
Abule Ado explosion: Irọ́ ńlá ní NNPC pa lórí ìbúghbàmù Abule Ado níbí tí ẹ̀mí èèyàn 23
Ọmọwe Yagboyaju ni eto idibo naa lọ ni irọwọ rọsẹ nitori gbogbo awọn ti ọrọ kan bi ajọ INEC, awọn ẹgbẹ oṣelu PDP ati APC to fi mọ awọn oṣiṣẹ eleto aabo tẹle alakalẹ ofin eto idibo.
O fikun ọrọ rẹ pe niwọn igba ti awọn ti ọrọ kan ninu eto idibo ko ba ri ara wọn pe awọn ju ofin lọ, ko le si rogbodiyan ninu iru eto idibo bẹẹ.
Àjọ INEC ò gbọdọ̀ kéde pé ètò ìdìbò gómìnà ìpínlẹ̀ Edo kò yanjú- Wike kìlọ̀
Alaga igbimọ ẹgbẹ oṣelu PDP to n ri si eto ipolongo eto idibo gomina ipinlẹ Edo to tun jẹ gomina ipinlẹ Rivers, Nyesom Wike, ti kilọ fun ajọ eleto idibo INEC pe ko maa kede wi pe eto idibo naa ko yanju.
Wike rọ ajọ INEC lati ṣe afihan ohun gbogbo ti wọn ba fẹ ṣe lori eto ibo gomina Edo lai fi igba kan bọkan ninu.
Gomina ipinlẹ Rivers ni awọn oṣiṣẹ eleto aabo gbọdọ ṣiṣẹ wọn bii iṣẹ ki wọn si maa faye gba ẹnikan kan lati da eto idibo naa ru.
Oríṣun àwòrán, Obaaseki/Ize-Iyamu
Wike ṣalaye pe awọn oṣiṣẹ eleto aabo ko si lọpọlọpọ ibudo ti wọn ti n ko esi idibo jọ eleyi to sọ pe ko yẹ ko ri bẹẹ.
Wike sọ pe oun nigbagbọ pe ajọ INEC ko ni ba orukọ ara jẹ, yoo si sẹ eto idibo naa ni aṣeyọri ti alakan n ṣe epo.
Lakotan, gomina ipinlẹ Rivers ni oun ti ẹgbẹ PDP ko fẹ gbọ ni pe ki INEC kede ibo gomina Edo pe ko fori sọ ibi kan.
Wo bí èsì ìdìbò ìpínlẹ̀ Edo ṣe ń jáde
Eto idibo ti pari ni ipinlẹ Edo bayii, ohun ti awọn oludibo atawọn onwoye n foju sọna fun bayii ni esi idibo lati mọ ẹni ti yoo maa ṣe akoso iṣejọba ni ipinlẹ naa fun ọdun mẹrin.
O kere ta ijọba ibilẹ mejila ninu mejidinlogun to wa ni ipinlẹ ni yoo kopa ribiribi lonii lati yan ẹni ti yoo di gomina wọn gẹgẹ bi gomina to wa lori alefa lọwọlọwọ labẹ ẹgbẹ oṣelu PDP yoo ṣe maa gbena woju oludije ti ẹgbẹ oṣelu APC, Pasitọ Ize-Iyamu.
Bo tilẹ jẹ pe nibẹrẹ pẹpẹ, oludije mẹrinla lo wa ṣugbọn awọn oluwoye ti wo o fin fin pe gbogbo awọn toku ti bila to si ti ku ija laarin erin meji, PDP ati APC.
Awọn ijọba ibilẹ ti iroyin n s pe idibo oni yoo ti waye ni Egor, Ikpoba/Okha, Oredo, Ovia North-East, Ovia South-West, Uhunmwode, Akoko Edo, Owan West, Owan East, Etsako East, Etsako West ati Etsako Central.
Ẹgbe oṣelu Peoples Democratic party ti ni ki awọn ọlọpaa jawọ ninu idunkoko mọ awọn Gomina ẹgbẹ naa to wa ni ipinlẹ Edo fun idibo Gomina nibẹ.
Ninu atẹjade kan ti akọwe ipolongo ẹgbẹ naa, Kola Ologbondiyan fi sita o ni iwa yi ko bojumu nitori awọn ọlọpaa ko dẹgun le awọn Gomina APC to wa fun idibo Edo.
Ologbondiyan to ni alaga ẹgbẹ Uche Secondus koro oju si iwa awọn ọlọpaa yi ni ọna lati da wahala silẹ ni wọn n ba bọ.
Oríṣun àwòrán, PDP
Pdp sọ pe o jẹ iyalẹnu fawn pe awọn ọlọpaa ko de ọdọ awọn Gomina ẹgbẹ oṣelu APC bi Gomina Abdullahi Ganduje ti Kano ati akẹgbẹ rẹ Hope Uzodinma ipinlẹ Imo.
Wọn ni bẹẹ naa ni igbakeji aar ile aṣofin agba Sẹnetọ Ovie Osagie naa n yan fanda kiri ile alaga ẹgbẹ APC tẹlẹ Adams Oshiomole.
Ileeṣẹ ọlọpaa ko ti fesi sọrọ yi bẹẹ naa si ni APC naa ko ti fesi.
Idibo Gomina ipinlẹ Edo yoo waye lọjọ Kọkandilogun oṣu Kẹsan nibi ti Gomina Godwin Obaseki ati Pasitọ  Ize-Iyamu yoo ti jọ maa figa gbaga.
Nigeria Airforce shortlist 2020: Iléeṣẹ́ ọmọogun òfúrufú kéde orúkọ àwọn tó yege ìdánwò àṣewọ'léeṣẹ́ ológun náà
Oríṣun àwòrán, Nigeria airforce
Ileeṣẹ ọmọogun ofurufu lorilẹede Naijiria ti gbe orukọ awọn eeyan to yege ninu idanwo aṣewọle si ileeṣẹ naa jade.
Ni aṣalẹ Ọjọbọ ni ileeṣẹ ọmọogun ofurufu gbe orukọ wọn jade loju opo Twitter rẹ.
O wa rọ awọn eeyan to dije fun idanwo aṣewọle si ileeeṣẹ ọmọogun ofurufu 2020 airmen/airwomen recruitment lati lọ yẹ orukọ wọn wo.
Bakan naa ni wọn tun jẹ ko di mimọ fun awọn to ba yege pe ki wọn gbaradi fun ifọrọwanilẹnuwo ti yoo waye ni ibudo ọmọ ogun ofurufu to wa ni Kawo ni ipinlẹ Kaduna, iyẹn NAF Base, Kawo - Kaduna  laarin ọjọ kẹrinlelogun oṣu kẹsan si ọjọ kejila oṣu kọkanla ọdun 2020.
Awọn nnkan ti wọn ni awọn to ba yege fun ifọrọwanilẹnuwo naa yoo mu dani niwọnyi :
Palm Oil production: Wo ìdílé tí ìyá àti gbogbo ọmọ kara bọ iṣẹ́ ṣíṣe epo tà
Epo pupa wa lara awọn nkan gboogi ti wọn maa n lo fi ṣe o fẹrẹẹ to idaji gbogbo nkan tawọn eeyan ma lọ n ra lawọn ile itaja nla nla kaakiri agbaye gẹgẹ bi ajọ kan to n polongo lori ọrọ ayika ṣe sọ ọ.
Bakan naa ni Naijiria, ko sẹni to lee fọwọ rọ sẹyin ninu ohun gbogbo to ni ṣe plu ounjẹ ti wọn si tun maa n lo fun ohun ile bii ọṣẹ.
Lonii, ọpọlọpọ idile lo jẹ pe ọna ti wọn fi n bọ ara wọn lati ri jẹ ri mu ni ṣiṣe epo ta.
Ọkọ̀ méjì jóná ráùráú níbi tí ọkọ̀ tó gbé bẹntiróò ti gbiná
Wo bí ìfigagbágbá tani yòó di gómìnà Edo láàrin Obaseki àti Ize-Iyamu yóò ṣe lọ
Wo ohun to yẹ kóo mọ̀ nípa fọ́ọ̀mù 'self-certification' tí ìjọba àpapọ̀ ṣẹ̀ṣẹ̀ gbé kalẹ̀ àtàwọn tó kàn
Fun Ezinma Ogbona ati idile rẹ, ọdun ti pẹ ti wọn ti n ṣe eyi atohun atawọn ọmọ rẹ ni wọn si kara bọ ọ. Wọn ti pin bi wọn ṣe n ṣe e. Ọdọmọkunrin ni yoo gun igi ọpẹ lọ lati lọ maa fi ada ge idi ẹyin silẹ.
Awọn obinrin ni yoo ko o lọ ile lati yọ ẹyin kuro lara idi.
Agbẹ to n gbin ẹgẹ to si n ṣe epo pupa ni arabinrin yii jẹ, isẹ yii lo si n ṣe to fi n ran idile rẹ lọwọ lati san owo ileewe awọn ọmọ.
Bi oun ati awọn ọmọ rẹ ṣe n pawọpọ ṣe iṣẹ epo pupa yii jẹ iwuri gidi gan.
Ọkọ̀ méjì jóná ráùráú níbi tí ọkọ̀ tó gbé bẹntiróò ti gbiná
Wo bí ìfigagbágbá tani yòó di gómìnà lónìí láàrin Obaseki àti Ize-Iyamu yóò ṣe lọ
Wo ohun to yẹ kóo mọ̀ nípa fọ́ọ̀mù 'self-certification' tí ìjọba àpapọ̀ ṣẹ̀ṣẹ̀ gbé kalẹ̀ àtàwọn tó kàn
Yatọ̀ sí pé ó ṣe sọ́jà, tó tún jẹ́ ọkọ Oriṣabunmi, wo àwọn nkan tí o kò mọ̀ nípa Jimoh Aliu
Abass Akande: Obesere lóun ló kàn lẹ́yìn olóògbé Barrister àti Kollington nínú iṣẹ́ orin Fuji
Oríṣun àwòrán, Facebook/Abass Akande Obesere
Gbajugbaja olorin Fuji, Abass Akande ti ọpọ mọ si Obesere ti ja gudugbẹ ọrọ lulẹ lori eto ori redio kan niluu Ibadan, nipinlẹ Oyo.
Ninu ifọrọwerọ lori eto redio ọhun ni Obesere ti sọ pe oloogbe Sikiru Ayinde Barrister ati Alhaji Ayinla Kollington nikan lo jẹ baba fun oun ninu iṣẹ orin Fuji.
Obesere sọ pe oun gan an ni ipo agba ninu orin Fuji kan lẹyin oloogbe Barrister ati Kollington.
Abasido gẹgẹ bi orukọ inagijẹ rẹ mii ṣalaye pe Eleduwa da oun gẹgẹ bi ọga, o ni bakan naa si ni Oba Aṣẹda fi ohun ti oun yoo maa fi ṣe ipo olori jinki oun.
''Mo le bura pe were kan lo kilọ fun mi lọjọ ti mo fẹ gba pe ẹni to wa lẹyin mi ju mi lọ. Were naa n rin lọ loju titi nigba to sọ fun mi pe n o gbọdọ gba, ọdun 2007 lọrọ yii ṣẹlẹ,'' Obesere lo sọ bẹẹ.
O ṣalaye pe oun ko kọkọ fẹ gba ipo ọba orin Fuji nitori ede-ai-yede to wa laarin awọn olorin ṣugbọn oun gbaa lẹyin ti oun tun ero pa lori rẹ.
Nigba to sọrọ lori igba to bẹrẹ ere Fuji, o ni lọdun 1983 iyẹn bi ọdun mẹtadinlogoji sẹyin loun bẹrẹ si ni maa ri owo nibi iṣẹ orin Fuji.
Obesere ko ṣai sọ nipa oba orin oloogbe Ayinde Barrister, o ni Sikiru Ayinde ti papoda ni tootọọ ṣugbọn orukọ rẹ ko le parun laelae.
''Ko tiẹ dabi ẹni pe Barrister tiẹ ku rara, nitori gbogbo igba laye si n gbọ orukọ rẹ,'' Obesere lo woye bẹẹ.
O ni oun ti n ṣe akitiyan pẹlu awọn eeyan mii lati gbe eto kan kalẹ lati maa fi ṣe iranti oloogbe Barrister gẹgẹ bi eto ti wọn maa fi n ranti olorin Afro, Fela Anikulapo Kuti lọdọọdun.
Obesere tun mẹnu ba awo rẹ to jade laipẹ to pe akori rẹ ni ''Standout,'' o ṣalaye pe oṣu meje gbako loun fi ṣiṣẹ lori awo naa.
''Lasiko konle o gbele coronavirus ni mo bẹrẹ iṣẹ lori awo naa tori mo mọ pe awọn eeyan yoo mujo jo lẹyin ti covid-19 ba kasẹ nilẹ,'' Obesere lo sọ bẹẹ.
Ọjọ kẹtadinlọgbọn oṣu keje ọdun 2020 yii ni Obesere gbe awo orin ọhun jade.
Adult Bedwetting: Kí ló ń fa kí àgbàlagbà má a tọ̀ sí ilé?
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Aisan tabi ipenija lori ki agbalagba ma a tọ sile jẹ ọkan lara awọn aisan ọpọlọ ti o maa n ṣẹlẹ si awọn eniyan lawujọ.
Amọ, idẹyẹsini ti o maa n waye si awọn to ba ni iru ipenija yii kii jẹ ki wọn le ke gbajare sita tabi ki wọn lọ si ileewosan fun itọju.
Idẹyẹsi miran ni bi awọn araale ati ara adugbo ṣe n huwa si ẹni to ba ni ipenija yii nipa sisọ ọrọ ẹgan tabi huwa si wọn bi ẹni pe wọn kii ṣe eniyan ẹlẹran ara bii ti wọn.
Lati mọ ohun to n fa aisan yii, ileeṣẹ BBC ba Dokita onimọ iṣegun, Henry King to sọ ohun to n fa ipenija yii ati ọna ti a le gba ran ara wa lọwọ lati bori rẹ.
Ohun ti o sọ re e:
Aisan kokoro oju ara, Urinary Track Infections ma n fa ki agbalagba ma a tọ sile ti wọn ko ba moju to o ni kiakia.
Bẹẹ si ni aisan kokoro oju ara yii le mu ki eniyan to si ara rẹ ni oru tabi ni ọsan paapaa pẹlu.
Ẹni to ba ni iṣoro pẹlu ọpa ẹyin rẹ, Spine, o ṣeeṣe ko bẹrẹ si ni tọ si ara.
Àṣìṣe ọlọ́pàá àti Adájọ́ sọ mí di ẹni tí wọ́n dájọ́ ikú fún, ọpẹ́lọpẹ́ Fayoṣe tí ko buwọlu
Bakan naa ni ẹni to ba ni aisan jẹjẹrẹ to ti tan ka gbogbo ara rẹ lee maa tọ si ara.
O ṣeeṣẹ ki ẹni ti wọn ti fi iya jẹ̀ẹ lọna aitọ ma a tọ si ile.
Idi ni wi pe eni naa le fẹ gbagbe iya to jẹ ẹ nipa pipada si awọn iṣesi ti o maa n ṣe ni kekere.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Awọn oloyinbo maa n pe ipenija yii ni Catatonic, eleyii ti o dabi ki eniyan pada si kekere.
Eleyii yoo mu wọn ma a tọ sile bii ọmọde.
Dokita Henry King ni ẹnikẹni to ba n mu oti amupara ṣeeṣe ki o tọ sile.
Bakan naa ni awọn ọdọ to ba n lo oogun oloro naa le bẹrẹ si ni tọ si ara ati si ori ibusun wọn.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Iléeṣẹ́ ọlọ́pàá ní Kano tí ṣe àyẹ̀wò àwọn 13, 048 tó fẹ́ darapọ̀ mọ́ wọn
Facebook mú àyípadà bá àtẹ̀jíṣẹ́ síra ẹni lórí òpó Instagram, wo àwọn ǹkan tó kàn ọ níbẹ̀
Ẹ̀rọ CCTV tú àsírí ọkùnrin ẹni ọgbọ̀n ọdún tó fi ipá bá ọmọ ọdún mọ́kànlá lòpọ̀
Ọkùnrin tí wọ́n fẹ̀sùn kàn pé ó jí ǹkan nílé ìjọsìn rí ẹ̀wọ̀n he!
Wo bí èsì ìdìbò ìpínlẹ̀ Edo ṣe ń jáde
Manchester United vs Crystal Palace: Manchester United fi orí kó ògúlùtu ìyà olójú mẹ́ta sí ẹyọkan lọ́wọ́ Crystal Palace
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Awọn agba bọ wọn ni aile ja nii jẹ ojude baba mi o de ihin; ibi gbogbo nii gba alagbara o.
Bẹẹ gẹlẹ lọrọ ri ni papa iṣire Old Trafford loni nigba ti Manchester United gbalejo Crystal palace ni ibuba rẹ.
Amọṣa nigba ti ifẹsẹwọnsẹ naa wọ iṣẹju keje ni Townsend, atamatase Crystal palace gba goolu akọkọ wọle.
Gbogbo igbiyanju akọnimọọgba Manchester United, Olegunner Solkjaer atawọn agbabọọlu rẹ lati yii  oju ọrọ naa pada lo n jasi pabo.
Ni gba ti ifẹsẹwọnsẹ naa tun wọ iṣẹju kẹtalelaadọrin ni Crystal palace ba tun fọba lee pẹlu goolu pẹnariti nigba ti agbabọọlu ọwọ ẹyin fun Manchester, Lindelof fi ọwọ gbe bọọlu loju ile rẹ.
Ayew lo kọkọ gba pẹnariti naa to si gbaa si ọwọ aṣọle Mancxhester United ki alamojuto ifẹsẹwọnsẹ naa, Martin Atkinson to pe fun atungba lẹyin ayẹwo aworan VAR, eyi ti William Zaha wa gba wọle.
Manchester united da ẹyọkan pada pẹlu agbabọọlu tuntun ti wọn ṣẹṣẹ ra, Van de Beek nigbati ifẹsẹwọnsẹ naa wọ ọgọrin iṣẹju .
Amọṣa, Crystal Palace jẹ ko di mimọ pe ko tii rẹ awọn ati pe ayo ṣi wa lara awọn nigba ti Zaha ti gba goolu kẹta wọle ni iṣẹju karundinlaadọrun.
Edo Election 2020: Ààrẹ Buhari, Atiku àti àwọn èèkàn ìlú míràn ti n kí Obáseki ku oriire
Oríṣun àwòrán, Obaseki/ Twitter
Ààrẹ Muhammadu Buhari ti ránṣe kú orííre si Godwin Obaseki lẹ́yìn tó jáwé olúborí nínú ìdìbò gómìnà tó wáye lónìí nípìnlẹ̀ Edo.
Obaseki to jẹ́ olùdíje dupò gómìnà lábẹ́ ẹgbẹ́ òṣèlú PDP ló fi ìdí akẹgbẹ́ rẹ̀ labẹ̀ ẹgbẹ òṣèlú APC jánlẹ.
Nínú àtẹjáde ti Garba Shehu tó jẹ́ olùrànlọ́wọ́ pàtàkì fún ààrẹ Buhari lórí ìpolongo fi sita, aarẹ dúpẹ́ lọ́wọ́ àwọn elétò ìdìbò fún bi wọ́n ṣe ṣeto idibo naa nirọwọrọsẹ.
Ó fí kún-un pé èyi tọka si  àrídáju pé ìjọba ààrẹ Buhari nígbàgbọ́ nínú ètò ìdìbò ti kò ni kọ́nukọ́họ nínú.
Bákan náà lo fi ọ̀rọ̀ ránṣe si pé, kó ri àṣeyọri rẹ̀ gẹgẹ bi anfaani lati fi ọkan idupẹ  àti ìrẹ̀lẹ̀ han
Bákan náà ni igbákeji ààrẹ Nàìjíríà nígbà kan rí Atiku Abubakar náà ti gboriyin fún àwọn ènìyàn ìpinlẹ̀ Edo fún iṣẹ rere ti wọ́n ṣe láti gbé Obaseki wọlé fún sáà keji.
Nínú ọ̀rọ̀ tirẹ̀, Atiku ni Agbara àwọn bàbá ìṣàlẹ̀ ti dópin lórílẹ̀-èdè Nàìjíríà pẹ̀lú irú ìṣẹ̀lẹ̀ tó wáye ni ìpińlẹ̀ Edo lónìí àti pé agbára kan ti yóò dúró náà ni àgbàra àwọn oludibo.
Oríṣun àwòrán, Nysome Wike/twitter
Atiku rọ àwọn ènìyàn ìpińlẹ̀ Ondo láti gba ara wọ́n kúrò lọ́wọ́ bàbá ìsàlẹ̀ bi àwọn ènìyàn Edo ṣe ṣe.
Kò tán síbẹ̀, Gómìnà ìpińlẹ̀ Rivers, Nyesom Wike  náà wa lára àwọn to kọ́kọ́ ki Obaseki ku oríire ìjáwé olúborí.
Ó ní òun dúpẹ́ lọ́wọ́ àwọn ènìyàn ìpińlẹ̀ Edo fún àdúrò ti wọ́n àti pé òun ni ìgbàgba pé bí òun ṣe n kúro ni Edo báyìí òun mọ̀ pé, Obaseki yóò ṣe ìtójú wọ́n dáradára.
Oríṣun àwòrán, @Seyi Makinde
Gómìnà ìpińlẹ̀ Oyo Seyi Makinde ko gbẹ́yìn lára àwọn tọ kọ́kọ́ ki gómìnà Obaseki  àti igbákeji rẹ̀, Phillip Shaibu  ku oríire àṣeyọri ìdìbò.
Godwin Obaseki wọlé ìbò gómìnà lẹ́ẹ̀kejì ní ìpínlẹ̀ Edo
Oríṣun àwòrán, Twitter/Godwin Obaseki
Iroyin to n tẹ wa lọwọ bayii lo sọ wi pe Godwin Obaseki lo wọle ibo gomina ipinlẹ Edo.
Eyi tumọ si pe Obaseki to jẹ oludije ẹgbẹ oṣelu PDP fẹyin oludije APC Osagie Ize-Iyamu gbalẹ ninu idibo ọhun.
Ni bayii, Gomina Obaseki ti wọle gẹgẹ bi Gomina ipinlẹ Edo fun saa keji.
Obaseki jawe olubori ni ijọba ibilẹ to pọju ninu ibo naa ti Ize-Iyamu si te le e.
Ọga ajọ INEC for eto idibo gomina ipinlẹ Edo, Ọjọgbọn kpofure Rim-Rukeh lo kede Obaseki gẹgẹ bi ẹni to wọle ibo ọhun.
Ṣaaju ni Obaseki fi ẹgbẹ oṣelu APC silẹ lọ si ẹgbẹ PDP lẹyin ti o fidi rẹmi ninu idibo abẹle fun ipo gomina ẹgbẹ oṣelu APC.
Ẹwẹ, iyanlẹnu lo jẹ fun ọpọlọpọ pe Gomina Obaseki lo jawe olubori ni ijọba ibilẹ alako rẹ, Ize-Iyamu.
Lakotan, oludije PDP Obaseki ni ibo 307,955 nigba ti Ize-Iyamu si ni ibo 223,619 ninu ibo naa.
Ritual killer: Ọwọ́ ọlọ́pàá tẹ ọkùnrin tó gé akẹ́kọ̀ọ́ ọ̀rẹ́bìnrin rẹ̀ wẹ́lẹ́ wẹ́lẹ́ fún òògùn owó ní Ikorodu
Oríṣun àwòrán, Twitter/@Codedwizzy
Ọwọ awọn ọlọpaa ti tẹ afurasi ọkunrin kan, Owolabi Yusuf ti wọn fẹsun kan pe o ṣekupa akẹkọọ ile iwe giga gbogbonṣe kan, Toluwalase Kembi lati fi ṣe oogun owo.
Ohun ti a gbọ ni pe Kembi, ọmọ ogun ọdun ṣabẹwo si ọrẹkunrin rẹ ni Ikorodu eyi to sọ pe miliọnu meji owo naira loun gba lati fi ọmọdebinrin naa joogun.
Kembi to n gbe pẹlu awọn obi rẹ lagbegbe Tabon Tabon l'Agege pade iku ojiji lọjọ kejilọgbọn oṣu keje ọdun 2020 yii nigba to lọ sun nile Yusuf.
Yusuf ẹni ọdun mẹtalelọgbọn ni iroyin sọ pe o pa Kembi ti o si ge wẹlẹwẹlẹ lati fi ṣe oogun owo.
Ẹbi ọmọdebinrin ọhun sọ fun awọn akọroyin pe ileeṣe ọlọpaa ẹkun Elere l'Agege ko ti gbe oku akẹkọọ naa fawọn.
Lẹyin ọsẹ mẹta ti Yusuf ṣiṣẹ laabi yii tan lọwọ awọn agbofinro too tẹẹ lẹyin to ti sa lọ siluu Ilorin nipinlẹ Kwara.
Àṣìṣe ọlọ́pàá àti Adájọ́ sọ mí di ẹni tí wọ́n dájọ́ ikú fún, ọpẹ́lọpẹ́ Fayoṣe tí ko buwọlu
Afurasi ọhun ni a gbọ pe o jẹwọ fawọn ọlọpaa wi pe oun gbimọ pọ pẹlu awọn mẹta mii ninu eyi ti babalawo kan ti wọn n pe ni Owonikoko wa.
O ni babalawo ọhun gan an lo ni ki oun fi ọmọ oodo lu akẹkọọ naa pa to ba ti ṣabẹwo si i.
Kembi to ṣẹṣẹ kẹkọọ gboye ''ND'' nile ẹkọ giga gbogbonṣe n mura lati lọ fun ẹkọṣẹ ohun to lọ ṣe nile ẹkọ giga fun ọdun kan ki o tun ṣagbako iku ojiji.
Oluwatoyin Kembi to jẹ baba akẹkọọ naa sọ fawọn akọroyin pe awọn tiẹ ro pe ọmọ naa ti sọnu ni nigba ti ko pada wale lọjọ naa lai mọ pe awọn oniṣẹ ibi ti gee wẹlẹ wẹlẹ.
Yusuf sọ pe babalawo nikan lo mọ ibi ti oku Kembi wa.
Ẹwẹ, agbẹnusọ fun ileeṣẹ ọlọpaa ipinlẹ Eko, Muyiwa Adejobi ti ṣalaye pe iwadii si n lọ lọwọ lati mu awọn mẹta yoku ti gbimọ pọ pẹlu Yusuf lati pa Kembi.
Bolaji Faleke ni Olùkọ́ tó ń kọ́ wa ní àṣà oge ṣiṣe lórí BBC Yorùbá
Abiola Ebila: ''Operation Burst'' ti mú arákùnrin Eji olórí ''One Million Boys'' tó gba ipò Ebila
Oríṣun àwòrán, Abiola Ebila
"''Operation Burst'' ti mú Eji, tó gba ipò Ebila olórí ''One Million Boys'' ní ìpínlẹ̀ Oyo Àlàyé rèé lórí bí wọ́n ṣe pa Ebila, olórí àwọn ""One million boys"" n'Ibadan"
Ọwọ awọn agbofinro to n ṣiṣẹ pọ nipinlẹ Oyo ti a mọ si 'Operation Burst' ti tẹ igbakeji Abiola Ebila, to jẹ olori ẹgbẹ okunkun ''One Million Boys'' to n da ipinlẹ Oyo ruBí ẹgbẹ́ One Million Boys ṣe bẹ̀rẹ̀ rèé àti ọṣẹ́ tó ṣe n'Ibadan .
"Ọga ajọ ''Operation Burst'' ajagun fẹyinti, Col. Oladipo Ajibola lo fidi ọrọ yii mulẹ Ohun tí o kò mọ̀ nípa Ebila ""One Million Boys"" àti Ekugbemi, olórí ẹgbẹ́ òkùnkùn méjì tó da ìlú Ibadan rú ."
Laipẹ yii ni ajọ ọlọpaa ''Operation Burst'' yegi fun Ebila nibi to ti fẹ ji eeyan gba lati wa owo.
Lati igba ti Ebila ti fi iku ṣe ifa jẹ ni ''Eji'' ti gba ipo olori ninu ẹgbẹ okunkun ''One Million Boys.''
Eji tọ jẹ igbakeji Ebila naa ti wa ni gbaga awọn ọlọpaa bayii, yoo si foju ba ileẹjọ laipẹ.
Ọga ajọ ''Operation Burst'' ni awọn ọmọ ẹgbẹ okunkun ''One Million Boys'' ti fi ipinlẹ Oyo silẹ lọ sawọn ipinlẹ mii nitori awọn oṣiṣẹ eleto aabo ko foju wọn balẹ.
Oríṣun àwòrán, others
O ni ajọ ''Operation Burst'' ti mu ọpọlọpọ ọmọ Yahoo, ẹlẹgbẹ okunkun atawọn ọdanran mii yatọ si Ebila to ti fi iku ṣe ifa jẹ.
Ajagun fẹyinti, Col. Ajibola sọ pe ọwọja ''Operation Burst'' ti de awọn agbegbe tawọn ẹlẹgbẹ okunkun ti n ṣọṣẹ bi Foko,Odo Oba,Olomi Olodo, ati ẹkun Oke-Ogun to fi mọ gbogbo Oyo ipinlẹ Oyo lapapọ.
Àṣìṣe ọlọ́pàá àti Adájọ́ sọ mí di ẹni tí wọ́n dájọ́ ikú fún, ọpẹ́lọpẹ́ Fayoṣe tí ko buwọlu
Ko ṣai gboṣuba kare fun Gomina Seyi Makinde fun bi o ti n gbaruku ti awọn oṣiṣẹ eleto aabo lati gbogun ti iwa ibajẹ nipinlẹ Oyo.
O rọ awọn obi lati mojuto awọn ọmọ wọn bi wọn ti n gbaradi lati wọle pada lọjọ Aje wi pe ki wọn ranti ọmọ ẹni wọn ọn ṣe.
Iléeṣẹ́ ọlọ́pàá sọ afurasí ọlọ́pàá tó yìnbọn fún ọ̀dọ́kùnrin tó fún èèyàn lóyún s'átìmọ́lé
Oríṣun àwòrán, Facebook/Mohammed Adamu
Ileeṣẹ ọlọpaa ipinlẹ Rivers ti ju afurasi ọlọpaa kan to yinbọn fun ọdọkunrin ẹni ọdun mọkandinlogun, Ledisi Kote lẹsẹ lori ẹsun pe o fun ọmọdebinrin kan loyun.
Ni ijọba ibilẹ Gokana nipinlẹ Rivers ni iṣẹlẹ ọhun ti ṣẹlẹ.
Agbẹnusọ ileeṣẹ ọlọpaa, Nnamdi Omoni lo fidi ọrọ naa mulẹ fawọn akọroyin.
Omoni ṣalaye pe ileeṣẹ ọlọpaa ti gba ibọn lọwọ ọlọpaa naa, o si ti wa lahamọ ni ẹka ileeṣẹ ọlọpaa to n ṣewadii awọn ọdaran.
O fi kun ọrọ rẹ pe ọdọkunrin to yinbọn fun lẹsẹ naa wa nile iwosan nibi to ti n gba itọju.
Omoni sọ pe ni bi aago meje aarọ ọjọ kọkanlelogun, oṣu kẹjọ ni ọlọpaa yii ṣadeedee lọ si ile awọn Kote nibi to ti sọ wi pe oun fẹ ri i.
Ọlọpaa yii wọ inu yara Ledisi lọ fun ra rẹ lẹyin ti awọn ẹbi rẹ ko fẹ fi oju rẹ han.
Lẹyin to wọ ọdọkunrin yii sita tan lo dabọn bo o lẹsẹ.
Ilorin Rainstorm: Àwọn olùgbé rawọ́ ẹ̀bẹ̀ sí ìjoba lẹ́yìn tí ìjì òjò tó rọ̀ nílùú Ilorin ba ńkan púpọ̀ jẹ́
Oríṣun àwòrán, Justeventonline
Eeyan kan ti ku ninu iṣẹlẹ ojo alatẹgun to rọ nilu Ilorin ti awọn ọmọde meji kan si ti di awati lẹyin tomi gbe wọn lọ.
Eeyan kan mii ti orule ile wo lu mọlẹ n gba itọju lọwọ nile iwosan gẹgẹ bi awọn alaṣẹ ti sọ fun BBC.
Ileeṣẹ panapana ilu Ilorin lo fi idi ọrọ yi mulẹ fun akọroyin BBC Yoruba.
Ninu ifọrọwanilẹnuwo pẹlu oṣiṣẹ ileeṣẹ panapana to wa ni adugbo Folawiyo Ilorin, ọgbẹni Abdulkareem Jimoh ni ladugbo Ita Egba-Ita Ogunbo ni eeyan kan ti ku.
''A gba ipe ni alẹ ọjọ Abamẹta pe ile ti wo mọlẹ mọ awọn eeyan meji kan.
Nigba ti a de ibẹ, a ribi doola ẹnikan, ẹnikeji si padanu ẹmi rẹ''
Oríṣun àwòrán, Facebook/His'harq Hor'lamide
Ọgbẹni Jimoh tẹsiwaju pe omi gbe  awọn ọmọde meji lọ, ọkunrin kan ati obinrin kan  ladugbo Emirs Road ati ni Gaa Odota.
''Ọmọdekunrin ọmọ ọdun mẹwaa ni omi gbe lọ ni Odota ti ọmọ obinrin ọmọ ọdun mejila si ko si omi ni Emirs road.''
O salaye pe awọn ko ti i ri oku awọn ọmọ naa titi di asiko ti a ṣe akojọpọ iroyin yi.
Sugbọn awọn ṣi n wa wọn.
Oríṣun àwòrán, Just Event Online
Awọn olugbe ilu Ilorin ti n rawọ ẹbẹ si ijọba lati ṣe iranwọ fun wọn lẹyin ti iji ojo ṣe akoba fun dukia loru mọjumọ ọjọ Aiku.
Niṣe ni orule ọpọ ile ati ṣọọbu itaja ṣi danu ti awọn ile ati alapa ogiri laarin awọn agbo ile mii si wo danu.
Kaakiri oju opo ayelujara lawọn eeyan n pin aworan oṣẹ ti ojo naa ṣe ladugbo bi Alore, Ọmọda, Oko Olowo, Oju Ekuun ati Ita Ogunbọ.
Oríṣun àwòrán, Facebook/kifaayah.abdurraheem
Oríṣun àwòrán, Facebook/kifaayah.abdurraheem
Opo ina pupọ to fi mọ orule awọn ile ni ojo yi bajẹ ti ọpọ si ti di alainile lori bayi ni Ilorin.
Ijọba Ipinlẹ Kwara ninu atẹjade kan ti Rafiu Ajakaiye, agbẹnusọ Gomina fi sita ti ṣe agbekalẹ igbimọ pajawiri lati ṣe iranwọ fara ilu.
Oríṣun àwòrán, Facebook/Kwara State Government
Ajakaiye ni niṣe ni iroyin ijamba ti ojo naa ṣe mu ibanujẹ ba ọkan Gomina Abdulrahaman Abdulrazaq.
O ni Gomina ti paṣẹ ki wọn tete bẹrẹ iṣẹ lati gbe awọn opo ina ti ojo bajẹ dide lati le dena aburu mii.
Ọmọ méjì ò sọnù nínú àgbàrá òjò o! Ọ̀tọ̀ lọ̀rọ̀ táa ń pè yín sí - Aráa Ketu
Yatọ si iṣẹlẹ yi to waye awọn eeyan ipinlẹ Kwara paapa ni agbegbe ariwa ipinlẹ naa bi Pategi, Tsonga, Tsaragi ati Lade n koju omiyale agbara ya ṣọọbu.
Kwara wa lara awọn ipinlẹ ti ajọ to n ṣeto bi oju ọjọ ti ṣe ri ni yoo koju ipenija arọrọda ojo lọdun yi.
NISE NI OJO TO RO LEKO KUN OJU TITI
Road accident: Èèyàn mẹ́jọ jónà ráúráú nínú ìjàmbá ọkọ̀ akérò tó ṣẹlẹ̀ ní mọ́rosẹ̀ Eko sí Ibadan
Oríṣun àwòrán, News Central
Eleduwa ko ni jẹ ki a ṣi rin ni adura tawọn arinrin ajo maa n gba lọna irin ajo. Eeyan mẹjọ ọtọtọ lo jona raurau ninu ijamba ọkọ to ṣẹlẹ loju ọna mọrosẹ ilu Eko si Ibadan lopin ọsẹ yii.
Ọkọ bọọsi Mazda pẹlu nọmba AAA 249 VX ni ijamba naa ṣẹlẹ si lẹgbẹ afara Saapade ni bii aago mẹsan ku iṣẹju mẹẹdogun.
Ọga awọn ajọ ẹṣọ oju popo, FRSC ti ipinlẹ Ogun, Ahmed Umar lo fidi ọrọ yii mulẹ fawọn akọroyin.
Ọgbẹni Umar ṣalaye pe eeyan mọkanla lo wa ninu ọkọ naa ninu eyi ti mẹjọ ti dero ọrun ti awọn mẹta si mori bọ.
Lọgan ti ọkọ naa gbina lawọn ẹṣọ oju popo pe awọn oṣiṣẹ panapana, amọ ọwọ ti bọ sori ki wọn to de bẹ.
Abule Ado explosion: Irọ́ ńlá ní NNPC pa lórí ìbúghbàmù Abule Ado níbí tí ẹ̀mí èèyàn 23
Ajọ ẹṣọ oju popo sọ pe taya ọkọ akero naa lo fọ lori ere ti ọkọ ọhun si bẹrẹ si ni gbe okiti ki o too gbina.
Ọga ajọ ẹṣọ oju popo ni awọn to mori bọ ninu iṣẹlẹ naa si n gba itọju lọwọ nile iwosan to wa ni Sagamu.
Ọga awọn ẹṣọ oju popo wa rọ awọn awakọ lati maa bọwọ fun ofin oju popo ki wọn si maa rii pe taya ọkọ wọn duro deedee.
Emir Of Zazzau: El-Rufai kéde ọjọ́ mẹ́ta fún ìdárò Emir Zazzau, Buhari, Babangida náà ń ṣèdárò
Oríṣun àwòrán, Twitter/Aisha Buhari
Iku doro, iku ṣeka, iku ṣe bẹẹ mu ẹni 're lọ. Aarẹ Muhammadu Buhari atawọn eekan ilu mii n ṣedaro, Emir of Zazzau, HH Alh. Shehu Idris to jade laye lẹni ọdun mẹrinlelọgọrin.
Ọjọ Aiku ni Emir naa wọ kaa ilẹ niluu Zaria nibi ti ẹgbẹlẹgbẹ eeyan ti pejọ lati ṣe ẹyẹ ikẹyin fun un.
Ẹwẹ, ijọba ipinlẹ Kaduna ti kede ọjọ mẹta lati kẹdun Emir Zazzau to di oloogbe.
Gomina Nasir El-Rufai lo fọrọ naa lede loju opo Twitter rẹ nibi to ti ṣalaye pe awọn oṣiṣẹ ijọba yoo lọ si si ibi iṣẹ wọn lọjọ Aje ati ọjọ Iṣegun.
El-Rufai ni isinmi yoo wa lẹnu iṣẹ l'Ọjọbọ lati le kẹdun Alhaji Idris to papoda, bakan naa lo sọ pe wọn  yoo gbe asia walẹ kaakiri ipinlẹ Kaduna fun imọyi Emir Zazzau to lọ.
Abule Ado explosion: Irọ́ ńlá ní NNPC pa lórí ìbúghbàmù Abule Ado níbí tí ẹ̀mí èèyàn 23
Bakan naa ni Gomina El-Rufai sọ pe akanṣe adura yoo wa fun Emir to ku lọjọ kan naa.
Aarẹ Buhari sọ pe Emir to ku kopa ribiribi lati rii pe iṣọkan ati ibagbepọ alaafia wa laarin awọn ọmọ Naijiria.
Aarẹ ni gbogbo agbara ti Eledua fi jinki Alhaji Idris lo fi sin awọn eeyan rẹ ki ọlọjọ to de.
Ero pọ biba nibi isinku Emir ilu Zazzau, koda awọn oludaro kọ lati tẹle ilana itakete si ara ẹni nitori ajakalẹ aarun coronavirus.
Aya aarẹ orilẹede Naijiria, Aisha Buhari naa wa lara awọn to n ṣedaro Emir Zazzua to lọ.
Aisha sọ loju opo Twitter rẹ pe Alhaji Idris ti ṣe tiẹ ninu idagbasoke awujọ ko o to dagbere faye.
Aisha gbadura pe ki Eleduwa dẹ ilẹ fun ẹni 're to lọ.
Aṣiwaju Bola Tinubu naa ko ṣai fi iṣẹ ibanikẹdun trẹ ranṣẹ si idile Emir Zazzau to filẹ ṣaṣọ bora.
Tinuubu sọ pe Alhaji Idris kii ṣe ẹlẹyamẹya, bẹẹ si ni o kopa ribiribi ninu iṣọkan orilẹede Naijiria ki o to jade laye.
Olori orilẹede Naijiria nigba kan ri, ajagun fẹyinti, Ibrahim Babangida naa kẹdun pẹlu gomina ipinlẹ Kaduna lori iku Emir Zazzau.
Babangida ni Emir Zazzau gbiyanju lati rii pe ipinllẹ Kaduna wa ni iṣọkan pẹlu ọgbọn inu ti Eleduwa fi kẹ ẹ.
FinCen files: Báńkì HSBC ṣe agbódegbà fún àwọn oníjìbìtì owó èké láìnáání ìkìlọ̀
HSBC lawon oluwadii ti ṣi aṣọ ni oju rẹ pe o lọwọ ninu bi awọn onijibiti ṣe n  ko awọn iwe ẹgbẹlẹgbẹ dọla owo ilẹ Amerika ti wọn lu awọn oludokoowo kiri agbaye ni jibiti.
HSBC ni banki to tobi ju ni ilẹ Gẹẹsi, lo awọn idokoowo rẹ ni ilẹ Amerika lati fi gbe owo naa lọ si aṣuwọn rẹ to wa ni Hong Kong laarin ọdun 2013 ati 2014.
Inu iwe iwadii kan ti wọn pe ni FinCen ni aṣiri bi banki naa ṣe kopa ninu jibiti ẹlẹgbẹerun mejilelọgọta pọun naa wa.
Amosa, banki HSBC ṣalaye pe oun ko fi igba kankan kọja aala ofin lẹnu iṣẹ oun paapaa julọ nipa difi iroyin awọn nnkan bẹẹro awọn alaṣẹ to ba yẹ leti.
Awọn iwe iwadii naa se alaye bi awọn onijibiti idokoowo sogun dogoji Ponzi scheme ṣe bẹrẹ kete lẹyin ti wọn ni ki banki naa san owo to din diẹ ni biliọnu meji dọla owo ilẹ Amẹrika lorilẹedẹ Amẹrika fun biba awon eeyan kowo pamọ kiri lọna ti ko tọ.
Awọn agbẹjọro fun awọn oludokowo ti wọn lu ni jibiti labẹ eto naa ṣalaye pe o yẹ ki banki ọhuun ti gbe igbesẹ to yanranti labẹ eto naa.
Abule Ado explosion: Irọ́ ńlá ní NNPC pa lórí ìbúghbàmù Abule Ado níbí tí ẹ̀mí èèyàn 23
Ki ni jibiti idokoowo pnzi yii da ke lori?
Jibiti idokoowo ti wọn ṣekilọ fun banki HSBC lori rẹ yii ni wọn n pe ni WCM777. Oun lo ṣokunfa iku oludokowo kan, Reynaldo Pacheco ti wọn ba oku rẹ labẹ omini ile kan to wa ni Napa, California loṣu kẹrin ọdun 2014.
Awọn ọlọpaa sọ pe nṣe ni wọn sọọ ni okuta pa.
O rari wọ eto idokoowo naa, bẹẹni ireti wa pe yoo mu ọpọ awọn oludokoowo miran wọle lati di ọlọrọ jaburata.Arabinrin kan ti ọgbẹni Pacheco mu wọle padanu ẹgbẹrun mẹta dọla eleyi lo si ṣokunfa iku rẹ lọwọ awọn ajinigbe ti wọn bẹ lowẹ sii.
Okan lara awọn ọlọpaa to ṣe iwadi naa, Sajẹnti Chris Pacheco, (ko tan mọ ẹni to ku o), iwadii naa ni nse lo n gbiyanju lati mu aye dara fun awon eeyanlai mọ pe awọn gbajuẹ lo gba oun, o si fi ẹmi ara rẹ dii.
O ni jibiti ti idokoowo olowo ele Ponzi lu u lo ṣokunfa iku re.
Ki ni awọn ileri ti eto olowo ele onijibiti naa se fun wọn?
Ọmọ orilẹ-ede China kan ti orukọ rẹ n jẹ  Ming Xu lo da a silẹ ko si si ẹni fi bẹẹ mọ ohunkohun nipa boya ilẹ Amerika lo gbe bi o tilẹ jẹ oe awon eeyan kan n sọ pe ibẹ lo ti lọ si ileewe gba imọ keji ni fasiti.
Ni ilu Los Angeles ni arakunrin Xu, abi Dr. Phil gẹgẹ bi ọpọ ṣe maa n pe e tẹdo si. Nibẹ lo si ti n ṣe ojuse pasitọ ijọ awọn ijọ kan.
Ọgbẹni Xu ni idokowo kariaye loun n ṣw, eleyii ti yoo mu ere ida ọgọrun fun ẹnikẹni to ba kopa laarin ọgọrun ọjọ.
Ohun to n ṣe naa ni eto idokowo olowoele onijibiti Ponzi WCM777.
Nipasẹ idanileko kaakiri, loju opo Facebook ati YouTube owo to le ni ọgọrin miliọnu dọla ni wọn pa wọle nipasẹ ohun ti wọn n oe ni idokowo latiri ayelujara.
Celebrity wedding: Wo àwọn ìlúmọ̀ọ́ká tó ṣe ìgbéyàwó ní ọdún 2020 yìí
Oríṣun àwòrán, Instagram/officialkayodeadebayo
Iyawo dun lọsingin, ọkọ tun mi gbe. Adia fun awọn ilumọọka kan ti wọn ṣe igbeyawo lọdun 2020 yii.
Bo tilẹ jẹ pe, coronavirus ṣe awọn eeyan mọle, iṣede covid-19 ko dena mọ awọn ololufẹ yii lati di tọkọ taya.
Wọnyi ni awọn gbajumọ to ṣe igbeyawo alarede lọdun 2020 yii.
Adewale Adeleke ati Kani Ekanem
Adewale Adeleke ti inagijẹ rẹ n jẹ ''ChairmanHKN'' nin ẹgbọn gbajugbaja olorin takasufe, Davido.
Oun ati Davido jẹ ọmọbibi inu Adedeji Adeleke to lowo bii ṣẹkẹrẹ.
Oríṣun àwòrán, Instagram/chairmanhkn
Ninu oṣu keje ọdun 2019 ni Adewale dẹnu ifẹ kọ Kani eyi ti ọmọbinrin naa si ni ko si ṣiṣe ko ṣai ṣe, Adewale loun yoo ba lọ.
Gbogbo iyoku ti di itan bayii, Adewale ati Kani ti di lọkọlaya.
Oríṣun àwòrán, Instagram/chairmanhkn
Sandra Ikeji ati Arinze Samuel
Ọjọ kọkanla oṣu kinni ọdun 2020 ni Sandra Ikeji di aya lọọdẹ ọkọ rẹ, Arinze Samuel.
Oríṣun àwòrán, Instagram/sandraikeji
Yollywood: Sinimá Ajé Ọjà tún so Fathia àti Saheed Balogun pọ̀ nínú Sinimá
Oríṣun àwòrán, Instagram/sansraikeji
Anita Joseph ati MC Fish
Ọjọ kẹrinla oṣu keji ọdun 2020 ni Anita Joseph ati MC Fish ṣe igbeyawo niluu Eko.
Oríṣun àwòrán, Instagram/anitajoseph
Gbẹgẹdẹ gbiná! Toyin Abraham fẹ́ wọ́ Lizzy Anjọrin lọ sílé ẹjọ́
Àwọn òṣèré Nollywood tí wọn ò sí lóri amóhùmáwòrán mọ́
Àwọn fíìmù Nollywood ń mú kí òògùn owó àti ìjínigbé gbilẹ̀ síi - Fashola
Díẹ̀ lára àwọn òṣèré Nollywood ti wọ́n ti ṣe ìgbéyàwó lẹ́ẹ̀kejì
Oògùn olóró cocaine ni Toyin Abraham fi ń sayé - Lizzy Anjorin
Wọ àwòrán àwọn ẹbí òṣèré Nollywood yii!
Kíni ẹ mọ̀ nípa àwọn gbajúgbaja Yollywood?
Oríṣun àwòrán, Instagram/anita joseph
Kayode Adebayo ati Oluwafunmilayo Adebayo
Ọjọ keje oṣu kẹta ni Kayode Adebayo ṣe igbeyawo ti wọn si di lọkọ laya.
Oríṣun àwòrán, Instagram/officialkayodebowale
Òṣèré tíátà Toyin Abraham daya Kolawole Ajeyemi
Lẹ́yìn tí mo gbé ayé mi yẹ̀wò, mo ríi pé asán layé - Toyin Abraham
Iyabo Ojo, Toyin Abraham, Mercy Aigbe, ta làwọn òṣèrébìnrin yìí gbè lẹ́yìn lórí ọ̀rọ̀ ìfipábánilòpọ̀?
Ọkọ mi kò fẹ́ràn oúnjẹ òyìnbó àfi ti ìbílẹ̀ - Lizzy Anjorin
Òṣìṣẹ́ ológun Navy ni mí àmọ́ àwàdà ayélujára ló sọ mí di olókìkí - Cute Abiola
Ó ń bọ̀ lọ́nà! Odunlade Adekola, Femi Adebayo, Jenifa ṣi aṣọ lójú àwọn fíìmù tuntun tẹ́ẹ ti ń retí
Oríṣun àwòrán, Instagram/officialkayodeadebayo
Seilat Adebowale ati Adeyemo Olalekan
Oríṣun àwòrán, Instagram/seliat adebowale
Oríṣun àwòrán, Instagram/seliat adebowale
Lawuyi Ogunniran, àgbà ọ̀jẹ̀ òǹkọ̀wé Eégún Aláré dágbére fáyé!
Oríṣun àwòrán, @Oladapo
Agba ọjọ ninu onkọwe lede Yoruba kan tun ti ki aye pe o digbose!
Àjànàkú sùn bí òkè, erin wó kò le dìdi.Gbajúgbajà òǹkọ̀wé èdè Yorùbá, Lawuyi Ogunniran tí gbogbo àwọn olólùfẹ́ ìwé ìtàn Yorùbá mọ̀ sí Eégún Aláré ti dágbére fún ayé ní ẹnì ọdún márùnlélọ́gọ́rin.
Awọn ẹbi oloogbe ni Baba ko ṣaisan rara ki ọlọjọ to de.
Wọn ni koko ko ni ara ọta le, ati pe Baba Lawuyi ṣi ba ninu wọn sọrọ ni aarọ ana ki ọlọjọ to kan ilẹkun ni ọjọ kọkanlelogun, osu kẹsan an.
Ọpọ awọn onkọwe lo n ṣe idaro Baba Lawuyi Ogunniran ti ọpọ n pe ni Eegun Alare re ibi agba n re lẹni ọdun marunlelọgọrin.
"Bí ẹ ṣe mọ̀wé tó, ẹ wá dánrawò níbí pẹ̀lú ""Àpólà Ọ̀rọ̀ Orúkọ - Noun Phrase"
Wọn ṣapejuwe baba ni Olufọkansin tootọ, Ọrẹ atata, Baba rere to huwa igbe aye atata to tun jẹ abinu funfun bi ẹmu
Abule Ado explosion: Irọ́ ńlá ní NNPC pa lórí ìbúghbàmù Abule Ado níbí tí ẹ̀mí èèyàn 23
Lára àwọn ìwé tí olóògbé Lawuyi Ogunniran kọ nígbà ayé wọn ní wọ́nyí:
Àrẹ Àgó
Aríkúyẹrí
Awọn iwe miran ti Oloogbe Lawuyi Ogunniran tun kọ ni:
Ọmọ Alátẹ Ìlẹ̀kẹ̀
Níbo Láyé Dori kọ?
Oríṣun àwòrán, @Oladapo
Awọn iwe miran ti Lawuyi Ogunniran kọ ni:
Ìbàdàn Mesì Ọ̀gọ̀.
Atari ajanaku
Olọrun o mawada
Awọn ẹbi ni àwọn yoo kéde ètò ìsìnkú láìpẹ́.
Akomolede ati Aṣa lori BBC: Mọ̀ si nípa oríṣìí ẹ̀ka ìsọ̀rí ọ̀rọ̀ àti ìwúlò wọn
Bẹẹ lawọn eeyan miran tun ki oriki iku pe o tun ti doro bi o se maa n daa: Ikú dóró ikú ṣìka pẹlu adura pe ki baba Sùn un re ó.
Ó tún dàrìnnàkòÓ tún dojú àláÓ tún di bẹ́ni jọ́niÓ tún di béèyàn jọ̀ọ̀yàn.Ó dìgbà o baba
Oríṣun àwòrán, @Ladapo
Àjànàkú sùn bí òkè, erin wó kò le dìde.
Gbajúgbajà òǹkọ̀wé èdè Yorùbá, Lawuyi Ogunniran tí gbogbo àwọn olólùfẹ́ ìwé ìtàn Yorùbá mọ̀ sí Eégún Aláré ti dágbére fún ayé.
Awọn miran ni Bónírèsé Lawuyi ò fíngbá mọ́ èyí tó ti fín ò lè parun. Sùn un re o, baba
Oríṣun àwòrán, @Ladapo
Àjànàkú sùn bí òkè,Erin ṣubú kò leè dìdeLáwuyì ònígègé àràSùn-ùn-re o!
Ki Olorun ko dẹlẹ fun agba ọjẹ onkọwe yii ni adura BBC Yoruba
Akomolede ati asa Yoruba: Ẹ wá kọ́ nípa àpòtí ìṣura èdè wa lórí BBC Yorùbá
Mali transitional leaders: Bah Ndaw àti Assimi Goita ni wọ́n ní kó máa wa ọkọ̀ orílẹ̀-èdè Mali báyìí
Oríṣun àwòrán, @Lima
Minista to wa fun eto aabo lorilẹ-ede Mali tẹlẹ, Bah Ndaw ni wọn ti yan lati wa ọkọ orilẹ-ede naa fun ọdun kan ati aabọ gẹgẹ bi aarẹ to maa da eto iṣejọba pada sipo nibẹ.
Lọjọ Aje ni wọn fẹnuko pe ki oun ati Assimi Goita wa ọkọ orilẹ-ede naa de ibi oge nipa eto iṣelu.
Ogagunfẹyinti ni N'Daw jẹ ko to gba ipo yii  ni Mali.
Assimi Goita naa jẹ ọgagun, oun naa lo wa nidi bi awọn ologun ṣe gba ijọba loṣu to kọja ni Mali.
Assimi ni wọn ni ko jẹ igba keji Ogagunfeyinti Bah N'Daw bayii.
Abule Ado explosion: Irọ́ ńlá ní NNPC pa lórí ìbúghbàmù Abule Ado níbí tí ẹ̀mí èèyàn 23
Awọn mejeeji ni amuyẹ lati tukọ orilẹ-ede Mali ni asiko yii.
Diẹ lara amuyẹ naa ni pe adari asiko yii gbọdọ wa lati Mali, ko jẹ ẹni ọdun marundinlogoji si aadọrin ọdun, to maa ni iwa ọmọluwabi ti kii si fi ẹtna ṣe lawujọ.
Koda, amuyẹ miran ni pe ẹni naa ko gbọdọ ni ẹjọ iwa ọdaran nile ẹjọ.
Awọn amuyẹ yii naa ni ofin to de awọn minista ati awọn to ku ti wón maa yan sipo lati jọ ṣiṣẹ papọ.
Lasiko ipade ajọ ile Afirika, ECOWAS ni wọn ti fun awọn ọmọ ogun to gbajọba ni orilẹ-ede Mali  ni gbendeke ọjọ kẹẹdogun, oṣu késan an yii lati gbe ijọba silẹ fawọn alagbada.
Ogbologbo ijapa l'aafin Sọun
Police Clash: Ọlọ́pàá kọlu àwọn ọmọ onílẹ̀, ní ìbọn àṣìyìn bá pa ènìyàn méjì
Oríṣun àwòrán, Google
Rogbodiyan bẹ silẹ ni ilu Ikogbo ni ijọba ibilẹ Ado-Odo/Ota ni ipinlẹ Ogun lẹyin ti ibọn aṣiyin pa eniyan meji, ti ọpọlọpọ si farapa.
Awọn ti ọrọ naa ṣoju wọn ni ilu Ikogbo ati Imoṣe n ja si ọrọ ilẹ ni iṣẹlẹ naa waye.
Wọn fikun un wi pe ileẹjọ to paṣẹ ki wọn gbe ilẹ naa fun ilu Ikogbo lo da ija silẹ laarin wọn.
Gẹgẹ bi ọrọ awọn to wa ni ibi iṣẹlẹ naa, Onikogbo ti Ikogbo, Oba Nurudeen Osoja, pe awọn ọlọpaa lati wa fidi idajọ ileẹjọ mulẹ,ki wọn si pari aawọ to wa laarin ilu mejeeji.
Amọ, bi awọn araalu ọhun ṣe faraya lo mu ki awọn ọlọpaa bẹrẹ si ni yinbọn to si ba ọlọkada kan to n bọ lati ọja ati awọn ọmọ ileewe to n kọja, ti ọkan lara wọn si ku latari ọta ibọn to ba a.
Nibayii, ileeṣẹ ọlọpaa ni awọn ti fi panpẹ ọba mu awọn ọdọ mẹrin ti iṣẹlẹ naa ṣoju wọn, ati wi pe iwadii ti bẹrẹ ni pẹrẹwu lori iṣẹlẹ naa.
SS3 ní mo wà báyìí, mo sì ti gba àmì ẹ̀yẹ̀ púpò nílé-lóko gẹ́gẹ́ bí onílù - Ayansike
Agbẹnusọ ileeṣẹ ọlpaa nipinlẹ Ogun, Abimbola Oyeyemi fi idi iṣẹlẹ mulẹ, amọ o ni awọn araalu pe awọn ọlọpaa sibẹ lati pari aawọ to bẹ silẹ.
Amọ o ni awọn ọmọ onilẹ to fẹ gba ibọn lọwọ awọn ọ̀lọpaa lo yin ibọn to ba awọn eniyan meji to ba iṣẹlẹ naa lọ.
Onyinye Onwuka, ẹni ọgbọn ọdun ni wọn ti yinbọn pa lẹyin ti ija lori ẹni to ni ilẹ bẹ silẹ laarin iilu meji, Obodogwugwu ati Ugbolu ni ijọba ibilẹ Oshimili ni ipinlẹ Delta.
Iroyin fi lede wi pe Onyinyeeniyan ti wọn ko mọ yinbọn pa ni Ọjọ Aiku wa lati agbegbe Idigbe-Ocha ni agbegbe Okpanam.
Oríṣun àwòrán, @Police
Awọn ti iṣẹlẹ naa soju wọn ni lasiko ti ija n waye laarin awọn ọdọ lati ilu Ugbolu ti ko jinna si wọn ni wọn yinbọn pa Onyinye.
Ọpọlọpọ ọdun ni ija ti n waye laarin awọn adugbo mejeeji naa ti ko si ni iyanju tit di asiko yii.
Ọdun mẹrin sẹyin ni awọn ara agbegbe Ugbolu gbe ọrọ naa lọ si ileẹjọ ti wọn si jẹbi bọ lẹyin ti adajọ sọ wi pe awọn ara Idigbe-Ocha quarters, Okpanam lo ni ilẹ naa.
Ninu ọrọ tirẹ, agbẹnusọ fun ileeṣẹ ọlọpaa nipinlẹ Delta, DSP Onome Onovwakpoyeya sọ wi pe lootọ ni iṣẹlẹ naa waye, ti awọn si ti bẹrẹ iwadii lori iṣẹlẹ naa.
Onovwakpoyeya fikun un wi pe ohun ti awọn gbọ ni wi pe nitori ọrọ ilẹ ni wọn ṣe pa ọkunrin naa.
Ati wi pe nibayii, awọn ko i tii fi panpẹ ọba mu ẹnikẹni, amọ awọn eniyan wa ti bẹrẹ igbesẹ to tọ lati mọ awọn to wa ni idi iṣẹlẹ naa.
Toyin Atoyebi mechanic: Ẹ wo Toyin, ọmọbinrin ọdún 16 tó ń tún skadà àti gẹnẹrátọ̀ ṣe ní
Akomolede àti Aṣa: Ọ̀rọ̀ Ẹ̀yán ni Bunmi Femi Amao ń kọ́ wa lórí ètò Akọ́mọlédè àti Àṣà lórí BBC Yorùbá
Ẹyan oríṣi meje ló wa ninu girama ede Yoruba.
Arabinrin Bunmi aya Femi Amao lati ile iwe Graceland Heights School ni agbegbe Wọfun, Olodo ni ilu Ibadan ni ipinlẹ Oyo ni olukọ wa fun toni.
Ọrọ Ẹyan ni koko girama ti an gbe yẹwo loni.
Ẹyan Asapejuwe ni o maa n sọ fun wa sii nipa ọrọ orukọ.
Eto Akomolede ati Asa yii n waye lati ọwọ BBC Yoruba pẹlu ajọṣepọ ẹgbẹ Onimọ Yoruba YSAN ati apapọ ẹgbẹ Akomolede Naijiria.
Oriṣi ẹyan meje to wa ni olukọ Bunmi Femi Amao kọ wa loni.
Eyan Ajorukọ
Ẹyan Aṣapejuwe
Eyan Asorukọ
Eyan Atọka Aṣafihan
Eyan Aṣonka
Eyan Arọpo Orukọ
Eyan Afarajorukọ
Eyan Awẹ gbolohun Afarahe Aṣapejuwe.
Wo ohun tí òṣìṣẹ́ yí ṣe tí ọ̀gá rẹ̀ fi fún ní ẹ̀bùn owó £10 mílíọ̀nù
Oríṣun àwòrán, @others
Ọga ileeṣẹ kan fun ọmọiṣẹ rẹ to n fẹyinti ni ẹbunowo miliọnu mẹwaa pọun owo ilẹ Gẹẹsi lati fi sami ifẹyinti rẹ.
Ẹbun owo ti a n sọrọ rẹ naa wa fun awon ọṣiṣẹ ẹgbẹrun meje ati ẹẹdẹgbẹta ileeṣẹ naa  to wa lagbegbe South Wales ati ẹgbẹrun mẹta to wa loke okun.
Ọga agba ileeṣẹ Admiral', David Stevens ati iyawo rẹ, Heather lo gbe ẹbun owo ifẹyinti naa kalẹ.
Awọn oṣiṣẹ kan yoo gba ẹbun owo ẹgbẹrun kan pọun, awọn miran yoo si gba ẹẹdẹgbẹta pọun.
Akomolede àti Aṣa: Ọ̀rọ̀ Ẹ̀yán ni Bunmi Femi Amao ń kọ́ wa lórí ètò Akọ́mọlédè àti Àṣà lóri BBC Yoruba
Ọgbẹni Steven pẹlu iyawo rẹ ni wọn jumọ da ileeṣẹ adojutofo ọkọ naa silẹ lọdun 1991.
O ni inu oun dun lati ba awọn oṣiṣẹ naa ṣiṣẹ pọ.
Lati dupẹ lọwọ awọn oṣiṣẹ naa lona ti a gba ṣe yii gan an ni ohun to tọ.
"O fi kun un pe ""itẹpamọṣẹ wọn ati ifọkansin lẹnu iṣẹ lo mu ki ileeṣẹ Admiral o tubọ goke agba sii lati ibẹrẹ titi di eyi to fi n ni oṣiṣẹ to le ni ẹgbẹrun mọkan bayii kaakiri agbaye."""
Olori ileeṣẹ naa tẹlẹ, Henry Englehardt lo ti koko fun ọkọọkan awọn oṣiṣẹ ileeṣẹ naa ni ẹgbẹrun kan pọun eyi ti apapọ rẹ bọ si miliọn meje pọun nigba to n fẹyinti lọdun 2016.
Oṣiṣẹ mẹtadinlọgọta ni ileeṣẹ naa fi bẹrẹ gẹgẹ bi ileeṣẹ to n fi ẹ̀rọ ibanisọrọ foonu ta eto adojutofo fawon onibara wọn.
Hisbah mú ọkùnrin mẹ́ta tó pín fídíò ìfipábánilòpọ̀ ọmọdébìnrin 16 tó fẹ́ ṣèyàwó lórí ayélujára
Oríṣun àwòrán, Twitter/@ahmad
Ileeṣẹ agbonfinro ṣeria, Hisbah nipinlẹ Sokoto ti mu afurasi mẹta lori ẹsun pe wọn pin fọnran kan nibi ti wọn ti n dunkoko mọ ọmọdebinrin ọdunmẹrindinlogun kan lati fipa ba a lopọ.
Ọmọdebinrin naa ni a gbọ pe o mura lati ṣe igbeyawo lọjọ kẹtadinlogun oṣu kẹwaa ọdun 2020 yii tẹlẹ.
Ṣugbọn o wọgile igbeyawo ọhun nitori fidio tawọn afurasi naa pin kaakiri ori ayelujara.
Ọga awọn agbofinro Hisbah nipinlẹ Sokoto, Ọmọwe Adamu Kasarawa sọ fawọn akọroyin wi pe ọmọ eekan lagbo oṣelu ni ọkan lara awọn afurasi mẹta ọhun.
O ni awọn ti pari iwadii lori iṣẹlẹ naa, wọn o si foju ba ileẹjọ laipẹ.
Mama ọmọdebinrin naa ṣalaye pe lọdun 2017 ni ọkan lara awọn afurasi fipa ba ọmọ oun lopọ nigba to wa lọmọ mọdun mẹrindinlogun.
Iya ọmọ naa sọ pe ọdọkunrin naa fi fọnran ifipabanilopọ ọhun pamọ fun ọdun mẹta lati ba ọmọ ohun laye jẹ ni.
''Ogunjọ oṣu kẹfa ọdun 2020 yii ni ẹnikan ṣadeedee pe mi ti o si sọ fun mi pe oun ri fọnran kan kan ninu eyi ti Baffa Hayatu Tafida ti n fipa ba ọmọdebinrin lopọ,'' mama ọmọ naa lo sọ bẹẹ.
O ni afurasi naa tun fi fidio yii ranṣẹ si afẹsọna ọmọdebinrin yii atawọn mii lori ayelujara.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Mama ọmọdebinrin naa ṣalaye pe fidio yii gan an lo jẹ ki afẹsọna ọmọbinrin yii sọ pe oun ke ṣe mọ.
Mama ọmọbinrin sọ pe lọpọ igba ni baba  Tafida ti gbiyanju lati fa oju ọmọ oun mọ ra ki o le gbagbe ẹjọ naa.
Baba ọmọ ni lootọ ni iṣẹlẹ ọhun ṣẹlẹ, amọ oun ko figba kan dunkoko iku mọ iya ọmọdebinrin ọhun ko le fagile ẹjọ naa.
Abule Ado explosion: Irọ́ ńlá ní NNPC pa lórí ìbúghbàmù Abule Ado níbí tí ẹ̀mí èèyàn 23
OPC láwọn mú afurasí agbébọn ajínigbé mẹ́rin l'Oyo, ọlọ́pàá ní àpapọ̀ òṣìṣẹ́ elétò aàbò ló ṣiṣẹ́ náa
Oríṣun àwòrán, Gani Adams/facebook
Ẹgbẹ Oodua People's Congress, OPC ti kede pe awọn ti mu awọn agbebọn afurasi ajinigbe mẹrin lapa Oke Ogun nipinlẹ Oyo.
Oluṣakoso ẹgbẹ OPC nipinlẹ Oyo, Ọgbẹni Rotimi Olumo to fidi ọrọ yii mulẹ ṣalaye pe ibọn AK-47 mẹrin lawọn gba lọwọ awọn afurasi ọhun.
Ọgbẹni Olumo sọ pe awọn ti fi awọn afurasi ọhun le ileeṣẹ ọlọpaa ẹkun Igbeti lọwọ.
Ṣugbọn alukoro ileeṣẹ ọlọpaa ipinlẹ Oyo, Olugbenga Fadeyi ṣalaye fun BBC Yoruba pe apapọ awọn oṣiṣẹ eleto aabo pẹlu awọn fijilante lo jọ ṣiṣẹ pọ mu awọn afurasi mẹrin naa.
Nigba ti BBC Yoruba beere boya awọn ọmọ ẹgbẹ OPC wa ninu awọn to mu awọn agbebọn naa, alukoro ileeṣẹ ọlọpaa ipinlẹ Oyo ko le fidi rẹ mulẹ.
Akomolede àti Aṣa: Ọ̀rọ̀ Ẹ̀yán ni Bunmi Femi Amao ń kọ́ wa lórí ètò Akọ́mọlédè àti Àṣà lóri BBC Yoruba
''Ni nkan bii aago meje alẹ ogunjọ oṣu kẹsan an ọdun 2020 yii ni apapọ awọn oṣiṣẹ eleto aabo pẹlu awọn fijilante mu awọn afurasi mẹrin ọhun ninu igbo Igbeti lagbegbe Kisi,'' alukoro ọlọpaa lo sọ bẹẹ.
O ni mẹta lọwọ ba ninu wọn nigba ti awọn to ku sa lọ pẹlu ọgbẹ ibọn lara wọn.
Agbẹnusọ ileeṣẹ ọlọpaa ni awọn agbofinro ti fọn sinu igbo naa lati wa awọn yoku to sa lọ atawọn mii to ba tun wa ninu igbo naa.
NULGE election: Ẹgbẹ́ NULGE Oyo dìbò yan olóyè ẹgbẹ́ tuntun èyí tó tako àṣẹ iléẹjọ́
Oríṣun àwòrán, Twitter/Oyo
Ẹgbẹ awọn oṣiṣẹ ijọba ibilẹ NULGE, ẹka ti ipinlẹ Oyo, ti dibo yan awọn oloye igbimọ alaṣẹ tuntun fun ẹgbẹ naa.
Eto idibo ọhun to waye lalẹ tako aṣẹ ileẹjọ to sọ pe ki wọn si da etro idibo naa duro naa.
Adajọ N. C. S. Ogbuanya ti ileẹjọ to n ri si ọrọ awọn oṣiṣẹ ọba niluu Eko lo fote le eto idibo awọn oloye ẹgbẹ tuntun.
Ẹjọ to wa nile ẹjọ ọhun da le ẹjọ ti Ọgbẹni Hakeem Ojo Oyewo pe wi pe wọn yọ oun kuro gẹgẹ bi ọkan lara awọn oludije fun ipo aarẹ ẹgbẹ NULGE.
Ofin yii si wa sibẹ, bẹẹ ni ko si le jẹ ki wọn ṣe eto idibo miiran titi ẹjọ naa yoo fi ni iyanju nile ẹjọ.
Akomolede àti Aṣa: Ọ̀rọ̀ Ẹ̀yán ni Bunmi Femi Amao ń kọ́ wa lórí ètò Akọ́mọlédè àti Àṣà lóri BBC Yoruba
Amọ, ni idaji ni wọn dibo yan Kọmureedi Ayobami Olusegun Adeogun gẹgẹ bi alaga ẹgbẹ NULGE ipinlẹ Oyo.
Nigba ti wọn kde rẹ tan gẹgẹ bi ẹni to jawe olubori ninu eto idibo naa, Kọmureedi Adeogun ṣeleri pe oun ko ni ja awọn ọmọ NULGE kulẹ.
Alaga tuntun naa sọ pe oun ko ni ṣai maa tọ ipasẹ awọn to ti dipo olori mu ninu ajọ naa tẹlẹ.
O gbadura wi pe ki Eleduwa jẹ ki oun ruure ki oun sọ ọ 're.
Tolulope Arotile kú ṣùgbọ́n òrúkọ rẹ̀ kò parẹ́ mọ́ láí níléeṣé ọmọogun Nàìjíríà
Oríṣun àwòrán, Others
Gẹgẹ bi wọn ṣe ṣe ipinu lati ṣe ẹyẹ pataki ni iranti ajagunwakọ  ofurufu akọkọ ni Naijiria to gbẹmi mi loṣu diẹ sẹyin fun iṣẹ ribi ribi rẹ lati doju ija kọ awọn adigunjale atawọn ọdaran mii lorilẹede Naijiria.
Ileeṣẹ ogun oju ofurufu ti ṣeranti oloogbe Tolulope Arotile lonii
"Lọjọ kejilelogun oṣu kẹsan ni ileeṣẹ ogun oju ofurufu tun awọn yara ikọ ọmọogun to n jẹ ""Crew Room"" ṣe to wa ni 115 Special Operations Group ni ilu Port Harcourt ti wọn si sọ lorukọ Ajagun Tolulope Arotile."
Tolulope dagbere faye lọjọ kẹrinla oṣu karun ọdun 2020 lẹni ọdun mẹrinlelogun.
To fi mọ gbogbo yara idana, baluwẹ, ile ijẹun, yara iwọṣọ awọn awakọ ati ọpọlọpọ ile igbọnsẹ ni wọn tunṣe ti wọn fi sọ ọ lorukọ Tolulope Arotile.
Oríṣun àwòrán, Nigeria Airforce HQ
Nigba to n sọrọ nibi ayẹyẹ iranti yii, ọga awọn ọmọ ogun oju ofurufu, Ọgagun Sadique Abubakar ni awọn ṣe ẹyẹ yii fun oloogbe Arotile, kii ṣe ni iranti rẹ nikan ṣugbọn lati ṣe moriya fun awọn ọdọbinrin ni Naijiria lati kawe, ṣiṣẹ takun takun lati mu ala ire wọn ṣẹ.
Oríṣun àwòrán, Nigeria Airforce HQ
O wu ni lori lati sọ pe lẹyin iku oloogbe Tolulope, ọpọ ọdọbinrin lo ti fifẹ han lati darapọ mọ ọlogun ofurufu. Ọgagun Abubakar sọ bẹẹ.O ni awọn tun ṣe eyi lati fihan pe iṣẹ ire awọn eeyan ko gbudọ lọ lasan.
O tẹnu mọ ọ pe titi lai ni iranti Tolulope Arotile yoo wa lọkan awọn ologun.
Ninu atẹjade ti Ibikunle Daramola fọwọ si, awọn eeyan jankan jankan ninu iṣẹ ologun ati ni Naijiria lo peju sibi ayẹyẹ iranti naa.
Seyi Makinde: Àwọn obìrin tó dé láti Lebanon sọ ọmọ wọn tuntun jòjòló ní Seyi Makinde
Oríṣun àwòrán, Google
Idunnu subu lu ayọ fun awọn ara ipinlẹ Ọyọ lẹyin ti awọn obirin meji ti ori yọ lati ilẹ Lebanon sọ orukọ ọmọ tuntun jojolo ti wọn ṣẹṣẹ bi lorukọ Seyi Makinde.
Oluranlọwọ pataki fun Gomina ipinlẹ Oyo lori ọrọ awọn ọmọ ipinlẹ naa lokeere, Abilekọ Bolanle Sarumi-Aliyu ni inu awọn dun wi pe wọn sọ awọn ọmọ naa ni orukọ gomina Ṣeyi Makinde.
Sarumi-Aliyu to sọju gomina naa ni ibi isọmọlorukọ awọn ọmọ tuntun jojolo naa ni iṣẹ takuntakun ti gomina naa ṣe ko le di igbagbe fun ẹgbẹgbẹrun ọdun si isinyii.
Awọn ọmọkunrin jojolo naa ni wọn sọ ni Oluseyi Fahrihan ati Oluwaseyi Khalid.
Awọn iya awọn ọmọ naa dupẹ lọwọ gomina ipinlẹ Oyo, Seyi Makinde.
Koda, wọn gboriyin fun Alaga Ajọ to n risi ọrọ awọn ọmọ Naijiria ni oke okun, (NIDCOM), Abike Dabiri-Erewa ati awọn ajọ miran lagbaye ti wọn jẹ ko ṣeeṣe fun awọn obinrin yii lati pada si Niajiria lẹyin ọpọlọpọ ipọnju ti wọn la kọja ni Lebanon.
Sarumi ninu ọrọ rẹ ni o ṣe oun laanu wi pe ọpọlọpọ ọmọ Naijiria lo n la ipọnju kọja ni oke okun ti wọn wa, ti a ti wale si nira fun wọn.
O gba wọn ni imọran wi pe ko si ohun to dabi ile, ki awọn eniyan ye sa lọ si oke okun nitori wọn n wa ilẹ ọlọra.
Bakan naa ni o fi da awọn eniyan loju wi pe gomina Seyi Makinde n ṣiṣẹ takuntakun lati ri wi pe gbogbo awọn ọmọ ipinlẹ Oyo ti wọn fẹ wale lati okeere ni awọn yoo ranlọwọ lati ṣe bẹẹ.
Oluranlọwọ pataki fun Gomina ipinlẹ Oyo naa fikun wi pe ọpọlọpọ awọn ọmọ ipinlẹ naa ti wọn wa loke okun ni wọn n la ipọnju kọja nitori idẹyẹsini ati owo ẹru ti wọn n fi wọn ṣe.
Phone stealing: Iléẹjọ́ ní kí Yakubu gé oko àgọ́ ọlọ́pàá fọ́jọ́ méjì lẹ́yìn tó jí fóònù N8,700
Ileẹjọ majisireeti to wa ni Gwagwalada niluu Abuja ti dajọ pe ki ọmọkunrin kan Akeem Yakubu ge oko fun ọjọ meji ni agọ ọlọpaa to wa ni Gwagwalada.
Adajọ majisireeti Aliyu Shafa paṣẹ pe eyi ni iya ẹṣẹ Yakubu lẹyin to ji foonu ẹgbẹrun mẹjọ ati ẹdẹẹfbẹrin naira, N8,700.
Yakubu sọ fun ileẹjọ pe oun jẹbi ẹsun ole ti wọn fi kan oun, o ni lootọọ loun ji foonu, oun si ta a ni ẹgbẹrun marun un naira.
Yakubu ṣalaye pe aṣọ loun fi ẹgbẹrun marun un ti oun ta foonu ra.
Adajọ Shafa paṣẹ pe aago mẹwaa aarọ ni ki Yakubu maa bẹrẹ oko gige ni agọ ọlọpaa naa ki o si maa ṣiwọ iṣẹ laago meji ọsan.
Adajọ tun paṣẹ pe ki Yakubu pada si ọdọ awọn obi rẹ niluu Okene, nipinlẹ Kogi to ba ti pari ijiya ẹṣẹ rẹ.
Toyin Atoyebi mechanic: Ẹ wo Toyin, ọmọbinrin ọdún 16 tó ń tún skadà àti gẹnẹrátọ̀ ṣe ní
Adajọ majisireeti wa rọ Yakubu pe dẹkun iwa ibajẹ ti o ba ti bọ ninu eyi tan.
Nibi ti wọn ti fi foonu sina ko le gba ina sori batiri ni Yakubu ti jii gbe.
Agbẹjọro to ṣoju Yakubu nile ẹjọ, Yusuf Jibril rọ ileẹjọ lati jeburẹ lori ijiya ti wọn ba fẹ fun un.
Agbẹjọro Jibril sọ fun ileẹjọ pe Yakubu le di ọdaran nla ti ileẹjọ ba ran lẹwọn.
O ṣeeṣe ko jẹ wi pe ẹbẹ agbẹjọro rẹ lo jẹ ki adajọ fun ni ijiya ti ko pọju fun ẹṣẹ to ṣẹ.
Fuel price hike: Wo iye ìgbà tí ẹgbẹ́ òṣìṣẹ́ àtàwọn ọmọ Nàìjíríà ti ṣèwọ́de lórí àfikún owó epo bẹntírò
Oríṣun àwòrán, Twitter/@ayemojubar
Ẹgbẹ apapọ awọn oṣiṣẹ ni Naijiria, Nigeria Labour Congress(NLC) ti kede pe ohun yoo gunle iwọde lọjọ Aje ọjọ kejidinlọgbọn, oṣu kẹsan an lati fi ẹhonu han lori afikun owo epo bẹntiro ati ina ọba.
Igbimọ alaṣẹ NLC buwọlu igbesẹ igbimọ amuṣẹya ẹgbẹ naa lati bẹrẹ iwọde kaakiri orilẹede Naijiria lọjọ Aje to n bọ.
Lẹyin ti ijọba apapọ yọ owo iranwọ ori epo tan lo ṣe afiukun owo epo bẹntiro lati N145 si N161 to wa bayii.
Bakan naa ni ijọba kede afikun owo ina ọba lọna ilọpo meji eyi ti o mu ki ọpọ araalu ṣi maa ke pe inira nla lo jẹ fawọn.
Wọnyii ni iye igba ti ẹgbẹ oṣiṣẹ atawọn ọmọ Naijiria ti fẹhonuhan lori afikun owo epo bẹntiro lati ọdun 2003 ti Naijiria ti pada si ijọba awarawa.
Toyin Atoyebi mechanic: Ẹ wo Toyin, ọmọbinrin ọdún 16 tó ń tún skadà àti gẹnẹrátọ̀ ṣe ní
Ifẹhonuhan lori afikun owo epo ọdun 2003
Ẹgbẹ apapọ oṣiṣẹ, NLC labẹ olori rẹ nigba naa, Adam Osiomole gunle iyanṣẹlodi pẹlu iwọde lẹyin ti ijọba aarẹ Naijiria tẹlẹ ri, Olusegun Obasanjo ṣe afikun owo epo bẹntiro lati N26 naira lọ si N40.
Ijọba Obasanjo ṣalaye pe afikun owo epo waye nitori ijọba ṣe adinku owo iranwọ to wa lori ero.
Ijọba sọ pe ohun yoo na owo to ba jade lati ibẹ sori ẹka eto ẹkọ ati ilera.
Awọn oṣiṣẹ bẹrẹ iyanṣẹlodi pẹlu iwọde kaakiri orilẹede Naijiria.
Lọjọ kẹjọ oṣu keje ọdun 2003 lẹgbẹ NLC kede pe ohun wọgile le iyanṣẹlodi to gunle lẹyin to faramọ igbesẹ ijọba lati gbe owo epo si N34 lati N40.
Oríṣun àwòrán, Twitter/@ayemojubar
Ifẹhonuhan lori afikun owo epo ọdun 2004
Iyansẹlodi ati ifẹhonu han tun bẹrẹ lọdun 2004 lẹyin ti ijọba Obasanjo tun ṣe afikun owo epo bẹntiro lati N40 si N45.
Awọn ileewe, banki, ọfiisi ati ọpọlọpọ okoowo lo di titi pa lẹyin ti ẹgbẹ oṣiṣẹ NLC bẹrẹ iyaṣẹlodi kaakiri Naijiria.
Niluu Eko fun apẹẹrẹ, awọn olufẹhonukan bọ si oju titi ṣugbọn awọn ọlọpaa yin tajutaju soke lati tu wọn ka.
Awọn olori ẹgbẹ oṣiṣẹ sẹ ipade pẹlu ijọba Obasanjo, ṣugbọn ijọba fi aake kọri pe igbesẹ ohun ṣe pataki lati mu atunṣe ba ẹka eto ifọpo ni Naijiria.
Ifẹhonuhan lori afikun owo epo ọdun 2007
Ijọba Obasanjọ tun ṣe afikun owo epo bẹntiro lati N45 lọ si N70.
Eyi lo fa iyanṣẹlodi pẹlu iwọde kaakiri orilẹede Naijiria lọdun 2007.
Oríṣun àwòrán, Twitter/Omoyele Sowore
Gbogbo ileeṣẹ nla nla lo kogba sile, awọn oṣiṣẹ banki atawọn oṣiṣẹ ijọba ko lọ di ibi iṣẹ.
Lawọn agbegbe kan, awọn ọdọ n gba bọọlu loju titi lẹyin toju popo da paro paro.
Ijọba dunkoko mawọn ẹgbẹ oṣisẹ pe iyanṣẹlodi tawọn ẹgbẹ oṣiṣẹ gunle lodi si ofin, amọ wọn ni awọn ko ni wọgile iyanṣẹlodi ọhun ayafi ti ijọba ba mu afikun owo epo naa kuro.
Ijọba  aarẹ ana to ti di oloogbe, Umar Yar'Adua lo pada ṣe adinku owo epo naa, to si gbe lọ si N65.
Akomolede àti Aṣa: Ọ̀rọ̀ Ẹ̀yán ni Bunmi Femi Amao ń kọ́ wa lórí ètò Akọ́mọlédè àti Àṣà lóri BBC Yoruba
Ifẹhonuhan lori afikun owo epo ọdun 2012
Ọjọ kinni oṣu kinni ọdun 2012 ni ijọba Good luck Jonathan kede pe ohun ti mu owo iranwọ ori epo(subsidy) kuro.
Eyi lo mu ki ijọba gbe owo epo bẹntiro lọ si N141 lati N65, lẹyin naa lawọn eeyan bẹ sita ti wọn si bẹrẹ ifẹhonuhan kaakiri orilẹede Naijiria.
Oríṣun àwòrán, Twitter/@Ayemojubar
Ọjọta lawọn olufẹhonuhan fi ipade si niluu Eko, oniruuru awọn ajafẹtọ lo pade nibẹ nibi ti wọn ti n kọrin a ko nii gba si ijọba Jonathan leti.
Awọn sọja ni ijọba da sita lati le awọn olufẹhonuhan kuro loju titi kaakiri Naijiria.
O kere tan. akọsilẹ fihan pe eeyan mẹẹdogun lo ba iwọde naa lọ lọdun 2012.
LASEMA: Afẹ́fẹ́ gáàsì ṣe ìjàmba fún èèyàn 30, ilé 23,ọkọ 15 ní ìpínlẹ̀ Eko
Oríṣun àwòrán, Twitter/LASEMA
Ileeṣẹ pajawiri ti ni ko si ẹnikẹni to sọ ẹmi rẹ nu ninu ijamba ina afẹfẹ gaasi nipinlẹ Eko.
Ọjọ buruku ẹsu gbomimu lo jẹ fun awọn awọn eniyan agbegbe Balogun, Iju Ishaga nipinlẹ Eko ni Ọjọru.
Lẹyin ti ọkọ nla to n gbe afẹfẹ gaasi gbina to si jọ ile mẹtalelogun, ọja, ọkọ marundinlogun, ti eniyan ọgbọn si farapa ninu iṣẹlẹ naa.
Ajọ Lasema loju opo ikansiraẹni Twitter wọn ni awọn ọkọ nla to gbina naa gbe afẹfẹ gaasi wa si agbegbe naa ni ki o to gbina.
Awọn ọlọpaa, ileeṣẹ panapana ati ẹsọ alaabo NSCDC lo yara de ibi iṣẹlẹ naa ti wọn si pa ina naa, lẹyin to ti ṣọṣẹ.
Ajọ Lasema naa fikun wi pe awọn eniyan ọgbọn to farapa naa ti wa ni ileewosan kaakiri ipinlẹ Eko.
''Nigba ti awọn meji ti ifarapa wọn lagbara ti wa ni ileewosan ekọṣẹ ti ile iwa giga,Lagos State University Teaching Hospital,ni Ikẹja.''
Bakan naa ni wọn fikun wi pe ko si ẹmi ẹnikẹni to sọnu ninu ijamba ina naa.
Ọ̀pọ̀ èèyàn àti akẹ́kọ̀ọ́ pàdánù ẹ̀mí wọn sínú ìjàmbá iná ni ojú ọ̀nà Lokoja sí Abuja
Awọn eeyan kan ti padanu ẹmi wọn lẹyin ti ọkọ kan to gbe epo bẹtiro gbina ni Felele, loju ọna Lokoja si Abuja.
Ni nkan bi aago mẹjọ aabọ owurọ Ọjọru ni iṣẹlẹ naa waye.
Awọn ọmọ ileewe, to fi mọ awọn akẹkọọ ileewe Gbogbonise 'polytechnic' ti ipinlẹ Kogi to wa ni tòsí ibi ti ijamba naa ti waye, wa lara awọn to kú.
Iroyin fidirẹmulẹ pe ọkọ agbepo naa lo kọlu ọkọ miran nitosi GT Plaza, gbajugbaja ile oúnjẹ kan to tun jẹ ibudokọ fun awọn ọkọ to n lọ lati ipinlẹ
Kogi si ibomiran, to si gbina loju ẹsẹ.
Ijamba naa tubọ buru kọja bo ṣe yẹ nitori bi awọn ọkọ miran to n bọ tun ṣe n wọ inu ijamba naa lai mọ.
Bakan naa ni iwe iroyin The Nation sọ pe ọkọ to jona le ni mẹwaa.
Ni bayii, awọn oṣiṣẹ alaabo ojupopo, FRSC, ati panapana ti wa nibi iṣẹlẹ naa.
Àwọn aláṣẹ orílẹ̀-èdè Saudi Arabia ti kéde pé ètò Umrah yóò bẹ̀rẹ̀ padà lẹẹ́yìn oṣù bí mẹ̀fà ti wọ́n ti fòfide e
Oríṣun àwòrán, Others
Ijọba sọ pe lati ọjọ kẹrin, oṣu Kẹwaa ni awọn to n gbe ni orilẹ-ede naa yoo ni anfaani lati bẹrẹ eto adura Umrah, ti awọn to n gbe nilẹ okeere yoo
si le bẹrẹ ti wọn ni ọjọ kinni, oṣu Kọkanla.
Sugbọn ṣa, wọn ni adinku yoo ba iye eeyan to le kóra jọ pọ lẹẹkan naa. Bakan naa ni yoo loju àwọn ọmọ orilẹ-ede ti wọn yoo gba laaye lati kopa.
Ileesẹ to wa fun ọrọ abẹle ni Saudi Arabia ni ti ajakalẹ aarun coronavirus ba ti kasẹ nilẹ ni wọn o to o gba gbogbo eeyan laaye jakejado agbaye.
'Èmi gan máa ń béèrè lọ́wọ́ ara mi pé ta ni Wole Soyinka gangan'
Ọdọọdún ni awọn Musulumi kaakiri agbaye ma n lọ si orilẹ-ede Saudi Arabia fun eto adura Umrah, to jẹ irinajo mimọ keji ninu ẹsin Isilaamu.
Àmọ́ o, asiko to ba wu ẹni kọọkan lo le rinrinajo naa, yatọ si Hajj to jẹ ẹẹkan lọdun.
Ẹgbẹrun mẹwaa eeyan pere lo kopa ni Hajj ọdun 2020, dipo bi miliọnu meji to ma n kopa lọdọdun.
Lara ilana ti awọn alasẹ tun la silẹ ni pe ẹgbẹrun mẹrin eniyan ni yoo le kopa lojoojumọ fun Umrah lati ọjọ kinni, oṣu Kẹwaa.
Ti yoo si di ẹgbẹrun lọna ogun ninu oṣu Kọkanla, ti wọn ba ti ṣi anfaani silẹ fun awọn ọmọ ilẹ okeere.
Big Brother Naija Lockdown season: Ṣé èèwọ̀ ni kí Vee fọ pátá olólùfẹ rẹ̀ ni?
Oríṣun àwòrán, BBNaija
Awọn ololufẹ eto agbelewo Big Brother Naijiria to n lọ lọwọ ti  tu sita  lori ayelujara lati sọrọ takorawọn lori pe boya wọn lee fọ pata ololufẹ wọn bii ti Neo, akopa eto BBNaija to n fọ pata akopa ẹlẹgbẹ rẹ, Vee lori eto.
Sebi, ọrọ ifẹ bi adanwo ni lo difa fun bi o ṣe  ba Nengi to jẹ  olori ile bayi nile ẹlẹgbọn agba lojiji nigba to gbọ pe Neo n fọ pata Vee.
Neo ati Vee nikan ni ololufẹ meji ti ida Big Brother ko ti bẹ irẹpọ wọn si meji pe ki eeyan kan kọri sile, wọn ti wa yege lati wa lara awọn marun to kẹyin nile ẹlẹgbọn agba bayi lẹyin ti  ori yọ wọn pe wọn o le wọn lọ sile lọsẹ to kọja.
Toyin Atoyebi mechanic: Ẹ wo Toyin, ọmọbinrin ọdún 16 tó ń tún skadà àti gẹnẹrátọ̀ ṣe ní
Ninu fidio tawọn eeyan rọra ge lara eto naa to gba ori ayelujara kan, ẹrọ ayaworan ṣafihan Neo to n fọ aṣọ nigbati Nengi ati  Vee n wo o.
"Ọrọ ko ba tilẹ ma han sita bi ko ṣe igba ti Vee sọ pe ""Ololufẹ mi, ko ma si pata kan ninu aṣọ, ọrọ naa ba ṣe oju Nengi wara  wara to ya a lẹnu."
"Nengi kọkọ ka a sara ko sọrọ, nigba to ya lo ba fọhun pe ""Neo, ṣe pe o tun n fọ pataaa, haaa!Vee naa ba da a lohun pe  ""Neo mi gan mọ pe onimọtoto ni""."
Nengi wa sọ fun Neo pe o yẹ ẹ gan o.Iṣẹlẹ yii ti n mu ki ọpọlọpọ ọmọ Naijiria fọn ti wọn si ti n fesi.
"Awọn esi wọn n pa ni lẹrin jọjọ, ṣe ẹ mọ pe bi igbati o n ṣẹlẹ lẹyinkunle wọn lawọn to n wo eto naa ṣe maa n sọrọ...@Zoeman ni ""aṣe o tilẹ tun lẹnu lati sọ pe o ku pata kan, ara ni yoo san pa pata kan ọhun""."
"O ni arifin Neo ma pọ o.@Iamemzy ni ""Jeeesu, Neo n fọ pata, kilode tawọn ọkunrin maa n doju ti mi bayii lẹnu ọjọ mẹta""...@emmanueladem naa sọ loju opo Twitter pe o yẹ Vee gan o pe koda Ozo gan ko ṣe to bẹẹ."
LayhconOriṣiriṣi ọrọ ni awọn ololufẹ eto ori amohunmaworan BBNaija season 5 ti n sọ lẹyin ti ọkan lara awọn olukopa to de ipele asekagba, Laycon sọ pe SC ni jẹnotaipu oun.
Iroyin sọ pe alẹ ọjọ Aje ni Laycon sọ fun awọn akẹẹgbẹ rẹ lasiko ti wọn n jiroro.
Sugbọn kii gan-an ni iyatọ to wa laarin aisan aromọleegun 'Sickle Cell' SS ati SC?
Ọna kan naa ti eeyan n gba jogun eroja SS, ni ẹni to ba ni SC n gba jogun ti wọn naa lati ara awọn obi wọn.
Awọn kan wa to ni eroja SC yii to jẹ pe aisan sickle cell ma n jẹ jade ni ara wọn.
Eroja ara Hemoglobin SC yii ni aarun aromọleegun sickle cell keji to wọpọ julọ.
O si ma n waye ti ọmọ ba jogun eroja Hb C lara obi kan, ati Hb S lara òbí keji.
Botilẹjẹ pe àpẹẹrẹ kan naa ni ẹni to ni SC ati SS ma n ni, ipa ti SC ko fi bẹ ẹ l'agbara pupọ.
Onimọ eto ilera kan ṣalaye pe lootọ ni aridaju ko fi bẹ ẹ si lori bi ẹni to ba ni SC yoo ṣe pẹ laye to, o ni o yẹ ki ẹmi wọn ko gùn, ti wọn ba mojuto ilera wọn daadaa.
Bakan naa lo sọ pe àṣìṣe nla ni ti ẹni to jẹ SC ba fẹ SS tabi SS ni ọkọ tabi iyawo.
Ẹ̀jẹ̀ ara 'red blood cells, RBCs' ni aarun aromọleegun sickle cell ma n ba a ja, eyi ti wọn n pe ni sickle cell anaemia. Ó si jẹ ajogunba lati ara obi si ọmọ.
Fun ẹni ti ara rẹ ba dape, ni ṣe lo yẹ ki eroja red blood cell naa ri roboto, eyi to ma n mu ki o rọrun fun lati gba inu ọ̀pá to n gbe ẹjẹ.
Sugbọn fun ẹni to ba ni aarun aromọleegun sickle cell, eyi ko ribẹ. Ni ṣe ni ti wọn ma n da bi akọ́rọ́, ti wọn fi n kore ni oko.
Eyi si ma n mu ki wọn o di ọna ti ẹ̀jẹ̀ n gba lọ sinu àwọn ẹ̀yà ara. O si le fa irora.
Àwọn ami ti aarun aromọleegun sickle cell ma n fihan
Nigba ti ọmọ ba wa ni kekere, ni ami aarun sickle cell ti ma n jade ni ara. O le jẹ lati ọmọ oṣu mẹrin, sugbọn kii saba kọja oṣu mẹfa.
Bo tilẹ jẹ pe oriṣiriṣi ni aarun yii, ami kan naa ni gbogbo wọn ni. Bi wọn ṣe l'agbara to lo yatọ.
Diẹ lara wọn ni :
Ki aarẹ ko ma a mu ara, aito ẹjẹ ninu ara, iba apọnju 'jaundice', ọwọ ati ẹsẹ ẹni naa yoo wu, yoo si fa irora.
Bakan naa ni orisirisi aarun yoo ma ṣe ẹni naa ni gbogbo igba
Àyà, ẹyin, apá ati ẹsẹ yoo ma dun ẹni naa.
Iwo Kingmakers: Ìjọba Osun ní òun sí ń wo ọ̀rọ̀ Oluwo àtàwọn afọbajẹ lọ́wọ́ kó tó mọ ìgbésẹ̀ tó kàn
Oríṣun àwòrán, Oluwo/instagram
Yoruba ni agba kii wa lọja, kori ọmọ tuntun wọ, bẹẹ si ni agbalagba ti ko ba kẹu sọrọ, afaimọ ko ma kẹtan sare.
O ti to ọjọ mẹta bayii ti iporogan ti n waye laarin Oluwo tilu Iwo, Ọba Abduilrasheed Adewale Akanbi ati awọn afọbajẹ ilu naa.
Idi ni pe awọn afọbajẹ yii lo n kesi ijọba ipinlẹ Osun pe ko yọ Ọba Akanbi kuro nipo ọba nitori awọn ohun kan to tọkasi bii asemase rẹ.
Bi Oluwo se n salaye tirẹ, naa ni awọn ijoye, afọbajẹ ati araalu lapapọ ko sinmi lori awijare tiwọn naa, ti laasigbo naa si n fọnna soju lojoojumọ.
Lọwọ lọwọ bayii, Oluwo ti gbe awọn afọbajẹ naa lọ sile ẹjọ, ti awọn afọbajẹ naa si ti gbe Oluwo lọ sile ẹjọ miran.
Oríṣun àwòrán, Oluwo/instagram
Sugbọn bi eruku laasigbo naa se n sọ lala to nilu Iwo, ijọba ipinlẹ Osun ko fọhun rara lori ọrọ naa, titi to fi de ile ẹjọ bayii.
Idi ree ti BBC Yoruba fi kan si ijọba Osun lati gbọ tẹnu wọn lori isẹlẹ ọhun nitori bawọn ọmọde ba n ge igi ninu igbo, awọn agba lo maa n mọ ibi ti igi naa yoo wo si.
Nigba to n jẹwọ pẹlu wa, Kọmiṣọna fun ileesẹ to n ri si ọrọ ijọba ibilẹ ati oye jijẹ ni ipinlẹ naa, Adeleke Yekini Adebayo ni ijọba ipinlẹ Osun si n ṣagbeyẹwo ọrọ naa.
Obateru Akinruntan: Wíwá ohun tá jẹ títí láé ló gbé wa kúrò nílé Ife
O ni wọn si n wo iwe ẹhonu ti awọn afọbajẹ ilu Iwo kọ mọ Oluwo, Ọba Abdulrasheed Adewale Akanbi, Telu Kinni, ki awọn to gbe igbesẹ kankan.
"Adebayo ni  ""Mo le e sọ fun yin ni kedere pe, ootọ ni wọn kọ iwe mọ Oluwo, ṣugbọn ijọba ṣi n yẹ iwe naa wo lọwọ."""
Kọmisana naa, ti ọpọ eeyan mọ si Banik sọ pe, ijọba ipinlẹ Osun ko tii gbe igbesẹ kankan lori iwe ẹhonu ọhun.
O ṣalaye pe, ijọba yoo wo iwe ọhun wo finni-finni ko to gbe igbesẹ kankan, ṣugbọn ni bayii, o ṣi n ṣagbeyẹwo rẹ ni.
Oríṣun àwòrán, Instagram/oluwoofiwoland
Kọmiṣona naa pari ọrọ rẹ pe, ijọba ipinlẹ Osun yoo kede igbesẹ to kan fun awọn eeyan ipinlẹ Osun, ni kete to ba ti ṣe ipinnu lori ọrọ naa.
Lọwọ lọwọ bayii, awọn afọbajẹ mejila nilu Iwo ti n rọ ile ẹjọ giga ijọba ipinlẹ Osun, lati da Oluwo lọwọkọ, ko maa baa rọ wọn loye.
Ninu iwe ipẹjọ oloju ewe mejila ni agbẹjọro awọn afọbajẹ naa, John Enworo, ti fẹsun kan Oluwo pe, o ti n gbe igbesẹ lati fi awọn eeyan miran rọpo awọn afọbajẹ ọhun.
Ṣaaju ni awọn afọbajẹ ọhun ti kọwe mọ Oluwo lọdọ gomina ipinlẹ Osun, iyẹn Gboyega Oyetola lọjọ kẹsan an, oṣu Kẹsan an, ọdun 2020.
SS3 ní mo wà báyìí, mo sì ti gba àmì ẹ̀yẹ̀ púpò nílé-lóko gẹ́gẹ́ bí onílù - Ayansike
Wọn wa n rawọ ẹbẹ pe ko gba ade ọba lori Oluwo, nitori awọn iwa kobakungbe ti wọn fi kan an.
O ti to nnkan bi ọjọ mẹta kan ti eruku aawọ ti n waye laarin Oluwo ati awọn afọbajẹ naa to taku pe lilọ ni Oluwo gbọdọ lọ fun awọn.
Wayii, awọn afọbajẹ ọhun ti ke gbajare si ile ẹjo giga ipinlẹ Osun, lati dẹkun Oluwo ninu yiyẹ aga oye mọ awọn nidii.
Ki lo ti ṣelẹ sẹyin?
Oríṣun àwòrán, Instagram/oluwoofiwoland
Ani ka jẹ ekuru ko tan, se ni wọn tun n gbọn ọwọ rẹ sinu awo, ni ọrọ ariwo pe wọn fẹ yọ Oluwo tilu Iwo lori oye, eyi to gba igboro kan.
Bẹẹ ba gbagbe, o ti to ọjọ mẹta bayii ti eruku aawọ ti n waye laarin Oluwo ati awọn afọbajẹ to taku pe lilọ ni Oluwo gbọọdọ lọ fun awọn.
Lara awọn Baalẹ to wa nilu Iwo, lasiko ti wọn n ba BBC Yoruba sọrọ ni, awọn eeyan kan to n se ilara Oluwo, Ọba Abdulrasheed Adewale Akanbi, Telu Kinni, lo n pariwo pe awọn fẹ rọ loye.
Bẹẹ ni Oluwo naa ti salaye pe iwa ajẹbanu lo n da awọn afọbajẹ to fẹ rọ oun loye laamu nitori pe awọn eeyan kan lo gbe owo fun wọn lati se bẹẹ.
Amọ asaaju afọbajẹ tilu Iwo, tii tun se Osa ilu naa, Oloye Yekeen Bello, lasiko to n bawọn akọroyin sọrọ salaye pe, bi Oluwo fẹ, bo kọ, lilọ ni yoo lọ lori oye naa.
Nigba to n salaye idi ti eyi yoo fi ri bẹẹ, Oloye Bello ni ọrọ owo tijọba n fun awọn , eyiun Oluwo, awọn ijoye ati Baalẹ lo fa jaadi yii nitori pe Oluwo fẹ maa da owo naa na.
Bello ni ohun to buru jai ni ki Ọba maa fun awọn ijoye ni ẹgbẹrun mẹta si mẹrin losoosu lati maa mu lọ sile, bẹẹ ni oun, Osa, si ni igbakeji rẹ nilana oye ilu Iwo.
Oríṣun àwòrán, Instagram/oluwoofiwoland
"Aarin awa ati Oluwo ko gun rara nitori naa la se n kọwe ẹhonu pe ki wọn yọ loye.
O ro pe a ko laju, o n sọ fun wa pe ka lọ wa isẹ mii se nitori Ọba nikan lo ni owo tijọba n fun wa losoosu, o ro pe a ko mọ bo se n lọ, ẹrin rẹ pa mi nitori ko tii mọ nnkan kan."
Osa ilu iwo fikun pe, ọpọ eeyan lo n kọwe ẹhonu nipa Oluwo ati awọn iwa to n hu, koda, ohun tawọn eeyan maa n sọ nipa rẹ lawọn oju opo ibanidọrẹ lori ayelujara ko bojumu rara.
Iwa rẹ n ko abuku ba ilu Iwo ati orilẹede wa Naijiria lapapọ, ti Ọba ba se bo se yẹ, ko si ẹni ti yoo sọrọ si, amọ ti Ọba ko ba bọwọ fawọn ijoye rẹ ati agbaagba ilu, ki lẹ ro pe yoo sẹlẹ gan.
Oríṣun àwòrán, Oluwo/Instagram
Oloye Bello tẹsiwaju pe ọpọ igba lawọn ti gba Oluwo nimọran, ti ko gbọ, awọn ko si le tẹsiwaju lati maa fara daa mọ nitori idojuti nla ni Oluwo n ko ba awọn.
Osa Iwo ni, nitori iwa abuku Oluwo yii ni wọn se ni ko lọ rọọkun nile ninu ipade igbimọ awọn lọbalọba nipinlẹ Osun.
O ni to ba si jẹ pe awọn fẹ gba eyi kanri ni, ọrọ naa ko ba ti bọwọ sori fun Oluwo amọ awọn kii se ọmọde nitori naa lawọn se fi ọwọ ẹrọ mu ọrọ ọhun nigba naa.
Yemen Water Child: Ọmọdé 44 ni Sọ́jà pa, tí 100 míì sì kú látọwọ́ ohun ìjà olóró
Osa wa fọwọ gbaya pe ori ohun tawọn sọ si lawọn wa o pe, lilọ ni Oluwo yoo lọ nitori pe o si n tẹsiwaju lati maa ba awọn ni orukọ jẹ, bẹẹ ni ko setan lati yanju aawọ naa nitunbi n nubi.
Oríṣun àwòrán, Gistube
Kabiyesi Oluwo ti ilu Iwo, Ọba Rasheed Akanbi ti jẹ ko di mimọ fun awọn to n pe fun irọloye rẹ pe ọdun mẹtadinlaadọrin lo ku fun oun lati lo lori oye gẹgẹ bi Oluwo.
Ilẹ poyi ni ilu Iwo lọjọ Ẹti lẹyin ti awọn afọbajẹ kan dide pẹlu iwe ẹhonu si ijọba ipinlẹ ṣun lati rọ Oluwo loye nitori ohun ti wọn pe ni awọn iwa aṣemaṣe rẹ lori oye.
Bi awsn kan ṣe n wọde tako igbesẹ awọn afọbajẹ naa lawọn araalu miran n sọ pe ohun to tọ si kabiyesi oluwo naa.
Ọdun mẹtadinlaadọrin lo ku funmi lori apere awọn baba mi . gọfa ọdun ni n o lo laye. Awọn to fẹ le mi kuro lori oye yoo nilo lati ṣe pẹlẹ daadaa nitori asiko mi niyi.
Iwo Kingmakers: Ìlú fẹ́milóye ni Ọba Abdulrasheed Akanbi- Ẹgbẹ̀ Baálẹ̀ Iwo
Ìwa jẹgúdú jẹra àti àjẹbánu ló ń da àwọn afọbajẹ ti wọ́n fẹ́ yọ Olúwo ọba Abdulraheed Akanbi nípò.
Ó ni àwọn kan to fẹ́ jẹ ọba ni wọ́n ń fẹ yọ Olúwo kúrò nípò, nítori ìwà ọ̀tẹ ni
Èyí ni ọ̀rọ̀ tí Báálẹ̀ ìlú papa Ademola Adegoke tó sójú gbogbo àwọn Baálẹ jákèjádò gbogbo ilú Iwo, tó sàlàyé pé, Ilúfẹmilóye ni Oluwo jẹ gbogbo àwọn ọmọ ilú ló sì wà ni ẹ̀yin rẹ.
Adegoke ni àwọn afọbajẹ náà ń fẹ́ ki Oluwo, Oba Abdulrasheed Akanbi  maa ta ilẹ̀ mọ́ àwọn ènìyàn Iwo lórí nítorí wọ́n ni owó kò tó .
Láìẹ́k yìí ní àwọn kan wọ́n sọ fún Kabièsí láti maa ta ilẹ̀. Bákan náà lo fi kun pé, láti ìgbà tí o ti de orí oyè ni wọn ti n lo àwọn afọbajẹ kógun tii.
Ẹ̀wẹ̀, Ilé iṣẹ́ BBC pe ọ̀kan lára àwọn afọbajẹ ti wọ́n buwọ́lu iwé ẹsùn Yekini Oosa ti wọ́n fi síta pé ki o sàlàye lórí ìdí tí wọ́n fi fk yọ Oluwo.
"Èsì tí o fún BBC ni pé""Gbogbo rẹ lo ti wa lóri ayélujára ki a lọ wòó níbẹ̀ àti pé kò síi ọ̀rọ̀ ti òun fẹ́ sọ síi"
Oluwo kọ̀ láti sọ̀rọ̀ lórí àwọn afọbajẹ tó fẹ́ yọ ọ́ nípò, aráàlú fọ́n síta láti fẹ̀hónú hàn
Oba AbdulRasheed Akanbi, Oluwo ti fesi sawọn Afọbajẹ mejila ti wọn kọwe si Gomina Gboyega Oyetola pe ko rọ Oluwo loye.
Nigba to ba BBC Yoruba sọrọ, Oluwo sọ pe ohun ko ni ọrọ kankan ti oun le sọ nipa ọrọ naa.
Amọ, ohun to sọ nipe awọn oloye kan buwọlu iwe ti awọn oloye naa kọ si Gomina ipinlẹ Oṣun, nigba ti awọn mii kọ lati buwọlu iwe naa.
O ni ọrọ naa tun kan ẹnikan to n wa oye lati ọpọ ọdun sẹyin ti ko ri.
Ẹwẹ, ọpọ araalu Iwu lo fọn sita lati fi ẹhonu han lori igbesẹ awọn oloye to fẹ yọ Oluwa ni ipo.
Ọpọ ninu wọn lo n sọ pe Oba AbdulRasheed Akanbi ti ṣe iranwọ nla fun awọn araalu.
Wọn ni ki Oluwa maa ba ijọba rẹ lọ wi pe o tẹ awọn lọrun.
Oríṣun àwòrán, Instagram/oluwoofiwoland
Wo ìdí tí àwọn afọbajẹ ìlú Iwo ṣe fẹ́ kí ìjọba ìpínlẹ̀ Osun rọ Oluwo l'óyè
Igbimọ ijoye mejila nilu Iwo, ipinlẹ Osun, ti kọwe si ijọba ipinlẹ naa, lati rọ Oluwo ti Iwo, Oba Abdulrasheed Akanbi, loye, fun 'awọn iwa adojutini to hu gẹgẹ bi ọba. Awọn ijoye naa to ko ara wọn jọ labẹ orukọ' Awọn afọbajẹ ti ọrọ ilu kan gbọn-gbọn', beere fun igbesẹ yii ninu iwe ẹsun kan ti wọn fi ránṣẹ si gomina ipinlẹ Osun, Adegboyega Oyetola. Awọn ijoye naa fi ẹsun kan Oba Akanbi pe o kede ara a rẹ gẹgẹ bi Olu Ọ̀ba 'Emperor', lẹyin ti wọn fi jẹ ọba lọdun 2016. Wọn ni orúkọ oye tuntun yii jẹ nkan ti awọn ko gbọ ri ninu itan ilu Iwo.
Akomolede àti Aṣa: Ọ̀rọ̀ Ẹ̀yán ni Bunmi Femi Amao ń kọ́ wa lórí ètò Akọ́mọlédè àti Àṣà lóri BBC Yoruba
Wọn fi kun ọrọ wọn pe Oluwo tun da awuyewuye silẹ lasiko to kede ninu oṣu Keje ọdun naa, pe gbogbo ọkunrin ilẹ Yoruba, ni itẹ Ooni Ile-Ife tọ si. Ko tan sibẹ o, àwọn ijoye naa tun fi ẹsun kan Oba Akanbi pe o doju ija kọ awọn eeyan pataki nilu Iwo, ati ibomiran.Wọn ni lọwọ-lọwọ, Oluwo ba Oloye Abiola Ogundokun, Imran Adio (olori ẹṣin Isilaamu) to yọ nipo Otun Ajanasi, ja.
Oríṣun àwòrán, Instagram/oluwoofiwoland
"Bakan naa ni wọn lo sọ ọrọ abuku si Alaafin Ọyọ, Oba Lamidi Adeyemi ; Ooni Ile-Ife, Oba Adeyeye Ogunwusi ; Orangun Ila, ati awọn ọba miran nipinlẹ Osun.Àmọ́ o, Akọwe Iroyin fun Oluwo, Alli Ibrahim, sọ ninu atẹjade kan pe ""diẹ lara awọn to fọwọ si iwe ẹsun naa ko finu-findọ ṣe e.""Aṣini lọna kan lo fi agidi mu wọn."""
Toyin Atoyebi mechanic: Ẹ wo Toyin, ọmọbinrin ọdún 16 tó ń tún skadà àti gẹnẹrátọ̀ ṣe ní
"O ṣalaye pe kii ṣe igba akọkọ niyi ti ẹni naa ti n tabuku Oba Akanbi, sugbọn to n ja si ofo.""Dipo ijakulẹ, awọn aṣeyọri ti Oluwo ti ṣe tubọ n mu ki awọn ara ilu Iwo fẹran rẹ si ni."""
Kano-Niger rail line: PDP ní àìmèyí tó kàn n'ìgbèsẹ̀ ìjọba láti ná $1.95bn sórí reluwé làti Kano sí Niger Republic.
Oríṣun àwòrán, Twitter/Nigeria Railway Corporation
Ẹgbẹ osẹlu alatako PDP ti bu ẹnu atẹ lu bi ijọba apapọ orilẹ-ede Naijiria ti buwọlu $1,959,744,723.71, fun iṣẹ agbaṣe oju ọna ọkọ reluwe ti yoo so orilẹ-ede Naijiria pọ mọ Niger Republic.
Akọwe agba ati alukoro ẹgbẹ oṣelu PDP, Kola Ologbondiyan to ba BBC Yoruba sọrọ ṣalaye pe aimọ eyi to kan lo jẹ ki ijọba gbe igbesẹ naa.
Ọgbẹni Ologbindiyan sọ pe kii ṣe asiko ti ijọba ṣe afikun owo ina ati owo epo bẹntiro yii lo yẹ ki ijọba tun maa na ẹgbẹlẹgbe biliọnu owo dọla sori ojuurin reluwee lati Kano si orilẹede Niger.
''Nisinyii ti ijọba n ṣe oju ọna reluwee lọ si Niger lati ran wọn lọwọ, iranlọwọ wo lawọn ọmọ Naijiria gan an tii riu lati ọdọ ijọba yii,'' Ologbondiyan lo sọ bẹẹ.
Ologbondiyan ni ọgbọn ati ko owo jẹ naa ni gbogbo ohun ti ijọba apapọ n ṣe pẹlu ṣiṣe ojuurin lọ si ilẹ Niger.
Akọwe agba ati alukoro ẹgbẹ oṣelu PDP ni kii ṣe nitori araalu ni wọn fi n ṣe ohun ti wọn n ṣe lori reluwee lọ si Niger.
Ologbondiyan ni ẹgbẹ PDP ko tako ojuurin ti ijọba yii ṣe lati Eko si Ibadan nitori awọn mọ pe anfaani lo wa nibẹ fun araalu.
Oríṣun àwòrán, Twitter/Nigeria Railway Corporation
O ni nkan to ba yẹ ki ijọba Buhari fi si iwaju lo n fi sẹyin.
O ṣalaye pe ọkọ ojuurin ti ilu Eko si Ibadan ti ijọba Muhammadu Buhari fẹ ṣi gan an, ẹgbẹ PDP naa lo bẹrẹ rẹ.
Nibi ipade igbimọ alasẹ ijọba apapọ ti Aarẹ Muhammadu Buhari dari l'Ọjọru ni wọn ti fi ontẹ lu owo naa.
SS3 ní mo wà báyìí, mo sì ti gba àmì ẹ̀yẹ̀ púpò nílé-lóko gẹ́gẹ́ bí onílù - Ayansike
Minisita fun eto irinna, Rotimi Amaechi, gẹgẹ bi iwe iroyin The Punch ṣe jabọ, sọ fún awọn akọroyin pe ijọba buwọlu owo naa fun idagbasoke oju ọna ọkọ reluwe ti yoo so bẹrẹ lati ipinlẹ Kano-Dutse-Katsina-Jibia, titi de Maradi lorilẹ-ede Niger Republic.
Oju ọna irin naa, tó jẹ kilomita 248 ni ireti wa pe yoo sisẹ fun gbigbe eporọbi.
Oríṣun àwòrán, Twitter/Nigeria Railway Corporation
Yatọ si eyi, Amaechi tun sọ pe igbimọ naa tun buwọlu isẹ agba ṣe ti owo rẹ le ni biliọnu mẹta Naira ₦3.049bn, fun ṣíṣe, ayẹwo ati ikojade ẹ̀rọ ti yoo ma a gbe reluwe to ba ni ijamba kuro loju ọna.
Ẹwẹ, laarin oṣu kẹsan ọdun 2020 yii ni ileeṣẹ ọkọ ojuurin sọ tẹlẹ pe ọkọ reluwe yoo bẹrẹ si ni ṣiṣẹ lati ilu Eko si Ibadan.
Oludari ileeṣẹ reluwee lorilẹede Naijiria, Fidet Okhiria lo sọrọ naa niluu Ibadan nigba ti minisita eto irinna, Rotimi Amaechi n ṣe abẹwo ibi ti iṣẹ de lori ojuurin reluwee lati Eko si Ibadan ninu oṣu kẹjọ.
Okhiria sọ pe ibudokọ reluwee to wa ni Yaba ni irinna naa yoo ti gberasọ niluu Eko si Ibadan.
Ọgbẹni Okhiria ṣalaye pe awọn ọkọ reluwee naa yoo maa na Eko si Ibadan ni igba mẹrindinlogun lojoojumọ.
Magawa: Èkúté tó sàwárí bọ́mbù ilẹ̀ gbàmi ẹ̀ye wúrà PDSA
Oríṣun àwòrán, PDSA/PA
Magawa gba ami ẹyẹ wura lẹtin to sàwárí ọmi-ilẹ ni cambodia
Èkúté ńlá kan to dà bi òmìràn ti gba àmì ẹ̀yẹ wúrà fún iṣẹ́ rẹ̀ láti ma ṣe awári imọ-ilẹ
Magawa a maa ti fimu filẹ̀ lati ri imọ-ilẹ Mọ́kandinlógójì àti ti àwọn méjìdinlagbọ́n ti kò  bu gbàmu mọ lọ́wọ́ ri lati igba tó ṣe iṣẹ́ to yàn láàyò yìí.
Àwọn ilé iṣẹ́ ìtójú ẹranko kan ni ilẹ gẹẹsi ti wọ́n pe ni PDSA lo fún ni àmì ẹyẹ náà nítori iṣk ribiribi tó n ṣe lati dóòlà ẹmi àwọn ènìyàn, pàápàá jùlọ láwọ́n ibùdó to ti ṣiṣẹ́ ni Cambodia.
Ìròyìn sọ pé, ó lé ni mílíọ̀nù mẹ́fà imọ-ilẹ to wà ni ìlà-oòrùn- Gúúsù àwọn orílẹ̀-èdè Asia.
"Wọ́n kọọ́ sórí rẹ pé Àmìẹ̀yẹ wura PDSA "" Fún ẹranko to ní ìgbpoya àti ìtẹramọ́ṣẹ́ lẹ́nu iṣẹ́"" láàrín àwọn ẹranko ọgbọ̀n to ti gba irú ami ẹyẹ yìí rí, Magawa ni ẹranko àkọ́kọ́ to jẹ́ Èkúté."
Eeku náà tí kò tíì ju ọdún méje ló,  lọ fún ètò ẹ̀kọ́ rẹ̀ ni Belgium Charity Apopo to wà ni Tanzania níbi ti wọ́n ti ń tọ́ọ- Wọ́n máa n irú wọ́n ni HeroRATs- bí wọ́n ṣe ń ṣe àwárí imọ̀-ilẹ̀ àti ikọ́fée láti ọdún 1990.  Ẹranko náà gba ìwé ẹ̀rí lẹ́yín ọdún kan ètò ẹ̀ko
Oríṣun àwòrán, Getty Images
"Amiẹyẹ Fún ẹranko to ní ìgbpoya àti ìtẹramọ́ṣẹ́ lẹ́nu iṣẹ́"" láàrín àwọn ẹranko ọgbọ̀n to ti gba irú ami ẹyẹ yìí rí,"
" Iyi nla ni fún wa ní a ṣe ri àmìẹ̀yẹ yìí gbà Olùdari Apopo Christophe Cox sàlàyé fún ilé ìròyìn Press Association News Agency. "" Sùgbọ́n ǹkan nla ni fún àwọn ènìyàn Cambodia àti gbogbo àwọn ènìyàn tó n kojú ọ̀rọ̀ imó-ilẹ lágbáyé"""
Lónìí ni PDSA yóò kéde ètò àmìẹ̀yẹ Magawa lori ẹ̀rọ Ayelujara wọn
SS3 ní mo wà báyìí, mo sì ti gba àmì ẹ̀yẹ̀ púpò nílé-lóko gẹ́gẹ́ bí onílù - Ayansike
Gẹ́gẹ́ bi Apopo ṣe sọ Ìlú Tanzania ni wọ́n ti bi Magawa ti o sì wà ni ìwọ̀n kílò 1.2kg àti 70cm ní gígùn nígbà ti wọ́n bii. Èyí tóbi gaa ni sí irú àwọn èkúté míràn. Magawa  kò tóbi jù o si fúyẹ daadaa, eyi ló fún ni ànfani lati le rin lórí imọ-ilẹ láì jẹ́ ki o bú gbàmù.
Wọ́n kọ́ Magawa lati ma fi imú finlẹ̀ fún àwọn ǹkan bíi kẹ́míkà, àdó olóró, èyí túmọ̀ si pé, o le ṣe àwárí ìjìnlẹ̀ lórí imo\-ilẹ ki o sì wá jáde ni kíákíá.Ní kété to bá sì ti rí im'\o-ill yiìí yóò gbẹ́lẹ̀, bákan náà ni yóò pe ènìyàn ti wọ́n jọ ń ṣiṣẹ́ láti ṣe èyí tó kù ni àṣeyọri.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Èkúté tọ n wá ọmi-ilẹ gbàmì ẹyẹ wúrà PDSA
Gẹ́gẹ́ bí àjọ kan ti kìí ṣe ti ìjọbaHALO Trust, tó ń ri si ọ̀rọ̀ imọ-ilẹ Cambodia ti ni àkọsilẹ̀ àwọn ènìyàn tó le ni ẹgbẹ̀rún mẹ́rìnlélẹgbẹ̀ta tí imọ̀l-ilẹ ti pa àti ẹgbẹ̀rún lọ́nà mẹ́ẹ̀dọ́gbọ̀n àwọn mírà  tó ti gé ni ọwọ ati ẹsẹ nítori imọ-ilẹ láti ọdun 1979.
Akomolede àti Aṣa: Ọ̀rọ̀ Ẹ̀yán ni Bunmi Femi Amao ń kọ́ wa lórí ètò Akọ́mọlédè àti Àṣà lóri BBC Yoruba
LASEMA: Àwa àti panápaná ń ṣiṣẹ́ kára láti dènà ìjàmbá iná
Ajọ oṣiṣẹ pajawiri nipinlẹ Eko, LASEMA ni awọn ti le awọn eniyan kuro nibi ti iṣẹlẹ ọkọ agbepo to danu ti waye ni ilu Eko.
Adari Ajọ LASEMA, Damilola Oke-Osanyintolu lo fi atẹjade naa lede fun awọn eniyan.
Osanyintolu ni iṣẹlẹ naa waye ni agbegbe Aso-Odo, Badagry ni ipinlẹ Eko ni Ọjọ Iṣẹgun.
Nibayii, awọn oṣiṣẹ pajawiri ti wa nibẹ lati ri wi pe ọkọ naa ko gbina, lẹyin ti wọn le awọn eniyan kuro ni agbegbe naa.
Bakan naa ni wọn rọ awọn eniyan lati maṣe daba lati ma a ko epo bẹntirolu to danu naa, ki ijamba miran ma ba a waye.
'' A tii bẹrẹ si ni gbọn epo naa kuro nibi to da si, ki ijamba ina ma ba a waye.
Agbegbe naa ti a ko jẹ ki awọn eniyan gba kọja, ti fa sunkẹrẹ fakẹrẹ ọkọ ni oju ọna naa.''
LASEMA naa wa rọ awọn eniyan lati ṣe suru fun awọn, ki ijamba miran ma ba tun waye ni agbegbe naa.
Bakan naa ni wọn fi lede pe awọn yoo ma fito awọn araalu leti bi o ba ṣe n lọ.
Ọkọ kan ti jona rauru lori afara Ojuelegba nilu Eko.
Iṣẹlẹ naa to waye lalẹ ọjọ Abameta ko mu ẹmi kankan lọ ṣugbọn o ṣe idiwọ fun lilọ bibọ ọkọ lori afara naa.
Oríṣun àwòrán, LASEMA
Ninu atẹjade kan ti ọga agba ileesẹ pajawiri nilu Eko LASEMA, Olufemi Osanyintolu fi sọwọ si BBC, awọn eleto aabo ati panapana ni wọn jijọ pa ina to jo ọkọ naa.
Osanyintolu ṣalaye pe awọn ti lo irinsẹ agbe ọkọ lati fi gbe ajoku ọkọ naa kuro ti lilọ bibọ ọkọ si ti n lọ geere.
Oríṣun àwòrán, LASEMA
Bi ajalu ba waye ni igba akọkọ, a le sọ pe amuwa Ọlọrun nii ṣe.
Amọ to ba ti wa di nkan to n ṣẹlẹ lemọlemọ, kini ka ti ṣe eyi si?
Oríṣun àwòrán, TWITTER/LASEMA
Ibeere re to gbẹnu awọn ọmọ Naijiria paapa julọ awọn olugbe ilu Eko lori iṣẹlẹ ibugbamu to n waye leralera.
Niwọn igba ti a ko ba ti ribi le dahun ibeere yi lẹkunrẹrẹ, BBC Yoruba yoo gbiyanju lati gbe akọsilẹ jade nipa iye igba tawọn ibugbamu waye ni Eko lọdun 2020.
Oríṣun àwòrán, TWITTER/LASEMA
Isẹlẹ Ibugbamu gaasi ni Abule Ado
Ọjọ kẹẹdọgun ọsu kẹta ọdun yii jẹ ọjọ manigbagbe fun awọ́n olugbe adugbo Abule Ado nibi ti iṣẹlẹ ibugbamu ọpa gaasi ti ṣẹlẹ niluu Eko.
Abule Ado explosion: Irọ́ ńlá ní NNPC pa lórí ìbúghbàmù Abule Ado níbí tí ẹ̀mí èèyàn 23
Awọn eeyan marundinlọgbọn lo farapa ninu ijamba ọhun.
Ninu iṣẹlẹ taa n wi yi, o kere tan eeyan mẹtadinlogun lo padanu ẹmi wọn.
Bẹẹ naa ni ọpọ ile ati dukia farakasa iṣẹlẹ yi ti ọp si di alainile lori.
Oríṣun àwòrán, @followlasema
Ọjọ Kẹtadinlọgbọn Osu Kẹrin, Iṣẹlẹ ibugbamu ile epo NNPC
Adugbo Yaya Abatan ni Ogba nilu Eko ti oun naa wa labẹ ijọba ibilẹ Ifako Ijaiye ni ibugbamu taa n sọ yi ti waye.
Adugbo yi jẹ ibi tawọn eeyan pọ si ti aaye tawọn kan ti n ta ọkọ si farako pupọ ninu ibugbamu yi.
Oríṣun àwòrán, LASEMA/ TWITTER
Bi eeyan ba jẹ ori ahun, to ba ri iru ijamba to waye nibẹ, yoo kanu awọn eeyan.
Ohun to jẹ idunnu ni pe kii ṣe igba tawọn eeyan pọ nita nitori Covid-19. Bibẹ kọ, ọtọ lohun taa baa maa sọ.
Toyin Atoyebi mechanic: Ẹ wo Toyin, ọmọbinrin ọdún 16 tó ń tún skadà àti gẹnẹrátọ̀ ṣe ní
Ibugbamu gaasi naa ni eleyi to waye ni ibudo iwọkọ Alakia ni orile Iganm,u nilu Eko.
Awọn eeyan mẹrin farapa ninu iṣẹlẹ yi.
Oríṣun àwòrán, TWITTER/LASEMA
Ọjọ buruku ẹsu gbomimu ni Ọjọru ọjọ Kẹrinlelogun oṣu Kẹsan jẹ fun awọn eniyan agbegbe Balogun, Iju Ishaga nipinlẹ Eko.
Lọjọ  yi,  ọkọ nla to n gbe afẹfẹ gaasi gbina to si jo ile mẹtalelogun, ọja, ọkọ marundinlogun, ti eniyan ọgbọn si farapa ninu iṣẹlẹ naa.
Ajọ Lasema loju opo ikansiraẹni Twitter wọn ni awọn ọkọ nla to gbina naa gbe afẹfẹ gaasi wa si agbegbe naa ni ki o to gbina.
Oríṣun àwòrán, LASEMA
Loore koore ni awọn ajọ pajawiri n kilọ pe ki awọn eeyan sọrọ tita afẹfẹ gaasi ni itosi ibi tawọn eeyan n gbe.
Nilu Eko to ṣe pe ọpọ eeyan lo n lo afẹfẹ gaasi yi fun idana ati iṣowo, o di dandan ki ijọba wa wọrọkọ fi ṣada lọna ati dẹkun ibugbamu ni gbogbo igba.
Ni igba ti ibugbamu ti Abule Ado waye, alaga ijọba ibilẹ Ifakọ Ijaiye to fi mọ awọn ọmọ ile aṣofin to n ṣoju agbegbe naa mẹnu ba fifi ofin lelẹ eyi ti yoo kọdi tita afẹfẹ  gaasi letile.
Titi di ba ti ṣe n sọrọ yi, ofin naa ko ti di amuṣẹ.
'Èmi gan máa ń béèrè lọ́wọ́ ara mi pé ta ni Wole Soyinka gangan'
Sex workers strike: Àwọn aṣẹ́wó kílọ̀ fún Buhari kó dá'wó epo padà, bíbẹ́ẹ̀kọ̀, ìyanṣẹ́lódì ló kù
Laarin ọpọlọpọ eeyan lagbaye, iṣẹ aṣẹwo ni wọn mọ gẹgẹ bi iṣẹ to dagba julọ lagbaye.
O dabi eyi gan lo mu ki awọn olowo nọbi lorilẹede Naijiria, o gbe ohun soke lorilẹede Naijiria pe awọn igbesẹ ijọba apapọ n ni iṣẹ awọn naa lara gẹgẹ bi 'oṣiṣẹ'
Toyin Atoyebi mechanic: Ẹ wo Toyin, ọmọbinrin ọdún 16 tó ń tún skadà àti gẹnẹrátọ̀ ṣe ní
Awọn olowo nọbi gẹgẹ bi ọpọ ti maa n pe awọn aṣẹwo nilẹ Yoruba naa ti ke gbajare sita pe igbesẹ afikun owo epo ati owo ina ti ijọba apapọ gbe laipẹ yii kii ṣe eyi to ba awọn lara mu rara ati pe ki ijsba apapọ tete daa pada bi owo baba ijẹbu nikan lo lee mu ki awọn pẹlu maa gbe owo ori nọbi awọn soke.
Bakan naa ni wọn ṣeleri pe iyanṣẹlodi wa lara irinṣẹ ti awọn yoo lo lati fi ẹhonu awọn  han lori awọn igbesẹ ijọba naa.
Awọn olowo nọbi naa labẹ aṣia ẹgbẹ kan ti wọn pe ni Self Made Women SMW, ṣalaye lati ẹnu alaga wọn ni ipinlẹ Anambra, arabinrin Uto Nwanyi fi ẹsun kan ijọba apapọ pe ko nifẹ araalu rara ati pe inira ẹkunwo naa yoo ba awọn finra pupọ nitori pe yoo pa iye awọn to n na ohun ti wọn n ta wo.
SS3 ní mo wà báyìí, mo sì ti gba àmì ẹ̀yẹ̀ púpò nílé-lóko gẹ́gẹ́ bí onílù - Ayansike
"A ṣẹṣẹ ti ilu Abuja nibi ti a ti ṣe ipade pẹlu aarẹ apapọ ẹgbẹ wa lorilẹede Naijiria tan ni lori ọrọ ẹkunwo naa. Ki ni iṣoro ijọba wa gan? A ṣẹṣẹ kuro labẹ wahala ajakalẹ arun corona pẹlu awọn igbele gbogbo. Atun ṣẹṣẹ wọ inu oṣu ba-ba-ba ni ti a n lero pe a o tun maa pa ṣenji diẹdiẹ ni ijọba ba tun ni afikun owo ina ati epo lo kan, ṣe wọn fẹ pa wa ni?
O fi kun un pe bi iyanṣẹlodi awọn ko ba tu irun kan lara ijọba lori dida owo epo ati ina naa pada si bo ṣe wa tẹlẹ ri, a jẹ pe awọn yoo fi ida igba ninu ọgọrun un  kun owo ori ọja ti awọn naa n ta ni o.
O fi kun un pe ṣaaju asiko yii ẹgbẹrun kan ati ẹẹdẹgbẹta naira lawọn n gba fun ibalopọ ọlọwọ kukuru Short time ti awọn si n gba ẹgbẹrun marun un fun di ilẹ mọ kẹlẹlẹ daybraek.
Amọṣa, pẹlu bi ajakalẹ arun coronavirus ṣe kan ọrọ aje gbogbo aye, awọn ti jaa walẹ si ẹgbẹrun kan ati ẹgbẹrun mẹrin tabi mẹrin abọ.
Oríṣun àwòrán, dailypost.ng
Mike Bamiloye ti Mount Zion fi ọmọbìnrin rẹ̀ kan ṣoṣo, Darasimi fún ọkọ nílùú Ibadan
Oríṣun àwòrán, Joshua Mike Bamiloye/instagram
Ariwo ayọ tun sọ nile gbajugbaja osẹre ẹsin Kristiẹni, Mike Bamiloye, lasiko ti abigbẹyin rẹ, Darasimi, lọ sile ọkọ.
Ọjọ Ẹti ati Satide, ọjọ kẹsan-an ati ọjọ kẹwaa, oṣu Kẹwaa, ni ayẹyẹ igbeyawo naa waye nilu Ibadan.
Eto idana iyawo lo kọkọ waye, ti isin igbeyawo ati wẹjẹ-wẹmu si waye lọjọ Satide.
Oríṣun àwòrán, Joshua Mike Bamiloye/instagram
Bayii ni awọn ẹgbọn iyawo, idile wọn, ati idile ọmọ Alufaa ijọ Redeem, Leke Adeboye ṣe ro dẹdẹ fun ayẹyẹ naa
Diẹ lara aworan ayẹyẹ naa ti BBC Yoruba ri lori ayelujara fihan pe, o larinrin.
Oríṣun àwòrán, @Gospel film
Aṣọ bi oriṣi mẹta ni tọkọtaya tuntun naa wọ fun eto idana naa, ti wọn si wọ kaba funfun ati kootu funfun lọ si ṣọọṣi lọjọ Satide.
Oríṣun àwòrán, gospelfilmsng
Ijo ati ayọ ni baba ati iya iyawo, Mike ati Gloria Bamiloye fi sin Darasimi lọ sile ọkọ.
Aṣọ alarambara naa ko yọ awọn obi ati ẹbi wọn silẹ rara.
Oríṣun àwòrán, Mike bamiloye/facebook
Olorin Kristẹni, Lawrence Oyor ni ọkọ iyawo, to si jẹ ọmọ Oluṣọ Agutan Gomba Fortune to di oloogbe laipẹ yii.
Ninu fidio kan to ṣafihan awọn ẹgbọn iyawo, Damilola ati Joshua , to sọrọ nipa bi aburo wọn ṣe fi to wọn leti pe Lawrence dẹnu ifẹ kọ oun, awọn mejeeji sọ pe iṣẹ iranṣẹ orin kikọ ni Lawrence wa a ṣe lọdọ wọn, lo gba ibẹ dẹnu ifẹ kọ Darasimi""."
"Ọrẹ wa ni Lawrence o, amọ o gbe n kan gbẹyin wa.
Ṣugbọn a dupẹ lọwọ Ọlọrun pe irinajo naa jẹ adun lati ibẹrẹ pẹpẹ."
Oríṣun àwòrán, Mike bamiloye/facebook
Oluwadarasimi Mike-Bamiliye (gẹgẹ bi apeja orukọ rẹ) kẹkọ gboye ninu imọ ede Gẹẹsi ni fasiti Babcock, Naijiria.
Oríṣun àwòrán, Mike bamiloye/facebook
Bayii ni baba ati iya iyawo, Mike ati Gloria Bamiloye ṣe fi idunnu jo nibi idana ọmọ wọn, Darasimi
Ohun ni ọmọbinrin kan ṣoṣo ni idile Mike-Bamiloye, oun naa si jẹ oṣere Kristẹni bii ti baba rẹ, iya ati awọn  ẹgbọn rẹ ọkunrin meji.
Oríṣun àwòrán, Mike bamiloye/facebook
Asiko yii ni awọn obi ọkọ, ṣi oju iyawo ọmọ wọn wo.
Oríṣun àwòrán, Mike bamiloye/facebook
Mike ati Gloria Bamiloye niyii to n rọ ojo adura le ọmọ wọn lori, boṣe n rele ọkọ
Darasimi tun jẹ afi ewi sọrọ ati bẹẹ bẹẹ lọ.
Darasimi ni abigbẹyin, ọmọ kẹta fun idile oṣere Kristẹni Mike ati Gloria Bamiloye ti wọn jẹ gbajugbaja ninu awọn fiimu ẹsin Kristẹni ti awọn eeyan mọ si Mount Zion Films.
Oríṣun àwòrán, gospelfilmsng
Oríṣun àwòrán, gospelfilmsng
Ayẹyẹ idagbere 'Bridal shower' ti awọn ọrẹ iyawo ṣe fun ṣaaju ọjọ igbeyawo re e.
Kí ló ń ṣẹlẹ̀ nípa olùwọ́de EndSARS tí wọ̀n yìnbọ̀n lù ní Ogbomosho?
Ejò lọ́wọ́ nínú lórí ìdájọ́ ẹ̀wọ̀n gbére tí wọ́n dá fún Wòlíì Sotitobire, àwọn ọmọ ìjọ rẹ̀ yarí
Ejò lọ́wọ́ nínú lórí ìdájọ́ ẹ̀wọ̀n gbére tí wọ́n dá fún Wòlíì Sotitobire, àwọn ọmọ ìjọ rẹ̀ yarí
Oríṣun àwòrán, Mike bamiloye/facebook
Ọkọ iyawo, Lawrence, ati awọn ọrẹ rẹ re e to n dọbalẹ niwaju awọn obi iyawo rẹ.
Olorin Kristẹni ni Lawrence Oyor, to jẹ ọkọ Darasimi.
O kẹkọ gboye ninu imọ ofin ni fasiti ilu Ibadan lọdun 2013 to si tẹsiwaju ninu ẹkọ rẹ nileewe imọ ofin, Yola. Lawrence Oyor.
Oríṣun àwòrán, Mike bamiloye/facebook
Ọmọ Eleme ni ipinlẹ Rivers ni Lawrence Oyor, wọn bi i lọjọ kẹrindinlogun oṣu kẹfa ọdun 1992.
Oríṣun àwòrán, Mike bamiloye/facebook
Awọn ẹgbọn Darasimi mejeeji, ati awọn iyawo pẹlu ọmọ ọkan lara wọn
Ibeji ni Lawrence, orukọ ibeji rẹ a si maa jẹ Godswill.
Oríṣun àwòrán, Mike bamiloye/facebook
Bayii ni iya Lawrence ṣe fi owo yẹ ọmọ rẹ si, lasiko to n jo nibi eto idana naa
Akọrin Kristẹni lawọn mejeeji.
Oríṣun àwòrán, Instagram/gloriabamiloye
"Mo ki ara mi ku oriire laye, nitori pe mo fẹ ọ.
 Abajọ ti nkan fi n dara fun mi; abajọ ti mo fi ni iru awọn ọmọ to dara ti o bi fun mi; abajọ to fi dabi ẹni pe mo n lo àjídèwe, nitori pe o ko lo mi ni alobajẹ."""
Wọn yii ni diẹ lara ọrọ ti ogbontarigi osere fiimu ẹṣin Kristẹni, to tun jẹ Oludasilẹ ileesẹ Mount Zion Ministries, Mike Bamiloye, sọ lati fi mọ riri iyawo rẹ, Gloria Olusola Bamiloye, ni ayajọ ọdun kejilelọgbọn ti wọn ṣe igbeyawo.
Ninu akọsilẹ naa to fi si ori ayelujara Facebook, Mike Bamiloye sọ pe, oun ko ni ohunkohun bi i owo ati dukia, nigba ti Gloria gba lati fẹ oun, bo tilẹ jẹ pe awọn ẹbí wa gba wa ni imọran pe, ki a ma ṣe bẹ ẹ.
Oríṣun àwòrán, Facebook/Mike Bamiloye
Bamiloye ni ọpọlọpọ igba ni oun ti ṣẹ iyawo oun nipa ai fi aaye silẹ fun bose yẹ.
O ṣalaye pe, ọpọ igba ni isẹ Oluwa ma n gba gbogbo akoko oun, debi i pe oun kii ri aaye wa pẹlu rẹ.
"O ni ""Mo si n kekọọ lati mọ bi mo ṣe le fi ifẹ han si ọ bo ṣe yẹ."
 Ọpọlọpọ igba ni mo ma n wa ni agbedemeji ìwọ ati isẹ iranṣẹ... O ju isẹ iranṣẹ lọ, àmọ́ dandan ni fun mi lati ṣe iṣẹ ẹni to ran mi... 
Ọpọlọpọ igba ni mo ti kuna, nipa ai fi aaye silẹ lati wa pẹlu rẹ bose yẹ.
Oríṣun àwòrán, Facebook/Mike Bamiloye
Eyi si ni mo tọrọ idariji fun lọwọ rẹ, lonii.
"Dariji mi fun awọn asiko ti mo pariwo mọ ọ, nitori ẹrù isẹ iranṣẹ àti bukaata ile wọ̀ mi lọrun.
Ajinhinrere Bamiloye tẹsiwaju ninu ọrọ rẹ pe, oun ko ni koko isẹ kankan lọwọ ju ere ori itage lọ nigba ti oun gbe Gloria niyawo.
O ṣalaye pe ẹbí, ara ati ọrẹ lo da owo ti awọn fi ṣeto ayẹyẹ igbeyawo naa lọdun 1988,to fi mọ eyi ti wọn fi gba ile.
Oríṣun àwòrán, Facebook/Mike Bamiloye
Bamiloye sọ pe iyawo to n ṣe ojuṣe rẹ ni Gloria jẹ, debi i pe oun ko ni ìdí kankan lati jẹun nita.
Ko tan sibẹ o, o tun ni oun dupẹ lọwọ Ọlọ́run pe gbogbo àwọn obinrin ti oun kọkọ dẹnu ifẹ kọ ko gba lati fẹ oun.
Mo dupẹ pe mo ba ọ sọrọ igbeyawo lọdun marundinlogoji sẹyin; mo dupẹ pe o gbọran si àṣẹ Oluwa lati fẹ mi."
Oríṣun àwòrán, Facebook/Mike Bamiloye
"Mo dupẹ pe a di tọkọtaya ni ọdun mejilelọgbọn sẹyin; mo dupẹ pe iṣẹ iranṣẹ wa ri bo ṣe ri; mo dupẹ fun igbe aye rẹ."""
"O sapejuwe iyawo rẹ gẹgẹ bi iwe akaikatan, ""nitori pe bi mo ṣe n ka ọ si, ni mo n mọ awọn adun ati anfaani rẹ si."""
"Iyawo to ni ìtẹríba ni ọ, abajọ ti awọn ọmọ wa ọkunrin fi gbadura pe ki Ọlọrun fun wọn ni iyawo bi iru rẹ. Mo si dupẹ pe o ri bẹ ẹ fun wọn.
Ju gbogbo rẹ lọ, mo dupẹ fun ọfiisi tuntun ti o ṣi fun mi gẹgẹ bi ẹ̀bùn ayẹyẹ ọjọ ibi ọgọta ọdun ti mo pe.
Titi de opin ẹmi mi ni ma a ni ifẹ rẹ."
Oríṣun àwòrán, Instagram/gloriabamiloye
Se ẹ ti wo awọn sinima yii ri - Ide Esu, Agbara nla (Ayaaaaaaamatanga), Egun aimọ, Ogun atilewa,  Ibere opin aye...ati bẹẹ bẹẹ lọ?
To ba jẹ pe bẹẹ ni, a jẹ wipe ẹ kii ṣe ikoko rara tori ọdun gbọọrọ sẹyin ni orukọ Mike Bamiloye ti maa n ro leti awọn eeyan, pẹlu awọn fiimu to n ṣe sita.
Nigba to n ba BBC Yoruba sọrọ, Ajihinrere Mike Bamiloye, tii se ẹni to gbe awọn sinima awodamiẹnu naa sita ni ọdun gbọọrọ sẹyin, salaye nipa awọn asiri aseyọri rẹ.
Bamiloye sisọ loju rẹ faraye pe, oun kii ṣe pasitọ tabi adari ijọ kankan gẹgẹ bi awọn eeyan ṣe ma n fi oju wo bi igbagbọ rẹ ti gbona to.
Eyi ko si sẹyin ohun to jẹyọ latara awọn sinima rẹ ati iru awọn ọrọ to maa n fi sita lori ayelujara loore koore lẹnu ọjọ mẹta yii, to jọ mọ ka maa bu ẹnu atẹ lu awọn iwa kọọkan tawọn ọdọ n hu.
Oríṣun àwòrán, Instagram/gloriabamiloye
Bakan naa ni gbajumọ osere tiata ti ẹmi naa ni oun ko da ijọ kankan silẹ o.
"Mike Bamiloye ni ""mi o ki n ṣe pasitọ, mo ni ijọ ti emi naa n lọ gẹgẹ bi ọmọ ijọ, ti mo si ni pasitọ pẹlu, nigba kuugba ti a ba wa nile lorilẹede Naijiria, a n darapọ mọ ijọsin""."
Amọ Bamiloye ni iṣẹ iranṣẹ ijere ẹmi Kristẹni ti Ọlọrun pe oun si, nikan ni oun gbajumọ.
"Ṣe ""I am a Tiger"" ni itumọ ""Ayamatanga""?"
Oríṣun àwòrán, Instagram/gloriabamiloye
"Fun igba akọkọ, Mike Bamiloye ṣalaye ọrọ kan to jade ninu fiimu Agbara Nla to ṣe, ninu eyi ti obinrin kan, Bose to gba agbara okunkun lọwọ ọrẹ rẹ, Paulina, ti maa n kigbe ""Ayamatanga"", ki agbara Ọlọrun to tu u silẹ."
Ajihinrere Mike Bamiloye ni,ọrọ naa ko ni itumọ kankan lodi si oriṣiriṣi itumọ ti awọn eeyan n fun un.
"Emi ṣaa ni mo mọ ọrọ ti Ọlọrun fun mi, Ayamatanga kii ṣe I am a Tiger"" tabi ""I am at anger"" tawọn eeyan n wi o, baa ṣe pe e ninu ere gẹlẹ, bẹẹ ni Ọlọrun ṣe sọ fun mi, ti mo si kọ ọ silẹ""."
Akomolede ati Aṣa lori BBC: Kí ní ìtúmọ̀ Sílébù àti àmi ohun tó ń fún ni?
Nigba to ti jẹ wipe awọn ere wa da lorii ki idile toro, bibọ lọwọ ogun eṣu ati bẹẹ bẹẹ lọ ko si sẹni ti ko fẹ bọ lọwọ ogun tabi ti ko fẹ ki idile oun to.
Bamiloye ni idi niyi ti ere awọn ṣe wulo fun gbogbo ẹya tabi ẹsin.
"Koda o fi kun un pe, lara awọn sinima tuntun tawọn ṣẹ tun gbe jade bii ""The train, Shackles, Abejoye ati bẹẹ bẹẹ lọ, orilẹede ọtọọtọ to ju mẹwaa lọ, ni wọn ti fẹ ṣe akọkọ wo rẹ."
Obateru Akinruntan: Wíwá ohun tá jẹ títí láé ló gbé wa kúrò nílé Ife
Ha ha ha ha, Bamiloye rẹrin, o ni lootọ oun mọ pe iyawo oun rẹwa, ti awọn eeyan si maa n sọ ọ kan oun loju.
Amọ ti wọn ba ti sọ ọ, maa ni ẹ ṣeun. Ko sẹni to sọ fun mi ri pe, oun yoo gba iyawo mi o, abi boya awọn to n beere ibeere yii naa lo ni i lọkan.
Nigba to n salaye idi ti igbeyawo wọn se tọjọ di oni, Bamiloye ni awọn kii tasẹ agẹrẹ ko ipa ti ko yẹ ki awọn ti kii ṣe tọkọ taya ko ninu ere.
Fun apẹrẹ, lori ipa ọrẹkunrin si ọrẹbinrin, ọkunrin ko le gbe obinrin le itan o, bẹẹ si ni mi o le fẹnu ko iyawo oniyawo lẹnu ninu ere toripe a fẹ ko ye awọn eeyan.
Bamiloye ni eyi lodi si ofin Ọlọrun.
Oríṣun àwòrán, Instagram/gloriabamiloye
Awọn ọrọ Bamiloye lori ayelujara to n da ariwo silẹ:
"Bamiloye ni oun le jẹ ""Old school"" ṣugbọn oun ni oun n tẹ foonu funrarẹ oun, ti oun si n kọ ọrọ sita lojoojumọ lati jiṣẹ Ọlọrun."
O ni oun ko ko ọrọ oun jẹ lori imura buruku tawọn ọdọbinrin mii n mura lọ ṣọọṣi ati lori ọrọ awọn to n kanju lati ṣegbeyawo.
Ajihinrere Mike Bamiloye ati iyawo rẹ Gloria, ni ọmọ ọkunrin meji ati abigbẹyin obinrin kan, tawọn naa yan lọwọ ara wọn lati darapọ mọ iṣẹ iranṣẹ fiimu Kristẹni, ti baba ati iya wọn n ṣe.
Oríṣun àwòrán, Darasimi/Lawrence Oyor Instagram
O ṣe diẹ ti iroyin igbeyawo olorin Kristeni da oju opo ayelujara ru bi ti iroyin eleyi ta mu tọ yin wa.
Igbeyawo tawọn eeyan n jẹ ọrọ rẹ lẹnu yi si ni ti  Darasimi, ọmọ gbajugbaja oṣere, olukọtan Kristẹni, Mike Bamiloye  pẹlu olorin Kristẹni, Lawrence Oyor.
Igbeyawo naa yoo waye ni  oṣu kẹwa ọdun yi.
Ikede yi  ti mọlẹbi Mike-Bamiloye kan fidi rẹ mulẹ fun BBC  ti n da awọn eeyan lọrun ti awọn ọmọ Naijiria si ti n da si ọrọ ifẹ wọn.
Boya nitori pe ni ọdun yii ni baba  ọkọ afẹsọna Darasimi Mike-Bamiloye, iyẹn Rev. Dr Gomba Fortune jẹ Ọlọrun nipe, a ko mọ ṣugbọn ọrọ naa gbode kan.
Lawrence Oyor to jẹ afẹsọna Darasimi jẹ ẹni ọdun mejidinlọgbọn.
Ọmọwe  Gomba Fortune Oyor ni baba to bi lọmọ.
Oríṣun àwòrán, Facebook/Lawrence Oyor
"Ẹ gbọ ohun ti mọlẹbi Mike Bamiloye sọ fun BBC: ""Lagbara Ọlọrun, imura igbeyawo naa ti n lọ rẹgi rẹgi.''"
No reception wedding: Adewale ni àpèjẹ kò ṣe pàtàkì sí òun
''Nitori iru awọn eeyan nla nla ti yoo wa sibi igbeyawo ọhun ati titori a ni lati tẹle ofin ijọba, a o ṣe bi a ṣe le din ero ku.''
"O tẹsiwaju pe ''pẹlu iwe ipe nikan si ni awọn eeyan yoo fi wọle"","
Oríṣun àwòrán, Darasimi/Lawrence Oyor Instagram
Oluwadarasimi Mike-Bamiliye (gẹgẹ bi apeja orukọ rẹ) kẹkọ gboye ninu imọ ede Gẹẹsi ni fasiti Babcock, Naijiria.
Ohun ni ọmọbinrin kan ṣoṣo ni idile Mike-Bamiloye oun naa si jẹ oṣere Kristẹni bii ti baba rẹ, iya ati awọn  ẹgbọn rẹ ọkunrin meji.
Darasimi tun jẹ afi ewi sọrọ ati bẹẹ bẹẹ lọ.
Oríṣun àwòrán, Mike Bamiloye
Darasimi ni abigbẹyin, ọmọ kẹta fun idile oṣere Kristẹni Mike ati Gloria Bamiloye ti wọn jẹ gbajugbaja ninu awọn fiimu ẹsin Kristẹni ti awọn eeyan mọ si Mount Zion Films.
Ọjọ kẹrinla oṣu karun ni wọn bi i, ọmọ ilu Ilesa nipinlẹ Oṣun ni idile wọn nilẹ Yoruba. Darasimi ṣe agunbanirọ ni ipinlẹ Kebbi.
Yatọ si pe Lawrence jẹ olorin Kristẹni, o kẹkọ gboye ninu imọ ofin ni fasiti ilu Ibadan lọdun 2013 to si tẹsiwaju ninu ẹkọ rẹ nileewe imọ ofin, Yola.
Ọmọ Eleme ni ipinlẹ Rivers ni Lawrence Oyor, wọn bi i lọjọ kẹrindinlogun oṣu kẹfa ọdun 1992.
Ibeji ni Lawrence, orukọ ibeji rẹ a si maa jẹ Godswill.
Akọrin Kristẹni lawọn mejeeji.
Oríṣun àwòrán, Facebook/Lawrence Oyor
Lawrence lee sọ ede mẹta - Gẹẹsi, Yoruba ati Ibibio-Efik.
Baba Lawrence ni oloogbe Rev. Dr. Gomba Fortune.
Ondo election 2020: Kalejaye ní APC kò ní ṣ'èèrú nínú ìbò gómìnà tó ń bọ̀, Wike má gbé jàgídíjàgan wá
Oríṣun àwòrán, Facebook/Rotimi Akeredolu, Nyesom Wike
Ẹgbẹ oṣelu APC ti kilọ fun Gomina  ipinlẹ Rivers Nyesom Wike ko jawọ lapọn ti ko yọ nitori APC ko ni erongba lati yi ibo ninu ibo gomina ipinlẹ Ondo ti yoo waye lọjọ kẹwaa, oṣu kẹwaa, ọdun 2020 yii.
Ṣaaju ni Gomina Wkie to jẹ eekan ninu ẹgbẹ oṣelu PDP sọ lori ẹrọ amohunmaworan wi pe ẹgbẹ oṣelu APC ti ṣeto lati yi ibo gomina to n bọ l'Ondo.
Amọ, ninu atẹjade kan ti alukoro ẹgbẹ oṣelu APC ẹka ti Ondo, Alex Kalejaye fi sita lọjọ Ẹti, APC sọ pe kaka ki awọn yi ibo, ohun ti awọn yoo sọ fun araalu ni pe ki wọn dibo fun Gomina Rotimi Akeredolu lẹẹkan si i lẹyin iṣẹ ribiribi to ti ṣe laarin ọdun mẹrin akọkọ.
Ọgbẹni Kalejaye sọ ninu atẹjade ọhun pe Wike ko mọ bi eto idibo ṣe maa n lọ ni irọwọ-rọsẹ lo jẹ ko sọ pe idibo gomina ipinlẹ Edo to waye laipẹ yii lo lọ ni irọwọ rọsẹ julọ.
O ni ẹgbẹ APC ko nilo lati ṣe eeru ninu ibo ni ipinlẹ tawọn araalu ti gba ẹgbẹ naa tọwọ teṣẹ lọdun mẹrin sẹyin.
SS3 ní mo wà báyìí, mo sì ti gba àmì ẹ̀yẹ̀ púpò nílé-lóko gẹ́gẹ́ bí onílù - Ayansike
''O da wa loju ninu ẹgbẹ oṣelu APC pe Arakunrin Oluwarotimi Akeredolu, SAN ati oludije fun igbakeji Gomina pẹlu rẹ, Lucky Ayedatiwa to gbangba sun lọyẹ ninu eto idibo to n bọ papaa julọ pẹlu awọn iṣẹ akansẹ ti ijọba Akeredolu ti ṣe laarin ọdun mẹrin akọkọ nipinlẹ Ondo,'' Ọgbẹni Kalejaye lo sọ bẹẹ.
O tun kilọ fun Gomina Wike ninu atẹjade naa pe ki o maa gbe oṣelu bo ba a o pa a, boo ba o bu lẹsẹ wa si ibi idibo gomina ipinlẹ Ondo.
APC ni eto idibo lawọn fẹ ṣe kii ṣe ogun lawọn n gbaradi fun un.
Ebonyi rape: Èèmọ̀! Àwọn adigunjalè yabo ṣọ́ọ̀ṣì, fipá bá obìnrin kan lòpọ̀, yìnbọn fún òmííràn
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Awọn adigunjale yabo ṣọọṣi Assemblies of God Church niluu Abakaliki, ipinlẹ Ebonyi nibi ti wọn ti fipa ba ọmọbinrin lopọ.
Iroyin ti a gbọ ni pe ẹgbẹ oṣere awọn ọdọ lo n ṣe igbaradi fun ere ori itage ti wọn fẹ ṣe lọwọ ninu ṣọọṣi tawọn adigunjale ọhun fi de saarin aago kan si meji oru.
Awọn to mọ nipa iṣẹlẹ naa sọ fawọn akọroyin pe awọn janduku naa yinbọn fun ọdọbinrin keji ni itan rẹ lẹyin to kọ ki wọn fi ipa ba oun lopọ.
Bakan naa ni a gbọ pe awọn ole naa tun ko ọpọ nkan ṣọọṣi naa lọ.
Nigba ti akọroyin iwe iroyin abẹle ṣabẹwo si ṣọọṣi ọhun, ọkan lara awọn alagba ijọ naa to ba nibẹ fidi iṣẹlẹ naa mulẹ pe otitọ lo ṣẹlẹ.
Alagba naa ṣalaye pe awọn ti fi ọrọ naa to ileeṣẹ ọlọpaa leti, bakan naa lawọn si ti gbe awọn ọmọbinrin mejeeji lọ si ile iwosan fun itọju.
Alufaa ijọ naa ko si nile nigba ti akọroyin ṣabọwo si ṣọọṣi ọhun.
SS3 ní mo wà báyìí, mo sì ti gba àmì ẹ̀yẹ̀ púpò nílé-lóko gẹ́gẹ́ bí onílù - Ayansike
Nkechi Blessing: Blessing ní ìkébé òun tóbí ju ohun tí òun lè dọwọ́ bò lọ, gbogbo èèyàn ló mọ̀
Oríṣun àwòrán, Instagram/NkechiBlessingSunday
Yoruba bọ, wọn ni ọla abata lo n mu odo ṣan an, ọla baba ọmọ ni mu ọmọ yan.
Eyi lo difa fun gbajugbaja oṣere tiata Yoruba, Nkechi Blessing to sọ fawọn akọroyin pe ikebe ti Eleduwa fi jinki oun tobi ju ohun ti oun le dọwọ bo lọ.
Blessing ni gbogbo eeyan lo mọ pe Ọlọrun pari iṣẹ si ẹyin oun, o ni awọn to ni ipenija oju kan to ba sun mọ oun le mọ bi ikebe oun ṣe tobi to.
Gbajugbaja oṣere naa ni o jẹ iyalẹnu fun oun pe awọn kan n sọ kaakiri wi pe oun maa n ju idi oun fun ṣe ki a ri mi ṣugbọn o sọ pe ọrọ ko ri bẹẹ rara.
Blessing ni aṣiṣe nla lawọn to n sọ pe oun ju idi kiri ki awọn aye le maa sọrọ ṣe nitori iṣu Ọlọrun ti ko ṣe fọwọ bo ni ikebe naa jẹ foun.
O tun mẹnu idi ti o fi n gbaruku ti Laycom nile Ẹlẹgbọn Agba iyẹn Big Brother Naija.
Gbajugbaja oṣere Yoruba naa ni ọlọpọ pipe ni Laycom, eyi lo jẹ ki oun maa dibo fun un.
SS3 ní mo wà báyìí, mo sì ti gba àmì ẹ̀yẹ̀ púpò nílé-lóko gẹ́gẹ́ bí onílù - Ayansike
O ni oriṣiiriṣii ẹbun ni Eleduwa fi jinki Laycom eyi to jẹ ko ni ọpọlọpọ ololufẹ to n fẹran rẹ bi oju.
''Ọrọ yii kii ṣe nipa bi oju eeyan ba ṣe gurege si tabi dunwo si nitori ọpọ arẹwa obinrin atawọn ọkunrin ni wọn jọ wa nile Ẹlẹgbọn Agba, ṣugbọn nkankan wa to jẹ ki ọpọ eeyan fẹran Laycom yatọ,'' Blessing lo woye bẹẹ.
Blessing ni mama Laycom ati ọmọ rẹ obinrin ti n pe oun lori aago lati dupẹ fun bi oun ṣe n gbaruki ti i.
Ko ṣai ṣalaye pe awọn okowo oun loun gbajumọ bayii lati igba ti ajakalẹ aarun covid-19 ti ṣakoba fun gbogbo nkan to fi mọ ere ori itage naa.
Amọ, o ni oun n gbero lati gbe sinima kan jade ni bii oṣu meji si asiko yii.
Alaafin Oyo: Kíni 'Ẹ̀lẹ̀ daddy' Olorì Abbey Adeyemi ṣe tí ojú òpó ayélujára rẹ̀ fi ń yeruku lálá?
Oríṣun àwòrán, Instagram/currentalhaja
Lai si ani-ani, Olori Abbey jẹ ọkan lara awọn ''Ẹ̀lẹ̀ Daddy, afẹ́fẹ́ tí Alaafin Oyo, Oba Lamidi Olayiwola Adeyemi fi n mi.
Lọjọ Abamẹta, ọjọ kẹrinlọgbọn, oṣu Kẹsan, ọdun 2020 ni Olori fi oriṣiriṣii fọto rẹ ati ti Alaafin pẹlu pẹlu ọmọ ti Eleduwa fi jinki wọn si oju opo Instagram rẹ.
Lẹyin naa, ọpọ eeyan bẹrẹ si ni beere wi pe ki ni Olori n ṣe gan an?
Amọ, ninu ohun to kọ sori awọn to fi sori awọn fọto, Olori Abbey kọkọ gboṣuba rabandẹ fun Eleduwa fun ore-ọfe to fun oun.
O dupẹ fun Ọlọrun fun ọpọlọpọ ibukun to fi fun oun lati igba ti oun ti wa loke eepẹ.
Oríṣun àwòrán, Instagram/currentalhaja
Lẹyin naa lo bẹrẹ si ni dupẹ ni mẹsan an mẹwaa lọwọ olowo-ori rẹ, Alaafin Oyo.
Olori Abbey ni oun ko le ṣalai dupẹ lọwọ Iku Baba Yeye fun ifẹ ti ko ṣe fẹnu sọ to ni si oun, fun ọrọ ti oun n jẹ anfaani rẹ ati fun idunnu ati ayọ to n ri lara Oba Adeyemi.
Oríṣun àwòrán, Instagram/currentalhaja
''Kabiesi, lai si iranwọ yin ati ifẹ ti ko lẹgbẹ ti ẹ fihan si mi, ko ba ti si ẹni to n jẹ emi,'' Olori Abbey lo sọ bẹẹ.
O ni lai si ore-ọfẹ ti oun n ri jẹ lara Alaafin ni, oun ko le di iru obinrin t'oun da lonii.
Oríṣun àwòrán, Instagram/currentalhaja
Olori Abbey ni ọpẹ oloore, adaadatan ni, o ni lailai l'oun yoo maa dupẹ lọwọ Ọba Lamidi Adeyemi.
Oríṣun àwòrán, Instagram/currentalhaja
Ni ipari ọrọ rẹ ni Olori Abbey ki ara rẹ ku ayẹyẹ ọjọ ibi, o gbadura pe ki Eleduwa fi ẹmi gigun ati ayọ jinki oun.
Oríṣun àwòrán, Instagram/currentalhaja
BBNaija: Laycon, Nengi, Dorathy, Neo àti Vee ti jẹ ẹ̀bùn rẹpẹtẹ lórí ètò Big Brother Season 5
Oríṣun àwòrán, BIG BROTHER NAIJA
Awọn olukopa marun-un to kẹhin sori eto BBNaija season 5, Laycon, Nengi, Dorathy, Neo àti Vee
Awọn ololufẹ ato ori amohunmaworan, BBNaija 2020, ti n foju sọna fun ẹni ti yoo gba miliọnu marunlelọgọrin, to jẹ ẹbun ati owo, laarin awọn olukopa marun to kẹhin sori eto naa.
Ọjọ Aiku ni eto naa yoo wa sopin.
Ṣugbọn, awọn olukopa naa ti n jẹ ẹbun owo ati awọn ẹbun nla miran ṣaaju asiko yii.
Awọn kan lara wọn ti jẹ ẹbun irinajo igbafẹ, jijẹ aṣoju fun awọn ileeṣẹ to ṣe onigbọwọ eto naa.
Awọn kan lara wọn ti jẹ to miliọnu marun Naira.
Nitori naa ni BBC Yoruba ṣe ṣe akojọpọ ẹbun ti awọn olukopa lori eto naa ti jẹ.
Oríṣun àwòrán, BIG BROTHER NAIJA
Pupọ ninu awọn idije to waye lori eto naa ni Nengi ti jẹ ẹbun.
O si ti gba to owo to le ni miliọnu marun-un,  N5,328,000.
Yatọ si eyi, o tun ti jẹ ẹbun ounjẹ fun oṣu mẹta, eroja fun inu ile fun ọdun kan, paali eroja iṣaraloge, ọ̀dà, irinajo si ilu Abuja ati orilẹ-ede Scotland, ati Dubai fun ayẹyẹ One Africa Music Fest.
O tun jẹ owo Bitcoin to to ẹẹdẹgblta Dọla, ati aṣoju ileeṣẹ.
Oríṣun àwòrán, BIG BROTHER NAIJA
Laycon, ti ọpọ gbagbọ pe oun ni yoo jawe olubori ninu eto Big Brother Naija fun ọdun 2020, naa ti jẹ ọpọlọpọ ẹbun nibi awọn idije to waye.
Owo to ti jẹ ti le ni miliọnu marun-un Naira, N5,031,000.
Bakan naa lo ti jẹ ẹbun lati polowo ọja, eroja iṣaraloge, ounjẹ ọfẹ, ohun elo inu ile, aṣoju ileeṣẹ, irinajo si Scotland, ati ẹẹdẹgblta Dọla owo Bitcoin.
Oríṣun àwòrán, BIG BROTHER NAIJA
Dorathy, to jẹ gbaju-gbaja lori eto naa, ti ọpọ si sọ pe o konimọra, ti jẹ ẹbun owo to to miliọnu mẹrin Naira, N3,926,000.
Ko tan sibẹ o, o tun jẹ ẹbun foonu, ọda, eroja fun inu ile, ounjẹ ọfẹ, aṣoju ileeṣẹ, ati ẹẹdẹgblta Dọla owo Bitcoin.
Oríṣun àwòrán, BIG BROTHER NAIJA
Neo naa ko kawọ gbera lori eto Big Brother Naija Lockdown.
Oun naa ti jẹ ẹbun owo to le ni miliọnu mẹta Naira, N3,572,000.
Bakan naa lo jẹ ẹbun ohun elo inu ile, ounjẹ ọfẹ, aṣoju ileeṣẹ, ati ẹẹdẹgbẹta Dọla owo Bitcoin.
Oríṣun àwòrán, BIG BROTHER NAIJA
Vee gan-an ko ni i ṣanwọ ofo pada sile lẹyin eto BBNaija. Oun naa raaye jẹ ẹbun miliọnu meji aabọ Naira.
O tun jẹ ẹbun ohun elo inu ile, ounjẹ ọfẹ, aṣoju ileeṣẹ, irinajo si orilẹ-ede Scotland, ati ẹẹdẹgbẹta Dọla owo Bitcoin.
Ẹẹdẹgbẹta Dọla owo Bitcoin
Online Match Making: Ṣé aburú wà lórí yíyan ọkọ àbí aya lórí ayélujára?
Oríṣun àwòrán, KEMDI
Yoruba bọ wọn ni airin jinna, ni airi abuke ọkẹrẹ, bi eeyan ba rin jinna, yoo ri ibi ti wn ti n fi odo ibulẹ jẹun.
Rẹgi ni owe yii si ṣe pẹlu bi awọn obinrin ode oni ti ṣe bọ si oju ayelujara lati maa wa ọkọ, ti wọn si gbagbe asa wa to so mọ eto igbeyawo ati alarina.
Kii si ṣe awọn ọlọmọge nikan laa n wi, awọn to ti ṣe igbeyawo to sanpọn ati awọn mii ti ko ri ọkọ gan ko gbẹyin ninu awọn to n wa ọkọ lori ayelujara.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Bi eeyan ba lọ si oju opo Twitter tabi Instagram, to si tẹ ọrọ matchmaking sibẹ, yoo ri pe awọn oju opo alarina tọkọ-taya pọ nibẹ jaburata.
Lọpọ awọn oju opo itakun agbaye wọnyii, awọn obinrin, to fi mọ ọkunrin maa fi iroyin nipa ara wọn, iru ẹsin ti wọn n sin, ati iru ọkọ tabi aya, ti wọn n wa sita.
Diẹ lara awọn oju opo ololufẹ to gbajumọ lori ayelujara nilẹ Naijiria ni matchbybade, halal_matchmaking ati abujamatchmaking.
Ki lo n mu awọn obinrin gbe iru igbesẹ yii?
Aṣa Yoruba, lo ni ilana tirẹ nipa ọkọ fifẹ tabi iyawo nini, eyi ti a daye ba.
Bi a ti ṣe jogun ba lọdọ awọn babanla wa, bi ọkunrin ba ri obinrin to wu lọkan, yoo lọ nipasẹ alarina lati kan si awọn obi obinrin naa.
Ọkọ ìyàwó ẹlẹ́kún: N kò bá tí ba ẹnu jẹ́ lọ́jọ́ ìgbeyàwó, àwàdà ni mo se
Ojuse alarina si ni lati mọ hulẹ hulẹ nipa itan idile obinrin naa ati iru aisan to n se wọn ninu idile wọn.
Bi ọrọ ba wọ, ohun to kan ni ki wọn ṣe idana, ki igbeyawo si tẹle.
Gẹgẹ bi iwadi ti fi ye wa, lara awọn ohun to n mu ki obinrin maa wa ọkọ lori ayelujara tawọn kan sọ ni iwọnyii:
"Toríi ""Coro"", ẹ wo bí ètò ìsìn ìgbéyàwó orí ayélujára Zoom ṣe lọ"
Lọpọ igba ọkunrin lo maa n sọ ero ọkan lati fẹ obinrin.
Amọ ṣa ko saburu ti obinrin naa ba ni oun nifẹ ọkunrin yala labẹ ẹsin tabi aṣa Yoruba.
Erongba awọn eeyan lori ọrọ si ṣe ọtọọtọ
Ìran kan si ìkejì ló n gbèrò láti ṣe ìrú ìgbéyàwo àjùmọ̀ṣe 'Shao' fọ́mọ wọn
Ilẹ Yoruba nikan kọ ni o ti n ṣẹlẹ:
Ni oke ọya Naijria to ṣe pe wọn ko faramọ ki obinrin maa ṣe afihan ara rẹ si awọn ọkunrin, aṣa wiwa ọkọ loju ayelujara yii naa ti n gbalẹ nibẹ.
Ninu iwadii kan ti ileeṣẹ BBC ṣe, a ṣe alabapade oju opo pupọ ti awọn obinrin ti n wa ọkọ.
Oju opo wọnyii  ti o jẹ ti ajọ aladani a maa fun awọn eeyan lanfaani lati wa ọkọ tabi iyawo.
Ṣe aburu wa ninu wiwa ọkọ loju opo ayelujara?
A ko le sọ pato boya anfaani wa tabi ko si ninu yiyan ọkọ abi aya lori ayelujara nitori iriri onikaluku se ọtọọtọ.
Nibi tawọn kan ti n ri ọkọ tabi iyawo fẹ lori ayelujara, bẹẹ naa ni awọn miran n pade awọn aṣebi loju opo ayelujara.
Amọ ṣa, awọn onimọ nipa ọrọ ifẹ fi ikilọ sita pe, ki awọn eeyan fi ọgbọn ati oye lo loju opo ayelujara, ki wọn maa ba gbe eegun eleegun.
Ninu amọran wọn miran ni pe, ki awọn eeyan yii gbiyanju lati mọ ẹni ti wọn ba ṣalabapade daadaa nipa ibeere ati itọpinpin to peregede.
Wọn ni ki a maa gbagbe pe ọpọ alangba lo dakun de ilẹ, a ko mọ ẹni ti inu n run ninu wọn, ti asebi kii si kọ siwaju ori.,
Ki eledua ṣe ọkọ ati aya rere fun gbogbo mutumuwa.
Yemen Water Child: Ọmọdé 44 ni Sọ́jà pa, tí 100 míì sì kú látọwọ́ ohun ìjà olóró
Ase ibi gbogbo ni wọn ti n ko adiẹ alẹ, akoko kan yatọ sira wọn ni.
Bẹẹ ni ọrọ ri pẹlu awọn agbofinro to n sekupa awọn ọmọde ti ko gbe ohun ija lọwọ, tabi mọwọ mẹsẹ ninu iwa ọdara,
Akọtun isẹlẹ mii to tun waye nidi eyi ni ti ọmọde kan, Ruwaida, ti sọja fi ibọn fọ ori rẹ lorilẹede Yemen.
Ẹsẹ kan aye, ẹsẹ kan ọrun si ni ọmọ ọdun mẹfa naa wa bayii nile iwosan, ti awọn ẹbi rẹ si ti n sọ ohun toju wọn ri lori ayelujara.
Nigba to n ba BBC sọrọ, akọroyin kan ni iwadi fihan pe o ti to ọmọde mẹrinlelogoji ti awọn sọja ti fi ibọn pa nigba ti ọgọrun miran ku lati ọwọ ohun ija oloro.
Alaafin: Lẹ́yìn rògbòdìyàn ààfin Ọyọ, ẹ wo bẹbẹ tí Olorì Badra ń ṣe
Yoruba ni laala to roke, ilẹ lo n bọ, bẹẹ ni aaro kii gbona di alẹ.
Eyi la lee fi se apejuwe ọwọ rogbodiyan to n waye ni aafin Ọyọ nipa ọkan lara awọn ayaba Alaafin Ọyọ, Olori Badrat Olaitan Ajoke Adeyemi, eyi to ti lọ silẹ bayii.
Bẹẹ ba gbagbe Olori Badrat ni ariwo sọ nigba kan pe wọn lo ni ifẹ ikọkọ pẹlu Ọba Fuji,Wasiu Aynde Marshal.
Koda, awọn iroyin kan ti a ko le lee fidi rẹ mulẹ ni Alaafin ti le olori ọhun jade kuro ninu aafin rẹ.
Yemen Water Child: Ọmọdé 44 ni Sọ́jà pa, tí 100 míì sì kú látọwọ́ ohun ìjà olóró
Bẹẹ ni awọn eeyan kan n kun kiri pe ilu Eko ni olori Badra wa, to ti bẹrẹ igbe aye tuntun bayii, nitori iriri aye kii ti ni titi, ko ti ni pa, ọgbọn lo fi n kọ ni.
Sugbọn lẹyin rogbodiyan to gba ilu kan nipa olori Badra ọhun, BBC Yoruba lee fidi rẹ mulẹ pe, olori naa ti n dabira pada, to si n ba igbe aye rẹ lọ ni wẹlẹmu.
Ohun ta si lee sọ nipa awọn bẹbẹ ti olori Badra n dawọle ni pe ayaba naa ti gbajumọ isẹ aje rẹ ju ti tẹlẹ lọ, to si mu okoowo rẹ lọkunkundun.
Oríṣun àwòrán, Instagram/queenola2
Ni ọpọ oju opo ibanidọrẹ Olori Badra lori ayelujara, koko ohun to jẹ logun ni ipolowo awọn ọja aje rẹ, eyi to foju han pe kii se ẹyọ kan ni.
Olori Badra, tii se iya ibeji ni aafin Ọyọ, lo n polowo ọsẹ ati ororo ipara amaradan, agbo to n fa ọrọ kuro ni agọ ara tabi eyi to n se ikun pẹlẹbẹ.
Bakan naa ni Olori Badra tun ti sẹsẹ si sọọbu asọ tita bayii eyi to pe ni Queen Ajoke Closet, bẹẹ lo tun n ba awọn ileesẹ asaraloge miran se ipolowo ọja wọn.
Ayaba naa, tii se arẹwa obinrin, ni o ti fi gbogbo rogbodiyan to waye nipa rẹ laipẹ yii se afisẹyin, tii eegun fi asọ, to si n tẹsiwaju nipa aye ati ọrọ aje rẹ.
SS3 ní mo wà báyìí, mo sì ti gba àmì ẹ̀yẹ̀ púpò nílé-lóko gẹ́gẹ́ bí onílù - Ayansike
Bi o tilẹ jẹ pe BBC Yoruba ko le sọ pato boya aafin Ọyọ si ni Olori Badra si n gbe abi o ti kuro ninu aafin, gẹgẹ bawọn iroyin kan se n wi kiri.
Amọ ohun to da wa loju ni pe adirẹsi ilu Eko ni awọn ileesẹ aje ayaba naa wa, to si daju pe ilu Eko ni olori naa ti n ri taje se.
Koda, adugbo Ikeja ni adirẹsi sọọbu asọ tuntun ti olori naa sẹsẹ fẹ si bayii, osu Kẹwa to n bọ si lo ni sọọbu naa yoo di sisi.
Nigba to n kede aseyọri rẹ tuntun naa, olori Badra kọ soju opo Instagram rẹ pe ọjọ ti pẹ ti oun ti n gbaa lero lati si ibudo asọ tita, ti inu oun si dun pe ala oun naa papa wa si imusẹ.
Oríṣun àwòrán, Instagram/queenola2
Sọọbu onibeji, nibi ti wọn yoo ti maa ta asọ ati se ara loge si ni ayaba naa sẹsẹ fẹ si, nibiti wọn yoo ti maa se eekanna, din irun, lu eti, imu ati se irun lọsọ.
Ohun to wa nfoju han gbangba ni pe olori Badra ti n mọ ọpọ gbajumọ nilu Eko, paapa lẹnu ọrọ aje rẹ, to si n fi wsn soju opo ayelujara rẹ.
Sugbọn eyi to jẹ iyalẹnu ni ajọsepọ to wa laarin ayaba Ọyọ naa ati ilumọọka ọkunrin kan to maa n mura bi obinrin, tọpọ eeyan mọ si Bobrisky.
Akomolede àti Aṣa: Ọ̀rọ̀ Ẹ̀yán ni Bunmi Femi Amao ń kọ́ wa lórí ètò Akọ́mọlédè àti Àṣà lóri BBC Yoruba
Koda, ninu iwe ifitonileti ti ayaba Badra fisita nipa sọọbu asọ tuntun to fẹ si laipẹ yii, o n kesi awọn ololufẹ rẹ pe ki wọn wa pade oun lọjọ naa nilu Eko, ki wọn si tun wa foju kan Bobrisky, ọkunrin to n mura bii obinrin, ẹni ti oun yoo maa gba lalejo.
Ibeere ti ọpọ eeyan si n bi ara wọn ni pe iru ajọsepọ wo lo wa laarin Bobrisky ati ayaba nilu Oyo debi pe yoo maa pe wa sinu ibudo itaja rẹ.
Amọ BBC Yoruba wa n fi akoko yii ki iya Ibeji Alaafin ku oriire nipa ileesẹ aje tuntun rẹ, ta si gbadura pe aje yoo maa wọ igba.
BBNaija 2020 Winner: Laycon ti gba sọ̀wédowó, ilé fúláàtì àti àwọn nkan míràn
Oríṣun àwòrán, Big Brother Naija / Twitter
Oludari Agba fun ileeṣẹ MultiChoice Nigeria, to jẹ ileeṣẹ to ṣe agbatẹru eto Big Brother Naija, John Ugbe, ti sọ pe, BBNaija ti ọdun 2020 lo ni idibo to ti i pọju lọ.
O sọ eyi nibi ipade oniroyin kan, ti wọn ti pin ẹbun fun awọn to jẹ lori eto naa, eyi to wa sopin lọjọ Aiku.
Ọgbẹni Ugbe ṣalaye pe, milọnu lọna ẹẹdẹgbẹrun ni awọn eeyan di lapapọ fun awọn olukopa lori eto naa.
Bakan naa lo ṣalaye pe, biliọnu mẹta aabọ Naira ni wọn fi gbọ bukaata eto Big Brother Naija Lockdown 2020.
Oríṣun àwòrán, Big Brother Naija / Twitter
Ko tan sibẹ o, nibi ipade oniroyin naa ni wọn ti fun Olamilekan Agbeleshebioba 'Laycon', ni sọwedowo ọgbọn miliọnu Naira, ati awọn ẹbun miran to jẹ, gẹgẹ bi olubori ninu eto naa.
Yatọ si eyi, wọn tun kede apapọ iye ti olukopa kọọkan jẹ.
Oríṣun àwòrán, Big Brother Naija / Twitter
Lẹyin ti olukopa eto agbelewo BBNaija, Lekan Agbeleshebiọba ti ọpọlọpọ mọ si Laycon bori pẹlu ẹbun ti akojọpọ iye rẹ to miliọnu marundinlaadọrun naira, N85m ni okiki rẹ ti kan kalenkako ti ọpọlọpọ si ti n kii ku oriire.
Amọṣa, ikini ku oriire kan wa ti o ti n mu ki awọn ọmọ naijiria aatawọn ololufẹ Laycon kaakiri agbaye o maa pariwo 'ee ṣe' 'wọn tun de o' ati bẹẹbẹẹ lọ. Ikini naa ni ti ajọ agbowo ori ni ipinlẹ Eko to kii pe o ku oriire naa ṣugbọn ko maa gbagbe lati san owo ori rẹ bi o ti tọ lọdun 2021.
Eyi mu ki ọpọ awọn ololufẹ Laycon o gbohun soke pe ṣile kan ko gbọdọ re jẹ ninu owo aarẹ ẹgbẹ ICON naa.
Ibeere ti ọpọ wa n beere ni pe, ṣebi ẹbun owo ni wọn fun Laycon, o ṣe tun wa di ogun oni owo ori sisan.
Nigba ti BBC News Yoruba kan si alagba Mustapha Hussein Ọlanrewaju to jẹ akọṣẹmọsẹ iṣuna ati isiro owo, o ni ko souhun to buru ninu ohun ti ajọ naa sọ ati pe labẹ ofin, Laycon gbọdọ san owo ori lori ẹbun tẹtẹ oriire to jẹ naa.
O ni labẹ ofin owo ori sisan pin si meji. Owo ori sisan lori owo ati owo ori sisan lori dukia.
O ni Laycon yoo san owo ori lori ẹbun owo to jẹ ati awọn dukia to jẹ bii mọto, ile atawọn dukia miran ṣugbọn ko sohun to kan an pẹlu owo ori lori awọn irinajo afẹ silẹ okeere gbogbo ti wọn yan fun diẹ.
Akomolede ati Aṣa lori BBC: Kí ní ìtúmọ̀ Sílébù àti àmi ohun tó ń fún ni?
"O ni gbogbo iye owo yii ni wọn yoo ṣi pọ eyi ti wọn pe ni ""witholding tax"" lede oyinbo. O ni owo ori ti yoo san da lori awọn ohun ti ko ṣiṣẹ fun, iyẹn ""unearned tax"" lede oyinbo."
Ida mẹwaa apapọ owo iye ẹbun to jẹ lapapọ ni yoo san gẹgẹ bi owo ori bayii. Ni ti ọrs Laycon ti apapọ owo ohun to jẹ gẹgẹ bi ẹbun jẹ miliọnu marundinlaadọrun naira, N85m o ṣeeṣe ki owo ori ti Laycon yoo san o maa fara pẹ miliọnu mẹjọ abọ naira.
Awọn onimọ nipa iṣuna fi kun un pe kii ṣe ọwọ Laycon ni ijọba ipinlẹ to ba kan yoo ti gba owo ori yii bi ko ṣe latọwọ ileeṣẹ to ṣeto idije agbelewo BBNaija naa.
Idi niyi ti wọn fi n pee ni owo ori alayọọlẹ, iyẹn Witholding tax nitori ileeṣẹ naa ni yoo ti yọ owo naa ki wọn to ko iyoku le Laycon lọwọ lẹyin eto naa.
Oríṣun àwòrán, BBNaija/twitter
Olamilekan Agbelesebiọba 'Laycon', lo jawe olubori lori eto ori amohunmaworan, BBNaija season 5 Lockdown.
Ọjọ mọkanlelaalọgọrin ni awọn olukopa fi wa ninu ile Big Brother, nibi ti wọn ti kopa ninu oriṣiriṣi idije, faaji, ariya, ati bẹẹbẹ lọ.
Oludije ogun lo bẹrẹ idije naa, ṣugbọn awọn marun-un, Laycon, Vee, Dorathy, Nengi, ati Neo, lo gbẹyin sori eto.
Oríṣun àwòrán, BBNaija
Bayii ni awọn eeyan ṣe dibo to mu ki Laycon jawe olubori.
Lopin gbogbo ere, ibo ti awọn ololufẹ eto naa di ja Vee, Nengi, Neo ati Dorathy.
Ilu Eko ni wọn bi Leycon si.
Ọmọ ilu Bajuwen, ni ijọba ibilẹ Odẹda, ni ipinlẹ Ogun ni Lekan.
O kawe gba oye imọ ijinlẹ akọkọ ninu Philosophy, ni Fasiti ilu Eko lọdun 2016.
Nigba to wa ni fasiti, o ṣiṣẹ gẹgẹ bi amugbalẹgbẹ fun Ọga Agba ileeọẹ kan nilu Eko.
Oríṣun àwòrán, Twitter
Lẹyin to kawe gboye tan, o ṣiṣẹ gẹgẹ bi olutaja fun ileeṣẹ Bestman Games, Ikoyi, nilu Eko bakan naa.
Lẹyin naa lo darapọ mọ ileeṣẹ ijọba ipinlẹ Eko to wa fun eto iroyin, nibi to ti di amugbalẹgbẹ fun igbakeji ọga agba.
Lati kekere ni Laycon ti n kọrin. Ṣugbọn lọdun 2019, o darapọ mọ ileeṣẹ to n gbe orin jade, Fierce Nation. Nibẹ lo ti gbe awo orin kan to pe akọle rẹ ni 'Laycon'.
O kọ ọkan lara awọn orin inu awo naa pẹlu Reminisce ati Chinko-Ekun.
Awọn nkan ti Laycon to jawe olubori yoo ko lọ sile
•Dubai trip for 2 Irinajo silu Dubai fun eeyan meji
•Ile fulaati oni yaara ibusun meji
•Ọgbọn miliọnu Naira
•Irinajo lati lọ wo aṣekagba idije Champions League, ohun mimu Pepesi fun ọdun kan, ati firiiji Pepsi kan
•Foonu OPPO RENO
•Ọkọ jiipu Innoson G40
•Irinajo si ilu Dublin
•Tẹlifisan ati firiji nla
•Ati awọn nkan miran bi i indomie ati ipanu 'chinchin'
Ni deede aago meje alẹ ni eto naa, ti Ebuka Obi-Uchendu, ṣe atọkun rẹ.
Fireboy lo kọkọ forin da gbogob eeyan lara ya lori eto naa.
Lẹyin ti Big Brother ki awọn olukopa marun to kẹhin si ori eto naa, ni Ebuka kede pe Vee ti ja kuro lori eto naa.
Oríṣun àwòrán, BIG BROTHER NAIJA
Ẹni ọdun mẹtalologun ni Victoria Adeyeye, to jẹ akọrin. Ilu Eko lo fi ṣe ibugbe, bo tilẹ jẹ pe ilu London ni ni wọn bi si, to si ti dagba.
Ọdun kan sẹyin lo ko wa si ipinlẹ Eko, lati bẹrẹ iṣẹ orin kikọ,
Lasiko ti Ebuka fi ọrọ wa lẹnu wo lori irinajo ifẹ oun ati Neo, Vee sọ pe nigba ti awọn ba pada si aarin ilu, ni wọn yoo mọ ibi ti ori n gbe ẹsẹ lọ fun wọn.
Lẹyin naa ni gbajugbaja akọrin, Rema naa bọ si ori itage, to si kọ awọn orin rẹ, Beamer ati woman.
Oríṣun àwòrán, Instagram/Neo
Neo ni olukopa keji to ja kuro lori eto naa l'alẹ aṣekagba.
Oun paapa sọ pe opin ko ti i deba irinajo ifẹ oun ati Vee, ṣugbọn oun kii ṣe ọkunrin to sare ma n mu ọrọ ifẹ ni kole-kole.
Ninu ọrọ to sọ, Neo sọ pe oun ti ṣetan lati jaramọ eyikeyi iṣẹ aje to ba yọju.
Bi Neo ṣe kuro lori eto naa, ni Fireboy tun pada sori itage lati kọ orin fun igbadun awọn olukopa, ati awọn ololufẹ eto naa.
Oríṣun àwòrán, BIG BROTHER NAIJA
Nengi ni olukopa kẹta to ja kuro lori eto naa ni aṣekagba. Eyi to mu ko ku Laycon ati Dorathy.
Nengi sọ pe oun ti n fura pe oun yoo já.
O sọ pe okoowo oun ni oun yoo gbajumọ lẹyin eto BBNaija.
Arinrin oge 'model' ni Nengi.
Lẹyin ti Nengi kuro ni Big Brother kede asiko ti to fun Dorathy ati Laycon lati fi ile naa silẹ, lẹyin aadọrin ọjọ.
Oríṣun àwòrán, BBNaija/Twitter
Bayii ni Laycon ati Dorathy, #se kuro ninu ile Big Brother lẹyin aadọrin ọjọ.
Davido ati Mayorkun naa fi orin da awọn eeyan laraya lori asẹkagba eto naa.
Oríṣun àwòrán, BBnaija
Iyalẹnu si ni eyi jẹ, nitori pe awọn alakoso eto BBNaija ko kede tẹlẹ pe awọn gbajugbaja olorin mejeeji yoo kọrin ni aṣekagba.
Oríṣun àwòrán, @BBNaija/twitter
Oni lonii jẹ, ẹni a bẹ lọwẹ. Lonii la o mọ ẹni ti yoo gbade eto agbelewo ile Ẹlẹgbọn Agba, BBNaija 2020.
Ṣugbọn awọn iṣẹlẹ kan to jẹ manigbagbe waye lori eto naa.
Lara wọn ni bi awọn olukopa kan ṣe ṣe ere ifẹ.
Praise ati Ka3na lo kọkọ jẹ jẹ eso ifẹ.
Oríṣun àwòrán, @official_ka3na/@itz__praise
Ọjọ Ẹti kan ni eyi waye lẹyin ariya alẹ ti wọn ṣe.
Ninu fidio to gba ori ayelujara, abẹ aṣọ ibora ni awọn mejeeji naa wa, to si jẹ pe bi ara wọn ṣe n lọ si ọtun, ati osi, lo fihan pe 'wọn n dan nkan wo'.
Iyalẹnu lo jẹ fun awọn ololufẹ wọn, nitori pe ko si adehun ifẹ laarin awọn mejeeji.
Yemen Water Child: Ọmọdé 44 ni Sọ́jà pa, tí 100 míì sì kú látọwọ́ ohun ìjà olóró
Ọpọ eeyan to si ti n ro pe 'tọkọtaya' naa yoo tun pada da wọn laraya ti ni ijakulẹ bayii, nitori pe awọn mejeeji ti ja kuro ninu eto naa.
Ariwo Erica ati Kiddwaya ni awọn eeyan tun npa lori ayelujara .
Eyi ko ṣẹyin fidio kan ti awọn ololufẹ eto naa fi sita loru ọjọ kan, to si ṣafihan awọn 'ololufẹ' mejeeji nibi ti wọn ti n 'fun ara wọn ni eso ifẹ jẹ'.
Oríṣun àwòrán, Twitter
Lẹyin eto ti wọn ti le Lilo ati Ka3na pada sile lalẹ ọjọ Aiku,  ni iṣẹlẹ naa waye.
Ori aga ijoko ni awọn mejeeji ti kọkọ bẹrẹ, ti wọn si n fi ọwọ pa ara wọn lara. Koda, idi Erica ṣi silẹ ya-n-ya, ti ọwọ Kidd si bu idi naa so.
Lẹyin naa, ti gbogbo awọn olukopa to wa nile wọle lọ ọ sun, ni awọn mejeeji jọ wa pọ lori ibusun kan naa.
Bi awọn kan ṣe n sọ pe niṣe ni Kidd n ki ika si oju ara Erica, ni awọn kan sọ pe ibalopọ taara ni wọn n ni.
Ko tan sibẹ o, ninu fidio naa lo ti han bi Erica paapa n ke ha, yu, bi ẹni n gbadun nkan to dun.
Awọn ololufẹ eto ile ẹlẹgbọn agba, BBNaija tun sọrọ lori ohun to ṣẹlẹ laarin olori ile, Ozo ati igbakeji rẹ, Nengi lalẹ Ọjọru mọju Ọjọbọ kan.
Awọn kan tiẹ n binu tẹlẹ pe BBNaija ko ri fọnran ohun to ṣẹlẹ laarin Ozo ati Nengi wo.
Ọpọ lo fẹ ri bawọn mejeeji ti jọ sun pọ ninu ile Ozo to jẹ olori ile.
Ṣugbọn ẹrọ ayaworan kamẹra ko ṣafihan ohun to n lọ laarin awọn mejeeji.
Amọ, laarọ Ọjọbọ lawọn eeyan ri fidio kan ninu eyi ti Nengi ti gbagbe irọri rẹ to fi ṣami aye rẹ lori ibusun pẹlu Ozo.
Ki Ozo to di olori ile ati Nengi di igbakeji, awọn mejeeji ko tii jọ sun papọ ri lori ibusun kan naa, bi o tilẹ jẹ pe wọn sun mọ ara wọn.
Ṣugbọn ohun to jẹ ki ọpọ ololufẹ eto BBNaija nipa awọn mejeeji ni pe Ozo nífẹẹ Nengi, amọ Nẹngi ni oun ko fẹ ni ololufẹ ninu ile ẹlẹgbọn agba BBNaija.
Ọrọ ibalopọ ko ṣẹṣẹ ma a waye laarin awọn olukopa ninu eto naa lati igba to ti bẹrẹ.
Oríṣun àwòrán, Instagram/BBNaija
Oni lonii jẹ, ẹni a bẹ lọwẹ. Lonii la o mọ ẹni ti yoo gbade eto agbelewo ile Ẹlẹgbọn Agba, BBNaija 2020.
Obitibiti owo, miliọnu marunlelọgọrin naira(N85m) ni ẹni to ba jawe olubori ninu awọn oludije marun un to ku, Laycon, Nengi, Vee, Neo ati Dorathy yoo gba lọle.
Atọkun eto naa, Ebuka Obi-Uchendu ti sọ pe, ẹni ti ibo rẹ ba pọju ninu awọn marun un to ku, ni yoo gbade BBNaija ti ọdun yii.
Eto BBNaija ti ọdun yii lami laaka, o kun fun oriṣiiriṣii iṣẹlẹ eyi to ti sọ ọpọ awọn oludije di ilumọọka.
Yatọ si awọn marun un to ku ninu ile naa, awọn ti wọn ti yọ kuro gan an ti di eeyan ti ọpọlọpọ n tẹle loju opo ayelujara wọn.
Awọn olukopa naa ti n jẹ ẹbun owo ati awọn ẹbun nla miran ṣaaju asiko yii.
Oríṣun àwòrán, BIG BROTHER NAIJA
Awọn olukopa marun-un to kẹhin sori eto BBNaija season 5, Laycon, Nengi, Dorathy, Neo àti Vee
Awọn kan lara wọn ti jẹ ẹbun irinajo igbafẹ ati jijẹ aṣoju fun awọn ileeṣẹ to ṣe onigbọwọ eto naa.
Awọn kan lara wọn si ti jẹ to ẹbun owo miliọnu marun Naira.
Nitori naa ni BBC Yoruba fi ṣe alaye lẹkunrẹrẹ nipa ẹni to ṣeeṣe ko gbade BBNaija ti ọdun yii.
Laycon:
Oríṣun àwòrán, Instagram/Laycon
Olamilekan ''Laycon'' Agbeleshe lo ṣeeṣe ko gbade eto BBNaija ti ọdun yii, nitori ogunlọgọ eeyan to n fifẹ han si, ti wọn si n dibo fun ni gbogbo igba.
Lati ibẹrẹ eto naa ni ọpọ awọn ololufẹ eto BBNaija ti fẹran Laycon to fi di oni ti eto naa yoo pari.
Lootọọ ni pe awọn eeyan ko mọ pe o lẹbun orin kikọ ko to de ile Ẹlẹgbọn Agba, ṣugbọn lẹyin to wọle BBNaija tan, lawọn ilumọọka olorin takasufe ati gbajugbaja oṣere bii Tunde Ednut, Reminince, Yinka Ayefele, Nkechi Blessing n satilẹyin fun.
"Awọn mii to tun n gbaruku ti Laycon ni Lateef Adedimeji, Olaniyi ""Sanyeri"" Afonja, Ufuoma McDermott, Broda Shaggy ati Lekan KingKong."
Awọn eeyan to le ni miliọnu kan ati igba (1.2m) lo n tẹ le Laycon loju opo Instagram rẹ.
Owo to ti jẹ ti le ni miliọnu marun-un Naira, N5,031,000.
Bakan naa lo ti jẹ ẹbun lati polowo ọja, eroja iṣaraloge, ounjẹ ọfẹ, ohun elo inu ile, aṣoju ileeṣẹ, irinajo si Scotland, ati ẹẹdẹgbẹta Dọla owo Bitcoin.
Dorathy:
Oríṣun àwòrán, Instagram/Dorathy
Dorathy Bachor, to jẹ gbaju-gbaja lori eto naa, ti ọpọ si sọ pe o konimọra, lo ṣeeṣe ko gba ipo keji nitori bi awọn eeyan ṣe n dibo fun un.
Ẹgbẹ awọn ololufẹ rẹ ''DExplora'' n dibo fun Dorathy witi-witi, koda awọn ni igi lẹyin ọgba rẹ ti ko ti fi di ero ile.
Ọpọ igba lo ti wa lara awọn oludije ti BBNaijia fẹ le lọle, ṣugbọn awọn olukopa bii Prince ati Ozo lo lọ dipo rẹ.
Eeyan ẹgbẹrun un lọna ọtalelẹgbẹrin o din mẹwa (850,000) lo n tẹle e loju opo Instagram rẹ.
Ẹwẹ, Dorathy ti jẹ ẹbun owo to ku diẹ ko to miliọnu mẹrin Naira, N3,926,000.
Ko tan sibẹ o, o tun jẹ ẹbun foonu, ọda, eroja fun inu ile, ounjẹ ọfẹ, aṣoju ileeṣẹ, ati ẹẹdẹgbẹta Dọla owo Bitcoin.
Nengi:
Oríṣun àwòrán, Instagram/Nengi
"Rebecca ""Nengi'' Hampson lo ṣeeṣe ko gba ipo kẹta lonii bi eto BBNaija ọdun 2020 yoo ti wa si ipari."
Eeyan to din diẹ ni miliọnu kan (948,000) lo n tẹle e loju opo Instagram rẹ, ti wọn si wa lara awọn ti wọn n dibo fun un ni gbogbo igba.
Nengi yoo figa gbaga pẹlu Dorathy fun ipo keji, ṣugbọn Ozo to fi ifẹ han si Nengi nigba to si wa nile BBNaija ti rọ awọn ololufẹ rẹ, lati dibo fun Nengi.
Nengi si ti gba ẹbun owo to le ni miliọnu marun-un, N5,328,000 tẹlẹ lori eto.
Yatọ si eyi, o tun ti jẹ ẹbun ounjẹ fun oṣu mẹta, eroja fun inu ile fun ọdun kan, paali eroja iṣaraloge, ọ̀dà, irinajo si ilu Abuja ati orilẹ-ede Scotland, ati Dubai fun ayẹyẹ One Africa Music Fest.
Nengi tun jẹ owo Bitcoin to to ẹẹdẹgblta Dọla, ati aṣoju ileeṣẹ.
Vee:
Oríṣun àwòrán, Instagram/vee
"Victoria ""Vee"" Adeyele lo kan bayii. Oun lo ṣee ṣe ko gba ipo kẹrin lonii ninu awọn oludije marun un to ku nile Ẹlẹgbọn Agba."
Ọpọ awọn ololufẹ BBNaija lo ti fẹran Vee papaa julọ nitori ibaṣepọ rẹ pẹlu Laycon ninu ile.
Bo tilẹ jẹ pe awọn ololufẹ rẹ ko pọ to bẹẹ, ori lo gbe de ipele to kẹyin nile Ẹlẹgbọn Agba.
Ẹgbẹrun un lọna ẹẹdẹgbẹta eeyan lo n tẹle Vee loju opo Instagram rẹ.
Oun naa ti jẹ ẹbun miliọnu meji aabọ Naira.
O tun jẹ ẹbun ohun elo inu ile, ounjẹ ọfẹ, aṣoju ileeṣẹ, irinajo si orilẹ-ede Scotland, ati ẹẹdẹgbẹta Dọla owo Bitcoin.
Neo:
Oríṣun àwòrán, Instagram/Neo
Neo Akpofure ni o ṣeeṣe ki o gba ipo to kẹyin ni BBNaija ti ọdun 2020 yii.
Neo naa dabi Vee ti ori ko yọ lawọn igba to ti wa lara awọn ti BBNaija fẹ le lọ sile.
Eeyan bi ẹgbẹrun lọna irinwo le mẹjọ, lo n tẹle Neo loju opo Instagram rẹ.
Oun naa ti jẹ ẹbun owo to le ni miliọnu mẹta Naira, N3,572,000.
Bakan naa lo jẹ ẹbun ohun elo inu ile, ounjẹ ọfẹ, aṣoju ileeṣẹ, ati ẹẹdẹgbẹta Dọla owo Bitcoin.
Atupalẹ ẹbun fun ẹni to ba gbade BBNaija ọdun yii ni ọgbọn miliọnu naira(N30m), ile pẹtẹẹsi oni yara meji, ọkọ SUV kan, irinajo afẹ si ilu Dublin lorilẹede Scotland atawọn ọpọlọpọ ohun elo ninu ile
Wo nkan ti awọn olukopa to ti já kuro lori eto naa jẹ:
Ẹẹdẹgbẹta Dọla owo Bitcoin
Obateru Akinruntan: Wíwá ohun tá jẹ títí láé ló gbé wa kúrò nílé Ife
Yoruba ni bi ọmọ ko ba itan , yoo ba arọba, tii se baba itan.
Olugbo tilẹ Ugbo, Ọba Frederick Obateru Enitiolorunda Akinruntan ti salaye fun BBC Yoruba pe ilẹ Ugbo lo ilẹ Yoruba lapapọ.
Ọba Akinruntan sọ pe Oghonne ni orukọ ọba Ile Ifẹ n jẹ tẹlẹ, eyi to tumọ si ẹni ọwọ ati ẹni iyi ati igbakeji orisa, inu rẹ si ni wọn ti fa Ooni yọ.
O ni Ikedu ni ede ti awọn Ugbo n sọ nile Ife, Ugbomokun si ni orukọ Ile Ife tẹlẹ.
Ọba alaye naa salaye pe ọna lati wa ohun tawsn yoo jẹ titi laelae lo mu awsn kuro nilu ile Ife lọ silẹ Igbo tawọn wa bayii, nibi ti awọn ti ni ọpọlọpọ ẹja ati epoo rọbi.
Bakan naa lo tun sọ nipa oju ti wọn fi n wo Moremi, to da awọn .
Amọ sa, Ooni tilu Ile Ife, Ọba Enitan Adeyeye Ogunwusi naa ti fesi pe ọpọ eeyan lo n sọ itan ti ko tọ lasiko yii amọ oun ko ni ija pẹlu ẹnikẹni, ohun ti Eledumare ran oun wa se, ni oun fẹ gbajumọ.
Iyabo Ojo: Wọ́n gba N51,950 lọ́wọ́ mi ní pápákọ̀ òfurufú láì ṣe àyẹ̀wò Coronavirus fún mi
Oríṣun àwòrán, Instagram/iyaboojofespris
Gbajumọ osere tiata lobinrin, Iyabo Ojo ti figbe ta lori iwa gbajuẹ tijọba Naijiria n hu lori ayẹwo arun Coronavirus.
Iyabo Ojo, lo sẹsẹ gunlẹ si papakọ ofurufu Muritala Muhammed nilu Eko lati Ilẹ Turkey ni aarọ ọjọ Aje.
Iyabọ ni iwa irẹnijẹ nijọba n se fawọn arinrinajo silẹ okeere tabi to de lati ilẹ okeere nidi ayẹwo arun Coronavirus.
Iyabọ ni aarọ ọjọ Aiku ana si ni oun se ayẹwo arun Coronavirus, ki oun to kuro ni papakọ ofurufu Instabul, lorilẹede Turkey.
Ayẹwo naa si lo ni o jẹ ki wọn gba oun laaye lati wọ ọkọ ofurufu wa sorilẹede yii ni ana.
Obateru Akinruntan: Wíwá ohun tá jẹ títí láé ló gbé wa kúrò nílé Ife
Koda, o ni oun tun paarọ tikẹti oun ati akoko ti oun yoo rinrin ajo, ki oun le gba esi ayẹwo covid 19 naa, eyi ti yoo jẹ ki wsn jẹ ki oun wọ baalu wa sile.
Iyabo Ojo tẹsiwaju pe laarọ ọjọ Aje oni ni oun wọle silẹ Naijiria pẹlu esi ayẹwo coronavirus naa, ti wọn ko tiẹ yẹ iwe naa wo lai naani wahala ti oun se lorilẹede Turkey.
Amọ fun iyalẹnu oun, se ni wọn tun n beere owo mii, tii se gbẹrun mejilelaadọta naira o din diẹ, N51, 950.00 lọwọ oun fun ayẹwo Covid 19.
Oríṣun àwòrán, Instagram/iyaboojofespris
"Wọn ko tiẹ se ayẹwo kankan fun mi, wọn kan gba owo lọwọ mi ni, ti wọn si fi ẹrọ yẹ ara mi wo bo se n gbona si.
Lẹyin eyi ni wọn fun mi ni iwe kan lati tun lọ se ayẹwo Coronavirus ni adugbo Lekki.
Bẹẹ ni mo n beere pe ki lo sẹlẹ si ayẹwo Coronavirus ti mo se lana, se ẹbu ni?
Haa, iwa alọni lọwọ gba ati irẹnijẹ gbaa ni eleyi. Iyabo Ojo pariwo."
Osere tiata naa wa n beere pe ki lo de tijọba Naijiria ko maa se ayẹwo arun Covid 19 fawọn arinrinajo to gunlẹ ni papakọ ofurufu gẹgẹ bi wọn ti n se nilẹ Turkey?
SS3 ní mo wà báyìí, mo sì ti gba àmì ẹ̀yẹ̀ púpò nílé-lóko gẹ́gẹ́ bí onílù - Ayansike
O fikun pe ọtalerugba o din mẹwa 250TL owo Turkey ni oun san lati fi se ayẹwo Coronavirus ọhun, eyi to to ẹgbẹrun mẹẹdogun naira wa ni Naijiria.
Bẹẹ ni oun si gba esi ayẹwo naa laarin wakati mẹfa pereninu papakọ ofurufu ti oun ti se ayẹwo ọhun.
Eyi si lo mu ko maa kọminu pe ki lo de ti wọn gba owo oun ni papakọ ofurufu nilu Eko, ti wọn si fun oun ni iwe lati lọ se ayẹwo arun Coronavirus ni adugbo Lekki?
Haa, iya ma jẹ mi o. Afi bii ẹni pe eyi ko tun to, se ni awọn osisẹ asọbode naa tun fikun iya naa. Se bi iya nla ba gbe ni sanlẹ, ke ke ke mii tun maa n gori rẹ ni.
Toyin Atoyebi mechanic: Ẹ wo Toyin, ọmọbinrin ọdún 16 tó ń tún skadà àti gẹnẹrátọ̀ ṣe ní
Iyabo fikun pe awọn osisẹ asọbode tun fẹ gba owo lọwọ oun si lori awijare pe awọn ẹru to ba kọja ẹgbẹrun lọna aadọta naira, oun yoo sanwo itanran fun.
Ọmọ, mo wọ mọ wọn lọwọ ni o, emi to jẹ pe wọn ti kan mi ni eewo tẹlẹ, ti wọn ti ja mi kulẹ, fine kọ, fanta ni.
"Iyabo Ojo wa n fi ika hanu pe ""ki lo de ti orilẹede Naijiria ko mọ ju owo lọ, a si ku imura ajọdun ominira ọgọta ọdun Naijiria o."""
Kunle Afolayan: Òun àti Mike Ezuruonye ń gbéná wojú ara wọn lórí ayélujára
Oríṣun àwòrán, Instagram
Nnkan ko rọgbọ laarin awọn eekan meji lagbo ere sinima lorilẹede Naijiria, Mike Ezuruonye ati Kunle Afọlayan lasiko yii.
Awọn mejeeji yii lo n kọlu ara wọn, ti wọn si n tahun si ara wọn lori ayelujara lori awọn atẹjade kan ti awọn mejeeji gbe jade loju opo ayelujara wọn.
Gbajugbaja oṣere sinima ede oyinbo ati igbo ni Naijiria, Mike Ezuruonye lo bọ sori ayelujara lati ko bilala ọrọ fun Kunle Afọnlayan.
Eyi ko sẹyin bo ṣe ni o gbe atẹjade ori ayelujara kan ti arabinrin kan fi soju opo rẹ jade si gbangba.
Arabinrin naa, ti orukọ rẹ lori ayelujara njẹ Mwandu Chibwe kọ iwe kan si Kunle Afọlayan loju opo instagram rẹ, nibi to ti n fi ẹsun kan Mike.
Obateru Akinruntan: Wíwá ohun tá jẹ títí láé ló gbé wa kúrò nílé Ife
O ni onijibiti ẹda gbaa ni ati pe o ti lu ọpọlọpọ awọn obinrin ni jibiti, bẹẹ lo tun pe osere tiata naa ni gbajuẹ.
Ọrọ yii ni Kunle Afọlayan ba gbe si ita gbangba loju opo Instagram rẹ, eyi to bi Mike ninu.
Ninu esi rẹ ti oun pẹlu gbe soju opo ayelujara Instagram rẹ, Mike Ezuruonye laali Kunle Afọlayan pe, ohun to ṣe ku diẹ kaa to.
O ni Kunle Afọlayan ti n fihan ni ọpọlọpọ igba pe, oun korira ẹya Igbo ati pe, ọjọ idẹyẹsi rẹ si awọn ẹya naa ti pẹ.
"Ninu atẹjade ori ayelujara naa, Mike ni ""ọwọ kekere ti mo ni fun ẹ ti parẹ..."""
O ni ko yẹ ki Kunle Afọlayan maa ṣe bi ẹni ti ko mọ pe awọn eeyan kan a maa fi orukọ awọn eekan oṣere lu jibiti ati pe, ajọ EFCC ti ran awọn kan to fi orukọ oun lọ sẹwọn.
Amọ ṣa, Kunle Afọlayan ti ranṣẹ pada loju opo Instagram pe, oun ko mọọmọ kọ ọrọ naa ati pe, kii ṣe bi oun ṣe lero lo ṣe gbaa.
"Kunle Afọlayan ṣalaye pe, lẹsẹkẹsẹ loun ti jẹ ko di mimọ fun arabinrin naa pe ""Ẹ gba mi o, ewo n temi"""
Bakan naa lo fi kun un pe, oun ko korira ẹya igbo tabi dẹyẹsi wọn, bi o ti wulẹ o mọ.
"Mi o mọ ohun to lee fa aṣigbọ ati aṣitumọ yii. Lootọ gbogbo aye lo mọ pe gbogbo nnkan ti aṣa ati iṣe Yoruba to jẹ temi duro fun ni mo n gbe ga.
SS3 ní mo wà báyìí, mo sì ti gba àmì ẹ̀yẹ̀ púpò nílé-lóko gẹ́gẹ́ bí onílù - Ayansike
Sibẹ mi o ṣai ni ibaṣepọ pẹlu awọn eeyan ẹya miran, paapaa julọ, awọn eya Igbo nitori naa, kii ṣe ohun to bojumu fun emi ati Mike Ezuruonye lati wa sọ ọrọ naa di ti ẹlẹya-mẹya.
Ọ̀dọ́mọkùnrin ẹni ọdun mẹ́rìndínlọ́gbọ̀n ṣá bàbá rẹ̀, ẹni ọdún àádọ́rin pa
Oríṣun àwòrán, Martenslawfirm.com
Arakunrin ẹni ọdun mẹrindinlọgbọn kan ni wọn fi ẹsun kan pe o pa baba rẹ, alagba Christopher Ogum ni ilu Umuomaku nijọba ibilẹ Orumba South nipinlẹ Anambra
Ṣọfẹli ikọle ni wọn ni o fi pa baba rẹ ti wọn ni ọjọ́ ori rẹ jẹ aadọrin ọdun ti o si sare sin in ni oloku oru sinu saare kan ti ko gbẹ jin pupọ.
Iroyin latẹnu awọn akọroyin iwe iroyin abẹle kan ṣalaye pe igbiyanju Chris afurasi naa lati sa mọ ofin lọwọ lo bọ si pabo pẹlu bi awọn ara adugbo ṣe mu u ti wọn si lu u bi ẹni maa ku .
Awọn aladugbo naa ni wọn fi ipa mu u lati fi saare to sin baba rẹ naa si han ti wọn si tun ni ko hu oku rẹ jade pada.
Nigba to n fidi ọrọ naa mulẹ fun awọn akọroyin, alukoro ileeṣẹ ọlọpaa ni ipinlẹ Anambra, Haruna Mohammed ṣalaye pe ọwọ ti ba afurasi naa,
Ati pe wọn si ti gba irinṣẹ to fi ṣiṣẹ buruku naa lọwọ rẹ gẹgẹ bi ẹri lati lo nile ẹjọ́
Obateru Akinruntan: Wíwá ohun tá jẹ títí láé ló gbé wa kúrò nílé Ife
Wo àṣírí tó gbé ìgbéyàwó Remi àti Bola Tinubu dúró bó tilẹ̀ jẹ́ pé ẹ̀sìn wọn yàtọ̀
Oríṣun àwòrán, MOtherhood-in-style
Iyawo Aṣiwaju ẹgbẹ oṣelu APC, Bola Tinubu, Oluremi Tinubu ti sọ pe iṣoro iyandaagbe lo sọ oun di ẹlẹsin Kristiẹni tootọ.
Remi Tinubu, to jẹ sẹnetọ fun ẹkun Lagos Central, gẹgẹ bi Iwe Iroyin ori ayelujara, Motherhood-in-Style ṣe sọ, sọ lasiko ifọrọwanilẹnu wo kan to ṣe pẹlu ileeọẹ amohunmaworan TVC pe lasiko ti oun n da gbe pẹlu ọmọ meji lorilẹ-ede America ni oun di onigbagbọ.
O ṣalaye pe oun di atipo ni America pẹlu ọmọ oun meji, lasiko ti ijọba Ọgagun Sani abacha, ni Naijiria fi ọkọ oun si ẹwọn, nitori ọrọ June 12.
Tinubu: Nítorí Tinubu, àwọn ọmọge Sanwo-Olu da ìlù bolẹ̀
Bakan naa lo sọ pe bi oun ṣe di obinrin akọkọ gẹgẹ bi iyawo gomina ipinlẹ Eko, mu ki oun mọ pe itọni Ọlọrun nikan lo le mu oun ṣe aṣeyọri lori ipo naa.
Bi ọdun marun ni mo fi n ṣe atipo, ti eeyan ba si ni iṣoro, Ọlọrun nikan lo le sa ba."
Asiko ti mo wa ni America ni mo di atunbi.
O fikun ọrọ rẹ pe oriṣiriṣi ijọ ni oun wa Ọlọrun de.
"O le debi i pe mo ni aisan to n mu ni gbagbe nkan 'Amnesia', nigba ti mo pada de, nitori pe iṣoro naa ti pọju.
Nitori naa si ni mi o ṣe fẹran lati ma a lọ si ode ariya, nitori ọpọ eeyan ni mi o damọ mọ."""
Oríṣun àwòrán, Rauf Aregbesola/facebook
O ni oun ko ju ẹni ọdun mẹrinlelọgbọn lọ nigba ti oun ati ọkọ oun (Bola Tinubu) pinya, fun igba akọkọ. Koda, ọrọ naa le debi i pe ọna ẹburu ni a n gba rira lẹẹkan l'oṣu mẹfa.
Laipẹ yii lo ṣe ayẹyẹ ọjọ ibi ọgọta ọdun.
Inira gba a ni asiko naa jẹ fun mi, paapa bukaata awọn ọmọ. Nitori naa, iriri ọtọ lo pada jẹ, nigba ti mo pada si Naijiria lati di iyawo gomina.
Lori bi oun ati ọkọ rẹ ṣe jẹ ẹlẹsin ọtọọtọ, Sẹnetọ Tinubu sọ pe oun ko ri bi nkan babara nigba ti oun ati ọkọ rẹ pade.
"O ni ""ọmọ ijọ Anglica ni mi, ọpọ Kristiẹni lo si n fẹ Musulumi lasiko naa. Koda, ẹgbọn mi obinrin lo mu emi ati ọkọ mi mọra."""
"Nkan kan ni pe, baba mi sọ fun ọkọ mi pe ""mo nireti pe o ko ni di ọmọ mi lọwọ lati ma a lọ si ṣọọṣi.'' O si ṣeleri pe oun ko ni ṣe bẹ ẹ."""
"Otitọ to wa nibẹ ni pe, ọkọ mi pọn ẹsin mi le gan-an, emi naa si pọn ti ẹ le. Nitori naa ni ko sẹ si ija."""
Remi Tinubu tun ṣalaye pe oun ko fi igba kankan ni iṣoro ri, nitori pe oun fẹ Musulumi lọkọ, bakna naa ni ọkọ rẹ ko fi agidi mu awọn ọmọ wọn lasi ṣe ẹsin Islam.
"¨Ilana ẹsin Kristẹni ni mo fi tọ awọn ọmọ mi dagba, bo tilẹ jẹ pe orukọ Musulumi ni wọn n jẹ."""
BB Naija: Kí ló pa Elisha Abbo, Leycon àti Naira Marley pọ̀, tí àríyá yóò fi wáyé?
Inu ẹni kii dun, ka pa mọra ni ọrọ awọn ololufẹ Olalekan Agbeleshebioba, ti sps eeyan mọ si Leycon, to gbegba oroke ninu asekagba idije BB Naija fun tọdun 2020.
Idi ni pe Senator to n soju ẹkun idibo Ariwa Adamawa, Elisha Ishaku Abbo ti kede pe oun fẹ se apejẹ ati ayẹyẹ idawọ idunnu pẹlu Leycon to jawe olubori naa.
Ninu fidio kan to gba ori ayelujara kan bayii, ni Sẹnatọ Abbo ti kede pe, nitori oun se agbatẹru fun Leycon, o di dandan ko jawe olubori ninu idije naa.
"Gbogbo ẹyin ololufẹ Leycon, ẹ sunmọ lonii bi ka dijọ se ariya. Mo ti sọ fun yin pe Lecon n gbe owo ile BB Naija bọ wa sile, o si ti de bayii.
Akomolede ati Aṣa lori BBC: Kí ní ìtúmọ̀ Sílébù àti àmi ohun tó ń fún ni?
Nitori naa, ẹyin ti Naira Marley, nibo lẹ wa? O ya, a n lọ silu Eko lọ se ariya, Naira Marley, o ya sunmọ ibi, jẹ ka ls se ariya fun Lekan ooooo."
Bẹẹ ba si gbagbe, Sẹnatọ Abbo yii ni ẹnu n kun lati ọdun to kọja lori ẹsun pe o lu obinrin kan ninu ile itaja, ti fidio naa si gba ori ayelujara kan.
Amọ ọjọ Aje ni iroyin gbalẹ pe, ile ẹjọ giga ilu Abuja ti ni ki Sẹnatọ Abbo yii lọ san miliọnu lọna aadọta naira fun obinrin naa, ti Abbo fiya jẹ.
Obateru Akinruntan: Wíwá ohun tá jẹ títí láé ló gbé wa kúrò nílé Ife
Lẹyin wakati mẹrinlelogun ti idajs naa waye, ni akọtun fidio miran tun lu sori ayelujara ninu eyi ti Sẹnatọ Elisha Abbo ti n kesi Naira Marley pe kawọn lọ silu Eko, ls se ariya fun Lekan.
Ibeere ti ọpọ eeyan wa n beere ni pe, ki lo pa Sẹnatọ Elisha Abbo, Naira Marley ati Lekan pọ?
Oríṣun àwòrán, Punchng
Saaju la ti mu iroyin wa fun yin pe, ile ẹjọ giga ilu Abuja, to wa ni Maitama, ti dajọ pe ki sẹnetọ to n ṣoju ẹkun idibo Ariwa Adamawa, Elisha Abbo, san aadọta miliọnu Naira, gẹgẹ bi owo itanran, fun oṣiṣẹ ile itaja kan to  fi iya jẹ.
Oṣu karun-un, ọdun 2019 ni fidio kan jade sori ayelujra, to si ṣafihan bi Sẹnetọ Abbo ṣe n ko igbaju, igbamu fun obinrin kan ni ṣọọbu ti wọn ti n ta awọn eroja ibalopọ nilu Abuja.
Ọpọlọpọ ọmọ Naijiria lo koro oju si ihuwasi sẹnetọ naa.
Eyi mu ki ọrọ naa de ileeṣẹ ọlọpaa, ti wọn si kọkọ gbe e lọ si ile ẹjọ majisireti kan ni agbegbe Zuba, nilu abuja.
Ṣugbọn, adajọ ile ẹjọ naa, Abdullahi Ilelah, wọgile ẹjọ naa, lẹyin ti Abbo kọwe pe oun ko ni ẹjọ kankan latiu jẹ.
Arabinrin naa, Osinibibra Warmate, pẹlu iranlọwọ awọn agbẹjọro rẹ, pe ẹjọ miran si ile ẹjọ giga ilu abuja, ti wọn si fi ẹsun kan Sẹnetọ Abbo pe o tẹ ẹtọ rẹ mọlẹ.
Onidajọ ile ẹjọ giga naa, Samira Bature si ti dajọ pe ki Sẹnets Abbo san miliọnu lọna aadọta Naira fun arabinrin Warnate, lati fi tu u ninu.
Akomolede ati Aṣa lori BBC: Kí ní ìtúmọ̀ Sílébù àti àmi ohun tó ń fún ni?
Olukọ wa lonii ni Niyi Osunlolu, oun si ni yoo maa kọ wa nipa itumọ silebu.
Gẹgẹ bii alaye olukọ, Silebu ni ọrọ tabi ege ọrọ ti eemi le gbe jade lati ẹnu ni ẹẹkan soso laisi isoro kankan.
O ni a le ge ọrọ si silebu niye igba ti eemi ba jade.
Bakan naa ni olukọ salaye pe, iye igba ta ba ni imọ afẹfẹ latinu ẹdọ fooro wa, lo n sọ iye Silebu to wa ninu ọrọ kan.
Alaye olukọ pọ lori Silebu, ẹ wa nnkan fidi le lati kẹkọọ siwaju nipa ege ọrọ, taa mọ si Silebu yii.
BB Naija winner 2020: Laycon ní òun kò lérò pé òun le mókè, àgbéga orin lòun bá lọ sílé náà
Oríṣun àwòrán, Instagram/itslaycon
Ẹni to gbegba oroke ninu idije BB Naija fọdun 2020, Olamilekan Agbeleshebioba, ti gbogbo eeyan mọ si Laycon ti kede pe oun ko bun iya oun gbọ, ki oun to lọ kopa ninu eto naa.
Laycon, ẹni to sisọ loju ọrọ yii lasiko to n kopa lori akanse eto kan ni ikanni BBC Yoruba, salaye pe eeyan meji ni oun fi igbesẹ oun naa to leti, eyiun Maneja ati ẹgbọn oun.
Amọ o ni o da oun loju pe iya oun n se atilẹyin fun oun lasiko ti oun wa nile BB Naija naa, to si maa n gbadura fun aseyọri oun nitori pe gbogbo ohun ti oun ba dawọle, ni iya oun maa n sugba rẹ.
Oríṣun àwòrán, Instagram/itslaycon
Laycon, ẹni to salaye pe oun ko ni lero rara pe oun le jawe olubori ninu idije naa, fikun pe oun naa gbero lati kopa lori eto naa, ki oun lee se agbelarugẹ orin ti oun n kọ ni.
Nigba to n mẹnuba ọjọ manigbagbe fun lasiko to wa lori eto BB Naija, Olamilekan ni ayajọ Johnny Walker ati Guinness stars, ti oun, Vee ati Nengi wa ni isọri kannaa, ni oun ko le gbagbe laelae.
Ondo Elections 2020: Ọgọ́rùn-ún ọdún tí a máa lò lórí oyè l'Ondo, ẹ ó rí àrà - Ojon YPP
Nigba ta bi Laycon nipa obinrin to n pariwo lori ayelujara pe oun ti loyun fun, Olamilekan ni laelae, ọrọ ko ri bẹẹ, irọ si lo wa nidi rẹ nitori obinrin kankan ko ni oyun fun oun.
Ẹ wo fidio ifọrọwerọ BBC Yoruba pẹlu Laycon naa ni oju opo wa ni Facebook wa:
Bakan naa lo sisọ loju rẹ pe, ọrẹ oun ni Vee, bẹẹ ni ko si ọjọ kankan to jẹ ọjọ ibanujẹ fun oun lasiko ti oun wa nile BB Naija.
Awọn ohun to ti ṣẹlẹ si Laycon saaju asiko yii:
Oríṣun àwòrán, NAirametrics
Saaju la ti sọ fun yin pe, Gomina ipinlẹ Ogun, Dapo Abiodun ti fun yan oludije to bori ninu ile BB Naija lọdun yii, Olamilekan Agbeleshebioba, ti ọpọ eeyan mọ si Laycon gẹgẹ bi asoju fun ipinlẹ naa.
Bakan naa ni gomina Abiodun tun fun Laycon ni ẹbun ile oni yara mẹta ati owo to to miliọnu marun naira gẹgẹ bii owo iwuri lati mọ riri rẹ.
Gomina ipinlẹ Ogun sisọ loju ọrọ yii lasiko to n gbalejo Laycon ni ọọfisi rẹ to wa ni Oke Mọsan nilu Abeokuta.
"Gomina Abiodun ni ""Emi funra mi n foju sọna lati ba ọ sisẹ gẹgẹ bi awokọse iwa rere, aseyọri, abuda gidi, iwa tutu ati ododo, eyi tii se ara abuda ijọ̀ba ipinlẹ Ogun, koda, agbegbe Odeda lo ti wa."""
O wa gba Laycon nimọran lati lo agbara rẹ fun didẹkun awọn iwa kotọ lawujọ, awọn iwa ti kii se ti ọmọluabi atawọn iwa ibi miran.
Ijoba ipinle Ogun naa ti ki Lekan ku oriire pelu erongba lati jo sise papo sii lodun to m bo.
Won gboriyin fun un gẹ́gẹ́ bii ogidi ọmọ Ogun to tẹpa mọsẹ
Oríṣun àwòrán, OGIRS
Ijọba ipinlẹ Ogun se sadankata Lekan pe omọ to se e fi yangan ni fun awọn ọdo asiko yii,
Koda, won ti ranṣẹ ikini ku orire si 'ọmọ ologo' Laycon, to jẹ owo ati ẹbun BBNaijia to kasẹ nilẹ lọjọ Aiku.
Ijọba Ogun  ko danu duro lori ikinni nikan, wọn tun ni ko ma gbagbe lati san owo ori rẹ fun ọdun 2021 ninu owo to jẹ naa.
Ati pe inu awon si maa dun lati jọ́ dowopọ sii lodun to m bo
Ki lo ti kọ́kọ́ sẹlẹ̀?
Laycon, kú oríire àmọ́ bá ń kó owó orí nínú ẹ̀bùn rẹ nílé BB Naija - Ìjọba Eko
Oríṣun àwòrán, Twitter/jidesanwoolu/BBNaija
Ijọba ipinlẹ Eko ti ranṣẹ ikini ku orire si 'ọmọ ologo' Laycon, to jẹ owo ati ẹbun BBNaijia to kasẹ nilẹ lọjọ Aiku.
Ijọba Eko ko danu duro lori ikinni nikan, wọn tun ni ko ma gbagbe lati san owo ori rẹ fun ọdun 2021 ninu owo to jẹ naa.
Loju opo Twitter ajọ to n mojuto gbigba owo ori nipinlẹ Eko LIRS ni wọn fi ọrọ yii sọwọ, lati le ran Laycon leti pe, awọn n duro de owo ori rẹ ninu owo to gba.
Ọrọ yii  ti n mu ki awọn eeyan maa sọ orisirisi ero wọn nipa rẹ lori ayelujara.
Bi awọn ṣe n sọ pe o yẹ tabi ko yẹ ki Olamilekan san owo ori, lawọn miran n jiyan lori iye owo ori ti Laycon jẹ gangan.
Koda, awọn miran n gba a ni imọran lati rọra na owo naa, ko ba ma na owo ori to yẹ ki o san pọ mọ.
Naijiria ko yatọ si awọn orileede mii lagbaye ti awọn eeyan ti n san owo ori lori owo tẹtẹ tabi idije idaraya ti wọn ba jẹ.
Ni Naijiria ko si agbelewọn to yatọ lori owo ori awọn elere idaraya tabi awọn to n ṣe iṣẹ amuludun.
Owo ori ti wọn n san ko yatọ si eyi ti onikaluku n san lori owo to wọle fun lọdun.
Oríṣun àwòrán, Twitter/BBNaija
Fun idi eyi Laycon yoo ni lati san owo ori lori owo to jẹ ninu idije yi ati apapọ iye ẹbun to ri gba ayafi eleyi ti ijọba ba yọnda fun labẹ ofin.
Amọ ṣa ijọba ipinlẹ ibi to ba ti jẹ owo bi apẹrẹ ti Laycon to waye ni Eko yi ni o lẹtọ lati gba owo naa lori apapọ owo ti Laycon ba pa wọle lọdun .
Kò yẹ kí ìjọba máa ní àwọn mẹ̀kúnú lára lásìkò Coronavirus yìí- Rewane
Akitiyan ìjọba láti mú kí àwọn ọmọ Nàìjíríà san owó orí
Nigeria @ 60: Wo àwọn àdínkù tó ti dé bá àṣà àti èdè Yoruba
Oríṣun àwòrán, @ogundamisi
Iran Yoruba jẹ ọkan gboogi lara awọn ẹya to laami laaka, to si tun tobi julọ ni Naijiria.
Iwọ Oorun ilẹ Afrika ni ẹya Yoruba fi ṣe ibugbe, bo tilẹ jẹ Naijiria ni Yoruba pọ si ju, ṣugbọn awọn ọmọ Yoruba tun wa ni Benin, Togo ati lawọn agbegbe kan ni orilẹ-ede Ghana.
Gẹgẹ bi awọn onimọ ṣe sọ, ko din ni miliọnu mẹtadinlaadọta awọn Yoruba to wa kaakiri agbaye.
Ohun kan pataki to ya ẹya Yoruba sọtọ laarin awọn ẹya to ku lagbaye, paapaa ni Naijiria, ni ibọwọ f'agba, ede, aṣa, aṣọ wiwọ, ounjẹ, igbeyawo, ati bẹẹ bẹẹ lọ.
Obateru Akinruntan: Wíwá ohun tá jẹ títí láé ló gbé wa kúrò nílé Ife
Ṣugbọn lati nnkan bi ọgọta ọdun sẹyin ti Naijiria ti gba ominira lọwọ awọn oyinbo alawọ funfun, n ṣe lo da bi pe nnkan wọnyi ko ri bo ṣe wa tẹlẹ nigba aye awọn baba nla wa.
Wo diẹ lara awọn aṣa ati iṣe Yoruba, to ti n dẹnukọlẹ lati nnkan bi ọgọta ọdun sẹyin.
Ìkíni nilana adayeba:
Gbogbo eeyan lo mọ kaakiri agbaye pe, ṣe ni ọmọde maa n dọbalẹ ki agba, to ba jẹ ọkunrin, ti obinrin a si kunlẹ pẹlu orunkun mejeji, lati ki agbalagba nilẹ Yoruba.
Oríṣun àwòrán, @MBuhari
Ṣugbọn o jọ bi ẹni pe ko ri bẹẹ mọ laye ode oni, n ṣe lo ba dabi pe awọn eeyan ti n yi ikunlẹ tabi idọbalẹ pada si ibọnilọwọ.
Awọn agba miran kii tilẹ reti ki awọn ọdọkunrin dọbalẹ ki awọn mọ, bẹẹ ni awọn obi ko kọ awọn ọmọ wọn lati dọbalẹ tabi kunlẹ ki wọn kaarọ mọ debi pe wọn yoo ki oriki wọn.
Se ni awọn ọdọkunrin aye ode oni maa n gbiyanju lati bọ awọn agbalagba lọwọ, koda a fi bi ẹni pe afin ọba nikan ni awọn eeyan ti n naa tan bayii, eyii ti ko yẹ ko ri bẹẹ.
Oúnjẹ:
Lara awọn ounjẹ ilẹ Yoruba to lamilaaka ni iyan, amala, adalu, ikọkọkọrẹ, ti awọn ọbẹ bii gbẹgiri ati ewedu, ẹfọ riro ati bẹẹ bẹẹ lọ.
Laye ode oni, ọpọ ọmọ Yoruba, papa awọn ọdọ ni ko mọ bi wọn ṣe n se awọn ounjẹ wọnyii, ẹlomiran ko tilẹ jẹ wọn ri.
Oríṣun àwòrán, @Quora
Ootọ ni pe awọn ounjẹ kan jẹ ti awọn ilu ti o yatọ sira wọn, ṣugbọn pupọ ninu awọn ọmọ Yoruba ode oni lo nifẹ ounjẹ oyinbo ju ilẹ wọn lọ.
"Abajọ ti wọn ṣe n pe awọn ọmọ aye ode oni ni awọn ọmọ iran ""indomie."""
Ẹsin abalaye:
Laye atijọ, ẹsin abalaye, ti ọpọ mọ si ẹsin ibilẹ ni awọn Yoruba maa n se, to fi mọ awọn ọdun bii, Osun-Oṣogbo, Ẹyọ, Ogun, Ọdun Ọlọjọ, ọdun Ijẹṣu, ati bẹẹ bẹẹ lọ.
Gbogbo awọn ọdun wọnyii ni adinku ti de ba ju ti atẹyinwa lọ nitori ẹsin igbagbọ, ẹsin Musulumi ati igbalode.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Adinku ti de ba iye awọn ẹlẹsin abalaye nitori igbagbọ awọn eeyan pe Satani ni wọn n sin.
Igbeyawo:
Yatọ si bi wọn ṣe n ṣe ayẹyẹ igbeyawo laye atijọ, bi awọn eeyan ṣe n gbe iyawo sile ti yatọ gbaa si ti aye atijọ.
Laye ọjọhun, baba ọkọ ni yoo lọ ba baba iyawo lati beere fun aya fun ọmọ rẹ, awọn ọmọ naa si le jẹ majesin nigba naa, ṣugbọn ko ni nnkan se.
Oríṣun àwòrán, Wojuola
Laye ode oni oju opo ikansiraẹni bii Instagram ati Facebook ni ọpọ ti n ri ọkọ tabi aya, ọpọ a si ti fun ara wọn loyun tan ki awọn obi wọn to mọ ẹni ti wọn n ba ṣere ifẹ.
Ede:
Bo tilẹ jẹ pe ọpọ awọn oyinbo alawọ funfun lo ti tẹkọ leti wa si Naijiria lati kọ nipa ede, aṣa ati ẹsin abalaye Yoruba, pupọ ninu awọn awọn ọmọ Yoruba ni ko le e sọ ede naa.
Awọn onimọ kan ti di ẹbi iṣẹlẹ yii ru awọn obi to n sọ ede Gẹẹsi si awọn ọmọ wọn ninu ile dipo ede abinibi wọn.
Akomolede ati Aṣa lori BBC: Kí ní ìtúmọ̀ Sílébù àti àmi ohun tó ń fún ni?
Eyii to buru ju nibẹ ni bi awọn ti ko kuro ni Naijiria ri, ko se le e sọ ede Yoruba, bẹẹ ede Gẹẹsi ti wọn n sọ naa ko dan mọran lẹnu wọn.
Nibo la n lọ?
Awọn eeyan kan ti n beere ohun ti yoo ṣelẹ si ede ati aṣa Yoruba, ti yoo ba fi pe ọgọrun ọdun ti Naijiria gba ominira lọwọ oyinbo alawọ funfun.
Ti iran Yoruba ko ba fẹ ki ede ati aṣa wọn parun, ojuse gbogbo wa ni!
US Presidential Election Debate 2020: Trump àti Biden bínú sọ̀rọ̀ síra wọn lásìkò ìtàkurọ̀sọ
Oríṣun àwòrán, Reuters
Fun igba akọkọ, itakurọsọ waye lọjọ Isegun laarin awọn oludije aarẹ gbankọ meji, to n du aga akoso ilẹ Amerika mọ ara wọn lọwọ.
Donald Trump to wa latinu ẹgbẹ oselu Republican ati Joe Biden to jẹ oludije fun ẹgbẹ oselu Democratic ni wọn dijọ sọ ohun ti wọn fẹ gbe se fun ilu, ti ọpa asẹ ba tẹeyikeyi  lọwọ lẹyin ibo aarẹ naa ti yoo waye losu Kọkanla ọdun 2020.
Itakurọsọ naa to waye ni Cleveland, nipinlẹ Ohio ni omilẹgbẹ eeyan lorilẹede Amẹrika ati ni gbogbo agbaye tẹti gbọ.
Amọ fun iyalẹnu ọpọ eeyan, se ni awọn oludije mejeeji naa tutọ si ara wọn loju lasiko itakurọsọ ọhun, paapaa, nigba ti wọn n se agbeyẹwo laasigbo iwa ẹlẹyamẹya to kọja lọ ati arun Coronavirus ti ọwọja rẹ le koko lorilẹede Amẹrika.
Oríṣun àwòrán, Reuters
Ọrọ lori arun Coronavirus lasan gba to ogun isẹju, ti wọn si n tako ara wọn lori ipa ti ọwọja itankalẹ arun naa ko lori ọrọ aje orilẹede Amẹrika, abẹrẹ ajẹsara, lilo ibomu-bonu ati ọwọ ti aarẹ Trump fi mu arun naa nibẹrẹ.
A si lee ni ibinu ni awọn mejeeji fi n sọrọ sira wọn lasiko itakurọsọ naa, ti wọn si tun fija pẹẹta ninu ọrọ wọn lori awọn ẹka to nii se pẹlu igbe aye ọmọniyan bii iwa ọdaran, eto ilera, koda, ọrọ ẹbi wọn gan tun da ija silẹ.
Koda, ọrọ naa su ẹni to se atọkun eto itakurọsọ yii, Chris Wallace nitori bi awọn mejeeji se n tako ara wọn, ti ekinni si n tẹnu bọ ọrọ ekeji lasiko to ba n sọrọ lọwọ.
Oríṣun àwòrán, Reuters
Igba ti ọrọ naa fọnna soju ni akoko ti wọn pe Trump nija pe ko wa bu ẹnu atẹ lu iwa ẹlẹyamẹya lorilẹede Amẹrika, ati bi awọn alawọ funfun se n jẹ gaba lori awọn alawọ dudu.
Asiko yii si ni Trump taku delẹ lati bu ẹnu atẹ lu ijẹgaba naa, sugbọn dipo bẹẹ, se lo kesi ikọ kan to n jẹ Proud Boys, pe ki wọn gbaradi ni sẹpẹ.
Alẹ ariwo, ija ati asọ gbaa si la lee pe akoko itakurọsọ naa fun awọn oludibo ti ko tii pinnu nipa ẹni ti wọn yoo dibo wọn fun.
A si lee ni itakurọsọ naa tubọ poruru ọkan wọn siwaju ni nitori bi Trump se n tako ofin to de eto naa, to si n tutọ si alatako rẹ loju, naa ni Biden n pe ede abuku ati oko ọrọ si Trump .
Akọsilẹ nipa itakurọsọ naa si fihan pe igba mẹtalelaadọrin ni awọn oludije ipo aarẹ mejeeji gba ọrọ mọ ara wọn lẹnu, ninu eto naa to waye fun wakati kan ati aabọ.
Oríṣun àwòrán, @thehill
Saaju la ti mu iroyin wa fun yin pe, eto idibo sipo Aarẹ orilẹ-ede Amẹrika ti sun mọ etile, awọn oludije sipo Aarẹ ọhun ti n gbaradi fun itakurọsọ ti yoo waye loṣu Kẹsan an ati ni oṣu Kẹwaa ọdun 2020.
Itakurọsọ laarin Aarẹ Donald Trump ati oludije sipo Aarẹ Joe Biden yoo waye lawọn ọjọ wọnyii:
Bakan naa ni igbakeji Aarẹ Amẹrika Mike Pence ati oludije sipo igbakeji Aarẹ, Kamala Harris, naa yoo maa na tan bi owo ni ọjọ keje, oṣu Kẹwaa, ọdun 2020 ni Salk Lake City, Utah.
Akoko ti itakurọsọ naa yoo maa waye lawọn ọjọ naa ni aago meji si aago mẹta abọ ọsan.
Ohun ti itakurọsọ naa yoo da le lori:
Awọn olujiroro naa yoo sọrọ fun iṣẹju marundinlogun lori awọn akori wọnyi:
Oríṣun àwòrán, Reuters
Aarẹ Trump ati Biden yoo ni iṣẹju meji pere lati fesi si ibeere ti awọn eeyan ba ni, ki wọn to bọ si gbagede.
Ireti awọn eeyan nibi itakurọsọ naa:
Ọpọ awọn onimọ nipa eto oṣelu kaakiri agbaye lo ti n sọrọ lori ohun to le ṣẹlẹ nibi ifọrọwerọ awọn oludije ọhun.
Bi awọn kan ṣe n sọ pe Trump yoo fakọyọ nitori kii ṣe ajoji si iru ifọrọwerọ bẹẹ, lawọn miran n sọ pe Biden naa kii ṣe ẹran rirọ.
Ọkan lara awọn alatilẹyin Trump, Mike Harlow sọ fun BBC pe ere ọwọ lasan ni Trump yoo fi Biden ṣe ninu itakurọsọ ọhun.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Bakan naa ni Reem Sabha sọ pe ibẹru oun ni pe, bo tilẹ jẹ pe Biden le e gbiyanju lati ta putu,  o ṣeṣe ki awọn eeyan ma dibo fun nitori akitiyann rẹ ninu ijiroro naa..
"O ni ""Ẹru n ba mi nitori awọn eeyan kan ti n sọ pe Joe Biden ko ni okun to lati jẹ Aarẹ Amẹrika ti awọn miran si n lero pe o ti n dagba ju ẹni ti yoo di ipo Aarẹ mu."""
Gẹgẹ bi awọn onwoye ohun to n lọ nipa eto oṣelu Amẹrika ṣe so, itakurọsọ awọn oludije ni ipa ninu ipinu awọn oludibo lori ẹni ti wọn yoo dibo wọn fun.
Boya Trump ni yoo tẹsiwaju gẹgẹ Aarẹ lẹyin idibo naa ni tabi Biden yoo yẹ aga m,ọ nidii, gbogbo ẹ wa lọwọ awọn oludibo.
Marriage in Zamfara: Sẹ́nétọ̀ Kabiru Marafa ní àìsí ìrànwọ́ fọ́mọ òrukàn ló jẹ́ kí òun di ẹrù ìyàwó fún wọn
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Sẹ́nẹ́tọ̀ nígbà kan rí láti ìpínlé Zamfara, tí ṣe ìrànwọ́ ẹrù ìyàwó fún ìyàwó mẹ́tàlá kan tí wọ́n jẹ́ ọmọ òrùkan ní Gusau, olú ìlú ìpínlẹ̀ Zamfara.
Inú ìdùnnú ni àwọn ọmọ òrukàn yìí wa nítorí pé, wọn kò lérò pé wọn yóò rí irú ẹrù ìyàwó tí wọ́n rí lọ́fẹ̀ẹ́ yìí dì, gẹ́gẹ́ bíi ọmọ òrukàn.
Sẹ́nẹ́tọ̀ Kabiru Marafa sọ pé, òun ṣe ìrànwọ́ yìí ni nítorí pé òun wòye bí àwọn ọmọ tí àwọn agbébọn sọ di ọmọ òrukan ṣe pọ̀ tó ní Ìpínlẹ̀ náà.
"Sẹ̀nẹ́tọ̀ ọ̀hún sọ pé: ""Ní Ìpínlẹ̀  Zamfara báyìí, àwọn ọmọ orukan yóò tó ẹgbẹ̀rún lọ́nà ọgọ́ta, tó sì jẹ́ pé àwọn ọmọ òrukàn yìí ò sì ní olùrànlọ́wọ́."
"O ni àyàfi ẹni tó bá wo ti Ọlọ́run, tí ó ríi pé ó yẹ kó ràn wọ́n lọ́wọ́ """
"Ó tún fi kún un pé: ""Nígbà tí àsìkò ìgbéyàwó ọmọ mi tó, mo wàásù fún un pé kó má jẹ́ kí wọn nà owo ni ìnákúnàá níbi ètò ìgbéyàwó rẹ̀, nítorí a le fi owo naa ṣe iranwọ fun àwọn aláìní."
"Mo sì dúpẹ́ lọ́wọ́ Ọlọ́run pé ó fagilé àwọn ohun to le gbọn owo lọ níbi ìgbéyàwó rẹ̀, tó sì lọ owó ọ́hún lati fi ran àwọn ọmọ òrukàn mẹ́tàlá di ẹrù ìyàwó wọn."""
Ó ní àwọn ọmọ òrukàn pọ̀ tí wọ́n ti dájọ́ ìgbéyàwó sọ́nà, ṣùgbọ́n tí wọ́n ń sún ọjọ́ náà sí wàjú nítorí pé kò sí owó.
Oríṣun àwòrán, FACEBOOK
Eyí ló fà á tí mo fi ríi pé ó tọ́ kí n sa àwọn tí wọ́n ti dájọ́ ìyàwó wọn tipẹ́ nítorí kí n lè bá wọn di ẹrù ìyàwó kí wọ́n leè báà rọ́nà lọ.
Wọ́n sún ìgbéyàwó sí wájú nítorí àìní.
Sẹ́nẹ́tọ̀ Marafa sọ pé, ọmọbìnrin kan wa tí wọ́n sún ìgbéyàwó rẹ̀ sí wájú ní ẹ̀ẹmẹ̀sán nítorí àìní.
"Tí a bá sì ronú nípa ìgbéyàwó ọhun, ọpọ nǹkan tí wọ́n ó nàá kò tó nǹkan, ṣùgbọ́n wọn kàn ń sún ìgbéyàwó náà sí wájú ni nítorí jíjẹ ọmọ òrùkàn àti àìní.
Akomolede ati Aṣa lori BBC: Kí ní ìtúmọ̀ Sílébù àti àmi ohun tó ń fún ni?
Ní àwọn gbèríko, ẹ ó ríi pé wọn ń sún ìgbéyàwó sí wájú nítorí àìní, àwọn ènìyàn wa kìí sìí rán irú àwọn ọmọ òrukàn yìí lọ́wọ́.
Eléyìí ló fà á tí mo fi ṣe ìrànlọ́wọ yìí, a ó sì tẹ̀síwajú láti máa wá irú àwọn ọmọ òrukàn yìí jáde, tí a ó ṣí mà ràn wọń lọ́wọ́."
Àwọn ẹbí àwọn tí wọ́n rí ìrànwọ́ yìí gbà sọ pé, kò sí nǹkan tí àwọn lè sọ lóríi bí wọ́n ṣe báwọn nu omijé àwọn nù, yatọ si pe ki awọn dupẹ.
Obateru Akinruntan: Wíwá ohun tá jẹ títí láé ló gbé wa kúrò nílé Ife
Wọn ni tẹlẹ, awọn ko ri igbeyawo ọmọ wọn ṣe nitori àìní owó tí wọn yóò fi di ẹrù ìyàwó fún wọn, eléyìí tí wọ́n tí bà wọ́n ṣe báyìí.
Ighalo Transfer Fee: Ilé aṣòfin Osun ní òun kẹ́ẹ́fín pé àpò àdáni ní owó náà wà
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ile Igbimo Asofin ipinlẹ Osun ti bẹrẹ iwadii lori ẹgbẹrun mẹwaa pọnun, to kan ẹgbẹ agbabọọlu Osun United, lara owo adehun to gbe Odion Ighalo lọ si Manchester United.
Idi ni pe ile asofin kẹfin pe owo naa ti wọ apo aladani kan.
Ẹgbẹ agbabọọlu ipinlẹ Osun ọhun, ti o n jẹ Prime FC, ni  Ighalo ti gba bọọlu kẹyin ko to lọ si ilẹ okeere, nibi to ti darapọ mọ ẹgbẹ agbabọọlu Norwegian kan ni Lyn Oslo lọdun 2007.
Ọkan lara awọn to sun mọ kọmisọna to n ri si ọrọ ere idaraya Yemi Lawal, wa lara awọn ti wọn pe si ipade ni ile igbimọ asofin fun iwadii ọrọ naa lọsẹ to kọja.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Bakan naa, ni awọn miran to tun wa nibi ipade ti alaga igbimọ ile lori ọrọ ere idaraya, Abdullahi Adegbile pe ni awọn Alakoso ẹgbẹ agbabọọlu Osun United.
Akọwe ẹgbẹ agbabọọlu naa, Kabiru Adekunle ati adele adari igbimọ alabojuto ere idaraya ni Osun, Rotimi Oludunmoye naa peju si bẹ pẹlu.
Bakan naa ni wọn darukọ Gbenga Ololade to jẹ adari Prime FC nigba naa, gẹgẹ bi ọkan lara awọn to mọ nipa owo ti wọn fi ra Ighalo lọ nigba naa.
Alaga igbimọ ile asofin fun ere idaraya, Adegbile salaye pe, igbimọ naa ko ti pari iwadii wọn lori ọrọ naa.
SS3 ní mo wà báyìí, mo sì ti gba àmì ẹ̀yẹ̀ púpò nílé-lóko gẹ́gẹ́ bí onílù - Ayansike
Lẹyin ti a gbọ iroyin, a pe gbogbo awọn ti ọrọ kan. Lẹyin iwadii lẹkunrẹrẹ, mo fi n da yin loju pe a sọ abajade nkan to ṣẹlẹ ni gbangba, a o si tun wọn pe ninu ọsẹ yii.
Ọkan lara awọn oṣiṣẹ Osun United ti ko fẹ ki orukọ oun jade, sọ fun ile iṣẹ iroyin Punch pe, ẹgbẹrun mẹwaa pọun wọle sinu akanti banki Access Osun United, ninu oṣu kaarun ọdun.
O fi kun pe, aarẹ ẹgbẹ agbabọọlu naa tẹlẹ ati adari ile iṣẹ to n ri si ọrọ ere idaraya lọwọ, nikan ni wọn le buwọlu iwe owo akanti ọhun.
O ni ipade pẹlu ile igbimọ asofin ko tii ni iyanju.
Toyin Atoyebi mechanic: Ẹ wo Toyin, ọmọbinrin ọdún 16 tó ń tún skadà àti gẹnẹrátọ̀ ṣe ní
"Ko si aniani, owo wọle si apo owo Osun United, sugbọn wọn ko tilẹ bun awọn alaṣẹ Osun United to ni akanti naa leti rara.
Alaga igbimọ naa ni ki a tun pada wa fun ipade miran lori ọrọ ọhun ni ọjọ Eti to kọja, sugbọn o ṣeni laanu pe, awọn ọmọ ile igbimọ asofin ko yọju."
Ololade, to jẹ adari Prime FC lasiko naa salaye pe, ile igbimọ asofin wa lori ọrọ naa ati pe, wọn ti kilọ fun awọn pe ẹnikẹni ko gbọdọ ba awọn oniroyin sọrọ, titi ti iṣẹ iwadii yoo fi pari.
Goitre Patients: Àwọn èèyàn tó ní àrùn gẹ̀gẹ̀ ní ọ̀pọ̀ ìkórira àti ìdẹ́yẹsí ní àwọn ń kojú
“Ọpọ wa lo ti n gbe arun gẹgẹ yii kiri fun ọdun mẹwa, mẹẹdogun ati mẹẹdọgbọn nitori ẹru n ba wa lati se isẹ abẹ.”
Eyi ni ibẹru ti ọkan lara awọn eeyan to ni arun gẹgẹ nilu Badagry fihan fun ikọ iroyin BBC Yoruba lasiko to n ba wa sọrọ.
Awọn alarun gẹgẹ naa ni ẹrun isẹ abẹ n ba awọn lati se nitori awọn le e ku, lo mu kawọn pinnu lati mase se isẹ abẹ naa.
Koda, wọn fidi rẹ mulẹ pe agbo ni awọn n lo si arun naa, amọ fun ọpọ ọdun, bakan naa ni ọmọ se ori.
Ọpọ wọn si lo sọ nipa idojuti, idẹyẹsi ati ikorira ti wọn n koju lawujọ nitori arun gẹgẹ to n ba wọn finra.
Sugbọn pupọ wọn ti setan bayii lati lọ fun isẹ abẹ lẹyin ti wọn ri awọn eeyan to se isẹ abẹ arun gẹgẹ nipinlẹ Eko, ti iku ko si pa wọn.
Sunday Igboho: N kò gba kọ́bọ̀ lọ́wọ́ ẹnikẹ́ni láti wá ọ̀daràn jáde nínú igbó Kishi
Oríṣun àwòrán, Sunday Adeyemo
Ọjọ nla ati manigbagbe ni ọjọ ti ilumọọka ajafẹtọ ẹni kan, Oloye Sunday Adeyemo, ti ọpọ eeyan n pe ni Sunday Igboho yabo igbo Kishi.
Ilu Kishi ni iroyin tan kalẹ pe awọn afurasi agbesunmọmi ati afẹjẹwẹ ti n huwa laabi ninu igbo igbafẹ Old Oyo National Park to wa nilu naa.
Koda, wọn n ji awọn eeyan gbe lagbegbe naa, wọn n fi tipa ba awọn obinrin lopọ, ti wọn si tun n gba oko lọwọ awọn agbẹ.
Ọpọ eeyan ni awọn adunkooko mọ ni yii ti pa nilu Kishi to wa nijọba ibilẹ Irepo nipinlẹ Oyo, ti wọn si ti sọ awọn miran di alaabọ ara.
Sunday Igboho: Fulani kò leè dúró, táa bá lo ohun ta jogún lọ́dọ̀ àwọ̀n bàbá wa
Awọn iwa ibi yii lo ta Sunday Igboho nidi kan nirọlẹ ọjọ Isẹgun, ọjọ kejilelogun osu Kẹsan ọdun 2020, ti oun ati ọmọlẹyin rẹ fi gba ilu Kishi lọ lati bawọn afurasi afẹjẹwẹ naa fija pẹẹta ninu igbo Old Oyo National Park.
Amọ niwọn igba to jẹ pe a kii ri ẹni sagbara, ọwọọwọ si ni ọmọ ejo n rin, Sunday Igboho ko da nikan lọ silu igbo naa.
Lara awọn to kọwọ rin pẹlu Igboho ni awọn ọmọ ologun ti Area C, awọn osisẹ aabo ara ẹni laabo ilu ati awọn ẹsọ oju ni alakan fi n sọri, taa mọ si fijilante.
Oríṣun àwòrán, Sunday Adeyemo
Irọlẹ si ni wọn wọ igbo naa titi di owurọ ọjọ keji, ti wọn n wa awọn afurasi ọdaran naa kiri inu igbo to fẹ naa.
Ni kete to gunlẹ si ilu Kishi ati awọn ikọ rẹ, aafin Iba tilu Kishi ni Igboho kọkọ morile, nibi to ti lọ se ago laafin si ori ade naa, ajeji kii sa wọ ilu, ki onilẹ ma mọ.
Nigba to n sọrọ lori idi to fi gbe igbesẹ naa, Sunday Igboho salaye pe oju ko gbọdọ ti ilẹ Yoruba lo mu ki oun fi ẹmi ara oun lelẹ lati lọ koju awọn afurasi apamọ lẹkun jaye naa.
Oríṣun àwòrán, Sunday Adeyemo
N ko gba kọbọ lọwọ ẹnikẹni ki n to gbe igbesẹ yii, ifẹ iran Yoruba ti mo ni si lo mu mi se bẹẹ. Mo mọọmọ fi ẹmi ara mi lelẹ, fun isọkan ati alaafia Yoruba ni, ti Ọlọrun si lo awọn eeyan lati ti mi lẹyin.
Sunday Igboho wa se sadankata si ileesẹ ologun ilẹ wa atawọn ileesẹ agbofinro yoku to tii lẹyin lati gbogun ti iwa ọdaran lagbegbe Oke Ogun.
Bakan naa lo ki awọn ẹsẹ fijilante nijọba ibilẹ Irepo, Olorunsogo ati Oorelope fun isẹ takuntakun ti wọn n se ninu Igbo ọhun lati sẹ eegun ẹyin awọn agbesunmọmi yii ati ifẹ ilẹ baba wọn ti wọn ni.
Igboho tun gbosuba fun gomina Seyi Makinde ati Iba tilu Kishi fun aayan wọ̀n lati fi ẹsẹ eto aabo mulẹ lagbagbe naa.
O wa tun gbara ta lori bi awọn agbẹ to jẹ iran Yoruba se n fi oko wọn silẹ fun awọn afurasi ọdaran to n ba wọn lalejo, ti wọn si n sa asala fun ẹmi wọn.
O ni ilẹ baba wa niyi, awọn agbẹ naa kii si se ajeji, nitori naa, ko si ohunkohun to yẹ ko maa dun mahuru mahuru mọ wọn lori ilẹ baba wọn.
Lara awọn ẹru ti wọn ri ni ibuba awọn afurasi ajinigbe lasiko abẹwo wọn naa ni ibọn AK 47 mẹrin, ibọn AK 49 kan, ọpọ ọta ibọn, awọn ẹrọ foonu alagbeka ati owo beba pupọ.
Goitre Patients: Àwọn èèyàn tó ní àrùn gẹ̀gẹ̀ ní ọ̀pọ̀ ìkórira àti ìdẹ́yẹsí ní àwọn ń kojú
Lẹyin aayan wọn ọhun, alukoro ileesẹ ọlọpaa nipnilẹ Oyo, Olugbenga Fadeyi ni ọwọ tẹ awọn afurasi ajinigbe mẹta to n sisẹ laabi ni agbegbe ijsba ibilẹ Irẹpọdun.
Ondo election 2020: Iléeṣẹ́ ọlọ́pàá ní PDP ló ń polongo ní Owo, APC kàn ń kọjá lọ ni
Oríṣun àwòrán, @EyitayoJegedeCO
Lẹyin ikọlu awọn ẹgbẹ oselu APC ati PDP nipinlẹ Ondo, ọpọ awọn eniyan ipinlẹ naa lo ti n foya pe. se eto idibo yoo lọ ni irọwọ rọsẹ nipinlẹ naa bayii?
Gbogbo rukerudo oselu to n gba ọgbẹ lara awọn eeyan lẹnu lọọlọ yii nipinlẹ Ondo ati iporuru ọkan araalu nipa eto idibo to n bọ, lo mu ki BBC Yoruba kan si ẹgbẹ oselu mejeeji to n taporogan ni Ondo.
Olabode Richard Olatunde, to jẹ  agbenusọ fun ikọ ipolongo ibo Rotimi Akeredolu, lasiko to n ba BBC Yoruba sọrọ naa gba pe nnkan to n ṣẹlẹ ni agbo oselu nipinlẹ Ondo n kọni lominu.
A rọ awọn agbofinro lati ba wa pẹtu sawọn ẹgbẹ PDP ninu, bi ikọlu ojoojumọ yii se n lọ n kọni lominu
Olatunde ni Ikọlu lọtun losi lo n waye si ẹgbẹ oselu APC sugbọn eyi to sẹlẹ lọjọ Isẹgun kii ṣe lori ẹgbẹ oṣelu APC, bikoṣe ikọlu si ilu Owo.
Bii igba ti PDP kogun wọ ilu ni, ti ẹ ba de Owo bayii, ọpọ ọmọ Owo lo wa ni ile iwosan ti awọn ọkọ si bajẹ loriṣiriṣi.
Oríṣun àwòrán, @EyitayoJegedeCO
O ni iwoye awọn ni pe, nitori oludije labẹ ẹgbẹ oṣelu APC Rotimi Akeredolu wa lati ilu Owo, ni wọn se n dunkoko mọ wọn, ki wọn maa ba jade wa dibo lọjọ idibo.
"Lori ẹsun ti PDP fi kan APC pe, oun lo n ṣe awọn iṣẹ ibi yii, Olatunde ni ""yoo dara kí awọn oniroyin beere fọto awọn janduku to di ọna, ootọ ibẹ ni pe, ko si janduku kankan, eke lasan ni. """
"Awọn ọmo ẹgbẹ oselu PDP ti wu gbogbo awọn patako atọka ẹgbẹ APC to wa ni Emure.
Oríṣun àwòrán, @newsbreakngr
Ni bayii, wọn ti mu ọkan lara wọn, o si ti wa ni agọ ọlọpaa, awon meje ti wọn ka ibọn mọ lọwọ ninu awọn ọmọ ẹgbẹ oselu PDP, ni ile ẹjọ ti ni ki wọn gbe wọn lọ si Olokuta."
Asaaju ikọ ipolongo Akeredolu fikun pe alafia ni awọn eniyan ipinlẹ Ondo n fẹ, alafia naa si ni APC n fẹ.
Ara n fẹ arakunrin Akeredolu nitori awọn iṣẹ idagbasoke to ti ṣe, awọn ara ilu si n fẹ iṣẹ idagbasoke yii, ni wọn yoo ṣe dibo fun Akeredolu, nitori naa, alafia gbọdọ jọba lọdọ APC lasiko idibo.
Ninu ọrọ tirẹ asoju ẹgbẹ Oṣelu People's Democratic Party (PDP), ni ẹgbẹ naa jẹ ẹgbẹ alaafia, amọ ọpọ igba ni APC maa n dena de awọn.
PDP ni awọn fẹ alafia nitori pe ko tọ lati foro yaro, ninu nkan to sẹlẹ lana, ẹgbẹ PDP ko si setan lati maa ja.
PDP ni ọrọ ni awọn yoo maa ba awọn eniyan sọ lati ri daju pe, wọn jade lati dibo nitori nnkan ti ẹgbẹ oselu keji n fẹ ni lati ko ipaya ba àwọn ara ilu, ki wọn maa ba jade dibo.
Lori ọrọ naa, agbẹnusọ ọlọpa ni ipinlẹ Ondo ni, ọga agba ọlọpaa ti bẹrẹ eto iwadii lori iṣẹlẹ to waye ni ilu Owo lana.
O ni nnkan to jẹ kayeefi ni pe, bi PDP se n fọnrere naa, ni APC n pariwo si ara wọn.
Oríṣun àwòrán, @RotimiAkeredolu
Sugbọn o ni agọ ọlọpaa to wa ni ayika ibi iṣẹlẹ naa ni, bi awọn ṣe gbo iro ibọn ni awọn bẹ ibudo naa wo, sugbọn nnkan ti wọn fi to awọn leti ni pe, awọn ẹgbẹ oselu PDP lo n ṣe ipolongo nibẹ, ti awọn ẹgbẹ oṣelu APC si n kọja.
O ni títì di asiko yii, ko si ẹni to le sọ nnkan to ṣẹlẹ.
Ju gbogbo rẹ lọ, agbẹnusọ ọlọpaa ni idibo ti yoo waye ni ipinlẹ Ondo yoo lọ ni irọwọrọsẹ nitori pe gbogbo ibi ti o lewu ni awọn ti moju to, lati ri daju pe gbogbo nkan lọ deede.
Goitre Patients: Àwọn èèyàn tó ní àrùn gẹ̀gẹ̀ ní ọ̀pọ̀ ìkórira àti ìdẹ́yẹsí ní àwọn ń kojú
O ni ki gbogbo eniyan ni ifọkanbalẹ, ki wọn si jade lọ dibo nitori gbogbo eto lo ti wa nilẹ lati ri pe alafia jọba.
Oríṣun àwòrán, @newsbreakngr
Ni bayii to ku nnkan bi ọjọ diẹ ki eto idibo sipo gomina ipinlẹ Ondo waye, awọn alatilẹyin ẹgbẹ oṣelu APC ati PDP ti kọju ija sira wọn lẹẹkan si ni ipinlẹ ọhun.
Awọn agbẹnusọ ẹgbẹ mejeji fidi rẹ mulẹ pe, lootọ ni iṣẹlẹ naa waye, ti wọn si n di ẹbi iṣẹlẹ ọhun ru ara wọn bi ọmọ iya meji, to n wi awijare niwaju iya wọn.
Iṣẹlẹ naa waye ni ilu Ipele ati Owo, nibi ti awọn eeyan kan ti farapa ti awọn ọkọ si bajẹ.
Atẹjade kan ti agbẹnusọ fun ikọ ipolongo Eyitayo Jegede, tii se oludije gomina labẹ ẹgbẹ oṣelu PDP fi lede ni, awọn janduku lati inu ẹgbẹ APC lo ṣe ikọlu si awọn.
Asaaju ikọ olupolongo ibo fun oludije PDP, Fasua Kayode ni awọn janduku naa yinbọn lu ọkan lara awọn ọmọ ẹgbẹ oun loju ati ni idodo, ninu akọlu ọhun.
Oríṣun àwòrán, theprecisionng
Fasua fi kun pe, ṣe ni wọn gbe ọkunrin naa digbadigba lọ si ile iwosan ijọba ipinlẹ Ondo, eyi to wa ni ilu Akure fun itọju pajawiri.
Agbẹnusọ fun ẹgbẹ naa fi kun pe, wọn tun yinbọn lu awọn ọmọ ẹgbẹ PDP meji miran yatọ si ọkunrin ti wọn gbe lọ sile iwosan, bẹẹ ni wọn tun dana sun ọkọ ipolongo wọn ni ilu Oba-Akoko.
"O ni ""Ṣaaju ki wọn to ṣakọlu si wa, awọn janduku naa ti kọkọ dí ẹnu ọna to wọ ilu Ipele, eyi to jẹ ilu iya oludije labẹ asia ẹgbẹ wa, iyẹn Eyitayo Jegede."""
PDP àti APC fi ìbọn dárà l'Ondo, ọ̀pọ̀ èèyan farapa, àìmọye dúkìá ṣòfò
Ẹwẹ, agbẹnusọ ẹgbẹ APC, Olatunde Olabode sọ pe, irọ patapata ni ẹsun ti PDP fi kan ẹgbẹ oun, o ni ẹgbẹ PDP gan lo ṣakọlu si APC.
"O ni ""N ṣe ni Jegede bẹ awọn ẹru iku rẹ lọwẹ lati kọlu awọn ara ilu Ipele ati Ijebu, ni ijọba ibilẹ Owo."""
"Olabode tẹsiwaju pe ""Inu ibẹru ni awọn eeyan wa wà bayii nitori bi awọn janduku Eyitayo ṣe n yibọn ni ilu Owo."""
Agbẹnusọ ẹgbẹ APC naa ni awọn janduku PDP lo da ilu Owo ru, ti wọn si n ṣakọlu si ẹnikẹni to ba wọ aṣo tabi fila Akeredolu tabi eyii to ni akọle ẹgbẹ APC lara.
"O pari ọrọ rẹ pe ""ko din ni ogun ọkọ ti wọn bajẹ ati ọkẹ aimoye awọn ara ilu ti wọn lu ni ilu bara."""
Obateru Akinruntan: Wíwá ohun tá jẹ títí láé ló gbé wa kúrò nílé Ife
Femi Fani-Kayode: Ọ̀rẹ́ lásán ni Halima Yusuf jẹ́ sí mi, kìí ṣe àfẹ́sọ́nà mi
Oríṣun àwòrán, Femi Fani Kayode
Halima Yusuf ati Femi Fani Kayode
Nnkan bi ọjọ diẹ sẹyin ni iroyin kan gbode lori ayelujara pe, Minisita tẹlẹ feto irina ọkọ ofurufu, Femi Fani-Kayode fẹ gbe iyawo tuntun.
Bẹẹ ba si gbagbe, ko tii ju bi osu kan lọ, ti iroyin gbalẹ lori ayelujara pe igbeyawo Fni-Kayode ati iyawo ile rẹ ti fori sanpọn.
Ṣugbọn minisita ọhun ti fọhun sita pe, irọ patapata ni iroyin naa.
O ni oun ko ṣetan lati gbe iyawo lasiko yii, obirin ti awọn eeyan n ṣọ pe oun fẹ gbe niyawo, Alima Yusuf, kii ṣe afẹsọna oun, bikoṣe ọrẹ lasan.
Goitre Patients: Àwọn èèyàn tó ní àrùn gẹ̀gẹ̀ ní ọ̀pọ̀ ìkórira àti ìdẹ́yẹsí ní àwọn ń kojú
Fani-Kayode lo kede ọrọ naa ninu atẹjade kan to fi sita loju opo Instagram rẹ, nibi to ti parọwa si awọn eeyan lati dẹkun pinpin iroyin ofege nipa oun kiri lori ayelujara.
"O ni ""Awọn kan ti  n gbe ahesọ kan kiri lori ayelujara pe mo n mura fun igbayawọ laipẹ, irọ ni o."""
Omidan Halima Yusuf, ti wọn n pe ni afẹsọna mi kii ṣe afẹsọna mi rara, ọrẹ lasan lo jẹ si mi, o si tun jẹ olufọkantan ati ẹni apọnle lọwọ mi.
Fani-Kayode ṣalaye pe obinirin naa, yatọ si awọn eeyan miran, jẹ olutunu fun oun lasiko yii, ati pe oun mọ riri rẹ ninu aye oun.
Minisita naa pari ọrọ rẹ pẹlu ẹbẹ pe, ki gbogbo awọn gboyi-sọyi lọ so ewe agbejẹ mọwọ nitori oun ko ṣetan lati gbe obinrin naa niyawo.
Tani Halima Yusuf?
Ọmọ bibi ipinlẹ Bornu ni Halima, ṣugbọn ipinlẹ Gombe lo fi n ṣebugbe pẹlu awọn ẹbi rẹ, ko to tẹkọ leti lọ si ilu Abuja ni nnkan bi ọdun diẹ sẹyin lati bẹrẹ iṣẹ owo ṣiṣe.
Oríṣun àwòrán, Halima Yusuf
Halima Yusuf
Gẹgẹ bo ṣe sọ loju popo Instagram rẹ, Halima ni alaṣẹ ati oludari ileeṣẹ Sly Royal, nibi to ti n ta aṣọ awọn obinri ati awọn ẹṣọ ara.
Bakan naa lo tun ṣọ pe oun n ṣowo awọn ohun aṣara loge fun awọn obinrin.
Goitre Patients: Àwọn èèyàn tó ní àrùn gẹ̀gẹ̀ ní ọ̀pọ̀ ìkórira àti ìdẹ́yẹsí ní àwọn ń kojú
Bo tilẹ jẹ pe o ṣoro lati sọ iye ọjọ ori rẹ, ati ileewe to lọ lasiko yii, ọpọ eeyan lo ti n woye pe, o yẹ ko sọrọ lori ibaṣepọ rẹ pẹlu Femi Fani-kayode.
Osun Deputy Chief of Staff Fraud: Agbẹjọ́rò Binuyo ní ìbanilórúkọjẹ́ ní wọ́n fí ẹ̀sùn gbájúẹ̀ ṣé fún
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Owoẹyẹ ni oun ko mọ ohun ti oun n se mọ, ti wọn si fi oogun gba owo to le ni miliọ̀nu lọna mejidinlogoji naira lọwọ oun.
Agbẹjọro fun igbakeji olori oṣiṣẹ lọọfisi gomina ipinlẹ Osun, Abdullah Binuyọ, ti fesi si iroyin to gbode pe awọn ọlọpaa ti fẹsun gbajuẹ kan an oun.
Wahab Ismail, to jẹ agbẹjọro Binuyo, ti wa fi atẹjade sọwọ si BBC Yoruba lori ọrọ yii, to si ni wọn fẹ ba orukọ onibara oun jẹ ni pẹlu iroyin yii.
Saaju asiko yii ni awọn iwe iroyin kan ti gbe iroyin pe, ọfisi ọga agba ọlọpaa Naijiria ti pe Abdullahi Binuyo lẹjọ, lori ẹsun mẹrin to da lori iwa gbajuẹ ati iwe yiyi.
O ni ko si ootọ ninu ẹsun naa, to ni igbakeji olori osisẹ lọọfisi gomina l‘Osun gbimọran pẹlu awọn eeyan kan, lati lu arakunrin Tunde Ajalani ni gbajuẹ owo to to $120,000.
Goitre Patients: Àwọn èèyàn tó ní àrùn gẹ̀gẹ̀ ní ọ̀pọ̀ ìkórira àti ìdẹ́yẹsí ní àwọn ń kojú
Wahab ni ''Ọrọ naa jẹ ọrọ iwa agabagebe ti awọn to gbe jade ko si na tan . Wọn mọọmọ fẹ fi tabuku Binuyo ni''
O ṣalaye pe, bo tilẹ jẹ pe lootọ ni Binuyo mọ si idunadura to waye laarin awọn to ṣe owo to fori sanpọn naa, wọn ko le mu labẹ ofin pe o jẹbi.
O fi kun pe, iye owo ti wọn n sọ ọhun kii ṣe ẹgbẹrun lọna ọgọfa dọla, bi kii ṣe pe ẹgbẹrun lọna ọgọrun dọla nii ṣe.
Oríṣun àwòrán, Twitter/nigeria police
Agbẹjọrọ naa tun sọ pe, lati nkan bii ọdun kan sẹyin ni awọn ti da owo naa pada, ti awọn agbẹjọro rẹ ati ọlọpaa naa jẹri si.
O wa pari ọrọ rẹ pe, awọn yoo tọ ipasẹ ofin lati tako ibanilorukọjẹ ti wọn fẹ ṣe fun Binuyo yii.
Labẹ ofin orilẹede Naijiria, awọn ẹsun ti wọn fi kan Binuyo jẹ eleyi ti ijiya wa fun labẹ ofin, to ni ṣe pẹlu iwa jibiti ati awọn ẹsẹ miran.
Nigeria at 60: Tọ́ka sí àwọn ìpínlẹ̀ tó wá lórí òfìfo máàpù yìí láti dán ìmọ̀ rẹ̀ nípa Nàìjíríà wo
Njẹ o le tọka si awọn ipinlẹ yii jakejado awọn ẹkun mẹfẹfa ni Naijiria? Iṣẹju mẹta pere ni o ni lati dahun ibeere ogun yii, ire o!
(Tẹ aarin ipinlẹ ninu maapu)
(Tẹ aarin ipinlẹ ninu maapu)
(Tẹ aarin ipinlẹ ninu maapu)
(Tẹ aarin ipinlẹ ninu maapu)
(Tẹ aarin ipinlẹ ninu maapu)
(Tẹ aarin ipinlẹ ninu maapu)
(Tẹ aarin ipinlẹ ninu maapu)
(Tẹ aarin ipinlẹ ninu maapu)
(Tẹ aarin ipinlẹ ninu maapu)
(Tẹ aarin ipinlẹ ninu maapu)
(Tẹ aarin ipinlẹ ninu maapu)
(Tẹ aarin ipinlẹ ninu maapu)
(Tẹ aarin ipinlẹ ninu maapu)
(Tẹ aarin ipinlẹ ninu maapu)
(Tẹ aarin ipinlẹ ninu maapu)
(Tẹ aarin ipinlẹ ninu maapu)
(Tẹ aarin ipinlẹ ninu maapu)
(Tẹ aarin ipinlẹ ninu maapu)
(Tẹ aarin ipinlẹ ninu maapu)
(Tẹ aarin ipinlẹ ninu maapu)
Ẹ yaa lọ gbe iwe iba gbepọ ẹda!
Ẹ maa kawe yin deede.
Onimọ nipa Naijiria, O nṣe daada
Coronavirus update: A kò ní gba owó lọ́wọ́ ará ìlú fún ohun eèlò àyẹ̀wò Covid-19 tí a ṣẹ̀sẹ̀ ṣe - NIMR
Oríṣun àwòrán, @nimrnigeria
Ileeṣẹ to n ṣe iwadii nipe eto ilera ni Naijiria, Nigerian Institute of Medical Research, NIMR, ti kede pe ọfẹ ni ohun eelo ti wọn ṣẹṣẹ ṣe, eyii to lagbara lati ṣayẹwo arun Covid-19 pẹlu esi rẹ laarin ogoji iṣẹju.
Ọkan lara awọn oṣiṣẹ ileeṣẹ naa to ba BBC Yoruba sọrọ, Dokita Iwalokun Bamidele lo ṣi aṣọ loju ọrọ naa.
"O ni iṣẹ takun takun ti awọn oṣiṣẹ ileeṣẹ naa ṣe lo jẹ ko ṣeeṣe lati ṣagbekalẹ irinṣẹ ọhun ti wọn pe orukọ rẹ ni ""SARS-COV-2."""
Bo tilẹ jẹ pe Iwalokun ni oun ko tii le sọ igba ti awọn ọmọ Naijiria yoo ni anfani lati bẹrẹ si n lo ẹrọ ọhun fun ayẹwo, o ni iṣẹ n lọ lọwọ lati pari gbogbog eto to ni ṣe pẹlu lilo rẹ.
Nipa bi awọn eeyan yoo ẹ maa lo erọ naa, o ni yoo wa ni awọn ile iwosan ijọba ti awọn to ba fẹ ṣe ayẹwo yo maa lọ sibẹ fun ayẹwo wọn.
Ni ti pe awọn eeyan yoo san owo ayẹwo ọhun,  Iwalokun sọ pe ko si ohun to jọ bẹẹ.
Goitre Patients: Àwọn èèyàn tó ní àrùn gẹ̀gẹ̀ ní ọ̀pọ̀ ìkórira àti ìdẹ́yẹsí ní àwọn ń kojú
"O ni ""Mi o lero pe awọn eeyan yoo san owo kankan lati lo ẹrọ na fun ayẹwo arun Covid-19 rara, nitori ara anfani ijọba fun awọn eeyan niyẹn."""
Ẹwẹ, alaga ẹgbẹ awọn dokita ni Naijiria, NMA, Ọjọgbọn Innocent Ujah ki awọn oṣiṣẹ ileeṣẹ NIMR ku iṣẹ takun takun fun igbiyanju wọn lati ṣagbekalẹ ẹrọ ọhun.
Ujah, to ti fi igba kan jẹ oludari ileeṣẹ naa sọ pe ko rọrun lati gbe iru ẹro ayẹwo bẹ jade ni Naijiria lai si atilẹyin owo iranwọ lati ọdọ ijọba.
"O ni ""Mo ki adari ileeṣẹ naa fun igbiyanju rẹ lati gbe ẹrọ naa jade, paapaa lasiko yii ti ijọba ko fi bẹẹ gbe owo kalẹ fun iwadii imọ ijinlẹ, bẹẹ ko le e si idagbasoke laisi iwadii ijinlẹ to peye."""
"Ọjọgbọn naa pari ọrọ rẹ pe ""Oju ti awa ẹgbẹ awọn dokita fi wo agbekalẹ ẹrọ yii ni pe o jẹ ohun to dara pupọ, inu wa dun, o si tun jẹ ohun iwuri, nitori naa, a ki NIMR ku oriire."""
Lẹyin naa lo rọ ijọba apapọ lati maa ṣatilẹyin fun iwadii imọ ijinlẹ ni Naijiria nipa pipese owo fun awọn ileeṣẹ to n ṣe iwadii.
Nigeria at 61: Ikọ̀ Boko Haram, ìbò June 12, ìwọ́de EndSARS wà lára ìṣẹ̀lẹ̀ tí kò bá sọ Nàíjíríà sójú ogun
Oríṣun àwòrán, @andybes50484929
Orilẹede Naijiria jẹ orilẹede to n san fun wara ati oyin, ti ọba oke si fi ọpọ ohun alumọọni jinki rẹ, ki ogun abẹle to wọle de lọdun 1967.
Bakan naa ni awọn ọlọpọlọ pipe ẹda kun orilẹede yii dẹnu ni ẹka eto iselu, ọrọ aje, eto ẹkọ, imọ ẹrọ, eto ilera ati bẹẹ bẹẹ lọ.
Sugbọn ni aarin ọdun mọkanlelọgọta ti Naijiria ti n tukọ ara rẹ, lai si ọwọ awọn eebo amunisin nibẹ, oju ti ri.
Ọ̀rọ̀ Buhari lọ́jọ́ Òmìnira 2021: A ṣetán láti fi gbogbo ẹni tó bá rúfin sí gbaga òfin
Nàìjíríà kàn wà ni, ẹ ò páàsì, ẹ ò féèlì, ẹ ò kúrò ní kíláàsì kan náà - Àwọn ọ̀dọ́
Aara ti san, atẹgun nla ati iji lile ti fẹ pẹlu, koda, iji ti ja lorilẹede Naijiria, eyi to ti dunkooko mọ eto irẹpọ ati isọkan orilẹede yii, diẹ si lo ku ki orilẹede yii tuka.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ọba Oke nikan si lo mọ idi taa fi wa papọ titi di oni, bi o tilẹ jẹ pe diẹ lo ku, ki iji da omi inu agbọn orilẹede Naijiria nu, paapaa lati ipasẹ ogun abẹle ta ja kọja.
Amọ lero ti awọn eeyan kan, orilẹede yii ko tii kọgbọn rara lati ipasẹ ogun abẹle naa, ta ba wo awọn iwa adaluru ta tun n hu.
Koda, aimọye awọn isẹlẹ adaluru lo ti waye, ti ko ba tun pada di ogun abẹle miran, amọ ti Ọba oke ba wa dẹkun rẹ.
Oríṣun àwòrán, @mavel
Idi ree ti BBC Yoruba fi wọ inu itan lọ lati se agbeyẹwo igba meje ọtọọtọ ti ẹpọn agbo Naijiria ti mi, amọ ti Ọlọrun ko jẹ ko ja, ba se n se ajọdun ominira.
Ọpọ ọmọ Naijiria, paapaa awọn ọdọ ni ko le gbagbe iwọde EndSARS yii, eyi to ku diẹ ko sọ Naijria sinu ogun abẹle miran.
Awọn ọdọ Naijiria lo ko ara wọn jọ lati tako iwa ika ati ifiyajẹni tawọn ọlọpaa n hu, paapaa awọn ikọ ọlọpaa to n gbogun tiwa idigunjale ni Naijiria, ti wọn n pe ni SARS.
Awọn ọdọ lo yari pe ki ijọba apapọ wọgile ikọ naa nitori iwa ika ti wọn n hu sawọn ọdọ ati bi wọn se n pa wọn ni ipakupa.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Laarin osu kẹsan si ikẹwa ọdun 2020 ni awọn ọdọ yii fi n se iwọde alagbara eyi to mu ki ijọba kede pe oun tu ikọ SARS naa ka.
Amọ eyi ko mu kawọn ọdọ naa dẹkun iwọde ọhun, ti wọn si n gbe idi dina lati dena lilọ bibọ ọkọ ati ero, titu ọgba ẹwọn silẹ, kikọlu awọn osisẹ ọlọpaa, ti wọn si tun n kslu awọn ileesẹ ati dukia ijọba gbogbo.
Idi ree tawọn ipinlẹ kan fi kede ofin konile o gbele lọna ati fopin si ifẹhonuhan awọn ọdọ yii.
Sugbọn ni ogunjọ osu Kẹwa ọdun 2020, tijọba ipinlẹ Eko kede ofin konile o gbele tiẹ, ni iroyin tan kalẹ ni irọlẹ ọjọ naa pe awọn ologun ti lọ kọlu awọn ọdọ to n se iwọde lẹnu iloro Lekki nilu Eko.
Oríṣun àwòrán, Twitter
Ọpọ ọdọ ni wọn lo jalaisi lọjọ naa, tawọn miran si fara pa bi o tilẹ jẹ pe ileesẹ ologun ni oun ko yin ọta ibọn to le gbẹmi eeyan nibẹ.
Isẹlẹ naa lo mu ki ibinu awọn ọdọ tubọ ru soke, ti awọn janduku kan si ya si igboro lọjọ keji yika Naijiria, wọn n jo ile, mọto, ileesẹ ijọba, agọ ọlọpaa, bẹẹ ni ọpọ ẹmi ba rogbodiyan naa rin.
Ọpọ Ọba oke ti ko jẹ ki ọrọ naa ju bo se wa lọ, ko to ba wa bomi pa ina rẹ, amọ rabaraba isẹlẹ naa ko ti tan nilẹ ni Naijiria.
Igba keji ti isọkan ati ifẹsẹmulẹ Naijiria yoo mi pupọ nilẹ ni asiko ti ijọba ologun Ibrahim Badamosi Babangida wọgile eto idibo aarẹ ta di lọjọ kejila osu Kẹfa ọdun 1993.
Eto idibo aarẹ naa, ti wọn ni Oloye MKO Abiola lo bori rẹ, nijọba ologun Babangida wọgile, eyi to fa laasigbo nla, paapaa nilẹ Yoruba.
Oríṣun àwòrán, @MKO_Abiola10
Awọn ẹlẹgbẹjẹgbẹ ajafẹtọ ẹni nilẹ yii ati ni awujọ agbaye lapapọ ni wọn gbọnmu lori igbesẹ naa ti oniruuru iwọde ati atako si n waye.
Lasiko naa, ara ko rọ okun, bẹẹ ni ko rọ adiẹ pẹlu, tawọn osisẹ gunle iyansẹlodi, awọn osisẹ elepo rọbi ko sisẹ, ohun gbogbo dẹnu kọlẹ, ti ẹya Yoruba si n dunkooko lati ya kuro nilẹ Naijiria ti wọn ko ba kede oloye Abiola bii aarẹ Naijiria.
Nitori ọrọ yii nijọba Babangida fi yẹba kuro lori aleefa, ti ijọba ologun miran, ti Sani Abacha lewaju rẹ, si gba akoso orilẹede yii lọwọ rẹ.
Oríṣun àwòrán, Wikipedia
Sugbọn sibẹ, ilu ko tuba tusẹ, titi ti Sani Abacha fi ku sori aleefa, MKO Abiola naa jade laye, ti ijọba ologun Abubakar Salami si gba akoso orilẹede yii lọdun 1998.
Ijọba Salami yii lo seto idibo mii, ti Oloye Olusegun Obasanjọ fi jawe olubori ninu ibo aarẹ to waye lọdun 1999, eyi to fopin si laasigbo oselu ati ti ẹlẹya mẹya naa.
Ọba oke si lo mu ki ẹsẹ Naijiria duro re pada, bibẹẹkọ, wahala ibo June 12 ko ba ti ree isọkan ati irẹpọ Naijiria ni ẹfasẹ.
Oríṣun àwòrán, Sabah
Isẹlẹ miran to tun n dunkooko mọ isọkan ati irẹpọ orilẹede Naijiria, to si tun wa nibẹ lọwọlọwọ bayii ni idasilẹ ati ọsẹ ikọ adunkooko msni Boko Haram.
Gẹgẹ ba se gbọ, ikọ alatilẹyin awọn oloselu ni ikọ naa, eyi ti Mohammed Yussuf ko sodi, amọ nigba to ya lo parada di ijọ ẹlẹsin Islam.
Ikọ Boko Haram yii lo n beere pe oun n fẹ amulo ofin Sharia lorilẹede Naijiria, ti ko si gbọdọ si ohunkohun to jọ mọ ẹkọ iwe tabi ọlaju igbalode.
Oríṣun àwòrán, @BokoHaramWatch
Awọn ọmọ ikọ Boko Haram yii wa gbagbo sori nigba ti asaaju wọn, Mohammed ku si ahamọ awọn agbofinro, ti wọn si bẹrẹ si ni soro bii agbọn.
Wọn ri atilẹyin ikọ agbesunmọmi lagbaye, Al Queda gba, tawọn naa si bẹrẹ si ni yin ado oloro kaakiri orilẹede Naijiria.
Bi o tilẹ jẹ pe ẹkun ariwa ni ọwọja ikọ afẹjẹwẹ Boko Haram naa pọ si, sibẹ, awọn eeyan ẹkun iwọ oorun ati ila oorun guusu Naijiria naa n mọ ipa rẹ lara.
Awọn ọmọ ikọ Boko Haram maa n jo ile, pa eeyan bo se wu wọn, wọn n ji eeyan gbe gba owo, ti wọn ko si mọ ọmọde tabi agba, koda, eremọde ni ado oloro jiju jẹ fun wọn.
Oríṣun àwòrán, @trueNija
O tiẹ to akoko kan, ti ẹkun guusu Naijiria n beere pe ti ajọse ko ba see se, ki wsn jẹ ki onikaluku pinya, ki alaafia lee jọba.
Ọpọ ẹmi lo bọ sọwọ awọn ọmọ ikọ Boko Haram eyi to si tun n peleke si bayii, bi o tilẹ jẹ pe ẹkun ariwa Naijiria lo n fi ara gba ikọlu wọn julọ.
Sugbọn nigba ti ina wọn jo de ori koko, akude nla lo mu wọ isọkan ati irẹpọ Naijiria, ọpẹ Ọlọrun ti ko si fẹ ki okun irẹpọ ati isọkan ja ni orilẹede yii.
Ikọlu miran to tun n fẹju mọ isọkan orilẹede Naijiria ni aawọ ojoojumọ to n waye laarin awọn Fulani darandaran ati awọn agbẹ.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Bi wahala yii si se n waye lẹkun ariwa, paapaa lawọn ipinlẹ to wa ni ẹkun aarin gbungbun Naijiria bii Plateau ati Benue, naa lo n waye ni guusu Naijiria.
Ko fẹẹ si ipinlẹ kan kan to bọ lọwọ ikọlu awọn Fulani darandaran yii, ti wọn n wa oko tutu fawọn maalu wsn lati jẹ.
Ọpọ igba si ni itorin ti sọ nipa oniruuru ọsẹ ti wọn n se fawọn agbẹ, yatọ si pe wsn n ba ire oko wọn jẹ, wọn yoo tun sa wọn lọgbẹ tabi gba ẹmi wọn.
Oríṣun àwòrán, ECWA
Atobi ma see bawi la lee pe awọn darandaran naa, nitori ọwọ ofin kii saba mu wọn, ohun gbogbo ti wọn ba si se, asegbe ni.
Ọwọja ikọlu wọn naa wa tubọ peleke si lasiko ti ijọba Muhammadu Buhari de ori aleefa, ẹni ti oun gan jẹ ẹya Fulani.
Bi awọn darandaran, ti iwadi ni ọpọ wọn kii se ọmọ Naijiria si se n gba ẹmi ni Plateau, ni wọn n se ọsẹ ni Benue, ti ipinlẹ Oyo, Ekiti, Akwa Ibom, Rivers ati bẹẹ bẹẹ lọ si n pariwo wọn pẹlu.
Bi ijọba ko se lee dẹkun ati wawọ isẹ laabi awọn darandaran yii wọlẹ, lo n dunkooko mọ isọkan ati irẹpọ Naijiria, ti gbogbo ẹya si n kọrin ki Ọlọmu da ọmu iya rẹ gbe.
Lọwọlọwọ bayii, ikọlu awọn darandaran naa ko tii ni ojutu, eyi to n dunkooko gidi mọ irẹpọ Naijiria nibayii to n sami ajọdun ominira ọgọta ọdun rẹ.
Eto aabo to mẹhẹ pupọ lorilẹede Naijiria ti sokunfa ọpọ aisedeede eyi to dunkooko mọ ifẹsẹmulẹ ati isọkan rẹ.
Lọwọ lọwọ bayii, okun irẹpọ Naijiria ti yinrin,  Ọba oke nikan si lo lee se ti okun irẹpọ naa ko fi ni rẹ ja laipẹ, gẹgẹ bi igbakeji aarẹ, Yemi Osinbajo se woye.
Oríṣun àwòrán, @Chibuzo76881211
Eyi ko si sẹyin orin lilọ laa lọ, bilẹ yii ko ba wọ mọ, a lọ ilọ miran tuntun, ti ọpọ ẹya to wa ni Naijiria n kọ lẹnu.
Awọn ẹya Yoruba, Igbo, Efik atawọn ẹya ke ke ke miran lo gba pe ẹya Hausa/Fulani n jẹ gaba le awọn lori, ti wọn si n pariwo pe ki ipinya wa.
Lọpọ igba ti eto idibo ba si n bọ, ni ariwo yoo gba ilẹ kan, ti ibẹru bojo yoo si wa pe se orilẹede Naijiria ko ni pin si yẹlẹyẹlẹ bayii.
Koda, orisun ọrọ aje wa gan n fa isoro, tawọn ẹya ti epo rọbi pọ si naa si n dunkooko pe awsn fẹ ya kuro ni Naijiria lati lee se akoso ohun alumọni ti ọba oke fi jinki awọn.
Oríṣun àwòrán, Olayomi Koiki
Bi iran Yoruba se n beere fun idasilẹ orilẹede Oduduwa, ni Igbo n beere fun idasilẹ orilẹede olominira Biafra.
Ẹgbẹ ọmọ bibi ẹya kọọkan bii Arewa, Afenifere, Ohaneze, Pandef ati bẹẹ bẹẹ lọ ni orin isọkan Naijiria ko si lẹnu wọn mọ, orin bo le di ogun , ko di ogun ni wọn n kọ.
Koda, ọrọ ẹlẹsinjẹsin ati ẹlẹya mẹya gan wa lara ohun to n mi ẹsẹ isọkan ati irẹpọ Naijiria , tawọn klẹsin Kristiẹni ati Musulumi si n fi ojoojumọ tutọ si ara wọn loju.
Oríṣun àwòrán, @Dray4lyf
Iwa ipani nipakupa naa n dakun wahala yii, ti ọpọ ẹya ko si ni igbẹkẹle mọ ninu orilẹede Naijiria.
Ta ba wa wo oniruuru isoro ati isẹlẹ to n mi ifẹsẹmulẹ Naijiria, ki ni ọna abayọ?
Ọpọ eeyan lo si n beere pe, se Naijiria yoo se ajọdun ọgọrun ọdun gẹgẹ bii orilẹede kan soso bi?
Ado Ekiti Blind Couple: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú
Idahun si ibeere naa wa lọwọ iwọ ati emi ati iwa ta ba hu lati fẹsẹ irẹpọ Naijiria mulẹ tabi pagidina rẹ.
Queen Elizabeth and Nigeria at 60: Obabinrin Elizabeth kí Nàìjíríà kú oríire òmìnira ọgọ́ta ọdún
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Obabainrin ilẹ Gẹẹsi, Obabinrin Elizabeth keji kí Nàìjíríà kú oríire òmìnira ọgọ́ta ọdún
Obabainrin ilẹ Gẹẹsi, Obabinrin Elizabeth keji ti ransẹ ikinni si Aarẹ Muhammadu Buhari lori ajọdun ominira ọgọta ọdun ti Naijiria n se laarọ ọla.
Ileesẹ ilẹ Britiko to wa ni Naijiria, British High Commission lo gbe isẹ oriire na wa fun Aare Buhari
Ogbeni Femi Adesina to jẹ oluranlọwọ pataki fun Aare Buhari lo fi ikinni naa lede fun awọn akọroyin.
"Lara ohun ti Obabinrin Elizabeth sọ ni pe: "" Pẹlu ayọ ati inu didun ni m fi ki Naijiria ku oriire ọgọta ọdun lẹyin ominira."
Mo gbadura ilọsiwaju sii fun orile-ede Naijiria.
UK ati Naijiria ni ajọsepọ to dan mọran ti awọn mejeeji si jọ n se anfani fun ara wọn.
Itan awa mejeeji jọ ara wọn, bẹẹ naa si ni awọn eeyan wa jọ ara wọn.
"Mo gbagbọ pe ki ajọsepa yii tun tẹsiwaju lọjọ iwaju""."
Ojọ̀ kinni, osu kẹwaa, ọdun 1960 ni Naijiria gba ominira
Akomolede ati Aṣa lori BBC: Kí ní ìtúmọ̀ Sílébù àti àmi ohun tó ń fún ni?
Independence Day Nigeria: Lamido Sanusi gbóṣùbà fún ìjọba lórí bó ṣe yọwọ́ ìrànwọ́ epo
Oríṣun àwòrán, @Realshisha
Emir ilu Kano nigba kan ri, Sanusi Lamido ni ọpọ awọn to n kigbe kiri pe awọn n ja fun ẹtọ ẹkun awọn, ifẹ apo wọn nikan ni wọn fẹ.
O ni lẹyin ti wọn ba fi ija ẹlẹmẹya ati ẹsin de ipo ijọba tan, wọn maa bẹrẹ si sin ilu nibamu pẹlu ifẹ ọkan wọn.
Lamido sọrọ yii nibi eto kan ti ijọ Convenant Christian Centre, ti pasitọ Poju Oyemade n dari  pe ni ipinlẹ Eko.
Nibi ipade ori ayelujara ọhun, ni wọn ti pe gomina tẹlẹ fun ile ifowopamọ apapọ Naijiria naa, lati wa sọrọ lori ọrọ ija ẹlẹyamẹya ati ẹlẹsin to n fojoojumọ peleke si ni Naijiria.
Ìṣẹ̀lẹ̀ Kàyéèfì: Ìpáǹle tú Abass Owonikoko sí ìhòòhò ayé, kó tó gba kéú lọ́gbà ẹ̀wọ̀n
"O ni isoro naa ko fi bẹẹ niṣe ""pẹlu awọn eniyan orile-ede yii, bikose awọn ọtọkulu rẹ"""
"Mi o lero pe awọn ti wọn ni awọn n ja fun ẹya Hausa, Igbo tabi Yoruba ni ifẹ awọn eniyan naa lọkan.
Ni kete ti wọn ba ti de ijọba tan, imọ ti ara wọn ati ẹbi wọn nikan lo ku.
Ko si ẹni kankan to n soju Arewa, Guusu tabi Ila oorun, nnkan ti mo nsọ ni pe, wọn ni awọn n soju ibẹ sugbọn irọ ni."
Ninu itan Naijiria, ko ti si ijọba ti ko ni asoju lati gbogbo ẹya Naijiria.
Oríṣun àwòrán, @Realshisha
Nnkan akọkọ to yẹ ka mojuto ni pe, a gbọdọ gbagbe ero pe nigba ti eniyan ba wa nijọba, lo n jẹ asoju ẹya abi ẹsin rẹ, ko yẹ ki o ri bẹẹ.
"Sanusi ni, ọkan lara isoro Naijiria ni ọrọ"" Federal Character "" lai fi ti ijafafa ati mimọ iṣẹ doju ami ṣe, ko ni itumọ kankan"""
Lasiko to n fi iyatọ han laarin iṣẹ aladani ati iṣẹ ijọba, Sanusi sọ pe, o ṣe pataki lati ṣe agbekalẹ ilana ti yoo yọwọ oṣelu kuro patapata ninu iṣẹ ijọba.
"O salaye, ""O yẹ ki a ni"" federal Character, sugbọn ki lo de ti a ni minisita, to mọṣẹ rẹ doju ami, to si n mu esi jade, sugbọn ti a tun ni minisita miran ti ko le gbe nkan tuntun ṣe?"
"Ki lo de to jẹ pe ẹya ni ""Federal Character n gbajumọ, lai fi ti awọn to mọ iṣẹ naa ṣe si."
Sanusi wa dupe lọwọ ijọba lori bi wọn se yọwọ iranwọ kuro lori epo, o ni nkan to tọ lati ṣe ni, nitori pe, o ti pẹ to yẹ ki ijọba ti ṣe tori bi eto ọrọ aje ṣe ri.
Oríṣun àwòrán, @tundefashola
Ninu ọrọ tirẹ minisita fun iṣẹ ode ati ilegbe, ọgbẹni Babatunde Fashola ni ki awọn ọmọ Naijiria kọju si ijọba ipinlẹ ati ibilẹ, fun ọna abayọ si isoro wọn, kaka ti wọn yoo fi maa di gbogbo rẹ le ijọba apapọ lọrun.
Fashola ni kii ṣe ijọba apapọ lo ni ile ẹkọ alakọbẹrẹ tabi ile iwosan alabọde ijọba ibilẹ.
Ni Naijiria, ile ẹkọ girama to jẹ ti ijọba apapọ ko ju ọgọrun kan ati meje lọ.
"Mo fẹ rọ awọn eniyan lati lọ ka, iwe ofin Naijiria.
Obateru Akinruntan: Wíwá ohun tá jẹ títí láé ló gbé wa kúrò nílé Ife
O ni ida mẹẹdọgbọn ninu ida ọgọrun ni agbara ti ijoba apapọ ni, ile igbimọ asofin ati ẹka idajọ lo ni eyi to pọju lọ.
Ileeṣẹ ọlọpa ipinlẹ Eko ti fi ikilọ sita pe, ki ara ilu kankan maa ṣe kopa ninu iwọde loni tii ṣe ayajọ ominira Naijiria.
Ikilọ yii kun ikede ti ileeṣẹ ọlọpaa Naijiria lapapọ ti fi sita ṣaaju pe, awọn yoo da ọlọpaa sita jakejado Naijiria lati dena iwa kankan ti yoo ṣakoba fun alafiaa ilu.
Lasiko ipade kan pẹlu awọn ọga ọlọpaa ni ipinlẹ Eko, ni Kọmisana ọlọpaa Eko, Hakeem Odumosu fi ikilọ yi sita.
O ni awọn ko ni fi aye gba akojọ kankan tabi iwọde, to fi mọ ifẹhonu han eyi to le mu ipalara ba iṣọkan Naijiria.
Ẹwẹ, ijọba ipinlẹ Eko fun ara rẹ ati ti ipinlẹ Ogun ti ni, ko ni si afẹfẹ yẹyẹ kankan lasiko ajọdun ominira Naijiria.
Ni ti ipinlẹ Ogun, awọn tun sọ pe, ko ni si lilọ bibọ ọlọkada bẹrẹ lati alẹ ọgbọnjọ oṣu Kẹsan titi di owurọ ọjọ keji oṣu Kẹwa.
Bẹẹ ni wọn ni konileogbele yoo wa lalẹ ọjọ meji, iyẹn ọgbọnjọ oṣu Kẹsan ati ọjọ Kini oṣu Kẹwa
Ninu awọn to n palẹmọ lati ṣe iwọde lọjọ ayajọ ominira Naijiria ni Omoyele Sowore ati awọn ajafẹtọ ominira mii, labẹ akori RevolutionNow.
Bẹẹ naa ni awọn agbarijọpọ ẹgbẹ ọmọ Yoruba mii naa ni awọn fẹ ṣe iwọde lati beere fun Oduduwa Republic.
Awọn ikede wọn yii, yala lati ọdọ ileeṣẹ ọlọpaa ati awọn ijọba ipinlẹ, lawọn eeyan ti n ṣe eemọ si ṣugbọn ti awọn onwoye ni ko ba ofin mu.
Loju opo Twitter awọn eeyan ti n sọ tẹnu wọn nipa aṣẹ tawọn ijọba gbe kalẹ.
10,000 Police constables: Ilé ẹjọ́ wọ́gilé ètò ìgbanisíṣẹ́ tí ọgá ọlọ́pàá ṣé lọdun 2019
Oríṣun àwòrán, @PoliceNG
Ọrọ ti di maa kẹru rẹ pada sile fawọn ọlọpaa ẹgbẹrun mẹwa, ti ọga agba ọlọpaa Naijiria ṣeto igbanisiṣẹ fun lọdun 2019.
Eyi ko si sẹyin bi ile ẹjọ kotẹmilọrun ni Abuja ti ṣe wọgile eto igbaniṣiṣẹ ti wọn fi gba wọn wọle ni 2019.
Igbimọ adajọ ẹlẹni mẹta to gbe idajọ kalẹ lori ọrọ yii ni, ọga ọlọpaa Mohammed Adamu ko laṣẹ tati ṣeto igbanisiṣẹ.
Wọn ni ajọ to n ri si ọrọ akosọ ileeṣẹ ọlọpaa, Police Service Commission, lo laṣẹ lati ṣeto igbaniwọle siṣẹ.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Police Recruitment: Ìlé ẹjọ ti pasẹ pe ki ilé iṣẹ́ ọ̀lọ́pàá dá ìgbaniwolé
Fanfa lori ọrọ yii ko ṣẹṣẹ bẹrẹ nitori loṣu Kẹsan ọdun 2019 ni ajọ to n sakoso ileesẹ ọlọpaa (PSC) ti gba ileẹjọ lọ, lati le fidi agbara wọn mulẹ, nipa gbigba eeyan ṣiṣẹ ọlọpaa.
Ababọ ẹjọ ti wọn pe ni pe, ile ẹjọ giga Abuja dajọ are fun ọga ọlọpaa, Adamu ṣugbọn PSC faake kọri, ti wọn si gba ile ẹjọ kotẹmilọrun.
Goitre Patients: Àwọn èèyàn tó ní àrùn gẹ̀gẹ̀ ní ọ̀pọ̀ ìkórira àti ìdẹ́yẹsí ní àwọn ń kojú
Adajọ Olabisi Ige, to jẹ adajọ to lewaju ninu idajọ naa ni iwe akoso isẹ ọlọpaa lo fun ajọ PSC ni agbara, lati le gba eeyan ṣiṣẹ ọlọpaa.
Ile ẹjọ ni ilana iṣakoso to ni pe ọga ọlọpaa lo ni aṣẹ lati gba eeyan ṣiṣẹ ko fẹsẹmulẹ, nitori naa igbaniṣiṣẹ yii ko bofin mu.
Independence Day Nigeria: Atinuke Oladeru ni kẹ yé ṣépè fún Nàíjíríà mọ́, ẹ pa ohùn dà
Yoruba ni ẹyin lo n di akukọ, bi ọmọde oni ko ba ku, o daju pe agba ni yoo da.
Bẹk ni ọrọ ri pẹlu Atinuke Oladeru Christiana toun naa pe ọgọta ọdun lonii ti orilẹede Naijiria n sami ajọdun ọgọta ọdun to gba ominira.
Asiko ti pọpọ sinsin ominira Naijiria n lọ lọwọ ni ọjọ Kinni osu Kẹwaa ọdun 1960, ni wọn bi arabinrin Oladeru sile aye.
Nigba to n sọrọ lori awọn ohun to n fẹ atunse lorilẹede Naijiria, Oladeru wa ijọba nimọran lati mojuto eto aabo, ilera, eto ẹkọ, airisẹ se awọn ọdọ ati iwa isekupani laibikita.
Bakan naa lo gba awọn ọmọ Naijiria nimọran lati ye sepe fun orilẹede yii, amọ ki wsn pa ohun wọn da, ki wọn si maa se adura fun.
Oladeru ni epe la n sẹ fun Naijiria lati ọgọta ọdun to ti gba ominiria, to si n beere pe igba wo gan wa la fẹ maa gbadura fun?
Oduduwa Republic: Ẹgbẹ́ YOVOLIB ní ìjọba kò gbọdọ̀ gbé Gani Adams àti Banji Akitoye
Oríṣun àwòrán, Olayomi Koiki
Awọn eeyan to n pe fun idasilẹ orilẹede olominira Oduduwa ti kọ iwe ẹhonu lọ sọdọ ajọ isọkan agbaye, United Nations, UN.
Bakan naa ni wọn tun fi iwe naa sọwọ si ajọ isọkan ilẹ Yuroopu, EU, ajọ isọkan ilẹ Afirika, Au, ijọba ilẹ Gẹẹsi , ajọ to n ja fun ẹtọ ọmọniyan atawọn gomina to wa nilẹ Yoruba pẹlu ipinlẹ Kogi ati Kwara.
Koko ohun ti wọn n beere fun ninu iwe ẹhonu naa ni pe ki aabo to peye wa lawọn ipinlẹ to wa nilẹ Kaarọ oojire.
Awọn eeyan naa si lo wa labẹ aburada ẹgbẹ kan to n sọrọ fun ominira ilẹ Yoruba, ti wọn pe ni Yoruba Voice Liberation (YOVOLIB).
Oríṣun àwòrán, Olayomi Koiki
Ẹgbẹ YOVOLIB wa fewe ọmọ mọ ijọba apapọ lorilẹede Naijiria leti lati mase gbe awọn asaaju to n ja fun ominira ilẹ Yoruba bii Aarẹ Ọna Kakanfo, Iba Gani Adams.
Bakan naa lo tun ni mimi kankan ko gbọdọ mi Aarẹ apapọ fun ọmọ Yoruba lagbaye, Yoruba World Congress, YWC, Ọjọgbọn Banji Akitoye pẹlu awọn eeyan miran.
Iwe ẹhonu naa ni ti ijọba Naijiria ba fi ọwọ kan awọn asaaju Oodua pẹrẹ, wọn yoo gburo awọn.
Oríṣun àwòrán, Olayomi Koiki
Bakan naa ni wọn n ke si aarẹ Muhammadu Buhari lati se ohun mẹrin ti yoo mu ki Naijiria bọ lọwọ idẹyẹsi ati ifiyajẹni lagbaye.
Aarẹ ẹgbẹ YOVOLIB nilẹ United Kingdom, Ọmọwe Adekunle Ogunmola tun rọ awọn awujọ agbaye lati sọ fun ijọ Buhari pe ko ye lo ọta ibọn lati tako awọn eeyan to n se iwọde ni Naijiria.
Yomi Fabiyi: Fíìmù ‘Owó orí ẹlẹ́wọ̀n’ jẹ́ ká mọ̀ pé ìgbà ìpọ́njú làá mọ ọ̀rẹ́
O yẹ ki ijọba bọwọ fun ẹtọ araalu lati fi ero wọn han sita, ko si dẹkun  hihu iwa ipa si awọn eeyan to ba n se iwọde."
"Ojuse awọn agbofinro ni lati tọpinpin iwọde to ba n waye, ki wsn si ri pe alaafia jọba lasiko naa, amọ eyi ko ri bẹẹ ni Naijiria."""
Ko din ni ogoji awọn oluwọde lati ẹgbẹ Save Nigeria Group to ti ko si panpẹ ileeṣẹ ọlọpaa ni ipinlẹ Eko bayii lẹyin ti wọn tapa si aṣẹ kọmiṣona ọlọpaa ipinlẹ ọhun lodi iwọde.
Awọn agbofinro mu awọn oluwọde naa lagbegbe Ojota ati Maryland nigba ti wọn n gbiyanju lati tu awọn eeyan naa ka.
Ni agbegbe Maryland yii kan naa ni awọn ọlọpaa ti tu awọn olufẹhonuhan kan ka labẹ asia ẹgbẹ #RevolutionNow to n pe fun ayipada si iṣejọba Naijiria.
Bakan naa ni awọn agbofinro tu awọn to n ṣe iwọde pe ki ẹya Yoruba da yatọ ni Naijiria ka ni Alausa.
Ṣaaju ni ileeṣẹ ọlọpaa ipinlẹ naa ti kọkọ fofin de iwọde ni ọjọ kini, oṣu Kẹwaa, ọdun 2020 ninu atẹjade to fi ṣowọ si awọn akọroyin.
Ṣugbọn awọn eeyan ni kii ṣe akoko niyii lati fidi mọle nitori bi nnkan ṣe n lọ ni Naijiria ko dara to, ko si si ohun miran ti wọn lee ṣe ju ki wọn erongba lede fun ijọba nipa ifẹhonuhan.
Ki lo ti ṣẹlẹ sẹyin?
Iwọde lati tako ipo ti Naijiria wa gbera nilu Eko
Ikọ to n ja fun ẹtọ ọmọniyan to n jẹ Revolution Now ti bẹrẹ iwọde kaakiri ilu Eko.
Iwọde naa lo gbera ni aago mẹwa aarọ, ti ọpọ ero si n wọ kiri oju popo.
Oniruuru akọle ni awọn oluwọde naa gbe lọwọ ninu eyi ti wọn ti n tabuku ijọba to wa lode ni orilẹede Naijiria.
Bakan naa ni wọn koro oju si iwa ijẹgaba, ifiyajẹni ati airisẹse awọn ọdọ ni Naijiria.
Oniruuru orin to tako ijọba ẹgbẹ oselu APC si ni wọn fi sẹnu, eyi to n tabuku ijọba ati oloselu Naijiria.
Ọpọ awọn oluwọde naa lo de fila alawọ ọsan, tii se awọ idamọ ẹgbẹ Revolution Now.
Koda, awọn oluwọde naa ko bẹru awọn agbofinro to duro go go go soju popo lati dena iwọde naa.
Awọn agbofinro naa si lo safihan pe awọn korira awọn ẹgbẹ oselu to wa ni Naijiria, nitori bi wọn se n kọrin eebu mọ awọn oloselu latinu ẹgbẹ APC, naa ni wọn ko yọ tẹgbẹ PDP silẹ.
Wọn ni gbogbo wọn ni wọn lọwọ si bi orilẹede Naijiria se wa yii.
Awọn oluwọde naa ni wọn ni awọn fẹ ayipada si awọn adari to n se ijọba lọwọ ni Naijiria, ti wọn si n fẹ ki iyipda wa.
Lara awọn adugbo ti wọn si se iwọde de ni adugbo Ojọta, Berger, Ikeja ati bẹẹ bẹẹ lọ.
A o maa mu ẹkunrẹrẹ iroyin naa wa fun yin laipẹ.
Sunday Igboho: Sé èmi nìkan ló wà ní Nàíjíríà ni, ó lé ní 1m ọlọ́pàá tó yí ilé mi po
Yoruba Independence rally: Sunday Igboho ní àwọn àgbàgbà Yoruba dalẹ̀
Ilumọọka ajafẹtọ ẹni kan nilu Ibadan Oloye Sunday Adeyemo, ti ọpọ eeyan mọ si Sunday Igboho se amusẹ ileri rẹ lati se iwọde lọjọ ominira.
Bẹẹ ba gbagbe, o ti to ọjọ mẹta bayii mẹta ti ikede ti n lọ pe Sunday Igboho yoo ko awọn eeyan kan sodi, lati se iwọde fun ominira ilẹ Yoruba.
Oríṣun àwòrán, Olayomi Koiki
Ninu fidio kan to gba ori ayelujara kan, lo se afihan Sunday Igboho ati awọn ẹlẹgbẹjẹgbẹ miran nilẹ Yoruba, ti wọn kora jọ siwaju ile Igboho, pẹlu asọ ẹgbẹ Yoruba ati akọle lọwọ wọn.
Nibẹ si ni wọn ti n pariwo pe awọn ọlọpaa atawọn ọlọpaa ọtẹlẹmuyẹ, n di awọn lọwọ lati se iwọde, bẹẹ ni awọn agbofinro naa n yẹ ara awọn eeyan to peju sibẹ wo, boya wọn gbe ohun ija oloro lọwọ.
Oríṣun àwòrán, Olayomi Koiki
Nigba to n sọrọ nibi ipejọpọ naa, Sunday Igboho koro oju si bi ọpọ eeyan, to n leri leka tẹlẹ, se sa sẹyin lati bawọn peju se iwọde naa.
O ni o se oun laanu fun awọn ọmọ Yoruba pe, wọn ko le duro sori ọrọ ti wọn ba sọ lai jẹ è wọn wa ni oko ẹru.
"A ni a fẹ se iwọde alaafia lati beere ẹtọ wa lọwọ ijọba Naijiria, kii se pe a fẹ ja, kii se pe a fẹ da ilu ru tabi gba ijọba, wọn wa ko ọlọpaa bii miliọnu kan ati Sọja pẹlu ọtẹlẹmuyẹ si gbogbo ọna ile mi.
Oríṣun àwòrán, Olayomi Koiki
Se emi nikan ni ọmọ Naijiria ni, se emi nikan ni ọmọ Yoruba ni? Gbogbo awọn ọmọ Yoruba yoku wa salọ.
Gbogbo ẹyin tẹ jẹ baba wa, tẹ wa lọ fi wa gba owo, gbogbo ẹyin tẹ jẹ ẹgbọn wa, ẹ salọ, o yẹ kẹ ronu ẹyin Yoruba, sugbọn awa fidi rẹ mulẹ pe, ọmọ ọkọ lawa.'
Sunday Igboho ni o yẹ kawọn baba Yoruba naa bẹru Ọlọrun, ilẹ Yoruba yoo si bi gbogbo wọn, awọn alalẹ yoo si bi gbogbo awọn to salọ.
Goitre Patients: Àwọn èèyàn tó ní àrùn gẹ̀gẹ̀ ní ọ̀pọ̀ ìkórira àti ìdẹ́yẹsí ní àwọn ń kojú
O ni oun ti se iwọn ti oun le se, amọ ti wọn ba setan fun irẹpọ Yoruba, ki wọn ke si oun, to si n beere pe se o dara bi awọn ajeji se n fi oju Yoruba gbolẹ nilẹ baba wọn.
Igboho wa fi ọwọ gbaya pe, bi okunkun pẹ titi, imọlẹ yoo tan, laipẹ laijinna, ominira yoo si tẹ ilẹ Yoruba lọwọ.
October 1 Celebrant: Atinuke Oladeru ni kẹ yé ṣépè fún Nàíjíríà mọ́, ẹ pa ohùn dà
Nigeria Independence Day: Aráàlú fa ìbínú yọ lórí ọ̀rọ̀ tí Buhari sọ fún àyẹyẹ òmìnira
Oríṣun àwòrán, @Xahraddeen_
Buhari, ayẹyẹ kí là ń ṣe gan, ṣé ti ìpànìyàn àbí ìjínigbé? - Aráàlú ń bèèrè
Aarẹ Muhammadu Buhari tí bá àwọn ọmọ Naijiria sọrọ, bi orile-ede yii se n se ayẹyẹ ominira ọgọta ọdun.
O mẹnuba oniruuru awọn nnkan to n ba orile-ede yii fira to si pe fun ifaraji, ifẹ ọmọlakeji ati igbara ẹni niyanju láti máa ṣe nkan to tọ.
Lẹyin ti aarẹ Muhammadu sọrọ tan, ọpọ awọn ọmọ Naijiria lo ti n fi ero wọn han lawọn oju opo ibaraẹnidọrẹpọ loju opo itakun agbaye.
Odeh ninu atejisẹ rẹ soju opo Twitter ni, ki aarẹ ranti pe ko si nkan iwuri kankan ninu ayẹyẹ ominira ọgọta ọdun ti Naijiria.
O ni ko si itẹsiwaju kan bikose pe nkan ń buru sii ni.
Ninu ọrọ tirẹ @fingertrickz ni ọna àbáyọ kan ṣoṣo to yẹ, ni kí ijọba din owo awọn ọmọ ile ìgbímọ asofin ku, ti awọn miran si n fẹdun ọkan wọn han lori ọrọ airiṣẹse, lẹyin ọpọ ọdun ti wọn ti jade ile iwe.
Lori ọrọ iye ti awọn orile-ede miran to ni epo rọbi n ta epo bẹtiro fun ara ilu aarẹ ni
Egypt ₦211
Saudi Arabia ₦168
Chad ₦362
Niger ₦346
Ghana si n ta ni ₦326, ti Naijiria si ti n taa ni ₦161 báyìí.
Goitre Patients: Àwọn èèyàn tó ní àrùn gẹ̀gẹ̀ ní ọ̀pọ̀ ìkórira àti ìdẹ́yẹsí ní àwọn ń kojú
Ọpọ ọmọ Naijiria lo gbana jẹ lori eyi pe, ko tọ ki aarẹ maa fi owo epo Saudi we tí Naijiria nitori anfani ti Saudi n jẹ lati ọdọ ijọba ko ni afiwe, si iya ti ijọba Naijiria fi n jẹ ara ilu .
Ẹlomiran tiẹ n beere pe elo ni owo osu osisẹ ni Naijiria ati ti Saudi, Ghana, Chad, Egypt.
Gbajugbaja akoroyin ni Naijiria, Fisayo Soyombo ni ibanujẹ ni ọjọ oni nitori ọrẹ oun ti awọn ajinigbe jigbe ti pe ọjọ meji ni akamọ wọn.
O ni o jẹ nkan itiju pe iru iṣẹlẹ yii n waye ni orile-ede to ti pe ọgọta ọdun, ijọba ko le pese nnkan tó ṣe koko lara nnkan ti ara ilu nilo, eyi to jẹ aabo to peye.
Ibeere ti Thomas Ibu ni tirẹ ni pe, ajọyọ kini Naijiria n ṣe gan-an?
Ṣe ti owo epo to wọn gogo ni? Tabi ti ọrọ ina mọnamọna to lọ soke ni? Ijinigbe gbogbo ati ipaniyan jakejado Naijiria, ṣe ti ainiṣẹ lọwọ awọn ọdọ ni abi kini gan-an.?
Ọpọ loju opo twitter lo ń beere ibere yii bakan naa pe, ki ayẹyẹ ti a n se gan-an?
Ẹnikan ni orile-ede ti a n ṣe ayẹyẹ rẹ yii, kii se eyi to yẹ wa.
Ọgọta ọdun, ikuna isejọba ati ajẹbanu.
October 1 Celebrant: Atinuke Oladeru ni kẹ yé ṣépè fún Nàíjíríà mọ́, ẹ pa ohùn dà
Ọgọta ọdun eto ọrọ aje to dẹnukọlẹ.
Ọgọta ọdun ninu gbigbọkan le epo rọọbi nikan ati aini isokan laarin awọn ẹya rẹ.
Oríṣun àwòrán, @perlikspictures
Amofin agba ati ajafẹtọ ọmọniyan, Femi Falana ti sọ fun BBC pe ominira ti Naijiria n ṣajọyọ rẹ kii ṣe ominira rara, bikoṣe omi inira.
Falana ni ọrọ ti Aarẹ Buhari sọ nipa owo epo nigba to n ba awọn ọmọ Naijiria sọrọ ko bojumu to, ati pe ko lẹtọọ ki Aarẹ maa ṣafiwe igbe aye awọn ọmọ naijiria si ti awọn eeyan Saudi Arabia.
O ni Ọrọ aje orilẹ-ede wa ko ṣe dede nitori awọn to n ṣelu ko gbọ eyii ti awọn ara ilu n ṣe bikoṣe eyii ti ajo IMF ati banki agbaye ba sọ."""
Amofin agba naa sọ pe itan ati afarawe iye ti wọn n ta epo ni Saudi Arabia ati Egypt ko kan awọn ara ilu lasiko yii, bikoṣe pe ki aijọba sọ fun wọn bi igbe aye wọn yoo ṣe gbe pẹẹli ju ti atẹyinwa lọ.
Falana ni ti Aarẹ Buhari ba fẹ ṣe afiwe, ni ṣe lo yẹ ko bẹrẹ lati owo oṣu to kere ju ti awọn ọmọ orilẹ-ede Saudi Arabia n gba si ti Naijiria ko to sọrọ nipa iye ti wọn n san fun owo epo.
"O ni ""Ọfẹ ni owo ile iwe ati eto ilera ni Saudi, bakan naa ni ile iwe Ghana dara ju ti Naijiria lọ, idi ree ti awọn ọmọ ilẹ yii ṣe n kẹkọọ lọhun."
Falana pari ọrọ rẹ pe o yẹ ki ijọba wo iru iya to n jẹ awọn ara ilu, ko si wa ọna abayọ sii ko to maa ṣafiwe iye owo epo.
Ẹwẹ, nigba to n da si ọrọ naa, akọwe ẹgbẹ Afenifere, Yinka Odumakin ni bo tilẹ jẹ pe o ti pe ọgọta ọdun ti Naijiria gba ominira kuro loko ẹru ijọba ilẹ Gẹẹsi, inu oko ẹru naa ṣi ni awọn ọmọ Naijiria wa sibẹ.
Oríṣun àwòrán, @TVCconnect
O ni bo tilẹ jẹ pe o ti pe ọgọta ọdun ti Naijiria gba ominira lọwọ ijọba amunisin oyinbo alawọ funfun, abẹ ijọba amunisin abẹ ile ni Naijiria wa sibẹ.
Odumakin sọ pe Naijiria ti di ilu to n ba aye awọn ọmọ onilu jẹ, eyii to mu ki ọpọ eeyan maa funrere pe ki Naijiria tu ka.
Gẹgẹ bo ṣe sọ, o ni Naijiria ko ni ilọsiwaju kankan to lamilaaka lati ọgọta ọdun sẹyin.
"O tẹsiwaju pe ""Ina Naijiria n jo ajorẹyin ni, nitori ko si olori tuntun kankan to jẹ nilẹ yii ti asiko rẹ ko buru ju ti ẹni to jẹ ṣaaju rẹ lọ."""
Bo tilẹ jẹ pe Odumakin sọ pe Afẹnifẹre ko fẹ ki Naijiria tu ka, ṣugbọn o ni erongba ẹgbẹ ọhun ni ki atunto de ba eto ijọba Naijiria.
Ki lo ti ṣẹlẹ sẹyin?
Oríṣun àwòrán, Femi Adesina
Aarẹ Muhammadu Buhari ti sọ pe, kii ṣe Naijiria ni epo rọbi ti wọn ju lagbaye nitori epo wọn ni awọn orilẹ-ede kan bii Ghana ati Niger ju Naijiria lọ.
Buhari lo kede bẹẹ nigba to n bawọn ọmọ Naijiria sọrọ laarọ ọjọ kinni, oṣu Kẹwaa, ọdun 2020, fun ajọyọ ọgọta ọdun ti Naijiria gba ominira lọwọ oyinbo alawọ funfun.
Bakan naa lo fi kun pe, owo epo Naijiria lo si dinwo julọ lẹkun iwọ oorun Afirika nitori N326 ni wọ́n ń ta jáálá epo ní Ghana, N211 ní Egypt, ní ìgbà tó jẹ́ N168 ní Saudi Arabia.
Aarẹ wa woye pe, kò mú ọpọlọ lọ́wọ́ kí owó epo bẹntiróòlù ní Nàìjíríà dinwo ju ti orilẹede Saudi Arabia lọ.
Oríṣun àwòrán, @misspetitenaija
Ondo Governorship Elections 2020: Ìjọba ìbílẹ̀ mẹ́ta yìí ní yóò sọ ẹni tí yóò jáwé olúbori ninú ìdìbò Ondo
Kẹ̀rẹ̀kẹ̀rẹ̀, ọjọ́ ìdìbò sípò gómìnà ìpínlẹ̀ Ondo yóò wáyé lọ́jọ́ Satide ọjọ́ kẹwàá, oṣù kẹwàá ọdún 2020, ibi yìí ni àwọn ènìyàn ìpínlẹ̀ náà yóò fi ọwọ́ ara wọn yan ẹni tí yóò tún dári wọ́n fún ọdún mẹ́rin míran.
Àwọn olùdíje dùpò lábẹ́ ẹgbẹ̀ òṣèlú kọ̀ọ̀kan yẹ ki wọ́n ni ìbò tó jọju láti ìjọba ìbílẹ̀ méjìdílógún tó wà ni ìpińlẹ̀ náà ti yóò gbéwọn dé orí àléfà.
Àwọn ìjọba ìbílẹ̀ tó wà ni ìpínlẹ̀ náà ni Akoko North East, Akoko North West, Akoko South East, Akoko South West, Akure North, Akure South, Ifedore, Ile Oluji/Okeigbo, Ondo East, Ondo West, Owo, Ilaje, Okitipupa, Ose, Odigbo, Ese Odo, Idanre àti Irele.
Ṣùgbọ́n ìjọba ìbílẹ̀ mẹ́ta tó tóbi jù kan ni àwọn ènìyàn fójú sí nítorí ìtàn ìdìbò àgbègbè náà látẹ́yín wá. Àwọn ìjọba ìbílẹ̀ yìí ni yóò sọ ẹni ti yóò jáwé olúbóri.
Ìjọba ìbílẹ̀ Akure South ló tóbi jùlọ ní ìbílẹ̀ Ondo tí wọ́n sì ní ènìyàn tó dín díẹ̀ ní ẹgbẹ̀rùn okòó-lé-lẹẹ́dẹ̀gbẹ̀ta ti eniyàn oòkó-dín-lọ́ọ̀dúnrún si fọ́rúkọ sílẹ̀ fún ìdìbò.
Lásìkò ìdìbò ọdún 2016, ìjọba ìbílẹ̀ náà fún gómìnà tó wà lórí àléfà Rotimi Akeredolu ni ìbò tó dín díẹ̀ ni ẹgbẹ̀rún mẹ́rrìndílọ́gbọ̀n, èyí ló ga jùlọ ní gbogbo àwọn ìjọba ìbílẹ̀ tó kù.
Ní ọdún 2012, ìjọba ìbílẹ̀ yìí kan náà ló fún olùdíje dupò lábẹ́ ẹgb òṣèlú Labour Olusegun Mimiko láti wọlé fún sáà kejì, o rí ìbò tó dín díẹ̀ ni ẹgbẹ̀rún lọ́nà ààdọ́ta.
Ní ọdún 2020, ìjóba ìbílẹ̀ yìí ni yóò fi ìdí rẹ̀ múlẹ̀, ẹni ti yóò jáwé olúborí gẹ́gẹ́ bi gómìnà ìpínlẹ̀ Ondo
Ẹ̀wẹ́, ìjọba ìbílẹ̀ yìí gan ni olùdíje dupò lábẹ́ ẹgbẹ́ òṣèlú People's Democratic Party, (PDP) Eyitayo Jegede ti wá.
Àwọn ibudó ìdìbò ẹdẹ́gbẹ̀ta àtí mọ́rùndílógójì tó ti wà ni ìpińll Ondo láti ẹyìn wá ti fi hàn pé, PDP àti APC yóò jọ jàdu ìbò ní ìjọba ìbílẹ̀ yiìí ni.
Lẹ́yìn ìjọba ìbílẹ̀ Ilajẹ ìjọba ìbílẹ̀ Ondo West lo tún kan, èyí sí ni ìjọba ìbílẹ̀ kẹ̀ta to tóbi jùlọ ní ìpínlẹ̀ Ondo. Ènìyàn ẹgbẹ́rún lọ́nà ààdójọ ni olùdìbò tó ti fórúkọ sílẹ̀.
Àwọn ènìyàn ìjọba ìbílẹ̀ yìí pẹ̀lú jẹ ọkàn lára àwọn tí yóò sọ ẹni tíò jáwé olúborí.
Nínú ìtàn ìpińlẹ̀ yìí pẹ̀lú, wọ́n sábà má ń wò ó bóyá ọkàn lára àwọn olùdíje dupò wá láti ìjọba ìbílẹ̀ náà.
Ṣùgbọ́n ni àsìkò yìí  ìjọba ìbílẹ̀ yìí ni Olusegun Mimiko ti wá tí ó sì wà lẹ́yìn ọkàn lára àwọn olùdíjẹ lábẹ́ Zenith Labour Party (ZLP) Agboola Ajayi.
Bóya àwọn ènìyàn wọ́nyìí yóò wá dúró sẹ́yìn ọmọ wọ́n ni sáá yií, àwọn náà yóò sọ ẹni ti yoo jáwé olúbori.
Lọ́wọ́lọ́wọ́ báyìí, ìjọba ìbílẹ̀ Owo ló ni Gómìnà tó wà lórí àléfà nínú ọdún 2020.
Gómìnà Rotimi Akeredolu ti ẹgbẹ́ òṣèlú APC tó tún jẹ gómìnà tó wà lórí oye jẹ́ ọmọ ìjọba ìbílẹ̀ náà.
Owo ni ibudó ìdìbò ìgbà àtí mẹ́rìnlélọ́gọ́ta tí wọ́n si ni ènìyàn ẹgbẹ̀rún lọ́nà ọgọ́fà dín díẹ̀ tó ti fi orúkọ sílẹ̀ fún ìdìbò tó n bọ.
"Gbogbo ènìyàn ni yoo maa fi oju si ìjọba ìbílẹ̀ yìí lára nítori pé, ọ̀pọ̀ ló ní ìgbàgbọ́ pé, ""ọmọ wa ni ẹ jẹ kó ṣee"" ni wọ́n yoo fi ṣe."
Bí wọ́n ko bá wa dibo fun ọmọ wọ́n, ẹnikẹni ti ọ̀pọ̀ wọ́n bá gbà láti dibò fún ni yóò jáwé olúbori fún ìdìbò náà.
Ǹkan míràn tó tún lé yí ǹkan padà ni pé, tí gbogbo ìjọba ìbílẹ̀ mẹẹ̀dógún tó kù bá wá pinu láti gbárùkù tí ẹni kan nínú àwọn olùdíje yìí, láti bórí àwọn Ijọba ìbílẹ̀ mẹ́ta tó kù.
Ṣùgbọ́n ni ọ̀pọ̀ ìgbà ọwọ́ àwọn ìjọba ìbílẹ̀ mẹ́ta yìí ni ọ̀rọ̀ wà.
Ondo Governorship Elections 2020: INEC ní ìjọba ìbílẹ̀ Ilaje ní ìṣẹ̀lẹ̀ tó burú jùlọ tí wáyé nínú ìbò 2016
Lára ìgbésẹ̀ ìjọba láti le ri i dájú pé ètò ìdìbò lọ ní ìrọwọ́rọsẹ̀ ní ìpínlẹ̀ Ondo, àjọ elétò ìdìbò (INEC) ní òun ti bèèrè fun iranwọ àwọn ilé iṣẹ́ elétò ààbò to pọ.
Ó ní àwọn ọmọ ológun, àwọn ọlọpàá àti àjọ elétò ààbò gbogbo yóò wà láwọn ibi kọ́lọ́fín, ti gbogbo àwọn ẹni ibi maa n fara pamọ́ sí.
Bakan naa ni INEC ni àwọn òṣìṣẹ́ aláàbò náà yóò ri i dájú pé, ìdìbò ti kò mú wàhálà dání, pàápàá jùlọ láwọn iha kọ̀ọ̀kan ni ìpínlẹ̀ náà lo waye lọjọ Kẹwaa osu Kẹwaa ọdun yii.
INEC ní o tó àwọn ilé orí omi bíi méjìlélọ́gọ́ta àti ibudó ìdìbò ọ̀rinlérúgbà ó din mẹ́wàá to wa ni agbègbè ẹsẹ̀ odò, tawọn oju omi tó tó ẹgbẹ̀rún mẹ́ta àti mẹ́sàn sì wà ni ìpinlẹ̀ náà.
Bẹ́ẹ ni àwọn òṣìṣẹ́ tí yóò lọ ṣiṣẹ́ nibẹ̀ yóò jẹ́ ẹgbẹ̀rún kan àti ọgọ́rin.
Kọmísọ́nà àjọ INEC, tó tún jẹ́ alága ìròyìn àti ìtanijí Festus Okoye ni àwọn ti kàn si ilé iṣẹ́ ọmọogun ojú omi àti àwọn ọlọpàá inú omi, láti sin àwọn èròjà tí wọ́n yóò lò fún ìdìbò lágbègbè náà.
Saájú àsìkò yìí, o ni àwọn àgbègbè eti odò náà fi han pé, màgòmágó le ṣẹlẹ̀ níbẹ̀, nítorí bi ibẹ̀ ṣe rí.
Oríṣun àwòrán, Others
Okoye ní láti le ri dájú pé, ètò ìdìbò lọ ni irọwọ́rọsẹ̀, àjọ INEC ti kan sí ọlọpàá ojú omi, àwọn ọmọogun ojú omi àti àwọn ilé iṣẹ́ ààbò tó farapẹ láti ràn wọ́n lọ́wọ́.
Àwọn ibudó ìdìbò ọ̀rinlérúgbà ó din mẹ́wàá to wa ni agbegbe omi yii, ló wà ni ìjọba ìbílẹ̀ Ese-Odo àti ilaje, ti wọ́n si ni àwọn ilé orí omi bíi méjìlélọ́gọ́ta.
Yomi Fabiyi: Fíìmù ‘Owó orí ẹlẹ́wọ̀n’ jẹ́ ká mọ̀ pé ìgbà ìpọ́njú làá mọ ọ̀rẹ́
Ẹ̀wẹ̀, sáájú ni àdàri ètò àjọ kan tí kìí ṣe ti ìjọba YIAGA, Cynthia Mbamalu ti kéde pé, pẹlú àwọn ìrírí nínú ìdìbò 2016, ìjọba ìbílẹ̀ Ilaje ní àwọn ìròyìn to buru ju ti n wá.
Ó ní láti ri dájú pé ìdìbò yìí kò dàbí àwọn èyí tó ti ṣẹ̀lẹ̀ láti ẹyìn wá, àjọ elétò ìdìbò gbọdọ pèsè ètò ààbò tó péye ni àwọn ibùdó ìdìbò tó wà ní eti omí, lásìkò tí wọn bá n pín nǹkan ìdìbò àti lásíkò ìdìbò gan.
Ẹ fura, làásìgbò le wáyé ní ìjọba ìbílẹ̀ mẹ́fà yìí lásìkò ìbò gómìnà Ondo - YIAGA
Oríṣun àwòrán, Nguher Gabrielle Zaki
Awọn ajọ ajafẹtọ ọmọniyan ti ke gbajare si awọn alaṣẹ lati dena jagidijagan ati awọn iwa kotọ mii, to le waye lasiko idibo Gomina to n bọ nipinlẹ Ondo.
Ninu iwadii ti ajọ YIAGA gbe jade ṣaaju idibo, eyi ti wọn fi ṣọwọ ṣawọn akọroyin, wọn darukọ awọn ijọba ibilẹ mẹfa ti iwa ipa ti le waye lasiko ibo ni Ondo.
Lara awọn agbegbe naa la ti ri ijọba ibile bii Akoko South-West, Akure South, Idanre, Owo, Akoko South-East ati Ese-Odo.
YIAGA ni eyi ri bẹẹ nitori awọn nnkan tawọn ti foju ri lasiko ipolongo ibo, bii iwa ipa, ikọlu si alatako, biba ọkọ jẹ ati lilọ kaakiri pẹlu ohun ija oloro, se gbilẹ lawọn agbegbe naa.
Oríṣun àwòrán, Nguher Gabrielle Zaki
'' O jẹ ohun to fọwọ kan wa lẹmi wi pe, idibo Gomina yii le mu ki awọn iwa ti ko tọ waye, paapa bi awọn ti ọrọ kan ṣe n huwa ipa bayii''
Ajọ ọhun wa mẹnuba awọn alatilẹyin ẹgbẹ oṣelu APC, PDP, ZLP ati LP gẹgẹ bi awọn to n hu iwa ipa yii, ti wọn si tun jẹ ẹni to n fara ko iwa jagidijagan pẹlu.
Wọn ni bi wọn ko ba dẹkun iru iwa bayii, awọn oludibo le maa jade sita lasiko ibo nitori ibẹru bojo.
Oríṣun àwòrán, Nguher Gabrielle Zaki
Lakotan YIAGA wa gba ajọ eleto idibo ni imọran pe, ki wọn ba awọn alẹnulọrọ sọrọ lọna ati jẹ ki ibo lọ ni irọwọrọsẹ.
Bẹẹ ni wọn ni ki wọn tẹsiwaju pẹlu ṣiṣe afihan esi idbo loju opo ayelujara eyi ti yoo jẹ ki onikaluku ri okodoro bi idibo ti ṣe lọ
lagbegbe wọn.
October 1 Celebrant: Atinuke Oladeru ni kẹ yé ṣépè fún Nàíjíríà mọ́, ẹ pa ohùn dà
Champions league draw: Kà bí Juventus àti Barcelona, PSG àti Man United, pẹ̀lú Bayern ati Athletico Madrid yoo ṣe dáná sun ara wọn ní Champions League tọdun yii
Oríṣun àwòrán, Giveme sport
Iyikoto idije champions league fun ti saa idije bọọlu ọdun yii ati ọdun 2020/21 waye lọjọbọ.
Ohun to gbẹyẹ lasiko iyikoto naa ni bi wọn ṣe mu ẹgbẹ agbabọọlu Juventus ati Barcelona pọ si ipin kan naa.
Eyi tumọ si pe Ronaldo ati Messi yoo tun fojurinju lati ta okoto ayo lori papa. Ẹ si mọ pe ṣonṣo meji ni wọn ti ko gbọdọ fojurinju nitori ọkan ni lati tẹ fun ekeji ni.
Bi awọn ipin ipele komẹsẹ o yọ idije champions league fun saa 2020/21 yoo ṣe lọ niyi:
Igba akọkọ niyi ti Messi ati Ronaldo yoo maa forikori lati igba ti Ronaldo ti fi Real Madrid silẹ lọ si Juventus.
Nigeria Independence Day: Ìyàpa ẹ̀yà, èdè àti ẹ̀sìn ló mú akùdé bá ìṣọ̀kan Nàíjíríà
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ninu awọn lẹta ti ọpọ awọn akọroyin lati ilẹ afirika ati awọn onkowe kọ, BBC salaye lori isoro to buru julọ to n koju orilẹede adulawọ ti awọn eeyan rẹ pọ julọ ni Afirika, bo se n se ayẹyẹ ọgọta ọdun to gba ominira kuro lọwọ ijọba ilẹ gẹẹsi.
Ọna wo ni eniyan le gba lati ko oniruuru ẹya jọ ni isọkan, ki o si mu inu gbogbo wọn dun?
Eyi jẹ isoro akọkọ ti Naijiria koju fun ọdun mẹwaa akọkọ to gba ominira, nkan to si tun n koju titi di asiko yii ree, nibayii to ti pe ọgọta ọdun.
Awọn oniruuru ariyanjiyan to maa n waye lo da lori ọrọ ẹlẹyamẹya, ti wọn o si ma sọ pe, ki lo tọ si ẹya yii, ki lo tọ si tọhun, nigbawo, ni asiko wo, nibo ati pe bawo?
Tabi bawo ni wọn se huwa si ẹya kan, to yatọ si ẹya miran?
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Orilede Naijiria ni oniruuru ẹya to le ni ọọdunrun, sugbọn ẹya mẹta lo bori gbogbo rẹ, eyiun ẹya Yoruba, Hausa ati Igbo.
Ẹya ọtọọtọ ni awọn eniyan wọnyii, ki awọn gẹẹsi to da gbogbo wọn pọ soju kan, ti wọn si n ṣe ijọba apapọ lonii pẹlu ipinlẹ mẹrindinlogoji ati olu ilu ni Abuja.
Oniruuru iwọde ati ifẹhonu han lo ti waye nitori ọrọ ati se ijọba, eyi si ti mu ki awọn ẹya Igbo fariga pe, awọn fẹ fi Naijiria silẹ, eyi si ni ọrọ Biafra to n waye titi di asiko yii.
Ọpọ nkan lo pin awọn ọmọ Naijiria si ọtọọtọ, bii asa, ẹsin, awọn ilana ijọba lati ẹyin wa ati eyi to o n ja lọwọ, bii ọrọ awọn agbesumọmi to n fojojumọ pa awọn eniyan lẹkun.
O le ni miliọnu mẹtala ọmọde ti ko lọ si ile iwe, eyi lo si pọju ni gbogbo agbaye, gẹgẹ bi ajọ Unicef se sọ, ida mọkandinlaadọrin awọn ọmọde ti ko lọ sile ẹkọ lo wa lati iha ariwa Naijiria.
Sibẹ awọn iha ariwa yii lo maa n gba gbogbo ipo to se gboogi ninu ijọba, wọn pọ to miliọnu lọna aadọrun, ninu eniyan miliọnu lna igba to wa ni Naijiria.
Iha ariwa Naijiria ni ipinlẹ Ogun ninu ipinlẹ mẹrindinlogoji to wa ni orilede naa.
O ṣeni laanu pe, ile iṣẹ to ri si bi a ṣe n pin awọn ẹya fun igbanisẹ (Federal Character) gan ni isoro, nítorí awọn ti ko koju osuwọn ni wọn ko sẹnu iṣẹ ijọba. eyi ni ọrọ Ike Ikweremadu.
"Awọn oṣiṣẹ yii a maa mu adinku ba iṣẹ ijọba, ti wọn si sọ ọ di nnkan yẹpẹrẹ.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Koda, awọn oṣiṣẹ ti ko koju osuwọn yii wọn a tun se ọga lẹnu iṣẹ ju awọn ti wọn ni iwe ẹri to koju osuwọn ju ti wọn lọ.
Awọn to wa ni ile iṣẹ Federal Character"" yii naa lo n ri si bi wọn se n yan ọga lawọn ile iṣẹ nlanla ijọba."""
Ninu ọgọta ọdun ti Naijiria pe lonii, ẹya Ariwa ti dari orilẹede yii fun ọdun mejidinlogoji, nipasẹ iditẹ gbajọba lati ọwọ awọn ologun.
Aimọye itan nipa bi awọn eeyan se maa ṣiṣẹ takuntakun lai ri igbega, ti awọn miran yoo si lo magomago lati goke, paapaa julọ, nitori pe awọn eniyan wọn lo wa nibẹ.
Goitre Patients: Àwọn èèyàn tó ní àrùn gẹ̀gẹ̀ ní ọ̀pọ̀ ìkórira àti ìdẹ́yẹsí ní àwọn ń kojú
Lọdọdun ni awọn iwe iroyin maa n gbe jade pe, iye maaki bayi ni a le fi gba akẹkọọ wọle si fasiti, tabi lati gba awọn akẹkọọ wọle si ile ẹkọ sẹkọndiri ijọba apapọ.
Awọn akẹkọọ lati iha Arewa ni wọn maa n beere maaki to kere julọ lọdọ wọn yatọ si awọn ọmọ to wa lati iha Guusu.
Nigba ti maaki to kere julọ lati wọ ile iwe ba jẹ igba fun ẹni to wa lati Guusu, wọn le fi maaki mọkandinlogoje gba ọmọ lati ariwa, si ile ẹkọ kan naa.
"Ni ọpọ igba, ko si iwuri fun ẹni to ba se nnkan ọtọ, ""Federal Character"" naa tun fi ofin de e pe, ki ibaraẹnise to dan mọran le wa, gbogbo ẹya ni o gbọdọ peju fun ipo ijọba."
SS3 ní mo wà báyìí, mo sì ti gba àmì ẹ̀yẹ̀ púpò nílé-lóko gẹ́gẹ́ bí onílù - Ayansike
Iru nnkan bayii ko fi aaye gba ẹni to koju osuwọn fun isẹ naa, yala, wọn samojuto ẹya to ti wa.
Ọpọ ọmọ Naijiria to mọ iwe, tabi mọ iṣẹ doju amin, ko ni ri iṣẹ se lati fi tẹ orilede wọn siwaju nitori awọn ti wọn mọwe bẹẹ pọ, aaye kekere si lo wa fun ipinlẹ to ti wa.
Awọn miran gba pe, nnkan to dara ni Federal Character, sugbọn wọn nilo atunto diẹ si iṣẹ ti wọn se.
Mo ni igbagbọ pe, gbogbo ọmọ Naijiria ni ipo aṣẹ ijọba tọ si. Sugbọn awọn ọmọ Naijiria naa gbodọ mọ iṣẹ wọn de oju ami
Awọn akọṣẹmọṣẹ wa ni gbogbo ẹkun Naijiria, ti wọn si gbọdọ wa wọn jade.
October 1 Celebrant: Atinuke Oladeru ni kẹ yé ṣépè fún Nàíjíríà mọ́, ẹ pa ohùn dà
Se bi gbogbo eniyan lagbaye lo mọ pe awọn ọmọ Naijiria ni ọpọlọ pupọ, ni gbogbo ẹka imọ, paapaa julọ lati awọn ẹkun ariwa ti wọn ro pe wọn ko kawe to.
"Ọpọ igba ni awọn alatako ijọba ti maa n naka alebu si aarẹ Muhammadu Buhari, lori ọrọ ""Federal Character"" pe o yẹ ki wọn kaṣẹ rẹ nilẹ."
Mi o ni isoro pẹlu ẹya Naijiria kankan, sugbọn mo ni isoro nipa bi awọn ijọba se n dari iyanisipo. Ekweremadu lo sọ eyi lọdun 2018 niwaju ile asofin.
Lọwọ lọwọ bayii, mẹtadinlogun ninu Ogun awọn olori ẹka eto aabo ni Naijiria, ti aarẹ Buhari yan, ẹkun ariwa ni wọn ti wa,
Mẹrindinlogun ninu wọn si jẹ musulumi bi tirẹ.
Akomolede ati Aṣa lori BBC: Kí ní ìtúmọ̀ Sílébù àti àmi ohun tó ń fún ni?
Mẹẹdogun ninu mọkanlelogun awọn igbakeji ọga ologun lo wa lati ariwa, ti mẹrindinlogun ninu wọn si jẹ musulumi.
"Lasiko to n gbeja ọga rẹ, agbẹnusọ fun aarẹ Buhari, Garba Shehu sọ fun mi pe, ""se iwọ le fi ẹni ti o ko mọ si ipo aṣẹ ọmọogun, ti o ba jẹ adari?"
"Ipo yii kan naa ni onkọwe Wole Soyinka wa, nigba to n tọka si pe, awọn kan yoo maa tẹle ara wọn, ti wọn ti jẹ ẹya to pọ."""
Ẹwẹ, agbẹnusọ Aarẹ tọkasi pe, wọn ti naka alebu si awọn ijọba to ti koja tẹlẹ naa pe, wọn maa n gba awọn eniyan to jẹ ẹya wọn sisẹ, ju ẹya miran lọ.
Obateru Akinruntan: Wíwá ohun tá jẹ títí láé ló gbé wa kúrò nílé Ife
"Ti awọn eniyan ko ba si ni ijọba, ẹni naa yoo ma ri aṣiṣe awọn miran ni - ọgbẹni Shehu.
 Nigba ti Obasanjo wa ni ijọba, ọpọ awọn eniyan lo n fẹsun kan pe o n yan awọn eniyan iha iwoorun - guusu sipo"""
Awọn ẹgbẹ kan ni iha guusu ti ni ọna abayọ kan ṣoṣo ni pe, ki Naijiria tuka, ki olukuluku ẹya si wa ni aaye ara rẹ gẹgẹ bi orilẹede.
"Awọn oloselu kan ati awọn onwoye miran ni ""atunto"" ni nkan to yẹ, ti ẹkun kọọkan yoo le ma maa dari ara wọn, eyi yoo si mu isọkan ati irẹpọ ba Naijiria."
Toyin Atoyebi mechanic: Ẹ wo Toyin, ọmọbinrin ọdún 16 tó ń tún skadà àti gẹnẹrátọ̀ ṣe ní
Bakan naa ni wọn ni yoo mu ki adinku ba bi agbara se wa loju kan nilu Abuja.
Gbogbo ilana ti Naijiria ba pada gunle, bi yoo se maa gun akasọ lati lọ aadọrin ọdun ominira yii, nkan ẹyọ kan to ṣe pataki ni pe:
Ọjọ iwaju Naijiria wa lọwọ bi ijọba to ba n bọ, yoo se mu isọkan wa laarin gbogbo ẹya.
Sunday Igboho: Gani Adams ní wọn kò fìgbà kankan fi ìwọ́de October 1 tó òun létí
Gani Adams: Irọ́ ni wọn ń pa, mi ò sálọ sí France nítorí ìwọ́de
Iba Gani Adams,Aarẹ Ọna Kakanfo ilẹ Yoruba ti tu kẹkẹ ọrọ nipa idi ti ko fi kopa ninu iwọde Oduduwa Republic, ti Sunday Igboho lewaju rẹ.
Ninu ifọrọwanilẹnuwo to ṣe pẹlu BBC Yoruba, Adams ni ori ayelujara ni Sunday Igboho ti n kesi oun lati wa kopa ninu iwọde, ko kan si oun nile.
''Ṣe bi ti o ba fẹ pe mi ki n wa dara pọ mọ yin, wa a wa ba mi ni ile, gẹgẹ bi aarẹ? Wa a wa ni aarẹ o, mo wa ba yin nile. Mo fẹ ki ẹ wa lewaju wa ninu iwọde nilu Ibadan''
Wo Adigun ọmọ ọdún mẹ́rin tí òwe Yorùbá àti ìtúmọ̀ gbó lẹ́nu rẹ̀ ju tìrẹ̀ lọ
Aarẹ Adams ni lootọ ni oun ko lodi si igbiyanju Sunday Igboho ṣugbọn ''ọrọ ajijagbara kọja ọrọ Ibadan tabi Igboho nikan''
Yoruba Independence rally: Sunday Igboho ní àwọn àgbàgbà Yoruba dalẹ̀
O ni koda, lẹyin ti Sunday Igboho pari iwọde, ko pe oun lori aago lati sọ pe awọn ti ṣetan, to si ni gbigba orilẹede Oduduwa kọja ọrọ ẹnu lori ayelujara lasan.
Adams ni ti eeyan yoo ba ko ero jọ̀ fun iwọde, iru ẹni bẹẹ yoo ni ẹgbẹ to kojọ, ti wọn yoo maa tẹle lẹyin lati se iwọde, to si n beere pe ki ni orukọ ẹgbẹ ti Igboho da silẹ.
Nigba ti BBC Yoruba beere lọwọ rẹ boya o wa lara awọn agbagba Yoruba ti Sunday Igboho naka abuku si pe wọn gba owo ẹyin, ni wọn ko fi darapọ mọ iwọde, Aarẹ Gani Adams faraya, to si ni ọrọ ko ri bẹẹ.
''Iru ibeere wo lo n bi mi yẹn? O o lọ beere pe ta lo ni OPU to wa ninu Yoruba One Voice? Ni ijọ ti iwọ ti n ṣe akọroyin, nijọ wo lo gbọ pe Gani Adams gba abọde ri?''
Ìṣẹ̀lẹ̀ Kàyéèfì: Ìpáǹle tú Abass Owonikoko sí ìhòòhò ayé, kó tó gba kéú lọ́gbà ẹ̀wọ̀n
Gani Adams ṣalaye siwaju pe, ọna ti Sunday Igboho n gba tabuku awọn agbaagba Yoruba ko bojumu.
O ni lọpọ igba Sunday Igboho kan maa n gbe kamẹra lẹyin, ki awọn eeyan baa le sọ pe o n ja fun ẹtọ Yoruba ni.
O mu apejuwe wa pe oun, Gani Adams, lo kọkọ ke gbajare lori ọrọ awọn ọdaran to n ji awọn eeyan gbe ni Oke Ogun, ki Sunday Igboho to ko awọn ayaworan lẹyin lọ si inu igbo.
''Ti eeyan ba fẹ koju awọn ọdaran, ṣe o maa n gbe kamẹra lọwọ? Ṣebi ti wọn baa ti mu wọn tan lo yẹ ko wa ṣalaye faraye gbọ?''
Auxilliary : Sunday Igboho kìí ṣe ọmọ ìbàdàn, òun gan ló ń dá Ibadan ru
Ni akotan ọrọ rẹ, o wa gba Sunday Igboho nimọran lati fi pẹlẹ ṣe ijijagbara rẹ, nitori kii ṣe oun nikan lo le gba ominira tawọn Yoruba n beere yii.
''Gbogbo wa naa kọ ni a o jade sita fun iwọde. Ati pe, ti ko ba di pe o di dandan, olori kii kan sọrọ jaujau. Bi o ba ni ọrọ lati sọ, awọn ọmọ lẹyin rẹ lo yẹ ki wọn sọrọ''
Bi a ko ba gbagbe, Sunday Igboho, to jẹ ọkan lara awọn to n lọgun Oduduwa Republic ati awọn agbarijọpọ ẹgbẹ Yoruba mii ṣe iwọde lọjọ Kini oṣu Kẹwa, lati tako bi ilu ko ṣe rọgbọ.
Obateru Akinruntan: Wíwá ohun tá jẹ títí láé ló gbé wa kúrò nílé Ife
Nigba ti Igboho n ba awọn eeyan sọrọ, o ni awọn olori Yoruba ti awọn jijọ fẹ ṣe iwọde yii yiṣẹ pada, nitori pe wọn ti gba owo lọdọ ijọba.
Gani Adams: Irọ́ ni wọn ń pa, mi ò sálọ sí France nítorí ìwọ́de
Nigeria prison experience: Abass Owonikoko dèrò ẹ̀wọ̀n fún ọdún 27 torí ìwà ìpáǹle, kó tó gba kéú lọ́gbà ẹ̀wọ̀n
Yoruba ni fi ọrẹ rẹ han mi, ki n sọ iru eeyan to jẹ nitori aguntan to ba n ba aja rin yoo jẹ igbẹ.
Bẹẹ ni ọrọ ri pẹlu ọkunrin kan, Abass Abiodun Owonikoko, tii se onisowo ounjẹ lọja Bodija nilu Ibadan.
Awọn isẹlẹ Kayeefi miran ti ẹ le nifẹ si:
Ija ni Owonikoko atawọn ọrẹ rẹ mẹrin miran lọ ja lẹyin eegun lọdun 1993, ti wọn si pa eeyan meji.
Eyi lo ba de ọgba ẹwọn, ti wọn fi dajọ iku fun, sugbọn ti gomina Ibikunle Amosun ba yi pada , to si gba idande lẹyin ọdun mẹtadinlọgbọn.
Inu ọgba yii lo wa to fi di imaamu, o keu, to si gba alukurani.
Àwọn ìtàn Mánigbàgbé tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí:
Ẹnu onikan la ti n gbọ kanun, ẹ gbọ ọrọ latẹnu ọkunrin yii funra yin.
Ondo Election 2020: Agboola Ajayi ní ₦12m lòun ń gbà lóṣù, kìí ṣe ₦13m
Igbakeji gomina nipinlẹ Ondo, Agboola Ajayi ti fesi pada fun gomina Rotimi Akeredolu, to ni oun n gba miliọnu mẹtala naira losu.
Ajayi, tii se oludije gomina fẹgbẹ oselu ZLP lọwọ lọwọ bayii wa salaye pe, miliọnu lọna ọtalelẹẹdẹgbẹrin o din mẹwa naira, 750m ni gomina Akeredolu n gba losoosu fun owo ipese aabo taa mọ si Security Vote.
Ko tan sibẹ o, Ajayi tun fikun pe miliọnu lọna aadọjọ naira, 150m, ni Akeredolu tun n gba lowo osu, to si n fun oun ni miliọnu mejila naira ninu rẹ losu.
Igbakeji gomina ipinlẹ Ondo sisọ loju ọrọ yii ninu atẹjade kan ti akọwe iroyin rẹ, Allen Sowore fisita pẹlu afikun pe, ẹnu ya oun pe Akeredolu n pariwo pe oun n fun Ajayi ni miliọnu mẹtala naira losu, bii ẹni pe ẹbun lo n fun-un.
Oríṣun àwòrán, @AAjayiAgboola
O ni gomina Akeredolu ko fun oun ju miliọnu mejila naira lọ losu, ti ko tiẹ wa fun oun mọ bayii.
Ajayi salaye pe awọn owo naa lo wa fun owo itọju ọọfisi oun, owo ajẹmọnu awọn osisẹ to wa lọdọ oun, owo epo mọto ati itọju awọn ẹsọ oun.
Owo yii le pọ lootọ amọ ko to fun iye eeyan to tọ si ati awọn eeyan ta fi gbọ bukata wọn.
Yomi Fabiyi: Fíìmù ‘Owó orí ẹlẹ́wọ̀n’ jẹ́ ká mọ̀ pé ìgbà ìpọ́njú làá mọ ọ̀rẹ́
Bakan naa lo tun sisọ loju rẹ pe, iyawo ati ọmọ Akeredolu n gba ọpọ miliọnu naira bii owo ajẹmọnu losoosu lai si ni ipo kankan ti ofin la kalẹ.
Oríṣun àwòrán, @RotimiAkeredolu
Saaju la ti mu iroyin wa fun yin pe, Gomina Ipinlẹ Ondo ati oludije lẹgbẹ oṣelu APC, Oluwarotimi Akeredolu ti ni ohun gbogbo ni oun fi tẹ Igbakeji gomina ni ipinlẹ Ondo, Agboola Ajayi lọrun, amọ o ya abara mu oore jẹ.
Gomina Akeredolu sọ eleyii lasiko to n ba awọn eniyan sọrọ lori ẹrọ amohunmaworan ni ipinlẹ Ondo.
Akeredolu ni Agboola Ajayi ko fẹ duro di igba tirẹ, o fẹ fi waduwadu gba ipo gomina, eleyii ti ko le ṣeeṣe.
"Mo ma n ran Agboola lati soju mi ni awọn ibi to ṣe pataki, amọ ko ni itẹlọrun.
Awọn eniyan ti kilọ fun mi lati maṣe gbe ọkan le Agboola, amọ mi o gbọ titi to fi bẹrẹ si ni ṣe alatako mi.
Oríṣun àwòrán, @RotimiAkeredolu
Ko si igbakeji gomina to n gba owo oṣu ti Agboola n gba ninu itan ipinlẹ Ondo, ẹgbẹrun mẹtala miliọnu naira lo n gba ni owo oṣu .
Gbogbo nnkan ni mo fi tẹ lọrun, amọ o ṣi fi ọbẹ ẹyin jẹ mi ni isu."
Amọ, gomina Akeredolu fikun wi pe, gbogbo awọn alatako oun ni oun ṣetan lati dariji gẹgẹ bi ọmọ lẹyin Kristi ti oun jẹ, ko le e mu ki oun ni ikunsinu si ẹnikẹni.
Gomina naa ni o da oun loju wi pe, oun yoo jawe olubori ninu eto idibo sipo gomina to n bọ, nitori awọn ti ṣiṣẹ ribiribi ni ipinlẹ Ondo.
Ìṣẹ̀lẹ̀ Kàyéèfì: Ìpáǹle tú Abass Owonikoko sí ìhòòhò ayé, kó tó gba kéú lọ́gbà ẹ̀wọ̀n
"Gbogbo iṣẹ akanṣe ti ijọba Mimiko ṣe pati, ni a ti pari patapata, ti a si tun kọ ẹẹdẹgbẹta ileewe alakọbẹrẹ ni ipinlẹ naa, eleyii to ti mu ilọsiwaju ba eto ẹkọ ni ipinlẹ Ondo.
A tun ti gba owo lati tun adagun omi Owena ṣe ati awọn marun un miran, eleyii ti yoo mu ilọsiwaju ba ipese omi ni ipinlẹ Ondo."
Ondo election 2020: Irọ́ ni pé ẹgbẹ́ òṣèlú mẹ́wàá korajọ láti fi olùdíje kan sílẹ̀ fún ìbò gómìnà - LP, NRM
Oríṣun àwòrán, @inecnigeria
Irọ ni o, ko si n kan to jọ ọ pe, a ti fi ẹgbẹ oṣelu wa silẹ.
Eyi ni esi ti alaga ẹgbẹ oṣelu Labour Party nipinlẹ Ondo, Ọgbẹni Amos Agunloye ati oludije fun ipo gomina, fẹgbẹ oṣelu National Rescue Movement, NRM, Ọgbẹni Funmilayo Ataunoko sọ.
Eyi ni wọn fi n tako iroyin kan to jade sori ayelujara pe, wọn ti darapọ mọ ẹgbẹ oṣelu mẹjọ miran lati fa oludije kan ṣoṣo silẹ, fun eto idibo gomina ipinlẹ Ondo to n bọ.
Ninu iroyin naa, ti awọn ileeṣẹ iroyin abẹle kan gbe sita ni wọn ti sọ pe, Olugbemi Ogunbameru (SDP) ati Comrade Israel Ayeni (AAC), ti fi ọwọ si iwe adehun, lati yan oludije kan labẹ aburada Conference of INEC Registered Political Parties (CIRPP).
Oríṣun àwòrán, ondostate.gov.ng
Awọn eeyan mii ti wọn tun darukọ pe o se adehun naa ni awọn alaga ẹgbẹ oṣelu bi i Prince Niran Toyin (APGA), Ọgbẹni Olaoluwa Adesanya (APP) ati Oloye Tokunbo Adetoro (ADC).
Bakan naa ni wọn ni Ajibola Falaiye (Accord), Olagookun Peter (NNPP), Felix Funso Oloro (APM), Funmilayo Ataunoko (NRM) ati Amos Agunloye (LP) lọwọ si adehun naa.
Ṣugbọn ninu ọrọ ti wọn ba BBC sọ, Ọgbẹni Amos Agunloye sọ pe irọ ni iroyin naa.
Ìṣẹ̀lẹ̀ Kàyéèfì: Ìpáǹle tú Abass Owonikoko sí ìhòòhò ayé, kó tó gba kéú lọ́gbà ẹ̀wọ̀n
Ko ṣe e ṣe fun mi lati darapọ mọ ẹgbẹ oselu miran, nigba ti mo ni oludije temi.
"Ninu ọrọ ti ẹ naa, oludije fun ẹgbẹ osẹlu NRM Ọgbẹni Funmilayo Ataunoko sọ pe ""awọn kan lo n sọ pe a ti gba owo lọwọ ẹgbẹ osẹlu , ṣugbọn irọ ni."
"Eyi lo mu ka fi atẹjade sita pe, a ko gba owo lọwọ ẹnikẹni, emi naa fẹ ẹ dije, a si fẹ ẹ jawe olubori ninu idibo to n bọ ni."""
FG Survival Fund: Wo bi o ṣe le fi orúkọ sílẹ̀ láti j'ànfàání owó ìrànwọ́ ìjọba Nàìjíríà gẹ́gẹ́ bi oníṣẹ́ ọwọ́, oníṣẹ́ àdáni àti awakọ̀
Oríṣun àwòrán, MSME Survival Fund/twitter
Awọn oniṣẹ ọwọ, ati ọlọkọ eero, ni ọpọn sun kan ninu eto owo iranwọ ti ijọba Naijiria n ṣe nitori aarun Covid-19.
Ọjọ kinni, oṣu Kẹwaa, ọdun 2020 ni wọn ṣe ifilọlẹ eto naa fun ipele tuntun yii.
Gẹgẹ bi ikede ti awọn alamojuto eto naa fi sita, iranwọ naa wa fun awọn olokoowo adana kekeeke jakejado Naijiria, lati tu wọn lara fun owo ti wọn padanu nitori itankalẹ aarun coronavirus ni lara ọrọ aje wọn ku.
Eto naa ti bẹrẹ fun awọn olokoowo ni ẹka eto ẹkọ, irinajo afẹ, ati awọn miran, ni ọjọ kọkanlelogun, oṣu Kẹsan, ọdun 2020, yoo si pari ni ọjọ kẹkdogun, oṣu Kẹwaa.
Fun awọn oniṣẹ ọwọ ati awọn ọlọkọ eero, ẹgbẹrun mẹtalelaadoje (333,000) ni yoo jẹ anfaani lara owo ti ijọba fẹ ẹ fun wọn.
Ẹgbẹrun lọna ọgbọn Naira ni ijọba yoo fun ẹni kọọkan wọn.
Awọn alamojuto eto naa sọ pe isọri mẹta ni wọn yoo pin awọn oniṣẹ ọwọ ati ọlọkọ eero naa si.
Awọn to wa ni isọri kinni yoo ṣe iforukọsilẹ ni ọjọ kinni, oṣu Kẹwaa si ọjọ kẹẹdogun, oṣu Kẹwaa.
•Abuja
•Lagos
•Kaduna
•Ogun
•Kano
•Anambra
•Borno
•Bauchi
•Abia
•Rivers
•Plateau
•Delta
Ipinlẹ mejila ni yoo kopa ni isọri keji. Wọn o si bẹrẹ eto ti wọn ni ọjọ kọkandinlogun, oṣu Kẹwaa, si ọjọ kọkanlelọgbọn, oṣu Kẹwaa.
Ọjọ kẹsan, oṣu Kọkanla si ọjọ kọkanlelogun, oṣu Kọkanla, ni isọri kẹta yoo kan ipinlẹ mẹtala to ku.
O gbọdọ jẹ olokoowo kekere (to ni oṣiṣẹ) tabi oniṣẹ adani
Ida marunlelogoji (45%) awọn ti yoo jẹ anfaani eto naa ni yoo jẹ obinrin, ida marun yoo si jẹ awọn akanda ẹda.
To ba jẹ ileeṣẹ, o gbọdọ ti fi orukọ silẹ lọdọ ajọ to n mojuto ọrọ awọn ileeṣẹ, Corporate Affairs Commission; o gbọdọ ni to oṣiṣẹ mẹta; bakan naa ni ọga ilẹẹṣẹ naa gbọdọ jẹ ọmọ Naijiria, to ni nọmba BVN.
Fun awọn oniṣẹ adani, awọn awakọ bọọsi, awakọ takisi, to fi mọ awọn takisi igbalode bi i Uber ati Bolt, ati awọn mọkaliiki.
Awọn oniṣẹ ọwọ bi birikila, jorin-jorin, ati bẹẹbẹẹ lọ, ni eto naa kan.
Nigeira at 60 independent celebration: Sanwo-Olu gbàlejò àwọn akẹ́kọ̀ọ́ ̣ọgọ́ta, El-Rufai dá ẹlẹ́wọ̀n 25 sílẹ̀
Oríṣun àwòrán, KDSG
Gomina ipinlẹ Eko, Babajide Sanwo-Olu ti gbalejo akẹkọọ ọgọta lati ileewe alakọbẹrẹ ni ipinlẹ Eko lati ṣe ayajọ ọjọ ominira orilẹ-ede Naijiria.
Ninu atẹjade ti akọwe eto iroyin fun gomina Sanwo-Olu, Gboyega Akosilekọ jade, ni wọn ti fi lede pe igbalejo naa waye ni Ile Ijọba ni Marina, lagbegbe Tafewa Balewa Square (TBS) ni ilu Eko.
Oríṣun àwòrán, Babajide sanwoolu
Gomina sanwo-olu wa gba awọn akẹkọọ ni imọran lati mase ro orilẹede Naijiria pin, nitori yoo dara fun wọn.
O fikun un wi pe gomina Eko, lo ayẹyẹ naa lati fi ṣe idanilẹkọ fun awọn ọmọde naa lori bi wọn ṣe le mu iwuri ba orilẹede Naijiria ati awọn ohun to yẹ ki wọn ṣe gẹgẹ bi ọmọ orilẹede Niajiria rere.
Ìṣẹ̀lẹ̀ Kàyéèfì: Ìpáǹle tú Abass Owonikoko sí ìhòòhò ayé, kó tó gba kéú lọ́gbà ẹ̀wọ̀n
Bakan naa ni Gomina Sanwo-Olu rọ awọn ọmọ naa lati ma hu iwa rere ti yoo mu idagbasoke ati iṣọkan gbooro si ni Naijiria.
Ni ipinlẹ Kaduna, Gomina Nasir El- Rufai da awọn ẹlẹwọn marundinlọgbọn silẹ lati ṣe ayẹyẹ ayajọ ọjọ ominira orilẹede Naijiria.
Akomolede ati Aṣa lori BBC: Kí ní ìtúmọ̀ Sílébù àti àmi ohun tó ń fún ni?
Gomina El-Rufai ni ọjọ aanu ni Ọjọ ominira Naijiria, nitori naa ni awọn ṣe ṣaanu fun awọn ẹlẹwọn ti wọn wa ni ọgba ẹwọn ni Kaduna.
O ni bi awọn ṣe yọnda awọn kan lati ma a lọ sile layọ ati alaafia ni awọn din iye ọjọ ti awọn miran fe lo ni ọgba ẹwọn ku.
Gomina ipinlẹ Kaduna fikun un pe alaafia jẹ ijọba oun logun lọna ati mu idagbasoke ba ipinlẹ Kaduna ni asiko ijọba awọn oun ati ni ọjọ iwaju.
SS3 ní mo wà báyìí, mo sì ti gba àmì ẹ̀yẹ̀ púpò nílé-lóko gẹ́gẹ́ bí onílù - Ayansike
EFCC arrests 10 in Oyo: Àwọn afurasí mẹ́wàá ní EFCC mú ní Ibadan lórí ẹ̀sùn gbájúẹ̀
Oríṣun àwòrán, Efcc
Àjọ EFCC ti mú ọdọkùnrin mẹwàá lórí ẹsùn jìbìtì lílù lórí ayélujára ní Oyo
Ajọ to n gbogun ti iwa ibajẹ ni Naijiria ti a mọ si Economic an Finanicial Crimes Commisssion, EFCC ti mu awọn ọdọ mẹwaa lori ẹsun jibiti ori ayelujara ni Ibadan.
Awọn ti ọwọ tẹ naa ni: Isaac Ogundayo, Abass Sodiq, David Ayodele, Kelvin Etiowe, Afolabi Seun, Saheed Olalekan, Oluwatobi Damilola, Sukanmi Odofin, Ademola Okumola, ati Joseph Damilare.
Ogbeni Wilson Uwujaren to jẹ adari ẹka ifitonileti fun ajọ EFCC ni ipinle Oyo salaye pe ibuba wọn ni ojule 4, Opopona Ajinde, ni Akala Expressway ni Ibadan.
O ni laarọ oni ọja Eti ni EFCC lọ ka wọn mọ lẹyin ti wọn ti gba ifitonileti lati ọdọ awọn eeyan kan ni ọpọlọpọ ọsẹ sẹyin.
SS3 ní mo wà báyìí, mo sì ti gba àmì ẹ̀yẹ̀ púpò nílé-lóko gẹ́gẹ́ bí onílù - Ayansike
Uwujaren ni wọn yoo gbe awọn mẹwẹẹwa yoo foju a ile ẹjọ ni kete ti iwadii ba ti pari lori wọn,
O salaye pe iwadii naa ni yoo sọ́ iru ẹ́sun ti wsn yoo fi koju koowa ninu wọn
Ìṣẹ̀lẹ̀ Kàyéèfì: Ìpáǹle tú Abass Owonikoko sí ìhòòhò ayé, kó tó gba kéú lọ́gbà ẹ̀wọ̀n
Yomi Fabiyi: Fíìmù ‘Owó orí ẹlẹ́wọ̀n’ jẹ́ ká mọ̀ pé ìgbà ìpọ́njú làá mọ ọ̀rẹ́
Yoruba ni ọwọ epo ni ọmọ araye n ba ni la, wọn kii ba ni la ọwọ ẹjẹ.
Ẹkunrẹrẹ alaye nipa owe yii lo wa ninu sinima tuntun ti Yomi Fabiyi n ya lọwọ, to pe akọle rẹ ni ‘Owo Ori Ẹlẹwọn,”
Nigba ti BBC Yoruba kan si ibi to ti n ya sinima naa, ọpọ awọn akikanju osere la ba ni oko ere naa, ti wsn n sisẹ karakara. Yatọ si Yomi Fabiyi to ni ere, a tun ri Muka Ray, Ronke Odusanya, Adekola Tijani ati bẹẹ bẹẹ lọ.
Nigba to n sọ nipa sinima naa, Yomi Fabiyi ni sinima Owo ori ẹlẹwọn lo n sọ fun wa pe ka mase gbe ara le ọrẹ lasiko ti nnkan n dun fun wa.
O ni igba ipọnju laa mọ ọrẹ, bi oorun si tilẹ mu to, sanmọ dudu diẹ yoo wa.
FIBAN: Ìpàdé àláàfíà wáyé láàrin KWAM 1 àti FIBAN, ìjà pari
Gbonmi si omi o to to waye laarin ẹgbẹ awọn sọrọsọrọ Naijiria ta mọ si FIBAN ati akọrin Fuji KWAM 1 ti pari.
Ọrọ naa yanju lẹyin ipade alaafia kan to waye tawọn mejeeji si ni awọn ti pana ohunkohun to n da wahala silẹ.
Ni aafin Olu ti ilu Itori ni ipade yi ti waye ti Wasiu Ayinde si sọ pe oun ko paṣẹ ki awọn ọmọ gbẹ oun kankan lu Mc Murphy.
Nitori naa aarẹ ẹgbẹ FIBAN Desmond Nwachukwu ti wa pasẹ ki awọn ọmọ ẹgbẹ naa jeburẹ ki wọn si bẹrẹ si ni lo orin KWAM 1 lori eto wọn.
Oríṣun àwòrán, Instagran/kingwasiuayindemarshal
Àwọn ọmọ ẹgbẹ́ FIBAN ti fi ààké kọrí lórí ìṣẹ̀lẹ̀ to wáyé láàrin MC Murphy tó jẹ́ ọmọ ẹgbẹ́ wọ́n ní ìpińlẹ̀ Ogun àti gbájúgbaja olórín fújì, King Wasiu Ayinde Mashall.
Nínú ọ̀rọ̀ rẹ̀ lásìkò tó bá BBC Yoruba sọ̀rọ̀, ní ààrẹ ẹgbẹ́ FIBAN Desmond Nwachukwu sàlàyé pé, àwọn ṣì ń dúró de Ọjọ́rú ọjọ keje, ọdún yìí kí àwọn tó gbé ìgbẹ́sẹ̀ tó kan lórí ọ̀rọ̀ náà.
Nwachukwu ní, lẹ́yin ọjọ́ náà, ti Wasiu Ayinde ko ba bẹ̀bẹ̀ gẹ́gẹ́ bi àwọn ṣe kọ̀wé ránṣẹ́ sí í lórí ǹkan ti àwọn ń fẹ́ kó ṣe, lawọn yoo ṣe iwọde lọ sọdọ Kabiyesi iku baba yeye lati rọ ọ loye gẹgẹ bi Mayegun ilẹ Yoruba.
'N500 dé fún gbogbo ọmọ tuntun lóṣooṣù bí mo bá di gómìnà Ondo - Adeleye AAC
Ó  ní ìdí tí àwọn fi fẹ́ kí wọ́n gba oyè lọ́wọ́ Máyégún gbogbo ilẹ̀ Yorùbá ní pé ìwà tó hù kò bá ìlànà oyè tó jẹ́ lọ nítorí náà, Aláàfin Ọyọ Ọba Lamidi Adeyemi gbọ̀dọ gbà á lọ́wọ́ rẹ.
Lórí ẹgbẹ̀rún lọ́nà ọgọ́rún Náírà ti Murphy gbà lọ́wọ́ K1, o ní láti le dáàbò bo ẹ̀mi rẹ nítori túlàsì ni wọ́n fi fún un ni owó náà. Tí ọ̀rọ̀ bá sì ti rí bẹ́ẹ̀, ó ti pọndandan ki ènìyàn dáàbò bo ẹmi ara rẹ náà.
Lẹ́yìn tí Wasiu Ayinde bá wá ti gbé ìgbésẹ̀ tí ẹgbẹ̀ náà bèrè fún ni àwọn yoo tó mọ̀ boya àwọn yóò dá owó náà padà bi bẹ́ẹ̀ kọ́, owó ọhun kò tí tó ǹkan ti àwọn fi ṣe ìtọ́jú MC Murphy.
Ó rọ gbogbo olórin láti so ewe agbéjẹ́ mọ́wọ́ lórí bi wọ́n ṣe máa n huwa sí àwọn akọròyìn, ìwà ìyànjẹ to fi mọ ìwà àitọ sí àwọn akọròyìn ní Naìjíríà.
Bákan náà ló fi kún un pé, ìdáhùn ọkan lára amúgbálẹ́gbẹ̀ẹ́ K1 to bá BBC Yoruba sọ̀rọ̀ tó sí ló àwọn ọ̀rọ̀ kan, ẹgbẹ náà ni láti mọ̀ bóya òun gan ló fún un láṣẹ lati sọ̀rọ̀.
Bákan náà ni wọ́n gbọdọ̀ tọ̀rọ̀ àforijì lórí ọ̀rọ̀ náà.
Àwọn ọmọ FIBAN kò gbọdọ̀ lo orin Wasiu Ayinde mọ́ lẹ́yìn ìfìyàjẹní Murphy- FIBAN
Wasiu Ayinde fi bàtà tẹ̀ mí lórí àti imú mọ́lẹ̀, ọmọ ẹ̀yìn rẹ̀ gbá mi létí
Ẹgbẹ awọn oniroyin aladani, FIBAN ti kede pe ọmọ ẹgbẹ wọn kankan ko gbọdọ lo orin Wasiu Ayinde kankan mọ lori eto wọn.
Aarẹ ẹgbẹ FIBAN, Desmond Nwachukwu lo fi lede ninu atẹjade kan lati fesi si iṣẹlẹ to ṣẹlẹ laarin Wasiu Ayinde ati oniroyin Wole Sorunke ti wọn n pe ni MC Murphy.
Nwachukwu ni iṣẹlẹ naa ko dun mọ awọn ninu nitori pe ki i ṣe igba akọkọ ni yii ti Kwam 1 yoo ma hu iru iwa bayii ni igba de igba.
O ni ọrọ abuku ni asoju Kwam 1, Kunle Rasheed sọ nipa iṣẹlẹ naa fun BBC News Yoruba nibi to ti sọ fun ẹgbẹ FIBAN lati sa ipa wọn lori iṣẹlẹ naa, koda wọn le e gbe awọn lọ si ileẹjọ.
''Ma a bẹ awọn ọmọ ẹgbẹ lati da ọrọ Rasheed nu, nitori ko si otitọ kankan to sọ pẹlu ọrọ kubakugbe to sọ si ẹgbẹ FIBAN.''
''Rasheed tabuku lu wa nitori pe o pe wa ni ẹgbẹ ti ko ni oye nipa iṣẹ to n ṣẹ''
''Nitori naa ni bayii, ko si ọmọ ẹgbẹ wa kankan ti yoo lo orin Kwam 1 lori eto wa kaakiri iwo oorun orilẹede Naijiria.''
''Bakan naa ni a ti ranṣẹ si awọn adari ileeṣẹ radio ati amọhunmaworan lati tẹlẹ aṣẹ wa lati maṣe lo orin Kwam 1 mọ.''
Ẹgbẹ FIBAN fi kun un wi pe awọn yoo ṣewode lọ si aafin ti Alaafin Oyo lati fi aidunnu wọn han si iwa ifiyajẹni ti Kwam 1 n wu lawujọ.
Bakan naa ni awọn yoo bẹrẹ lọwọ Alaafin lati rọ ọ loye Mayegun ti Ilẹ Yoruba nitori ihuwasi rẹ ti ko ba ọna asa ati iṣe Yoruba mu.
Ni owurọ ọjọ Abamẹta ni ariwo gba ilẹ kan pe, ilumọọka akọrin Fuji ati Mayegun ilẹ Yoruba, Wasiu Ayinde Mashall, ti ọpọ eeyan mọ si Kwam 1, gba gbajumọ agbohunsafẹfẹ kan leti loju agbo.
Alákòso orín Wasiu Ayinde Mashall, Adebayo Olasoju to ba BBC Yoruba sọrọ lórí fóònù ṣàlàyé pé, ọ̀rọ̀ tó ṣẹlẹ kìí ṣe èyí tó yẹ ki ó jáde rárá nítóri, ọmọ iṣẹ́ K1 ni MC Murphy.
Kété ti ọrọ náà bẹrẹ si ni ran ka ni BBC kan si àwọn to jẹ́ ti K1, nítori owe àgbà ló sọ pé agbẹ́jọ́ ẹnikan dájọ àgbà òṣìkà ni.
Tí ọ̀rọ̀ bá ṣẹlẹ̀ láàrín K1 àti MC Murphy ti Murphy kò si le pé Wasiu Ayinde to wá gbé ẹjọ lọ sí ọ̀dọ̀ àwọn oníròyìn , òun ló mọ
"Tí àwọn FIBAN bá sì fẹ́ lọ sí ilé ẹjọ́, kí wọ́n nìsó níbẹ̀ Ọ̀rọ̀ ti a ń múgbọ́ jú ti Murphy lọ, a ò ni ẹjọ́ kankan ti a fẹ́ bá a rò"""
Alakoso orin Kwam 1, Adebayo Olaasoju sọ fun BBC Yoruba pe, ọrọ naa ko ri bẹẹ rara nitori Kwam 1 ko lee gba ẹnikẹni leti rara.
Wo Adigun ọmọ ọdún mẹ́rin tí òwe Yorùbá àti ìtúmọ̀ gbó lẹ́nu rẹ̀ ju tìrẹ̀ lọ
"Awọn wo lo na a, se Kwam 1 ni. Ọmọ Wasiu ni MC Murphy now, ko si yẹ ko gbe ọrọ naa lọ sọdọ awọn akọroyin, oun n gan mọ pe oun ko sọ ootọ bi ọrọ naa se ri.'
Bakan náà BBC bá ilumọọka agbohunsafẹfẹ naa ti wọn pe ni Wole Sorunke, ti ọpọ eeyan mọ si MC Murphy, ẹni tii se oludari eto gbogbo nileesẹ radio Fresh FM to wa nilu Abeokuta náà sọ̀rọ̀.
Gẹgẹ bi iroyin naa se wi, nibi ayẹyẹ ọjọ ibi ọgọta ọdun Olu tilu Itori, Ọba Abdulfatai Akorede Akamọ ni isẹlẹ naa ti waye, lasiko ti wọn pe Kwam 1, ko wa kọrin nibẹ.
A gbọ pe Mayegun se agbohunsafẹfẹ yii, bii ọsẹ tii se oju, to si fi se ẹlẹya lori ọrọ ti ko to nnkan.
Ọna lati fi idi otitọ mulẹ nipa iroyin yii, lo mu ki BBC Yoruba kan si MC Murphy, ka le mọ bi isẹlẹ naa se waye.
Nigba to n ba BBC Yoruba sọrọ, Murphy ni lootọ ni ọmọ isẹ gbajumọ olorin Fuji , Wasiu Ayinde, to pe orukọ rẹ ni KC gba oun leti, ti Wasiu Ayinde funra rẹ gan si fi bata tẹ oun ni ori ati ẹnu mọlẹ.
O fikun pe, lẹyin to tẹ oun lori ati ẹnu tan, ni Wasiu to wa sẹsẹ tun n gbe oun lori dide, eyi ti ko bojumu rara.
Mo kọkọ n wo pe se ẹgbọn n ba aburo rẹ wi ni abi ibo ni mo ti se asise? Abi nnkan kan sẹlẹ ti Alhaji ko ri ni, abi nnkan ti ko yẹ ki wọn sọ fun wọn ni wọn gbọ ni, ko tiẹ ye mi."""
Oríṣun àwòrán, Instagran/kingwasiuayindemarshal
Murphy ni oun lọ siwaju Kwam 1 lati nawo fun ni, ki o le ki ẹnikan ti oun n ba se onigbọwọ, ki oun si fi ọrọ ẹni naa to leti pe onitọun fẹ wa na lowo fun loju agbo.
Amọ o ni, Wasiu Ayinde ko dahun, ti oun si sọkalẹ loju agbo naa.
"Sugbọn bi mo se sọkalẹ ni mo gbọ gba leti mi, ti wọn si da mi dọbalẹ, ti wọn n fi bata tẹ mi lori mọlẹ. Gbogbo awọn ero to wa loju agbo lo binu, ti wọn si kuro nibẹ.
Murphy ni Olu ti ilu Itori tawọn lọ ba se ayẹyẹ ti bẹ oun, nitori oloye ni oun nilu Itori, oun si ni Aarẹ Amuludun fun gbogbo ilu Itori.
Yomi Fabiyi: Fíìmù ‘Owó orí ẹlẹ́wọ̀n’ jẹ́ ká mọ̀ pé ìgbà ìpọ́njú làá mọ ọ̀rẹ́
Mo maa n promote awọn olorin, mo si mọ pe Wasiu gbọ ọrọ ti ko yẹ ni nitori ko ye mi nipa oun ti wọn gba mi leti si, kii si se eeyan bẹẹ."""
Nigba ta bi pe ki lo fẹ se nipa isẹlẹ yii, MC Murphy ni isẹlẹ naa ti kọja agbara oun, ti olu ile ẹgbẹ awọn agbohunsafẹfẹ ni Naijiria, FIBAN, si ti tẹsẹ bọ ọrọ naa.
"Wasiu Ayinde funra rẹ gan ti n bẹ mi, to si ti pe mi pe, ki n ranti pe oun ni ẹgbọn oun. Ti Wasiu ba na mi ni kọrọ, o to eeyan to le na mi, amọ eyi to se ni gbangba lo ku diẹ kaa to.
Ọlọrun kan fẹ ki iru nnkan bayii sẹlẹ ni, ki Alhaji Wasiu ma baa se iru nnkan bayii mọ."
Ìṣẹ̀lẹ̀ Kàyéèfì: Ìpáǹle tú Abass Owonikoko sí ìhòòhò ayé, kó tó gba kéú lọ́gbà ẹ̀wọ̀n
O wa rọ awọn akọroyin atawọn adari eto, ta mọ si MC pe, ki wọn maa bọwọ fun ara wọn, ki wọn ma si toju bọ ayẹyẹ ti wọn ko ba pe wọn si, tori awọn abuku bii eleyi.
Goitre Patients: Àwọn èèyàn tó ní àrùn gẹ̀gẹ̀ ní ọ̀pọ̀ ìkórira àti ìdẹ́yẹsí ní àwọn ń kojú
Sunday Igboho: Gani Adams ní ìwọ́de kọ́ ni Ààrẹ ọ̀nà Kakańfò fi ń bẹ̀rẹ̀ ogun
Oríṣun àwòrán, @OPCGANIADAMS
Ìlànà 'Referendum' nìkan la fi le gba orílẹ̀èdè Oduduwa, kìí ṣe ìwọ́de
Aarẹ Ọnakakanfo, Iba Gani Adams tun ti ja gudugbẹ ọrọ mii silẹ, lori ọrọ ijijagbara Oduduwa Republic ti ajafẹtọ ọmọniyan, Sunday Adeyemo, ti ọpọ mọ si Sunday Igboho, wa lara awọn to n ṣagbatẹru rẹ.
Nigba ti Gani Adams n ba BBC Yoruba sọrọ, Aarẹ Ọnakakanfo sọ pe, ọgbọn lọrọ to wa nilẹ yii gba ki ṣe agbara kaka.
Aarẹ ni gbogbo nkan ti Igboho n ṣe papaa julọ lori ayelujara ni oun n fi oju sununkun wo.
Gani Adams ni awọn si n wo o boya Igboho tootọ ni gbogbo ohun ti Igboho ṣi n ṣe.
Oríṣun àwòrán, Instagram/aare_gani_adams
O ni oun gan an faramọ ki ẹya Yoruba ya kuro lara orilẹede Naijiria, amọ ọ ni ọna ti eeyan le gbee gba.
''Ọrọ orilẹede ni a n sọ yii o, kii ṣe ọrọ ilu Ibadan tabi ọrọ Sunday Igboho nikan,'' Gani Adams lo sọ bẹẹ.
Aarẹ Ọna Ọ́kakanfo sọ pe eto idibo ''ṣe ẹ fẹ, abi ẹ o fẹ'' ti awọn oloyinbo maa n pe ni ''referendum'''loun faramọ pe o jẹ ọna kan ti Yoruba fi le ya kuro lara Naijiria.
O kilọ fun Igboho pe ko yee wa ọta kun ọta nipa bi o ti n sọrọ ko bakun pe gbe si agbaagba ilẹ Yoruba.
Yomi Fabiyi: Fíìmù ‘Owó orí ẹlẹ́wọ̀n’ jẹ́ ká mọ̀ pé ìgbà ìpọ́njú làá mọ ọ̀rẹ́
Gani Adams ṣalaye awọn agba to n bu yii gan an le wa wulo fun ijijagbara Oduduwa Republic to ba ya.
O ni Sunday Igboho ni lati kọwọ ọmọ rẹ bọ aṣọ, ki o si tẹẹ jẹjẹ ti o ba fẹ rin jina ninu ijijagbara.
''Awa ni a ja fun eto ijọba awarawa lorilẹede Naijiria, amọ iwọde kọ ni aarẹ fi maa n bẹrẹ ogun,'' Aarẹ Ọnakakanfo lo woye bẹẹ.
Gani Adams ni ti o ba doju rẹ tan, ''ori ti a fi ṣe ewe si wa nibẹ.
Ìṣẹ̀lẹ̀ Kàyéèfì: Ìpáǹle tú Abass Owonikoko sí ìhòòhò ayé, kó tó gba kéú lọ́gbà ẹ̀wọ̀n
O ni nigba naa lawọn eeyan yoo ri agbara aarẹ, ''agbara aarẹ a wa jade.''
O ni ibẹrẹ pẹpẹ ni gbogbo ohun tawọn Sunday n ṣe lori ọrọ Oduduwa Republic.
''Mo n duro de awọn eeyan wa lori ọrọ ''referendum'' ki n to mọ oun maa ṣe,'' Aarẹ Ọna kakanfo lo sọ bẹẹ.
O ni ko si ọjọ iwaju fun orilẹede Naijiria yii mọ, idi si ni yii ti oun fi maa gbaruku ti ọrọ Oduduwa Republic.
''Awa ko le jẹ ki awọn alakatakiti ẹsin maa ju bọmbu lu awọn eeyan wa nilẹ Yoruba, o ni ohun ti a agba nigba ti a gba ominira kọ lo n ṣẹlẹ bayii,'' Gani Adams lo woye bẹẹ.
Aarẹ Ọna kakanfo ni nkan ti awa n wa gẹgẹ bi ẹya Yoruba kọ, ni awọn Hausa ati Fulani n wa.
Ogun kiliing: Ọmọ olóògbé ní oúnjẹ ni bàbá òun ń jẹ nínú ṣọ́ọ́bù, kí ìbọn tó bàá
Oríṣun àwòrán, @jacobscarlene1
Ọmọ mejidinlogun ni ọkọ wa fi silẹ, ko si ẹni ti yoo ran wa lọwọ.
Ọkan lara awọn iyawo ọkunrin ''Panel Beater'' kan, Moses Atanda, ti ọta ibọn osisẹ asọbode, Custom, ṣeesi ba ninu sọọbu rẹ nipinlẹ Ogun, Titilayo Atanda, lo sọ bẹẹ.
Ọmọ ''panel beater'' naa, Adeniyi Atanda ni ounjẹ ni baba oun n jẹ lọwọ nigba ti ibọn baa nibi to ti n ṣọọbu rẹ.
Iyawo mẹrin ni Ọgbẹni Atanda fi si aye lọ lai ro tẹlẹ.
Titilayo ṣalaye fawọn akọroyin pe, ọpọ ninu awọn ọmọ ti oloogbe fi silẹ lọ ni wọn si wa nile iwe, nigba tawọn mii si n wa lẹnu ikọṣẹ.
Yomi Fabiyi: Fíìmù ‘Owó orí ẹlẹ́wọ̀n’ jẹ́ ká mọ̀ pé ìgbà ìpọ́njú làá mọ ọ̀rẹ́
Titilayo sọ pe, oniṣowo pẹpẹpẹ lawọn iyawo ṣugbọn ọkọ awọn naa lo n tọju gbogbo awọn ninu ẹbi.
''A o tiẹ mọ ohun ti a le ṣe, a ko ni ohun kankan, ko si ẹni ti yoo ba wa sanwo ileewe awọn ọmọ ati ipese ounjẹ fun wọn,'' Titilayo lo sọ bẹẹ.
Titilayo ni iṣẹ ọkọ rirọ (panel beater) nikan ni ọkọ awọn n ṣe, kii ṣe awọn to maa n ṣe fayawọ ọja wọle lati orilẹede mii wọ Naijiria.
Ọkan lara awọn oloogbe naa, Gabriel Atanda sọ fawọn akọroyin pe, oun wa pẹlu baba oun ninu ṣọọbu nigba tawọn ẹṣọ aṣọbode bẹrẹ si ni yinbọn lagbegbe naa.
Ìṣẹ̀lẹ̀ Kàyéèfì: Ìpáǹle tú Abass Owonikoko sí ìhòòhò ayé, kó tó gba kéú lọ́gbà ẹ̀wọ̀n
O ni gbogbo igba lawọn aṣọbode ọhun maa n yinbọn lagbegbe naa, ti awọn eeyan yoo si maa wo wọn bi fiimu.
Baba mi sọ fun mi atawọn mii pe, ki a sa pamọ sinu ṣọọbu ki ọta ibọn ma baa ṣeesi ba wa.
Kete ti mo bọ sinu ṣoọbu tan ni mo rii pe ẹjẹ ti bo bo baba mi, lẹyin ti ibọn awọn aṣọbode ti ba a.
O ni awọn gbe baba oun digbadigba lọ si ile iwosan, amọ ọwọ ti bọ sori.
Ekiti Bank Robbery: Iléeṣẹ́ ọlọ́pàá rí ọkọ̀ mẹ́ta gbà lọ́wọ́ adigunjalè báńkì Iyin-Ekiti
Oríṣun àwòrán, @tosinsammy_s
Ọjọ buruku, Eṣu gbomi mu lọjọ Ẹti, ọjọ keji oṣu kẹwaa ọdun 2020 jẹ niluu Iyin-Ekiti, nibi tawọn adigunjale ti yabo ile ifowopamọ WEMA ti wọn si gbe ẹgbẹlẹgbẹ miliọnu owo naira lọ.
Amọ, ileeṣẹ ọlọpaa ipinlẹ Ekiti ti kede pe, oun ti ri ọkọ mẹta tawọn adigunjale naa lo, lati ṣiṣẹ ibi wọn.
Ninu atẹjade kan ti agbẹnusọ fun ileeṣẹ ọlọpaa Ekiti, Ọgbẹni Sunday Abutu fi sita ṣalaye pe ado oloro IED, igbo, ọti ati foonu meji lawọn ri ninu awọn ọkọ naa.
Ileeṣẹ ọlọpaa ni mẹwaa lawọn adigunjale naa, awọn ọkọ ti wọn si lo fi fọ banki naa ni ọkọ ayọkẹlẹ Volkswagen Golf pẹlu nọmba GED 906 AA, Acura MDX Jeep pẹlu nọmba LSR 327 CD, ati Toyota Camry to ni nọmba No GED 106 ER.
Oríṣun àwòrán, @tosinsammy_s
Ileeṣẹ ọlọpaa ni apa awọn agbofinro to n ṣọ banki naa ko ka wọn, nitori bi wọn ṣe pọ wa, ti gbogbo wọn si wọle lẹẹkan naa.
Agbẹnusọ fun ileeṣẹ ọlọpaa ṣalaye pe, ko si ẹni to ba iṣẹlẹ naa lọ.
Ọgbẹni Abutu wa rọ awọn araalu lati mase foya, nitori iwadii ti bẹrẹ lati rii pe ọwọ tẹ awọn aṣebi naa.
O ni awọn adigunjale naa fẹsẹ fẹ, ti wọn si fi ọkọ ti wọn gbe wa silẹ nigba tawọn ọlọpaa de ibẹ, ti wọn si kọju ija kọ wọn.
Ileeṣẹ ọlọpaa Ekiti rọ awọn araalu Iyin-Ekiti pe, ki wọn fi to awọn ọlọpaa leti ti wọn ba kẹfin ẹnikan to ṣeeṣe ko wa lara awọn adigunjale naa.
Ìṣẹ̀lẹ̀ Kàyéèfì: Ìpáǹle tú Abass Owonikoko sí ìhòòhò ayé, kó tó gba kéú lọ́gbà ẹ̀wọ̀n
Ẹnikan ti iṣẹlẹ ọhun ṣoju rẹ ṣalaye fawọn akọroyin pe, ni bii aago mẹta aabọ ọsan lawọn adigunjale naa de banki ọhun.
O ni ohun ija ado oloro bii ''dynamite'' ni wọn fi ṣilẹkun ile ifowopamọ si naa, nibi ti wọn ti ji owo ko lọ.
Wasiu Ayinde fi bàtà tẹ̀ mí lórí àti imú mọ́lẹ̀, ọmọ ẹ̀yìn rẹ̀ gbá mi létí
Ni owurọ ọjọ Abamẹta ni ariwo gba ilẹ kan pe, ilumọọka akọrin Fuji ati Mayegun ilẹ Yoruba, Wasiu Ayinde Mashall, ti ọpọ eeyan mọ si Kwam 1, gba gbajumọ agbohunsafẹfẹ kan leti loju agbo.
Orukọ ilumọọka agbohunsafẹfẹ naa ni wọn pe ni Wole Sorunke, ti ọpọ eeyan mọ si MC Murphy, ẹni tii se oludari eto gbogbo nileesẹ radio Fresh FM to wa nilu Abeokuta.
Gẹgẹ bi iroyin naa se wi, nibi ayẹyẹ ọjọ ibi ọgọta ọdun Olu tilu Itori, Ọba Abdulfatai Akorede Akamọ ni isẹlẹ naa ti waye, lasiko ti wọn pe Kwam 1, ko wa kọrin nibẹ.
Adigun Olowe Yoruba Proverbs: Israel Adebayo tó ń pa òwe Yorùbá ọgbọ̀n lẹ́ẹ̀kan ṣoṣo
Igba ti baba mi wa laye, wọn fẹran ki wọn maa fi owe sọrọ, o da bii pe ẹbun ọmọwe lo sọ̀kalẹ̀ latori baba mi sori emi to si bọ sori ọmọ mi
Adebayo Olamilekan Israel ni orukọ abisọ rẹ ṣugbọn ti gbogbo eniyan mọ ọ si Adigun Olowe Yoruba.
"Baba rẹ, Adebayo Oladimeji Ishola ni lati kekere ti awọn ti bi ọmọ naa lo ti maa n ṣe awọn nkan awoṣi ẹnu silẹ eyi to si mu ki iya iya rẹ fun un ni alajẹ ""Ara""."
Wọle Ṣoyinka: Owe ran mi leti MKO Abiọla
Ikú tó ń pa ojúgbà ẹni..., kí ni ìparí òwe náà?
Ìtàn tó rọ̀ mọ́ òwe ‘aṣọ kò bá Ọ́mọ́yẹ mọ́...’ rèé
Ǹjẹ́ o ti ẹ̀ mọ ìtumọ̀ òwe tí bàbá Ọ̀lọ́fà iná pa yìí?
Ọmọ meji ni wọn ti bi ṣaaju Adigun Olowe Yoruba ti wọn bi nigba to pe ọdun kan geerege ti ọmọ ti wọn bi ṣaaju rẹ ku.
Tẹẹ ba tun ni ko gbe iwe ti ileewe rẹ jade, yoo ya yin lẹnu.
Baba rẹ ni o rọrun fun oun gan lati yi ọrọ gẹẹsi pada si ede Yoruba eyi ti ọmọ rẹ naa yan laayo.
O ni ọjọ kan lo kọkọ bẹrẹ rẹ tawọn ṣaadede ri i to tun ọrọ ti oun sọ lede Yoruba ati gẹẹ́si sọ papọ lẹẹkan ṣoṣo titi to fi dori pe o lee sọ owe ọgbọ̀n ati itumọ rẹ lede gẹẹ́si.
MC Murphy ko sọ òótọ́ ọ̀rọ̀ to wà níbẹ̀, tó ba wùú kó sọ òótọ- Adebayọ
Tí àtúntò kò bá wáyé ní Naijiria, ó ṣeéṣe kó túká- Pásítọ̀ Adeboye
Ìrọ́ ní fídío tó ń jà rànyìn, mi ò fí ìyà jẹ ìyàwó tí mo kọ̀ sílẹ̀- Femi Fani-Kayode
End SARS, End SWAT: MC Oluomo ní òun kọ́ ló rán àwọn jàǹdùkú sáwọn olùwọ́de l'Eko
Oríṣun àwòrán, Twitter/mcoluomo
Alaga ẹgbẹ awakọ ero NURTW ni ipinlẹ Eko, Alaaji Musiliu Akinsanya ti ọpọ mọ si MC Oluọmọ ti ṣapejuwe ẹsun ti awọn kan n fi kan an pe oun lo ran awọn janduku lati ls da iwọde #ENDSARS ru l'Eko gẹgẹ bi irọ lasan.
O ṣalaye ninu fọnran kan to fi si oju opo Twitter rẹ pe gbogbo ara ni oun ti fi ti iwọde naa lẹyin lati ibẹrẹ pẹpẹ nitori naa oun ko lee si nidi idaru rẹ.
O wa fi egun le pe ki iṣẹ oun daru bi oun ba mọ si awọn jaduku to lọ kọlu awọn eeyan naa.
Àwọn ikọ̀ mẹ́fà tí kò lè jẹ́ kí ìwọ́de #End SARS, #End SWAT wa sópin lásìkò yìí
Oríṣun àwòrán, others
Wo ìsọ̀rí àwọn tó jẹ́ kí ìwọ́de End SARS lárinrin àti ìtumọ̀Iwọde End SARS to n lọ lọwọ kaakiri awọn ilu nla ni Naijiria ni ọpọ awọn onwoye ohun to n lọ ti sọ pe o jẹ ọkan Pataki lara awọn iwọde to ni eto julọ ni Naijiria.Iwọde naa to ti n gbẹnule ọjọ kẹjọ bayii ni awọn ọdọ Naijiria fi n bere fun fifopin si iwa Baṣọrun Gaa ti awọn oṣiṣẹ ẹka ileeṣẹ ọlọpaa, SARS, n wu si awọn ọdọ ti wọn n fẹsun iwa jibiti kan lọna aitọ.Bi ọpọ ero ṣe n darapọ mọ iwọde naa lojojumọ lawọn miran n gbe igbesẹ ki ifẹhonuhan ọhun dun, ko si larinrin.
Wo diẹ lara awọn to fi adun ati aṣeyọri si iwọde End SARS naa to n lọ lọwọ:
1.Awọn elere idaraya:
Ọkan lara awọn oluwọde naa gbe alupupu Power bike rẹ wa sojuko ọhun lati da awọn eeyan laraya.
Ni agbegbe Alausa, ẹnikan tilẹ gbe kẹkẹ ati aja rẹ wa, ti oun ati aja rẹ si n fi kẹkẹ ọhun dárà.
Yatọ si eyi, ọpọ igba ni wọn maa n fi awọn orin da awọn eeyan laraya, bii orin Fela Anikulapo, Naira Marley, Eedris Abdulkareem, ati bẹẹ bẹẹ lọ.
Oríṣun àwòrán, @Davido/Fortune
2.Awọn to n kọ orin:
Ohun kan Pataki to mu iwọde End SARS ladun to si jẹ ki ijọba mọ ohun ti wọn n bere fun ni orin End SARS ti awọn oluwọde n kọ leralera.
"Bi awọn to ṣaaju ṣe n kọ orin naa ni awọn elegbe n kọ tẹle wọn pe ""End SARS!"""
Oríṣun àwòrán, others
3.Awọn alasia:
Isọri awọn miran to jẹ ki iwọde End SARS ni itumọ ni bi awọn eeyan kan ṣe n gbe asia orile¬̣-ede Naijiria lojuko iwọde naa.
Ọkunrin lara awọn eeyan naa tilẹ ti di gbajumọ nitori bo ṣe maa n gbe asia naa to si ma n ju sọtun ati si osi.
Ni Enugu, ọdọbinrin kan  tilẹ so asia naa mọ ori, o joko sori ere kan to ga to si n wa ẹkun mu nitori ohun ti awọn oṣiṣẹ SARS ti fi oju mọlẹbi rẹ ri.
Oríṣun àwòrán, Other
4.Awọn onimọtoto:
Iyatọ kan gboogi to wa laarin iwọde End SARS yii ati awọn to ti kọja lọ ni bi awọn eeyan kan ṣe palẹmọ ojuko iwọde lẹyin ti awọn eeyan ba pada sile wọn tan.
Awọn eeyan naa n ṣe iṣẹ takuntakun lati ri pe ko si idọti Kankan lojuko ti iwọde ti n waye.
5.Awọn olupese:
Isọri awọn eeyan yii ni awon to n fun awọn olufẹhonuhan ni ounjẹ ki wọn baa le ni okun lati tẹsiwaju ninun iwọde ọhun.
Awọn ni olupese ounjẹ, omi ati ohun irinsẹ fun awọn oluwọde, bi awọn kan ṣe parapọ da owo burẹdi ni awọn miran parapọ da owo DJ ti yoo da wọn laraya.
Oríṣun àwòrán, @Falz
6.Awọn oluṣeto:
Lara awọn oluṣeto ni awọn gbajumọ lawujọ to fi ẹnu si ọrọ naa, to si n ṣatilẹyin fun awọn olufẹhunuhan.
Diẹ lara awọn oluṣeto ni a ti ri olorin takasufe, oṣere tiata ati awọn gbajumọ kaakiri agbaye.
Oríṣun àwòrán, @Police
Awọn miran lara wọn gbe owo kalẹ fun iwọde naa, bẹẹ ni awọn mii ẹwẹ n ru wọn soke lati tẹsiwaju ninu iwọde ọhun.
Lara awọn eeyan ọhun ni Falz, Toyin Abraham, Kanyew West, ati bẹẹ bẹẹ lọ.
O ṣeeṣe ki ajakalẹ aarun coronavirus bẹ silẹ lorilẹede Naijiria fun igba keji- Ọjọgbọn Faduyile
Ìwọ́de 'End SARS' lè tan àjàkálẹ̀ arùn coronavirus lẹ́ẹ̀kejì ní Nàìjíríà- Ọjọ̀gbọ́n Faduyile
Alaga ajọ ẹgbẹ awọn dokita oniṣegun oyinbo tẹlẹ, Ọjọgbọn Francis Faduyile lo fidi ọrọ yii mulẹ fun BBC Yoruba.
Ọjọgbọn Faduyile ṣalaye pe lootọ ni akọsilẹ fihan pe awọn to n lugbadi aarun covid-19 lojoojumọ ko pọ mọ.
Aàrẹ àná NMA, Francis Faduyile ní ìwọ́de 'End SARS' lè ṣe okùnfà àjàkálẹ̀ arùn covid 19 lẹ́ẹ̀kejì ní Nàìjíríà
Ọjọgbọn Faduyile ṣalaye pe ti ajakalẹ arun ba bẹ silẹ lẹẹkeji, ọwọja rẹ maa n ṣaa ba le ju ti igba akọkọ lọ.
Amọ, o sọ pe ewu nla lo wa ninu akọsilẹ to n fihan pe eeyan perete lo n ko aarun covid-19 lojoojumọ nitori ọpọ lo ti n sinmi bayii pe corovavirus ti lọ.
Dokita Faduyile sọ pe eyi gan an le mu ki coronavirus tun bẹ silẹ fun igba keji.
Ọjọgbọn iṣegun naa ṣalaye pe ti ajakalẹ aarun ba bẹ silẹ lẹẹkeji, ọwọja rẹ maa n ṣaa ba le ju ti igba akọkọ lọ.
Abayọmi Aranmọlatẹ, Dr Laser: Vagino Plasty àti iṣẹ́ abẹ ẹwà Obìnrin ló jẹ mí lógún
Aarẹ ẹgbẹ awọn dokita ni Naijira, NMA tẹlẹ tun sọ pe afaimọ ki aarun covid-19 maa tun bẹ silẹ lẹẹkeji pẹlu bi ọpọ eeyan ti n ṣe iwọde #EndSARS lai bikita nipa coronavirus.
O ni ko si ẹni to n tele awọn ilana lati dena aarun coronavirus bi wọn ti n ṣe ifẹhonuhan #EndSARS.
Ọna lati dena itankalẹ coronavirus lasiko iwọde #EndSARS
Ọjọgbọn Faduyile ṣalaye pe ko ṣi ṣiṣe ko si ai ṣe lori ọrọ ate dena coronavirus ju pe ki awọn eeyan maa tẹle ilana itakete si ara ẹni lọ bi wọn ti n ṣe iwọde.
Dokita Faduyile tun sọ pe ọna miran lati daabo ara ẹni lasiko iwọde yii ni lilo ibomu.
O ni nipa lilo ibomu ni eeyan ko le ko aarun coronavirus lara awọn oluwọde miiran.
EndSARS protest in Nigeria: Mr Macaroni, Falz, Wizkid, Tiwa Savage àtàwọn míì ṣe ìwọde
Dokita Faduyile sọ pe awọn oluwọde yii wa lati oriṣiiriṣii ile to yatọ eleyi to le mu ki aarun covid-19 tete tan kalẹ laarin wọn.
O tun fikun ọrọ rẹ kẹmika apakokoro naa yoo ṣe iranwọ nipa dibaabo bo ara ẹni lọwọ covid-19 lasiko yii.
Bakan naa lo sọ pe awọn eeyan ko gbọdọ lati maa fọ ọwọ wọn loorekoore lasiko yii.
Eegunjobi Omotanbaje Ajobiewe- Èébú ní wọ́n kọ́kọ́ ń bù mí nígbà tí mo bẹ̀rẹ̀ ẹ̀ṣà pípé ní
Ìfẹ́hònúhàn 'End SARS' ń tẹ́síwájú láì jẹ́ pé Buhari ṣe...
Àwọn olùwọ́de kọ̀ láti dáwọ́ dúró lẹ́yìn tí IGP tú SARS ká
Ọjọ Aiku, ọjọ kọkanla, oṣu Kẹwaa ni Ọga Agba ileesẹ ọlọpaa, Mohammed Adamu kede pe oun ti tu ẹka ileesẹ ọlọpaa SARS ká.
Eyi waye lẹyin ọjọ mẹrin ti awọn ọdọ ti n fi ẹhonu han, ti wọn si n ṣe iwọde kaakiri Naijiria.
Sugbọn ṣa, iwọde ipolongo #ENDSARS ko ti i dawọ duro.
Bi iwọde ṣe n waye ni awọn agbegbe bii Lekki nilu Eko, lo n waye ni ilu Abuja ni Onitsha.
Wo diẹ lara bi iwọde naa ṣe n lọ:
Kinni awọn ibeere wọn lẹyin ti wọn tu SARS ka?
Awọn ọdọ naa n sọ pe o di igba ti Aarẹ Muhammadu Buhari fun'ra rẹ ba kede pẹlu aṣẹ, to si fi ontẹ lu u ju ikede ori ahọn lasan lọ.
Wọn ni nitori pe eyi jẹ igba kjarun un ti ijọba maa kede lori ọrọ SARS ṣugbọn to jẹ irọ. Wo ìgbà mẹ́rin tí ìjọba ti tú ikọ̀ ọlọ́pàá SARS ká sẹ̀yín ṣùgbọ́n....
Lara ohun ti wọn n pariwo ni pe ki ileesẹ ọlọpaa tu awọn oluwọde #ENDSARS to wa ni ahamọ rẹ silẹ.
Iroyin sọ pe awọn ọlọpaa mu awọn oluwọde kan.
Wọn tun n fẹ ki ileesẹ fiyajẹ awọn ọlọpaa to ti sẹku pa eeyan ni Naijiria lai ṣe egbe.
Oríṣun àwòrán, @PoliceNG
Aworan FSARS
Koda, wọn n fẹ ki ileesẹ ọlọpaa gbe igbimọ kan, ti kii ṣe ti ọlọpaa kalẹ, ti yoo mojuto iwadii ati igbẹjọ gbogbo àwọn ọlọpaa ti wọn ba fi ẹsun kan pe o fiya jẹ tabi pa ẹnikẹni, laarin ọjọ mẹwaa.
Ko tan sibẹ o, wọn ni awọn fẹ àtúnṣe ati afikun si owo oṣu awọn ọlọpaa Naijiria, boya ti wọnba n gba owo oṣu to dara bii ti agbofinro ilẹ okeere, ori wọn yoo pe sii ni bi wọn a ṣe maa ba ara ilu to pọ fun aabo to peye
Ati pe ki wọn ṣe ayẹwo ilera ọpọlọ fun awọn ọlọpaa SARS tẹlẹ, ki wọn o si tun ṣe idanilẹkọ fun wọn, ki wọn o to darapọ mọ ẹka ileeṣẹ ọlọpaa miran.
Iwọde #ENDSARS ni Lekki
Ni ṣe ni àwọn oluwọde naa di oju ọna marosẹ Lekki si Epe, pẹlu oriṣiriṣi akọle ti wọn gbe dani.
Ọjọ Ẹti ni Aarẹ Muhammadu Buhari sọ pe oun ti paṣẹ fun Ọga Agba ileeṣẹ ọlọpaa Naijiria ni aṣẹ lori igbesẹ ti yoo gbe lori iwọde #ENDSARS to n lọ kaakiri orilẹ-ede Naijiria, lẹyin ti awsn mejeeji ṣe ipade lọjọ Ẹti.
Aarẹ Buhari ninu ikede to fi sita loju opo Twitter lori ọrọ na sọ pe ki awọn ọmọ Naijiria o ma ṣe ṣiyemeji lori igbesẹ atunto ti awọn n ṣe nileeṣẹ ọlọpaa.
"O ni ""gbogbo igba ni wọn n fi to mi leti lori igbesẹ atunsẹ to n lọ lati fi opin si bi awọn ọlọpaa ṣe ma n fi iya jẹ ni, ati awọn iwa ti ko tọ miran. Ati lati ri i daju pe awọn ọlọpaa n jiyin iṣẹ fun araalu."""
Ipade ti aarẹ ṣe pẹlu Ọga Agba ọlọpaa waye lẹyin ọjọ meji ti awọn ọdọ bẹrẹ iwọde ojoojumọ lati ọjọru nipinlẹ Eko, ati awọn ipinlẹ miran ni Naijiria.
Buhari sọ pe ọga ọlọpaa ti gba aṣẹ lọwọ oun lati gbe igbesẹ lori awuyewuye to n waye lati ọdọ araalu lori iwakiwa to wa lọwọ awọn ọlọpaa SARS, ati lati ri i daju pe awọn ọlọpaa to hu iwa ti ko tọ foju wina ofin.
Ninu ọrọ to kọ si ori ayelujara Twitter, Buhari bẹ awọn ọmọ Naijiria lati mu suuru, bo tilẹ jẹ pe wọn ni ẹtọ lati ṣe iwọde lori ohun ti ko ba dun mọ wọn ninu.
Olufọkansin ni ọpọ lara awọn ọlọpaa Naijiria, to si n fi ara ṣiṣẹ lati pese aabo fun ẹmi ati dukia ni Naijiria, ao si ni dawọ atilẹyin wa duro ki wọn o le ṣe iṣẹ wọn.
Ondo election 2020: Àwọn ara ìpínlẹ̀ Ondo ránṣẹ́ sí Akeredolu ohun ti wọ́n ń retí ní báyìí
Ọga Agba fun ileeṣẹ ọlọpaa orilẹ-ede Naijiria, Mohammed Adamu ti bu ẹnu atẹ lu bi awọn oluwọde EndSars nipinlẹ Delta ṣe pa ọlọpaa kan.
Ọjọbọ ni iṣẹlẹ naa waye nilu Ughelli, lasiko ti awọn ọdọ ṣe iwọde lati polongo fun pipa ẹka ileeṣẹ ọlọpaa to n risi iwa idigunjale, SARS, rẹ.
Ileeṣẹ ọlọpaa sọ pe awọn oluwọde naa mu iwa janduku mọ, ti wọn si ti ipa bẹ ẹ pa Kọburu ọlọpaa kan, Etaga Stanley, ni ipa ika.
Yatọ si Kọburu ti wọn pa, Sajẹnti kan naa, Patrick Okuone, naa tun fi ara pa yanna-yanna nibi iṣẹlẹ ọhun, nitori ibọn ti awọn oluwọde yin.
Awọn oluwọde naa tun mu ibọn AK-47, ati ọta ibọn marundinlọgbọn.
Iroyin sọ pe lẹyin ti awọn ọlọpaa naa yinbọn si aarin awọn oluwọde ni awọn ọdọ naa gba ẹsan nipa pipa ọlọpaa naa.
Ọgbẹni Adamu sọ pe lootọ ni iwọde jẹ ọna ti awọn ara ilu le gba fi ẹhonu han si ijọba, amọ o yẹ ki wọn o ma a ṣe pẹlu iwa ọmọluabi.
"O ni ""ileeṣẹ ọlọpaa ko ni la oju rẹ silẹ mọ, ki awsn ara ilu ma a kọlu awọn oṣiṣẹ rẹ, tabi awọn oṣiṣẹ eleto aabo miran."""
Bakan naa lo tun ti paṣẹ fun Kọmisanaa ọlọpaa nipinlẹ Delta lati ṣewadii iṣẹlẹ naa, ko si ri i pe ọwọ tl awọn to hu iwa naa.
Oríṣun àwòrán, TWITTER
Awọn ọdọ ni ọgọọrọ ti korajọ lati fẹhọnuhan tako iṣekupani awọn ọlọpaa SARS lorilẹede Niajiria.
Iwọde naa bẹrẹ lati Computer Village, ni Ikeja lọ si olu ileeṣẹ awọn ọlọpaa to wa ni Ikeja, lati fi ẹhonu wọn han lori bi awọn ikọ ọlọpaa kogberegbe ṣe n paniyan bo ṣe wu wọn ni Naijiria.
Awọn ọdọ naa ṣeleri wi pe, ifẹhọnuhan naa yoo tẹsiwaju fun ọjọ meji kaakiri ipinlẹ Eko.
Oríṣun àwòrán, TWITTER
"Awọn ọdọ gbe iwe akọle lorisirisi dani bii opin gbọdọ de si iwa ifiyajẹni lọna aitọ ""Say no to brutal injustice"", irun ori to ta koko kii ṣe ẹsẹ,"
"Dreadlocks are no crimes, ọlọpaa yẹ ko ma a ṣọ wa ni, kii ṣe ki wọn ma a gba owo ọwọ wa, ""Protect not exploit' ati eleyii ti wọn kọ pe ki ọlọpaa Naijiria ye pa wọn,  ""Nigeria police stop killing us'."
Ninu ọrọ ti awọn ọdọ naa sọ, wọn ni ijọba gbọdọ fi opin si iṣẹ awọn ọlọpaa SARS ni Naijiria.
''Pẹlu gbogbo ikede ti Ọga Agba ọlọpaa kede, o ṣi fihan gbangba pe, ikọ SARS ko jẹwọ ninu iwa buruku ti wọn n hu si awọn ara ilu.''
Bakan naa ni wọn kesi Ọga agba ọlọpaa lati ṣe iwadii ẹsun ipaniyan ti wọn ki kan awọn ikọ SARS, eleyii ti wọn ni awọn lọgalọga naa mọ nipa rẹ.
Oríṣun àwòrán, TWITTER
Saaju la ti mu iroyin wa fun yin pe,akọrin takasufe, Naira Marley ti ṣalaye fun ileeṣẹ ọlọpaa Naijiria pe awọn to ṣe irun dada sori kii ṣe ọdaran o.
Nigba to n takurọsọ loju opo Instagram rẹ lori ọrọ awọn ọlọpaa SARS pẹlu alukoro ileeṣẹ ọlọpaa, Frank Uba, Marley ni awọn obinrin to n wọ sikẹẹti penpe ko tumọ si pe alaṣẹwo ni wọn.
Naira Marley sọ pe oun wọgile iwọde ti oun gbero lati ṣe tẹlẹ nitori aabo awọn eeyan kii ṣe pe bo ya ẹru n ba oun.
Oríṣun àwòrán, Instagram/nairamarley
Amọ, oun naa ko faramọ aba awọn eeyan pe ki wọn ko ọlọpaa SARS nlẹ, o ni ijọba ko nilo lati ko ọlọpaa nilẹ wi pe atunṣe ni wọn nilo.
Olorin takasufe ti ọpọ mọ si Marlian wi pe niṣe lo yẹ ki wọn ko awọn ọlọpaa SARS kuro loju titi.
O ni ohun to ba mu ki wọn ko SARS nlẹ, ijọba gbọdọ fopin si ajọ to n gbogun ti iwa ibajẹ, EFCC naa.
Naira Marley tun beere lọwọ alukoro ileeṣẹ ọlọpaa bo ya o tọnu lati kamẹra ọlọpaa to ba n ṣiwa wu.
Uba da lohun pe ko lodi si ofin lati kamẹra ọlọpaa to ba n ṣe ohun ti ko da, amọ o kilọ pe ki awọn ṣe mẹdọ pẹlu awọn oṣiṣẹ eleto aabo to ba gbebọn dani.
Naira Marley rọ awọn ọmọ Naijiria lati ṣe iranwọ fun ileeṣẹ ọlọpaa nipa pipese awọn ohun elo ti wọn nilo lẹnu iṣẹ.
Ilé iṣẹ́ ọlọ́pàá ń ṣe ìpàdé pẹ̀lú Naira Marley lọ́wọ́lọ́wọ́
Ọ̀gá àgbà àjọ ọlọ́pàá Nàìjíríà ní àwọn ń fí àsìkò yìí pé àwọn ọdọ́ Nàìjíríà pé, gbogbo àriwo wọn ni àwọn ti gbọ́ lórí àwọn ìwà ìbàjẹ́ tí àwọn kan ń hù nínú iṣẹ́ ọlọ́pàá pàápàá jùlọ àwọn ikọ SARS.
Ilé iṣẹ́ ọlọ́pàá ló sọ èyí lójú òpó twitter rẹ̀ lásìkò to n kàn si @officialnairam1 pé àwọn ti ṣetan láti ṣe ìpàdé pọ̀ pẹlú ilé iṣẹ́ ọ̀dọ́ àti àwọn míràn tí ọ̀rọ̀ kan ní Nàìjíríà láti wá ọ̀nà àbáyọ sí ìṣòrò náà.
Ọ fí kún un pé ní ọjọ́ ìṣẹ́gun, ọjọ́ kẹfa oṣu yìí, àwọn ṣetan láti ṣe ìpàdé pọ̀ pẹ̀lú Naira Marley láti dáhun gbogbo àwọn ìbéèrè tó bá ni láti sọ lórúkọ àwọn ọ̀dọ́ Naìjíríà lórí ọ̀rọ̀ SARS àti àwọn ǹkan míràn tó jẹ wọ́n lógún.
'N500 dé fún gbogbo ọmọ tuntun lóṣooṣù bí mo bá di gómìnà Ondo - Adeleye AAC
Ilé iṣẹ́ ọlọ́pàá fi han pé àwọn ti ṣetan láti bá àwọn ti ọ̀rọ̀ kan láti ri dájú pé, àwọn ọlọ́pàá bọ̀wọ̀ fún ẹtọ́ àrá ìlú àti la'ti ni ìbáṣepọ tó dán mọ́ràn láàrín ọlọ́pàá àti àrá ìlú.
Ẹ̀wẹ̀ Naira Marley náà ti kọ sí ojú òpó Twiiter rẹ @officialnairam1 pé àwọn kò ni ṣe ìfẹhonu hàn mọ́, ṣùgbọ́n ó ké si àwọn ọ̀dọ́ pé, ikéde náà wà fún ki àrá ìlú  le ni ìfọ̀kanbalẹ̀.
O fi kun pé, àwọn ń retí ǹkan ti wọ́n yóò ṣe , sùgbọ́n ó ṣe pàtàkì kí ki gbogbo ọ̀dọ́ ṣe ara wọn lọ́kan látu yanjú ìṣòro tó wà nílẹ̀.
Oríṣun àwòrán, NAira Marley/Facebook
Gbajugbaja olorin ọmọ Naijiria, Naira Marley ti bọ soju opo ayelujara lati kede pe oun yoo lewaju iwọde ifẹhonuhan lodi si iwa ti awọn ọlọpaa SARS n wu ni lorilẹede.
Afeez Fashola ti gbogbo eeyan mọ si Naira Marley fi lede loju opo Twitter rẹ pe oun yoo dari iwde ifẹhonuhan wọọrọwọ lọjọ Aje ọsẹ yii to si sọ fun awọn ololufẹ rẹ ki wọn darapọ.
Bakan naa o jẹ ko di mimọ pe awọn ikọ SARS kan ti ko lọwọ ninu iru ibajẹ yii atawọn ọlọpaa kan ti fifẹ han lati darapọ mọ iwọde naa.
Ti ẹ ba pade SARS tabi oṣiṣ alaabo kankan lọjọ Aje, ẹ ma ṣe ba wọn ja. Wọn ti fi aye gba wa lati beere ibeere, ṣugbọn ẹ ma ja tabi ba ohunkohun jẹ. Iwọde alafia la fẹ ṣe.
Si eyi, ọpọlọpọ awọn to n tẹle Marley lo da si ọrọ naa ti wọn si n ṣe afikun tabi idi ti ọrọ rẹ ko fi ta leti wọn. Awọn kan ni kii ṣe ọrọ ibọn yiyin nikan bikoṣe yiyẹ foonu eeyan wo ati ifiyajẹni.
Ẹwẹ, awọn olorin mii atawọn oṣere mii naa ti fi ọrọ sita lodi si iwa yii to fi mọ awọn mii naa ti wọn fifẹ han lati darapọ mọ iwọde ọhun.
Fun apẹrẹ, olorin ọmọ Naijiria mii ti wọn mọ si Runtown toun naa lero lẹyin loju opo ayelujara naa wa lara awọn to n ṣagbatẹru iwọde yii.
Igbakeji aarẹ orilẹede Naijiria, Yemi Osinbajo ni ọrọ ikọ ọlọpaa SARS ṣe n pa awọn araalu gbọdọ wa si opin.
Yemi Osinbajọ sọ ọrọ yii loju ọpọ ikansiraẹni Twitter rẹ ni Ọjọ Aiku.
Osinbajọ ni ọrọ naa gba ero ati atunṣe, eleyii ti aarẹ Buhari sọ wi pe awọn yoo wa ọna abayọ fun iṣekupani awọn ikọ ọlọpaa yii.
''Inu mi bajẹ si iṣẹlẹ yii pẹlu bi awọn ikọ SARS  ṣe n fi panpẹ mu awọn eniyan lai ni di.''
''Ọpọlọpọ eniyan ni ẹmi wọn ti ba iṣẹlẹ iwa ipa ti ikọ SARS n lo pẹlu awọn eniyan''.
Bakan naa ni igbakeji aarẹ naa fikun wi pe ki awọn yoo mu atunto ba ikọ ọlọpaa naa.
Oríṣun àwòrán, davidoofficial
O to gẹẹ! Ọga ọlọpaa lorilẹede Naijiria, Mohammed  Adamu ti paṣẹ wi pe awọn ọlọpaa SARS ko gbọdọ kaakiri ilu mọ lati oni lọ.
Bakan naa ni ọga ọlọpaa tun sọ pe ọlọpaa SARS ko gbọdọ da awọn araalu duro lati maa tu ẹru wọn mọ.
Alukoro ileeṣẹ ọlọpaa, DCP Frank Mba ṣalaye ninu atẹjade kan to fi sita lorukọ ọga ọlọpaa Naijiria pe awọn ọlọpaa SARS ko gbọdọ duro soju titi mọ dabi dari igbokegbodo ọkọ loju popo mọ.
Bakan naa ni ọga ọlọpaa tun paṣẹ pe ọlọpaa kankan ko gbọdọ mu ẹnikẹni nigba ti o ba wọ aṣọ ile.
Ọga ọlọpaa sọ pe iṣẹ awọn SARS bayii ko gbọdọ ju ki wọn maa gbogun ti awọn adigunjale tabi awọn ajinigbe lọ.
Lati owurọ ọjọ Aiku ni ọgọrọ eeyan ti yabo oju ayelujara nibi ti wọn ti n kepe ijọba lati wọgile ọlọpaa nitori ọṣẹ ti wọn n ṣe fun ọpọ araalu papaa julọ awọn ọdọ.
Ẹwẹ, ileeṣẹ ọlọpaa FSARS meji, Monday Uchiola and Okechukwu Ogbonna lori ẹsun iwa idunkoko mọ araalu lọni aitọ.
Àṣìṣe ọlọ́pàá àti Adájọ́ sọ mí di ẹni tí wọ́n dájọ́ ikú fún, ọpẹ́lọpẹ́ Fayoṣe tí ko buwọlu
Ohun tójú àwọn èèyàn tún rí tí wọ́n figbé ENDSARS bọnu
Lọwọlọwọ, awọn ọmọ Naijiria tun ti wu ọna ti awọn ọlọpaa kogberegbe SARS fi n huwa si awọn araalu sita.
Iṣẹlẹ to ṣẹlẹ pato to fi tun wu eyi jade ko ṣẹyin iroyin kan to sọ pe ikọ SARS yinbọn pa ọkunrin kan lọjọ Abamẹta.
Iṣẹlẹ ọhun ni wọn ni o waye niwaju ile itura Wetland lagbegbe Ughelli ni ipinlẹ Delta.
Gẹgẹ bi iroyin naa ṣe sọ, ikọ SARS yinbọn pa ọkunrin naa tan wọn si na papa bora.
Ẹwẹ, eyi ti mu iriwisi ọtọọtọ jade latẹnu awọn Naijiria ati pe bi iṣẹlẹ naa ko ba fidi mulẹ, eeṣe ti awọn alaṣẹ tọrọ kan bii Sunday Dare to jẹ minisita fun ọrọ ọdọ ati idagbasoke ere idaraya, gomina Eko Babajide Sanwoolu fi da si i ati lasiko yii gan?
"Babajide Sanwoolu ni ""aabo awọn araalu lo jẹ mi logun gẹgẹ bi oluṣọ agba ni ipinlẹ Eko"". O ti fi da awọn eeyan loju pe awọn yoo gbe igbesẹ to tọ kiakia."
Awọn ọmọ Naijiria ti fọn sori ayelujara lati bẹrẹ si ni sọ ohun toju wọn n ri lọwọ awọn ọlọpaa SARS pẹlu #ENDSARS.
Kii ṣe ajoji mọ bi iroyin ṣe maa n jade lọtun losi lori ọṣẹ ti ikọ SARS n ṣe si awọn araalu yala ọkunrin tabi obinrin.
Wo Adigun ọmọ ọdún mẹ́rin tí òwe Yorùbá àti ìtúmọ̀ gbó lẹ́nu rẹ̀ ju tìrẹ̀ lọ
Akure Shootings: Bí àwọn alátìlẹ́yìn ẹgbẹ́ APC àti PDP ṣe ṣe ara wọn léṣe rèé
Oríṣun àwòrán, theelitetimes.com.ng
Ọkunrin kan ti ko tii si aridaju orukọ rẹ ni iroyin sọ pe wọn pa nibi ija to bẹ silẹ laarin awọn alatilẹyin gomina ipinlẹ Onodo, Rotimi Akeredolu ati awọn ti oludije ẹgbẹ alatako ni Ondo iyẹn PDP, Eyitayo Jẹgẹdẹ.
Iforigbari naa waye ni agbegbe Obanla nilu Akure ti ọpọlọpọ eeyan si farapa yatọ fun eeyan kan ti o fori laku.
Eeyan kan ti iṣẹlẹ yii ṣoju rẹ ni fun ọpọlọpọ wakati ni ilọsoke ilọsodo ati katakara ni agbegbe naa fi kawọ gbera tori igboro to daru.
Ati ẹgbẹ oṣelu APC ati PDP lo n di ẹbi iṣẹlẹ yii ru ara wọn lori.
Laipẹ yii ni eeyan marun farapa lasiko ti ẹgbẹ mejeeji yii kan naa doju ibọn kọ ara wọn ni ilu Oba-Akoko ti awọn alatilẹyin ẹgbẹ mejeji farapa yanayana ti ọpọlọpọ ọkọ si ba jẹ
Lara awọn fọnran to jẹyọ lori ayelujara twitter ni awọn wọnyii
Ọpọ awọn eniyan Ondo lo ti n ke gbajare pe ki awọn oludije dupo gomina lati pe awọn alati lẹyin wọn sabẹ nitori pe idibo kii ṣe ogun .
Wọn ni igba akọkọ ree ti iru iwa jagidijagan yii yoo ma waye ni ipinlẹ Ondo.
Nigba ti BBC Yoruba kan si ajọ ọlọpaa ipinlẹ Ondo, agbẹnusọ ajọ naa Teeleo Ikoro salaye pe nkan bi aago mẹjọ abọ alẹ ana ni awọn gba ipe pe awọn ẹgbẹ kan n ja.
O ni loju ẹsẹ naa ni awọn gbẹra pẹlu aṣẹ kọminsọna ọlọpaa ni ipinlẹ naa lati lọ se iwadii.
Agbẹnusọ ọlọpaa ni nigba ti awọn de ibẹ, nkan ti awọn ri ni pe, ati awọn alatilẹyin ẹgbẹ oṣelu APC ati ti PDP naa ni wọn n ja.
O ni wọn bẹrẹ si ni dana jọ si titi, sugbọn ọlọpaa tu wọn ka ni ana, ti awọn si fi awọn ọlọpaa sọ ibẹ, Sugbọn wọn tun pada wa lonii.
Ikoro ni ko si ẹni to ku ninu ija naa, bakan naa lo fi ọkọ awọn ara ilu balẹ to ba di asiko idibo, awọn ọlọpaa n bọ lati awọn ipinlẹ Naijiria to ku lati ku ọlọpaa ipinlẹ Ondo lọwọ.
NSCDC ṣèèṣì yìnbọ̀n pa ọlọ́pàá ọ̀tẹlẹ̀múyẹ́ DSS l'Osun
Oríṣun àwòrán, NSCDC
Ọkan lara awọn oṣiṣẹ ajọ abo ara ẹni laabo ilu, NSCDC, Sunday Dade ṣeeṣi yinbọn pa ọlọpaa ọtẹlẹmuyẹ DSS kan Seyi Adebowale nipinlẹ Osun.
Iṣẹlẹ naa ni a gbọ pe o ṣẹlẹ ni aafin ọba to wa ni Kuta, ijọba ibilẹ Ayedire nibi ti Gomina Adegboyega Oyetola ti lọ ṣi afara kan ti ileeṣẹ ọmogun ilẹ kọ.
Ohun ti a gbọ ni pe Dade n yinbọn soke pẹlu idunnu nigba ti wọn n ṣi afara naa lẹyin naa ni ọta ibọn ti ṣeeṣi ba Adebowale.
Agbẹnusọ fun ajọ NSCDC, Adigun Daniel to fidi iṣẹlẹ ọhun mulẹ ṣalaye pe eṣi lo ṣe fun Dade, ko mọọ mọ yinbọn fun un.
O ṣalaye siwaju sii pe Dade ti n jẹjọ bayii lori iṣẹlẹ naa.
Ọga agba ileeṣẹ ọmogun ilẹ ni Naijiria, Tukur Buratai naa wa ni ibi ayẹyẹ ṣiṣi afara ọhun.
Internet fraud: Ọwọ́ EFCC tẹ afurasú 'Yahoo boy' Olawale àti pásítọ̀ CAC tó lu Hayatou ní jìbìtì N12.7m
Oríṣun àwòrán, Twitter/EFCC Nigeria
Ajọ to n gbogun ti iwa ibajẹ ati iṣowo ilu kumọkumọ, EFCC ti mu ọdọkunrin kan, Adebayo Olawale ati pasitọ ijọ CAC Ile Ife, Gbenga Moses Adesoju lori ẹsun pe wọn lu Umar Hayatu ọmọ ipinlẹ Gombe ni jibiti owo to din diẹ ni miliọnu mẹtala naira(N12.7m).
Agbẹnusọ fun ajọ EFCC, Wilson Uwujaren lo fọrọ yii lede loju opo ayelujara Twitter ati Facebook ajọ naa.
Ọgbẹni Uwujaren ṣalaaye pe ọwọ tẹ Olawale ati pasitọ rẹ ni Ile Ife lẹyin tawọn ẹbi Hayatou fi ọrọ jibiti naa to ajọ EFCC leti.
Ajọ EFCC ṣalaye pe awọn afurasi mejeeji naa gbimọ pọ lu Hayatou ni jibiti lori ayelujara ati ẹrọ ibaraẹnisọrọ lẹyin ti wọn parọ fun un pe o jẹ ẹbun ọkọ ati awọn foonu olowo nla pẹlu iṣẹ to n doju ti iṣẹ.
Ninu atẹjade ti EFCC fi sita, ajọ naa sọ pe Olawale lo ayederu oju opo Williams Angellina ati Omolola Adebayo lati tan Hayatou jẹ wi pe baba oun ni ileeṣẹ loke okun.
O tun parọ fun Hayatou pe baba oun ṣetan lati yan an si ipo adari ni ẹka ileeṣẹ naa to wa ni ilu Eko ni Naijiria.
EFCC ni Olawale tun fi ọpọ ayederu fọto ile ati ọkọ ti wọn yoo fun Hayatou ranṣẹ si i.
Bakan naa ni Olawale tun parọ fun Hayatou pe oun yoo fun lẹbun ẹgbẹrun un lọna ọgbọn owo dọla($30,000) ati ''iPhone'' olowo iyebiye to fi mọ goolu.
Iwadii ajọ EFCC lo fihan pe owo to din diẹ ni miliọnu mẹtala naira(N12.7m) to gba lọwọ Hayatou wa ninu apo ikowosi Olawale ni banaki kan to n lo.
EFCC ṣlaaye pe afurasi keji, pasitọ Adesoju naa gba ẹbun ọkọ BMW kan, ilẹ ati ọpọ tabua ninu owo ti Olawale gba lọwọ Hayatou.
Ajọ EFCC ni awọn mejeji yoo foju ba ileẹjọ lẹyin ti iṣẹ iwadii ba ti pari.
Sotitobire: Àwọn ọmọ ìjọ yarí, wọ́n ní ejò lọ́wọ́ nínú lórí ìdájọ́ tí wọ́n dá fún Alfa Babatunde
Ọrọ ko tii tan lori idajọ ẹwọn gbere ti ileẹjọ giga niluu Akure da fun pasitọ ijọ Sotitobire Praising Chapel, Alfa Babatunde lẹyin tawọn ọmọ ijọ rẹ tako idajọ naa.
Adajọ Olusegun Odusola ni Babatunde jẹbi ẹsun igbimọ pọ lati ji Kolawole Gold, ọmọ ọdun kan to di awati nile ijọsin naa niluu Akure lọdun 2019.
Awọn ọmọ ijọ Sotitobire to ba BBC sọrọ sọ pe inuni-bini wolii ijọ Sotitobore tawọn eeyan kan n ṣe lo jẹ ileẹjọ dajọ ẹwọn gbere fun un.
Wọn ni Wolii Babatunde ko mọwọ ko mẹsẹ nipa ọrọ to ṣẹlẹ ọhun, koda wọn ni ko si ninu ile ijọsin naa nigba ti iṣẹlẹ naa sẹlẹ.
''Wọn lọ si ile rẹ lati wa bo ya ọmọ naa wa nibẹ, koda wọn wo pata obinrin ti wọn nile rẹ, ṣugbọn wọn ko ri nkankan, idajọ yii kudiẹ kaato,'' ọmọ ijọ Sotitobire kan lo sọ bẹẹ.
Elomiiran to tun jẹ ọmọ ijọ naa sọ pe ọpọ eeyan lo yabo ṣọọṣi Sotitobire lẹyin ti iṣẹlẹ ọhun ṣẹlẹ tan, o ni awọn eeyan naa sọ ina ṣọọṣi wọn si ba ṣọọṣi naa jẹ.
Wọn ni ko si ẹni to le fidi ẹsun ijọmọgbe ti wọn kan alufaa Babatunde mulẹ, wọn ni awọn mii tiẹ sọ pe pasitọ ọhun ri ọmọ naa mọlẹ laaye ni.
Amọ wọn ni ko si ẹni to ni ẹri to daju to le fihan pe alufaa Babatunde jẹbi ẹsun ti wọn fi kan an.
Alufaa Babatunde atawọn ọmọ ijọ marrun un mii ni adajọ Odusola dajọ ẹwọn gbere fun un lọjọ Iṣẹgun ọjọ kẹfa oṣu kẹwaa ọdun 2020.
Ẹ gbà mí o! Bí mo ṣe ń dàgbà ni ǹkan ọmọkùnrin mi ń tóbi síi àmọ́ obìnrin ni mi'
Ìdájọ́ ẹ̀wòn gbére kò ní kí Wòlíì Sotitobire má lọ sí ilèẹjọ́ kòtẹ́milọ́rùn - Agbẹjọ́rò Pásítọ̀ Alfa Babatunde
Agbẹjọro to n ti n gba waju gba ẹyin fun Pasitọ Alfa Babatunde ti ijọ Sotitobire Praising Chapel, Akinyemi Omoware ti ṣalaye ọrọ fun araye gbọ pe onibara oun ṣi lanfani ati gbà ile ẹjọ kotẹmilọrun lọ lẹyin idajọ.
Ṣaaju nigbati igbẹjọ naa ṣẹṣẹ bẹrẹ lowurọ ọjọ Iṣẹgun ni adajọ ti yọnda fun agbẹjọro naa ko ṣe gaafara fun awọn ninu ile ẹjọ nigba tọrọ fẹ di aawọ laarin oun atirẹ.
Idi ni wipe agbẹjọro Sotitobi rẹ ke pe adajọ pe ko sun igbẹjọ naa siwaju eyi to ti waye lọpọlọpọ igba tawọn eeyan si ti n reti idajọ ikẹyin'
Ni adajọ ba ni lai lai, oun ko ni sun ẹjọ siwaju mọ. Lẹyin eyi agbẹjọro Sotitobire bọ ẹwu ofin to si jade nile ẹjọ.
Ẹwẹ, nigbati adajọ si ti da ẹjọ ẹwọn gbere fun un tan, agbẹjọro rẹ nigbati BBC Yorba fi ọrọ wa a lẹnu wo jẹ ko di mimọ pe, ìdájọ́ ẹ̀wòn gbére kò ní kí Wòlíì Sotitobire má lọ sí ilèẹjọ́ kòtẹ́milọ́rùn.
Ondo Elections 2020: Ọgọ́rùn-ún ọdún tí a máa lò lórí oyè l'Ondo, ẹ ó rí àrà - Ojon YPP
Oníṣẹ́ ọwọ́, oníṣẹ́ àdáni, awakọ̀, ẹ wo ọ̀nà láti gba lára owó ìrànwọ́ Covid-19 tí ìjọba gbékalẹ̀
Wo ọ̀nà àbáyọ sí bo ṣe ń han‘run
Dapo Abiodun yan Laycon ní aṣojú pẹ̀lú ẹ̀bún ₦5m àti ilé oníyàrá mẹ́ta
ENDSARS: Ẹ̀yin ọmọ Nàìjíríà, ẹ ṣè ìrànwọ́ irinṣẹ́ fáwọn ọlọ́pàá- Naira Marley bẹ̀bẹ̀
Àwọn kan ṣónú bí wọ́n bá di gómìnà, ẹ fún wa láyè láti wá parí iṣẹ́ táa bẹ̀rẹ̀ - Akeredolu
Adajọ Olusegun Odusola, tile ẹjọ giga ilu Akure ti kede pe asaaju ijọ Sotitobire, Wolii Alfa Babatunde jẹbi ẹsun ijọmọgbe.
Bakan naa lo ni awọn eeyan marun yoku ti wọn n jẹjọ pẹlu rẹ, naa jẹbi sise onigbọwọ jiji ọmọ ọdun kan naa, Gold Kolawole gbe, ni ọdun to kọja.
Nigba to n gbe idajọ oniwakati marun ati abọ rẹ kalẹ, lori ẹsun ijọmọgbe onikoko mẹfa, adajọ Odusola ni ijọ Sotitobire ko kọbi ara si isẹlẹ bi ọmọ naa, se di awati lasiko ijọsin.
'N500 dé fún gbogbo ọmọ tuntun lóṣooṣù bí mo bá di gómìnà Ondo - Adeleye AAC
Adajọ ni se ni ijọ naa n tẹ siwaju lati maa ba isin ọjọ isinmi wọn lọ titi di aago marun irọlẹ lẹyin ti wọn ti ji ọmọdekunrin, ọmọ ọdun kan naa lọ lati ọwọ ọsan.
Adajọ wa gbe idajọ kalẹ pe, awọn olujẹjọ kinni de ikẹfa ninu ẹjọ naa, jẹbi ẹsun iditẹ lati ji ọmọ gbe ti wọn fi kan wọn.
Bẹẹ ba si gbagbe, Wolii Alfa Babatunde, tii se adari ijọ Sotitobire ni afurasi ati olujẹjọ akọkọ ninu ẹjọ ọhun.
Adajọ tẹsiwaju pe awọn ọlọpaa gan ni ọwọ wọn ko mọ lori isẹlẹ yii, ti a ba wo ọwọ ti wọn fi mu isẹlẹ naa, to si bu ẹnu atẹ lu bi wọn se na iya iya ọmọ ti wọn n wa naa, ti wọn si tun ti mọle, lai jẹ pe wọn gbe wa sile ẹjọ.
Nigba to n gbe idajọ kalẹ lori ẹsun sise onigbọwọ lati ji ọmọ gbe, adajọ Odusola ni awọn olujẹjọ kinni de ikẹfa jẹbi ẹsun naa
Nigba to n yiiri ẹsun kẹta wo, tii se biba awọn ẹri to se koko nipa ẹjọ naa jẹ, adajọ ni ki olujẹjọ keje, Peter Anjorin maa lọ sile ni alaafia, tori ko jẹbi gbogbo awọn ẹsun ti wọn fi kan rara.
Ni yajo yajo bo ṣe n tẹ wa lọwọ lati ipinl Ondo ni pe agbẹjro Alfa Babatunde Sotitobire iyẹn Bayo Ayenakin ni oun yọ ọwọ ninu igbẹjọro to yẹ ko waye lonii.
O fẹrẹẹ dabii fa ki n fa laarin oun ati adajọ. O ni oun ko ni le maa farahan siwaju sii lori ẹjọ naa tori wipe adajọ kọ lati sun ẹjọ naa siwaju.
Agbẹjọro kọkọ pe fun ki wọn sun ẹjọ naa siwaju lonii lori oun to pe ni aridaju mẹrindinlogun ṣugbọn adajọ faake kọri to si fagile ipẹjọ rẹ.
O ti wa fun adajọ Ayenakin ni gaafara lati bọ ẹwu rẹ ko si kuro nile ẹjọ niwọn igba ti ọrọ ko ti wọ.
Yoruba ni bi a ba da ọjọ, ọjọ a pe, bi a ba da osu, osu a ko, bo pẹ titi, ogun ọdun n bọ wa ku ọla
Bẹẹ ni ọrọ ri pẹlu igbẹjọ Wolii Alfa Babatunde, ti ijọ Sotitobire nilu Akure, ẹni to n koju ẹsun ijinigbe lati ọdun kan ati osu diẹ sẹyin.
'N500 dé fún gbogbo ọmọ tuntun lóṣooṣù bí mo bá di gómìnà Ondo - Adeleye AAC
Iroyin to wa n tẹ BBC Yoruba lọwọ ni yajoyajo ni pe, ọjọ Kẹfa osu Kẹwaa ọdun 2020, ni wolii naa yoo mọ ibi ti ori n ba ẹsẹ rẹ ree.
Awọn agbẹjọro ti ji de ile ẹjọ bẹẹ si ni ile ẹjọ ti kun fọfọ.
Idi ni pe lọla ode yii ni idajọ yoo waye  nile ẹjọ giga ilu Akure lori ẹsun ijọmọgbe ti wọn fi kan Alfa Babatunde ati ọmọ ijọ rẹ mẹfa miran.
Kọmisana feto idajọ ati agbẹjọro agba nipinlẹ Ondo, Adekola Olawoye lo fidi ọrọ yii mulẹ fawọn akọroyin pẹlu afikun pe lọla ọde yii ni Adajọ Olusegun Odusola, to n gbọ jọ Sotitobire yoo gbe idajọ rẹ kalẹ.
Olawoye ni aago mẹsan owurọ, lọjọ Isẹgun ni idajọ naa yoo maa waye nile ẹjọ giga ilu Akure.
Bẹẹ ba gbagbe, lọdun to kọja ni iroyin gba ilẹ kan nilu Akure pe ọmọ ọdun kan, Gold Babatunde di awati lasiko to wa ni ijọ awọn ọmọde inu ijọ Sotitobire nilu Akure.
Gbogbo igbiyanju lati sawari ọmọdekunrin naa si lo ja si pabo, ti awọn agbofinro si mu wolii naa, atawọn ọmọ ijọ rẹ mẹfa lori ẹsun ijọmọgbe
Bi igbẹjọ ba se n waye lọjọ Isẹgun, ni BBC Yoruba yoo maa mu wa fun yin.
World Teachers Day: Ẹ̀kúnrẹ́rẹ́ àlàyé rèé nípa ìlànà àkànṣe owó oṣù tuntun fáwọn òlùkọ́
Oríṣun àwòrán, Google
Ni Ayajọ Ọjọ awọn olukọ lagbaye, World Teachers Day ni Aarẹ Buhari kede ilana tuntun fun owo oṣu awọn olukọ ni Naijiria.
Minisita fun eto ẹkọ, Adamu Adamu to ṣoju aarẹ Buhari, lo ka ikede naa jade fun awọn eniyan ni ibi ayẹyẹ ohun ni ilu Abuja.
Ọpọlọpọ awọn eniyan si lo ti n beere pe bawo ni ilana owo oṣu tuntun yii yoo ṣe lọ, ati wi pe, ki ni awọn alakalẹ tuntun naa da le lori.
Idi ree ti BBC Yoruba fi se akojọpọ alaye nipa ilana owo osu tuntun ti aarẹ́ Buhari kede fawọn olukọ naa.
Saaju la ti kọkọ mu iroyin wa fun yin pe aarẹ Muhammadu Buhari ti kede ilana akanse owo osu fawọn olukọ lorilẹede yii.
Ikede yii si lo n waye ni oni ọjọ Isẹgun, ọjọ Karun osu kẹwaa, tii se ayajọ ọjọ awọn olukọ lagbaaye.
Oríṣun àwòrán, @OfficialSeyiMakinde
Minisita feto ẹkọ, Adamu Adamu , to soju aarẹ Buhari nibi eto ti wọn fi n sami ọjọ olukọ nilu Abuja, lo sisọ loju ọrọ yii.
Adamu ni Buhari gbe igbesẹ naa lati se iwuri fawọn olukọ jakejado Naijiria, ki wsn lee sa ipa wọn lati sisẹ kara siwaju si, ki wsn si tun lee dantọọ lẹnu isẹ.
Ojú àwọn èèyàn Ondo ti là pé ìnira ni ẹgbẹ́ APC mú wá - Jegede PDP
Bakan naa ni aarẹ Buhari tun sisọ loju r pe, lati akoko yii lọ, awọn olukọ ko ni fẹyin ti mọ lẹnu isẹ lẹyin ti wọn ba ti lo ọdun marundinlogoji, amọ o tun fi ọdun marun kun ọdun ifẹyinti wọn.
Eyi tumọ si pe ogoji ọdun ni awọn olukọ yoo maa lo lẹnu isẹ bayii, ki wọn to fẹyin ti.
Ibadan State Creation: Sẹ́nẹ́tọ̀ Kola Balogun jíṣẹ́ tí CCII ran, ó gbé àbá ìdásílẹ̀ ìpínlẹ̀ Ibadan lọ sí Abuja
Oríṣun àwòrán, @YorubaHistory
Sẹnẹtọ Kola Balogun, to n ṣoju ẹkun guusu ipinlẹ Oyonile asofin agba nilu Abuja, tun ti gbe ẹbẹ fun idasilẹ ipinlẹ Ibadan lọ siwaju ile.
Niwaju igbimọ to n ri si ayẹwo ati atunṣe iwe ofin orilẹede Naijiria, ti igbakeji aarẹ ile, Sẹnẹtọ Omo Ovie Omo Agege jẹ alaga rẹ, ni Kola Balogun gbe iwe ẹbẹ naa si.
Sẹnẹtọ Balogun sọ pe, oun ti jiṣẹ igbimọ CCII to ranṣẹ si oun wi pe, ki oun gbe aba naa lọ siwaju ile aṣofin.
O ni ẹkun Ibarapa naa yoo wa lara ipinlẹ Ibadan tawọn n beere fun, ba le ṣeeṣe.
Oríṣun àwòrán, Facebook/Senator Kola Balogun
Sẹnẹtọ Balogun ni, ina ilu Ibadan n jo ajo rẹyin ninu awọn ilu to jẹ olu ilu ijọba alagbada, lẹyin ti Naijiria gba ominira tan.
Sẹnẹtọ naa sọ pe, oun yoo ṣa gbogbo agbara oun lati rii pe ile aṣofin jiroro lori idasilẹ ipinlẹ Ibadan, nigba ti o ba ya.
Oloye Balogun ni oun ko tii bẹrẹ si ni ro nipa ati dije ninu ibo gbogbogbo ọdun 2023.
Ojú àwọn èèyàn Ondo ti là pé ìnira ni ẹgbẹ́ APC mú wá - Jegede PDP
Sẹnẹtọ Balogun ni ohun to jẹ oun logun bayii ni lati ṣe gbogbo ohun ti oun ṣeleri fawọn araalu, to dibo fun oun.
Kwam1: Kìí ṣe emí ni mó ràn ẹni tó sọ̀rọ̀ abùkù sí FIBAN níṣẹ́- Wasiu Ayinde
Oríṣun àwòrán, k1deultimate/Instagram
Ọba orin fuji Wasiu Olasunkanmi Marshal K1 tí fi ọ̀rọ̀ síta pé, òun jìnà gédégédé sí ọ̀rọ̀ kan tí alákoso orin rẹ̀ sọ pẹ̀lú BBC News Yoruba lọ́jọ́ Aiku.
Nínú ọ̀rọ̀ alakoso orin Wasiu, Adebayo Olasoju lásìkò ìfọ̀rọ̀wánilẹ́nu lórí ǹkan tó ṣẹlẹ̀ níbi ayẹyẹ tí wọ́n ti fẹ̀sùn kan pé Wasiu Ayinde lu gbájugbàja sọ̀rọ̀sọ̀rọ̀ kan ni ìpínlẹ̀ Ogun ló ti sọ̀rọ̀ àlufànsá sí ẹgbẹ́ FIBAN.
Ọ̀rọ̀ yìí sì ló yọ idà lápó àwọn FIBAN ti wọ́n si tí ni àfi tí Wasiu Ayinde ba gbé àwọn ìgbésẹ̀ kan kí àwọn tó dẹ̀yìn lẹ́yìn lílọ sí ọ̀dọ̀ Aáàfìn Oyo láti gba oyè Máyégun to jẹ kúrò lọ́wọ́ rẹ̀.
Nínú ọ̀rọ̀ tí ẹgbẹ́ FIBAN bá BBC Yorùbá sọ lánàá ni wọ́n ti sọ̀pé'Nítori ààbò ẹmí MC Murphy ló fi gbá  #100,000  lọ́wọ́ K1 lọ́jọ́ ìṣẹ̀lẹ̀', èyí si ni wọ́n sàlàye pé, nígbà ti Wasiu Ayinde ba túba ni àwọn yóò mọ̀ bóya àwọn yóò dá owó náà padà tàbí bẹ́ẹ̀kọ́.
Nínú àtẹjáde ti agbẹnusọ K1 Kunle Rasheed fi sọwọ́ sí BBC News Yoruba ló ti sàlàyé pé àwọn ọ̀rọ̀ àbùkù tí amúgbálẹ́gbẹ̀ K1 Adebayo Olasoju sọ si ẹgbẹ́ FIBAN yì kìí ṣe ìṣèsí tàbi ìwòye K1 rárá.
Àtẹjáde náà ni K1 ko fún ẹni tó sọ̀rọ̀ náà lásẹ láti sọ̀rọ̀ lórí ìṣẹ̀lẹ̀ náà, nítórí náà K1 yọ ara rẹ̀ pátápátá kúrò nínú gbogbo ǹkan tó sọ si ẹgbẹ́ FIBAN. Bákan náà ni K1 rọ FIBAN àti gbogbo àwọn ilé iṣẹ́ ìròyìn tó kù láti tẹ̀síwájú nínú àjùmọ̀ṣe wọ́n tó dánmọ́nrán.
Ondo 2020: Alága PDP láwọn ò fún ẹgbẹ́ mọ́kànlá tó darapọ̀ mọ́ wọn lówó kankan, ó wù wọ́n ni
Alaga ẹgbẹ oṣelu PDP, Fatai Adams ti sọ pe PDP ko fawọn ẹgbẹ oṣelu mọkanla to darapọ mọ ẹgbẹ naa fun ibo gomina Ondo ọjọ Abamẹta.
O ni awọn oludije gomina ẹgbẹ mọkanla yii ti gba lati sẹ atilẹyin fun oludije fun ipo gomina PDP, Eyitayo Jegede fun ibo to n bọ.
Ọgbẹni Adams ṣalaye pe awọn ẹgbẹ naa sọ pe eto ti PDP ni fawọn eeyan ipinlẹ tẹ wọn lọrun.
Awọn ẹgbẹ oṣelu naa ni AP, SDP, ADC, APP, APGA, APM, NNPP, NRM, LP, YPP ati AAC.
Dino Melaye: Ẹ̀yin ara Ondo, ẹ kígbe pé kò fẹ́ èrú ìbò, kí ìbò yín má ba à wọmi
Oríṣun àwòrán, Instagram/dinomelaye
Sẹnatọ Dino Melaye to soju ẹkun idibo Iwọ Oorun Guusu Kogi nile asofin agba kẹjọ to kọja ti gba awọn eeyan ipinlẹ Ondo nimọran lati bẹrẹ si kigbe pe awọn tako eru ibo.
Melaye ni bibẹẹkọ awọn to fẹ yi ibo yoo yi esi ibo ọjọ Satide to n bọ mọ wọn lọwọ, ti wọn ko ba bẹrẹ si ni mu igbe bọnu bayii pe ki magomago ibo mase waye.
Dino Melaye gbe imọran yii kalẹ lori eto ileesẹ BBC Kan pẹlu afikun pe bi ariwo tawọn eeyan ipinlẹ Edo pa lati tako ibo yiyi lo jẹ ki aseyọri ibo gomina waye nibẹ.
Bakan naa ni Sẹnatọ nile asofin agba kẹjọ naa tun gba awọn ọmọ Naijiria nimọran pe ki wọn mase maa gbẹnu dakẹ, amọ ki wọn pariwo sita lati tako awọn igbesẹ ijọba ti ko ba dun mọ wọn ninu.
Dino Melaye nánwó fún Ayefẹlẹ lójú agbo
"Dipo ki ijọba maa bẹru araalu to gbe wọn sipo, araalu lo n bẹru ijọba bayii nitori ibẹru ti ijọba ti gbin sọkan wọn, wsn ko si fẹ ku tabi lọ si atimọle.
Se ni ijọba tun n di kun ẹru araalu lasiko yii ti Coronavirus ti mu ki ọrọ aje ọpọ eeyan dẹnu kọlẹ, to si jẹ pe ara ilu lo n pese owo fun ijọba, dipo ki ijọba wa ọna ti yoo fi mu adinkun ba ajaga to wuwo to wa lọrun awọn araalu."
Melaye ni ẹẹmẹta ree tijọba ti safikun owo epo lati igba ti Coronavirus ti bẹrẹ, ti kii ba si se ijọba ti aarẹ n se, se o yẹ ko tun safikun owo ina ati owo ori ọja lasiko yii.
Oríṣun àwòrán, Instagram/dinomelaye
O wa gba ijọba nimọran lati jẹ ki eto atunto orilẹede yii tawọn araalu n beere fun waye bibẹẹ kọ, fun ara atunto ni yoo se ara rẹ, eyi to lee mu iyapa ati ipinya waye fun Naijiria.
Nigba to n sọrọ lori bawọn ọmọ orilẹede yii se n beere fun wiwọgile ẹka ọlọpaa SARS to n gbogun ti iwa idigunjale, asofin agba naa ni aarẹ Buhari funra rẹ lo yẹ ko bọ sita lati kede pe oun wọgile isẹ awọn SARs yii, bi bẹẹ kọ, iyipada kankan ko ni waye.
Se bi igba kẹrin ree laarin ọdun mẹta ti wọn yoo kede pe awọn fofin de ẹka SARS amọ irọ lo wa nidi rẹ, o digba ti aarẹ ba sọrọ, ki wọn to mu isẹ se lori rẹ, gbogbo ohun tawọn ọlọpaa n sọ yẹ, irọ ni.
'N500 dé fún gbogbo ọmọ tuntun lóṣooṣù bí mo bá di gómìnà Ondo - Adeleye AAC
Nigba to n salaye ọna to gba ko ọrọ jọ, to fi di onile ati mọto rẹpẹtẹ, to si n wọ asọ asiko, Melaye ni oun ko lọwọ ninu iwa ọdaran, bẹẹ ni oun ko gba isẹ agbase lọdọ ijọba, nitori wọn ko ba ti ri idi oun.
Isẹ to mọ ni mo n se. Mo n se katakara ilẹ ati ile, okoowo nilẹ yii ati loke okun, bẹẹ ni mo si tun nko ọja wọle. Ọdọ to ba si fẹ mọ nipa okoowo to lee tete mu owo wọle, lee kan si mi, to ba si jẹ pe mo n se mọkaruru ni, ijọba ko ba ti ridi mi.
Lakotan, Dino Melaye ni oun fẹran orin kikọ pupọ, to si seese lọjọ iwaju, ki oun gbe awo orin jade sita tabi ki oun di akọrin.
Orin wa ninu ẹjẹ mi, Ọlọrun si lo fi ami ororo yan mi lati maa kọrin, ọna kan ree ti mo si n gba lati fi ọrọ ransẹ sawọn eeyan, bẹẹ ni orin n sisẹ ti mo n ran-an.
Obateru Akinruntan: Wíwá ohun tá jẹ títí láé ló gbé wa kúrò nílé Ife
Bakan naa lo fikun pe olootọ ẹda ni oun, ẹni to korira ka maa fi dudu pe funfun, iwa otitọ yii si ni oun yoo maa sọ titi lai naani inu ẹgbẹ oselu ti oun wa.
Gani Adams: Iléesẹ́ ọlọ́pàá Oyo ṣe àfihàn àwọn afurasí, òníjìbìtì
Oríṣun àwòrán, Nigeria Police Force, Oyo state
Ileesẹ ọlọpaa ipinlẹ Ọyọ ti safihan awọn afurasi ọdaran ti ọwọ wọn tẹ jakejado ipinlẹ naa.
Lara awọn afurasi naa ni awọn afurasi ajinigbe to n ṣe ọsẹ ninu igbo Old Oyo Forest Reserve, to wa ni oju ọna Igbeti si Kisi ni agbegbe Oke-Ogun.
Ọwọ tun tẹ awọn to ma n fi owó ṣe sogun-dogoji, to lu ọpọ eeyan ni jibiti nilu Igboho.
Nigba to n sọrọ ni olu ileesẹ ọlọpaa nipinlẹ Oyo, to wa ni adugbo Eleyele nilu Ibadan, Kọmisanna ọlọpaa, Joe Nwachukwu Enwonwu, sọ pe, ọwọ tẹ àwọn agbebọn naa lasiko irinajo ọjọ mẹta ti awọn ọlọpaa ati ọlọdẹ fi n gbọn igbo Kishi yẹbẹyẹbẹ.
'Aragbe laye'
Ọgbẹni Enwonwu sọ pe, awọn afurasi naa ni Aare Ona Kakanfo ilẹ Yoruba, Iba Gani Adams ta àwọn alasẹ lolobo si, nipa iṣẹ buruku ti wọn n ṣe ni agbegbe Oke-Ogun.
"O ni ""awọn janduku naa fi nkan ijagun oloro dena de awọn olookowo maalu kan, ni ọjọ kẹẹdogun, oṣu Kẹsàn-án, ni nkan bi aago mẹfa irọlẹ."
"Lẹyin naa ni awọn afurasi ajinigbe/adigunjale naa ránṣẹ si ẹbí awọn eeyan naa, ti wọn si gba owo itusilẹ lọwọ wọn."""
Ondo Elections 2020: Ọgọ́rùn-ún ọdún tí a máa lò lórí oyè l'Ondo, ẹ ó rí àrà - Ojon YPP
Lẹyin ti ọrọ naa de ọdọ awọn ọlọpaa, ni wọn gbe igbesẹ pẹlu iranlọwọ àwọn ọlọdẹ, ti ọwọ si tẹ mẹta lara wọn.
Ibọn AK-49 marun, ọta ìbọn mẹtalelọgọrin, foonu mẹsan, N77,800, ati awọn nkan miran ni wọn ba ba lọwọ wọn.
Bakan naa ni ọwọ tẹ awọn ọmọ ikọ olówó èlé, to lu awọn olugbe ilu Igboho ni jibiti owo to to miliọnu mẹta Naira, N2, 700,000, ko to o di pe wọn sa kuro ni ilu naa lọ si Badagry nipinlẹ Eko.
Atunto Naijiria la n fẹ - Aarẹ Onakakanfo, Gani Adams
Ilu Badagry ni ọwọ ti tẹ wọn, nibi ti wọn tun ti n ṣe iru òwò naa.
Nilu Igboho, Noble City Global Concept, ni orúkọ ti awọn onijibiti naa pe ara wọn, ti wọn si lo Achievers Nicor Fund Social Economic Development Scheme ni Badagry.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ile ẹjọ kan nilu Sokoto, ti paṣẹ pe ki wọn o mu ọdọmọkunrin kan to ya fidio ọmọbinrin kan, lẹyin to tipa ni ibalopọ pẹlu rẹ, to si tun fi si ori ayelujara.
Ọjọ igbeyawo ọmọbinrin naa ku diẹ ni iṣẹlẹ naa waye, eyi to mu ki ọkọ afẹsọna rẹ sọ pe oun ko ṣe igbeyawo pẹlu rẹ mọ, lẹyin ti fidio ihoho rẹ jade sori ayelujara.
Ọjọ Aje ni wọn gbe Aminu Hayatu Tafida lọ sile ẹjọ majisireti kan, ti wọn si fi ẹsun ifipabanilopọ, ibanilorukọ jẹ, ati pe o tun sọ ọrọ odi.
Ondo Elections 2020: Ọgọ́rùn-ún ọdún tí a máa lò lórí oyè l'Ondo, ẹ ó rí àrà - Ojon YPP
Iroyin sọ pe Aminu ati ọrẹ rẹ mẹta ni wọn gbe lọ sile ẹjọ, nitori wọn ran an lọwọ lati pin fidio naa kaakiri ori ayelujara.
Awọn mẹtẹẹta ni Umar Abubakar, Mas'ud Abubakar Gidado, ati Aliyu Shehu Kangiwa.
Ọlọpaa to rojọ tako wọn nile ẹjọ, ASP Samuel Sule, sọ pe awọn ẹsun ti wọn fi kan wọn tako ofin iwa ọdaran nipinlẹ Sokoto.
Awọn mẹrẹẹrin sọ pe awọn ko jẹbi awọn ẹsun ti wọn fi kan wọn ọhun.
Agbẹjọro fun Aminu, AY Abubakar, sọ pe ẹsun ti awọn ọlọpaa fi kan onibara oun ko lẹsẹ nilẹ, nitori pe akọsilẹ akọkọ tileeṣẹ ọlọpaa kọ, ko sọ pato ẹsun ti wọn fi kan an.
EkitiRapeCastration: ìgbésẹ̀ míì lè dẹ́kun ìwà ìfipábánilòpọ̀
Oríṣun àwòrán, Rolling stone
Bakan naa ni agbẹjọro fun awọn mẹta to ku, Yahaya Gwaza, sọ pe ko si ẹri to fihan pe awọn olujẹjọ lọwọ si isẹlẹ naa.
Eyi si lo mu ki adajọ ile ẹjọ naa, Shu'aibu Ahmad, sun igbẹjọ si ọjọ kọkandinlogun, oṣu Kẹwa, lati fun ileeṣẹ ọlọpaa ni aaye lati ko ẹsun ti wọn yoo fi kan wọn jọ.
Bakan naa lo paṣẹ pe ki wọn fi wọn si atimọle titi di igba naa.
Èyí ni ìtàn bí ẹni tí mó gbọ́njú mọ̀ bíi bàbà ṣe fipá bá mi lájọṣepọ̀
Oṣu to kọja ni awọn ọlọpaa agbegbe taa mọ si Hisbah nipinlẹ Sokoto, mu awọn ọdọ naa fun pe, wọn fi fidio to ṣafihan bi ọkan lara wọn ṣe n ba ọmọbinrin kan ni ibalopọ tipatipa, si ori ayelujara.
Iroyin sọ pe oṣu yii lo yẹ ki ọmọbinrin naa ṣe igbeyawo, amọ afẹsọna rẹ ti sọ pe oun ko ṣe mọ, lẹyin ti fidio naa jade.
Oludari ajọ Hisbah, Dokita Adamu Bello Asarawa sọ fun BBC pe, iya ọmọbinrin ọhun sọ fun ajọ naa pe, ọdun 2017 ni ọmọkunrin naa tan ọmọbinrin ọhun lọ sile itura kan, to si ya fidio rẹ nigba to wa ni ihoho, lẹyin to fi ipa balopọ tan.
Amọ, igba ti ọjọ igbeyawo ọmọbinrin naa ku diẹ, lo fi fidio naa sita.
Obateru Akinruntan: Wíwá ohun tá jẹ títí láé ló gbé wa kúrò nílé Ife
"Ọmọkunrin naa jẹwọ fun wa nigba ti ọwọ tẹ ẹ, pe lootọ ni oun hu iwa naa. Ọwọ wa tẹ ọrẹ rẹ meji, awọn naa si sọ pe ọmọkunrin naa lo ran awọn.
Nitori naa, ọwọ awọn ọrẹ rẹ mejeeji ni fidio naa gba de ori ayelujara."""
Ọmọ ọdun mẹtadinlogun ni ọmọkunrin ọhun nigba ti iṣẹlẹ yii waye, ti eyi obinrin si jẹ ọmọ ọdun mẹrindinlogun.
Anambra Rape: Ìdí ti mo fi bá ọmọ ọdún méje lòpọ̀- Ejike Kanu
Oríṣun àwòrán, Hamisu Mallamawa
Iwaju ile Musa
Ọkùnrin ẹni ọdún mẹ́tàlélọ́gbọ̀n kan ni wọ́n ti fí pánpẹ́ ọba mú nítorí ó fipá bá ọmọ ọdún méje tó jẹ́ aládùgbò rẹ̀ lòpọ̀.
Ejike Kanu ni wọn ni ó tan ọmọ kan wọ sọ́ọ̀bù ìyàwó rẹ̀ níbi tí ó ti fipá bá ọmọ náà lòpọ̀.
Ìṣẹ̀lẹ̀ ọ̀hún tó wáyé ní Okpoko, ní ẹgbẹ́ Onisha, ìjọba ìbílẹ̀ Ogbaru, ìpínlẹ̀ Anambra bẹ́ẹ̀ sì ni àwọn ọlọ́pàá ti mú u ti wọ́n sì ti bẹ̀rẹ̀ ìwádìí wọ́n lórí ọ̀rọ̀ náà.
Ìdájọ́ òdòdò ló fẹsẹ̀ múlẹ̀ lórí ọ̀rọ̀ Pásítọ̀ Sotitobire - Agbẹjọ́rò fún ìjọba
Kanu ni iṣẹ́ esù ló mu òun gbé ìgbésẹ̀ náà lásìkò tí àwọn ọlọ́pàá ń bèrè ìdí tó fi hu irú ìwà bẹ́ẹ̀.
Agbẹnusọ ọlọ́pàá ìpińlẹ̀ náà, Haruna Mohammed to fi ìdí ìṣẹ̀lẹ̀ náà múlẹ̀ sàlàyé pé ilé iṣẹ́ ọlọ́pàá ti dárí ẹjọ́ náà sí ẹ̀ka ìwádìí ìwà ọ̀daran.
" A ti ṣe àbẹ̀wò sí ibi ìṣẹ̀lẹ̀ náà, à sì ti gbé ọmọ ọ̀hún lọ sí ilé ìwòsàn fún àyẹ̀wò àti ìtọ́jú, tí àwọn dókìtà sì fi ìdí rẹ̀ múlẹ̀ pé lóòtọ́ ni wọ́n fi ipá bá ọmọ náà lòpọ̀.
Bákan náà ni ọkùnrin ọhun jẹ́wọ́ pé lóòtọ́ ni òun fi ipá bá ọmọ náà lòpọ̀, sùgbọ́n iṣẹ́ esù ni.
Ondo Elections 2020: Ọgọ́rùn-ún ọdún tí a máa lò lórí oyè l'Ondo, ẹ ó rí àrà - Ojon YPP
Oríṣun àwòrán, Hamisu Mallamawa
Musa Adamu ti ori ko yọ lọwọ awọn ajinigbe
Ó ṣojú mi kòró làwọn agbébọn ṣe fipá bá ọmọ ọdún mẹ́wàá lòpọ̀!
Ohun ti oju Musa Adamu, olugbe ilu Mallamawa ri lasiko tawọn agbebọn ṣigun bo abule rẹ fọjọ meji kọja afẹnusọ.
Baba ọlọmọ mẹwa yii, to ni iyawo meji sọ fun BBC pe awọn agbebọn to le ni aadọta lo yabo abule awọn ni ipinlẹ Katsina, nila oorun ariwa Naijiria.
O ni lowurọ ọjọ Aiku ti wọn wa ba awọn loko, awọn ọdaran yii gbe ọrẹ oun ati awọn eeyan miran to n ṣiṣẹ loko lọjọ naa.
O ni Inu oko ni mo wa pẹlu ọrẹ mi, ti awọn ẹni a wi yii de lori alupupu, ti wọn si di ibọn mọra. Ki  a to mọ ohun to ṣẹlẹ, wọn ko wa si ori ọkada, ti wọn si gbewa lọ si oko miran."""
Oríṣun àwòrán, Hamisu Mallamawa
Musa joko s'aarin awọn to wa ba yọ pe ori ko yọ lọwọ ajinigbe
''Lapapọ, eeyan mejila ni wọn ji gbe ni abule Mallamawa''
O tẹsiwaju pe ''awọn obinrin mẹrin wa laarin wa, ọmọge mẹta ati adelebo kan. Nisoju mi ni wọn se fipa ba awọn mẹrẹẹrin lopọ.
Ọmọdebinrin, ọmọ ọdun mẹwa kan to wa laarin wọn kan n sunkun ni bi wọn ṣe n fipa ba a lopọ''
Adamu ni wọn sọ fun adelebọ kan ti wọn fipa ba lopọ pe, awọn ko ni tusilẹ nitori pe awọn gbadun rẹ.''Wọn daju gan ni.''
Oríṣun àwòrán, Hamisu Mallamawa
Iwaju ile Musa
Adamu sọ pe awọn agbebọn naa ti wọn wọ aṣọ Fulani, ti wọn si tun n sọ ede wọn, sọ pe awọn fẹ gba miliọnu kan naira lọwọ ẹni kọọkan.
Nipa ti ounjẹ, Adamu to ribi moribọ sisọ loju rẹ pe okele tuwo kọọkan ni wọn n fun awọn lọsan ati alẹ.
"Eeyan ko le pe nnkan ti wọn n fun wa lounjẹ rara nitori gbẹmi ro lasan ni. Okele kan tuwo laarọ, lọsan ati alẹ ni wọn n fun wa lojumọ''
Àwọn kan ṣónú bí wọ́n bá di gómìnà, ẹ fún wa láyè láti wá parí iṣẹ́ táa bẹ̀rẹ̀ - Akeredolu
Musa salaye pe nigba ti awọn ajinigbe yii sun, lawọn ribi tu okun, tawọn si yọ salọ.
''Emi ati ọrẹ mii ribi tu okun nigba ti wọn sun lọ. Ohun to dun mi ni pe a ko ribi doola awọn eeyan mẹwa to ku.T i a ba fi ni ka ran wọn lọwọ, aṣiri ko ba tu''
Tijo tayọ ni Adamu fi darapọ mọ ẹbi rẹ pada, to si ni yoo ṣe diẹ ki oun to pada soko.
Agbẹnusọ ọlọpaa nipinlẹ Katsina, Gambo Isah fidi iṣẹlẹ yii mulẹ fun BBC, to si ni awọn n ṣapa lati doola awọn ti wọn jigbe.
Wo Adigun ọmọ ọdún mẹ́rin tí òwe Yorùbá àti ìtúmọ̀ gbó lẹ́nu rẹ̀ ju tìrẹ̀ lọ
O ti ṣe diẹ ti ipinlẹ Aarẹ Buhari, iyẹn Katsina ati awọn ipinlẹ mii ni iwọ oorun ariwa Naijiria, ti n koju ipenija aabo lọwọ awọn ajinigbepawo.
Lọjọ Kẹwa oṣu Kẹfa ọdun 2020, eeyan mẹwa lawọn agbebọn pa ni Faskari ti wọn si tun pa eeyan mẹẹdogun loṣu to tẹle.
Iṣẹlẹ keji yi waye ni ilu Yargamji ni ipinlẹ Katsina yi kan naa.
Funke Akindele: Òun àti ọkọ rẹ gba ìdáríjì lọ́wọ́ ìjọba ìpínlẹ̀ Eko
Oríṣun àwòrán, Instagram/FunkeAkindele
Gomina ipinlẹ Eko, Babajide Sanwo-Olu ti fun gbajugbaja oṣere, Funke Akindele ti gbogbo eniyan mọ si Jenifa ati ọkọ rẹ, Abdulrasheed Bello, JJC Skillz ni aṣẹ ma a lọ lailẹbi lọwọ ipinlẹ Eko.
Funke Akindele ati ọkọ rẹ ni wọn jẹbi ẹsun ṣiṣẹ ayẹyẹ ọjọ ibi tako ofin to de itankalẹ arun Coronavirus ni Oṣu Kẹrin, ọdun 2020.
Ti ijọba si fun wọn ni idajọ lati ṣiṣẹ ilu gẹgẹ bi iya fun ofin ti wọn tẹ oju rẹ mọlẹ.
Sanwo-Olu ninu atẹjade to fi lede ni Ojọ Ẹti ni, awọn tu awọn ọkọ ati iyawo silẹ, lẹyin imọran lati ọdọ ajọ Advisory Council on Prerogative of Mercy.
Oríṣun àwòrán, Instagram/FunkeAkindele
Ijọba fi lede wi pe aṣẹ naa tẹle iwe ofin ipinlẹ naa to gba gomina laaye lati ṣe bẹẹ (Section 212 1& 2 ) labẹ ofin ọsun 1999.
Bakan naa ni Gomina Sanwo-Olu da awọn ẹlẹwọn mẹrindinlọgọta silẹ  ni awọn ọgba ẹwọn kaakiri ipinlẹ naa.
Olotu eto idajọ nipinlẹ Eko, Kayode Oyekanmi ti wa rọ awọn to jẹ anfaani yii lati yẹra fun iwa ọdaran ki wọn si tẹle aṣẹ ati ofin ilu.
Obateru Akinruntan: Wíwá ohun tá jẹ títí láé ló gbé wa kúrò nílé Ife
Ni oṣu Kẹrin, ọdun 2020 ni ajafẹtọ ọmọniyan to tun jẹ agbẹjọrọ agba rọ gomina Sanwo-Olu lati da Funke Akindele ati ọkọ rẹ silẹ.
Iyabo Ojo ní lóòtọ́ ni òhun ti ṣe iṣẹ́ abẹ rí, ṣùgbọ́n kìí ṣe pé nítorí ọkùnrin tàbí afẹ́ ayé, ṣùgbọ́n nítorí pé mó fẹ́ ni ìgboyà nínú ara mí ni mó ṣe ṣe e""."
Iyabo Ojo fi idi ọ̀rọ̀ yìí múlẹ̀ lásíkò tó ṣe ìfọ̀rọ̀wérọ̀ pẹ̀lú BBC. O ní nígbà ti òun bi àkọbi ọmọ òun ni òun ṣe àkíyèsí pé, ọ̀rá pọ̀ jù ní ìkù òun, òun si ṣe ìpinnu pé ti òun bá ti ni owó lọ́wọ́ òun yóò lọ ṣe ǹkan ti o wú òun.
Oríṣun àwòrán, Iyaboojofespris/instagram
"Ó ní nígbà tí owó díẹ̀ yọ sọ́wọ́ ni òun gba ọ̀nà Turkey lọ láti lọ ṣe iṣẹ́ abẹ náà, ""àsìkò yìí ni ìròyìn gbòde nítori mo ṣe àìsàn lẹyìn iṣẹ́ abẹ náà."""
Àwọn dókìtà ní mo ṣàìsàn nítorí àwọn èròjà tó má n bá ààrùn jà lára mí kò pọ tó, Ṣùgbọ́n ọpẹ́ ni fún Ọlọ́run.
Lákọ lákọ nìbọn ń ró níbí táwọn Ọlọ́pàá àti Sọ́jà tí ń gbáradì fún ìdìbò Ondo
Gbájúgbaja òṣèré tíátà Yoruba náà sàlàyé pé ariwo ti àwọn ènìyàn ń pa lóríI pé, àwọn òṣèré tíátà n kọ́lé ńla, tàbi wọ́n ń ra ọkọ̀, kìí ṣe gbogbo òṣèré ni ọkùnrin ń kówó fún kí wọ́n to ṣe aṣeyọrí.
"Kìí ṣe gbogbo òṣèré tíátà náà ló n fí ọ̀nà àlùmọ̀kọ́rọ́yi ri owó, ""ọ̀pọ̀ wà ló n ṣe ìṣẹ́ ọwọ́ rẹ̀ pẹ̀lú oníruuru òwò láti rí owó."
Oríṣun àwòrán, Nkechi /Instagram
Nkechi Blessing Sunday náà ra kẹ̀kẹ́ ìrìnsẹ̀ fún ọkunrin kan to ni ìpèníja ara.
Nkechi Blessing ni, ọkunrin kan to n jẹ́ Busari Taofeek Ademola kọ ọ̀rọ̀ ránṣẹ́ sí orí intagram òun pé òun nílò kẹ́kẹ̀ ìrìn ti àwọn arọ máa ń lò.
mo lọ sí ibi àtẹ̀jíṣẹ́ rẹ̀, ibẹ̀ ni mo ti ri pé ó ti kọ̀wé ránṣẹ́ sí mi tẹ́lẹ̀ tó tọrọ kẹ̀kẹ́, ṣùgbọ́n Ibadan ló n gbé Nkechi ni ká ma fa ọ̀rọ̀ gún òun ke sí ènìyàn òun kan tó ń gbé ni Ibadan.
Gbájúgbajà òṣèré Nollywood náà ni kété ni òun ti fi kẹ̀kẹ́ náà àti àwọn ǹkan elò míràn ránṣẹ́ si i.
Nkechi Blessing ni kìí ṣe pé òun kọ èyí kí ẹnikẹni le sọ pé ènìyàn dáada ni òun, ṣùgbọ́n òun gbé fọ́ran rẹ̀ síta fún àwọn ènìyàn láti náwọ ìrànwọ́ si i.
Oríṣun àwòrán, SHAFFYBELLO/INSTAGRAM
Nínú ọ̀sẹ̀ yìí bákan náà, gbájúgbaja nínú eré tíátà Nollywood òyìnbó àti Yoruba tó tún jẹ́ olórin, náà ṣe ọjọ́ ìbí.
Gẹ́gẹ́ bi ó ṣe kọ ọ́ sójú òpó instagram rẹ̀ lówùrọ̀ òní, Shaffy Bello ni, ilé olóke márùn dara gan ni.
"Ọ̀pọ̀ àwọn akẹ́gbẹ́ rẹ̀ nínú eré tíátà ló n ki i kú ewu ọjọbi ààdọ́ta ọdún ti àwọn ọlóyìnbó n pè ni ""Golden Jubilee""."
Iyabo Ojo: Ololade Abuta ní káwọn gbéborùn dákẹ́ lórí jeep túntún Boss Lady
Oríṣun àwòrán, iyaboojofespris
Gbajumọ olokoowo kan nilu Eko, Ololade Abuta ti kede fun araye pe kawọn eeyan to sọ ohun ti oju wọn ko to nitori ọkọ Jeep tuntun ti Iyabo Ojo sẹsẹ ni.
Ololade, nigba to n kede bẹẹ loju opo Twitter rẹ lọsan Ọjọru, tun salaye pe ọpọ ahesọ ọrọ ni oun ti gbọ nipa ọkọ naa.
O ni oun fẹ wa kede fun araye pe owo oju oogun oju oun ni oun fi ra ọkọ naa bii ẹbun fun Iyabo Ojo nitori awọn oore kan to ti se fun oun.
"Abuta ni "" Iya to se atilẹyin wa ni mo ra ọkọ Range Jeep fun, ẹnikẹni ti ko si seranwọ fun wa la ra kaadi ipe fun, eyiun Recharge card."
Oríṣun àwòrán, iyaboojofespris
"Lonii Iyabo Ojo, mo mọ riri rẹ fun obinrin rere to jẹ, lootọ ni o ko pe nitori ko si ẹda to pe amọ o ni ọkan to dara, to si jẹ ọkan lara awọn eeyan ti mo mọ riri wọn."""
Ololade ni oun kii se ẹni to maa n sọrọ lori ayelujara tabi maa ko ko bẹẹrẹ fun ẹnikan nitori atẹnujẹ amọ Iyabo Ojo jẹ eeyan kan to yẹ lẹni ti a gbe sla fun.
Ondo Elections 2020: Ọgọ́rùn-ún ọdún tí a máa lò lórí oyè l'Ondo, ẹ ó rí àrà - Ojon YPP
O fikun pe ojo ti n pa igun oun ati Iyabo bọ, ọjọ ti pẹ, to si ti to ọdun mẹẹdogun tawọn ti mọ ara awọn.
O ni yatọ si pe Iyabo jẹ oninure, se lo tun fi gbogbo ara se atilẹyin fun oun, ọrọ si pọ ti oun fẹ sọ nipa rẹ, amọ ti oun ba kọ silẹ, ọpọ eeyan ni ko ni le ka a.
"Hen hen, mo gbọ pe awọn eeyan kan n sọ ahesọ ọrọ kiri pe ọkunrin kan lo ra mọto Jeep naa fun Iyabo Ojo, to wa sọ fun mi pe ki n kede pe emi ni mo ra fun oun.
Nigba ti mo gbọ, mo rẹrin arintakiti amọ nigba to ya, n ko le rẹrin mọ, ti aanu irufẹ awọn eeyan naa si n se minitori pe o seese ko jẹ ipo ailowo lọwọ wọn lo faa, ti wsn se n ronu bẹẹ tabi pe wọn jẹ ahun."
Ololade wa gbadura pe Ọlọrun yoo bukun fun wa de ipo to jẹ pe ati ra iru ẹbun bii mọto nla bayii ko ni jọ wa loju rara nigba ta ba ri owo ra a.
Kia naa si ni Iyabo Ojo funra rẹ ti fesi si ọrọ naa, to si ni oun nifẹ Ololade pupọ fun ikede to se naa.
Okonjo-Iweala WTO DG nomination: Kíni ìdí tí orílẹ̀-èdè America ṣe tako ìyànsípò Okonjo-Iweala gẹ́gẹ́ bi olórí ajọ WTO
Oríṣun àwòrán, TEAMNGOZI
Lootọ ni wọn ti fi orukọ ọmọ orilẹ-ede Naijiria, Ngozi Okonjo-Iweala silẹ lati di oludari agba fun ajọ okoowo l'agbaye, World Tradr Organisation (WTO).
Ṣugbọn, ọjọ kẹsan-an, oṣu Kọkanla, ni ireti wa pe ajọ naa yoo kede erongba rẹ.
Ọpọ ninu awọn aṣoju orilẹ-ede ninu ajọ naa, to parapọ mọ awọn ọmọ igbimọ lati yan Ọga Agba tuntun, lo fọwọ si iyansipo Okonjo-Iweala.
Orilẹ-ede America nikan ni aṣoju ti ko faramọ iyansipo rẹ nibi ipade to waye l'Ọjọru.
Kété tí wọ́n bá ti báa yín sùn tàn torí pé ẹ tóbi, ẹ gbà pé ìfẹ́ yẹn ti parí - Auntie Remi Ọlọ́yàn ńlá
Oríṣun àwòrán, WTO/WEBSITE
"Gẹgẹ bi Akọroyin BBC lori eto ọrọ aje, Andrew Walker, ṣe ṣalaye, oludije fun ipo naa lati orilẹ-ede South Korea, ni America faramọ, nitori ""iriri to ni nipa okoowo, ati ipá lati ṣe amojuto daadaa""."
Wọn ko sọ idi ti wọn fi tako Okonjo-Iweala.
Ṣugbọn, o di igba ti igbesẹ to kẹhin ba waye, ki ijiroro to o tan.
Bi ọrọ naa ṣe n lọ,  lootọ ni Okonjo-Iweala, ni ibo to pọju, amọ iyansipo rẹ ko ti i fi ẹsẹ mulẹ.
Ijiroro ṣi n lọ lọwọ lori boya ajọ WTO faramọ ẹni to ni ibo to pọju lọ.
Àwọn obìnrin mánigbàgbé sáà ìjọba tiwantiwa yìí
Ọwọ́jà coronavirus yóò ṣì wà pẹ̀lú àgbáyé fún ìgbà pípẹ́- Ngozi Okonjo-Iweala
Wo imọran Fọlọrunṣọ Alakija fun awọn ọdọ adulawọ
"Ọkan lara awọn akọroyin lati Naijiria to ni anfaani lati mojuto eto idibo naa, Oluwamayowa Tijani, sọ fun BBC Pidgin pe ""iṣoro to wa nibẹ ni pe orilẹ-ede America ko faramọ Okonjo-Iweala""."
Nkan ti orilẹ-ede America si le ṣe lati gbe erongba wọn lẹyin, ni lati wa awọn orilẹ-ede mii ti yoo darapọ mọ wọn lati tako o.
Ajọ̀ WTO lo ma n mojuto ijiroro ati adehun okoowo laarin awọn orilẹ-ede.
Nibẹ si ni awọn orilẹ-ede ti le yanju aawọ to ba waye laarin wọn nitori okoowo.
Okonjo, to ti fi igba kan jẹ minisita fun eto inawo ni Naijiria, ni obinrin akọkọ to de ipo naa lati ọdun mẹẹdọgbọn ti wọn ti da ajọ WTO silẹ.
Adetoun Ogunṣẹyẹ: ìrìnàjò ẹ̀kọ́ mi títí dé òkè kò rọrùn rárá
Oun naa si tun ni ọmọ ilẹ Africa akọkọ to de ipo naa.
Apapọ ibo mẹrinlelọgọrun ni oun nikan ni, ninu ibo mẹrinlelọgọjọ ti awọn aṣoju di.
Eyi yoo mu ko fi ẹyin minisita fun okoowo l'orilẹ-ede South Korea, Yoo Myung- he, ti wọn jọ de ipele to kẹhin.
Bi ipinnu Ngozi Okonjo-Iweala lati di Oludari ajọ WTO ṣe n jọ ọ bọ̀ diẹdiẹ
Ipinnu Minisita feto ọrọ aje Naijiria tẹlẹ Ngozi Okonjo Iweala lati di ipo adari ajọ idokowo lagbaye WTO mu n sunmọ mimu ṣẹ bọ diẹ diẹ.
Eyi ko sẹyin bi o ti ṣeeṣe ki wọn kede orukọ rẹ lojobọ lara awọn meji to tẹsiwaju de abala ìkẹyìn eto iyansipo tó n lọ lọwọ.
Ni bi nkan ti ṣe ri yi, oun ati ọmọ orileede South Korea Yoo Myung- he ni wọn yoo fi orukọ wọn ṣọwọ ninu awọn marun un to ṣẹku tẹlẹ.
Obinrin ni awọn mejeeji.
Bi o ba fi le jawe olubori yoo jẹ obinrin akọkọ lati Afrika ti yoo di ipo yi mu.
Àwọn onwoye si n sọ pe yiyan ọmọ Afrika si ipo yi yoo mu idagbasoke ba karakata nilẹ naa eyi ti o daduro si ida meji si mẹta idokowo lagbaye.
Bakan naa ni adari ajọ naa tuntun ti wọn ba yan yoo ni lati pẹtu saawọ idokowo laarin Amerika ati China.
Ṣaaju ni aarẹ Trump ti kọdi iyansipo awọn adajọ si igbimọ ipẹtusaawọ ajọ naa.
Eyi si n ṣakoba fun ajọ naa nipa ṣiṣe iṣẹ rẹ lẹkunrẹrẹ.
Loṣu to n bọ ni wọn yoo kede ẹni ba pegede fi ipo olori WTO.
Ondo Elections 2020: Ọgọ́rùn-ún ọdún tí a máa lò lórí oyè l'Ondo, ẹ ó rí àrà - Ojon YPP
Ta ni Ngozi Okonjo-Iweala to dupo olori ajọ okowo agbaye WTO?
Ọjọgbọn Ngozi Okonjo-Iweala jẹ minisita ijọba meji lorilẹede Naijiria-2003 si 2006 labẹ aarẹ Oluṣẹgun Ọbasanjọ, 2011 si 2015 labẹ iṣejọba aarẹ Goddluck Jonathan.
Banki agbaye ni Ọjọgbọn Ngozi Okonjo-Iweala ti n ṣiṣẹ ki aarẹ Oluṣẹgun Ọbasanjọ to pe e wa sile wa ṣe minisita fun eto iṣuna lorilẹede Naijiriaoun ni obinrin akskọ ti yoo ṣe minisita fun eto iṣuna ati minisita fun ọrọ ilẹ okeere lorilẹede Naijiria.
Oríṣun àwòrán, @NOIweala
Pupọ ọmọ orilede Naijiria ni ko ni gbagbe minisita 'alaṣọ ankara' yii pẹlu gele 'ipakọ o gbọ ṣuti' rẹ
Ọkan lara awọn eekan to lagbara labẹ iṣejọba aarẹ Ọbasanjọ laarin ọdun 2003 si 2006 ni Okonjo-Iweala, o si ko ipa ribiribi ninu bi awọn igbimọ orilẹede agba kan lagbaye ṣe wọgile gbese biliọnu mejidinlogun dọla, $18bn ti orilẹede Naijiria jẹ ṣaaju igba naa.
Pupọ ọmọ orilede Naijiria ni ko ni gbagbe minisita 'alaṣọ ankara' yii pẹlu gele 'ipakọ o gbọ ṣuti' rẹ.
2021 Nigerian Budget: Àbádòfin ìṣúná 2021 ré kọjá ìpele ìkejì nílé aṣòfin àgbà
Oríṣun àwòrán, SENATE NIGERIA
Aba isuna  oni triliọnu mẹtala ti aarẹ Muhammadu Buhari fi ṣọwọ s'awọn aṣofin ti rẹ kọja ipele  kika Ikeji ni ile aṣofin agba.
Lọjọbọ ni awọn aṣofin agba tẹti si kika rẹ ti wọn sì ni ko tẹsiwaju abala to kan.
Igbesẹ yi waye lẹyin ijiroro ọlọjọ mẹta lori awọn koko to wa ninu abadofin yi ti aarẹ pe orukọ rẹ ni aba isuna idapada ati iduro sinsin ọrọ aje Naijiria.
Lọjọbo to kọja ni aarẹ Buhari tẹ abadofin naa siwaju ile aṣofin.
Ọkọọkan ejeeji lawọn aṣofin n sagbeyẹwo aba isuna naa t'awọn kan si n naka abuku si ibi to ku diẹ si b'awọn mii ṣe n gbosuba fún ùn.
Ohun kan to kan awọn aṣofin lominu ni iye ti wọn kọ sinu rẹ pe Naijiria yoo fi seto gbese to le ni triliọnu mẹta naira ati erongba lati ya owo to le ni triliọnu marun un lati fi seto isuna.
Oríṣun àwòrán, @Abujang
Aarẹ Buhari ti gbe eto iṣuna ọdun 2021 lọ siwaju ile igbimọ asofin mejeeji ni Abuja.
Ọkan ninu atupalẹ eto iṣuna naa ti awọn eeyan n pariwo bayii lori ayelujara ni ti owo to le ni biliọnu mẹwaa naira ti Aarẹ Buhari ni wọn fẹ fi tun àwọn wáyà ina ati inu ile Aso Rock se ni Abuja.
Wọn ni wọn ti fi afojusun lati na o din diẹ ni biliọnu marun un naira lori atunṣe ati ipese awọn wáyà ina.
Wọn yoo si na biliọnu marun un naira le ni ọọdunrun lori atunṣe awọn ọọfiisi ati ile inu Aso Rock to jẹ ileejọba ni Abuja to jẹ olu ilu Naijiria.
"Awọn alakalẹ bi wọn ṣe fẹ na owo naa ni wọn gbe si abẹ ""ERGP 7102245"" to jẹ atunṣe awọn waya ina ni eyi ti wọn maa na N4,854,381,299."
"Ati atunse awọn ile gbigbe ati ọọfiisi ti wọn yoo ti na: N153,693,262 ati N5,244,027,241."""
coronavirus prevention badge update: Wo òótọ́ àti irọ́ tó wà nínú báàjì àyà náà
Wọn ni miliọnu marun un  ati igba naira ni wọn yoo fi yanju ọrọ atunse jẹnẹratọ  amunawa ti wọn yoo si fi miliọnu marundinlaadọta N45m ra epo jẹnẹratọ.
Wọn ni wọn yoo fi N274m fi san owo ina ọba PHCN ti wọn yoo si fi N67.1m sanwo lilo ayelujara (Internet)
Abayọmi Aranmọlatẹ, Dr Laser: Vagino Plasty àti iṣẹ́ abẹ ẹwà Obìnrin ló jẹ mí lógún
Wo owó tí Buhari bù fún ẹ̀ka kọ̀ọ̀kan nínú ìṣúná ọdún 2021
Aarẹ Muhammadu Buhari gbe aba kalẹ lọjọbọ siwaju ile asofin apapọ ilẹ wa eyi ti apapọ rẹ totriliọnu mẹtala naira (₦13.08trn).
Ninu aba isuna naa, oniruuru ileesẹ ijọba ati lajọlajọ ni ijọba se alakalẹ iye ti wọn yoo naa fun ọdn to n bọ, to si bu owo naa fun wọn.
Oríṣun àwòrán, Femi Adesina
Èyí ní àtúpalẹ̀ ètò ìṣúná fọ́dún 2021
Aarẹ Buhari, lasiko to n gbe aba isuna naa kalẹ salaye pe gbogbo awọn akanse isẹ to n lọ lọwọ nijọba yoo sa ipa rẹ lati pari lọdun 2021, to fi mọ awọn oju popo ati oju irin.
Bakan naa ni ijọba ko gbagbe ẹka to n pese ina ọba, eto irinna oju irin ati eto ẹkọ alakọbẹrẹ ati ipese ilera alabọde ninu eto isuna naa.
Oríṣun àwòrán, Femi Adesina
Bi alakalẹ eto isuna fun ọdun 2021 yoo ṣe lọ niyii:
Aya mi, dáríjìn mí fún bí n kò ṣe fi ìfẹ́ hàn tó sí ọ bó ṣe yẹ - Mike Bamiloye
Ìdí tí Gúúsù Akure, Owo àti ìwọ̀orun Ondo yóò fi sọ ẹni tí yóò jáwé olúborí nínú ìbò gómìnà Ondo
Kẹ̀rẹ̀ kẹ̀rẹ̀ Okonjo-Iweala ń súnmọ́ ipò olórí WTO bọ̀
Bode George ní Fayose gọ̀, ó fẹnu họra, Fayose ní ''ẹ ò lè pa mí bí ẹ ṣe pa Bola Ige
Ènìyàn 5, ilé 25 ilé ìtajà 16 àti àwọn ǹkan mírà lo bá ìṣẹ̀lẹ̀ iná náà rìn.
Ọkùnrin kọ́ ló ra jeep fún Iyabo Ojo, òógùn ojú mi ni mo fi rà á fun
Kanu Ejike fipá bá ọmọ ọdún méje lò pọ̀ nínú sọ́ọ̀bù ìyàwó rẹ̀
Oríṣun àwòrán, Nigeria Presidency
Aarẹ orilẹede Naijira, Muhammadu Buhari ti gbe aba isuna oni triliọnu mẹtala naira (₦13.08trn) kalẹ sile asofin apapọ ilẹ fun ọdun 2021,
Aba isuna naa lo fi triliọnu meji o le diẹ (₦2.2trn) pọ ju ti ọdun to kọja lọ, eyi to din diẹ ni triliọnu mskanla naira (₦10.805).
Nigba to n gbe aba isuna naa ka iwaju ile, aarẹ Buhari ni ipenija nla to n koju ijọba oun bayii ni ọna lati ri owo gbọ bukata eto isuna naa.
O fikun pe awọn minisita oun yoo bẹrẹ si ni tọpinpin bi wsn se n gba owo ori wọle lati ri daju pe ohun gbogbo n sisẹ bo se yẹ.
Oríṣun àwòrán, Nigeria Presidency
Owo isuna ọdun to n bọ naa ni wọn gbe le pasipaarọ owo naira ilẹ wa si Dọla tilẹ Amẹrika, eyi tii se naira ọrinlelọọdunrun o din kan (₦379) si dọla kan.
Owo agba epo to wa ni ogoji dọla si ni wọn gbe isuna naa le, ti ireti si wa pe wọn yoo ri owo to din diẹ ni miliọnu meji dọla ($1.86m) lojumọ.
Awọn ohun to sẹlẹ niwaju ile lasiko to aarẹ n gbe aba isuna kalẹ:
Deede aago mọkanla aarọ ọjọbọ ni aarẹ bẹrẹ kika eto isuna naa niwaju awọn asofin apapọ ilẹ wa.
Ondo Elections 2020: Ọgọ́rùn-ún ọdún tí a máa lò lórí oyè l'Ondo, ẹ ó rí àrà - Ojon YPP
Ọpọ awọn osisẹ agbofinro si la gbọ pe wọn peju wamu wamu sile asofin apapọ naa, ti aarẹ Buhari ti n gbe aba isuna naa kalẹ.
Saaju ni alaga igbimọ ile to wa feto isuna nile asofin agba ilẹ wa, Sẹnetọ Barau Jibril ti kede pe ilana gbigbe aba isuna tọdun yioi kalẹ yoo yatọ si ti tẹlẹ nitori arun coronavirus to gbode kan.
Gẹgẹ bo se wi, awọn yoo tẹle ilana to dena arun Coronavirus naa, ti adinku yoo si ba iye eeyan ti yoo tẹle aarẹ wa sile asofin apapọ, ki ile maa baa kun akunju.
SS3 ní mo wà báyìí, mo sì ti gba àmì ẹ̀yẹ̀ púpò nílé-lóko gẹ́gẹ́ bí onílù - Ayansike
Bisola Ajayi: Àwọn ọlọ́pàá dóòlà agbẹjọ́rò tí wọ́n jígbé ní Port Harcourt
Bisola Ajayi lẹyin ti awọn ọlọpaa doola rẹ.
Ẹka ileeṣẹ ọlọpaa to n gbogun ti ijinigbe nipinlẹ Rivers, ti doola agbẹjọro, ẹni ọdun mẹẹdọgbọn kan, Bisola Ajayi lọwọ awọn ajinigbe.
Ọjọ Aiku to kọja ni iroyin jade sori ayelujara pe, awọn ajinigbe ti gbe agbẹjọro obinrin kan, Bisola Ajayi, nipinlẹ Rivers.
Ile rẹ to wa ni agbegbe Rumuokwurusi, nijọba ibilẹ Obio-Akpor, nilu Port Harcourt ni wọn ti ji i gbe lọjọ kẹrin, oṣu Kẹwaa, ọdun 2020.
Kọmisanna ọlọpaa ni Rivers, Joseph Mukan, sọ fun awọn akọroyin pe oru Ọjọru, ọjọ keje, oṣu Kẹwaa, ni awọn ọlọpaa yabo igbo kan ni Okomoko, Etche, ti ko ju irinajo iṣẹju mọkandinlọgbọn lọ si papakọ ofurufu ilu Port Harcourt.
Ìdájọ́ òdòdò ló fẹsẹ̀ múlẹ̀ lórí ọ̀rọ̀ Pásítọ̀ Sotitobire - Agbẹjọ́rò fún ìjọba
Nibẹ ni wọn ti doola Bisola, ati ọkunrin kan, Paul Nyulaku.
Nyulaku ni wọn kọkọ jigbe lọjọ naa, ki wọn to fi ọkọ ayọkẹlẹ rẹ, gbe Bisola.
Nigba to n ba awọn akọroyin sọrọ lẹyin ti awọn ọlọpaa doola rẹ, Bisola sọ pe iwaju ẹbi rẹ ni wọn ti gbe e, ti wọn si gbe e lọ si ibi ti oun ko mọ.
Wọn sọ fun un pe awọn ti pa gbogbo ẹbi rẹ, ti wọn si beere fun aadọta miliọnu Naira, owo itusilẹ rẹ. Ṣugbọn nigba ti yoo fi di ọjọ keji, wọn ti sọ ọ di miliọnu lọna igba Naira.
Oríṣun àwòrán, Bisola Ajayi
Bisola sọ pe oun dupẹ lọwọ Ọlọrun pe awọn ọlọpaa tete doola oun, nitori pe wọn ti pinnu lati pa a nigba ti iroyin ijinigbe rẹ ti n tan kiri.
Ẹnikeji ti awọn ọlọpaa doola, Nyulaku, ni awọn ajinigbe naa kọkọ gbe ni nkan bi aago mẹfa irọlẹ ọjọ Aiku, ọjọ kẹrin, oṣu Kẹwa.
Nibi to ti lọ fun ọrẹ rẹ kan ni nkan, ni awọn ọkunrin kan to wọ aṣọ ọmọ ologun ti dena de e.
"Wọn sọ fun mi pe ọlọpaa ni awọn, ki wọn o to fi ipa wọ inu ọkọ mi. Wọn fun mi mọlẹ. Bi mo ṣe n gbiyanju lati gba ara mi silẹ, ni awọn fi ibọn gba mi, ti ara mi si n sẹjẹ.
Wọn lu mi pupọ, titi mo fi ṣe bi ẹni pe mo ti daku. Nigba naa ni wọn to o gbe mi lọ si ibi ti mi o mọ."""
Nyulaku sọ pe ogun milọnu Naira ni wọn beere fun lọwọ oun, ti wọn si n finna mọ ko le tete sọ fun mọlẹbi rẹ lati san owo naa.
Paul Nyulaku lẹyin ti awọn ọlọpaa doola rẹ.
Kọmisanna ọlọpaa ipinlẹ rivers, Mukan sọ pe ọkan lara awọn ajinigbe naa, Chinedu Chigbu, ẹni ọdun mọkandinlogoji, fi ara pa lasiko ti awọn ọlọpaa doju ija kọ wọn. Wọn gbe e lọ sile iwosan, amọ o pada ku.
Awọn ajinigbe to ku sa wọ inu igbo, amọ awọn ọlọpaa ba ibuba wọn jẹ, wọn si tun ko ibọn aK-47 kan, ibọn magasinni kan, ati ọgọrun ọta ibọn.
Gracious David-West, afurasí tó fẹ̀mí ọ̀dọ́bìnrin mẹ́sàn án ṣòfò nílé ìtura PortHarcourt gbàdájọ́ ikú lónìí
Ti irọ ba lọ logun ọdun, awọn Yoruba ni ọjọ kan ṣoṣo lotitọ yoo ba a.
Iroyin taa gbọ́ ni wipe ile ẹjọ ilu PortHarcourt ti dajọ iku nipa yiyẹgi fun afurasi apaayan, Gracious David West ti wọn ni o n pa awọn obinrin kaakiri ilu PortHacourt ti ọwọ si tẹ ni nkan bii oṣu melo sẹyin.
Ẹsun ipaniyan ọdọbínrin mẹsan an kaakiri awọn ile itura niluu Port Harcourt ni wọn fi kan David-West ti adajọ to da ẹjọ rẹ, Adolphus Enebeli ṣe fi lede.
Afurasi mii ti orukọ rẹ n jẹ Nimi Thankgod, oun naa  gba idajọ lori ẹsun pe o tabuku oku eeyan.
Igbẹjọ naa ti n lọ fun bi ọdun kan lẹyin tawọn eeyan bẹrẹ si ni ri oku awọn ọdọbinrin kaakiri ile itura niluu Portharcourt, ọna kan naa si ni gbogbo wọn n gba ku.
Awọn ọdọbínrin mẹsan an ti afurasi David-West ṣekupa niyii:
1. Maureen Ewuru l'ọgbọnjọ oṣu keje, 2019 nile itura Hotel D/Line.
2. Wọn ri oku Jennifer Nkwocha ni Venice Hotel GRA Phase 2, Port Harcourt lọjọ kẹrinla oṣu kẹjọ ọdun 2019.
3. Ni Toki Hotel Port Harcourt wọn ti ri oku Blessing Effiong.
4. Linda Waripa ku si Avery Guest House, Oyigbo lọjọ kẹfa oṣu kẹsan an, 2019 ni Port Harcourt.
5. Dorcas Francis ni wọn rí oku tiẹ ni Imperial Hotel Trans Amadi, Port Harcourt lọjọ kẹsan an oṣu kẹsan an ọdun 2019.
6. Wọn ri oku Rose Samuel ni Lasus Steve Hotel ni Omoku lọjọ kejila oṣu kẹsan an ọdun 2019.
7. Kelechi Bridget Onuoha ku si Pachik Hotel lọjọ kẹtala oṣu kẹsan an ọdun 2019.
8. Lọjọ kejidinlogun oṣu kẹsan an ọdun 2019 ni won ri oku Patience Hamo ni Torox Guest House ni Port Harcourt.
9. Anthonia Ibe ku si TM Hotel Wimpey Port Harcourt.
Benita Etim nikan lo mori bọ.
Ọga ọlọpaa ipinlẹ Rivers lasiko naa, Dandaura ṣalaye pe yatọ si awọn obinrin mẹsan an yii, David-West tun jẹwọ pe oun tun ṣekupa obinrin kan niluu Eko, ọkan ni Owerri, omiran ni Sapele, ọkan ni ilu Aba, ọkan ni Benin ati ọkan ni ilu Ibadan.
Pẹlu mẹsan an niluu Port Harcourt, obinrin mẹẹdogun lo jẹ lapapọ ti afurasi naa sọ dero ọrun alakeji.
''Ẹ gbudọ̀ ṣe àwọn ǹkan wọ̀nyí lọ́jọ́ ìdìbò gómìnà l'Ondo bí bẹ́ẹ̀ kọ́ ...'
Ondo State Election result 2020: Bí èsì ìdìbò gómìnà ìpínlẹ̀ Ondo ṣe ń jáde rèé..
Lẹ́yìn tí àwọn ènìyàn ìpínlẹ̀ Ondo dìbò tàn; èsì ìdìbò ti ń jáde báyìí...
Ni ibudo idibo ti wọ́n ti kọ
Ẹ̀yin ti Ondo, èsì ẹgbẹ́ òṣèlú rèé
EndSARS Ogbomosho: Gómìnà Makinde f'òkò kan pẹyẹ méjì nílé àwọn tó kàgbákò ìwọ́de EndSARS àti ààfin Soun
Oríṣun àwòrán, Seyi Makinde
Loju opo Twitter gomina Seyi Makinde, o jẹ ko di mimọ pe oun ti ṣe ibẹwo si idile mẹta ti awọn ọdọ mẹta ti ṣalabapade iku nitori iwọde EndSARS.
A bẹrẹ igbesẹ yii nipa ṣiṣe moriya fun awọn idile naa fun adanu wọn a si tun ṣeleri lati ṣe ju bẹẹ lọ fun wọn.
"A ba gbogbo awọ́n to padanu eeyan lasiko iwde EndSARS kẹdun. Gẹgẹ bi ijọba, ako ni sare gbagbe ohun to ṣẹlẹ lẹnu ọjọ diẹ sẹyin yii to ja si iku Isiaka Jimoh, Ganiyu Moshood ati Adeoye Taiwo.
Bakan naa, gomina fidi ọrọ mulẹ pe oun ti ṣe ibẹwo si aafin Soun ti Ogbomoso to si ni oun ti jẹjẹ lati fun Kabiyesi ni Ọgrun miliọnu naira lati bẹrẹ atunṣe gbogbo nkan to bajẹ lasiko ti awọn olufẹhonuhan yabo aafin.
Oríṣun àwòrán, Seyi Makinde
Lẹyin ọjọ meji ti awọn ọdọ ilu Ogbomoso yabo aafin lati lọ fẹhonuhan, a gbọ iroyin pe gomina ipinlẹ Oyo, Seyi Makinde ti ṣebẹwo si aafin Soun.
Iroyin to n tan kalẹ kan ṣugbọn ti a ko tii le fidi rẹ mulẹ tun sọ pe gomina Makinde paṣẹ lọgan pe ki wọn fun Soun ti Ogbomoso, Oba Jimoh Oyewumi ni Ọgọrun miliọnu naira lati tun aafin ṣe nibi ti awọn olufẹhonuhan EndSARS ti ba ọpọlọpọ nkan jẹ ni ọjọ Aiku ọjọ kọkanla oṣu kẹwa ọdun 2020.
Nigba ti BBC Yoruba kan si agbẹnusọ aafin Soun Ogbomoso, Toyin Ajamu sọ pe lootọ ni gomina ti ṣabẹwo si aafin ni nkan bii aago mọkanla owurọ si mejila lati wa ba wọn kẹdun iṣẹlẹ to ṣẹlẹ.
Lori ọrọ pe boya gomina Seyi Makinde fun Kabiyesi ni ẹbun owo ọgọrun miliọnu naira, Toyin Ajamu ni oun ko le sọ boya wọn fun Kabiyesi ni owo tori ko ṣe oju oun.
Mi o mọ nipa iyẹn. Gẹgẹ bi alakoso ipinlẹ Oyo, ohun gbogbo to ba bajẹ o (gomina) ni lati ni atunṣe si i, boya o wa ran eeyan lati ri Kabiyesi ni kọrọ lati ṣe iyẹn, mi o le sọ""."
Ọgbẹni Toyin to jẹ akọwe Kabiyesi ni Kabiyesi fi ọrọ sita lati rọ awọn ọdọ ki wọn ma ṣe jagidijagan tori gẹgẹ bi gomina ṣe s pe ainiṣẹ lo n fa ọpọlọpọ nkan bayii torinaa Kabiyesi rọ gomina lati pese iṣẹ fun awọn ti ko niṣẹ lọwọ.
Ifẹhonuhan wa lab ofin ṣugbọn ki eeyan ṣe e ni alafia ni nkan to tọ.
"O fi kun un pe ikọlu ti awọn ọdọ ṣe si aafin jẹ ohun to dun ni gan o si jẹ nkan iyalẹnu ṣugbọn ibinu o ṣe nkankan tori pe atawọn ọmọ to ba nkan jẹ, ati gbogbo ọmọ Ogbomoso, ọmọ Kabiyesi ni gbogbo wọn""."
Gbogbo igbiyanju lati gbọ latẹnu ọfiisi gomina Seyi Makinde lori ọrọ owo naa titi di bi a ṣe n sọrọ yii ko tii so eso rere.
Ọlọ́pàá méjì dèrò ọ̀run nínú ìjàmbá ọkọ̀ l'Akure lẹ́yìn tí wọ́n kúrò níbi tí Akeredolu ti gba ìwé-ẹ̀ri moyege
Alaafia ti pada si aafin Ṣọun Ogbomọṣọ, koda aafin ni gbogbo wa sun mọju.
Eyi ni esi ti Agbẹnusọ fun Sọun Ogbomọṣọ, Ọgbẹni Toyin Ajamu lasiko to n ba BBC Yoruba sọrọ lori rogbodiyan to wa ye ni aafin naa lọjọ Aiku.
O ṣalaye pe alaafia ni aafin wa ki awọn ọdọ naa to yawọ aafin.
"Wọn ti bẹrẹ idarudapọ laarin ilu tẹlẹ, emi ati awọn oloye si lọ sibẹ lati pẹtu si wọn ninu l'orukọ kabiesi, amọ wọn ko ti ẹ jẹ ki a sọrọ.
Niṣe ni wọn n ju okuta si agọ ọlọpaa."
O ni ohun to mu awọn lọ sibi ti wọn ti n fa wahala ni pe lọ ni pe awọn ọlọpaa n pariwo si aafin lati wa a ba awọn ọdọ naa sọrọ gẹgẹ bi ọmọ ilu, nitori wọn n gbiyanju lati dana sun agọ ọlọpaa ni.
Ṣugbọn, gbogbo igbiyanju wa lati da wọn lẹkun, to fi mọ awọn ikede ti a ṣe lori rẹdio, ni ko wọ wọn leti.
Abayọmi Aranmọlatẹ, Dr Laser: Vagino Plasty àti iṣẹ́ abẹ ẹwà Obìnrin ló jẹ mí lógún
Agbenusọ Sọun fi kun un pe ko ti i ju iṣẹju mẹwaa ti wọn bẹrẹ ipade pẹlu minisita fun ọrọ ọdọ, Sunday Dare, to wa ba ẹbi ọmọkunrin ti ibọn ba lọjọ Satide, Jimoh Isiaka kẹdun, ti awọn ọdọ naa fi kọlu aafin, ti wọn si bẹrẹ si ni ju okuta sinu aafin.
O ni wọn ba nkan to pọ jẹ ni aafin.
Oríṣun àwòrán, Twitter/Bdayo90
Lori iroyin to n lọ pe eeyan bi mẹjọ ni ọlọpaa fi ibọn pa, Ọgbẹni Ajamu sọ pe wọn o pa ẹnikẹni ninu aafin, ati pe oku ti awọn ọdọ naa gbe wa si aafin ni awọn ọlọpaa n wọ jade pada ninu fidio kan to wa lori ayelujara.
"Eeyan meji si lo ku, kii ṣe mẹjọ tabi mẹwaa ti wọn n pariwo.
O ṣeeṣe ko jẹ aṣita ibọn lo ba awọn to ku, nitori pe awọn ọmọ kekere ti ọjọ ori wọn wa laarin ọdun mẹwaa si mẹẹdogun ni ibọn ba."
SS3 ní mo wà báyìí, mo sì ti gba àmì ẹ̀yẹ̀ púpò nílé-lóko gẹ́gẹ́ bí onílù - Ayansike
Boya ibi ti wọn ti n woran ija laarin awọn ọlọpaa ati awọn to n ṣe iwọde ni ibọn ti ba wọn.
Ẹni ori yọ ipade di ile ni ọrọ da nilu Ogbomosho nibi ti awọn ọdọ kan ti yabo aafin Soun Ogbomoso.
Lọwọlọwọ bo ṣe n kan wa lara ni pe awọn kan ti yabo aafin Soun Ogbomoso, Oba Oladunni Oyewumi Ajagungbade kẹta ti wọn si ti ba ọpọ dukia jẹ.
Iroyin sọ pe ṣe ni wọn kọkọ ṣe ikọlu si agọ ọlọpaa kan ni tosii aafin Soun ki wọn to raaye wọle si wọn lara.
BBC Yoruba kan si akọwe aafin Soun Ogbomoso, Arakunrin Totin to si  jẹ ko di mimọ pe ẹni ori yọ o dile ni tori awọn n sa asala fun ẹmi awọn.
Bakan naa ni Minisita fun ọrọ awọn ọdọ Naijiria, Sunday Dare, to wa laafin Soun lasiko iṣẹlẹ yi fi han pe tootọ ni  iṣẹlẹ yi waye.
Oríṣun àwòrán, Twitter/@afobaje1000
Loju opo Twitter Sunday Dare to jẹ ọmọ bibi Ogbomoṣo, ni awọn janduku ya bo aafin Soun ti wọn si da ipade igbimọ ilu tawọn n ṣe lọwọ, ru.
O ni bi wọn ṣe n sọ oko ni wọn n fọ ilẹkun ati gilaasi ninu aafin naa.
Gẹgẹ bi a ti ṣe gbọ awọn ọdọ ti kọkọ ṣe iwọde lọ si aafin naa lati fẹhonu han lori iku Isiaq Jimoh ti wọn yinbọn pa nibi iwọde ENDSARS lọjọ Abamẹta.
Oríṣun àwòrán, Twitter/@IsaacIfeoluwa9
Nigba ti awọn ọdọ yi de aafin, wọn ko ba nkan jẹ ṣugbọn ko pẹ si igba ti wọn kuro lawọn janduku kan yabo aafin lasiko ti Minsisita ati Soun n ṣe ipade.
Bo tilẹ jẹ pe a ko le sọ boya ẹnikẹni farapa nibi rogbodiyan naa, awọn iroyin ati aworan, ati fidio to wa lori ayelujara n sọ pe awọn kan ku.
Oríṣun àwòrán, Twitter/Bdayo90
Gomina Seyi Makinde to n tukọ ipinlẹ Oyo ti kẹdun iku ọmọdekunrin ti wọn yinbọn lu lasiko iwọde ENDSARS to waye nilu Ogbomoso.
Makinde ni Jimoh Isiaq pada ku lẹyin ti wọn gbe e lọ si ile iwosan fasiti Bowen University ni Ogbomosho.
Oríṣun àwòrán, Twitter/Seyi Makinde
Yatọ si Jimoh, Makinde tun ba awọn mọlẹbi Abdulrasaq Olawale, Oluwadamilare Gbohunmi ati awọn marun un mii ti wọn farapa kẹdun.
O ni awọn wọnyi n gba itọju lọwọ ni ile iwosan .
Igba akọkọ ree ti ẹnikankan labẹ ijọba yoo gba pe ibọn ba Jimoh Isiaq.
O ni iṣẹlẹ yi jẹ eyi ti ko yẹ ko waye ati pe oun ti kan si Kọmiṣọnna ọlọpaa ipinlẹ Oyo lati tọ pinpin ohun to fa iṣẹlẹ yi.
Ṣaaju ni ileeṣẹ ọlọpaa ipinlẹ Oyo sọ fun BBC pe awọn ko yin ibọn lu awọn oluwọde ati wi pe afẹfẹ gaasi tajutaju lasan ni awọn yin lu awọn to yabo agọ ọlọpaa
Makinde ni iwọde ENDSARS ṣafihan bi nkan ko ṣe rọgbọ lawujọ mọ to si tun ni o mu ki eeyan maa ṣeemọ bi agbara ko ti ṣe si lọdọ Gomina ti wọn pe ni alaṣẹ ijọba ipinlẹ.
Ni bayi o ti wa pinnu lati kan si awọn mọlẹbi ọmọdekunrin ti wọn yinbọn pa yi to si ni oun yoo ri i pe iwadii ọfintoto waye lori awọn to mọ nipa iku rẹ.
Nínú ọ̀rọ̀ rẹ̀, agbẹjọrò tó wà lórí ọ̀rọ̀ yìí, Hussein Afolabi nígbà tó bá BBC Yoruba sọ̀rọ̀ sàlàyé pé, ilé iṣẹ́ ọlọ́pàá ìpínlẹ̀ Oyo sọ pé àwọn kò yin ìbọn tàbi tajútaju fún àwọn olùwọ́de.
Agbẹ́jọrò náà ní gẹ́gẹ́ bi àgbẹnusọ ọlọ́pàá ìpińlẹ̀ Ipinlẹ Oyo ni, Olugbega Fadeyi ṣe sọ, ó ni area Commander ti òun pè sàlàyé pé, kìí ṣe ọlọ́pàá ló yìn ìbọ̀n nílú Ogbomosho.
O ní: ìyàlẹ́nu ló jẹ́ pé agbẹnusọ ọlọ́pàá padà sọ fún àwọn akọròyìn pé, wọ́n yin tájútaju sí wọ́n, èyí túmọ̀ sí pé ǹkankan wà níbl tí wọ́n kò sọ.
Níbayìí Afolabi ni ǹkan ẹyọ kan ti àwọn ń bèrè fún ni pé kí ilé iṣẹ́ ọlọ́pàá mú ẹni tó ṣe irú iṣẹ́ ibi náà jáde
Hussein Afolabi ní kìí ṣe Isiaq nìkan ko ni ọlọ́pàá yìn níbọ̀n, àwọn méjì míràn wà ní ilé ìwòsàn níbi ti wọ́n ti n gba ìtọ́jú
Ó fi kun un pé gbogbo ìgbésẹ̀ tó yẹ ni ò ń gbé lọ́wọ́ láti túṣu désàlẹ̀ ìkòkò ọ̀rọ̀ náà.
Hussein ni ṣe ariwo ti awọn eeyna n pa naa kọ ni yii lasiko yii.
O fi idaniloju han pe gbogbo iwadii to yẹ ni wọn yoo ṣe bayii.
Oríṣun àwòrán, Twitter/iam_wandeyinka
Ogbomosho Shooting: Irọ́ ni pé a yìnbọ̀n lú olùwọ́de EndSars - Ọlọ́páà
Oju opo Twitter n gbana jẹ lori iroyin to gbode pe awọn ọlọpaa yinbọn lu arakunrin oluwọde kan lọjọ Abamẹta.
Iroyin naa jẹ eyi to ti mu iriwisi orisirisi wa latari fọnran fidio arakunrin kan tawọn oluwọde n gbe digba digba pẹlu ẹjẹ lara rẹ.
BBC ko ribi fidi otitọ fọnran fidio yii mulẹ ṣugbọn iroyin to tẹwa lọwọ lọdọ awọn to wa ni Ogbomosho ni ikọlu waye laarin awọn oluwọde ati ọlọpaa.
Ẹri ti a gbọ wi pe ikọlu waye ni eyi to han ninu fidio kan ti gbajumọ ori ayelujara Lekan King Kong fi sita nibi ti awọn oluwọde ti n figbe ta pe ọlọpaa n yinbọn lu awọn.
Iwọde naa jẹ ọkan lara awọn eleyi to n waye jakejado Naijiria lati fi pe fun iwọgile ikọ ọlọpaa FSARS ti ara ilu ni wọn dẹgun le awọn pupọ.
Nigba ti BBC Yoruba pe ago alukoro ọlọpaa ipinlẹ Oyo Fadeyi Olugbenga lati fi mọ nkan to n ṣẹlẹ gaan,  o ni ko si ohun to jọ bẹ.
Oríṣun àwòrán, Twitter/tonaishere
''A kan tu awọn oluwọde ka nigba ti wọn fẹ yabo ileeṣẹ ọlọpaa ni  Ogbomosho ni. A ko yinbọn bẹ si ni ko si ẹni ti ibọn ba tabi to ku''
Fadeyi ṣalaye siwaju pe awọn oluwọde naa fẹ fipa bori awọn ọlọpaa ni ṣugbọn awọn ko gba fun wọn.
O ni lọwọ bayi, alafiaa ti pada si ilu Ogbomosho.
Ondo State Election result 2020: INEC kéde èsì ìbò gómìnà níjọba ìbílẹ̀ méjìlá
Oríṣun àwòrán, @R_Akeredolu
Ajọ eleto idibo nilẹ wa, INEC, ti bẹrẹ ikede esi ibo gomina nipinlẹ Ondo bẹrẹ lati oru ọjọ Satide si Aiku.
Ibo kika naa, to bẹrẹ ni bii aago mejila aabọ loru ọjọ Aiku, ni alamojuto eto idibo gomina ni ipinlẹ Ondo, Ọjọgbọn Idowu Olayinka, tii se ọga agba fasiti Ibadan, ṣide rẹ.
Nigba to n ki awọn alẹnulọrọ ninu eto idibo naa kaabọ, Ọjọgbọn Olayinka ti ka esi idibo ijọba ibilẹ mẹẹdogun ninu mejidinlogun to wa ni ipinlẹ Ondo.
Awọn ijọba ibilẹ ti wọn kọkọ fi fi bẹrẹ naa ni Ifedore, Ile oluji/oke igbo, Irele ati Akoko North West.
Titi di asiko yii eyitayo Jegede ni meta nigba ti Akeredolu Rotimi ni mejila ninu ijọba ibilẹ mẹẹdogun ti wọn ti ka
Ṣaaju, ninu ọrọ ikinni kaabọ rẹ, Kọmiṣọnna fajọ eleto idibo nipinlẹ Ondo, Oluwatoyin Akeju dupẹ lọwọ gbogbo awọn eeyan to wa nikalẹ fun atilẹyin wọn, lati ri daju pe eto idibo naa kẹsẹ jari.
Alakoso apapọ fajọ eleto idibo to n bojuto ipinlẹ Ondo, Ọmọwe Ademola Ogunmola ninu ọrọ tiẹ, wa gboriyin fawọn oludibo, fun bi wọn se jẹ ki ileri ajọ INEC, lati se aseyọri kọja ohun to waye nipinlẹ Edo, di mimusẹ.
Ni kete ti eto kika naa bẹrẹ si ni awọn ijọba ibilẹ miran n wọle, yatọ si ti mẹrin to wa nilẹ saaju.
Nigba ti yoo si fi di aago meji aabọ oru, ajọ INEC ti kede esi ibo nijọba ibilẹ mejila ninu mejidinlogun to wa nipinlẹ Ondo.
Awọn ijọba ibilẹ ti wọn kede naa ni Irele, Ile Oluji, Ondo East, Owo, Akoko North East, Akoko South West, Idanre, Akoko North West, Akure North, Akoko South East and Akure South.
Awn ijọba ibilẹ mẹfa yoku ti wọn ko tii kede ni Ondo West, Odigbo, Okitipupa, Ilaje, Ese Odo ati Ondo West.
Ninu awọn esi ibo ti wọn kede naa, ijọba ibilẹ mẹta pere ni ẹgbẹ oselu PDP ti moke, nigba ti ẹgbẹ oselu APC jawe olubori nijọba ibilẹ mẹsan.
Awọn ijọba ibilẹ ti PDP ti moke ni ijọba ibilẹ Ifedore, Akure North ati Akure South.
Awọn ijọba ibilẹ ti APC ti moke ninu mẹsan to ti jawe olubori bayii ni, Akoko North West, Akoko North East, Akoko South East ati Akoko South West.
Oríṣun àwòrán, @AAjayiAgboola
Awọn yoku ni le Oluji/Okeigbo, Owo, Idanre ati Ondo East.
Deede aago meji oru ni ajọ INEC kede pe oun fẹ lọ rẹju diẹ naa lati sinmi, ti oun yoo si pada ni aago mẹsan owurọ ọjọ Aiku, lati kede awọn esi ibo to ku lawọn ijọba ibilẹ mẹfa.
SS3 ní mo wà báyìí, mo sì ti gba àmì ẹ̀yẹ̀ púpò nílé-lóko gẹ́gẹ́ bí onílù - Ayansike
Coronavirus prevention badge update: Wo òótọ́ àti irọ́ tó wà nínú báàjì àyà náà
Awọn eeyan to lagbara pọ to n wọ baaji naa nitori pe wọn ko fẹ ni coronavirus.
Jeane Anez to jẹ aare fidihẹ orilẹ-ede Bolivia, Senatọ Dino Melaye, Ọmọọba Uche Secondus àti Dimtry Reskov to jẹ agbẹnusọ aarẹ Russia wa lara awọn oloselu ti wọn ti wọ baaji aya yii.
Wọn gbagbọ pe o n dena itankalẹ ajakalẹ arun Covid 19 ni wọn ṣe n wọ ọ.
Bẹẹ awọn akọṣẹmọṣẹ ni iro to jina si ootọ ni pe baaji naa  n dena ajakalẹ arun coronavirus.
Koda, wọn ni o le fa nkan miran si agọ ara ẹni to wọọ.
Wo ẹkunrẹrẹ abọ iwadii naa lori fidio yii.
EndSars protests: Fọ́tò àti ìtàn èèyàn tí ikú wọ́n ní ọ́wọ́ ọlọ́pàá Nàìjíría nínú
Oríṣun àwòrán, Ori ayelujara
Iwọde ẹ fi opin si ọlọpaa Sars #ENDSARS, to wọ ọjọ kẹrin bayii, o ti bẹrẹ lati Ọjọbọ, ọjọ kẹjọ, oṣu Kẹwa, ọdun 2020, kaakiri Naijiria.
Eyi kọ ni igba akọkọ ti awọn ọmọ orilẹ-ede Naijiria ti n polongo, beere fun idajọ lori iku awọn araalu to jẹ alaiṣẹ, amọ ti ileeṣẹ ọlọpaa pa.
Awọn ọdọ ti ṣe iwọde ni awọn asiko kan lati fi aidunnu wọn han si iwa ifiyajẹni ti awọn ọlọpaa ma n hu, ti wọn si n polongo fun fifi opin si ẹka ọlọpaa SARS.
Iwọde to n waye lasiko yii kii ṣe laarin ilu nikan, wọn gbe iwọde naa de ori ayelujara pẹlu ami idanimọ #ENDSARS. Eyi si ti mu ki ọrọ naa de akiyesi ọpọ ilumọọka ni Naijiria ati ilẹ okeere.
Koda, awọn ọmọ ilẹ okeere kan, ati awọn ọmọ Naijiria to n gbe nibẹ ti darapọ mọ iwọde naa.
Oríṣun àwòrán, Twitter
Ọjọ kẹwaa, oṣu Kẹwa, ọdun 2020 ni ibọn ba Jimoh Isiaka, lasiko iwọde #ENDSARS to waye nilu Ogbomọṣọ, nipinlẹ Oyo.
Ṣugbọn ileeṣẹ ọlọpaa sọ pe awọn kọ lo yinbọn mọ ọdọmọkunrin naa.
Iku rẹ fa awuyewuye lori ayelujara, ti ọpọ eeyan si n sọ pe ko tọ ọ bi awọn ọlọpaa tun ṣe yinbn paayan lasiko ti iwọde n waye tako wọn.
Oríṣun àwòrán, AFP
Igbakeji Balogun ẹgbẹ agbabọọlu Remo Stars ni Kazeem Tiamiyu, ko to o kagbako iku ojiji nilu Sagamu, nipinlẹ Ogun.
Ẹgbẹ agbabọọlu rẹ fi ikede sita pe awọn ọlọpaa SARS kan fi ẹsun jijẹ onijibi kan Kazeem, koda lẹyin to fi kaadi idanimọ rẹ han wọn.
'Mo fẹ́ ìdájọ́ òtítọ́ àti òdodo lóríi ikú àìmọ̀dí tí wọ́n fi pa ọmọ mi'
Lasiko ti wọn jọ n ṣe ariyanjiyan yii ni wọn ti i jabọ ninu ọkọ wọn, ti ọkọ miran si gba.
Ẹni ọdun mọkanlelogun ni nigba to ku l'oṣu Keji, ọdun 2020.
Oríṣun àwòrán, OWOROTV
Ọjọbọ, ọjọ kejidinlọgbọn, oṣu Karun un, ọdun 2020 ni Tina Ezekwe ku, lẹyin ọjọ diẹ ti ọlọpaa kan ti wọn sọ pe o mu ọti yo.
Lo ba yinbọn mọ ọ lasiko to n gbiyanju lati mu awakọ kan to ru ofin isede coronavirus nilu Eko.
#JusticeforTina: Àwọn obi Tina Ezekwe ń bèrè fún ìdájọ́ òdodo pẹ̀lú omijé lójú
Iku Tina mu ki awọn eeyan faray pupọ, ti wsn si fi #JusticeforTina beere fun idajọ lori iku rẹ, lori ayelujara.
Oríṣun àwòrán, FACEBOOK/CHIBUIKE DANIEL IKEAGUCHI
Ẹni ogun ọdun ni Chibuike Daniel nigba to ku.
Akọrin ni, ti awọn eeyan mọ orukọ inagijẹ rẹ si 'Sleek'. Koda, o sṣe idanwo aṣewọle sileewe giga ni Naijiria, JAMB l'ọdun 2020.
Ẹgbọn rẹ, Maureen Ikeaguchi, to ba BBC Pidgin sọrọ, sọ pe lọjọ kọkandinlogun, oṣu Kẹsan, ọdun 2020, ti isẹlẹ naa waye, Sleek lọ ṣe abẹwo si ọrẹ rẹ kan ni adugbo Elelenwo, nijọba ibilẹ Obio Akpor, nipinlẹ Rivers.
Wọn ri awọn ọlọpaa ẹka to n risi ijinigbe, amọ wọn ro pe awọn ọlọpaa SARS ni. Bi wsn ṣe n gbiyanju lati salọ kuro nibẹ, ni ọkan lara awọn ọlọpaa naa yinbọn mọ aburo rẹ, to si yọri si iku fun.
Oríṣun àwòrán, KOLADE JOHNSON/FACEBOOK
Adugbo Onipetesi, nilu Eko, ni ibọn ti ba Kolade Johnson, ni ọjọ kọkanlelọgbọn, oṣu Kẹta, ọdun 2019.
Ibọn ti awọn ọlọpaa ẹka to n gbogun ti ẹgbẹ okunkun yi lo ba Kolade, ni ibudo kan ti wọn ti n wo ere bọọlu.
Iku tiẹ naa fa ariwo lori ayelujara.
Oríṣun àwòrán, Others
Ọjọ kẹrin, oṣu Kejila, ọdun 2019, ni ọjọ ti oko ibanujẹ wọ inu ẹbi Sammani Zangon Marikita, nilu Kno.
Ibọn ọlọpaa naa lo sọ ọmọkunrin naa di eero ọrun lọsan gangan.
Oríṣun àwòrán, FACEBOOK/CHIMA IKWUNADO
Gẹgẹ bi ohun ti baba rẹ sọ fun BBC, ẹni ọdun mejilelọgọrun ni Musáb, to si jẹ pe oṣu mẹrin ṣaaju iku rẹ lo pada si orilẹ-ede Naijiria, lati India to ti lọ kẹkọọ nipa imọ kọmputa.
Awọn ti iṣẹlẹ iku rẹ ṣoju sọ fun BBC Pidgin pe ọlọpaa kan to n ṣọ banki lo yinbọn mọ ọmọkunrin naa nitori ede aiyede to n waye laarin oun ati awakọ kẹkẹ kan to kọlu ọkọ ayọkẹlẹ rẹ.
coronavirus prevention badge update: Wo òótọ́ àti irọ́ tó wà nínú báàjì àyà náà
Ẹsun idigunjale ni awọn ọlọpaa mu Chima fun, nipinlẹ Rivers, amọ ahamọ ti wsn fi si lo ku si.
Ẹgbọn Chima, Anthony Ikwunado sọ fun BBC pe awọn ọkunrin mẹrin miran ti wọn mu pẹlu Chima sọ pe ọjọ kẹtalelogun, oṣu Kejila, ọdun 2019, lo ku.
Okùnrin SARS náà sọ pé òun máa pa èèyàn síbi ni- Aladugbo
"O ni ""wọn fi iya jẹ Chima, wọn kan ẹsẹ rẹ. Koda wọn sọ fun mi pe niṣe ni wọn so o mọ oke aja fun wakati meji ti wọn fi lọ fun irinkiri wọn. Igba ti wọn de ti wọn tu u silẹ, niṣe lo jabọ lulẹ bi odi kókò. Lẹyin naa ni wọn gbe sinu ọkọ wọn, ti wọn si gbe e lọ."
Iyawo Ogah, Ada, sọ fun ileeṣẹ BBC Pidgin pe lasiko ti ọkọ rẹ n gbe oun ati smọ lọ sileewe, lo ni aawọ pẹlu awọn osṣiṣẹ to n dari ọkọ loju popo.
O ni ko to iṣẹju melo ti wọn fi bẹrẹ si ni fi kondo lu u, ti wọn si tun wọ nilẹ lọ si agọ ọlọpaa.
Iṣẹlẹ naa to waye ni ogunjọ, oṣu Kẹta, ọdun 2019, lo yọri si iku rẹ.
SS3 ní mo wà báyìí, mo sì ti gba àmì ẹ̀yẹ̀ púpò nílé-lóko gẹ́gẹ́ bí onílù - Ayansike
Nigeria Accident: Ènìyàn 17 kú nínú ìjàmbá ọkọ̀ mẹ́ta tó ṣẹlẹ̀ ní Osun, òpópónà Ibadan sí Eko àti Delta
Oríṣun àwòrán, Twitter
Eniyan mẹtadinlogun lo ku, ti ọgọọrọ eniyan si farapa ninu ijamba ọkọ to waye ni awọn opopona ni ipinlẹ Osun, Ogun, Delta ati ipinlẹ Eko.
Iroyin ni eniyan mẹsan an ni ẹmi wọn ba ijamba ọkọ laarin ọpọlọpọ ọkọ to waye ni ipinlẹ Osun.
Eniyan mẹrin ku ninu ijamba ọkọ to waye nipinlẹ Ogun, pẹlu eniyan meji si sọ ẹmi wọn nu ninu ijamba ọkọ to waye nipinlẹ Delta ati ilu Eko.
Agbegbe Igbelajawa, Erin Ijesa ni ọkọ nla meji ti kọlu ara wọn nipinlẹ Osun.
Awọn ọkọ meji to k lu ara wọn ni opopona Ilesha-Akure naa lo gbina ti ọkọ mẹsan an si jona raurau.
Ijamba ọkọ naa fa sunkẹrẹ-fakẹrẹ ọkọ titi de Ipetu/Eti Oni/ Iperindo/ Ilesha road, eleyii si mu ki ọpọlọpọ ọkọ ha si oju kan naa fun ọpọlọpọ wakati ti Ajọ FRSC, ọlọpaa ati Ajọ panapana fi ṣiṣẹ lati la ọna fun awọn eniyan lati ṣiṣẹ.
Oríṣun àwòrán, Twitter
Gomina ipinlẹ Osun, Adegboyega Oyetola ba awọn ẹbi ati ara awọn eniyan to sọ ẹmi awọn eniyan wọn daro.
Nipinlẹ Ogun, ijamba ọkọ to waye naa ṣẹlẹ ni ori afara Saapade, to lọ si opopona Ibadan si Eko.
Oríṣun àwòrán, Twitter
Ajo FRSC to fidi iṣẹlẹ naa mulẹ sọ wi pe aṣiwa ọkọ lo fa a iṣẹlẹ naa ni idaji ọjọ Aje naa, ti ẹmi eniyan mẹfa si lọ si iṣẹlẹ naa.
Ni ilu Eko, ijamba ọkọ to waye lori afara Third Mainland Bridge, ti wọn n lọ si Iyana Oworo naa mu ẹmi eniyan meji lọ.
Bakan naa ni ilu Delta, eniyan meji sọ ẹmi wọn nu ni opopona Ughelli-Warri ni aarọ Ọjọ Aiku, ti awọn mẹfa si farapa.
Oríṣun àwòrán, Twitter
Eeyan méje ti jẹ Ọlọrun nipe nibi ile alaja mẹta to wo ni ipinlẹ Eko lọjọ Aiku, ọjọ kọkanla, oṣu Kẹwaa, ọdun 2020.
Kii ṣe ajoji mọ bi ile ṣe n wo lọtun losi ni ipinlẹ Eko ti o si maa n mu ẹmi awọn eeyan lọ tabi ki wọn farapa nigba ti wọn yoo fi doola wọn.Ile naa ti wọn n kọ lọwọ lo wa ni adugbo Odo, Obalende, nijba ibilẹ Eti-Osa ni ilu Eko.
Oríṣun àwòrán, LASEMA
Pato ohun to fa a to fi wo ko tii ye ẹnikẹni ṣugbọn ajọ to n ri si iṣẹlẹ pajawiri ni Eko, LASEMA atawọn ajọ adoola mii ni awọn ti ri ogun eeyan doola laaye wọn si ti gbe wọn lọ si ileewosan kiakia.
Bakan naa ni ajọ naa sọ pe ajọ to n risi ọrọ ile kikọ nipinlẹ Eko, LASBCA, ti titi ile naa pa tẹlẹ ṣaaju iṣẹlẹ buruku yii.
Oríṣun àwòrán, lasema
Amọ ẹni to ni ile naa pada gba ọna alumọkọrọyi bẹrẹ iṣẹ nibẹ ni owurọ ọjọ Aiku.
Ọga Agba ajọ LASEMA, Olufemi Oke-Osanyintolu sọ ninu atẹjade kan pe aigbọran si ofin lo pada yọri si bi ile naa ṣe wo, to si mu ẹmi awọn eeyan kan lọ.
Oríṣun àwòrán, lasema
Ajọ LASEMA sọ pe ijọba ti ti ile naa pa tẹlẹ,amọ ẹni to ni fi aigbọran tẹsiwaju pẹlu kikọ rẹ ko to o wo lulẹ lọjọ Aiku
Oríṣun àwòrán, lasema
Ṣugbọn, ọkunrin mẹfa, obinrin kan lo ba iṣẹlẹ naa rin ti wọn si ti gbe wọn lọ sile igbokusi.
Oríṣun àwòrán, LASEMA/TWITTER
Oríṣun àwòrán, lasema
Awọn kan to farapa diẹ gba itọju pajawiri nibi ti iṣẹlẹ naa ti waye, ki wọn o to gbe wọn lọ sileewosan.
Ẹwẹ, alukoro ajọ LASEMA, Nosa Okubor ni igbiyanju ṣi n lọ lọwọ lati doola awọn eeyan toripe wọn o mọ iye eeyan ti ile naa wo lu nigba ti a  fi n ko iroyin yii jọ.
Oríṣun àwòrán, Google Maps
Ajọ to n mojuto iṣẹlẹ pajawiri ni ipinlẹ Eko, iyẹn, Lagos State Emergency Management Agency, LASEMA ti fidi iṣẹlẹ ijamba ọkọ naa mulẹ nipinlẹ Eko pe ẹmi meji ba iṣẹlẹ naa rin.
Ogbeni Nosa Okunbor to jẹ agbẹnusọ ajọ LASEMA fi atẹjade naa sita lọjọ Aiku pe agbegbe Okokomaiko si Iyana Isashi ni ijamba ọkọ naa ti ṣẹlẹ.
Oríṣun àwòrán, @Lasema
O ni ajọ LASEMA ti ko awọn to ṣeṣe ni Oke afa ninu ejigbo naa lọ sile iwosan.
O ni didide kia si amojuto iṣẹlẹ naa lo tun jẹ ki iku to wa nibẹ mọ niwọnba bẹẹ nitori bi wọn se de ibẹ ni wọn doola ẹmi awọn to ha sinu ọkọ naa ati awakọ ti wọn pe ni Olasupo Adedeji to n gbe ni Asenuga ni ibudokọ Ile iwe ni Ikotun.
"Ogbeni Nosa ni pe: "" bi ajọ LRT se rii pe awakọ bọọsi akero kekere naa ti kọlu ọkọ akero miran to si wọ ọ lọ kọlu okọ ajagbe ti wọn wa soju kan nibẹ."
Lori ere ni ọkọ naa kọlu ọkọ ajagbe naa ti awọn eeyan si ha si abẹ rẹ.
Ati pe awọn meji miran tun farapa ni Okokomaiko loru ọjọ Ẹti.
"Wọn ti pese itọju to yẹ fun awọn to farapa niwọnba ti wọn si ko awọn to ku lọ si Trauma Centre""."
coronavirus prevention badge update: Wo òótọ́ àti irọ́ tó wà nínú báàjì àyà náà
LASEMA salaye pe loju ẹsẹ ni awakọ kan ati ero kan dagbere faye ni Okokomaiko si Iyana Isashi lopopona Badagry.
Ọkọ ajagbe to ni nọmba AAA 95 XX lo bajẹ loju ọna pẹlu ẹru irin to ko ni eyi to fi jẹ ki sunkéré fakéré o pọ lọna.
SS3 ní mo wà báyìí, mo sì ti gba àmì ẹ̀yẹ̀ púpò nílé-lóko gẹ́gẹ́ bí onílù - Ayansike
Bakan naa ni ọkọ ajagbe akẹru miran to ni nọmba GDD 962 ZT to kọ awọn pali ohun mimu ni awakọ rẹ gbagbe sunlọ ti o si ja le ọkọ bọọsi akero ti nomba rẹ jẹ SMK 343 YA ati LSD 818 XX ti awọn naa wa ninu sunkẹrẹ fakéré ọkọ nibẹ.
LASEMA ni wọn ti palẹmọ oku awọn to doloogbe lọ si Lagos State Environmental Health Monitoring Unit Officials.
Nkechi Blessing: Gbajúgbajà òṣèré ní ó sàn fún òun láì tíì lọ́kọ báyìí ju kí òun lọ́kọ láì láyọ lọ
Oríṣun àwòrán, Instagram/nkechiblessingsunday
Gbajugbaja oṣere tiata Yoruba, Nkechi Blessing tun ti ja gudugbẹ ọrọ mii lẹyin to sọ pe o san fun oun lai tii lọkọ bayii ju ki oun ti ṣe igbeyawo lọ.
Nkechi to sọrọ yii lori ayelujara ṣalaye pe o san fun oun ki oun ni ayọ lai tii lọkọ ju ki oun wa lọọdẹ ọkọ pẹlu inanujẹ ọkan lọ.
''Ẹyin omugọ ti ẹ n pariwo ẹnu pe ki n lọ ṣe igbeyawo, ti o ba ka yin lara, ẹ wa fi ipa mu mi ki ẹ si sin mi lọ si ile ọkọ,'' Blessing lo sọ bẹẹ.
Gbajugbaja oṣere ọhun to awọn eeyan ko mọ ẹnikan ni pato gẹgẹ bi ọrẹkunrin ṣalaye pe ko si ohun to buru ninu ki eeyan maa ti lọ sile ọkọ ni wọn igba to ba ti layọ.
Laipẹ yii ni Blessing tun sọ fawọn akọroyin pe ikebe ti Eleduwa fi jinki oun tobi ju ohun ti oun le dọwọ bo lọ.
Oríṣun àwòrán, Instagram/nkechiblessingsunday
O ni gbogbo eeyan lo mọ pe Ọlọrun pari iṣẹ si ẹyin oun, o ni awọn to ni ipenija oju kan to ba sun mọ oun le mọ bi ikebe oun ṣe tobi to.
Gbajugbaja oṣere naa ni o jẹ iyalẹnu fun oun pe awọn kan n sọ kaakiri wi pe oun maa n ju idi oun fun ṣe ki a ri mi ṣugbọn o sọ pe ọrọ ko ri bẹẹ rara.
Blessing ni aṣiṣe nla lawọn to n sọ pe oun ju idi kiri ki awọn aye le maa sọrọ ṣe nitori iṣu Ọlọrun ti ko ṣe fọwọ bo ni ikebe naa jẹ foun.
O tun mẹnu idi ti o fi n gbaruku ti Laycom nile Ẹlẹgbọn Agba iyẹn Big Brother Naija.
Gbajugbaja oṣere Yoruba naa ni ọlọpọ pipe ni Laycom, eyi lo jẹ ki oun maa dibo fun un.
Akomolede àti Aṣa: Ọ̀rọ̀ Ẹ̀yán ni Bunmi Femi Amao ń kọ́ wa lórí ètò Akọ́mọlédè àti Àṣà lóri BBC Yoruba
Ondo election 2020: Gómìnà Akeredolu la Jegede mọ́lẹ̀ wọlé ìbò gómìnà Ondo fún sáà kejì
Oríṣun àwòrán, Twitter
Aarẹ orilẹede Naijiria, Muhammed Buhari ti ki gomina ipinlẹ Ondo, Oluwarotimi Akeredolu ku oriirẹ pẹlu bi o ṣe jajabọ ninu idibo sipo gomina to waye ni ipinlẹ Ondo.
Aarẹ Buhari fi eyi lede gba ọwọ oluranlọwọ pataki ninu eto iroyin igbalode, Bahir Ahmad, eleyii to fi si oju opo Twitter.
Oríṣun àwòrán, TWITTER
O ni '' Akeredolu ku orire iyansipo gẹgẹbi gomina fun ọdun mẹrin miran lati tukọ ipinlẹ Ondo''.
Oríṣun àwòrán, TWITTER
Akeredolu ti ẹgbẹ oṣelu APC la Jedege mọlẹ pẹlu ibo 29,2830, ti Jegede ti ẹgbẹ oṣelu PDP si ni ibo 195,791.
Awọn ololufẹ ẹgbẹ oṣelu PDP ti ni awọn ko gba wi pe Eyitayo Jegede fidirẹmi, amọ ajọ eleto idibo INEC lo ṣe magomago fun wọn.
Oríṣun àwòrán, Facebook
Eyi ko ṣẹyin bi Ajọ INEC ṣe kede gomina ipinlẹ Ondo, Oluwarotimi Akeredolu gẹgẹ bi ẹni to jawe olubori ninu idibo sipo gomina nipinlẹ Ondo.
Bakan naa ni alukoro ẹgbẹ oṣelu nipinlẹ Ondo, ni awọn ṣi n gba alaye lori esi idibo naa lọwọ nitorinaa awọn ko tii le fesi.
''Eyitayo Jegede naa ko i tii ṣetan lati sọrọ lori esi idibo naa, ti asiko ba to, yoo sọrọ''
Ololufẹ Eyitayọ Jegede miran to sọrọ ni oun ko tun ṣe oṣelu mọ lẹyin bi Eyitayọ Jegede ṣe fidirẹmi.
Lasiko ti akọroyin BBC kaakiri agbegbe Eyitayo Jegede, ni ṣe lo pa lọlọ ti ko si si ẹni to n dunnu ni agbegbe naa.
Gomina ipinlẹ Ondo, Oluwarotimi Akeredolu ti ni ifẹ ti oun ni si awọn araalu lo jẹ ki wọn dibo fun oun gẹgẹ bi  gomina fun saa keji.
Gomina Akeredolu sọ eyi lasiko to jawe olubori ninu didbo sipo gomina ni ipinlẹ Ondo.
Oríṣun àwòrán, Akereolu/Facebook
Akeredolu tun dupe lọwọ aarẹ Muhammadu Buhari ati igbakeji rẹ, Yemi Osinbajo fun atilẹyin wọn saaju ati lasiko idibo naa.
Bakan naa lo dupẹ lọwọ gomina ipinlẹ Eko, Babajide Sanwo-Olu, gomina ipinlẹ Ekiti, Kayode Fayemi,  Gomina ipinlẹ Ogun tẹlẹ, Ibikunle Amosun,gomina ipinlẹ Kogi, Yahaya Bello, gomina ipinlẹ Kebbi ati gomina ipinlẹ Jigawa.
Bakan naa lo dupẹ lọwọ Lucky Ayedatiwa to dije gẹgẹ bi igbakeji gomina, to si rọ ki o maṣe da oun lẹyin o rẹyin.
O tun dupẹ lọwọ awọn ti wọn jọ dije dupo labẹle pe wọn ba oun ṣiṣẹ.
Oríṣun àwòrán, Facebook/Rotimi Akeredolu
Ninu ọrọ tirẹ, Gomina ipinlẹ Eko, Babajide Sanwo-Olu ni ibi giga ni ipinlẹ Ondo n lọ, nitori naa ki wọn ma a gbadura fun un lati mu gbogbo ileri rẹ ṣẹ.
Gomina Rotimi Akeredolu ti wọle ibo gomina ipinlẹ Ondo to waye lọjọ Abamẹta, ọjọ kẹwaa, oṣu kẹwaa, ọdun 2020.
Akeredolu to jẹ oludije labẹ ẹgbẹ oṣelu APC la oludije ẹgbẹ oṣelu PDP, Eyitayo Jegede to sun mọ ọ julọ ninu eto idibo naa mọlẹ.
Eyi tumọ si pe Akeredolu ti wọle ibo gomina ipinlẹ Ondo bayii fun igbakeji.
Akeredolu lo moke ninu ijọba ibilẹ to pọ julọ ni ipinlẹ Ondo nigba ti Jegede oludije PDP atawọn to ku si tẹ le e.
Ninu esi idibo awọn ijọba ibilẹ ti wọn kọkọ ka, APC moke ninu ijọba ibilẹ mejidinlogun to wa ni Ondo.
Oríṣun àwòrán, @Akeredolu
Akeredolu ati igbakeji rẹ
Akeredolu lo gba  ju bẹrẹ lati ijọba ibilẹ Akoko North West, Akoko North East, Akoko South East ati Akoko South West.
coronavirus prevention badge update: Wo òótọ́ àti irọ́ tó wà nínú báàjì àyà náà
Awọn yoku ni Ile Oluji/Okeigbo, Owo, Idanre ati Ondo East.
Awọn ijọba ibilẹ ti PDP ti moke ni ijọba ibilẹ Ifedore, Akure North ati Akure South.
A o maa mu ẹkunrẹrẹ iroyin naa wa fun yin ni kopẹ kopẹ.
Nigeria movie industry: Àgbà òṣèré, Lere Paimo ní àìgbọràn ló ń da ọ̀pọ̀lọpọ̀ àwọn
ENDSARS: Wo ìgbà mẹ́rin tí ìjọba ti tú ikọ̀ ọlọ́pàá SARS ká sẹ́yìn ṣùgbọ́n...
Oríṣun àwòrán, Police
Oga Agba ọlọpaa, Muhammed Adamu ti kede pe ijọba ti tu ikọ ọlọpaa SARS ka lẹyin ti awọn eniyan ko dawọ duro lori ifẹhọnu han ti wọn n ṣe pẹlu asia #EndSARS.
Amọ kii ṣe igba akọkọ ni yii ti Ọga ọlọpaa yoo tu ikọ SARS ka, ati wi pe igba kẹrin leleyii.
Akojọpọ re e lori igba mẹrin ti ikọ ọlọpaa ti tu SARS ka lorilẹede Naijiria.
Ọga agba ọlọpaa lorilẹ-ede Naijiria, Mohammed Asamu paṣẹ ki ikọ FSARS ye e kaakiri lati ma a wo ọkọ ati dukia awọn eniyan mọ loju popo, tabi ki wọn ma a gbe ọkọ kaakiri lati fi ṣe ọṣẹ.
Amọ, ikọ SARS ko dawọ duro rara nitori wọn ko jawọ ninu irinkerindo wọn, tabi wiwu iwa ipa si awọn araalu.
Oríṣun àwòrán, NPF
Lẹyin ti ọlọpaa pa ọkan lara awọn ọmọ ẹgbẹ agbabọọlu Remo Stars,  Tiamiyu Kazeem ni ilu Sagamu, nipinlẹ Ogun ni IGP Mohammed Asamu sọ wi pe ki wọn ti gbogbo ileese ikọ SARS kaakiri orilẹede Niajiria.
Ni igba naa, igbakeji ọga ọlọpaa to n risi iwa ọdaran lawujọ, Peter Ogunyonwo lo kede rẹ lasiko ti wọn n ba awọn ẹbi Tiamiyu kẹdun lẹyin iku ọmọ wọn.
Ileeṣẹ ọlọpaa lorilẹede Niajiria ṣe apejuwe ikọ SARS naa gẹgẹ bi agbekalẹ to ni aṣiṣe ninu.
Oríṣun àwòrán, Remo Stars/Police
Ọga Agba ọlọpaa lorilẹede Niajiria to jẹ adele nigba naa, Mohammed Adamu lo tu ikọ SARS ti ijọba apapọ ka patapata( ohun kan naa lo ṣe ni Oṣu Kẹwaa, ọdun 2020).
Ọga Adamu paṣẹ fun gbogbo awọn kọmiṣọnna ọlọpaa lorilẹ-ede Naijiria lati ri pe wọn tu ikọ naa ka.
Bakan naa ni ọga ọlọpaa naa paṣẹ fun olu ilu ileeṣẹ ọlọpaa ni ilu Abuja lati tu ikọ SARS ti Abuja ka.
Ni ọdun 2018 ti wọn da ikọ SARS silẹ, ohun ti wọn sọ ni wi pe awọn wọnyii ko ni ma a da awọn eniyan duro lọna, lati ma wo ohun ti wọn gbe sinu ọkọ.
Ikọ ọlọpaa si fikun wi pe ọlọpaa to ba ṣe aṣemaṣe yoo fi oju wina ofin laarin wakati mẹrindinlogun.
Amọ titi di asiko yii, ko si ohunkohun to yi pada.
Oríṣun àwòrán, YASUYOSHI CHIBA
Ni ọdun 2017,  bakan naa ni Ọga Ọlọpaa tẹlẹ, Ibrahim Idris fi opin si ki ọlọpaa ma a da awọn eniyan duro wi pe wọn fẹ wọ ohun ti wọn gbe.
Aṣẹ ti ọga ọlọpaa gbe jade naa ni wi pe gbogbo awọn ọlọpaa to ba n ṣiṣẹ ni ẹka naa, ki wọn jawọ ninu rẹ.
Bakan naa ni IGP nigba naa paṣẹ ki awọn ọlọpaa ma a wọ aṣọ iṣẹ wọn pẹlu ami idanimọ lasiko iṣẹ.
Ileeṣẹ ọlọpaa lorilẹede Naijiria da ikọ naa silẹ lati le koju ole jija ati iwa ọdaran lawujọ.
Abayọmi Aranmọlatẹ, Dr Laser: Vagino Plasty àti iṣẹ́ abẹ ẹwà Obìnrin ló jẹ mí lógún
Saaju ni ijọba ti kọkọ kede ifopin si SARS
Ọga agba ajọ ọlọpaa ni wọn yoo gbe gbogbo awọn agbofinro naa to n ṣiṣẹ ni ikọ SARS lọ si ẹka mii nileeṣẹ ọlọpaa kan naa.
Ọga agba ajọ ọlọpaa tun ni wọn yoo ṣe ilana tuntun jade fun awọn ọlọpaa lori kikoju awọn adigunjale atawọn iwa ipa mii.
Oríṣun àwòrán, Twitter/aminuyaro_
O ni awọn yoo gbe igbimọ araalu atawọn alẹnulọrọ kalẹ lati pese anfani fawọn araalu lati maa foju gaani ati lati maa gba awọn alaṣẹ ileeṣẹ ọlọpaa lori awọn ọrọ nla to kan araalu.
Lati lee koju awọn iwa aidaa si awọn araalu, awọn yoo ṣe agbekalẹ ikọ aṣewadii ti awọn ẹgbẹ araalu ti awọn yoo si maa fi awọn ti igba iwa yii ba ṣi mọ lori jofin.
Ọga ọlọpaa tun tẹnumọ igbaradi ileeṣẹ ọlọpaa lati fi orukọ rere pe ileeṣẹ ọlọpaa Naijiria to fi mọ aato nilana ikọṣẹmọṣẹ fun ṣiṣe iṣẹ wọn fun awọn araalu.
Gbogbo igboro Naijiria lo ti kun fun ajọyọ paapaa laarin awọn ọdọ nitoripe ohun ti wọn n bere fun lọwọ ijọba papa tẹ wọn lọwọ.Awọn gbajugbaja laarin awọn ọdọ Naijiria bii olorin, oṣere, adẹrinpoṣonu lo dide lati dari awọn ọdọ akẹgbẹ wọn.
Lẹyin ọpọlọpọ igba ti awọn ọmọ Naijiria ti n fọnmu lori pe ki ijọba gbe igbesẹ lori bi awọn ikọ agbofinro SARS ṣe n ṣe awọn araalu lọṣẹ ni aṣeyọri yi to waye.
"Nibayii ti ijọba ati ọga agba ọlọpaa ti jẹ awọn ọdọ ni hoo, ajọyọ tun bẹrẹ ti awọn kan si tun ni ọrọ lati sọ fun ijọba.""Yipeeeeee"" pẹlu aworan ijo lẹsẹ ni gbajugbaja oṣere, Toyin Abraham fi ṣafihan ajọyọ rẹ loju opo instagram."
"Ni ti olorin Falz, o fi ye awọn ọdọ Naijiria pe ""eyi ni agbara ti ẹ ni. Ẹyin ati emi lapapọ. Ibẹrẹ ọtun ree"""
"Runtown ṣe atunpin atẹjade ọkan lara awọn amugbalẹgbẹ aarẹ Buhari to kede ọga agba ọlọpaa ti tu ikọ SARS ka. O kọ akọle tirẹ pe ""bi a ba wa papọ, a ni okun""."
"Gbajugbaja oṣere Yoruba mii, Iyabo Ojo ni ""ẹ bori ninu eyi na! A bori! O fi ye wa pe agbara wa ninu fifohunṣọkan.''"
"O wi fun awọn ọdọ Naijiria pe bi wọn ba si wa ko awọn ikọ SARS pada wa, a o tun tẹsiwaju ninu ifẹhonuhan""."
Oríṣun àwòrán, Nigerioa Police Force
Ijọba apapọ Naijiria ti paṣẹ ki wọn tu ikọ ọlọpaa FSARS ka ni kiakia.
Ọga patapata ileeṣẹ ọlọpaa Naijiria, Mohammed Adamu lo kede ọrọ yi nigba to n ba awọn akọroyin sọrọ lọjọ Aiku.
Adamu sọ pe igbesẹ yi jẹ idahun si igbe tawọn ọmọ Naijiria n pa lori ikọ naa.
Orisi ẹsun ni awọn ara ilu fi kan awọn agbofinro yii kaakiri Naijiria ati ni ilẹ okeere nibi ti iwọde ti waye kaakiri.
Adamu ni bẹrẹ lati wakati yi, gbogbo awọn oṣiṣẹ ikọ yi ni wọn yoo darapọ mọ ẹka ileeṣẹ ọlọpaa mi.
Loju opo Twitter wọn, alukoro ọlọpaa Frank Mba ṣalaye koko marun un ti iyipada yi yoo tẹle.
Ileeṣẹ Aarẹ Naijiria naa fi ikede yi sita loju opo wọn ni Twitter.
Lẹnu ọjọ mẹta yi ni ariwo ati iwọde bẹrẹ si ni gbalẹ tawọn eeyan Naijiria si ni ki ijọba tu FSARS ka.
Ijọba ni ko si ohun  to n jẹ FSARS mọ ni gbogbo ipinlẹ mẹrindinlọgbọn to wa ni Naijiria ati ni Abuja
Ijọba ni awọn yoo pin awọn agbofinro ẹka FSARS yii kaakiri ẹka ileeṣẹ ọlọpaa miran.
Ijọba ni awọn yoo kede ẹka ọlọpaa miran ti yoo ma gbogun ti awọn adigunjale.
Ijọba ni ajọ agbofinro ati ara ilu tuntun ni awọn yoo ṣe agbekalẹ re lati ma risi ẹsun to ni i ṣe pẹlu ara ilu.
Nigeria movie industry: Àgbà òṣèré, Lere Paimo ní àìgbọràn ló ń da ọ̀pọ̀lọpọ̀ àwọn
Abayọmi Aranmọlatẹ, Dr Laser: Vagino Plasty àti iṣẹ́ abẹ ẹwà Obìnrin ló jẹ mí lógún
Ìdí tí mo fi yan iṣẹ́ abẹ ojú ara obìnrin láàyò rèé- Dr Laser
Vagino Plasty ni iṣẹ abẹ ẹwa obinrin ti ero ko pọ nibẹ rara- Dokita Aranmolate
Ẹwa obinrin ṣe pataki pupọ si wọn.
Dokita to n ṣiṣẹ abẹ lori mimu ẹwa obinrin pọ sii, oniṣegun oyinbo Ayobami Aranmolate salaye awọn igbesẹ to rọ mọo ati idi ti oun fi yan iṣẹ abẹ yii laayo fun BBC Yoruba.
Dr Laser sọ nipa bi iṣẹ abẹ naa ṣe wọn to ati awọn ibi ti oun ti lọ kọ ẹkọ nipa iṣẹ abẹ didi oju ara obinrin to ba fẹ lẹyin ibimọ pada.
O ni ọgbọn isegun yii wa lati ọdọ Olorun ni ati pe ọpọlọ naa kii ṣe ti atọwọda rara.
Ondo election 2020: Àwọn ara ìpínlẹ̀ Ondo ránṣẹ́ sí Akeredolu ohun ti wọ́n ń retí ní báyìí
Inu wa ko dun ṣugbọn.... Alaga ẹgbẹ oṣelu SDP
Lẹyin ti ajọ INEC kede Rotimi Akeredolu pe oun lo wọle ibo lẹẹkeji ni ipinlẹ Ondo lọjọ Aiku ni awọn eeyan sọ ohun to wa ni ọkan koowa wọn.
Ogbẹni Oladele Olugbemi to jé alaga ẹgbẹ SDP ni Ondo salaye fun BBC pe ko si ohun ti ẹgbẹ naa le ṣe lẹyin awọn eeyan ipinlẹ Ondo.
O ni: O dun wa pe wọn ti ta ibo wọn ni Ondo nitori pe igboro ko rẹrin.
Ogbeni Olalere Ola to jẹ aṣoju ADP sọ nipa bo ṣe pe ebi ati iṣẹ lo jẹ ki awọn eeyan ta ibo wọn laiwo ẹyin wo ni Ondo.
Ogbeni victor Olabintan to jẹ aṣoju ẹgbẹ APC to gbegba oroke ni tirẹ sọ pe inu gbogbo ọmọ ẹgbẹ APC dun pupọ si abajade esi idibo naa.
Awọn ADP ni inu Olorun kod un si ipinlẹ Ondo bayii.
Awọn ara ilu naa ba BBC sọrọ, wọn ṣalaye ohun to wu wọn ati ohun ti wọn n reti lọdọ Akẹti to jẹ gomina tuntun to wọle bayii.
Edo after election: Àwọn aṣòfín ní ìpínlẹ̀ Edo ti yọ Abẹnugan Ilé, Francis Okiye bí jìgá
Oríṣun àwòrán, Facebook
Ile Igbimọ Aṣofin ni ipinlẹ Edo ti yọ Abẹnugan Ile, Francis Okiye kuro ni ipo.
Iyọkuronipo rẹ ko ṣẹyin bi adari ọmọ ile to pọju lọ, Henry Okhurobo ṣe ni ki wọn yọ ọ lori ẹsun pe oun lo iwa agbara pẹlu wọn.
Awọn mẹsan an ninu awọn mẹwaa to wa nibi ijoko ile naa lo buwọlu lẹta iyọnipo rẹ.
Oṣu Keje, Ọdun to kọja ni ija ti bẹrẹ laarin awọn ọmọ Ile, lẹyin ti awọn mẹsan an kan lalẹ Ọjọ Kẹtadinlogun, Oṣu Keje yan abẹnugan Ile laarin awọn mẹrinlelogun to jẹ ọmọ ile igbimọ aṣofin ipinlẹ naa, ti wọn ṣẹṣẹ dibo yan, labẹ aṣẹ gomina ipinlẹ Edo, Godwin Obaseki.
Awọn aṣofin mẹrinla to ku ko si ni ibi ti wọn ti gbe igbesẹ naa, ti wọn si tako igbesẹ naa ati ẹgbẹ oṣelu APC si kọ igbeṣẹ naa, wọn si kesi gomina Obaseki lati pa aṣẹ miran.
Amọ, Ileẹjọ Giga nipinlẹ Rivers tako igbẹsẹ ki gomina pa aṣẹ miran.
Igbiyanju lati ṣe ibura wọle fun awọn aṣofin tuntun naa lo fori sanpọn, nigba ti awọn kan le wọn kuro ni Ile Igbimọ Aṣofin, lẹyin ti wọn ni wọn n tun ayika ati Ile Igbimọ Aṣofin naa ṣe lọwọ.
Amọ, ẹgbẹ oṣelu APC ni gomina ipinlẹ Edo lo kọ awọn janduku si Ile igbimọ aṣofin nitori ko fẹ ki wọn yọ oun kuro ni ipo.
Bakan naa ni ileẹjọ miran paṣẹ ki Ile Igbimọ Aṣofin apapọ ma ṣe lo agbara lori Ile Igbimọ Aṣofin ipinlẹ Edo.
Abayọmi Aranmọlatẹ, Dr Laser: Vagino Plasty àti iṣẹ́ abẹ ẹwà Obìnrin ló jẹ mí lógún
Eleyii pẹlu ohun to mu ki ija ati ikunsinu to wa laarin gomina ipinlẹ Edo, Obaseki ati gomina ana nipinlẹ naa, Adams Oshiomolẹ to jẹ alaga ẹgbẹ oṣelu APC nigba naa.
Awọn kan sọ wi pe Gomina Obaseki to wa ni idi bi wọn ṣe le Obaseki kuro ni ẹgbẹ oṣelu APC ni wọọdu rẹ, Oshiomole naa si ri daju pe Obaseki to jawe olubori ninu idije sipo gomina labẹle ni ẹgbẹ oṣelu APC, ti Pasito Osagie Ize-Iyamu si bori.
Nibayii ti gomina ipinlẹ Edo, Godwin Obaseki ti wọlẹ pada, awọn oniroyin bere ẹ lọwọ boya yoo gba ki awọn aṣofin mẹrinla ti ẹgbẹ oṣelu APC pada si Ile Igbimọ Asofin?
Amọ, Obaseki dahun wi pe oun ko laṣẹ lati burawọle fun awọn mẹrinla naa, lẹyin ti wọn kọ lati ṣe ayẹyẹ iburawọle.
Ondo election 2020: Àwọn ara ìpínlẹ̀ Ondo ránṣẹ́ sí Akeredolu ohun ti wọ́n ń retí ní báyìí
End SARS protest: Lára àwọn ìlú tí ìwọ́de ti wáyé ní Ibadan, Ado Ekiti, Osogbo, Ado Ekiti ati Eko
Se ni eto okoowo dẹnu kọlẹ kaakiri awọn ipinlẹ to wa nilẹ wa Naijiria ati olu ilu ilẹ wa Abuja.
Idi ni pe awọn oluwọde yika orilẹede yii, to n beere fun opin ọlọpaa SARS, ni wọn gbe igi dana lawọn opopona ati papakọ ofurufu.
Koda, awọn ọlọja ko lee si sọọbu tabi patẹ ọja wọn lasiko ti iwọ̀de naa n waye, ti ohun gbogbo si dẹnu kọlẹ.
Se ni awọn akẹkọọ pada sile ni lai le kẹkọọ tawọn ile iwe gbogbo si gbe ilẹkun wọn tipa, bẹẹ ni awn to yẹ ko joko sedanwo NECO, ko le wa sile iwe.
Koda, laasigbo to waye lati ipasẹ iwọde to n lọ lọwọ yika Naijiria yii ko yọ awọn osisẹ ọba silẹ pẹlu, nitori wọn ko ri ọkọ wọ tabi gbe lọ sibi isẹ wọn.
Awọn osisẹ to si ti de ibi isẹ ni wọn gan sare gbe ilẹkun ọọfisi wọn ti, ki wọn lee tete pada sile ki ohun gbogbo to fọnna soju.
Awọn oluwọde naa, laarọ ọjọ Aje, si ni wọn n kọ oniruuru orin to n tabuku ijọba Buhari.
Lati igba ti iwọde End SARS ti bẹrẹ, gbogbo awọn ilu nla nla ni Naijiria lo ti ni imọlara iwọde naa, lara awọn ilu nla nla ti iwọde naa ti milẹ titi ni Eko, Abuja, Osogbo, Ibadan, Ilorin, Ado Ekiti, Abeokuta ati bẹebẹẹ lọ.
BBC Africa Eye tú àṣírí ìfìyàjẹni àwọn òṣìṣẹ́ aláàbò
Ohun ti awọn oluwọde naa n beere fun ni pe, ki ijọba apapọ fopin si SARS, ki wọn si tun fi oju gbogbo awọn ọlọpaa to fi iya jẹ ara ilu lọna aitọ wina ofin.
Nilu Ado Ekiti, tii se olu ilu ipinlẹ Ekiti, iroyin to wa lati ibẹ ni se lawọn oluwọde oluwọde naa ti gbogbo opopona pa lai si lilọ bibọ ọkọ ati ero
Oríṣun àwòrán, @Ekitiupdate
Awọn opopona to gbajumọ ti wọn tipa naa ni ọna Fajuyi Park, Okeyinmi, Ijigbo, Adebayo, Basiri ati Ajilosun.
Awọn oluwọde yii ni wọn n kọ orin ibilẹ wa ati tipinlẹ Ekiti, ti wọn si gbe oniruuru akọle to n tabuku aarẹ Buhari ati ijọba rẹ lọwọ.
Oríṣun àwòrán, @sosintayo
Ipinlẹ Eko:
Lara awọn ibi ti wọn gbe iwọde ọhun de ni ilu Eko ni, opopona marosẹ Lekki si Ajah, Alausa ni Ikeja, Oba Akran, Allen Avenue, ati bẹbẹ lọ.
Se ni wọn si ti awọn opopona to gbajumọ pa nilu Eko, to si nira fawn eeyan ati ọkọ lati kọja lati adugbo kan si omiran.
Lara awọ̀n adugbo ti wọn ti pa ni opopona Allen si oba Akran, koda paro paro ni awọn agbegbe naa da.
Bakan naa ni awọn oluwọde sọ iloro ti ijọba ipinlẹ Eko ti n gba owo ibode ni Lekki di ile, nitori ọpọ ninu wọn lo kọ lati pada sile wọn, bakab naa ni wọn sọ ibẹ di ile ijọsin lọjọ Isinmi.
Oríṣun àwòrán, @ajplus
Lekki
Ipinlẹ Ogun:
"Ni ipinlẹ Ogun, awọn olufẹhonuhan korajọ si opopona marosẹ Eko si Ibadan, iyẹ loju ọna to lọ si Mowe ni ipinlẹ Ogun, ti wọn si n kọrin pe ""Sọrọ soke"" ati pe ki ijọba apapọ ""End SARS."""
Oríṣun àwòrán, @VoicingNG
Iwọde naa di ọna mọ awọn arinrinajo to n bọ lati Ibadan si ilu Eko, bakan naa ni ko si ọpna lati relọja lati Eko si Ibadan.
Oríṣun àwòrán, @itz_chibuisky
Abeokuta
Yatọ si eyii, awọn oluwọde tun gbọna ọfiisi gomina ipinlẹ Ogun, Dapọ Abiodun lọ lati sẹ ifẹhonuhan nibẹ.
Ipinlẹ Osun:
Lara iṣẹlẹ to lamilaaka ninu iwọde End SARS ni eyii to waye ni ilu Osogbo lẹyin ti gomina ipoinlẹ naa, Gboyega Oyetola yọju si awọn oluwọde naa, ṣugbọn ti awọn janduku kan ṣekọlu sii.
Ipinlẹ Ondo:
Bakan naa ni ọmọ sori nilu Akure tori se ni awọn oluwọde ọhun gbe idi dana lawọn opopona nlanla nipinlẹ Ondo, ti ko si si lilọ bibọ ọkọ ati ero.
Ni ti awọn eeyan ilu Akure, adura ni wọn fi iwọse wọn ṣe ni bi wọn pe ipade adura lati fi ifẹhonuhan.
Oríṣun àwòrán, @CAPT__Vincent
Akure
Ọgangan iwaju ọfisi gomina ipinlẹ ọhun, Rotimi Akeredolu ni wọn patẹ eto adura naa si, ti wọn si n ke pe Eledua pe ko da si ọrọ Naijiria.
Yatọ si pe awọn naa gbadura, wọn tun ṣe iwọde kaakiri ilu Akure de agbegbe ọja NEPA, Alagbaka, olu ileeṣẹ ọlọpaa ni ọna Igbatoro, ati bẹẹbẹẹ lọ.
bakan naa ni awọn eeyan to n fi ẹhonu han yii tun gbe apẹ kana loju popo, ti wn si n se ounjẹ lọ lai bikita.
Ipinlẹ Kwara:
Oríṣun àwòrán, @TheLonerMan
Ilorin
Orita Challenge ni awọn oluwọde End SARS fi ipade wọn si ni ilu Ilorin, bakan naa ni wọn tun gbe iwọde naa de Tanke Tipper Garage, ki wọn to fi abọ si ile ijọba ipinlẹ ọhun.
Iroyin kan tilẹ sọ pe awọn eeyan naa di oju ọna to bẹẹ ti gomina Abdulrahman Abdulrazaq fi gbe alupupu lọ ile rẹ.
Oríṣun àwòrán, @TheLazyCheff
O kere tan, ọjilenigba din mẹfa miliọnu naira ni ijọba ipinlẹ Eko ti padanu nitori awọn ẹnu iloro ti wọn ti n gba owo ibode to di titipa, lati igba ti iwọde End SARS bẹrẹ.
Gẹgẹ bi abọ iwadii ti ileeṣẹ to n ṣakoso awọn ẹnu ibode naa, Lekki Concession Company, LLC, gbe jade, amọ ijọba Eko ṣi n pa owo lori awọn ipolowo ọja to wa lori awọn iloro ọhun.
Ọkan lara awọn kọmiṣọna ipinlẹ Eko, ti ko fẹ fi orukọ rẹ lede ni, o kere tan, ijọba n reti miliọnu mẹwaa naira lojumọ lori afara to so Lekki pọ mọ Ikoyi nikan ṣoṣo.
Oríṣun àwòrán, @Justapollion
Bakan naa ni iye ti Admiralty Circle Plaza, to wa loju ọna marosẹ Lekki-Epe maa n pa lojumọ kan, ko din ni miliọnu mẹrindinlogun naira.
Kọmiṣona naa fi kun pe, iye ti ijọba maa n ri lori afara Lekki-Ikoyi loṣu ko din ni ọọdunrun miliọnu naira, nigba ti oju ọna Lekki-Epe maa n pa nnkan bii ẹẹdẹgbẹta miliọnu naira loṣu fun ijọba.
"O ni ""Ko din ni ẹgbẹrun lọna ọgọrin ọkọ to maa n gba ẹnu awọn iloro naa lojojumọ, ṣugbọn lati igba ti iwọde End SARS ti bẹrẹ, iloro naa ko pa owo kankan wọle mọ."""
Blind Couples: Pẹ̀lú ìpèníjà ojú, tọkọtaya bímọ mẹ́ta, tí wọn sì tún ń ṣiṣẹ́ olùkọ́
Nigba ti awọn akọrọyin kan si agbẹnusọ ileeṣẹ LLC, Veronica Jacob, o ni oun ko ni ọrọ kankan lati sọ nipa awọn iloro naa lọwọ yii.
O ti le ni ọsẹ kan ti awọn ọdọ kaakiri Naijiria ti gunle ifẹhonuhan, lori bi awọn oṣiṣẹ ẹka to n gbogun ti iwa idigunjale ni ileeṣẹ ọlọpa, SARS, ṣe pa awọn eeyan lọna aitọ.
Wo àwọn ọ̀nà tí o lè gbà láti di ọjọ́ ogbó pẹ̀lú olólùfẹ́ rẹ
Ifẹhonuhan naa ti mu ki ijọba apapọ tu ẹka ileeṣẹ ọlọpaa naa ka to si gbe omiran, SWAT, kalẹ, ṣugbọn ọdọ naa ni o ku nibọn n ro.
Oriṣiriṣi awọn gbajumọ ni Naijiria ati lawọn orilẹ-ede miran lagbaye lo ti n ṣegbe lẹyin iwọde ọhun.
Oríṣun àwòrán, royzkingin / Twitter
Ọna ara ni iwọde a ko fẹ ọlọpaa SARS mọ gbayọ lopopona marosẹ ilu Benin nipinlẹ Edo, nigba tawọn ọdọ di oju popo pa.
Awọn ọdọ to n se iwọde naa, ti oju wọn ko rẹrin rara, ni wọn gbarodan jọ siwaju ẹnu ọna abawọle fasiti Benin, to wa lopopona marosẹ Benin si Ore.
Iyalẹnu lo wa jẹ pe opopona marosẹ ti wọn di pa yii, ni wọn gbe agbada kana si lati se irẹsi ati ọbẹ fun ounjẹ alẹ.
Oríṣun àwòrán, royzkingin / Twitter
Ara ọna tawọn ọdọ yii si n gba fi ẹhonu han ree lati tako ipo ti orilẹede Naijiria wa lọwọ lọwọ bayii.
Bakan naa ni wọn n se iwọde lati ke si ijọba pe ko fi opin si awọn ọlọpaa to n gbogun ti iwa idigunjale, taa mọ si SARS, ti wọn n yọ wọn lẹnu.
Oríṣun àwòrán, royzkingin / Twitter
Se lawọn ọdọ naa da ina igi soju popo naa, ti wsn si gbe apẹ kana, bẹẹ ni wọn fọ irẹsi nu soju titi naa.
Koda wọn din ẹran lati fi jẹ irẹsi jọlọfu ọhun, ti ohun gbogbo si n se yatayoto.
Oríṣun àwòrán, royzkingin / Twitter
Igbesẹ wọn naa fa sunkẹrẹ fakẹrẹ ọkọ ni opopona marosẹ Benin si Ore, tawọn ọlọkọ ko si le tẹsiwaju lẹnu irin ajo wọn naa.
Oríṣun àwòrán, @FCT
Aṣẹ ti  Minisita olu ilẹ Naijiria, Mallam Mohammed Bello pa ti mu ki awọn oluwode bẹnu atẹ lu u, t'awọn kan si ni awọn o kọ lati gbe e lọ si ile ẹjọ.
Lara awọn to tako àṣẹ rẹ yi la ti ri Aisha Yesufu, awọn agbẹjọro to fi mọ awọn ajafeto-omoniyan.
Àwọn oluwọde  #EndSARS yii n ṣé iwọde lati pe fun iwogile ikọ ọlọpaa SARS ati pe ki ijọba fi iya to tọ jẹ awọn to ti ṣọṣẹ ibi fun ara ilu sẹyin.
Wọn si ni awọn ṣetan lati gbena woju Minisita Mohammed Bello lori aṣẹ to pa ki wọn máa ṣe iwọde.Gege bi wọn ti ṣe sọ,wọn ni ko le di awọn lọwọ lati ma se iwọde.
Fídíò bí àwọn jàndùkú yabò àwọn olùwọ́de #ENDSARS ní Alausa l'Eko
Bẹẹ naa lawọn ẹgbẹ ajafeto-omoniyan kan ati awọn agbẹjọro bẹnu àtẹ lu igbesẹ yi, pe minista fun FCT ni Abuja to jẹ olu ilu Naijiria ko ni agbara aṣẹ lati sọ pe ki iwọde ma wa nitori pe ẹtọ ọmọ Naijiria ni.
Wọn ní otubante ni aṣẹ yi jẹ ti ko si ba ofin Naijiria mu.
Ẹwẹ agbarijopo ẹgbẹ àwọn Gomina ariwa Naijiria ti ni awọn ko lodi si ikọ SARS.
Gomina ipinle Plateau to tun je alaga ẹgbẹ naa lasiko to n ba awon akọroyin sọrọ nilẹ ijoba ni SAR Swulo fawọn nipa kikoju ipenija aabo ni Ariwa Naijiria.
Wọn de ọrọ yi lade pẹlu atejade kan leyin Ipade to waye ni ọjọru pe gboyin gboyin lawọn wa lẹyin oga ọlọpaa lati se atunto ileesẹ ọlọpaa.
Kini o ti kọkọ ṣẹlẹ?
#EndSARS: Àwọn olùwọ́de kọ etí ikún sí àṣẹ ijọba, wọ́n tẹ̀sìwájú ìwọ́de l'Abuja
SARS Nigeria: Àwọn olùwọ́de kọ etí ikún sí àṣẹ ijọba, wọ́n tẹ̀sìwájú ìwọ́de l'Abuja
Awọn oluwọde #EndSARS kọ eti ikun aṣẹ ijọba ilu Abuja to fofin de iwọde nitori itankalẹ aarun coronavirus.
Niṣe ni ọgọọrọ awọn olufẹhonuhan bọ soju oju ti wọn si tẹsiwaju pẹlu ifẹhonuhan wọn.
Koda wọn tun gbe iwọde wọn lọ si iwaju ile igbimọ aṣofin agba niluu Abuja.
Awọn onimọto ko ti ẹ ri aaye kọja lagbegbe olu ile iṣẹ ijọba apapọ lẹyin tawọn oluwọde di ọna to wọ inu ibẹ lọ.
Ẹwẹ, ajọ FCTA to n ṣakoso ijọba olu ilu Naijiria, Abuja ti kọkọ fofin de iwọde ki wọde kaakiri ilu Abuja.
Igbesẹ yi waye lẹyin ti iwọde #EndSARS gbode kan kaakiri orilẹede Naijiria.
Minisita ilu Abuja, Muhammad Bello sọ pe awọn oluwọde naa ko tẹle ilana coronavirus lo jẹ ki ajọ FCTA gbe igbesẹ yii.
Ninu atẹjade ti ajọ FCTA fi sita lonii Ọjọbọ, ajọ naa ṣalaye pe lootọọ ni awọn ọmọ orilẹede Naijiria lẹtọ labẹ ofin lati ṣe iwọde wọọrọwọ lori ohun ti ko ba tẹ wọn lọrun.
Ajọ naa sọ pe ọna ti wọn n gba ṣe iwọde ọhun tako ilana ati dena itankalẹ aarun coronavirus bii itakete si ara ẹni.
Ajọ naa tun sọ pe ifẹhonuhan ti wọn n ṣe lori fopin si ọlọpaa SARS  eyi ti ijọba ti fagile jẹ inilara fawọn ọmọ Naijiria mii.
EndSars, EndSwat: Ọlọ́pàá ti fi ìbọn lù mí láyà rí torí mó ní 'extra tyre' méjì- afẹ́hònúh
Wo bí àwọn jàndùkú ṣe yabò àwọn olùwọ́de #ENDSARS ní Alausa l'Eko àti Abuja
Wahala ti waye laarin awọn oluwọde #ENDSARS nilu Abujaati awọn ọdọkunrin kan, ti ko faramọ iwọde to n lọ lọwọ.
Oju ọna olobiripo (roundabout) Berger to wa ni iṣẹlẹ naa ti waye, nibi ti awọn eeyan ti n wọde lati owurọ kutu.
Lasiko ti awọn oluwọde naa n pariwo ẹ fi opin si SARS, ati awọn nkan miran, ni awọn janduku naa ya de, ti wọn si bẹrẹ si ni kọlu wọn pẹlu àdá ati igi.
Koda, wọn ba awọn ọkọ kan jẹ, wọn si tun fọ kilaasi ọpọlọpọ ọkọ ti wọn ba nibi iwọde naa.
Awọn eeyan kan si tun farapa.
Bakan naa ni ọrọ ṣe ri ni agbegbe Alausa nilu Eko.
Iroyin to n tẹ wa lọwọ ni pe awọn janduku ti yabo awọn to n ṣe iwọde #ENDSARS ni ileeṣẹ ijọba ipinlẹ Eko to wa ni Alausa.
Akọroyin BBC Yoruba to wa nibi iwọde naa jabọ pe ada, okuta ati awọn nkan ija mii ni awọn janduku naa ko dani.
Bakan naa ni ẹnikan lara awọn to n ṣe iwọde farapa lasiko naa.
Ṣugbọn ṣa, awọn oluwọde naa pada le awọn janduku naa lọ.
Sotitobire: Ọkọ mi kò mọ̀ Jegede PDP rí, kódà kò fa ẹnikẹ́ni kalẹ̀ dípò Akeredolu- Bisola
Adari ijọ Daystar Christian Centre, Pasitọ Sam Adeyemi ti fi ohun rẹ si ifẹhọnuhan to n ja ranyin kaakiri lorilẹede Naijiria pẹlu asia #EndSARS.
Pasitọ Sam Adeyemi sọ ọrọ naa loju opo ikansiraẹni Twitter rẹ.
Sam Adeyemi rọ aarẹ Muhammadu Buhari, awọn ajọ amuṣẹya, awọn aṣofin Ile Igbimọ Aṣofin, awọn gomina ati gbogbo awọn obi lati lo ifẹhọnuhan yii fun ohun rere.
Pasito Adeyemi ni: ''Ọdun mẹrindinlọgbọn si mẹtadinlọgbọn sẹyin ni awọn ti ṣe iru ifẹhọnuhan yii ri to si di ohun to jẹ ki eto oṣelu tiwantiwa jinlẹ de ibi to de loni ni Naijiria.''
''O fihan gbangba pe awọn ọdọ asiko yii ko ni tẹriba fun iwa agidi ti ijọba ma n lo pẹlu awọn eniyan nigbakan ri.''
EndSARS protest in Nigeria: Mr Macaroni, Falz, Wizkid, Tiwa Savage àtàwọn míì ṣe ìwọde
Adari ijọ naa ni: ''Ni asiko yii, awọn eniyan ti gbọnju ti wọn si mọ ọna lati ja fun ẹtọ wọn ni ọna igbalode lorilẹede Naijiria.''
''Nibayii, iṣejọba to ba gbọ ti araalu nikan lo le ni aṣeyọri ni Naijiria, nitori awọn ọdọ ti gbọn bayii.''
Adari ijọ Daystar Christian Centre, Pasitọ Sam Adeyemi fikun wi pe awọn ọlọpaa ni alakọja ti wọn dojukọ nitori aisan owo oṣu wọn deede lo mu ki awọn naa ma a ṣe aṣiṣe.
Bakan naa ni Pasitọ Sam Adeyemi rọ Aarẹ Buhari lati gbọ ohun ti awọn araalu sọ, ki o wọ ibi ti bata ti n ta wọn lẹsẹ, ki o si ṣe atunṣe.
Ọ̀ba Eniitan Ogunwusi Ọjaja II, Ooni Ile Ifẹ ti sọ pe wamu wamu loun wa lẹyin awọn ọdọ Naijiria lori iwọde ENDSARS to gbode.
Ori ade yi ni niṣe ni iwọde naa mu idunnu ati ayọ wa si ọkan oun nitori awọn ọdọ ti taju pẹlu ohun kan ati afojusun kan naa.
A ri ọrọ yi ka loju opo Twitter Ooni pẹlu ẹkunrẹrẹ alaye ati akawe oun to ṣẹlẹ ti o fi sọ bẹẹ.
Ooni ṣalaye pe irufẹ iriri tawọn ọdọ n koju lọdọ oṣiṣẹ SARS ti ṣẹlẹ si ọmọ bibi oun lobirin koda o fẹ ẹ padanu mi rẹ lọwọ wọn.
Oba Alaye yi ni ti iru eleyi fi le ṣẹlẹ si ọmọ oun, aimọye ọdọ ni iru rẹ yoo ti ṣẹlẹ si.
Ooni wa ni ibeerẹ ohun rẹrẹ ni Naijiria ni iṣẹlẹ yi jẹ fun ara ilu ati awọn ọlọpaa naa.
Ooni ni oriade akọkọ ti yoo gbaruku ti awọn oluwọde ENDSARS ni Naijria lati igba to ti bẹrẹ ni nkan bi ọjọ marun un sẹyin.
Oríṣun àwòrán, Twitter/Buhari
Aarẹ Muhammadu Buhari ti sọrọ fun igba akọkọ lati igba ti iwọde to n pe fun kika ikọ ọlọpaa FSARS kuro nilẹ ti bẹrẹ.
Ninu fọnran fidio ti aarẹ fi si oju opo rẹ ni Twitter, o ni atuntọ iṣẹ ọlọpaa n bọ lẹyin ti ijọba tu FSARS ka.
Bakan naa ni aarẹ ni ijọba ko ṣalai mọ nipa ohun to n ṣẹlẹ nitori naa ki ara ilu ṣe ṣuuru, atunto yoo waye.
Buhari ni: ''Igbesẹ akọkọ ni pe a tu SARS ka lara ipinu wa lati mu atunto to gbooro ki awọn ọlọpaa baa le ṣe
Iṣẹ wọn to jẹ didaabo bo ẹmi ati ọna ijẹ ara ilu''
Bẹẹ naa ni aarẹ ni gbogbo awọn to taṣẹ agẹrẹ sofin ni yoo foju wina ofin.
O tunbọ daro iku oluwọde to padanu ẹmi rẹ ni Ogbomosho nipinlẹ Oyo iyẹn Isiaq Jimoh.
Aarẹ ni oun ti paṣẹ ki iwadii bẹrẹ lati tọ piinpin iku to pa.
Kaakiri Naijiria ni iwọde ti n waye lọjọ keji ti ijọba lawọn tu ikọ ọlọpaa FSARS ka.
Abayọmi Aranmọlatẹ, Dr Laser: Vagino Plasty àti iṣẹ́ abẹ ẹwà Obìnrin ló jẹ mí lógún
Ohun tawọn ọmọ Naijiria n sọ ni pe titu SARS ka nikan ko to bi kii ṣe pe ki ijọba ṣe atunto iṣẹ ọlọpaa.
Ariwo ''Executive Order'' lawọn eeyan n mu bẹnu pe ki aarẹ buwọlu aṣẹ ti yoo fofin de FSARS patapata.
Ondo election 2020: Àwọn ara ìpínlẹ̀ Ondo ránṣẹ́ sí Akeredolu ohun ti wọ́n ń retí ní báyìí
Awọn oluwọde ENDSARS ba BBC sọrọ
School Reopening: Ìjọba ìpínlẹ̀ Eko kéde ṣíṣí gbogbo kíláàsì iléèwé padà
Oríṣun àwòrán, AFP
Ijọba ipinlẹ Eko ti kede ọjọ ti gbogbo kilaasi awọn ileewe aladani ati ti ijọba ni ipinlẹ naa yoo wọle.
Eyi n waye lẹyin oṣu mẹfa ti wọn ti awọn ileewe pa nitori ajakalẹ aarun Coronavirus lorilẹede Naijiria.
Ijọ̀ba ipinlẹ Eko fi sita loju opo Twitter wọn pe kọmisọna eto ẹkọ nipinlẹ Eko, Folasade Adefisoye kede pe gbogbo awọn kilaasi to ku ti ko tii wọle tẹlẹ lee wọle pada.
Iwọle wọn yoo bẹrẹ lati ọjọ Aje, ọjọ kọkandinlogun oṣu kẹwa ọdun 2020.
Ìjọba Kwara kéde ọjọ iwọlé àwọn akẹkọọ lẹyìn ìséde Covid 19!
Ìmọ̀ràn márùn ùn láti ẹnu olùkọ́ni tó fakọyọ lágbàyé lórí kíkọ ọmọ lásìkò yìí
Mọ síi nípa ohun tó ṣẹlẹ ní àwọn ibi tí wọn ti ṣilẹkùn ilé ìwé padà lẹyìn Covid 19
Abayọmi Aranmọlatẹ, Dr Laser: Vagino Plasty àti iṣẹ́ abẹ ẹwà Obìnrin ló jẹ mí lógún
Arabinrin Folasade sọ pe awọn ṣe ipinu yii lẹyin ọpọlọpọ ijiroro ati gbigba imọran pẹlu ati lọdọ tọrọ kan ati awọn akọṣẹmọṣẹ lori aabo to fi mọ awọn oludari awọn ileewe to ni kilaasi fun awọn ọjẹ wẹwẹ.
O fi kun un pe iwọle pada yii jẹ fun saa ikẹkọọ ọdun 2020/2021 o si kan awọn kilaasi jẹleosinmi paapaa naa atawọn nọọsiri alakọbẹrẹ.
Bakan naa ninu atẹjade kan ti adari ẹka ọrọ to kan araalu ni ileeṣẹ naa, Kayode Abayomi fi sita, o rọ awọn adari ileewe girama to jẹ aladani ki wọn tẹle ofin aabo eyi ti ijọba ti ṣaju fi sita lasiko Covid-19.
O tun sọ fun wọn pe ki wọn tẹle ofin imọtoto gẹgẹ bi ijọba ipinlẹ ṣe paṣẹ fun wọn nipasẹ ọfiisi to n ṣamojuto imọ ẹkọ to ye kooro (Office of Education Quality Assurance).
Wọn kilọ pe ọfiisi OEQA yoo maa ṣe amojuto igbaradi awọn ileewe to si jẹ pe awọn ni yoo maa fun awọn ileewe ni iwe aṣẹ lati wọle pada to si ni ki gbogbo awọn oludasilẹ ileewe aladani ri i daju pe wọn gba iwe aṣẹ lati ọfiisi ọhun ki wọn to wọle pada.
Increased DSTV tariff: MultiChoice ní àfikún owó epo, owó iná pẹ̀lú owó orí VAT ló jẹ́ káwọn fowó kún tàríìfù DSTV
Oríṣun àwòrán, Twitter/Super Sport
Ti ko ba nidi, obinrin kii jẹ ikumolu. Ileeṣẹ MultiChoice Group to ni ileeṣẹ amohunmaworan DSTV ti ṣalaye fawọn ọmọ Naijiria ohun to ṣe okunfa bi wọn ti gbowo le tariifu ẹrọ amohunmaworan naa.
Ileeṣẹ MultiChoice Group bi ijọba apapọ ti ṣe afikun owo ori VAT, epo rọbi  ati ina mọnamọna lo jẹ kawọn naa gbowo le DSTV.
Oludari ileeṣẹ MultiChoice Group, John Ugbe lo sọrọ yii niwaju igbimọ ile aṣoju-ṣofin to ṣe iwadii afikun owo tariifu DSTV.
O tun fesi lori bi awọn eeyan kan ti n sọ pe ileeṣẹ naa ko ṣe eto iranwọ fawọn ọmọ Naijiria lasiko coronavirus, MultiChoice Group ni ohun ti gbe biliọnu kan naira fun ijọba apapọ gẹgẹ bi owo iranwọ.
Ileeṣẹ MultiChoice Group ṣalaye siwaju si pe bi ọrọ aje to dẹnu kọlẹ ṣe n ṣakoba fawọn ọmọ Naijiria lo n ṣe akoba fun ileeṣẹ ọhun naa.
Lọjọ kẹtadinlogun oṣu kẹta 2020 yii ni ile igbimọ aṣoju-ṣoju gbe igbimọ kan kalẹ lati ṣe iwadii afikun owo tariifu DSTV ni Naijiria.
coronavirus prevention badge update: Wo òótọ́ àti irọ́ tó wà nínú báàjì àyà náà
Bakan naa ni ile tun pinnu lọjọ keji oṣu kẹfa pe ki ileeṣẹ DSTV wa wi tẹnu rẹ lori ọrọ tariifu naa.
Ninu ọrọ rẹ, alaga igbimọ to n ṣe iwadii ileeṣẹ DSTV, Unyime Idem sọ pe ile bẹrẹ iwadii lẹyin tawọn ọmọ fi ẹhonu han lori afikun owo tariifu DSTV.
Ile ti sun ijoko lori ọrọ naa siwaju lai lọjọ lẹyin ijoko ọjọ Aje.
Abayọmi Aranmọlatẹ, Dr Laser: Vagino Plasty àti iṣẹ́ abẹ ẹwà Obìnrin ló jẹ mí lógún
Ondo police accident: Ọlọ́pàá mẹ́sàn án tó farapa nínú ìjàmbá ọkọ̀ Akure t'éèyàn méjì ti kú sì wà nílé ìwòsàn
Oríṣun àwòrán, Facebook/AIT Online
Awọn ọlọpaa mẹsan an to farapa ti wọn farapa ninu ijamba ọkọ to ṣẹlẹ lọjọ Iṣẹgun si n gba itọju lọwọ nile iwosan.
Kọmiṣọnna ọlọpaa ipinlẹ Ondo, Bolaji Salami lo sọ bẹẹ fun BBC Yoruba.
O ni awọn ọlọpaa naa ni o ba iṣẹlẹ naa lọ, yatọ si awọn to farapa.
Amọ, kọmiṣọnna Salami ṣalaye siwaju sii pe oun ko le sọ gbogi ohun to ṣe okunfa iṣẹlẹ ọhun.
O ni iwadii si n lọ lọwọ lori ohun to fa iṣẹlẹ ijamba ọkọ naa lopopona papakọ ofurufu niluu Akure.
Ìya Emma oní POS ṣẹ̀ṣẹ̀ rékọjá lọ síbí ilé yẹn ni àtọmọdé, ó sì wó pa wọ́n - Láńlọọ̀dù Obalende
Awọn kan sọ pe ere aṣaju lo fa a nigba ti awọn miiran taya ọkọ ti wọn wa ninu lo fọ lori ere eyi to mu ki ọkọ naa bẹrẹ si ni gbokiti.
Awọn ọlọpaa ọhun ti wọn jẹ mọkanla ninu ọkọ n bọ lati ọfiisi ajọ eleto idibo INEC nibi ti wọn ti fun Gomina Rotimi Akeredolu ni iwe ẹri moyege lẹyin to wọle ibo gomina Ondo nigba ti ijamba naa ṣẹlẹ.
Sotitobire: Ọkọ mi kò mọ̀ Jegede PDP rí, kódà kò fa ẹnikẹ́ni kalẹ̀ dípò Akeredolu- Bisola
Ọlọ́pàá méjì dèrò ọ̀run nínú ìjàmbá ọkọ̀ l'Akure lẹ́yìn tí wọ́n kúrò níbi tí Akeredolu ti gba ìwé-ẹ̀ri moyege
Ọlọpaa meji ti dero ọrun ninu ijamba ọkọ to ṣelẹ lopopona papakọ ofurufu ilu Akure lonii ọjọ kẹtala oṣu kẹwaa ọdun 2020 yii.
Kọmiṣọnna ọlọpaa ipinlẹ Ondo, Bolaji Salami lo fidi ọrọ naa mulẹ fun BBC Yoruba.
Oríṣun àwòrán, Twitter/@femi_desmond
Ọga ọlọpaa naa ni awọn ọlọpaa ọhun ti wọn jẹ mọkanla ninu ọkọ ti wọn n bọ lati ọfiisi ajọ eleto idibo INEC nibi ti wọn ti fun Gomina Rotimi Akeredolu ni iwe ẹri moyege lẹyin to wọle ibo gomina Ondo nigba ti ijamba naa ṣẹlẹ.
Ọgbẹni Salami ni awọn ọlọpaa ọhun n pada si ibi ti wọn ti n ṣiṣẹ ni ijamba naa ti ṣẹlẹ.
Ọga ọlọpaa Ondo ni oun gbọ pe taya ọkọ ti wọn wa ninu rẹ lo fọ lori ere ti ọkọ naa si bẹrẹ si ni gbokiti.
O fikun ọrọ rẹ pe oun n lọ si ile iwosan tawọn ọlọpaa mẹsan an to mori bọ ti n gba itọju.
EndSars, End SWAT, Nigeria protest: Buharii ní àkókò tó táwọn ọ̀dọ́ yóò fòpin sí ìwọ́de náà
Oríṣun àwòrán, Senatengr
Aarẹ Muhammadu Buhari ti n ba awọn aṣiwaju ile igbimọ aṣofin apapọ jiroro nibi ipade kan lori ipo ti Naijiria wa bayii.
Gẹgẹ ba ti gbọ, afojusun ipade ọsan ọjọ Isinmi naa ni lati wa nnkan ṣe sawọn ẹdun ọkan tawọn ọdọ to n sewọde gbe siwaju ijọba, eyi to da lori ọna lati dẹkun iwa kotọ awọn ọlọpaa.
Aarẹ ile aṣofin agba, Sẹnetọ Ahmad Lawan pẹlu olori ile aṣofin-ṣoju, Fẹmi Gbajabiamila si lo n ba aarẹ se ipade naa.
Amugbalẹgbẹ fun aarẹ Buhari lori ọrọ ibanisọrọ ori ayelujara, Bashir Ahmad lo fi eyi sita loju opo Twitter rẹ, @BashirAhmad.
Wo àwọn ọ̀nà tí o lè gbà láti di ọjọ́ ogbó pẹ̀lú olólùfẹ́ rẹ
Lẹyin ipade naa, aarẹ ile aṣofin apapọ, Sẹnetọ Ahmad Lawan ṣalaye fun awọn akọroyin pe, ijọba apapọ ti tẹwọ gba gbogbo ẹhonu awọn ọdọ to n wọde naa.
O fikun pe asiko to fun wọn lati dẹkun iwọde naa, ki wọn le fun ijọba lanfani ati aaye lati mojuto awọn ẹhonu ti wọn gbe kalẹ.
Oríṣun àwòrán, Instagram/profosinbajo
Ẹyin ọmọ Naijiria ẹ jeburẹ o, ẹ forijin wa, lootọọ lo yẹ ki ijọba apapọ ti wa nkan ṣe si ọrọ awọn olufẹhonuhan lori ọlọpaa #EndSARS / End SWAT.
Igbakeji aarẹ orilẹede Naijiria, Ọjọgbọn Yemi Osinabjo lo sọrọ yii ninu atẹjade kan to fi sita to si tun wa loju opo Twitter rẹ.
Ọjọgbọn Osinbajo ni ''mo mọ pe ẹ n binu, o si yẹ bẹẹ. O ye mi yekeyeke bi ọpọ ọdọ orilẹede ni inu wọn ko dun.''
''Ọpọ lo ro pe a ti dakẹ ju lọri ọrọ to wa nilẹ wi pe igbesẹ ijọba kudiẹ kaato. Wọn jare wa,'' Osinbajo lo sọ bẹẹ.
Igbakeji Aarẹ ni ''ọgọọrọ ọmọ Naijiria ni awọn ọlọpaa ti fi iya jẹ lọna aitọ, eyi ko si bofin mu.''
''Ojuṣe wa ni lati daabo bo awọn ọdọ papaa julọ lọwọ awọn ti ijọba n sanwo fun un lati daabo bo wọn,'' Ọjọgbọn Osinbajo lo woye bẹẹ.
Osinbajo gbagbọ pe iwọde #EndSARS to n lọwọ kaakiri orilẹede Naijiria ju ọrọ awọn ọlọpaa to n dunkoko mawọn ọdọ lọ nikan.
O ṣalaye pe ijọba ti n ṣe ipade pẹlu awọn tọrọ kan lati ojutu si ohun tawọn ọdọ to n ṣe iwọde n beere fun.
''Emi fun ra mi ni alaga ipade pẹlu awọn gomina ipinlẹ mẹrindinlọgbọn ati minisita olu ilu Naijiria, Abuja nibi ti a ti gbe igbimọ ti yoo ṣe iwadii iwa ika tawọn ọlọpaa #SARS ti hu.
Bakan naa ni igbakeji Aarẹ kẹdun pẹlu idile Jimoh Isiaq ti ibọn ọlọpaa pa niluu Ogbomoso atawọn mii naa to ti ba iwọde #EndSARS lọ.
End SARS, End SWAT: Ó pé mi bí SARS kò ṣe sọ mí dolówọ́- Fulani Kwajafa
Mi ò mọ̀ nípa àwọn tọ́ọ̀gì tó da ìwọ́de EndSARS Alausa rú, mo ṣì wà lẹ́yìn yín digbí! - Sanwoolu
Ijọba ipinlẹ Eko ti ni oun ko lọwọ ninu idaru to waye nibi iwọde EndSARS to waye ni agbegbe Alausa ipinlẹ Eko.
Wọn si ni awọn kọ lawọn ṣe onigbọwọ awọn janduku to ṣaadede ya wọ ibẹ lati da iwọde ti awọn ọdọ n ṣe lodi si iwa aburu ti awọn ọlọpaa Naijiria n hu.
Kọmiṣọnna eto iroyin ni ipinlẹ Eko, Gbenga Omotoso ninu atẹjade kan to fi sita ni ẹsun naa to n ja ranyin ranyin lori ayelujara jẹ ete awọn ọta lati ko nkan jọ lodi si ijọba.
Oríṣun àwòrán, twitter/babajide Sanwoolu
O ni, bẹẹ, ijọba ipinlẹ Eko lo ti n ṣa gbogbo ipa lati yanju iṣoro to wa nilẹ nipa gbigbaruku ti awọn ọdọ ninu akitiyan lati wa alaafia Naijiria.
Bakan naa gomina Babajide Sanwoolu fi si oju opo instgram pe oun ni imọlara ohun tawọn ọdọ n ja fun torinaa ko ṣeeṣe ki oun tun ran awọn janduku lati wa da iwọde wọn ru.
Mo bu ẹnu atẹ lu ikọlu to waye yii mi o si laye laye gbe lẹyin mọndaru ati iwa ipa si araalu.
Gomina Sanwoolu fi idaniloju han pe awọn ti y a ipinlẹ Eko sọtọ lati faaye gba awọn igbesẹ awọn oluwọde tori pe nkan to tọ ni wọn n ṣe.
Lowurọ ọjọbọ ọsẹ yii ni awọn janduku ti wọn dira pẹlu ohun ija ṣaadede yabo ibi ti awọn ọdọ ti n ṣe iwọde ni agbegbe Alausa ni Eko nibi to jẹ pe awọn ọdọ kan sun mọju niwaju ọfiisi gomina.
Sotitobire: Ọkọ mi kò mọ̀ Jegede PDP rí, kódà kò fa ẹnikẹ́ni kalẹ̀ dípò Akeredolu- Bisola
Bi ẹ ko ba gbagbe, igba keji ree ti gomina Sanwoolu yoo yọju si awọn oluwọde koda o tun ba gbe patako soke.
Ati pe o tun diidi gbera lọ silu Abuja lati lọ jiṣẹ awọn ọdọ fun aarẹ to si gba esi bọ fun wọn.
Oríṣun àwòrán, Twitter/Nigerian Army
Ẹ lọ ki ọwọ ọmọ bọ aṣọ, bii bẹẹ kọọ, ẹ o kan idin ninu iyọ. Bayii ni ileeṣẹ ọmọ-ogun ori ilẹ ṣe kilọ fawọn to n ṣe iwọde #EndSARS kaakiri Naijiria.
Ninu atẹjade ti ileeṣẹ ologun ori ilẹ fi sita, wọn ni awọn sọja ṣetan lati lo gbogbo agbara wọn lati daabo bo ijọba awarawa orilẹede Naijiria.
Adele alukoro ile iṣẹ ologun Naijiria, Col Sagir Musa, to fi atẹjade ọhun sita ṣalaye pe ileeṣẹ ologun wa lojufo lati rii pe alaafia jọba ni Naijiria ni gbogbo igba.
O sọ ninu atẹjade ọhun to fi si oju opo Facebook ileeṣẹ ologun ori ilẹ pe Aarẹ Muhammadu le fi ọkan tan awọn ọmọ-ogun Naijiria lọjọkọjọ.
Col Musa sọ pe awọn omogun oriilẹ Naijiria duro gbọingbọin lẹyin Aarẹ Buhari ati iwe ofin orilẹede Naijiria bakan naa.
Ileeṣẹ ologun wa rọ ẹnikẹni to ba fẹ da rogbodiyan silẹ tabi ṣe ohun kohun to le dunkoko mọ ijọba awarawa Naijiria pe ki wọn semẹdọ.
Adele alukoro ile iṣẹ ologun Naijiria tun rọ awọn ọmọ-ogun pe ki wọn wa lojufo lai bikita ohun tawọn to n da rogbodiyan silẹ n ṣe.
End SARS, End SWAT: Ó pé mi bí SARS kò ṣe sọ mí dolówọ́- Fulani Kwajafa
Bakan naa nileeṣẹ ọmogun sọ fawọn araalu pe ki wọn fọkan balẹ, wọn ni awọn ṣetan lati daabo bo wọn.
Amọ yii ko ba ọpọ eeyan lara mu lori ayelujara.
@peterparne ni tiẹ sọ pe awọn meji lo n tako alaafia ati iṣọkan orilẹede Naijiria lẹyin to kọkọ ki wọn ku iṣẹ.
O ni ijọba fun ra rẹ ati ẹgbẹ agbesunmọmi Boko Haram lo n tako alaafia orilẹede Naijiria.
Ọpọ awọn ọdọ ti wọn lara awọn to n ṣe iwọde ni wọn fesi pe alaafia lawọn n lepa, ati pe iwọde wọọrọwọ lawọn n ṣe.
Eegunjobi Omotanbaje Ajobiewe- Èébú ní wọ́n kọ́kọ́ ń bù mí nígbà tí mo bẹ̀rẹ̀ ẹ̀ṣà pípé ní
Wọn ni alaafia lawọn n lepa lo jẹ kawọn maa ṣe ifẹhọnuhan eyi ti ko lodi si ofin.
Ẹ wo èrò bìbà níbi ìwọ́de #EndSARS ní ìlú Ibadan
Kaka ki ewe agbọn agbọn dẹ, niṣe lo n le koko si. Iwọde #EndSARS ti gberasọ niluu Ibadan naa lẹyin ti o ti mulẹ tan niluu Eko.
Opopona mọrosẹ agbegbe Iwo Road ni ilu Ibadan ti kun fọfọ fun ọgọrọ awọn ọdọ to n wọde tako ọlọpaa SARS.
Lilọbibọ ọkọ ti dawọ duro lati owurọ oni ọjọ kẹtala oṣu kẹwa ọdun 2020 yii.
Pupọ ninu awọn ero ọkọ lo n bọọlẹ ti wọn si n fi ẹsẹ wọn rin lọ si ibi ti ọkọ n gbewọn lọ.
EndSars, EndSwat: Ọlọ́pàá ti fi ìbọn lù mí láyà rí torí mó ní 'extra tyre' méjì- afẹ́hònúh
Wọnyii ni awọn aworan bi iwọde #endSARS ṣe n lọ niluu Ibadan.
Oluwo jọgbọdọ Orunmila àti àwọn eeyan rẹ nibi iwọde #End Sars ati #Sarsmustend to n lọ lọwọ ni ilu Ibadan.
coronavirus prevention badge update: Wo òótọ́ àti irọ́ tó wà nínú báàjì àyà náà
A máa ná N10.2 bílíọnù fi tún wáyà iná àti inú ilé Aso Rock ṣe- Buhari
Wo ìdí tí Tẹni, ọ̀dọ́mọdé olórin obìnrin kìí fi ń ṣí ìhòhò rẹ silẹ̀
Wo ìgbà mẹ́rin tí ìjọba ti tú ikọ̀ ọlọ́pàá SARS ká sẹ̀yín ṣùgbọ́n....
Wọ́n kò pa ẹnikẹ́ni sí ààfin Ṣọun Ogbomosọ, òkú tí àwọn ọdọ́ gbé wa ni ọlọ́pàá wọ́ jáde- Agbẹnusọ Ṣọ̀un
Àwọn aṣòfín ní ìpínlẹ̀ Edo ti yọ Abẹnugan Ilé, Francis Okiye bí jìgá
Mọ̀ sí i nípa díẹ̀ lára àwọn èèyàn tí ikú wọn 'láti ọwọ́ ọlọ́pàá' milẹ̀ tìtì ní Nàìjíríà
Ènìyàn 17 kú nínú ìjàmbá ọkọ̀ mẹ́ta tó ṣẹlẹ̀ ní Osun, òpópónà Ibadan sí Eko àti Delta
Ẹ bá mi tú gbogbo àwọn Olùwọ́de #End SARS tí ẹ mu ní ìpínlẹ̀ Eko sílẹ̀- Gomina Sanwo Olu
Kò gbọdọ̀ sí ìfẹ̀họ́núhàn EndSARS ní ìpínlẹ̀ Rivers - Gomina Wike
Oríṣun àwòrán, Empics
EndSARS protest in Nigeria: Mr Macaroni, Falz, Wizkid, Tiwa Savage àtàwọn míì ṣe ìwọde
EndSARS School Resumption: Àwọn akẹ́kọ̀ọ́ lè padà sílé ìwé láti ọjọ́ Ajé - Ìjọba ìpińlẹ̀ Eko
Oríṣun àwòrán, Lagos state Govt/twitter
Ìjọba ìpínlẹ̀ Eko ti kéde pé àwọn àkẹ́kọ̀ọ́ nílé ẹ̀ka ìjọba àti àládàni lé wọle pada sẹ́nu ékọ́ wọ́n láti ọja Aje, ọjọ́ keji, Osu kọkanla, ọdún 2020.
Kọmísọ́nà ètò ẹ̀kọ́ arábìnrin Folasade Adefisayo ló sọ èyí di mímọ̀ nínú àtẹ̀jáde kan to fọ́wọ́si lọ́jọ́bọ̀.
"Àtéjáde náà to ka báyìí pé, "" Ìjọba ìpínlẹ̀ Eko ti buwọ́lu ki àwọn akẹ́kọ̀ọ́ padà sí ilé ìwé yálà nilé ìwé alákọ̀ọ́bẹ̀rẹ̀ ni tàbi aládàni jákèjádò ìpińlẹ̀ Eko lọ́jọ́ keji, Osu kọkanla, sùgbọn àwọn tó ń gbe ilé ìwé le wọle ni ọjọ́ Aiku, ọjọ kini oṣu Kọkanla."
Oríṣun àwòrán, Lagos state
Ìjọba ìpínlẹ̀ Eko ti iléèwé pa nítorí ìwọ́de #EndSARS
Oríṣun àwòrán, @Sanwo Olu
Ijọba ipinlẹ Eko ti ti ileewe pa ti o si ti paṣẹ ki gbogbo awọn akẹkọọ ileewe ijọba ati ti aladani o fi idi mọle nitori wahala iwọde #ENDSARS to n lọ lọwọ.
Kọmiṣọna feto Ẹkọ, arabinrin Fọlaṣade Adefisayọ to kede eyi ni nitori abo ẹmi ati dukia awọn akẹkọọ , obi atawọn olukọ wọn ni wọn fi gbe igbesẹ yii.
O wa rọ awọn obi ati alagbatọ lati mojuto awọn ọmọ wọn ki wọn maa baa di ohun elo fawọn  to lee fẹ sa asawọ wọ inu iwọde naa lati sọọ di ọna ati da rugudu silẹ lawujọ.
Bakan naa lo tun rọ awọn ileewe lati lo awọn ọna ikẹkọ ori ayelujara fi maa kọ awọn akẹkọọ wọn naa titi di igba ti wọn yoo fi kede ọjọ iwọle tuntun.
Oríṣun àwòrán, Babajide Sanwo-Olu/twitter
Gomina ipinlẹ Eko, Babajide Sanwo-Olu ti kede pe ọwọ ijọba ti tẹ diẹ lara awọn ọlọpaa to mu awọn oluwọde #EndSARS nipinlẹ Eko.
Awọn ọlọpaa naa ni Isipẹkitọ Bagou Michael, Isipẹkitọ Ekpoudom Etop, Sajẹnti Nnamdi Majura, ati Sajẹnti Akinyemi Benson.
Gomina sọ pe awọn ọlọpaa naa ti n koju igbimọ olubawi nileeṣẹ ọlọpaa ni kiakia., ati pe ijọba yoo mojuto igbẹjọ wọn.
Oríṣun àwòrán, @Sanwo Olu
Yatọ si eyi, Sanwo-Olu tun kede pe ijọba ti ṣeto miliọnu lọna igba Naira, lati fi tu awọn eeyan to kagbako ifiyajẹni lọwọ ọlọpaa,  ati igbimọ oluwadii ti yoo ṣe amojuto rẹ.
Bakan naa lo sọ pe ijọba ti ṣiṣẹ lori awọn fidio ati aworan to jade sori ayelujara ni Ọjọbọ, eyi to safihan bi awọn janduku to kọlu awọn oluwọde kan ni Alausa, ṣe n sọkalẹ ninu ọkọ BRT to jẹ ti ijọba.
Ọgbẹni Sanwo-Olu sọ pe awọn ri diẹ lara wọn tọka si, ti ileeṣẹ ọlọpaa yoo si tọpasẹ wọn de ibuba wọn lati ri i pe wọn jẹ iya ẹṣẹ wọn.
Oríṣun àwòrán, @Apata
Ẹgbẹ awọn agbẹjọrọ ni Naijiria ti a mọ si Nigerian Bar Association (NBA) ti kede pe awọn ṣetan lati pese iranl\woọ fun gbogbo oluwọde ti awọn agbofinro sọ si gbaga nitori iwọde #EndSARS.
Olumide Apata to jẹ Aarẹ ẹgbẹ naa lapapọ ni Naijiria lo kọkọ fi ikede yii sori ikanni ayelujara twitter rẹ ki ọpọ awọn agbẹjọrọ miran to maa tun ṣe ikede kan naa loju opo ibararẹnisọrọ wọn kaakiri.
EndSARS protest in Nigeria: Mr Macaroni, Falz, Wizkid, Tiwa Savage àtàwọn míì ṣe ìwọde
O ni ọrọ iwa tani-o-mumi ti awọn ọlọpaa kogberegbe FSARS ti ijọba ṣẹṣẹ tuka yii kọja bẹẹ lori awọn iroyin to lu ayelujara pa lasiko yii.
Apata ni awọn ọlọpaa kogberegbe naa kii bọwọ fun ofin ibọwọ fun aabo awọn ara ilu.
Ni eyi to bi awọn iwọde ninu ojo ati ninu oorun yii.
Apata fidi ẹ mulẹ pe ẹgbẹ awọn agbẹjọro ti ṣetan lati ṣatilẹyin fun iwọde alaafia to n lọ lọwọ naa.
Apata ni koda, ẹgbẹ NBA ti gbe igbesẹ pẹlu agbẹjọrọ agba awọn ipinlẹ bii Ogun, Eko ati Edo.
Sotitobire: Ọkọ mi kò mọ̀ Jegede PDP rí, kódà kò fa ẹnikẹ́ni kalẹ̀ dípò Akeredolu- Bisola
Apata ni NBA ṣetan lati ṣiṣẹ papọ fun idagbasoke Naijiria ati pe ki awọn eeyan le bọwọ fun ofin ati ẹtọ awọn ọmọ Naijiria.
Eegunjobi Omotanbaje Ajobiewe- Èébú ní wọ́n kọ́kọ́ ń bù mí nígbà tí mo bẹ̀rẹ̀ ẹ̀ṣà pípé ní
Obalende Building Collapse: Gbogbo àwọn to há sọ́bẹ́ ilé tó wó la mọ̀
Igbakeji alaga ẹgbẹ awọn Lanlọọdu ni agbegbe Odo nibi ti ile alaja mẹta ti wo ni Obalende, Eko sọ fun BBC Yoruba pe bi mọlẹbi ni gbogbo awọn to n gbe ni Obalende.
O ṣalaye bi iṣẹlẹ̀ naa ṣe  ṣakoba fun ọpọlọpọ idile. Ṣe ni arabinrin Ebun Ekemode n darukọ awọn to ba iṣẹlẹ naa rin ni kọọkan.
"O menuba pe: ""Gbogbo awọn to ṣẹlẹ si ko seyi ti ko lẹjẹ lọrun ninu gbogbo wọn."
"Awọn to n ta ounjẹ, ọmọde to wọle lọ kirun, awọn oṣiṣẹ to n kọle gan gbogbo wọn lo ku sabẹ ile naa""."
O fọn ipe si ijọba pe nibayii, gbogbo ipele ile kikọ ni ki ijọba maa wa yẹwo lati rii daju pe kii ṣe ayederu ohun elo ni wọn n lo.
Welder Rape: Adájọ́ rán bàbá ọlọ́mọ méjì tó fi ipá bá ọmọ ọdún mẹ́rin lò pọ̀ lẹ́wọ̀n gbére
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ile ẹjọ giga kan ni ilu Akure ni ipinlẹ̀ Ondo ni guusu Iwọ oorun Naijiria ti dajọ ẹwọn gbere farakunrin oniṣẹ jorin-jorin kan to fipa ba ọmọdebinrin ọmọ ọdun mẹrin lo pọ.
A gbọ pe arakunrin naa, Modupe Oni, ṣe aṣemaṣe yii nilu Ifon ni ijọba ibilẹ Ose.
O sọ fun adajọ pe oun ko jẹbi ẹsun naa.
Gẹgẹ bi ileeẹjọ ti ṣe fidi ọrọ naa mulẹ, wọn ni Oni fipa ba ọmọde naa lopọ nigba ti o wa ra ẹpa lọdọ iyawo rẹ.
Iyawo rẹ ko si nile lo ba tan ọmọ naa wọ inu iyara to si fipa ba a lajọṣepọ.
EndSARS protest in Nigeria: Mr Macaroni, Falz, Wizkid, Tiwa Savage àtàwọn míì ṣe ìwọde
Nigba ti ọmọ naa yoo fi pada de ile, o tu kẹkẹ ọrọ fawọn obi rẹ ti wọn si sare gbe e lọ si ile iwosan.
Nibẹ ni ayẹwo ti fihan pe lootọ ni wọn fipa ba a lopọ.
Say no to rape: Àwọn òṣèré tíátà Yorùbá pariwo síta lórí wàhálà ìfipábánilòpọ̀
Lasiko igbẹjọ agbẹjọro ijọba pe ẹlẹri mẹrin wa ti afurasi naa si jẹri niwaju Adajọ fun ara rẹ.
Oni sọ pẹ ọrọ naa ko ribẹ ṣugbọn Adajọ Samuel Bola ni ọrọ to sọ niwaju ile ẹjọ yatọ si eyi to kọsilẹ lọdọ ọlọpaa.
Abayọmi Aranmọlatẹ, Dr Laser: Vagino Plasty àti iṣẹ́ abẹ ẹwà Obìnrin ló jẹ mí lógún
Lẹyin naa lo dajọ ẹwọn gbere fun baba ọlọmọ meji naa.
Lẹyin eyi ni Adajọ Oni gboriyin fun ọmọdebinrin naa pe o dara to ni igboya lati sọrọ sita.
Rape: Ayé obìnrin tí wọ́n fipábálòpọ̀ kò lè rí bákàn náà mọ́
Otedola bridge fire: Ọkọ̀ akẹ́rù rí ìjánu rẹ̀ já ló kọlù ọkọ̀ agbépo tó fa ìjàmbá iná ní Otedola lópópónà Lagos-Ibadan- LASEMA
Oríṣun àwòrán, @LASEMA
Ajọ to n mojuto iṣẹlẹ pajawiri loju popo ni ipinlẹ Eko, LASEMA ti sọrọ lori ohun to ṣẹlẹ ninu ijmaba ina afara Ọtẹdọla.
Alaga ajọ naa, ọmọwe Olufemi Damilola Oke-Osanyintolu lo fi soju opo ayelujara bi ọrọ naa ṣe ṣẹlẹ.
Oríṣun àwòrán, LASEMA
O ni laago meji oru oni ni LASEMA gba ipe nipa ijamba ina naa lopopona Eko si Ibadan.
Leyin naa lo ni awọn Osise LASEMA dide si didẹwọ ina naa.
Ki lo fa ijamba ina naa?
Alaga ajọ LASEMA ṣalaye pe kete ti wọn de sibẹ ni wọn ri i pe ọkó akẹru to tobi to iwọn ogoji ẹsẹ bata to kun fun aṣọ oriṣiriṣi to n gbe lọ ni ijanu ọkọ rẹ ja.
Wọn ni eyi ṣẹlẹ lasiko ti ọkọ naa morile agbegbe Berger ni ijanu rẹ naa ja.
Oríṣun àwòrán, @LASEMA
Ọkọ akẹru yii lo wa lọ kọlu ọkọ agbepo bẹntiroo oni lita ẹlẹgbẹrun metalelọgbọn.
Bi wọn ṣe kọlura wọn yii lo jẹ ki ina sọ ti o si di ijamba naa.
Ogbomsho shooting, End Sars, End SWAT: Isiaka fi ọmọbìnrin kan àti ìyàwó tó lóyún sínú síl
Ajọ LASEMA, ẹṣọ oju popo, FRSC, ati LNSC naa ti tete de ibẹ lati mojuto iṣẹlẹ naa ko ma pọ ju bẹẹ lọ.
LASEMA ni ko si ẹni to ku ninu iṣẹlẹ naa ninu eyi ti wọn ti n dari awọn ọkọ ki wọn gba ọna Ọjọta tabi 7 Up lati din sunkẹrẹ-fakẹrẹ ọkọ ku.
Wọn ni awọn ti gbe ajoku awọn ọkọ mejeeji kuro nibẹ.
Igbokegbodo ọkọ si ti n lọ bi o ti yẹ loju opopona Eko si Ibadan bayii
Gbajúgbajà òsèré tó tún mọ́ ọbẹ̀ sè
Saaju laarọ oni ọjọ Satide:
Ọkọ̀ agbépo méjì gbiná ní orí afárá Otedola ní ìpínlẹ̀ Eko!
Tanker explosion on Otedola bridge: Ọkọ̀ agbépo gbiná ní orí afárá Otedola!
Iroyin to n tẹ wa lọwọ ni pe ko sẹni to tii le mọ iye eeyan to ba iṣẹlẹ naa rin bayii
Oríṣun àwòrán, others
Ọkọ agbepo meji ti gbina lori afara Otedola ni agbegbe Berger ni ipinlẹ Eko ni idaji oni.
Laarọ kutu oni, ọjọ abamẹta, ọjọ ketadinlogun, oṣu kẹwaa ni iṣẹlẹ yii ṣẹlẹ.
Ọpọlọpọ lo ti fi si oju opo twitter wọn ohun to n ṣẹlẹ ni afara Otedola bayii
Wọn ni ọkọ agbepo mejeeji naa ni epo rọbi wa ninu wọn.
Titi di asiko yii, a ko tii le só ohun to ṣokunfa iṣẹlẹ naa ati iye awọn ti iṣẹlẹ naa kan.
A o maa mu wa fun yin ohun to ba selẹ nibẹ......
End SARS, End SWAT: Ó pé mi bí SARS kò ṣe sọ mí dolówọ́- Fulani Kwajafa
Ki lo ti kọkọ ṣẹlẹ sẹyin?
A ti yanjú ìṣẹ̀lẹ̀ ìjàmbá ọkọ̀ agbépo tó dànù lágbègbè AIT, Alagbado - LASEMA
Alagbado tanker overturned: Àjọ LASEMA láwọn ti yanjú ìṣẹ̀lẹ̀ ìjàmbá ọkọ̀ agbépo tó dànù lágbègbè AIT, Alagbado
Oludari agba ajọ LASEMA ni  awọn ti di gbogbo ibi ti iṣẹlẹ yii ti waye pẹluu kiki foomu ki iṣẹlẹ naa ma tun lọ bi omii.
Oríṣun àwòrán, Twitter/LASEMA
Iṣẹlẹ ọkọ agbepo to dawo ni agbegbe ibi ti ileeṣẹ amohunmaworan AIT wa ni Alagbado, ipinlẹ Eko ti ni iyanju bayii.Ajọ to n ri si iṣẹlẹ pajawiri nipinlẹ Eko, LASEMA lo fi atẹjade sita pe awọn ti gbe ọkọ naa to gun to iwọn ẹsẹ bata ogun le awọn ọlọpaa lọwọ ki wọn maa ba iṣẹ lorii rẹ.Oludari agba ajọ LASEMA, Ọmọwe Olufemi Oke-Osayintolu ni  awọn ti di gbogbo ibi ti iṣẹlẹ yii ti waye pẹluu kiki foomu ki iṣẹlẹ naa ma tun lọ bi omii.
Awọn ileeṣẹ mii to pawọpọ pẹlu ajọ LASEMA fun aṣeyọri iṣẹ naa ko ma baa pa awọn olugbe agbegbe naa lara ni ileeṣẹ panapana ipinlẹ Eko atawọn ọlọpaa.Nibayii, ohun gbogbo ti pada bọ sipo ti igbokegbodo ọkọ si ti bẹrẹ pada.
Ẹ ṣọ́ra ní òpópónà AIT, ọkọ̀ agbépo kan ti yí dánù lọ́nà agbègbè Alagbado
Ileeṣe to n ri si iṣẹlẹ pajawiri ni ipinlẹ Eko, LASEMA, ti kede pe ọkọ agbepo kan ti yi danu lagbegbe Alagbado ni Eko.
Wọn ni nọmba ọkọ agbepo to yi danu naa ni: LSROIXX.
Oríṣun àwòrán, @LASEMA
Ọkọ agbepo naa ni wọn ni o jẹ toni iwọn ogun ẹsẹ bata.
Ọmọwe Femi Damilola Oke-Osanyitolu to jẹ adari ajọ naa lo fi soju opo wọn.
Ajọ LASEMA ni o dabi pe awakọ agbepo naa n sare ni ko to ṣubo.
Titi di asiko ti iroyin yii n jade, epo inu rẹ ko tii maa danu si oju titi ṣugbọn LASEMA n kilọ fawọn eniyan agbegbe opopona AIT ni alagbado pe ki wọn ṣọra ṣe nibẹ.
Ati pe ki énikẹni ma ṣe da ina kankan lasiko yii nibẹ.
Oríṣun àwòrán, @LASEMA
Ṣaaju nibẹrẹ ọsẹ yii:
Ìjàmbá ọkọ̀ akérò àti tírélà pa èèyàn mẹ́rin lọ́nà mọ́rosẹ̀ Ore sí Benin
Ore-Benin Road accident: Ìjàmbá ọkọ̀ pa èèyàn mẹ́rin lọ́nà mọ́rosẹ̀ Ore sí Benin
Ọkọ akero ẹlẹni mẹrinla to n rinrin ajo lati ilu Eko lọ si Enugu ni a gbọ pe o lọ fori sọ ọkọ tirela laarọ ọjọ Iṣẹgun.
Oríṣun àwòrán, Faceboo/Frscedo Edo SEctor Command
Eeyan mẹrin lo dero ọrun ninu ijamba ọkọ to ṣẹlẹ lopopona Ọrẹ si ilu Benin ninu eyi ti awọn mẹrin miiran ti farapa.
Ọkọ akero ẹlẹni mẹrinla to n rinrin ajo lati ilu Eko lọ si Enugu ni a gbọ pe o lọ fori sọ ọkọ tirela laarọ ọjọ Iṣẹgun.
Awọn ti iṣẹlẹ naa ṣoju wọn ṣalaye pe tirela naa n lọri lọwọ ni ọkọ akero ọhun lọ kọ lu u lati ẹyin.
Oṣiṣẹ ajọ ẹṣọ oju popo, FRSC kan ṣalaye ere a-sa-ju ọkọ akero naa lo ṣokunfa ijamba ọkọ naa.
O ni ti ere rẹ ko ba pọju ni, o ṣeeṣe ki ijamba ọhun ma ṣẹlẹ.
Awọn mẹwaa lo mori bọ ninu ijamba naa nigba tawọn to farapa si n gba itọju nile iwosan.
Sotitobire: Ọkọ mi kò mọ̀ Jegede PDP rí, kódà kò fa ẹnikẹ́ni kalẹ̀ dípò Akeredolu- Bisola
Online child abuse: Ọlọ́pàá mú afurasí 31 tó ń dúnkokò máwọn ọmọdé lórí ayélujára
Oríṣun àwòrán, Twitter/Metropolitan Police
Ileeṣẹ ọlọpaa ilẹ Gẹẹsi ti mu afurasi mọkanlelọgbọn lori ẹsun idunkoko mọ awọn ọmọde lori ayelujara.
Ileeṣẹ ọlọpaa ṣi ti gba foonu atawọn ẹrọ kọmputa pẹlu awọn nkan mii to le ni ọdunrun un fun bi ọsẹ kan bayii.
Laarin ọjọ kejidinlọgbọn oṣu kẹsan an ọdun 2020 yii si ọjọ kẹta oṣu kẹwaa ni ileeṣẹ ọlọpaa mu awọn afurasi ọhun niluu London.
Ileeṣẹ ọlọpaa Met sọ pe awọn si n ṣe iwadii ọpọlọpọ ẹsun lilo iwa ipa lori awọn ọmọde nipa ṣiṣe ayẹwo foonu atawọn ẹrọ kọmputa ti wọn n lo.
Ọga ọlọpaa ọtẹlẹmuyẹ, Helen Flanagan sọ pe ileeṣẹ ọlọpaa ko beṣu bẹgba lati rii wi pe awọn daabo bo awọn araalu.
O rọ awọn obi atawọn ọdọ lati wa lojufo lori awọn ọna tawọn ọdaran kan fi n ṣakoba fawọn araalu lori ayelujara.
Sotitobire: Ọkọ mi kò mọ̀ Jegede PDP rí, kódà kò fa ẹnikẹ́ni kalẹ̀ dípò Akeredolu- Bisola
EndSWAT: Wo àwọn Májẹ̀kóbàjẹ́ tó wà nídìí ìwọ́de #EndSARS / End SWAT
Oríṣun àwòrán, others
Iwọde End SARS to n lọ lọwọ kaakiri awọn ilu nla ni Naijiria ni ọpọ awọn onwoye ohun to n lọ ti sọ pe o jẹ ọkan Pataki lara awọn iwọde to ni eto julọ ni Naijiria.
Iwọde naa to ti n gbẹnule ọjọ kẹwaa bayii ni awọn ọdọ Naijiria fi n bere fun fifopin si iwa Baṣọrun Gaa ti awọn oṣiṣẹ ẹka ileeṣẹ ọlọpaa, SARS, n hu si awọn ọdọ ti wọn n fẹsun iwa jibiti kan lọna aitọ.
Bi ọpọ ero ṣe n darapọ mọ iwọde naa lojojumọ lawọn miran n gbe igbesẹ ki ifẹhonuhan ọhun dun, ko si larinrin.
Wo diẹ lara awọn to fi adun ati aṣeyọri si iwọde End SARS naa to n lọ lọwọ:
1.Awọn elere idaraya:
Ọkan lara awọn oluwọde naa gbe alupupu Power bike rẹ wa sojuko ọhun lati da awọn eeyan laraya.
Ni agbegbe Alausa, ẹnikan tilẹ gbe kẹkẹ ati aja rẹ wa, ti oun ati aja rẹ si n fi kẹkẹ ọhun dárà.
Yatọ si eyi, ọpọ igba ni wọn maa n fi awọn orin da awọn eeyan laraya, bii orin Fela Anikulapo, Naira Marley, Eedris Abdulkareem, ati bẹẹ bẹẹ lọ.
Oríṣun àwòrán, others
2.Awọn to n kọ orin:
Ohun kan Pataki to mu iwọde End SARS ladun to si jẹ ki ijọba mọ ohun ti wọn n bere fun ni orin End SARS ti awọn oluwọde n kọ leralera.
"Bi awọn to ṣaaju ṣe n kọ orin naa ni awọn elegbe n kọ tẹle wọn pe ""End SARS!"""
End SARS, End SWAT: Ó pé mi bí SARS kò ṣe sọ mí dolówọ́- Fulani Kwajafa
3.Awọn alasia:
Isọri awọn miran to jẹ ki iwọde End SARS ni itumọ ni bi awọn eeyan kan ṣe n gbe asia orile-ede Naijiria lojuko iwọde naa.
Oríṣun àwòrán, others
Ọkunrin lara awọn eeyan naa tilẹ ti di gbajumọ nitori bo ṣe maa n gbe asia naa to si ma n ju sọtun ati si osi.
Ni Enugu, ọdọbinrin kan  tilẹ so asia naa mọ ori, o joko sori ere kan to ga to si n wa ẹkun mu nitori ohun ti awọn oṣiṣẹ SARS ti fi oju mọlẹbi rẹ ri.
Gbajúgbajà òsèré tó tún mọ́ ọbẹ̀ sè
4.Awọn onimọtoto:
Iyatọ kan gboogi to wa laarin iwọde End SARS yii ati awọn to ti kọja lọ ni bi awọn eeyan kan ṣe palẹmọ ojuko iwọde lẹyin ti awọn eeyan ba pada sile wọn tan.
Oríṣun àwòrán, Others
Awọn eeyan naa n ṣe iṣẹ takuntakun lati ri pe ko si idọti Kankan lojuko ti iwọde ti n waye.
Oríṣun àwòrán, others
5.Awọn olupese:
Isọri awọn eeyan yii ni awon to n fun awọn olufẹhonuhan ni ounjẹ ki wọn ba a le ni okun lati tẹsiwaju ninun iwọde ọhun.
Awọn ni olupese ounjẹ, omi ati ohun irinsẹ fun awọn oluwọde, bi awọn kan ṣe parapọ da owo burẹdi ni awọn miran parapọ da owo DJ ti yoo da wọn laraya.
Oríṣun àwòrán, @Falz
6.Awọn oluṣeto:
Lara awọn oluṣeto ni awọn gbajumọ lawujọ to fi ẹnu si ọrọ naa, to si n ṣatilẹyin fun awọn olufẹhunuhan.
Diẹ lara awọn oluṣeto ni a ti ri olorin takasufe, oṣere tiata ati awọn gbajumọ kaakiri agbaye.
Awọn miran lara wọn gbe owo kalẹ fun iwọde naa, bẹẹ ni awọn mii ẹwẹ n ru wọn soke lati tẹsiwaju ninu iwọde ọhun.Lara awọn eeyan ọhun ni Falz, Toyin Abraham, Kanyew West, ati bẹẹ bẹẹ lọ.
Oríṣun àwòrán, others
Ìjọba ìpínlẹ̀ Eko ti kéde orúkọ àwọn ọlọ́pàá tó fi ìyà jẹ àwọn olùwọ́de End Sars
Àjọ elétò ìdìbò kéde ọjọ́ tí ìdìbò aàrẹ Nàìjíríà 2023 yóò wáyé
Ìyá gómìnà Seyi Makinde dágbére fáyé lẹ́ni ọdún 81
Àbádòfin ìṣúná 2021 ré kọjá ìpele ìkejì nílé aṣòfin àgbà
Oríṣun àwòrán, TWITTER/
Àwọn ìṣẹ̀lẹ̀ mánigbàgbé tó wáyé nibi ìwọ́de ENDSARS Nàìjíríà
Iwọde ENDSARS to n lọ lọwọ ni Naijiria jẹ eleyi to milẹ titi.
Lati igba to ti bẹrẹ awọn ọmọ Naijiria ti tẹwọ gba a, ti wọn ni awọn yoo fi aato si ti yoo fi bi eso iyipada rere ti wọn n fẹ koda awọn to wa nilẹ okeere naa gbaruku ti wọn.
Orisirisi ni nkan to waye nibẹ ṣugbọn a ni ki a ṣe akojọpọ diẹ lara awọn ohun manigbagbe to waye nibẹ.
Àwọn ìṣẹ̀lẹ̀ mánigbàgbé tó wáyé nibi ìwọ́de ENDSARS Nàìjíríà
Oríṣun àwòrán, veeQtor
Diẹ ree ninu wọn:
Feere pinpin fawọn obinrin ni ibi iwọde Lekki jẹ nkan tawọn eeyan kan saara si.
Ohun ti wọn fi ṣe bẹẹ ree.
Niṣe ni awọn eeyan kan n fi ọwọ kan awọn obinrin lọna aitọ nibi iwọde nitori naa ni wọn fi fun wọn ni feere pe ki wọn fi pariwo sita.
Iwọde ko ni k'awọn eeyan ma sokun ifẹ pọ; ki wọn tun ṣe ayẹyẹ ọjọ ibi
Iwọde yii ti bi ọmọ orisirisi.
Bi awọn kan ti ṣe ya sidi ijo ati orin lawọn mii fi asiko iwọde polongo ifẹ ti awọn mii tiẹ sokun ifẹ pọ.
Koda awọn to ṣe ayẹyẹ ọjọ ibi wọn laarin awọn oluwọde wa.
Oríṣun àwòrán, Twitter/diranabiola
Awọn aworan bi eyi to wa labẹ yi ṣafihan awọn to ṣe ọjọ ibi ati awọn to pari igbeyawo gẹgẹ bii tọkọtaya tuntun ti a so pọ ti wọn si gba ibẹ lọ si iwọde.
Eegunjobi Omotanbaje Ajobiewe- Èébú ní wọ́n kọ́kọ́ ń bù mí nígbà tí mo bẹ̀rẹ̀ ẹ̀ṣà pípé ní
Awọn to n fi ẹbun ta oluwọde ati agbofinro lọrẹ naa ko gbẹyin:
Lasiko iwọde #End SARS yii naa ni awọn ọmọ Naijira n nawọ iranwọ sawọn oluwọde.
Bi wọn ti ṣe n gbe ounjẹ ati omi ni awọn kan n fi nkan eelo itọju alaisan to fi mọ ibomu ṣọwọ si awọn oluwọde.
Sotitobire: Ọkọ mi kò mọ̀ Jegede PDP rí, kódà kò fa ẹnikẹ́ni kalẹ̀ dípò Akeredolu- Bisola
Nilu Abuja awọn oluwọde fi imoore han plu bi wọn ti ṣe fi aworan arakunrin kan ti wọn lo fun awọn ni ounjẹ lasiko iwọde naa han lori ayelujara
Yatọ si eyi, awọn oluwọde tun fun awọn agbofinro ni omi mu laibikita pe wọn n koju awọn.
Koda, wọn nawọ ifẹ ati iranlọwọ si awọn agbofinro pe iwọde yii a bi eso atunṣe owo oṣu fun awọn ọlọpaa ti ijọba ba gba ohun ti awọn oluwọde n fẹ ki alaafia ati abo to peye le wa fun gbogbo olugbe Naijiria.
Oríṣun àwòrán, Twitter/AmDanky
Akojọpọ awọn eeyan maa n mu ki awọn eeyan da panti silẹ boya lẹyin ti wọn jẹun tan tabi ti wọn ba mu ohun mimu tan.
Oríṣun àwòrán, veeQtor
Kaakiri ibi iwọde ni awọn ọdọ ti ṣe ohun iyalẹnu kan pẹlu bi wọn ti ṣe n ko panti lẹyin ti wọn ṣe iwọde tan.
Niṣe ni awọn ọdọ Naijiria kan fi ara wọn jin lati maa ṣa awọn idọti lẹyin awọn iwọde lojoojumọ.
Oríṣun àwòrán, Gidi_Traffic
Iwa yi jẹ eleyi to mu inu ọpọ eeyan dun ti wọn si  n kan saara sawọn oluwọde naa
EndSARS protest in Nigeria: Mr Macaroni, Falz, Wizkid, Tiwa Savage àtàwọn míì ṣe ìwọde
Nibi tero ba pọ si o ṣeeṣe ki eeyan sọ nkan nu tabi ko gbagbe nkan si eeyan mii lọwọ.
Lasiko iwọde yi awọn eeyan sọ nkan nu paapaa lasiko ti o ba di pe wọn n sa fun awọn agbofinro.
Nibi tawọn eeyan ti n sa yi, awọn mii sọ foonu ati nkan ini wọn nuu.
Amọ ṣa bi wọn ti ṣe n sọ nkan nuu naa ni awọn to ri n da pada fun wọn.
EndSars, EndSwat: Ọlọ́pàá ti fi ìbọn lù mí láyà rí torí mó ní 'extra tyre' méjì- afẹ́hònúhàn
Opọ oluwọde sọrọ ilẹ kun lori ọrọ Endsars ati EndSwart ti wọn fẹ ki ijọba wa ojutu si lati gbogun ti ifiyajẹni lọna aitọ to n ṣẹlẹ si awọn eniyan Naijiria lati ọwọ awọn agbofinro.
Awọn osere ati alawada bii: Yomi Fabiyi, Jigan, Mr Macaroni atawọn èèyan fariga lori ọrọ ifiyajẹni lọna aitọ awọn agbofinro Naijiria.
Ọpọ n beere pe kini awọn oluwọde tun n fẹ lẹyin ti ijọba Buhari ti kede pe oun tu awọn ọlọpaa kogberegbe SARS ka.
Awọn oluwọde ni kii ṣe pe ki ijọba yi orukọ SARS pada si SWAT ni awọn beere fun bikoṣe pe ki ijọba foju awọn to huwa ibi han pẹlu idajọ to yẹ fun wọn.
Ki ijọba tun owo osu ọlọpaa ṣe pẹlu ilana ikọni gẹgẹ bi akọṣẹmọṣẹ agbofinro asiko yii ati bẹẹ bẹẹ lọ.
Awọn oluwọde salaye diẹ nipa awọn ohun ti wọn ti la kọja lọwọ awọn agbofinro sẹyin.Ìya Emma oní POS ṣẹ̀ṣẹ̀ rékọjá lọ síbí ilé yẹn ni àtọmọdé, ó sì wó pa wọ́n - Láńlọọ̀dù Obalende
Koda, wọn ni ija ṣẹṣẹ bẹrẹ ni titi ijọba Buhari yoo fi pese eto aabo to yẹ fun awọn ara ilu.
Àwọn jàndùkú yabò àwọn olùwọ́de #ENDSARS ní Alausa l'Eko
End Sars, End SWAT, Aisha Yesufu: Ó ní ìdí tí mo fi ń wọ Hijabu lọ ṣe ìwọ́de- Aisha
Oríṣun àwòrán, other
Ọpọ eeyan lagbaye lo mọ Aishaa Yesufu gẹgẹ bi ajafẹtọ araalu ṣugbọn ohun ti o ṣokunkun si ọpọ ni idi ti o fi jẹ pe ẹwu hijab lo yan laayo lati maa wọ fun ti iwode #ENDSARS to gbode kan lọwọ yii.
Amosa, ẹ maa laagun jina o, Aishaa Yesufu funrarẹ ti ṣalaye idi abajọ.
Oríṣun àwòrán, Others
Ninu ọrọ kan to ba BBC News sọ, Aishaa Yesufu ni aburo oun gan an lo kọkọ pe oun pe oun dabi eṣin o kọ'ku janduku ninu aworan oun ti wọn kọkọ ya nibi iwode naa ninu aṣọ yii.
Oríṣun àwòrán, others
Aisha ni ṣaaju aworan naa, ẹyin loun maa n duro si ki awon oluwode to jẹ ọdọ le e wa niwaju ki oun to wa ṣakiyesi pe awọn ọlọpaa kan fẹ maa dun mọhurumọhuru mọ wọn.
Aisha fi kun un pe awọn ọmọ oun gan a maa dara pọ mọ oun nibi iwọde biotilẹ jẹ pe ọkọ oun ko lẹmiu  ki oju aye tan si eeyan lara.
Oríṣun àwòrán, Other
O ni ohun to fa sababi ti oun fi n wọ Hijabu lọ sode iwọde EndSARS ni pe ẹsin oun fi aye rẹ silẹ.
EndSars, EndSwat: Ọlọ́pàá ti fi ìbọn lù mí láyà rí torí mó ní 'extra tyre' méjì- afẹ́hònúh
Islam, ẹsin ti mo yan laayo lo paṣẹ fun gbogbo obinrin lati maa bo ihoho wọn nibikibi ti wọn ba n lọ. Idi rẹ niyi ti mo fi n wọọ kaakiri, ṣugbọn eyi ko ni pe ki n yan ẹni ti ko ba wọọ ni pọṣin o.
Eegunjobi Omotanbaje Ajobiewe- Èébú ní wọ́n kọ́kọ́ ń bù mí nígbà tí mo bẹ̀rẹ̀ ẹ̀ṣà pípé ní
Iwọde tako ẹka ọlọpaa SARS lorilẹ-ede Naijiria ṣi n tẹ siwaju lainaani ikede ti ọga ọlọpaa patapata lorilẹ-ede Naijiria, Mohammed Adamu ṣe ni ọjọ Abamẹta pe wọn ti wọgile ẹka SARS.
Ìya Emma oní POS ṣẹ̀ṣẹ̀ rékọjá lọ síbí ilé yẹn ni àtọmọdé, ó sì wó pa wọ́n - Láńlọọ̀dù Obalende
Farting offense: Ọkùnrin yasó nínú ọkọ̀ Uber rí ẹ̀wọn he ní ilẹ̀ Gẹ̀ẹ́sí
Oríṣun àwòrán, Twitter/Uber Uk
Eleduwa ko daa akitan iso ni wọn maa n wi nilẹ ku otu o jiire. Ọrọ ko ri bẹẹ fun ọkunrin ti wọn fẹsun iwa kan kan lẹyin to yaso ninu ọkọ Uber.
Ileeṣẹ iroyin Bristol Live lorilẹede Uk fẹsun kan ọkunrin pe o yaso o si tun ṣe ikọlu fun awakọ Uber nitori pe oun fi ẹhonu han.
Agbẹjọro Anthony Bignall sọ fun ileẹjọ Bristol Crown pe iwa ti ọkunrin hu kudiẹ kaato.
Lọdun 2019 ni iṣẹlẹ ọhun ṣẹlẹ nigba ti James Mallett to n gbe ni Kingswood yaso nibi to joko si lẹyin ọkọ pẹlu awọn eeyan mẹta mii niga ti wọn n lọ si ile ijo lalẹ.
Ileẹjọ ni idunkoko mọ fun awakọ Uber naa, Aleksander Bonchev ti to gẹẹ nitori awọn ero mii naa ti ṣe ikọlu fun un lẹyin wa.
Olupẹjọ James Scutt ṣalaye fun ileẹjọ pe awakọ Uber ọhun Bonchev sọ fun Mallet pe ko kuro ninu ọkọ oun.
O ni lẹyin naa ni Mallet bẹrẹ si ni ba Bonchev ja ti o si fọwọ ba a lori.
EndSars, EndSwat: Ọlọ́pàá ti fi ìbọn lù mí láyà rí torí mó ní 'extra tyre' méjì- afẹ́hònúh
Ti were ba sun kan ogiri, were naa yoo pada, adia fun awakọ Uber to fesi pada pẹlu ẹṣẹ loju Mallet ti o si kan an mọlẹ.
Obinrin kan to wa pẹlu Mallet ni wọn sọ pe o fa a kuro nibi tawọn mejeeji ti jọ fija pẹta.
Olupẹjọ ni Ọgbẹni Mallet tun huwa ipa si awọn agbofinro nibi iṣẹlẹ naa.
Sotitobire: Ọkọ mi kò mọ̀ Jegede PDP rí, kódà kò fa ẹnikẹ́ni kalẹ̀ dípò Akeredolu- Bisola
Ṣugbọn agbẹjọro Mallet sọ fun ileẹjọ pe onibara oun kii ṣe onijagidijagan.
Lẹyin ọ rẹyin, ileẹjọ dajọ ẹwọn oṣu mẹfa fun Mallet pẹlu iṣẹ ilu fun ọjọ diẹ.
Iṣẹlẹ naa si tun mu awakọ Uber naa padanu iṣẹ rẹ lẹyin ti ko le lọ sibi iṣẹ nitori o farapa nibi iṣẹlẹ naa.
Alaafin Oyo: Kí ló ń ṣẹlẹ̀ láàfin Oyo táwọn èèyàn fi ń ki Alaafin ní mẹ́sàn án mẹ́wàá?
Oríṣun àwòrán, Facebook/Alaafin Oba Adeyemi III
Ẹni ọdun ba laye, o yẹ ko ṣọpẹ. Ọgọọrọ eeyan lo ti n ki Alaafin Oyo, Oba Lamidi Olayiwola Adeyemi kẹta ku ayẹyẹ ọjọ ibi ọdun mejilelelọgọrin loke eepẹ.
Lara awọn ọtọkulu to ti Alaafin ku ayẹyẹ ọjọ ibi ni oludije fun ipo gomina ipinlẹ Oyo fẹgbẹ oṣelu ZLP ninu idibo gbogbo ọdun 2019, Oloye Sharafadeen Alli.
Oloye Alli ni Oba Adeyemi yatọ ninu awọn ọba alaye nilẹ Yoruba nipa gbigbe aṣa ati iṣe Yoruba larugẹ.
Ninu iṣẹ ikini to fi ranṣẹ si baba, Oloye Alli sọ pe Alaafin jẹ ọba to n lepa alaafia, idagbasoke ati ilọsiwaju ilẹ Yoruba to fi mọ gbogbo orilẹede Naijiria.
O ni ko si ẹni ti ko mọ pe aṣaaju ni Alaafin ninu igbelarugẹ aṣa Yoruba nile, loko, lẹyin odi ati kaakiri gbogbo agbaye tawọn ọmọ Yoruba wa.
Bakan naa lo lu Oba Adeyemi lọgọ ẹnu lori ipa ti o n ko lati rii wi pe iran Yoruba ko gbẹyin lorilẹede Naijiria.
O gbadura pe ki Eledua fi ẹmi gigun ati alaafia ara jinki baba bi wọn ti pe ẹni ọdun mejilelọgọrin loke eepẹ.
Alaga ajọ to ri si eto ibaraẹnisọrọ ni Nigeria Communications Commission, NCC, Ọjọgbọn Adeolu Akande naa ko gbẹyin ninu awọn to n ki Oba Alaafin ku ọdun ọjọ ibi wọn.
Ọjọgbọn sọ pe ninu awọn ọlọgbọn eeyan ni Alaafin, koda o ni ẹbun nla ni Oba Adeyemi jẹ fun ilẹ Afirika.
O ni ọpọ igba ni Kabiyesi Adeyemi ti ba oun sọrọ ọgbọn laafin Oyo nigba nigba ti oun fi jẹ akọroyin fun ileeṣẹ iroyin Tribune.
EndSars, EndSwat: Ọlọ́pàá ti fi ìbọn lù mí láyà rí torí mó ní 'extra tyre' méjì- afẹ́hònúh
Ọjọgbọn Akande ni anfaani lo jẹ fun oun pe oun naa bu mu ninu omi ọgbọn Alaafin.
Oun naa gbadura ilera to peye ati ẹmi gigun fun Kabiyesi Alaafin.
Eegunjobi Omotanbaje Ajobiewe- Èébú ní wọ́n kọ́kọ́ ń bù mí nígbà tí mo bẹ̀rẹ̀ ẹ̀ṣà pípé ní
Seyi Makinde: Ọ̀sẹ̀ àkọ́kọ́ ní December ni màá sìnkú ìyá mí
Oríṣun àwòrán, @seyiamakinse
Gomina ipinlẹ Oyo, Seyi Makinde ti ṣapejuwe iya rẹ gẹgẹ bi obinrin to ni akinkanju, to ṣe gbẹkẹle, to ṣiṣẹ karakara nigba aye rẹ.
Seyi Makinde lo sọ eyi lasiko to gbalejo Deji ti ilu Akure, to ṣe abẹwo si lati ba kẹdun lori iku iya rẹ to papoda ni ẹni ọdun mọkanlelọgọrin.
Makinde ninu ọrọ rẹ sọ wi pe, iya oun to jẹ ọmọ ilu Akure fihan gbangba pe, awọn ara ilu Akure jẹ eniyan ọtọ to ṣe e fi ọkan tan.
''Ti o ba ri ọmọ ilu Akure, ohun ti wa ri ni awọn eniyan to jẹ akinkanju, ti ọrọ wọn si ṣee gbẹkẹle.
Oríṣun àwòrán, @seyiamakinse
Bakan naa ni gomina Makinde kede pe, o di ọsẹ kini, Oṣu Kejila, ọdun 2020 ki oun to ṣe oku iya oun to papoda.
Gomina wa dupẹ lọwọ Deji ti Akure fun abẹwo rẹ, to si fi da wọn loju pe, awọn ara ilu Akure yoo ko ipa ribiribi ninu eto isinku iya oun.
Bẹẹ si ni gomina ipinlẹ Oyo lo asiko naa, lati fi ki awọn eniyan ipinlẹ Ondo, fun atilẹyin ti wọn ṣe fun ẹgbẹ oṣelu PDP, lasiko idibo sipo gomina to waye ni Osu Kẹwaa, ọdun 2020.
Wo àwọn ọ̀nà tí o lè gbà láti di ọjọ́ ogbó pẹ̀lú olólùfẹ́ rẹ
''Paapaa ilu Akure, wọn fihan pe awọn ṣetan lati jẹ ki ọmọ wọn di gomina ipinlẹ naa pẹlu bii wọn ṣe dibo wọn fun ẹgbẹ oṣelu PDP''
''Amọ, a o tẹsiwaju lati ma a rọ awọn ẹkun to ku nipinlẹ Ondo, lati fi ọwọ sọwọpọ fun gomina to wa lati ilu Akure, nipinlẹ Ondo.''
Akomolede ati Asa: Mọ̀ si nípa àwọn ọ̀nà tí Yorùbá ń gbà ran ara wọn lọ́wọ́
Ninu ọrọ tirẹ, Deji ti ilu Akure ni iya Gomina naa, Abigail Omojolagbe Makinde to wa lati idile Omoregie, jẹ idile ti awọn eniyan mọ fun iwa ọtọ ati awọn eniyan to ṣe e gbẹkẹle.
Deji naa si gbadura ki Olorun fi ọrun kẹ mama to doloogbe.
Oríṣun àwòrán, @Makinde
Iya to ṣe ọlọkọ to wa gomina ipinlẹ Oyo wa saye, Arabinrin Abigail Omojolagbe Makinde ti faye silẹ.
Bo tilẹ jẹ pe gomina Makinde funrarẹ ko tii fi ọrọ sita, iroyin taa gbọ ni pe Mama Abigail dakẹ lowurọ ọjọbọ ọjọ kẹẹdogun oṣu kẹwa ọdun 2020.
Oríṣun àwòrán, @Makinde
Ni ibẹrẹ ọdun yii ni wọn ṣe ayẹyẹ ọgọrin ọdun ti mama naa pe lorilẹ aye.
Oríṣun àwòrán, @Makinde
Lẹyin aisan ranpẹ toripe ọjọ ogbo ni mama wa lọ sinmi.
Ṣaaju asiko yii gomina Makinde ti ṣapejuwe iya rẹ ri gẹgẹ bii ẹni ti wi bẹ ki wọn ba a bẹẹ to si ni oun fi iru eyi jọ iya to bi oun lọmọ.
Ọpọlọpọ ọrọ ni gomina Seyi Makinde sọ nibi ayẹyẹ ọjọ ibi ti iya rẹ ṣe gbẹyin eyi to fihan pe o mọ riri iya yii ko si ko iyan rẹ kere.
A o mu ẹkunrẹrẹ iroyin wa fun yin bo ba ṣe n lọ.
Eegunjobi Omotanbaje Ajobiewe- Èébú ní wọ́n kọ́kọ́ ń bù mí nígbà tí mo bẹ̀rẹ̀ ẹ̀ṣà pípé ní
INEC, 2023 election: Àjọ eleto ìdìbò kéde ọjọ́ tí ìdìbò ààrẹ Nàìjíríà 2023 yóò wáyé
Oríṣun àwòrán, @INEC
Ajọ eleto idibo orileede Naijiria ti kede ọjọ ti idibo aarẹ Naijiria yoo waye lọdun 2023.
Alaga ajọ naa Ọjọgbọn Mahmood Yakubu lo kede ọrọ yi lỌjọbọ ni olu ilẹ naa Abuja.
Mahmood ni ibo aarẹ yoo waye ni ọjọ Kejidinlogun, oṣù Keji, ọdun 2023.
Lasiko ti wọn ṣe ifilolẹ igbimọ ile aṣojuṣofin lori agbeyewo iwe ofin Naijiria, Mahmood kesi awọn aṣofin ọhun lati yara ṣiṣẹ yi ki idibo to wọle.
Eegunjobi Omotanbaje Ajobiewe- Èébú ní wọ́n kọ́kọ́ ń bù mí nígbà tí mo bẹ̀rẹ̀ ẹ̀ṣà pípé ní
ENDSARS, End SWAT: Ààrẹ Buhari ló pa àṣẹ tó mú kí iléeṣẹ́ ọlọ́pàá ó dá ikọ̀ SARS sílẹ̀, Fulani Kwajafa tó dá SARS sílẹ̀ ṣàlàyé
Oríṣun àwòrán, Aisha yesufu
Kaakiri agbaye, ọrọ ikọ kogberegbe ọlọpaa ti ọpọ mọ si SARS lo gbaye kan bayii.
Eleyii ti ko ṣẹyin iwọde to n waye kaakiri orilẹ-ede Naijiria bayii nibi ti awọn eeyan ti n gbe ohun soke lati tako idasilẹ ikọ naa.
Njẹ ẹ mọ pe SARS ni baba?
Ikọ SARS bẹrẹ ni ọdun 1984 lati gbogun ti gulegule awọn adigunjale lorilẹ-ede Naijiria.
Ikọ BBC lọ ṣawari Baba SARS, Alagba Fulani Kwajafa to da ikọ naa silẹ.
Ninu ọrọ rẹ o ni, ọga agba ọlọpaa patapata lorilẹ-ede Naijiria nigba naa, Etim Inyang lo pe ipade kan pẹlu awọn eekan ileeṣẹ ọlọpaa lati dẹkun ọwọja idigunjale lasiko naa.
Nibi ipade naa ni wọn ti fi ẹnu ko pe ki wọn da ikọ pataki kan silẹ ti yoo maa gbena woju awọn adigunjale naa nigba naa.
Fulani Kkwajafa to wa ni ipo kọmiṣọnna ọlọpaa nigba naa ni wọn yan lati ko ikọ naa jọ.
Gẹgẹ bi ọrọ to sọ, ọga ọlọpaa Kwajafa ṣalaye pe iye ọlọpaa to bẹrẹ ikọ naa ko ju marundinlọgọrin nigba naa, oun loun si fi ọwọ ara oun yan wọn.
Sotitobire: Ọkọ mi kò mọ̀ Jegede PDP rí, kódà kò fa ẹnikẹ́ni kalẹ̀ dípò Akeredolu- Bisola
Baba Sars ni agbegbe Adeniji Adele ni olu ileeṣẹ wọn wa nigba naa.
O ni ojuṣe ọlọpaa SARS nigba naa ko ju mimu awọn adigunjale lọ, bẹẹni iwe ojuṣe ati ihuwasi wa fun gbogbo awọn ọlọpaa ikọ naa nigba naa.
Lara awọn ohun to wa ninu iwe naa ni iṣẹ iwadii, ati mimu awọn afunrasi.
Bakan naa lo ni laarin ọdun  1984 si ọdun 1989 ko si igba kankan ti ọlọpaa ikọ naa kankan  lori laya lati yinbọn pa araalu.
"O ni: ""Ikọ SARS ti a da silẹ lọdun 1984 yatọ si ikọ SARS to wa nilẹ bayii nitori pe ohun kan ṣoṣo ti o lee mu ki ọlọpaa ikọ SARS o yọ ibọn jade nigba naa ni bi adigunjale ba yọ ibọn lati yin si wọn."""
Ọga ọlọpaa Kwajafa ṣalaye pe aṣẹ ti ijọba ologun igba naa labẹ olori ologun, Ọgagun Muhammadu Buhari gbe sita fun ọga ọlọpaa nigba naa, Etim Inyang pe ko lọ wa nnkan ṣe si iṣẹlẹ idigunjale to n fojojumọ pọ si lorilẹede Naijiria, bi bẹẹkọ iṣẹ oun atawọn lọgalọga nileeṣẹ ọlọpaa naa yoo lọ sii.
Nibayii, iwọde ṣi n lọ o lati dẹkun gulegule iwa komẹtọ tawọn ọẹọpaa ikọ naa n hu.
ASUU strike: Ìjọba Nàìjíríà ti gbà láti san N30b owó àjẹmọ́nú fún ASUU
Oríṣun àwòrán, @ui
Oṣu mẹfa ni iyanṣẹlodi naa fi waye
Ijọba apapọ Naijiria ti gba lati yọnda biliọnu lọna ọgbọn Naira, fun ajẹmọnu awọn olukọ fasiti ni Naijiria.
Ijọba sọ pe oun yoo san owo naa diẹdiẹ laarin oṣu Karun-un ọdun 2021 si oṣu Keji, ọdun 2022.
Nibi ipade ti awọn aṣoju ijọba ati awọn adari ẹgbẹ awọn olukọ fasiti, ASUU, ti aarẹ wọn, Ọjọgbọn Biodun Ogunyemi, ṣe ni alẹ Ọjọbọ ni wọn ti kede eyi.
Gẹgẹ bi iwe iroyin Punch ṣe jabọ, ijọba tun ṣelelri lati na biliọnu lọna ogun Naira, lati fi ṣe atunṣe eto ẹkọ ni Naijiria.
Gbogbo igbesẹ yii ni ireti wa pe yoo fi opin si iyanṣẹlodi oṣu meje ti ẹgbẹ ASUU wa lori rẹ.
Oríṣun àwòrán, @SenChrisNgige
Chris Ngige, Minisita fun ọrọ oṣiṣẹ ni Naijiria
Ṣaaju ni iroyin sọ pe Minisita fun ọrọ awọn oṣisẹ ni Naijiria, Chris Ngige sọ pe iyanṣẹlodi naa fi aaye silẹ fun awọn oluwọde End Sars lati ma a lo awọn akẹkọọ fun iwọde naa.
End SARS, End SWAT: Ó pé mi bí SARS kò ṣe sọ mí dolówọ́- Fulani Kwajafa
Ngige sọ pe lati bi ọsẹ kan ni ijsba ti n ṣiṣẹ lati fi opin si iyanṣẹlodi naa, to si sọ pe adura awsn ni pe ki ipade ti wọn ṣe naa so eso rere.
Katsina kidnap: Ìyá àti ọmọ ọdún mẹ́ta gba òmìnira lọ́wọ́ ajínigbé lẹ́yìn tí wọ́n san ₦1.2 mílíọ́nù owó ìtanràn
Oríṣun àwòrán, @IAMSPonline
Iyawo Alhaji Aliyu Mai-Yadi Charanchi ati ọmọ rẹ ọmọ ọdun mẹta ti gba ominira lọwọ awọn ajinigbe to ji wọn gbe ni ipinlẹ Katsina.
Iṣelẹ naa waye ni ijọba ibilẹ Charanchi, ni ipinlẹ ọhun, ni aarọ ọjọ Iṣẹgun.
Awọn eeyan naa gba ominira lọwọ awọn ajinigbe naa lẹyin ti awọn ẹbi wọn san owo itanran ti ko din ni miliọnu kan ati ẹgbẹrun lọna igba naira.
Sotitobire: Ọkọ mi kò mọ̀ Jegede PDP rí, kódà kò fa ẹnikẹ́ni kalẹ̀ dípò Akeredolu- Bisola
Gẹgẹ bi iwe iroyin abẹle Punch ṣe fidi ẹ mulẹ .
"Ọkan lara awọn ẹbi wọn ti ko fẹ fi orukẹ rẹ lede sọ pe ""₦1.2 miliọnu owo itanran ni a gbe lọ fun awọn ajinigbe naa lẹyin ti a ba wọn duna dura tan, ko pẹ si asiko naa ti wọn tu wọn silẹ."""
End SARS, End SWAT: Ó pé mi bí SARS kò ṣe sọ mí dolówọ́- Fulani Kwajafa
Bo tilẹ jẹ pe gbogbo akitiyan lati ba awọn ti ọrọ naa ṣelẹ si ati agbẹnusọ ileesẹ ọlọpaa ipinlẹ Katsina sọrọ lo ja si pabo, awọn eeyan to n gbe ni agbegbe naa sọ pe  isẹlẹ ọhun waye ni nnkan bii aago mejila abọ oru ọjọ Iṣẹgun.
Ṣugbọn awọn eeyan to n gbe ni agbegbe naa sọ pe  isẹlẹ naa waye ni nnkan bii aago mejila abọ oru ọjọ Iṣẹgun.
'Owó tí mo ń rí lórí Garri ni mo fi ń ran ọkọ lọ́wọ́'
Iroyin ni ṣe awọn ajinigbe ọhun di ihamọra bi ẹni n lọ oju ogun ki wọn kọlu ile Alhaji naa, ti wọn si gbe iyawo ati ọmọ rẹ lọ.
End SARS protest today: Ṣé òótọ́ ni pé Anonymous ti já gbogbo ojú òpó ìjọba Nàìjíríà gbà lórí Twitter?
Oríṣun àwòrán, @FaruqBashar
Awọn agbọnaẹburuwọle si ori itakun agbaye, Anonymous, ti kede pe wọn ti ja gbogbo itakun ayelujara ijọba Naijiria gba ni atilẹyin fun iwọde End SARS to n lọ lọwọ.
Anonymous lo kede bẹẹ lẹyin to ja oju opo Twitter ti ileeṣẹ ijọba apapọ to n ri si ọrọ igbohunsafẹfẹ, NBC, gba ni afẹmọju ọjọ Ẹti.
"Lẹyin naa ni wọn kọ akọle kan pe ""Awa Anonymous ti ja gbogbo itakun Twitter ijọba Naijiria gba lati ṣatilẹyin fun ifẹhonuhan End SARS."""
Oríṣun àwòrán, @nbcgovng
Awọn ẹruku naa tun bere lọwọ awọn to wa loju opo NBC ọhun irufẹ oju opo ileeṣẹ ijọba apapọ ti wọn n fẹ ki awọn tun ja gba.
Ṣugbọn nigba ti ileeṣẹ iroyin BBC ṣe abẹwo si ọpọ  ninu oju opo ti ijọba apapọ n ṣakoso rẹ, a rii pe digbi ni wọn ṣi wa.
O ti to nnkan bi ọjọ mẹwaa ti awọn ọdọ naijiria ti gunlẹ iwọde End SARS, ti wọn si bere fun atunto si ileeṣẹ ọlọpaa, ati opin si ẹka rẹ to n gbogun ti iwa idigunjale, SARS.
End SARS, End SWAT: Ó pé mi bí SARS kò ṣe sọ mí dolówọ́- Fulani Kwajafa
FG Covid Palliatives: Àjọ SERAP ń wá ìdájọ́ tó tọ́ lórí rògbòdìyàn jíjí ǹkan ìrànwọ́ Covid-19
Oríṣun àwòrán, SERAP
Ajọ ajafẹtọ ọmọniyan kan ní Naijiria, SERAP ti ke si ajọ to n ri si ọrọ iwa ibajẹ ICPC lati tu iṣu de isalẹ koko gbogbo rogbodiyan to rọ mọ ẹsun pe ijọba kọ lati pin nkan iranwọ Covid-19 fawọn araalu.
Iroyin yii hande nigba ti fọnran kan bẹrẹ si ni tan kalẹ lori ayelujara bi awọn janduku kan ṣe n yabo awọn ile ti wọn n ko ẹru si jakejado orilẹede Naijiria.
Eyi lo mu ki ajọ SERAP lọjọ Aiku kọ iwe ipẹjọ si ajọ ICPC lati rii daju pe wọn tọpinpin awọn iṣẹlẹ yii ki wọn si fi ẹnikẹni ti igba rẹ ba ṣi mọ lori jofin ti wọn ba fidi rẹ mulẹ pe lootọ ni awọn kan n ko gbogbo nkan iranwọ to yẹ ki wọn pin lasiko Covid-19.
O da bii wipe awọn alaṣẹ ni ki awọn eeyan kan jokoo sile ṣugbn wọn kọ lati pin nkan iranwọ lati mu asiko naa dẹrun fun awọn ti ko rọwọ họri lawujọ, SERAP kọ eyi sinu ipẹjọ wọn.
"Lafikun, SERAP ni ""Ẹsun pe wọn ko nkan iranwọ pamọ kaakiri ipinlẹ to fi mọ ikuna idọgba ninu pinpin  awn nkan naa fawọn to ku diẹ kaato fun atawọn tiya n jẹ nilu ti di eyi ti wọn n fi ẹtọ wọn dun wọn to yẹ ki wọn ran wọn lọwọ""."
Oríṣun àwòrán, NPF
Ọga agba awọn ọlọpaa ni Naijiria, Muhammed Adamu ti fohun silẹ pe ẹni to ba tasẹ agẹrẹ yoo lori aṣẹ tuntun to ṣẹṣẹ jade fun araalu yoo foju wina ofin.
Ọgbẹni Adamu lo paṣẹ fawọn ọlọpaa lati ko gbogbo irinṣẹ ti wọn nilo ati ikọ alaabo jọ lati lee dẹkun gbogbo rogbodiyan to n ṣẹlẹ jakejado orilẹede Naijiria.
Eyi n waye lẹyin bi jiji ẹru ẹlẹru ko ṣe n waye laipẹ yii ni lemo lemo ni Naijiria lara rẹ ni awọn nkan  to yẹ ko jẹ awọn nkan irọrun fun pinpin lasiko Covid 19, awọn ọja nile itaja nla nla ati awọn nkan ini awọn eeyan jankan jankan lawujọ.
Fun idi eyi, ọgbẹni Adamu paṣẹ pe ki awọn ọga ọlọpaa ko awọn ikọ́ wọn sita ki wọn ja alafia ilu gba pada lọwọ awọn ọdaran to n fi aṣọ oluwọde bora ti wọn si n da omi alafia ilu ru.
Ninu ọrọ ti alukoro ileeṣẹ ọlọpaa, DCP Frank Mba fi sita, Ọga agba Adamu pa aṣẹ fun gbogbo awọn igbakeji rẹ, awọn kọmisọna ọlọpaa, awọn adari igun ọlọpaa kọọkan awọn ọgagun to moju to awọn bareke ni ipele ijọba ipinlẹ titi de ijọba apapọ, awọn ọlọ́paa MOPOL atawọn ikọ alaabo to ku lati tu sita fun iṣẹ yii.
O fi kun un wipe ki gbogbo awọn oṣiṣẹ alaabo yii pata gba gbogbo igboro kan ki wọn si ri i daju pe alafia jọba lawọn ibi ti iṣẹlẹ idigunjale yii ti ṣọṣẹ.
Ileeṣẹ ọmọogun ti ṣalaye pe awọn ko tii ni ọrọ kankan lati sọ bayii, lori iṣẹlẹ to waye lagbegbe Lekki TollGate nilu Eko ni alẹ ọjọ Iṣẹgun.
Ninu ifọrọwerọ kan to ṣe lọjọbọ, alakoso eto iroyin lolu ileeṣẹ ọmọogun Naijiria, Ọgagun John Enenche ṣalaye pe, niwọn igba ti gomina ipinlẹ Eko ti gbe igbimọ oluwadi kalẹ, ọrọ yowu ti awọn ba sọ bayii, lee pagidina iṣẹ igbimọ naa.
O ni ẹsun lasan ṣi ni awọn ọrọ to n kaakiri pe awọn ṣọja yinbọn pa awọn oluwọde kan, ati pe awọn akọṣẹmọṣẹ kan ti sọ pe, iroyin eke ni pe awọn ologun lo pa awọn to ku naa, kii ṣe ootọ.
O wa rọ awọn ọmọ Naijiria lati fiye denu, ki wọn si ṣe suuru fun abajade iwadi lori iṣẹlẹ buruku naa.
Sanwo Olu búra fún ìgbìmọ̀ tí yóò má a ṣe ìdájọ́ àwọn ọlọ́pàá tó bá hùwà kò tọ́ sáwọn ará ìlú ní Eko
Oríṣun àwòrán, Babajide sanwo-olu
Gomina ipinlẹ Eko, Babajide Sanwo Olu ti ṣagbekalẹ igbimọ ti yoo maa ri si idajọ awọn ti awọn agbofinro ba fiya jẹ ni ipinlẹ Eko.
Igbimọ yii ni Sanwo Olu gbekalẹ lẹyin ti ijọba Naijiria tu ikọ awọn olọpaa  kogberegbe ka kaakiri Naijiria.
Ni ile ijọba ni Marina ni wọn ti ṣe ibura fun awọn ọmọ igbimọ naa.
Awọn naa ni: Adajọ Doris Okuwobi to je alaga ti wọn bura fun lẹyin eyi ti awọn ọmọ igbimọ naa kọja lọ si ile LASWA to wa ni Falomo ni Ikoyi.
Sanwo Olu ni ijọba oun setan lati yanju ọrọ ifiyajẹni to n fa iwọde kaakiri Naijiria  lasiko yii.
O mẹnuba awọn iṣẹlẹ to ti ṣẹlẹ lati ọsẹ meji sẹyin pe nitootọ ni awọn ara ilu laṣẹ lati fi ẹhonu han si nkan ti ko ba tẹ wọn lọrun.
Gomina ni: Awọn ọdọ yii ti fi ohun marun un ti wọn fẹ ranṣẹ si ijọba, funra mi ni mo fi jiṣẹ fun aarẹ Buhari ni Abuja, Mo ti tu gbogbo awọn ti wọn mu satimọle nitori iwọde silẹ, mo ti ri owo igba milionu naira fun awọn opo ati ẹbi awọn ti wọn pa.
Sotitobire: Ọkọ mi kò mọ̀ Jegede PDP rí, kódà kò fa ẹnikẹ́ni kalẹ̀ dípò Akeredolu- Bisola
Bawo ni wọn yoo ṣe ṣiṣẹ:
Sanwo Olu ni oṣu mẹfa ni awọn igbimọ naa ni lati fi ṣiṣẹ.
Iṣẹ wọn ni lati ṣagbeyẹwo awọn ẹri ti awọn eeyan fi ranṣẹ ki wọn si ṣe ohun to yẹ lori ipaniyan lọna aitọ gbogob to ti waye sẹyin ni ipinlẹ Eko.
Wọn tun ni agbara lati fi ọrọ wa awọn oṣiṣẹ SARS ti ijọba apapọ ti tuka lẹnuwo lori awọn ẹsun naa ki wọn si yọ okodoro.
O ni abala ofin karun un ti Tribunal of Inquiry law lo fun wọn lagbara lati gbe abajade iwadii wọn sita pẹlu irufẹ idajọ iya to tọ si ẹni ti ade iwa ibajẹ ba ṣimọ lori.
Sanwo Olu ni ọrọ yii ko yọ awọn olọpaa ti wọn ti gba iṣẹ lọwọ wọn silẹ.
O gba wọn nimọran lati ṣiṣẹ laini ibẹru ẹnikẹni ati lai ṣegbe fun ẹnikẹni.
O tun ṣeleri atilẹyin ijọba fun awọn ọmọ igbimọ naa.
Adajọ Okuwobi to jẹ alaga igbimọ naa sọrọ lorukọ ijọba pe didun lọsan yoo sọ fun idajọ ododo lori awọn ti ọpọ n ṣe iwode nitori wọn.
Wo nọ́mbà tí o le è pè láti gba owó gbà-má-bínú tí ọlọ́pàá bá fìyà jẹ ọ́ lọ́nà àìtọ́ l'Eko
Báyìí ni o ṣe leè fi ẹjọ́ ọlọ́pàá tó bá fìyà jẹ ọ́ lọ́nà àìtọ́ sun ìjọba ìpínlẹ̀ Eko
Gomina ipinlẹ Eko, Babajide Sanwo-Olu ti gbe igbimọ ẹlẹni meje kan kalẹ ti yoo maa ṣagbeyẹwo ẹsun fifi iya jẹ ara ilu lọna aitọ ti awọn oṣiṣẹ ileeṣẹ ọlọpaa n hu.
Bakan naa ni igbimọ ọhun yoo maa bojuto bi ijọba yoo ṣe maa san owo gba-ma-binu fun ẹnikẹni ti ọlọpaa ba fiya jẹ lọna aitọ ni ipinlẹ naa.
Sanwo-Olu lo kede igbeṣe yii lẹyin iwọde End SARS ti awọn eeyan gunlẹ kaakiri orilẹ-ede Naijiria, paapaa ni ipinlẹ Eko.
Sanwo Olu ni awọn ara ilu le bẹrẹ si ni pe awọn nọmba wọnyi 0901 051 3203; 0901 0513204 ati 0901 051320 lati fi ọrọ awọn ọlọpaa to ba tasẹ agẹrẹ to ijọba leti.
Bo tilẹ jẹ pe nọmba naa ko wọle nigba ti a pe e, ṣugbọn Gomina Sanwo-Olu ti ni awọn eeyan le bẹrẹ si n pe awọn nọmba naa lati ọsẹ to n bọ.
Wo nọ́mbà tí o le è pè láti gba owó gbà-má-bínú tí ọlọ́pàá bá fìyà jẹ ọ́ lọ́nà àìtọ́ l'Eko
Wo diẹ lara awọn eeyan to wa ninu igbimọ tuntun naa:
Doris Okuwobi
Wọn bi adajọ-fẹyinti Doris Okuwobi ni ipinlẹ Eko ni ọjọ Kẹwaa, oṣu kinni, ọdun 1955.
O kawe gboye gẹgẹ bi amofin ni ile ẹko awọn agbẹjọro to wa ni ipinlẹ Eko lọdun 1997.
Okuwobi ṣiṣẹ fun ọpọlọpọ ọdun ko to fẹyinti ni ileeṣẹ to n ri si eto idajọ ti ipinlẹ Eko loṣu kinni, ọdun 2020, lẹyin to ti ṣiṣẹ fun ọdun mejilelogoji.
Doris Okuwobi ni alaga igbimọ naa.
Ebun Adegboruwa, SAN
Agbẹjọrọ agba ni Ebun Adegboruwa, ṣugbọn ko to de ipo naa, o ṣiṣẹ miran bii iṣẹ agegẹdu ni inu igbo ipinlẹ Ondo, Edo ati Delta.
O kẹkọọ jade nile iwe Obafemi Awolowo to wa ni ilu Ile Ife, nibi to ti darapọ mọ ẹgbẹ awọn to n ja fun ẹtọ awọn akẹkọọ.
Ko pẹ si akoko to wọm ile iwe naa ti wọn le oun atawọn eeyan mọkanlelọgọta miran kuro nile iwe naa lẹyin ti wọn dari ifẹhonuhan kan lọdun na lọhun, ki oloye Gani Fawehinmi to gba ẹjọ wọn ro.
Bakan naa ni wọn fi panpẹ ofin gbe laye ọgagun Sani Abacha to si lo oṣu mẹsan an latimọle ki wọn tu silẹ lẹyin iku ọgagun naa.
Oríṣun àwòrán, @jidesanwoolu
DIG Taiwo Lakanu
Wọn bi Taiwo Lakanu ni ọjọ kejila, oṣu Kẹwaa, ọdun 1959 ni Lagos Island, ni ipinlẹ Eko.
O si kawe jade ni Fasiti ijọba apapọ to wa ni ilu Eko, UNILAG, ko to tẹsiwaju ni Leeds Metropolitan nilẹ Gẹẹsi.
Bakan naa lo tun kawe ni ile iwe eto abo to wa ni Jos, Abuja ati Accra, ni Ghana.
Lakanu ṣiṣẹ ọlọpa fun ọpọ ọdun ko to fẹyinti lọdun 2019.
Patience Udoh
Patience Udoh jẹ ọkan gboogi lara awọn obinrin akinkanju to n ja fun ẹtọ awọn eeyan ni ipinlẹ Eko.
Oun si ni ẹni ti yoo maa ṣoju awọn ara ilu ninu igbimọ ẹlẹni meje ọhun
Segun Awosanya
Ọkan gboogi lara awọn to n ṣagbatẹru iwọde End SARS ni Segun Awosanya jẹ.
Wọn bii ni ọjọ kọkanla, oṣu Keji, ọdun 1978 ni ipinlẹ Eko.
Awosanya wa lara awọn ti ijọba apapọ bẹ lọwẹ lati ṣatungbeyẹwo ikọ SARS ko to parada di FSARS.
Olutoyin Odusanya
Agbẹjọro to dantọ ni iya afin Olutoyin Odusanya, o si tun jẹ ọkan lara ọmọ ẹgbẹ awọn agbẹjọro ni Naijiria, NBA.
Lara awọn ibi ti Odusanya ti kawe ni Ilẹ Gẹẹsi, ilu Abeokuta ati ipinlẹ Eko.
Odusanya gboye gẹgẹ bi agbẹjọro ni Naijiria lọdun 1990 ko to kawe siwaju sii.
Lọwọ yii, oun ni oludari ileeṣẹ Citizens Mediation Centre to maa n pẹtu si aawọ laarin awọn ara ilu, o tun jẹ ọkna lara awọn ọmọ ẹgbẹ Human Rights Commision, to maa n ja fun ẹtọ ara ilu.
End SARS Protest: Babangida ní ejò lọ́wọ́ nínú lórí ìsẹ̀lẹ̀ rògbòdìyàn tó ń wáyé káàkiri Nàìjíríà
Adari orilẹede Naijiria labẹ ijọba ologun nigba kan ri, Ọgagun Ibrahim Babangida  ti ni ko si rogbodiyan kankan to le bẹ silẹ ju wakati mẹrinlelogun lo ti ko si ọwọ ijọba nibẹ.
Ọgagun Ibrahim  Babangida lo fi lede bẹẹ loju opo Twitter rẹ, lẹyin ti awọn ipinlẹ kaakiri orilẹede Naijiria n koju rogbodiyan lasiko ifẹhọnuhan tako ifiyajẹni awọn ọlọpaa lorilẹede Naijiria.
Babangida ni oun sọ ọrọ ti Ọgagun Sani Abacha sọ nigba aye rẹ pe '' ti rogbodiyan ba ti ju wakati mẹrinlelogun lọ, oṣiṣẹ ijọba kan wa ni idi iṣẹlẹ naa niyẹn.''
O fikun un wi pe adari rere lo le e tukọ orilẹede Naijiria lasiko ti a wayii, nitori iru iṣẹlẹ bayii ni o ma n fihan boya eniyan jẹ adari rere abi bẹẹ kọ.
Bakan naa ni Babangida bu ẹnu atẹ lu  iṣekupani awọn afẹhọnuhan lorilẹ-ede Naijiria nigba ti awọn ikọ Ologun Naijiria da ibọn bo wọn ni agbegbe Lekki Tollgate ni ilu Eko ati kaakiri Naijiria pẹlu.
Babangida ni kosi ọmọ Naijiria kankan to yẹ ko sọ ẹmi rẹ nu lori pe oun bere fun ẹtọ rẹ lọwọ ijọba tiwantiwa.
Oríṣun àwòrán, @not_oyedepo
2015 ni mo ti ń kígbe pé gudugbẹ̀ máa já ní Nàíjíríà - Oyedepo
Oyedepo ní àwọn ọ̀dọ́ lẹ́tọ̀ọ́ láti tako bí ọlọ́pàá ṣe ń pa wọ́n ní ìpakúpa
Biṣọọbu Oyedepo jẹ ọkan pataki lara awọn ojiṣẹ Ọlọrun ni Naijiria ti kii fi ọrọ sabẹ ahan sọ lori ojuṣe tabi aṣiṣe ijọba
Pasitọ agba ninu ijọ Living Faith lagbaye, David Oyedepo ti da si ọrọ iwọde End SARS to n lọ kaakiri awọn ilu nla nla ni Naijiria.
Oyedepo sọ pe digbi ni oun wa lẹyin awọn oluwọde naa nitori gbogbo eeyan lo ni aṣẹ labẹ ofin lati fi erongba wọn sita nipa ifẹhonuhan.
David Oyedepo kede bẹẹ ninu iwaasu rẹ to se laarọ ọjọ isinmi oni ni olu ijọ rẹ to wa nilu Ota.
Biṣọọbu naa ni, bo tilẹ jẹ pe oun ti fi igba kan dakẹ lori ọrọ Naijiria, ṣugbọn oun ti kilọ ṣaaju ninu ọdun 2015 pe, ewu n bẹ loko longẹ ni Naijiria, ati pe gudugbẹ kan yoo ja laipẹ.
Oríṣun àwòrán, @DavidOyedepoMin
"Oyedepo ni ""Akoko to buru ju ninu itan orilẹ-ede yii ni ọdun marun un ṣẹyin, ti wọn n pa eeyan ni ipakupa."""
O ni bayii ti wọn ti bẹrẹ si n pa awọn ọdọ ni ipakupa, wọn lẹtọọ lati sọ pe o to gẹ.
Bi ẹ ko ba gbagbe, o ti le ni ọsẹ kan ti awọn ọdọ kaakiri Naijiria ti gunle ifẹhonuhan, lori bi awọn oṣiṣẹ ẹka to n gbogun ti iwa idigunjale ni ileeṣẹ ọlọpa, SARS, ṣe pa awọn eeyan lọna aitọ.
Wo àwọn ọ̀nà tí o lè gbà láti di ọjọ́ ogbó pẹ̀lú olólùfẹ́ rẹ
Oriṣiriṣi awọn gbajumọ ni Naijiria ati lawọn orilẹ-ede miran lagbaye lo ti n ṣegbe lẹyin iwọde ọhun.
Biṣọọbu Oyedepo jẹ ọkan pataki lara awọn ojiṣẹ Ọlọrun ni Naijiria ti kii fi ọrọ sabẹ ahan sọ lori ojuṣe tabi aṣiṣe ijọba.
Ki lo ti ṣẹlẹ sẹyin?
Oríṣun àwòrán, Instagram/Kunle Afod
Ọrọ ifẹhonuhan awọn ọdọ lori ati fi opin si ọlọpaa SARS ati SWAT ti ijọba ṣẹṣẹ yi orukọ wọn pada si ko yọ ẹnikankan silẹ mọ o.
Ọpọ olorin takasufe bi Davido, Falz, Wizkid atawọn adẹrinpoṣonu bii Mr Macaroni, Woli Agba lo ti darapọ mọ iwọde #EndSARS.
Amọ, awọn oṣere ori tiata Yoruba naa ko gbẹyin nibi iwọde ọhun.
Wọnyii lawọn oṣere ori itage Yoruba tawọn naa n kopa ninu ifẹhonuhan #EndSARS to n lọ lọwọ:
Odunlade Adekola
Gbajugbaja oṣere tiata Yoruba, Odunlade Adekola palẹ awọn akẹgbẹ rẹ naa bọ soju popo lati ṣe iwọde #EndSARS ati SWAT.
Niṣe ni Odunlade gbe gbohungbohun dani to fi n sọrọ nibi iwọde naa.
Bakan naa ni Odunlade tun gbe beba ninu eyi ti wọn kọ oriṣiiriṣii nkan si bii ''ọlọpaa, ẹ dẹkun ifiyajẹni, ipaniyan, ẹ ṣe atunṣe ileeṣẹ ọlọpaa,'' ati bẹẹ bẹẹ lọ.
Gbajúgbajà òsèré tó tún mọ́ ọbẹ̀ sè
Ijebu
Gbajugbaja oṣere meji Ijebu ati Afeez Owo lo jọ di beba kan ti wọn kọ ''END SARS NOW'' si dani ninu iwọde #EndSARS naa ni.
Bakan naa ni wọn daṣa ''sọrọ soke'' to lu oju ayelujara pa bayii.
Awọn naa n sọ pe opin gbọdọ de ba ijọba buruku lorilẹede Naijiria gẹgẹ bi awọn oluwọde mii ṣe n sọ.
Ogbomsho shooting, End Sars, End SWAT: Isiaka fi ọmọbìnrin kan àti ìyàwó tó lóyún sínú síl
Toyin Abraham
Ilumọọka oṣere, Toyin naa ko gbẹyin nibi ifẹhonuhan #EndSARS.
Toyin sọ ninu iwọde naa pe ijọba gbọdọ tẹti si ohun tawọn oluwọde n beere fun.
O ni SARS ati SWAT gbọdọ wa si opin lorilẹede Naijiria lai beṣu bẹgba.
Mercy Aigbe
Aworan ibi to ti gbe ibọn dani to si duro niwaju ọkọ awọn ọlọpaa ni gbajugbaja oṣere Mercy Aigbe fi si oju opo Instagram tiẹ.
Mercy sọ pe oun n duro de asiko ti wiwọ aṣọ ọlọpaa ninu ere tiata yoo jẹ nkan iwuri fun oun.
Oun naa kepe ijọba lati fopin si iwa ifiyajẹni awọn ọlọpaa SARS.
O ni opin gbọdọ de ba ọlọpaa SARS ati SWAT ti ijọba ṣẹṣẹ yi orukọ wọn pada si.
Tola Oyediran: Buhari, Makinde, Sanwo-Olu ń ṣèdárò Tola Oyediran ọmọ Obafemi Awolowo tó papòdà
Oríṣun àwòrán, Tribuneonline
Ọpẹ eekan lagbo oṣelu lo ti n ranṣẹ ibanikẹdun si ẹbi mama Tola Oyediran tii ṣe akọbi obinrin Oloye Obafemi Awolowo to jade laye lọjọ Ẹti.
Aburo oloogbe naa, Ọmọwe Tokunbo Dosunmu-Awolowo to ba BBC Yoruba ṣalaye pe ni bii deedee aago mejila ọsan ti mama jẹ Ọlọrun nipe.
Ẹwẹ, Aarẹ Muhammadu Buhari ti kẹdun pẹlu idile oloogbe Tola Oyediran.
Ninu atẹjade ti oludamọran Aarẹ Buhari lori ọrọ iroyin, Garba Shehu fi sita, Buhari ni ki wọn dupẹ lọwọ Eledua fun igbe aye to daara ti mama gbe nigba to wa laye.
Buhari ni oloogbe naa gbiyanju agbara rẹ lati ṣe iranwọ fawọn eeyan to layika rẹ eleyi ti awọn eeyan yoo maa fi ṣe iranti rẹ lọ laelae.
Aarẹ gbadura wi pe ki ọlọrun tẹ mama si afẹfẹ rere ki O si tun awọn ẹbi rẹ ninu.
Ogbomsho shooting, End Sars, End SWAT: Isiaka fi ọmọbìnrin kan àti ìyàwó tó lóyún sínú síl
Gomina Seyi Makinde ipinlẹ Oyo naa ti ṣapejuwe iku mama Oyediran gẹgẹ bi adanu nla fun orilẹede Naijiria.
Ninu iṣẹ ibanikẹdun to fi ṣọwọ si igbimọ alaṣẹ iwe iroyin Tribune, Makinde ni lootọọ ni mama ti ku, ṣugbọn ipa to ni lawujọ ko le parẹ laelae.
Oríṣun àwòrán, Tribune Newspaper
Bakan naa lo sọ pe awọn eeyan yoo maa ṣe iranti mama Oyediran gẹgẹ bi ẹnikan to tẹ le awọn ilana ti Oloye Awolowo la kalẹ titi to fi ku.
Makinde ko ṣalai ki aburo oloogbe, Dokita Dosunmu-Awolowo ati iyawo igbakeji aarẹ Dolapo Osinbaji pẹlu igbakeji Aarẹ rẹ ku ara fẹraku.
Gomina ipinlẹ Eko, Babajide Sanwo-Olu naa ko gbẹyin ninu awọn to n ṣedaro ẹn'ire to lọ.
O ni adanu nla ni iku mama Oyediran jẹ fun ẹbi, atawọn ọrẹ rẹ to fi mọ ile iwe iroyin Tribune.
Sanwo-Olu ni olori to ṣee fi ọkan tan ni mama nigba aye rẹ ati pe ẹlẹyinju aanu ati onirẹlẹ eniyan ni.
Tola Oyediran ọmọ Obafemi Awolowo ti jáde láyé
Iku n pa ni, ilẹ n jẹ eeyan. Iroyin to n tẹ wa lọwọ lo sọ pe Tola Oyediran Awolowo ti papoda.
Ọjọ kinni oṣu kejila ọdun 2020 yii ni mama Oyediran to jẹ ọkan ninu awọn ọmọ olootu ijọ iwọ oorun guusu Naijiria nigba kan ri, Oloye Obafemi Awolowo ko ba ṣe ayẹyẹ ọjọ ibi ọgọrin ọdun laye.
Oun ni omọ Awowlọwọ to dagba ju ki iku to mu un lọ.
Tola si ni alaga igbimọ alaṣẹ iwe iroyin Tribune titi ti o fi faye silẹ.
Dokita Tokunbọ Dosunmu ṣalaye fun BBC pé Arabinrin Tola Oyediran Awolowo ko ṣaarẹ rara ki ọlọjọ to de.
O ni nkan bii aago mejila ọsan oni ni alumuntu wọle de were to mu ẹgbọn oun lọ.
Bakan naa lo ni ẹbi ṣi wa ninu irora ati iyalẹnu pe ṣe gbogbo ẹ ti pari naa ni yẹn ni asiko yii.
BBC gbadura pe ki Olorun tu ẹbi ti ọrọ kan naa ninu lasiko yii
Gbajúgbajà òsèré tó tún mọ́ ọbẹ̀ sè
ENDSARS, End SWAT: Gomina Obiano yọ ọ̀gá ikọ̀ SARS nípò
Oríṣun àwòrán, facebook Chief Willie Obiano
Gomina  ipinle Anambra, Willie Obiano ti gba iṣẹ lọwọ James Nwafor to jẹ ọga awọn ọlọpaa SARS ni ipinlẹ naa to si ṣe ileri fun un pe yoo fimu ko ata ofin.
Gomina Obiano kede eyi lasiko to darapọ mọ awọn ọdọ to n ṣewọde tako iwa buruku awọn ọlọpaa ni ipinlẹ Anambra.
O ni iyi nla lo jẹ fun oun layyi farapọ mọ awọn ọdọ yii lọna ati fi erongba wọn han ati pe oun yoo rii daju pe James Nwafor jẹjọ lẹyin to gba iṣẹ lọwọ rẹ.
Gomina Obiano ni oun ni lati gbaruku ti awọn ọdo naa nítori pe awọn gan ni igi leyin ọgba aṣeyọri oun nibi ibo.
Oríṣun àwòrán, @WillieObiano
Bakan naa lo kede ohun mẹta ti oun fẹ gbe ṣe lati ran awọn ọdọ ni ipinlẹ naa lọwọ ninu eyi to ni fifi James Nwafor jofin wa.
Akọkọ, ijọ apapọ ti tu ikọ SARS ka, ṣugbọn emi funra mi yo ṣe abẹwo sawọn ọfiisi SARS gnogbo to wa ni ipinlẹ Anambra lati rii daju pe wọn tu ẹnikẹni ti wọn ba fi sinu ahamọ silẹ.
"Ekejii, iṣẹ ti bọ lọwọ James Nwafor to jẹ olori iko SARS tẹlẹ ni Anambra, yoo si jẹjọ;
Ẹkẹta, Nrii daju pe.ijọba apapọ gbe igbesẹ gnogbo to ba yẹ lati rii pe igbe aye idẹrun de ba awọn ọdọ ni ipinlẹ Anambra."""
Gbajúgbajà òsèré tó tún mọ́ ọbẹ̀ sè
Abajade ipade Obiano pelu awọn ọdọ:
Lati gbe igbe aye idẹrun kalẹ ni ipinlẹ Anambra, Gomina Obano pinnu lati gbe igbimọ alakoyawọ kan kalẹ lati gbe awọn iwa kotọ to waye labẹ ikọ SARS ni ipinlẹ naa yewo.
Adajófẹyinti V.N. Umehi ni yoo jẹ alaga fun igbimọ naa ti yoo pari iṣẹ laarin ọgbọn ọjọ
Igbimọ naa yoo ni:
Aṣoju kan latodo egbe awon akekoọ.
Awon olori ọdọ lati eka idibo apapọ,
Agunbaniro kan,
Alaga ajọ ajafẹto araalu kan, alaga ehbe ọdọ ni ipinlẹ Anam ra
Aṣoju ẹka ọdọ lẹgbẹ Ohaneze,
Alaga ẹka ọdọ lẹgbẹ ilu gbogbo ni Anambra
Alaga egbe ọmọlẹyin Kristi, CAN ni ipinlẹ Anambra
Asoju biṣọọbu agba ijọ Anglican
Asoju Biṣọọbu agba ijọ Aguda,
Asoju ẹgbẹ ijọ emi mimọ PFN,
Asoju alaga igbimọ awọn lobaloba ni Anambra,
Agbejoro agba ni Anambra,
Kọmiṣonna fun ọrọ ọdọ awon meji to jere julọ ni igbimọ iṣejọba ipinlẹ naa.
Amugbalẹgbẹ fun gomina lori ọrọ aabo.
Everton vs Liverpool: VAR gba Everton sílẹ̀ lọ́wọ́ ogun ẹ̀yìn Liverpool, ọ̀mì ayò 2-2 ní wọ́n gbá ní Merseyside
Oríṣun àwòrán, Premierleague.com
Salah gba goolu kan wọle eyi to jẹ ọgọrun goolu rẹ ni idije Premiership ṣugbọn alayo meji meji ni Liverpool at Everton ta.
Ifẹsẹwọnsẹ naa to waye ni gbagede ibuba Everton to wa ni Merseyside pari pẹlu awọn oniruuru arisọ to kan ikọ mejeeji.
Mane, atamatase ẹgbẹ agbabọọlu Liverpool lo kọkọ mi awọn nigba ti ifẹsẹwọnsẹ naa wọ iṣẹju kẹta amọṣa, Michael Keane daa pada nigba ti ifẹsẹwọnsẹ naa de iṣẹju kọkandinlogun.
Omi alayo kọn yii ni wọn gbe wọ isinmi aarin ifẹsẹwọnsẹ naa ki Liverpool to tun fi goolu kan sii nigba to di iṣẹju kejilelaadọrin lati ẹsẹ Mo Salah.
Oríṣun àwòrán, Premierleague.com
Iran ko ti tan ni ifẹsẹwọnsẹ naa nitori lẹyin iṣẹju mẹsan si asiko goolu yii ni Calvert-Lewin daa pada bi owo baba ijẹbu fun Everton.
Richarlison, agbabọọẹu Everton gba kaadi pupa ti wọn fi lee jade ninu ifẹsẹwọnsẹ naa.
Iroyin ayọ ti ko ba jẹ fun Liverpool ni ipari ifẹsẹwọnsẹ naa nigba ti Henderson gba goolu kan wọle ṣugbọn ayẹwo igbalode VAR dawọn lẹkun idunnu naa.
Pẹlu esi ifẹsẹwọnsẹ yii, Everton lo ṣi n lewaju loke tente tabili liigi ilẹ Gẹẹsi bayii ti liverpool si n tẹlee pẹly ami mẹwaa.
Dolapo Badmus: Abayomi Shogunle, Dolapo Badmus ṣì wà lẹ́nu iṣẹ́ ọlọ́pàá-PSC
Oríṣun àwòrán, Pulse.ng
Iroyin kan jẹyọ lori ayelujara pe awọn ọlọpaa kan ti padanu iṣẹ wọn eleyi to ti wa di kale n kako lori ayelujara.
Ko si idi meji ti iroyin naa fi lu oju opo ayelujara pa ju pe orukọ awọn ilumọọka ọlọpaa meji kan wa nibẹ.
Abayọmi Shogunlẹ to jẹ olori ikọ agbohungbaroye (Police Public Complaint Unit) nileeṣẹ ọlọpaa tẹlẹ ati Dọlapọ Badmus to figbakan ri jẹ alukoro ileeṣẹ ọlọpaa ni ipinlẹ Eko ati ni ẹkun keji, Zone II wa lara orukọ awọn mẹtadinlogoji ti wọn da oruks wọn sinu iwe naa.
Iroyin naa jade loju opo twitter @AyooAkanji ṣugbọn arakunrin A.A to ni oju opo Twitter naa ti jade lati ṣalaye pe aimọọsọ oun ni ko jẹ kawọn eeyan mọọ gbọ nitori pe kii ṣe awọn ti wọn le lẹnu iṣẹ ọlọpaa nikan lo wa ninu orukọ ti oun gbe sita.
O tubs yannana rẹ siwaju sii pe, Abayoọmi Shogunlẹ ati Dọlapọ Badmus ko si lara awọn ti wọn le lẹnu iṣẹ ọlọpaa, ara awọn ti wọn gba ni ikilọ atawọn ti wọn ja okun wọn ni awọn mejeeji yii wa.
Ẹwẹ, ajọ akoso ileeṣẹ ọlọpaaloriulẹede Naijiria, PSC naa ti ṣalaye pe awọn ko le ọlọpaa meji yii o.
Alukoro ajọ naa, Ikechukwu Ani ṣalaye fun awọn iwe iroyin abẹle kan lorilẹede Naijiria pe iroyin ofege ni iroyin naa nitori pe ajọ naa ko tii joko ṣe ipade debi ti yoo maa le ẹnikẹni ni iṣẹ.
India: Arakunrin ti wọn doola ẹmi rẹ kuro ni Ile igbokusi pada jade laye
Arakunrin Balasubramanyam ti wọn doola ẹmi rẹ kuro ninu ẹrọ amohuntutu to wa ni ile igbokusi ti papoda.Balasubramanyam to jẹ ẹni ọdun mẹrinlelaadọrin lo n gbe ni ilu Tamil Nadu, lorilẹede India.
Ojo Aje ọsẹ yii ni wọn gbe arakunrin naa lọ si ile iwosan, ti wọn ko si sọ ohun to ṣe e, lẹyin naa ni wọn gbe e lọ si ile igbokusi.
Amọ, ọjọ Keji ti awọn agbokusi de lati lọ sin in ni wọn ba a nibi ti o ti n gbọn, ti wọn si tete mọ wi pe o si wa laaye.
Wọn sare gbe e lọ si ile iwosan, amọ o jade laye ni ọjọ Eti.
Adari ileewosan ijọba ni agbegbe Salem, Dokita Balajinathan ni wọn gbe alaarẹ naa wa pẹlu bi o ṣe n gbọn naa, amọ o ku lẹyin ti o lugbadi aisan ọna ọfun.
Dokita naa ni ohun ko le sọ ni pato, igba ti arakunrin naa ti wa ninu yara igbokusi ninu otutu naa.
Lẹyin ti dokita kan ni ileewosan aladani sọ wi pe o ti jade ni aye ni ọjọ Aje, ni awọn ẹbi rẹ fi pada wa lati gbe oku rẹ losin.
Amọ wọn ko ri iwe ẹri to fihan gbangban pe lootọ, lo ti ku amọ aburo baba naa ni oun buwolu iwe eri pe ẹgbọn oun ti ku.
nnnnnn
Ọlọpaa ni agbegbe naa ni awọn ẹbi ati awọn ara naa ko ri sabuke iwe eri pe o ti ju jade.
Nibayii, wọn ti bere ẹjọ pẹlu awọn mọlẹbi baba naa, nitori iwakuwa wọn lo jẹ ki arakunrin naa ku.
Awọn ẹbi rẹ ni o tun ni arun ọpọlọ naa pelu ẹ, Balasubramanyam fi iyawo kan ati ọmọ meji ati aburo rẹ.
Ko i tii ran gbangba boya ijọba yoo ṣewadii ileewosan aladani naa, bakan naa ni awọn mọlẹbi ati dokita naa ko gbe ipe BBC lati ṣewadii naa.
Premier league: Góòlù Sterling tún gbé Manchester city borí Arsenal lẹ́ẹ̀kansi
Oríṣun àwòrán, Premierleague.com
Ija ọga ati ọmọ iṣẹ lo waye lọjọ Satide nigba ti ẹgbẹ agbabọọlu Manchester City gba alejo Arsenal ni papa iṣire Etihad.
Lẹyin ti akọnimọọgba Arsenal, Mikel Arteta fẹyinti gẹgẹ bii agbabọọlu, ọdọ akọnimọọgba Manchester city, Pep Guardiola lo ti kọṣẹ akọnimọọgba ki o to wa gba iṣẹ akọnimọọgba Arsenal.
Eyi mu ki ọpọ maa fi oju ifigagbaga laarin ọga ati ọmọṣẹ wo ifẹsẹwọnsẹ to ba waye laarin wọn.
Nigba ti ifẹsẹwọnsẹ naa wọ iṣẹju kẹtalelogun ni Sterling, agbabọọlu Manchester City ṣide goolu ifẹsẹwọnsẹ naa.
Igba keji niyi ti ikọ Arsenal ati Manchester city yoo maa waako lori papa lati igba ti Arteta ti fi Manchester city silẹ wa di ipo akọnimọọgba mu ni ẹgbẹ agbabọọẹu Arsenal.
Love Making at Old Age: Eré ìfẹ́ wa kò wà láti bímọ, a kàn ń tẹ̀ẹ́ sójú rẹ̀ ni
Awọn tọkọ-taya meji yii ba BBC Yoruba sọrọ lori awọn ohun ti wọn n ṣe to ran wọn lọwọ lati ri ọjọ alẹ papọ gẹgẹ bii tọkọ-taya.
Bẹẹ ni wọn tun sọ nipa irufẹ ounjẹ ti wọn n jẹ, eyii to maa n fun wọn ni okun.
Gẹgẹ bi ọkọ ṣe sọ, o ni “Nigba ti mo wa ni kekere, mo maa n jẹ ororo pupọ, ṣugbọn ni bayii, mo maa n jẹ epo pupa...”
Bakan naa lo ni oun ti fi oyin dipo ṣuga.
Aya rẹ naa sọ pe awọn ounjẹ ti wọn maa n jẹ lasiko yii ni ẹwa, ẹfọ, igbin, ẹja, ati bẹebẹe lọ dipo ẹran ẹlẹjẹ.
Onimọ nipa oun to yẹ ki eeyan maa jẹ kole di ogbo to da si ọrọ naa ni “o yẹ ka maa jẹ ounjẹ to maa fun wa ni okun, ki a maa ṣere idaraya, ki a ma si maa wo aago alaago sare.”
Nipa ohun ti eeyan le ṣe lati gbadun ọjọ rẹ titi dalẹ, mama agba naa ni ohun kinni ni ki eeyan ma ṣe atojubọ, ko si gba ọlọrun gbọ.
Bakan naa ni ọkọ rẹ ni ko yẹ ki eeyan maa ṣe ju ara rẹ lọ nitori ko sin ẹni to le ni ohun gbgogbo tan nile aye.
EndSARS Protest Update: Ọwọ́ pálábá àwọn tó fọ́ ShopRite fún ìgbà kejì ségi
Awọn janduku to kọlu ile itaja ShopRite ladugbo Fate, ni ilu Ilorin ko fi ti isede ti ijọba kede ṣe, eyi to bẹrẹ lọjọ Abamẹta.
Se ni awọn janduku  tun pada lati ji nnkan nile itaja naa.
Ẹ wo ojú àwọn jàndùkú tí ọwọ́ ọlọ́pàá tẹ nígbà tí wọ́n lọ kó ọjà ọlọ́jà ní Shoprite Ilorin
Amọ ikọ ọlọpaa kogberegbe ati awọn ẹṣọ oju lalakan fi n ṣọri n gbiyanju lati ri pe wọn ko tun ji nnkan kò níbẹ.
Akọroyin BBC to wọ inu ile itaja naa ni, ṣe ni awọn janduku ba ọpọ dukia jẹ nibẹ.
Sugbọn ọwọ palaba awọn eeyan naa segi nitori ati ọkunrin ati obinrin ni awọn agbofinro mu l'owurọ ọjọ Abamẹta.
Awọn eeyan naa ni won gba ọna ẹyin wọ inu ile itaja naa laarọ ọjọ Satide lati ko ẹrun nibẹ fun igba keji.
Arabinrin kan ti wọn mu sọ wipe, ọmọ oun tẹle oun wa nitori naa, ki wọn jẹ ki oun gbe ọmọ lọwọ lọ agọ wọn lẹyin ti ọwọ ba a tan.
Yatọ si ile itaja Shoprite ti wọn kọlu, awọn janduku yii tun lọ ṣọsẹ ladugbo Taiwo, nibi ti wọn ti yabo ile itaja Fonemart.
Ọkan lara awọn oṣiṣẹ ile itaja ọhun sọ fun BBC pe, ọja ti awọn jnanduku na ji ko, fẹẹ to ọgbọn miliọnu naira.
Oríṣun àwòrán, Abdulrahman Abdulrazaq
Ijọba ipinlẹ Kwara bu atẹ lu awọn to ja ile igbeohun ini Covid-19 si
Won ni: ''Ijọba ibilẹ kan lo ku ki a pin awọn ounjẹ iranwọ Covid-19 ti awọn eniyan jigbe lo fun''
Ijọba ipinlẹ Kwara ti ni iwa buruku ni awọn janduku to ja ile igbe ohun ini iranwọ Covid-19 si hu ni ilu Ilorin.
Ninu atẹjade ti kọmisọnna fun eto iroyin, Harriet Afolabi- Oshatimehin fi lede awọn ijọba mẹrindinlogun lo ni ohun iranwọ ti awọn eniyan jigbe lọ naa.
Ati wi pe ijọba ibilẹ kan lo ku ki awọn gbe awọn ohun iranwọ naa fun , nitori marundinlogun ninu wọn ti gba ohun iranwọ ti wọn.
Ijọba ni Ajọ CACOVID ati ifọwọsowọpọ ijọba ipinlẹ naa ni wọn ti bẹrẹ si ni pin awọn ohun elo ounjẹ naa fun awọn alaini nipinlẹ naa, ti wọn si ti bẹrẹ lati oṣu diẹ ṣẹyin.
Ti ẹ ko ba gbagbe, Ọjọ Kẹtalelogun, Oṣu Kẹsan an, ọdun 2020, ni ijọba ipinlẹ Kwara pẹlu iranwọ Ajọ CACOVID ṣe ifilọlẹ awọn ohun iranwọ naa, ati bi wọn yoo ṣe pin ti yoo kari gbogbo eniyan.
Nibayii, ijọba ti ni awọn ti ọwọ tẹ nibẹ yoo foju wina ofin, eleyii ti yoo ko awọn yoku lọgbọn.
Bakan naa ni wọn kilo fun awọn janduku lati ti ọwọ ọmọ wọn bọ aṣọ, nitori awọn ko ni gba ki ẹnikẹni  da rogbodiyan silẹ nipinlẹ naa.
Akomolede ati Asa: Mọ̀ si nípa àwọn ọ̀nà tí Yorùbá ń gbà ran ara wọn lọ́wọ́
"Àwọn kan ní ìpínlẹ̀ Kwara já ilé ìkó-ǹkan-sí wọ́n pín "" CaCovid Palliative"" fáwọn èrò ní Ilorin"
"Ọpẹ́lọpẹ́ àwọn ẹ̀sọ́ aláà[bò àwọn Jàǹdùkú tún yabo ilé tí ""Covid 19 Palliative"" waà"
Ọpẹlọpẹ awọn ẹṣọ alaabo, awọn janduku tun yabo ile igbe ohun iranwọ Covid-19 si ni Ilorin
EndSars Protest: Aworan lori ayelujara safihan ọgọọrọ eniyan to n gbe igbe ohun iranwọ Covid-19 si ni Ilorin
Ijọba Kwara ni awọn ti gbọ pe awọn janduku naa n bọ wa ko ohun iranwọ Covid -19
Ẹṣọ alaabo nipinlẹ Kwara ti bori awọn janduku to ṣekọlu si ile igbohun iranwọ Covid-19 si ni agbegbe Ilorin Cargo nipinlẹ Kwara.
Awọn janduku naa lo ṣe ikọlu sibẹ lasiko ti ijọba bẹrẹ si ni pin awọn ohun iranwọ naa fun awọn eniyan to wa ni agbegbe naa.
Ijọba ipinlẹ Kwara ni awọn ohun iranwọ Covid-19 naa wa nibẹ nitori ijọba apapọ ṣẹṣẹ fi sọwọ si wọn ni ipinlẹ naa ni.
Ijọba ni saaju igba ti awọn janduku naa ṣekọlu si ibẹ, awọn ti gbọ wi pe awọn n bọ lati wa hu iwa ipa si wọn ni agbegbe naa.
Ti wọn ṣi ṣetan lati kọ awọn ohun iranwọ ti wọn fẹ fun awọn ti ojo arọrọda ṣọṣẹ si agbegbe wọn, to si ba awọn ohun ini wọn ka.
Ni asiko ti wọn n fi iroyin yii lede, ijọba ni awọn ṣi n tiraka lati kapa awọn jagidijagan naa.
Amo, aworan to n jayin lori ayelujara fihan gbangba bi awọn eniyan ṣe n gbe awọn ohun elo ounjẹ kuro ni ibẹ, ti aẉọn ẹsọ alaabo ko si se wọn ni ijamba.
Àwọn Janduku ya bo Ede wọ́n pin ohun eelo idera ajakale  arun Covid 19.
Ase bo ṣe wa ni liki naa lo wa ni gbanja.
Lẹyin ti okiki iroyin kan lọjọbọ pe, awọn eeyan kan kọlu ibudo iko nnkan awọn ohun elo iranwọ lasiko ajakalẹ arun COVID-19 pamọ si nilu Eko, awọn eeyan kan naa tun ti ṣe bẹẹ nipinlẹ Osun bayii.
Iroyin sọ pe lojumọ ọjọ Ẹti lawọn eeyaEde gbàlejò jàńdùkú tó fọ́ ilé ẹrù ìjọba n kan tun ya bo ibudo iko nnkan awọn ohun elo iranwọ lasiko ajakalẹ arun COVID-19 pamọ si nilu Ẹdẹ, ni ipinle
Oríṣun àwòrán, Screen shot
Jàǹdùkú ya bo ilé ẹrù ìjọba Osun, wọ́n kó èròjà ìdẹ̀rùn Covid-19 lọ
Ni ile kan ti wọn n pe ni Hocoa house ni ilu Ẹdẹ  ni wọn ko awọn ohun irọrun COVID-19 naa si.
Awọn ọdọ atawọn araalu naa ya bo ile nla naa ni nnkan bii agogo mejila ku ogun i'sẹju lowurọ ọjọ Ẹti ti wọn si ko awọn ounjẹ bii noodles, irẹsi, ṣuga, garri atawọn  ounjẹ miran ti wọn gbe pamọ fun irọrun COVID-19 ni ipinlẹ naa.
Awọn kan laera awọn ọdọ naa gbe kẹkẹ, ọkada, ọkọ bọọsi lati fi ko awọn ounjẹ ti wọn n ji ko nibẹ naa.
Awon janduku ti sekolu si ile ikohunpamọsi nilu Eko nibi ti wọn ko awọn ohun amayedẹrun Covid -19 si.
Iṣẹlẹ naa waye ni agbegbe Mazamaza ni ijọba ibilẹ Amuwo Odofin ni ipinlẹ Eko.
Lara awọn to wa ni agbegbe naa ni awọn janduku ja ile igbe nkan pamo si naa, ti wọn si ko gbogbo awọn ohun eelo amayederun Covid-19 to wa nibẹ.
''Agogo mẹjọ aarọ ni iṣẹlẹ naa ti bẹrẹ, nigba ti awọn janduku naa si ko ohun ti wọn nilo tan, wọn pe awọn ara adugbo lati wa bẹrẹ si ni ko awọn ohun elo naa.
''Ohun ti a kọkọ gbọ ni iro ibọn, ti wọn si jawọ ile igbohunsi naa, lẹyin naa ni wọn pe awọn ara adugbo lati wa ma a ko awọn ounjẹ naa lọ́fẹ̀ẹ́
''Awọn ohun eelo ounjẹ ti awọn eniyan n ko naa jẹ eleyii ti wọn kọ orukọ Covid-19 si lara.''
Kini Ijoba sọ?
Amọ, ijọba ipinlẹ Eko ninu atẹjade ti ko si ẹni to buwọlu sọ wi pe, ile ikohunsi to jẹ ọkan lara ti  ijọba ni awọn janduku lo ṣe ikọlu si naa,
Ati wi pe awọn ohun eelo naa wa fun awọn ti nkan ko lo deede fun ni awujọ.
Bakan naa ni wọn fikun un wi pe Ajọ awọn aladani CACOVID  lo fun ijọba ni awọn eelo ounjẹ naa,
Ki wọn le e pin fun araalu lati Ọjọ Kejilelogun, Oṣu Kẹsan, odun 2020, ko to di wi pe awọn eniyan ṣekọlu si agbegbe naa.
Ohun eelo bii, Irẹsi, garri, suga, indomie to to ọna ọgọrun un lọna ẹgbẹrun o le ni awọn fẹ fun awọn ara Eko gba ọwọ ajọ CACOVID.
Oríṣun àwòrán, Twitter/oluwaseunfunmi
Buhari, ìwọ́de yóò yíwọ́, tó ba jẹ́ ki ológun bẹ̀rẹ̀ 'Operation Crocodile Smile' 
Operation Crocodile Smile: Ọmọ Nàíjíríà ní àsìkò ìwọ́de kọ́ ló yẹ kí ológun ṣe àkànṣe ètò
Awọn oluwọde ri ikede ileesẹ ologun lati bẹrẹ operation Crocodile Smile bii ara ọna lati da awọn ologun sita, ki wọn lee bomi pa ina iwọde to n lọ lọwọ.
Ọpọ ọmọ Naijiria lo ti n fesi si ikede ileesẹ ologun lati bẹrẹ akanse eto igbogun tiwa ọdaran ti wọn pe ni Operation Crocodile Smile.
Awọn ọdọ to n se iwọde, awọn ẹlẹgbẹjẹgbẹ ajafẹtọ ọmọniyan atawọn agbẹjọro ti wọn tako igbesẹ naa ni awọn fura pe o seese ki ejo lọwọ ninu lori igbesẹ ologun yii.
Bakan naa ni wọn n fa ijọba leti pe ko tun ero rẹ pa lori ikede ologun naa, paapaa lasiko yii ti iwọde n waye yika Naijiria lati tako iwa ika awọn ọlọpaa, ti wọn si n beere fun ifopin si ọlọpaa SARS.
Awọn eeyan tun wa n kọminu lori igbesẹ ologun lati bẹrẹ akanse eto naa lasiko yii ti arun Coronavirus si wa lode.
Wọn wa n fewe ọmọ mọ aarẹ Buhari leti pe bawọn ologun ba tun bẹrẹ akanse eto lasiko yii, ọrọ naa lee yiwọ pupọ.
Ọjọ Satide nileesẹ ologun kede pe oun fẹ bẹrẹ akanse eto igbogun tawọn agbesunmọmi ati ọdaran lawujọ ni ori ayelujara.
Blind Couples: Pẹ̀lú ìpèníjà ojú, tọkọtaya bímọ mẹ́ta, tí wọn sì tún ń ṣiṣẹ́ olùkọ́
Koda, awọn oluwọde ri ikede ileesẹ ologun lati bẹrẹ operation Crocodile Smile bii ara ọna lati da awọn ologun sita, ki wọn lee bomi pa ina iwọde to n lọ lọwọ.
Oríṣun àwòrán, Nigerian Army/ Twitter
Ileesẹ ologun Naijiria ti kede pe oun fẹ gunle akanse eto operation Crocodile Smile fun ọdun 2020 jake jado orilẹede yii.
Atẹjade kan ti adele oludari ẹka alarina nileesẹ ologun, ọgagun Sagir Musa fisita lọjọ Satide lo sísọ loju ọrọ yii.
Atẹjade naa ni ọjọ Isẹgun, ogunjọ oṣù kẹwaa ọdun 2020 ni eto naa yoo bẹrẹ, ti yoo si pari l'ọjọbọ, ọjọ kọkanlelọgbọn oṣù Kejila.
Ileesẹ ologun ni akanse eto ni Crocodile smile ọdun yii nitori ogun nla lo fẹ gbe ti iwa ọdaran lori ayelujara.
Akanse eto naa, to jẹ akọkọ tileese ologun kan yoo ṣe nilẹ Afirika, lo wa lati ṣe awari awọn eeyan to n kede iroyin aṣọdun lori ayelujara.
Bakan naa ni iroyin naa ni akanse eto yii yoo seranwọ lati sedamọ awọn ọmọ ikọ Boko Haram to n sa kuro lẹkun ila oorun ariwa Naijiria, lọ sáwọn agbegbe miran nitori báwọn ọmọ ologun ṣe n finna mọ wọn.
Ileesẹ ologun wa fọwọ sọya fun ifẹsẹmulẹ aabo ati alaafia to peye yika Naijiria, to si n beere atilẹyin araalu fun aseyọri akanse eto naa.
Lizzy Anjorin: Owó iná ọba kọjá agbára wa, ìjọba kò fẹ́ ká nísinmi
Oríṣun àwòrán, Instagram/ Lizzy Anjorin
Gbajugba oṣere lorilẹede Naijiria, Lizzy Anjorin ti kesi awọn ọdọ, lati ri wi pe wọn ṣe iwọde tako ifiyajẹni ati ipaniyan awọn ọlọpaa ni pẹlẹ putu.
Anjọrin sọ eyi lori ẹrọ ayelujara, nigba to n kaakiri awọn ileeṣẹ ọlọpaa to wa ni agbegbe Ajah nipinlẹ Eko.
Lara awọn agọ ọlọpaa to kan si ni, nibi to ti ba awọn ọga ọlọpaa ibẹ sọrọ ni Ajiwe, Langbasa, Maroko, Ilasan ati Ikota.
Ninu fidio naa ni Anjorin ti rọ awọn ọdọ lati ri wi pe wọn fi suuru ṣe iwọde naa, nitori awọn obi awọn ọdọ naa ṣi nilo wọn.
''Awọn obi wa ran wa lọ si ileewe lati le jere awọn ọmọ wọn, nitori naa ẹ pada si ile layọ ati alaafia ki ireti le wa fun awọn obi''
''Mo rọ yin ki ẹ ṣe jẹjẹ nitori awọn onijagudujagan le lo ifẹhonuhan naa lati fi hu iwa buburu lasiko yii''.
Oríṣun àwòrán, Lizzy Anjorin/Instagram
Oṣere naa ni oun wa lẹyin awọn ọdọ to n fẹhọnuhan nitori ọdọ ni oun naa, ti wọn si gbọdọ ja fun ifẹ ara ilu.
Bakan naa ni o fikun wi pe, awọn ọdọ kii ṣe adari ni ọla mọ, adari loni ni awọn ọdọ, nitori naa ni wọn gbọdọ ja fun eto awọn ọmọ Naijiria.
O rọ awọn eniyan lati ṣe ifẹhọnuhan ninu ile wọn, tabi ki wọn bọ si adugbo wọn ni ọkọọkan ati ejeeji lati ṣe ifẹhọnuhan tako iṣekupani awọn ọlọpaa.
Wo àwọn ọ̀nà tí o lè gbà láti di ọjọ́ ogbó pẹ̀lú olólùfẹ́ rẹ
''Awọn ọlọpaa ko le e dun mahuru-mahuru mọ wa nitori ẹtọ wa ni lati fẹhọnuhan tako nnkan ti ko ba ba wa lara mu.''
'' Jẹun ki o yo daradara ki o to lọ ṣewode, ma lọ lai si ounjẹ ninu rẹ.''
''Ẹni to ba ni ounjẹ ko fun ọmọnikeji rẹ, pẹlu omi, awa ọdọ asiko yii kii ṣe alajẹbanu tabi wọbia''
''Bakan naa ti wahala ba ṣẹlẹ, ẹ ma kọkọ ma a yaworan, ẹ sa asala fun ẹmi yin ati ẹnikeji rẹ''
Ẹwẹ, gbajugba osere lorilẹede Naijiria, Lizzy Anjorin naa tun sọrọ lori owo gọbọi ti awọn ẹka amunawa lorilẹede Naijiria mu wa fun wọn loṣu.
Eegunjobi Omotanbaje Ajobiewe- Èébú ní wọ́n kọ́kọ́ ń bù mí nígbà tí mo bẹ̀rẹ̀ ẹ̀ṣà pípé ní
O ni ẹgbẹrun lọna ẹgbẹrun naira, ₦100,000 ni wọn mu wa fun oun gẹgẹ bi owo ina to lo laarin oṣu kan, ti ko si si ina naa deede.
''Ohun gbogbo di owo gogo, ₦28,000 si ₦35,000 ni wọn n ta irẹsi ni ọja, nitori naa a fẹ ayipada ti ijọba ṣeleri fun wa.
Nibayi naa, Lizzy Anjorin ti lọ si agọ ọlọpaa to wa ni Ajiwe, ni Ajah, lati gba beeli awọn ọdọ to n se iwọde, tawọn ọlọpaa mu si ahamọ wọn.
Amọ nibẹ ni awọn ọlọpaa ti sọ fun wi pe, awọn ko fi panpẹ ọba mu ẹnikẹni to jẹ afẹhọnuhan, o ni ọga ọlọpaa ni agbegbe naa ti kilọ fun osisẹ rẹ lati maṣe mu afẹhọnu kankan lagbegbe naa.
Sotitobire: Ọkọ mi kò mọ̀ Jegede PDP rí, kódà kò fa ẹnikẹ́ni kalẹ̀ dípò Akeredolu- Bisola
Bakan naa ni awọn ọlọpaa naa fi da loju pe, ko si rogbodiyan ni agbegbe naa, nitori awọn afẹhọnuhan naa ṣe iwọde wọn ni pẹlẹ putu.
Awọn ọlọpaa naa sọ fun Lizzy Anjorin pe, awọn to ṣe magomago ti awọn eniyan wa fi ẹjọ wọn sun, lo wa ni ọgba ẹwọn nibẹ.
Ọkan lara awọn ọdọ to jẹ afẹhọnuhan lagbegbe naa fidi rẹ mulẹ fun Lizzy pe, ko si wahala kankan nitori pẹlu suuru ni wọn fi aidunnu wọn han.
Amọ, o fikun wi pe awọn ọlọpaa ni agbegbe Surulere nipinlẹ Eko ni wọn mu awọn ọdọ to n ṣe ifẹhọnuhan lagbegbe naa ni oru mọjumọ.
Bẹẹ si ni Lizzy Anjorin tẹsiwaju lati ma lọ si awọn ileeṣẹ ọlọpaa to wa ni agbegbe naa, to si n rọ awọn araalu atawọn ọdọ lati maa fi ọwọ fun ẹlomiran, ki wọn le gba ohun ti wọn fẹ.
O ni bi oun ko ba le darapọ mọ awọn oluwọde to wa loju popo, o yẹ ki oun le seranwọ lati gba awọn ọdọ ti ọlọpaa ba ko silẹ.
Bakan naa lo rọ awọn gbajumọ miran lati lọ sawọn agọ ọlọpaa to wa ladugbo wọn, lati gba awọn ọdọ to n se iwọde, ti ọlọpaa ba mu si ahamọ silẹ.
EndSARS Protest Update: Ẹgbẹ́ àgbà Yorùbá ní ọwọ́ alágbarà ẹ̀yìn odi ló wà nídi ìkọlù tó wáyé l'Eko
Oríṣun àwòrán, @_el_aaameen/via reuters
Aṣiwaju ẹgbẹ Yoruba lagbaye, Yoruba World Congress, YWC, Alagba Banji Akintoye, ti koro oju si bi aarẹ Muhammadu Buhari ṣe foju rena iṣẹlẹ to waye ni Lekki.
O wa ṣapejuwe bi awọn ologun se kọju ibọn sawọn ọdọ to n sewọde ni Lekki Eko gẹgẹ bi ikọlu si ilẹ Yoruba.
O ni bi aarẹ Buhari ṣe dakẹ lori iṣẹlẹ naa fihan pe iṣẹlẹ naa lọwọ kan awọn araata ninu lati da oju ilẹ Yoruba de'lẹ.
Ninu atẹjade kan to fi sita lọjọ Ẹti, Akintoye ni asiko wa to bayii ki ajọ iṣọkan agbaye, ajọ orilẹede Yuroopu, ajọ iṣọkan ilẹ Afirika, AU, orilẹede Amẹrika ati ilẹ Gẹẹsi, lati dide wa fun atunto asopọ Naijiria ti wọn ṣe ni ọdun 1914.
Oríṣun àwòrán, EPA
Atẹjade naa, to fi sita lẹyin ipade ẹgbẹ naa lowurọ ọjọ Ẹti, aarẹ ẹgbẹ YWC ni o kọ ni lominu pe, awọn ikọlu to waye fun wakati mejidinlaadọta laidakẹ, lee waye ni Naijiria yii, lai si pe ijọba ka awọn to n ṣiṣẹ laabi naa lọwọ ko.
O ni ọrọ ti aarẹ ba awọn ọmọ Naijiria sọ ko jọ bi eyi to ti inu ọkan rẹ wa, afi bii pe n ṣe ni wọn kan an nipa fun un.
Ẹgbẹ Oodua Peoples Congress, OPC, ti bu ẹnu ẹtẹ lu bi awọn ọmọ ologun Naijiria ṣe ṣina ìbọn fun awọn ọdọ to ṣe iwọde#ENDSARS ni Lekki nipinlẹ Eko.
Alẹ ọjọ Iṣẹgun ni iṣẹlẹ naa waye lẹyin ti àwọn ọdọ naa ti n ṣe iwọde kaakiri Naijiria pe ki ijọba fi opin si aṣilo agbara awọn ọlọpaa.
Ninu ọrọ ti ẹgbẹ OPC sọ, o kilọ fun awọn janduku to n lo anfaani rogbodiyan to waye ọhun lati ma a fi ja ole, to si tun n ba dukia ijọba jẹ, lati mase ṣọ Iwọ-oorun Gusu Naijiria di ibudo ogun.
"Akọwe ẹgbẹ naa, Amofin Yinka Oguntimehin, to fi atẹjade sita lorukọ ẹgbẹ sọ pe ""iwa ẹranko gba a ni iṣẹlẹ to waye ni Lekki""."
"O ni ""o han gbangba pe awọn ọta Iwọ-oorun Gusu Naijiria, to jẹ ilẹ Yoruba, lo awọn iwọde alaafia to waye naa, lati doju ogun kọ ẹkùn naa""."
Oríṣun àwòrán, Twitter/Oluwaseunfunmi
O fi kun ọrọ rẹ pe, labẹ isejọba ologun ti oloogbe Sani Abacha dari, ni nkan ti ri bayii ni Naijiria kẹhin.
Bakan naa lo rawọ ẹbẹ si ajọ agbaye, United Nations, lati finna mọ ijọba Naijiria, ko le ṣe iwadii iṣẹlẹ naa.
"O jẹ ibanujẹ pe ijọba apapọ kuna lati dahun ibeere awọn oluwọde naa, eyi to mu ki iwọde alalaafia di itajẹ silẹ, didana sun dukia ati kiko sọọbu awọn eeyan.
 Mo tun n sọ ọ lẹẹkan si pe, ki ijọba apapọ dẹ́kun titan awọn oluwọde to n fi ẹ̀mí wọn wewu lati beere fun igbe aye idẹrun."
Oríṣun àwòrán, @PoliceNG
"O ni iru igbesẹ bẹẹ yoo koba irufẹ ijọba bẹ ẹ to jẹ pe ara ilu lo dibo yan an sipo, paapa nilẹ Iwọ-oorun Gusu Naijiria ."""
"O ni oun kẹdun pẹlu awọn ẹbi oluwọde to ku sinu iṣẹlẹ naa, o si gboriyin fun awọn ọdọ Naijiria fun bi wọn ṣe"" fi igboya ati iduro ṣinṣin polongo fun àtúnṣe nileesẹ ọlọpaa, ti aisi isejọba gidi ba jẹ""."
Oríṣun àwòrán, Facebook/Adoration Ministry Enugu
Ojisẹ Ọlọrun kan ninu ijọ Aguda, Fada Ejike Mbaka ti sọrọ lori iwọde EndSARS, to si ni ipo ti awọn ọdọ wa ni Naijiria ko dara rara.
Mbaka, ninu fidio kan to fi soju opo Facebook ijọ rẹ, Adoration Ministry, ni ọpọ igba loun ti maa n ke sawọn ọdọ lati taji loju oorun wọn.
O ni ti ajaga ba ti wuwo ju bose yẹ lọ, ti ko si se fara da mọ, awọn eeyan yoo ja lati bọ ninu rẹ, pẹlu afikun pe, igbe aye awọn ọdọ Naijiria ko wu ni lori rara.
Ojisẹ Ọlọrun naa ni kii ẹbi Buhari ni awọn isẹlẹ to n waye yii, nitori ko to de ipo ni atako sawọn ọlọpaa SARS ti n waye, paapaa lati aye awọn ijọba to ti kogba wọle.
Oríṣun àwòrán, Facebook/Adoration Ministry Enugu
"SARS kọ ni isoro kansoso taa ni, lẹyin isoro SARS yii, awọn isoro wa yoo si maa tẹsiwaju, abi bawo ni awọn ọdọ ko se ni risẹ oojọ se.
Awọn Sẹnatọ wa n joko le aimọye biliọnu naira, bo si se wa ree lati ọjọ ti alaye ti daye, eyi si kọja ọrọ Buhari."
Mbaka wa gbe imọran kalẹ pe ohun to yẹ ko jẹ wa logun bayii ni eto ti Naijiria ni fawọn ọdọ rẹ ati ipese awọn ohun eelo amayederun.
O ni ọpọ awọn oju popo wa ni ko se rin nitori koto ati gegele, ta ba si ni ka maa pariwo nikan ni, ariwo laa pa titi ti ewu yoo fi hu lori wa, sugbọn awọn ọdọ ko gbọdọ dakẹ.
Oríṣun àwòrán, Facebook/Adoration Ministry Enugu
Ojisẹ Ọlọrun naa tun salaye pe ibeere to yẹ ka maa bi awọn asaaju wa ni pe ki ni wọn n fi owo epo wa se, se wọn kan fi n ra dukia silu Dubai ni.
O ni ẹtahoro ọmọ Naijiria lo n na owo wa, ti eyi ba si tẹsiwaju, ewu si n bẹ loko longẹ.
Oríṣun àwòrán, LAGOS STATE GOVERNMENT
Àwọn oníjàgídìjágan kọlu aafin Oba ìlú Eko àti iléesẹ́ ìròyìn LTV
Ileeṣẹ iroyin ipinlẹ Eko ti wa ni titi pa bayii lẹyin ti awọn onijagidijagan yabo ileeṣẹ naa.
Awọn oṣiṣẹ ileeṣẹ naa ni ijọba ti fun awọn laṣẹ lati kuro ni agbegbe naa, ti wọn ko si si ni ori afẹfẹ lọwọlọwọ bayii.
Ẹni ti iṣẹlẹ naa ṣoju rẹ ni awọn onijagidijagan naa ṣekọlu si awọn ileeṣẹ naa, ti wọn si ba awọn ohun ini wọn jẹ.
Akomolede ati Asa: Mọ̀ si nípa àwọn ọ̀nà tí Yorùbá ń gbà ran ara wọn lọ́wọ́
O fikun pe ileeṣẹ iroyin LTV, Eko FM, Traffic Radio, ati Radio Lagos ni wọn ti tipa bayii lati dẹkun biba awọn ohun ini awon eniyan jẹ ati ti ijọba.
Bakan naa ni wọn yabo aafin ọba ilu Eko to wa ni agbegbe Iga Idugaran, ni agbegbe Lagos Island, nibi ti wọn ti n ba awọn ọkọ ati dukia jẹ.
Aworan fidio to n ja ranyin kaakiri ṣe afihan awọn onijanduku ti wọn gbe ọpa aṣẹ ọba naa, ti wọn si n salọ.
Olugbe agbegbe Lagos Island sọ wi pe awọn to ṣekọlu si ile iya gomina Sanwo-Olu naa lo ṣekọlu si ile ọba naa.
''Nigba ti awọn janduku naa n lọ si ile baba Sanwo-Olu, awọn ọlọpaa ko wọn lọna, ti wọn si yinbọn fun wọn, amọ wọn bori awọn ọlọpaa naa, ti wọn si salọ fun wọn.
Eleyii lo mu wọn lọ si ile Oba ilu Eko, ti wọn si yabo ibẹ pe ọba naa pẹlu ijọba, nitori awọn ileeṣẹ ijọba ni awọn n ṣekọlu si.
Oríṣun àwòrán, Instagram
Àwọn oníjàgídìjágan kọlu aàfin Oba ìlú Eko àti iléesẹ́ ìròyìn LTV
Aisha Buhari polongo àwo orin tó ní Nàíjíríà ń ṣun ẹ̀jẹ̀ lásìkò ìwọ́de
EndSars: Aisha Buhari kígbe kí ìjọba gba àwọn ará Àríwá lọ́wọ́ ètò ààbò tó mẹ́hẹ
Iyawo aarẹ Naijiria, Aisha Buhari ti kesi ijọba lati gbe igbesẹ ni kiakia, nidi ipese eto aabo to mẹhẹ ni ẹkun iwọ oorun Ariwa orilẹede yii.
Aisha Buhari se ikede naa loju opo Facebook rẹ, lẹyin ti awọn ọdọ yika Naijiria fariga pe, ifiyajẹni ati iṣekupani lọwọ awọn ọlọpaa gbọdọ dopin ni Naijiria.
Iyawo aarẹ Buhari se eyi nipa fi fi ara awo orin ti oṣere tiata kan lede Hausa, Adam Zango gbe jade soju opo Twitter rẹ.
"Akọle awo orin naa ni ""Arewa na kuka"", eleyii to tun mọ si pe ''Ariwa Naijiria n sun ẹkun''."
Oríṣun àwòrán, Twitter
Pẹlu orin naa ni Aisha Buhari kọ atẹjade to fi pe fun ki opin de ba eto aabo to dẹnukọlẹ ni Ariwa orilẹede Niajiria naa.
"Pẹlu Hashtag, ti iyawo aarẹ kọ ni ede Hausa, to si pe ni  ""#AChechijamaa"", eyi to tunmọ si ipe fun itusilẹ awọn eniyan."
Igba akọkọ kọ ni yii ti Aisha Buhari yoo sọrọ tako isejọba ọkọ rẹ, nitori bi ilana isejọba aarẹ naa ko mu idagbasoke ba orilẹede Naijiria.
Fidio orin naa lo ṣe afihan aarẹ orilẹede Naijiria, Muhammed Buhari, nibi ti o ti n ṣe ipade pẹlu awọn adari eto aabo lorilẹede Naijiria.
Wo àwọn ọ̀nà tí o lè gbà láti di ọjọ́ ogbó pẹ̀lú olólùfẹ́ rẹ
Lara awọn ohun ti orin naa sọ ni pe:
''Ni orukọ Olorun, a bẹyin ki ẹ tẹti silẹ si awọn eniyan yin, a nilo iranlọwọ, Ariwa orilẹede Naijiria n sunkun/ Ẹjẹ ti wọn ta silẹ, awọn eniyan n ku/dukia si n bajẹ.''
Ikọ Agbẹsunmọmi Boko Haram ti pa ẹgbẹgbẹrun awọn eniyan ni Ariwa orilẹede Naijiria, ti ọpọlọpọ si ti di alairile gbe.
Fun igba diẹ bayii, ni awọn ọdọ ti bẹrẹ si ni ṣe ifẹhọnuhan kaakiri orilẹede Niajiria, lati tako iṣekupani ojoojumọ lati ọwọ awọn ọlọpaa Niajiria paapaa ikọ SARS.
Eegunjobi Omotanbaje Ajobiewe- Èébú ní wọ́n kọ́kọ́ ń bù mí nígbà tí mo bẹ̀rẹ̀ ẹ̀ṣà pípé ní
Bakan naa ni ijọba fi lede wi pe, awọn ti tu ikọ SARS naa ka, ti wọn si gbe ikọ ọlọpaa SWAT dide lati koju iwa ọdaran lawujọ.
Amọ, awọn ọdọ lorilẹede Naijira ni irọ ni igbeṣẹ ijọba, nitorinaa awọn kọ ikọ SWAT kaakiri Naijiria.
Láàrin wákàtí mẹ́ta, wọ́n dá ₦4m fún àkàndá ẹ̀dá tó kópa nínú ìwọ́de
Yoruba bọ wọn ni bi Oluwa ba n se rere, a sọ pe o n se ibi.
Oniruuru itumọ ni iwọde awọn ọdọ to n lọ lọwọ lee ni fun ọpọ eeyan, bi awọn miran se ro pe ohun buburu ni, amọ ohun ayọ lo n jẹ fawọn eeyan miran.
Idi ni pe iwọde awọn ọdọ to n fẹhonu han, ti wọn si n beere fun fifi opin si isẹ awọn ọlọpaa SARS, ti mu iroyin ayọ ba ọdọbinrin kan, Jane to jẹ akanda ẹda.
Ọdọbinrin naa ni wọn ti ge ẹsẹ rẹ kan, to si n fi irin rin lati fi sikeji ẹsẹ rẹ.
Oríṣun àwòrán, @aproko_doctor
Amọ ipenija ara yii ko da ọmọbinrin naa duro lati dara pọ mọ awọn akẹẹgbẹ rẹ ninu iwọde ti wọn n se.
Aarọ ọjọ isinmi si ni wọn gbe iroyin nipa iwa akinkanju Jane yii sori ayelujara, ẹni ti wọn ni ko nisẹ lọwọ lati ọdun 2013 nitori ipenija ara to ni.
Awọn ọdọ akẹẹgbẹ rẹ yii ni wọn ni ihuwasi Jane naa wu awọn lori, ti awọn si fẹ seto iranwọ owo fun.
Ọpọ ọdọ to ka ikede yii nipa ọmọbinrin akanda ẹda naa ni ori wọn wu, ti wọn si n da owo jọ si apo asunwọn ti wsn gbe kalẹ fun Jane.
Wo àwọn ọ̀nà tí o lè gbà láti di ọjọ́ ogbó pẹ̀lú olólùfẹ́ rẹ
Fun iyalẹnu, laarin wakati mẹta ti ikede ẹdawo ọhun de ori ayelujara, awọn ọdọ yii atawọn ọmọ Naijiria miran ti da owo to fẹ wọ miliọnu naira fun Jane.
Awọn ọdọ naa ni awọn fẹ ra ẹsẹ atọwọda fun ọmọbinrin naa, ko le e maa rin lai lo igi mọ.
Ọba oke nikan si lo lee sọ iye ti Jane yoo ri ko jọ ki ilẹ oni to su, eyi to n parọwa siwa pe ilẹ aanu Oluwa kii su.
EndSARS Protest Update: Ìjọba ìpínlẹ̀ Eko ní àwọn ń wádìí èèyàn 229 lọ́wọ́ lórí làásìgbò tó wáyé l'Eko
Ijọba ipinlẹ Eko ni eeyan igba o le mọkandinlọgbọn lọwọ tẹ fun lilo anfani iwọde #EndSARS lati fi jale ni ipinlẹ Eko
Ileeṣẹ eto idajọ ni ipinlẹ Eko ni ijọba ti n yẹ iwe ẹsun ọkọọkan wọn wo bayii.
O ni ọwọ ọlọpaa tẹ awọn afunrasi naa fun oniruuru ẹsun iwa ọdaran bii ile jijo, ipaniyan, ole jija biba dukia onidukia jẹ ati ikọlu ṣaaju ati lẹyin ofin konile o gbele ti gomina Babajide Sanwo-Olu kede lati mu alaafia bọ sipo.
O ni lẹyin ti wọn ba gbe faili ẹsun ọkọọkan wọn yẹ wo tan, awọn to ba lẹjọ lati jẹ ninu wọn yoo kọri si ile ẹjọ lọjọ Aje.
Oríṣun àwòrán, Babajide sanwo-olu
Gomina Babajide Sanwo-Olu ti dẹ okun konile o gbele ọlọjọyipo to fi sita silẹ bayii.
Nibi ikede to ba awọn oniroyin sọ nileejọba ipinlẹ Eko, gomina Sanwo-Olu ni bẹrẹ lati ọjọ Satide, agogo mẹjọ owurọ si mẹfa irọlẹ ni konile o gbele naa yoo maa wa bayii.
Oríṣun àwòrán, LASG
Gomina ipinlẹ Eko, Babajide Sanwo-Olu ti sọ pe ibanujẹ lo jẹ fun oun, bí àwọn janduku ṣe ja iwọde ipolongo #ENDSARS gba.
O ni lati ibẹrẹ pẹpẹ iwọde naa ni oun ti fi ara mọ, sugbọn o ni o kọni lomiinu bi awọn janduku ti ko nifẹ ijọba ati araalu, ṣe bẹrẹ si ni ba dukia ijọba jẹ.
O ni bakan naa ni wọn n jo ile, fọ sọọbu, ti wọn si tun pa ọlọpaa eyi to mu ki awọn ọlọpaa naa bẹrẹ si ni gbe ìbọn kaakiri ilu.
Iṣẹlẹ to waye ni Lekki lọjọ Iṣẹgun ba ni lọkan jẹ, gbogbo wa si ti fẹnu kò pe iru iṣẹlẹ naa ko tun ni waye mọ.
Gomina Sanwo-Olu sọ pe ko si ẹni to fun awọn sọja to yinbọn mọ awọn oluwọde ni Lekki nipinlẹ Eko ni àṣẹ lati ṣe bẹ ẹ.
Gbogbo nnkan to ṣẹlẹ yii la fi ọwọ wa tun ṣe, mo ṣe tan lati sisẹ, sugbọn mo nilo iranlọwọ yin. 
O fi kun ọrọ rẹ pe, ijọba yoo gbe igbimọ kalẹ lati ṣe iwadii àwọn nkan to fa awọn wahala to waye ọhun.
Oríṣun àwòrán, Screenshot
Gomina ipinlẹ Eko wa rawọ ẹbẹ si awọn obi lati ba awọn ọmọ wọn sọrọ pe, ki wọn ma ṣe darapọ mọ awọn janduku to n ba dukia ijọba jẹ.
Ẹ kilọ fawọn ọmọ yin lati gba alaafia laaye, ẹ pariwo o to gẹẹ lori laasigbo to n lọ lọwọ yika ipinlẹ Eko lati ipasẹ iwọde EndSARS.
Bakan lo kesi awọn ọba, baalẹ ati awọn olori ẹṣin musulumi, Kristẹni ati ẹṣin ibilẹ lati fi ọwọ sowọpọ pẹlu ijọba, ki opin le ba rogbodiyan to n waye nipinlẹ Eko.
#EndSARS: Wo ohun táwọn jàǹdùkú ṣe sí ilé ẹjọ́ Igboṣere l'Eko
Ileeṣẹ ọlọpaa ti fi ikilọ sita pe ko saye iwọde mọ ni ipinlẹ Eko bẹrẹ lati agogo mẹrin ọjọ Iṣẹgun Ogunjọ oṣu kẹwaa ọdun 2020.
Ileeṣẹ ọlọpaa ipinlẹ Eko lo kede bẹẹ ninu Atẹjade kan ti alukoro ileeṣẹ ọlọpaa naa, Muyiwa Adejobi fi sita lọjọ Iṣẹgun.
O ṣalaye pe lẹyin agbeyẹwo awọn ikọlu to waye lasiko iwọde naa lawọn ibikan nipinlẹ Eko ni wn se ipinnu ọhun.
Adejobi ni awọn ikọlu yii lo nii se pẹlu kikọlu awọn ọlọpaa ati ileeṣẹ ọlọpaa pẹlu awọn araalu.
O ni eyi fihan pe awọn janduku ti sa asawọ wọnu iwọde naa, wọn si ti n lo anfani iwọde ọhun lati fi dana iwa laabi kaakiri ipinẹ Eko.
O ni pẹlu bi gomina Babajide Sanwo-Olu si ti kede ofin konile o gbele bayii, ileeṣẹ ọlọpaa ti ko awọn ọlọpaa kogberegbe da sigboro lati lati rii daju pe aṣẹ koni o gbele ọlọjọyipo naa fidi mulẹ daadaa.
Ni owurọ ọjọ Iṣẹgun lawọn janduku kan nibi iwọde ENDSARS l'Eko kọlu agọ ọlọpaa kan lagbegbe Orile ti wọn si dana sun un.
Oríṣun àwòrán, PMNews
Lẹyin ti ọga ọlọpaa patapata lorilẹede Naijiria wọgile ikọ SARS gẹgẹ bi ara ipe awọn ọdọ to n wọde fun fifi opin si iwa aṣemaṣe ikọ naa ati ileeṣẹ ọlọpaa lapapọ, ikọ tuntun ti wọn fẹ da silẹ yoo bẹrẹ igbaradi ni ọjọ Aje.
Eyi ni awọn amuyẹ ti ileeṣẹ ọlọpaa ni yoo wa fun awọn ọlọpaa ti yoo darapọ mọ ikọ naa.
Ọga agba patapata nileeṣẹ ọlọpaa Naijiria, Muhammed Adamu ṣalaye ni ọjọ Aiku pe awọn ọlọpaa ti yoo darapọ mọ ikọ kogberegbe ti wọn fẹ fi rọpo SARS naa gbọdọ ni awọn amuyẹ wọnyii.
Ọga ọlọpaa Adamu ṣalaye pe awọn ọlọpaa ti oun yan si ikọ naa
1.Wọn jẹ ọdọ ẹlẹjẹtutu
2.Wọn ni okun ati agbara.
3.Wọn ti lo ọdun meje tabi jubẹẹ lọ lẹnu iṣẹ ọlọpaa
4.Wọn ko ni abawọn lẹnu iṣẹ wọn
5.Wọn ko ni ẹsun iwa ibajẹ kankan lẹnu i'sẹ
6.Wọn ko ni ẹsun titẹ ẹtọ araalu mọlẹ tabi ṣi ibọn lo.
7.Wọn sangun lati farada eto idanilẹkọ ati igbaradi ikọ SWAT
Ọga ọlọpaa Adamu ṣeleri pe awọn ọlọpaa iks naa yoo ṣe iṣẹ wọn bi iṣẹ bi o ti tọ ati bi o ti tọna.
Blind Couples: Pẹ̀lú ìpèníjà ojú, tọkọtaya bímọ mẹ́ta, tí wọn sì tún ń ṣiṣẹ́ olùkọ́
Ọrọ Oluwa ẹdẹ ni, bẹẹ si ni ni awamaridi ni pẹlu nitori ero rẹ kọja ti ẹda.
Ẹ wo tọkọtaya yii, Malaam Sulaiman Abdulquadri ati aya rẹ, Mujidat ni wọn ni ipenija oju, amọ ti wsn pinnu lati fẹ ara wọn.
Nigba ti wọn n ba BBC Yoruba sọrọ, tọkọtaya Abdulquadri ni ọpọ ikorira, idẹyẹsi ati aropin lawọn n koju lọdọ awọn eeyan awujọ, ti wọn ro pe awọn ko le se rere laye.
Ọkọ ni awọn obi oun bi oun ni afọju ni nigba ti aya salaye pe, arun ẹfọju oju Glaucoma lo fọ oun loju.
Lọwọ lọwọ bayii, ọmọ mẹta ni Ọba Oke fi jinki wọn, ti wọn si tun n sisẹ olukọ.
Awọn mejeeji wa n rawọ sawọn ẹlẹyinju aanu ọmọ orilẹede yii, lati dide iranwọ owo fun wọn ki wọn le pari ile wọn ti wọn n kọ lọwọ.
Lekki Toll gate: Àwọn ọlọtẹ̀ ló ń gbìyànjú láti dá ọ̀tá sílẹ̀ láàrin èmi àti ẹ̀yin ènìyàn mi - Jagaban
Oríṣun àwòrán, ASIWAJU TINUBU
Agba ẹgbẹ oṣelu All Progressives Congress, Asiwaju Bola Ahmed Tinubu ti ni gbogbo asiko iwọde EndSARS atohun to tẹyin rẹ wa to fi mọ iṣẹlẹ pipa awọn oluwọde kan ni Lekki Tollgate l'Eko kan tun n ba ọrọ jẹ fun oun ni.
Tinubu figbe ọrọ yii bọ ẹnu nigba to ri i pe ẹjọ nihin lọhun fẹ pọ lori oun. o ni lakọkọ, wọn fẹsun kan oun pe oun lo ṣagbatẹru ifẹhonuhan ọhun, nigba to ya wọn tun ni oun lo ran awọn lati yinbọn lu awọn oluwọde ni ibode Lekki lọjọ Iṣẹgun ọsẹ to kọja lati tu wọn ka.
Tinubu ni iṣẹ awọn ọta leleyii tori wọn n sọ pe oun n pa owo latara Lekki Tollgate ọhun tẹlẹ toun si ti n padanu rẹ lọpọlọpọ nitori iwọde.
Ẹwẹ, Asiwaju ṣapejuwe pe irọ patapata gbaa ni wipe awọn to n ditẹ mọ oun ninu oṣelu lo kan n lo wọn lati kẹyin oun ati ijọba ipinlẹ ati ijọba apapọ sira.
Ṣaaju ninu ọrọ kan to sọ lọj Aiku nigba ti wọn fi ọrọ wa Tinubu lẹnu wo lo ti s pe oun kọ ni alakoso Lekki Tollgate, oun ko si ni owo nibẹ.
"Ṣugbọn o gba o si sọ pe ""emi ni alagbatẹru ati oludari agba ileeṣẹ iroyin the Nation ati ileeṣ amohunmaworan TVC"" eyi ti awọn janduku tun kọlu ti wọn si jo nina rau-rau."
Tinubu ni sibẹsibẹ, oun ko ran sọja tabi ọlọpaa lati dena oun ti wọn ṣe si awọn ileeṣẹ oun tori oun ko fẹ ki ẹnikẹni ku bo tilẹ jẹ pe idokoowo oun ni wọn bajẹ.
O ni iṣẹlẹ to n waye yii ko ṣe oun lanfani kankan nipa ti oṣelu tabi na miiran bikoṣe pe o tun ba ọrọ jẹ fun oun ni toripe ọpọ eeyan lo n tabuku ba oun lọna aitọ si ohun ti oun ko mọwọ mẹsẹ.
Amọ sibẹ sibẹ, mo duro lẹyin awọn ọmọ Naijiria digbi lati ṣe iwọde alafia.
'Egbò tó ti fẹ́ẹ̀ jiná ni ìtàn bí wọ́n ṣe pa Soun Ogbomoso, Ọba Olayode tẹ ń bèrè'
Oríṣun àwòrán, twitter/Gboyega Akosile
Awọn gomina kan ni ẹkun Iwọ-oorun Gusu Naijiria ti ṣe abẹwo ibanikẹdun si gomina ipinlẹ Eko, Bababjide Sanwo-Olu.
Abẹwo yii ko yọ awọn minisita kan to jẹ ọmọ ilẹ Yoruba silẹ.
Ni ile ijọba ipinlẹ Eko to wa ni Marina ni Sanwo-Olu ti gba wọn ni alejo.
Gomina ipinlẹ Oyo, Seyi Makinde, Kayode Fayemi ti Ekiti, Gomina Rotimi Akeredolu lati ipinlẹ Ondo, to fi mọ minisita fun ina mọnamọna, Babatunde Fashola, minisita fun ọrọ awọn ọdọ ati idagbasoke ere idaraya, Sunday Dare.
Oríṣun àwòrán, Twitter/gboyega akosile
Gomina Sanwo-Olu mu wọn lọ si diẹ lara awọn dukia ijọba ati aladani ti awọn janduku dana sun.
Lara awọn to tun wa nibi abẹwo naa ni minisita fun ọrọ abẹle, Rauf Aregbesola, ati minisita keji fun eto ilera, Olorunninbe Mamora, to fi mọ minisita fun okoowo ati ọrọ awọn ileeṣẹ, Niyi Adebayo.
Minisita fun iwakusa, Olamilekan Adegbite naa wa nibẹ.
Ìjọba ìpínlẹ̀ Eko tí kéde ìlànà ìséde tuntun fún ará ìlú
Ṣé lóòtọ́ ni Afenifere fún àwọn èèyàn ẹ̀yà Igbo ní wákàtí 48 láti fi ilẹ̀ Yorùbá sílẹ̀?
Ẹni tó jí ọ̀pá aṣẹ ń bọ̀ wá túbá fúnrarẹ̀, mo fi dáa yín lójú gẹ́gẹ́ bí ìyá - Erelu Kuti
Òkú ọ̀dọ́ 15 ni mo kà ní Lekki amọ́ mo kábàámọ̀ pé a gbà kí ológun gbé okù wọn lọ - DJ Switch
Lasiko abẹwo naa ni Gomina Sanwo-Olu mu wọn lọ si diẹ lara awọn dukia ijọba ati aladani ti awọn janduku dana sun.
Gẹgẹ bi Akọwe iroyin ati ikede fun Gomina Sanwo-Olu, Gboyega Akosile ṣe sọ, Gomina ipinlẹ Ondo, to tun jẹ olori awọn gomina nilẹ Yoruba, Rotimi Akeredolu ṣapejuwe iṣẹlẹ to waye nipinlẹ Eko, gẹgẹ bi ibudo ogun.
O ni eyi ko ṣẹyin iye nkan ti awọn janduku to ja iwọde ENDSARS gba, bajẹ.
"Awọn nkan to ṣẹlẹ yii, mu ki a gbagbọ pe ọrọ naa kii ṣe oju lasan.
Awọn nkan to ṣẹlẹ yii tu aṣiri pe ẹkun yii wa ninu ewu lọwọ awọn to fẹ sọ ọrọ aje rẹ di akurẹtẹ."""
Oríṣun àwòrán, Punch newspapers
Agba ẹgbẹ oṣelu APC lorilẹede Naijiria, Bola Ahmed Tinubu ni oun ti beere lọwọ gomina ipinlẹ Eko boya oun lo fun awọn ṣọja to yinbọn ni agbegbe Lekki lalẹ ọjọ Iṣẹgun lasẹ lati yin si awọn oluwọde nibẹ.
Bọla Tinubu sọ eyi di mimọ lasiko to ṣabẹwo si gomina Sanwo-Olu ni ile ijọba ipinlẹ Eko to wa lagbegbe Marina.
"Tinubu to ni idi abẹwo oun gan ni lati mọ hulẹhulẹ iṣẹlẹ naa ni lara awọn ibeere ti oun wa bi gomina Sanwo-Olu nipa iṣẹlẹ naa ni pe 'ṣe oun lo paṣẹ ki awọn ṣọja yinbọn sawọn oluwọde naa?"""
"Bi kii ba ṣe oun, ta lo paṣẹ naa?"" ""ṣe o mọ pe wọn kọlu awọn eeyan nibi iṣẹlẹ naa?"
Bakan naa ni Oloye Tinubu tun jẹ ko di mimọ peawọn oluwọde to wa ni agbegbe Lekki Tollgate lasiko ti iṣẹlẹ naa waye pẹlu ni ibeere lati dahun leyi to ni yoo ran ijọba lọwọ lati lee ṣi aṣọ loju ohun gbogbo to ṣokunkun sraye nipa ikọlu naa.
Awọn ibeere to ni awọn oluwọde naa gbọdọ fesi si niyi.
1.Bawo ni wọn ṣe de ibẹ?
2.Iye asiko wo ni wọn fi wa nibẹ
3.Iru awọn eeyan wo ni awọn oluwọde to wa nibẹ.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ọpọ ipinlẹ lo n koju aawọ abẹnu ninu ẹgbẹ APC lorilẹede Naijiria
Agba ọjẹ oloṣelu ninu ẹgbẹ All Progressives' Congress, APC, Asiwaju Bola Ahmed Tinubu ti ṣe abẹwo si gomina ipinlẹ Eko, Babajide Sanwo-Olu lati ba a kẹdun lori awọn iṣẹlẹ to waye nipinlẹ Eko l'ọsẹ yii.
Lasiko abẹwo naa to waye nile ijọba ipinlẹ ọhun to wa ni Marina nilu Eko, ni Tinubu ti ba awọn oniroyin sọrọ, to si sọ pe irọ ni iroyin to sọ pe oun sa kuro ni Naijiria lasiko rogbodiyan to waye.
"Bakan naa lo sọ pe awọn to fi ara gbọta nibi iṣẹlẹ ipaniyan to waye ni Lekki  ""naa ni ẹjọ lati jẹ́""."
O sọ pe wọn ni lati sọ iru eeyan wo ni wọn jẹ, bawo ni wọn ṣe de ibẹ, ati pe bawo ni wọn ṣe pẹ to nibẹ.
Lootọ la fẹ ẹ ranwọn lọwọ, ṣugbọn a ṣi gbọdọ gba ọrọ ti yoo ran ijọba lọwọ lati le mura silẹ fun ọjọ iwaju, ati lati mọ igbesẹ to yẹ.
"Asiwaju Tinubu sọ pe oun ko kuro ni ilu Eko. O ni ""mi o lọ si ibi kankan, ọmọ Eko ni mi, eminaa si ni Asiwaju ilu Eko."
Emi ṣi ni Jagaban.
Awọn iroyin kan sọ pe ni kete ti wahala #ENDSARS gba ọna miran yọ, ni Ahmed Tinubu ti salọ si ilu Paris, l'orilẹ-ede France. Awọn kan tiẹ tun sọ pe ilu London lo salọ.
"Bakan naa lo sọ pe oun kẹdun pẹlu ẹbi awọn to ku, ati awọn to farapa nibi iṣẹlẹ to waye."""
"O sọ pe ""mo wa lati ba gomina kẹdun, ati lati tọrọ aaye lọwọ rẹ lati ṣe abẹwo si diẹ lara awọn to farapa, to ṣi wa nile iwosan, ati lati mọ bi ao ṣe pese iranlọwọ lori igbesẹ ti ijọba fẹ ẹ gbe."""
O ni ayederu iroyin ni awọn iroyin to sọ pe oun salọ, tabi pe awọn kan ji ọmọ rẹ ọkunrin, Seyi Tinubu gbe nitori iṣẹlẹ naa.
Oríṣun àwòrán, @AsiwajuTinubu
Aṣiwaju ẹgbẹ oṣelu APC, Bola Ahmed Tinubu ti sọ pe, oun ko lee ba ẹnikẹni lọwọ ninu iṣekupani ọpọ eniyan.
Tinubu lo sọ ọrọ naa, nigba to n da si bi awọn ọmọ ileeṣẹ ologun ṣe ṣina ibọn bolẹ fun awọn olufẹhonuhan End SARS ni Lekki Toll Gate, to wa ni ilu Eko lọjọ Iṣẹgun.
O sọ fun ileeṣẹ iroyin abẹle Channels pe, ko bojumu to bi awọn ọmọ ogun naa ṣe lo ọta ibọn to lee gbẹmi eeyan lati tu awọn oluwọde  ka.
Tinubu bu ẹnu atẹ lu igbesẹ ti awọn ọmọ ogun naa gbe.
Wo àwọn ọ̀nà tí o lè gbà láti di ọjọ́ ogbó pẹ̀lú olólùfẹ́ rẹ
"O ni ""Emi ko le darapọ mọ ẹnikẹni lati gba ẹmi ọpọ ero, lai lai."
Bakan naa ni gomina ipinlẹ Eko tẹlẹ naa sọ pe kii ṣe oun lo ni ileeṣẹ Lekki Concession Company, to n mojuto bi Toll Gate naa ṣe n pa owo wọle fun ijọba Eko.
"O ni ""Mi o lọwọ ninu Toll Gate, bẹẹ ni kọbọ mi ko si nibẹ."""
Aṣaaju ẹgbẹ oṣelu APC naa tẹsiwaju pe oun ko mọwọ mẹsẹ ninu bi Toll gate ṣe n pa owo wọle, bẹẹ si ni oun ko lọwọ ninu iku awọn oluwọde.
Sotitobire: Ọkọ mi kò mọ̀ Jegede PDP rí, kódà kò fa ẹnikẹ́ni kalẹ̀ dípò Akeredolu- Bisola
Wahala bẹ silẹ ni Toll Gate naa lẹyin wakati diẹ ti ijọba ipinlẹ Eko kede ofin konile-o-gbele, ṣugbọn ti awọn oluwọde ọhun kọ lati fi agbegbe naasilẹ.
O kere tan, ọgbọn eeyan lo fara gbọgbẹ ọta ibọn lẹyin ti awọn ologun sina bolẹ nibẹ.
Ṣugbọn ileeṣẹ ologun ti sẹ pe oun ko mọwọ mẹsẹ ninu bi wọn ṣe dana ibọn bo awọn oluwọde.
Oríṣun àwòrán, @AsiwajuTinubu
Gomina tẹlẹ nipinlẹ Eko ati asiwaju ẹgbẹ oṣelu APC, Bola Ahmed Tinubu, ti sọrọ nipa iwọde ENDSARS to gbode jake jado Naijiria.
Tinubu, ninu ikede to fi sita loju opo Twitter rẹ lọjọ Aje ni lootọ lawọn oluwode lẹtọ lati fehonu han ṣugbọn nibi ti wọn ba ọrọ de yii,asiko to lati sinmi iwọde.
O ti pe ọjọ mejila ti iwọde ENDSARS naa ti bẹrẹ yika Naijiria.
Bakan naa lo tun kan sara si ipinnu awọn oluwọde naa, to si bẹnu atẹ lu awọn janduku to n da omi alaafia Naijiria ru.
"Ẹ́yin ọdọ ti ri ere nipa awọn tẹ n beere fun lati ipasẹ iwọde tẹ n se, amọ, ẹ gbọdọ sọra se, kẹ ma ba padanu awọn ere naa nitori bi iwọde ọhun se n di ọlọjọ gbọọrọ.
Akomolede ati Asa: Mọ̀ si nípa àwọn ọ̀nà tí Yorùbá ń gbà ran ara wọn lọ́wọ́
Tinubu ni awọn oluwọde ni lati fun ijọba Buhari laaye, ko le ṣe amuṣẹ awọn ileri to fẹ ṣe nipa ọrọ to wa nilẹ yii, paapa atunto ileeṣẹ ọlọpaa.
Igba akọkọ ree ti Tinubu yoo da sí iwọde to gba ile, gba oko ni Naijiria.
Kaakiri Naijiria si ni iwọde yii ti ṣe idiwọ fun lilọ bíbọ ọkọ ati ero, to si tun mu ki ọrọ aje dẹnu kọlẹ pẹlu.
Oríṣun àwòrán, Reuters/aisha yesufu
Bi awọn ọdọ lorilẹede Naijiria ṣe n wọde lati tako iwa kotọ awọn ọlọpaa ati iṣejọba ti ko fararọ lati nnkan bii ọsẹ kan sẹyin,iwọde n lọ lawọn agbegbe miran lagbaye, ojo iwọde Naijiria to n rọ ni ko jẹ kaye mọ pe awọn eeyan iwọde ,miran lagbaye n tọ sara.
Ni ilẹ Afirika nikan, orilẹede Ivory Coast ati Namibia naa n foju wina tiwọn titi kan awọn orilẹede bii Hong Kong, Thailand, Chile ati Belarus lawọn eeyan ti n fi ẹhonu wọn han lori ọkọ o jọkan idi to kan koowa wọn.
Ni ibẹrẹ oṣu kẹwaa ọdun 2020 ni iwọde fopin si iwa kotọ ọlọpaa ti ọmọ si #ENDSARS bẹrẹ ni Naijiria.
Ninu iwóde yii ni ogunlọgọ awọn ọdọ ti ya bo igboro lati pe fun wiwagbo dẹkun si iwa aitọ awọn ọlọpaa.
Koko ẹhonu marun un lawọn oluwọde naa gbe kalẹ pe awọn fẹ ki ijọba mojuto ki wọn si tete gbe igbesẹ to tọna lori rẹ.
Nitori eyi ileeṣẹ ọlọpaa pa ikọ SARS rẹ; bẹẹni ijọba apapọ ti ṣalaye fawọn ipinlẹ gbogbo lorilẹede Naijiria lati tete gbe igbimọ oluwadi kalẹ lati boju wo gbogbo ẹsun ati ẹhonu tawọn araalu n gbe sita.
Igbimó naa yoo mojuto  ọrọ naa ki wọn si gbe lọ siwaju ileeṣẹ eto idajọ fun eto to tọ labẹ ofin.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ni ọjó kẹjọ, oṣu kẹwaa, ọdun 2020, awọn eeyan orilẹede Namibia ya wọ oju popo gbogbo lolu ilu orilẹede naa, Windhoek.
Wón se eyi lati fi ẹhonu han tako iwa ipa si awọn obinrin lẹyin ti awọn ọlọpaa ri oku arabinrin kan, Shannon Wasserfall lẹyin oṣu mẹfa ti wọn ti n wa a.
Afẹfẹ tajutaju tea gas, ọta ibọn onirọba ni awọn ọlọpaa fi tu awọn oluwọde naa ka.
Orilẹede Namibia wa lara awọn orilẹede ti iwa ifipabanilopọ pọ ju si ni Africa
Oríṣun àwòrán, Reuters
Ni oṣu kẹwaa, ọdun to kọja lawọn ara Chile ni tiwọn ti n  wọde nitori owo ọkọ to gbowo leri.
Amọṣa iwọde naa ba tun yipada si eyi ti a fi n fẹhonu han lori ọwọngogo , aisi iṣuna to jọju fun ẹka eto ẹkọ ati bẹẹ bẹẹ lọ
Ni ọjọ kejidinlogun ni awọn oluwọde naa rin kaakiri fun ayajọ ọdun ti kan iwọde wọn                         a
Awọn ọlọpaa só pe awón  ọlọpaa mejidinlogun ni o fara pa nibi iwọde naa.
Oríṣun àwòrán, Reuters
Ọpọ ọdọ lorilẹede Thailand lo n wọde nibi ti wọn ti n ke si olotu ijọba orilẹede naa, Pratyuth Cha-ocha o kọwe fi ipo silẹ
Awọn ọdọ naa n beere fun atunṣe iwe ofin orilẹede naa, ki wọn si ṣeto idibo tuntun, ki wọn si tun fi opin si idunmọhuru sawọn ajafẹtọ araalu nibẹ.
Oríṣun àwòrán, AFP
Iwọde tako ijọba ni Hong Kong ti n walẹ diẹdiẹ.
Abadofin kan lori lile eeyan kuro ni orilẹede naa lo tan ina wa ibinu araalu nibẹ.
Abadofin naa yoo fun awọn afurasi iwa ọdaran lanfani ati gbe ni orilẹede China bẹrẹ lati ọjọ kini, oṣu kẹrin nitori ninu ero wọn, abadofin naa yoo fi idajọ ododo dun awọn ọmọ HongKong.
Ehonu marun un  ni wọn gbe ka iwaju ijọba.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Idibo ni Belarus nibi ti olori ilẹ naa, Alexander Lukashenko to ti wa nipo fun ọpọlọpọ ọdun tun bori lo fa wahala iwọde ni Belarus pẹlu bi ọpọlọpọ awọn eeyan ṣe n ni makaruru wa ninu  idibo naa lati gbe Lukashenko
O le lẹgbẹrun lọna ọgọrun un awọn eeyan to peju si Central Minsk, to jẹ olu ilu orilẹede naa fun ọjọ Aiku mẹrin ọtọtọ ni ṣiṣẹ n tẹle, bẹẹni o le ni ẹgbẹta eeyan tawọn agbofinro ti de mọ kulu ahamọ .
Akomolede ati Asa: Mọ̀ si nípa àwọn ọ̀nà tí Yorùbá ń gbà ran ara wọn lọ́wọ́
Lori eto Akomolede ati Asa lori BBC Yoruba fun tọsẹ yii, ohun ta gbeyẹwo ni asa iran ara ẹni lọwọ.
Yoruba ni ajeje ọwọ kan ko gbe ẹru dori, nitori naa lo fi se pataki lati maa ran ara wa lọwọ.
Olukọ wa lọsẹ yii, Arabinrin Funke aya Falade-Young si ti wa nikalẹ lati kọ wa nipa orisirisi asa iran ara ẹni lọwọ to wa ati anfaani wọn.
Olukọ wa salaye lori ilana sise Ajọ, Aaro ati Ọwẹ lati fi ran ara wa lọwọ ati iyatọ to wa laarin wọn.
Bakan naa la tun mọ nipa awọn ọna ta le gba lati san eto yii pada laarin awọn eeyan to ba n kopa ninu rẹ.
Arabinrin Funke Falade-Young salaye ni kikun fun gbogbo wa bi asa iranraenilowo se se pataki nile Yoruba
Ẹ fi ara balẹ, kẹ maa ba olukọ wa bọ, lati kẹkọ nipa asa ilẹ Yoruba to da lori eto riran ara ẹni lọwọ.
Coronavirus: Ìpínlẹ̀ méjìlá tó wà ní ìṣọ̀rí àkọ́kọ́ ní yóò gba owó ìrànwọ́ lọ́sẹ̀ yìí
Oríṣun àwòrán, @Fredick_Leonard
Lati ibẹrẹ ọsẹ yii lọ, ijọba apapọ yoo bẹrẹ si san owo iranwọ pẹ pẹ pẹ fawọn olokoowo ke ke ke ati alabọde.
Awọn eeyan yii ni wọn ti yege lati kopa ninu eto iranwọ arun Coronavirus ti apapọ owo rẹ to biliọnu marundinlọgọrin naira.
Ọjọ Kẹwaa osu Kẹsan ọdun 2020 si ni ijọba apapọ sefilọlẹ eto mejeeji naa, labẹ ileesẹ to wa fun ifẹsẹmulẹ ọrọ aje nilẹ Naijiria.
Awọn olokoowo ke ke ke ati alabọde to to miliọnu kan ati ẹgbẹrun lọna ẹẹdẹgbẹrin si ni yoo jẹ anfaani eto naa.
Oríṣun àwòrán, @Fredick_Leonard
Amugbalẹgbẹ fun aarẹ lori okoowo alabọde pẹlu ọọfisi igbakeji aarẹ ati alakoso eto naa, Tola Adekunle sọ fawọn akọroyin nilu Abuja pe eto sisan owo naa yoo bẹrẹ lọsẹ yii.
Adekunle ni isọri isọri lawọ n se eto pinpin owoya naa, ti ipinlẹ mejila si wa labẹ isọri kan, eyi ti yoo jẹ ko rọrun lati tọpinpin eto naa.
Lọwọ lọwọ bayii, ipinlẹ mejila ti setan lati gba owoya naa, a si lero pe ki ọsẹ yii to pari, a san owo naa fun wọn."
Akomolede ati Asa: Mọ̀ si nípa àwọn ọ̀nà tí Yorùbá ń gbà ran ara wọn lọ́wọ́
Ori awọn onisẹ ọwọ lati ti kọkọ bẹrẹ, eeyan ẹgbẹrun mẹrin ati aabọ si ni yoo jẹ anfaani owo iranwọ naa nipinlẹ kọọkan.
Bakan naa ni awakọ ero ẹgbẹrun mẹrin ati aabọ yoo jẹ anfaani rẹ, eyi ti yoo mu ki apapọ akopa nipinlẹ kan jẹ ẹgbẹrun mẹsan.
"Gbogbo apapọ awọn eeyan ti yoo jẹ anfaani eto naa ni isọri akọkọ, tii se ipinlẹ mejila si jẹ ẹgbẹrun lọna mẹrinlelaadọta."""
EndSars Protest: TB Joshua, Indaboski àtàwọn Wòlíì méjì míràn ti kéde wàhálà ìwọ́de sáájú
Oríṣun àwòrán, Twitter, Facebook, AFP
Ni asiko ti ọdun tuntun ba n kan ilẹkun gbọn-gbọn, tabi to ba wọle de, kii se ajeji mọ lati ri awọn ojisẹ Ọlọrun kan, ti wọn yoo sọ asọtẹlẹ nipa awọn nnkan ti yoo sẹlẹ ninu ọdun naa.
Bi o tilẹ jẹ pe arun Coronavirus bẹ jiga saarin agbaye ninu ọdun 2020, amọ ko daju pe ojisẹ Ọlọrun kankan sọ asọtẹlẹ nipa rẹ, lati mu kawọn eeyan gbaradi fun.
Ninu osu kẹwaa ọdun 2020 yii naa ni iwọde EndSARS waye, ninu eyi ti ọpọ ẹmi ati dukia ti baa rin, ti laasigbo si gbode pẹlu.
Amọ nibayii, awọn ojisẹ Ọlọrun kan to gbajumọ bii isana ẹlẹẹta lorilẹede Naijiria, ti fọwọ gbaya pe awọn ti sọ asọtẹlẹ nipa rogbodiyan naa saaju.
Diẹ lara awọn ojisẹ Ọlọrun ti wọn si ti kede pe awọn ti sọ asọtẹlẹ nipa iwọde EndSARS ati ipaniyan to tẹle ree:
Oríṣun àwòrán, Twitter/tbjoshua
Ọkan lara awọn wolii lorilẹede Naijiria to maa n sọ asọtẹlẹ loore-koore ni oludasilẹ ijọ Synagogue lagbaye, TB Joshua.
Wolii ijọ Sinagọgu naa si ti sọ asọtẹlẹ to fara pẹ laasigbo to tidi iwọde EndSARS yọ, amọ o kan jẹ pe ọjọ ti pẹ, to ti sọ asọtẹlẹ naa.
Asọtẹlẹ naa si lo sẹ lẹyin ọdun meje to ti kede nipa rẹ.
Ninu iwaasu rẹ to se ninu ijọ rẹ to wa nilu Eko, lọjọ Kẹrinla, osu Keje, ọdun 2013, ti wọn si gbe sori ayelujara,  ni TB Joshua ti n ke tantan nipa ajalu to n bọ.
Oríṣun àwòrán, Screenshot
"Ninu fidio naa, ti ileesẹ kan gbe sita lo ti n pariwo pe ""Iran ti mo ri niyi, ẹ fa awọn ọdọ yin mọra, mo ri ijijagbara awọn araalu tii se Revolution."
Mo ri ti ọpọ eeyan ya bo oju popo, o seese kẹ le da iwọde duro, amọ ẹ ko le da ijijagbara duro.
O seese kẹ le dawọ ijijagbara naa duro ni ibẹrẹ pẹpẹ amọ nigba to ba ya, wahala naa yoo fẹju sii, ti ko si ni dawọ duro mọ.
Awọn nnkan ti mo ri pe yoo waye ree, orilẹede Naijiria, ẹ gbadura.
Wolii Chukwuemeka Odumeje, ti ọpọ eeyan mọ si Indaboski naa jẹ wolii keji to kede pe Ọlọrun ti fi isẹlẹ EndSARS han oun saaju.
Loju opo Instagram rẹ si lo ti kọkọ se alabapin iroyin naa, to si tun tun sọ lẹyin ti rogbodiyan suyọ lẹyin iwọde EndSARS.
Oríṣun àwòrán, Instagram/odumeje_dlion
Indaboski ni nibẹrẹ ọdun 2020 ni oun ti sọ asọtẹlẹ pe ki olori di ori rẹ mu ni nitori ọdun yii kii se ọdun awada tabi ẹfẹ rara, ọdun ija ati wahala gbaa ni.
"Ẹ gbọ mi, ẹ gbadura fun orilẹede Naijiria nitori idaru-dapọ, rogbodiyan nibi gbogbo. Mo ri awọn agbegbe kan ti wọn kede isede konile o gbele.
Amọ awọn eeyan tako ikede naa, ti wọn si bọ sita lati fi ẹhonu han lai bikita fun aabo ẹmi wsn rara."
Bakan naa ni Wolii Samuel ninu iran rẹ fun ọdun tuntun, ti sọ asọtẹlẹ lori rogbodiyan EndSARS.
Oríṣun àwòrán, prophet_i_o_samuel
Ninu asọtẹlẹ naa lo ti kede pe oun ri awọn eeyan to mura bii ologun, ti wọn n se iwa ika sawọn araalu ati ọpọ ọmọ orilẹede Naijiria.
Bakan naa ni mo tun ri awọn ọdọ, ti wọn n sare sọtun-sosi lasiko iwọde, ti ọpọ ẹmi si bọ sinu rẹ, bakan naa ni awọn dukia sofo pẹlu.
Wolii kẹrin to kede nipa asọtẹlẹ rẹ saaju lori rogbodiyan ati iwọde EndSARS ni Wolii Jeremiah Omoto Fufeyin.
Oríṣun àwòrán, Facebook/Prophet Jeremiah Omoto Fufeyin
Lọjọ Kejilelogun osu Kefa ọdun 2020 si lo ti sọ saaju pe orilẹede Naijiria, lati ipasẹ awọn ipinlẹ kan yoo mi titi, ti gbogbo agbaye yoo si gburo rẹ.
"Iku yoo pọ lati ipasẹ rogbodiyan nla kan to n bọ, mo si n rọ awọn ọdọ lati gbadura gidi lori isẹlẹ naa.
Ọkan gboogi lara awọn ajafẹtọ ọdọ lorilẹede, Oloye Sunday Adeniyi Adeyemo ti ọpọ eniyan mọ si Sunday Igboho, ti pe fun alaafia laarin awọn ọdọ kaakiri orilẹede Naijiria.
Oríṣun àwòrán, Igboho
O fi ikilọ yii lede nigba to n sọrọ lori ifẹhọnuhan EndSars ti awọn janduku n lo lati fa rogbodiyan kaakiri orilẹede Naijiria.
O rọ awọn ọdọ lati ri ifẹhọnuhan EndSars gẹgẹ bi ọna ati beere fun ọjọ ọla to dara lọwọ ijọba, eleyii ti wọn wa n lo lati ba ohun ini ijọba jẹ.
''Nitori naa, mo bẹ awọn ọdọ lati jọwọ fi gbogbo iwa ipa silẹ, ki wọn si gba alaafia laaye.''
O ni:  ''Lilo iwa ipa, ija ati jijo ohun ini ijọba ati ti awọn eniyan ko ni wa ọna abayọ si iṣoro to doju kọ orilẹede Naijiria.''
''Nitori naa, mo fẹ kẹ gba alaafia laaye, ki a si duro de ijọba lati sọrọ lori ibeere ti awọn ọdọ bere lọwọ wọn.''
Amọ, Sunday Igboho bu ẹnu atẹ lu bi ikọ ọmọogun Naijiria ṣe yinbọn lu awọn afẹhọnuhan ni Lekki Toll-Gate nipinlẹ Eko.
Bẹẹ si lo tako gbogbo iṣekupani to waye kaakiri orilẹede Naijiria gba ọwọ awọn janduku ati awọn ọlọpaa lorilẹede Naijiria.
Bakan naa lo ni iwa buruku ni awọn ikọ ọmọogun to yinbọn naa hu, nitori owo ori awọn ọmọ Naijiria ni wọn fi n sanwo oṣu wọn, ti wọn si fi ra ibọn naa fun wọn.
Sunday Igboho wa kesi ijọba apapọ lati ri wi pe wọn ṣewadii finifini lati mọ awọn to ṣiṣẹ ibi yii, ki wọn si fi wọn jofin.
Ìwọ́de EndSARS ló ń sọ pé inú ń bí àwọn ọ̀dọ́, ìjọba, ẹ náání wọn - Obasanjo
Ọ́ba Enitan Ogunwusi ni awọn ọdọ ti gba akoso orilẹede yii, lati ọjọ akọkọ iwọde, si ni wọn ti se afihan pe awọn ni abuda asaaju rere.
Agba kii wa lọja, ki ori ọmọ tuntun wọ, idi ree ti awọn agba meji nilẹ Yoruba fi fori kori lori iwọde EndSARS to n lọ lọwọ yika Naijiria.
Awọn agbaagba mejeeji naa ni Oloye Olusegun Obasanjo ati Ọọni tilu Ile Ife, Ọba Adeyeye Enitan Ogunwusi, ti wọn sọrọ lori iwọde naa.
Oloye Obasanjo, lasiko to lọ se kara o le si ọọni salaye pe iwọde to n lọ yika Naijiria yii ti fun ijọba lanfaani lati sọ fun araalu pe oun naani wọn.
Obasanjọ ni iwọde yii lo n safihan inu to n bi awọn ọdọ Naijiria, eyi to yẹ ki ijọba tete kọbi ara si.
Aarẹ ana ni Naijiria naa ni o le ni ida ọgọta ninu ọgọrun awọn eeyan Naijiria ti ọjọ ori wọn ko to ọdun marundinlogoji, ti wọn si n fi oju sọna fun igbe aye to dara amọ ti wọn n jijagudu pẹlu eto ẹkọ lọwọ.
Ọpọ wọn gan ni ko ni anfaani si ẹkọ iwe, to si jẹ pe aisi anfaani lati se rere ti da irẹwẹsi si awọn ọdọ to kawe lọkan, o si yẹ ko ye wa pe o di dandan ki wọn si ideri lori omi to n ho naa."""
Amọ mo mọ pe ọpọ anfaani lo wa fun ijọba lati samulo rẹ lori ipese idẹrun fun awọn ọdọ, aarẹ, gẹgẹ bii baba orilẹede ati awọn ọdọ, to si ni ọmọ tirẹ, o yẹ ko mọ bi awọn ọdọ ti le huwa.
Nigba to wa n fesi, Ọba Ogunwusi ni iwọde yii jẹ ọna lati fi isẹ ransẹ sijọba pe awọn ọdọ naa lee se nnkan lọna to dara.
"Ta ba wo iwọde naa, a ri pe awọn ọdọ ti gba akoso orilẹede yii, lati ọjọ akọkọ iwọde, si ni wọn ti se afihan pe awọn ni abuda asaaju rere.
Bakan naa ni wọn n jiyin isẹ iriju wọn laarin ara wọn, ti wsn si n se ojuse to yẹ, eyi to n paroko fun ijọba nipa bawọn ọdọ ilẹ yii ti dangajia to."
Ọba Ogunwusi wa rawọ ẹbẹ sawọn ọdọ naa lati jeburẹ, ki wọn si duro de ohun ti ijọba fẹ se lori ibeere wọn.
EndSARS Protest: Àwọn olùwọ́de Endsars ló já sọ́ọ̀bù kìí ṣe torí ebi - Femi Adesina
Oríṣun àwòrán, femi Adesina/twitter
Agbẹnusọ ààrẹ Muhammadu Buhari lórí ìròyìn àti ìpolongo, Femi Adesina ni kìí ṣe ebi tàbi òsì ló mú ki àwọn ènìyàn maa já ilé, já sọ́ọ̀bù tàbi bá ǹkan jẹ́ bí kò ṣe ìfẹ̀hónúhàn #EndSars.
Adesina sọ ọrọ náà lásìkò tó ṣe ìfọ̀rọ̀wánilẹ́nuwò ni orí móhùmáwòràn kan pé, kí a maa lọ ẹbi àti ìyà mọ bí wọ́n ṣe ń já sọ́ọ̀bù, dàbí ẹni pé ènìkàn sọ pé ìwà adigunjalè dára ni.
"Gẹ́gẹ́ bi o ṣe sọ ọ́ "" Ìwà ọ̀daràn ni ọ̀daràn ń jẹ́, ṣe a lé sọ pé ǹkan tó dára ni adigunjale ṣe, nítori pé ó tòsì tàbi kò lówó?"
"Tí a ko ba ti lé foriji ẹnii to gbé ìbọ̀n lọ jalè nítorí kò lọ́wọ́, bẹ́ẹ̀ náà ni a ò le fọwọ́ ra awọn to já sọ́ọ̀bù lóri.
Agbẹnusọ ààrẹ náà sàlàyé pé, nítori pé ìwọ́de náà ti pẹ́ ju bi o ṣe yẹ lọ ló mú kí ààyè gba àwọn tó ṣe aburu náà.
Ó ní tí wọn ò bá jó àgọ́ ọlapàá ni, ètò ààbò kò ni dojúbolẹ̀, àwọn ọ̀daran kò sì ni rí iṣẹ́ ṣe.
Adesina ni, bí wọ́n ṣe n sọ pé, orílẹ̀-pedpe Nàìjíríà ni olú-ilú àwọn òtòsì lágbàyé, kìí ṣe orí ìjọba yii ni òṣì náà ti bẹ̀rẹ̀, bí kìí ṣe bi àwọn adarí ti ṣe ṣe owó ìlú mákumaku láti ààdọ́ta ọdún sẹ́yìn, kìí ṣì ṣe ǹkan ti ìjọba tọ n bẹ lóde le ṣe láàrin ọdun méjì
Nínú ọ̀rọ̀ rẹ̀, ó ni àwọn ìgbẹ́sẹ̀ ààrẹ Buhari yóò mú ènìyàn ọgọ́rùn mílíọ̀nù kúrò nínú òṣì ni ọdún mẹ́wàá síbí.
NUJ ní báwọn ọlọ́pàá ṣe ń ti akọ̀ròyìn mọ́lé láìtọ́ sàfihàn ìwà taniómúni wọn
Oríṣun àwòrán, @MBuhari
Ẹgbẹ awọn akọroyin nilẹ wa, NUJ, ti kesi aarẹ Muhammadu Buhari lati ba awọn ọmọ Naijiria sọrọ nipa iwọde EndSARS to n lọ lọwọ.
Atẹjade kan ti olu ile ẹgbẹ akọroyin nilu Abuja fisita, ti akọwe apapọ ẹgbẹ, Shuaib Usma Leman fọwọsi, ni ọrọ yii ti jẹyọ.
Ẹgbẹ NUJ ni ẹnu n ya oun nipa bi aarẹ Buhari se dakẹ lai fọhun lori iwọde EndSARS to n lọ lọwọ, eyi to ti da omi alaafia orilẹede yii ru.
Kété tí wọ́n bá ti báa yín sùn tàn torí pé ẹ tóbi, ẹ gbà pé ìfẹ́ yẹn ti parí - Auntie Remi Ọlọ́yàn ńlá
Bakan naa ni NUJ tun kesi ọga agba ọlọpaa pata loriẹede yii lati fopin sawọn iwa ifiyajẹni ti wọn n se sawọn akọroyin.
Oríṣun àwòrán, NUJ national Headquater
O wa beere pe ki wọn tu akọroyin kan, Tom Oga Uhia, tii se oludasilẹ iwe iroyin Power Steering Magazine to wa lahamọ silẹ.
Atẹjade naa ni o ti to ọsẹ kan nayii ti wọn ti fi Tom sahamọ pẹlu asẹ minisita keji feto ohun amusagbara, Godwin Jeddy Agba, lori ẹsun pe o ba oun lorukọ jẹ.
NUJ ni niwọn igba ti awọn ọlọpaa ko ti lee gbe Tom lọ sile ẹjọ lati igba naa, bi wọn se fi si ahamọ tubọ tu asiri iwa tani yoo mu mi tawọn ọlọpaa n hu.
Oríṣun àwòrán, @MBuhari
Atẹjade yii ni oun gba pe wọn ko tii gbe awọn igbesẹ ti yoo wa ojutu sawọn ohun to n fa ẹhonu awọn oluwọde.
Bakan naa lo kesi aarẹ Muhammadu Buhari lati jade wa bawọn ọmọ Naijiria sọrọ, ko si sọ awọn ọna ti yoo gba wa ojutu sawọn ẹhonu oluwọde.
Atẹjade NUJ wa n beere pe se aarẹ Buhari ti padanu ohun rẹ ni, tori awọn ọmọ Naijiria n reti ọrọ rẹ nibayi ti Naijiria joko le agba ẹtu, to lee bu nigbakugbaa.
Oríṣun àwòrán, Babajide SanwoOlu
Gomina Babajide Sanwo-Olu tipinlẹ Eko ti kede isede konile o gbele nipinlẹ́ Eko.
Atẹjade kan ti gomina Sanwo-Olu fisita salaye pe alase yipo ni isede naa, ti yoo gba gbogbo ọjọ.
Ijọba gbe igbesẹ naa nitori rogbodiyan to bẹ silẹ laarin ifẹhọnuhan EndSars.
Nigba to n sọrọ lori iwọde EndSARS to n lọ lọwọ naa, gomina ipinlẹ Eko ni pẹlu iyalẹnu ni oun fi n tọpinpin bi iwọde naa, to bẹrẹ ni alaafia se wa di eyi to n dunkoko mọ awọn araalu ati igbayegbadun awujọ.
Ọpọ eeyan lo ti padanu ọwọ ati ẹsẹ wọn sọwọ awọn janduku naa, ti wọn sapamọ sabẹ awọn oluwọde yii, ti wọn si n da omi alaafia ipinlẹ naa ru.
O ni gẹgẹ bii ijọba to mọ ohun to n se, to si mu iwọde EndSARS lọkunkundun, a ko ni fọwọ lẹran, ki ilu dojuru mọ wa lọwọ.
Nitori idi eyi, mo ti wa kede isede oni wakati mẹrinlelogun yika gbogbo ipinlẹ Eko, bẹrẹ lati aago mẹrin irọlẹ oni."
"Ko gbọdọ si lilọ bibọ ọkọ ati ero kankan ni gbogbo awọn agbegbe to wa nipinlẹ Eko yatọ si awọn onisẹ kose maase nikan."""
Iwọde EndSARS to n lọ lọwọ yika Naijiria tun ti gba ọna miran yọ ni agbegbe Apapa Iganmu nipinlẹ Eko.
Idi ni pe awọn janduku to ti ja iwọde naa gba, ti dana sun agọ ọlọpaa to wa lagbegbe yii ni deede aago mẹwa ku isẹju mẹẹdogun laarọ yii.
Koda, iroyin kan ti ko tii fidi mulẹ ni awọn ọlọpaa lo yinbọn mọ awọn janduku naa, eyi to mu ki wọn dana sun agọ ọlọpaa ibẹ.
Oríṣun àwòrán, @VoiceofOndo
Lọwọ lọwọ bayii, iwọde naa si n tẹ siwaju nilu Eko, tawọn oluwọde si ti di awọn opopona nlanla to wa nilu naa.
Nigba ta kan sileesẹ ọlọpaa ipinlẹ Eko lori isẹlẹ yii, alukoro fun ileesẹ ọlọpaa naa, Muyiwa Adejobi salaye pe, ileesẹ ọlọpa yoo fi ikede sita laipẹ.
O ni ikede yii ni yoo sọrọ lẹkunrẹrẹ nipa bi isẹlẹ naa se waye.
Oríṣun àwòrán, @aproko_doctor
Iroyin to n tẹ wa lọwọ ni yajoyajo ni igboro ilu Akure ti daru nitori iwọde EndSARS to gbode.
A gbọ pe awọn oluwọde naa n jo sọọbu, taya, ti wọn si di gbogbo ọna gboogi nilu Akure pa.
Koda, se ni awọ̀n eeyan to jade laarọ oni n sa kijokijo kiri lati sa asala fun ẹmi wọn.
Alukoro ileeṣẹ ọlọpaa ipinlẹ Ondo, Tee-Leo Ikoro, ti fidi rẹ mulẹ fun BBC Yoruba salaye pe, ilu Akure n gbona giri laarọ oni nitori awọn oluwọpde End SARS tó dí gbogbo oju ọna.
Oríṣun àwòrán, @joeshooar
Ikoro lọ sọ ọrọ naa ninu ifọrọwerọ pẹlu BBC Yoruba.
"O ni ""O ni ootọ ni pe igboro ti daru ni ilu Akure lẹyin ti awọn janduku to darapọ mọ awọn oluwọde End SARS, di gbogbo oju ọna to yẹ ki awọn eeyan gba pa."""
Ikoro fi kun pe gbogbo awọn ọna to ṣe pataki ni ilu naa ni awọn oluwọde naa di ti, wọn ko si jẹ ki awọn to nibi re ri ọna kọja.
Akomolede ati Asa: Mọ̀ si nípa àwọn ọ̀nà tí Yorùbá ń gbà ran ara wọn lọ́wọ́
O ṣalaye pe iwọde ọhun n lọ ni ẹrọ pẹlẹ ṣaaju akoko yii ni ipinlẹ Ondo, ṣugbọn o dabi pe nnkan ti n yiwọ bayii.
Bo tilẹ jẹ pe o ni oun ko le fi idi rẹ mulẹ pe awọn oluwọde naa n jo ṣoọbu lagbegbe Arakalẹ ni Akure, ṣugbọn ori alupupou ni oun wa, ti oun si n kaakiri ilu naa lati woye bi ohun gbogbo ṣe n lọ.
Ikoro pari ọrọ rẹ pe, kọmiṣọna ọlọpaa ipinlẹ Ondo ti bẹrẹ ipade pẹlu awọn ẹlẹkajẹka lọna ati wa ojutu si rogbodiyan naa to n rugbo bọ.
Sotitobire: Ọkọ mi kò mọ̀ Jegede PDP rí, kódà kò fa ẹnikẹ́ni kalẹ̀ dípò Akeredolu- Bisola
"Ẹwẹ, ọkan lara awọn olugbe ilu Akure, Oluwatosin  Oladapo sọ fun BBC Yoruba pe ""Gbogbo ibi ni awọn oluwọde naa ti di bayii, koda wọn n jo taya lagbegbe Old Garage, awọn eeyan ko si ri ọna kọja."""
A n se akojọpọ ẹkunrẹrẹ iroyin yajoyajo lọwọ, a o maa gbe ẹkunrẹrẹ iroyin naa sori atẹ iroyin wa laipẹ. Ẹ jọwọ, ẹ tun oju opo iroyin yi yẹwo, ki ẹ lee ri ẹkunrẹrẹ iroyin ọtun laipẹ.
EndSARS: Olórí ilé aṣofín-ṣòfin ní ìṣúnà 2020 gbọdọ̀ pèsè owó fún ASUU bí bẹ́ẹ́kọ̀...
Oríṣun àwòrán, @femigbaja
Olori ile asoju-sofin nilẹ wa, Femi Gbajabiamila ti sọrọ nipa awọn isẹlẹ to se koko to n waye nilẹ wa, paapaa iwọde EndSARS.
Gbajabiamila, ẹni to sọrọ yii ninu akanse ọrọ to bawọn araalu atawọn asoju-sofin sọ nibi ijoko ile asoju-sofin to waye lọjọ Isegun, wa kede awọn igbesẹ to fẹ gbe loti yanju awọn isẹlẹ naa.
Gbajabiamila ni lakọkọ, oun ko ni buwọ lu eto isuna ọdun 2020 lai jẹ pe o pese owo iranwọ fawọn mọlẹbi awọn eeyan to jalaisi lasiko iwọde naa.
Bakan naa lo ni oun ko ni buwọlu eto isuna ọhun, ti ko ba pese owona fun ẹgbẹ ASUU lati wa idahun si ohun ti wọn n beere fun.
Oríṣun àwòrán, @femigbaja
Olori ile asoju-sofin ni ile asofin naa yoo tun ri daju pe ijọba gbe igbesẹ lati se atunse ati atunto awọn ileeẹkọ giga gbogbo nilẹ wa, ti yoo fi ba ode oni mu.
O ni oun ko ni buwọlu eto isuna naa, ti ko ba ya owo nla sọtọ lati se atunse awọn ileẹkọ giga wa.
Ko tan sibẹ, Gbajabiamila tun ni oun yoo ri daju pe oun kan sawọn mọlẹbi awọn eeyan to padanu ẹbi wsn lasiko iwọde EndSARS yii, lati tu wọn ninu.
Akomolede ati Asa: Mọ̀ si nípa àwọn ọ̀nà tí Yorùbá ń gbà ran ara wọn lọ́wọ́
O fikun pe, Ile asofin yoo tun saayan lati ri daju pe aba ofin to n se atunto si eto idibo nilẹ wa dohun, lọna ti pese idibo to mọyan lori ni Naijiria.
Olori ile asoju-sofin tun fọwọ gbaya pe atunse ofin ilẹ wa yoo waye, eyi ti yoo mu ko dangajia lati fidi ẹtọ ọmọniyan mulẹ.
Bakan naa lo ni ile asofin yoo sisẹ lori ọna tawọn ẹkun kọọkan yoo fi maa se akoso awọn ohun alumọọni to wa ni ẹkun wọn, gẹgẹ bawọn ọmọ ilẹ yii ti n fẹ.
Blind Couples: Pẹ̀lú ìpèníjà ojú, tọkọtaya bímọ mẹ́ta, tí wọn sì tún ń ṣiṣẹ́ olùkọ́
Gbajabiamila wa koro oju si iwa ta ni yoo mu mi tawọn ọlọpaa n hu, to si ni wọn ko ga ju ofin lọ lọna kọna, eyi to ba si tapa si ofin, lo yẹ ki ọbẹ ofin ba.
EndSars Protest slang: Kíní ìtumọ̀ Sọ̀rọ̀ Sókè tí àwọn afẹ̀họ́núhàn EndSars ń lò káàkiri
Oríṣun àwòrán, Small Doctor
Ojọgbọn imọ Ede Yoruba, Bisoye Ẹlẹsin ti salaye fun BBC idi ti ''Sọrọ Soke'' ṣe di akanlo ede lorilẹ-ede Niajiria lasiko ifẹhọnuhan tako ifiyajẹni ọlọpaa kaakiri orilẹede Naijiria.
Eyi ko ṣẹyin bi awọn ọdọ ni ipinlẹ Eko ṣe pariwo fun gomina ipinlẹ Eko, Babajide Sanwo-Olu lati ''sọrọ soke'' lasiko to n ba awọn ọdọ afẹhọnuhan sọrọ nipinlẹ Eko.
Lati igba naa ni awọn afẹhọnuhan EndSars ti bẹrẹ si ni lo ọrọ naa kaakiri, to fi mọ oke okun.
Akomolede ati Asa: Mọ̀ si nípa àwọn ọ̀nà tí Yorùbá ń gbà ran ara wọn lọ́wọ́
Kíní ìtumọ̀ Sọ̀rọ̀ Sókè tí àwọn afẹ̀họ́núhàn EndSars ń lò káàkiri:
Bisoye Ẹlẹsin to ba BBC Yoruba sọrọ ni ede lagbara lawujọ nitori naa ni ede asa ṣe n jade ninu ọrọ ti awọn eniyan ma n lo.
O ni bi ede ṣe n gbooro si ni agbegbe kan ni awọn eniyan a maa lo bi o ṣe wulọ si fun ohun ti wọn nilo rẹ fun.
''Ẹwa ede ni ki awọn eniyan lo gẹgẹ bi ọrọ asa(slang) lawujọ fun iwulo wọn''
Imọ wa ti ko pọ nipa ede lo jẹ ki a maa tẹmbẹlu rẹ''
Nibayii, sọrọ soke ti di akanlọ ede, eleyii to tumọ si wi pe awọn eniyan ti n lo o ju bi a ṣe mọ ọ si lọ
Ìpínlẹ̀ Oyo àti Osun sàlàyé ìdí tí wọn kò fi tí ṣè ifilolẹ ìgbìmò igbẹjọ aṣemáṣe SARS
Buhari, jáde bá ọmọ Nàíjíríà sọ̀rọ̀, orí àgbá ẹ̀tù la dúró lé - NUJ pariwo
N kò ní buwọ́ lu ìṣúná tí kò pèsè owó fún ẹ̀bí àwọn tó kú nínú ìwọ́de EndSARS - Gbajabiamila
Kò sáyè iwọ́de mọ́ l'Eko ẹ lọ tọwọ́ yín bọṣọ - Ọlọ́pàá
Awọn eniyan gboogi wo lo ti ''Sọrọ Soke'' ni Ilẹ Yoruba?
Obafemi Awolowo jẹ ọkan gboogi lara awọn to ja fun ominira orilẹede Naijiria, ti o ''sọrọ soke'' nigba aye rẹ lori aṣemaṣe ti ijọba n ṣe nigba naa.
Lara awọn sọrọ to sọ ni pe '''awọn ọlọla ni orilẹede Naijiria yoo wọ wahala ti wọn ko ba tọju awọn alaini ati awọn mẹkunu to wa ni awujọ.
Olusegun Obasanjo to ti fi igba kan jẹ adari orilẹede Naijiria ma n sọrọ soke lati igba de igba, ti yoo si tọka si awọn ohun ti ko tọ ti ijọba to wa lode n ṣe ati ọna abayọ si iṣoro to n koju orilẹede Naijiria.
Baba Obasanjo ni orilẹede Naijiria ni ohun alumọni to jẹ wi pe ko yẹ ki iya ati iṣẹ ma a jẹ ẹnikẹni.
Nitori naa Niajiria yoo gbe igbesẹ to yẹ nigba ti asiko ba tọ lati ri wi pe iṣẹ dopin ni Naijiria.
Ọjọgbọn ati onkọwe Wole Soyinka jẹ eniyan kan gboogi to n fa fun ẹtọ awọn ọmọ Niajiria, awọn alawodudu nile ati loko ni ọpọlọpọ igba.
Lara awọn ọrọ to ti sọ lati fi soro sọke ni pe'' gbogbo eniyan lo lẹtọ si idajọ ododo, ati ẹtọ ọmọniyan'', '' orilẹede Naijiria ti la iṣọrọ kọja nitori awọn onijẹgudujẹra, o si ti su wọn.''.
Lọpọ igba ni pasitọ David Oyedepo ti ma n sọrọ soke tako ijọba paapaa lori eto abo,ẹsin ẹlẹyamẹya ni Niajiria.
Laiko aarun Coronavirusw yii ni Oyedepo bu ẹnu atẹ lu ijọba aarẹ Muhammadu Buhari lori bi o ṣe gba ki ọja maa si , amọ ki awọn eniyan ma lọ si ile ijọsin.
Ni ọpọlọpọ igba naa ni adari ijọ Redeem, Pasitọ Enoch Adeboye ti ma n kesi awọn eniyan to wa nipo lati ṣe ohun to tọ lawujọ, ti yoo tun sọrọ nipa idile ati igbe aye onigbagbọ.
Laipẹ yii lo ke si aarẹ Buhari lati ṣe kanmọ nipa atunto orilẹede Naijiria, ki o ma ba pin yẹlẹyẹlẹ.
EndSARS Protest Update: Iléèṣẹ́ ọlapàá sọ pé Ọlọ́pàá mẹ́fà ni jàndùkú pa, wọ́n tún kọlù àgọ́ ọlọ́pàá márùn-ún lásìkò ìwọ́de
Awọn janduku pa ọlọpaa mẹfa, wọn ṣe akọlu si agọ ọlọpaa marun un lasiko ifẹhonuhan #EndSARS nipinlẹ Ọyọ
Ileeṣẹ ọlọpaa ipinlẹ Ọyọ ti ṣe afihan awọn afurasi ọdaran to dana sun agọ ọlọpaa nilu Isẹyin.
Awọn afurasi ti ọlọpaa mu fun didana sun agọ ọlọpaa niluu Isẹyin
Lara awọn afurasi naa ni;
Taoreed Hamsat ẹni ọdun mẹrindinlọgbọn,
Tajudeen Ibrahim ẹni ogoji ọdun,
Moshood Fatai ẹni ọdun mọkandinlogoji,
Musibau Abubakar ẹni ọdun mọkanlelogun.
Bakan naa ni Sikiru Aliu ẹni ọdun mẹẹdọgbọn,
Fasasi Fatai, ẹni ọdun mẹrinlelogun,
Isiaka Olaniyi, ẹni ọdun mejilelọgbọn,
Raheem Toheeb, ẹni ọdun mejidinlọgbọn
Ati Adeleke Akeem, ẹni ọdun mejilelogoji.
Ngozi Okonjo-Iweala ló borí gẹ́gẹ́ bí obìnrin àkọ́kọ́ tó di olórí ajọ okoòwò l'ágbàáyé, WTO
Ẹ má à gbìyànjú láti bo àṣírí ìpànìyàn tó wáyé ní Lekki, á ní ẹ̀rí tó dájú - Amnesty International
Àkùkọ dojú ìjà kọ ọlọ́pàá, ikú ló já sí fún agbófinró
Wo àwọn ìpínlẹ̀ tí ọlọ́pàá ti bẹ̀rẹ̀ àyẹ̀wò ojúlé sí ojúlé káàkiri Nàìjíríà torí ohun tí wọ́n jí kó
Lasiko to n ṣe afihan awọn ọdaran naa l'Ọjọru ni olu ileeṣẹ ọlọpaa to n bẹ ni agbegbe Ẹlẹyẹle ilu Ibadan, kọmisana ajọ ọlọpaa nipinlẹ Ọyọ, Joe Nwachukwu Enwonwu ṣe alaye wi pe ọlọpaa mẹfa ni wọn da ẹmi wọn legbodo.
Bẹẹ sini awọn ọdaran naa tun dana sun agọ ọlọpaa marun un ọtọọtọ, ti wọn si tun ji awọn nnkan ijagun lọ.
Enwonwu parọwa si awọn eeyan awujọ lati ọrọ to ileeṣẹ ọlọpaa leti ti wọn kẹẹfin awọn ọdaran to ji awọn ohun elo ijagun ọlọpaa lọ.
Lara ohun elo ti wọn ri gba pada lọwọ awọn  afurasi naa ni ẹrọ amunawa kekere kan, aago ara ogiri mẹsan an,  alupupu Bajaj kan, alupupu Hero marundinlaadoje ati alupupu TVS kan pẹlu nọmba iforukọsilẹ DGB 215QK.
Gómìnà ìpínlẹ̀ Oyo, Seyi Makinde ti ṣe ìpàdé pẹ̀lú àwọn èèkàn ní Ìpínlẹ̀ náà lórí ọ̀nà àbáyọ sí ìfẹ̀hónúhàn #EndSARS àti nǹkan tó jẹyọ lórí ẹ̀.
Makinde ní ọ̀sẹ̀ tó ń bọ̀ ni ìjọba rẹ̀ yóò ṣe àgbékalẹ̀ ìgbìmọ̀ ìwádìí lórí ìfìyàjẹni ọlọ́pàá ní Ìpínlẹ̀ náà.
Mo tun fẹ fi asiko yii fi da awọn eeyan Oyo loju daadaa pe iṣejọba wa yoo tẹsiwaju lati maa fi ti ẹyin araalu ṣaaju.
Ọrọ yii jẹ jade nigba ti gomina naa pe ipade awọn lọba lọba, igbimọ awọn alaga ijọba ibilẹ, ati awọn igbimọ idagbasoke ilu to fi mọ awọn alufaa.
"Láàrín ìṣẹ́jú díẹ̀, ẹ ka ìwé Akinwumi Ishola, ""Nítorí Owó"" lórí Akomolede Yoruba"
Oríṣun àwòrán, Seyi Makinde
Ipade rẹ pẹ́lú awọn eekan yii waye lati jiroro lorii ọna itẹsiwaju fun ipinlẹ naa lẹyin ọpọpọlọ ọsẹ titi iwọde ifẹhonuhan EndSARS ti fa.
Bakan naa, Makinde fi kun un pe awọn yoo mojuto iṣoro ọrọ aje to ti pa awọn araalu lara.
A ti da ẹẹdẹgbta miliọnu naira sọtọ fun iranwọ idokoowo kekeke a o si gba ọdọ ẹgbẹrun marun-un si iṣẹ ijọba ni oṣu diẹ si isisiyii.
Bakan naa o ni awọn yoo pin iṣi kaarun nkan iranwọ Covid-19 lopin ọsẹ yii.
O ni gẹgẹ bo ṣe wa ninu ofin orilẹede Naijiria ti ọdun 1999, awọn yoo maa da abo bo ẹtọ gbogbo ara ipinlẹ Oyo.
Bi ẹ ko ba gbagbe, ọjọ diẹ sẹyin ni wahala bẹ silẹ lagbegbe Iwo Road niluu Ibadan latari iwọde EndSARS ti gomina Seyi Makinde si lọ ṣabẹwo sibẹ.
Gomina Ṣeyi Makinde ti yọju si Iwo Road lorii rogbodiyan to n ṣẹlẹ nibẹ.
Lati owurọ ni ariwo ibọn ti n dun ni kikan kikan ni agbegbe Iwo road lọ si Abayọmi-Idi-Apẹ.
Iroyin ti a gbọ ni pe, awọn janduku kan fẹ yawọ agọ ọlọpaa to wa ni Testing Ground ni opopona Iwo road, lẹyin ti wọn dana sun ọkọ Operation Burst kan ni agbegbe naa.
Bi awọn ọlọpaa ṣe n yin ibọn, ni wọn n fin tajutaju naa pẹlu.
O ṣoju mi koro ni awọn ọlọpaa meji ni awọn janduku naa pa, ti wọn si dana sun wọn.
Ọgọrọ awọn olugbe adugbo naa lo n sa asala fun ẹmi wọn bayii.
Saaju la ti sọ fun yin pe ko din ni eeyan meji ti wọn ti pa lagbegbe Ọjọọ nilu Ibadan lasiko ti awọn eeyan kan ti wọn funra si pe wọn jẹ janduku kọlu agọ ọlọpaa kan nibẹ lasiko iwọde #EndSARS.
Gẹgẹ bi ohun ti awọn ileeṣẹ iroyin abẹle kan sọ, ohun ti awọn eeyan n sọ ni pe awọn ọẹọpaa lo ṣeeṣe ki wọn ṣina ibọn bolẹ fawọn eeyan naa.
Iroyin sọ pe iwọde naa n lọ wọọrọwọ ki awọn janduku kan to jaagba ti wọn si bẹrẹ si nii ju okuta ati igo si agọ ọlọpaa naa. Eyi lawọn eeyan kan ni o mu ki awọn ọlọpaa o ṣina ibọn bolẹ sawọn oluwọde naa ti meji si ku.
Oríṣun àwòrán, Seyi makinde/twitter
Nnkan bi wakati kan ni wọn ni iro ibọn fi n dun lakọlakọ ti kaluku si sa asala fun ẹmi wọn.
Bakan naa ni gomina ipinlẹ Ọyọ, Seyi Makinde tun ti paṣẹ ki gbogbo ileewe wa ni titi pa nitori wahala to n jẹyọ nipasẹ iwọde #EndSARS ni ipinlẹ naa.
Bakan naa ni Makinde tun ko awọn ikọ agbofinro Operation Burst si igboro lawọn agbegbe ti ina wahala ti n jo julọ lati mu ki alaafia jọba nibẹ.
Oríṣun àwòrán, Seyi makinde/twitter
Bakan naa lo tun ṣalaye pe ileeẹ eto idajọ ni ipinlẹ Ọyọ ti fa gbogbo iwe ifisun ti wọn fi kan awọn oluwọde #EndSARS ni ipinlẹ naa ya, bẹẹni wọn si ti tu gbogbo awọn ti wọn fi si atimọle silẹ.
Bakan naa lo rọ awọn araalu lati ma foya ki wọn si maa gbe igbe alaafia lọ. O wa fi nọmba ipe pajawiri 615 sita pe ki ẹnikẹni tawọn eeyan tabi ẹgbẹ ba n da iṣẹ aje rẹ laamu pe fun iranwọ ni kiakia.
ENDSARS: Nítorí ìwọ́de #EndSARS, ìjọba gbé iléèwé tì pa ní Oyo, Ekiti, Ondo, Eko, Edo, Plateau àti Osun
Lọwọ lọwọ yii ipinlé Osun, Ondo, Ekiti, Eko, Plateau, Edo ti gbe ilọkun ile iwe ti pa.
Koda, ipinlẹ́ Ogun ti ni ojoojumọ ni ijọba oun yoo maa satunse ofin alakale, ti yoo mu ki alaafia joba lasiko iwode #End SARS to ti n bi ige ati Adubi kaakiri Naijiria bayii.
Ọrọ iwọde #EndSARS to bẹrẹ bi ipe alaafia awọn ọdọ fun ijọba lati dẹkun iwa aitọ awọn ọlọpaa, paapaa, ikọ SARS ti wa di wahala to n mu ki ijọba o maa kaya soke lori igbayegbadun araalu.
Ni Ọjọ Aje awọn janduku ni ipinlẹ Edo ya bo awọn ọgba ẹwọn meji ti wọn si tu awọn ẹlẹwọn to wa nibẹ silẹ.
Bakan naa ni ọjọ aje kan naa awọn janduku miran ṣọṣẹ ni ipinlẹ Eko ti wọn si tun tẹsiwaju lowurọ ọjọ Iṣẹgun nibi ti wọn  ti dana sun awọn agọ ọlọpaa ti iroyin si tun kede rẹ pe ẹmi awọn eeyan kan lọ sii ti awọn miran si tun farapa.
Gẹgẹ bi ara igbesẹ lati dena ifẹmiṣofo, awọn ijọba ipinlẹ kọọkan ti n gbe igbesẹ nitori rẹ lati ti ileewe pa.
Lẹyin gbogbo wahala to ṣẹlẹ lọjọ Aje, gomina ipinlẹ naa, Godwin Obaseki kede ofin konile o gbele ọlọjọ yipo eleyi to tumọ si pe ko si si ijade lọ si ibikibi ti kan awọn ileewe.
Oríṣun àwòrán, AProkodoctor/twitter
Ni ọjọ Aje ni ipinlẹ Eko ti kede pe ki gbogbo ileewe, yala ti ijọba ni tabi ti aladani o wa ni titi pa titi di igba ti alaafia yoo fi jọba ni ipinlẹ naa pẹlu ọwọ tuntun ti ọrọ iwọde #EndSARS n yọ.
Ni ọjọ kejila oṣu kẹwaa ọdun 2020 ni ijọba ipinlẹ Eko kede wiwọle ni Ọjọ kọkandinlogun oṣu kẹwaa.
Ọjọ kọkandinlogun naa ti awọn akẹkọọ wọle ni ijọba ipinlẹ naa kede pe ki awọn akẹkọọ o gbe ile wọn naa titi di igba ti ọrs yoo fi tutu nigboro.
Oríṣun àwòrán, Akinfe Akintunde
Awọn akẹkọọ ni ipinlẹ Ondo ṣẹṣẹ wọle ni Ọjọ Aje, ọjọ kọkandinlogun ni lẹyin ti wọn ti fi iwe kikọ ni kilaasi rẹ ni oṣu kẹta ọdun yii nitori ajakalẹ arun COVID-19.
Amọ, ọjọ keji ti wọn bẹrẹ iwe kikọ pada ni ijọba tun kede ki olukuluku akẹkọọ ati olukọ o fi idi mọle wọn nitori gbọnmọgbọnmọ wahala awọn janduku to ti ja iwọde #EndSARS gba ti wọn si ti fi n da ilu laamu bayii.
Ni ọjọ Iṣẹgun ni gomina Rotimi Akeredolu kede pe ki gbogbo iloro ileewe ni ipinlẹ Ondo di titipa lẹyin tawọn janduku ti gba igboro kan pẹlu awọn ohun elo  ija loriṣiriṣi ti wọn si ti sọ iwọde di nnkan miran.
Ni ọan ọjọ Iṣẹgun ni gomina Makinde ba awọn eeyan ipinlẹ Ọyọ sọrọ lori rukerudo to n waye lori bi awọn janduku kan ṣe ti sa wọ aarin awọn oluwọde ni ipinlẹ Ọyọ ti wọn si ti n lo iwọde naa lati fi kọlu awọn dukia ijọba, ẹmi ati dukia araalu.
Ninu ọrọ to ba awọn eeyan ipinlẹ Ọyọ sọ naa,  Gomina Makinde ṣalaye pe ko gbọdọ si ileewe ti yoo ṣi fun ẹkọ kikọ bẹrẹ lati ọjọru, ọjọ kọkanlelogun, oṣu kẹwaa.
O ni wọn yoo wo bi nnkan yoo ṣe ri lọjọ Ẹti, ọjọ kẹtalelogun oṣu kẹwaa lati mọ boya aṣẹ naa yoo tẹsiswaju abi kawọn akẹkọọ pada sẹnu ẹkọ wọn.
Ni ipinlẹ Ekiti, ijọba ipinlẹ naa ti ti gbogbo  ileewe pa; yala ileewe aladani ni tabi ti ijọba fun iyoku ọsẹ yii.
Akọroyin BBC nibẹ jẹ ko di mimọ pe kọmiṣọna fun Eto Ẹkọ, imọ sayẹnsi ati imọ ẹrọ, Ọmọwe Ọlabimpe Aderiye ṣalaye pe igbesẹ naa di kanranngida lati daabo bo ẹmi awọn akẹkọọ, olukọ atawọn oṣiṣẹ miran kaakiri awọn ileewe.
Ijọba ipinlẹ naa ni lati gba ti iwọde naa ti bẹrẹ, ẹnu ọjọ mẹta yii ti n mu idiwọ wa fawọn akẹkọọ ati oṣiṣẹ ileewe gbogbo lati de ileewe wọn.
O ni o di ọjọ kẹrindinlọgbọn oṣu kẹwaa ki ileewe to tun ṣi pada.
Lekki Shooting: Ohun tó ṣẹlẹ̀ kò sí nínú ìlànà ológun, Buhari gbọ́dọ̀ ṣèwádìí
Oloye Ọlabọde Ibiyinka George to jẹ ajagunfẹyinti, oloṣelu ati alakoso to lorukọ nilẹ yii, ti ke si aarẹ Buhari lati gbe iwadii kalẹ lori iṣẹlẹ ipaniyan Lekki.
Bode George ni iwa ti ko tọ fun ologun ni lati kọju ibọn si awọn eeyan ti ko di ihamọra ogun, paapaa julọ nigba tawọn ti wọn n dojukọ jẹ ọdọ orilẹẹde ti wọn jẹjẹ lati maa daabobo.
Bode George woye ọrọ yii nigba to n fesi si isẹlẹ isekupani to waye ni Lekki lọ̀jọ Isẹgun.
Bakan naa, ọpọlọpọ awọn ọmọ Naijiria ati orilẹede agbaye lo n kerora lori wahala to ṣẹlẹ ni agbegbe Lekki Tollgates.
Eyi ko si sẹyin iroyin ibọn yinyin awọn ṣọja si awọn oluwọde nibẹ, ti ọpọlọpọ si n fi ero wọn han lori iṣẹlẹ naa atawọn ohun gbogbo to tẹle.
Oríṣun àwòrán, LASEMA
Ninu ifọrọwerọ rẹ pẹlu BBC Yoruba lori isẹlẹ yii, Bode George ṣalaye pe wọn ko gbọdọ gba ọrọ naa sori akitan lai jẹ pe wọn wadii gbogbo bi iṣẹlẹ naa ṣe jẹ, ki wọn si fi awọn to ba ṣẹ jofin.
'Bawo la ṣe maa kọju ibọn sirawa? To ba wa lati ita ni ọta ti wa wa nkọ, ki la maa kọ si wọn?
Alagba George ni ara ere ijọba awarawa naa ni ilana ipẹtu-saawọ dipo lilo ibọn.
O fi kun un pe, ara ohun to yẹ ki ijọba ṣe bayii ni ifikuluku, ipẹtu-saawọ ati ifidaniloju pe nnkan yoo di ṣiṣe lori ẹhonu wọn.
Oríṣun àwòrán, @jidesanwoolu
Yika orilẹede Naijiria ni awọn araalu ti n se ọfọ awọn eeyan wọn to dagbere faye lojiji lati ipasẹ iwọde EndSARS to di rogbodiyan.
Bi o tilẹ jẹ pe awọn alasẹ ko ti se akojọpọ iye eeyan to faye silẹ, sibẹ awọn akojọps awọn isẹlẹ to waye lawọn ipinlẹ kọọkan fihan pe, nnkan ko fara rọ.
Lati aarọ ọjọ Isẹgun ni rogbodiyan ti gbode kan lawọn ipinlẹ kan bii Eko, Oyo, Osun, Ekiti, Ondo, Plateau ati Kano.
Nilu Eko, Ibadan ati Plateau, awọn janduku to ja iwọde gba mọ awọn oluwọde EndSARS lọwọ dana sun awọn agọ ọlọpaa kan.
Agọ ọlọpaa Iganmu nilu Eko, Ọọjọ nilu Ibadan ati ti Plateau ni wọn jo kanlẹ, ti ẹmi awọn ọlọpaa kan si bọ lasiko isẹlẹ naa.
Ko tan sibẹ, awọn araalu naa fara gba ninu isẹlẹ yii, ti awọn eeyan si ku nilu Eko, Ibadan ati Plateau.
Koda, ilu Akure, Osogbo ati Ado Ekiti ni rogbodiyan ti fọnna soju, tawọn gomina lawọn ipinlẹ yii si kede pe kawọn ile ẹkọ wa ni titipa.
Bakan naa ni ipinlẹ Edo, Eko, Plateau , Ondo ati Ekiti.
Sugbọn eyi to pabambari ninu awọn isẹlẹ naa, to fi mu ki ọjọ Isẹgun ana jẹ ọjọ buruku, esu gbomi mu ni bi awọn sọja ati ọlọpaa se da si iwọde to n waye ni Lekki, nipinlẹ Eko.
Iroyin ni ọpọ ọdọ to n se iwọde lo jade laye, ti akọsilẹ ko si tii salaye iye wọn ni pato, nigba ti ọpọ eeyan wa nile iwosan, ti wọn n gba itọju lati ipasẹ ọgbẹ ti wọn ni.
Bakan naa, ni awọn ọdọ bii ọgbọn ti n gba itọju lọwọ nile iwosan nitori ọgbẹ ọta ibọn.
Sugbọn ileesẹ ologun ilẹ wa ti fesi lori ẹsun naa, to si ni oun ko mọ ohunkohun nipa rẹ.
Nigba to n sẹ lori awọn ikede kan tawọn araalu fi soju opo Twitter ni alẹ ana, ileesẹ ologun Naijiria ni iroyin ede gbaa ni iroyin naa.
O fikun pe ko si ọmọ ologun kankan to wa nibi isẹlẹ naa.
Ina ibọn n sọ lala ni agbegbe Lekki Tollgate ni ipinlẹ Eko lalẹ ọjọ Iṣẹgun nibi ti awọn ologun ti yin ibọn ati eroja iṣere fireworks lati tu awọn oluwọde ka.
Iroyin fidi rẹ mulẹ pe awọn oluwọde naa ṣi  peju babi sibi iwọde ni iloro Lekki Tollgate naa lai naani aṣẹ konile o gbele ti ijọba pa bẹrẹ lati agogo mẹrin irọlẹ ọjọ Iṣẹgun kan naa.
Wahala bẹ silẹ nigba tawọn oluwọde naa bẹrẹ si ni gbọ iro ibọn ni kikankikan ti ọrọ naa si di boo lọ o yago.
Ko si ẹni lee sọ iye awọn eeyan to fara kaasa ninu idarudapọ naa.
Akọroyin BBC to wa nibẹ ṣalaye pe ohun ti iro rẹ jọ iro ibọn ni awọn ṣọja naa kọkọ fi bẹrẹ ki wọn to bẹrẹ si ni yin iṣere ọdun Banga lati tu wọn ka.
Eniola Badmus: Ẹ má se ọ̀fọ̀ mi, alaàyè ní mí, ń kò kú - Eniola Badmus
Oríṣun àwòrán, eniola_badmus
Gbajumọ osere tiata, Eniola Badmus ti kede pe kawọn eeyan ye sọkun oun nitori alaye ni oun, oun ko tii ku rara.
Eniola, to fi fidio soju opo Instagram rẹ wa sọ fawọn ololufẹ rẹ, ẹbi ara ati ọrẹ pe ko ko ko ni ara oun le .
Lalẹ ọjọ Isẹgun ni iroyin kan n ja kiri ori ayelujara pe Eniola Badmus wa lara awọn eeyan tawọn sọja yinbọn mọ ni agbegbe Lekki lati pinwọ iwọde EndSARS to n waye nibẹ.
Amọ Eniola se fidio naa sita lati fi ọkan awọn ololufẹ rẹ naa balẹ pe ibọn ko ba oun.
Oríṣun àwòrán, eniola_badmus
"Eniola ni "" Mo wa laye, bẹẹ ni mo wa laaye, ko ko ko ni ara ọta mi le. Mo si dupẹ lọwọ gbogbo ẹyin tẹ kan si mi ."
Ara mi ya, ko si si ohun to se mi, koda n ko jade sita lonii.
N ko jade kuro nile ni ana, n ko si nile iwosan.
O fikun pe oun fi aago ipe oun silẹ nile lasiko ti oun rin lọ fun ere idaraya, nigba ti oun de ni oun ri pe awọn eeyan ọọdunrun ti pe oun.
O ni ẹnu ya oun pupọ, to si n dupẹ pe wọn ku ifẹ oun.
EndSARS protest: Ikọ̀ Operation Burst gba ìgboro kan n‘Ibadan
"Ninu ibẹrubojo ni ọpọlọpọ awọn olugbe ilu Ibadan wa bayii nitori iwọde awọn ikọ ologun ""Operation burst""."
L'owurọ Ọjọru ni ibọn awọn ikọ naa n dun lakọlakọ ni agbegbe Baṣọrun.
Bakan naa ni wọn tun ṣe iwọde kaakiri awọn agbegbe bi i Oluyọle, Bẹẹrẹ, Adeọyọ, Iwo road lati ko awọn nnkan ti awọn olufẹhonuhan fi di opopona kuro loju ọna.
Ọpọlọpọ awọn ontaja lo ti ṣọọbu wọn pa, eeyan perete lo si n rin n'igboro gẹgẹ bi awọn ẹlọmii ṣe deju molẹ pẹlu ifoya.
Awọn agbegbe bii UI, General gas to fi mọ Ajibọdẹ, Sango ati Ọjọọ lo da paroparo.
Ijade ikọ ologun naa ni ko se lẹyin ikọlu ni awọn janduku kan ṣe si agọ ọlọpaa to n bẹ ni agbegbe Ọjọọ lọsan ọjọ iṣẹgun nibi ifẹhonuhan #ENDSARS.
Atẹjade lati ọwọ Kọmisọna ajọ ọlọpaa nipinlẹ Ọyọ, Joe Nwachukwu Enwonwufi idi rẹ mulẹ wi pe, awọn janduku naa dana sun agọ ọlọpaa to wa ni Ọjọọ.
Bakan naa lo ni wọn ṣekupa ọlọpaa meji bẹẹ sini awọn ọlọpaa meji mii ti di awati.
Kọmisọna ajọ ọlọpaa nipinlẹ Ọyọ fi kun ọrọ rẹ pe, awọn janduku naa tun yawọ ibi ti wọn n ko nnkan ijagun si ti wọn si ko awọn ibọn AK- 47 kan lọ.
Nibayii gbogbo ifẹhonuhan #ENDSARS ni awọn ọdọ ti so rọ jakejado ipinlẹ Ọyọ, wọn ṣe ikede naa l'ọjọ Iṣẹgun.
Oríṣun àwòrán, @DirectorSolomon
Iroyin to n tẹ wa lọwọ ni awọn eeyan kan ti sọ ina si ileesẹ agbohunsafẹfẹ TVC nilu Eko.
Bi o tilẹjẹpe isede wa nilu Eko, sibẹ ko ye ẹnikẹni bawọn eeyan naa se raye wa jo ileesẹ naa.
Iroyin naa ni wọ̀n n jo ileesẹ ọhun, amọ a ko tii le sọ iye dukia to bajẹ nibẹ.
Awọn fidio ti awọn eeyan n fi lede loju opo Twitter fi han pe awọn janduku naa gbe epo kerosine lọwọ, ti wọn si n jo ọkọ akero to jẹ ti ileeṣẹ ọhun ninu ọgba wọn.
Bakan naa ni fidio ti ọkan lara awọn oṣiṣẹ ileeṣẹ naa, Morayo Afolabi-Brown,  fi fido lede loju opo Instagram rẹ, nibi to ti sọ pe awọn janduku naa ti se awọn oṣiṣẹ ileeṣẹ naa mọle.
Oríṣun àwòrán, Gidi_Traffic/DirectorSolomon
Ọpọ eeyan lo gbagbọ pe agba oselu APC, Oloye Bola Tinubu lo ni ileesẹ naa.
Ẹwẹ, awọn jaduku miran si ina si awọn ọkọ akero ijọba ipinlẹ Eko, BRT ni Oyingbo.
A n se akojọpọ ẹkunrẹrẹ iroyin yajoyajo lọwọ, a o maa gbe ẹkunrẹrẹ iroyin naa sori atẹ iroyin wa laipẹ. Ẹ jọwọ, ẹ tun oju opo iroyin yi yẹwo, ki ẹ lee ri ẹkunrẹrẹ iroyin ọtun laipẹ.
Lekki Shooting: UN, Biden, Clinton àtàwọn gbajúmọ̀ lágbááyé tó korò ojú sí ípànìyàn Lekki
Oríṣun àwòrán, @JoeBiden
Akọwe Gbogboogbo fun ajọ agbaye, United Nations, Antonio Guterres, ti bu ẹnu ẹtẹ lu ipaniyan to waye nipinlẹ Eko ni ogúnjọ, oṣu Kẹwaa.
Ninu atẹjade kan ti agbenusọ rẹ, Stephane Dujarric, fi sita, o ba awọn mọlẹbi to padanu eeyan wọn ninu iṣẹlẹ naa, to si tun gbadura fun ilera awọn to farapa.
Bakan naa lo kesi ijọba Naijiria lati ṣe iwadii àwọn to wa nidi ipaniyan ọhun, ko si fi oju wọn wina ofin.
"O ni ""ajọ agbaye ti ṣe tan lati ṣe iranlọwọ fun lori igbesẹ wiwa atunse."""
Oríṣun àwòrán, @sanwoolu
Bakan naa ni Akọwe ijọba ilẹ America nigba kan, Hilary Clinton ti kesi Aarẹ Muhammadu Buhari, ati ileesẹ ologun Naijiria lati fi opin si pipa awọn ọdọ to ṣe iwọde #ENDSARS.
Joe Biden ni ki ologun ati Buhari fopin si ipaniyan
Oludije fun ipo aarẹ lorilẹede Amerika latinu ẹgbẹ oselu Democrat, Joe Biden, ti koro oju si iwa ipaniyan sawọn oluwọde naa.
Biden to kede bẹ́ẹ́ ninu atẹjade kan to fisita lori rogbodiyan Naijiria wa sọ̀ fun Buhari atawọn ologun lati dawọ ipaniyan naa duro.
Bakan naa ni Biden ni gba gba gba ni orilẹede Amẹrika wa lẹyin awọn oluwọde to n fi ẹhonu han wọọrọwọ.
Lara awọn ilumọọka l'agbaye to tun ti koro oju si ipaniyan ati idaru-dapọ to n waye ni Naijiria ni Olori Alufa ijọ Church of England ni Canterbury, Justin Welby.
Ninu ọrọ to kọ sori ayelujara Twitter rẹ ni owurọ Ọjọru, o ni oun koro oju si awọn iroyin ipaniyan to n waye nipinlẹ Eko, ati awọn ibomiran ni Naijiria.
"O ni ""mo ti rọ Aarẹ Buhari ni taara lati pèsè aabo fún ẹmi. Mo si tun n sọ ni gbangba bayii."""
"O ni oun ba Naijiria kẹdun, to si gbadura ki ""Ọlọrun gba Naijiria là""."
Oríṣun àwòrán, @jidesanwoolu
Gomina ipinlẹ Eko, Babajide Sanwo-Olu ti bawọn eeyan ipinlẹ Eko sọrọ lori ipaniyan to waye ladugbo Lekki nilu Eko.
Sanwo-Olu , ninu ikede rẹ to waye ni owurọ ọjọ Isẹgun salaye pe oun sepade peẹlu awọn asaaju ẹsin ati ẹgbẹ ajafẹtọẹni, tawọn si fẹnuko pe kawọn oluwọde naa maa pejọ si Alausa ati ẹnu iloro bode Lekki.
O ni ko si gomina ipinlẹ kankan to lasẹ lori ileesẹ ologun ilẹ wa ati bi wọn se n sisẹ wọn.
O wa fọwọ gbaya pe kó si eeyan kankan to ku ninu ikọlu ologun Naijiria s'awọn oluwọde ENDSARS ni Lekki lọjọ Isẹgun.
O ni bi o tilẹ jẹ pe awọn parọwa sawọn oluwọde lati tuka ki aago mẹrin irọlẹ to lu, amọ arọwa awọn ko se aseyọri ni Lekki.
Oríṣun àwòrán, @jidesanwoolu
Sanwo-Olu ni meji ninu awọn eeyan to fara gba ọgbẹ ni Lekki ni wọn sisẹ abẹ fun loru mọju, ti ara wọn si ti n balẹ.
"Mo si ti pasẹ pe ki wọn so gbogbo isẹ ijọba rọ na fun ọjọ mẹta, ayafi awọn osisẹ alaabo nikan.
Bakan naa ni mo pasẹ pe ka fa asia Naijiria wa silẹ fun ọjọ mẹta lati sedaro awọn eeyan to ba iwọde EndSARS lọ."
O wa fi da awọn eeyan ilu Eko loju pe, oun yoo sa ipa oun lati se awari awọn ohun to sẹlẹ ni Lekki lalẹ ọjọ Isẹgun.
Wo àwọn ọ̀nà tí o lè gbà láti di ọjọ́ ogbó pẹ̀lú olólùfẹ́ rẹ
O ni oun ati àwọn amugba legbe oun ati Komisana ilera sabewo s'awọn ile ìwòsan to wa ni Eko mojumọ, la ti ki awọn to f'arapa.
Gomina ipinlẹ Eko Babajide Sanwo Olu tun kesi awọn ọdọ ati oluwọde ipinlẹ Eko lati faaye gba alaafia laaye.
EndSARS Protest Update: DJ Switch ṣàlàyé ohun tójú rẹ̀ rí níbi ìfẹ̀míṣòfò àwọn olùwọde EndSARS ní Lekki
Oríṣun àwòrán, @djswitch_
Gbajugbaja aseto orin to wa nibi iṣẹlẹ iṣekupani tawọn oluwọde to waye ni Lekki Toll Gate ni ilu Eko, DJ Switch, ti ṣalaye ohun toju rẹ ri lọjọ naa.
DJ Switch ni awọn ọmọ ogun to dihamọra atawọn ọlọpaa, lo ṣina ibọn bolẹ fun awọn oluwọde EndSARS lalẹ ọjọ Iṣẹgun.
DJ Switch lo sọ ọrọ naa ninu fidio to fi lede loju opo Instagram rẹ.
O ni ko din ni eeyan marundinlogun to di oloogbe nibi iṣẹlẹ naa, ti oun atawọn olufẹhonuhan miran si gbe awọn to ṣeṣe lọ ba awọn ọmọ ogun, ti awọn ọmọ ogun naa si gbe oku wọn lọ.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Gẹgẹ bo ṣe sọ, o ni ohun kan ti oun kabamọ ni bi wọn ṣe gbe oku awọn eeyan lọ ba awọn sọja ọhun.
"DJ Switch ni ""Mo kabamọ pe a ṣe bẹẹ nitori ṣe ni awọn ọmọ ogun naa ko oku awọn eeyan naa sinu ọkọ, ti wọn gbe wa."""
Bakan naa lo tun ṣafihan awọn ọta ibọn to ri ṣa lagbegbe ti iṣẹlẹ naa ti waye.
O sọ pe awọn ọlọpaa wa si ibi ti iṣẹlẹ naa to waye lẹyin ti awọn ọmọ ogun kọlu wọn tan, ti wọn si fi gaasi tajutaju tu wọn ka.
Oríṣun àwòrán, EPA
Dj Switch tun tan imọlẹ si awọn ọrọ kan to ti n tan ka lori ayelujara nipa awọn ohun to ti sọ ṣaaju.
"O ni ""ẹ jọwọ mi o ṣọ pe eeyan 78 lo ku o, nigba ti mo n ṣe fidio lọwọ, awọn meje ti ku silẹ, ṣugbọn lẹyin ti ẹrọ ibanisọrọ mi ku, awọn 15 miran tun dagbere faye."""
Bo tilẹ jẹ pe o sọ pe oun ko le fidi rẹ mulẹ boya wọn ju bẹẹ lọ, ṣugbọn o fi kun pe ọpọ eeyan lo fara gbọta ibọn.
Oríṣun àwòrán, Instagram/djswitch_
Akinkanju obinrin naa pari ọrọ rẹ pe, oun ko faramọ bi awọn eeyan ṣe n jo awọn ọkọ akero, ṣugbọn oun yoo ṣi tun kopa ninu iwọde kannaa lọjọ iwaju.
Orukọ abisọ DJ Switch ni Obianuju Catherine Udeh, o jẹ olorin to gbegba oroke ninu idije X Factor akọkọ iru rẹ, ti ileeṣẹ ibaraẹnisọrọ Glo ṣagbatẹru rẹ lọdun 2013.
#EndSARS : Àwọn ọ̀dọ́ dáná sun tírélà akẹ́rù tẹrùtẹrù ní Ekiti
Oríṣun àwòrán, djswitch_
Ni kete ti iroyin gbode pe awọn ọmọ ileeṣẹ ologun ti kalẹ si Lekki Toll Gate ni ilu Eko, ti iro ibọn si n dun lọtun losi ni DJ Switch bẹrẹ si n ṣe fidio lati lati agbegbe naa loju opo Instagram rẹ lori bo ṣe n lọ.
Fidio ọhun ṣafihan bi awọn eeyan ṣe fara gba ọta ibọn, ti awọn oluwọde to wa nibẹ si n gbiyanju lati yọ ọta ibọn naa, ati lati doola ẹmi awọn eeyan miran to farapa.
Bo tilẹ jẹ pe ileeṣẹ ologun ti sẹ pe oun ko mọ ohunkohun nipa iṣẹlẹ naa, ṣugbọn ibeere ti awọn eeyan n bere bayii ni pe, ta ni akinkanju obinrin DJ Switch yii gan?
Ta ni DJ Switch?
Orukọ abisọ DJ Switch ni Obianuju Catherine Udeh, o jẹ olorin to gbegba oroke ninu idije X Factor akọkọ iru rẹ, ti ileeṣẹ ibaraẹnisọrọ Glo ṣagbatẹru rẹ lọdun 2013.
O jẹ ọmọ ilu Udi, ni ipinlẹ Enugu, oun si ni abikẹyin iya rẹ.
Oríṣun àwòrán, Instagram/djswitch_
O kẹkọọ jade ninu imọ Geology ni Fasiti ijọba apapọ to wa ni ilu Port Harcourt, ni ipinlẹ Rivers.
Okiki rẹ bẹrẹ si n kan lẹyin ti oun ati ẹgbẹ rẹ Da Pulse jawe olubori ninu idije orin Star Quest lọdun 2009.
"Lẹyin naa lo gbe awo orin kan jade eyii to pe akori rẹ ni ""So tey,"" ti olorin takasufẹ ilẹ Amẹrika, Busta Rhynes kopa ninu rẹ."
Ko pẹ si asiko naa to darapọ ileeṣẹ to n gbe orin jade, Sony Music.
DJ Switch jẹ ọkan gboogi lara awọn to n lọgun iwọde End SARS lori ayelujara.
EndSARS Protest Update: Ọ̀gá àgbà ọlọ́pàá àti ọ̀gá àjọ ọlọ́pàá ń késí àwọn òṣìṣẹ́ wọn
Oríṣun àwòrán, Nigerian Police Force
Ọga agba awọn ọlọpaa, Muhammed Adamu ti ni ki awọn ọlọpaa maa daabo bo ara wọn lodi si ikọlu.
O ni awọn oṣiṣẹ wọn ati awọn ọlọpaa ni ẹtọ lati da abo bo ara wọn ni asiko ti wọn ba ri ikọlu lojukoroju.
Lọjọ Ẹti ti ọga agba ọlọpaa n ṣe ibẹwo si awọn ileeṣẹ ọlọpaa to wa kaakiri olu ilu orilẹede yii ni ilu Abuja lo sọ bẹẹ.
O si fi asiko kan naa gba awọn ọlọpaa to ti kuro lẹnu iṣẹ wọn loju popo fun bii ọjọ marun un latari pipa ọlọpaa to le ni ogun lasiko ifẹhonuhan to jade jakejado Naijiria.
Irufẹ ọrọ yii kan naa ni ọga ajọ to n moju to ọrọ ọlọpaa ni Naijiria, Ikechukwu Ani kesi wọn lati pada si ẹnu iṣẹ wọn kiakia tabi ki wọn gba iwe idaduro.
Bo tilẹ jẹ pe ohun to ṣẹlẹ si awọn akẹgbẹ wọn mejilelogun to tẹri si iku ni ọsẹ diẹ sẹyin lo mu wọn kuro loju popo ṣugbọn bayii wọn ti ni eyi kii ṣe awawi lati sa kuro, ki wọn pada bi bẹẹ kọ, iṣẹ a bọ lọwọ ẹni bẹẹ.
Tóo bá pá lórí, Mílíìkì sóyà àtàwọn ǹkan mẹ́ta yìí leè mú irun rẹ hù padà!
Ọga ọlọpaa, Adamu n fi ẹsun sita pe awọn afẹhonuhan EndSARS ti ni i lọkan lati ṣe ibi sawọn ọlọpaa to si fi kun un pe ijọba ati ileeṣẹ ọlọpaa Naijiria yoo to ṣagbejade eto iranwọ fun idile awọn ọlọpaa to ku lasiko ifẹhonuhan naa.
O fi kun un pe irẹpọ orilẹede yii wa lọ́wọ́ iru atilẹyin ti awọn ọlọpa ba ri latọdọ araalu toripe bi eyi ba n bajẹ, o ma n faaye gba awọn janduku lati bẹrẹ iwa ipa wọn laarin ilu.
"Ọga ọlọpaa ni awọn ni ijọba gbẹkẹle ki awọn janduku ma baa gba akoso igboro ilu nitorinaa ""ko si bi eeyan ṣe fẹ́ bi wa ninu to tabi sọrọ abuku si wa ti a o ni ṣe iṣẹ wa bo ṣe yẹ."
Niwọn igba ti a mọ pe ijọba ti wa lẹyin wa, a n gba yin niyanju lati maa ṣe iṣẹ yin lọna to tọ. A rọ yin lati jẹ akọṣẹmọṣẹ ṣugbọn bi ẹnikẹni ba wa fi ilọkulọ lọ yin, ẹ lee da abo bo ara yin.
"Ọgbẹni Adamu ni ""baa ba nsọ̀rọ̀ ẹtọ ọmọniyan, eniyan ẹlẹran ara ni ọlọpaa naa nitorinaa idaabobo fun ẹtọ awọn ọlọpaa naa yoo wa. tori eyi la ṣe n fi ọrọ yii sita loju gbogbogbo pe a ni lati da abo bo ara wa""."
'Egbò tó ti fẹ́ẹ̀ jiná ni ìtàn bí wọ́n ṣe pa Soun Ogbomoso, Ọba Olayode tẹ ń bèrè'
Oríṣun àwòrán, EPA/Nigeria Police
Ọga agba ọlọpaa lorilẹede Naijiria, Mohammed Adamu ti kọ àbájáde ọ̀rọ̀ tí ajọ Amnesty International sọ pe awọn ọlọpaa yinbọn pa awọn oluwọde EndSARS.
Ninu atẹjade kan ti ileeṣẹ ọlọpaa fi sita lọjọ Ẹti, Ọga ọlọpaa, Adamu sọ pe abajade ajọ Amnesty International to hande lọjọ kọkanlelogun oṣu kẹwa dun 2020 to kọ pe awọn ọlọpaa yinbọn ba awọn to n ṣe iwọde wọọrọwọ n ṣi awọn eeyan lọkan ko si ki n ṣe ootọ wipe o lodi si gbogbo aridaju to wa nilẹ.
Kété tí wọ́n bá ti báa yín sùn tàn torí pé ẹ tóbi, ẹ gbà pé ìfẹ́ yẹn ti parí - Auntie Remi Ọlọ́yàn ńlá
Ẹwẹ, ọga agba ọlọpaa fọhun pe awọn ọlọpaa ṣiṣẹ gẹgẹ bii akọṣẹmọṣẹ ti awọn kan si fi ẹmi wọn lelẹ fun alafia lasiko ifẹhonuhan to waye kaakiri awọn ipinlẹ kan lorilẹede Naijiria.
Awọn esi to wa nita fihan pe ọlọpaa mejilelogun padanu ẹmi wọn ti awọn mii si farapa lasiko ifẹhonuhan naa. Ọga ọlọpaa ni ipo ti awọn to farapa gan wa nile iwosan bayii kọja afẹnusọ.
Lasiko ifẹhonuhan to ṣẹlẹ kaakiri orilẹede Naijiria yii, ọga agba ọlpaa ni agọ ọlọpa igba o le marun atawọn ibudo mii to fi mọ awọn nkan amayerọrun faraalu ni awọn kan lara awọn afhonuhan bajẹ.
Ọga ọlọpaa ni ileeṣẹ awọn ni ifarajin si igbesẹ atunṣe ti ijọba apapọ n ṣe lọwọlọwọ ni Naijiria.
Oríṣun àwòrán, Daily Trust
Ẹ má gbìyànjú àti bo àṣírí ǹkan tó ṣẹlẹ̀ ní Lekki, a ní ẹ̀rí tó dájú
Ajọ ajafẹtọ ẹni kan l'agbaye, Amnesty International, ti kilọ fun ijọba orilẹ-ede Naijiria, lati ma bo aṣiri bi awọn kan ṣe yinbọn mọ awọn oluwọde ni Lekki, nipinlẹ Eko.
Oludari ajọ naa, Osai Ojigho sọ pe awọn fi ikilọ naa sita, nitori pe awọn iṣẹlẹ to n waye bayii fihan pe ijọba fẹ ẹ bo aṣiri iṣẹlẹ naa, gẹgẹ bi iṣe rẹ ni gbogbo igba ti ileeṣẹ ologun ba paayan lọna ti ko ba ofin mu ni Naijiria.
Ileeṣẹ ologun ti kọkọ sọ pe oun ko lọwọ ninu iṣẹlẹ naa, ṣugbọn to tun yi ọrs pada lọjọ Iṣẹgun pe, gomina ipinlẹ Eko lo ranṣẹ pe awọn lati da alaafia pada si aarin ilu.
Amọ 'sa, gomina paapa ti kọkọ sọ pe oun ko fun wọn ni aṣẹ nitori pe oun ko ni agbara lati paṣẹ fun ileeṣẹ ologun.
Ajọ Amnesty sọ pe oun ni ẹri to pọ, lati fihan pe awọn ọmọ ogun lo yinbọn mọ awọn oluwọde naa, eyi to pa awọn kan, ti awọn mii si farapa.
Ati pe, awọn onimọ nipa rogbodiyan ninu ajọ naa ti ṣe iwadii, wọn si ri i daju pe ileeṣẹ ologun lọwọ ninu ipaniyan to waye ni Lekki.
Kété tí wọ́n bá ti báa yín sùn tàn torí pé ẹ tóbi, ẹ gbà pé ìfẹ́ yẹn ti parí - Auntie Remi Ọlọ́yàn ńlá
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Lẹ́yìn ọ̀sẹ̀ kan ti gbómi-si-omi- ò tó tí wáye lórii pé tani o pàsẹ fún àwọn ọmọgún orílẹ̀-èdè Nàìjíríà láti jáde sígborò tí àwọn olùwọ́de fí faragba ọ̀ta ìbọ̀n nibi iwọde EndSARS ti àwọn míràn sì gbà ibẹ̀ kú.
Onírúurú ìròyìn ló ti tàn kálẹ̀ tí gómìnà ìpińlẹ̀ Eko sì ti jáde pé àwọn àgbára kan tó jú òun lọ ló ṣe ìṣẹ́ ibí náà, àti pé, gbogbo ìwádìí tó bá yẹ ni ìjọba yóò ṣe láti ríi dájú pé, ìdájọ́ òdodo jẹyọ fún àwọn tó pàdánù ẹ̀mí wọ́n tàbí tí wọ́n fara gbọgbẹ́.
Àjẹ́ ké lánàá, ọmọ kú lónìí ni ọ̀rọ̀ Tinubu àti ìṣẹ̀lẹ̀ Lekki Tollgate - Bode George
Ẹ̀wẹ̀, ilé iṣẹ́ ọmọogun Nàìjíríà nínú àtẹ̀jáde tó fi síta ló ti sàlàyé pé, ọmọogun orílẹ̀-èdè Nàìjíríà kò dédé jáde sítà, bíkòṣe pé, ìjọba ìpínlẹ̀ Eko ló bẹ òun lọ́wẹ̀ láti ràn ìlú lọ́wọ́ lẹ́yìn tí àwọn ọ̀daran kan tí n jó àgọ́ ọlọ́pàá tí wọ́n sì ń ba ǹkan jẹ́ ní nìlú Eko.
Nínú àtẹ̀jáde náà tí Major Osoba Olaniyi tó jẹ́ adélé ìgbákeji àdári alukoro 81 Division fọwọ́sí ló ti sàlàyé pé, ilé iṣk ọmọogun ṣe àkíyèsí ìròyìn tó ń jà ràìn-ràìn lórí ayélujára pé, àwọn ọmọ ogún 81 Division ló yìnbọ pa àwọn olùwade ìfẹ̀hónúhan ni ìloro Lekki lógúnjọ, oṣù kẹ̀wàá, ọdún 2020.
Ilé iṣẹ́ ọmọogun ni irọ́ tó jìnà sí òótọ́ ni ọ̀rọ̀ náà pé àwọn yìnbọ̀n tàbi pa ẹnikéni ní àsìkò sún, ẹ̀yí nìkàn kọ́, ó fi kun pé, ọ̀pọ̀ ẹ̀rí ló wà nígboro pé àwọn ko pa ẹnikẹ́ni.
Osoba ní lẹ́yìn tí ìjọba pé àwọn, àwọn ọmọgun náà ríi dájú pé, ìlànà tó tọ́ àti èyí tó yẹn láti bá ará ìlú ṣe ni àwọn lò, ìbọ̀n yínyìn tàbí ìpànìyàn kankan kò sì wáye.
'Oyenusi ló mú mi wọ ẹgbẹ́ adigunjalè kó tó di pé mo b'Ólúwa pàdé'
Oríṣun àwòrán, Nigeria Army
Oríṣun àwòrán, Screenshot
Àwọn ọ̀dọ́ fi ọ̀nà àrífín pe Tinubu lórí aago àmọ́ ó ní òun kò mọwọ́-mẹsẹ̀ nípa ìpànìyàn Lekki
Oríṣun àwòrán, @AsiwajuTinubu
Asiwaju ẹgbẹ oselu APC nilẹ wa, tii tun se gomina tẹlẹ nipinlẹ Eko, Asiwaju Bola Ahmed Tinubu, tun ti sọrọ lori isẹlẹ isekupani to waye ni Lekki fun igba keji.
Lọtẹ yii, ori ẹrọ ibaraẹnisọrọ ni Tinubu ti bawọn ọdọ kan takurọsọ nipa isẹlẹ naa lọjọru.
Nigba to n salaye bi ifọrọwerọ Tinubu ati awọn ọdọ kan lori aago, amugbalẹgbẹ Tinubu feto iroyin, Tunde Rahman kede loju opo Twitter rẹ pe igbesẹ naa safihan pe oloselu to dantọ ni.
"O wa sapejuwe agba oselu naa bii ""ẹni to rọrun lati ri, onirẹlẹ ẹda, to si n se atilẹyin fawọn ọdọ lasiko ti wọn n se iwọde alaafia EndSARS."""
Oríṣun àwòrán, @Sanwoolu
Rahman ni lai naani ọna arifin tawọn ọdọ naa gba ba Tinubu sọrọ, sibẹ o tiraka lati salaye awọn ọrọ naa fun wọn.
Tinubu ni ofege ati ẹbu ni iroyin to n ja kiri ori ayelujara nipa isẹlẹ ipaniyan to waye ni Lekki lọjọ Isẹgun.
Atẹjade naa ni Tinubu ko mọ awọn to n pe lori aago ri, sibẹ, o gbe ipe wọn, to si salaye fun wọn pe oun kọ ni oun ni ileesẹ LCC to n gba owo bode ni iloro Lekki.
Oríṣun àwòrán, @jidesanwoolu
Bakan naa lo ni Tinubu salaye pe oun ko mọwọ mẹsẹ lori bi awọn ologun se de bode Lekki lati doju ibọn kọ awọn ọdọ.
O ni lootọ ni Tinubu fidi rẹ mulẹ pe, bi gbogbo ọmọ Naijiria yoku se gbọ nipa rogbodiyan n waye lẹnu bode Lekki, naa ni oun naa gbọ.
Tinubu fikun pe oun ko ni imọ nipa isẹlẹ naa rara saaju akoko to waye, tabi ko awọn ologun ransẹ.
O wa tẹnumọ pe gomina Sanwo-Olu ti pasẹ pe ki iwadii bẹrẹ lori isẹlẹ naa, to si rọ gbogbo araalu lati bomi suuru mu.
Ajọ ajafẹtọ ọmọniyan, SERAP ti kọwe mọ ijọba ati ileeṣẹ ologun Naijiria lọdọ ile ẹjọ agbaye to n gbọ ẹsun iwa ọdaran, ICC.
SERAP fẹsun kan ijọba apapọ pe o lo awọn janduku atawọn ologun lati mọọmọ pa awọn oluwọde l'Eko.
Ninu iwe to kọ si agbẹjọro agba ICC, Fatou Bensouda, o ni ki ile ẹjọ naa pe aṣoju ijọba Naijiria lati wa jẹjọ lori ẹsun ifẹmi awọn oluwọde ṣofo.
"O ni ki ICC ""bẹrẹ iwadii ni kankan, lori iroyin to gbode nipa bi ijọba ṣe lo awọn tọọgi, ọmọ ogun atawọn oṣiṣẹ agbofinro, lati ṣẹru ba ati lati pa awọn oluwọde alaafia ni Abuja, Eko, Edo, Osun, Plateau ati ni Kano."
Oríṣun àwòrán, @Sanwoolu
SERAP ni ki ile ẹjọ ọhun wadii awọn to wa nidi ikọlu naa, paapaa bi awọn oloṣelu, ọmọ ogun ati awọn oṣiṣẹ eto aabo to lọwọ ninu iṣẹlẹ naa.
Ninu iwe naa to kọ lọjọ kọkanlelogun, oṣu Kẹwaa, ọdun 2020, ti igbakeji adari rẹ, Kolawole Oluwadare buwọlu, SERAP ni o ti pẹ ti ijọba Naijria ti maa n tẹ ẹtọ awọn ara ilu loju mọlẹ.
"O ṣalaye pe ""o ti lẹ ni ọpọlọpọ ọdun ti ijọba Naijiria kii le fi awọn to ba pa oluwọde jofin, eyii to ti wa di aṣa bayii."""
"Ajọ naa sọ siwaju si pe, ikọlu ti ijọba ṣe si awọn oluwọde ni Lekki, Alausa ati kaakiri Naijiria n ṣafihan pe, ijọba Buhari ko bọwọ fun ẹtọ ọmọniyan, bakan naa ni ko naani ẹmi eeyan ati aye lati sọrọ bo ṣe wu wọn."""
SERAP wa pe fun ki ile ẹjọ kan nipa fun ijọna Naijiria lati fi oju awọn aṣebi lede, ki wọn si fi wọn jofin.
Olusegun Obasanjo bọ́hùn nípa ìṣẹ̀lẹ̀ ìpànìyàn
Oríṣun àwòrán, Thisdaylive
Aarẹ ana lorilẹede Naijiria, Oloye Oluṣẹgun Ọbasanjọ ti ke gbajare sita pe, asiko to fun aarẹ Muhammadu Buhari bayii lati sọrọ soke, ki ọrọ to kọja atunṣe bayii lorilẹede Naijiria.
Ninu atẹjade kan to fi ṣọwọ si BBC News Yoruba, oloye Oluṣẹgun Ọbasanjọ ni nibi ti ọrọ de duro bayii, o ti kuro ni ere sinima, aarẹ si gbọdọ gbe igbesẹ akin, gẹgẹ bii obi ati olori.
O ni aarẹ Buhari gbọdọ fi iwa irẹlẹ, ẹni to lẹran eeyan lara ati ijolootọ lati dahun si awọn ibeere awọn eeyan yii, ki o si rii daju pe idajọ ododo waye nibi to yẹ.
Bakan naa lo tun rọ awọn ọdọ to n wọde naa pe, ki awọn pẹlu gba alaafia laaye bi wọn ṣe n gbe ẹhonu wọn sita.
O ni kikọlu awọn dukia ati araalu yoo tubọ mu ki ipinya wa laarin wọn ni, eleyii to si lee da omi iṣọkan aarin wọn ru.
"Inu mi bajẹ gidigidi nipa rogbodiyan to n waye lọwọ bayii lorilẹede Naijiria; mo si n fi eyi rọ ijọba atawọn eeyan orilẹede Naijiria lati yago fun wahala ki wọn si gba alaafia laaye.
CACOVID Palliatives: Ọwọ́ Ọlọ́pàá tẹ àwọn tó lọ kó ǹkan ìrọ̀rùn Covid-19
Oríṣun àwòrán, Yabgi Mohammed
Awọn agbofinro ti n fi ṣikun ọba mu awọn to kọlu awọn ile itaja ati ileeṣẹ aladani lati ji ọja ati dukia awọn eeyan ko lẹyin iwọde EndSARS.
Ko din ni irinwo o le mẹsan eeyan ti wọn ti mu ni ipinlẹ Kwara, Plateau, Benue ati Abuja.
Awọn ọlọpaa Plateau fi panpẹ ofin mu afurasi mẹrinlelaadọsan tuntun, eyii to ṣalekun iye eeyan ti wọn ti mu bayii si ọọdunrun o le meje lapapọ.
Ni Calabar, wọn mu afura ọgọrin, gomina Ben Ayade si ti kede ẹbun owo ọgọrun miliọnu naira fun ẹnikẹni to ba le ṣamọna bi ijọba ṣe le ri awọn afurasi to ku.
Iroyin ni ọpọ ninu awọn ẹru ti awọn eeyan ji ko ni wọn n fi silẹ ni oriṣiriṣi kọrọ adugbo lẹyin ti ileeṣẹ ọlọpaa bẹrẹ ayẹwo ojule si ojule.
Láàrín ìṣẹ́jú díẹ̀, ẹ ka ìwé Akinwumi Ishola, Nítorí Owó"" lórí Akomolede Yoruba"
Kọmiṣọna ọlọpaa ni ipinlẹ Cross River, Abdulkadir Jimoh sọ pe ọpọ ninu ẹru ti awọn eeyan ji ko ni wọn ti ri pada.
Lara awọn  ẹru to ni wọn ti ri pada naa ni kẹkẹ ẹlẹsẹ mẹta atawọn ohun elo amohun bu gbamu to jẹ ti ileeṣẹ Calabar International Conference Centre, CIIC.
Kọmiṣọna ọhun rọ awọn agba adugbo atawọn olori ẹlẹsin lati tu aṣiri gbogbo awọn ti wọn ba fura si pe o lẹbọ lẹru.
"O ni ""a ti mu afurasi ọgọrin a si ti bẹrẹ iwadi lori wọn, a fun gbogbo awọn to ji ẹru ẹlẹru ko labẹ asia iwọde EndSARS ni wakati mẹrinlelogun lati da awọn ẹru naa pada tabi ki wọn foju wina ofin."""
Ni Kwara, ileeṣẹ ọlọpaa ti fi oju afurasi 144 lede ni Ilorin lori awọn ẹru ti wọn ji ko.
Bakan naa ni ileeṣẹ ọlọpaa ni ipinlẹ Ondo ti bẹrẹ si ni fimu finlẹ lori awọn afurasi kan naa kaakiri ipinlẹ ọhun, ọwọ si ti tẹ eeyan mẹwaa o kere tan.
Àwọn ọbá aláye ilẹ̀ Yorùbá márùn-ún pẹ̀lú ọ̀pá àṣẹ wọn
'Egbò tó ti fẹ́ẹ̀ jiná ni ìtàn bí wọ́n ṣe pa Soun Ogbomoso, Ọba Olayode tẹ ń bèrè'
Eko, Kwara, Osun àtàwọn ìpínlẹ̀ míì tí àwọn èèyàn ti jí oúnjẹ ìrànwọ́ Covid-19 kó
Lẹyin ti ọpọ awọn ipinlẹ ti kede ofin konile-o-gbele nitori iwọde EndSARS, awọn janduku bẹrẹ si nii kọlu awọn ile ti ijọba ko ounjẹ iranwọ Covid-19 si, ti wọn si bẹrẹ si n ji i ko.
Oṣu Kẹjọ ọdun 2020 ni ajọ Coalition Against Covid-19, CACOVID, ni o oun bẹrẹ si n pin awọn ounjẹ iranwọ naa, ṣugbọn ti ọpọ awọn ọmọ Naijiria sọ pe awọn ko ri ohunkohun.
Awọn ipinlẹ wọnyii ni awọn janduku ti lọ ji ounje iranwọ Covid-19 ko.
Ni ọjọ Satide, ọjọ kẹrinlelogun, oṣu Kẹwaa ọdun 2020 ni awọn kan bori awọn ẹṣọ alabo, ti wọn si kọlu ile ti ijọba ipinlẹ naa ko ounjẹ Covid-19 si.
Iṣẹlẹ naa mu ki igbakeji gomina ipinlẹ ọhun kede igbele oni wakati mẹtalelọgbọn ni ilu Jalingo.
Ilu Ede ni awọn eeyan ti rọlu ile ti ijọba ko ounjẹ iranwọ Covid-19 si ni Cocoa House ti wọn si bẹrẹ si n ji ko.
Gẹgẹ bi nnkan ti ijọba ipinlẹ naa sọ, ounjẹ naa wa fun pinpin fun awọn eeyan ilu, ṣugbọn wọn n duro de aṣẹ lati ọdọ ọọfisi CACOVID ni Abuja ki wọn to bẹrẹ pinpin rẹ.
Lẹyin naa ni ijọba ipinlẹ ọhun kede konile-o-gbele tuntun fun wakati mẹrinlelogun.
Àwọn ọbá aláye ilẹ̀ Yorùbá márùn-ún pẹ̀lú ọ̀pá àṣẹ wọn
Ọ̀nà láti sọ ọ̀rọ̀ ajé ilẹ̀ Yorùbá di akúrẹtẹ̀ ni àwọn ìkọlù tó wáyé ní Eko - Àwọn gómìnà
Ìjọba ìpínlẹ̀ Eko tí kéde ìlànà ìséde tuntun fún ará ìlú
'Egbò tó ti fẹ́ẹ̀ jiná ni ìtàn bí wọ́n ṣe pa Soun Ogbomoso, Ọba Olayode tẹ ń bèrè'
Ọjọ Ẹti, ọjọ kẹtalelogun, oṣu Kẹwaa ọdun 2020 ni awọn eeyan ipinlẹ Kwara ya bo ibi ti ijọba ko ounjẹ iranwọ Covid-19 si niluu Ilorin.
Ijọba ipinlẹ ọhun sọ pe ijọba ibilẹ kan lo ni ounjẹ naa nitori wọn ti pinpin gbogbo eyii to ku fun awọn ara ilu.
Agbegbe Buruku ni awọn eeyan ipinlẹ Plateau ti ri ile ti ijọba ko awọn ounjẹ naa si, wọn si ji gbogbo rẹ ko daadaa.
Lẹyin iṣẹlẹ naa ni ijọba sọ pe oun kò kó ounjẹ naa pamọ ṣugbọn oun n duro ki iwọde EndSARS tan nilẹ ki oun to pin ni.
Lẹyin ti ijọba Kogi sọ pe oun ti pin ounjẹ iranwọ Covid-19 ni awọn ara ilu ri ile to ko ounjẹ naa pamọ si.
Ni ti ipinlẹ Ekiti, ijọba ti sọ pe oogun pakopako ati ajilẹ ni awọn eeyan ji ko dipo ounjẹ iranwọ Covid-19.
Wọn ni ileeṣẹ ijọba to n ri si iṣẹlẹ pajawiri lo ni awọn ajilẹ ati pakopako ti wọn ji ko, kii ṣe ounjẹ.
Ọjọ Abamẹta ni awọn eeyan yabo Gwari, ti wọn si ko gbogbo ounjẹ Covid-19 to wa nibẹ lọ.
Ijọba ipinlẹ naa sọ lẹyin iṣẹlẹ naa pe, lara ibi ti wọn kọlu jẹ ti ajọ NAFDAC, nibi ti wọn n ko awọn oogun to ti bajẹ pamọ si.
Adamawa
Ijọba ipinlẹ Adamawa kede igbele oni wakati mẹrinlelogun lẹyin ti awọn eeyan ya bo ile to ko ounje naa pamọ si lọjọ Aiku.
Gomina ipinlẹ naa, Ahmadu Umaru Fintiri sọ pe wọn ti pin awọn ounjẹ ọhun ṣugbọn awọn to ku ni wọn n gbe igbesẹ lati pin lọjọ Aje, ọjọ kẹrindinlọgbọn, oṣu Kẹwaa, ọdun 2020, ki wahala to bẹ silẹ.
Agbegbe Maza-maza ni awọn eeyan kọkọ kọlu lati ji ounjẹ iranwọ Covid-19 to wa nibẹ.
Iṣẹlẹ na waye leyin ikọlu ti ileeṣẹ ọmọ ogun ṣe si awọn oluwọde EndSARS ni Lekki Toll Gate.
Awọn ipinlẹ to ti pin ounjẹ tiwọn tan:
Ipinlẹ Zamfara ati Bauchi wa lara awọn ipinlẹ to sọ pe wọn ti pin ounjẹ Covid-19 awọn tan nitori wọn ni ko si ounjẹ Kankan mọ nile ti wọn ko pamọ si.
Ni ti Bauchi, gomina Bala Mohammed sọ pe awọn janduku naa gbiyanju lati kọlu ile ti awọn ko ounjẹ naa si ṣugbọn ofo ni wọn ba, nitori wọn ti pin gbogbo rẹ tan.
Ijọba ipinlẹ Eko ti sọrọ lori awọn erojẹ ounjẹ fun eto idẹrun Coronavirus, tawọn araalu kan ji ko nibudo ẹru ti wsn ko pamọ si, lọjọ bọ.
Atẹjade kan tijọba fisita ni awọn eroja ounjẹ naa, to pọ babi, kii se ti ipinlẹ Eko nikan, gbogbo ẹkun iwọ oorun Guusu Naijiria lo ni.
Atẹjade kan to wa loju opo Twitter ijọba Eko, ti adele Kọmisana feto ọgbin, Abisola Olusanya fọwọsi, lo sisọ loju ọrọ yii.
Ijọba Eko ni ọjọ kejilelogun osu Kẹsan ọdun 2020 ni Gomina Babajide Sanwo-Olu tẹwọgba awọn eroja ounjẹ naa latọwọ ajọ to n pese eto idẹrun arun Coronavirus, CACOVID.
Oríṣun àwòrán, @followlasg
O ni ijọba n tun awọn eroja ounjẹ naa di lọwọ ni to si n pin kaakiri, ko to di pe iwọde EndSARS wọle de, to si se idiwọ fun wọn lati tẹsiwaju lori rẹ.
Koda, ibudo ikẹru si ọhun kii se ti ijsba, wọn kan gbe silẹ fun wa lati lo ni.
Ijọba ipnilẹ Eko wa kabamọ lori bi awọn araalu se ya bo ibudo ọhun, to si mọ riri atilẹyin ajọ CACOVID, to pin fun.
Oríṣun àwòrán, @GovKaduna
Awọn gomina lẹkun ariwa Naijiria ti sọrọ lori rogbodiyan to gbode kan lati ipasẹ iwọde EndSARS.
Awọn gomina naa lo gbe atẹjade kan sita lẹyin ipade pajawiri ti wọn se lọjọbọ nilu Kaduna, eyi ti gomina Simon Lalong ti Plateau fọwọ si.
Wọn woye pe, ete ati doju ijọba Buhari bolẹ ni iwa ipa, janduku ati ẹlẹyamẹya to gbode nitori ipe fun wiwọgile awọn ọlọpaa SARS.
Awọn gomina naa wa n kọminu pe, ki lo de ti iwọde naa si tẹwaju lẹyin ti ijọba apapọ ti wọgile awọn ọlọpaa SARS naa.
Gẹgẹ bi atẹjade naa ti wi, awọn gomina naa forikori, ti wọn si jiroro pupọ nipa eto aabo orilẹede yii, paapaa iwọde EndSARS to mu ọpọ ẹmi ati dukia lọ.
Oríṣun àwòrán, @GovKaduna
A sakiyesi pe ejo lọwọ ninu iwọde janduku, ẹlẹyamẹya ati ẹlẹsinjẹsin pẹlu ti oselu to gbode, tawọn alainikanse naa si setan lati wo orilẹede yii palẹ, ti wọn si n fẹ ki ayipada isejọba waye.
Ẹgbẹ awọn gomina lẹkun ariwa Naijiria naa wa n ke sawọn ọmọ Naijiria nile loko, lati tako awọn ọta orilẹede yii nipa sise atilẹyin fun aarẹ Buhari, ijọba apapọ ati eto ijọba alagbada.
Oríṣun àwòrán, @GovKaduna
Bakan naa ni wọn tun ni awọn se akiyesi awọn alẹnulọrọ lati ilẹ okeere, ti wọn n lọwọ ninu isẹlẹ yii, ti wọn si kesi gbogbo ọmọ Naijiria lati foju sọri, paapaa awọn ọdọ.
A wa n rọ awọn araalu lati dẹkun iwa ọyaju, ati atako sawọn ẹya miran to n gbe ni ipinlẹ yin nitori ara isẹ ọwọ awọn ọta to n fẹ ayipada ijọba niyi lai seto idibo.
Awọn gomina naa wa n beere fun agbekalẹ ajọ eleto idajọ ti yoo sewadi iwa idaluru ati ipaniyan to waye lasiko iwọde EndSARS.
Oríṣun àwòrán, @jidesanwoolu
Gomina ipinlẹ Eko, Babajide Sanwo-Olu tun ti sọrọ lori isẹlẹ ipaniyan to waye ladugbo Lekki lọjọ isẹgun.
Sanwo-Olu sọrọ fun igbakeji lori ipaniyan to waye ni Lekki ati bawọn janduku se soro nilu Eko lọjọru lasiko to n kopa lori eto ori mohunmaworan kan nipinlẹ Eko.
Gbogbo ifẹhonuhan yii ti n waye saaju ki wọn to bura fun mi bii gomina, ki ijọba ipinlẹ ni ọlọpaa tiẹ si lo le yanju ọrọ yii nitori wọn yoo jẹ ọlọpaa agbegbe.
Bakan naa ni gomina ipinlẹ Eko ni wọn yoo daabo bo ẹrọ ayaworan CCTV to wa ni Lekki, tawọn yoo si pe awọn akọsẹmọsẹ lati ri daju pe wọn ko ba ẹrọ naa jẹ.
"A le se agbekalẹ igbimọ igbimọ oluwadii aladani lopin ọsẹ, to si seese ki wọn bẹrẹ isẹ lọjọ Aje.
Oríṣun àwòrán, @jidesanwoolu
Ọkọ nla marun la padanu lanaa, ti wọn si tun kọlu ọkọ ipe pajawiri wa, wọn jo ileesẹ LASEMA, tawọn osisẹ ibẹ si sa asala fun ẹmi wọn, eyi ti ko jẹ ki wọn le lọ pa ina to jo awọn idudo lanaa."
"Goomina ipinlẹ Eko naa salaye pe oun wa n bi ara oun leere pe ""Bawo la se rin, ta fi ba ara wa niru ipo yii? Ta fi n jo ọkọ akero ijaba ati ile ẹjọ to ti wa lati aye baye?"""
O ni ẹnu wa n ya oun pe ki lo de ta fi maa ba awọn dukia ijọba jẹ.
Oríṣun àwòrán, @jidesanwoolu
A gbọdọ fopin si iwa ibinu yowu to le wa nitori ilu Eko nikan ni ko ti si iwa ẹlẹya mẹya abi ẹlẹsinjẹsin, nitori ọkan soso ni wa.
O wa gba gbogbo ara ilu nimọran lati fimọ sọkan ju ti tẹlẹ lọ, ka si wo egbo ọkan wa san nitori ko ni dara, ka jẹ ki ohun rere tawọn baba nla wa fisilẹ fun wa bajẹ.
Amọ o fikun pe olori osisẹ ni ọọfisi aarẹ wa pe oun pada lẹyin ipade igbimọ alasẹ ijọba naa.
Oríṣun àwòrán, @Odolz
Sanwo-Olu tun salaye pe oun ko tii ri aaye ba aarẹ Muhammadu Buhari sọrọ lori isẹlẹ naa, titi di akoko yii.
O ni oun pe aarẹ Buhari lori isẹlẹ ipaniyan naa laarọ ana, amọ wọn n bun mi gbọ pe ko tii de si ọọfisi.
O fikun pe oun tun pada pe lori aago, amọ ti wọn sọ fun oun pe o wa ni ipade igbimọ alasẹ ijọba ilẹ yii to n waye lana.
Bakan naa ni Sanwo-Olu ni olori ileesẹ ọmọ ologun ilẹ wa ti pe oun lori isẹlẹ to waye lọjọ Isẹgun ọhun.
Gomina ipinlẹ Eko, ninu ifọrọwanilẹnuwo ọhun tun sisọ loju rẹ pe ijọba oun ti gbe igba miliọnu naira kalẹ bii owo gba ma binu fawọn eeyan to fori sọta iwọde EndSARS naa.
Oríṣun àwòrán, @MBuhari
O wa rawọ ẹbẹ sawọn ọdọ to n sewọde lati fi orukọ eeyan meji silẹ, ti yoo soju wọn ninu igbimọ oluwadii ti ijọba gbe kalẹ lori ẹhonu wọn.
Gomina ipinlẹ Eko ni asiko to to yẹ ki wọn faaye gba awọn ipnilẹ lati ni ọlọpa tiwọn, koda, o ni ọrọ naa ti pẹ ju.
Oríṣun àwòrán, @ProfOsinbajo
Igbakeji aarẹ nilẹ wa, Ọjọgbọn Yemi Osinbajo ti sọrọ lori isẹlẹ to waye ni ẹnu iloro bode Lekki lọjọ Isẹgun.
Osinbajo, ẹni to fi atẹjade sita loju opo Twitter rẹ lọjọru lẹyin ọjọ kan ti isẹlẹ naa waye ni orilẹede Naijiria yoo gba idajọ ododo fawọn oluwọde EndSARS to kagbako iku ojijij naa.
Igbakeji aarẹ wa fi ika hanu pe, ọpọ awọn ohun ta padanu lati ipasẹ iwọde naa ni a ko le ri wọn pada mọ titi laelae.
Osinbajo, ẹni to fidi rẹ mulẹ pe oun ti ba ọpọ awọn oluwọde to fara gbọgbẹ, ti wọn wa nile iwosan sọrọ, tun wa kẹdun pẹlu awọn araalu ati ọlọpaa yika ilẹ wa, ti ikọlu naa kan.
EndSARS protest Update: Afẹnifẹre ní ara ti kan àwọn èèyàn, ìjọba sì ló fà á
Ẹgbẹ afẹnifẹre ti sọ pe atunto ni ọna abayọ kan ṣoṣo si iṣoro.
Akọwe ẹgbẹ naa, Yinka Odumakin lo sọ bẹẹ ninu ifọrọwerọ rẹ pẹlu BBC Yoruba.
Odumakin sọ pe, ohun to n ṣẹlẹ lọwọ pẹlu iwọde EndSARS kii ṣe ọrọ ẹlẹyamẹya, ṣugbọn o ti pẹ ti ara ti n kan awọn eeyan.
"O ni ""awa ko fi ọwọ si pe ija ti awọn eeyan n ja jẹ ti ẹlẹyamẹya, ṣugbọn ara n ni awọn eeyan naa, ni wọn fi ṣe ohun ti wọn n ṣe."""
Oríṣun àwòrán, @AmnestyNigeria
Akọwe Afenifere naa ni ohun to yẹ ki ijọba ṣe ni ko wa ọna lati yanju iṣoro to wa nilẹ dipo ko maa yinbọn pa awọn eeyan ilu.
Odumakin wa gba ijọba ni imọran pe o yẹ ko dahun ohun ti awọn eeyan n beere.
"O ni ""lọna kinni, o yẹ ki ijọba ṣe ohun ti awọn eeyan n bere, lẹyin naa, o yẹ ki a bẹrẹ atunto ilu yii ni kiakia."
Ọmọ ẹgbẹ Afenifere ọhun sọ pe iya n jẹ awọn eeyan, nitori naa o yẹ ki ijọba wa gbogbo ọna lati tan ijiya wọn dipo ko maa ṣina ibọn bo wọn.
Oríṣun àwòrán, Reuters
Lati igba ti iṣẹlẹ isekupani awọn oluwọde End SARS ti waye ni Lekki, ni awọn janduku ti bẹrẹ si n da ilu ru ni ipinlẹ Eko.
Bi wọn ṣe n jo agọ ọlọpaa, ni wọn n ṣe wọn leṣe, ti wọn si tun n kọju ija si araalu, ọba alaye atawọn ileesẹ ijọba pẹlu ti aladani.
Alukoro ileeṣẹ ọlọpaa ipinlẹ Eko, Muyiwa Adejobi sọ fun BBC Yoruba pe, awọn janduku ti jo ọọfisi ọlọpaa marundinlogun lapapọ.Ọ̀rọ̀ Nàíjíríà kúrò ní sinimá àwòrẹ́rìn-ìn, Buhari gbé ìgbésẹ̀ bíi òbí àti olórí - Obasanjo gbarata
Adejobi ni bi awọn oluwọde ṣe n sọ oko si awọn oṣiṣẹ wọn naa, ni wọn n yinbọn si wọn lati pa wọn tabi se wọn leṣe.
O fidi rẹ mulẹ pe, ko din ni ọlọpaa meji toun lee fidi rẹ mulẹ pe wọn dagbere faye lati ipasẹ awọn ikọlu to waye yika ilu Eko naa.
Yatọ si awọn ọọfisi ileeṣẹ ọlọpaa ti wọn dana sun, tun wo diẹ lara awọn ileeṣẹ miran ti awọn janduku ọhun tun ti ṣọṣẹ l'Eko.
Oríṣun àwòrán, TVC
Oríṣun àwòrán, @jidesanwoolu
Saaju la ti sọ fun yin pe gudugbẹ ọrọ ti jabọ lati ẹnu ẹgbẹ ajafẹtọ ẹni lagbaye, Amnesty International, ẹka ti orilẹede Naijiria lori iwa ipaniyan to waye ni Lekki lọjọ Isẹgun.
"Atẹjade kan ti ẹgbẹ Amnesty naa fi soju opo rẹ lori Twitter, lo pe akọle rẹ ""Ẹ se iwadii bawọn ologun se pa awọn oluwọde EndSARS""."
Atẹjade naa ni salaye pe awọn oluwọde mejila ni awọn agbofinro yinbọn pa ni Lekki lọjọ Isẹgun.
Bakan naa lo ni iwa isekupani ọhun tun waye ni Alausa, tawọn osisẹ sọja ati ọlọpaa to pa wọn si gbe oku wọn pamọ, gẹgẹ bi wọn ti maa n se.
Oríṣun àwòrán, @AmnestyNigeria
Bakan naa ni ẹgbẹ ajafẹtọ ẹni ọhun tun sisọ loju rẹ pe lati igba ti iwọde EndSARS ti bẹrẹ, eeyan mẹrindinlọgọta lo ti ba isẹlẹ naa lọ.
O ni lọjọ Isẹgun nikan, eeyan mejidinlogoji lapapọ lo jade laye lasiko iwọde ọhun yika orilẹede wa.
Ẹgbẹ Amnesty ni iwadii oun lori isẹlẹ naa lati ipasẹ awọn fidio to jade, ọrọ awọn ti isẹlẹ naa soju wọn ati abẹwo sile iwosan lo fidi isẹlẹ naa mulẹ.
Oríṣun àwòrán, @AmnestyNigeria
O ni awọn ẹri yii fihan pe awọn sọja yinbọn mọ awọn oluwọde lootọ ni Lekki laarin aago meje ku isẹju mẹẹdogun si mẹsan alẹ.
Ẹgbẹ ajafẹtọ ẹni naa wa koro oju si iwa ika naa pẹlu afikun pe iwa kikọju ibọn sawọn oluwọde jẹ ara titẹ ẹtọ wọnsi ipejọpọ, isọrọ sita ati igbe aye loju.
Bakan naa lo bu ẹnu atẹ lu iwadii kan to ni awọn osisẹ ijọba yọ ẹrọ ayaworan to n ka isẹlẹ silẹ, CCTV to wa ni bode Lekki nibi tawọn oluwọde naa wa lati ọsẹ meji sẹyin.
Oke Obi-Enadhuze:, Lekkitollgate, EndSars: Mọ̀ síí nípa Oke Obi
Oríṣun àwòrán, @DanielOE16
Gẹgẹ bi akọsilẹ nipa rẹ to wa ni oju opo ayelujara LinkedIn rẹ, Oke kekọọ gboyè imọ ijinlẹ akọkọ ninu imọ kọmputa ni Fasiti eto ọgbin ti ijọba apapọ to wa niluu Abeokuta, nipinlẹ Ogun laarin ọdun 2016 si 2020.
O maa n sisẹ lati ṣe agbekalẹ ìrísí ọjà 'product design'.
Oke si ti ṣe iṣẹ fun awọn ileesẹ bi i Lifebank Nigeria, ileesẹ kan to wa fun fifi ẹjẹ silẹ lori ayelujara.
Bakan naa lo darapọ mọ ile ifowopamọ Sterling ni oṣu Karùn-ún, ọdun 2020, ibẹ lo si ti n sisẹ titi di akoko iku rẹ.
Gẹgẹ bi ọkan lara awọn akẹẹgbẹ rẹ nileesẹ naa, Temie Gíga-Bosun ṣe sọ loju opo Twitter rẹ, ọlọpọlọ pipe ni Oke, to si jẹ onitiju eniyan.
Bakan naa lo sapejuwe Oke gẹgẹ bi eeyan daadaa.
Akomolede ati Asa: Mọ̀ si nípa àwọn ọ̀nà tí Yorùbá ń gbà ran ara wọn lọ́wọ́
Jàńdùkú gún ẹ̀gbọ́n mi lọ́rùn pa, jó ilé àti mọ́tò wa méjì, kòròfo la wà
Àbúrò' olóògbé ní kìí ṣe àsìta ìbọn ló pa ẹ̀gbọ́n òun, jàǹdùkú ni
A kii gbe inu ile ẹni, ka fọrun rọ, ase irọ patapata ni.
Idi ni pe onimọ kan nipa agbekalẹ oju opo ayelujara, Oke Obi-Enadhuze ni wọn ti kede pe asita ibọn ti dẹmi rẹ legbodo.
Oloogbe naa si lo se oju opo ti wọn ti lee fi ẹjẹ silẹ fun idoola ẹmi lori ayelujara.
"Oke, ẹni ti ọrọ iku rẹ n ja rainrain lori ayelujara lọwọ lọwọ, lo jade laye lẹyin to fi ọrọ kan siju opo Twitter rẹ pe ""Ko ni tan fun Naijiria."""
Oke, to kẹkọọ nipa imọ nipa ẹrọ ayarabiasa, ni iroyin kan sọ pe ibọn ba nile rẹ to wa lopopona Paul, Mafoluku-Oshodi nilu Eko.
Oríṣun àwòrán, @odolz
Bi o tilẹ jẹ pe ko si ẹni to tii le sọ ẹkunrẹrẹ iroyin nipa iku rẹ lori ayelujara, amọ awọn kan ni asita ibọn lo lọ ya ba Oke ninu ile, ẹni to si wa loju opo Twitter titi di aago meji ku isẹju mẹfa lọsan Ọjọru.
Wọn kọkọ ni ọta ibọn kan to wa lati agọ ọlọpaa Makinde lo ran ọdọkunrin naa sọrun lori ayelujara, lasiko tawọn janduku ya bo agọ ọlọpaa naa lati sun nina.
Wọn ni o seese ko jẹ pe ọta ibọn lo seese ba ọkunrin naa lasiko tawọn ọlọpaa n le awọn janduku sẹyin, ki wọn maa ba sisẹ ibi wọn.
Oríṣun àwòrán, Lagos State Government
Sugbọn ẹni kan to pe ara rẹ ni aburo oloogbe naa, Daniel Obi-Enadhuze, ti wa kede loju opo Twitter pe awọn janduku lo wọle wa pa ẹgbọn oun, kii se asita ibọn rara.
Daniel, lasiko to n salaye bi isẹlẹ naa se waye ni lẹyin tawọn janduku yege lati jo agọ ọlọpa Makinde naa nina, ni wọn ya wa si baraki ilegbe awọn ọlọpaa, ti oun ati iya oun n gbe.
O ni wọn bẹrẹ si ba gbogbo mọto to wa nibẹ jẹ, to fi mọ ọkọ meji ti iya oun ni, ti wọn dana sun.
Ọkunrin naa ni lẹyin eyi ni wọn tun bẹrẹ si yẹ gbogbo ile awọn wo, ti wọn si n ko ohun gbogbo ti ọwọ wọn ba ba, ti wọn si gun ẹgbọn oun ni ọbẹ lọrun.
Oríṣun àwòrán, @Jidesanwoolu
Wọn tiẹ tiraka lati gun emi naa lọbẹ lọrun, amọ ọwọ wọn yẹ, ti wọn si fi ọbẹ ya mi ni agbọn.
Emi ati iya mi saayan lati gbe ẹgbọn mi lọ siwaju agọ ọlọpaa lati wa iranwọ amọ awọn janduku si n soro lọwọ.
"Ọmọlanke la papa fi gbe ẹgbọn mi lọ sile iwosan lẹyin o rẹyin, nibi to ti dakẹ."""
Daniel ni gbogbo ohun tawọn sisẹ fun laye awọn ni oun ati iya oun ti padanu bayii, wọn jo ile awọn nina, ti ẹgbọn oun si tun fi ẹmi rẹ di.
Emi ati iya mi ti di alainile lori bayii amọ a wa ni alaafia, a si n dupẹ lọwọ gbogbo awọn eeyan to wa ba wa kẹdun lasiko ọfọ yii.
Oríṣun àwòrán, @Odolz_
Ileeṣẹ ọlọpaa ti ke sita lori bi awọn janduku to fi iwọde End SARS boju, ṣe n kọlu awọn ọọfisi atawọn oṣiṣẹ wọn ni ipinlẹ Eko.
Ileeṣẹ ọlọpaa kede bẹẹ ninu atẹjade kan to fi ṣọwọ si awọn akọroyin, eyi ti alukoro ileeṣẹ naa ni ipinlẹ Eko, Olumuyiwa Adejobi, buwọlu.
O ni awọn janduku naa pa ọlọpaa meji ni agọ wọn to wa ni Orile, bẹẹ ni wọn tun ṣe ogunlọgọ ọlọpaa leṣe, ki wọn to dana sun awọn agbegbe mẹwaa mii, ti awọn ọlọpaa maa n korajọ si.
Lara awọn agọ ọlọpaa ti ọrọ naa kan ni ti Igando, Layeni, Denton, Ilenbe Hausa, Ajah, Amukoko, Ilasa, Cele labẹ Ijesha.
Bakan naa ni wọn tun kọlu ọọfisi SARS to wa ni Ajegunle, Ebute-Ero Mushin nibi ti wọn ti ṣina ibọn fun ọlọpaa meji, pẹlu Ojo ati Ajegunle nibi ti wọn ti jo ọkọ ọlọpaa meji-meji.
Oríṣun àwòrán, @Harforbaje1
"Ko tan sibẹ, atẹjade naa ni ""Awọn janduku ọhun tun dana sun banki mẹta, ti wọn si ji ẹgbẹlẹgbẹ owo ko lọ, ṣugbọn a ri diẹ lara mu ti a si gba ohun ija oloro ati owo ti wọn ji ko lọwọ wọn."""
Ni Ajegunlẹ, wọn dana sun ọfiisi ijọba ibilẹ Ajeromi Ifelodun ti wọn si tun ba awọn dukia jẹ nibẹ.
Awọn janduku naa tun ṣakọlu si afin ọba ilu Eko, ile itaja Shoprite, ileeṣẹ ọkọ oju omi ni Marina ati ile iya Gomina ipinlẹ Eko to wa ni Akerele.
Oríṣun àwòrán, @Chinasanworu
Bakan naa ni wọn tun jo ọọfisi awọn VIO ni Ojodu, ile ẹjọ magisireti ni Igbosere, ileeṣẹ iroyin TVC ati The Nation, ati bẹẹ bẹẹ lọ.
Ileeṣẹ ọlọpaa naa fi kun pe, ọpọ eeyan lo dagbere faye nitori ikọlu awọn janduku naa, ti awọn mẹrin kan si farapa yanayana.
Lẹyin naa lo ni bo tilẹ jẹ pe awọn eeyan lẹtọ labẹ ofin lati ṣe ifẹhonuhan, ileeṣẹ ọlọpa ko ni faye gba iru rogbodiyan bayii mọ.
EndSARS Protest Update: Àwọn olórí orílẹ̀èdè yí nígbàkanrí sọ̀rọ̀ nípa ọ̀nà láti dẹ́kun ìwọ́de ọ̀dọ́ lọ́jọ́ iwájú
Oríṣun àwòrán, Presidency nigeria
Awọn olori orilẹede Naijiria nigbakan ri ti mu amọran wa lori bi orilẹede Naijiria ṣe le dena irufẹ iwọde to waye lori #EndSARS eleyii to fa rogbodiyan ti ko lẹgbẹ lawọn ipinlẹ kan lorilẹede Naijiria.
Nibi ipade finukonu ti wọn ṣe pẹlu aarẹ Muhammadu Buhari lori wahala to ṣẹyi lasiko ati lẹyin iwọde naa lawọn olori orilẹede Naijiria nigba kan ri naa ti jẹ ko di mimọ pe omi nii poro ina, ojo ni poro ọgbẹlẹ, ohun to lee pa oro irufẹ wahala bẹẹ ni ipese iṣẹ fun awọn ọdọ, mimu ọrọ aje gbooro sii ati ṣiṣeto ọna fun awọn oludokoowo lati ilẹ okeere lati wọle wa.
Lara awọn olori orilẹede Naijiria to kopa ninu ipade naa eleyii ti wọn ṣe lori ayelujara ni Ọgagunagba Yakubu Gowon, Oloye Oluṣẹgun Ọbasanjọ, Ọgagun Ibrahim Babangida, Oloye Ernest Shonekan, Ọgagun Abdusalami Abubakar pẹlu aarẹ ana, Goodluck Jonathan.
Awọn olori orilẹede Naijiria naa ṣalaye, ninu atẹjade kan ti Fẹmi Adeṣina to jẹ agbẹnusọ fun aarẹ Buhari, pe ko tọna bi awọn eeyan kan ṣe lo anfani rukerudo naa lati maa tan ina ipinya lorilẹede Naijiria.
Bakan naa ni wọn tun ba mọlẹbi awọn eeyan to padanu ẹmi wọn lasiko rogbodiyan naa kẹdun.
Wọn fi kun un pe lootọ lawọn araalu lẹtọ lati se iwọde wọọrọwọ, ko si si ijọba kan to lee tako eyi.
Oríṣun àwòrán, @MBuhari
Aarẹ Muhammadu Buhari ti fidi rẹ mulẹ pe, ẹmi eeyan mọkandinlọgọrin lo sọnu nitori rogbodiyan to waye ninu iwọde EndSARS kaakiri Naijiria.
Buhari lo fidi ọrọ naa mulẹ nigba to n ṣe ipade pẹlu awọn Aarẹ Naijiria tẹlẹ ri.
Àwọn tó wà níbi ìpàdé náà ni Oloye Olusegun Obasanjo, Goodluck Ebele Jonathan, Yakubu Gowon, Abdusalam Abubakar àti Ernest Shonekan.
O ni lara awọn to ku ni ara ilu mọkanlelaadọta, ọlọpaa mọkanla ati ṣọ́ja meje.
Buhari wa kede pe iku awọ̀n eeyan naa dun oun pupọ, to si ni irufẹ ajalu bayii ko yẹ ko waye rara, ti ko si nitumọ.
Oríṣun àwòrán, @NGRPresident
Wahala bẹ silẹ lọjọ Iṣẹgun ni nnkan bii aago meje ku iṣẹju marundinlogun, nigba ti awọn ọmọ ologun dana ibọn ya awọn oluwọde ni Lekki Toll Gate, to wa ni ilu Eko.
Lẹyin iṣẹlẹ naa ni awọn eeyan tu si igboro ti wọn si bẹrẹ si n dana sun awọn agọ ọlọpaa, ile ijọba ati dukia ilu.
Buhari sọ fun awọn Aarẹ tẹlẹri naa pe, gbogbo ohun ti awọn oluwọde n beere fun ni ijọba oun ti gbọ, awọn yoo si ṣiṣẹ le lori.
Oríṣun àwòrán, Femi Adesina
Agbẹnusọ Aarẹ kan sọ fun BBC pe, Aarẹ fidi rẹ mulẹ fun awọn Aarẹ tẹlẹ naa pe, eeyan mọkandinlọgọrin lo ku nitori iṣẹlẹ naa, ṣugbọn ko ṣalaye boya awọn eeyan to gbẹmi mi ni Lekki wa lara awọn ti Buhari darukọ.
Buhari wa fọwọ gbaya pe oun yoo ri daju pe aabo wa fun ominira ati ẹtọ araalu, ti oun si setan lati raga bo isọkan orilẹede Nàíjíríà.
Ki lo ti ṣẹlẹ sẹyin?
Oríṣun àwòrán, @MBuhari
Awọn ọmọ Naijiria kan tun ti sọ ero ọkan wọn lori ọrọ ti Aarẹ Muhammadu Buhari ba wọn sọ lẹyin rogbodiyan to waye nitori iwọde EndSARS.
Akọwe agba ẹgbẹ awọn agbaagba ilẹ Yoruba, Yoruba Council of Elders, Dokita Kunle Olajide lo sọ bẹẹ fun BBC Yoruba.
O ni Aarẹ ko sọrọ nipa ohun ti awọn ọmọ Naijiria n reti ko sọ, ṣugbọn ọna miran lo ya si.
"Olajide sọ pe ""lakọkọ, o yẹ ko kọkọ ba awọn ẹbi awọn to padanu ẹmi wọn ni Lekki kẹdun, ko si gbadura pe iru rẹ ko ni waye mọ."""
#EndSARS : Àwọn ọ̀dọ́ dáná sun tírélà akẹ́rù tẹrùtẹrù ní Ekiti
Lẹyin naa, ko tun fi da wọn loju pe gbogbo awọn to lọwọ ninu ikọlu naa ni ijọba yoo fi imu wọn danrin.
Akọwe YCE ọhun ni o yẹ ki Aarẹ Buhari rawọ ẹbẹ si awọn ọdọ, ko si rọ awọn obi wọn pe ki wọn bawọn sọrọ, ki wọn le dawọ iwọde naa duro dipo bawọn ologun ṣe ṣina ibọn fun wọn.
Olajide wa gba Aarẹ nimọran pe o yẹ ki atunto de ba bi ijọba Naijiria ṣe n lọ, ki alaafia le jọba.
Ẹwẹ, agbẹjọro ati ajafẹtọ ọmọniyan kan, Dele Farotimi sọ pe, isọkusọ ni ọrọ ti Aarẹ ba awọn ọmọ Naijria sọ ninu igbohunsafẹfẹ to ṣe.
BBC Africa Eye tú àṣírí ìfìyàjẹni àwọn òṣìṣẹ́ aláàbò
Farotimi sọ fun BBC Yoruba pe, Aarẹ Buhari ko tẹle ofin lo jẹ ki wọn maa pa eeyan ninu ijọba rẹ, ti ko si ṣe bi ẹni pe nkan babara n ṣẹlẹ.
O ni awọn fidio to wa kaakiri to ṣafihan bi awọn ọlọpaa ṣe n pa eeyan ju mẹwaa lọ, ṣugbọn Aarẹ sebi ẹni ti nnkankan ko ṣelẹ.
Ni ti awọn oluwọde, o ni ki wọn kọkọ pada sinu ile wọn na, ki wọn si ṣe ijiroro lori igbesẹ to kan.
Oríṣun àwòrán, Femi Adesina
Ọpọ awọn ọmọ Naijiria ti bẹrẹ si n fi ero wọn han lẹyin ti Aarẹ Buhari ba wọn sọrọ tan lalẹ Ọjọbọ.
Ninu igbohunsafẹfẹ naa ni Aarẹ ti kọkọ ka awọn aṣeyọri rẹ lati igba to ti gori alefa, lẹyin naa lo kede pe, ijọba ti n gbe igbesẹ lati ṣeto ẹkunwo owo oṣu fun awọn oṣiṣẹ ọlọpaa.
Bakan naa lo tun paṣẹ fun awọn agbofinro lati pana iwọde to n da rogbodiyan silẹ ni Naijria.
Ṣugbọn pupọ awọn ọmọ Naijiria lo n sọ pe, ohun ti awọn n reti pe ki Aarẹ sọ, kọ lo ba awọn sọ.
Koda, o pari ni ọrọ ti ọpọ ọmọ Naijiria n kọ loju opo Twitter wọn, to si foju han pe, ohun to wa ninu ọrọ aarẹ naa ti toju su wọn.
Oríṣun àwòrán, State House
Bi wọn ṣe n sọko ọrọ lori ikanni ayelujara Twitter naa, ni wọn bu ẹnu ẹtẹ lu Aarẹ loju opo Facebook.
Bakan naa ni awọn kan naa n sọ pe, adiye Buhari kuku n laagun ṣugbọn iyẹ ara rẹ ni ko jẹ ka mọ.
"Eyes Allison lori Twitter sọ pe, ""o yẹ ki awa ọdọ orilẹ-ede yii ji giri, kii ṣe akoko yii lo yẹ ka simi, iranu ni gbogbo eyi ti Aarẹ n sọ."""
"Kenolisa ni ""ọlọlajulọ, ẹ jọ ibeere temi ni pe, ki ni ohun gan pato ti ẹ ni fun awọn ọdọ orilẹ-ede yii?"
"Edwared Boye ni tirẹ sọ pe ""Aarẹ, o dami loju pe ẹ ko tii ri awọn fidio to n tan ka lori ayelujara nibi ti wọn ti pa awọn oluwọde ni Lekki."""
Ni ti Titilope Oyewusi, epe lo fi ranṣẹ si Aarẹ nigba to n ba awọn ọmọ Naijiria sọrọ lọwọ.
Oríṣun àwòrán, Facebook
Imọran ti Aminat Yetunde Olanrewaju Aminu fun Aarẹ ni ti rẹ ni pe, ko fi ijọba silẹ fun awọn ọdọ lati maa dari.
Wo awọn nnkan miran ti awọn ọmọ Naijiria n sọ si Aarẹ.
Oríṣun àwòrán, Femi Adesina
Saaju la ti sọ fun yin pe, Aarẹ Buhari ti ke si awọn ọdọ to n wọde kaakiri orilẹede Naijiria lati pada sile olukaluku wọn ki wọn si dẹkun iwa bẹẹ nitori ẹdun ọkan wọn ti wọn fẹ ki ijọba gbọ ti dun korokoro leti oun ati ijọba oun.
Aarẹ Buhari ti ni ijọba oun ko ni faaye gba ẹnikẹni lati maa ba awọn dukia ilu jẹ ati pe ẹnikẹni to ba ṣe bẹẹ n gbena woju abo orilẹede Naijiria ni ati pe ẹnikẹni to ba ṣe bẹẹ yoo foju wina ofin to ba yẹ.
Aarẹ Muhammadu Buhari ba awọn ọmọ orilẹede Naijiria sọrọ loni lori wahala to ti jẹyọ pẹlu iwọde #EndSARS to gbode lorilẹede Naijiria.
Aarẹ Buhari ni oun ko ṣai mọ ipenija araalu lori iwa kotọ awọn ọlọpaa ikọ SARS naa.
O ni lootọ araalu lẹtọ lati wọde ki wọn si fi ẹhonu wọn han gẹgẹ bi iwe ofin Naijiria ṣe laa kalẹ,
Amọṣa ofin naa jẹ ko di mimọ pe ko si araalu ti iwe ofin fun laaye lati fi erongba ti fi ẹhonu rẹ han fi di araalu miran lọwọ.
O nigbogbo awọn ẹhonu marun un ti wọn fi kalẹ ni ijọba oun tẹwọgba ti oun si ti bẹrẹ igbesẹ lori rẹ.
Aarẹ Buhari mẹnu ba awọn iwa ikọlu gbogbo tawọn oluwọde naa ti gbe ṣe eleyi to si ni o mu ibanujẹ ba oun gẹgẹ bi aarẹ, paapaa julọ iku awọn eeyan kan lasiko naa.
Bakan naa ni aarẹ Buhari tun bu ẹnu atẹ lu ohun to pe ni iroyin ofege kaakiri awọn iroyin ori ayelujara gbogbo eleyi to ni o ti kun orilẹede Naijiria ni awọ ti ko tọ lawujọ agbaye.
O ni irọ ni pe ijọba oun ko ni itara nipa aabo ẹmi ati dukia awọn ọmọ orilẹede Naijiria nitoripe oniruuru igbesẹ ati eto ni oun ti gbe kalẹ lati rii pe aye dẹrun fun araalu.
Aarẹ Buhari fi kun un pe ijọba oun ti dari ajọ to n ri si eto owo oṣu fawọn oṣiṣẹ ọba lorilẹede Naijiria lati tete ṣe iṣẹ lori afikun owo oṣu awọn ọlọpaa atawọn oṣiṣẹ ajọ alaabo yoku lorilẹede NAijiria ki o lee kun oju iwọn.
Aarẹ ni ki awọn orilẹede agbaye maa gbọ ọrọ lagbọye ki wọn to maa gbe ọrọ kalẹ nipa orilẹede Naijiria.
Akomolede ati Asa: Mọ̀ si nípa àwọn ọ̀nà tí Yorùbá ń gbà ran ara wọn lọ́wọ́
Kí làwọn kókó ohun tí Ààrẹ Buhari yóò bá ọmọ Nàìjíríà sọ̀rọ̀ l''aago méje alẹ́ òní?
Aarẹ Muhammadu Buhari yoo ba awọn ọmọ orilẹede Naijiria sọrọ ni agogo meje ọjọbọ.
Amugbalẹgbẹ fun aare lori ọrọ iroyin, Fẹmi Adesina lo sọ eyi.
O ni lẹyin ipade rẹ pẹlawọn ọmọ igbimọ abo ni Naijiria aarẹ yoo sọrs lori hilahilo to n waye lati igba ti iwọde #EndSARS ti dẹsẹru bi ẹsẹ telọ.
A n se akojọpọ ẹkunrẹrẹ iroyin yajoyajo lọwọ, a o maa gbe ẹkunrẹrẹ iroyin naa sori atẹ iroyin wa laipẹ. Ẹ jọwọ, ẹ tun oju opo iroyin yi yẹwo, ki ẹ lee ri ẹkunrẹrẹ iroyin ọtun laipẹ.
#EndSARS: Wo ohun táwọn jàǹdùkú ṣe sí ilé ẹjọ́ Igboṣere l'Eko
#EndSARS : Àwọn ọ̀dọ́ dáná sun tírélà akẹ́rù tẹrùtẹrù ní Ekiti
Iyaloja Oyo state: Àwọn ọlọ́jà ń sèdárò Ìyálọ́jà ìpínlẹ̀ Oyo, Wuraola aya Kola Daisi tó dolóògbé, wọ́n yan asojú míràn
Ẹgbẹ awọn ọlọja nipinlẹ Ọyọ ti sapejuwe iyalọja ipinlẹ Oyo gẹgẹ bi akọni obinrin to jẹ oninu ire, lẹyin to papoda lẹni ọdun mẹrindinlọgọrun.
Alhaja Wuraola Asake Kola Daisi dagbere faye leni odun merindinlaadorun un.
Oloye Rotimi Jogunosinmi to je mogaji agboole Jogunosinmi ni adugbo Oja Oba to tun je omo oloogbe lo fidi e mule.
O ni eyin DRovans ni  agbegbe Ringroad ni Ibadan ni iyaloja yoo ti wo kaa ile lo,.
Lodun 2008 ni komisonna fun oro obinrin ati idagbasoke agbegbe nigba naa, Arabinrin Deborah Oyelade fi Oloogbe Wuraola je iyaloja lasiko gomina Adebayo alao Akala.
Aarẹ ẹgbẹ awọn ọlọja naa ni ilu Ibadan, Alhaji Dauda Oladepo lo sọrọ naa lasiko to n ba awọn ẹgbẹ kẹdun ni ilu Ibadan.
Oladepo ni iku iyalọja naa ba wọn lọkan jẹ gidigidi, to si ba wọn lojiji.
Ẹwẹ, ẹgbẹ awọn ọlọja naa ti kede pe awọn ti yan Yeye Justina Iyabode Ogundoyin lati ṣe adele iyaloja ipinlẹ Ọyọ ni kiakia.
Akomolede ati Asa: Mọ̀ si nípa àwọn ọ̀nà tí Yorùbá ń gbà ran ara wọn lọ́wọ́
Ninu ọrọ rẹ, Iyalode Ogundoyin ṣe apejuwe  Iyalajẹ to doloogbe naa gẹgẹ bi iya rere to duro ni ipo iya fun ọpọlọpọ eniyan.
Agogo mẹrin, ọjọ kejilelogun, oṣu kẹwaa naa ni wọn yoo sin ni ile rẹ.
Awọn ọlọja naa ni awọn ko le e gbagbe iyalọja naa titi ayeraye, nitori o duro ti wọn nigba to le ati igba to dara.
Bakan naa ni wọn gbadura fun awọn ẹbi naa lati mu ọkan le, wi pe edua yoo wa pẹlu wọn.
EndSARS Protest Updates: Feminist Coalition sọ fáwọn ọ̀dọ́ láti fòpin sí ìwọ́de
Ẹgbẹ kan to n lewaju ninu eto akoso iwọde EndSARS ni Nigeria, The Feminist Coalition, ti kede pe oun ti yọwọ yọsẹ kuro ninu iwọde naa.
Bakan naa lo kede pe oun ti se alaye lori owo ti wọn ri ko jọ fun iwọde naa, ti apapọ rẹ jẹ miliọnu mẹtadinlaadọjọ naira.
Ọjọbọ ni ẹgbẹ Feminist Coalition kede pe oun ko ni ni ohunkohun se pẹlu iwọde kankan mọ. O salaye pe asẹ ti aarẹ Muhammadu Buhari pa ninu ọrọ to ba awọn ọmọ Naijiria sọ, pe ki wọn fi opin si iwọde wọn, lo mu ki oun se ipinnu ọhun.
O wa rọ awọn alatilẹyin ẹgbẹ naa nilẹ yii ati loke okun, lati dẹkun fifi owo sọwọ sinu apo asunwọn ẹgbẹ naa ti wọn fi n ko owo jọ, eyi towo inu rẹ bayii jẹ miliọnu lọna mẹtadinlaadọjọ naira.
Oríṣun àwòrán, @feminist_co
Bakan naa ni ẹgbẹ Feminist Coalition tun rawọ ẹbẹ sawọn ọdọ pe ki wọn dẹkun iwọde naa, niwọn igba ti aarẹ ti ba araalu sọrọ, ti ko si mẹnuba ohunkohun to nii se pẹlu ibọn yinyin to waye ni Lekki.
O ni dipo bẹẹ, se ni aarẹ Buhari se atilẹyin fun ikede konile o gbele to wa lawọn ipinlẹ kan lorilẹede yii, to si rọ awọn eeyan lati dẹkun iwọde fun aabo ẹmi wọn.
Ko tan sibẹ, ẹgbẹ Feminisit Coalition tun pẹlu alaafia ni awọn oluwọde EndSARS fi n se iwọde wọn yika Naijiria, ti wọn si safihan iwa ọlọgbọn.
Oríṣun àwòrán, @feminist_co
Amọ nibi ti ọrọ de bayii, a gbọdọ daabo bo ẹmi ara wa ati tawọn ọmọ ẹgbẹ wa pẹlu.
Nipa ti owo ti wọn ri kojọ, tii se miliọnu lọna mẹtadinlaadọjọ naira fun iwọde naa, o ni awọn ti na miliọnu lsna ọgọta ninu rẹ laarin ssẹ meji, gẹgẹ bi alaye to wa lori ayelujara wọn.
Oríṣun àwòrán, @VillaUpdates1
Atamatase ẹgbẹ agbabọọlu Super Eagles, John Ogu ti ke si awọn akẹgbẹ rẹ, lati maṣe kopa ninu ifẹsẹwọnsẹ Naijiria to n bọ lọjọ iwaju.
O ni oun n pe ipe naa nitori iha ti ijọba apapọ kọ si iwọde End SARS.
Agbabọọlu naa, to ti gba bọọlu fun Naijiria ni igba mẹrindinlọgbọn sọ pe, ṣiṣe bẹẹ yoo jẹ ki ijọba apapọ mọ bi ọrọ ṣe gbona si lara wọn.
O ni kawọn oloselu kesi awọ̀n ọmọ wọn lati maa lọ soju Naijiria ninu ifẹsẹwọnsẹ Super Eagles to n bọ
Kii ṣe Ogu nikan ni ọmọ Naijiria to jẹ agbabọọlu to bu ẹnu atẹ lu ọwọ ti ijọba fi mu iwọde naa, paapaa lẹyin ifẹmiṣofo to waye ni Lekki.
"Ṣaaju ni Odion Ighalo, to n gba bọọlu fun Manchester United nilẹ Gẹẹsi, ti kọkọ sọ pe ""itiju nla gbaa"" ni ijọba Naijiria jẹ lẹyin ikọlu Lekki."
Ajọ ajafẹtọ ọmọniyan lagbaye, Amnesty International sọ pe ko din ni eeyan mejila to ku nibi iṣẹlẹ naa.
Ṣugbọn ileeṣẹ ologun ti sẹ pe ohun ko mọ ohun nipa iṣẹlẹ to waye ni Lekki,  bẹẹ na ni ijọba ipinlẹ Eko naa ni oun ko mọ ohunkohun nipa rẹ, ti Aarẹ Muhammadu Buhari naa ko si sọrọ.
Iwọde End SARS bẹrẹ lati pe fun opin si ẹka ileeṣẹ ọlọpa to n ri si iwa idigunjale, SARS, lori iwa aṣemaṣe ti wọn n wu ati bi wọn ṣe n tẹ oju ẹtọ awọn eeyan mọlẹ.
#EndSARS : Àwọn ọ̀dọ́ dáná sun tírélà akẹ́rù tẹrùtẹrù ní Ekiti
Àjọ NBC fi ẹgba ìbáwí rẹ̀ na AIT, Arise TV àti Channels nítorí ìwọ́de ENDSARS
Oríṣun àwòrán, Twitter/ait/channels/arise
Ajọ to n mojuto eto igbohunsafẹfẹ lori redio ati tẹlifisan ni Naijiria, NBC, ti na ẹgba ibawi rẹ si ileeṣẹ agbohunsafẹfẹ mẹta, AIT, Arise TV, ati Channels.
Ajọ naa fi ẹsun kan wọn pe wọn tapa si ofin to de igbohunsafẹfẹ, nipa ṣiṣe afihan awọn fidio ti wọn ko ṣe iwadii rẹ.
Adele Ọga Agba ajọ NBC, Ọjọgbọn Armstrong Adachaba, kede eyi nibi ipade oniroyin kan to waye nilu Abuja lọjọ Aje.
Ajọ NBC sọ pe awọn ileeṣẹ amohunmaworan mẹtẹẹta yii fi awọn fidio nipa ibọn yinyin to waye ni Lekki sita, lai wadii boya otitọ ni wọn tabi ayederu.
Gẹgẹ bi ikede ti ajọ naa fi sita, owo itanran ti wọn yoo san wa laarin miliọnu meji si miliọnu mẹta Naira.
Ọsẹ to lọ ni ajọ naa ti kọkọ fi atẹjade sita, lati fun awọn ileeṣẹ agbohunsafẹfẹ ni ilana ti wọn yoo tẹlẹ lori iwọde naa.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Owe Yoruba kan lo ni ọrọ okeere, bi ko ba lekan, yoo dinkan ni.
Bẹẹ ni ọrọ ri pẹlu awọn iroyin gbogbo tawọn eeyan maa n ju sori ayelujara, to fi mọ awọn aworan abi fidio nipa isẹlẹ kan.
Bi eeyan ko ba si se iwadi bo se yẹ, tabi ko ka ojulowo iroyin lati awọn ileesẹ iroyin bii BBC Yoruba, to maa n tọpinpin iroyin bo se yẹ, afaimọ ki eeyan ma sẹ dẹsẹ.
Koda, isẹlẹ ikọlu bo waye laipẹ yii nibi iwọde EndSARS lẹnu bode Lekki, ti bi oniruuru nnkan miran laarin ilu nitori iroyin eke tawọn eeyan kan n pin kiri nipa isẹlẹ naa.
Koda, awọn iroyin, aworan ati fidio to jinna sootọ nipa isẹlẹ Lekki lo lu ori ayelujara kan, eyi to mu ko fẹ lọwọ iwa ẹlẹyamẹya ninu bayii.
Awọn iroyin, aworan ati fidio eke ti wọn pin kiri lori isẹlẹ Lekki:
Ni kete ti isẹlẹ ikọlu Lekki waye ni ọjọ Isẹgun, ogunjọ kẹwaa, ni iroyin kan ti gba ori ayelujara pe awọn ologun ti yinbọn pa awọn ọdọ to le ni aadọrin.
Awọn miran tilẹ se onkaa tiwọn lati ogun si mẹẹdọgbọn, eyi to mu ki ori ọpọ ọmọ Naijiria gbona.
Oríṣun àwòrán, @HQNigerianArmy
Sugbọn lẹyin igba ti gomina ipinlẹ Eko, Babajide Sanwo-Olu se abẹwo yika awọn ile iwosan ilu Eko loru mọju ọjọ ti isẹlẹ naa waye, o fidi rẹ mulẹ pe ẹmi kan soso lo ku nile iwosan ti wọn gbe awọn oluwọde to fara gbọgbẹ lọ.
Bakan naa ni wọn ri oku ẹlomiran nile igbokusi to wa ni Yaba, ti ọgbẹ ọta ibọn si wa lara rẹ, amọ ko sẹni to le sọ boya asiko iwọde EndSARS ni oloogbe naa ti jade laye.
Oríṣun àwòrán, @Innex9
Aworan miran to tun n fọ ni lori ni ti oku agunbanirọ kan ti wọn n pin kiri pe wọn yinbọn pa nilu Eko.
Sugbọn nibẹ naa ni wọn ti n tako ẹni to pin aworan naa lori ayelujara pe irọ ni.
Wọn ni wọn ya aworan naa ninu ere sinima kan, kii si se otitọ ni ọrọ naa.
Bakan naa ni ẹnikan gbe soju opo Twitter rẹ pe gbajumọ osere tiata kan, Eniola Badmus ti fara gba ọta ibọn latọwọ awọn ologun ni Lekki.
Iroyin naa ni ẹsẹ kan aye, ẹsẹ kan ọrun ni Eniola wa, ti wọn si  du ẹmi rẹ lọwọ nile iwosan.
Amọ alẹ ọjọ naa ni Eniola kede loju opo Twitter ati Instagram rẹ pe ko si ohun to se ohun, saka ni ara oun da.
Oríṣun àwòrán, eniola_badmus
Ori ayelujara gbona pẹlu iroyin tawọn eeyan kan n pin kiri pe ijsba Eko lo pasẹ pe ki ileesẹ amunawa mase fun adugbo Lekki ni ina ọba.
Wọn ni eyi lo fun awọn ologun ni anfaani lati fi okunkun boju, sisẹ ibi lọjọ Isẹgun naa.
Oríṣun àwòrán, @EKEDP
Amọ iwadi fihan pe eyi ko ri bẹẹ nitori ina tawọn ara adugbo Lekki nlo ni wọn n pese funra wọn.
Bakan naa si ni ajọ EKEDC ti fi iroyin sita pe ebu lasan ni iroyin naa.
Iroyin miran lo ni asita ibọn tawọn ọlọpaa yin lo ba ọkunrin kan lọjọru, lasiko taọn janduku fẹ jo agọ ọlọpaa Makinde to wa ni Mafoluku.
Oríṣun àwòrán, @DanielOE16
Sugbọn ẹnikan to pe ara rẹ ni aburo oloogbe, Daniel, jade sita pe awọn janduku lo wọle gun ẹgbọn ohun lọrun pa, kii si se asita ibọn ọlọpaa lo baa.
Lara ẹbu iroyin to gba ori ayelujara nipa isẹlẹ Lekki ni pe obinrin kan Ugwu Blessing Ugochukwu padanu ẹmi rẹ lasiko to jo, to si mu asia Naijiria lọwọ.
Amọ iwadii wa fihan pe irọ gbaa ni , ti agbẹnusọ obinrin naa si ni lootọ ni SARS gbe Ugochukwu lọdun 2018 amọ ko si ohun to se.
Iroyin yii gba ori ayelujara kan pe tawọn oluwọde ba ti mu asia orilẹede Naijiria lọwọ, awọn ologun ko ni kọju ibọn si wọn.
Sugbọn ninu ifọrọwerọ BBC pẹlu agbẹjọro kan, Onyekachi Umah, o ni lootọ ni ọwọ nla wa fun asia ilẹ wa amọ eyi ko tumọ si pe ologun ko lee gbe igbesẹ lori rẹ.
Ẹbu iroyin miran to tun gba ori ayelujara ni aworan ati iroyin kan  to safihan awọn alufa ijọ aguda, ti wọn n rin lọwọ.
Akọle to wa labẹ aworan naa lo ni wọn n se iwọde lati se atilẹyin fun iwọde EndSARS ni.
Sugbọn kia ni ijọ Katoliki kede loju opo Twitter rẹ pe iroyin naa ki se otitọ nitori ọjọ pẹ ti awsn ti ya aworan naa.
Akiolu Staff of Office: Àwọn ológun láwọn ló dóòlà Ọba Eko àti ìdílé rẹ̀ ṣáájú ìwọ́de EndSARS
Oríṣun àwòrán, LASG
Aṣe ọrọ ikọlu tawọn ọdọ kan ṣe si aafin ọba ilu Eko, Rilwan Akiolu naa lọra pọ mọ awọn iṣẹlẹ  iwọde ifẹhonuhan nipinlẹ Eko.
Nigba to n ṣafihan fọnran kan niwaju igbimọ igbẹjọ naa lori bi awọn janduku ṣe kogun ba aafin ọba Akiolu, ọga agba ologun to n ṣalaye ọrọ lorukọ ileeṣẹ ogun Naijiria, Brigadier Taiwo ni ọpẹlọpẹ awọn ni idile ọba fi bọ lọwọ awọn janduku.
Ati Ọba ati gbogbo idile rẹ ni ileeṣẹ ogun Naijiria fi ọkọ oju omi Ferry gbe lọ si ibi kan to ni aabo to daju. Ọgbẹni Taiwo n sọ eyi bo ṣe n fi fọnran bi wọn ṣe n gbe Ọba Akiolu ati mọlẹbi rẹ wọ inu ọkọ ologun ki wọn to gbe wọn sa kuro laafin.
Wọn ti kọlu awọn oniruuru ile itaja ati ọfiisi ti wọn si ji ọpọ nkan ko ti wọn ba nkan jẹ. Awọn ologun ṣalaye pe koda awn janduku ọhun tun gbiyanju lati yabo ile ijọba ipinlẹ Eko ṣugbọn wọn bẹgi dina wọn.
"Wọn gbiyanju lati ya wọ inu ọgba ẹwọn Ikoyi ni Eko, to fi mọ ẹka ileeṣẹ ọlọpaa 81 Division atawọn ọlọpaa lo ṣeranwọ lati dena wọn.
Bi iku ba n pa ojugba ẹni, owe nla lo n pa fun ni, ojo to ba si pa ikan ọrẹ, gbogbo ọrẹ ni eji n pa.
Eyi lo mu ki igbimọ awọn ọba alaye to wa nipinlẹ Eko fi pakiti mọlẹ lọ ba Ọba ilu Eko, Rilwan Akiolu kẹdun lori ọpa asẹ rẹ tawọn janduku gbe lọ .
Bẹẹ ba gbagbe, asiko rogbodiyan to tẹle iwọde EndSARS ni ọjọ Kọkanlelogun osu Kẹwaa ọdun 2020, ni awọn janduku kan ya bo aafin ọba naa, ti wọn si ji ọpa asẹ ati bata rẹ gbe lọ.
Ayangburen tilu Ikorodu, Ọba Kabiru Sotobi tii se igbakeji alaga igbimọ lọbalọba naa, si lo sọrọ lorukọ awọn ọba alaye yoku to ko sodi, lọ si aafin Iga Iduganran lagbegbe Lagos Island.
Oríṣun àwòrán, Facebook/Hrm Oba Rilwan Akiolu
Ayangburen wa koro oju si hihu iwa eewọ lori ọpa asẹ naa ati si ipo ọba alaye nipinlẹ naa, ti igbimọ awọn lọbalọba lapapọ si foju laifi wo isẹlẹ naa.
Ọba alaye naa, to ni awọn ko ni fi ọwọ yẹpẹrẹ mu isẹlẹ naa tun fikun pe ko yẹ ki irufẹ rogbodiyan bayii waye nitori gomina ipinlẹ Eko, Babajide Sanwo-Olu tete dide si ibeere awọn ọdọ naa.
Pistachio Green Puppy: Àwọn ẹgbẹ́ rẹ̀ jẹ́ aláwọ̀ funfun, tí òun sì jẹ́ aláwọ̀ ewé
Ko tan sibẹ o, Onisoro tilu Tomaro, Oba Muhammed Adio Yussuf ati Obanikoro tilu Eko, Oloye Adesoji Obembe naa koro oju si isẹlẹ ọhun.
Awọn mejeeji wa rọ ijọba lati fun awọn ọba alaye ni ojuse pataki lati se lagbegbe wọn, dipo ki wọn kan fi wọn di gẹrẹu lasan.
Oríṣun àwòrán, LASG AND SCREENSHOT, Seyi Soremekun
Erelu Kuti Kẹrin ti ilu Eko, Erelu Abiola Dosumu ti fesi lori ọrọ ọpa aṣẹ Ọba ilu Eko ti awọn janduku kan dede ji gbe kuro laafin lọjọru ọsẹ.
O ni ootọ ni pe inu n bi gbogbo eniyan lọwọ ni Naijria ti ilu si n gbona janjan ati pe o n ya awọn eeyan lara lati sọ bi nkan ṣe ri lọkan wọn.
Erelu Kuti mẹnu le ọrọ yii lori eto ifọrọwanilẹnuwo kan lori ẹrọ amohunmaworan kan nibi to ti sọrọ tẹdun tẹdun bi abiyamọ.
Gẹgẹ bi iya ati ipo mi, mo ti parọwa si awọn to gbe ọpa aṣẹ lọ, o si da mi loju pe ẹni to gbe e lọ yoo pada wa tuba funrarẹ, yoo gbe pa aṣẹ naa wa yoo si tọrọ aforiji""."
Kété tí wọ́n bá ti báa yín sùn tàn torí pé ẹ tóbi, ẹ gbà pé ìfẹ́ yẹn ti parí - Auntie Remi Ọlọ́yàn ńlá
"Erelu ni lai ṣe jagidijagan ni naa ni yoo fẹsẹ ara rẹ rin wa lati da ọpa aṣẹ naa pada. O ni ""a o ni tọwọ ofin bọ o bẹẹ si ni ao ni pa awọn ọmọ wa ṣugbọn mo n fi daa yin loju wipe iranti ati agbara awọn alalẹẹlẹ yoo dari rẹ pada wa""."
Ki gbogbo nkan to da bi o ṣe da yii, omi alafia ni wọn fi wẹ ilu Eko ti ipẹtu saawọ si maa n waye lai ni wahala, o ni alafia ọhun naa si ni yoo pada jọba ti awọn ọdọ to ṣe iṣẹ laabi naa yoo fi pada wa bẹbẹ.
Erelu ni eyi fihan gbangba pe awọn gẹgẹ bii adari ati obi ti kuna ninu iṣe wọn eyi tawọn si gbudọ dide tara ṣaṣa si.
Erelu Kuti ṣalaye pe Ọpa aṣẹ ti Ọba tuntun yatọ si ọpa aṣẹ amurode. O ni Ọpa aṣẹ eyi ti wọn maa n gbe le ọba tuntun to ba ṣẹṣẹ jẹ lọwọ kii dede si larọwọto araalu.
Aabo to daju wa fun ọpa aṣẹ gidi. Ọpa aṣẹ amurode ni Ọba maa n gbe kaakiri eyi si ni eyi ti awọn janduku ri gbe lọ.
Amọ sibẹ sibẹ Erelu ni oun ri bi awọn ọdọ naa ṣe n sọrọ pẹlu ibinu oun si ni imọlara rẹ gẹgẹ bi iya tori bi eeyan ba n ba ọmọ sọrọ, o ni iru esi to yẹ keeyan ri.
Nigba tẹẹ ba ri ọmọ ọdun mẹtalelogun to kan dede joko, ko ṣiṣẹ, ko sabọ, ko lọ ileewe, ẹ o ti mọ pe nkan ti yiwọ.
O ni laarin oṣu mẹta, ni kiakia, ijba ati awọn adari ipinlẹ Eko gbudọ ṣeto nkan ti wọn lee ṣe lati pese iṣẹ fun awọn ọdọ toripe wọn o le gbọ nkankan ti awọn n sọ bayii.
Mo rii bi oju awọn ọdọ naa ṣe pọn rẹrẹ fun ibinu to si jẹ pe kii ṣe gbogbo wọn ni oniwa jagidijagan. Atiraka lo pọ ninu wọn. Tori naa ilana ati wa na abayọ si eyi gbudọ jẹ eyi to gbe iwa obi soju.
Idile ọba Akinsemoyin ti Lagos Island ti dide si ọrọ ọpa asẹ Ọba Eko, Rilwan Akiolu ti awọn janduku kan ji gbe lọ lọjọru.
Saaju la ti sọ fun yin pe awọn janduku naa ya bo aafin ọba Akiolu lasiko isede tijọba ipinlẹ Eko kede rẹ tori iwọde EndSARS to di rogbodiyan.
Awọn janduku naa si lo gbe ọpa asẹ, bata, owo ati eroja ounjẹ lọ ninu aafin ọba naa, koda, wọn ba aafin ọhun jẹ kanlẹ, to fi mọ adagun omi iwẹ ọba, taamọ si swimming pool.
Amọ nibayi, idile Akinsemoyin, ti ọba Akiolu ti jade wa, ti wa ke fewe ọmọ mọ awọn janduku ti ọpa asẹ naa wa lọwọ wọn lati da pada lẹyẹ o sọka.
Oríṣun àwòrán, Screenshot
Bakan naa ni wọn n sekilọ pe, tawọn janduku naa ba kọ eti ọgbọin si ikilọ naa, lai da asẹ ọba pada, ohun ti oju wọn ba ri, ki wọn fara mọ.
Atẹjade kan ti idile ọba Akinsemoyin fisita lori isẹlẹ naa, eyi ti Ọmọọba Salami-Abisako ati Ọmọọba Adeyemi Sarumi fọwọsi, wa fun awọn jandukan naa ni ọjọ kansoso pere lati da ọpa asẹ pada sinu aafin.
Wọn ni ti wọn ko ba tẹle ikils naa, omi le tẹyin wọ igbin lẹnu fun wọn.
Oríṣun àwòrán, Screenshot
Idile ọba Akinsemoyin sisọ loju rẹ pe, oun wa lẹyin iwọde EndSARS naa nibẹrẹ pẹpẹ lati tako ifiyajẹni ati ipani nipakupa latọwọ awọn agbofinro wa, toun si bu ẹnu atẹ lu ni gbogbo ọna.
Amọ, o ni bi iwọde naa se yiwọ buru jai, toun si koro oju si pẹlu.
Atẹjade naa wa kesi Apena fẹgbẹ awo Osugbo, Opa, Akala atawọn olori alawo miran pẹlu awọn eeyan to di asa ilẹ wa mu, lati tete sawari ọpa asẹ ọba Akiolu, ki oju ma ba ti itẹ ọba.
Oríṣun àwòrán, LASG and Screenshot
Ni Ọjọru ọsẹ yii ni awọn janduku kan ya wọ aafin Ọba Isalẹ Eko, Ọba Rilwan Akiolu, to wa ni adugbo lasiko rogbodiyan to ṣẹlẹ ni ipinlẹ Eko nitori iwọde EndSARS.
Yatọ si pe awọn janduku naa ba nkan jẹ ninu aafin naa, ni ṣe ni wọn tun ji ọ̀pá àṣẹ ọba gbe lọ.
Ohun to daju ni pe, nkan pataki ni ọ̀pá àṣẹ jẹ fun ọba nilẹ Yoruba, eyi si lo mu ki BBC Yoruba ba awọn onimọ nipa àṣà ati ìṣe ilẹ Yoruba sọrọ.
Araba ilu Osogbo, Oloye Ifayemi Elebuibon ati Alagba Peter Fatomilola, panupọ sọ pe, ọ̀pá àṣẹ ọba kii ṣe ohun amusere.
Oríṣun àwòrán, LASG
Ninu ọrọ ti ẹ, Alagba Fatomilola sọ pe, ọba ti ko ba ri ọ̀pá àṣẹ dabi pe ọba naa ti sọ ipo rẹ nu ni, ọgbẹni lasan si ni.
O ni nilẹ Yoruba, ọba ti ọ̀pá àṣẹ ba ra mọ lọwọ, boya wọn ji lọ ni o, tabi nitori nkan miran, kii ṣe ọba mọ, idi ni pe, ọ̀pá naa lo fi n pasẹ fun gbogbo ilu to jẹ ọba le l'ori.
Ni ero ti ẹ, Oloye Elebuibon sọ pe aṣẹ lọba ma n pa, ọba kii daba, nitori ọ̀pá to wa lọwọ rẹ, idi si niyii ti wọn fi ma n pe ọba ni alasẹ ikeji òrìṣà.
O fi kun ọrọ rẹ pe, o ṣe ni laanu pe iru iṣẹlẹ naa waye, paapa nilẹ Yoruba.
Oríṣun àwòrán, Screenshot
"Nkan to buru pupọ ni awọn to ji ọ̀pá àṣẹ gbe ṣe, nitori pe ko yẹ ki a maa fi awọn ọba wa wọlẹ.
Ibi ọwọ, ibi àṣẹ ni aafin ọba, kii ṣe ile igbafẹ, nitori pe ibi ti wọn n ko awọn nkan isẹnbaye pamọ si ni.
Ọba to ba jẹ ni ibikibi nilẹ Yoruba, to si ṣe gbogbo oro ati awọn nkan to yẹ ko ṣe ko to o di ọba, kii ṣe eeyan lasan mọ, o ti di òrìṣà."
Alagba Peter Fatomilola sọ pe, to ba jẹ pe laye àtijọ́ ni, gbogbo ilu yoo sọ pe ki ọba naa wa a lọ nitori pe kii ṣe oun lo ni i, fun gbogbo ọba to ba jẹ ni.
Oríṣun àwòrán, Screenshot
Wọn si tun le ṣe etutu lati mu ki ẹni to ji ọ̀pá da a pada tabi ki ọ̀pá àṣẹ fi ẹsẹ ara rẹ rin wa.
"Oloye Elebuibon ni ti ẹ sọ pe, ẹni to lọ ọ gbe ọ̀pá àṣẹ ọba ni isalẹ Eko ""ti fi ara rẹ ṣepe lai mọ""."
O ṣalaye pe etutu ni wọn o ṣe lati ri ọ̀pá àṣẹ naa, ati lẹyin ti wọn ba da a pada tan, ki gbogbo nkan le tuba, ko le tu ṣẹ.
"Awọn to ji ọ̀pá àṣẹ ọba fi tabuku ọba naa ni.
Wọn fẹ ki ọba naa wa lai ni àṣẹ, ọ̀wọ̀ ati agbara.
Oun naa si gbọdọ gbe gbogbo igbesẹ lati da awọn nkan naa pada."
Fatomilola fikun pe, Peter Fatomilola ní 'Ọ̀gbẹ́ni' lásán ni ọba tí kò rí ọ̀pá àṣẹ rẹ̀’ nitori ko ni asẹ lẹnu mọ.
Oríṣun àwòrán, Screenshot
Lori ibeere yii, Fatomilola sọ pe oye to lagbara ni ipo ọba laye atijọ, sugbọn awọn ọba ode oni ko lẹnu ọrọ mọ, nitori pe oloṣelu lo n fi wọn joye.
Awọn oloṣelu lo ni àṣẹ bayii, kii ṣe ọba mọ. Oloṣelu ma n ba awọn ọba wi bi ọmọ ọdọ, awọn ọba ti sọ ara wọn di yẹ̀bù-yẹ́bù, awọn oloṣelu naa si ti ba àṣà wa jẹ.
"Elebuibon ni ""ejo ọrọ naa lọwọ ninu, nitori pe olè ile lo n ṣilẹkun fun ti ode, bakan naa lo sọ pe eyi fihan pe awọn ọta ti wa ni ayika ọba."""
Oloye Yemi Elebuibon sọ pe, o ti ṣẹlẹ ri, àmọ́ kii ṣe lati ọwọ awọn janduku.
O ni o ma a n ṣẹlẹ, paapa ti wọn ba fẹ ẹ sọ agbara iru ọba bẹ ẹ di yẹpẹrẹ, nitori pe o kọ lati ṣe awọn nkan to yẹ ko ṣe, boya ìrúbọ tabi nkan míì, tabi to ba n ṣe aigbọran.
Sugbọn kii ṣe bi i ki awọn janduku rọ́ wọ aafin.
EndSARS Protest Update: Aráàlú gbé ajílẹ̀ àti oògùn apakòkòrò dípò oúnjẹ ìrànwọ́ Covid-19 l'Ekiti
Oríṣun àwòrán, @Areatalkr
Lẹyin ikọlu to waye nibi iwọde EndSARS ni Lekki Toll Gate l'Eko, ni ọpọ awọn ara ilu kan bẹrẹ si n kọlu awọn ile ti ijọba ko awọn ounjẹ to yẹ ko pin lasiko igbele Covid-19 si.
Gẹgẹ bi ọpọlọpọ fidio to n tan kalẹ lori ayelujara, ilu Eko ni awọn eeyan naa ti kọkọ kọlu awọn ile ti wọn ko ounjẹ naa si, ti wọn si ri ọpọ ounjẹ ko.
Ko pẹ si asiko naa ti awọn eeyan ipinlẹ miran bii Oyo, Osun, Kwara ati Ekiti naa bẹrẹ si n kọlu irufẹ ibudo nnkan pamọ si bẹẹ ni ipinlẹ wọn, lati ko ounjẹ ọhun.
Ṣugbọn ni ti ipinlẹ Ekiti, ọrọ ko ri bẹ nitori ohun ti a gbọ ni pe, oogun apakokoro ati ajilẹ ni awọn eeyan ji ko dipo ounjẹ.
"Lara awọn to ke gbajare ni ọkunrin kan ti orukọ rẹ n jẹ Babajide lori Twitter to sọ pe ""gbogbo ipinlẹ ni awọn eeyan ti n ji ounjẹ iranwọ Covid-19 ti ijọba fi pamọ ko, ayafi Ekiti ti awọn eeyan rẹ n ko oogun apakokoro ati ajilẹ."""
Yatọ si ọgbẹni yii, awọn eeyan miran na tun n lọgun lori ayelujara pe majele ni ẹnikẹni to ba ro pe oun ko ounjẹ Covid-19 l'Ekiti ko.
Ṣaaju ni ijọba ipinlẹ naa ti kọkọ ke gbajari pe awọn janduku kan n gbimọ lati kọlu awọn ile ikẹru si ni ipnlẹ naa nitori pe wọn wa ounjẹ iranwọn Covid-19.
Ninu atẹajde ti kọmiṣona fun eto iroyin, Akin Omole fi lede, o ni ijọba Ekiti kò kó ounjẹ iranwọ Covid-19 pamọ sibi kankan nitori o ti pin gbogbo rẹ lasiko igbele.
Oríṣun àwòrán, @Areatalkr
Ṣugbọn ṣe ootọ ni pe ounjẹ iranwọ Covid-19 ni awọn eeyan ko l'Ekiti tabi ko ri bẹẹ?
Ijọba Ekiti ko tii sọ ohunkohun nipa ọrọ yii.
#EndSARS : Àwọn ọ̀dọ́ dáná sun tírélà akẹ́rù tẹrùtẹrù ní Ekiti
Teslim Folarin: Ọwọ́ tẹ àwọn tó kó nkan tówó rẹ̀ tó N200m nílée Sẹ́nétọ̀ tó n ṣojú Oyo Cental
Oríṣun àwòrán, @BolanleCole
Ọwọ sinkun ọba ti tẹ lara awọn to ṣe ikọlu silee Sẹnetọ to n ṣoju ẹkun arin gbungbun ipinlẹ Oyo nile igbimọ aṣofin, Teslim Folarin,
Lasiko ikọlu naa pẹlu afihan fọnran to gba ori ayelujara kan, ọpọlọpọ nkan ti ko lonka ni awọn afurasi janduku naa ji ko.
Latori awọn ọkada tuntun ti iroyin ni o le ni ọọdunrun, firiiji, ẹrọ ilọta ati ọpọlọpọ nkan mii ti iye rẹ to ọpọlọpọ miliọnu naira.
Iru iṣẹlẹ bayii ti n waye kaakiri orilẹede Naijiria lẹnu ọjọ mẹta yii.
Ẹwẹ, gẹgẹ bi ikọ apapọ awọn oṣiṣẹ alaabo ipinlẹ Ọyọ iyẹn Operation Burst ṣe sọ ọ, wn ti gba eeyan marun mu ti wọn lọwọ ninu iṣẹlẹ naa ti wọn si ni ijọba atawọn oṣiṣẹ alaabo to ku ti da si i.
Wọn fi kun un pe akitiyan ti n lọ lọwọ lati tun fi ọwọ ofin mu awọn mii sii to lọwọ ninu ikọlu si ile aṣofin naa.
Lyin iṣẹlẹ yii, iroyin sọ pe ohun gbogbo ti pada sipo bo ṣe yẹ ni agbegbe naa ni ilu Ibadan.
Bí àwọn jàndúkù ṣe yabo ilé Sẹ́nétọ̀ Teslim Folarin, tí wọ́n kó ẹ̀rọ ata, ọ̀kadà, fírìíjì àti àwọn nkan tí owó rẹ̀ tó N200m
Ni ọsan ọjọ Satide ni iroyin jade pe awọn janduku kan yabo ile sẹnetọ to n ṣoju ẹkun idibo aarin gbungbun Oyo.
Oludamọran pataki fun Sẹnetọ Folarin, Ọgbẹni YSO Olaniyi sọ fun BBC Yoruba pe ni owurọ kutukutu ọjọ Satide ni awọn janduku naa to to igba niye, kọlu ile naa to wa ni Oluyole Estate nilu Ibadan, ti wọn si ko awọn nkan ti Sẹnetọ ra fun idẹrun ara ilu salọ,
Lara nkan ti wọn ko ni ọkada bi igba, ẹrọ to n lọ ata, firiji, ẹrọ ti wọn fi n pọ taya ọkọ, ati awọn nkan miran.
Oríṣun àwòrán, yso olaniyi
Diẹ lara awọn ọkada to ku sinu ile naa lẹyin ti awọn janduku ko lọ lara rẹ.
Olaniyi ṣalaye pe ninu oṣu Kejila ọdun 2020 ni Asofin Folarin fẹ ẹ pin awọn irin'ṣẹ naa fun awọn eeyan ti ko ri ọwọ rọri ni ẹkùn idibo rẹ, amọ awọn janduku ti ko gbogbo rẹ lọ.
Ilẹ̀ Yorùbá pátá ló ni oúnjẹ ìdẹ̀rùn Covid-19 tẹ kó l‘Eko - Ìjọba Eko figbeta
Òkú ọ̀dọ́ 15 ni mo kà ní Lekki amọ́ mo kábàámọ̀ pé a gbà kí ológun gbé okù wọn lọ - DJ Switch
Májèlé olóró lẹ gbé l‘Ekiti dípò èròjà oúnjẹ Covid-19 - Ariwo sọ lórí ayélujára
Apena fẹ́gbẹ́ Oṣugbo, Opa, Akala àtẹ̀yin awo, ẹ wa ọ̀pá àṣẹ Ọ́ba Akiolu jáde
Ọwọ́ ọlọ́pàá tẹ àwọn tó lọ kó ọjà ọlajà ní Shoprite Ilorin
O ṣalaye pe niṣe ni wọn kọkọ fi iya jẹ ẹṣọ alaabo to wa ninu ile naa, ti wọn fi raaye ṣiṣẹ ibi wọn.
Bakan naa lo sọ pe ọwọ pada tẹ diẹ lara wọn to sa pamọ sinu ile naa nigba ti awọn ọlọpaa de si ibẹ.
"Ọgbẹni Olaniyi sọ pe ""abẹ ibusun, ati awọn ibomiran bi kọnbọọdu, ni awọn janduku naa sa pamọ si, ki ọwọ to o tẹ wọn."
"Ọwọ tẹ awọn kan naa laarin igboro, a si ti fa gbogbo wọn le awọn agbofinro lọwọ.
Ṣugbọn ọpọlọpọ awọn nkan ni wọn ti ko lọ ki awọn oṣiṣẹ alaabo to o de si ile naa."""
O fi kun ọrọ rẹ pe awọn to wa ninu ile naa lasiko ikọlu ọhun fi ara pa, amọ ẹmi ẹnikẹni ko ba a lọ. Bakan naa lo sọ pe Sẹnetọ Teslin fun'ra rẹ ko si nile lasiko iṣẹlẹ ọhun.
EndSARS: Àwọn ayédèrú ìròyìn tó gbà'gboro kan lásìkò ìwọ́de #EndSARS
Oríṣun àwòrán, Reuters
Awọn ọdọ kan lorilẹede Naijiria ya wọ igboro lati wọde tako wahala ati iwa kotọ awọ ọlọpaa lorilẹede Naijiria fun bi ọsẹ meji ki awọn janduku to ja a gba mọ wọn lọwọ.
Nibayii awọn ọdọ ti wa ya wọ ile, bẹẹni ijọba kaakiri awọn ipinlẹ lorilẹede Naijiria si ti wa kede konile o gbele lati lee da alaafia pada silu ṣugbọn awọn eeyan ṣi n sọrọ lori ayelujara nipa rẹ.
Ara awọn ohun to ṣokunfa laaṣigbo to ti ara iwọde naa ṣẹyọ ni oniruuru iroyin ofege gbogbo to lu ori ayelujara pa.
Diẹ lara awọn iroyin naa ni a fẹ gbe yẹwo lati mọ awọn to jẹ ayederu ninu wọn atawọn to jẹ otitọ.
Aworan kan jade lori ayelujara to ṣafihan arabinrin kan, Ugwu Blessing Ugochukwu to joko sori ere kan pẹlu omije loju ati aṣia orilẹede Naijiria lọwọ rẹ eyi to rinlẹ lori ayelujara.
Arabinrin naa ni awọn ọlọpaa ti pa awọn arakunrin oun, wọn si ti ju wọn si inu kọnga.
Lootọ ni aworan naa han pe arabinrin yii darapọ mọ iwọde ni ẹkun ila oorun gusu orilẹede Naijiria, ṣugbọn ikọ ọlọfintoto BBC ti a mọ si BBC Reality Check kan si arakunrin kan to sun mọ arabinrin Ugochukwu, ti wọn pe orukọ́ rẹ ni Gideon Obianime. O ni ko sohun to jọ ọ.
O ni lootọ ni ikọ SARS ti arabinrin naa mọle lawọn akoko kan ni ọdun 2018 ṣugbọn ko si eyikeyi arakunrin rẹ kankan ti ikọ naa pa.
Bi eeyan gbe aṣia orilẹede Naijiria dani, ko daabo bo lọwọ ikọlu ologun
Ahesọ ọrọ yii jade pe ṣọja ko lee yinbọn pa ẹnikẹni to ba n mu aṣia orilẹede Naijiria dani.
Pẹlu pe ko si ẹri fun eyi, nṣe ni ahesọ yii di kale n kako lori ayelujara.
Amọṣa, ko si ẹri to gbe ọrọ yii nidi.
A ti beere lọwọ awọn ologun boya wọn kii yinbọn fun ẹnikẹni to ba di aṣia orilẹede mu, ṣugbọn wọn ko tii dahun.
Nigba ti iwọde naa kọkọ bẹrẹ, fidio kan jade sita eyi to ṣafihan agbẹnusọ fun aarẹ Buhari, Fẹmi Adeṣina bi ẹni pe o n pe iwọde naa ni ere ọmọde
Ọpọ lo n wo Fẹmi Adesina gẹgẹ bi ẹni to n fi iwọde naa ṣe yẹyẹ.
Amọṣa, fidio ọjọ to ti pẹ sẹyin ni lasiko ti agbẹnusọ fun aarẹ Buhari, Fẹmi Adeṣina fi n ba ikọ ileeṣẹ iroyin abẹle Channelstv sọrọ lori iwọde miran to waye nigba naa.
Iwọde ẹbẹ kan ti a mọ si Revolution Now ni agbẹnusọ fun aarẹ Buhari, Fẹmi Adeṣina n sọrọ nipa rẹ ninu fidio naa, oṣu meji sẹyin ki iwọde #EndSARS Now to waye ni iwọde ti a n sọrọ rẹ yii ti waye, ti ọrọ naa si ti jade.
Fidio kan jade nipa wahala to waye ni ile itaja nla kan ni ipinlẹ Ọṣun nibi ti awọn eeyan kan ti lọ fọ ileetaja nla naa ti wọn si ko ẹru olowo iyebiye lọ.
Ori oju opo Twitter kan to jẹ ti ẹgbẹ oṣelu APC nilẹ Gẹẹsi ni o ti jade pe awọn oluwọde lo n ji ẹru ko.
Amọṣa awọn eeyan kan lori ayelujara ti ṣalaye pe irọ nla gbaa ni iroyin ti ẹgbẹ oṣelu naa gbe. Wọn ni kii ṣe fidio EndSARS ni koda fidio iṣẹlẹ laaṣigbo 'ẹ kuro lorilẹede wa'to waye ni South Africa ni fidio naa jẹ.
Nigba ti BBC ba ọkan lara awọn to ni ile itaja naa sọrọ o fi idi rẹ mulẹ pe lootọ ni wọn fọ ṣọọbu awọn lasiko laasigbo naa ni South Africa, amọṣa awọn ti pada si ẹnu owo bayii.
Ọkan lara awọn iroyin to jade loju opo Twitter ti ọpọlọpọ si gba bi ẹni gba igba ọti ni iroyin kan to tọka si awọn Biṣọọbu ijọ Aguda kan pe awọn naa wọde lati ṣatilẹyin fun iwọde EndSARS.
Amọṣa, aworan yii kii ṣe ti isinyi, ti ọjọ pipọ sẹyin ni.
Ayẹwo aworan lọna igbalode lori ayelujara fihan pe ni oṣu kẹta ọdun 2020 ni aworan iṣẹlẹ naa ti waye lasiko ti awọn Biṣọbu ijọ Aguda lorilẹede Naijiria ṣe ipade apapọ wọn, (CBCN) ni ilu Abuja ti wọn si wọde lati fi ẹhonu han lori iṣẹlẹ ipaniyan ati ijinigbe to wa di tọrọfọnkale nigba naa.
Lootọ awọn ẹgbẹ Bisọbu Aguda fi atẹjade sita ti wọn fi fi atilẹyin han fun iwọde awọn ọdọ lori wahala awọn ọlọpaa to waye ṣugbọn ko si igba kankan ti wọn jade sita lati darapọ mọ iwọde naa.
Afikun iroyin lati ọwọ Linnete Baahati ti ẹka BBC Monitoring ati Yẹmisi Adegoke ti BBC Africa.
Yoruba Staff of Office: Àwọn ọbá aláye ilẹ̀ Yorùbá márùn-ún rèé pẹ̀lú ọ̀pá àṣẹ wọn
Oríṣun àwòrán, Screenshot
Ni ilẹ kaarọ ojiire, ọpa aṣẹ jẹ ohun kan pataki to ni itumọ tir ninu aṣa iran Yoruba to bẹẹ ti pataki rẹ ṣe dede pẹlu ade ori ọba gan funrarẹ tori o wa lara aṣẹ ti ọba ni.
Ọkan lara awọn ọrọ to fọnka ori ayelujara lẹnu ọjọ mẹta yii ni iroyin bi awọn ọdọ janduku kan ṣe ya wọ aafin Oba rilwan Akiolu ti ilu eko ti wọn si ji ọpa aṣẹ gbe lọ.
"Kete ti ọba ba ti gori oye nilẹ Yoruba, ati ọ́pọ́ aṣẹ, ade ọba, irukẹrẹ lo ti di awọn nkan ami aṣẹ fun ọba alade naa eyi ti awọn eeyam si fi maa n pe wọn ni ""alaṣẹ ikeji oriṣa""."
Diẹ lara awọn ba ilẹ Yoruba tawọn ti ọpa aṣẹ wọn lọjọ iwuye ree.
Oríṣun àwòrán, Oba Lamidi/Premium Times
Oba Lamidi Adeyemi keji lo gba ọpa aṣẹ lọwọ Alaafin Gbadegesin Ladigbolu II lọdun 1970 lẹyin ogun abẹle igba naa. Lasiko naa, gomina Ọgagun Robert Adeyinka Adebayo lo wa nipo, nigba naa lo gori oye ti wọn si gbe ọpa aṣẹ le e lọwọ. Ko ko ko ni Ọba Adeyemi, Alaafin Iku Baba Yeye ṣi le lori alefa pẹlu bi baba ṣi ṣe n bi sii to si n rẹ sii.
Oríṣun àwòrán, Ooni of Ife
Kẹti kẹti ni ilu Ile Ife lasiko ti Ooni tuntun, Oba Adeyeye Ojaja II ṣe iwuye gẹgẹ bii Ọọni ikọkanlelaadọta ti Ile Ife.
Lẹyin ọdun mẹtalelọgbọn ati ọjọ kan ti Ooni ti tẹlẹ naa ṣe iwuye ni ti Ooni naa waye eyi ti gomina Old Oyo nigba naa lọhun, Oloogbe Bola Ige ti gbe ọpa aṣẹ le e lọwọ.
Torinaa, Ogunwusi gori oye ni ọjọ kẹrindinlọgbọn lẹyin ọpọlọpọ fa ki n fa a ija oye to gbona janjan laarin gbogbo awọn Arẹmọ oye to wa lasiko naa.
Oríṣun àwòrán, Olubadan/Guardian
Lọjọ karun oṣu kẹta dun 2016 ni Olubadan to wa lori oye bayii, Oba Saliu Akanmu Olasupo Adetunji, Aje Oguguniso I gba ọpa aṣẹ.
gomina ana ni ipinlẹ Oyo to ti di oloogbe bayii, Abiola Ajimobi lo gbe ọpa aṣẹ le ọba Saliu lọwọ to si sọ ọrọ iyanju lọjọ naa pe ki awn oloye alabaṣiṣẹpọ rẹ takete si gbogbo ọrọ oṣelu.
Oríṣun àwòrán, Oluwo of Iwo, amazon Stories
Oba Abdulrasheed  Adewale Akanbi gba pa aṣẹ gẹgẹ bi Alayeluwa ti ilu Iwo ni ọjọ kẹrindinlogun oṣu kini ọdun 2016.
Gomina ipinlẹ Osun lọdun naa, Ọgbẹni Rauf Aregbesola lo gbe ọpa aṣẹ le Oluwo lọwọ.
Ọluwo jẹ ọkan lara awọn ọba to jẹ ọdọ to si tun maa n sọrọ daadaa lori ayelujara.
'Egbò tó ti fẹ́ẹ̀ jiná ni ìtàn bí wọ́n ṣe pa Soun Ogbomoso, Ọba Olayode tẹ ń bèrè'
Oríṣun àwòrán, Oluwo Facebook
Oríṣun àwòrán, Osemawe/Alchetron
Osemawe ti ilu Ondo jẹ ọkan lara awọn  ọba alaye ni Ilu Ondo, ipinlẹ Ondo.
Osemawe Ondo, Oba (Dr.) Victor Adesimbo Kiladejo, Jilo III gba ọpa aṣẹ ni ọdun 2006.
Gẹgẹ bi iroyin ṣe sọ ọ, o ayẹyẹ ọdun mẹwaa lori oye ninu oṣu kọkanla ọdun 2016.
Lekki Tollgate shooting: Fídíò táa ní lọ́wọ́ kò ṣàfihàn gbogbo ohun tó ṣẹlẹ̀ nírọ̀lẹ́ ọjọ́ náà - LCC
Oludari ileeṣẹ to n ṣakoso Lekki Tollgate, Lekki Concession Company ni fọnran ti awọn ni lọwọ nipa ohun gbogbo to ṣẹlẹ nigba ti wọn fẹsun kan pe awọn sọja yinbọn lu awọn afẹhonuhan to n ṣewọde EndSARS ni ogunjọ oṣu kẹwa ọdun 2020 ko ka gbogbo nkan to ṣẹlẹ nirọlẹ ọjọ naa silẹ.
Oludari ileeṣẹ naa, Abayomi Omomuwasan toun naa farahan niwaju igbimọ aṣedajọ ipinlẹ Eko lori awọn iṣẹlẹ pataki to waye lọjọ Aje fi apoti kan han igbimọ naa eyi to ni ẹrọ ayaworan CCTV wa ninu rẹ to ya fidio gbogbo nkan to ṣẹlẹ ni Lekki Tollgate lọjọ ti wọn yinbọn. Ṣugbọn o ṣalaye pe fidio naa to n wo gbogbo ohun to nṣẹlẹ dede duro ni dede ago mẹjọ alẹ eyi si ni dedee akoko ti iroyin sọ pe ibọn yinyin bẹrẹ.
O ni idi ti kamẹra naa fi dakẹ iṣẹ ni pe tori irinṣẹ ti wọn so o mọ ti ni iṣoro nibikan.
Wọn ko tilẹ fi fọnran naa han igbimọ tabi araalu loni ti wọn mu u lọ siwaju igbimọ lẹyin ọrọ ti wọn sọ.
Bakan naa, Abayomi ni fidio naa ko ni ọrọ labẹ tori awọn kan fi n wo igbokegbodo ọkọ ni...
Ọrọ ti pọ bayii lori fidio to wa lori ọrọ ẹrọ ayaworan CCTV gẹgẹ bi iroyin ṣe n fo kiri pe wọn mọọmọ yọ ẹrọ ayaworan ọhun kuro ni Tollgate ṣaaju akoko ti wọn bẹrẹ si ni yinbọn ni.
Nigba to n fesi si ibeere, oludari ileeṣẹ naa gba pe wọn yọ ẹrọ ayaworan kuro eyi ti wọn n lo lati fi mọ awọn ọkọ to kọja laarọ ọjọ iṣẹlẹ ibọn yinyin naa.
Ọgbẹni Omomuwasan ba sọ fun awọn araa igbimọ ọhun pe ki ẹrọ ayaworan naa ṣi wa lọwọ ile ẹjọ.
Ẹwẹ, nipa ti ina ti wọn ni o dede ku ni Lekki Tollgate, o ni ko sẹni to pa ina. O ni ohun to ṣẹlẹ ni pe awọn oṣiṣẹ awọn ni ko tan ina naa silẹ ki wọn to lọ sile nitori konileogbele to wa lode nipinlẹ Eko eyi ti ijọba Eko kede lọjọ iṣẹlẹ yii gangan.
Lẹyin ifikunluku ati idibo lori ayelujara, agbarijọpọ ẹgbẹ ajafẹtọ ti forukọ ọdọ meji ranṣẹ ni Eko lati jẹ ọmọ igbimọ iwadii to n tọ pipin iṣẹlẹ ikọlu to waye ni Lekki.
Oríṣun àwòrán, Twitter/TemiOanu
Lara iṣẹ igbimọ yi ni ki wọn ṣe akojọ ẹsun, fi ọrọ wa awọn eeyan lẹnu wo ki wọn si tun fi idi ododo mulẹ lori ifiyajẹni tabi ipaniyan.
Orukọ awọn meji ti wọn yan yi ni Rinu Oduala ati Majekodunmi Oluwaseun.
Oríṣun àwòrán, falzthebahdguy
Ṣaaju ki a to bẹrẹ si ni gbe iroyin igbẹjọ igbimọ yii, a ni ki a se atupalẹ iroyin nipa awọn ti wọn yan lati ṣoju ọdọ ati iru akitiyan wọn to mu ki ipo yi tọ si wọn.
Bi ẹ ba ti n fọkan ba iwọde ENDSARS bọ, yoo ṣoro ki ẹ to ma da arabinrin yi mọ ninu awọn oluwọde ni ipinlẹ Eko.
Oduala Olorunrinu kii ṣe ẹni to ga pupọ ṣugbọn bi eeyan ba foju di i, yoo kan idin ninu iyọ.
Ajafẹtọmọniyan yi to lewaju paapa ni ile ijọba ni Eko wa lara awọn to kọkọ gbe igba iwọde ki awọn gbajumọ mii to wa darapọ mọ wọn.
Oríṣun àwòrán, @SavvyRinu
Rinu jẹ akikanju ti ko fi igba kankan tura silẹ lori ṣiṣe deede laarin ijọba ati ara ilu.
Akọṣẹmọṣẹ ni o jẹ nipa biba eeyan polowo ọja loju ayelujara ti a si tun maa da si ọrọ to ni ṣe pẹlu mimu irọrun ba ara ilu.
Oríṣun àwòrán, Twitter/TemiOanu
Loju opo rẹ ni Twitter ati Instagram, orisirisi aworan lo wa nibẹ lawọn ibi to ti n kopa ninu iwọde.
Lasiko ti wọn bẹrẹ si ni ro wipe o yẹ ki awọn oluwọde ni aṣoju, o wa lara awọn ti wọn dibo yan lori ayelujara ki o to wa pada laanfaani ati jẹ ọmọ igbimọ iwadii.
Arakunrin yi ni ẹnikeji ti wọn yan lati ṣoju awọn ọdọ ninu igbimọ iwadii nipinlẹ Eko.
Bii ti Rinuola, Temitope naa jẹ ọdọ ti o mu jijafẹtọmọniyan ni ọkunkundun.
Oríṣun àwòrán, Twitter/TemiOanu
Loju opo rẹ ni Twitter, o fi ọrọ idupẹ imoore awọn to yan sipo gẹgẹ bi aṣoju ọdọ.
O gba ladura pe ki awọn maa ṣe ja ireti awọn to yan wọn sipo kulẹ.
Loju opo Twitter niṣe lawọn ọdọ n fi ọrọ iwuri ranṣẹ si awọn aṣoju wọnyi.
Ninu awọn to fi ọrọ adura ati iwuri ranṣẹ ni ilumọọka gbajumọ nii Falz ati awọn mii wa to ni ki awọn aṣoju yi ma gbabọde.
Ijoko igbimọ yi yoo maa waye ni gbogbo ọjọ Iṣẹgun,ọjọ Ẹti ati ọjọ Abamẹta ni ile ẹjọ apẹtusaawọ ipinlẹ Eko to wa ni 1A, Remi Olowude Street, Maruwa Roundabout, Lekki.
Aarẹ Muhammadu Buhari ti sọrọ nipa igbimọ yi to si ni ''oun wa lẹyin igbimọ naa bi ike''
Aarẹ sọ pe oun ni gbagbọ pe igbimọ yi yoo jẹ ki awọn oluwọde ati ọlọpaa to padanu ẹmi wọn ri idajọ ododo gba.
Aláàfin ní tí kìí bá ṣe òṣèlú ni, Ìwó ló yẹ kó jẹ́ olú ìlú ìpínlẹ̀ Osun
Oríṣun àwòrán, Oluwo's Palace
Ogun ọdun akọkọ ti mo lo lori oye ko dẹrun rara, mo lee sọ pe ojumọ kan idamu kan ni.
Eyi ni ọro gbankọgbi ti Alaafin gbe kalẹ ni ilu Iwo lasiko to fi ṣe abẹwo si Oluwo ti ilu Iwo, Oba Abdulrasheed Akanbi nibẹ.
Alaafin, Ọba Lamidi Adeyẹmi III ni ojumọ kan wahala kan loun koju fun ogun ọdun akọkọ ti oun lo loye.
Alaafin Oyo, iku Baba Yeye, Ọba Lamidi Adeyẹmi III bẹ Oluwo ti ilu Iwo, Ọba Abdulrasheed Akanbi wo ni aafin rẹ nilu Iwo.
Oríṣun àwòrán, Oluwo's palace
Oríṣun àwòrán, Oluwo's Palace
O ni asawọ oselu ninu aato ipo ọba ilẹ Yoruba kun ara ohun to n fa wahala ati edeaiyede laarin ilẹ Yoruba.
Ninu ọrọ rẹ, Alaafin ni kani ilana iṣẹṣe ati itan abalaye ni wọn tẹle ni, ilu Iwo lo yẹ ko jẹ olu ilu ipinlẹ Ọsun dipo Osogbo ti wọn fi ṣe olun ilu ipinlẹ Ọsun.
O ni idi ni pe, Baalẹ ni Ataọja ilu Oṣogbo ati Akirun ti ilu Ikirun nigba iwaṣẹ ki alaafin to wa gbe ade le wọn lori ati pe ni gbogbo asiko naa, Ọba alade ni Oluwo.
Ninu ọrọ rẹ, Oluwo tilu Iwo, Ọba Abdulrasheed Akanbi kọminu lori aigbọraẹniye to n waye laarin awọn ọbalaye ni ilẹ Yoruba, pẹlu ipe si alaafin latinbẹrẹ igbesẹ iṣọkan awọn ọbalaye ki ilẹ Yoruba lee pada si ipo ọlanla rẹ lawujọ agbaye.
O sapejuwe Alaafin gẹgẹbi asiwaju ọbalaye ni ilẹ Yoruba ati lorilẹede Naijiria lapapọ, to si ni ọrọ ati iṣe rẹ ṣe pataki lasiko ti awujọ awọn lọbalọba n koju ipenija iṣọkan bayii.
Alaafin Adeyẹmi III, fi idi rẹ mulẹ pe lootọ iṣọkan ṣọwọn laarin awọn oriade atipe ko sohun meji to fa eyi ju wi pe awọn wọn ti ti oṣelu bọ gbigbe awọn ọba si akasọ to yẹ koowa wọn.
O fi da Oluwo loju pe oun yoo gbe igbesẹ lori ọrọ naa bi o ti tọ ati bi o ti yẹ.
Oríṣun àwòrán, Oluwo's Palace
"Ìjọba Eko kọ orúkọ sí ""Palliatives"" tiwọn lára o, mo ní ẹrù tèmi f'ọjọ́ ìbí mi tí wọ́n jí - Họ́nọ́rébù Agunbiade"
"Báyìí ni 50 Kobo ṣe dá ìfẹ̀hónú ""Ali Must go"" sílẹ̀ tó mú ọ̀pọ̀ ẹ̀mí akẹ́kọ̀ọ́ lọ"
Ẹ gbọ́ Ohun tí Desmond Elliot àti Mojisola Alli-Macaulay sọ lórí ayélujára táwọn ọmọ Nàìjíríà fi ìbínú
Kété tí wọ́n bá ti báa yín sùn tàn torí pé ẹ tóbi, ẹ gbà pé ìfẹ́ yẹn ti parí - Auntie Remi Ọlọ́yàn ńlá
"Oluwo ti ilu Iwo, Ọba Abdulrosheed Adewale Akanbi ti rọ ìjọba àpapọ ati awọn ìjọba ipinlẹ lati fi awọn Ọba alaye sinu igbimọ oluwadii ti wọn gbé kalẹ lori aṣemáṣe awọn ọlọpaa SARS.Oluwo lo sọ ọrọ naa ninu atẹjade kan tó fi ṣọwọ́ sí BBC Yoruba.O ni yatọ sí Ileeṣẹ ọlọ́pàá, ààfin awọn ọba ti ori wọn pe, naa jẹ ọkan gbóògì lara ibi ti awọn èèyàn maa n fi ori pamọ́ sí ti wọn ba wa nínú ìṣòro, paapaa eyii to le la ẹmi lọ.Gẹgẹ bo ṣe sọ, òní ""ṣiṣe eyii yóò mú kí àwọn Ọba alaye mọ ohun tó n lọ ati ohun ti awọn èèyàn n dojukọ, yóò sì tún gb'awọn láàyè lati ṣiṣẹ ipẹtu sí aawọ."
Ọba alaye naa sọ pé àwọn igbimọ ti wọn gbé kalẹ ni awọn ipinlẹ kan kò ni Ọba ninu, eyii ti ko yẹ kó rí bẹ́ẹ̀.
O ni ojúṣe ọba to mọ iṣẹ rẹ n'isẹ ni eto abo ilu to n jọba lé lórí.
"Atẹjade ọhun tẹsiwaju pe, ""ààfin ọba náà wà lára àwọn ibi tí wọn ṣe ikọlu sí nígbà rogbodiyan ifẹhonuhan EndSARS, nítorí náà ló ṣe ṣe pàtàkì kí àwọn Ọba lọwọ nínú ìgbìmọ̀ oluwadii ti ijọba gbe kalẹ."""
Oluwo parí ọrọ rẹ pe, ki ijọba yan awọn Ọba sinu awọn igbimọ naa nitori iṣẹ ìlú láwọn n ṣe, ati pe awọn lọbalọba ṣetan lati gbé ìgbésẹ̀ ki àlàáfíà leè wa laarin ilu.
Ni ọjọ Satide ni iroyin kan pe awọn eeyan kan ti kọlu olu ileeṣẹ ijọba ibilẹ Iwo ti wọn si ba a jẹ kanlẹ.
Awọn eeyan wọnyi naa ni iroyin tun fi kun un pe wọn n gbero ati lọ kọlu aafin kabiyesi Oluwo eleyi ti wọn ni awọn araalu gbọ ti wọn si fariga pe ko ni ṣẹlẹ.
Lọgan ti awọn araalu hu ọrọ naa gbọ ni wọn ba sare bọ sita lọ di gbogbo ọna to de aafin ti wọn si duro ni igbaradi lati koju ẹnikẹni ti yoo ba loun yoo kọlu aafin naa ati kabiyesi wọn.
Ni gbogbo asiko yii, inu aafin ni Kabiyesi Oluwo wa ti o si ni, awọn 'ko mọ ohunkohun to n lọ nita'
Ninu ọrọ to ba BBC News Yoruba sọ, Kabiyesi Oluwo ti ilu Iwo ṣalaye pe aṣiri to n bẹ laarin oun atawọn araalu Iwo ti wọn fi duro gba-gba-gba lati daabo bo ohun ko ju pe oun ti n sin wọn gẹgẹ bii baba ilu.
Baba gbogbo ilu Iwo ni mo jẹ, Ẹẹmẹta lsẹ la n pin ounjẹ fawọn ti ko ni lati jẹ.
O ni awọn araalu Iwo fihan pe awọn mọ riri iṣẹ iranwọ, itọju ilu ati mimojuto igbayegbadun wọn ni wọn fi dide lati daabo bo oun ati aafin.
Kabiyesi, Ọba Akanbi Abdulrasheed ṣalaye pe iyatọ to wa laarin oun atawọn ọba alaye miran gbogbo ni pe oun ko ri ipo ọba gẹgẹ bi ipo lati jẹ gaaba le araalu lori tabi ko ọrọ ilu sabẹ, ṣugbọn oun ti lo asiko ti oun ti lo lori oye lati fi tan iṣoro araalu ati aini wọn.
Bi ẹ ko ba gbagbe, laipẹ yii ni awọn ọdọ ilu Eko ya bo aafin kabiyesi Ọba ilu Eko, Akiolu ti wọn si fọ aafin rẹ gbe awọn ohun iṣẹmbaye titi kan ọpa aṣẹ Ọba naa lọ.
'Egbò tó ti fẹ́ẹ̀ jiná ni ìtàn bí wọ́n ṣe pa Soun Ogbomoso, Ọba Olayode tẹ ń bèrè'
Kíni Gómìnà Sanwo-Olu sọ nípa ìṣẹ̀lẹ̀ ìpànìyàn Lekki tó ń mú awuyewuye wà lórí ayélujára?
Oríṣun àwòrán, Twitter/jidesanwoolu
Gomina Babajide Sanwo-Olu  ti ni ijọba apapọ ati ti  ipinlẹ Eko yoo ṣapa lati ri pe ẹnikẹni to lọwọ si ipaniyan Lekki yoo foju wina ofin.
Sanwo-Olu fidi ọrọ yi mulẹ ninu ifọrọwerọ pẹlu ileeṣẹ iroyin CNN lọjọ Aje.
O ṣalaye fun atọkun eto ''Connect the World'' iyẹn Becky Anderson pe awọn yoo fi fọnran fidio CCTV to ya iṣẹlẹ naa ṣọwọ si igbimọ iwadii.
Igba akọkọ ree ti Gomina Sanwo-Olu sọ ni pato pe lootọ lawọn ọmọ ogun yinbọn lu awọn oluwọde.
'' A o ri pe iwadii ẹkunrẹrẹ waye ta o si pe awọn to ba mọ nipa rẹ lẹjọ. Dajudaju, wọn yoo kawọ pọnyin rojọ. Gbogbo ipa la o ṣa lati rii pe wọn wa wi tẹnu wọn''
''Awọn eeyan sọ pe wọn pa ẹbi ati ọrẹ wọn. Nitori naa igbimọ iwadii yi yoo ko gbogbo ọrọ jọ ki a ba le ṣe atunṣe ati itanran to yẹ''
Bẹẹ naa lo ni oun ni igbagbọ pe iyipada rere ni yoo tẹle ohun to ṣẹlẹ lẹnu ọjọ mẹta yi.
''Mo nigbagbọ pe iyipada yoo waye fun idi meji.Akọkọ ni pe ohun to ṣẹlẹ paapa ni Eko kọja afẹnusọ.Ikeji ni pe o jẹ ipe fawa ijọba lati mọ ohun tawọn ọdọ fẹ kaṣe''
Loni ọjọ Kẹtadinlọgbọn oṣu Kẹwa ni igbimọ to n gbẹjọ ifiyajẹni lati ọdọ ikọ SARS yoo bẹrẹ ijoko wọn.
Yatọ si iwadii lori ọrọ SARS igbimọ naa yoo tọ pinipin iṣẹlẹ to waye ni Lekki ni ilu Eko nibi tawọn eeyan ti padanu ẹmi wọn.
MSME free business registration: Oníṣẹ́ alàdáni, ẹ wo ọ̀nà láti jẹ ànfàní ìforúkọsílẹ ọ̀fẹ́ tí ìjọba gbékalẹ̀
Oríṣun àwòrán, MSMES SURVIVAL FUND/TWITTER
Aarẹ Muhammadu Buhari ti buwọlu anfani iforukọsilẹ ọfẹ fawọn to ba fẹ forukọ ileeṣẹ wọn silẹ pẹlu ileeṣẹ to n fontẹ lu orukọ ileeṣẹ ni Naijiria,CAC.
Bẹrẹ lati ọjọ kẹtadinlọgbọn oṣu Kẹwa ni anfani yi yoo fi ṣi silẹ fawọn onileeṣẹ kekeeke ati alabọde(Meduim Small and Micro Entrepreneurs (MSME) to to ẹgbẹrun lọna ojilenigba le mewaa (250,000).
Igbesẹ yi jẹ ọna kan gboogi ti ijọba lawọn fẹ fi ran onileeṣẹ kekeeke lati fidi ileeṣẹ wọn mulẹ lẹyin Covid-19.
Kété tí wọ́n bá ti báa yín sùn tàn torí pé ẹ tóbi, ẹ gbà pé ìfẹ́ yẹn ti parí - Auntie Remi Ọlọ́yàn ńlá
Oluranlọwọ aarẹ Buhari  lori ọrọ iroyin ori ayelujara, Bashir Ahmad  lo fi ọrọ yi soju opo Twitter.
O ni ajọ CAC yoo forukọ ileeṣẹ ẹgbẹrun mẹfa le ni ẹgbẹta lawọn ipinlẹ mẹrinlelọgbọn ni Naijiria.
Amọ ṣa ẹgbẹrun meje ati ẹẹdẹgbaarun le ni mẹfa (7,906) ni yoo jẹ anfaani yi ni Abuja.
Ni Abuja  ẹgbẹrun mẹsan o le ni mẹrinlelọgọrin,9,084 nigba ti Kano yoo si ni aaye fun ẹgbẹrun mẹjọ le ni irinwo eeyan (8400).
Iforukọsilẹ ọfẹ yi yoo bẹrẹ lati ọjọ kẹtadinlọgbọn oṣu Kẹwa ọdun 2020.
Ohun to yẹ ko ṣe ree:
Àwọn ọmọ ogun Nàìjíríà tú àṣírí ẹni tó rán wọn níṣẹ́ lọ kojú àwọn olùwọ́de EndSARS ní Lekki Tollgate
Kò sí àfikún ọjọ́ ìdáríjì fáwọn jàndùkú tó jí ohun iyebíye gbé lọ nípinlẹ̀ Osun - Gómìnà Oyetola
Àgbàrá òjò gbé alága àdúgbò àti èèyàn méjì mìí lọ nílùú Ibadan
Àjẹ́ ké lánàá, ọmọ kú lónìí ni ọ̀rọ̀ Tinubu àti ìṣẹ̀lẹ̀ Lekki Tollgate - Bode George
EndSARS Protest Update: Tunde Bakare ní ìwọ́de ọ̀dọ̀ jẹ́ ìparí sáà kan àti ìbẹ̀rẹ̀ òmíràn
Oríṣun àwòrán, Tunde bakare
Oluṣọ-agutan ijọ Latter Rain, Tunde Bakare ti sọrọ fun igba akọkọ lori iwọde EndSARS ati rogbodiyan to tẹle.
Ninu ọrọ to bawọn ọmọ Naijiria sọ, eyi to fi soju opo Twitter rẹ l'Ọjọbọ ni Bakare ti bọhun nipa iṣẹlẹ ibanujẹ naa.
Bakare ni asia orileede Naijiria ti ni abawọn ẹjẹ awọn ọmọ wa pẹlu ikọlu tàwọn ologun ṣe sáwọn oluwọde ni Lekki.
Abala keji orin ibilẹ Naijiria lo ni a o fi asia ailabawọn le awọn ọmọ wa lọwọ amọ o ṣe ni laanu pe Asia to ni abawọn ẹjẹ wọn, la fẹ gbe le wọn lọwọ.
Oluṣọ-agutan ìjọ Latter Rain fikun pe iwọde EndSARS to waye jẹ ipari iran kan lorilẹ-ede Naijiria ati ibẹrẹ iran miran.
O ni iwọde naa jẹ ifarahan ibẹrẹ orile-ede Naijiria tuntun ati ifehonuhan awọn araalu ti wọn n pe ni eeyan lasan.
Ọlọ́pàá mẹ́fà, àgọ́ ọlọ́pàá márùn-ún ló bá wàhálà ìwọ́de #ENDSARS lọ nípìnlẹ̀ Oyo - Kọ́mísánnà
Ẹ má à gbìyànjú láti bo àṣírí ìpànìyàn tó wáyé ní Lekki, á ní ẹ̀rí tó dájú - Amnesty International
Àwòrán nǹkan aláràmbarà oríṣiríṣi táwọn jàǹdùkú jí gbé lẹ̀yìn ìwọ́de EndSARS
Àwọn tó mọ̀ nípa ìpànìyàn Lekki yóò fojú winá òfin - Sanwo-Olu sí Becky Anderson
Àjẹ́ ké lánàá, ọmọ kú lónìí ni ọ̀rọ̀ Tinubu àti ìṣẹ̀lẹ̀ Lekki Tollgate - Bode George
 Iwọde EndSARS lo fi da mi loju pe iran tuntun ni Naijiria ti dìde, ti wọn fi isọkan sọrọ, ti wọn ko si gba ki wọn pa ina wọn tabi fi ọwọ bo wọn lẹnu tori asiko SọrọSoke la wa yii.
Nigba to n ṣe iranti ikọọkan awọn eeyan to ku lati ọwọ ọlọpaa SARS ati lasiko iwọde, Bakare wa kesi ijọba lati fi imu awọn ologun to kọlu oluwọde ni Lekki danrin.
Bakan naa lo tun rọ ijọba lati ṣe amusẹ ibeere awọn ọdọ, ki iku awọn oloogbe ma ba a ja si asan.
EndSars Protest: Ǹkan mẹ́ta ti Gómìnà Babajide Sanwo-Olu pinu fún àwọn ọlọ́pàá ìpińlẹ̀ Eko
Gómìnà ìpińlẹ̀ Eko, Babajide Sanwo-Olu ti pàsẹ fáwọn ilé tó ń ṣètò ẹ̀kọ́ ọ̀fẹ́ ní ìpińlẹ̀ Eko láti fún ọmọ àwọn ọlọ́pàá tó bá ìṣẹ̀lẹ̀ abájádè ìfẹ́hónú ọ̀rọ̀ EndSars rìn.
Bákan náà ni Sanwo-Olu tún ni gbogbo ẹbí wọ́n ni yóò gba owó ìrànwọ́.
Gómìnà tún kéde pé, ètò wà nílẹ̀ láti tún gbogbo àwọn àgọ́ ọlọ́pàá tí wọn ti dáná sun, tí wọn yóò sì ra ọkọ̀ míràn tí àwọn jàndùkú ti bàjẹ́.
Babajide ṣe àwọn ìlérí yìí lásìkò to sàbẹ̀wò sí olú ilé iṣẹ́ ọlọ́pàá ní ìlú Ikeja láti báwọn sọ̀rọ̀ ìwúrí.
Àtẹ̀jáde kan fi yéni pé, ó kéré tàn àgọ́ ọlọ́pàá mọ́kàndílọ́gbọ̀n ní wọ́n sùn níná, ti àwọn ibùdó ọlọ́pàá kéékèké mẹ́tàdínlógún sì lọ síi pẹ̀lú.
O ní ojúṣe ko ṣee fọ́wọ́yẹpẹrẹ nu láwùjọ nítorí ìwà ìbàjẹ́ àwọn kan láàrín ọlọ́pàá, àti pé àìsí ọlọ́pàá láàrín ìlú lẹnú ọjọ́ mẹ́tà  jẹ́ ǹkan ti ó kan gbogbo ará ìlú.
"Kọmísọ́nà ọlọ́pàá tí fí ìwé ẹ̀dùn ọlọ́pàá ṣọwọ́ sí ìjọba, àtàwọn ǹkan ti yóò mú ìwúrí bá àwọn ọlọ́pàá lásìkò yiì.
Lẹ́yìn gbogbo làásìgbò tó wáyé lọ́sẹ̀ tó kọjá. Èmi gẹ́gẹ́ bíi gómìnà mo gba gbogbo ọ̀rọ̀ náà gẹ́gẹ́ bi ẹ̀bi mi, pàápàá jùlọ àwọn ǹkan alò ti kò tó, láti ọjọ́bọ, ọjọ́ kọkàndílọ́gbọ̀n, oṣù kẹwàá, gbogbo àwọn ǹkan ti ó wà nínú ìwé ẹbẹ̀ yìí ni àó máa gbé ìgbésẹ̀ lórí ẹ"""
" Pàtàkì jùlọ nínú àwọn ìwé ẹ̀bẹ̀ ọlọ́pàá ní fífún àwọn ọmọ ọlọ́pàá tó d'olóògbé ni ẹ̀kọ́-ọ̀fẹ́, mo si ti dári àjọ tó n mójú tó ètò ẹ̀kọ́-ọ̀fẹ́ nípìnlẹ̀ Eko láti fún gbogbo àwọn ọmọ wọ́n ni ẹ̀kọ́-ọ̀fẹ́.
Gẹ́gẹ́ bi Sanwo-Olu ṣe sọ gbogbo ọlọ́pàá tó bá ń ṣiṣẹ́ ní ìpínlẹ̀ Eko yóò ni ètò adójútòfò ẹ̀mí (Life Insurance).
Bákan náà lo fi kun un pé, òun yóò pèsè ẹ̀rọ amúná wá 150kva fún àwọn ọlọpàá àti pé ìjọba yóò sowọ́n pọ mọ́ ilé iṣẹ́ mọ̀nàmọ́nà aládani, tí wọn yóò fi máa ní iná ni gbogbo ìgbà ìgbà.
Ẹ̀wẹ́, gómìnà ìpínlẹ̀ Borno, ọjọgbọ́n Babgana Zulum ṣe ìfílẹlọlẹ̀ ẹbún owó, ẹgbẹ̀rún lọ́nà ààd'ọ́ta naírà fún gbogbo àwọn opó tí ọkọ wọ́n kú nítorí wọ́n faraji lati daabo bo ilú (fijilante àti àwọn ọdẹ) tí wọ́n si dara[ọ̀ mọ ọmọogun gẹ́gẹ́ bi ará ìlú.
Bákan náà ni Gómìnà tún ṣe afilọlẹ ètò ẹ̀kọ́ ọ̀fẹ́ fún àwọn ọmọ wọ́n bákan náà
Báyìí ni 50 Kobo ṣe dá ìfẹ̀hónú Ali Must go"" sílẹ̀ tó mú ọ̀pọ̀ ẹ̀mí akẹ́kọ̀ọ́ lọ"
Kété tí wọ́n bá ti báa yín sùn tàn torí pé ẹ tóbi, ẹ gbà pé ìfẹ́ yẹn ti parí - Auntie Remi Ọlọ́yàn ńlá
Baldness: Àwọn tí irun wọ́n ti gbá rìfáàsì sọ ìrírí wọn àti àǹfàní tí wọ́n ń jẹ
Ṣé lóòtọ́ ni pé orí olówó ni ti apárí?
...Ìgbà míì, àwọn báábà ò kí ń béèrè pé ṣé ẹ fẹ́ gẹrun orí, irun àgbọ̀n nìkan la máa ń gẹ̀ nígbà tí kò sí ǹkankan lórí, kondoro ni.
Awọn apari gbàgbọ pé púpọ nínú awọn to ṣe agbejade awọn nkan gidi lagbaye, apari ni wọn.
Ọkan ninu wọn ṣe afiwe onimọ Sayẹnsi, Michael Farraday gẹgẹ bi eeyan nla to si jẹ apari.
Bí Ọlọrun bá tiẹ fún mi ní irun àgbọn, máà dúpẹ, àwọn kan wa to jẹ pe kodoro bayii ni.
Ni ti dokita, o sọ oniruuru idi ti eeyan le fi pa lori yala kunrin tabi obinrin.
"Dokita Tunde Adeife jẹ ko di mimọ pe o le niṣe pẹlu ajogunba idile nigba miran. ""To ba ti wa ninu idile kan, to jẹ wipe tẹẹ́ ba ṣa ọkunrin mẹwaa ninu idile, eeyan marun a pari ninu wọn, ẹ o ti mọ pe ajogunba ni""."
Ni ti obinrin, o ṣalaye pe bi irun ti wọn maa n ṣe ba ti le ju to si yọ lati ibi gbongbo rẹ, obirin naa ti di apari niyẹ ti ko si si ohun ti onimọ iṣegun oyinbo kankan le ṣe si i.
O ṣalaye pe to ba kan ge laarin ni, atunṣe ṣi wa.
Remilekun Fatolu bú sẹ́kún fún ohun tó ti pàdánù láyé torí ọyàn ńla rẹ̀.
Ẹwẹ, dokita Tunde ni awọn ounjẹ afunilẹjẹ kan wa to le jẹ ki irun hu daadaa.
Awọn abẹrẹ wa taa le lo, ti a ba ti gun ibi isal ibi ti irun ti n jade wn a si lẹ wọn mọ ibi tori ti n pa ti yoo si bọ si deede pada.
Koda o ni awọn obirin gan lee pada ni irun iwaju to ti fa l sipakọ pada nipa aramanda iṣẹ ọwọ awọn.
Desmond Elliot, Mojisola Alli-Macaulay fa ayélujára ya torí ọ̀rọ̀ wọn níle aṣòfin Eko
Oríṣun àwòrán, Desmond Elliot, Mojisola Macaulay
Arabinrin Mojisola Alli-Macaulay to jẹ akẹgbẹ aṣofin nipinlẹ Eko sọ wi pe ko si igba ti awọn ọdọ lorilẹede Naijiria kii fa igbo nitori naa ni ori wọn ṣe n gbona ni igba gbogbo
Iroyin ni ibi ijoko Ile Aṣofin nipinlẹ Eko ni Alli-Macaulay ti sọ ọrọ naa lẹyin rogbodiyan to waye lasiko ifẹhọnuhan EndSars, ti awọn onijagidijagan gba mọ wọn lọwọ.
Alli-Macaulay ni ti awọn omo Naijiria ba ti fa igbo tan ni wọn ma n lọ si ori ẹrọ ayelujara lati lọ sọ isọkusọ.
Nitori naa a gbọdọ ko awọn ọdọ wa lati ko ara wọn ni ijanu ati bi o ṣe yẹ ki wọn huwa lawujọ.
Eyi ni ohun mẹwaa to yẹ kẹ ẹ mọ nipa Arabinrin Asofin Mojisola Alli-Macaulay;
Oríṣun àwòrán, Mojisola Alli-Macaulay
Oríṣun àwòrán, Mojisola Alli-Macaulay
Oríṣun àwòrán, Mojisola Alli-Macaulay
Kété tí wọ́n bá ti báa yín sùn tàn torí pé ẹ tóbi, ẹ gbà pé ìfẹ́ yẹn ti parí - Auntie Remi Ọlọ́yàn ńlá
Ohun tí òṣèré àti aṣòfin, Desmond Elliot sọ táwọn ọmọ Nàìjíríà gbà sí ìbínú
Oríṣun àwòrán, Desmond Elliot/Facebook
Ọrọ Desmond Eliot ni awọn ọmọ Naijiria fi bọnu lori ẹrọ ayelujara nipa ọrọ to sọ lori bi awọn Ologun ṣe da ibọn bo awọn afẹhọnuhan tako ifiyajẹni awọn ọlọpaa ni Lekki Toll gate,ni ipinlẹ Eko.
Desmond Eliot ni ki awọn gbajumọ lawujọ ati awọn oloṣere ki wọn ye sọrọ kubakugbe lori ayelujara mọ, amọ ki wọn lọ gba kaadi idibo wọn, ki wọn dibo fun ẹni ti wọn fẹ ninu eto idibo to n bọ,a bi ki awọn furawọn dije dupo.
Bakan naa lo ni orilẹede Niajiria yoo di ohun igbagbe ti awọn ọmọ Naijiria ko ba jawọ ninu bi wọn ṣe n ji awọn nkan gbe tabi fi ina si awọn ile.
Elliot gboriyin fun Abẹnugan Ile Igbimọ Aṣofin to bu ẹnu atẹ lu ifiyajẹni to waye ni Lekki Toll gate.
''Inu mi dun pẹlu ọrọ ti Abẹnugan Ile Igbimọ Aṣofin sọ nipa iṣẹlẹ to waye ni Lekki, amọ o ba oun ninu jẹ pẹlu bi awọn ọmọ Naijiria ṣe n ṣepe, ti wọn tun lo ji ọpa ọba gbe laafin Ọba Ilu Eko.
'Ifiyajẹni, ọrọ kubakugbe ati ikorira ti pọju lorilẹede Naijiria.''
Oríṣun àwòrán, Desmond Elliot
Bakan naa ninu fidio miran to fi lede, o fihan gbangba pe oun ko fọwọsi abadofin to de bi awọn ọmọ eniyan ṣe n sọrọ lori ẹrọ ayelujara, amọ ohun ti oun sọ ni pe, ki wọn ma lo ẹrọ ayelujara lati fi da orilẹede Naijiria ru.
Amọ, gbogbo ọrọ to sọ yi bi awọn ọmọ Naijiria ninu, ti wọn si fi ọrọ gun un lara lori ẹrọ ayelujara.
Ọpọlọpọ awọn to sọrọ to fi mọ Davido ni '' igbagbọ awọn ninu Desmond Eliot ti dopin, pẹlu ọrọ iranu to sọ jade lẹnu''.
Bakan naa ni awọn eniyan kesi awọn ara Surulere lati dibo yọ ọ kuro ni ipo, nitori ko ṣe ifẹ awọn araalu mọ.
Gbajugbaja oṣere ni Desmond Eliot ko to di wi pe wọn dibo yan an gẹgẹ bi aṣofin to soju ẹkun Surulere ni Ile Igbimọ Aṣofin ipinlẹ Eko.
Kété tí wọ́n bá ti báa yín sùn tàn torí pé ẹ tóbi, ẹ gbà pé ìfẹ́ yẹn ti parí - Auntie Remi Ọlọ́yàn ńlá
Kogi Commissioner: Àlàyé rèé bí Kọmíṣọ́nnà ìlera Kogi ṣe bù sẹkùn lórí amóhùnmáwòrán
Oríṣun àwòrán, channelstv
Awọn ọmọ Naijiria ti gba oju opo ayelujara lati tun da si ọrọ kan to n ja wititi lọkan awọn eeyan.
Iṣẹlẹ yi ni ṣe pẹlu Kọmisana eto ilera ipinlẹ Kogi to ṣaadede bu sẹkun lasiko to n ṣe ayẹwo bi awọn janduku ṣe ba ẹrọ ayẹwo olowo iyebiye jẹ nile iwosan Kogi.
Fọnran fidio yi to gbode kan loju opo ayelujara ti ileeṣẹ iroyin Channels TV gbe sita ṣafihan Dokita Saka Haruna to bu sẹkun nigba to n ba awọn akọroyin sọrọ.
Ohun ati awọn akẹgbẹ rẹ kan ni wọn kọwọrin ṣayẹwo si ile ikẹru irinṣẹ ilera pamọ si ni Lokoja.
Ninu fọnran ọhun, a ri i bi awọn janduku ṣe ba nkan jẹ lorisirisi.
Ninu ọrọ to sọ lẹyin ti wọn kaakiri wo nkan to bajẹ, arakunrin Saka ni yoo nira fun ipinlẹ Kogi lati pada bọ sipo latari ijamba ti awọn janduku yi ṣe. Lo ba kan sẹkun.
Kete ti fọnran fidio Kọmisana yi lu oju ayelujara lawọn eeyan ti bẹrẹ si ni bu ẹnu atẹ lu u pe ẹkun eke lo n sun.
Oríṣun àwòrán, Sreenshot
Iṣẹlẹ ẹkun sisun tabi wiwu iwa ti yoo mu ki ara ilu kaanu wọn paapa lati ọwọ awọn oloṣelu tabi awọn to dipo mu kii ṣe tuntun ni Naijiria.
Ẹkun sisun Kọmisana yi si ti wa mu kawọn eeyan maa darukọ awọn to jẹ gbajumọ ẹlẹkun ori amohunmaworan mii laipẹ yi bi:
Oríṣun àwòrán, kimbbby1
Kété tí wọ́n bá ti báa yín sùn tàn torí pé ẹ tóbi, ẹ gbà pé ìfẹ́ yẹn ti parí - Auntie Remi Ọlọ́yàn ńlá
Bo tilẹ jẹ wipe a ko le sọ boya lootọ lọrọ dun wọn ti wọn fi bu sẹkun, awọn araalu ko foju rere wo iwa yi.
Lọdọ ọpọ eeyan, oju awada ni wọn fi n wo awọn to ba hu iru iwa yi niwaju kamẹra tabi lasiko ipolongo.
Electricity Tarrif: A kò tíì gbé àwọn oníbàrà wa sórí tàríìfù tuntun - IKEDC
Oríṣun àwòrán, @EKEDP
Ileeṣẹ apinaka ni ipinlẹ Eko, Ikeja Electric Distribution Company, IKEDC, ti sọ pe awọn ko tii bẹrẹ si ni gba idiyele owo ina tuntun lọwọ awọn onibara wọn.
Alukoro ileeṣẹ naa, Felix Ofulue lo kede bẹẹ ninu ofọrọwerọ pẹlu BBC Yoruba.
"O ni ""Niwọn igba ti a ko tii gba aṣẹ lọwọ ajọ to n ṣakoso ileeṣẹ wa, a ko lee bẹrẹ si ni gba owo ina tuntun ọhun lọwọ awọn eeyan."""
"Ofuleue sọ pe iye owo ti awọn eeyan n san lọwọ yii naa ṣi ni iye ti wọn n san tẹlẹ ki wọn to gbe aba idiyele owo tuntun naa jade."""
Ni ti awọn onibara wọn ti iye ina ti wọn n ri gba kò tó ti iye owo ti wọn san, o ni o ṣeṣe ki irufẹ awọn eeyan bẹẹ ti jẹ gbese ina tẹlẹ ki wọn to gba mita ti wọn n lo.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Aadota odun ree ti e ti n paro atunse ise yin fawon omo Naijiria lero awon kan
O ni ileeṣẹ awọn yoo kọkọ yọ iye owo gbese ti irufẹ ẹni bẹẹ jẹ tẹlẹ, ki wọn to fi iye owo to ku fun ni ina.
Ni ti iyatọ to wa ninu idiyele atijọ ati tuntun yii, Ofulue sọ pe awọn eeyan yoo maa san owo ina gẹgẹ bi wọn ṣe n lo ina si.
"Bakan naa lo tu ṣalaye pe wọn pin isọri owo naa si ọna marun un eyii to pe ni ""Band A, B, C, D ati E."""
Ofulue ni awọn to wa ni isọri D ati E ko ni nipin ninu idiyele owo tuntun naa nitori akoko ti wọn fi n ri ina lo ko pọ to ti awọn to wa ni isọri A, B ati C.
Tóo bá pá lórí, Mílíìkì sóyà àtàwọn ǹkan mẹ́ta yìí leè mú irun rẹ hù padà!
Gẹgẹ bo ṣe sọ, iye wakati ti awọn to wa ni isọri D fi n lo ina lojumọ jẹ nnkan bii wakati mẹjọ, nigba ti awọn to wa ni isọri E n lo ina ijọba fun nnkan bii wakati mẹrin din diẹ.
Eyii to n tumọ si pe ninu idiyele tuntun naa, iye akoko ti eeyan fi n lo ina ni yoo ṣe odiwọn bi wọn yoo ṣe maa san owo ina si, eyii ko si ni nkan ṣe pẹlu iye owo ti wọn ra ina ọhun.
Kété tí wọ́n bá ti báa yín sùn tàn torí pé ẹ tóbi, ẹ gbà pé ìfẹ́ yẹn ti parí - Auntie Remi Ọlọ́yàn ńlá
Oyo Politics: Ilé aṣòfin ìpínlẹ̀ Oyo jáwée lọ sinmi nílé fún alága ìgbìmọ̀ mẹ́tàlá káàkiri ìjọba ìpínlẹ̀
Oríṣun àwòrán, Seyi Makinde
Ile igbimọ aṣofin ipinlẹ Oyo ti kede lọjọ Iṣẹgun pe wọn jawe lọ sinmi nile diẹ fun awọn alaga fidihẹ mẹtala lawọn ijọba ibilẹ kaakiri ipinlẹ Oyo.
Idaduro ti ko ni gbedeke yii da lori pe wọn ko tẹle ohun ti ile fẹnuko le lori nipa ipo ti kiko awọn irinṣẹ kọọkan lati sakani wọn pada lọ sile aṣofin.
Awọn ijọba ibilẹ ti igbesẹ yii ta ba ni:
Akinyele East LCDA; Ido LG; Oluyole LG; Ibadan North East LG; Lagelu West LCDA; Soro LCDA ati Ogbomosho Central LCDA.
Awọn to tun kan ni:
Ogbomosho South LCDA; Ajorosun LCDA; Ibarapa North West LCDA; Itesiwaju LG; Oyo East LG ati Oyo South East LCDA.
Ileeṣẹ ọlọpaa ipinlẹ Oyo ti  fi panpẹ wọn mu eeyan mẹta lara awọn ti wọn furasi pe wọn lọwọ ninu ijinigbe alaga kansu kan ṇi ipinlẹ Oyo.
Gomina ipinlẹ Oyo, Seyi Makinde lo fi eyi hande nigba to n ba awọn lọga lọga lẹnu iṣẹ ọlọpaa sọrọ ni olu ileeṣẹ wọn to wa ni Eleyele, Ibadan lọjọ Aje.
Oríṣun àwòrán, @Newsweek
Bo tilẹ jẹ pe awọn ọlọpaa o tii fi ẹkunrẹrẹ sita lori bi  ọwọ ṣe tẹ̀ wọn, Gomina Seyi Makinde gboriyin fun awọn ọlọpaa fun iṣẹ takuntakun ti wọn ṣe.
Bi ẹ ko ba gbagbe, wọn kede iroyin ijinigbe alaga kansu Iganna nipinlẹ Oyo, ọgbẹni Jacob Adeleke ni ọjọ kẹrindinlọgbọn oṣu kẹwaa.
Atoun ati dẹrẹba rẹ ni wọn jigbe nirọlẹ ọjọ Aiku loju ọna Iseyin-Ado nigba ti wọn n lọ si Ibadan fun ipade kan pẹlu Gomina Seyi Makinde lowurọ ọjọ Aje.
EndSars, EndSwat Protest: Òbí agbábọ̀ọ̀lù Gbenga Tiamiyu Kaka àtàwọn míì tí ọlapàá pa sọ̀r
Ẹwẹ, ikede jade pe wọn ti gba itusilẹ lọjọ Ẹti, ọgbọnjọ Oṣu kẹwaa.
Ko si aridaju boya wọn san owo itanran kankan lati mu ki itusilẹ wọn ya kiakia.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Kini o kọkọ ṣẹlẹ lẹyin ti wọn ji alaga kansu gbe tẹlẹ?
Ẹ wo bí orílẹ̀èdè Amẹrika ṣe dóòlà ẹ̀mí ọmọ ilẹ̀ wọn tí wọ́n jígbé ní Naijiria
US Citizen Rescue: Ẹ wo bí orílẹ̀èdè Amẹrika ṣe dóòlà ẹ̀mí ọmọ ilẹ̀ wọn tí wọ́n jígbé ní Naijiria
Ọ̀sẹ yii ni wọn ji arakunrin Philip Walton gbe ni iha ariwa orilẹede Naijiria.
Ikọ ọmoogun orilede Amẹrika ti doola ẹmi ọmọ orilede wọn ti wọn jigbe ni iha ẹkun ariwa orilẹede Naijiria.
Gẹgẹ bi atẹjade ti awọn alaṣẹ orilẹede Amerika fi lede, arakunrin ti wọn jigbe naa, ti orukọ rẹ n jẹ Philip Walton lo n ṣiṣẹ agbẹ lorilede Naijiria.
Awọn alaṣẹ naa ni awọn ajinigbe naa ko ṣiṣẹ fun ẹgbẹ agbesunmọmi kankan, amọn awọn agbebọn ti wọn n wa owo ni.
Ọjọ Iṣẹgun, Ọjọ Kẹtadinlọgbọn ni wọn ji arakunrin Walton gbe ninu ile rẹ ti ko jina si ibode Niger.
Orilẹede Amerika naa ni awọn ko ni kuna lati ma a da abo bo awọn ọmọ orilẹede wọn kaakiri ibi ti wọn ba wa ni agbaye.
Bakan naa ni wọn dupẹ lọwọ ijọba orilẹede Naijiria fun ifọwọsowọpọ wọn to jẹ ki idoola ẹmi naa ṣeeṣe.
Ileeṣẹ ọlọpaa ipinlẹ Ọyọ ti fidi rẹ mulẹ pe alaga fidihẹ ijọba ibilẹ Iganna, Jacob Adeleke ati awakọ rẹ ti gba ominira lọwọ awọn ajinigbe.
Wọn ji awọn eeyan naa gbe nigba ti wọn n rinrin ajo lọna to wọ ilu Ibadan ni nnkan  bi ọjọ mẹfa sẹyin.
Oríṣun àwòrán, @PulseNigeria247
Ṣaaju ni awọn oṣiṣẹ ileeṣẹ ọlọpaa pẹlu ifọwọsowọpọ awọn ọmọ ẹgbe Vigilante Group of Nigeria ti n wa inu igbo ti wọn fura si pe awọn ajigbe ọhun ti n ṣọṣẹ.
Alukooro ileeṣẹ ọlọpaa ipinlẹ Oyo, Olugbenga Fadeyi sọ fun awọn akọroyin pe,l lootọ nio ọkunrin naa ti gba ominira, o si ti darapọ mọ awọn ẹbi  rẹ.
Oríṣun àwòrán, @Newsweek
Wọn ji alaga ọhun ati awakọ rẹ gbe ni opopona Okeho-Ado Awaye, iyẹ ni ipinlẹ Oyo lasiko to n mura lati ṣe ipade pẹlu gomina Seyi Makinde.
Tóo bá pá lórí, Mílíìkì sóyà àtàwọn ǹkan mẹ́ta yìí leè mú irun rẹ hù padà!
Iroyin ni awọn ajinigbe naa bere pe awọn yoo gba owo ti iye rẹ to igba miliọnu naira ki wọn to tu awọn eeyan naa silẹ.
Bo tilẹ jẹ pe awọn mejeji ti gba ominira bayii, a ko lee fidi rẹ mulẹ boya alaga naa tabi awọn ẹbi rẹ san owo ọhun ki wọn to gba ominira.
Idanre Kingship tussle:Adelé Ọba Idanre ní Ọba Aroloye wà lórí ìtẹ́ nígbà tí àwọn jàndùkú lù ú
Idanre Kinship: Owa Idanre o rán ẹnikẹ́ni si Temilolu, awọn ọ̀dọ́ ìlú ló ń  bínú
Adele Ọba Alade Idanre, Temilolu Akinboola ti ṣalaye fun BBC bi awọn janduku kan ṣe ya bo aafin rẹ ti wọn si lu u ni ilu bara.
Temilolu sọ pe inu ile igbọnsẹ ni oun farapamọ si lọjọ naa ki awọn janduku ọhun to fi tipatikuku wọ oun jade lọ si aafin Owa ilu Idanre, Ọba Frederick Aroloye.
Oríṣun àwòrán, Temilolu Akinboola
O ni wahala bẹrẹ lẹyin ti wọn fi oun jẹ Adele Ọba tan, ti wọn si ti ọja ilu Alade.
"Gẹgẹ bo ṣe sọ, o ni ""Mo gburo ọkada ti wọn pọ rẹrẹ, ti wọn n pariwo, ti wọn si n kọ orin bi ẹni to n lọ soju ogun, bẹẹ naa ni wọn n pariwo Adele da, Adele da!?"
"O ni "" Wọn gba mi loju, wọn lu mi, wọn si fi aṣọ mi wọ mi sita."""
Temilolu sọ pe awọn janduku naa kọlu awọn oloye oun mẹta, bẹẹ ni wọn kan apa ọkan lara wọn.
Oríṣun àwòrán, Temilolu Akinboola
Adele naa sọ pe Ọba Aroloye wa lori itẹ nigba ti awọn janduku naa n na oun ninu aafin rẹ.
O pari ọrọ rẹ pe eredi gbogbo rogbodiyan naa ko ṣẹyin bi wọn ṣe fi oun jẹ oye Adele, eyii ti Owa ilu Idanre sọ pe o lodi si aṣa ilu naa.
Oríṣun àwòrán, Temilolu Akinboola
Gbogbo akitiyan lati kan si Ọba Frederick Aroloye lati sọ bi ọrọ naa ṣe jẹ lo ja si pabo.
Oríṣun àwòrán, Temilolu Akinboola
Ẹwẹ, ninu atẹjade kan to fi lede, o ni irọ pọnbele ni gbogbo ohun ti Adele sọ, nitori oun ko ran janduku kankan lati fi iya jẹ.
Ṣugbọn Aroloye sọ pe o lodi si iṣẹṣe ilu Idanre ki obinrin jẹ Adele Ọba.
Gbogbo igbiyanju BBC lati ri Owa ba sọrọ jasi pabo titi di asiko yii
John Amanam: Ìfẹ́ tí mo ní sí àbúrò mi ló sọ mi dí ẹni tó ń ṣe 'Prosthetic' báyìí
Ki lo ti ṣẹlẹ sẹyin?
Oríṣun àwòrán, @HighTableAfrica
Rogbodiyan bẹ silẹ ni ilu Alade Idanre, iyẹn ni ipinlẹ Ondo lori ẹni to yẹ ko gori itẹ Ọba Olusegun Akinbola to di oloogbe lọjọ kẹrindinlogun,oṣu Kẹwaa, ọdun 2020.
Lẹyin ọjọ meji ti Ọba naa waja ni wọn fi akọbi ọmọ rẹ obinrin, Temilolu Akinboola, sori oye gẹgẹ Adele, ṣugbọn o da bii pe igbesẹ yii ko dun mọ awọn kan ninu.
Iroyin ni lẹyin ọjọ karun un ti wọn fi Temilolu jẹ adele ni awọn janduku kọlu afin rẹ ti wọn si luu ni ilu bara toun ti iya rẹ.
Ninu iwe ẹbẹ kan to kọ si kọmisọnna ọlọpaa ipinlẹ Ondo, adele Ọba ọhun ṣalaye ohun ti oju rẹ ri lọwọ awọn janduku to kọlu afin naa.
Oríṣun àwòrán, The Cable
Lara awọn ọkọ ti wọn sọ pe awọn janduku bajẹ ni afin na
"O ni awọn tọọgi ọhun ""ti iye wọn to ogun ya bo afin oun lori ọkada pẹlu ibọn, ada, kondo atawọn ohun ija oloro miran"" lati ṣakọlu si afin naa."
Temilolu fẹsun kan Owa ti ilu Idanre, Frederick Aroloye, pe oun lo ran awọn janduku naa lati ṣakọlu si oun.
Bakan naa lo sọ pe awọn janduku ọhun ba gbogbo ọkọ to wa ninu afin naa jẹ, bẹẹ ni wọn tun ko awọn ohun ini oun bii ounjẹ, ọti ẹlẹrindodo, aṣọ olowo iyebiye, ohun ẹṣọ ara, ẹrọ kọmputa alagbeka ati owo lọ.
Adele naa fi kun un pe awọn janduku ọhun fi agidi gbe oun lọ si afin Aroloye nibi ti wọn ti fi ija jẹ oun niwaju rẹ.
Temilolu sọ pe awọn tọọgi naa fi iya jẹ oun atawọn eeyan miran to wa ni afin lọjọ naa ki wọn to gbe oun sori ọkada lọ afin Aroloye.
Tóo bá pá lórí, Mílíìkì sóyà àtàwọn ǹkan mẹ́ta yìí leè mú irun rẹ hù padà!
O ni Owa ti ilu Idanre joko sori itẹ rẹ to si n wo bi awọn janduku naa ṣe n na oun ni ilu bara.
Ẹwẹ, ninu atẹjade kan ti Aroloye fi lede, o ni irọ pọnbele ni gbogbo ohun ti Adele ọhun sọ, nitori oun ko ran janduku kankan lati fi iya jẹ.
Ṣugbọn Aroloye sọ pe lodi si iṣẹṣe ilu Idanre ki obinrin jẹ Adele Ọba.
AFCON Qualifier: Kò séwu fún gbogbo àwọn tí yóò kópa nínú ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ Naijiria àti Sierra Leone ní Benin - Obaseki
Oríṣun àwòrán, @daily_trust
Gomina ipinlẹ Edo, Godwin Obaseki ti sọ pe abo to peye yoo wa fun gbogbo awọn agbabọọlu atawọn ero iworan ti yoo wa nibi ifẹṣewọn laarin ikọ Super Eagles ati Leone Stars ti orilẹ-ede Sierra Leone lọsẹ to n bọ.
Ifẹsẹwọnsẹ naa to jẹ igabradi idije ife ẹyẹ ilẹ Afrika, AFCON, ti yoo waye lọdun 2021 ni yoo waye ni papa iṣẹre Samuel Ogbemudia ni ilu Benin.
Bakan naa ni ifẹsẹwọnjsẹ to lamilaaka akọkọ ti yoo waye ni papa iṣẹre naa lati igba ti wọn ti ṣatunṣe rẹ.
O tun jẹ ifẹsẹwọnsẹ to lamilaaka ti ikọ Super Eagles yoo gba lati igba ti ajakalẹ arun Coronavirus ti bẹrẹ.
Oríṣun àwòrán, @NGSuperEagles
Ifẹsẹwọnsẹ naa yoo waye lọjọ kẹtala, oṣu kọkanla, ọdun 2020, lẹyin ọjọ ti iburawọle gomina Obaseki fun saa keji gẹgẹ bii gomina.
Olubadamọran pataki fun gomina ọhun lori ọrọ to n lọ, Crusoe Osagie sọ pe ijọba ipinlẹ naa ti ṣetan lati dabo bo gbogbo eeyan ti yoo peju sibi ifẹsẹwọnsẹ ọhun.
"Gẹgẹ bo ṣe sọ, o ni ""idunnu wa ni lati ṣagbatẹru igbaradi idije AFCON 2021 laarin ikọ Super Eagles ati Leone Stars ni papa iṣẹre Ogbemudia."""
John Amanam: Ìfẹ́ tí mo ní sí àbúrò mi ló sọ mi dí ẹni tó ń ṣe 'Prosthetic' báyìí
Idanre kings: Ọba Aroloye ko rán ẹnikẹ́ni si Temilolu, awọn ọ̀dọ́ ìlú ló ń bínú
Laipẹ yii ni Adele Ọba Alaade ilu kan labẹ ilu Idanre, Temilolu Akinboola ṣalaye fun BBC, bi awọn janduku kan ṣe ya bo aafin rẹ ti wọn si lu u ni ilu bara.
Temilolu sọ pe, inu ile igbọnsẹ ni oun farapamọ si lọjọ naa ki awọn janduku ọhun to fi tipatikuku wọ oun jade lọ si aafin Owa ilu Idanre, Ọba Frederick Aroloye.
Oríṣun àwòrán, Temilolu
O ni wahala bẹrẹ lẹyin ti wọn fi oun jẹ Adele Ọba ti ó jẹ́ bàbá òun tan, ti wọn si ti ọja ilu Alaade gẹgẹ bi aṣa ati iṣẹṣe ilu naa ati awọn ilẹ Yoruba miran ti ọba ba wọ aja.
"Gẹgẹ bo ṣe sọ, o ni ""Mo gburo ọkada ti wọn pọ rẹrẹ, ti wọn n pariwo, ti wọn si n kọ orin bi ẹni to n lọ soju ogun, bẹẹ naa ni wọn n pariwo Adele da, Adele da!?."
Ọmọọba Temilolu salaye pe, lẹyin naa ni wọn gbe oun lọ si aafin Ọwa Idanre, ọba Frederick Aroloye to jẹ alakoso awọn ilu mẹta to wa labẹ rẹ.
Amọ awọn ọdọ ilu Idanre naa ti fesi lori isẹlẹ pe Owa Idanre o rán ẹnikẹ́ni si Temilolu.
Oríṣun àwòrán, Temilolu
Sùgbọn ọtọ lọrọ ṣe lasiko ti agbẹnusọ kabiyesi ti ilu Owa Idanre, ọgbẹni Kehinde Olarewaju Adesiyan salaye pe, kìí ṣe Owa Idanre lo ran awọn eniyan si ọmọọba Temilolu.
O ni bi Adele se ti ọja pa pe wọn fẹ se idaro baba rẹ to waja, ló bi awọn ọdọ ninu.
Ọgbẹni Adesiyan ni aṣa ati iṣẹṣe ko ye ọmọọba naa nitori lati ilẹ ni gbogbo eniyan ti mọ pe, Idanre ati awọn ilu to wa labẹ rẹ kii fi obinrin jẹ Adele bi ko se Lisa to dabi asoju ọba lo maa n ṣe Adele.
O fi kun pe irọ patapata ni pe wọn lu ọmọọba naa nitori gbogbo fọto to wa ni ikawọ aafin fi han pe, ko si ẹni to luu.
Oríṣun àwòrán, Owa Idanre Palace
Oríṣun àwòrán, Idanre palace
Rivers Police:wọ́ ọlọ́pàá ti tẹ àwọn afurasí tó lọ gbin ǹkan abúgbàmù sí ṣọ́ọ̀ṣì bàbá gómìnà Wike
Ijọba ipinlẹ Rivers ti fi panpẹ ofin mu eeyan meji kan toripe wọn lọ gbe nkan oloro abugbamu si ijọ baba gomina ipinlẹ naa, Nyesome Wike iyẹn Christian Church International.
Ijọ naa wa ni agbegbe Azikiwe, opopona Mile 2 Diobu niluu Port Harcourt.
Nigba ti ile iṣẹ iroyin BBC ṣebẹwo si agbegbe naa, ikọ ọlọpaa to nimọ nipa ado oloro yẹ ayika ṣọọṣi naa wo bẹẹ si ni awọn ẹṣọ alaabo wa nibẹ wamuwamu.
Ọkùnrin tó fẹ́ fipábámilòpọ̀ fín ǹkan sí mi lójú ló ṣe rọ́nà wọlé sí mi lára
Gẹg bi iroyin to tẹ wa lọwọ, iṣẹlẹ naa waye lalẹ ọjọ Abamẹta, ṣe ni awọn ọmọ ijọ sa asala fun ẹmi wọn ti ẹnikẹni ko si farapa.
Awọn ọdọ adugbo naa lo wa gba ọdọ meji, afurasi ti wọn ni gbe ohun abugbamu naa kalẹ ki awọn ọlọpaa to de.
Nibayii, ikọ alaabo ti gba gbogbo agbegbe naa kan ti wọn ko si fun eeyan tabi ọkọ kankan laye lati gba ibi ti nkan ti ṣẹlẹ yii kọja.
Wọ́n rò pé mo ya wèrè ni Saudi lẹ́yìn ikú ọkọ mi
Oríṣun àwòrán, @Wike
Gomina Nyesom Wike sọ pé òun kọ́ ló rán àwọn sọ́jà láti má a pàáyàn ni Oyigbo
Gomina ipinlẹ Rivers, Nyesom Wike, sọ pe oun kọ lo ran awọn sọja láti lọ paayan ni Oyigbo.
Lori amohunmaworan ileesẹ kan l'abẹle, lo ti sọ bẹ ẹ, nitori bi iroyin ṣe n lọ kaakiri pe awọn sọja n pa araalu nijọba ibilẹ Oyigbo, ti gomina kede àṣẹ konile-o-gbele fun, lati ọjọ mejila sẹyin.
Ikede naa waye lẹyin ti àwọn afurasi ọmọ ẹgbẹ to n polongo fun idasilẹ orilẹ-ede Biafra, IPOB, já iwọde EndSars gba, eyi to yọri si iku sọja mẹfa, ati ọlọpaa mẹta.
Koda, wọn dana sun agọ ọlọpaa mẹta ni agbegbe naa.
Saaju ni Wike ti buwọlu àṣẹ kan, to fi fofin de ẹgbẹ IPOB nipinlẹ Rivers, to si pasẹ fun awọn alaga ijọba ibilẹ, ati awọn oṣiṣẹ eleto aabo lati wa gbogbo ọmọ ẹgbẹ IPOB nipinlẹ naa jade, lati fi oju wina ofin nile ẹjọ.
Akomolede àti Asa lórí BBC Yorùbá: Mọ̀ síi nípa ẹ̀kún ìyàwó níbí
Gomina Wike ni nkan ti oun sọ ni pe ki awọn eleto aabo ri i daju pe wọn fidi ofin to de IPOB mulẹ, ati lati ri i pe ko si ikorajọpọ awọn ọmọ ẹgbẹ naa ni gbogbo ijọba ibilẹ to wa nipinlẹ Rivers.
Wike sọ pe o rọrun fun wọn lati fi Oyigbo boju ṣe ikọlu, nitori pe o sunmọ ipinlẹ Abia.
"Isọkusọ ni bi awọn eeyan ṣe n sọ pe mo ran awọn sọja jade lati pa awọn eeyan ẹ̀yà Igbo.
Ṣe emi ti mi o l'agbara lati pasẹ fun ọlọpaa, ni ma a pasẹ fun sọja?
Bakan naa ni ileesẹ ologun ti ṣẹ́ lori iroyin to sọ pe awọn sọja n lọ lati ojule si ojule, lati pa eeyan.
Agbenusọ fun ìpín Kẹfa ileesẹ ologun to wa nilu Port Harcourt, Ọgagun Charles Ekeocha, sọ fun ileesẹ Radio Nigeria pe lootọ ni oun mọ pe awọn ni àkànṣe isẹ ni Oyigbo, sugbọn irọ ni pe awọn kọlu awọn
eeyan.
O ni Ko ṣe e ṣe fun wa lati deede kọlu awọn eeyan. Nigba ti ẹ ba de ibẹ lẹ o mọ boya irọ tabi òótọ́ ni iroyin tẹ n gbọ nita"""
EndSars, EndSwat Protest: Òbí agbábọ̀ọ̀lù Gbenga Tiamiyu Kaka àtàwọn míì tí ọlapàá pa sọ̀r
Sugbọn awọn eeyan kan to n gbe ni Oyigbo ti sa kuro nibẹ, nitori ibẹru pe ewu wa fun ẹ̀mí awọn, ati nitori isede ti ko jẹ ki wọn o raaye jade ṣe ohunkohun lati ọsẹ kan sẹyin.
Monday Bakor, to n gbe ni Oyigbo, sọ fun BBC Pidgin pe ọwọ rẹ ni iyawo afẹsọna rẹ, Queen Nwazuo kú si, lẹyin ti ọta ìbọn fọ́ ilẹkun irin to wa lẹnu ọna sọọbu wọn, ti wọn ti pa mọ ara wọn nitori bi ìbọn ṣe n
dun.
O sọ pe oju ẹsẹ lo ku.
Ẹlòmíì, Bani Jackreece sọ pe ni nkan bi aago mẹrin idaji ni oun raaye salọ lọjọ Aiku, ọjọ kinni, oṣu Kọkanla, nitori ibẹru ẹ̀mí oun, ati bi oun ko ṣe raaye ra oúnjẹ tabi gba owo ni banki.
Ọpọlọpọ awọn ẹgbẹ lo si ti kesi ipinlẹ Rivers, lati fi opin si isede ni Oyigbo, ki awọn eeyan le jade ra oúnjẹ.
Ìbẹ̀rù-bojo gbalẹ̀ ní Oyigbo lẹ́yìn tí ọlọ́páà mẹ́ta àti sọ́jà kú nínú rògbòdìyàn EndSARS
Ìbẹ̀rù-bojo gbalẹ̀ ní Oyigbo lẹ́yìn tí ọlọ́páà àti sọ́jà kú nínú rògbòdìyàn EndSARS
Ninu ibẹru lawọn eeyan to n gbe ni ijọba ibilẹ Oyigbo nipinlẹ Rivers atawọn olokowo nibẹ wa bayii lẹyin eto aabo to mẹhẹ nibẹ.
Lọjọ kọkanlelogun oṣu kẹwaa to lọ yii ni ijọba ipinlẹ kede ofin konle o gbele nijọba ibilẹ Oyigbo atawọn ibomiiran niluu Port Harcourt lẹyin tawọn afurasi ọmọ ẹgbẹ IPOB da rogbodiyan silẹ nibi iwọde EndSARS.
Agọ ọlọpaa meta ni wọn dana sun, koda awọn janduku ọhun tun sọ ina si ileẹjọ to wa ni Oyigbo.
Ọlọpaa mẹta atawọn sọja ṣagbako iku ninu rogbodiyan naa.
Gomina ipinlẹ Rivers, Nysome Wike wọgile ofin isede lawọn agbegbe kan niluu Port Harcourt lọjọ kejidinlọgbọn oṣu kẹwaa ṣugbọn eyi ko kan ijọba ibilẹ Oyigbo.
John Amanam: Ìfẹ́ tí mo ní sí àbúrò mi ló sọ mi dí ẹni tó ń ṣe 'Prosthetic' báyìí
Ṣugbọn lati Ọjọru ọsẹ to lọ ni ọpọ araalu ti n kuro ni Oyigbo lẹyin tawọn agbofinro bẹrẹ si ni kaakiri lati rii pe ofin konle-o-gbele to wa lode mulẹ.
Charles Akah to n gbe ni Oyigbo sọ pe inu ile loun wa lati ọjọ kọkanlelogun oṣu kẹwaa ti ijọba ti kede ofin konle-o-gbele nipinlẹ Rivers.
O ṣalaye pe awọn n sọja n mu awọn ọdọ kaakiri, eyi lo jẹ ki ọpọ maa bẹru lati jade nile.
''A o le lọ gbowo nita tabi ra ohun kankan, a n bẹ ijọba pe ki o wa nkan ṣe si ọrọ yii,'' Akah lo sọ bẹẹ.
Bani Jackreece ti oun naa n gbe lagbegbe Oyigbo sọ fun BBC pe laago mẹrin idaji loun sa kuro nile nitori ẹru n ba oun lori eto aabo to mẹhẹ nibẹ.
Amọ alukoro ileeṣẹ ọlọpaa ipinlẹ Rivers, Nnamdi Omoni sọ fun BBC pe oun ko gbọ pe awọn agbofinro n mu awọn eeyan kan ni Oyigbo.
Omoni ṣalaye pe awọn agbofinro to n wọde ni ijọba ibilẹ naa lo jẹ ki alaafia maa jọba diẹdiẹ nibẹ bayii.
Akitiyan lati gbọrọ lẹnu Ọgagun agba Charles Ekeocha to jẹ olori  ileeṣẹ olọgun 6 Division Nigerian Army ni Port Harcourt lori ẹsun pe awọn sọja n mu awọn araalu ni Oyigbo ja si pabo.
WAEC 2020 result checker: Wo nkan tí yóò ṣẹlẹ̀ sí àwọn akẹ́kọ̀ọ́ tí àjọ WAEC gbẹ́sẹ̀ lé èsì ìdánwò wọn
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Miliọnu kan abọ awọn akẹkọọ to pegede ninu idanwo naa
Wo nkan tí yóò ṣẹlẹ̀ sí akẹ́kọ̀ọ́ tí àjọ WAEC gbẹ́sẹ̀ lé èsì ìdánwò wọn.
Ajọ to n mojuto idanwo asejade nileewe girama, WAEC gbẹsẹ le awọn esi idanwo àwọn akẹkọọ kan.
Ajọ to n ṣeto idanwo WAEC sọ pe esi idanwo akẹkọọ to le ni ẹgbẹrun lọna igba (215, 149) to ṣe idanwo ọdun 2020, ni oun gbẹsẹ le.
Ìdá 13.98% awọn to ṣe idanwo ni ọrọ yii kan.
Patrick Areghan to jẹ oludari ajọ naa ni Naijiria sọ ninu atẹjade kan pe igbesẹ naa waye nitori pe awọn fura pe awọn akẹkọọ náà ṣe mago-mago lasiko idanwo.
Agbenusọ fun ajọ WAEC, Demianus Ojieogu sọ fun BBC Pidgin pe awọn akẹkọọ ti ọrọ kan ko ti i le ṣe nkankan, nitori pe awọn ṣi n ṣe iwadii lati mọ boya lootọ ni wọn ṣe mago-mago lasiko idanwo.
Igbimọ oluwadii ni yoo sọ boya wọn o gbẹsẹ le esi akẹkọọ to ṣe mago-mago, tabi wọn yoo gbe esi awọn ti ko jẹbi jade.
Akomolede àti Asa lórí BBC Yorùbá: Mọ̀ síi nípa ẹ̀kún ìyàwó níbí
Ẹni ti wọn ba gbẹsẹ le esi idanwo rẹ yoo tun IDANWO WAEC ṣe ni, sugbọn lẹyin ọdun meji.
Ọdun meji ni ajọ WAEC yoo fi fi ofin de wọn, gẹgẹ bi ibawi fun ṣíṣe mago-mago lasiko idanwo.
Yatọ si eyi, akẹkọọ 81,718 ni wọn ko ti i gbe esi idanwo wọn jade, nitori pe àṣìṣe wa lori rẹ. Ni kete ti ajọ naa ba ti pari atunse lori wọn, ni awọn akẹkọọ naa yoo ni anfaani si i.
Oríṣun àwòrán, @Omojuwa
Ajọ WAEC gbé èsì ìdánwò ọdun 2020 jáde
Ajọ WAEC to n ṣe akoso idanwo ile iwe girama ni apa iwọ oorun ilẹ Afirika ti gbe esi idanwo awọn akẹkọọ oniwe mẹwaa ọdun 2020 yii jade.
Oludari ofiisi ajọ naa ni Naijiria, Ọgbẹni Patrick Areghan lo fi ikede naa soju opo Twitter ajọ WAEC.
Ninu awọn akẹkọọ 1,549,740 to ṣe idanwo naa, awọn 1,338, 348 lo pegede ninu iṣẹ marun un ninu mẹsan an ti wọn ṣe eyi to jẹ ida mẹrindinlaadọrun un ninu ida ọgọrun un to ṣe idanwo naa.
Ṣugbọn awọn akẹkọọ 1,003, 668 lo pegede ninu iṣẹ marun un to fi mọ ede Gẹẹsi(English Language) ati Iṣiro(Mathematics).
Ajọ WAEC ni esi idanwo naa ko ba ti jade tẹlẹ ṣugbọn rogbodiyan to ṣẹlẹ lẹyin ifẹhonuhan #EndSARS lo ṣe idiwọ.
Ajọ WAEC ni awọn ọfiisi ohun kan naa faragba ninu iṣẹlẹ lasiko rogbodiyan #EndSARS to ṣẹlẹ lorilẹede Naijiria.
Laarin ọjọ kẹtadinlogun, oṣu kẹjọ,  ọdun 2020 lawọn akẹkọọ ṣe idanwo naa eleyi to yẹ ki esi rẹ jade lọjọ ketadinlọgbọn, oṣu kẹwaa tii ṣe ọjọ marundinlaadọta ti wọn ṣe idanwo ọhun.
EndSars, EndSwat Protest: Òbí agbábọ̀ọ̀lù Gbenga Tiamiyu Kaka àtàwọn míì tí ọlapàá pa sọ̀r
Bayii ni o ṣe le wo esi idanwo WAEC rẹ
Alukoro ajọ WAEC, Demianus Ojijeogu tun ṣalaye pe awọn akẹkọọ le ri esi idanwo wọn ninu atẹjiṣẹ ori foonu.
Bayii ni o ṣe le wo esi idanwo rẹ lori foonu
Awọn nọmba kan wa ti o nilo lati fi wo esi idanwo rẹ.
Ohun ti wa fi ranṣẹ si ''32327'' ni ''WAEC*ExamNo*PIN*ExamYear.''
John Amanam: Ìfẹ́ tí mo ní sí àbúrò mi ló sọ mi dí ẹni tó ń ṣe 'Prosthetic' báyìí
Electricity new tariff: ''Àjọ NERC ti fún Disco láṣẹ láti padà sí owó tàríìfù tuntun iná mọ̀nàmọ́ná''
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Aadota odun ree ti e ti n paro atunse ise yin fawon omo Naijiria lero awon kan
Otitọ ni wi pe ileeṣẹ ina mọnamọna Disco ti pada si owo ina tuntun ti wọn ni ki awọn araalu maa san.
Ọkan lara awọn oṣiṣẹ ileeṣẹ Disco Ikeja ti ko fẹ ki BBC darukọ rẹ lo fidi ọrọ yii mulẹ fun BBC Yoruba.
O ṣalaye pe ọjọ kinni oṣu kọkanla ọdun 2020 yii ni ajọ to n ṣakoso awọn ileeṣẹ mọnamọna, NERC ti fawọn laṣẹ lati pada si owo in a tuntun.
Ṣugbọn ohun to jẹ iyalẹnu ni pe ọpọ awọn onibara lo ti n kọminu pe lati inu oṣu kẹwaa ni ileeṣẹ Disco ti bẹrẹ si fawọn onibara wọn ni ni biili tuntun.
Nigba ti a beere bo ya ijọba apapọ mọ si bi wọn ṣe bẹrẹ si gba tariifu tuntun, oṣiṣẹ Disco naa sọ pe ajọ NERC nikan lo le dahun ibeere yii.
O ni ọpọ araalu ni wọn n dibọn pe awọn ko mọ nitori wọn ko faramọ igbesẹ Disco lori ọrọ tariifu ina tuntun.
Oríṣun àwòrán, others
''Gbogbo awọn onibara wa lo n sọ kaakiri pe ọfẹ ni ijọba n gbe mita ina mọnmọna fawọn eeyan, ṣugbọn niṣe ni wọn dakẹ lori ọrọ tariifu tuntun,'' oṣiṣẹ Disco lo sọ bẹẹ.
Ẹwẹ, ajọ ajafeto-ọmọniyan kan ni Naijiria, SERAP ati awọn eeyan mejilelọọdunrun mii, ti pe aarẹ Buhari ati ile aṣofin lẹjọ tẹlẹ lori afikun owo epo bentiroo ati owó ina ọba.
EndSars, EndSwat Protest: Òbí agbábọ̀ọ̀lù Gbenga Tiamiyu Kaka àtàwọn míì tí ọlapàá pa sọ̀r
"SERAP ati awọn ti wọn dijọ pe ẹjọ yii ni awọn fẹ ki ile ẹjọ ""f'ọwọ rọ afikun owo epo ati ina ọba sẹyin."
"Alaye wọn ni pe awọn eeyan to dipo nla mu ninu ijọba ko le maa gbadun, ki wọn wà ni k'ara ilu maa ṣe ifarada."""
Ninu awọn ti wọn pe lẹjọ yii la ti ri igbakeji aarẹ, Yemi Osinbajo, aarẹ ile aṣofin agba Ahmad Lawan, Olori ile aṣoju-ṣofin, Femi Gbajabiamila ati awọn mii.
John Amanam: Ìfẹ́ tí mo ní sí àbúrò mi ló sọ mi dí ẹni tó ń ṣe 'Prosthetic' báyìí
EFCC: Ìwádìí lórí ẹ̀sùn ìwà jẹgúdújẹrá tí wọ́n fi kan Babatunde Fowler tó jẹ́ àdàrí iléeṣẹ́ FIRS tẹ́lẹ̀
Oríṣun àwòrán, Google
Ileeṣẹ to n gbọ ẹsun iwa ibajẹ, EFCC ti bẹrẹ si ni fi ọrọ wa Ọga Ajọ to n risi owo ori labẹle lorilẹede Naijiria, Babatunde Fowler lẹnu wo.
Agbẹnusọ fun Ajọ EFCC, Wilson Uwujaren lo fi idi ọrọ naa mulẹ pe Fowler wa ni ileeṣẹ wọn lọwọlọwọ nibi ti wọn ti n fi ọrọ wa lẹnu wo.
EndSars, EndSwat Protest: Òbí agbábọ̀ọ̀lù Gbenga Tiamiyu Kaka àtàwọn míì tí ọlapàá pa sọ̀r
Ajọ EFCC fi iwe pe arakunrin Fowler to tun jẹ adari ajọ to n risi ọrọ owo ori labẹle nipinlẹ Eko, ti oun naa si jẹ ipe wọn ni Ọjọ Aje.
Amọ, Ajọ EFCC naa ko sọ iru iwadii ti wọn n ṣe, ti wọn fi fi iwe pe e.
John Amanam: Ìfẹ́ tí mo ní sí àbúrò mi ló sọ mi dí ẹni tó ń ṣe 'Prosthetic' báyìí
Ibadan: Oluwapọ̀nmile sọ ìrírí rẹ̀ lọ́wọ́ àwọn sójà tó fìyàjẹ́ ní Ibadan
Oluwapọ̀nmile sọ ìrírí rẹ̀ lọ́wọ́ àwọn sójà tó fìyàjẹ́ ní Ibadan
"Arakunrin Ẹmiọla David Oluwapọnmile ṣe alabapade ikọ ologun ""Operation Burst"" ni agbegbe Bẹẹrẹ nilu Ibadan ti wọn si fi abẹ ṣekele fa irun ori rẹ."
Iredi ti ikọ naa fi ṣe bẹẹ ni ko si han si ẹnikẹni titi di asiko yii.
Oniṣowo ni Ẹmiọla, bakan naa lo si jẹ agbẹ ọlọsin adiyẹ.
"Ninu ọrọ ti o ba BBC Yoruba sọ, o ni ile ijọsin ni oun ti n bọ l'ọjọ aiku ti oun si pada ikọ ologun ""Operation Burst"" ni agbegbe Bẹẹrẹ nilu Ibadan."
O tẹsiwaju pe oun ti fẹ gun ọkada ki ọkan ninu awọn ikọ naa to ke si oun wi pe oun ni ẹjọ lati jẹ.
Ẹmiọla kọkọ fẹ ṣe agidi ṣugbọn ibọn ti awọn ikọ naa gbe lọwọ ko ṣee yaju si.
Nigba ti yoo fi de ọdọ ẹni to pee, ẹsun ti wọn fi kan an ni pe irun to gbe si ori ti kun ju.
"Ere ni, awada ni, Ẹmiọla ṣe alaye wi pe ọrọ to jade lẹnu awọn ikọ ologun naa ni pe, ""Kaabọ si ibi ti a ti n fa ori fun awọn ọmọ alaigbọran""."
Lẹyin-ọrẹyin wọn fi abẹ ṣekele ṣe irun rẹ baṣabaṣa wọn si tun fi ipa gba ẹẹdẹgbẹta naira lọwọ rẹ gẹgẹ bi i owo irun ti wọn baa fa.
Ẹmiọla fi kun ọrọ rẹ pe oun tun ba awọn ẹlomii ni akata awọn ikọ ologun yii ti oun si tun ni lati san owo irun wọn naa pẹlu nitori wọn ti lu wọn gẹgẹ bi i ejo aijẹ nitori airi owo san.
Alaye mii ti Ẹmiọla ṣe fun BBC Yoruba ni pe awọn ikọ yii tun lu obinrin ni agbegbe Ogunpa nilu Ibadan nitori pe aṣọ to wọ ko tẹ wọn lọrun.
Oríṣun àwòrán, Twitter
Igbe to Ẹmiọla fi ta ni ori itakun ayelujara lo mu ki okiki iṣẹlẹ naa kan kaakiri.
Eyii lo mu ki ijọba ipinlẹ Ọyọ kan sii nipasẹ alamọran pataki fun gomina Ṣeyi Makinde lori ọrọ awọn ọdọ.
"Nibayii, kele ofin ti gbe awọn aṣoju ikọ ""Operation Burst"" ti wọn fi ẹsun kan."
Adari ikọ naa, Captain Usolo lo kede rẹ lọjọ Aje lẹyin ti o tọrọ aforijin lọwọ awọn eeyan ti wọn yanjẹ.
Australia: Igbe ayekòótọ́ sàànfàní, ó kó olówó rẹ̀ yọ lọ́wọ́ ikú gbígbóná
Oríṣun àwòrán, NATIONAL GEOGRAPHIC SOCIETY
Arakunrin ọmọ Australia kan ti f'orin ọpẹ bẹnu lẹyin ti ayekootọ rẹ ko yọ lọwọ ina to sadede ṣeyọ nile rẹ laarin oru.
Bi kii ba ṣe ti ariwo ẹiyẹ rẹ yi to ta ji loju orun,o ṣeeṣe ki o jona mọ ile ti eeyan kankan ko si ni mọ.
Asunfọnfọn ni Anton Nguyen n sun lọwọ nile alaja-meji rẹ ni Brisbane, Queensland lasiko ti ina sadede  ṣeyọ loru Ọjọru.
Oríṣun àwòrán, Google
"O sọ fun ileesẹ iroyin ABC pe "" sadede ni mo gbọ ariwo kan ti ayekootọ mi, Eric, si bẹrẹ si ni pariwo. Bi mo ṣe ji ni yẹn ti mo ṣi n gbọ oorun eefin to pọ"""
"O ni ""kia ni mo gbe Eric,ti mo fẹ gba ọna eyinkule sa jade  ṣugbọn  mo ri ti ina n jọ nibe ti mo ṣi gba isalẹ ile mi sa jade"""
EndSars Protest:Ọ̀gá Àgba Ọlọ́pàá ṣàbẹ̀wò sí ìpínlẹ̀ Eko lẹ́yìn ìfẹ̀họ́núhàn EndSars
Nigba t'awọn panapana yoo fi de ni nkan bi ago kan oru, ina ti gba gbogbo ile kan.
Wakati kan gbako ni ikọ panapana mẹrin fi wọ'ya ija pelu ina ọhun ki wọn to rẹyin rẹ ni agbegbe Kangaroo Point.
Arakunrin  Nguyen, to n da gbele sọ pe lẹyin apamọwọ kekere kan ati ẹiyẹ oun ti ori ko yọ, awọn ko farapa botilewu ko kere mọ.
"Ọga ileesẹ panapana Queensland Cameron Thomas ni niṣe ni ayekootọ naa n lọgun ""Anton"" titi ti olowo rẹ fi taji loju oorun."
Ilẹ naa ni awọn ẹrọ to n tani lolobo ti eefin ba ṣeyọ nile ṣugbọn ayekootọ naa lo kọkọ figbe ta
Iwadii n lọ lọwọ lati mọ ohun to fa ina yi titi di bi a se n ko iroyin yi jọ.
Kayeefi nla ṣẹlẹ niluu Abeokuta tii ṣe olu ilu ipinlẹ Ogun ni ọgbọnjọ oṣu kẹwaa ọdun 2020.
Kayeefi ọhun ni pe ọkọ ati aya rẹ, Pa Israel Akojede ati Mama Esther jẹ Ọlọrun nipe lọjọ kan naa laarin wakati diẹ si ara wọn lẹyin ti wọn ti jọ gbe gẹgẹ bi lọkọlaya fun ọdun mejilelaadọrin.
Oríṣun àwòrán, Pinterest
Pa Akojede ku ni bi ago mẹta oru ọjọ Ẹti, lẹyin naa ni aya rẹ papoda nigba to gbọ iku ọkọ rẹ lẹyin wakati diẹ.
Ẹni ọdun mẹtalelọgọrun un ni Pa Akojede ti o gbe ni agbegbe Gbonagun Obantoko ṣe nigba ti aya rẹ jẹ ẹni ọdun mejidinlọgọrun un ki ọlọjọ to de.
Ọgbẹni Joseph Akojede to jẹ akọbi wọn lọkunrin ṣalaye pe iyalẹnu ni iṣẹlẹ naa jẹ fun gbogbo ẹbi.
Ọgbẹni Akojede ohun ti awọn n ro tẹlẹ nipe iku awọn mejeeji ko le jina sira wọn nitori bi ṣe fi ifẹ ba ara wọn lo.
EndSars, EndSwat Protest: Òbí agbábọ̀ọ̀lù Gbenga Tiamiyu Kaka àtàwọn míì tí ọlapàá pa sọ̀r
''Lati igba ti mo ti wa ni kekere ni mo ti maa n ṣe akiyesi baba ati mama mi, ifẹ to wa laarin wọn pọju, ko si ẹni to le ya wọn,'' Ọgbẹni Akojede lo sọ bẹẹ.
Ọgbẹni Akojede ni ''aṣọ kan naa ni wọn jọ maa n wọ, ohun kan naa ni wọn jọ gbagbọ, bakan naa ni wọn maa n gbamọran lọwọ ara wọn.''
O ni oun ko ri ibi ti wọn maa n jara wọn niyan ri, ''mama mi maa sọ pe ohun ti ọkọ oun ba ti sọ ni abẹ ge.''
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Olanrewaju Akojede to jẹ ọkan lara awọn ọmọ ọmọ oloogbe sọ pe iku awọn mejeeji dabi ere ori itage awọn gbajugbaja ololufẹ meji, ''Romeo and Juliet'' ti wọn fẹ ara wọn bi oju.
Olanrewaju ni o jẹ iyalẹnu fun oun pe ẹrọ ibaraẹnisọrọ kan naa lawọn mejeeji jọ lo pọ.
EndSARS: Makinde kéde ìrànwọ́ fáwọn ẹbí ọlọ́pàá tó bá rògbòdìyàn EndSARS lọ láti inú N500m tí a yà sọ́tọ̀
Oríṣun àwòrán, Twitter/Seyi Makinde
Gbogbo awọn ẹbi ọlọpaa to ba rogbodiyan iwọde EndSARS lọ ni ipinlẹ Oyo la o ṣeranwọ owo fun.
Gomina Seyi Makinde ipinlẹ Oyo lo ṣeleri bẹẹ nigba to ṣabẹwo si olu ileeṣẹ ọlọpaa ipinlẹ naa to wa niluu Ibadan lọjọ Aje.
Makinde sọ pe ninu ẹẹdẹgbẹta miliọnu naria ti ijọba Oyo ya sọtọ fawọn to fara kaasa ninu rogbodiyan ifẹhonuhan EndSARS ni ijọba yoo ti mu ṣe iranwọ fawọn ẹbi awọn ọlọpaa naa.
Gomina ipinlẹ Oyo rọ awọn ọlọpaa lati gbagbe ohun gbogbo to ṣẹlẹ ki wọn ṣiṣẹ pọ pẹlu ijọba lati rii wi pe alaafia jọba pada kaakiri ipinlẹ Oyo.
''Mi o fẹ ki ileeṣẹ ọlọpaa ri iwọde EndSARS gẹgẹ bi ọna lati tako awọn agbofinro bi ko ṣe ọna lati rii pe awujọ wa dun un gbe ju ti bi o ti wa lọ,'' Makinde lo sọ bẹẹ.
Makinde ni ọna kan gbogi lati jẹ ki awọn araalu mọ pe ọrẹ ni ọlọpaa jẹ si wọn ni nipa ihuwa ọmọluabi lẹni iṣẹ.
Gomina Makinde kẹdun pẹlu ileeṣẹ ọlọpaa lori ọlọpaa marun un to ba iṣẹlẹ naa lọ ati ọlọpaa mejila to farapa nipinlẹ Oyo.
O ni ijọba ko ni da ọrọ naa dawọn ọlọpaa papaa julọ lori bi awọn janduku kan tun ti dana sun agọ ọlọpaa marun un.
Makinde ni ajumọṣe ijọba atawọn araalu ni idagbasoke awujọ.
Ninu ọrọ tiẹ, igbakeji ọga ọlọpaa agba, DIG Leye Oyebade to n ṣakoso iwọ oorun gusu rọ awọn ọlọpaa lati wa lojufo, ki wọn si ri pe alaafia jọba pada nipinlẹ Oyo.
EndSars, EndSwat Protest: Òbí agbábọ̀ọ̀lù Gbenga Tiamiyu Kaka àtàwọn míì tí ọlapàá pa sọ̀r
Use of hijab: Ìjọba ti buwọ́lu lílo hijab láwọn iléèwé ní ìpínlẹ̀ Osun
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Lẹyin atotonu fun ọpọlọpọ ọdun, ijọba ipinlẹ Osun ti fọwọ si kawọn akẹkọọbinrin maa lo hijab nipinlẹ naa.
Ijọba ṣe okede ọhun ninu atẹjade kan ti arabinrin C. K. Olaniyan, to jẹ oludari agba ni ẹka eto ẹkọ ipinlẹ Osun fi sita lẹyin ti ọrọ naa ti wa nile ẹjọ fun ọjọ pipẹ.
Ijọba ṣalaye pe bi o tilẹ jẹ pe ijọba ti fọwọ lilo hijab lawọn ileewe, kii ṣe dandan fun awọn akẹkọọ maa wọ papaa julọ awọn akẹkọọ ti kii ṣe ẹlẹsin musulumi.
Ti ẹ o ba gbagbe, ọjọ kẹrinla oṣu keji ọdun 2013 ni ẹgbẹ musulumi nipinlẹ Osun gbe ijọba ipinlẹ naa lọ si ileẹjọ pe ki ijọba faye gbawọn akẹkọọ to jẹ musulumi lati maa wọ hijab nile iwe.
Ọrọ naa si ti fẹ da aawọ silẹ lawọn ileewe to jẹ ti ijọba nipinlẹ Osun.
Níbo ni owó Crowd 1 ti wá? Níbo ni owó Crowd 1 ń lọ? ni ìbéèrè tí spọ̀ ń bèèrè
Ijọba rọ awọn alaṣẹ ileewe ijọba lati maa kọ eti ikun si aṣẹ ileẹjọ lori lilo hijab, bi bẹẹ kọọ, aigbọran si ileẹjọ ni irufẹ iwa bẹẹ yoo jẹ.
Atẹjade naa ṣalaye pe ijọba ko ni ṣe ohun kan to tako ipinlẹ naa gẹgẹ bi ipinlẹ to wa fun gbogbo araalu lai fi ti ẹsin kankan ṣe.
EndSars, EndSwat Protest: Òbí agbábọ̀ọ̀lù Gbenga Tiamiyu Kaka àtàwọn míì tí ọlapàá pa sọ̀r
Ibadan Tailor: Ilé-ẹjọ́ dá ẹjọ́ lòdì sí ìwà ọ̀gá ọlọ́pàá sí télọ̀ rẹ̀
Oríṣun àwòrán, Oyo Insight
Ileẹjọ majisreeti to wa lagbegbe Iyakangu niluu Ibadan ti yi ẹjọ ti ọga ọlọpaa DPO, CSP Alex Sani Gwazah pe telọ kan, Lukman Adeniyi danu.
DPO Gwazah eleyii ti ko tii yọju sile ẹjọ lati igba ti igbẹjọ naa ti bẹrẹ pe Adeniyi lẹjọ pe o ba aṣọ ti oun gbe fun lati ran jẹ.
Ọga ọlọpaa DPO naa sọ ninu ẹjọ to pe telọ Adeniyi pe iwa ọdaran gbaa ni aranṣọ ọhun hu.
Aṣoju ọga ọlọpaa naa sọ fun ileẹjọ pe DPO naa ko le yọju sile ẹjọ nitori o wa igbimọ to n ṣewadi iwadii ifẹhonuhan EndSARS.
Bí o bá bá ààrùn ìpẹ́pẹ́ gbígbẹ lára arẹwà obìnrin rẹ̀, kí loó ṣe?
Ṣugbọn agbẹjọro telọ sọ pe irọ nla ni, o fidi rẹ mulẹ pe DPO naa ko si lara igbimọ to n ṣewadi iwọde EndSARS.
Ninu idajọ rẹ, Majisreeti Olajumoke Akande yi ẹjọ DPO naa danu, o si ni ki telọ Adeniyi maa lọ lalaafia.
Adajọ Majisreeti Akande sọ ninu idajọ rẹ pe bi ẹjọ to pe telọ yìí ba ṣe pataki si i, yoo waye lati wa nile ẹjọ fun igbẹjọ.
Adajọ ni ọga ọlọpaa Gwazah ko ni idi bo ti le wu kori lati ma yọju sile ẹjọ, to ba jẹ pe ọrọ naa ka a lara.
Ẹwẹ, agbẹjọro telọ Adeniyi, Jubril Mohammed ni oun ṣetan lati gbe ẹjọ naa lọ siwaju igbimọ igbẹjọ ti Gomina Seyi Makinde ipinlẹ Oyo ṣẹṣẹ ṣe ifilọlẹ rẹ.
O ni ọga ọlọpaa DPO gbọdọ san owo gba maa binu fun Adeniyi nitori ẹjọ to pe e ko l'ẹsẹ nlẹ.
"Ṣaaju nigba ti ọrọ yii ṣẹlẹ̀, DPO ọlọ́pàá naa ju télọ̀ yii sátìmọ́lé, o tun gbé e lọ sílé ẹjọ́ n'Ibadan torí o ni ""ó ba aṣọ mi jẹ́''."
Telọ Lukman Adeniyi wọ gau niluu Ibadan lẹyin ti DPO ileeṣẹ ọlọpaa to wa lagbegbe Iyaganku gbe lọ sile ẹjọ.
Ẹsun ti DPO naa, Alex Gwazarzah fi kan Adeniyi ni pe o gbe aṣọ oun fun ọmọṣẹ rẹ lati ran.
Aawọ ṣẹlẹ laarin awọn mejeeji lẹyin ti ọga ọlọpaa ni Adeniyi ti ba aṣọ oun jẹ.
Alukoro ileeṣẹ ọlọpaa ipinlẹ Oyo, Olugbenga Fadeyi ṣalaye pe ọga ọlọpaa Gwazarzah ti sọ fun Adeniyi tẹlẹ pe oun lo ma ran aṣọ ti oun gbe fun un funra rẹ.
Ọgbẹni Fadeyi ni ọrọ bẹyin yọ nigba ti Adeniyi gbe aṣọ ọhun fun ọmọ iṣẹ rẹ lati ran.
Alukoro ileeṣẹ ọlọpaa sọ pe ọga agba ọlọpaa ipinlẹ Oyo ti gbọ si ọrọ naa, yoo si wa nkan ṣe sii.
Telọ naa ni Alhaji Idris Bawa kan ti oun ti mọ fun ọun mẹwaa lo mu oun mọ DPO ọhun.
Orlando Owoh: Èmí àti Oladipupo Owomoyela jọ lọ ẹ̀wọ̀n Alágbọn- Caroline Owoh, aya Orlando
Adeniyi ni DPO Gwazarzah dunkoko mọ oun nigba ti oun lọ gbe aṣọ rẹ fun un lori ẹsun pe oun ko ran aṣọ naa daadaa.
''Ọga ọlọpaa Gwazarzah gbami leti, o si tun gba aṣọ mejila ti mo ba ran an lai san ọgọta ẹgbẹrun un naira ti a jọ fẹnu ko si,'' Adeniyi lo sọ bẹẹ.
Adeniyi ṣalaye pe DPO ọhun ni ki oun wa gba owo lọjọ Abamaẹta ọjọ kinni oṣu kọkanla ni o fi o ju oun si atimọle.
Iroyin sọ pe ọjọ Aje ni Adeniyi kuro latimọle ọjọ Iṣẹgun ni ọga ọlọpa DPO gbe lọ si ileẹjọ.
Dokita to n ṣetọju arun ọpọlọ kan, Dare Omowumi, ti sọ pe idi ti awọn eeyan ṣe maa n ṣedajọ gbigbona latọwọ ara wọn ni ara gbibona ati ai lee ni suuru.
Omowumi tun ni a i ki n riidajọ ododo gba lati ọdọ awọn agbofinro lo faa ti awọn eeyan ṣe maa n ṣe idajọ lati ọwọ ara wọn.
Dokita Omowumi lo sọ ọrọ naa lẹyin ti awọn ọdọ kan dana sun ọkọ akero lẹyin ti awakọ rẹ pa ọlokada kan ninu ijamba ọkọ to waye lagbegbe Idi Ape, ni ilu Ibadan.
Dokita ọhun sọ fun BBC Yoruba pe, ni ọpọ igba ti awọn eeyan ba ko ẹjọ lọ si agọ ọlọpaa, awọn ọlọpaa naa kii ṣe idajọ ododo nitori bi wọn ṣe maan gbe ẹbi fun alare nigba miran lo n jẹ ki awọn eeyan ṣe idajọ funran wọn.
O fi kun pe kii ṣe ohun to bojumu ki awọn eeyan maa dana sun ọkọ nigba ti ijamba ọkọ ba ṣẹlẹ nitori wọn ko mọ ẹni to jẹbi iṣẹlẹ naa ki wọn to ṣe idajọ ọwọ ara wọn.
Dokita naa pari ọrọ rẹ pe ni ṣe lo yẹ ki awọn eeyan gbe ẹnikẹni to ba ṣeṣe ninu ijamba ọkọ lọ sile iwosan, ki wọn si tun fi ọrọ naa to ileeṣẹ ọlọpaa leti kaka ki wọn ṣedajọ funra wọn.
EndSars Protest:Ọ̀gá Àgba Ọlọ́pàá ṣàbẹ̀wò sí ìpínlẹ̀ Eko lẹ́yìn ìfẹ̀họ́núhàn EndSars
Ẹwẹ, alukoro ileeṣẹ ọlọpaa ipinlẹ Oyo, Olugbenga Fadeyi sọ fun BBC Yoruba pe kii ṣe ohun to bojumu ki awọn ara ilu maa ṣe idajọ lati ọwọ ara wọn.
"O ni ""atubọtan ṣiṣe idajọ lati ọwọ ara ẹni kii so eso rere nitori kii jẹ ki awọn agbofinro mọ ẹni to jẹbi."""
"Fadeyi ni ""awọn ara ilu ko laṣẹ lati ṣe idajọ lati ọwọ ara wọn, idi niyẹn ti ọlọpaa fi wa laarin ilu."""
O fi kun pe awọn eeyan to maa n dana sun ọkọ n ru ofin to rọ mọ didana sun dukia.
Agbofinro naa ṣalaye pe ti ijamba ọkọ ba waye, ohun to yẹ ki awọn ara ilu ṣe ni ki wọn fi to ọrọ naa lọ ọlọpaa lati bẹrẹ iwadii.
EndSars, EndSwat Protest: Òbí agbábọ̀ọ̀lù Gbenga Tiamiyu Kaka àtàwọn míì tí ọlapàá pa sọ̀r
Fadeyi pari ọrọ rẹ pe ai kii fi ọrọ ijamba ọkọ to ọlọpaa leti ni kii jẹ ki awọn eeyan ri idajọ ododo gba lẹyin iru iṣẹlẹ bẹẹ.
Lẹyin naa lo gba awọn ara ilu niyanju lati dẹkun ṣiṣe idajọ ọwọ ara ẹni nitori o lodi si ofin.
Awọn ọdọ kan to n fapajanu ti dana sun ọkọ akero kan lowurọ Ọjọru nilu Ibadan lẹyin ti awakọ naa kọlu ọlọkada kan ti o si da ọmi rẹ legbodo.
Aṣoju ẹṣọ aabo oju popo ni agbegbe naa, Arabinrin Uche Chukwurah fi idi ọrọ mulẹ pe ni agbegbe Idi-Apẹ ni rogbodiyan naa ti ṣẹlẹ.
Chukwurah ni eeyan mẹjọ ni ijamba naa kan lara awọn to n bẹ ninu ọkọ akero kan, ọkọ ayọkẹlẹ kan ati ọlọkada, ṣugbọn ọlọkada yẹn nikan lo gbẹmi mi.
Aṣoju ẹṣọ aabo oju popo naa tẹsiwaju pe ijanu ọkọ akero naa to dẹnukọlẹ lo fa ijamba naa, pẹlu alaye wi pe awọn ọdọ kan ti inu bi lori iṣẹlẹ naa ni wọn dana sun ọkọ akero naa loju ẹsẹ.
O ṣoju mi koro naa fi idi ọrọ mulẹ wi pe lori ere ni ọkọ naa ti kọlu ọlọkada ti gbemi mi loju ẹsẹ.
Lẹsẹkẹsẹ ni awakọ sa lọ ti awọn ọdọ kan si dana sun ọkọ akero naa.
Wọn tẹsiwaju wi pe ọkọ akero naa dede ya lọ si oju opopona ibi ti ọlọkada naa n gba bọ ti o ko si ẹnu rẹ.
Agolo afẹ́fẹ́ gáàsì kan ti gbina ni agbegbe IJora nipinlẹ Eko lọsan Ọjọbọ, ko si tii lojutuu ni akoko ti a n ko iroyin yii jọ.
Ẹnikan to mọ ẹkunrẹrẹ to jẹ oṣiṣẹ ileeṣẹ gaasi naa sọ fun BBC pe o ti le ni wakati kan ti ina yii ti n jo.
"Lara ohun ti a kojọ, ibi iṣẹlẹ naa jẹ ibi ti wọn n ko gaasi pamọ si ti wọn si n pe ni ""gas farm"" ni agbegbe ibi ti ileeṣẹ ati katakara pọ si ni Eko."
Awọn oṣiṣẹ ajọ to n ri si iṣẹlẹ pajawiri ni ipinlẹ Eko, LASEMA ti de ibi iṣẹlẹ ina naa ti wọn si n gbiyanju lati pa a.
O to ọkọ panapana marun to ti wa nikalẹ lati pa ina ọhun.
A o maa mu ẹkunrẹrẹ wa fun yin loju opo yii bo ba ṣe n lọ...
Ekiti Ghost Workers: Gómìnà Fayemi ní N400m ló ń sọnù ní ọdọọdún nítorí àwọn tó ń gba owó òṣù láì ṣiṣẹ́
Oríṣun àwòrán, Google
Gomina ipinlẹ Ekiti, Kayode Fayemi ti sọ wi pe iye owo ti ipinlẹ Ekiti n sọnu ni ọdọọdun to irinwo miliọnu Naira nitori awọn to n ṣiṣẹ lai gba owo ni awọn ijọba ibilẹ.
Akọwe eto iroyin fun gomina Kayode Fayemi, Olayinka Oyebode lo fi lede bẹẹ ninu atẹjade kan.
Ninu atẹjade naa ti wọn pe akọle rẹ ni 'Ekiti Loses N19.3m Monthly To LG Ghost Workers - Report', ni Fayemi ti kọminu lori bi awọn oṣiṣẹ ijọba ibilẹ wa ni ipinlẹ Eko ti wọn si n gba owo oṣu ni ipinlẹ Ekiti.
Gomina Fayemi ni o ṣeni laanu wi pe awọn to n gba owo oṣu yii ko le e sọ pato ohun ti wọn n fi owo oṣu naa ṣe.
Gomina naa fi ero rẹ han lẹyin ti o ri esi iwadii ti ijọba gbekalẹ lati ṣe ayẹwo awọn oṣiṣẹ ijọba ibilẹ naa.
'' O kere tan eniyan mejilelọgọtalelelọọdunrun lo n gba owo oṣu lai ṣiṣẹ ni ijọba ibilẹ to wa ni ipinlẹ Ekiti.''
'' A ko gbọdọ dakẹ lori ọrọ yii mọ nitori awọn kan joko si Eko, wọn si n gba owo oṣu ni Ekiti lai nidi''
Bakan naa ni gomina Fayemi naa wa fikun wi pe awọn yoo fi ohun gbogbo sipo ti iru awọn iwa buruku yii ko ni waye mọ.
Nazir Sarkin Waka: 'Mo ṣetán láti lo gbogbo ayé mi tókù lẹ́wọ̀n'
Oríṣun àwòrán, Nazir Sarkin Waka
'Mo ṣetán láti lo gbogbo ayé mi tókù lẹ́wọ̀n'
Arakunrin olorin ọmọ Naijiria kan, Nazir Sarkin ti ni oun ṣetan lati lo gbogbo igbesi aye oun lẹwọn nitori ohun to gbagbọ.
O jẹ ohun ti ọpọ awọn ololufẹ rẹ ko ni fẹ gbọ seti ṣugbọn gbajugbaja olorin ọmọ iha Ariwa Naijiria naa, Nazir Ahmed ti ọpọlọpọ mọ si Sarkin Waka ti lo wakati mẹrinlelogun bayii ni ọgba ẹwọn Kurmawa ni ipinlẹ Kano.
Oríṣun àwòrán, @Nazir
Ni ọjọbọ ni ile ẹjọ kan ni Kano dajọ pe ki wọn gbe olorin naa lọ si ẹwọn titi yoo fi le ṣe ohun ti wọn bere fun gẹgẹ bii beeli rẹ.
"Iṣoro ti Sarki Waka ni jẹ pẹlu ajọ to n bojuto aṣẹ gbigba lorii awọn orin ati ere sinma to n jade latari awo orin meji to gbe jade lai gba lansẹẹsi lọwọ wọn iyẹn ""Gidan Saratu ati ""Sai Hakuri""."
Ṣugbọn awọn eeyan ni toriipe o bu ẹnu atẹ lu iṣesi gomina ipinlẹ Kano, Abdullahi  Ganduje ninu ọkan ninu awọn orin naa ti awọn olorin mii naa si bẹrẹ si ni ṣe ohun to ṣe.
Bi wọn ṣe n gbe e lọ sẹwọn lo sọ ọrọ sorii Whatsapp to si ka ohun ara rẹ silẹ pe oun ṣetan lati lo gbogbo aye oun lẹwọn fun ohun ti oun gbagbọ ninu rẹ.
Aburo rẹ toun funrarẹ jẹ olootu to n gbe ere sinima sita ba BBC sọrọ pe ohun to wa nidi ọrọ yii gangan ni pe ijọba kanlẹ ni nkan lodi si Sarkin Waka ni biko ṣe bẹẹ, ko yẹ ki eyi ṣẹlẹ.
"Ibi ti gbajugbaja olorin yii ti gba orukọ rẹ, Sarkin Waka eyi to tumọ si ""Ọba Orin"" wa latọdọ Emir ana ipinlẹ Kano, Sanusi Lamido Sanusi."
Wọn ni orin naa ti jade to si ti n tan ka ki Ganduje to di gomina.
Aminu ni awọn yoo tẹsiwaju lati maa ja fun Nazir ki wọn le tu u silẹ.
Koda o ni awọn fẹ ṣe lara ohun ti ileẹjọ beere fun ni Ọjọbọ ṣugbọn adajọ ti kuro nile ẹjọ nigba naa.
Ọkan lara ohun ti wọn beere fun ni ki wọn wa ọgagun Hisbah kan lati ijọba ibilẹ Kano to ba wu wọn eyi ti wọn si ti ṣe.
O sọ fun BBC ninu ifọrọwanilẹnuwo pe nigba ti wọn kọkọ mu Sarkin Waka nibẹrẹ ọdun yii, alaga ajọ to n fun awọn olorin ati elere ni lansẹẹsi ni ko si ọwọ oṣelu kankan ninu ohun to ṣe bikoṣe riru ofin.
Oríṣun àwòrán, Twitter/Nigeria Police Force
Ileeṣẹ ọlọpaa ti ṣe koriya fun awọn ọlọpaa lorilẹede Naijiria, eyi wa lara ohun ṣuyọ lẹyin rogbodiyan to tẹle ifẹhonuhan #EndSARS.
Ọga agba ọlọpaa ni Naijiria Mohammed Adamu lo ṣalaye pe gbogbo ẹbi ọlọpaa to ba rogbodiyan iwọde EndSARS lọ nijọba yoo ṣeranwọ fun.
Ọgbẹni Adamu tun ni awọn agbofinro to farapa ninu iṣẹlẹ naa yoo gba igbega lẹnu iṣẹ.
Niluu Benin nipinlẹ Edo ni Adamu ti sọrọ yii nigba to ṣabẹwo si olu ileeṣẹ ọlọpaa to wa ni Benin.
Ọga agba ọlọpaa tun ṣabẹwo si awọn agọ ọlọpaa ti awọn janduku kan dana sun niluu Benin.
Agọ ọlọpaa meje ati ọpọ ọkọ tawọn ọlọpaa fi n ṣiṣẹ ni wọn dana sun lasiko rogbodiyan to bẹ silẹ lẹyin ifẹhonuhan EndSARS.
''Ijọba ko gbagbe awọn ọlọpaa ni Naijiria. Ọpọ atunṣe lo n lọ lọwọ lati rii pe awọn agbofinro gbaye gbadun,'' ọga ọlọpaa lo sọ bẹẹ.
Adamu ni awọn ọlọpaa to ti fẹhinti lẹnu iṣẹ gan an yoo ri owo ifẹyinti wọn gba.
O ni oun n ṣiṣẹ pọ pẹlu ajọ to n ri si ọrọ ọlọpaa lati rii pe gbogbo eto yii di ṣiṣe.
Orlando Owoh: Èmí àti Oladipupo Owomoyela jọ lọ ẹ̀wọ̀n Alágbọn- Caroline Owoh, aya Orlando
Rebiulding Lagos: Sanwo-Olu buwọ́lu ìgbésẹ̀ ìjọba láti tún Eko ṣe lẹ́yìn rògbòdìyàn EndSARS
Oríṣun àwòrán, Twitter/Babajide Sanwo-Olu
Gomina ipinlẹ Eko, Babajide Sanwo-Olu ti buwọlu igbesẹ ijọba lati tun gbogbo ohun to bajẹ lasiko ifẹhonuhan EndSARS ṣe nipinlẹ Eko.
Sanwo-Olu gbe igbimọ ẹlẹni mẹjọ kalẹ ti yoo ṣe amujuto atunṣe ohun gbogbo tawọn janduku bajẹ.
O tun sọ fun igbimọ naa lati ṣiṣẹ lori ọjọ iwaju ipinlẹ Eko ki wọn si tun ṣiṣẹ lori ọna lati wẹ oju egbo ti iwọde EndSARS da san.
Awọn ọmọ igbimọ naa wa lati ileeṣẹ ijọba, alaadani atawọn ajọ agbaye ti wọn ti yọnda ara wọn fun iṣẹ atunṣe ipinlẹ Eko lẹyin iṣẹlẹ EndSARS.
Ọgbẹni Yemi Cardoso ni alaga igbimọ ọhun nigba ti Ọjọgbọn Kanyisola Ajayi, Ọgbẹni Gbenga Agboola, Arabinrin Bola Adesola, Ọgbẹni Sam Egube, Ọgbẹni Jimi Hotonu, Ọgbẹni Abubakar Suleiman ati ọmọ ẹgbẹ ajọ agbgaye alaanu kan jẹ ọmọ ẹgbẹ igbimọ ọhun.
Sanwo-Olu tun ṣe ifilọlẹ igbimọ mẹfa miiran ti yoo ri si bi ipinlẹ Eko yoo ṣe pada bọ sipo ni kiakia.
Gomina Sanwo-Olu ni asiko ti to lati gbagbe ohun to ṣẹlẹ ki gbogbo ara ipinlẹ Eko fọwọ sọwọpọ lati tun Eko ṣe pada.
Orlando Owoh: Èmí àti Oladipupo Owomoyela jọ lọ ẹ̀wọ̀n Alágbọn- Caroline Owoh, aya Orlando
Gomina ipinlẹ Eko ni ọgọọrọ eeyan lo yọnda lati ṣiṣẹ pọ pẹlu ijọba lati ṣatunṣe ipinlẹ naa lẹyin rogbodiyan to ṣẹlẹ.
O ni ijọba yoo gbe abadofin lori ati tun ipinlẹ Eko ṣe lọ si iwaju ile igbimọ aṣofin lai pẹ.
US Election 2020: Wo ìyàtọ̀ láàrin ìjọba Joe Biden sí ti Donald Trump bó ṣe kan orílẹ̀èdè àgbáyé
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ohun akọkọ ti ijọba aarẹ orilẹede Amerika labẹ Aarẹ Donald Trump kọkọ ṣe nigba ti wọn de ipo ni lati fihan agbaye pe orilẹede Amerika ni yoo saju ninu ohun gbogbo,'America First'.
Aarẹ Donald Trump tako awọn adehun ti wọn ṣe pẹlu awọn orilẹede miran lagbaye, ti o si gbe igbesẹ bi o ṣe wu u lai naani idọrẹpọ laarin orilẹede.
Amọ, aarẹ ti wọn ṣẹṣẹ dibo yan, Joe Biden ti ni igbesẹ ti oun yoo yatọ patapata si aarẹ Trump, o ni gbogbo idọrẹpọ pẹlu orilẹede to ṣe pataki lagbaye, ti aarẹ Trump gbegile ni oun yoo tun to pada.
Lara awọn ohun ti Joe Biden yoo ṣe ni lati ṣe atunṣe pẹlu Ajọ NATO lagbaye.
Bakan naa ni orilẹede Amẹrika yoo pada si Ajọ Eto Ilera lagbaye, ki wọn si saaju igbogun ti aarun Coronavirus.
Oríṣun àwòrán, View Press
Joe Biden ni oun yoo pada si adehun ti orilẹede Amẹrika ni pẹlu agbaye lori idẹkun oju ọjọ gbigbona, eleyii ti wọn pe ni 'Paris Climate Change.'
Eleyii jẹ ọkan lara awọn adehun ti aarẹ Donald Trump tako, to si yọ orilẹede Amerika kuro ninu adehun naa.
Joe Biden ti ni oun ṣetan lati ṣe adehun miran papọ pẹlu awọn orilẹede agbaye lati le mu idẹrun ba orilẹede Amerika lori ọrọ aje wọn ti aarẹ Donald Trump fofin de.
Ọdun 2018 ni Aarẹ Trump yọ orilẹede Amẹrika kuro ninu adehun ti wọn ni pẹlu Iran lati jẹ ki wọn dẹwọ ipese ija ogun ọlọgọọrọ, Nuclear.
Oríṣun àwòrán, Reuters Handout
Joe Biden ni oun yoo tọ ipasẹ aarẹ Trump lati fopin si iranwọ orilẹede Amẹrika pẹlu ogun abẹle lorilẹede Yemen.
Lẹyin ti awọn eniyan paapaa awọn aṣofin lorileede Amerika koju oro si, nitori ọpọ ẹmi to ti ṣofo ninu ogun abẹle Yemen naa.
Joe Biden ti ni oun yoo tẹlẹ ipasẹ aarẹ Donald Trump ninu adehun rẹ pẹlu orilẹede United Arab Emirates, nitori Biden fẹran orilẹede Isreal.
Amọ, o ni awọn yoo ṣe agbeyẹwo agbegbe 'West Bank' to n fa ija laarin oriḷede Palestine ati Isrẹli fun ọpọlọpọ ọdun bayii.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Bi o tilẹ jepe aarẹ Donald Trump fẹran aarẹ orilẹede Russia, Vladmir Putin, to si ṣetan lati dariji i.
Amọ, Joe Biden ni awọn ṣẹṣẹ bẹrẹ pẹlu orilẹede Russia, nitori awọn yoo ṣewadii bi wọn ṣe tọwọbọ eto idibo wọn ni ọdun 2016.
Bakan naa ni wọn sọ wi pe awọn yoo gbe tẹsiwaju lati fofin ọrọ aje ilẹ Russia,
Joe Biden ni o dun mọ oun ninu bi o ṣe waye bẹẹ labẹ aarẹ Donald Trump, ti  yoo si tẹsiwaju ni abẹ iṣejọba oun.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Aarẹ Trump fi igunpa gun gbogbo agbaye
CHINA:
Ni ọdun 2017, aarẹ Donald Trump ṣe apejuwe adari ilẹ China, Xi Jinping gẹgẹ bi ọrẹ oun ti awọn si jọ fẹran ounjẹ aladun bii sokoleeti.
Amọ, ija waye laarin wọn pẹlu bi aaṛẹ Trump ṣe ni China lo n pin arun Coronavirus kaakiri lagbaye, ati bi China ṣe n gba ọrọ aje wọ Amẹrika  lọwọ.
Joe Biden ni awọn ko ni tọ ipasẹ Donald Trump, awọn yo ran orilẹede China lọwọ lori ọrọ aje wọn ati lati mu ibasepọ to dan mọran waye laarin awọn orilẹede mejeeji.
Oríṣun àwòrán, Reuters
Aarẹ ana lorileede Naijira Olusegun Obasanjo ti pẹlu awọn olori kọọkan lagbaye to n fi ikini ku oriire ranṣẹ si Joe Biden to jaweolubori ninu idibo Amẹrika.
Ninu atẹjade kan ti agbẹnusọ rẹ fi sita, Obasanjo ni aṣeyọri Biden jẹ aṣeyọri daada lori aburu ati pe aṣeyọri Biden kii ṣe ti Amrika nikan bi kii ṣe ti gbogbo agbaye.
Bẹẹ naa ni Obasanjo ba Kamala Harris yọ gẹgẹ bi obinrin alawọdudu akọkọ ti yoo de ipo igbakeji aarẹ Amẹrika.
Yatọ si Obasanjọ, olootu ijọba Canada Justin Trudeau, Taoiseach Micheál Martin ti Ireland ati Keir Starmer olori alatakọ nilẹ Gẹẹsi fi ọrọ ikini ranṣẹ loju opo Twitter
Titi di igba ta fi n ko iroyin yi jọ, olootu ijọba ilẹ Gẹẹsi, Boris Johnson, aarẹ Russia Vladmir Putin ati aarẹ Naijiria Muhammadu Buhari ko ti fi ikini ranṣ si Biden ati Harris.
Aarẹ Donald Trump ti fesi si iroyin pe alatako rẹ Joe Biden lo jaweolubori ninu idibo aarẹ ilẹ Amẹrika.
Ninu atẹjade to wa lati ọdọ awọn agbẹnusọ rẹ, Trump ni ''gbogbo wa la mọ idi ti Biden fi n sare lati kede ara rẹ gẹgẹ bi ẹni to jaweloubor ti awọn eeyan rẹ nileeṣẹ iroyin naa si n ṣapa lati ran lọwọ.Wọn ko fẹ ki ododo jade ni''
Oríṣun àwòrán, Reuters
Trump wa poinu pe bẹrẹ lati ọjọ Aje to n bọ, oun yoo gba ileẹjọ lọ lati ri pe wọn tẹle ofin idibo ti ẹni to jaweolubori si fidi sori aga.
Trump ko ni aridaju gbogbo ọrọ rẹ to n sọ pe awọn eeyan Biden n gbiyanju pe ki wọn ka ibo toun ti pe wọn ko jẹ ibo to tọ.
Ohun ta gbọ ni pe Aarẹ Trump wa nibi to ti n gba ''gọọfu'' nigba ti iroyin ikede afojusun pe Biden wọle ipo aarẹ kan lara.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Oludije ẹgbẹ oṣelu Democrat Joe Biden lo wọle ibo aarẹ orilẹ-ede Amẹrika.Biden la oludije ẹgbẹ Republican Donald Trump mọlẹ ninu eto idibo tawọn ọmọ ilẹ Amẹrika ti tu yaya tu yaya jade.Biden ni ibo awọn aṣoju 273 nigba ti Trump ni 214 eyi to fihan gbangba pe Biden lawọn ọmọ orileede Amẹrika lati tukọ   ilẹ naa fun ọdun mẹrin tó n bọ.
Awọn ipinlẹ to ṣe pataki bíi Pennsyvannia, Georgia, Michigan, Wisconsin, Nevada ati Arizona ni Biden ati Trump ti jọ figa gbaga ninu eto idibo ọhun.Lati Ọjọru ni Trump ti sọ pe oun lo jawe olubori ninu eto idibo ọhun nigba ti Biden naa ni o da oun loju pe oun yoo bori ninu ibo aarẹ Amẹrika.Biden lo ti ni ibo to pọju julọ ninu itan eto idibo aarẹ orilẹ-ede Amẹrika.Ẹwẹ, Trump fidirẹmi ninu ẹjọ to pe lori kika ibo lawọn ipinlẹ kan.Adajọ ni ko si to le fidi rẹ mulẹ pe magomago wa ninu eto idibo Amẹrika.
EndSARS aftermath: Iléeṣẹ́ kò ní gba ẹnikẹ́ni láàyè láti ṣe ìfẹ̀hónúhàn kankan mọ́ ní ìpínlẹ̀ Eko
Oríṣun àwòrán, Twitter/Babajide Sanwo-Olu
Ileeṣẹ ọlọpaa ipinlẹ Eko ti ṣeleri pe ohun ko ni faye gba iwọde tabi ifẹhonuhan kan mọ kaakiri ipinlẹ naa.
Ikilọ yii jade lẹyin ti ileeṣẹ ọlọpaa ni awọn kan n gbero lati ṣe iwọde miran ki wọn le fi ẹhonu wọn han daadaa lori iwa ifiyajẹni awọn ọlọpaa, eto aabo to mẹhẹ ati iṣejọba ti ko rọ araalu lọrun.
Ileeṣẹ ọlọpaa ni idi ti ohun ko fi ni faye gba iwọde mii ni pe ipinlẹ Eko ko tii bọ ninu ofo ko laarọ to tẹle iwọde EndSARS to lọ.
Ninu atẹjade ti alukoro ileeṣẹ ọlọpaa Eko, Olumuyiwa Adejobi fi sita ileeṣẹ ọlọpaa ni wọn ti fi to awọn leti pe awọn kan tun fẹ da rogbodiyan lati tẹsiwaju aawọ to ṣẹlẹ lasiko iwọde EndSARS.
''Idi eyi lo jẹ ki ileeṣẹ ọlọpaa maa kilọ fun ẹnikẹni tabi ẹgbẹ kẹgbẹ kan to ba n gbero lati ṣe iwọde yala ifẹhonuhan wọọrọwọ tabi lile pe ileeṣẹ ọlọpaa atawọn eṣọ aabo mii ko ni gba fun wọn,'' Adejobi lo sọ bẹẹ.
AbdulQudus Bello ṣàlàyé bí òun ṣe dí aláàbọ̀ ara nítorí pọpọ́ọ̀fù àti ìbínú jàǹdùkù àdúgbò
O ni ẹnikẹni to gbimọ lati da alaafia ilu ru lasiko yii ti ipinlẹ ifẹhonuhan EndSARS ṣẹṣẹ lọọlẹ tan yoo jẹ iyan rẹ ni iṣu.
Bakan naa ni ileeṣẹ ọlọpaa kilọ fawọn obi ninu atẹjade naa lati kilọ fawọn ọmọ wọn pe ki wọn maa jẹ ki ẹnikẹni lo awọn ọmọ wọn fun ifẹhonuhan kankan nitori awọn janduku ni yoo ja iru iwọde bẹẹ gba.
Ileeṣẹ ọlọpaa tun rọ gbogbo olugbe ipinlẹ Eko lati kọ eti ikun si ẹnikẹni to ba pe wọn si ibi iwọde kankan.
2021 Budget: Wo ìgbà márùnn ún tí Buhari ti rìnrin àjò lọ sókè òkun fún ìtọ́jú ara rẹ̀
Oríṣun àwòrán, Instagram/Bashir Ahmad
Ẹ tun ile iwosan Aso Rock ṣe ki Aarẹ Muhammadu Buhari ye lọ soke okun lọ gbatọju mọ.
Igbimọ aṣofin agba l'Abuja to n ri ọrọ pinpin ipo ati ohun ini ijọba lai ṣegbe lẹyin ẹya kan lo sọrọ yii nigba ti wọn n jiroro lori eto iṣuna to le ni biliọnu kan naira ti ijọba ya sọtọ fun ile iwosan ileeṣẹ aarẹ.
Igbimọ naa ni ohun yoo buwọlu aba eto iṣuna naa ṣugbọn aarẹ Buhari ko gbọdọ lọ si oke okun lọ gba itọju mọ.
Wọn yii ni igba marun un ti Aarẹ Buhari ti lọ gba itọju nilẹ okeere.
Ọjọ karun un oṣu keji, ọdun 2016
Ni bi oṣu mẹjọ to bẹrẹ ijọba gẹgẹ bi aarẹ orilẹede Naijiria, Aarẹ Buhari rinrin ajo lọ si ilu London lọjọ karun un oṣu keji ọdun 2016.
Atẹjade lati ileeṣẹ ijọba ṣalaye pe ọrọ ara Buhari lo mu gunle irinajo naa.
O pada si Naijiria lati irinajo naa lọjọ kẹwaa oṣu keji ọdun 2016.
Ọjọ kọkandinlogun oṣu kinni, ọdun 2017
Aarẹ Buhari mori le ilẹ Gẹẹsi lọjọ kọkandinlogun oṣu kinni, ọdun 2017.
Ileeṣẹ aarẹ sọ pe itọju ara rẹ lo mu ki aarẹ Buhari gunle irinajo ọhun si ilu Oba.
Ọjọ kẹwaa oṣu kẹta ọdun 2017 ni Buhari pada si Naijiria lẹyin to lo ọjọ mọkanlelaadọta lorilẹede UK.
AbdulQudus Bello ṣàlàyé bí òun ṣe dí aláàbọ̀ ara nítorí pọpọ́ọ̀fù àti ìbínú jàǹdùkù àdúgbò
Ọjọ kọkanlelogun oṣu kẹsan an, ọdun 2017
Ọjọ kọkanlelogun oṣu kẹsan an ọdun 2017 ni Aarẹ Buhari gbera lati ilu London lọ si orilẹede Amẹrika.
Aarẹ rinrin ajo naa lati lọ gba itọju fun agọ ara rẹ.
Ọjọ mẹrin ni Buhari lo nilẹ Amẹrika ko to pada si ilu Abuja lọjọ kẹẹdọgbvọn oṣu kẹsan an ọdun 2017 .
Ọjọ kẹsan an oṣu kẹrin, ọdun 2018
Buhari fi orilẹede Naijiria silẹ lọ si ilẹ Gẹẹsi lọjọ kẹsan an oṣu kẹrin ọdun 2018.
Ọjọ mẹtala gbako ni Buhari nilẹ Uk ki o to pada wale lọjọ kọkanlelogun oṣu kẹsan an ọdun 2018.
Ijọba ni isinmi ọlọdọọdun ni Aarẹ Buhari lọ fun nilẹ Gẹẹsi.
Buhari kopa ninu ipade awọn orilẹede to gbominira lati ọdọ ilẹ Gẹẹsi, bakan naa lo ṣe ipade pẹlu Olootu ijọba ilẹ Gẹẹsi Theresa May nigba naa.
Orlando Owoh: Èmí àti Oladipupo Owomoyela jọ lọ ẹ̀wọ̀n Alágbọn- Caroline Owoh, aya Orlando
Ọjọ kẹjọ oṣu karun un ọdun 2018
Aarẹ Buhari tun gbera lọ si ilẹ Uk lọjọ kẹjọ oṣu karun un ọdun 2018.
Iroyin to jade lati ileeṣẹ ṣalaye pe itọju ara lo mu ki Buhari rinrin ajo lọ si ilẹ okeere.
Ọjọ kọkanla oṣu karun ọdun 2018 ni Buhari pada si Naijiria lẹyin to gba itọju tan niluu London.
Oríṣun àwòrán, @DailyPostNGR
Buhari, dẹ́kun à ti máa lọ sókè òkun fún ìtọ́jú, tún ilé ìwòsàn Aso Rock ṣe- Sẹ́nátọ̀
Ọmọ ile igbimọ aṣofin kan lati ipinlẹ Kaduna, Danjuma La'ah, ti rọ awọn ọmọ ile igbimọ aṣofin agba lati sọ fun Aarẹ Muhammadu Buhari pe ko dẹkun ati maa lọ si oke okun fun itọju.
Aṣofin naa ni ki Aarẹ bẹrẹ si n lo ile ile iwosan to wa ni ile rẹ, iyẹn ni Aso Rock, to wa niluu Abuja to jẹ olu ilu Naijiria.
La'ah lo sọ ọrọ naa nigba ti akọwe ile Aarẹ, Tijani Umar gbe eto iṣuna ọdun 2021 lọ siwaju ile aṣofin naa.
Ninu eto iṣuna ti Umar gbe lọ siwaju ile ọhun, ₦1.3 biliọnu ni wọn ya sọtọ fun ile iwossan to wa nile Aarẹ ninu eto iṣuna ọdun 2021 ti iye rẹ jẹ ₦19.7 biliọnu.
Nigba to n sọrọ lori eto iṣuna ọhun, ọgbẹni La'ah sọ pe ti Aarẹ atawọn oṣiṣẹ rẹ ba dẹkun ati maa lọ gba itọju loke okun, yoo rọrun lati tun ile iwosan to wa ni Aso Rock ṣe.
O ni igbimọ to n ri si eto iṣuna ọhun yoo buwọlu eto iṣuna ile iweosan to wa nile Aarẹ, ṣugbọn Aarẹ atawọn to sun mọ ọ gbọdọ dẹkun irinajo oke okun fun itọju.
Oríṣun àwòrán, @NGAuthentic
"Gẹgẹ bo ṣe sọ, o ni ""Aarẹ wa kii ṣe ẹni to yẹ ki wọn maa gbe lọ soke ni gbogbo igba to ba n ṣaisan."""
O gbọgbọ maa gba itọju nilẹ yii, a si ni lati ri daju pe ijọba tun awọn ile iwosan wa ṣe.
Aṣofin naa fi kun pe awọn yoo maa ṣayẹwo ile iwosan Aarẹ ọhun  lati ri pe gbogbo ohun to yẹ ko wa nibẹ ni wọn pese.
Kabex End SARS: Àwọn ìṣẹ̀lẹ̀ tó làmìlaaka tó wáyé nínú oṣù Kẹ́wàá ọdún 2020
Oríṣun àwòrán, @thecableng
Oṣu kẹwaa ọdun 2020 jẹ oṣu kan ti ọpọlọpọ awọn ọmọ Naijiria ko lee gbagbe ninu itan nitori awọn iṣẹlẹ to waye ninu oṣu ọhun.
Lara awọn iṣẹlẹ manigbagbe naa ree:
Iwọde #EndSARS
Iwọde EndSARS bẹrẹ lẹyin ti fidio kan fa ori ayelujara ya lọjọ kẹta, oṣu Kẹwaa, ọdun 2020, eyii to ṣafihan bi awọn ọlọpaa SARS ṣe yinbọn fun ọkunri na niwaju ile itura Wetland, to wa ni Ugheli, ni ipinlẹ Delta.
Iṣelẹ naa lo ta epo si ifẹhonuhan EndSARS lori ikanni Twitter.
Oríṣun àwòrán, @thecableng
Ṣugbọn nigba ti iyẹn ṣi n lọwọ, ni iroyin kan tun jade pe awọn oṣiṣẹ SARS tun ti pa olorin takasufe kan to jẹ ọmọ ogun ọdun, ti orukẹ rẹ n jẹ Daniel Chibuike.
Lẹyin naa ni awọn eeyan bẹrẹ iwọde kaakiri awọn ilu nla ni Naijiria ati loke okun, ti wọn si n ke gbajare si ijọba apapọ pe ko fi opin ẹka ileeṣẹ ọlọpaa SARS naa.
AbdulQudus Bello ṣàlàyé bí òun ṣe dí aláàbọ̀ ara nítorí pọpọ́ọ̀fù àti ìbínú jàǹdùkù àdúgbò
Igba to di ọjọ kẹjọ, oṣu Kẹwaa, ọdun 2020 ni iwọde ita gbangba bẹrẹ ni pẹrẹwu, ti ọpọ awọn gbajumọ ni Naijiria ati kaakiri agbaye si n sọ pe wọn fi ọwọ si iwọde ọhun.
Ifẹmiṣofo ni Lekki Toll Gate
Ni nnkan bi aago mẹfa abọ ogunjọ, oṣu Kẹwaa, ọdun 2020, ni awọn ẹṣọ alabo ṣina ibọn bolẹ fun awọn oluwọde to kọ lati fi iloro naa silẹ lẹyin ti ijọba ipinlẹ Eko ti kede ofin konile-o-gble oni wakati mẹrinlelogun.
Oríṣun àwòrán, @jharmo
Olorin takasufe kan, Dj Switch ka iṣẹlẹ naa silẹ loju opo Instagram rẹ, to si sọ pe awọn ọlọpaa atawọn ọmọ ogun lo ṣiṣẹ ibi naa, ṣugbọn ileeṣẹ ologun ti ni oun ko mọwọ mẹsẹ ninu iṣẹlẹ ọhun.
Jiji ounjẹ iranwọ Covid-19 ko
Lẹyin ti iwọde EndSARS gbọna mii yọ ni awọn janduku ja iwọde naa gba, ti wọn si bẹrẹ sii kọlu awọn ile ti ijọba ko ounjẹ iranwọ Covid-19 pamọ si.
Wọn ni o yẹ ki ijọba ti pin awọn ounjẹ naa, ṣugbọn wọn ko pa lati lu ni gbanjo.
Oríṣun àwòrán, @CDDWestAfrica
Awọn miran tun ṣakọlu si ọpọ agọ ọlọpaa ni ipinlẹ Eko, alukoro ileeṣẹ ọlọpaa ipinlẹ Eko tilẹ sọ fun BBC pe ko din ni agọ ọlọpaa marundinlogun ti awọn janduku naa dana sun.
EndSars, EndSwat Protest: Òbí agbábọ̀ọ̀lù Gbenga Tiamiyu Kaka àtàwọn míì tí ọlapàá pa sọ̀r
Ikọlu gomina ipinlẹ Osun
Ọjọ kọkandinlogun oṣu Kẹwaa yii kan naa ni awọn janduku kan ṣakọlu si gomina ipinlẹ Osun, Gboyega Oyetola, nibi iwọde EndSARS ni ilu Osogbo.
Awọn janduku ọhun sọ oko, kondo atawọn ohun ija miran si gomina ọhun, ti awọn eeyan si farapa.
Akomolede àti Asa lórí BBC Yorùbá: Mọ̀ síi nípa ẹ̀kún ìyàwó níbí
Awọn ẹlẹwọn salọ ni Edo
Igba ti iwọde EndSARS n lọwọ ni awọn janduku kọlu ọgba ẹwọn to wa ni opopona Sapele, ti wọn si tu awọn ẹlẹwọn silẹ.
Nnkan bi ẹgbẹrun meji ẹlẹwọn ni awọn janduku naa fun ni ominira, eyii to mu ki gomina Godwin Obaaseki kede igbele oni wakati mẹrinlelogun.
Igbohunsafẹfẹ Aarẹ Muhammadu Buhari
Lẹyin ti iwọde EndSARS ti bẹrẹ lọpọ eeyan kaakiri Naijiria ti n reti ki Aarẹ Muhammadu Buhari sọrọ soke ṣugbọn ko wi nnkan.
Ẹwẹ, lẹyin ti awọn ṣọja yinbọ fun awọn oluwọde ni iloro Lekki, ti gbogbo ọrọ si dojuru ni Aarẹ to sọrọ soke.
Orlando Owoh: Èmí àti Oladipupo Owomoyela jọ lọ ẹ̀wọ̀n Alágbọn- Caroline Owoh, aya Orlando
Ṣugbọn o ṣeni laanu pe igbohunsafẹfẹ naa ko tẹ awọn ọmọ Naijiria lọrun nitori wọn ni ọkọ Aisha ko mẹnuba ohun ti wọn reti ko sọ.
Bi awọn kan ṣe n sọ pe ifakoko ṣofo lasan ni igbohunsafẹfẹ naa lawọn miran n sọ pe ki ṣe Aarẹ lo ṣe igbohunsafẹfẹ ọhun.
Florence Ajimobi: Àwọn Káfíńtà ti kó igi dé láti tún òrùlé ilé ìtajà tó jóná ṣe
Awọn agba ni ọjọ taa ba ri ibi, ni ibi n wọ ilẹ, ohun to ba si ti ya kan, kii tun pẹ ms.
Eyi lo mu ki aya gomina ana nipinlẹ Oyo, Florence Ajimobi tete pakiti mọlẹ lati se atunse ibudo itaja rẹ to jona.
Bẹẹ ba gbagbe, alẹ ana la mu iroyin wa fun yin pe abala kan lọwọ ẹyin ibudo itaja aya Ajimobi naa, Grandex, to wa ladugbo Bodija nilu Ibadan gbina.
Amọ nigba ti ikọ iroyin BBC se abẹwo sibudo itaja naa loni, a se akiyesi pe aayan ti n lọ lati se atunse abala ile itaja to jona naa.
Ikọ iroyin BBC Yoruba kofiri awọn Kafinta ti wọn ti ra igi da silẹ lati tun orule to jona kan, to si seese ki isẹ atunse naa bẹrẹ lọla.
Oríṣun àwòrán, oyoinsight.com
Saaju la ti sọ fun yin pe, ina nla kan ti ṣẹyọ to si ṣakoba fun ọpọ dukia ni ile itaja iyawo Gomina ipinlẹ Oyo tẹlẹ, arabinrin Florence Ajimobi.
Ile itaja igbalode  taa n sọ yi ni Grandex Supermarket to wa ni agbegbe Bodija nilu Ibadan.
Iṣẹlẹ yi to se awọn eeyan ni haa, waye lẹyin ọjọ mẹta ti Arabinrin Florence jade ile opo iku ọkọ rẹ, Sẹnẹtọ Abiola Ajimobi .
Awọn ti iṣẹlẹ naa ṣoju wọn sọ pe ina naa ṣadede ṣẹyọ lọsan ọjọ Aiku lati ọwọ ẹyin ile itaja naa ti ko si pẹ to fi ran kaakiri.
Titi di igba ta fi n ṣe akojọ iroyin yi, a ko ti fidi ọrọ mulẹ lori ohun to fa ina naa.
Oríṣun àwòrán, @aishambuhari
Aya gomina ipinlẹ Oyo tẹlẹ, Abiola Ajimobi to ti di oloogbe bayii, Florence Ajimobi ti jade ile opo lẹyin ogoje ọjọ.
Abiola Ajimobi papoda lọjọ karundinlogun, oṣu Kẹfa, ọdun 2020 nile iwosan aladani kan nipinlẹ Eko, lẹyin to lugbadi arun Covid-19.
Lẹyin iku rẹ ni aya rẹ ọhun wọle opo ologoje ọjọ gẹgẹ bi ilana ẹsin Musulumiṣe gbe kalẹ.
Nigba ti wọn n sọrọ lẹyin ti aya gomina tẹlẹri ọhun jade ile opo, ẹgbẹ awọn obinrin ninu ẹgbẹ oṣelu APC baa ṣajọyọ, wọn si tun kii ku oriire.
Oríṣun àwòrán, @vanguardngrnews
Ninu atẹjade ti awọn obininrin na fi lede, wọn ki aya Ajimobi ku irọju ati afarada lẹyin iku ọkọ rẹ.
Atẹjade naa ti olori awọn obinrin ẹgbẹ APC ipinlẹ Oyo, Mabel Williams ati igbakeji rẹ, Toyin Ajibade buwọlu ki Florence Ajimobiu ku irọju.
"Wọn ni ""a ti gba f'Ọlọrun pe olori ati aṣiwaju wa ti dagbere faye, a si n fi akoko yii ṣeranti rẹ."""
A si fẹ fi akoko yii sọ fun aya olori wa, iyẹn, Florence Ajimobi pedigbi ni a wa lẹyin lọjọ gbogbo.
Petrol tanker accident: Èèyàn méjì àti ọkọ̀ 29 ló jóná níbi ìṣẹ̀lẹ̀ táńkà agbépo tó gbiná ní mọ́rosẹ̀ Eko sí Ibadan
Ajọ ẹṣọ oju popo, FRSC to ṣalaye ni kiku ohun to ṣe okunfa ijamba ọkọ agbepo bẹntiro to ṣẹlẹ loju ọna mọrosẹ ilu Eko si Ibadan.
Ninu atẹjade ti ajọ FRSC fi sita, alukoro ajọ naa  Bisi Kazeem ṣalaye pe taya tanka naa lo fọ lori ere eyi to mu ṣubu ti o si gbina.
Ọgbẹ Kazeem tun fidi rẹ mulẹ pe eeyan meji lo ba iṣẹlẹ naa lọ nigba ti ọkọ mọkadinlọgbọn ti wọn gbe si ẹgbẹ titi jona raurau.
Ajọ FRSC tun fikun ọrọ rẹ ninu atjade naa pe awọn janduku kan kọju ija sawọn ẹṣọ oju ọna atawọn panapana pẹlu oriṣiiriiṣi ohun ija oloro.
''Niṣe lawọn ẹṣọ oju ọna atawọn panapana sa asala fun ẹmi wọn lọ si agọ ọlọpaa to wa ni tosi ni Isheri.
Ọga agba ajọ FRSC, Ọmọwe Boboye Oyeyemi bu ẹnu ẹtẹ lu iṣẹlẹ naa.
Oríṣun àwòrán, @Stanley
Ọmọwe Oyeyemi ni ajọ FRSC n ṣe akitiyan lati bawọn tọrọ kan sọrọ ki opin le de ba awọn ọkọ tanka agbepo to n gbina loju ọna kiri.
Ajọ FRSC ti wa sọ fawọn araalu pe lilọ bibọ ọkọ ti n ja geere bayii loju ọna mọrosẹ Eko si Ibadan lẹyin  tawọn ti ko awọn ọkọ to jona ninu iṣẹlẹ ọhun kuro loju popo.
Ajẹ eṣọ oju popo ti wa rọ awọn awakọ loju ọna ọhun pe ki wọn ṣe jẹjẹ loju popo.
Ọkọ̀ táńkà agbépo tó gbiná lójú ọ̀nà mọ́rosẹ̀ Eko sí Ibadan dá súnkẹrẹ fàkẹrẹ sílẹ̀
Sunkẹrẹ fakẹrẹ ti di ọna mọrosẹ ilu Eko si Ibadan pa lẹyin ti ọkọ tanka agbepo bẹntiro kan gbina loju popo naa.
Agbegbe afara Kara loju ọna Eko si ilu Ibadan ni iṣẹlẹ ọhun ti ṣẹlẹ.
Iroyin ti a gbọ ni pe ina ọhun si n jo to fi di deedee aago kan oru ọjọ Abamẹta, ọjọ keje oṣu kọkanla ọdun 2020 lai si awọn oṣiṣẹ panapana nibẹ.
Awọn ero ti wọn n rinrin ajo kuro niluu Eko ni iṣẹlẹ ọhun ti dena mọ lẹyin ti wọn ko ri ọna kọja.
Ẹni to wa nibi iṣẹlẹ naa sọ pe ọpọ awakọ ti n kuro loju popo wọn ti wọn si kọju si awọn to n bọ wa si ilu Eko eleyi ti wọn n pe ni ''one way.''
A o maa mu ẹkunrẹrẹ iroyin naa wa fun yin laipẹ.
Bose Okeowo: Àárẹ̀ kékeré ló sọ mi dí aláàbọ̀ ara yìí ṣùgbọ́n...
EndSARS Protest Update: Seun Kuti dá ẹgbẹ́ tí baba rẹ̀, Fela Kuti dá silẹ̀ ní ọdún 1979 padà
Oríṣun àwòrán, Twitter
Ọdun 1979 ni Fela Kuti ṣe ifilọlẹ ẹgbẹ Movement of the People lati dije dupo aarẹ lorilẹede Naijiria nigba naa ki ijọba to daa ru.
Ṣeun Kuti to jẹ ọkan lara awọn ọmọ gbajugbaja olorin, Fela Kuti ti bu ẹnu atẹ lu igbesẹ ileeṣẹ ọlọpaa ni ipinlẹ Eko lati tako ifilọlẹ ẹgbẹ tuntun, Movement of the People ti wọn ṣe agbekalẹ rẹ.
Seun Kuti lasiko to n ba awọn oniroyin sọrọ ni Kalakuta Museun ni Ikẹja, nipinlẹ Eko sọ wi pe ileeṣẹ ọlọpaa ko ni aṣẹ lati tako ifilọlẹ ẹgbẹ naa eyi to jẹ agbende ẹgbẹ yii kan naa ti baba rẹ gbe kalẹ nigba aye rẹ.
Seun ni ''oyinbo buruku ni wọn kọ sibẹ, ti kọmisọnna ọlọpaa ni ipinlẹ Eko si buwọlu''.
Saaju asiko yii ni ikọ ọlọpaa ipinlẹ Eko ti fi atẹjade ranṣẹ si ẹgbọn Seun Kuti, Yeni wipe wọn yoo foju wina ofin ti wọn ba ṣe ipade kankan bii ti ifẹhọnuhan EndSars ni ile igbafẹ ''Fela Shrine'' naa.
Bakan naa ni aworan jade lori ayelujara nibi ti awọn ọlọpaa ti duro wamuwamu niwaju ile igbafẹ naa, ti wọn ko si gba ki ẹnikẹni wọle tabi jade.
Amọ, Seun Kuti ati ikọ rẹ lo agbegbe miran lati ṣe ifilọlẹ ẹgbẹ, Movement of the People naa eleyii ti baba rẹ Fela Kuti gbe kalẹ ni ọdun 1979.
Fela Kuti gbe ẹgbẹ naa kalẹ lati dije dupo aarẹ orilẹede Naijiria, eleyii ti ijọba Naijiria nigba naa fofin de lati dije dupo ninu idibo to waye nigba naa.
Seun Kuti ninu ọrọ rẹ ni ẹgbẹ naa wa fun ominira awọn eniyan lorilẹede Naijiria.
''Mo fẹ fi daa yin loju pe ẹgbẹ Movement of the People ko ni doju ti awọn ọmọ Naijiria nitori yoo wa fun awọn araalu ni.
Afojusun wa ni ki awọn owọn oṣiṣẹ lorilẹede Naijiria gbaruku ti ẹgbẹ naa, ki wọn si ja fun ominira orilẹede Naijiria.
''A gbọdọ ṣiṣẹ papo pẹlu awọn araalu lati rii wi pe ko si ẹnikẹni to gbẹyin ninu ijijagbara naa''
Seun Kuti ni gbogbo ẹgbẹ to n ja fun ominira orilẹede Naijiria lo gbọdọ parapọ bii ti igba ti Naijiria gba ominira ni ọdun 1960 lati tun ṣiṣẹ pọ fun ominira orilẹede Naijiria.
Awọn agbaagba ogbontagi agbẹjọro ni Naijiria, awọn ẹgbẹ, at'awọn eekan ilu, ti bẹnu atẹ lu bi ijọba apapọ orilẹ-ede Naijiria ti pe awọn oluwọde EndSARS ni agbesunmọmi.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Wọn sọ oko ọrọ si ijọba lori bi banki apapọ orilẹ-ede Naijiria, CBN ti gbe gbe apo ikowosi awọn oluwọde EndSARS ti pa.
Ijọba apapọ lo banki CBN lati ti apo ikowosi ogun eeyan ninu awọn oluwọde EndSARS, lori ẹsun pe owo to wa ninu apo ikowosi naa le wa fun igbesunmọmi.
Ẹgbẹ àwọn agbẹjọro ni Naijiria, NBA ni igbesẹ fihan pe ijọba to wa lode ko lootọọ.
Oríṣun àwòrán, Reuters
Alukoro ẹgbẹ NBA, Ọmọwe Raps Nduka sọ pe, iwọde EndSARS wa ni ibamu pẹlu ofin orile-ede Naijiria, bakan naa lo ni ohun ti wọn n beere lọwọ ijọba t'ọna.
Agbẹjọro Nduka ni gbigbẹsẹ le apo ikowosi awọn oluwọde EndSARS fihan pe, arumọjẹ lasan ni ileri ti ijọba ṣe lati wa ojutu si iwa ifiyajẹni awọn ọlọpaa tawọn oluwọde fẹ dopin.
Ninu ọrọ tiẹ, agbẹjọro agba, Mike Ozekhome(SAN) ni pipe awọn oluwọde EndSARS ni agbesunmọmi lodi sofin.
Ozekhome to bẹnu atẹ lu igbesẹ banki CBN lati ti apo ikowosi awọn oluwọde EndSARS pa ni, awọn ọmọ Naijiria ni ẹtọ labẹ ofin lati ṣe ifẹhonuhan.
Sickle Cell In Nigeria: Makinde ní ìgbàgbọ́ ninú ìdílé òun ṣèdíwọ́ láti ṣàyẹ̀wò ẹ̀jẹ̀
Ozekhome ni gbogbo ọgbọn tí ijọba n da ni lati dunkoko mawọn igbimọ to n ṣewadi iwa ifiyajẹni awọn ọlọpaa lawọn ipinlẹ kan.
Ninu ọrọ tiẹ, agbẹjọro to tun jẹ ajafẹtọ, Jiti Ogunye ni banki apapọ Naijiria, CBN fẹ sọ ara rẹ di oniyẹyẹ, pẹlu igbesẹ lati ti apo ikowosi awọn oluwọde EndSARS pa.
"Ogunye ni ile ifowopamọ ijọba ni CBN ṣe, kii ṣe ẹṣọ eto alaabo ni Naijiria."""
Oríṣun àwòrán, @BashirAhmaad
Igbakeji akọwe agba fajọ iṣọkan agbaye, UNO, Arabinrin Amina Mohammed ti sọ pe, o ṣeeṣe ki obinrin jẹ aarẹ orilẹ-ede Naijiria lẹyin Aarẹ Muhammadu Buhari ba pari ijọba rẹ.
Arabinrin Mohammed wa rọ awọn obinrin ni Naijiria lati gba ipo aṣiwaju aarẹ ilẹ Naijiria lọdun 2023.
Mohammed to ṣiwaju igbimọ awọn oṣiṣẹ agba ajọ UNO to n ṣabẹwo si Naijiria sọrọ yii niluu Abuja lọjọ Iṣẹgun.
Arabinrin Mohammed sọ pe, awọn obinrin to le gori aleefa gẹgẹ bi aarẹ orilẹ-ede Naijiria wa daadaa.
Oríṣun àwòrán, Twitter/Amina J. Mohammed
Asiko ti to fawọn obinrin lati dide nitori wọn ko idaji ninu awọn oludibo.
Ohun to ku fawọn obinrin ni lati ni atilẹyin awọn ọkunrin ni Naijiria, Mohammed lo sọ bẹẹ.
Igbakeji akọwe agba ajọ UNO ni ko si idi kan to le ni ki obinrin maa jẹ aarẹ Naijiria.
Lakotan, o ni awọn ọmọ orileede Naijiria gbọdọ fọwọ s'ọwọ pọ lati tun Naijiria ṣe lai fi ti ẹya tabi ọrọ oṣelu ṣe.
Gbogbo wa lo ni ojuṣe lati ṣe, idi niyii ti a fi gbọdọ ṣiṣẹ pọ fun igbega orileede Naijiria, Mohammed lo woye bẹẹ.
Oríṣun àwòrán, Instagram/Bashir Ahmad
Aarẹ Muhammadu Buhari ti rawọn ẹbẹ si awọn ọmọ Naijiria pe ti wọn ko ti ri ipa ijọba wi pe ki wọn ṣe suuru pẹlu oun.
Bakan naa ni Buhari bẹ awọn ti wọn gbagbọ pe ijọba to wa lode ko gbiyanju to pe ki wọn maa fi ṣe ibinu.
Minisita eto iroyin ati aṣa, Lai Mohammed lo gbẹnu aarẹ sọrọ yii nibi ipade to waye ni gbongan kan niluu Ilorin pẹlu awọn olori ijọba, awọn ọdọ, akẹkọọ, oṣiṣẹ, awọn iyalọja atawọn tọrọ kan lori rogbodiyan iwọde EndSARS.
Nigba ti o n jiṣẹ aarẹ Buhari nibi ipade naa, minisita eto iroyin ati aṣa sọ pe ''ijọba to wa lode mu ọrọ awọn ọdọ atawọn araalu lọkunkundun.
Ọgbẹni Mohammed ṣalaye pe ifẹ awọn ọdọ to wa lọkan ijọba Buhari lo jẹ ki o maa ṣe ọpọ eto ti yoo ṣe awọn ọdọ lanfaani.
''Ṣugbọn bi ijọba wa ko ba tii ni ipa lori gbogbo araalu, ẹ gba bẹẹ pẹlu wa,'' Mohammed lo ṣo bẹẹ,
Bose Okeowo: Àárẹ̀ kékeré ló sọ mi dí aláàbọ̀ ara yìí ṣùgbọ́n...
Minisita ni ijọba Buhari ko ri owo to pọ na lati fi ṣe ijọba bii awọn ijọba to ti wa ṣaaju.
Ọgbẹni Mohammed tun sọ pe ajakalẹ arun coronavirus ṣakoba nla fun ijọba ati gbogbo eeyan, o ni Naijiria n ṣẹṣẹ n bọ lọwọ ipa to buru ti covid-19 ni lori ọrọ aje ni.
''Ẹbẹ ni a n bẹ wi pe ki ẹ ni suuru ki ẹ si ran ijọba lọwọ,'' Minisita eto iroyin lo sọrọ yii.
AbdulQudus Bello ṣàlàyé bí òun ṣe dí aláàbọ̀ ara nítorí pọpọ́ọ̀fù àti ìbínú jàǹdùkù àdúgbò
O ni ijọba Buhari gbe miliọnu marunlelaadọrin kalẹ lati ṣe iranwọ fawọn ọdọ lẹnu iṣẹ wọn.
Minisita eto iroyin ati aṣa ni ẹgbẹẹgberun un awọn ọdọ ni wọn ti jẹ anfaani oniruuru eto bi N-POWER, N-TECH, N-AGRO ati MSMEs labẹ ijọba Buhari.
Gomina ipinlẹ Kwara, Abdulrazaq Abdulrahman, Emir Ilorin, Alhaji  Sulu Gambari atawọn leekan leekan mii lo wa nibi ipade ọhun.
Ondo Kidnap: Ọlọ́pàá ní ìyàwó adarí òṣìṣẹ́ Ondo tì gba òmìnira lẹ́yìn ọjọ́ méjì ní páńpẹ́ àwọn agbébọn
Oríṣun àwòrán, @OndoFirstBorn
Ileeṣẹ ọlọpaa nipinlẹ Ondo lawọn ti ribi doola ẹmi iyawo adari oṣiṣẹ ipinlẹ Ondo to wa ni ọdọ awọn ajinigbepawo.
Ọjọ meji gbako ni  Arabinrin Ale  ati arabinrin kan ti wọn ko darukọ rẹ lo nigbekun awọn alaburu yi.
Alukoro ọlọpaa Teo-Leo Ikoro ṣalaye fun BBC pe awọn ọlọpaa pẹlu fijilante ni wọn jijọ ṣawari awọn meji wọn yi.
O tun ṣalaye pe awọn ko san owo ẹmi fawọn ajinigbe naa nitori wọn salọ ni nigba ti wọn ri pe awọn agbofinro ti n sunmọ awọn.
''Awọn mejeeji ta doola wa lalaafia ti wọn si ti pada sọdọ mọlẹbi wọn.Ninu igbo tawọn aṣebi yi gbe wọn lọ la ti ri wọn.''
Lọjọbọ ni awọn ajinigbe wọn yi da ọkọ arabinrin Ale lọna lopopona Ondo-Akure nigba ti wọn dari pada si Akure lati Eko.
Ninu ọrọ rẹ Leo sọ pe inu awọn dun pe awọn ko doju  ija kọ awọn ajinigbe yi nitori o le ṣakoba fẹmi awọn ti wọn ji gbe.
Ileeṣẹ ọlọpaa ni ipinlẹ Ondo ti fi da awọn eniyan loju wi pe ki ọjọ oni to pari awọn a doola ẹmi iyawo adari awọn oṣiṣẹ ti wọn jigbe lọ pada.
Agbẹnusọ ileeṣẹ ọlọpaa nipinlẹ Ondo, Teo-Leo Ikoro lo sọ bẹẹ fun BBC News Yoruba lasiko ifọrọwanilẹuwo lori iṣẹlẹ ijinigbe naa.
Ikoro ni lootọ ni iṣẹlẹ naa waye ni agbegbe Owena ni ipinlẹ Ondo, eleyii to sunmọ ibugbe awọn ologun ni ipinlẹ Ondo.
''Ohun to ṣẹlẹ ni pe awọn agbebọn naa dasi wọn lọna, ti wọn si gba ọkọ lọwọ wọn pẹlu awọn to wa ninu ọkọ''
''Awọn meji jajabọ ninu ọkọ naa, ti wọn si pe ọlọpaa.''
''Lẹsẹkẹsẹ ni awọn ọlọpaa ati soja ti tọ ipaṣẹ awọn ajinigbe naa lọ, amọ wọn ti sa wọ inu igbo rere''
''Nibayii, awọn ọlọpaa pẹlu awọn ikọ ọmọogun to wa ni ipinlẹ Ondo ti n wa wọn, to si da wa loju pe ki ilẹ oni to ṣu wọn yoo gba itusilẹ''
Ni Ọjọbọ oṣẹ yii ni iroyin gbe e pe awọn ajinigbe ti ji ọkan lara awọn iyawo Adari Oṣiṣẹ nipinlẹ Ondo, Arakunrin Olugbenga Ale lọ lasiko to n bọ lati ilu Eko to ti lọ ra ọja.
Ọkan lara awọn iyawo Adari Oṣiṣẹ nipinlẹ Ondo, Arakunrin Olugbenga Ale ni awọn agbebọn ti jigbe lọ nipinlẹ Ondo.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Arabinrin naa ni awọn agbebọn dasi ni agbegbe Owena, ni opopona Ondo si Akure lasiko ti oun ati obinrin miran to wa ninu ọkọ rẹ n bọ lati ipinle Eko ti wọn ti lọ ra ọja.
Awọn ti iṣẹlẹ naa ṣoju wọn ni alẹ Ọjọbọ ni iṣẹlẹ naa waye lẹyin ti awọn agbebọn naa pa ọba Olufọn ti Ifọ ni agbegbe Elegbeka ni opopona Ọwọ si Ifọn.
Awọn ti iṣẹlẹ naa ṣoju wọn ni ọkan lara awọn to wa ninu ọkọ naa to jẹ obinrin sa mọ awọn ajinigbe naa lọwọ.
Bakan naa ni wọn  wi pe awọn ajinigbe naa yọnda awakọ ọkọ iyawo adari oṣiṣẹ nipinlẹ Ondo naa.
Wọn fikun wi pe Gomina ipinlẹ Ondo, Oluwarotimi Akeredolu mọ nipa iṣẹlẹ naa, ti wọn si ti lọ si ranṣẹ ibanikẹdun si wọn ni ile wọn.
Ileeṣẹ ọlọpaa ipinlẹ Ondo ni ọwọ awọn ti tẹ afurasi ajinigbepawo mẹrin, ti awọn si doola ẹmi awọn eeyan mẹwaa ninu eeyan mẹrindinlogun ti wọn ji gbe nipinlẹ naa.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ijinigbe ti a n wi yi waye l'Ọjọbọ ni opopona marose Akure si Owo gẹgẹ bi alukoro ọlọpaa Ondo, ọgbẹni Tee-Leo Ikoro ṣe sọ .
Ninu ifọrọwerọ pẹlu BBC, o ṣalaye pe lootọ lawọn eeyan mẹrindinlogun ti ọkunrin ati obinrin si wa ninu wọn ko si ọwọ awọn ajinigbe wọnyi.
Ikoro ni ''A ti mu eeyan mẹrin ti a fura si pe wọn mọ si iṣẹlẹ yi; ti a si tun doola ẹmi awọn mẹwaa ti wọn ji gbe. O ku eeyan mẹfa ti a ko ti ri ninu wọn''
Awọn iwe iroyin Naijiria kan jabọ pe awọn ti o kagbako awọn ajinigbe wọnyi n dari bọ pada lati ipade oloṣooṣu awọn iyalọja Akure ni.
Ileeṣẹ iroyin abẹle sọ pe ninu awọn ti wọn ji gbe ni iyalọja Isua Akoko, arabinrin Helen Edward wa.
Nigba ti BBC beere lọwọ Leo-Ikoro boya lootọ ni  iyalọja naa wa lara awọn ti wọn ribi doola o ni oun ko le sọ pato nitori awọn ti ọlọpaa doola pọ.
''Ati ọkunrin ati obinrin la ribi doola. Mi o mọ boya ẹni ti wọn n pe ni Iyalọja wa lara wọn ṣugbọn mo maa ṣe iwadii lori rẹ''
Alukoro ọlọpaa ni awọn ṣi n gbiyanju lati ṣawari awọn eeyan mẹfa to ku.
'Bí aya bá kọ ọkọ rẹ̀ silẹ̀, kó wà láì lọ́kọ̀'
Agbẹjọ́ro ọ̀dọ́ fèsì níbi ìjókòó ìgbìmọ̀ tó ń ṣe ìwádìí ìfìyàjẹni nìpínlẹ̀ Eko
Coronavirus in Oyo: Ìjọba ní gbogbo ìpéjọpọ̀ tí kò bá tẹ̀lé òfin ìdènà àrùn ni òun yóò tìpa
Oríṣun àwòrán, @seyiamakinde
Ijọba ipinlẹ ti gbe ilẹkun ileẹkọ giga kan tipa nitori ajakalẹ arun Coronavirus to suyọ nibẹ.
Igbimọ amusẹya ti ijọba gbe kalẹ fun arun Coronavirus lo sawari isẹlẹ naa, ti wọn ko si kede orukọ ile ẹkọ giga ti aje ọrọ naa si mọ lori sita.
Ijọba wa leri leka pe oun setan lati tilẹkun ileẹkọ, ibudo ijọsin tabi ileesẹ to ba tako ilana to n dena arun Coronavirus pa.
Ijọba Oyo ni awọn ibudo gbogbo gbọdọ maa tẹle ofin to dena sisun mọ ara ẹni pẹki pẹki, lilo ibomu ati ọsẹ ifọwọ, to si tun n rọ awọn araalu lati maa fi oju sọri.
Atẹjade kan ti igbimọ amusẹya ọhun fisita salaye pe, awọn igbesẹ naa pọn dandan nitori bi wọn tun se kẹẹfin ọwọja arun Coronavirus nile ẹkọ giga kan nipinlẹ naa.
Atẹjade naa ni titẹle awọn ilana to n dena Coronavirus nikan ni ọna lati dẹkun itankalẹ ati ọwọja arun naa.
Queen Badra Olaitan: Ọ̀pọ̀ nnkan tó bàmí nínú jẹ́ ni ojú mi rí lọ́dún 2020
Oríṣun àwòrán, Instagram/@queenola2
Yoruba ni oju ẹni maa la, a ri to, oju ẹni maa la, a ri iyọnu, bẹẹ si ni ẹni ti yoo ba ga, ẹsẹ rẹ yoo tiirin.
Awọn asamọ ọrọ yii lo n se apejuwe itan igbe aye Olori Badrat Olaitan Aajoke Adeyemi, gẹgẹ bo se salaye loju opo Instagram rẹ, lasiko to n se ayẹyẹ ọjọ ibi rẹ.
Olori Badrat to bi ọmọ mẹta fun Ọba Adeyemi, rọra se ajọyọ ọjọ ibi ọdun Kọkanlelọgbọn rẹ lori ayelujara naa ni lẹwọlẹ.
A o ranti pe ni ọdun to kọja ni Ayaba Badra se ayẹyẹ ọgbọn ọdun ni aafin Oyo tilu tifọn, to si n pokiki rẹ lori awọn oju opo ayelujara.
Oríṣun àwòrán, Instagram/@queenola2
Amọ nigba to n sọrọ lori ọjọ ibi rẹ naa, to waye lọjọ Kẹta osu Kọkanla ọdun 2020, Olori Badra ni oju oun ti ri nnkan lọdun 2020 ta wa yii.
"O ni ""Oju mi ti ri ọpọ nnkan lọdun yii, Mo ja aimọye ija, wọn ja mi kulẹ, ọkan mi rẹwẹsi, wọn parọ mọ mi, ti mo la ipo ibanujẹ kọja."""
Olori Badra fikun pe, oun tun ka ọpọ iroyin lawọn oju opo ayelujara nipa ara oun, ti oun gan alara ko mọ nipa rẹ rara, eyi to se ajeji si oun alara.
O wa fikun pe oun gbogbo lo n sisẹ pọ fun rere ni, nitori pe ko ye oun lasiko ti oun n la awọn isẹlẹ naa kọja pe oun fẹ lọ sipo to tun ga ju ipo ti oun wa lọ ni.
Oríṣun àwòrán, queenola2 Instagram
Ti mo ba sọ itan igbesi aye mi fun yin, o seese kẹ ba mi sọkun, o si ti wa ye mi bayii pe gbogbo ohun to n dan kọ ni wura, sugbọn Alihamdulilahi, mo ti ri iwosan ọkan.
Ayaba Adeyemi naa wa rọ awọn ololufẹ rẹ lati se adura fun oun ni ayajọ ọjọ ibi rẹ naa.
Olori Badrat, bẹẹ ba gbagbe, ni ẹnu n kun pe o ti kuro ni aafin Ọba Lamidi Olayiwola Adeyemi Kẹta gẹgẹ bii olori rẹ.
Eyi ko si sẹyin awuyewuye ọrọ kan to gba ori ayelujara kan lasiko kan pe, arẹwa ayaba naa n ni ifẹ ikọkọ pẹlu Ọba Fuji, King Wasiu Ayinde Marshall, Kwam 1.
Pẹlu awọn ohun ti olori Badra kọ sori ayelujara naa, o ti n foju han pe o seese ko ma si lara awọn olori to n gbe pẹlu Ọba Adeyemi mọ, ninu aafin rẹ nilu Oyo.
Bakan naa, Olori Badra ti si ile itaja asọ nla kan si adugbo Ikeja nilu Eko ninu ọdun 2020 yii, eyi to tun n mu kawọn eeyan maa ni ilu Eko ni Ayaba Badra n gbe bayii, kii se Oyo mọ.
Ibadan Market looting: Ọjà ẹgbẹ̀lẹ́gbẹ́ mílíọ̀nù ni jàǹdùkú kó lọ́jà Agbeni, wọ́n tún sọná sun ṣọ́ọ̀bù
Oríṣun àwòrán, @Fedfireoyo
Awọn janduku yabo ọja Agbeni Ologede niluu Ibadan lọjọ Abamẹta, nibi ti wọn ti ji ọpọ nnkan ko ninu ṣọọbu mẹẹdogun, ti wọn si sọna si awọn ṣọọbu naa.
Iroyin ti a gbọ ni pe, ọja to to ẹgbẹlẹgbẹ miliọnu owo naira lawọn janduku ọhun jigbe lọ.
Awọn kan tiẹ sọ pe, awọn janduku naa sọna sawọn ṣọọbu ọhun lati le bo iṣẹ ibi ti wọn ṣe mọlẹ.
Awọn to n gbe agbegbe naa, ti wọn ri eefin ina to sọ lala, ni wọn kan si ileeṣẹ panapana ipinlẹ Oyo, ni nnkan bii aago mẹfa owurọ ọjọ Abamẹta.
Oríṣun àwòrán, @Fedfireoyo
Ṣugbọn ọga agba ileeṣẹ panapana ipinlẹ Oyo, Ọgbẹni Moshood Adewuyi ṣalaye pe, awọn janduku ọhun kọju ija si awọn panapana pẹlu ada atawọn ohun ija oloro miran nigba ti wọn de ibẹ.
Iṣẹlẹ ọhun ni a gbọ pe, o da ibẹru-bojo silẹ lagbegbe naa lẹyin tawọn eeyan n gbọ iro ibọn nigba tawọn ẹṣọ Operation Burst kọju ija si awọn janduku naa.
Pistachio Green Puppy: Àwọn ẹgbẹ́ rẹ̀ jẹ́ aláwọ̀ funfun, tí òun sì jẹ́ aláwọ̀ ewé
Ọgbẹni Adewuyi sọ pe awọn ẹṣọ Operation Burst to koju awọn janduku naa ri pe alaafia jọba pada lagbegbe ọhun.
Iroyin kan tun sọ pe, ọwọ ti tẹ awọn meji to wa lara awọn to ṣagbatẹru iṣẹlẹ laabi yii.
Bisi Alimi: Èmi tí mò ń tọrọ ilé gbé ní London, wá di onílé méjì
Oríṣun àwòrán, Instagram/bisialimi
Ọrọ ifẹ bi adanwo ni lawọn Yoruba maa n wi. Eyi lo difa fun Bisi Alimi to fẹ ọkunrin ẹgbẹ rẹ, Anthony Davis gẹgẹ bi ọkọ.
Bisi Alimi, ẹni to n dupẹ lọwọ Eleduwa fun ayẹyẹ igbeyawo rẹ pẹlu Davis, to pe ọdun mẹrin lọjọ Aiku.
Alimi sọ loju opo Instagram rẹ pe, ko si ọna mii lati ṣayẹyẹ ọdun kẹrin igbeyawo oun ati Davis, ju bi awọn ṣe ṣẹṣẹ ra ile keji niluu London.
''Mi o le gbagbọ pe emi, to jẹ pe mi o rile gbe, ti awọn ọrẹ gba sile, lo wa di onile niluu London, ile ti kii ṣe ẹyọ kan amọ meji,'' Alimi lo sọ bẹẹ.
Alimi wa dupẹ lọwọ gbajugbaja agbohunsafẹfẹ nni, Funmi Iyanda, fun bo se gbaruku ti oun ninu irin-ajo aye rẹ.
Bakan naa lo tun dupẹ lọwọ awọn ọrẹ rẹ miran ti wọn ti ṣe iranwọ kan tabi omiran fun un.
Alimi tun rọ awọn eeyan lati mase kaarẹ pẹlu ohun ti wọn fẹ jẹ laye, o ni bo pẹ bo ya, yoo pada wa si imuṣẹ, bi wọn ko ba kaarẹ.
Ọgbẹni Alimi tun gbadura loju opo Instagram pe, oun ati ọkọ oun yoo ṣe ọpọlọpọ ọdun laye.
Cholera in Oyo: Èèyàn Mọ́kànlá dèrò ọ̀run n‘Ibadan torí àrùn àìmọ̀dí
Oríṣun àwòrán, @OfficialSeyiMakinde
O kere tan, eniyan mọkanla lo ti padanu ẹmi wọn lẹyin ti awọn ara agbegbe ijọba ibilẹ Lagelu lugbadi aisan aimọdi.
Awọn marun mii ṣi wa ni ile iwosan nibi ti wọn ti n doola ẹmi wọn lọwọ.
Iroyin ti a ko le fi idi rẹ mulẹ ni aisan onigbameji ni, nitori awọn ami ti awọn eniyan to lugbadi aisan aimọdi naa n fihan.
Amọ, ijọba ni awọn ko lee fi idi ọrọ naa mulẹ ni isinsinyii, amọ awọn ti bẹrẹ ayẹwo ati iwadii lori iru aisan to jẹ.
Oríṣun àwòrán, @OYSG
Awọn ara adugbo Ariku ni agbegbe naa ni isẹlẹ yii ti kọkọ bẹrẹ, ti eniyan marun si ti papoda nitori arun naa.
Lẹyin naa ni arun ọhun tan ka de agbegbe Lagun, ti o si tun mu ẹmi eniyan mẹfa lọ lẹẹkan naa.
Alaga ijọba ibilẹ Lagelu, Kelani Abdullahi ni awọn ti bẹrẹ iwadii ni pẹrẹwu lori aisan naa, to si fi idi rẹ mulẹ pe, lootọ ni eniyan mọkanla ti jẹ Olorun ni pe, ti eniyan mẹrin mii si wa ni ileewosan.
Akomolede ati Aṣa lori BBC:Wo ìrúfẹ́ ìgbeyàwó méje tó wà nílẹ̀ Yorùbá àti ojúṣe Alárinà
Bakan naa ni Kọmisọna fun eto ilera nipinlẹ Ọyọ, Bashiru Bello ni awọn ko i tii le fi idi rẹ mulẹ pe, aisan onigbameji' 'Cholera' lo n ṣeku pa awọn eniyan naa.
Amọ, o fikun wi pe, aisi imọtoto wọpọ ni awọn agbegbe ti arun naa ti bẹ silẹ ni ipinlẹ Ọyọ.
Oríṣun àwòrán, @TheRoyOsuji
Ẹbi  iyalọja Isua Akoko ti ni ko i tii si ẹni to doola ẹmi Iyalọja naa nitori o ṣi wa ni panpẹ awọn ajinigbe.
Eyi ko ṣeyin ikede awọn ọlọpaa pe awọn ti doola ẹmi awọn ti ajinigbe gbe lọ ni ọsẹ to kọja ni Isua Akoko.
Agbẹnusọ ileeṣẹ ọlọpaa ni ipinlẹ Ondo, Teo-Leo Ikoro ni awọn ti doola ẹmi awọn arinrinajo ti awọn ajinigbe ṣekọlu si ni ọsẹ to kọja ni ipinlẹ naa.
Amọ, awọn ẹbi Iyalọja naa ni awọn ṣi ba iya awọn sọrọ ni panpẹ awọn ajinigbe, to ṣi n bẹbẹ pe ki awọn jọwọ da owo jọ, lati san fun awon ajinigbe to n beere owo ẹmi lọwọ wọn.
Ifa Worshippers: Àwọn ẹlẹ́sìn ìbílẹ̀ ń fẹ́ kíjọba pín èrè òṣèlú alágbádá yíká gbogbo ẹ̀sìn
Ọmọ iyalọja naa, Abilekọ Alaba Edward ni gbogbo ilu Isua Akoko lo hoo fun ayọ nigba ti wọn gbọ iroyin pe, awọn ọlọpaa ti doola ẹmi iyalọja naa, amọ ibanujẹ lo jẹ fun awọn wipe ọrọ ko ri bẹẹ.
Nibayii, Abilekọ naa ni awọn ajinigbe ni ki awọn lọ mu miliọnu marun wa, lẹyin ti wọn kọkọ beere fun miliọnu mọkanla naira, amọ ko si eleyii ti awọn lagbara lati san ninu owo naa.
Ati wipe, iyalọja naa nikan ni obinrin  to wa laarin awọn arinrinajo marun ti awọn ajinigbe naa ṣekọlu si.
Bose Okeowo: Àárẹ̀ kékeré ló sọ mi dí aláàbọ̀ ara yìí ṣùgbọ́n...
Bakan naa ni awọn oloyeni ilu Isua Akoko wa kesi ileeṣẹ ọlọpaa lati tẹle aṣẹ Ọga Agba ọlọpaa lorilẹede Naijiria, Muhammed Adamu to ni ki awọn ọlọpaa pada si oju popo lati doola ẹmi awọn arinrinajo,
''Nitori ibẹru pe awọn ọlọpaa wa ni oju popo jẹ ki ijinigbe rọlẹ si ni agbegbe naa.''
Awọn oloye naa wa kesi ileeṣẹ ọlọpaa lati mase jẹ ki awọn janduku ati ọdaran gba iṣakoso orilẹede Naijiria nitori aibikita awọn ọlọpaa.
Oríṣun àwòrán, Bisi Alimi Foundation
Awọn Yoruba lo maa pa a lowe pe, bi ko ba nidi, obinrin kii jẹ Kumolu.
Emir ilu Birnin Gwari nipinlẹ Kaduna, Mallam Zubairu Jibrin Maigwari II ti wa woye pe, iwa iṣekuṣe akọ sakọ ati abo sabo to gbilẹ kan, lo ṣokunfa eto aabo to mẹhẹ lapa ariwa orilẹede Naijiria.
''Lonii lapa ariwa Naijiria, aimọye ọkunrin lo n fẹ ọkunrin ẹgbẹ rẹ, tawọn obinrin si obinrin naa ṣi n bara wọn ṣe ṣina ni gbangba lai fibo rara,'' Emir Birnin Gwari lo sọ bẹẹ.
Mallam Maigwari II ni awọn iwa idọti yii gan an ti to, ki Ọlọrun binu si apa Ariwa orilẹede Naijiria.
Oríṣun àwòrán, Facebook/Emir of Birnin Gwari
Emir naa sọ pe, ohun kan to le mu ki Ọlọrun yọnu si apa Ariwa Naijiria ni pe, ki wọn wolẹ adura, ki wọn si tọrọ idarijin ẹsẹ lọwọ Eleduwa.
Emir ilu Birnin Gwari ni ''a nilo igbala ọkan, Ọlọrun nikan lo le ra wa pada pẹlu awọn iwa buruku ta n hu yii. Ko sẹni to le ṣe e.''
O ni aṣa ki akọ maa fẹ akọ ati abo si abo ti di meji tọrọ bayii, eyi ti ọpọ fi n yangan lawujọ.
Pistachio Green Puppy: Àwọn ẹgbẹ́ rẹ̀ jẹ́ aláwọ̀ funfun, tí òun sì jẹ́ aláwọ̀ ewé
Mallam Maigwari II sọ pe, ko si ibẹru Ọlọrun mọ, o ni ohun to ba wu ibinu Ọlọrun ko ṣe, ni iwa bawọn eeyan se kọ lati bẹru rẹ.
Emir Birnin Gwari ni idi gan naa niyii ti arelu ati ajaalu fi n ṣẹlẹ lagbegbe Ariwa orilẹede Naijiria.
Lekki Toll Gate: CNN vs Lai Mohamamed rèé o!
Oríṣun àwòrán, CNN
Ileesẹ iroyin agbaye ni,CNN, ti fesi si ọrọ Minisita feto iroyin Naijiria Lai Mohammed to ni ijọba yoo fofin de ileesẹ iroyin naa lori ayederu iroyin to gbe jade nipa isẹlẹ iyinbọn paniyan to waye ni Lekki.
Ileesẹ naa sọ pe iwadii to mundadoko lawọn se ki awọn to gbe iroyin naa jade nitori gbọin gbọin lawọn duro lori iroyin tawọn gbe jade ṣaaju lori iṣẹlẹ naa.
Lasiko to n sọrọ pẹlu awọn akọroyin lọjọbọ ni Minisita Lai Mohammed sọ pe ko si ẹnikankan to ku ninu ikọlu to waye ni Lekki.
Bẹẹ lo sọ pe ko si mọlẹbi kankan to jade sita lati wa kede pe awọn padanu eeyan kankan lasiko ikọlu to waye logunjọ osu Kẹwa ọdun 2020.
CCC Genesis Global: Ǹkan mẹ́wàá tí ẹ ò gbọ́ rí nípa Israel Oladele, Woli ìjọ Genesis Global
Ẹ̀ṣọ Gbajabiamila yìnbọn pa fẹ́ńdọ̀ kan l'Abuja, àwọn akẹgbẹ́ rẹ̀ fẹ ṣe iwọde
Báyìí ni olùwọ́de EndSARS, Eremosele Adene ṣe gba òmìnira lọ́wọ́ ọlọ́pàá Nàìjíríà
CCC Genesis Global: Ǹkan mẹ́wàá tí ẹ ò gbọ́ rí nípa Israel Oladele, Woli ìjọ Genesis Global
O fi kun ọrọ rẹ pe ẹka to n mojuto iye awọn eeyan to ku nipinlẹ Eko naa ti kesi araalu to ba padanu eeyan wọn kankan lati wa ran awọn lọwọ fun eto  idanimọ oku to ba ku laarin ọjọ Kọkandinlogun si ọjọ Kẹtadinlọgbọn Osu Kẹwa.
CNN sọ pe lọpọ igba lawọn gbiyanju lati ba ileesẹ ologun Naijiria sọrọ ati ileesẹ ọlọpaa.
Wọn ni ileesẹ ọlọpaa kọ lati fesi ti atẹjade kan lati ọdọ ijọba ipinlẹ Eko si ni awọn ko ni nkankan sọ lasiko ti igbimọ iwadii si n joko lori ọrọ naa.
Ninu iwadii ati iroyin ti CNN gbe jade wọn lawọn kan si awọn akọsẹmọsẹ to salaye pe asẹku ọta ibọn tawọn fi han jẹ iru eyi tawọn ọmọ ileesẹ ologun Naijiria n lo.
Bakan naa ni wọn ni gbogbo fọnran fidio tawọn fi han jẹ ojulowo sugbọn ti Minisita layederu ni.
CNN ni Minsita Lai Mohammed ko mu ẹri kankan wa lati fi han pe ayederu ni fidio awọn tabi pe awọn ọta ibọn naa kii se tawọn ọmọ ogun Naijiria.
Ilẹ̀ Amẹ́ríkà wà lẹ́yìn àwọn olùwọ́de, Buhari dẹ́kun ìpànìyàn - Joe Biden
Buhari, máṣe gbá ìpànìyàn Lekki sórí ààtàn, kò yẹ́ kí ológun yin ọ̀dọ́ níbọn - Bode George
Wo ohun tí Fashola rí níbi ìṣẹ̀lẹ̀ Lekki Tollgate tó ń fa ariwo lórí ayélujara
Taa gan ló ni Lekki Toll gate láàrin aráàlú àti Asiwaju Tinubu?
Minisita eto ibanisọrọ ati iroyin lorilẹede Naijiria, Lai Mohammed ti sọ pe, awọn ọmọ ologun ko yinbọn lu oluwọde kankan nibi iṣẹlẹ Lekki Toll gate to waye loṣu kẹwaa, ọdun 2020.
Lai Mohammed lo sọ ọrọ naa nibi ipade awọn akọroyin kan to waye ni ilu Abuja, nibi to ti sọ iha ti ijọba apapọ kọ si iwadii CNN ọhun.
O ni irọ patapata ni iroyin ti ileeṣẹ CNN gbe jade pe awọn ọmọ ogun pa awọn oluwọde ni Lekki lalẹ ọjọ naa.
Lai Mohammed ni ori ayelujara lasan lawọn ọmọ Naijiria ti n pariwo pe sja paayan, ko sẹni to ni aridaju.
Minisita naa ṣalaye pe gbogbo ipinlẹ Eko ni ijọba da awọn sọja si lẹyin ti ijọba Eko bere fun iranlọwọ wọn nitori apa awọn agbofinro ko ka iwọde naa mọ, kii ṣe Lekki nikan.
O ni wọn sọ fun awọn ologun naa iru iha to yẹ ki wọn kọ si awọn oluwọde ki wọn to de iloro Lekki ti awọn oluwọde wa, ati pe wọn ko yin ibọ pa eeyan kankan.
Bo tilẹ jẹ pe Lai ni awọn ṣoja naa yinbọn, ṣugbọn o ni kii ṣe ọta to lagbara lati gbẹmi eeyan ni wọn yin, ati pe inu afẹrẹ lasan ni wọn yin ibọn naa si, wọn ko doju rẹ kọ ẹnikẹni.
Bí o bá bá ààrùn ìpẹ́pẹ́ gbígbẹ lára arẹwà obìnrin rẹ̀, kí loó ṣe?
Nigba to n bu ẹnu atẹ lu iroyin ileeṣẹ CNN, Lai sọ pe ko si oku kankan ti wọn ri he ni iloro Lekki, ati pe ko si ẹbi kankan to wa sọ fun ijọba pe eeyan wọn di awati lẹyin iṣẹlẹ naa.
O tẹsiwaju pe ki ẹnikẹni to ba ni ẹri pe awọn ologun ṣekupa ọpọ eeyan ni Lekki le lọ fi ẹri naa han niwaju igbimọ to n ṣewadii iṣẹlẹ ọhun, tabi ko gbẹnu dakẹ.
Ni ti CNN, lai Mohammed ṣalaye pe iwadii ofege ni wọn ṣe, eyii to yẹ ko jẹ ohun itiju fun wọn gẹgẹ bii ileeṣẹ iroyin to kari aye.
Lai sọ pe, inu ijọba apapọ dun si iṣẹ ti awọn ologun ati awọn agbofinro  ṣe ni Lekki Toll gate, nitori wọn fi ẹmi ara wọn sinu ewu fun abo ilu.
Lẹyin naa lo ṣalaye pe ko din ni ọmọ ogun mẹfa ati ọlọpaa mẹtadinlogoji ti ẹmi wọn ba atunbọtan ifẹhonuhan EndSARS ọhun lọ, yatọ si awọn ọkọ ati agọ ọlọpaa to jona.
Oríṣun àwòrán, @AyowoleSanyaolu
Ijọba ipinlẹ Eko ti fesi si iroyin iwadii CNN lori ohun to waye ni Lekki Toll gate logunjọ, oṣu kẹwaa, ọdun 2020.
Nigba ti  BBC kan si ijọba, wọn ni awọn ko ni ohunkohun lati sọ lori fidio ti ileeṣẹ iroyin CNN gbe jade, eyii to n ṣafihan pe ijọba pa irọ lori iṣẹlẹ to waye lẹnu iloro naa.
Wọn ni awọn ko le sọ ohun kankan lọwọ yii lori fidio CNN titi di igba ti esi igbimọ ti wọn kalẹ lati ṣe iwadii iṣẹlẹ naa yoo fi jade jade.
Agbẹnusọ gomina Babajide Sanwo-Olu, Gboyega Akosile sọ fun BBC pe, iwadii ṣi n lọ lọwọ, nitori naa yoo ṣoro lati sọ ohunkohun lasiko yii.
Oríṣun àwòrán, BABAJIDE SANWO-OLU/TWITTER
Iwadii ti ileeṣẹ iroyin CNN ṣe fi han pe awọn ọmọ ileesẹ ologun Naijiria dana ibọn ya awọn oluwọde EndSARS ni Lekki Toll Gate.
Ṣugbọn ileeṣẹ ologun ti fesi pe ko si ootọ ninu ọrọ ọhun, nitori awọn ko yibọn lu ẹnikẹni.
Wọn ni ọta ti wọn yin kii ṣe eyii to le gbẹmi eeyan ati pe inu afẹfẹ lasan ni awọn yin ibọn naa si.
Oríṣun àwòrán, Other
Ninu iwadii CNN, wọn ni ọpọlọpọ wakati ni awọn fi yẹ awọn fidio kan ti awọn eeyan ya nibi iṣẹlẹ ọhun wo, bẹẹ ni wọn si tun gba ọrọ lẹnu awọn oṣoju mi koro, awọn ti ọrọ naa ṣe si atawọn ti wọn padanu ẹbi wọn nibi iwọde naa.
CNN ni gbogbo awọn ẹri wọnyii ni wọn ko jọ pọ ki wọn to gbe iwadii wọn jade.
Ki lo ṣelẹ sẹyin?
Oríṣun àwòrán, EPA
Awọn oluwọde ENDSARS to gbe asia orilẹ-ede Naijiria dani ni agbegbe Ikeja nilu Eko, lọjọ kẹẹdogun, oṣu Kẹwaa, sun 2020
Ijọba orilẹ-ede United Kingdom, ti fesi lori iwe ẹsun ti awọn ọmọ Naijiria fọwọ si, ti wọn si fi ransẹ si.
Iwe naa lo n ke si awọn orilẹ-ede agbaye to wa ninu ajọ Commonwealth, lati fi 'iya' jẹ awọn olori Naijiria gẹgẹ bi ibawi, fun ẹnikẹni ninu wọn to lọwọ ninu titẹ ẹtọ ọmọniyan loju, gẹgẹ bi ofin ajọ naa ṣe sọ.
Ọmọ Naijiria bii okoolerugba o din diẹ (219,665) lo fi ọwọ si iwe ẹsun naa lọ sọdọ ijọba UK.
Ile aṣofin orilẹ-ede UK sọ pe, ominu nkọ oun lori rogbodiyan to waye lasiko iwọde ENDSARS, ati pe awọn ṣi n duro de iwadii ti ijọba Naijiria yoo ṣe lori ẹsun ifiyajẹni ti araalu fi kan awọn ọlọpaa.
Oríṣun àwòrán, @GOVUK
Iwe ẹsun to ba ti ni ju ẹgbẹrun lọna ọgọrun eeyan to fọwọ si , ni ile aṣofin orilẹ-ede UK ma n jiroro le lori, iwe ẹhonu ENDSARS yii si ti le ni ẹgbẹrun lọna igba.
Amọ ṣa, wọn ni awọn kii sọ igbesẹ ti awọn yoo gbe lori awọn iwe ẹsun naa ni gbangba.
Ajàfẹ́tọ ọmọniyàn kan, Kenechukwu Okeke ti fẹ̀sùn ìwà ọ̀daràn kan àádọ́tà èèyàn nílé ẹjọ́ Májísíreeti kan nílùú Abuja.
Ẹ̀ṣùn tó fi kàn wọ́n dá lórí ipa ti wọ́n kó nínú ìwọ́de ìfẹ̀hónúhàn #Endsars tó wáye ni oṣù tó kọjá.
Okeke fẹ̀sùn kàn pé lásìkò ìfẹ̀hónú hàn náà, ọ̀pọ̀ dúkìá ló sòfò, ìdí sì nìyìí tí wọn fi gbọdọ̀ fi àwọn tó wà lẹ́yìn ìwọ́de náà jófin.
Àwọn tó pè lẹ́jọ́ náà ni, Damini Ogulu ti àwọn ènìyàn mọ̀ sí Burna Boy, David Adeleke (Davido) Folarin Falana (Falz); Debo Adebayo (Mr Macaroni), àti Maryam Akpaokagi (Taoma).
Peter àti Paul Okoye, Innocent Idibia (Tuface), Bankole Wellington (Banky W), Tiwa Savage, Michael Ajereh (Don Jazzy ) àti Yemi Alade.
Oríṣun àwòrán, Kenechuckwu/twitter
Àwọn míràn tún ni Pasitọ, Daystar Christian Centre, Sam Adeyemi, ajàfẹ́tọ ọmọniyan, Aisha Yesufu; agbábọ́ọ̀lù Nàìjíríà nígbà kan rí, Kanu Nwankwo; ọ̀mọ̀wé Joe Abah, Kiki Mordi, gbájugbajà òṣèré Nollywood Yul Edochie àti Uche Jombo.
Feyikemi Abudu, Olorunrinu Oduala, Pamilerin Adegoke, Japhet Omojuwa, Ayo Sogunro àti Deji Adeyanju náà kò gbẹ́yìn.
Oríṣun àwòrán, Kenechukwu/twitter
Oríṣun àwòrán, Kenechukwu/twitter
Ọjọ́ Ajé ló gbé ọ̀rọ̀ náà lọ sí ilé ẹjọ́, pé àwọn ènìyàn náà kó ipa ribiribi nínú ìfẹ̀hónúhàn EndSars, èyí tó padà yìí sí rògbòdìyàn
Nínú ìwé ẹ̀sùn tó fi pẹjọ́ lo ti sàlàyé pé, gbogbo nkan ìní òun ló bàjẹ́ poo.
Oríṣun àwòrán, Screenshot
Kókó ohun tí ìràn Yorùbá ń fẹ́ lọ́dọ̀ ìjọba àpapọ̀ nìyí
Oríṣun àwòrán, @BashirAhmaad
Awọn agbaagba nilẹ kaarọ oojire, ninu eyi ti awọn gomina ipinlẹ Oodua mẹfẹẹfa wa, ti se ipade pẹlu ijọba apapọ nilu Abuja lọjọ Aiku.
Lara awọn to si wa nibi ipade naa tun ni awọn ọba alaye nilẹ Oodua, awọn minisita lati ẹkun iwọ oorun guusu Naijiria, awọn gomina ati ikọ asoju ijọba.
Aarẹ Muhammadu Buhari si lo se atọna ipade ọhun lẹyin iwọde EndSARS ati rogbodiyan to tẹle, eyi to se okunfa ole jija, idaluru ati biba alaafia ilu jẹ, paapaa nilu Eko.
Lara awọn ọba alaye to wa nibi ipade Ọọni ti Ile Ife, Alaafin ti Oyo, Eleko ti Eko, Ọ́lọwọ ti Ọwọ, Ọrangun ti Oke-Ila, Ayangburen ti Ikorodu ati Alawẹ tilu Aawẹ pẹlu Olu ti Ilaro ati Ọwa-Ooye ti Okemesi.
Orisirisi lo n jẹyọ nibi iwadii igbimọ to n gbẹjọ ifiyajẹni ati iwa aitọ lati ọdọ ọlọpaa si ara ilu nipinlẹ Eko.
Ni ijoko ipade naa to waye kẹyin, n ṣe ni ọgagun to n ṣoju ileeṣẹ ologun niwaju igbimọ naa ṣalaye pe, awọn ko yinbọn pa oluwọde kankan ni Lekki.
Ninu ọrọ rẹ Ọgagun Musa Etsu-Ndagi sọ pe, Gomina Babajide Sanwo-Olu pe oun lori ago lalẹ ọjọ Isẹgun ti isẹlẹ Lekki naa waye, to si ni ọgagun kan torukọ rẹ n jẹ Bello, ti n yinbọn lu awọn oluwọde ni Lekki.
Olori ọwọ kẹsan ileesẹ ologun (9 Brigade) naa sọ ọrọ yii, ninu iwe ijẹri to kọ siwaju igbimọ oluwadi ọhun lọjọ Ẹti.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Musa ni kete ti ọrọ yii to oun leti, ni oun ti pe Bello to jẹ ọga ọwọ karundinlaadọrin ileeṣẹ ologun (65 Battalion) to wa ni Bonny Camp, to si sọ fun oun pe ibọn ti ko ni ọta ninu, lawọn yin soke, kii ṣe ọta gidi.
Ọga ologun naa tẹnumọ pe, awọn ọmọ ogun ko yinbọn lu oluwọde tabi pa ẹni kankan, ati pe iroyin to ni awọn pa awọn eeyan nipakupa lalẹ ogunjọ oṣu Kẹwa ọdun yii, kii ṣe ootọ.
Bẹẹ lo tun sọ pe, awọn ọmọ ogun ko gbe oku ẹnikankan kuro nibi iṣẹlẹ naa.
Oríṣun àwòrán, @LASG
Bello ni koda, niṣe ni inu awọn oluwọde naa dun nigba ti wọn ri awọn ati pe, oun paapaa fun awọn oluwọde ni omi ati ati ọti ẹlẹrindodo pẹlu imọran pe, ki wọn pada sile.
Yatọ si awọn wọnyii, awọn ọgagun mii to wa jẹri niwaju igbimọ naa ni ọgagun to n dari 81 Military Intelligence Brigade to wa ni Victoria Island, ọgagun Ahmed Taiwo, olori oṣiṣẹ ọmọ ogun 81 Division V.I kanna, Nsikak Edet ati ọgagun Francis Omata to n dari 81 Division Garrison.
Pistachio Green Puppy: Àwọn ẹgbẹ́ rẹ̀ jẹ́ aláwọ̀ funfun, tí òun sì jẹ́ aláwọ̀ ewé
Ohun to jẹyọ ninu ọrọ awọn ọgagun wọnyi ni pe, iwọde naa to kọkọ n lọ nirọwọrọṣẹ, pada di onijagidijagan.
Ninu ẹri ti wọn jẹ niwaju igbimọ naa, wọn sọ pe awọn ologun ko yinbọn lu oluwọde, bi kii ṣe pe awọn yin ibọn ti ko ni ọta soke, lati fi tu wọn ka.
EndSARS Protest Update: Ìwé ẹ̀ṣùn 50 wà nílẹ̀ bí Makinde ṣe ń fi ìgbìmọ̀ olùwádìí lọ́lẹ̀
Oríṣun àwòrán, @seyiamakinde
Ẹla lọrọ, bi a ko ba la a, kii ye ni, ọrọ okeere si ree, bi ko ba le ọkan, yoo din kan.
Idi ree ti gomina ipinlẹ Oyọ, Seyi Makinde fi lo anfaani ifilslẹ igbimọ olugbẹjọ ẹsun ifiyajẹni ọlọpaa lati maa se alaye awọn ọrọ kan.
Lara alaye naa si ni pe awọn agbaagba ilẹ Yoruba to lọ sepade pẹlu ijọba apapọ laipẹ yii ko faramọ mọ aba to n gbogun ti amulo awọn oju opo idọrẹpọ lori ayelujara.
Gẹgẹ bi Makindeti salaye loju opo Twitter rẹ lọjọ Isẹgun, o ni iroyin naa tako ohun ti ipade awọn asaaju ilẹ Yoruba pẹlu ijọba apapọ fi ẹnu ko le lori patapata.
Oríṣun àwòrán, @seyiamakinde
"O ni "" Igun ta duro le lori ni pe niwọn igba ti ofin to n se akoso ori ayelujara tọdun 2015 ti wa nilẹ, a ko nilo ofin miran mọ lati gbogun ti oju opo ayelujara."""
Wayi o, gomina ipinlẹ Oyo naa ti sefilọlẹ igbimọ ẹlẹnu mọkanla ti yoo tanna wadi awọn oniruuru ẹsun ifiyajẹni tawọn ọlọpaa ti se fun araalu.
Adajọ agba tẹlẹ nipinlẹ Oyo, oloye Badejoko Adeniji si ni alaga igbimọ oluwadii naa.
Awọn ọmọ igbimọ yoku ni Oluwole Akintayo, alaga ẹgbẹ agbẹjọro nipinlẹ Oyo, Amofin Babs Oduyoye, tii se oludamọran fun gomina lori ọrọ oselu ati arabinrin Adebobola Agbeja, tii se ọkan lara smọ igbimọ fun apapọ awọn ọdọ nilẹ wa.
Awọn ọmọ igbimọ yoku ni Olumide Akintayo, Wunmi Odutayo, Nasir Sulaiman, Mary Kolawole, Mariam Badmus, Saheed Falowo ati Olufolakemi Ogundele.
Sickle Cell In Nigeria: Makinde ní ìgbàgbọ́ ninú ìdílé òun ṣèdíwọ́ láti ṣàyẹ̀wò ẹ̀jẹ̀
Gomina Makinde ni iwe ẹsun aadọta lo ti wa nilẹ latọdọ awọn araalu, to si n kesi awọn eeyan ipinlẹ Oyo lati tubọ fi iwe ẹsun ransẹ si igbimọ naa.
O wa rọ awọn ọmọ igbimọ oluwadii naa lati se bo ti tọ, ati bo se yẹ lasiko ijoko wọn.
Oríṣun àwòrán, Reuters
Aarẹ Ile Igbimọ Aṣofin lorilẹede Naijiria, Ahmed Lawan ti kesi awọn aṣofin, lati pese iṣẹ fun awọn ọdọ atawọn ohun amayedẹrun mii.
Lawan parọwa bẹẹ lasiko to n sọrọ nipa eto isuna ẹka ileeṣẹ ijọba to n risi eto ọgbin, ti wọn n beere fun owo to din diẹ ni ogoji biliọnu naira (N139,458, 322,208.00) ninu eto isuna Triliọnu mẹtala o din diẹ naira (N13.8 trn) ti Aarẹ Buhari gbe kalẹ fun ọdun to n bọ.
Lawan ni eto ọgbin ṣe pataki lati pese iṣẹ fun awọn ọdọ nitori ti ifẹhọnuhan miran ba tun waye ni Naijiria, awọn aṣofin ati awọn to wa ni ijọba yoo fi ẹmi wọn sofo nitori awọn ọdọ naa n fapajanu lọwọ.
O ni bi ijọba ko ṣe naani ipese iṣẹ ati ohun amayedẹrun ti yoo ran awọn ọdọ lọwọ lati ri  iṣẹ se, ti wọn ko si ni ma a fi ẹsẹ gbalẹ kaakiri igboro mọ, ko dara to.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
"Aarẹ Ile Igbimọ Aṣofin naa ni ""a dupẹ pe awọn ọdọ to wa ni igboro lo ṣe ifẹhọnuhan akọkọ, ti wọn si ṣe ni irọwọrọsẹ, ki awọn janduku to gba a mọ wọn lọwọ, ti wọn si ba ohun ini awọn eniyan jẹ, ati ti ijọba."
''Nitori naa, eto isuna ọdun 2021 yẹ ko dojukọ ipese iṣẹ fun awọn ọdọ, paapaa awọn to wa ni igberiko, ki wọn ba le ri iṣẹ se, ti wọn ko fi ni ronu janduku tabi ifẹhọnuhan ti yoo doju ijọba bolẹ.''
''Ohun to yẹ ki a se ni lati lọ ba wọn ni igberiko ti wọn wa, ki a mase duro ki wọn wa si igboro, nitori ti wọn ba ri iṣẹ to dara ṣe ni igberiko, ti igbe aye wọn si ni itumọ, wọn ko ni raye janduku abi hu iwa ọdaran.''
Oríṣun àwòrán, Getty Images
''Fun awa aṣofin ti wọn dibo yan, a gbọdọ le jabọ fun awọn eniyan to fi wa si ipo, awọn to jẹ pe ọpọlọpọ wọn wa ni abule, ki a si ma fi ẹtọ wọn dun wọn.''
''Nitori ti rogbodiyan miran ba tun bẹ silẹ ni orilẹede Naijiria, awọn to wa ni ipo ijọba ni yoo fori fa julọ nibẹ.''
'' Ẹ jẹ ki a lo ẹka eto ọgbin lati pese iṣẹ fun awọn ọdọ, ki aye wọn ba le ni itumọ, ki awọn naa le jẹ eniyan laye''
Oríṣun àwòrán, Twitter/Ahmed Lawan
Bakan naa ni Alaga Igbimọ ile asofin lori eto ọgbin, Abdullahi Adamu ni, otitọ ni ọrọ ti Aarẹ ile igbimọ asofin sọ, Ahmed Lawan, amọ o ni o pọn dandan ki ijọba fikun owo eto isuna ẹka naa, ki wọn ba le kẹsẹjari.
Oríṣun àwòrán, EPA
Kọmisana feto idajọ ati agbẹjọro agba nipinlẹ Eko, Moyosore Onigbanjo SAN, ti rọ ileẹjọ lati tu awọn oluwọde EndSARS silẹ.
Awọn oluwọde naa lo to ọtalerugba o din meje 253 ninu ọtalelọọdunrun ati ẹyọ kan, 361 to wa ni atimọle ọlọpaa nipinlẹ naa.
Atẹjade kan tileesẹ eto idajọ fisita fawọn akọroyin lo sisọ lori igbesẹ naa.
Kọmisana feto idajọ ni ẹka agbefọba nileesẹ naa ti sagbeyẹwo awọn ẹsun ti awọn ọlọpaa fi kan awọn oluwọde ọhun, ti wọn si ri daju pe wọn ko sẹ si ofin.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
O ni faili ogoji to jẹ mọ awọn oluwọde ọtalelọọdunrun ati ẹyọ kan nileesẹ ọlọpaa fi ransẹ si ẹka agbefọba lọjọ kẹfa osu kọkanla ọdun 2020.
"Onigbanjo salaye siwaju pe ""Wọn ti sagbeyẹwo ẹsun ti wọn fi kan afurasi mọkanlelọgọjọ lọjọ naa, ti wsn yoo si fi awọn yoku ransẹ lọjọ Aje ọsẹ yii."""
Lara awọn afurasi oluwọde bii ọtalelọọdunrun ati ẹyọ kan ọhun, ẹka agbefọba yoo ba awọn mejilelaadọrun se ẹjọ.
Ẹjọ naa yoo da lori awọn ẹsun to nii se pẹlu idaluru, ole jija, ile fifọ, ipaniyan ati idigunjale, nigba ti awọn afurasi bii ọtalerugba o din meje yoo gba idande.
Pistachio Green Puppy: Àwọn ẹgbẹ́ rẹ̀ jẹ́ aláwọ̀ funfun, tí òun sì jẹ́ aláwọ̀ ewé
Wayi o, o tun ti n rugbo bọ nidi iwọde EndSARS bayii, to si seese kawọn ọdọ tun gunle iwọde miran lọjọ Aje ọla.
Iwọde ọhun, tawọn ọdọ pe ni abala keji iwọde EndSARS lo wa lati tako iwa idunkooko ijọba atawọn agbofinro nitori iwọde akọkọ ti wọn se saaju.
Iwọde naa si ni wọn ni ko sẹyin bi banki apapọ ilẹ wa, CBN, se gbẹsẹ le apo asunwọn owo awọn oluwọde EndSARS lọjọ Ẹti to kọja.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Bakan naa ni wọn tun sediwọ fun awọn oluwọde to fẹ rinrin ajo silẹ okeere lati se bẹẹ, tile ẹjọ giga kan nilu Eko si fontẹ lu asẹ ijọba naa.
Awọn ọdọ naa, ti wọn n kesi ijọba lati wọgile awọn igbesẹ ọhun ti ko ba fẹ ri pipọn oju awọn, si ti n korajọ bayii nilu Eko ati Abuja lati na tan bii owo pẹlu ijọba.
Suicide: Ẹ wo ọkùnrin tó dáná sún ọ̀rẹ́bìnrin rẹ̀ nítorí kó gbà látí jẹ́ aya rẹ̀
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Iwadii ti fihan pe arakunrin kan ti orukọ rẹ n jẹ, Nicodemus Nomyange ti dana sun ara rẹ ati ọrẹbinrin rẹ, Shininenge Pam nitori o kọ lati jẹ aya afẹsile rẹ.
Iṣẹlẹ naa waye ni ile orẹbinrin rẹ naa to wa ni agbegbe Inikpi, ni Makurdi to jẹ olu ilu ipinlẹ Benue.
Awọn ti iṣẹlẹ naa ṣoju wọn ni arakunrin Nomyange naa lọ si ile afẹsọna rẹ pẹlu galọọnu epo bẹntiroo, to fi dana sun ile naa.
Awọn ololufẹ mejeeji si ku si inu ile ọrẹbinrin naa.
Awọn ara adugbo ni  o ti to igba diẹ ti awọn ololufẹ yii ti n fẹ ara wọn, amọ ija bẹrẹ nigba ti ọrẹbinrin naa kọ lati fẹ ẹ bi ọkọ nitori o ni o dagba ju oun lọ.
Nomyange yii ni awọn ti ọrọ naa ṣoju wọn sọ wipe o ti ni iyawo pẹlu ọmọ, amọ o bẹrẹ si ni fẹ orẹbinrin rẹ yii, to si gba ile to n gbe fun un pẹlu dukia.
Amọ, awọn ti ọrọ naa ṣoju rẹ ni orẹbinrin Shininenge kọ lati fẹ ọkunrin naa gẹgẹ bi iyawo keji lẹyin ti awọn ọrẹ rẹ ni Nomyange ti dagba julọ, nitori ẹni ogoji ọdun o le ni.
Awọn ara adugbo ni iṣẹlẹ naa ya awọn lẹnu nitori orẹkunrin naa kii ṣe oni jagidijagan, amọ ṣaadede lo wa si ile ọrẹbinrin naa pẹlu galọọnu bẹntiroo, ti awọn si ro wipe wọn fẹ lo o fun ẹrọ alupupu wọn ni.
''Lẹyin ti ọrẹkunrin naa wọle ti obinrin ọhun ni wọn ti ilẹkun mọ ara wọn''
'' Ohun ti awọn ara adugbọ kọkọ ri ni eefin to n jade lati inu yara naa, ti gbogbo igbiyanju wọn lati pa ina ọhun jasi pabo.''
Ati wipe ki awọn panapana to pa ina naa, ẹmi ti bọ lara awọn ololufẹ mejeeji.
Agbẹnusọ ileeṣẹ ọlọpa nipinlẹ naa, DSP Catherine Anene ni awọn ara adugbo naa ni awọn ri ọkunrin naa to gbe bẹntiroo wọle, ti awọn si rọ pe gẹnẹratọ ni wọn fẹ lo o fun.
Anane fikun pe iwadii ti bẹrẹ ni pẹrẹwu lori iṣẹlẹ naa, ati ohun to fa iṣẹlẹ naa gangan.
Ara meriri, mo ri ori olongbo lori atẹ ni ọna ti iwa ifipabanilopọ pẹlu awọn majesin tun gba yọ bayii.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Abi ki ni ka ti pe ti baba agba kan to n ba ọmọ ọmọ rẹ ni ajọsepọ, titi to fi di oyun.
Ileesẹ ọlọpaa ipnnlẹ Ogun lo fi ọrọ naa sita pe ọwọ ti tẹ baba agba naa, Hunsu Sunday, ẹni aadọrin ọdun, to fun ọmọ ọmọ rẹ, ọmọ ọdun mẹẹdogun loyun.
Ọjọ Isẹgun ni ọwọ sinkun ọlọpaa tẹ baba akumọmojudi naa, nigba ti ẹgbọn ọmọ ọhun mu ẹjọ tọ ileesẹ ọlapaa lọ.
Agbẹnusọ fun ileesẹ ọlọpaa nipinlẹ Ogun, Abimbola Oyeyemi ni ẹkun ileesẹ ọlọpaa to wa nilu Ado Odo ni wọn mu ẹsun naa lọ.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ọmọdebinrin naa lo ti n gbe lọdọ baba agba ọhun lati igba ti iya rẹ ti jade laye, to si ti n fi ẹjọ sun anti rẹ pe baba agba maa n ba oun lopọ ni gbogbo igba, ti ooyi si n kọ oun.
Nigba ti wọn fi ọrọ wa baba agba naa lẹnu wo, se lo jẹwọ pe lootọ ni oun maa n jẹ dodo lara ọmọ ọmọ oun amọ oun ko tiẹ mọ pe o ti fẹraku.
Ileesẹ ọlọpaa ni iwadi ti n tẹsiwaju lori isẹlẹ naa.
Obinrin ẹni ọdun mẹrinlelogun kan, ti fi eyin ge okó ọkunrin kan, to fi ipa ba a lopọ jabọ, lẹyin ti ọkunrin naa sọ pe ko fi ẹnu fa okó rẹ.
Agbegbe Obuasi, ni ẹkun Ashanti lorilẹede Ghana ni iṣẹlẹ naa ti waye ni ọjọ Satide.
Iroyin sọ pe, ẹni ti wọn fi ẹsun ifipabanilopọ kan, deede wọ yaara Juanita laarin oru.
Agbẹnusọ fun ileeṣẹ ọlọpaa ni agbagbe naa, ASP Godwin Ahianyo si fidi iṣẹlẹ naa mulẹ fun BBC.
Rape cases in Nigeria: Ọmọ ọdun 5 àti 14 ni Kalu wà nígbà tí obìnrin fipá ba lòpọ̀
"Obinrin naa kọ silẹ ninu iwe akọsilẹ ileeṣẹ ọlọpaa pe ""ọkunrin ọhun, lẹyin to fipa ba mi lopọ tan, tun ni ki n mu okó rẹ, ti mo si ge oko naa jabọ""."
Ọkunrin ọhun, Emmanuel Ankron, ẹni ọdun mẹtalelogun, wọ yara akẹkọọ obinrin naa pẹlu àdá lọwọ, ati ibọn agbelẹrọ pelebe, to si fi tipa ba lopọ.
Lẹyin to ji owo rẹ tan, o tun gbe tẹlifisan, ati foonu, lo ba tun beere pe ko fi ẹnu fa nkan ọmọkunrin oun, irufẹ ere ibalopọ ti wọn n pe ni 'blow job'.
Bi ọmọbinrin naa ṣe ge okó rẹ jẹ niyẹn o, ti ẹjẹ si bẹrẹ si ni i tu jade, eyi lo si mu ki afurasi naa sa jade ninu yara naa.
Nnkan ọkunrin ti obinrin ge jabọ
Ninu ibẹru ṣi ni Juanita wa, to fi lọ fi ọrọ naa to awọn ọlọpaa leti. Lẹyin naa lo lọ sileewosan Anglogold Ashanti, fun itọju.
Nibi to ti n gba itọju lo ba ri pe ileewosan ọhun ni afurasi to fi ipa balopọ naa wa fun itọju, lo ba bẹrẹ si ni pariwo pe ki wọn o ba oun mu u.
Awọn ọlọpaa pada ri ageku okó naa to fi eyin ge jabọ, wọn si ti mu lọ sileewosan fun itọju.
Ifa Worshippers: Àwọn ẹlẹ́sìn ìbílẹ̀ ń fẹ́ kíjọba pín èrè òṣèlú alágbádá yíká gbogbo ẹ̀sìn
Iwadii ṣi n lọ lọwọ lori iṣẹlẹ yii.
Awọn alaṣẹ sọ pe obinrin naa ge e afurasi naa jẹ, lẹyin to ti kọkọ fi ipa ni ibalopọ pẹlu rẹ, to tun wa a sọ pe ti ko ba fun oun ni 'blow job', oun ko ni i kuro ni ile rẹ.
Boko Haram Sponsors: Ẹbí àwọn ọmọ Nàìjíríà mẹ́fa tó rí ẹ̀wọ̀n he ní UAE nítorí Boko Haram sọ pé àkóba ni ọ̀rọ̀ nàá
Mọlẹbi awọn kan lara ọmọ Naijiria mẹfa ti wọn dajọ ẹwọn fun l'orilẹ-ede United Arab Emirates, fun nitori ibaṣepọ wọn pẹlu ik Boko Haram ti sọ pe akoba ni ọrọ naa.
"Ẹnikan to ba iwe iroyin Daily Trust sọrọ ni ""iṣẹ paṣi-paarọ owo ati eto bibani fi owo ranṣẹ, ni awọn eeyan naa n ṣe ni Dubai, to si ṣe e ṣe ko jẹ aimọkan lo mu wọn ba onibaara wọn fi owo ranṣẹ si Naijiria laimọ pe ikọ Boko Haram ni wọn n fi ranṣẹ si."""
Ati pe wọn ti n ṣe okoowo yii ki wọn o to bọ si pakute awọn to n ran wọn niṣẹ laimọ.
Ọjọ Aiku ni iroyin jade pe wọn ti dajọ ẹwọn fun ọmọ orilẹ-ede Naijiria mẹfa ni ile ẹjọ giga ijọba apapọ ti ilu Abu Dhabi, nilẹ United Arab Emirate (UAE), fun ẹsin gbigbọ bukaata Boko Haram.
Iroyin naa ni idajọ ẹwọn laelae ni wọn fun meji lara wọn, Surajo Abubakar Muhammad ati Saleh Yusuf Adamu.
Awọn mẹrin to ku, Ibrahim Ali alhassan, AbdurRahman Ado Musa, Bashir Ali Yusuf, ati Muhammad Ibrahim Isa, gba idajọ ẹwọn ọdun mẹwaa.
Atẹjade kan ti olubadamọran fun aarẹ Buhari lori ọrọ ilẹ okeere, Abike Dabiri Erewa fisita loju opo Twitter rẹ lọjọ Aje, lo sisọ loju eleyi.
Dabiri ni o seese fun awọn ti wọn dajọ fun naa lati lọ sile ẹjọ to ga julọ lati tako idajọ naa to ba wu wọn.
Oríṣun àwòrán, @NigerianArmy
Idajọ naa fihan pe, awọn afurasi naa lọwọ ninu fifi owo toto $782,000 ranṣẹ si ikọ Boko Haram laarin ọdun 2015 si 2016, bo tilẹ jẹ pe awọn to sunmọ wọn sọ pe nnkan to ba ofin mu ni wọn fi owo naa ranṣẹ fun.
Ọjọ ti pẹ ti oriṣiriṣi ibeere ti n waye lori orisun ti ikọ Boko Haram ti n ri owo, igba akọkọ si niyii ti orukọ ẹnikẹni jade si gbangba nipa rẹ.
Oríṣun àwòrán, Daily Trust
Akojọpọ owo ti wọn fi ranṣẹ, gẹgẹ bi iwe iroyin Daily Trust ṣe jabọ
Iroyin sọ pe, laarin ọjọ kẹrindinlogun, oṣu Kẹrin si ọjọ kẹtadinlogun, oṣu Kẹrin, ọdun 2017, ni awọn ọlọpaa mu wọn , ti wọn si tu ile wọn wo.
Iroyin sọ pe, awọn meji akọkọ finnu-findọ darapọ mọ Boko Haram ni Naijiria, eyi to tako ofin igbesunmọmi ni UAE, to si le yọri si idajọ iku tabi ẹwọn gbere.
Wọn fi ẹsun kan awọn mẹrin yoku pe wọn n pese iranlọwọ fun ikọ naa.
Amọ ṣa, mọlẹbi wọn sọ pe akoba ni ọrọ naa.
Wọn ni iṣẹ paṣi-paarọ owo ati eto bibani fi owo ranṣẹ, ni awọn eeyan naa n ṣe ni Dubai, to si ṣe e ṣe ko jẹ aimọkan lo mu wọn ba onibaara wọn fi owo ranṣẹ si Naijiria laimọ pe ikọ Boko Haram ni wọn n fi ranṣẹ si.
Ifa Worshippers: Àwọn ẹlẹ́sìn ìbílẹ̀ ń fẹ́ kíjọba pín èrè òṣèlú alágbádá yíká gbogbo ẹ̀sìn
Bakan naa ni iroyin sọ pe, awọn agbofinro ṣi n wa eeyan meji, to jẹ ọmọ Naijiria, ti wọn fi ẹsun kan pe awọn lo ma n gbe iṣẹ fifi owo ranṣẹ fun awọn eeyan naa.
Ifa Worshippers: Àwọn ẹlẹ́sìn ìbílẹ̀ ń fẹ́ kíjọba pín èrè òṣèlú alágbádá yíká gbogbo ẹ̀sìn
Yoruba ni tiwa n tiwa, akisa ni ti aatan,  ọmọ kii si ba ipele iya rẹ, ko si asọ da.
Ẹsin abalaye ti kọja bẹẹ pẹlu awọn agbelarugẹ to ti baa ati ọpọn imọ to wa ninu rẹ.
Lasiko ti BBC Yoruba lọ jọsin pẹlu awọn onisẹse ti ijọ Imọlẹ Olodumare, a ri pe diẹ ni iyatọ to wa laarin bi wọn se n jọsin nibẹ ati nile ijọsin tawọn ọmọlẹyin Kristi.
Se ti orin aladun lati ẹnu awọn ẹgbẹ akọrin wọn ni abi ọna tawọn ẹlẹyinju ẹgẹ obinrin ati alakọwe n gba jere ọkan si iwa rere lawujọ wa.
Ninu ifọrọwerọ rẹ pẹlu BBC Yoruba, Ọmọwe Ifayemi Ifatunde ni awọn onisẹse n fẹ ki ijọba pin ere iselu alagbada de ọdọ gbogbo ẹsin pata pata.
Bakan naa lo tun n fẹ ki ijọba pese gbogbo anfaani to n fun awọn Kristiẹni ati Musulumi de ọdọ awọn onisẹse.
APC Crisis: Àwọn ọmọ ẹgbọ́ APC kan ti n yarí nítorí àì tí ṣe ìpàgọ́ ẹgbẹ́
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Alaga Ẹgbẹ́ òsèlú APC ní Èkìtì ni àwọn kò ní ṣé ipolongo ti ko ba sì ààbò tó péye
Awọn iroyin kan ti n lọ labẹnu pe, o ṣe e se ki igbimọ alakoso ẹgbẹ oṣelu All Progressives Congress, APC, ṣe ipade apapọ ko to o di ọjọ  Keresi, ọjọ kẹẹdọgbọn, oṣu Kejila ọdun 2020.
Ati pe, igbimọ naa yoo beere fun afikun saa rẹ pẹlu oṣu mẹfa, nitori asiko ti ko fi bẹ ẹ si fun mọ.
Lẹnu ọjọ mẹta yii ni awuyewuye n waye laarin awọn ọmọ ẹgbẹ kan pe, wọn yoo koro oju si igbimọ naa ti ko ba fi ṣeto ipagọ gbogboogbo 'National Convention' ẹgbẹ naa ni kiakia.
Ṣugbọn ṣa, awọn kan tun n sọ pe, ko jọ pe ipagọ naa yoo waye titi di ọdun 2021.
Akomolede ati Aṣa lori BBC:Wo ìrúfẹ́ ìgbeyàwó méje tó wà nílẹ̀ Yorùbá àti ojúṣe Alárinà
Ẹ o ranti pe ọjọ Karundinlọgbọn, oṣu Kẹfa, ọdun 2020, ni wọn tu igbimọ oludari ti Alaga ẹgbẹ APC nigba kan, Adams Oshiomole ko sodi ka, ti wọn si gbe igbimọ fidihẹ, ti gomina ipinlẹ Yobe, Mai Mala Buni, dari kalẹ.
Ohun ti ofin ẹgbẹ naa sọ ni pe, oṣu mẹfa pere ni saa igbimọ fidiẹ naa, to si gbọdọ ṣe ipagọ gbogboogbo laarin akoko naa, nibi ti wọn yoo ti yan awọn adari ẹgbẹ tuntun.
Ifa Worshippers: Àwọn ẹlẹ́sìn ìbílẹ̀ ń fẹ́ kíjọba pín èrè òṣèlú alágbádá yíká gbogbo ẹ̀sìn
Amọ ko dabi ẹni pe igbaradi kankan ti n waye lati ṣe ipagọ naa lọdun yii.
Ṣaaju ni olori igun kan ninu ẹgbẹ oṣelu APC nipinlẹ Zamfara, Sẹnetọ Kabiru Marafa, sọ pe ki Buni mu ọ̀kan ninu ko kọwe fi ipo silẹ, tabi ko ṣe ipagọ l'oṣu Kejila.
Asamọ ọrọ kan lo ni ile to ba gbogun ti ara rẹ, ko ni duro, bẹẹ si ni adiẹ kii jẹ ifun ara wọn.
Amọ eyi ko ri bẹẹ ninu ẹgbẹ oselu to n se ijọba lọwọ lorilẹede Naijiria nitori akọtun laasigbo to n da omi alaafia ẹgbẹ oselu naa ru bayii.
Idi ni pe gbogbo aayan igbimọ fidiẹ to n tukọ ẹgbẹ APC lọwọ lọwọ lati yanju aawọ abẹnu to n daamu ẹgbẹ oselu naa, lo ja si pabo.
Aarẹ orilẹede yii, Muhammadu Buhari lo kọkọ saaju igbesẹ lati doola awọ to suyọ ninu ẹgbẹ APC nitori bi ile ẹjọ se yẹgi mọ alaga rẹ, Adams Oshiomole nidi.
Mai Mala Buni, alaga fidihẹ fẹgbẹ oselu APC ati gomina ipinlẹ Yobe
Nibayii, lẹyin ti atẹgun ti fẹ si saa to yẹ ki alaga fidi hẹ ti wọn yan lẹyin Oshiomole lo nipo, ni awọn ọmọ ẹgbẹ oselu PDP kan tun ti n lọgun pe, ki wọn se agbekalẹ ojulowo ikọ oludari fẹgbẹ oselu naa.
Awọn eekan ẹgbẹ PDP kan, ti wa kesi igbimọ fidihẹ naa, ti gomina ipinlẹ Yobe, Mai Mala Buni ko sodi lati pe ipade apapọ ẹgbẹ oselu APC losu to n bọ, ki wọn le dibo yan awọn ọmọ igbimọ amusẹ tuntun.
Awọn eeyan naa ni awọn ọmọ igbimọ amusẹ ọhun ti tasẹ agẹrẹ pẹlu gbigbe awọn igbesẹ ti ko si ninu ojuse wọn, ti wọn ko si yẹ lati maa tukọ ẹgbẹ oselu naa mọ.
Ọkan lara awọn ọmọ ẹgbẹ APC to n fapa janu, Sẹnetọ Kabiru Marafa ni awọn ọmọ igbimọ fidihẹ APC ti kọja aaye wọn pupọ.
Marafa, ẹni to dije dupo gomina nipinlẹ Zamfara tẹlẹ ni, bi igbimọ fidihẹ naa se n fi orukọ awọn ọmọ ẹgbẹ oselu naa silẹ jakejado Naijiria kii se ojuse wọn.
Oríṣun àwòrán, Buhari Salihu
"Marafa, lasiko to n ba BBC sọrọ ni ""eto iforukọsilẹ ti wọn gunle naa kii se ara isẹ wọn, yoo kan tubọ da ẹgbẹ ru ni."""
Amọ agba oselu kan ninu ẹgbẹ oselu APC, tii tun se oludamọran fun aarẹ lori ọrọ ile asofin, Hon Kawu Sumaila salaye pe igbimọ fidihẹ naa ko tiii tasẹ agẹrẹ rara.
Kawu ni o di dandan ki igbimọ fidiẹ naa ri si eto iforukọsilẹ awọn ọmọ ẹgbẹ, eyi to maa n waye ni ọdun mẹfa mẹfa lati mọ bi ẹgbẹ naa se ni eeyan si.
Bẹẹ ba si gbagbe, ara aawọ abẹnu to n waye ninu ẹgbẹ oselu APC yii lo mu ki wọn padanu ipo gomina nipinlẹ Edo.
Bakan naa ni awọn onwoye se akiyesi pe ijakulẹ nla lee waye fun ẹgbẹ oselu naa lọdun 2023 fẹgbẹ APC, ti aarẹ Muhammadu Buhari ba pari saa rẹ.
Ifa Worshippers: Àwọn ẹlẹ́sìn ìbílẹ̀ ń fẹ́ kíjọba pín èrè òṣèlú alágbádá yíká gbogbo ẹ̀sìn
A ko setan lati yan adari ẹgbẹ tuntun - Igbimọ Fidihẹ
Wayi o, igbimọ fidihẹ fẹgbẹ oselu APC ti gbọnmu pe oun ko ni seto ipade apapọ awọn ọmọ ẹgbẹ naa lati yan awọn adari tuntun gẹgẹ bawọn kan se n beere fun.
Atẹjade kan ti akọwe apapọ fẹgbẹ APC, Yekini Nabena fisita salaye pe ayafi ti aawọ abẹnu ẹgbẹ naa ba di afiẹyin, ni ipade apapọ ẹgbẹ yoo to waye.
Atẹjade naa ni wọn ti gbe igbimọ kalẹ lawọn ipinlẹ kan, eyi ti yoo wa ojutu si aawọ aarin wọn, ti eyi si ti n fidi mulẹ nipinlẹ Oyo, Ondo, Ekiti, Edo, Bauchi, Cross River, Enugu ati Zamfara.
Bakan naa ni Hon Kawu fikun pe ti wọn ba pari iforukọsilẹ awọn ọmọ ẹgbẹ pẹlu yiyanju aawọ aarin wọn, ni eto ipade apapọ yoo to waye.
Bose Okeowo: Àárẹ̀ kékeré ló sọ mi dí aláàbọ̀ ara yìí ṣùgbọ́n...
Ninu alaye rẹ, Sẹnetọ Marafa ni ko tii si ọna ati yanju aawọ nipinlẹ Zamfara ti oun ti wa, nitori to ba ri bẹẹ ni, o yẹ ki wọn ti kan si oun.
O ni oun wa lara awọn ti inu n bi, ti ẹgbẹ APC ti sẹ, ti wọn si gbọdọ tu ninu pẹlu aafikun pe, ti igbimọ fidihẹ naa ko ba dẹkun ojuse aitọ to n se, oun yoo gbe wọn lọ sile ẹjọ.
Sugbọn awọn onwoye kan ti salaye pe, aawọ abẹnu ẹgbẹ oselu APC lo seese ko tẹsiwaju wọnu eto idibo ọdun 2023, ta ba wo iyapa, ati ikunsinu to wa laarin awọn ọmọ ẹgbẹ naa.
Shina Rambo: Mo ti di atúnbí àti ajíhìnrere, ń kò jẹ́ orúkọ àtijọ́ mọ́
Oríṣun àwòrán, Fresh FM Facebook
Gbajugbaja ogboju adigunjale ni amọ to ti wa di ojisẹ Ọlọrun bayii, Shina Rambo ti pa orukọ da.
Orukọ tuntun to n jẹ bayii ni Sina Jesu.
Rambo, ti ọpọ eeyan n pariwo pe o ti ku, lo ni alaaye ni oun, isẹ Oluwa si ni oun n se, to si foju han fun araye.
Shina Rambo naa, to jẹ gbajumọ ọdaran taye n polongo rẹ tẹlẹ, ki ọwọ ofin to tẹ ẹ, lo tun yọju kulẹ sileesẹ Fresh FM nilu Ibadan lọjọ Aiku lati kopa lori eto redio kan.
Gbajugbaja akọrin Tungba nni, Yinka Ayefele funra rẹ si lo jẹ atọkun eto naa, nibi to ti n ju oniruuru ibeere si Rambo.
'Oyenusi ló mú mi wọ ẹgbẹ́ adigunjalè kó tó di pé mo b'Ólúwa pàdé'
Rambo, ẹni to pe orukọ ara rẹ ni Oluwasina Oluwagbemiga lo salaye pe, oun ti di ojisẹ Ọlọrun ati ajihinrere fun Jesu, ti iyipada nla si ti ba aye oun.
O wa jẹwọ pe oun gan ni ogbontagi ọlọṣa to n mi ilu titi fun ọpọlọpọ ọdun, bi oun si se n jale, ni oun tun npa alaisẹ, ti oun si n fi imu agbofinro danrin.
Rambo ni ọpọ agbofinro ni ẹnu yoo ya lati gbọ pe oun ti wọn ni oun ti ku lo si wa laaye lonii.
"Baba mi jẹ gbajumọ ẹda ati ologun to n lọ lati agbegbe kan si omiran yika orilẹede yii.
Oríṣun àwòrán, Wikipedia
Lọna ati gba agbara okunkun, ibi mọkanlelogun ni mo lọ, lara wọn ni Minna nipinlẹ Niger ati oro nipinlẹ Kwara."
"Mo wa nilu idanre nipinlẹ Ondo fun ọjọ mọkanlelaadọrun, nibi ti wọn ti ni ki n maa mu ọmu obinrin kan gẹgẹ bii ounjẹ ati omi, ki agbara okunkun le wọnu ara mi.
Lẹyin o rẹyin, mo ni agbara okunkun ẹgbẹrun lọna ẹẹdẹgbẹwa ati ẹyọ kan, 901, eyi ti mo n lo lati maa poora lasiko ti mo ba huwa ọdaran, tabi sọ ara mi di ẹlomiran.
Ti wọn ba pa mi nibikan, mo ni agbara lati ji dide, ki n si tun fara han ni ibomiran."
Oríṣun àwòrán, NAN
Amọ iroyin naa ni Rambo wa kabamọ, to si n fi ika hanu lori awọn iwa aidaa to hu naa eyi to fi da orilẹede Naijiria joko fun ọpọ ọdun, to si ni awọn ẹmi aimọ lo faa.
Rambo ni ni kete ti oun fi aye oun fun Jesu ni ẹmi Ọlọrun wọ inu oun lọ, to si pasẹ fun oun lati jọwọ gbogbo agbara okunkun naa ati iwa buruku, ki oun si maa waasu .
O ni oun ti jere ọkan pupọ fun Ọlọrun lati ipasẹ iwaasu ti oun n se, ti oun si tun ti da ọpọ ile ijọsin silẹ pẹlu.
Ifa Worshippers: Àwọn ẹlẹ́sìn ìbílẹ̀ ń fẹ́ kíjọba pín èrè òṣèlú alágbádá yíká gbogbo ẹ̀sìn
Ogbontagi adigunjale tẹlẹ naa ni ohun ti oun kabamọ julọ ni iku aya oun ati ọmọ mẹta, ti awọn to wa mu oun, amọ ti wọn ko ba opun pa.
Shina Rambo wa parọwa sawọn eeyan to si n huwa ọdaran lati jawọ, ki wọn si ronupiwada, ki ibinu Ọlọrun ma baa de ba wọn.
PENGASSAN Strike: Bí ìjọba bá dá wà lohùn lórí IPPIS láàrin wákàtí mẹ́rìnlélógún, a o so ìyanṣẹ́lódì rọ̀
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Iyanṣẹlodi ti awọn oṣiṣẹ agba to n ṣiṣẹ lẹka epo rọbi ni Naijiria, PENGASSAN, seleri lati gunle lọjọ Aje. ti gberasọ.
Fun idi eyi, o ṣeeṣe ki araalu tun fara gba ọwọn gogo epo bẹntiroo, bi ijọba ko ba tete da awọn oṣiṣẹ yi lohun.
Akọwe ẹgbẹ naa. Lumumuba Okugbawa lo fidi ọrọ yi mulẹ ninu ifọrọwanilẹnuwo pẹlu BBC Yoruba.
Saaju ni o ti fi atẹjade kan sita nibi to ti paṣẹ pe ki gbogbo awọn ọmọ ẹgbẹ ni gbogbo ẹka wọn ti gunle iyanṣẹlodi bẹrẹ lati ago mejila ọjọ Aiku mọjumọ ọjọ Aje.
Oríṣun àwòrán, @chukwudi52
Gẹgẹ bi alaye ti o ṣe fun akọroyin wa, o ni lati ọdun 2014 lawọn ti n dunadura pẹlu ijọba lori ọrọ yii, ṣugbọn pabo ni gbogbo rẹ ja si.
Koda o ṣalaye pe, gbedeke ọlọjọ meje tawọn fun ijọba yii kii ṣe akọkọ iru rẹ.
''A ti kọkọ fun ijọba ni gbedeke ọlọjọ meje akọkọ, lẹyin naa la fun wọn lọjọ meje si, ṣugbọn ko so eso rere kankan''
O ni ijọba lẹtọ lati ṣagbekalẹ eto to ba wu lati maa fi san owo osu oṣiṣẹ rẹ ṣugbọn eto yii ni gbọdọ faye gba awọn owo ajẹmọnu kan tawọn ọmọ ẹgbẹ awọn gba.
Oríṣun àwòrán, Lumumba Okugbawa
''A ko lodi si lilo IPPIS ṣugbọn ijọba ko fẹ seto bi yoo ti ṣe jẹ ki a ri gbogbo awọn ajẹmọnu ati owo miń to tọ si wa gba.''
''Ẹka wa yatọ nitori awọn oṣiṣẹ wa a maa wa lori omi fun ọjọ to pẹ, ti wọn a si maa san awọn owo ajẹmọnu kan fun wọn. IPPIS ti ijọba gbe kalẹ ko faye gba sisan owo yii.''
Lumumba ni awọn ṣi ṣe ipade pẹlu ijọba lọjọ meji ṣẹyin, ti wọn si ni igbesẹ yoo waye lati ṣatunṣe gbogbo ẹdun ọkan wọn.
O ni ẹka to n ṣeto owo oṣu oṣiṣẹ (Salaries and Wages Commission) lawọn reti ki wọn ṣe atunṣẹ to yẹ, ni ibamu pẹlu aṣẹ lati ọdọ akọwe agba fun ijọba apapọ (SGF).
Oríṣun àwòrán, pengassanhq
''Bi wọn ba kesi wa laarin wakati mẹrinlelogun pe awọn ti ṣetan lati gbe wa pada si ori eto ti wọn ti n sanwo wa tẹlẹ, a ko ni kọ lati pada si ẹnu iṣẹ.
Bi o si jẹ ti IPPIS naa ni, ko ṣa ti faye gba owo ajẹmọnu wa. Ko buru.''
Iyanṣẹlodi lẹka epo rọbi ni Naijiria ti wọn gunle yii wa ni ajọṣepọ pẹlu awọn oṣiṣẹ awakọ epo rọbi, NUPENG, nitori naa, o ṣeeṣe ki awọn araalu ma ri epo bẹntiroo ra.
Ifa Worshippers: Àwọn ẹlẹ́sìn ìbílẹ̀ ń fẹ́ kíjọba pín èrè òṣèlú alágbádá yíká gbogbo ẹ̀sìn
''Bi awọn ile epo ba ti ta epo to wa ni akoto wọn tan, wọn ko ni ri omiran nitori awọn ọlọkọ epo bẹntiroo ati ọja miran ko ni gbe epo labẹ aṣẹ wa.''
O wa rọ ijọba lati tete wa wọrọkọ fi ṣada, ki ara ma ba ni ara ilu.
Ọrọ owo oṣu sisan nipasẹ IPPIS yii jẹ eleyi tawọn olukọ fasiti Naijiria naa fi tori rẹ fariga, ti wọn si ti kọ lati ṣiṣẹ fun nnkan bi oṣu mẹfa bayi.
Ẹgbẹ́ OPC nílùú Ibadan ke gbàjarè lórí ọkọ̀ akẹ́rù ńlá tó kó Fulani ati Hausa wọ̀lú Ibadan
Oríṣun àwòrán, Olumo
Daru-dapọ waye ni adugbo Maje, to wa ni agbegbe Soka, nilu Ibadan.
Eyi ko ṣẹyin iroyin kan to ni ọkọ akero nla 'luxurious bus' ko awọn eeyan kan to ṣe ajoji si adugbo naa wọ ibẹ.
Lati fi idi iṣẹlẹ naa mulẹ, alukoro ẹgbẹ New Era OPC, Akinpẹlu Adesina, sọ fun BBC pe irú ńkan bẹ́ẹ̀ ti ṣẹ̀lẹ̀ rí ni ǹkan bi osu meji sẹyin tó sì jẹ́ pé Sunday Adeyemo Igboho lo tú àsìrì náà lásìkò ọ̀hún.
Ó kó OPC lọ sí sibẹ̀ tó sì tún pé àwọn ọlọ́pàá láti mú wọ́n ní ìgbà náà.
Ọgbẹni Adesina sàlàye pé kò sí àrídájú kankan níbi èyí tó ṣẹ̀ṣẹ̀ wáyé, àfi tó bá jẹ pé, àwọn OPC ń sẹ̀ṣẹ̀ bá ǹkan to ti ṣẹlẹ̀ sẹ́yìn ní.
Ọgbẹ́ni Olumo ní ti rẹ̀ fi fóto sọ́wọ́ sí BBC tó jẹ́ bi ẹri pé ǹkan náà ṣẹlẹ̀ lónìí ní àgbègbè Maje ni Soka, ìlú Ibadan
Oríṣun àwòrán, Olumo
"Ero ti pọ lé wọn lórí pé wọn ò gbọ̀dọ já wọn sílẹ̀. O ni lóòtọ ni pé kò si ẹya Yoruba kan nínú rẹ̀ bíkòṣe Bororo, Fulani àti Hausa.
Ó ní àwọn fura pé àwọn Fulani darandaran ni wọn, sùgbọ́n lẹ́yìn ti wọn kó wọ́n lọ si àgọ́ ọlọ́pàá, à o mọ nkan ti ọlọ́pàá ń ṣe pẹ̀lú wọn.
Yàtọ sí ọkọ̀ akẹrò mẹ́ta (Luxury Buses) ti ìwé ìròyìn kan  sọ, Olumo ni ẹyọkan péré ni òun rí tí oun si ya fótò rẹ̀ gẹ́gẹ́ bi ẹ̀rí.
Àmọ́, Adesina ni tiẹ sọ pé àwọn o gbọ́ ǹkan to jọ bẹ àti pé agbègbè Soka ni òun wà bi òun ṣe ń bá BBC sọ̀rọ̀.
Oríṣun àwòrán, Olumo
Akomolede ati Aṣa lori BBC:Wo ìrúfẹ́ ìgbeyàwó méje tó wà nílẹ̀ Yorùbá àti ojúṣe Alárinà
Ninu eto ẹkọ wa lori eto Akomolede ati Asa lori BBC lọsẹ yii, ohun ta a maa gbe yẹwo ni oniruuru asa igbeyawo meje to wa nilẹ Yoruba.
Gẹgẹ bi Olukọ wa lọsẹ yii, Arabinrin Adetunji lati ileẹkọ girama Isabatudeen nilu Ibadan ti salaye, lara awọn igbeyawo ilẹ Yoruba la ti ri iyawo Ọsingin, nibi ti wọn yoo ti fẹ iyawo nisu lọka.
Awọn yoku ni igbeyawo Asante, nibi ti wọn yoo ti ji iyawo gbe lọ sile ọkọ rẹ, igbeyawo ọkọ kaalẹ ninu eyi ti obinrin yoo ti salọ sile ọkọ ati bẹẹ bẹẹ lọ.
Ẹ fara balẹ gbọ eto yii lẹkunrẹrẹ lati mọ nipa awọn igbeyawo to ku ati ojuse awọn alarina ninu igbeyawo.
Amadou Toumani Toure: Ọdún 72 ló lò lókè èèpẹ̀, kó tó jáde láyé
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Aarẹ tẹlẹ fun orilẹede Mali, Amadou Toumani Toure ti jade laye.
Ọdun mejilelaadọrin ni oloogbe naa lo loke eepẹ, ko to ki aye pe o digbose.
Aarọ ọjọ Isẹgun oni ni Toure mi kanlẹ lorilẹede Turkey nibi to ti n gba itọju lọwọ.
Ọjọ diẹ ẹyin ni aarẹ ana lorilẹede Mali naa gunlẹ silẹ Turkey pẹlu baalu olokoowo kan to ja si olu ilu Turkey, Istanbul.
Ki Toure to kuro nilẹ Mali, si lo ti se isẹ abẹ kan nilu Bamako, eyi to nii se pẹlu aisan ọkan.
Akomolede ati Aṣa lori BBC:Wo ìrúfẹ́ ìgbeyàwó méje tó wà nílẹ̀ Yorùbá àti ojúṣe Alárinà
Ọdun 2002 ni aarẹ orilẹede Mali tẹlẹ naa jẹ aarẹ titi wọ osu kẹta ọdun 2012, tawọn ologun fi tipa gba ijọba lọwọ rẹ.
Ọgagun Amadou Haya Sanogo si lo lewaju iditẹ gbajọba naa.
Gbogbo agbaye si lo n kan saara si oloogbe naa pe oun lo fopin si isejọba ologun fun ọpọlọpọ ọdun ni Mali.
Bakan naa lo tun fa akoso fun ijọba alagbada lẹyin to seto idibo apapọ lorilẹede Mali lọdun 1992.
Orukọ inagijẹ ti wọn fun oloogbe Amadou Toumani Toure si ni Ologun fun ijọba alagbada."""
UK Covid Vaccine: Abẹ́rẹ́ àjẹsára Covid-19 yóò dé sí Nàìjíríà nínú oṣù kíní ọdún 2021
Oríṣun àwòrán, WHO
Ìjọba orílẹ̀-èdè Nàìjíríà tí kéde pé abẹ́rẹ́ àjẹsára Covid-19 yóò dé sí Nàìjíríà ni inú oṣù kíní ọdún 2021.
Mínísítà tó n rí sí ètò ìlera, Osagie Ehanire lo fìdí ìròyìn náà múlẹ̀ l'Ọjọ́rú lẹ́yìn ìpàdé ìgbìmọ̀ aláṣẹ́ ìjọba tó wáye.
Ó ní àwọn onímọ̀ nípa ìṣègún ń ṣiṣẹ́ takuntakun láti le sọ pàtó irú àbẹ́rẹ́ ti yóò dára fún àwọn ọmọ Nàìjíríà, pàápàá jùlọ nítorí orílẹ̀-èdè Nàìjíríà kò ni amú omítutu tó tuntùn tó ìwọ̀n ọgọ́rin.
Ìjọba àpapọ̀ ti kéde ṣáájú pé àwọn ń retí abẹ́rẹ́ tí yóò tó ogún mílíọ̀nù ni ìbẹ̀rẹ̀ ọdún 2021.
Arábìnrin ẹni àádọ̀rún ọdún ló kọ́kọ́ gba abẹ́rẹ́ àjẹsára tí Pfizer ṣe síta
Arabinrin ẹni aadọrun ọdun kan ti di ẹni akọkọ ti yoo gba abẹrẹ ajẹsara Covid-19 tuntun ni ilẹ Gẹẹsi.
Eyi wa lara eto fifun ọpọ eeyan labẹrẹ yi kaakiri ilẹ naa.
Margaret Keenan ti yoo pe ọdun mọkanlelaadọrun lọsẹ to n bọ sọ pe ẹbun ọjọ ibi to dunmọ oun ju ni wọn fun oun yi.
Ni nkan bi ago mẹfa abọ kọja iṣẹju kan ni o gba abẹrẹ yi, akọkọ abẹrẹ ẹgbẹrun lọna ẹgbẹrin ti ile iṣẹ Pfizer/BioNTech gbe jade.
Ireti wa pe miliọnu mẹrin eeyan ni yoo ri  abẹrẹ yi gba nigba toṣu yoo ba fi pari.
Awọn agbalagba tọjọ ori wọn kọja  aadọrun ọdun ati awọn oṣiṣẹ ilera ni yoo kọkọ jẹ anfaani abẹrẹ yi lọna ati daabo bo awọn to wa ninu ewu julọ.
Nọọsi agba nileewosan University Hospital Coventry lo fun ni abẹrẹ naa.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ilẹ Gẹẹsi ni orileede akọkọ lagbaye to ti bẹrẹ si ni lo abẹrẹ ajẹsara ti Pifizer pọn lẹyin ti ijọba fontẹ lu lilo rẹ lọsẹ to kọja.
Abẹrẹ naa kii ṣe dandan.Ẹni to ba wu lati gba a ni wọn yoo fun.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Awọn onimọ sayẹnsi ti gbe abẹrẹ ajẹsara ti yoo koju arun Coronavirus jade.
Ileeṣẹ apoogun Pfizer ati BioNTech lo se abẹrẹ ajẹsara naa jade.
Wọn wa sapejuwe ọjọ ti wọn gbe abẹrẹ naa, ti yoo koju arun Coronavirus jade, gẹgẹ bi ọjọ to lamilaaka ni igbe aye awọn onimọ sayẹnsi ati gbogbo ẹda alaaye.
Awọn apoogun naa ni awọn ti lo abẹrẹ ajẹsara naa ni ara eniyan bii ẹgbẹrun lọna mẹtalelogoji ni orilẹede mẹfa, ti ko si ni ipalara kankan fun wọn.
Ileeṣẹ apoogun naa ni awọn yoo bẹrẹ si ni pese abẹrẹ ajẹsara naa fun iṣẹlẹ pajawiri lati opin osu yii.
Oríṣun àwòrán, Reuters
Awọn onimọ sayẹnsi ti sọ wi pe, abẹrẹ ajẹsara tabi oogun oyinbo to lagbara ni awọn lero wi pe o le koju arun Coronavirus lagbaye.
Iwadii abẹrẹ ajẹsara tuntun yii fihan wi pe, awọn eniyan yoo nilo ati ma a gba ni ẹẹmeji laarin ọsẹ mẹta, ki o le ṣiṣẹ daradara lara.
Iwadii ti wọn ṣe ni orilẹede Amerika, Germany, Brazil, Argentina, South Africa ati Turkey fihan pe, laarin ọjọ meje ti wọn ba ti gba abẹrẹ ajẹsara keji naa ni arun naa yoo dopin lagọ ara ẹni to ba lo.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
O ṣeeṣe ko jẹ pe eniyan perete ni yoo le ri abẹrẹ ajẹsara yii gba ninu ọdun yii.
Ileeṣẹ apoogun,Pfizer ati BioNTech ni awọn yoo pese abẹrẹ ajẹsara naa ni ọlọgọọrọ, ki awọn le gbe lọ si ọdọ ijọba lati fi ontẹ lu.
Lẹyin ti wọn ba ti fi ontẹ lu abẹrẹ ajẹsara naa, ni wọn ṣẹṣẹ le gbe lọ si awọn orilẹede to wa lagbaye.
Bakan naa ni wọn ni awọn yoo pese abẹrẹ ajẹsara miliọnu aadọta ki ọdun yii to pari, ti awọn yoo si pese abẹrẹ ajẹsara biliọnu kan o le ni ọdun to n bọ.
Oríṣun àwòrán, EPA
Kii ṣe gbogbo eniyan ni yoo ni anfaani si abẹrẹ ajẹsara yii lẹẹkan naa.
O ṣeeṣe ko jẹ awọn oṣiṣẹ ni ileewosan ati awọn oṣiṣẹ eto ilera ni yoo kọkọ ni anfaani abẹrẹ ajẹsara yii.
Bakan naa ni awọn orilẹede kọọkan ni yoo sọ ẹni ti yoo kọkọ ni anfaani si awọn abẹrẹ ajẹsara yii.
Cancer: Àṣe ara mi ni iso ti n run gbogbo bí mo ṣe n ṣèrànwọ́ lórí jẹjẹrẹ
Amọ, o ṣeeṣe ki Ilẹ Gẹẹsi kọkọ fun awọn agbalagba ati awọn ti wọn tete n ko arun Coronavirus yii nitori ailera ara wọn.
Wọn tun fikun wi pe, bii abẹrẹ ajẹsara naa ba ṣe ṣiṣẹ si lara awọn eniyan ni yoo sọ bi wọn yoo ṣe lo si fun awọn eniyan.
Amọ, awọn ọdọ langba ti eroja idena aisan ara wọn ji pepe lo ṣeeṣe ki wọn ma tete ri abẹrẹ ajẹsara naa gba.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Awọn ibeere wa lorisirisi ti ko tii si idahun si.
Amọ a ko mọ boya abẹrẹ ajẹsara naa yoo dẹna itankalẹ arun naa lati ara eniyan kan si omiran, boya yoo pa kokoro naa ni kiakia, ti ẹni to nii ko si ni lee ko ran ẹlomiran.
Ati wipe ibeere ṣi wa lori igba ati akoko ti abẹrẹ ajẹsara naa yoo ṣiṣẹ da lara eniyan, ṣe ọdun kan ni abi oṣu melo?
Bakan naa ni ipenija wa lori bi wọn yoo ṣe fun eniyan miliọnu lọna ọgọrin ni abẹrẹ ajẹsara, ti o si ṣe wi pe wọn gbọdọ gbe oogun naa ṣi ibi to ba tutu bii inu yinyin (minus 80C).
Iwadii fihan wi pe, oogun naa ko ni aleebu kankan fun ẹni to ba lo o, amọ a ko le sọ wipe otitọ ni lai wẹyin, nitori oogun paracetamol ti ko ni abawọn, naa ni ipenija tirẹ.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ọpọlọpọ abẹrẹ ajẹsara ni o ṣi wa labẹ ayẹwo ipele kẹta lọwọ, amọ eleyii lo si mu aṣeyọri jade.
Ohun ti abẹrẹ ajẹsara naa ṣe ni lati wọ inu isan ara lọ, ti yoo si pese eroja ara 'protein' ti yoo dena arun Coronavirus to fẹ ba sẹẹli ara jẹ.
Bakan naa ni abẹrẹ ajẹsara naa yoo tun awọn sẹẹli ara ti arun Coronavirus ti bajẹ ṣe pada.
Eleyii yoo si mu ara ẹni to ba ni aarun naa ji pepe pada.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Kini awọn adari orilede lagbaye sọ nipa abẹrẹ ajẹsara naa?
Oluranlọwọ pataki fun ijọba lori eto ilera ni Ilẹ Gẹẹsi, Ọjọgbọn Chris Whitty ni, esi ayẹwo naa ṣe afihan iru agbara ti imọ sayẹnsi ni ati ifọkanbalẹ pe ọdun to n bọ yoo dara lati koju arun Coronavirus.
Aarẹ ilẹ Amẹrika ti wọn ṣẹṣẹ dibo yan, Joe Biden ni iroyin ayọ ni abẹrẹ ajẹsara naa jẹ fun gbogbo eniyan ni agbaye.
"''O di dandan ki a ni igbẹkẹle pe opin aarun Covid-19 ti n sun mọ etile, ti ko si jinna mọ."""
Olootu ijọba Ilẹ Gẹẹsi sọ wi pe, abajade ayẹwo abẹrẹ ajẹsara naa fihan wi pe yoo koju arun Coronavirus, nitori naa awọn ti bẹrẹ igbesẹ lati ri wi pe awọn arugbo ati awọn ti arun Conavirus n tete mu ni awọn kọkọ fun ni abẹrẹ ajẹsara naa.
Awọn onimọ sayẹnsi ni fasiti Oxford naa ni ọkan awọn balẹ nitori aṣeyọri nla lo jẹ fun awọn, ti arun Coronavirus naa ko si ni pẹ lọ si okun igbagbe.
Professor Peller: Ọlọ́wọ́ idán àkọ́kọ́ nílẹ̀ Áfíríkà tó ń pidán fáwọn aṣaájú orílẹ̀èdè
Oríṣun àwòrán, Intagram/shinapeller
Bi ogun ẹni ba da ni loju, aa fi gbari ni, ohun ti eeyan ba si mọ se, bi idan lo n ri.
Ọrọ Ọjọgbọn Moshood Folorunso Abiola Peller kii se ohun ti eeyan le sọ tan ni oojọ, asọpati ni nitori ọpọ isẹ aramọnda idan pipa to gbe ile aye se.
Fun awọn ọdọ iwoyii, wọn le ma ranti awọn pidanpidan mii tabi ri wọn wo loju aye nitori asa idan pipa ti n lọ sokun igbagbe.
Mo bẹ̀rẹ̀ ẹ̀ṣẹ̀ jijà ní ọmọ ọdún méjì, inú mi dùn pé bàbá mi fi mí sí ọ̀nà ẹ̀ṣẹ̀ jíjà - Tijani Azeez
Sugbọn ko si ọmọ Naijiria tabi ọmọ ilẹ Kaarọ Oojire to ti to ogoji ọdun, ti ko ni ranti orukọ Professor Peller, ni kete to ba gbọ.
Bi onirese Peller ko ba si fin igba mọ, awọn eyi to ti fin silẹ, ko le lọ sokun igbagbe laelae nitori titi aye la maa se iranti rẹ.
A ko si le gbagbe awọn ipa to ko si agbega iran Yoruba lati ipasẹ isẹ to yan laayo, tii se idan pipa.
Bi itan igbe aye ati diẹ lara awọn ohun ti akọni ọlọwọ idan, Ọjọgbọn Abiola Peller gbe ile aye se ree, ko to silẹ bora.
Oríṣun àwòrán, Intagram/shinapeller
Ilu Isẹyin, lagbegbe Oke Ogun nipinlẹ Oyo ni wọn ti bi Ọjọgbọn Moshood Folorunso Abiola Peller, ti ọpọ mọ si Professor Peller ni ọdun 1941
Idile Musulumi pọnbele lo ti jade gẹgẹ bi ẹsin naa se wọpọ nilu Isẹyin, Moshudi olori pupa si ni inagijẹ rẹ nigba to wa ni kekere.
Oríṣun àwòrán, Intagram/shinapeller
Idi ni pe eeyan pupa ni Abiola Peller, ti irun ori rẹ si pọn bii osun, amọ to n dudu diẹdiẹ nigba to dagba.
Ile ẹkọ alakọbẹrẹ Musulumi ati Native Authority nilu Isẹyin lo ti ka iwe alakọbẹrẹ rẹ, ko to morile ilu Ibadan.
Ilu Ibadan yii si lo ti bẹrẹ isẹ idan pipa lọdun 1954, to si n lọ yika Ibadan, Eko ati Oyo lati pidan.
Amọ nigba to di ọdun 1959, Peller pa isẹ da, to si di asoju ileesẹ ontaja G.B.O ati ilumọọka onisowo pẹrẹu.
Sugbọn niwọn igba to jẹ pe abinibi yatọ si adayekọ, isẹ idan to wa ninu ẹjẹ Peller ko se bo mọlẹ, idi si ree to fi tun pada sidi isẹ naa lọdun 1964.
Nibayii, ilẹ India ni Peller gba lọ lati lọ wa imọ kun imọ rẹ ninu idan pipa, se gbogbo agbaye lo kuku mọ pe orilẹ-ede India ni ile idan pipa.
Ọdun kan ati aabọ ni Peller lo ni India lati fi kọ isẹ idan pipa si, o wa morile orilẹ-ede Liberia lati tẹdo si nigba to kuro ni India.
Nigba to di ọdun 1966, lo tun pada wa sile nitori ajo ko dabi ile, to si bẹrẹ si ni fi isẹ idan pipa pa ọwọ da.
Oríṣun àwòrán, Intagram/shinapeller
Yoruba ni arise ni arika, arika si ni baba iregun, ohun ta ba gbe ile aye se loni, yoo di itan to ba di ọla.
Bẹẹ ni ọrọ awọn aseyọri aramanda ti Ọjọgbọn Peller fi idan da nigba aye rẹ.
Ẹnikan kii ba Yinmiyinmi du imi si lọrọ rẹ, to ba di ibi ka pidan, to le mu omi loju ẹni tabi mu ki aya ẹni ja de idi.
Oríṣun àwòrán, Intagram/shinapeller
Ni orilẹ-ede Naijiria ati Afirika lapapọ, ẹyẹ ti yoo se bii ọkin ko si lawujọ ẹyẹ ni ọrọ idan Abiola Peller, ti gbogbo eeyan si gba pe oun ni pidanpidan to dantọ julọ.
Koda, lẹyin ti Peller papoda, ko tii si ẹni kan to le pidan bii baba ọlọwọ idan yii.
Bo si se n la ẹnu ọba silẹ lasiko iworan idan rẹ, naa ni ero iworan yoo sẹmi lọ ti idan Peller ba wọra ja.
Koda, fasiti kan nilẹ Gẹẹsi, University of Birmingham gan an ko le gbagbe idan nla kan ti Peller pa ni papa isere King George V lọdun 1972, eyi to wa pada di papa isere Onikan lonii.
Awọn manigbagbe ara ti Peller da nidi idan pipa:
Fasiti Birmingham wa se apejuwe Peller bii akọni apidan to ni igboya, ọla ati akikanju lara, ti idan to n pa si rọ ọ lrun pupọ.
Awọn akọni asaaju awujọ ati orilẹ-ede ti Peller ti fi idan da lara ya:
Lara awọn asaaju orilẹ-ede ti Peller ti fi idan dalaraya ni aarẹ ilẹ Togo to ti di oloogbe, Gnassingbe Eyadema ati Samuel Kanyon Doe ti orilẹ-ede Liberia ati aarẹ ilẹ Benin, Mathieu Kerekou.
Kii kuku se pe Peller ati Samuel Doe sadede di ọrẹ, se bi o lọ pidan lọdun 1970 ni nilu Monrovia, ti ero si ya si papa to ti n pidan naa.
Eyi lo si mu ki ijọba Liberia tete ko awọn agbofinro da sagbegbe naa lati ri i pe ohun gbogbo lọ leto leto, lara awọn agbofinro to wa nibẹ naa si ni Samuel Doe.
Se ẹyin lo n di akukọ, nigba to ya, Samuel Doe pada di aarẹ ilẹ Liberia lati ipasẹ iditẹ gbajọba, to si kesi Peller pe ko wa fi idan da oun naa lara ya.
Bakan naa nilẹ wa Naijiria, Oloye Obafemi Awolowo naa wa lara awọn asaaju oloselu to gbadun idan Peller, lasiko to fi jẹ olootu ijọba ẹkun Iwọ oorun guusu Naijiria.
Oríṣun àwòrán, Intagram/shinapeller
Wọn se apejuwe Peller bi eeyan to ni ifẹ pupọ, ti oun ati aya rẹ, Alhaja Silifat Adeboyin Peller si nifẹ ara awọn nigba ti onitọun wa nile ẹkọ girama.
A gbọ pe Peller lọ pidan nile ẹkọ girama iseyin District Grammar School lọdun 1967 ni, lo ba foju kan arẹwa obinrin naa laarin awọn akẹkọ to wa woran.
Ibẹ ni wọn ti fi eso ifẹ lọlẹ, eyi to dagba di igi alọye, to si so eso rere, ti ọmọge ọjọ naa si di Lady Peller, to n ba ọkọ rẹ sere idan.
Ọdun 1971 ni wọn se igbeyawo, ti wọn si bi isu ati iwalẹ fun ara wọn.
Bi o tilẹ jẹ pe Abiola Peller fẹ ọpọ obinrin bii aya, ti wọn si se abiyamọ fun, amọ eyi ti okiki rẹ kan julọ, ti aye si mọ mọ baba ọlọwọ idan naa ni Lady Peller.
Iku ati igbẹyin aye Moshood Folorunso Abiola Peller:
Ọjọ nla, ọjọ manigbagbe ni ọjọ keji, osu Kẹjọ, ọdun 1997 ti iku wọle wẹrẹ, to si mu baba ọlọwọ idan lọ nile rẹ ladugbo onipaanu nilu Eko.
Inu ile rẹ yii lo wa ni ọjọ naa, lọwọ aago meje alẹ, to sẹsẹ ti ode de, to si n kirun alẹ lọwọ, ti awọn abẹnipa-gbowo wọle tọ wa, ti wọn si da ẹmi rẹ legbodo.
Ori irun kiki ni iku airotẹlẹ naa de ba Peller, ti wọn si fi ibọn pa, bẹẹ ni ko si ẹni to le sọ awọn eeyan to wa nidi isẹlẹ naa ati idi ti wọn fi se bẹẹ, titi di akoko yii.
Ọdun mẹrindinlọgọta pere ni akọni ọlọwọ idan yii lo loke eepẹ, ki wọn to ja okun ẹmi rẹ lainidi.
Oríṣun àwòrán, Instagram/ladypeller
Yoruba ni bi ina ba ku, a fi eeru boju, bi ọgẹdẹ ba si ku, yoo fi ọmọ rọpo, bi oloye ba ku, o sa maa n fi oloye silẹ ni.
Ọba oke fi awọn ọmọ oloriire lọkunrin lobinrin jinki Abiola Peller, ti gbogbo wọn si n gbe oke eepẹ se rere lọjọ oni.
Koda, ọmọ rẹ kan, Shina Peller ni asoju-sofin to n soju ẹkun idibo isẹyin, Itesiwaju, Kajola ati Iwajowa nipinlẹ Oyo, nile asoju sofin apapọ bayii.
A wa n gbadura pe ki Ọba Oke fi ọrun kẹ baba ọlọwọ idan, Ọjọgbọn Moshood Folorunso Abiola Peller.
Ohun pataki ta ri kọ ninu itan aye akọni ọlọwọ idan yii ni pe ka mase fi àrà sinu ku.
Gbogbo abuda ati ọgbọn atinuda ti Ọba oke ba fun wa lati ọrun, ni ka maa lo fun agbelarugẹ iran ọmọniyan.
Oríṣun àwòrán, Intagram/shinapeller
Bi Abiola Peller ko tilẹ pẹ pupọ laye, ki wọn to ran sọrun ọsan gangan, sibẹ, ipa kekere kọ lo ko lati mu ki ẹmi ẹda gun si pẹlu ọwọ idan to ni.
Ipokipo ti ẹda ba si wa, ipa rere ta le fi lelẹ fun agbega iran ọmọniyan, ni ka jẹ ko jẹ wa logun.
Ọjọgbọn Moshood Folorunso Abiola Peller, ọrun re rẹ o.
Canada Asylum: Ọ̀pọ̀ ọ̀dọ́ Nàíjíríà ń bèèrè láti ṣàtìpó ní Canada
Oríṣun àwòrán, High Commission of Canada to Nigeria
Laipẹ la mu iroyin wa fun yin pe obinrin kan to kopa ninu iwọde Endsars, to si kede ikọlu awọn ologun ni Lekki, DJ Switch, ti ri atipo gba lọ silẹ Canada.
Lati igba ti iroyin bi DJ Switch se ja pa naa gbalẹ́ kan, ni ọpọ awọn ọdọ miran naa ti n ya lọ si ileesẹ asoju ijọba orilede Canada ni Naijiria to wa nilu Eko.
Koko ohun ti wọn si n beeere ni pe ki ijọba ilẹ Canada naa fi aaye gba awọn plu lati wa se atipo lọdọ rẹ, gẹg bo ti se fun obinrin naa.
Oniruuru awijare lawọn ọdọ naa mẹnuba pe o mu kawọn beere fun atipo naa, eyi ti wọn lo nii nnkan se pẹlu idunkooko mọ ẹmi awọn.
Oríṣun àwòrán, Twitter/DJ switch
Sugbọ̀n nibayii, olu ileeṣẹ asoju ijọba orilẹ-ede Canada ti sọ pe, ilẹ naa kii ṣadeedee gbawọn aṣatipo si orilẹ-ede naa.
Ileeṣẹ asoju naa sọrọ yii nitori awon ọmọ Naijiria to fẹ ja pa bii ọkan lara awọn oluwọde EndSARS, DJ Switch to ti fi ilu silẹ bayii.
Ohun to yẹ ki o mọ nipa ṣiṣe atipo tabi ṣiṣe abẹwo si orilẹ-ede naa ree:  Canada
Ileeṣẹ ọhun ṣalaye pe orilẹ-ede Canada n ṣiṣẹ pọ pẹlu igbimọ to n ri si ọrọ awọn aṣatipo ni ajọ iṣọkan agbaye, UNHCR at'awọn ẹgbẹ mii lati ṣe idanimọ awọn to nilo atipo gan an.
Oríṣun àwòrán, dj_switchaholic
Nibo ni DJ Switch wa? Se o ti sa kuro ni Naijiria ni? Orilẹede wo lo wa gan, ati pe, ta lo n dunkooko mọ ẹmi rẹ?
Eyi ni ibeere to gba ẹnu awọn ọmọ Naijiria kan nipa obinrin yii, DJ Switch, ẹni to tu asiri fun araye nipa ikọlu ologun sawọn oluwọde EndSARS ni Lekki ni ogunjọ osu Kẹwa ọdun 2020.
Bi wọn ba sọ fun awọn eeyan pe wọn wa ibi ti Obianuju Catherine Udeh wa, o ṣeese ki ọpọ maa beere pe ta lo n jẹ bẹẹ.
Ṣugbọn bi a ba ti fi inagijẹ DJ Switch kun ibeere yii, ko ni jẹ ohun iyalẹnu nitori ọpọ lo gba ori ayelujara ni Naijiria lọ ti wadii nipa akọni obinrin naa.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Eyi ko si ṣẹyin bi iroyin ti ṣe gbode pe, gbajugbaja gbajumọ ori ayelujara ati DJ yii ti sa kuro ni Naijiria lọ si orilẹede Canada.
Bawo lo ṣe de kuro ni Naijiria ati pe nigba wo lo lọ?
Ninu  iroyin to tẹ wa lọwọ eyi ti ileeṣẹ Iroyin Naijiria Punch gbe jade, amugbalẹgbẹ akọrin takasufe Peter Okoye ta mọ si Mr P fidi ọrọ mulẹ fun ileeṣẹ iroyin naa pe, DJ Switch ti kuro ni Naijiria
Ninu ifọrọwerọ naa pẹlu Charles Abi, o ni lootọ ni pe alaafia ni DJ Switch wa ati pe o ti rinrinajo kuro ni Naijiria.
Amọ ṣa, arakunrin Abi ko sọ ibi ti DJ Switch ka nlẹ lọ.
Oríṣun àwòrán, djswitch_
Abi ni nitori idunkoko mọ ẹmi ti DJ Switch ni Naijiria ati aabo ti ko si fun ẹmi rẹ, lo mu ko tete sa asala fun ẹmi rẹ.
''A ko fẹ sọ nnkankan lasiko yii, ootọ ọrọ ibẹ si ni yẹn. Ọrọ idunkoko lọrọ taa n wo yii nitori wọn ti n dun koko mọ pupọ.
Ootọ ibẹ ni pe, DJ Switch ko si ni Naijiria lọwọ yii. A o ni sọ boya Canada lo wa ṣugbọn ko si ni Naijiria bayi ati pe alaafia lo wa.''
Nipa iroyin to gbode pe DJ Switch ba awọn aṣofin ilẹ Canada sọrọ, Abi ni oun ko le sọ boya bẹẹ lo ri.
''Mi o le sọ fun yin pe o sọrọ niwaju ile aṣofin ilẹ Canada amọ bi ẹ ba ri ti ile aṣofin Canada fi ọrọ to jọ mọ bẹẹ sita, a jẹ pe o ri bẹẹ ni yẹn.
Ọga mi ti kilọ fun mi pe, ki n ma kọ nkankan si oju opo rẹ, bi asiko ba to, yoo sọrọ''
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ohun ti BBC ṣe iwadii ree:
Iwadii BBC ṣafihan pe DJ Switch ko kọ nkankan si oju opo rẹ lati le tọka ibi to wa.
Ṣugbọn a ri fọnran fidio ipade igbimọ ile asofin Canada kan to n gbẹjọ nipa ẹtọ ọmọniyan nilẹ okeere eyi to waye lọjọ Kẹfa oṣu Kọkanla ọdun yii.
Ninu fidio naa ti wọn gbe soju ayelujara, ni DJ Switch ati awọn ẹlẹri mii bi Osai Ojigho ti Amnesty International ti sọrọ.
Tim Okafor ati Stella Nkemdimrim to ṣoju awọn ọmọ ẹgbẹ Biafra to wa ni Canada ati Abdulrazaq Namdas ṣalaye fun alaga igbimọ naa, Peter Fonseca, nipa ohun to ṣẹlẹ ni Naijiria sawọn oluwọde ENDSARS.
Ko si ohun to tọka si pe Canada ni DJ Switch wa nigba to kopa ninu ipade yii ṣugbọn o sọ ninu fidio naa pọnbele pe, oun ti kuro ni Naijiria.
Oríṣun àwòrán, Screenshot/parlvu.parl.gc.ca/
Bakan naa akọrin takasufe P Square to jẹ ọga Charles Abi, naa ṣẹnu pẹmu, ti ko si sọ nkankan to jọ mọ ọrọ DJ Switch loju opo rẹ.
Yatọ si awọn arigbamu yii, ijọba Naijiria naa ko ti sọ boya bi Switch ti sa kuro nilu de eti igbọ wọn ati iru igbeṣẹ ti wọn fẹ gbe nipa rẹ.
Bi a ko ba gbagbe DJ Switch wa lara awọn to lewaju iwọde ENDSARS, ti o si ṣalabapin fọnran fidio to ṣafihan bi awọn eeyan ṣe n rọ yika oluwọde kan ti wọn yinbọn lu ni Lekki.
Oríṣun àwòrán, EPA
Bo tilẹ jẹ pe ijọba ti jade lati sọ pe awọn ko dena  mọ oluwọde kankan lati maṣe rinrinajo kuro nilẹ Naijiria, amọ ijọba gbe igbesẹ kan laipẹ yii to fi han pe, o ṣeeṣe ki wọn maa dunkoko mọ awọn to ni nnkan ṣe pẹlu iwọde naa.
Bi a ko ba gbagbe, Modupe Odele agbẹjọro awọn oluwọde naa ṣalaye pe, awọn oṣiṣẹ ajọ to n risi iwọle-wọde da oun pada ni papakọ ofurufu Murtala Mohammed ni Eko lasiko to fẹ rinrinajo kuro ni Naijiria.
O ni wọn pada da iwe irinna oun pada ṣugbọn oun ko ribi ba baalu to yẹ fun irinajo naa lọ.
Oríṣun àwòrán, djswitch_
Bẹẹ naa tun ni ile ifowopamọ agba Naijiria CBN, gbegi le asunwọn owo awọn oluwọde kan to fi mọ Rinu Oduala ati Majekodunmi Temitope, ti wọn n ṣoju ọdọ nibi ijoko igbimọ iwadii ti ijọba Eko gbe kalẹnipa iwa ọlọpaa EndSARS.
Awọn mejeeji ti tori igbesẹ naa binu kuro ninu igbimọ ọhun.
Arabic on Naira: CBN ní owó gọbọi ní yóò ná Nàíjíríà láti tẹ owó tuntun jáde
Oríṣun àwòrán, Twitter/Nairametrics
Ileẹjọ giga apapọ nilu Eko ti ṣetan lati gbẹjọ lori ẹsun t'agbẹjọro kan gbe wa siwaju rẹ pe, ki ile ifowopamọ apapọ Naijira, CBN, yọ Keu ti wọn kọ si ara Naira kuro.
Lọjọ iṣẹgun yi ni igbẹjọ yii yoo waye.
Agbẹjọro taa n wi yii, Malcolm Omirhobo tun fẹ ki ile ẹjọ paṣẹ fun ileeṣẹ ologun Naijiria lati yọ alifabẹti ati ọrọ keu to wa lara ami idanimọ wọn.
O ni ipe yii di dandan nitori Naijiria kii ṣe ilẹ ta ti n tẹle ofin ẹsin tabi ilẹ to n tẹle ofin ẹsin Islam.
Agbẹjọro yii tun fẹ ki wọn fi ede abinibi Yoruba, Igbo, tabi Hausa parọ ọrọ kewu tabi ede gẹẹsi to ba wa lara owo Naijiria.
Oríṣun àwòrán, @Emefiele
Ṣugbọn Banki apapọ Naijiria, CBN, ti sọ fun ile ẹjọ giga ijọba apapọ nipinlẹ Eko pe, owo gọbọi ni yoo na orilẹ-ede Naijiria lati tẹ owo tuntun jade.
Ile ifowopamọ agba Naijiria naa ni kikọ nnkan lede larubawa kii ṣe ami idanimọ ẹsin Islam.
O ni ọpọ awọn eeyan to n gbe lagbegbe ariwa Naijiria ni wọn n sọ ede larubawa bo tilẹ jẹ pe ede Gẹẹsi ni ede tofin Naijiria fontẹ lu gẹgẹ bi ede ajumọsọ.
Governor's Pension: Kwara fẹ́ ṣé bí Èkó, ó dẹ́kun sísan owó ìfẹ̀yìntì fáwọ̀n Gọ́mìnà àná àti igbákejì wọn
Oríṣun àwòrán, Facebook/Saraki/Abdulrahaman
Ipinlẹ Kwara ti ṣetan lati ba ipinlẹ Eko ko anko, nipa yiyi ofin to ya owo ifẹyinti sọtọ fawọn Gomina tẹlẹ ati igbakeji wọn.
Lọjọ Ẹti ni ọrọ yii jẹyọ lati ọdọ Rafiu Ajakaiye, tii se agbẹnusọ fun Gomina Abdulrahaman Abdulrazaq.
Ajakaiye ni Gomina yoo fi aba iyipada naa ṣọwọ si awọn aṣofin lọṣẹ to n bọ, lati ṣe ayipada ofin ni kiakia.
''Gomina ti tẹti si ohun tara ilu sọ eyi ti o tako sisan owo ifẹyinti fawọn Gomina ati Igbakeji wọn''
Oríṣun àwòrán, facebookpage adbulrahman
''Ni ibamu pẹlu adehun ipolongo rẹ, Gomina yoo fi aba yii ṣọwọ si awọn aṣofin fun agbeyẹwo lọsẹ to n bọ''
Bẹẹ naa ni Ajakaiye sọ ninu atẹjade naa pe, Gomina ni ''yoo da ki awọn aṣofin pe ipade apero araalu lati sọ erongba wọn lori ọrọ yii''
O fi kun pe, Gomina Abdulrahman ro pe asiko ti to bayi ki  wọn wọgile ofin naa, ki wọn baa le lo owo ọhun fun idagbasoke ipinlẹ Kwara.
Kwara ni ipinlẹ akọkọ to lawọn yoo tẹle ipaṣẹ Eko.
Ondo Land Death: Opó àti àbúrò olóògbé ní aáwọ̀ ilẹ̀ ló fá ikú òjijì fún Olayinka Olabode
Amọ gomina ipinlẹ Delta, Ifeanyi Okowa, ti sọ ṣaaju pe oun ko ni pa ofin yii rẹ nitori Delta kii ṣe Eko.
Lọpọ awọn ipinlẹ Naijiria ni ofin to bu owo tabua fawọn Gomina ati igbakeji wọn ti wa nilẹ lẹyin ti wọn ba pari saa wọn yala ọdun mẹrin tabi mẹjọ.
Oríṣun àwòrán, Tinubu
Asíwájú ẹgbẹ̀ òṣèlú All Progressive Congress (APC) tó tún jẹ́ gómìnà ìpińlẹ̀ Eko nígbà kan rí tí gbóríyìn fún gómìnà ìpińll Eko, Babajide Sanwo-Olu lórí ìgbésẹ̀ túntun tó gùnlé.
Lánàá òde yìí ni Gómìnà Babajide Sanwo-Olu sàlàyé pé, òun ń pinu láti kásẹ̀ òfin tó ní kí wan ma san owó ìfẹ̀yìntì fún àwọn gómìnà tó ti jẹ rí àti àwọn ìgbákeji wọ̀n.
Lọ́jọ́rú ni Tinubu fi ọ̀rọ̀ náà léde lójú òpó twitter rẹ̀ ló ti kí gómìnà ìpińlẹ̀ Eko ku oríre fún abájá bi ó ṣe ka ìsúnà owó ọdún 2021 ti o pé akọlé rẹ̀ ni títa ìrètí jí.
Sickle Cell In Nigeria: Makinde ní ìgbàgbọ́ ninú ìdílé òun ṣèdíwọ́ láti ṣàyẹ̀wò ẹ̀jẹ̀
O ní ìgbésẹ̀ gómìnà láti fòpin si owó ìfẹ̀yìnti fún àwọn gómìnà ànà àti igbákejì wọ̀n, ó jẹ́ ìgbésẹ̀ akin tí òun si fi gbogbo ara dúró ti gómìnà lórí ìgbésẹ̀ náà.
Mo rẹọ gbogbo àwọn gómìnà APC tó kù láti gbé irú ìgbésẹ̀ bẹ́ẹ̀
Grandma Maruwa: Ó yẹ kí obìnrin sisẹ́ láì wojú ọkọ kó tó jẹun
Ìṣúná 2021 yóò ṣíjú ọ̀dọ́ kúrò nínú ìwá Yahoo-Yahoo - Sanwo-Olu
Oríṣun àwòrán, Twitter/Mr_JAGss
Gomina  Babajide Sanwo-Olu ti gbe aba iṣuna oni triliọnu kan Naira le diẹ (₦1.155 Trn) fọdun 2021 kalẹ, niwaju ile aṣofin ipinlẹ Eko.
Bakan naa ni Sanwo-Olu fi erongba rẹ han, lati wọgile ofin sisan owo ifẹhinti fawọn Gomina tẹlẹ nipinlẹ Eko ati igbakeji wọn.
Lasiko to n sọrọ niwaju awọn aṣofin, Sanwo-Olu ni igbesẹ yii wa ni ibamu pẹlu ipinnu lati mu adinku ba owona ijọba.
Ipinlẹ Eko wa lara awọn ipinlẹ Naijiria to fi ofin gbe sisan owo yii lẹyin (Payment of Pension Law 2007) ṣugbọn awọn araalu n lọgun pe owo ti wọn n san fawọn to fi ipo silẹ naa ti pọju.
Aba iṣuna ọdun 2021 ti Sanwo-Olu gbe kalẹ naa, lo pe akori rẹ ni ‘aba iṣuna to sọ ireti ji pada’.
Ninu aba naa o ni awọn yoo doju kọ pipese ohun amayedẹrun ati mimu igbe aye rọrun fawọn ọdọ nipa awọn eto orisirisi.
Fun idi eyi, o ni awọn yoo ya N9.16 billion sọtọ lati gbe oju awọn ọdọ kuro nibi iwa yahoo yahoo ati iwa ọdaran mi.
Oríṣun àwòrán, Twitter/Mr_JAGss
Ẹka ọgbin, irina, aabo ati ẹkọ naa ko gbẹyin ninu awọn ti yoo jẹ ninu mudunmudun iṣuna ọdun 2021 yii.
Alaafin Oyo: Níbo ni Olorí Anu àti Dami wà?
Oríṣun àwòrán, Instagram/Queen Anu/Queen Dami
Iroyin kan to n lọ lori ayelujara ni pe, olori meji tun ti kuro ni aafin Alaafin ilu Oyo, Ọba Lamidi Adeyemi kẹta.
A gbọ pe meji lara awọn 'ẹlẹ daddy' ọhun, Olori Damilola ati Olori Anu, lo sa kuro ni aafin Oyo.
Ohun ti iroyin naa sọ ni pe Olori Damilola, to jẹ iyawo kekere, lo tapa si ọkan lara awọn ofin to de ihuwasi wọn ni aafin, eyi to mu ki wọn o ti i mọ yara ibawi to wa ninu aafin Oyo.
Ko tan sibẹ o, iroyin naa sọ pe fun bi ọsẹ kan ni Olori Damilola, to bi ibeji fun alaafin, fi wa ninu ẹwọn naa, to si jẹ pe gbogbo dukia rẹ ni wọn gba lọwọ rẹ.
Oríṣun àwòrán, Instagram/officialqueen_dami
Ko si aworan ikini ku ayẹyẹ ọjọ ibi fun Alaafin loju opo Instagram Olori Anu, amọ o wa ni oju opo ti Dami
Bakan naa ni iroyin sọ pe, lọgan ti wọn fun ni ominira, lo sa kuro ni aafin pẹlu akẹẹgbẹ rẹ, Olori anu, ti wọn si sa lọ si ipinlẹ Eko.
Koda, iroyin sọ pe aarin oru ni wọn fi sa kuro nilu Oyo lọ si Eko.
Lootọ ni BBC Yoruba ko ti i le sọ pato otitọ to wa ninu iroyin yii, amọ awọn akiyesi kan ti a ri lori ayelujara Instagram Olori Anu re e:
Oríṣun àwòrán, Instagram/queen Anu
Awọn arigbamu yii lo mu ki BBC Yoruba kan si Olori Anu lori ẹrọ ibanisọrọ rẹ, lati fi idi ootọ ọrọ nipa iroyin yii to n lọ lori ayelujara mulẹ, lati mọ boya o si wa ni aafin Oyo abi o ti kuro.
Nigba to n dahun ibeere wa lori aago, Olori Anu sọ pe ọrọ igbesi aye oun ni, ati pe oun ko ni ohunkohun sọ nipa iroyin naa.
"O ni ""ọrọ igbeyawo mi pẹlu Alaafin ni, ko kan ẹnikẹni, ọrọ ara mi ni."""
Bẹẹ ba si gbagbe, BBC Yoruba ti se ifọrọwanilẹnuwo ri fun Olori Anu, ẹni to yonbo Ọba Adeyemi pupọ, to si ni o n kẹ oun loju-nimu, eyi ti ọdọkunrin miran ko le se.
O ni ifẹ nla lo wa laarin oun ati Ọba naa, ti oun ko si kabamọ rara pe oun fẹ Alaafin, tii se ẹni ọdun mejilelọgọrin ni ọkọ.
Alaafin: Olori Aanu Adeyemi ṣàlàyé ìdí tó ṣe gẹ́ Oba Lamidi Adeyemi ti ìlú Oyo
Ni ti Olori Dami, a ko ṣakiyesi ayipada kankan loju opo Instagram rẹ.
Oṣu Kẹjọ, ọdun 2020 ni iroyin nipa igbeyawo rẹ pẹlu Alaafin jade sita, bo tilẹ jẹ pe o ti n gbe ni aafin tipẹ, to si ti bi ọmọkunrin kan fun baba.
Oríṣun àwòrán, Instagram/queen_Dami
Ṣe ẹ o gbagbe pe ninu ọdun 2020 yii kan naa, ni iroyin sọ pe, wọn ti le ọkan lara awọn olori alaafin to gbajumọ julọ lori ayelujara, Olori Badirat, kuro ni aafin.
Ẹsun ti iroyin sọ pe wọn fi kan nigba naa ni pe, o n ni ifẹ ikọkọ pẹlu gbaju-gbaja olorin Fuji, Wasiu Ayinde, K1.
Bo tilẹ jẹ pe Badirat tabi aafin ilu Ọyọ ko fi idi iroyin naa mulẹ titi di asiko yii, awọn akiyesi kan nipa nkan ti Badirat n fi sori ayelujara Instagram rẹ n fihan pe, o ṣe e ṣe ko jẹ ootọ ni iroyin naa.
Bakan naa lo fi oju han pe ilu Eko ni Olori Badra n gbe bayii, to si ti si ile itaja nla kan si adugbo Ikeja nilu Eko eyi to si losu kẹwaa ọdun 2020.
Oríṣun àwòrán, Instagram/queenola2
Ninu ile itaja naa lo ti n ta aṣọ, ati ohun ẹsọ iṣaraloge, to si tun sọ lọjọ ayẹyẹ ọjọ ibi rẹ to kọja pe, awọn nkan to ṣẹlẹ si oun lọdun 2020 ba oun lọkan jẹ, to si jẹ ki oun mọ pe ohun gbogbo to n dan kọ ni wura.
Sickle Cell In Nigeria: Makinde ní ìgbàgbọ́ ninú ìdílé òun ṣèdíwọ́ láti ṣàyẹ̀wò ẹ̀jẹ̀
Ẹkọ ko pin si ibi kan, ojoojumọ si ni eeyan yoo maa kọ ẹkọ si nile aye.
Titilayo Makinde jẹ alarun foniku fọlande, ti oloyinbo n pe ni sickle cell laimọ titi to fi pe ẹni ọdun mejidinlogun.
Makinde ni ẹsin igbagbọ tawọn n sin nile awọn mu ko nira lati tete maa lọ sile iwosan, eyi si lo sediwọ fun awọn obi oun lati mọ nigba toun wa ni ọmọ ọwọ.
Titilayo wa sọ nipa idẹyẹsi, abuku ati ijakulẹ ifẹ tawọn alarun naa maa n koju lawujọ ati iriri rẹ pẹlu.
Bakan naa ni ọkọ afẹsọna rẹ, Bamidele Toluwalase naa salaye fun BBC Yoruba nipa isoro to la kọja ki awọn obi rẹ to fi ọwọ pe ko fẹ Titilayo, tii se alarun sickle cell.
Balarabe Musa: Kókó ohun márùn-ún nípa gómìnà Kaduna tẹ́lẹ̀ tó dólóògbé
Oríṣun àwòrán, Hutudole
Iroyin iku agba ọjẹ oloṣelu Balarabe Musa jẹ eleyi ti o fọwọ kan ọpọ lẹmi ni Naijiria.
Ninu awọn ti wọn jọ jẹ irọ, Balarabe ni o fẹ ṣẹku ninu oloṣelu ti ko fi ọrọ isọkan ati idagbasoke Naijiria ṣere rara.
Lootọ, ohun ti ọpọ yoo ranti nipa Balarabe Musa ni pe oun ni Gomina alagbada akọkọ ninu akọsilẹ orilẹede Naijiria, ti wọn yọ kuro nipo.
Ṣugbọn ti eeyan ba ṣe iwadii daada yoo ri pe awọn nkan manigbagbe mii wa to ya Balarabe sọtọ laarin awọn oloṣelu ẹgbẹ rẹ ni Naijiria.
Oluṣiro ati olukọni ni Balarabe Musa  jẹ:
Ninu awọn ọmọ Naijiria to n duro gẹgẹ bi alatako fawọn olori ti ko ba ṣejọba daada ni Naijiria, ni Balarabe Musa wa.
Lati igba to ti bẹrẹ irinajo rẹ lagbo ọṣelu lo ti n tako awọn to wa ni ijọba, to si maa n ṣapejuwe awọn olori gẹgẹ bi ẹni to n ṣe ijọba fun anfaani awọn to ri jajẹ lawujọ nikan.
Balarabe Musa ati Buhari ti ṣe pọ nigba kan ri:
Ohun manigbagbe kan ti a tun le tọka si nipa Balarabe Musa ni pe o ti fi igba kan gbaruku ti aarẹ Muhammadu Buhari ninu idibo aarẹ ọdun 2007.
Gẹgẹ bi alaga fun agbarijọpọ ẹgbẹ oṣelu ni Naijiria, CNPP, Musa ni Buhari jẹ ẹni t'eeyan le f'ọkan tan ju Umaru Musa Yar Adua ẹgbẹ PDP.
Amọ ṣa, nigba ti Buhari naa yoo fi di aarẹ, Balarabe ko ṣẹnu ku lati tako ijọba rẹ.
Sickle Cell In Nigeria: Makinde ní ìgbàgbọ́ ninú ìdílé òun ṣèdíwọ́ láti ṣàyẹ̀wò ẹ̀jẹ̀
PRP ni ẹgbẹ to ṣe to fi fẹyinti nidi oṣelu:
Agba ọjẹ oloṣelu nii, Aminu Kano lo da ẹgbẹ Peoples Redemption Party PRP silẹ nigba aye rẹ.
Ọrọ akọmọna ẹgbẹ yii to ni mimu aye dẹrun fawọn alaini lawujọ, jẹ eleyi ti Balarabe Musa nifẹ si.
Idi ree ti o fi dije dupo labẹ asia ẹgbẹ naa ni ọdun 1979.
Balarabe jẹ olori ẹgbẹ Peoples Redemption Party ni saa oṣelu awarawa ikẹrin ni Naijiria.
O jẹ oludije ipo aarẹ labẹ asia ẹgbẹ naa ninu idibo to waye lọdun 2003 ṣugbọn airi owo tẹ iwe ikede ipolongo ara ogiri ṣakoba fun erongba rẹ lati fi di aarẹ.
Nigba ti ipenija ilera de ba lo fi ipo olori ẹgbẹ naa silẹ lọdun 2018.
Balarabe Musa ko faramọ idasilẹ ikọ Amọtẹkun:
Idasilẹ ikọ alaabo lawọn ipinlẹ kaarọ o jiire jẹ ọkan lara ohun ti Balarabe bẹnu atẹ lu.
Ninu ifọrọwerọ pẹlu awọn akọroyin, o ṣalaye pe ''ọna ati fidi orilẹede Oduduwa Republic mulẹ'' lawọn to ṣe idasilẹ ikọ alaabo yii n wa.
Oríṣun àwòrán, Twitter/ShehuSani
Ọrọ rẹ yii ko dun mọ awọn agba Yoruba ninu, ti ọjọgbọn Wole Soyinka si sọ pe Balarabe kuna pẹlu ọrọ to sọ yii.
Toun ti bẹẹ, Balarabe pada sọ pe nitori ifẹ Naijiria loun fi sọ bẹẹ ati pe oun ko fẹ maa ba ẹnikẹni takurọsọ nipa idasilẹ ikọ yii.
Ko figba kan dakẹ lori eto atunto Naijiria - 'Restructuring'
Loore koore ni Balarabe Musa a maa sọrọ nipa bi nkan ṣe n lọ ni Naijiria.
Ni pataki Musa a maa bawọn pe fun atunto Naijiria lọna ti gbogbo ẹkun to wa ilẹ yii yoo fi jẹ anfaani iṣejọba.
Lara ohun to sọ sẹyin ni pe ki ba da ti Naijiria ba pada si iṣejọba ẹlẹkunjẹkun mẹfa bi ti atijọ.
Koda o tun kesi awọn ọmọ ilẹ Naijiria lati gbera nlẹ ṣe ijijagbara ti yoo ko wọn yọ lọwọ ijọba All Progressives Congress, APC to wa lori oye.
Oríṣun àwòrán, Hutudole
Saaju la ti mu iroyin wa fun yin pe gomina ana nipinlẹ Kaduna, Balabe Musa ti jade laye.
Ọdun mẹrinlelọgọrin ni Balarabe Musa lo loke eepẹ, ko to jẹ Ọlọrun nipe.
Iroyin iku Musa ni sẹnatọ Shehu Sani fi si oju opo Twitter rẹ ni aarọ ọjọru.
Sani wa gbadura pe ki Oluwa fi ori jin ẹni re to lọ.
Osu Kẹwa ọdun 1979 ni Balarabe Musa wọle sipo gomina nipinlẹ Kaduna gẹgẹ bi gomina alagbada akọkọ nipinlẹ naa.
Amọ ti wọn yẹ aga mọ nidi lọjọ Kẹtalelogun osu Kẹfa ọdun 1981 gẹgẹ bii gomina, eyi to mu ko jẹ gomina alagbada akọkọ ni Naijiria ti wọn yoo yọ nipo.
Ọjọ Kọkanlelogun osu Kẹjọ ọdun 1936 ni wsn bi Balarabe Musa sile aye silu Kaya nipinlẹ Kaduna.
Gbogbo ọmọ Naijiria ni yoo mọ ipa Balarabe Musa lara nitori ọpọ igba lo maa n sọrọ tako awọn iwa kotọ ti ijọba to wa lori oye n hu.
Balarabe Musa kii si se ẹni to n fi ẹya tabi ẹsin se ninu ọrọ rẹ.
Rahama Sadau blasphemy: Ẹ̀kúnrẹ́rẹ́ ìròyìn rèé nípa bóyá wọ́n dájọ́ ikú fún òṣeré Kannywood
Oríṣun àwòrán, George Okoro
Rahama Sadau ninu aworan to da awuyewuye silẹ
Osere tiata Kannywood kan, Rahama Sadau ti figbe ta pe ko si ẹnikẹni to mu oun ati pe, ofege ni iroyin to gbode pe wọn ti dajọ iku fun un.
Sadau fi ikede yii sita loju opo rẹ ni Twitter rẹ nirọlẹ ọjọ iṣẹgun.
Ikede rẹ naa ko ṣẹyin bi iroyin ṣe gba ori ayelujara kan pe wọn ti gbe osere tiata naa lọ si ileẹjọ Sharia, ti wọn si dajọ iku fun tori pe o ṣatọna bi  awọn kan ṣe sọrọ abuku si Anọbi Muhammad.
"O ni ''Mi o mọ ibi ti iroyin yi ti wa. Mo si rọ awọn eeyan lati sinmi ahesọ ọrọ ti ko nidi."""
Oríṣun àwòrán, Rahama Sadau
Lọsẹ to kọja ni Rahama ṣe alabapin awọn aworan rẹ kan to fara rẹ silẹ loju opo ayelujara.
Bi awọn eeyan kan si ṣe n gbosuba kare fun lori aworan yii, ni awọn miran n bẹnu atẹ lu.
Aworan naa da awuyewuye silẹ, tawọn eeyan kan si n sọrọ abuku si Anọbi Muhammad ninu ọrọ ti wọn kọ sabẹ aworan naa loju opo Twitter Rahama.
Ko si ẹnikankan to mu mi:
Amọ bi awọn eeyan kan ṣe n pe Rahama Sadau lori ago nipa idajọ iku ti wọn gbọ pe wọn se fun, lo mu ko bọ si oju opo Twitter rẹ lati salaye pe wọn ko mu oun.
''Awọn ọlọpaa ko fiwe pe mi, bẹẹ si ni mi o gba iwe ipẹjọ kankan. Mo fẹ fi da awọn ololufẹ mi loju pe alaafia ni mo wa, ko si si ẹjọ kankan ti wọn fi kan mi''
''Fawọn to fẹ sọ ọrọ yii di bamii, ti o le mu wahala wa, mo bẹ yin, ẹ tọwọ ọmọ yin ba sọ''
O fi kun ọrọ rẹ pe ''asiko yi jẹ akoko inira fun mi. Kii ṣe igba yii lo yẹ ka tun maa tan iroyin ofege ka. Mo dupẹ lọwọ awọn to kan si mi''
Alaafin Oyo: Olorì Anuoluwapo Adeyemi gba àmì ẹ̀yẹ lórí oge ṣíṣe
Oríṣun àwòrán, Royal Image Photography
Aya Alaafin ilu Oyo tẹlẹ, Olori Anuoluwapo ti kede pe wọn ti fun oun ni ami ẹyẹ fun ipa ti oun ko nipa eto oge ṣiṣe.
Olori Anuoluwapo lo kede bẹẹ loju opo Instagram rẹ lọsan ọjọ Aje.
"Nigba to n kede ami ẹyẹ naa, o ni ""mo ki gbogbo wa ku oriire o, ami ẹyẹ yii wa fun gbogbo awọn ẹbi mi loju opo Instagram yii nitori mi o jẹ ohun kankan laisi Ọlọrun ati ẹyin ololufẹ mi."""
"Kí ni ""Present tense"" lédè Yorùbá?"
Ileeṣẹ iroyin City People lo fun Anuoluwapo ni ami ẹyẹ ọhun lọjọ Aiku, ọjọ kọkandinlọgbọn, oṣu kọkanla, ọdun 2020.
Anuolouwapo jẹ ọkan lara awọn Olori Alaafin ilu Oyo, Ọba Lamidi Adeyemi III, eyii ti awọn eeyan kan gbagbọ pe oun ni aayo Kabiesi.
Ṣugbọn ni nnkan bi oṣu diẹ sẹyin ni iroyin gbode pe Olori naa ti ko kuro ni aafin Iku Baba Yeye.
Ṣaaju akoko naa ni iroyin ti kọkọ gbode pe họwuhọwu n waye laarin Kabiesi ati Olori yii lẹyin ti awọn kan fẹsun kan Olori ọhun pe o ni ibaṣepọ pẹlu gbajugbaja Olorin fuji kan.
Ṣugbọn Olori Anuoluwapo ati olorin fuji naa ti sọ pe ahesọ lasan ni, nitori ko si ohun to jọ bẹẹ.
Ọkùnrin tó fẹ́ fipábámilòpọ̀ fín ǹkan sí mi lójú ló ṣe rọ́nà wọlé sí mi lára
Oríṣun àwòrán, Instagram/queen__aanu
Yoruba ni ba ba dakẹ, tara ẹni maa n bani dakẹ ni, igi gogoro ma gun mi loju, ati okeere si la tii lọ ọ.
Eyi lo mu ki aayo Alaafin tilu Oyo tẹlẹ, Olori Anu fi n kigbe gbami-gbami fun araye nipa awọn ewu to ni oun n la kọja.
Saaju la ti kọkọ mu iroyin wa fun yin nipa ikede ti Olori naa gbe soju opo Twitter rẹ, nibi to ti pariwo pe ẹmi oun si wa ninu ewu tori pe oun kọ Alaafin.
Olori Anu, ninu igbe to fi bọnu naa, tun tẹsiwaju pe a kii dakẹ ku, ẹnikan kii si wo sun daran, idi si ree ti oun ko fi ni panumọ nitori ewu to n rọ dẹdẹ lori oun.
Oríṣun àwòrán, Instagram/queen__aanu
"Mo n pariwo sita lati daabo bo ẹmi mi ni nitori ko yẹ ki idunkooko mọ ẹmi mi wa tori pe mo ko kuro ninu Aafi
N ko le di awọn ọmọ mi lọwọ lati mọ baba wọn laelae, amọ gẹgẹ bi iya, oun to tọ fun mi ni lati ko wọn sọdọ mi."
Olori Anu wa kere pe ẹnu ya oun lati sawari rẹ pe wọn n yaju sawọn mọlẹbi oun nitori pe alaafin ko mọ ibi ti oun wa.
Bakan naa lo tun fi kun pe, gbogbo igbiyanju lati ji oun gbe lo ja si pabo, idi si ree ti oun ko fi le panumọ rara mọ, o ti to gẹ.
Oríṣun àwòrán, Instagram/queen__aanu
Mo kọ lati maa gbe ninu igbekun, maa si sa gbogbo ipa mi gẹgẹ bo se wa labẹ ẹtọ ti mo ni lati wa ni ominira. Mo fẹ gbe ile aye lati se iya awọn ọmọ mi.
Olori Anu ni oun n lo anfaani ikede naa lati tọrọ aforijin lọwọ ẹnikẹni ti oun ba ti ja kulẹ tabi to n binu si oun nitori ikede naa.
"O di dandan ki n pariwo sita ni nitori ẹmi mi ko de mọ. Ẹmi mi se pataki si mi. Mo si fẹ maa rin, maa yan kiri lati bẹru pe ẹnikẹni n sọ mi kiri.
Oríṣun àwòrán, Queen_Aanu/Instagram
Bakan naa ni n ko fẹ maa bẹru lori pe ohunkohun to jẹ aburu le sẹlẹ si mi."
Olori Anu naa wa pari ọrọ rẹ pe oun dupẹ pe ẹ fi oye gbe alaye oun.
Oríṣun àwòrán, Instagram/queen__aanu
Saaju la ti sọ fun yin pe, Olori Anu ti bọ soju opo Instagram ni irọlẹ Ọjọru lati kede fun araye pe oun ti kuro ninu aafin.
Anu, ẹni to ni pẹlu ibanujẹ ni oun fi n kọ ikede naa tun ni ó pọn dandan lati ṣe bẹẹ nitori ẹ̀mí oun atawọn ọmọ oun wa ninu ewu.
Olori naa, to bi ibeji fun Alaafin wa kede fun araye pe bi ijamba kankan ba ṣe oun atawọn ọmọ oun, Alaafin ni kí wọn mu.
O ni nitori pe oun kuro ninu igbeyawo oun ni wọn ṣe n dunkooko mọ ẹ̀mí oun, oun si wa n pariwo pe, Alaafin lo wa nidi rẹ, bi ibi ba sẹlẹ si òun.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí:
"Kii ṣe ifẹ ọkan mi lati da igbeyawo mi ru lainidi, n ko si le tẹsiwaju mọ lati maa gbe ninu igbekun.
Oríṣun àwòrán, @queen_anu
O wu emi naa lati lati gbe ile aye bo ṣe yẹ, ki n si jẹ iya rere to dara julọ fun awọn ọmọ mi."
Olori Anu ni oun kọ lati ba awọn akọroyin sọ̀rọ̀ nitori ọrọ asiri aye oun ni eyi jẹ, ati fun aabo awọn ọmọ oun.
Olori naa ni oun pinnu lati rọra kuro ninu aafin lai pariwo, ki oun le wa nile aye lati ṣe iya awọn ọmọ oun ni.
Amọ o ni o da oun loju pe ẹ̀mí oun wa ninu ewu, idi si ree ti oun fi kuro ninu igbeyawo oun, amọ oun ko ni panumọ nipa rẹ.
Oríṣun àwòrán, Queen_Aanu/Instagram
"Mo mọ pe awọn eeyan ti ni ero wọn nípa mi, boya o tọ tabi ko tọ, lori idi ti mo fi fẹ ọba alaye naa tabi kuro ninu igbeyawo ọhun.
Lai sọ̀rọ̀ pupọ, mo fẹ kẹ wa wọ bata ti mo bọ silẹ wo, ẹ ki ẹsẹ bọ wo, kẹ le mọ bo ṣe ri ati bo ṣe n ta mi lẹsẹ si, kẹ to maa da mi lẹjọ."
Olori Anu ni kii ṣe pe oun n fẹ kawon eeyan kanu oun, ni oun ṣe fi ikede naa sita àmọ́ oun kan fẹ ko wa ni akọsilẹ ni.
Ore Hospital Mortuary: Ìjọba Ondo ní òun yóò gbé ibùdó ìgbókùsíí kúrò nílé ìwòsàn náà
Oríṣun àwòrán, @OndoStateHealth
Ìjọba Ondo ṣetán láti wá ojútùú sí bí mọ́súárì ilé ìwòsan Ore ko ṣe ráyè gba òkú mọ́
Ore General Hospital: Ìjọba Ondo yóò wá wọ̀rọ̀kọ̀ ṣàdá lórí bí mọ́súárì ilé ìwòsan Ore ko ṣe ráyè gba òkú mọ́
Ijọba ipinlẹ Ondo ti sọ pe, oun ṣetan lati wa ojutuu sí bi ile igbokusi, mọsuari ile iwosan ijoba to wa Ore ṣe kun fọfọ, debi pe ko raye gba oku mọ bayii.
Adele Kọmiṣọnna eto ilera ipinlẹ naa, Dokita Ajibayo Adeyeye, to ba BBC Yoruba sọrọ ṣalaye pe, lootọọ ni mọsuari ile iwosan naa ti kun debi pe ita ni wọn n tẹ oku si bayii, eleyi to le fa ajakalẹ arun lagbegbe naa.
Ifa Worshippers: Àwọn ẹlẹ́sìn ìbílẹ̀ ń fẹ́ kíjọba pín èrè òṣèlú alágbádá yíká gbogbo ẹ̀sìn
Dokita Adeyeye ni, oku awọn eeyan to ku ninu ijamba ọkọ lopopona mọrosẹ Ore si ilu Benin, lawọn ọlọpaa maa n ṣaaba gbe lọ si mọsuari ile iwosan naa.
Adele Kọmiṣọnna eto ilera ipinlẹ Ondo ni, ọrọ naa ti ju agbara awọn oṣiṣẹ ile iwosan ọhun lọ nitori wọn o ti yanju ọrọ awọn alaisan ti wọn n tọju tan, ka to wa sọ nípa àwọn to ti ku.
Ọga ile iwosan naa sọ fun mi pe, awọn ọlọpaa ko dẹkun gbigbe oku awọn eeyan wa lẹyin ti ile igbokusi ile iwosan ọhun ti kun, Dokita Adeyeye lo sọ bẹẹ.
Akomolede ati Aṣa lori BBC:Wo ìrúfẹ́ ìgbeyàwó méje tó wà nílẹ̀ Yorùbá àti ojúṣe Alárinà
Dokita Adeyeye ni oun lọ si ile iwosan naa lati ri bi nkan ṣe ri gan an níbẹ, o ni ijọba ko ba sọ mọsuari ile iwosan naa di nla amọ ko s'aye mọ níbẹ.
Kọmiṣọnna eto ilera Ondo ni, ohun ti ijọba n gbero lati ṣe bayii ni ki wọn ko mọsuari kuro nile iwosan ọhun, lati lọ kọ ọ sí ibo miran.
Dokita Adeyeye ni lai deena pẹnu, ijọba ipinlẹ Ondo n ṣiṣẹ lori ọrọ naa.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Saaju la ti mu iroyin wa fun yin pe o se e se ki ajakalẹ arun bẹ silẹ lagbegbe Ore nipinlẹ Ondo nitori iwadii ti fihan pe ọgọọrọ oku lo sun sori ara wọn nile iwosan ijọba to wa nilu naa.
Gẹgẹ bi iwe iroyin Punch ti salaye, se ni wọn gbe awọn oku silẹ kaakiri awọn ilk ile iwosan naa, ti ojo si n pa wọn mọ ibẹ.
Awọn aworan to ba ni lẹru ati fidio to ba ni ninujẹ nipa ayika ibudo igbokusi to wa nile iwosan naa, fihan pe awsn oku ti kun de ẹnu ọna, ti wsn si fi paanu bo awọ́n miran mọlẹ.
Koda, wọn tun lo biriki lati se aala laarin oku kan si ekeji, bẹẹ si ni ninu ibi kan to dabi yara, oku ọkunrin ati obinrin lọpọlọpọ lo wa nilẹ ilẹ.
Oríṣun àwòrán, @OndoStateHealth
Iyalẹnu tun lo jẹ pe oku meji mii ti wọn fẹyin ti lara ogiri ni wọn ti gbẹ di egungun, to si jẹ pe ẹrọ amunawa kekere meji pere ni ibudo igbokusi naa ni.
Awọn ara adugbo ibi ti ile iwosan ijọba naa wa ni ọrọ naa ti ka laya, to si ti ko ipaya ati irẹwẹsi ba.
Nigba to n sọrọ lori isẹlẹ yii, Kọmisana feto ilera, Ajibayo Adeyeye ni ibi ti wọn kọ ile iwosan naa si lo fa isoro nitori oju titi lo wa.
"Ọpọ awọn eeyan to lugbadi ijamba ọkọ ni wọn maa n gbe wa sile iwosan naa, ti wsn yoo si gbagbe wọn sibẹ.
Nigba mii, awọn ọlọpaa yoo kan gbe oku miran wa, ti wsn yoo si gbe wọn kalẹ lai boju wẹyin mọ."
Grandma Maruwa: Ó yẹ kí obìnrin sisẹ́ láì wojú ọkọ kó tó jẹun
Adeyeye fikun pe pupọ ninu awọn oku naa lo ku lati ipasẹ ijamba ọkọ lai ri ẹni beere wọn, ti ẹjọ si tun n lọ lọwọ nipa iku awọn oku miran eyi ti ko jẹ ki wọn le e sin wọn.
O wa pari ọrọ rẹ pe bawọn eeyan to ni ilẹ lagbegbe naa se maa n taku lati fi ilẹ wọn silẹ pe ki wọn sin awsn oku naa si, lo mu ko nira lati sin awsn oku naa papọ.
Amọ o woye pe o seese ki wọn wa ibudo kan ti wọn yoo ti dana sun awọn oku naa, ti ko ba si ọna abayọ miran, lọna ati wa ojutu si isẹlẹ yii.
Ginimbi Genius Kadungure: Ẹ wo àwọn ọkọ̀ bọ̀gìnì tí ọ̀dọ́mọdé olówó kó jọ lẹ́ni ọdún 36
Oríṣun àwòrán, Genius Ginimbi Kadungure/INSTAGRAM
Ọpọlọpọ awuyewuye lo ti suyọ lẹyin iku ọdọmọde olowo ati gbajugbaja oniṣowo, Genius Kadungure alias Ginimbi, to ku ni Ọjọ Kẹjọ, Oṣu Kọkanla, ọdun 2020.
Lara awọn ọrọ to suyọ lori ẹrọ ayelujara nii ṣe pẹlu isalẹ ọrọ rẹ, ti wọn ni ko mọ.
Bi awọn kan ṣe n sọ wi pe ejo lo n pọ owo fun un ni igba aye rẹ, ni awọn miran sọ wi pe isalẹ ọrọ rẹ lẹgbin lọna mii.
Lara awọn to n sọrọ lori ẹrọ ayelujara ni, awọn mọ daju wi pe inu yara ibusun rẹ ni ejo ohun wa, ti o ti n pọ owo fun un.
Awọn ọrẹ Ginimbi ti jade lati sọ wi pe, ko si otitọ kankan ninu ọrọ pe ejo lo n pọ owo fun Ginibi ati wi pe, ki wọn fi oloogbe naa silẹ ki o sun ire.
Oríṣun àwòrán, Genius Ginimbi Kadungure/INSTAGRAM
Ronald Muzambe, to jẹ ọkan lara awọn ọrẹ timọtimọ rẹ, sọ pe ahẹsọ ọrọ lasan ni ati wi pe ki lo de ti awọn eniyan ko ṣewadii ọrọ Ginimbi lasiko to wa laye.
''Gbogbo eniyan to wa laye lo ni anfaani fun ọdun mẹrindinlogoji lati ṣe iwadii ọrọ Ginimbi, amọ wọn ko ṣe e''
''Ti ko ba ti si ẹni to wadii ọrọ rẹ kulẹkulẹ nigba ti o wa laye, nitori naa ki wọn jawo lati ma sọ ọrọ rẹ laida lẹyin to papoda.''
Oríṣun àwòrán, Genius Ginimbi Kadungure/INSTAGRAM
Muzambe ni ki wọn fi oku orun silẹ ko sun ni alaafia.
O si rọ awọn eniyan lati lo oju aanu ti wọn ni lati fi kẹdun pẹlu ẹbi ati ara to fi silẹ, ki wọn si ṣelede lẹyin ẹni to doloogbe.
Ẹni ọdun mẹrindinlọgbọn ni Ginimbi nigba ti o di ilumọọka kaakiri orilẹede Zimbabwe nigba ti o bẹrẹ idokowo epo rọọbi ati afẹfẹ gaasi liquefied petroleum (LP).
Oríṣun àwòrán, Genius Ginimbi Kadungure/INSTAGRAM
Igba naa lo ti si bẹrẹ si ni ṣe ayẹyẹ diẹdiẹ, ko to wa di gbajugbaja lawujọ.
Laarin awọn ọdun wọnyii ni Ginimbi ra awọn ọkọ bogini nla nla, ti yoo si fi si oju opo rẹ lori ayelujara ti ọkọ tuntun ba de.
Ki o to ku, o ṣẹṣẹ ra ọkọ Lamborghini Aventador, to ṣe apejuwe rẹ gẹgẹ bi ohun amuṣere tuntun.
Bi o tilẹ jẹpe ileeṣe BBC ko le e fi idi iroyin naa mulẹ, amọ Ileeṣẹ iroyin Times Live fi awọn ọkọ to ni silẹ ko to ku lede bayii;
Awọn ọkọ bogini ti wọn ṣe akọsilẹ rẹ wọnyii ko mọ ọkọ bọgini BMW loriṣiriṣi, to di mọ Jaguar ati Lexus.
Ginimbi Genius Kandungure ni ọpọ eeyan mọ si ọdọmọde olowo to maa n se ọpọ ayẹyẹ olowo nla  loore koore, ko to dagbere faye.
Ni ọdun 2010, Ginimbi se apejẹ alagbara kan fun ayẹyẹ ọjọ ibi rẹ, to si ni dandan ni kawọn alejo ti oun pe wọ asọ funfun wa sibi ayẹyẹ ọjọ ibi rẹ naa.
Oríṣun àwòrán, Ginimbi Genius Kadungure
Ilu Harare, ni orilẹede Zimbabwe si lo ti se ayẹyẹ ọhun, lati igba naa si ni o ti di eewọ fun ẹnikẹni lati wọ asọ to yatọ si asọ funfun lọ sibi ayẹyẹ ti Ginimbi ba se.
Ni ọdun meji lẹyin eyi, eyiun lọdun 2012, Ginimbi tun se ayẹyẹ ọjọ ibi olowo nla miran, amọ orilẹede Boswana lo lọ nigba naa.
Ko tan sibẹ o, lọdun 2013, Ginimbi tun se ayẹyẹ ọlọjọ mẹta ninu ile rẹ to kọ si abule rẹ , Domboshava, eyi to fi n wẹ ile awodamiẹnu to kọ si agbegbe naa.
Oríṣun àwòrán, Ginimbi Genius Kadungure
Bakan naa lọjọ kẹwaa osu kẹwaa ọdun taa wa yi, ọdun 2020, ọdọmọde olokoowo naa tun sami ọjọ ibi rẹ, to si tun fi iwe ipe sita lati pe ọpọ alejo ni janti rẹrẹ.
Nibẹ lo tun ti kede pe apejẹ alasọ funfun ni ayẹyẹ ọjọ ibi oun naa, ẹnikẹni ko si gbọdọ wọ asọ miran wa sibi inawo oun yatọ si asọ funfun.
Ayẹyẹ naa, to pe osu kan ati ọjọ mẹta gbako lonii, lo jẹ ohun ti ọpọ eeyan si n sọrọ lori rẹ nipa bo se larinrin to, amọ ọlọjọ ibi naa, Ginimbi ti jade laye.
Ondo Land Death: Opó àti àbúrò olóògbé ní aáwọ̀ ilẹ̀ ló fá ikú òjijì fún Olayinka Olabode
O wa se ni laanu pe iku ijamba ọkọ lo da ẹmi ọdọmọde olowo, to nifẹ asọ funfun naa legbodo lati ipasẹ ijamba ọkọ kan to se agbako rẹ ninu ọsẹ yii.
Oríṣun àwòrán, Ginimbi Genius Kadungure
Ọlọla to gbajumọ lorilẹede Zimbabwe, Ginimbi Genius Kadungure ti sọ fun awọn ebi rẹ, bo ṣe fẹ ki wọn ṣin oku rẹ ki o to papoda.
Awọn mọlẹbi rẹ lo fi lede pe, ki o to papoda ni o ti fi ọrọ ikẹyin silẹ lori bi o ṣe fẹ ki wọn sin oku rẹ.
Ọjọ Kẹjọ, Oṣu Kọkanla, ọdun 2020 ni Ginimbi Genius Kadungure papoda ninu ijamba ọkọ to waye ninu ọkọ bọgini rẹ.
Ginimbi Genius Kadungure sọ fun awọn ẹbi rẹ wi pe aṣọ funfun ni ki gbogbo eniyan to ba fẹ wa si ibi isinku oun wo.
Eyi ko ṣẹyin bi gbajumọ naa ṣe ma n wọ aṣọ funfun nigba to wa laye.
Oríṣun àwòrán, Ginimbi Genius Kadungure
Awọn ẹbi rẹ ni ile nla rẹ ni wọn yoo sin Ginimbi Genius Kadungure si ni Ọjọ Satide , ọsẹ yii
Bakan naa ni ẹgbọn rẹ obinrin, Abilẹkọ Juliet fi lede pe, aburo oun ti ma n sọ wi pe ohun fẹ ki aye gbọ ki ọrun mọ nigba ti o ba kuro laye, ti wọn ba fẹ sin oku oun.
O ni ki wọn ma fi waduwadu sin oku oun, ki wọn ṣe e ni ṣiṣẹ n tẹle.
Bakan naa lo ni Ginimbi Genius Kadungure fi oun silẹ pe, awọn ọrẹ oun to wani oke okun gbọdọ peju pesẹ si ibi isinku oun.
Oríṣun àwòrán, Ginimbi Genius Kadungure
'O ni gbogbo eniyan gbọdọ wọ aṣọ funfun naa ni ọjọ gan an ti wọn ba fẹ sin oku oun, ki wọn si fun awọn eniyan laaye lati peju pese sibẹ.'
Nibayii, Juliet ni awọn ti ta atibaba nla meji si iwaju ita ile baba awọn nibi ti isinku naa yoo ti waye, ki wọn to lọ si itẹ rẹ ninu ile nla rẹ ni Ọjọ Satide.
Bakan naa lo fikun wi pe awọn elere lorisirisi lo ti wa ni kalẹ , lati fi orin aladun tẹ awọn ololufẹ Ginimbi Genius Kadungure lọrun, lati ṣe idaro ẹni ire to lọ.
Ti ẹ ko bamọ, Ginimbi Genius Kadungure to doloogbe naa, dabi olowo Hushpuppi ni Naijiria.
Civilian JTF: Kí ló mú aṣáájú Yorùbá tako ìgbésẹ ológun láti gbà ọdẹ́ ìbílẹ̀ JTF ṣiṣẹ ní Borno?
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Awọn agbaagba ẹgbẹ iṣọkan ilẹ Yoruba ti gbarata lori igbesẹ ileeṣẹ ologun Naijiria lati gba ọmọ ikọ alaabo abẹle Civilian JTF irinwo ni Bornu siṣẹ ologun Naijiria.
Ninu ohun tawọn agba wọnyi sọ fun BBC Yoruba ninu ifọrọwanilẹnuwo, wọn ni ọgbọn irẹjẹ leyi jẹ, to si tubọ fidi ọrọ mulẹ pe, aparo kan ga ju ọkan lọ ninu iṣejọba Naijiria.
Alagba Ayo Adebanjo to jẹ olori ẹgbẹ Afenifẹre ilẹ Yoruba wa lara awọn to ni igbesẹ naa ku diẹ kaato.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Alagba Adebanjo ni irẹjẹ gbaa ni iwa yii jẹ ati pe awọn ti n sọrọ tako iru nnkan bayii.
Agba ọjẹ naa ni nitori iru nkan bayi lawọn fi n lọgun pe ''ki atunto iṣejọba ta mọ si Restructuring waye ni Naijiria''
''A ti ni ki wọn ṣe atunto tipẹ lati le mu iru irẹjẹ yii kuro. A ti n sọ pe o yẹ ki a ni ikọ ọlọpaa ati ologun fun ipinlẹ kọọkan.''
"Ohun ta ba si ro pe o da fun iha kan Naijiria, iru rẹ yẹ ko da fun awọn to ku, ti Naijiria ko ba ti ṣe atunto yii, ilu ko le rọgbọ."""
Nigeria Independence Day: Sé ẹ mọ̀ pé ọdún 1956 ló yẹ́ ká ti dòmìnira ṣùgbọ́n....
''Wọn ko fẹ ṣe atutnto yi nitori ohun ni wọn fi n ko gbogbo ọrọ wa lọ si ọdọ wọn, ko tọ ki wọn gba awọn kan si iṣẹ ologun laifi tawọn apa Naijiria mii ṣe.
Bashorun Seinde Awogbofa to jẹ akọwe Afenifere naa da si ọrọ yii.
O ni lootọ ni pe wọn ni ipenija aabo wa ni ariwa Naijiria ṣugbọn ipenija aabo ko yọ apa Naijiria kankan silẹ.
''Gbigba eeyan siṣẹ ologun ni eto tirẹ, ohun to yẹ ni ki ijọba gba gbogbo eeyan lai da apa orilẹede Naijira kan si.'
Afẹnifẹre ni ọrọ atunto lawọ́n tori ẹ yan Atiku laayo
Alagba Awogbofa ni ohun tawọn n wi yii, awọn aṣoju lati ariwa Naijiria bi Sẹnẹtọ Ali Ndume naa ko dakẹ lori rẹ, paapa bi ijọba ti ṣe fẹ forijin awọn ọmọ ikọ Boko Haram to yiwa pada.
O wa pe fun iranwọ fawọn ologun Naijiria, ki wọn ba le sẹ aṣeye ti alakan n ṣepo lori awọn agbesunmọmi Boko Haram, to n da omi alafiaa Naijiria ru.
Oríṣun àwòrán, @HQNigerianArmy
Awọn ọmọ Naijiria kan ti fariga lori igbesẹ ileesẹ ologun ilẹ wa lati gba awọn ikọ ojulalakan fi n sọri si aarin wọn.
Ọjọbọ ni ileesẹ ologun kese pe oun ti gba irinwo awọn ọmọ ikọ alajumọse to jẹ araalu (Civilian JTF) nipinlẹ Borno si aarin wọn.
Awọn eeyan naa, ti ọpọ wọn jẹ ọdẹ ibilẹ, ni wọn ni yoo maa seranwọ fun ileesẹ ologun lati gbogun ti ikọ Boko Haram to n ba ipinlẹ naa finra ati apapọ ẹkun ariwa Naijiria.
Amọ igbesẹ naa ti n mu ki awọn ẹya to wa ni Naijiria maa fura pe ejo lọwọ ninu lori ọrọ yii, ti eruku ariwo si n sọ lala.
Ẹgbẹ Arewa to duro awọn eeyan to wa lati ariwa Naijiria n tiẹ fara mọ igbesẹ naa ni digbi amọ ikọ Afenifere to wa fun iran Yoruba ti tako igbesẹ naa patapata.
Oríṣun àwòrán, @HQNigerianArmy
Bakan naa ni ẹgbẹ Ohaneze Ndigbo to duro fun awọn eeyan ẹkun ila oorun Naijiria ati ẹgbẹ awọn eeyan aarin gbungbun Naijiria, Middle Belt Forum naa koro oju si igbesẹ naa.
Ko tan sibẹ, ẹgbẹ agbarijọpọ awọn eeyan to n gbe ni aarin gbungbun guusu Naijiria, Pan Niger Delta Forum, naa ti fọnmu pe ko yẹ ko ri bẹẹ.
Ninu awijare awọn ẹgbẹ Afenifere ni ọmọ ogun ẹlẹkunjẹun fun ẹkun kan ni ijọba apapọ n ko jọ.
Yinka Odumakin, tii se akọwe apaps fun ẹgbẹ Afenifere salaye pe awọn ẹkun yoku ni Naijiria kii se omugọ, ko si bi ẹya yoku yoo se ni igbẹkẹle ninu ijọba pẹlu iru iwa yii.
Ondo Land Death: Opó àti àbúrò olóògbé ní aáwọ̀ ilẹ̀ ló fá ikú òjijì fún Olayinka Olabode
"O ni ""sebi awọn eeyan ẹkun ariwa yii lo tako agbekalẹ ikọ alaabo Amotekun fun kun iw oorun guusu losu diẹ sẹyin, ki lo wa de ti wọn fi se iks ologun fun ẹkun wsn."
Bakan naa ni ẹgbẹ Pandef, Ohaneze Ndigbo ati Middle Belt Forum fọnmu lori igbesẹ ologun naa, ti wọn si ni o ti foju han gbangba bayii pe ẹka ologun Naijiria ti doju de.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ileeṣẹ ọlọpaa  Eko ti rọ eyikeyi araalu to ba ni iriri pe ọlọpaa ṣe aṣemaṣe si wọn lati tara fi ẹjọ ọlọpaa bẹẹ sun, ki wọn ba le foju rẹ jofin.
Alukoro ọlọpaa Eko, Olumuyiwa Adejobi lo fidi ọrọ yii mulẹ ninu ifọrọwerọ pẹlu BBC.
O ni igbesẹ yii wa ni ibamu pẹlu ifarajin ileeṣẹ ọlọpaa lati ri pe awọn oṣiṣẹ rẹ ko tẹ oju ẹtọ araalu loju mọlẹ bi tatẹyin wa.
Adejobi wa ṣalaye ni meni meji nipa igbesẹ ti ara ilu le gbe lati fẹjọ oṣiṣẹ ọlọpaa to ba tasẹ agẹrẹ si ofin sun wọn fun iwadii to yẹ..
Wo igbesẹ to gbe lati fi ẹjọ ọlọpaa sun:
Kọ iwe ẹhonu rẹ si ọọfisi Kọmisana Eko:
Olumuyiwa ni aaye wa fara ilu lati kọ iwe wọn si ọọfisi Kọmisana ọlọpaa fun ipinlẹ Eko, to wa ni opopona Muiz Banire ,GRA Ikeja.
O ni ninu iwe yii, wọn gbọdọ pe akiyesi alukoro ileesẹ ọlọpaa si ọrọ naa, ko ba le ri idahun to yẹ.
Alukoro ọlọpaa Eko tun sọ pe, bi wọn ba ri aaye ki wọn fi ọwọ ara wọn wa fi iwe yii sọwọ, ki wọn si ri pe wọn ni ẹda rẹ lọwọ fun amojuto to ba ya.
Anfaani wa lati pe sori ago:
Ilana ikeji ti Alukoro ọlọpaa ṣalaye ni pe, araalu le gba lati fẹjọ ọlọpaa to ba ṣaṣemaṣe sun, ni pipe ileesẹ ọlọpaa lori aago.
O ni anfaani yii ko wulẹ mu wahala pupọ wa ju pe, ki wọn mọ nọmba to yẹ ni pipe lọ.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Adejobi ni ẹka ọlọpaa to n gbọ ẹsun lati ọdọ araalu ti wọn n pe ni Public Complaints Bureau, ni o wa nidi ẹka to n gba ipe araalu yii lori ago.
Nọmba awọn ẹka yi to ka sita ni: 09010003792 tabi 09010512350
Fi aworan tabi fidio asemase ọlọpaa si oju opo ayelujara:
Adejobi ni ko si aburu nibi ki eeyan ya aworan tabi fọnran fidio, gẹgẹ bi ẹri lati fi han ileesẹ ọlọpaa nipa oṣiṣẹ rẹ to ba hu iwa ti ko da.
O sọ pe ileeṣẹ ọlọpaa ni awọn akọṣẹmọṣẹ ti yoo yẹ iru ẹri bẹ wo finifini.
Amọ o ni pẹlu bi awọn eeyan ti ṣe n fi iroyin ofege lorisirisi sita, eyi ti ko ba daa ju ni ki wọn wa si ẹka ọlọpaa lati fẹjọ sun.
Igba ọtun ti de nipa kikoju iwakiwa laarin awọn ọlọpaa:
Adejobi sọ pe awọn ṣeṣẹ le ọlọpaa mẹwa kuro lẹnu iṣẹ lori iwa ko tọ lẹnu iṣẹ ni nilu Eko.
Igbesẹ yii gẹgẹ bo ti ṣe wi, wa lara ọna ati ṣatunto iṣẹ ọlọpaa ni ibamu pẹlu ilana ode oni.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ọga ọlọpaa ọhun jade lati inu ọfiisi lati bere ohun to ṣẹlẹ, lo ba tun yin ọga naa nibọn
''Awọn ti ọrọ yii kan jẹ awọn tara ilu fẹsun kan lati ọdun 2019 si 2020, ninu wọn, awọn eeyan meje kan wa ta le lẹnu iṣẹ, ti a si tun ni ki wọn lọ jẹjọ aṣemaṣe''
O ni atunto naa yoo jẹ eleyi ti yoo maa waye lati igba degba.
Alaafin Oyo: Ọmọ Yorùbá sọ fún olorì Anu pé kò yẹ kó tú àṣírí ìkọ̀kọ̀ ìgbéyàwó rẹ̀ sí gbangba
Oríṣun àwòrán, Instagram/queen__aanu
Awọn ọmọ Naijiria ti bẹrẹ si ni wi tọkan wọn jade nipa igbesẹ olori Aanu, ayaba Alaafin Oyo, to sa kuro ni aafin tọmọtọmọ.
Loju opo BBC News Yoruba, niṣe lawọn kan n bẹnu atẹ lu igbesẹ rẹ, tawọn mii si ni o dara bo ti ṣe sa asala f'ẹmi ara rẹ.
Loju opo Instagram rẹ, ni olori Aanu ti sọrọ sita pe, ti nkankan ba ṣẹlẹ si oun lẹyin toun fi aafin silẹ, Alaafin ni ki awọn eeyan mu.
Ọrọ pe ki awọn eeyan da ẹbi ru Alaafin yii ni arakunrin kan Paul Temitope Ilesanmi fi da lohun pe, ko si nkankan ti yoo ṣelẹ si alayeluwa.
O ni lẹyin igba ti olori Aanu ti jẹ owo Alaafin tan, ko le ṣadede sa kuro.
''Wo Alaafin kii ṣe ọkunrin lasan, to kan le jẹ (owo rẹ), ti wa wa salọ''
Bakan naa ni ẹnikan naa sọ loju opo BBC pe, ko yẹ ki olori maa tu aṣiri ohun to ṣẹlẹ ni kọkọ faraye gbọ.
Benny Fortune Akinyemi wa fi ibeere le fun olori Aanu pe ''Nigba ti nkan n rọsọmu laarin olori ati Alaafin, ta lo gbọ si?
Ṣugbọn o ni awọn eeyan miran to sọ pe, ki awọn eeyan foju aanu wo Aanu nitori o ṣeeṣe ki o ma jẹ oju lasan lo mu kuro ni aafin.
Ninu ọrọ ti wọn, wọn ni olori ko le ṣadede gbe igbesẹ to gbe, bi kii ṣe pe ẹmi rẹ wa ninu ewu lootọ.
Titi di igba ti a fi n ṣe akojọ iroyin yii, aafin Oyo ko ti fesi si gbogbo ohun ti olori Aanu n sọ.
Ninu awọn olori to kuro laafin laipẹ yii ni olori Aanu wa.
Kayode Olabode killed in Ondo : Opó àti àbúrò olóògbé ní ikú Kayode Olabode kìí ṣe àtọ̀runwá
Ọkunrin kan nilu Akure, Kayode Olabode, ni wọn ni ọlọpa mẹta kọlu, to si sagbako iku ojiji lati ipasẹ sọbiri ti wọn fi gba lori.
Gẹgẹ bi opo oloogbe. Olayinka Olabode ati aburo oloogbe, Olugbenga Agbebi ti salaye fun BBC Yoruba, wọn ni awọn ọlọpaa naa fẹ gba ilẹ ọhun fun ara wọn ni, ti wọn si salaye awọn ohun to mu ifura lọwọ nipa iku oloogbe naa ati bi ejo se lọwọ ninu.
Amọ ileesẹ ọlọpaa ipinlẹ Ondo ti wa fesi pe aisan ẹjẹ ruru lo mu ẹmi oloogbe naa lọ, iku rẹ ko si wa lati ọwọ ẹnikẹni.
Alukoro fun ileesẹ ọlọpaa Ondo, Tee-Leo Ikoro ni awọn ti tu awọn afurasi to wa ni ahamọ silẹ lẹyin abajade iku Olabode, ti wọn si ri pe iku atọrunwa ni, ko ni ọwọ aye ninu.
Petrol Pump Price: Ọmọ Nàíjíríà ń bèèrè pé níbo ni oúnjẹ́ Kérésì yóò ti wá torí lítà epo tó di ₦170
Oríṣun àwòrán, Twitter
Awọn ọmọ Naijiria ti ni awọn yoo ranti igba ati akoko aarẹ Buhari lori oye, gẹgẹ bi asiko ti iya, ebi ati iṣẹ peleke si julọ lorilẹede Naijiria.
Awọn ọmọ Naijiria to sọ eyi loju opo Twitter wọn n fesi si ijọba to tun fi owo kun owo epo bẹntirol.
Atẹjade kan ti Ileesẹ to n se katakara epo rọbi lorilẹede Naijiria, PPMC kede pe lati akoko yii lọ, owo lita epo bẹntiro kan yoo di naira marundinlọgọjọ naira ati kọbọ mẹtadinlogun lati ibudo ifọpo(₦155.17).
Ẹgbẹ awọn to n ta epo ni Naijiria, IPMAN ti wa fi lede wi pe, nisinyii ti ijọba tun ti gbe owo le owo epo, awọn yoo ma a ta lita kan ni iye owo toto N168 to N170.
Eleyii bi awọn ọmọ Niajiria ninu, ti ọpọlọpọ wọn si faraya lori ẹrọ ayelujara.
Oríṣun àwòrán, Twitter
Lara awọn eniyan jankan jankan lawujọ ati ẹgbẹ to fi ero wọn han ni Minisita fun ọrọ eto ẹkọ ni Naijiria, Obiageli Ezekwesili ati ẹgbẹ ọmọ Yoruba, Afẹnifẹre.
Ezekwesili ni ijọba Buhari ko bikita iru iya ati iṣẹ to wa lorilẹede Naijiria, ati bi aisi iṣẹ ṣe n peleke si lojoojumọ.
O ni lasiko yii ti awọn eniyan ṣẹṣẹ n pada si ipo nitori ajakalẹ arun Coronavirus to mu wọn joko sile fun ọpọlọpọ oṣu lai ri ounjẹ jẹ, ni ele owo epo tun n waye.
Bakan naa ni adari ẹgbẹ Afẹnifẹre, Ayo Adebanjo ni orilẹede Naijiria labẹ iṣejọba aarẹ Buhari ti fihan pe, inu ibanujẹ ni ọpọlọpọ awọn ọmọ Naijiria wa, lai si ọna abayọ fun wọn.
Ondo Land Death: Opó àti àbúrò olóògbé ní aáwọ̀ ilẹ̀ ló fá ikú òjijì fún Olayinka Olabode
Adebanjọ ni iroyin to n pa oun lẹkun ni wi pe, iṣejọba aarẹ Buhari ti fihan pe ko si ohun rere kan to le e jade nibẹ.
Amọ lara awọn ọmọ Naijiria to fi ero wọn han lori ẹrọ Twitter ni, oun dupẹ lọwọ aarẹ Buhari nitori o mu aye le fun awọn eniyan ni asiko rẹ, ti ọpọ yoo si ma a ṣe apejuwe rẹ gẹgẹ bi aarẹ ti ko naani awọn araalu.
Ẹlomiran ni afikun owo epo yii yoo mu ki owo oṣu awọn eniyan di radarada, ti ko si ni si igbẹkẹle kankan fun awọn eniyan.
Ọpọlọpọ awọn ọmọ Naijiria ni awọn ko tilẹ reti ki awọn jẹun ni ọdun keresi to n bọ lọna yii, nitori atijẹ atimu ti di inira fun awọn eniyan lorilẹede Naijiria.
Ileesẹ to n se katakara epo rọbi nilẹ wa, PPMC, to wa labẹ ẹka ileesẹ NNPC, ti kede afikun owo jala epo Pẹtiroolu lorilẹede yii.
Oríṣun àwòrán, NNPC
Atẹjade kan ti ileesẹ naa fisita ni Ọjọru kede pe lati akoko yii lọ, owo lita epo pẹtiro kan yoo di naira marundinlọgọjọ naira ati kọbọ mẹtadinlogun (₦155.17).
Lita epo pẹtiro kan si lo wa ni Naira mẹtadinlaadọjọ tẹlẹ (₦147.67) eyi to mu ki afikun owo to ba lita epo kan bayii jẹ naira mẹjọ.
Atẹjade naa ni oni, ọjọ Ẹti ni afikun owo epo naa yoo bẹrẹ.
Oríṣun àwòrán, PPMC Release
Gẹgẹ bi alaye ajọ PPMC, owo ti lita  epo pẹtiro n ba wọle lati oke okun ti di ₦128,89 bayii, dipo ₦119.77 to wa losu kẹsan ati ikẹwa to kọja.
O ni afikun naira meje to ba owo ti epo n ba de naa yoo mu alekun ba owo lita epo rọbi kan.
Bẹẹ ba gbagbe, lati inu osu Kẹfa ti ijọba ti yọwọ kuro ninu ipese owo iranwọ fun epo rọbi, igba kẹrin ree ti lita epo pẹtiro yoo gbowo lori.
Electronic Car in Lagos: Sanwo-Olu ní ìbùdó fún gbígbé bátìrì ọkọ̀ kaná yóò wà yíká Eko
Oríṣun àwòrán, Twitter/LAGOS STATE GOVERNMENT
Gomina ipinlẹ Eko, Babajide Sanwo-Olu ti sisọ loju ọkọ kan ti wọn se labẹle, to n lo batiri ina ọba lai lo epo pẹtiro.
Nigba to n sọrọ nibi ayẹyẹ ifilọlẹ ọkọ ayọkẹlẹ naa nileesẹ Volkswagen nilu Eko, Sanwo-Olu ni ibudo naa yoo tubọ pese isẹ oojọ si labẹle fawọn araalu.
O ni ijọba ipinlẹ Eko yoo ba ileesẹ naa dowopọ nidi ipese ọkọ naa nipa pipese awọn ibudo ti awọn ọlọkọ yoo ti maa gbe batiri ọkọ wọn le ori ina, jakejado ipinlẹ Eko.
Iran ta n ri nipa ọjọ iwaju ni pe imọ ẹrọ yoo lu ilẹ pa, o si yẹ ki ijọba ipinlẹ pese ayika to jiire fun eyi, ki awọn ọdọ wa le ri isẹ oojọ se.
Oríṣun àwòrán, Twitter/LAGOS STATE GOVERNMENT
Sanwo-Olu ni o ti foju han bayi pe gbogbo agbaye ati Naijiria ti n gbara kuro lori epo rọbi, eyi si ni ọjọ ọla ta n ri.
Ọkọ igbalode naa, lo le sare daada laisi eefin, ti eeyan si le gbe batiri rẹ le ina lati gba agbara ninu ile abi nibi isẹ.
Emmanuella: Ohun mẹ́wàá tó yẹ kóo mọ̀ nípá Emmanuella tó kọ́ ilé ńlá fún ìyá rẹ̀
Oríṣun àwòrán, officialemanuella
Ọpọlọpọ awọn ilumọọka lo ti n gboriyin fun adẹrinpoṣonu, Emmanuella lẹyin to kọ ile nla fun iya rẹ.
Ọjọ Satide ni ọmọbinrin naa fi awọn aworan ile naa lede lori ẹrọ ikansiraẹni, Instagram.
Kò tọ́ sí Ọlọ́pàá láti ti ọmọ mi mọ́lé tórí ore tó ṣe lásìkò ìwọ́de EndSARS - Iya Eremosele
Ààrẹ ti kọ̀wé fipò sílẹ̀ torí èèyàn méjì t'ọ́lọ́pàá pa níbi ìfẹ̀hónúhàn lòdì sí ìjọba
Ọpẹ́ o! Wo bí agbábọ́ọ̀lù Super Eagles tẹ́lẹ̀, Christian Obodo tí wọ́n jígbé lẹ́ẹ̀kejì ṣe móríbọ́
Awọn ọlọ́pàá gbòde kan ní Ajah, ọwọ́ tẹ àwọn afurasi tó ń jalè
Àṣírí tú! Ikọ̀ ìwádìí BBC ṣí àwọn tó ń jí ìkókó gbé sí gbangba
Pásítọ̀ Sam Adeyemi, Taaooma, Falz àti gbogbo àwọn tí ilé ẹjọ́ fẹ́ rí nìyìí
Irọ́ ńlá ni pé àwọn sọ́jà ń wá olùwọ́de EndSARS DJ Switch- Ọ̀gágun Ahmed Taiwo
Yoruba ni  ọmọ ti yoo jẹ asamu, kekere ni yoo ti maa jẹnu samusamu.
Bẹẹ ni ọrọ ri pẹlu ọmọde to jẹ gbajugaja adẹrin posonu lori ayelujara, ti ọpọ eeyan mọ si Emmanuella.
O ti to bii ọdun melo kan ti ọmọde naa ti maa n dẹrin pa ẹẹkẹ awọn eeyan, ti ọpọ si maa n wo fidio rẹ lori ayelujara nitori ọrọ iwuri ati adanilaraya to maa n sọ.
Emmanuella, to bẹrẹ awada sise lori ayelujara lọmọ ọdun marun, ti wa kede loju opo Instagram rẹ pe, oun ti ra ile awodamiẹnu kan fun iya oun.
O wa kede pe oun n fi ile mọriri ọpọ atilẹyin, adura ati iwuri ti iya oun n se fun oun ni.
Oríṣun àwòrán, officialemanuella
Iya mi, mo mọ pe ile kekere lẹ n fẹ, ile naa niyi, sugbọn ẹ darijin mi, maa pari ile nla fun yin lọdun to n bọ, ẹ ma paya, eyi ko ni mu koju wa ri mabo.
Ọdun 2010, eyiun ọdun mẹwa sẹyin ni wọn bi Emmanuela, to si ti pe ọdun marun to ti bẹrẹ awada sise lawọn oju opo ayelujara.
Emmanuella, tii se ọmọ bibi ipinlẹ Imo, ni wọn bi silu Portharcourt, to si ti gba oniruuru ami ẹyẹ nilẹ yii ati loke okun,
Alaafin: Tí kò bá sí ìbàlẹ̀ ọkàn fún mi láàfin Oba Oyo, mi ò ní dúró síbẹ̀- ayaba Aanu Adenike Adeyemi
Oríṣun àwòrán, Instagram/queen_aanu
Aláàfin fi mí lọ́kàn balẹ̀, gbogbo ohun tí mo fẹ́ ló ń ṣe fún mi- Olori Aanuoluwapo
Akunlẹyan ladayeba, ori lẹlẹjọ. Ayaba Alaafin Oyo, Aanuoluwapo Adenike Adeyemi ṣi aṣọ loju eegun ọrọ nigba naa ti o ba BBC Yoruba sọrọ.
Ayaba Aanuoluwapo ni oun ko kabamọ lọna kankan pe Iku Baba Yeye ni oun fi ṣe ade ori oun.
O ni ori ko mọ ibi ti o n gbe eṣẹ ree, Olori Aanuoluwapo sọ pe Eleduwa nikan lo mọ nipa irin ẹda laye.
O ni lọpọ igba eeyan lero tiẹ ki Ọlọrun ni ero to yatọ fun eeyan.
Olori Aanuoluwapo ṣalaye lootọọ ni Alaafin jinna si oun tefetefe lọjọ ori, amọ o ni o ṣeeṣe ki ọdọmọbinrin fẹ ọdọkunrin ẹgbe ki o wa ṣẹlẹ pe ọdọkunrin naa ko pẹ to fi jẹ Ọlọrun nipe.
Ayaba Alaafin ni oun ko ni iya mọ, nitori oun ko tun ni fẹ fẹ ọkọ ti ọkan oun ko ni balẹ.
O ni ọkan oun balẹ lọdọ Alaafin ati wi pe gbogbo ohun ti oun n fẹ ni Alaafin n ṣe fun oun.
Olori Aanuoluwapo ni ti ko ba rii bẹẹ ni, oun ko ni duro ti Alaafin gẹgẹ ọkan lara awọn ayaba laafin Oyo.
''Awawi asan nikan lawọn eeyan maa n gbe kiri nipa wa, amọ ni ti temi, igbesẹ mi lati fẹ Alaafin tẹmi lọrun dọba,'' Ayaba Aanuoluwapo lo sọ bẹẹ.
EndSARS Protest: Ojú àwọn ọmọ Nàìjíríà tí yóò farahàn níwájú adájọ́ rèé
Oríṣun àwòrán, Sam Adeyemi, Maryam Apaokagi
Ile ẹjọ Majisireeti kan niluu Abuja ti ke si Kọmisọna ọlọpaa to wa ni olu ilu naa lati ṣewadii eeyan aadọta ti wọn fẹsun kan pe wọn ṣe onigbọwọ iwọde ifẹhonuhan EndSARS.
Eyi jẹ jade ninu lẹta ti adajọ Majisireeti, Omolola Akindele kọ ranṣẹ si kọmisọna ọlọpaa lẹyin iwe ipẹjọ ti ajafẹtọ ọmọniyan kan Ọgbẹni Kenechukwu Okeke kọ.
Lara awọn ti olupẹjọ naa ko orukọ wọn jọ niyii:
Oríṣun àwòrán, Sam Adeyemi
Okeke to ni lasiko iwọde naa, wọn ba ọpọlọpọ dukia oun jẹ nitorina gbogbo awọn to ṣagbatẹru rẹ gbudọ foju fina ofin.
Awọn oluwọde ENDSARS ba BBC sọrọ
Maryam Apaokagi (Taaooma)
Oríṣun àwòrán, APaokagi Maryam/Facebook
Awọn mii ti wọn pe lẹjọ ni awọn olorin bii Peter ati Paul Okoye, Innocent Idibia (Tuface), Bankole Wellington (Banky W), Tiwa Savage, Michael Ajereh (Don Jazzy), Ayo Balogun (Wizkid), ati Yemi Alade.
'Mo ní àṣírí ìyá tó fẹ́ ọmọ rẹ̀ láya fún Boko Haram torí ẹbí rẹ̀'
Oríṣun àwòrán, falzthebahdguy
Awọn ajafẹtọmọniyan to wa lara wọn ni Aisha Yesufu; Balogun ẹgbẹ agbabọọlu Super Eagles tẹlẹri, Kanu Nwankwo; oludari agba ileeṣẹ to n ri si atunṣe ilu tẹlẹri, Ọmọwe Joe Abah.
Oríṣun àwòrán, @AishaYesufu
Oríṣun àwòrán, Debo Adebowale
Akọroyin, Kiki Mordi, to fi mọ awọn oṣere Yul Edochie and Uche Jombo naa wa lori iwe ipẹjọ naa.
Oríṣun àwòrán, @Davido
Bakan naa, awọn ajafẹtọ ori ayelujara bii Feyikemi Abudu, Olorunrinu Oduala, Pamilerin Adegoke, Japhet Omojuwa, Ayo Sogunro, ati Deji Adeyanju, ati Tope Akinyode.
Oríṣun àwòrán, @burnaboy
Ninu lẹta rẹ, adajọ Akindele fun awọn ọlọpaa ni ọsẹ meji lati ṣewadii ọrọ naa ki wọn si da esi pada fun ileẹjọ.
Oríṣun àwòrán, Instagram/djswitch
Ọgagun Brig. Gen. Ahmed Taiwo to ṣoju ileeṣẹ ologun oriilẹ niwaju igbimọ to n ṣe iwadii lori ifẹhonuhan EndSARS nipinlẹ Eko ti sọ pe irọ nla ni pe ileeṣẹ ologun n wa ọkan lara awọn oluwọde EndSARS Obianuju Catherine Udeh ti ọpọ mọ si DJ Switch.
Ọgagun Taiwo fidi ọrọ yii mulẹ niwaju igbimọ ọhun to n ṣe itọpinpin ibọn yinyin si awọn oluwọde logunjọ oṣu kẹwaa ọdun 2020 ni Lekki Toll Gate.
''Ọpọ eeyan lo fẹran ki wọn maa gbe iroyin to buru jai nipa orilẹede Naijiria papaa julọ ileeṣẹ ologun oriilẹ fun gbogbo agbaye,'' Brig. Gen. Taiwo lo sọ bẹẹ.
Ọgagun Taiwo ni ''laipẹ yii ni DJ Switch ke gbajare pe ileeṣẹ ologun n wa oun, eleyi ti ko ri bẹẹ rara.''
O ni iṣẹ pọ fun awọn sọja lati ṣe nipinlẹ Eko ju ki wọn maa wa ẹnikan tabi eeyan meji kan kiri.
''Ko ye mi ibi ti DJ Switch ti gbọ wi pe ileeṣẹ ologun oriilẹ n wa,''  Brig. Gen. Taiwo lo sọ bẹẹ niwaju igbimọ oluwadii.
DJ Switch sọ tẹlẹ naa pe oun ṣe iranwọ lati yọ ọta ibọn to ba awọn olufẹhonuhan kan ni Lekki Toll Gate ninu fidio to fi sori oju opo Instagram rẹ.
Iroyin kan tiẹ sọ pe DJ Switch ti fi Naijiria silẹ lọ ṣe atipo nilẹ okeere lẹyin to sọ pe awọn eeyab kan n dunkoko mọ oun.
Latest ASUU strike update: Ẹgbẹ́ òṣìṣẹ́ ASUU tí gbà láti fòpin sí ìyanṣẹ́lódí lẹ́yìn tí ìjọba gbà látí sàn N70bn
Oríṣun àwòrán, Facebook/ASUU
Ẹgbẹ awọn olukọ fasiti, ASUU ti gba lati fopin si iyanṣẹlodi ti wọn ti gunlẹ lati oṣu mẹjọ sẹyin .
Ẹgbẹ awọn oṣiṣẹ ASUU naa ṣepade pẹlu ijọba apapọ ti Minisita fun ọ̀rọ iṣẹ ati oṣiṣẹ, Chris Ngige n ṣe adari fun.
Lara awọn nkan ti ASUU ati ijọba apapọ jọ ni adehun le lori ni owo ajẹmọnu awọn oṣiṣẹ, owo oṣu awọn oṣiṣẹ, ọrọ awọn ile iwe fasiti ni awọn ipinlẹ ati apo owo iṣuna IPPIS ti wọn kọ lati gbawọle, ti wọn si fi apo iṣuna UTAS pari rẹ.
Lẹyin ipade wakati mẹjọ, Chris Ngige ni o da oun loju wi pe ọna abayọ ti waye ninu ijiroro wọn, ti wọn yoo si fopin si iyanṣẹlodi wọn laipẹ.
Ngige ni gbogbo nkan ti ASUU bere lọwọ wọn ni awọn ti ṣe amọ ẹgbẹ naa nilo lati ba awọn ọmọ ẹgbẹ wọn sọrọ lori abajade ipade wọn.
Adebola Ademilua: Àìrísẹ́ ṣè lẹ́yìn ìwé kíkà ló sọ mi dí ìyá onírú, mo dúpẹ́ tèmi
Oṣu mẹjọ sẹyin ni ẹgbẹ oṣiṣẹ ASUU ati ijọba apapọ ti n fori gbari ti wọn si ti gunle iyanṣẹlodi tako igbesẹ ijọba lori asunwọn apo owo IPPIS.
Ẹgbẹ oṣiṣẹ ASUU kọkọ bẹrẹ iyanṣẹlodi ni Ọjọ Kẹsan an, Oṣu Kẹta, ọdun 2020 lẹyin ti ijọba ni awọn ko ni san owo oṣu fun awọn olukọ ti ko ba darapọ mọ aṣunwọn owo Integrated Personnel and Payroll Information System (IPPIS).
Àṣírí tú! Ikọ̀ ìwádìí BBC ṣí àwọn tó ń jí ìkókó gbé sí gbangba
ASUU ni asunwọn owo naa ko le ṣiṣẹ fun awọn nitori bi ileewe giga ṣe n ṣe akoso ara wọn, amọ awọn le gbẹ ajọ University Transparency Accountability Solutions (UTAS) silẹ ti yoo si rọpọ IPPIS ọhun.
Nibayii, ijọba ti gba lati san iye owo to to biliọnu aadọrin naira lati fi san owo oṣu awọn oṣiṣẹ ati owo ajẹmọnu wọn.
Amọ, ẹgbẹ ASUU ti ni awọn yoo kan si awọn ọmọ ẹgbẹ wọn yoku lati jiroro lori igbesẹ ijọba ati lati kede ọjọ ti awọn yoo pada si ẹnu iṣẹ.
Alaga Ẹgbẹ olukọni Fasiti ni Naijiria, ASUU, nipinlẹ Eko, Ọmọwe Dele Ashiru sọ pe oun ko gbọ nipa ipade ti ijọba apapọ sọ pe oun yoo ṣe ni ọsẹ yii pẹlu awọn olukọ.
Ọmọwe Ashiru sọ pe iyansẹlodi si n lọ lọwọ, nitori pe awọn ko tii yanjú ọrọ pẹlu ijọba apapọ.
O sọ eyi gẹgẹ bi esi si ikede ti ijọba apapọ Naijiria fi sita pe oun yoo ṣepade pẹlu ẹgbẹ ASUU ni ọsẹ yii lati yanju nkan to mu ki ẹgbẹ naa wa ni iyansẹlodi fun ọpọlọpọ oṣu.
Ninu ifọrọwanilẹnu kan to ṣe pẹlu ileesẹ iroyin Channels, Minisita fun eto igbani sisẹ ati ọrọ awọn oṣiṣẹ, Ọmọwe Chris Ngige fidi rẹ mulẹ pe ijiroro yoo bẹrẹ pada pẹlu awọn olori ẹgbẹ awọn oṣiṣẹ agba ni fasiti, SSANU ati awọn alasẹ eto ẹkọ lati yanju ọrọ to wa laarin ijọba ati ẹgbẹ ASUU.
Ọmọwe Ngige ni oun ni ireti oun ni pe wọn o ri ọrọ naa yanjú ni ọsẹ yii , ti eto ẹkọ yoo si bẹrẹ pada ni awọn Fasiti.
Bakan naa lo sọ pe ijọba apapọ ń ṣe awọn ipade miran labẹnu, nibi ti wọn ti ṣe akọsilẹ awọn nkan pataki ti yoo yanju ọrọ naa.
Ilana imọ ẹ̀rọ tuntun ti ijọba fẹ ẹ ma fi san owo osu awọn olukọ naa (Integrated Payroll and Personal Information System, IPPIS) lo fa iyansẹlodi tí ASUU gunle.
Aarẹ ẹgbẹ ASUU, Biodun Ogunyemi sọ pe inira ni ilana tuntun naa yoo mu ba awọn ọmọ ẹgbẹ rẹ.
O ṣalaye pe ileesẹ to n mojuto imọ ẹ̀rọ IPPIS ma n yọ lara owo oṣu awọn.
O ni ilana ti awọn Fasiti ṣe funra wọn, iyẹn 'University Transparency and Accountability Solutions', ni awọn ọmọ ẹgbẹ fẹ ẹ fi ma a gba owó oṣu wọn.
Ti ijọba ba ti faramọ nkan ti a fẹ́, awa naa ṣetan lati pada si ẹnu isẹ wa.
Oṣu Kẹta, ọdun 2020, ni ẹgbẹ ASUU ti bẹrẹ iyansẹlodi.
Ko si ohun to ni ibẹrẹ ti ko lopin. O dabi ẹni pe iyanṣẹlodi ti ẹgbẹ olukọ fasiti, ASUU ti gunle fun oṣu meje bayii ti fẹ wa si opin.
Ajọ ASUU lo sọ fawọn akẹkọọ fasiti ijọba apapọ loju opo Twitter rẹ lati gbaradi fun iwọle pada sile iwe wọn.
Ajọ ASUU sọ pe o yẹ ki iroyin ayọ le jade ni Ọjọru ọsẹ yii nigba ti wọn ba tun ṣepade ipẹlu ijọba.
Ni ọjọ Aje, ọjọ kẹsan oṣu kọkanla ọdun 2020 ni ẹgbẹ ASUU ṣe ipade pẹlu ijọba apapọ nibi ti wọn gba lati foju diẹ lara ohun ti wọn n beere fun lọwọ ijọba han.
Nibi ipade ọhun naa ni wọn ti gbe ilana sisan owo oṣu lawọn fasiti yẹwo, iyẹn UTAS yatọ si IPPIS ti ijọba gbe kalẹ.
Minisita ọrọ iṣẹ ati igbaniṣiṣẹ, Dokita Chris Ngige sọ lọjọ Ẹti to lọ pe oun yoo tun ṣe ipade mii pẹlu ẹgbẹ ASUU lọsẹ yii.
Ngige ni oun ni igbagbọ ipade naa yoo so eso rere nitori awọn yoo lanfani lati wa ojutuu si gbogbo ohun to ku diẹ kaato ti ASUU n fẹ atunṣe lori rẹ.
Ọjọ kẹrinlelogun oṣu kẹta ọdun 2020 ni ASUU bẹrẹ iyanṣẹlodi lẹyin ti wọn sọ pe ijọba ko mu ileri adehun ti o ni pẹlu ẹgbẹ naa lọdun 2019 ṣẹ.
Ilana sisan owo oṣu awọn olukọ fasiti pẹlu ilana IPPIS naa jẹ ọkan lara ohun ti ẹgbẹ ASUU ko faramọ.
EndSARS: Fayemi ní ọlọ́pàá ti fìyà jẹ òun náà rí, gbọin-gbọin lòun wà lẹ́yìn àwọn ọ̀dọ́ lórí ìwọde EndSARS
Oríṣun àwòrán, facebook/Kayode Fayemi
Gomina ipinlẹ Ekiti, Ọmọwe Kayode Fayemi ti sọ pe oun ṣetan lati darapọ mawọn ọmọ Naijiria ti wọn to n beere fun atunṣe awọn ọlọpaa Naijiria nitori ọlọpaa ti fiya jẹ oun ri.
Fayemi sọrọ yii nibi ipade awọn tọrọ kan lori iwọde EndSARS to waye sẹyin niluu Ado Ekiti lọjọ Aiku ọjọ kẹẹdogun oṣu kọkanla ọdun 2020.
Gomina ipinlẹ Ekiti tun sọ fawọn eeyan to wa nibi ipade naa wi pe Aarẹ Muhammadu Buhari ṣetan lati gba ọrọ awọn to n beere fun iyipada iwa awọn ọlọpaa Naijiria.
''Ọrọ iwa ifijẹni awọn ọlọpaa kan onile bẹẹ naa ni o kan alejo. Lọdun 2014 ti mo gbegba ibo gomina l'Ekiti lẹẹkeji ni mo ni iriri iwa ifiyajẹni awọn ọlọpaa,'' Fayemi lo sọ bẹẹ.
Fayemi to kuna ninu ibo ọhun to waye lọjọ kọkanlelogun oṣu kẹfa ọdun 2014 ṣalaye pe lagbegbe Mugbagba niluu Ado Ekiti lawọn ọlọpaa ti yin tajataju fun oun ti ko si tun jẹ kawọn gomina ẹgbẹ oṣelu APC wọ ipinlẹ Ekiti lati ṣe ipolongo ibo fun oun.
Amọ o ni awọn ọlọpaa mii naa wa ti wọn ṣe daadaa fun oun, nitorinaa, o ni kii ṣe gbogbo wọn ni ko dara.
Gomina Ekiti ni ko si ohun to buru ninu ifẹhonuhan EndSARS to waye nitori ohun ti yoo mu iyipada rere ba awujọ ni.
Ọmọwe Fayemi sọ pe awọn ọdọ ipinlẹ Ekiti ṣe iwọde naa nirọwọrọsẹ eleyi to si tọna labẹ ofin.
Fayemi ni ''awọn ọdọ Naijiria n binu nitori ajakalẹ arun coronavirus ko jẹ ki wọn ri ileewe lọ, bakan naa ni iyanṣẹlodi ẹgbẹ olukọ fasiti ASUU n mu inu bi wọn.''
''Ju gbogbo rẹ lọ, ebi n pa araalu ni Naijiria latari bi ọrọ aje orilẹede yii ti dẹnu kọlẹ,'' Fayemi lo sọ bẹẹ.
O ni ijọba ti ṣetan lati ṣe ohun gbogbo tawọn ọdọ n beere eyi to mu wọn ṣe iwọde EndSARS.
Yoruba World Assembly: Ìlú Ibadan ni wọ́n tí ṣe àgbẹ́kalẹ̀ ẹgbẹ́ ọmọ Yorúbá tuntun
Oríṣun àwòrán, Google
Olufilọlẹ ẹgbẹ ọmọ Yoruba tuntun, Comrade Victor Taiwo ti ni awọn gbe ẹgbẹ Yoruba World Assembly silẹ lati wa ọna abayọ si aisi ifẹ ati ifimọsọkan laarin awọn ọmọ Yoruba.
Victor Taiwo to sọrọ nibi ifilọlẹ to waye ni ilu Ibadan naa ni ilẹ Yoruba nilo idagbasoke.
Ẹgbẹ naa ni ilọsiwaju ọmọ Yoruba ninu ọrọ aje, ihuwasi, eto ẹkọ ati ẹsin gbọdọ wa ni ifimọsọkan fun ilọsiwaju.
Taiwo ni ẹgbẹ awọn Yoruba to ku ti kuna lati ṣe ohun to tọ, eleyii to jẹ ki ifaṣẹyin wa fun ilẹ Yoruba.
'' Ẹ wo bi eto aabo ṣe dẹnukọlẹ ni ilẹ Yoruba, ti ijinigbe n waye loore-koore lai ka awọn ẹmi ti awọn ajinigbe n pa ni ilẹ Yoruba''
''Lẹyin ti wo gbogbo iṣẹlẹ yii ni a ṣe apero awọn agbagba ilẹ Yoruba, ki a to da ẹgbẹ Yoruba World Assembly silẹ''
''Otitọ si ni pe imọ awọn ọmọ Yoruba ko ṣe ọkan ni gbogbo igba, nitori aigbọraẹniye to wọpọ laarin awọn agbaagba''
''A ko nifẹ si iru ẹgbẹ ti ina wọn n jo ajorẹyin mọ, nitori naa ni ẹgbẹ ti yoo mu ifimọsọkan ni okunkundun ṣe koko, o ṣe pataki.''
Lasiko ti ẹgbẹ tuntun naa  n sọrọ lori ipo ti Ọjọgbọn Banji Akintoye wa gẹgẹ bi '' Adari ni ilẹ Yoruba, wọn ni Akintoye ti yọ ara rẹ kuro ninu ẹgbẹ ọmọ Yoruba nitori naa ki i se adari wọn mọ.
Yoruba World Assembly fikun pe Akintoye ti ja ọpọlọpọ ẹgbẹ to gbimọpọ yan an gẹgẹ bi adari, nitori naa kii ṣe adari wọn mọ.
Titi di asiko ti a n ko iroyin yii jọ, Ọjọgbọn Banji Akintoye ko tii fesi si igbesẹ ti awọn to fi ẹgbẹ yii lọọlẹ gbe.
Ondo politics: Ta ló ń lépa ẹ̀mí Eyitayo Jegede, olùdíje gómìnà Ondo lẹ́gbẹ́ òṣèlú PDP?
Oríṣun àwòrán, Eyitayo Jegede
Lẹyin idibo sipo gomina to waye ni ipinlẹ Ondo, eyi ti Gomina Akeredolu ti fi ẹyin oludije fun ẹgbẹ oṣelu PDP, Eyitayọ Jẹgẹdẹ atawọn oludije marundinlogun miran gbolẹ, ko daju pe ọrọ ti tan laarin Akeredolu ati Eyitayọ o.
Nibayii, ohun ti Eyitayọ Jẹgẹdẹ n pariwo rẹ sita bayii ni pe awọn eeyan kan n lepa ẹmi oun.
O ni eyi ko si ṣẹyin bi oun ṣe pe ẹjọ kotẹmilọrun tako abajade ibo gomina ipinlẹ Ondo to waye lọjọ Kẹwaa oṣu kẹwaa ọdun 2020.
Atẹjade kan eyi ti agbẹnusọ fun Amofin Jẹgẹdẹ, Gbenga Akinmoyọ gbe jade ṣalaye pe awọn hu gbọ pe awọn alagbara kan n ṣe ipade lori igbesẹ ipẹjọ naa eleyii ti wọn ni o ṣeeṣe ko ṣẹ wọn leegun ẹyin.
Oríṣun àwòrán, Arakunrin akeredolu/twitter
Amọṣa o, ikọ ipolongo fun Gomina Rotimi Akeredolu ati igbakeji rẹ, Aiyedatiwa ti ṣe akawe ẹsun naa gẹgẹ bi yẹyẹ lasan lati fi mu ki awọn eeyan ri toun ro.
"Atẹjade kan ti ikọ naa gbe jade latọwọ Ọlabọde Richard Ọlatunde ṣalaye pe ko si ẹni ti ko mọ pe ""abaniwọran ba o ri da ni Jẹgẹdẹ"" ati pe o fẹ ki wọn mọ pe oun naa ṣi wa loju agbo oṣelu ni."
O ni bi o ba jẹ lootọ ni ọrọ ọhun ri, ile lo yẹ ki Jẹgẹdẹ o wo nitori pẹlu aawọ ọrọ adari to n waye laarin ẹgbẹ oṣelu PDP, ko yẹ ko wota lati mọ awọn to lee maa lepa ẹmi rẹ.
Oyo: Ìpàdé kí ilẹ̀ Yorùbá le è dára la bá lọ, dùǹdú ìyà làwọn ṣọ́jà dín fáwọn ọmọ ẹgbẹ́ wa- Agbekoya
Abuja-Kaduna, Katsina Kidnap: Bí àwọn agbébọn ṣe jí ASP Ọlọ́pàá méjìlá gbé lójú ìbọn rèé
Oríṣun àwòrán, AFP
Lati ọjọ mẹwaa sẹyin ni awọn igbakeji supiritẹ́ndẹ́ẹ̀tì mejila ti ko sọwọ awọn agbebọn ni ilu kan laarin ipinlẹ Katsina si ipinlẹ Zamfara ṣugbọn nibayii, iroyin ijinigbe wọn ti gbode kan tori ohun ti awọn iyawo wọn sọ.
Ẹbi awọn ọlọpaa naa sọ fun BBC pe, ṣe ni wọn n lọ si ipinlẹ Borno lati lọ ṣe akanṣe iṣẹ kan ni ipinlẹ Zamfara nigba ti awọn agbebọn da wọn lọna ti wọn si ji wọn gbe.
Iyawo ọkan lara wọn sọ fun ileeṣẹ BBC pe oun ko tii gbọ latọdọ ọkọ oun fun odidi ọjọ mẹta afi igba ti oun lọ si bareke awọn ọlọpaa nibi to ti gbọ pe wọn ji ọkọ oun gbe.
Bí o bá bá ààrùn ìpẹ́pẹ́ gbígbẹ lára arẹwà obìnrin rẹ̀, kí loó ṣe?
O fi kun un pe oun pada gba ipe latọdọ ọkọ oun ṣugbọn ranpẹ lo jẹ, to n ṣalaye nkan ti wọn n foju ri lọwọ awọn ajinigbe ọhun.
O pe mi lori ago lọjọru, o si sọ fun mi pe oun wa lọwọ  awọn ajinigbe, ti ọkan lara awọn ajinigbe naa si sọ fun mi pe ki n lọ maa wa miliọnu kan naira owo itanran.
O ni oun ko tii gbọ ohùn ọkọ oun lati ọjọ naa ṣugbọn awọn ọlọpaa ti pe oun lati maa wo itanran ọhun.
"Obinri naa ṣalaya pe ""eeyan kọọkan wa ni a fẹ da 800,000 naira lati gba awọn eeyan wa ti wọn jigbe silẹ, a ko lee sun bayii , adura ni a si n gba ki a le ri wọn layọ ati alaafia."""
Gẹgẹ bo ṣe sọ, o ni ọkan lara awọn obinrin ti wọn ji ọkọ rẹ gbe fi ọmọ marun un silẹ fun oun ti oun n tọju lati igba iṣẹlẹ ọhun ti waye.
Oyo: Ìpàdé kí ilẹ̀ Yorùbá le è dára la bá lọ, dùǹdú ìyà làwọn ṣọ́jà dín fáwọn ọmọ
Nigba ti BBC kan si agbẹnusọ ileeṣẹ ọlọpaa ipinlẹ Zamfara ati Katsina ti iṣẹlẹ naa ti ṣẹ, wọn ni awọn ko gbọ ohun kankan nipa iṣẹlẹ ọhun.
Ṣugbọn sibẹ, awọn obinrin naa ko dakẹ ẹkun pe ki ijọba ba wọn wa ọkọ awọn ri.
Ẹbi awọn lọgalọga mejila lẹnu iṣẹ ọlọpaa ti wọn jigbe lojuna wọn lọ si ilu Zamfara, ipinlẹ Borno ti n damu bayii.
Àṣírí tú! Ikọ̀ ìwádìí BBC ṣí àwọn tó ń jí ìkókó gbé sí gbangba
Ki lo ti ṣẹlẹ sẹyin?
Oríṣun àwòrán, Twitter/Gov Kad
Ijọba ipinlẹ Kaduna ti kede pa awọn agbegbọn ti ji awọn ọmọ ileewe giga fasiti Ahmadu Bello Fasiti ni opopona Abuja si Kaduna.
Kọmisọnna fun ọrọ abẹle, Samuel Aruwan lọ fi lede ninu atẹjade pe adari ileewe giga naa lo fi to ijọba leti.
O ni adari ileewe giga Ahmadu Bello University, Zaria, Prof. Kabir Bala, fi to ijọba leti wi pe awọn ọmọ ileewe awọn mẹjọ wa lara awọn eniyan ti wọn jigbe ni ọpopona naa.
Amọ, awọn kan sọ wi pe awọn akẹkọọ to le ni ọọdunrun to jẹ akẹkọọ imọ Ede Faranse n lọ si ipinlẹ Eko fun eto ẹkọ ni French Language Village ni iṣẹlẹ naa waye.
Wọn tun fi orukọ akẹkọọ mẹjọ naa sita ti awọn agbebọn jigbe naa.
Bakan naa ni kọmisọnna fi kun un wi pe awọn agbebọn ṣe ikọlu si agbegbe Albasi, ti wọn si pa eniyan mejila ni opin ọsẹ.
Oríṣun àwòrán, Facebook/Nasir el-Rufai
Nibayii, awọn araalu agbegbe naa ti sa kuro ni ilu, ki awọn agbegbọn naa ma tun pada wa.
Kọmisọnna fun ọrọ abẹle, Samuel Aruwan ni awọn agbofinro ti bẹrẹ si ni wa awọn agbegbọn ọhun.
Amọ, awọn eniyan ti bu ẹnu atẹ lu ijọba ipinlẹ Kaduna nitori wọn ko fi eto aabo sipo ni awọn oju popo ati awọn agbegbe to wa ni igberiko ipinlẹ naa.
Gomina ipinlẹ Kaduna, Nasir El- Rufai ti fi ọrọ ikẹdun sọwọ si awọn ti wọn padanu eniyan ninu ikọlu agbebọn naa.
El-Rufai wa parọwa si awọn eniyan lati fkanbalẹ nitori awọn ti bẹrẹ si ni sọ awọn agbebọn naa, ti awọn yoo si fi wọn jofin.
Ondo state Amotekun: Léyìn tí ìwọ́de EndSARS parí tán ni ìwà ọ̀daràn búrẹ́kẹ ní Naijiria
Oríṣun àwòrán, @OndoFirstBorn
Adari ikọ Amotekun ni ipinlẹ Ondo, Adeleye Olusanyero, ti sọ fun BBC pe lati igba ti awọn janduku ti ja iwọde EndSARS gba mọ awọn oluwọde lọwọ ni eto abo ti mẹhẹ ni ipinlẹ Ondo.
Olusanyero lo sọ bẹ ninu ifọrọwerọ pẹlu BBC Yoruba.
Adari Amotekun naa ni yatọ si ohun to ṣẹlẹ lẹyin iwọde EndSARS, iwa ọdaran naa ti n peleke sii lasiko ti ọdun ba ti n sunmọ etile.
O ṣalaye pe ikọ Amotekun ni ipinlẹ Ondo n ṣiṣẹ takuntakun lati rii pe iwa ọdaran di ohun igbagbe ni ipinlẹ naa.
"Gẹgẹ bo ṣe sọ, o ni ""ninu awọn ti wọn ji gbe ni ilu Owo, laarin wakati mẹrin si akoko ti wọn ji wọn gbe ni a gba eeyan marun un mu pada."""
Bi a ṣe n sọrọ lọwọ yii, awọn afurasi meje to ji eeyan gbe ni agbegbe ilu Owo ni a ti fi panpẹ ofin mu ti a si ti fa le ọlọpaa lọwọ.
Oríṣun àwòrán, @OndoFirstBorn
Olusanyero sọ fun BBC pe ojojumọ ni ikọ Amotekun maa n kaakiri ni ipinlẹ Ondo lati aago mẹjọ alẹ si marun un aarọ.
"O ni ""bi mo ṣe n ba yin sọrọ lọwọ yii, eeyan mẹrinla ni a ti da sinu igbo lati maa wa awọn iya ati ọmọ ti wọn ji gbe laipẹ yii."""
Nigba to n da si ọrọ naa, onimọ nipa eto abo kan, Tunde Akande, ni ti ọdun ba ti n sumọle ni iwa ọdaran bii ijinigbe ati idigunjale maa n pọ si ni Naijiria.
Oyo: Ìpàdé kí ilẹ̀ Yorùbá le è dára la bá lọ, dùǹdú ìyà làwọn ṣọ́jà dín fáwọn ọmọ
Akande ni o yẹ ki awọn eeyan maa ṣọra wọn lasiko yii nitori oju ni alakan fi n ṣọri.
O ni aarin awọn ara ilu ni awọn ọdaran n gbe, nitori na lo fi yẹ ki awọn eeyan maa ṣe amí fun awọn oṣiṣẹ eto abo nitori wọn ko lee da iṣẹ naa ṣẹ.
Eégun àti orò, bí wọ́n ṣe jọ bí Ẹ̀ṣà Egúngún nílẹ̀ Yorùba rèé
Ẹwẹ, alukoro ileeṣẹ ọlọpaa ipinlẹ Ondo, Tee-Leo Ikoro sọ fun BBC pe alaafia ni ipinlẹ Ondo wa nitori awọn ọlọpaa n ṣiṣẹ wọn bi iṣẹ.
Ikoro ni awọn ọlọpaa ti gba awọn ti wọn ji gbe pada, ọwọ si ti tẹ awọn ọdaran to n ji eeyan gbe, nitori naa ko sewu loko.
Ogun NYSC: Àjọ NYSC lé àgùnbánirọ̀ 96 padà nítorí oyún, àìlera míràn
Oríṣun àwòrán, Peace ben williams blog/ nairaland
Ajọ agunbanirọ lorilẹede Naijiria ni ipinlẹ Ogun ti ṣalaye pe agunbanirọ mẹrindinlọgọrun ninu  awọn agunbanirọ ti wọn fi ṣọwọ si ipinlẹ naa ni wọn le pada kuro nibi eto ifinimọle ti wọn maa n ṣe fawọn agunbanirọ ki wọn to bẹrẹ isinruulu wọn.
Bí o bá bá ààrùn ìpẹ́pẹ́ gbígbẹ lára arẹwà obìnrin rẹ̀, kí loó ṣe?
Alakoso ajọ agunbanirọ NYSC ni ipinlẹ Ogun, Belinda Faniyi, ṣalaye ni ilu Sagamu, nibi eto ibura fawọn agunbanirọ ti wọn ṣẹṣẹ fẹ bẹrẹ isinruulu ni ipinlẹ Ogun wipe awọn agunbanirọ naa ni wọn da pada nitori pe wọn loyun, wọn n tọ ọmọ lọwọ atawọn ailera miran.
Eégun àti orò, bí wọ́n ṣe jọ bí Ẹ̀ṣà Egúngún nílẹ̀ Yorùba rèé
O ni idi ti eyi fi waye nipe awọn iṣẹ alagbara ati ere idaraya gbogbo ti awọn agunbanirọ yoo maa ṣe lasiko eto ifinimọle naa yoo lewu fun awọn to loyun, awọn to n tọ ọmọ tabi ni ailera yoowu ni agọ ara wọn.
Labẹ eto ati ilana eto agunbanirọ lorilẹede Naijiria, o loju awọn eeyan to lee kopa ninu eto naa
Ajimobi School: Makinde ní Ajimobi, àwọn tó ṣàkóso iṣẹ́ àgbàṣe iléèwé Oba Akinbiyi lẹ́jọ́ láti jẹ́; Olowofela, kọmíṣọ́nà Ajimobi ní kí Makinde ó tẹlẹ̀ jẹ́jẹ́
Oríṣun àwòrán, Ajimobi/twitter
Laipẹ yii ni gomina ipinlẹ Ọyọ paṣẹ iwadii lori bi wọn ṣe fa iwe iṣẹ agbaṣe oni irinwo miliọnu naira fun kikọ ileewe girama igbalode Oba Akinbiyi to wa lagbegbe Ọrẹmeji ni ilu Ibadan ya.
Ni ọjọ Aje ni gomina Makinde pa aṣẹ yin lẹyin abẹwo rẹ si ileewe naa nibi ti iroyin sọ pe o ti ri  awọn ariwisi ti ko ṣe fi oju fo da.
Bí o bá bá ààrùn ìpẹ́pẹ́ gbígbẹ lára arẹwà obìnrin rẹ̀, kí loó ṣe?
Gomina Makinde ṣalaye pe lai ti ju ọdun kan lọ, ogiri, atawọn ohun ẹṣọ iwọlẹ taili ti wọn lo ti n dibajẹ pẹlu afikun pe ko daju pe wọn kọ ile naa bi o ti ṣe  yẹ ni ibamu pẹlu ilana to tọna fun kikọ ile.
O ni orukọ ileewe naa gan ti wọn kọ sori patako ti n ṣi danu.
O ni awọn eeyan to wa nidi ikọle naa nigba naa yoo dahun ibeere lori idi ti wọn fi kọkọ fa iwe iṣẹ naa ya lọwọ kọngila ti wọn gbe fun, bakan naa lo ni wọn yoo tun dahun ibeere loribi wọn ṣe gbe iṣẹ naa fun eto oju awo lawo fi ngbọbẹ, direct labour pẹlu irinwo miliọnu  naira ti o si tun jẹ pe iṣẹkiṣẹ ni wọn ṣe.
'Mo ní àṣírí ìyá tó fẹ́ ọmọ rẹ̀ láya fún Boko Haram torí ẹbí rẹ̀'
Amọṣa ọkan lara awọn kọmiṣọna ni iṣejọba gomina Ajimọbi nigba naa, Ọjọgbọn  Olowofẹla ti ke si Makinde pe ko fi oloogbe Ajimọbi lọrun silẹ ko si lalafia.
Olowofẹla to jẹ kọmiṣọna feto ẹkọ nigba naa ṣalaye pe igba ti iṣẹ naa n falẹ lọwọ agbaṣẹṣe ti wọn gbe e fun to si han gbangba pe agbaṣẹṣe naa ko lagbara iṣẹ ti wọn gbe fun un naa ni gomina paṣẹ ki wọn gba iṣẹ agbaṣe naa kuro lọwọ rẹ ki wọn gbee fun ileeṣẹ ijọba to n mojuto iṣẹ ode lati pari.
O ni o yẹ ki Makinde o yẹ gbogbo iwe akọsilẹ nipa iṣẹ naa wo  ko to bẹrẹ si ni sọ ọrọ alufansa si oloogbe Ajimọbi to jẹ gomina nigba ti wọn ṣe iṣẹ akanṣe naa.
ENDSARS: Mínísítà fún Iléesẹ́ Ọlọ́pàá sọ pé ìjọba yóò rí dájú pé irú rògbòdìyàn #ENDSARS kò wáyé mọ
Minisita fun ileesẹ ọlọpaa Naijiria, Muhammad Dingyadi sọ pe ijọba apapọ ti pinnu lati ri i daju pe rogbodiyan kankan bi eyi to waye lasiko iwọde #ENDSARS, ko waye mọ ni Naijiria.Ile ijọba nilu Abuja ni Dingyadi ti sọ ọrọ yii, gẹgẹ bi iwe iroyin abẹle, The Punch, ṣe jabọ iroyin, lẹyin ipade ti Aarẹ Muhammadu Buhari ṣe pẹlu awọn ọmọ igbimọ eto abo gbogboogbo.
"Dingyadi ni Aarẹ Buhari sọ pe gbogbo àwọn ti ti ọrọ kan, to fi mọ awọn ọdọ, ni ijọba yoo sisẹ pẹlu wọn, lati ri i pe iru iṣẹlẹ naa ko waye mọ, ati lati fi eto alaafia mulẹ ni Naijiria.Lori ibeere ti awọn akọroyin bi Minisita naa pe boya ki kọlu awọn to ba fẹ ẹ ṣe iwọde wá lara igbesẹ ti ijọba yoo gbe, Dingyadi ni ""lori ọrọ #ENDSARS ti ẹ beere, nkan ti a n sọ ni pe ijọba yoo tẹsiwaju lati ma a jiroro, ati lati"
"ma a tẹti si nkan ti awọn ti ọrọ kan ba n sọ."" Ko si tun ni ṣe ohunkohun lai sọ fun wọn, lati le dena iru rogbodiyan #ENDSARS to mu ki awọn kan ba dukia ijọba ati ti araalu jẹ."""
Oríṣun àwòrán, Twitter/houseNGR
Sugbọn ṣa, awọn ọmọ ilẹ igbimọ asoju-sofin to wa lati inu ẹgbẹ oṣelu PDP, ti kilọ fun ijọba apapọ lati sọra ṣe lori awọn ọrọ to ṣuyọ nipasẹ iwọde #ENDSARS.Bakan naa ni wọn rọ ọ lati bu ọwọ fun awọn ọdọ.Wọn ni ijọba gbọdọ tẹlẹ awọn ilana eto isejọba awaarawa, lati yanju ọrọ awọn ti ọlọpaa mú nitori ipa ti wọn ko ninu iwọde naa, lai tẹ ẹtọ wọn loju.Olori àwọn aṣofin naa, Kingsley Chinda, sọ ninu atẹjade kan pe awọn igbesẹ ti ijọba ti gbe lori ọrọ naa, fihan pe ijọba ko bọ̀wọ̀ fun araalu, tabi naani wọn.
Queen Ereba Psoriasis: Níṣe ló dàbíi pé mo wà nínú àhámọ́ tí mi ò ṣẹ̀dá fúnra mi
Ṣe lo kan dede bẹrẹ si ni ri nkan kurukuru lara rẹ. Amọ ko si bi wọn ṣe lo gbogbo ipara ati ogun apakokoro ara to wa ni Naijiria to, ko ran an. Igba yẹn gaan lo ṣẹṣẹ wa mọ pe o ju agbara oun lọ.
Àfi ṣuuuu ti gbogbo ẹ bo ara rẹ latori de ọmọ ika ẹsẹ.
Aarun ipẹpẹ gbigbẹ lara eyi ti awọn dokita pe ni Psoriasis lo kọlu Queen Ereba.
Eyi si fa irẹwẹsi si aye rẹ tori ko si agọ ara rẹ kankan ti aarun yii ko lẹ mọ.
Bíbéèrè ìbálòpọ̀ láti ṣe ìwé ìrìnà sọ òṣìṣẹ́ iléèṣẹ́ ọmọ Nàìjíríà dèrò ilé
O ro pe o ti tan fun oun laye koda wipe ala oun ko lee laye di mimuṣẹ.
Ko lee ṣe ohun gbogbo bo ṣe wu u, ko lee wọ iru aṣọ to ba yan laayo lati wọ.
Koda o ni lati pa ileewe ti nigba kan nitori aisan yii.
"Queen Ereba pada di onkọwe ati ololufẹ ohun meremere. Nibi ti aarun yii ba a finra de, o ti ṣe iwe jade ti akọle rẹ n jẹ ""Psoriasi, finding your light""."
Wo ìdí tí akẹ́kọ̀ọ́jáde 96 kò fi ní leè ṣe àgùnbánirọ̀ wọn l'Ogun
Àwọn oniròyìn ló tú àṣírí ààbò Prof Peller, tí wọn fi ri pa - Lady Peller
Trump news: Biden tun fẹyin Trump gbolẹ ninu atunka ibo to waye ni Georgia
Ijawe olubori Joe Biden tun ti f'ẹsẹ rinlẹ sii pẹlu bo ti ṣe tun fìdí aarẹ Trump janlẹ ninu atunka ibo to waye ni Georgia.
Nipinlẹ mẹta ni wọn ti f'ọwọ rọ ẹjọ ti Trump pẹ lori abajade ibo ti Biden ti kogo ja.
Ninu atunka ibo to waye ni Georgia yi ibo 12284 ní o fi ju ti alatako rẹ ninu ẹgbẹ Republican gẹgẹ bi ofin ayẹwo ti ṣe sọ.
Ọgbẹni Biden sọ pe o da oun loju pe Ọgbẹni Trump mọ pe oun ko ni pegede ninu ibo naa to sì hu iwa ti ko bojumọ latari rẹ.
Biden to dije labẹ asia ẹgbẹ oṣelu Democrat n palẹmọ lati gba ibura wọlé sipo loṣu Kini ọdun gẹgẹ bi aarẹ ikẹrindinlaadọta orileede Amẹrika.
Apapọ ibo ti Biden fi ya Trump wa ni mílíọ̀nù marun un lé diẹ.
Ni ti ibo Electoral College a n fojú sun pe yoo to 306 sí 232 ti aarẹ Trump.
Electoral College yi ni Amẹrika n lo lati fi yan ẹni tí yoo dipo aarẹ mu.
Bí o bá bá ààrùn ìpẹ́pẹ́ gbígbẹ lára arẹwà obìnrin rẹ̀, kí loó ṣe?
Ni Ọjọbọ lakọwe ipinlẹ Georgia, Brad Raffensperger, sọ pe atunka ibo to waye ko yí iye aṣeyọri ti Biden ṣe  ni Georgia pada.
"Ninu atẹjade tó fi sita o ni ""Atunka ibo manigbagbe to waye ni Georgia tunbọ fidi ọrọ mu'lẹ pe ilana idibo tuntun tá samulo ka to si tun gbe ojulowo esi ibo jade"""
"O salaye pe ""Aṣeyọri eyi jẹ fún iṣẹ ribi ribi t'awọn oṣiṣẹ eto idibo labẹle ati jakejado Amẹrika se lati pari isẹ nla yi lasiko perete"""
Atunka ibo yi  fihan pe iyato to waye laarin aṣeyọri Biden lẹyin atunka ati ti tẹlẹ  ko ju ida
0.73% lawọn agbegbe kọọkan ti ti ọgbẹni Trump ko si to  0.5%.
Lọjọ Ẹti ni wọn yoo fontẹ lu esi naa.
Aarẹ Amẹrika, Donald Trump, ti jawe lọ rọkun nile fun oṣiṣẹ rẹ kan to tako pe ko si magomago ninu idibo Aarẹ ti wọn ṣẹṣẹ di laipẹ yii.
Trump ni oun gbaṣẹ lọwọ ọkunrin ọhun, ti orukọ rẹ n jẹ Chris Krebs, fun ọrọ to sọ lori aṣemaṣe to waye ninu idibo naa.
Lati igba ti ẹkọ ti n foju mimu han pe Joe Biden ni yoo jawe olubori ninu idibo naa ni ọgbeni Trump ti n funrere pe idibo ọhun lọwọ magomago ninu.
Ṣugbọn awọn oṣiṣẹ ajọ eleto idibo ilẹ Amẹrika ti sọ pe idibo Aarẹ ọdun 2020 lo lamilaaka julọ ninu itan orilẹ-ede Amẹrika.
Trump gbaṣẹ lọwọ Krebs lẹyin to ti kọkọ jawe lọ rọkun nile fun adari ileeṣẹ eto abo, Mark Esper lẹyin ti iroyin kan sọ pe Aarẹ Trump ko le fọkan tan mọ.
Oríṣun àwòrán, Reuters
Awọn kan tilẹ ti n sọ pe Trump yoo tun gbaṣẹ lọwọ ọga agba ajọ CIA, Gina Haspel ati ọga agba ajọ FBI, Christopher Wray, ko to fi ọọfisi Aarẹ silẹ loṣu kinni ọdun 2021.
Gẹgẹ bi awọn ti Trump ti jawe lọ rọkun jile fun ṣaaju, oju opo Twitter ni Krebs ti gbọ pe iṣẹ ti bọ lọwọ oun.
Lẹyin to gbọ pe Aarẹ ti gbaṣẹ lọwọ rẹ, Krebs sọ loju opo Twitter tirẹ pe oun ko kabamọ kankan, ati pe inu oun dun lati sin orilẹ-ede oun.
Bí o bá bá ààrùn ìpẹ́pẹ́ gbígbẹ lára arẹwà obìnrin rẹ̀, kí loó ṣe?
Nigeria Politics: Àwọn gómìnà lábẹ́ àsíá ẹgbẹ́ PDP tó darapọ̀ mọ́ APC rèé
Oríṣun àwòrán, Twitter/@wynny49
Ninu eto oṣelu kaakiri agbaye ni awọn oloṣelu ti maa n fi ẹgbẹ oṣelu kan silẹ lọ omiran, oriṣiriṣi idi si ni wọn fi maa n ṣe bẹẹ.
Awọn idi naa le jẹ nitori afujusun irufẹ oloṣelu bẹẹ tabi ede aiyede ninu ẹgbẹ.
Ni Naijiria, oloṣelu miran yoo ti gori alefa labẹ asia ẹgbẹ kan tan ko to fi ẹgbẹ naa silẹ lati darapọ mọ ẹgbẹ alatako.
Iwọnyii ni awọn gomina marun un ni Naijiria to ti fi ẹgbẹ moṣelu PDP silẹ lati darapọ mọ ẹgbẹ APC lati igba ti ijọba ti pada sọwọ alagbada ni Naijiria.
Rochas Okorocha - Imo
Rochas Okorocha jẹ ọkan gboogi lara awọn gomina ẹgbẹ PDP to darapọ mọ APC.
Oṣu karun un ọdun 2013 ni Okorocha fopin si ibaṣepọ to wa laarin rẹ ati ẹgbẹ PDP ni ilu Oweri.
Bí o bá bá ààrùn ìpẹ́pẹ́ gbígbẹ lára arẹwà obìnrin rẹ̀, kí loó ṣe?
Nibi ipade ita gbangba kan to waye ni Oweri lati ṣami si ọdun meji rẹ lori alefa ni Okorocha ti kede pe oun ti darapọ mọ ẹbi tuntun, to si rọ awọn ololufẹ rẹ lati tẹle oun lọ si ẹgbẹ tuntun naa.
Abdulfatah Ahmed - Kwara
Ọdun 2014 ni gomina ipinlẹ Kwara, Abdulfatah Ahmed, fi ẹgbẹ oṣelu PDP silẹ lọ darapọ mọ ẹgbẹ APC.
Lọdun naa lọhun, Ahmedssọ fun awọn akọroyin pe oun darapọ mọ ẹgbẹ tuntun fun anfani awọn eeyan ipinlẹ Kwara.
Ṣugbọn lẹyin ọdun mẹrin, iyẹn lọdun 2018, ni ọkunrin naa yi ohun pada, to si tun pada sinu ẹgbẹ PDP.
Rotimi Amaechi - Rivers
Rotimi Amaechi ni gomina ipinlẹ Rivers laarin ọdun 2007 si 2015.
Oríṣun àwòrán, @wynny49
Lọdun 2014 nigba to ṣi wa lori alefa gẹgẹ bii gomina ipinlẹ naa labẹ asia ẹgbẹ PDP ni o fi ẹgbẹ ọhun silẹ to si darapọ mọ ẹgbẹ oṣelu APC.
Lẹyin ti Muhammadu Buhari di Aarẹ Naijiria lọdun 2015 lo yan Amaechi gẹgẹ bii minisita to n ri si irinajo oju popo.
Dave Umahi
Ọjọ kẹtadinlogun, oṣu kọkanla ọdun 2020 ni Dave Umahi fi ẹgbẹ oṣelu PDP silẹ to si darapọ mọ ẹgbẹ APC.
Nigba to n ba awọn akọroyin sọrọ lẹyin ikede naa, Umahi sọ pe oun fi ẹgbẹ APC nitori aiṣododo to wa ninu ẹgbẹ ọhun.
Oríṣun àwòrán, @Southeast_trend
Awọn oloṣelu kan n sọ pe Umahi ni afojusun lati gbe apoti ipo Aarẹ  lọjọ iwaju lo jẹ ko darapọ mọ APC, ṣugbọn gomina ọhun ti fesi.
"O ni ""mo fẹ sọ ni gbangba bayii pe, mi o darapọ mọ APC nitori pe mo fẹ di Aarẹ, irọ pata ni gbogbo awọn to n gbe iru iroyin bẹẹ kiri n pa."""
Eégun àti orò, bí wọ́n ṣe jọ bí Ẹ̀ṣà Egúngún nílẹ̀ Yorùba rèé
Mr Eazi àti Temi Otedola mú ọ̀rọ̀ jáde lẹ́nu bàbá olówó Femi Otedola lórí ìfẹ́ wọn
Oríṣun àwòrán, Instagram/temiotedola
Baba olowo Fẹmi Ọtẹdọla ti da ibeere bo ọmọ rẹ Temi Ọtẹdọla ati afẹsọna rẹ, gbajugbaja akọrin takasufe, Mr. Eazi pe nigba wo gan ni wọn yoo gbe ere ifẹ wọn de ibi ere igbeyawo.
Temi ọmọ Ọtẹdọla lo fi fọto kan soju opo Instagram rẹ pe oun ati ololufẹ oun Mr. Eazi yoo bẹrẹ eto igbohunsafẹfẹ ori ayelujara kan laipẹ, ki awọn eeyan o maa fojusọna.
"Baba rẹ, eekan olowo ni Naijiria ati lagbaye, Fẹmi Ọtẹdọla lo ba na ibeere nla sii loju opo naa pe ""Moremiii, nigba wo lẹ fẹ ṣegbeyawo?""."
Awọn ọmọ Naijiria ko si tiI jami lori esi ti wọn n fun ọrọ baba Temi. Bi ọpọlọpọ wọn ṣe n yin in lawọn mii n pe o gbe igbesẹ baba rere ti awọn miran si n ke sawọn ẹyẹle ifẹ mejeeji, iyẹn Temi Ọtẹdọla ati Mr. Eazi pe ki awọn naa ṣe kiakia.
Gẹgẹ bi awọn iroyin abẹle ṣe sọ, o  ti le ni ọdun mẹta bayii ti awọn mejeeji yii ti n ṣe ajọṣepọ ifẹ, o si da bii ẹni pe eyi ti n pẹ ju loju baba wọn to si n fẹ ki wọn sọ kini ọhun dohun ni kiakia.
Oríṣun àwòrán, Instagram/temiotedola
Oríṣun àwòrán, Instagram/temiotedola
Oríṣun àwòrán, Instagram/temiotedola
Bí o bá bá ààrùn ìpẹ́pẹ́ gbígbẹ lára arẹwà obìnrin rẹ̀, kí loó ṣe?
Lẹyin iku Ginimbi ọrẹ rẹ, Davido ni asan lohun meremere aye jẹ
Oríṣun àwòrán, Twitter/davido
Ilumọọka olorin takasufe ọmọ Naijiria ti ọpọ mọ si Davido ti ni gbogbo ohun meremere aye ko jẹ nkankan si oun.
Davido to se pe a maa safihan awọn ẹsọ  ati ọkọ ayọkẹlẹ lorisirisi ninu fidio orin rẹ ati loju opo ayelujara lo di ẹni to n waasu lẹyin iku ọrẹ rẹ ni, gbajumọ ayelujara ọmọ Zimbabwe, Ginimbi.
Lasiko to n kopa ninu eto kan lori ileesẹ  redio Apple Music pẹlu DJ Cuppy lo sọrọ yi to si ni awọn nkan yoyoyo aye ko jọ ohun loju mọ.
Lori eto naa Davido sọ pe lọwọ yi, nini anfaani lati maa mi soke silẹ lo se patakai si oun.
O wa fi lede bakan naa pe lati igba ti ọrẹ oun Ginimbi ti papoda ni oun ti ri pe asan lori asan lawọn nkan meremere aye jẹ.
''Nise lo da bi ẹni pe gbogbo awọn nkan meremere aye ko jẹ nkankan si mi mọ.
Mo sẹsẹ padanu ọrẹ timọtimọ kan ni lati Zimbabawe torukọ rẹ n jẹ Ginimbi.
Eeyan daada lo jẹ, Ki si ni nkan ti eeyan n  ni laye ti ko ni.
Gbogbo nkan lo ni''
Bí o bá bá ààrùn ìpẹ́pẹ́ gbígbẹ lára arẹwà obìnrin rẹ̀, kí loó ṣe?
Asẹyinwa asẹyinbọ, iku rẹ kọmi lẹkọ pe ko si nkan ta ni laye yi to ju atẹgun taa n mi sinu lọ.
O le jẹ olowo tabi talaka sugbọn ipo kipo too ba wa, maa dupẹ pe o wa laye''
Akọrin yi tunbọ salaye pe okiki toun ni jẹ ki awọn eeyan maa gbe ọmọ rẹ obinrin gẹgẹ nileẹkọ rẹ.
''Nigbakigba ti ọmọ mi ba lọ si ileewe, a maa sọ fun awọn eeyan pe 'Davido ni baba mi.Wọn a maa tori eleyi foju ọtọ wo sawọn akẹgbẹ rẹ.''
Super Eagles: Sunday Dare, mínísítà eré ìdarayá ní kò dájú pé Gernot Rohr kún ojú ìwọ̀n àti ṣàkóso Super Eagles
Oríṣun àwòrán, Twitter/Sunday Dare
Kii ṣe iroyin mọ pe awọn agbabọọẹu ikọ Super Eagles ja ọpọ awọn ololufẹ ere bọọẹu ni Naijiria kulẹ ninu ifẹsẹwọnsẹ to waye pẹlu Seirea Leone lopin ọsẹ to kọja ati ni ọjọ Iṣẹgun.
Ifẹsẹwọnsẹ naa kun ara ifẹsẹwọnsẹ lati mọ orilẹede ti yoo lọ kopa ninu idije ife ẹyẹ ere bọọẹu ilẹ Afirika, CAN ti yoo waye lọdun 2021.
Ireti ọpọ onwoye ni pe bi ẹni fi ẹran jẹkọ ni yoo ri fun ikọ super Eagles ati pe nigba ti yoo ba fi pari ifẹsẹwọnsẹ onibeji pẹlu orilẹede Serea Leone naa ni ilu Benin ati ikeji rẹ ni Freetown ọna yoo ti la fun un lati tẹsiwaju lọ si idije naa.
Amọṣa, ẹkọ ṣoju mimu fun ikọ Super Eagles. Goolu mẹrin ni wọn ti fi lewaju Serea Leone ni ilu Benin, ki o to di pe awsn agbabọọlu fi ogun ẹyin ja wọn ti wọn si da mẹrẹẹrin pada.
Nigba ti wọn yoo si gba oju keji ifẹsẹwọnsẹ naa ni orilẹede Serea Leone, ọmi ni wọn ta.
Nibayii, minisita ere idaraya, Sunday Dare ti ni, ifẹsẹwọnsẹ mejeeji naa fihan pe muṣemuṣe akọnimọọgba ikọ naa, Genot Rohr ko gba muṣe to ni nitori naa awọn yoo wa wọrskọ fi ṣada lori rẹ.
Loju opo ẹlẹyẹ Twitter rẹ ni o ti sọ ọrọ yii.
O ni ohun to yẹ ikọ Super Eagles gẹgẹ bi ọkan lara awọn alagbara ere bọọlu lagbaye kọ niyi, nitori naa igbesẹ atunṣe yoo waye lọgan.
Amotekun Oyo: Iṣẹ́ ti bẹ̀rẹ̀ ní pẹrẹu fún Àmọ̀tẹ́kùn ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́ lẹ́yìn ìdánilẹ́kọ̀ọ́ ọlọ́sẹ̀méjì gbáko
Gomina ipinlẹ Ọyọ Onimọẹrọ Ṣeyi Makinde ti ṣiṣọ loju ikọ Amọtẹkun ẹka ti ipinlẹ Ọyọ nibi ayẹyẹ kan to waye nilu Ọyọ l'Ọjọru.
Ninu ọrọ ti o sọ nibi ipejọpọ naa, Makinde ni lati igba ti wọn ti ṣe ifilọlẹ ikọ naa ni ijọba ipinlẹ Ọyọ ti n sa ipa rẹ lati jẹ ki Amọtekun bo si oju iṣẹ.
O ni botilẹ jẹ pe ajakalẹ aarun COVID-19 ati awọn nnkan mii ṣe idiwo fun eto igbaniwọle sinu ikọ naa, lẹyin ọrẹyin awọn ọmọ ẹgbẹ Amọtẹkun ti o to bi i ẹgbẹrun kan o le lẹẹdẹgbẹta ni wọn pada gba wọle ti wọn ti ṣe
idanilẹkọ fun bayii.
Makinde fi kun ọrọ rẹ pe ọna kan gboogi lati wa ojutu si iṣoro eto aabo ni idasilẹ ikọ Amọtẹkun.O ni ikọ olominira Amọtẹkun ṣugbọn wọn o maa kun awọn ẹṣọ aabo ijọba apapọ to ku lọwọ lati gbogun ti awọn ajinigbe ati awọn ọdaran mii gẹgẹ bi wọn o ṣe maa ṣe iwọde lọsan ati loru.
Gomina ipinlẹ Ọyọ fi idaniloju han pe dundun lọsan yoo so lẹyin agbekalẹ ikọ Amọtẹkun.Lara awọn to pejupesẹ sibi eto naa ni adara ikọ Amọtẹkun, Ajagunfẹyinti Ajibola Kunle Togun, Ajagunfẹyinti Olayanju Olayinka, ladelade-loyeloye ati awọn aṣoju ijọba ipinlẹ Ọyọ.
EndSARS: Oluwo ṣàlàyé ọ̀nà tí ìwọ́de #EndSARS míràn yóò fi kẹ́sẹ járí
Oríṣun àwòrán, facebook/Emperor Abdulrasheed Adewale Akanbi Telu
Fun ẹyin ti ẹ ba ro pe iran ti tan lẹyin iwọde #ENDSARS to mi orilẹede Naijiria tititi laipẹ yii, a dara ki ẹ tun ero yi ro daadaa.
Nibayii, Oluwo ti ilu Iwo, Ọba Abdulrasheed Akanbi ti ke sawọn ọdọ ni ipinlẹ Ọṣun pe nigbakugba ti o ba tun ya lati ṣe iwọde miran tako iwa aitọ lorilẹede Naijiria, oun gan an ni ki wọn wa pe lati lewaju iwọde naa o.
Ẹyin naa kọ haa?
Bẹẹni Kabiyesi ṣe sọ ọ lasiko to n sọrọ nibi aperọ atunbọtan iwọde #EndSARS to waye ni ilu Oṣogbo.
Ijọba ipinlẹ Ọṣun gbe apero naa kalẹ lati jiroro loro awọn ọgbọn ati aṣiṣe to waye lasiko iwọde naa pẹlu ọna ati mu idagbasoke jade fun itẹsiwaju ipinlẹ naa.
Kabiyesi Oluwo, ba Akanbi ni oun ṣetan lati lewaju awọn ọdọ ninu iwọde yoowu ti wọn ba fẹ ṣe lati rii daju pe ẹhonu wọn de ọdọ awọn alaṣẹ gbogbo to ba yẹ.
Sotitobire: Ọkọ mi kò mọ̀ Jegede PDP rí, kódà kò fa ẹnikẹ́ni kalẹ̀ dípò Akeredolu- Bisola
O ni lara awọn aṣiṣe to farahan lasiko iwọde #EndSARS to waye naa ni aisi awọn eeyan kan ni pato ti wọn lee tọka si gẹgẹ bi olori tabi aṣiwaju.
O ni eyi lo ṣokunfa bi o ṣe rọrun fawọn janduku lati ja iwọde naa gba mọ wọn lọwọ ti wọn si lo anfani naa lati fi fọ ile ati dukia araalu gbogbo.
O ni ọna kan gboogi lati ṣe iwọde ti yoo kẹsẹjari ni lati ni awọn aṣiwaju to ṣee tọka si fun ijiroro pẹlu ijọba.
Prophet Israel Oladele: Ẹ̀tanú pé Olùṣọ́ CCC Genesis Global kò fẹ́ Laide Williams-Oni ló ṣe rán an lọ́ sí ẹ̀wọ̀n ọdún kan
Oríṣun àwòrán, Genesis Global
Igbakeji oluṣọ CCC Genesis Global, Olusọ Oba lo ṣiṣọ loju eegun lori iroyin pe wọn ti ran olusọ Israel Oladele Ogundipe lọ si ẹwọn ọdun kan lootọ eyi to jẹ awuyewuye tẹlẹ.
Olusọ Oba sọ fun BBc Yoruba wipe lọọto ni oluṣọ Genesis ti lọ si ọgba ẹwọn bayii ti yoo si lo ọdun kan nibẹ, amọ ọrọ naa ni kọnu-nkọhọ ninu.
Olusọ Oba fi ẹsun kan Laide Williams-Oni pe nitori ọrọ ifẹ ti ko wọ laarin awọn mejeeji nitori olusọ Genesis kọ lati fẹ arabinrin naa ni ọrọ ṣe ri bayii.
Oríṣun àwòrán, Genesis Global
Bawo ni aawọ laarin Laide Williams-Oni ati oluṣọ CCC Genesis Global ṣe ṣẹlẹ?
Igbakeji olusọ CCC Genesis Global, Olusọ Oba ni ọdun 2002 si ọdun 2006 si ni awọn mejeeji fẹ ara wọn gẹgẹ bi ololufẹ.
O gbero lati fẹ ẹ sile gẹgẹ bi aya ni amọ nigba ti o di ọdun 2007 ni Genesis fi silẹ nitori o ri wi pe Laide ni ọkọ tirẹ si oke okun, pẹlu awọn ọmọ ti o ti bi sibẹ.
Oríṣun àwòrán, Facebook/Genesis Global
''Genesis bere imọran lọwọ ijọ pe ṣe ki oun fẹ ẹ, ki wọn to wa gba a ni imọran pe ko fi silẹ nitori o le ba ọjọ ọla rẹ jẹ''
''Wọn ni ki o fi silẹ nitori o le tabuku ba ọjọ ọla rẹ'.'
Bakan naa ni Genesis ri atẹjiṣẹ ti ọkọ rẹ kọ si Laide pe ko ma fi awọn silẹ ni oke okun pẹlu ọmọ ti o gbe lọwọ.
Nitori Laide ma n ṣe bii ẹni ti ko ni ọkọ to ba ti wa ni Naijiria, amọ ọkọ rẹ wa ni oke okun.''
Amọ, ni ọdun 2007 ti Genesis wa fẹ iyawo rẹ ni wahala bẹrẹ, ti Laide sọ wipe ki Genesis wa da gbogbo nkan to gba ni ọwọ ohun pada.
Adájọ́ ní Seun Egbegbe ṣì lẹ́jọ́ láti jẹ́ lórí ẹ̀sùn gbájúẹ̀
Bí o bá bá ààrùn ìpẹ́pẹ́ gbígbẹ lára arẹwà obìnrin rẹ̀, kí loó ṣe?
Olusọ Oba ni Laide mọ awọn eniyan daadaa ni ipinlẹ Eko, paapaa awọn adajọ ni wọn ṣe da iru idajọ bẹẹ fun un.
Oba ni Laide ti leri wi pe ti Genesis ko ba fẹ oun, gbogbo ohun ini ti oun fun un ni o ma da pada fun oun.
''Lootọ ni Laide ran Genesis lati ba ohun ra ilẹ ni ọna mẹta, amọ Laide ri meji gba pada.''
Oluso Oba fi kun un pe 'kKo ri ẹyọkan gba pada nitori awọn to onilẹ ni wọn ko gbọdọ de ibi ilẹ naa mọ.''
Bakan naa ni Genesis jẹwọ wi pe lootọ ni oun sọ wi pe oun yoo da gbogbo owo ti oun gba pada ni ọwọ rẹ pada.
Ati awọn aṣọ pẹlu ohun ini to fi ranṣẹ si oun tabi to ra fun oun to ba n pada wa si Naijiria.
Nitori naa ni adajọ ṣe ni o jẹbi ẹsun iwa ole nitori o gba owo lọwọ obinrin naa, ti ko si da ilẹ rẹ pada fun un.
Ni adajọ wa ni ko lọ si ẹwọn ọdun kọọkan fun ẹsun ole ati iwa jibiti, amọ yoo lọ si ẹwọn naa papọ lẹẹkan.
Ṣe Genesis to wa ni ẹwọn yoo da ijọsin durọ ni Ọjọ Isinmi?
Olusọ Oba ni Genesis to wa ni ẹwọn fun ọdun kan ko ni da ẹsin durọ ninu ile ijọsin naa.
O ni pasitọ to lọ si ẹwọn ko le da isin duro nitori pe ijọ duro fun ara rẹ ni yatọ si olusọ.
Olusọ fi kun un wi pe eniyan daadaa ni Genesis, amọ ibanilorukọjẹ ni gbogbo ohun to waye yii.
Amọ, titi di asiko yii, a ko tii ri Laide Williams-Oni ba sọrọ lati sọ ti ẹnu rẹ.
Oríṣun àwòrán, Facebook/Genesis Global
Ṣaaju, awuyewuye to gbode ni pe ṣé lóòtọ́ ni pásítò ìjọ Celestial, Israel Oladele Ogundipe rẹ́wọ̀n he?
Ọpọlọpọ iroyin lo n ja ranyin lori ẹrọ ayelujara lori iroyin pe olusọ ijọ Celestial Church of Christ, Genesis Global, Israel Oladele Ogundipe ti rẹwọn ọdun meji he lori ẹsun pe o lu obinrin kan to wa ni orilẹede Amerika ni jibiti.
Iroyin naa ni Adajọ Olabisi Akinlade ti ileẹjọ giga ni ipinlẹ Eko to ran an lọ si ẹwọn lori ẹsun oniga meje, amọ ti o da ẹsun marun un nu nitori ko fi idi mulẹ.
Wọn ni o lu arabinrin Olaide William Oni ni jibiti miliọnu mọkanla naira.
Amọ, iroyin naa ni Genesis sọ wi pe oun ko jẹbi ẹsun ti wọn fi pe e.
Igbiyanju wa lati pe olusọ Genesis sọrọ lori  aago jasi pabo, amọ ọmọ ijọ rẹ to ba wa sọrọ ni wọn n ṣe isin lọwọ ni ile isin, amọ ko le fi idi rẹ mulẹ pe boya Genesis wa ninu ẹsin naa.
Oríṣun àwòrán, Facebook/Genesis Global
Ẹwọn ọdun kan ni pásítò ìjọ Celestial ti Genesis Global, Israel Oladele Ogundipe ri he kii ṣe meji..
Bakan naa ni akọroyin kan sọ wi pe oun ba agbẹjọrọ Pasitọ Israel Oladele Ogundipe rẹ sọrọ, ati wi pe ẹwọn ọdun kan lo ri he kii ṣẹ ọdun meji.
'' Ohun to ṣẹlẹ ni wi pe Aunty Laide ati Genesis jẹ ololufẹ akọkọ si ara wọn, ati wi pe ọrọ naa ni bo ṣe jẹ ninu.''
Bakan naa ni akọroyin naa ni Ilẹ Gẹẹsi ni Aunty Laide wa kii ṣẹ orilẹede Amerika ti iroyin naa gbe jade.
O tun fikun wi pe ọdun 2007 ni wọn ti wa lori ọrọ naa, ti arabinrin Laide naa gbimọpọ pẹlu Bukky Jesse lati ran an lọ si ẹwọn bi wọn ṣe ṣe ni ọdun 2011'.
O pari ọrọ rẹ wi pe ki awọn eniyan gbọdọ kọ ọgbọn lara iṣẹlẹ naa nitori ti o ko ba ni fẹ obinrin gẹgẹ bi aya, ma gba owo ni ọwọ rẹ.
Bakan naa ni atẹjade kan fihan bi adari ijọ CCC Praiseville, Kunle Hamilton se bu ẹnu atẹ lu awọn olusọ ti wọn ko ko ara wọn nijanu.
AMCON gbẹ́sẹ̀lé gbogbo ǹkan ìní Jimoh Ibrahim tó lé ní N69 bíliọ̀nù
Oríṣun àwòrán, Jimoh Ibrahim
Ajo to n moju to nkan ini ni Naijiria (AMCON) ni oun ti gba awọn nkan ini to se gboogi lọwọ Jimoh Ibrahim to jẹ alakoso ati asagbateru Global Fleet Oil and Gas ati NICON Investment nilu Eko ati Abuja nitori gbese owo biliọnu aadọrin naira.
Ninu atẹjade ti ajọ naa fi sita lo ti ṣalaye pe igbesẹ ti oun gbe wa ni ibamu pẹlu idajọ ile ẹjọ giga ijọba apapọ, ẹka ti ilu Eko lati ẹnu adajọ R. M Aikawa.
"AMCON ni ""ni ibamu pẹlu idajọ ile ẹjọ ni ọjọru ọjọ kejidinlogun, 2020, lawn fi laṣẹ lati gba nkan ini rẹ to le ni mejila."
Awọn nkan ini naa ni ile ișẹ NICON Investment Limited ti Plot 242, opopona Muhammadu Buhari, Central Business District, Abuja;
NICON Hotels Limited building ti Plot 557, Port-Harcourt Crescent, iyana  Gimbiya Street, Abuja ati  ile NICON Lekki Limited to wa ni  No. 5, Customs Street, nilu Eko.
Bí o bá bá ààrùn ìpẹ́pẹ́ gbígbẹ lára arẹwà obìnrin rẹ̀, kí loó ṣe?
"Awọn to ku ni ile rẹ ti Abuja International Hotels Limited nlo ni No. 3, Hospital Road, Eko ati Plot 242, Muhammadu Buhari Way, Abuja;
Ile  Allied Bank tẹlẹ to wa ni opopona marose Mile 2, Oshodi, Apapa nilu Eko  Energy House to wa ni  No. 94, opopona Awolowo, Ikoyi, nilu Eko, NICON Building ni No. 40, Madeira, Maitama, Abuja;
Ile igbe kan ni Road 2, House A14, Victoria Garden City, Eko; NICON Hotels Building ni  Plot 3, Road 3, Victoria Garden City, Eko ati Ile ti  NICON Luxury Hotel's wa ni  Garki I, FCT, Abuja.
'Mo ní àṣírí ìyá tó fẹ́ ọmọ rẹ̀ láya fún Boko Haram torí ẹbí rẹ̀'
Ko tan sibẹ̀, yatọ si gbigba gbogbo awọn nkan ini wọnyi, gbogbo apo owo rẹ ni Banki naa kun nkan ti ile ẹjọ ni ki wọn gbẹsẹ le to fi mọ awọn apo owo banki ile iṣẹ gbogbo ti Jimoh Ibrahim ni, lara rẹ ni Global Fleet Oil & Gas Limited ati NICON Investment Limited eyi to wa ninu gbogbo iwe ti wọn fi pẹjọ Suit No. FHL/L/CL/776/2016 ni ijoko ti agbejọro Aikawa ri dajọ lọjọru, ọjọ kẹrin oṣu kọkanla ọdun 2020.
Ile ẹjọ tun ni ki AMCON gba gbogbo ajẹmọnu to le tọ si Jimoh Ibrahim ni awọn ile isẹ rẹ meeeji to wa ni  Rẹ-insurance Company Limited PLC ati NICON Insurance company plc, Niferia Stockbrokers Limited ati NICON Trudtees Limited "
Agbẹnusọ AMCON, Jude Nwauzor fidi rẹ mulẹ pe gbogbo awọn ile iṣẹ ti ile ejọ fi lede ni AMCON ti gba, o fi ku pe pelu iranwọ ọlọpaa ati ile ẹjọ, ko si wahala kankan to waye lasiko ti AMCON n gba gbogbo nkan wonyi ni ilu Eko ati Abuja
Atunse ofin AMCON ti fun wọn ni agbara lati lati koji ẹnikẹni to ba jẹ owo ti wọn si kọ lati san.
Paul Okoye fàbínú yọ lórí ọ̀rọ̀ìkíni tí ìyàwó ìbejì rẹ̀ Lola Omotayọ kọ, ẹ wo ohun tó sọ
Oríṣun àwòrán, Instagram
Tẹbi tọrẹ a maa fi ayajọ ọjọ ibi kini ku orire,gbogbo wa la mọ bẹ.
Sugbọn ti ọjọ yi ba wa di ọjọ ti eeyan tako ọrọ si ara ẹni, ki lo le fa iru nkan bayi?
Ibeere to gbẹnu awọn ọmọ Naijria re lẹyin ti ilumọọka olorin takasufe nii  Paul Okoye, P Square, bẹrẹ si ni tako ọrọ si iyawo ibeji rẹ, Peter Okoye ti ọrọ naa si gbori ayelujara kan.
Lola Omotayo to jẹ iyawo Peter Okoye lo ki ọkọ rẹ ku orire ọjọ ibi loju opo ayelujara.
Lẹyin to ki olowo ori rẹ tan, lo ba ki ibeji rẹ Paul Okoye sugbọn kiki yi tun mu ọrọ arọwa lọwọ.
Oríṣun àwòrán, Instagram iamKingRudy
Ninu ọrọ rẹ o sọ pe
"Hmmm…. ẹyin ibeji @peterpsquare @iamkingrudy bi ẹ fẹ bi ẹ kọ, ọmọ iya ni yin. E kii se ọmọ iya nikan, ibeji ni yin.
Mo ki yin ku ayajọ ọjọ ibi! Bintin laye,ẹ ma fi asiko sofo.Ibọwọfunraẹni ati ifẹ se pataki.Bi a se n dagab si, o yẹ
ki a mọ pe aye yi ko se fi falẹ asiko ko si duro de ẹni kan.
Mo wi temi naa!''
Ọrọ yi ko ba Paul nibi to ti gbe da ti ko si jẹ ko pẹ to fi fesi pada fun Lola.
O sọ kobakungbe ọrọ si Lola to si ni oju aye lasan lo n se nitori lati bi ọdun meloo  sẹyin awọn ko  ki ara wọn.
O ni nitori ki awọn eeyan baa le foju eeyan daada wo lo fi  maa n bọ si oju opo ayelujara lọdọdun lati ki oun.
Ẹ wo ẹkunrẹrẹ ọrọ naa bo ti se sọ soju opo Instaagram
Oríṣun àwòrán, Instagram/iamkingrudy
Agbemaja ko si ni Yoruba a maa wi, a ja ma pari ohun lo buru.
Ija laarin awọn Ibeji olorin takasufe yi jẹ eleyi tawọn ololufẹ wọn ti n sọ pe ko wa si opin.
Sugbọn pẹlu itakoọrọsiraẹni to n waye yi, ko daju pe ọrọ naa yoo niyanju.
Titi di igba ta fi n sakojọ iroyin yi , Peter Okoye ko ti fesi si ọrọ ti ibeji rẹ sọ.
Bẹẹ  ni Lọla iyawo rẹ naa ko fesi pada.
Prophet Israel Oladele: Kilo gbe e de ijọ Celestial?
Oríṣun àwòrán, Genesis Global
Idile ẹlẹsin musulumi ni wọn bi Woli Israel Oladele si. Orukọ abisọ rẹ ni Wasiu.
O si jẹ ọmọ ilu Abeokuta, nipinlẹ Ogun.
Awọn obi rẹ pada di ẹlẹsin Kristiẹni, ti wọn si n lọ sinu ijọ kan ni agbegbe Oshodi nipinlẹ Eko.
Gẹgẹ bi akọsilẹ itan igbesi aye rẹ to wa lori ayelujara itakun agbaye ijọ naa, genesisglobal.org, idile ti ko ri ọwọ rọri lo ti wa, nitori oju owo pọn awọn obi rẹ pupọ.
Oríṣun àwòrán, Genesis global/facebook
O kiri ọja bi mọin-mọin ati burẹdi, bakan naa lo sẹ awọn iṣẹ pẹẹpẹẹpẹ lati ran awọn obi rẹ lọwọ gẹgẹ bi akọbi.
Iṣẹ ati oṣi to ba awọn obi rẹ finra ko jẹ ko lọ si ileewe tayọ ileewe girama. Koda, ko kẹkọọ pari ti ko fi lọ mọ.
Itan igbesi aye Wooli Oladele Ogundipe sọ pe idile rẹ ko fẹran ijọ alaṣọ funfun, nigba to wa ni kekere.
Igbagbọ wọn ni pe awọn to n lọ si awọn ijọ naa maa n ṣe oogun, ati awọn nkan ti ko tọ gẹgẹ bi Kristiẹni to jẹ atunbi.
Ijọ Aposteli Kristi, CAC, ni oun ati awọn obi rẹ n lọ. Iwaju ile wọn si ni ile ijọsin naa wa.
O sọ pe awọn kan riran si iya oun nigba to loyun pe ọmọ inu rẹ yoo ṣiṣẹ fun Ọlọrun, amọ iṣẹ alfa tabi imaamu ni awọn obi rẹ n fọkan si nitori ẹlẹsin Musulumi ti wọn jẹ lasiko naa.
Ifa Worshippers: Àwọn ẹlẹ́sìn ìbílẹ̀ ń fẹ́ kíjọba pín èrè òṣèlú alágbádá yíká gbogbo ẹ̀sìn
Ṣugbọn iṣẹlẹ buruku kan waye ni ọjọ kan.
Iya Oladele jẹ ẹnikan lara awọn obinrin inu ijọ naa ni owo, ti ko si ri i san.
Ni obinrin naa ba wa sile wọn, to si pariwo le iya rẹ lori lati san owo naa.
Ibi ti ariwo ti n waye ni obinrin naa ti ya aṣọ kan ṣoṣo ti iya Oladele maa n wọ jade, mọ ọ lọrun.
Oladele sọ pe iṣẹlẹ naa mu itiju ati ibanujẹ ba oun. Eyi lo si mu ko pinnu lati ma lọ si ṣọọṣi naa mọ, nitori itiju.
The New Pandemic: Kíni àwọn onímọ̀ sáyẹ́ńsì ń sọ nípa rẹ̀?
Eyi lo mu ko darapọ mọ ijọ Cele kan ti ko jinna si ile wọn.
Gẹgẹ bi ẹni to mọ ilu lilu, Oladele bẹrẹ si ni ba wọn lu ilu ninu ijọ naa.
Kẹrẹ-kẹrẹ, lo ba di ọmọ ijọ Celestial. O ni kii ṣe idaamu, tabi aisan lo gbe oun de inu ijọ alaṣọ funfun.
Nibẹ lo ti bẹrẹ si ni 'gun oke ẹmi', ti ko si ni mọ nkan to n lọ ni ayika rẹ fun bi ọjọ meje, lai mu omi tabi jẹun, to si sọ n sọ asọtẹlẹ.
O si ti n ṣiṣẹ alufaa ijọ Cele fun ọdun mẹrinla gbako.
Afojusun rẹ si ni lati da yatọ si awọn ijọ Cele yooku, nipa iwaasu ati isẹsi wọn.
Oríṣun àwòrán, Genesis Global
Wòlíì Genesis kan yẹra díẹ̀ ni, ó máa tó wọlé padà bí olè lóru- Adelé pásítọ̀ Oladele
Adelé pásítò Oladele ní wòlíì Genesis kan yẹra díẹ̀ ni, ó máa tó wọlé padà bí olè lóru
Adaba o naa ni a n kungbẹ, ina n jo ẹyẹ oko n lọ ni ijọ Celestial Church of Christ Genesis Global fi ṣe lẹyin ti ileẹjọ dajọ ẹwọn ọdun meji fun alakoso ijọ naa, Woli  Israel Oladele lori ẹsun gbajuẹ.
Niṣe ni ijọ naa kun fọfọ ni isin ọjọ isinmi akọkọ to waye ninu ijọ ọhun lẹyin ti woli naa rẹwọn he.
Adele oluṣọ woli Oladele, Samuel Oba sọ ninu iwaasu rẹ pe ohun to ṣẹlẹ ko le fa iwariri ninu ijọ naa.
O ni Woli Genesis kan yẹra diẹ ni, ''ti akoko ba to, yoo wọle pada bi ole loru.''
''Ṣugbọn awọn ọta lo kan n polongo ohun ti ko ṣẹlẹ kaakiri,'' Pasitọ Oba lo sọ bẹẹ ninu iwaasu rẹ.
Pasitọ Oba tun fi igboya sọrọ pe ''mo wa nibi ti ẹ ba fẹ gbe mi, ẹ wa gbemi.''
Alufaa ọhun tun sọ pe ko si ohun ti awọn fẹ ki ọlọrun ṣe fun Woli Genesis ti ko tii ṣe fun tẹlẹ.
O rọ gbogbo awọn ọmọ ijọ CCC Genesis Global wi pe ki wọn kun fun ayọ, ki wọn si maa ṣe bi ẹni ti ibanujẹ ba nitori ohun to ṣẹlẹ si alufaa Oladele.
Eégun àti orò, bí wọ́n ṣe jọ bí Ẹ̀ṣà Egúngún nílẹ̀ Yorùba rèé
Israel Oladele Ogundipe (GENESIS) ni oludari ati alakoso ijọ Celestial Church of Christ, Genesis Global, ọkan ninu awọn ẹni ifami ororo yan tawọn ololufẹ rẹ n warii fun gẹgẹ bí ajinrere fun ijọ CCC lagbaye.
Olusọaguntan ni pẹlu, ó jẹ olukọ ati onisesẹ Aposteli.
Ọmọ ilu Igboore ni ilu Abeokuta ipinlẹ Ogun ni woli Israel Oladele ṣugbọn ọmọ atapata dìde ni to si jẹ iya ki o to de ipo to wa.
Ẹni ọdun marundinlaadọta ni Israel Oladele Ogundipe.
Ṣaaju, awọn ọmọ ijọ rẹ ti ba BBC Yoruba sọrọ pe:
Akomolede ati Aṣa lori BBC:Wo ìrúfẹ́ ìgbeyàwó méje tó wà nílẹ̀ Yorùbá àti ojúṣe Alárinà
Oríṣun àwòrán, Genesis Global
Bí o bá bá ààrùn ìpẹ́pẹ́ gbígbẹ lára arẹwà obìnrin rẹ̀, kí loó ṣe?
Oríṣun àwòrán, Genesis Global
Prophet Israel Oladele: Àwọn ìlúmọ̀ọ́ka tó ti jọ́sìn ní ijọ CCC, Genesis Global rèé
Oríṣun àwòrán, Facebook
Ọpọ eeyan lo ṣi n sọrọ lori idajọ ẹwọn ọdun meji ti ileẹjọ da fun oludari ati alakoso ijọ Celestial Church of Christ, Genesis Global  Israel Oladele Ogundipe (GENESIS) lori ẹsun gbajuẹ.
Ileeṣẹ BBC Yoruba ti ṣe oriṣiiriṣii akojọpọ iroyin lori ọrọ yii lati igba ti idajọ ọhun ti jade.
A o tun ṣe ayẹwo awọn gbajugbaja lawujọ to ti jọsin ri ni ijọ CCC, Genesis Global  Israel Oladele Ogundipe (GENESIS).
Gani Adams
Oríṣun àwòrán, Gbedu, Genesis Global
Aarẹ Ọnakakanfo ilẹ Yoruba, Iba Gani Adams wa lara awọn ilumọọka to ti jọsin niijọ Celestial CCC (GENESIS) labẹ akoso pasitọ Ogundipe.
Aarẹ Ọnakakanfo lọ ṣe idupẹ ni ijọ Genesis Global, fọnran isin naa si lu ori ayelujara pa lẹyin to jọsin tan nibẹ.
Gani Adams sọ ninu ọrọ rẹ pe Pasitọ Ogundipe wa lara awọn ojiṣẹ Ọlọrun toun bu ọla fun julọ lorilẹede Naijiria.
''Ẹmi irẹlẹ ti mo ri lara Pasitọ Oladele lo mu mi lọ ṣe idupe ninu ijọ rẹ,'' Gani Adams lo sọ bẹẹ.
Gani Adams tun sọ pe Pasitọ Oladele jẹ iranṣẹ Ọlọrun ti o ni ẹmi Ọlọrun.
''Bi mo ṣe jẹ aarẹ Ọnakakanfo wa lara asọtẹlẹ ti pasitọ Oladele sọ nipa mi eyi to wa si imuṣẹ,'' Gani Adams lo woye bẹẹ.
Wasiu Ayinde K1 De Ultimate
Oríṣun àwòrán, Genesis Global
Alhaji Wasiu Ayinde K1 De Ultimate naa lara awọn ilumọọka to ti ṣabẹwo si ijọ Celestial CCC (GENESIS) labẹ akoso pasitọ Ogundipe.
K1 De Ultimate ṣere ninu ijọ naa pẹlu awọn ọmọlẹyin rẹ.
Alhaji Ayinde kọ ninu orin nibẹ pe ayọ ni fun gbogbo awọn ijọ Genesis ati fun oun naa to fi mọ idile oun.
Wasiu tun kọ ninu orin pe awọn to n binu Pasitọ Ogundipe le maa binu lasan nitori ẹni ti Ọlọrun gba fun un ni.
K1 De Ultimate tun ki gbogbo awọn alatilẹyin Pasitọ Oladele ninu orin rẹ bakan naa.
Pasitọ Ogundipe naa dupẹ lọwọ K1 De Ultimate pẹlu idọbalẹ, bakan naa lo tun gbadura fun olorin naa.
Wàhálà mìíràn déba Trump bí Biden ṣ tún gbégbá orókè nínú atunka ibo Georgia
A dúro bí iké lẹ́yìn ìròyìn táa gbé jáde nípa Lekki Tollgate; CNN tako Lai Mohammed
Ìtàn ayé Abiola Peller, ọlọ́wọ́ idán tó fi ọ̀bẹ gé ìyàwó rẹ̀ sí méjì
Woli Agba ati Dele Omo Woli
Oríṣun àwòrán, Woli Agba Ayo Ajewole
Adẹrinpoṣonu, Ayo Ajewole ti ọpọ mọ si Woli Agba ati iṣọmọgbe rẹ, Mide Oladimeji ti ọpọ mọ si Dele ọmọ Woli naa ṣabẹwo si Genesis Global.
Woli Agba ati Dele fi ijo bẹẹ niwaju ijọ lasiko ti isin n lọ lọwọ, koda Pasitọ Ogundipe naa ko gbẹyin.
Woli Agba ati Dele pẹlu awọn ọmọlẹyin rẹ lo pitu meje ti ọdẹ n pa ninu igbo pẹlu ere ori itage ti wọn da awọn ọmọ ijọ naa laraya.
Pasitọ Ogundipe fi ẹmi imoore han nipa gbigba adura fun Woli Agba atawọn ọmọlẹyin rẹ pe oke oke lẹyẹ n fọ un pe loke loke ni yoo maa lọ.
Chief Commander Ebenezer Obey
Akọrin Juju tẹlẹ to ti di ajihinrere papaa julọ ninu orin kikọ bayii, Chief Commander Ebenezer Obey naa ti lọ ṣere ninu ijọ Genesis Global.
Ki Obey to bẹrẹ ere niwaju ijọ naa, o kọkọ bu adura julẹ fun Pasitọ Ogundipe.
O beere fun ilọsiwaju ohun rere gbogbo ti Eleduwa n ṣe lati ọwọ pasitọ naa.
Koda, gbajugbaja akọroyin Dele Momodu naa wa labẹ isin nigba ti Obey ṣere ninu ijọ Genesis Global.
9ice ati Atorise
Oríṣun àwòrán, Alanre Teriba
Gbajugbaja olorin takasufe, Abolore Adegbola ti ọpọ mọ si 9ice ati Lanre Teriba ti wọn n pe ni Atorise naa ṣere ni ṣọọṣi Genesis Global.
9ice kọ oriṣiiriṣii orin to ti gbe jade ninu awo rẹ niwaju ijọ Genesis Global.
Atorise naa da orin bolẹ niwaju ijọ Genesis Global.
Niṣe ni Atoriṣe n yira mọlẹ nigba ti o n kọrin da awọn ọmọ ijọ lara ya.
Omo Ghetto: Funke Akindele ṣàlàyé bí àwọn agbébọn ṣe kọlù wọn làsíkò tí wọ́n ń ya fíìmù
Oríṣun àwòrán, Instagram/Funke Akindele
Gbajugbaja oṣere Nollywood, Funke Akindele ti ṣalaye ohun ti awọn agbebọn fi oju rẹ ri lasiko ti wọn yabo ile itura to wa lasiko to n ṣe fiimu Ọmọ Ghetto.
Funke Akindele sọ ọrọ yii loju opo ikansiraẹni Instagram rẹ lasiko to n ba awọn eniyan sọrọ ni ojukoroju' Instagram Live' to waye laipẹ yii.
O ni iṣẹlẹ yii waye ni nkan bii ọdun mẹsan an sẹyin.
Ọkùnrin tó fẹ́ fipábámilòpọ̀ fín ǹkan sí mi lójú ló ṣe rọ́nà wọlé sí mi lára
Lara awọn to kopa ninu fiimu naa ni orẹ timọtimọ Funke Akindele, Bimbo Thomas to kọ lati jẹ ki awọn ole naa ṣekupa Funke Akindele.
''O ti pẹ ti emi ati Bimbo ati Eniola Badmus ti jẹ ọrẹ timọtimọ. ''
''Nkan bii ọdun mẹsan an ṣẹyin lasiko ti a n ṣe fiimu apa keji Ọmọ Ghetto, to si yẹ ki Eniola wa darapọ mọ wa ninu yara ile itura ti mo wa, amọ o kọ.''
Oríṣun àwòrán, Instagram/Bimbo Thomas
''Émi ati Bimbo la wa papọ lalẹ ọjọ naa lẹyin ti mo bẹ ẹ wi pe mi o fẹ da sun, ki o wa sun pẹlu mi.''
''Awọn ole naa wọ inu ile itura naa, wọn si bẹrẹ si ni gba ilẹkun ibi ti mo wa, amọ Bimbo ni ki n lọ si abẹ ibusun lati sapamọ, tabi ki n lọ si ile iwẹ.''
''Ile iwẹ ni mo sa pamọ si nigba ti awọn agbebọn naa wọle, ti wọn si bẹrẹ si ni bere pe nibo ni Funke Akindele wa?''
''Bimbo kọ lati sọ fun wọn, nigba ti wọn bẹrẹ si ni na a ni mo sa jade wi pe ki wọn ma pa a, ti wọn si bẹrẹ si ni naa emi naa, amọ Bimbo n pariwo ki wọn fi mi silẹ.''
''Lẹyin ọjọ mẹta ti iṣẹlẹ naa waye ni mo bere lọwọ rẹ idi ti ko fi sọ ibi ti mo wa fun awọn adigunjale naa, Bimbo ni o dara ki oun ku ju ki Funke Akindele ku lọ.''
Fiimu Ọmọ Ghetto saga ti Funke Akindele ṣẹṣẹ ṣe jẹ apa keji akọkọ rẹ to ti ṣe jade tẹlẹ.
Afeez Oyetoro Saka"" ní 'toríi kóòtù àyálò ni òun fi ń wá ọ̀rẹ́ ọdún 34 sẹ́yìn."
Oríṣun àwòrán, Mpmania
Ṣe ẹ mọ Afeez Oyetoro ti orukọ inagijẹ rẹ ninu ere n jẹ Saka?
Dajudaju ọpọ eeyan lo mọ Saka gẹgẹ bi agba ọjẹ apanilẹrin ninu ere sinima lorilẹede Naijiria.
Amọṣa, alagba Saka ni ki iṣu oun to di iya, iya diẹ kọ lo jẹ lọwọ odo.
Saka sọ ọrọ yii ninu awọn ọrọ kan to kọ nigba to gbe fọto rẹ kan to fi soju opo Instagram rẹ sita.
Saka ni atapata dide loun atipe nibi to le de, ayawọ kootu ni oun fi ṣe ayẹyẹ igbaniwọle, Matriculation, nigba ti oun wọle gẹgẹ bii akẹkọọ ni fasiti Ọbafẹmi Awolọwọ, OAU ni ilu Ile Ifẹ lọdun 1986.
Ariwo ayọ n lọ lọtun losi lọgba fasiti naa fun ayẹyẹ igbaniwọle awọn akẹkọọ ti emi ko si ni ireti lati bawọn darapọ ṣe nitori pe mi o ni kootu ti mo le wọ fun ayẹyẹ naa.
Saka ni eyi mu ki inu oun bajẹ gidigidi ti oun si ka jọ si ori ibusun oun ninu ibanujẹ ọkan.
Oríṣun àwòrán, Instagram/simplysaka
Bí o bá bá ààrùn ìpẹ́pẹ́ gbígbẹ lára arẹwà obìnrin rẹ̀, kí loó ṣe?
Amọṣa, Saka ni ọrẹ oun kan lo gba oun kalẹ to si ya oun ni kootu rẹ ti oun fiṣe ayẹyẹ ayajọ naa.
O fi kun pe ọrẹ oun yii lo wa gba oun silẹ lọwọ ainikopa lọjọ naa lọhun.
O ni ohun to dun oun jọjọ bayii ni pe oun n wa akẹkọọ naa ti awọn jọ gbe nileewe titi di oni ti oun ko si rii.
O wumi ki n ri akẹgbẹ mi naa lati dupẹ lọwọ rẹ. Ọlọrun yoo maa ba gbogbo wa pade lawọn ikorita aini wa.
Salami report on EFCC: Ààrẹ Buhari tẹ́wọ́ gba àbájáde ìwádìí lórí àjọ EFCC, ìròyìn kan ní wọ́n fẹ́ yọ Magu nípò
Oríṣun àwòrán, Ripples
Igbimọ oluwadii ti Onidajọ Ayo Salami gbe kalẹ lati wadii awọn ẹsun ti wọn fi kan Adele Alaga ajọ EFCC tẹlẹ, Ibrahim Magu, ti sọ pe ki wọn o da Magu duro.
Ọjọ Ẹti ni igbimọ naa gbe àbọ̀ iwadii rẹ fun Aarẹ Muhammadu Buhari, to si gba aarẹ nimọran lati yan adele alaga ajọ EFCC tuntun, ti yoo wa nipo fun ọdun meji.
Bakan naa ni igbimọ naa gba  Aarẹ nimọran lati yan adele alaga ajọ naa, lati ibomiran yatọ si ileesẹ ọlọpaa.
Saaju asiko yii, ileesẹ ọlọpaa ni wọn ti ma n yan gbogbo àwọn to ti ṣe alaga ajọ to n gbogun ti iwa ibajẹ naa,lati igba ti wọn ti da a silẹ.
Àwọn ẹsun bi kiko owo jẹ, ati aṣilo ipo ni wọn fi kan Magu, eyi to mu ki ijọba ni ko lọ rọọkun nile naa, titi iwadii yoo fi pari lori awọn ẹsun naa.
Wàhálà mìíràn déba Trump bí Biden ṣe tún gbégbá orókè nínú atunka ibo Georgia
Ìtàn ayé Abiola Peller, ọlọ́wọ́ idán tó fi ọ̀bẹ gé ìyàwó rẹ̀ sí méjì
Charly Boy: Nítorí ọ̀rọ̀ tí Charly boy kọ́ nípa bi ọmọ rẹ̀ ṣe jẹ́ ẹni tó n ní ìbálòpọ̀ pẹ̀lú obìnrin ẹgbẹ́ rẹ̀, Dewy Oputa ti fárígá fún bàbá rẹ̀ pé kó yé fi òun wá ojú rere
Oríṣun àwòrán, Twitter/charly boy
Ọmọbinrin agba olorin, Charly boy, Dewy Oputa ko foju rere wo baba rẹ bayii o fun ohun to kọ soju opo ayelujara nipa rẹ, o si ti fesi fun baba rẹ pe ko fi tirẹ ṣe tirẹ o.
Ni ọjọ Ẹti ni Charly boy ti ọpọ tun mọ si area fada bọ soju opo Instagram rẹ nibi to ti sọ pe ohun sunmọ awọn ọmọ oun o, oun si ni ifẹ wọn, nitorina nigba ti ọmọ oun obinrin jade lati sọ fun oun pe abobinrin bii toun lopọ loun jẹ, iyẹn Lesbian, nṣe loun gbaa tọwọ tẹsẹ o.
Tí mo ba ti múra bí ọkùnrin fi kọrin, kò sí ọ̀dọ̀ ààrẹ́ tí mi ò lè wọ̀- Erelu, ọmọ Elemure Ekiti
Amọṣa ọmọ rẹ obinrin tọrọ ọhun kan ti lọ fesi fun baba rẹ lori atẹjade to gbe soju opo Instagram rẹ naa.
Dewy ni ṣe ni baba oun fẹ maa fi oun gba irawọ kawọn eeyan lee maa ka ọrs rẹ loju opo ayelujara rẹ.
Esi ti area fada fun naa ni pe ọmọ mi, maa ṣe bayii. O mọ pe mo nifẹ rẹ gidi gan ni.
Gbajugbaja oludanilaraya, Charly Boy 'Area Fada', ti sọ ni gbangba bi inu rẹ ṣe dun sí pe oun ni ọmọ to jẹ ololufẹ ibalopọ obìnrin si obìnrin ẹgbẹ rẹ.
Ori ayelujara ibaraẹni dọrẹẹ ni Area Fada ti sọ nipa oriṣiriṣi èrò inu rẹ nigba ti ọmọ rẹ abigbẹhin l'obinrin, Dewy Oputa sọ fun pe 'Lesbian' ni oun.
"O ni ""nigba ti ọmọ mi sọ fun mi pe oun ma n ni ibalopọ obìnrin si obìnrin 'lesbian', oriṣiriṣi nkan lo wa si ọkan mi bi a ṣe jọ n ṣorọ lori foonu."
" Mo ṣa n ro oriṣiriṣi nkan. Koda, mo da ara mi ni ẹbi. Ọkan mi daru.
Mo tun ro ọrọ ẹ̀sìn pe ṣe ọrun àpáàdì kọ ni ọmọ mi yoo lọ bayii?"
Gẹgẹ bi gbajumọ naa ṣe sọ, o ni oun ti n gbaradi fun oṣu diẹ lati ja fun ẹtọ àwọn to n ni ibalopọ ọkunrin sọkunrin, ati obinrin si obinrin, saaju ki ọmọ oun to o sọ ọrọ naa fun oun.
Lẹyin ọpọlọpọ idaru-dapọ ati ero lorisirisi, Charly Boy sọ pe ko si ohunkohun to le fa ipinya laarin oun ati eyikeyi ninu ọmọ òun.
Yatọ si eyi, o tun kọ ọ sibẹ pe iwa omugọ ni ki òbí ro pe oun kuna ninu ojuṣe oun ti ọmọ ba jẹ iru eeyan bẹ ẹ. Ati pe, gbogbo òbí jẹ àwọn ọmọ wọn ni ifẹ ti ko ni ìdí.
"Bo tilẹ jẹ pe Charly Boy pari gbogbo ọrọ rẹ pẹlu ""mo nífẹ̀ẹ́ ọmọ mi to jẹ lesbian"", o dabi ẹni pe iroyin to fi sita naa ko dun mọ ọmọ rẹ Dewy ninu, nitori esi to kọ si abẹ ọrọ naa lori ayelujara pe baba oun n kọ nkan sori ayelujara nitori awọn ololufẹ rẹ."
Ọọni Adeyeye gbé orúkọ àrẹ̀mọ rẹ̀ jáde, ẹ kọ́ ẹ̀kọ́ nípa àwọn ǹkan tí wọ́n fi gbàdúrà f'ọ́mọ ọba
Oríṣun àwòrán, Ooniadimula
Ilẹ Yoruba ni asa isọmọlorukọ ara ọtọ
Bẹẹ idalu kuku ni iṣelu ni awon agba n sọ.
Awọn ohun eelo ati ohun ti ẹnu n jẹ ni awọn agba maa n ko sita fi ṣadura fun ikoko tuntun ti a ba bi nilẹ oodua.
Ni ọjọ mẹjọ si ni ikomọjade ọmọ tuntun nilẹ Yoruba.
Adebola Ademilua: Àìrísẹ́ ṣè lẹ́yìn ìwé kíkà ló sọ mi dí ìyá onírú, mo dúpẹ́ tèmi
Isomọlorukọ ọmọ tuntun ti o jẹ arole Oọni Ifẹ: Kílódé tí Ọọni Ife, Oba Ogunwusi kò fi gbọdọ̀ rí ọmọ rẹ̀ tuntun ti Olorì Naomi bí títí di bíi ẹ̀yìn oṣù mẹ́fà?
Ni ibi isọmọlorukọ Arẹmọ Oba Adeyey Ogunwusi, Ojaja I to jẹ Oọni Ile Ife ni awọn ohun eelo ikomọjade tun ti jade.
Oyin. Orogbo, Obi, Iyọ suga, Ireke, Aadun, Igbin, Ẹja, ỌtiṢinaapu ati awọn nkan miran ni awọn agbaagba lo lati fi sọ ọmọ tuntun ti a bi na ni orukọ.
Awọn ohun eelo yii mu awọn adura ati asọtẹlẹ da ni fun ẹjẹ ọrun tuntun naa ni eyi to n mu aṣẹ dani ninu igbagbọ iran Yoruba.
Taa ni Ọọni àná tí Ọba Ogunwusi forúkọ ọmọ rẹ̀ sọ?
Ooni ile Ifẹ, Oba Adeyeye Enitan Ogunwusi ti muleri ṣẹ lori adehun to ṣe pe oun yoo sọ ọmọ rẹ tuntun lorukọ Ooni to ṣaaju rẹ .
Fun idi eyi o ti ni ọmọ tuntun naa yoo ma jẹ orukọ pẹlu Ooni Tadenikawo Adesoji Aderemi to jẹ Ooni ṣaaju.
Ikede yi waye loju opo Twitter Ooni lẹyin ọjọ kẹjọ tọmọ naa d'aye ti wọn si ti yoo si ṣe etutu ọlọsẹmẹta tori ki o baa le ri bi o ti ṣe yẹ ko ri.
Alaafin ni awọn kan si Ifa nipasẹ Araba Agbaye olori awọn onifa lagbaye ki awọn to sọ orukọ yi di mimọ faraye.
Ooni salaye siwaju pe Araba Agbaye fi orukọ ọmọ naa le Oloye Lowa ilu Ife Adekola Adeyeye lọwọ ki wọn to wa kede rẹ setigbọ ero to pe sita.
Ẹkunrẹrẹ orukọ ọmọ naa ni Tadenikawo, Adesoji, Aderemi, Eri-Ifeoluwasimi, Adeiwa, Inioluwa, Ademide, Adegbite, Diekoloreoluwa, ọmọ Ogunwusi.
Saaju ni Ooni ti ṣadehun pe oun yoo sọ ọmọ tuntun ti a bi lọjọ Kejidinlogun oṣu Kọkanla ọdun 2020 lorukọ ọkan lara awọn Ooni to jẹ saaju rẹ.
Ooni Tadenikawo Adesoji Aderemi ni o jẹ Ooni ikọkandinlaadọta ni Ile Ife.
Lasiko igbe aye rẹ, o jẹ oye Gomina  adulawọ akọkọ laye eebo amunisin.
Oríṣun àwòrán, @oluwole_dada
O jẹ ara awọn eeyan to kọkọ laju, o kọ ẹkọ iwe, o lowo, o lọla, o gbajumọ, o si jẹ asaaju ilu.
Ọjọ kejidinlogun, oṣu kọkanla, ọdun 2020 ni Ooni Ile Ife, Adeyeye Enitan Ogunwusi, kede lori ayelujara pe Olori oun, Naomi Ogunwusi, ti bi ọmọ ọmọkunrin tuntun.
Bi ọpọ awọn eeyan ṣe n ki Onirisa ayọ abara tintin, lawọn miran n sọ pe Ọba lọla lo de yẹn.
Lagos King: Mátikú ọba tó lo lo ọdun mẹta lórí oyé latari rogbodiyan Eko
Ṣugbọn ṣe ootọ ni pe ọmọ tuntun ti Ooni ṣẹṣẹ bi ni yoo jẹ Ooni lọjọ iwaju?
Idi ree ti ileeṣẹ iroyin BBC Yoruba ṣe kan si Araba awo ilu Oṣogbo, Ifayemi Elebuibọn lati tanj imọlẹ si ọrọ naa.
Oríṣun àwòrán, Oniadimula
Elebuibọn ni, pe Ooni bi ọmọ ọkunrin ko tumọ si pe ọmọ naa ni yoo gori itẹ lọjọ iwaju.
O ni, bi wọn ṣe n yan ọba nilẹ Yoruba tẹlẹ ko to di pe ijọba ati ọlaju de, ti ijọba si n lọwọ ninu ọba yiyan.
Elebuibọn ni ki wọn to yan Ooni, tabi Ọba nilẹ Yoruba, idile ti oye ba kan lo maa fa ẹni ti wọn ba n fẹ ko dori itẹ silẹ, ti awọn afọbajẹ yoo si di ifa lati mọ boya asiko irufẹ Ọba bẹẹ yoo san awọn ara ilu.
"O ni ""wọ maa pe idilẹ ti oye bá kan, lẹyin naa ni wọn yoo to bi ifa lere."""
Bí o bá bá ààrùn ìpẹ́pẹ́ gbígbẹ lára arẹwà obìnrin rẹ̀, kí loó ṣe?
Awọn idile ti oye kan yoo da'fa, bẹẹ ni awọn afọbajẹ naa yoo da'fa.
"O ni kii ṣe akoko niyii lati maa sọ pe ọmọ tuntun ti Ooni bi ni yoo di Ọba lọla ""nitori wọn ko mọ iru ori to yan, Ọba le bi ọmọ mẹwaa, kii si ṣe dandan ni pe akọbi ni yoo gori itẹ lẹyin baba rẹ, o le jẹ abigbẹyin."""
Fun gbogbo awọn to n sọ pe Ooni ti bi Ọba lọla, Elebuibon sọ pe ti wọn ni wọn n sọ yẹn nitori gbogbo igi kọ lo maa n so olu.
Araba awo ilu Oṣogbo pari ọrọ rẹ pe, ifa lo ma n yan Ọba laye atijọ, ṣugbọn bayii oju ni wọn fi n yan ẹni to lọla tabi to lorukọ lawujọ lati di ọba.
"O ni ""eeyan le lowo lọwọ ṣugbọn ko ma lori oye."""
Oluwo Ìwo ṣ'àlàye lori oyé oba oni lawàni
Erelu Elemure: Ìyá mi rò pé mi ò lè tibi kíkọrin bíi bàbá mi là
Yoruba ni bi baba ba ku, baba nii kù. Adia fun ọmọ bibi inu gbajugbaja olorin ilu Ekiti, Elemure Ogunyemi ti gbogbo eeyan mọ si Elemure iyẹn Funmilayo Elemure to fiwa jọ baba ninu gbogbo nkan.
Erelu Elemure ni orukọ itage rẹEde Ekiti kan naa ti baba rẹ, Peter Ogunyemi elemure to ti di oloogbe bayii ma fi n kọ orin loun naa nlo, koda bii ọkunrin lo yan lati maa mura ninu ẹwu bii Agbada, Sokoto ati sọọrọ.
Gẹgẹ bo ṣe ṣalaye fun BBC Yoruba, ara ọtọ to n gba mura lo n fun un ni ọgbọn atinuda fun iṣẹ rẹẹ bẹẹ si ni o ni oun n ri iyi ati ọwọ gba latara eyi.
O sọ bi iya rẹ ṣe kọkọ sọ ireti nu ninu oun to yan laayo yii to si sọ fun un pe ko le ṣe oriire nibẹ amọ ṣe ni ohun ati ilu ijo mama gan yipada nigba tinkan ti ọmọ rẹ, Erelu elemure n ṣe bayii ti di iwuri nla fun un.
Delta Assault: Ọkùnrin tó pe ìyàwó rẹ̀ lájẹ̀ẹ́ tì í mọ́lé fọ́dún mẹ́rin, fún un lóyún nígbà mẹ́ta
Oríṣun àwòrán, HARRISON GWAMNISHU
Eemọ lukutu pẹbẹ, ileeṣẹ ọlọpaa ipinlẹ Delta ti mu ọkunrin kan, Ame Edjeke lori ẹsun pe o ti iyawo rẹ inu yara kan fun ọdun níbi ti o ti fi iya oriṣiiriṣii jẹ ẹ.
Afurasi naa Edjeket, ẹni ọdun mọkanlelogoji ni a gbọ pe o fun obinrin ọhun loyun lẹẹmẹta lera nigba to wa ni igbekun nile wọn to wa ni Orerokpe nipinlẹ Delta.
Ọkùnrin ti iyawo rẹ yii ti bi ọmọ mẹjọ fún ni iroyin sọ pe burẹdi nikan lo fun obinrin naa jẹ nigba to fi ti i mọle.
Tí mo ba ti múra bí ọkùnrin fi kọrin, kò sí ọ̀dọ̀ ààrẹ́ tí mi ò lè wọ̀- Erelu, ọmọ Elemure Ekiti
Bakan naa ni a tun gbọ pe ọkunrin naa ko jẹ ki iyawo rẹ wẹ tabi lo ile igbọnsẹ lasiko to fi wa ni igbekun.
Ṣugbọn aṣiri tu lẹyin tawọn ẹlẹyinju aanu kan fi ọrọ naa to ẹgbẹ ajafẹtọ kan ti orukọ rẹ n jẹ Behind Bars Defenders leti.
Ẹgbẹ yìí gan an lo gbe ọrọ naa dọdọ awọn ọlọ́pàá.
Oludari ẹgbẹ ọhún, Harrison Gwamnishu sọ fawọn akọroyin pe ọkunrin naa ni iyawo oun lo wa nidi bi oun ko ṣe lowo lọwọ.
Oríṣun àwòrán, HARRISON GWAMNISHU
Afurasi naa ti wa ni akolo awọn ọlọpaa bayii nigba ti iyawo rẹ si n gba itọju lọwọ nile iwosan.
Nigba ti o n fidi ọrọ naa múlẹ, agbẹnusọ ileeṣẹ ọlọpaa ipinlẹ Delta, Onome Onovwakpoyeya ṣalaye pe Ọgbẹni Edkepek ni ajẹ ni iyawo oun, o si larun ọpọlọ loun fi tii mọle tori ko sí ẹni to fẹ ran an lọwọ.
O tun sọ fawọn ọlọpaa pe oun gbiyanju lati da obinrin pada fawọn ẹbi rẹ, ṣugbọn wọn kọ ọ.
Bakan naa lo tun sọ fawọn ọlọpaa pe oun ti gbe iyawo oun kaakiri ile babalawo ki oun to da pada sini ile.
LAUTECH: Ìgbésẹ̀ pínpín dúkìá àti gbèsè fásitì LAUTECH ti bẹ̀rẹ̀
Oríṣun àwòrán, lautech
Ọrọ aawọ laarin ipinlẹ Ọyọ ati Ọṣun lori ta lo ni fasiti imọ ẹrọ Ladoke Akintọla ti jẹrodo lọ mumi bayii pẹlu bi ajọ to n ṣamojuto fasiti lorilẹede Naijiria, NUC ti ṣe kede rẹ lọjọ Ẹti pe ipinlẹ Ọyọ ni yoo maa gba akoso fasiti naa bayii.
Bakan naa lo tun kede rẹ pe, ileewosan nla ti fasiti naa iyẹn, LAUTECHTH to wa ni ilu Oṣogbo yoo jẹ ti ipinlẹ Ọṣun.
Ni ọdun 1990 ni wọn da fasiti naa silẹ labẹ ipinlẹ Ọyọ atijọ. Ilu Ogbomọṣọ ni wọn gbe Ọgba ikọni fasiti naa si ki wọn to lọ da ile ẹkọṣẹ iṣegun rẹ si Oṣogbo.
Amọṣa nigba ti wọn da ipinlẹ Ọṣun silẹ lati ara ipinlẹ Ọyọ atijọ lọdun 1991, awọn ipinlẹ mejeeji bẹrẹ eto ajumọni lori fasiti naa.
Akọwe agba ajọ NUC, Ọjọgbọn Abubakar Rasheed ṣalaye nilu Abuja pe ipenija to n waye lori akoso fasiti naa laarin awọn ipinlẹ mejeeji yii to si n mu idiwọ ba yiyan giwa atawọn agba oṣiṣẹ miran ni fasiti ọhun pẹlu sisan owo oṣu awọn oṣiṣẹ lasiko lo ṣokunfa pinpin ti wọn pin akoso rẹ.
Ọjọgbọn Abubakar Rasheed tun jẹ ko di mimọ pe awọn gomina ipinlẹ mejeeji lo finufindọ buwọlu iwe adehun lori pinpin iṣakoso fasiti naa.
O ni igbesẹ lori pinpin awọn dukia ati gbese to wa lọrun ileewe fasiti naa laarin awọn ipinlẹ mejeeji ti bẹrẹ.
Lekki Tollgate Killing: Agbẹjọ́rò kan fẹ́ kí Babajide Sanwo-Olu farahàn níwájí ìgbìmọ̀ olùwádìí láti wẹ ara rẹ̀ mọ́
Oríṣun àwòrán, Twitter/ babajidesanwo-olu
Gomina Babajide Sanwo-Olu gbọdọ foju han niwaju igbimọ oluwadi lori ẹhonu awọn oluwọde #EndSARS ati iṣẹlẹ ibọn yinyin lu awọn oluwọde to waye lagbegbe Lekki Tollgate l'Eko.
Agbẹjọro fun diẹ lara awọn oluwọde naa kan, Adesina Ogunlana lo sọ bẹẹ.
Amofin Ogunlana ni ileeṣẹ ologun ti ṣalaye niwaju igbimo naa pe gomina lo ranṣẹ pe awọn wa si iloro Lekki Tollgate; nitorinaa yoo ṣe pataki ki gomina naa wa wi tẹnurẹ.
Tí mo ba ti múra bí ọkùnrin fi kọrin, kò sí ọ̀dọ̀ ààrẹ́ tí mi ò lè wọ̀- Erelu, ọmọ Elemure Ekiti
Labẹ ofin orilẹede Naijiria, aarẹ, igbakeji aarẹ, gomina atawọn igbakeji wọn ko lee farahan niwaju ile ẹjọ kankan tabi igbimọ to ba ni ojuṣe ile ẹjọ ninu.
Olori ọwọ kọkanlelọgọrin ileeṣẹ ọmọogun Naijiria, Ọgagun Ahmed Taiwo ṣalaye pe gomina Sanwo-Olu lo kan si ọgagun agba ileeṣẹ ọmọogun oriilẹ, Tukur Buratai pe ko ko ọmọogun lọ si Lekki Tollgate.
Amofin naa ṣalaye fun ileeṣẹ iroyin kan pe o ṣe pataki ki gomina ipinlẹ Eko naa foju han o lati fihan pe lootọ lo duro ṣinṣin ninu ibọwọ fun ofin.
Amọṣa titi di bayii, gomina ko tii sọ boya yoo farahan niwaju igbimọ naa.
Prophet Israel Oladele: Wo bi wọ́n ṣe n ṣe àmójútó ilé ìjọsìn CCC Genesis Global
Oríṣun àwòrán, Genesis global
Gẹgẹ bi akọsilẹ to wa lori ayelujara itakun agbaye ijọ CCC Genesis Global ṣe  sọ, oun ni ijọ Celestial to tobi julọ, to si n yara dagba soke julọ ni agbaye.
Eeyan to le ni ẹgbẹrun mẹta lo ma n jọsin ninu ijọ naa ninu isin ọjọ Aiku.
Oludasilẹ ijọ naa, Alufaa Isreal Oladele Ogundipe, ni Oluṣọ ijọ naa.
Lẹyin rẹ, awọn oludari ati iranṣẹ Ọlọrun mejidinlogoji lo tun wa lẹyin rẹ.
Oríṣun àwòrán, Genesis global
Awọn ọkunrin ọlọla
Eyi ni ẹgbẹ awọn ọkunrin to n jọsin ninu ijọ CCC Genesis Global. Ohun ti wọn n ṣe ninu ẹgbẹ naa ni lati ma a kọ ara wọn ni ẹkọ lati jẹ ọkunrin gidi, gẹgẹ bi ọkọ, baba, oṣiṣẹ inu ijọ ati adari.
Oríṣun àwòrán, ccc genesis global/instagram
Ile ijọsin awọn ọmọde
Ibi yii ni awọn ọmọ wẹwẹ ati ọdọ ti ọjọ ori wọn wa labẹ ọdun kan si ọdun mẹtadinlogun ti ma n jọsin.
Ẹgbẹ awọn woli ọkunrin ati obinrin
Awọn wọnyii ni ariran, agbẹnusọ, iranṣẹ, oluṣọ. Ati aṣoju ninu ijọ naa, to ma n fi adura jagun. O jẹ akojọpọ awọn awọn woli to ma n sọ asọtẹlẹ, awọn to ma n la ala, ariran ati awọn to ma n fi ede oriṣiriṣi sọrọ.
Ẹgbẹ awọn ọmọ Sioni
Ẹka yii ni ti iṣẹ iranṣẹ awọn obinrin inu ijọ. Ikorajọpọ wọn ni lati ma a kọ awọn obinrin lati dagba ninu ẹmi. Awọn obinrin ti ọjọ ori wọn bẹrẹ lati ọdun mejidinlogun soke lo wa ninu ẹgbẹ naa.
Oríṣun àwòrán, Genesis global
Ẹgbẹ awọn aladura
Awọn wọnyii lo ma n fi adura jagun fun awọn ọmọ ijọ naa, ati ẹnikẹni to ba fi ẹbẹ adura ranṣẹ sinu ijọ naa.
Ẹka igbani nimọran
Awọn to wa ninu ẹgbẹ yii lo ma n gba awọn ọmọ ni imọran lori lori ohunkohun ti wọn ba n la kọja.
Oríṣun àwòrán, Genesis global
Awọn aṣọna
Awọn wọnyii lo ma n duro ni awọn ẹnu ọna to wọ inu ṣọọṣi naa. Lara wọn lo tun ma n tun pẹpẹ ile ijọsin ṣe, ti wọn si tun ma n gba ọrẹ.
Yatọ si awọn ti a ka silẹ yii, awọn ẹka oriṣiriṣi lo tun wa ninu ijọ CCC Genesis Global, to ma n ko ipa lasiko isin.
Oríṣun àwòrán, Genesis global
Awọn akọrin-Ẹka awọn to n mojuto igbohunsafẹfẹ eto isin ninu ijọ naa.
Awọn lo ma n ya aworan ati fidio ti isin ba n lọ lọwọ, ati amojuto iṣẹ iranṣẹ ori amohunmaworan ijọ naa.
Ẹgbẹ awọn olukini -Awọn eeyan to ma n ki awọn alajo kaabọ sinu ijọ naa.
Ẹgbẹ awọn olufifunni -Awọn to wa ninu ẹgbẹ yii lo ma n ṣoju ijọ lati fun awọn ọmọ ijọ ti ko ni i, ni ounjẹ, owo ati aṣọ.
Oríṣun àwòrán, ccc genesis global/instagram
Wọn tun ma n ṣeto fifun awọn alaini awujọ ni iranlọwọ loṣooṣu.
Ẹgbẹ eleto ilera - Eyi ni ẹgbẹ awọn onimọ iṣegun oyinbo to ma n tọju awọn alaisan lasiko iṣẹ iranṣẹ ilera ọfẹ, ati ẹnikẹni to ba nilo itọju lasiko ti isin n lọ lọwọ.
Awọn eleto aabo - Ojuṣe awọn to wa ni ẹka yii ni lati daabo bo ile ijọin, awọn oṣiṣẹ ati awọn olujọsin ati dukia wọn, lọwọ ole, ati awọn iṣẹlẹ buruku miran.
Oríṣun àwòrán, Genesis global
Ikọ awọn alatunṣe - Awọn to wa ninu ikọ yii lo ma n tun inu ati ayika ile ijọsin ṣe lasiko ijọsin ati lẹyin rẹ.
Awọn olubẹwo - Awọn eeyan yi lo ma n ṣe amojuto awọn to ba ṣẹṣẹ darapọ mọ ijọ CCC Genesis Global. Wọn si tun ma n bẹ wọn wo lẹyin rẹ.
Awọn ajihinrere - Awọn to wa ni ẹka yii lo ma n kede ihinrere kaakiri lati jere ọkan fun Jesu.
AbdulQudus Bello ṣàlàyé bí òun ṣe dí aláàbọ̀ ara nítorí pọpọ́ọ̀fù àti ìbínú jàǹdùkù àdúgbò
Kegel: Eré ìdárayá tí àwọn onímọ̀ sọ pé ó n fikún adùn ìbálòpọ̀ fún obìnrin, tó tún n fún ọkùnrin ní agbára
Awọn onimọ ilera maa n sọ pe pataki ni ere idaraya jẹ, ninu ilera ẹda.
Bẹẹ si ni oriṣiriṣi ere idaraya wa, ṣugbọn o ni awọn to n ṣanfaani fun ibalopọ laarin takọ-tabo.
Dokita onimọ nipa bi egungun inu ara ṣe n ṣiṣẹ, Abubakar Ahmad Tsafe, ti ileewosan Gbogboogbo Farida, nilu Gusau nipinlẹ Zamfara, sọ nipa awọn iwulo ati anfaani ere idaraya fun ibalopọ to dara fun ọkunrin ati obinrin.
Dokita naa sọ pe ere idaraya le ran ọkunrin lọwọ lati fi opin si ti tete da 'ejaculation', aile ṣe deede ninu ibalopọ.
O tun le mojuto ki nkan ọmọkunrin o ma ṣiṣẹ.
O ni o tun le ṣe iranlọwọ lori iṣoro ti ọkunrin ba ni pẹlu ile itọ rẹ.
Fun awọn obinrin, ere idaraya le fun ile itọ ati ẹya ara to wa fun ọmọ bibi, ni okun.
Dokita Abubakar Ahmad Tsafe sọ pe ere idaraya Kegel, jẹ eyi ti ko nira rara, to si ma n fun awọn iṣan to wa lara egungun to so ara ati ẹsẹ pọ 'pelvis', ni okun.
Ẹya ara 'pelvis' yii kan naa lo gbe awọn ẹya ara to gbe nkan smọkunrin ati oju ara obinrin duro.
O wa laarin ikùn ati itan.
Iwe iroyin magasiini Healthline Health sọ pe ere idaraya Kegel ma n jẹ ki ile itọ ṣiṣẹ daadaa.
O si tun ma n fun eeyan ni agbara ati fun ibalopọ.
Oriṣiriṣi nkan lo ma n din agbara ẹya ara 'pelvis' ku.
Nigba ti ọkunrin ba wa ni ọdọ, wsn ma n ni agbara.
Amọ bi wọn ba ṣe n dagba, ni yoo ma a rẹ ẹya ara naa, eyi ti yoo nipa lori bi wọn ṣe n ni ibalopọ.
Gẹgẹ bi Magasinni Healthline ṣe sọ, ere idaraya Kegel ma n mu ki adun ati ifẹ si ibalopọ, pọ si lara awọn ọkunrin.
O ma n dena ki ọkunrin tete dà àtọ lasiko ibalopọ, to si ma n din iṣoro ki ọkunrin o ma le ṣe ku.
Yatọ si eyi, Dokita Tsafe sọ pe ere idaya  naa ma n mu ki ọkunrin le pa itọ mọra fun igba pipẹ.
Tóò bá fún ọkùnrinn lóúnjẹ́ tóo tẹ́ kiní yẹn sílẹ̀ fún un dáadáa... - Yinka TNT
Oriṣiriṣi nkan lo le mu ki aarẹ ba 'pelvis' obinrin tabi ba a jẹ.
Eyi le waye nipasẹ oyun tabi ọmọ bibi.
O si le jẹ nipasẹ isẹ abẹ ile itọ tabi aisan ninu ile itọ.
Ṣugbọn dokita sọ pe ayipada le wa ti iru obinrin bẹ ẹ ba n ṣe ere idaraya Kegel.
O ni o tun ma n mu ki obinrin gbadun ibalopọ ju ti tẹlẹ lọ.
O sẹ pataki lati da orisun awọn iṣan naa mọ.
Healthline sọ pe o le da wọn mọ nipa kiki ika ọwọ to mọ si inu oju ara rẹ, ki o si pa awọn iṣan oju ara naa pọ daadaa mọ ika naa.
Ọna miran tun ni pe ki ọkunrin tabi obinrin gbiyanju lati da itọ duro lasiko ti wọn ba n tọ lọwọ.
Awọn iṣan ti wọn fi da itọ duro ni  ti pelvis, ti yoo si fun wọn ni òye aaye to wa.
Oriṣiriṣi ere idaraya yii lo wa - o le ṣe e lori iduro, ti o ba joko, tabi ki o sun si ilẹ
Eyi to wọpọ ju ni ki o sun silẹ, ki o si kọ oju si oke. Lẹyin naa, gbe itan soke, na ọwọ si iwaju, ki o si ka orunkun rẹ ko.
Dokita Tsafe sọ pe o le ṣe ere idaraya yii laarin iṣẹju aaya mẹta si marun, sinmi, ki o tun bẹrẹ pada.
Bakan naa ni fun ọkunrin ati obinrin.
O tun le ṣe ere idaraya naa nipa jijoko, ki o si ka ẹsẹ rẹ ko si abẹ ara wọn.
O le ṣe e fun iṣẹju diẹ, sinmi, ki o si tun tẹsiwaju.
Omiran tun ni pe ki o fi aya sun, ki o si gbe iku rẹ soke, pẹlu ọwọ rẹ ko di ẹọẹ rẹ mejeeji mu lati ẹyin.
Dokita sọ pe ko si asiko ti eeyan ko le ṣe ere idaraya yii, boya ni owurọ, ọsan tabi alẹ. Koda, o le ṣe nibi ti ko si ni gbangba nibi iṣẹ rẹ.
Taye Currency: Seyi Makinde fún Taye Currency lẹ́bùn ọkọ̀ bọ̀kìnnì Toyota Prado 2020
Oríṣun àwòrán, Instagram/Taye Currency
Ori lo mọ iṣẹ aṣela laye. Awọn kan yan iṣẹ orin kikọ laayo, amọ wọn o ri ṣe nibẹ nitori iṣẹ orin kọ lori ran wọn.
Ṣugbọn bii ti olorin Fuji, Ọgbẹni Taiwo Akande Adebisi ti ọpọ mọ si Taye Currency kọ nitori iṣẹ orin kikọ juu ṣe fun un.
Lopin ọsẹ yii ni Gomina ipinlẹ Oyo, Seyi Makinde fi ọkọ jiipu bọginni Toyota Prado 2020 ta a lọrẹ.
Taye Currency to fi ilu Ibadan ṣe ibugbe fi fidio ọkọ naa soju opo Instagram rẹ nibi to ti dupẹ lọwọ Gomina Makinde fun ẹbun nla to fun un.
''O ṣe Ọlọrun mi, eyi pọju. @seyi_amakinde jọ mi loju, o ya mi lẹnu. Mo dupẹ gan an fun ọkọ Toyota Prado 2020,'' ọrọ ti Taye Currency sọ niyii loju opo Instagram rẹ niyii.
Taye Currency ni ''ibukun aṣalẹ leleyi lati ọdọ Gomina ipinlẹ Oyo, Seyi Makinde.
Olorin Fuji naa gbadura pe ki Eleduwa bukun orilẹede Naijiria, ki o si tun bukun ipinlẹ Oyo.
''Omi tuntun, igba ọtun, ipinlẹ Oyo, iṣẹ ya. Mo dupẹ lọpọlọpọ,'' Taye Currency lo sọ bẹẹ.
Ẹwẹ, oṣu kejila ọdun 2019 ni Makinde yan Taye Currency gẹgẹ bi oludamọran rẹ lori ọrọ aṣa ati irinajo igbafẹ nipinlẹ Oyo.
Iroyin ti a gbọ nipe Gomina Makinde yan an sipo naa nirori iṣe takun takun to ṣe ṣaaju ibo gomina ọdun 2019 to gbe e wọlẹ gẹgẹ bi gomina ipinlẹ Oyo.
Philip Shekwo: Aága ẹgbẹ́ APC ní ìpínlẹ̀ Nasarawa tí àwọn agbébọn jí gbé ti kú
Oríṣun àwòrán, Other
Alaga ẹgbẹ oṣelu All Progressive Congress, APC, nipinlẹ Nasarawa, Philip Shekwo ti ku.
Ileeṣẹ ọlọpaa nipinlẹ Nasarawa ti fidirẹmulẹ fun BBC pe o ku lẹyin ti awọn agbebọn ji i gbe lọjọ Satide.
Agbẹnusọ fun awọn ọlọpaa nipinlẹ naa, ASP Rahman Nansel sọ pe wọn ti gbe oku rẹ lọ si ileewosan, nitori iwadii ṣi n tẹsiwaju.
Owurọ ọjọ Aiku ni BBC gbọ iroyin pe awọn agbebọn kan ji alaga ẹgbẹ osẹlu APC gbe.
Awọn ọlọpaa sọ pe ni nkan bi aago mọkanla, alẹ Satide ni wọn wọ inu ile rẹ, ti wọn si gbe e salọ.
Ati pe ni kiakia ni awọn lọ si ile naa, ti awọn ati awọn agbebọn naa si jọ doju ija kọ ara wọn, amọ wọn papa ri gbe lọ.
Ọjọ Aiku si ni wọn ri oku rẹ nibi ti ko jina si ile rẹ.
ASP Nansel sọ pe bi awọn ṣe jọ doju ibọn kọ ara awọn fihan pe awọn agbebọn naa pọ gan-an.
Iṣẹlẹ ijinigbe ko ṣẹṣẹ ma a waye ni apa Ariwa Naijiria, ati awọn ibomii.
The New Pandemic: Kíni àwọn onímọ̀ sáyẹ́ńsì ń sọ nípa rẹ̀?
Lagos State Task Force: Lóòótọ́, a tí mú Ọlọ́páà to f'ọ̀nà ẹ̀bùrú gba owó ẹ̀yìn N100k lọ́wọ́ awakọ̀
Oríṣun àwòrán, TWITTER/Taskforce112
Ọwọ palaba ọga ọlọpaa kan ti ṣegi  lẹyin to gba owo abẹtẹlẹ ẹgbẹrun lọna ọgọrun Naira lọwọ awakọ to tapa sofin oju popo nilu Eko.
Alukoro igbimọ amuṣẹya lori ọrọ ayika Adebayo Taofik lo sọ fun BBC Yoruba pe ọga ọlọpaa yi wọ gau lẹyin ti o gba owo lọwọ awakọ naa  to rufin lagbegbe Lekki Ajah.
Popoola Kayode lo pe orukọ ọga yi to si ni ọkan lara awọn ọmọ igbimọ amuṣẹya lori gbigbogun ti iwa to lodi si ofin irina nii ṣe.
Adebayo ni lẹyin toun ati awọn ọmọ iṣẹ rẹ mu awakọ obinrin kan Didi Ekanem to n gba One Way lọjọ Kejidinlogun oṣu Kọkanla, wọn gbe ọkọ rẹ lọ si Alausa ni ibamu pẹlu ofin.
O ni Kayode gbẹyin awọn ọmọ ṣẹ rẹ lati sọ fun Obinrin naa ko san owo ẹgbẹrun lọna ọgọrun Naira  ki o ba le fi ọrọ naa ṣe oku ọrun.
Ṣugbọn asiri awo yi pada tu si ọwọ awọn igbimọ amuṣẹya lọwọ lẹyin ti iwe iroyin kan gbe ọrọ bi Kayode ṣe ni ki Ekanem san owo si akoto ifowopamọ si rẹ.
Alukoro Taofik Adebayo ṣalaye siwaju pe  ọga igbimọ amuṣẹya yi Olayinka Egbeyemi sọ pe lootọ ni iroyin to gbode pe ọlọpaa ọmọ igbimọ naa lo gba owo abẹtẹlẹ.
O ni kia lawọn ti ṣe iwadii tawọn si ba owo naa lakoto rẹ.
Oríṣun àwòrán, Others
Adebayo sọ pe ọga awọn paṣẹ lẹyin ti asiri ti tu ki awọn mu Kayode lọ si ileeṣẹ ọlọpaa fun ijiya to tọ si.
''A rọ araalu lati yago fun fifi owo abẹtẹlẹ lọ awọn agbofinro wa.,Mo fẹ fi da yin loju pe ati ẹni gbe epo laja ati ẹni gbaa, awọn mejeeji ni yoo foju wina ofin.Ile ẹjọ nikan lo le sọ iye tẹni ba tapa si ofin irina yoo san, akoto ijọba si ni owo yi yoo lọ''
Bẹẹ naa lo sọ pe ki awọn ara ilu ma ṣe jafara lati fẹjọ eyikeyi ọlọpaa to ba beere owo abẹtẹ sun ni kiakia.
Oríṣun àwòrán, BSodiq
Ijọba ipinlẹ Eko ti kede pe awọn yoo ta ọkọ mẹrinlelogoji ti wọn gbẹsẹle lọwọ awọn eeyan to tapa s'ofin to rọ mọ irinajo oju popo ni ipinlẹ naa.
Agbẹnusọ gomina Babajide Sanwo-Olu, Gboyega Akosile lo kede bẹ ninu atẹjade kan to fi lede loju opo Twitter rẹ.
"O ni ""Igbimọ amuṣẹya lori ọrọ ayika ni ipinlẹ Eko fẹ fi akoko yii sọ fun awọn eeyan ilu pe, lẹyin ti a gba aṣẹ lọwọ ile ẹjọ gẹgẹ bi ilana ofin, a o lu awọn ọkọ ti a gbẹsẹle lọwọ awọn to tapa s'ofin ni gbanjo."""
O sọ pe eyi yoo si waye ni gbagede ileeṣẹ ajọ wọn wa to wa lẹyin ile itaja Shoprite, ni Ikeja.
O tẹsiwaju pe wọn gbẹsẹle awọn ọkọ naa lẹyin ti aẉon awakọ wọn tapa s'ofin irinna oju popo ti ipinlẹ Eko gbe kalẹ lọdun 2018.
Bakan naa lo tun fi orukọ ati nọmba idanimọ awọn ọkọ ti wọn fẹ lu ni gbanjo naa lede pẹlu.
Oríṣun àwòrán, Gboyega Akosile
Aworan awọn ọkọ ti ijọba fẹ lu ni gbanjo
Ṣaaju ni ijọba ipinle Eko ti kọkọ kede pe ẹnikẹni ti ọwọ ba tẹ pe o tapa s'ofin naa yoo ki ọkọ rẹ ni odigboṣe.
Lẹyin naa lo bẹrẹ si n lọgun, to si n kilọ fun awọn eeyan pe ki wọn ṣọra fun titapa si ofin irinna oju popo.Ṣugbọn ọpọ awakọ lo kọ eti ọgbọin si ikilọ naa, eyii to ṣalekun sunkẹrẹ-fakere oju popo ipinlẹ ọhun.
Akomolede ati Aṣa lori BBC:Wo ìrúfẹ́ ìgbeyàwó méje tó wà nílẹ̀ Yorùbá àti ojúṣe Alárinà
Omotara: Mo kábámọ̀ ìwà tí mo hù sí ọmọ alágbe, mo wá a títí ṣùgbọ́n mi ò mọ ibi tó wà
Oríṣun àwòrán, MOtara/instagram
Gbajumọ ori ayelujara Naijiria tiṣẹ bọ lọwọ rẹ Omotara ti ni oun kabamọ iwa aibowọfọmọlakeji ti oun hu si ọmọde alagbe kan.
Ninu fọnran fidio kan to gboju ayelujara kan la ti ri ti o ti n fi ọti ẹlẹrindodo la ọmọde yi loju ti iwa yi si mu kawọn eeyan faraya si.
Ninu ifọrọwanilẹnuwo pẹlu ileeṣẹ BBC, Omotara sọ pe lati alẹ ọjọ ti fọnran fidio naa jade loun ti n sunkun toun ko si ri orun sun.
Omotara ni: ''Mo kan fẹ tọrọ aforijin nitori gbogbo nkan to ṣẹlẹ kan n waye lera wọn ni. Mi o kan ti ẹ mọ nkan ti mo fẹ se bayi.''
''Mo ti wa ọmọ naa titi. Mo lọ lọjọ Aje, ọjọ Iṣẹgun. Titi di ba ṣe n sọrọ yi mo tun wa a lọ ti mi o si ri''
O ni bi oun ṣe n wa ọmọ naa lọ ni oun n gbe nkan lọwọ lati fun un ṣugbọn awọn ko pade.
Oríṣun àwòrán, The LadyMOTARA
Omotara ni: ''Gbogbo nkan ti mo gbe lọ bi i ọti ẹlẹrindodo niṣe ni mo maa n gbe e fawọn ti mo ba ri nibẹ.
Wọn ni wọn ti gbe ọmọ naa lọ si ilẹ Ariwa pada''
Kini o ṣẹlẹ sẹyin?
Ladugbo Ketu ni iṣẹlẹ yiti waye. Awọn eeyan ilu Eko si faraya nigba ti wọn ri fidio naa to ya ninu ọkọ rẹ to n fi ọti ẹlẹrindodo la ọmọde naa loju.
Niṣe ni Motara n fi ọmọ naa ṣe yẹyẹ bo ti ṣe n tọrọ ọti ẹlẹrindodo to si n sare tẹle ọkọ.
Eégun àti orò, bí wọ́n ṣe jọ bí Ẹ̀ṣà Egúngún nílẹ̀ Yorùba rèé
Awọn onibara to wa ni adugbo naa sọ pe awọn ko fẹ ki Omotara mọ ibi tọmọ naa wa nitori awọn ko fẹ ki nkankan ṣẹlẹ sii.
Gẹgẹ bi alaye ti Omotara ṣe pe alumajiri ni ọmọ naa.
Omotara ṣalaye siwaju fun ileeṣẹ BBC pe ''Nigba ti mo pada de ibẹ ni mo to mọ bi iwa ti mo hu ti ṣe buru to.''
Akẹkọgboye jade ni Poly Ibadan ọhun ni ''Mo ri awọn alagbe to ku ti wọn si bẹnu atẹ lu mi. Ẹbẹ ni mo ṣaa n bẹ  ki wọn maa binu si mi. Mi o mọọmọ''
"Ọmọ atapata dide lemi naa, mo si tun jẹ Kristẹni. Eelo ni mo ti ni?
Kini mo ti da laye ti maa ma fi eeyan ṣe yẹyẹ?
Oba Adedokun Abolarin ti Oke Ila: Ó ya ọ̀pọ̀ tó súnmọ́ mi lẹ́nu bí mo ṣe ń kọ́
Lowurọ oni ti i ṣe ọjọ Kẹrindinlọgbọn, oṣu Kọkanla, oju opo ayelujara Twitter gbọn akanti rẹ yọ kuro loju opo wọn tori o tako ilana Twitter ati Instagram.
Ilana to dabi ẹni pe Motara tapa si ni eleyi to ni i ṣe pẹlu''Bibu eeyan tabi didunkooko mọ ẹni keji'' tabi eyi to ni i ṣe pẹlu Bibọwọ fawọn alabase loju opo  Instagram.
Awọn ilana yii ti tako ki eeyan maa tabuku ọmọlakeji loju opo ayelujara.
Nibi tọrọ yi de bayi, awọn eeyan ilẹ Faranse naa ti mu ọrọ Omotara gbọ loju opo Twitter ti wọn si faraya gidi gan an.
Akọ́mọlédè àti Àṣà lórí BBC Yorùbá: Kọ̀ síi nípa iṣẹ́ tí oúnjẹ ń ṣe lára níbí
Aibọwọ fọmọlakeji ti koba  gbajugbaja orí ayélujára kan to fi padanu ìṣe àkànṣe olówó ńlá to n ṣe fun ileeṣẹ ọti ẹlẹrindodo Naijiria kan.
Ọrọ yi ko ṣyin bi fidio kan to ṣafihan bi o ṣe n fi ohun mimu naa la ọmọ alagbe kan to n tọrọ jẹ lọwọ rẹ loju ninu ọkọ lasiko sunkẹrẹ fakẹrẹ ṣe gbode.
Eekan ori ayelujara yii tawọn eeyan mọ si Motara fi fidio bi o ṣe n fi mínírà la ọmọdebinrin kan to n bẹ ẹ loju.
Motara si jẹ ki ọmọ yii sare le ọkọ rẹ tori ko kan le re kekere mu lara ọti ẹlẹrindodo naa.
Awọn ọmọ Naijiria ti gbana jẹ lorii fidio yii to bẹẹ tawọn kan n wọn kobiewu epe fun gbajugbaja ori ayelujara yii.
Oríṣun àwòrán, Twitter screenshot
Mílíọ́nù mẹ́wàá Náírà ni ilé ẹjọ́ ni kí Kábíyèsí san gẹ́gẹ́ bí owó ìtaran ilẹ̀ tí ó gbà lọ́nà àìtọ́
Wo ọ̀nà tí ọrọ̀ ajé Naijiria tó dẹnu kọlẹ̀ gba kàn ọ
Ẹran ara ọlọ́pàá di èkìrí ẹran súyà, wo àwọn tó jẹ́ níbẹ́..
Wọ́n ti rí òkú Alága ẹgbẹ́ APC ní Nasarawa tí àwọn agbébọn jí gbé lọ́jọ́ Satide
Oríṣun àwòrán, Twitter screenshot
Fidio to tan kalẹ yii jade lẹyin ọjọ diẹ ti Motara ṣẹṣẹ kọ itan soju opo rẹ to n ṣalaye bi nkan ṣe le fun oun ati iya rẹ ti iya n kiri ọja loju popo ko to wa di pe papa oko rẹ di tutu to di ọlọrọ.
Lawọn eeyan ba n fọnmu pe loun to mọ aawọ iṣẹ to si tọ ọ wo daadaa, ko yẹ ki Motara ṣe ọmọbinrin kekere yẹn bẹẹ.
Oríṣun àwòrán, The LadyMOTARA
Arabinrin Motara to n gbe niluu Ibadan yii fi sita pẹlu alaye pe oun kan n mu ọmọ naa ṣere ni ati pe oun pada fun un lowo.
Ṣugbọn alaye yii ko dabii pe o tẹ awọn ileeṣẹ to n ṣe ọti ẹlẹrindodo ti  Motara fi n la ọmọ naa loju lọrun.
Ileeṣẹ Brothers Keeper to  n ṣe ọti naa eyi ti Mọtara mu lọwọ ninu fidio ọhun ti fi atẹjade sita gbangba pe awọn yoo da gbajugbaja ori ayelujara yii duro gẹgẹ bii alukoro ati agbẹnusọ ileeṣẹ awọn.
Oríṣun àwòrán, Twitter screenshot
Ileeṣẹ naa kọjalẹ pe ohun ti Motara ṣe lodi si igbagbọ ati afojusun awọn pe o n foju tẹmbẹlu  eeyan.
Ni idahun, Motara ti fi ọrọ itọrọ aforiji sita fawọn ololufẹ rẹ pe oun ro pe ẹfẹ lohun ti oun ṣe yoo mu wa ni amọ oun tọrọ aforiji.
Ko jẹ bo ṣe jẹ, awọn ọmọ Naijiria ti n wa ọna ati kowojọ lati mu ọmọdebinrin alagbe naa kuro loju popo ki wọn si ran an lọ ileewe.
Oríṣun àwòrán, Twitter screenshot
Ìjọba Naijiria faraya nínú lẹ́tà tó kọ sí CNN lórí ìwádìí rẹ̀ nípa ìṣẹ̀lẹ̀ Lekki Toll Gate
Iṣu ata yáan yàan! Iṣẹ́ fẹ́ bọ́ lọ́wọ́ ọlọ́pàá tó gba N100k lọ́wọ́ awakọ̀ tó gbaOne way"" l'Eko"
Kíni àjọ ọlọ́pàá ń ṣe lórí bí agbófinró ṣe ń ṣèèṣì pànìyan lójoojúmọ́?
Wọ́n ti fòfin ọdún márùn ún de Aàrẹ̀ CAF, Ahmad Ahmad
Oríṣun àwòrán, Twitter screenshot
UK Parliament on Nigeria: Geoffrey Onyeama ni aṣofin UK kò lágbára láti sọ̀rọ̀ lórúkọ ìjọba UK
Oríṣun àwòrán, @Geoffrey
Minista fun ọrọ ilẹ okeere ni Naijiria, Geoffrey Onyeama ti fesi pada fun awọn aṣofin United Kingdom pada lori ọrọ idajọ ifiyajẹni lasiko iwọde EndSars ni Naijiria.
Geoffrey Onyeama dahun si ibeere lori ọrọ idajọ awọn aṣofin UK lasiko to n ba awọn akọroyin sọrọ nilu Abuja to jẹ olu ilu Naijiria ni ọjọru.
"O ni: "" A ti kàn si awọn ijọba UK lori ọrọ yii, ohun ti mo ro ni pe ipade naa jẹ ti awọn aṣofin UK ni kii ṣe agbẹnusọ ti ijọba."
"Awa naa si ti n ba wọn fikunlukun, a ti ṣalaye ipa ti ijọba Naijiria ko lori iwọde #EndSars naa fun awọn to yẹ ninu ijọba UK pẹlu ohun to ṣẹlẹ ni pato""."
Oba Adedokun Abolarin ti Oke Ila: Ó ya ọ̀pọ̀ tó súnmọ́ mi lẹ́nu bí mo ṣe ń kọ́
Onyeama ni ohunkohun to ba wu aṣofin kọọkan lo le fi ẹnu ara rẹ sọ nigba to ba wu u ṣugbọn kii ṣe lati sọ ero ara rẹ lorukọ ijọba UK.
O ni ohun to ṣe pataki ni lati rii pe idajọ ti ijọba ba fẹ ṣe ko ṣegbe fẹnikan tabi fi sibi ti ko yẹ ko fi si.
Ati pe, o di dandan fun ijọba Naijiria lati pese awọn ohun eelo iwadii lori bi iṣẹlẹ naa ṣe ṣẹlẹ gangan fun awọn to yẹ ninu ijọba ki wọn to gbe igbesẹ kankan.
Ọrọ yii n waye lẹyin ti awọn Asofin UK jiroro lori ijiya to yẹ fun ẹnikẹni ni ijọba tabi ninu awọn agbofinro ti ade iwa ibajẹ ohun ti iwadii ba fihan pe o ṣẹlẹ ninu iwọde #EndSars loṣu kẹwaa, ọdun yii ba ṣi mọ lori ni Naijiria.
Theresa Villers, okan ninu awọn aṣofin ni UK lo fi to awọn to ku rẹ leti pe awọn eeyan 220, 330 lo ti buwọlu iwe ẹsun naa ni eyi to fun wọn ni aṣẹ lati gbe e yẹwo.
Wọn ni ki ijọba UK ronu igbesẹ to yẹ ni gbigbe lati fiya jẹ awọn alaṣẹ Naijiria to ba tapa si ẹtọ ọmọniyan lasiko iwọde naa ni Naijiria.
Ilé aṣòfin orílẹ̀-èdè UK  n gbèrò fífí ìyà jẹ àwọn adarí Naijiria tó lọ́wọ́ nínú rògbòdìyàn ENDSARS
Àwọn aṣòfin UK ṣetán láti fìyà jẹ àwọn adarí Naijiria tó lọ́wọ́ nínú rògbòdìyàn ENDSARS
Ile aṣofin ilẹ Gẹẹsi, ti n jiroro lori iwe ipẹjọ kan ti wọn si n gbero lati fiya jẹ awọn alaṣẹ Naijiria to ba lọwọ ninu ipaniyan ENDSARS.
Ọjọ Aje ni ile aṣofin naa fẹnuko ninu idibo pe ijiya yoo wa fun awọn olori ijọba to lọwọ ninu lilo ipa lori awọn oluwọde alaafia naa, ni ogunjọ, oṣu Kẹwaa.
Eeyan to le ni ẹgbẹrun lọna igba lo fọwọ si iwe ẹsun naa pe ki ajọ Commonwealth fiya jẹ awọn adari Naijia
Wọn ni fifi iya jẹ orilẹ-ede Naijiria lapapọ yoo pa awọn ọmọ Naijiria lara.  Nitori naa ni wọn ṣe fẹ ki ijọba wadii awọn to lọwọ si iṣẹlẹ naa.
Awọn ọmọ ile aṣofin naa tun koro oju si iṣejọba Aarẹ Muhammadu Buhari, fun bo ṣe n kọlu awọn to kopa ninu iwọde ENDSARS, to tun n dẹruba wọn.
Akọ́mọlédè àti Àṣà lórí BBC Yorùbá: Kọ̀ síi nípa iṣẹ́ tí oúnjẹ ń ṣe lára níbí
Idibo naa waye, nitori iwe ẹsun kan ti awọn ọmọ Naijiria to le ni ẹgbẹrun lọna igba (220,000) fi ọwọ si
Awọn aṣofin naa n fẹ ki ijọba United Kingdom ṣe iwadii awọn ẹsun aṣilo agbara, ati awọn olori ijọba ni Naijiria to lọwọ si ipaniyan to waye ni Lekki nipinlẹ Eko.
Bakan naa ni wọn koro oju si ijọba ṣe gbẹsẹ le apo asunwọn awọn oluwọde naa.
Wọn tun jiroro lori ipa ti UK n ko ninu eto ẹkọṣẹ ati tita nakn ijagun fun ileeṣẹ alaabo Naijiria.
Ijiya to ṣe e ṣe ko waye fun awọn alakoso ijọba ati eleto aabo, ni fifi ofin de irinajo wọn silẹ okeere, ati gbigbẹsẹ le dukia wọn.
Oríṣun àwòrán, @Falz
Ijọba Naijiria ko ti i fi igba kan sọ pe lootọ ni awọn eleto aabo yinbọn mọ awọn oluwọde naa.
Ọjọ kejila, oṣu Kọkanla, ọdun 2020, ni ijọba orilẹ-ede United Kingdom, ti fesi si iwe ẹsun ti awọn ọmọ Naijiria kọ si.
Awọn eeyan naa n fẹ́ ki ajọ commonwealth fiya to tọ si ẹni to ba tapa si ẹtọ ọmọniyan, jẹ awọn adari Naijiria.
Awọn oluwọde ENDSARS ba BBC sọrọ
Ile aṣofin United Kingdom si fesi pe rogbodiyan to waye lasiko iwọde ENDSARS kọ oun lomiinu.
Ati pe oun n duro de abajade iwadii ijọba Naijiria lori ẹsun ifiyajẹni ti wọn fi kan awọn ọlọpaa.
Oba Adedokun Abolarin ti Oke Ila: Ó ya ọ̀pọ̀ tó súnmọ́ mi lẹ́nu bí mo ṣe ń kọ́
Akọ́mọlédè àti Àṣà lórí BBC Yorùbá: Kọ́ síi nípa iṣẹ́ tí oúnjẹ ń ṣe lára níbí
Iyan lounjẹ, ọka loogun, airi rara la n jẹ ẹkọ...
Oriṣiriṣi ounjẹ ni Yoruba n jẹ fun idagbasoke ara wọn.
Awọn ounjẹ ile Yoruba ni koko ti a n gbe yẹwo lonii lori eto akomolede ati Asa lori BC Yoruba.
Arabinrin Stella Adedeji lati ile iwe CAC Grammar school ni ilẹ Olujii ni ipinlẹ Ondo to wa ni iwọ oorun guusu Naijiria ni olukọ wa fun toni.
Oríṣun àwòrán, others
Awọn ire oko ilẹ Yoruba pọ, bẹẹ naa si ni irufẹ ounjẹ ti a le ri lara wọn kọ sisọ.
Olukọ wa kọ wa ni kikun nipa oriṣi isọri ounjẹ bii ounjẹ Oniyọ, ounjẹ Ẹlẹran/ Ọlọra, ounjẹ Asemiro, ounjẹ Afaralokun ati ounjẹ amaradan to wa.
Oríṣun àwòrán, others
Wo awọn nkan ti a le fi ẹgẹ, iṣu ati eree ṣe sii nibi.
Pe awọn ọmọ rẹ ki wọn wa kọ e\kọ loni lori eto Akomolede ati Asa lori BBC Yoruba
Oríṣun àwòrán, others
Grammy awards 2021 - Burna Boy, Beyoncé, àti Dua Lipa, wà lára àwọn ti wọ́n fi orúkọ wọn sílẹ̀
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Igba akọkọ kọ niyii ti wọn yoo fi orukọ Burna Boy silẹ fun ami ẹyẹ Grammy, amọ ko gba a ri
Wọn ti fi orukọ akọrin, ọmọ Naijiria, Burna Boy, silẹ fun ami ẹyẹ Grammy fun ọdun 2021.
Awo orin rẹ, 'Twice as Tall', ni wọn fi orukọ rẹ silẹ fun, ni iṣọri orin to dara julọ ni agbaye, Best Global Music Award.
Isọri naa wa fun awọn awo orin to ni o kere tan, ìdá mọkanlelaadọta ohùn orin igbalode.
Burna Boy ati akọrin mẹrin miran ni wọn jọ fi orukọ wọn silẹ fun isọri yii.
FU CHRONICLES
Antibalas
TWICE AS TALL
Burna Boy
AGORA
Bebel Gilberto
LOVE LETTERS
Anoushka Shankar
AMADJAR
Tinariwen
Akọ́mọlédè àti Àṣà lórí BBC Yorùbá: Kọ̀ síi nípa iṣẹ́ tí oúnjẹ ń ṣe lára níbí
Igba wo lo maa waye?
Ọjọ kọkanlelọgbọn, oṣu Kinni, ọdun 2021, ni eto ami ẹyẹ Grammy yoo waye.
Ohun si ni ikẹtalelọgọta ti yoo waye, pẹlu isọri ami ẹyẹ ọgọrin.
Ṣugbọn ko ti i si aridaju lori bi eto naa yoo ṣe lọ, tabi awọn akọrin ti yoo ṣere nibẹ, nitori aarun covid-19.
Awọn isọri to ku ni
1.Awo orin fun ọdun 2020
BLACK PARADE
Beyoncé
Beyoncé & Derek Dixie, olootu; Stuart White, omojuẹrọ/alasopọ orin; Colin Leonard, amojuẹrọ
COLORS
Black Pumas
Adrian Quesada, olootu; Adrian Quesada, amojuẹrọ/alasopọ orin; JJ Golden, amojuẹrọ
Oba Adedokun Abolarin ti Oke Ila: Ó ya ọ̀pọ̀ tó súnmọ́ mi lẹ́nu bí mo ṣe ń kọ́
ROCKSTAR
DaBaby Featuring Roddy Ricch
"SethinTheKitchen, olootu; Derek ""MixedByAli"" Ali, Chris Dennis & Liz Robson, amojuẹrọ/alasopọ orin; Susan Tabor, amojuẹrọ"
SAY SO
Doja Cat
Tyson Trax, olootu; Clint Gibbs, amojuẹrọ/alasopọ; Mike Bozzi, amojuẹrọ
EVERYTHING I WANTED
Billie Eilish
Finneas O'Connell, olootu; Rob Kinelski & Finneas O'Connell, amojuẹrọ/alasopọ orin; John Greenham, amojuẹrọ
DON'T START NOW
Dua Lipa
Caroline Ailin & Ian Kirkpatrick, olootu; Josh Gudwin, Drew Jurecka & Ian Kirkpatrick, amojuẹrọ/alasopọ orin; Chris Gehringer, amojuẹsrọ
CIRCLES
Post Malone
Louis Bell, Frank Dukes & Post Malone, olootu; Louis Bell & Manny Marroquin, amojuẹrọ/alasopọ orin; Mike Bozzi, amojuẹrọ
SAVAGE
Megan Thee Stallion Featuring Beyoncé
Beyoncé & J. White Did It, olootu; Stuart White, amojuẹrọ/alasopọ orin; Colin Leonard, amojuẹrọ
Ẹ wo ẹkunrẹrẹ orukọ nibi
Ilé ẹjọ́ tú ìgbéyàwó ọdún mẹ́wàá ká nítorí ẹ̀sùn ìbálòpọ̀ ọlọ́jọ́ gbọọrọ àti òògùn owó
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ile ẹjọ ibilẹ Mapo nilu Ibadan, ti tu igbeyawo ọlọdun mẹwa kan, nitori ẹsun ibalopọ alainigbedeke, ati oogun owo.
Iyawo, Basirat Adeyoyin lo gbe ọkọ rẹ, Adeyoyin Niyi lọ sile ẹjọ, to si fi ẹsun kan an pe o fẹ fi oun ṣe oogun owo.
Ninu ọrọ to sọ nile ẹjọ, Basirat ni ara bẹrẹ si ni fun oun , nigba ti ọkọ oun (Niyi) ko ṣe idaro lẹyin ti oun padanu oyun, nitori pe ibalopọ ti awọn n ni ti pọju.
"O ni ""Ninu ọdun 2018, Niyi dele lọjọ kan, lo ba sọ fun mi pe wọn riran si oun  pe oun gbọdọ ni ibalopọ fun ọjọ meje gbako, lai fi pa ọjọ kankan jẹ."
Emi naa ba gba fun, lai jiyan pẹlu rẹ, ti mi o si ronu pe yoo lẹyin.
Arabinrin Basirat ṣalaye pe oyun oṣu mẹta ti wa ninu oun ṣaaju asiko ibalopọ naa.
Ṣugbọn, oun padanu oyun naa ni ọjọ keji ti awọn bẹrẹ ibalopọ ọlọjọ meje.
"Fun'ra mi ni mo tọju ara mi nileewosan.
Oba Adedokun Abolarin ti Oke Ila: Ó ya ọ̀pọ̀ tó súnmọ́ mi lẹ́nu bí mo ṣe ń kọ́
Iyalẹnu si lo jẹ bi Niyi ṣe sọ fun mi pe ki a tẹsiwaju pẹlu ibalopọ naa, lai fi ti ẹjẹ to ṣi n jade lara mi ṣe."""
Basirat sọ pe oun fi ọrọ naa lọ awọn obi ati ẹbi oun. Gbogbo apẹẹrẹ lo si fihan pe Niyi fẹ ẹ fi oun ṣe oogun owo ni.
Nitori iṣẹlẹ yii ni Basirat ṣe gbe Niyi lọ sile ẹjọ pe ki wọn o tu igbeyawo wọn ka.
Ṣugbọn nigba to n sọrọ nile ẹjọ, Niyi ni lootọ ni oun beere fun ibalopọ ọlọjọ gbọọrọ.
"Amọ ẹsun miran lo fi kan iyawo rẹ pe ""iyawo oun buru ju nkan ti agbara oun ka lọ, ati pe kii ka nkan si""."
O ni ki ile ẹjọ ko awọn ọmọ mejeeji ti awọn bi fun oun, ti wọn ba tiẹ fẹ tu igbeyawo ka, nitori pe Basirat ko le mojuto wọn.
O ṣalaye pe ọmọkunrin kan ni adugbo ti wọn n gbe ti fi ipa ba ọmọ rẹ akọbi lo ri, ti Basirat ko si sọ fun oun.
O ni isẹlẹ naa waye nitori pe iya wọn ma n pẹ ko to o kuro ni ibi to ti n ta ọja.
Akọ́mọlédè àti Àṣà lórí BBC Yorùbá: Kọ̀ síi nípa iṣẹ́ tí oúnjẹ ń ṣe lára níbí
Ninu idajọ rẹ, Adajọ ile ẹjọ naa, Onidajọ Odunade Ademola sọ pe ile ẹjọ naa ko ni i ma woran, titi wahala yoo fi ṣẹlẹ ki oun to gbe igbesẹ to yẹ.
Lẹyin naa lo tu igbeyawo naa ka, ki alaafia le jọba.
Bakan naa lo ko awọn ọmọ mejeeji fun Basirat. Amọ o paṣẹ fun Niyi lati ma a fun wọn ni ẹgbẹrun mẹwa, loṣooṣu fun owo ounjẹ.
Yoo si tun ma a san owo ileewe wọn, ati bukaata to ku.
'Bí aya bá kọ ọkọ rẹ̀ silẹ̀, kó wà láì lọ́kọ̀'
Senator Ishaku Abbo: ìdí rèé tí mò fi fi kọ̀wé fi PDP sílẹ̀ darapọ̀ mọ́ ẹgbẹ́ òṣèlú APC
Oríṣun àwòrán, senatorishakuabbo
Sẹnẹtọ Elisha Abbo, ti wọn fi ẹsun kan pe o lu obinrin kan nile itaja eroja ibalopo nilu Abuja ti fi ẹgbẹ oṣelu PDP silẹ.
Sẹnẹtọ naa to n soju ẹkun idibo Ariwa ipinlẹ Adamawa sọ pe oun darapọ mọ APC nitori gomina ipinlẹ naa Umaru Fintiri to n dari ẹgbẹ radarada.
Lowurọ ọjọru lo fi ọrọ yi lede ninu iwe to ka seti igbọ awọn ọmọ ile aṣofin agba nilu Abuja.
Kete to kede ọrọ yi lawọn ọmọ ẹgbẹ APC to wa nile figbe bọ nu lati baa yọ pe o darapọ mọ awọn.
Yatọ si ọrọ Gomina to ni ko dari ẹgbẹ bo ti ṣe yẹ, Abbo ni Aarẹ Buhari jẹ iwuri foun nipa pe o kara mọ arisiki awọn ara ilu ju gbogbo awọn aarẹ ti tẹlẹ lọ.
''Loni mo darapọ mọ ẹgbẹ APC ati aarẹ Muhammadu Buhari lati jijọ pawọpọ gbe Naijiria ga''
Ninu alaye to ṣe ninu iwe to ka sita, Abbo tun sọ pe lati igba ti Naijiria ti pada si ijọba awarawa lọdun 1999, ko ti si aarẹ to mu ọrọ arailu lọkunkundun bi ti Buhari.
Iwa fifi ẹgbẹ kan silẹ lati lọ darapọ mọ ẹgbẹ mii jẹ eleyi tawọn oloṣelu Naijiria fẹran lati maa ṣe.
Oríṣun àwòrán, senatorishakuabbo
Yatọ si awọn aṣofin awọn tara ilu dibo yan gẹgẹ bi Gomina naa a maa hu iru iwa yi.
Laipẹ yi ni Gomina ipinlẹ Ebonyi, David Umahi da họwuhọwu silẹ pẹlu bo ti ṣe fi ẹgbẹ PDP silẹ lati lọ darapọ mọ ẹgbẹ oṣelu APC to wa lori oye.
Oba Adedokun Abolarin ti Oke Ila: Ó ya ọ̀pọ̀ tó súnmọ́ mi lẹ́nu bí mo ṣe ń kọ́
Free Pad: Scotland ti di orílẹ̀-èdè àkọ́kọ́ tó bẹ́rẹ̀ pínpín páàdì ǹkan osu fún gbogbo obìnrin lọ́fẹ̀ẹ́
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Orílẹ̀-èdè Scotland ti di orílẹ̀-èdè àkọ́kọ́ to n pin ìlédìí ìkàn oṣù lọ́fẹ̀ẹ́ fún gbogbo obìnrin.
Lọ́jọ́ Iṣẹ́gun ọsẹ̀ yìí ni àwọn ọmọ ilé ìgbìmọ̀ aṣòfin dìbò láti gba àbá náà wọle kí ó le di òfin tí ará ìlú yóò tẹ̀lé (Free Provison Scotland)
"Èyí túmọ̀ sí pé, ojúṣe ìjọba ìbílẹ̀ ni láti máa pèsè àwọn páàdì yiìí fún gbogbo ẹni to ba nílò rẹ̀."""
Ọmọ ilé asofin lábẹ́ ẹgbẹ́ òṣèlú Labour Monica Lennon to ti jàjàjà lóri òṣì lásìkò ǹkan oṣù yìí lati ọdun 2016 sàlàyé pé àjàkálẹ̀ ààrùn Corornavirus  ti sọ ọ dí dandan báyìí.
Òṣì lásìkò ǹkan oṣù máa n wáye ti àwọn ènìyàn kò bá níṣẹ́ tó n mówó jáde láti ra àwọn páàdì ǹkan oṣù tó jẹ́ ojúlówó.
Ìwádìí kan ti Young Scot ṣe fáwọ̀n akẹ́kọ̀ọ́ fi idí rẹ̀ múlẹ̀ ọkan nínú àwọn akẹ́kọ̀ọ́ mẹ́rìn ń tiraka lati ra ìléèdí ǹkan oṣù ni.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Wọ́n ń pinnu láti máa pín àwọn ìledìí yìí, bi wọ́n ṣe máá n pín kọndọọmu fáwọn ọkùnrin nílé iwé gírámà àti ni fásitì, ilé ìwòsàn ti wọ́n bá ti ṣíṣẹ́ abẹ, àti ni àwọn ibi ti wọ́n ti n ta oogun, yálà ki wọn lọ bèrè fún tàbi ki wọ́n kọọ síwèé.
Gbogbo àgbáyé ni olúkúlùkù tí n wá ọ̀nà láti fòpin si òṣì lágbègbè wọ́n.
Ní ilẹ̀ Gẹ́ẹ̀sì, wọ́n fun àwọn ọmọ ilé iwé alákọ̀ọ́bẹ̀rẹ̀ àti girama ni inú oṣù kíní ọdún.
Oba Adedokun Abolarin ti Oke Ila: Ó ya ọ̀pọ̀ tó súnmọ́ mi lẹ́nu bí mo ṣe ń kọ́
Àwọn ìpińlẹ̀ kan ni Amẹrika, naa ti sọọ di ofin pe ki wọ́n maa fun awọn akẹ́kọ̀ọ́ ni iléèdi nkan oṣù lọ́fẹ̀ẹ́.
Kódà, orílẹ̀-èdè Nàìjíríà ti darapọ̀ mọ́ àwọn kan lágbàyé, bi wọn ṣe yọ owó orí kúrò nínú àwọn èròjà ǹkan osu.
Orílẹ̀-èdè bí Kenya, Canada, Australia, India, Colombia, Malayhsia, Nicaragua, Jamaica, Uganda, Lebanon àti Trinidad & Tobego náà ti yọwó orí nínú ìléèdí obìnrin
Akọ́mọlédè àti Àṣà lórí BBC Yorùbá: Kọ̀ síi nípa iṣẹ́ tí oúnjẹ ń ṣe lára níbí
Fatai Rolling Dollar: Baba 70 jayé kọjá 70 kó tó dágbére fáyé pé ó dìgbóṣe!
Oríṣun àwòrán, Google
Fatai Rolling Doller, àgbà ọ̀jẹ̀ olórin tí ọ̀dọ́ ń wò ní àwòkọ́ṣe rere
Fatai Rolling Dollar: Baba 70 jayé kọjá 70 kó tó dágbére
Wọn kere si Number, Ori wa a dara, Saworo, Eko Akete, Baba Wa, To ba fe mo Dollar, Aduke, Feso Jaiye, Iyawo Ma pa mi...
Melo la fe ka leyin adipele.
A o lee fọwọ kọ gbogbo orin ti oloogbe ilumọọka olorin ọmọ Yoruba, Olayiwola Fatai Olagunju, Fatai Rolling Dollar tí ọpọlọpọ si mọ si Baba 70 kọ.
Wo igba ewe Fatai Rolling Doller:
Gẹgẹ bi ọmọ idile oye, wọn bi i lọdun 1927 si idile Oloye Olagunju ni Ede, ipinlẹ Oṣun.
Lọdọ awọn akẹgbẹ rẹ akẹkọọ lo ti ri alajẹ orukọ to n jẹ, nigba naa lọhun o ṣi jẹ bii ọmọ ọdun mẹsan an pere.
Eyi waye tori bo ṣe ni iwa ko ṣa a ma a ko owo shile meji ti baba rẹ maa n fun un  gẹgẹ bii owo ti yoo fi ra nkan awọn aburo rẹ meji nigba ti baba wọn ba ti ṣe iṣẹ lọ si Ghana gẹgẹ bii awakọ.
Oríṣun àwòrán, Google
Owó Shile meji yii pọ ju oun ti awọn ẹlẹgbẹ rẹ maa n ni lọwọ nigba yẹn torinaa ni wọn ṣe kuku fi jẹ oye ẹni ti yoo maa yi owo ẹyọ onidẹ lasiko ti wọn ba fẹ gba eree bọọlu.
Nibo ni Fatai Rolling doller kawe de?
Ko lee lọ ileewe mọ lọdun 1944 nigba ti baba rẹ ku, lo ba bẹrẹ si ni kọ iṣẹ mọkaliiki.
Fatai  Rolling Dollar gba ọna ojú omi sa lọ pelu ọkọ ojú omi kan nigba to wa lọmọ ọdun mokandinlogun.
Eyi to mu ki iya rẹ ni ki wọn ti i mọ ile ẹ̀kọ́ṣe kan nitori iwa ipanle rẹ.
Nibẹ lo ti kọ iṣẹ ọwọ tuntun nípa orin kiko sugbọn nigba to sú u, o pinnu láti bẹ̀rẹ̀ isẹ orin kíkọ.
Bawo ni Fatai Rolling Doller ṣe bẹrẹ iṣe orin gangan?
"Bo ṣe bẹ̀rẹ̀ gẹgẹ bii alu ohun eelo orin ninu gbajugbaja ẹgbẹ́ olorin ""Kokomba bands"" ni 1940s niyii."
"Nigba ti aṣọ Kokomba bands ko wọ igba mọ, lo ba bẹrẹ si ni lu ìlù ""Agidigbo""."
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Kini o ṣẹlẹ si Rolling Doller ni ilu Eko?
"Lẹyin ìgbà díẹ̀ to ṣe laalaa nilu Eko, o ri isẹ lati maa lu Agidigbo pẹlu ẹgbẹ́ ""Willie Payne band"" lẹ́yìn eyi to darapọ mọ ẹgbẹ́ akọrin  ""JO Araba band"" lọdun 1953."
Ogo rẹ bá bẹ̀rẹ̀ si nii tán, o bẹ̀rẹ̀ si ni ṣeré orin lori itage fún iléese Nigeria Broadcasting Corporation.
Amosa, pupọ owó tó bá wọlé nígbà náà lọhun, ọwọ oga orin lo máa ń lọ táwọn ọmọṣe elegbe kan máa ń rí taataata.
"Ìhà ti Fatai yara kọ sí eyi ni pe o bẹ̀rẹ̀ si kọ ara rẹ bí wọn ṣe ń lu ohun eèlò orin ""gìtá"" eyi to bẹ̀rẹ̀ lọdun 1955 pẹlu gita tí kii lo batiri tabi iná ayafi afẹ́fẹ́."
Bawo ni ẹgbẹ Fatai Rolling Doller ṣe bẹrẹ?
"Fẹrẹẹ, nigba to fi di ọdun 1957, o ti da ẹgbẹ́ ""Fatai Rolling Dollar & African Rhythm Band"" silẹ."
Ko si pẹ rara lẹyin eyi, wọn ti bẹ̀rẹ̀ si ni ṣe àwo orín fun ilé isẹ Philips West Africa Record ti wọn si ti fi orúkọ ẹgbẹ́ rẹ silẹ láti ṣeré lọjọ òmìnira orílẹ̀èdè Naijiria lọdun 1960.
Lara awọn àgbà olorin to tun jẹ gbajugbaja to darapo mọ ẹgbẹ́ orin Fatai Rolling Dollar lọdun 1958 ni Ebenezer Obey, to di ọkan gbòógì lára àwọn Irawọ olorin Juju ni Naijiria.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Obey padà fi ẹgbẹ́ Fatai silẹ pẹlu awọn ọmọ ẹgbẹ́ mẹfa míì lọdun 1963. Fatai Rolling Dollar, Ọmọ ìdílé oyè tó gbé igbá ori
Fatai Rolling Dollar: Baba 70 kú nígbà tó ku ọdún kan kó pé 70.
Wọn kere si Number, Ori wa a dara, Saworo, Eko Akete, Baba Wa, Toba fe mo Dollar, Aduke, Feso Jaiye, Iyawo Ma pa mi...
Cancer: Àṣe ara mi ni iso ti n run gbogbo bí mo ṣe n ṣèrànwọ́ lórí jẹjẹrẹ
Meloo la fe ka leyin adipele. A o lee fọwọ kọ gbogbo orin ti oloogbe ilumọọka olorin ọmọ Yoruba, Olayiwola Fatai Olagunju, Fatai Rolling Dollar tí ọpọlọpọ si mọ si Baba 70 kọ.
Gẹgẹ bi ọmọ idile oye, wọn bi i lọdun 1927 si idile Oloye Olagunju ni Ede, ipinlẹ Oṣun.
Lọdọ awọn akẹgbẹ rẹ akẹkọọ lo ti ri alajẹ orukọ to n jẹ, nigba naa lọhun o ṣi jẹ bii ọmọ ọdun mẹsan an pere.
Eyi waye tori bo ṣe ni iwa ko ṣaa maa ko owo shile meji ti baba rẹ maa n fun gẹgẹ bii owo ti yoo fi ra nkan awọn aburo rẹ meji nigba ti baba wọn ba ti ṣe iṣẹ lọ si Ghana gẹgẹ bii awakọ.
Oríṣun àwòrán, Google
Owó Shile meji yii pọ ju oun ti awọn ẹlẹgbẹ rẹ maa n ni lọwọ nigba yẹn torinaa ni wọn ṣe kuku fi jẹ oye ẹni ti yoo maa yi owo ẹyọ onidẹ lasiko ti wọn ba fẹ gba eree bọọlu.
Ko lee lọ ileewe mọ lọdun 1944 nigba ti baba rẹ ku, lo ba bẹrẹ si ni kọ iṣẹ mọkaliiki.
Fatai  Rolling Dollar gba ọna ojú omi sa lọ pelu ọkọ ojú omi kan nigba to wa lọmọ ọdun mokandinlogun eyi to mu ki iya rẹ ni ki wọn ti i mọ ile ẹ̀kọ́ṣe kan nitori iwa ipanle rẹ.
Nibẹ lo ti kọ iṣẹ ọwọ tuntun nípa orin kiko sugbọn nigba to sú u, o pinnu láti bẹ̀rẹ̀ isẹ orin kíkọ.
"Bo ṣe bẹ̀rẹ̀ gẹgẹ bii alu ohun eelo orin ninu gbajugbaja ẹgbẹ́ olorin ""Kokomba bands"" ni 1940s niyii."
Oríṣun àwòrán, Getty Images
"Nigba ti aṣọ Kokomba bands ko wọ igba mọ, lo ba bẹrẹ si ni lu ìlù ""Agidigbo""."
"Lẹyin ìgbà díẹ̀ to ṣe laalaa nilu Eko, o ri isẹ lati maa lu Agidigbo pẹlu ẹgbẹ́ ""Willie Payne band"" lẹ́yìn eyi to darapọ mọ ẹgbẹ́ akọrin  ""JO Araba band"" lọdun 1953."
Ogo bá bẹ̀rẹ̀ si nii tán, o bẹ̀rẹ̀ si ni ṣeré orin lori itage fún iléese Nigeria Broadcasting Corporation,
Amosa, pupọ owó tó bá wọlé nígbà náà lọhun, ọwọ oga orin lo máa ń lọ táwọn ọmọṣe elegbe kan máa ń rí taatata.
Oba Adedokun Abolarin ti Oke Ila: Ó ya ọ̀pọ̀ tó súnmọ́ mi lẹ́nu bí mo ṣe ń kọ́
"Ìhà ti Fatai yara kọ sí eyi ni pe o bẹ̀rẹ̀ si kọ ara rẹ bí wọn ṣe ń lu ohun èlò orin ""jita"" eyi to bẹ̀rẹ̀ lọdun 1955 pẹlu jita tí kii lo batiri tabi iná ayafi afẹ́fẹ́."
Fatai Rolling Dollar pẹlu ohun ti gbogbo eeyan fi mọ ọ jẹ gbajugbaja olorin to ma n ta jita pọ mọ orin kíkọ ó sì tun jẹ ó onímọ̀ nípa duuru ibilẹ Yoruba to ń jẹ Agidigbo.
Oun ni aye mọ ni agba ọjẹ ninu awọn orin ibilẹ ilẹ̀ Afirika (African Folk Music) ti wọn si tun mọ ọ ní ọkan ninu awọn ọba orin igbalode ni Iwọ-Oorun Afirika.
O ti kọrin débi ti oun ati ẹgbẹ orin to wa nigba naa kọ orin awọn ẹlẹmu orílẹ̀èdè Ghana si ilu highlife ti ilẹ Yoruba eyi si jẹ ẹkọ nla fáwọn ọmọ lẹyin rẹ.
Oríṣun àwòrán, Google
"Fẹrẹẹ, nigba to fi di ọdun 1957, o ti da ẹgbẹ́ ""Fatai Rolling Dollar & African Rhythm Band"" silẹ."
Ko si pẹ rẹ, wọn ti bẹ̀rẹ̀ si ni ṣe àwo orí fun ilé isẹ Philips West Africa Record ti wọn si ti fi orúkọ ẹgbẹ́ rẹ silẹ láti ṣeré lọjọ òmìnira orílẹ̀èdè Naijiria lọdun 1960.
Lara awọn àgbà olorin to tun jẹ gbajugbaja to darapo mọ ẹgbẹ́  orin Fatai Rolling Dollar lọdun 1958 ni Ebenezer Obey, to di ọkan gbòógì lára àwọn Irawọ olorin Juju ni Naijiria.
Obey padà fi ẹgbẹ́ Fatai silẹ pẹlu awọn ọmọ ẹgbẹ́ mẹfa míì lọdun 1963.
Ṣe wahala wá ti ọkọ bá kọ̀ láti fún aya tó ti kọ̀ silẹ lára ogún rẹ?
Ṣùgbọ́n ẹgbẹ́ orin yìí sì ń tà wàrà wàrà títíi 1960s kanlẹ̀ amọ ti yoo fi di ipari 60s, awọn ẹ̀yà orin Juju míì tó ń jáde bẹ̀rẹ̀ si ni bo irawọ rẹ mọ́lẹ̀ nitorinaa láti rí jẹ,
O bẹ̀rẹ̀ si nii ṣòwò yiya awọn eeyan ni awọn irinṣẹ rẹ lágbègbè Moshalashi lẹgbẹ Fela Kuti Kalakuta Republic ni ilu Eko.
Ajalu inu aye Fatai Rolling doller:
Lọdun 1977, ajalu kan kọlu Fatai, o pàdánù gbogbo irinṣe to fi ń ṣòwò si ọwọ àwọn adigunjale.
Bí owó rẹ ṣe dojude, o ko lọ si ile fulaati kékeré kan, ibi gan ni àwọn iya kekeke tí bẹ̀rẹ̀ si ni gorii ńlá to gbe e sanlẹ.
Lẹyin ajalu gbogbo ohun to pàdánù, Rolling Dollar to ni ọmọ mẹẹdogun láti ọwọ obinrin mẹrin tun foju sọkún marun ninu awọn ọmọ rẹ to fi mọ àwọn iya wọn nitori ìṣẹ́ àti àìsàn.
Oríṣun àwòrán, Google
Lo ba n rọ lu oniruuru isẹ lati lee bọ ilé sugbọn lọdun 2002, gbajugbaja olorin àti adari orin Steve Rhodes, ṣàwárí rẹ o si wu u jade pada eyi to mu un bẹ̀rẹ̀ si ni ṣíṣe pẹlu Tony Allen.
Àwọn àwo orin to ṣe jáde ko to jade laye ni Fatai Rolling Dollar Returns lọdun 2010 ati Better Life ni 2011.
Nigba to ṣàìsàn láwọn ọdun yii, isẹ ti kuro ninu ọrọ  rẹ to bẹẹ to fi n rìnrìn àjò lọ orílẹ̀èdè Amẹrika fun itọju. Igba naa ni wọn sagbejade aisan to ń ṣe e gẹgẹ bii aisan jẹjẹrẹ ọna ọfun.
Baa ba n sọ̀rọ̀ awọn agba olorin ni Naijiria, ara ọ̀tọ̀ ni Fatai Rolling Dollar tori ọna to ń gba kọrin tiẹ̀ yatọ gedegbe.
Kii janpata lati ta jita rẹ bo ba n kọrin lọwọ.
Ṣe ni yóò maa yọ fẹẹrẹ lọwọ rẹ bí ẹni ń fi nkan ṣeré .
Oríṣun àwòrán, Google
Èyí sì ti mu ki ọpọlọpọ wárí fun un koda tohun ti oríṣiríṣi ayẹsi àti ami ẹyẹ to ti gba lagbaye.
Lara awọn to mọ riri isẹ orin Fatai Rolling Dollar ni ile isẹ ìròyìn BBC nigba ti gbajugbaja olorin míì, Ade Bantu sọ nípa rẹ lori eto kan pe, kii ṣe pe Fatai padanu ẹ̀bùn rẹ kankan.
Ati pe, o ṣi n da awọn eniyan lara ya lori itage leyin to si ti le lọgọrin ọdun nigba naa.
Koda, aarẹ Naijiria tẹlẹ, Goodluck Jonathan gbagbọ ni tiẹ̀ pe alafo ti iku Rolling Dollar ṣi silẹ yoo nira fun ẹnikẹni lati dí. Ko si parọ
Oríṣun àwòrán, Google
Njẹ a tíì ri ẹni to ń kọrin bii tirẹ di oni?
Oun fúnra rẹ ti ṣe ifọrọwanilẹnuwo pẹlu akọroyin Will Rose ti BBC ni Naijiria, ilé isẹ iroyin AFP.
Olórin gidi gbọdọ mọ bi wọn ṣe ń lo ohun eelo orin kan.
Fatai lórí eto naa ni o n rí òun lara bi awọn olorin kan to ya ọlẹ tí wọn a kan maa wa owo ọ̀fẹ́ kiri...
Akomolede àti Asa lórí BBC Yorùbá: Mọ̀ síi nípa ẹ̀kún ìyàwó níbí
Kini o tun wa ṣẹlẹ si Fatai Rolling Doller lẹyin igba naa?
Igbe aye olóògbé Pa Fatai Rolling Dollar dabii igba teeyan n wo sinima ni.
Iyẹni, sinima eeyan ti iya jẹ titi titi ko to je eeyan laye ti ọrọ̀ rẹ tun wa poora to yi i sinu isẹ ki Ẹlẹda to faaye gba a padà nítorí fun bii ọdun mẹẹdọgbọn ni ko fi si ninu isẹ orin to bẹẹ.
"Ẹwẹ, orin ti ọpọlọpọ pada fi n ranti rẹ ju naa ni eyi to kọ ko to ku, ""Wọn Kere si Number"" eleyii to fi ta sáwọn èwe to ba fẹ máa ruga si agba."
Pistachio Green Puppy: Àwọn ẹgbẹ́ rẹ̀ jẹ́ aláwọ̀ funfun, tí òun sì jẹ́ aláwọ̀ ewé
Kini a le sọ nipa iku Fatai Rolling Doller?
Nigba to dagbere faye, awọn iwe iroyin Naijiria kan ni lẹyin ọjọ mẹwaa lori akete aisan lo dakẹ ni ile iwosan Marritol Hospital, Surulere, Eko.
Wọn sin in ni ọjọ kẹtàlá, oṣù kẹfà, ọdun 2013 nile rẹ to wa ni Ikorodu, Eko.
"Iwadii fihan pe nigba to ku, Fatai Rolling Dollar ko niwe ẹri ọjọ ti wọn bi i sugbọn pẹlu isiro ọpọlọpọ eeyan, ""Baba 70"" jẹ ẹni  ọdun mẹrindinlaadọrun un ko to dagbere fàyè."
Bolaji Faleke ni Olùkọ́ tó ń kọ́ wa ní àṣà oge ṣiṣe lórí BBC Yorùbá
Elon Musk, Ọ̀gá àgbà iléeṣẹ́ SpaceX, Tesla CEO ń bá Bill Gates du ipò ẹni tó lówó jùlọ ṣèkejì lágbayé
Oríṣun àwòrán, @Musk
Ipin idokoowo Musk niileeṣẹ Tesla to n ṣe ọkọ ẹlẹntiriki l'Amẹrika lo sọ di olowo nla.
Elon Musk ti goke lori atẹ awọn eeyan to lowo ju lagbaye.
Eyi fihan pe ni bi a ṣe n sọrọ yii ọga agba ileeṣẹTesla ati SpaceX naa ti di eeyan to lowojulọ lagbaye pẹlu Bill gate bayii pẹlu bi guruji rẹ ṣe tun rugọgọ sii lọjọ Aje.
Ipin idokoowo ileeṣẹ rẹ to n ṣe ọkọ to n lo ina manamana, electric automaker bu igba jẹ gidigidi.
Eyi lo si mu ki iye ọrọ rẹ ni owo dọla ilẹ Amẹrika o wọ biliọnu mẹtadilaadoje o le ($127.9).
Oríṣun àwòrán, @Musk
Eyi wa gẹgẹ bi atọna awọn ọlọrọ lagbaye, Bloomberg Billionaires index, ṣe gbe iwadii rẹ kalẹ lori awọn eeyan ẹẹdẹgbẹta to lowo julọ lagbaye.
Fun ọpọlọpọ wakati ni odiwọn ọrọ rẹ gan an fi kọja ti Bill Gates.
Bill Gates ni oludasilẹ ileeṣẹ imọẹro kọmputa Microsoft ti odinwọn ọrọ tirẹ jẹ aadoje biliọnu o din ọdunrun miliọnu dọla, ($127.7)
Iwadi tuntun ti atọna awọn ọlọrọ lagbaye, Bloomberg Billionaires index, gbe jade n fidirẹ mulẹ pe biliọnu mejidinlaadoje biliọnu dọla ($128b) ni odinwọn ọrọ awọn mejeeji bayii.
Oríṣun àwòrán, @Musk
Ipin idokoowo Musk ni ileesẹ Tesla lo mu ki ọrọ rẹ o ga sii.
Eyi jẹ pẹlu ida ogun ninu ọgọrun ipin idokoowo ileeṣẹ naa to jẹ tirẹ gẹgẹ bi atọna awọn ọlọrọ lagbaye, Bloomberg Billionaires index, se sọ.
Ida okooleleedegbeta ati mẹrin, (524%) ni ipin idokoowo ileeṣẹ Tesla ti fi lọ soke lọdun 2020,
Eyi to mu ki alekun ọ̀rọ̀ Musk o le pẹlu nnkan bii ọgọrun un biliọnu dọla ($100 billion)
Lootọ ọrọ Bill Gates ko ba pọ ju ọrọ rẹ lọ kani ki i ṣe ti itọrẹ aanu ti Bill Gates n ṣe kaakiri agbaye.
Bill Gates ati aya rẹ ṣeleri lọdun diẹ sẹyin lati maa lo ọgọọrọ owo to ba n wọle fun wọn lati fi ṣaanu fun awọn to ba ku diẹ kaato fun lagbaye.
Ọga agba ileeṣẹ Amazon (AMZN), Jeff Bezos ni eeyan to lowo julọ lagbaye bayii pẹlu ọrọ to to biliọnu mejilelọgọsan dọla ($182 billion).
Oríṣun àwòrán, @Musk
Ta ni Elon Musk?
Orilẹede South Africa ni wọn ti bii, igba to ta oju opo isanwo ori ayelujara, Paypal fun ileeṣẹ eBay lo fi pa owo to le ni ọgọjọ biliọnu dọla ($160m)
Oba Adedokun Abolarin ti Oke Ila: Ó ya ọ̀pọ̀ tó súnmọ́ mi lẹ́nu bí mo ṣe ń kọ́
Yatọ si ileeṣẹ SpaceX, o lowo ninu idasilẹ ileeṣẹ miran bii Tesla, ileeṣẹ to n ṣe ọkọ to n lo ina ẹlẹntiriki dipo epo rọbi, Hyperloop ati bẹẹ bẹẹ lọ.
Ni odun mọkanla sẹyin ni wọn da ileeṣẹ Tesla silẹ, ki o to wa di gbajugbaja ileeṣe to n ṣe ọkọ ẹlẹntiriki lagbaye lọdun 2019.
Akọ́mọlédè àti Àṣà lórí BBC Yorùbá: Kọ̀ síi nípa iṣẹ́ tí oúnjẹ ń ṣe lára níbí
Ma ro ara rẹ pin ni koko iroyin yii, nitori pe ko si owo lọwọ rẹ lonii ko sọ pe o ko ni di ọlọrọ lọla.
Tẹ ipa mọ iṣẹ ọwọ rẹ lai ṣe ọlẹ.
Eni to ba jale lo ba ọmọ jẹ nilẹ Yoruba.
Port Harcourt dumped babies: Iléeṣẹ́ ọlọ́pàá rí òkú ọmọ ọjọ́ kan he lórí ààtàn ní Port Harcourt
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Iléeṣẹ́ ọlọ́pàá palẹ̀ òkú ọmọ ọjọ́ kan mọ́ lẹ́yìn t́i wọ́n jùú sórí ààtàn.
Ileeṣẹ ọlọpaa to wa ni Mile 1 Diobu, ni Port Harcourt, iyẹn ni ipinlẹ Rivers ti palẹ oku ọmọ ọjọ kan mọ, eyii ti ẹnikan gba ju si ile idalẹsi ni opopona Ikwerre.
Awọn eeyan to n gbe lagbegbe naa lo ke gbajare sita, lẹyin ti wọn dede ri ọmọ tuntun jojolo lori aatan ni nnkan bii aago mẹsan an aṣalẹ Ọjọru.
Nigba to n ba BBC sọrọ, Prince Wiro, lati ajọ Centre For Basic Rights And Accountability Campaign sọ pe, ọmọ ọhun ṣi wa laaye nigba ti oun foju gan ni rẹ, ṣugbọn o ti gbẹmi mi nigba ti awọn ọlọpaa yoo de ibẹ.
Wiro ni iwa to butu jai ni ẹni to ju ọmọ naa nu swa, paapaa lasiko ti ọpọ awọn lọkọ-laya kan ko ri ọmọ gbe jo.
O ni yatọ si pe iwa ọhun jẹ ohun to buru jai, o tun jẹ ohun to lodi si ẹtọ awọn ọmọ wẹwẹ labẹ ofin.
"Wiro sọ pe ""a maa n gba awọm ọdọbirin nimọran pe ki wọn maa lo oogun to le dena oyun."""
"A gbúdọ̀ wẹ̀ ọmọ tuntun pẹ̀lú epo pupa, kàìnkàìn ìbílẹ̀ àti ọṣẹ dúdú'
Wiro ni: Ṣugbọn ti oyun ba de, a maa n sọ fun wọn ki ẉon kan si Welfare, ileeṣẹ FIDA, tabi ile awọn ọmọ alaini iya to wa ni Port Harcourt kaka ki wọn sọ odidi ọmọ nu sori aatan."""
O tẹsiwaju pe ọpọ lo n wa ọmọ ti wọn ko ri to bẹẹ ti awọn  kan fi n ra ọmọ lọna aitọ.
"Wiro pari ọrọ rẹ pe ""idi ree ti a fi n bẹ awọn ọdọ wọnyii ki wọn ye sọ ọmọ nu mọ."""
Ọsẹ mẹta sẹyin ni awọn to n tu ọkọ ṣe ri oku ọmọ okunrin jojolo kan ti wọn ju sori aatan ni adugbo Elechi, ni agbegbe Diobu yii kan naa.
Oba Adedokun Abolarin ti Oke Ila: Ó ya ọ̀pọ̀ tó súnmọ́ mi lẹ́nu bí mo ṣe ń kọ́
Diego Maradona: Ohun mẹ́wàá pàtàkì nípa Maradona àti ìbáṣepọ̀ rẹ̀ pẹ̀lú ẹlẹ́sẹ̀ ayò Diego Costa rèé
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Erin wo, ajanaku sun bi oke! Gbogbo agbaye papaa julọ awọn ogbontarigi agbabọọlu atawọn ololufẹ ere bọọlu lo n ṣe idaro Diego Amando Maradona to jade laye l'Ọjọru lẹni ọgọta ọdun.
Ilumọọka elege ara ni agbabọọlu ọmọbibi orilẹede Argentina, Maradona jẹ, koda awọn eeyan kan gbagbọ pe oun ni agbabọọlu to dantọ julọ ninu iwe itan.
Maradona wa lati idile ti wọn ko ṣaaba rọwọ fi họri, o si goke agba di agbaọjẹ agbabọọlu kaakiri agbaaye.
Maradona gba ami ẹyẹ pẹlu oriṣiiriṣii ẹgbẹ agbabọọlu lorilẹede Argentina, Italy ati Spain.
Eyi ti ọpọ eeyan ko le gbagbe laelae ni idije ife ẹyẹ agbaye eyi ti Maradona gba pẹlu orilẹede rẹ lọdun 1986.
Lara awọn abawọn ti awọn eeyan ṣaaba maa n tọka si ni mimu oogun oloro ati ọti lile nigba to n gbabọọlu.
Oba Adedokun Abolarin ti Oke Ila: Ó ya ọ̀pọ̀ tó súnmọ́ mi lẹ́nu bí mo ṣe ń kọ́
Ohun mẹwaa pataki to yẹ ki o mọ ree nipa Diego Maradona
1. Maradona gbarada nigba to gba ami ẹyẹ liigi ọjẹwẹwẹ Argentina pẹlu ẹgbẹ agbabọọlu Boca Juniors lọdun 1982.
2. Lọdun 1984, Maradona fi ikọ agbabọọlu Boca Juniors silẹ lọ si Napoli lorilẹede Italy.
Oun lo ṣagbatẹru bi Napoli ṣe gba ami ẹyẹ Serie A ti wọn gba lọdun 1987 ati 1990, ami ẹyẹ Serie A meji pere ti wọn gba ninu itan wọn.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Diego Maradona gba ife ẹyẹ agbaye ọdun 1986
3. Maradona nikan ni balogun ẹgbẹ agbabọọlu to ṣoju orilẹede rẹ fun akoko to pọ julọ.
Igba mẹrindinlogun ọtọtọ ni Maradona ṣoju Argentina ninu idije ife ẹyẹ agbaye.
4. Ọmọ ọdun mẹẹdogun ni Maradona wa nigba to bẹrẹ si ni maa gbabọọlu lẹyin to darapọ mọ ẹgbẹ agbabọọlu Boca Juniors logunjọ oṣu kẹwaa ọdun 1979.
5. Ọjọ kẹtadinlọgbọn oṣu keji ọdun 1977 ni Maradona bẹrẹ si ni ṣoju orilẹede Argentina.
Oríṣun àwòrán, Rex Features
Maradona lagbabọọlu ti o pegede julọ nidije agbaye ọdun 1986
Ọmọ ọdun mẹrindinlogun lo wa nigba naa, orilẹede Hungary ni Argentina koju lọjọ naa.
6. Ẹgbẹ agbabọọlu Argentinos Juniors ti fi orukọ Maradona sọ papa iṣere wọn, Estadio Diego Armando Maradona ni papa isẹre naa n jẹ bayii.
7. Lọdun 1996, Maradona sọ pe ''mo ti loogun oloro, mo si n loogun oloro, mo si maa loogun lọ laelae.''
Kí lo mọ̀ nípa ìbẹta kan ṣoṣo tí Alaafin Oyo bí? Wọ́n pé ọdún méjìlá báyìí
Kílódé tí Ọọni Ife, Oba Ogunwusi kò fi gbọdọ̀ rí ọmọ rẹ̀ tuntun ti Olorì Naomi bí títí di bíi ẹ̀yìn oṣù mẹ́fà?
Ilé ẹjọ́ dájọ́ ẹgba mẹ́ẹ̀dóògún fún ọ̀daràn tó jí Iphone ní Kaduna
Wo dókítà ọmọ Nàìjíríà tí àgbáyé ń wárí fún nítorí abẹ́rẹ́ àjẹsára COVID-19
Wo ọkùnrin ẹni ọdún 55 tí wọ́n ká agbárí  èèyàn mẹ́rin, àti àwọn ẹ̀yà ara mìí mọ́ lọ́wọ́ ní Ogun
Ìyàwó wọ sòkòtò fún ayẹyẹ ìgbéyéwò rẹ̀, ní wáhálà bá bẹ́ sílẹ̀
8. Lọdun 2000, ajọ to n ṣagbatẹru ere bọọlu lagbaaye, FIFA fi ẹbun agbabọọlu to dantọ julọ ninu iwe itan fun Maradona ati Pele orilẹede Brazil.
9. Maradona sọ fun ra rẹ pe Dalma ati Giannina ni ojulowo ọmọ oun nigba ti awọn yoku jẹ aṣiṣe atipe tori owo oun loun fi bi awọn ọmọ yoku.
10. Wọn sọ ẹlẹsẹ ayo Diego Costa to jẹ ọmọbibi orilẹede Brazil to n ṣoju Spain lorukọ Maradona.
Akọ́mọlédè àti Àṣà lórí BBC Yorùbá: Kọ̀ síi nípa iṣẹ́ tí oúnjẹ ń ṣe lára níbí
Qdot: Ọ̀rẹ́ mi ni Funmi Awelewa, kò sí ọ̀rọ̀ ìfẹ́ láàrin wa- Fakoya Qudus Oluwadamilare
Oríṣun àwòrán, Instagram/qdot
Olorin taka sufee, Fakoya Oluwadamilare Qudus ti ọpọ mọ si Qdot ja gudugbẹ ọrọ lulẹ ninu ifọrọwerọ to ṣe pẹlu BBC Yoruba l'Ọjọru, ọjọ kẹẹdọgbọn oṣu kẹwaa ọdun 2020.
Qdot sọ ninu ifọrọwerọ naa pe lati ilẹ loun ti fẹran orin ijọ Kerubu, o ni iyẹn gan an lo jẹ ki oun ṣe awo orin to da bi orin ṣọọṣi ijọ C & S.
Olorin takasufee naa ṣalaye pe mama mama oun ti oun gbọdọ rẹ lo jẹ ẹleṣin kristẹni lẹyin ti mama baba oun to n tọju oun papoda.
Ọkùnrin tó fẹ́ fipábámilòpọ̀ fín ǹkan sí mi lójú ló ṣe rọ́nà wọlé sí mi lára
O ni iya baba oun ati baba oun, ẹlẹsin musulumi ni wọn.
Qdot sọ pe ẹlẹsin kristẹni ati musulumi ni oun, amọ oun faramọ ẹsin kristẹni ju musulumi lọ.
''Mo mọ nipa ilana ẹsin kristẹni ju musulumi lọ,'' Qdot lo sọ bẹẹ.
Oríṣun àwòrán, Instagram/qdot
Nigba to n sọ nipa awọn awo to ti ṣe jade, o ni eyi ti oun pe akọle rẹ ni 'Alọmọ Mẹta' lo gbe oun jade gẹgẹ bi olorin.
''Orin yẹn ya mi lẹnu gan an, orin naa lo gbe mi lọ si ilu London to pe okiki mi kaakiri, lati ibẹ ni mo ti n ri ode 20000, 30000 gba,'' Qdot lo ṣalaye bẹẹ.
Qudus Fakoya ni orin yẹn yi ọpọ nkan pada ninu igbe aye oun.
''Ẹnikan ra odidi ọkọ fun mi tori orin 'Apala ti mo kọ,'' Qudus lo sọ bẹẹ.
Olorin Qdot tun tan imọlẹ si ọrọ kan tawọn kan n gbe kiri lori ayelujara pe o ṣeeṣe ko jẹ pe ọrọ ifẹ wa laarin rẹ ati oṣere ori itage, Funmi Awelewa.
Oríṣun àwòrán, Instagram/qdot
Qdot ni ''ọrẹ mi ni Funmi Awelewa, a kii ṣe afẹsọna ara wa rara.''
Bakan naa lo tun sọ pe oun o ra G Wagon fun osẹrebinrin miiran, Sotayo.
O ni ''nigba ti n ko ti ra G Wagon fun iya Kudus. Orin lasan nio.''
Oríṣun àwòrán, Instagram/qdot
Lori ọrọ igbeyawo, Qdot ni oun ko ti ṣetan bayii, amọ laipẹ lai jina oun naa yoo ṣe igbeyawo.
Qdot ṣalaye pe yatọ si pe oun gbe ọdọ awọn agba dagba, oun tun maa ka iwe Yoruba daadaa bakan naa loun tun gbe niluu Ibadan.
Ko ṣai gboṣuba fun olorin takasufee mii 9ice fun awokọṣe rere to jẹ fun oun ninu fifi ede Yoruba kọ orin takasufee.
Adebola Ademilua: Àìrísẹ́ ṣè lẹ́yìn ìwé kíkà ló sọ mi dí ìyá onírú, mo dúpẹ́ tèmi
Operation Falcon: Omi tẹ̀yìn wọ̀gbín lẹ́nu fáwọn ọmọ Nàìjíríà mẹ́ta tó lu èèyàn 50,000 ní gbájúẹ̀ jákèjádò àgbáyé
Oríṣun àwòrán, Interpol
Awọn afurasi ọmọ Naijiria mẹta kan to lu ijọba ati awọn ọlọdani lorileede to le ni aadọjọ ni gbajuẹ lọwọ ti tẹ nilu Eko.
Agbarijọpọ awọn ọlọpaa ọtẹlẹmuyẹ ati akẹgbẹ wọn lati Interpol ni wọn pawọpọ mu awọn afurasi wọn yi.
O le ni ọdun kan tawọn agbofinro ti n tọ pinpin wọn ti wọn si ti ri eeyan ẹgbẹrun lọna aadọta ti wọn ti ko si ọwọ awọn aṣebi yi.
Gẹgẹ bi alaye ti Interpol fi sita ninu atẹjade, wọn ni ''niṣe lawọn afurasi wọn yi  fọna ẹburu lu awọn eeyan ni gbajuẹ nipa fifi imeeli ayederu ransẹ''
Wọn tẹsiwaju pe wọn lo awọn ''virus'' buruku ti wọn fi ranṣẹ yi wọ inu akoto owo ileeṣẹ ijọba ati awọn ileeṣẹ ọlọdani to le ni aadọjọ kaakiri agbaye.
Interpol ko darukọ wn lẹkunrẹrẹ ninu atjade naa ṣugbọn wn ni awọn tọwọ tẹ wa lara ikọ onigbajuẹ to pin si ẹka lorisirisi.
Wọn ni awọn ṣi n wa awọn to ku ti iwadii ṣi n tẹsiwaju.
Awọn onwoye sọ pe lasiko ajakalẹ Coronavirus yi, niṣe ni ọwọja awọn to n lu gbajuẹ oju ayelujara n pọ si.
Ọmọ Yahoo tú àṣírí ara rẹ̀ fún, bí wọ́n ṣe ń ṣe é BBC Yorùbá
Bank robbery: Àwọn ọlọ́pàá ti bẹ́ síta láti ṣàwárí àwọn olè 30 tó jówó kó ní Union Bank l'Ondo
Oríṣun àwòrán, Nigeria Police Force
Ileeṣẹ ọlọpaa nipinlẹ Ondo ti sọ pe awọn akọṣẹ mọṣẹ ọlọpaa ti bẹ sita lati ṣe awari awọn adigunjale ti wọn yabo ile ifowopamọ Union Bank to wa niluu Ode-Irele nipinlẹ Ondo.
Agbẹnusọ ileeṣẹ ọlọpaa l'Ondo, Tee Leo-Ikoro to fidi ọrọ naa mulẹ ṣalaye pe adigunjale naa to ọgbọn niye.
Ni deedee ago mẹrin irọlẹ ni awọn adigunjale naa rọna wọle si ile ifowopamọ Union Bank naa.
Leo-Ikoro sọ pe agọ ọlọpaa to wa niluu naa lawọn ọdaran naa kọkọ kọlu ki wọn to morile ile ifowopamọ nibi ti wọn ti ji obiti biti owo lọ.
Bakan naa, agbẹnusọ fun ileeṣẹ ọlọpaa fidi rẹ mulẹ pe awọn adigunle jale naa ji ọpọ ibọn ko lọ ni agọ ọlọpaa.
O ni ado oloro lawọn ọdaran ọhun lo lati fọ ibi tawọn ọlọpaa n ko ibọn pamọ si.
Amọ, Leo-Ikoro sọ pe ko si ẹni to ba iṣẹlẹ ọhun bo tilẹ jẹ wọn yinbọn fun awọn eeyan kan.
Agbẹnusọ ileeṣẹ ọlọpaa ko ṣai fidi rẹ mulẹ pe awọn adigunjale naa ko ni lọ lai foju wina ofin.
Adebola Ademilua: Àìrísẹ́ ṣè lẹ́yìn ìwé kíkà ló sọ mi dí ìyá onírú, mo dúpẹ́ tèmi
Violence against women: Ọkọ mi bẹ̀rẹ̀ sí ní lù mí lẹ́yìn tí mo lòdì sí ibálọ̀pọ̀ láti ihò ìdí lẹ́yìn
Oríṣun àwòrán, others
Sabira Haliu(kii ṣe orukọ rẹ gan an gan an) to jẹ ọmọ ọdun mẹtadinlogoji ti n gbe ile ti wọn si n kọ lọwọ pẹlu ọmọ rẹ mẹrin niluu Kaduna lẹyin sa kuro mile ọkọ rẹ.
Sabira ṣalaye pe oun fi ile ọkọ oun silẹ lẹyin ti ọkunrin naa bẹrẹ si ni lu oun lalubami nitori oun lodi si ibalopọ lati iho idi lẹyin.
''Lati ọmọ ọdun mẹẹdogun ni awọn obi mi ti sin mi lọ si ile ọkọ, o si ti pe ọdun mẹwaa ti mo ti wa nile ọkọ bayii nibi ti mo ti bimọ mẹrin,'' Sabira lo sọ bẹẹ.
Sabira sọ pe wahala bẹrẹ ni ile ọkọ oun ni bi ọdun meji sẹyin nigba ti ọkọ oun to jẹ awakọ beere fun ibalopọ iho idi lati ẹyin eyi ti oun kọ jalẹ.
Sabira ni ''lati igba naa ni o ti bẹrẹ si ni lu mi bi bara, nigba kuu gba to ba ti sọ pe ibalopọ lati iho idi ya, mo maa kọ jalẹ.''
O ni oun gbẹjọ ọkọ oun lọ si agọ ọlọpaa, awọn ọlọpaa si ranṣẹ pe ọkọ oun.
Adebola Ademilua: Àìrísẹ́ ṣè lẹ́yìn ìwé kíkà ló sọ mi dí ìyá onírú, mo dúpẹ́ tèmi
Sabira ni: ''Ṣugbọn ohun ti ọkọ mi sọ fawọn ọlọpaa ni pe oun n beere fun ibalopọ lati ẹyin nitori oun ko fẹ ki n bimọ mọ ni,'' Sabira lo sọ bẹẹ.
O ni awọn ọlọpaa bii leere pe kilode ti ko fi ṣe ifito sọmọ bibi ti ko ko ba fẹ ki oun bimọ mọ, lẹyin naa ni wọn kilọ fun un lati maa dan iru rẹ wo mọ.
Amọ kaka ki ewe agbọn dẹ, niṣe lo n le koko sii, ọkọ Sabira ko dẹkun bibeere fun ibalopọ lati iho idi, bẹẹ ni ko si dẹkun lilu iyawo rẹ.
Mo tun lọ fi ẹjọ rẹ sun awọn ọlọpaa lẹẹkeji lẹyin ti mo ri pe ọkọ mi ko ṣetan lati yipada.
''Ṣugbọn ohun tawọn ọlọpaa sọ fun mi ni pe ki n fi ọrọ naa silẹ fun Ọlọrun, lẹyin igba naa ni mo palẹ ẹru mi mọ ti mo si kuro nile ọkọ mi pẹlu awọn ọmọ mẹrin.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Obinrin yii to n tọrọ owo loju popo ni Kaduna ṣalaye pe ọkọ oun ti ko kuro nibi tawọn jọ n gbe, nọmba foonu ko tiẹ lọ mọ bi oun ba pe e.
Sabira ni oun ti oun sọ fun ọkọ oun ki awọn to pinya ni pe oun yoo fẹ ọkọ mii, o si sọ pe o tẹ oun lọrun.
Akọ́mọlédè àti Àṣà lórí BBC Yorùbá: Kọ̀ síi nípa iṣẹ́ tí oúnjẹ ń ṣe lára níbí
Ọmọ Jerry Rawlings ké gbàjarè pé àwọn gbájúẹ̀ fẹ́ forúkọ bàbá rẹ̀ gbowó ìsìnkú
Oríṣun àwòrán, ZANETOR AGYEMAN-RAWLINGS/TWITTER
Ọmọbinrin to dagbaju laarin ọmọ aarẹ orile-ede Ghana to papoda laipẹ ti figbe ta pe awọn gbajuẹ́ n fi orukọ baba oun gbowo isinku loju opo ayelujara.
Zanetor Rawlings fi ọrọ yi sita ninu atẹjade loju opo Facebook rẹ lọjọbọ wi pe awọn opo ayederu ni wọn lo lati gba owo yi jọ.
O ni niṣe ni wọn n sọ awọn to ba ti ba oun kẹdun ti wọn si n ranṣẹ si wọn lati mu owo isinku baba rẹ wa.
Aṣoju ile aṣofin Ghana to n ṣoju ẹkun idibo Klottey Korle ni Zanetor n ṣe.
Lọjọ kejila, oṣu Kọkanla ni Jerry John Rawlings aarẹ Ghana fi aye silẹ lẹni ọdun mẹtalelaadọta.
Ijọba aarẹ Nana Akufo-Ado ti ṣaaju kede ọjọ meje idarọ lorile-ede Ghana gẹgẹ bi wọn ṣe n palẹmọ isinku ti ijọba fẹ se fun.
Adebola Ademilua: Àìrísẹ́ ṣè lẹ́yìn ìwé kíkà ló sọ mi dí ìyá onírú, mo dúpẹ́ tèmi
Nigeria's Lekki EndSars Shooting: Ohun tó tí ṣẹlẹ̀ rèé níbi ìjókò Igbìmọ̀ ìwádìí ikọlù Lekki
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Awọn ọmọ igbimọ iwadii ṣe abẹwọ sawọn ibi ti ikọlu ti waye ni Lekki
Isẹlẹ iyinbọnpaniyan to waye loṣu to kọja ni Lekki Tollgate lasiko iwọde ENDSARS nilu Eko lọpọ kaakiri agbaye ti bẹnu atẹ lu.
Yatọ si pe wọn jijọ gba pe wọn yinbọn nibẹ, awọn oluwọde ati agbofinro Naijiria ko fẹnuko lori ohun to ṣẹlẹ ni pato lalẹ ọjọ naa.
Ireti ni pe agbekalẹ igbimọ iwadii yoo yanju ọrọ naa paapa eyi to ni ṣe pẹlu iwa ipa lati ọdọ awọn ọlọpaa si araalu.
Ṣugbọn ọrọ ko ri bẹẹ titi di bi a ṣe n sọrọ yi.
Awọn akọroyin wa to wa ni Eko n jabọ fun wa bi nkan ti ṣe n lọ nibi ijoko igbimọ iwadii ti ijọba gbe kalẹ lati tọ pinpin ọrọ yi.
Talo paṣẹ fawọn ọmọogun pe ki wọn lọ si Lekki Toll Gate?
Yiyọju awọn ologun ni Toll Gate Lekki lasiko iwọde alalaafia ko dun mọ ọpọ ninu ti wọn si ti n beere pe talo paṣẹ ki wọn lọ sibẹ? ni ibeere nla lasiko yii.
Gomina Babajide Sanwo-Olu Eko logunjọ oṣu Kẹwaa paṣẹ konile-o-gbele lati dẹkun ikọlu to n waye lawọn agbegbe kan ni Eko latari iwọde ENDSARS.
Saaju asiko yii ti iwọde naa n lọ laisi wahala ni awọn janduku kan gba a sii
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Gbayawu ni Lekki Toll Gate wa tawọn eeyan si n kọja lai si idiwọ
Wakati diẹ lẹyin to paṣẹ yi, awọn ọmọogun de si Lekki Tollgate nibi tawọn oluwọde patẹ si lati bi ọjọ meloo kan sẹyin.
Ni idahun si idi ti awọn ologun fi wa nibẹ, Gomina Sanwo-Olu sọ fun ileeṣẹ iroyin Arise TV ni ọjọ Kejilelogun, oṣu Kẹwaa pe oun ko lagbara lati paṣẹ ki awọn ologun lọ si aaye iwọde.
Amọ, ileeṣẹ ologun sọ fun igbimọ iwadii lọjọ Kọkanla, oṣu Kọkanla, pe Sanwo-Olu lo pe awọn lati wa sibẹ.
Ọgagun Ahmed Taiwo ni Sanwo-Olu funrarẹ lo pe awọn lati wa sibẹ nitori ipa awọn ọlọpaa ko ka ohun to n ṣẹlẹ.
Nibi ijoko igbimọ naa omiran to waye lọjọ Kọkanlelogun, oṣu Kọkanla ni aṣoju ologun to wa nibẹ ni iṣẹ ti wọn bẹ awọn kii ṣe lati tu awọn oluwọde ka.
Bi ko ṣe pe ki ''awọn da alaafia pada si agbegbe Eti-Osa nibi ti Lekki Toll gate wa''
Gomina Sanwo-Olu ko ti i fesi sọrọ tawọn ologun sọ.
Ṣe awọn ologun yinbọn to ni ọta ni tootọ abi bẹẹkọ?
Ọpọ ẹsun ni awọn eeyan ti fi kan ọlọpaa ati ologun pe wọn yinbọn ọlọta lu awọn oluwọde.
Ajọ ajafẹtọmoniyan Amnesty Internnational sọ pe eeyan mejila lo ku.
Nigba ti igbimọ iwadii yoo fi bẹrẹ ijoko ileeṣẹ ologun lawọn ko yinbọn lu ẹnikankan ati pe ọta ti ko loro lawọn yin ni Lekki Toll Gate lu awọn oluwọde.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
DJ Switch to fi fidio iyinbọn lu oluwọde han ti sa asala fẹmi rẹ kuro ni Naijiria
Lọjọ Kokanlelogun, oṣu Kọkanla ni ọgagun Taiwo sọ fun igbimọ naa pe awọn ọmọ ogun gbe ọta to loro ati eyi ti ko ni lọwọ.
Wọn ni idi ni pe awọn janduku ti darapọ mọ iwọde naa lati fi da nkan ru.
Lasiko ifọrọwanilẹnuwo, aṣoju ologun yi ni awọn janduku sọ oko lu awọn ologun to n kaakiri lagbegbe Oriental Hotel ki eeyan to de Lekki Toll Gate.
Ọmọoogun kan,gẹgẹ bi o ti ṣe wi, farapa.
O ni: ''Ki a to de Oriental Hotel ni wọn ti n sọ oko lu  awọn ọmọogun ti wọn si fi ọta ti ko loro dawọn lohun pada.
Wọn ṣe ọmọogun kan leṣe, Okuta ba a ni ete rẹ.
Ti wọn ba sọ oko luwa, ohun ti a le fi da wọn lohun pada ni ọta ibọn ti ko loro.''
Ki lohun ti BBC jabọ?
Lọpọ ijoko igbimọ ati lawọn igba mii ti wọn ba awọn akọroyin sọrọ, ileeṣẹ ologun n sọ pe BBC jẹri si i pe awọn yinbọn soke ni ati pe awọn ko yinbọn lu awọn oluwọde.
Akọroyin BBC Pidgin, Damilola Banjo ninu iroyin to fi sọwọ ṣapejuwe ohun ti oju rẹ ri ni Lekki lasiko to wa nibẹ.
#EndSARS : Àwọn ọ̀dọ́ dáná sun tírélà akẹ́rù tẹrùtẹrù ní Ekiti
Kini Damilola Banjọ sọ?
Damilola ni oun kuro nibi ikọlu naa lẹyin nkan bi iṣẹju marundinlọgbọn jabọ pe:
"Ki a to kuro ni Lekki, awọn ologun n yinbọn soke ti a si sa asala fun ẹmi wa.
Mo ri arakunrin kan ti ko le e mi daadaa''
 Mo lero pe ohun to fa eyi ni pe aya rẹ n ja nitori bi awọn ologun ṣe n yinbọn leralera ati pe gbogbo ayika  ibẹ ni ko rọgbọ''"
''Wọn tẹ siwaju lati maa yinbọn fun nkan bi ogun iṣẹju ti a si daya delẹ ki awọn eeyan ma ba a tẹwa mọlẹ.
Ọga mi ti a jijọ wa nibẹ sunmọ awọn ologun, to si sọ fun wọn pe akọroyin ni wa ki wọn to jẹ ki a jade lalaafia.
O to nkan bi ogun si iṣẹju marundinlọgbọn ki a to ribi jade''
Ta lo pa CCTV?
Ọrọ miran to tun mu awuyewuye wa ni ti CCTV ti a mọ si kamẹra to ka ohun to waye nibi ikọlu Lekki lalẹ ikọlu naa silẹ.
Lasiko to n jẹri niwaju igbimọ ọga ileeṣẹ Lekki Concession Company to n mojuto Toll Gate, Abayomi Omomuwasan, sọ pe kamẹra naa sinmi lati maa ṣiṣẹ ni nkan bi aago mẹjọ alẹ
Ninu idahun rẹ si ẹsun pe wọn mọọmọ pa ina lasiko ikọlu naa, ọgbẹni Omomuwasan sọ pe nitori aṣẹ konileogbele ti ijọba gbe kalẹ lawọn fi ni kawọn oṣiṣẹ awọn maa lọ sile.
Nitori eyi o ni wọn  ko le tan ẹrọ amunawa lẹyin igba ti ina ọba lọ.
Gomina Sanwo-Olu sọ fun CNN ni idahun si ibeere yi pe oku meji lo wa ni ile igbokupamọ si to si ni ki awọn araalu mu ẹri wa tabi ki wọn yọju  ti wọn ba padanu mọlẹbi ninu iṣẹlẹ naa.
Ṣugbọn ileeṣẹ ologun ni awọn ko pa ẹnikankan ni Lekki Toll Gate.
Ọgagun Taiwo sọ fun igbimọ naa pe eeyan kan ku lopopona Admiralty Road ati pe iku rẹ ko waye latari iṣẹlẹ Lekki.
O ni awọn ọlọpaa naa gbe oku eeyan kan wa lati adugbo Yaba nilu Eko bakan naa.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Oluwarinu Odulala wa lara awọn to n ṣoju ọdọ to si kopa ribiribi ninu iwọde ENDSARS
Titi di igba wo ni igbimọ yoo fi joko?
Adajọ fẹyinti Doris Okuwobi lo n dari igbimọ yi.
Awọn mii  to pẹlu rẹ wa lati ajọ ajafẹtọmoniyan, ajọ to n mojuto ẹtọọmoniyan ni Naijiria, Human Rights Commission, Citizens Mediation Centre ati awọn aṣoju ọdọ meji.
O ti le ni iwe ifẹhonuhan ọgọrun un le ni mẹwaa ti igbimọ naa ti gba.
Ireti wa pe wọn yoo gbọ gbogbo ẹsun yi nisoju awọn agbẹjọro ati awọn olujẹri.
Igbimọ ẹlẹni mẹjọ yii bẹrẹ lọjọ Kẹtadinlọgbọn, oṣu Kẹwaa ti wọn yoo si fi oṣu mẹfa ṣe iwadii lati gbẹjọ ifiyajẹniyan lọwọ ọlọpaa lọna aitọ.
Bẹẹ naa ni wọn yoo daba ijiya to ba tọ fawọn ọlọpaa to ṣe aṣemaṣẹ pẹlu owo gba ma binu to ba tọ si awọn ti wọn fiya jẹ lọna aitọ.
Yollywood: Lágbo tíátà lọ́sẹ̀ yìí, Toyin Abraham fi orin yẹ́ Iyabo Ojo sí níbi ìsìnkú ìyá rẹ̀, Òṣùpá fíi ìkíni ọjọ́ ìbí ránṣẹ́ sí Pasuma
Oríṣun àwòrán, @falzthebahdguy/iyaboojofespris/kemifilaniblog
Agbo oṣere tiata lọsẹ yi lamilaka pẹlu awọn iṣẹlẹ manigbagbe to waye nibẹ.
Bo ti lẹ jẹ wi pe awọn iṣẹlẹ kan jẹ ohun to ba tijo tayọ wa, awọn miran ko fi tara tara jẹ ohun idunnu.
Ninu oṣẹ taa n wi yi, nibẹ ni awọn kan ti ṣe oku iya wọn tawọn mii ṣe ayẹyẹ ọjọ ibi ti wọn si da awọn mi lọla pẹlu pe wọn fi orukọ wọn sọri opopona.
Ọkùnrin tó fẹ́ fipábámilòpọ̀ fín ǹkan sí mi lójú ló ṣe rọ́nà wọlé sí mi lára
Ni meni meji, ẹ jẹ ka wo ohun to ṣele lagbo awọn oṣere
Wahala fawọn ti wọn ko fi opopona sọri wọn!
Akọle ree ti Falz the bahd guy kọ soju opo rẹ ni Instagram lati fi han pe wọn ti fi orukọ opopona sọri rẹ.
Falz Falana Lane lorukọ ti wọn sọ oju ọna naa baa tiẹ mọ adugbo ibi ti opopona naa wa.
Oríṣun àwòrán, falzthebahdguy
Falz to jẹ ọmọ gbajugbaja agbẹjọro agba Naijiria, Femi Falana wa lara awọn ọdọkunrin ti o n mi agbo akọrin ati oṣere Naijiria titi.
Yemi Alade ati Dorathy Bachor wa lara awọn to fi ọrọ ikini ranṣẹ si
Igba ipọnju laa mọ ọrẹ.
Ninu awọn elere tiata Yoruba lobinrin to jẹ wọlewọde  ara wọn ni Toyin Abraham ati Iyabo Ojo wa.
Oríṣun àwòrán, Iyabo ojo/Toyin Abraham
Bi igba pe ka ni ''five and six'' lawọn mejeeji yi ti awọn Yoruba a maa pe ni kori kosun.
Lasiko isinku Iya Iyabo Ojo, Toyin Abraham jẹwọ pe ọrẹ tootọ loun pẹlu bi o ti ṣe fi orin iyin dagbere fun iya ọrẹ rẹ.
Ṣaaju asiko yi ni Iyabo Ojo ti kede eto isinku iya rẹ to si n fi orisirisi aworan iya rẹ soju opo Instagram rẹ.
Kunle Afod, Saidi Balogun, Salawa Abeni to fi mọ Sound Sultan wa lara awọn to ki Wasiu Alabi Pasuma ''ọrọbọkibọ Creator'' ku orire ajọdun ọjọ ibi.
Iba Barakah bi awọn eeyan ti ṣe mọ tun fi ọdun kan kun ọjọ lorilẹ eepẹ ni ọjọ Eti tii ṣe ọjọ Kẹtadinlọgbọn oṣu Kọkanla ọdun 2020.
Oríṣun àwòrán, Pasuma
Amọ ṣa, eyi to ṣe ni ni ''Awww'' ninu awọn aworan ati ọrọ ikini lọjọ ibi rẹ ni ti ọrẹ rẹ Kingsaheed Osupa to fi aworan yi ati ọrọ soju opo Instagram.
Ninu aworan yi, o ni ọrẹ atijọ da ju eyi ta ṣẹṣẹ ni lọ.
O tun fi adura si pe Iba-Wassy ọlọpẹ yoo ṣe ọpọ ọdun laye.
Barister lo bi gbogbo oníṣẹ́ fújì -Oṣupa
Pasuma naa da lohun to si ni oun dupẹ ore yi.Koda o pe Osupa ni inagijẹ rẹ ti ọpọ eeyan ko mọ''jacky''
EndSARS, Daniel Chibuike Ikeaguchi: ọlọ́pàá yìbọn pa Sleek ní Port Harcourt niléẹjọ́ bá bú N50 mílíọ̀nù, owó gbà má bínú
Oríṣun àwòrán, SLEEK DC/FACEBOOK
Aadọta miliọnu naira ni Adajọ ni ki ileeṣẹ ọlọpaa o san fun ẹbi Sleek.
Ile ẹjọ giga ipinlẹ Rivers kan to fikalẹ silu PortHarcourt ti paṣẹ pe ki ileeṣẹ ọlọpaa, ọga ọlọpaa Naijiria, kọmiṣọnna ọlọpaa atawọn ọlọpaa meji miran o san owo gba maa binu naa.
Awọn ikọ yii ni yoo san  aadọta miliọnu naira fun ẹbi oloogbe Daniel Chibuike Ikeaguchi ti inagijẹ rẹ n jẹ 'Sleek'.
Ni ọjọ kọkandinlogun, oṣu kẹsan an, ọdun 2020 lawọn ọlọpaa ikọ agbogun tiwa ijinigbe, Anti-Kidnapping Unit, ileeṣẹ ọlọpaa pa Sleek.
Ni ilu Port Harcourt ni ipinlẹ rivers to jẹ ẹkun guusuguusu Naijiria ni eleyii to mu ki wọn pe illeeṣẹ ọlọpaa lẹjọ itapa si ẹtọ ọmọniyan.
Ni ijoko ile ẹjọ naa meji lawọn ọlọpaa ko ti yọju ti wọn ko si tun ranṣẹ ki wọn to farahan ni ijoko ile ẹjọ naa to kẹyin lọjọ kẹtalelogun, oṣu kọkanla, ọdun 2020 lati wa pẹjọ tako ẹsun ti olupẹjọ naa n fi kan wọn.
Oríṣun àwòrán, SLEEK DC/FACEBOOK
Onidajọ S.C. Amadi ninu idajọ rẹ ni bi ọlọpaa ṣe ṣeku pa Sleek tako iwe ofin orilẹ-ede Naijiria ati pe bi wọn ko tun ṣe fi ọlọpaa to yin in nibọn pa naa jẹjọ ko bofin mu rara.
Amọṣa dipo biliọnu kan naira tawọn ẹbi Ikeaguchi n bere fun fun, aadọta miliọnu naira ni Adajọ Amadi naa paṣẹ ki wọn san fun ẹbi ologbe naa lẹyẹ o ṣọka.
Oríṣun àwòrán, SLEEK DC/FACEBOOK
Agbẹjọro fun ẹbi ologbe naa, Noble Njoku ṣe apejuwe idajọ naa gẹgẹ bi eyi to dara pupọ ti yoo si jẹ ifaleti fawọn ọlọpaa ti wọn n fi eeyan kọ ibọn yinyin.
Awọn obi Sleek, Dominic Ikeaguchi Oyekwu pẹlu ṣalaye pe idajọ naa yoo wo ọgbẹ wọn san de aaye kan bi o tilẹ jẹ pe ọmọ awọn ko le e pada saye mọ.
Adebola Ademilua: Àìrísẹ́ ṣè lẹ́yìn ìwé kíkà ló sọ mi dí ìyá onírú, mo dúpẹ́ tèmi
Oluwo: Oluwo ṣàlàyé ohun tó ń mú káwọn èèyàn máa gba tirẹ̀ láwùjọ
Oríṣun àwòrán, Instagram/oluwo of iwo land
Oluwo ilu iwo, ọba Abdulrasheed Akanbi ti ṣalaye ohun to n mu ki tẹrutọmọ gba toun gẹgẹ bi kabiyesi.
Ninu ọrọ kan to fi sita loju opo Instagram rẹ, Oluwo jẹ ko di mimọ pe ifẹ ti awọn eeyan n ni si oun pẹlu ọwọ ti wọn n fun oun ko ṣa dede wa bikoṣe nipasẹ ohun ti oun n ṣe faraalu
Ba Akanbi ṣalaye pe bi eeyan ba ti n ṣe ohun to tọ lawujọ, o di didan karaalu o fẹran rẹ.
Oba Adedokun Abolarin ti Oke Ila: Ó ya ọ̀pọ̀ tó súnmọ́ mi lẹ́nu bí mo ṣe ń kọ́
Ọkùnrin tó fẹ́ fipábámilòpọ̀ fín ǹkan sí mi lójú ló ṣe rọ́nà wọlé sí mi lára
Male Fertility: Wo àwọn oúnjẹ márùn ún tó ń mú kí àtọ̀ ọkùnrin dára sí i
Ọmọ bibi jẹ ohun to ṣe pataki ni igbe aye awọn ẹda paapaa ọkunrin ati obinrin.
Ohun pato to wọpọ laarin ọkunrin ati obinrin ni ore ọfẹ ti wọn ni lati sọ eso nipa bibi ọmọ ọkunrin ati obinrin.
Ọpọlọpọ nkan lo n fa airọmọbi lara ọkunrin ati obinrin, amọ awọn ounjẹ asaraloore kan wa lati mu atọ okunrin dara si.
Dokita Ugo Ezentirioha sọrọ lori awọn ounjẹ bii ẹja, ẹran, ẹyin ati awọn nkan miran
Jijẹ ẹja loorẹ koore paapaa eleyii to ni eroja ''Omega 3 fatty acids'' n ṣe atọ ọkunrin loore nipa ṣiṣẹ iranwọ fun bi ẹjẹ ṣe n lọ si ibi atọ ọkunrin.
Cancer: Àṣe ara mi ni iso ti n run gbogbo bí mo ṣe n ṣèrànwọ́ lórí jẹjẹrẹ
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Jijẹ eso ṣe pataki fun ọkunrin ki atọ rẹ le dara si.
Awọn eso bii ọgẹdẹ, carrot, ọsan, berries naa n ṣiṣẹ takuntakun lati jẹ ki atọ ọkunrin dara si.
Fun apẹrẹ, ọgẹdẹ ni eroja bi vitamin B1,C magnesium ati bromelain ti wọn n ṣiṣẹ takuntakun ni ara ọkunrin.
Bakan naa ni Carrot ni awọn eroja ara bii beta-carotene ti kii jẹ awọn sẹẹli ara ti ko dara ṣe aṣemaṣe.
Ọsan naa ni eroja Vitamin C ni ara.
Akwụkwọ nri na-acha ndụ ndụ dịka ụgụ na ndị ọzọ na-enyekwa aka
Awọn ẹfọ to ba jẹ alawọ ewe ni awọn eroja ara bii folate, eleyii to n ran obinrin lọwọ ni ati tete loyun, ti o si ma n jẹ ki atọ ọkunrin duro ni ara obinrin.
Bakan naa ni ẹpa naa dara ni ara lati mu ki atọ ọkunrin dara si ni ara.
Ẹyin jẹ ọkan lara awọn eroja to ṣe koko ni ara eniyan.
O ni awọn eroja ara bii vitamin E, zinc ati protein eleyii ti o fun awọn agọ ara awọn eniyan lati ṣiṣẹ.
BBC findings on lekki shooting: Ẹ wa wo àwọn tó ṣì ń wá ẹbí wọn nínú ìṣẹ̀lẹ̀ End SARS 2020
Ẹyin le jẹ ki eroja ara ji pepe, ki atọ ara ọkunrin le ṣiṣẹ dara dara.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Tomato naa n ko ipa ribiribi ninu awọn eroja ara paapaa ki atọ ọkunrin le dara si.
Wọn ni eroja ara ti orukọ rẹ n jẹ lycopene, eleyii to n mu ki ara ji pepe.
O dara ki ọkunrin ma a jẹ tomato daradara, ki atọ rẹ le dara.
Jijẹ ẹran dara ni ara bakan naa lo si ni awọn abawọn.
Ọkan lara awọn eroja to ni ni zinc, folic acid ati selenium to n mu ki ato okunrin dara si.
Amọ ko dara ki eniyan jẹ ẹ ni ajẹju nitori o le mu ki suga ara pọsi, to si le e fa ijamba si ara.
Oríṣun àwòrán, Instagram/Utakaegbe
Ẹpa / Imumu
Orisirisi ẹpa to wa lo dara ni ara to si n mu ki atọ ọkunrin dara si ju tẹlẹ lọ ti wọn ba n jẹ loore-koore.
Awọn apẹẹrẹ ẹpa ni ''Tiger Nuts'' ti awọn kan n pe ni ofio tabi imumu, agbọn, asala ati bẹẹ bẹẹ lọ.
Garlic, iyẹn ayuu ati awọn eso miran naa ni bii Vitamins C, E, B12, D ati zinc naa.
Adebola Ademilua: Àìrísẹ́ ṣè lẹ́yìn ìwé kíkà ló sọ mi dí ìyá onírú, mo dúpẹ́ tèmi
Ikorodu student death: Ìròyìn sọ pé ìjọba, agbófinró ṣì ń wá olùkọ́ tó lu akẹ́kọ̀ọ́ pa ní Ikorodu nítorí ibéèrè ìṣirò
Oríṣun àwòrán, Ridwan Oyewumi
Nibo ni olukọni to lu akẹkọọ pa nileewe aladani kan ni ilu Ikorodu wa bayii?
Eyi ni ibeere to gba ẹnu ọpọ awọn eeyan to gbọ si iṣẹlẹ buruku naa eyi to waye lọjọbọ ọjọ kẹrindinlọgbọn oṣu kọkanla ọdun 2020.
Iroyin ti a n gbọ ni pe olukọ naa ti wọn pe orukọ rẹ ni Ọgbẹni Emma ti fi ẹsẹ fẹ, awọn alaṣẹ ipinlẹ Eko ṣi n wa a titi di bi a ṣe n sọrọ yii.
Ọgbẹni Emma ni iroyin sọ pe o lu Ọgbẹni Boluwatifẹ Omelaja nileewe aladani to n lọ nitori pe ko lee dahun ibeere iṣiro kan to bi i.
Gẹgẹ bi a ṣe gbọ, aburo Boluwatifẹ, Lateef ti oun pẹlu jẹ akẹkọọ nileewe naa lo wa ṣilẹkun ọrọ fun awọn obi rẹ pe olukọ rẹ lo lu u pa.
Ohun ti awọn alaṣẹ ileewe naa ṣe lalaye fun awọn obi rẹ gẹgẹ bi a ṣe gbọ ni pe, o fo ṣanlẹ ku ni kilaasi rẹ ni.
Adebola Ademilua: Àìrísẹ́ ṣè lẹ́yìn ìwé kíkà ló sọ mi dí ìyá onírú, mo dúpẹ́ tèmi
Koda wọn ni olukọ to lu u pa naa wa lara awọn to gbe oku rẹ wa ba awọn obi rẹ nile, laimọ pe oun gan lo wa ni idi ọrọ naa.
Ohun ti a gbọ ni pe ẹka to n ri si imunadoko ati ijageere eto ẹkọ ni ipinlẹ Eko, Office of Education Quality Assurance ti bẹrẹ iwadii lori rẹ.
Amọṣa titi di bi a ṣe n sọrọ yii, ọjọ mẹrin lẹyin ti iṣẹlẹ naa ṣẹlẹ, ko si ẹni to tii kofiri olukọni to ṣiṣẹ laabi naa.
Oríṣun àwòrán, Ridwan Oyewumi
Awọn mọlẹbi ti ọmọ wọn ṣadede fo sanlẹ ku nileewe rẹ,Elihans Schools,ni Iṣawo Agric, Ikorodu ti sọ fun BBC pe awọn ko ro pe amuwa Ọlọrun ni iku rẹ jẹ.
Boluwatife Omeleja akẹkọọ ọmọ ọdun merinla ni iroyin gbode loju opo ayelujara pe wọn gbe oku rẹ wale lati ileewe lỌjọbọ to kọja.
Ridwan Oyewumi to sọ fun BBC pe oun ni ẹgbọn Bola fidi ọrọ mulẹ pe lootọ ni wọn gbe oku Boluwatife wa lati ileewe rẹ, Elihans College Ikorodu lọjọbọ.
Ọkùnrin tó fẹ́ fipábámilòpọ̀ fín ǹkan sí mi lójú ló ṣe rọ́nà wọlé sí mi lára
O ni ko pẹ si igba ti wọn gbe oku Bolu wa ni awọn ti sare lọ sin ni ibamu pẹlu ilana isinku musulumi.
Ridwan ṣalaye pe baba awọn sọ pe awọn ko ni ṣẹjọ lori iku Bolu ṣugbọn awọn ni lati mọ ohun to ṣeku pa Bolu.
Alaye ti BBC gbọ ninu ọrọ ti Ridwan kọ si oju opo rẹ ni Twitter  ati eleyi to sọ fun wa ni pe ẹni to nileewe ti Bolu n lọ lo ṣadede pe baba oun lọjọbọ.
O ni wọn sọ fun wọn ki wọn tete maa bo wa nitori Bolu ti daku nileewe.
''Nigba ti Daddy wa gbọ, niṣe ni wọn gbera lati maa lọ si ileewe rẹ. Amọ loju ọna ni wọn ti pade olukọ ati ẹni to nileewe ti wọn gbe Bolu bọwa ninu ọkọ''
Ìyá Darasimi: Ọlọ́run fi ìbejì rẹ̀ mí lẹ́kún, lẹ́yìn ikú Darasimi tó mu sódà
Ridwan ni Daddy awọn ri pe Bolu ko ṣọrọ ti wn si sare gbe lọ si bi ile iwosan meji ki o to di pe awọn dokita sọ pe Bolu ti ku.
Alaye ti Ridwan sọ pe ọrẹ Daddy awọn to ni ileewe sọ fawọn ni pe olukọ beere ibeere lọwọ Bolu to si ni ko wa ṣalaye niwaju patako fawọn iyoku rẹ.
Oríṣun àwòrán, Facebook/Omelaja Boluwatife Taofeek
''O lọ siwaju kilasi ti wọn si fun ni ẹfun ko kọ alaye soju patako.Ibẹ ni Bolu ti daku.Nkan ti wọn sọ fun wa niyẹn''
O tun sọ pe ko pẹ si igba ti wọn ri pe Bolu ku ni ọrẹ Daddy(ẹni to ni ileewe) gba wa ni imọran lati wa ilẹ lọ sin Bolu si.
''Awọn ni wọn ra aṣọ, awọn ni wọn san owo fun awọn to gbẹ ilẹ.A pada sin oku rẹ si ilẹ Daddy wa ti o w ani toosi''
Ọrọ gbọna mii yọ gẹgẹ bi Ridwan ṣe sọ nigba ti ẹgbọn Bolu to wa ni ileẹkọ kan naa de lati ileewe ni irọlẹ.
Ridwan ni ẹgbọn rẹ, Lateef sọ pe olukọ kan(Mr Emma)  lo lu Bolu ni kilasi to fi pada wa daku.
''Igba t i ẹgbọn rẹ sọ ọrọ yi fun wa lasiri pada wa tu pe ohun ti wọn sọ fun wa pe Bolu daku kii ṣe ootọ''
Ridwan ni awọn to jẹ ẹgbọn fun oun wa olukọ ti wọn pe orukọ rẹ ni Mr Emma lọ si ile rẹ lọjọbọ ṣugbọn wọn ko ba ni ile.
Oríṣun àwòrán, elihanschools.com
O ni awọn tun wa lọ lọjọ Ẹti naa ti awọn ko si mọ ibi to gba lọ.
''Daddy wa lawọn ko ni ṣẹjọ lori ọrọ yi ṣugbọn wọn ni ti awọn akọroyin ba wa beere ọrọ nipa iku Bolu awọn yoo ṣalaye fun wọn''
''Nkan ti awa mọlẹbi kan fẹ ni pe ki a mọ Boya iku amuwa lati ọdọ Ọlọrun ni iku Bolu tabi eeyan lo wa nidi rẹ''
BBC Yoruba pe nọmba ẹni to nileewe naa Oduwole GA ti awọn mọlẹbi Bolu fi ranṣẹ siwa.
Amọ ẹni to gbe ago naa ṣalaye pe agọ ọlọpaa lawọn wa nitori naa awọn ko ni le da wa lohun lasiko taa pe.
Bakan naa ni BBC pe ọga ọlọpaa(DPO) Ikorodu lori ago to si ni oun ko mọ nipa iṣẹlẹ naa.
Iku ọmọdekunrin yi jẹ eleyi ti a o maa tọ pinpin rẹ lati mọ ohun to ṣẹlẹ wa si eti igbọ yin.
Ṣugbọn bayi, mọlẹbi ti sin Bolu, ileewe ko ti fesi ti a ko si le sọ ni pato ibi ti olukọ ti wọn fẹsun kan pe o lu Bolu to fi daku wa.
Boko Haram attack: Gómìnà Zulum sọ̀rọ̀ lórí ohun tí Ààrẹ Buhari lè ṣe láti dẹ́kun ìpànìyàn Boko Haram ní Borno
Oríṣun àwòrán, @MBuhari
Aarẹ Muhammadu Buhari ti paṣẹ fun awọn ọmọ ogun lati doju ija kọ awọn ọmọ ẹgbẹ agbesumọmi Boko Haram.
Bakab naa ni Aarẹ tun sọ pe ko si oun to ṣe koko lasiko yii ju aabo lori ẹmi ati dukia awọn ọmọ Naijiria lọ.
Buhari lo sọ ọrọ naa loju opo Twitter rẹ lalẹ ọjọ Aje, lẹyin ti awọn ọmọ ẹgbẹ Boko Haram pa awọn eeyan mẹtalelogoji ni ipinlẹ Bornu.
"Aarẹ ni ""Ko si ohun kankan to ṣeṣe koko lasiko yii ju abo lori ẹmi ati dukia awọn ọmọ Naijiria."""
Mo si maa ri daju pe ileeṣẹ ologun atawọn ẹṣọ alabo miran yoo ni gbogbo irinṣẹ to yẹ ki wọn ni lati le gbogun ti iwa iṣẹrubalu.
"Buhari tẹsiwaju pe ""Bi a ṣe n ṣọfọ awọn ẹmi to sọnu lọwọ, a ti paṣẹ fun awọn ọmọ ogun lati lọ gbena woju awọn ọmọ ẹgbẹ agbesumọmi."""
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ṣaaju ni Aarẹ Buhari ti kọkọ bu ẹnu atẹ ikọlu ti ẹgbẹ naa ṣe si awọn agbẹ ninu oko irẹsi kan, ni ilu Koshebe, nipinlẹ Borno, nibi ti wọn ti dumbu eeyan mẹtalogoji bi ẹni dumbu ẹran.
Iṣẹlẹ naa ti mu ki ọpọ ọmọ Naijiria ke si Aarẹ pe ko da gbogbo awọn ọga ologun Naijiria duro lẹnu iṣẹ.
Bakan naa lawọn eeyan kan n sọ pe, ti Aare Buhari ko ba le e wa ojutu si eto abo to mẹhẹ, ko kọwe fi ipo silẹ.
Oríṣun àwòrán, Borno state government
O kere tan eeyan aadọfa lawọn ikọ aṣekupani Boko Haram ti ran lọ sọrun ọsangaan ninu ikọlu kan to waye ni ipinlẹ Borno.
Ṣaaju la gbọ pe eeyan mẹtalelogoji lo ba iṣẹlẹ naa lọ amọ bayii ti ajọ isọkanb agbaye ti toju bọ ọrọ naa wọn ni eeyan aadọfa lo ba iṣẹlẹ naa lọ.
Ọrọ yi wa ninu atẹjade kan ti oludari eto iranwọ fawọn atipo ajọ naa ,Edward Kallon fi sita lọjọ Aiku.
Yatọ si awọn to ku yi, ọpọ lo farapa ninu ikọlu naa.
Loju opo ayelujara, niṣe lawọn eeyan n gbarata ti ọpọ si n di ẹbi ru ijọba aarẹ Buhari fun pe ko mojuto eto aabo bo ti ṣe yẹ.
Ninu ọr awọn eeyan , wọn ni ijọba ni la ti wa wọrọkọ fi ṣada lori ọrọ awọn agbesunmmi yi to jẹ pe ojujumọ lo n peleke si.
Oríṣun àwòrán, Twitter
Imam of Peace tweet
Oríṣun àwòrán, Twitter
Emeodi Mba tweet
Oríṣun àwòrán, Twitter
Aproko Doctor
Wọn ti sin awọn agbẹ onirẹsi mẹtalelogoji tawọn agbebọn Boko Haram kọlu lọjọ Ẹti ti wọn si du loko ti wọn ti n ṣiṣẹ ọgbin wọn.
Gomina ipinlẹ Borno, Ọjọgbọn Babangana Umara Zulum lo lewaju awọn olugbe ilu Zabarmari lowurọ ọjọ Aiku ti isinku naa waye lati sinku awọn agbẹ onirẹsi naa.
Oríṣun àwòrán, Borno Government House
Oríṣun àwòrán, Borno State Government
Gomina Zulum ni ọrọ ti di adiyẹ ba lokun fawọn eeyan agbegbe naa nitori bi wọn joko sile ebi yoo pa wọn, bi wọn tun lọ siṣẹ loko bayii, awọn agbebọn Boko Haram lo tun n lọ ree pa wọn si oko iwa nkan jẹ.
O ni lootọ olugbe ilu Zabarmari ni ijọba ibilẹ Jere lawọn eeyan ti wsn pa naa, amọṣa ileto Koshebe ni ijọba ibilẹ Mafa ni wọn ti da ẹmi wọn legbodo.
Gomina Zulum ni lootọ oku eeyan mẹtalelogoji ni wọn sin lowurọ ọjọ Aiku, sibẹ ko tii si ẹni lee sọ ni pato iye awọn eeyan ti wọn pa.
O fi kun un pe ọkan lara awọn olugbe ilu naa ti ko fẹ da orukọ ara rẹ ṣalaye fun oun lasiko isinku naa pe awọn oku miran ṣi wa ni ibudo ikọlu naa ti awọn eeyan agbegbe naa ko tii loore ọfẹ lati gbe pada wale nitori awọn eeyan ṣi wa ti wọn ṣi n wa bayii nibẹ.
Oríṣun àwòrán, AFP
Aarẹ orilẹede Naijiria, Muhammadu Buhari ti bu ẹnu at lu bi awọn agbevọn kan ṣe pa agbẹ ogoji.
Aarẹ ṣapejuwe ohun ti wọn wọn ṣe yii ninu atẹjade ti agbẹnusọ aarẹ, Garba Shehu fi sita loju opo Twitter bii iwa ẹni to sinwin.
"Mo bu ẹnu atẹ lu bi awọn agbesunmọmi ṣe pa awọn agbẹ wa to n ṣiṣẹ karakara lori oko irẹsi wọn ni ipinlẹ Borno.
Iṣẹlẹ dun gbogbo ọmọ orilẹede Naijiria lapapọ bẹẹ si ni ọkan mi wa lọdọ idile awọn agbẹ yii lasiko ti wọn kẹdun awọn eeyan wọn."
Aarẹ gbadura ki Ọlọrun tẹ wọn si afẹfẹ rere.
Iroyin naa to tẹwa lọwọ lalẹ ọjọ Abamẹta sọ pe awọn ikọ agbesunmọmi Boko Haram lo ṣeku pa awọn agbẹ ogoji to n ṣiṣẹ ni oko wọn lọjọ Abamẹta kan naa.
Lowurọ ọjọ Abamẹta ni iṣẹlẹ to fọwọ kan ni lẹmi yi waye ni agbegbe Kwashebe Zamarmari ijọba ibilẹ Jere gẹgẹ bi awọn aradugbo ṣe sọ fun BBC.
Ọkùnrin tó fẹ́ fipábámilòpọ̀ fín ǹkan sí mi lójú ló ṣe rọ́nà wọlé sí mi lára
Gẹgẹ baa ṣe gbọ, agbegbe naa jẹ ibi kan ti awọn ikọ agbesunmọmi Boko Haram ati ikọ Islamic State West Africa Group kii ṣe alejo pẹlu ikọlu wọn.
Amọ ko tii si ẹgbẹ kankan bii alara to jade wa sọ pe awọn lawọn ṣe ikọlu naa.
Wọn ni lasiko tawọn agbẹ naa n ge irẹsi loko ni ikọlu yi waye.
Eeyan mẹfa mi lagbọ pe wọn farapa ninu ikọlu yi.
Iroyin kan sọ pe wọn so awọn agbẹ naa mọ igi ti wọn si fi ọbẹ ge wọn lọrun.
Titi di bi a ti ṣe n sọrọ yi, ileeṣẹ ologun Naijiria ati ileeṣẹ ọlọpaa ko ti fesi si iṣẹlẹ yi.
Boko Haram ati ISWAP si n da bira lariwa orileede Naijiria toun ti pe awọn alaṣẹ ni awọn ti kapa wọn.
Loṣu to ṣẹṣẹ kọja yii ni ikọ Boko Haram pa agbẹ mejilelogun to n ṣiṣẹ loko wọn ninu iṣẹlẹ meji ọtọọtọ.
Ẹ̀tanú pé Olùṣọ́ Genesis kò fẹ́ Laide Williams-Oni ló ṣe rán an lọ́ sí ẹ̀wọ̀n ọdún kan - CCC Genesis Global
Wo nkan tó sọ Woli ìjọ Genesis Global di ọmọ ìjọ Cele lẹ́yìn tó kúró nínú ìjọ C.A.C.
Ekiti Murder: Àwọn agbébọn tún pa Alùfáà Baptist kan ní Ekiti
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Oluṣọ aguntan ijọ onitẹbọmi Solution Baptist Church ni ilu Ikẹrẹ Ekiti, Ẹniọwọ Johnson Ọladimeji lawọn agbenipa kan ti pa ni ipinlẹ Ekiti.
Iroyin sọ pe, inu ọkọ rẹ ni wọn pa a si lopopona Igbara Odo si Ikẹrẹ Ekiti.
Ọkùnrin tó fẹ́ fipábámilòpọ̀ fín ǹkan sí mi lójú ló ṣe rọ́nà wọlé sí mi lára
Awọn eeyan kan ni ipinlẹ Ọsun ni iranṣẹ Ọlọrun naa ti n bọ ki wọn to yinbọn pa a.
Iroyin sọ pe awọn ọmọ ijọ rẹ to reti rẹ ti wọn ko rii ko de ni Ọjọbọ to ṣeleri pe oun yoo de ni wọn kebosi sita ti wọn si bẹrẹ si ni wa a ki o to di wi pe wọn ṣawari oku rẹ ni opopona naa.
Ol.ori ijọ Onitẹbọmi (Baptist Church) ni ipinlẹ Ekiti, Ẹniọwọ Adeyinka Aribasoye ṣalaye pe ilu Ipetu Ijesha ni iranṣẹ Ọẹọrun naa ti n bọ lẹyin to lọ ki iya rẹ nibẹ.
Yoruba Taboo: Èèwọ̀ ni fún ọba láti gbé Bibeli tabi Kurani dání dípò ifá- Elebuibon, Agẹṣin Àdìmúlà
Oríṣun àwòrán, Alaafin of Oyo oba adeyemi lamidi III
Ọpọlọpọ ọba ti a n pe ni ọba ni ilẹ Yoruba bayii ni ko ba iyẹn ni pe wọn kii ṣe ọba.
Eyi ni ọrọ ọkan lara awọn afọbajẹ ilẹ Yoruba kan, Oloye Fagbenle Adedayọ Agẹṣin Adimula ati afọbajẹ ilu Ila Ọrangun ọkan lara awọn ilu iṣẹmbaye ilẹ Yoruba.
Ninu ifọrọwerọ rẹ pẹlu BBC News Yoruba, Agẹsin Adimula ilu Ila Ọrangun ṣalaye pe awọn  ọbalaye kan wa lori itẹ ti wọn kii ṣe ọba bayii eleyi to si n faa ti eku ko fi n ke bi eku ti ẹyẹ ko si maa ke bi ẹyẹ mọ lawọn apa kan ilẹ Yoruba bayii.
Bakan naa ni Araba ti ilu Osogbo, Oloye Fayẹmi Ẹlẹbuibọn pẹlu kin ọrọ yii lẹyin ti wọn ni ọba ti ko ba ṣe oro ibilẹ ki o to de ori oye kii ṣe Ọba.
"Oloye Ẹlẹbuibọn ni ohun to mu ki ọba yatọ si awọn eeyan yoku naa ni ""oro ti ọba nṣe, ẹkọ ti wọn kọ ọba, awọn nnkan ibilẹ bii ifoju ba odu ati mimu wọn tẹ ifa pẹlu ṣiṣe oro idile gbogbo ti wọn jọba le lori fun wọn. Nnkan to jẹ ki ọba o yatọ si eeyan lasan niyẹn. Ọba ti ko ba si ti ṣe kii ṣe ọba niyẹn""."
Oloye Adedayọ ṣalaye pe  Ọba yoo wu to ba dori aleefa ni ilana Bibeli tabi Kurani kii ṣe Ọba gẹgẹ bi ilana Ọba jijẹ ni ilẹ Yoruba.
Ọkùnrin tó fẹ́ fipábámilòpọ̀ fín ǹkan sí mi lójú ló ṣe rọ́nà wọlé sí mi lára
Ọba ti a lee pe ni Ọba, ti aṣa Yoruba wa lori rẹ, ti awọn eewọ Yoruba si wa lori rẹ ni awọn ọba to jẹ wi pe bi awọn baba nla wa ṣe nfi ọba jẹ ni wọn ṣe fi wọn jẹ,
O ni ọba ti yoo ba pe ara rẹ ni ọba ni ilẹ Yoruba gbọdọ jẹ ọba ti wọn ṣe iwadii rẹ lati inu ifa, to si de ipebi to si lo iye ọjọ to yẹ ko lo ni ipebi; to si jẹ gbogbo nnkan to yẹ ko jẹ, to si yẹ ko mu mu.
Baba Ẹlẹbuibọn ni Ọba to ba rọ mọ Bibeli tabi Kurani lori oye gbọdọ ranti pe ilẹ Yoruba ni oun ti jẹ ọba kii ṣe ilẹ Larubawa tabi Isrẹli. O ni ọpọ ohun ti awọn ọba n dimu lara ẹsin ilẹ okeere lo n tako ilana ilẹ Yoruba ati ohun ti ọba ni lati mọ.
Oríṣun àwòrán, Ile oodua
O ni ẹnikẹni to ba ti mọ pe oun yoo tẹle ẹsin okeere dipo atọna iṣẹmbaye ti wọn fi jọba gbọdọ fi oye silẹ fun awọn ọmọ oye ti wọn 'setan lati tẹle ilana ọpakutẹlẹ fun ọba jijẹ nilẹ Yoruba.
Oloye Agẹsin Adimula naa fara kin ohun ti baba Ẹlẹbubọn ṣe ni alaye. O ni ko si ohun ẹni to lee fi atọna miran to yatọ si ifa jẹ ọba nilẹ Yoruba ti ko ni ta ko awọn eewọ gbogbo ti ipo naa da le lori ti yoo si ni ipa lori ilu.
Oríṣun àwòrán, Ile oodua
Lati ọjọ pipẹ lawọn igbagbọ kan ti waye nipasẹ iroyin tawọn eeyan ti gbọ nipa jijẹ ọba nilẹ Yoruba. Lara rẹ ni pe gbogbo ẹni ba ti n jẹ ọba lo gbọdọ jẹ ẹdọ tabi ọkan eeyan ki o to jọba?
Gẹgẹ bi alaye ti Araba ti ilu Oṣogbo, oloye Ifayẹmi Ẹlẹbuibọn ṣe fun BBC News Yoruba, ko si ọba to n jẹ ọkan ki o to de ori itẹ. Oloye Ẹlẹbuibọn ni ara ọna ti awọn ẹlẹsin okeere fi ba ẹsin abalaye jẹ niyi ki awọn eeyan lee maa fi oju ibajẹ wo ẹsin naa.
Baba ni lootọ oro wa ti wọn maa n ṣe fun ẹni to ba fẹ jẹ ọba ni ilẹ Yoruba,oro yii ni wọn maa ni ki ọba jẹ ti wọn yoo si bii pe ki lo jẹ o ti oun naa yoo si dahun pe oun ti jẹ ọba, amọṣa gẹgẹ bi ayipada ti ṣe ba ọpọlọpọ nnkan lawọn ẹsin okeere wọnyii naa ni ayipada ti de ba ọpọlọpọ nnkan ni iṣẹṣe nilẹ Yoruba.
'Bí aya bá kọ ọkọ rẹ̀ silẹ̀, kó wà láì lọ́kọ̀'
Oloye Agẹṣin adimula ila pẹlu ṣalaye pe, lootọ laye atijọ awọn eeyan kan maa n sọ ọ kiri pe ọba n jẹ ẹdọ eeyan ki o to jsba, amọṣa kii ṣe otitọ.
O ni ara awọn agbekalẹ ti awsn eeyan kan ti ko mọ nipa ọrọ ọba jijẹ nilẹ Yoruba maa n sọ kaakiri ni eyi lati lee gbin ẹru ati ọwọ yii ipo ọba ka.
Aye ọjọun lawọn kan n parọ, ọba kan kii jẹ ẹdọ, irọ ni wọn n pa. Ohun ti a n pe ni ijẹ ọba inu ẹsẹ ifa lo wa
Ifa ni yoo yan Ọba gẹgẹ bi oloye Agẹṣin Adimula ṣe sọ, koda, ifa ni wọn n ṣe fun ọba to fii di Ọba alade ni ilẹ Yoruba, kii ṣe ẹdọ jijẹ gẹgẹ bi awọn eeyan kan ṣe maa n sọ.
O ni gbogbo ahesọ ọrọ bẹẹ lo wa ki awọn eeyan lee maa bẹru ọba ati paapaa ki wọn le maa wo o pe hee,
Oríṣun àwòrán, Alaafin Oyo Oba Adeyemi Lamidi III
Gẹgẹ bi baba Ifayẹmi ẹlẹbuibọn ṣe sọ, ipalara wa fun ilu ati Ọba gan to jẹ laifi ti ilana ijọba ni ilẹ Yoruba ṣe.
"Baba ṣe apẹlrẹ ilu ile ifẹ nigba ti awọn ijoye Ọọni ba fẹ kii, wọn a ni ""eku a jiṣẹ, ẹja a jiṣẹ, ẹran a jiṣẹ, owo a jiṣẹ"" Riran ni wọn n ran awọn nnkan wọnyii ni iṣẹ gẹgẹ bi iwure ni."
Bi ọba kan ba wa kọ to ni ilana larubawa tabi Isrẹli loun yoo tẹlẹ, ohun ti wọn fi sọri ilẹ Yoruba yatọ si ohun ti wọn fi sọri ilẹ awọn ilu ti ẹsin okeere wọnyii ti wa.
O nigẹgẹ bi gbogbo eewọ ṣe ni atunbọtan naa ni igbesẹ ọba lati yẹ kuro loju opo iṣẹṣẹ ti eto ijẹọba nilẹ Yoruba dale naa ṣe ni atunbọtan.
Obateru Akinruntan: Olugbo Obateru akinruntan ṣalaye ìdí ohun tó ń ṣẹlẹ̀ láàrín òhun àti Ooni Ile Ife
Oríṣun àwòrán, Twitter/Obatakinruntan
Olugbo ti ilu Ugbo, Ọba Frederick Ọbatẹru Akinruntan ti ṣalaye ohun to n ṣẹlẹ laarin oun ati Ọọni ile ifẹ.
Olugbo ni awọn eeyan ti oye ko ye lo n ro pe aawọ wa laarin oun ati Ọọni ile Ifẹ. Gẹgẹ bi ọrọ rẹ ọmọ iya loun ati Ọọni jẹ.
O ni ohun ti oun ṣi n tẹnumọ ni pe awọn eeyan Ugbo lo ni ifẹ ti wọn si ti tẹdo sibẹ ki Oduduwa atẹwọnrọ to de lati tẹdo sibẹ.
Ọba Akinruntan sọ ọrọ yii di mimọ lasiko to fi n ṣe ajọyọ ayẹyẹ ọdun kọkanla ti o n lo lori itẹ gẹgẹ bii Olugbo ti ilu Ugbo.
O ni Ọbamakin Ọsangangan to jẹ Ọọni akọkọ ni iran baba nla oun ati pe ileto mẹtala ni baba oun ti ni ni ile iIfẹ ki Oduduwa to de.
Bakan naa lori ọrọ abo lorilẹede Naijiria, Kabiyesi naa pe fun idasilẹ Ọlọpaa agbegbe. O ni bi awọn fijilante ba darapọ ṣiṣẹ pẹlawọn ọlọpaa, eto abo to mẹhẹ lorilẹede Naijiria a duro deede.
Oby Ezekwesili: Mínísítà tẹ́lẹ̀ ní ohun tó ń ṣẹlẹ̀ lórílẹ̀èdè Nàìjíríà báyìí fihàn pé Ààrẹ Buhari nílò àyẹ̀wò ọpọlọ
Oríṣun àwòrán, Twitter/oby ezkwesili
Ẹ ba wa ṣayẹwo ọpọlọ ati ilera ara aarẹ wa o?
Eyi ni igbe ti Oby Ezekwesili, minisita tẹlẹ lorilẹede Naijiria kesita loju opo twitter rẹ  latari bi nnkan ṣe nlọ si lorilẹede Naijiria bayii.
Oby Ezekwesili ni ẹtọ ọmọ Naijiria ni bayii lati mọ bi ilera ẹni to n tukọ iṣẹjọba orilẹede wọn ṣe jafafa si atipe dokita agba ileewosan ile ijọba Aso rock ko ni lee ṣe irufẹ ayẹwo bẹẹ.
Minisista tẹlẹ naa ni ayafi ki wọn ṣe agbekalẹ igbimọ oluwadii iṣegun kan lati ṣe ayẹwo naa.
"Ero mi ni pe ni ipele ti a de bayi lorilẹede Naijiria pẹlu bi ọkọ orilẹede yii ṣe n fi logbologbo, o yẹ ka fi ọrọ ẹtọ si ẹgbẹ kan lori ilera aarẹ Buhari.
A nilo lati ṣe ayẹwo ijipepe ilera ara ati ọpọlọ aarẹ orilẹede Naijiria lati mojuto ojuṣe ipo to di mu."
Adebola Ademilua: Àìrísẹ́ ṣè lẹ́yìn ìwé kíkà ló sọ mi dí ìyá onírú, mo dúpẹ́ tèmi
O ni bi nnkan ṣe ri lorilẹede Naijiria bayii fihan pe asiko yii kii ṣe asiko fun awọn ọmọ orilẹede Naijiria lati joko kawọgbera tabi fi ọwọ leran.
"O fi kun pe, ""Gẹgẹ bi ọmọ orilẹede Naijiria tọrọ n dun, mo pe fun igbekalẹ igbimọ oluwadii iṣegun kan lati ṣe ayẹwo naa nitori a ko le gbara le dokita ileewosan ile ijọba mọ lati fun wa ni iroyin to ṣee fọkan tan""."
Ipe ajafẹtọ ọmọniyan to tun figbakanri jẹ minisita feto ẹkọ lorilẹede Naijiria naa ko lee ṣai da lori bi ọrọ eto abo lorilẹede Naijiria ti ṣe n di awo-dọwọboju bayii, paapaajulọ pẹlu ti awọn agbẹ onirẹsi to le ni ọgọrun tawọn agbebọn Boko Haram pa lopin ọsẹ to kọja.
Kòkòrò oyin lé ọ̀pọ̀ èèyàn kúrò nílé l'órílẹ̀-èdè Cameroon
Oríṣun àwòrán, @BBOWT
Inu ibẹru ni awọn eeyan to n gbe ni awọn agbegbe kan nilu Maroua, lorilẹ-ede Cameroon wa bayii, nitori bi kokoro oyin ṣe yabo wọn.
Eeyan marun-un, ninu eyi ti ọmọde mẹrin wa, lo ti di eero ileewosan nitori iṣẹlẹ naa.
Eyi si ti mu ki awọn alasẹ o gba awọn araalu ni imọran láti fi ile wọn silẹ, titi ti wahala naa yoo fi wa sopin.
Yatọ si eyi, àwọn oṣiṣẹ pana-pana ti wa ni ilu naa lati koju awọn kokoro ọhun.
Ohun to jẹ iyalẹnu fun awọn araalu naa ni pe ko si ẹni to mọ ibi ti awọn kokoro oyin ọhun ti wa.
Oríṣun àwòrán, @Planet_Bee
Saaju asiko yii, aṣọ ekisa ni awọn eeyan naa ma n dana sun lati le awọn kokoro ọhun.
Wọn ma n se eyi nitori pe eefin ati ooru ina ma n le àwon kokoro oyin kuro nibi ti wọn ba wa.
Sugbọn ṣa, igbesẹ naa ko sisẹ ni asiko yii nitori pe awọn oyin naa ko duro si oju kan.
Idi si niyii ti wọn fi ránṣẹ si awọn oṣiṣẹ pana-pana lati koju wọn.
Ọkùnrin tó fẹ́ fipábámilòpọ̀ fín ǹkan sí mi lójú ló ṣe rọ́nà wọlé sí mi lára
Elebuibon: Lẹ́yìn ọ̀pọ̀lọ́pọ̀ oṣù tí òjò kò rọ̀ ní orílẹ̀èdè Cuba, Ọba ilẹ̀ Yorùbá ló pàṣẹ kí ó rọ̀ tó sì rọ̀
Ilẹ Yoruba kii ṣe eyi ti a lee fọwọ rọ sẹyin nitori ẹya ti Eleduwa ṣayan ni.
Araba awo ilu Osogbo, Oloye Ifayẹmi Ẹlẹbuibọn lo sọ eyi ninu ifẹrọwerọ rẹ pẹlu BBC News Yoruba.
O ni ohun to yẹ ki awọn ọmọ Yoruba o ṣe bayii, bẹrẹ latori awọn ọbalaye to jẹ olori wọn ni lati mu aṣa ati iṣe wọn lọkunkundun.
Ghana Election Special Voters list 2020: Báyìí ni àwn òṣìṣẹ́ tó dá yàts ṣe ní ọjọ́ ìdìbò tiwọn lọ́tọ̀
Awọn ọlọpaa, ologun, oniroyin atawọn to n wa ọkọ agboku ni orilẹede Ghana ti wọn jẹ oṣiṣẹ akanṣe ti n dibo lonii ṣaaju ọjọ keje oṣu kejila ti idibo gangan yoo waye.
Akanṣe eto idibo yii ti aj eleto idibo orilẹ̀ede ghana ṣe agbekalẹ rẹ jẹ fun awọn oṣiṣẹ koṣeemani ti yoo maa ṣiṣẹ fun awọn ara Ghana lọjọ keje oṣu kejila ọdun yii.
Nkan bii oludibo 109,577 lo n dibo bayii jakejado orilẹede naa kaakiri igun bii mejila ti ajọ eleto idibo fun laṣẹ lati kọkọ dibo
eto idibo toni bẹr ni agogo meje owurọ eyi ti yoo si pari ni nkan bii ago marun irọlẹ oni.
Oṣiṣẹ alaabo n dibo
Ọba Samule Kolapo Adegbite Adedoyin: Wo ohun tí wọ́n sọ nípa Owa Ale ìlú Ikare tó wàjà
Ọjọ kinni, oṣu Kẹsan an, ọdun 2020 ni Owa Ale ti ilu Ikare, Ọba Samule Kolapo Adegbite Adedoyin jade laye lẹyin to ti lo ọdun mejidinlaadọta lori itẹ.
Ọpọ awọn ara ilu Ikare atawọn ẹbi Ọba alaye naa lo n ṣedare lẹyin rẹ lẹyin to lọ darapọ mọ awọn baba nla rẹ lẹni ọdun marundinlaadọrun un.
Nigba ti ikọ ileeṣẹ iroyin BBC ṣe abẹwo si aafin rẹ lọjọ to papoda, aṣoju rẹ, Oloye Olabisi Babajide sọ iru eeyan ti Ọba alaye naa jẹ ko to waja.
O ni “Owa Ale jẹ ẹni to ko awọn eeyan mọra, o si tun jẹ ẹni to ni iwa tutu.”
Bakan naa ni Oloye naa tẹsiwaju pe akoko Ọba alaye ọhun san awọn eeyan ilu Ikare nitori pe oriṣirṣi awọn ilọsiwaju lo de ba ilu naa lasiko to wa lori oye.
Oloye babajide tun mẹnuba diẹ lara oriki Kabiesi naa.
Ẹ wo fidio yii fun ẹkunrẹrẹ.
Borno Zabarmani massacre: Ípànìyàn tó wáyé ní Borno fihàn pé omi n bẹ lámù fún ètò ààbò - Tinubu
Ípànìyàn tó wáyé ní Borno lọ́jọ́ Sátidé fihàn pé omi n bẹ lámù fún ètò ààbò ní Naijiria - Tinubu
Bí Boko Haram ṣe pa àwọn àgbẹ̀ ní Borno fihàn pé ọ̀rọ̀ ààbò Naijiria n fẹ́ akitiyan si - Bola Tinubu
Oloye ẹgbẹ oṣelu All Progressives Congress, APC, Bola Tinubu ti sọ pe bi Boko Haram ṣe pa awọn agbẹ onirẹsi nipinlẹ Borno lọjọ Satide fihan pe igbogun ti awọn agbesunmọmi ṣi nilo akitiyan si ko to o le wa sopin.
Ninu lẹta kan ti Tinubu kọ si gomina ipinlẹ Borno, Zulum, lati ba kẹdun iṣẹlẹ naa to waye ni Zabarmani, lo ti sọ eyi.
Ko din ni agbẹ onirẹsi mẹtalelogoji ti Boko Haram bẹ lori nibẹ.
Ọpọlọpọ eeyan lo si ti bu ẹnu ẹtẹ lu ipaniyan naa.
Tinubu sọ pe pipa ti wọn pa awọn agbẹ naa, to n tiraka lati pese fun ẹbí wọn ati oúnjẹ fun orile-ede Naijiria, ko yatọ si iwa ika ati ti Satani.
O gboriyin fun Gomina Zulum, fun gbogbo akitiyan rẹ lati ri pe awọn ti ogun sọ di alainilelori, pada si ilu abinibi ati isẹ oojọ wọn.
Eyi to ni o ti mu idagbasoke ba ipese oúnjẹ ni Naijiria, ati idunnu ba awọn eeyan naa.
Adari ile igbimọ aṣojuṣofin ilẹ Naijiria, Femi gbajabiamila ti fi lede pe aarẹ Muhammadu Buhari ti gba lati wa siwaju ile aṣojuṣofin bayii.
Eyi ko sẹyin ọrọ ikọlu to waye ni ilu Kushebe Zabarmani nibi ti ikọ Boko Haram ti dumbu ọpọlọpọ awọn agbẹ onirẹsi to bẹẹ ti ko tii ni pato onka iye awọn to fori fa iku naa.
Ọjọbọ ọsẹ ni Gbajabiamila n sọ fun awọn oniroyin lẹyin to ṣepade kan pẹlu aarẹ ni ile rẹ.
Lọjọ Aje ọsẹ ni ile igbimọ aṣojuṣofin Naijiria kọwe pe aarẹ Buhari lati wa wi tẹnu rẹ nipa iṣoro aabo to n koju orilẹede yii.
Bakan naa, o tun ṣalaye awọn igbesẹ ti ijọba rẹ n gbe lati fopin si iwa iṣoro yii.
Bi ẹ ko ba gbagbe, ikọ Boko Haram latẹnu adari wọn tun ṣẹṣẹ ṣe fidio kan jade ni ninu eyi to ti ṣalaye bi awọn ṣe pa awọn agbẹ naa.
"'Ọkọ mi wa ọkọ̀ tẹ ""Poly Bag"" lásán, àfi gbùùàà! Àdó okoró búrẹ́kẹ'"
Gẹgẹ bi ile igbimọ aṣofin mejeeji ṣe n ke si aarẹ buhari lati da wa wi tẹnu rẹ ati pe ko gba iṣẹ lọwọ awọn ọga awọn ologun tori wọn ni wọn ti kuna ninu iṣẹ wọn.
Ile igbimọ aṣofin agba ni tiwọn to tẹnu mọ ọ́ pe ọrọ̀ aje orilẹede Naijiria ti wa di akurẹtẹ gbaa to bẹẹ to fi jẹ wipe awọn Boko Haram ti n gbe nkan di ọna lawọn apa ibi kọọkan ni Borno.
"Awọn ibudo yii ni wọn ti n da awọn agbẹ to n lọ si oko duro lati maa gba owo lọwọ wọn"". Tori eyi wọn ni dandan ni ki aarẹ ṣe atunto ẹka abo ni Naijiria."
Igba kẹta ree ti ile aṣofin n funpe si aarẹ Buhari lati yọ awọn ọga awọn ologun. Titọ yii n jẹ jade latari awọn agbẹ onirẹsi tawọn Boko Haram dumbu bi ẹran ni Borno ti ko si tii si ojutuu.
Wo bí ìlànà tuntun lórí gbígba físà UK lẹyìn Brexit ṣe kàn ọ́
Abẹ́rẹ́ àjẹsára Covid-19 ti Pfizer ṣe yóò di lílò láti ọ̀sẹ̀ tó ń bọ̀
Àwọn afurasí ṣá ìgbákejì kọmísọ́nà ọ̀gá ọlọ́pàá láàké dójú ikú
"'Ọkọ mi wa ọkọ̀ tẹ ""Poly Bag"" lásán, àfi gbùùàà! Àdó okoró búrẹ́kẹ'"
Oríṣun àwòrán, @Thenichenews
Niṣe lawọn ọmọ ile igbimọ aṣoju-ṣofin l'Abuja ti ke si Aarẹ Muhammadu Buhari lati wa ṣalaye ibi ọrọ de duro nipa eto abo orilẹ-ede Naijiria.
Wọn gbe igbesẹ naa lẹyin ti awọn aṣoju lati ipinlẹ Bornu da aba pe o yẹ ki Aarẹ Buhari yọju si ile ọhun.
Bi ẹ ko ba gbagbe, opin ọsẹ to kọja yii ni awọn ọmọ ẹgbẹ Boko Haram dumbu eeyan mẹtalelogoji bi ẹni dumbu ẹran ninu oko irẹsi kan ni ipinlẹ naa.
Ṣaaju ni ariyanjiyan ti kọkọ waye laarin awọn ọmọ ile igbimọ aṣoju lori boya ki wọn ke si Aarẹ tabi ki wọn ma ṣe bẹẹ.
Eyii to mu ki agbẹnusọ ile naa, Femi Gbajabiamila parọwa si awọn eeyan ọhun pe ko bojumu lati ke si Aarẹ lati wa tu aṣiri igbesẹ ti ijọba n gbe lori eto abo, nitori ko le so eso rere.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ṣugbọn awọn kan ninu ile naa faake kọri pe ko si ohun to buru ninu ki Aarẹ wa ṣo fun awọn ọmọ Naijiria awọn ohun to n ṣe lori eto abo ẹmi ati dukia wọn.
Lẹ́yìn ọ̀pọ̀lọ́pọ̀ oṣù tí òjò kò rọ̀ ní orílẹ̀èdè Cuba, Ọba ilẹ̀ Yorùbá ló
Ṣugbọn lẹyinorẹyin, ọkan lara awọn to daba pe ki wọn pe Aarẹ, Ahmed Jaha ni o ti di ọranyan ki Aarẹ yọju sile naa, ti awọn aṣoju miran si ṣegbe lẹyin rẹ ki gbogbo ile to gba aba ọhun wọle.
Bo tilẹ jẹ pe ile igbimọ aṣoju naa fọwọ si pe ki Aarẹ wa wi tẹnu rẹ lori eto abo Naijiria, wọn ko tii sọ ọjọ ti Aarẹ yoo wa.
Ọjọ Satide, ọjọ kọkandinlọgbọn, oṣu Kọkanla, ọdun 2020 ni awọn ọmọ ẹgbẹ Boko Haram ṣekupa awọn eeyan mẹtalelogoji lagbegbe Marrabati ati Hammayya, lẹba ijọba ibilẹ Jere, ni ipi9nlẹ Bornu.
Wo ohun tí wọ́n sọ nípa Owa Ale ìlú Ikare, Ọba Samule Kolapo Adegbite Adedoyin tó wàjà
Boko Haram: Oluwatobi Adeigba, Ọkọ mi ń lọ siṣẹ́ fún àjọ INEC ló kàgbákò ikú - Opó Adeigba
Pẹlu bi awayemalọ kan o ṣe si, ọna ti awọn mii gba lọ ṣi ń sọ ọpọlọpọ ẹbi ati ara sinu ibanujẹ ailopin.
Ọmọ ipinlẹ Kogi ni Adeigba Oluwatobi to ti di oloogbe bayii latari igbesunmọmi Boko Haram ni ipinlẹ Yobe nibi to ti sinruulu lọdun 2011.
Amọ lati igba naa di akoko yii, iyawo rẹ ṣi n wa ẹkun mu lojoojumọ nigbakuugba to ba n sọ itan bo ṣe ṣẹlẹ.
Ìdí tí a fi pa àwọn àgbẹ̀ onírẹ̀sì ní Borno, Boko Haram ṣàlàyé nínú fídíò tuntun
"'Boko Haram ti gbilẹ̀ kan nílẹ̀ Hausa, wọ́n ti ń ní ""Check Point"" láti gba owó lọ́wọ́ àwọn àgbẹ̀'"
Wọ́n ti rẹ ipò ọ̀gágun Olusegun Adeniyi sílẹ̀ lẹ́yìn tó jẹ̀bi títú àṣírí kùdiẹ-kudiẹ iléeṣẹ́ ológun lórí ayélujára
Èèyàn 281 ló kó covid-19 lọ́jọ́ Ìṣẹ́gun, 123 wá láti ìpínlẹ̀ Eko nìkan
Kii kuku ṣe pe o n rinrin rederede kiri, iṣẹ ti wọn gbe fun un lati lọ ṣe gẹgẹ bi oṣiṣẹ agunbanirọ ajọ eleto idibo, INEC nigba naa ni ọkọ to wa ninu rẹ kan rekọja lori ọra dudu kan loju popo lai mọ pe iku iku ni wn gbe sinu ọra naa.
"Dẹrẹba gan ri ọra Poly Bag"" ọhun, o n wo o niwaju ṣugbọn ko mọ pe ado oloro lo wa ninu rẹ. Wọn ti tẹ ẹ tan, o kan bugbamu ni""."
Iyawo oloogbe, Adefunke Adeigba to ni awọn kaakiri dọ awọn gomina ipinlẹ ti ọkọ rẹ ti wa ati ti ipinlẹ ti wọn n gbe titi titi, ṣi n rọ ijọba lati ran idile oun lọwọ ki iya ma baa jẹ awọn ọmọ ti Danjiel Oluwatobi fi silẹ lọ.
Obasanjo: Mo lòdì sí ìgbé ayé tí Gani Adams ń gbé látẹ̀yìnwá, ṣùgbọ́n n kò bá a jà - Obasanjo
Oríṣun àwòrán, Eagleonline
Aarẹ ana lorilẹede Naijiria, Oloye Oluṣẹgun Ọbasanjọ ti ni ko si idi fun oun lati pari ija pẹlu Aarẹ ọna Kakanfo ilẹ Yoruba, Iba Gani Adams.
Oloye Ọbasanjọ ni idi ni pe ko si igba kan yala latẹyinwa tabi nisinyi ti ija wa laarin oun ati Iba Gani Adams, nitori naa ko si idi lati maa pari ija ti ko si.
Ninu atẹjade kan eyi ti amugbalẹgbẹ fun Oloye Ọbasanjọ lori ọrọ iroyin, Kẹhinde Akinyẹmi fi sita lọrọ yii ti jẹyọ.
"'Ọkọ mi wa ọkọ̀ tẹ ""Poly Bag"" lásán, àfi gbùùàà! Àdó okoró búrẹ́kẹ'"
Aarẹ Ọbasanjọ ṣalaye pe sababi ni ipade oun ati Iba Gani Adams ni ile agba ilẹ Yoruba to tun jẹ aṣiwaju ẹgbẹ Afẹnifẹre ni agbegbe Lekki Phase 1 jẹ, kii ṣe lati pari ija kankan.
Aarẹ ana naa ṣalaye pe ko si ohun meji ti oun ni tako aarẹ ọna kakanfo ilẹ Yoruba naa ju igbe aye rẹ atẹyinwa lọ ti ko ba iṣe oun mu.
Gbogbo ibeere Gani Adams lati bẹ oloye Oluṣẹgun Ọbasanjọ wo yala nigba to wa nipo gẹgẹ bi aarẹ ati lẹyin to fi ipo silẹ ni oloye Ọbasanjọ kọ.
Akọ́mọlédè àti Àṣà lórí BBC Yorùbá: Kọ̀ síi nípa iṣẹ́ tí oúnjẹ ń ṣe lára níbí
Oloye Ọbasanjọ ṣalaye ninu atẹjade naa pe, 'Lootọ ni mo bẹ Oloye Ayọ Adebanjọ wo ni ile rẹ to wa ni agbegbe Lekki Phase 1 ni ọjọ keji oṣu Kejila ọdun 2020 ti mo si pa Gani Adams nibẹ'.
Mi o ni ija tabi aawọ kankan bi o ti wulẹ o mọ pẹlu Gani Adams, ṣugbọn igbe aye rẹ atẹyinwa ti ko ba irinajo mi mu ni mo tako
Bi ẹnikẹni ba lero pe mo ni aawọ pẹlu oun to nilo ka pari, irufẹ ipari ija bẹẹ ko lee waye nibomiran yatọ si ile mi ni Abẹokuta.
Ooni Ile Ife: Emir Kano bẹ ààfin Ọọ̀ni wò, Ọọni Ogunwusi ṣàlàyé ìpayà tó gbòde lórí yíyọ tí Ganduje yọ Sanusi lóyé Emir Kano
Oríṣun àwòrán, Ile oodua
Ọọni ile ifẹ, Ọba Adeyẹye Ogunwusi ni ibẹru bojo gbode nigba ti ayipada ipo waye ni ilu Kano nitori gbogbo eeyan lo mọ pe bi wahala ba ṣẹlẹ ni ilu Kano, nnkan o lee rọrun lorilẹede Naijiria.
Ọọni ile ifẹ ṣalaye pe nigba ti ijọba ipinlẹ Kano rọ Emir Sanusi Lamido Sanusi loye to yan Emir Ado Bayero sipo, ọkan ọpọ eeyan lo n gbọn riri nitori ko si ẹni to mọ ibi ti afẹfẹ ọrọ naa yoo fẹ si.
Ọọni Adeyẹye Ogunwusi sọrọ yii lasiko ti Emir ilu Kano, Alhaji Ado Bayero bẹ ẹ wo ni aafin rẹ nilu Ile Ifẹ.
Ọlọrun ṣeun fun alaafia to jọba nigba ti Emir tuntun joye ni ilu Kano. Gbogbo wa lẹru ba lori iyipo pada to waye ni Kano nitori a mọ pe wahala yoo wa ni Naijiria bi wahala ba bẹ silẹ ni ilu Kano, ṣugbọn a dupẹ lọwọ Ọlọrun pe alaafia jọba.
Ọọni Ogunwusi ṣalaye pe lara ohun to mu alaafia jọba lorilẹede Naijiria ni irẹpọ to wa laarin awọn ọbalaye, paapaa julọ gẹgẹ bi Ọọni ana, Okunade Sijuwade Olubuse II, Emir ana ni ilu Sokoto, Alhaji Ado Bayero pẹlu Obi ana ni ilu Onitsha ṣe ba ara wọn dọrẹ pọ, eleyi to ni o ṣe ọpọlọpọ anfani fun orilẹede Naijiria.
Bakan naa ni Ọọni Ogunwusi tun ke sawọn agbaagba lorilẹede Naijiria lati ṣilẹkun silẹ fawọn ọdọ nitori, gẹgẹ bi o ṣe sọ,  awọn lo ni orilẹede Naijiria.
Lẹ́yìn ọ̀pọ̀lọ́pọ̀ oṣù tí òjò kò rọ̀ ní orílẹ̀èdè Cuba, Ọba ilẹ̀ Yorùbá ló
Ẹ jẹ ki a kọ wọn, ki a tun tun wọn kọ, eyi gan ni yoo mu idẹrun ba wa. A ko ni lati duro de ijọba, ki olukuluku ṣe ipa tirẹ lo tọ.
Ṣaaju ninu ọrọ rẹ ni Emir ilu Kano, ti pe fun, 'ajọṣepọ ati ajumọkẹgbẹ pọ lati finuwenu lori gbigbogun ti iṣoro to n koju eto ẹkọ, igbanisiṣẹ ati idagbasoke ilu laarin awọn ọdọ lorilẹede Naijiria nitori nipasẹ eyi ni ọna abays fun iṣoro atigbadegba to n koju orilẹede Naijiria lee ti yọju.'
Amotekun Osun: A ò gbé Amotekun kalẹ̀ láti máa yọjú sí ọ̀rọ̀ tí kò sí lábẹ́ òfin
SERAP and Pension: Àjọ SERAP ké sí Buhari lórí èròngbà àwọn Gómìnà láti ná N17trillion nínú owó ìfẹ̀yìntì òṣìṣẹ́
Oríṣun àwòrán, @SERAPNigeria
Ajọ ajafẹtọmọniyan kan ni Naijiria SERAP ti kesi aarẹ Buhari lati maa ṣe jẹ ki awọn Gomina ya triliọn mẹtadinlogun ninu owo ifẹyinti awọn oṣiṣẹ Naijiria.
Lọsẹ to kọja ni awọn Gomina kede ipinnu wọn lẹyin ti Gomina Nasir Elrufai jabọ ipade igbimọ ọrọ Aje lati ya ninu owo ifẹyinti oṣiṣẹ fun ipese awọn ohun amayedẹrun.
India: Ẹ wo bí àwọn ènìyàn ṣe  dóòlà èmí erin tó jálulẹ̀
Ninu lẹta kan ti igbakeji adari ajọ naa, Kolawole Oluwadare fi sita lọjọ Aiku o ni ''fifi aaye gba awọn Gomina lati ya ninu owo yi yoo ṣe akoba fawọn to ni owo naa''
O tẹsiwaju pe ''bi eeyan ba wo bi wọn ti ṣe n lu owo ifẹyinti ni ponpo ni Naijiria ati bawọn ipinlẹ kọọkan kii ṣe sootọ, ko yẹ ki wọn jẹ ki wọn  ya ninu owo yi''
Ninu iwe yi ti wọn tun fi ṣọwọ si Minisita eto idajọ Naijiria SERAP ni ko ba ofin ilẹ Naijiria mu ki awọn Gomina maa foju si owo ifẹyinti awọn oṣiṣẹ lara ni gbogbo igba.
O ni inu awọn yoo dun ti ijọba Buhari baa le sọ ''igbesẹ to ti n gbe lati kọdi awọn Gomina lati ma ṣe ya ninu owo yi laarin ọjọ mẹrinla tawọn fi iwe ranṣẹ sii''
SERAP wa sọ pe bawọn ko ba gburo esi kankan lati ọdọ ijba laarin ọjọ mẹrinla awọn yoo gbe igbesẹ nile ẹjọ lati jẹ ki ijọba ṣe ohun tara ilu n fẹ lori ọrọ yi.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ipinu awọn Gomina orileede Naijria labẹ aṣia ẹgbẹ Nigeria Governors Forum lati ya triliọnu mẹtadinlogun owo ifẹyinti awọn oṣiṣẹ ti n mu awuyewuye wa.
Ko si ṣẹyin bawọn Gomina ti ṣe sọ ipinu yi lẹyin ipade wọn to waye laipẹ yi pe awọn buwọlu aba meji ọkan ti wọn, ikeji ti banki apapọ CBN to fẹ ya ninu owo ifẹyinti oṣiṣẹ.
Ikede yi jẹ eyi ti ko dun mọ awọn oṣiṣẹ ninu ti wọn si ti tutọ soke foju gba a pe ki wọn maa dan wo rara.
Ninu ọrọ ti aṣoju awọn oṣiṣẹ fẹyinti sọ fun ileeṣẹ iroyin Naijiria Punch, wọn ni awọn Gomina ti ko da ipin ti wọn ninu owo ifẹyinti oṣiṣẹ ko lẹtọ lati ya ninu rẹ.
''Awọn Gomina ko lẹtọ si owo yii. Kii ṣe owo wọn tori naa bawo ni wọn ṣe fẹ buwọlu aba lati ya owo ti wọn ko da sinu rẹ?''
Oríṣun àwòrán, NGFSecretariat
Ìgbátí ìgbámú àná látọwọ́ sọ́jà obìnrin ti bá arákùnrin náà dé iléèwòsàn
Oríṣun àwòrán, NGFSecretariat
Bunmi Ogunkolade to jẹ olori ẹka iroyin ẹgbẹ oṣiṣẹ fẹyinti Nigerian Union of Pensioners ṣalaye si pe ''pupọ awọn ijọba ipinlẹ ni ko da si owo ifẹyinti oṣiṣẹ'' .
Ogunkolade ṣalaye siwaju pe awọn ti ṣaaju kilọ fun ijọba apapọ lati ma ṣe tọwọ bọ owo ifẹyinti awọn oṣiṣẹ to si fi kun pe awọn ni yoo san owo yi pada tawọn Gomina ko ba ribi daa pada.
Labẹ ofin to de eto owo ifẹyinti ni Naijiria, awọn alakoso owo ifẹyinti yi ni wọn lẹtọ lati fi owo yi dokowo lọna ti yoo pawo wọle fawọn to ni.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ohun ta gbọ ni pe iye owo apapọ to wa ninu akoto owo ifẹyinti awọn oṣiṣẹ Naijira to triliọnu mọkanla Naira le diẹ bayi.
Ohun tawọn Gomina lawọn fẹ fi owo yi ṣe ni eto ipese ohun amayedẹrun fara ilu ti Gomina Kayode Fayemi to jẹ alaga ẹgbẹ awọn Gomina si ni awọn ti buwọlu aba owo yiya yi pẹlu eyi ti banki apapọ naa sọ pe awọn fẹ ya ninu owo ifẹyinti oṣiṣẹ.
Awolowo: Àwọn èèkàn ìlú péjú s'Ibadan níbi ìsìnkú màmá Omotola àkọ́bí obìnrin Awolowo tó wọ káà ilẹ̀ lọ
Oríṣun àwòrán, Tribuneonline
Iku pa abiri, abiri lọ, iku pa abiri, abiri rọrun. Mama Omotola Oyediran tii ṣe akọbi lobinrin Oloye Obafemi Awolowo ti wọ kaa ilẹ lọ.
Awọn eekan lagbo oṣelu bii igbakeji aarẹ orilẹede Naijiria, Ọjọgbọn Yemi Osinbajo, Asiwaju Bola Tinubu, Gomina ipinlẹ Osun tẹlẹ ri, Bisi Akande lo peju pesẹ si ilu Ibadan lati ṣe ẹyẹ ikẹyin fun mama.
Gomina ipinlẹ Eko, Babajide Sanwo-Olu, Kayode Fayemi ti ipinlẹ Ekiti, Gomina Rotimi Akeredolu ipinlẹ Ondo, Aminu Tanbuwal atawọn ọtọkulu miiran lo wa nibi eto isinku ọhun ni Ibadan.
Ninu iwaasu rẹ, Alufaa Archbishop ijọ Methodist to ti fẹyin bayii, the Most Reverend Ayo Ladigbolu sọ pe mama Omotola fiwa jọ Oloye ati mama H.I.D. Awolowo nipa ṣiṣe aanu fawọn eeyan.
Alufaa Ladigbolu sọ pe Mama Omotola gbe igbe aye rẹ ni ibamu pẹlu ilana ti Oloye Awolowo la kalẹ ki o to papoda.
O fikun ọrọ rẹ pe olotitọ ati olododo eeyan to ṣe fi ọkan tan ni mama Omotola.
''Iwa to dara ti mama hu titi ti o fi jẹ Ọlọrun nipe, lọwọ awọn obi rẹ lo ti kọ gbogbo rẹ,'' alufaa Ladigbolu lo sọ bẹẹ.
Ìgbátí ìgbámú àná látọwọ́ sọ́jà obìnrin ti bá arákùnrin náà dé iléèwòsàn
Alufaa naa ko ṣai sọ iṣepataki awọn obinrin lawujọ, o ni iru awọn obinrin bii mama Omotola lo le mu idagbasoke ba Naijiria.
O rọ awọn alaṣẹ ni Naijiria lati fun awọn obinrin lanfani lati di ipo olori mu ki wọn le lo ẹbun ti Eleduwa fun wọn fun anfaani gbogbo araalu.
''Ajijagbara ati ajafẹtọ ọmọniyan ni mama Omotola titi ọjọ aye rẹ ti o fi jade laye,'' alufaa Ladigbolu lo sọ bẹẹ.
Mama Omotola ṣe igbeyawo pẹlu ọjọgbọn A.B.O.O. Oyediran to jẹ ọga agba ile ẹkọ fasiti ilu Ibadan, U.I. nigba kan ri.
"Kayeefi: 'Ọkọ mi ṣẹ̀ṣẹ̀ ní kí n lọ se mọ́í-mọ́í, tó ṣẹ̀ bá mi ṣeré tán ni mo gbọ́ pé ""Mopol"" yìnbọn pa á'"
Tola Oyediran ọmọ Obafemi Awolowo ti jáde láyé
Ọjọ kẹrindinlogun oṣu kẹwaa ọdun 2020 yii ni mama Oyediran fi aye silẹ.
Mama Omotola to jẹ ọkan ninu awọn ọmọ olootu ijọ iwọ oorun guusu Naijiria nigba kan ri, Oloye Obafemi Awolowo ko ba ṣe ayẹyẹ ọjọ ibi ọgọrin ọdun laye.
Oun ni omọ Awowlọwọ to dagba ju ki iku to mu un lọ.
Tola si ni alaga igbimọ alaṣẹ iwe iroyin Tribune titi ti o fi faye silẹ.
Alaafin Oyo: Oba Lamidi Adeyemi ní ''tí a bá yọwọ́ àwọn ọba alayé kúrò, kò ní sí Nàìjíríà mọ́
Oríṣun àwòrán, Facebook/Alaafin Oba Adeyemi III
Awọn Yoruba maa sọ pe agba ko ni tan lorilẹ. Eyi lo difa fun ọrọ nla kan ti Alaafin Oyo, Oba Lamidi Olayiwola Adeyemi sọ laipẹ yii laafin Oyo.
Alaafin ni ti a ba yọwọ awọn ọb alaye kuro, ko ni si ohun ti a n pe ni Naijiria mọ.
Alaafin sọrọ yii nigba ti Emir ilu Kano, Alhaji Aminu Ado-Bayero kan si i ni aafin rẹ niluu Oyo.
''Ni ọpọ igba ni mo ti kọ nipa iṣepataki ojuṣe awọn lọba lọba ninu idasoke orilẹede Naijiria,'' Alaafin lo sọ bẹẹ.
Alaafin sọ fun Ado-Bayero pe inu oun dun pẹlu baba rẹ to ti waja nitori awọn jọ ja fita fita fun ida marun un owo to n lọ si ijọba ibilẹ tawọn ọba n jẹ anfaani rẹ lonii awọn si ṣẹgun.
Oba Adeyemi ni oun yoo teṣiwaju lati maa ja fun awọn ọba alaye nitori awọn gan an ni oṣuka ti ko jẹ ki ẹru awujọ yi danu.
''Nitori naa, lai si awọn ọba alaye, ko le si ohun ti ba maa pe ni Naijiria mọ,'' Alaafin lo woye bẹẹ
Alaafin ko ṣai fi aidunnu rẹ lori eto iṣejọba ko ṣe gba ibi yan awọn ọba alaye mọ.
Oríṣun àwòrán, Facebook/Alaafin Oba Adeyemi
Ninu ọrọ tiẹ, Emir ilu kano Ado-Bayero sọ pe iyi lo jẹ fun oun lati ṣe abẹwo si Alaafin lode Oyo.
O ni oun pinnu lati kan si Alaafin fun itẹsiwaju ibaṣepọ to ti pẹ to wa laarin baba oun, Emir ilu Kano to ti waja ati Oba Adeyemi.
''A wa si ilu Oyo lati mu omi ọgbọn ati lati gba ire lọdọ Alaafin,'' Ado-Bayero lo sọ bẹẹ.
Ado-Bayero fikun ọrọ rẹ pe ilu Oyo ati kano ni ọpọ nkan ti wọn jọ ara wọn lati ẹka eto ẹkọ, aṣa to fi de ibi ọrọ okowo ati ọrọ-aje.
O ni ko si ẹni to le kọ iyan Alaafin kere ni Naijiria ninu ki eeyan mọ itan.
Ogun Police: Àwọn jàǹdùkú kọlu ọlọ́pàá, DPO faragbọta, ọlọ́pàá mẹ́rin di àwátì
Oríṣun àwòrán, AFP
Ìgbà àkọ́kọ́ kọ́ nìyí tí irú ìṣẹ̀lẹ̀ bẹ̀ yòó wáyé
Bi awọn to n ṣọ araalu ba di ẹni ti awọn janduku wa bẹrẹ si ni jigbe, kini ki ara yooku wa a ṣe?
Ibeere to gba ọkan awọn eeyan nipinlẹ Ogun ree lẹyin ti awọn janduku ji ọlọpaa mẹrin gbe ti wọn si tun yinbọn lu ọga agọ ọlọpaa, DPO, kan.
Ṣugbọn ohun taa tun ri gbọ lati ileeṣẹ ọlọpaa ipinlẹ Ogun, wọn ti ribi doola mẹta ninu awọn ọlọpaa tawọn janduku ji gbe yi.
Ladugbo Aba Tuntun, Ijebu Igbo ni ijọba ibilẹ Ijebu North ni  ipinlẹ Ogun niṣẹlẹ yi ti waye.
Alukoro ọlọpaa ipinlẹ Ogun, Abimbola Oyeyemi lo fi ọrọ yi to awọn akọroyin lati ọjọ Abamẹta.
O sọ pe ọlọpaa kan arakunrin Emmanuel Gene lo ṣi yi wa lọdọ awọn ajinigbe yi ati pe awọn ti da ọlọpaa sita lati ṣawari rẹ.
Nipa mimu awọn to wa nidi iṣẹlẹ yi, alukoro yi ni afurasi mẹta lawọn ti mu ti wọn si ti n wi tẹnu wọn nipa iṣẹlẹ yi.
Gẹgẹ bi Oyeyemi ti ṣe sọ, baalẹ abule naa lo fi iwe ranṣẹ si awọn ọlọpaa lati wa ba wọn koju awọn kan ti wọn ni nkan ija lọwọ,
''Ọga ọlọpaa agọ to wa ni Ijebu Igbo lo lewaju pẹlu awọn fijilante lati koju awọn obilẹjẹ yi.
Abalọ ababọ, wọn ri awọn ibọn atamatase mẹfa gba, ibọn ẹtu mẹrindinlogun ati ọta''
''Wọn mu awọn afurasi naa.
India: Ẹ wo bí àwọn ènìyàn ṣe  dóòlà èmí erin tó jálulẹ̀
Nigba ti wọn n gbe wọn lọ si agọ ọlọpaa lawọn janduku kan dawọn lọna ti wọn si ji ọlọpaa mẹrin gbe''
O fi kun un pe: ''Wọn yinbọn lu DPO ti wọn si tu awọn afurasi ti ọlọpaa mu silẹ''
Oyeyemi wa pari ọrọ rẹ pe awọn ti doola ọlọpaa mẹta ti iwadii si n tẹsiwaju lati ṣawari awọn ti o ku.
Ìgbátí ìgbámú àná látọwọ́ sọ́jà obìnrin ti bá arákùnrin náà dé iléèwòsàn
"Abike Dabiri-Erewa: Ìròyìn òfégè ní pé mò kò ""Palliatives""pamọ́ sí ilé mí"
Oríṣun àwòrán, Willy Ibimina Jim-george
Alaga ajọ to n risi ọrọ awọn ọmọ Naijiria lẹyin odi, Abike Dabiri Erewa ti ke gbajare lori iroyin to gbode pe o ko awọn nkan iranwọ Covid-19 pamọ sile rẹ.
Abike Dabiri-Erewa sọ pe iroyin ofege gbaa ni ọrọ yi.
Dabiri fesi si ọrọ yi ni idahun si ibeere akọroyin ile iṣẹ iroyin Vanguard lasiko idibo atundi to waye nipinlẹ Eko lọjọ Abamẹta.
Dabiri ni ẹsun toun ko mọwọ mẹsẹ ni wọn fi n kan oun.
Gẹgẹ bi iwe iroyin Vanguard ti ṣe sọ, wọn ni awọn kan ti ko foju han lo gbe iroyin naa sita loju opo ayelujara pe Dabiri ko awọn nkan iranwọ yi pamọ si ile rẹ to wa ni GRA Ikorodu.
Bẹẹ naa lo fi kun pe iroyin ofege naa tọka pe Abike Dabiri kọ orukọ oludije sipo Sẹnẹtọ Tokunbo Abiru si ara awọn nnkan iranwọ Covid yii.
Ninu idahun rẹ, Abike Dabiri ni '' O ya mi lẹnu lati kaa wi pe mo ko Palliatives pamọ  sile.Ko bimi ninu ṣugbọn mi o ro pe o yẹ ka wa ba ọmọluabi jẹ nitori oṣelu''
Nigba ti BBC kan si Sẹnẹtọ Dabiri loju opo Whatsapp rẹ lati fesi si ọrọ yi, o  fi aworan iroyin naa ranṣẹ lai sọ nkan mii mọ.
Oríṣun àwòrán, Abike Dabiri Erewa
Ìgbátí ìgbámú àná látọwọ́ sọ́jà obìnrin ti bá arákùnrin náà dé iléèwòsàn
Kìí ṣéé àwàdà, Ẹ wó arákùnrin Kenya tó 'jíǹde' ní mọ́ṣúárì tó padà wá kú
Oríṣun àwòrán, CitizenTV
Lẹyin ọsẹ kan ti iroyin gbode kan pe Peter Kigen jinde ni mọṣuari, arakunrin kan ni Kenya ti pada wa ku.
Gẹgẹ bi ohun ta ri ka lawọn iwe iroyin ilẹ naa, wọn ni lọsẹ to kọja lawọn to n tọju oku ṣaadede rii to taji lasiko ti wọn n palẹmọ oku rẹ.
Wọn ni niṣe lo bẹrẹ si ni pariwo ki o to wa pada tun daku nigba naa.
Arun to lagbara gan an n daamu Peter Kigen, ẹni ọdun mejilelọgbọn ti o si n gba itọju ni ile iwosan ki wọn to ni ko maa lọ sile.
Lọsẹ to kọja, o sọ fun ileeṣẹ iwe iroyin Daily Nation pe inu oun dun lati tun maa jẹ ero aye pada.
O sọ fun ileeṣẹ iwe iroyin naa pe ''Iṣẹ Ọlọrun ni''
Iroyin 'ajinde' rẹ yi mu kawọn eeyan maa ṣe eemọ loju opo ayelujara ni Kenya.
Oríṣun àwòrán, Kapkatet Hospital
Koda awọn aṣoju ile aṣofin Kericho County jiroro lori ọrọ yi.
Wọn tori rẹ ṣagbekalẹ igbimọ iwadii lati le tọ pinpin iṣẹlẹ yi.
Abajade kan sọ pe awọn oṣiṣẹ ilera ko ṣaṣemaṣe kankan ninu ọrọ yi.
Lọjọbọ lagbẹnusọ mọlẹbi rẹ kan sọ fun ileeṣẹ iwe iroyin Standard newspaper pe: ''Nigba ti  a gbe Kigen de ile iwosan Kericho County Hospital lati Kapkatet, wọn sọ fun wa pe o ti dakẹ''
Ọgbẹni Hezbon Tonui  ni awọn gbe e lọ sibẹ lati gba itọju to peye si i ni ṣugbọn ẹpa ko boro mọ.
India: Ẹ wo bí àwọn ènìyàn ṣe  dóòlà èmí erin tó jálulẹ̀
Overweight and pot belly: Wo oríṣìí oúnjẹ márùn ún tó lè dẹ́kun ikùn yíyọ àti ara àsanjù
Oríṣun àwòrán, Food Ace
Njẹ iwọ ominu n kọ ẹ lori bi o ṣe n yọkun tabi bi o ṣe n tobi sii?
Wo ọna ti o le gba dẹkun yiyọkun ati titobi sii pẹlu alaye onimọ nipa ounjẹ jijẹ yii.
Akọṣẹ-mọṣẹ nipa ounjẹ jijẹ to tun jẹ nọọsi, Adanna Monday ni o ṣe pataki ki onikaluku maa se ounjẹ to ba fẹ jẹ fun ra rẹ.
Bakan naa lo sọ pe o yẹ ki eeyan ni gbedeke ounjẹ ti yoo maa jẹ nigba kuu gba.
Ninu ọrọ rẹ, ''jijẹ ounjẹ lasiko ati deedee le jẹ ki ara asanju, aisan bii ẹjẹ ruru ati arun itọ ṣuga jina si agọ ara eeyan.''
Isọri ounjẹ marun un ree ti o le jẹ lati maa sanra asanju tabi yọkun
1. Eso
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Nọọsi Adanna sọ pe jijẹ oriṣiiriṣii eso bii mọngoro, ọsan oronbo atawọn eso mii dara fun ilera agọ ara.
Cancer: Àṣe ara mi ni iso ti n run gbogbo bí mo ṣe n ṣèrànwọ́ lórí jẹjẹrẹ
O eso bi ''apple'' ati ''strawberries'' jẹ eso aṣara loore ati pe ko ni jẹ ki ọra pọju ninu agọ ara.
Adanna ni irufẹ awọn eso yii ni ohun aṣara loore kan ti wọn n pe ni ''fibre'' ninu.
2. Ẹfọ tabi ewebẹ
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Nọọsi Adanna ni jijẹ ewe ''pumpkin'' ati amunututu dara fun agọ ara.
O ni bi awọn ewe ẹfọ yii ti dudu were were lo jẹ ki o ṣe anfaani fun ara.
Adanna ni iru awọn ewe yii lo maa n kọju ija arun to le ṣuyọ ninu agọ ara.
3. Ẹja ati ẹran adiẹ
Oríṣun àwòrán, Getty Images
''Jijẹ ẹja bi ẹja abori tabi ẹja crocker yoo ṣeranwọ lati maa sanra ju tabi yọkun,''Adanna lo sọ bẹẹ.
O fikun ọrọ rẹ pe ẹran adiẹ ati tolotolo naa wulo nitori wọn maa n dena arun ninu ara.
Adanna ni irufẹ ẹran bayii ko ni jẹ ki ara sun soju kan naa eyi to le nu eeyan yọkun tabi sanra ju.
4. Ounjẹ afara lokun
Oríṣun àwòrán, Food Ace
Adanna ṣalaye siwaju pe awọn ounjẹ afara lokun bi irẹsi ti eeyan ba kore rẹ ninu oko dara fun ara.
O ṣalaye pe iru ounjẹ bẹẹ to fi mọ ananmọ maa n ko ni jẹ ki ọra pọ lara eeyan eleyi to le mu tobi tabi yọkun.
5. Awọn ounjẹ ọlọra aṣaraloore
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Awọn ounjẹ bi ẹpa, ororo olifi, ẹja mọnkẹrẹ ati avocado ni ọra to le ṣe ara loore ninu.
Adanna ni awọn ounjẹ yii dara fun ọkan ṣugbọn ajẹju wọ ko dara.
Akọṣẹ-mọṣẹ nipa ounjẹ ọhun ajẹju awọn ounbjẹ yii le mu ki eeyan sanra ju tabi yọkun.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Lakotan, Adanna rọ awọn eeyan lati maa mu omi to pọ tabi jẹ eso to ni omi ninu daadaa..
Promise Akinlade: ọmọ ọdún mọ́kànlá tó ń fi ìlù dárà bíi àgbàlagbà sọ̀rọ̀ nípa tálẹ́ǹtì rẹ
Tottenham sọ ọjọ́ ìsinmi olóyin di ''Black Sunday'' mọ́ Arsenal lọ́wọ́ pẹ̀lú ìgbájú-ìgbámú
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ti eleyi kii ba ṣe ijamba nla? Ẹ jọwọ kinni ka ti pe eyi naa?
Igbaju igbamu ni kẹri kẹri n ba rode ni ẹgbẹ agbabọọlu Tottenham fi ṣe fun Arsenal ninu ifẹsẹwọnsẹ wọn ọjọ Aiku ninu idije Premier League.
Afi bi ala ni ọrọ naa ri nigba tawọn ẹgbẹ agbabọọlu olorogun mejeeji ti wọn fi apa ariwa ilu London ṣe ibujoko kọju ija si ara wọn.
Ki a to wi, ki a to fọ, ẹlẹsẹ ayo, Heung-Min Son ṣi gbada lori Eṣu lẹyin to gba goolu goolu aramọnda kan wọle Arsenal ni bii iṣẹju mẹtala.
Arsenal gbiyanju lati da goolu naa pada, ṣugbọn pabo ni gbogbo igbiyanju ja si.
Amọ eruku tun sọ lala nigba to ku diẹ ki ipele akọkọ ifẹsẹwọnsẹ naa pari lẹyin ti Harry Kane gbayo mii wọle Arsenal.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Gbogbo igbiyanju Arsenal lati gbayo wọle Tottenham ni ipele keji ifẹsẹwọnsẹ ọhun, pabo lo ja si.
Arsenal ti wa ni ipo kẹẹdogun bayii lori tabili idije Premier League.
Ifẹsẹwọnsẹ mẹfa ọtọtọ ni wọn ti fidi rẹmi rẹmi bayii bayii ninu mọkanla ti wọn ti gba ni saa bọọlu tuntun yii.
Ẹgbẹ agbabọọlu Tottenham ti Jose Mourinho jẹ akọnimọọgba wọn lo si wa loke tente bayii lori tabili idije EPL.
Ghana 2020 election: Jean Adukwei Mensa,Tani akíkanjú obìnrin tí yóò kéde èsì ìbò aàrẹ Ghana?
Ghana Electoral Commission [EC] Jean Mensa
Jean Adukwei Mensa ni ẹni ti gbogbo eeyan yoo maa foju si lara gẹgẹ bi alaga ajọ eleto idibo Ghana lọdun 2020.
Ohun ni yoo mojuto eto idibo ti ikede ẹni to ba jawe olubori yoo si tẹnu rẹ jade ninu idibo ti yoo waye lọjọ Keje osu Kejila ọdun yi.
Ṣaaju asiko yi ni ajọ eleto idibo Ghana ti ni awọn yoo ri pe idibo ti ko laahẹ ninu waye koda wọn tun pese nọmba ibaraẹnisọrọ tawọn eeyan le pe si ti wọn ba ri aiṣedede kankan.
Nọmba naa ti wọn ko ni sanwo lati pe si ni (0800-100-100).Anfaani wa lati pe nọmba yi lati ago mẹfa aarọ di ago mẹfa irọlẹ.
Die ree lara ohun to yẹ ko mọ nipa alaga ajọ eleto idibo Ghana [Jean Adukwei Mensa].
Oríṣun àwòrán, Presidency of Ghana
LOati igba to ti dori oye lọdun 2018, awn kan ti n naka abuku si pe ti ijọbọ ori aleefa lo n ṣe
Oríṣun àwòrán, Ghana web
Ondo 2020 Tribunal: Ìgbìmọ̀ olùgbẹ̀jọ́ ìbò gómìnà yóò gbérasọ lọ́jọ́ Iṣẹgun
APC,PDP, ZLP àtawọn ẹgbẹ́ miran ni Ondo
Igbimọ igbẹjọ idibo Gomina ipinlẹ Ondo ti n palẹmọ lati  bẹrẹ ijoko.
Ninu idibo naa to waye ni ọjọ Kẹwaa, oṣu Kẹwaa, ọdun 2020 ti Gomina Rotimi Akeredolu ti ẹgbẹ oṣelu APC lo gbegba oroke.
Adajọ Umar Abubakar ni yoo lewaju awọn adajọ meji mii ti yoo gbẹjọ ọhun bẹrẹ lati ọjọ Kẹjọ oṣu Kejila ọdun 2020.
Agboola Ajayi: Igbákejì gómìnà ìpínlẹ̀ Ondo tó fẹ́ yẹ àga mọ́  Akeredolu nìdí
Agbẹjọro oludijẹ ẹgbẹ PDP, Eyitayo Jegede tii ṣe Onyechi Ikpeazu lo fiwe pe Gomina Akeredolu ati ẹgbẹ APC fun aṣemaṣe to tako ofin ilẹ yi.
Lara kudiẹkudiẹ to mẹnu ba ni pe Gomina Akeredolu kọ ni ẹgbẹ rẹ dibo yan lati ṣoju wọn ninu idibo Gomina.
Ni ibamu pẹlu ohun tofin ilẹ yi sọ, o ni Gomina ipinlẹ ko le jẹ alaga ẹgbẹ ti yoo yan ẹlomii lati dije dupo.
O salaye pe Gomina ipinlẹ Yobe, Mai Mala Buni lẹni to tako ofin yi nipa pe o di ipo alaga ẹgbẹ APC mu to si tun yan Akeredolu lati dije dupo Gomina.
Yatọ si alaye yi gẹgẹ bi kan lara idi ti ko yẹ ki wọn fi gba  iyansipo Akeredolu wọle, Jegede tun ni iwa janduku waye lawọn ijọba ibilẹ kan ati aaye idibo lawọn ibomiran.
Promise Akinlade: ọmọ ọdún mọ́kànlá tó ń fi ìlù dárà bíi àgbàlagbà sọ̀rọ̀ nípa tálẹ́ǹtì rẹ
Death During Sex: Àwọn nǹkan mẹ́ta tó le ṣekú pa ọkùnrin lásìkò ìbálòpọ̀ rèé
Oríṣun àwòrán, © ROYALTY-FREE / CORBIS
Lọpọ igba la maa n gbọ iroyin pe ọkunrin tabi obinrin re sọda di ero ọrun lasiko ibalopọ.
Lara ohun to n fa iru iku yi la gbọ pe ailera wa, ailemidaada tabi awọn ipenija ara miran.
Ṣugbọn iwadii awọn onimọ ti n waye lati mọ ohun pato to le ṣokunfa ki eeyan ku lasiko ibalopọ.
Dokita Issa Dahabreh ti ile iwosanTufts Medical Center to wa ni Boston, Amẹrika ri ẹri pe irẹwẹsi ọkan a maa ṣe okunfa iku awọn eeyan lasiko ibalopọ.
Cancer: Àṣe ara mi ni iso ti n run gbogbo bí mo ṣe n ṣèrànwọ́ lórí jẹjẹrẹ
O ni lasiko ibalopọ, ibalopọ dabi ere idaraya ti yoo mu ki ara eeyan ji pepe.Fawọn ti kii baa ṣe igbaradi tabi ere idaraya loore koore eyi le mu ki wọn maa kaju oṣunwọn to.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ki lo le ṣekun pa ọkunrin lasiko ibalopọ?
1) Lilo oogun ṣaaju ibalopọ
Awọn oogun amarajipepe kan wa tawọn eeyan maa n ra lati lo fun ibalopọ.Ninu wọn ni Viagra wa.
Tohun ti pe awọn dokita sọ pe o le mu ki nkan ọmọ ọkunrin gbera daada, ko yẹ ki eeyan maa lo ni gbogbo igba to ba fẹ ni ibalopọ
Eyi lo mu ki ọpọ awọn ọkunrin to ba ni aisan ọkan (pupọ ni kii mọ pe awọn ni gaan) maa ni ipenija lasiko ibalopọ ti eyi a si maa fa iku fawọn miran ti ọkan wọn ko ba gbe agbara oogun naa.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ohun tawọn dokita sọ ni pe ki eeyan lo ẹyọ kan tabilẹti oogun yi ṣaaju ibalopọ ṣugbọn awọn mii maa n lo ju bẹ lọ.
2) Aisan ọkan:
Dr McGinger Ibeneme sọ fun BBC pe nitori ibalopọ a maa mu ki eeyan ṣiṣẹ agbara, eyi le ṣakoba fẹni ba ni aisan kan.
O ni bi kaṣan to n gbe ẹjẹ ko ba lagbara to, ti ẹjẹ baa n gba inu rẹ lasiko ibalopọ, o le dipọ ti eyi yoo si ṣakoba fẹni naa.
Promise Akinlade: ọmọ ọdún mọ́kànlá tó ń fi ìlù dárà bíi àgbàlagbà sọ̀rọ̀ nípa tálẹ́ǹtì rẹ
O tun fi kun pe isọwọ bi ẹjẹ ṣe n tu gba inu kaṣan lasiko ibalopọ ti wọn n pe ni ''adrenaline rush'' le mu inira wa lasiko ibalopọ.
Koko ọrọ ni pe bi ẹjẹ ba n tu yaya ninu ara pupọ, ti ko ba si atẹgun to n gba inu ẹjẹ naa bo ti ṣe yẹ, eeyan n kọ lẹta si iku ni yẹn.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
3) Rọ lapa rọ lẹsẹ:
Dokita  Ibeneme sọ pe ti eeyan ba n ni ibalopọ pupọ paapa ẹni to ba ni ifunpa to ga, o le ṣakoba fun un .
Awọn onimọ sọ pe o ṣoro ki eeyan to ba gba ọna yi rọ lapa ko ku ṣugbọn eeyan le rọ lapa nipa ibalopọ.
Ojú mi ti rí lọ́pọ̀ lọpọ̀, àmọ́ mo dúpẹ́ pé mo ti pé ọdún márùn ún lórí oyé- Ooni
Oyo physically challenged protest: Ìdí rèé táwọn àkàndá ẹ̀dá fi dí iwájú iléeṣẹ́ ìjọba ìpínlẹ̀ Oyo pa l'Agodi n'Ibadan
Oríṣun àwòrán, Megaiconmagazine
Sunkẹrẹ fakẹrẹ gbode kan l'Agodi niluu Ibadan lọjọ Aje ọjọ keje oṣu kejila ọdun 2020 yii lẹyin tawọn onipenija ara bọ soju popo lati fẹhonuhan.
Awọn akanda ẹda ọhun to wa lati ijọba ibilẹ mẹtalelọgbọn kaakiri ipinlẹ Oyo lu oju opo ileeṣẹ ijọba to wa lagbegbe Agodi n'Ibadan pa.
Ohun ti wọn n beere ni pe ki ijọba gba awọn onipenija ara sii ninu awọn oṣiṣẹ ti kii ṣe awọn olukọ lawọn ileewe kaakiri ipinlẹ Oyo.
Laipẹ yii ni Gomina Seyi Makinde sọ pe ki ajọ to n ri si ọrọ awọn olukọ gba ẹgbẹrun un meje olukọ, ati ẹgbẹrun un meji awọn ti kii ṣe olukọ nipinlẹ Oyo.
Gomina Makinde tun sọ pe ki wọn gba awọn oṣiṣẹ eleto abo megaadi ẹgbẹjọ.
Amọ awọn akanda eeyan to n ṣe iwọde ṣalaye pe awọn ti ijọba mu ninu awọn ti kere ju.
Promise Akinlade: ọmọ ọdún mọ́kànlá tó ń fi ìlù dárà bíi àgbàlagbà sọ̀rọ̀ nípa tálẹ́ǹtì rẹ
Wọn ni awọn n rawọ ẹbẹ si Gomina Makinde lati wa nkan ṣe si ọrọ naa.
Awọn olufẹhonuhan naa duro wamu wamu sẹnu geeti to wọ ileeṣẹ ijọba ipinlẹ Oyo eleyi ti ko jẹ kawọn oṣiṣẹ ri aye wọle.
Awọn to ni ipenija ara sọ pe awọn lo sun mọ oṣi ati iṣẹ ju awọn abarapa eeyan lọ.
Cancer: Àṣe ara mi ni iso ti n run gbogbo bí mo ṣe n ṣèrànwọ́ lórí jẹjẹrẹ
Ọkan lara awọn akanda ẹda naa to bawọn akọroyin sọrọ, Adegbuyi Adekunle ṣalaye pe ida marun un ninu ọgọrun tii ṣe 350 lo yẹ ki wọn fawọn.
O ni eeyan mọkandinlaadọjọ(149) pere ni ijọba fun ni iṣẹ ninu awọn ti wọn ṣẹṣẹ gba.
Oba Adeyeye Ogunwusi: Ojú mi ti rí lọ́pọ̀ lọpọ̀, ọ̀pọ̀ èèyàn ni kò tilẹ̀ gbàgbọ́ pé mo lè jọba- Ooni
Irin ajo mi kun fun oriṣiiriṣii iṣẹlẹ nla ṣugbọn mo dupẹ lọwọ Ọlọrun O ka mi yẹ.
Ooni Ile Ife, Oba Adeyeye Enitan Ogunwusi lo sọrọ yii nigba to n dupẹ lọwọ Eleduwa fun anfaani ti o ni lati pe ọdun marun un lori itẹ baba rẹ.
Ọba Ogunwunsi ni oju oun ti ri lọpọ lọpọ ninu irin ajo ki oun to jọba.
Ooni sọ pe irin ajo oun kun fun oriṣiiriṣii iṣẹlẹ nla, ati pe ọpọ ni ko gbagbọ pe oun le de ori ọtẹ gẹgẹ Ooni Ile Ife.
Oba Ogunwunsi ni oni ni a ri ko si ẹda to mọ ọla, o ni oun ko le dupẹ tan lọwọ ọlọrun.
Victoria Kolawole: Òṣèré tíátà Yorùbá ní òun kò tíì ṣe ìgbéyáwó àmọ́ òun kò wá ọkọ''
Oríṣun àwòrán, Instagram/victoriakolawole
Oṣere tiata Yoruba Victoria Kolawole sọrọ o fa komookun rẹ yọ ninu ifọrọwerọ pẹlu BBC Yoruba.
Victoria ya agbado ha sawọn eeyan lẹnu nigba to fesi si ibeere ti ẹnikan beere pe kilode to maa fi n ṣi ara silẹ.
Idahun rẹ ni pe ara oun rẹwa lo jẹ ki oun maa ṣi ara mi silẹ.
Ti ẹrin ti ọyaya ni Victoria fi ṣalaye pe ti Ọlọrun ba ṣe ore fun eeyan, ko yẹ ki eeyan maa pa a mọ ra.
''Emi nikan ko le maa da ara mi wo ni jare, ẹ maa binu si mi,'' osẹre Victoria lo sọ bẹẹ.
Nigba ti o sọ nipa bi o ṣe bẹrẹ ere ori itage, Victoria ni awọn obi oun ko kọkọ gba pe ki oun ṣe ere ori itage.
Akomolede ati Asa lori BBC: Olùkọ́ Kikelomo  Ogunboye tan ìmalẹ̀ sí ìwà olè ọ̀gá ọlọ́pàá
Mama mi tiẹ kunlẹ bẹ mi wi pe ki n maa ṣe ere ori itage nitori ''baba mi ko gbọdọ gbọ.''
Victoria ni baba oun fẹ ki oun kawe di dokita tabi agbẹjọro ni.
''Ṣugbọn nigba ti owo bẹrẹ si ni wọlẹ, niṣe ni wọn gbaruku ti mi,'' Victoria lo sọ bẹẹ.
''Koda ọkunrin ti mo n fẹ tẹlẹ atawọn obi rẹ naa sọ pe ko le fẹ oṣere,'' Victoria lo ṣalaye bẹẹ.
O ni oun ni lati fi ọrẹkunrin naa silẹ nitori ifẹ ti oun ni si ere tiata.
Oṣere Victoria sọ pe oun ti n ṣere fun bi ọdun mẹwaa bayii.
O tun ṣalye pe awọn ti wọn ni ibalopọ lagbo oṣere tiata nitpri ko si ẹni to le fi tipa mu wọn.
Promise Akinlade: ọmọ ọdún mọ́kànlá tó ń fi ìlù dárà bíi àgbàlagbà sọ̀rọ̀ nípa tálẹ́ǹtì rẹ
Victoria ni oṣerekunrin ti ka mi mọ inu yara nile itura ri nibi tawọn ti n ṣere, ṣugbọn ọgbọn ni oun fi le e jade.
Bakan naa ni oṣere naa sọ pe oun ko ti lọ sile ọkọ, amọ oun ko wa ọkọ, ''ẹnikan si wa loju ọpọ bayii.''
Fake Kidnap: Ọlọ́pàá Eko ń wá arákùnrin tó parọ́ gba owó ìjínigbé 700k lọ́wọ́ mọ̀lẹ́bí ọ̀rẹ́bìnrin rẹ̀
Oríṣun àwòrán, LagosPoliceng
Ọwọ palaba arabinrin kan to gbimọran pẹlu ọrẹkunrin r pe ko ji oun gbe ti ṣegi.
Ileeṣẹ ọlọpaa ipinlẹ Eko lo kede ọrọ yi lasiko ti wọn ṣafihan awọn afunrasi ọdaran tọwọ tẹ fun orisi ẹsẹ.
Olumuyiwa Adejobi to jẹ alukoro ọlọpaa ni arabinrin Precious Chukwu ẹni ọdun mejilelogun ati Ujunwa Offiah jijọ lẹdi apo pọ pẹlu Ifesinachi Blessed lati parọ pe awọn ji Ujunwa gbẹ.
Ninu alaye rẹ, o ni Precious ati Ujunwa jẹ ọrẹbinrin si Ifesinachi to n ṣiṣẹ awakọ takisi Uber. Ifesinachi ti na papa bora bayi.
Olumuyiwa tẹsiwaju pe niṣe ni Ifesinachi gbe Ujunwa pamọ sibi kan to si pe awọn mọlẹbi rẹ pe ki wọn san ọgbọn miliọnu lati fi doola rẹ.
Lẹyin ọpọ atotonu, awọn mọlẹbi Ujunwa san ẹgbẹrun lọna ẹẹdẹgbẹrin Naira fun Ifesinachi.
Iwadii ọlọpaa lẹyinwa ṣafihan pe arumọjẹ ijingbe lo waye ti wọn si gba Ujunwa ati Precious to ṣalatilẹyin fun Ifesinachi.
Lọwọlọwọ bayii, wọn ko mọ ibi ti Ifesinachi sa lọ ṣugbọn Ujunwa ati Precious tawọn mejeeji jẹ ọrẹbinrin Ifesinachi ti wa lahamọ ọlọpaa.
Yatọ si awọn afurasi yi ti wọn ṣafihan wọn, wọn tun fi arakunrin ogboju ọlọṣa kan Fatai Ismail han.
Oríṣun àwòrán, LagosPoliceng
Fatai  ti inagijẹ rẹ n jẹ 'small'  ni wọn sọ pe o n damu awọn eeyan Langbasa ladugbo Ajah.
Alukoro ọlọpaa ni ọwọ ọlọpaa tẹ Fatai plu iranwọ awọn fijilante ati ara adugbo lasiko to lọ fọ ile itaja nla kan ni Ajah.
Akomolede ati Asa lori BBC: Olùkọ́ Kikelomo  Ogunboye tan ìmalẹ̀ sí ìwà olè ọ̀gá ọlọ́pàá
Ghana election: Ààrẹ Akufo-Addo la Mahama mọ́lẹ̀ wọlé ìbò ààrẹ Ghana fún sáà kejì
Oríṣun àwòrán, Facebook/Nana Akufo-Ado
Aarẹ orilẹde Ghana, Nana Akufo-Addo ti wọlẹ ibo aarẹ ilẹ fun saa keji.
Ọga ajọ eleto idibo ilẹ Ghana, Jean Mensa lo kede pe Akufo-Addo la alatako rẹ, John Mahama mọlẹ ninu eto idibo naa.
Ọjọ Aje ni eto idibo naa tawọn ọmọ orilẹede Ghana ti tu yaya tu yaya jade dibo waye.
Ta ni Nana Akufo- Addo to wọle ibo aarẹ Ghana lẹẹkeji?
Ọjọ kọkandinlọgbọn oṣu kẹta ọdun 1944 ni wọn bi Akufo-Addo ni Accra tii ṣe olu ilu orilẹede Ghana.
Ọgbẹni Akufo-Addo kii ṣe aimọ fuloko lagbo oṣelu orilẹede Ghana.
O ṣiṣẹ gẹgẹ bi agbẹjọro agba orilẹede Ghana laarin ọdun 2001 si ọdun 2003.
Oríṣun àwòrán, Facebook/Nana Akufo-Addo
Bakan naa ni Akufo-Addo jẹ minisita ọrọ ilẹ okeere laarin ọdun 2003 si 2007 labẹ aṣẹ Aarẹ John Kuffour.
Oun si ni alaga ajọ ECOWAS to n ri si ọrọ aje awọn orilẹede to wa ni iwọ oorun ilẹ Afirika bayii.
Afo-Addo ti kọkọ dije fun ipo aarẹ labẹ asia ẹgbẹ oṣelu NPP lọdun 2008 ati 2012 ṣugbọn o fidi rẹmi lẹẹ mejeeji.
Lọjọ kẹsan an oṣu kejila ọdun 2016 ni Akufo-Addo tun gbegba ibo aarẹ ninu eyi to ti fẹyin aarẹ Johna Mahama to wa lori oye gbalẹ ti o si wọle.
Mahama naa lo tun fidi rẹmi bayii lẹyin nti Akufo-Addo wọle fun saa keji.
Secret Cults in Nigeria: Ìyá àti ọmọ tó wà nínú Márúwá bá ìjà ẹgbẹ́ òkùnkùn lọ
Ko din ni ogun eeyan to dagbere faye nigba ti ọpọ miran fi ara gbọgbẹ lorisirisi lasiko tawọn tawọn ẹgbẹ okunkun fija pẹẹta nilu Ijebu Ode.
Gẹgẹ bi iwe iroyin Punch ti sọ, ọsẹ meji sẹyin ni ija naa ti bẹrẹ, ti apapọ iye eeyan to si ti ba rin ti le ni ogun.
Iroyin naa ni ẹgbẹ okunkun Eiye ati Aiye ni wọn n doju ija kọ ara wọn, eyi to mu ki ohun gbogbo poluku musu lawọn agbegbe kan nilu naa.
Lara awọn adugbo ta gbọ pe ọrọ naa kan ni Gareeji Epe, Ejinrin Road, Adefisan, Gareeji Ibadan, Onirugba, Tatina ati oju ọna Benin si Ondo.
Koda wọn ni iya kan ati ọmọbinrin rẹ, ti wọn wa ninu kẹkẹ Maruwa ni ọta ibọn seesi ba, ti wọn si jẹ Ọlọrun nipe.
Oriṣiriṣi ọna ni eto igbani wọle maa n gba ninu awọn ẹgbẹ okunkun
Ọpọ eeyan niroyin naa lo ku iku aimọdi lati ipasẹ wahala naa ni gareeji Epe, Road, Adefisan, Gareeji Ibadan, Onirugba, Tatina ati oju ọna Benin si Ondo.
Bẹẹ si ni ọpọ awọn eeyan lo n sa asala fun ẹmi wọn lasiko rogbodiyan awọn ọmọ ẹgbẹ okunkun naa.
Oríṣun àwòrán, verifiedNG
Lẹyin bi ọsẹ meji ti ọdọbinrin kan danu sun ile ọrẹkunrin rẹ nibi ti ina ti mu ololufẹ rẹ to wa nile, ọdọbinrin mii tun ti dana si ọrẹkunrin rẹ lara ni ijọba ibilẹ Gboko nipinlẹ Benue.
Iroyin ti a gbọ ni pe ọdọbinrin naa gbe igbesẹ yii lẹyin ti ololufẹ rẹ lati ṣe igbeyawo pẹlu rẹ.
Ohun tawọn to mọ nipa iṣẹlẹ naa sọ ni pe ọdọbinrin yii sọna si ile ololufẹ rẹ lẹyin ọkunrin naa ti orukọ rẹ n jẹ Jude atawọn ti sun tan.
Ni deedee aago kan aabọ oru ni a gbọ pe obinrin yii lọ ṣiṣẹ laabi ọhun.
Ṣugbọn ori ko awọn to wa ninu ile yọ bo tilẹ ina mu Jude eyi to mu ki ara rẹ bo yanayana.
Apa ina ko pọju lara mama rẹ ati aburo rẹ ọkunrin ti wọn jọ wa nile lasiko iṣẹlẹ naa.
Ojú mi ti rí lọ́pọ̀ lọpọ̀, àmọ́ mo dúpẹ́ pé mo ti pé ọdún márùn ún lórí oyé- Ooni
Awọn mẹtẹẹta ti wa ni ile iwosan bayii nibi ti wọn ti n gba itọju fun ara wọn.
Agbẹnusọ ileeṣẹ ọlọpaa ipinlẹ Benue, DSP Catherine Anene fidi iṣẹlẹ naa mulẹ fawọn akọroyin.
Akomolede ati Asa lori BBC: Olùkọ́ Kikelomo  Ogunboye tan ìmalẹ̀ sí ìwà olè ọ̀gá ọlọ́pàá
Anene ṣalaye pe lootọọ nile iṣẹ ọlọpaa gba ipe pe ọdọbinrin kan tu epo si ile ọrẹkunrin rẹ ti o si tun fi ina sii.
Amọ agbẹnusọ ileeṣẹ ọlọpaa awọn ko tii ri ọdọbinrin naa mu.
Cancer: Àṣe ara mi ni iso ti n run gbogbo bí mo ṣe n ṣèrànwọ́ lórí jẹjẹrẹ
Ooni Ile Ife: Ooni Adeyeye Ogunwusi àti Olòrì Naomi gbé Àrẹ̀mọ tuntun wọ ṣọ́ọ̀ṣì
Oríṣun àwòrán, Ooniadimula
Latari ayẹyẹ iwuye ọdun marun lori itẹ ti Ọọni Adeyeye Enitan Ogunwusi n ṣe, Kabiyesi ti fi idupẹ kadi ayẹyẹ naa nilẹ pẹlu lilọ si ile ijọsin lọ dupẹ lọwọ Oluwa.
Pataki lara awọn to ba Ojaja II wọ ṣọọṣi ni Arẹmọ tuntun ti Eleduwa ṣẹṣẹ fi jinkii oun ati iyawo rẹ, wolii Naomi iyẹn  Arẹmọ Tadenikawo Adesoji Aderemi Ogunwusi.
Oríṣun àwòrán, Ooniadimula
Ṣe ni ile ijọsin kun amọ pẹlu ofin ijina sira ẹni laarin awọn oloye Ile Ife, awọn ọtọkulu ilu araali Ife ati tẹbi tara to wa ba Kabiyesi ṣe ajọyọ.
Ninu ile ijọsin St Paul's Anglican Church, Ayegbaju, Ile-Ife ni Ọọni ti lọ fi ẹmi imore rẹ han si Oluwa.
Pẹlu gbogbo ogo si Ọlọrun to ga julọ to mu mi de ibi ti mo de yii lori it awọn baba mi. Mo ba wọn jọsin nile ijọsin atibẹrẹpẹpẹ ẹbi mi, St Paul's Anglican Church, Ayegbaju, Ile-Ife loni lati fi ọpẹ fun Oluwa ati lati kasẹ ayẹyẹ ọdun marun ti mo pe lori itẹ.
Oríṣun àwòrán, adesola_ogunwusi
Laipẹ yii ni wọn gbe Arẹmọ Tadenikawo wọ inu aafin Ile Ife fun igba akọkọ ti wọn si fi oju rẹ han faraye fun igba akọkọ.
'Pásítọ̀ ló sọ fún mi pé Ọlọ́run pè mí láti di Olokun tó ń bọ omi'
Oríṣun àwòrán, Ooni Palace
Ọọni ti Ile Ife to tun jẹ Arole Oodua, Ọọni Adeyeye Enitan Ogunwusi, Ọjaja II ti fi oju ọmọ wọn han faraye fun igba akọkọ lọjọ Iṣẹgun ọsẹ.
Ọọni gbe Arẹmọ Tadenikawo Adesoji Aderemi Ogunwusi wọ inu aafin Ile Ife fun igba akọkó.
Awọn AGBA IFE ti Ile Ife lo tẹwọ gba a lati ki i kaabọ eyi ti Obalufẹ ti Ifẹ, Oba Idowu Adediwura, dari wọn.
Awọn oloye miran to wa nibẹ ni awọn MODEWA eyi ti Lowa, Adimula Ife, Oloye Adeola Adeyeye dari, to fi mọ awọn EMESE eyi ti Sarun Oriowo Oyeyemi dari.
Ojú mi ti rí lọ́pọ̀ lọpọ̀, àmọ́ mo dúpẹ́ pé mo ti pé ọdún márùn ún lórí oyé- Ooni
Gbogbo wọn pata lo ki Arẹmọ ati iya rẹ, Olori ShilekunOla Ogunwusi (Yeyeluwa), ẹbi, ara ati ojulumọ kaabọ si aafin.
Promise Akinlade: ọmọ ọdún mọ́kànlá tó ń fi ìlù dárà bíi àgbàlagbà sọ̀rọ̀ nípa tálẹ́ǹtì rẹ
World Aniti-Corruption day: Awolowo, Azikwe, Abacha àtàwọn olórí ìjọba tí aje ìwà ìjẹkújẹ ti ṣí mọ́ lórí rí ní Nàìjíríà
Oríṣun àwòrán, others
Èyí ni àwọn aṣíwájú ìjọba táje ìwà ìjẹkújẹ ti ṣí mọ́ lórí láàrin ọdún 1960 sí àsìkò yí
Ọrọ iwa ijẹkujẹ kii ṣe ajeji lorilẹede Naijiri. Koda ọpọ ti rii gẹgẹ bii baraku pẹlu isejọba, oṣelu ati igbe aye awọn ọmọ Naijiria lapapọ.
Bẹrẹ lati igba ti orilẹede Naijiria ko tii gba ominira ati lẹyin igbominira rẹ.
Eyi ni agbeyẹwo awọn eekan ti wọn ti fi ẹsun iwa ijẹkujẹ kan ti wọn si ti jẹbi.
Omolola Arohunmolase Welder: Mo ti fí iṣẹ́ 'Welder' gbayì láwùjọ, tó mo fi tọ́ ọmọ yanjú
Nnamdi Azikiwe:
Ni ọdun 1956, igbimọ oluwadii kan ti a da pe ni Foster-Sutton Tribunal of Inquiry se iwadii olootu ijọba ẹkun ila oorun ọjọhun,
Ọmọwe  Nnamdi Azikiwe, lori ẹsun pe o n lo ipo rẹ lati fi ṣe akoso banki  African Continental Bank  (ACB) nigba naa.
Iwe ofin to de ihuwasi awọn to di ipo oṣelu mu ( The code of conduct) yannana rẹ pe ẹnikẹni to ba di ipo ilu mu gbọdọ fi ipo yoowu to ba dimu ni ileeṣẹ aladani gbogbo silẹ ni kete to ba ti de ori oye.
Igbimọ oluwadii Foster-Sutton Tribunal kẹfin pe Ọmọwe Azikiwe ko ja okun to so oun ati banki naa pọ lẹyin to jẹ olooyu ijoba ẹkun ila oorun Naijiria.
Igbimọ naa ṣalaye pe Azikiwe ṣi lo agbara ati ipo rẹ lati maa fi fa ire lọ sọdọ banki naa (Report of the Foster-Sutton Tribunal of Inquiry, 1956: 42; Sklar, 2004: 185).
Bẹẹ si ree Azikiwe, ileeṣẹ Azikiwe at'awọnẹbi rẹ ni wọn ni ipin idokoowo to pọ julọ ni banki naa nigba naa.
Abajade: ko si ẹni lee sọ ni pato idi ti awọn alaṣẹ nigba naa ko fi fi Azikwe jofin.
Akomolede ati Asa lori BBC: Olùkọ́ Kikelomo  Ogunboye tan ìmalẹ̀ sí ìwà olè ọ̀gá ọlọ́pàá
Oloye Ọbafẹmi Awolowo:
Ni ọdun 1962, oloye Obafemi Awolọwọ to jẹ olotu akọkọ fun ijọba iwọ oorun Naijiria nigba naa pẹlu koju ẹsun ikowojẹ. Igbimọ oluwadii Coker Commission of Inquiry lo ṣewasii rẹ, wọn si ni o jẹbi ẹsun naa.
Ni ọdun 1954, ajọ ontaja ẹkun iwọ oorun Naijiria, Western Region Marketing Board ni owo to to miliọnu mefa ati ẹgbẹrun lọna igba pọun (£6.2 milion) ninu aṣuwọn rẹ.
Amọṣa, nigba ti yoo fi di ọdun 1962, owooya to le ni miliọnu meji abọ pọun (£2.5 million) lo wa lọrun ajọ naa lẹyin ti wọn ni ọpọ owooya lawọn ileeṣẹ ijọba kan gba ti wọn ko san pada.
Igbimo Coker Commission of Inquiry ni Oloye Awolowo jẹbi lori isubu ajo naa nitori ko tẹlẹ ilana to tọ fun ẹni to ba di ipo ilu mu lati tẹle (Coker Commission, 1962; Magid, 1976: 73).
Itan Omi Erin
Ni ọdun 1994 igbimọ oluwadii Okigbo panel ti wọn gbe kalẹ fun atunto banki apapọ Naijiria na ika ọwọ rẹ ko mọ si aarẹ ologun nigba naa, Ọgagun agba Ibrahim Babangida.
Koda, ọrọ naa kan ọgagun agba Sani Abacha ati gomina Banki apapọ nigba naa, Alhaji Abdulkadir Ahmed.
Nigeria movie industry: Àgbà òṣèré, Lere Paimo ní àìgbọràn ló ń da ọ̀pọ̀lọpọ̀ àwọn
Wọn ni pe wọn lọwọ si bi wọn ṣe ṣe owo to le ni biliọnu mejila dola ( $12.4 billion) owo ere ori epo laarin ọdun 1988 si 1994.
Igbimọ naa ni awọn eekan ijoba Babangida nigba naa lẹdi apo pọ pẹlu awọn oṣiṣẹ banki apapọ Naijiria lati lu owo naa ni ponpo nipa ninaa sori awọn akanṣe iṣẹ ti ko ṣe e tọka si.
(Okigbo Panel Report, 1994).
Ojú mi ti rí lọ́pọ̀ lọpọ̀, àmọ́ mo dúpẹ́ pé mo ti pé ọdún márùn ún lórí oyé- Ooni
Ọgagun agba Sani Abacha:
Ṣaaju iku rẹ lọdun 1998, ọgagun agba Sani Abacha ni olori ijọba ologun ni Naijiria.
Lẹyin iku rẹ ni ọpọ iwadii n fihan pe obitibiti owo ni o ko lọ pamọ si oke okun.
Titi di bi a se n sọrọ yii owo ti llori orilẹede yii naa ko pamọ ti Naijiria ko tii gba n lọ biii
Lagos: Ojú àwọn ará Èkó rí màbo pẹ̀lú òjò àrọ̀ọ̀rọ̀dá dá wàhálà sílẹ̀ ní Eko
Bẹẹ si ni iye owo ti wọn ti gba pada lawọn orilẹede oke okun to ko wọn pamọ si ti to.
Amọṣa, yatọ sawọn asiwaju ijọba wọnyiajọ EFCC ti wọn gbe kalẹ lasiko isejọba Olusẹgun Obasanjọ ti se ọpọ iṣẹ ti wọn si ti gbe ọpọ awọn eekan ati oloselu ju si gbaga fun ẹsun ikowojẹ.
Diẹ lara wọn niyi:
Oloye Sunday Micheal Afọlabi.
Oloye Afọlabi ti ọpọ mọ si SM ni minisita f'ọrọabẹle labẹ isejọba Olusẹgun Obasanjọ nipasẹ bẹẹ oun ni alakoso eto kaadi idanimọ orilẹede Naijiria akọkọ nigba naa eyi ti owo agbase rẹ jẹ igba o le mẹrinla miliọn dola ($214million).
Amọsa ọrọ bẹyin yọ nigba ri oorun ijẹkujẹ bẹrẹ si ni run sita labẹ eto naa.
'Èmi gan máa ń béèrè lọ́wọ́ ara mi pé ta ni Wole Soyinka gangan'
Ọrọ bẹyin yọ pẹlu bi wọn ṣe gbe iṣẹ agbase naa fun ileeṣẹ
SAGEM S.A., lati ilẹ France nigba ti ileeṣẹ itẹwe abo lorilẹede Naijiria (Nigerian Security Printing and Minting Company, NSPMC), naa fifẹ han lati gba iṣẹ naa ni owo to dinwo ju ti ileeṣẹ Faranse naa lọ.
Akosilẹ iwadii fihan pe ika alebu na si Hussaini Akwanga to jẹ minisita fun oro oṣiṣẹ nigba naa, Sunday Michael Afolabi to jẹ minisita fun ọrọ abẹlẹ pẹlu Mahmud Shata to jẹ igbakeji rẹ.
Tafa Balogun:
Ọga ọlọpaa Naijiria ni Tafa lasiko isejọba Oluṣẹgun Ọbasanjọ ki wọn to fi panpẹ ofin gbe lori ẹsun pe o se owo to din diẹ ni biliọnu mẹfa naira baṣubaṣu (N5.7billion).
Wọn fi si ẹwọn oṣu mẹfa lẹyin ti ajo EFCC fi ẹsun aadọrin to ni se pẹlu ikowojẹ kan an.
Ikogosi-Ekiti: Ilu ti omi tutu ti dapọ mọ gbigbona
Lucky Igbinedion:
Gomina ipinlẹ Edo tẹlẹ, Lucky Igbinedion ni Gomina akọkọ ti yoo ri pipọn oju ofin fun kiko owo ilu jẹ. Ajọ EFCC fi ẹsun kan an pe o ko owo to le ni miliọnu mẹrinlelogun dọla ($24million) jẹ.
Oríṣun àwòrán, others
O ba ajọ naa ṣe dunadura lodun 2008 lati san lara owo to ko jẹ pada ki o si maa.gba ile rẹ.lọ dipo ẹwọn.
Ṣe wahala wá ti ọkọ bá kọ̀ láti fún aya tó ti kọ̀ silẹ lára ogún rẹ?
Diepreye Alamueyesigha:
Gomina ipinlẹ Bayelsa tẹlẹ ni, ni ọdun 2007 ni wọn ran an lọ si ẹwọn ọdun meji lloriikowojẹ.
Ọjọ diẹ lo lo ninu rẹ lẹyin to lo bii ọdun meji ninu ahamọ lasiko to n reti igbẹjọ rẹ.
Africa Eye: Wo ìtàn ìyá kan ìyá kan àtàwọn olè ajọ́mọgbé tó n ta ọmọ ní Kenya
Eniola Badmus kilọ fun awọn to n bu pe o ti sanra ju lati dẹyin lẹyin oun.
Oríṣun àwòrán, Joshua Adetunji
"O ṣeeṣe ki ẹ ti ẹ ti maa gbọ bi awọn eeyan kan maa ṣe maa n sọ pe, ara sisan kii ṣe arun.Lo difa fun gbajugbaja oṣere tiata Yoruba, Eniola Badmus to ke gbajare si awọn eeyan to maa n bu ẹnu atẹ lu lori ayelujara pe o ti sanra ju.Eniola sọ pe ""Eẹyin eeyan ẹ ma ran mi lọ si iboji ọsan gangan, ni ṣe ni sanran o, mi o ji yin lẹran jẹ."""
"O ni ara oun ti wọn fi n bu oun naa ni oun pa owo wọle fun oun.Gẹgẹ bo ṣe sọ, o ni ""ara ti ẹ n bu yii na lo n mu oujẹ wọle fun mi, bakan naa ara ti ẹ n bu yii naa lo maa n fun yin ni ayọ ati idunu ti ẹ ba n wo mi lori ẹrọ tẹlifiṣọn yin nile.""Eniola tun rọ awọn ololufẹ, ẹbi ati ọrẹ to maa n sọ pe o ti tobi ju lati bu omi suru mu."
"O ni ""ẹyin ti ẹ n fun mi lọrun lori ọrọ ara sisan yii, ẹ jọwọ ẹ fi mi lọrun silẹ ki n ṣaye mi bo ṣe wu mi.""Eniola tun ṣalaye nipa bi awọ eeyan ṣe maa n bu lojojumọ nitori o jẹ ẹni to sanra, o si sọ pe eyii ko dun mọ oun ninu.Oṣere naa pari ọrọ rẹ pe bi awọn eeyan ṣe maa n bu ẹni to ba sanra lo n mu ki ọpọ ninu wọn ronu pa ara rẹ."
Muhammadu Buhari: Amòfin Adebayo wá kábàámọ̀ pé ọ̀pọ̀ nǹkan ni wọ́n ń tọwọ́ òṣèlú bọ
Oríṣun àwòrán, @NGRPresident
Oni Ọjọbọ lo yẹ ki Aarẹ Muhammadu Buhari farahan niwaju ijoko ile asofin apapọ fun ilẹ Naijiria.
Ọsẹ to kọja ni awọn ọmọ ile igbimọ aṣoju-ṣofin ranṣẹ si, nitori ọrọ eto aabo aabo to mẹhẹ yika Naijiria.
Igbesẹ awọn asofin lati ransẹ pe Buhari waye lẹyin ti ikọ Boko Haram pa awọn agbẹ kan nipinlẹ Borno.
Ariyanjiyan si ti n waye lori boya Buhari yoo lọ ọ tabi ko ni i lọ, paapa lẹyin ti Agbẹjọro Agba Naijiria, to tun jẹ Minisita fun eto idajọ, Abubakar Malami sọ l'Ọjọru pe, awọn aṣofin ko ni ẹtọ labẹ ofin lati ranṣẹ pe Buhari.
"Awijare Malami ni pe aarẹ ti ṣe aṣeyọri to pọ, ""fun bo ṣe da yinyin ado oloro, ipaniyan, ati biba dukia jẹ duro"", ko to o di aarẹ lọdun 2015."
Oríṣun àwòrán, @MBuhari
O ni awọn ilana ti Buhari n gba yanju ọrọ eto aabo gẹgẹ bi Oludari gbogbo ileeṣẹ aabo, kii ṣe nkan ti gbogbo aye gbọdọ mọ.
"Ṣugbọn ṣa, agbẹjọro kan, Amofin Sali Adebayo sọ fun BBC Yoruba pe ""awọn ofin fi aaye gba awọn aṣofin, lati ranṣẹ pe aarẹ lori ohunkohun ti wọn ba n fẹ alaye lori rẹ""."
Amofin Adebayọsọ pe wọn  ni agbara lati yọ ọ ni ipo aarẹ, to ba kuna lati farahan niwaju wọn, pẹlu ibo ìdá meji ninu mẹta apapọ wọn.
Omolola Arohunmolase Welder: Mo ti fí iṣẹ́ 'Welder' gbayì láwùjọ, tó mo fi tọ́ ọmọ yanjú
"Iyẹn ti wọn ko ba ṣe ojusaaju oṣelu nitori o ṣe ni laanu pe ọpọ nkan ni a n fi ọrọ oṣelu yanju ni Naijiria.
O si ṣe e ṣe ki awọn aṣofin ma ṣe nkankan fun Buhari ti ko ba yọju si wọn, nitori pe ọmọ ẹgbẹ oṣelu rẹ, APC, lo pọju nibẹ."
Wọn ko si ni i ṣe ohunkohun lati tako ẹgbẹ wọn.
Oríṣun àwòrán, Twitter/Presidency Nigeria
"Saaju la ti sọ fun yin pe, Agbẹjọro agba orilẹede Naijiria, Abubakar Malami ti ni ile igbimọ aṣofin ko lẹtọ labẹ ofin lati pe aarẹ Muhammadu Buhari wa siwaju wọn lati wa ṣalaye ohunkohun.Malami ṣipaya eyi l'Ọjọru ọsẹ ninu ọrọ to pe akọle rẹ ni ""Pipe Buhari lẹjọ: Ile aṣofin n ṣe lodi alakalẹ ofin"".Agbẹjọro agba ni ""ile igbimọ aṣofin ko lagbara kankan labẹ ofin lati gbero rẹ tabi ṣe agbekalẹ eto ti o le pe aarẹ ko wa ṣalaye ọrọ lorii iṣẹ awọn ologun ati bi wọn ṣe n lo wọn."
Bakan naa, o mẹnu ba pe ẹtọ ti aarẹ ni lati yan pe oun fẹ farahan niwaju ile aṣofin lati ba wọn sọrọ torinaa ki ile aṣofin maa pe aarẹ lẹjọ tabuku ba ipo aarẹ.Ni ọjọ kinni oṣu kejila ọdun ni ile igbimọ aṣoju-ṣofin da abaa ki wọn pe aarẹ Buhari lati wa jabọ fun wọn lorii otitọ to wa nidii ọrọ abo lorilẹede Naijiria.Wọn ṣe ipinu yii lasiko ijoko ile kan nibi ti ọmọ ile to n ṣoju ipinlẹ Borno sọ aba kan lorii iṣẹlẹ bi Boko Haram ṣe ṣekupa awọn agbẹ onirẹsi mẹtalelogoji nipinlẹ rẹ.Ẹwẹ, ni idahun si eyi, oluranlọwọ pataki si aarẹ lori ọrọ ori ayelujara, Lauretta Onochie kede lọjọ Aje wipe Aarẹ yoo ba apapọ ile igbimọ aṣofin sọrọ.
Corruption in Nigeria: Ojíṣẹ Ọlọ́run kan ní báwọn òbí ṣe ń jí owó ìlú kò, ní wọ́n ń fi lé ọmọ lọ́wọ́
Oríṣun àwòrán, @MBuhari
Ojisẹ Ọlọrun kan ti woye pe ogun ti aarẹ Muhammad Buhari n gbe ti iwa ajẹbanu ko tii kun to rara.
Oludasilẹ ile ijọsin kan nilu Eko, Wolii Adegboyega Ajani lo woye ọrọ yii lasiko ipade akọroyin kan to ṣe lati sami ayajọ gbigbe ogun tiwa ajẹbanu lagbayee.
Ojisẹ Ọlọrun naa fikun pe, awọn elesinjesin gan ti kuna ninu gbigbe ogun tiwa ajẹbanu.
"Ni gbogbo agbaye, tàwọn eeyan ba gbọ nipa iwa ajẹbanu, owo jiji nikan ni wọn maa n ro si eyi to jẹ asise.
O dabi igba ti eeyan n wa ojutu si isoro mẹta amọ ti onitọun gbajumọ ẹyọ kanṣoṣo, to si fi awọn isoro yoku silẹ.
Oríṣun àwòrán, Adegboyega Ajani
Idi ree to fi yẹ ka tete san sokoto wa ko le lati gbogun tiwa ajẹbanu naa.
Nigba to n sọrọ lori bi ajẹbanu naa ṣe n fẹju si, Wolii Ajani ni yoo nira diẹ kiwa ajẹbanu to kasẹ nilẹ ni Naijiria.
Bi awọn obi ṣe n ko owo ilu, naa ni wọn n fi iwa àjẹbánu ọhun le awọn ọmọ wọn lọwọ, eyi ti ko ni jẹ ka tete ri ọna abayọ siwa ajẹbanu naa."""
Omolola Arohunmolase Welder: Mo ti fí iṣẹ́ 'Welder' gbayì láwùjọ, tó mo fi tọ́ ọmọ yanjú
Ojisẹ Ọlọrun naa ni gbogbo ẹka awujọ ni iwa ajẹbanu ti gogo pupọ, tàwọn oloselu atawọn gbajumọ si n ko owo ilu, ti wọn si tun n fi le awọn ọmọ wọn lọwọ.
Wolii Ajani wa rọ awọn ojisẹ Ọlọrun lati maa waasu tako iwa ibajẹ naa, ko le di ohun itan ni Naijiria
Agba onkọwe, Ọjọgbọn Wole Soyinka ti sọ pe, oun ko gbagbọ pe Naijiria wa ni abẹ idari ẹnikẹni.
O sọ eyi nibi ayẹyẹ ikojade iwe rẹ tuntun, 'Chronicles of the happiest people on earth', nilu Eko.
Ọjọgbọn Wole Soyinka ṣapejuwe ọdun 2020 gẹgẹ bi eyi to ti buru julọ ti oun mọ lorilẹ-ede Naijiria.
O ni kii ṣe nitori ajakalẹ aarun Covid-19 nikan, ṣugbọn ọpọlọpọ awọn iṣẹlẹ to waye, ati iha ti ijọba kọ si wọn.
O to ogoji ọdun ti Soyinka ti n kọ iwe naa, ko to o gbe jade lọdun 2020.
'Èmi gan máa ń béèrè lọ́wọ́ ara mi pé ta ni Wole Soyinka gangan'
Soyinka ni bi nkan ṣe ri bayii ni Naijiria, awọn ọmọ Naijiria ko mọ ibi ti wọn n lọ, tabi ibi ti irinajo wọn yoo pari si.
"Nnkan ti de ikorita ti eeyan ko ni idaniloju ibi to n lọ, ati ibi ti yoo pari rẹ si.
Bi mo ṣe sọ tẹlẹ, ọpọlọpọ nkan to n ṣẹlẹ ko jẹ kii eeyan o gbagbọ pe ẹnikẹni wa ni iṣakoso."""
Soyinka sọ pe ọdun 2020 kii ṣe ọdun to dara rara fun oun, ni gbogbo ọna.
Rashidi Ladoja: Èmi kìí ṣe olóṣèlú mọ́, n kò sí nínú ẹgbẹ́ òṣèlú kankan
Oríṣun àwòrán, Akanbi Abiola/Facebook
Gomina ana nipinlẹ Oyo, Sẹnetọ Rashidi Ladoja ti asalaye idi to fi ls se abẹwo si gomina tẹlẹ nipinlẹ Eko, Asiwaju Bola Ahmed Tinubu.
Abẹwo naa eyi to ti n fa awuyewuye lori ayelujara ni Rashidi Ladoja ti wa kede pe ko ni nnkan se pẹlu eto idibo ọdun 2023.
Akọwe feto iroyin fun Sẹnetọ Ladoja, Lanre Latinwo sọ lọjọru pe Rashidi Ladoja lọ sile Tinubu lati ba kẹdun lori ọpọ dukia to padanu lasiko rogbodiyan EndSARS nilu Eko ni.
O wa yan pe ko si ohun to jọ mọ ọrọ oselu rara ninu ijiroro awọn agba oselu mejeeji naa lasiko abẹwo ọhun .
Omolola Arohunmolase Welder: Mo ti fí iṣẹ́ 'Welder' gbayì láwùjọ, tó mo fi tọ́ ọmọ yanjú
Latinwọ ni Ladoja lo fi oko kan pa ẹyẹ meji lasiko irinajo rẹ silu Eko naa, ẹni to fi ẹsẹ kan ya sile Tinubu lati ba kẹdun lasiko ti agba oselu naa lọ sibi ayẹyẹ isisnku kan nilu Eko.
Bakan naa lo tun foju laifi wo ọrọ kan to ni igbesẹ Ladoja naa tako ofin ẹgbẹ oselu rẹ, pẹlu afikun pe oloye Ladoja kii se oloselu mọ, ti ko si kede inu ẹgbẹ oselu to wa fun ẹnikẹni.
Google searches Nigeria 2020: Hushpuppi, Naira Marley, Rema, ASUU wà lára ohun táwọn èèyàn ń wá
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Oju opo Google maa n saba ṣagbejade ọrọ ti awọn eeyan n wa julọ lori itakun wọn, ti onikaluku orilẹede n wa lọdọọdun.
Bakan naa ni oju opo yii maa ṣagbejade mẹwaa loke tente lara awọn orin, ere idaraya, awọn oṣere ati fiimu wọn gangan to fi mọ ifọrọwanilẹnuwo to fakọyọ.
Labẹ isọrii awọn mẹwa to pọju tawọn eeyan n bi google leere nipa wọn ju, awọn olorin ọmọ Naijiria bii Rema, Naira Marley, Omah Lay ati ajaweolubori eto ile Ẹlẹgbọn agba (Big Brother Naija Lock down Season 5), Laycon naa wa nibẹ.
Ẹni akọkọ lorii ila awọn ti wọn n wa ju lori google ni aarẹ tuntun ti wọn dibo yan l'Amẹrika, Joe Biden, lẹyin naa ni Rema ati Naira Marley tẹle e.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Gbajugbaja oṣere fiimu Hausa, Rahama Sadau ni o wa nipo kẹrin. Ninu oṣu kọkanla ni Rahama gbayi lori google tori awọn fọto rẹ to fọnka sorii ayelujara.
"Awọn fọto yii da wahala silẹ gẹgẹ bi awọn eeyan ṣe ni o lodi si ilana ""Prophet Mohammed"" ti awọn mii si ni awọn o rohun to buru nibẹ."
Maryam Sanda, obinrin ti wọn fẹsun kan pe o pa ọkọ rẹ lọdun 2017, ti ile ẹjọ si dajọ iku nipa yiyẹgi fun un nibẹrẹ ọdun yii, naa wa lara awọn ohun ti wọn n wa loju opo agbaye yii.
Gẹgẹ bi google ṣe sọ ọ, Maryam Sanda ni ẹni ikẹẹsan lori ayelujara ni Naijiria lọdun yii, tawọn eeyan fẹ mọ nipa rẹ
Wo ẹkunrẹrẹ oniruuru isọri ohun tawọn eeyan n wa ati awọn to gba ipo kinni gẹgẹ bi google ṣe gbe e jade:
Awọn eeyan ti wọn n wa nipa wọn ju (Nigeria):
Nkan gboogi mẹwa tawọn eeyan n wa lọdun yii ni Naijiria lorii Google:
Iru ounjẹ, nkan mimu ati ipanu tawọn eeyan n beere ju nipa rẹ ni Naijiria lorii Google:
Awọn orin mẹwaa tawọn eeyan tẹ soju opo Google lọdun 2020:
"Awọn ibeere bii ""bawo ni wọn ṣe n ṣe burẹdi jẹ ọkan lara ibeere to wa loke ohun tawọn eeyan n bi Google ju lọdun 2020."
Awọn ibeere ọhun ni:
Rev Fr Ejike Mbaka: Ìfọ̀rọ̀wánilẹ́nuwò ní BBC bá dé ọ̀dọ̀ òjíṣẹ́ Ọlọ́run, ìyà ló fi pàdé wọn
Oríṣun àwòrán, Facebook/Adoration Ministry Enugu Nigeria
Gbajugbaja ojisẹ Ọlọrun kan ninu ijọ Aguda katoliki, Fada Ejike Mbaka  atawọn ọmọ ijọ rẹ kan kọlu awọn akọroyin BBC meji ati awakọ wọn nilu Enugu.
Awọn akọroyin naa, Chioma Obianinwa ati Nnamdi Agbanelo pẹlu awakọ wọn, Ndubuisi Nwafor ni awọn fada meji mii tẹle lọ sibi ifọrọwanilẹnuwo sọdọ Mbaka.
Awọn fada mejeeji naa ni  orukọ wọn n jẹ Cajethan Obiekezie ati igbakeji rẹ, Solomon Orakam
Fada Obiekezie, to se agbatẹru eto ifọrọwanilẹnuwo naa, lo lewaju ikọ iroyin BBC lọ sinu ijọ Adoration Ministry ti Mbaka n lewaju rẹ ni deede aago mẹwa owurọ.
Oríṣun àwòrán, Facebook/Adoration Ministry Enugu Nigeria
Eto ifọrọwanilẹnuwo naa ko tete waye ni kete ti wọn de ile ijọsin naa, tori Mbaka n waasu lọwọ.
Ikọ iroyin BBC ti Fada Obiekezie lewaju rẹ, wa morile ile Mbaka lẹyin ti isin naa pari ni deede aago marun irọlẹ lati seto ifọrọwanilẹnuwo ọhun.
Nigba ti fada Mbaka si wọnu ile, awọn ikọ iroyin BBC wa ninu ọkọ wọn nita, ni Fada Obiekezie ba wọnu ile lati lọ jiroro pẹlu fada Mbaka, amọ ko pẹ ni awọn gende ọkunrin bii ogun yi mọto ikọ iroyin BBC ka.
Gẹgẹ bi akọroyin wa, Chioma Obianinwa se salaye, awọn ọkunrin naa gba awọn irinsẹ akọroyin olowo iyebiye ti wọn gbe dani, ti wọn si dunkooko lati pa wọn danu nitori pe wọn ni wọn kọ 'awọn iroyin ti ko dara nipa Fada Mbaka'.
Oríṣun àwòrán, Facebook/Adoration Ministry Enugu Nigeria
"Obianinwa ni ""Mbaka sọ pe ka duro titi di ipari isin ti oun n se fun ifọrọwanilẹnuwo naa. Awọn ọkunrin to wa nita ile naa ni BBC Igbo maa n kọ iroyin ti ko dara nipa Mbaka."
"Wọn bẹrẹ si na Nnamdi, Solomon ati Ndubuisi. Won fun wọn ni ọpọ ọsẹ alagbara lori ati ni gbogbo ara."""
Akọroyin BBC naa tẹsiwaju pe Mbaka ati Obiekezie jade wa latinu ile nigba ti wọn gbọ ariwo ija to n lọ nita, ti Fada Mbaka si kọju si oun naa, bẹẹ lo n fi awọn ika ọwọ rẹ gun oun loju, to si n pe oun ni 'Elesu'.
Omolola Arohunmolase Welder: Mo ti fí iṣẹ́ 'Welder' gbayì láwùjọ, tó mo fi tọ́ ọmọ yanjú
"Igbesẹ Mbaka yii gan lo sewuri fun awọn gende ọkunrin naa lati maa tẹsiwaju nidi ikọlu ti wọn n se, ti Fada Mbaka naa si n pariwo lati maa bu wa.
O pasẹ fun awọn ọkunrin naa lati gba awọn ẹrọ ibaraẹnisọrọ ati ẹrọ ayaworan wa.
Wọn ni awọn yoo pa wa lai si ohunkohun ti yoo sẹlẹ, ti wọn si si irun atọwọda ti mo de sori.
Bakan naa ni wọn fun Nnamdi lọrun, ti Fada Obiekezie si n pariwo fun wọn lati dẹkun ikọlu naa sugbọn se ni wọn kọju ija si oun naa, ti wọn si gba ẹrọ ibaraẹnisọrọ rẹ pẹlu. Chioma Salaye."
"Kí ni ""Present tense"" lédè Yorùbá?"
"Obianinwa ni ikọlu naa dawọ duro nigba ti oun pariwo pe ""Gbogbo aye ni yoo mọ pe ile Fada Mbaka ni wọn ti pa awọn."""
"Igba yii ni Fada Mbaka wa sọ fun wa pe ka maa lọ ki awọn gende oun to pa wa. O pasẹ fun wọn pe ki wọn da awọn foonu ati irinsẹ wa ti wọn gba pada, ti wọn si le wa jade kuro ninu agbala wọn.
Awọn ọkunrin naa tun n tẹle wa titi ta fi filu naa silẹ lọ gba iwosan ati iranwọ ọlọpaa."
Nigba ti ileesẹ BBC pe Fada Mbaka lati oju opo Facebook rẹ, o ti pa aago rẹ.
Ode/Isinigbo land Crisis: Ìjọba ìpínlẹ̀ Ondo kéde òfin konile-o-gbele ní Ode ati Ishinigbo
Oríṣun àwòrán, Paradisenews
Ijọba ipinlẹ Ondo ti kede ofin konile-o-gbele oni wakati mẹrinlelogun ni ilu Ode ati Ishinigbo, to wa ni ijọba ibilẹ Ariwa Akure.
Igbele naa ti wọn ni yoo bẹrẹ lẹsẹkẹsẹ ni ijọba ipinlẹ Ondo kede lẹyin rogbodiyan to bẹ silẹ laarin ilu memeji lati nnka bi ọsẹ kan sẹyin.
Ninu atẹjade ti kọmiṣọna ọrọ to n lọ, Donald Ojogo fi ṣọwọ si awọn akọroyin, o ni gomina Rotimi Akeredolu ti dari awọn agbofinro lati bẹrẹ iwadii lori ohun to fa iṣẹlẹ naa.
Atẹjade ọhun fi kun pe wọn ti bẹrẹ ti n tọpasẹ gbogbo awọn to lọwọ ninu rogbodiyan naa.
Bakan naa lo ni wọn ti paṣẹ fun awọn agbofinro lati ri daju pe ofin konile-o-gbele naa mulẹ.
Bo tilẹ jẹ pe Ode ati Ishinigbo nikan ni ofin ọhun wa fun, Ojogo sọ pe ko ni si kalọ kabọ awọn eeyan ni ilu mejeji titi di igba ti ijọba yoo tun kede igbesẹ tuntun lori ọrọ ọhun.
Oríṣun àwòrán, Paradisenews
Ibi ti a ba pe ni ori, ẹnikan kii fi ibẹ tẹlẹ ni Yoruba n wi, bẹẹ si ni wọn ni Ọba lo ba lori ohun gbogbo.
Amọ eyi ko ri bẹẹ fun awọn ọba alaye nilu Ode ati Isinigbo ti wọn mule tira wọn nijọba ibilẹ Ariwa Akure nipinlẹ Ondo.
Idi ni pe awọn ilu mejeeji lo n doju ija kọ ara wọn nitori aawọ ilẹ, ti ọrọ naa si ti dogun dọdẹ, koda, wọn ti gbe ara wọn lọ sile ẹjọ pẹlu.
Sugbọn kaka ki wọn duro de idajọ ileẹjọ, se ni wọn doju akọtun ija kọ ara wọn bẹrẹ lati ọsẹ to kọja.
Ọba ilu Ode lo ni oun lo ni ilẹ kan to wa ni agbegbe Isinigbo tawọn eeyan ti kọle le lori, to si ni ki wọn wa sanwo fun ilẹ naa.
Nigba to n salaye bi isẹlẹ naa se waye fun awọn akọroyin, Ajagunode tilu Ode, Ọba Sunday Boboye ni oun ti gba idajọ lori ilẹ naa lọdun 2017 ati 2019, tawọn eeyan Isinigbo ko si gbe igbesẹ lati tako idajọ ọhun nile ẹjọ Kotẹmilọrun.
Oríṣun àwòrán, @PoliceNG
O ni dipo eyi, se ni awọn ọdọ ilu Isinigbo wa ka oun mọle lọsẹ to kọja pẹlu ohun ija oloro.
O ni deede aago mejila oru ni wọn gunlẹ si aafin oun lati kọlu oun, ori ogiri aafin si ni oun ati olori oun meji gba salọ.
"O to awọn janduku mẹwa ti wọn ya bo aafin mi pẹlu awọn ohun ija oloro, ti wsn si n beere pe nibo ni Kabiyesi wa?
Wọn ba gbogbo aafin mi jẹ patapata, ta si ti ko wa si aafin tuntun bayii amọ alẹ ọjọ Aje tun ni wọn tun ya wa ba wa lẹẹkan si.
Oríṣun àwòrán, Paradisenews
Ajagunode fikun pe igba karun tawọn janduku naa yoo wa ka oun mọ aafin ree lati igba ti aawọ ilẹ naa ti bẹrẹ. "
"Asọ kansoso lo ku fun mi laye lọrun bayii, wọn ti jo gbogbo dukia mi, to fi mọ awọn ọkọ ayọkẹlẹ mi ati eyi ti mo sẹsẹ ra ni osu mẹta sẹyin."""
O fikun pe oun ti fi ọrọ naa to ijọba atawọn agbofinro leti nipa awọn ikslu ojoojumọ yii, oun si n fẹ ki wọn gba oun ati ẹbi oun ki oun ma baa ku lojiji.
Nigba to n ba BBC Yoruba sọrọ lori isẹlẹ yii, Igbakeji akọwe fun agbegbe Isinigbo, Ọmọọba Joseph Akinsilu naa fi ẹsun kan Ajagunode pe o ko awọn janduku wa si aafin ọba awọn lati kọlu.
Oríṣun àwòrán, Paradisenews
O ni isẹlẹ naa waye mọjumọ ọjọ Ẹti oni, ti Ọba awọn si wa lẹsẹ kan aye, ẹsẹ kan ọrun.
Ọba wa wa ni coma bayii, wọn ti jo aafin atawọn ọkọ ọba wa, ti ọba wa si n gbọn, koda ile ti wọn bajẹ ni agbegbe wa le ni ọgọjọ, to fi mọ ile temi gan alara.
Akinsilu salaye pe Ajagunode lo kọkọ gbe awọn lọ sile ẹjọ lori ilẹ ti awọn ti kọle le lori, to si ni kawọn wa san ẹẹdẹgbẹta miliọnu naira lori ilẹ naa.
"Bi o tilẹ jẹ pe a ko jẹbi bọ lati ile ẹjọ, se ni Boboye tun tun ẹjọ pe nile ẹjọ naa dipo ko pe ẹjọ kotẹmilọrun, a si n rọ ijọba ki wọn gba wa lọwọ rẹ.
Omolola Arohunmolase Welder: Mo ti fí iṣẹ́ 'Welder' gbayì láwùjọ, tó mo fi tọ́ ọmọ yanjú
Nigba ti BBC Yoruba kan sileesẹ ọlọpa ipinlẹ Ondo, Agbẹnusọ fun ileesẹ ọlọpaa Ondo, Leo Ikoro salaye pe lootọ ni ikọlu mejeeji naa waye ni ọsẹ to kọja ni aafin Ajagunode, ti ikọlu miran si tun waye mọjumọ ọjọ Ẹti ni aafin ọba Isinigbo.
O wa fọwọ gbaya pe ileesẹ ọlọpaa yoo se iwadii to yẹ nipa awọn ikọlu yii, ti wọn si tun ti n saayan lati ri pe alaafia pada si agbegbe mejeeji naa.
Adeola Smart and Malivehood Wedding: Diamond kún ara aṣọ ìyàwó, Cake jẹ́ alájá 16
Oríṣun àwòrán, Istagram/malivelihood
Ọpọ eeyan to peju sibi igbeyawo Adeola Smart, tii se ọmọbinrin Senatọ Smart Adeyemi ati ọkọ rẹ, Olusola Awujoola ni ko ni gbagbe aramọnda igbeyawo naa laelae.
Idi ni pe awọn isẹlẹ manigbagbe lo waye nibi igbeyawo naa, ti ko fẹ sẹlẹ ri lorilẹede Naijiria.
Ọjọ manigbagbe si ni ọjọ Satide, ọjọ Karun osu Kejila ọdun 2020 naa ti eto igbeyawo ọhun, ti wọn pe ni igbeyawo ọmọ ọba waye.
Iyatọ nla si lo wa nipa igbeyawo naa si eyi to ti n waye tẹlẹ, bẹrẹ lati ori ife imumi, akara oyinbo, ẹbun wi wọn ha, ounjẹ ti wọn se ati asọ iyawo funra rẹ.
Awọn eeyan to lorukọ yika Naijiria si ni wọn peju pesẹ sibi ayẹyẹ igbeyawo naa, eyi to kasiara.
Oríṣun àwòrán, Instagram/cakes_by_la
Oríṣun àwòrán, Instagram/thebridalmoments
Kaba iyawo ti arabinrin iyawo asẹsẹgbe naa wọ lọ sile ijọsin lo kun fun kiki okuta olowo iyebiye diamond.
Orukọ iya iyawo to ti di oloogbe, tii se Yemisi, ni wọn kọ si ara asọ iboju ti wọn ran si ara asọ igbeyawo naa, eyi ti wọn fi diamond kọ.
Oríṣun àwòrán, Istagram/malivelihood
Nigba ti wọn wa nile ijọsin, bo se wu ọkọ iyawo lo sọ ẹjẹ igbeyawo rẹ, ti ko si tẹle ilana ẹjẹ ti ile ijọsin maa n ka fun tọkọtaya.
Ọkọ iyawo naa, ti ọpọ eeyan mọ si Malivelihood lo jẹ ilumọọka onisowo okuta iyebiye bii goolu, diamond ati awọn ẹsọ ara lorisirisi.
Nigba to yẹ ko sọ pe ni '...Ni didun ati nigba ikoro, nigba ilọrọ ati nigba ipọnju...' amọ se ni Malivehood sọ pe ',,,Nigba ilọrọ ati nigba Ilọrọ.
Bẹẹ si ni iyawo rẹ, Adeola naa n dinju si, to si n na ika soke pe o kare lae fun bo se sọ ẹjẹ rẹ ọhun.
Oríṣun àwòrán, MojiDelano
Ohun to tun jẹ ara meeriri ta gbọ nipa igbeyawo naa ni bi awakọ kabukabu kan, ti orukọ rẹ n jẹ Austin to gbe alejo lọ sibi ayẹyẹ naa, se jẹ ọkọ ayọkẹlẹ Lexus kan ti wọn fi dije nibẹ.
Iye owo ayọkẹlẹ Lexus naa ni miliọ̀nu mẹ́ta ati ẹgbẹrun lọna irinwo naira (N3.4m).
Bakan naa ni awọn alejo miran tun jẹ ẹbun aago ọwọ olowo iyebiye, eyi ti wọn fi se ẹbun hiha nibi igbeyawo naa.
Oríṣun àwòrán, Istagram/malivelihood
A gbọ pe ẹgbẹrun meji apo ododo ni ọkọ nla mẹfa wa ja sibi ayẹyẹ naa, eyi ti wọn lo lati fi se ibudo igbalejo fun ayẹyẹ igbeyawo ọhun ni ọṣọ to rẹwa.
Coronavirus in Nigeria: Amúgbálẹ́gbẹ́ Gómìnà SanwoOlu kó àrùn COVID-19 ràn án, àmọ́ wọ́n ní àrùn náà kò dá a wólẹ̀
Oríṣun àwòrán, Twitter/babajide sanwoOlu
Ni ọjọ Abamẹta ni iroyin gbode pe gomina ipinlẹ Eko, Babajide SanwoOlu ti ko arun COVID-19.
Kọmiṣọna feto ilera ni ipinlẹ naa, Ọjọgbọn Akin Abayọmi lo kede rẹ lẹyin ti wọn ti kọkọ kede lọjọ Ẹti pe yoo lọ yara rẹ sọtọ titi ti igba ti esi ayẹwo kan to ṣe yoo jade.
Gomina SanwoOlu ni lati ṣe ayẹwo naa nitori iroyin fihan pe ọkan lara awọn amugbalẹgbẹ rẹ kan ti kọkọ ko arun naa laarin ọsẹ ọhun.
Amọṣa kọmiṣọna feto ilera, Akin Abayọmi ni COVID-19 to ṣe gomina naa kii ṣe eyi tii da ni wolẹ nitori awsn afihan kekeke lo n fi han lara gomina naa.
O fi kun un pe ikọ ilera lati ile iwosan ajakalẹ arun, IDH to wa lagbegbe Yaba ti bẹrẹ eto itọju fun gomina naa.
Oríṣun àwòrán, Silverbirdtv
Gomina ipinlẹ Eko, Babajide Sanwo-Olu ti yẹra fawọn eeyan fun igba diẹ naa.
Eyi ko ṣẹyin bi amugbalẹgbẹ rẹ kan ṣe ko arun COVID-19 laipẹ yii.
Kọmiṣọna feto ilera ni ipinlẹ Eko, Ọjọgbọn Akin Abayọmi salaye pe igba mẹta ọtọọtọ ni wọn ti ṣe ayẹwo fun gomina Sanwo-Olu ṣugbọn piri bayii lolongo rẹ n ta.
O fi kun un pe, ayẹwo miran yoo waye fun gomina naa lọjọ Abamẹta lati mọ boya o ti ko arun naa abi bẹẹkọ.
Ẹwẹ, nipinlẹ Kaduna, Gomina El-Rufai naa ti wọ yara iyasọtọ lọ bayii pẹlu bi o ṣe ni awọn kan ninu mọlẹbi, alabaṣiṣẹ ati amugbalẹgbẹ oun, ti ko arun naa.
Promise Akinlade: ọmọ ọdún mọ́kànlá tó ń fi ìlù dárà bíi àgbàlagbà sọ̀rọ̀ nípa tálẹ́ǹtì rẹ
El-Rufai, to ṣalaye ninu ọrọ kan to ba awọn eeyan ipinlẹ naa sọ ni yiyẹra oun jẹ ara ọna igi gogoro maa gun mi loju, atokere laa tii woo, ti oun n gbe lati fi dena itankalẹ arun naa, aibaamọ bi oun pẹlu ba ti koo.
O ni oun yoo ṣi maa yẹra fun awọn eeyan titi di igba ti esi ayẹwo lati mọ boya oun ni, eyi ti yoo waye lọjọ Aiku, ba ti waye.
Ni oṣu kẹta ọdun yii ni Gomina El-Rufai ti kọkọ lugbadi aarun naa.
Senate Hearing: Iléeṣẹ́ epo rọ̀bì ná ₦14.4m lórí báíró, ₦46m lórí ìwé, ₦56m fún tónà
Oríṣun àwòrán, @MBuhari
Ọrọ di agbọdamiẹnu lasiko tawọn ọmọ igbimọ tẹẹkoto lori aṣuwọn owo ilu nile aṣofin agba n gbọ ọrọ lẹnu oluyẹweowo wo agba lorilẹede Naijiria.
Abọ iwadi ti oluyẹ́we owo wo agba gbe wa siwaju igbimọ ile lo sisọ loju rẹ pe miliọnu mẹrindinlọgọfa Naira (₦116m), ni ileeṣẹ to n mojuto epo rọbi na lati fi ra bairo, iwe ati ohun elo itẹwe laarin ọdun kan.
O yannana rẹ siwaju pe, ninu owo naa, miliọnu mẹrinla abọ naira ni wọn na lori bairo ikọwe nikan, miliọnu mẹrindinlaadọta naira ni wọn fi tẹ iwe alakọle Letterhead ileeṣẹ naa, ti wọn si fi miliọnu mẹrindinlọgọta naira ra awọn ohun elo fun ẹrọ itẹwe (Photocopy) ileeṣẹ naa.
Oríṣun àwòrán, Twitter/MBuhari
Oluyẹweowo wo agba naa fi kun un pe, nṣe ni wọn wa pin inawo naa si wẹwẹ kaakiri awọn agbaṣẹṣe mẹrin, lati rii pe iṣẹ agbaṣe to kan ọkọọkan wọn ko ju miliọnu marun naira ti ofin fun oludari agba ileeṣẹ ijọba lagbara lati buwọlu lọ.
Bakan naa lo ni ọrọ ri fun inawo lori iwe alakọle ti wọn na miliọnu mẹrindinlaadọta le lori, eyi to ni wọn pin fun ileeṣẹ agbaṣẹṣe mọkanla ti ọkọọkan wọn si gba miliọnu marun naira.
Oríṣun àwòrán, @SPNigeria
Amọṣa, aṣoju ileeṣẹ epo rọbi ni ijọba apapọ, Godwin Akubo, ni wọn gbe igbesẹ naa jade lati tete mojuto ohun to n jẹ awọn ipin kọọkan to wa labẹ ileeṣẹ naa ni.
O fi kun un pe ilana gbogbo to tọ labẹ ofin ni wọn tẹle.
Dapo Ojora: Ẹ̀gbọ́n ìyàwó Bukola Saraki kú l'Eko, èdè aìyedè wà lórí bó ṣe kú
Oríṣun àwòrán, Twitter/bukaola saraki
Ni alẹ ọjọ Ẹti ni iroyin jade sigboro pe, ilumọọka ọmọ jayejaye ilu Eko ni, Dapọ Ọjọra ti jade laye.
Yatọ si pe ẹni ọdun mejidinlaadọta ni, ohun to n ṣe ọpọ eeyan ni haa-hin bayii ni iroyin pe o yinbọn pa ara rẹ ni.
Dapọ jẹ ọkan lara awọn ọmọ gbajugbaja oniṣowo nni, Otunba Kunle Ojọra; oun si tun ni aburo fun Toyin Saraki to jẹ iyawo aarẹ ile aṣofin agba tẹlẹ, Sẹnetọ Bukọla Saraki.
Bi o tilẹ jẹ wi pe ọpọ lo n sọ kiri pe, Dapọ ṣeku pa ara rẹ ni, sibẹ Sẹnetọ Saraki ti sọrọ sita pe awọn agbofinro ti bẹrẹ iwadii lori rẹ.
Oríṣun àwòrán, Olubayode Alebiosu
Amọṣa, ileeṣẹ ọlọpaa ti ni awọn ti bẹrẹ iwadii lori iku wọọkilu mọ naa, lati mọ boya lootọ ni arakunrin naa gbẹmi ara rẹ.
Atẹjade kan ti alukoro ileeṣẹ ọlọpaa l'Eko, Olumuyiwa Adejọbi fi sita, wa rọ araalu lati gboju kuro nidi ohun tawọn akọroyin kan n sọ pe o ṣokunfa iku rẹ.
Ileeṣẹ ọlọpaa bu ẹnu atẹ lu ahesọ iroyin gbogbo to n lọ nipa bi iku oloogbe naa ṣe waye.
Oríṣun àwòrán, Thisdaylive
Femi Fani-Kayode atawọn eekan ilu mii n daro Dapo Ojora
Niwọn igba to jẹ pe bi ọdẹ ba ku, ọdẹ lo n ṣoro lẹyin ọdẹ, awọn eekanlu lorisirisis ti bọ soju opo ayelujara wọn lati daro Dapo Ojora to di oloogbe.
Lara awọn eekanlu naa lati ri Femi Fani-Kayode, ẹni to sọ loju opo Twitter rẹ pe o ba oun lọkan jẹ lati gbọ iku ọkunrin naa.
O dun mi lati gbọ pe Dapo Ojoro ti lọ lẹyin ọdun mẹsan ta padanu Gbegi, ẹgbọn rẹ."
"O ti to aadọta ọdun ti mo ti mọ Dapo, ta si jọ maa n gba Polo papọ, o si jẹ ọkan lara awọn alaanu ti mo sun mọ julọ."""
Oríṣun àwòrán, @realFFK
ICC: Ẹ̀rí wà pé àwọn ológun Nàíjíríà ń hùwà ìka sí Boko Haram àti ọmọnìyàn
Oríṣun àwòrán, Reuters
Awọn ileesẹ agbofinro ilẹ wa lo seese ko lọ jẹjọ ẹsun iwa ọdaran si ọmọniyan nileejọ agbaye to n gbọ ẹsun iwa ọdaran.
Ẹsun ti wọn fi kan awọn agbofinro naa ni pe wọn huwa ọdaran lasiko ti wọn lọ koju ikọ agbesunmọmi Boko Haram lẹkun ariwa orilẹede yii.
Agbefọba kan nileejọ agbaye naa, Fatou Bensouda lo sisọ loju ọrọ naa ninu atẹjade kan to fisita nipa iwadi ohun to n waye ni Naijiria.
O ni awọn koko ẹri ti wa nilẹ lati foju awọn ileesẹ agbofinro lorilẹede Naijiria wina ofin nipa ihuwasi wọn si ikọ Boko Haram.
Oríṣun àwòrán, AFP
"Gẹgẹ bi awọn ikọ Boko Haram yoo se jẹjọ ẹsun hihu iwa ọdaran loju ogun, naa lawọn ileesẹ ologun Naijiria yoo jẹjọ awọn iwa aidaa ti wọn hu bii ipaniyan, ifipabanilopọ, ifiyajẹni ati iwa ika lọdọ ileẹjọ ICC.
Bakan naa ni ileẹjọ ICC n sewadi ileesẹ ologun ilẹ wa lori ẹsun gbigba awọn ọmọde ti ọjọ ori wọn ko ti to ọdun mẹẹdogun sisẹ ologun.
O ni wọn n gba awọn ọmọde naa laaye lati maa kopa ninu iwa ikorira, ifiyajẹ eeyan tori ọrọ isẹda wọn ati ti oselu to fi mọ awọn iwa kotọ mii si ọmọniyan.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Yatọ si eyi, bakan naa ni Bensouda fikun pe awọn ologun naa yoo tun jẹjọ lori pe wọn kopa ninu iwa kikan nipa fun araalu lati poora, kiko awọn eeyan kuro lagbegbe wọn, ibinu si eeyan kan, kikọlu araalu ati mimu wọn si ahamọ laitọ."""
₦50 Duty Stamp: Iléẹjọ́ korò ojú sí CBN bó ṣe ń yọ owó táwọn báńkì olókoòwò fi pamọ́ sọ́dọ̀ rẹ̀
Oríṣun àwòrán, @cenbank
Ileẹjọ giga ilu Asaba ti kede pe ko tọna rara kawọn banki maa yọ aadọta naira lori iwe ifowopamọ ti onibara kọọkan ba kọ tabi fi ransẹ lati ori foonu wọn.
Adajọ Nnamdi Dimgba to gbe ẹjọ naa kalẹ ni aadọta naira ti wọn pe ni Stamp Duty naa jẹ owo kotọ ti onibara banki kọskan to ba fẹ fi owo pamọ n san.
Adajọ Dimgba lo kede bẹẹ lori ẹjọ kan to waye laarin olokoowo kan, Rupert Irikefe ati banki apapọ ilẹ wa, CBN pẹlu banki olokoowo Zenith ati agbẹjọro agba ni Naijiria.
Irikefe lo tọ ile ẹjọ naa wa pe ko kede pe banki CBN ko lẹtọ lati maa yọ lara owo ti banki Zenith ba fi pamọ sọdọ rẹ tabi gba aadọta naira lori ẹgbẹrun kan naira bii owo sitanpu.
Oríṣun àwòrán, @cenbank
O ni ileẹjọ kotẹmilọrun ti kọkọ gbe idajọ kalẹ saaju pe owo naa ko tọna, to si jẹ iwa aibọwọ fun ofin fawọn banki naa lati tẹsiwaju maa yọ ninu owo toun ba fi pamọ sọdọ wọn.
Bẹẹ si ni gbogbo ẹbẹ ti banki CBN se lati mu ki ile ẹjọ wọgile igbẹjọ naa lo ja si pabo, ti adajọ si tun koro oju si ọwọ tawọn ileesẹ ijọba fi maa n mu idajọ ileẹjọ.
Igbo Olodumare: Ohun gbogbo tó wà nínú ìwé Fagunwa ló wà nínú igbó náà
Oríṣun àwòrán, @KunleJONISE
Fun igba akọkọ, ẹnu alagba Daniel Olorunfemi Fagunwa, ti ọpọ eeyan mọ si D.O Fagunwa ni wọn ti gbọ nipa Igbo Olodumare.
Iwe yii ti Fagunwa kọ lọdun 1949 si ni awọn eeyan kan gbagbọ pe o jẹ iwe arosọ keji ti wọn yoo kọ ni ede Yoruba lẹyin iwe Ogboju Ode Ninu Igbo Irunmole.
Idi ni pe akọni onkọwe naa kọ iwe kan to pe akọle rẹ ni Igbo Olodumare, ti ọpọ eeyan si maa n ro pe arosọ lasan ni iwe naa.
Sugbọn ọpọ eeyan ni ko mọ pe Igbo kiji-kiji kan wa nipinlẹ Ondo lagbegbe ilu Okegbo, tii se ilu abinibi Fagunwa, ti wọn n pe ni Igbo Olodumare.
Irinajo si Igbo Olodumare lati ilu Okegbo, to wa loju ọna Ife si Ondo si to ogun Kilomita.
Oríṣun àwòrán, Wikipedia
Fun iyalẹnu, ọpọ awọn orukọ ti Fagunwa mẹnuba ninu iwe rẹ lo wa ninu Igbo Olodumare ta n sọrọ rẹ yii bi o tilẹ jẹ pe awọn ohun aramọnda bii iwin, idan, ati ọpọ adiitu ti poora nibẹ.
Sugbọn ẹ jẹ ka wo awọn ohun to wa ninu igbo naa to farapẹ awọn ohun ti Fagunwa mẹnuba ninu iwe rẹ.
Ni ẹnu ọna abawọle igbo ẹrujẹjẹ naa ni akọle kan wa to n se apejuwe ọna sinu igbo ọhun.
Amọ ohun iyalẹnu ni bi wọn se ni igbin tobi ju ijapa lọ ninu igbo naa.
"Akọle naa si lo ni ""Eyi ni ọna ilu Igbo Olodumare nibi ti igbin ti ga ju Ijapa lọ"
Wo ohun tí yóò ṣẹlẹ̀ ní ìpàdé àwọn èèkàn Yorùbá láti mú kẹ́ẹ dìbò fún Tinubu ní 2023
Kollington ṣàlàyé bí orin Fuji ṣe bẹ̀rẹ̀ gan an ní Nàiìjíríà
Oríṣun àwòrán, @battravels
Bakan naa ni Oke Langbodo wa ninu Igbo Olodumare , ara igi kan si ni wsn so akọle to n juwe ọna sori oke naa si.
Irin arinwọdi si ni ki eeyan to gun oke yii, eyi ti kii se eremọde rara.
Ori oke yii si ni wọn ti sọ pe igbin tobi ju ijapa lọ, aarin gbungbun Igbo Olodumare si ni Oke langbodo wa.
Oríṣun àwòrán, @battravels
Ere baba onirungbọn yẹukẹ naa wa ninu igbo olodumare yii.
Baba naa, ninu aworan yii lo de fila, ti irungbọn rẹ si gun lọ gbọọrọ, bẹẹ lo dudu pẹlu.
Koda, baba naa fi igi kan hanu to dabi ikoko taba, to si joko dabu ẹsẹ rẹ sori ara wọn.
Oríṣun àwòrán, Sunshine
Ẹsẹ bata to to mẹtalelaadọrin ni eeyan yoo ka ko to de ori Apata Adimula, nibi ti awọn agbaagba meje ti lọ sepade pẹlu Ojola ibinu, tii se olori ejo aye gbogbo, gẹgẹ bo se wa ninu iwe Fagunwa.
Fagunwa ni ẹẹkan ninu ọdun kan si ni Ojola ibinu naa maa n jade sita, ẹni to sọ pe o ni ori bii ti eeyan.
Oríṣun àwòrán, @TaoheedLawal
Aginju Idakẹrọrọ yii ni Fagunwa se apejuwe rẹ pe o dakẹ mini-mini, eku ati ẹyẹ kii ke nibẹ, bi abẹrẹ si bọ silẹ, eeyan yoo gbọ iro rẹ.
Fun iyalẹnu, ni aginju idakẹrọrọ ninu Igbo Olodumare loju aye, wọn kii faye gba ki ẹnikẹni bara wọn sọrọ, wọn kan maa n fi ọwọ se apejuwe fun ara wọn ni.
Oríṣun àwòrán, @CAPRITOLU
Ibẹ tutu mini mini lootọ, to si dabi ẹni pe ojo sẹsẹ rọ ni nigba ti awọn agbegbe yoku ninu igbo naa si gbona.
Bakan naa ni oju ọna si Isalu Ọrun, Ibujoko Olowo Aye ati odo ewe gbese ati Ọgbun Ainisalẹ wa ninu Igbo Olodumare gẹgẹ bi Fagunwa ti se apejuwe rẹ.
Inter-family marriage: Wo oríṣìí àrùn márùn ún tí ìgbéyàwó láàrin ìbátan máa ń fà
Oríṣun àwòrán, others
Igbeyawo laarin ibatan si ibatan wọpọ laarin ẹya Hausa ati Fulani ju bi ọpọ ṣe ro lọ.
Amọ, bi o ti wu ki o ri, igbeyawo laarin ọmọ tẹgbọn taburo fun apẹẹrẹ maa n jẹ ki ibaṣepọ to dan mọran wa laarin ẹbi.
Ṣugbọn awọn dokita oniṣegun oyinbo sọ pe, ewu maa n wa ninu irufẹ igbeyawo bẹẹ nigba mii gẹgẹ bi iwadii tawọn onisayẹnsi ṣe.
Dokita Ibrahim Musa ti ile iwosan ẹkọṣẹ ogun ni ilu kano to jẹ akọṣẹ-mọṣẹ nipa ṣisẹ iwadii lori ẹjẹ ati aarun inu ẹjẹ sọ pe, igbeyawo laarin ibatan ni ewu kiko arun lati ara awọn obi ninu.
Gẹgẹ bi iwadii ti awọn onimọ sayẹnsi ṣe, Dokita Musa ni wọnyii ni awọn arun ti igbeyawo laarin ibatan le fa.
Omolola Arohunmolase Welder: Mo ti fí iṣẹ́ 'Welder' gbayì láwùjọ, tó mo fi tọ́ ọmọ yanjú
Arun foniku-fọlande:
Dokita Musa ni arun kan to wọ pọ ninu awọn arun ti igbeyawo laarin ẹbi maa n fa, ni arun foniku-fọlande, taa mọ si sickle cell.
O ni awọn obi maa n ṣaa ba ni iru iṣọri ẹjẹ kan naa tawọn oloyinbo n pe ni ''genotype.''
Dokita naa ṣalaye pe iru arun yii yoo maa ran lọ ni ti awọn ọmọ tẹgbọn taburo to ba ni iru ẹjẹ bẹẹ ba si n fẹ ara wọn.
Dokita fikun ọrọ rẹ pe, awọn arun ajogunba kan tiẹ wa ti igbeyawo laarin ibatan maa n fa, eleyi tawọn ẹbi gan an kii ṣaba mọ.
Promise Akinlade: ọmọ ọdún mọ́kànlá tó ń fi ìlù dárà bíi àgbàlagbà sọ̀rọ̀ nípa tálẹ́ǹtì rẹ
Arun ajogunba:
Iwe iroyin Lancet Health Magazine lọdun 2013 ṣalaye pe, arun inu ẹjẹ obi le ṣakoba fun awọn ọmọ ti wọn ba bi.
Fun apẹẹrẹ, obinrin to fẹ ọkunrin ibatan rẹ, o ṣeeṣe ki awọn ọmọ to ba bi ni iru arun to wa lara awọn obi ọkunrin naa.
Iṣẹ iwadii awọn onimọ iṣegun fidi rẹ mulẹ pe, wahala arun maa n ṣẹlẹ nigba ti igbeyawo ba waye laarin ọmọ tẹgbọn taburo.
Iṣẹ iwadii naa ṣalaye pe, awọn ọmọ to ba jade lati inu igbeyawo ibatan si ibatan papaa julọ, tawọn obi wọn ba jogun arun kan tabi omiran lara awọn obi tiwọn naa.
Adebola Ademilua: Àìrísẹ́ ṣè lẹ́yìn ìwé kíkà ló sọ mi dí ìyá onírú, mo dúpẹ́ tèmi
Bibi akanda ọmọ:
Ajọ eleto ilera NHS sọ pe, iṣoro arun ajogunba wa kaakiri ni gbogbo awujọ lagbaaye.
Ṣugbọn ajọ naa ni bibi akanda ọmọ ṣa baa wọ pọ laarin igbeyawo ibatan si ibatan.
Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó
Iwadii ajọ NHS tun fihan pe, igbeyawo laarin ẹbi wọpọ laarin awọn ọmọ orilẹede Pakistan to n gbe ni UK.
Iṣẹ iwadii ọhun fidi rẹ mulẹ pe, ọpọ iru igbeyawo bẹẹ ni o ṣeeṣe ki wọn bi ọmọ to ni ipenija ara.
Dokita Musa ni niwọn igba ti arun kan tabi omiran ti wa ninu ẹbi, yoo maa ran lọ ni, tawọn ọmọ iru ẹbi bẹẹ ba n fẹ ara wọn.
"Kí ni ""Present tense"" lédè Yorùbá?"
Arun ọpọlọ:
Arun mii ti igbeyawo laarin ẹbi maa n fa ni arun ọpọlọ, gẹgẹ bi iwadii awọn onimọ sayẹnsi ṣe sọ.
Dokita Musa tun sọ pe, awọn arun ajogunba lo maa ṣaa ba jẹ ki oyun bajẹ lara obinrin.
Itaniji: Oluwo sọ ìtàn bí Orunmila ṣe jìyà nílùú Iwo àti ayọ̀ tó gbẹ̀yìn rẹ̀ torí sùúrù
Bakan naa lo ṣalaye pe aisan ẹjẹ ruru naa tun wọ pọ ninu igbeyawo laarin ẹbi.
''Iru rẹ ṣẹlẹ laipẹ yii nijọba ibilẹ Batsari nipinlẹ Katsina, nibi ti awọn ọkunrin ati obinrin kan ti wọn jẹ ọmọ ibeji ti fẹ ara wọn. Mẹrin ninu awọn ọmọ ti wọn bi lo ni ipenija ara,'' Dokita Musa lo sọ bẹẹ.
Dokita ni awọn ọmọ naa ni ipenija oju ati imu.
Nigeria movie industry: Àgbà òṣèré, Lere Paimo ní àìgbọràn ló ń da ọ̀pọ̀lọpọ̀ àwọn
Arun jẹjẹrẹ oju:
Dokita Ramatu Hassan to jẹ olulanilọyẹ nipa arun jẹjẹrẹ oju ni Naijiria tẹlẹ ṣalaye fun BBC pe, igbeyawo laarin ẹbi maa n fa arun jẹjẹrẹ oju.
Dokita Hassan ni ''arun yii maa n bẹrẹ nigba ti ọmọ ba wa ni ikoko, yoo si maa gbilẹ sii bi ọmọ ṣe n dagba, nigba to ba ya ọmọ naa le ma riran mọ.''
Oríṣun àwòrán, Getty Images
O ṣalaye pe iru arun yii wọ pọ lapa ariwa orilẹede Naijiria, nibi ti iru igbeyawo bẹẹ ti wọpọ.
''Irun arun jẹjẹrẹ oju yii ti maa n mu ọmọ ti wọn tiẹ to bi sile aye nitori arun ajogunba ni,'' Dokita Hassan lo sọ bẹẹ.
Murder In Ibarapa: Aborode tó tún jẹ́ olóṣèlú kàgbákò ikú òjijì lọ́nà oko
Oríṣun àwòrán, Facebook/Fatai Aborode
Agbébọn tún gbẹ̀mí àgbẹ̀ míì lọ́nà oko lágbègbè Ibarapa
Awọn agbebọn ṣekupa oludije fun ile igbimọ aṣojo-ṣofin agba l'Abuja nigba kan ri labẹ asai ẹgbẹ oṣelu Accord, Ọmọwe Fatai Aborode
Ọmọwe Aborode to jẹ oludari ileeṣẹ Kunfayakun Green Treasures Ltd ni a gbọ pe awọn afurasi ti irisi wọn jọ tawọn Fulani darandaran yinbọn pa lẹba oko rẹ, lọna ilu Apodun ni Igangan, ijọba ibilẹ Ariwa Ibarapa.
Ọjọ Ẹti ọjọ kọkanla oṣu kejila ọdun 2020 yii ni deedee aago mẹrin irọlẹ ni iroyin sọ pe wọn pa oloṣelu ọhun lori alupupu, lẹyin to kuro ni oko rẹ pẹlu ẹni ti o ba n mojuto oko naa.
Amọ, ẹni ti wọn jọ wa lori alapupu mori bọ lọwọ awọn janduku afẹmiṣofo naa.
Ẹnikan to mọ nipa iṣẹlẹ naa ṣalaye pe, wọn gbe oloṣelu ọhun digba digba lọ si ile iwosan ṣugbọn ẹlẹmi ti gba a.
Agbẹnusọ fun ileeṣẹ ọlọpaa ipinlẹ Oyo, SP Olugbenga Fadeyi ti fidi iṣẹlẹ ọhun mulẹ.
SP Fadeyi ṣalaye ninu atẹjade to fi sita laarọ ọjọ Abamẹta pe awọn agbebọn lo ṣekupa oloṣelu naa lẹyin ti wọn ja a lole tan.
O ni ileeṣẹ ọlọpaa ti bẹrẹ iṣẹ lati ṣe awari awọn ọdaran naa to ti sa lọ.
Iṣẹlẹ yii waye lẹyin ti awọn agbẹ ṣe ipade tan lori ati wa ojutu si iṣẹlẹ iṣekupani awọn Fulani darandaran niluu Ibadan.
Adebola Ademilua: Àìrísẹ́ ṣè lẹ́yìn ìwé kíkà ló sọ mi dí ìyá onírú, mo dúpẹ́ tèmi
RCCG Congress 2020: Pásítọ̀ ní owó Naira yóò sì tún gbé pẹ́ẹ́lí lẹ́ẹ̀kàn síi
Oríṣun àwòrán, @thehgcongress
Alabojuto gbogbogbo fun ijọ Redeemed Christian Church of God, RCCG, Pasitọ Enoch Adeboye ti sọ pe owo Naira yoo si tun pada niyi lawujọ awọn owo orilẹ-ede to gbe pẹẹli julọ lagbaye.
Adeboye lo sọ ọrọ naa laarọ ọjọ Abamẹta nibi ipade adura Holy Ghost Congress to maa n waye lọdọdun ni Olu ijọ naa to wa lọna marosẹ Eko si Ibadan.
Ẹni ọdun mejidinlaadọrin ọhun gbadura pe ki Ọlọrun da si eto iṣuna Naijiria, ko si tun yi ọkan awọn alaṣẹ to n mọọmọ ṣe awọn eto to n pa owo Naira lara pada.
Adeboye sọ itan kan fun awọn eeyan to wa nibi ipade adura naa pe, ni ọpọ ọdun ṣeyin, oun nilo ẹgbẹrun marun un naira pere lẹyin ti oun pe ọpọ ero sibi ipade adura pẹlu ileri pe oun yoo gbọ bukata jijẹ ati mimu wọn.
Bo tilẹ jẹ pe ko ni owo naa lọwọ, o ni Ọlọrun pese owo ọhun lọna iyanu.
"Pasitọ naa ni ""owo Naira niye lori lọdun naa lọhun, yoo si tun niye lori lẹẹkan sii."""
Oríṣun àwòrán, @thesignalng
Gbogbo awọn to n mọọmọ rẹ owo naira silẹ, Ọlọrun yoo da si ọrọ wọn ki ilẹ ọla to mọ.
Ọpọ ọmọ Naijiria to ti n lọgun pe owo naira ko niyi mọ lati nkan bi ọdun diẹ sẹyin, paapaa lẹyin ti owo dollar kan parada di ẹẹdẹgbẹta naira.
Awọn to maa n ṣẹ owo ilẹ okere, Bureau De Change, sọ pe idi ti owo naira ṣe n lọ soke silẹ ko ṣẹyin awọn eeyan kan.
Ẹwẹ, banki apapọ Naijiria, CBN, ni owo dollar kan ko to irinwo naira, gẹgẹ bi iṣiro to wa loju opo wọn lori ayelujara.
Oríṣun àwòrán, Facebook/Godwin Obaseki
Gomina ipinlẹ Edo, Godwin Obaseki ti ṣalaye pe, oludari ijọ Redeemed Christian Church of God, Enoch Adeboye gbadura foun, o si tun sọ asọtẹlẹ pe oun yoo wọle ibo gomina ipinlẹ Edo fun saa keji.
Gomina Obaseki sọrọ yii lasiko to n jẹri nibi akanṣe eto ọlọdọọdun ijọ Redeem, RCCG Holy Ghost Congress ti ọdun 2020 yii lọjọ Ẹti.
Obaseki ni ''nigba ti ogun gbona giri giri, emi ati iyawo mi ṣabẹwo si Daddy G.O. ni ipagọ ijọ Redeem to wa lopopona ilu Eko si Ibadan.
''Lẹyin ti mo ṣalaye ipenija mi lagbo oṣelu tan, pasitọ Adeboye sọ pe ''ọmọ mi, ma foya, iwọ ni yoo bori, wa si wọle ibo gomina lẹẹkeji,'' Obaseki lo sọ bẹẹ.
Gomina ni oun pada lọ ri alufaa Adeboye nigba ti idibo gomina ọhun ku diẹ, o si tun sọ foun pe gbogbo rẹ maa dara lẹyin ''to gbadura fun mi tan.''
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ẹgbẹ oṣelu APC lo gbe Obaseki wọle fun saa kinni gẹgẹ bi gomina ipinlẹ Edo.
Ṣugbọn ẹgbẹ APC ko fun un lanfaani lati jẹ oludije ẹgbẹ ọhun ninu idibo ọdun 2020, lẹyin rogbodiyan to ṣẹlẹ pẹlu alaga gbogbo-gboo ẹgbẹ oṣelu naa tẹlẹ, Adam Oshiomole.
Pasitọ Osagie Eze-Iyamu ni APC fun lanfaani lati dije fun ipo gomina, labẹ asia ẹgbẹ oṣelu naa dipo Obaseki.
Eyi lo mu ki Obaseki lọ sinu ẹgbẹ oṣelu PDP, nibi to wọle ibo gomina ipinlẹ lẹẹkeji.
Students kidnap: Garba Shehu ní iléeṣẹ́ ológun ti yabo ibùdó àwọn jàndùkú tó jí àwọn akẹ́kọ̀ọ́ lọ nílé ìwé katsina
Oríṣun àwòrán, AFP
Oluranlọwọ aarẹ Muhammadu Buhari lori ọrọ iroyin, Garba Shehu ti sọ pe ileeṣẹ ologun ti ṣe awari awọn janduku agbebọn to ji awọn akẹkọọ ileewe girama to wa ni Kankara, nipinlẹ Katsina.
Shehu to fọrọ yii lede loju opo Twitter rẹ ṣalaye pe awọn ologun ti ṣe akitiyan lati doola awọn akẹkọọ to wa lakata awọn janduku ọhun.
O ṣalaye pe ninu igbo Zango/Paula ni Kankara lawọn sọja pẹlu itanlọwọ awọn ọmogun ofurufu ti ri awọn janduku ajinigbe naa.
Ninu atẹjade ti Shehu fi lede ọhun ni o ti sọ pe ko si ikankan to fara gbọgbẹ ninu awọn akẹkọọ ti wọn gbe lọ bo tilẹ jẹ pe awọn sọja atawọn agbebọn naa kọju ija si ara wọn.
Bakan naa ni Shehu sọ pe Aarẹ Muhammadu Buhari ti bu ẹnu atẹ lu iṣẹlẹ naa, o si paṣẹ pe ki eto abo to nipan wa ni gbogbo ileewe.
Akẹkọọ mẹrinlelaadọta ni a gbọ pe awọn janduku agbebọn ọhun ji lọ lọjọ Ẹti nileewe to wa ni kankara ni Katsina.
Iṣẹlẹ naa ṣẹlẹ kete ti Buhari bẹrẹ abẹwo ọlọsẹ kan si ipinlẹ Katsina tii ṣe ipinlẹ rẹ.
Buhari kẹdun pẹlu awọn obi awọn akẹkọọ ti wọn jigbe lọ atawọn alaṣẹ ileewe naa.
Ìjọba Katsina ti gbogbo ilé ìwé tí àwọn akẹ́kọ̀ọ́ ń gbé pa lẹ́yìn àkọlù tó wáyé níbẹ̀
Gomina ipinlẹ Katsina, Aminu Masari ti paṣẹ pe ki wọn ti gbogbo ile iwe ti awọn akẹkọọ n gbe ni ipinlẹ naa pa.
Masari lo kede bẹẹ lẹyin ti awọn agbebọn kan ṣakọlu sile iwe awọn akẹkọọ to jẹ ọkunrin nikan loru ọjọ Ẹti, ti wọn si ji lara wọn gbe lọ.
Gomina ọhun ṣabẹwo sile iwe naa toun pẹlu igbakeji rẹ, Mannir Yakubu, ti wọn si ṣeleri fun awọn eeyan Kankara nibi ti iṣẹlẹ naa ti waye pe ijọba apapọ yoo sa gbogbo ipa rẹ lati ṣawari awọn akẹkọọ to poora.
Titi di akoko ti a n ko iroyin yii jọ, ko ṣeni to tii le sọ iye awọn akẹkọọ to di awati ni pato.
Oríṣun àwòrán, GALI KANKARA
Ileeṣẹ ọlọpaa ipinlẹ naa ni awọn n ṣe iwadii lọwọ, ṣugbọn iroyin ni ko din  ni irinwo akẹkọọ to poora.
Ile iwe ọhuun, Government Science Secondary School, to jẹ ti awọn akẹkọọ ọkunrin nikan ní akẹkọọ to le ni ẹgbẹrin.
Awọn eeyan to n gbe lagbegbe ibi ti iṣẹlẹ naa ti waye sọ pe irinwo le mẹfa ni wọn ti ri lara awọn ọmọ ile iwe naa, ṣugbọn wọn ko le sọ ibi ti awọn to ku wa.
Yoruba bọ wọn ni ọmọ ẹni ku san ju ọmọ ẹni nu lọ,  eyi lo difa fun Gomina ipinlẹ Katsina to bẹ sẹkun gbaragada lẹyin tawọn janduku agbebọn yabo ileewe girama kan to wa ni Kankara, nipinlẹ Katsina nibi ti wọn ti ji ọpọ akẹkọọ lọ.
Iṣẹlẹ yii ṣẹ lẹyin wakati diẹ ti Aarẹ Muhammadu Buhari gunlẹ si ipinlẹ naa fun abẹwo ọlọsẹ kan.
Ileeṣẹ ọlọpaa ipinlẹ Katsina ṣalaye pe ni aago mọkanla aabọ alẹ ọjọ Ẹti lawọn gbọ pe awọn janduku pẹlu ibọn AK47 lọwọ wọn yabo ileewe girama to wa ni Kankara.
Ileeṣẹ ọlọpaa ni ọpọ awọn akẹkọọ lo sa asala fun ẹmi wọn nigba tawọn kọlọnbiti ẹda ọhun de ọgba ileewe wọn.
Koda ọga ọlọpaa DPO ṣalaye fawọn akọroyin pe akẹkọọ igba lo ti pada si ileewe naa lẹyin ti wọn ti sa sinu igbo lati alẹ ọjọ Ẹti.
Ileeṣẹ ọlọpaa lawọn si n ka awọn akẹkọọ lati mọ bo ya awọn janduku agbebọn naa ri awọn akẹkọ ji gbe lọ.
Ṣugbọn ẹnikan ti ọrọ naa ṣoju rẹ sọ fun BBC pe lootọọ lawọn agbebọn ji awọn akẹkọọ lọ ni ileewe naa.
Ọga ọlọpaa naa fikun ọrọ rẹ pe awọn ọlọpaa to ṣọ ileewe ọhun kọju ija sawọn janduku naa nibi ti ọlọpaa kan ti farapa.
O ni ọlọpaa to ṣeṣe naa n gba itọju lọwọ bayii nile iwosan.
Iroyin kan sọ pe ilegbe awọn oṣiṣẹ to wa nile iwe naa lawọn ọdaran naa kọkọ lọ ni nibi ti wọn ti ji iyawo ọkan lara awọn gbe.
Lẹyin naa ni wọn lọ si ilegbe awọn akẹkọọ nibi ti wọn gbe awọn akẹkọọ ti ẹnikan ko tii mọ iye rẹ lọ.
Awọn kan tun sọ pe awọn ologun lọ si ileewe naa lati doola awọn akẹkọọ ṣugbọn wọn pada ji awọn akẹkọọ kan lọ.
Shiloh 2020: Oyedepo ní òun kò le tòṣì láéláé! Ẹni tó bá ń bínú kàn ń bínú lásán ni
Oríṣun àwòrán, Facebook/Bishop David Oyedepo
Oludasilẹ ijọ Living Faith ti ọpọ mọ si Winners, Biṣọọbu David Oyedepo tun ti sọ pe oun ko le toṣi laelae!
Biṣọọbu Oyedepo sọrọ yii nigba ti o n waasu nibi akanṣe eto ọlọdọọdun ijọ Winners, Shiloh 2020 niluu Ota, ipinlẹ Ogun.
Biṣọọbu Oyedepo ni majẹmu ti Ọlọrun ti la kalẹ ninu iwe mimọ ti oun n tẹle ko le jẹ ki oṣi mọ ile oun laelae.
O ṣalaye pe niwọn igba ti orun ba n yọ loke ti ilẹ si n su u, majẹmu to sọ oun di ọlọrọ ko le yipada laelae.
Biṣọọbu Oyedepo ni Ọlọrun sọ fun oun pe ilọrọ ninu Oluwa kii ṣe ileri, kii sii ṣe ọrọ adura ati aawẹ. Ti eeyan ko ba ko ipa tirẹ, Ọlọrun naa ko ni ṣe ohun kan.''
''Nigba naa ni mo ke Yeeeehhh! Mo o le toṣi laelae. Ẹni to ba fẹ lọrọ ninu Oluwa ko gbọdọ fi idamẹwa ati ififunni ṣere,'' Oyedepo lo sọ bẹẹ.
Ọlọrun tun sọ ohun miiran fun mi lẹyin ti mo ka iwe ti Kenneth ati Gloria Copeland lori ilọrọ ninu Oluwa tan.
Oyedepo ni: ''O sọ fun mi pe bi Oun ṣe maa n ṣi ferese ọrun si awọn eeyan naa ni Oun maa ṣi ferese ọrun sori ileeṣẹ.
Apẹẹrẹ iru rẹ to wa ninu Bibeli ni Abarahamu to san idamẹwaa lori gbogbo ohun to ko bọ lati oju ogun.
Biṣọọbu Oyedepo ni lati igba naa ni ijọ Winners ti bẹrẹ si ni san idamẹwaa eyi ti o si n jẹ ki ferese ọrun maa tubọ ṣi sori ijọ naa sii.
Ojú mi ti rí lọ́pọ̀ lọpọ̀, àmọ́ mo dúpẹ́ pé mo ti pé ọdún márùn ún lórí oyé- Ooni
Ìjọ 10,000 tuntun ni a dá sílẹ̀ láì gba owó ọrẹ lọ́wọ́ ọmọ ìjọ lásìkò àrùn Coronavirus- Oyedepo
Oluṣọ agutan agba ijọ Living Faith, pasitọ David Oyedepo ti ṣi aṣọ loju eegun pe bo tilẹ jẹ arun Covid-19 ba gbogbo agbaye finra lọdun 2020, ẹka ẹgbẹrun mẹwaa tuntun  ni ijọ naa ṣi lai gba kọbọ lọwọ ọmọ ijọ kankan.
Oyedepo lo sọ ọrọ naa lọjọ Abamẹta to jẹ aṣekagba ipade adura Shiloh, eyii to maa n waye lọdọdun.
Oríṣun àwòrán, @AdedejiKenny16
"Gẹgẹ bo ṣe sọ, o ni ""bo tilẹ jẹ pe arun naa n dun mọhuru mọhuru, ẹgbẹrun mẹwaa ẹka tuntun ni ijọ yii ṣi lai gba owo ọrẹ kankan, a o fi oju imu eṣu danrin."""
Nigba to n sọrọ ṣaaju nipa arun Covid-19, Oyedepe sọ pe oun ko gbagbọ pe Covid-19 kan wa nibi kankan .
"O ni ""ti wọn ba bere lọwọ mi nipa Covid-19, esi mi ko ju pe, Covid-19 wa, bẹẹ ni ko si."""
Oríṣun àwòrán, @LFCGoshen
Ẹni to ba gbagbọ ninu Covid-19 ni arun naa yoo ran, ẹni ti ko ba gbagbọ ninu rẹ ko ni lugbadi arun naa.
Lẹyin naa lo sọ siwaju si pe ọpọ eeyan lo ti ri iwosan gba lọwọ arun Covid-19 ninu ijọ oun.
Promise Akinlade: ọmọ ọdún mọ́kànlá tó ń fi ìlù dárà bíi àgbàlagbà sọ̀rọ̀ nípa tálẹ́ǹtì rẹ
Ọgbà ẹ̀wọ̀n ni wọ́n ti já ìbálé Esra lábẹ́ àwáwí àyẹ̀wò wúndíá
Ninu aworan yii, obinrin kan sọ iriri rẹ lori bi o ṣe la iwa ifipa ṣe ayẹwo funni lọgba ẹwọn labẹ awawi a n ṣe ayẹwo abale funni.
Bi o tilẹ jẹ pe ko si imọ sayẹnsi to gbe e lẹsẹ,  o le ni ogun orilẹede ti awọn ayẹwo abale ti wọn n fipa ṣe yii ti n waye gẹgẹ bi ajọ iṣọkan agbaye ṣe sọ.
Ileeṣẹ BBC lede larubawa, BBC Arabic ba Esra, ọkan lara awọn to tii ṣe ẹwọn ri nitori ọrọ oṣelu lorilẹede Egypt sọrọ; o si ṣalaye iriri rẹ nipa ayẹwo ibale afipa ṣe lasiko to fi wa lọgba ẹwọn.
A yi orukọ rẹ pada lati daabo bo.
Ember Month Security: Ọwọ́ pálábá àwọn ọmọ ẹlégbẹ́ òkùnkùn 15 ségí ní ìpínlẹ̀ Eko
Oríṣun àwòrán, Lagos Police
Ijọba ipinlẹ Eko ni ọwọ awọn ti tẹ awọn ọdaran ti wọn n da agbegbe Ikorodu ati Lekki/Ajah laamu nipinlẹ Eko.
Agbẹnusọ ileeṣẹ ọlọpaa ni ipinlẹ Eko, Olumuyiwa Adejobi, ninu atẹjade to fi lede naa ni ikọ ọlọpaa to wa ni Ikorodu lo mu awọn ọdaran naa.
Adejobi ni ohun to ṣẹlẹ ni wi pe araalu kan lo ji pe awọn ọlọpaa ni aago mẹrin owurọ lati agbegbe Agunfoye,
Nigba ti ikọ ọlọpaa Ikorodu yoo fi de ibẹ ni ọwọ tẹ arakunrin Taiye Lasisi, ti wọn mu pẹlu ibọn ilewọ lọwọ rẹ.
Lẹyin ti ọlọpaa fi panpẹ mu tan ni wọn tu gbogbo agbegbe naa yẹbẹ yẹbẹ, ti ọwọ si tẹ awọn yoo ku.
Lara awọn mẹtala ti wọn mu naa jẹ awọn ẹlẹgbẹ okunkun Aiye, ti wọn si wọn si ti gbe wọn lọ si atimọle.
Oríṣun àwòrán, Lagos Police
Bakan naa ni wọn ri awọn ohun ini gba lọwọ wọn bi ẹrọ ilewọ ati awọn ohun ini miran.
Ninu ọrọ tirẹ, Kọmisọnnna ọlọpaa nipinlẹ Eko, Hakeem Odumosu ni iwadii ti bẹrẹ lori iṣẹlẹ naa, ati wi pe awọn ko ni fi aye gba iwa ipa ati iwa ọdaran kankan nipinlẹ Eko.
Ìjà kan to waye laarin awọn ọmọ ẹgbẹ meji nilu Ejigbo ti ṣokunfa iku arakunrin kan, Abeeb Abifarin ti agboole Oke Dada nilu Ejigbo nipinlẹ Osun.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Lọjọ isegun ni o padanu emi rẹ ninu ìjà yọbẹ y'ada laarin awọn ẹgbẹ meji nilu naa.
Bakan naa la gbọ pe ọpọ eeyan lo farapa ninu ìjà yii, tó bẹrẹ ni irọlẹ ọjọ Aje ladugbo Ori Eru laarin awọn ọmọ ẹgbẹ Lion Base Club, ti agboole  Olukola ati awọn ti Isalẹ Agooji Club.
Ohun taa gbọ ni pe, wọn yìnbon pa Abeeb bí ọwọ agọ meje kú iṣẹju mẹẹdogun aṣalẹ ọjọ Aje nigba ti ìjà yi bẹ sílẹ.
Awọn kan ti ọrọ naa soju ni, wọn ge apa rẹ jabọ ninu ikọlu yi.
Àdá, àáké, ati fila pupa jẹ́ diẹ lara ami idanimọ awọn ẹgbẹ okunkun ni Naijiria
Ara adugbo naa kan to ba awọn akọroyin sọrọ, ṣugbọn ti ko fẹ ki wọn darukọ rẹ sọ pe, ọkunrin kan t'awọn ko mọ orukọ rẹ naa tun ku lọjọ ìṣẹgun lẹyin t'awọn agbofinro pẹtu sí aawọ náà tan.
Amọ ṣa ileesẹ wa kò ti ribi fidi ọrọ bayi mu'lẹ.
Pupọ awon ilé ìtajà ni Ejigbo ni wọn sáré ti pa nitori wahala yii, ti won sì tun ti ileesẹ awọn oṣiṣẹ ijọba ibilẹ Ejigbo naa pa, ki awọn oṣiṣẹ pada sílé.
2020 in Retrospect: Ìjàmbá iná, ilé tó dàwó, ìwọ́de àti àrùn Covid-19 wà lára ìṣẹ̀lẹ̀ 2020
A tún padà gbọ pe awọn to dojú ìjà kọ ara wọn ọhun tun gbe ìjà wọn dé adugbo Sagan, Orieru, Port junction ati roundabout pẹlu nkan ija oloro titi di afẹmọju lojo Ìṣẹgun.
A kò tíì le sọ nkan to fa ìjà yi pato sugbọn finfinfin t'awọn akọroyin lagbegbe naa gbọ ni pe, owo ẹbùn ọdun to to ẹgbẹrun lọna aadọjọ naira (N150,000) lo dá ìjà silẹ.
Oríṣun àwòrán, Plustv africa
Ohun to n mu ki ọpọ eeyan maa dawọle idajọ ọwọ ara ẹni, taa mọ si Jungle Justice, ni ainigbagbọ to kuna ninu eto idajọ ododo ti ofin gbe kalẹ.
Eyi ni ọrọ Amofin Akeem Fadun, eekan agbẹjọro kan nilu Eko lasiko to n ba BBC Yoruba sọrọ lori ohun to mu ki idajọ ọwọ lawujọ di lemọ-lemọ.
Kii ṣe ani-ani mọ pe awọn eeyan ni ipinlẹ Ọyọ n se gbọnmọgbọnmọ fifi idajọ afurasi sọwọ ara wọn, eleyi to si ti n kọ ọpọlọpọ eeyan ati awọn onwoye lominu.
Laarin bi ọsẹ diẹ sẹyin bayii, ko din ni eeyan mẹfa ti awọn eeyan ti dana sun ninu isẹlẹ ọtọọtọ, tori pe wọn fura iwa aidaa kan tabi omiran si wọn.
Oríṣun àwòrán, Tade Oludayo
Amofin Akeem Fadun ni ọpọ igba ni araalu maa mu ọdaran lọ si agọ ọlọpaa ṣugbọn to jẹ wi pe wọn yoo tun ri ọdaran bẹẹ nigboro lẹyin wakati tabi ọjọ diẹ.
Bakannaa lo tun pe fun eto ilanilọyẹ fun araalu lori ipenija ati ewu to wa lori idajọ ọwọ.
Eekan amofin naa fi kun un pe, ọdaran ni ẹnikẹni to ba lọwọ ninu iṣẹlẹ idajọ ọwọ labẹ ofin.
Oríṣun àwòrán, @PoliceNG
O ni nibi ti ọrọ de duro bayii, ijọba gbọdọ bẹrẹ si ni fi awọn to ba n lọwọ ninu iṣẹlẹ didana sun afurasi tabi idajọ ọwọ jofin, lati lee jẹ ifaleti fun awọn eeyan mii lọjọ miran.
Onimọ nipa ofin naa ko ṣai yannana rẹ pe, wahala iwọde #EndSARS to kọja laipẹ yii ti n fun awọn eeyan ni igboya lati hu awọn iwa kotọ.
"Wọn ti lero pe bi awọn ṣe parapọ ba ọpọ dukia jẹ, ti wọn si ṣe ọpọ iwa jagidijagan lasiko naa, ti ko si si ẹni to mu wọn sii, ni awọn ṣe lee maa hu iwa kotọ naa lọ.
Oríṣun àwòrán, Abdulmumin Rabiu
Ijọba gbọdọ fi awọn eeyan jofin daadaa lori iwa aburu yii, lati jẹ ki araalu mọ pe iyatọ wa laarin kiko ara jọ pọ, ja fun ẹtọ labẹ ofin ati kiko ara jọ pọ hu iwa ọdaran."
Bakannaa ni Amofin Akeem Fadun tun mu aba wa pe, bi araalu ko ba ni igbagbọ ninu ilana idajọ lorilẹede yii, boya ki wọn maa gbe igbimọ kan kalẹ, lati maa tọpinpin bi awọn agbofinro ṣe n yanju awọn afurasi ti wọn ba gbe wa si ọdọ wọn.
Ẹwẹ, nigba ti BBC News Yoruba kan si ijọba ipinlẹ Ọyọ, kọmiṣọna feto iroyin ati aṣa, Ọmọwe Wasiu Ọlatubọsun ṣalaye pe ijọba n gbe igbesẹ lati tubọ mu ki okun ati koriya wa fun awọn agbofinro lati ṣiṣẹ wọn.
Oríṣun àwòrán, Facebook/Dr. Wasiu Adewale Olatubosun
Ọmọwe Ọlatubosun ni itaniji ti bẹrẹ lori iwa kotọ yii, lati mu ki araalu mọ wahala to rọ mọ irufẹ iwa didana sun awọn afurasi.
Bakan naa lo tun rọ awọn ọlọpaa lati rii pe gbogbo afurasi ti wọn ba mu de ọdọ wọn, ni wọn foju wina ofin.
Yoruba ni ọjọ gbogbo ni ti ole, amọ ọjọ kan soso pere ni ti olohun.
Akomolede ati Aṣa: Mọ̀ síi nípa ìró afárànma àti agbárànmọ́ fáwẹ́ẹ̀lì Yorùbá
Bẹẹ lọrọ ri fun awọn adigunjale meji kan lọjọru nilu Ibadan nigba ti wọn ja ọkunrin kan lole amọ ti ọwọ palaba wọn segi.
Atẹjade kan ti ileesẹ ọlọpa fisita lori isẹlẹ naa salaye pe deede aago mẹta aabọ irọlẹ ọjọru ni isẹlẹ naa waye si ọkunrin kan, ti wọn pe orukọ rẹ ni Tobi Adebayo, ẹni ọdun mẹtadinlọgbọn to wa ninu ọkọ ayọkẹlẹ rẹ.
Gẹgẹ bi ileesẹ ọlọpaa ti wi, adugbo Favours, lopopona Awolowo si Bodija nilu Ibadan ni awọn ọkunrin meji to wa lori ọkada ti sẹburu ọkọ Toyota Corolla rẹ, ti wọn si fi tipa gba foonu ati apo kan ti iwe wa ninu rẹ.
Amọ ẹnikan ti isẹlẹ naa soju rẹ ni owo to to miliọnu marun naira lo wa ninu apo naa, ti ọkunrin ọhun to jẹ olokoowo gbe lọwọ.
Atẹjade naa ni ni kete tawọn adigunjale naa sisẹ laabi ọhun tan, ni wọn fẹsẹ fẹ lori ọkada wọn amọ ti Adebayo atawọn araalu gba ya wọn  pẹlu ọkọ rẹ titi to fi le wọn de adugbo dandaru.
Lojiji ni ọkada naa ja sinu koto nla kan, tawọn adigunjale naa si jabọ, bẹẹ ni ọkan ninu wọn dagbere faye loju ẹsẹ nigba ti ekeji fara gbọgbẹ, ti ara rẹ si bo falafala.
Atẹjade ileesẹ ọlọpaa naa ni, ni kete ti iroyin naa kan ọga ọlọpaa to wa ni agọ ọlọpaa Agodi lara lo morile ibi isẹlẹ naa amọ ko to de ibẹ, ẹpa ko boro mọ.
Africa Eye: Wo ìtàn ìyá kan ìyá kan àtàwọn olè ajọ́mọgbé tó n ta ọmọ ní Kenya
Idi ni pe awọn araalu tinu n bi, ti wọn le ni igba, ti dana sun adigunjale to fara gbọgbẹ naa, tawọn ọlọpaa si ti gbe ajoku rẹ lọ sile igbokusi.
Bakan naa ni ileesẹ ọlọpaa ni aayan ti n lọ lati tanna wadi isẹlẹ naa siwaju si.
Sugbọn isẹlẹ naa da sunkẹrẹ fakẹrẹ ọkọ silẹ ladugbo dandaru si Mokola, tawọn osisẹ Amotekun naa si bawọn peju sibi isẹlẹ ọhun, bẹẹ ni wọn n dari ọkọ lagbegbe naa pẹlu lati dena sunkẹrẹ fakẹrẹ.
Awọn igara ọlọṣa ti yinbọn pa ọkunrin ọlọdẹ kan lagbegbe Mọniya nilu Ibadan.
Arakunrin naa ti awọn ọlọpaa pe orukọ rẹ ni Isau Yisah ni wọn sọ wi pe o n ṣe ṣọ ile epo kan lagbegbe naa lasiko ti awọn ọlọṣa fi ya bo adugbo naa lọjọ Abamẹta.
Gẹgẹ bi ohun ti awọn iroyin kan sọ, awọn ọlọdẹ agbegbe naa, ninu eyi ti Yisah wa doju kọ awọn ọlọṣa naa ki o to di pe awọn ọlọṣaa naa pa Yisah lagbegbe Asanmajana ti ileepo naa wa.
Ohun ti awọn eeyan kan n sọ lagbegbe naa ni pe boya oloogbe naa da awọn kan lara awọn ọlọṣa naa mọ ni wọn ṣe pa.
Ọgbà ẹ̀wọ̀n ni wọ́n ti já àbálé Esra lábẹ́ àwáwí àyẹ̀wò wúndíá
Ileeṣẹ ọlọpaa ni ipinlẹ Ọyọ, la gbọ pe o ti fi idi iṣẹẹ idigun jale naa mulẹ ti wọn si ni iwadii ti bẹrẹ.
Gẹgẹ bi atẹjade kan ṣe sọ, wọn ti gbe oku arakunrin naa lọ sileewosan nla ijsba to wa lagbegbe Mọniya.
Seun Kuti: Seun, ọmọ Fela, lóòtọ́ lóun yìnbọn níbi yánpọnyánrin pẹ̀láwọn tó wa ọkọ̀ dí ilé òun, àtipé bó jẹ́ ìjọba àpapọ̀ ló ṣ'àìtọ́ nílé òun ìbọn á sọ
Seun Kuti, ọmọ agba ojẹ olorin Fẹla Kuti ti ṣalye faraye gbọ pe nipa wahala to ṣẹlẹ ni agbegbe rẹ lalẹ ọjọ Satide to fa yanpọnyanrin.
O ni lootọ lawọn yinbọn nibi yanpọnyanrin naa ṣugbọn awọn to ti ika bọ oun lẹnu lo mu ki oun faraya.
Ni owurọ ọjọ Aiku ni iroyin jade pe Seun da wahala silẹ nibi apejẹ kan lagbegbe Ikẹja to si tun fa ibọn yọ.
Seun kuti ni lootọ loun n gbe ni agbegbe kan ti wọn pe ni Akin Oshiyẹmi lagbegbe Ikẹja ti oun si ti wa nibẹ fun bi ọdun mọkanla bayii.
O ni awọn eeyan kan ti n dokoowo ile itura si adugbo wọn ni wọn n fa inira fun oun atawọn aladugbo oun.
Seun ni awọn eeyan kan lo bẹrẹ apejẹ alariwo nla kan ni adugbo oun lati owurọ bi agogo mẹsan abs owurọ, ti wọn ko si dawọ rẹ duro di aṣalẹ.
Ṣeun ni bakan naa ni awọn to wa nibi apejẹ naa wa ọkọ di gbogbo ile ti awọn to n gbe ladugbo naa ko si ri aye ati wọle tabi jade.
O ni nigba ti oun fẹ jade kuro nile loun rii pe wọn ti gbe ọkọ di oun ti oun si ti n wa awọn to wa ọkọ di oun mọle ti onitọun si yọju to n pe ki oun ṣimẹdọ loun ba fi igbaju daa lohun.
O ni awọn alamojuto abo nibi ayẹyẹ taraalu n pe ni bouncers ni wọn kọkọ wa ba oun to si n halẹ pe oun yoo da sẹria fun oun lo fa wahala.
Ọmọ agba olorin naa ṣalaye pe lootọ ni awọn ṣina ibọn bolẹ, oun o si sa fun ẹnikẹni o nitori pe adugbo oun loun wa, ẹnikẹni to ba si ṣe aṣemaṣe, awa maa da sẹria to tọ fun un ni.
Seun ni bo ba jẹ ijọba apapọ gan lo wa si ile oun lati wa da wahala silẹ, tabi mu oun lai gba iwe aṣẹ, ohun maa ṣina ibọn bolẹ funwọn ni.
Ọgbà ẹ̀wọ̀n ni wọ́n ti já àbálé Esra lábẹ́ àwáwí àyẹ̀wò wúndíá
2023 Presidency: Adelé alága APC l'Eko ní àdéhùn wà láàrín Buhari àti Tinubu lórí ìdíje ipò ààrẹ lọ́dún 2023
Oríṣun àwòrán, Facebook/Asiwaju Bola Tinubu
Adele alaga ẹgbẹ oṣelu APC nipinlẹ Eko, ọgbẹni Tunde Balogun ti ṣalaye pe aarẹ Muhammadu Buhari, Asiwaju Bola Tinubu atawọn eekan mii ninu ẹgbẹ jọ ṣe adehun lọdun 2014 pe apa iwọ oorun Gusu ni oludije fun ipo aarẹ lọdun 2023 yoo ti wa.
Ọgbẹni Balogun sọ pe ko ni boju mu ti ẹgbẹ APC ba kọ eti ikun si adehun yii.
Awọn kan ti n sọ pe awọn ogunna gbongbo ọmọ ẹgbẹ APC kan ti n gbimọ lati gba ipo adari ẹgbẹ naa ati lati bẹrẹ iṣẹ lori idibo gbogbogbo ọdun 2023.
Ẹwẹ, igbimọ alaṣẹ ẹgbẹ oṣelu APC, NEC labẹ adari aarẹ Buhari ṣe afiku akoko ti igbimọ amuṣẹya ti Mai Mala Buni ṣagbatẹru pẹlu oṣu mẹfa sii.
Bakan naa ni igbimọ NEC buwọlu agbekalẹ igbimọ alaṣẹ to ti di tutuka tẹlẹ.
Amọ, ohun ti alaga APC ipinlẹ Eko n sọ ni pe ki awọn agbaagba to da ẹgbẹ oṣelu APC silẹ ma gbagbe adehun ọdun 2014.
''Mo mọ pe eniyan iyi lawọn aṣiwaju ẹgbẹ oṣelu APC, adehun kan ti wọn ni lo mu ki Buhari ṣoju ẹgbẹ naa ninu ibo aarẹ ọdun 2015 ati ọdun 2019,'' Ọgbẹni Balogun lo sọ bẹẹ.
O ni ṣiṣe nkan mii yatọ si adehun ọdun 2014 ko ni ṣenu 're fun ẹgbẹ APC.
Oríṣun àwòrán, Facebook/Asiwaju Bola Tinubu
''Igbimọ fidihẹ to ajọ NEC ṣe agbekalẹ rẹ ko si ninu ofin ẹgbẹ oṣelu APC, ṣugbọn ọmọ ojulowo ọmọ ẹgbẹ ni mi, n ko ni fẹ tako ẹgbẹ,'' Balogun lo sọ bẹẹ.
O ni awọn kan n ja fita fita nitori ti ara wọn lati rii wi pe wọn ba ẹgbẹ oṣelu APC jẹ.
Balogun sọ pe ko si ohun to buru nibẹ ti ẹgbẹ ba gbaruku ti Tinubu nitori o jẹ ọkan lara agba oṣelu nilẹ Afirika.
Ẹwẹ, Gomina ipinlẹ Eko tẹlẹ to jẹ minisita akanṣe iṣẹ ati ilegbe bayii, Babatunde Fashola naa sọ laipẹ yii pe o ṣe pataki ki APC ranti adehun ọdun 2014.
Anthony Joshua vs Pulev highlights: Ẹ̀bùn ọdún Kérésìmesì ni àseyọrí Joshua lẹ́yìn tó na Pulev lálùbolẹ̀ - Dapo Abiodun
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Gomina ipinlẹ Ogun, Dapo Abiodun ti ki abẹṣẹkubiojo,Anthony Joshua ku oriire lẹyin to bori  ojugab rẹ lati orilẹ-ede Bulgaria, Kubrat Pulev ni gbagede SSE Arena ni ilu London lalẹ ọjọ Abamẹta.
Ninu atẹjade kan ti agbẹnusọ rẹ, Kunle Somorin fi lede, Abiodun ni Johsua gbe ogo ipinlẹ Ogun ga.
Gẹgẹ bi ohun ti gomina naa sọ, o ni ẹbun nla ni aṣeyọri naa jẹ, ati pe yoo tun jẹ ohun iwuri fun awọn elomiran lati tẹpa mọ ohunkohun ti wọn ba yan laayo.
"Atẹjade naa ni ""gbogbo wa ni ipinlẹ yii ni a gbadura fun aṣeyọri rẹ lai wo ti ẹsin."""
Mo le ka aṣeyọri nla to waye lalẹ ana ni London gẹgẹ bi ẹbun ọdun Keresimesi lati ọdọ Ọlọrun ati Anthony Joshua fun gbogbo wa ni ipinlẹ Ogun.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Abiodun ṣalaye pe Anthony Joshua, to tun jẹ ọmọ bibi ipinlẹ Ogun ti gbe ogo Naijiria ga, o si tun fi han awọn eeyan pe orilẹ-ede Naijiria ṣi maa bori gbogbo idojukjọ to n la kọja.
Gomina naa sọ pe adura awọn eeyan lo n gba lori abẹṣekubiojo naa ti ade IBF, WBA ati WBO ko tii fi bọ mọ lọwọ.
Nigba to n sọrọ loju opo Twitter rẹ, Abiodun fi kun pe aṣeyọri naa ti fi han pe gbogbo owo ti ijọba ipinlẹ Ogun ati akitiyan rẹ lori ere idaraya ko lọ lasan.
Ọgbà ẹ̀wọ̀n ni wọ́n ti já àbálé Esra lábẹ́ àwáwí àyẹ̀wò wúndíá
Alẹ ọjọ Satide, ọjọ kejila, oṣu kejila ọdun 2020, ni ija naa waye ni gbagede SSE Arena, ni ilu London, nibi ti Joshua ti fi ẹṣe ja Pulev bọ bi apo irẹsi.
Yatọ si Abidoun, Aarẹ Muhammadu Buhari naa ti ki Joshua ku orrire aṣeyọri ọhun.
Oyo Coronavirus: Makinde ní kò sí ọwọ́jà Coronavirus ẹlẹ́ẹ̀kejì ní ìpínlẹ̀ Oyo
Oríṣun àwòrán, Seyi Makinde/Facebook
Gomina ipinlẹ Oyo, Seyi Makinde ti sọ pe akọsilẹ fihan pe ọwọja keji arun covid-19 ko tii wọ ipinlẹ naa.
Makinde ni lootọọ ni akọsilẹ NCDC ṣe afihan pe ọwọja coronavirus ẹlẹẹkeji n peleke sii ni Naijiria lojojumọ.
Amọ, Makinde sọ pe iwadii ati ayẹwo ti ipinlẹ Oyo ṣe lori bi coronavirus ṣe n ran nipinlẹ naa fihan pe, ko buru ju ti at'ẹyin wa lọ.
Gomina makinde sisọ loju ọrọ yii lasiko to n se ipade akọroyin lori arun Coronavirus ati eto aabo ipinlẹ Oyo.
Atẹjade ajọ NCDC fihan pe eeyan to le ni irinwo lo ko coronavirus laarin ọsẹ meji nipinlẹ Oyo.
Makinde ṣalaye pe ipinlẹ Oyo ṣe ayẹwo Coronavirus fun ẹgbẹrun lọna ogun eeyan láàrin oṣu kẹta si oṣu kejila ọdun 2020.
Oríṣun àwòrán, Seyi Makinde/Facebook
Makinde ni ẹgbẹrun mẹta ninu awọn eeyan ọhun ni ayẹwo fihan pe wọn ni covid-19.
A tun ti ṣe ayẹwo fun ẹgbẹrun mẹrinla eeyan mii nipinlẹ Oyo lati oṣu kejila ọdun 2020 si akoko yii, eeyan mẹrindinlẹẹdẹgbẹrin(696) ni ayẹwo fihan pe wọn larun coronavirus, Makinde ṣalaye.
Gomina Makinde ni ijọba oun ko ni kaarẹ nipa eto ilanilọyẹ lori ati dena Coronavirus nipinlẹ Oyo.
"O ni ajakalẹ arun covid-19 si wa ni Naijiria, amọ ""sayẹnsi n sọ fun wa pe a le bori arun naa nipa ṣiṣọra."""
Makinde ni ohun to tọ ni pe ki onikaluku tẹle sayẹnsi.
Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó
Gomina ko ṣai rọ awọn eeyan ipinlẹ Oyo lati maa tẹle Ilana idaabo bo ara ẹni lọwọ covid-19 nípa wíwọ ibomu, fifọwọ deede ati itakete sí ara ẹni.
Gomina ipinlẹ Oyo ni ijọba n ṣiṣẹ lati rii pe ajọṣepọ to dan mọran wa si laarin ile iwosan UCH ati ile iwosan ajakalẹ arun to wa ni Olodo n'Ibadan.
Bakanna lo ṣọ pe ijọba n ṣe eto ilanilọyẹ fawọn ile iwosan aladani lori ati maa tẹle Ilana ati gbogun ti ajakalẹ arun covid-19.
"Gomina ni ijọba tun ti n ba ileeṣẹ aladani kan sọrọ lori ipsese afẹfẹ emi ""oxygen"" fawọn alarun Covid-19 to ba nilo rẹ."
Oríṣun àwòrán, Twitter/seyi makinde
Ijọba ipinlẹ Oyo ti bẹnu atẹ lu bawọn kan ti se n gbe irọ kiri nipa ikọ Amọtẹkun, lati le foju kere aseyọri wọn, ki wọn si fi da wahala silẹ nilu.
Agbẹnusọ Gomina Seyi Makinde lori ọrọ ẹrọ ayelujara Jide Ajani lo sọrọ yii, pẹlu bi awọn eeyan kan se n fi ẹsun kan Amotekun Oyo pe wọn n pa eeyan lainidi.
Lara ẹsun naa ni ọkan to ni se pẹlu iku awọn eeyan meje kan, to fi mọ arakunrin kan ati awọn ọmọ rẹ meji ti wọn pa lọjọ Abamẹta, lẹyin ikọlu to waye laarin ikọ Amọtẹkun pẹlu awọn agbebọn ni Aiyete Ibarapa.
Losu Kejila ọdun to lọ, ikọ Amọtẹkun tun ni wọn lo pa akẹkọọ kan ti wọn ni adigunjale ni.
Bẹẹ naa ni ẹnu ko sin lẹyin ikọ naa lori iku ọlọpaa kan to waye ni agbegbe Sango ni ilu Oyo lọjọ Kẹrin osu Kini.
Ohun ti Ajani sọ si gbogbo awọn ẹsun tawọn eeyan fi n kan Amọtẹkun ni pe, wọn n lo ẹsun ẹlẹyamẹya lati fi doju ija kọ Amọtẹkun lọna a ti bawọn jẹ.
O ni ahesọ tawọn eeyan n gbe ka paapa lori isẹlẹ to n waye ni Ibarapa jẹ ọna ati da omi tutu sookan aya Gomina Seyi Makinde.
LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé
Ninu atẹjade to fi sita, Ajani sọ pe''Ki lo de tawọn eeyan fi n ti irọ ẹlẹyamẹya mọ Amọtẹkun pẹlu bi wọn se koju awọn ọdaran? Se wọn fẹ pa ikọ naa rẹ ni? Wọn o ti se aseyọri.''
O tẹsiwaju pe, awọn to n gbe ahesọ ọrọ kiri fẹ si Gomina Makinde lọna ni. Wọn ti kuna wọn si ti mu ofo. Awọn to fẹ lo Amọtẹkun lati fi maa kọrin ẹlẹyamẹya yoo kan idin ninu iyọ. Ala ti ko ni le sẹ ni''
Gẹgẹ bo ti se sọ́, isẹ yi Amọtẹkunse lawọn ijọba ibilẹ mẹrin to ja si iku eeyan mẹjẹ wọn ko da nikan se.
O ni awọn ati ẹgbẹ Miyetti Allah awọn fijilante ati ọlọde ni wọn gbarijọpọ koju awọn ọdaran nibẹ.
Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó
O fi kun pe ko si ootọ ninu ọrọ pe awọn n doju ija kọ awọn eeyan ẹya kan ni.
O salaye pe o yẹ ki wọn gbosuba kaare fun ikọ Amọtẹkun ni pẹlu bi wọn ti se doju ija kọ awọn ọdaran ni lawọn ijọba ibilẹ mẹrin.
''Ohun to tun yẹ ki a gboriyin fun ni ajọsepọ laarin Amọtẹkun ati awọn fijilante ọlọdẹ ati Miyetti Allah. Koda kii se Miyetti Allah lasan, awọn Fulani bawọn lọwọ ninu ibasepọ yii, ti wọn si fi ọrọ to Seriki awọn Fulani leti''
Oríṣun àwòrán, Twitter/seyi makinde
Alaga ajọ alaabo nipinlẹ Ọyọ, Oyo State Security Network ti ọpọ mọ si Amọtẹkun, Ọgagunfẹyinti, Ajibọla Toogun ti alaye awọn ohun ti awọn oṣiṣẹ amọtẹkun ko ni ṣe .
Oniruuru ahesọ ọrọ lo ti n waye nipa ipa ti awọn oṣiṣẹ Amọtẹkun yoo maa ko gan ti ẹru si n ba ọpọ pe ṣe wọn ko ni tọ ipasẹ aṣiṣe ọlọpaa pẹlu.
Ọgagunfẹyinti Toogun ni amọtẹkun ko si fun ṣiṣọ awọn dukia tabi ileeṣẹ aladani.
Bakan naa lo ni wọn ko lee di ohun elo fun sinsin tabi gba gbese pada fun awsn ileeṣẹ.
O ni laipẹ igbimọ agbohungbaroye kan yoo di gbigbekalẹ fun araalu lati maa fi ariwisi wọn nipa iṣẹ ati iṣe Amọtẹkun ṣọwọ si.
O ni idi niyi ti wọn fi rii pe wọn lẹ orukọ ati nọmba idanimọ ọkọọkan wọn mọ aya aṣọ ti wọn ba wọ.
Ojú mi ti rí lọ́pọ̀ lọpọ̀, àmọ́ mo dúpẹ́ pé mo ti pé ọdún márùn ún lórí oyé- Ooni
Ondo politics: Ilé ẹjọ́ da ìpèjọ́ pé Akeredolu kọ ló wọlé ìdìbò ìpińlẹ̀ Ondo nù
Oríṣun àwòrán, Akeredolu
Ilé ẹjọ́ gíga kan ní ìlú Abuja ti da ẹjọ́ to ní Gómìnà Oluwarotimi Akeredolu kọ́ ló wọlé gẹ́gẹ́ bii gomina lábẹ́ àsíá ẹgbẹ́ òṣèlú All Progressive Congress (APC) nínú ìdìbò gómìnà tó wáyé nípìnlẹ̀ Ondo.
Adajọ́ Okon Abang nínú ìdájọ rẹ̀ lọ́jọ́rú ni ó ti kọ́ja ọjọ́ mẹ́rìnlá kí olùpẹ̀jọ́ to mu ẹjọ́ wá silé ẹjọ́ gẹ́gẹ́ bi abala iwé òfin 285(9) ṣe làá silẹ̀ lórí ẹjọ to bá níṣe pẹ̀lú ìdìbò.
Olùpẹjọ́ ni olùdíje dùpò gómìnà míràn lábẹ̀ ẹgbẹ́ òṣèlú APC Nathaniel Adijutelegan tó díje pẹ̀lu Akeredolu lásìkò ìdìbò abẹ́lé láti yan ẹni ti yóò dupò gómìnà nínú ẹgbẹ́ náà.
Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsèjẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọ
Ó pe ẹgbẹ́ lẹ́jọ́ fún irú ìlànà ti ó tẹ̀lé láti dìbò yan olùdíje dupò gómìnà lábẹ́ àsíà ẹgbẹ́ òṣèlú APC nípìnlẹ̀ Ondo.
Abang ni, ìṣẹ̀lẹ̀ náà ti wáye láti ọjọ kẹtàdínlógún, oṣu kèje ọdún 2020 lásìkò tí wọ́n yan gómìnà ìpinlẹ̀ Kogi Yahaya Bello gẹ́gẹ́ bii alága ètò ìdìbò abẹ́lé náà, tí wọ́n sì gbà láti dìbò ní ọ̀nà tí kìí ṣe ìdìbò olójúkorojú, ọjọ́ kéta, oṣù kéjó, ọdún 2020 ni Adojutelegan ṣẹ̀ṣẹ̀ pe ẹjọ́.
Bákan náà ni ilé ẹjọ tún fi kún-un pé àwọn ẹsùn míràn tó wà nibẹ̀ kìí ṣe ǹkan ti ó kan ilé ẹjọ́ bíkòṣe ǹkan ti wọ́n yóò lọ yanju láàrin ara wọn ninu ẹgbẹ́, nítori náà ó da ẹjọ́ ọhun sígbó.
Ohun to kọkọ ṣẹlẹ ti iléẹjọ́ fi fk dájọ́ bóyá Gómìnà Akeredolu yẹ láti du ipò gómìnà ní ìpínlẹ̀ Ondo
Oríṣun àwòrán, Twitter/akeredolu
Nigba ti wọn kọkọ pe ẹjọ naa, o dabii pe ọrọ ko tii tan fun Akeredolu, gomina ipinlẹ Ondo lẹyin ọpọlọpọ ọsẹ ti eto idibo gomina ipinlẹ Ondo ti gbee wọle fun saa keji.
Yatọ si pe alatako rẹ lẹgbẹ oṣelu PDP, Eyitayọ Jẹgẹdẹ n pe ẹjọ kotẹmilọrun ta ko o nile ẹjọ bayii lori esi idibo naa, ogun abẹle naa n ba Akeredolu finra pẹlu bii ọkan lara awsn ti wọn jijọ dije fun aṣia ẹgbẹ oṣelu APC fun idibo gomina naa,
Ọmọwe Nathaniel Adojutẹlẹgan ti pe e lẹjọ nile ẹjọ giga apapọ kan nilu Abuja pe ọna ti wọn fi yan an lati di aṣia ẹgbẹ naa ko ba ofin mu ati pe o tako ilakalẹ ofin idibo apapọ ilẹẹwa, Electoral Acts tọdun 2010.
Ọmọwe Adojutẹlẹgan n fapajanu pe iwe oruks awọn aṣojudibo ti wọn lo lasiko idibo abẹlẹ ẹgbẹ oṣelu naa ti wọn ti yan Akeredolu lati dije lorukọ ẹgbẹ oṣelu naa tako abala ikẹtadinlaadọrun iwe ofin idibo orilẹede Naijiria naa ati iwe ofin ẹgbẹ oṣelu APC.
Loni ọjọ kẹrinla oṣu kejila ọdun 2020 ni onidajọ Okon Abang to n gbọ ẹjọ naa ya sọtọ fun idajọ rẹ.
Ni ọjọ kẹta oṣu kẹjọ ọdun 2020 ni idibo abẹnu ẹgbẹ oṣelu APC fun awọn oludije ipo gomina nipinlẹ Ondo waye ti Akeredolu si bori.
Africa Eye: Wo ìtàn ìyá kan ìyá kan àtàwọn olè ajọ́mọgbé tó n ta ọmọ ní Kenya
US election 2020: Àlàyé rèé lórí bí èèyàn 538 ṣe ń yan ààrẹ lé èèyàn mílíọ̀nù 331 ní Amẹ́ríkà
Awọn igbimọ agbaọjẹ oludibo alaṣẹ ni ilu Amẹrika, Electoral College ti buwọlu ibo to gbe Joe Biden ti ẹgbẹ oṣelu Democratic wọle gẹgẹ bi aarẹ.
Ibuwọlu naa waye lọjọ Aje lẹyin ti idibo aarẹ lorilẹ-ede naa ti waye ni ọjọ kẹta, oṣu kọkanla, ọdun 2020.
Ninu idibo naa ni ti Biden gbegba oroke pẹlu ibo awọn igbimọ agbaọjẹ oludibo alaṣẹ ni ilu Amẹrika, Electoral college nibi to ti ni ibo 306 ti Trump si ni 232.
O ti tun bori ninu ididbo apapọ araalu to ti ni ibo to le ni ọgọrin miliọnu si ibo adọrin miliọnu o le diẹ ti Trump ni.
Ki lo ṣẹlẹ lọjọ Aje, ọjọ kẹrinla, oṣu kejila, ọdun 2020?
Ni ọjọ Aje, ọjọ kẹrinla, oṣu kejila, ọdun 2020 lawọn ọmọ igbimọ oludibo alaṣẹ, Electoral College parapọ lati fi ontẹ lu ibo to gbe Joe Biden gẹgẹ bi aarẹ tuntun fun orilẹ-ede Amẹrika.
Igbesẹ yii, bi o tilẹ jẹ wi pe amọ ni, ṣugbọn fifi aake kọri ti aarẹ Donald Trump faake kọri lori gbigbe ijọba silẹ ṣe pataki.
Trump ni pe oun ko lee gba pe Joe Biden lo bori idibo aarẹ orilẹ-ede Amẹrika to waye lọjọ kẹta, oṣu kọkanla, ọdun 2020.
Gbogbo aadọta ipinlẹ to wa lorilẹ-ede Amẹrika lo ti buwọlu abajade ibo naa.
Wọn gba pe ẹgbẹ oṣelu Democrats to ni ibo miliọnu mọkanlelọgọrin o le ẹgbẹrun lọna ọọdunrun, (81.3m) to duro fun ida mọkanlalaadọta o le diẹ (51.3%) lo wọle.
Ẹgbẹ oṣelu Republican si ni ibo miliọnu mẹrinlelaadọrin ati ẹgbẹrun lọna igba, (74.2m) to din diẹ ni ida mẹtadinlaadọta (46.8%)
Amọṣa lorilẹede Amẹrika, ilana ti wọn fi n yan aarẹ wọn yatọ si bi wọn ṣe n ṣe lọpọ orilẹede jakejado agbaye.
Lẹyin ibo naa lọjọ Aje aarẹ ti wọn ṣẹṣẹ dibo yan, Joe Biden abajade ibo awọn igbimọ agbaọjẹ oludibo alaṣẹ ni ilu Amẹrika, Electoral college fihan pe ifẹ araalu lo papa ṣẹ.
O ni eto iṣejọba awarawa lorilẹede Amẹrika la ipenija nla kọja, sibẹ o duro ṣinṣin.
Bakan naa lo bu ẹnu atẹ lu aarẹ Trump pe asiko to ko gba fun Ọlọrun, bi o tilẹ jẹ wi pe Trump ko tii sọ ohunkohun lori rẹ.
Awọn wo ni  igbimọ agba ọjẹ oludibo alaṣẹ ti wọn n pe ni Electoral College?
Awọn igbimọ agba ọjẹ oludibo alaṣẹ ti wọn n pe ni Electoral College gan an lo lagbara ati yan aarẹ o.
Koda bi oludije kan ba ni ibo to pọ julọ nipasẹ araalu, bi awọn igbimọ agba ọjẹ oludibo alaṣẹ yii ba dibo fun alatako rẹ, alatako yẹn ni yoo di aarẹ
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ẹ maa jẹ ko ru u yin loju, alaye re e.
Kí làwọn nǹkan tó lè rán ọkùnrin sí ọ̀run alákeji lásìkò ìbálòpọ̀ pẹ̀lú obìnrin?
Coronavirus: ''Ìjọba kò tíì pàṣẹ ìlànà ìtakété-síra-ẹni padà nínú BRT la ò ṣe máa tẹ̀le''
Ìjọba gbé ilé ijó oníhòhò tì pa lórí ẹ̀sùn títàpá sí ìlànà àti dẹ́kun coronavirus
Wo àwọn oúnjẹ márùn ún tó ń mú kí àtọ̀ ọkùnrin dára síi
Akomolede ati Asa lori BBC: Olùkọ́ Kikelomo  Ogunboye tan ìmalẹ̀ sí ìwà olè ọ̀gá ọlọ́pàá
Ọgbà ẹ̀wọ̀n ni wọ́n ti já àbálé Esra lábẹ́ àwáwí àyẹ̀wò wúndíá
Africa Eye: Wo ìtàn ìyá kan ìyá kan àtàwọn olè ajọ́mọgbé tó n ta ọmọ ní Kenya
Wo àwọn Adelé-Ọba aládé méje tó jẹ́ obìnrin nílẹ̀ Yorùbá
Mi ò le tòṣì láéláé! Ẹni tó bá ń bínú kàn ń bínú lásán ni- Oyedepo
Lóòtọ́ ni mo yìnbọn níbi yánpọnyánrin tó wáyé ládúgbò mi-Seun Kuti
Wo àwọn ohun tí Amotekun kò ní le è ṣe mọ́ ní ìpínlẹ̀ Oyo...
Covid-19 second wave: ''Ìjọba kò tíì pàṣẹ ìlànà ìtakété-síra-ẹni padà nínú BRT la ò ṣe tíì ma tẹ̀le''
Oríṣun àwòrán, Facebook/LBLS
Kaka ki ewe agbọn dẹ, niṣe lo n le koko sii. Bẹẹ lọrọ ṣe ri pẹlu ajakalẹ coronavirus ẹlẹẹkeji to n kan ilẹkun bayii lorilẹede Naijiria papaa julọ nipinlẹ Eko.
Gẹgẹ bi akọsilẹ ajọ to n gbogun ti ajakalẹ arun ni Naijiria, NCDC, eeyan to din ọgọrin ni ẹgbẹrun mẹrun(3,820) lo ko arun coronavirus lapapọ ni Naijiria lọsẹ to kọja.
Koda Gomina Babajide Sanwo-Olu ipinlẹ Eko naa wa lara awọn eeyan ọhun.
Ajọ NCDC sọ pe igba akọkọ ree tawọn to larun naa yoo pọ to bayii ni nkan bi oṣu mẹrin sẹyin.
Awọn oṣiṣẹ eleto ilera si ti sọ pe ami leyi jẹ pe ajakalẹ arun covid-19 ẹlẹẹkeji n kan ilẹkun gbọngbọn papaa nipinlẹ Eko.
Ṣugbọn akiyesi wa ni pe awọn ọkọ akero to fi mọ ọkọ akero ijọba BRT ko tẹle ilana itakete sira ẹni ti ajọ NCDC la kalẹ mọ.
Niṣe ni gbogbo ọkọ naa n kun fọfọ lai si aga ijoko kan to ṣofo.
Oríṣun àwòrán, Facebook/LBSL
BBC Yoruba kan si ọga agba ileeṣẹ ọkọ akero BRT ipinlẹ Eko, Ọgbẹni Idowu Oguntona lori ọrọ yii.
Ọgbẹni Oguntona gba pe lootọọ ni awọn ko tẹle ilana itakete sira ẹni mọ ninu awọn ọkọ ero BRT nitori ijọba ipinlẹ Eko ko tii paṣẹ pe ki awọn maa ṣe bẹẹ ni.
Ọga ọkọ BRT ni awọn si n ri wi pe awọn ero wọ ibomu wọn, lo sanitisa sọwọ, bakan naa lawọn n yẹ ara wọn wo bo ya o gbona tabi ko gbona lati le mọ bo ya wọn ni covid-19.
Akomolede ati Asa lori BBC: Olùkọ́ Kikelomo  Ogunboye tan ìmalẹ̀ sí ìwà olè ọ̀gá ọlọ́pàá
O fikun ọrọ rẹ pe awọn ko gba kawọn ero maa duro ninu awọn ọkọ naa mọ, wọn kan n joko lasan an ni.
Ọgbẹni ṣalaye pe ijọba Eko naa ti n wo ṣaakun ọwọja covid-19 lẹẹkeji lati mọ iru ilana ti wọn tun fẹ gbe kalẹ.
Amọ, ọga agba ọkọ ero BRT ipinlẹ Eko ko ṣai ṣalaye pe ijọba ni lati roo daadaa ki wọn to gbe ilana mii kalẹ nitori akoba ti coronavirus ti ṣe fun ọrọ aje tẹlẹ.
Ọgbà ẹ̀wọ̀n ni wọ́n ti já àbálé Esra lábẹ́ àwáwí àyẹ̀wò wúndíá
Sex party: Ìjọba gbé ilé ijó oníhòhò tì pa lórí ẹ̀sùn títàpá sí ìlànà àti dẹ́kun coronavirus
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ileeṣẹ ọlọpaa gbe ile ijo ibalopọ ti pa lori ẹsun pe wọn kuna lati tẹle ilana ati gbogun ti ajakalẹ arun coronavirus fun igba keji laarin ọsẹ kan.
Ile ijo naa to wa niluu Paal lorilẹede Belgium di titi pa lọjọ Ẹti to lọ ni deedee ago mẹsan an aabọ.
Gbogbo awọn mẹwaa to wa nibẹ ni wọn ni ki wọn sanwo itanran to din diẹ ẹgbẹrun lọna ọgọfa.
Ọpọ awọn ọkunrin ati obinrin to wa nihoho lawọn ọlọpaa ri lati oju ferese, bakan naa ni wọn paaki ọkọ sita rẹgẹdẹ.
Awọn ọlọpaa ko kọkọ raye wọle lẹyin ti wọn ti ilẹkun ile ijo onihoho naa.
Amọ awọn oṣiṣẹ panapana lo fi ipa ṣi ilẹkun naa ki awọn ọlọpaa to raye wọle.
Akomolede ati Asa lori BBC: Olùkọ́ Kikelomo  Ogunboye tan ìmalẹ̀ sí ìwà olè ọ̀gá ọlọ́pàá
Eeyan mẹfa lọwọ ọlọpaa kọkọ tẹ ki wọn to mawọn mẹrin mii ninu eyi ti ọkan lara wọn ti lọ sa pamọ.
Igba keji ree tawọn ọlọpaa yon fi ipa ṣi ilẹkun ile ijo laarin ọsẹ kan lorilẹede Belgium.
Ọgbà ẹ̀wọ̀n ni wọ́n ti já àbálé Esra lábẹ́ àwáwí àyẹ̀wò wúndíá
Lọjọ kinni ,oṣu kejila, ọdun 2020 yii lawọn ọlọpaa mu ọkunrin mẹẹdọgbọn ni ihoho niluu Brussels nibi ti oloṣelu aṣofin ilẹ Hungary ti n saa lọ.
Awọn agbofinro mawọn ọkunrin naa lẹyin tawọn ara adugbo lọ fẹjọ sun ileeṣẹ ọlọpaa pe ariwo awọn ọkunrin pọ lati ile ijo ti wọn wa lẹkun tawọn ololufẹ akọ sakọ pọ si ni rue des Pierres.
Africa Eye: Wo ìtàn ìyá kan ìyá kan àtàwọn olè ajọ́mọgbé tó n ta ọmọ ní Kenya
Africa Eye: Wo ìtàn ìyá kan ìyá kan àtàwọn olè ajọ́mọgbé tó n ta ọmọ ní Kenya
Opọ lo ro pe ko si ọna abayọ kuro ninu iya ju tita ọmọ wọn lọ
Orilẹ-ede Kenya ni BBC ti lọ ṣe iwadii àwọn tó ń jí ọmọ gbé ta fawọn to n woju Oluwa ninu iwadii BBC Africa Eye ti ọtẹ yii.
Wo itan iya kan ati awọn ole ti wọn n ji ọmọ gbe ta.
Wọn n ṣafihan awọn ikọ naa ati ọna ti wọn n gba ṣe iṣẹ ibi ọwọ wọn.
Simon Chelugui to jẹ akọwe igbimọ iṣẹ ati idaabobo awujọ ṣeleri pe ọwọ ofin yoo kọ gbogbo wọn
Sarah sọ idi to fi gbiyanju lati ta ọmọ rẹ.
Sarah jẹ ọmọ orukan to jẹ ẹni ọdun mẹtadinlogun nigba to gboyun.
Kankara Abduction: Àwọn ológun ṣàlàyé ìdí tí wọ́n fi yọ̀nda àwọn tó jí àwọn akẹ́kọ̀ọ́ gbé.
Ile iṣẹ ologun Naijiria ti ṣipaya awọn nkan kọọkan lorii bi wọn ṣe ri awọn akẹkọọ to le ni ojilelọọdunrun ti awọn ajinigbe ji gbe ni ileewe Kankara, ipinlẹ Katsina doola pada.
Awọn ologun ṣipaya pe ati agbara ohun ija oloro ati eyi tii kii ṣe ti ohun ija lawọn papọ fi ri i pe wọn doola gbogbo awọn ọmọ ọkunrin naa lai farapa.
Alakoso eto irorin fun ileeṣẹ ologun, Ọgagun John Enenche ati oludari ẹka ọgbọ tẹlẹ nileeṣẹ ologun, Ọgagunfẹyinti Ahmed Jibrin lo ṣe ẹkunrẹrẹ alaye bi wọn ṣe ṣe e lọjọ Abamẹta lori eto oroorọ ileeṣẹ amohunmaworan Nigerian Television Authority, NTA.
Jibrin ni lẹyin ti wọn ji awọn ọmọ naa gbe, minisita  dari ikọ awọn olori awọn ologun ati olugbaninimọran nipa abo lọ si Katsina ati Kankara.
Risikat Moromoke Azeez: Inú èmí àti Òbí mi dùn nígbà ti Risi bí ọmọ olójú búlù- Wasiu
O ni minisita paṣẹ pe ki ikọ awọn ọmọ ogun ri i pe wọn doola awọn ọmọkunrin naa lai farapa ati ni kiakia.
Kete lẹyin aṣẹ naa ni awọn ọmọ ogun gba ọna mẹrin ọtọọtọ lati doju kọ awọn ajinigbe ọhun pẹlu iranlọwọ kaakiri lati ri i pe wọn di gbogbo agbegbe ti wọn wa gbagba.
O ni awọn ajinigbe ọhun mọ pe awọn ti wa ni ahamọ awọn ologun tori wọn ni imọlara pe wọn ti wa lagbegbe lati inu afẹfẹ ati loriilẹ.
Nigba ti wọn sunmọ ibi ti awọn ọmọ naa wa, ikọ ọmọ ogun doju kọ atako loriṣiriṣi eyi ti wn mu kuro ti wọn si tẹra mọ wiwọ inu aginju lọ.
"Jibirin ṣalaye pe bo tilẹ jẹ ko si ikankan ninu awọn ọmọ wọn ba agbara ọpọlọpọ awọn ọdaran naa jẹ. ""Wọn di awọn ologun lọwọ irina fun ọpọlọpọ wakati ki wọn to ri wọn bori""."
O  ni nigba ti awọn ọmọ ogun n ṣe tiwọn, bẹẹ naa ni idunadura ọrọ n lọ lẹgbẹ mii fun idoola wọn.
O jẹ ko di mimọ pe wọn ko lee sọ awọn ajinigbe naa di alailagbara patpapata toripe ṣe ni wọn n fi awọn akẹkọọ daabo bo ara wọn awọn ko si fẹ pa awọn ọmọ na lara.
Lorii bi Boko Haram ṣe n pariwo pe awọn lawọn ji wọn gbe, Jibrin ni irọ ni, wọn kan n wa ọna ati gbajumọ sii ni.
(Abubakar) Shekau ko ni ọna kankan lati ji wọn gbe toripe ọpọ igbesẹ ti jade lati bẹgi dina wọn lkun Ila Oorun-Ariwa torinaa o han daju pe awọn ajinigbe lo ji awọn ọmọ naa.
Ni tirẹ, Enenche ni nkan to lewu gidi ni igbesẹ ti wọn gbe lati doola awọn akẹkọọ ọhun tori bi wọn ko ba fi ikọṣẹmọṣẹ ṣe iru iṣẹ yii, o lee yiwọ.
Ogun ti oo le gboju le agbara rẹ ati ohun ija ni eyi bikoṣe ipa too ni lati ṣe e yanju.
Eyi tumọ si pe o ni lati pa awọn ọta rẹ lẹnu mọ koo si gba ohun too fẹ gba lai yin ọta ibọn kan ṣoṣo.
O ni bi nkankan ba ṣe awọn akẹkọọ ọhun ni, awọn ologun naa lawọn ọmọ Naijria yoo da ẹbi rẹ le lori.
Agbẹnusọ gomina Aminu Masari fi aridaju han pe lootọ ni awọn ọmọ naa ti darapọ mọ ẹbi wọn pada lalafia lẹyin ayẹwo ilera fihan pe ara wọn pe.
Zlatan: Ọ̀rẹ́ ni mo sìn lọ ‘studio’ tí mo fi bẹ̀rẹ̀ orin lẹ́yìn tí mo kùnà ìdánwò WAEC
Bi afẹfẹ alafiaa ti ṣe n fẹ lu ijọba ati awọn obi tọmọ wọn jajabọ lọwọ ajinigbe ni Katsina, ijọba Amẹrika ti n kesi awọn tọrọ kan pe, ki wọn maa gbagbe lati tọ pinpin awọn to wa nidi iṣẹlẹ yi.
Ninu atẹjade kan ti ileeṣẹ asoju orileede Amẹrika to wa ni Naijiria fisita, ni ọrọ yi wa.
Ileesẹ Amẹrika wa bu ẹnu atẹ lu iṣẹlẹ ifipajinigbe awọn akẹkọọ to le ni ọọdunrun naa.
Bakan naa ni wọn ba awọn mọlẹbi tọmọ wọn sọnu kẹdun ati awọn ẹsọ alaabo to padanu ẹmi wọn ninu iṣẹlẹ yii.
Amrika wa tẹpẹlẹ mọ bo ti ṣe pataki to ki ile ẹkọ jẹ aaye ifọkanbalẹ tawọn ọmọ ti le kẹkọ, ti wọn yoo si ti gbooro si.
Lakotan, Amẹrika ni o ṣe dandan ki ijọba ri wipe awọn to lọwọ ninu iṣẹlẹ ijinigbe naa foju wina ofin debi to lapẹrẹ.
Titi di igba ti awọn ọmọ yi fi pada de, ko si ihalẹ to milẹ lati ọdọ ijọba Katsina tabi ijọba apapọ lori pe awọn yoo fiya jẹ ẹnikẹni to ba mọ si ijingbe awọn akẹkọọ yii.
Eyi to pọ ninu ọrọ wọn ni ki wọn kọkọ ri awọn ọmọ yi lalaafia.
Ko ti si aridaju boya wọn sanwo idoola lati fi gba awọn ọmọ yi pada.
Amọ Gomina ipinlẹ Katsina sọ pe ẹgbẹ Miyetti Allah ko ipa ribiribi ninu idunadura ti wọn fi doola ẹmi awọn akẹkọọ naa.
Orin lọfẹ-lọfẹ ni baba fun wa lo gba ẹnu ijọba apapọ Naijiria kan lori itusilẹ awọn akẹkọ-kunrin ni Katsina, ti Boko Haram mu sigbekun.
Nigba to n fidi itusilẹ awọn akẹkọọ naa mulẹ, gomina ipinlẹ Katsina, Aminu Bello Masari ni koko lara awọn akẹkọ naa le, ti wọn si wa nilu Tsafe nipinlẹ Zamfara, nibi ti wọn yoo ti gbe wọn wa silu wọn Kankara loni ọjọ Ẹti.
Masari ni ikọ darandarn labẹ ẹgbẹ Miyetti Allah ati Macaban lo seranwọ lati gba idande awọn akẹkọọ naa.
Bakan naa lo fikun pe ijọba apapọ ko san eepinni fawọn ajọmọgbe naa, idunadura lasan ni awọn se.
"Lara awọn to kopa ninu eto idunadura naa ni olugbaninimọran mi, awọn lọga-lọga lẹnu isẹ ologun, ọlọpaa ati ikọ Miyetti Allah.
Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsèjẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọ
Masari tun fikun pe awọn janduku agbesunmọmi lasan lo ko awọn akẹkọọ naa, wọn kii se Boko Haram.
Ijọba wa fidi rẹ mulẹ pe awọn akẹkọọ naa yoo de ọdọ awọn obi wọn ki ilẹ ọjọ Ẹti oni to su.
Oríṣun àwòrán, Boko Haram
Ìròyìn tó tẹ ilé iṣẹ́ BBC lọ́wọ́ sọ pé, àwọn ọmọ tó lé ni ọ̀ọ́dúnrún ni ilé ìwé GSSS Kankara ti wọ́n jí gbé tí gba òmìnir báyìí.
Gẹ́gẹ́ bi àkọwé àgbà fún ìpínlẹ̀ Katsina  Alhaji Mustapha Inuwa ṣe sọ, àwọn ọmọ náà ti wà ni Tsafe, ní ìpínlẹ̀ Zamfara to pa ààlà pẹ̀lú Katsina.
Ó fi kun pé, àwọn ọmọ náà yóò de ìpínlẹ̀ Katsina ni alẹ́ òní pẹ̀lú ìrànlọ́wọ́ àwọn ẹlétò ààbò tí wọ́n yóò wọ́n yóò sì fójú kan ààrẹ.
Ìrìnàjò Tsafe sí Zamfara tí kílomita ìgba àti díẹ̀, èyí yóò gbà wọ́n ni wákàtí mẹ́tà kí wọ́n tó débẹ̀ nítóri ipò tí ọ̀nà náà wà nígbà ti Tsafe sí kankara jẹ́ kílòmítà mẹ́tàlélọ́gọ́rín
Lẹ́yìn ọjọ́ mẹ́fà ti àwọn ọmọ náà ti wà ni ọwa àwọn ajínigbe.
Abike Dabiri ní akẹ́kọ̀ọ́ 333 tí gba ìtúsílẹ, àmọ́ kò pẹ́ ló tún pahùndà
Oríṣun àwòrán, Katsina govt
Àwọn aláṣẹ ìjọba ni Nàìjíríà ti kéde pé àwọn ọmọ tó lé ní ọ̀ọ̀dúrún tí àwọn ajínígbé kó nílé ìwé ìjọba ni ìlú Kankara nípìnlẹ̀ Katsina, ti gba ìtússílẹ̀
Lórí àtẹ̀jíṣẹ́ twitter lọ́sàn òní ni, alága àjọ tó n ri sí ọ̀rọ̀ ilẹ̀ okere Abike Dabiri Erewa sàlàye pé, àwọn ti rí àwọn ọmọ náà gbà.
Oríṣun àwòrán, Dabiri
Sáájú àsìkò yìí, ní fọ́nran kan jẹyọ níbi ti àwọn àkẹ́kọ̀ọ́ ti wọ́n jí gbé náà ti n bẹ ìjọba pé, ko dá isẹ idoola ẹmi to n se duro, ko si ko gbogbo àwọn sójà pàda si bareke.
Bakan naa ni ọmọ to sọrọ ninu fidio naa ni ki ijọba mase gbiyanju lati wá tu àwọn sílẹ̀ ni ahamọ Boko Haram.
Oríṣun àwòrán, Boko Haram
Ọmọkunrin náà wa bẹ́ ìjọba pé ko bá àwọn ajínígbé sọ̀rọ̀ lórí ǹkan tí wọ́n ba fẹ́ gbà kí àwọn le lọ ilé àwọn ni àlááfíà.
Ẹ̀wẹ́, Abike Dabiri ti tún kọ sórí àtẹjíṣẹ́ twitter rẹ̀ pé, kìí ṣe òun ni òun kọ àkọlé pé àwọn ọmọ náà ti gba ìtúsílẹ̀ àti pé, ó ṣeeṣe kó jẹ́ àwọn ènìyàn tó ló àtẹ̀jísẹ́ òfégè ni orúkọ òun ló kọ̀ọ́.
Oríṣun àwòrán, Abike/ Dabiri
Èyí ti mú kí ọ̀pọ ọmọ Nàìjíríà máá pé alága NICOM síta pe opurọ ni.
Koda, awọn kan ni ipilẹ orilẹede naijiria ni wọn fi irọ mọ, tawọn kan si ni igbe aye ayederu gan ni Abike Dabiri n gbe funrarẹ.
Oríṣun àwòrán, Abike dabiri
Wayi o, ko sẹni to ti le fi okodoro ọrọ mulẹ boya lootọ ni awọn akẹkọkunrin to le ni ọọdunrun naa ti ri idande gba abi bẹẹ kọ.
Sugbọn bo ba se jẹ, a ko ni jẹ ki eti yin di nipa isẹlẹ naa.
Ìjọba ìpínlẹ̀ Zamfara ti pàṣẹ kí wọ́n gbé iléèwé mẹ́wàá tìpa lẹ́yìn ìkọlù Katsina
Oríṣun àwòrán, TWITTER/@BELLOMATAWALLE1
Ijọba ipinlẹ Zamfara ti fofin sita ni kiakia pe ki wọn gbe awọn ileewe ti awọn akẹkọọ ti n gbe ninu ọgba ileewe atawọn ileewe alalọde kan tipa ni ipinlẹ naa.
Agbẹnusọ fun gomina Zailani Bappah lo fidi ọrọ̀ yii mulẹ fun BBC.
Iroyin taa gbọ ni Ọgbẹni Ibrahim Abdullahi to jẹ Kọmisọna eto ẹkọ ṣe ikede yii nigba to n ba awọn oniroyin sọrọ nilu Gusau, olu ilu ipinlẹ naa.
O ṣalaye pe awọn ileewe to fara gba aṣẹ yii pa aala pọ pẹlu ipinlẹ Katsina ti wọn ti ṣẹṣẹ ji awọn akẹkọọto le lọọdunrun gbe, ipinlẹ Kaduna ati Sokoto.
Kọmisọna ọhun jẹ ko di mimọ pe awọn ipinlẹ mẹtẹta yii sun mọ bebe idigunjale to si ni ipinu yii ṣe pataki lati dena ikọlu mii si awọn ileewe ọhun.
Kollington ṣàlàyé bí orin Fuji ṣe bẹ̀rẹ̀ gan an ní Nàiìjíríà
O fi kun un wipe igbesẹ ọhun gan ṣe pataki nitori iṣoro aabo to wa lorilẹede yii ati lati dena iru nkan to ṣẹlẹ nileewe Girama Government Science Secondary School ni ilu Kankara, ipinlẹ Katsina.
Abdullahi fi da awọn obi ati alagbatọ loju pe aabo awọn akẹkọọ lo ṣe koko si ijọba ipinlẹ to fi mu wọn gbe igbesẹ naa.
O fi lede pe ijọba ti pari gbogo eto bi wọn yoo ṣe ko awọn oṣiṣẹ alaabo lọ maa ṣọ awọn ileewe to ku ti wọn ko tipa.
Lara awọn ileewe to fara gba aṣẹ tuntun yii ni ileewe meje tawọn akẹkọọ n gbe ninu ọgba rẹ atawọn ileewe alalọde mii.
Awọn ileewe ti akẹkọọ n gbe nibẹ ni G.S.S. Tsafe, G.S.S. Magaji, G.A.S.S. Zurmi, G.G.S.S. Moriki, Science Secondary School Shinkafi, Science Secondary School Dansadau, ati Science Secondary School ni Bukkuyum.
Bakan naa, awọn ileewe alalọde to wa lara wọn ni G.D.S.S. ni Nasarawa Mailayi, G.D.S.S Gusami, ati G.D.S.S. Gurbin Bore.
Oríṣun àwòrán, @Aminu Bello Masari
Awọn ọmọ ikọ agbesunmọmi Boko Haram ti fi ohun sita pe awọn lawọn ji awọn akẹkọọ ni girama Kankara ni ipinlẹ Katsina.
Ninu fọnran agbohunsilẹ kan ti olori ẹgbẹ naa, Abubakar Shekau fi sita, lẹyin ọjọ mẹta ti wọn ji awọn ọmọ naa gbe.
Eyi waye lasiko ti ijọba ipinlẹ Katsina n sọ pe awọn janduku lo ji awọn akẹkọọ ileewe girama Dankara Science Secondary School naa gbe ati pe ijiroro ti n lọ laarin ijọba atawọn janduku naa lori ohun ti wọn fẹ fun itusilẹ awọn ọmọ naa.
Eyi ti fa ọpọlọpọ ariyanjiyan ati ibeere pe ta gan an lo ji awọn ọmọ yii gbe?
Ijọba ni awọn janduku agbebọn kan ti kan si awọn pe awọn lawọn ṣiṣẹ laabi naa ti wọn si ti bẹrẹ idunadura, pẹlu bi ikọ Boko Haram tun ṣe sọ tirẹ yii, ewo lewo ni ibeere to gbẹnu ọmọ kan.
Gomina Bello Masari ṣalaye lasiko to ba aarẹ Buhari lalejo nileerẹ nilu Daura pe awọn ileeṣẹ alaabo ati ologun ti ri ibuba awọn janduku naa wọn si ti n gbe igbesẹ lori rẹ.
Oríṣun àwòrán, @Aminu Bello Masari
Gomina ipinlẹ Katsina, Bello Masari ti sọ fun Aarẹ Muhammadu Buhari pe awọn to ji awọn akẹkọọ ile iwe girama to wa ni Kankara, ni ipinlẹ naa ti kan si awọn.
Oluranlọwọ pataki si Aarẹ, Garba Shehu lo fi ọrọ naa lede lẹyin abẹwo ti Masari ṣe si Aarẹ Buhari ni ilu Daura.
O ni gomina ọhun, tohun ti igbakeji rẹ, Manir Yakubu sọ pe awọn agbebọn naa ti kan si wọn, ati pe idunadura ti n lọ lori bii awọn akẹkọọ naa yo ṣe pada wale."""
O ṣalaye pe awọn ẹṣo alabo ti mọ agbegbe ibi ti awọn ọmọ naa wa, ati pe awọn ọmọ Naijiria yoo gbọ iroyin ayọ nipa awọn ọmọ naa laipẹ.
Gomina Masari sọ pe afojusun Aarẹ Buhari ni lati ṣawari awọn ọmọ ọhun.
Ẹ wá gbọ òwe lẹnu ọmọ Igbo bíi àgbà ilẹ Yoruba
Oru ọjọ Ẹti to kọja ni awọn janduku agbebọn kan ṣadede kọlu ileewe naa to wa fun awọn akẹkọọ ọkunrin nikan, ti wọn si ji awọn akẹkọọ kan gbe, nigba ti awọn miran sa asala fun ẹmi wọn.
Ṣaaju ni ariyanjiyan ti kọkọ waye lori iye awọn akẹkọọ to poora ni pato, ṣugbọn lẹyin ọjọ meji ni gomina Masari sọ pe nnkan bii ọọdunrun akẹkọọ lo di awati.
Africa Eye: Wo ìtàn ìyá kan ìyá kan àtàwọn olè ajọ́mọgbé tó n ta ọmọ ní Kenya
Oríṣun àwòrán, @Aminu Bello Masari
Akẹ́kọ̀ọ́ 333 ni a kò tíì le sọ nípa wọn nílé ẹ̀kọ́ Kankara Katsina- Ìjọba Nàìjíríà
Iroyin tuntun nipa awọn akẹkọọ girama GSSS Kankara Katsin nipe pupọ ninu awọn akẹkọọ naa ni ko ti i di riri lẹyin ọjọ kẹta.
Gomina ipinlẹ Katsina, Aminu Bello Masari sọ fun awọn akọroyin pe, akẹkọọ 333, ni awọn ko ti i ri pada.
O sọ ọrọ naa lẹyin ipade to ṣe pẹlu awọn eleto aabo ni alẹ ọjọ Aiku.
Gomina naa ṣalaye pe 849 ni gbogbo akẹkọọ to wa ni ile ẹ̀kọ́ naa. Inu ọgba ile ẹ̀kọ́ ni awọn ọmọ naa n gbe.
Alẹ ọjọ Ẹti ni awọn afurasi janduku kọlu ile ẹ̀kọ́ náà, eyi to fa awuyewuye jakejado Naijiria.
Ijọba orilẹ-ede Naijiria si ti sọ pe awọn ọmọ ogun ti yi agbegbe ti wọn fura si pe ibẹ ni awọn agbebọn naa fi ara pamọ si.
Oríṣun àwòrán, @Aminu Bello Masari
Gomina Bello Masari fi kun ọrọ rẹ pe oun ti ṣe ipade pẹlu awọn lọga-lọga nileesẹ ologun, lẹyin ti oun ṣe abẹwo si ile ẹ̀kọ́ naa, ati aarin ilu to wa.
Gomina naa ni:  ni ipade naa jẹ akitiyan ijọba lati le gba ẹ̀mí awọn ọmọ naa la.
Sugbọn, tako nkan ti Gomina Masari sọ, agbenusọ fun Aarẹ Muhammadu Buhari, Garba Shehu, sọ fun BBC pe awọn ọmọkùnrin to raaye sa mọ agbebọn naa lọwọ sọ pe ọmọ mẹwaa lo si wa ni ọdọ awọn agbebọn.
Oríṣun àwòrán, @Aminu Bello Masari
Iye àwọn ti Shehu sọ yii kere si nkan ti awọn oṣiṣẹ ile ẹ̀kọ́ naa ti kọkọ sọ.
Igba lara wọn lo ti pada sile, sugbọn Ọgbẹni Shehu sọ pe ijọba ń gbiyanju lati mọ iye akẹkọọ to ṣe e ṣe ko fọn kaakiri agbegbe naa, lẹyin ti wọn sa lasiko ikọlu to waye.
Awọn eleto aabo sọ pe bi ọjọ ṣe n gun ori ọjọ, ni didoola àwọn ọmọ naa yoo ma a ṣòro si, paapa ti awọn ọmọ naa ba ti tuka, tabi ti awọn agbebọn ba ko wọn si ibi ọtọọtọ.
Ọpọ eeyan lo si ti n bu ẹnu ẹtẹ lu Aarẹ Muhammadu Buhari, nitori pe ko yọjú si ile ẹ̀kọ́ naa, bo tilẹ jẹ pe o wa lẹnu ìsinmi nipinlẹ Katsina.
Omolola Arohunmolase Welder: Mo ti fí iṣẹ́ 'Welder' gbayì láwùjọ, tó mo fi tọ́ ọmọ yanjú
Dipo bẹ ẹ, igbimọ aṣoju lati ilu Abuja, ni Buhari ran lọ.
Irinajo to le diẹ ni wakati meji ni Kankara si ilu Daura ti Buhari wa.
Ẹwẹ, àwọn obinrin kan ti ṣe iwọde, nipinlẹ Katsina, lati beere fun ominira àwọn akẹkọọ ile ẹ̀kọ́ GSSS, Kankara.
Ọgbà ẹ̀wọ̀n ni wọ́n ti já àbálé Esra lábẹ́ àwáwí àyẹ̀wò wúndíá
Ẹ wá gbọ bí òwe Yoruba ṣe dùn lẹnu ọmọ Igbo
Imado iba ṣe bi ẹlẹdẹ a balu jẹ, ẹru iba j’ọba, eeyan iba ku ọkan.
Pupọ ninu awọn ọmọ ilẹ Yoruba lo maa n gbọ owe oke yii ṣugbọn ti wọn kọ mọ itumọ rẹ.
Ṣaṣa ninu awọn ọmọ Yoruba, paapaa awọn ọmọ aye ode oni ni ko tilẹ mọ iru ẹranko to n jẹ imado, anbelete itumọ owe naa.
Ṣugbọn ki ni imado? Iru ẹranko wo ni Yoruba n pe ni imado?
Ki ni itumọ owe yii ati pe bawo ni owe naa ṣe jọ mọ ohun to n ṣẹlẹ laye ode oni?
Ẹ wo fidio yii fun ẹkunrẹrẹ bii ọmọ Igbo, Jude Chukwuka ṣe ṣe atupalẹ owe naa.
Sudan removed from terrorist list: America yọ Sudan kúrò nínú ìwé orílẹ̀-èdè tó ń ṣagbátẹrù ẹgbẹ́ agbésùnmọ̀mí lágbàyé
Oríṣun àwòrán, @Suribelle1
Ọọfisi ijọba ilẹ Amẹrika to wa ni Khartoum ti kede pe wọn ti yọ orukọ orilẹ-ede Sudan kuro lara awọn orilẹ-ede to n ṣatilẹyin fun ẹgbẹ agbesumọmi lagbaye.
Ninu atẹjade kan ti ijọba Amẹrika fi lede loju opo Facebook rẹ lo ti kede ipinu naa.
"Ikede naa ni ""lẹyin ifitonileti ọlọjọ marundinlaadọta, akọwe ijọwe ijọba ti buwọlu adehun ti a fi yọ orilẹ-ede Sudan kuro lara awọn orilẹ-ede to n ṣagbatẹru iṣerubalu lagbaye."""
Ṣaaju ni Aarẹ Donald Trump ti kọkọ kede loṣu Kẹwaa pe jọba Amẹrika yoo yọ orukọ Sudan kuro lara awọn orilẹ-ede agbesumọmi naa lẹyin to ba ti san owo itanra $335 miliọnu fun awọn ẹbi atawọn eeyan to fara gba ninu akọlu ẹgbẹ al-Qaeda si ọọfisi ijọba Amẹrika lọdun 1998.
Oríṣun àwòrán, US embassy Khartoum
Olori ijọba orilẹ-ede Sudan, Abdalla Hamdok si ti fesi pe wọn ti fi owo naa ranṣẹ.
Ẹ wá gbọ òwe lẹnu ọmọ Igbo bíi àgbà ilẹ Yoruba
Wọn fi orukọ Sudan sinu iw gẹgẹ bii ọkan lara awọn orilẹ-ede to n ṣagbatẹru awọn ẹgbẹ agbesumọmi lọdun 1993 pẹlu Iran, North Korea ati Syria.
Ijọba Amẹrika gbe igbesẹ naa lẹyin ti adari ikọ al-Qaeda, Osama Bin Laden fi orilẹ-ede naa ṣebugbe lọdun naa lọhun, gẹgẹ bii alejo ijọba.
Africa Eye: Wo ìtàn ìyá kan ìyá kan àtàwọn olè ajọ́mọgbé tó n ta ọmọ ní Kenya
Omah Lay àti Tems yóò tó darí padà sí Nàìjíríà
Oríṣun àwòrán, Twitter / Bebe Cool / Odas
Ijọba orilẹede Naijiria ti fi aridaju han pe awọn olorin ọmọ Naijria meji ti orilede Uganda fẹsun kan, Omah Lay ati Tems yoo to dari wale.
Oludari ajọ to n ri si ọrọ awọn ọmọ́ Naijiria to wa nilẹ okere, Abike Dabiri-Erewa sọ fun ileeṣẹ BBC lọjọ Iṣẹgun ọsẹ pe orilẹede Uganda ti jawọ ninu ẹsun ti wọn fi kan wọn lẹyin ọjọ kan tawọn olorin yii farahan niwaju ile ẹjọ majisireeti Uganda.
Oríṣun àwòrán, Nicholas Bamulanzeki
Ileeṣẹ ọlọpaa ilẹ Uganda fi ẹsun kan Stanley Omah Didia ti inagijẹ rẹ jẹ Omah Lay, Temilade Openiyi to n jẹ Tems ati ọmọ Naijiria kan, Muyiwa Awoniyi pe wọn n mọọmọ ṣe ohun to lee pin arun to lee ran ka kiri.
Kollington ṣàlàyé bí orin Fuji ṣe bẹ̀rẹ̀ gan an ní Nàiìjíríà
Olorin ọmọ orilẹede Uganda, Bebe Cool fi aworan iwe ile ẹjọ ti wọn fi paṣẹ pe ki wọn tu awọn mẹtẹẹta silẹ sita loju opo Twitter.
Iwe naa lo ṣafihan pe inu gba ẹwọn kan ni Kigo ni wọn gbe wọn ju si.
Bakan naa, kan lara awọn oludije ipo aarẹ ni Uganda toun naa jẹ olorin, Bobi Wine ni agbẹjọro oun darapọ mọ wn ninu akitiyan lati dawọ ẹjọ ti wọn n pe lori awọn olorin ọmọ Naijiria yii duro to si ni inu oun dun bo ṣe ṣẹlẹ
Ki ni awọn Naijiria n sọ lori bi ijọba ṣe ran Omah atawọn to ku rẹ lọwọ?
Ọpọlọpọ ọmọ Naijiria to fi mọ awn oloṣelu lo n funpe si ijọba pe ki wn tete ba ijọba orilẹede uganda sọrọ ki Omah Lay atawọn to ku rẹ ma baa pẹ lẹwọn.
Nitori naa nigbati iroyin itusilẹ wọn bọ ode, ọpọ lo tu sori ayelujara lati dupẹ lọwọ gbogbo awọn to kẹnu bọ ọrọ naa ati bi ijọba Naijiria ko ṣe fa sẹyin rara lori ọrọ naa.
Adajọ kan ni Uganda ti ni ki wọn fi olorin ọmọ Naijiria, Omah Lay, Temilade Openyi, ti ọpọ mọ si Tems ati Muyiwa Awomiyi si ọgba ẹgba ẹwọn di Ọjọru.
O ni ki wọn fi Omah Lay si ẹwọn to wa ni Kitalya, nigba ti Tems yoo wa ni ẹwọn Kigo.
Wọn fi ẹsun kan Omah Lay atawọn ẹmẹwa rẹ nile ẹjọ majistrati Makidye pe wọn mọọmọ wu iwa to le mu ki arun Covid-19 burẹkẹ si lorilẹ-ede naa.
Ọpọ awọn ololufẹ olorin naa ni Najiria lo ti bẹrẹ si n bu ẹnu atẹ lu ẹsun ti wọn fi kan an, ti awọn mii si  sọ pe ejo lọwọ ninu.
Oríṣun àwòrán, omah_lay
Ileeṣẹ ọlọpaa Uganda ti gbe olorin takasufe ọmọ Naijiria, Stanle Didia, ti ọpọ awọn ololufẹ rẹ mọ si Omah Lay atawọn meji miran lọ sile ẹjọ.
Ileeṣẹ naa lo fi ikede naa sita loju opo Twitter rẹ lọjọ Aje.
"Wọn ni ""awọn ọmọ Naijiria mẹta, Stanle Didia, ti ọpọ awọn ololufẹ rẹ mọ si Omah Lay, Temilade Openiyi, ti ọpọ mọ si Tems, ati Muyiwa Awoniyi ti foju bale ẹjọ."""
Atẹjade naa tẹsiwaju pe ẹsun ti awọn eeyan naa n jẹjọ le lori ni titapa si ofin to rọ mọ ilana ajakalẹ arun Covid-19.
Ṣaaju ni ileeṣe naa ti kọkọ ka jale lati ga beeli wọn lẹyin ti wọn ni iwa ti wọn wu le yọri si iburẹkẹ arun naa lorilẹ-ede ọhun.
Oríṣun àwòrán, @canadian_chops
Ileesẹ ọlọpaa orilẹ-ede Uganda ti mu gbajugbaja akọrin takasufe, to jẹ ọmọ Naijiria, Omah Lay, ati awọn eeyan meji mii, fun titapa si ilana Covid-19.
Ileesẹ ọlọpaa Uganda fi iroyin naa mulẹ, ninu atẹjade kan ti alukoro rẹ, SP Patrick Onyango, fi sita lọjọ Aiku.
"O ni ""eeyan mẹta ni ọwọ wa ti tẹ, fun pe wọn lọwọ si ipago orin ita gbangba, ni Ddungu Resort, ni ilu Kampala, lọjọ Satide."
" Awọn ti ọwọ wa tẹ ni alamojuto ibudo naa, Ivan Ddungu, Omay Lay, ati alamojuto eto naa to pe Omay Lay sibi ariya naa, Prim Kasana.
Omay Lay fúnra rẹ sọ pe otitọ ni iroyin naa, loju opo ayelujara Twitter rẹ.
Ileesẹ ọlọpaa kọkọ  sọ pe awọn n wa alamojuto ileesẹ ọlọpaa ni agbegbe naa, nitori pe o kuna pe 'ko mọ' nipa iwa ọdaran to n waye ni agbegbe rẹ.
Ọwọ si ti pada tẹ ọlọpaa mẹta, fun pe wọn pa imọ pọ pẹlu awọn to ṣeto ariya naa, lati pese aabo nibẹ.
Oríṣun àwòrán, omah_lay
Yatọ si eyi, wọn ni ọwọ àwọn tun ti pada tẹ akọrin obinrin ti oun na jẹ ọmọ Naijiria, Temilade Openiyi 'Tems', fun ẹsun kan náà.
O fi fidio nipa ariya naa sita lọjọ Satide.
Awọn ọlọpaa sọ pe apejẹ ọsan àti alẹ ni awọn awọn to ṣe agbatẹru ariya naa sọ pe awọn n ṣe, sugbọn wọn bẹrẹ si ni pe awọn olorin wọle ni alẹ.
Ẹ wá gbọ òwe lẹnu ọmọ Igbo bíi àgbà ilẹ Yoruba
Awọn afurasi naa ti wa ni ileesẹ ọlọpaa Katwe, ẹsun iwa to le mu ki aarun Covid-19 pọ si lao si fi kan wọn""."
"Nitori pe, ni ibẹrẹ itankalẹ coronavirus, ni aarẹ ti pàṣẹ pe ki opin o deba ariya orin ita gbangba. Àṣẹ naa si wa sibẹ.
 A koro oju si iwa àwọn onimọtara ẹni nikan, to fi ẹ̀mí ọpọlọpọ ọmọ orilẹ-ede Uganda sinu ewu, nitori pe wọn n wa owo."""
Africa Eye: Wo ìtàn ìyá kan ìyá kan àtàwọn olè ajọ́mọgbé tó n ta ọmọ ní Kenya
Iroyin sọ pe agbenusọ ileesẹ ọlọpaa ni ẹkùn Kampala, Luke Owoyesigyire ní o se e ṣe ki wọn o ṣe ayẹwo aarun Covid-19 fun awọn afurasi naa.
Ti esi ayẹwo ba fi han pe wọn ni i, ohun lao fi ṣe ẹri nile ẹjọ.
Àmọ́ ṣa, awọn ololufẹ Omah Lay ti n faraya lori ayelujara, ti wọn si n fi #freeOmahLay beere fun itusilẹ rẹ.
Lagos tanker accident: Ọkọ̀ àjàgbé agbépo kan tún dànù l'Eko
Oríṣun àwòrán, lasema
Ọkọ ajagbe agbepo kan ti ṣubu  lagbegbe Shasha nitosi Akowọnjọ nilu Eko.
Ajọ to n mojuto iṣẹlẹ pajawiri nipinlẹ Eko LASEMA ni awsn ti gbe gbogbo igbesẹ to yẹ ni gbigbe lati dẹkun wahala to le fẹ sọ nibẹ.
Alaga ajọ LASEMA, Ọmọwe Olufẹmi Damilsla Oke-Ọsanyintolu ti rọ awọn olugbe agbegbe naa lati ṣe pẹlẹ titi digba ti wọn yoo fi gbe e kuro nibẹ.
Akomolede ati Aṣa: Mọ̀ síi nípa ìró afárànma àti agbárànmọ́ fáwẹ́ẹ̀lì Yorùbá
Coronavirus in Lagos: Sanwo-Olu ti ilé ẹ̀kọ́ pa, fòfin de ayẹyẹ àdúgbò àti òde fàájì torí ọwọ́jà àrùn
O n bọ, o n bọ, awọn laa dẹ de e, eyiun laye ijọun amọ lode toni, oju ni wọn n mu to.
Eyi lo mu ki gomina ipinlẹ Eko, Babajide Sanwo-Olu pakiti mọlẹ lati ka ọwọja itankalẹ arun Coronavirus to n pelesi nipinlẹ naa ko nipa awọn igbesẹ kan.
Lara igbesẹ to si gbe naa ni fifi fofin de gbogbo ayẹyẹ aarin àdúgbò, kánífà òpín ọdún ati gbogbo ode faaji nitori ọwọja arun Coronavirus lẹẹkeji.
Sanwo-Olu lo sọ ọrọ naa ninu atẹjade kan to wa loju opo ijọba ipinlẹ Eko.
Gẹgẹ bi Sanwo-Olu ṣe sọ, àwọn ilé ijó kò ti di ṣíṣí títí di àsìkò yìí, ṣugbọn ki wọn ti eyikeyi to ba ti di ṣiṣi pada titi di gbedeke aláìlọ́jọ́.
Zlatan: Ọ̀rẹ́ ni mo sìn lọ ‘studio’ tí mo fi bẹ̀rẹ̀ orin lẹ́yìn tí mo kùnà ìdánwò WAEC
Bakan naa ni Sanwo-Olu tun pàṣẹ pé kí gbogbo ilé ẹ̀kọ wà ní títì pa titi di asiko ti ijọba yoo mọ igbesẹ to kan.
Bẹẹ naa ni kí gbogbo àwọn òṣìṣẹ̀ ìjọba lati ipele ikẹrinla si isalẹ maa ṣiṣẹ lati ile wọn fun ọjọ mẹrinla gbako, bẹrẹ lati ọjọ Aje to n bọ, àyàfi to bá jẹ́ pàjàwìrì tàbi tí wọn bá jẹ àwọn oṣíṣẹ kòṣeemáni.
Ni ti awọn ile ijọsin, o ni ki awọn adari ẹsin ri daju pe awọn eeyan to peju si ṣọọṣi àti mọ́sálásì kò kọ́ja ààdọ́tà lọ, ìsìn kò sì gbọdọ̀ kọ́ja wákàtí méjì pere.
Àṣẹ yìí jẹ́ ọ̀kan lára alàálẹ̀ ìjọba ipinlẹ Eko lórí ìlera ará ìlú to fi síta lọ́jọ́ Eti.
Baruwa Gas Explosion: Àwọn tó forí sọta ìjàmbá iná ń bẹ ìjọba láti dìde ìrànwọ́
Sáájú ni gómìnà ọhun ti fara kasa ààrùn Coronavirus, sùgbọ́n ó ti n gbádùn.
Ètò kóníléógbélé alágo méjila oru si mẹ́rin ìdájú ti ìjọba àpapọ̀ gbé silẹ̀ kò ti kásẹ̀ nílẹ̀, bákan naa ni lílo ìbòmú ṣe pàtàkì láàrín èrò, nílé iṣẹ́, àti inú ọjà.
Oríṣun àwòrán, @Dawisu
Gomina ipinlẹ ipinlẹ Kano, Abdullahi Umar Ganduje, ti paṣẹ pe ki awọn ile ẹkọ eto ilera nipinlẹ naa ko wa ni titi pa.
Alẹ ọjọ Iṣẹgun ni aṣẹ yii jade lati ẹnu kọmisanna fun et ilera, Dokita Aminu Ibrahim Tsanyawa, to gba ẹnu gomina sọrọ.
Ṣaaju ni kọmisanna fun eto ẹkọ, Muhamaad Sanusi Kiru ti paṣẹ pe ki awọn ile ẹkọ aladani ati ti ijọba o wa ni titi pa.
Bo tilẹ jẹ pe ijọba ko sọ idi to fi pa aṣẹ naa, awọn kan sọ pe o ṣe e ṣe ko jẹ nitori bi awọn agbebọn ṣe ko awọn akẹkọọ nileewe Government Science Secondary School, Kankara nipinlẹ Katsina.
Ipinlẹ Kaduna naa ti kọkọ kede iru aṣẹ yii, amọ nitori itankalẹ Covid-19 ni.
Iwode fun Ochanya  ti won ba lopo waye nilu Eko
Nitori ọwọja keji ti aarun coronavirus n ba de bayii, ijọba ipinlẹ Kaduna ti kede pe ki  gbogbo awọn ileewe titi kan fasiti o wa ni titipa bẹrẹ lati Ọjọru, ọjọ kẹrindinlogun oṣu kejila ọdun 2020.
Oríṣun àwòrán, Twitter/ governor kaduna
Aṣẹ ti ijọba ipinlẹ naa fi sita rọ gbogbo awọn adari ileewe lati rii daju pe gbogbo idanwo wa sopin lẹyẹ o ṣọka ki wọn si ti ileewe gbogbo l'Ọjọru.
Igbesẹ yii waye pẹlu bi ajakalẹ arun naa tun ṣe n dabi ẹni to tun fẹ maa gbẹrẹgẹjigẹ sii.
Oríṣun àwòrán, Twitter/governor kaduna
Atẹjade kan ti ileeṣẹ  eto ẹkọ ijọba ipinlẹ naa fi sita rọ awọn ileewe lati rii daju pe wọn bẹgi le eto ẹkọ ninu ileewe, ki wọn wa ọna abayọ miran lati fi ṣeto ẹkọ fun awọn akẹkọọ to ba di dandan.
Akomolede ati Aṣa: Mọ̀ síi nípa ìró afárànma àti agbárànmọ́ fáwẹ́ẹ̀lì Yorùbá
Bakan naa ni wọn tun fi kun un pe awọn ileeṣẹ redio ati tẹlifiṣan ipinlẹ naa yoo tẹsiwaju lati maa ṣe eto ẹkọ lori ikanni wọn gẹgẹ bi wọn ti ṣe n ṣe tẹlẹ.
Kollington ṣàlàyé bí orin Fuji ṣe bẹ̀rẹ̀ gan an ní Nàiìjíríà
Akomolede ati Aṣa: Mọ̀ síi nípa ìró afárànma àti agbárànmọ́ fáwẹ́ẹ̀lì Yorùbá
Òfin mélòó ní o mọ̀ tí Àrànmọ́ Fáwẹ́ẹ̀lì Yorùbá gbọ́dọ̀ ní?
Akomolede ati Aṣa lori BBC Yoruba lo tun jade lonii.
Aranmọ Fawẹẹli ni olukọ to dantọ ni o n kọ wa bayii.
Alagba Oyewole Isaac lati ile ẹkọ Awaye Comprehensive Grammar School ni Ilẹ Oluji ni ipinlẹ Ondo ni olukọ wa lonii.
Agbara ti iro kọọkan ni lori ikeji rẹ wa lara ohun ti a n gbe yẹwo.
Eto yii jẹ ajóṣẹpọ ẹgbẹ Onimọ Yoruba, YSAN ati ti apapọ ẹgbẹ Akomolede ati Aṣa Yoruba ti Naijiria lapapọ.
Ofin to rọ mọ aran ma gbigba ati oriṣii Aranmọ mẹrin to wa wa lara koko ti a gbe yẹwo lonii pẹlu apẹẹrẹ.
New Covid 19 update: Ẹ̀yà kòkòrò Covid-19 míràn jáde ní ọgọ́ta agbègbè nílẹ̀ Gẹẹsi, àjọ elétò ìlera fọkàn ará ìlú balẹ̀
Oríṣun àwòrán, @NCDC
Ẹyà kòkòrò Covid-19 míràn yọjú ní ọgọta agbègbè nílẹ́ Gẹẹsi, àwọn eleto ìlera ni k'ara ilu má fòyà.
Akọwe ilera lorileede Gẹẹsi Matt  Hancock ti sọ fún àwọn aṣofin ile naa pe awọn ti ṣawari irufẹ ẹyà kokoro àrùn Covid-19 mi ti a máa yara tan ka.
Matt Hancock salaye pe o kere tan ọgọta agbegbe ni wọn ti ri akọsilẹ itankalẹ arun Covid-19 tuntun yi.
Matt ni awon ti fi to ajọ ilera agbaye leti ati pe ilese ayẹwo ilera ile naa Porton Down ti n se Iwadii nipa rẹ.
"Ọgbẹni Hancock ni ""awọn ko ri aridaju pe o n fa arun yi lagbara ju èyí to wa nilẹ lọ tabi pe abẹrẹ ajẹsara ko ni ṣiṣe mo."""
Akomolede ati Aṣa: Mọ̀ síi nípa ìró afárànma àti agbárànmọ́ fáwẹ́ẹ̀lì Yorùbá
Bẹẹ lo sàlàyé fún àwọn aṣofin ile ilẹ naa pe nise lawọn ṣakiyesi alekun iye àwọn to ni arun naa kaakiri London, Kent, apa kan agbegbe  Essex ati Hertfordshire.
A ko mọ bi ẹda kokoro yi se lagbara sí sugbon a gbodo gbe gbogbo igbesẹ tó yẹ ní kíákíá lati dẹkun rẹ pẹlu bi a ti ṣe n fun awọn eeyan labẹrẹ ajẹsara
Kollington ṣàlàyé bí orin Fuji ṣe bẹ̀rẹ̀ gan an ní Nàiìjíríà
Ọjọgbọn Alan McNally,  to jẹ akọṣẹmọṣẹ ni fasiti Birmingham, ni laarin ọsẹ bi meloo to kọja lawọn laabu ilẹ Gẹẹsi kẹfin kokoro tuntun yi.
" A  ti n gbé igbesẹ lati mọ bi ẹyà kokoro tuntun yi ti ṣe waye.
O ṣe pataki ki gbogbo eeyan fi ọkan woye ẹyà  kokoro tuntun yi nitori kokoro a máa yira pada lóòrèkóòrè ti o sí ṣeeṣe ki kokoro yi máa lọ ki sí maa bọ to ba ya"
Ọgbà ẹ̀wọ̀n ni wọ́n ti já àbálé Esra lábẹ́ àwáwí àyẹ̀wò wúndíá
Water drinking advantages: Wo ìpalára ní ọ̀nà mẹ́fà tó lè bá ènìyàn tí kò bá kí ń mu omi mímu tó ìwọn tó yẹ
Oríṣun àwòrán, others
Ìpalára mẹ́fà tó wà nínú kí èèyàn ṣalai mú omi ní ìwọ̀n ti ara nílò.
Ṣe gbogbo wa la kuku mọ wipe mimu omi deedee jẹ ọnà kan gboogi lati je ki ara wa ni okun ati alaafia.
Lasiko ti a wa yi, ti oorun a maa mu gidi gan an, omi mímu jẹ ọnà ti ará fi n ṣe idapada awọn okun to ba ti padanu nipasẹ lilọ bíbọ ati iṣẹ ṣiṣe.
Bi omi ko ba sì ni ọnà ọfún wa tabi ninu agọ ara wa, ko ni pẹ ti orisirisi ailera yóò máa bá agọ ara wa finra.
Díẹ ninu awọn ohun to yẹ ki o ṣọra fun ree ninu wọn:
1) Ara ko ni ji pepe to bo ti ṣe yẹ:
Ti ara ko ba ni omi tó bo ti ṣe yẹ,ara oluwaarẹ ko ni ji pepe lati se awọn iṣẹ to yẹ kó lè ṣe.
Lọpọ igba irẹwẹsi yoo ba ọkan eeyan ti gbogbo ara ko sí ní le ṣiṣẹ bo ti ṣe yẹ.
Kollington ṣàlàyé bí orin Fuji ṣe bẹ̀rẹ̀ gan an ní Nàiìjíríà
2) Ewu rọ lapa-rọ lẹsẹ(stroke):
Gẹgẹ bi iwadii kan ti awọn onimọ nipa ailera  kasan ara gbe jade, wọn ni aimaa mu omi daada le fa ki eeyan ni rọlapa rọlẹsẹ ti oloyinbo n pe ni Stroke.
Itaniji: Oluwo sọ ìtàn bí Orunmila ṣe jìyà nílùú Iwo àti ayọ̀ tó gbẹ̀yìn rẹ̀ torí sùúrù
3)  Ṣiṣe ibẹrẹ ko ni wa nirọwọrọsẹ:
Ounjẹ ti eeyan ba jẹ ti ko mu omi sí daada,iru oúnjẹ bẹ ko ni da daada lara onitọhun.
Nitori idi eyi ko dáa tó ki eeyan maa fi oungbẹ gbẹ ara rẹ tabi ko ma sey mu omi tó bo ti ṣe yẹ.
4) Ori fifọ:
Nitori pe ọpọlọ wa nilo omi ti yóò fi le ṣiṣẹ daada, bi eeyan ko ba mu omi daadaa ko sí tàbí ṣugbọn ori fifọ ko ni jẹ ki iru eeyan bẹ gbádùn ara rẹ.
5) Awọ ara ko ni jọlọ to:
Apẹrẹ bi eeyan ba ṣe n mu omi sí a máa hàn lara awọ ẹni bẹẹ.
Ìdí ni pé ara wa nilo omi ki o baa le ji pepe ko si máa dan daada.
Bi eeyan ba kọ ti ko mu omi daada n'isẹ ni awọ rẹ yoo hun jọ ti yoo si dabi arugbo ọsan gan an.
Awọ ti ko dan daada,ẹ fura si boya alawọ naa ko mu omi daadaa ni.
Ado Ekiti Blind Couple: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú
6) Ai mu omi máa n mu eeyan sanra:
Bi eeyan ko ba fẹ sanra púpọ,ọna kan to lè fi jo walẹ ni ko máa mú omi daadaa.
Ni idakeji bi eeyan ba fe sanra ko yàgò fún omi mímu ṣugbọn o dami loju pe ẹ ko ni fẹ ṣe bẹẹ.
Ẹ máa gbagbe ilera lóògùn ọrọ, bi a ba si fẹ kí awọ wàá máa dan bi ti ikoko,omi mímu wa lara ohun táa lè ṣe.
Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó
Fuji Music: Kollington Ayinla sọ ẹni tó dá orin Fuji sílẹ̀ gan an ní Nàiìjíríà
Agbaọjẹ olorin Fuji ni Naijiria, Alhaji Kollington Ayinla tun ti yanna na bi orin Fuji ṣe bẹrẹ lorilẹede Naijiria.
Ọpọ awuyewuye lo ti wa lori ẹni ti o bẹrẹ orin Fuji ni Naijira laarin oloogbe Sikiru Ayinde barrister ati Alhaji Kollington, Kebe n Kwara.
Amọ, Kollington fun ra rẹ naa ti fi kọ orin pe ''Edumare fiṣẹ yin wa gbogbo wa, lagbaja lo da Fuji silẹ, ọrọ awawi, tamẹdo lo da Fuji silẹ, Edumare fiṣẹ yin wa gbogbo wa.''
Ninu ifọrọwerọ rẹ pẹlu ileeṣẹ FUJI: A Opera, Kollington gba pe oloogbe Ayinde Barrister lo da ere Fuji silẹ nigba ti oun tẹ le e ninu iṣẹ orin Fuji.
Nibi akanṣe eto naa to waye ni Alliance Francaise de Lagos/The Mike Adenuga Center, Ikoyi, Kollington sọ pe orin Fuji ti kọja bẹẹ lasiko yii.
Kollington ṣalaye pe oun ko lero pe orin Fuji le di gbajugbaja orin bi o ti da lonii.
''Orin gidi ni orin Fuji, o ti kan kaakiri gbogbo agbaaye bayii, gbogbo eeyan ni Naijiria lo fẹ kọ orin Fuji bayii,'' Kollington lo sọ bẹẹ.
Alhaji Kollington fikun ọrọ rẹ pe ijinlẹ ede Yoruba lawọn maa n fi kọ orin Fuji ṣugbọn laye ode oni ''awọn ọmọ wa ti fi ede oyinbo si orin Fuji lati le jẹ ko jẹ itẹwọgba sii kaakiri agbaaye.
Ede Poly Rector suspension: Wọ́n ní kí ọ̀gá àgbà Pólì Ede lọ rọ́kún ńlé lórí ẹ̀sùn pé 'ó kan bẹ́ẹ̀dì sí ọ́fíìsì'
Oríṣun àwòrán, Facebook/John Adekolawole
Igbimọ alaṣẹ ile iwe giga Poli Ede ni ipinlẹ Osun ti ni ki ọga agba ileewe naa, John Adekolawole lọ rọkunle.
Agbẹnusọ ile iwe naa, Sola Lawal sọ fawọn akọroyin pe lootọọ ni wọn ti sọ pe ki ọga agba ile iwe lọ rọkunle.
Amọ Ọgbẹni Lawal kọ lati ṣalaye ohun to fa a ti igbimọ alaṣẹ ile iwe naa fi sọ fun Adekolawole lọ rọkun nile.
Agbẹnusọ ile iwe giga naa ṣalaye pe alaga ẹgbẹ awọn olukọ ASUP nile ẹkọ naa, Ọgbẹni Adekunle Masopa ti fi igbesẹ igbimọ alaṣẹ to awọn olukọ ileewe ọhun leti
Ọgbẹni Masopa alaga igbimọ alaṣẹ sọ idi mọkanlelogun tawọn fi ni ki ọga agba ileewe naa lọ rọkun nile.
Lara ẹsun ti wọn fi kan ọgbẹni Adekolawole ni pe o fi iṣẹ rẹ silẹ lai ṣe fun odidi oṣu kan.
Akomolede ati Aṣa: Mọ̀ síi nípa ìró afárànma àti agbárànmọ́ fáwẹ́ẹ̀lì Yorùbá
Bakan naa ni wọn tun fi ẹsun iwa ibajẹ lọfiisi kan Adekolawole pe niṣe lo lọ gbe bẹẹdi nla sinu ọfiisi rẹ eyi ti yoo jẹ ko maa sun lẹnu iṣẹ.
Ṣugbọn ohun ti agbẹnusọ ile iwe naa sọ ni pe oun gbọ pe igbimọ alaṣẹ ni ki ọga agba ileewe naa yẹba fun ọfiisi amọ oun ko ri iwe apilẹkọ to fidi rẹ mulẹ.
Amọ, Ọgbẹni Lawal ni ko si ewu kankan lori ọrọ naa, o ni gbogbo rẹ ni yoo ni iyanju laipẹ.
Africa Eye: Wo ìtàn ìyá kan ìyá kan àtàwọn olè ajọ́mọgbé tó n ta ọmọ ní Kenya
Marriage dispute: Ìyàwó mi fi mí sílẹ̀ kó lọ sílé ọkùnrin míì nínú báráàkì kan náà, àmọ́ mò sí tún fẹ́ràn rẹ̀
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Sọja kan to ti fẹyin ti lẹnu iṣẹ ologun, Richard Imana ti sọ fun ileẹjọ ibilẹ (Customary court) niluu Eko pe ko tu igbeyawo ọdun mẹwaa oun pẹlu aya rẹ ka.
Ọgbẹni Imana fi ẹsun kan iyawo rẹ, Nkem pe o fi oun silẹ, ko si tun foun laye lati ri ọmọ oun.
Imana sọ fun ileẹjọ naa pe Nkem ko kuro nile oun, o si ko lọ si ile ọkunrin mii ninu baraaki kan naa tawọn n gbe.
Ọgbẹni Imana to jẹ ẹni ọdun mọkandinlogoji ṣalaye pe iyawo oun ko lọ ba ọkunrin mii nigba ti iṣẹ gbe oun lọ si ipinlẹ Borno.
''Mo bẹrẹ si ni tọju awọn ọmọ wa nitori iyawo mi ko tọju wọn mọ,'' Imana lo sọ bẹẹ.
Sọja naa tun fikun ọrọ rẹ pe iyawo oun kọ lati buwọ luwe nigba ti dokita to n tọju oun ni ko ṣe bẹẹ nigba ti ara oun ko ya.
Oríṣun àwòrán, others
O ni iyawo oun tun mu abikẹyin awọn lọ si ọdọ mama rẹ lai gbaṣẹ lọwọ oun.
Amọ, sọja ọhun ni oun si fẹran iyawo oun lẹyin ti ọmọ mẹta ti wa laarin wọn.
Akomolede ati Aṣa: Mọ̀ síi nípa ìró afárànma àti agbárànmọ́ fáwẹ́ẹ̀lì Yorùbá
Ninu ọrọ tiẹ, Nkem sọ fun ileẹjọ pe ọdọ ọrẹ oun obinrin to wa nile ọkọ loun ko lọ lẹyin ti ọkọ oun ko fowo ounjẹ ranṣẹ si oun atawọn ọmọ mọ.
''Irọ ni pe mo ko lọ sile ọkunrin mii, ọdọ ọrẹ mi ni mo lọ nigba ti iṣẹ gbe ọkọ mi lọ si Borno,'' Nkem lo ṣalaye bẹẹ.
Ọgbà ẹ̀wọ̀n ni wọ́n ti já àbálé Esra lábẹ́ àwáwí àyẹ̀wò wúndíá
O rọ ileẹjọ lati bawọn yanju aawọ to wa laarin nitori oun si nifẹ ọkọ oun bo tilẹ jẹ pe ko nifẹ oun.
Aarẹ kootu naa, Ọmọba Adewale Adegoke sọ fawọn mejeeji lati jọ sọ asọyepọ laarin ara wọn.
Africa Eye: Wo ìtàn ìyá kan ìyá kan àtàwọn olè ajọ́mọgbé tó n ta ọmọ ní Kenya
Majeobaje: Gómìnà, ẹ gbé owó ńlá fún Amotekun kó le dábírà lẹ́ka ètò ààbò
Oríṣun àwòrán, Others
Ẹgbẹ kan to jẹ ti ọmọ bibi ilẹ Yoruba, Majeobaje ti ke sawọn gomina lẹkun iwọ oorun guusu Naijiria lati wa ojutu si ipenija eto aabo.
Bakan naa ni wọn woye pe awọn gomina nilẹ Kaarọ oojire to wa ni Eko, Oyo, Osun,Ogun,Ekiti ati Ondo ti kuna ninu ojuse wọn lati pese aabo to jiire silẹ Yoruba.
Atẹjade kan ti akọle rẹ n jẹ 'ẹ gba ẹmi wa la', ti ẹgbẹ Majeobaje naa kọ si gomina ipinlẹ Ondo, Rotimi Akeredolu, tii se alaga awọn gomina lẹkun yii, lo sisọ loju ọrọ naa.
Atẹjade naa, ti wọn fi ẹda rẹ sọwọ sawọn gomina yoku nilẹ Kaaro Oojire, wa kọminu lori iwa ipaniyan, ijinigbe, ifipabanilopọ atawọn iwa ọdaran mii, to n gogo nilẹ Yoruba.
Ẹgbẹ Majeobaje wa n kọminu lori idi ti ikọ Amotekun ko se tii bẹrẹ isẹ to jọju nidi idaabo bo ẹmi ati dukia nilẹ Yoruba, gẹgẹ bi awọn araalu ti n foju sọna fun.
Oríṣun àwòrán, Majeobaje
"Awọn janduku agbebọn ti gba ẹkun ariwa Naijiria kan, Awọn Fulani darandaran n sa fun asalẹ, awọn eeyan to n fori sọta ọsẹ Boko Haram n wa aabo.
Bẹẹ si ni awọn ọdọ ti ko ri isẹ se n wa isẹ kiri gbogbo ẹkun to wa ni Naijiria, ẹkun iwọ oorun guusu si ni gbogbo awọn eeyan ta mẹnuba yii n sa wa.'
Titara titara si ni wọn n rin pẹlu ibọn Ak47, ti wọn si n fi ipa aba awọn obinrin wa lopọ, bẹẹ ni wsn n gbẹmi eeyan laibikita, koda, wsn ko tun bọwọ fun ẹmi eeyan, asa ati ofin pẹlu."
Baruwa Gas Explosion: Àwọn tó forí sọta ìjàmbá iná ń bẹ ìjọba láti dìde ìrànwọ́
Ẹgbẹ Majeobaje wa rọ awọn gomina nilẹ Yoruba lati gbe owo kalẹ fun ikọ Amotekun, ki wọn si gba osisẹ to to sibẹ, ki wọn lee wa laarin ilu ati igberiko gbogbo.
Ẹgbẹ naa ni ti awọn gomina ilẹ Kaarọ Oojire ko ba san sokoto wọn ko le lati se ohun to tọ nidi didaabo bo araalu, awọn araalu le pinnu lati maa se ohun to ba wu wọn lati daabo bo ẹmi ati dukia wọn.
Oríṣun àwòrán, Nigerian Polcie Force
Ileeṣẹ ọlọpaa ipinlẹ Oyo ti fi hande pe lootọ ni awọn ajinigbe ji ọmọ orilẹede India meji ni ipinlẹ Oyo.
Alukoro ọlọpaa ipinlẹ Oyo, Olugbenga Fadeyi sọ fun BBC Yoruba pe awọn n ṣe akitiyan lati doola wọn ki wọn si fi panpẹ ofin mu awọn kọlọransi ẹda to ji wọn gbe ọhun.
Ẹwẹ nigba ti akọroyin bere boya lootọ ni wọn tun ji awọn ọlọpaa gbe nigba ti wọn n gbiyanju lati doola awọn ọmọ orilẹede India ọhun, alukoro ọlọpaa ni oun lee sọ dajudaju pe irọ ni.
Kollington ṣàlàyé bí orin Fuji ṣe bẹ̀rẹ̀ gan an ní Nàiìjíríà
Olugbenga ni ko si ọlọpaa kankan ni ipinlẹ Oyo to farapa tabi ti wọn jigbe nitori iṣẹlẹ yii. O ni ọgbọn awọn oniwa aburu ẹda lati tẹmbẹluu agbara ọlọpaa nipinlẹ Oyo ni.
Torinaa, ileeṣẹ ọlọpaa ni awn eeyan awọn ti kan si agbami iṣẹ fun itusilẹ awọn ọmọ India naa ti wọn jigbe ni ile ita ogun kan lagbegbe Toll Gate ni opopona Eko si Ibadan ni nkan bii ago mẹrin irọlẹ.
Opopona Eko si Ibadan ni wọn ti ji wọn gbe l'Ọjọru ọsẹ awọn eeyan wa si n ṣiṣẹ takun takun lati doola wọn pada ki wn lee wa pọ pẹlu ẹbi wọn Eyi ni alukoro ọlọpaa Oyo sọ.
Awọn mejeeji la gbọ pe awọn ajinigbe da lọna lasiko ti wọn n wa ọkọ jade ninu ọgba ile itaja ogun naa.
Tinubu 2023: Àwọn èèkàn ilẹ̀ Yorùbá ń ṣèpàdé ṣáájú dídìbò fún Tinubu ní 2023
Oríṣun àwòrán, Others
Asiwaju Tinubu
Ilẹkẹ ma ja sile, ilẹkẹ ma ja sode, ibi kan ni yoo kuku pada jasi nipa ẹya ti yoo jẹ aarẹ orilẹede Naijiria to mbọ.
Gẹgẹ bi awọn ọmọ Naijiria ṣe wa n reti ibi ti ilẹkẹ ipo naa yoo jasi laarin ẹya gboogi mẹta to wa lorilẹede Naijiria, awọn tọrọ kan ti bẹrẹ si ni gbe igbesẹ.
Ọjọ Iṣẹgun ọsẹ ni ilu Ibadan tii ṣe olu ilu ipìnlẹ Oyo, lawọn eekan tọrọ kan ni iha Guusu-Iwọ Oorun Naijiria yoo ti korajọ lati jiroro lorii ohun to wa niwaju fun il Yoruba ṣaaju idibo ọdun 2023.
''Buhari àti Tinubu ṣ'àdéhùn pé Yorùbá ni yóò jẹ́ olùdíje ipò ààrẹ APC lọ́dún 2023''
Ìjọba ìpínlẹ̀ Kaduna gbé iléèwé tì pa nítorí ọ̀wọ́ kejì àjàkálẹ̀ COVID-19
Ọkọ̀ àjàgbé agbépo kan tún dànù l'Eko
Kollington ṣàlàyé bí orin Fuji ṣe bẹ̀rẹ̀ gan an ní Nàiìjíríà
Ọmọ ile igbimọ aṣoju-ṣofin Naijiria tẹlẹ, Họnọrebu Rotimi Makinde lo fi ọrọ naa lede lorukọ ẹgbẹ South West Agenda 2023 eyi ti wọn pe ni SWAGA 23.
Wọn n ṣe eyi gẹgẹ bi igbaradi lati mu ala asiko oṣelu tuntun ni ilẹ Yoruba ṣẹ.
Awọn to ṣe agbatẹru eto naa ni yoo jẹ aaye lati kede ipinu awọn to ba fẹ lati to sẹyin agba ẹgbẹ oṣelu All Progressives Congress, Bola Ahmed Tinubu ki wọn lee fi orukọ rẹ ṣọwọ fun ipo aarẹ lọdun 2023.
Gbogbo awọn tọrọ kan lati ipinlẹ Eko, Oyo, Osun, Ondo, Ekiti ati Ogun yoo pade lati sọrọ lori awọn igbesẹ ti wọn yoo gbe ninu afẹfẹ oṣelu tuntun to ba fẹ.
Ìṣòro jíjẹ́ ìyá n dáàgbé ló sọ mí di àtúnbí krístíẹ́nì - Remi Tinubu
'Bí a kò bá fẹ́ ìbínú Ọlọ́run, a gbọ́dọ̀ jẹ́ kí Tinubu du ipò ààrẹ̀ lábẹ́ àsìá ẹgbẹ́ APC ní 2023'
Àbọ̀ ìpàdé bòńkẹ́lẹ́ láàrin Tinubu àti Buhari rèé
Akomolede ati Aṣa: Mọ̀ síi nípa ìró afárànma àti agbárànmọ́ fáwẹ́ẹ̀lì Yorùbá
Fibroid: Ǹjẹ́ o mọ pé o le ní oyún ìju tí o kò bá tètè bímọ?
Oríṣun àwòrán, Bsip
Aworan oyun iju
Iwadii imọ ijinlẹ kan ti fihan pe obinrin mẹta ninu mẹwaa, ti ọjọ ori wọn wa laarin ọdun mẹẹdọgbọn si ọgbọn ọdun, lo ma n ni oyun iju ni Naijiria.
Awọn ile iwosan ikọṣẹ iṣegun oyinbo to wa ni ilu Calabar, Port Harcourt ati Enugu, ni wọn ṣe iwadii naa.
Dokita agba ni ẹka ti wọn ti n mojuto awọn ẹya ara ti obinrin fi n bimọ, Obstetrics and Gynaecology, ni Ile iwosan ẹkọṣẹ iṣegun Fasiti Calabar, Ugwu Brown, sọ fun BBC pe, ìju lo wọpọ ju ninu awọn nnkan to ma n wu ninu ikun obinrin, ni Naijiria.
Oríṣun àwòrán, other
Dokita n lo ẹrọ Ultrasound lati mọ boya obinrin ni oyun iju
Dokita Brown sọ pe adinku le ba bi awọn obinrin ṣe n ni oyun iju, ti wọn ba le mojuto ilera wọn, nipa mimu adinku ba bi wọn ṣe n jẹ awọn ounjẹ to ni caffeine; tabi dena itọ ṣuga ati ẹjẹ riru, to fi mọ sisanra ju . O si tun ni ki obinrin tete bimọ le ran lọwọ.
Awọn ami oyun iju:
Bi oyun iju naa ba ṣe tobi to, iye to jẹ, ati ibi to wa ninu ile ọmọ, ni yoo sọ ami ti obinrin yoo ri.
Ṣugbọn Dokita Brown sọ pe ọpọlọpọ obinrin to ni oyun iju kii ri ami kankan.
Awọn ami to wọpọ ni:
Oríṣun àwòrán, other
Aworan oyun iju
Bi o sẹ le tọju oyun iju:
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Itọju ti wọn yoo fun obinrin to ba ni oyun iju nii ṣe pẹlu ọjọ ori, to ba ṣi fẹ ẹ bimọ, bi iju naa ṣe tobi si, ati ibi to wa ninu ile ọmọ.
Itọju gboogi to wa fun ni 'hysterectomy'; eyi ni ilana ti wọn n gba lati yọ ile ọmọ obinrin kuro ninu ara.
Ṣugbọn, itọju naa yoo jẹ nipa oogun lilo tabi iṣẹ abẹ.
Ganduje: Gòmìna Ganduje ni yíyọ Sanusi nípò Emir Kano wà fún àtúnṣe ètò oyè jíjẹ ní ìlú Kano
Oríṣun àwòrán, Twitter/Maigaskiya
Gomina ipinlẹ Kano, Ganduje ti sọ pe oun ko kabamọ bi oun ṣe rọ Emir ilu Kano tẹlẹ, Sanusi Lamido Sanusi loye.
O ni tẹlẹ gan an kii ṣe Sanusi lo tọ si ipo naa, awọn alagbara ijọba nigba naa lo kan fi iyansipo rẹ ṣe ọna ati fi la aarẹ igba naa, Goodluck Jonathan loju.
Gomina Ganduje to sọrọ nibi ifilọlẹ iwe kan nipa aarẹ ana, Goodluck Jonathan ṣalaye kikun nipa iṣẹlẹ naa.
O ni wi pe lasiko ti wọn yan Sanusi Lamido Sanusi gẹgẹ bii Emi ilu Kano loṣu kẹfa, ọdun 2020, lẹyin oṣu meji ti aarẹ Jonathan yọọ nipo gomina banki apapọ Naijiria, oun mọ pe kii ṣe igbesẹ to tọ nigba naa.
O ni nikete ti oun di gomina loun ti sọ ọ fun ara oun pe oogun ti Jonathan lo lori ọrọ Sanusi ṣe pataki pupọ.
Kollington ṣàlàyé bí orin Fuji ṣe bẹ̀rẹ̀ gan an ní Nàiìjíríà
Ganduje ni aarẹ ana, Goodluck Jonathan gbe igbesẹ akin lati yọ Sanusi nipo gomina banki apapọ Naijiria nitootọ.
Akomolede ati Aṣa: Mọ̀ síi nípa ìró afárànma àti agbárànmọ́ fáwẹ́ẹ̀lì Yorùbá
Bi o tilẹ jẹ pe o fa ẹtanu rẹ laarin awọn eeyan kan; sibẹ oun ri i gẹgẹ bi igbesẹ to tọ gẹgẹ bi oogun to yẹ ni lilo to dabi ọna abayọ lati wo wahala igba naa.
"Oogun naa, bi o tilẹ jẹ pe mi o kii ṣe dokita iṣegun oyinbo, oogun yii kan naa yoo wulo fun iṣẹ kan naa, arun kan naa ati fun eeyan kan naa.
Ọgbà ẹ̀wọ̀n ni wọ́n ti já àbálé Esra lábẹ́ àwáwí àyẹ̀wò wúndíá
Ganduje ni: Nitori naa mo gbe igbesẹ oogun ti Jonathan gbe lati doola ilana ati eto Ọba jijẹ ni Kano, mo si lo o daadaa."
Fun idi eyi. igun kan naa lemi ati aarẹ ana, Jonathan wa.
Africa Eye: Wo ìtàn ìyá kan ìyá kan àtàwọn olè ajọ́mọgbé tó n ta ọmọ ní Kenya
"Ẹ wo o, emi ko kabamọ rara nitori pe mo yọ Sanusi loye Emir ti Kano"""
Lasiko iṣejọba Rabiu Kwankwaso gẹgẹ bii gomina ipinlẹ Kano ni wọn fi Sanusi Lamido Sanusi joye Ẹmir ilu Kano ṣugbọn ni ọjọ Kẹsan an oṣu kẹta ọdun 2020 ni wọn rọọ loye.
Ekiti Bishop: Ìjọ Anglican pàṣẹ lọ rọọ́kún nílé fún Bíṣọ́ọ̀bù tó ń bá ìyàwó àlùfáà abẹ́ rẹ̀ sùn l'Ekiti
Oríṣun àwòrán, Newsdayng.com
Ijọ Anglican ni ipinlẹ Ekiti ti kọwe lọ ree gbe ile rẹ si Biṣọbu ijọ naa kan, Victor Adepoju lori ẹsun pe o ni ibalopọ pẹlu iyawo alufaa ẹgbẹ rẹ kan ninu agbegbe kan naa.
Biṣọbu Adepọju lo n ṣakoso daosisi ijọ naa to wa lẹkun Iwọ oorun Ekiti ni ipinlẹ naa.
Gẹgẹ bi lẹta ti awọn ileeṣẹ iroyin abẹle kan ni wọn kọ ṣọwọ si Biṣọọbu naa lati fi pe ko lọ rọọkun nile,
"Wọn ni Biṣọọbu Adepọju ""jẹwọ pe lootọ loun ba iyawo alufaa to wa labẹ oun sun"""
Bisọọbu yii lo n dari ijọ Anglican to wa ni Iwọ oorun Ekiti ni
Amọṣa, Biṣọbu Adepọju ko tii sọrọ kankan lori iṣẹlẹ yii.
Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsèjẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọ
Lagos-Ibadan Expressway: Ọ̀pá afẹ́fẹ́ gáàsì bẹ́ lópópónà márosẹ̀ Ibadan sí Eko
Oríṣun àwòrán, LASEMA
Iroyin ti jade bayii wipe ajọ to n ri si iṣẹlẹ pajawiri ni ipinlẹ Eko, LASEMA ti ri ọpa afẹfẹ gaasi to bẹ ni tosii ile iṣẹ iroyin Punch lagbegbe Magboro to wa ni opopona Eko si Ibadan.
A gbọ pe bi ọpa afẹfẹ gaasi naa ṣe bẹ wa latọwọ awọn oṣiṣẹ ileeṣẹ Julius Berger to n ṣiṣẹ ni opopona naa.
Gẹgẹ bi oludari agba ajọ LASEMA ṣe fi sita, nibayii, wọn ti di ọpa naa wọn si ti dena igbokegbodo ọkọ lagbegbe naa torii iṣẹ to n lọ lọwọ nibẹ.
Oríṣun àwòrán, LASEMA
Ṣaaju ni iroyin to n tẹ wa lọwọ bayii n fiye ni pe ọpa afẹfẹ idana gaasi kan ti bẹ lagbegbe Magboro, nitosi ileeṣẹ iwe iroyin Punch lopopona marosẹ Eko si Ibadan.
Ajọ ẹsọ oju popo lagbegbe naa ni awọn oṣẹ ileeṣẹ aṣọna Julius Berger ni wọn bẹ ọpa gaasi naa lasiko ti wọn fi n wa ilẹ lagbegbe naa fun ibudo iṣẹ wọn.
Bi a ṣe n sọrọ yii lilọ bibọ ọkọ lagbegbe na ti wa ni iduro.
Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsèjẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọ
Ọga agba ajọ ẹṣọ oju popo loju ọna naa wa ke sawọn ọlọkọ lati maṣe jaya nitori pe wọn ti kan san akọṣẹmọṣẹ to mọ nipa rẹ lati gbe igbesẹ ti ko ni fi jasi ijamba nla miran ti yoo la ẹmi lọ.
Akọroyin BBC News kan to ti de ibẹ ṣalaye pe iye afẹfẹ gaasi to n fẹ jade nibẹ pọ pupọ, bi awọn alaṣẹ ko ba si gbe igbesẹ to ba tọ ni kiakia, afaimọ ki ijamba nla o maa waye nibẹ.
Oríṣun àwòrán, LASEMA
Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn...
Florence sọrọ nipa gbigbe lagboole ti ero pọ si ati iṣoro rẹ fun ẹni to n woju Oluwa
"Florence Onwuasoanya ni abiyamọ to sọ ohun ti oju rẹ ri to lọwọ ẹjẹ ti oloyinbo n pe ni "" Rhesus Negative"" ni eyi to fi n sunkun asunrin."
Agboole nibi ti awọn obinrin bii meje si mẹjọ ti jọ n loyun lasiko kan naa ni Florence n gbe.
Pẹlu omije kikoro ati si ọpẹ Florence sọ nipa irinajo aye rẹ ati igbiyanju gbogbo to ṣe lati ri ọmọ gbejo gẹgẹ bii alaaye.
O ni: Gbogbo èèyàn lo n gbe ọmọ wale lẹ́yìn ibimọ ṣugbọn irinajo tèmi ko ri bẹ́ẹ̀.
Ilé mi túká, àyọ mi sọnù, ìdúnnú dàwátì, ọkọ pè mi ní àgbàná, ará ilé pè mi ní emere, Ogbanje nítorí ọmọ bíbí
Arabinrin Olufunlayo Banire to jẹ oludasilẹ ajọ to n pese iranlọwọ nipa Rhesus naa ba BBC sọrọ lori koko yii ati ipenija rẹ fun obinrin,
O gba ijọba Naijiria ni imọran lati pese abẹrẹ to yẹ lọfẹẹ fawọn obinrin.
Florence fi orin ọpẹ si Oluwa pari rẹ pe lẹyin igbesẹ to yẹ oun pada bi ọmọkunrin lantilanti to ti pe ọdun mẹwaa bayii ki eledumare baa woo ni awoye.
Ma ṣe ro ara rẹ pin ṣugbọn wa imọ kun imọ lori ohun to ba n yọ ẹ lẹnu gẹgẹ bii obinrin.
Covid 19 Palliative: Mínísítà dèrò àgọ́ ọlọ́pàá nítorí ẹ̀sùn kíkó owó ìrànwọ́ Covid-19 sápò
Oríṣun àwòrán, NCDC/Twitter
Mínísítà dèrò àtìmọ́lé lẹ́yìn tí wọ́n fẹ̀sùn kàn án pé ó lu owó ìrànwọ́ Covid-19 ní pónpó.
Minisita kan ti dero atimọle ni Indonesia lẹyin ti wọn fẹsun kan pe o gbọna ẹburu ji owo iranwọ Covid-19.
Wọn ti fi panpẹ ofin mu minisita to n ri si ọrọ awujọ ni Indonesia lẹyin ti wọn fẹsun kan pe o gba riba $1.2 miliọnu lori owo iranwọ ounjẹ fun awọn ti Covid-19 ṣakoba fun.
Wọn fẹsun kan Juliari Batubara lẹtin ti awọn ọlọpaa ṣawari orisiriṣi apo ti owo ọhun wa ni ikawọ rẹ.
Oríṣun àwòrán, others
Lẹyin naa lo lọ fa ara rẹ le ọlọpaa lọwọ, eyii to mu ko jẹ ẹni keji ti aje iwa ibaje yoo ṣi mọ lori ninu ijọba Aarẹ Joko Widodo laarin ọsẹ diẹ sira wọn.
Nigba to n sọrọ lori ẹsun ti wọn fi kan minisita naa, Aarẹ Widodo sọ pe oun ko ni bo aṣiri ẹnikẹni ti wọn ba ka iwa ibajẹ mọ lọwọ.
Akomolede ati Aṣa: Mọ̀ síi nípa ìró afárànma àti agbárànmọ́ fáwẹ́ẹ̀lì Yorùbá
Ṣaaju ni eto ọrọ aje Indonesia ti dẹnu kọlẹ nitori ajakalẹ arun Covid-19 to n ba gbogbo agbeye finra.
Lara ẹsun ti wọn fi kan Batubara ni pe o gba owo to le ni miliọnu kan dollar lọwọ awọn agbaṣẹṣe meji ti ijọba gbeṣẹ fun lati pese ounjẹ fun awọn ti arun Covid-19 ṣakoba fun eto ọrọ aje wọn.
Wọn ni minisita naa n gba nnkan bii ẹgbẹrun mẹwaa owo orilẹ-ede ọhun lori ounjẹ ti eeyan kọkan n gba lati ọdọ ijọba.
To ba jẹbi ẹsun ti wọn kan, o ṣeeṣe ko lọ sọgba ẹwọn fun nnkan bii ogun ọdun tabi ko san biliọnu kan owo orilẹ-ede ọhun gẹgẹ bii owo itanran.
Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsèjẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọ
Abiola Ajimobi: Tinubu ní àwọn ìpínlẹ̀ ló yẹ kó máa gba owó orí ọjà
Oríṣun àwòrán, @AsiwajuTinubu
Laarin oniruuru wahala to n ranju mọ eto abo ni Naijiria, aṣiwaju ẹgbẹ oṣelu APC, Bọla Ahmed Tinubu ti pe fun agbekalẹ ọlọpaa agbegbe ati ipinlẹ.
Aṣiwaju Tinubu ni asiko ti to bayii lati gbe ọlọpaa agbegbe kalẹ gẹgẹ bi ọna ati mu ki eto abo wa fun tẹru-tọmọ laisi pe araalu n kọ iha kokanmi si abo layika ati orilẹede wọn.
Bakan naa lo tun pe fun mimu adinku ba agbara to wa ni ijọba apapọ, ki idagbasoke le de ba awọn ipinlẹ atijọba ibilẹ.
Oríṣun àwòrán, Instagram/abiolaajimobi
Oloye Tinubu yannana ọrọ yii ninu ọrọ to fi ranṣẹ sibi apero ọlọdọọdun ti wọn fi sọri oloogbe Abiọla Ajimọbi, eyi to waye nilu Ibadan.
Agba oṣelu naa ni o yẹ ki ojuṣe gbigba owo ori lori ọja (Stamp duty) ati ibudo igbafẹ (Tourism tax) jẹ ohun tawọn ijọba ipinlẹ yoo maa gba.
Lara awọn to wa nibi apero ọlọdọọdun ti Abiola Ajimobi naa ni Ọọni ile Ifẹ, Ọba Adeyẹye Ogunwusi ati Gomina Dapo Abiodun tipinlẹ Ogun.
Oríṣun àwòrán, Instagram/abiolaajimobi
Awọn yoku ni Gomina Abdulahi Ganduje ti Kano, Gomina Kayode Fayemi ti Ekiti, Gomina Rotim Akeredolu ti Ondo ati Oloye Bisi Akande.
Bakan naa ni  Dokita Obafemi Hamzat, tii se igbakeji Gomina ipinlẹ Eko, Oloye Adebayo Adelabu, Ọmọwe Onikepo Akande, ati adele giwa fasiti Ibadan, Ọjọgbọn Babatunde Ekanọla ko gbẹyin nibi eto idanilẹkọ naa.
Muhammadu Buhari: PDP ṣàlàyé àwọn ẹ̀ṣẹ̀ ààrẹ bó ṣe ń ṣàjọyọ̀ ọ̀jọ́ ìbí
Oríṣun àwòrán, Facebook/Femi Adesina
Ẹgbẹ oselu PDP ti fi ọrọ iyanju ransẹ si aarẹ Muhammadu Buhari ni ayajọ ọjọ ibi ọdun kejidinlọgọrin to ko l'Ọjọbọ.
Atẹjade kan ti ẹgbẹ oselu PDP fisita lọjọ ayajọ aarẹ naa wa kesi Buhari lati tete wa aforijin lọwọ awọn ọmọ orilẹede yii dipo ko maa se ajọyọ ọjọ ibi.
PDP ni aarẹ sẹ awọn eeyan ẹkun iwọ oorun Naijiria pupọ, boya Ọlọrun si da si lati se ọjọ ibi ọdun kejidinlọgọrin ni, ko ba le ni anfaani lati ronu nipa awọn asise rẹ, ko si ronu piwada.
Atẹjade ẹgbẹ oselu PDP naa, ti akọwe ipolongo ẹgbẹ fun ẹkun iwọ oorun guusu, Lere Olayinka fọwọsi, wa mu wa siranti nipa ohun ti Buhari se awọn eeyan ẹkun iwọ oorun Naijiria.
Oríṣun àwòrán, Facebook/Femi Adesina
Aarẹ Buhari, nigba to jẹ olori Naijiria labẹ ijọba ologun, da ọkan awọn eeyan ẹkun naa laamu, to si tun kẹyin si ẹkun yii lasiko to jẹ alaga igbimọ apo asunwọn ẹdawo epo rọbi, PTF lasiko ijọba Sani Abacha.
O fikun pe ẹsẹ ti Buhari sẹ awọn eeyan ẹkun iwọ guusu Naijiria julọ ni bo se wọgile oju ọna ọkọ ayarabiasa ti wọn pe ni Metroline, tijọba Lateef Jakande gbe kalẹ.
"Isẹ lila oju ọna Metroline ti Buhari wọgile naa lo jẹ adanu fawọn eeyan ipinlẹ Eko, eyi towo rẹ to miliọnu lọna mejidinlọgọrin Dọla.
Oríṣun àwòrán, Facebook/Femi Adesina
To ba jẹ pe Buhari ko wọgile akanse isẹ oju ọna naa ni, sunkẹrẹ fakẹrẹ ọkọ to n lu igboro ilu Eko pa bayii ko ba ti waye, ti irọrun ko ba si bawọn olugbe Eko nidi igbokegbodo ọkọ."
Ẹgbẹ oselu PDP wa ki aarẹ Buhari ku oriire ọjọ ibi ọdun kejidinlọgọrin to ko, ti wsn si dupẹ lọwọ Ọlọrun pe o mu aarẹ se ọjọ ibi ọdun yii.
Oríṣun àwòrán, Facebook/EFCC
Ọwọ awọn agbofinro EFCC ti tẹ alfa kan torukọ rẹ n jẹ Jamiu Isiaka, to sọ ara rẹ di ọga ti n gba aṣọ alaṣọ bora nipa pipe ara rẹ ni alukoro fun aarẹ Buhari, Fẹmi Adeṣina.
Lati ipasẹ fifi ara ẹni pe ẹlomiran yii, lo ti lu oyinbo Koraa kan ni jibiti owo to to Ọgbọn miliọnu naira niye.
Bakan naa ni Alfa Jamiu tun dibọn pe oun ni oludari agba tẹlẹ fun ileeṣẹ ipọnpo rọbi orilẹede Naijiria, NNPC, lati ṣe gbajuẹ fun oyinbo Koraa naa.
Nigba ti wọn n foju rẹ han faye ri,  EFCC ni oniruuru ọgbọn arumọjẹ ni Jamiu ti fi gba oyinbo Koraa naa, ti orukọ rẹ n jẹ, Keun Sig Kim lati orilẹede South Korea.
Oríṣun àwòrán, Instagram/EFCC Nigeria
Jamiu ni oun fẹ ba eebo Kọraa naa gba aṣẹ lọwọ ajọ elepo rọbi NNPC, lati maa ra epo rọbi ni Naijiria.
Nigba ti wọn bii, Afaa Jamiu ni gbogbo owo ti oun gba lọwọ arakunrin naa, ẹbọ ati etutu ni oun fi ṣe fun un.
O ni ẹyẹ igun, awọ erin, ifun erin, ori ẹkun ati ẹdọ inaki loun fi owo gbajuẹ ọhun ra.
Akomolede ati Aṣa: Mọ̀ síi nípa ìró afárànma àti agbárànmọ́ fáwẹ́ẹ̀lì Yorùbá
Amọṣa EFCC ni iwadii awọn fihan pe, ile nla ni Afaa Jamiu kọ silu Ilọrin lara owo to gba lọwọ oyinbo Koraa, Keun Sig Kim.
Ni ọjọ kẹrinla oṣu kẹfa ọdun 2019, ni ajọ EFCC kọkọ fi oju Afaa Jamiu ba ile ẹjọ lori ẹsun mẹrin ọtọọtọ to nii se pẹlu iwa gbajuẹ ati jibiti lilu.
Muhammadu Buhari: Femi Adesina tọ́ka sáwọn ẹ̀rí pé kìí ṣe ẹ̀dà ààrẹ ló ń darí Nàíjíríà
Oríṣun àwòrán, @MBuhari
Kii se ohun tun mọ pe ki asaaju ikọ IPOB, Nnamdi Kanu ati awọn ọmọ Naijiria kan maa pe aarẹ orilẹede yii, Muhammadu Buhari ni ẹda eniyan.
Koda wọn ni kii se Buhari ti awọn dibo fun lo wa lori aleefa amọ o ti ku lasiko to se aisan, to si lọ gba iwosan nilu London lọdun 2017.
Kanu ni wọn ti fi ọkunrin kan, to pe orukọ rẹ ni Jubril lati orilẹede Sudan, rọpo aarẹ Naijiria to ni o ti di oloogbe ọhun.
Koda Kanu fi ọwọ sọya pe, oun ni awọn ẹri aworan to daju lọwọ lati fidi rẹ mulẹ pe, ẹlomiran lo n dari ijọba Naijiria, kii se Buhari.
Oríṣun àwòrán, @MBuhari
Sugbọn niwọn igba to se pe isọrọ ni igbesi, idi ree ti olugbanimọran fun aarẹ lori eto iroyin, Femi Adesina fi bọ sita lati sọrọ nipa iroyin to n ja rainrain nilẹ naa.
Adesina, ninu ọrọ kan to kọ ni ayajọ ọjọ ibi ọdun kejidinlọgọrin aarẹ Muhammadu Buhari salaye pe, aarẹ kii se ẹda rara, oun gan si ni, wọn ko fi ẹlomiran se rara.
Amugbalẹgbẹ fun aarẹ, ẹni to foju laifi wo ọrọ ti Kanu n gbe kiri yii, tun se apejuwe ọrọ naa bii ero awọn omugọ, eyi ti ọpọ ọlọgbọn gan tun n gba a gbọ pẹlu.
Oríṣun àwòrán, Facebook/FemiAdesina
Femi Adesina wa tọkasi awọn ẹri kan to fidi rẹ mulẹ pe wọn ko fi ẹlomiran rọpo aarẹ Buhari rara, oun fura rẹ lo n dari ijba Naijiria.
"Ni ọjọ ti aarẹ gunlẹ sorilẹede Naijiria lati London to ti lọ gba iwosan, ọjọ naa ni olori ẹka alaabo ilẹ wa, Ọgagun Abayomi Olonisakin n fi ọmọbinrin rẹ lọkọ.
Oríṣun àwòrán, @MBuhari
Mo wọ agbada ati fila, tii se asọ ibilẹ wa lọ sibi igbeyawo naa, nibẹ si ni mo ti lọ pade aarẹ Buhari ni papakọ ofurufu.
Gbogbo wa to lori ila lati ki aarẹ kaabọ, ti oun naa si n bọ wa lọwọ ni ẹyọ kọọkan, nigba to de iwaju mi lo ni 'Adesina, igba yii ni maa ri ẹ fun igba akọkọ to wọ asọ to dara julọ'."
Adesina ni awọn mejeeji ku silẹ fun ẹrin, tawọn ayaworan si ya awọn, eyi ti wọn lo lori mohunmaworan, ti ọpọ eeyan si n bi ohun leere pe ki lo mu ki awọn mejeeji rẹrin arintakiti bẹẹ.
Oríṣun àwòrán, @MBuhari
"Adesina wa n bi awọn eeyan to n siyemeji nipa Buhari pe ""Se ti kii ba se aarẹ lo n ba oun sọrọ, bawo ni yoo se mọ orukọ oun, ti yoo si tun mọ pe oun kii saba wọ asọ agbada?"""
Bakan naa ni Adesina mu wa si iranti pe akọroyin kan wa, Lindasay Barret to jẹ ọrẹ ọlọjọ pipẹ fun Buhari, to si ran oun lati ki aarẹ fun oun.
"O ni bi oun se n fi isẹ ikinni Barret jẹ fun aarẹ Buhari lo fesi pada pe ""Lindasay Barret, mo ranti pe emi ati ẹ pade loju ogun lọdun 1968."
Oríṣun àwòrán, @MBuhari
Se to ba jẹ Jubril ti Sudan ni, se yoo ranti ọrẹ rẹ ati ibi ti wọn ti pade loju ogun lọdun 1968, ẹ gbe irọ da sọhun, ko jẹ wa.
Amugbalẹgbẹ fun aarẹ wa kadi ọrọ rẹ nilẹ pe ololufẹ Naijiria ni aarẹ Muhammadu Buhari, ti oun si mọ ọbuda ati isẹ rere rẹ daradara.
Funke Akindele: Bukunmi Oluwasina ní ọ̀kan lára àlá òun ló wá sí ìmúṣẹ
Oríṣun àwòrán, Instagram/funkejenifaakindele/bukunmioluwasina
Yoruba ni inu ẹnu kii dun, ka pa a mọra.
Idi ree ti gbajumọ osere tiata lobinrin kan, Bukunmi Oluwasina fi n se jaginni yodo si oore nla kan to wọle tọọ.
Bukunmi, ẹni ti inu rẹ dun dẹyin lori oore naa, ti ko si le e pa a mọra, lo bọ soju opo Instagram rẹ lati kede nipa ifa to wọle tọ ọ fun araye.
'Pásítọ̀ ló sọ fún mi pé Ọlọ́run pè mí láti di Olokun tó ń bọ omi'
Ki ni Funke Akindele se fun Bukunmi to fa ariwo?
Bukunmi kọ soju opo ayelujara rẹ naa pe gbju-gbaja osere tiata kan, Funke Akindele ti ransẹ si oun , eyi to mu ki inu oun dun kọja aala.
Bukunmi ni pẹlu isẹ ti Funke Akindele ke si oun yii, o daju pe oun ti se oriire nile aye oun.
Ìjẹ̀bú: Àgbàlàgbà ni mo máa ń ṣe nínú eré tẹ́lẹ̀
Osere tiata naa wa sọ fun awọn ololufẹ rẹ naa pe ko le ye wọn idi ti oun fi n fo fayọ lori isẹ toun gba latọdọ Funke Akindele, oloye ni ọrọ naa yoo ye.
Bukunmi tun fikun pe ọkan lara ala ọjọ pipẹ oun, lo wa si imusẹ wẹrẹ yii, to si seese ko jẹ pe osere-binrin naa ti n da ọfun tolo lati kopa ninu ere tiata pẹlu Funke Akindele tii se agba ọjẹ ninu isẹ naa.
Bukunmi Oluwasina, to sẹsẹ se igbeyawo laipẹ yii, wa ke sawọn ololufẹ rẹ, lati ba ke Halleluyah, nitori oun n jo kiri inu ile ni pẹlu isẹ ayọ ti oun gba naa lọdọ Funke.
Bi o tilẹ jẹ pe ko sẹni to le sọ iru isẹ ti Funkẹ ran si ọdọmọbinrin osere tiata naa to fi n fo fayọ, sibẹ, Bukunmi naa ko se alaye iru oore to jẹ ninu ọrọ rẹ.
Oríṣun àwòrán, Instagram/bukunmioluwasina
Sugbọn ọpọ eeyan lo n kede pe, ifa to wọle tọ Bukunmi yii ko lee kọja pe Funke Akindele ke si lati wa kopa ninu isẹ tiata kan, eyi to le mu owo nla wọle fun.
Wayi o, awọn ololufẹ Bukunmi lo ti n ki ku oriire lori isẹ ti Funke Akindele, ti ọpọ eeyan mọ si Jenifa, ran si ọhun, ti wọn si tun n ba dupẹ lọwọ osere-binrin naa pe o ku ọmọ se.
Oríṣun àwòrán, Instagram/funkejenifaakindele
Ọpọ awọn eeyan to ba Bukunmi yọ si lo tun n ke si Jenifa lati ran isẹ ayọ si awọn naa, paapaa lasiko ọdun Keresimesi yii, kawọn pẹlu le maa jo kiri ka inu ile.
Lamidi Adedibu: Èyí ní àlàyé bí akọni olóṣèlú nílẹ̀ Ibadan ṣe sẹ̀ wá
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Wọ́n ti sàpèjúwé Lamidi Adedibu gẹ́gẹ́ bi ojúlówó ọmọ Iba Oluyole, ọ̀kan pàtàkì lára àwọn tó jàjà òmìnira nílẹ̀ Ibadan.
"Nínú ìwé ti wọ́n pe àkọle rẹ̀ ni ""Adedibu the Strongman and Generalissimo of Nigeria Politics"" èyí ti Hazeem Gbolarunmi àti olóyè Lekan Saka jìjọ kọ, ni ọ̀rọ̀ yìí ti jẹyọ."
Ìwé náà sọ nípa ìgbé aye gbajúgbajà olóṣèlú Ibadan náà, ti àwọn ọmọ àti olùgbé Ibadan ko le gbàgbé ipa tó kó nínú ètò òṣèlú.
Wọ́n ni yàtọ̀ si àwọn igbésẹ̀ akin tó gbé, àwọn ènìyàn kò le gbàgbé bi àwọn jànduku ṣe pọ̀ tó lásìkò rẹ̀ àti àwọn ìwà ìbàjẹ́ míràn tó jẹyọ nílùú Ibadan àti ni ìpińlẹ̀ Oyo lápapọ̀, lasiko aye oloogbe naa.
Zlatan: Ọ̀rẹ́ ni mo sìn lọ ‘studio’ tí mo fi bẹ̀rẹ̀ orin lẹ́yìn tí mo kùnà ìdánwò WAEC
Ẹ̀wẹ́, òǹkòwé náà sàlàyé pé, Adedibu fi ìwà jọ akọni lójú ogún ilẹ ìbàdan kan, ti orúkọ rẹ̀ tàn ká ilé, tàn ká oko, eyiun Iba Oluyole.
Oluyole jẹ adarí àwọn ọmọ ogun Ibadan, tí ìwà adarí rẹ si jẹ èyí tí ìlú ń fẹ́.
Ilé Olukuoye ni Oluyole ti wa, láti ara ọmọba Agbonyin to jẹ ọmọ aláàfin Abiodun, ẹni tii se Alaafin to jẹ́ pé oun níkan lo bori Basorun Gaa lásìkò Oyo atijọ.
Omolola Arohunmolase Welder: Mo ti fí iṣẹ́ 'Welder' gbayì láwùjọ, tó mo fi tọ́ ọmọ yanjú
Oluyole si tun jẹ ọkan lára àwọn tí wọ́n ń wò bí ẹni to gbé ilẹ̀ Ibadan ró.
Gẹ́gẹ́ bi Oluyole, ile Olupoyi ni Adedibu naa ti wa ni Oja-Oba Ibadan sùgbọ́n ó tan mọ́ Oluyole lati ilé ìyá rẹ̀.
A bí Adedibu ni ọjọ́ kẹrinlélógún, oṣù kẹwàá ọdun 1927 ni Oja -Oba Ibadan, ó jẹ́ ọkan lára to wá láti ilé tó ń joyè Olupoyi, tí a si le tọ ìràn rẹ̀ si Iba Oluyole.
Oríṣun àwòrán, Obasanjo Foundation
Lai si ti Adedibu ẹgbẹ oṣelu PDP ki ba maa ti ni Gomina lasiko isejọba mi.
Ọrọ iranti ree ti aarẹ ana, Olusegun Obasanjo fi ṣapejuwe agba ọjẹ oloṣelu ipinlẹ Oyo nni, Lamidi Adedibu, se arise ni arika.
"Obasanjo fi ọrọ yii lelẹ lasiko ifilọlẹ iwe kan ni iranti Adedibu, ti wọn pe akori rẹ ni ""Adedibu The Strongman and Generallisimo of Nigerian Politics: An X-ray of the Political Life of a Colossus"","
Ni gbọngan Trenchard ninu ọgba fasiti Ibadan ni aarẹ Obasanjo ti sọrọ naa, to si ni Adedibu ṣe bẹbẹ lasiko igbe aye rẹ.
Gẹgẹ bi o ti ṣe sọ, o ni 'Adedibu fi ipa manigbagbelelẹ lagbami oṣelu ilẹ kaarọ o jiire.
Baruwa Gas Explosion: Àwọn tó forí sọta ìjàmbá iná ń bẹ ìjọba láti dìde ìrànwọ́
''Mo ranti igba ti ọrọ pa wa pọ, to sọ fun mi pe oun dije lọdun 1954 pẹlu baba ẹni to fẹ du ipo Gomina lọdun 2003. Ile iwe girama ni mo wa ni igba naa''
''Lai si ti Adedibu, oludije fun ẹgbẹ oselu PDP ko ba maa le wọle ibo lati di Gomina lọdun 2003, nigba ti mo jẹ aarẹ Naijiria.
Nigba ta n wi yii, mo lọ ba Alagba Emmanuel Alayande to si sọ fun mi pe, ẹni to n du ipo Gomina ko kunju oṣunwọn''
Bo ti lẹ jẹ wipe Obasanjo ko darukọ ẹni naa, Gomina tẹlẹ ri, Rasidi Ladoja lo jẹ oludije ẹgbẹ PDP nigba naa, to si pada wọle si ipo Gomina.
Ladoja
Lakotan ọrọ rẹ, Obasanjo sọ pe oun lọ si ọdọ Adedibu to si ni lootọ lọrọ ti Alayande sọ.
Obasanjo tẹsiwaju pe, oun beere pe bawo ni ẹni ti ko kunju osunwọn yoo ṣe wọle ibo Gomina.
Ni idahun si ibeere yii, Adedibu ni to ba fẹ ki awọn jẹ ko ṣeeṣe, yoo wọle ibo naa.
''Mo sọ fun Adedibu pe ko jẹ ki o ṣeeṣe, ababọ rẹ ni gbogbo wa pada ri wi pe PDP wọle Gomina''.
Oríṣun àwòrán, Obasanjo/instagram
Ààrẹ àná lórílẹ̀-è[de Nàìjíríà Olusegun Aremu Obasanjo ni ipa pàtàkì ni ọ̀rọ̀ ọlórí àti àwọn adarí lórílẹ̀-èdè Nàìjíríà ni láti kó kí wọ́n tó borí ètò ààbò tó mẹ́hẹ, ètò ọrọ̀ ajé tó dojúdé àti ètò òṣèlú ti kò rọgbọ̀.
Obasanjo n sọ̀rọ̀ lásìkò àbẹ̀wò rẹ sí gómìnà ìpińlẹ̀ Oyo, Seyi Makinde nílùú Ibadan, ní bi tó ti sàlàyé pé, ìfọwọ́sowọ́pọ̀ ará ìlú gan ṣe pàtàkì láti mójútó ìṣòrò  tó wà nílẹ̀.
O ní gbogbo rògbòdìyàn tó n ṣẹlẹ̀ nílùú kìí ṣe tuntun bákan náà ni kìí ṣe ìṣòro tí kò ṣee bori, sùgbọ́n ó nílò ìfowọ́sowọ́pọ̀ àwọn ará ìlú bákan náà ni ìfarajì àwọn olórí.
Ìsòro tó bá de ba ọmọ ènìyàn , ènìyàn náà ni yóò yanju rẹ̀ Ó yẹ ki gbogbo ènìyàn fọ́wọ́sowapọ̀, bákan náà ni ó yẹ kí àwọn olórí dìde gírí láti mú ìsopọ̀ àwọn ènìyàn  wáyé.
Lásìkò àbẹwò Obasanjo si ẹbi Abiola Ajimobi, gómìnà àná ní ìpínlẹ̀ Oyo tó d'ológbèé lọ́jọ́sí, ni gómìnà Seyi Makinde ti gbaa ààrẹ àná lálejò.
Oríṣun àwòrán, Obasanjo/instagram
Nínú ọ̀rọ̀ Makinde ló ti sàlàyé fún ààrẹ àná pé, ipasẹ̀ rẹ̀ ni òun ń tọ ní ìpínlẹ̀ Oyo pàápàá jùló nínú isẹ́ ọgbìn.
Makinde ni, èyí ni láti mu ìdàgbàsókè bá igun mẹ́rẹ̀rin ìpińlẹ̀ Oyo  àti pé, òpó mẹ́rìn ní ìpínlẹ̀ Oyo dúró lé lórí. Ètò ẹ̀kọ́, ìlera, ètò ààbò àti ìdàgbàsókè, ètò ọrọ̀ ajé.
Lórí ìpè àwọn ènìyàn pé kí ààrẹ Buhari yọ àwọn ọgagun elétò ààbò nípò, Obasanjo ni òun kọ́ ni òun yàn wọ́n sípò, nítorí náà, òun kò le pè fún ìyọ̀ nípò wọ́n.
Baruwa Gas Explosion: Àwọn tó forí sọta ìjàmbá iná ń bẹ ìjọba láti dìde ìrànwọ́
Ọjọ nla ni Ọjọbọ ọjọ Kẹjọ osu Kẹwa ọdun 2020 ti isẹlẹ ibugbamu to fa ina alagbara waye ni adugbo Baruwa nilu Eko.
Awọn eeyan to fi ori sọta isẹlẹ ọpa gaasi to bẹ, eyi to di ijamba ina naa, ti wa n naka aleebu si ijọba ipinlẹ Eko, ti wọn si n fi ẹsun kan wọn pe o pa awọn ti lai da si awọn mọ.
Awọn eeyan naa ni ẹmi mẹjọ lo sofo sinu isẹlẹ ijamba ina ọhun, ti ile to to aadọta niye si jona kanlẹ lasiko isẹlẹ naa to ba tọmọde-tagba.
Ọkan lara awọn naa to ba BBC Yoruba sọrọ, ẹni to padanu ẹgbọn rẹ obinrin ati ọmọ meji sinu ofo ina ọhun tiẹ mẹnuba awọn ohun ti oju wọn n ri lẹyin ijamba naa.
Bakan naa ni awọn miran tun sọrọ nipa ọpọ eeyan miran to fori sọta ijamba lati ipasẹ ọpa gaasi to bẹ ọhun pẹlu isoro lọkan o jọkan ti wọn n la kọja.
Ko tan sibẹ, wọn tun mẹnuba awọn eeyan miran to fori sọta isẹlẹ naa ati iru ipo ti wọn wa nile iwosan lai jẹ pe ijọba wẹyin wọn wo.
Wọn wa n rawọ ẹbẹ sijọba ipinlẹ Eko lati dide sọrọ naa, ko si se iranlọwọ to tọ fun awọn.
Pierre Buyoya: Coronavirus ni wọn ló pa ààrẹ tẹ́lẹ̀ náà lẹ́ni ọdún 71
Oríṣun àwòrán, AFP
Aarẹ tẹlẹ ni orilẹede Burundi, Pierre Buyoya ti jade laye lẹni ọdun mọkanlelaadọrin.
Mọlẹbi oloogbe naa to fidi isẹlẹ naa mulẹ fun BBC ni Buyoya dagbere faye nilu Paris ni Ọjọbọ lati ipasẹ arun Coronavirus.
Ọgagun to ti fẹyinti naa lo lo ọdun mẹtala lori aleefa lẹyin to fi ipa gba ijọba lọwọ awọn asaaju rẹ.
Ni osu Kẹwa ọdun 2020 ni ile ẹjọ kan nilẹ Burundi ran lẹwọn lai si nibẹ lori ẹsun pe o gba ẹmi aarẹ akọkọ ti araalu dibo yan lorilẹede naa, Aarẹ Melchior Ndadaye lọdun 1993.
Isẹlẹ naa si ni wọn lo sokunfa rogbodiyan to ran eeyan bii ẹgbẹrun lọna ọọdunrun lọ sọrun.
Oríṣun àwòrán, Twitter@Pierre Buyoya
Amọ Buyoya ni oun ko jẹbi ẹsun asemase kankan rara.
Ni osu to kọja ni Buyoya kọwe fipo silẹ gẹgẹ bi asoju ajọ isọkan orilẹede Afirika si ilẹ Sahel pẹlu awijare pe oun fẹ gbajumọ ọna lati wẹ orukọ oun mọ.
Impeached Kenya Governor: Sonko Mbuvi ní àwọn alájẹbánu tóun dí lọ́wọ́ ló yọ òun nípò
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Gomina ilu Nairobi, tii se olu ilu Kenya, Mike Sonko Mbuvi ni wọn yọ kuro nipo lẹyin ti ile asofin agba orilẹede naa fi ontẹ lu iyọnipo tile asofin agbegba se.
Awọn asofin agba naa lo ni Sonko jẹbi ẹsun mẹrin ọtọọtọ ti wọn fi kan, paapaa julọ, iwa titapa si ofin, asilo ipo, hihu iwakiwa atawọn iwa ọdaran miran labẹ ofin.
Lara awọn ẹsun tawọn asofin ilu Nairobi fi kan gomina Sonko ni pe o lo owo ilu lati ran ọmọbinrin rẹ lọ silu New York lorilẹede Amerika lọdun 2018.
Bakan naa ni wọn lo tun se owo iranwọ eto ẹkọ fawọn ọmọ mẹkunnu nilu Nairobi basubasu.
Sonko ni ọpọ eeyan mọ bii ẹni to n gbe igbe aye olowo nla nipa wiwọ asọ ati goolu olowo iyebiye amọ gomina tẹlẹ naa ti sẹ lori awọn ẹsun ti wọn fi kan.
Baruwa Gas Explosion: Àwọn tó forí sọta ìjàmbá iná ń bẹ ìjọba láti dìde ìrànwọ́
Sonko ni awọn eeyan to kundun kiko owo ilu jẹ nilu Nairobi ti oun da lọwọ kọ nidi iwa ajẹbanu lo n ba oun ja lati ri ẹyin oun.
Kii se igba akọkọ ree ti ẹnu yoo kun Sonko nitori ẹnu kii sin lara rẹ. Awọn alasẹ ọgba ẹwọn lorilẹede Kenya fi ẹsun kan gomina ti wọn yọ nipo naa pe o sa kuro lọgba ẹwọn logun ọdun sẹyin.
Bẹẹ si ni Sonko gba pe lootọ ni oun sa kuro lọgba ẹwọn lasiko ifọrọwanilẹnuwo kan lori mohunmaworan.
Osu Kejila ọdun 2019 si ni wọn tun mu sahamọ pe o lọwọ ninu iwa ajẹbanu.
Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsèjẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọ
Gomina tẹlẹ naa lo fi ọpọ igo ọti lile Hennessy sinu apo imọtoto fun arun Coronavirus ti wọn n pin fawọn olugbe ilu Nairobi, to si ni ọti lile naa le dena arun Covid-19.
Sonko ni gomina keji to wa lori oye ti wọn yoo yọ nipo lori awọn ẹsun asemase.
Ireti si wa pe awọn eeyan ilu Nairobi yoo seto idibo miran lati yan gomina tuntun laarin osu meji niwọn igba ti Sonko ko ni igbakeji.
Zlatan: Ọ̀rẹ́ ni mo sìn lọ ‘studio’ tí mo fi bẹ̀rẹ̀ orin lẹ́yìn tí mo kùnà ìdánwò WAEC
Yoruba ni ori lo mọ ọlọla, ko si si ẹni to le sọ ori olowo lọla.
Omoniyi Temidayo Raphel, ti ọpọ eeyan mọ si Zlatan Ibile lasiko to n ba BBC Yoruba sọrọ ti ni oun ko mọ pe oun le di gbajumọ bayii nidi orin kikọ.
Akọrin takansufe naa, to ni wura ni itumọ orukọ inagijẹ Zlatan ti oun n lo, tun ni ọrẹ ni oun sin lọ si gba orin silẹ, ki wọn to ni ki oun naa wa kọrin.
Zlatan ni lootọ ni oun ti n kọrin lati ile ẹkọ girama ti oun si jẹ ẹbun ọkọ ayọkẹlẹ eyi to jẹ ki oun di ẹni akọkọ ti yoo lo ọkọ ninu idile oun.
Gbajumọ akọrin takansufe naa, to ni ẹmi lo maa n gbe ọpọ orin ti oun n kọ wa, tun fikun pe bọọlu lo wu oun lati gba, ka ni oun ko mọ orin kọ.
Nigba ta ni ko gba awọn ọdọ to n lu jibiti nidi isẹ yawuu nimọran, Zlatan ni ojuse obi wọn ni lati gba wọn nimọran, kii se isẹ toun.
Ọrọ pọ ti Zlatan ba BBC Yoruba sọ, ẹ mọ salai wo fidio yii fun ẹkunrẹrẹ iroyin.
Omoyele Sowore: Ẹgbẹ́ aṣòfin Amẹ́ríkà ní ìjọba ń tẹ ẹ̀tọ́ olùdíje ààrẹ́ tẹ́lẹ́ náà lóju
Oríṣun àwòrán, @YeleSowore
Ẹgbẹ awọn agbẹjọro ni orilẹede Amẹrika ti kesi ijọba ilẹ wa pe ko tu eekan lẹyin ọrun oludije tẹlẹ fun ipo aarẹ, Omoyele Sowore.
Ẹgbẹ naa ni ijọba ko ni ẹri to daju rara lati ba oludije aarẹ tẹlẹ naa se ẹjọ lori ẹsin idaluru ti wọn fi kan.
Bẹẹ ba gbagbe, Sowore ni ọwọ awọn agbofinro tẹ lọjọ Kẹta osu Kẹjọ ọdun 2019 lori ẹsun o n gbidanwo lati se iwọde kan to pe Revolution Now.
Iwọde naa si ni Sowore lo wa lati tako eto isejọba ti ko mọyan lori atawọn iwa aidaa miran ni Naijiria.
Lẹyin naa ni ijọba gbe asaaju ẹgbẹ Revolution Now ọhun lọ sile ẹjọ lori ẹsun pe o gbimọ lati da omi alaafia Naijiria ru to fi mọ lilu jibiti ati tita abuku aarẹ Muhammadu Buhari.
Oríṣun àwòrán, @YeleSowore
Amọ ẹgbẹ Amofin Amẹrika ni iti ọgẹdẹ ni awọn ẹsun ti wọn fi n kan Sowore ọhun, ko si to ohun to yẹ ki ijọba apapọ yọ ada si.
Wọn ni pipe fun iwọde alaafia kii se ete lati dijẹ gbajọba, bẹẹ si ni ẹjọ ti wọn n ba Sowore se ti tako ẹtọ to ni labẹ ofin lati sọ ohun to ba wu, pipejọ sibi to wu ati ẹtọ si igbẹjọ lai fi falẹ.
Zlatan: Ọ̀rẹ́ ni mo sìn lọ ‘studio’ tí mo fi bẹ̀rẹ̀ orin lẹ́yìn tí mo kùnà ìdánwò WAEC
Ẹgbẹ naa wa n rọ awọn agbofinro lorilẹede naijiria ati ijọba apapọ lati fi Sowore lọrun silẹ nitori awọn ẹri ti wọn ko jọ ko lẹsẹ nilẹ lati ba se ẹjọ.
Risikat Azeez: Kaosarat àti Hassanat gba ẹ̀bùn ẹ̀kọ́ ọ̀fẹ́ ₦1.5m ẹnì kọ̀ọ̀kan lọ́dún
Oríṣun àwòrán, Mofe Bamuyiwa
Bi ori ba pẹ titi nilẹ, yoo pada di ire ni, ori ẹni si ni gbe alawore ko ni.
Ojo iranlọwọ to n rọ fun tọkọ taya Risikat ati Abdulwasiu Dada, ti iyawo rẹ jẹ oloju buluu ko tii dawọ duro.
Idi ni pe oore ọtun miran tun sẹsẹ wọle tọ idile naa ati awọn ọmọ wọn wa ni.
'Pásítọ̀ ló sọ fún mi pé Ọlọ́run pè mí láti di Olokun tó ń bọ omi'
Bẹẹ ba gbagbe, iroyin gbalẹ ni osu kẹjọ ọdun 2020 nipa arabinrin Risikat, ti ọkọ rẹ Abdulwasiu le jade pẹlu ọmọdebinrin meji nitori pe tiya tọmọ ni oju buluu.
Ni kete ti iroyin naa jade sita, ni ọgọọrọ ọmọ Naijiria dide tako igbesẹ naa, ti aya gomina Kwara naa si da sọrọ wọn.
Lẹyin osu diẹ ti ọrọ naa ja rain-rain wọn pada so yigi fun tọkọ taya naa, ti aya gomina si gba ile fun wọn pẹlu silu Ilorin lati maa gbe.
Bakan naa ni aya gomina Kwara fi awọn ọmọdebinrin mejeeji naa sile iwe to jẹ ọkan lara awọn ile ẹkọ to dara julẹ ni ipinlẹ Kwara.
Risikat Moromoke Azeez: Inú èmí àti Òbí mi dùn nígbà ti Risi bí ọmọ olójú búlù- Wasiu
Orukọ awọn ọmọdebinrin oloju buluu  naa ni Kaosara ati Hassanat Abdulwasiu.
Amọ akọtun oore to tun wọle tọ idile naa bayii ni ti ẹbun ẹkọ ọfẹ ti oludasilẹ ile iwe wọn fun awọn ọmọbinrin meji ti tọkọtaya Dada bi.
Nigba to n fidi iroyin ayọ naa mulẹ fun BBC Yoruba, ọkọ iya Kaosara oloju buluu, Abdulwasiu ni lootọ ni oriire naa wọle ti idile oun.
O ni iyawo gomina Kwara lo mu awọn ọmọdebinrin naa lọ sile ẹkọ aladani Roemichs International School nilu Ilorin to jẹ olowo nla, eyi ti arabinrin Jumoke Harb da silẹ.
Ìdílé tí ọkọ da ọmọ síta tóríi ojú Búlùú tí wọ́n ní bá BBC sọ̀rọ̀
Gẹgẹ bi iroyin naa ti wi, Kaosara ati aburo rẹ wa lara awọn akẹkọọ mẹfa ti oludasilẹ ile ẹkọ naa, Harb fun ni ẹbun ẹkọ ọfẹ lọjọbọ lasiko ayẹyẹ opin ọdun.
Awọn akẹkọọ ile ẹkọ Roemichs yii ni wọn se idanwo fun lati figa gbaga, ki wọn le mọ akẹkọọ to pegede fun ẹbun ẹkọ ọfẹ naa, ti o to miliọnu kan abọ naira niye fun akẹkọọ kọọkan.
Lẹyin idanwo naa, akẹkọọ mẹrin lo yege lati janfaani eto ẹkọ ọfẹ naa nile ẹkọ girama ati ti alakọbẹrẹ to wa ninu ọgba ile ẹkọ naa
Owo yii si ni yoo gbọ bukata owo ileewe akẹkọọ naa, owo ilegbe, asọ ileewe ati awọn iwe ti wọn yoo lo fun ọdun kan.
Risikat Azeez: Ìyá àti bàbá ọmọ olójú búlù tí parí ìjà- wọ́n fẹ́ tún yìgì so
Nibi ayẹyẹ fifunni lẹbun ẹkọ ọfẹ naa si ni Kọmisana feto ẹkọ nipinlẹ Kwara, Hajia Fatimah Ahmed bawọn peju si.
Ninu ọrọ rẹ, Ahmed wa sapejuwe ileẹkọ Roemichs gẹgẹ bii ile ẹkọ to wa lara awọn ibudo ikẹkọọ to ni akọsilẹ eto ẹkọ to pegedejulọ.
Baba Kaosara, ninu ifọrọwerọ rẹ pẹlu BBC Yoruba lori isẹlẹ yii fi ẹmi imoore rẹ han pupọ fun awọn eeyan to se idile naa laanu.
Zlatan: Ọ̀rẹ́ ni mo sìn lọ ‘studio’ tí mo fi bẹ̀rẹ̀ orin lẹ́yìn tí mo kùnà ìdánwò WAEC
Abdulwasiu Dada wa se adura fun alaanu wọn, to fun awọn ọmọ rẹ mejeeji ni ẹbun ẹkọ ọfẹ naa pe Ọlọrun yoo tubọ maa mu ọwọ rẹ lọ siwaju.
Bakan naa lo gbadura fun aya gomina ipinlẹ Kwara to se alatọna oore naa, pe Ọba Oke yoo fun ni ẹmi gigun ati alaafia, ti wsn yoo si se aseye ti alakan n sepo lori oye.
Oyo 2021 Appropriation Bill: Makinde takú mọ́ àwọn aṣòfin lọ̀wọ̀ pé òun kò fẹ́ ìṣúná gbèsè
Oríṣun àwòrán, Facebook/Seyi Makinde
Yoruba ni ohun ti yoo ba dara nigbẹyin, o lee kọkọ wọ nibẹrẹ.
Bẹẹ ni ọrọ ri lori aba eto isuna ipinlẹ Oyo fọdun 2021, eyi to fa ede aiyede laarin gomina Seyi Makinde ati ile asofin ipinlẹ Oyo.
Bẹẹ ba gbagbe, ọjọ Kẹrindinlọgbọn osu Kọkanla ọdun 2020 ni Makinde gbe aba isuna ọdun to n bọ kalẹ siwaju awsn asofin lati yiiri wo, ki wọn si fontẹ lu.
Apapọ owo aba isuna naa ni biliọnu lọna ọrinlerugba o din mẹwa naira (N266bn), tijọba si n reti abọ ile asofin lori rẹ.
Oríṣun àwòrán, Facebook/Seyi Makinde
Amọ, iwadi BBC Yoruba fihan pe ariwo sọ laarin gomina Makinde ati awọn asofin naa  lẹyin ọjọ diẹ lori aba isuna ọhun.
Idi ni pe iwadi BBC fidi rẹ mulẹ pe ile asofin fi awọn akansẹ isẹ kan sinu aba isuna naa, eyi ti owo rẹ to biliọnu mẹwa naira, ti apapọ owo aba isuna naa si fo soke lọ si biliọnu lọna ọrinlerugba o din meje naira (N273bn).
Sugbọn igbimọ ile asofin to wa feto isuna, ninu awijare rẹ ni, ile ti fi aaye silẹ fun ẹka alasẹ lati gba owoya fi gbọ bukata aba isuna ọhun, eyi to mu ki aba isuna naa ga soke.
Oríṣun àwòrán, Facebook/Seyi Makinde
Ile asofin ni kii se pe awọn de idi fun aba isuna naa, tabi fi owo kun, eyi ti yoo bọ sapo awọn.
Amọ Gomina Makinde la gbọ pe o fi apa janu pe nibo ni oun yoo ti ri alekun biliọnu mẹwa naira lati fi gbọ bukata isuna ọhun lasiko ọda owo to n ba ilẹ wa finra yii.
Gomina Makinde ni oun ko fẹ ki owo isuna ọdun 2021 naa ga soke debi pe yoo nira lati gbọ bukata rẹ, eyi to le mu alekun ba gbese to wa lọrun ipinlẹ Oyo.
Amọ lẹyin o rẹyin, ile asofin ati ẹka alasẹ ipinlẹ Oyo fi ọgbọn agba yanju ede aiyede naa, to si yanju nitubi n nubi.
Zlatan: Ọ̀rẹ́ ni mo sìn lọ ‘studio’ tí mo fi bẹ̀rẹ̀ orin lẹ́yìn tí mo kùnà ìdánwò WAEC
Igun mejeeji si lo pada gba pe ko ni dara ki wọn se agbekalẹ isuna fọdun to n bọ ti yoo nira lati se amusẹ rẹ, tile asofin si yọ owo gbese to ni oun fi sori aba isuna ọhun, eyi to mu ko ga soke.
Lẹyin o rẹyin, ile asofin Oyo fontẹ lu aba isuna ọdun 2021 naa, eyi ti apapọ owo rẹ jẹ biliọnu lọna ọtalerugba naira o le mẹjọ (N268bn).
Dino Melaye Marriage Proposal: Se lóòtó ni sẹ́nátọ̀ Dino Melaye fẹ́ gbé ìyàwò tuntun
Oríṣun àwòrán, Bishopoftruth
Wọ́n ni ọ̀ba kìí wà láì ni olòrì láàfin, sùgbọ́n kìí ṣe ọba aláde tó wà nípò nikan lọ̀rọ̀ yìí bá wí o.
Gbogbo ọkùnrin tó bá ti bàlágà, tó sí lé mu ọwọ́ lọ sẹnu láì woju olójú, náà ni ìyàwó yẹ kó wà lẹ́ẹ̀dẹ̀ rẹ̀.
Ó dàbí ẹni pé, èyí ni ọmọbinrin kan rí tó fi gbà láti di aya lọ́ọ̀dẹ̀ Dino Melaye, tii se gbájúgbaja ṣẹ́nétọ̀ tí àtúndi ìbò Kogi West yọọ kúrò nílé ìgbìmọ̀ asofin l'Abuja laipẹ yii.
'Pásítọ̀ ló sọ fún mi pé Ọlọ́run pè mí láti di Olokun tó ń bọ omi'
Bí wákati díẹ̀ sẹyìn ni ìwé ìpè síbi wẹ̀jẹ-wẹ̀mu àti ayẹyẹ ìgbéyàwó Dino jẹyọ lórí ayélujara, níbi ti wọ́n ti ń pe àwọn ènìyàn sí ilé ìjọsin kan ni àgbègbè Ogudu nípìnlẹ̀ Eko.
Oríṣun àwòrán, Dino/twitter
Ninu iwe ipe sibi ase igbeyawo naa, ni aworan obinrin kan wa, ti orukọ rẹ n jẹ Susu, ẹni to pupa lawọ, to si rẹwa lobinrin.
Fọto Dino ati obinrin naa lo wa lara iwe ipe igbeyawo ọdun, ti wọn ni yoo waye ni ọjọ Satide, ọjọ keji ọdun Keresimesi, eyiun ọjọ kẹrindinlọgbọn osu Kejila ọdun 2020.
Dino Melaye gan ló ké gbàjare síta pé, àyínikè, àti àdàmọndi fọtọ ló jẹyọ lórí ayélujára nítori pé, òun kò mọ ọmọbinrin náà ri.
"Ó ní "" Báwó ni ń o ṣe ṣe ògbẹyàwó nígbà ti kò tíì san owó orí mi"""
Bákan náà ló ké gbàjarè pé, ìwà gbajuẹ 419 ni èyí nítorí pé òun kò mọ obìnrin náà rí débi ti àwọn yóò maa sọ̀rọ̀ ìgbéyàwó.
O ní kóda kó ṣe fíìmú àgbéléwo, irú rẹ̀ kò le wáyé, ko si si ààyè l'ágàbá SDM.
Kíni àwọn ọmọ Nàìjíríà n sọ lórí ọ̀rọ̀ yìí?
Bí àwọn kan ṣe ń kín ọmọbinrin náà lẹ́yìn pé kìí ṣe òní ni Dino Melaye ti mọ pé ọmọbinrin náà nífẹ̀ẹ́ Dino, tìí kìí sì fi pamọ lórí ayélujára, bẹ́ẹ̀ náà ni àwọn míràń sọ pé, ìgbésẹ̀ obìnrin náà kò bójúmu tó.
Bákan náà ni àwọn fótò míràn tó jẹ́ ti ọmọbinrin ọ̀hún àti Dino Melaye tún súyọ lórí ayélujara.
Oríṣun àwòrán, Dino/twitter
Muyiwa Ademola: A ó jọ rọ́ọ̀kì ọdún 2021 papọ̀ ni lágbára Ọlọ́run
Oríṣun àwòrán, authenticmuy
Ilumọka oṣere fiimu Yoruba, Muyiwa Ademola ti fi ọrọ ranṣẹ si àwọn ololufẹ rẹ ati awọn akẹgbẹ rẹ bo tilẹ jẹ pe o ṣi wa nile iwosan.
O fi akoko ikini rẹ́ ki awọn ololufẹ rẹ kuu ọdun Keresimesi o si ni ki wọn ma binu si oun pe kii ṣe ẹbi oun lati ma jade sọrọ si wọn latọjọ yii ṣugbọn ara n fẹ isinmi.
"Muyiwa ni ""ẹ ṣeun fun gbogbo ifẹ ti ẹ fi han si mi, ẹ ṣeun fun adura yin ati ọrọ ikini, mo dupẹ gidi gan""."
'Mo kàn máa ń lọ́ ayẹyẹ kiri torí ijó láì ṣe pé wọ́n pe mí ló sọ mí di DJ olórin Fuji nìkan'
Muyiwa ni oun ṣeleri pe oun yoo to gbera kuro lori akete aisan ti awọn yoo si jọ ṣe igbadun ọdun 2021 papọ.
To fi mọ awọn mọlẹbi rẹ, ọrẹ ati awọn akẹgbẹ rẹ ninu fiimu Yoruba lo ni wọn ṣeun fun gbobo ẹbun, owo, ọrọ ti wọ́n fi ranṣẹ si oun ni ipo ti o wa.
Laipẹ niroyin gbode kan pe  Muyiwa Ademola wa lori akete aisan ti agbẹnusọ rẹ si pada jade wa sọ oju abẹ niko gan lori ohun to ṣẹlẹ.
Awọn ololufẹ rẹ atawọn akẹgbẹ rẹ ti n woye wipe ki lo ṣẹlẹ gangan toripe ọwọ ti wọn n fa diriipu si nile iwosan ni wọn ri wọn ko ri oju rẹ.
Oríṣun àwòrán, authenticmuy
Agbẹnusọ rẹ, Wuraola sọ ninu ifọrọwanilẹnuwo kan pe lootọ ni Muyiwa wa ni ile iwosan to si jẹ wipe wahala iṣẹ ti wọ ọ lara ni.
"O ni ""o kan rẹ ẹ diẹ ni, kii ṣe aarẹ to buru. O kan ti rẹ ara ni. Gbogbo igba lo maa n ṣiṣẹ bii jaki lo ṣe mu ki aarẹ yẹn sinmi si i lara. Torinaa o nilo isinmi ni""."
'Ọ̀lọ́pàá shátà mi láti Mowe dé Magboro dé Shagamu, wọ́n ní ṣé mi ò mọ̀ pé ìjọ́ba ni mo ṣiṣẹ́ fún'
O ni beeyan ba n ṣiṣẹ bii ago ti ko sinmi, yoo pada dẹnukọlẹ ni. Iyẹn lo mu ki Muyiwa Ademola ṣi wa nile iwosan.
A o tii mọ igba ti wọn yoo ni ko maa lọ ile ṣugbọn a o fẹ ko wa nibẹ fun igba diẹ.
Wuraola ni kii ṣe aisan kan to le koko ṣugbọn awọn mọ pe ko ni sinmi to ba de ile tori gbogbo igba lo maa n wa lorii foonu rẹ to n ṣiṣẹ.
Aisan yii kii ṣe eyi to lee la ẹmi lọ, o kan jẹ eyi to maan  da eeyan lagara ni. Kii ṣabaa rẹ Muyiwa tori aṣiṣẹ-bi-ago ni. Wuraola lo sọ bẹẹ.
'Pásítọ̀ ló sọ fún mi pé Ọlọ́run pè mí láti di Olokun tó ń bọ omi'
Loju opo Instagram rẹ, ko fi oju ara rẹ han ṣugbn Muyiwa Ademola fi aworan sita to wa lori ibusun ile iwosan ti wọn si n fa diriipu si i lọwọ.
Ẹ o ba tilẹ ro wipe ori itage ni ṣugbọn pẹlu akọle to kọ sita, ko si ani ani pe o wa lori akete aisan.
Oríṣun àwòrán, authenticmuy
'Pásítọ̀ ló sọ fún mi pé Ọlọ́run pè mí láti di Olokun tó ń bọ omi'
Mi o tii fi iru atẹjade bayii sita ri ṣugbọn nitori ọpọlọpọ iṣẹ nla ati ifarajin to wa niwaju mi pọ.
Dajudaju awọn akẹgbẹ rẹ ninu ere Yoruba ti kan si i tori ọpọlọpọ wọn lo tu sori ayelujara ti wọn n ki i, ti wọn n rọ ọ ko ṣara giri.
Aisan ko ni jẹ ipin rẹ lailai. Piri lologo n ji, a kii bokurun eye lori ite. Ni agbara Ọlọrun, oo ni faisan logba. Eyi ni agba adura ti akẹgbẹ rẹ, Rasaq Olasunkanmi Olayiwola ti ẹ mọ si Ojopagogo ṣe fun un.
Oríṣun àwòrán, authenticmuy
Awọn mii to tun fọrọ ati adura ranṣẹ si Muyiwa ni Aisha Lawal, Kiitan Bukola, Bisola Badmus, Funsho Adeolu, Temitope Solaja ati awọn mii.
Oríṣun àwòrán, authenticmuy
Oríṣun àwòrán, mydemartins
Gbajugbaja osere tiata Yoruba Mide Martins ti n ke irora bo ti ṣe fori janlẹ lasiko to n ṣe ere sinima kan lọwọ.
Ikede yi to fi soju opo rẹ ni Instagram lo sọ pe ara oun ko ti ya daada nitori bi oun ti ṣe fori gbalẹ.
Ninu ọrọ to fi tẹle fnran fidio ati aworan boti ṣe farapa yi han, Mide sọ pe ''Igbesi aye awa oṣere tiata ko dẹrun!''
'Pásítọ̀ ló sọ fún mi pé Ọlọ́run pè mí láti di Olokun tó ń bọ omi'
O ni ''Ara mi ko ti bọ sipo latari bi mo ṣe forigbalẹ. Ki eledua fi oore si igbiyanju  gbogbo ni to n wa atijẹ ati mu ''
Lara awọn aworan to fi safihan ipalara yi lo wa ni isalẹ yi:
Oríṣun àwòrán, mydemartins
Oríṣun àwòrán, mydemartins
Okiki Bakare@kikibakare ti wọn jijọ n ṣe ere naa ti ko ti jade kan sara si Mide Martins bi o ti ṣe fi inira ori to la mọlẹ mọra .
O ni eyi ṣafihan pe ojulowo osere tiata ni Mide n ṣe ti o si ni ki eledua tete mu lara da.
Oríṣun àwòrán, mydemartins
Inter-tribal Marriage: Bàbá mi kọ̀ láti bá mi sọ̀rọ̀ torí ọ̀kọ akáta tí mo mú wálé
Tori iriri tirẹ, Jonah ti bẹrẹ si ni ṣe eto idanilẹkọ fawọn lọkọlaya afẹsọna lati gbaradi fun ọna ara ọtọ nipa bi wọn lee ṣafihan ololufẹ wọn to ba ṣajoji si ẹbi wọn.
Oun ni oludasilẹ Blindian Project to jẹ eto ori ayelujara to fi n yẹ awọn eeyan alawọdudu si latari irinajo ifẹ wọn pẹlu awọn ara Asia.
Bawo ni mo ṣe le fi afẹsọna mi han fawọn obi mi. Eyi ni ibeere to Jonah maa n ri gba ju latọdọ awọn ara Asia to maa n kan si i.
Niṣe lẹru n ba mi gaan to nira fun mi lati wo oju baba mi, gbogbo igba ni mo n doju bolẹ. Ọpọlọpọ ni ko ni ireti mọ nitori eyi.
Ajoṣepọ eto ti Jonah n ṣe pẹlu iyawo rẹ Swetha ni wọn n ṣe lati ṣeranwọ fawọn eeyan bii tiwọn to n ronu bi wọn ṣe le mu ọkọ tabi iyawo afẹsọna dele.
Risikat Moromoke Azeez: Inú èmí àti Òbí mi dùn nígbà ti Risi bí ọmọ olójú búlù- Wasiu
Jonah ati Swetha bẹrẹ eto ti wọn n ṣe yii lọdun 2017. Awọn ololufẹ mejeeji pade lọdun 2015 ti wọn si bẹr si ni yofẹ ara wọn lẹsẹkẹsẹ bo tilẹ jẹ pe wọn kii ṣe ọmọ orilẹede kan naa.
Wọn ri i wipe awọn jọ fran ohun kan naa to pọ loriṣiriṣi - ounjẹ, orin, afojusun iṣẹ, idagbasoke idile to jọrawọn.
"Ti wọn ba n ṣe eto ori ayelujara yii, wọn ni ọpọ eeyan lo maa n bere fun imọran awọn ti ibeere to ma n wọpọ si jẹ ""bawo ni mo ṣe le fi afẹsọna mi han fawọn obi mi""."
"Swetha ni ""ẹru maa n ba awọn eeyan, awọn eeyan ni ọpọlọpọ iṣoro to tan mọ aṣa nibi ti wọn ti wa paapaa ni Asia""."
O ni wọn maa n ronu bakan bakan boya nipa ohun ti awọn eeyan alawọdudu lee ṣe si tabi ko ran awọn ara Asia.
Eeyan kan tilẹ pe sori eto to n yọlẹ sọrọ kẹlẹ kẹlẹ torii pe ko fẹ ki awọn mọlẹbi rẹ gbọ ohun to n sọ.
Mo ti wa pẹlu ololufẹ mi fun ọdun meji ati abọ bayii o si ti su mi ki n ma gbe igbe aye oloju meji.
O sọ fun Jonah pe aburo oun obinrin nikan loun ti sọ fun to si n gbero lati sọ fun gbọn rẹ ọkunrin naa laipẹ ki ọrọ tilẹ to lee kan awọn obi wọn rara.
Ọkan mi n gbọn nipa ohun ti awọn obi wa maa sọ bi mo ba sọ fun wọn.
Jonah ati iyawo rẹ Swetha ti ran ọpọlọpọ eeyan lọwọ lati kọ wọn ni ọna ti wọn lee gba sọ fun obi wọn nipa ẹni ti wọn yan lati fẹ.
Oríṣun àwòrán, Sanya Salim
Sanya Salim ni nkan toun ṣe niyii o si rii pe ẹgbọn rẹ kunrin lo kọkọ ri ololufẹ rẹ soju.
Asiko kan wa ti baba mi kọ lati ba mi sọrọ fun ọpọlọpọ oṣu lẹyin ti mo s fun un nipa Michael, ẹgbọn mi lo ṣi aṣọ loju ọrọ eyi si ni ọrọ to tobi ju taa sọ papọ nipa ololufẹ mi.
Ẹwẹ, oniruuru iṣẹlẹ to ti ṣẹlẹ nilẹ Amẹrika laipẹ yii ti ja funrarẹ fun awọn eeyan alawọdudu laarin awn araa ilẹ Asia. Apẹrẹ ni ifẹhonuhan #Blacklivesmatter.
Mo yaa kẹnu bọ ọ̀rọ̀ gbogbo ifhonuhan to buru taa ri, nigba ti Kamala Harris tun wọle ggẹ bi igbakeji aarẹ Amẹrika, mo n sọ fun iya mi pe ṣẹẹ mọ pe abẹyameji loun naa bi emi ati Michael.
Mo lero wipe asiko ti a yan bọ si dede. Asiko ti awa sọ baba ọrọ ṣe kongẹ ohun daadaa fun wa, asiko ti ololufẹ meji lee ni ifọkanbalẹ lati jẹ ki awọn eeyan mọ wọn papọ ki wọn si maa ri wọn ni gbangba.
Jonah ati Swetha ni ireti pe iriri awọn ati igbesẹ iranwọ tawọn n gbe yoo ran awọn eeyan alawọdudu to wa ni Asia ati lagbaye lọwọ.
"Awọn ọmọ wa jẹ ọdun mẹrin ati mẹfa a si n jẹ ki wọn dagba papọ ti wọn si fẹran awọ ara wọn bo ṣe ba jade.
SERAP ké sí ààrẹ Buhari lórí èròngbà àwọn NCC àti NIMC lórí ìforúkọsílẹ̀ NIN
Oríṣun àwòrán, @SERAPNigeria
Ajọ ajafẹtọmọniyan kan ni Naijiria SERAP, ti kesi aarẹ Buhari lati jawọ ninu eto iforukọsilẹ awọn ọmọ Naijiria nipa nọmba idanimọ NIN.
Ajọ naa ninu atẹjade kan to fi sita lọjọ Aiku ni ihalẹ ijọba lati wọgile simu kaadi awọn eeyan ti ko ba ni nọmba yi ku diẹ kaatọ.
Kolawole Oluwadare, oludari ajọ SERAP lo fi atẹjade yi sita.
'Pásítọ̀ ló sọ fún mi pé Ọlọ́run pè mí láti di Olokun tó ń bọ omi'
SERAP ni ki aarẹ Buhari paṣẹ fun Minisita feto ibaraẹnisọrọ ati eto ọrọ aje ayelujara Isa Pantami ati ọga agba ileeṣẹ to n mojuto eto idanimọ ni Naijiria NIMC iyẹn Aliyu Abubakar lati jawọ ninu igbesẹ yi''"
Alaye SERAP ni pe awọn ọmọ Naijiria ti fi iroyin nipa ara wọn silẹ lọna aimọye to fi mọ ti BVN,iwe aṣẹ iwakọ, iwe irina ilẹ okere ati kaadi idibo.
Lọsẹ to kọja yi ni ijọba apapọ Naijiria gbe gbedeke kalẹ pe ki gbogbo awọn ileeṣẹ ẹrọ ibaraẹnisọrọ wọgile siimu awọn alabara wọn ti ko ba ti ni nọmba idanimọ NIN.
Bẹẹ lo tun sọ fun awọn ileeṣẹ yi lati fi to awọn alabara wọn leti pe ki wọn pese nọmba idanimọ yi lati fi mu iroyin wọn pe perepere.
Bakan naa ni wọn ni  ki wọn ma se ta simmu tuntun tabi forukọ awọn to ba fẹ ṣẹṣẹ gba siimu mii silẹ.
"Kolawole Oluwadare oludari SERAP wa sọ pe  ""Ko si ijọba kankan to lẹtọ lati gba ẹtọ araalu lọwọ wọn labẹ pe o fẹ ki wọn forukọsilẹ gba nọmba idanimọ.Ti awọn alaṣẹ ba kọ ti wọn tẹsiwaju pẹlu igbesẹ yi,idunkoko mọ ara ilu yoo peleke si ni ti ajọ NIMC to yẹ ko ṣiṣẹ rẹ bi iṣẹ yoo si dabi ẹsin inu iwe lasan ti ko le ta putu.''"
Wọn wa ṣe lalaye pe ''kaka ki ijọba maa mu awọn eeyan nipa tabi ki wọn maa dunkoko mọ awọn ileeṣẹ ẹrọ ibaraẹnisọrọ eyi ti yoo jẹ ki wọn wa ninu ewu COVID-19, ohun to tọ ni ki wọn jẹ ki NIMC ṣe isẹ rẹ bo ti ṣe wa ni ibamu pẹlu ofin to ṣe idasilẹ rẹ.''
SERAP kangun ọrọ rẹ pẹlu alaye pe ko si ohun to mumu laya ijọba debi pe ki wọn wa maa ni ki awọn eeyan maa ṣa kijokijo nitori pe wọn fẹ gba nọmba idanimọ NIN yi.
Yeye Olokun of Lagos Omolara Fasola Fanimokun: Pásítọ̀ ṣọ́ọ̀ṣì ló sọ ìran pé kí n di Olókun
Ipe mi ni Oloriṣa olokun, iṣẹ ti mo si yan laayo ni iṣẹ Amofin lorilẹede Naijiria.
Lati kekere ni mo ti maa n ri ara mi ti mo maa n wẹ, ṣere ninu omi
Wolii ni Yeye Olokun tẹlẹ fun ogun ọdun ni ṣọọṣi. Ọmọ Eko ni baba rẹ amọ ọmọ ipinlẹ Edo ni iya rẹ.
Yeye Omolara Fashola to tun jẹ amofin nipa ọrọ oju omi ṣalaye bo ṣe yan lati di yeye Olokun leti okun eyi ti ọpọlọpọ maa n pe ni Yemoja nilẹ Yoruba.
Ohun to yan laayo bayii dabii pe aṣa diran ni tori gẹgẹ bi Yeye ṣe sọ fun BBC Yoruba, ati ile baba ati ile iya rẹ ni wọn.
Lasiko ọkan lara ijọsin rẹ leti okun, o ba BBC Yoruba sọrọ lorii bi o ṣe jẹ ọmọ Musulumi to tun lo ogun ọdun ni ṣọọṣi gẹgẹ bii Kristẹni ati Wolii ijọ kan ko to wa gba ibi to ni ori da a lọ eyi tii ṣe bibọ okun.
Bakan naa o ṣalaye awọn nkan to gbagbọ ninu rẹ nipa aṣa ati iṣẹṣe Yoruba fun idagbasoke orilẹede pẹlu igbelẹyin imọ ofin.
Produced by Yemisi Oyedepo, Funmi Jokotade & Damilola Oduolowu
PTF Nigeria Covid-19: Ààrẹ Buhari ní iṣẹ́ sí wà nílẹ̀ tí ìgbìmọ̀ yóò ṣé kí wọ́n sì wá níbẹ̀ dì 2021
Oríṣun àwòrán, @MBuhari
Aarẹ orileede Naijiria Muhammadu Buhari ti fontẹ lu ki igbimọ amuṣẹya lori kikoju arun Covid-19 ni Naijiria  PTF maa ba iṣẹ wọn lọ di ọdun 2021.
Eyi ni koko to jẹyọ lyin abajade ipade aarẹ Buhari  pẹlu igbimọ yi lọjọ Iṣẹgun nile ijọba lAbuja.
O ni nitori pe itankalẹ arun Covid-19 ti wa n peleke si  ti Naijiria ṣi n gbiyanju lati ri abẹrẹ ajẹsara, o di dandan ki igbimọ yi si wa nibẹ di oṣu Kẹta ọdun 2021.
Yatọ si eyi, o ni asiko yi ni '' a gbọdọ ṣa gbogbo ipa ti mo si rọ awọn lọba lọba ati olori sin lati polongo si etigbọ awọn eeyan wa''
Ni ọjọ Aje ni aarẹ Buhari gbẹnu igbimọ naa kede pe ki awọn oṣiṣẹ ijọba apapọ wa joko sile fun ọṣẹ marun un lati le koju itankalẹ arun yi .
Bẹẹ naa ni igbimọ amuṣẹya yi ni ki awọn ileewe wa ni titi pa fun oṣu marun naa.
Oríṣun àwòrán, @NCDCgov
Pẹlu bi aarẹ ti ṣe ni ki igbimọ yi tẹsiwaju iṣẹ wọn, o tun ni ki awọn ọmọ Naijiria maa ṣe jafira ki wọn si daabo bo ara wọn paapa lasiko ọdun to de yi.
''Awọn aṣeyọri wa laarin oṣu mẹsan to kọja yi ko gbọdọ ja si asan tori naa mo wo ọrọ yi daada to si dami loju pe yoo kọdi itankalẹ arun yi ati iku awọn eeyan wa''
Oríṣun àwòrán, PTF
Oríṣun àwòrán, Instagram/pauldgoodguy
Olukoni
Lẹyin ti ijọba apapọ kede ilana tuntun lọna ati kawọ ipadabọ ajakalẹ arun Covid-19 ni Naijiria, awọn to n maa n dari ayẹyẹ kan ti sọ pe awọn yoo tẹlẹ ilana ti ijọba gbe kalẹ.
Lara awọn eeyan naa to ba BBC Yoruba sọrọ ni Segun Paul to jẹ adẹrin poṣonu loju opo Instagram, ti ọpọ awọn ololufẹ rẹ mọ si Olukọni.
Gẹgẹ bi Segun to ni eto kan lati ṣe ni ipinlẹ Eko lọjọ kẹtalogun, oṣu Kejila, ọdun 2020 ṣe sọ, o ni oun ti ṣe adinkun si iye eeyan ti yoo wa nibi eto naa.
"Adari ayẹyẹ naa sọ fun BBC pe ""ootọ ni pe ilana tuntun ọhun yoo pa iṣẹ wa lara, ṣugbọn idi niyẹn ti a fi din iye ero ti yoo wa nibi eto naa ku""."
Oríṣun àwòrán, @pauldgoodguy
Ilana naa yoo pa iṣẹ wa lara ṣugbọn aye o parẹ
Segun tẹsiwaju pe oun atawọn oṣiṣẹ oun yoo rii daji pe gbogbo awọn to wa nibi eto naa ni wọn tẹle ilana ti ajọ NCDC gbe kalẹ lati dena ajakalẹ arun ọhun.
Ṣé ẹ mọ̀ pé àṣà nílẹ̀ Yorùbá ni ìwà ọmọlúàbí?
"O ni ""oun ti a fẹ ṣe ni lati ṣe faaji ati wẹjẹ-wẹmu pẹlu awọn eeyan, kii ṣe pe a n reti ero pupọ."""
Gbogbo oun to yẹ ni ṣiṣe ni a maa ṣe ni ibamu pẹlu ilana Covid-19.
Lẹyin naa lo gba ijọba apapọ niyanju lati ṣe ohun ti yoo rọ awọn ara ilu lọrun ni gbogbo igbesẹ to ba n gbe lati kapa arun naa nitori igbele akọkọ ko rọrun fun awọn eeyan.
'Pásítọ̀ ló sọ fún mi pé Ọlọ́run pè mí láti di Olokun tó ń bọ omi'
Oríṣun àwòrán, PTF
Ijọba Naijria ti kede konileogbele  ọlọsẹ marun un gbako fawọn oṣiṣẹ ijọba apapọ lọna ati dẹkun itankalẹ Covid-19.
Yatọ si awọn oṣiṣẹ ijọba to wa ni ipele Kejila lọ si oke, ko ni si awọn oṣiṣẹ mii ti yoo wa si ibiṣ lasiko yi.
Bakan naa ni ikede yi sọ pe ki awọn ile ẹkọ gbogbo ti wọn yoo ti gba isinmi lati ọjọ Kejidinlogun oṣu Kejila wa ni titi pa fun ọsẹ marun lati asiko yi lọ.
Labẹ ikede ilana tuntun yi ti alaga igbimọ to n mojuto kikoju arun Covid-19 ni Naijiria Boss Mustapha sọ, gbogbo ile ounjẹ, ile igbafẹ ni wọn ni ko wa ni titi pa.
O ni igbimọ PTF ti ṣe agbeyẹwo gbogbo nkan to n lọ lagbaye ti awọn si ti fi aba to yẹ sọwọ si aarẹ fun ibuwọlu ni kiakia
Awọn nkan miran ti ilana tuntun yi mu iyipada ba ni:
Akomolede BBC Yoruba: Ṣé ẹ mọ̀ pé àṣà nílẹ̀ Yorùbá ni ìwà ọmọlúàbí?
B'eegun ẹni ba joo 're, ori a maa ya atọkun
B'ọmọ ẹni ba dara ka wi
Ọmọ to dara ti baba ni, eyi ti ko dara, ti iya ni
Awọn owe atawọn aṣayan ọrọ bi eleyi ko ṣajoji si iwa rere nilẹ Yoruba.
Iyaafin Adenke Okun jẹ agba nilẹ Yoruba, torinaa ni wọn ṣe jẹ olukọ to lee kọ nipa aṣa yii daadaa.
Aṣa ọmluabi jẹ ohun ti wọn fi n da eeyan mọ yatọ lawujọ kaakiri agbalaye torinaa ni ẹya Yoruba ṣe mu u lọkunkundun.
Aṣa Yoruba si fẹran keeyan maa hu iwa rere pupọ ni wọn fi maa n n pa aweọn owe to rọ mọ eyi.
Too ba mọ eeyan ki, awọn Yoruba ko naani ẹti ko ba mọ eeyan ki o. Koda bi ọmọkunrin o dọbalẹ ki igba aya rẹ kan ilẹ tabi ki ọmọbinrin fi orokun mejeeji kunlẹ ki agba, o lee gba igbati lọwọ obi nilẹ yoruba eyi to ṣajoji sawọn ẹya mii. Yoruba a ni ọmọ bẹẹ n gbin agbado ki agbalagba ni.
Fifi ohun rere sọrọ ati ọpọlọpọ ohun iwuri to yẹ ni iwa ni akẹkọ etoo Akọmọlede lorii BBC Yoruba ṣi lawẹlawẹ ninu fidio to wa loke yii.
Deeper LifeHigh School fèsì lórí akẹ́kọ̀ọ́ iléèwé wọn tí ìyá rẹ̀ ní àwọn olúkọ́ lù àti fipábálòpọ̀
Oríṣun àwòrán, DLHS
Awọn alaṣẹ ile ẹkọ giga Deeper Life High School ti fi sọ pe gbogbo eni ti igba iwa ibajẹ ba ṣi mọ lori nitori ọrọ ọmọkunrin akẹkọọ kan ti wọn fiya jẹ lawọn yoo fimu rẹ danrin.
Ni ọsẹ to kọja ni obinrin kan figbe ta lori ayelujara pe awọn ọga ile iwe mu ọmọ oun lọ si aarin awọn akẹkọọ ti wọn si fi iya jẹ ẹ gidi.
Lara ohun to ni wọn fi ṣe ọmọ naa ni pe awọn kan n dẹyẹsi ti wọn si tun ti ika bọ nidi nitori pe o n tọọle.
"Toríi ""Coro"", ẹ wo bí ètò ìsìn ìgbéyàwó orí ayélujára Zoom ṣe lọ"
Temitope Akinnusi: Ọ̀pọ̀ iléeṣẹ́ ló takú láti gbà mí síṣẹ́ torí mo ní ojú kan
Iṣẹlẹ yi waye ni ilu Akwa Ibom ti arabinrin naa si ni oun ti sọ fun awọn olukọ rẹ ṣaaju pe ọmọ naa n tọ sile ti wọn si ni o tẹ awọn lorun.
Oríṣun àwòrán, DLHS
Ṣugbọn  o ni ìyàlẹ́nu lo jẹ nigba ti ọga ile iwe gbe ọmọ naa kuro ni ositẹẹli rẹ lọ si aarin awọn to ju u lọ ti wọn si n ṣe iṣekuse pẹlu rẹ.
Ninu atẹjade ile iwe naa DLHS wọn salaye pe, idasile ile iwe naa ni lati fi ọrọ Ọlọ́run tọ awọn ọmọ ati lati jẹ eniyan to ni ibẹrun Ọlọrun.
Bakan naa lawọn alaṣẹ sọ pe iwadii n lọ lọwọ ati pe gbogbo eni ti igba ọrọ naa ba si mọ lori, awọn yoo fi imu rẹ danrin.
Wọn ni tori idi eyi, ki gbogbo ara ilu lo fi ọkan balẹ pe idajọ ododo ni awọn yoo ṣe
Ile ẹkọ Depper Life ni lọwọ lọwọ won ti ni ki ọga ile iwe naa lọ rọọkun nile nigba ti iwadii n tẹsiwaju.
Nigeria Customs: Ẹ̀ṣọ́ asọ́bode yìnbọn pa onífàyàwọ́, èèyàn méjì míì farapa nínú ikọlù Ayetoro
Oríṣun àwòrán, Facebook/Yemi Akintunde
Niṣe ni  ibanujẹ gbalẹ kan ni adugbo Kikelọmọ ni ilu Ayetoro ipinlẹ Ogun nibi ti awọn ẹṣọ aṣọbode ti yinbọn pa eeyan kan ti eeyan meji mii si farapa.
Iṣẹlẹ yi ti kii ṣe akọkọ iru rẹ waye laarin awọn ẹsọ asọbode ati awọn kan ti wọn fura si pe wọn n  ṣe owo fayawọ lagbegbe naa.
Ninu ifọrọwanilẹnuwo pẹlu alukoro ọlọpaa ipinlẹ Ogun, DSP Abimbola Oyeyemi, o fidi ọrọ naa mulẹ pe lootọ ni ikọlu yi waye.
Oyeyemi ni awọn gbọ iroyin pe awọn ẹṣọ aṣọbode nilu Ayetoro pa ọkan lara awọn onifayawọ to doju ija kọ wọn tawọn onifayawọ yi naa si ṣe ẹṣọ aṣọbode kan lese.
''Ọga ọlọpaa Ayetoro ati awọn DPO agọ ọlọpaa to wa lagbegbe naa ni Kọmiṣana ti ni ki wọn da alaafia pada si agbegbe naa''.
Ninu fọnran fidio kan ti ọkan lara awọn ọmọ ilu Ayetoro to si tun jẹ akọroyin pẹlu ileeṣẹ iroyin NTA,Yemi Akintunde pin soju opo Facebook rẹ, a ri ti awọn eeyan kan n gbe ẹnikan to ṣeṣe ku  ti wọn si n sọ ninu fidio naa pe ọta ibọn lo ba a lẹsẹ.
BBC Yoruba ba aṣoju ẹkun idibo Imeko Afon/Egbado North Federal Constituency iyẹn aṣofin Jimoh Olaifa sọrọ to si ni lootọ ni iṣẹlẹ ọhun waye.
Oríṣun àwòrán, Google Maps
Olaifa ni awọn eeyan oun nile ti n pe lati fi ọrọ naa to oun leti ati pe iru iṣẹlẹ bayi ko ṣẹṣẹ maa waye lagbegbe naa.
''Nigbakigba ti iru nkan bayi ba ṣẹlẹ, lọpọ igba awọn to maa n farapa a maa wa lọna mejeeji. Fayawọ nibẹ a maa fẹ gbe ẹru wọn wọle lagbegbe naa ti awọn agbofinro yoo si maa kọ di wọn''
Olaifa ni awọn ti parọwa sawọn ọdọ lagbegbe naa pe ki wọn dẹkun fayawọ ṣugbọn nitori ti ọpọ ko niṣẹ lọwọ, eti ikun ni wọn kọ si arọwa yi.
Ayetoro jina si olu ilu ipinlẹ Ogun, Abeokuta ni iwọn kilomita marundinlogoji.
Oríṣun àwòrán, Facebook/Olugbade Peter Ppex
O jẹ ọkan lara awọn agbegbe ti iṣẹ fayawọ to gbogo nitori pe ko jina si ibode Naijira ati Benin Republic.
Opopona Abeokuta-Imeko jẹ oju ọna kan ti eeyan yoo gba lati fi ja si Imeko lati Ayetoro.
Lẹyin Imekọ eeyan yoo kan Ilara ti ko jina si ala ibode Naijiria si Benin Republic.
Animal accident: Arákùnrin kan dóòlà ẹ̀mí Erin tí alùpùpù gbá lójú pópó
Oríṣun àwòrán, Photoshot
Ọmọ Erin kan ti alupupu gba loju titi ti ru u la lẹyin ti arakunrin kan doola ẹmi rẹ.
Ọgbẹni Mana Srivate ṣalaye fun ileeṣẹ akoroyin jọ Reauters pe oniruuru eto adoola ẹmi loun ti ṣe ninu irinajo iṣẹ oun-ṣugbọn oun ko ṣiṣẹ idoola ẹmi erin ri.
Fọnran fidio o to di gbajugbaja lori ayelujara, ṣafihan arakunrin naa nibi ti o ti n fi ọwọ mejeeji tẹ ara erin naa to ṣubu si aarin opopona kan.
Lẹyin iṣẹju marun ni erin naa dide.
Ọmọ erin naa n gbiyanju ati kọja loju opopona naa pẹlu awọn ẹranko ẹgbẹ rẹ kan lagbegbe Chanthaburi lorilẹede lorilẹede Thailand.
Bi awọn akẹgbẹ arakunrin naa ṣe n tọju arakunrin to gun alupupu to gba erin naa ni oun pẹlu n tọju erin ọhun funrarẹ.
Kiniun pa olusọ ọgba ẹranko
Justice Osei le dún bíi ẹranko 50
Kollington ṣàlàyé bí orin Fuji ṣe bẹ̀rẹ̀ gan an ní Nàiìjíríà
Christmas Message: Wo bí o ṣe lè dáàbò bo ara rẹ lásòkò ọdún Keresimesi
Lẹyin ti ileeṣẹ ijọba apapọ to n ri si eto abo abẹle, DSS, kede pe awọn kọlọrọsi kan n mura ati ṣakọlu sawọn agbegbe kan bi ọdun ṣe n pari lọ, ọpọ awọn awọn eeyan lo ti n woye ohun to yẹ ki wọn ṣe.
Yoruba bọ wọn ni oju ni alakan fi n ṣọri, eyii lo mu BBC Yoruba kan si akọṣẹmọṣẹ kan nipa eto abo, lori awọn ohun to yẹ ki eeyan ṣe fun abo ara wọn bi ọdun ṣe n pari lọ yii.
Babatunde Akande, to jẹ alaṣẹ ileeṣẹ eto abo aladani Europa Security Guard, sọ awọn ohun to yẹ ki awọn ara ilu ṣe atawọn nnkan ti ko yẹ ki wọn ṣe fun abo ara wọn.
Akande kọkọ gba awọn eeyan niyanju lati maa tọju awọn ọlọde to n ṣọ ile wọn.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
WHO ta bayar da shawarar mutane su gana da juna ta intanet
"O ni ""Ẹma fi ebi pa ọlọdẹ to n ṣọ ile yin lọdun yii o, ẹ ma sọ pe ṣebi o n gba owo oṣu."""
Bakan lo kilọ pe ki awọn eeyan maṣe rinrin ajo ti ko ba ṣe pataki.
"O ṣalaye pe ""kii ṣe gbogbo irinajo ni eeyan n lọ lasiko yii."""
Ẹ le fi owo ranṣẹ si ẹni to ba yẹ ki ẹ ṣabẹwo si ti abẹwo naa ko ba pọn dandan.
'Ọ̀lọ́pàá shátà mi láti Mowe dé Magboro dé Shagamu, wọ́n ní ṣé mi ò mọ̀ pé ìjọ́ba ni mo ṣiṣẹ́ fún'
Bẹẹ lo ni ki awọn eeyan ṣora nipa ohun ti wọn a maa sọ ni gbangba.
Ẹni to wa nile ọti to n dan ẹnu nipa iye owo to wa ninu apo banki rẹ kan n fi ara rẹ sinu ewu ni, nitori ko mọ irufẹ eeyan to wa layika rẹ nigab to n sọrọ.
Amoye nipa eto abo naa tun ṣalaye pe ki awọn eeyan maa gbiyanju lati maa pa iye owo to wa ninu apo ifowopamọ banki wọn rẹ lori ẹrọ alagbeka wọn.
'Pásítọ̀ ló sọ fún mi pé Ọlọ́run pè mí láti di Olokun tó ń bọ omi'
O ni ki awọn eeyan ṣora nipa iye owo ti wọn yoo maa da nibi ipade adugbo, bi wọn ṣe nawo nibi ariya ati awọn aṣọ to maa n ṣafihan bi wọn ṣe lowo si.
"Ni ti ori ayelujara, Akande sọ pe ""ẹ ṣọra fun irufẹ ohun ti ẹ o maa fi lede loju opo Facebook."""
Ẹlomiran yoo maa fi gbogbo igbesi aye rẹ sori Facebook.
Fun apẹrẹ, awọn kan maa n fi ibi ti wọn wa ati ibi ti wọn n lọ sori Facebook, eyii ko daa to.
Oríṣun àwòrán, @PoliceNG
Ni bayii ti ọdun keresimesi ati ayẹyẹ opin ọdun ku ọjọ perete, ileeṣẹ ọlọpaa Naijiria ti kede awọn ohun mẹfa to yẹ ki awọn ara ilu ṣe lati dabo bo ara wọn lopin ọdun.
Ọjọ Iṣẹgun ni ọọfisi ileeṣẹ ọlọpaa to n ri si ọrọ iroyin fi atẹjade naa lede niluu Abuja.
Ninu atẹjade ọhun ni wọn ti ṣalaye awọn ohun ti awọn eeyan le ṣe fun abo ara wọn, paapaa awọn to n rinrinajo ile ọdun, ni ibudokọ, papakọ ofurufu ati ibudokọ oju irin.
Wo awọn nnkan ti ọlọpaa ni ki o ṣe lasiko ti ọdun n lọ sopin yii fun abo ara rẹ:
Lẹyin ti ileeṣẹ ọlọpaa fi ọrọ naa lede tan ni wọn tun fi fido yii lede pẹlu.
Jebba Petrol Tanker Expolsion: Ilé ọgbọ̀n jó ènìyàn mẹ́fà pàdánù ẹmí ní Kwara
Oríṣun àwòrán, KWSG
Ọkọ̀ àjàgbé tó gbé epo bẹtiró ló gbiná ni ìpińlẹ̀ Kwara, ti ènìyàn mẹ́fà pàdánù ẹ̀mí wọ́n nígbà ti ilé tó lé ni ọgbọ̀n jóná lópónà Jebba ni ìjọba ìbílẹ̀ Moro Kwara.
Ìròyìn só pé, ìjánu ọkọ̀ náà lo já ti ọkọ̀ epo tó bọ láti sì ya wọ ààrín bi ti ilé àwọn ènìyàn ń gbé.
Àwọn ti ọ̀rọ̀ náà soju wọn ṣàlàyé pé, ìṣẹ̀lẹ̀ náà já sí ìbúgbàmù ńla lọ́wùrọ̀ ọjọ́rú ti ilé bí ọgbọ̀n sì jóná tó fi mọ àwọn sọ́ọ̀bù ìtajà.
Oríṣun àwòrán, KWSG
Agbẹ̀nusọ àwọn panapana ní ìpínlẹ̀ Kwara Hassan Adekunle ṣàlàyé pé òótọ́ ni ìṣẹ̀lẹ̀ náà ati pé òótọ́ àti pé àwọn ń gbìyànjú láti kápáa rẹ̀.
Ẹ̀wẹ̀, Ìjọba ìpinlẹ̀ Kwara ti bá àwọn ẹbí àwọn tí ẹ̀mí wọ́n sọnù nínú ìṣẹ̀lẹ̀ náà kẹdun.
Gómìnà ni ìbànujẹ́ ní ọ̀rọ̀ náà jẹ fún òun pàápàá jùlọ bí àwọn enìyàn ṣe pàdánù ẹ̀mí wọn ti ọ̀pọ̀ ǹkan okó, ilé ìgbé àwọn ènìyàn sì ṣe ṣègbé.
Ó rọ àwọn ẹbí àwọn olóògbé láti gba fún Ọlọ́rún,  bákan náà ló darí àjọ SEMA ti ìpínlẹ̀ náà láti ṣe kíákíá kí wọ́n mọ iyé ǹkan tó bàje kí ìjọba le mọ síi.
Gómínà sọ èyí nínú àtẹjade kan ti agbẹnusọ gómìnà fọ́wọ́ sí, Rafiu Ajakaye, ṣàlàyé pé gomínà tún dari àwọn ilé iṣẹ́ panápaná láti ṣa gbogbo ipá wọn láti pa iná náà.
'Ọ̀lọ́pàá shátà mi láti Mowe dé Magboro dé Shagamu, wọ́n ní ṣé mi ò mọ̀ pé ìjọ́ba ni mo ṣiṣẹ́ fún'
Ọwọ́ ọlọ́pàá tẹ ọkùnrin tó ń pe ara rẹ̀ ni Ahmed Musa
Oríṣun àwòrán, Kano Police Command
Ọwọ ileeṣẹ ọlọpaa ipinlẹ Kano ti tẹ ọkunrin kan to n pe ara rẹ ni balogun ẹgbẹ agbabọọlu Super Eagles, Ahmed Musa.
Wọn ni ọkunrin ọhun ti orukọ rẹ n jẹ Gambo Yakubu ti gba owo ti iye rẹ to ₦700,000 lọwọ awọn eeyan, lẹyin to fi da wọn loju pe oun yoo ba wọn ṣeto ati gba bọọlu loke okun.
Agbẹnusọ ileeṣẹ ọlọpaa ipinlẹ naa, DSP Abdullahi Haruna lo fidi iroyin naa mulẹ fun akọroyin.
"O ni ""ootọ ni pe afurasi ọhun n ṣiṣe pẹlu ileeṣẹ Ahmed Musa tẹlẹ ki wọn to le danu, lẹyin naa lo lọ ṣe ayederu iwe lati maa fi lu awọn eeyan ni jibiti."""
Ṣaaju ni oludari ileeṣẹ ti Ahmed Musa da silẹ ọhun ti kọkọ ta ọlọpaa lolobo nipa afurasi naa nitori bi ọpọ ero ṣe maa n wa sile iṣẹ wọn lati bere owo to gba lọwọ wọn.
Gẹgẹ bi ọrọ ti alukoro ọlọpaa naa sọ, nnkan bii eeyan marundinlogun ni afurasi naa ti lu jibiti  lẹyin ti wọn ti fun ni ẹgbẹrun marun un owo fọọmu lati lọ gba bọọlu niluu oyinbo.
"Haruna sọ pe ""apapọ iye owo to ti gba lọwọ awọn eeyan jẹ ₦ 700,000 to si sọ pe oun ti na owo naa fun awọn ọrẹbinrin oun."""
'Ọ̀lọ́pàá shátà mi láti Mowe dé Magboro dé Shagamu, wọ́n ní ṣé mi ò mọ̀ pé ìjọ́ba ni mo ṣiṣẹ́ fún'
Xmas Cuisine: Wo àwọn oúnjẹ oúnjẹ aládùn 10 tó gbayì lásìkò Kérésì
Oríṣun àwòrán, www.eatdrinklagos.com
Igba ọdun jẹ asiko tawọn eeyan maa n pejọ lati yọ ayọ ẹmi to rẹyin ọdun.
Lasiko ọdun 2020 ti ọpọ ewu ree awa taa ṣẹku kọja ko si ohun to yẹ ju ki a pe apejẹ pẹlu awọn ẹbi ọrẹ ati ojulumọ.
Njẹ ẹyin ni ipalẹmọ kankan ti ẹ n ṣe lati gbalejo lasiko ọdun yi, ki si ni iru ounjẹ ti ẹ fẹ fi dawọn lọrun?
Bi  ko ba tii mọ ounjẹ tẹ fẹ se, ẹ jẹ ki a ya yin lawọn ounjẹ aladun mẹwaa kan ti o jẹ arimalejẹ paapa lasiko ọdun yi
Jollof Rice
Bi wọn ba ni ka pe ogunagbongbo ounjẹ tawọn eeyan yan laayo lasiko ọdun yi, oke tente ni jọlọọfu yoo wa.
Kaakiri Naijiria ati lawọn orileede miran ni ilẹ Afrika ni ounjẹ yi ti jẹ gbajumọ ounjẹ ti awọn eeyan a maa fi ṣe inawo tabi ki wọn kan se fun jijẹ ni ile.
Oríṣun àwòrán, @EarlJoey_.
Bi ẹ ko ba ti ni awọn eronja lati fi ṣe jọlọ yin ti yoo maa fi ta sansan, ẹ tara ṣaṣa lọ si ọja lati lọ ra ki ọrọ ma ba di gobe lọjọ ọdun.
Bi ẹ ba ti ṣe tan, ẹ ma gbagbe lati fi tiwa naa ranṣẹ!
Bẹẹ ni. Ti o ba ti to ọjọ mẹta ti ẹ ti jẹ okele kẹyin nitori pe iṣẹ ko gba yin laaye lati peelo rẹ, asiko ọdun yi dara lati se ila alasepọ.
Bo ba ṣe amala lẹ fẹ fi lo ni tabi iyan ko si eleyi ti ko lọ pẹlu rẹ.
Oríṣun àwòrán, TPC
Lasiko taa wa yi, ila ko wọn pupọ lọja ṣugbọn awọn isọmọgbe ti yoo jẹ ki ila alasepọ yin ta lẹnu daada le fẹ gunpa diẹ.
Amọ ko si bo ti ṣe le wu ko jẹ, eeyan yoo ri tiẹ ra lọja.Bo ṣe ẹja gbigbẹ ni tabi aṣamọ ẹgun, bo si jẹ bokọtọ tabi adiẹ lẹle fi se ni, ko si eyi ti ko lọ.
'Ọ̀lọ́pàá shátà mi láti Mowe dé Magboro dé Shagamu, wọ́n ní ṣé mi ò mọ̀ pé ìjọ́ba ni mo ṣiṣẹ́ fún'
Bo se eleyi to di ti ẹ ko ni nilo ẹran ninu ọbẹ lẹ fẹ ni tabi eyi to toro mọ ẹfọ, ko si iru ẹgusi ti ẹ se lasiko ọdun ti awọn eeyan ko ni jẹ igbadun rẹ.
Iyan lawọn eeyan maa n saba fi jẹ ẹgusi paapa lasiko ọdun ṣugbọn awọn ẹlomi ko kọ lati fi jẹ Sẹmo tabi ẹba.
Oríṣun àwòrán, @others
Obẹ ẹgusi dún pupọ pẹlu Iyan, ẹba, fufu ati ounjé miran
Koda mo mọ eeyan kan to ṣe wi pe o le fi ẹgusi jẹ amala. Gbogbo rẹ lo lọ ko si wahala.
Ẹfọ a maa lọ pẹlu ẹgusi naa plu adiẹ tabi ogunfe.
Orin Orlando Owoh lo wa si ọkan bi a ti ṣe mẹnu ba asaro ninu apilẹkọ yi.
Iṣu la fi n se asaro sugbọn gegẹ bi gbogbo ounjẹ, eronja ta ba fi sinu rẹ la maa mu ki adun rẹ jade ju ara wọn lọ.
Awọn kan a maa fi ede sinu asaro ti wọn ko si ni fọ iṣu inu rẹ pupọ.
Oríṣun àwòrán, thepretendchef.com
Ninu idile miran ẹja tabi ẹran pẹlu ẹfọ ni wọn a maa fi se asaro.
Bi o ba ti to ọjọ mẹta ti ẹ farabalẹ se asaro, asiko ọdun yi jẹ igba ti ẹ le fi ṣapọnle awọn tiyin ti wọn a si maa pọnu la lẹyin ti wọn ba jẹ ẹ tan.
Ọba ni Jọlọọfu jẹ ninu ounjẹ ṣugbọn lọdọ awọn eeyan kan nilẹ kaarọ o jiire ori irẹsi ọfada ni wọn gbe  Ade ounjẹ iyi le lori.
Lati agbegbe Ọfada ni ipinlẹ Ogun ni wọn ti kọkọ gbin in ki o to di kari aye.
Irẹsi ọfada jẹ ti ibilẹ to maa n ṣara loore pupọ gẹgẹ bi awọn  kan ti ṣe sọ.
Oríṣun àwòrán, Others
Bi eeyan ba lọ si ibi ṣiṣe ti wọn n pin ounjẹ, witiwiti lawọn eeyan maa n du iresi ọfada ti ki si saba to laarin awọn alejo.
Nitori ifẹ tawọnm eeyan ni si iresi ọfada yoo mu ina awọn mọlẹbi rẹ dun ti o ba le dawọn lọrun pẹlu ofada lasiko ọdun yi.
Bi ẹ ko ba mọ bi wọn ti se n se iresi yi, ẹ wo fidio  to wa ni isalẹ yi fun ẹkunrẹrẹ alaye nipa ounjẹ́ aladun yi.
Ofada Rice: kíni ẹ̀yin gbádùn nínú ìrẹsì ọ̀fadà?
Awọn eeyan wa nilẹ Igbomina ni yoo mọ adun to wa nibi ounjẹ yi.
Ekuru nilẹ Yoruba jẹ ounjẹ tawọn eeyan maa n gbadun pẹlu ọbẹ ila tabi ọbẹ ata.
Bi o ba ṣe ẹni to mọ ọbẹ ata yi ṣe daada ni, o yẹ ki ẹ ba awọn eronja bi ẹja ọfọọrọ, pọnmọ ati nkan inu ẹran bi shaki pade ninu ọbẹ naa.
Oríṣun àwòrán, Others
Adun to wa ninu ekuru jijẹ yala bi ẹ ba fi ẹkọ jẹ tabi ki ẹ jẹ lasan ko la fiwe.
Lasiko ọdun yi, ẹ le yan ounjẹ yi laayo lati fi mu inu awọn mọlẹbi yin dun.
Awọn ounjẹ miran ti ẹ le gbadun lasiko yi ree:
Oríṣun àwòrán, Others
Ikọkọrẹ
Oríṣun àwòrán, Others
Oríṣun àwòrán, PuldeNg
Pasuma daughter: Mo bá ọmọ mi yọ̀ bó ṣé di ọmọ ogun orí omi ilẹ̀ Amẹrika - Wasiu Alabi Pasuma
Oríṣun àwòrán, Instagram
Gbajugbaja olorin fuji, Wasiu Alabi Pasuma ti ba ọmọ rẹ Opeyemi ṣajọyọ lẹyin ti ọmọ naa darapọ ileeṣẹ ọmọ ogun ori omi ilẹ Amẹrika.
Pasuma sọ pe aṣeyọri ọmọ naa jẹ ohun iwuri fun oun.
"Nigba to n kede iroyin naa pẹlu aworan ọmọ ọhun loju opo Instagram rẹ, Pasuma ni ""ẹ ba mi ṣajọyọ oriire o, ọmọ mi ti di ọkan lara awọn ọmọ ogun ori omi orilẹ-ede Amẹrika."""
'Mo kàn máa ń lọ́ ayẹyẹ kiri torí ijó láì ṣe pé wọ́n pe mí ló sọ mí di DJ olórin Fuji nìkan'
"O tẹsiwaju pe ""O kare ọmọ mi Opeyemi L'Amẹrika fun iwuri nla ti o jẹ fun emi ati iya rẹ, Ọlọrun yoo maa sin ọ lọ ninu irinajo iṣẹ ti o yan laayo yii."""
Ti ẹ ko ba gbagbe, obinrin bii mẹta lo bi ọmọ mẹwaa fun Pasuma, ti wọn jẹ obinrin mẹjọ ati ọkunrin meji.
Ọmọ ti Pasuma kọkọ bi ni Wasilat Ajibola to kẹkọọ jade ni fasiti Lead City to wa niluu Ibadan, iyẹn ni ipinlẹ Oyo.
Lara awọn ọmọ miran ti Pasuma tun bi ni Barakat, Wasbar, Amirah, Opeyemi, Sultan, Waris ati Aliyah.
Pasuma jẹ ọkan gboogi lara awọn olorin fuji to milẹ titi julọ ni Naijiria ati kaakiri agbaye.
'Ọ̀lọ́pàá shátà mi láti Mowe dé Magboro dé Shagamu, wọ́n ní ṣé mi ò mọ̀ pé ìjọ́ba ni mo ṣiṣẹ́ fún'
Survival fund: Èyí ni owó ìrànwọ́ #IGotSurvivalFund tí ìjọba àpapọ̀ ń fún àwọn ọmọ Nàìjíríà nítorí àjàkálẹ̀ àrùn Covid-19
Oríṣun àwòrán, MSMES SURVIVAL fund/twitter
Ijọba apapọ ṣalaye pe ni Ọjọbọ ni awọn ti bẹrẹ si ni san owo gba ma binu fun awọn eeyan ti ajakalẹ arun COVID-19 da ọrọ aje wọn ru labẹ eto owo iranwọ ti wọn pe ni MSME Survival Fund.
O dabi ẹni wi pe eyi gan lo mu ki koko ọrọ ori ayelujara, #IgotSurvivalFund o maa ja ranyinranyin loju opo ayelujara gbogbo ni Ọjọbọ.
'Mo kàn máa ń lọ́ ayẹyẹ kiri torí ijó láì ṣe pé wọ́n pe mí ló sọ mí di DJ olórin Fuji nìkan'
Awọn fọto atẹjiṣẹ to n ṣafihan pe wọn ti gbowo naa lati ọdọ ijọba apapọ pẹlu itọni latọdọ ijọba apapọ pe ki wọn fi aworan rẹ han lori ayelujara pẹlu koko ọrọ ori ayelujara, #IgotSurvivalFund pe awọn ti gba owo naa.
"Atẹjiṣẹ naa yoo bẹrẹ pẹlu koko ọrọ ori ayelujara naa, orukọ ẹni to janfani rẹ, orukọ ileeṣẹ rẹ, ibi ti ileeṣẹ naa wa nọmba idanimọ, ati ""I am a beneficiary of Survival Fund. Thank you Federal Govt."""
Owo ti wọn pin fawọn eeyan naa wa laarin ẹgbẹrun lọna ogun (N20,000) si ẹgbẹrun lọna aadọta naira, (N50,000)ni ọjọ kọkanlelogun oṣu kẹsan ọdun 2020 ni iforukọsilẹ fun eto owo iranwọ naa waye gẹgẹ bi iwadii ṣe fihan, ko si di ni miliọnu kan ati ẹẹdẹgbẹrin ọmọ orilẹede Naijiria to ni okoowo to janfani owo iranwọ naa.
Nigba ti ijsba bẹrẹ eto naa ileri to ṣe ni pe idan marundinlaadọta awsn eeyan ti yoo janfani eto naa yoo jẹ obinrin, ida marun  yoo jẹ awọn akanda.
Bakan naa ni wọn ṣeleri nigba naa pe awọn to wa lẹka igbokegbodo ọkọ bii awọn awakọ igbalode Bolt, atawọn oniṣẹ ọwọ bii plọmba, birikileya ati oniṣẹ ina ni yoo fẹrẹ kan julọ .
2nd wave of Covid-19: Wo bí àjọyọ̀ ọdún ṣe lè wáyé ní ìpínlẹ̀ rẹ̀ lọ́dún yìí lábẹ́ àwọn òfin tuntun nípa COVID-19
Oríṣun àwòrán, Gboyega oyetola/twitter
Wo bi ajọyọ ọdun ṣe lee waye ni ipinlẹ rẹ labẹ awọn ofin COVID-19 tuntun
Opin ọdun de, pọpọṣinṣin ọdun tẹlee, bẹẹni ipenija ati ipaya nipa ọwọ keji ajakalẹ aarun COVID-19 naa ko gbẹyin; gbogbo rẹ lopin ọdun 2020 yii naa ni.
Ni iru asiko yii, kaakiri agbaye lawọn eeyan yoo ti maa minijọjọ kiri ti wọn yoo si maa gbaradi fun oniruuru ipejọpọ pọpọṣinsin ọdun eleyii ti ko ni ri bẹẹ lọdun 2020 bayii nitori awọn akọtun iṣẹlẹ ajakalẹ aarun COVID-19 lagbye bayii, ti ko si yọ Naijiria silẹ.
Idi niyi ti awọn ijsba lẹkajẹka, ipinlẹ ati ti apapọ pẹlu ṣe ti gbe awọn aṣẹ kan silẹ fun titẹle lasiko ọdun yii ki ajakalẹ arun naa ma baa di tọrọ fọkale lorilẹede Naijiria.
Eyi ni awọn igbesẹ tawọn to wa ni ijanu iṣejọba lawọn ipinlẹ to wa lẹkun iwọ ooru gusu  orilẹede Naijiria gbe lati dena ọwọja aarun COVID-1
Oríṣun àwòrán, Twitter/rotimi akeredolu
Ipinlẹ Ondo wa lara awọn ipinlẹ to kọkọ gbe igbesẹ lori ilana bi awọn olugbe ipinlẹ naa yoo ṣe ṣe ọdun si.
Oríṣun àwòrán, Twitter/rotimi akeredolu
Iwọgile awọn ayẹyẹ Keresimesi ati opin ọdin gbogbo bii adura aisun  ọdun, ayẹyẹ ọlọpọ ero Carnival, pẹlu ayẹyẹ wẹjẹwẹmu gbogbo.
Oríṣun àwòrán, Gboyega akosile/twitter
Lẹyin ti gomina ipinlẹ naa ti lugbadi aarun COVID ti iroyin si tun ti n fihan pe iye awọn to n ko aarun naa lojoojumọ tunt ti n peleke sii gẹgẹ bi awọn agbejade ajọ to n gbogun ti ajakalẹ aarun lorilẹede Naijiria, NCDC ṣe n gbe e jade lojojumọ ni Gomina Babajide Sanwo-Olu ti gbe awọn ilana akọtun sita ti yoo de bi ọrs pọpọṣin'sin ọdun yoo ṣe lọ ni ipinlẹ naa.
Lara awọn ilana to gbe kalẹ ree.
Oríṣun àwòrán, Gboyega oyetola/twitter
Laipẹ yii ni awọn oluwadi ijinlẹ nipa kokoro arun ni ibudo iwadi imọ igbalode nipa kokoro arun to wa lọgba fasiti Redeemers University ni ilu Ẹdẹ pariwo sita pe o jọ bi ẹni pe ẹya tuntun kokoro aarun COVID-19 ti wọ ipinlẹ Ọṣun eleyi to ko jinijini bo ọpọ.
Ijọba ipinlẹ naa gbe awọn ilana kan kalẹ lati rii daju pe wahala ajakalẹ arun naa ko tun burẹkẹ lẹẹkeji.
Oríṣun àwòrán, Twitter/gboyegaakosile
Ipinlẹ Ekiti naa ko gbẹyin ninu igbesẹ ilana lati wa ọwọ ajakalẹ arun COVID-19 to tun fẹ maa gbẹnu soke bayii bọlẹ.
Seyi Makinde vs Oyo state teachers: Gómìnà ní àwọn Tíṣà tó fi ṣọ́ọ̀kì kọ ìdánwò sójú pátákó ní Ọ̀yọ́ fẹ́ ba òun lórúkọ jẹ́ ni
Oríṣun àwòrán, Twitter/makinde
Laipẹ yii ni okiki kan pe ṣọọki lawọn olukọni kaakiri awọn ileewe alakọbẹrẹ ni ipinlẹ Ọyọ fi kọ ibeere idanwo wọn soju patako nitori airi owo akoso ileewe gba lọwọ ijọba Gomina Seyi Makinde.
Ẹgbẹ awọn olukọ, NUT ni ipinlẹ naa ti lọ sori atẹgun lati pariwo sita pe oju patako lawọn olukọ kọ ibeere idanwo si fawọn akẹkọọ dipo titẹ ibeere naa sinu iwe nitori ohun ti wọn pe ni kikuna ijọba ipinlẹ naa lati san owo akoso ileewe, (school running grants) fun saa eto ẹkọ meji bayii.
Amọṣa gomina Makinde ti ṣalaye pe, awọn ẹgbẹ olukọ naa ko fẹ tu aṣiri ara wọn sita gbangba ni ati pe o yẹ ki wọn jihin lori owo ti wọn gba ṣaaju fun akoso awọn ileewe.
Gomina Makinde ni gbogbo owo ti ijọba fun wọn ṣaaju fun akoso ileewe ni oun ni ki wọn wa ṣe iṣiro rẹ ki wọn to lee tẹwọ gba omiran.
O ni gbogbo awọn ti wọn sọ ara wọn di eku ajẹnifẹni to n jẹ owo ilu yoo foju ba ajọ to n gbogun ti iwa ijẹkujẹ ni ipinlẹ Ọyọ, OYACA laipẹ.
'Mo kàn máa ń lọ́ ayẹyẹ kiri torí ijó láì ṣe pé wọ́n pe mí ló sọ mí di DJ olórin Fuji nìkan'
Coronavirus doctor's diary: Ìtàn àwọn arúgbó ẹni àádọ́rùn ún ọdún méjì tó di lọ́kọ-láyà lẹ́yìn ìbáṣepọ̀ ọgbọ̀n ọdún
Eto gbigba abẹrẹ ajẹsara COVID-19 ti bẹrẹ ni orilẹede Gẹẹsi. Awọn arugbo ti ọjọ ori wọn ti ju ọgọrun ọdun lọ atawọn oṣiṣẹ eto ilera ni wọn kọkọ n gba abẹẹrẹ ajẹsara naa fun.
Awọn arugbo meji kan ti wọn maa n ba ara wọn jo ki wọn to di lọkọlaya bayii lẹni aadọrun ọdun wa lara awọn ti wọn kọkọ pese abẹrẹ ajẹsara naa fun ni ilu Bradford nibi ti Dokita John Wright  ti ileewosan Ọba Bradforford Royal Infirmary ti gbọ nipa wọn.
Awọn mejeeji yii pade ni ibudo ijo kan ni ọgbọn ọdun sẹyin nibi ti wọn ti di ọrẹ ti wọn si jumọ n rinrin ajo lọ sawọn ode ijo kaakiri pẹlu awọn ọkọ ati iyawo wọn nigba naa.
Trevor Hirst ati Lily Abbot ni orukọ awọn mejeeji yii.
Trevour padanu iyawo rẹ, Rita ni ọdun mẹfa sẹyin, Lily pẹlu padanu ọkọ rẹ ni ọdun 2006 lẹyin igbeyawo ọdun marundinlọgọta.
'Mo kàn máa ń lọ́ ayẹyẹ kiri torí ijó láì ṣe pé wọ́n pe mí ló sọ mí di DJ olórin Fuji nìkan'
"Ọdun 2020 yii ni awọn mejeeji yii pe ẹni aadọrun ọdun bi o tilẹ jẹ wipe Lily fi ọjọ mẹfa ju Trevor lọ, a maa pe e ni ""Toy boy"" o ni iyẹn tumọ si ọmọ iṣere oun."
Fun ọpọlọpọ ọdun ni wọn fi n da gbe lọtọọtọ ti awọn ọrẹ wọn si n rọ wọn lati kuku maa gbe pọ gẹgẹ bii tọkọtaya.
Lily ni idahun oun ni ọpọ igba ni pe ko si idi fun igbepọ awọn nitori awọn mejeeji ti fi igba kan ri igbeyawo nitori naa wọn ko nilo igbayawo miran mọ. Awọn mejeeji yii ni wọn si ti ni ọmọ-ọmọ ati ọmọ-ọmọ-ọmọ.
Ilorin Killing: Ọmọ kan ṣoṣo lọ́wọ́ ìyá rẹ̀ dèrò ọrun torí ááwọ̀ báńgà ní Mọ́ṣáláṣí
Oríṣun àwòrán, Facebook/Nurudeen Musa
Awọn ara adugbo Ita Nmo nilu Ilorin ti ke gbajare s'awọn agbofinro lati ṣawari arakunrin kan to gun eeyan lọbẹ pa nitori Banga.
Ohun tá gbọ ni pe arakunrin to ko agbako iku ojiji naa, Abdulkadir Segi sọ fún ọkunrin kan, Kehinde Oloka pe ko ma yin banga sinu mọsalasi lasiko ti won n kirun janmọ.
Kaka ki Kehinde gbọ arọwa yii, se ni wọn lo sare lọ sí ilé, tó sì lọ mu ọbẹ wa.
Ka to wí ka to fọ, o ti gun Abdulkadir lọbẹ, nigba ti won yoo si fi gbé Abdulkadir dé ilé iwosan, ẹpa ko boro mọ, ẹlẹmi ti gba a.
Awọn ara adugbo to ba ileesẹ iroyin Punch sọrọ lori isẹlẹ yii sọ pe, Kehinde na papa bora ni kete to huwa laabi rẹ naa tan, t'awọn eeyan agbo-ile  rẹ, tó fi mọ awọn obi rẹ naa si sálọ.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Abdulkadir nikan lawọn obi rẹ bi gẹgẹ bí a ti ṣe gbọ, ti wọn ti sin ni ilana musulumi.
Ọrọ yii ti de etigbọ awọn ọlọpaa to wa ni Adewole, ti a si gbọ pe alukoro ọlọpaa ipinlẹ Kwara, Kehinde Okasanmi náà tí fidi ọrọ yii mu'lẹ.
Awọn ọlọpaa lawọn ti bẹrẹ iwadii lati wa afurasi yii kan nibi kibi to ba sa pamọ si.
Oríṣun àwòrán, Toba adedeji
Saaju la ti mu iroyin wa fun yin pe, wahala bẹ silẹ lagbegbe Sabo nilu Osogbo nibi tawọn janduku ti ṣọṣẹ lalẹ Ọjọbọ, tii ṣe aisun ọdun Keresimesi  ati owurọ ọjọ Ẹti tii ṣe ọjọ ọdun Keresimesi gangan.
Amọṣa ohun to n ṣe awọn eeyan ni haa-hin bayii ni pe boya lootọ lẹmi ba iṣẹlẹ naa lọ.
Bi o tilẹ jẹ wi pe awọn iroyin abẹle n fidi rẹ mulẹ pe eeyan kan ku ninu iṣẹlẹ naa, ileeṣẹ ọlọpaa ni awọn ko tii lee sọ boya ẹmi ba iṣẹlẹ naa rin nitori pe iwadi ṣi n lọ lọwọ.
Bawo ni iṣẹlẹ naa ṣe ṣẹlẹ?
Oríṣun àwòrán, Quartz
Awọn afunrasi janduku ya bo agbegbe Sabo ni ilu Osogbo lọjọ keresimesi ti wsn si da ibọn bolẹ nibẹ ti wọn si ṣe ọpọlọpọ awọn oniṣowo to n ba karakata wọn lọ nibẹ leṣe.
"Gẹgẹ bi ohun ti awọn eeyan agbegbe naa sọ, awọn janduku naa ya wọ agbegbe ọhun ni aṣalẹ Ọjọbọ  tii ṣe ọjọ aisun ọdun Keresimesi pẹlu awawi pe awọn fẹ ṣe eto isin idagbere ""candle night"" fun ọkan lara wọn to jade laye."
Amọṣa, kaka ki wọn fi mọ lori ohun ti wọn ni awọn wa ṣe, wahala ni wọn ni wọn fi da silẹ ti wọn si bẹrẹ si ni koju ija sawọn olugbe agbegbe naa atawọn ontaja to wa nibẹ.
Aarọ ọjọ Ẹti, iyẹn ọjọ ọdun Keresimesi gan an lawọn janduku naa tun pada wa si agbegbe naa.
Gẹgẹ bi awọn to wa nibẹ ṣe sọ, wọn yinbọn fun oniṣowo kan nibẹ ti awọn miran si tun farapa
'Mo kàn máa ń lọ́ ayẹyẹ kiri torí ijó láì ṣe pé wọ́n pe mí ló sọ mí di DJ olórin Fuji nìkan'
Amọṣa ileeṣẹ ọlọpaa ṣalaye fun BBC News Yoruba pe awọn ti da alaafia pada si agbagbe naa ati pe nibayii awọn ko tii lee sọ ni pato ohun gan to bẹrẹ wahala naa.
Alukoro ileeṣẹ ọlọpaa ni ipinlẹ Ọṣun, arabinrin Yẹmisi Ọpalọla ṣalaye pe iwadii ti n lọ lọwọ ati pe oun ko tii le sọ boya ẹmi kankan ba iṣẹlẹ naa lọ
Bi awọn iroyin abẹle ṣe n sọ, nnkan ṣi le diẹ lagbegbe naa bayii ati pe awsn Hausa to jẹ olugbe agbe naa pẹlu ti di ihamọra okuta, ọbẹ, ada ati ọkọ lati daabo bo ara wọn bi awsn janduku naa ba tun yọju.
'Ọ̀lọ́pàá shátà mi láti Mowe dé Magboro dé Shagamu, wọ́n ní ṣé mi ò mọ̀ pé ìjọ́ba ni mo ṣiṣẹ́ fún'
Christmans celebrations: Alaafin Oyo gba àdúrà ọdún fún àwọn ọmọ Nàìjíríà, pẹ̀lú ìmọ̀ràn lórí ààrùn COVID-19
Oríṣun àwòrán, facebook/Alaafin Oba Adeyemi III
Bi awọn eekan gbogbo ṣe n dawọ idunu pẹlu oniruuru ara ati ọrọ lọjọ Keresimesi, kabiyesi Alaafin ti ilu Ọyọ, Ọba Lamidi Adeyẹmi Ọlayiwọla kẹta pẹlu ti sọrọ.
Koko ohun mẹta si ni Baba sọ nipa Keresimesi lọdun yii.
"Akọkọ, ninu atẹjade to fi sita laafin rẹ  lọjọ Ẹti tii ṣe ọjọ ọdun keresimesi lagbaye, ""lorukọ awọn olori, atawọn ọmọọba laafin"", Kabiyesi Alaafin rọ awọn ọmọ Naijiria, paapaajulọ awọn Kristẹni lati maa tẹlẹ ẹkọ to kalẹ sawọn iwe mimọ gbogbo ninu idawọle wọn lojojumọ."
"O ni o ṣe pataki lati ""tẹsiwaju pẹlu igbagbọ ninu Ọlọrun"" lati mọ pe a o bori ajakalẹ aarun to n da aye laamu bayii."
"Ẹkeji, Alaafin gba adura fun mutumuwa pe ""ìkoko ọbẹ"" wọn o ni gbẹ, bẹẹni aka wọn ko ni ṣofo ati pe awọn ọmọ ilẹyii yoo ṣe rere ninu alaafia tii ṣe baalẹ ọrọ."
Ẹlẹkẹẹta ti iku Baba Yeye mẹnuba ni fun awọn ọmọ Naijiria lati maṣe gbagbe pe ajakalẹ aarun COVID-19 ṣi wa ni sakani wa.
Nitorinaa ki koowa o tẹle awọn ilana gbogbo to wa fun didena itankalẹ aarun naa.
Water Theraphy: Àwọn àmi méje tó ń tọ́ka sí pé oò kí ń mu omi bí ó ti tó
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Omi labuwẹ, omi labumu, omi naa ni wọn lo so aye ro, koda ọrọ Yoruba a maa sọ pe ẹnikan kii ba omi se ọta.
Awọn onimọ isẹgun a maa kilọ pataki ki eniyan maa mu omi, ati pe bi eniyan ko ba mu omi to, o le koba awọn eroja kan ninu ara.
Iye omi ti o yẹ ki eniyan maa mu loojọ niṣe pẹlu ilera ara.
'Pásítọ̀ ló sọ fún mi pé Ọlọ́run pè mí láti di Olokun tó ń bọ omi'
Gẹgẹ bi ẹgbẹ awọn onimọ sayẹnsi ilẹ Amerika ṣe sọ (U. S National Academies of sciences, Engineering and Medicine) o yẹ ki obinrin maa mu omi lita meji ati kọbu meje, nigba ti ọkunrin gbudọ maa mu omi lita mẹta ati  kọbu meje.
Oríṣun àwòrán, VCG
Ṣugbọn ọpọ ni kii mu omi deede yala nitori pe ko si aaye tabi ni ọpọ igba ko si aaye igbọnsẹ iṣẹju-iṣẹju layika wọn, ẹwẹ ẹlomiran ko tilẹ mọ pe omi ti oun n mu ko kun oju osuwọn to.
Kini awọn apẹrẹ to n safihan pe eniyan ko mu omi to.
1. Ẹnu eniyan yoo maa run: omi dara pupọ lati pese itọ, bakan naa ni o maa n ṣan awọn kokoro aigojuri inu ẹnu si isalẹ, eyi si maa n jẹ ki eniyan ni eyin ati erigi to ji pepe.
Oríṣun àwòrán, NurPhoto
2. Irẹwẹsi ninu agọ ara: ti eniyan ko ba mu omi to, eyi maa n jẹ ki omi dinku ni agọ ara nitori naa ara yoo maa rẹwẹsi, nitori pe iṣẹ pupọ ni fun ọkan gẹgẹ bi a ṣe mọ pe oun lo pọn ẹjẹ si ara, omi maa n pese afẹ ninu ara pẹlu, nitori naa ti iṣẹ ba ti poju fun ọkan irẹwẹsi yoo baa.
Nitori naa ti ara rẹ ba n fa tikọ nigbogbo igba kọda lẹyin ti o sun daada doju ami, o se pataki ki moju to dede omi ti o n mu.
3. Eniyan yoo maa ṣe aisan nigba gbogbo: Omi maa n ran ara lọwọ lati fọ idoyi ati awọn majele to wa ninu ara kuro, o si maa n fun eroja to maa n gbogun ti aarun lara lagbara.
'Mo kàn máa ń lọ́ ayẹyẹ kiri torí ijó láì ṣe pé wọ́n pe mí ló sọ mí di DJ olórin Fuji nìkan'
Ti omi ko ba to lagọ ara, o ṣeeṣe ki eniyan maa dubulẹ aisan ni gbogbo igba nitori ko si nkan ti yoo ba awọn kokoro to n fa aisan ja.
4. Ounjẹ ko ni da ninu: Omi maa n jẹ ki ounjẹ da ni kiakia, bakan naa ni o maa n jẹ ki eniyan maa lọ ile igbọnsẹ loorekoore.
Ti eniyan ko ba mumi bi o ti yẹ, omi to wa ni ara igbẹ eniyan ni agọ ara yoo mulo, eyi yoo si mu ki igbẹ iru ẹni bẹẹ le koko. Maa mu omi dede lati jẹ ki igbẹ rẹ rọ, ki ounjẹ si da lasiko ti o yẹ.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
5. Ara rẹ ko ni jọlọ daada: Omi maa n jẹ ki ara tutu to si maa mu ki awọn sẹẹli awọ ji pepe, ki si dabi ti ọmọ tuntun.
Sugbọn ti omi mimu ko ba to o ma njẹ ki awọ ara ṣe rakọrakọ ti o si yi bi ara agiliti. Iṣẹ to saba maa n se ni lati fọ idọti to le fa idiwọ kuro ninu ara, ti o ba n lo ipara olowo nla lati mu ki awọ rẹ jọlọ to si dabi ẹni pe ko ṣiṣẹ, gbiyanju omi Mimu deede.
6. Oo nifẹ lati maa mu tabi jẹ nkan didun ni gbogbo igba: Ti omi o ba to ni ara, ara ko ni le lo okun to nilo lasiko too nilo rẹ nitori naa yoo maa wa ohun amuṣagbara kiakia eyi ti o le ri ninu ṣuga ati awọn nkan didun miran.
Oríṣun àwòrán, Per-Anders Pettersson
7. Itọ rẹ yoo dinku: Ti ara ba gbẹ fun omi to nilo, ọkan yoo gba gbogbo omi to ri ni ayika lati le mu iṣẹ pipọ ẹjẹ tẹsiwaju, nitori naa ko ni si omi pupọ to ṣẹku ni ara fun itọ bi o ti yẹ.
Ti eniyan ko ba mu omi to, itọ eniyan le ni awọ ti ko ba oju mu to, ki o maa pọn tabi ki o ni oorun to lagbara ju bi o ṣe yẹ lọ.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Bakan naa eniyan le ni aarun to niṣe pẹlu oju ara (UTI). O o mọ pe oun mu omi bi o ti yẹ ti o ba n lọ ile igbọnsẹ looree koore ti itọ rẹ si mọ, ti ko pọn ti ko si tun ni oorun.
Nitori naa to ba jẹ pe iwọ kii mu omi bi o ti tọ, bi ọdun ṣe n lọ si opin yii jẹ ki o jẹ ipinu ọdun tuntun rẹ lati maa mu omi bi  o ti tọ ati bi o ti yẹ.
'Ọ̀lọ́pàá shátà mi láti Mowe dé Magboro dé Shagamu, wọ́n ní ṣé mi ò mọ̀ pé ìjọ́ba ni mo ṣiṣẹ́ fún'
Nollywood actors death 2020: Wo àwọn gbajúgbajà òṣèré fíìmù Yoruba àti olórin tí kò rí ọdún tuntun 2021
Oríṣun àwòrán, ...
Ohun toju ri lọdun 2020 to n kogba wọle lọ yii ti kuro ni keremi koda ti wọn ba n bi gbogbo eeyan lagbaye nipa iriri, ko si ẹni ti ori rẹ dọta ti ko ni lee sọ nkankan.
Ẹwẹ, isọri isọri ni awọn nkan to ṣẹlẹ, bi ko ṣe rọgbọ fawọn kan lo n dun yafunyafun fawọn mii.
Bi ọdun 2020 ṣe san awọn mii si owo, ọmọ ati aiku baalẹ ọrọ, bẹẹ lo gba owo iṣẹ, ọna atijẹ koda o tun gba awọn ẹbi awọn mii.
'Mo kàn máa ń lọ́ ayẹyẹ kiri torí ijó láì ṣe pé wọ́n pe mí ló sọ mí di DJ olórin Fuji nìkan'
Lara awọn to ṣọfọ ti wọn kẹdun awọn eeyan wọn to dagbere faye ni idile awọn oṣere ati olorin Yoruba kan to fi mọ agbo oṣere Tiata lapapọ.
Pa Kasumu (Kayode Odumosu)
Oríṣun àwòrán, Twitter
O ti to ọjọ diẹ ti iroyin pe aisan n ba gbajugbaja agba oṣere, Kayode Odumosu ti ọpọ mọ si Pa Kasunmu finra ti wa lode.
Koda ko si afibo nibẹ tori oun funrarẹ sọrọ jade pe adura kikan kikan loun nilo latọdọ awọn eeyan kii ṣe owo amọ ti awọn akẹgbẹ rẹ to fi mọ awọn ọdọ ninu awọn oṣere gan dide iranwọ fun un.
"Foluke Daramola to jẹ ọkan lara awọn ọdọ ipele eyi to pọwọle awọn agbaagba ni ""eyan daada ni wọn yatọ si pe wọn jẹ oṣere tiata.Iku wọn jẹ eleyi to fi ọwọ kan wa lẹmi''."
Awọn dokita ni o ni aisan rọpa rọsẹ, amọ iroyin sọ pe ailera rẹ tun buru sii lẹyin to pada de lati orilẹede India to ti lọ fun itọju.
Ni ile iwosan aladani kan ni agbegbe Lantoro, Abeokuta ni ipinlẹ Ogun ni oloogbe yii dakẹ si.
Osuntoun (Musiliat Arikeusola)
Oríṣun àwòrán, OTHER
"Ko si ẹni to ba n wo awọn ere ibilẹ Yoruba to kun fun aṣa, iṣe ati igbagbọ ẹya Yoruba ti ko ni mọ mama, Ọṣuntoun paapaa julọ nitori awọn ipa awọn ""ẹlẹmi agba"" to ko ninu awọn ere oloogbe Yẹkini Ajilẹyẹ."
Lara awọn ere ti oloogbe Osuntoun ti kopa ni Koto Orun, Aye Akamara, Koto Aye, ti gbogbo rẹ jẹ latọwọ oloogbe Ajilẹyẹ.
Oloogbe Ọṣuntoun funrarẹ naa gbe awọn ere kan jade bii 'Omi Ipin,' 'Imi Esin' ati 'Ogun Omo Iya le', to jẹ ere ti o ṣe gbẹyin, gẹgẹ bi ọgbẹni Adedokun ṣe sọ.
Ile rẹ lagbegbe Ijẹtu nilu Osogbo ni Mama dakẹ si.
'Pásítọ̀ ló sọ fún mi pé Ọlọ́run pè mí láti di Olokun tó ń bọ omi'
Toromagbe nínú fíìmù ''Arelu''
Oríṣun àwòrán, Facebook
Ẹni ọdun mẹtalelọgọta ni Oloye Abdul Tawab Olaitan Ile-Aje Adeniyi ko to jade laye.
Oloye Abdul Tawab Olaitan Ile-Aje Adeniyi lo kọpa ninu ere agbelewo ti wọn ṣe ni ọdun 1986, ti wọn si pe akọle rẹ ni ''Arelu''.
Oloye Abdul Tawab Olaitan Ile-Aje Adeniyi ni o kopa gẹgẹ bi ''Toromagbe'' ninu fiimu naa, to si jẹ ọkọ fun ''Ọwọ otori'' ti wọn gbe ninu aginju ninu fiimu kan naa.
Oloye Abdul Tawab Olaitan Ile-Aje Adeniyi pe ara rẹ ni araye-rọrun nitori iji gbe e lọ fun ọjọ mẹrinla lasiko ti wọn n ṣe fiimu ''Arelu'', ti o ni oun si le sọ nipa igbeaye eniyan nipa wiwo ọwọ rẹ.
Ogun Majek
Oríṣun àwòrán, Others
Gbolagade Akinpelu ti ọpọ eeyan mọ si Ogun Majek ti n ṣe àìsàn láti ọjọ́ mẹ́ta kan, kó tó kú ní Ọjọru.
Ilumọọka ni osere tiata Gbolagade Akinpelu, ti ọpọ eeyan mọ si Ogun Majek.
Ọrẹ timọtimọ ni Ogun Majek ati Musiliu Dasofunjo ti wọn tun jọ jẹ oṣere tiata, ti ọpọ eeyan mọ si Esu laalu.
Dasofunjo ni wọn gbe Majek digbadigba lọ si ileewosan UCH ni Ibadan, nigba ti aisan rẹ fẹ bọwọ sori amọ ẹpa ko boro mọ.
O fikun wi pe, kii se pe agba lo de si ọrẹ oun nitori ọjọ ori rẹ ko tii to nnkan, amọ asiko ti to, ni Majek fi di ero ọrun.
Aisan kidinrin ati aisan itọ suga ni Majek ti n ba finra fun ọpọlọpọ ọdun ko to jade laye.
Majek Fashek
Oríṣun àwòrán, Others
Gbajugbaja olorin Raggae ni Majekodunmi Fasheke, ọmọ Yoruba si ni amọ ti wan mọ ọ gẹgẹ bii gbajumọ lagbaye.
Orilede Amẹrika ni eto isinku rẹ ti waye nibi tawọn mọlẹbi rẹ nikan ti kopa nibẹ. Alamojuto ẹgbẹ akọrin rẹ Uzoma Omenka sọ eyi pe ki awọn eeyan ma binu toripe Covid-19 ko jẹ kawọn le wa sin in si Naijiria.
Majek Fashek tí wọ káà ilẹ̀ lọ!
Prisoner of conscience, Send down the rain, Little little patience, One Love, No woman no Life ati ọpọlọpọ ni awan orin to kọ nigba aye rẹ.
Ni ọjọ Aje, ọjọ kini, oṣu kẹfa, ọdun 2020 ni Majek Fashek jade laye lẹni ọdun mẹtadinlọgọta.
Ọjọgbọn Ayo Akinwale
Oríṣun àwòrán, Etsu Muazu Idris/Facebook
Wọn bi gbajugbaja oṣere fiimu ati olukọni ere ori itage, Ọjọgbọn Ayo Akinwale ni ilu Ibadan, ọmọ bibi ilu Ibadan si ni pẹlu.
Ẹni ti Ọlọrun da ti ko ṣee fara we ni Ọjọgbọn Ayo Akinwale. O mu gbogbo akẹkọọ bi ọmọ rẹ, oloju aanu si ni. Oludari ẹka imọ ẹkọ ere idaraya ni fasiti Ilorin, Abdulrasheed Adeoye sọ fun BBC Yoruba.
Gbogbo oye to yẹ keeyan gba ninu imọ iṣẹ Tiata lo gba nigba aye rẹ- oye Diploma, Degree, Masters, PhD ni ẹka Tiata fasiti ilu Ibadan.
Agbaọjẹ ni ti awan agbaagba orilẹede Naijiria gan mọ to bẹẹ ti aarẹ Buhari daro rẹ nigba to ku.
Lara awọn ere to ti kopa ni Afonja, Sango, Ladepo Omo Adanwo, Iranse Aje, Agbara Obinrin.
Ayo Akinwale jade laye lọjọ kẹtala oṣu kẹsan ọdun 2020 ni ile iwosan fasiti Ilorin.
Jimoh Aliyu
Oríṣun àwòrán, NTA ado-ekiti/city people magazine
Jimoh Aliu ṣe gudugudu meje ati yaya mẹfa lati mu iyatọ ba iṣẹ tiata lori mohunworan koda o tun ti jẹ ọmọ ologun ri nigba aye rẹ.
"Ko to ku, Aliu n ṣiṣẹ lori fiimu maarun, ti ireti wa pe awọn agbaagba oṣere Nollywood yoo kopa ninu rẹ. Ṣugbọn, iku mu u lọ lasiko to n ya ọkan ninu rẹ to pe akọle rẹ ni ""Olowo Ite""."
Oun ati gbajugbaja oṣerebinrin, Folake Aremu 'Oriṣabunmi', ti fi igba kan jẹ tọkọ-taya, kii wọn o to tuka lẹyin ogun ọdun.
Yatọ si Oriṣabunmi, O ni iyawo meji miran - Queen Bola ati Folashade.
Jimoh Aliyu ti ọpọ mọ si Aworo jade laye lẹni ọgọrin ọdun ni ọjọ kọkandilogun oṣu kẹsan ọdun 2020.
Gbenga Ajumoko
Oríṣun àwòrán, OTHERS
Gbajugbaja ni Gbenga Ajumoko naa laarin awọn agba oṣere fiimu Yoruba.
Oṣere ati onkọwe ni. Iroyin jade nigba kan pe o dubulẹ aisan nileewosan kan fun nkan bii oṣu mẹfa ni Sagamu Remo.
Iroyin ni o kọkọ n da ara rẹ tọju ni ki aisan naa to burẹkẹ sii ti wọn wa gbe e lọ si ile iwosan aladani kan ni ilu Ibadan nibi to dakẹ si.
Diẹ lara awọn iṣẹ ere to ti kopa ko to ku ni Enikeji (2017), Agbere (2017), Yeye Efun, Wound (2019), Ako Okuta (2018).
'Ọ̀lọ́pàá shátà mi láti Mowe dé Magboro dé Shagamu, wọ́n ní ṣé mi ò mọ̀ pé ìjọ́ba ni mo ṣiṣẹ́ fún'
Alhaji Yekeen Omobolanle (Baba Lẹgba)
Oríṣun àwòrán, Others
Wọn ṣàpèjúwe Baba Lẹgba gẹgẹ bi baba awọn oṣere nigba aye rẹ to ko awọn eniyan mora.
"Ẹni to jẹ adari ẹgbẹ awọn oṣere Yoruba ni ipinlẹ Ogun, Owolabi Ajasa ni ""bi o tilẹ jẹ pe oloogbe naa kii ṣe ọmọ ẹgbẹ oṣere TAMPAN nigba aye rẹ, to jẹ wi pe ọmọ ẹgbẹ ANTP ni, sibẹ o sunmọ gbogbo awọn oṣere""."
Aisan to rọmọ ọjọ ogbo lo ṣe Baba legba to fi papoda, amọ, ede aiyede to ṣẹlẹ laarin ẹgbẹ TAMPAN ati ANTP, lo mu ki ọpọ ma ri i mọ pupọ lori itage.
Baba Lẹgba lo maa n sere awada pẹlu baba Sala laye ọjọsi, ki agba to de.
Agba ọjẹ osere tiata naa jade laye nile rẹ to wa nilu Abeokuta nipinlẹ Ogun.
Toyosi Arigbabuwo
Oríṣun àwòrán, Toyọsi Arigbabuwo
Ọkan lara awọn ọrẹ timọtimọ Toyọsi Arigbabuwo ti wọn jọ n sisẹ tiata, Alhaji Musiliu Dasọfunjo salaye pe Arigbabuwo jẹ akikanju eeyan pupọ pupọ.
Isẹ aransọ ni Toyọsi kọkọ kọ nigba aye rẹ ko to ya si idi isẹ tiata, to si n fi ẹsa ẹkun iyawo kewi, eyi ti awọn eeyan mọ si, ko to wa da ẹgbẹ tiata tiẹ silẹ taa mọ Toyọsi Arigbabuwo Theather Group.
Bí ìtàn ayé Toyosi Arigbabuwo ṣe lọ rèé láti ẹnu Musiliu Dasofunjo àti Ogun Majek
Lẹyin eyi, o bẹrẹ si ni se ere fun ileesẹ mohunmaworan ijọba apapọ lasiko to wa ni WNTV ko to wa di NTA bayii.
Inu oṣu kini nibẹrẹ ọdun 2020 ni o dagbere faye.
Laditi (Femi Oyewunmi)
Oríṣun àwòrán, Facebook/Prince Kehinde Oyewunmi
Ọmọba Oyewunmi ni a gbọ pe o ti n ṣaisan fun ọjọ pipẹ, koda ọrẹ rẹ,Ọgbẹni Sayo Alagbe fidi rẹ mulẹ pe o ṣiṣẹ abẹ lori ẹyin rẹ.
Oloogbe Oyewunmi kopa ninu awọn ere tiata bii Aye Toto, Koto Ọrun, Ija Eleye atawọn ere tiata.
O jade jaye lẹni ọdun mẹrinlelọgọta lọjọ kejilelogun oṣu karun un ọdun 2020.
Tunde Bakare: Àwọn èèyàn kò gbọ́ ìwàáṣù mi délẹ̀, kí wọn tó bú mi lórí ọ̀rọ̀ Tinubu
Oríṣun àwòrán, @T_Bakare/@AsiwajuTinubu
Olusọagutan Tunde Bakare, ti i se asaaju ijọ Citadel Global, ti yọ suti ete sawọn eeyan to n foju laifi wo oriyin to gbe fun ipa ti Bola Tinubu ko si idagbasoke orilẹede yii.
Bẹẹ ba gbagbe, fidio kan lo lu sori ayelujara laipẹ yii, ninu eyi ti Bakare ti yonbo asaaju ẹgbẹ APC naa ninu iwaasu to se lori pẹpẹ ijọ rẹ.
Gbajugbaja oniwaasu naa si lo fi Tinubu we Jephtar ninu bibeli, pẹlu afikun pe gbajumọ oloselu naa ti ja ọpọ ogun fun ilọsiwaju ilẹ Yoruba.
Bakan naa lo ni o ti gba ipinlẹ Eko atawọn ipinlẹ yoku nilẹ Yoruba silẹ lọwọ ifiyajẹni ẹgbẹ oselu PDP laarin ọdun 1999 si 2007.
Iwaasu yii lo mu awuyewuye dani, ti ọpọ si n kọminu pe ki lo de ti Tunde Bakare ti ti laali Tinubu tẹlẹ, se wa yipada maa kọrin re ki i.
Oríṣun àwòrán, @T_Bakare
Nigba to n fun awọn alariwisi rẹ lesi ọrọ wọn, Bakare wa se apejuwe awọn eeyan to n bu ẹnu atẹ lu naa gẹẹ bii 'Agbokujo'.
O ni kii se pe oun gba owo lọwọ Tinubu, ki oun to kọrin rere kii, bẹẹ ni ko si ẹni to lowo lọwọ to bẹẹ lati sanwo isẹ fun oun.
O tun kesi awọn eeyan to n yọ suti ete si pe o ti gba owo ẹyin, lati fi ẹri to daju lelẹ, ti wọn ba ni lọwọ.
Ninu iwaasu miran to se lọjọ Aiku ana, eyi ti Bakare pe akori rẹ ni 'Ko si ẹni to mọ bii Ọlọrun', wa n beere pe ki lo de tawọn eeyan fi n tako oun lai gbọ ẹkunrẹrẹ iwaasu naa delẹ tan.
Oríṣun àwòrán, @AsiwajuTinubu
Bakare ni ọwọ Ọlọrun ni idajọ wa, ko si yẹ ki awọn eeyan maa fi iwanwara se idajọ ọmọnikeji nitori iwa ti wọn ti hu sẹyin.
O fikun pe lootọ ni oun yonbo Tinubu nipa awọn aseyọri to se nidi oselu amọ eyi ko tumọ pe oun fara mọ igbe aye rẹ
Jude Chukwuka: Wò ó bí òwé Yorùbá ṣe yọ̀ lẹ́nu ọmọ Igbo
Ojisẹ Ọlọrun naa ni nigba ti ọpọ eniyan n sun, Tinubu n sisẹ kara lati fi awọn eeyan rẹ sibi to lagbara.
O ni yoo nira fun ẹnikẹni lati bori oludije ti Tinubu ba ti lẹyin nipinlẹ Eko nitori akoko ko tii to fun wọn.
Oríṣun àwòrán, Sokoto catholic Diocese
Wayi o, Bisọọbu ijọ aguda ti Sokoto Ẹniọwọ, Matthew Kukah ni aarẹ Muhammadu Buhari ti fi ọjọ iwaju Naijiria rubọ nitori ifẹ ati ipinu rẹ lati mu ki iha Arewa Naijiria maa jẹgaba lori ẹya to ku.
Kukah sọ eyi ninu atẹjade iwe ikini rẹ fun ọdun keresimesi to pe akọle rẹ ni A Nation in Search of Vindication.' O ni Naijiria wa ninu okunkun birimu labẹ akoso aarẹ Buhari, ati pe o ṣe pataki ki aarẹ ṣalaye nkan to wa ni idi itajésilẹ ojoojumọ nitori eto abo to mẹhẹ.
O ṣapejuwe orilede Naijiria bi eyi ti ara ilu rẹ n rinrin ajo ọkọ oju omi ṣugbọn ti ko si awakọ, iwe irina ati ebute ibi ti yoo ti sọkalẹ.
"Kukah ni "" Aarẹ Buhari nilo lati ṣalaye fun ọmọ Naijiria ibi ti o ń dari ọkọ wọn lọ gan nitori pe o jọ pe inu okunkun birimu ni. ""Itajẹ silẹ ojoojumọ ti pọju o si kọja afẹnusọ, ṣe bi awọn oniṣẹ ibi yii yoo ṣe di ara ilu  lọwọ ati ẹsẹ ree abi o ti di nkan ti a o maa ba gbe titi lai?"""
"Aarẹ Buhari mọọmọ fi iran awọn ọmọ orilede yii to dibo fun rubọ ni, ó jọ bi ẹni pe, o ni ileri kan to gbọdọ muṣẹ fun awọn Arewa nitori naa o gbọdọ sọ ẹya toku di boo ba o pa a"" boo ba o bu u lẹsẹ. Imọ tara ẹni nikan ni aarẹ ni ṣe lai fi ti ara ilu ṣe."""
Oríṣun àwòrán, Kukah
'Mo kàn máa ń lọ́ ayẹyẹ kiri torí ijó láì ṣe pé wọ́n pe mí ló sọ mí di DJ olórin Fuji nìkan'
 Gbogbo ọmọ Naijiria ti ko ba ni parọ tan ara rẹ mọ pe ẹnikéni ti kii ṣe musulumi lati iha Arewa ko dan ida kan nkan ti aarẹ Muhammadu n dáwo lọọwọlọwọ bayii ti yoo si mujẹ bẹẹ. Awọn ọmọ ologun yoo ti ditẹ gba ijọba tipẹ tabi ki orilede yii ti béré ogun.
O ni nitori iwa aibikita aarẹ ajalu lori arelu ni aburu to n de ba Naijiria, orilede yii ti wa ninu wahala ati isoro to n ranju mọ ara ilu kọọkan.
Oríṣun àwòrán, Kukah
Ọpọ ala ati iran ara ilu lo si ti sọnu pẹlu, wọ́n ti ji ọrọ gbogbo ilu gbe, ti iwa ajẹbanu si ti ni éka loriṣiriṣi, awọn mitan ti gba émi ara wọn pẹlu.
Ẹwẹ, o rọ gbogbo ara ilu lati ma sọ ireti nu loju gbogbo isoro yii, inira, ibanuje ati ainireti to kun orilede Naijiria
Igbajo Osun King dead: Lẹ́yìn ìpapòdà Owa Igbajo, Ọba Fashare, àwọn afọbajẹ bẹ̀rẹ̀ ètùtù
Oríṣun àwòrán, Gbagede.com
Awọn igbimọ afọbajẹ ilu Igbajọ ni awọn ti bẹrẹ etutu ipapoda kabiyesi Ọwa ilu Igbajọ, Ọba Olufẹmi Fashade to waja.
Nibi ifọrọwerọ pẹlu awọn akọroyin to waye lj Aje, Oloye Adegboyega Awomọnlo to jẹ Aṣiwaju ilu Igbajọ ṣalaye pe wọn ti fi ọrọ naa to ijọba ipinlẹ Ọṣun leti pe Ọwa ti waja.
O fi kun un pe awọn etutu ati eto gbogbo to yẹ ti bẹrẹ. Bẹẹ si ni gbogbo awọn alẹnulọrọ nipa oyejijẹ ni ilu Igbajọ naa ti gbọ sii.
Ni ọgbọn ọdun sẹyin ni Ọba Fashade gun ori itẹ.
Iroyin kaakiri n sọ pe, kabiyesi Ọbalaye ilu Igbajọ, Ọwa Ilu Igbajọ Ọba Olufẹmi Adeniyi Fashade  ti waja.
Gẹgẹ bi iroyin ti a gbọ, Ọwa ilu Igbajọ waja lẹyin aarẹ ranpẹ to ṣe e.
Ni ọdun 1990, tii ṣe ọgbọn ọdun sẹyin ni Ọba Olufẹmi Fashade gun ori itẹ gẹgẹ bi Ọwa ti ilu Igbajọ ki o to jade laye.
Bi o tilẹ jẹ pe awọn igbimọ afọbajẹ ni ilu Igbajọ ko tii sọ ohunkohun lori iṣẹlẹ yii, igbagbọ ọpọ ọmọ ilu naa ni pe o di igba ti wọn ba ti pari gbogbo etutu ti wọn ba fẹ ṣe.
Gẹgẹ bi a ṣe gbọ, ẹni ọdun mẹtalelọgọrin ni Kabiyesi Ọwa ilu Igbajọ ki o to darapọ mọ awọn alalẹ.
A o maa mu ẹkunrẹrẹ wa fun yin nipa iroyin yii bo ba ṣe n jade.
Nollywood Yoruba: Allwell Ademola ní ara ọ̀nà àti máa dá aráàlú lárayá ló mú kí òun máa ṣe ọjọ́ ìbí 35 lọ́dọọdún
Oríṣun àwòrán, Instagram/allwellademola
Ni ohun to faa ti oun fi maa n ṣe ọjọ ibi karundinlogoji lọdọọdun ko ju wi pe oun fẹ maa mu inu awọn eeyan dun.
O ni oun kan fi n da awọn eeyan lara ya ni ati pe oun kii ṣe ọmọ ọdun ọdun marundinlogoji rara.
O ni ko rọrun ni ibẹrẹ fun oun lati bẹrẹ ere tiata; gẹgẹ bi o ṣe sọ, ere ọlọsọọsẹ ni oun fi bẹrẹ ni ileeṣẹ mohunmaworan apapọ ilẹẹwa NTA nigba naa.
O fi kun un pe ọdun ti baba oun yọnu si ere tiata ti oun n ṣe lo jade laye.
Gbajugbaja oṣere tiata naa ṣalaye pe pe Allwell Ademọla ni orukọ oun nitootọ nitori pe idamu kekere kọ ni oun fun iya oun ninu oyun, gẹgẹ bi awọn eeyan sọ sọ.
Oríṣun àwòrán, Instagram/allwellademola
"O ni itan sọ fun oun pe bi oun ṣe da iya oun laamu ninu oyun lo mu ki iya oun pariwo All is Well, iyẹn ni pe ""O dara""."
O ni sisanra oun fun oun ni ọpọlọpọ ipenija nigba ti oun bẹrẹ iṣẹ tiata. O ni ọpọlọpọ ni wọn maa n san fun oun pe ipa mama loun lee ko ninu ere sinima nitori pe oun sanra. O wa rọ awọn obinrin lati maṣe jẹ ki awọn eeyan o fi sisanra wọn bu irẹwẹsi sinu ọkan wọn.
Bakan naa lo ṣalaye lori igbeyawo rẹ ti awsn eeyan kan n sọrọ le lori pe ọrẹ ọkọ ounloun fẹ.
Oríṣun àwòrán, instagram/Allwell
Allwell Ademọla ṣalaye pe ọrẹ oun ni ọkunrin naa lati ipilẹ. Nigba ti oun ati ọkọ ti oun fẹ fẹ pade lo mu ko mọ ọrẹ oun naa ti awọn mejeeji si di ọrẹ.
Amọṣa o ni ọkọ oun ku nigba to ku diẹ ki wọn gbeyawo, bakan naa si ni afẹsọna ọrẹ ọkọ oun naa to tun jẹ ọrẹ oun fi silẹ lẹyin ọdun mẹjọ.
"Eyi lo mu ko kọnu ifẹ si oun lẹyin igba diẹ pe "" a ko kuku mọ nnkan ti Ọlọrun ọba fi ṣe."" Bi o tilẹ jẹ pe o ni oun kọkọ faake kọri lori ọrọ naa, ṣugbọn lẹyin ọpọlọpọ imọran oun gba fun un."
Amọṣa, o ni nitori awọn nnkan kan to ṣẹlẹ ajọṣepọ naa ko ju oṣu mẹjọ ti wọn fi tuka.
Lara awọn ibeere to tun tan imọlẹ si ni ajọṣepọ to wa laarin oun ati Sunkanmi. Allwell Ademọla ni lootọ ajọṣepọ wa laarin oun ati Sunkanmi ṣugbọn ajọṣepọ ẹgbọn si aburo, ẹni to gbe eeyan dide ti ko si ni fẹ ki teeyan o bajẹ ni.
Àwọn àmi méje tó ń tọ́ka sí pé oò kí ń mu omi bí ó ti tó
'Pásítọ̀ ló sọ fún mi pé Ọlọ́run pè mí láti di Olokun tó ń bọ omi'
Ibadan Jungle Justice: Àwọn èèyàn kan ní alárùn ọpọlọ ni Saheed, tawọn mii ni ajínigbé ni
Oríṣun àwòrán, @essienudom
Fun igba ti ko fẹrẹ ṣee ka mọ bayi lẹnu ọjọ mẹta yii ni ilu Ibadan,  iṣẹlẹ idajọ ọwọ miran tun waye.
Eeyan meji ọtọọtọ l'awọn ero dana sun lagbegbe ASAS ni Molete  ati Oke Ado ni ilu Ibadan lọjọ Aje.
Agbegbe Oke Ado ni wọn ti kọkọ dana sun ọkunrin kan ki ekeji to waye lagbegbe ASAS ni Molete.
Amọṣa, oniruru iroyin lo n waye lori ohun to ṣokunfa bi wọn ṣe dana sun arakunrin ti wọn pa lagbegbe Oke-Ado.
Bi awọn eeyan kan ti isẹlẹ naa soju wọn ṣe n wipe ajinigbe ni Saheed, lawọn miran n wipe kii ṣe ajinigbe, aarẹ ọpọlọ diẹ lo n ṣe e.
Oríṣun àwòrán, @essienudom
Awọn to pe e ni ajinigbe ṣalaye pe, Saheed pọn ọmọlangidi ti ọpọ mọ si 'bebi' si ẹyin, eleyii to maa fi n tan awọn ọmọde lagbegbe naa.
Olugbe agbegbe naa kan la gbọ pe o pariwo sita nigba to ni oun ri Saheed to n tan ọmọ ọdun mẹrin kan pẹlu erongba lati ji gbe. Bi aladugbo wa ṣe mọ pe Saheed fẹ ji ọmọde naa gbe ni, ko tii si ẹni to le sọ.
Eyi ni won pe o mu ki ọpọ ero lagbegbe naa ya bo o.
Ọrọ naa tun le sii nigba ti wọn ni wọn ba ẹgbẹrun lọna igba ati aadọta naira lara rẹ.
'Pásítọ̀ ló sọ fún mi pé Ọlọ́run pè mí láti di Olokun tó ń bọ omi'
Ẹwẹ, ọkan lara awọn olugbe agbegbe Odo Ọna nibi ti wọn ni Saheed n gbe ṣalaye pe, aisan ọpọlọ lo n ba Saheed finra diẹdiẹ, ati pe kii ṣe ajinigbe gẹgẹ bi wọn ṣe sọ.
Ẹni naa ti wọn pe orukọ rẹ ni Bamidele Emmanuel salaye pe, iṣẹ agbaṣe ọkọ fifọ ati agbaru lo maa n ṣe fawọn eeyan lagbegbe naa.
O ni iṣẹ dẹrẹba lo n ṣe tẹlẹ ati pe aisan naa de si i lẹyin ti wọn ji ọkọ bọọsi to n wa lọ.
Zlatan: Ọ̀rẹ́ ni mo sìn lọ ‘studio’ tí mo fi bẹ̀rẹ̀ orin lẹ́yìn tí mo kùnà ìdánwò WAEC
O ni ọlọkọ bọọsi naa ko gbagbọ pe wọn ji ọkọ naa lọ ni, eyi to mu ko fi Saheed sun ni agọ ọlọpaa; lẹyin to kuro ni agọ ọlọpaa naa ni aisan ọpọlọ naa bẹrẹ.
Iṣẹlẹ idajọ ọwọ ti di eyi to n fi ojojumọ waye ni ipinlẹ Ọyọ bayii to si nkọ lominu nibẹ.
Ileeṣẹ ọlọpaa wa bu ẹnu atẹ lu bi awọn eeyan ṣe n fi idajọ si ọwọ ara wọn bayii, eyi ti wọn ni o ti wa n di lemọlemọ, paapaa ni ilu Ibadan ati ipinlẹ Ọyọ lapapọ.
'Ọ̀lọ́pàá shátà mi láti Mowe dé Magboro dé Shagamu, wọ́n ní ṣé mi ò mọ̀ pé ìjọ́ba ni mo ṣiṣẹ́ fún'
Atẹjade kan lati olu ileeṣẹ ọlọpaa ipinlẹ Oyo ṣalaye pe, kọmiṣọna ọlọpaa ni ipinlẹ naa ti jawe ikilọ ranṣẹ sawọn to kundun idajọ ọwọ nibẹ ati pe ẹnikẹni ti ọwọ ba tẹ yoo kabamọ ṣiṣe bẹẹ.
Oríṣun àwòrán, @PoliceNG
Eeyan meji ọtọọtọ l'awọn ero dana sun lagbegbe ASAS ni Molete ati Oke Ado ni ilu Ibadan lọjọ Aje.
Amọṣa ori ko eeyan kan miran yọ nigba ti awọn oṣiṣẹ ikọ Amọtẹkun gba a silẹ lọwọ awọn ero to n binu naa.
Awọn ọlọpaa ni ko tii si ẹni to lee sọ pato ohun to ṣẹlẹ tawọn eeyan fi da ina sun awọn mejeeji yii.
Iṣẹlẹ idajọ ọwọ ti di eyi to n fi ojojumọ waye ni ipinlẹ Ọyọ bayii,eyi to si nkọ ọpọ eeyan lominu nibẹ.
Jude Chukwuka: Wò ó bí òwé Yorùbá ṣe yọ̀ lẹ́nu ọmọ Igbo
Eeyan ti ori ko yọ naa ni wọn ṣalaye pe, o ṣi n gba itọju lọwọ nile iwosan awọn ọlọpaa to wa lagbegbe Ẹlẹyẹle ni ilu Ibadan.
Ileeṣẹ ọlọpaa bu ẹnu atẹ lu bi awọn eeyan ṣe n fi idajọ si ọwọ ara wọn bayii eyi ti wọn ni o ti wa n di lemọlemọ bayii ni ilu Ibadan ati ipinlẹ Ọyọ.
Atẹjade kan lati ileeṣẹ ọlọpaa ni ipinlẹ ṣalaye pe, kọmiṣọna ọlọpaa ni ipinlẹ naa ti jawe ikilọ ranṣẹ sawọn to kundun idajọ ọwọ nibẹ ati pe ẹnikẹni ti ọwọ ba tẹ yoo kabamọ ṣiṣe bẹẹ.
Oríṣun àwòrán, undark magazine
Saaju la ti mu iroyin wa fun yin pe opo ina mọnamọna ti wo pa ọlọkada kan ati obinrin kan  lagbegbe Iwo road ni ilu Ibadan.
Gẹgẹ bi iroyin ṣe sọ, ọlọkada naa ati obinrin ọhun n dunadura lori iye owo ni lasiko ti opo ina naa fi wo luwọn ni ina ara waya ori rẹ si pa wọn.
Awọn eeyan agbegbe naa pe orukọ ọlọkada naa ni Kabiru ṣugbọn wọn ni oluyọle ni ọpọlọọ eeyan mọọ si.
Awọn ti iṣẹlẹ naa ṣe oju wọn ṣalaye pe olounjẹ ni arabinrin naa, o si wa si agbegbe naa ni lati wa gba ẹgbẹrun kan naira ti ọkan lara awọn ọlọkọ ero lagbegbe naa jẹ ni ki iṣẹlẹ buruku naa to ṣẹlẹ.
Amọṣa, ileeṣẹ mọnamọna ẹkun Ibadan, IBEDC ti darukọ awọn ti ina gbe naa ti wọn si pe orukọ wọn ni Ọgbẹni Ọladeji Ọlatunji pẹlu Arabinrin Kẹmi Degoke.
Wọn lawọn ba awọn mọlẹbi wọn kẹdun.
Ninu atẹjade kan to fi sita lọjọ Abamẹta, ọga agba ileeṣẹ mọnamọna lẹkun Ibadan, IBEDC, ọgbẹni Jọhn Ayọdele ni awọn ti n ba awọn mọlẹbi naa jiroro lọna ati tu wọn ninu bi o ti wulẹ o mọ.
Bakan naa lo fi kun un pe igbesẹ ti bẹrẹ lori wiwadii bi iṣẹlẹ naa ṣe ṣẹ ati ohun gan to sokunfa rẹ.
Bone straight hair: Èlò ló bá dé, ibí tí wọ́n tí n ta àti ìbéèrè mí nípa irun àlàfẹ̀ yí
Oríṣun àwòrán, Teni/Instagram
Olorin Teni naa ba wọn kọwọrin lati fi irun yi ṣakọ loju opo ayelujara rẹ
Bi wọn baa n darukọ awọn ohun ẹṣọ ati oge tawọn obinrin n ran lẹnu ni Naijiria lẹnu lọọlọ yi, o di dankan ka darukọ Bone Straight Hair Wig.
Bẹẹ ni, bẹrẹ lọdọ awọn Slay Queen to fi dori awọn Mama o ni gba, niṣe ni wọn n fi irun afikun yi da awọn eeyan lọrun lori ayelujara.
Ninu awọn to ba wọn kọwọrin irun oge yi ni Tenimakanaki, gbajugbaja akọrin ọmọ Naijiria wa.
Loju opo rẹ lori ayelujara, niṣe lo fi aworan ara rẹ han pẹlu irun yii to si pe akọle rẹ ni ''SUGARMUMMY''
Bone Straight Hair -Ki gaan lo n jẹ bẹ?
Irufẹ irun awọsori fawọn obinrin ni Bone straight  jẹ to si gun daada bẹẹ lo tun lẹ lọwọ.
Nkan ta gbọ ni pe iru irun yi wa lorisirisi ni bo ti ṣe gun si. Awọn kan gun diẹ tawọn mii si gun gidi gaan.
Amọ ṣa ohun to jẹ iyalẹnu gẹgẹ bi aṣaraloge kan ti ṣe sọ fun BBC ni pe ''Bone Straight Hair'' ti wa tipẹ. Kii ṣe tuntun.
O ni ṣugbọn ''igba laye, asiko ti Bone Straight Hair lo de tawọn eeyan fi n ran ọrọ rẹ lẹnu.''
Ni ṣoki, gbogbo awọn ohun to yẹ ki o mọ nipa irun afikun yi ree:
Elo ni wọn n ta Bone Straight Hair ni Naijiria?
Bi o ba ti ṣe gun si, irufẹ rẹ ati iwọn rẹ ni wọn fi n ta iru irun yi ni Naijiria.
O le ri irun yi ra ni nkan bi ẹgbẹrun lọna ọgọta Naira si ẹgbẹrun lọna ọọdunrun Naira tabi ju bẹẹ lọ.
Irufẹ irun Bone Straight Hair to wa
Oríṣun àwòrán, tenimakanaki Instagram
Oloju kan Single Drawn[Bone Straight Hair]: Eleyi ni orisi irun ti wọn papọ ninu afikun irun naa.
Iru irun yi maa n ki dada lọwọ oke, bo ba de aarin, yoo diku to ba si wa kan isalẹ yoo tinrin gaan.
Owo tiẹ ko gunpa bi awọn irun Bone Straight to ku.
Alakanpọ meji Double Drawn [Bone Straight Hair]: Bakan naa ni iwọn gigun irun yi ṣe maa n ri.
Itumọ rẹ ni pe o kun loke, o kun laarin ati ni isalẹ sugbọn o wọn diẹ ju alakọkọ oloju kan lọ.
Onipele akanpọ Super Double Drawn [Bone Straight Hair]: Bi ẹ baa n gbọ pe o pọ, pọ pọ, irufẹ irun Bone Straight yi lo n jẹ bẹ.
Ninu ida ọgọrun, o kere tan o maa n ni ida marundinlaadọrun si ida aadọrun ti wọn gun bakan naa.
Bi o ba wọ iru irun taa n wi yii, yoo da bi ẹni pe irun rẹ gangan lo de sori. Ọga patapata awọn irun Bone Straight leyi jẹ.
Oríṣun àwòrán, Teni di Entertainer
Bi o ko ba si lowo lọwọ daada, ma ṣe ba wọn daṣa pe o fẹ ra iru irun yi.
Ibi to ti le ra irun [Bone Straight Hair] ni Naijiria?
O le ri irun yi ra lọdọ awọn to n ta irun paapa awọn to n gbe wa lati ilẹ Asia.
Lati ọdọ awọn to n gbe wa lati China, Vietnam ati awọn mii to wa ni Naijiria o le ri ra lọdọ wọn.
Ohun kan to maa n jẹ ki awọn obinrin maa fẹ ṣe ara wọn leṣe lori iru irun yi ni iye ti wọn n ta wọn.
Ibi owo rẹ ba mọ loo fi gbadun irun yii si lọrọ to wa nilẹ.
Nigerian Fraudsters: Ìwádìí BBC fihàn pé ìdajì àwọn gbájúẹ̀ lágbàyéé wá láti Nàíjíríà
Ileesẹ BBC se aknase iwadii kan nipa awọn ọdọ to n lu jibiti lati ori ayelujara taa mọ si Yahoo Boys ati ohun to sun wọn de ibẹ.
Iwadii naa si fi han pe ọpọ awọn gbajuẹ yii lo maa n lo oju opo BEC lori ayelujara lati dibọn bii ọga ileesẹ kan, ti wọn yoo si gba owo lọwọ ẹni to ba ba wọn dowo pọ.
Iwadii ọhun tun fi han pe orilẹede aadọta lagbaye ni awọn onijibiti naa wa amọ idaji wọn lo jẹ ọmọ Naijiria.
Bẹẹ ba si gbagbe, laipẹ yii si ni ọwọ tẹ gbajumọ onijibiti kan lati Naijiria, Ramon Abass, ti ọpọ eeyan mọ si Hushpuppi ati awọn mẹta miran.
Ọkan ninu awọn ọdọ gbajuẹ to ba BBC sọrọ ni oun fẹ lowo bi oludari oju opo Facebook, Mark Zuckerberg ni oun se n lu jibiti.
Fidio yii si lo tu asiri ọna tawọn ọdọ ọmọ Naijiria naa n gba lu jibiti naa atawọn ọsẹ ti wọn ti se.
2021 Prophecies: Ayodele ní ọwọ́ pálábá Abubakar Shekau yóò ségi lọ́dún tuntun
Oríṣun àwòrán, Facebook/Primate Babatunde Elijah Ayodele
Oludasilẹ ijọ INRI, Primate Elijah Ayodele ti gbe awọn asọtẹlẹ to le ni igba sita fun ọdun 2021.
Wolii naa, to maa n sọ asọtẹlẹ lọdọọdun nipa awọn isẹlẹ ti yoo waye ninu ọdun tuntun tun salaye pe awọn agbegbọn yoo tubọ kọlu ilu Abuja lọdun 2021.
Bakan naa lo tun ni aawọ to maa n waye laarin awọn agbẹ ati darandaran yoo tubọ pọ si ninu ọdun 2021 ati siwaju si, jakejado Naijiria.
Ko tan sibẹ, Wolii Ayodele ni laipẹ laijinna ni ọwọ palaba asaaju ikọ Boko Haram, Abubakar Shekau yoo segi, ti ina yoo si dilẹ lẹyin asunsunjẹ rẹ.
Nigba to n sọrọ lori epo rọbi, ojisẹ Ọlọrun naa sọ asọtẹlẹ pe awọn ileepo ifọpo rọbi to jẹ ti ijọba yoo tubọ dojude, ti wọn yoo si di akurẹtẹ amọ ileepo aladani ti Dangote kọ yoo gbinnaya.
Oríṣun àwòrán, Facebook/Primate Babatunde Elijah Ayodele
Bakan naa ni Ayodele sasọtẹlẹ pe o seese ki aarẹ to wa lori aleefa ati ọkan lara awọn aarẹ to ti jẹ tẹlẹ jade laye, ti omiran yoo si fi asọ penpe roko ọba.
O tẹsiwaju pe awọn gende agbebọn yoo kọlu awọn sọọsi pupọ ninu ọdun 2021, ti wọn yoo si tun maa ji awọn asaaju ijọ gbe lọ pẹlu.
Bakan naa lo ni ọpọ awọn oloselu ni yoo dero ọrun lairotẹlẹ nitori ikọlu oselu lọdun 2021.
Jude Chukwuka: Wò ó bí òwé Yorùbá ṣe yọ̀ lẹ́nu ọmọ Igbo
"Ikọlu nla yoo waye lati ọdọ awọn Darandaran si awọn agbẹ ni ẹkun ariwa ati ila oorun Naijiria, ti Ọlọrun si fi han mi pe ọpọ awọn darandaran naa ni wsn n lo fun awọn idi kan, ti asiri rẹ ko ni pẹ tu.
Saaju la ti sọ fun yin pe, oludasilẹ ijọ INRI Evangelial, Wolii Elijah Ayodele ti kede pe, ẹkun ariwa orilẹede Naijiria si ni ipo aarẹ yoo duro si lọdun 2023.
Wolii Ayodele, ẹni to n sọ asọtẹlẹ nipa awọn isẹlẹ ti yoo waye ninu ọdun tuntun 2021 wa sekilọ fun gbogbo awọn eeyan to n foju sọna pe ipo aarẹ yoo wa si guusu Naijiria lati gbagbe ero naa.
Ojisẹ Ọlọrun naa ni oludije fun ipo aarẹ mii lati ẹkun ariwa Naijiria ni Buhari yoo fa akoso Naijiria le lọwọ lẹyin ibo gbogbo gboo ọdun 2023.
Ẹkun ariwa Naijiria ko ni fi oju rere wo ẹya miran to ba fẹ gba akoso lọwọ ijọba Buhari, nitori naa, ẹlomiran lati apa oke ọya ni Buhari yoo fa akoso orilẹede yii le lọwọ."""
Kogi vs Bayelsa: Primate Ayodele sọ àsọtẹ́lẹ̀
Wolii Ayodele fikun pe igbesẹ naa le fa rogbodiyan lọdun 2023, eyi ti yoo buru pupọ ju awọn iriri laasigbo ti Naijiria ti foju wina rẹ sẹyin lọ.
O wa sekilọ pe o seese ko jẹ pe ibo ọdun 2023 naa ni yoo fopin si orilẹede ti wọn n pe ni Naijiria , eyiun tawọn alasẹ ba fi kuna lati se atunto orilẹede yii.
Yoo dara ki Naijiria se amulo ijọba apapọ tootọ tabi ko pin si yẹlẹyẹlẹ niotir ọrọ lee bẹyin yọ lẹyin ibo ọdun 2023.:
Bakan naa ni wolii naa wa n rọ asaaju ẹgbẹ oselu APC, Bola Ahmed Tinubu lati jami lori afojusun rẹ lati dije fun aarẹ orilẹede yii.
Nigerian Fraudsters: Ìwádìí BBC fihàn pé ìdajì àwọn gbájúẹ̀ lágbàyéé wá láti Nàíjíríà
Wolii Ayodele ni gbogbo erongba Tinubu, Bukola Saraki, Aminu Tambuwal, Kayode Fayemi ati Amaechi lati dije fun ipo aarẹ Naijiria ni yoo ja si pabo ni 2023.
O fikun pe agbara kan wa ti ko ni jẹ ki erongba Tinubu lati di aarẹ Naijiria jọ bi o tilẹ jẹ pe oke tente lo wa, wọn yoo kan erongba rẹ labuku, ti yoo si ja wa silẹ.
Ojisẹ Ọlọrun naa tun rọ Tinubu lẹẹkan si lati gbagbe erongba rẹ naa, ko ma si sopo daba lati dije fun ipo aarẹ rara nitori ala ti ko le sẹ lo rawọ le.
Oríṣun àwòrán, @PoliceNG
Awọn gende agbegbọn  ti wọn furasi bii darandaran ti ji eeyan meji gbe loju ọna Isan-Iludun nipinlẹ Ekiti lọjọ ọdun keresimesi.
Deede aago mẹfa irọlẹ ni awọn agbegbọn naa da ibọn bo ọkọ ayọkẹlẹ Lexus ti wọn wa ninu rẹ nigba ti wọn de ibi ti oju ọna ko ti dara.
Amọ Ọba Oke ko ọkan lara wọn yọ nigba ti awọn ọmọ ikọ Amotekun tete gba ọkan silẹ ninu wọn amọ ti awọn ajinigbe naa wọ ekeji wọ inu igbo ni tipatipa.
Nigba to n bawọn akọroyin sọrọ lọjọ Abamẹta nipa isẹlẹ naa, oludari ikọ Amotekun nipinlẹ Ekiti, Ajagunfẹyinti Joe Komolafẹ ni pẹlu ibọn ni awọn agbegbọn fi da ọkọ awọn eeyan naa duro.
Nigerian Fraudsters: Ìwádìí BBC fihàn pé ìdajì àwọn gbájúẹ̀ lágbàyéé wá láti Nàíjíríà
Komolafẹ wa rọ awọn araalu lati mase foya nitori ikọ rẹ atawọn agbofinro n sisẹ papọ lati pese aabo to peye lasiko ọdun, ti wọn yoo si tun doola ẹmi ẹni ti wọn jigbe naa.
Mercy Aigbe: Ara ń ta mí lórí bí Èṣù ṣe dojú kọ ìgbéyàwó tó ń dàrú lójoojúmọ́
Oríṣun àwòrán, Instagram/realmercyaigbe
Ilumọọka osere tiata nni, Mercy Aigbe ti sọrọ nipa igbeyawo ati iha to kọ si.
Osere tiata naa, to sọrọ naa loju opo Instagram rẹ tun ni oun sẹsẹ gbe sinima kan jade ni to da lori igbeyawo, eyi to gbe akọle rẹ ni 'Ki ni Igbeyawo'.
Mercy ni bi o tilẹ jẹ pe oun ti kuro lọdọ oun, sibẹ oun ko tii sinmi lori ọrọ ifẹ, oun ko si lee pa ifẹ ti laelae.
"Awọn eeyan maa n bi mi pe Mercy, se o ko ni pada lọ sọdọ ọkọ rẹ mọ ni tabi tun ọkọ miran fẹ? Amọ otitọ ibẹ ni pe n ko mọ idahun fun ibeere yii.
Okoowo mi ni mo gbajumọ, mo n tọju awọn ọmọ mi ati isẹ ti mo yan laayo. Nigba to ba ya, ohunkohun to ba yọju nipa ọrọ ifẹ ati igbeyawo, maa mọ bi maa se yanju rẹ."
Oríṣun àwòrán, Instagram/realmercyaigbe
Gẹgẹ bii osere sinima, a da bii ojisẹ Ọlọrun to yẹ ko maa tọ awọn araalu sọna ni, ki wọn si maa ri ẹkọ kan abi omiran kọ ninu awọn ere ta ba n gbe jade.
Mercy ni igbeyawo ko yẹ ko dabi igba ti a mu ni lẹru. O ni o yẹ ko jẹ ifọwọsowọpọ ni , ki ẹnikan ninu igbeyawo gba ẹnikeji laaye lati dagba, ko si le da nnkan se.
O fikun pe o maa n bani ninu jẹ bi ọpọ igbeyawo se n fori sanpọn, paapa nitori bi awọn eeyan kan se maa n se igbeyawo nitori awọn idi ti ko yẹ.
Nigerian Fraudsters: Ìwádìí BBC fihàn pé ìdajì àwọn gbájúẹ̀ lágbàyéé wá láti Nàíjíríà
"Bi igbeyawo se n dojude n ba mi lẹru. O dabi ẹni pe esu mọọmọ dojukọ igbeyawo bayii ni, to si n baa jẹ, ti ọpọ lọkọ-laya si n ronu pupọ nipa igbeyawo wọn to fori sanpọn.
Osere tiata naa wa n gbarata pe ki lo de tawọn eeyan yoo fi owo iyebiye ra asọ ẹbi fun ayẹyẹ igbeyawo amọ lẹyin osu diẹ ni iru igbeyawo bẹẹ yoo fi ori sanpọn.
O wa n gba wọn nimọran pe ti wọn ba ti ri daju pe awọn ko ba ara awọn mu tabi ti iwa wọn ko papọ, yoo dara ki wọn mase se igbeyawo.
'Pásítọ̀ ló sọ fún mi pé Ọlọ́run pè mí láti di Olokun tó ń bọ omi'
Bakan naa ni Mercy ni ifarada se koko ninu igbeyawo, ti tọkọtaya yoo si ni iwa ipamọra amọ oun tako igbeyawo to ba ni iwa ipa ninu, eyi to le mu okun ẹmi wọn lọ lojiji.
Lootọ ni awọn ọkunrin jẹ ori amọ o yẹ ki wọn mọ pe awa obinrin ni ọrun, bi ko ba si si ọrun, ori ko le duro, nitori naa lo se yẹ ki asọyepọ ati igbọraẹniye wa laarin lọkọ-laya."""
O wa gba awọn tọkọ-taya nimọran pe ki wọn sa asala fun ẹmi wọn nibi ti iwa ipa ba ti wa ninu igbeyawo, ẹ mase fara daa tabi duro sibẹ.
Awọn ọrọ eebu mii gan buru ju ki wọn na eeyan lọ. Ti ọkan ninu lọkọlaya ba si maa n binu pupọ, iru ẹni bẹẹ gbọdọ lọ fun igbani nimọran abi itọju.
Bobrisky: Ìpinu mi fọ́dún 2021 ni lati yí padà si obìnrin patapata
Idris Olarewaju Okunneye, ti gbogbo ènìyàn mọ̀ si Bobrisky ti fi ọ̀rọ̀ léde fún gbogbo àwọn olólùfẹ̀ nipa isẹ to yan laayo.
Gẹ́gẹ́ bi o ṣe kọ sójú òpó instagram rẹ̀ láìpẹ́ yìí, o ni pé òun ti ni ìpinu tuntun fun ọdún 2021.
Bobrisky sàlàyé sójú òpó rẹ̀ pé, òun ti lo ọdún mẹ́ẹ̀dọ́gbọ̀n àkọ́kọ́ òun gẹ́gẹ́ bi ọkùnrin sùgbọ́n ti òun kò ri ayọ àti ìdúnu kankan nibẹ̀.
Ó ní òun tálákà ju èkúté sọ́ọ̀sì lọ, òun kò rí ǹkan kan tọ́ka si bó tilẹ̀ jẹ́ pé, òun kẹ́kọ́ọ̀ gboyè ìsírò owó (Accounting) ni fásitì ìpínlẹ̀ Eko síbẹ̀, òun kan n fi ẹsẹ̀ gbálẹ̀ títì kiri ni.
Nigerian Fraudsters: Ìwádìí BBC fihàn pé ìdajì àwọn gbájúẹ̀ lágbàyéé wá láti Nàíjíríà
Ọkunrin náà wá kéde pé ni báyìí òun ti ṣetan láti gbé ìgbésẹ̀ tó kan láti di obìnrin pátápáta.
"Kí n tó gbé ìgbésẹ̀ yìí, lọ́jọ́ kan mo ròó pé kíni mo fẹ́ fi ayé mi ṣe? Tí mo ba darapọ̀ mọ́ àwọn adigunjalè, wọ́n a kan pa mi dànu lọ́jọ́ kan ni àti pé mí ò ni ẹ̀mí ká jalè tàbí kí a lu ènìyàn ni jìbìtì.
Lásìkò tí mò n dàgbà, mó ni àwọn àmúyẹ obìnrin lára, ìgbàyìí ni mo pinu láti máa múra bi obìnrin, mo si ri pé, mo bẹ̀rẹ̀ si ni ri owó.
'Pásítọ̀ ló sọ fún mi pé Ọlọ́run pè mí láti di Olokun tó ń bọ omi'
Èyí ló wá mú mi wọ inú rẹ lọ, mo bẹ̀rẹ̀ si ni lo òògun, mo sì n tójú ara mí, bí gbogbo ǹkan ṣe n gún régé nìyẹn, ti àwọn ọkùnrin ń pè mí, ti mo bẹ̀rẹ̀ dí ni ri iṣẹ́ gba níbi gbogbo"""
Fún ìdí èyí, Bobrisky ni òun dára gẹ́gẹ́ bi obìnrin ju okùnrin lọ, òun sì bọ̀wọ̀ fún gbogbo àwọn obìnrin.
Ó wa rọ àwọn ènìyàn láti mase da òun lẹ́bi .
Ẹ̀wẹ̀, sáájú nínú síníma kan ti àkọlé rẹ̀ jẹ́ (Skin) ló ti sọ ìtàn ìgbési aye rẹ̀ pé, ǹkan ẹyọ kan ti òun kabamọ̀ ni pé òun bóra.
Oríṣun àwòrán, Bobrisky
Bobrisky ni ọ̀rọ̀ ara bíbó kìí ṣe ǹkan tó dẹrun rára, bi ó ṣe n lo ìpara ọwọ́, ni wàá maa lo ti ẹsẹ̀, ó ni ni ọ̀pọ̀ ìgbà ọmọ ènìyàn máa n kánjú.
"Emi gẹ́gẹ́ bi Bobrisky mo kánju ju àsìkò mi lọ ni mo ṣe sáre di ǹkan ti mo dà lónìí, gẹ́gẹ́ bi o ṣe sọ nínú (SKIN)
Oríṣun àwòrán, Bobrisky
Oríṣun àwòrán, Bobrisky
2020 in Retrospect: 'Mummy Calm down', 'Sọrọ soke were' àtàwọn àṣà tó milẹ̀ lọ́dún 2020
Oríṣun àwòrán, Getty Images/ooreoluwa
Ni ọdun 2020, ko si ẹni ti ko mọ pe ilẹ rọ, paapaa julọ pẹlu ajakalẹ aarun COVID-19 ati awọn oniruuru wahala miran to waye kaakiri agbaye.
Lara awọn laasigbo naa la ti ri Black lives matter ati ENSARS amọ sibẹ sibẹ, ko ṣai si awọn asiko tabi idi diẹdiẹ fun idaraya ati idaraẹni ninu dun ninu ọdun yii.
Lara awọn idaraya to waye lọdun 2020 lawọn aṣayan aṣa to gbode laarin rẹ, eleyi to mu ẹrin ati ipenija dani, bẹẹ ni awọn miran mu ijigiri dani pẹlu.
Ẹ jẹ ka mu diẹ lara awọn aṣa wọnyii ni ṣisẹ n tẹle:
Mummy Calm down:
Hmmm, bi eniyan ba wo bi aṣa yii ṣe bẹrẹ, bi ẹrin bi ere naa ni.
Ọmọdekunrin kan Ooreoluwa, ni iya rẹ n ba wi fun aigbọran to hu, amọ ṣa nibi ti ọmọ naa ti n gbiyanju ati bẹẹ iya rẹ, lo ti n pariwo Mummy calm down""."
Iya rẹ lo ya fidio ẹbẹ rẹ yii, to si fi ransẹ si ẹgbọn rẹ lati jẹ ko mọ iru alawada ti Ooreoluwa jẹ.
Oríṣun àwòrán, Instagram/babajidesanwoolu
Ẹgbọn iya rẹ naa si lo gbe fọnran aworan ọhun sori ayelujara eleyi to tan kaakiri agbaye, to fi sọ ọmọdekunrin naa di ilumọọka, koda, gomina ipinlẹ Eko, Babajide Sanwo-Olu gan kan si ọmọdekunrin naa.
"Lati igba naa ni ""Mummy calm down"" ti di aṣa to gbajugbaja."
Koda awọn oloṣelu lo o fun ipolongo ibo, bẹẹ ni awọn ileeṣẹ kaakiri lo aṣa naa fun ipolowo ọja ati itaniji paapaa lasiko ti ajakalẹ arun COVID-19 gbalẹ kan.
Sọrọ soke were, maa disguise:
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ara awọn aṣa to milẹ lasiko iwọde #EndSARS niyi.
Koda, asa naa lo di ọrọ akọmọna fun awọn oluwọde to n pe fun iwọgile ikọ ọlpaa SARS naa kaakiri orilẹede Naijiria ati loke okun nigba naa.
Gbogbo oluwọde, koda awọn ti ko gbọ ede Yoruba, gan pẹlu n pariwo sọrọ soke' nigba ti iwọde ọhun fọnna soju to bẹẹ gẹẹ, to si wa di ohun apejuwe fun iran ọdọ iwoyii.
Oríṣun àwòrán, Reuters
"Ọrọ akọmọna naa, eyi to n se iwuri fun awọn ọdọ lati mase dakẹ tabi panumọ lori iwakiwa lo mu ki wọn maa pe iran iwoyi ni ""Sọrọsoke generation"" bayii."
Kwarantain tabi Qurantine lede oyinbo:
Oríṣun àwòrán, Anadolu agency
Aṣa yii jade lasiko ti ajakalẹ aarun COVID-19 wọ orilẹede Naijiria, ti ijọba si n ko awọn to ba ṣẹṣẹ ti ilẹ okeere de pamọ si igbele, eleyii ti wọn n pe ni Qurantine lede Gẹẹsi.
Ẹ jẹri awọn ọmọ Naijiria, ko pẹ pupọ ti wọn fi gba eyi gẹgẹ bi aṣa lati maa lo fun ẹni ti wọn ba fẹ pa ti si ẹgbẹ kan.
"Fun apẹẹrẹ wọn lee ni, ""Mo ma ti Kwarantain (qurantine) ọrọ yẹn."
Ma ko paliatifu (Palliative) mi:
Oríṣun àwòrán, Twitter/oluwaseunfunmi
Lara awọn aṣa to gba ibi ajakalẹ arun COVID-19 lorilẹede Naijiria yọ naa leyii, bi o tilẹ jẹ wi pe lẹyin ti ọwọ kini ajakalẹ arun naa ti n rọlẹ lo waye.
Bakan naa lo tun nii ṣe pẹlu iwọde #EndSARS to waye loṣu kẹwaa ọdun 2020.
"Palliative' lawọn ohun arẹmọlẹkun ti awọn ileeṣẹ aladani pa owo pọ ra fun mimu aye dẹrun diẹ fun araalu lasiko igbele COVID-19 nigba naa.
Amọṣa, lasiko ti iwọde #EndSARS gba ibomiran yọ, tawọn janduku ja a gba mọ awọn to ṣeto rẹ lọwọ, lawọn eeyan fi bẹrẹ si ni ja awọn ile ikẹrusi kaakiri nigba naa.
Eyi lo mu ki aṣa yii jẹyọ pe Ma ko Palliative mi"" O tumọ si ma ko mi ni nnkan lọ. Fun apẹrẹ, ""Alaye ko fi ọgbọn ko paliative mi jọọ."""
We move:
Oríṣun àwòrán, Reuters
Lasiko iwọde #EndSARS ni eyi jẹyọ.
Lasiko ti iwọde naa ṣi n lọ ni irọwọrọsẹ, ti awọn oluwọde n bẹ awọn ile ijọba wo lati fi ẹhonu wọn han si aye familete n tutọ awọn ọlọpaa kogberegbe SARS.
"Asiko naa si ni awọn ọdọ to n sewọde maa n pariwo ""We move"" ti wọn ba ti fẹ kuro ni ibudo kan si ikeji."
"Amọ ṣa, lẹyin iwọde yii lawọn eeyan kuku sọ ọ di aṣa, ti aṣa ""We move"" fi gberassọ titi de aarin awọn ọmọ Naijiria to wa loke okun pẹlu."
Mad o:
Eyi tun ni aṣa miran to gbaye kan lọdun 2020 yii, aṣa yii si jẹ ọrọ iyanu.
Asiko ti wọn maa n lo aṣa yii ni igba ti nnkan iyanu ba ṣẹlẹ, ti awọn eeyan lee ṣe haa si.
"Dipo ki wọn pariwo haa, ni wọn a maa pariwo ""mad o""."
Diẹ lara awọn aṣa to la'lẹ hu jade lọdun 2020 ree, ewo lẹyin mọ ti ẹ lee fi kun un?
Third Mailand Bridge: Ìjọba àpapọ̀ yóò ṣí afárá Third Mainland Bridge lẹ́yìn tó tìí pa lóru ọjọ́ Kérésìmesì
Oríṣun àwòrán, The guardian nigeria
Ijọba apapọ sọ pe afara Third Mainlainland Bridge ti wọn gbe ti pa lati oru ọjs Kersimesi mọjumọ ọjọkeji ọdun yoo di ṣiṣi silẹ pada lati oru ọjọ Aiku, ọjọ kẹtadinlọgbọn oṣu kejila ọdun 2020.
Ijọba ti ṣaaju kede pe wakati mejilelaadọrin, iyẹn ọjọ mẹta  ni wọn yoo fi ti afara naa pa lati lee fun awọn kọngila to n ṣiṣẹ atunṣe lori rẹ lanfani ati ṣe awọn atunṣe ti wọn nilo lati ṣe laisi idiwọ tabi idena lilọ bibọ ọkọ.
Amọṣa, alakoso opopona ijọba apapọ lẹkun Eko, Olukayọde Popoọla ṣalaye pe wọn ni lati ṣii ṣaaju ọjọ ti wọn kede tẹlẹ fun ṣiṣi rẹ nitori bi awọn kọngila ti ṣe tete pari iṣẹ naa ni.
Idi ti wọn fi kede titi pa rẹ ni ki wọn lee dẹkun gbogbo mimi ati gbigbi-gbagba ti awọn ọkọ to ba n lọ lee maa fa lasiko ti wọn fi n ṣe awọn iṣẹ kan nibẹ.
Lati oṣu keje ọdun 2020 ni wọn ti bẹrẹ iṣẹ atunṣe lori afara Third Mainland Bridge ti wọn si kọkọ ni yoo gba oṣu mẹfa ki wọn to pari rẹ ki wọn to sun un siwaju pẹlu oṣu kan leyi to tums si pe oṣu keji ọdun 2021 ni iṣẹ atunṣe lori rẹ yoo pari, dipo oṣu kini ọdun 2021.
Olusegun Obasanjo: Ẹ máṣe bú Ọlọ́run torí ọrọ̀ ajé tí kò dára àti òṣì tó gbalẹ̀ ní Nàíjíríà
Oríṣun àwòrán, Olusegun Obasanjo Presidential Library
Aarẹ ana ni Nigeria, Olusegun Obasanjo ti woye pe orilẹede yii ko se awọn ohun to tọ lati mu mu agbega ba ọrọ aje rẹ to mẹhẹ, ko si mu adinku ba isẹ ati osi.
Oloye Obsanjo woye ọrọ yii ninu isẹ to fi ransẹ fun ibẹrẹ ọdun tuntun, to si wa n sekilọ pe kawọn asaaju Naijiria dẹkun didi ẹbi isẹlẹ aisi eto aabo to peye, ọrọ aje ti ko dara, osi atawọn ipenija miran to n ba ilẹ yii finra, ru Ọlọrun.
"Pẹlu ọpọ ohun alumọni to wa lorilẹede yii, ko yẹ ki Naijiria wa lara awọn otosi orilẹede, bẹẹ si ni ko yẹ ki awo ijọba abi ọmọ Naijiria kankan sun ninu ebi.
Oríṣun àwòrán, Olusegun Obasanjo Presidential Library
Mo fẹran akọmọna  ileewe kan to ni sisẹ ko si gbadura, sugbọn fun awọn eeyan miran, gbadura ko to sisẹ ni, bi o tilẹ jẹ pe ọna tẹ gba gbe ọrọ yii kalẹ kọ ni koko.
Ohun to se pataki ni pe kẹ sisẹ, isẹ sise ati adura gbigba gbọdọ lọ papọ ni."
Obasanjo wa tẹnumọ pe o yẹ ka sisẹ lorilẹede yii, gẹgẹ ba se n gbadura ninu ọdun tuntun 2021, ko le jẹ ọdun ologo fun wa, amọ lai jẹ pe a sisẹ, eyi ko le ri bẹẹ.
2020 in Retrospect: Ìjàmbá iná, ilé tó dàwó, ìwọ́de àti àrùn Covid-19 wà lára ìṣẹ̀lẹ̀ 2020
Aarẹ tẹlẹ ni Naijira naa wa fikun pe, awa ara wa lo yẹ ka bu nitori ipo ti orilẹede wa wa bayii, kii se Ọlọrun, ohun tawọn alasẹ ati ero ẹyin ni Naijiria yan ree.
Obasanjo wa gbadura pe Ọlọrun yoo mu ki ọdun tuntun 2021 dara fun wa amọ isẹ sise nikan ni amin rẹ.
Oríṣun àwòrán, Olusegun Obasanjo Presidential library
Saaju la ti mu iroyin wa fun yin pe, Aarẹ orilẹede Naijiria tẹlẹri, Ọgagun Oluṣẹgun Obasanjọ, ti salaye bo ṣe jajabọ lọwọ ogun iditẹ gbajọba to waye lọdun 1976, ti ọgagun Buka Dimka dari rẹ.
Ọbasanjọ ni Ajagunfẹhinti Olu Bajọwa lo gba oun la lọwọ awọn aditẹgbajọba naa, lọna ti Bajọwa fun ara rẹ ko mọ.
O sọ ọrọ yii lasiko ayẹyẹ ọjọ ibi ọgọrin ọdun Olu Bajọwa to waye ni ilu Igbotako, ni ijọba ibilẹ Okitipupa, ni ipinlẹ Ondo.
Aarẹ orilẹede Naijiria tẹlẹri, Ọgagun Oluṣẹgun Obasanjọ wa sapejuwe Bajọwa gẹgẹ bi ẹni to ni irẹlẹ ọkan, to si n bọwọ fun agba.
Obasanjọ ni nigba ti ogun iditẹgbajọba Dimka waye ni ọdun 1976, ọpẹlọpẹ ipa ti Bajọwa ko lọjọ naa lọhun, lo ko oun yọ.
Oríṣun àwòrán, TWITTER
''Lasiko ti iditẹgbajọba naa waye ni Bajọwa bi ọmọ ọkunrin jojolo, ti o si fẹ sọ ni orukọ mi, nitori naa o sọ wi pe, oun n bọ wa si ile ọdọ mi.
"Eyi lo mu ki n tẹsẹ duro de, to si jẹ ki n pẹ ju asiko ti mo maa n jade kuro ninu ile lọ, owurọ ọjọ naa ni Dimka ṣọṣẹ."""
Obasanjo fikun pe nigba ti Bajọwa de, to si beere pe oun fẹ sọ ọmọ tuntun naa ni orukọ oun, o ni oun fun aṣẹ lati lo orukọ oun.
"Nitori naa mi o gba ọna ti mọ ma n gba nitori mo ti pẹ, awọn sọja naa si ṣẹsẹ kọlu Reinumuje to gba ọna ti mo maa n gba tẹlẹ, wọn ro wi pe emi ni mo wa ninu ọkọ naa.'
Oríṣun àwòrán, Olusegun Obasanjo Presidential library
Wọn yinbọn lu ọkọ rẹ, wọn si pa Murtala Muhammed ninu iditẹ-gbajọba to waye ọhun, bi Bajọwa ṣe gba mi la lọwọ awọn aṣekupani niyẹn.''
Baba Obasanjọ tun sapejuwe Olu Bajọwa gẹgẹ bi ẹni to jẹ akinkanju ologun, to si saaju ọwọ kọkanla ikọ ọmọ ogun ilẹ wa, 11 battallion, lasiko ogun abẹle to waye lorilẹede Naijiria.
Jude Chukwuka: Wò ó bí òwé Yorùbá ṣe yọ̀ lẹ́nu ọmọ Igbo
Jude Chukwuka: Wò ó bí òwé Yorùbá ṣe yọ̀ lẹ́nu ọmọ Igbo
Jude Chukwuka, tii se ọmọ Igbo, amọ to gbọ ede Yoruba tun ti gbe tuntun de.
Lọtẹ yii, owe ati awọn asayan ọrọ ni gbajumọ elere tiata naa tun gbe de.
Chukwuka ninu fidio yii salaye awọn owe gbankọ meji ni ede Yoruba, itumọ wọn ati awọn iwulo wọn pẹlu.
Iyalẹnu si ni yoo jẹ fun ojulowo ọmọ Yoruba ti ko le da owe kankan pa, pe ọmọ ẹya Igbo tun gbọ owe Yoruba ju lọ.
2020 in Retrospect: Ajibade Babalade, Michael Ojo, Razak Oyadeyi wà lára àwọn tó kú lọdún yìí
Oríṣun àwòrán, Facebook/BBC
Ọdun 2020 lamilaka, to si jẹ ọdun manigbagbe paapa julọ pẹlu ajakalẹ arun Covid-19 to ṣọṣẹ jakejado agbaye.
Lorilede wa Naijiria, a mọ riri ajakalẹ yii lara pẹlu awọn eeyan ti iku mu ẹmi wọn lọ nitori ajakalẹ arun Coronavirus naa, eyi to tun mu ki idenukọlẹ ba eto ọrọ aje titi di akoko yii.
Bi a ba wo agbo osere ere idaraya, awọn tó ba ọdún yi lọ yala lati ipasẹ Covid-19 tabi nnkan mii, pọ yanturu.
Oríṣun àwòrán, Facebook/Ajibade Babalade
Lọjọ kẹrin oṣu Kẹsan ni agbẹyin fun ìkọ Super Eagles dagbere faye ni Ibadan .
Babalade, to jẹ ẹni ọdun mejidinlaadọta ṣe aarẹ diẹ, ti won sì gbé lọ sí ilé ìwòsan agba fasiti Ibadan, UCH  níbi to padà ku si.
Ajibade jẹ ogbontarigi agbẹ́yìn to soju Naijiria ninu ikọ Super Eagles, to si ba wọn gba ife ẹyẹ bàbà lọdun 1992 ninu idije AFCON to waye ni Senegal.
Chineme Martins:
Oríṣun àwòrán, Facebook/Martins Chineme
Ikú agbabọọlu ẹni ọdun mẹtalelogun yii dun ọpọ eeyan nitori igbagbọ wọn ni pé ti Naijiria ba ni eto ilera tó péye lori papa iṣere Lafia ni, ko bà maa ku.
Lọjọ Kẹjọ oṣù Kẹta ni Martins dagbere faye lasiko Ifẹsẹwọnsẹ ẹgbẹ agbabọọlu rẹ, Nassarawa United ninu liigi bọọlu Naijiria, NPFL.
Sadede ni Chineme daku lori papa ni abala keji ifẹsẹwọnsẹ naa nigba ti Nassarawa United n koju Katsina United.
Oríṣun àwòrán, Facebook/John Felagha
Ọgbọnjọ oṣu Kẹjọ ni aṣọle nigba kan ri fún ìkọ U17 ati U20  Naijiria kú ní Senegal.
Felagha jẹ ọkan lára ìkọ Golden Eaglets nigba ti won gba baba ni Switzerland lọdun 2009, bo ti le jẹ wipe ko ribi dé ojú ile lasiko idije naa.
Oríṣun àwòrán, @ExtraSportsNG
Okedeyi  jẹ ọkan lára àwọn adari idije bọọlu alapẹrẹ basket ball ni Naijiria ki ọlọjọ to dé.
Bẹẹ lo tun jẹ oguna gbongbo ọmọ ẹgbẹ àwọn rẹfiri bọọlu alapẹrẹ ni Naijiria.
Lasiko idije ti Total sagbatẹru rẹ nibẹrẹ ọdun yii lawọn eeyan ri Okedeyi kẹyin.
Okedeyi jẹ alukoro ẹgbẹ awọn to n gba bọọlu alapẹrẹ nilu Eko ṣaaju ikú rẹ.
Oríṣun àwòrán, @nbbfonline
Ikú ọmọdebinrin yii jẹ eyi ti a ko ba ti kéde ka ni wọn tete mọ nkan to n ṣe pato.
Ìdí ni pé ọtọ ní nkan t'awon onimọ ilera n tọju rẹ fún amọ nigba ti wọn yóò fi mọ nkan to se gangan, ẹpa ko boro mọ.
Oríṣun àwòrán, @titansbasket
Gbajumọ ababọọ̀lu alapẹrẹ ni ọmọ ọdun mẹrindiinlogun naa, to si sẹsẹ fẹ joko kọ idanwo asejade ile ẹkọ girama agba ni, ki iku to pa oju rẹ de.
Ọjọ kejidinlogun osu Kẹrin lo dagbere faye pe o digbose.
Michael Ojo:
Oríṣun àwòrán, @odds_12
Ọmọ Naijiria ati ilẹ Amẹrika yii ku nitori ọkan rẹ to sọsẹ silẹ lasiko igbaradi lori papa ere bọọlu alapẹrẹ.
Ni papa isere idaraya Partizan ti ìkọ Crvena Zvezda, lorileede Serbia ti n gbaradi lo ti daku.
Nígbà tí wọn yoo fi gbé dé ilé iwosan kan lagbegbe naa, o ti dakẹ.
Aremu Adu:
Oríṣun àwòrán, @LASG
Olukọni ere idaraya naa jẹ ilumọọka nibi ka maa ṣatọna awọn ọjẹ wẹwẹ ere idaraya nipinlẹ Eko.
Ọjọ Kẹwa oṣù Kaarun ọdun 2020 lo ki ayé pe o digba.
Ọpọ lawọn elere idaraya ni Naijiria ti wọn ti tipasẹ Coach Adu gun oke agba nidi ere idaraya.
Ninu awọn to kọ la ti awọn to ti wa nilẹ Amẹrika nibi ti wọn ti n tẹsiwaju pẹlu ẹkọ wọn.
Oríṣun àwòrán, @thenff
Ninu awọn ti ajọ ere bọọlu Naijiria NFF padanu lọdun 2020 ni Emmanuel Ibah wa.
O jẹ alakoso NFF lagbegbe Guusu Naijiria, to sì tun jẹ alaga ẹgbẹ ere bọọlu ni Akwa-Ibom titi di igba to fi faye silẹ.
Ẹni ọdun mọkanlelọgọta lo jẹ lasiko ti ọlọjọ dé.
Cute Abiola: Mo ti n bá agbẹjọ́rò mí sọ̀rọ̀ láti gbé ìgbésẹ̀ òfin lórí ẹ̀ṣùn náà
Oríṣun àwòrán, @victoryomogiate
Yoruba ni ọrọ ifẹ, bii adanwo ni, oro ọfa ifẹ si mu ju oro abẹ lọ ninu ọkan.
Boya eyi lo mu ki ọmọbinrin kan, Victory Omogiate fi n leri leka pe oun le gba ẹmi ara oun nitori ijakulẹ ifẹ to ba pade lati ọdọ gbajumọ adẹrinposonu kan lori ayelujara, Cute Abiola.
Bẹẹ ba ri iroyin naa ka, ọjọ ọdun Keresimesi ni alawada naa, Abdulgafar Ahmad Oluwatoyin, ti ọpọ tun mọ si Ankara Gucci, gbe soju opo Instagram rẹ pe oun ti ni iyawo afẹsọna, ti orukọ rẹ n jẹ Adedamola Adewale @Adeherself.
Amọ nigba ti Victory ri ikede yii ka, lo ba kede loju opo Twitter rẹ pe @dysel pe Cute Abiola ti lu oun ni jibiti ara, ti ikede nini afẹsọna naa si fẹ da oun lori ru.
Oríṣun àwòrán, @victoryomogiate
Bakan naa ni ọmọbinrin ọhun n sepe pe awọn afẹsọna mejeeji naa ko ni ri ayọ ninu igbeyawo wọn tori Cute Abiola lo oun nilokulo ni aimọye igba.
Kii se pe o fi tipa ba mi lopọ amọ o dibọn bi ẹni pe o nifẹ mi, o si ti pẹ ju fun mi ko to ye mi pe o kan n lo mi ni."
"Lootọ n ko ni ẹri to daju lọwọ nitori mo ti pa ọpọ itakurọsọ wa loriayelujara rẹ, ti mo si ro pe sise bẹẹ yoo jẹ ki n tete gbagbe rẹ ati awọn nnkan to sẹlẹ laarin wa."""
Oríṣun àwòrán, @victoryomogiate
Victory ni ki ẹnikẹni mase da oun lẹjọ nitori wọn ko mọ isoro ti oun n la kọja lati bi ọdun kan sẹyin, to si tun fi aworan ti oun ati Cute Abola ya soju opo Twitter rẹ́, lasiko ti ọrọ wọn wọ.
"O ni ""Nigba ti Abiola fi atẹjisẹ ransẹ si mi, ẹnu ya mi, tori oju opo Instagram mi la ti kọkọ bẹrẹ nibi to ti ni oun fẹ maa ba mi jade."
"Bi o tilẹ jẹ pe mo lọ tikọ saaju lati gba fun, amọ nigba to ya mo fun ni nọmba mi, ta si bẹrẹ si ni sọrọ lọsan loru, to si n yọ mi lẹnu pe oun fẹ ba mi dọrẹ pọ."""
Oríṣun àwòrán, @victoryomogiate
Victory fikun pe oun ati adẹrinposonu naa bẹrẹ si ni ajọsepọ, ọjọ kan si wa to dabi ẹni pe oun tabuku ara oun nipa gbigbe nnkan ọkunrin rẹ sẹnu lasiko ti awọn n sere ifẹ, bẹẹ lo tu omi nnkan ọkunrin si oun lẹnu.
"Mo ro pe mo ti ri ọkọ temi ni lai mọ pe o kan n lo mi lati gbadun ara rẹ ni, ti n ko si le gbagbe bo se sọ mi di oniyẹyẹ.
Ọmọbinrin naa ni lẹyin ti Cute Abiola ti seleri aye ati ọrun fun oun, lo wa ja oun ju silẹ, lẹyin to ti lo oun tan.
Oríṣun àwòrán, @victoryomogiate
Ko si to ba mi ni ajọsepọ, ni mo ti sọ fun pe emi kii se oninabi, amọ to seleri fun mi pe oun ko ni ja mi kulẹ laelae."""
Victory ni ọrọ bi Cute Abiola yii se ni afẹsọna naa gbọdọ jẹ irọ nla, bẹẹ si ni to ba sẹ pe irọ ni oun n pa, oun setan lati gbe awọn aworan ihoho rẹ to wa lori foonu oun sita.
Bakan naa lo dunkoko pe ti oun ba gbẹmi ara oun, Abdulrazak Abiola lo faa, oun si ni ki wọn mu pe o pa oun nitori bo se kede pe oun ti ni afẹsọna ti ba oun lọkan jẹ lọpọlọpọ.
Oríṣun àwòrán, @victoryomogiate
Awọn idunkooko ọmọbinrin naa lo mu ki BBC Yoruba kan si Cute Abiola, ti ọpọ eeyan tun mọ si Lawyer Kunle lati gbọ tẹnu rẹ, ka si wadi ododo daju nipa awọn ẹsun ti ọmọge yii fi kan.
Nigba to n ba wa sọrọ lori isẹlẹ naa lorukọ onibara rẹ, agbẹjọro fun Cute Abiola, Amofin Fatai Adebanjo ni ẹsẹ ofin ni awọn yoo fi yanju ọrọ naa.
Onibara mi sẹsẹ fi ọrọ naa to mi leti ni, a si ti n fẹ gbe igbesẹ to tọ sofin lori rẹ, bi a ba si fẹ gbe igbesẹ ofin, ko yẹ ki onibara sọ ọrọ kankan lori ayelujara lori rẹ.
Oríṣun àwòrán, @victoryomogiate
Bakan naa lo fikun pe gbajumọ ti aye mọ ni mọ ni onibara oun, nitori naa, eeyan kan ko kan le wa lati fẹ fi onibara oun gun oke nitori iru iwa bayii pọ nilu ta wa yii, obinrin naa si kan fẹ jẹun ni lati bẹyin bẹbọjẹ fun onibara oun.
Awọn ọrọ ti obinrin yi sọ, tawọn ọjọgbọn ba gbe yẹwo, ejo lọwọ ninu, to si foju han pe ọmọbinrin yẹ sa pamọ sawọn abẹ ika kan, a si ti fala sawọn ọrọ kan ti ọmọbinrin naa sọ, eyi to fihan pe ọrọ rẹ ko rinlẹ to.
Lagos COVID-19: Ará òkè òkun tó ń wọlé sí Nàíjíríà, Ẹ ṣọ́ra fún gbígba ayédèrú ìwé ẹ̀rí àyẹ̀wò COVID-19
Oríṣun àwòrán, twitter/Akin abayomi
Ijọba ipinlẹ Eko ti pariwo sita pe awọn eeyan kan ti n ta ayederu iwe ẹri ayẹwo Coronavirus ni ipinlẹ naa.
Kọmiṣọna feto ilera, Ọjọgbọn Akin Abayọmi ṣalaye pe ọpọlọpọ awọn arinrinajo wọle lati oke okun lo jẹ pe iwe ẹri ayẹwo COVID-19 ti wọn n gbe kiri kii ṣe ojulowo.
O ni ijọba ipinlẹ Eko ti n gbe igbesẹ lati rii daju pe ọwọ tẹ awọn eeyan to wa nidi iwa ibajẹ naa.
Jude Chukwuka: Wò ó bí òwé Yorùbá ṣe yọ̀ lẹ́nu ọmọ Igbo
Ọjọgbọn Abayọmi ni ọpọ awọn to n wọle lati ilẹ okeere lo ni ajakalẹ aarun naa, bẹẹ ni iye awọn to nii laarin wọn n pọ si ni.
O ni laipẹ ijọba yoo fi panpẹ ofin ko gbogbo awọn to n ra tabi ta ayederu iwe ẹri ayẹwo COVID-19 naa.
Davido and Burna boy fight in Ghana: Kí ló fa gbas-gbos láàrín Davido àti Burna boy lórílẹ̀èdè Ghana?
Oríṣun àwòrán, davido/burnaboy/instagram
Meji ninu awọn eekan akọrin takasufe lorilẹede Naijiria, Davido ati Burna Boy ba ara wọn wọ ijakadi ni ile ijo kan lorilẹede Ghana.
Iroyin sọ wi pe awọn mejeji yii gbena woju ara wọn nigba ti Burnaboy wọ ile ijo kan nibi ti Davido ti n gbafẹ.
Awọn fidio kan to wa lori ayelujara n ṣe afihan bi Davido ṣe gbarata ṣugbọn ti awọn eeyan n dii mu.
Amọṣa ko si ẹni tii lee sọ ohun gan to fa ija naa ṣugbọn awọn tọrọ naa ṣoju wọn ni Davido ti kọkọ wa ninu ile ijo naa ki Burnaboy to de.
Yatọ si eyi, awọn fidio kan naa tun n fihan pe eekan akọrin miran, Whizkid pẹlu wa ninu ile ijo yii pẹlu ṣugbọn ti ko da si wahala to n lọ naa.
"Amọṣa, ninu ọrọ kan to fi si oju opo Twitter rẹ, eyi ti ọpọ ri gẹgẹ bi esi si ohun to ṣẹlẹ naa, Davido kọ ọ pe, ""Emi yoo kuku fi iṣẹ orin yii silẹ fun yin"" eleyii si ti mu ki awọn ololufẹ rẹ maa sọ ọrọ loriṣiriṣi."
Oríṣun àwòrán, ScREESnHOT
Kidnapping in Nigeria: Arìnrìnàjò kan ṣàlàyé bí orí ṣe ko yọ lọ́wọ́ ajínigbé
Oríṣun àwòrán, Facebook/Remi Oladoye
Ọkunrin kan ti ori ko yọ ti salaye ohun toju rẹ ri nidi isẹlẹ ijinigbe to n waye lemọlemọ, paapaa loju ọna Ilesa si Ekiti.
Remi Oladoye, ẹni to salaye bii isẹlẹ naa se waye fun BBC Yoruba ni, ti kii ba se ọpẹ Ọlọrun ati ti awakọ to wa ọkọ ti oun wa, boya isẹlẹ buruku ko ba waye tabi ki oun se ọdun tuntun ni akata awọn ajinigbe.
O fikun pe, agbegbe ilu Erinmo Ijesa si Iwaraja ni ọkọ awọn de lọjọ Aje ana, ni deede aago meje si meje aabọ, to fi se alabapade isẹlẹ ijinigbe to n waye lọwọ lagbegbe naa.
"A ri pe ọkan lara awọn mọto to wa niwaju wa duro lojiji, tawọn gende agbebọn to jade lati inu igbo tiiki to wa laarin ilu mejeeji yii si yọ ibọn sawọn ero to wa ninu mọto naa.
Oríṣun àwòrán, Facebook/Remi Oladoye
Inu igbo nla ti igi tiiki wa yi ni awọn ajinigbe naa maa n fara soko si lati sisẹ ibi wọn
Bi wọn se n ja wọn lole lọwọ, kia ni awakọ tiwa, to ti mọ nipa isẹlẹ to n waye lọwọ naa, nitori ọmọ Efon Alaaye ni, ti fa ọkọ jade lati sẹri pada.
Amọ ibi to yiwọ ọkọ si, agbegbọn miran naa wa nibẹ, to na ibọn si wa amọ awakọ tiwa jafafa pupọ nidi ọkọ wiwa, to si salọ."
Bakan naa lo ni ọkọ meji mii naa fi awakọ toun se awokọse, tawọn naa si fi ere sẹri pada wa si aarin ilu loju ibọn, lẹyin isẹju mẹwa ti ọkọ tiwa ti moribọ.
Akọroyin naa tẹsiwaju pe ọkọ awọn sẹri pada sinu ilu Erinmọ lati duro diẹ ki isẹlẹ naa fi rekọja lọ, ki awọn to tun mu ọna ajo awọn pọn.
O ni nibi ti awọn duro si yii naa lawọn ti n sọ fawọn ọkọ miran to n bọ pe ki wọn mase lọ siwaju nitori ewu to wa lọna.
"Nibẹ ni ọkan lara awọn awakọ naa ti n yi nilẹ, to si n dupẹ lọwọ Ọlarun pe o da ẹmi oun si, ti ko si tun bọ si igbekun awọn ajinigbe.
Awakọ mii ni koda, awọn ajinigbe naa yinbọn mọ ọkọ oun, bẹẹ lo ni oun ko awọn ọmọ oun si ẹyin ọkọ, ta si ri oju ibọn lara mọto rẹ.
Oríṣun àwòrán, Facebook/Remi Oladoye
Ohun ti yoo ba pa ni, to ba si ni ni fila, ka maa dupẹ lo tọ
Awakọ keji naa si ni oun fi oju oun ri korokoro bayii, tawọn ajinigbe ọhun n ko awọn ero inu ọkọ ti wọn da duro wọnu igbo lọ, ki oun to bọ mọ wọn lọwọ."
Oladoye salaye siwaju si pe awọn araalu ti oun ba sọrọ gan fidi isẹlẹ naa mulẹ pe lemọ-lemọ ni isẹlẹ ijinigbe maa n waye lagbegbe naa.
O ni awọn ọlọdẹ atawọn oloko maa n ri awọn ero to bọ sọwọ ajinigbe ninu igbo, ti wọn yoo ti fẹẹ na ẹlomiran ninu wọn pa.
"Nigba ti BBC Yoruba beere pe se o ri irisi awọn eeyan to n sisẹ ibi naa, akọroyin naa ni "" A ko ri wọn lọ titi, amọ iwadii mi mi lọdọ awsn to ri wọn fihan pe awọn Fulani ni wọn, ti isẹlẹ naa si tun lọwọ awọn araalu ninu."""
Oladoye ni ibi ti isẹlẹ naa ti waye ko to kilomita meji si ibi tawọn sọja duro si, ti wọn ko si yọju rara sibi isẹlẹ naa.
Fulani Kidnapping: Owó púpọ̀ la san kí wọ́n tó fi mi sílẹ̀
O wa pari ọrọ rẹ pe bi kii ba se pe ọkọ ọhun duro fun isẹju marun lati gbe eeyan kan nilu Efon Alaaye ni, ọwọ awọn ajinigbe naa ni oun ko ba ko si.
O ni boya awọn ẹbi oun ko ba wa ninu pe wọn n wa owo kiri bayii lati ba idande oun lọwọ awọn ajinigbe naa ni.
A n fẹ agbofinro ati Amotekun lagbegbe wa ni gbogbo igba - Elerinmo
BBC Yoruba tun ba ọba alaye lagbegbe naa, Ẹlẹrinmọ tilu Ẹrinmọ, Oba Dokita Michael Adebowale Odunayo Ajayi, Arowotawaya Keji sọrọ nipa isẹlẹ ijinigbe to n waye lemọ-lemọ ni agbegbe naa.
Ninu ọrọ rẹ, Ọba Ajayi ni lootọ ni isẹlẹ naa waye pẹlu afikun pe asiko ọdun la wa yii, iru isẹlẹ bayii si maa n wọpọ.
Oríṣun àwòrán, Facebook/Oba Michael Odunayo Ajayi
"Awọn eeyan to n sisẹ ibi yii kii se ara ibi, gbogbo awọn isẹlẹ naa si la ti gbe wa si iwaju ijọba, asofin atawọn agbofinro pe ki wọn dojukọ agbegbe yii daada.
Ibi kii se agbegbe ti wọn yoo maa wa lẹẹkọọkan nitori o yẹ kawọn Amotekun ati Civil Defence wa nibi ni gbogbo igba amọ ko si nkankan nibẹ."
Passover Night: Òjíṣẹ́ Ọlọ́run ní o lè gbàdúrà ìparí ọdún nílé rẹ láì lọ sí ṣọ́ọ̀ṣì
Oríṣun àwòrán, CAC worldwide
"Lílọ ""Cross-over night"" kò ní kí ọdún ó yabo láì ní ìpinnu tàbí ètò f'ọ́dún tuntun- Pásítọ̀ Ajifowowe"
"Cross-over night: Pásítọ̀ Ajifowowe ní ""o lè gbàdúrà ìparí ọdún nílé rẹ láì lọ sí ṣọ́ọ̀ṣì"""
A ko gbọdọ tapa si ofin ijọba lori adura ipari ọdun 2020 si 2021 nitori ajakalẹ arun coronavirus.
Pasitọ Alfred Femi Ajifowowe lo sọrọ yii fun BBC Yoruba.
Bẹẹ ba gbagbe, ijọba ipinlẹ Eko ti sọ tẹlẹ pe ẹnikẹni to ba tapa si ofin konile o gbele lati ago mejila oru si ago mẹrin owurọ, yoo sanwo itanran lati ẹgbẹrun lọna ogun naira sí ẹgbẹrun lọna ẹẹdẹgbẹta naira.
Nigba to n fesi si ọrọ yii, Pasitọ Ajifowowe sọ pe iwe mímọ ní kí a maa bọwọ fun awọn alaṣẹ.
Oríṣun àwòrán, Facebook/Pastor E.A. Adeboye
"O ni ""fun idi eyi, awọn Kristẹni ni lati gbọran, ki wọn si gbadura ipari ọdun yala nile wọn tabi ki wọn ṣe isin ipari ọdun ninu ṣọọṣi wọn ki o si pari si ago mọkanla dipo mejila to maa n pari tẹlẹ."""
Ni ṣọọṣi tiwa, ago mọkanla alẹ la o pari isin adura opin ọdun wa, ki awọn eeyan le lanfaani lati pada si ile wọn ki iṣede to bẹrẹ laago mejila.
Èmi nìkàn kọ́ ni mó n ṣe àkójọ orin- Fasoyin
"Pasitọ Ajifowowe ni ""lilọ si ""Cross-over night"" ko ni ki ọdun o yabo fun eeyan, bi ko ṣe ki eeyan ni ipinnu lori ọdun tuntun."""
Pasitọ Ajifowowe ni ko sí ohun kan ti yoo yipada fun ẹnikẹni ti ko ba ni ipinnu tabi eto fun ọdun tuntun.
"O ni ko si ohun to wa ninu ""Cross-over night"" ju kí eeyan fi ọna ara rẹ le Ọlọrun lọwọ ninu gbadura lọ."
Bakanna, olugbe ilu Eko ti ko darukọ ara rẹ sọ fún BBC Yoruba sọ pe, fun anfaani araalu ni ijọba ṣe sọ pe k'awọn eeyan gbe ile wọn lati ago mejila oru si ago mẹrin owurọ.
Alapinni Oosa ṣàdúrà fún gogbo ọmọ kúoótù, oò jíire bí?
"O ṣalaye siwaju síi pe Ọlọrun gan an lo fi awọn alaṣẹ ijọba sori oye, eyi to tumọ si pe ""a gbọdọ gbọran sí wọn lẹnu."""
"Arabinrin naa tun sọ pe ko si bi awọn eeyan ko ṣe ni sun mọ ara wọn ju bo ti yẹ lọ ninu isin ""Cross-over night."""
Obinrin naa fikun ọrọ rẹ pe awon eeyan le ṣe isin ipari ọdun nile wọn lai lọ si ṣọọṣi.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Bi itankalẹ arun Covid-19 ṣe peleke si ni Naijiria, awọn gomina ipinlẹ kọọkan to fi mọ apapọ ẹgbẹ Kristẹni ni Naijiria wọgile ìsìn aisun ọdun tuntun, ti wọn maa ṣe lọdọọdun.
Asiko isin yii lawọn ile ìjọsìn máa n fi sadura ati ìsìn lati fi sure nkan daada ti wọn ba n fẹ lọdun tuntun.
"Ìsìn oru ọdun tuntun Cross over service"" je ìsìn pàtàkì fawọn Kristẹni àti awọn musulumi kọọkan ṣugbọn nitori ajakalẹ Covid-19, ilana oriṣirisi ni wọn gbé kalẹ t'awọn mi sí wọgile ìsìn naa lodun yii."
Awọn ipinlẹ kan nilẹ kaarọ o jiire ti wọgile ìsìn yi patapata lọdọ wọn.
Ijọba Eko lo kọkọ wọgile ìsìn oru mojumọ naa, to sì ni awọn ṣe bẹẹ nitori aṣẹ ijọba apapọ lori isede ago mejila oru sí aagọ mẹrin afẹmọjumọ.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Pẹlu ilana tí ijọba gbe kalẹ yii, ọpọ àwọn ilé ìjọsìn n gbero lati ko idaji ọmọ ijọ wọn jọ lati ṣe ìsìn, ki gbedeke akoko isede to to.
Ni ipinlẹ Ogun, ijọba fòfin de ìsìn aisun ọdun tabi ipejọpọ kankan ni ipinle ọhun.
Amọ ṣa ẹgbẹ ọmọ Kristẹni ipinlẹ naa fẹ ki ijọba gbẹsẹ kuro lórí òfin yii.
Ijọba Oyo ko fi oju kekere mu ọrọ yii, ti wọn sì ti fohun silẹ pe awọn ko ni yẹ lori ipinu wiwọgile ijọsin aisun ọjọ ọdun.
Sugbọn iroyin to tun tẹ wa lọw nirọlẹ Ọjọru lo fi lede pe ìjọba Oyo naa tun ti pahunda, to si faaye gba awọn ile ijọsin lati se aisun ọdun.
Amọ o fi ote le pe awọn ọmọ igbimọ amusẹya lori Coronavirus yoo maa lọ yika awọn ile ijọsin naa lati ri pe ero to wa nibẹ ko ju aadọta lọ.
2020 in Retrospect: Ìjàmbá iná, ilé tó dàwó, ìwọ́de àti àrùn Covid-19 wà lára ìṣẹ̀lẹ̀ 2020
Nipinlẹ Ondo, Alaga tẹẹkoto lori kikoju Covid-19 ni ipinlẹ Ondo, Adesegun Fatusi ni, ko daa to ki olori awujọ tabi ẹsin maa kesi awọn eeyan lati tapa si ofin ijọba lori ọrọ ilera.
Ni ti ijọba ipinlẹ Osun, o ti kọkọ wọgile isin yii sugbọn wọn tun ipinu wọn da ro.
Kọmisana feto iroyin Funke Egbemode sọ pe, ijọba to n gbaroye araalu ni awọn jẹ, nitori naa, lawọn fi yi ipinu pada lori isin aisun ọjọ ọdun tawọn wọgile saaju.
"O sọ pe ""Ijọba Osun ti pinu lati jẹ ki awọn eeyan korajọ fun isin yii sugbọn ile ijọsin ti yoo ba se isin gbọdọ ri pe awọn eeyan pari rẹ lasiko, ti wọn ko si ni kọja aago kan oru''"
Baruwa Gas Explosion: Àwọn tó forí sọta ìjàmbá iná ń bẹ ìjọba láti dìde ìrànwọ́
Isin Cross over ori ayelujara:
Ohun ti ile ijọsin Redeemed Christian Church sọ fun awọn ọmọ ijọ rẹ ni pe lori ayelujara lawọn yoo ti se isin tọdun aisun dun tawọn.
Ninu atẹjade ti wọn fi sita, wọn ni eyi wa lati bọwọ fun ilana tawọn ijọba apapọ ati ipinlẹ gbe jade nitori itankalẹ Covid-19.
Bakan naa ni ijọ Winners Chapel ti kọkọ kede pe isin aisun ọdun ko ni waye ni gbogbo ẹka ijọ naasutgbọn nigba to ya, lo tun da ọrọ rẹ ro, to si ni isin naa yoo waye pẹlu awọn ilana kan.
Bo ti lẹ jẹ wi pe oludasilẹ ijọ naa ti saaju bẹnu atẹ lu idena akojọpọ ijọsin, amọ Bisọọbu David Oyedepo ni oun yi ipinu pada nitori isin tawọn maa n se kii kọja ago mẹwa si ago mẹrin owurọ ni gbogbo ọjọ Kọkanlelọgbọn osu Kejila ọdọọdun.
O ni dipo isin oru ọjọ ọdun, awọn yoo se isin lọjọbọ ti yoo gba awọn ni nkan bi wakati meji si mẹta, ati pe, lọjọ ọdun awọn yoo se isin kan laago meje aarọ, tawọn yoo si fi han lori ayelujara.
Bẹẹ naa ni oludasilẹ ijọ Mountain of Fire and Miracles Ministry, sọ pe ijọsin awọn yoo waye laarin ago mẹsan si mọkanla. O ni eyi to ku awọn yoo maa se lori ayelujara titi wọ ọjọ ọdun.
Ni ti ijọ Deeper, awọn sọ pe ago mẹwa alẹ lawọn yoo bẹrẹ isin aisun ọdun tuntun.
Covenant Christian Centre to wa ni Eko sọ pe awọn eeyan yoo kopa ninu isin awọn laarin ago meje alẹ si ago mẹsan alẹ.Amọ eyi to ku awọn yoo se loju opo ayelujara lati ago mọkanla alẹ di ago kan owurọ.
CAN ti saaju sọ fun BBC pe awọn ko mọ nkankan nipa ilana ti ijọba gbe kalẹ lori isin oru aisun ọdun sugbọn wọn yi ohun pada ninu atẹjade kan.
Aarẹ CAN Samson Ayokunle sọ fun gbogbo awọn ile ijọsin Naijiria lati bọwọ fun ofin ki wọn si tẹle ilana ijọba nipa isin ọjọ aisun ọdun.
Wọn ni ko si ''ifarajin to pọju lati wa ọna idẹkun ajakalẹ yi patapaa''
CAN wa parọwa sawọn ile ijọsin gbogbo nipinlẹ ti ijọba ti wọgileisin yi  lati se isin wọn ki ọjọ to lọ ki wọn si palẹmọ o pẹ ju ago mọkanla alẹ.
Oríṣun àwòrán, Catholic Church of Nigeria
Ẹgbẹ́ ọmọlẹ́yìn Kírístì ni Nàìjíríà (CAN) ti rọ àwọn ìjọ ni gbogbo ìpinlẹ̀ Nàìjíríà, tó fi mọ ìlú Abuja, láti tẹ̀lé gbogbo ìlànà ìjọba lórí ọ̀rọ̀ Covid-19.
Nínú ọ̀rọ̀ rẹ̀, àgbẹnusọ ààrẹ CAN, Pásítọ̀ Bayo Oladeji tó sọ̀rọ̀ lórúkọ ààrẹ ẹgbẹ́, Dókítà Supo Ayokunle ni, gbogbo àwọn alága ìpínlẹ̀ ni àwọn ti jọ sọ̀rọ̀ yé pọ láti tẹ̀lé òfin ti ìjọba ìpínlẹ̀ ti wọ́n wà bá là sílẹ̀ lori sise aisun ọdun tuntun.
Oladeji ní gẹ́gẹ́ bi ìròyìn tó tẹ́ ẹgbẹ́ CAN àpapọ̀ lọ́wọ́, ìjọba apapọ̀ kò fi ìgbà kankan sọ pé ki àwọn ìjọ máse péjú fún ètò ìsìn ìrékọjá sínú ọdún tuntun, sùgbọ́n àwọn ìpińlẹ̀ kan sọ pé, lá kò sí ǹkan tó jọ ọ́.
Gẹ́gẹ́ bí ìgbésẹ̀ tí àjọ CAN ń gbé, àwọn yóò fi àtẹjáde kan síta lónìí ọjọ́ ìṣẹ́gún láti sọ fún gbogbo àwọn ọmọ ẹgbẹ́ láti tẹ̀lé ǹkan ti ìjọba ìpínlẹ̀ wọ́n bá sọ.
Oríṣun àwòrán, Ayokunle
Oladeji sàlàye pé, ó ṣeni láànu pé, sọ́ọ̀sì nìkan ni ìjọba n kọjú sí lórí títèlé àlàálẹ̀ òfin Covid-19, bí ó ti lẹ̀ jẹ́ pé gbogbo òfin yìí ni àwọn ìjọ ń tẹ̀lé.
"Tí ẹ bá lọ sínú àwọn ọjà wa, kò sí ẹni tọ n tèlé ìlàna òfin Covid-19, ko si si ẹni tó mú wọ́n si.
Kódà gbogbo àwọn olóṣèlú wa ni à n ri lóri amóhùnmáwòràn bi wọ́n ṣe n ṣe ètò òṣèlú láì tẹ̀lé òfin Covid-19 sùgbọ́n tó bá ti di ọ̀rọ̀ sọ̀ọ́sì..."
Bákan náà lo rọ àwọn ìjọ pé, ki wọ́n fi alafo tó péye silẹ̀ dáada láàrín àwọn ara sọ́ọ̀sì ki wọ́n ma ba fún pọ́.
Zlatan: Ọ̀rẹ́ ni mo sìn lọ ‘studio’ tí mo fi bẹ̀rẹ̀ orin lẹ́yìn tí mo kùnà ìdánwò WAEC
Ó tún ni àwọn rọ wọ́n kí wọ́n ṣe ìsìrìn náà sáájú àsìkò tí wọ́n maa n ṣee tẹ́lẹ̀ ki olúkúlùkù sì pàda síé wọ́n kí ilẹ̀ tó ṣú.
Gbogbo ǹkan ti ìjọba n ṣe yìí fún ànfàní olúkúlùkù ni, nítórí náà gbogbo ǹkan ti a bá le ṣe, láti dẹ́kun àjàkálẹ̀ ààrùn Covid-19 ki ó fi kásẹ̀ nílẹ̀, ni à ó ṣe.
Tí a bá ti ṣe, ti àìsàn yìí bá ti lọ pátápátá, à ó pada si bí a ṣe ń ṣe tẹ́lẹ̀.
'Ọ̀lọ́pàá shátà mi láti Mowe dé Magboro dé Shagamu, wọ́n ní ṣé mi ò mọ̀ pé ìjọ́ba ni mo ṣiṣẹ́ fún'
Bákan náà ló tun rọ àwọn ìjọ tó ni onírúúrú ààyè nínu ilé ìjọsin wọ́n, pé ki wọ́n pin àwọn ènìyàn síbẹ̀ tàbi kí wọ́n pín ìsì wọ́n sí ọ̀nà ọ̀tọ̀ọ̀tọ, ki èrò má ba pọ nínú ìsìn.
Sáájú àsìkò yìí ni ẹ̀ka CAN ti ìpínlẹ̀ Ondo ti ni, kò sí ǹkan tó kan àwọn pẹ̀lú ọ̀rọ̀ ìjọba nítórí náà àwọn yóò ṣe ìsìn òpin ọdún ní tàwọ́n.
2020 in Retrospect: Ìjàmbá iná, ilé tó dàwó, ìwọ́de àti àrùn Covid-19 wà lára ìṣẹ̀lẹ̀ 2020
Bo se ku ọjọ kan pere ti ọdun 2020 yoo kogba wọle, ta si ki ara wa kaabọ sinu ọdun tuntun, BBC Yoruba bojuwo ẹyin lati wo awọn isẹlẹ manigbagbe to waye ninu ọdun naa.
Gẹgẹ baa se mọ pe tibi-tire la dale aye, tibi-tire la sẹda eeyan, bẹẹ gẹgẹ naa ni tawọn isẹlẹ manigbagbe yii, ti wọn jẹ ire ati ibi.
Bi o tilẹ jẹ pe isẹlẹ ayọ ko to nnkan, amọ awọn isẹlẹ ibi pọ lọ jaburata bii ijamba ina, ọpọ ile to dawo lulẹ, ijinigbe, aifararọ eto aabo, omiyale ati ọpọ iwọde lorisirisi.
Ẹnu ko gba iroyin lawọn isẹlẹ yii, ẹ sa wo fidio yii lati mọ si nipa awọn isẹlẹ ati iroyin to kasiara lọdun 2020.
A ku oju lọna ọdun tuntun.
Adewole Oniluola: Tunde Kelani ni ikú àgbà Àyàn náà tún mú kí ilẹ̀ Yorùbá sọ ohun rere nù
Oríṣun àwòrán, Sikiru Adepoju
Gbajumọ ayan kan nilẹ Yoruba, to tun n lu ilu fun oloogbe Ayinla Omowura, gbajumọ akọrin Apala, ti jade laye ni alẹ ọjọ Isegun.
Ọdun mẹtadinlọgọrun lo lo loke eepẹ, ko to tẹri gbasọ.
Deede aago mẹwa owurọ ni gbajumọ onilu naa mi kanlẹ nile rẹ ladugbo Keesi nilu Abeokuta.
Oniluola jẹ ipe Ọlọrun lẹyin osu kan ti wọn se ayẹyẹ ọjọ ibi rẹ eyi tawọn eeyan jankanjankan peju si.
Oríṣun àwòrán, Facebook/Kamilu Adewole
Nigba to n fidi isẹlẹ iku baba Oniluola mulẹ fun BBC Yoruba,  ilumọọka osere tiata kan, Tunke Kelani  salaye pe aago mẹrin irọlẹ oni Ọjọru ni oloogbe naa yoo wọ kaa ilẹ sun.
O ni aarẹ agba lo pa Adewole, ọdun mẹta si lo ku ko pe ọgọrun amọ awọn dupẹ fun Ọlọrun pe o da ẹmi wọn si di akoko yii.
Tunde Kelani ni ko si ẹni ti ko mọ pe oloogbe naa lo jẹ igi lẹyin ọgba fun ẹgbẹ osere Ayinla Omowura, Oniluola yii si lo ni ẹbun ilu lilu julọ ni agbaye.
"Ilu Oniluola ati ajọsepọ rẹ pẹlu Omowura lo jẹ ki Ayinla di ilumọọka, ti awọn mejeeji fi jọ ni okiki papọ.
Adewole nikan lo ku ninu awọn ti wọn dijọ wa ninu ẹgbẹ olorin Ayinla Omowura, gbogbo awọn eeyan yoku ti lọ.
Tunde Kelani ni ko tii pe osu kan ti awọn peju se ayẹyẹ ọjọ ibi fun Oniluola, ti awọn ko si mọ pe ọlọjọ ti n sunmọ.
2020 in Retrospect: Ìjàmbá iná, ilé tó dàwó, ìwọ́de àti àrùn Covid-19 wà lára ìṣẹ̀lẹ̀ 2020
Kelani ni Isẹlẹ yii n powe fun awa ọmọ Yoruba pe nnkan meremere ti Ọlọrun fun awa ọmọ Yoruba ti n lọ diẹdiẹ niyẹn."
O ni o se ni laanu pe awa taa wa lẹyin wọn ko wo awokọse awọn agbaagba yii lati le sọ pe nnkan ti awa naa ti gbe se ni eleyi.
"Bi ere, bi ere awọn eeyan ti Ọlọrun fun ni ẹbun ilu lilu nilẹ Yoruba ti n lọ tan, ko si si awọn eeyan to maa gba ipo wọn."""
O fikun pe ohun to jẹ ko se ni laanu pe iran Yoruba tun padanu Adewole ree.
Bakan naa lo ni iku oloogbe naa ti fi opin si saa igbe aye kan nilẹ Yoruba.
O wa gbadura pe Ọlọrun yoo dẹ ilẹ fun ẹni re to lọ naa.
2021 Prophecies: Olagoke ní ẹni tó bá fi ara rẹ̀ sílẹ̀ fún Ọlọ́run, yóò ríran
Oríṣun àwòrán, Facebook/Ariyo Olagoke
Asọtẹlẹ ọdun 2021 ti onimọ nipa ẹsin Islam, Sheik Sabitu Ariyo Olagoke sọ, eyi ti BBC gbe jade ti n fa oniruuru auyewuye lori ayelujara.
Olagoke lọjọ aisun ọdun tuntun lo kede nipa awọn isẹlẹ alagbara ti yoo waye lọdun tuntun, ninu eyi to ti sọ pe iwọde miran to ju ti Endsars lọ tun n bọ losu kẹta ọdun 2021.
Sugbọn awọn asọtẹlẹ yii ni awọn ọmọ Naijiria kan, paapaa awọn musulumi tako pe ko ba ilana ẹsin Islam mu.
Ninu alaye awọn eeyan  to fesi si asọtẹlẹ ti onimọ yii gbe kalẹ, wọn ni esin Islam ko faye gba ki eeyan maa sọ asọtẹlẹ nitori ko si ẹni to ni imọ ikọkọ.
Oniruuru awọn ọrọ kobakungbe ni wọn n sọ nipa awọn asọtẹlẹ naa, eyi to n kọ ọpọ eeyan lominu.
Idi ree ti BBC Yoruba se ba Sheik Olagoke sọrọ lati mọ boya lootọ ni iwa sisọ asọtẹlẹ ko si ninu ẹsin Islam.
Ninu ifọrọwerọ rẹ, Olagoke ni ''Alainimọ ẹsin Islam lo maa sọ wi pe ẹsin ko faye gba ki eeyan maa sọ asọtẹlẹ''
Ojisẹ Ọlọrun naa, to tako ero awọn eeyan to ni ko si asọtẹlẹ ninu Islam, tun salaye pe ''Bi ẹ ba wo inu Kurani ninu Surah Kẹtadinlọgọta (57) ẹsẹ Kejilelogun  si ikẹtalelogun(22 -23), ko si isẹlẹ to n waye ninu aye, inu ẹmi la a kọkọ gbe si''
Surah ti ọjọgbọn yi n sọ nigba ti a sagbeyẹwo rẹ jẹ Surah Hadid, to si sọ ọrọ nipa pe ko si nkankan ti yoo sẹlẹ si ẹda ọmọniyan ni aburu, ti kii se pe o ti wa ninu akọsilẹ lọdọ Ọlọrun(Allah).
Surah naa tẹsiwaju pe, o rọrun fun Ọlọrun (Allah) lati sọ di imusẹ sugbọn ko sọ nipa pe eeyan le mọ nkan to wa ninu akọsilẹ yii tabi ko le sọ di imusẹ fawọn eeyan.
Ọjọgbọn Sabitu salaye siwaju pe ''Aanu ati ibukun ni ki eeyan le riran, sugbọn ọpọ awọn to ni ẹbun yii, n se ni wọn fi n sofo''
Èmi nìkàn kọ́ ni mó n ṣe àkójọ orin- Fasoyin
O fi kun pe ''ẹni to ba fi ara rẹ silẹ to si n gbọ bi Ọlọrun ti se n ba sọrọ yala ninu Kurani ni tabi ninu bibeeli, iru eeyan bẹẹ yoo si ma riran.''
''Awọn to n sọ́ wi pe ko tọna, wọn ti ju ara wọn silẹ, a ko le ran wọn nisẹ, awọn ni wọn n ran ara wọn nisẹ.''
Ojọgbọn naa wa fidi rẹ mulẹ pe, nkan meji ni kii mu asọtẹlẹ di mimu sẹ lode oni.
Akọkọ alaye to se ni pe, ki awọn eeyan maa mu ifẹ inu ti wọn wọ inu asọtẹlẹ tabi ọna ati ri owo gba.
Alapinni Oosa ṣàdúrà fún gogbo ọmọ kúoótù, oò jíire bí?
''Bi a ba fi iran se inunibini si ijọba kan, ka sọ wi pe ijọba rẹ yoo kogba wọle lọla, iru nkan bayi kii mu ki asọtẹlẹ di imusẹ.
Ẹlẹẹkeeji  to ni kii mu ki asọtẹlẹ di mimu sẹ ni ki awọn eeyan kan gbọ asọtẹlẹ, ki wọn ma sisẹ tọ imusẹ asọtẹlẹ ọhun.
Oríṣun àwòrán, Professor Sabit Ariyo Olagoke
Saaju la ti kọkọ mu iroyin wa fun yin pe onimọ nipa ẹsin Islam, Ọjọgbọn Sabitu Ariyo Olagoke ti gba awọn ọmọ Naijiria nimọran lati mase bẹru aṣọtẹlẹ, nitori yoo palẹ ọkan wọn mọ fun bi ọdun tuntun yoo ṣe ri ni.
Sabitu Ariyo Olagoke ni ki orilẹede Naijiria ba le e tẹsiwaju ni ọdun 2021, awọn ẹlẹsin gbọdọ fi ọwọ sowọpọ lati mu alafia jọba ni agbegbe wọn.
Alfa Olagoke wa kilọ fun awọn eniyan lati maṣe fi oju di arun Coronavirus nitori yoo mu ọpọ ẹmi lọ, ti wọn ko ba tẹle awọn ofin to rọ mọ didẹkun itankalẹ arun naa.
"Onimọ ẹsin Islam naa, ẹni to pe akori asọtẹlẹ rẹ ni ""What 2021 has in store for Nigeria"", kede awọn ọrọ naa lati mọsalasi Shafaudeen In Islam Worldwide ni Wakajaye Ibadan."
Lara awọn asọtẹlẹ naa ree:
Alapinni Oosa ṣàdúrà fún gogbo ọmọ kúoótù, oò jíire bí?
Onimọ nipa ẹsin Islam, Ọjọgbọn Sabit Ariyo Olagoke naa wa rọ ijọba lati mu ọrọ eto aabo lọkunkundun, ki o ma ba da wahala silẹ ni ọdun tuntun.
Bakan naa ni Alfa naa rọ ijọba ati ẹgbẹ awọn olukọ Fasiti lati ṣe ojuṣe wọn, ki eto ẹkọ le tẹsiwaju, ki awọn ọdọ ma ba a tọwọ bọ iwa ọdaran.
2021 Prophesies: Wòlíì Kolawole ní Ọlọ́run ló fi Makinde sípò, kìí ṣe àṣìṣe ní ìyànsípò rẹ̀
Oríṣun àwòrán, Facebook/@OfficialSeyiMakinde
Ojisẹ Ọlọrun kan to fi ilu Ibadan se ibujoko, Wolii Richard Kolawole ti kede awọn iran nla to ri lori gomina ipinlẹ Oyo, Onimọ ẹrọ Seyi Makinde.
Wolii Kolawole, lasiko to n sọ asọtẹlẹ rẹ fọdun 2021 tiwe iroyin Tribune gbe jade tun kede pe afaimọ ki aawọ nla to n waye laarin Makinde ati Ayodele Fayose ma doju ẹgbẹ oselu PDP bolẹ lorilẹede Naijiria.
Ojisẹ Ọlọrun naa ni yoo dara ki Makinde ati Fayose tete pe ara wọn joko lati yanju aawọ naa nitunbi n nubi, ko to pẹ ju, bi bẹẹ kọ, o le lẹyin bii oku iya jọjọ.
Ko tan sibẹ o, Wolii naa tun ni awọn ọmọ ẹgbẹ oselu PDP ti Seyi Makinde jade latinu rẹ ati ẹgbẹ oselu alatako, APC, ti n ditẹ nla mọ gomina naa.
Fayose gọ̀, ó fẹnu họra, Ọlọ́run á gbẹ̀san lára rẹ̀, àdàbí...- Bode George
O wa rọ awọn eeyan ipnilẹ Oyo lati tete kunlẹ adura fun gomina Seyi Makinde.
"Ọlọrun lo mọọmọ yan gomina Seyi Makinde lati dari ipinlẹ Oyo, kii si se asise lo fi de ipo naa. Amọ lọwọlọwọ bayii, wọn ti n ditẹ nla mọ.
Oluwa sọ pe iditẹ laagbara naa ko sẹyin ete lati yẹ aga gomina mọ Makinde nidi ninu ibo 2023, Oluwa ni yoo dara ko tete yanju isoro naa.
Mo wa n rọ gbogbo eeyan lati maa gbadura fun Seyi Makinde ko le ru re, ko si sọ re, nitori awọn eeyan to n ditẹ naa ti n leri-leka lati yẹ aga mọ nidi.
Alapinni Oosa ṣàdúrà fún gogbo ọmọ kúoótù, oò jíire bí?
Yoo dara ki gomina Makinde to ile rẹ, ki awọn isoro yii lee di ohun itan saaju ọdun 2023.
Wolii Kolawole tun fikun pe ọwọja iwa ijinigbe yoo tubọ pọ si lorilẹede Naijiria ni 2023, ti isẹlẹ ẹkun omi pupọ ati ijamba ina  yoo si waye ni ọpọ ipinlẹ.
O wa rọ awọn gomina ipinlẹ kọọkan lati san sokoto wọn ko le, ki wọn si setan lati koju awọn ipenija nla naa.
Deborah Adebola Fasoyin: Èmi kọ́ ló gbé orin ọdún ń lọ sópin kalẹ̀, CAC ló ni í ni mó n ṣe àkójọ orin- Fasoyin
Orin ọdun n lọ sopin jẹ eyi to gbajumọ laarin ọpọ eeyan lai fi ti ẹsin se nitori ọpọ adura to pọ ninu orin naa.
Ti ọdun ba si ti n lọ sopin ni orin naa maa n gbalẹ kan , eyi tawọn eeyan n lo lati se adura funra wọn.
Ọna lati mọ nipa bi agbekalẹ orin naa se waye, lo mu ki BBC Yoruba kan si asaaju ẹgbẹ akọrin obinrin ninu ijọ CAC to kọ orin naa, Mama Deborah Adebola Fasoyin.
Nínú ìfọ̀rọ̀wérọ̀ rẹ, ìya Fasoyin sàlàyé pé àgbáríjọ àwọn akọrin CAC ló jọ máa wọ inú àwẹ̀ àti àdúra láti ṣe àkójọ orin gbogbo orin wọn.
Ìyá Fasoyin sàlàyé pé lẹ́yin àdúra àti àwẹ́ ní wọn yóò wá mú àwọn ti ẹmi mímọ bá fí sí wọ́n lakan láti gbé síta.
O wa fidi rẹ mulẹ pe ọjọ Kọkandinlogun osu Kẹsan ọdun 2020 yii ni wọn ṣe orin náà si ẹ̀yà Igbo àti Hausa fún ànfàni àwọn ti kò gbọ́ Yorùbá.
Divorce in Nigeria: Abilékọ kan ṣàlàyé lórí ìdí tó fi gb'oyún láti ìta wá sọ́ọ̀dẹ̀ ọkọ
Oríṣun àwòrán, The Star
Abilekọ kan to n gbe ilu Ibadan, Toyin Bello ti sọ ohun to ri lọbẹ to fi waro ọwọ, lori bi o ti gba ki ọkunrin mii fun un loyun lọọdẹ ọkọ rẹ.
Nigba to n jẹjọ nile ẹjọ kọkọ-kọkọ niluu Ibadan, Bello beere pe ki ileẹjọ tu igbeyawo ọdun mẹrindinlogun pẹlu ọkọ oun ka, nitori aileṣe bii ọkunrin rẹ.
Bello ti kọkọ fẹsun kan ọkọ rẹ pe, o fi Ibalopọ dun oun fun ọdun mẹwaa.
Obinrin naa sọ fun ileẹjọ pe, oun gbe igbesẹ lati gb'oyún lati ita nitori itiju airọmọ bi.
Èmi nìkàn kọ́ ni mó n ṣe àkójọ orin- Fasoyin
Mi o fẹ ki oju ti ọkọ mi nitori airọmọbi lo jẹ ki n gba oyun lati ita,"" arabinrin Bello lo sọ bẹẹ."
Bello ni ọkọ oun tun fẹ ṣeku pa oun ko le jogun ile oun.
Mo kuro nile lati maa gbe ni ṣọọṣi lagbegbe Asi n'Ibadan, Oluwa mi, mi o le maa fi akoko mi ṣofo mọ pẹlu Dotun, ọjọ ti n lọ lori mi. Ẹ jọwọ, ẹ tu igbeyawo yii ka, Bello rọ ileẹjọ.
Alapinni Oosa ṣàdúrà fún gogbo ọmọ kúoótù, oò jíire bí?
Henry Agbaje to jẹ aarẹ ileẹjọ naa tu igbeyawo ọhun ka, o si pàṣẹ pe ki Dotun kuro ninu ile ti wọn jọ n gbe laarin ọjọ méje.
Amọ, Ọgbẹni Dotun tako idajọ naa, o si rọ ileẹjọ lati ba oun bẹ iyawo oun.
Dotun ni lootọọ ni pe oun ni ailera lati fun obinrin loyun, ṣugbọn iyawo oun naa ti ilẹkun mọ ri, ko jẹ ki oun wọle tọ ọ.
Adejare Adeboye: Olúwa yóò dá gbogbo ohun ta sọnù ní 2020 padà ní ilọ́po méje fún wa
Yoruba ni ohun to ba dara n fẹ adura, bakan naa ni ohun to ba ku diẹ kaato.
Ọpọ Ijakulẹ lọmọ Naijiria ba pade lọdun 2020 to kogba wọle, idi ree ta fi nilo ọpọ adura ninu ọdun tuntun 2021 ta bẹrẹ yii.
Eyi lo mu ki BBC Yoruba tọ ọkan lara awọn ilumọọka ojisẹ Ọlọrun ni Naijiria, Pasitọ Enoch Adejare Adeboye lọ, pe ko fi ojo adura bẹrẹ ọdun tuntun fun gbogbo wa.
Baba gbadura, ilẹ kun, ẹ wo fidio adura yii, kẹ si maa se amin witiwiti.
Insecurity in Nigeria: Arewa ní owó ìdáǹdè ìjínigbé ni agbébọn fi ń ra ohun ìjà olóró
Oríṣun àwòrán, Facebook/Nigeria Police Force
Ẹgbẹ apapọ awọn ọmọ bibi ẹkun ariwa Naijiria, Arewa, ti n ke gbajare ninu ọdun tuntun lori eto aabo to dojude loke ọya.
Alaga apapọ fẹgbẹ Arewa, Oloye Audu Ogbeh lo ke gbajare bẹẹ ninu atẹjade kan to fisita.
Ogbeh ni Rakunmi ati lawọn janduku n lo bayii lati gbe awọn ado iku ati ibọn ajabaalu walẹ wọ Naijiria wa, lati awọn ẹnu bode to wa lapa ariwa orilẹede yii.
Ninu atẹjade naa to pe akọle rẹ ni 'Awọn ẹnu bode wa ati aifararọ eto aabo', tun sisọ loju rẹ pe lati awọn orilẹede to mule ti Naijiria ni wọn ti n ko awọn ohun ija oloro naa wa.
Adejare Adeboye: Olúwa yóò dá gbogbo ohun ta sọnù ní 2020 padà ní ilọ́po méje fún wa
Ogbeh, ẹni ti ko darukọ awọn orilẹede to mule ti wa naa, wa fikun pe ipinlẹ Sokoto ati Zamfara lawọn ti gbọ nipa iroyin yii, nitori awọn lo ba ilẹ Niger paala.
Alaga ẹgbẹ Arewa naa ni ojuse ẹgbẹ naa ni lati fi ọrọ yi to ijọba apapọ atawọn agbofinro leti, ki wọn le gbe igbesẹ to tọ nitori o n bọ, o n bọ, awọn laa dẹ de.
Bakan naa lo sisọ loju rẹ pe, owo ti awọn ajinigbe naa ba gba lọwọ mọlẹbi ẹni ti wọn mu nigbekun, ni wọn fi n ra awọn ohun ija oloro naa.
Èmi nìkàn kọ́ ni mó n ṣe àkójọ orin- Fasoyin
O wa parọwa pe kawọn agbofinro maa bẹrẹ si yẹ ara awọn Rakunmi to n wọ ẹnu bode wa wo finnifinni, nitori eyi yoo se ilẹ Naijiria loore pupọ.
Ẹgbẹ Arewa wa n kọminu pe iye awọn agbegbọn yii lo n di pupọ si lojoojumọ, ko si ni pẹ ki wọn to ni awọn ohun ija oloro to yanranti lọwọ, ju awọn agbofinro lọ.
Leah Sharibu: Ẹbí ní ìjọba Buhari kò ní àwáwí láti máṣe gba ìdáǹdè akẹ́kọ̀ọ́bìnrin náà
Oríṣun àwòrán, @Frank_Obiora
Iya to bi Leah Sharibu, ọmọbinrin ti Boko Haram ji gbe lati ọdun meji le diẹ sẹyin, ti dubulẹ aisan lọjọ Keresimesi, to si ti n gba itọju nile iwosan.
Bẹẹ ba gbagbe, ọjọ Kakandinlogun osu Keji ọdun 2018 ni Boko Haram ji akẹkọbinrin aadọfa ko lọ nile ẹkọ girama obinrin to wa nilu Dapci nipinlẹ Yobe.
Bi o tilẹ jẹ pe Boko Haram fun awọn akẹkọọ yoku nidande amọ Leah Sharibu, tii se ọmọ ọdun mẹrinla nigba naa, nikan ni wọn ko tu silẹ.
Gẹgẹ bi iwe iroyin Punch ti sọ, igba akọkọ kọ ree ti iya Leah yoo wolẹ aisan lọjọ ọdun Keresi nitori bo ti se naa ree lọdun 2018 ati 2019.
Adejare Adeboye: Olúwa yóò dá gbogbo ohun ta sọnù ní 2020 padà ní ilọ́po méje fún wa
Agbẹnusọ fun idile naa, Gloria Puldu sisọ loju rẹ pe keresi kẹta ree ti Leah yoo se ni ahamọ ajinigbe.
O wa n rọ ijọba lati se amusẹ ileri rẹ lati gba idande Leah ni ahamọ Boko Haram.
O ni ko si awawi fun ijọba lori bi ko se le gba itusilẹ akẹkọọbinrin naa, niwọn igba to gba idande awọn akẹkọọkunrin Kankara laarin ọjọ mẹfa pere.
Pastor Adeboye: Kò sí ẹni tó sọ fún wa pé àjẹ́ ní COVID-19 àti pé òru ló n fò- Pasitọ Adeboye
Oríṣun àwòrán, Twitter
Pasitọ igba Ijọ Redeem Christian Church of God, Enoch Adeboye ti bu ẹnu atẹ lu ijọba orilẹede Naijiria lori bi wọn ṣe fofin de isin irekọja si ọdun 2021.
Adeboye lo sọ bẹẹ lasiko to waasu ni isin Ọjọ Isinmi, Ọjọ Kẹta, Osu Kini, ọdun 2021 ni ile ijọsin rẹ.
O ni o ṣe ni laanu pe ijọba n kede fun awọn eniyan lati ṣe isin ọdun tuntun ni ago mẹwaa, aago mọkanla nigba ti o yẹ ki wọn rekoja si ọdun tuntun.
''Nitori naa ni a ṣe joko si ile wa, ti a si ṣe isin ni aago mejila, ti a fi rekọja si ọdun tuntun''
''Ko si ẹni to sọ fun wa pe, ajẹ ni Coronavirus to n fo loru, to si le e panijẹ ni oru, iyẹn aago mejila gan an.''
Bakan naa ni baba kesi awọn eniyan lati lọ si ile ounjẹ Buka lati lọ jẹun, ti ijọba ba kọ lati fun wọn laaye lati lọ si awọn ile ounjẹ igbalode.
Ọpọlọpọ awọn Naijiria ni wọn ti n fi esi fun ijọba lori ohun ti baba Adeboye sọ naa, ti o si n pa ọpọlọpọ eniyan lẹrin.
Oríṣun àwòrán, Instagram/frmbakaofficial
Ti Aarẹ Muhammadu Buhari ko ba mura, ẹsẹ ijọba rẹ lọdun 2021 yii.
Alufa ijọ Aguda to tun jẹ oludari ijọ Adoration Ministries niluu Enugu, Rev Fr Ejike Mbaka lo sọ asọtẹlẹ yii.
Alufaa Mbaka ṣalaye pe bo ya ijọba Buhari yoo wa sopin tabi ko ni wa sopin da lori bi Buhari ba ti yara ṣiṣẹ si.
Ninu ọrọ rẹ, Mbaka gba ijọ apapọ ni imọran lati pese iṣẹ fawọn ọdọ ni Naijiria lati le dẹkun iwa jagidijagan tawọn ọdọ tun le gunle.
O ni bi bẹẹ kọ, iwa ipa awọn ọdọ le da oju ijọba Buhari bolẹ.
Alufaa Mbaka ko ṣai sọrọ sawọn ọmọ ile igbimọ aṣofin agba l'Abuja lẹyin to ṣapejuwe wọn gẹgẹ bi ajinigbe.
''Ibinu Ọlọrun n bọ lori gbogbo ọpọ awọn oloṣelu to ti kowo ijọba jẹ,'' Mbaka lo sọ bẹẹ.
Bakan naa lo tun sọ pe ibinu Ọlọrun tun wa lori awọn olori orilẹede Naijiria nigba kan ri atawọn to wa lori aleefa lọwọ nitori wọn ti sọ awọn ọdọ di atọrọjẹ lawọn orilẹede mii.
Mbaka kilọ fawọn eeyan lati maa kọ eti ikun sawọn asọtẹlẹ oun bi bẹẹ kọ, asọtẹlẹ naa le ṣẹ mọ wọn lori.
Ìjọ Mountain of Fire fi àwọn àsọtẹ́lẹ̀ ìbẹ̀ru sítà fuń ọdun 2021
Ijọ Mountain of Fire ti fi awọn asọtẹlẹ jade fun ọdun 2021 sita, bii awọn ojisẹ Ọlọrun miran ṣe n sọtẹlẹ nipa awọn isẹlẹ ti yoo waye lọdun tuntun 2021 ati bi ọdun naa yoo se ri.
Oludasilẹ Ijọ MFM, Daniel Olukoya pe akọle awọn asọtẹlẹ naa ni 'Year of Restoration and Revival', lasiko isin ọdun tuntun ninu ile ijọsin rẹ.
Oríṣun àwòrán, Twitter
Olukoya wa rọ awọn ọmọ Naijiria lati ma a gba adura, ki wọn si kun fun nitori ohun gbogbo ti wọn n fẹ ni yoo tẹ wọn lọwọ ti wọn ba gbadura.
''Adura kikankikan ni wọn nilo lati koju arun Coronavirus ti gbongbo, ti gbongbo.''
''Ọpọlọpọ ẹkun ohun ipayinkeke yoo pọ ninu ọdun tuntun naa, nitori naa ni adura ṣe ṣe koko''
Oríṣun àwòrán, Twitter
''Ọpọlọpọ idojukọ ati idunkoko mọni ni yoo waye ninu ọdun tuntun naa.''
''Ti a ko ba gbadura kikan-kikan, esu yoo gbogun ti orilẹede naa, ti ifẹhọnuhan ohun ija yoo si gbode kan.''
''Baamu Gilead nikan lo le gba awọn eniyan la lọwọ ipayinkeke ati iditẹmọni ti yoo waye ninu ọdun 2021 naa''
Bakan naa ni o ni ki awọn eniyan gbadura kikan ki omiyale agbara ya sọọbu ati awọn iṣelẹ pajawiri layika, ko ma gba ọdun naa jẹ mọ awọn eniyan lọwọ.
Ọpọ eeyan lo n fapa janu pe ọdun 2020 to kọja lọ ko dara to, ti wọn si n foju sọna si awọn ohun rere tabi isẹlẹ ti yoo waye lọdun 2021, eyi ti yoo jẹ ki wsn gbaradi de ọdun tuntun naa.
Bi o tilẹ jẹ pe lara awọn asọtẹlẹ tawọn ojisẹ Ọlọrun naa sọ lọdun 2020 ko wa si imusẹ, sibẹ, ọpọ wsn tun ti jade bayii lati sọ ohun ti ẹmi sọ fun wsn pe yoo waye ninu ọdun 2021.
Awọn ojisẹ Ọlọrun to ti sọ asọtẹlẹ tiwọn jade fun ọdun 2021 ree:
Odu ni wolii Ayodele ni agbo awọn ojisẹ Ọlọrun, kii si se aimọ fun oloko lagbo awọn ọmọlẹyin Kristi pẹlu.
Koda,aimọye asọtẹlẹ lo ti sọ lati aimọye ọdun sẹyin, tawọn kan ninu wọn si wa si imusẹ nigba ti awọn miran kuna lati sẹ.
Oríṣun àwòrán, Primate Elijah Ayodele
Ojisẹ Ọlọrun yii, tii se oludasilẹ ijọ INRI Evangelical, ninu asọtẹlẹ fọdun 2021 ti wa kede pe awọn nnkan wọnyi  yoo waye:
Oludasilẹ ijọ Tabernacule naa, T B Joshua ko ti  fi ọrọ asọtẹlẹ kan sita dabi alara fun ọdun tuntun 2021.
Oríṣun àwòrán, @T B Joshua
Bisọọbu David Oyedepo: Esu n lo arun Coronavirus lati dide kọlu ijọ Ọlọrun ni
Awọn adura to dabi asọtẹlẹ ni Bisọọbu David Oyedepo, ti ijọ Winners Chapel gbe sita nipa ọdun 2021, lara awọn adura naa si ree:
Ọpọ isẹlẹ iyalẹnu ni yoo waye ninu ọdun 2021
Adejare Adeboye: Olúwa yóò dá gbogbo ohun ta sọnù ní 2020 padà ní ilọ́po méje fún wa
Nibayii ti ọdun ti wa wọle de, o dabi ẹni pe awọn ojisẹ Ọlọrun naa n sọra se lati sọ asọtẹlẹ nipa ohun ti yoo waye lọdun 2021.
Idi ni pe ọpọ eeyan lo n tabuku awọn ojisẹ Ọlọrun naa pe ọpọ awọn asọtẹlẹ ti wọn kede lọdun 2020 ni ko wa si imusẹ.
Omoyele Sowore: Ẹyin ọ̀dọ́, ẹ jáde wá ṣe ìwọ́de àìṣùn ọdún láti tako ìjọba burúkú
Oríṣun àwòrán, @YeleSowore
Iroyin kan to gba ori ayelujara kan lo n wipe awọn agbofinro tun ti mu asiwaju ẹgbẹ ajafẹtọ ẹni Revolution Now, Omoyele Sowore si ahamọ.
Sowore atawọn ọmọ ẹgbẹ ajafẹtọ ẹni naa ni wọn se iwọde kan to pe akori rẹ ni 'Resolute 2021', bẹrẹ ni alẹ aisun ọdun titi wọnu ọdun tuntun.
Bakan naa tun ni irufẹ iwọde naa tun waye lawọn ipinlẹ kan lorilẹede yii bii Ondo, Kaduna ati Osun mọjumọ ọjọ ọdun tuntun 2021.
Oríṣun àwòrán, @YeleSowore
Saaju ni alẹ ọjọ aisun ọdun tuntun ni Sowore ti kede loju opo Twitter rẹ pe ki ẹnikẹni to ba nifẹ lati kopa ninu aisun iwọde naa, jade sita .
O ni ki awọn oluwọde ọhun mu abẹla ati paali ikede lọwọ, eyi to n sọ awọn ohun ti wọn n fi ehonu han le lori nipa ijọba Muhammadu Buhari.
Oríṣun àwòrán, @YeleSowore
Bakan naa lo n rọ wọn pe ki wọn pin awọn aworan ati fidio ti wọn ba ya lasiko iwọde naa soju opo ayelujara wọn.
Gẹgẹ ba se gbọ, awọn agbofinro ko jẹ ki iwọde naa tutu, ti wọn fi sẹburu adari iwọde naa nilu Abuja atawọn oluwọde miran, ti wọn si gbe wọn lọ sibi ti ẹnikẹni ko mọ.
RevolutionNow: Ẹ̀rù ò bàwá, a ṣetan láti wà ní àtì mọ́lé- olùfẹ̀hónúhàn
Nibayi  ọmọ Naijiria lo ti wa n kesi aarẹ Muhammadu Buhari lori ayelujara pe ko tu Omoyele Sowore silẹ ni ahamọ, ko si ye lo ọlọpaa lati dunkoo mọ araalu.
Oluwo Jogbodo Orunmila: Ẹsẹ odù Ifa ló fi ṣúre fún ọmọ Nàíjíríà ní àyájọ́ ọdún tuntun
Adura lọtun losi, ni mu ẹmi ẹda gun.
Ọpọ ojo adura lo ti n rọjo sori awọn ọmọ Naijiria lati ileesẹ BBC Yoruba lati igba ta ti wọnu ọdun tuntun 2021.
Nilana ti ibilẹ, Baba Awo, Oluwo Jogbodo Orunmila naa ree, to n rọjo adura sori awọn araalu gẹgẹ bii iwure ọdun tuntun.
Muhammadu Buhari 2021 Broadcast: Ààrẹ ní àwọn ọ̀dọ́ yóò gbádùn àtìlẹyìn òun lọ́dún tuntun
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Aarẹ Naijiria, Muhammadu Buhari ba awọn eniyan orilẹ-ede naa sọrọ nipa ọdun tuntun, lọjọ kinni, oṣu Kinni, ọdun 2021.
Nkan akọkọ to sọ ni pe O dupẹ lọwọ Ọlọrun to sọ Naijiria ninu ọdun 2020, to si tun fun  ni oore ọfẹ lati ri ọdun tuntun.
O ni ọdun 2020 ni ọdun to lagbara ju lati igba ti Naijiria ti wa gẹgẹ bi orilẹ-ede.  Eyi ko ṣẹyin aarun Covid-19.
Bakan naa lo fikun ọrọ pe ijọba yoo ra abẹrẹ ajẹsara, ti yoo si pin kari gbogbo ẹkùn lai ṣe ojuṣaaju.
Adejare Adeboye: Olúwa yóò dá gbogbo ohun ta sọnù ní 2020 padà ní ilọ́po méje fún wa
O ṣalaye pe ọdun 2020 yoo dan ẹmi ifarada ati okun rẹ wo gẹgẹ bi orilẹ-ede  wo, boya o le la wahala kọja.
Amọ o jade ninu rẹ pẹlu ireti ọtun pe o le koju gbogbo iṣoro to ba koju wa lọdun 2021.
O ni ao gbọdọ ṣa i ma daro awọn eniyan wa ti ko ni iru anfaani bẹ ẹ.
Naijiria yoo duro, yoo si ṣe aṣeyege.
Aarẹ mẹnuba pe nigba ti awọn ọdọ orilẹ-ede Naijiria jade sita lati ṣe iwọde ENDSARS, ijọba tẹti gbọ wọn.
Mo tun lo anfaani ọdun tuntun yi lati tun ẹjẹ jẹ fun awọn ọdọ to nilo iranlọwọ wa pe, didadaabo bo orilẹ-ede yii, lo le daabo bo ọjọ iwaju awọn iran to n bọ.
"Afojusun ijọba yii ni lati ṣe nkan marun ti awọn ọdọ naa beere fun, nitori a ni oye pe didara Naijiria lo jẹ gbogbo wa logun."""
Buhari sọ pe nigba ti gbogbo rogbodiyan naa bẹrẹ, oun jẹjẹ pe gbogbo nkan to ba gba ni oun yoo fun.
Èmi nìkàn kọ́ ni mó n ṣe àkójọ orin- Fasoyin
A ti gbọ ohun yin, ao si tẹsiwaju lati maa tẹti si yin.,
Lori ọrọ awọn ọdọ bakan naa, Aarẹ Buhari sọ pe oun yoo ṣiṣẹ pọ pẹlu awọn aṣofin lati pese ayika to dara fun wọn lati ṣamulo ọgbọn inu wọn, ti a le ṣe iranlọwọ fun, jakejado Naijria.
Alapinni Oosa ṣàdúrà fún gogbo ọmọ kúoótù, oò jíire bí?
Gẹgẹ bi aarẹ yin ti ẹ dibo yan, ẹjẹ ti ma a jẹ fun yin, gẹgẹ bi iṣe mi ni pe, ma a ṣa ipa mi lai ṣe ojuṣaaju.
Femi Adesina: Ààrẹ Buhari ti gbìyànjú tó, ẹ sinmi agbaja àti ìbàjẹ́ rẹ̀
Oríṣun àwòrán, Facebook/Femi Adesina
Oludamọran pataki fun aarẹ Buhari lori eto iroyin ati ikede, Femi Adesina, ti sọ oko ọrọ si awọn to n bu ẹnu ẹtẹ lu aarẹ, o ni ki wọn din ẹkun sisun wọn ku lọdun 2021.
Ninu ọrọ apilẹkọ rẹ to fi sita, Adesina sọ pe ẹlẹkun ni awọn to n bu aarẹ Buhari nitori pe wọn kudun lati ma a bu titi de ori nkan ti ko ni itumọ.
Femi Adesina sọ pe ọdun iṣẹ aṣekara ni 2021 jẹ, ki ijọba le ṣayeyọri lori awọn akaṣe iṣẹ to dawọ le.
Ọdun to yẹ lati sinmi agbaja ni, to yẹ ki awọn ẹlẹkun to n ṣe ibajẹ aarẹ wa iṣẹ ṣe, ki wọn o le fi aaye gba ijọba lati gbajumọ iṣẹ to wa lọwọ rẹ.
Adejare Adeboye: Olúwa yóò dá gbogbo ohun ta sọnù ní 2020 padà ní ilọ́po méje fún wa
O tẹsiwaju pe ẹnikẹni to ba nifẹ orilẹ-ede Naijiria, gbọdọ pinnu lati mase di ijọba lọwọ lọdun yii.
O ni lootọ ni ipenija wa lori eto aabo, ọrọ aje, airiṣẹ ṣe, ati awọn nkan mii. Ṣugbọn o yẹ ki wọn ma a yin ijọba ni, ki wọn o si mu ori rẹ wu lati ṣe daadaa si.
Ọpọlọpọ awọn ti ko mọ riri isẹ Buhari, lo n jẹ anfaani aṣeyọri ijọba rẹ, pẹlu bi awọn kan lara wọn sẹ n wọ ọkọ oju'rin ti iṣakoso rẹ filọlẹ.
Èmi nìkàn kọ́ ni mó n ṣe àkójọ orin- Fasoyin
Adesina ni kii ṣe pe oun ni ki wọn o ma bu ẹnu ẹtẹ lu aarẹ lọdun 2021, amọ ko gbọdọ jẹ koko iṣẹ ti wọn yan layo.
O ni bi nkan ṣe buru to fun Naijiria lori eto ọrọ aje, owo oṣu awọn oṣisẹ ati awọn to ti fẹhinti, to fi mọ ipese owo fun nkan amayedẹrun ati iṣẹ agbẹ ko dawọ duro, nitori aṣẹ ti Buhari pa fun minisita fun eto inawo.
To ba jẹ awọn ijọba asiko kan ni, apo ara wọn ni wọn o da iwọnba owo to wa nilẹ si.
Bea Lewis: Ọ̀rọ̀ Dangote lu Twitter pa lẹ́yìn tí ọmọbìnrin rẹ̀ nílẹ̀ Amẹrika sọ̀rọ̀ sókè
Oríṣun àwòrán, Instagram/iambealewis
Gbajugbaja oniṣowo ọmọ Naijiria, Aliko Dangote ni ẹnin akọkọ tawọn eeyan yoo maa sọ nipa rẹ lori ayelujara lẹyin ti ọmọbinrin ilẹ Amẹrika kan, Bea Lewis sọ pe awọn ti fẹ ra ri.
Lọjọ ọdun, ọjọ kinni oṣu kinni ọdun 2021 ni Lewis to jẹ oniṣowo niluu Atlanta l'Amẹrika fi si oju opo Instagram rẹ pe oun ti jẹ ọrẹbinrin ọkunrin ilẹ Afirika to lowo julọ lagbaaye.
Amọ Lewis sọ ninu ọrọ to fi lede loju opo Instagram rẹ pe Dangote ja oun kulẹ lori ọrọ ifẹ to wa laarin wọn.
Boya awọn eeyan ko ba ti ka ọrọ arabinrin naa kun ṣugbọn niṣe lo fi fọto tawọn mejeeji jọ ya soju opo Instagram rẹ.
Oríṣun àwòrán, Instagram/Bea lewis
Fọto yii atawọn mii gan an lo jẹ ki awọn ọmọ Naijiria bẹrẹ si ni gba ọrọ naa bi ẹni n gba igba ọti lori ayelujara, papaa julọ loju opo Twitter.
Bi awọn eeyan ṣe n sọ oriṣiiriṣii lori ọrọ naa, Dangote ko tii fesi kan, ko si ye ẹnikan bo ya lootọọ ni Lewis fẹ baba olowo naa ri.
Lewis ko ṣai ki Dangote fun ọpọ ẹkọ ti oun ri kọ lara rẹ nigba ti awọn fi n fẹ ara awọn.
Adejare Adeboye: Olúwa yóò dá gbogbo ohun ta sọnù ní 2020 padà ní ilọ́po méje fún wa
O ni Dangote loun ri ẹkọ kọ lara rẹ julọ ninu gbogbo eeyan ti oun ti ba pade laye.
''Biba olowo bi Dangote sọrọ lojoojumọ yoo jẹ ki eeyan ni oye to yatọ nipa aye,'' Lewis lo woye bẹẹ.
Ero awọn ọmọ Naijiria ṣọtọọtọ lori ayelujara lori ọrọ Lewis ati Dangote.
Bi awọn kan ṣe n fi ọrọ naa ṣe ẹfẹ lawọn kan gbe ọrọ naa ka ori.
Ta ni Bea Lewis gan an?
Gẹgẹ bi ohun to kọ si oju opo LinkedIn rẹ, Lewis kẹkọọ ninu imọ ọrọ aje ati ẹkọ imoye ni fasiti ipinlẹ Georgia lorilẹede Amẹrika.
A ko le sọ bo ya o jade nile iwe naa lọdun 2012 tabi 2013.
Oríṣun àwòrán, BEA LEWIS
Ilumọọka ni Lewis niluu Atlanta nitori ibi to ti n ta ounje fawọn eeyan lalaalẹ.
Oun ni oludasilẹ ileeṣẹ ounjẹ kan ti orukọ n jẹ Atlanta Meal Prep.
Lewis tun sọ loju opo Twitter rẹ pe oun ni ọmọdebinrin kan.
Bakan naa lo tun sọ nipa ọkọ rẹ ninu ọrọ mii to fi lede loju opo Twitter rẹ.
Lakotan, Lewis mọ nipa ọti waini daadaa, koda o maa n ta ọti waini.
Yollywood: Àwọn òṣèré Yorùbá t'Élédùwà gbà fún àmọ́ tí wọn kìí ṣe ọmọ ilẹ̀ Yorùbá
Oríṣun àwòrán, Instagram
Yoruba bọ, wọn ibi ti ori ba da ni si laa gbe. Bi ọrọ ti ri ree fawọn gbajugbaja oṣere ori itage Yoruba ṣugbọn ti wọn kii ṣe ọmọbibi ilẹ kaarọ oo jiire.
Ede Yoruba wọn dan mọran, koda wọn maa n pa owe ninu ere nibi ti ede Yoruba ye wọn de.
Lootọọ ni wọn wa lati awọn ipinlẹ mii lapa Gusu orilẹede Naijiria, amọ ere ori itage Yoruba lori fi ran wọn.
Wọnyii lawọn gbajugbaja oṣere ori itage Yoruba ti wọn kii ṣe ọmọ ilẹ Yoruba.
Mercy Aigbe (Ipinlẹ Edo)
Oríṣun àwòrán, Instagram/realmercyaigbe
Wọn bi oṣere Mercy Aigbe lọjọ kinni oṣu kinni ọdun 1978 ni ipinlẹ Edo.
Yatọ si ere ṣiṣe, Aigbe tun maa n dari ere, bakan naa lo tun jẹ oniṣowo.
Ilumọọka ni Mercy jẹ lagbo ere tiata Yoruba, odu ni kii ṣe aimọ fun oloko.
Ilu Benin tii ṣe olu ilu ipinlẹ Edo lo ti wa.
Kelvin Ikeduba (Ipinlẹ Delta)
Oríṣun àwòrán, Facebook/Kelvin Ikeduba
Odu ni Ọgbẹni Kelvin Ngozi Ikeduba lagbo oṣere tiata Yoruba, ki ṣe aimọ fun oloko.
Ọjọ kọkanlelogun oṣu kẹjọ ọdun 1976 ni wọn bi Ikeduba.
Oriṣiiriṣii ipa ni Ikeduba maa n ko ninu ere, eyi to si ti mu un gba oniruuru ami ẹyẹ nibi ere ṣiṣe.
Bi Ikeduba ṣe maa n ṣere Yoruba naa lo maa n kopa ninu ere oloyinbo.
Lootọọ ni Ikeduba jẹ ọmọ ipinlẹ Delta, ṣugbọn agbegbe Ebute-Meta niluu Eko ni wọn bi i si.
Fathia Balogun (Ipinlẹ Delta)
Oríṣun àwòrán, Facebook/Fathia Williams
Ta ni ko mọ gbajugbaja oṣere Fathia Balogun lagbo ere ori itage Yoruba ayafi ẹni to ba fẹ ṣe eke.
Ọmọ ipinlẹ Delta ni Fathia i ṣe.
Ọjọ karun oṣu keji ọdun 2021 yii ni Fathia yoo pe ọdun mejilelaadọta loke eepẹ.
Ilu Ikeja ni wọn bi Fathia si nipinlẹ Eko lọjọ karun un oṣu keji ọdun 1969.
Toyin Abraham (Ipinlẹ Edo)
Oríṣun àwòrán, Instagram/Toyin Abraham
Tọmọde tagba lo mọ Toyin Abraham ninu ere itage Yoruba ṣiṣe.
Toyin gbaju gbaja lagbo oṣere Yoruba kii ṣe diẹ, koda o ti ṣe oriṣiiriṣii fiimu Yoruba.
Amọ ọmọbibi ilu Auchi ni ipinlẹ Edo ni Toyin.
Toyin maa n dari ere, koda o tun maa n ṣe olootu rere yatọ si ere ṣiṣe ti ọpọ mọ ọn si gan an.
Ọjọ karun un oṣu kẹsan an ọdun 1982 ni wọn bi Toyin, o si gbe ilu Ibadan dagba.
Oṣere tiata ẹgbe rẹ, Adeniyi Johnson ni Toyin kọkọ fẹ, amọ igbeyawo ọhun fori ṣanpọn ki o to fẹ Kola Ajeyemi ti wọn jọ wa papọ bayii.
Regina Chukwu(Ipinle Enugu)
Oríṣun àwòrán, Instagram/Regina Chukwu
Regina Chinedu Chuwku ti ọpọ mọ si Regina Chukwu jẹ ọmọ ipinlẹ Enugu amọ ilu Eko lo ti dagba.
Ọjọ kẹtalelọgbọn oṣu kẹta ọdun 1980 ni wọn bi Regina.
Ilu Eko lo ti lọ ile iwe girama ki o to tẹsiwaju lọ si ile iwe gbogbonṣe Lagos State Polytechnic.
"Regina ti kopa ninu oriṣiiriṣii ere bii Akun"", ""Awolu ati Awalu"", ""Ewatomi"", ""Idaro"", ""Ogunso"" atawọn ere Yoruba mii."
Regina ṣe igbeyawo amọ o padanu ọkọ rẹ lẹyin ọdun mẹrin ti wọn ṣe igbeyawo.
Ṣugbọn Eleduwa fi ọmọ meji, ọkunrin kan ati obinrin kan ta idile rẹ lọrẹ ki ọkọ rẹ to papoda.
Deeper Life Scandal: Iléẹjọ́ ní kí òbí akẹ́kọ̀ọ́ tó ní wọ́n fipá bóun lòpọ̀ yé sọ̀rọ̀ mọ́ lórí ayélujára
Oríṣun àwòrán, /Deeper Life High SchoolDeborah Okezie
Ileẹjọ majisireeti to wa niluu Uyo, nipinlẹ Akwa Ibom ti tun kilọ fun iya akẹkọọkunrin girama Deeper Life nilu Uyo ọmọ ọdun mọkanla, Deborah Archibong to fi ẹsun kan awọn akọ ẹlẹgbẹ rẹ pe wọn n fi tipa ba oun lopọ pe ko ye sọrọ lori ayelujara mọ.
Ti ẹ o ba gbagbe, ileeṣẹ ọlọpaa ipinlẹ Akwa Ibom ṣafihan eeyan meje tawọn ọmọ kekere wa ninu wọn lori ẹsun ifipabanilopọ pẹlu Don-Davis Archibong akẹkọọ  ileewe DLHS niluu Uyo.
Ẹsun onikoko mẹrin ni wọn fi kan awọn eeyan naa eleyi to lodi si ofin ipinlẹ Akwa Ibom lori ẹsun iwa ọdaran nipinlẹ naa.
Agbẹjọro Arabinrin Archibong, David Okokon sọ fawọn akọroyin lọjọ kẹfa oṣu kinni ọdun 2021 ti igbẹjọ waye kẹyin lori ọrọ naa pe ileẹjọ kilọ fun obinrin naa pe ko maa sọrọ lori ẹrọ ayelujara mọ.
Ṣaaju akoko yii, Arabinrin Archibong maa n sọrọ loore koore lori ayelujara lori ẹsun ifapabanilopọ pẹlu ọmọkunrin rẹ, Don-Davis.
Ẹwẹ, ileẹjọ ko fawọn akọroyin ni anfaani lati wọle lasiko igbẹjọ naa.
Sunday Igboho fulani ultimatum: Àwọn ará Kebbi àti Zamfara ló n jínígbé ní Oke Ogun- Serik
Iléẹ̀kọ́ Deeper Life, ẹ san N100m owó gbà má bínú fún ọmọ mi, kẹ sì tọrọ àforíjìn - Òbí akẹ́kọ̀ọ́
Yoruba ni ti ọrọ ba se n pẹ nilẹ, yoo maa gbọn si ni.
Ọrọ akẹkọkunrin kan to fi ẹsun kan awọn akọ ẹlẹgbẹ rẹ pe wọn n fi tipa ba oun lopọ, nilegbe awọn akẹkọọ girama Deeper Life nilu Uyo, to ti n ja rainrain nilẹ fun bii ọjọ melo kan, ti wa n gbọn si bayii.
Idi ni pe awọn obi akẹkọkunrin ọmọ ọdun mọkanla naa ti kọwe sile ẹkọ ọhun lati beere ọgọrun miliọnu naira owo gba ma binu.
Iwe naa, ti wọn kọ si ọga ileẹkọ girama naa ni wọn pe akori rẹ ni 'Asilo, ọyaju, idẹyẹsini, ifiebipani, ifiyajẹni ati iwa agabagebe si ọmọ awọn'.
Oluwo Jogbodo Orunmila: Ẹsẹ odù Ifa ló fi ṣúre fún ọmọ Nàíjíríà ní àyájọ́ ọdún tuntun
Agbẹjọro awọn obi akẹkọkunrin naa, David Okokon, lo fi iwe naa sọwọ sile ẹkọ Deeper Life ọhun, lọjọ kejilelogun osu kejila ọdun 2020.
Okokon wa n fun ileewe naa ni ọjọ mọkanlelogun pere lati san ọgọrun miliọnu naira yii, ko si tun tẹ iwe itọrọ aforiji sita ninu iwe iroyin ilẹ wa meji, ti wọn n ri ka nilu Uyo.
"Agbẹjọro naa ni ""iru iwa bayii n bi ni ninu, o le seku pani , to si tun jẹ iwa agabagebe ẹsin wipe wọn fiya jẹ ọmọ onibara mi nipa biba eeyan rere rẹ jẹ ni kekere."
Adejare Adeboye: Olúwa yóò dá gbogbo ohun ta sọnù ní 2020 padà ní ilọ́po méje fún wa
"A wa n fi tọwọ-tọwọ beere ọgọrun miliọnu naira bii owo gba ma binu fun iwa idojutini, ifiyajẹni ati ailọwọ tẹ hu si ọmọ onibara mi, eyi ti yoo fi setọju ara rẹ."""
Nibayii, ijọba ipinlẹ Akwa Ibom ti yọwọ-yọsẹ kuro ninu iwadii to n se nipa ẹsun ifipa ba akẹkọkunrin naa lo pọ.
Joe Biden Innauguration: Tani ìyàwó Joe Biden tí yóò jẹ obìnrin akọ̀kọ nílẹ̀ Amẹrika?
Ọba Rilwan Akiolu: Fídíò kan lórí ayélujára ṣàfihàn Eleko tó ń jó wọ ààfin Iga Iduganran
Oríṣun àwòrán, @Oreoluwa_Finnih
Iroyin kan to n ja rain-rain lori ayelujara lo ni Eleko tilu Eko, Oba Rilwan Akiolu ti pada sinu aafin rẹ to wa ni Iga Iduganran.
Fidio kan to n ja rainrain lori ayelujara, lo fidi eyi mulẹ bi o tilẹ jẹ pe Ọba Akiolu ko tii tẹ atẹjade kankan sita nipa igbesẹ yii.
Bẹẹ ba gbagbe, ọjọ Kọkanlelogun osu Kẹwa ọdun 2020 ni Ọba Akiolu kuro ninu aafin rẹ laarin awọn ẹsọ alaabo to dihamọra.
Isẹlẹ naa si lo waye lasiko ti awọn janduku ẹda kan ya bo aafin Iga Iduganran nilu Eko lasiko rogbodiyan to tẹle iwọde EndSARS.
Lẹyin ti awọn osisẹ alaabo gbe ọba Akiolu kuro ninu aafin naa, ni awọn janduku naa raye sisẹ ibi ọwọ wọn, ti wọn si ko awọn ẹru kan kuro ninu aafin ọhun.
Oríṣun àwòrán, Screenshot
Lara awọn dukia Ọba Akiolu ti wọn ji ko ni ọpa aṣẹ rẹ, bata ọba, ọpọ apo irẹsi atawọn ẹru miran, koda wọn tun ba awọn nnkan mii jẹ nibẹ, paapaa ni ibudo igbalejo ọba naa.
Lati igba ti isẹlẹ naa si ti waye, ko si ẹni to le sọ pato ibi ti ọba Akiolu fara pamọ si, ti awuye-wuye si tun n waye nipa ọpa asẹ rẹ tawọn janduku naa ji gbe.
Bakan naa ni ko si ẹni to mọ boya wọn ti da ọpa asẹ ọhun pada.
Oríṣun àwòrán, Screenshot
Amọ lọjọ Ẹti, eyiun ọjọ Kinni osu Kinni ọdun 2021, tii se ọjọ ọdun tuntun, ni fidio kan gba ori ayelujara kan, ninu eyi taa ti ri ọba Akiolu to n jo wọnu aafin rẹ lọ.
Ọba naa, ti ọpọ ọdọ rọgba yi ka lo pa kaja aọ Saki funfun lai wọ buba kankan sori rẹ, o de fila asọ funfun, wọ bata funfun, to si mu ọpa kan lọwọ.
Bakan naa ni ọba Akiolu lo ibomu funfun gẹgẹ bi ara ilana to n dena itankalẹ arun Coronavirus.
Oríṣun àwòrán, Screenshot
Awọn onilu dundun ati Sẹkẹrẹ ni wọn n kan ilu si Kabiesi nibadi, toun naa si njo si ilu naa eyi to ni  ' Esuru se aseju, o tẹ lọwọ oniyan.'
Bi Ọba Eleko si se n jo, naa lo n fi ẹsẹ rin lọ sinu aafin, ti ọpọ eeyan to wa nibẹ naa si n sa a ni mẹsan-mẹwaa, bẹẹ ni wsn n ba jo pẹlu.
Bi o tilẹ jẹ pe a ko tii fidi rẹ mulẹ boya lootọ ni Kabiesi ti wa ninu aafin Iga Iduganran, amọ iwadii si n lọ lọwọ lori rẹ, eyi ta mu wa fun yin laipẹ.
Oríṣun àwòrán, LASG and Screenshot
Amọ ọrọ kan ti amugbalẹ́gbẹ́ gomina ipinlẹ́ Eko feto ilera, Oreoluwa Finnih kọ soju opo Twitter rẹ lo fidi isẹlẹ naa mulẹ, pẹlu fidio ọ̀hun to gbe soju opo naa.
Akọle to kọ sabẹ fidio naa ni pe ' Ọba tilu Eko, Alayeluwa Ọba Rilwan Babatunde Osuolale Aremu Akiolu fi ọla nla wọ aafin Iduganran lọjọ Ẹti,, ọjọ Kinni, osu Kinni ọdun 2021.
Oyo SSG Office Burgled: Ìjọba Oyo dúnkookò mọ́ iléeṣẹ́ tó bá gbé ìròyìn èké síta
Oríṣun àwòrán, @seyimakinde
Idaji ọjọ ọdun ni iroyin kan gbalẹ pe awọn adigunjale ti ja wọ ọọfisi akọwe ijọba ipinlẹ Oyọ, Arabinrin Olubamiwo Adeosun lọjọbọ, tii se ọjọ aisun ọdun tuntun.
Gẹgẹ bi iroyin naa ti wi, eyi ti awọn ileesẹ iroyin kan gbe sita ( BBC Yoruba ko gbe iroyin naa tori ko si ọna lati fidi rẹ mulẹ nigba naa), wọn ni igba keji ree ti isẹlẹ naa yoo waye.
Iroyin naa ni akọwe ijọba ko si ni orilẹede yii lasiko ti isẹlẹ naa waye, ti wọn ko si tii mu ẹnikẹni lori isẹlẹ ọhun bi o tilẹ jẹ pe awọn agbofinro yi ọọfisi naa ka.
Bakan naa ni iroyin ọhun sọ pe, awọn adigunjale yii tun fọ ọọfisi Akeem Ademola Ige, tii se oludamọran fun gomina Makinde lori eto ilera.
Amọ nibayii, ijọba ipinlẹ Oyo ti fesi  pe iroyin eke gbaa ni iroyin naa nitori ko si ohun to jọ iru isẹlẹ bẹẹ rara.
Atẹjade kan ti akọwe feto iroyin fun gomina ijọba ipinlẹ Oyo, Taiwo Adisa fisita ni gbogbo awọn agbofinro to wa lọgba Secretariat lo fidi rẹ mulẹ pe ofuutu fẹẹtẹ, aasa ti ko ni kaun ni ọrọ naa.
Oluwo Jogbodo Orunmila: Ẹsẹ odù Ifa ló fi ṣúre fún ọmọ Nàíjíríà ní àyájọ́ ọdún tuntun
Awọn ileesẹ iroyin to gbe iroyin naa ni wọn ko se iwadii to yẹ nipa isẹlẹ naa, ki wọn to gbe sita, eyi to mu ki wọn kuna ninu ojuse wọn lati maa gbe iroyin ododo sita.
Bakan naa lo fikun pe awọn ileesẹ iroyin naa ko le sọ pato awọn dukia tawọn ole naa ji ko lọọfisi akọwe ijọba, eyi to fidi rẹ mulẹ pe omulomu ni wọn n mu.
Ijọba ipinlẹ Oyo wa dunkooko pe ileesẹ iroyin to ba gbe iroyin eke bii iru eyi yoo foju wina ofin nitori abala ofin wa nilẹ to de titẹ iroyin eke sita.
Adejare Adeboye: Olúwa yóò dá gbogbo ohun ta sọnù ní 2020 padà ní ilọ́po méje fún wa
O ni ko si ileesẹ iroyin to dantọ ti yoo tẹ irufẹ iroyin ti ko fidi mulẹ bayii sita, eyi to le e ta ẹrẹ si asọ ala ijọba Oyo.
Mí ò gba àbẹ́tẹ́lẹ̀ rí ní ọgbọ̀n ọdún ti mo fi ṣíṣẹ́ ọlọ́pàá- CSP Francis Osagie
Oríṣun àwòrán, Igberetv
Ọ̀gá ọlọ́pàá kan ti kọ̀wé fi iṣẹ́ ọlọ́pàá sílẹ̀ nítorí ǹkan ti ó pè ni ìyànjẹ lẹ́nú iṣẹ́ ọlọ́pàá.
CSP Francis Osagie Erhabor, DPO ọlọ́pàá tó wà ní ẹ̀ka 'D' divison Itam ni Uyo tó jẹ́ olúùlú ìpínlẹ̀ Akwa Ibom.
Nínú ọ̀rọ̀ rẹ̀ lásìkò tí àwọn ilé iṣẹ́ kan fún ni àmìn ẹ̀yẹ ọlọ́pàá tọ pegedé jùlọ ni Nàìjíríà gẹ́gẹ́ bi àwọn ènìyàn ṣe díbò fun lórí ayélujára, lò ti sọ pé, ní ìwọ̀n ọgbọ̀n ọdún tí òun tí n ṣíṣẹ́ ọlọ́pàá òun kò ti gbà àbẹ̀tẹ́lẹ̀ rí.
Erhabor tó ti kọ̀wé fiṣẹ́ ọlọ́pàá sílẹ̀ báyìí sọ pé òun ti kọ mílíọ̀nù 864 owó àbẹ̀tẹ́lẹ̀ rí.
Lásìkò tó n ṣe ìfọ̀rọ̀wérọ̀ pẹ̀lú IgereTV , ló fi ẹ̀dùn ọkàn rẹ̀ hàn pé wan yan òun jẹ lẹ́nu iṣẹ́ ọlọ́pàá bi wọ́n ṣe kọ̀ láti fún òun ni ìgbéga ni ẹ̀ẹ̀mẹta ọ̀tọ̀ọ̀tọ̀ pẹ̀lú gbogbo iṣẹ́ akin tí òun ti ṣe.
"Gẹ́gẹ́ bi ó ṣe sọ; Mo wọ iṣẹ́ ọlọ́pàá gẹ́gẹ́ bi ""Cadet inspector"" ni ọjọ́ keji , oṣù kẹrin ọdún 1990, mo wà ni ọmọ ọdún mẹ́tàdínlógún nígbà náà.'Ọ̀pọ̀ àwọn ọgá àgbà ti mó bá lẹ́nu iṣẹ́ lásìkò náà lo sọ fún mi pé, irú mi gan ni wọ́n ń wá lẹ́nu iṣẹ́ ọlọ́pàá."
Mo nífẹ̀ẹ́ orílẹ̀-èdè yìí gan, mo si ri iṣẹ́ ọlọ́pàá gẹ́gẹ́ bi ibi tí mo ti le sin ilú bàbá mi
 Gẹ́gẹ́ bi olùdári àgbàgbè ọ̀pá epo ni ìpínlẹ̀ Edo, mo kọ mo kọ mílíọnù mẹ́fà abọ ọlọ́ṣọ̀ṣẹ̀, owó náà jẹ́ 288mílíọ̀nù ni ọdún kan àti 864 ni ààrín ọdún mẹ́ta tí mo lò níbẹ̀bẹ̀
"Bó tilẹ̀ jẹ́ pé, ọ̀pọ̀ àwọn alábà ṣiṣẹ́ pọ̀ mi ló ń pè mi ni òpònú, sùgbọ́n ò''otọ́ ìbẹ̀ ni pé, bí wọ́n bá tun gbá àdáwò irú rẹ̀ wá ni ọjọ́ míràn, ń o tún bori.
Ibanujẹ ọkàn ló jẹ́ fún mi láti ri àwọn ọmọ tọ wọ iṣẹ́ lẹ́yìn mi tí wan sì n gba ìgbéga, odidi ọgbọ̀n ọdún ni mo fi sòfò"""
Alaafin Oyo: Bá wo ni òrékelẹ́wà Adedoja tó gbàmì ẹ̀yẹ ''Miss Oyo 2020'' ṣe jẹ́ sí Alaafin?
Oríṣun àwòrán, Instagram/princessadedojaadeyermi
Ọpọ lo mọ oniruuru arẹwa mọ Oba Lamidi Olayiwola Adeyemi, Alaafin Oyo.
Amọ, bi awọn arẹwa Olori ṣe rọgba yi Iku Baba ka naa ni Eleduwa fi awọn ọmọ to rẹwa ta baba lọrẹ.
Laipẹ yii ni Ọmọbabinrin Adedoja Adeyemi gba ami ẹyẹ arinrin oge gẹgẹ bi ọdọbinrin to rẹwa julọ nipinlẹ Oyo.
Adedoja, ẹni ọdun mẹrinlelogun gba la awọn oludije mii ti wa lati ẹkun mẹrinla ipinlẹ mọlẹ lati gba ami ẹyẹ naa.
Ọmọbabinrin Adedoja gba ẹbun ọkọ ayọkẹlẹ Toyota Camry lọ ile atawọn ẹbun miiran.
Adedoja to kẹkọọ gboye nipa itan nile iwe fsaiti ipinlẹ Oṣun, UNIOSUN ti lọ si aafin Oyo fun adura lati ẹnu baba lẹyin to pegede tan nibi idije to ti kopa.
Ọmọbabinrin Adedoja n kẹkọọ lọwọ bayii lati gboye ẹkeji ni fasiti ilu Eko, UNILAG lori ilẹ Afirika.
Oun ni oludari ẹgbẹ kan to n ṣeranwọ fawọn ọmọ to ba ni arun foni ku fọla n de tawọn oloyinbo maa n pe ni SS.
Sexual benefits: Àwọn ànfààní tó wà nínú ìbálọ̀pọ̀ fún ọkàn àti ara
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Igbeyawo alarede to larinrin ko tii pe lai si ibalopọ ti tọkọ taya yoo jọ gbadun nibẹ.
Ibalopọ to dun jẹ ọkan lara ohun to maa n mu ajọṣepọ to dan mọran wa laarin ọkọ ati iyawo.
Bakan naa, awọn onimọ nipa ibalopọ tun sọ pe ibalopọ maa n ran tọkọ taya lati gbaradi fun ipenija ti wọn le koju ninu igbeyawo wọn lọjọ iwaju.
Oriṣiiriṣii ọna ni lọkọ laya le gba lati rii wi pe wọn gbadun ibalopọ pẹlu ara wọn.
Ọna kan lati ṣe eyi ni igbiyanju lati jẹ ki ibalopọ gbona giri giri. Nigba mii, bi lọkọ laya ṣe n sọrọ nipa ibalopọ niṣe pẹlu bi ibalopọ laarin awọn mejeeji ṣe maa ri.
Bi lọkọ laya ṣe n wo ara gan an ṣe pataki nipa ninu ibalopọ tawọn mejeeji yoo jọ gbadun.
Wiwọ iru awọn aṣọ kan fun ọkọ tabi iyawo ẹni naa le jẹ ki lọkọ laya jọ gbadun ibalopọ.
Anfaani ibalopọ fun ọkan ati ara
Dokita Gloria G. Bramer to jẹ onimọ nipa ibalopọ ṣalaye pe gbogbo ero eeyan nipa ibalopọ bẹrẹ lati inu ọpọlọ.
Dokita Bramer ni oriṣiiriṣii anfaani lo wa ninu ibalopọ fun agọ ara eeyan.
O ni ko si ohun to da bii ki eeyan gbadun ibalopọ.
Lẹyin ibalopọ, oorun kan maa wa ni ṣha, Ibalopọ maa n ṣeranwọ fun eeyan lati sun daadaa.
Bi ara eeyan ṣe maa n ri lẹyin ti eeyan ba ti goke lọ tan to si tun sọkalẹ maa n jẹ ki eeyan tete ri oorun sun ni kiakia.
Dokita Bramer ṣlaaye pe ti eeyan ba ṣe iwadii awọn lọkọ laya ti inu wọn ba dun papọ, wọn gbọdọ jẹ tọkọ taya to n ṣe ibalopọ daadaa.
Ninu iṣẹ iwadi kan to ṣe agbeyẹwo ẹgbẹrun un mẹrin tọkọ taya, awọn ti ara wọn dantọ julọ lawọn to n ṣe ibalọpọ deedee.
Awọn naa ni wọn tun nifẹ si ibalopọ julọ ninu awọn ti wọn ṣe agbeyẹwo fun naa.
Dokita Bramer rọ awọn eeyan lati ni ibalopọ ki inu wọn si dun.
Dokita onimọ nipa ibalopọ sọ pe o dara lati maa ni ibalopọ to dun nitori ara wa.
O ni ibalopọ maa n ṣe iranwọ fun eeyan lati mọ iyi ara yatọ si igboya to maa n fun eeyan.
Bi eeyan ba ṣe n ni ibalopọ to dara si pẹlu ọkọ tabi iyawo eeyan lo ṣe maa mọ iyi ara rẹ to.
Awọn dokita onimọ nipa ibalopọ sọ pe oogun gidi ni ibalopọ jẹ fawọn to maa n ni irora ni isalẹ ikun wọn lasiko nkan oṣu.
Akọsilẹ fihan pe ọpọ iyawo ile lo maa n sọ pe ibalopọ maa n jẹ ki wọn gbadun irora to maa n ba nkan oṣu wa.
Awọn onimọ nipa ibalopọ ni ọpọ tọkọ taya ni kii fẹ ṣe ibalopọ deedee mọ nigba ti wọn ba ti n dagba.
Wọn ni ewu to wa nibẹ  gan an ni pe oju ara obinrin le ti bẹ fun ti oun ati ọkọ rẹ ko ba maa ṣe ibalopọ deedee.
Yoruba people: Sunday Igboho sọ̀rọ̀ lórí ohun tó kan fún ilẹ̀ Yorùbá lọ́dún 2021
Oríṣun àwòrán, Facebook/Sunday Igboho
Bi ọpọ pasitọ ati aafa ṣe n sọ asọtẹlẹ lori ohun ti yoo ṣẹlẹ lọdun tuntun ọdun 2021 yii, ajafẹtọ Sunday Adeyemo ti ọpọ mọ si Sunday Ighoho ti sọrọ akin lori ohun to kan fun ilẹ Yoruba.
Sunday Ighoho sọrọ yii lori ẹrọ amohunmaworan pẹlu awọn ọdọ kan ti wọn kan si nile rẹ.
Ọgbẹni Adeyemo sọrọ o fa komookun rẹ yọ pe ọdun ominira ni ọdun 2021 yii jẹ fun ilẹ Yoruba.
Sunday Igboho ni awọn ọdọ lo n jiya ju ni Naijiria, nitori diẹ ni tawọn agbalagba nibẹ.
''Abọwaaba lọrọ awọn agbaagba ilẹ Yoruba, awọn ọdọ lo yẹ ki a ṣe ara wa lọkan,'' ọgbẹni Adeyemo lo sọ bẹẹ.
Sunday Ighoho ni o ti wa ninu akọọlẹ pe ọdun ayọ ati ọdun ominira ni ọdun 2021 jẹ fun ilẹ kaarọ o jiire.
O ṣalaye oun atawọn mii to fẹ ki Yoruba gbaye gbadun ko ni ohun kan ṣe pẹlu awọn ọlọpaa ati sọja.
Sunday Igboho ni ọpọ ọdọ lo ti ka iwe gboye ni ile ẹgọ giga fasiti tan lai ri iṣẹ ṣe.
O gbadura pe gbogbo awọn to ba ṣe abosi tabi da ilẹ Yoruba, ilẹ Yoruba yoo da fun wọn.
Sunday ṣalaye pe ọpọ lo ro pe oun kan ṣadedee dakẹ lori ọrọ ilẹ Yoruba.
Amọ, o sọ pe agbo oun to fẹyin rin, agbara lo lọ mu wa.
Ọgbẹni Adeyemo rọ awọn ọdọ pe ki wọn maa ṣojo, ki wọn si mura lati ja fun ẹtọ wọn.
O ni awọn ọdọ ti wọn maa n ran lati tako awọn ọdọ ilẹ Yoruba to n beere fun ẹtọ wọn ni ori wọn ko pe.
Alleged Sexual harassment: Ẹ̀gbọ́n baba Barakat ṣàlàyé bó ti gbé e lọ sílé kọmísọ́nà Ogun tí wọ́n ní kó lọ rọ́kún ńlé
Oríṣun àwòrán, Facebook/Abiodun Abudu-Balogun
Bi o tilẹ jẹ pe ọgbẹni Adesola Melojuekun to jẹ baba ọmẹdebinrin Barakat Melojuekun to fẹsun iyọnilẹnu fun ibalopọ kan Kọmisana fọrọ ayika nipinlẹ Ogun, Abiodun Abudu-Balogun ni oun ko nifẹ lati ṣe ẹjọ, awuyewuye ko tii tan an lori ọrọ naa.
Ọgbẹni Lasisi Saheed to jẹ ẹgbọn baba Barakat ti ṣalaye bi ohun ti ṣe gbe ọmọdebinrin ọdun mẹrindinlogun naa lọ sile Họnarebu Abudu-Balogun.
Ọgbẹni Saheed fidi rẹ mulẹ pe lootọọ loun gbe ọmọ aburo oun lọ sile kọmiṣọnna ọrọ ayika, amọ oun ko mọ nkan to ṣẹlẹ ninu ile laarin Barakat ati Abudu-Balogun.
Ninu fidio kan to fi sori ayelujara, Saheed ṣalaye pe Barakat tẹle kọmiṣọnna naa lọ sinu yara kan lẹyin ti oun mu  de bẹ tan.
''Awọn mejeeji si tun jọ jade sita pada lẹyin bi iṣẹju mẹwaa ti wọn jọ wọle lọ, mi o mọ ohun kan ju bayẹn lọ,'' Saheed lo ṣalaye bẹẹ.
Saheed ni ''lọjọ kọkanlelọgbọn oṣu kejila ọdun 2020 ni a ṣe ipade kan nile kọmiṣọnna ọrọ ayika ipinlẹ Ogun nibi to ti sọ pe oun nilo ẹni to ba mọ nipa lilo ẹrọ kọmputa, eleyi ti mo sọ fun un  pe mo mọ ọmọdebinrin kan to mọ nipa lilo ẹrọ kọmputa daadaa.''
''Wọn ni ki n mu ọmọ naa wa, lẹyin naa ni mo lọ ṣalaye fun Barakat ti mo fi si gbe e lọ sile kọmiṣọnna ọhun,'' Saheed ṣalaye.
Lẹyin ti baba Barakat ati oun gan an ti pohun da pe awọn o ṣejọ mọ lori ọrọ naa, ẹka ileeṣẹ ọlọpaa ipinlẹ Ogun to n ri si iṣẹ iwadii ẹsun ọdaran ti sọ pe ohun yoo tu iṣu de isalẹ koko lori ọrọ naa.
Kí ló mú kí Baba Barakat tó fẹ̀sùn ìyọnilẹ́nu torí ìbálòpọ̀ kan kọmísọ́nà àyíká ìpínlẹ̀ Ogun pàlù ẹnu dà?
Ọrọ ti n gbọna mi yọ lori awuyewuye  laarin Kọmisana fọrọ ayika nipinlẹ Ogun ati mọlẹbi ọmọdebinrin kan to fẹsun kan an pe o n yọ ọmọ naa lẹnu lori ibalopọ.
Idi ni pe baba ati  ọmọ naa, Adesola Melojuekun ti ṣe fọnran fidio mi sita nibi ti o ti ni awọn ko lẹjọ ro pẹlu Kọmisana Abiodun Abudu-Balogun mọ.
Oríṣun àwòrán, BBC
Ninu fọnran ti  baba Barakat fi sita yi , o ni ede aiyede lo waye laarin Barakat ati Kọmisana Abiodun.
Baba Barakat nikan kọ lo gbe fidio sita.
Barakat naa fi fidio sita laipẹ si igba ti wọn ni ki kọmisana lọ rọọkun nile.
Baba Barakat ninu fidio taa ri sọ pe ''Aigbọraẹni ye kan waye laarin Kọmisana ati ọmọ mi,lẹyin ti a  si ti ti ri bayi, mo ro pe o yẹ ki n fi to araalu ati awọn eeyan ilẹ okere leti pe ki a jẹ ki ọrọ yi tan sibẹ''
O tẹsiwaju pe ''Mi o ṣẹjọ mọ , mo si fẹ ki ẹ ṣalatilẹyin mi lori ipinu mi yi bi ẹ ti ṣe ṣe fun mi ṣaaju nibẹrẹ ọrọ yi.''
BBC ko ti ribi fidi ododo fidio yi rinlẹ yala lati ọdọ baba tabi ọmọ ti ọrọ yi kan.
Nigba taa kan si alukoro ọlọpaa Ogun,Abimbola Oyemyemi  ti ijọba ni ki wọn ṣe iwadii ọrọ naa, niṣe lo kọ lati gbe ago rẹ.
Amọ ṣa ninu fọnran fidio yi, Baba Barakat ko sọ boya kọmisana tọrọ aforijin bẹẹ naa ni ko tọrọ aforijin lọdo Kọmisana lori pe o ba orukọ rẹ jẹ.
Bi a ko ba gbagbe, laipẹ yi ni Ijọba ipinlẹ Ogun  sọ pe ki kọmiṣọna fun ọrọ ayika, Họnarebu Abiodun Abudu-Balogun lọ rọkun nle lẹyin ti wọn fẹsun iwa ipa ibalopọ kan an pẹlu ọmọdebinrin.
Ijọba sọ ninu atẹjade kan ti akọwe ijọba ipinlẹ, Ọgbẹni Tokunbo Talabi fi sita lọjọ Aiku pe igbesẹ ijọba yii yoo wa sibẹ titi di asiko ti iwadii lori ọrọ naa yoo fi pari.
Barakat Melojuekun to jẹ ọmọ ọdun mẹrindinlogun ni wọn fẹsun kan Abudu-Balogun pe o n yọ lẹnu fun ibalopọ.
Kọmiṣọnna naa fun ra ti kọkọ fi atẹjade kan sita pe oun ko mọwọ mẹsẹ lori ẹsun ti wọn fi kan oun.
Ṣugbọn ijọba ṣalaye pe oun ko ni ṣegbe lẹyin ẹnikan lo jẹ ki oun sọ fun kọmiṣọnna tọrọ kan lati dawọ iṣẹ duro naa fun igba.
Ijọba Ogun sọ ninu atẹjade to fi sita pe ohun yoo ri wi pe ohun fidi ododo mulẹ lori ọrọ naa.
Ẹwẹ, ijọba ipinlẹ Ogun ti paṣẹ fun kọmiṣọnna ọrọ ayika lati jọwọ gbogbo ohun to wa lọwọ rẹ fun akọwe agba ẹka ijọba to n ri si ọrọ ayika.
Bola Tinubu: ''Ìròyìn òfegè lásán ni! Tinubu kò lùgbàdí coronavirus''
Oríṣun àwòrán, Facebook/Asiwaju Bola Tinubu
Faabada! Gomina ipinlẹ Eko tẹlẹ, Aṣiwaju Bola Tinubu ti sọ pe ahesọ lawọn kan n gbe kiri pe oun ti karun coronavirus.
Ọrọ naa ti lu ori ayelujara pa pe Tinubu ti lugbadi covid-19, o si n gba itọju lọwọ nile iwosan lorilẹede Faranse loke okun.
Ṣugbọn Tinubu to gba ẹnu oluranlọwọ rẹ, Tunde Rahman sọrọ ṣalaye pe igba mẹẹdogun loun ti ṣe ayẹwo fun covid-19 eleyi to si ja si pe ṣaka lara oun da.
Ọgbẹni Rahman ni irọ funfun balau lati ọrun apaadi ni iroyin ọhun.
''Koko lara Asiwaju le, ko si ṣaisan, bẹẹ ni ko ni arun coronavirus,'' Rahman lo sọ bẹẹ.
Ọgbẹni Rahman sọ pe lootọọ ni Tinubu ko si ni Naijiria lọwọ yii, ṣugbọn o ṣalaye pe ilẹ Faranse kọ ni Asiwaju wa gẹgẹ bi iroyin kan ṣe sọ lori ayelujara.
''Ilu London ni Tinubu wa, kii ṣe orilẹede Faranse gẹgẹ iroyin ẹlẹjẹ ṣe sọ lori ayelujara,'' Ọgbgẹni Rahman ṣalaye.
Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi
Titi di oni, sisọ iwọ ati olubi smọ nu ti di aṣa eyi ti o maa n waye ni kete ti ibi smọ tuntun ba ti waye.
Amọṣa awọn ims tuntun ti fihan bayii pe ko si idi fun wa lati maa sọ iwọ ati olubi awọn ọmọ tuntun ti a ba ṣẹṣẹ bi mọ nitori agbara iwosan ọpọlọpọ arun gbẹmigbẹmi lo wa ninu wọn.
Gẹgẹ bi awọn onimọ ti ṣe sọ, ko din ni ọgọrin aisan gbẹmigbẹmi ati baraku ti wọn lee fi awọn eroja aṣaralore to wa ninu iwọ ati olubi ọmọ tuntun wo.
Koda awọn aisan bii foniku-fọla dide (Sickle cell), warapa (Epilepsy) ati Rọlapa-rọ lẹsẹ (Stroke) wa lara awọn aisan ti wọn n fi iwọ ati olubi ọms wo bayii.
Gẹgẹbi awọn onimọ iṣegun ṣe sọ, ko din ni alaisan mẹẹdogun ti wọn ti ri iwosan kuro lọwọ aisan foniku-fọla dide ni Naijiria nipasẹ imọ lilo iwọ ati olubi ọmọ fi ṣe iwosan yii, eleyii ti a mọ si Stem cell.
Amotekun: Olórí ikọ̀ Amotekun l’Oyo ní àwọn ọ̀tá ìtẹ̀síwájú ń sa ipá láti ba ikọ̀ Amotekun lórúkọ jẹ́
Oríṣun àwòrán, Twitter/oyo state government
Adari ikọ Amọtẹkun nipinlẹ Ọyọ, Ajagunfẹyinti Olayinka Olayanju ti ṣe alaye wi pe awọn eeyan kan ti inu wọn ko dun si idasilẹ ikọ naa lo n sa ipa wọn lati ta ẹrẹ ba aṣọ ala ikọ eto aabo abẹnu ti ijọba fi lọlẹ.
Ninu ọrọ to ba akọroyin BBC Yoruba sọ l'ọjọ Iṣẹgun, Ọlayanju ni lara awọn ohun elo awọn abanilorukọ jẹ naa ni iroyin ofege ti wọn gbe kaakiri.
O tẹsiwaju wi pe iwa ọdaran to le ni ogoji ni ikọ Amọtẹkun ti dẹkun rẹ laarin oṣu mẹfa ti ikọ naa bẹrẹ iṣẹ, bẹẹ sini eeyan mẹji ọtọọtọ ni ikọ naa ti ran lọ atimọle nipasẹ ijọba, ṣugbọn dipọ ki awọn eeyan kan ki ikọ naa kuuṣẹ, gbogbo ọna ti ijọba yoo fi kabamọ lori idasilẹ ikọ Amọtẹkun ni wọn n wa kiri.
Bakan naa ni Ọlayanju tan imọlẹ si awuyewuye to n waye lori ẹsun ti wọn fi kan Amọtẹkun wi pe aṣoju ikọ naa yinbọn fun akẹkọọ fasiti ilẹ Ibadan kan ati oṣiṣẹ ọlọpaa kan laarin oṣu meji sira.
O ni lootọ ni Amọtẹkun ṣekupa ọkan lara awọn ọdaran to n yọ awon olugbe agbegbe Ọyọ lẹnu lọganjọ oru, ṣugbọn iṣẹlẹ naa ti waye ki wọn to fi idi ọrọ mulẹ wi pe akẹkọọ fasiti ilẹ Ibadan ni afurasi naa.
Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi
Lorii kọnstabu ọlọpaa ti iroyin sọ pe aṣoju ikọ Amọtẹkun kan yinbọn fun ni agbegbe Ọyọ bakan naa, Ọlayanju ṣalaye pe kii ṣe pe Ibrahim Ogundele, oṣiṣẹ ajọ Amọtẹkun naa ṣa dede ṣina ibọn bolẹ fun ọlọpaa naa, iyẹn Fatai Yẹkini ni itan.
Gẹgẹ bi o ṣe sọ, ko si idi fun Ibrahim lati ṣina ibọn fun Fatai nitori pe wọn ko ni ikunsinu, ija tabi ita ti ṣaaju iṣẹlẹ naa.
Kodaa, o ni ọrẹ ni awọn mejeeji.
"Ajagunfẹyinti Ọlayanju ṣalaye pe awọn ọlọpaa lo ranṣẹ pe awọn oṣiṣẹ ikọ Amọtẹkun lati wa kun wọn lọwọ tu oju agbo awọn eeyan kan to n ṣe ajọdun kanifa ""Carnival"" ọdun tuntun ni ilu Ọyọ lẹyin ti awọn ọẹọaa ti kọkọ kilọ fawọn agbodegba eto naa ṣaaju pe wọn ko gbọdọ ṣe ohun to jọọ."
"O ni ibọn ọwọ Ogundele ṣa dede yin ni eyi ti oyinbo n pe ni ""accidental discharge"" ti o si ba ọlọpaa naa ni itan."
Akomolede BBC: Onírurú gbólóhùn léde Yorùbá àti irúfẹ́ gbolóhùn tó wà nínú èdè Yorùbá
Ni kete ti iṣẹlẹ naa ṣẹlẹ ni wọn si ti gbe e lọ si ileewosan, ti oṣiṣẹ ọlọpaa naa si pada si ilẹ rẹ lẹyin ti o gba itọju tan laarin wakati mẹrinlelogun.
BBC Yoruba beere iru idanilẹkọ ti ikọ  Amọtẹkun gba ki wọn to bẹrẹ iṣẹ ati ibi ti wọn ti ri nnkan ijagun wọn, ẹsi ti adari ikọ naa fọ ni wi pe awọn ologun ati ọlọpaa lo ṣe idanilẹkọ fun awọn aṣoju ikọ Amọtẹkun fun ọsẹ mẹta gbako nile ẹkọ giga kan to n ba nilu Ọyọ.
Lara idanilẹkọ ti wọn si gba ni bi wọn ṣe le gba ibọn mu, bi wọn ṣe le ṣe ọfintoto ọrọ, bi wọn ṣe n hu iwa pẹlu ara ilu ati awọn ẹṣọ aabo mii.
Ṣugbọn Ọlayanju fi kun ọrọ rẹ pe ijọba kọ lo fun ikọ Amọtẹkun ni ibọn ati awọn nnkan ijagun ti wọn n lo.
O ni pupọ ninu awọn aṣoju ikọ naa lo ti fi igba kan jẹ ọdẹ tẹlẹri, ti wọn si ni awọn nnkan ijagun ti wọn n lo.
"Adari ikọ Amọtẹkun fi ku ọrọ rẹ wi pe awọn eeyan kan wa ti wọn fẹ lati kopa ninu ikọ Amọtẹkun, ṣugbọn awọn ko fi aye gba wọn nitori ọwọ wọn ko mọ, eyii lo mu ki wọn gun le igbesẹ ""bi adiyẹ ba da mi loogun nu, maa si fọọ lẹyin""."
Oríṣun àwòrán, Premium
Ni ọjọ Aje ni iroyin jade si igboro aye pe oṣiṣẹ ikọ alaabo Amọtẹkun kan ti yinbsn fun ọlọpaa kan ni ilu Ọyọ.
Nibayii, ikọ alaabo Amọtẹkun ni ipinlẹ Ọyọ ti ṣalaye lori bi iṣẹlẹ naa ṣe ṣẹlẹ.
Adari ikọ Amọtẹkun ni ipinlẹ Ọyọ, Ajagunfẹyinti Ọlayinka Ọlayanju ṣalaye pe kii ṣe pe Ibrahim Ogundele, oṣiṣẹ ajọ Amọtẹkun naa ṣa dede ṣina ibọn bolẹ fun ọlọpaa naa, iyẹn Fatai Yẹkini ni itan.
Gẹgẹ bi o ṣe sọ, ko si idi fun Ibrahim lati ṣina ibọn blẹ fun Fatai nitori pe wọn ko ni ikunsinu, ija tabi ita ti ṣaaju iṣẹlẹ naa.
"Ajagunfẹyinti Ọlayanju ṣalaye pe awọn ọlọpaa lo ranṣẹ pe awọn oṣiṣẹ ikọ Amọtẹkun lati wa kun wọn lọwọ tu oju agbo awọn eeyan kan to n ṣe ajọdun kanifa ""Carnival"" ọdun tuntun ni ilu Ọyọ lẹyin ti awọn ọẹọaa ti kọkọ kilọ fawọn agbodegba eto naa ṣaaju pe wọn ko gbọdọ ṣe ohun to jọọ."
"O ni ibọn ọwọ Ogundele ṣa dede yin ni eyi ti oyinbo n pe ni ""accidental discharge"" ti o si baọlọpaa naa ni itan."
Ni kete ti iṣẹlẹ naa ṣẹlẹ ni wọn si ti gbe e lọ si ileewosan, ti awọn ọlọpaa si mu Ibrahim Ogundele to jẹ oṣiṣẹ ikọ Amọtẹkun naa timọle.
Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi
Ọkan lara awọn oṣiṣẹ ajọ eleto abo tiwantiwa, iyẹn Amọtẹkun ni ipinlẹ Ọyọ, Ibrahim Ogundele ti yinbọn si ọlọpaa kan ni ilu Ọyọ.
Gẹgẹbi iroyin ṣe sọ, ikọ Amọtẹkun ni agbegbe  Isalẹ Ọyọ ni Sbẹni Ogundele wa pẹlu.
Bakan naa ni iroyin fi kun un pe Kọsitabu ni ọlọpaa ti wọn yinbọn si naa ni agọ ọlọpaa Ojongbodu ni ilu Ọyọ, orukọ rẹ a si maa jẹFatai Yẹkini.
Awọn ti iṣẹlẹ naa ṣoju wọn ni ẹsẹ osi ni ọta ibọn naa ti baa ti wọn si ti gbe e lọ si ileewosan nla ijọba ipinlẹ Ọyọ to wa lagbegbe Owode ni ilu Ọyọ.
Awọn ti iṣẹlẹ naa ṣe oju wọn ṣalaye pe lasiko ti awọn ọlọpaa lati agọ ọlọpaa Ojongbodu n gbiyanju ati tu awọn ọdọ kan to n gbaradi ati ṣe ajọdun ọlọdọọun wọn ti a mọ si Carnival ni iṣẹlẹ naa ṣẹlẹ.
US Election: Ààrẹ Trump pe òṣìṣẹ́ ìdìbò ní Georgia pé ko 'wa'ìbò láti dojú ìbò tó gbé Biden wọlé dé
Wọn ti gba ohun aarẹ Trump torilẹede Amẹrika silẹ nigba to pe olori eto idibo kan nipinlẹ Georgia lori aago pe ko wa kun iye ibo ẹgbẹ oṣelu Republican lati yi esi ibo arẹ nibẹ pada;
Mo fẹ wa ibo ẹgbẹrun mọkanla o le ọrinlelẹẹdẹgbẹrin ni ọrọ ti aarẹ Donald Trump sọ fun alamojuto ọrọ ilẹ okeere ni ipinlẹ Georgia, Brad Raffensperger ninu fọnran ohun ti wọn ka silẹ kan eleyii ti ileeṣẹ iwe iroyin Washington post gbe jade.
Amọṣa,  Ọgbẹni Raffensperger to pe ni ko sohun to jọọ.
Joe Biden lo gbegba oroke ni ipinlẹ Georgia atawọn ipinlẹ nlanla miran ninu ibo aarẹ to waye loṣu kọkanla ọdun 2020  lati igba naa si ni Aarẹ Trump ti n pariwo pe eru wa ninu idibo naa ṣugbọn ti ko lee mu ẹri kankan sita.
Gbogbo ipinlẹ aadọta to wa lorilẹede Amẹrika ni wọn ti fi ontẹ lu esi idibo aarẹ naa naa, awọn miran ṣe eyi lẹyin atunka esi idibo naa.
Bakan naa ni ile ẹjọ si ti ta ọgọta ipẹjọ ti Trump pe lori ibo naa nipa sita pe ko lẹsẹ nlẹ.
Oríṣun àwòrán, EPA
Ninu akọsilẹ ohun ti wọn ka silẹ naa eleyi ti ileeṣẹ iroyin Washington post gbe sita, Aarẹ Donald Trump n fi ọgbọn ko alakoso ọrọ ilẹ okeere ni ipinlẹ Georgia naa laya jẹ.
"O n pariwo pe oun loun bori ibo ni ipinlẹ Georgia ati pe ""ko si ohun to buru bi o ba ni ẹ tun ibo naa ka ni""."
"Ọgbẹni Raffensperger fun un lesi pe: ""ipenija ti ẹyin gẹgẹ bi aarẹ  n koju, ni peiroyin ti ẹ n gbe kiri kii ṣe ootọ rara."""
Igba to ya ni Aarẹ Trump ba tun mu ọrọ miran ys pe ahesọ ọrọ to n kaakiri ni pe awọn kan ti ya iwe idibo naa ti wọn si ti ko awọn ohun elo idibo kuro lagbegbe Fulton county, eleyi ti agbẹjọro fun Ọgbẹni Raffensperger ni ko si ootọ kankan nibẹ.
Koda aarẹ Trump gbiyanji ati fi ipẹjọ dunkoko mọ oṣiṣẹ idibo naa.
O wa pe fun afikun ibo ẹgbẹrun mọkanla o le ọrinlelẹẹdẹgbẹrinkun ibo rẹ, eleyi ti yoo fun un ni ibo miliọnu meji ati irinwo ẹgbẹrun o le mẹta le laadọrin ati ẹgbẹta oo le mẹrinlelọgbọn, 2,473,634 eyi ti yoo mu ki ibo rẹ fi ẹyọ kan le ju ti Joe Biden to ni ibo miliọnu meji ati irinwo ẹgbẹrun o le mẹta le laadọrin ati ẹgbẹta oo le mẹtalelọgbọn, 2473,633.
Ṣugbọn Ọgbẹni Raffensperger jẹ ko di mimọ fun Trump pe gba-gba-gba lawọn duro lori esi ti awọn gbe sita.
Oyo Insecurity: Kí lo dé tí ìpànìyàn, ìjínigbé, ìdigunjalè ń peléke síi lábẹ́ Gómìnà Makinde?
Oríṣun àwòrán, Facebook/Sherifat Adisa
Eeyan mẹta lo di oloogbe ni ilu Igboọra ni ipinlẹ Ọyọ lasiko ti awọn ajinigbe ṣọṣẹ nileepo Subawah Oil filling station to wa lagbegbe opopona Idere.
Awọn ọmọ ọdun mẹsan meji ti wọn jẹ ibatan wa lara awọn ti wọn pa lasiko iṣẹlẹ naa nigba ti iroyin sọ pe iya ọkan ninu wọn naa tun fara gbọta.
Ọga agba ile epo naa, Arabinrin Sherifat Adisa  wa lara awọn ti awọn ajinigbe naa ji gbe lọ si ibi ti ẹnikẹni ko mọ ki wọn to wa ri oku rẹ lẹsẹ o gbeji kan ni ọjọ Aiku.
Olugbe ilu naa kan ṣalaye fun awọn oniroyin pe awọn to faragbọta naa wa lara awọn to pẹlu arabinrin Sherifat lati sa asala fun ẹmi wọn ni alẹ ọjọ Abamẹta ti wọn ni iṣẹlẹ naa ṣẹlẹ.
Arabinrin to faragbọta naa ni wọn sọ pe o n bọ pẹlu awọn ọmọ meji lati ilu Igboọra wa si Idere ki ọlọkada to n gbe wọn bọ to ja wọn silẹ lẹgbẹ titi lati lee ra epo ni ile epo naa nibi ti ọta ibọn ti ba wọn.
Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi
Ileeṣẹ Ọlọpaa ti ṣalaye pe ọwọ ti tẹ awọn afurasi kan bayii nipasẹ ajọṣepọ laarin ọlọpaa atawọn ọlọdẹ adugbo nibẹ.
Bakan naa ni alukoro ileeṣẹ ọlọpaa ni ipinlẹ Ọyọ, Fadeyi Olugbenga tun jẹ ko di mimọ pe ifimufinlẹ n lọ ni kikankikan kaakiri agbegbe naa lati lee mu awọn afurasi miran ti wọn n fẹ sa mọ ofin lọwọ nibẹ.
Bakan naa ni ileeṣẹ ọlọpaa kede pe awọn ajinigbe tun ji eeyan kan ti wọn pe orukọ rẹ ni Dokita Akindele lagbegbe Tapa, ni ijọba ibilẹ Ibarapa North.
Inu ileewosan rẹ ni wọn ni wọn ti jii gbe.
Bi a ko ba gbagbe awọn agbebọn kan pa eekan ẹgbẹ oṣelu PDP Fatai Aborode nigba to n dari bọ lati oko rẹ.
Ni ọjọ kọkanla oṣu kejila ọdun 2020 ni wọn da lọna lopopona Apodun ni Igangan,gẹgẹ bi ọlọpaa ṣe wi.
Awọn afurasi mẹrin ni wọn ni wọn ṣiṣẹ yi ti awọn ọlọpaa ṣi yi n wa awọn afurasi naa di ba ti ṣe n sọrọ yi.
Laarin Tapa ati Aiyete ni Fatai Aborode ti dakẹ nigba ti wọn n gbe lọ si ile iwosan to wa ni Igboora.
Ẹwẹ ẹgbẹ alagbata epo aladani ni Naijiria ti kesi Gomina Makinde lati wa wọrọkọ fi ṣada lori iṣekupani ati ijinigbe to n gbogo ni ipinlẹ Oyo.
Ẹgbẹ naa fi ọrọ yi sita ninu atẹjade kan lọjọ Aiku lẹyin iku Alhaja Sherifat tawọn ajinigbe ṣeku pa.
Lagos schools resumption: Dókítà Faduyile ní ewu ń bẹ tórí coronavirus táwọn akẹ́kọ̀ọ́ ba wọlé padà báyìí
Oríṣun àwòrán, Twitter/Babajide Sanwo-Olu
Ewu n bẹ loko Longẹ, Longẹ gan an ewu.
Aarẹ ẹgbẹ awọn dokita oyinbo ni Naijiria tẹlẹ, Ọjọgbọn Francis Faduyile lo kilọ pe ewu wa nibẹ tawọn akẹkọọ ileewe alakọbẹrẹ ati girama ba fi le wọle bayii pẹlu bi ọwọja coronavirus lẹẹkeji ṣe ṣoro.
Ṣaaju ijọba ipinlẹ Eko kede pe o ṣeeṣe kawọn akẹkọọ ileewe alakọbẹrẹ ati girama pada sile iwe lọjọ kejidinlogun oṣu kinni ọdun 2020 yii.
Ṣugbọn Ọjọgbọn Faduyile to ba BBC Yoruba sọrọ lori atiwọle pada awọn akẹkọọ nipinlẹ Eko ṣalaye ko si ẹni to le sọ bi ajakalẹ arun covid-19 ṣe maa ri lasiko ti ijọba da pe awọn akẹkọọ le wọle.
O ni agbeyẹwo bi arun naa ṣe n tan kalẹ ni bii ọsẹ meji si asiko yii lo maa sọ bo ya awọn akẹkọọ le pada sile iwe wọn bayii.
Ọjọgbọn Faduyile ni o ṣe pataki fawọn eeyan lati maa ṣọra ṣe, ki wọn maa lo ibomu wọn, ki wọn si maa fọwọ wọn deedee.
Iroyin ti a n gbọ ni pe awọn ile iwosan ti kun fọfọ nipinlẹ Eko pẹlu awọn to ṣẹṣẹ lugbadi arun coronavirus.
Wo ìgbà tí àwọn akẹ́kọ̀ọ́ yóò wọlé ní ìpínlẹ̀ Eko
Ijọba ipinlẹ Eko ti Kede pe ile Ekọ alakobẹrẹ ati girama ko le pada senu EkọIjọba ipinlẹ Eko ti kede pe gbogbo ilé iwe aladani ti kii ba ti se ile Eko giga fasiti, ile ẹkọ olukoni agba tabi ile ẹkọ gbogbonise si wa ni titi pa titi di asiko ti ijọba yoo kede asiko iwọle tuntun  nitori owoja ajakalẹ aarun Coronavirus to tun wọle fun igbakeji yii.
Ninu atẹjade ti olori eto ara ilu nile isẹ to n ri si eto ẹkọ nipinlẹ Eko Kayode Abayomi fọwọsi salaye pe eyi mu ki gbogbo ile iwe to ti pinu lati wọle lọjọ ni kẹrin osu kini ọdun 2021 si wa ni titi pa.
Abayomi rọ awọn obi, alagbatọ ati awọn akẹkọọ lati tẹle ilana ipara ẹnimọ lati dena itankalẹ arun COVID-19, bi wiwọ ibomu, ijina sira ẹni, fifọwọ deede ati lilo sanitisa loorekoore.
Oyo Insecurity: Kí lo dé tí ìpànìyàn, ìjínigbé, ìdigunjalè ń peléke síi lábẹ́ Gómìnà Makinde
Oríṣun àwòrán, Facebook/Sherifat Adisa
Ileeṣẹ ọlọpaa nipinlẹ Oyo sọ pe awọn n wa afurasi to ku ti wọn lọwọ si ipaniyan oniṣowo obinrin kan ati awọn ibatan rẹ meji ni Ibarapa.
Olugbenga Fadeyi to fi ọrọ yi to awọn oniroyin leti ninu atẹjade kan,sọ pe ọrọ ipaniyan yi ti to Kọmisana Oyo, Nwachukwu Enwonu leti ati pe iwadii n tẹsiwaju.
Iṣẹlẹ ipaniyan taa n wi yi waye ni agbegbe Idere ni ijọba ibilẹ Ibarapa lọjọ Keji oṣu Kini ọdun 2020.
Sunday Igboho: Ẹ fi Ògún búra fún wa láti jà fún ilẹ̀ Yorùbá láì gbé Amotekun sábẹ́ ìjọba
Gẹgẹ bi iroyin to tẹwa lọwọ, arabinrin oniṣowo ti wọn pa yi lo n jẹ Alhaja Serifat Adisa to si jẹ oludari ile epo Subawa ni opopona Igboora/Idere.
Yatọ si Alhaja Adisa, awọn ibatan rẹ meji faragbọta ti awọn oniṣẹ ibi yi tun yin mama awọn ọmọ ọdun mẹsan yi nibọn.
Atẹjade yi tun fidi ọrọ mulẹ pe lẹyin wakati diẹ ti wọn ṣọṣẹ ni awọn olubi yi tun lọ ji dokita kan gbe nile rẹ ni Ibarapa yi kan naa.
''Nipa ijinigbe dokita kan ti orukọ rẹ n jẹ Dokita Akindele ni Tapa lagbegbe ariwa Ibarapa nipinlẹ Oyo lọjọ Keji oṣu Kini ọdun yi, ọrọ yi n jẹ ohun kọ ileeṣẹ ọlọpaa lomi nu''
Lẹnu lọọlọ yi, niṣe ni iṣẹlẹ ipaniyan ati ijinigbe n peleki si ni Ipinlẹ Oyo.
Bi a ko ba gbagbe awọn agbebọn kan pa eekan ẹgbẹ oṣelu PDP Fatai Aborode nigba to n dari bọ lati oko rẹ.
Ni ọjọ kọkanla oṣu kejila ọdun 2020 ni wọn da lọna lopopona Apodun ni Igangan,gẹgẹ bi ọlọpaa ṣe wi.
Awọn afurasi mẹrin ni wọn ni wọn ṣiṣẹ yi ti awọn ọlọpaa ṣi yi n wa awọn afurasi naa di ba ti ṣe n sọrọ yi.
Laarin Tapa ati Aiyete ni Fatai Aborode ti dakẹ nigba ti wọn n gbe lọ si ile iwosan to wa ni Igboora.
Ẹwẹ ẹgbẹ alagbata epo aladani ni Naijiria ti kesi Gomina Makinde lati wa wọrọkọ fi ṣada lori iṣekupani ati ijinigbe to n gbogo ni ipinlẹ Oyo.
Ẹgbẹ naa fi ọrọ yi sita ninu atẹjade kan lọjọ Aiku lẹyin iku Alhaja Sherifat tawọn ajinigbe ṣeku pa.
DNA Paternity: Tó bá wáyé pé ẹ kò mọ ẹni tó lọmọ, ohun tí àwọn àgbààgbà Yorùbá máa ń ṣe rèé
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Araba awo ilu Osogbo, Oloye Ifayẹmi Ẹlẹbuibọn ti da si Ọrọ DNA to gba igbooro kan lori iṣẹlẹ ka gbọmọ ọba fun Oṣun to n waye laarin lọkọlaya .
Ninu ifọrọwerọ pẹlu BBC agbaọjẹ ede ati aṣa Yoruba yi ti lawa lọyẹ lori oun taa ṣe nilana ti Yoruba ti a ba fura si pe awọn ọmọ to wa lọọdẹ wa kii ṣe ojulowo ọmọ ọkọ.
Elebuibon ṣalaye pe lootọ ni obinrin maa n  mọ ẹni to bimọ fun ṣugbọn to ba ṣẹlẹ pe irin ẹsẹ obinrin ko mọ, awọn mọlẹbi tabi ọkọ fun ara rẹ le fi tibilẹ tọ pinpin ẹni to lọmọ.
Owe yi ni Baba Elebuibon fi kin ọrọ wọn lẹyin ti o si ba wa ṣide alaye lori iṣẹlẹ ki a maa gbe ọmọ ọlọmọ fun ọkọ ẹni.
Wọn sọ pe pupọ iru iṣẹlẹ yi ko yọ awọn obinrin lẹsẹ silẹ botilẹjẹ pe awọn ọkunrin naa ọwọ wọn ko mọ tanyanyan
''Ọwọ awọn obinrin lọrọ ti maa n wọ.Ti ọkọ tabi iyawọ ko ba ṣeke si ara wọn, ko yẹ ko si nkan ti yoo mu ki wọn fẹ mọ boya emi ni mo lọmọ tabi emi kọ''
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Lara ọna ti Elebuibon ṣalaye pe awọn Yoruba fi maa n mọ boya ọmọ ọkọ ni wọn gbe fun ree:
Nigba ti obinrin naa ba bimọ tan wọn a ni ko gbe ọmọ wa ko si wọle lọ. Lẹyin to ba wọle, wọn a da omi si ori orule ti iya ọmọ naa yoo si sa wọle lẹẹmeje.
Elebuibon sọ pe wọn a maa ṣe eleyi ''lati mọ boya ọmọ ọkọ ni ọmọ naa ni tootọ''
Ọna keji ti agba awo yi ṣalaye  ni nipa ṣiṣe oosa idile.
Alagba Yemi Elebuibon ṣalaye pe wọn a tun maa ''gbe ọmọ lọ si ọdọ ooṣa lati mọ boya idile ọkọ  naa lo ni ọmọ ọ́hun ni tootọ''
Oro yi gẹgẹ bi alaye ko papọ ni ilu si ilu tabi ni idile si idile.Lati laelae lo si ti maa n wa
''Ẹlọ mii wọn a ni ki iya rẹ jẹ nkankan fun ọjọ meloo kan, ẹlo mii wn a gbe ọmọ yẹn lọ si idi ooṣa ti wọn a fi sibẹ fọjọ meloo kan''
Yatọ si awọn oro idile yi, Araba tun sọ pe awọn oro idile mii yoo niṣe pẹlu ki wọn gbe ọmọ si eti odo tabi ki o sun ti ere ejola mọjumọ.
Nigba ti a beere pe ki wa ni yoo ṣẹlẹ ti wọn ba ri wi pe ọmọ yi kii ṣe ọmọ ọkọ, wọn fesi pada bayi:
''Yoruba kii ṣaba fẹ gba ọmọ ale.Wọn ni ti ile baa n toro ọmọ ale ibẹ ni ko ti dagba ṣugbọn nigba mi ọkọ maa n gba lati tọju iru ọmọ bẹ bi tiẹ''
Lakotan ọrọ alagba Elebuibọn, wọn ni ti ọkọ ba dariji iyawo tabi to gba lati tọju ọmọ tiu iyawo ba gbe wa lati ile ọkọ mii, ko si aburu nibẹ.
New date for School resumption: Ìjọbá àpapọ̀ tún yíhùn padà lórí ọjọ ìwọlé àwọn akẹ́kọ̀ọ́
Oríṣun àwòrán, Ogun govt
Ijọba apapọ lorilẹede Niajiria ti paṣẹ ki gbogbo ileewe wọle pada ni Ọjọ Kejidinlogun, Oṣu Kini, Ọdun 2021.
Eyi ko ṣẹyin ipade to waye laarin Minisita fun eto Ẹkọ,Malam Adamu Adamu ati awọn kọmisọnna fun eto Ẹko ni ilu Abuja.
Iroyin ni aṣẹ naa ko ṣẹyin ipade ati atilẹyin lati ọdọ awọn gomina ipinlẹ, adari ileewe, awọn adari awọn akẹkọọ ati awọn akẹkọọ.
Wọn ni gbogbo wọn fi ọwọ si wi pe ki awọn ileewe ṣi pada kaakiri Naijiria.
Akọwe agba fún ilé iṣẹ́ eto Eko ni Naijria lo fi idi ọrọ naa mulẹ
Amọ, ijọba ni gbogbo awọn akẹkọọ ati olukọ lo gbọdọ tẹle awọn ofin to rọmọ didẹkun itankalẹ arun Coronavirus lorilẹede Naijiria.
Oríṣun àwòrán, Min edu
Oríṣun àwòrán, Ministry of edu
Oríṣun àwòrán, Adamu Adamu
Ìjọba àpàpọ̀ ni ni òun yóò ṣe àtúngbéyẹ̀wò àsìkò ìwọ̀lé àwọn akẹ́kọ̀ọ́ ní Nàìjíríà.
Sáájú ni ìjọba ti ní àwọn akẹ́kọ̀ọ́ yóò padà sílé ìwé ni ọjọ́ kejìdílógun, oṣù kíní ọdún 2021, sùgbọ́n ojoojúmọ ni ààrùn Coronavirus n péleke sí.
Mínísítà fún ètò ẹ̀kọ́, Adamu Adamu  ló sọ èyí di mímọ lásìkò tó n dáhùn ìbéèrè  àwọn akọròyìn níbi ìpàdé àwọn oníròyìn ti ìgbìmọ̀ amúṣẹ́ ṣe lórí Covid-19 ti ààrẹ yan nílùú Abuja.
"Mínísítà ní "" Lórí ìwalé ọjọ́ kejìdílógún, a ó ṣe àtúngbéyẹ̀wò rẹ̀."""
"A tí sọ níbi ìpàdé PTF tí a ṣe lónìí, tó bá di ọ̀la, ilé iṣk ètò ẹ̀kọ́ yóò mọ ìgbésẹ̀ tó kù."""
Sáájú àsìkò yìí ni ìjọba ti kéde pé, kí àwọn akẹ́kọ̀ọ́ ní gbogbo ipele padà sí ilé ẹ̀kọ́ ni ọjọ́ kejìdínlógún , oṣù kíní ọdún 2021.
Ijọba ipinlẹ Eko ti pada kede ọjọ kejidinlogun oṣu kini ọdun 2021 gẹgẹ bii ọjọ iwọle tuntun fun awọn akẹkọọ fun saa eto ẹkọ keji.
"Atẹjade kan ti ileeṣẹ eto ẹkọ ni ijọba ipinlẹ Eko, fi sita ṣalaye pe kọmiṣọna eto ẹkọ nipinlẹ Eko Arabinrin Fọlaṣade Adefisayọ lo kede eyi ni ""ibamu pẹlu aṣẹ ati idari ijọba apapọ ati ọwọja ọwọ keji ajakalẹ aarun COVID-19 to n ja lọwọlọwọ."""
ni opin ọsẹ to kọja ni ijọba ipinlẹ Eko ti kọkọ kede pe gbogbo awọn ileewe alakọbẹrẹ ati girama ko ni lee wọle bayii ayi pe iwọle wọn di ọjọ mii ọjọ ire.
"O wa rọ awọn ileewe lati ṣeto aye to tọ fun awọn akẹkọọ tabi olukọ ti ara wọn ko ba ya lati maa kọ ẹkọ tabi ṣiṣẹ wọn lati ile nipasẹ ayelujara iyẹn, ""Virtual learning"" tabi ""Virtual work"""
Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi
Akomolede BBC: Onírurú gbólóhùn léde Yorùbá àti irúfẹ́ gbolóhùn tó wà nínú èdè Yorùbá
Gbogbo ọrọ ti eeyan ba sọ ninu ede Yoruba lo bọ si abẹ gbogbohun, ọkọọkan lo si ni atọka ti a fi n mọ wọn.
"Ninu eto ""Akọmọlede Yoruba"" ti ọtẹ yii Gbolohun ati ipin rẹ ni a gbe yẹwo."
Akure Lady Suicide: A kò ní ṣe ìwádìí kankan lórí òṣìṣẹ́ Shoprite tí wọ́n ló gba ẹ̀mí ara rẹ̀ nílùú Akure-Ọlọ́páà
Oríṣun àwòrán, Others
Ileeṣẹ ọlọpaa nipinlẹ Ondo ti fesi si ọrọ iku arabinrin kan ti wọn sọ pe o gbẹmi ara rẹ ni Akure.
Alukoro ọlọpaa Ondo Tee-Leo Ikoro ṣalaye fun BBC pe ''ẹni to ba gbẹmi ara rẹ, ko si iwadi kankan taa le ṣe , ẹni ti ku ti ku ''.
Ikoro ni lootọ ni awọn gbọ nipa iṣẹlẹ naa ṣugbọn awọn ko lọ sibẹ lati lọ wo nitori iṣẹlẹ igbẹmi ara ẹni kii ṣe ohun tawọn tun le ṣe iwadi le lori.
''Nkan kekere ni, ko si ẹsẹ kankan ti eeyan ba gbẹmi ara rẹ.Paapa julọ nigba ti ẹnikankan ko ba  fi ọrọ yi to ọlọpaa leti''
O ni Ọlọpaa kii ṣadede ṣe iwadii ẹsun pe eeyan gbẹmi ara rẹ ayafi ti ẹni naa ba gbiyanju ti ko ri ara rẹ pa,.
''Nigba naa lo to wa di ẹsẹ pe o fẹ gbẹmi ti ko lẹtọ lati gba.Bi bẹ kọ, bo ba ku , ko si nkankan taa le ṣe si''
Yatọ si eyi, Ikoro sọ pe ohun ko ro wi pe o gbẹmi ara rẹ ni.
Iroyin iku arabinrin yi jẹ eleyi ti awọn eeyan Akure ti n ṣeemọ si lati igba to deti igbọ awọn eeyan.
Laisun ọjọ ọdun tuntun ni wọn ba oku  Jumoke Kehinde ninu iyara rẹ ladugbo Kajola,opopona Oda ni Akure.
Ẹni ọdun mẹtalelogun naa  ti wọn lo jẹ oṣiṣẹ ile itaja Shoprite la gbọ pe wọn da duro lẹnu iṣẹ lọjọ taa n wi yi.
Suicide Prevention: ìwọ́de yìí wáyé láti gbógun ti pípa ara ẹni
BBC gbiyanju lati ba oludari ile itaja Shoprite naa kan sọrọ ṣugbọn o ni oun ko bawọn ṣiṣẹ mọ nitori naa oun ko ni le dahun si ibeere wa.
Ko ti si aridaju boya lootọ lo mu ogun sniper tawọn kan sọ pe o ṣokunfa iku rẹ.
Nitori pe  ileeṣẹ ọlọpaa naa ti ṣe sọ pe awọn ko wulẹ lọ sibẹ lọ ṣe iwadii, ko si ẹni to le sọ pato iru iku to pa Jumoke.
A n gbiyanju lati ba awọn mọlẹbi Jumoke sọrọ.
Ni kete ti a ba ri wọn kan si la o mu alaye wa lati ọdọ wọn nipa ohun to le faa ki Jumoke gbẹmi ara rẹ to ba ṣe pe lootọ ni pe o ṣe bẹ.
NERC Electricity Tariff: àfikún owó iná 'tariff' làti N2 sì N4 la ṣé dipo ìdá 50% tàwọn èèyàn n sọ́
Oríṣun àwòrán, NERC
Ko si ootọ ninu ọrọ pe a ti fikun iye owo tarifu mọnamọna tawọn ara ilu n san.
Ikede yi lo waye lati ọdọ ajọ to n mojuto ọrọ ina mọnamọna ni Naijiria, NERC.
Loju opo Twitter ileeṣẹ naa ni wọn fi ọrọ yi si ti wọn si ni awọn ko fi kun iye owo tawọn to n jẹ anfaani ina wakati mejila lojumọ n san iyẹn awọn to wa ni akasọ D ati E.
Ni itẹsiwaju alaye ajọ naa wọn ni afikun to waye ko ju alekun lati Naira meji si Naira mẹrin fun Kilowat kan laarin wakati kan fawọn to wa lori akasọ A B C D ati E.
Ohun ti wọn lo fa alekun yi ko ju bi igbowolori nkan lọja ti ṣe n waye ati iye owo dọla ti ko duro loju kan.
Alaye yi ti wọn lawọn ṣe lati tako iroyin ẹlẹjẹ to n ja rain pe awọn ṣe afikun ida aadọta ninu ida ọgọrun iye owo ina tara ilu n san koba awọn eeyan lara mu.
Idi ni pe agbeyẹwo afikun ti wọn lawọn ṣe yi(N2.00-N4.00) fi han pe o ju ida aadọta ti wọn n tako pe kii ṣe ootọ.
Koda ida ọgọrun ni wọn ṣe eyi  to ju iye tawọn oniroyin gbe jade lọ.
Kia lawọn eeyan ti n tọka si ohun ti wọn n sọ yi ti wnsi ni ati aadọta ati ọgọrun, nigba wo ni wọn sọ fun ara ilu ki wn to ṣe afikun?
Insecurity in Nigeria: Soyinka ní Buhari kò le jókòó síle ìjọba láti dojú Boko Haram bolẹ̀
Oríṣun àwòrán, @HQNigerianArmy
Gbajumọ onkọwe nni, Ọjọgbọn Wole Soyinka ti pe aarẹ Muhammadu Buhari nija lori eto aabo to mẹhẹ to n ba ilẹ Naijiria finra.
Ọjọgbọn Soyinka ni ala ti ko le sẹ ni fun ijọba Buhari, ti aarẹ ba joko fẹytinti nile ijọba Aso Rock, to si lero pe yoo ri ẹyin awọn agbesunmọmi ati atajẹsilẹ ni gbẹfẹ.
Soyinka woye ọrọ yii lasiko to n kopa lori eto ori mohunmaworan kan nilu Eko.
Gbajugbaja onkọwe naa wa kede pe, agbajọ ọwọ lo yẹ ka fi ọrọ eto abbo to mẹhẹ naa se nitori ikọ fẹjẹwẹ Boko Haram, agbegbọn atawọn ọdaran miran ti gbakoso Naijiria.
Soyinka ni ipo ti Naijiria wa bayii ti de ipo koyemimọ, ti ijsba si gbọdọ setan lati sanwo fun awọn eeyan ti yoo ran wa lọwọ lati doju ija kọ awọn ọdaran ati ikọ afẹjẹwẹ naa.
Oríṣun àwòrán, Facebook/Professor Wole Soyinka's Admirers
"Awọn eeyan kan wa to yẹ ka di ẹbi ọrọ eto aabo to mẹhẹ le lori, lara wọn si ni asn asaaju orilẹede yii to ti tukọ Naijiria sẹyin, ti wọn ko tete riran pe ohun gbogbo le buru to bayii.
Inu mi si dun pe awọn ọlaju lapa oke ọya naa ti n sọrọ soke lori awọn isẹlẹ yii, ti wọn si ti n gbe awọn igbesẹ to yẹ ki wọn ti gbe ni aimọye ọdun sẹyin.
Koda, lara wọn gan jẹwọ fun mi pe awọn ti n sanwo aabo ẹmi fawọn apaayan lati jẹ ki wọn rile aye gbe.
Amotekun: Àwọn olóṣèlú, àwọn tó kùnà jíjẹ́ ọmọ ikọ̀ Amotekun ló ń gbé ìròyìn ìbàjẹ́ kiri
Amọ Soyinka wa daba pe oun ko ba fara mọ ilana sise koriya fun araalu ninu eyi ti wọn yoo ti se idanilẹkọ fun wọn,.
O ni idanilẹkọ nipa ibọn lilo se koko, paapa fawọn agbẹ, ki wọn le fi ọwọ kan mu ọkọ to fi n ro oko ati ọwọ keji mu ibọn, ti yoo fi daabo bo ẹmi ati eto ikore rẹ.
Oríṣun àwòrán, unicef usa
Saaju la ti sọ fun yin pe, ileeṣẹ ọlọpaa ipinlẹ Ondo ti mu ọmọ ẹkọṣẹ ti wọn pe orukọ rẹ ni Temitope Adeniyi, to gbe ọmọ ọga rẹ ati kaadi igbowo ATM ọga rẹ sa lọ.
Agbẹnusọ ileeṣẹ ọlọpaa, Tee-Leo Ikoro lo fidi ọrọ naa mulẹ fawọn akọroyin.
Iṣẹlẹ ọhun waye ni ṣọọbu telọ kan lagbegbe Oke-Bola niluu Ondo.
Ileeṣẹ ọlọpaa ṣalaye pe awọn ti gba ọmọ ti ọdọbinrin naa gbe sa lọ lọwọ rẹ.
Ọgbẹni Ikoro fiku ọrọ rẹ pe ko si ohun kan to ṣe ọmọ naa nigba tawọn gba a lọwọ rẹ.
Èèmọ̀ wọ̀lú, Ọmọ ẹ̀kọ́ṣẹ́ gbé ọmọ ọ̀gá rẹ̀ àti káàdì ìgbowó ATM sálọ l'Ondo!
Ọmọ ẹkọṣẹ telọ kan ti gbe ọmọ tuntun jojolo ọga rẹ salọ ni ilu Ondo pẹlu kaadi igbowo ATM rẹ.
Gẹgẹ bi iroyin ti ileeṣẹ ọlọpaa ni ipinlẹ Ondo fi idi rẹ mulẹ fun BBC News Yoruba, ọkọ iya ọmọ naa ti orukọ rẹ n jẹ Stella Babatunde lo mu arabinrin naa ti orukọ tirẹ n jẹ Temitọpẹ Adeniyi wa kọ iṣẹ lọdọ rẹ.
Gẹgẹ bi ohun ti a gbọ, iyawo ọrẹ rẹ ni ọkọ arabinrin yii pe Temitọpẹ ki o to di pe akara tu sepo.
Nigba ti ọrọ di ifanfa lẹyin to ji ọmọ ati kaadi igbowo ATM ọga rẹ gbe salọ tan ni ọrọ to han sita pe wọle-wọde ikọkọ n lọ laarin ọkọ Stella ati ọmọ ẹkọṣẹ rẹ naa, Temitọpe, ati pe ololufẹ rẹ ni.
Gẹgẹ bi ohun ti arabinrin Stella Babatunde sọ, ọkọ rẹ mu arabinrin naa wa kọṣẹ ni ọdọ rẹ ni ọjọ kẹta oṣu kejila ọdun 2020, ṣugbọn o ni oun maa n ṣakiyesi pe ibasọrọ ori foonu maa n waye laarin ọkọ oun ati arabinrin naa lasiko to ba wa ni ṣọbu ti oun ti n ṣe iṣẹ telọ oun.
Ni ọjọ keji oṣu kini ọdun 2021 yii ni arabinrin naa gbe ọmọ ọga rẹ pọn ti ọga rẹ si fun un ni kaadi igbowo ATM rẹ  pe ki o ba oun gba ẹgbẹrun mẹta Naira ti ọkan lara awọn onibara rẹ fi ranṣẹ sii lori ẹrọ igbowo POS.
Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi
Amọṣa Stella Babatunde ni lilọ rẹ ni oun ri lati igba naa ati pe Ko pada wale mọ lati igba naa o.''"
Araabinrin naa ṣalaye siwaju sii pe ni kete ti oun ko ti kẹfin ọmọ ẹkọṣẹ rẹ naa mọ loun ti pe ọkọ oun to mu wa lati ṣalaye fun un ṣugbọn iha ko kan mi ni ọkọ naa n kọ si ọrọ naa, to bẹẹ gẹ to fi jẹ wi pe awọn ara adugbo gan fẹ pawọ pọ luu ni alubami nigba to de.
Amọṣa ni agọ ọlọpaa ni ọkọ arabinrin naa ti wa jẹwọ pe lootọ ere ifẹ n bẹ laarin oun ati ọmọ ẹkọṣẹ iyawo oun naa ṣugbọn oun ko mọ nipa ọmọ to gbe salọ.
Alukoro ileeṣẹ Ọlọpaa ni ipinlẹ Ondo, Leo Ikoro fi idi iṣẹlẹ naa mulẹ, O si ṣalaye fun BBC News Yoruba pe iwadi ti nlọ lori rẹ ati pe ileeṣẹ ọlọpaa ti mu awọn afurasi kan lori rẹ.
Ritual killers: : Ọwọ́ ọlọ́pàá tẹ afurasí tó gé ojú-ara ọmọdébìnrin ọdún mẹ́fà fún ètùtù ọlà
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ariwo eemọ, irú kileyi lo ṣi n gba ẹnu ọpọ eniyan ni Naijiria, nitori iroyin kan to jade pe awọn eeyan buruku kan gé abẹ́ ọmọbìnrin ọdun mẹfa nipinlẹ Bauchi.
Iroyin sọ pe ọgbọnjọ, oṣu Kejila, ọdun 2020 ni iṣẹlẹ naa waye.
Botilẹjẹ pe ọmọdébìnrin naa si n gba itọju nileewosan, agbenusọ awọn ọlọpaa nipinlẹ Bauchi, DSP Muhammad Wakil sọ nkan ti awọn obi le ma a ṣe lati daabo bo awọn ọmọ wọn lọwọ irú awọn ọdaran bẹ ẹ.
Nkan akọkọ ni pe ki awọn obi o ma a mojuto ìrìn ọmọ wọn; mọ ibi to wa, awọn to wa nibẹ pẹlu rẹ ati nkan to n ṣe.
Nkan keji ni pe da ẹnikẹni to ba n pe ọmọ rẹ ni ọkọ tabi iyawo mi, lẹ́kun.
Idi ni pe nipasẹ iru nkan bẹ ẹ lo ti n bẹrẹ, titi ti nkan buruku yoo fi ṣẹlẹ.
 Ti o ba fi aaye gba ẹnikẹ́ni lati ma a pe ọmọ rẹ to jẹ ọmọde ni iyawo mi, o ma n mu ki iru ọmọ bẹ ẹ gba ki ẹni naa ṣe ohunkohun to wu si i.
Bi iṣẹlẹ naa ṣe waye Ọga ọlọpaa naa sọ pe iṣẹlẹ to ṣẹlẹ sì ọmọ ọdun mẹfa yii jẹ ọkan lara awọn nkan to buru ju ti oun riri gẹgẹ bi ọlọpaa.
" Eletutu ọlà kan lo ni ki awọn ọdọmọkunrin mejeeji lọ mu ojú ara ọmọdebinrin wa, ki wọn o le di olowo.
Ohun lo mu ki wọn o fi ọgbọn tan ọmọ ọdun mẹfa naa pe awọn fẹ ẹ ran nisẹ.
Nise ni wọn fi aṣọ penpe bo ẹnu rẹ, ti wọn si gbe lọ sinu ile kan ti wọn n kọ lọwọ.
 Ninu ile naa ni wọn ti fi nkan ge idọ 'clitoris' rẹ ti eletutu sọ pe yoo sọ wọn di olowo."
Wọn fi ọmọ naa silẹ ninu agbára ẹjẹ, wọn si salọ.
" DSP Wakil tun sọ pe ọwọ ti tẹ ẹnikan lara awọn eeyan to ṣe iṣẹ ibi naa, sugbọn wọn ṣi n wa ẹnikan to ku ati ẹni to fẹ ẹ bá wọn ṣe etutu.
Gomina ipinlẹ Bauchi, Bala Mohammed ti gbé miliọnu kan Naira silẹ fun itọju ọmọdebinrin naa, o si tun pasẹ fun awọn oṣiṣẹ alaabo lati se gbogbo nkan ti yoo mu ki ọwọ tẹ awọn meji to ku.
Bakan naa ni dokita nileewosan ti ọmọ naa ti n gba itọju sọ pe owo ti gomina gbé kalẹ ti tẹ àwọn lọwọ, ati pe ara rẹ ti n ya diẹdiẹ.
O ṣalaye pe awọn tun gbọ pe awọn eeyan kan n fi orukọ ọmọ naa tọrọ owo lori ayelujara. O ni ki awọn eeyan naa jawọ, nitori pe ijọba ti ṣèlérí lati san gbogbo owo itọju rẹ.
Oluwo Jogbodo: Ìmẹ́lẹ́ jẹ́ orísun àìnílárí, Ifá ṣe ìkìlọ̀ rẹ̀ fáwọn ará Ibadan kí wọ́n tó làlùyọ-Olúwo Jọ̀gbọ̀dọ́
Lọsẹ yii, lori ọrọ iṣiti ọlọọọsẹ BBC News Yorùbá pẹlu Oluwo Jọgbọdọ ti a pe ni Itaniji lori BBC News Yoruba"", titẹpa mọṣẹ, jijina si iwa imẹlẹ la gbe yẹwo."
Ohun ti eyi si tumọ si pe ko si iṣẹ kan to ṣe e fi ọwọ rọ sẹyin ninu iṣẹ aṣejẹ ẹda. Iba jẹ iṣe birikila, iba jẹ iṣẹ apọnmita, iṣẹ ni iṣẹ njẹ.
Koda awọn agba bọ wọn ni iṣẹ kii pa ni, aiṣe rẹ gan an ni abuku.
A mu ọrọ iṣiti ọtẹ yii jade lati inu ẹsẹ ifa to ys si awọn ara Ibadan ni igba iwasẹ nipa titẹpa iwa imẹlẹ.
Eekan agbaṣaga, Oluwo Jọgbọdọ tun mu ọrọ itaniji jade, paapaa fun awọn ọdọ lori titẹpa mọ ẹkọ tabi iṣẹ ti wọn ba yan laayo nitori iṣẹ ni mu ni bọ loko igbekun oṣi ati iṣẹ.
Nollywood: Ẹ fura o, ẹnìkan ti n fi orúkọ mi ṣe gbájúẹ̀ lórí ayélujára fún Kóló tí mò n tà - Tawa Ajisefinni
Oríṣun àwòrán, Instagram/Tawa Ajisefini
Oṣerebinrin, Tawa Ajisefinni Alli ti ke gbajare sita lori bi eeyan kan ṣe n lu awọn onibaara rẹ ni jibiti lori ayelujara.
Ajisefinni to sọ ọrọ pẹlu ẹ̀dùn ọkan ninu fidio kan to fi si ori ayelujara Instagram rẹ sọ pe o jẹ ibanujẹ fun oun pe ẹnikan ń parọ gba owó lọwọ àwọn to fẹ ẹ ra ọja ti oun n ta.
Yatọ si pe o jẹ osere, Tawa tun n ta kóló, to jẹ apoti oni kọ́kọ́rọ́ ti ẹni to ba ra a le ma fi owo pamọ si.
Piggy bank ni wọn n pe ni ede Gẹẹsi.
Ori ayelujara Instagram si lo ti n ta a.
Ninu fidio naa, Ajisefinni sọ pe ọpọlọpọ eeyan ni ẹni naa ti fi orukọ oun gba owo kóló lọwọ wọn, lai fun wọn ni ojà ti wọn fẹ ẹ ra.
Ori ayelujara WhatsApp ni 'onijibiti' naa ti ma n ba awọn to fẹ ẹ ra Kolo sọrọ, ti yoo si fun wọn ni nọ́mbà akanti banki ti ẹ lati sanwo si.
Akiyesi ni pe nọ́mbà naa ti Tawa Ajisefinni fi sita jẹ ti orilẹ-ede America.
Sugbọn ṣa, Arabinrin Tawa ti ki awọn onibaara rẹ ni lọ, lati kọkọ ma a ba oun sọrọ l'ori Instagram tabi WhatsApp, ki wọn o to san owo lati ra kolo ti oun n ta.
Bakan naa lo tun fi oriṣiriṣi epe ati ọrọ buruku ránṣẹ si ẹni naa to fi ẹsun kan pe o fẹ ẹ ba okoowo oun jẹ.
Orisabunmi: Ta ni Gbajúgbajà òṣèré tíátà Yorùbá, Orisabunmi tó jáde láyé?
Oríṣun àwòrán, Instagram/toyosiadesanya
Gbajugbaja agba oserebinrin, Folake Orisabunmi ti jade laye.Owurọ Ọjọru ni awọn akẹẹgbẹ rẹ kan bi Toyosi Adesanya bẹrẹ si ni ṣe idaro iku rẹ lori ayelujara Instagram wọn.A kò ti fidi igba to ku tabi nkan to pa a mulẹ lasiko ti a kọ iroyin yii, sugbọn ao ma mu ẹkunrẹrẹ iroyin wa fun yin to ba se n tẹ wa lọwọ.
Iroyin sọ pe ẹni ọgọta ọdun ni Oriṣabunmi ki o to jade laye.
Ọjọ Kẹwaa, oṣu  Kẹwaa, ọdun 1960 ni wọn bi nilu Ola nipinlẹ Kwara.
Orukọ abisọ rẹ ni Fọlakẹ Arẹmu ṣugbọn Oriṣabunmi ni ọpọ eeyan mọ si.
Iya orisa, tabi ajẹ funfun ni orukọ ti ọpọ miran tun maa n pe e nitori awọn ipa ti o maa n ko ninu ere itage ati sinima.
O lọ si ileewe alakọbẹrẹ ati Girama ni ilu Eruku nijọba ibilẹ Ekiti nipinlẹ Kwara.
Ọkan lara awọn iyawo agba oserekunrin, Jimoh Aliu, to doloogbe lọdun 2020 ni Orisabunmi. Sugbọn, àwọn mejeeji ti kọ ara wọn silẹ saaju iku wọn.
Lati nkan bi ọdun 1980 ni Orisabunmi ti jẹ gbajugbaja fun ipa Yeye Ọsun to ma n ko ninu ere.
Ọkọ rẹ nigba kan, Jimoh Aliu lo sawari rẹ gẹgẹ bi oṣere lasiko to fi n ṣe iṣẹ olukọ nipinlẹ Kwara.
Àwọn ere to jẹ ti Aliu 'Aworo' si lo fi bẹrẹ ere sisẹ ni pataki julọ, ere ori itage 'Ori ma binu' lo fi bẹrẹ isẹ ere ṣíṣe, ṣugbọn ipa Orisabunmi to ko ninu ere Arelu ni nkan bi ọdun 1980 lo sọ ọ di gbajugbaja.
Lootọ, Oloogbe Jimoh Aliu lo kọ nisẹ ere ṣíṣe, sugbọn iroyin sọ pe bo ṣe mọ ọfọ pipa ko sẹyin bi wọn ṣe tọ ọ dagba. Idi ni pe idile eleegun ni wọn ti bi; Iya rẹ si jẹ ọmọ ile Ọlọsun.
Bi ọdun mejilelogoji ni Orisabunmi fi sisẹ ere ṣíṣe ki iku to o mu lọ.
Oun fúnra rẹ gbe awọn sinima bi Atupa Imole, Ase Ilu, ati Tani Ọ jáde.
Yatọ si iṣẹ olukọ, Orisabunmi tun sisẹ akọ̀wé ni ileesẹ Sunny Radio nipinlẹ Kwara.
A n se akojọpọ ẹkunrẹrẹ iroyin yajoyajo lọwọ, a o maa gbe ẹkunrẹrẹ iroyin naa sori atẹ iroyin wa laipẹ. Ẹ jọwọ, ẹ tun oju opo iroyin yi yẹwo, ki ẹ lee ri ẹkunrẹrẹ iroyin ọtun laipẹ.
Orisabunmi: Èyí ni àlàyé lórí àsìkò ìkẹyìn olóògbé Orisabunmi àti ohun tó paá gan láti ẹnu Baba Ijesa
Oríṣun àwòrán, Instagram/themakingstv
Kii ṣe iroyin mọ bayii pe gbajugbaja oṣere tiata ati sinima Yoruba, Iyaafin Fọlakẹ Arẹmu ti ọpọlọpọ eeyan mọ si Oriṣabunmi ti jade laye, amọṣa ohun ti o n ṣe ọpọlọpọ eeyan, paapaajulọ awọn ololufẹ wọn ni kayefi ni irufẹ iku to pa wọn.
Eyi ko ṣa dede ri bẹ bikoṣe nitoripe ko si eeyan to gbọ iroyin aarẹ kankan nipa eekan oṣere naa ki ọlọjọ to de.
"Amọṣa ninu fidio kan to fi si ori ikanni ayelujara, Facebook, eekan apanilẹrin ati elere itage, Ọlanrewaju Omiyinka ti ọpọ mọ si Baba Ijeṣa jẹ ko di mimọ pe ""ikọ lasan"" lo pa oloogbe Oriṣabunmi."
Baba Ijẹṣa ṣalaye pe ko si idi fun oloogbe naa lati ku kani awọn ohun elo irapada ẹmi gbogbo to yẹ ba wa lawọn ileewosan lorilẹede Naijiria ni.
Baba ijẹṣa ṣalaye pe ohun to n ba awọn oṣere ninu jẹ pups julọ ni pe ijọba orilẹede Naijiria ko ṣai maa ja araalu to dibo fun wọn kulẹ.
Bakan naa lo fi idi rẹ mulẹ pe ọjọ Iṣẹgun, ọjọ karun un oṣu kini ọdun 2021 ni Oriṣabunmi jade laye.
Bakan naa ni aarẹ ẹgbẹ awọn oṣere sinima, TAMPAN, Bọlaji Amuṣan ti ọpọ mọ si Baba Latin pẹlu fi idi eyi mulẹ ninu ifọrọwerọ rẹ pẹlu ileeṣẹ iroyin abẹle kan.
Ni alẹ ana (Ojọ Iṣẹgun) ni wọn ku Baba Latin ṣalaye.
Oríṣun àwòrán, Instagram/standard_presenter
Nigba to n tẹsiwaju ninu fidio naa, Baba Ijẹṣa ni ọpọlọpọ awọn oṣere ni inu wọn ko dun si bi ijọba lẹkajẹka gbogbo ṣe n ja awọn oṣere sinima kulẹ nipa aitọju wọn ati airi tiwọn ro.
Ninu ọrọ rẹ, O ni o yẹ ki Mama Oriṣabunmi, gẹgẹ bi awọn oṣere ṣe maa n pe e o wa ni ili Ilẹ Oluji fun iṣẹ sinima kan ti Lọla Adegoke ti ọpọ mọ si Mọremi agbaye fẹ ya nibẹ ni ti Mama Oriṣabunmi funra rẹ gan ti pe lati le tete mọ ọjọ ti yoo kan ipa ti o fẹ ko nibẹ.
Bakan naa lo ni Oriṣabunmi ṣẹṣẹ pari iṣẹ kan to lọ ya ni ilu Ẹdẹ ni ipinlẹ Ọṣun laipẹ yii ni pẹlu ti ko si si ohun kan to ṣe ilera rẹ.
Ko si nnkankan to ṣe iya yii nibẹ. A jọ n ṣe awada, a jọ n jo nibẹ ni
O ni Oriṣabunmi n wu ikọ, ko lee mi daadaa. O fi kun un pe ka ni ileewosan ti wọn gbee lọ ni ohun  elo iranwọ fun eemi, o ṣeeṣe ki Oloogbe Oriṣabunmi ṣi wa laye.
Amotekun: Àwọn olóṣèlú, àwọn tó kùnà jíjẹ́ ọmọ ikọ̀ Amotekun ló ń gbé ìròyìn ìbàjẹ́ kiri
Iroyin aitọ ko yee jade nipa ikọ Amọtẹkun ni ipinlẹ Ọyọ lẹnu Ọjọ mẹta yii, ṣugbọn adari ikọ naa ni awọn ọta ilọsiwaju lo n wa ni idi rẹ.
Chief (Mrs.) Opral Benson: Ìdí rèé tí Oba Eko ṣe fi Olóyè Opral Benson jẹ Yeye Oge ìlú Eko
Oríṣun àwòrán, City People
Ọpọ eeyan ni ko mọ ohun to mu ki Ọlọlajulọ, Oba Eko nigba kan ri, Oba Adeyinka Oyekan fi Opral Benson jẹ oye Yeye ilu Eko.
Lọdun 1973 ni eto naa waye nibi ti Oba Oyekan to ti waja bayii ti fi Mama Benson jẹ oye.
Mama Benson to ti pe ẹni ọdun marunlelọgọrin bayii di Yeye Oge ilu Eko nitori bi o ṣe maa n mura daadaa nigba naa lasiko ni orilẹ-ede Naijiria ṣẹṣẹ gba ominira.
Àwọn ìtàn mánigbàgbé tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí:
Ọpọ lo tilẹ ro pe inagijẹ lasan ni ni Yeye Oge ti Benson n jẹ.
Rara o, Oba Eko lo fi oye naa da a lọla nitori bi o ṣe gboge lawujọ.
Oríṣun àwòrán, SeriouslyDoughnuts
Oloye Rasheed Gbadamosi, onimọ nipa iṣowo to ti di oloogbe bayii sọ nigba aye rẹ nipa bi Benson ti gbajugbaja pẹlu ara mimu ati oge ṣiṣe nigba to fi wa ni sangoode.
Oloye Gbadamosi ni gbogbo eeyan ni Benson maa n da lọrun nigba naa pẹlu imura rẹ ati bi o ṣe gbọ oge,
Koda. Oloye Gbadamosi kọ ọrọ apilẹkọ nipa Mama Benson nigba to pe ọgọrin ọdun loke eepẹ.
Oríṣun àwòrán, Opral Benson
Ninu ọrọ rẹ, Oloye Gbadamosi ṣalaye pe ''lẹyin to ṣe igbeyawo tan pẹlu Oloye T.O.S. Benson, ti o si fi Liberia orilẹede abinibi rẹ silẹ wa si ilu Eko, o di ẹni aji tana wo laarin ọdun mẹrin ni Naijiria.''
''Lakọkọ, imura rẹ ati bi o ṣe gboge lo jẹ ko di ẹni ti gbogbo eeyan fẹran, ati ọkunrin ati obinrin lo nifẹ rẹ,'' Oloye Gbadamosi lo sọ bẹẹ.
Koda. Mama Benson ko ṣe akitiyan kankan lati di ẹni tawọn akọroyin n kọ nipa rẹ ti wọn fi bẹrẹ si ni gbe iroyin nipa orekelẹwa naa.
Bi awọn oniwe iroyin ṣe n kọ nipa Benson lawọn sọrọsọrọ lori ẹrọ amohunmaworan naa n gbe wa sori eto.
Oríṣun àwòrán, Instagram/opralbenson
Opral Benson pe ọdun marunlelọgọrin laipẹ yii, ṣugbọn ko tiẹ da bi ẹni to ti pe ọdun marunlelọgọrin loke eepẹ.
Opral Benson gboge de bi pe o da ileeṣẹ iṣaraloge, Chic Afrique Beauty Company Ltd. silẹ.
O tun da omiran Opral Benson Beauty Training Institute silẹ lọdun 1985.
Nibo ni Opral Benson ti wa?
Wọn bi Opral Benson si idile Johnson ati Lilly Mason ni Arthington lorilẹede Liberia ni awujọ awọn ọlọrọ lati ilẹ Amẹrika ni Liberia.
Awọn baba nla rẹ wa si Liberia lati ipinlẹ South Carolina lati orilẹede Amẹrika lọdun 1869.
Ẹgbọn baba rẹ kan lobinrin, Aunty Margaret lo kọkọ sọ ọ ni Opal eyi ti itumọ rẹ jẹ goolu iyebiye oloriṣiiriṣii awọ.
Ṣugbọn oun fun ra rẹ yiorukọ naa pada si Opral nigba ti o n dagba.
Benson bẹrẹ ileewe nile iwe alakọbẹrẹ AME to wa ni Arthington ni Liberia ko to lọ si ileewe Arthington Central School ati College of West Africa fun ikleewe girama.
Oríṣun àwòrán, Opral Benson
Benson bi ọmọ akọbi rẹ nigba to wa nile iwe girama fun ọkan lara awọn olukọ rẹ, John Bilson nigba naa.
Lẹyin to bimọ tan ni wọn fun un ni eto ẹkọ ọfẹ eyi to mu lọ kawe sii nile ẹkọ Morris Brown College.
Benson ṣiṣẹ gẹgẹ bi oludari eto nipa ọrọ awọn akẹkọọ ni ileewe giga fasiti ilu Eko, UNILAG lọdun 1973 ti Oba Eko fi joye kan naa.
Wọn tun yan an sipo gẹgẹ bi ọkan lara ọmọ igbimọ ajọ agunbanirọ, National Youth Service Corps.
O tun wa ninu igbimọ Nigerian Olympic Committee lọdun 1982.
Oyo palliatives stealing: Èèyàn mẹ́ta dèrò iléẹjọ́ lórí ẹ̀sùn jíjí ẹrù palíétìfù covid-19 ìpínlẹ̀ Oyo tà
Oríṣun àwòrán, Facebook/Seyi Makinde
Awọn oṣiṣẹ ijọba ipinlẹ Oyo mẹta ti dero ileẹjọ lori ẹsun pe wọn ji ohun elo iranwọ fun araalu lori coronavirus ta.
Agbẹnusọ fun ileeṣẹ ọlọpaa ipinlẹ Oyo, SP Olugbenga Fadeyi, lo fidi ọrọ yii mulẹ fun BBC Yoruba.
Awakọ pẹlu ipinlẹ Oyo, Ọgbẹni Adebiyi Azeez, Ọgbẹni Sunday Akinleye ati Kafayat Babalola ni wọn fẹsun kan pe wọn gbimọ pọ ta ogoji baagi ṣuga ninu ẹru palietifu covid-19 ipinlẹ Oyo.
Ẹsun onikoko mẹta ole jija, igbimọpọ ati gbigba ẹru ole.
Ọgbọnjọ oṣu kejila ọdun 2020 ni wọn sọ pe awọn mẹtẹẹta gbimọ pọ da ọran yii ni ẹka ijọba to n ri si ọrọ ijọba ibilẹ ati ọrọ oye nipinlẹ Oyo.
Ileeṣẹ ọlọpaa sọ fun ileẹjọ Majisireeti to wa ni Iwo Road pe awọn eeyan yii lo ọkọ ijọba lati ko ẹru palietifu lọ ta fun ẹni to ra a.
Olupẹjọ ASP Sunday Ogunremi ṣalaye pe ẹru tawọn eeyan mẹta yii ji ta to ẹgbẹrun lọna ọgọta owo naira.
Ọgbẹni Ogunremi tun sọ wi pe irufẹ ẹru bẹẹ ko wa fun tita.
Awọn mẹtẹẹta sọ pe awọn ko jẹbi ẹsun ti wọn fi kan awọn.
Adajọ Majisireeti Ọgbẹni Taiwo Oladiran fun awọn mẹtẹẹta ni beeli lẹyin ti ẹnikọọkan wọn san ẹgbẹrun lọna ogun naira.
Adajọ Oladiran ti sun igbẹjọ si ọjọ kẹjọ oṣu keji ọdun 2021 yii.
Èèyàn kan kú, ẹni mẹ́ta farapa nínú àkàsọ̀ ìgbàlódé(lift) tó já ní Cocoa House n'Ibadan
Oríṣun àwòrán, Facebook
Ile isẹ  Odu'a  Investment Company Limited ni  nkan bi aago mọkanla owurọ oni ni awọn osisẹ to n mojuto atunse akasọ igbalode fun igbokegbodo to yanranti  lenu iṣẹ ni wahala dede ṣẹyọ ti akasọ naa si ja lọlẹ.
Ninu atẹjade ti adari igbokegbodo ile isẹ Victor Ayetoro fọwọsi lo ti salaye pe akasọ naa kuna ti ọkọ to n gbe eniyan lọ soke sodo si ja lulẹ.
O ni o ṣe ni laanu pẹ okan ninu awọn osiṣẹ to n sisẹ nibẹ ba iṣẹlẹ nla ibi naa rin.
Awọn osisẹ to  ku ninu rẹ farapa diẹ ti wọn si ti n gba itọju nile iwosan.
Oludari ile iṣẹ naa ti gbọ si iṣẹlẹ naa ti awọn asoju wọn si ti de lati mojuto iṣẹlẹ ọhun, bakan naa ni wọn ti fi ọrọ naa to ọlọpaa leti.
Atẹjade naa fi kun pe ile iṣẹ ba ẹbi oloogbe oun kẹdun  o si bẹ eedua ko fun wọn ni opre ofẹ lati bori iṣẹlẹ ajalu yii
TrumpBanned: Twitter ní ó tó gẹ́ ,o yọ Ààrẹ́ Donald Trump dànù lórí ẹ̀rọ títí láé
Oríṣun àwòrán, Reuters
Oju opo ibaranisọrọ Twitter fi gbegi dina oju opo aarẹ Amẹrika Donald Trump titi lae nitori ewu ti Trump le ṣe nipa lilo opo rẹ lati da ikọlu silẹ.
"Twitter sọ pe awọn be igbesẹ yi lẹyin tawọn ṣe ''agbeyẹwo finifin lori  awọn ọr to n jade lati oju opo rẹ iyẹn @realDonaldTrump """
Igbesẹ yi n waye lẹyin ti pupọ ninu awọn ilumọọka oju opo ibaraẹnisọrọ ti n yọ Trump ati awọn alatilẹyin rẹ kuro loju opo wọn.
Ṣaaju asiko yi lawọn oloṣelu ati ati gbajumọ lawujọ ti n lọgun lori opo Twitter pe ki wọn yọ Trump kuro nibẹ patapata.
Lọjọbọ to kọja yi ni iyawo aarẹ tẹlẹ Michelle Obama ko si Twitter pe ki wọn dẹkun bi Trump ti ṣe n hu iwakiwa lori opo naa ki wọn si yọ kuro nibẹ.
Lọjọru ni  Twitter gbegi dina oju opo aarẹ Trump fun wakati mejila lẹyin to pe awọn awọn eeyan to yabo ile aṣofin Capitol ni akikanju
Ọgọrọ awọn alatilẹyin rẹ lo yabo ile aṣofin lasiko tawọn aṣofin fẹ fontẹ lu iyansipo Biden gẹgẹ bi aarẹ tara ilu dibo yan ninu idibo aarẹ.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ikọlu towaye lọjọ yi ṣokunfa iku ọlọpa kan ati araalu mẹrin.
Lẹyin iṣẹlẹ yi niTwitter sọ pe awọn yoo yọ Trump kuro lori opo awọn titi lae to ba fi tako ilana lilo oju opo naa.
Fun anfaani ẹyin ti ẹ n beere, n ko lọ si ibi ayẹyẹ ifilọlẹ ijọba Joe Biden ati ibura rẹ gẹgẹ bi aarẹ tuntun orilẹede Amẹrika logunjọ oṣu yii.
Aarẹ ilẹ Amẹrika Donald Trump lo fọrọ yii lede lẹyin ti ẹgbẹ oṣelu alatako, Democrat n gbimọ lati yọọ nipo.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ikọlu ile igbimọ aṣofin to wa ni Capitol nibi ti awọn ololufẹ Trump ti yabo awọn aṣofin eyi ti ẹmi eeyan marun ti lọ si bayii lo ṣe okunfa igbesẹ ẹgbẹ Democrat lati beere fun iyọnipo Trump.
Ẹgbẹ oṣelu Democrat ni Trump gbọdọ kọwe fi ipo silẹ, bi bẹẹ kọọ awọn yoo kuro.
Ẹwẹ, iwe ofin ilẹ Amẹrika fun igbakeji aarẹ lagbara lati ṣe ojuṣe aarẹ ti aarẹ ko ba lanfaani lati wa nibi ifilọlẹ ijọba aarẹ tuntun.
Aarẹ Trump ko ṣai bẹnu atẹ lu iṣẹlẹ Capitol ninu fidio kan to ṣe nibi to ṣeleri pe eto igbejọba kalẹ fun Biden yoo lọ ni irọwọ-rọsẹ.
A ti fòfin de Trump lórí Facebook àti Instagram lẹ́yìn ìkọlù ilé aṣòfin ní Capitol- Zuckerberg
Oludasilẹ oju opo ayelujara Facebook ati Instagram, Mark Zuckerberg ti kede igbesẹ ileeṣẹ naa lati fofin de Aarẹ Donald Trump lori oju opo ayelujara naa.
Ọgbẹni Zuckerberg ṣalaye pe titi ti Trump yoo fi gbejọba fun Joe Biden to wọle gẹgẹ bi aarẹ tuntun orilẹede Amẹrika ni Trump ko fi ni lanfaani lati lo Facebook ati Instagram.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
O ni eleyi ko ṣẹyin rogbodiyan ti ileeṣẹ naa gbagbọ pe Trump lo ṣagbatẹru rẹ nibi tawọn ololufẹ rẹ ti yabo ile aṣofin ilẹ Amẹrika ni Capitol.
Iroyin kan tiẹ sọ pe eeyan mẹrin lo gbẹmi mi nibi iṣẹlẹ naa nigba tawọn olofẹhonuhan kọlu awọn agbofinro.
Awọn olufẹhonuhan ọhun yabo ile aṣofin lati ṣe idiwọ fawọn ọmọ ile lati fontẹ lu idibo Biden gẹgẹ bi aarẹ tuntun ilẹ Amẹrika.
Amọ pabo ni gbogbo akitiyan wọn jasi nori wọn pada fontẹ lu idibo to gbe Biden wọle, koda Igbakeji Aarẹ, Mike Pence lo ṣoju Trump nibẹ.
Zuckerberg ni awọn ti faye gba Trump lati lo facebook ati Instagram lati sọ oriṣiiriṣii ohun to wu u lati igba to ti wọle gẹgẹ bi aarẹ Amẹrika.
Ṣugbọn o ni awọn ko ni gba ki Trump maa oju opo facebook ati Instagram lati maa da rogbodiyan silẹ lọwọ akoko perete to ku fun un ti yii lo gẹgẹ bi aarẹ Amẹrika.
Àwọn aṣòfin àpapọ̀ l'Amerika fa ìrètí Donald Trump ya, wọ́n buwọ́lu Joe Biden gẹ́gẹ́ bí ààrẹ
Ileegbimọ aṣofin orilẹede Amẹrika ti buwọlu Joe Biden ati Kamala Harris gẹgẹ bi aarẹ ati igbakeji aarẹ tuntun lorilẹede Amẹrika.
Awọn aṣofin apapọ naa buwọlu awọn ibo isọri-isọri lẹyin ti ile aṣofin agba ati aṣọju da awọn aba to tako esi ibo ni ipinlẹ Pennsylvania ati Arizona nu.
Oríṣun àwòrán, Reuters
Awọn ololufẹ aarẹ to n fipo silẹ, Donald Trump ya wọ ile aṣofin apapọ naa ni ọjọru ti wọn si da eto igbọwọle esi idibo naa ru ki o to di pe awọn aṣofin pada sẹnu ijoko lati buwọlu esi idibo naa loru mọju Ọjọbọ lẹyin ti awọn agbofinro ti le awọn oluwọde naa sita.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Nibayii, aarẹ Donald Trump ti kede pe eto ayipada iṣejọba yoo waye ni irọwọ rọsẹ ni Ogunjọ oṣu kini ọdun yii.
Ninu atẹjade oju opo twitter kan ti ọgbẹni Dan Scavino, ọkan lara awọn amugbalẹgbẹ aarẹ Trump fi sita, O ni:
Bi o tilẹ jẹ wi pe n o faramọ abajade idibo yii, ti awọn ẹri to wa nilẹ  si n fihan pe bẹẹ lo ri, amọṣa eto ayipada iṣejọba yoo waye ni irọwọ rọsẹ ni Ogunjọ oṣu kini ọdun yii.
Aarẹ Trump ko lee lo oju opo Twitter ara rẹ lati fi gbe atẹjade rẹ naa sita nitori ileeṣẹ Twitter ti gbẹsẹ le oju opo rẹ, lẹyin ti o sọ awọn ọrọ ti ọpọ onwoye wo pe o ṣokunfa wahala to bẹ silẹ nileegbimọ apapọ orilẹede naa l'Ọjọru.
Oríṣun àwòrán, Reuters
"Lọjọru ni okiki kàn pe awọn alatilẹhin Aarẹ ilẹ America, Donald Trump fi agidi wọ ile aṣofin orilẹ-ede naa, Capitol Hill, ti wọn si bẹrẹ si ni pariwo ""Trump la fẹ""."
Asiko yii gan-an ni apapọ ile aṣofin mejeeji ń ṣe ijiroro papọ lati buwọlu awọn esi idibo apapọ to waye lọdun 2020, ati iyansipo Joe Biden gẹgẹ bi aarẹ tuntun.
Lasiko iwọde naa to pada di rogbodiyan, awọn ọlọpaa yinbọn obinrin kan, eeyan mẹta mii si kú nitori iṣẹlẹ pajawiri to de ba ilera wọn.
Gbogbo eyi waye lẹyin ti Aarẹ Trump sọ ọrọ kan lọjọ naa, nibi to ti kesi awọn alatilẹhin rẹ lati ya lọ si Capitol fun ifẹhonuhan.
Awọn olori orile-ede kaakiri agbaye si ti n koro oju si iṣẹlẹ naa.
Oríṣun àwòrán, Screenshot
Aarẹ orilẹ-ede Naijiria nigba kan, Goodluck Jonathan sọ pe ko tọ ọ ki erongba tabi afojusun ẹnikẹni nidi oṣelu mu itajẹ silẹ dani, botilẹjẹ pe ko darukọ America ninu ọrọ rẹ.
"O ni ""o san lati fìdírẹmi , kí alaafia si jọba, ju ki eeyan o de ipo àṣẹ lọna to mu ẹ̀mí eeyan lọ."
Oríṣun àwòrán, Screenshot
"Olootu ijọba orilẹ-ede Canada, Justin Trudeau ṣọ pe"" iporuru ọkan ati ibanujẹ ni iṣẹlẹ to waye ni America, to mule ti wa, jẹ fun awọn eeyan ni orilẹ-ede mi"
Iwa ipanle ko le bori nkan ti awọn eniyan n fẹ lailai. Ijọba awaarawa gbọdọ fẹṣẹ mulẹ, bẹẹni yoo si ri.
Oríṣun àwòrán, Screenshot
Olootu ijọba orilẹ-ede United Kingdom, Boris Johnson sọ pe nkan itiju ni iṣẹlẹ to waye ni America jẹ́, nitori pe ijọba awaarawa ni orilẹ-ede naa fẹ jakejado agbaye.
 O se pataki bayii pe ki gbigbe ijọba kalẹ lọ ni alaafia.
Oríṣun àwòrán, Screenshot
Aarẹ ajọ ilé Yuroopu, Ursula von der Leyen sọ pe gbigbe agbara kalẹ pẹlu alaafia lo ṣe pataki julọ.
Mo ni igbagbọ ninu okun ti ilẹ America ati isejọba awaarawa rẹ ni... Joe Biden lo bori ninu idibo naa.
Oríṣun àwòrán, Screenshot
Ọga Agba ajọ NATO, Jens Stoltenberg sọ pe ki wọn o bọ̀wọ̀ fun esi idibo aarẹ ilẹ America.
Oríṣun àwòrán, Screenshot
Nicola Sturgeon sọ lori ayelujara Twitter rẹ pe ibẹru nla ni nkan to ṣẹlẹ ni America jẹ, ati pe ki itiju ba awọn to pilẹ rogbodiyan naa.
Oríṣun àwòrán, Screenshot
Aarẹ igbimọ olusakoso nilẹ Yuroopu, Charles Michel sọ pe iyalẹnu nla ni iṣẹlẹ to waye ni Amerika jẹ.
O fi kun ọrọ rẹ pe oun jẹri ilẹ America pe yoo ri daju pe agbara de ọwọ Biden lai mu wahala dani.
Oríṣun àwòrán, Screenshot
Olootu ijọba orilẹ-ede India, Narendra Modi naa kọ ọrọ sori ayelujara Twitter pe o jẹ ibanujẹ fun oun nigba ti oun ri iroyin nipa rogbodiyan to waye ni Washington.
O si gba wọn nimọran pe ki wọn o jẹ gbigbe ijọba silẹ pẹlu alaafia tẹsiwaju.
Oríṣun àwòrán, Screenshot
Aarẹ orilẹ-ede Chile, Sebastian Pinera bu ẹnu ẹtẹ lu rogbodiyan to waye ni Capitol Hill, ati pe orilẹ-ede oun kọ igbesẹ to fẹ ẹ yí isejọba awaarawa pada ni America.
Ilẹ America ni orilẹ-ede Chile gbarale lati ẹsẹ ofin mulẹ.
Oríṣun àwòrán, Screenshot
Olootu ijọba orilẹ-ede Fiji to dari iditẹgbajọba lọdun 2006 naa ti faraya lori rogbodiyan to waye ni Capitol Hill.
"O ni ""iwa ipanle to waye ni Washington lonii jẹ ìwọ̀sí si ijọba awaarawa kaakiri agbaye."
 Isejọba awaarawa tootọ jẹ nkan alumọọni ti orilẹ-ede kankan ko gbọdọ fi ṣeré. O dawaloju pe ilẹ America yoo fi opin si iṣẹlẹ buruku yii laipẹ. 
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Obinrin kan ti jade laye lẹyin ti wọn yinbọn fun un ni ọrun lasiko rogbodiyan to waye ni ileegbimọ aṣofin orilẹede Amẹrika lọjọru.
Awọn iroyin abẹle nibẹ kọkọ fihan pe awọn oṣiṣẹ adoola ẹmi gbiyanju lati doola ẹmi arabinrin naa ki awọn ọlọpaa to wa fi idi rẹ mulẹ lẹyin wakati diẹ pe arabinrin naa ti ku nipasẹ ọgbẹ ibọn naa.
Bi o tilẹ jẹ wi pe wọn ko darukọ rẹ, awọn ọlọpaa ni araalu ni kii ṣe ọlọpaa tabi aṣofin.
"Awọn aṣofin apapọ orilẹede Amẹrika n joko lati buwọlu esi idibo aarẹ ọdun 2020 ninu eyi ti Joe Biden ti wọle gẹgẹ bi aarẹ, amọṣa awọn oluwọde to jẹ ololufẹ aarẹ Trump to n palẹmọ ati fipo silẹ ya bo gbagede ile aṣofin Capitol ti wọn si bẹrẹ si ni pariwo ""Trump la fẹ"" ki wọn to fi ipa ja wọ ile naa."
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ninu ọrọ to ba awọn eeyan orilẹ€de naa sọ, aarẹ ti wọn ṣẹṣẹ dibo yan lorilẹede Amẹrika, Joe Biden niọrọ naa kuro ni iwọde o ti di igbimọ-ditẹ-gba ijọba.
O si ke si aarẹ Trump lati mu ẹjẹ to ṣe lati daabo bo iwe ofin orilẹede naa ṣẹ ni[pa fifopin si ikọlu naa.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
"Lẹyin ọpọlọpọ wakati ti awọn eeyan ti n ke sii pe ko pẹtu si awọn ololufẹ rẹ ti wọn n ṣe iwọde naa, Aarẹ Trump gbe fidio kan sita  lẹyin iṣẹju diẹ ti Joe Biden ke si, nibẹ lo si ti ke sawọn oluwọde naa pe ki wọn ""pada si ile wọn."""
"Trump ṣalaye pe ""Mo mọ pe o n dun yin lọkan"" ti o si tun ṣi n pariwo pe ""wọn ji ibo naa ni"""
Amọṣa ọpọ onwoye titi kan awọn ọmọ ẹgbẹ oṣelu rẹ ni ile aṣofin apapọ orilẹede naa atawọn alajọṣepọ rẹ gbogbo ni wọn ti bu ẹnu atẹ lu ihuwasi rẹ paapaa, ọrọ to sọ li owurọ ọjọru eyi ti ọpọ woye pe o ṣokunfa iwọde naa ati ihuwasi aarẹ Trump ni ọpọlọpọ wakati ti iṣẹlẹ naa fi waye.
Orisabunmi: Ààrẹ ẹgbẹ́ òṣèré TAMPAN, Baba Latin sọ̀rọ̀ lórí ìgbà tí ìsìnkú Orisabunmi yóò wáyé
Oríṣun àwòrán, Gboah.com
Nigba wo ni wọn yoo sin gbajumọ eekan oṣere tiata ati sinima Yoruba ni, Oriṣabunmi?
Eyi gan an ni ibeere to n jade lẹnu ọpọ awọn ololufẹ oloogbe naa ti wọn fẹ bu ọla ikẹyin fun.
Ọpọ awọn ololufẹ ere tiata ati sinima Yoruba lo ji si iyalẹnu ati ibanujẹ ọkan l'Ọjọru nigba ti iroyin iku oloogbe naa jade si igboro.
Iroyin sọ pe ni ọjọ Iṣẹgun ni arabinrin Fọlakẹ Arẹmu ti ọpọ mọ si Oriṣabunmi jade laye.
Gẹgẹ bi iwe ibanikẹdun kan ti awọn iwe iroyin abẹle ṣalaye pe aarẹ ẹgbẹ awọn oṣere tiata Yoruba ti a mọ si TAMPAN, Bọlaji Amuṣa ti ọpọ mọ si Baba Latin fi ọwọ si, ko tii si ẹni mọ igba ti wọn yoo sin oku Oriṣabinrin.
Ikede eto isinku rẹ yoo waye laipẹ
Baba Latin ni aloyinlohun ni Oriṣabunmi to gbo lede pẹlu ohun to dun leti.
Ọmọ bibi Ilu Olla ni ipinlẹ Kwara si ni Oriṣabunmi jẹ.
NIN Registration: Mínísítà ní bó yá n'ìjọba kò ní dá ìforúkọsílẹ NIN dúró tórí ewu Covid-19
Oríṣun àwòrán, NIMC
Minisita keji fun eto ilera ni Naijiria, Dokita Olorunnimbe Mamora ti sọ pe o ṣeeṣe ki ijọba so iforukọsilẹ kaadi idanimọ  NIN rọ nitori ewu coronavirus.O ni ewu kiko coronavirus wa ninu bi ọpọ eeyan ṣe n to si ibudo iforukọsilẹ kaadi kaakiri Naijiria.Dokita Mamora rọ ajọ NIMC lati ronu ọna miiran ti wọn fi le maa ṣe iforukọsilẹ fawọn eeyan lọna ti ero ko fi ni maa pọ to bi wọn ṣe n pọ bayii.
"Mamora to jẹ ọkan lara ọmọ igbimọ amuṣẹya PTF to n ri si ati dẹkun coronavirus ni Naijiria ṣalaye pe ojuṣe ijọba ni lati daabo bo ọmọ Naijiria ni gbogbo igba.""Inu mi ko dun si bi ero ṣe n pọ lawọn ibudo iforukọsilẹ fun NIN, o dabi ọna ti arun le gba maa ran bi ina inu ọyẹ, eleyi ti a ko fẹ ko ṣẹlẹ,"" Dokita Mamora lo woye bẹẹ.Amọ, o fikun ọrọ rẹ pe ileeṣẹ ijọba to n ri si eto ibaraẹnisọrọ to n ṣagbatẹru eto kaadi idanimọ NIN naa ti n ro ọna mii ti wọn le gbe ọrọ naa gba ti ko fi ni da ajakalẹ arun silẹ.Ijọba apapọ lo paṣẹ fawọn ileeṣẹ ẹrọ ibaraẹnisọrọ lati ja awọn onibara wọn ti ko ba ni kaadi idanimọ NIN kuro loju opo wọn.Ọjọ kẹsan an oṣu keji ọdun 2021 yii ni ijọba fawọn eeyan da lati so kaadi idanimọ NIN wọn pọ mọ nọmba ẹrọ ibanisọrọ wọn."
NIMC Mobile App: Wo bí o ṣe lè gba nọ́mbà NIN rẹ tàbí so ó pọ̀ mọ nọ́mbà fóònù rẹ lórí App tí NIMC ṣẹ̀ṣẹ̀ ṣe
Oríṣun àwòrán, Nimc
Awọn ọmọ Naijiria ti le lo ẹ̀rọ ibanisọrọ alagbeka wọn bayii lati gba nọ́mbà idanimọ NIN, lai ṣẹṣẹ ma a to.
Ajọ to n mojuto eto naa, National Identity Management Commission, NIMC ti ṣe 'App' kan ti yoo fun wọn ni anfaani lati gba kaadi idanimọ NIN, tabi fi rọpo kaadi naa.
Wo ilana lati lo 'App' naa
Sugbọn ṣa, ajọ naa tun ti kede pe o nilo lati san owo fun àwọn ayipada kan nipa akọsilẹ rẹ lori kaadi NIN, botilẹjẹ pe ọ̀fẹ́ ni gbigba nọ́mbà NIN.
Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi
Oludari kan ninu ajọ naa, Funmi Opesanwo sọ pe oriṣiriṣi eto ayipada tabi atunse ni ajọ naa ma n ṣe, sugbọn kii ṣe ọ̀fẹ́.
Lati ṣe atunse si akọsilẹ nipa ọjọ ìbí rẹ, ẹgbẹrun mẹẹdogun Naira ni wa a san.
Lati paarọ adirẹsi rẹ, ẹẹdẹgbẹta Naira ni.
To ba jẹ pe o fẹ ẹ gba kaadi miran ni, ẹgbẹrun márùn-ún lo ba de.
Lagos Tanker Explosion:Ọkọ̀ agbépo gbiná l'Eko
Orisabunmi : Afeez Ọwọ ṣàlàyé ìdí tó fí padà yọ àwòrán Orisabunmi kúrò lójú òpó rẹ̀
Afeez Ọwọ ṣàlàyé ìdí tó fí padà yọ àwòrán Orisabunmi kúrò lójú òpó rẹ̀
Ni idahun si ariwo tawọn eeyan n pa lori oju opo rẹ, gbajugbaja oṣere sinima Yoruba, Afeez Ọwọ ti yọ aworan ikede oku Orisabunmi kuro loju opo Instagram rẹ.
Igbesẹ yi to fidi rẹ mulẹ fun ileeṣẹ BBC Yoruba lo sọ pe oun ṣe gbe lẹyin ti oun ri pe awọn eeyan faraya lori aworan naa.
Afeez Ọwọ tun bọ ṣalaye pe oun naa mu aworan yi loju opo mii ni ti awọn oṣere miran naa si tun ti mu lọdọ oun.
O ni o jẹ iyalẹnu fun oun pe awọn eeyan bẹrẹ si ni gba ọrọ naa bi ẹni gba igba ọti lai beere ibi toun ti ri aworan naa.
''Ṣebi ẹyin naa ni BBC ti fi mi kọ akọle lai wadi ọrọ lọwọ mi?Ta lẹni to ni oun sọ fun mi pe kin yọ aworan naa? Nigba wo lo pe mi?''
BBC Yoruba wa salaye fun pe awọn kan si lori ago rẹ lati fesi si ọrọ naa ṣugbọn o ti pa foonu rẹ nigba taa fi pe e.
Yatọ si eyi, Ọwọ ti yọ aworan naa kuro loju opo rẹ ti ko si ni rọrun lati ri ibi tawọn eeyan ti ṣalaye fun pe ki o yọ kuro.
Bakan naa, Afeez Ọwọ ko ṣọ pato ibi to ti mu aworan yi bẹẹ si ni ko tọrọ aforijin pe oun lo aworan naa eyi to ṣafihan Orisabunmi ninu posi botilẹjẹ wi pe ọtọ lẹni to lo aworan rẹ.
Oríṣun àwòrán, AFEEZ OWO/ORISABUNMI
'Òkú Orisabunmi' dá wàhálà sí 'Afeez Ọwọ' lọ́rùn
Mọlẹbi arabinrin kan to ku ni Amẹrika ti Afeez Owo fi aworan rẹ pe ti Orisabunmi ti kesi osere tiata naa ko yọ aworan naa kuro loju opo rẹ.
Afeez Ọwọ fi aworan yi sita soju opo rẹ nipa iku Oriṣabunmi eyi to fi n fa  awuyewuye debi pe awọn  kan to fi mọ mọlẹbi obinrin to lo aworan rẹ ti n bẹnu atẹ lu.
Lasiko ti awọn eeyan n ṣe idaro iku gbajugbaja oṣerebinrin ere tiata Yoruba nii, Orisabunmi,orisirisi ọna lawọn eeyan fi n kẹdun iku rẹ.
Ṣugbọn ibanikẹdun eleyi ti Afeez Owo ṣe yi ti mu ibinu wa ati ọrọ kobakungbe lati ọdọ awọn eeyan.
Aworan taa n wi yi ṣafihan Orisabunmi nigba to wa laye ati aworan ẹnikan to wa ninu posi ti kii ṣe Orisabunmi.
Mọlẹbi arabinrin ti o wa ninu posi yi ti BBC Yoruba ba sọrọ, Olorunmodimu Nike Ebunoluwapo jẹ olutaja lori opo Instagram @ike_store_epitome_of_fashion.
Ninu ifọrọwanilẹnuwo o sọ fun BBC Yoruba pe ohun ti kesi Afeez Owo lati yọ aworan mọlẹbi oun kuro loju opo rẹ ṣugbọn o keti ikun si ipe yi.
Afeez Ọwọ kọ si oju opo rẹ ni Instagram lori aworan yi pe ki eledua tẹ Oriṣabunmi ṣafẹfẹ rere.
Oríṣun àwòrán, AFEEZ OWO
Lootọ lo jọ pe o n ba awọn eeyan kẹdun iku Orisabunmi ṣugbọn aworan to fi gbe idaro rẹ lẹyin gaan kii ṣe ti Oriṣabunmi.
Pupọ awọn to wa si oju opo rẹ  mi ni iwa aibọwọ fun ẹni to lọ ni Afeez Owo hu pẹlu aworan yi.
BBC Yoruba gbiyanju lati pe Afeez Owo lori ẹrọ alagbeka rẹ ṣugbọn nọmba rẹ ko lọ.
Titi di igba ta fi n ṣe akojọpọ iroyin yi, Afeez Owo ko ti yọ aworan yi kuro loju opo rẹ.
Lagos Tanker Explosion:Ọkọ̀ agbépo míràn tún gbiná l‘Eko
Ọkọ agbepo kan ti gbina ni agbegbe Oshodi ni ilu Eko.
Aworan ati fọnran fidio iṣẹlẹ naa to wa loju opo Twitter ṣafihan pe ina nla n jo nitori ọkọ agbepo naa to dẹgbẹ lulẹ.
Iṣẹlẹ yi si ti mu ki sunkẹrẹ fakẹrẹ ọkọ wa ni ọna mejeeji to wọ Oshodi iyẹn ibudokọ Toyota ati oju ọna marose Apapa.
Titi di igba ta fi n ko iroyin yi jọ awọn oṣiṣẹ panapana ati ajọ iṣẹlẹ pajawiri n gbiyanju lati pa ina naa.
Atẹjade lati ọdọ ọga agba LASEMA Dokita Damilola Oke-Osanyintolu ni oṣiṣ awọn ati oṣiṣẹ panapana ti dkun ina naa.
O ni awọn ṣi n ṣiṣẹ lati ri pe wọn gbe ajoku ọkọ agbepo naa kuro ni oju ọna.
Ko ti si ikede kankan pe ẹnikẹni ba iṣẹlẹ ina yi lọ.
Coronavirus: Ibidapo Obe, Femi Odekunle àti Duro Ajeyailemi wà lára àwọn tí Covid-19 pa
Ẹni to ba leti, ko gbọ ohun ti ẹmi n sọ fun ijọ ni ọrọ ọwọja arun Coronavirus to n gbalẹ kan bii ọwara ojo bayii.
Lati osu keji ọdun 2020 ti arun naa ti ran de orilẹede Naijiria, ọpọ ẹmi lo ti ba rin eyi ti ko yọ olowo abi talaka silẹ, koda ati ọkunrin ati obinrin ni arun naa n da ẹmi wọn legbodo.
Bakan naa, ọpọ awọn ilumọọka ọmọ ilẹ yii ni arun naa ti ran sọrun lairotẹlẹ, lara wọn si ni Abba Kyari, Abiola Ajimobi, Buruji Kashamu, Tunde Oshinowo ati bẹẹ bẹẹ lọ.
Nibayii ti isi keji ọwọja arun naa tun n gbilẹ siwaju lọdun 2021, ọpọ ẹmi lo tun ti ba rin, to fi mọ awọn ọjọgbọn nile ẹkọ fasiti, marun lara wọn si ree.
Oríṣun àwòrán, @Presidency
Ọjọ Isẹgun, ọjọ Kọkandinlọgbọn osu Kejila ọdun 2020 ni Coronavirus mu ẹmi gbajumọ olukọ fasiti yii lọ lẹni ọdun mẹtadinlọgọrin.
Ibudo iyasọtọ fun itọju awọn alarun Covid-19 to wa nilu Abuja ni Odekunle ju awa silẹ si, lasiko ijagudu pẹlu arun Coronavirus, eyi to mu ko maa gba ẹrọ to n fun ni ni afẹfẹ sara.
Onimọ to pegede nipa ihuwasi ọdaran ni Odekunle lorilẹede Naijiria, to sisẹ olukọ fun ọpọlọpọ ọdun ko to fẹyinti.
Titi to fi di ọjọ iku rẹ, Ọjọgbọn Olufẹmi Odekunle jẹ ọmọ igbimọ oludamọran fun aarẹ Buhari lori iwa ajẹbanu.
Oríṣun àwòrán, Unilag
Oye Ibidapo Obe jade laye lọjọ Kẹta osu Kinni ọdun 2021 lasiko to wọja ija pẹlu arun Coronavirus.
Obe, tii se ọmọ bibi ilu Ile Ifẹ ni baba isalẹ ati alaga igbimọ alakoso fun ileeẹkọ fasiti ẹkọsẹ ọwọ akọkọ ni Naijiria to wa nilu Ibadan, eyi to di mu titi di ọjọ iku rẹ.
Bakan naa ni oloogbe yii ti jẹ ọga agba fun fasiti Eko nigba kan ri, laarin ọdun 2000 si 2007, ko to fẹyin ti.
Ọdun mọkandinlaadọrin ni Ibidapo Obe, tii se onimọ nipa imọ ẹrọ,  lo loke eepẹ, ko to dagbere faye.
Iroyin kan ti wọn n pin kiri lori ayelujara ni ko pẹ ti Obe de lati ibi ayẹyẹ kan lo wolẹ aisan, to si n fi ami arun Coronavirus han, ki wsn to gbe lọ sile iwosan.
Amọ aisan lo se wo, ko si ẹni  to ri ti ọlọjọ se.
Oríṣun àwòrán, Unilag
Duro Ayeyailemi ni oludari agba tẹlẹ fun ẹka imọ ẹkọ ni fasiti Eko.
Lẹyin ọjọ kẹta ti wọn kede iku Ọjọgbọn Ibidapo Obe, naa ni wọn kede iku Ajeyailemi pe arun Coronavirus lo da ẹmi rẹ legbodo laipe ọjọ.
Iroyin kan ni ayẹyẹ kan naa ni oloogbe yii ati Ibidapo Obe dijọ lọ, to si see se pe ibẹ ni wọn ti ko arun Coronavirus to n pa ọpọ eeyan.
Ibudo iyasọtọ fun itọju awọn alarun Coronavirus fun fasiti Luth ni Idi Araba nilu Eko, ni ọjọgbọn naa ku si .
Ẹni aadọrin ọdun ni ọjọgbọn Ajeyailemi ko to dagbere faye, to si kaye nilẹ Naijiria ati loke okun.
Oluwo Jogbodo Orunmila: Ẹsẹ odù Ifa ló fi ṣúre fún ọmọ Nàíjíríà ní àyájọ́ ọdún tuntun
Awọn ọjọgbọn mẹta miran la tun gbọ pe wọn jade laye amọ ti a ko le fi idi ootọ ọrọ nipa iku wọn mulẹ.
Ọjọgbọn Kayode Adesogan, Ọjọgbọn obinrin abiona ati Ọjọgbọn Folabi Olumide.
Awọn iroyin kan ti ko fẹsẹ mulẹ salaye pe arun Coronavirus lo mu ẹmi awọn ọjọgbọn mẹtẹẹta ọhun lọ.
A wa n gbadura pe ki Ọba oke tẹ awọn alaisi yii si afẹfẹ rere.
Oríṣun àwòrán, Abdulrasheed Uba Sharada
Saaju la ti mu iroyin wa fun yin pe oludije fun ipo aarẹ fẹgbẹ oṣelu PDP, Alhaji Atiku Abubakar ti gba abẹrẹ ajẹsara Covid-19 ti ileeṣẹ apoogun Pfizer ṣe.
Niluu Dubai ni orilẹede United Arab Emirates ni Alhaji Abubakar ti gba abẹrẹ ọhun.
Oluranlọwọ Atiku lori ọrọ iroyin, Ọgbẹni Paul Ibe lo fidi ọrọ yii mulẹ fun BBC.
Agbẹnusọ fun Atiku ṣalaye pe oludije ipo aarẹ fẹgbẹ oṣelu PDP gba abẹrẹ ọhun lati jẹ awokọṣe fawọn ọmọ Naijiria.
O ni ohun ti Atiku n sọ fawọn ọmọ Naijiria ni pe ki wọn tu jade ló gba abẹrẹ naa ti ijọba ba ti pese abẹrẹ naa ni Naijiria.
Ọwọja ẹlẹẹkeji arun coronavirus naa n le si lẹnu ọjọ mẹta yii papaa julọ nipinlẹ Eko.
Electric tarrif hike: Ìjọba àpapọ̀ jáwọ́ lórí àfinkún owó iná mọ̀nàmọ́ná fún ìgbà díẹ̀
Oríṣun àwòrán, twitter/Ministry of power nigeria
Ijọba apapọ ti jaws lori eto afikun owo ina mọnamọna ti ajọ to n ṣakoso ẹka naa kede lọjọ diẹ sẹyin.
Ijọba apapọ ke si ajọ NERC lati sinmi lori afikun owo ina naa titi di igba ti igbimọ tẹẹkoto ti wọn gbe kalẹ lati ṣe ayẹwo rẹ yoo fi pari iṣẹ wọn lopin oṣu yii.
Minisita fun ọrọ ina mọnamọna, Sale Mamman ṣalaye ninu atẹjade kan to fi sita loju opo Twitter rẹ pe, yoo dara ki wọn fi ikuluku pẹlu awọn ẹgbẹ oṣiṣẹ naa ki wọn lee fi ẹnu ọrọ jona si ibi kan naa.
Ni ọjọ diẹ sẹyin ni ajọ to n ṣakoso ẹka ipese ina mọnamọna lorilẹede Naijiria, NERC kede pe afikun ti de ba owo ori ina mọnamọna lati naira meji lori oṣuwọn ina mọnamọna kan si naira mẹrin.
Iwo ritual killining: Monsuru ní ọtí lòun fi owó mu lẹ́yìn tí òun bá ta ẹ̀yà ara àwọn tí òun bá pa
Oríṣun àwòrán, dailypost nigeria
Awọn agba bọ, wọn ni bi a ba n rin irinajo ki a wo ẹni ti a n ba lọ, nitori ati ile ati ode ni apani wa.
Iroyin nipa Monsuru Tajudeen ẹni ọgbọn ọdun kan ti ọwọ ọlọpaa ni ipinlẹ Ọṣun tẹ lori ẹsun pe o n pa eniyan ti o si n ta ẹya ara wọn fawọn to n fi eniyan ṣetutu ọla.
Ilu Iwo lọwọ awọn agbofinro ti ba Monsuru ti o si jẹwọ pe eeyan meji ni oun ti pa. O ni ọrẹbinrin oun ti orukọ rẹ njẹ gan wa lara awọn eeyan ti oun ti pa.
Bakan naa, ọkan lara awọn ọrẹ, Hamzat Akeem ẹni ọdun marundinlọgbọn to jẹwọ pe oun loun tan Gafari ọkan lara awọn ọrẹ oun lọ si ile Mọnsuru nibi ti wọn ti gba ẹmi rẹ.
O ni ẹgbẹrun marun naira ni wọn fun oun ninu owo naa.
Awayewaṣere Yusuf ti o n ra awọn ori eeyan lọwọ Mọnsuru naa jẹwọ pe ẹgbẹrun lsna ogun naira ni oun maa n san fun ori kọọkan ti oun ba ra lọwọ mọnsuru lati fi ṣe etutu ọla.
Bakan naa ni Lukman Garuba, ẹni ọdun mọkanlelogbọn ti wọn mu pẹlu rẹ naa ṣalaye pe ẹya ara eeyan ni oun maa n ra lọwọ Mọnsuru ati pe ẹgbẹrun meji naira loun maa n san fun un.
"Nigba to n ba awọn oniroyin sọrọ, Mọnsuru ni: ""Ohun ti a ma n ṣe nipe a ma n fun awọn to ba ko si wa lọwọ lọrun pa ni, lẹyin ti wọn ba ti ni igbagbọ ninu wa tan."
"Nigba miran, a ti ba wọn lopo tan ni alẹ, ki a to wa fun wọn ni ọrun pa ki ilẹ to mọ, ti a o si ge ara wọn si wẹlẹwẹlẹ lati lọ ta wọn."""
Orisabunmi: Àbúrò èèkàn òṣèré Orisabunmi tó jáde láyé ní ọjọ́ méjì péré ló lò níléèwòsàn kí ikú tó dé
Oríṣun àwòrán, Tundeolayusuf/instagram
Awọn iroyin tuntun tun jade nipa iku oloogbe Fọlakẹ Arẹmu ti ọpọ mọ si Oriṣabunmi, eekan oṣere tiata ati sinima lorilẹede Naijiria to jade laye ni ọjs diẹ sẹyin.
Ọjọ meji ni aisan to ṣe Oriṣabunmi fi ṣe, gẹgẹ bi aburo rẹ, iyaafin Toyin Akinoso ṣe ṣalaye fun ileeṣẹ iroyin abẹle kan.
Ni kete ti aisan naa bẹrẹ lo si lọ si ileewosan nibi to dakẹ si.
Iyaafin Akinoso to jẹ aburo oloogbe naa ni awọn jumọ ṣere lati ọjọ kejila oṣu kejila ọdun 2020 titi di ọjọ kini ọdun 2021.
O ni iba lasan lo ṣe Oloogbe Oriṣabunmi to fi lọ si ileewosan nibi ti o ti jade laye.
O niiku to ṣe gbogbo ẹbi ni kayefi ni iku Oriṣabunmi.
Ohun ti inu mi kan dun si ni pe bi o ṣe lo ile aye rẹ.
Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi
O ni eeyan nla ni Ọlọrun gba lọwọ ẹbi naa ati pe Ọlọrun nikan lo lee di aye to fi silẹ.
O ni ọrọ to sọ fun oun ni ọjọ kini ọdun 2021 ni pe ki awọn maa gba adura.
O ni o tẹẹ mọ oun leti pe ki awọn maa dupẹ ni nitori pe wọn ko duro ibanujẹ lori ẹnikẹni ninu ẹbi naa laimọ pe yoo jade laye laipẹ.
Elon Musk: Owó rẹ jù àpapọ̀ owó Dangote àti àwọn èèyàn 19 míràn tó lówó jùlọ ní Áfíríkà
Oríṣun àwòrán, @Musk
Ko si ani ani mọ,nilẹ toni to mọ yi, Elon Musk lẹni to lowo julọ lagbaye.
Owo rẹ gẹgẹ bi wọn ti ṣe ṣagbekalẹ rẹ ti re kọja biliọnu marundinlaadọwa dọla.
Ipo kini to ṣe pe Jeff Bezos to ni Amazon wa nibẹ tẹlẹ ti di ti Musk bayi iyẹn ẹni  to ni ileeṣẹ ọkọ ẹlẹktriki, Tesla.
Yatọ si pe Musk jẹ olokoowo ọmọ ilẹ South Afrika, to si tun niiwe igbelu Canada ati Amẹrika, ki lawọn nkan miran to ṣe wi pe awọn eeyan ko mọ nipa rẹ?
Ni meni meji, awọn ohun to yẹ ki ẹ mọ nipa rẹ ree:
Aliko Dangote Naijiria to jẹ ẹni to lowo julọ ni Afrika ati awọn olowo ẹgbẹ rẹ mi ko sunmọ owo Elon Musk.
Lọdun 2020, iwe igbadegba Forbes to maa n gbe orukọ awọn olowo jade sọ pe apapọ owo awọn eeyan ogun to lowo julọ ni Afrika lọdun 2020 ko ju biliọnu mẹtalelaadọrin le diẹ dọla lọ.
Oríṣun àwòrán, Google
Ìwádìì Oxfam fihàn pé owó àwọn olówó yìí tó 29.9 billion US dola, eléyìí tó ká owó ìṣúná Naijiria fún ọdún 2017.
Owo Dangote to lewaju ninu wọn jẹ biliọnu mẹwa le diẹ dọla ti Nassef Sawiris ọmọ Egypt to tẹle si wa ni biliọnu mẹjọ dọla.
Oríṣun àwòrán, Google
Àwọn olówó Naijiria 5 tí owó wọn ju owó ìsúná Naijiria lọ!
Mike Adenuga to ni ileeṣẹ Globacom lo wa ni ipo kẹta pẹlu biliọnu meje dọla le diẹ.
Oju opo Twitter gbanajẹ ni ọdun 2020 lẹyin ti Elon Musk kede orukọ ọmọ ti oun ati akọrin Grimes ṣẹṣẹ bi.
Ọpọ eeyan lo ro wi pe Elon Musk n ṣwada ni nigba to sọ pe awọn yoo maa pe ọmọ naa ni X Æ A-12.
Oríṣun àwòrán, @Musk
Eyi si mu ki ọpọ maa beere pe ki ni itunmọ orukọ yi ati pe bawo ni wọn yoo ṣe maa pe.
Iya ọmọ naa pada ṣalaye itunmọ orukọ naa  loju opo rẹ ni Twitter.
Amọ ṣa ni ti yin tootọ awa gaan ko mọ bi a o ti ṣe pe orukọ naa.
Lara awọn to sọrọ ti ko mu ọgbọn wa nipa Covid-19 ni Elon Musk wa.
Ọkan lara ohun to sọ ni pe nigba ti yoo ba fi di oṣu Kẹrin ọdun 2020, ko ni fẹ si eeyan ti yoo ni arun naa nilẹ Amẹrika.
Oríṣun àwòrán, @Musk
Yatọ si eyi, ọpọ igba lo ti kọ si oju opo Twitter rẹ pe ki wọn ma ṣe iṣede tabi konileogbele nitori Covid-19.
Ninu ọrọ rẹ, fifi ofin de awọn eeyan ki wọn ma jade dabi ki eeyan maa ṣe ijọba amfipamuni.
Igba akọkọ ree ti Elon Musk yoo pa owo to to biliọnu dọla.
Saaju ki o to ta Pay Pal lo ti fi owo to pa nidi tita ileeṣẹ Zip2 lati fi da ileeṣẹ miran X.com silẹ.
X.com yi lo gbooro to fi wa da PayPal silẹ.
Nibi ti owo Elon Musk pọ de ti a ba ni ka fi kọ afara 2nd Niger Bridge ti ijọba Naijirira ti n kọ lati ọjọ yi, afara iru rẹ lọna 288.6 ni a o ri kọ.
Idi ni pe ti a ba se isiro iye owo afara naa tii ṣe 653 miliọnu dọla ta yọ kuro ninu owo Elon Musk tii ṣe 188.5 biliọnu dọla afara to fẹ ẹ to ọrinlenigba le mẹsan la o kọ ninu rẹ.
Orisabunmi: Ìkúnlẹ̀ Abiyamọ ò! Lẹyìn ikú ẹ̀gbọ́n Orisabunmi, àbúrò rẹ̀ tún jáde láyé
Oríṣun àwòrán, thenewstrack.com.ng
Awọn mọlẹbi oserebinrin tiata Naijiria, Orisabunmi, ti tun wa ninu ẹkun ohun ibanujẹ ni kopẹ-kopẹ ti wọn padanu ẹgbọn Orisabunmi, iyẹn alagba Steve Onisola.
Lọsan ọjọ Abamẹta ni arabinrin Bukola Janet Ademola, to jẹ aburo abikẹyin fun iya Orisabunmi naa jade laye.
BBC Yoruba fidi ọrọ yi mulẹ lati ẹnu ọkan lara awọn to sunmọ arabinrin Bukola Janet, wolii ajihinrere Obaloluwa Hephzibah.
Ninu alaye rẹ, Wolii Hephzibah ni ọdọ arabinrin Janet ni oun gbe dagba.
Oríṣun àwòrán, Facebook/Hephzibah
Koda  o sọ pe ọpọ eeyan lo maa n pe oun ni akọbi Janet Bukola.
Hephzibah ni iku arabinrin Bukola Janet jẹ nkan ti o fọwọ kan ni lẹmi, to si ba ni lojiji pẹlu.
''Wọn ku lọsan ana. Ẹni to si ku lana yẹn lo tọ emi dagba. Ọdọ wọn ni mo gbe dagba.
"Aburo Orisabunmi ni wọn jẹ. Awọn ni abikẹyin mama to bi Orisabunmi."""
Oríṣun àwòrán, Facebook/Janet Bukola
Nigba ti BBC Yoruba beere lọwọ Hephzibah nipa iroyin to n ja pe Covid-19 lo ṣokunfa iku arabinrin Bukola Janet, o ni awọn ko ro bẹẹ.
''Kii ṣe Corona. A le pe ni ''shock'' ati pe wọn ni Hypertension ti eleyi si n ba wọn finra tẹlẹ.''
Oniṣẹ aṣerun lọṣọ toloyinbo n pe ni Hairdresser ni arabinrin Janet Bukola jẹ nilu Ibadan.
Ọjọ Kejila Osu Keji ọdun yii ni arabinrin Bukola Janet ko ba pe ẹni ọdun mẹtalelaadọta gẹgẹ bi Wolii Hephzibah  ti ṣe sọ.
Oríṣun àwòrán, Orisabunmi
Lakotan Hephzibah sọ fun BBC pe ilu Ibadan ṣi ni oku arabinrin Janet wa.
Ko ti daju igba ti wọn yoo sin nitori oku ti Oriṣabunmi to jẹ ẹgbọn ati ẹgbọn wọn agba, Steve Onisola ṣi wa nilẹ bayi, ti awọn mọlẹbi ko ti kede igba ti wọn yoo sin wọn.
Lara awọn ẹbi to ṣẹku fun arabinrin Janet bayii ni ẹgbọn rẹ obinrin Alhaja Abiodun Dan Kazeem to jẹ iyawo sọrọ sọrọ Adeniyi Dan Kazeem.
Saaju la ti sọ fun yin pe iroyin iku ẹni to jẹ ẹgbọn si gbajugbaja oṣere ere tiata Folake Aremu, Orisabunmi, ti desi eti igbọ wa.
Ẹgbọn rẹ yi, Steve Onisola jẹ oludari ẹgbẹ agbabọọlu alapẹrẹ awọn obinrin ni Kwara,Kwara Falcons Basketball Club nigba aye rẹ.
Alaga ẹgbẹ awọn to n gba bọọlu alapẹrẹ ni Kwara Dokita Joseph Adeyemo lo fidi ọrọ yi mulẹ fawọn akọroyin lọjọbọ.
Gẹgẹ bi ohun taa gbọ, ko pe wakati mẹrinlelogun sigba ti Oriṣabunmi jade layi ti Onisola tii ṣe ẹni ọdun mọkanlelaadọrin ki duniya pe o digbere.
Oniṣola ti fi igba orisirisi jẹ alakoso ẹgbẹ Falcons ki wọn to wa yan sipo oludari eto ẹgbẹ naa.
Oríṣun àwòrán, Facebook/steveolaniyi.onisola
O wa lara awọn to ṣapa ti ẹgbẹ naa fi gba agbega si abala liigi to gajulọ ni ọdun 2013.
Bakan naa lo jẹ ọkan lara awọn to gba ami ẹyẹ fadaka nibi idije liigi Kwese lọdun 2018.
Onisola jẹ ọkan lara awọn akọnimọọgba akọkọ ẹgbẹ naa ti wn da silẹ laarin ọdun 1970-80
Oríṣun àwòrán, Facebook/steveolaniyi.onisola
O tun jẹ ọmọ ẹgbẹ igbimọ bọọlu alapẹrẹ ni ipinlẹ Kwara ṣaaju iku rẹ.
Adeyemọ ṣapejuwe iku rẹ gẹg bi eyi to fọwọkan ẹmi awọn elere idaraya ati mọlẹbi rẹ nipinlẹ Kwara.
Afeez Ọwọ ṣàlàyé ìdí tó fí padà yọ àwòrán Orisabunmi kúrò lójú òpó rẹ̀
Yollywood artists: Mide Martins ní Kìí ṣe gbogbo ìgbéyàwó ló ń túká nítorí àgbèrè
Oríṣun àwòrán, Instagram
Ọpọlọpọ iṣẹlẹ lo waye ni agbo ere awọn oloṣere ni ọsẹ yii, to fi mọ gbajugbaja osere, Iyaafin Fọlakẹ Arẹmu ti ọpọlọpọ eeyan mọ si Oriṣabunmi to padanu ẹmi rẹ lẹyin aisan ranpẹ, ti aburo rẹ naa si tun dagbere fun aye laarin ọjọ meji.
Eyi ya awọn ololufẹ rẹ lẹnu pupọ nitori ko si ẹni to gburo aisan nipa rẹ, ki ọlọjọ to de.
"Amọṣa ninu fidio kan to fi si ori ikanni ayelujara, Facebook, eekan apanilẹrin ati elere itage, Ọlanrewaju Omiyinka ti ọpọ mọ si Baba Ijeṣa jẹ ko di mimọ pe ""ikọ lasan"" lo pa oloogbe Oriṣabunmi."
Laarin ọjọ meji ti iṣẹlẹ iku orisabunmi waye, ni a tun gbọ pe aburo rẹ̣ naa tun jẹ Olorun nipe.
Ki o to di oloogbe, oun ni adari ikọ agbabọọlu Kwara State Falcon Football club.
Mide Martins
Gbajugbaja oṣere Yoruba, Mide Martins ti gba awọn ololufẹ rẹ ni iyanju wi pe ọpọlọpọ nkan lo n ba igbeyawo jẹ yatọ si ki ọkọ abi iyawo ma a ṣe agbere.
Mide Martins lo sọ bẹẹ loju opo ikansiraẹni Instagram rẹ,nibi ti o ti n gba awọn ololufẹ rẹ ni iyanju lori  igbeyawo ati awọn ohun to n fa idarudapọ ninu ile.
Mide ni igbeyawo mii n daru nitori ọkọ tabi aya ko koi bi ara si ekeji rẹ, ti ẹlomiran ko si mọ bi wọn ṣe n tọrọ idariji ẹsẹ lọwọ ọrẹkunrin ati ọrẹbinrin.
Mide Martins fikun wi pe awọn ohun to le gbe igbeyawo duro ni ki eniyan ni irẹlẹ ọkan ati imumọra loore-koore.
Bobrisky
Gbajugbaja ilumọọka to jẹ ọkunrin, amọ to n wọ asọ obinrin ti darukọ ''Honourable Deji'' lasiko ti o n kọ awọn obinrin ni ọna ati ma fi igbadun wọn han fun ọkunrin lasiko ibalopọ.
Eyi ti mu ki ọpọlọpọ awọn ọmọ Naijiria ma a bere nipa ẹni to n jẹ ''Honourable Deji'' lori ẹrọ ikansiraẹni Twitter kaakiri.
DJ Cuppy ati Zlatan
Oju opo ikansiraẹni Twitter n gbona jainjain lowurọ  Ọjọ Ẹti ni lẹyin ti gbajugbaja olorin ati ọmọ Femi Otedola, DJ Cuppy ke gbajare sita pe ọrẹ ati akẹgbẹ oun, ti awọn jọ kọ orin 'Gelato'  ti gbegile oju opo ikansiraẹni Instagram ati Whatsapp rẹ fun osu mẹwaa bayii.
DJ Cuppy fikun wi pe oun ko mọ idi to fi gbe igbesẹ bẹẹ, ti kii si ṣe pe awọn ni ija ti tẹlẹ.
Vee - BB Naija
Arabinrin to kopa ninu idije BBNaija lockdown, Vee ti kesi awọn eniyan lati ṣe suuru nipa wiwa ọrọ ati owo ni aye ti a wayii.
Vee ni ti awọn ẹlomiran ba sọ bi awọn ṣe n ri owo awọn, awọn eniyan yoo ma ṣe suuru ni igba gbogbo.
LASU Best Graduating Student: Wo ẹ̀bùn owó gọbọi tí Sanwo-Olu fún akẹ́kọ̀ọ́ tó gba ipò kínní ní fásítì LASU l'Eko
Oríṣun àwòrán, Twitter/Gbenga Omotoso
Olorin kan lko kọrin pe ''bata rẹ a dun koko ka, ti o ba kawe rẹ.''
Bẹẹ gẹgẹ lọrọ ri fun ọdọkunrin Shotunde Oladimeji Idris, akẹkọọ ile iwe giga fasiti ipinlẹ Eko, LASU to ṣe ipo kinni ninu gbogbo awọn akẹgbẹ rẹ ti wọn jọ kẹkọọ gboye jade.
Gomina ipinlẹ Eko, Babajide Sanwo-Olu ṣe imọnyi fun Shotunde pẹlu ẹbun miliọnu marun un owo naira.
Ko tan sibẹ o, gomina tun kede iṣẹ nileeṣẹ ijọba ni Marina fun Shotunde.
Ọgbẹni Shotunde, ẹnui ọdun mejilelogun kẹkọọ gboye ninu ẹkọ iadari okowo.
Bakan naa ni Gomina Sanwo-Olu tun fun akẹkọọ to pegede julọ ninu awọn akẹkọọ to gboye ẹkeji ni LASU, Olabanjo Olusola Aanu naa lẹbun miliọnu marun un naira.
Olubanjo to kẹkọọ nipa imọ ẹrọ kọmputa gba ipo 5.0 eyi to tumọ si pe gbogbo maaki lo gba tan an.
Nigerian universities resumption: Wó ọjọ́ ti àjọ NUC kéde pé àwọn akẹ́kọ̀ọ́ fásítì Nàìjíríà yóò wọlé
Ọpẹ o, ajọ NUC to n ri si ọrọ ile iwe giga fasiti lorilẹede Naijiria ti sọ fawọn giwa ile ẹkọ fasiti ni Naijiria pe ki wọn jẹ ki awọn akẹkọọ wọle pada lọjọ kejidinlogun oṣo kinni ọdun 2021 yii.
Ninu atẹjade kan ti NUC fi sita, ajọ naa ṣalaye pe wiwọle pada awọn fasiti wa ni ibamu pẹlu iyọnda ajọ amuṣẹya PTF lori coronavirus pe kawọn ileewe wọle.
O ti pe oṣu mẹsan tawọn akẹkọọ fasiti ti wa nile tori iyanṣẹlodi tawọn olukọ wọn gunle ati ajakalẹ arun covid-19.
Loṣu kejila ọdun 2020 ni igbimọ PTF sọ pe ki awọn ileewe di ṣiṣi pada lẹyin ti wọn ti wa ni titi pa nitori ajakalẹ arun coronavirus.
Igbakeji akọwe agba ajọ NUC, Ọgbẹni Chris Maiyaki ṣalaye ninu atẹjade ọhun pe awọn ileewe naa gbọdọ tẹle awọn ilana ti ajọ NCDC la kalẹ lori ati gbogun ti arun coronavirus.
O ni kii ṣe igba akọkọ ree ti ajọ NUC yoo paṣẹ fawọn fasiti lati tẹle ilana kan tabi omiran.
DNA: Njẹ́ o mọ pé obìnrin lè bí Ìbejì tí wọ́n yóò sì ní bàbá ọtọ́ọ̀tọ̀?
Taiwo ati Kehinde Olanrewaju (kii ṣe orukọ wọn gangan ree) jẹ ọmọ meji akọkọ ti obi wọn bi.
Nipa ti jijọ, wọn ko foju jọ ara wọn to bẹẹ ṣugbọn eleyi ko jẹ tuntun nitori awọn ibeji mi wa to jẹ pe wọn kii jọ ara wọn.
Nigba ti wọn wa lọmọ ọdun mẹfa, Kehinde farapa ti wọn si nilo lati ṣe iṣẹ abẹ fun.
Iṣẹ abẹ naa nilo ki wọn gba ẹya ara baba rẹ kan, ki o to le gbadun.
Awọn dokita ṣetan, wọn ṣe ayẹwo baba rẹ ṣugbọn wọn ri wi pe ẹya rẹ ko papọ mọ ti Kehinde.
Nkechi Blessing: Mi ò gbá ẹ mú nígbà tóo dákú níbí ìsìnkú Mama Nkechi tórí ... - Toyin Abraham
Báyìí ni mo ṣe san nínú oore Ọlọ́run tó fi Kábíyèsì Ooni ti Ile Ife ta èmi Silekunola lọ́rẹ - Olorì Wòlíì Naomi
Àwọn obìnrin ń ṣe igbéyàwó pẹ̀lú igi láti ṣààmì ètò ìdàgbàsókè ìlú wọn
2021 Twin Festival: Aráàlú ní Ifá ló sọ pé ìbejì yóò pọ̀ ní Igboora, kìí ṣe jíjẹ Ìlasa
Ọrọ naa ṣe wọn ni kayeefi, ti o si mu ki baba Kehinde maa beere pe bawo leyi ti ṣe jẹ.
Asẹyinwa aṣẹyinbọ, wọn ṣayẹwọ DNA fun Kehinde, ti wọn si ri wi pe kii ṣe ọmọ baba rẹ ṣugbọn ayẹwo fihan pe oun lo bi Taiye.
Njẹ eeyan le bi ibeji fun baba ọtọọtọ?
Nigba ti wọn n salaye bi eyi se ri bẹẹ, awọn dokita ni o ṣeese ki o ṣẹlẹ bẹẹ niwọn igba ti iya awọn ọmọ naa ba ni ibalopọ pẹlu awọn ọkunrin meji lasiko kan naa ṣaaju ki o to loyun.
Wọn ni iru iṣẹlẹ yii ṣọwọn amọ o le ṣẹlẹ.
Orukọ ti wọn pe iru isẹlẹ yi ni ede gẹẹsi ni ‘Heteropaternalsuperfecundation’.
Bawo lo ṣe n ṣẹlẹ:
Awọn onimọ ṣayensi fidi ọrọ mulẹ pe, iṣẹlẹ superfecundationis yii ṣọwọn laarin awọn eeyan ṣugbọn lagbo ẹranko, iru rẹ a maa wọpọ daadaa.
Ni ṣoki, oun to ṣẹlẹ ni pe, àtọ̀ orisi meji ọtọọtọ ni yoo dapọ mọ ẹyin obinrin lasiko ibalopọ ọtọọtọ, ti yoo si bi ibeji lati ara ọkunrin ọtọọtọ.
Ẹ̀mí kan náà ló n darí ìrìnàjò wa táa fi jọ kọ́lé papọ̀- Ìbejì
Iru iṣẹlẹ yii kan naa to waye ni orileedẹ Vietnam lọdun 2016, Ọjọgbọn Le Dinh Luong, to jẹ aarẹ awọn onimọ ẹya ara Vietnam Genetic Association, ṣayẹwo awọn ibeji kan ti wọn ko foju jọ ara wọn, to si fidi ọrọ mulẹ pe wọn kii ṣe ọmọ baba kan naa.
O ni iru iṣẹlẹ yi ko wọpọ ''koda o ni awọn ibeji to ni baba ọtọọtọ bayii ko ju mẹwa lọ tawọn mọ lagbaye''
O tẹsiwaju pe, o ṣeeṣe ki awọn mii wa ṣugbọn tawọn obi wọn ko mọ pe baba ọtọọtọ lo bi wọn tabi ki wọn si maa fẹ pariwo rẹ faraye gbọ.
Awọn onimọ tẹsiwaju pe, ki iru nkan bayii to le ṣẹlẹ yoo jẹ wi pe, ẹyin meji ọtọọtọ to n dọmọ lara obinrin ni yoo wa ninu ile ọmọ obinrin naa, ti aatọ awọn ọkunrin mejeeji to ba ba lopọ lasiko kan naa, yoo si da pọ mọ wọn lọtọọtọ.
O tun le ṣẹlẹ ti ile ọmọ obinrin ba pese ẹyin lẹẹmeeji lera wọn, ti awọn ẹyin ọtọọtọ yii ba si dapọ mọ aatọ ọkunrin meji ọtọọtọ to ni ibalopọ pẹlu obinrin naa.
Glorious Twins: Taiwo àti Kehinde Ekundayo ní ọ̀dọ́ ìyá àgbà ní àwọn ti ẹ̀bún orin kíkọ
Ti adura ba gba ti o di oyun, oun ti yoo ṣẹlẹ ni pe awọn ọmọ meji pẹlu baba ọtọọtọ ni obinrin naa yoo bi.
Yatọ si iṣẹlẹ ta fidi rẹ mulẹ pe o waye ni Vietnam lọdun 2016, awọn irufẹ iṣẹlẹ yii to waye ni ti ilẹ Amẹrika nilu New Jersey lọdun 2015.
Ibeji obinrin lawọn ọmọ yii, awọn si ni ikẹta irufẹ isẹlẹ yii ti akọsilẹ wa pe o ṣẹlẹ ni Amẹrika.
Awọn irufẹ isẹlẹ mii to tun waye ni ti orileede Turkey nibi ti awọn ileeṣẹ iroyin ni awọn ibeji kan ni baba ọtọọtọ lọdun 2010.
Wo àwọn ìbejì tó lẹ́ pọ̀ lẹ́yìn àṣeyọrí ìṣẹ́ abẹ dókìtà 70
Apejuwe la fi wọn ṣe ṣugbọn ko tumọ si pe ko le ṣẹlẹ ni Naijiria naa.
Taa n tiẹ mọ boya iru rẹ ti waye ṣugbọn tawọn mọlẹbi  ko kan fẹ polongo ṣetigbọ araye.
Alaafin: Ààyò mi, ọkùnrin tó rẹwà jùlọ àti kọ́kọ́rọ́ ọkàn mi wà lára ọ̀rọ̀ ìwúrí táwọn olorì fi kí Ọba Adeyemi
Oríṣun àwòrán, Instagram/olori_omoh_one
Bi aadọta ọdun ti Alaafin ilu Ọyọ, Ọba Lamidi Adeyẹmi Kẹta gori oye ṣe n kanlẹkun, oriṣiriṣi ikini ati ọrọ idunnu ni awọn olori laafin rẹ ti n fi sita.
Pupọ ninu awọn olori naa lo bọ sori ayelujara Instagram ati Facebook wọn, lati ki Kabiesi ku oriire, ti wọn si tun lo anfaani naa lati fi imọriri wọn han.
Ko si sẹni ti yoo ka ọrọ ikinni naa, ti ori rẹ ko ni wu nipa kiki ati kiki tawọn ayaba naa se, eyi to n yonbo Ọba Adeyemi.
Diẹ lara awọn olori to ki ọba Adeyemi ree ati ọrọ ikinni ti wọn fi n ki ọkọ wọn lawọn oju opo ayelujara wọn.
Ayaba Mujidat Adeyemi: Aayo mi ni Ọba Adeyemi
Oríṣun àwòrán, Instagram/adeyemimujidat
Ninu ọrọ ikinni tiẹ si Ọba Adeyemi, Ayaba Mujidat Adeyemi ni aayo oun ni Kabiyesi jẹ, ti yoo si ma a jẹ lailai.
O ki Kabiyesi lorukọ rẹ ati ti awọn ọmọ rẹ pe - Kabiyesi, Oba Nla, Oba to nfi Oba je, Oba to ngba idobale Oba, Alowolodu bi iyere, afinju Oba ti lo golu.
O wa gbadura pe ki Alaafin tubọ lo ọpọlọpọ ọdun lori itẹ awọn baba rẹ.
Ayaba Sulat Motunrayo Adeyemi: Ọkọ mi ni ọkunrin to rẹwa julọ
Oríṣun àwòrán, Facebook/Ayaba Motunrayo Adeyemi
Ayaba Sulat Motunrayo Adeyemi sọ pe oun ati awọn ọmọ oun ba ọkunrin to rẹwa julọ, to jẹ oniwa jẹẹjẹ, ati ọlọyaya ku ayẹyẹ aadọta ọdun lori itẹ.
"O ni Ade a pẹ lori yin, irukẹrẹ a pẹ lọwọ yin, igba ọdun, ao jọ ma lo igba ni."""
Ayaba Memunat Adeyemi: Alaafin lo ni kọkọrọ ọkan mi lọwọ
Oríṣun àwòrán, Instagram/olori_omoh_one
Ayaba Memunat Adeyemi sọ pe, Akikanju ni Alaafin jẹ fun oun, ẹni to ni kọkọrọ to ṣi ọkan oun, ọkunrin pataki to ma n da oun lọrun ni gbogbo igba, ati baba awọn ọmọ oun.
O ni ọpọlọpọ ayọ ni Kabiyesi ti mu wọ aye oun.
Ayaba Folashade Adeyemi: Alekun ara ọkọ mi yoo maa pọ si
Ayaba Folashade sọ pe oun ki Kabiesi ku ayẹyẹ aadọta ọdun lori itẹ, o si gbadura ki alekun ilera ati okun pọ si fun baba.
Olori Damilola Adeyemi:
Oríṣun àwòrán, Instagram/officialqueen_dami
Ọrọ ikini ti Olori Damilola Adeyemi fi ranṣẹ si Alaafin yatọ diẹ si ti awọn akẹẹgbẹ rẹ.
O ni oun ni olori to jẹ oloriire julọ ni aafin Kabiesi, nitori pe wọn ko ti i bi oun nigba ti Alaafin jọba. Ṣugbọn oun ṣoriire pe oun jẹ ara awọn olori rẹ lasiko ayẹyẹ nla yii.
Mo nireti pe olori rẹ ni ma a tun jẹ ti mo ba tun aye wa.
Ayaba Rukayat Abiodun Adeyemi: Baba to nifẹ ọmọ ati ọkọ to nifẹ aya ni Alaafin
Oríṣun àwòrán, Facebook/Queen Abbey Adeyemi
Ayaba Rukayat Abiodun Adeyemi ṣapejuwe asiko Alaafin lori oye pe, o ti mu ọpọlọpọ ibukun, idagbasoke ati alaafia wa silu Ọyọ ati awọn ilu to wa ni abẹ rẹ.
Baba lo jẹ fun mi, ọkọ to ni ifẹ aya, ati awokọṣe fun awọn ọmọ mi.
O gbadura pe ki Allah da ẹmi Kabiesi si ninu ọrọ ati ilera to peye, fun idagbasoke ilu Ọyọ ati agbagbe rẹ.
Oríṣun àwòrán, facebook/Alaafin Oba Adeyemi III
Yoruba ni bi ọọdẹ ko ba dun, bi igbẹ nilu n ri, bi ilu ko ba si dun pẹlu, ko si ọmọ talaka ti yoo le rode ẹmu.
Bẹẹ lọrọ ri pẹlu isọri keji ọwọja ajakalẹ arun Coronavirus to tun gbode bayii, eyi to n se akoba feto ọrọ aje, to si tun n se idiwọ fun ọpọ ayẹyẹ ni sise.
Lọwọ lọwọ bayii, arun naa ti se idiwọ fun Alaafin tilu Oyo, Ọba Lamidi Olayiwola Adeyemi lati sami ayẹyẹ aadọta ọdun to gori itẹ awọn baba nla rẹ.
Ayẹyẹ naa, to yẹ ko bẹrẹ lonii ọjọ Aiku ni wọn ti kede pe ko ni le waye mọ nitori awọn idi kan to da lori bi ọwọja arun Covid-19 se n ja kiri ilu.
Oríṣun àwòrán, Facebook/Alaafin Oba Adeyemi III
Bi o tilẹ jẹ pe eto lati sami ayẹyẹ aadọta ọdun ti ọba alaye naa gba ade, ti debi to lapẹrẹ, ti wọn si ti fi iwe pe ọpọ awọn eeyan jankanjankan lati peju sibi ayẹyẹ naa, sibẹ ayẹyẹ naa ko lee see se lasiko yii.
Atẹjade kan to wa lati aafin Oyo, ti Iku Baba Yeye funra rẹ fọwọsi salaye pe lootọ ni oun ti seto ayẹyẹ idupẹ alarinrin amọ oun fẹ tun ero oun pa lori igbasẹ naa.
"Pẹlu irora nla ninu ọkan mi ati aabo fun ẹmi eeyan, ni mo fi rọ awọn Oyomesi lori idi ta fi gbọdọ sun ayẹyẹ naa siwaju titi di ọjọ mii, ọjọ re, ti arun Coronavirus yoo kasẹ nilẹ.
Oríṣun àwòrán, Alaafin of Oyo
Lara awọn idi ti mo si se gbe igbesẹ irora naa ni lati bọwọ fun ofin itakete sira ẹni pẹlu bi yoo se nira lati gbalejo lati ilẹ okeere , ti wọn si gbọdọ lo ọsẹ meji ni yara iseraẹnilọjọsi ki wsn fara kinra pẹlu ẹlomiran, eyi to le ma see se."
Alaafin wa kede pe aabo ẹmi awọn eeyan lo jẹ oun logun ju ayẹyẹ ki ayẹyẹ lọ, idi si ree ti oun ko fi ni se ayẹyẹ aadọta ọdun ti oun gba ade, ọlọsẹ kan ọhun mọ.
Oríṣun àwòrán, Alaafin of Oyo
Orisabunmi: Elebuibon ní àfọwọ́fà wà lára nǹkan tó n fa Àkúfà nílẹ̀ Yorùbá
Laipẹ yii ni gbajugbaja oṣerebinrin, Folake Aremu, ti ọpọ eeyan mọ si 'Oriṣabunmi' kú, ṣugbọn ti ẹgbọn ati aburo rẹ naa tun kú laarin ọjọ mẹta pere.
Eyi si ti mu ki ọpọ eeyan o ma a beere, paapaa awọn ọmọ ilẹ Yoruba pe, ṣe o ṣe e ṣe ko jẹ Akufa ni ọrọ iku wọn to waye ni tẹle n tẹle yii?
Ọ́na lati wa idahun si iwoye awọn eeyan naa lo mu wa pe baba awo, Ifayemi Elebuibon lati mọ ohun to n jẹ akufa, idi to fi le waye ati ọna abayọ si isoro naa.
Bakan naa, awọn eeyan miran lero pe arun idile le sokunfa iku tẹle n tẹle, idi si ree ta tun fi tọ dokita oloyinbo lọ lati mọ boya ootọ ni, ka le se ọtun ati osi lai ba ibikan kan jẹ.
Ki ni Yoruba n pe ni Akufa?
Gẹgẹ bi akọsilẹ to wa ni ori ayelujara ifayemisielebuibon.blogspot.com, Akufa ni ki iku aitọjọ o waye lera-lera lẹyin iku eeyan kan ninu ẹbi kan, agboole tabi ilu.
Ọmọbinrin Araba ilu Oṣogbo, Oloye Ifayẹmi Ẹlẹbuibọn, ni Ifayẹmisi Ẹlẹbuibọn to ni oju opo ayelujara naa.
O ni igbagbọ Yoruba ni pe, ẹni to kọkọ ku naa ko da kú, ṣugbọn o fa awọn eeyan mii dani lati sin in lọ si ọrun.
Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo
Ki lo maa n fa Akufa?
Oloye Ifayẹmi Ẹlẹbuibọn, lasiko to n ba BBC Yoruba sọrọ ninu ifọrọwanilẹnu kan woye pe, o ṣe e ṣe ko jẹ akufa ni iṣẹlẹ iku tẹle n tẹle to waye ninu ẹbi gbajugbaja oṣere-binrin naa.
O ṣalaye pe akufa ti wa tipẹ, to ba si jẹ pe ni aye atijọ ni, aṣiri iṣẹlẹ naa yoo ti tu sita, ko to o ṣẹlẹ.
O ni nigba mii, ẹni to kọkọ ku le jẹ pe oun ni okun to so ẹbi ro, ti iran yoo si jade si ẹbi naa pe ki wọn o sẹ etutu ki okun ẹbi naa ma ja. Nitori pe iku ọwọọwọ lo ma n tẹle iku iru eeyan bẹ ẹ.
Ti wọn ba ṣe etutu, iku naa yoo re danu, amọ ti wọn ko ba ṣe e, ewu ni.
Ẹlẹbuibọn sọ pe oriṣiriṣi nkan lo ma n fa akufa ninu ẹbi kan. O ni o ṣe e ṣe ko jẹ pe awọn ẹlẹyẹ lo ti leri lati ma a pa wọn.
Itakun agbaye ifayemisielebuibon.blogspot.com tun ṣalaye pe, Akufa le waye ti ẹlẹda oku to ku ko ba ni isinmi tabi to ba n binu si awọn alaaye.
Yatọ si eyi, Akufa tun le waye ti ẹbi ko ba ṣe awọn etutu to yẹ ni sise tabi wọn ko ṣe e daadaa, nigba ti ẹni akọkọ ku gẹgẹ aṣa.
Oluwo Jogbodo Series: Ìmẹ́lẹ́ jẹ́ orísun àìnílárí, Ifá ṣe ìkìlọ̀ rẹ̀ fáwọn ará Ibadan kí
Itan bi Ilẹ ṣe di ẹni ti ko le sọrọ mọ nitori Akufa:
Elebuibon wa lo itan bi Ilẹ ṣe di ẹni ti ko le sọrọ mọ, eyi to da lori awọn ọmọ iya mẹta to pa ẹranko agbọnrin, ti wọn si fi nkan di i bi oku wọ aarin ilu, nitori ki wọn o ma ba fun ẹnikẹni jẹ lara ẹran naa.
Nibi ti wọn ti n lọ, ni wọn ba awọn ẹlẹyẹ lọna to n ṣe ipade. Sugbọn, ẹsẹ oku ẹran naa lo yọ silẹ, ti awọn ẹlẹyẹ fi ri pe, kii ṣe oku eeyan ni wọn di.
Eyi lo ki awọn ẹlẹyẹ pinnu le wọn lori, lati pa wọn ni ẹyọ kọọkan, orukọ wọn si ni Kutannle, Oleegba, ati Tẹtẹrẹgun.
Ṣugbọn ṣa, iyawo Ọrunmila, tii se Ilẹ, gbọ lasiko ti awọn ẹlẹyẹ ṣe imulẹ naa.
Gẹgẹ bi itan naa ti sọ, ko pẹ ti wọn jẹ ẹran naa, ti akọbi fi bẹrẹ si ni ṣe aisan, eyi to mu ki iya wọn salọ si ọdọ Ọrunmila fun iwosan ọmọkeji to tun bẹrẹ aisan.
Ṣugbọn ọmọ naa ku, ko to o de ile.
Àwọn fíìmì òde òní ń kọ́mọ lólè àti ọ̀pọ̀ ìwà burúkú
Ko ju ọjọ mẹta ti wọn sin oku akọbi, ni ọmọ keji naa bẹrẹ aisan, ti iya wọn tun sare lọ sọdọ Ọrunmila, ṣugbọn ọmọ naa tun ku.
Ki ọmọ kẹta ma ba ku, lo tun mu ki iya wọn pada si ile Ọrunmila, ṣugbọn iyawo rẹ, Ilẹ lo ba nile.
Nibẹ ni Ilẹ ti sọ fun pe, ọrọ ẹran ti awọn ọmọ rẹ di bi oku eeyan, nitori ki wọn o ma ba a fun ẹnikẹni jẹ lara rẹ, lo n fa akufa.
O sọ fun iya wọn pe, ko pa odidi ẹran kan, ko si ko gbogbo ifun ati ẹjẹ rẹ fi ṣe etutu, ko si gbe e lọ si orita awọn ẹlẹyẹ, ti ko ba fẹ ki ọmọ kẹta naa o ku.
O ni ko gbe ọrun rẹ lọ si idi Eṣu.
Igbesẹ ti ilẹ gbe yii, lo mu ki awọn ẹlẹyẹ gba ohùn lẹnu rẹ ti ko fi le sọrọ mọ.
"Elebuibon fikun pe, ""Nkan to ma n fa akuba le jẹ nipasẹ nkan ti obi se, tabi awọn ọmọ."
"Ti wọn ko ba si ti ri eeyan sọ fun wọn, iku naa yoo tẹsiwaju ni."""
Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó
Lori nkan ti awọn eeyan to kù ninu ẹbi naa le ṣe lati dena tabi fi opin si akufa, Baba Ẹlẹbuibọn sọ pe wọn yoo difa, lati mọ nkan ti wọn yoo fi ṣe etutu.
Yatọ si eyi, o ni niwọn igba to jẹ pe ẹsin Kristiẹni ati Islam ti wa bayii, ẹbi ti ọrọ ba kan le gbadura nilana ẹsin wọn.
Dokita Ikebese Wilson sọ fun BBC Yoruba pe iwadii imọ sayẹnsi nipa ohun to se okunfa iku to pa awọn eeyan ẹbi Orisabunmi (Post mortem) nikan lo le fihan boya orisun kan naa ni iku wọn ti wa.
O ni yatọ si pe o le jẹ aarun Covid-19 to wa nita, o ni iwadii yoo da lori iru aisan tabi awọn ami aisan ti gbogbo wọn fihan ṣaaju iku wọn.
Dokita Ikubese ṣalaye pe, iku awọn eeyan yii tun le jẹ awọn aisan ajogunba bi ẹjẹ riru ati itọ ṣuga, ṣugbọn ayẹwo oku naa lo le sọ nkan to jẹ.
"Coronavirus Update: Gomina Sanwo-Olu sún ọjọ́ ""ṣiṣẹ́ láti ilé"" síwájú fún àwọn òṣìṣẹ́ ìjọba"
Oríṣun àwòrán, Twitter/gbenga omotoso
Ijọba ipinlẹ Eko ti pàṣẹ fawọn oṣiṣẹ ìjọba ti wọn ko to ipele Kẹrinla lati tubọ maa ṣiṣẹ lati ile wọn lọnà ati dẹkùn itankalẹ aarun Covid-19.
Labẹ aṣẹ yi, ile ni gbogbo awọn ti ko ba to ipele  yi yoo ti ma ṣiṣe di ọjọ kini oṣu Keji ọdun 2021.
Atẹjade ti olori awọn oṣiṣẹ nipinlẹ Eko Hakeem Muri Okunnu fi sita salaye pe aṣẹ igbele yi ko kan awọn ti o n ṣiṣẹ to se pataki.
Gomina  Babajide Sanwo-Olu ti buwọlu afikun ọjọ t'awọn oṣiṣẹ ìjọba Eko yoo fi ṣe iṣẹ lati ile fawọn ti ko to ipele Kẹrinla
Gomina wa rọ awọn oṣiṣẹ lat da aaboo bo ara wọn nipa bíbọwọ fún ilana idaabobo ti ijọba gbe kalẹ
Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsèjẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọ
Muri-Okunola tun tẹsiwaju pe ki wọn máa tẹlé àtẹ eto iṣẹ tó wà nilẹ ki gbogbo nkan baa le máa lọ ní irọwọrọsẹ lawọn ileesẹ ìjọba nipinlẹ ọhun.
Ìpínlẹ̀ Eko, Oyo àti Ogun ní abẹ́rẹ́ covid-19 tí yóò kàn wọ́n kéré, wọ́n fẹ́ ra ti wọn.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Covid-19 vaccine: Ìjọba Oyo, Eko fẹ́ ra abẹ́rẹ́ àjẹsára fún aráàlú
Ijọba ipinlẹ Eko, Ogun ati Oyo wa lara awọn ipinlẹ to bu ẹnu ẹtẹ lu bi ijọba apapọ ṣe pin abẹrẹ ajẹsara Covid-19 fawọn ipinlẹ ni Naijiria.
Akọsilẹ ajọ NPHCDA to n ri eto abẹrẹ ajẹsara Covid-19 fi sita wa safihan bi yoo se pin abẹrẹ naa fawọn ijọba ipinlẹ.
Oríṣun àwòrán, Reuters
Kano - 3,557 , Lagos - 3,131, Katsina - 2,361, Kaduna - 2,074, Bauchi -1,900, Oyo - 1,848, Rivers - 1,766, Jigawa - 1,712, Niger - 1,558 , Ogun - 1,473.
Sokoto - 1,468, Benue - 1,423, Borno - 1,416, Anambra - 1,379, Kebbi - 1,268, Zamfara - 1,336, Delta - 1,306, Imo - 1,267, Ondo - 1,228, Akwa Ibom -1,161.
Africa Eye: Wo ìtàn ìyá kan ìyá kan àtàwọn olè ajọ́mọgbé tó n ta ọmọ ní Kenya
Adamawa - 1,129, Edo - 1,104, Plateau - 1,089, Enugu - 1,088; Osun - 1,032; Kogi - 1,030; Cross River - 1,023; Abia - 955; Gombe - 908; Yobe - 842; Ekiti - 830; Taraba - 830; Kwara - 815; Ebonyi - 747; Bayelsa - 589; FCT - 695, Nasarawa - 661.
Gomina Seyi Makinde ipinlẹ Oyo sọ pe abẹrẹ ti ijọba apapọ pin fun ipinlẹ Oyo ti kere ju.
Makinde ni ijọba yoo ra abẹrẹ naa fúnra rẹ, ki awọn eeyan ipinlẹ naa le jẹ anfaani abẹrẹ ọhun.
Akomolede ati Aṣa: Mọ̀ síi nípa ìró afárànma àti agbárànmọ́ fáwẹ́ẹ̀lì Yorùbá
Bakanna, Kọmiṣọna feto iroyin ati aato ni ipinlẹ Eko, Gbenga Omotosho sọ pe, iyalẹnu ni bi ajọ NPHCDA ṣe pin abẹrẹ Coronavirus fawọn ipinlẹ jẹ.
Ọgbẹni Omotosho ni ko si adehun kankan laarin ijọba apapọ ati awọn ipinlẹ lori iye abẹrẹ ti yoo kan ipinlẹ kọọkan, ki ajọ NPHCDA to gbe nọmba ti yoo kan ipinlẹ kọọkan jade.
Kọmiṣọna ni ijọba ipinlẹ yoo ra abẹrẹ ajẹsara Covid-19 tirẹ fawọn eeyan ipinlẹ naa.
Amọ, o ni ipinlẹ Eko ko ní ṣalai gba eyi ti ijọba apapọ pin fun wọn.
Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó
Ipinlẹ Ogun ni tiẹ sọ pe, ko gba ibikan ye oun bi ijọba ṣe pin iye abẹrẹ ti yoo kan ipinlẹ kọọkan.
Oludamọran fun Gomina ipinle Ogun lori eto iroyin, Ọgbẹni Remmy Hazzan lo kede bẹẹ.
Hazzan sọ pe ipinlẹ Eko, Ogun ati Olu ilu Naijiria Abuja ti ajakalẹ arun Covid-19 ti ṣọṣẹ julọ, ló yẹ kó lanfaani abẹrẹ ajẹsara Covid-19 ju awọn ipinlẹ to ku lọ.
Ko tii ye wa nipinlẹ Ogun, idi ti a ko fi gba ju iye abẹrẹ perete ti ajọ NPHCDA pin kan wa lọ, Ọgbẹni Hazzan lo sọ bẹẹ.
LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé
Ẹwẹ, ẹgbẹ awọn dokita ni Naijiria, NMA ti rọ ijọba apapọ lati fun awọn oṣiṣẹ eleto ilera lanfaani ati kọkọ gba abẹrẹ ajẹsara Covid-19.
Aarẹ ẹgbẹ NMA, Ọjọgbọn Innocent Ujah ni, awọn oṣiṣẹ eleto ilera lo n foju wina ajakalẹ arun coronavirus julọ nitori awọn lo n tọju awọn to larun naa nile iwosan.
O fikun ọrọ rẹ pe, ko si ohun to buru níbẹ ti awọn oloṣelu ati awọn to ba ri ọwọ họri ba lọ gba abẹrẹ naa loke okun.
Oríṣun àwòrán, @didacus_dee
Ṣugbọn o seni laanu pe ọpọlọpọ araalu ni ko tẹle ilana idaboobo lọwọ arun naa, bo tilẹ jẹ pe lojoojumọ ni ijọba ati awọn alaṣẹ eto ilera n polongo pe ka tẹle ofin itakete sira ẹni.
Lara awọn akiyesi wa, paapaa nipinlẹ Eko ni pe, awọn ọkọ ero n ko ero kun inu ọkọ wọn lai bọwọ fun ilana arun Coronavirus.
Ṣaaju nigba ti arun naa kọkọ gbalẹ, ijọba paṣẹ fun awakọ ero lati din ero wọn ku, ki wọn o si ri daju pe awọn ero naa wọ ibomu.
Ṣugbọn lasiko yii, ko wọpọ lati ri awọn eero ọkọ to wọ ibomu, bẹẹ ni awọn awakọ naa n ko ọpọ ero laisi titakete sira ẹni.
Ṣé lóòtọ́ọ́ ni pé ìtọ̀ àti imí màálù le wo ààrùn coronavirus?
Lori eyi, Kọmisana fun eto iroyin nipinlẹ Eko, Ọgbẹni Gbenga Omotoso sọ fun BBC pe, gbogbo igba ni ijọba n kilọ fun awọn awakọ yii, to si tun n ba awọn olori wọn ṣe ipade loore-koore, nitori ki wọn o le maa tẹle ilana Covid-19.
"O ni ""Ọkọ meji ni ọwọ ti tẹ, ti ijọba si ti sọ fun awọn naa pe, o ṣe e ṣe ki wọn o padanu iwe irinna wọn gẹgẹ bi awakọ, ti wọn ba tun kọ lati tẹle ofin ijọba lori Coronavirus."""
Oríṣun àwòrán, @adelajaniyi
O ni awọn awakọ naa lo kọ lati gbọran si aṣẹ ijọba.
O ṣalaye pe ko rọrun fun ijọba lati gbe igbesẹ to le lori ọrọ naa, nitori pe ọpọ eeyan lo tun n bu ijọba fun bi awọn agbofinro ṣe n ko awọn eeyan kan nile ijo.
Awọn oṣiṣẹ ilu bi LASTMA ti ijọba n ran lati mu iru awọn awakọ bẹ ẹ, n fi ẹmi wọn wewu ni.
O yẹ ki awọn araalu naa mọ pe ija yii kii ṣe tijọba nikan.
Ahmad Lawal: Ojúṣe olórí ni láti pèsè ààbò fáráàlú, kìí ṣe àwáwí
Oríṣun àwòrán, @Presidency
Aarẹ ile aṣofin agba niluu Abuja, Sẹnẹtọ Ahmad Lawan ti rọ awọn olori ni Naijiria pe, ki wọn ye ṣe awawi nipa ipenija ti wọn n doju kọ.
Sẹnẹtọ Lawan sọrọ yii nibi ayẹyẹ ranpẹ ọjọ ibi ọdun kejilelọgọta rẹ lọjọ Iṣẹgun niluu Abuja.
Ojuṣe gbogbo awa olori ni lati wa nnkan se sí awọn ipenija to n dojuko kọ awọn ọmọ Naijiria, Lawan lo woye bẹẹ.
"Amọ Sẹnẹtọ Lawan ni ""kii ṣaaba rọrun nigba mii ṣugbọn awọn araalu maa n ro pe eremọde ni, ẹni to ba de ibẹ lo maa mọ pe ko rọrun."""
Ṣugbọn aarẹ ile aṣofin agba ni ko gbọdọ si awawi kankan.
Oríṣun àwòrán, @HQNigerianarmy
Sẹnẹtọ Lawan sọ pe, oun ni igboya ninu ile igbimo aṣofin agba l'Abuja lati ṣe awọn ofin ti yoo wa ojutuu si iṣoro to n doju kọ orilẹede Naijiria.
Sẹnẹtọ Lawan ko ṣai gboṣuba fawọn aṣofin fun iṣọkan to wa laarin wọn bo tilẹ jẹ pe ọtọọtọ lẹgbẹ oṣelu wọn.
O kii wọn ku iṣẹ ribiribi ti wọn n ṣe nipa ṣiṣe ofin ti yoo mu ilọsiwaju ba Naijiria.
Gbogbo awọn sẹnẹtọ akẹgbẹ rẹ to wa nibi ayẹyẹ naa, lo ki aarẹ ile aṣofin agba ku oriire ọjọ ibi ọdun kejilelọgọta rẹ.
Oríṣun àwòrán, @HQNigerianArmy
Saaju la ti mu iroyin wa fun yin pe igbakeji aarẹ, Yemi Osinbajo ti gba gbogbo ọmọ Naijiria nimọran lati mu isọkan orilẹede yii lọkunkundun nitori ninu irẹpọ ni Naijiria ti le lagbara si.
Osinbajo, ẹni to parọwa naa ni lai fi ti ẹya, ẹsin, ẹgbẹ oselu tabi iyapa miran se, ifẹ nikan lo le gbe Naijiria ro.
Igbakeji aarẹ parọwa bẹẹ nibi akanse isin alajumọse lati bẹrẹ ọsẹ iranti awọn ologun eyi to waye lọjọ Aiku nile ijọsin National Christian Centre, nilu Abuja.
Osinbajo, ti akọwe ijọba, Boss Mustapha soju fun fikun pe gbogbo orilẹede to ba ni iyapa ẹya ati ẹsin lo maa n ja fitafita lati lati jere to wa ninu iyapa wọn.
Oríṣun àwòrán, @ProfOsinbajo
O wa rọ awọn ọmọ Naijiria lati fi ara wọn jin fun ifẹ ati isọkan orilẹede yii ati idagbasoke awujọ wa, lọna ati bu ọla fun awọn ologun to ti sun soju ija.
"Awọn akọni ologun to ti sun loju ija yii lo fi ẹmi wọn lelẹ fun isẹ idoola awọ nilẹ yi ati nibi gbogbo, iranti wọn si la jẹjẹ lati bọwọ fun ninu orin orilẹede wa to ni 'isẹ awọn akọni wa ko ni ja si asan.'
A seleri pe ẹjẹ wọn ti wọn ta silẹ ko ni ja si ofo, eyi si jẹ ajaga ti awọn alaaye gbọdọ maa ru kiri."
Oríṣun àwòrán, Facebook/Nigeria Airforce
Bakan naa ni Igbakeji Aarẹ tun kọrin re ki oloogbe Tolulope Arotile, ẹni to se ise akọni losu  kẹwa ọdun 2019, nigba to di obinrin akọkọ ti yoo wa baalu ijagun ninu itan idasilẹ ẹka ologun ofurufu Naijiria.
"Bi o tilẹ jẹ pe wọn ge ẹmi rẹ kuru amọ o mu ala rẹ sẹ, eyi to wa lati daabo bo isọkan naijiria, alaafia rẹ ati ipese aabo to peye.
Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó
Yoruba ni ẹnu ẹni laa fi n pe Temidire nitori ohun ta ba beere, bẹẹ ni yoo ri.
Ohun ti Ibitoye Olatunde Michael gba lero pe ọkọ ti oun ba se funra ara oun, ni oun yoo kọkọ lo, ti wa si imusẹ.
Olatunde, lasiko to n ba BBC Yoruba sọrọ salaye pe ọdun 2016 ni oun bẹrẹ si jo irin mọ irin lati se mọto naa, to si gba oun ni odidi ọdun mẹta ko to pari.
Amọ Olatunde ni aisi owo lo mu ki msto naa pẹ, ko to dide amọ ti owo ba wa, ko gba oun ju osu mẹta lọ.
Ọkunrin naa to kẹkọjade nile ẹkọ fasiti ni ẹka imọ nipa eweko tun fikun pe oun ko ms isẹ ajorinmọrin tẹlẹ, amọ aniyan oun lo ti oun de idi rẹ.
O ni ọda owo, ohun eelo ati irinsẹ lo n da oun laamu, erongba oun si ni lati maa se mọto fun lilo awọn ọmọ Naijiria.
Àwọn ìtàn mánigbàgbé tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí:
Adejare Adeboye: Àwọn kan ní ṣé ọ̀nà láti gba owó oṣù àkọ́kọ́ lọ́wọ́ ọmọ ìjọ kọ́ ní ìkéde ààwẹ̀ ọlọ́jọ́ 63
Oríṣun àwòrán, @PastorEAAdeboye
Awọn eeyan lori ayelujara ti ko ẹnu bo Pasitọ igba fun ijọ Redeemed, RCCG, Olusọagutan Enoch Adeboye lori aawẹ ọlọjọ mẹtalelọgọta to kede .
Pasitọ Adeboye paṣẹ lọjọ Aiku, ọjọ kẹwaa oṣu kini ọdun 2021 pe ki gbogbo awọn ọmọ ijọ naa lagbaye gba awẹ ọjọ mẹtalelọgọta naa.
Gẹgẹbi iransẹ Ọlọrun naa ṣe sọ, ọpẹ ni ọjọ mọkanlelogun akọkọ ti wọn ba aawẹ naa yoo da le lori, ọjọ mọkanlelogun keji yoo da lori adura fun idile and bibeere fun aanu.
Pasitọ Adeboye ni ipele kẹta awẹ naa yoo wa lati gba adura fun ijọ, idile ati ara wọn.
Oríṣun àwòrán, @PastorEAAdeboye
Amọ ọpọ ọmọ Naijiria ko jẹ ki ikede naa balẹ loju opo Twitter, bi wọn ṣe n ka ikede naa, ni wọn n fesi loniruuru le lori.
Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó
Fun awọn kan, bi eto oselu orilẹde Naijiria ṣe dagun lo mu ki ijọ maa kede awẹ ọlọjọ gbọọrọ bii eyi ti ijọ RCCG kede naa.
Oríṣun àwòrán, @PastorEAAdeboye
Bi o tilẹ jẹ pe awon kan dahun pe ṣaaju iṣejọba to wa lode bayii ni ijọ naa ti n seto awẹ ati adura ibẹrẹ ọdun.
Oríṣun àwòrán, @PastorEAAdeboye
Ẹwẹ, awọn kan naa n beere pe ṣe kii ṣe ara ọna ati maa gba owo osu akọkọ lọwọ awọn ọmọ ijọ ni wọn se kede aawẹ naa, gẹgẹ bi awọn ijọ kan ti maa nṣe.
Coronavirus in Nigeria: Èèyaǹ 135 ló ṣọ ṣẹ̀ṣẹ̀ kó àrùn Coronavirus ní Naijiria
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ninu atẹjade ti ajọ to n gbogun ti ajakalẹ arun ni Naijria, NCDC, ṣẹṣẹ gbe jade loru Ọjọbọ, eeyan márùndínlógóje, 185, lo ṣẹṣẹ lugbadi Covid-19 ni Naijiria.
Bo tilẹ jẹ pe apapọ awọn to ti ri iwosan ti le ni 146,000, awọn ti arun naa ti mu ẹmi wọn lọ ti le diẹ ni ẹgbẹrun meji.
Atupalẹ iye awọn to ṣẹṣẹ lugbadi Covid-19 ni Naijiria ti NCDC gbe jade ree:
Lagos-41
Imo-20
Ogun-14
FCT-10
Kebbi-11
Rivers-10
Akwa Ibom-8
Plateau-4
Ebonyi-3
Kaduna-3
Kano-3
Osun-3
Oyo-2
Ekiti-1
Gombe-1
Nasarawa-1
Oríṣun àwòrán, NCDC
Abajade ti ajọ NCDC fi lede loju opo Twitter rẹ loru mọju ti fi han pe eeyan mẹsan an lo ba arun Covid-19 lọ ni Naijiria.
Bakan naa ni ajọ ọhun tun kede eeyan mẹ́tàdínláàdọ́wàá, 187, to ṣẹṣẹ ko arun naa ni Naijiria.
Ṣugbọn ikede naa tun fi han pe ọọdunrun ati mẹtalelogun, 323, eeyan ri iwosan gba, ti wọn si ti pada sile wọn.
Iye awọn to ṣẹṣẹ ko arun Covid-19 ni Najiria ree ati ipinlẹ ti wọn ti wa.
Eko-42
Taraba-29
Edo-17
Abia-13
Rivers-11
Kaduna-10
Katsina-9
Oyo-9
Kwara-7
Plateau-7
Ondo-5
Bayelsa-4
Cross River-4
Ogun-4
Osun-4
Akwa Ibom-3
Borno-3
Nasarawa-3
Oríṣun àwòrán, @NCDCgov
Ajọ to n gbogun ti ajakalẹ arun ni Naijiria, NCDC, ti kede eeyan mọ́kàndínlọ́gọ́sàn án to ṣẹṣẹ ko arun Coronavirus ni Naijiria lọjọ Iṣẹgun.
Ṣugbọn ikede naa tun fi han pe eeyan meji jẹ Ọlọrunn jope nipasẹ arun naa, nigba ti ọọdunrun ati ogun eeyan ri iwosan gba, ti wọn si ti pada sile wọn.
Lẹnu ọjọ mẹta yii, iye awọn to n ko arun ọhun ti n dinku si ju ti atẹyinwa lọ.
Iye awọn to ṣẹṣẹ ko arun Covid-19 ni Najiria lọjọ Iṣẹgun ree ati ipinlẹ ti wọn ti wa.
Eko -47
Kaduna-21
Rivers-18
Akwa Ibom-14
FCT-11
Edo-10
Cross River-9
Ogun-9
Nasarawa-6
Ebonyi-5
Ekiti-5
Zamfara-5
Delta-4
Kano-4
Osun-4
Plateau-3
Abia-2
Gombe-1
Sokoto-1
Oríṣun àwòrán, @NCDCgov
Ajọ to n gbogun ti ajakalẹ arun ni Naijiria ti gbe onka iye eeyan tuntun to ṣẹṣẹ lugbadi arun Covid-19 jade lọjo Aje.
Gẹgẹ bii ohun ti wọn gbe jade koju opo Twitter wọn, eeyan òjìlènígba dín meji, 338, lo lugbadi arun naa.
Lẹnu ọjọ mẹta yi, iye awọn to n ko arun ọhun ti n dinku si ju ti atẹyinwa lọ.
Iye awọn to ko arun Covid-19 ni Najiria lọjọ Aje ree ati ipinlẹ ti wọn ti wa.
Eko -72
Kwara-28
Bauchi-19
Kaduna-19
Edo-17
Ogun-15
Nasarawa-13
Rivers-10
FCT-9
Ondo-8
Akwa Ibom-5
Gombe-5
Niger-5
Osun-5
Plateau-4
Oyo-3
Kano-1
Oríṣun àwòrán, TWITTER
Àjọ NCDC ti  kede pe awọn eeyan 205  mii lo lùgbàdì ààrùn Coronavirus ni Nàìjíríà ni Ọjọ Ẹti.
Eeyan 2013 lo ti ba ajakalẹ arun coronavirus lọ bayii ni orilẹede Naijiria.
Lapapọ, eeyan 160,537 ni akọsilẹ ajọ NCDC sọ pe wọn ti  o ni arun Covid-19 ni Naijiria bayii.
Amọ, awọn 144,714  lo ti gba iwosan ninu wọn.
Iye awọn to ko arun covid-19 ni Najiria ati ipinlẹ wọn.
Ondo-33
Lagos-25
FCT-22
Bauchi-21
Akwa Ibom-15
Kaduna-14
Katsina-13
Ogun-13
Rivers-11
Edo-8
Ekiti-4
Imo-4
Kano-3
Nasarawa-2
Niger-2
Oríṣun àwòrán, NCDC
Àjọ NCDC ti  kede pe awọn eeyan 399 mii lo lùgbàdì ààrùn náà ni Nàìjíríà ni Ọjọ Ẹti.
Eeyan 2009 lo ti ba ajakalẹ arun coronavirus lọ bayii ni orilẹede Naijiria.
Lapapọ, eeyan 160,332 ni akọsilẹ ajọ NCDC sọ pe wọn ti  o ni arun covid-19 ni Naijiria bayii.
Amọ, awọn 144,059  lo ti gba iwosan ninu wọn.
Iye awọn to ko arun covid-19 ni Najiria ati ipinlẹ wọn.
Lagos-101
Anambra-96
Edo-50
Abia-29
Imo-28
Ogun-19
Akwa Ibom-16
Kaduna-13
FCT-7
Bayelsa-6
Kano-6
Oyo-6
Delta-5
Rivers-5
Nasarawa-4
Ebonyi-3
Osun-3
Gombe-2
Adinku diẹ ba iye eeyan to lugbadi arun Covid-19 ni Naijiria lỌjọbọ.
Oríṣun àwòrán, NCDC
Ninu atẹjade ti ajọ to n gbogun ti ajakalẹ arun ni Naijria NCDC ti ṣe sọ, eeyan mẹjọ lo ku laarin Ọjọru si Ọjọbọ tawọn ọ̀rìnlénígba lé meje mii lugbadi arun naa.
Lọjọru yi kan naa ni ileeṣẹ to n mojuto ilera alabọde ni Naijiria fiwe sita lori iroyin to gbode pe abẹrẹ Astra-Zeneca to n ṣeku paayan lo wa nita.
Ninu ọrọ ti agbodegba ileeṣẹ yi fi sita, o ni Naijiria ko gba ẹda abẹrẹ naa to ni kọnunkọhọ ninu.
Pupọ awọn ipinlẹ lo ti n ri abẹrẹ gba ninu miliọnu mẹrin ti ijọba Naijria ri gba lọwọ ajọ COVAX to n ṣeto abẹrẹ yi lọfẹ.
Atupalẹ iye awọn to lugbadi Covid-19 ni Naijiria ti NCDC gbe jade ree:
Lagos-107
Kwara-26
Akwa Ibom-23
Bauchi-22
Ogun-21
Rivers-19
Kaduna-14
FCT-11
Abia-8
Edo-8
Ekiti-6
Kano-5
Gombe-4
Osun-4
Oyo-3
Plateau-3
Nasarawa-2
Delta-1
Oríṣun àwòrán, NCDC
Ikede yi wa loju opo wọn ni Twitter.
Ipinlẹ Eko ko si ninu awọn ipinlẹ ti wọn gbe iroyin wọn jade ti Bauchi si le tente pẹlu eeyan marundinlọgrin.
Ni akọsilẹ, apapọ awn to ti lugbadi arun naa bayi ni Naijiria ti di 159,646 ti awọn ti arun naa pa si jẹ 1,993.
Atupalẹ bi nkan ti ṣe ri lawọn ipinlẹ to ku ree:
Bauchi-75
Lagos-36
Akwa Ibom-33
FCT-32
Nasarawa-29
Kaduna-26
Rivers-25
Ogun-22
Oyo-21
Edo-20
Taraba-18
Imo-17
Ondo-17
Borno-8
Plateau-7
Zamfara-4
Osun-3
Kano-1
Oríṣun àwòrán, NCDC
Awọn eeyan to padanu ẹmi wọn lati owo arun Covid-19 ni Naijiria ti di 1,988 lẹ́yin ikede ti ajọ to n gbogun ti ajakalẹ arun ni Naijiria NCDC gbe jade loju opo wọn.
Gẹgẹ bi iṣe wọn, ikede naa fun ti ọjọ Iṣẹgun ṣalaye iye awọn eeyan tuntun to ṣẹṣẹ lugbadi arun naa.
Ohun ta ri nibẹ ni pe eeyan 346 tuntun lo ṣẹṣẹ lugbadi arun naa ni Naijiria ti apapọ iye awọn to ti ni arun naa bayi si jẹ 159,252.
Atupalẹ awọn ipinlẹ ati bi wọn ti ṣe ni arun naa si leyi:
Lagos-86
Bauchi-64
Kaduna-26
Kwara-26
FCT-24
Rivers-23
Plateau-22
Ogun-16
Ebonyi-14
Bayelsa-12
Cross River-10
Edo-8
Akwa Ibom-5
Ekiti-3
Gombe-2
Kano-2
Osun-2
Delta-1
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ajọ to n gbogun ti ajakalẹ arun ni Naijiria NCDC ti gbe onka iye awọn eeyan to  ṣẹṣẹ lugbadi Covid-19 jade lọjọ Aje.
Lori atẹ tuntun yi, ipinlẹ Eko ti wọn ko gbe onka awọn to lugbadi arun naa jade nibẹ lọjọ Aiku ti pada soke pẹlu eeyan mejilelgọrun.
Ijọba ati awọn eleto ilera ni Naijiria ti bẹrẹ si ni fawọn eeyan ni abẹrẹ ajẹsara Covid-19 ti ireti si wa pe pupọ eeyan ni yoo ri gba ninu abẹrẹ naa.
Lapapọ awọn to ti lugbadi arun naa bayi, ikede ti NCDC fi sita loju opo Twitter sọ pe 158,906 ni wọn jẹ.
Eeyan mẹtala lo ku lọjọ Aje ti apapọ awọn taarun naa mu lọ si jẹ 1,982.
Atupalẹ bi nkan ṣe ri lawọn ipinlẹ kọọkan ree:
Lagos-102
Enugu-65
Edo-56
FCT-23
Ogun-20
Osun-18
Bayelsa-18
Rivers-15
Kaduna-14
Plateau-10
Oyo-8
Bauchi-7
Kano-5
Delta-4
Nasarawa-3
Niger-2
Ekiti-1
Oríṣun àwòrán, NCDC
Oríṣun àwòrán, NCDC
Ipinlẹ Eko ko si lori atẹ awọn ipinlẹ tawọn eeyan ti lugbadi Coronavirus eyi ti ajọ NCDC gbe jade fun ọjọ Aiku.
Enugu ni ipinlẹ to le tente pẹlu eeyan mejidinlọgọrin ti Bauchi si tẹle pẹlu eeyan mtadinlọgọrin.
Igba akọkọ kọ niyi ti ipinlẹ Eko ko ni si lori akasọ ṣugbọn ti wọn pada gbe iroyin awọn to lugbadi arun naa nibẹ jade ki il to ṣu.
Lapapọ, iye awọn to ti padanu mi wọn lọwọ Covid-19 ni Naijiria bayi jẹ 1,969 ti awọn 158,506 ni akọsilẹ wa pe wọn lugbadi arun naa.
Atupalẹ bi awọn eeyan ti ṣe lugbadi arun yi lawọn ipinlẹ Naijiria ree:
Enugu-78
Bauchi-37
Rivers-22
Imo-18
Ogun-16
FCT-15
Akwa Ibom-13
Kaduna-13
Kebbi-11
Kwara-9
Edo-7
Ekiti-6
Borno-5
Yobe-5
Kano-4
Nasarawa-3
Osun-3
Anambra-2
Plateau-2
Oríṣun àwòrán, NCDC
Oríṣun àwòrán, NCDC
Niṣe ni iye awọn to lugbadi arun Covid-19 dinku ni Naijiria lọjọ Abamẹta pẹlu ikede lati ọdọ ajọ to n gbogun ti ajakalẹ arun iyẹn NCDC.
Lati iye eeyan 371 si 195 iyatọ eeyan 176 lo waye ninu onka tuntun ti ajọ naa fi soju opo Twitte wọn.
Awọn to lugbadi arun naa lapapọ di eeyan 158,237 ti awọn 137,645 si ti gba itọju tara wọn si ti ya.
Ni onka awọn to ba arun naa lọ, ajọ NCDC sọ soju opo wọn pe wọn jẹ eeyan 1,964 lapapọ ni Naijiria.
Atupalẹ bi awọn eeyan ṣe lugbadi arun naa ree lawọn ipinlẹ Naijiria.
Lagos-70
Kaduna-22
Abia-20
Edo-18
Kano-10
Akwa Ibom-9
Rivers-7
FCT-7
Borno-6
Bauchi-5
Osun-5
Oyo-5
Plateau-3
Ekiti-3
Niger-2
Ogun-2
Zamfara-1
Oríṣun àwòrán, NCDC
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ajọ to n gbogun ti ajakalẹ arun ni Naijiria ti gbe onka iye eeyan tuntun to ṣẹṣẹ lugbadi arun Covid-19 jade fọjọ Ẹti.
Ni oju opo wọn lori Twitter eeyan ọkanlelaadọrinlelọọdunrun,371, lo lugbadi arun naa.
Lẹnu ọjọ mẹta yi, iye awọn to n ko arun ọhun ṣebi ni dinku.
Oríṣun àwòrán, NCDCgov
Bakan naa ni orileede Naijria ti gba abẹrẹ ajẹsara ti awọn eeyan si ti bẹrẹ si ni gba a.
Lọjọ Ẹti ni ẹni akọkọ ti ṣe oṣiṣẹ ilera kan gba abẹrẹ naa ti awọn miran si ti n gba lẹyin rẹ.
Ipinlẹ Eko si le tente ninu awọn ibi ti ọwọja arun ọhun peleke si .
Awọn eeyan 158,042 ni wọn ti lugbadi Covid-19 bayii ti awọn 137,025 si ti gba iwosan lẹyin itọju.
Iye awọn to ku jẹ 1,954 lapapọ.
Oríṣun àwòrán, Reuters
Iye awọn to ko arun Covid-19 ni Najiria ni Ọjọ Ẹti niyii ati ipinlẹ wọn.
Lagos-101Èèyàn 371 míràn ló ṣẹ̀ṣẹ̀ tún lùgbàdì Covid-19 ní Nàìjíríà
Rivers-54
Anambra-31
Ebonyi-23
Imo-23
Kwara-22
Kano-20
Taraba-17
Akwa Ibom-16
FCT-15
Abia-13
Kaduna-13
Osun-5
Edo-4
Oyo-4
Kebbi-3
Ogun-3
Ekiti-2
Nasarawa-1
Zamfara-1
Àjọ NCDC ti  kede pe awọn eeyan 708 mii lo ṣẹṣẹ lùgbàdì ààrùn náà ni Nàìjíríà.
Eeyan 1,951 lo ti ba ajakalẹ aarun Coronavirus lọ bayii ni orilẹede Naijiria.
Lapapọ, eeyan 157,671 ni akọsilẹ ajọ NCDC sọ pe wọn ti larun Covid-19 ni Naijiria bayii.
Amọ, awọn 136,335  lo ti gba iwosan ninu wọn.
Iye awọn to ko arun covid-19 ni Najiria ni Ọjọ Ẹti niyii ati ipinlẹ wọn.
Adamawa-180
Lagos-141
Ondo-60
Anambra-54
Rivers-41
Taraba-33
Edo-30
Abia-22
Kaduna-22
FCT-21
Akwa Ibom-20
Kano-20
Plateau-11
Ekiti-10
Kebbi-10
Nasarawa-10
Bayelsa-7
Ogun-5
Osun-5
Oyo-5
Gombe-1
Àjọ NCDC ti  kede pe awọn eeyan 479 mii lo lùgbàdì ààrùn náà ni Nàìjíríà ni Ọjọ Aje.
Eeyan 1,923 lo ti ba ajakalẹ arun coronavirus lọ bayii ni orilẹede Naijiria.
Lapapọ, eeyan 156,496 ni akọsilẹ ajọ NCDC sọ pe wọn ti  o ni arun covid-19 ni Naijiria bayii.
Amọ, awọn 134,551  lo ti gba iwosan ninu wọn.
Iye awọn to ko arun covid-19 ni Najiria ati ipinlẹ wọn.
Lagos-153
Enugu-75
Rivers-50
FCT-40
Kaduna-18
Ebonyi-17
Plateau-17
Edo-17
Borno-16
Oyo-12
Kano-11
Abia-10
Cross River-10
Taraba-9
Nasarawa-7
Bauchi-4
Bayelsa-3
Delta-3
Ekiti-2
Niger-2
Ogun-2
Akwa Ibom-1
Èèyàn 371 míràn ló ṣẹ̀ṣẹ̀ tún lùgbàdì Covid-19 ní Nàìjíríà
Eeyan 1,915 lo ti ba ajakalẹ arun coronavirus lọ bayii ni orilẹede Naijiria.
Lapapọ, eeyan 156,017 ni akọsilẹ ajọ NCDC sọ pe wọn ti larun covid-19 ni Naijiria bayii.
Amọ, awọn 133,904  lo ti gba iwosan ninu wọn.
Iye awọn to ko arun covid-19 ni Najiria ni Ọjọ Ẹti niyii ati ipinlẹ wọn.
Eko-120
Edo-38
Kaduna-25
FCT-23
Imo-23
Delta-19
Akwa Ibom-17
Plateau-17
Rivers-16
Nasarawa-15
Kwara-13
Oyo-9
Ogun-8
Bauchi-4
Osun-4
Kano-3
Kebbi-3
Niger-2
Katsina-1
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Àjọ NCDC ti  kede pe awọn eeyan 240 mii lo lùgbàdì ààrùn náà ni Nàìjíríà ni Ọjọ Ẹtì.
Eeyan 1,907 lo ti ba ajakalẹ arun coronavirus lọ bayii ni orilẹede Naijiria.
Lapapọ, eeyan 155,657 ni akọsilẹ ajọ NCDC sọ pe wọn ti larun covid-19 ni Naijiria bayii.
Amọ, awọn 133,768  lo ti gbadun ninu wọn.
Iye awọn to ko arun covid-19 ni Najiria ni Ọjọ Ẹti niyii ati ipinlẹ wọn.
Anambra-85
Lagos-82
Osun-17
Ogun-10
Kwara-9
FCT-8
Kano-7
Abia-6
Borno-4
Edo-2
Bayelsa-2
Kaduna-2
Rivers-1
Àjọ NCDC ti  kede pe awọn eeyan 341 mii lo lùgbàdì ààrùn náà ni Nàìjíríà ni Ọjọ Ẹtì.
Eeyan 1,905 lo ti ba ajakalẹ arun coronavirus lọ bayii ni orilẹede Naijiria.
Lapapọ, eeyan 155,417 ni akọsilẹ ajọ NCDC sọ pe wọn ti larun covid-19 ni Naijiria bayii.
Amọ, awọn 133,256  lo ti gbadun ninu wọn.
Iye awọn to ko arun covid-19 ni Najiria ni Ọjọ Ẹti niyii ati ipinlẹ wọn.
Eko-96
Rivers-41
Kaduna-33
Edo-21
Osun-20
Akwa Ibom-17
FCT-17
Ondo-15
Gombe-11
Kano-11
Imo-10
Ekiti-9
Kebbi-9
Kwara-8
Oyo-8
Borno-6
Enugu-3
Plateau-3
Delta-1
Niger-1
Ogun-1
Àjọ NCDC ti  kede pe awọn eeyan 600 mii lo lùgbàdì ààrùn náà ni Nàìjíríà ni Ọjọ Ẹtì.
Eeyan 1,902 lo ti ba ajakalẹ arun coronavirus lọ bayii ni orilẹede Naijiria.
Lapapọ, eeyan 155,076 ni akọsilẹ ajọ NCDC sọ pe wọn ti larun covid-19 ni Naijiria bayii.
Amọ awọn 132,544  lo ti gbadun ninu wọn.
Iye awọn to ko arun covid-19 ni Najiria ni Ọjọ Ẹti niyii.
Eko -169
Taraba-92
Ogun-65
Cross River-57
FCT-38
Rivers-28
Kwara-26
Akwa Ibom-25
Osun-21
Plateau-12
Borno-9
Gombe-9
Abia-8
Ebonyi-8
Ekiti-7
Kano-7
Delta-6
Oyo-6
Bauchi-3
Nasarawa-3
Sokoto-1
Èèyàn 875 míì ti kúrò nílé ìwòsàn, àmọ́ Coro tún ti gbẹ̀mí èèyàn mẹ́jọ o ní Nàìjíríà
Covid-19 tun ṣekú pa èèyàn mẹjọ l'Ọjọru, ọjọ kẹrinlelogun oṣu keji ọdun 2021.
Amọ ẹgbẹrin eeyan ati marunlelaadọrin lo fi ile iwosan silẹ ni Ọjọru bakan naa lẹyin ti wọn ti gbadun tan.
Eeyan 1,885 ni arun coronavirus ti ṣeku pa bayii ni Naijiria, nigba ti eeyan 130,818 ti jajabọ lọwọ arun naa.
Pẹlu iye awọn ọtalelẹgbẹta eeyan din marun tuntun to karun ọhun l'Ọjọru, o ti pe 153,842 eeyan to ti ni arun naa ni Naijiria bayii.
Ipinlẹ Eko lo tun lewaju pẹlu oji le lugba eeyan to lugbadi covid-19 ni Ọjọru.
Iye awọn to ko arun covid-19 ni Najiria ni Ọjọru niyii.
Lagos-240
Ogun-88
Rivers-56
FCT-51
Kaduna-43
Kano-25
Plateau-21
Taraba-19
Edo-17
Abia15
Delta-13
Nasarawa-11
Akwa Ibom-10
Kwara-10
Oyo-10
Kebbi-9
Borno-5
Bayelsa-4
Gombe-4
Ekiti-2
Osun-2
153,842
Èèyàn 170 ló kó coronavirus ní ìpínlẹ̀ Eko nìkan lọ́jọ́ Ìṣẹ́gun
Ajọ to n gbogun ti ajakalẹ aarun lorilẹ-ede Naijiria, NCDC ti kede pe eeyan aadọsan miran lo ko arun coronavirus nipinlẹ Eko nikan lọjọ Iṣẹgun ọjọ kẹtalelogun oṣu keji ọdun 2021.
Ajọ naa tun ṣalaye loju opo Twitter rẹ pe ẹẹdẹgbẹta eeyan ati mọkanlelaadọrin lo lugbadi arun naa kaakiri Naijiria lọjọ Iṣẹgun.
Pẹlu iye awọn eeyan tuntun yii, o ti pe 153,187 eeyan to ti ni arun naa ni Naijiria bayii.
'Tí mi ò bá rí ògùn rà fún ọmọ mi, á máa gé ara rẹ̀ jẹ tí ẹ̀jẹ̀ yóò máa ṣàn'
Awọn 129,943 si ti ri iwosan gba, nigba ti eeyan 1,874 ti jẹ Ọlọrun nipe.
Iye awọn to ko arun covid-19 ni Najiria lọjọ Iṣẹgun niyii.
Lagos-170
Ogun-65
FCT-45
Kwara-34
Abia-32
Enugu-32
Kano-25
Oyo-22
Ondo-21
Rivers-19
Kaduna-19
Benue-18
Bayelsa-12
Kebbi-12
Nasarawa-11
Akwa Ibom-9
Delta-8
Ekiti-6
Niger-5
Bauchi-3
Imo-3
129,300 ló ti jàjà bọ́ lọ́wọ́ Covid-19 ní orílẹ́èdè Nàìjíríà
Ajọ to n gbogun ti ajakalẹ aarun lorileede Naijiria NCDC ti kede pe eeyan 129,300 lo ti ri iwosan lọwọ arun coronavirus bayii.
Ṣugbọn eeyan 1,862 ni o ti ba arun lọ lorilẹede Naijiria lati igba ti ajakalẹ arun ọhun ti bẹ silẹ.
Ojilelẹẹdẹgbẹta eeyan le meji lo tun larun Covid-19 ni Naijiria lọjọ Aje, ọjọ kejilelogun oṣu keji ọdun 2021.
Eeyan 152,616 lapapọ ni ajọ NCDC sọ pe o lo ti ni arun coronavirus kaakiri orilẹede Naijiria.
Ipinlẹ Eko lo si n lewaju iwaju ninu awọn ipinlẹ ti arun naa ti pọju.
Eeyan mọkandinlọgọrun lo tun lugbadi covid-19 l'Eko lọjọ Aje.
Iye awọn to ko arun covid-19 ni Najiria lọjọ Aje niyii.
Lagos-99
Kwara-91
Ebonyi-48
Ogun-44
Kaduna-42
Oyo-33
Ondo-25
FCT-24
Kebbi-23
Osun-20
Ekiti-17
Nasarawa-12
Imo-11
Delta-10
Gombe-9
Kano-8
Katsina-7
Rivers-7
Edo-5
Plateau-4
Bauchi-3
Covid-19 gbẹ̀mí èèyàn mẹ́jọ lọ́jọ́ Àìkú ní orílẹ́èdè Nàìjíríà
Àjọ NCDC ti  kede pe awọn eeyan 521 mii lo lùgbàdì ààrùn náà ni Nàìjíríà ni Ọjọ́ Aiku.
Ajọ naa ni eeyan mẹjọ lo tun ti gbẹmi mi nipasẹ arun naa bayii.
Ipinlẹ Eko lo si lewaju nibi ti eniyan 166 ti lugbadi arun ọhun, nigba ti eeyan mejilelaadọta larun naa nipinlẹ Ogun.
Lapapọ bayii, eeyan 152,074 ni akọsilẹ ajọ NCDC fihan pe wọn ti ko arun covid-19 ni Naijiria.
Amọ eeyan to din diẹ ni ẹgbẹrun lọna aadoje(128,619) lo ti ri iwosan gba ti wọn si ti lọ si ile wọn.
Apapọ awọn ti arun ọhun din diẹ ni ẹgbẹrun meji eeyan(1,839).
Akọsilẹ awọn ipinlẹ to nii covid-19 lọjọ Aiku re e:
Lagos-166
Ogun-52
Rivers-47
Adamawa-37
Ebonyi-37
Akwa Ibom-25
Osun-21
Bayelsa-18
Kaduna-17
Oyo-16
FCT-15
Ekiti-14
Kano-12
Edo-12
Borno-9
Yobe-8
Ondo-6
Nasarawa-4
Bauchi-2
Kwara-3
Coronavirus ti ṣekúpa èèyàn 1,831 ní Nàìjíríà báyìí - NCDC
Ajọ to n gbogun ti aarun lorileede Naijiria NCDC ti gbe ikede iye awọn to lugbadi aarun Covid-19 ni Naijiria fun ọjọ Abamẹta, ogunjọ oṣu keji ọdun 2021 jade.
Ninu ohun ti ajọ NCDC gbe jade loju opo ẹyẹnkọrin Twitter wọn, eeyan 645 lo tun kun awọn to lugbadi aarun yi.
Ipinlẹ Eko si lo lewaju nibi ti ojilelugba eeyan le meji ti ko arun ọhun lọjọ Abamẹta.
Ipinlẹ Ogun lo sikeji pẹlu eeyan mejilelaadọrin, Abuja wa ni ipo kẹta pẹlu aadọta eeyan.
Mẹrinlelogun lo larun naa lati ipinlẹ Osun, mẹtadinlogun nipinlẹ Oyo, mọkanla lati Ekiti nigba ti mọkanla tun lugbadi arun naa lati ipinlẹ Ondo.
Lagos-282
Ogun-72
FCT-50
Kaduna-33
Osun-24
Imo-23
Abia-21
Borno-18
Oyo-17
Edo-15
Nasarawa-15
Taraba-14
Ekiti-11
Ondo-11
Plateau-11
Kano-10
Rivers-7
Delta-5
Bauchi-3
Jigawa-3
Nibayii, eeyan 151,553 lo ti larun covid-19 ni Naijiria, 128,005 ninu wọn si ti jajabọ, amọ 1,831 eeyan lo ti ba arun naa lọ.
A ti rí ẹ̀yà Coronavirus tuntun ní Nàìjíríà- NCDC
Ajọ NCDC ti kede loju opo twitter wọn pe wọn ti ri ọkan lara ẹya aajakalẹ arun Coronavirus ni Naijiria bayii.
Wọn pe orukọ rẹ ni:  ẹ̀yà SARS-CoV-2 ní Nàìjíríà.
Ajọ naa kede pe ki awọn eeyan ṣọra ṣe ṣugbọn ki wọn ma jaya ju nitori ẹjẹ riru.
Wọn ni iwadii to jinlẹ ti bẹrẹ bayii ki wọn le mọ igbese to kanlati mojutoo.
Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó
Èèyàn 627 ni COVID-19 ti pa ní Nàìjíríà láàrín oṣù Dìsẹ́mbà sí àsìkò yìí, 16 ló kú l'Ọ́jọ́bọ̀ nìkan
Ààrùn COVID-19 tún gba ẹ̀mí  èèyàn 16 ní Nàìjíríà, ènìyan 877 míràn sì kún iye àwọn tó láàrùn náà
Eeyan mẹrindinlogun ni COVID-19 tun ṣekupa lorilẹede Naijiria lọjọbọ; pẹlu bi iku to n tipasẹ arun naa wa ṣe n peleke sii lorilẹede Naijiria.
Gẹgẹ bi akọsilẹ ajọ to n gbogun ti ajakalẹ arun lorilẹede Naijiria, NCDC ṣe sọ loju opo ẹyẹ nkọrin Twitter rẹ, ẹgbẹrun kan o le ẹgbẹrin ati mẹta, 1,803 lawọn ti arun naa ti ran jade laye lorilẹede Naijiria.
Eyi fihan pe laarin ọjọ kini oṣu kejila ọdun 2020 si asiko ti a wayi, eeyan okoolelẹgbẹta o le meje, 627 larun naa ti pa lorilẹede Naijiria.
Ajọ NCDC tun jẹ ko di mimọ pe eeyan ọrinlelẹgbẹrin o din mẹta, 877 lo tun ko arun naa lọjọbọ.
Nibayii iye awọn to ni arun naa jẹ ẹgbẹrun lọna aadọja ati ojilelugba o le mẹfa, 150, 246 ninu eyi ti awọn  ẹgbẹerun lọna ọgọfa o le mẹfa ati irinwo o le mẹtadinlogun, 126, 417 ti ri iwosan.
Lagos-273
Kaduna-87
Rivers-58
Akwa Ibom-47
Ebonyi-47
Edo-46
Ogun-46
Abia-34
Imo-34
Kano-34
Oyo-26
Osun-22
Gombe-20
Ekiti-19
Cross River-15
FCT-15
Plateau-11
Enugu-9
Kebbi-8
Borno-7
Niger-6
Bayelsa-5
Nasarawa-4
Kwara-2
Katsina-1
Sokoto-1
Ajọ to n gbogun ti aarun lorileede Naijiria NCDC ti gbe ikede iye awọn to lugbadi aarun Covid-19 ni Naijiria fun Ọjọru, ọjọ kẹtadinlogun oṣu keji jade.
Ninu ohun ti ajọ NCDC gbe jade loju opo ẹyẹnkọrin Twitter wọn, eeyan 869 lo tun kun awọn to lugbadi aarun yi.
Ipinlẹ Eko lo tun pada sipo iwaju lori rẹ lọtẹ yii lẹyin ọjọ diẹ ti o ti fi wa silẹ lori atẹ ọwọja arun COVID-19 ti ajọ naa maa n gbe jade lojumọ pẹlu okoolelugba o le mẹsan an eeyan to tun nii.
Ipinlẹ Rivers tẹle pẹlu 79 ti Taraba Oyo ati Ogun si tẹle pẹlu 73, 66, ati 66 ni ṣisẹ n tẹle
Lagos-229
Rivers-79
Taraba-73
Oyo-66
Ogun-60
FCT-58
Plateau-56
Kwara-38
Ondo-38
Osun-24
Kano-22
Nasarawa-21
Abia-19
Edo-19
Akwa Ibom-19
Cross River-10
Delta-9
Benue-8
Ekiti-6
Borno-6
Katsina-4
Bauchi-3
Bayelsa-1
Zamfara-1
Àjọ NCDC ti fi ọrọ sita pe aarun COVID-19 tun ti ran eeyan mẹrindinlogun lọ sọrun lọjọ Iṣẹgun lorilẹede Naijiria.
Bakan naa ni ajọ tun ṣalaye pe eeyan okoolelẹẹdẹgbẹta (520) lo tun ko aarun naa ninu ikede to fi sita lọjọ kẹrinla oṣu keji ọdun 2021.
NCDC sọ pe ipinlẹ Ondo lo ṣiwaju pẹlu ọgọfa eeyan tuntun to ko aarun naa.
Awọn ipinlẹ mii to nii arun naa niwọnyii:
Anambra-344
Oyo-172
FCT-148
Benue-107
Rivers-95
Ogun-59
Ondo-56
Ebonyi-53
Kaduna-52
Plateau-46
Kwara-36
Enugu-30
Akwa Ibom-26
Osun-22
Edo-20
Abia-17
Kano-16
Borno-15
Cross River-10
Delta-8
Gombe-8
Imo-7
Ekiti-5
Sokoto-4
Jigawa-3
Bayelsa-3
Nasarawa-3
Zamfara-3
Àjọ NCDC ti  kede pe awọn eeyan 574 lo lùgbàdì ààrùn náà ni Nàìjíríà ni Ọjọ́ Aje.
aj naa ni eeyan mẹjọ lo tun ti gbẹmi mi nipasẹ arun naa bayii.
Ipinlẹ Kwara ni eniyan 98 to lugbadi ọhun, nigba ti ilu Eko naa ni akọsilẹ eeyan 81 to ni arun ọhun.
Akọsilẹ awọn ipinlẹ to nii re e:
Kwara- 98
Lagos- 81
Edo- 59
Ondo- 44
FCT- 41
Kano- 34
Ogun- 33
Kaduna- 29
Osun- 28
Enugu- 23
Rivers- 18
Delta-16
Akwa Ibom-15
Bauchi-12
Imo-10
Borno-8
Niger-8
Kebbi-7
Nasarawa-5
Gombe-3
Ekiti-2
Lọwọyii apapọ iye awọn to ti ko aarun naa ni Naijiria jẹ ẹgbẹrun mẹrindinlaadọjọ o le okoolelẹẹdẹgbẹrun ati mẹjọ, 146, 928
Ẹgbẹrun mẹtalelọgọfa ati mẹsan, 123, 009 eeyan lo ti riwosan.
Àjọ NCDC ti fi ọrọ sita pe aarun COVID-19 tun ti ran eeyan marun un lọ sọrun lọjọ Valentine lorilẹede Naijiria.
Bakan naa ni ajọ tun ṣalaye pe eeyan okoolelẹẹdẹgbẹta (520) lo tun ko aarun naa ninu ikede to fi sita lọjọ kẹrinla oṣu keji ọdun 2021.
NCDC sọ pe ipinlẹ Ondo lo ṣiwaju pẹlu ọgọfa eeyan tuntun to ko aarun naa.
Awọn ipinlẹ mii to nii arun naa niwọnyii:
Ondo-120
Borno-41
Ebonyi-37
Benue-33
Plateau-30
FCT-29
Nasarawa-25
Ogun-25
Edo-24
Osun-24
Katsina-22
Kaduna-21
Niger-20
Kwara-14
Ekiti-13
Yobe-10
Oyo-4
Bayelsa-1
Jigawa-1
Lọwọyii apapọ iye awọn to ti ko aarun naa ni Naijiria jẹ ẹgbẹrun mẹrindinlaadọjọ o le mẹrinlelọgọsan, 146, 184
Ẹgbẹrun lọna ọgọfa ati ojilelẹgbẹrin o din meji (120, 838) eeyan lo ti riwosan
Àjọ NCDC ti fi ọrọ sita pe eeyan mẹtala miran ni aarun COVID-19 tun ti ran lọ sọrun lọjọ kan ṣoṣo lorilẹede Naijiria.
Bakan naa ni ajọ ọhun fi kun un pe ni ipinlẹ Eko nikan ṣoṣo, eeyan okoolelọọdunrun o din ẹyọkan, (319) lo tun ti kagbako aisan Covid-19.
Wọn si tun kede rẹ pe awọn ẹgbẹrun kan o le ogoje ati mẹta (1,143) lo tun lugbadi aarun naa lọjọ Ababmẹta ọjọ kẹtala oṣu keji ọdun 2021 ni Nàìjíríà lọ́jọ́bọ̀.
Lẹyin ipinlẹ Eko ni ilu Abuja naa ni akọsilẹ eeyan mẹtadinlọgọjọ, (157) to ni arun ọhun. Awọn ipinlẹ mii to nii ni:
Lagos-319
FCT-157
Kwara-90
Oyo-74
Enugu-72
Nasarawa-69
Imo-58
Osun-51
Gombe-49
Kaduna-31
Edo-23
Katsina-23
Kebbi-23
Ogun-22
Kano-19
Rivers-19
Ebonyi-18
Plateau-14
Delta-7
Ekiti-5
Lapapọ bayii, eeyan 145, 664 ni akọsilẹ Ajọ NCDC fihan pe wọn ti larun covid-19 ni Naijiria ti awọn 120, 399 ti gba itusilẹ amọ eeyan 1,747 lo ti gba tibi aisan yii ku.
Àjọ NCDC ti  kede pe awọn eeyan 1005 lo lùgbàdì ààrùn náà ni Nàìjíríà ni Ọjọ́ Ẹti.
Ipinlẹ Eko ni eniyan 204 to lugbadi ọhun, nigba ti ilu Abuja naa ni akọsilẹ eeyan 75 to ni arun ọ́hun.
Akọsilẹ awọn ipinlẹ to nii re e:
Lagos-204
Kwara-155
Oyo-124
Plateau-80
FCT-75
Edo-56
Osun-48
Ondo-41
Kaduna-40
Rivers-40
Taraba-35
Borno-32
Ekiti-21
Ogun-20
Kano-14
Bayelsa-8
Delta-7
Bauchi-3
Jigawa-2
Àjọ NCDC ti fi ọrọ sita pe ni ipinlẹ Eko nikan ṣoṣo, eeyan 236 lo kagbako aisan Covid-19 ti wọn si tun kede pe awọn 938 lo lùgbàdì ààrùn náà ni Nàìjíríà lọ́jọ́bọ̀.
Lẹyin ipinlẹ Eko ni ilu Abuja naa ni akọsilẹ eeyan 123 to ni arun ọ́hun. Awọn ipinlẹ mii to nii ni:
Plateau-92
Benue-63
Katsina-53
Oyo-50
Osun-45
Kaduna-43
Edo-33
Ogun-31
Ebonyi-31
Akwa Ibom-30
Kano-26
Gombe-18
Bauchi-16
Delta-12
Imo-11
Cross River-10
Rivers-10
Niger-5
Lapapọ bayii, eeyan 143,516 ni akọsilẹ Ajọ NCDC fihan pe wọn ti larun covid-19 ni Naijiria ti awọn 118,012 ti gba itusilẹ amọ eeyan 1,710 lo ti gba tibi aisan yii ku.
Àjọ tó n gbógun ti àjàkalẹ̀ ààrùn ní Nàìjíríà, NCDC tí kéde pé òun ti ṣe ìwé ìtọ́ni tí àwọn tó bá ni ààrùn covid-19 le lò láti ṣe ìtọ́jú ara wọn nínú ilé.
Lójú òpó twitter àjọ náà ló gbe sí lọ́jọ́ Iṣẹ́gun pé àwọn ti ṣe ìwé ìléwọ́ tí yóò ràn àwọn tó bá ni ààrùn Covid-19 ti ko lágbára púpọ̀ láti le ṣe ìtọ́jú ara wọn nínú ilé.
Nínú ìwé náà ni àkorí mẹ́ta:
*Ọ̀nà láti ṣe ìtọ́ju ara ẹni nínú ilé
* Ọ̀nà láti dènà ààrùn náà lẹ́ẹ̀kejì
* Ọ̀nà láti mọjú tó ààrùn náà tó bá ti n fi àwọn àmì kan hàn
Tọ ojú ìlà yìí láti kaàwọn ìlànà náà kí o lé mọ bi ọ ṣe le ṣe ìtọ́jú ààrùn covid-19 ninu ilé.
Ẹ̀wẹ̀ àjọ náà tún kéde pé ènìyàn 1,056 lo tun lùgbàdì ààrùn náà ni Nàìjíríà lọ́ja ìṣẹ́gun lòdì sí ènìyàn 643 tó jẹyọ lọjọ́ ajé.
Lagos-214
Osun-120
FCT-116
Plateau-88
Ebonyi-75
Kwara-73
Gombe-70
Ondo-57
Rivers-47
Akwa Ibom-38
Edo-25
Oyo-23
Kano-22
Delta-19
Katsina-18
Borno-16
Nasarawa-13
Ekiti-8
Ogun-8
Bauchi-4
Benue-1
Jigawa-1
Ìpínlẹ̀ mẹ́jìlélógún ni àwọn tó ni ààrùn náà ti jẹyọ.
Ní báyìí, ènìyàn 115,755 ló ti jàjàba lọ́wọ́ ààrùn covid-19 nígbà ti ènìyàn 1,694 ti báarìn.
Àjọ NCDC ti kilọ pé, ààrùn Covid-19 kò tíì tán nílẹ̀, ọwájà rẹ̀ sí n takálé, ta ká oko títí di àsìkò yìí.
Lásìkò tí ọgá àgbà àjọ náà Chikwe Ihekweazu ń sọ̀rọ̀ níbi ètò ìjábọ̀ ojojúmọ́ ti ìgbìmọ̀ PTF máa sẹ, pé ó ṣe pàtàkì láti jìnà réré síbi ayẹyẹ ti èrò bá pọ̀ sí  kí wọ́n sì má fọwọ́ déedé.
Ẹ̀wẹ̀, nínú àtẹ̀jáde olójoojúmọ́ lójú òpó twitter NCDC  ni wọ́n ti kéde kéde pé ènìyàn 643 ló tún ṣẹ̀ṣẹ̀ lùgbàdì ààrùn covid-19 nínú èsì àyẹ̀wò tó jáde lọ́jọ́ ajé.
Wo ìgbé àyé ìyá àti ọmọbìnrin tó ń fi iṣẹ́ aṣẹ́wó jẹun
Oyo-88
Lagos-86
Rivers-55
Edo-54
Akwa Ibom-53
Adamawa-52
Plateau-45
Kaduna-41
FCT-34
Kwara-27
Benue-20
Kano-19
Delta-18
Nasarawa-16
Niger-15
Bayelsa-11
Borno-5
Bauchi-2
Sokoto-2
Ìpínlẹ̀ Oyo ló dúró lókè tẹéńté lórí tábílì lọ́tl yìí nígbà ti Eko wà ni ipò kẹta.
Gẹ́gẹ́ bi NCDC se sọ, àwọn ènìyàn 744 lo gba ìtúsílẹ̀ ni ìpínlẹ̀ Eko, 100 nípìnlẹ̀ Rivers, 78 ní ìpínlẹ̀ Plateau, 72 ní Kaduna nígbà tí wọ́n tú ènìyàn 2 sílẹ̀ ni Benue..
Ní báyìí ènìyàn 14,391 ló ti ni ààrùn covid-19 ni Nàìjíríà nígbà tí 114,635 gba ìtúsílẹ̀ nígbà tí ènìyàn 1,673 ti bá ààrùn covid-19 lọ.
Láti bí ọ̀sẹ̀ díẹ̀ sẹ́yìn báyìí ni ọwọ́jà ààrùn coronavirus ti n peléke sii, sùgbọ́n àbájáde èsì àyẹwò olójoojúmọ́ ti àjọ NCDC máa ń gbé jáde lójoojúmọ́ fi hàn pé èsì àyẹ̀wò ọja Aiku ṣẹ́ pẹ́rẹ́.
Ní ọjọ́ Aiku àjọ NCDC fi léde pé, ènìyàn méjì lé lẹ́ẹ̀dẹ́gbẹ̀ta ló ni ààrùn náà lórílẹ̀-èdè Nàìjíríà ni àwọn ìpínlẹ̀ ti èsì tí jáde.
Ipò kẹsan ni ìpínlẹ̀ Eko tó máa n sábà lé wájú wà lónìí nígbà ti ìpińlẹ̀ Ondo, Kwara àti Rivers gbégbá orókè nínú àwọn ìpińlẹ̀ to ni ààrùn náà.
Àlàyé ipò ti ìpínlẹ̀ kọ̀ọ̀kàn tó jẹyọ wà rèé:
Ondo-90
Kwara-89
Rivers-53
Borno-45
Gombe-32
FCT-28
Imo-26
Ogun-25
Lagos-22
Kaduna-14
Kano-14
Edo-13
Osun-11
Cross River-10
Yobe-9
Ekiti-7
Kebbi-6
Nasarawa-6
Oyo-5
Jigawa-1
Ní báyìí apapọ ènìyàn tó ti lùgbàdì ààrùn coronavirus ni Nàìjíríà ni 139,748, ènìyàn  113,525 lo ti san ti wọn sì ti padà sílé wọn  nígbà ti ènìyàn 1,667 ti bá ìṣẹ̀lẹ̀ náà rìn.
Lánàá òde yìí ni àjọ NCDC fìdí rẹ̀ múlẹ̀ pé, ènìyàn mílíọ̀nù kan ni òun ti ṣe ayẹwò fún ni Nàìjíríà láti bi ọdún kan sẹ́yìn.
Coronavirus in Nigeria: Ènìyàn 1,588 tún ti lùgbàdì ààrùn Covid-19 ní Nàijíríà.
Àjọ tó n gbógun ti ààrùn coronavirus ní Nàìjíríà (NCDC) tí kéde lóru mójúmọ́ pé ènìyàn 1,588 ló tún ṣẹ̀ṣẹ̀ lùgbàdì ààrùn coronavirus ni Nàìjíríà.
Gẹ́gẹ́ bí wọ́n ṣe gbé e sójú òpó twitter wọn pé, ìpínlẹ̀ Eko ló ṣì tún léwájú nínú àwọn ìpińlẹ̀ tó ni ààrùn náà jùlọ pẹ̀lú ènìyàn 535 tó jẹ́ iye kan náà gẹ́gẹ́ bíi ìròyìn tí ìjẹta, Anambra ló tẹ̀lé pẹ̀lú ènìyàn 218, Oyo jẹ́ 155, Abuja 150.
Kano-124, Gombe-60, Kaduna-49, Ebonyi-48, Plateau 46, Akwa Ibom-39, Niger-37, Edo-33, Katsina-23, Rivers-18, Taraba-15, Nasarawa-14, Ogun-11, Delta-9, Ekiti-2, Jigawa-2 ní ọjọ́ Àbámẹ́ta.
Ní báyìí àpapọ̀ àwọn tó ti ní ààrùn coronavirus ni Nàìjírí ti jẹ́ 139,242, ènìyàn 112,557 ti rí ìwòsan nígbà tí ènìyàn 1,647 tí bá ìṣẹ̀lẹ̀ ààrùn Covid-19 lọ.
Coronavirus in Nigeria: Ènìyàn 1,340 tún ti lùgbàdì ààrùn Covid-19 ní Nàijíríà
Ajọ to n gbogun ti aarun lorileede Naijiria, NCDC ti gbe ikede iye awọn to lugbadi aarun Covid-19 jade ni Naijiria.
Ninu ohun ta a ri ka loju opo wọn ni Twitter ni pe eeyan 1,340 tuntun mii lo tun lugbadi aarun yii.
Olu ile orilẹede Naijiria, Abuja to lewaju ipinlẹ ti ọwọja aarun yi pọ si lori atẹ;
FCT-320
Lagos-275
Rivers-117
Oyo-100
Akwa Ibom-57
Ogun-51
Ebonyi-48
Benue-44
Adamawa-42
Imo-38
Kwara-35
Gombe-32
Kaduna-31
Edo-29
Osun-29
Kano-24
Ekiti-15
Katsina-14
Delta-13
Nasarawa-13
Jigawa-10
Sokoto-3
Rivers-36
Niger-32
Oyo-32
Borno-29
Kaduna-27
Delta-18
Kwara-17
Cross River-9
Ekiti-8
Bauchi-7
Ogun-7
Sokoto-6
Bayelsa-3
Ajọ to n gbogun ti aarun lorileede Naijiria, NCDC ti gbe ikede iye awọn to lugbadi aarun Covid-19 jade ni Naijiria.
Ninu ohun ta a ri ka loju opo wọn ni Twitter ni pe eeyan 1634 tuntun mii lo tun lugbadi aarun yii.
Ipinlẹ Eko to lewaju ipinlẹ ti ọwọja aarun yi pọ si lori atẹ;
Lagos-440
Anambra-160
FCT-158
Rivers-134
Abia-103
Oyo-90
Enugu-81
Osun-73
Gombe-54
Kwara-50
Ogun-32
Plateau-32
Akwa Ibom-31
Ondo-24
Borno-23
Delta-23
Ebonyi-21
Taraba-21
Bayelsa-16
Kaduna-15
Nasarawa-13
Jigawa-12
Bauchi-11
Kano-11
Zamfara-4
Sokoto-2
Ajọ to n gbogun ti aarun lorileede Naijiria, NCDC ti gbe ikede iye awọn to lugbadi aarun Covid-19 jade ni Naijiria.
Ninu ohun ta a ri ka loju opo wọn ni Twitter ni pe eeyan 676 tuntun mii lo tun lugbadi aarun yii.
Ipinlẹ Eko to lewaju ipinlẹ ti ọwọja aarun yi pọ si lori atẹ;
Lagos-227
Rivers-73
Niger-69
Plateau-56
FCT-50
Kano-44
Oyo-43
Ogun-27
Gombe-18
Ondo-15
Enugu-10
Osun-10
Cross River-8
Edo-8
Nasarawa-7
Bauchi-4
Kaduna-3
Ekiti-2
Zamfara-2
Ajọ to n gbogun ti aarun lorileede Naijiria, NCDC ti gbe ikede iye awọn to lugbadi aarun Covid-19 jade ni Naijiria.
Ninu ohun ta a ri ka loju opo wọn ni Twitter ni pe eeyan 685 tuntun mii lo tun lugbadi aarun yii.
Ipinlẹ Eko to lewaju ipinlẹ ti ọwọja aarun yi pọ si lori atẹ;
Lagos-355
Kaduna-58
Nasarawa-46
Kano-40
Akwa Ibom-33
Katsina-26
Ogun-25
Osun-21
Rivers-16
Edo-15
Oyo-13
Ondo-12
Borno-11
Ekiti-9
Kebbi-3
Plateau-2
Ajọ to n gbogun ti aarun lorileede Naijiria NCDC ti gbe ikede iye awọn to lugbadi aarun Covid-19 jade ni Naijiria.
Ninu ohun ta a ri ka loju opo wọn ni Twitter ni pe eeyan 1883 tuntun mii lo tun lugbadi aarun yii.
Ipinlẹ Eko to lewaju ipinlẹ ti ọwọja aarun yi pọ si lori atẹ.
Lagos-1040
FCT-298
Anambra-86
Rivers-54
Taraba-45
Ogun-42
Oyo-40
Akwa Ibom-38
Sokoto-30
Ebonyi-30
Imo-28
Kaduna-28
Osun-27
Kano-21
Benue-19
Edo-17
Gombe-15
Ekiti-9
Delta-8
Jigawa-3
Kwara-2
Bayelsa-2
Plateau-1
Ajọ to n gbogun ti aarun lorileede Naijiria NCDC ti gbe ikede iye awọn to lugbadi aarun Covid-19 jade ni Naijiria.
Ninu ohun ta ri ka loju opo wọn ni Twitter eeyan 1114  tuntun mii lo lugbadi aarun yi.
Ipinlẹ Eko to lewaju ipinlẹ ti ọwọja aarun yi pọ si lori atẹ.
Ajọ to n gbogun ti aarun lorileede Naijiria NCDC ti gbe ikede iye awọn to lugbadi aarun Covid-19 jade fọjọbọ ni Naijiria.
Ninu ohun ta ri ka loju opo wọn ni Twitter eeyan 864 tuntun mii lo lugbadi aarun yi.
Ipinlẹ Eko to maa n lewaju ipinlẹ ti ọwọja aarun yi pọ si ko si lori atẹ.
Abuja lo lewaju pẹlu 129 ti Anambra Rivers ati Benue si tẹle pẹlu 87,82 ati 80.
Ipinlẹ Oyo pọnwọ lewọn pẹlu eeyan 76.
Apapọ awọn ti aarun yi mu lọ ni Naijiria nilẹ oni to mọ si jẹ 1547.
Awọn to ri iwosan gba lapapọ ni Naijiria lati igba ti aarun ọhun ti bẹrẹ jẹ 100,853 bayi.Gbogbo awọn to lugbadi Covid-19 bayi wa ni isiro 127,024.
864 new cases of #COVID19Nigeria;
FCT-129
Anambra-87
Rivers-82
Benue-80
Oyo-76
Plateau-61
Kaduna-54
Delta-51
Nasarawa-38
Kwara-36
Edo-32
Katsina-26
Kano-24
Taraba-18
Ogun-14
Sokoto-11
Gombe-10
Jigawa-7
Akwa Ibom-6
Cross River-6
Zamfara-5
Bauchi-5
Osun-4
Ekiti-2
Ọwọja aarun Covid-19 ni Naijiria tun ti n gbori soke pẹlu bi eeyan 1,861 tuntun mii ṣe lugbadi aarun ọhun lọjọru.
Ninu akọsilẹ ti ajọ to n gbogun ti aarun yi fi sita loju opo wọn, eeyan mejilelogun lo ku ti apapọ  awọn to ri iwosan si jẹ 100,365.
Lọjọru yi kan naa ni aarẹ Muhammadu Buhari buwọlu ofin eyi to sọ di ẹsẹ fẹnikẹni ti ko ba lo ibomu.
Ijiya ẹwọn oṣu mẹfa ni aarẹ fi lelẹ fẹnikẹni ti o ba kọ lati wọ ibomu ni ita.
Bẹẹ naa ni  ofin yi tun fi gbogbo awọn ilana to wa nilẹ tẹlẹ rinlẹ.
Ni apapọ bayii iye awọn to ti lugbadi aarun Covid-19 ni Naijiria ti di 126,160.
Atupalẹ bi nkan ti ṣe ri ree lawọn ipinlẹ kọọkan.
1,861 new cases of #COVID19Nigeria;
Lagos-773
FCT-285
Oyo-138
Rivers-111
Plateau-92
Nasarawa-83
Kaduna-59
Enugu-57
Imo-57
Edo-43
Kano-27
Kwara-20
Ebonyi-19
Abia-17
Ogun-12
Osun-12
Katsina-8
Bayelsa-6
Bauchi-5
Delta-5
Borno-4
Jigawa-4
Zamfara-1
Lọjọ Iṣẹgun, eeyan mẹẹdogun lo padanu ẹmi wọn lọwọ aarun Covid-19  gẹgẹ bi ikede lati ọdọ ajọ to n gbogun ti ajakalẹ aarun ni Naijria NCDC ṣe sọ.
Ninu atupalẹ awọn to lugbadi aarun naa, wọn s bakan naa pe eeyan 1,303 tuntun mii lo ko aarun yi ti awọn ejidinlọgọrinleniirinwo si wa lati ipinlẹ Eko.
Abuja tẹle Eko pẹlu eeyan ọkanlelẹwaalenigba.
Nassarawa, Rivers ati ati Kwara lo pọnwọ lewọn lori atẹ.
Lapapọ iye awọn to lugbadi aarun naa ni Naijiria bayi jẹ 124,299 ti awọn to si ba aarun naa lọ jẹ 1,522
Ajọ to n gbogun ti ajakalẹ arun ni Naijiria, NCDC, ti kede pe eeyan 1,430 lo lugbadi arun coronavirus lọjọ Aje kaakiri orilẹede Naijiria.
Ẹrinlelogojilelẹẹdẹgbẹrin eeyan lo wa lati ipinlẹ Eko nikan nigba ti ọgọrun  wa lati ipinlẹ Plateau.
Mẹtadinlọgọrin wa lati Oyo, mejilelọgbọn lati ipinlẹ Kwara ti marun un si wa lati ipinlẹ Ekiti.
Lapapọ eeyan 112,996 lo ti karun naa lorilẹede Naijiria bayii, nigba ti 98,359 ninu wọn ti ri iwosan.
Eeyan 1,507 ni arun covid-19 ti ṣekupa ni Naijiria.
Ikede iye awọn to lugbadi Covid-19 ti ajọ NCDC gbe jade lọjọ Aiku ni Naijiria ṣe afihan adinku diẹ ninu awọn to lugbadi aarun naa.
Lẹnu ọjọ mẹta yi, bi kii wọn maa gbe iroyin eeyan to kọja ẹgbẹrun koda a ti ri eyi to le ni ẹgbẹrun meji eeyan to lugbadi aarun naa ti wọn fi sita.
Ni bayi, wọn ni eeyan 964 tuntun mi lo lugbadi aarun Covid-19 ni Naijiria ti awọn meji si padanu ẹmi wọn.
Ipinlẹ Eko naa si ni ibi ti ọwọja aarun yi ti pọju lọ pẹlu eeyan 36o ti Jigawa ni eyi to kere julọ pẹlu eeytan mẹrin.
Atupalẹ bi awọn ipinlẹ iyoku ti ṣe ri ree:
Lagos-360
FCT-88
Ogun-73
Imo-72
Kaduna-67
Plateau-57
Abia-41
Osun-41
Rivers-32
Kano-26
Niger-24
Benue-23
Edo-20
Cross River-20
Akwa Ibom-8
Nasarawa-6
Zamfara-6
Ekiti-6
Jigawa-4
121,566 confirmed
97,228 discharged
1,504 deaths
Ipinlẹ Eko ti wọn ko kọkọ fi sori atẹ ipinlẹ tawọn eeyan ti lugbadi arun Covid-19 lọjọ Ẹti ti pada soke bayi pẹlu eeyan mejidinlẹẹdẹgbẹta to lugbari aarun naa.
Ninu ikede ti ajọ NCDC fi sita loju opo wọn ni Twitter, eeyan to ṣẹṣẹ lugbadi aarun Covid-19 ni Naijiria bayi jẹ 1,633.
Eeyan marun un mii lo padanu ẹmi wọn lọwọ aarun yi ti o si mu ki apapọ awọn to ku ni Naijiria bayi jẹ 1,502.
Awọn tara wọn ya ti di eeyan 95,901 ti apapọ awọn to ti ko aarun naa si jẹ 120,602.
1,633 new cases of #COVID19Nigeria;
Lagos-498
Plateau-214
FCT-176
Rivers-99
Kaduna-98
Edo-87
Anambra-86
Akwa Ibom-50
Osun-47
Kano-40
Oyo-40
Kwara-39
Ebonyi-28
Niger-28
Taraba-28
Ogun-27
Ondo-21
Ekiti-12
Katsina-7
Borno-6
Delta-2
120,602 confirmed
95,901 discharged
1,502 deaths
Ikede iye awọn to lugbadi Covid-19 ni Naijiria ti ajọ NCDC gbe jade gẹgẹ bi iṣe wọn ko sọ nkankan nipa iye awọn to lugbadi aarun naa ni ipinlẹ Eko.
Gẹgẹ bi ajọ naa ti ṣe sọ , yatọ si iroyin Eko ti wọn ko gbe sita, aṣikọ waye ninu iye awọn to lugbadi aarun naa ni Zamfara.
Dipo eeyan mẹta to yẹ ki wọn kọ, eeyan kan ṣoṣo ni wọn sọ pe o lugbadi aarun ọhun.
Lori oke tente ni ipinlẹ Kaduna wa pẹlu eeyan 545 to lugbadi aarun naa nibẹ ti Abuja siu tẹle lẹyin pẹlu eeyan 235.
Niger lo ni iye eeyan to kere julọ ti apapọ eeyan to ni aarunnaa ni Naijiria lọwọ yi si jẹ 118, 138.
Atupalẹ awọn ipinlẹ to ku ree:
1483 new cases of #COVID19Nigeria;
Kaduna-545
FCT-235
Plateau-127
Nasarawa-80
Oyo-72
Delta-65
Rivers-64
Kano-46
Ogun-46
Bayelsa-30
Gombe-30
Abia-28
Osun-27
Edo-25
Ondo-14
Sokoto-12
Zamfara-10
Bauchi-8
Imo-5
Jigawa-4
Ekiti-4
Borno-4
Niger-2
1964 new cases of #COVID19Nigeria;
Lagos-824
FCT-246
Plateau-166
Kaduna-128
Ogun-76
Nasarawa-74
Anambra-69
Edo-50
Rivers-45
Ondo-44
Niger-40
Oyo-38
Adamawa-35
Kano-31
Akwa Ibom-27
Gombe-19
Kwara-13
Ekiti-12
Delta-6
Kebbi-6
Bauchi-5
Ebonyi-4
Osun-3
Zamfara-1
Covid-19 ti ṣekúpa èèyàn 1,478 báyìí ní Nàìjíríà, 92,336 ti jàjàbọ́
Covid-19 ti ṣekúpa èèyàn 1,478 báyìí ní Nàìjíríà, 92,336 ti jàjàbọ́
Ajọ to n gbogun ti ajakalẹ aarun lorilẹ-ede Naijiria, NCDC ti kede pe eeyan 1386  miran ti kun iye awọn to ti ni aarun COVID-19 ni Naijiria.
Pẹlu iye awọn eeyan tuntun yii, o ti pe 114,691 eeyan to ti ni arun naa ni Naijiria bayii.
Awọn 92,336 ti ri iwosan gba, nigba ti eeyan jẹ Ọlọrun nipe.
Lagos-476
Rivers-163
FCT-116
Kaduna-114
Oyo-68
Plateau-62
Ogun-56
Imo-55
Osun-55
Edo-51
Anambra-50
Kwara-44
Kano-17
Ebonyi-14
Cross River-10
Delta-10
Jigawa-8
Bayelsa-6
Ekiti-6
Borno-2
Taraba-2
Zamfara-1
Gẹgẹ bi akọsilẹ yii, ipinlẹ Eko lo si n ni awọn to pọ julọ to ni arun coronavirus ni Naijiria.
Ìpínlẹ̀ Eko ló ń léwájú nínú àwọn tó lùgbàdì Covid 19 lánàá- NCDC
Ibi ni ọrọ de duro lori itankalẹ ajakalẹ arun Covid 19 ni Naijiria:
Lagos-551
FCT-209
Oyo-83
Plateau-65
Kaduna-64
Enugu-61
Rivers-44
Ondo-39
Benue-37
Akwa Ibom-31
Kano-19
Delta-18
Gombe-18
Ogun-16
Edo-15
Kebbi-10
Ebonyi-9
Jigawa-4
Osun-3
Zamfara-3
Borno-1
Nasarawa-1
Coronavirus tún ṣekúpa èèyàn mẹ́rìnlá lọ́jọ́ Ajé, ẹni 1,617 míì tún kó
Ajọ NCDC to n gbogun ti ajakalẹ arun ni Naijiria tun ti kede pe eeyan 1,617 lo ko arun coronavirus lọjọ Aje, ọjọ kejidinlogun oṣu kinni ọdun 2021 yii.
Gẹgẹ bi akọsilẹ ajọ NCDC, eeyan mẹrinla mii ni covid-19 tun ṣekupa lọjọ Aje eyi to mu di 1,449 to ti gbẹmi mi bayii nipasẹ covid-19 ni Naijiria.
Ipinlẹ Eko lo tun siwaju ninu awọn ipinlẹ to larun naa julọ pẹlu eeyan 776 lọjọ Aje.
Mẹtalelaadọta lo lugbadi arun ọhun lati ipinlẹ Ogun, marunlelogoji l'Osun.
Wọnyii ni atupalẹ iye awọn to lugbadi arun covid-19 ni Naijiria lọjọ Aje:
Lagos-776
Kaduna-147
Kwara-131
FCT-102
Plateau-78
Edo-59
Ogun-53
Osun-45
Rivers-37
Taraba-36
Nasarawa-34
Adamawa-33
Kano-26
Delta-20
Ebonyi-16
Bayelsa-11
Gombe-11
Borno-2
Lapapọ, eeyan 112,004 ni akọsilẹ fihan pe wọn ti larun covid-19 ni Naijiria nigba ti 89,939 ti ri iwosan.
Èèyàn 1444 ló tún kó coronavirus lórílẹ́èdè Nàijíríà lọ́jọ́ Àìkú
Ajọ to n gbogun ti ajakalẹ arun ni Naijiria, NCDC, ti kede pe eeyan 1444 lo lugbadi arun coronavirus lọjọ Aiku kaakiri orilẹede Naijiria.
Ẹẹdẹgbẹrun eeyan lekan(901) lo wa lati ipinlẹ Eko nikan nigba ti 136 wa lati ipinlẹ Plateau.
Mẹrinlelaadọta wa lati Abuja, mọkandinlọgbọn lati ipinlẹ Osun, mẹrindinlogun lo ko arun naa nipinlẹ Oyo.
Eeyan mejidinlọgbọn lo ni coronavirus nipinlẹ Ogun lọjọ Aiku, .
Lapapọ eeyan 110,387 lo ti karun naa lorilẹede Naijiria bayii, nigba ti 89,317 ninu wọn ti ri iwosan.
Eeyan 1,435 ni arun covid-19 ti ṣekupa ni Naijiria.
Èèyàn 1,598 míì tún ti lùgbàdì covid-19 ní Nàijíríà, 1,420 ló ti kú báyìí
Ajọ to n gbogun ti ajakalẹ arun ni Naijiria, NCDC ti kede loju opo Twitter rẹ pe eeyan 1,598 lo tun ko coronavirus lọjọ Abamẹta kaakiri orilẹede Naijiria.
Ọta le ni irinwo lekan(461) o lekan ninu wọn lo wa lati ipinlẹ Eko eyi to pọ julọ.
Olu ilu Naijiria Abuja lo ṣe ipo keji nibi ti igba eeyan o le mẹfa ti lugbadi coronavirus lọjọ Abamẹta.
Eeyan 168 lo ni covid-19 nipinlẹ Rivers, mọkandinlaadọta l'Ogun, ọgbọn lati ipinlẹ Oyo, mọkanla l'Ondo nigba ti eeyan meje karun naa l'Ekiti.
Wọnyii ni atupalẹ iye awọn to lugbadi arun covid-19 ni Naijiria lọjọ Abamẹta:
Lagos-461
FCT-206
Plateau-197
Rivers-168
Kaduna-116
Anambra-53
Ogun-49
Ebonyi-47
Edo-42
Sokoto-32
Imo-31
Katsina-31
Oyo-30
Akwa Ibom-27
Delta-16
Kano-16
Abia-15
Niger-15
Ondo-11
Bayelsa-10
Borno-9
Kebbi-8
Ekiti-7
Jigawa-1
Lapapọ, eeyan 108,943 ni akọsilẹ fihan pe wọn ti larun covid-19 ni Naijiria nigba ti 85,367 ti ri iwosan.
Eeyan 1,420 lo ti ba arun coronavirus lọ ni Naijiria.
Ìbẹ̀rù-bojo gbalẹ̀ lórí ṣíṣí iléèwé padà lọ́jọ́ Ajé bí èèyàn 1867 ṣe kó covid-19 lọ́jọ kan ṣoṣo
Ẹgbẹrun meji eeyan o din dẹ(1867) lo lugbadi arun coronavirus lọjọ Ẹti lorilẹede Naijiria.
Eyi ni igba akọkọ tawọn to ni covid-19 ni Naijiria lọjọ kan yoo pọ to bayii.
Ipinlẹ Eko lo si n lewaju pẹlu awọn to larun naa julọ, ẹẹdẹgbẹrin eeyan le ni mẹtala(713) lo karun ọhun nipinlẹ Eko nikan lọjọ Ẹti.
Ipinlẹ Plateau to wa ni ipo keji nibi ti ọta le lugba eeyan o le mẹtala(273) ti karun naa.
Eeyan mọkandinlọgọrin lo ko covid-19 l'Oyo lọjọ Ẹti, mẹtadinlogoji l'Ogun ati Osun.
Bi iye awọn eeyan to ṣẹṣẹ ko arun naa nipinlẹ kọọkan ni Naijiria ṣe lọ ree:
Lagos-713
Plateau-273
FCT-199
Kaduna-117
Oyo-79
Enugu-58
Ondo-53
Kano-49
Sokoto-43
Ogun-37
Osun-37
Nasarawa-36
Rivers-28
Benue-24
Delta-24
Niger-24
Gombe-18
Edo-15
Taraba-12
Bayelsa-10
Ekiti-9
Borno-6
Zamfara-2
Jigawa- 1
Eeyan 107,345 lo ti larun covid-19 lapapọ kaakiri orilẹede Naijiria bayii, eeyan 84,535 lo ti ri iwosan nigba ti ti 1,413 ti ba arun coronavirus lọ.
Nibayii, ọpọ eeyan lo ti kọminu pẹlu ikede ijọba apapọ pe ki awọn ileewe wọle pada lọjọ Aje, ọjọ kejidinlogun oṣu kinni ọdun 2021.
NCDC àti NYSC bẹ̀rẹ̀ ìpàdé lórí ṣíṣí ìpàgọ́ àwọn àgùnbánirọ̀
Ajọ to n gbogun ti ajakalẹ arun ni Naijiria, NCDC, ti kede pe awọn yoo ṣiṣẹ papọ pẹlu ajọ agunbanirọ, NYSC, lori ṣiṣi ipagọ awọn agunbanirọ abala keji ti ọdun 2020 kaakiri Naijiria pada.
Ninu atẹjade ti NDCD fi lede loju opo Twitter rẹ, o ni wọn yoo ṣe ipade ita gbangba kan lori ayelujara lati jiroro lori bi ipagọ naa yoo ṣe lọ laisi ibẹru pe awọn agunbanirọ yoo lugbadi arun Coronavirus.
Nibi ipade ọhun ti yoo waye loju opo ibaraẹnisọrọ Zoom ni NDCD, pẹlu ajọṣepọ NYSC ati PTF yoo ti da awọn ọdọ naa lẹkọọ lori awọn ohun to yẹ ki wọn ṣe lati dabo bo ara wọn.
Ibi ti o ti le ṣe iforukọlẹ lati kopa ninu ipade naa ree.
Ẹwẹ, ajọ yii kan naa tun ti kede pe eeyan 1,479 miran ti lugbadi arun naa ni Naijiria.
Apapọ awọn to ni arun ọhun bayii ti pe 105,478, awọn 83,830 ti ri iwosan nigba ti awọn 1,405 ti jẹ |olọrun nipe.
Bi iye awọn eeyan to ṣẹṣẹ ko arun naa nipinlẹ kọọkan ni Naijiria ṣe lọ ree:
Lagos-697
FCT-201
Nasarawa-80
Plateau-74
Rivers-72
Edo-46
Adamawa-43
Osun-39
Akwa Ibom-35
Delta-31
Anambra-27
Oyo-24
Kano-21
Abia-19
Enugu-19
Ogun-18
Sokoto-12
Bauchi-7
Taraba-7
Ekiti-4
Gombe-4
Imo-4
Bayelsa-2
Jigawa-2
Zamfara-1
Ajọ to n gbogun ti ajakalẹ aarun lorilẹ-ede Naijiria, NCDC ti kede pe eeyan 1,398 miran ti kun iye awọn to ti ni aarun COVID-19 ni Naijiria.
Pẹlu iye awọn eeyan tuntun yii, o ti pe 103,999 eeyan to ti ni arun naa ni Naijiria bayii.
Awọn 82,555 ti ri iwosan gba, nigba ti eeyan 1,382 jẹ Ọlọrun nipe.
Eko -542
FCT-131
Oyo-120
Rivers-113
Plateau-111
Kaduna-71
Kwara-71
Akwa Ibom-34
Sokoto-31
Benue-28
Ogun-27
Kano-26
Kebbi-17
Osun-12
Nasarawa-11
Delta-10
Gombe-10
Bayelsa-9
Borno-9
Edo-8
Ekiti-3
Jigawa-2
Katsina-2
Ajọ to n ri si igbogun ti ajakalẹ arun ni Naijiria, NCDC, ti ni kii ṣe gbogbo awọn to ni arun Coronavirus lara lo maa n ṣafihan awọn apẹrẹ rẹ, nitori naa ki awọn ara ilu ṣora ṣẹ.
NCDC lo kede bẹẹ loju opo Twitter rẹ, nibi to ti sọ pe ọrọ naa ti di oju lalakan fi n ṣọri bayii.
Bakan naa lo tun kede eeyan 1,270 tuntun to tun ṣẹṣẹ lugbadi arun naa ni Naijiria.
Gẹgẹ bi ikede ọhun ṣe sọ, eeyan mejila tuntun miran lo ku lọjọ Iṣẹgun nitori arun ọhun ni Naijiria.
Ni bayii apapọ iye eeyan to ti ni arun naa ni Naijiria ti wọ 102,601.
Bi awọn ipinlẹ to ṣẹṣẹ tun ni arun naa ṣe lọ ree.
Lagos-435
FCT-234
Oyo-103
Plateau-86
Rivers-71
Enugu-51
Nasarawa-41
Delta-39
Edo-39
Osun-33
Niger-31
Sokoto-23
Ondo-16
Taraba-13
Ebonyi-12
Kano-10
Abia-9
Bayelsa-8Èèyàn 371 míràn ló ṣẹ̀ṣẹ̀ tún lùgbàdì Covid-19 ní Nàìjíríà
Bauchi-7
Imo-5
Katsina-3
Gombe-1
Ajọ to n ri si igbogun ti ajakalẹ arun ni Naijiria, NCDC, ti sọ pe ọrọ Covid-19 ti n kọja oju ẹ, ati pe o ṣeṣe ki ile iwosan má le gba iye awọn to n lugbadi arun naa mọ bayii.
Adari ajọ ọhun, dokita Chikwe Ihekweazu lo fi ọrọ naa lede ninu awọn atẹjade kan loju opo Twitter rẹ nigba to n sọrọ lori bi arun naa ṣe n peleke si ni Naijiria lati nnkan bi oṣu kan sẹyin.
O ni ibẹru itankalẹ arun naa bẹrẹ si n pọ si lẹyin ti awọn oṣiṣẹ ileeṣẹ to n risi eto iforukọsilẹ ati nọmba idanimọ, NIMC, pada ṣenu iṣẹ lẹyin idaṣẹsilẹ ranpẹ ti wọn gunle, ti obitibiti ero si ya bo ileeṣẹ wọn.
Bi ẹ ko ba gbagbe, ọpọ ero bẹrẹ si n ya bo ileeṣẹ naa ni kete ti ijọba apapọ paṣẹ fun awọn ileeṣẹ ẹrọ ibaraẹnisọrọ pe ki wọn ja okun ila awọn ti ko ba forukọsilẹ fun nọmba idanimọ NIN lọjọ kẹrinla, oṣu Kejila, ọdun 2020.
Nnkan bii ọgọjọ miliọnu awọn ọmọ Naijiria ti ko fẹ padanu ila ipe wọn lo bẹrẹ si n ṣu bo awọn ẹka ileeṣẹ NIMC ọhun kaakiri Naijiria, eyii ti NCDC  sọ pe o lagbara ran itankalẹ arun Coronavirus lọwọ.
LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé
Ṣugbọn ọrọ naa dojuru lẹyin ti awọn oṣiṣẹ NIMC daṣẹ silẹ nitori ibẹru pe arun ọhun le de wọn lalejo bi ọpọ ero ṣe n ya bo ileeṣẹ wọn.
Ẹwẹ, ajọ NCDC tun ti kede eeyan 1,244 miran to ṣẹṣẹ lugbadi arun naa ni Naijiria.
Nibi ọrọ de duro bayii, apapọ awọn to ti ni arun naa ni Naijiria je 101,331.
Bo tilẹ jẹ pe eeyan 80,491 lo ti ri iwosan gba, awọn 1,361 lo ti jẹ Ọlọrun nipe.
LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé
Yoruba ni ọmọ ti yoo ba jẹ asamu, kekere ni yoo ti maa jẹnu samu-samu.
Oladimeji Shotunde, to gba apapọ maaki to ga julọ nile ẹkọ fasiti ipinlẹ Eko, LASU ni akẹkọọ akọkọ ti yoo gba iru maaki to ga bẹẹ ninu itan ileẹkọ naa.
Amọ ohun to ya ni lẹnu julọ ni pe Oladimeji, lasiko to n ba BBC Yoruba sọrọ ni oun ko de ile iyawe-kawe ri lati lọ kawe, ki oun to jẹ akẹkọọ to pegede julọ.
Sotunde, ti baba rẹ jẹ atọkọse, ti iya rẹ si n ta ọja ke ke ke ninu sọọbu kan, fikun pe oun maa n lọ ran baba oun lọwọ lati tun ọkọ se ni sọọbu rẹ.
Àwọn ìtàn mánigbàgbé tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí:
Bakan naa lo tun maa n lọ ẹrọ ata ni owurọ fun iya rẹ to ni ẹrọ ata to fi n pawo wọle, ko to ls sile ẹkọ.
Shotunde ni oun kii se igi iwe nitori wakati kan pere ni oun fi n kawe lojumọ.
O wa gba awọn akẹẹgbẹ rẹ nimọran lati ni isẹ ọwọ kan ni pato yato si iwe, nitori iwe nikan ko to jẹun mọ laye ode oni.
Orisabunmi: Mọ̀lẹ́bí kan ní kíì ṣe Coronavirus ló pa ẹ̀gbọ́n àti àbúró ìyá òòṣà
Oríṣun àwòrán, Bukola Janet
Awọn agba bọ, wọn ni eti to ba gbọ alọ, o yẹ ko gbọ abọ.
Eyi lo mu ki awọn mọlẹbi akinkanju osere tiata lobinrin to di oloogbe, Folake Aremu, ti ọpọ eeyan mọ si Orisabunmi se fesi lori ọrọ to n ja rain-rain lawujọ.
Orisabunmi ẹni to jade laye lọsẹ kan sẹyin ni ẹgbọn rẹ ọkunrin ati aburo rẹ obinrin ku lẹyin rẹ, laarin ọjọ mẹta sira wọn.
Idi si ree ti awọn eeyan kan to gbọ nipa isẹlẹ naa se n pariwo pe itankalẹ arun Coronavirus lo mu ẹmi awọn alaisi mẹtẹẹta lọ.
Oríṣun àwòrán, Instagram/Toyosi Adesanya
Awọn eeyan miran ni nibi ayẹyẹ kan ti Orisabunmi lọ lọjọ aisun ọdun Keresi, nibi to ti n jo ninu fidio kan to gbalẹ lori ayelujara niwaju olorin ẹmi kan, Esther Igbekele, ni osere tiata naa ti ko arun Coronavirus.
Iroyin naa lo ni awọn apẹrẹ aisan to se Orisabunmi to fi jade laye, ti ko si le mi daadaa ati ikọ to n hu, fi ara jọ arun Coronavirus, to si see se ko ti ko arun naa ran awọn ẹbi rẹ.
Koda, awọn eeyan miran lawujọ min tun woye pe, iku awọn eeyan naa le jẹ akufa, ti ọwọ aye si wa ninu rẹ.
Oríṣun àwòrán, Instagram/themakingstv
Sugbọn nigba ti wọn n fesi lori ero awọn eeyan awujọ naa, ọkan lara ẹbi Orisabunmi salaye pe irọ to jinna sootọ ni ọrọ naa.
Eti wa ti kun nipa awọn ahesọ ọrọ to lu igboro pa pe awọn etẹgbọn-taburo to ku ninu ẹbi wa, jade laye lati ipasẹ arun Coronavirus."
Amọ mo n mu da yin loju pe ofuutu fẹẹtẹ, aasa ti ko ni kaun ni ahesọ ọrọ naa, yoo si dara ki awọn eeyan kọ ẹyin si.
"Ko ye mi ohun ti awọn eeyan to n tan ahesọ ọrọ naa nipa ẹbi Onisola fẹ gba nidi rẹ, nitori ilu Ibadan ni Orisabunmi ati anti Bukky, aburo rẹ ku si, nigba ti ẹgbọn wọn ku silu Ilorin."""
O tun salaye siwaju si pe sababi lasan ni iku awọn mẹtẹẹta to waye lasiko kanna jẹ, kii si se arun Coronavirus lo pa wọn.
"O fikun pe ""awọn iku wọn kan se pẹki n pẹki ni, eyi ti kii se ohun ta n gbadura fun, a si ti n gbadura pe ki Ọlọrun dawọ iru isẹlẹ ibi bayii duro ninu ẹbi wa."""
LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé
Bakan naa, ninu ifọrọwerọ ti BBC Yoruba se fun ajihinrere Obaloluwa Hephzibah, to jẹ ẹni to gbe lọdọ aburo Orisabunmi, o ni kii se arun Coronavirus lo mu ẹmi arabinrin Bukola Janet, tii se aburo Orisabunmi lọ.
Hephzibah, ninu ifọrọwerọ naa ni bi wọn se tufọ iku Orisabunmi fun aburo rẹ, ni irẹwẹsi ọkan ba a, ti ọkan rẹ ko si lagbara to lati gba iroyin iku ẹgbọn rẹ naa mọra.
Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó
O fikun pe Bukola Janet ti n wo aisan ẹjẹ ruru tẹlẹ, ki iroyin ojiji nipa iku ẹgbọn rẹ to wọle de.
NIN Registration App: Má lu jìbìtì ayélujára, wo bo ṣe le dá ojúlówó àti ẹbu áàpù NIMC mọ̀
Oríṣun àwòrán, NIMC
Ajọ to n mojuto iroyin nipa kaadi idanimọ awọn ọmọ Naijiria ti kede laipẹ yii pe, ki awọn ọmọ Naijiria tara sasa lọ gba nọ́mba idanimọ NIN wọn ki wọn ba maa padanu opo ibaraẹnisọrọ wọn.
Amọ pẹlu ikede yi naa ni wọn fi ọna tawọn eeyan yoo fi le ri nọmba yii, paapa fawọn to ba fẹ so nọmba siimu ibaraẹnisọrọ wọn miran mọ eyi ti wọn fi ṣe iforukọsile NIN.
Labẹ anfaani yii, wọn ni ki wọn gba appu NIMC kan ti yoo jẹ ki isopọ awọn siimu mii mọ akọkọ yii rọrun.
Ohun to fọwọ kan ni lẹmi ni pe, awọn obilẹjẹ eeyan kan ti n fi ayederu aappu sita lati maa fi se ijamba fawọn ti ko ba mọ.
Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó
A beere lọwọ onimọ kan nipa igbekalẹ appu orisirisi ti a mọ si app developer.
Arakunrin Olamiji Gabriel ba BBC Yoruba sọ pe, nkan ti ijọba Naijiria se ni pe wọn ti so nọmba siimu onikaluku mọ nọmba NIN rẹ.
O ni awọn to lọ forukọsilẹ lati gba nọmba NIN laipẹ yii yatọ si awọn to ti ni tẹlẹ, wọn beere nọmba BVN wọn lọwọ wọn ki wọn ba le so awọn nọmba yi papọ.
O ni nitori eyi,  bi eeyan ba fẹ download appu NIMC yii, ko ri pe eyi to wa lati ọdọ ijọba lo download bi bẹẹ kọ, awọn alaburu le lo aapu ayederu yii lati fi wọ owo inu akanti wọn, ti wọn yoo si se ipalara fun wọn.
Oluwo Jogbodo Orunmila: Ẹsẹ odù Ifa ló fi ṣúre fún ọmọ Nàíjíríà ní àyájọ́ ọdún tuntun
''Gbogbo awọn ti wọn ti lọ download ayederu appu, nkan ti wọn yoo bi wọn ni pe, ki wọn san owo ki wọn baa le ri nọmba NIN wọn. Ijọba ko si ni ki wọn maa gba owo kankan lati fi gba nọmba yii''
Olamiji tẹsiwaju pe, nitori pupọ awọn eeyan wa ni Naijiria ni kii fẹ se suuru, ẹlomii yoo san owo yii lati le fi tete ri nọmba NIN gba.
Ki ni ipalara to le ba ọ, ti o ba gba gbarọgudu aapu?
O ni aburu to wa nibẹ kii se ti owo perete ti eeyan ba san, bi kii se pe awọn obilẹjẹ yi le lo ọna eru lati wọ inu akanti eeyan nigba ti wọn ba ti mọ nọmba BVN ati NIN.
O ni wọn yoo dahun awọn ibeere kọọkan ti ile ifowopamọ ba bi wọn, ti yoo le jẹ ki wọn gba owo jade ninu akanti eeyan.
''Ti wọn ba ti le ri ọjọ ibi eeyan, Date of birth tabi BVN eeyan, wọn le fi gba owo ninu akanti eeyan''
''Se ẹ ri token ti wọn maa fi n sọwọ si ori nọmba foonu ẹni to ba ni akanti, dipo ko lọ si ori foonu yin, ọdọ awọn to se appu ayederu yii ni yoo lọ si.
LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé
Bi wọn ba ti ni BVN yin, token ati ọjọ ibi yin, ọrọ ti bu se ni yẹn''
Nipa nkan to yẹ ki awọn eeyan wo, ki wọn to le gba ojulowo aapu NIMC, o ni ko si bi eeyan ti se le da wọn mọ yatọ afi ki ijọba apapọ sọ fun awọn ọmọ Naijiria, eyi to jẹ ojulowo tabi ayederu.
''Ayafi ki ijọba jade sita lati fi oju opo ti wọn gangan han araalu, ki wọn si fi ami idanimọ to yatọ fun araalu si oju opo tawọn eeyan mọ wọn si lọna abayọ.
Bi bẹẹ kọ awọn obilẹjẹ yii yoo tun se ẹda aapu ti ijọba, ti wọn yoo si maa fi se ijamba fara ilu''.
Oluwo Jogbodo Orunmila: Oluwo sọ ìtàn bí Orunmila ṣe jìyà nílùú Iwo àti ayọ̀ tó gbẹ̀yìn rẹ̀ torí sùúrù
Yoruba ni Suuru ni baba iwa, ibinu ko si da nnkan fun ẹnikẹni, abuku ni ko ba ni.
Bi onibinu ati alagidi ba si fi ogun ọdun sisẹ, ọjọ kan soso ni yoo fi ẹsẹ yi danu.
Oluwo, ninu ọrọ itaniji wa fun ti ọsẹ yii, salaye ohun to faa ti wọn fi n pe aya ni iyawo ati bi Orunmila se jiya niwo amọ to se suuru, eyi to mu ki ayọ gbẹyin ọrọ rẹ nigbẹyin.
Àwọn ìtàn mánigbàgbé tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí:
O wa gba awọn ọdọ nimọran lati maa ni suuru, ki wọn si pa ibinu ti nitori suuru ni baba iwa, agba to ba si ni suuru, ohun gbogbo lo ni.
Oluwo ni ẹni to ba ni suuru, yoo ni ifarada, ipamọra ati gbogbo nnkan.
Fun iwọ ti o jẹ onibinu, oninufufu ati alagidi, ẹ sunmọ ibi kẹ wa kọgbọn lati ẹnu baba awo Oluwo Jọgbọdọ Orunmila.
Oba Lamidi Adeyemi: Aláàfin àkọ́kọ́ tí yóò lo àádọ́ta ọdún lórí ìtẹ́
Oríṣun àwòrán, @AlaafinofOyo
Yoruba ni ori ti yoo dade, ko ni ṣe alai dade, ọrun ti yoo si lo ejigbara ilẹkẹ, ko ni ṣalai lo ó, ibadi ti yoo lo mọsaji, aṣọ ọba to jinna koro koro, ko kuku ni ṣe alai lo.
Bẹẹ ni ọrọ Ọba Lamidi Olayiwola Adeyemi kẹta rí,ẹni ti ori gbe de ipo awọn baba rẹ leyin ọpọ ifigagbaga laarin awọn ọmọ oye to le ni mẹwa, ti wọn dìjọ du ipo.
Ọjọ nla si ni ọjọ Kẹrinla osu Kinni ọdun 1971 ti atọbatẹlẹ ko to jọba, Lamidi Atanda Olayiwola Adeyemi gori itẹ awọn baba nla rẹ.
Gomina ologun nigba naa to ti di oloogbe, Ajagunfẹyinti Robert Adeyinka Adebayo si lo gbe ọpa asẹ le lọwọ gẹgẹ bii Alaafin Ọyọ.
Oríṣun àwòrán, Facebook/The Alaafin of Oyo
Ọmọ ọba ni Lamidi Atanda, baba rẹ si ni Alaafin Adeniran Adeyemi, koda, ọmọ ọmọ ọba tun ni pẹlu nitori baba to bi baba rẹ, Alaafin Alowolodu Adeyemi naa jẹ Alaafin.
Amọ sibẹsibẹ, eyi ko ni ki o ma figa gbaga pẹlu awọn ọmọ oye yoku to fẹ jọba nikete ti Alaafin Gbadegesin Ladigbolu keji waja lọdun 1970.
Àwọn ìtàn mánigbàgbé tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí:
Yoruba ni ajise bi Ọyọ laa ri, Ọyọ kii se bi baba ẹni kọọkan, a si lee ni asamọ yii faramọ ninu ilana igbe aye Oba Lamidi Olayiwola Adeyemi Kẹta ba ba wo isesi rẹ lori oye.
Oba Adeyemi ko to jọba jẹ osisẹ adojutofo ati akansẹ to dantọ, to si ni iriri ba se n se akoso eyi to wulo pupọ fun lasiko to di ọba alaye.
Tẹ ba si fẹ mọ siwaju si nipa itan igbe aye Ọba Adeyemi, ẹ ka itan igbe aye rẹ nibi lati mọ bo se lo aye rẹ ko to jọba ati bo se dori oye.
Gẹgẹ ba se mọ pe ipo pataki ni ipo Alaafin ninu itan Yoruba, to si se asaaju ninu odiwọn ipo awọn oriade nilẹ kaarọ Oojire.
Ko si si ọba alaye ti yoo ni bawo ni ti Alaafin se jẹ nitori odu nla ni, kii se aimọ fun oloko, ko si si ẹni ti yoo kọ iyan rẹ, ti ko ni fi ewe boo.
Ta ba si n sọrọ nipa ọla, iyi ati ẹyẹ, a le sapejuwe  Alaafin Adeyemi bi ọba alade to n fi ọla wu ni, ẹni to jẹ atọbatẹlẹ, ko to jọba.
Oríṣun àwòrán, @AlaafinofOyo
Ko si yẹ ko ya ẹnikẹni lẹnu pe ọba to lọla, niyi ati ẹyẹ yii lo aadọta ọdun lori oye eyi to mu agbega nla ba agbegbe rẹ.
O si yẹ ko ye wa pe ohun aseyọri gbaa ni ki ọba alade kan lo aadọta ọdun lori oye, bẹẹ si ni ko si ni akọsilẹ pe Alaafin kankan lati ẹyin wa lo aadọta ọdun nipo.
Amọ ka ba le mọ bi ẹyẹ yii se pọ to fun Ọba Adeyemi gẹgẹ bi Alaafin akọkọ ti yoo lo aadọta ọdun nipo, o yẹ ka woju wẹyin wo iye ọdun ti diẹ lara awọn baba nla rẹ to jẹ Alaafin lo, to fẹ ẹ sun mọ adota ọdun.
Oríṣun àwòrán, v@AlaafinofOyo
Akọsilẹ fi ye wa pe Alaafin to fẹ sunmọ aadọta ọdun lori oye lẹyin Ọba Adeyemi ni Alaafin Siyanbola Ladigbolu to jọba laarin ọdun 1911 si 1944, ẹni to lo ọdun mẹtalelọgbọn nipo.
Bakan naa ni Oba Alowolodu Adeyemi Kinni, tii se baba fun baba Oba Adeyemi naa jọba laarin ọdun 1876 si 1905, to si lo ọdun mọkandinlọgbọn lori oye.
Oba Atobatele Arugba naa jọba laarin ọdun 1837 si 1859, to si lo ọdun mejilelogun nipo.
Bakan naa ni Alaafin Adeniran Adeyemi keji, tii se baba ọba Lamidi Adeyemi, ẹni to jọba laarin ọdun 1945 si 1955, to si lo ọdun mẹwa pere lori oye, ki wọn to yọ nipo.
O si daju pe aye ti ẹsin Oba Adeniran Adeyemi ko jẹ, ti wọn fi yọwọ rẹ ninu awo, ni iru idi rẹ, tii se ọmọ rẹ n jẹ lori aleefa.
A si le se apejuwe Ọba Lamidi Adeyemi bii oloriire, ti Ọlọrun gba fun, to si ri aanu pupọ gba.
Oríṣun àwòrán, Instagram/olori_omoh_one
Kii se pe a sọ asọdun ta ba ni idagbasoke alailẹgbẹ ba ilu Ọyọ lati aadọta ọdun ti Lamidi Adeyemi ti wa lori itẹ bii Alaafin Ọyọ.
Awọn ileesẹ nla nla, ileesẹ alabọde atawọn ileesẹ kereje kereje lo ti lalẹ hu nilu Ọyọ lẹyin ti Ọba Adeyemi di Alaafin.
Bakan naa ni eto igbayegbadun buyaari si nilu naa, to jẹ ilu to dakẹ jẹjẹ tẹlẹ ki Alaafin yii to debẹ.
Fun awọn onwoye ohun to n lọ lawujọ, alaafin kii fi ọrọ asa sere, ta si le ni o kogiri mọ ojuse rẹ bi ọba alaye lati ri daju pe awọn asa, ise ati ede wa ko lọ sokun igbagbe.
Ẹni ti itan ko ba si ye, to ba tọ Alaafin lọ, oye yoo ye kedere nipa ohun to ba fẹ mọ, ti ọba alaye naa si jẹ iwuri fun ọpọ ọmọ Yoruba, paapaa lasiko to ba n hu awọn itan manigbagbe jade.
Oríṣun àwòrán, @AlaafinofOyo
Yatọ si eyi, ipa kekere kọ ni Adeyemi n ko si idagbasoke orilẹede Naijiria, to si maa n kopa ti kii se keremi si awọn ohun to n lọ lorilẹede yii.
Bẹẹ ba si gbagbe, ọpọ lẹta ni Alaafin maa n kọ si awọn adari to ba wa nipo boya labẹ ijọba apapọ ni abi lawọn ipinlẹ.
O yẹ kẹ ranti lẹta to kọ si aarẹ Muhammadu Buhari lati jẹ ko mọ bi ori se n ta araalu si nipa ọrọ aje to dagun ati eto aabo to mẹhẹ, eyi to lapa rere.
Bakan naa ni Alaafin tun da si ọrọ aawọ ija agba to n waye nipinlẹ Ekiti, to si kọ lẹta si gomina ipinlẹ naa, Kayode Fayemi, lati pe akiyesi rẹ si ọrọ naa ati ọna atunse nipa rẹ.
Tun wẹ, ọpọ awọn gomina oloselu ati ti ologun to ti jẹ nipinlẹ Ọyọ lo mọ ipa ribi ribi ti Alaafin ko lati jẹ ki isejọba wọn se aseyọri.
A si le sọ pe Ọba Lamidi Olayiwola Adeyemi ti sisẹ pọ pẹlu awọn gomina to to mọkanlelogun lati ri si idagbasoke ipinlẹ Ọyọ.
Oríṣun àwòrán, @AlaafinofOyo
A le sọ pe Ọba Adeyẹmi ri aye wa ni gbogbo ọna nitori gbogbo ohun ti eeyan maa n gbe ile aye se, ni Alaafin ti se ni aseyọri.
O ni ẹmi gigun, o ni alaafin, Ọ́ba Adeyemi tun lowo, o lọla, o ni gbajumọ, bakan naa lo n sọla ni agbala rẹ pẹlu awọn orekelẹwa obinrin, to si tun jẹ alayelugba ti awọn ọba ẹgbẹ rẹ n wari fun.
BBC Yoruba wa n ba Ọba Lamidi Olayiwola Atanda Adeyemi Alowolodu yọ ayọ aadọta ọdun rẹ lori itẹ, ta si n gbadura pe ade yoo pẹ lori, bata yoo pẹ lẹsẹ, ẹsin ọba yoo si jẹ oko pẹ. Asẹ.
Domestic Violence in Benue: Ọmọ ọdún mẹ́tàdínlógún dáná ṣun ọ̀rẹ́kùnrin rẹ̀ lẹ́yìn eré ìfẹ́
E wo ni ki ololufẹ sun lalẹ, ki wọn fi ẹnu ko ẹnu, ki o si ji pẹlu irora ina ni ara rẹ, eyi to si jasi iku ọrẹkunrin rẹ.
Bayii ni ọrọ ifẹ laarin Elvis Chinma Omah, to n ta oogun ati ọrẹbinrin rẹ ri ni ilu Markurdi, to jẹ olu ilu Benue.
Ọmọ ọdun mẹtadinlogun ni ọrẹbinrin Omah ti awọn mejeeji si jẹ ọrẹ kori kosun, ti wọn si ti jẹ ololufẹ fun ọdun mẹta.
Ifẹ wọn gbona to bẹẹ ti wọn ṣe ibura fun ara wọn wi pe, awọn ko ni dalẹ ara awọn, ati wi pe igbeyawo ni yoo kẹyin irinajo ifẹ wọn.
Amọ ọjọ ko tọjọ, osu ko to osu, ti olobo ta ọrẹbinrin pe Omah, to gbẹmi le bi ọkọ afẹsọna ti n nifẹ ikọkọ pẹlu obinrin miran.
Esther bẹrẹ si ni binu nigbati awọn ọrẹ rẹ sọ fun wi pe Omah ti ni ẹlọmiran o, to si ti fẹ ṣe igbeyawo pẹlu rẹ ni abule wọn.
Bi o tilẹ jẹ pe Omah sọ wi pe ko si otitọ ninu ọrọ naa fun Esther, amọ ko gbagbọ, ti o si pinu lati dana sun arakunrin naa, ki ifẹ wọn kuku pari.
Esther lasiko to n wi tẹnu rẹ fun awọn ọlọpaa sọ pe, Omah lo gba ibale oun, to si ṣe ileri fun oun wi pe oun ko ni dalẹ.
Amọ, o ni Omah ko ṣe olotitọ pẹlu oun, n ṣe lo n ko obinrin kaakiri, ti yoo si sọ fun oun pe ki oun sun si ori ilẹ, nigba ti awọn ọrẹbinrin rẹ ba n wa si inu ile.
Lẹyin ọpọlọpọ ija ni o kọ Omah silẹ, amọ o ni Omah wa bẹ oun pada wi pe ki awọn pari ija, ki ifẹ wọn si pada si bi o ṣe wa tẹlẹ.
Esther gba ẹbẹ Omah, amọ o gbe garawa bẹntirol dani, to si tọju rẹ si ita ki o to wọle tọ Omah lo ninu ile rẹ.
Omah ṣẹṣẹ de lati Enugu ni nigbati Esther wọle tọ ọ wa, lẹyin ti wọn pari ija laarin ara wọn.
Esther se ounjẹ alẹ fun, wọn jẹun, ti wọn si gbadun ara wọn, ki o to di wi pe wọn gba ibusun lọ.
Lẹyin ti wọn jọ sun, ni Esther dide to si lọ gbe bẹntirol, to si da a yika yara Omah, ko o to sọ ina si.
Itaniji: Oluwo sọ ìtàn bí Orunmila ṣe jìyà nílùú Iwo àti ayọ̀ tó gbẹ̀yìn rẹ̀ torí sùúrù
Esther salọ si ile ijọsin to wa nibẹ lẹyin ti ina sọ ninu yara Omah.
Awọn ara adugbo lo gbọ igbe Omah, ki wọn to sare lati doola ẹmi rẹ, amọ o ti jona kọja keremi, ti o si jasi iku rẹ.
Agbẹnusọ fun olu ileeṣẹ ọlọpaa ni Benue ni, otitọ ni iṣẹlẹ naa waye ati wipe awọn yoo gbe Esther lọ si ileẹjọ lẹyin ti iwadii ba pari lori iṣẹlẹ naa.
Bakan naa ni ileeṣẹ ọlọpaa naa fikun wi pe, iru iṣẹlẹ bẹẹ mẹta lo ti waye ni ipinlẹ naa, nibi ti awọn ololufẹ ti dana sun ara wọn.
Students Kidnap Coverage: Akòrọ̀yìn Nàìjíríà korò ojú sí ìròyìn òkèèrè lórí ìjínigbé akẹ́kọ̀ọ́bìnrin
Awọn àgba bọ, wọn ni ọrọ okeere, ti ko ba le kan, a si din kan.
Ohun lo difa fun akọroyin ati onkọwe ọmọ Naijiria, Adaobi Tricia Nwaubani, to be ẹnu atẹ lu agbekalẹ iroyin awọn ileeṣẹ iroyin ilẹ okeere, lori awọn iṣẹlẹ ijinigbe awọn akẹkọọbinrin nile iwe wọn lorilẹ ede Naijiria.
O ni asọdun awọn ileeṣẹ iroyin pọ bẹrẹ lati iṣẹlẹ ijinigbe awọn akẹkọọbinrin ile iwe Chibok lọdun 2014, to fi de bi iṣẹlẹ ile iwe Kankara ni Katsina.
O ni bi awọn akọroyin ti dẹnu bo ọrọ awọn akẹkọọbinrin to le lugba ti wọn jigbe ni Chibok nipinlẹ Bornu, ṣugbọn awọn nnkan to t'ẹyin rẹ jáde ko dara.
Ṣaaju iṣẹlẹ Chibok, ẹkọọkan lawọn ọmọ Naijiria maa n ri adarí Boko Haram, Abubakar Shekau yala lori ayelujara tabi ẹrọ amohunmaworan.
Shekau bẹrẹ si ni kọ awọn eeyan lominu lẹyin to dunkoko iku mọ aarẹ Naijiria nigba naa, Goodluck Jonathan, ati aarẹ Amẹrika igba naa, Barack Obama.
Ṣugbọn lẹyin iṣẹlẹ Chibok, awọn ileeṣẹ iroyin ilẹ okeere bẹrẹ sí ni gbe ohun gbogbo ti Shekau ba ti sọ.
Shekau naa bẹrẹ si ni fun wọn ni oriṣiiriṣii fidio awọn akẹkọọbinrin ti wọn jigbe to si eleri lati ta wọn.
Awọn ti wọn jigbe ti ṣalaye pe niṣe lawọn ajinigbe maa n dunnu nigba kuu gba tawọn ileeṣẹ iroyin ba n sọ nípa ìṣẹlẹ náà.
Ọpọ iroyin tawọn kan n gbe kiri lori iṣẹlẹ Chibok gan an kii ṣe otitọ.
Bo tilẹ jẹ pe awọn ileeṣẹ iroyin ilẹ okeere ri iṣẹlẹ ijinigbe ileewe Chibok bi ikọlu eto ẹkọ ọmọbinrin ni Naijiria, ṣugbọn ọrọ ko ri bẹẹ.
Lara awọn to jajabọ lọwọ awọn ajinigbe Boko Haram sọ pe ohun tawọn janduku to yabo ileewe awọn fẹ jale lasan an ni.
Oríṣun àwòrán, AFP
Bi Boko Haram ṣe bẹrẹ si ni so ado oloro mọ awọn ọmọdebinrin lara lẹyin iṣẹlẹ Chibok fihan pe wọn ṣe bẹẹ k'awọn akọroyin tun le maa sọ nipa wọn ni.
Oríṣìíríṣìí ọmọ Naijiria lo ti bọwọ s'ọwọ awọn ajinigbe ti wọn si ti san owo lati gba ominira, amọ kii ṣe bi ti ọdunrun  ùn awọn ọdunkunrin akẹkọọ ile iwe girama ilu Kankara ni Katsina nipari ọdun 2020.
Oríṣun àwòrán, The office of the First Lady
Ṣugbọn awọn ileeṣẹ iroyin ilẹ okeere so iṣẹlẹ naa pọ mọ iṣẹlẹ ijinigbe awọn akẹkọọbinrin Chibok to ti ṣẹlẹ bi ọdun mẹfa sẹyin.
Lakotan, onkọwe yii ni bi awọn ileeṣẹ iroyin ilẹ okeere yìí ti n ṣe agbekalẹ iroyin lori awọn janduku ajinigbe ati Boko Haram ṣe pataki.
Bakanna lo sọ pe ijọba gbọdọ wa nnkan ṣe sọ̀rọ̀ eto abo to mẹhẹ ni Naijiria ki wọn si ṣe iranti awọn ti wọn ti ṣeku pa.
Seyi Makinde-Olaniyan: Igbákejì Gómìnà Oyo ní kò síjà láàrin òun àti Gómìnà
Oríṣun àwòrán, Facebook/Engr Remi Olaniyan
Igbakeji Gomina ipinlẹ Oyo, Amoju-ẹrọ Raufu Olaniyan ti ṣalaye pe iroyin ayederu lawọn kan n gbe kiri pe, ija wa laarin rẹ ati Gomina Seyi Makinde.
Igbakeji Gomina Oyo, to ba BBC Yoruba sọrọ l'Ọjọbọ ṣalaye pe, oun ko figba kan sọ sita pe ija wa laarin awọn mejeeji, bẹẹ ni Makinde fun ra rẹ naa ko sọ fun ẹnikan pe oun ati igbakeji oun n ja.
Amoju-ẹrọ Olaniyan ni awọn oloṣelu kan, ti wọn n wa oju rere Gómìnà ipinlẹ Oyo lo wa nidi ọrọ naa.
Asiko oṣelu ni a wa yii, awọn to n gbe iru iroyin yii n wa bi okele wọn yoo ṣe pọn lọdọ gomina ni, igbakeji gomina lo sọ fun BBC bẹẹ.
Iroyin kan ti kọkọ jade pe igbakeji gomina ipinlẹ Oyo sọ pe ija to wa laarin oun ati Makinde ko le pari laelae.
Oríṣun àwòrán, Facebook/Engr Remi Olaniyan
"Amọ, Amoju-ẹrọ Olaniyan sọ fun BBC pe, ""ohun to ba wu onikaluku lo le fi ẹnu rẹ sọ nitori ijọba awaarawa lo wa lode."""
Igbakeji gomina ipinlẹ Oyo ni awọn to n gbe irufẹ iroyin bayii mọ ohun ti wọn ni lọkàn fun ra wọn .
Bakan naa lo tun fikun ọrọ rẹ pe, ero ọkan awọn akọroyin lasan, ni awọn ileeṣẹ iroyin to gbe iru iroyin bayii sita, oun ko ba ẹnikẹni ja tabi ni ẹnikẹni sinu.
Wọn ni mo n binu tori gomina ko fa awọn isẹ kan le mi lọwọ, amọ bi gomina fa isẹ le mi lọwọ, agunla, bi ko si fa a le mi lọwọ, ko si wahala, jẹjẹ mi ni mo n lọ.
Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó
Ọgbẹni Olaniyan ti sọ tẹlẹ ninu atẹjade kan ti oluranlọwọ rẹ lori eto iroyin, Omolere Omoetan fi sita pe, ojuṣe oun gẹgẹ bi igbakeji gomina ipinlẹ Oyo ni lati ṣiṣẹ pọ pẹlu Gomina Makinde.
O ni oun ṣetan lati tẹsiwaju nipa ṣiṣe bẹẹ, bakanna lo ni oun ko ni kaarẹ nitori ohun tawọn eeyan kan n sọ kiri.
Bolu Akin Olugbade: Ọkọ̀ olówó iyebíye Roll Royce Limousine mẹ́wàá nìkan ni ọlọ́lá yìí gùn nígbà ayé rẹ̀
Oríṣun àwòrán, Bolu Akin-Olugbade
Ọpọlọpọ ọlọla ati eniyan jankan lo ti n ṣedaro oniṣowo Bolu Akin- Olugbade to ki aye pe o digba o ṣe, nigba ti arun Coronavirus gba ẹmi rẹ.
Gomina ipnlẹ Ogun, to fi mọ awọn eekan lawujọ lo ṣedaro rẹ gẹgẹ bi gbajumọ to si tun jẹ eniyan pataki ni awujọ.
Bakan naa ni wọn si ba ẹbi ati ara kẹdun lẹyin ti o dakẹ ni ile iwosan to ti n gba itọju arun Covid 19, ki ọlọjọ to de.
Ọmọ olowo ati ọlọla ni Bolu Akin-Olugbade, toun naa si sisẹ lati lowo, bi igbesi aye rẹ si se lọ ree.
Oríṣun àwòrán, Bolu Akin-Olugbade
Ọjọ Keji, Oṣu Kẹrin, ọdun 1956 ni wọn bi Akin-Olugbade si idile baba ọlọla ati oniṣowo to tun jẹ Balogun Owu nilu Abeokuta, Babatunde Akin-Olugbade.
Bolu lọ si ile iwe Corona ni ilu Eko, lẹyin naa lo tẹsiwaju lọ kọ imọ ofin ni Fasiti kan ni ilu London, ni Ilẹ Gẹẹsi.
Akin-Olugbade tun tẹsiwaju si lati kawe gba oye imọ ofin to de awọn ileeṣẹ ni fasiti California, ni orilẹede Amẹrika.
Agbẹjọro ni Akin-Olugbade, to si n ṣe idokowo ninu rira ile ati ile kikọ, epo rọbi, ile ifowopamọsi ati bẹẹ bẹẹ lọ.
Oríṣun àwòrán, Bolu Akin-Olugbade
Titi di ọjọ iku rẹ ni ẹni ọdun mẹrinlelọgọta, oun ni oloye Aarẹ ọna kankanfo ti ilu Owu.
Akin-Olugbade ati iyawo rẹ, Ladun, ti wọn ti fẹ ara wọn fun ogoji ọdun, ni Eledumare fi ọmọ ati ọmọọmọ kẹ.
Aarẹ Bolu Akin-Olugbade fẹran ọkọ bọgini nigba aye rẹ, paapaa eleyii ti wọn n pe ni Rolls Royce.
Oríṣun àwòrán, Bolu Akin-Olugbade
Oríṣun àwòrán, Bolu Akin-Olugbade
Ọdaju ni iku, iku ti kii gba owo tabi dukia afi ẹmi ẹda, ka ni iku n gba owo ni, owo nla ni ko ba gba lati fi ẹmi ọlọla Akin-Olugbade silẹ.
Amọ a gbadura pe ki Ọba oke tẹ oloogbe naa si afẹfẹ rere.
Onila/Agindigbi Communities: Ọdún mẹ́ta ní àwa 18 fi dá #400,000 tí a fi kọ́ ilé ìwé
Oríṣun àwòrán, Kwara Govt
Ìjọba ìpińlẹ̀ Kwara, Abdulrahaman Abdulrazaq ti sàbẹ̀wò ilé iwé alákọbẹ̀rẹ̀ Nomadic ti Agindigbi àti St Luke LGEA oníla lẹ́gbẹ̀ẹ́ Agbamu níjọba ìbílẹ̀ Irepodun, ìpínlẹ̀ Kwara.
Gómínà lọ síbl láti lọ sẹ àdápada owó ti àwọn òbínrin márùndílọ́gbọ̀n kan ti náà lati fi kọ ilé ẹ̀kọ́ fún àwọn ọmọ wọ́n ni abúlé náà.
Sáájú ni Ẹ̀ka BBC ti ṣe àbẹ̀wò sí ìlú náà níbi tí láti ṣe ìfọ̀rọ̀wánilẹ́nu wò lórí bi wọ́n ṣe kọ yàrá ìkẹ́kọ̀ọ́ ojúlé mẹ́ta, nígbà ti ilé ìwé kejì ń kọ tíwọn lọ́wọ́, wọ́n tí n dá owó náà pamọ́ láti ọdún 2017
Gómìnà ìpínlẹ̀ Kwara nígbà tó de ìlú náà ló sọ fún wan pé, kí wọ́n sọ iye ti wọ́n ti na lórí kíkọ́ ilé Ẹ̀kọ́ náà tọ sí fún ìlú kọ̀ọ̀kan ní ẹgbẹ̀rún lọ́na ẹdẹ́gbẹ̀ta Náírà.
Gómínà fí ìdúnu rẹ̀ hàn fún ìgbésẹ̀ akin ti àwọn obìnrín náà gbé láti ṣe iṣk ribirni tí wọ́n ṣe lórí ẹ̀kọ́ àwọn ọmọ wọ́n.
Báwo ni ọ̀rọ̀ náà ṣe bẹ̀rẹ̀?
Àwọn obìnrin tó ṣe àkọ́jọpọ̀ owó yìí sàlàyé pé, ilé ìwé tí àwọn ọmọ náà ń lọ tẹ́lẹ̀, bí òòrùn bá ràn orí wan ni, bí ojò bá rọ̀ orí àwọn yìí náà ni gẹ́gẹ́ bi Deborah Aweda ọkan lára àwọn obí tó n dá owó náà ṣe sọ.
Arabinrin Aweda ni àwọn obìnrín márùndínlọ́gbọ̀n bẹ̀rẹ̀ si ni yọ ẹgbẹ̀run méjì nínú ẹgbẹ̀rún mẹ́wàá Nàìrà ti ìjọba àpapọ̀ ń fún wọ́n n lósoo'sù, àti pé ọdún mẹ́ta ni àwọn fi dá #480,000 tí àwọn sì bẹ̀rẹ̀ kíkọ́ rẹ̀.
Ní ti ìlú Keji, àwọn obìnrín méjìdílógún ló darapọ̀ tí wan sì ń dá ẹgbẹ̀run méjì àbọ̀ lóṣooṣù, àwọn pẹ̀lú lo ọdún méji kí wọ́n tó kọ tan, wọ́n ni #400, 000 ni àwọn ri kójọ, lẹ́yìn ti wọ́n kọ ilé náà tán ni wọ́n tún gba àwọn olùkọ́ méjì tó n kọ́ àwọn ọmọ náà tí wan sì ń san ẹgbẹ̀rún méje náírà fún wọ́n lóṣooṣù.
"Lásíkò tó sàbẹ̀wò síbẹ̀, ó ni "" mò ń dá owó ti àwọn obìnrin tó kọ́ àwọn ilé ìwé yìí"
Oríṣun àwòrán, Kwara state Gov
Nínú ọ̀rọ̀ rẹ̀ ọ̀kan olórí ọ̀dọ́ ní ìliú náà Abolaji Sunday fẹ̀dun ọkàn rẹ̀ hàn pé ijọba tí gbàgbé àwọn ilú náà sińú ìyà àti ìṣẹ́
Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú
Ọba alara ni Ọba Oke, ara to ba si wu lo ma n fi ẹda ọwọ rẹ da. Ko si yẹ ki ẹnikẹni ro pe o ti tan fun oun, ti Eledua ba fi dara to wu u.
Eyi ni ọrọ iwuri to ti ẹnu tọkọtaya Omoniyi ati Elizabeth Oke, ti wọn ni ipenija oju jade lasiko ti wọn n ba BBC Yoruba sọrọ nilu Ado Ekiti.
Awọn tọkọtaya mejeeji yii ko si jẹ ki ipo ti wọn wa se idiwọ fun wọn lati yan isẹ oojọ kan laayo nitori wọn ni isẹ ọwọ ti wọn n se.
Iyawo lo maa n fi ilẹkẹ da ara to ba wu lati fi se baagi, bata, apamọwọ, apẹ fulawa ati bẹẹ bẹẹ lọ, ti ọkọ rẹ yo si kiri awọn ọja naa lọ sawọn ọọfisi ati sọọbu.
Awọn tọkọtaya to ni ipenija oju naa ni kii se pe wọn bi awọn mọ ipo yii amọ ipenija lo de lasiko ti awọn wa nile ẹkọ, ti awọn ko si le riran mọ.
Àwọn ìtàn mánigbàgbé tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí:
Wọn wa n rọ awọn eeyan awujọ lati ye maa ro pe ko yẹ ki iru awọn eeyan to ba ni ipenija bayii jade laye tabi pe o ti tan fun wọn.
Wọn ni Ọba Oke lo fi awọn da ara to wu u, ẹni to ba si le se iranlọwọ fun iru awọn, ko se e, sugbọn awọn si n dupẹ lọwọ Ọlọrun fun isẹda awọn.
Trump Impreachment: Donald Trump, Bill Clinton ati Richard Nixon
Oríṣun àwòrán, Alamy
Aarẹ orilẹede Amẹrika, Donald Trump ti di Aarẹ akọkọ ti Ile Igbimọ Aṣofin yọ kuro nipo lẹẹmeji ọtọọtọ.
Eleyii ti mu aarẹ Trump darapọ mọ awọn aarẹ to ti jẹ lorilẹede Amerika ri, ti wọn si ti yọ nipo.
Nkan to ṣẹlẹ si awọn aarẹ naa ree:
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Arakunrin Andrew Johnson ni aarẹ akọkọ lorilẹede Amerika ti Ile Igbimọ Asofin yoo dibo lati yọ kuro ni ipo.
Lasiko ogun abẹle ni orilẹede Amẹrika, ni Aarẹ Andrew Johnson to jẹ ọmọ ẹgbẹ oselu Democrat, fi ori gbari pẹlu awọn ọmọ ẹgbẹ oṣelu Republicans to jẹ awọn lo pọju ninu Ile Igbimọ Asofin.
Ohun to fa ija wọn ni ọrọ lati ṣe atunṣe iha Guusu orilẹede Amerika ti o ti bajẹ nitori ogun abẹle naa.
Awọn ọmọ ẹgbẹ oṣelu Republicans kan nigba naa, parapọ lati fi iya jẹ awọn to jẹ adari tako iṣọkan ilẹ Amẹrika.
Eyi lo wa lati daabo bo ẹtọ awọn ẹru ti wọn tu silẹ, amọ aarẹ Johnson lo agbara rẹ lati gbegile igbese ẹgbẹ Democrats yii.
Oríṣun àwòrán, Library Of Congress
Bakan naa ni Aarẹ Johnson tun kọ fun awọn aṣofin lati dena isẹlẹ naa lasiko to fẹ yọ ọkan lara awọn minisita rẹ to jẹ ọta rẹ, iyẹn Edwin Stanton lasiko ti ile Aṣofin lọ fun isinmi.
Yiyọ ti wọn yọ Johnson mu ki awọn ọmọ Ile Aṣofin gbe igbesẹ lati yọ aarẹ naa ni ipo.
Lẹyin idibo ile igbimọ Aṣofin kekere, ti wọn si yọ nipo, amọ ile Aṣofin agba fi silẹ nitori idibo naa ku eniyan ẹyọ kan ko pe ida mẹta ti wọn nilo lati yọ kuro nipo gẹgẹ bi aarẹ.
Kini ipalara iyọkuro fun Andrew Johnson?
Iroyin kan sọ wi pe, Johnson dubulẹ to si sunkun nigba ti o gbọ pe Ile Igbimọ Aṣofin Agba ti dena iyọkuro nipo rẹ.
Johnson jẹjẹ lati ṣe daradara ju ti tẹlẹ lọ, amọ pabo lo jasi nitori awọn ọta rẹ si duro sibi ati subu rẹ.
Ni ọdun 1869 ni ẹgbẹ oṣelu Democrats kuna lati di ipọ aarẹ mu, ti oludije lẹgbẹ oṣelu Republican, Ulysses S Grant si gba ijọba.
Kini awọn ohun ti Andrew gbeṣe ni asiko rẹ?
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ọdun 1972 ni wahala de fun Aarẹ Richard Nixon, lẹyin ti wọn ṣekọlu si olu ileeṣẹ ẹgbẹ Democrats to wa ni Watergate ni Washington DC.
Lẹyin naa ni iwadii fihan pe, owo eto idibo to gbe Nixon wọle, ni wọn san fun awọn adigunjale to ṣe ikọlu si Watergate naa, ti o si fa akọba fun awọn oṣiṣẹ Ile Ijọba, White House.
Fun ọdun meji gbako ni Nixon fi tiraka lati pana ẹsun naa, amọ ko ṣeeṣe, to si jasi ijakulẹ rẹ.
Ni ọdun 1974 ni ile aṣofin bẹrẹ igbeṣẹ lati yọ nipo, lẹyin ti iwadii fi ohun Nixon han, nibi ti o ti n sọ fun oṣiṣẹ ọtẹlẹmuyẹ CIA lati da ọwọ iwadii ikọlu Watergate duro.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Bi o tilẹ jẹ wi pe Ile Igbimọ Aṣofin tiraka lati dibo yọ nipo, amọ ko waye.
Nixon ni Oṣu Kẹjọ, ọdun 1974 kọwe fi ipo silẹ, oun si ni aarẹ orilẹede Amerika ti yoo kọwe fi ipo silẹ.
Kini ipalara fifi ipo silẹ fun Nixon?
Igbakeji aarẹ, Gerald Ford lo gba ipo aarẹ lẹyin ọsẹ mẹfa ti Nixon fi ipo silẹ.
Bakan naa ni wọn dari gbogbo ẹṣẹ rẹ jin lasiko to wa ni ipo.
Amọ ẹgbẹ oṣelu Republican kuna lati bori ninu idibo sipo aarẹ to waye ni ọdun meji lẹyin iṣẹlẹ naa.
Jimmy Carter ti ẹgbẹ oṣelu Democrat lo rọpo rẹ gẹgẹ bi aarẹ orilẹede Amẹrika.
Kini awọn ohun manigbagbe to ṣe?
Ko si ohun miran to fa ijakulẹ rẹ yatọ si wahala Watergate naa, amọ o yari pe oun ko jẹbi ẹsun ti wọn fi kan oun.
Ọdun 1994 ni Nixon jade laye, lẹyin ogun ọdun to fi ipo silẹ nitori ẹsun iwa ipa ti wọn fi kan an.
Ohun ti Aarẹ Bill Clinton sọ lasiko to n sọrọ lẹyin iku rẹ ni wi pe, ki awọn eniyan dari gbogbo ẹsẹ rẹ ji i, ki wọn si ye sọrọ rẹ ni aida mọ.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Lẹyin ọdun diẹ ti Bill Clinton parọwa si awọn eniyan lati dariji Nixon ni wahala tun suyọ fun oun naa.
Clinton to jẹ ọmọ ẹgbẹ oṣelu Democrat ni wọn bẹrẹ si ni ṣe iwadii rẹ lẹyin ọdun kan to de ipo aarẹ.
Ohun ti wọn n se iwadii rẹ le lori ni wi pe, o ra awọn ile kan ni idakọnkọ ati ẹsun ifipabanilopọ laarin rẹ ati Monica Lewinsky, to jẹ oṣiṣẹ ile Ijọba, White house.
Lẹyin iwadii ọlọjọ gbọọrọ, Clinton ni irọ ni wọn pa mọ oun, ati pe oun ko jẹbi ẹsun ifibanilopọ ti wọn fi kan oun nitori oun ko ni ibalopọ pẹlu Monica.
Awọn aṣofin dibo lati yọ Clinton nitori awọn ẹsun ti wọn fi kan an yii, amọ ile aṣofin agba tu Clinton silẹ lati ma a lọ lalafia.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Kini ipalara fun Bill Clinton?
Fun odidi ọdun kan ni ẹsun ifipabanilopọ laarin Lewinsky ati Clinton gba orilẹede Amẹrika kan.
Amọ, lasiko yii gan ni awọn eniyan dibo fun pe awọn ni igbagbọ ninu rẹ fun ju atẹyinwa.
Iroyin fihan pe ida mẹtadinlaadọrin ọmọ Ilẹ Amerika lo dibo pe awọn fi ọwọ si Clinton gẹgẹ bi aarẹ Amẹrika.
Awọn ọmọ ẹgbẹ oṣelu Republicans nikan lo padanu iṣẹ wọn, ti wọn si tun padanu awọn idibo ti wọn ṣe ni awọn ilu kọọkan.
Oríṣun àwòrán, NewYork Times
Ọdun 2001 ni Clinton kuro ni ipo aarẹ, amọ ẹgbẹ oṣelu rẹ kuna lati bori gẹgẹbi aarẹ, ti George Bush si di aarẹ ilẹ Amẹrika lẹyin rẹ.
Ohun to leke tente lasiko iṣejọba rẹ ni ẹsun ifipabanilopọ pẹlu Monica Lewinsky.
Ati igbiyanju lati yọ nipo ti ko ṣeeṣe
Bakan naa ni igbagbọ ti awọn eniyan ni ninu rẹ to fi mu ki wọn dibo mo ni igbagbọ ninu rẹ fun ni gbogbo asiko laasigbo ẹsun ifipabanilopọ.
Bi awọn eniyan ṣe gba tirẹ fihan pe igbiyanju ati yọ nipo ko ni ipa buburu lori rẹ bii ti awọn asaaju rẹ mejeeji.
Kwara: Dókítà 66 ló síṣẹ́ abẹ fún àwọn ìbejì tó lẹ̀pọ̀ ní ilé ìwòsàn fasiti Ilorin
Oríṣun àwòrán, UITH
Fásitì ìkọni nílùú Ilorin (UITH) ti kede fún gbogbo àye ni Ọjọ́bọ bi wọ́n ṣe ṣe aṣeyọri iṣẹ́ abẹ fún àwọn ibejì tí wọ́n lẹpọ wá sáyé.
Nínú ọ̀rọ̀ rẹ Gíwá ilé ìwosan náà ọjọ̀gbọ́n Abdaullah Yussuf fí aṣeyọri náà sọri ìṣẹ́ takuntakun àti ìfarajì àwọn dókítà mẹ́rìndíláádọ́rin tó péjú ṣe iṣẹ abẹ náà.
Ó ni bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé, irinṣẹ́ tó wà nínú ilé ìwòsan náà ko kójú òsùwọn tó síbẹ̀ wọ́n ṣe aṣeyọri.
Ọjọ̀gbọ́n náà ní ìdí tí ọ̀pọ̀ fi má a ń sá lọ si òkè okun fún ìtọ́ju àti àwọn iṣk abẹ́ báyìí ni pé ọ̀pọ̀ àwọn irinṣẹ tó wà ni Nàìjíríà ló ti gbó.
Giwa UITH fi kún pé, oníruuru ẹ̀ka ìṣègùn  mẹ́rìndílógún ni àwọn ti sa àwọn dókítà tí wọ́n ṣiṣẹ́ náà jọ láti ṣe aṣeyọri
 Nígbà tí wọ́n gbé àwọn ọmọ náà dé, à kò tilẹ̀ kọ́kọ́ mọ ibi ti wan ti lẹ̀pọ̀ ni pàtó, A kàn gbiyanju láti ṣeranwọ ní, nítori ko si irinṣẹ́ tó yẹ.
Bákan náà ni wọ́n dúpẹ lọ́wọ́ àwọn tí wọ́n ṣe ìrànwọ́ láti mú kí iṣẹ́ náà ṣeese pàápà'jùlọ nípa pípèsè owó tí sì fún ọ̀pọ̀ ní ìwúrí láti ṣe iṣẹ́ abẹ náà
Oríṣun àwòrán, UITH
Goriola Hassan: ‘Tattoo’ tó wà lára mi, kò dí ọba jíjẹ lọ́wọ́, ara oge ṣíṣe ni
Oríṣun àwòrán, Instagram/goriolahassan
Gẹgẹ bi aṣa ilẹ Yoruba, o ni awọn etutu kan ti ilu gbọdọ ṣe ati eyi ti ọmọ oye to ba fẹ jọba naa ni lati ṣe, ki o to le gori oye.
Amọ, o dabi ẹni pe gbogbo nkan lo ti yipada bayii bo ya nitori pe aye ti di aye ọlaju ni.
Oṣere tiata kan ree, Goriola Hassan to sọ pe, oun ko ṣe etutu kankan, ki oun to jẹ ọba ilẹ Uba Imobi nilẹ Ijẹbu nipinlẹ Ogun.
Ọgbẹni Hassan to ti jẹ Ọba ilẹ Uba Imobi bayii sọ pe, lootọọ ni pe wọn gbọdọ ṣe awọn eto, amọ ni toun, ko si ohun to jọ etutu rara.
Oríṣun àwòrán, Instagram/somolu
''Ko digba ti wọn ba to lo odidi eeyan ṣe irubọ, ki eeyan to le jọba, a o ni lati faye ni ẹnikeji lara,'' Oba ilẹ Uba lo sọ bẹẹ.
Bakan naa ni Kabiyesi Uba ṣalaye pe, oye ti oun jẹ ko na oun owo bii ti wulẹ ko mọ.
Oba ilẹ Uba ni ''idile ọba ni wọn bi mi si, ati idile mama ati baba mi ni wọn n maa n jọba.''
O nigba ti oun de lati orilẹede Amerika, lawọn araalu wa ba oun pe ki oun jẹ ọba ilẹ Uba.
''Mi o ni lati nawo kankan, awọn ilu gan an lo ṣe inawo ibẹ,'' Kabiyesi Uba lo ṣalaye bẹẹ.
Oríṣun àwòrán, Omogoriola Hassan
Lori ọrọ awọn olori laafin, Oba ilẹ Uba ni oju kan lada ni lọrọ oun, o ni iyawo kan toun ni, ti tẹ oun lọrun.
''Mi o le nifẹ obinrin meji pọ lẹẹkan naa, nitori naa, o maa nira fun mi lati ni olori meji laafin,'' Oba Uba lo woye bẹẹ.
Bẹẹ ba si gbagbe, gbajumọ osere tẹlẹ naa lo fẹ ọkan lara awọn osere tiata lobinrin, Ayo Adesanya, ko to di pe aarin wọn daru.
Oríṣun àwòrán, Omogoriola Hassan
Kabiyesi tun sọ fawọn akọroyin pe, ko si ohun tuntun labẹ ọrun mọ lori laali tawọn oloyinbo n pe ni ''tattoos'' to wa lara oun.
O ni lati ayebaye lawọn Yoruba ti maa n le laali sara fun oge ṣiṣe, ''laye ode oni ni wọn kan n pe ni ''tattoo.''
Lakotan, Kabiyesi Uba ni oun n gbero lati pe awọn gbajugbaja oṣere tiata wa si ilẹ Uba, lati le wa dokoowo ki awọn araalu si jẹ anfaani rẹ.
Ifayemi Elebuibon: Mo jẹ páànù ìyà nítori mo fẹ́ mọ̀ọ́kọ, mọ̀ọ́kà
Awọn agba bọ, wọn ni ọmọ ti yoo ba jẹ Aṣamu, ati kekere ni iru wọn ti maa n ṣẹnu ṣamu ṣamu.
Bayii lọrọ ri pẹlu ilumọọka oniṣegun ibilẹ to tun jẹ agba babalawo, Araba ilu Osogbo, Oloye Ifayemi Elebuibon.
Elebuibon sọ fawọn akọroyin pe, lati ọmọ ọdun mẹrin ni oun ti n fi ọfọ se iwosan fawọn ọrẹ oun.
''Iṣẹ Ifa ni baba mi n ṣe, oun lo si n kọ mi nipa Ifa ati iṣẹṣe, ọjọ kan tiẹ wa ti mo ọkan lara awọn ohun ti baba mi ti mọ wo lara ọrẹ mi kan to farapa,''Elebuibon lo sọ bẹẹ.
Oríṣun àwòrán, Ifayemi Elebuibon
O ni ọfọ ni oun mu bọnu nigba ti oju ibi ti ọrẹ oun fi ṣeṣe naa n ṣẹjẹ.
Elebuibon sọ pe iyalẹnu lo jẹ fawọn to wa nibẹ lọna naa pe oun fi ọfọ da ẹjẹ jade duro.
Araba ilu Osogbo ṣalaye siwaju pe, oun tun fi ọfọ ji saye ẹnikan to daku pada.
''Baba mi kọ mi ni oriṣiiriṣii nkan nipa Ifa nigba ti mo wa ni ọmọ kekere, koda o tun gba onifa mii, Agbongbon Awo ilu Osogbo, Oloye Faniyi Ajani lati maa kọ mi ni Ifa,'' Oloye Elebuibon ṣalaye.
Itaniji: Oluwo sọ ìtàn bí Orunmila ṣe jìyà nílùú Iwo àti ayọ̀ tó gbẹ̀yìn rẹ̀ torí sùúrù
Elebuibon ni oun jẹ paanu iya, nitori ki oun le mọọ kọ, mọọ ka.
''Lati ilẹ ni baba mi ti sọ fun mi pe n ko ni lọ si ile iwe nitori iṣẹ Ifa akọsẹkaye mi sọ pe mo gbọdọ ṣe.
Ṣugbọn mo nifẹ si ki n mọ iwe kọ ati ki n mọ iwe ka. Mo maa n wo bawọn ọmọkunrin mẹta kan ṣe maa n ṣiṣẹ amurele wọn nile ọga mi onifa lagbegbe Oke Popo.
Amọ igbaju igbamu lo maa n bade lọdọ ọga mi, nitori ko fẹ ki n ni ohun kan ṣe pẹlu ileewe,'' Oloye Elebuibon lo ṣalaye bẹẹ.
Ado Ekiti Blind Couple: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú
Elebuibon ni oun ko titori iya ti ọga oun fi jẹ oun ṣe, oun rii pe oun le kọwe, oun si le mọọ ka pẹlu.
Ṣebi Yoruba bọ, wọn ni ko si ẹni to mọ ibi ori n gbe e lọ. Elebuibon ni iṣẹ Ifa ti gbe oun de orilẹede Amerika ati kaakiri agbaaye.
O ni oun maa n ṣaaba lọ si Amẹrika lati kọ awọn eeyan lẹkọọ lori aṣa Yoruba ati ilẹ Afirika, bakan naa lo ni oun maa n ṣe etutu fawọn onibara oun nibẹ.
Koda Elebuibon ni oun ti kọ awọn akẹkọọ fasiti ipinlẹ San Francisco ri l'Amerika.
Paystack Shola Akinlade: Ìgbésẹ̀ 5 yìí ni mo gbé tíléeṣẹ́ Stripe fi dókòwò $200m pẹ̀lú mi
Oloye Elebuibon ni ọkan oun balẹ pe awọn ọmọ oun ko kẹyin si Ifa sise.
O ni idunnu lo jẹ fun oun pe awọn ọmọ oun n polongo Ifa kiri origun mẹrin agbaye.
Araba ilu Osogbo ni iwe tawọn ọmọ oun ka ko ni ki wọn pa iṣẹ Ifa ṣiṣe ti.
''Irọ ni pe ọba tuntun maa n jẹ ọkan ọba to ku bii ara etutu ni ipebi,'' Oloye Elebuibon lo wi bẹẹ.
O ni ko si ẹsin yala ẹsin ibilẹ, musulumi tabi kristẹni to fọwọ si ki wọn maa fi eeyan ṣe irubọ.
Oloye Elebuibon sọ pe awọn to ba n ṣe iru nkan bayii n ṣe lati fi tabuku ẹsun abalaye ni.
Nigba ti awọn akọroyin beere iye ọdun ti eeyan fi le kọ iṣẹ Ifa, o ni o kere tan kikọ iṣẹ Ifa yoo gba ọdun mẹwaa ati abọ.
Elebuibon ni o le ju ọdun mẹwaa lọ nitori ẹkọ kikọ nipa Ifa ko le tan laelae.
DNA: Wo àkójọpọ̀ ọ̀nà méje tí ọmọ àlè fi le wọnú ilé láì jẹ́ pé ìyàwó ṣe aṣemáṣe
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Wo bí ìyàwó ṣe le gbé ọmọ Ọbà fún Ọ̀ṣun láì yan àlè
O to ọjọ mẹta kan ti ọrọ gbigbe ọmọ ọba fun ọsun ti n ja rain-rain lawujọ wa.
Eyi ko si sẹyin bi awọn ọkọ ninu idile se n gbe igbesẹ lati se ayẹwo awọn ọmọ wọn boya wọn jẹ ojulowo ọmọ ọkọ abi ọmọ ale.
Iwadii si ti fihan pe orilẹede Naijiria lo se ipo keji, lẹyin orilẹede Jamaica, ti isẹlẹ gbigbe ọmọ Ọba fun Ọsun ti maa n waye.
Pupọ isẹlẹ gbigbe ọmọ ale wọnu ile si ni awọn eeyan saba maa n di ẹbi rẹ ru awọn iyawo ile pe wọn se asemase nita pẹlu ọkunrin mii.
Oríṣun àwòrán, DNA
Ero ọpọ eeyan ni pe ti iru ifẹ ikọkọ bẹẹ ba ja si oyun fun abilekọ, lo maa n ti iru ọmọ bẹẹ mọ ọkọ rẹ lọrun ninu ile.
Wọn ni bi ayẹwo DNA wa waye lori iru ọmọ bẹẹ, ni ọkọ yoo to mọ pe ọmọ ọlọmọ ni oun n pe ni ọmọ oun.
Amọ iwadi iwadii ijinlẹ kan ree, eyi to salaye bi ọmọ ale se le wọnu idile lai jẹ pe iyawo ile se asemase pẹlu ọkunrin miran nita.
DNA tẹgbọn-taburo tabi ti baba ati ọmọ lee sunmọ ara wọn tabi ko jẹ nkankan naa.
Bi ọkan ninu wọn ba si ni ajọsepọ pẹlu  iyawo ẹnikeji ninu ẹbi naa, boya ẹgbọn ba iyawo aburo sun, abi baba ba iyawo ọmọ rẹ sun, to si di oyun.
Ti obinrin bẹẹ ba gbe ọmọ naa fun ọkọ rẹ gangan, to ba di ọjọ iwaju, ti ayẹwo DNA si waye lori ọmọ yii, iwadii fihan pe ayẹwo DNA ọmọ naa ko ni fihan pe ọmọ ale ni.
Idi ni pe DNA baba to fun iya rẹ loyun ati baba to n pe ni baba rẹ jẹ nnkan kannaa tori ẹbi ni wọn.
Irufẹ baba bẹẹ ti wọn sọ fun pe ojulowo ọmọ ni ọmọ rẹ, ko ni mọ pe ọmọ oun kọ, ọmọ ọlọmọ to jẹ mọlẹbi oun ni.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Gẹgẹ ba se mọ pe ko si ẹnikẹni tabi ohunkohun to pe ayafi ọlọrun ọba.
Bẹẹ na lo se ri pẹlu oniruuru imọ ẹrọ sayẹnsi ti oyinbo n se nitori asise lee waye lati ipasẹ ẹrọ naa, paapaa ti ko ba sisẹ bo se yẹ.
Bakan naa si ni ọmọ sori pẹlu ilana ati imọ ẹrọ ti wọn n gba se ayẹwo DNA.
Ti asise ba si waye, o see se ki wsn pe ọmọ ọkọ ni ọmọ ale tabi ọmọ ale ni ọmọ ọkọ eyi to lewu pupọ.
Bi wọn ba si pe ọmọ ọmọ ni ọmọ ale, ile ti daru, tiru ọmọ bẹẹ yoo si di ọmọ ale titi ayeraye lai jẹ pe iya rẹ yan ale tabi gbe ọmọ ọba fun ọsun.
Iru isẹlẹ yii ko si le mai waye nilẹ Afirika, ti itọju ati imọ ẹrọ ko ti kun to.
Iwadii naa ti fihan pe o see se ki wọn paarọ ọmọ mọ iyawo ile lọwọ nile iwosan lai jẹ pe o mọ nipa rẹ.
Irufẹ isẹlẹ bayii si le waye ni orisi ọna meji eyi to nii se pẹlu iwa amọọmọ se latọdọ awọn osisẹ eleto ilera, olugbẹbi alaboyu tabi dokita.
Bakan naa ni isẹlẹ yii le waye nipa asise lai jẹ pe awọn olutọju alaisan tabi eleto ilera mọọmọ paarọ ọmọ.
Paystack Shola Akinlade: Ìgbésẹ̀ 5 yìí ni mo gbé tíléeṣẹ́ Stripe fi dókòwò $200m pẹ̀lú mi
Eyi maa n waye nifọwọ kọwọ pẹlu awọn osisẹ eleto ilera nile iwosan, to ti gba owo lati paarọ ọmọ laarin iyalọmọ kan si ekeji.
Nigba miran, wọn le paarọ ọmọbinrin si ọkunrin tabi ọkunrin si obinrin, ti iya ti wọn paarọ ọmọ rẹ ko si ni mọ pe ọmọ ọlọmọ ni wọn gbe fun oun.
Idi ni pe ti obinrin ba sẹsẹ bimọ, ẹmi ati itọju ara rẹ ni yoo kọkọ du, ọmọ tawọn agbẹbi ba si gbe fun pe o bi naa si ni yoo gbe wale.
Nigba miran, o le jẹ pe akoko ti iya ikoko naa kọ si baluwẹ lawọn olubi ẹda naa yoo ri aaye paarọ ọmọ sira wọn.
Ti wọn ba sẹsẹ bi ọmọ tuntun nile iwosan ijọba, wọn yoo so orukọ baba ọmọ naa mọ ọmọ ọhun lọwọ lati tete daa mọ laarin ọpọ ọmọ tuntun ti wọn bi wọn si akoko kan naa.
Ni ọpọ ile iwosan ijọba yii, ọpọ ọmọ tuntun ti wọn ba bi sile iwosan naa lasiko kan naa, ni wọn yoo gbe wa sibudo ti wọn ti n wẹ wọn.
Bi wọn ko ba si sọra, orukọ ti wọn kọ si ọwọ iru ọmọ tuntun bẹẹ le jabọ laimọ, ti yoo si nira lati mọ iru ọmọ ẹni tii se.
Ti iru isẹlẹ naa ba si waye fun ọmọ tuntun meji tabi mẹta, eyi le mu ki awọn agbẹbi gbe awọn ọmọ yii fun iya to ba wu wọn, ti iyawo yoo si gbe ọmọ ọlọmọ wale fun ọkọ rẹ laimọ.
Ado Ekiti Blind Couple: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú
Ni ọpọ igba ti isẹlẹ ifipanilopọ ba waye, asa awujọ ni lati sọ fun obinrin ti wọn ba fipa ba lopọ pe ko panu mọ.
Bi obinrin naa ba si fi ọrọ yii se apamọra, ti ko si tun lọ sile iwosan fun ayẹwo ati itọju ara rẹ, ewu n bẹ loko longẹ.
Bi iru obinrin bẹẹ ba ni ibalopọ pẹlu ọkọ rẹ ni tooto igba ti isẹlẹ ifipanilopọ naa waye, o see se ko loyun, ko si jẹ pe ẹni to fipa ba lopọ lo ni oyun.
Iru iya bẹẹ le gbe ọmọ ale wọle lai fura pe oun ti gbe ọmọ ọba fun ọsun.
Ni awọn ile iwosan ti wọn ti n fi atọ pamọ, o see se ki pasipaarọ atọ ọkunrin kan si ti ẹlomiran waye.
Eyi si le waye bi lọkọlaya ba n wa ọmọ, ti wọn si ni ki ọkọ wa fi atọ silẹ, ki wọn le fi ilana IVF gbe sinu iyawo rẹ.
Amọ bi wọn ba ti paarọ atọ iru ọkọ iyawo bẹẹ, o le loyun pẹlu atọ ọkunrin miran laimọ.
Ayẹwo DNA lọjọ iwaju si le fihan pe  ọmọ ale ni iyawo gbe wale.
Uganda elections 2021: Ààrẹ Yoweri Museveni ló jáwé olúborí ìdìbò ààrẹ ní Uganda
Oríṣun àwòrán, AFP
Aarẹ to tí n ṣe ijoba bọ lati ọdún marundinlogoji lorilẹede Uganda, Yoweri Museveni lo tun pegede ninu idibo ààrẹ to waye nilẹ naa gẹgẹ bi awọn eleto idibo ti ṣe kede.
Ikede yi nwaye toun ti pe awọn alatilẹyin oludije aalatako Bobbi Wine  fẹsun kan wọn pe orisirisi magomago lo waye ninu idibo ọhun.
Ajọ eleto idibo ni Ọgbẹni Museveni ri to ibo ida  mọkandinlọgọta 59% ninu ida ọgọrun ti alatako rẹ Ọgbẹni  Wine si ri ida marundinlogoji ibo tii ṣe 35%.
Ṣaaju ni ọgbẹni Wine to jẹ akọrin takasufe ti leri lati ṣàfihàn ẹri makaruru to waye ninu idibo naa.
Amọ ajọ ọhun sọ pe ko si ohun to jọ bẹẹ ninu ibo to waye lọjọbọ.
Awọn to n woye eto idibo naa bẹnu àtẹ lu bi ijoba ti ṣe gbegi dina ojú òpó ayelujara nilẹ naa lasiko idibo.
Wọn ni igbesẹ yi ko je ki awọn eeyan ni igbagbọ ninu eto idibo to waye
Bakan naa ni ọgbẹni  Wine sọ pe kete ti anfaani ayelujara ba sì silẹ pada òun yoo mu ẹri wa lati fi jẹri ọrọ rẹ.
Ọgọrọ eeyan lo padanu ẹmi wọn ninu ikọlu to waye ṣaaju idibo.
Bẹẹ naa ni awọn alatako ni ijọba n dun koko mọ awọn.
Pẹlu esi yi aarẹ Museveni yoo ṣe ijoba fún saa kẹfà  ni ẹni ọdun mẹrinlelaadọrin.
Ẹnikan kiki jẹ, ki ilẹ o fẹ lawọn Yoruba maa n wi. Amọ bi ti aarẹ prilẹede Uganda, Yoweri Museveni kọ o.
Oríṣun àwòrán, EPA
Aarẹ Museveni to dije fun ipo aarẹ fun saa kẹfa ninu idido Ọjọbọ lo lewaju gẹgẹ bi awọn esi ibo ti wọn ti ṣe sọ.
Oludije fẹgbẹ oṣelu alatako to ti figba kan jẹ akọrin ri, Bobi Wine ni eeru pọ ninu eto idibo ọhun, ati pe niṣe wọn yi ibo rẹpẹtẹ.
Awọn onwoye to tẹle eto idibo naa sọ pe ẹrọ alatagba to dẹnu kọlẹ fun ọjọ mẹta ni Uganda ko jẹ ki awọn eeyan ni igbagbọ ati igboya ninu eto idibo naa.
Ṣugbọn ileeṣẹ eleto idibo sọ pe ko si ohun to jọ eeru tabi magomago ninu eto idibo naa.
Ọjọ Abamẹta tii ṣe ọjọ kẹrindinlogun oṣu kinni ọdun 2021 yii ni esi ibo to ku yoo jade.
Ọpọ eeyan lo ku lasiko rogbodiyan to ṣẹlẹ ni Uganda ṣaaju eto idibo aarẹ.
Awọn ọmọ ẹgbẹ oṣelu alatako tun ti fi ẹsun idunkoko mọ ni kan ijọba ilẹ naa.
Aarẹ Museveni ti n ṣe ijọba orilẹede Uganda fun ọdun marundinlogoji bayii.
Oludije fẹgbẹ osẹlu alatako, Robert Kyagulanyi ti orukọ inagije n jẹ Bobi Wine figbe ta lọjọ Ẹti nigba ti esi ibo bẹrẹ si ni jade pe awọn sọja rọgba yi ile oun ka.
Amọ, agbẹnusọ fun ijọba, Don Wanyama ni asọdun lasan an ni Wine n sọ.
Wanyama ṣalaye pe eeyan pataki ni Wine jẹ lasiko yii, iyẹn lo jẹ ki ijọba ni kawọn ẹṣọ wa nile rẹ fun abo to muna doko.
Oluwo 5th coronation anniversary: Èyí ni àwọn ìgbà mẹ́jọ tí ọ̀rọ̀ Oluwo di ariwo nígboro láàrín ọdún márùn ún rẹ̀ lóyè
Oríṣun àwòrán, osun state government
Ni ọjọ kẹrindinlogun oṣu kini ọdun 2016 ni wọn fi Ọmọọba Abdulrasheed Akanbi jẹ oye gẹgẹ bi Oluwo ti ilu Iwo, oun si ni Ọba kẹrindinlọgbọn ti yoo joko lori itẹ naa.
Idile Oye Gbaase ni Oluwo Abdulrasheed Akanbi ti ṣẹ jade wa, ilu Canada lo si wa to ti n ṣe iṣẹ Kọngila ki wọn to fi jẹ Ọba lẹyin ọdun meji ti Oluwo ana, Ọba Ashiru Tadeṣe ti waja.
Lati igba to si ti de ori ipo, orukọ Kabiyesi Abdulrasheed Akanbi kii wọn loju ewe iroyin, ni ọpọ igba lo si maa n jẹ nitori awon ohun to ni ariwisi kan tabi omiran.
Idi niyi ti a fi n gbe awọn iṣẹlẹ manigbagbe to ti waye laarin ọdun marun Oluwo ilu Iwo, Ọba Abdulrasheed Akanbi nipo.
Wiwọ aṣọ oyinbo pẹlu ade ilu Iwo lori itẹ.
Oríṣun àwòrán, oluwo
Lootọ awọn ọba kii ṣe angẹli, ṣugbọn ipo to lagbara ti ko si yẹ ko ni aleebu kankan ni awọn Yoruba to wọn si, idi si niyi ti wọn fi maa n fi oju igbakeji Olodumare wo wọn.
Nigba ti Ọba Akanbi kọkọ de ori itẹ lara awọn ariwisi to kskọ jade sii ni bi o ṣe n wọ awọn aṣọ oyinbo si abẹ ade ilu Iwo lori itẹ ilu Iwo. Eyi da ọpọlọpọ awuyewuye silẹ nigba naa nitori oju kotọ ni ọpọ onwoye atawọn ọmọ ilẹ kaarọ oojiire fi wo eyi nigba naa.
Gbogbo awijare ti kabiyesi Oluwo si n fi sita lori igbesẹ naa nigba naa ni ko tẹ awọn eeyan lọrun, ki o to di wi pe o tun ọrọ naa ṣe nigba naa.
Oríṣun àwòrán, oluwo of iwo/twitter
Ni ọdun 2018 ni Oluwo kede pe oun gangan ni Emir ilẹ Yoruba lasiko ti wọn fi n ṣe ayẹyẹ iwe-lawani fun Fadhilaru Sheikh Yahquub Abdul-Baaqi Mohammed gẹgẹ bii Waziri ilẹ Yoruba.
"Emi ni Emir Yoruba.
Niwọn igba ti alaafin Ọyọ ba laṣẹ lati yan Aarẹ Ọna kakanfo ati Iyalode ilẹ Yoruba, Emi naa ni agbara ati aṣẹ lati yan Waziri fun ilẹ Yoruba gẹgẹ bi itan ṣe fi idi rẹ mulẹ pe Oluwo ni ọba akọkọ to gba ẹsin Islam ni ilẹ Yoruba."
Eyi fa ọpọ faa sihin, faa-sọhun nigba naa eleyi to mu ki ọpọ tilẹ pariwo si ọbalaye naa nigba naa pe boya ko kuku gbe ade Iwo silẹ ko gba oke ọya lọ lati lọ jẹ Emir rẹ to fẹ jẹ.
Oríṣun àwòrán, oluwo of iwo/twitter
Lara awọn agbọgbọntinu iroyin ariwisi to so mọ Oluwo Abdulrasheed Aknbi leti aṣọ laarin ọdun ọdun marun un rẹ loye ni ti ọrọ ẹsin ni ilu Iwo.
Akọkọ, ni bi o ṣe lewaju gbigbe irun dide lasiko irun yidi kan ni ilu Iwo eyi ti awọn ẹlẹsin Musulumi ni ilu naa ati nibomiran bu ẹnu atẹ lu pe o kyu diẹ kaato nitori ojuṣe awọn Imaamu lo fẹ gbaṣe bẹẹ.
Ko pẹ ti Oluwo Akanbi de ori itẹ ti Iṣẹlẹ yii fi ṣẹ nigba naa lọdun 2016. Oluwo funrarẹ si ni oun ni olori ẹsin ni ilu Iwo, nitori naa oun laṣẹ lati gbe irun dide tabi lewaju adura ni yidi. Ọpọ awọn onimọ ẹsin Islam nigba naa lo si sọ  wi pe Oluwo Abdulrasheed Akanbi ko ni gbogbo ilana ati ẹtọ ti o yẹ fun ẹni to lee ṣiwaju adura bẹẹ.
Lẹyin eyi ni wahala tun bẹrẹ laarin oun ati Imaamu agba Mọṣalaṣi ilu Iwo, Sheihk Adio. Koda wọn gbe aawọ yii de ori irun yidi nibi ti Imaamu naa ti fi ẹsun kan Oluwo Akanbi pe o gbimọnran ati ba iyawo oun lajọṣepọ.
Bi o tilẹ jẹ wi pe Kabiyesi Oluwo ni ko sohun to jọ bẹẹ, sibẹ ọpọ lo pariwo sita pe irufẹ eyi ko ṣee maa gbọ seti si ọbalaye.
Oríṣun àwòrán, oluwo/twitter
Lootọ ni awọn agba bọ ti wọn ni ko si apọnle fun ọba ti ko ni olori. Amọṣa, Ọba Akanbi ṣe eyi to le kenka ni tirẹ nipa gbigbe ade le olori rẹ lori.
Ninu itan Yoruba, ko fẹẹ tii si ọba kan to gbe ade le iyawo rẹ lori ri. Idi ni pe Yoruba gbagbọ pe ko si idi fun ade meji lati wa ninu ilu kan naa lẹẹkan ṣoṣo.
Amọṣa o, Oluwo ti ilu Iwo gbe ade le Chanel Chin aya rẹ lori. O ni idi ti oun fi ṣe bẹẹ ni pe Oduduwa to jẹ baba Yoruba gbe ade le iyawo rẹ, Olokun lori.
Ohun ati aya rẹ naa ja ajatuka loṣu kejila ọdun 2019 eleyi to tun tu oniruuru ẹgbin sita.
Oríṣun àwòrán, oluwo/twitter
Lootọ, nigba ti Oluwo n gori itẹ, Ọọni ile Ifẹ Adeyẹye Ogunwusi ti dade ni ile Oodua, ṣugbọn ọrẹ ati kekere wa ni wọn pe awọn mejeeji.
Amọṣakini ọhun yipada lẹyin asiko diẹ. Oniruuru idi lawọn eeyan n gbe dide fun ohun to le faa aawọ laarin awọn ọbalaye mejeeji yii.
Aawọ naa n lọ labẹnu fun ọpọlọpọ igba ki o to bẹ lu sita fun araye nibi eto ipade awọn lọbalọba kan to waye ni ipinlẹ Rivers nibi ti Oluwo ti fẹsun kan Ọọni pe ọkan lara awọn oṣiṣẹ alaabo rẹ lu oun.
Oluwo ni Ọọni ile Ifẹ lo paṣẹ fun oṣiṣẹ rẹ naa lati ti oun. Eleyi fa ọpọlọpọ ariwisi nigba naa debi wi pe awọn oloye Iwo kan tilẹ koro oju si Oluwo ti wọn si ni ko tọwọ ọmọ rẹ bọṣọ.
Oluwo gba Ọba ẹgbẹ rẹ ni ikuuku, awọn ọba ipinlẹ Ọṣun ba baa wi
Oríṣun àwòrán, oluwo/twitter
Afi bii pe iran ariwisi Ọba Abdulrasheed Akanbi ko tii to nkan lọrọ ri ni ọdun 2020 nigba ti iroyin jade si igboro pe Ọbalaye naa lu Agbowu ti Ilu Ọgbaagbaa,  Ọba Dhikrulahi Akinrọpo lasiko ipade ipẹtusaawọ kan laarin awọn ọbalaye ni ijọba ibilẹ Iwo ati Ọla-Oluwa.
Bi o tilẹ jẹ wipe Oluwo ni ọrọ kobakungbe ti Agbowu n sọ si oun lo ṣokunfa dundu iya ti oun din fun un jẹ niwaju ọga ọlọpaa ẹkun kọkanla, Zone 11 lọjọ naa.
Eyi ko dun mọ ọpọ ọmọ Yoruba ninu rara ti wọn si bu ẹnu atẹ lu iwa yii.
BBC News Yoruba gbe iroyin naa jade nigba naa
Ki lo fa Ija lọbalọba ni ilu Iwo
Oríṣun àwòrán, facebook/emperor Abdulrasheed Adewale Akanbi telu
Awọn agba oye ilu Iwo kan pe birikoto ni ọdun 2020 lati yọ oluwo Akabi. Ko si idi meji ju awọ n ariwisi ti o n wọ tọọ lẹyin eleyi ti wọn ni o n ta ẹrẹ ba Itẹ ilu Iwo.
Awọn afọbajẹ mejila naa kọwe ẹhonu si gomina Oyetọla pe Ọba Abdulrasheed Akanbi ko ṣojuṣe rẹ gẹgẹ bi Oluwo daadaa.
"Lara awọn ẹsun loniraanran ti wọn si ka sii lẹsẹ ni ""ẹsun ṣisafojudi si Ọọni ile Ifẹ, ija to ba Imaamu Adio ja, Alaafin Ọyọ ati Ọrangun Ila"""
Oríṣun àwòrán, facebook/emperor Abdulrasheed Adewale Akanbi telu
Lara awọn ọba to ni ifẹ awọn alaini ati arugbo ni Oluwo wa. Eyi si tubọ jẹyọ lasiko ti ajakalẹ aarun Coronavirus jade sita lọdun 2020.
Lara awọn Ọba to mu idẹrun tọ awọn eeyan wọn paapaa nipa pinpin ohun jijẹ ati mimu fun awọn alaini ati arugbo ilu  ni Oluwo Akanbi wa.
Ọpọ igba ni Ọbalaye yii si maa n wọ inu ilu tọ awọn ti ko ni lọ atawọn arugbo lati ṣe itọrẹ aanu fun wọn, eyi mu ọpọlọpọ awọn mẹkunu ilu Iwo o fẹran rẹ pẹlupẹlu gbogbo ariwisi to n wọ tọ ọbalaye naa lẹyin.
Past week events: Àwọn ìṣẹ̀lẹ̀ ńlà lọ́sẹ̀ tó kọjá tó fi mọ́ bí Covid-19 ṣe gbẹ̀mí èèyàn 23 lọ́jọ́ kan ṣoṣo
Oríṣun àwòrán, Getty Images
A o ni rin arin fẹsẹ ṣi lagbara Edumare. Idi abajọi adura yii ni pe awọn iṣẹlẹ to lami laaka kan ṣẹlẹ lọsẹ to kọja yii ni Naijiria.
Wọnyii ni diẹ lara awọn iṣẹlẹ ọhun to waye kaakiri orilẹede Naijiria.
Lara awọn iṣẹlẹ ọhun ni ijinigbe awọn oniṣowo ohun ti ẹnu n jẹ loju ọna wọn si ilu Aba nipinlẹ Abia.
Awọn ajinigbe agbebọn ji awọn oniṣowo 27 lọna ajo wọn lati Kano si Aba
Lati ilu Kano lawọn oniṣowo naa ti n bọ ki awọn agbebọn ajinigbe naa to dawọn lọna.
Oríṣun àwòrán, OTHER
Lorun ọjọ Aiku ọsẹ to lọ lawọn oniṣowo naa fi ilu Kano silẹ lọ Aba ni ireti lati pada si kano lẹyin ti wọn ba ra ọja tan.
Ẹgbẹ awọn ọdọ oniṣowo ninu ọja aringbungbun Kano ṣalaye pe taya ọkọ tawọn eeyan naa wa ninu rẹ lawọn ajinigbe ọhun dabọn bo.
Lẹyin naa lawọn agbebọn ọhun ji gbogbo wọn gbe lọ.
Oríṣun àwòrán, TWITTER/@CHIKWE_I
Ile iwosan awọn alarun covid-19
Coronavirus ṣekupa eeyan mẹtalelogun(23) lọjọ kan ṣoṣo ni Naijiria
Ajọ NCDC to n gbogun ti ajakalẹ arun ni naijiria kede l'Ọjọbọ ọjọ kẹrinla oṣu kinni ọdun yii pe eeyan mẹtalelogun ni arun covid-19 gbẹmi wọn lọjọ naa.
Ajọ NCDC fi lede loju opo Twitter rẹ pe eeyan 1,479 lo ko arun ọhun l'Ọjọbọ kan naa.
Eeyan 1,275 lo jajabọ lọwọ coronavirus lọjọ naa ti wọn si gba ile wọn lọ.
Eeyan 697 ninu awọn to ko arun covid-19 lọjọ naa lo wa lati ipinlẹ Eko nikan.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Iranti ọjọ tawọn ologun pa Olootu ijọba Naijiria akọkọ Tafawa Balewa ati Sardauna ilu Sokoto
Ọjọ Ẹti ọjọ kẹẹdogun oṣu kinni ọdun 2021 yii lo pe ọdun marunlelaadọta ti awọn ologun ṣekupa Olootu ijọba Naijiria akọkọ, Alhaji Tafawa Balewa ati Sardauna ilu Sokoto, Ahmadu Bello.
Awọn mejeeji wa lara awọn ajijagbara fun ominira orilẹede Naijiria.
Balewa ni o jẹ olootu ijọba Naijiria lẹyin ti Naijiria gba ominiran tan lọdun 1960 nigba ti Bello si jẹ olori ijọba apa Ariwa Naijiria ki wọn to pa wọn lọjọ kẹẹdogun, oṣu kinni, ọdun 1966.
Awọn Naijiria si n ṣe iranti iṣẹ ribi ribi ti wọn ṣe fun ilọsiwaju orilẹede yii.
Oríṣun àwòrán, @NGRPRESIDENT
Buhari kede ṣiṣi ibode ori ilẹ Naijiria pada
Lọsẹ to lọ yii naa ni Aarẹ Muhammadu Buhari kede ṣiṣi ibode oriilẹ Naijiria pada lẹyin to ti wa ni titi pa fun ọdun kan.
Laarin oṣu to lọ ni Aarẹ Buhari paṣẹ ṣiṣi ibode mẹrin ki gbogbo ibode to di ṣiṣi pada bayii.
Ado Ekiti Blind Couple: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú
Ninu oṣu kẹjọ ọdun 2019 ni ijọba gbe awọn ibode Naijiria ti pa lati dẹkun ṣisẹ fayawọ ireṣi ati ohun elo ijagun wọ Naijiria.
Ọga agba ajọ aṣọbode, Muhammad Babandede lo fidi ọrọ naa mulẹ fun BBC pe Buhari ti paṣẹ ṣiṣi ibode oriilẹ pada.
Itaniji: Oluwo sọ ìtàn bí Orunmila ṣe jìyà nílùú Iwo àti ayọ̀ tó gbẹ̀yìn rẹ̀ torí sùúrù
Association of Stingy Men: Akeugbagold ní àpẹẹrẹ wèrè díẹ̀díẹ̀ ni k'ẹ́ni tó lówó láhun sí obìnrin
Oríṣun àwòrán, Twitter/ITS DON JAZZY AGAIN
Ẹ lọ ṣọra yin o, gbogbo ẹyin ti ẹ n pe ara yin ni ẹgbẹ awọn ọkunrin alahun, Association of Stingy Men.
Onimọ nipa ẹsin musulumi Alhaji Taofeek Akeugbagold lo sọrọ yii lori ẹrọ amohun-maworan.
Laipẹ yii ni ọrọ ''Association of Stingy Men'' gba ori ayelujara pa ti awọn eeyan si n gba ọrọ naa bi ẹni n gba igba ọti.
''O pa mi lẹrin nigba ti mo gbọ ọrọ awọn ọdọ ti wọn n pe ara wọn ni ẹgbẹ awọn ọkunrin to lahun,'' Akeugbagold lo sọ bẹẹ.
Aafa Akeugbagold ni apẹẹrẹ were diẹdiẹ ni ọrọ ẹgbẹ ''Association of Stingy Men'' ti awọn kan n sọ.
Ado Ekiti Blind Couple: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú
O ni ohun ti Ọlọrun sọ ni pe ki ọkunrin nawo fun obinrin, ki o si fi owo tọju rẹ.
Akewugbagold sọ pe ''ẹni to jẹ ọkọ ni ko ri owo na fun un yii, bẹẹ ale si ni o nawo fun obinrin yii, awọn kan wa ni awọn ni ọmọ ẹgbẹ ''Association of Stingy Men.''
Aafa naa ni Ọba oke to da obinrin sọ pe ''owo ti ẹ n na fawọn obinrin, ọkan lara awọn ọna ti ọkunrin maa n fi ṣe idari obinrin ni gẹgẹ bi ọkọ rẹ, ayafi ti ẹ ko ba lowo lọwọ loku.''
Aafa Akeugbagold ni ṣiṣe ahun si awọn obinrin ko yatọ si ki eeyan ṣi ilẹkun fun ole.
Akeugbagold ni abamọ ni yoo gbẹyin iru awọn ọkunrin to ba lowo lọwọ ṣugbọn ti wọn n ṣe ahun si obinrin.
Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó
School resumption: Ilé aṣojú-ṣòfin l'Abuja dábàá kí ìjọba sún ìwọlé àwọn akẹ́kọ̀ọ́ síwájú pẹ̀lú oṣù mẹ́ta torí covid-19
Ile aṣoju-ṣofin l'Abuja ti sọ pe ki ijọba apapọ sun ọjọ iwọle awọn akẹkọọ pada kuro lọjọ Aje ọjọ kejilelogun, oṣu kinni, ọdun 2021 yii.
Ile da aba pe ki ijọba sun iwọle awọn akẹkọọ siwaju pẹlu oṣu mẹta siwaju sii nitori bi arun coronavirus ti n pọ si lojoojumọ.
Alaga ile lori eto ẹkọ, Ọjọgbọn Julius Ihonvbere lo ṣi aṣọ loju eegun ọrọ yii ninu atẹjade kan to fi sita lorukọ igbimọ rẹ.
Ọjọgbọn Ihonvbere sọ pe ijọba apapọ ko fi ọrọ iwọle awọn akẹkọọ to ile aṣofin leti ko to kede ọjọ ti wọn maa wọle pada.
Alaga igbimọ ile aṣoju-ṣofin sọ pe eeyan bi ẹẹdẹgbẹta lo n ni arun coronavirus lojumọ nigba tawọn ileewe wa ni titi pa.
Ṣugbọn Ọjọgbọn Ihonvbere ṣalaye pe o kere tan eeyan to le lẹgbẹrun kan lo n larun naa lojoojumọ bayii ti ijọba paṣẹ pe kawọn akẹkọọ pada sile iwe lọjọ kejidinlogun oṣu kinni yii.
''Kilode ti ijọba ṣe fẹ ṣe ileewe pada nigba ti ko tii si eto to mọyan lori lati rii pe ko ni ṣi ewu fawọn akẹkọọ lori ọrọ coronavirus ti wọn ba wọle pada bayii?'' Ọjọgbọn Ihonvbere lo beere bẹẹ.
Ihonvbere sọ pe ibeere to yẹ ki a bi ara wa ni pe ''ṣe a ti gbaradi fun wiwọle pada awọn akẹkọọ?''
Ẹwẹ, ijọba ipinlẹ Edo ti sun iwọle awọn akẹkọọ nipinlẹ naa si oṣu to n bọ nitori bi coronavirus ṣe n gbilẹ sii lojoojumọ ni ipinlẹ naa.
Ado Ekiti Blind Couple: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú
Covid-19: Oluwo ní àṣẹ Ọlọ́run ni pé coronavirus ò lè wọ ìlú Iwo, àmọ́ òun ń wọ ìbòmú tórí olórí t'óun jẹ́
Oríṣun àwòrán, Instagram/oluwoofiwoland
Oba AbdulRasheed Akanbi, Oluwo ti ilẹ Iwo ti sọ idi to fi n wọ ibomu lẹyin to ti sọ tẹlẹ pe arun coronavirus ko le wọ Iwo laelae.
Oluwo sọ fun BBC Yoruba pe oun si duro lori ọrọ ti oun sọ pe covid-19 ko le wọ ilẹ Iwo, ṣugbọn oun n lo ibomu nitori ipo olori ti oun wa ni.
''Aṣẹ Ọlọrun Ọba ni pe gbogbo arun bi coronavirus ko le wọ ilẹ Iwo, ohun lo jẹ ki sọ tẹlẹ pe covid-19 ko gbọdọ wọ ilu Iwo.
Mo si tun sọ pe ki arun coronavirus to ba fẹ wọ Iwo pe ki o wa mu mi nitori ọfiisi Ọlọrun ni mo wa, ti coronavirus ba ti mu mi, o ti mu Ọlọrun naa niyẹn.
Nitori emi kọ ni ọba, Ọlọrun ni ọba. Ọdọ rẹ si ni gbogbo arun ati gbogbo nkan wa.
Lati igba ti mo si ti paṣẹ yii naa, ko si ẹni to ko arun coronavirus niluu Iwo, amọ Ọlọrun ni ilu Iwo nikan ni Oun fun mi.
Ado Ekiti Blind Couple: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú
Awọn ọba ilu miiran naa to ba lẹmi iru rẹ le paṣẹ bẹẹ niluu ti wọn naa,'' Oluwo lo sọ bẹẹ.
Oluwo ni oun si gbagbọ pe ẹnikẹni to ba gbe ailera wọ ilu Iwo, aṣẹ naa loun maa pa ti Ọlọrun yoo si fun wọn lalaafia.
Kabiyesi ni oun n wọ ibomu lati jẹ awokọṣe rere fawọn ọmọ Naijiria nitori ifẹ ti oun ni si wọn.
Oluwo ni ko ni boju mu ki oun maa lo ibomu lawujọ gẹgẹ bi olori.
Oba AbdulRasheed Akanbi gbadura pe ki Eleduwa ''ba wa le covid-19 wọlẹ lọ ni Naijiria.''
''Mo fẹ ki ọrọ aje Naijiria pada gbeeru si, kawọn eeyan si wa lalaafia kaakiri orilẹede Naijiria,'' Oluwo lo sọ bẹẹ.
Akomolede ati Aṣa: Mọ̀ síi nípa ìró afárànma àti agbárànmọ́ fáwẹ́ẹ̀lì Yorùbá
Jubril Martins-Kuye: Mínísítà lẹ́ẹ̀méjí, Jubril Martins-Kuye ti jáde láyé
Oríṣun àwòrán, Premium times
Eekan oloṣelu kan ni ipinlẹ Ogun to tun ti fi igbakan ri jẹ minisita fun karakata ati idaleeṣẹsilẹ lorilẹede Naijiria, Jubril Martin Kuye ti jade laye.
Nnkan bii agogo mẹwaa owurọ ọjọ Aiku lo jade laye.
Ni ọjọ kẹrindinlogun, oṣu kẹjọ ọdun 1942 ni wọn bi Oloogbe Jubril Martins Kuye ki Aarẹ ana, Goodluck Jonathan to yan an gẹgẹ bii minisita lọjọ kẹfa, oṣu kẹrin, ọdun 2010.
Bakan naa lo tun di ipo minisita abẹle fun eto iṣuna labẹ iṣejọba aarẹ Oluṣẹgun Ọbasanjọ titi di ọdun 2003.
Ko tii si iroyin kankan to tii jade nipa ohun to ṣokunfa iku rẹ, ṣugbọn iroyin sọ pe ilu rẹ, Agọ Iwoye lo mi eemi ikẹyin sii
Ado Ekiti Blind Couple: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú
Igboho Ultimatum to Fulani: Ẹni bá mọ Sunday Igboho kó bá wa bẹ̀ẹ́ o, a ò mọ ibi tí a lè kó lọ, Seriki Fulani pariwo síta
Igboho Ultimatum to Fulani: Ẹni bá mọ Sunday Igboho kó bá wa bẹ̀ẹ́ o,
Kini yoo ṣẹlẹ?
Ibeere ti ọpọ n beere lasiko yii ni yi.
Nitori pe o ku bii wakati diẹ si asiko ti gbendeke ọjọ meje ti eekan ọmọ Yoruba ni, Oloye Sunday Adeyẹmọ ti ọpọ mọ si Sunday Igboho fun awọn Fulani lagbegbe Ibarapa yoo pe.
Sẹriki Fulani ipinlẹ Ọyọ, Alhaji Abdulkadir ti ke gbajare sita pe ẹnikẹni to ba mọ Oloye Sunday Igboho ko ba awọn rawọ ẹbẹ sii ni nitori pe ko si ibi ti awọn lee ko lọ bayii mọ lẹyin aadọta ọdun.
Alhaji Abdulkadir to ba BBC News Yoruba sọrọ ṣalaye pe gbogbo ibi to yẹ lawọn n sa kaakiri lọ bayii lati wa ọna abayọ si ọrọ naa.
Sunday Igboho fulani ultimatum: Àwọn ará Kebbi àti Zamfara ló n jínígbé ní Oke Ogun- Serik
O ni lootọ ijọba n fi awọn lọkan balẹ pe Sunday Igboho ko ni lee ṣe ohun to wi sibẹ gbogbo awọn eeyan to ba mọọ lawọn n bẹ bayii ki wọn ba awọn pẹtu sii ninu ki wọn si le joko sọrọ naa ni itubi inubi.
Alhaji Abdulkadir to ni bi awọn aletilapa darandaran to sọ ara wọn di darandaran naa ṣe n ṣọṣẹ fun awọn ọmọ onilẹ lagbegbe naa ni wọn n ṣọṣẹ fun awọn gan an pẹlu to jẹ Fulani to tẹdo si agbegbe naa.
LASTMA Yesufa: Àwọn dókítà gbìyànjú lórí ojú mi ṣùgbọ́n...
Seriki ni awọn ti kan sawọn agbofinro, awọn si ti kan sawọn ọbalaye lagbegbe Ibarapa lati lee wojutu si ọrọ naa to si jẹ pe wọn n fi awọn lọkan balẹ ni pe yoo lojutu laipẹ.
O ni awọn ko palẹ ẹru kankan mọ nibẹ nitori awọn ko tilẹ mọ ibi ti awọn lee dorikọ nitori pe agbegbe naa ni gbogbo awọn mọ ni ile lẹyin ti ọpọ wọn ti gbe nibẹ fun ọpọlọpọ ọdun.
Ẹgbẹ ọmọ Yoruba, Afenifere ti sọrọ lori aṣẹ ọlọjọ meje ti Oloye Sunday Adeyẹmọ fun awọn Fulani ni Oke Ogun nipinlẹ Oyo.
Ogbeni Yinka Odumakin ti o jẹ Akọwe ipolongo ẹgbẹ naa, salaye ninu ifọrọwanilẹnuwo pẹlu BBC Yoruba pe nitootọ ni ohun to n ṣẹlẹ ni Oyo n banilọkan jẹ.
O ni sibẹ Sunday Igboho kii ṣe gomina, bẹẹ ko si ninu ijọba bikoṣe ogidi ara ilu.
Ati pe gẹgẹ bii ara ilu, iwe ofin Naijiria ko faaye gba a lati paṣẹ kuro nilu fun ẹlomiran.
Odumakin ni gomina Makinde nikan lo lagbara lati paṣẹ bẹẹ gẹgẹ bi gomina Akeredolu ṣe se ni ipinlẹ Ondo.
Akomolede ati Asa: Alagba Ajibola láti Fakunle ní olùkọ́ wa lórí ètò ìró lónìí
Odumakin ni ẹgbẹ Afenifẹre ti parọwa fun Sunday Igboho lati ni suuru ki iran Yoruba fi le pa amukuru pẹlẹ ọrọ awọn Fulani ajinigbe yii.
O ṣalaye pe Gomina Makinde lo ni agbara lori eto aabo ipinlẹ rẹ.
"O ni: "" Ati pe iran Yoruba maa n bọwọ fun ofin "" Federalism"" ti a n practice ni eyi to fun Makinde lagbara lati daabo bo ara ipinlẹ rẹ"""
Oríṣun àwòrán, Facebook/Sunday Igboho
Ǹkankan kò gbọdọ̀ ṣe Sunday Igboho - Àwọn ọ̀dọ́ Ibarapa sí Makinde, Buhari:
Àwọn ọ̀dọ́ Ibarapa kìlọ̀ fún Makinde, Buhari  lórí gbèndéke tí Igboho fún àwọn Fulani
Ẹgbẹ awọn ọdọ agbegbe Ibarapa labẹ asia Ibarapa youths consultative Forum ( IYCF ) ti kilọ fun aarẹ Muhammadu Buhari ati ijọba ipinlẹ Oyo lati sọra ṣe lori ọrọ Oloye Sunday Igboho.
Ninu atẹjade ti wọn fi lede ni wọn ti sọ fun Gomina Makinde wi pe nkankan ko gbọdọ ṣe Igboho, lẹyin to fun awọn Fulani to wa ni agbegbe Ibarapa ni ọjọ meje lati kuro ni agbegbe naa.
Igboho ni tori ijinigbe ojoojumọ to n waye ni agbegbe naa ni o mu ki oun gbe iru igbesẹ bẹẹ.
America Inauguration Joe: Wo àwọn eré orí ìtàgé tí Donald Trump ṣe kó tó fi ipò aàrẹ sílẹ̀
Ati wi pe awọn Fulani bẹrẹ si ni jo ile ni agbegbe Igangan ni ipinlẹ Oyo, lẹyin ti Igboho ṣe ibẹwo si Sheriki awọn Fulani ni agbegbe naa, ti ọpọlọpọ ọdọ to jẹ Yoruba si farapa.
Ẹgbẹ Ibarapa Youth ninu ọrọ wọn sọ wi pe awọn wa lẹyin ọrọ ti Igbohọ sọ.
Ati wi pe ko si ọmọ Yoruba ododo ti yoo ri bi awọn Fulani ṣe dana sun ile, ti yoo si gboju kuro nibẹ.
Oríṣun àwòrán, Instagram/sunday_igboho1
Wọn fẹsun kan awọn Fulani darandaran lagbegbe naa wi pe awọn ni wọn n pa eniyan, ti wọn ji awọn eniyan gbe, ti wọn si n hu iwa ọdaran lagbegbe naa.
Gbendeke ti Igboho fun awọn Fulani naa ti da ọpọlọpọ rogbodiyan silẹ ni ipinlẹ Oyo, ti awọn Fulani ni agbegbe Ibarapa si ni awọn ko ni ibi kankan n lọ.
Ni ọjọ Satide, ọjọ Kẹrindinlogun, oṣu kinni, ọdun 2021 ni iroyin jade lori ayelujara pe eekan ajafẹtọ Yoruba kan, Oloye Sunday Adeniyi ti ọpọ mọ si Sunday Igboho fun awọn Fulani ni gbendeke ọjọ meje lati fi ilẹ Yoruba silẹ.
Amọ,Gómìnà ipinlẹ Oyo, Seyi Makinde ní ìjọba kò sí lẹ́yìn Sunday Igboho lórí gbèǹdéke tó fún àwọn Fulani, to si paṣẹ fun àwọn ọlọ́pàá lati ṣe iwádìí rẹ̀.
US Vice President:Ẹ wo ìtàn obìnrin àkọ́kọ́ tí yóò jẹ igbákejì Ààrẹ ilẹ́ Amẹrika?
Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún un
Ni ọjọ Satide, ọjọ Kẹrindinlogun, oṣu kinni, ọdun 2021 ni iroyin jade lori ayelujara pe eekan ajafẹtọ Yoruba kan, Oloye Sunday Adeniyi ti ọpọ mọ si Sunday Igboho fun awọn Fulani ni gbendeke ọjọ meje lati fi ilẹ Yoruba silẹ.
Gẹgẹ bi fidio to gba ori ayelujara kan naa ṣe fihan, Sunday Igboho wọ inu awọn Gaa Fulani kan lọ lagbegbe Ibarapa nibi ti o ti fun awọn Fulani to wa nibẹ ni gbendeke ọjọ meje eleyi ti yoo pari ni ọjọ kejilelogun, oṣu kini, ọdun 2021 lati fi ilẹ naa silẹ.
Akomolede ati Aṣa: Mọ̀ síi nípa ìró afárànma àti agbárànmọ́ fáwẹ́ẹ̀lì Yorùbá
"O ni eyi ko ṣẹyin bi ""awọn eeyan ilẹ Yoruba ṣe ni awọn ko fẹ wọn"""
Ọrọ yii ti da oniruuru ọrọ silẹ laarin awọn olugbe ipinlẹ Ọyọ ati ilẹ Yoruba lapapọ.
Bi awọn kan ṣe n sọ pe awọn ti ohun to sọ lẹyin, ni awọn miran n sọ wi pe ta ni Igboho lati maa pa iru aṣẹ bẹẹ?
Oríṣun àwòrán, Screenshot
Ohun ti Sunday Igboho gbe igbesẹ ati ọrọ to sọ le lori ni gulegule ijinigbe to n waye lẹkun Ibarapa lẹnu lọwọlọwọ yii.
O ni laarin oṣu diẹ sẹyin awọn eekan ipinlẹ Ọyọ ati agbegbe Ibarapa ti awọn ajinigbe ti wọn fura si pe wọn jẹ Fulani darandaran ji gbe.
O ni yala ti wọn pa tabi fi gbowo gọbọi kii ṣe kekere eyi ti iwadii awọn si ti fihan pe awọn to n ṣe iṣẹ yii lọpọ igba maa n fara sinko si Gaa awọn Fulani kaakiri ti wọn kii sii foju wọn han sita.
Ado Ekiti Blind Couple: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú
Kinni Igboho tun sọ?
Nigba to ba ileeṣẹ iroyin BBC News Yoruba sọrọ, Oloye Sunday Igboho sọrọ ilẹ kun.
O ṣalaye iṣẹlẹ arakunrin kan to ti oke okun wale wa si ilu Igangan wa dako ṣugbọn tawọn Fulani kan da ẹran lọ jẹ oko rẹ.
O ni igba to lọ fi ẹjọ sun awọn aṣiwaju awọn Fulani naa ni wọn de e mọlẹ wọn si tẹẹ pa.
O ni eyi atawọn iṣẹlẹ miran lo faa ti oun fi woo pe ko yẹ ko ri bẹ ti oun fi ni asiko to lati kọrin O to gẹẹ.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Amọṣa awọn alaṣẹ awọn Fulani ni ipinlẹ Ọyọ ti ṣalaye pe ko sohun to jọọ rara ati pe awọn eeyan wọn ko ni ibi kankan ti wọn n ṣi lọ gẹgẹ bi Igboho ti ṣe pa a laṣẹ.
Wọn ni ijọba lo laṣẹ ati ẹtọ lati gbe irufẹ gbedeke bẹẹ kalẹ, bẹẹ nigba ti ijọba tabi awọn agbofinro ko sọ ohun to jọ bẹẹ, ko si idi fun awọn lati gbe igbesẹ lori rẹ.
"Ninu ọrọ to ba BBC News Yoruba sọ, Seriki Fulani ni ipinlẹ Ọyọ, Alhaji Yakubu Bello ṣalaye pe Oloye Igboho ""mu madaru"" wa saarin awọn olugbe agbegbe naa."
O ni Igboho n fa madaru laarin Yoruba atawọn Fulani nibẹ ni nitori ibagbepọ alaafia lo wa laarin awọn ẹya gbogbo lagbegbe naa.
Ninu ọrọ rẹ, Alhaji Bello ni lootọ Oloye Sunday Igboho mu ibẹru ba awọn eeyan nibẹ.
Sugbọn wọn ko ni faaye silẹ fun ohun to lee fa ipinya laarin awọn Fulani ati Yoruba nibẹ.
" Awọn ijọba ti gbe igbesẹ lori ohun to n ṣẹlẹ lagbegbe naa. Ni ipinlẹ Ọyọ, alaafia wa fun wa, Yoruba ati Fulani, ọmọ iya kan naa ni wa.
Itaniji: Oluwo sọ ìtàn bí Orunmila ṣe jìyà nílùú Iwo àti ayọ̀ tó gbẹ̀yìn rẹ̀ torí sùúrù
Inu oko kan naa lawọn Fulani ati agbẹ n gbe. Bi ibajẹ kankan ba si waye laarin wọn, wọn yoo yanju rẹ laarin ara wọn laisi wahala kankan."
Seriki Fulani ni ipinlẹ Ọyọ ni awọn Fulani ko lee kuro lagbegbe naa gẹgẹ bi Igboho ṣe sọ, awọn fa ọrọ naa le ijọba lọwọ nitori pe ijọba lo ni ilu, awọn lo si lẹtọ lati gbe igbesẹ lori ọrọ naa.
LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé
Alukoro ileeṣẹ ọlọpaa ni ipinlẹ Ọyọ, CSP Olugbenga Fadeyi ṣalaye fun BBC News Yoruba pe ọrọ naa ko ṣe ajeji si awọn ọlọpaa.
O ni yatọ si pe wọn ti da awọn ọlọpaa ati ikọ agboguntiwa ibajẹ si agbagbe naa, awọn alaṣẹ ileeṣẹ ọlọpaa ti n forikori lori ohun ti wọn yoo ṣe si ọrọ naa.
O fi kun un pe pipana rogbodiyan tabi wahala to lee fẹ ṣuyọ lawọn ọlọpaa wa fun, wọn si ti n gbe igbesẹ gbogbo lati rii pe ko si ohunkohun tabi ẹnikẹni to da omi alaafia ilu ru.
Ekiti budget: N1.4bn ni ìjọba ìpínlẹ̀ Ekiti yòó ná lórí Amotekun lọ́dún 2021
Oríṣun àwòrán, Facebook/Kayode Fayemi
Biliọnu kan ati irinwo miliọnu (N1.4bn) ni ipinlẹ Ekiti yoo na lori ẹṣọ eleto abo Amotekun lọdun 2021.
Kọmiṣọnna eto iṣuna fun ipinlẹ naa, Ọgbẹni Femi Ajayi lo fọrọ yii lede nigba to n ṣe atupalẹ eto iṣuna N109.666bn fun ipinlẹ Ekiti lọdun 2021.
Kọmiṣọnna ṣalaye pe owo ti ijọba ya sọtọ lati na lori Amotekun ṣe pataki nitori bi eto abo ti mẹhẹ kaakiri orilẹede Naijiria bayii.
O ni iṣẹlẹ ijinigbe, aawọ laarin awọn agbẹ atawọn darandaran n pọ si lojoojumọ ni Naijiria.
Kọmiṣọnna eto iṣuna ṣalaye pe ojuṣe ijọba ni lati daabo bo awọn eeyan ipinlẹ Ekiti ati dukia wọn, ''ohun lo jẹ ki Gomina Kayode Fayemi da ẹṣọ eleto abo Amotekun silẹ.
Ọgbẹni Ajayi sọ pe N550m ni ijọba ya sọtọ fun rira ẹrọ kamẹra ''drone'' ti wọn fi maa ṣe iwadii awọn ọdaran lati mọ ibi ti wọn wa.
Itaniji: Oluwo sọ ìtàn bí Orunmila ṣe jìyà nílùú Iwo àti ayọ̀ tó gbẹ̀yìn rẹ̀ torí sùúrù
Kọmiṣọnna eto iṣuna tun ṣalaye pe N2.4bn ni ijọba ya sọtọ lati bẹrẹ fasiti ẹkọ imọ ẹrọ Bamidele Olumilua nipinlẹ naa.
Bakan naa ni Ọgbẹni Ajayi sọ pe biliọnu mẹjọ ni ipinlẹ Ekiti yoo na lori eto ẹkọ, eto ilera ati awọn eto ṣiṣe iranwọ fawọn eeyan ipinlẹ ọhun.
BBC findings on lekki shooting: Ẹ wa wo àwọn tó ṣì ń wá ẹbí wọn nínú ìṣẹ̀lẹ̀ End SARS 2020
Kọmiṣọnna ni eto iṣuna ọdun 2021 da lori imupada sipo ọrọ aje ipinlẹ Ekiti lẹyin ti arun covid-19 ti ṣakoba fun ọrọ fun ọrọ aje Naijiria.
Ọgbẹni Ajayi ni ijọba ṣetan lati rii pe gbogbo iṣẹ to ya owo sọtọ fun lati ṣe lo di ṣiṣe lọdun 2021.
Coronavirus pandemic: Kàféèfì! ''Ice cream'' lùgbàdì kó àrùn covid-19
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Lati igba ti arun coronavirus ti bẹ silẹ kaakiri agbaye, ẹgbẹlẹgbẹ miliọnu eeyan lo ti lugbadi arun naa.
Eeyan nikan ni a mọ pe arun naa n mu, a ko tii gbọ pe o mu ẹranko.
Ṣugbọn ohun to jẹ kayeefi ni pe iroyin kan lati orilẹede China sọ pe ''ice cream'' fun lila ti lugbadi coronavirus.
Iroyin naa sọ pe ayẹwo ti wọn ṣe nigba mẹta fihan pe ''ice cream'' naa ni arun covid-19 lara.
Ajọ Tianjin to n gbogun ti ajakalẹ arun lorilẹede China ti bẹrẹ si ni wa awọn eeyan to ti fọwọ kan ''ice cream'' naa ti ileeṣẹ ounjẹ Tianjin Daqiaodao ṣe.
Gbogbo ounjẹ ti ileeṣẹ naa ṣe jade ni ijọba ti fi ote le bayii lati igba ti iroyin ''ice cream'' to lugbadi covid-19 ti jade.
Itaniji: Oluwo sọ ìtàn bí Orunmila ṣe jìyà nílùú Iwo àti ayọ̀ tó gbẹ̀yìn rẹ̀ torí sùúrù
Dokita Stephen Griffin to jẹ onimọ nipa awọn kokoro arun ni fasiti Leeds sọ fawọn akọroyin pe ko si ifoya lori bo ya covid-19 le maa gba ibẹ ran kaakiri.
Dokita Griffin ṣalaye pe o ṣeeṣe ko jẹ wi pe ara eeyan kan ni arun ọhun ti ran mọ ''ice cream.''
Ado Ekiti Blind Couple: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú
Onimọ nipa kokoro arun naa sọ pe bo ya nitori ibi to tutu ti wọn ko ''ice cream'' naa si lo jẹ ki kokoro coronavirus si wa laaye di igba ti wọn ṣe ayẹwo.
Amọ, o sọ pe ko si ewu lọri iṣẹlẹ naa, ati pe iti ọgẹdẹ lọrọ naa, ko too yọ ada si.
Akomolede ati Aṣa: Mọ̀ síi nípa ìró afárànma àti agbárànmọ́ fáwẹ́ẹ̀lì Yorùbá
Ni bayii, 1,662 awọn oṣiṣẹ ileeṣẹ to ṣe ''ice cream'' naa sita ti wa ni iyasọtọ.
Ijọba China ṣalaye pe 4,836 ''ice cream'' naa ni ileeṣẹ ọhun ṣe sita, amọ 2,089 ninu rẹ ni wọn ti so pa bayii.
School resumption: Ìjọba Eko ní òun kò s'éwu lórí covid-19 pẹ̀lú ìwọlé àwọn akẹ́kọ̀ọ́
Oríṣun àwòrán, Twitter/Lagos Ministry of Education
Lonii ọjọ kejilelogun oṣu kinni ọdun 2021 yii lawọn akẹkọọ pada sile iwe ni Naijiria fun saa igbẹkọ tuntun, bo tilẹ jẹ pe covid-19 n pọ sii lojoojumọ.
Iyalẹnu lo jẹ fun ọpọ eeyan pe awọn akẹkọọ wọlẹ pada sile iwe nipinlẹ Eko to jẹ wi pe nibẹ lawọn eeyan ti ko arun coronavirus julọ ni Naijiria.
Ati wi pe ijọba ipinlẹ Eko paṣẹ fawọn oṣiṣẹ ìjọba ti wọn ko to ipele Kẹrinla lati tubọ maa ṣiṣẹ lati ile wọn lọnà ati dẹkùn itankalẹ aarun Covid-19.
Ṣugbọn kọmiṣọnna eto iroyin ati ọgbọn inu ipinlẹ Eko, Ọgbẹni Gbenga Omotoso ṣalaye lẹkunrẹrẹ idi ti ipinlẹ Eko fi gba ki awọn akẹkọọ wọle pada lọjọ Aje.
Lakọkọ, Ọgbẹni Omotoso ni ijọba apapọ lo paṣẹ pe ki awọn akẹkọọ pada sile iwe fun saa eto igbẹkọ tuntun.
Bakan naa ni kọmiṣọnna sọ pe awọn akọṣẹ-mọṣẹ nipa eto ilera lo ni ko si ewu pe awọn akẹkọọ le wọle.
''Ti awọn akọṣẹ-mọṣẹ ba sọ pe ewu wa nibi ṣiṣi ileewe pada, ijọba ko ni ṣi ileewe pada,'' Omotoso lo sọ bẹẹ.
Itaniji: Oluwo sọ ìtàn bí Orunmila ṣe jìyà nílùú Iwo àti ayọ̀ tó gbẹ̀yìn rẹ̀ torí sùúrù
Omotoso ni oun ti n kaakiri awọn ileewe nipinlẹ Eko, oun si rii pe awọn ileewe n tẹle awọn ilana lati dẹna ajakalẹ arun coronavirus.
Kọmiṣọnna ni awọn olukọ atawọn akẹkọọ lo n lo ibomu, bẹẹ ni wọn n fi omi fọwọ,  koda wọn n takete si ara wọn gẹgẹ bi ajọ NCDC to n gbogun ti ajakalẹ arun ni Naijiria ṣe laa kalẹ.
O ni ọrọ awọn oṣiṣẹ ijọba ti wọn ko tii pada si ẹnu iṣẹ yatọ si ọrọ iwọle awọn akẹkọọ.
Ọgbẹni Omotoso ni ijọba ipinlẹ Eko tun n pin ibomu fawọn ti ko ni lawọn ileewe.
Ado Ekiti Blind Couple: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú
Kọmiṣọnna eto iroyin ati ọgbọn inu sọ pe ijọba ko fi ẹmi awọn akẹkọọ wewu nipa wiwọle pada wọn.
O ni imọran awọn akọṣẹ-mọṣẹ ni ijọba ipinlẹ Eko n tẹle lori ọrọ ati wọle pada awọn akẹkọọ ati ajakalẹ arun coronavirus.
Police vs Gang clash in Kaduna: Ọlọ́pàá mẹ́rin kú, ọ̀kan dàwátì níbí ìkọlù tó wáyé ní Birnin-Gwari ní ìpínlẹ̀ Kaduna
Oríṣun àwòrán, @Nigeria Police
Awọn agbofinro ti fidiẹ mulẹ fun ileeṣẹ iroyin BBC pe o kere tan ọlọpaa mẹrin lo padanu ẹmi wọn nibi ikọlu ọjọ Ẹti.
Ikọlu naa waye larin awọn agbofinro ati awọn agbebọn ni agbegbe Birnin Gwari ni ipinlẹ Kaduna ni ariwa Naijiria.
Koda, alukoro fun ileeṣẹ ọlọpaa, Frank Mba ni awọn ṣi n wa ọlọpaa kan to dawati nibi iṣẹlẹ naa.
Mba ṣalaye pe awọn agbebọn naa dena de awọn agbofinro lọna ni nibi ti o le ni ọgọrun un wọn fi kọlu awọn agbofinro lasiko ti wọn n padabọ lati ibi ti wọn ti lọ ṣiṣẹ ni ipinlẹ Niger
Bakan naa ni awọn ọlọpaa ni irọ ni pe awọn agbebọn ti ji olopaa mejidinloguin gbe ni Kaduna.
BBC findings on lekki shooting: Ẹ wa wo àwọn tó ṣì ń wá ẹbí wọn nínú ìṣẹ̀lẹ̀ End SARS 2020
Ileeṣẹ ọlọpaa ni awọn agbofinro mẹrindinlogun lo wa nibi ikọlu naa ati oku ọlọpaa mẹrin ni awọn ri gbe kuro nibẹ pẹlu ibọn wọn.
Ọlọpaa mọkanla ni wọn ye e nigba ti wọn ṣi n wa ọlọpaa kan to dawati nibẹ ni eyi ti awọn ko tii le sọ nipato ohun to ṣẹlẹ sii.
Itaniji: Oluwo sọ ìtàn bí Orunmila ṣe jìyà nílùú Iwo àti ayọ̀ tó gbẹ̀yìn rẹ̀ torí sùúrù
Ṣaaju ni awọn ọlọpaa ti fidi iṣẹlẹ mii mulẹ ni Kaduna to mu ẹmi eeyan marun un, o kere tan lọ.
Ikọlu yii lo mu ẹmi iya arugbo ẹni ọgọrin ọdun kan lọ ati olori ileto kan ati awọn miran.
Ado Ekiti Blind Couple: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú
Kọmiṣọnna fun aabo abẹlẹ nipinlẹ Kaduna, Samuel Aruwan ṣalaye pe awọn agbebọn naa dojule agbegbe Giwa, Igabi ati Chikun.
Sugbọn wọn ko tii le sọ nipato awọn ti wọn wa nidi ikọlu opin ọsẹ yii.
Ni ibẹrẹ ọsẹ to kọja ni wọn ji eniyan mejidinlogun gbe laiyọ awọn ọmọ ọwọ ati abiyamọ silẹ ni abule kani Birnin-Gwari ni Kaduna.
Akomolede ati Aṣa: Mọ̀ síi nípa ìró afárànma àti agbárànmọ́ fáwẹ́ẹ̀lì Yorùbá
Igboho Ultimatum to Fulani: Sunday Igboho wà lọ́nà Ibarapa, Seriki Fulani ní àwọn kó níbiì lọ, àrọ̀wà ló kù
Oríṣun àwòrán, Snapshot
Ọkan awọn eeyan ni ipinlẹ Ọyọ, paapaa awọn eeyan agbegbe Ibarapa ṣe n fo lori gbendeke ti Oloye Sunday Igboho fun awọn Fulani to n gbe lagbegbe naa ṣe lonii ọjọ Ẹti.
Sẹriki Fulani, Alhaji Abdulkadir ṣalaye fun BBC News Yoruba pe inu Gaa awọn lawọn ṣi wa ni ireti pe aawọ ati aigbọraẹniye naa yoo pari ni tubi inubi.
Bi a ṣe n sọrọ yii, ikọ Oloye Sunday Igboho ti gbera kuro ni ilu Ibadan ti wọn si ti morile agbegbe Ibarapa lati lọ ree fi idi ileri ti wọn ṣe ni ọjọ Ẹti.
to kọja pe awọn yoo wa le awọn Fulani kuro lagbegbe naa mulẹ.
Gẹgẹ bi ọrọ ti a gbọ lati ẹnu ikọ Oloye Sunday Igboho, gbogbo wọn ati olori wọn ni wọn ti mu irinajo pọn bayii.
Ninu ifọrọwerọ rẹ, Alhaji Abdulkadir, Seriki Fulani ṣalaye pe awọn ọlọpaa ti wa ni Gaa wọn nibẹ lati fi idi ofin ati alaafia mulẹ.
Sunday Igboho fulani ultimatum: Àwọn ará Kebbi àti Zamfara ló n jínígbé ní Oke Ogun- Serik
Kini o ti ṣẹlẹ sẹyin nile Igboho laarọ yii?
Ikọ iroyin BBC News Yoruba wa ni ile Oloye Igboho lowurọ oni lati mojuto gbogbo igbera rẹ.
Sugbọn lasiko ti eekan ọmọ Yoruba naa yoo fi gbera kuro nile rẹ, ko si akọroyin to lee sọ nitori gbogbo awọn oniroyin ni wọn ni ko ṣe gaya fun un naa nitori ati jade rẹ ko pẹ mọ.
Lawal Ayankemi Oluwatoyin: Mo kọ̀ láti máa tọrọ owó nítorí ojú mi tó fọ́, iṣẹ́ ló wù mí
Amọṣa ni asiko ti a fi n ko iroyin yii jọ, ohun ti a kojọ pọ lati ọdọ awọn ikọ rẹ ti wọn jumọ rinrinajo naa ni pe awọn ti wa lọna.
Ati pe, laipẹ ni wọn yoo si gunlẹ si Ibarapa ti wọn yoo si morile Gaa awọn Fulani naa.
Oríṣun àwòrán, oyoinsight
Lọwọlọwọ ni awọn eeyan ipinlẹ Oyo n gbe ni inu fu, aya fu latari gbendeke ọjọ meje ti Sunday Igboho fun awọn Fulani.
Gbendeke yii ko ṣẹyin bi wọn ṣe n ji awọn eeyan gbe ti wọn tun n pa awọn ọmọ ilu ni ẹkun Oke Ogun ni ipinlẹ Oyo.
Eyi si ti mu oriṣiriṣi jade pẹlu Igboho, Makinde ati awọn eekan ilẹ Yoruba.
Iroyin to n tẹ wa lọwọ bayii ni pe ẹgbẹ awọn Onimaalu, Miyetti Allah ti n pe fun alaafia ki ọla to jẹ gbendeke Oloye Sunday Adeyemo to pe.
Alaga ẹgbẹ naa nipinlẹ Oyo, Alhaji Saliu Ibrahim Dede lo fi atẹjade sita pe alaafia ati iṣọkan lo ku lasiko yii ti Miyetti Allah n wa ni ẹkun Oyo.
LASTMA Yesufa: Àwọn dókítà gbìyànjú lórí ojú mi ṣùgbọ́n...
Dende ni o ṣe pataki ki awọn Yoruba gba awọn Fulani tọwọtẹsẹ ki awọn ẹya mejeeji jọ mojuto aabo ati alaafia awọn olugbe ẹkun naa lasiko yii.
O ni lootọ ni awọn iṣẹlẹ ijinigbe ati ipaniyan ẹkun Igangan ati Ibarapa kọnilominu ati pe iran kọọkna lo ni awọn ọmọ buruku laarin awọn eeyan rẹ ṣugbọn eyi ko sọ pe gbogbo iran naa ni ko dara.
Adari Miyetti Allah naa ni iṣoro eto aabo naa ko dun mọ awọn Fulani ninu ṣugbọn o parọwa fun Oloye Igboho lati yọwọ ninu gbendeke ọjọ meje naa.
O ni ki Igboho fi ayọ tẹwọgba awọn Fulani ni wọn n fẹ.
O ni awọn ṣetan lati jọwọ awọn ti ade iwa ibajẹ ba ṣi mọ lori silẹ fun ofin.
A ti pe ki ipade maa wa loorekoore laarin awọn agbẹ ati darandaran.
US Vice President:Ẹ wo ìtàn obìnrin àkọ́kọ́ tí yóò jẹ igbákejì Ààrẹ ilẹ́ Amẹrika?
Ẹ wo ohun tí Seriki Fulani sọ fún gómìnà Makinde nípa Sunday Igboho
Seriki Fulani fi ẹjọ́ Sunday Igboho sun gómìnà Makinde nípa gbèǹdéke tó fún wọn
Lẹyin ti iroyin ti n ja ranyinranyin nilẹ pe Oloye Sunday Igboho ti fun awọn Fulani lagbegbe Ibarapa ni ipinlẹ Ọyọ ni gbendeke ọjọ meje lati fi agbegbe naa silẹ, awọn Fulani lagbegbe naa ti ke gbajare tọ Gomina Makinde lọ.
Seriki Fulani nipinlẹ Ọyọ, Alhaji Saliu Abubakar ṣalaye fun amugbalẹgbẹ gomina ipinlẹ Ọyọ lori ọrọ aabo, Sunday Odukọya ohun to ṣẹlẹ.
O ni pe ọpọlọpọ awọn fulani to n gbe ni Gaa naa ni wọn farapa lasiko ti Oloye Sunday Igboho atawọn ọmọlẹyin rẹ wa si agbegbe naa.
Oríṣun àwòrán, oyoinsight
O ni ahere meje lawọn to ba oloye Sunday Igboho kọwọrin wa dana sun.
O ni bi iṣẹlẹ naa ṣe waye ṣi jẹ iyalẹnu fun awọn ti o si n ke si ijọba lati gba awọn silẹ.
Aṣoju ijọba ipinlẹ Ọyọ naa, Ọgbẹni Odukọya rọ awọn Fulani naa lati fọwọ wọnu o si ṣeleri fun wọn pe ijọba yoo ṣe iwadii to ba tọ lori rẹ.
BBC findings on lekki shooting: Ẹ wa wo àwọn tó ṣì ń wá ẹbí wọn nínú ìṣẹ̀lẹ̀ End SARS 2020
Sunday Igboho vs Fulani : IG pàṣẹ pé kí Kọmísọ́nnà Oyo mú Igboho wà sí Abuja láti fojú bá ilé ẹjọ́
Oríṣun àwòrán, NIGERIA POLICE
Ọga patapata ileeṣẹ ọlọpaa Naijiria ti paṣẹ pe ki Kọmiṣọnna ọlọpaa ipinlẹ Oyo, arabinrin Ngozi Onadeko mu Sunday Igboho to l'oun n ja fun ẹtọ ati isọkan ilẹ Yoruba.
Agbẹnusọ aarẹ Buhari, Garba Sheu lo fidi ọrọ yi mulẹ lasiko to n sọrọ lori eto BBC Hausa kan ti wọn pe ni: ''Ra'ii Riga ''.
O ni oun ṣẹṣẹ ba ọga ọlọpaa, Mohammed Adamu sọrọ tan ni to si ni oun ti paṣẹ ki kọmiṣọnna Oyo mu Igboho wa si Abuja.
Lẹnu ọjọ mẹta yi ni orukọ Sunday Igboho ti gbode kan paapa lori ayelujara lẹyin to ṣabẹwo si ilu Igangan to si fi gbendeke ọlọjọ meje lelẹ fawọn Fulani ilu naa lati kuro nibẹ.
Bẹẹ lo kesi gbogbo awọn Yoruba ni Oyo ati ipinlẹ mii lati gberasọ tako awọn Fulani ọdaran ajinigbe to n da omi alaafia ilẹ Yoruba ru.
Sunday Igboho fulani ultimatum: Àwọn ará Kebbi àti Zamfara ló n jínígbé ní Oke Ogun- Serik
Malam Garba Shehu ṣalaye pe igbesẹ awọn to n da omi laafi ilu ru jẹ ipenija fun ijọba nitori bi awọn ti wọn lawọn n ja fun ẹtọmọniyan yi ṣe n kọdi ijọba.
O ni aṣẹ to wa nilẹ lati ọdọ ọga agba ọlọpaa ni pe ki wọn gbe Sunday Igboho lọ si Abuja ki wọn si lọ ṣẹjọ rẹ nibẹ.
Saaju ni ọṣẹ yi ni Gomina ipinlẹ Ondo, Rotimi Akeredolu naa ti fun awọn darandaran Fulani lọjọ meje ki wọn kuro ninu igbo ipinlẹ naa.
Ọrọ yi da fakinfa silẹ ti aarẹ Buhari si kilọ fun un lati ma ṣe danwo.
Oríṣun àwòrán, BBC/Seyimakinde
Ninu atẹjade kan ti kọmiṣọna feto iroyin ati ọrọ aṣa ni ipinlẹ Ọyọ, Ọmọwe Wasiu Ọlatunbọsun fi sita ṣalaye pe wọn kan fẹ fi ohun akasilẹ naa ko awọn eeyan laya jẹ ni.
Ohun akasilẹ naa, ninu eyi ti arabinrin kan ti orukọ rẹ n jẹ Rẹmi lati ilu London to n ke sawọn eeyan ilu Ibadan lati joko si ile wọn ti n lọ kaakiri.
Amọṣa kọmiṣọnna feto ẹkọ nipinlẹ Ọyọ ni ara ọna lati ta ẹrẹ si aṣọ ala ijọba to wa lode ni ipinlẹ Ọyọ ni, ati pe ọgbọn ati ba igbesẹ ati ilakaka ijọba lori ọjọ abo loju jẹ ni.
O wa rọ awọn eeyan ipinlẹ Ọyọ, paapaa julọ awọn olugbe Ibadan lati maa ba iṣẹ oojọ wọn lọ laisi wahala tabi ibẹrubojo rara.
Ijọba ipinlẹ Oyọ ti rọ awọn eeyan lati keti ọgbọin si iroyin ati ohun akasilẹ to n lọ kaakiri.
Ohun naa kilọ pe ki awọn olugbe ilu Ibadan o joko sile ni ọjọ Ẹti ọjọ kejilelogun nitori gbendeke ọjọ meje ti Sunday Igboho fun awọn Fulani lagbegbe Ibarapa, eleyi to pari lọjọ naa.
LASTMA Yesufa: Àwọn dókítà gbìyànjú lórí ojú mi ṣùgbọ́n...
Ọ̀rọ̀ n ba ọ̀rọ̀ bọ́ lori Fulani ati Igboho.
Pẹlu bi ariwo ṣe n lọ lọtun losi lori gbendeke ọjọ meje ti Oloye Sunday Adeyẹmọ, fun awọn Fulani lagbegbe Ibarapa oke ogun lati kuro lori ilẹ nibẹ:
Akomolede ati Asa: Alagba Ajibola láti Fakunle ní olùkọ́ wa lórí ètò ìró lónìí
Gomina ipinlẹ Ọyọ, Onimọẹrọ Ṣeyi Makinde ni oun ko mọ nipa igbesẹ tabi ọrọ ti eekan ọmọ Yoruba naa sọ.
Oloye sunday Adeyemọ yii ti ọpọ mọ si Sunday Igboho lo ni iṣẹ ibi ti awọn Fulani n ṣe ni Oke ogun ti pọ ju.
Igboho ni o to gẹ, ki onikaluku gba ilu ẹ lọ.
Gomina Makinde ni oun si ti paṣẹ fun awọn agbofinro lati bẹrẹ si nii wadi oloye Sunday Igboho lori ọrọ to sọ naa.
Gomina Makinde ṣalaye pe ko si ẹni to fi iṣẹ ran Oloye Sunday Igboho lati lọ jẹ fun awọn fulani naa.
O ni pe gẹgẹ bi iṣejọba to ko akoyawọ, gbogbo ẹya ati ede ni aye gba labẹ ofin ni ipinlẹ Ọyọ ati pe ẹfọ ko lee le ẹfọ lawo.
Nigba ti BBC kan si ijọba ipinlẹ Oyo lori ọrọ yii, agbẹnusọ Seyi Makinde sọrọ ilẹ kun.
Ninu ọrọ to ba BBC News Yoruba sọ, agbẹnusọ fun gomina Seyi Makinde, Ọgbẹni Taiwo Adisa ṣalaye ipo gomina Makinde lori ọrọ naa.
America Inauguration Joe: Wo àwọn eré orí ìtàgé tí Donald Trump ṣe kó tó fi ipò aàrẹ sílẹ̀
O ni pe Gomina Makinde ti ran ikọ kan lọ si Gaa awọn Fulani naa lati lọ fi wọn lọkan balẹ pe ko si mimi kan to lee mi wọn lẹsẹ ni ipinlẹ Ọyọ.
Makinde ni ipinlẹ Oyo wa fun tẹrutọmọ to fẹ lati gbe igbe aye alaafia.
Bakan naa lo kilọ fun awọn Fulani ati Yoruba pe irẹpọ lo ṣe pataki lasiko yii ni Naijiria.
BBC findings on lekki shooting: Ẹ wa wo àwọn tó ṣì ń wá ẹbí wọn nínú ìṣẹ̀lẹ̀ End SARS 2020
O ni ijọba ipinlẹ Ọyọ ko wa lẹyin iwa ẹlẹyamẹya
 Yatọ si pe ijọba ipinlẹ Ọyọ ko lọwọ sii, wọn ti paṣẹ ki awọn agbofinro waa kan lati beere ohun to ri lọbẹ to fi waaru ọwọ. Lẹyin ti wọn ba ti fọrọ waa lẹnuwo yoo lee sọ ohun to ri to fi dan iru iwa bẹẹ wo.
O ni Oloye Sunday Igboho fẹ da wahala silẹ lagbegbe Oke Ogun ati ẹkun Ariwa ipinlẹ Ọyọ ni, ti ijọba ko si gbe lẹyin rẹ tabi mọ si awọn igbesẹ rẹ naa.
"Lere Paimo: Eda Onile-ola ṣàlàyé bí fíìmù ""Ogbori Elemosho"" ṣe sọ ọ́ di ìlúmọ̀ọ́ká"
Oríṣun àwòrán, Twitter/Nollywood Circle
Awọn agba bọ, wọn ni ori lo mọ iṣẹ aṣela. Ohun lo difa fun agbaọjẹ oṣere tiata Yoruba, Oloye Lere Paimo ti iṣẹ to yan laayo sọ ọ di ilumọọka.
Nigba to b'awọn akọroyin sọrọ laipẹ yii, gbajugbaja oṣere naa ti inagijẹ rẹ n jẹ Eda Onile-ola ṣalaye bi fiimu itan Ogbori Elemosho ṣe ṣọ ọ di olokiki ninu ere tiata.
Ninu esi rẹ si ọrọ t'awọn oṣere kan ṣọ pe awọn kii ṣaaba fẹ ṣe fiimu to da lori itan ilẹ Yoruba nitori kii lowo lori bi awọn fiimu agbelewo to wọpọ lasiko yii, Oloye Paimo ni irọ nla ni.
Eda Onile-ola ṣọ pe fiimu Ogbori Elemosho ti oun ṣe ta, ati pe fiimu yii lo mu ki ijọba apapọ foun loye MFR pẹlu awọn ilumọọka ọlọrọ bíi Aliko Dangote ati Mike Adenuga niluu Abuja.
Koda ajọ awọn akọṣẹ-mọṣẹ olokowo, Chartered Institute of Commerce ṣẹṣẹ fi oye Ọmọwe da mi lọla ni, nibayii, orukọ mi ti di Oloye Ọmọwe Lere Paimo, Eda Onile-ola ṣalaye.
O ni lati inu fiimu itan ilẹ Yoruba loun ti ri awọn oye yii gba, nibẹ naa loun tun ti ra ọkọ oriṣiiriṣii
Sunday Igboho fulani ultimatum: Àwọn ará Kebbi àti Zamfara ló n jínígbé ní Oke Ogun- Serik
"Eda Onile-ola ni nibi iṣẹ tiata yii naa ni oun ti ran awọn ọmọ lọ sile iwe. ""Ẹ sọ fun mi kinni eeyan tun n wa laye?"""
Agbaọjẹ oṣere yii bu ẹnu atẹ lu bi awọn oṣere asiko yii  kii ti fẹ gbe ere jade lori itan ilẹ Yoruba.
O ni ọpọ awọn oṣere yii kii le ronu jinlẹ lati kọ iru itan bẹẹ ni.
US Vice President:Ẹ wo ìtàn obìnrin àkọ́kọ́ tí yóò jẹ igbákejì Ààrẹ ilẹ́ Amẹrika?
Eda Onile-ola ni oun atawon akẹgbẹ oun ṣe iwadii lọdọ awọn agbaagba ilẹ Yoruba ki awọn to gbe ere bi Ogbori Elemosho ati Saworo Ide jade.
Ṣugbọn iwa ainirẹlẹ ko le jẹ k'awọn ọmọ iṣẹyii to n ṣere tiata lọ b'awọn agbaagba fun iwadii lori ere, Oloye Paimo lo sọ bẹẹ.
Eda Onile-ola fikun ọrọ rẹ pe oun at'awọn akẹgbẹ oun ko yaju s'awọn ọga awọn, bẹẹ ni awọn si bọwọ fawọn to ju awọn lọ lọjọ ori.
Mo fẹ da ileewe ikẹkọọ ere tiata silẹ nibi ti mo ti maa kọ̀ awọn ọdọ nipa ere ṣiṣe, itan kikọ ati ijo jijo ninu ere, Eda Onile-ola lo ṣalaye bẹẹ.
O ni iru awọn ere toun fẹ maa kọ awọn ọdọ gbọdọ kọ awọn eeyan lẹkọọ.
America Inauguration Joe: Wo àwọn eré orí ìtàgé tí Donald Trump ṣe kó tó fi ipò aàrẹ sílẹ̀
Lere Paimo ni ohun to fi dabi ẹni pe awọn eeyan ko ṣaaba ri oun ninu ere mọ ni pe awọn olootu ere ni ko ṣaaba pe oun atawon akẹgbẹ oun sí ere mọ.
Eda Onile-ola ṣọ pe iwa ti ko boju mu ni ki wọn maa kun atike soju ọdọ lati ṣe bi arugbo ninu ere nigba t'awọn agba oṣere wa nilẹ.
Gbajugbaja osere yii tun koro oju si bi ọpọ oṣere ti n bo ara, ṣi ara wọn silẹ ti wọn si n lo awọn ede ti ko dun un gbọ leti ninu ere.
Akomolede ati Asa: Alagba Ajibola láti Fakunle ní olùkọ́ wa lórí ètò ìró lónìí
O ni iru awọn iwa bayii ko ba aṣa Yoruba mu, ati pe oun at'awọn akẹgbẹ oun ko dan iru rẹ wo nigba t'awọn bẹrẹ ere tiata.
Oloye Paimo ni awọn kilọ ni aimọye igba fawọn oṣere to n huwa bayii, amọ ọpọ ninu wọn lo kọ eti ikun.
Ninu awọn ti Eledumare fi ẹbun ijo jijo jinki, ọkan ni Eda Onile-ola jẹ.
BBC findings on lekki shooting: Ẹ wa wo àwọn tó ṣì ń wá ẹbí wọn nínú ìṣẹ̀lẹ̀ End SARS 2020
Oloye Paimo ni Eduwa fi ijo jijo rọ oun debi pe ko si akẹgbẹ oun kan to le jo bi oun ṣe n jo.
Ijo ti mo n jo lo mu ki awọn kan gbe mi lọ si orilẹ-ede Amẹrika lọdun 2017 fun ayẹyẹ ọjọ ibi mi, Eda Onile-ola lo wi bẹẹ.
O ni ọpọ lo yanu nigba ti oun f'ẹsẹ rajo ti wọn si sọ pe oun n jo bi gbajugbaja olorin Juju, King Sunny Ade.
Abeokuta Petrol tanker fire: Gomina Dapo Abiodun gbégilé ọkọ̀ agbépo lórí afárá ní ìpínlẹ̀ Ogun
Oríṣun àwòrán, Twitter/Dapo Abiodun
Gomina ipinlẹ Ogun, Dapo Abiodun ti paṣẹ ki ọkọ agbepo kankan ma gun ori afara mọ nipinlẹ naa.
Eyi ko ṣẹyin ọkọ agbepo to gbina ni ilu Abeokuta, ti ẹmi eniyan mẹfa si lọ si iṣẹlẹ naa pẹlu ọpọlọpọ ọkọ to jona raurau.
Gomina Abiodun lori Twitter rẹ ba awọn ẹbi ati ara to faragba ninu iṣẹlẹ naa kẹdun.
Oríṣun àwòrán, Twitter/Dapo Abiodun
Bakan naa ni o fikun wi pe awọn ti ranṣẹ si awọn to dokita to mọ nipa itọju awọn ti ina ba jo lati wa ranwọlọwọ pẹlu itọju awọn to farapa ninu ijamba ọkọ naa.
Oríṣun àwòrán, Twitter/Dapo Abiodun
Tirela naa lo ṣubu lẹyin to ti kọkọ kọlu ọkọ Jeep Lexus kan ko to gbina.
Oríṣun àwòrán, Twitter/Dapo Abiodun
Wọn ti ra rọ awọn awakọ pe ki wọn gba ọna miiran yatọ si opopona Kuto Road ati banki GTB.
Oríṣun àwòrán, Twitter/ Dapo Abiodun
Niṣe ni ero lọ biba nibi ti ọkọ agbepo naa ti n jona ti wọn si n ṣe idiwọ fawọn oṣiṣẹ panapana.
Ọkọ tirela agbepo bẹntiro kan ti gbana lopopona Kuto Road si Okemosan niluu Abeokuta nipinlẹ Ogun.
Oríṣun àwòrán, Twitter/Ogun State Government
Ọpọ eeyan nin a gbọ pe o farapa nibi iṣẹlẹ naa.
Awọn panapana si n ja fita fita lati pa ina ọhun.
Tirela naa ṣubu lẹyin to ti kọkọ kọlu ọkọ Jeep Lexus kan ko to gbina.
Okere tan ọkọ mẹrin ni a gbọ pe o jona raurau nibi iṣẹlẹ naa ti awọn to wa ninu rẹ si sa asala fun ẹmi wọ.
Akomolede ati Asa: Alagba Ajibola láti Fakunle ní olùkọ́ wa lórí ètò ìró lónìí
Wọn ti ra rọ awọn awakọ pe ki wọn gba ọna miiran yatọ si opopona Kuto Road ati banki GTB.
Niṣe ni ero lọ biba nibi ti tanka naa ti n jona ti wọn si n ṣe idiwọ fawọn oṣiṣẹ panapana.
Adigunjalè 24 tó ń jí epo rọ̀bì la mú ní Ondo- Ikọ̀ ọmọogun orí omi
Sunday Igboho fún Fulani Oyo ní gbèǹdéke, Seriki fulani yarí, ọlọ́pàá dá síi...
Wo ìpalára ní ọ̀nà mẹ́fà tó lè bá ènìyàn tí kò bá kí ń mu omi mímu tó ìwọn tó yẹ
Ọlọ́pàá mẹ́rin kú, ọ̀kan dàwátì níbí ìkọlù tó wáyé ní Birnin-Gwari ní ìpínlẹ̀ Kaduna- Ọga Ọlọ́pàá
Ẹbẹ lawọn oṣiṣẹ ileeṣẹ panapana n bẹ awọn ero wi pe ki wọn sun sẹyin ki awọn le ri ina ọhun pa.
BBC findings on lekki shooting: Ẹ wa wo àwọn tó ṣì ń wá ẹbí wọn nínú ìṣẹ̀lẹ̀ End SARS 2020
Ondo Fulani ultimatum: Ìjọba Ondo ní òun kò bẹ̀rù idúnkokò mọ́ni iléeṣẹ́ ààrẹ lórí gbèdéke tó fáwọn darandaran
Oríṣun àwòrán, Twitter/Arakunrin Akeredolu
Ẹru o bodo, ẹni ti yoo wọ odo lominu n kọ.
Ijọba ipinlẹ Ondo ti sọ pe oun ko bẹru idunkoko mọni lati ileeṣẹ aarẹ lori ọrọ awọn Fulani darandaran nipinlẹ naa.
Ṣaaju akoko yii lọjọ Iṣẹgun ọjọ kọkandinlogun, oṣu kinni, ọdun 2021 yii ni ijọba ipinlẹ Ondo sọ fawọn darandaran to wa ninu igbo ijọba pe ki wọn forukọ silẹ pẹlu ijọba, bii bẹẹ kọ, wọn gbọdọ fi igbo ọba silẹ.
Lẹyin naa ni agbẹnusọ fun Aarẹ Muhammadu Buhari, Garba Shehu sọ pe ijọba Ondo ko laṣẹ lati le ẹnikankan kuro lori ilẹ ti wọn ba n gbe nibi kibi ni Naijiria.
Ẹwẹ, ajọ Northern Elders' Forum (NEF) naa sọ fawọn Fulani darandaran to wa l'Ondo lati kọ eti ikun si gbedeke ti gomina fun wọn.
Ṣugbọn akọwe iroyin fun Gomina Rotimi Akeredolu, Segun Ajiboye sọ fun BBC Yoruba pe idunkoko lati ileeṣẹ aarẹ ko le dẹru ba ijọba ipinlẹ Ondo.
LASTMA Yesufa: Àwọn dókítà gbìyànjú lórí ojú mi ṣùgbọ́n...
Ọgbẹni Ajiboye sọ pe amofin agba to mọ tifun-tẹdọ ofin ni Gomina Akeredolu, nitori naa ko si ẹnikan to le ṣe ohun to lodi si ofin.
Akọwe iroyin fun Gomina Ondo ni ofin lo gbe orilẹede Naijiria ro.
O ni aabo eeyan ipinlẹ Ondo lo jẹ ijọba Gomina Akeredolu logun bayii, kii ṣe ipo tabi agbara.
O fikun ọrọ rẹ pe akeregbe lo maa juwe ibi a fokun si lọrọ naa maa jẹ lori gbedeke ọjọ meje ti ijọba fawọn darandaran nipinlẹ Ondo.
Ẹgbẹ́ Afenifere bu ẹnu ẹ̀tẹ́ lu Aárẹ Buhari lórí gbèńdéke tí Akeredolu fún àwọn darandaran Fulani
Ẹgbẹ ọmọ Yoruba, Afenifere  ti bu ẹnu ẹtẹ lu bi ileesẹ aarẹ Naijiria ṣe koro oju si gbedeke ọjọ meje ti ijọba ipinlẹ Ondo fun awọn darandaran Fulani, lati kuro ni gbogbo igbó nlanla nipinlẹ naa.
Ninu atẹjade kan ti Akọwe ipolongo ẹgbẹ naa, Yinka Odumakin fi sita l'Ọjọru lo ti sọ pe ohun ti ileesẹ aarẹ sọ yii ko jẹ iyalẹnu, o ni sugbọn àṣẹ Gomina Rotimi Akeredolu ni ẹgbẹ naa faramọ.
US Vice President:Ẹ wo ìtàn obìnrin àkọ́kọ́ tí yóò jẹ igbákejì Ààrẹ ilẹ́ Amẹrika?
Bo ṣe jẹ pe lasiko ti Gomina Akeredolu fun awọn darandaran naa ni gbedeke láti fi ipinlẹ Ondo silẹ, ni ileesẹ aarẹ to o gbọ ohun àwọn ará ipinlẹ Ondo fihan pe ọrọ to ba kan ẹ̀yà Fulani nìkan lo ma n ka ijọba to wa l'ode lára.
Oríṣun àwòrán, Google
O ṣalaye pe ipalara to pọ ni awọn ọdaran Fulani ti mu ba ipinlẹ Ondo, ati awọn ìlú ati abule mii nilẹ Yoruba lasiko yii.
"O ni "" ijọba to fẹ ẹ fi ojuṣe rẹ silẹ lai ṣe bi ti ijọba apapọ, ni yoo kawọ gbera lori ọrọ naa""."
Sunday Igboho fulani ultimatum: Àwọn ará Kebbi àti Zamfara ló n jínígbé ní Oke Ogun- Serik
O fikun ọrọ rẹ pe ẹgbẹ Afenifere faramọ erongba ijọba ipinlẹ Ondo lori bo ṣe sọ pe ìhà kò kan mi ni itumọ ọrọ ti agbenusọ Ààrẹ Buhari, Garba Shehu sọ.
O kesi gbogbo ọmọ Yoruba tootọ lati ti Gomina Akeredolu lẹyin lori ipinnu rẹ.
"Gomina gbọdọ lo gbogbo agbara to wa ninu ofin lati le gbogbo awọn ọdaran kuro ninu awọn igbó  to wa nipinlẹ Ondo.
 Gbogbo awọn gomina yooku naa si gbọdọ fi alaga wọn ṣe awokọse. """
America Inauguration Joe: Wo àwọn eré orí ìtàgé tí Donald Trump ṣe kó tó fi ipò aàrẹ sílẹ̀
Isọkusọ ni oludamọran fun Aarẹ Muhammadu Buhari, Garba Shehu n sọ lori ọrọ awọn darandaran ti ijọba ipinlẹ Ondo sọ pe ki wọn kuro ninu igbo ijọba ti wọn ko ba ti forukọ silẹ.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Shehu to jẹ oludamọran fun Aarẹ Muhammadu Buhari lori ọrọ royin sọ pe aṣẹ ti Gomina Rotimi Akeredolu pa lodi si iwe ofin orilẹede Naijiria.
Shehu ni o kuna fun Gomina Akeredolu lati le awọn darandan to ti n gbe ipinlẹ Ondo ni gbogbo aye wọn kuro ninu igbo ijọba nitori awọn aṣawọ kan to n ṣiṣẹ ibi.
Ṣugbọn agbẹjọro ati ajafẹtọ, Jiti Ogunye ni ko si ohun to kan Shehu ninu ọrọ naa.
Ati wi pe, ta lo sọ pe Shehu ni agbẹnusọ fun ẹgbẹ awọn darandaran, Miyetti Allah?
Agbẹjọro Ogunye ni ohun ti Akeredolu sọ wa ni ibamu pẹlu iwe ofin orilẹede Naijiria.
''Ojuṣe gomina ni lati pese eto abo to peye fawọn araalu, nitorinaa, ohun to dara ni Akeredolu n ṣe,'' Jiti Ogunye ṣalaye.
Ogunye ni ijọba apapọ ko laṣẹ lori ilẹ awọn ipinlẹ ni Naijiria, o ni ilẹ ti ijọba apapọ laṣẹ lori rẹ ko ju ilẹ ilu Abuja tii ṣe olu ilu Naijiria lọ.
Ogunye ni ko tiẹ boju mu ki awọn eeyan maa da ẹran ninu igbo ijọba, o ni oun ti igbo ijọba wa fun kọ niyẹn.
O ni ọpọ awọn eeyan lawọn daran daran ti da ẹmi wọn legbodo, koda o ni ti ṣẹlẹ si mọlẹbi oun kan ri.
Agbẹjọro Ogunye ni ọrọ orilẹede Naijiria nilo asọyepọ lori bawọn eeyan kan ṣe maa n gbe ọrọ ti ko kan wọn sori ju ọlọrọ gan an lọ.
Darandaran tí kò bá forúkọ sílẹ̀ gbọdọ̀ fi ìgbó ìjọba sílẹ̀ l'Ondo, Akeredolu fèsì sọ́rọ̀ Garba Shehu
Ijọba ipinlẹ Ondo ti da ijọba apapọ lohun lẹyin to sọ pe Gomina Rotimi Akeredolu ko laṣẹ lati le awọn darandaran kuro ninu igbo ijọba l'Ondo.
Ninu atẹjade ti oludamọran fun Aarẹ Muhammadu Buhari, Garba Shehu fi sita lọjọ Iṣẹgun, o ṣalaye pe igbesẹ naa tapa si ofin orilẹ-ede Naijiria.
Oríṣun àwòrán, Facebook/Arakunrin Akeredolu
Shehu ni o kuna fun Gomina Akeredolu lati le awọn darandan to ti n gbe ipinlẹ Ondo ni gbogbo aye wọn kuro ninu igbo ijọba nitori awọn aṣawọ kan to n ṣiṣẹ ibi.
Oludamọran si aarẹ ni o kuna fawọn ọmọ Naijiria lati maa sọ pe ẹya kan tabi awọn eeyan ipinlẹ kan lo wa nibi iṣẹlẹ ijinigbe ati awọn iwa ọdaran mii.
O ni ijọba aarẹ Buhari ṣetan lati rii pe awọn eeyan n tẹle ofin iwe orilẹede Naijiria, eleyi to jẹ ki ijọba sọ fawọn ẹgbẹ awọn musulumi kan to ni ki Biṣọọbu ilu Sokoto Matthew Hassan Kukah wọn ko laṣẹ lati sọ fun un pe ko fi ilu naa silẹ.
Ṣugbọn kọmisọnna eto iroyin ipinlẹ Ondo, Donald Ojogo ṣalaye pe ijọba ko ni ki awọn Fulani fi ipinlẹ naa silẹ.
''Ohun ti Gomina sọ ni pe awọn darandan to ko ba forukọ silẹ pẹlu ijọba ipinlẹ Ondo gbọdọ fi igbo ijọba silẹ,'' Ojogo ṣalaye.
Akomolede ati Asa: Alagba Ajibola láti Fakunle ní olùkọ́ wa lórí ètò ìró lónìí
O ni ọrọ ti Shehu sọ dabi ki eeyan maa dakun iṣoro to wa nilẹ tẹlẹ ni eleyi to si ṣakoba fun iṣokan orilẹede Naijiria.
Ojogo ni ijọba ipinlẹ Ondo si wa lori ẹsẹ rẹ pe awọn darandran ti ko ba forukọ silẹ gbọdọ kuro ninu igbo ijọba laarin ọjọ meje.
Fulani kìí ṣe ajínigbé! Akeredolu kò ní ká pòórá nínú igbó ìjọba l'Ondo, ohun tí Gómìnà sọ rèé...- Miyetti Allah
Alaga ẹgbẹ  awọn Fulani darandaran, Miyetti Allah Cattle Breeders Association (MACBAN) nipinlẹ Ondo, Alhaji Bello Garba ti sọrọ soke lori aṣẹ Gomina akeredolu.
Joe Biden Innauguration: Tani ìyàwó Joe Biden tí yóò jẹ obìnrin akọ̀kọ nílẹ̀ Amẹrika?
O ni pe irọ funfun balau ni iroyin to sọ pe Gomina ipinlẹ Ondo, Oluwarotimi Akeredolu ti awọn Fulani darandaran ni ọjọ meje lati kuro ni igbo ijọba to wa ni ipinlẹ naa.
Alhaji Bello to ba BBC Yoruba sọrọ ṣalaye pe Gomina Akeredolu nifẹ araalu ati alejo ju ko paṣẹ pe ki awọn Fulani kuro l'Ondo.
Oríṣun àwòrán, Twitter/Rotimi Akeredolu
Alaga Miyetti Allah l'Ondo sọ pe oun atawọn ọmọ ẹgbẹ awọn ṣe ipade pọ pẹlu Gomina Akeredolu lọjọ Aje lati bi ago mẹkanla to fi di ago kan ọsan.
Ki wa ni Miyetti allah sọ pe Gomina Akeredolu sọ fun awọn?
Alhaji Garba ni ''oun ti Gomina sọ ni pe oun ko fẹ ki awọn ọmọ kekeke maa da maalu mọ nipinlẹ Ondo.
Gomina tun sọ pe Fulani kankan ko gbọdọ da ẹran ninu igboro mọ.
Gomina Akeredolu tun sọ fun wa pe a ko gbọdọ da ẹran ninu igbo ijọba loru mọ.
Akeredolu tun sọ fun wa atawọn agbẹ pe ki a wa lojufo nitori awọn to n fi orukọ Fulani ṣe iṣẹ ibi nipinlẹ Ondo.
BBC findings on lekki shooting: Ẹ wa wo àwọn tó ṣì ń wá ẹbí wọn nínú ìṣẹ̀lẹ̀ End SARS 2020
Gomina tun fun awa Fulani darandaran to ba fẹ ma a ṣiṣẹ ni ipinlẹ Ondo lati fi orukọ wọn silẹ pẹlu awọn alaṣẹ,'' Alaga Miyetti Allah ṣalaye.
Alhaji Garba fikun ọrọ rẹ pe awọn eeyan ti maa n ṣaaba sọ pe Fulani lawọn ajinigbe nigba kuu gba ti iṣẹlẹ ijinigbe ba ti ṣẹlẹ.
''Fulani kii ṣe ajnigbe, ẹgbẹ ni awọn ajinigbe, wọn kii ṣe Yoruba, bẹẹ ni wọn kii ṣe Igbo,'' alaga Miyetti Allah lo sọ bẹẹ.
O ṣalaye pe eto aabo to mẹhẹ nipinlẹ Ondo ko ṣẹyin bi ipinlẹ naa ṣe ni ibode pẹlu ipinlẹ Edo, Ekiti. Ogun ati Kogi.
Covid-19 vaccine in Nigeria: Abẹ́rẹ́ àjẹsára yóò wọ Naijiria láìpẹ́
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ìjọba àpapọ̀ gbé ₦10b kalẹ̀ fún ìpèsè abẹ́rẹ́ àjẹsára Covid-19 alábẹ́lé
Covid-19 vaccine in Nigeria: Abẹ́rẹ́ àjẹsára yóò wọ Naijiria láìpẹ́
Minisita eto ìlera, Osagie Ehanire ti sọ pé ìjọba àpapọ̀ ti gbe biliọnu mẹwaa naira kalẹ fún ìpèsè abẹrẹ ajẹsara labẹle.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Osagie ni Naijiria ti n ba awọn tó n po oogun náà sọrọ lori ìpèsè rẹ.
Àwọn ohun tó yẹ kí o mọ nipa abala akọkọ abẹrẹ ajẹsara ti wọn yóò kó wọ Naijiria laipẹ ree.
Akomolede ati Asa: Alagba Ajibola láti Fakunle ní olùkọ́ wa lórí ètò ìró lónìí
Awọn ọmọ Naijiria ti yóò kọkọ gbà abẹrẹ ọhún ti ileeṣẹ Pfizer-BioNTech ṣe yóò gba abẹrẹ náà ni oṣù kẹta, ọdún 2021.
Ìparí oṣù Kejì ni ìjọba gbagbọ sọ pe ẹgbẹrun lọna ọgọrun abẹrẹ náà yóò balẹ sí Naijiria.
Awọn wo ni abẹrẹ náà yóò kan?
- Awọn oṣiṣẹ eto ìlera
- Awọn adari to ṣe pataki
- Awọn ti iṣẹ wọn ṣe pàtàkì bíi àwọn òṣìṣẹ́ ni papakọ ofurufu
BBC findings on lekki shooting: Ẹ wa wo àwọn tó ṣì ń wá ẹbí wọn nínú ìṣẹ̀lẹ̀ End SARS 2020
- Awọn ọlọpaa kan at'awọn aṣobode
- Awọn oṣiṣẹ ile iwosan ti wọn ti n ṣe ayẹwo Covid-19
- Awọn àgbàlagbà tó ti pé aadọta ọdún sókè
Ijoba apapọ ti sọ pé ọfẹ ni abala akọkọ abẹrẹ náà yóò jẹ fún àwọn ọmọ Naijiria.
Ẹwẹ, ìjọba àpapọ̀ tun ti n ba ileeṣẹ kan ni China jíròrò lórí bí wọn yóò ṣe kó mílíọ̀nù mejilelogoji abẹrẹ miran wọlé.
Ǹjẹ àgbo lè ṣe òògùn coronavirus?
Coronavirus: Ṣé ọtí leè dènà tàbí pa àrùn Coronavirus bi?
Akomolede ati Asa: Alagba Ajibola láti Fakunle ní olùkọ́ wa lórí ètò ìró lónìí
Alagba Ajibola ṣalaye ni ọrikiniwin ohun ti iparojẹ ati isunki jẹ.
Ile ẹkọ Fakunle Comprehensive Grammar School ni Osogbo ni ipinlẹ Osun.
Iparoje ati Isunki ni Alagba Ajibola lolukọ to dantọ to n kọ wa nipa eto iro ati giram yii.
Iro konsonanti, iro fawẹli ati iro ohun ni ọpakutẹlẹ iparojẹ ati isunki.
Bawo  ni iparojẹ ati isunki ṣe n waye ninu sisọ ati kikọ Yoruba?
Kinni Isunki?
Ona wo ni isunki n gba waye?
Wo bi iparojẹ ṣe n jẹyọ
Bawo ni awọn ọrọ wọnyii ṣe yipada?
Layelaye- laelae
Kekere- kekee
Olorun- Oloun
Oju ibọ- ojubọ
Iya Alaje- Iyalaje
Idi ọkọ- Idikọ?
Marwa NDLEA: Ta ni Mohammad Buba Marwa tó ṣẹ̀ṣẹ̀ di ọ̀gá àgbà àjọ NDLEA?
Oríṣun àwòrán, @Marwa
Wo àwọn ohun tó yẹ kí o mọ̀ nípa Mohammad Buba Marwa tó ṣẹ̀ṣẹ̀ di ọ̀gá àgbà àjọ NDLEA.
Mohammad Buba Marwa ni ọga agba tuntun ti ìjọba apapọ ṣẹṣẹ Yan fún ajo to n gbogun ti lilo egbogi oloro ni Naijiria, NDLEA.
Nigba to bẹrẹ iṣẹ ni ọọfisi rẹ tuntun, lọjọ Aje, o ni o jẹ ohun tó n kọ òun lominu pe pupọ nínú àwọn ọdọ Naijiria lo n lo egbogi oloro.
"Marwa sọ pé ""nnkan bíi 14.1 mílíọ̀nù ọmọ Naijiria lo n lo oriṣiriṣi oogun oloro."""
Gẹgẹ bó ṣe sọ, iye ọjọ orí awọn tó n lo oogun náà jẹ láti ọdún marundinlogun sí mẹrinlelọgọta, lẹyin naa ló ṣèlérí pé adinku yóò dé bá iye èèyàn náà labẹ idari ohun.
Oríṣun àwòrán, NDLEA
Ta ni Mohammad Buba Marwa?
Wọn bí Mohammad Buba Marwa ni ọjọ kẹsán án, oṣù Kẹsán án, ọdún 1953.
O wa lati ìjọba ìbílẹ̀ Michika, ni ipinlẹ Adamawa.
Buba Marwa kawe ni ile ẹkọ awọn ologun to wa ni Zaria, nipinlẹ Kaduna.
Lẹyin naa ló tẹkọ leti lọ sí Pittsburgh, nibi to ti kọ ẹkọ nipa ìmọ ibaṣepọ laarin awọn orilẹ-ede, ko to gboye síi nipa ìmọ eto ìlú ní Fasiti Harvard.
Awọn ibi to ti ṣiṣẹ sẹyin:
O ṣiṣe gẹgẹ bíi gomina ipinlẹ Bornu labẹ ijoba ologun lọdun 1992, ìyẹn nigba ti ọgagun Ibrahim Babangida jẹ Ààrẹ.
Òun tun ni gomina ipinlẹ Eko lọdun 1996 nigba ti ọgagun Sani Abacha jẹ Ààrẹ ologun.
Ni 2003, Marwa fi ipo rẹ silẹ gẹgẹ bíi alaga àti Olùdarí ileeṣẹ ọkọ ofurufu Albarka Airlines.
Loṣu Kejìlá ọdún 2006, o kede pe òun fẹ du ipo ààrẹ labẹ àsìá ẹgbẹ òṣèlú PDP, ṣugbọn o fìdí janlẹ, èyí tó mú kó ṣegbe lẹyin Umaru Musa Yar'Adua to padà di Ààrẹ.
Ni 2007, Marwa di aṣojú Naijiria sí orilẹ-ede South Africa.
Akomolede ati Asa: Alagba Ajibola láti Fakunle ní olùkọ́ wa lórí ètò ìró lónìí
Lọdun 2011 o gbe àpótí ipo gomina labẹ àsìá ẹgbẹ Congress for Progressive Change, CPC, nipinlẹ Adamawa, ṣugbọn o tun fidi janlẹ.
Lẹyin-o-rẹyin, Marwa darapọ mọ ẹgbẹ òṣèlú APC lọdun 2015 lẹyin tí wọn búrawọle fún Ààrẹ Muhamadu Buhari.
Makinde vs APC in Oyo: Makinde ní alátakò tó bá fẹ́ mọ iyì òun nígboro, APC fárígá pé ẹ̀tàn ló fi ń ṣe ìjọba rẹ̀
Oríṣun àwòrán, Twitter/seyi makinde
Ọrọ ti di gbas-gbos laarin gomina Seyi Makinde ati ẹgbẹ alatako to lamilaaka ju nipinlẹ Ọyọ, iyẹn ẹgbẹ oṣelu APC lori itẹwọgba rẹ laarin awọn eeyan ipinlẹ Ọyọ.
Gomina Makinde ṣalaye ninu ifọrọwerọ kan to ṣe pe gbọgbọrọ bayii ni oun fi ju awọn alatako oun to n fi ẹnu ẹgan sọrọ oun.
Makinde ni oun to da oun loju pe lọwọ yii wọn n gbadun oun nigboro, koda oun ṣetan lati kọwọrin pẹlu awọn eeeyan to pe ni ẹlẹgan ati alatako oun ni igboro lati mọ ẹni ti araalu n fẹ ninu oun ati wọn.
"Laarin ọdun kan abọ ti mo ti fi wa lẹnu iṣejọba, mo mọ pe awọn ẹlẹnu ẹgan yoo wa,
Sugbọn mo gbọdọ gbe oju mi le afojusun mi.
Nitori naa mo ti pinnu lọkan mi pe emi ati awọn eeyan bẹl o ni jọ ṣere ẹlẹdẹ ninu ẹrẹ. Inu mi dun pe awọn eeyan n gba ti wa nigboro."
Bi wọn ba lawọn o ni gbọ, mo fẹ ki wọn jẹ ka js kọwọrin ni igboro Oje ka wa wo awọlumatẹ ninu wa
BBC findings on lekki shooting: Ẹ wa wo àwọn tó ṣì ń wá ẹbí wọn nínú ìṣẹ̀lẹ̀ End SARS 2020
Amọṣa, ẹgbẹ oṣelu APC ti da gomina Makinde lohun pe ko ye tan ara rẹ.
Ninu atẹjade kan to fi sita, APC si ti ko ba han si gomina Makinde, awọn eeyan ipinlẹ naa ko ri tirẹ ro mọ nitori ohun ti wọn pe ni aikun oju iwọn rẹ.
Akomolede ati Asa: Alagba Ajibola láti Fakunle ní olùkọ́ wa lórí ètò ìró lónìí
"Wọn ni: ""Ohun to le buru jai ni ki gomina ti wọn ti dibo yan lọdun meji sẹyin ṣi maa jo ijo iṣẹgun kiri dipo ko joko ṣe iṣẹ ti ilu dibo yan an fun."""
"APC ni idahun awọn si ipenija ta lo gbayi ju ti gomina Makinde n gbe kalẹ ni lati bii leere pe ki lohun to ti gbe goke kuro nipo to baa lati ogun oṣu to ti wa nipo gomina."""
US Vice President: Ẹ wo ìtàn obìnrin àkọ́kọ́ tí yóò jẹ igbákejì Ààrẹ ilẹ́ Amẹrika!
Sẹnetọ Kamala Harris ti ni bio tilẹ jẹpe oun ni obinrin akọkọ ti yoo dipo igbakeji aarẹ mu lorilẹede Amẹrika, oun gbagbọ wi pe ọpọlọpọ eniyasn ni yoo jẹ lẹyin oun.
Kamala Harris ni awọn arinrinajo wa si orilẹ-ede Amerika lati orilẹede India ati Jamica.
Ki o to di igbakeji aarẹ, oun ni olootu eto idajọ ni ipinlẹ California.
Ẹkunrẹrẹ itan aye rẹ wa ninu fidio yii...
Divorce: Ìyàwó fi ẹ̀sùn kan ọkọ rẹ̀ pé ó máa n bá àwọn ọmọ ìjọ rẹ̀ ní ìbálòpọ̀
Oríṣun àwòrán, others
Ọrọ di irọ ni, ootọ ni, lasiko ti ajinhinrere obìnrin kan, Chinwe Ekwe, to jẹ ẹni ọdun mọkandinlaadọta fi ẹsun kan ọkọ rẹ to jẹ pasitọ pe o ma n ba awọn ọmọ ijọ rẹ sun.
Chinwe sọ ọrọ yii lasiko to n fesi si iwe ikọsilẹ ni ile ẹjọ ibilẹ to wa ni Igando nipinlẹ Eko.
Ọkọ rẹ, Pasitọ Paul Ekwe fi ẹsun kan Chinwe pe o n gbero lati pa òun.
Arabinrin Chinwe sọ pe nise ni ọkọ oun ma n ba awọn obinrin miran ni ibalopọ, eyi ti ko yọ iyawo ile silẹ.
"O ni ""gbogbo nkan ni mo fi n ṣe itọju rẹ nipa ti ẹmi ati ara. Sugbọn o tun yàn lati ma a ṣe isekuse pẹlu oriṣiriṣi obinrin."
 Koda, o gbe obirin kan to jẹ iyawo ile wa sinu ile wa gẹgẹ bi iyawo rẹ tuntun, to si le mi jade.
Sunday Igboho fulani ultimatum: Àwọn ará Kebbi àti Zamfara ló n jínígbé ní Oke Ogun- Serik
Arabinrin Chinwe sọ pe nise ni ọkọ oun n ba orúkọ oun jẹ kiri pe oun gbeero lati pa a.
O ni ko si èrè kankan fun oun ti oun ba pa ọkọ ti oun bi ọmọbìnrin meje fun.
" Nitori pe o fẹ ẹ fẹ iyawo mii lo ṣe n parọ mọ mi.
Emi ni mo n gbọ gbogbo bukaata rẹ, àmọ́ awọn ale rẹ lo n fi owo ra oúnjẹ fun."""
US Vice President:Ẹ wo ìtàn obìnrin àkọ́kọ́ tí yóò jẹ igbákejì Ààrẹ ilẹ́ Amẹrika?
Bakan naa ni Chinwe sọ pe ọkọ oun ti fi ọlọpaa mu oun ri, fun ẹsun to fi kan pe oun ba sọọsi rẹ jẹ, ti oun tun ji ní miliọnu márùn-ún Naira.
Sugbọn ṣa, Chinwe bẹ adájọ pe ko ma ṣe tu igbeyawo wọn ka, nitori pe oun ṣi nifẹ ọkọ oun botilẹ jẹ pe alagbere ni.
Kini awijare Pasitọ Ekwe?
Nigba to n ṣorọ nile ẹjọ, Pasitọ Paul Ekwe to jẹ ọkọ Chinwe sọ pe dandan ni ki ile ẹjọ tu igbeyawo ọdun mejidinlọgbọn naa ka nitori pe iyawo oun fẹ ẹ pa oun.
Ekwe sọ pe alagidi ati ẹni to fẹran ija ni Chinwe.
Ija ojoojumọ lo kun inu igbeyawo wa. Chinwe ti sọ ile mi di ibi inira ati aisi ifọkanbalẹ fun mi.
O tun fi ẹsun kan iyawo rẹ pe o sọ awọn ọmọ oun di ọ̀tá oun, debi i pe o fẹ ìkan lara wọn fun ọkọ lai jẹ ki oun mọ.
O bẹ ile ẹjọ lati tu igbeyawo wọn ka nitori pe ifẹ ti oun ni si iyawo oun nigba kan ko si mọ.
Ile ẹjọ si ti sun ẹjọ wọn si ọjọ kọkandinlogun, oṣu Kinni, ọdun 2021.
Akomolede ati Asa: Alagba Ajibola láti Fakunle ní olùkọ́ wa lórí ètò ìró lónìí
Ìjọba Eko ti ń lu ọkọ̀ 88 tà ní gbàǹjo ni Alausa ni Ikeja
Wo ọnà tí olè gbà jàǹfàní ọkọ́ lọ́wọ́ ìjọba Eko kí ilẹ̀ ò í tó ṣú
Awọn alaṣẹ ijọba ipinlẹ Eko fẹ lu ọkọ mejidinlaadọrin ta ni gbanjo lẹyin ti awọn to ni wọn ti yaafi wọn fun ijọbanitori oniruuru ofin irina ọkọ ti won tapa si.
Lọjọru ni too waye gege bi ohun ti alukoro ikọ amuṣẹya lori ọrọ ayika at'awọn ẹsun miran nipinlẹ Eko, Adebayọ Taofeeq sọ.
Ninu atẹjade to fi sita, o ni wọn ti gba iwe aṣẹ ile ẹjọ lori rẹ.
Lara awọn ẹsẹ ti awọn to ni ọkọ naa ṣẹ nigbigba ọna ti ko tọ ati bẹẹbẹ lọ.
Eto irinna ọkọ nipinlẹ Eko laa kalẹ pe ẹnikẹni ti wọn ba mu to n gba ọna ti ko lẹtọ si lati gba yoo jowo ọkọ rẹ fun ijọba nitabi ko tilẹ fi ẹwọn jura sii.
Sunday Igboho fulani ultimatum: Àwọn ará Kebbi àti Zamfara ló n jínígbé ní Oke Ogun- Serik
Igba keji niyi ti ijọba ipinlẹ Eko yoo maa lu awon ọkọ ti wọn ba gba lọwọ awọn to rufin irinna ta ni gbanjo. Losu kọkanla ọdun 2020 ni wọn kọkọ ta ọkọ mẹrinlelogoji.
Joe Biden Innauguration: Tani ìyàwó Joe Biden tí yóò jẹ obìnrin akọ̀kọ nílẹ̀ Amẹrika?
Nibayii, iyeoko ti wọn ti lu ta ni gbanjo jẹ mejilelaadọjọ ṣugbọn alukoro ikọ naa ko sọ boya ẹnikẹni ti lọ si ẹwọn.
BBC findings on lekki shooting: Ẹ wa wo àwọn tó ṣì ń wá ẹbí wọn nínú ìṣẹ̀lẹ̀ End SARS 2020
Bi ijọba ṣe fẹ lu awọn ọkọ naa ta ni gbanjo loni, ijọba ipinlẹ Eko ti salaye fawọn to ni ọkọ naa pe awọn pẹlu lee darapọ lati ra awọn ọkọ ọhun bi elomiran ko ba naa lowo to ju tiwọn lọ.
Kini awọn ara ilu n sọ nipa bi awọn mọtọ naa:
Awọn ọmọ Naijiria sọrọ ilẹ kun lori igbesẹ ijọba ipinlẹ Eko yii
Nigba ti BBC de ibi ti wọn ti n ta awọn ọkọ naa, ẹnu ya wa bi ero ṣe pọ to nibẹ ni Alausa, ni Ikeja nipinlẹ Eko.
Bi awọn kan ṣe n yin ijọba pe ohun ti wọn ṣe dara.
Ni awọn miran n ni ko dara to lasiko yii
Awọn miran si n kilọ fawọn olugbe ipinlẹ Eko lori titẹle ofin irinna bi o ti yẹ ki wọn ma baa bọ sọwọ.
Akomolede ati Asa: Alagba Ajibola láti Fakunle ní olùkọ́ wa lórí ètò ìró lónìí
America, Biden inauguration: Ohun kókó mẹ́fà tí yòó ṣẹlẹ̀ níbi ìbúra ìjọba tuntun Biden àti Harris
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ori ti yoo jọba ko ni ṣai jọba. Ọni ogunjọ oṣu kinni ọdun 2021 ni wọn yoo ṣe ibura fun Joe Biden gẹgẹ tuntun orilẹede Amerika.
Oun ati igbakeji rẹ, Kamala Harris to jẹ obinrin akọkọ ninu itan ilẹ Amerika ti wọle ibo gẹgẹ bi igbakeji aarẹ Amerika ni wọn yoo bura fun un.
Biden ni yoo jẹ aarẹ ẹlẹẹkẹrindinlaadọta ti ilẹ Amerika yoo dibo yan.
Biden la Donald Trump mọle ninu idibo aarẹ orilẹede Amerika to waye laipẹ yii.
Wọnyii lawọn nkan marun un to yẹ ki o mọ nipa ayẹyẹ ifilọlẹ ijọba Biden lorilẹede Amerika:
''Iṣọkan Amerika'' lakori ayẹyẹ ifilọlẹ ijọba Biden
Iṣọkan orilẹede Amerika ni akori ayẹyẹ ibura ati ifilọlẹ ijọba Biden, eleyi n sọ nipa irinajo mii lati mu ilẹ Amerika pada sipo fun ọjọ iwaju to adara.
Igbimọ to n ri si ayẹyẹ ifilọlẹ ijọba Biden ati Harris lo fidi ọrọ yii mulẹ.
US Vice President:Ẹ wo ìtàn obìnrin àkọ́kọ́ tí yóò jẹ igbákejì Ààrẹ ilẹ́ Amẹrika?
Niwaju igba asia Amerika ni ayẹyẹ ibura Biden yoo ti waye
Ko ni si ero nibi ayẹyẹ ifilọlẹ aarẹ tuntun orililẹede Amerika l'Ọjọru.
Igbimọ to n ri si ayẹyẹ ifilọlẹ ijọba aarẹ tuntun l'Amerika ti ri asia to din diẹ ni igba mọlẹ nibi ti ibura Biden ati Harris yoo ti waye.
Awọn asia yii ni yoo duro fawọn ẹgbẹẹdbẹrun un ọmọ ilẹ Amẹrika ti ko lanfaani lati wa nibi ayẹyẹ naa.
America Inauguration Joe: Wo àwọn eré orí ìtàgé tí Donald Trump ṣe kó tó fi ipò aàrẹ sílẹ̀
Lady Gaga ni yoo kọrin ogo ilẹ Amerika
Olorin takasufe Lady Gaga ni yoo kọ orin ogo ilẹ Amerika nibi ifilọlẹ ijọba aarẹ tuntun, Biden.
Gbajugbaja olorin Jennifer Lopez ati Garth Brooks naa yoo kọrin nibi ayẹyẹ ifilọlẹ ijọba Aarẹ Biden.
Akọrin ewi, Amanda Gorman, ọmọ ọdun mejilelogun yoo ka ewi sawọn eeyan leti nibi ayẹyẹ ọhun.
Biden yoo gbe ododo lọ si iboji ọmogun Amerika
Aarẹ Biden, igbakeji rẹ, Harris, aarẹ Amerika tẹlẹ, barack Obama, George W. Bush ati Bill Clinton pẹlu awọn iyawo wọn yoo gbe ododo lọ si iboji ọmogun Amerika gẹgẹ bi aṣa.
Ibi igboku si to wa ni Arlington ni wọn yoo gbe ododo ọhun lọ.
Nibẹ ni awọn ẹṣọ ologun yoo ti bẹrẹ si ni tẹle Biden.
BBC findings on lekki shooting: Ẹ wa wo àwọn tó ṣì ń wá ẹbí wọn nínú ìṣẹ̀lẹ̀ End SARS 2020
Mike Pence ni yoo wa nibi ayẹyẹ ibura kii ṣe Donald Trump
Igbakeji Aarẹ Trump ni yoo wa nibi ayẹyẹ idagbere dipo Aarẹ Trump.
Pence ni yoo gba iṣe Trump ṣe nibi ayẹyẹ ti yoo waye ọfiisi awọn ologun lolu ilu Amerika, Washington DC.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Orin Burna Boy wa lara orin ti wọn maa kọ nibẹ lonii:
Orin ọmọ Naijiria ni, Burna boy wa lara rin ti wọn ti to kalẹ lati lo nibi ayẹyẹ ifilọlẹ iṣejọba aarẹ tuntun ilẹ America.
Destiny ni orukọ akọle orin Burna boy naa pẹlu awọn olorin agba ọjẹ agbaye.
Orin mẹrindinlaadọta ni wọn ti ṣeto lati lo bnibẹ lonii.
Eyi ni wọn lo ṣafihan iyatọ ninu iṣọkan eyi ti ilẹ America gbagbọ ninu rẹ pe onikaluku le yatọ ninu ifẹ.
Awọn olorin b=miran ti wọn yoo lo ni Beyoncé's Find Your Way Back, Kendrick Lamar ati Mary J. Blige's Now Or Never, Bob Marley ati Di Wailers' Could You Be Loved ati Dua Lipa's Levitating.
Akomolede ati Asa: Alagba Ajibola láti Fakunle ní olùkọ́ wa lórí ètò ìró lónìí
Awọn orin naa ni kikun ni:
KOTA the Friend- Lupita's interlude
The Beatles - Come together
Jason Derulo - Pick up the pieces
Bruce Springsteen - We take care of our won
Daryl Hall and John Oates- You make my dreams come true
The Weeknd- What you need
Mac Miller- Blue World
Heatwave- The Groove line
A Tribe Called Quest -Award Tour
MF Doom - Coffin Nails
Free Nationals- Eternal light
Burna Boy- Destiny
Led Zeppelin- Fool in the rain
Bob Marley & The Wailers - Could You Be Loved
Curtis Mayfield -Move on Up
Jill Scott- Golden
The Impressions -We're a Winner
Dua Lipa - Levitating
The Doobie Brothers- What a Fool Believes
Bill Withers- Lovely Day
Chris Brown- Mirage
Shania Twain- Still the One
Oddisee- That's Love
Anitta, Major Lazer- Make It Hot
Whitney Houston, Kygo- Higher Love
Earth, Wind & Fire- That's the Way of the World
Vampire Weekend- Unbelievers
Beyonce- FIND YOUR WAY BACK
Jackie Wilson - (Your Love Keeps Lifting Me) Higher & Higher
SZA- Good Days
Vampire Weekend- Step
Fulani Herdsmen Killing: Ẹran dídà káàkiri di ẹ̀ṣẹ̀ ní Oyo àti Ogun
Oríṣun àwòrán, @Muhammed Gumi
Ijọba ipinlẹ Oyo kede pe o ti di ofin bayii pe awọn darandaran ko gbọdọ da ẹran mọ kaakiri ipinlẹ naa.
Eyi ko sẹyin bi eto aabo ti dẹnukọlẹ ni ilẹ Yoruba pẹlu awọn darandaran ti wọn fẹsun ijinigbe ati ipaniyan kan kaakiri awọn ipinlẹ marun un ni ilẹ Kaarọ Oojire
Akowe iroyin fun Gomina Seyi Makinde, Taiwo Adisa lo sisọ loju ọrọ yii pẹlu afikun pe awọn darandaran ni anfaani lati ra ilẹ ti wọn yoo ti ma a da ẹran wọn kaakiri ipinlẹ Oyo.
O ni awọn darandaran gbọdọ mọ wi pe, ọrọ aje tara wọn ni ọsin ati katakara ẹran jẹ, nitori naa, ko yẹ ki wọn fi da awọn ẹlomiran laamu.
"Ofin tuntun nipinlẹ Oyo fi idi rẹ mulẹ pe, idokowo ara ẹni ni isẹ darandaran, nitori naa, ijọba gba wọn laaye lati ra ilẹ lọwọ ijọba lati lo fun iṣẹ wọn''
Jude Chukwuka: Wò ó bí oríkì àwọn ìlú Yorùbá ṣe yọ̀ lẹ́nu ọmọ Igbo jú ọmọ onílùú lọ
''Amọ ofin naa ko fi aye gba dida ẹran kaakiri ni igboro kọja aala ti wọn fun wọn ni ori ilẹ tijọba yoo ya wọn lo fun ọdun mẹta, wọn yoo si pada wa ṣe iforukosilẹ miran fun ọdun mẹta mii''
''Ijọba ti kọ fun awọn ọmọde lati ma a da ẹran kaakiri ayafi ki agbalagba kan duro ti wọn.''
Bakan naa ni ijọba ipinlẹ Ogun ni awọn ti bẹrẹ igbesẹ lati sọ ọ di ofin pe ki awọn darandaran wa ma a fi orukọsilẹ, ki wọn to le ṣiṣẹ nipinlẹ naa.
Sunday Igboho fulani ultimatum: Àwọn ará Kebbi àti Zamfara ló n jínígbé ní Oke Ogun- Serik
Abẹnugan ile igbimọ Aṣofin nipinlẹ Ogun, Olakunle Oluomo naa ti ni o da oun loju pe awọn yoo buwọlu abadofin naa ni Oṣu Keji, ọdun 2021.
Olakunle Oluomo fikun wi pe gbogbo awọn ti ọrọ naa kan, gbọdọ fi ọwọ sowọpọ pẹlu ijọba, ki abadofin naa le kẹsẹ jari.
Oríṣun àwòrán, Facebook/Seyi Makinde
Saaju la ti mu iroyin wa fun yin pe Baajigan Ilu Ilaji Ile, nijọba ibilẹ Iwajowa nipinle Oyo, Oba Lawal Oyeleye Oyedepo ti woye pe ewu n bẹ loko Longẹ pẹlu bi ijọba ipinlẹ Oyo ti pàṣẹ pe ki igba ẹṣọ eleto abo Amọtẹkun lọ si agbegbe Ibarapa.
Ikọ Amotekun naa nijọba ni yoo lọ dẹkun aawọ to n ṣẹlẹ laarin awọn eeyan agbegbe naa atawon Fulani darandaran.
Nigba to n ba BBC Yoruba sọrọ, Baajigan ni ko sí apa ẹni to ka awọn ẹṣọ Amọtẹkun nitori wọn o sí labẹ ijọba ibilẹ.
Kabiyesi Oyedepo sọ pe, awọn ẹṣọ Amọtẹkun ko niru nidi lo jẹ ki ọpọ ninu wọn maa ṣiwa hu s'awọn to ju wọn lọ.
Baajigan ilu Ilaji Ile ṣalaye pe, ati ọga ati awọn ọmọṣẹ Amọtẹkun, iwa kan naa ni gbogbo wọn jọ n hu.
Oríṣun àwòrán, @Muhammed Gumi
Alaga ijoba ibilẹ kankan ko lagbara lori ẹṣọ Amọtẹkun, awọn mii n ṣiṣẹ daadaa lara wọn ṣugbọn awọn to n huwa aitọ lo pọju ninu wọn,"" Baajigan ṣalaye."
"Ọba Oyedepo ni ""laipẹ yii ni a ṣe ìpàdé pọ pẹlu DPO ọga ọlọpaa at'awọn ọtẹlẹmuyẹ ni ijọba ibilẹ Iwajowa, awọn Amọtẹkun ko wa nitori wọn ko si labẹ ijọba ibilẹ."""
Ọba Oyedepo tilu Ilaji Ile tun ṣalaye fun BBC Yoruba bi awọn Fulani darandaran ti da maalu ba ire oko awọn agbẹ jẹ lagbegbe Oke Ogun.
"Oko agbado eeka mẹwaa ti emi gan an ti mo jẹ ọba da, gbogbo rẹ lawọn Fulani fi maalu jẹ tan.
Ifọrọwerọ  pẹlu Gani Adams lori ọrọ Sunday Igboho
Awọn Fulani yii tun maa n da maalu wọ aarin ilu, n ṣe lawọn maalu yii yoo fọn kaakiri ninu ilu, ohun ti wọn n ṣe fun wa buru jai, Ọba Oyedepo lo sọ bẹẹ."
Baajigan ilu Ilaji Ile wa rawọ ẹbẹ sí ijọba apapọ lati wa nnkan ṣe sí ọrọ eto abo to mẹhẹ lagbegbe Oke Ogun nipinlẹ Oyo.
Ẹwẹ, ọgagun ẹṣọ Amọtẹkun nipinlẹ Oyo kọ lati sọrọ nigba ti BBC Yoruba pè e lori ago.
O ni oun ni lati gba aṣẹ lọwọ ijọba, ki oun to le sọ ohunkohun nipa ọrọ naa.
Oríṣun àwòrán, Facebook/@OfficialSeyiMakinde
Gomina ipinlẹ Oyo, Onimọ ẹrọ Seyi Makinde ti fesi lori aayan rẹ lati mu ki eto aabo fẹsẹ rinlẹ lagbegbe Oke Ogun.
Makinde, ninu atẹjade kan ti amugbalẹgbẹ rẹ feto iroyin, Taiwo Adisa fisita salaye pe, lodi si ero awọn ẹgbẹ oselu alatako nipinlẹ naa, oun ti se isẹ takuntakun lẹka eto aabo.
Gomina Makinde ni oun ti ko dara ni bi ẹgbẹ oselu alatako se n tọwọ oselu bọ aifararọ eto aabo lagbegbe Oke Ogun ati Ibarapa, to fi mọ awọn agbegbe miran nipinlẹ Oyo.
"Kedere ni aayan mi han fun araye nidi ipese eto aabo to peye si agbegbe Oke Ogun ati Ibarapa, koda, mo fi ikọ Operation Burst sọwọ sibẹ.
Oríṣun àwòrán, Facebook/Seyi makinde
Ogunlọgọ awọn ologun, ọlọpaa ati osisẹ aabo ara ẹni laabo ilu, Civil defence lo wa ninu ikọ alabo Operation Burst naa, ti wọn si kun awọn agbegbe mejeeji biba.
Bakan naa ni mo ti fi ikọ awọn ọlọpaa kogberegbe, Mopol sọwọ sibẹ, to si dabi ẹni pe ilu Agọ Are, ni Oke Ogun, gan ni ibujoko wọn wa bayii."
Makinde tun tẹ siwaju pe, ikọ Amotekun gan ti pọ bii esu lawọn agbegbe yii, ti isẹ akin ti wọn n se nibẹ si ti bẹrẹ si so eso rere.
Sunday Igboho: N kò fẹ́ oyè ọ̀gá àgbà páta fún ikọ̀ Amotekun nílẹ̀ Yorùbá
O ni iwa tẹnbẹlẹkun, ikorira ati inunibini ni ko jẹ ki awọn alatako ri ọpọ aseyọri ijọba oun lẹka eto aabo naa, ti wọn si mọọmọ diju lati ri.
O wa mẹnuba awọn ọrọ to n tẹnu awọn eekan ninu ẹgbẹ oselu APC jade, to fi mọ Minisita feto ere idaraya, Sunday Dare, gẹgẹ bii eyi to ba ni ninujẹ.
" O se ni laanu pe iru eeyan to wa ninu igbimọ alakoso ijọba apapọ ti ko se aseyọri kankan lẹka eto aabo ilẹ Naijiria naa n sọrọ.
Sunday Igboho: Fulani kò leè dúró, táa bá lo ohun ta jogún lọ́dọ̀ àwọ̀n bàbá wa
Amọ o se pataki ka jẹ ko mọ awọn aseyọri wa lẹka eto aabo, bo tilẹ jẹ pe a ko fẹ maa ba gba ọrọ bi ẹni gba igba ọti."
Makinde wa sọ fun awọn alatako rẹ pe, dipo ki wọn tọwọ oselu bọ ọrọ aabo yii, ko ba dara ki wọn kẹdun pẹlu awọn eeyan ipinlẹ Oyo nipa gbigbe ero gidi kalẹ lati mu agbega ba ipese eto aabo to pegede.
Oríṣun àwòrán, Facebook/Seyi Makinde
Saaju la ti mu iroyin wa fun yin pe Gomina ipinlẹ Oyo, Enginia Seyi Makinde ti salaye pe ijọba oun ko le gbinyanju lati fopin si isoro aifararọ eto aabo nipa sise atilẹyin fawọn eeyan to n tẹ ofin loju.
Gomina Makinde, sisọ loju ọrọ naa lasiko to n sọrọ nibi ipade to waye nilu Akure laarin awọn gomina ilẹ Yoruba ati ẹgbẹ darandaran Miyetti Allah.
Makinde fikun pe isoro eto aabo ko le tan nilẹ tijọba ba se atilẹyin fun ẹni to ba n ru ofin lọwọ ara rẹ, to si n koro oro lai bọwọ fun ofin sawọn eeyan to gba pe wọn huwa aidaa.
Makinde ni oun ko le se atilẹyin fun iru ẹni bẹẹ, to n huwa to le sọ orilẹede yii sinu ogun ẹlẹyamẹya , nitori o yẹ ka le mọ ohun ti yoo gbẹyin iru isẹlẹ bẹẹ.
Oríṣun àwòrán, Facebook/Seyi Makinde
O ni oun yoo yan lati se atilẹyin fun awọn agbofinro nipinlẹ oun ni, lati pese awọn eto iranwọ fun wọn, ti yoo jẹ ki wsn se isẹ wọn doju ami.
Gomina ipinlẹ Oyo tun sọ siwaju pe oun yoo se iranwọ fun ibagbepọ alaafia laarin awọn alamuleti oun nipa sise iwuri fun awsn eeyan ipinlẹ Oyo lati maa gbe pọ ni alaafia.
Oríṣun àwòrán, Facebook/Seyi Makinde
O ni awsn yoo dijọ koju ọta awọn papọ ni, ti wsn jẹ ọdaran to wa ninu ẹya gbogbo, toun yoo si tun maa pese anfaani fawọn araalu, lọna ati mu ikayasoke ku laarin wọn.
Gomina ipinlẹ Oyo, Seyi Makinde sọ pe oun ti gbọ nipa awọn kan to n pin iwe fawọn Fulani lati kuro lori ilẹ wọn ni ipinlẹ Oyo.Ìjọba Oyo korò ojú sí ìròyìn tó ń jáde pé káwọn èèyàn Ibadan ó gbélé nítorí Igboho
Ti ẹ o ba gbagbe, ajafẹtọ Sunday Adeyemo ti ọpọ mọ si Sunday Igboho ti kọkọ fawọn Fulani to wa ni agbegbe Ibarapa nipinlẹ Oyo lati kuro lori ilẹ ti wọn wa lori ẹsun pe awọn lo wa nidi iṣẹlẹ ijinigbe ati iṣekupani to n ti waye kaakiri ipinlẹ naa.
Makinde ní ẹnikẹ́ni tó bá dúnkokò mọ́ Fulani láti kúró lórí ilẹ̀ Oyo yóò fojú winá òfin
Amọ, Makinde ni iwe ofin orilẹede Naijiria laa kalẹ pe awọn ọmọ Naijiria ni ẹtọ lati maa gbe lalaafia nibi kibi to ba wu wọn kaakiri orilẹede yii.
Gomina ipinlẹ Oyo ni iwe ofin Naijiria yii ni oun bura pe oun ko ni tapa si gẹgẹ bi gomina.
''Ẹnikẹni to ba fi ipa mu ẹnikẹni lati kuro lori ilẹ ti wọn n gbe nipinlẹ Oyo yoo foju wina ofin,'' Makinde ṣalaye.
Sunday Igboho fulani ultimatum: Àwọn ará Kebbi àti Zamfara ló n jínígbé ní Oke Ogun- Serik
Gomina rọ ẹnikẹni to ba n gbero lati dunkoko mọ ẹnikẹni lati kuro nibi ti wọn n gbe wi pe ki wọn lọ ki ọwọ mọ bọ aṣọ.
Makinde ni ''Hausa tabi Fulani to n wa ibi ti yoo ti ko ẹran wọn jẹ oko kọ ni ọta wa nipinlẹ Oyo.'
Awọn ọta wa nipinlẹ Oyo kii ṣe awọn agbẹ to n dako lati jẹ ati lati ta fun araalu.
''Ijọba wa n gbiyanju lati wa egbo egbo dẹkun fawọn janduku agbebọn atawọn ọdaran to n ṣọṣẹ ni ipinlẹ Oyo.
Bakan naa ni Makinde ke pe awọn lọbalọba lati maa gba ẹnikan kan laaye lati lo wọn da alaafia to wa ni ipinlẹ Oyo ru.
Makinde tun kepe awọn alaga ijọba ibilẹ kaakiri ipinlẹ Oyo lati ṣiṣẹ pọ pẹlu awọn lọbalọba atawọn agbofinro lati rii pe alaafia jọba.
Ooni advise to Tinubu: Ooni Ile Ife pàrokò sí Tinubu pé kó lo ọgbọ́n dípò agbára f' ọ́dún 2023
Oríṣun àwòrán, @ooni
Ooni advise to Tinubu: Ooni Ile Ife pàrokò sí Tinubu pé kó lo ọgbọ́n dípò agbára f' ọ́dún 2023
Ọọni Ilẹ Ifẹ, Ọba Adeyẹye Ogunwusi Ọjaja keji ti paroko ranṣẹ si Asiwaju Bola Tinubu pe ohun to nilo julọ ni ọgbọn dipo agbara ninu ilepa rẹ lati di Aarẹ lọdun 2023.
Oríṣun àwòrán, others
Lasiko to fi n gbalejo awọn eekan ilẹ Yoruba to n ja fun idije Asiwaju Bola Tinubu fun ipo aarẹ lọdun 2023, SWAGA ni afin rẹ nile Ifẹ.
Eekan ọmọ Oduduwa ni Asiwaju Tinubu jẹ, inu gbogbo wa lo si n dun sii
Ọọni Ogunwusi tun pe fun iṣọkan ilẹ Yoruba paapaa laarin awọn oloṣelu to wa lati ẹkun iwọ oorun gusu Naijiria.
"O ni awọn oloṣelu "" yii kan naa gbọdọ kọkọ mojuto ọrọ ara wọn nitori awọn yii kan naa lo n ti ẹgbẹ oṣelu kan bẹ si omiran."""
Sunday Igboho fulani ultimatum: Àwọn ará Kebbi àti Zamfara ló n jínígbé ní Oke Ogun- Serik
"Ooni wa rọ awọn to n satilẹyin fun ilepa Tinubu lati di aarẹ naa pe, ""Ọgbọn ni ẹyin ati olori yin nilo, kii ṣe agbara."""
Ọọni Ile ifẹ ni aisi iṣọkan ko lee ran ẹya Yoruba lọwọ ni igbaradi fun ibo ọdun 2023.
Ooni rọ awọn oloṣelu lati maa mu anfani apapọ Yoruba ṣaaju dipo imọtaraẹni nikan.
O ni l'ọpọ igba wahala ati laasigbo ni iwa awọn oloṣelu maa n jasi fun araalu.
Joe Biden Innauguration: Tani ìyàwó Joe Biden tí yóò jẹ obìnrin akọ̀kọ nílẹ̀ Amẹrika?
Nollywood Yoruba epic movies: Wo àwọn sinimá mẹ́wàá tó gbé sinimá Yorùbá sáyé lọ́pọ́ ọdún sẹ́yìn
Oríṣun àwòrán, Screenshot
Ọpọlọpọ awọn ere itage ati sinima lawọn agba oṣere ni ilẹ Yoruba ti gbe jade eleyi to ti mi orilẹede Naijiria ati oke okun tititi.
Ṣaaju asiko yii, itan ati agbekalẹ ere Yoruba maa n mu ọpọlọpọ lọkan to bẹẹ gẹ ti awọn ti kii ṣe ọms Yoruba.
Akomolede ati Aṣa lori BBC:Wo ìrúfẹ́ ìgbeyàwó méje tó wà nílẹ̀ Yorùbá àti ojúṣe Alárinà
Bẹẹ, wọn ko si gbọ Yoruba pẹlu nigba naa maa n joko ti awọn eeyan to ba gbọ lati maa tu ohun ti wọn ba sọ nitori igbesẹ ṣisẹ n tẹle awọn ere sinima naa, a maa fa eeyan to ba n wo o lọkan, yala o gbọ ede Yoruba ti wọn n sọ ni tabi ko gbọ.
'Èmi ò kí ń lu ìyàwó mi'
Ni awọn nnkan bii ọgbọn ọdun si ogoji ọdun sẹyin, awọn ere manigbagbe kan to jẹ Yoruba pọ lọ biba, ṣugbọn mẹwaa ninu wọn la o maa gbe yẹwo ninu  akọsilẹ yii.
Oríṣun àwòrán, Screenshot
Ko si aniani bi eeyan ba sọ pe sinima ogbori ẹlẹmọṣọ wa lara awọn sinima to jade ni ilẹ Yoruba to si jẹ manigbagbe. Sinima ti ọwọja rẹ tan kalẹ kọja orilẹede Naijiria ni ti ọpọ ẹya ati ede si wo o.
Iṣe ati itan ere naa pẹlu awọn oṣere to ṣe ni wọn dun un wo.Itan iṣẹdalẹ ilu Ogbomọṣọ ni, Ogbori Ẹlẹṣọ, ni ipa ti Lalude ko ninu ere naa , ti Lere Paimọ si ko ipa Ṣọun Ogunlọla nibẹ.
Oríṣun àwòrán, Screenshot
"Ere kan ti ọpọ ọmọ Yoruba, paapaajulọ awọn onworan sinima Yoruba ni sinima ""Ti Oluwa nilẹ""."
Ninu sinima yii ni Alhaji Kareem Adepọju ti ọpọ mọ si Baba Wande ti di ilu mọọka. Sinima to kọ ẹkọ to si tun panilẹrin ni.
Ti Oluwa nilẹ da lori pataki ti Yoruba so mọ awọn dukia ilu, paapaa ilẹ Oriṣa.
Bolaji Faleke ni Olùkọ́ tó ń kọ́ wa ní àṣà oge ṣiṣe lórí BBC Yorùbá
Ohun to gbe soke ni bi Yoruba ṣe maa n bọwọ fawọn ohun iṣẹdalẹ rẹ pẹlupẹlu idukoko aṣa ọlaju.
Awọn eeyan kan fẹ ra ilẹ fi ṣe owo nla ni wọn ba kan si oloye ilu naa kan, iyẹn Oloye Ọtun (Baba Wande)
Wọn gbe owo gọbọi fun lẹyin o rẹyin gbogbo awọn to lọwọ si tita ilẹ naa loriṣa ilu naa pa.
"Láàrín ìṣẹ́jú díẹ̀, ẹ ka ìwé Akinwumi Ishola, ""Nítorí Owó"" lórí Akomolede Yoruba"
Adapọ awada laarin ẹkọ ti wọn fẹ fi sinima naa gbe jade tun jẹ ki ọpọlọpọ onworan o tun gbadun sinima naa pẹlu awọn eekan alawada bii Kayọde Ọlaiya (Adẹrupọkọ)
Tunde Kelani lo dari ere naa naa lọdun 1993, Kareem Adepoju lo kọ ọ. Awọn agba oṣere bii
Dele Odule, Lekan Oladapo, Yemi Shodimu, Yetunde Ogunsola, Oyin Adejobi, Gbolagbade Akinpelu, Jide Oyegunle, Akin Sofoluwe naa kopa ninu ere naa.
Oríṣun àwòrán, Screenshot
"Ọkan lara awọn iwe akagbadun ti Ọjọgbọn Akinwunmi Iṣhọla kọ ni ọdun 1974 ni ""O leku"". O le ku yii ni eekan onisinima, Alagba Tunde Kelani sọ di sinima ni ọdun 1997."
Itan ere ifẹ laarin ololufẹ Aṣakẹ, Lọla ati Ṣade ti wọn fẹ fẹ Ajani ni nnkan bii aadọta ọdun sẹyin ni iwe ati sinima yii. Gbogbo ohun elo ti wọn si lo nibẹ lo ṣe afihan eyi.
Ìtàn ọ̀rẹ́ tó fi ògùn gba ọkọ ọ̀rẹ́ rẹ̀ ni Akomolede BBC Yorùbá fẹ́ kọ́ wa lònìí
Sinima yii lo si ṣe agbende iro ti ko ju orokun lọ tawọn eeyan n lo ni aye igbaun pada sagbo faari eyi ti a wa n pe ni ole ku.
Ajani jẹ akẹkọ ipele aṣekagba ni fasiti to n wa afẹsọna nitori ipe iya rẹ to n fẹ ko ṣe igbeyawo ni kiakia.
Sinima yii rinlẹ lasiko to jade nigba naa.
Oríṣun àwòrán, Screenshot
Ọkan lara awọn ere to gbilẹ ni nnkan bii ọgbọn ọdun sẹyin ni ere yii.
Oloogbe Ajilẹyẹ lo ṣe. Nigba naa, awọn ere to ṣe afihan igbagbọ Yoruba ninu aye akamara ni oloogbe Ajilẹyẹ maa n ṣe nigba naa.
Eégun àti orò, bí wọ́n ṣe jọ bí Ẹ̀ṣà Egúngún nílẹ̀ Yorùba rèé
Ija laarin awọn awọn ẹlẹyẹ funfun ati dudu ni sinima naa da le lori.
Awọn agba oṣere bii Oloogbe Ajilẹyẹ, Oyiboyi, Kọledowo, oloogbe Oriṣabunmi, Abija ati bẹẹbẹl lọ lo wa ninu sinima yii.
Oríṣun àwòrán, Screenshot
Ọkan lara awọn ere sinima to milẹ nigba to jade ree. Ere ifẹ ni Alagba Yẹmi Ayebọ maa n saba n ṣe nigba naa pẹlu awọn orin ifẹ ninu rẹ.
Lẹyin ipapoda Ade Love, ko fi bẹẹ si awọn sinima ifẹ to ni alafibọ orin ninu mọ ki Yẹmi Ayebọ to de pẹlu sinima Yẹmi my Lover. Sinima naa da lori omidan  Moji ati Yẹmi ṣugbọn ti o ba inira diẹ pade.
Lọdun 1990 ni ere naa jade, awọn osere bii Abija, Yẹmi lukuluku, Thompson, Alabi yellow ati bẹẹbẹẹlọ.
Oríṣun àwòrán, Screenshot
Ere miran niyi to tun gbajumọ lọpọ ọdun sẹyin.
Alhaji Yẹkini Ajilẹyẹ lo gbe sinima naa jade nigba naa. Itan Ewurẹ abami kan to n hu iwa buruku ni sinima yii da le lori.
Awọn agbagb oṣere bii Grace Oyin-Adejọbi (Iya Osogbo), Kọledowo,  ati bẹẹbẹlọ.
Oríṣun àwòrán, Screenshot
Ọkan lara awọn gbajumọ ere sinima to waye laarin ogun ọdun si ọgbọn ọdun sẹyin ni sinima Owoblow jẹ.
Ọpọ onwoye sinima Yoruba lo si n sọ pe ere yii gan lo sọ Taiwo Hassan (Ogogo) ati Yinka Quadri(kura) di gbajugbaja.
Sinima naa da lori ọdọkunrin kan to di janduku ati ọlọsha lẹyin ti wahala awọn ẹbi rẹ tii sita.
Akomolede ati Asa: Alagba Ajibola láti Fakunle ní olùkọ́ wa lórí ètò ìró lónìí
Awọn agbofinro ran baba rẹ lọ sẹwọn, ileewe si lee jade nitori aile san owo ileewe.
"Wọle gbiyanju ohun gbogbo to lee ṣe lati tọju iya rẹ atawọn aburo rẹ ṣugbọn ko bọ si ki o to di ajẹgboro lẹyin ti wọn koo mọ ""roga"" ti ko si fẹ pada lọ ba iya rẹ mọ nitori ojuti."
Awọn eekanosere to kopa ninu rẹ ni Racheal Oniga, Bayo Bankole, Adebayọ Salami (Ọga Bello), Adewale Ẹlẹṣọ, Kayọde Odumoṣu, Binta Ayọ Msgaji, Sam Loco Efe, Bimbọ Akintọla, Ọmọọba Leke Ajao
Oríṣun àwòrán, Screenshot
Ere awada ni Larinlọọdu jẹ. ọkan lara awọn eekan alawada igba naa, Babatunde Omidina (Baba Suwe) ati aya rẹ oloogbe Monsurat Omidina (Mọladun).
Gbajugbaja agbe sinima sita ni, Shan George, Jide Kosọkọ, Yọmi King (Ọpẹbẹ), Yẹmi Ẹlẹshọ, Dele Odul.
Akomolede ati Asa: Alagba Ajibola láti Fakunle ní olùkọ́ wa lórí ètò ìró lónìí
BMuka Ray, Rẹmi Surutu, Doris Simeon, oloogbe Henrietta Kosokọ, oloogbe Alaaran, oloogbe Yọmi Ogunmọla, Gbenga Adewusi naa ba wọn lọwọ si sinima naa nigba naa.
Itan rẹ da lori Baba onile kan (Baba suwe)
Oríṣun àwòrán, Screenshot
Ara awọn sinima ti alagba Ọlaiya gbe sita ni. oloogbe Ajidara ko ipa manigbagbe ninu sinima yii.
Sinima naa da lori fifi ipa wa owo pẹlu awọn alafibọ awada ninu rẹ.
Awọn eekan oṣere bii  Branch, Bimbọ ọshin, Ajidara, Ọlaiya ati bẹẹbẹẹ lọ.
Oríṣun àwòrán, Screenshot
Ara awọn sinima ti Tunde Kelani gbe jade ni Saworo idẹ. Itan to yannana ipo eto oṣelu lorilẹede Naijiria nigba naa ni Saworoidẹ.
Lasiko ti orilẹede Naijiria wa labẹ iṣejọba ologun to si n gbaradi fun ijọba alagbada ni.
Akomolede ati Aṣa: Mọ̀ síi nípa ìró afárànma àti agbárànmọ́ fáwẹ́ẹ̀lì Yorùbá
Awọn eekan oṣere bii Kọla Oyewọ, Lere Paimọ, Bukky Wright, Kunle Bamtẹfa, Kọla Ọlaiya (Adẹrupọkọ), oloogbe Bayọ Faleti, Ọjọgbọn Akinwunmi Ishọla,
Ere yii lo gbe Kunle Afọlayan ati Kabirat Kafidipẹ jade faye ri.
"Kí ni ""Present tense"" lédè Yorùbá?"
Igboho Ultimatum to Fulani: Ẹni bá mọ Sunday Igboho kó bá wa bẹ̀ẹ́ o,
Stolen watch: Ilé ẹjọ́ gba béèlì, John Okonkwo ọkùnrin kan tó jí aago ọwọ́ tí iye rẹ̀ tó ₦33.8 mílíọ̀nù l'Eko
Oríṣun àwòrán, others
Ọkùnrin ẹni ọdun mejidinlogoji kan ti foju bale ẹjọ majisreeti to wa ni Yaba, nílùú Eko, lẹyin ti wọn fẹsun kan an pe o ji aago ọwọ ti iye owo rẹ le ni mílíọ̀nù mẹtalelọgbọn.
Wọn fi ẹsun mẹta kan John Okonkwo pe o ditẹ, o wọ dukia ẹlomiran lai tọrọ aye, pẹlu ero lati jale.
Ṣugbọn Okonkwo ti sọ pé òun kò jẹbi ẹsun náà.
Agbofinro to gbe afurasi ọhun lọ ile ẹjọ, DSP Roman Unuigbe sọ fún ile ẹjọ náà pé Okonkwo ṣe iṣẹ ibi naa lọlọ kejilelogun, oṣu Karun ùn, ọdun 2020, ni ọja Trade Fair to wa ni ilu Eko.
O ni afurasi naa fọ ṣọọbu Chidi Dimugonabo,  o sí ji pálí aago ọwọ ti iye rẹ jẹ N33.8 mílíọ̀nù.
Unuigbe sọ pé iwa ti afurasi naa wù lòdì sí òfin ipinlẹ Eko, eyii to tako iwa òdaran ti wọn gbé kalẹ lọdun 2015.
O sàlàyé fún ile ẹjọ ọhun pe ìjìyà ohun ti Okonkwo ṣe ni ẹwọn ọdun meji, ati ọdún méje gẹgẹ bí òfin ipinlẹ naa ṣe sọ.
Sunday Igboho fulani ultimatum: Àwọn ará Kebbi àti Zamfara ló n jínígbé ní Oke Ogun- Serik
Adajọ Adeola Adedayo gba beeli afurasi naa pẹlu mílíọ̀nù méjì naira ati oniduuro to dantọ.
Lẹyìn náà ló sún ẹjọ ọhun sí ọjọ keji, oṣù Kejì,  ọdún 2021.
Lawal Ayankemi Oluwatoyin: Mo kọ̀ láti máa tọrọ owó nítorí ojú mi tó fọ́, iṣẹ́ ló wù mí
Lawal Ayankemi: Mo ti sọ ireti nu lori aye mi ṣugbọn...Arabinrin yii ṣalaye fun BBC pe gbogbo nkan ṣa deede funfun ni eyi to n ba oun ninujẹ.
Lawal Ayankemi Oluwatoyin to ni ipenija oju ṣugbọn ti ko jẹ ko di oun lọwọ iṣẹ ṣiṣe ṣalaye fun BBC Yoruba ohun ti oju rẹ ri to.
O ni oun ti sọ ireti nu lori bi igbesi aye oun ṣe n lọ lẹyin ti oju mejeeji fọ nigba to fẹ ṣe idanwo JSS3 ipele giram kekere.
Ayankemi mẹnuba igbiyanju obi, ati ẹbi rẹ nile iwosan, lọdọ alaafaa ati Wolii ṣugbọn to ja si pabo.
Wọ́n kò bí mi láfọ́jú ṣugbọn ọrọ ti yipada.
Bayii Ayankemi n fi ilẹkẹ dara loriṣiiriṣii bii ko ṣe baagi ati awọn nkan miran fun tita.
O n ṣe ọṣẹ ifọbọ olomi, egbogi apakokoro atawọn nkan miran.
O ni oun ko fẹ tọrọ owo bikoṣe pe ki oun ri iṣẹ nitori oun kawe de ipele NCE fun ti olukọ tabi ki awọn eeyan maa ba oun ra ọja ti oun n ta.
Mo kọ̀ lati tọrọ owo, iṣẹ ni mo n wa- Ayankemi Lawal.
Coronavirus in Nigeria: Buhari buwọ́lu bílíọ̀nù N6.45b láti dá ibùdó afẹ́fẹ́ gáàsì sílẹ̀ fún ìtójú àwọn alárùn covid-19
Oríṣun àwòrán, Instagram/bashir ahmad
Aarẹ Muhammadu Buhari ti buwọlu owo to le ni biliọnu mẹfa naira N6.45bn fun ibudo idasilẹ afẹfẹ gaasi fun itọju awọn to larun coronavirus lorilẹede Naijiria.
Ibudo mejidinlogoji kaakiri Naijiria ni awọn ibudo naa yoo wa.
Ṣaaju akoko yii ni ajọ amuṣẹya PTF ti sọ lọjọ karun un oṣu kinni pe ijọba apapọ yoo da ibudo gaasi silẹ kaakiri gbogbo ipinlẹ mẹrindinlọgbọn ni Naijiria.
Ninu atẹjade kan ti ijọba fi sita l'Ọjọbọ, ijọba ya $671,000 sọtọ fu atunṣe awọn ibudo afẹfẹ gaasi lawọn ile iwosan kan ni Naijiria.
Ijọba ko sọ gbedeke nigba ti awọn ibudo gaasi naa yoo pari.
Minisita eto iṣuna, Zainab Ahmed sọ fun igbimọ NEC to n ri si eto ọrọ-aje pe igbesẹ ijọba naa ṣe pataki fun itọju awọn ọmọ Naijiria ti ọwọja ẹlẹẹkeji covid-19 n ba finra.
Sunday Igboho fulani ultimatum: Àwọn ará Kebbi àti Zamfara ló n jínígbé ní Oke Ogun- Serik
Ẹwẹ, eeyan 1964 lo lugbadi coronavirus l'Ọjọbọ ni Naijiria eyi to tii pọ julọ lọjọ kan ṣoṣo.
Ko si ẹni to le sọ pato iye awọn alarun coronavirus to nilo afẹfẹ eemi kaakiri ile iwosan ni Naijiria.
Amọ, ijọba sọ pe ki ọrọ naa pe ninu irora ni ọpọ eeyan to larun coronavirus wa.
Ibrahim El-Zakzaky: Zeenat lùgbàdì covid-19 lọ́gbà ẹ̀wọ̀n, IHRC rọ Buhari kó tú òun àti ọkọ rẹ̀ sílẹ̀
Zeenat El-Zakzaky ti lugbadi arun coronavirus lọgba ẹwọn to wa pẹlu ọkọ rẹ, Ibrahim  El-Zakzaky niluu Kaduna.
Ọmọkunrin kan ṣoṣo to ku fun olori awọm musulumi Shiite,  Ibraheem Zakzaky ṣalaye pe iya oun ti n fi awọn apẹẹrẹ coronavirus han ki wọn to ṣe ayẹwo fun un.
Ọmọkunrin El-Zakzaky ni ayẹwo ti awọn dokita obi oun ṣe lo fihan pe mama oun ti lugbadi arun coronavirus.
O ni awọn dokita ọhun tun ṣe oriṣiiriṣii irufẹ ayẹwo miiran fun iya oun lọgba ẹwọn.
Ibraheem ni o ṣe pataki lati fidi rẹ mulẹ pe ijọba ti dena mọ iya oun lati lọ gba itọju lori arun inu egungun orunkun(arthritis) ti o mu un fun ọpọ ọdun.
Lawal Ayankemi Oluwatoyin: Mo kọ̀ láti máa tọrọ owó nítorí ojú mi tó fọ́, iṣẹ́ ló wù mí
Ẹwẹ, ajọ ajafẹtọ ọmọniyan, IHRC ti kepe Aarẹ Muhammadu Buhari wi pe ko da El-Zakzaky ati aya rẹ silẹ lọgba ẹwọn lati le daabo bo wọn lọwọ arun coronavirus.
Bakan naa ni ajọ ọhun tun kọwe si ajọ iṣọkan agbaye, UNO lati sọ fun ijọba orilẹede Naijria pe ko fi wọn silẹ.
Sunday Igboho fulani ultimatum: Àwọn ará Kebbi àti Zamfara ló n jínígbé ní Oke Ogun- Serik
Ajọ IHRC ṣalaye siwaju si pe arun covid-19 ti iyawo El-Zakzaky ti ni bayii le wu awọn mii silẹ lara rẹ nitori ailera to ni.
Ajọ ajafẹtọ ọmọniyan naa ni ọgba ẹwọn ti olori awọn musulumi Shiite wa le ṣakoba nla fun ilera rẹ papaa julọ bi arun covid-19 ṣe n pọ si lojoojumọ yii.
LASTMA Yesufa: Àwọn dókítà gbìyànjú lórí ojú mi ṣùgbọ́n...
IHRC sọ pe iwa to buru jai ni ijọba Naijiria hu lori bi o ti ju tọkọ-taya si ọgbọn wọn nigba ti ileẹjọ ko tii sọ pe wọn jẹbi ẹsun ti wọn fi kan wọn.
El-Zakzaky ati aye rẹ Zeenat ti wa ni ẹwọn fun ọdun mẹfa bayii.
Akomolede ati Asa: Alagba Ajibola láti Fakunle ní olùkọ́ wa lórí ètò ìró lónìí
Igboho vs Fulani: Báyìí ni nǹkan ṣé ń lọ nílé Sunday Igboho lónìí
Lati ile Oloye Sunday Adeyẹmọ ti gbogbo eeyan mọ si Sunday Igboho tako iroyin to gba ori ayelujara kan wi pe ileeṣẹ ologun ati awọn Fulani ti yii ile ajafẹtọmọniyan naa ka.
Ko si ohunkohun to jọ bẹẹ lasiko ti akọroyin BBC Yoruba ṣe abẹwo si ile Oloye naa to n bẹ ni agbegbe Soka niluu Ibadan lowurọ ọjọ Ẹti.
Sunday Igboho ati alabaṣiṣẹ pọ rẹ n bẹ nile, bẹẹ si ni ohun gbogbo n lọ bi o ti wa tẹlẹ ri.
Bakan naa ni ọkanojọkan ere idaraya n lọ ninu ọgba ile naa.
Iwadii fi idiẹ mulẹ wi pe Igboho ṣi ni ṣe eto lati rin irinajo lọ si Ibarapa lowurọ oni, ṣugbọn akoko ti yoo gbera ni ko ti i han si ẹnikẹni lasiko ti a ṣe akojọpọ iroyin yii.
Amọ, ileeṣẹ ọlọpaa ipinlẹ Oyo ti rọ awọn eeyan ipinlẹ naa pe ki wọn fọkan balẹ wi pe ko si iyọnu.
Ẹwẹ, Gomina Seyi Makinde ipinlẹ Oyo na ti sọ fawọn eeyan ipinlẹ naa pe ko si ewu lẹgbẹrun ẹkọ lori ọrọ idunkoko mọ awọn Fulani pe ki wọn kuro lori ilẹ ipinlẹ Oyo lagbegbe Ibarapa.
Wọnyii ni awọn aworan bi gbogbo nkan ṣe n lọ nile Igboho laarọ ọjọ Ẹti to ni oun n lọ si Ibarapa.
Ondo robbers vs Army attack: Adigunjalẹ̀ kolu sójà ní Ondo, wọ́n yìnbọn lú wọ́n ní àyà àti ní apá
Oríṣun àwòrán, TWITTER
Awọn adigunjalẹ ti ṣekọlu si awọn ikọ ọmọogun nipinlẹ Ondo.
Eyi waye lasiko ti awọn ọmọogun naa wa lẹnu iṣẹ ti wọn ni opopona Owo-Ifon, nipinlẹ Ondo.
Agbẹnusọ ileeṣẹ ọlọpaa,Tee-Leo Ikoro to fi idi ọrọ naa mulẹ ni iṣẹlẹ naa waye ni Ọjọ Eti.
''Ẹnu iṣẹ ni awọn ọmọogun naa wa nigba ti wọn wa ọkọ de ibi ti awọn ole naa ti n ṣọṣẹ''
''Awọn ole naa yinbọn mọ ọkọ awọn soja naa, ti ibọn si ba ọkan ni aya, ekeji ni apa''
Sunday Igboho fulani ultimatum: Àwọn ará Kebbi àti Zamfara ló n jínígbé ní Oke Ogun- Serik
''Lẹyin yii ni wọn sa lọ sinu igbo, ti wọn si fi awọn eniyan ti wọn n ja lole lọ''
Agbẹnuṣọ ileeṣẹ ọlọpaa naa ni awọn ọmọogun to farapa naa ti wa ni ileewosan ijọba apapọ, Federal Medical Centre, Owo.
Oríṣun àwòrán, @policeNG
Sọja ati ọlọpaa kọnsitebu kan to ṣẹṣẹ wọ iṣẹ ọlọpaa nipinlẹ Ondo, David Friday ti wa ni akolo awọn agbofinro bayii lori ẹsun idigunjale.
Kọmiṣọnna ọlọpaa ipinlẹ Ondo sọ pe ọlọpaa naa ti kọkọ ji alupupu (ọkada) kan gbe tẹlẹ lago ọlọpaa to ti n ṣiṣẹ.
Agọ ọlọpaa to wa ni Olofin ni ijọba ibilẹ Idanre ipinlẹ Ondo ni Friday ti n ṣiṣẹ ki aje iwa ibajẹ naa to ṣi mọọ lori.
Sọja to jẹ ọkan lara wọn afurasi ti wọn fẹsun idigunjale ọhun kan, Innocent Victor n ṣiṣẹ pẹlu barake awọn ologun Naijiria, 32 Artillery Brigade, to wa ni Owena.
Ẹsun ti wọn fi kan wọn ni pe wọn di ọbẹ atawọn ohun elo ija mii mọra lorita Ojadale nibi ti wọn ti wọn ṣe ikọlu fawọn eeyan ti wọn si tun ja wọn lole.
Ẹrọ ibanisọrọ Itel ti wọn n ta ni N8500, epo bẹntiro jẹrika ọgbọn ati ẹgbẹrun lọna aadoje lekan(N131,000) ni wọn gba lọwọ wọn.
Lawal Ayankemi Oluwatoyin: Mo kọ̀ láti máa tọrọ owó nítorí ojú mi tó fọ́, iṣẹ́ ló wù mí
Kọmiṣọnna ọlọpaa ipinlẹ Ondo, Bolaji Salami tun sọ tẹlẹ pe Friday ti kọkọ ji alupupu(ọkada) kan gbe tẹlẹ lago ọlọpaa to ti n ṣiṣẹ.
Kọmiṣọnna ọlọpaa ni ẹjọ alupupu ti Friday ji lo n jẹ lọwọ nigba ti wọn gab mu pe o gbimọ pọ pẹlu sọja lati ja awọn eeyan lole pẹlu ọbẹ lọwọ.
LASTMA Yesufa: Àwọn dókítà gbìyànjú lórí ojú mi ṣùgbọ́n...
''Lara awọn eeyan ti ja lole lo dawọn mọ nigba ti ileeṣẹ ọlọpaa ṣe afihan wọn,'' Ọgbẹni Salami ṣalaye.
Ọga ọlọpaa naa ni awọn afurasi ọhun yoo foju ba ileẹjọ ni kete ti iṣẹ iwadii ba ti pari lori wọn.
Ẹwẹ, Victor to jẹ sọja ninu awọn afurasi naa ni oun ko jẹbi ẹsun ti wọn kan oun.
Sunday Igboho vs Fulani: Mo ń padà bọ̀ ní Ibarapa lọ́sẹ́ tó ń bọ̀- Igboho, Gbogbo dúkìá mi làwọn ọmọ Igboho jó tán-Seriki Fulani
Eekan ọmọ Yoruba ti ọrọ nipa rẹ n ja ranyinranyin lori ọrọ awọn Fulani lagbegbe Ibarapa ni ipinlẹ Ọyọ, Oloye Sunday Igboho ti sọ pe oun n pada lọ si ibuba awọn Fulani lagbegbe naa lọsẹ to n bọ.
Sunday Igbohoto ba awọn eeyan Ibarapa sọrọ lasiko to ko awọn ọmọlẹyin rẹ lọ ṣe ohun to pe ni jijawe o to gẹẹ fawọn Fulani to n wa nidi ijinigbe ati ipaniyan lagbegbe naa.
Eyi waye lẹyin gbendeke ọjọ meje to fun awọn Fulani naa lati fi ko aasa wọn kuro lagbegbe naa.
Iroyin to tẹ wa lọwọ ṣalaye pe Oloye Igboho kaakiri gbogbo agbegbe naa pẹlu ọwọ ero lẹyin lati kilọ fawọn ajinigbe nibẹ eleyi ti omilẹgbẹ awọn ọmọ Ibarapa baa rin pọ.
Amọṣa, gẹgẹ bi a ṣe gbọ lati ọdọ ikọ oloye Igboho, wọn ni wọn ko de gaa ile Seriki Fulani.
Nitori pe: gẹgẹ bi o ṣe sọ, Igboho ni pe oun pẹlu kọmiṣọnna ọlọpaa tuntun ni ipinlẹ Ọyọ, Ngozi Onadẹkọ ni yoo jọ lọ sọdọ Seriki Fulani atawọn fulani rẹ lọjọ iṣẹgun to n bọ.
Oloye Igboho fi da awọn eeyan Ibarapa loju pe asiko idẹkun to fun gulegule ijinigbe ati ipaniyan latọwọ awọn ti wọn furasi pe wọn jẹ fulani darandaran lagbegbe naa.
Kini Seriki Fulani sọ fun BBC bayii?
Amọṣa Seriki Fulani ni ipinlẹ Ọyọ, Alhaji Saliu Abdulkadir ti ke gbajare sita.
O ni pe gbogbo ile oun ni wọn jo, bẹẹni ọkọ pupọ lawọn eeyan kan jo pẹlu lasiko ti wọn ya bo gaa oun lagbegbe Iganagan lọjọ Ẹti.
Ninu ifọrọwerọ rẹ pẹlu BBC News Yoruba, Seriki Fulani Abdulkadir ṣalaye pe ọgọọrọ awọn eeyan ti oun furasi pe wọn jẹ ọmọlẹyin Oloye Sunday Igboho.
Ati pe wọn ya wọ Gaa oun lati dana sun awọn dukia olowo iyebiye nibẹ ti wọn si tun gbẹmi awọn eeyan oun kan pẹlu.
Sunday Igboho fulani ultimatum: Àwọn ará Kebbi àti Zamfara ló n jínígbé ní Oke Ogun- Serik
Gẹgẹ bi Seriki Fulani, Alhaji Saliu Abdulkadir ṣe sọ fun BBC News Yoruba ninu ifọrọwerọ kan, gbogbo awọn ile to wa nibẹ ni wọn dana sun pẹlu ọkọ atawọn ohun miran.
Alhaji Abdulkadir ni n ṣe lawọn oṣiṣẹ alaabo n woran lasiko ti igbesẹ ati dana sun gaa naa n waye ni.
Igboho Ultimatum to Fulani: Ẹni bá mọ Sunday Igboho kó bá wa bẹ̀ẹ́ o,
Seriki ni ibudo ifarapamọ si ni oun atawọn eeyan oun wa bayii ti wọn ti n sọrọ.
O fi kun un pe gbogbo ileri ti Oloye Igboho ṣe lo mu ṣe ti ko si si agbofinro to daa lọwọ duro.
Kini Sunday Igboho sọ fun BBC bayii?
Nigba ti a kan si ikọ Oloye Sunday Igboho, ohun ti wọn sọ ni pe ko si oun to jọọ rara.
Koda, wọn ni pe Oloye Sunday Igboho ko de gaa Seriki Fulani naa rara ni Igangan lanaa.
LASTMA Yesufa: Àwọn dókítà gbìyànjú lórí ojú mi ṣùgbọ́n...
"Wọn ni:  ""bi o tilẹ jẹ pe awọn eeyan agbegbe naa rọ ọ lati tẹle awọn debẹ"" ṣugbọn ti Igboho rọ wọn lati ṣe suuru ni ibi ti wọn de duro naa nitori alaafia ni ipinlẹ Ọyọ paapaa julọ lagbegbe naa""."
Yoruba Independence rally: Sunday Igboho ní àwọn àgbàgbà Yoruba dalẹ̀
Ikọ Igboho sọ pe: Nibẹ lo si ti fi ye wọn pe oun n pada bọ lagbegbe naa ni ọsẹ to n bọ pẹlu ọga ọlọpaa ni ipinlẹ Ọyọ lati le e mu oju aje konisọ.
"Ni ipari agbẹnusọ Igboho ni pe: ""O ṣeeṣe ko jẹ wi pe lẹyin ti Baba kuro nibẹ lawọn eeyan agbegbe naa lọ kuku fi ibinu wọn han ti wọn fi ṣe bẹẹ,"
"ṣe ẹyin naa mọ pe lọjọsi ti baba lọ, lẹyin ti baba kuro nibẹ awọn fulani kan ṣi kọlu awọn eeyan agbegbe naa ti wọn si pa ninu wọn"""
Lawal Ayankemi Oluwatoyin: Mo kọ̀ láti máa tọrọ owó nítorí ojú mi tó fọ́, iṣẹ́ ló wù mí
Sunday Igboho: Mo ṣé iṣẹ́ mọkaliki ri, bẹ́ẹ̀ sì ní mò tí ṣiṣẹ́ aponmità kí n tó rìnnà ko oríire
Oríṣun àwòrán, Sunday_igboho1/Instagram
Ni oni ọjọ Kẹwa, osu Kẹwa ọdun 2021 ni ayajọ ọjọ ibi gbajumọ ajijagbara ọmọ ilẹ Yoruba nni, Oloye Sunday Adeyemo, ti ọpọ eeyan tun mọ si Sunday Igboho.
Nilẹ kaarọ o jiire, orilẹede Naijiria ati ni awujọ agbaye pata, ọrọ to n gbẹnu awọn ọmọ Yoruba ati ẹya miran ni ti họwu-họwu laarin Sunday Igboho ati ijọba apapọ.
Bakan naa ni awọn ohun ti Igoho se nipa ikọlu awọn afurasi darandaran Fulani si agbegbe Ibarapa, ijijagbara fun ọmọ Yoruba ati bi wọn se fi si ahamọ nilẹ Benin Republic si n ja rain-rain.
Ọrọ yii gbale o gba oko, debi pe akọni ọmọ Yoruba naa n koju igbẹjọ nilu Cotonou, nibẹ lo si ti n sami ọjọ ibi ọdun kọkandinlaadọta rẹ loke eepẹ.
Ọna lati sami ajọdun ọjọ ibi yii lo mu ki BBC se akojọpọ ohun mẹfa to se koko nipa Igboho, eyi ti ẹ ko mọ tabi gbọ ri nipa rẹ.
Sunday Igboho: Fulani kò leè dúró, táa bá lo ohun ta jogún lọ́dọ̀ àwọ̀n bàbá wa
Sunday Igboho di ilumọọka lasiko laasigbo Modakẹkẹ ati Ife:
Ilu Modakeke ni ipinlẹ Osun ni Sunday Adeyemo dagba si bo tilẹ jẹ wi pe ilu Igboho ni ipinlẹ Oyo ni ilu abinibi rẹ.
Lasiko aawọ Modakeke Ife, Igboho ko ipa ribiribi lati fi gbe lẹyin awọn eeyan Modakeke.
Iwa akikanju ati isẹ takuntakun to se lasiko laasigbo naa lo mu ki awọn kan fi n sọ pe o loogun gan an bii Arọni.
Ninu ifọrọwanilẹnuwo pẹlu ileeṣẹ iroyin Tribune lọdun 2019 o sọ pe ''mo korira ki wọn maa yan eeyan jẹ. Idi ree ti mo fi gbe lẹyin Modakeke''
''Modakeke ni baba mi n gbe, ibẹ ni mo dagba si, ibẹ la kọle si, ti mo si bimọ sibẹ.
Se ki n yaju silẹ ki eeyan kan wa dana sun ile baba mi ni?
Sunday Igboho fulani ultimatum: Àwọn ará Kebbi àti Zamfara ló n jínígbé ní Oke Ogun- Serik
O ṣe iṣẹ mọkaliki, gun ọkada ati apọnmita ri, ki o to wa di ọlọla:
''Ọmọ atapata dide ni mi, baba mi ko si ni kọbọ'' ni apejuwe ti Sunday Igboho a maa saba ṣe to ba n juwe ara rẹ.
A ko ri akọsilẹ ibi to kawe de ṣugbọn ninu awọn fidio orisirisi to n fi soju opo rẹ ni Instagram, Igboho sọ pe oun jẹ iya to pọ, ki oun to jẹ eeyan laye.
Lẹyin to ṣiṣẹ mọkaliki, pọn omi ta ti, to n tun ọkada, lo bẹrẹ si ni ta ọkọ tokunbọ to si tatibẹ da ileeṣẹ Adesun Business Concept silẹ nilu Osogbo
Lara orukọ apejẹ ‘Baba Igboho’ ti baba rẹ n jẹ, lo ti mu Igboho inu orukọ rẹ:
Awọn to mọ Igboho ati itan rẹ yoo jẹri si wi pe gbajugbaja oloṣelu, Lamidi Adewolu Ladoja ko ipa ribiribi ninu igbesi aye Igboho.
Oun gan an fun ara rẹ ko ko iyan Ladoja kere ti a si maa fi imoore rẹ han si loorekoore.
Koda, isẹ kekere kọ ni Igboho se lati ri pe iya ko jẹ Rashidi Ladoja gbe lasiko to fi wa nipo, ti wọn si yọ lori oye fun osu mọkanla gbako.
Tiri di akoko yii, aarin Sunday Igboho ati Rashidi Ladoja si gunmọ, koda, aarin wọn ko se ri rara.
Sunday Igboho: Ladoja ní bí ìjọba kò bá fi ẹ̀lẹ̀ ṣe, ọ̀pọ̀ ajìjàgbara míì yóò dìde
O ni Ajọsepọ pẹlu awọn olorin, oloṣelu, elere tiata Yoruba ati awọn alfa nilẹ Yoruba
Saheed Osupa wa lara awọn ilumọọka olorin Yoruba to maa n kọrin ki Sunday Igboho.
Awọn oloṣelu ati elere sinima jankan jankan naa a maa ba a ṣe pọ.
Bi eeyan ba de oju opo rẹ ni Instagram niṣe lo kun fun aworan orisirisi to ba awọn eekan ilu ya.
Oríṣun àwòrán, Sunday Igboho
Rasheed Ladoja lo mu gẹgẹ bi awokọse
Ọjọ ọjọọkan ni Sunday Igboho ati Gomina ipinlẹ Oyo nigba kan ri Rasheed Ladoja pade nilu Ibadan.
Gẹgẹ bi awọn kan ti ṣe sọ, ibi ti Igboho ti n ja fun ẹtọ awọn eeyan ni Ladoja to foju si lara to sifa mọra ko maa ba ohun siṣẹ gẹgẹ bi amugbalẹgbẹ
Ọdọ Ladoja ni Igboho ti wọ agbo oṣelu to si di wọlewọde awọn eekan oloṣelu ni ipinlẹ Oyo.
Koda ninu ohun to sọ ni pe awọn kan fun ohun lowo lati fidalẹ Ladoja ṣugbọn oun ko dalẹ rẹ.
Iyawo meji lo ni, wọn o si baa gbe pọ ni Naijiria:
Ninu ile janran ti Sunday Igboho kọ si adugbo Sooka nilu Ibadan ko si iyawo kankan to n ba a gbe ninu ile naa.
Yatọ si awọn ọmọ iṣẹ rẹ ati amugbalẹgbẹ rẹ ti wọn jijọ wa nibẹ, ko si iyawo tabi ọmọ rẹ nibẹ.
Oríṣun àwòrán, Sunday Igboho
Ohun ti a gbọ ni pe iyawo rẹ kan wa ni orile-ede Germany ti ikeji naa si wa ni Canada.
Sunday ni oun ni ọmọ obinrin atri ọkunrin ṣugbọn o kọ lati sọ pato iye awọn ọmọ to bi fun awọn akọroyin.
Ọpọ igba ni wọn maa n ki Sunday Igboho ni Baba Dammy, Baba Ayomide ati bẹẹ bẹẹ lọ.
Sunday Igboho: Ṣé Igboho ṣetán láti ṣe ìpàdé pẹ̀lú Seyi Makinde àti ọlọ́pàá?
Oríṣun àwòrán, Facebook Sunday Igboho/OfficialSeyiMakinde/
Ọrọ aawọ to n waye lagbegbe Ibarapa ni ipinlẹ Oyo ti n ṣebi ẹni niyanju bọ diẹdiẹ pẹlu bi ijọba ti ṣe fẹ ṣepade pẹlu ọga ọlọpaa ati awọn lọba lọba nibẹ.
Afojusun ipade yii, gẹgẹ bi alaye ti igbakeji alaga igbimọ lọbalọba Oyo, Olugbọn tilu Orile-Igbọn, Oba Francis Olusola Alao ṣe sọ, ni lati da alaafia pada si agbegbe ọhun.
Lẹnu lọọlọ yi, laasigbo n waye pẹlu bi gbajugbaja ajafẹtọ Yoruba kan, Sunday Igboho ṣe lọ silu Igangan, lati kilọ fawọn ajinigbe, ọdaran ati apaniyan to wa lgbegbe Ibarapa lati so ewe gbejẹ mọ ọwọ.
Eyi ko ṣẹyin bi awọn eeyan ṣe n ke irora lori ẹsun ipaniyan ati ijinigbe to n waye lati ọwọ awọn ọdaran kan laarin awọn ẹya Fulani to tẹdo si agbegbe naa.
Oríṣun àwòrán, Sunday Igboho
Iroyin naa ni ọba alade naa ni ikọ lati ọdọ Gomina, omiran lati ọdọ ọga ọlọpaa ti Kọmisana tuntun Ngozi Onadeko yoo dari, ni yoo wa nibi ipade naa pẹlu ikọ asoju awọn lọbalọba.
''Mo n lọ si Ibarapa lọjọ Aiku lati lọ ṣe ipade pẹlu awọn lọbalọba Ibarapa. Kọmisana ọlọpaa yoo wa nibẹ, Aṣoju ọga ọlọpaa ati aṣoju ijọba naa yoo wa nibẹ''
''Alaafia la fẹ lagbegbe naa. Mo n lọ si ipade yii gẹgẹ bi igbakeji alaga igbimọ lọbalọba. Mo si ti sọ fun gbogbo awọn lọbalọba ni Ibarapa pe ki wọn peju sibẹ''
Ọba alaye naa tẹsiwaju pe ''igbesẹ n waye lati pari aawọ yi ni Tede, Agọ Arẹ ati agọ Amodu ni ijọba ibilẹ Atisbo. Emi ni mo n dari gbogbo eto yii ta si fẹ kawọn eeyan jẹ ki alaafia jọba''
Sunday Igboho fulani ultimatum: Àwọn ará Kebbi àti Zamfara ló n jínígbé ní Oke Ogun- Serik
Amọ ibeere to n gba ẹnu awọn eeyan ni pe se wọn ti gba Sunday Igboho sẹyin ninu ipade yii ni?
bakan naa ni wọn n beere pe se Igboho yoo lọ sibi ipade naa, ka si mọ boya gbogbo rogbodiyan naa yoo jẹ rodo, lọ mumi lẹyin ipade yii?
Sugbọn ọpọ ni o see se ki wọn ma pe Igboho sibi ipade naa nitori ọga patapata ọlọpaa ti paṣẹ saaju pe ki wọn mu Sunday Igboho wa si Abuja lati wa jẹjọ niwaju ile ẹjọ.
Titi di ba ṣe n ko iroyin yii jọ, ko si aridaju pe Kọmisana ọlọpaa ni Oyo ti tẹle aṣẹ ti ọga ọlọpaa pa.
Bakan naa ni iroyin kan ni awọn olori Fulani to wa ni Igangan ni oun ti sa asala fẹmi oun lẹyin ti awọn kan dana sun ile Seriki.
Ko daju boya awọn olori Fulani yoo wa nibi ipade yii ṣugbọn bi nkan ba ti ṣe n lọ si, gbogbo rẹ la o maa mu tọ yin wa.
Sunday Igboho: Àwọn olùgbé Igangan ní ó sàn káwọn kú, ju kí Seriki Fulani padà sílùú lọ
Oríṣun àwòrán, Nuj Kwara
Àwọn olùgbé ìlú Igangan níjọba ìbílẹ̀ Ibarapa nípìnlẹ̀ Oyo tí búra o, pé láí, àwọn kò le gbà kí Seriki Fulani, Abdulkadri Saliu pada wá sí ìlú Igangan.
Gẹ́gẹ́ bi wọ́n ṣe sọ, gbígba Seriko Fulani padà wá sí inú ìlú náà kò yàtọ́ sí pé ènìyàn fẹ́ fọ́wọ́ ara rẹ̀ gba ẹ̀mi ara rẹ̀ ni.
Wọ́n fikun pé yóò san kí àwọn kú, jú kí wọ́n gbà á padà lọ.
Gbogbo ìlú yóò ya pa ara wọn ju kí a fi ààyè gba Seriki pada lọ, ó sì sàn kí a fi ẹ̀mí wa lélẹ̀, ju kí àwa àti ìràn wa tún dúró sí abẹ́ Seriki Fulani Igangan 
Olùdásílẹ̀ Igangan Development Advocate, (IDA), Oladiran Oladokun lo sọ bẹ́ẹ̀ fún àwọn oníròyìn lónìí.
Ilorin Conjoined Twins: Àwọn òbí ìbejì tó lẹ̀pọ̀ ní ọ̀kàn àwọn bàjẹ́ láti rí ibèjì wọn tó
Oladokun ń fèsì sí ọ̀rọ̀ tí Seriki Fulani sọ fáwọn oníròyìn lọ́jọ́bọ pé, ó wú òun láti pada sí ìlú Igangan tí wọ́n bá fún òun ni ànfàní míràn.
Saliu, tí àwọn ẹbi rẹ̀ ń ṣe àtìpó nílùú Ilorin lọ́wọ́lọ́wọ́ lo sọ di mímọ̀ lọ́jọ́bọ.
Tí ẹ o bá gbàgbé, ó pé ọjọ́ mẹ́jọ lónìí tí Sunday Igboho lọ sí ìlú Igangan, láti láti lé àwọn Fúlàni tó n huwa ibajẹ́ níbẹ̀ jáde.
Oladokun sàlàyé pé, láti ìgbà tí wọ́n ti lé Seriki Fulani agbègbè náà, ni èémí àláfíà ti wọ̀lú.
Sunday Igboho: Fulani kò leè dúró, táa bá lo ohun ta jogún lọ́dọ̀ àwọ̀n bàbá wa
Ó fi kún pé, àwọn olùgbé àdúgbò náà ti n fẹ̀dọ̀ lórí òróǹro báyìí, tí olúkúlùkù sì tí ń pada sí ẹnu iṣẹ́ oko wọ́n láì sí ìbẹ̀rù ìjínigbé tàbí fífi ipá báni lòpọ̀.
Olórí IDA sọ pe àwọn ènìyàn ìlú náà ni àwọn kò fẹ́ àṣẹ ti yóò da omi aláfíà, ti àwọn ń gbadun lọ́wọ́lọ́wọ́ rú láàrín ìlú náà.
Ó wá rọ ilé iṣẹ́ ààrẹ àti gómínà ìpińlẹ̀ Oyo, Seyi Makinde láti bẹ̀rẹ̀ ìwádìí tó péye lórí ẹ̀sùn ti wọ́n fi kan Seriki Fulani, ki wọ́n si di òkodoro inú rẹ̀ mú láti fi ẹnikẹni ti igbá ọ̀rọ̀ náà bá ṣímọ́ lórí jófin.
Ó wù mí kí ń padà sí Igangan, tí wọn bá fún mi láàyè - Seriki Fulani
Seriki Fulani nilu Igangna, Saliu Abdulkadir ti sisọ loju rẹ pe ilu Ilorin ni awọn ẹbi oun  wa bayii amọ oun sare wa sapa oke ọya fun abẹwo.
Seriki, lasiko to n bawọn akọroyin sọrọ nilu Ilorin ni awọn ẹbi oun to wa ni Ilorin ti tẹwọ gba awọn amọ oun setan lati pada maa gbe nilu Igangan ti wọn ba gba oun laaye lẹẹkan si, ti alaafia si jọba pada.
"Ko si ẹnikẹni to pe mi si ipade kankan titi di akoko yii, ko si ibi ti mo fẹ gbe mọ nilu Igangan, gbogbo ọkọ ati ile mi ni wọn ti jo nina.
Sunday Igboho: Fulani kò leè dúró, táa bá lo ohun ta jogún lọ́dọ̀ àwọ̀n bàbá wa
Bi mo se n ba yin sọrọ yii, apa ariwa ni mo wa, amọ awọn ọmọ mi wa nilu Ilorin nitori mo ni ile kan nibẹ ti wọn de si.
Seriki wa sisọ loju rẹ pe oun ko sẹ awọn eeyan Igangan rara, nitori awọn janduku ilu naa lo jẹ ọmọ onilu, ti ọwọ ọlọpaa si ti ba wọn, wọn wa lọgba ẹwọn Agodi.
Lọwọ lọwọ bayii, asaaju awọn janduku naa, Janbele wa lagọ ọlọpa, eyi si wa lara ohun to n da ọta silẹ laarin awa Fulani atawọn eeyan ilu naa."
Ilorin Conjoined Twins: Àwọn òbí ìbejì tó lẹ̀pọ̀ ní ọ̀kàn àwọn bàjẹ́ láti rí ibèjì wọn tó
Lọjọ ti Fatai Aborode ku, awọn janduku yii fi awa atawọn Yoruba sinu igbekun ni, gbogbo wọn ni wọn si ri bi Fatai se n bẹbẹ, to si ni oun setan lati san iyekiye bii owo irapada ẹmi.
"Amọ awọn apaayan naa ko gba owo abi ẹbẹ rẹ, ti wọn si pa a."""
Seriki Fulani wa ffi ọwọ sọya pe irẹpọ wa laarin oun ati agboole ti wọn ti bi Aborode, tii se ile Alagbẹdẹ
Seriki Fulani ní ìlú Igangan níjọba ìbílẹ̀ Ibarapa nípìnlẹ̀ Oyo, Alhaji Salihu Abdulkadir ti fẹ̀sù kan pé ajafẹ́tọ ọmọ Yorùbá, Sunday Adeyemo, ti gbogbo ènìyàn mọ̀ sí Sunday Igboho, àti àwọn ìsọ̀mọ̀gbé rẹ̀ pa méje nínú àwọn ènìyàn òun lásìkò tí wọn wa síbẹ̀.
Sáájú ni Igboho ti fún àwọn Fulani ni gbèdéke ọjọ́ méje láti kúrò ninú ìlú Igangan.
Lẹ́yìn ti ọjọ́ náà pé ni Sunday Igboho lọ ilú náà lọ́jọ Ẹtì tó kọ́já nítori pe ó fi ẹ̀sùn kan wọ́n pé àwọn ni wọ́n wà nídìí, ìpàniyan, ìjínigbé àti ìfipá bánilòpọ̀ tó n wáye níbẹ̀.
AbdulKadir sọ pé Fulani méje, àti ǹkan ìní tó tó mílíọ̀nù lọ́nà ẹ̀ẹ̀dẹ́gbẹ́ta náírà ni òun pàdànú.
Awọn ile mi, ọkọ mejila to jẹ temi, awọn ọmọ mi ati alejo meje ni wọn dana sun, ti a ko si ri oku meji ninu wọn, bẹẹ́ ni wn ji awọn ẹran ọsin mi ko lọ.
Sunday Igboho: Fulani kò leè dúró, táa bá lo ohun ta jogún lọ́dọ̀ àwọ̀n bàbá wa
Bákan náà ni ó fi kun pé, òun kò lọ́wọ́ nínú gbogbo ẹ̀sùn ti wọ́n fi kan òun nípa ìjínígbe ni agbègbè náà, pàápàá jùlọ ìpànìyàn ọmọwé gboye Havard tó jẹ́ ọmọ ìlú náà, ọ̀mọ̀wé Fatai Aborode ti wọ́n pa ni ìpakúpa.
Lásìkò tó n bá àwọn akọ̀ròyìn sọ̀rọ̀ nílùú Ilorin, ti ṣe olúùlú ìpińlẹ̀ Kwara lo ti ni irọ́ pọ́nbélé ni Sunday Igboho ń pa mọ́ òun.
Ó ní òun àti ẹbí òun tí n gbé ìlú Igangan láti bí àádọ́ta ọdún sẹ́yìn, ti ko sì sí ẹni tó yẹ òun lọ́wọ́ wò.
Ó wa ké pe gbogbo àwọn Emir àwọn ìpínlẹ̀ Arewa mọ́kàndínlogun àti àwọn olóyè, láti dide iranlọ́wọ́ fún gbogbo Fulani tó wà ni ilẹ̀ Yoruba.
Bákan náà lo fi kún pé, nígbà ti wọn wá fi ẹjọ́ ọmọ Fulani kan ti wọ́n ń pe ni Omomogeto sun oun, ẹni ti wọ́n lo fipa bá ọmọbìnrin kan lò pọ̀, òun fá à le ọlọ́pàá lọ́wọ́ ni.
Sunday Igboho fulani ultimatum: Àwọn ará Kebbi àti Zamfara ló n jínígbé ní Oke Ogun- Serik
"Lẹ́yìn ti wọ́n mu, ti wọ́n ṣe ìwádìí, tí aje ọ̀rọ̀ náà sì ṣí mọ́ lórí, mo fi si ìkáwọ́ àwọn ọlọ́pàá ni.
Bákan náà ni wọ́n fipa bá ọmọbinrin miraǹ to jẹ́ ọmọ Igangan lòpọ̀ lọ́dún tó kọja, debi pé, ọmọbinrin náà kú, kò sí ǹkan ti wọ́n ṣe sí ẹni tó bá ọmọbinrin náà lòpọ̀ di òní yìí.
O wa kesi ijọba lati tanna wadi awọn ẹsun naa, ẹnikẹni to ba si jẹbi ni ko fi imu ko ata ofin.
Ọkan lara awọn ọmọ Seriki Fulani ilu Igangan tawọn janduku ṣe ikọlu si Gaa wọn, ti ṣalaye ohun ti oju wọn ri fun BBC.
Arakunrin Umar Salihu Abdulkadir sọ fun BBC, lasiko ifọrọwerọ rẹ pẹlu a, lati nkan bi ago mẹrin ọsan tawọn ti sa kuro ni Igangan, awọn ko duro titi di ago mẹta oru tawọn de ipinlẹ Ogun.
O ni pupọ awọn eeyan awọn lawọn ko mọ ibi ti wọn wa, to fi mọ Seriki Fulani to jẹ baba oun.
Salihu ni niṣe ni awọn to ṣigun wa ba awọn bẹrẹ si ni yin ibọn, ti wọn si dana sun ile laisi idiwọ kankan.
Ninu ọrọ rẹ o ni Sunday Igboho ko lẹbi iṣẹlẹ naa, bi ki ṣe pe awọn ijọba ati ọlọpaa kọ lati pese aabo to peye fawọn.
''Ijọba ati awọn ọlọpaa tan wa pe ko ni si nkankan sugbọn nigba ti awọn janduku de, nise ni wọn sa lọ.''
Ọkọ mọkanla, ile ainiye ati aimọye maalu lo ni awọn janduku bajẹ nigba ti wọn kọlu awọn.
O ni ẹsun ti wọn fi n kan awọn Fulani yii ko ri bẹẹ nitori bi awọn ajinigbe ṣe n gbe Yoruba, naa ni wọn n ji Fulani naa gbe.
Nipa ẹsun pe Seriki lo n gba owo lọwọ awọn ajinigbe o sọ pe irọ nla ni.
''Gbogbo ọrọ ti wọn n sọ yii, ọna ati da Oduduwa Republic wọn silẹ ni wọn n ba kaakiri.''
Ọmọ Seriki naa tun ni mọsalasi, aaye ti wọn ti n pese wara maalu ati awọn dukia mii ni awọn janduku naa baje ni Igangan.
BBC se alabapade iyawo akọkọ Seriki Fulani, arabinrin Mariam ti wọn ṣe leṣe, to si n gba omi sara.
Lasiko ti BBC bẹ obinrin naa wo nijọba ibilẹ Odeda nilu Abeokuta, apa kan ori rẹ la ri ti wọn lẹ pilasita mọ oju ọgbẹ to wa lori rẹ.
Mariam ni inu yara oun ni awọn janduku kan to jẹ ẹya Yoruba wa ka oun mọ, ti wọn si sa oun ni ọbẹ lori.
Bi o tilẹ jẹ pe a gbiyanju lati ba Mariam, aya Seriki Fulani naa sọrọ, amọ ko le e sọrọ daadaa ju pe o darukọ rẹ fun wa lọ.
Bakan naa la ri okun ti wọn ti sẹsẹ fa omi si ara obinrin naa lara.
Ṣaaju ni BBC Yoruba ti laanfaani lati ba Seriki sọrọ lẹyin ikọlu to waye si Gaa wọn ni Igangan.
Ninu alaye to ṣe, Seriki ni oun naa sa kuro ni ati pe ibudo ifarapamọ si lohun ati awọn eeyan oun wa, tawọn ti n ba wa sọrọ.
Ileeṣẹ ọlọpaa ipinlẹ Oyo ninu atẹjade kan ti wọn fi sita, tan imọlẹ sohun to ṣẹlẹ ni Igangan.
Atẹjade naa ti Fadeyi Olugbenga fọwọ si lorukọ Kọmisana ṣalaye pe, omi alaafia ilu daru lẹyin ti Sunday Igboho lọ si Igangan lọsan ọjọ Kejilelogun oṣu Kini.
Sunday Igboho fulani ultimatum: Àwọn ará Kebbi àti Zamfara ló n jínígbé ní Oke Ogun- Serik
Fadeyi ni lẹyin ti Igboho lọ tan lawọn janduku yabo aaye ibugbe awọn Fulani pẹlu nkan ija orisirisi ti wọn si dana sun ile.
''Nibi ikọlu yii, wọn ṣe awọn eeyan leṣe, to fi mọ ọlọpaa kan nibi to ti n ṣe iṣẹ rẹ''
''Nitori bi nkan ti ṣe ri yii, Kọmisana ọlọpaa n parọwa si awọn araalu lati faaye gba alaafia, kawọn ọdọ si ma ṣe jẹ ki wọn lo wọn fi da ogun ẹlẹyamẹya silẹ''
Akungba Akoko Accident: Fásitì Adekunle Ajasin ṣún ìdánwò síwájú láti bọ̀wọ̀ fáwọn akẹ́kọ̀ọ́ tó kú
Oríṣun àwòrán, Twitter/@gbemidennis
Awọn alaṣẹ fasiti Adekunle Ajasin, Akungba-Akoko, ti paṣẹ pe ki ileewe naa di titi pa ni kiakia.
Ninu ikede ti Adele Akọwe ileewe naa, Opeoluwa Akinfenwa fi sita lọjọ Aiku, awọn alasẹ sọ pe igbesẹ naa waye nitori bi awọn akẹkọọ ṣe ṣe iwọde.
Wọn si ti fun gbogbo akẹẹkọ ni gbedeke aago mẹfa irọlẹ ọjọ Aiku, ọjọ kẹrinlelogun, oṣu Kinni, ọdun 2021, lati fi ọgba ileewe silẹ.
Iroyin sọ pe awọn akẹkọọ ati awọn ọdọ ilu Akungba-Akoko tu jade ni ọjọ Aiku, lati fi ẹhonu han nitori ijamba ọkọ akẹru to pa awọn eeyan lọjọ Satide.
Ijamba naa ni iroyin sọ pe o waye lasiko ti ọkọ nla kan to ko simẹnti to jẹ ti ileeṣẹ Dangote, sọ ijanu rẹ nu, to si yawọ awọn ṣọọbu kan ni ẹgbẹ fasiti Adekunle Ajasin to wa nilu naa.
Awọn akẹkọọ fasiti naa wa lara awọn eeyan to padanu ẹmi wọn sinu ijamba naa.
Oríṣun àwòrán, @Advisers_corner
Adura ti ọpọ eeyan maa n gba ni pe ki ọba oke mase jẹ ka rin lọjọ ti ebi yoo pa ọna.
Amọ eyi ko ri bẹẹ fun awọn eeyan mẹjọ kan nilu Akungba Akoko nipinlẹ Ondo lọjọ Abamẹta nigba ti wọn ko agbako ijamba ọkọ.
Gẹgẹ bi iroyin to de setigbọọ ikọ iroyin BBC Yoruba ti wi, o kere tan, eeyan mẹjọ lo kagbako iku ojiji lasiko ijamba ọkọ naa to waye ni deede aago mẹfa irọlẹ.
Iroyin naa fikun pe awọn akẹkọọ fasiti Adekunle Ajasin naa wa lara awọn eeyan to dero ọrun ọhun, ti ọpọ eeyan miran si fara pa.
Oríṣun àwòrán, @KingMikasaa
Ohun to fa sababi isẹlẹ naa ni ti ọkọ akẹru kan to jẹ tileesẹ Dangote ti ijanu rẹ sọsẹ silẹ, to si ya lọ kọlu awọn eeyan to wa lawọn ọja ati ibudo itaja to wa lẹba fasiti Adekunle Ajasin naa.
Ilu Ikare Akoko ni wọn ni ọkọ akẹru ọhun ti n bọ, asiko to si n sọkalẹ lati ori oke to wa lẹba fasiti naa ni bireeki rẹ sọsẹ silẹ, to si kọlu ọpọ eeyan.
Ẹnikan ti isẹlẹ naa soju rẹ ni Gbogbo awọn akẹkọọ to wa nibudo itaja lo kọlu, to fi mọ awọn eeyan to n rin lẹba oju ọna."
Iwadii fihan pe awọn akẹkọọ to fori sọta ijamba naa ni wọn n mura idanwo ti yoo waye lọjọ Aje silẹ, ti wọn si lọ sibudo itaja naa lati lọ se awọn ẹda iwe ti wọn nilo.
Oríṣun àwòrán, @KingMikasaa
Wayi o, adele akọwe agba fun fasiti Adekunle Ajasin, Opeoluwa Akinfemiwa ti fi atẹjade kan sita ni kete ti isẹlẹ naa waye.
Ninu atẹjade naa si lo ti wa pasẹ pe ki wọn ti ẹnu ọna abawọle sinu ọgba ile ẹkọ naa to wa loju titi.
Atẹjade naa, to kẹdun pupọ pẹlu awọn ẹbi akẹkọọ ti isẹlẹ iku ojiji naa kan, wa jẹjẹ pe ijọba ipinlẹ Ondo ati awọn oludari ile ẹkọ fasiti naa ti n wa ọna abayọ sirufẹ isẹlẹ yii lọjọ iwaju.
Bakan naa ni wọn kede pe wọn ti sun idanwo akẹkọ to yẹ ko bẹrẹ lọjọ Aje siwaju di ọjọ miran, ọjọ re nitori isẹlẹ asekupani ọhun, lọna ati bu ọwọ fawọn akẹkọọ to papoda.
Sunday Igboho: OPC ní ọ̀gá ọlọ́pàá, Operation Burst àti Civil Defence wà pẹ̀lú àwọn
Akọwe ipolongo fun ẹgbẹ OPC new Era, Adesina Akinpelu ti salaye bi irinajo Sunday Igboho se lọ silu Igangan lọjọ Ẹti.
Nigba to n ba BBC Yoruba sọrọ lori irinajo Igboho naa, Akinpelu fidi rẹ mulẹ pe kii se Igboho nikan kọ lo da lọ silu Igangan lọjọ Ẹti.
Akọ̀we ipolongo OPC New Era naa ni gba gba gba ni ẹgbẹ naa wa lẹyin Sunday Igboho nitori ka rin, ka pọ, yiyẹ nii yẹ ni.
"Akinpelu fikun pe ""Awa ẹgbẹ OPC New Era, The Reformed OPC, Agbekoya, Ẹgbẹ ọdọ Oodua Liberation, Oodua Alliance ati ẹgbẹ ọdọ nilu Igangan la gbaruku ti Sunday Igboho lọ silu Igangan lọjọ Ẹti."
Bakan naa lo ni awọn duro ni agọ ọlọpaa ẹkun Eruwa lasiko ti awọn n lọ silu Igangan lọjọ Ẹti, ti ọga agba ọlọpaa lẹkun naa si kọwọrin pẹlu awọn lọ si agbegbe naa.
"Koda, a se alabapade awọn osisẹ aabo ara ẹni laabo ilu, Civil Defence ati awọn ologun, a sọkalẹ ninu ọkọ wa, ta si salaye fun wọn pe alaafia la n ba lọ.
A sọ fun wọn pe a n lọ sọ fun Seriki Fulani to wa nilu Igangan pe ko kilọ fawọn Fulani to n paayan pe ki wọn fi agbegbe naa silẹ.
Wọn gba wa laaye lati lọ silu naa, taa si bawọn eeyan ilu naa sọrọ, ta si fi wọn lọkan balẹ pe ko ni si ewu mọ lati akoko naa lọ."
Adesina Akinpelu fikun pe ọkada aadọta lo tẹle awọn latilu Eruwa, ọkada naa si di ẹgbẹrun kan nigba tawọn de Igbo Ora, nigba ti wọn yoo si fi wọ ayete, iye awọn ọkada naa ko lonka mọ.
O ni deede aago mẹta ọsan lawọn de Igangan lọjọ Ẹti, ti awọn si kuro ni aago mẹfa kọja ogun isẹju nirọlẹ, ti ko si si jagidijagan kankan.
O ni ọkọ Sunday Igboho lo lewaju awọn, tawọn si fi ọrọ werọ pẹlu awọn ọmọ ologun to wa loju popo.
"Akinpelu ni ""Gbogbo ikọ OPC to wa lẹkun iwọ oorun guusu Naijiria lo n ti Igboho lẹyin, a si n se atilẹyin fawọn baba wa lẹkun yii."
"Ki wọn si to le ri Igboho gbe, gbogbo ikọ ajijagbara nilẹ Yoruba ni wọn yoo kọkọ gbe na, bẹẹ si ni kii se gbogbo Fulani ni Igboho ni ki wọn ko aasa wọn, awọn to jẹ ọdaran laarin wọn ni."""
Oríṣun àwòrán, Facebook/Sina Akinpelu
Wayi o, awọn ẹgbẹ kan to jẹ tọmọ wọn ẹgbẹ kan to jẹ tọmọ Yoruba, Yoruba Council of Elders ati Oodua Peoples Congress, OPC ti tako asẹ ọga ọlọpaa lati mu Oloye Sunday Igboho.
Saaju la ti mu iroyin wa fun yin pe ọga agba ọlọpaa ti pasẹ fun Kọmisana ọlọpaa nipinlẹ Oyo lọjọ Ẹti lati lọ mu Igboho wa silu Abuja.
Asẹ naa lo waye nitori bi Igboho se pasẹ fawọn ọdaran kan laarin ẹya Fulani to n gbe lagbegbe Ibarapa lati ko aasa wọn, ti wọn ko ba dẹkun ipaniyan, ijinigbe ati ifipabanilopọ.
Sunday Igboho fulani ultimatum: Àwọn ará Kebbi àti Zamfara ló n jínígbé ní Oke Ogun- Serik
Akinpelu, nigba to n salaye lori isẹlẹ to waye nilu Igangan ninu eyi ti wọn ni awọn eeyan kan dana sun ile Seriki Fulani, Akinpelu ni awọn ko mọ ohunkohun nipa isẹlẹ naa.
"Akinpelu ni ""lootọ ni inu n bi awọn ọdọ ilu naa, ti wọn si fẹ fi ẹhonu han, amọ a kilọ fun wọn pe wọn ko gbọdọ fa laasigbo kankan lẹsẹ, ki ijọba maa baa mu wọn."""
Akipelu ni lẹyin ti Sunday Igboho ati ikọ rẹ kuro nilu naa, awọn pada lọ sọ fawọn ọlọpaa pe awọn ti setan, ti awọn si pada silu Ibadan.
O ni awọn ko mọ nipa ohunkohun to sẹlẹ mọ lẹyin rẹ.
Igboho Ultimatum to Fulani: Ẹni bá mọ Sunday Igboho kó bá wa bẹ̀ẹ́ o,
Wayi o, ẹgbẹ apapọ fawọn agbaagba nilẹ Yoruba, Yoruba Council of Elders, YCE, ti kesi aarẹ Muhammadu Buhari lati bawọn ọmọ orilẹede yii sọrọ lori wahala awọn ọdaran Fulani.
Akọwe apapọ fun ẹgbẹ naa, Dokita Akin Olajide, lasiko to n bawọn akọroyin sọrọ ni iwa ika tawọn ọdaran kan ninu ẹya Fulani n hu ti pọ ju.
O fikun pe ihuwasi ati ọrọ tawọn amugbalẹgbẹ aarẹ kan n hu tabi sọ jade kan n bu epo p€triroolu si aawọ naa ni.
O ni ọpọ eeyan lawọn ọdaran Fulani ti ran sọrun ọsan gangan, wọn n fi tipa bawọn obinrin sun, ti wọn si tun ba ọpọ ire oko awọn agbẹ jẹ.
Olajide wa fi ọwọ gbaya pe iru awọn iwa ọdaran bẹẹ ko le tẹsiwaju, to si gba ijọba nimọran lati tẹẹ jẹjẹ nidi ete rẹ lati gbe Sunday Igboho si ahamọ.
Sunday Igboho: Seriki Fulani àti ẹbí rẹ̀ gba inú igbó dé ìpínlẹ̀ Ogun
Yatọ si ọmọ Seriki, BBC ri iyawo akọkọ Seriki Fulani, arabinrin Mariam ti wọn ṣe leṣe to si n gba omi sara.
Lasiko ti BBC bẹ obinrin naa wo, apa kan ori rẹ la ri ti wọn lẹ pilasita mọ oju ọgbẹ to wa lori rẹ.
Mariam ni inu yara oun ni awọn janduku kan to jẹ ẹya Yoruba wa ka oun mọ, ti wọn si sa oun ni ọbẹ lori.
Bi o tilẹ jẹ pe a gbiyanju lati ba Mariam, aya Seriki Fulani naa sọrọ, amọ ko le e sọrọ daadaa ju pe o darukọ rẹ fun wa lọ.
Toyin Abraham: Ẹ wo ohun báwọn ọmọ ìṣọta ṣe ya bó màmá Ire lẹ́nu iṣẹ́
Oríṣun àwòrán, Instagram/toyin_abraham
Awọn ọmọ adugbo ṣe ọṣẹ fun eekan osere tiata Yoruba, Toyin Abraham nibi to ti lọ ya sinima kan, to pe akọle rẹ ni Ige, laipẹ yii.
Gẹgẹ bi ohun ti oun funrarẹ sọ ninu fidio kan, awọn ọraisa naa yabo ibi to ti lọ ya sinima naa, ti wọn si n beere owo gọbọi, ki wọn to lee jẹ ki oun atawọn ikọ rẹ fi irọrun ya sinima naa.
Amọ gbogbo bi Toyin ṣe n fi ohun irẹlẹ ba awọn eeyan naa sọrọ, lo n ja si pabo, to si n rọ wọn lati gba owo lọ fi ra ọti lile.
Lẹyin ti wọn faa sọtun ati sosi, lo fun awọn janduku naa ni ẹgbẹrun mẹwaa Naira lati fi lọ gbadun ara wọn.
Oríṣun àwòrán, Instagram/toyin_abraham
Amọṣa awọn janduku naa fariga pe owo naa ti kere ju fun wọn, ti wọn si ni ko tubọ gbọn ọwọ si.
Toyin Abraham wa ṣalaye fun wọn tirẹlẹ tirẹlẹ pe owo ko fi bẹẹ pọ lọwọ oun.
O ni oun ṣẹṣẹ san ẹgbẹrun lọna ọgọfa naira fun awọn ti oun lo gẹgẹ bi ero, ni ibudo ti oun ti n ya sinima naa ni, eyi si lo mu kawọn janduku naa gba owo naa lọwọ rẹ.
Bakan naa lo ṣalaye pe, oun ti kọkọ fun wọn ni ẹgbẹ̀run marun naira tẹlẹ lati fi mu ẹlẹrindodo ati pe, ko tun yẹ ki wọn daamu oun mọ lori ọrọ owo.
Nigba to n salaye isẹlẹ yii loju opo Instagram rẹ, Toyin Abraham ni awọn yoo fun awọn eeyan yii ni owo, wọn yoo tun maa fapa janu pe o kere, awọn n fẹ si.
O ni irufẹ isẹlẹ yii ni awọn maa n la kọja loore koore lasiko ti awọn ba n ya sinima sugbọn awọn si nifẹ awọn eeyan naa sa.
Sunday Igboho: N kò fẹ́ oyè ọ̀gá àgbà páta fún ikọ̀ Amotekun nílẹ̀ Yorùbá
Sunday Igboho: N kò fẹ́ oyè ọ̀gá àgbà páta fún ikọ̀ Amotekun nílẹ̀ Yorùbá
Ṣe lootọ ni pe wọn fẹ fi oloye Sunday Adeyẹmọ, ti ọpọ mọ si Sunday Igboho jẹ olori gbogbo iko amọtẹkun ilẹ Yoruba?
Ibeere to n ja kaakiri ree bayii lẹyin ipade apapọ awọn gomina ipinlẹ ilẹ Yoruba to waye lọjọ Aje nilu Akurẹ, tii ṣe olu ilu ipinlẹ Ondo.
Sunday Igboho lo bọ si agbami ojutaye iroyin lẹyin to gbe gbedeke ọjọ meje kalẹ fawọn Fulani nilu Igangan lagbegbe Ibarapa laipẹ yii.
Igboho ni ki awọn ọdaran Fulani naa ko aasa wọn nitori iwa ifipabanilopọ, ijinigbe, idigunjale ati ipaniyan ti wọn n hu.
Awọn eeyan kan to sunmọ Igboho bi iṣan ọrun, la gbọ pe wọn lu awo ọrọ naa si awọn akọroyin leti.
Amọ nigba to n fesi lori ahesọ ọrọ naa fun awọn akọroyin, ti BBC Yoruba wa lara wọn, Sunday Igboho ni oun ko fẹ ipo oludari patapata fun ikọ Amotekun yika ilẹ Yoruba, ti wọn n yọ ọ naa.
O ni oun to jẹ oun logun bayii ni bi awọn ọdaran Fulani yoo se fi ilẹ Yoruba silẹ, ti alaafia yoo si jọba pada.
Sunday Igboho fulani ultimatum: Àwọn ará Kebbi àti Zamfara ló n jínígbé ní Oke Ogun- Serik
"N ko nilo ipo olori Amotekun tabi owo lọdọ ẹnikẹni tabi oloselu kankan.
Alaafia fun awọn Yoruba lo jẹ mi logun lasiko yii, kii se ipo rara."
Sunday Igboho wa rọ awọn gomina to n daba iyansipo naa lati mase fi oun jẹ oye naa.
Lootọ ni awọn kan lara awọn alatilẹyin Sunday Igboho ko fọwọ si igbesẹ naa, amọ sibẹsibẹ ọpọ wọn lo ti gba aba naa wọle gẹgẹ bi a ṣe gbọ.
Ikọ Amọtẹkun lawọn ijọba ẹkun iwọ oorun gusu orilẹede Naijiria gbe kalẹ lati koju gulegule awọn Fulani darandaran to n da omilẹgbẹ ọran kaakiri ẹkun naa.
Oríṣun àwòrán, Sunday Adeyemo
Saaju la ti mu iroyin wa fun yin pe Ajafẹtọ ọmọ Yoruba to lewaju lori ọrọ aawọ to da lori gulegule awọn Fulani si ẹya Yoruba, Sunday Igboho ti sọ pe, oun ko bẹru ihalẹ atimọle ti awọn alaṣẹ n daba rẹ.
Ninu fọnran fidio kan to lu ayelujara pa ni o ti sọ ọrọ yii, to si tun dupẹ fawọn agbaagba Yoruba fatilẹyin wọn.
Igboho sọ pe ''awọn darandaran ko le le wa kuro lori ilẹ wa, oju wa ti ṣi bayi, ayafi ti wọn ba fẹ pa wa lo ku''
O wa kesi awọn alatilẹyin rẹ lati mase kọ ẹnu eebu sawọn ọba alade ilẹ Yoruba.
Bakan naa ni Igboho n fọwọ gbaya pe ẹru ko ba oun rara lori asẹ ọga agba ọlọpaa to ni ki wọn mu oun wa.
Oríṣun àwòrán, @SundayIgboho2
''Ẹ maṣe tẹnbẹlu awọn ọba Yoruba wa tabi ki ẹ bẹnu atẹ lu wọn. Mo fi ogun bura, inu awọn naa ko dun si ohun to n sẹlẹ yii. Wọn ti n sọrọ soke bayii''
"O ni ""idi ree ti gbogbo wọn ati awọn olori ilẹ Yoruba fi dide pe ki wọn ma ṣe mu Sunday Igboho."""
''Ohun to bani ninujẹ ni bi wọn ṣe n ṣe wa baṣubaṣu, ti wọn n pa awọn ọmọ obinrin wa, ti awọn afurasi apaayan darandaran yii tun n fipa bawọn lo pọ.A ko le lọ si oko mọ, a ko le lọ sodo.O to gẹ!''
Bi a ko ba gbagbe laipẹ yi ni ọga patapata ọlọpaa Naijiria paṣẹ ki Kọmisana ọlọpaa ni ipinlẹ Oyo mu Sunday Igboho wa si Abuja lati wa jẹjọ.
Eyi waye lẹyin to lọ si Ibarapa lati lọ sọ fun olori awọn Fulani nibẹ pe ki wọn kuro nilẹ awọn laarin ọjọ meje.
Oríṣun àwòrán, https://www.instagram.com/sunday_igboho1/
Eekan ọmọ Yoruba nni, Oloye Sunday Adeyẹmọ, ti ọpọ mọ si Sunday Igboho, ti sọrọ fun igba akọkọ lyin to sabẹwo silu Igangan lọjọ Ẹti.
Sunday Igboho ṣalaye pe asiko to fawọn alakoso iṣejọba ni ilẹ Yoruba lati mọ pe, bi wọn ba kuna lati mojuto abo araalu to dibo fun wọn, ko si igba ti araalu o ni gbe ara wọn nija.
Oloye Sunday Igboho ṣalaye eyi ninu awọn atẹjade kan to fi sita loju opo Twitter rẹ, @SundayIgboho2
Igboho ni o ṣeni laanu pe awọn iwa ti aye rẹ o si fawọn ọmọ Yoruba to tẹdo si agbegbe miran lorilẹede Naijiria, ni wọn n fi n lọ Yoruba lori ilẹ won.
Oríṣun àwòrán, @SundayIgboho2
Oloye Igboho ni omilẹgbẹ awọn eekan ọmọ Yoruba lo ti jade laye nipasẹ awọn agbebọn darandaran Fulani, ninu eyi to ti darukọ gbajugba oniṣegun ibilẹ ni, ti ọpọ mọ si ọkọ Oloyun ati Ọmọwe Aborode.
"O ko lee ri ọmọ Yoruba ko lọ maa paniyan ni ipakupa nilu Kano.
Bi ọmọ Yoruba ba gba Hausa/Fulani loju, wọn lee tori rẹ bẹ ẹ lor,i ka to wa sọ pe ko ba nnkan oko jẹ"
O ni ko si nnkan ti ijọba tii ṣe lori gbogbo awọn ti awọn afurasi Fulani darandaran pa nilẹ Yoruba, sibẹ ojojumọ l'ẹmi n ṣofo si.
Oríṣun àwòrán, @SundayIgboho2
Igboho ni gbogbo awọn to n sọ ahesọ ọrọ kiri pe nitori owo, ipo abi gbajumọ loun se gbe igbesẹ naa, ko mọ iru eeyan ti oun jẹ ni.
O fikun pe gẹgẹ bi ọmọ agbegbe Oke Ogun ni ipinlẹ Ọyọ, asiko kan wa sẹyin to jẹ pe ifọkanbalẹ l'awọn eeyan fi n gbe aye wọn lagbegbe naa eleyii ti kori bẹẹ mọ bayii.
L'awọn igba naa a maa n pada lati oko nibii agogo kan oru laisi ibẹru tabi ikayasoke pe ẹnikan le e kọlu wa.
Oríṣun àwòrán, @SundayIgboho2
O ni nnkan o fara rọ mọ lagbegbe naa nitori gulegule awọn kọlọransi darandaran Fulani kan.
Sunday Igboho wa fi ọwọ gbaya pe idunkooko ileesẹ ọlọpaa ko le da jinni-jinni bo awọn eeyan ipinlẹ Oyo nitori o gba oun ni akoko ati igbaradi ki oun to gbe igbesẹ to lagbara yii, eyi to jẹ ipinnu to bọ sasiko.
Oríṣun àwòrán, @SundayIgboho2
O fikun pe igbesẹ́ naa waye nitori ara wa ati ọjọ ọla iran to n bọ.
Sunday Igboho: Àwọn olórí Fulani tọrọ àforíjìn, wọ̀n ń fẹ́ ibagbepọ̀ àlàáfíà ni Ibarapa
Oríṣun àwòrán, GALAXY TV
Awọn olori Fulani to n gbe ni agbegbe Ibarapa ati Oke Ogun ni ipinlẹ Oyo ti tọrọ aforijin lori iwakiwa tawọn eeyan wọn hu eyi to fa gbọnmisi omi o to nibẹ.
Wọn ṣe ipinu bakan naa lati faye gba ibagbepọ alaafia laarin awọn ati awọn alabagbe wọn.
Ọrọ yii wa lara ababọ ikọ ti ijọba ipinlẹ Oyo gbe dide lati ṣabẹwo si Ibarapa ati awọn agbegbe mii ni Oke Ogun.
Ninu atẹjade ti agbẹnusọ Gomina Oyo Taiwo Adisa fi sita, o ṣalaye pe igbimọ naa kan si Igangan, Tede and Ago Are ati ile Seriki Fulani ti wọn sọ ina si.
Ni Igangan ni awọn eeyan ilu ti tu kẹkẹ ọrọ silẹ nipa aburu ti wọn ni Seriki naa n hu ni iwa.
Oríṣun àwòrán, GALAXY TV
Akọwe ẹgbẹ idagbasoke Igangan, Lawal Akeem ni ọrọ Seriki ,Alhaji Saliu Abdukadir, ti su awọn ara ilu pẹlu bi ọwọ rẹ ko ṣe mọ ninu awọn ẹsun iwa ọdaran lorisirisi.
O fi kun pe awọn ara ilu ti san owo idoola to to aadọta miliọnu naira lọwọ awọn ajinigbe Fulani.
Bẹẹ lo ni lemolemọ awọn Fulani nipa biba oko awọn eeyan wọn to jẹ agbẹ jẹ, ati fifi ipa ba awọn obinrin lo pọ kọja afarada.
Ọdọ kan naa ni Ilu Igangan, Taiwo Adeagbo, gẹgẹ bi Fatai Adisa ṣe sọ, ni o kere tan obinrin mẹẹdogun lawọn Fulani ti fipa ba lopọ.
Oríṣun àwòrán, GALAXY TV
Gbogbo awọn ẹsun naa lo ṣeeṣe ko mu awọn Seriki Fulani Igbo Ora ati ti Eruwa, Alhaji Idris Abubakar, ati Alhaji Sule Mohammed, wa aforijin lọdọ ara ilu.
Wọn ni awọn ṣetan lati ṣiṣẹ pọ, ki alaafia le rinlẹ lagbegbe naa.
Ẹwẹ, awọn eeyan mii to sọrọ nibi ipade naa, bi oluranlọwọ pataki fun Gomina Makinde lori ọrọ aabo, Fatai Owoseni, parọwa sawọn olori ilu, awọn ọdọ Yoruba ati Fulani, lati yago fun iwa ipa, ki wọn si dijọ maa gbe pọ lalaafia.
Atẹjade naa ni Kọmisana ọlọpaa nipinlẹ Oyo ati awọn aṣoju mii ti ijọba yan, ni wọn jijọ kọwọrin ṣabẹwo sawọn ilu naa ni agbegbe Ibarapa ati Oke Ogun.
Oríṣun àwòrán, GALAXY TV
Lakotan,  o ni Kọmisana ọlọpaa ni orisirisi ọrọ lo ti n tankalẹ nipa iṣẹlẹ to n waye lawọn agbegbe yii ṣugbọn kii ṣe ootọ pe ijọba ko ṣe nkan si iṣẹlẹ ijinigbe ati ipaniyan to n waye nibẹ.
Atẹjade naa fikun pe ''awọn ti mu to afurasi ọdaran mọkanlelaadọta to lọwọ si awọn iwa aburu yii ati pe, awọn yoo ṣe iwadi to peye lori ẹsun ti wọn fi kan Seriki pe o n lẹdi apo pọ pẹlu awọn aṣebi''
African Eye: Wo Jane Mugo, obìnrin bíi ọkùnrin tó ń ṣiṣẹ́ ọ̀tẹlẹ̀múyẹ́ bíi James Bond
Isẹ atọpinpin tabi ọlọfintoto la mọ bii isẹ to wa fun awọn ọkunrin nitori ọpọ ewu to rọ mọ.
Gbogbo ẹni to ba si maa n wo sinima ilẹ okeere ni yoo ranti akikanju ọkunrin kan ti wọn n pe ni James Bond ati ọpọ ewu to maa n la kọja nidi isẹ ọlọfintoto to yan laayo ninu sinima.
Bẹẹ ni ọrọ ri pẹlu obinrin yii lorilẹede Kenya,m ti orukọ rẹ n jẹ Jane, ẹni ti isesi ati isẹ rẹ fara jọ ti James Bond.
Ọtẹlẹmuyẹ Jane Mugo ni ilumọọka osisẹ atọpinpin aladani to gbajumọ julọ lorilẹede rẹ, ti ẹnu kii si sin lara rẹ.
Jane ni ọkẹ aimọye iwa ọdaran ni oun ti wa ojutu si amọ lọna mii, o maa n se ofin tara rẹ, lọwọ ara rẹ.
Jane maa n lo oniruuru ọna lati sewadi iwa ọdaran, lara rẹ ni amulo ọmọlangidi, taa mọ si Teddy Bear ati aago ara ogiri.
Àwọn ìtàn mánigbàgbé tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí:
Ẹ wa nnkan fidi le lati wo fidio akọni obinrin yii, to n sisẹ akikanju bii ọkunrin, to si n ba ewu rin lai bẹru.
Sunday Igboho: Gani Adams ní dídákẹ́ òun lórí ìṣẹ̀lẹ̀ Igangan kìí ṣe ìwà ojo
Aarẹ Ọna kakanfo ilẹ Yoruba, Oloye Gani Adams ti leri leka, to si tọ ilẹ la pe gbogbo igbinyanju awọn ẹya kan lati sọ ilẹ Yoruba di ibudo ogun lawọn yoo tako.
Oloye Gani Adams jẹjẹ yii lasiko to n fesi lori ọrọ ti ẹgbẹ apapọ eeyan Arewa, ACF ati Miyetti Allah sọ pe ogun n bọ nitori atako ti wọn n se si ẹya Fulani lẹkun iwọ guusu Naijiria.
"Adams sisọ loju ọrọ yii ninu atẹjade kan ti amugbalẹgbẹ rẹ fisita eyi to pe akori rẹ ni ""Aifararọ eto aabo: Alawada ni ẹgbẹ ACF ati Miyetti Allah"""
Bẹẹ ba gbagbe, ẹgbẹ Arewa ati Miyetti Allah lo koro oju si awọn igbesẹ ti Sunday Igboho gbe, ti wọn si n pariwo pe ki ijọba gbe ti si ahamọ, bẹẹ ni wọn ni ogun le waye.
Oríṣun àwòrán, Iba Gani Adams
Amọ ninu ọrọ rẹ, Gani Adams ni alawada lasan ni ẹgbẹ mejeeji naa, bẹẹ si ni ko si irufẹ idunkooko to wu ki wọn se, ti oun ko ni fi daabo ilẹ Yoruba lọwọ awọn darandaran apaniyan.
"Yoo dara ki awọn ẹgbẹ mejeeji lati apa oke ọya naa sọ ọrọ ti wọn n sọ jade, bi bẹẹ kọ, wọn yoo ri ibinu ilẹ Yoruba.
Bi wọn se n sọ ọrọ arunilayasoke yii tumọ si pe ẹkun ariwa Naijiria n lu ilu ogun amọ a ko ni gba ki wọn sọ ilẹ Yoruba di ibudo ogun."
Sunday Igboho fulani ultimatum: Àwọn ará Kebbi àti Zamfara ló n jínígbé ní Oke Ogun- Serik
Aarẹ Ọna Kakanfo ilẹ Yoruba ni iwadi oun fihan fihan pe taa ba wo awọn ohun to n waye lori ayelujara lẹnu ọjọ mẹta yii, o ti foju han pe awọn ọta kan wa ninu ile ati nita ẹkun iwọ oorun guusu Naijiria.
"O ni ""awọn eeyan yii lo n lo iwa akọni Sunday Igboho lati dete iwa ibanilorukọ jẹ si mi, ti wọn si fẹ fi gbogbo iwa akikanju, laalaa ati aayan mi lati ọdun mejidinlọgbọn sẹyin sinu idanwo."""
Adams ni bi oun se dakẹ lati ọjọ mẹta sẹyin ko safihan pe ojo ni oun, amọ gẹgẹ bi ipo oun bii Aarẹ Ọna Kakanfo ilẹ Yoruba, o di dandan ki oun gbe igbesẹ lasiko to ba yẹ.
Bakan naa lo ni oun gbọdọ fikunlukun pẹlu awọn eeyan, ki oun to le gbe igbesẹ kankan.
Sunday Igboho: Fulani kò leè dúró, táa bá lo ohun ta jogún lọ́dọ̀ àwọ̀n bàbá wa
"Ohun ti Igboho sọ ko buru rara to ipe fun ogun abẹle ti ẹgbẹ Arewa ati Miyetti Allah lapapọ n pe, o si seni laanu pe ijọba apapọ dakẹ lai fọhun pẹlu isoro awọn darandaran apaniyan yii.
Iwadii ti fihan pe awọn ọmọ Yoruba to le ni ọọdunrun ni wọn ti jade laye lati ọwọ Fulani darandaran ni ọpọ agbegbe nilẹ Yoruba.
Bakan naa ni ọpọ ni wọn ti ji gbe salọ, tawọn ẹbi wọn si san owo ti apapọ rẹ le ni aimọye biliọnu naira gẹgẹ bii owo itanran."
Lawal Ayankemi Oluwatoyin: Mo kọ̀ láti máa tọrọ owó nítorí ojú mi tó fọ́, iṣẹ́ ló wù mí
Gani Adams kasẹ ọrọ rẹ nilẹ pe, lati igba ti awọn Fulani ti wọ ilẹ kaarọ Oojire lọdun 1818, ni wọn ti se ọpọ ijamba lẹkun iwọ oorun guusu Naijiria.
O ni o si foju han pe guusu Naijiria ni afojusun wọn, idi si ree to fi jẹ pe ẹnikẹni to ba tako awọn Fulani darndarn ti di ọta awọn eeyan ẹkun ariwa Naijiria.
Sunday Igboho: Bí Alaafin, Ooni, Olubadan ṣe tì mí lẹ́yìn fihàn pé ìrẹ́pọ̀ ti dé sáàrin Yorùbá
Eekan ọmọ ilẹ Yoruba to n lewaju ipe fun didẹkun wahala awọn darandaran nilẹ Yoruba, oloye Sunday Adeyẹmọ ti ọpọ mọ si Sunday Igboho tun ti sọrọ nipa isẹlẹ to waye naa.
Lọtẹ yii, Sunday Igboho ti kan sara si awọn lọbalọba ati agbaagba ilẹ Yoruba, ti wọn dide ṣi ọrọ wahala awọn darandaran Fulani nilẹ to n waye bayii.
O ni eyi fihan pe ilẹ Yoruba ti ṣetan lati kọ awọn igi aitọ tawọn ajeji n ki bọ ọ loju.
Ninu ọrọ to sọ ninu fidio kan to jade, lẹyin aṣẹ ọga ọlọpaa ni Naijiria, pe ki wọn fi panpẹ ofin mu u nitori wahala to waye ni gaa awọn Fulani lagbegbe Ibarapa, ni Igboho sisọ loju ọrọ naa.
Sunday Igboho: Fulani kò leè dúró, táa bá lo ohun ta jogún lọ́dọ̀ àwọ̀n bàbá wa
Sunday Igboho ṣalaye pe, iwuri nla lo fun oun pe awọn agba oriade bi Ooni ile Ife ki foonu mọlẹ, lati sọ fun aarẹ Buhari pe ina ti jo dori koko, ko saye mọ lati fi ọmọ Yoruba ṣe etutu Naijiria mọ.
Bakan naa lo ni Alaafin pẹlu ti kọ lẹta ikilọ lori ọrọ naa, ti Awujalẹ Ijẹbu, Olubadan tilẹ Ibadan ati Ataọja Oṣogbo naa ko si dakẹ lori isẹlẹ yii.
Igboho tun gbe oriyin fawọn eekan ọmọ bibi ilẹ Yoruba bii Oloye Oluṣẹgun Ọbasanjọ, Ọjọgbọn Wọle Soyinka ati Femi Fani Kayọde.
Sunday Igboho fulani ultimatum: Àwọn ará Kebbi àti Zamfara ló n jínígbé ní Oke Ogun- Serik
Bakan naa lo yonbo gomina ana ni ipinlẹ Ekiti, Ayodele Fayose, Dele Momodu ati Aarẹ Ọna Kakanfo, Iba Gani Adams fun bi wọn ṣe dide si ọrọ naa.
O wa rọ awọn ọmọ Yoruba gbogbo lati bọwọ fawọn agbagba ilẹ Yoruba nibi ti ọrọ naa de duro bayii.
Igboho ni o ti han gbangba pe awọn agbaagba pẹlu ti ji giri lati sa ipa gbogbo to yẹ fun aabo ati idagbasoke ilẹ Yoruba.
South West Governors-Miyetti Allah meeting: Àṣà dída ẹran níbikíbi di èèwọ̀
Koko mẹwa ti wọn fẹnu ko le lori nibi ipade awọn gomina ati Miyetti Allah
Ipade awọn gomina nilẹ Yoruba ati ẹgbẹ awọn darandaran Miyetti Allah ti waye lọjọ Aje, to si ti wa sopin pẹlu.
Atẹjade kan ti wọn fisita lẹyin ipade naa, salaye nipa awọn ohun tawọn gomina ilẹ Yoruba ati ẹgbẹ Miyetti Allah fi ẹnu ko le lori.
Atẹjade naa ti wọn fi sita nilu Akure nibi ti ipade naa ti waye Dokita Kayode Fayemi, tii se alaga ẹgbẹ awọn gomina lorilẹede Naijiria fọwọsi.
Aarẹ ẹgbẹ darandaran Miyetti Allah, Mohammed Kirowa to bawọn to peju sibi ipade to n waye ni ọfiisi Akeredolu lọwọ lọwọ bayii, naa ti sọrọ nipa iwa ika tawọn darandaran n hu.
Kirowa lasiko to n ba ipejọpọ awọn ọlọpaa ati gomina ilẹ Yoruba sọrọ sọ pe awọn daran-daran ti pa awọn Fulani naa ri.
Kii ṣe awọn agbẹ nikan ni wọn n pa, wọn n pa awọn Fulani naa, koda, ọpọlọpọ Fulani ni wọn ti ji gbe, ti wọn pa. Gbogbo rẹ si la koro oju si.
Bakan naa ni Korowa fikun pe Baba oun ti wa ni ilẹ Yorùbá lati ọdun marunlelọgọrun sẹyin, ilẹ Yoruba si ni wọn fi ori oun sọlẹ si.
Ipade apero ti n lọ lọwọ nilu Akure laarin awọn gomina ilẹ Yoruba ati awọn adari ẹgbẹ daran-daran, Miyetti Allah.
Ipade naa ko ṣẹyin bi gomina Rotimi Akeredolu ṣe fun awọn afurasi ọdaran daran-daran to n ṣọṣẹ ni inu igbo nipinlẹ Ondo, ni gbedeke lati kuro nibẹ.
Ọjọ Aiku, ọjọ kẹrinlelogun, oṣu Kinni, ọdun 2021, ni gbedeke naa pari.
Aṣẹ naa waye nitori bi awọn daran-daran kan ṣe n fi iṣẹ wọn boju ṣiṣẹ ibi, ti wọn n pa eeyan, ji eeyan gbe, digun jale, ti wọn si tun n fipa ba obinrin lopọ.
Nigba to n sọrọ nibi ipade naa, Gomina ipinlẹ Ekiti, Kayode Fayemi sọ pe ko si ẹni to fẹ ẹ le awọn Fulani kuro nilẹ Yoruba.
"O ni ""Ko si ẹni to fẹ ẹ le Fulani jade kuro nilẹ yoruba, ile yin re e ."
Awọn ọdaran la fẹ ẹ le jade kuro laarin awọn daran-daran Fulani, kii ṣe lati le awọn Fulani to ti n gbe nibi fun ọpọlọpọ ọdun.
Lara awọn to peju sibi ipade naa ni awọn olori ileeṣẹ eto aabo nipinlẹ Ondo, ati awọn ipinlẹ to mu le tii.
Wamu-wamu ni awọn oṣiṣẹ eleto aabo naa duro sibi ipade naa
Ṣaaju ipade naa, Gomina Akeredolu, Kayode Fayemi ti ipinlẹ Ekiti, ati akẹẹgbẹ wọn lati ipinlẹ Jigawa, Abubakar Badru pẹlu Abubarka Bagudu ti ipinlẹ Kebbi, ti ṣe ipade ikọkọ kan.
Gomina Seyi Makinde, Gboyega Oyetola, Rotimi Akeredolu, Kayode Fayemi, ati awọn adari ẹgbẹ Miyetti Allah
Sunday Igboho: Ọkọ̀ bọ́ọ́sì àti Taxi láwọn jàǹdùkú tó jólé gbé wá
Ileesẹ ọlọpaa ipinlẹ Oyo ti kede pe oun ti gba abọ awọn osisẹ oun nipa isẹlẹ bi ina se jo ile Oloye Sunday Igboho.
Agbẹnusọ fun ileesẹ ọlọpaa ipinlẹ Oyo, Olugbenga Fadeyi, lo fidi isẹlẹ naa mulẹ ninu atẹjade kan lọjọ Isẹgun
Ileesẹ ọlọpaa ni iroyin to tẹ oun lọwọ lo fidi rẹ mulẹ pe awọn janduku to wa jo ile Igboho lo wa pẹlu ọkọ bọọsi ati taxi.
Agbẹnusọ fun ileesẹ ọlọpaa Oyo fikun pe awọn janduku naa yinbọn soke ni ọpọ igba, ki wọn to jo ile Igboho to wa ladugbo Soka, nilu Ibadan.
O fikun pe ileesẹ ọlọpaa ipinlẹ Oyo ti bẹrẹ iwadi kikun nipa isẹlẹ naa, eyi to waye ni deede aago mẹta oru
Ikọ iroyin BBC Yoruba ti balẹ sile ajafẹtọ iran Yoruba nni, Oloye Sunday Igboho ti ile rẹ jona mọjumọ ọjọ Aje.
Abẹwo BBC Yoruba si ile to jona ọhun fihan pe laarin aago meji si mẹta oru ni isẹlẹ ọhun waye.
A tun gbọ pe ile to jona naa jẹ ile atijọ Sunday Igboho, eyi to ti gbe tẹlẹ ri, to si wa ni adugbo Soka nilu Ibadan, nibi to sunmọ ile to n gbe lọwọ lọwọ.
Ọkan lara awọn olugbe adugbo ti Sunday Igboho n gbe tẹlẹri ni agbegbe Soka sọ fun BBC Yoruba wi pe, awọn eeyan kan lo dede wa dana sun apa ibi kan ninu ile naa.
Wọn fi idi ọrọ mulẹ wi pe, o to ọkọ mẹta ọtọọtọ ti awọn eeyan to sisẹ ibi yii gbe wa, lati dana sun ile naa.
Lara nnkan ti wọn ri lẹyin iṣẹlẹ naa lẹba ile to jona ọhun ni kẹẹgi epo bentiro ati awọn ọta ibọn.
Bakan naa ni iwadii fi idiẹ mulẹ wi pe, ẹmi ẹnikẹni ko ba iṣẹlẹ naa lọ, bi o tilẹ jẹ pe ọpọ dukia to wa ninu ile naa lo jona kanlẹ.
Pupọ ninu awọn to n gbe ile naa tẹlẹri, ni wọn ti ko lọ si ile tuntun nibi ti Sunday Igboho ko lọ ni agbegbe Soka bayiii.
Oríṣun àwòrán, Koikimedia
Saaju la ti mu iroyin wa fun yin pe ijamba ina ti waye ni ile gbajugbaja ajafẹtọ ọmọ Yoruba nii, Oloye Sunday Adeyemo, ti gbogbo eeyan mọ si Sunday Igboho.
Ile Igboho naa lo wa ni adugbo Soka, nilu Ibadan.
Ijamba ina yii, gẹgẹ ba se gbọ, waye lọjọ Aje tawọn Gomina iwọ oorun guusu ilẹ yi fẹnuko lẹyin ipade to waye ni Akure, pẹlu awọn olori Fulani lati dẹkun wahala to n waye lagbegbe naa
Ohun to ṣokunfa ina yi ko ye ẹnikankan ṣugbọn ninu fọnran fidio kan ti BBC Yoruba ri, niṣe lawọn eeyan kan n ṣe afihan bi ina ti ṣe jo ile naa, to si ba ọpọlọpọ duki Sunday Igboho jẹ.
Oríṣun àwòrán, Koikimedia
Bi o tilẹ jẹ pe a ko tii le fi aridaju fidio yii mulẹ ṣugbọn gẹgẹ bi awọn ohun to wa ninu rẹ ti sọ, lẹyin ti ina ọba lọ ni alẹ ọjọ Aje ni isẹlẹ ina ṣadede ṣẹyọ nibẹ.
Wọn ni awọn panapana lo sare wa lati dẹkun ina naa ṣugbọn ko si aridaju pe eeyan kankan farapa tabi ku ninu ijamba ina yii.
Loju opo Sunday Igboho yala ni Instagram tabi Twitter ko ti fi ọrọ sita nipa iṣẹlẹ yii.
Ni kete ti a ba ti ri aridaju bi ijamba ina naa ṣe waye, a o fi to yin leti, ẹ maa ba wa kalọ.
Sunday Igboho: Ojudu tó pè mí ní tọ́ọ́gì kò lówó mi lọ́wọ́, mo kọjá ẹni tí wọn ń fi owó dí lẹ́nu
Oríṣun àwòrán, Instagram/Sunday Igboho
Gbajugbaja ajijagbara ọmọ Yoruba, Sunday Adeyemo ti ọpọ mọ sí Sunday Igboho ti sọ pe, ọrọ ijijagbara fún Yoruba ti oun wa lori rẹ ti di odo to n ṣan ti ko le boju w'ẹyin mọ bayii.
Nigba to n fesi sí ọrọ ti Sẹnatọ Femi Ojudu sọ nipa rẹ ninu ifọrọwerọ pẹlu ileesẹ mohunmaworan kan, ti fidio rẹ lu ori ayelujara pa,  ni Igboho ti fesi bẹẹ.
Babafemi Ojudu lo ni Tinubu fun Sunday Igboho lowo pe ko ma da rogbodiyan silẹ lasiko idibo Gomina ipinlẹ Ekiti, Igboho ni isọkusọ gbaa ni Sẹnatọ Ojudu n sọ lẹnu.
Koda Igboho ke pe Ọgbẹni Ojudu wi pe ko fi ọmọbibi inu rẹ bura ti o ba dáa lójú pe, oun gba owo lọwọ rẹ ni tootọọ.
Sunday Igboho ni ọna lati da omi tutu si oun lọkan lori ọrọ ijijagbara fun iran Yoruba ni isọkusọ ti Sẹnatọ Ojudu n sọ kiri.
Oríṣun àwòrán, Sunday Igboho
Ṣugbọn baalu to ti fo ni wọn n juwọ si, ni ọrọ ijijagbara fun Yoruba da bayii, Igboho ṣalaye.
Igboho ni ọpọ oloṣelu Io ti ranṣẹ si oun pe ki oun maa fa wahala pẹlu awọn Fulani darandaran nitori ibo ọdun 2023.
Amọ, Igboho ni oun ti oun n fẹ ni pe ki gbogbo nkan pada bọ sipo nilẹ Yoruba.
O ni bamu bamu laa yo lawọn oloṣelu bi Sẹnẹtọ Ojudu n ṣe nilẹ Yoruba nigba ti nkan ko fara rọ fun ọpọlọpọ eeyan nilẹ Yoruba.
Sunday Igboho: N kò fẹ́ oyè ọ̀gá àgbà páta fún ikọ̀ Amotekun nílẹ̀ Yorùbá
Awọn Fulani n pa awọn eeyan wa, awọn to ka iwe ko ri iṣẹ ṣe, awọn obinrin wa ti di aṣẹwo nitori airiṣẹ ṣe, Igboho lo sọ bẹẹ.
Ọgbẹni Adeyemo sọ pe, owo tó yẹ ki àwọn oloṣelu fi tọju awọn ọmọ Yoruba ni wọn n ko lọ si oke okun.
Femi Ojudu gan an to n sọrọ ko lowo lọwọ to mi, mo kọja ẹni ti ẹ le fi owo di lẹnu, Igboho ṣalaye.
"Igboho ni oun ko ""lọmọ tabi iyawo ni Naijiria ti Fulani fẹ jigbe, amọ iran Yoruba ni mo n ja fun."""
"Ọgbẹni Adeyemo ni ""eto abo to mọyan lori lo jẹ mi logun kaakiri ilẹ Yoruba, to ba jẹ ti emi nikan ni, miliọnu kan Fulani ko le da mi lọna."""
Sunday Igboho: Fulani kò leè dúró, táa bá lo ohun ta jogún lọ́dọ̀ àwọ̀n bàbá wa
Ẹyin oloṣelu, ẹyin naa mọ pe mo mọ gbogbo aṣiri yin lori bi ẹ ti n ko gbogbo owo to yẹ ki ẹ fi pese eto abo to peye nilẹ Yoruba, tori naa, ẹ lọ ṣọra yin o, Igboho kìlọ.
Ọgbẹni Adeyemo ni Sẹnẹtọ Ojudu ko le sanwo oun ti oun ba fẹ ṣe tọọgi lẹyin rẹ.
Koda o fikun ọrọ rẹ pe, Sẹnẹtọ Ojudu ko ní irú awọn ọkọ bọginni to wa lagbala oun, ki wa lo de to fi n ba oun ni orukọ jẹ kiri.
Ajafẹtọ ọmọ Yoruba nni, Sunday Igboho ti fesi si awọn koko ọrọ ti gbajumọ akọroyin ati oloselu kan, Babafemi Ojudu kọ nipa rẹ.
Ojudu, tii se oluranlọwọ pataki si aarẹ Muhammadu Buhari lo kọ apilẹkọ kan sita nipa Sunday Igboho lọjọ Aje, eyi to dabi ẹni ta epo si asọ aala ajafẹtọ Yoruba naa.
Ojudu lo sọrọ nipa awọn ajọsepọ Sunday Igboho ati agba oselu ninu ẹgbẹ oselu APC, Bola Ahmed Tinubu, eyi to fẹ jẹ ọrọ asiri laarin awọn mẹtẹẹtẹ.
Amọ nigba to n fesi sawọn ohun ti Ojudu kọ nipa rẹ, Igboho ni gbogbo ọgbọn ti Ojudu ati awọn to ran nisẹ yii n da nipa oun, pabo ni yoo ja si.
Sunday Igboho fulani ultimatum: Àwọn ará Kebbi àti Zamfara ló n jínígbé ní Oke Ogun- Serik
O ni oun fẹ ki Ojudu sọra ṣe nitori ko si ootọ ninu ọrọ to n sọ pe oun gba owo lọwọ oloṣelu kankan.
''Nitori 2023 ni Ojudu ati awọn to n ran niṣẹ fi fẹ ba ilẹ Yoruba jẹ. Ati ojudu ati awọn to ran niṣẹ, Ọlọrun ko ni fun wọn ṣe''
"''Mo fẹ fi da gbogbo eeyan loju pe, oloselu meji pere ni mo ba se, awọn naa ni oloogbe Lam Adesina ati Sẹnetọ Rashidi Ladoja."""
African Eye: Wo Jane Mugo, obìnrin bíi ọkùnrin tó ń ṣiṣẹ́ ọ̀tẹlẹ̀múyẹ́ bíi James Bond
"Igboho ni ""Ojudu mẹnuba pe mo lọ ba baba Adedibu lọdun 2009 amọ eyi fihan pe irọ lasan ni ọkunrin yii n pa nitori ọdun 2008 ni baba Adedibu jade laye."
Ninu ọrọ apilẹkọ yii, Ojudu ni agba oloṣelu ilẹ Yoruba kan fun Sunday Igboho lowo lati maṣe da atundi ibo Gomina ru nipinlẹ Ekiti lọdun 2009.
Koko to wa ninu ọrọ ti Babafemi Ojudu sọ nipa Sunday Igboho ati Tinubu niyi:
Oríṣun àwòrán, BBC Sport
Saaju la ti mu iroyin wa fun yin pe, Sunday Igboho, tii se gbajugbaja ajafẹtọ Yoruba, ti awọn kan lọ dana sun ile rẹ ni adugbo Soka ni Ibadan, ti sọrọ lori isẹlẹ naa.
Sunday Igboho, lasiko to n bawọn akọroyin sọrọ, ninu eyi ti BBC Yoruba wa lara wọn lo ti kede pe, o jẹ iyalẹnu fun oun pe awọn Yoruba kan n lẹdi apo pọ pẹlu awọn Fulani lati maa tako oun.
Igboho sọ pe ''o jẹ iyalẹnu fun mi pe awọn Yoruba gan lo wa n pete pero pẹlu awọn Fulani darandaran lati wa sọ ina si ile mi.'
Ile mi ti wọn jo nina naa si dun mi gidigidi amọ eyi ko ni da omi tutu si mi lọkan lati ja fun iran Yoruba.
O fikun pe apapọ awọn dukia ti ina ọhun baana yoo to aadọta miliọnu naira.
Igboho ni ohun ti oun n ja fun ni pe ki ijinigbe ati ipaniyan lati ọwọ awọn ọdaran Fulani yii wa sopin nilẹ Yoruba.
O fikun pe oun ko ni dakẹ titi ti awọn ọdaran Fulani naa ba kuro nilẹ Yoruba.
Nigba tawọn akọroyin beere lọwọ rẹ pe, ta lo fura si pe o le wa nidi iṣẹlẹ ina naa, Ajafẹtọ ilu ọhun ni oun ko le darukọ ẹni kankan ṣugbọn ''bi iku ile ko ba pani ti ode o le pani''
''Ti ko ba lọwọ awọn Yoruba kan ninu...ki lo de ti wọn ko ṣe wa ba mi, ti wọn ba mọ wi pe awọn le ja? Sebi ile mi ni mo wa?
Ti wọn ba mọ pe awọn to bẹẹ, ti wọn si lagbara, wọn ko ba wa ba mi ninu ile ti mo n gbe, a wa mọ ẹni to jẹ ọkunrin laarin wa.
N ko ni oju opo Twitter ati Facebook, awọn ayederu oju opo ni wọn n si kiri lorukọ mi - Igboho
Wayi, Sunday Igboho ti kede fun gbogbo aye pe oun ko ni oju opo Twitter rara tabi Facebook rara.
Igboho, lasiko to n bawọn akọroyin sọrọ ni awọn ayederu oju opo Facebook ati Twitter ni awọn alaida kan si lorukọ oun lati fi maa tu awọn eeyan jẹ.
Oríṣun àwòrán, @SundayIgboho2
''Gbogbo nkan ti ẹ ba ri nibẹ, ẹ sọra se pẹlu wọn, mi o ni oju opo Facebook tabi Twitter kankan''
O ni irọ ni gbogbo ohun tawọn eeyan n ka nipa oun lawọn oju opo ikansiraẹni naa.
O wa rọ awọn eeyan pe ki wọn ma ṣe tẹle ọrọ to wa nibẹ nitori oun ko ni oju opo kankan.
Amope Onibata: Kìí ṣe gbogbo ọkùnrin ló gbà kí ń ṣe bàtà fún àwọn
Ori lo mọ isẹ asela, ohun ti ọkunrin ba si se, obinrin naa le se daradara nigba mii.
Bẹẹ ni ọrọ ri pẹlu akẹkọjade fasiti ipinlẹ Ekiti, Olamide Adeyemi, ti ọpọ eeyan mọ si Amope Onibata.
Olamide, lasiko to n ba BBC Yoruba sọrọ salaye pe iyansẹlodi ẹgbẹ awọn olukọ fasiti lo mu ki oun gbero lati kọ isẹ bata sise, ti oun si le se oniruuru bata bayii.
O ni oun kọkọ bẹrẹ isẹ naa nipa biba awọn ọlọpa dan bata wọn pẹlu pọlisi, ti oun si n ri owo nibẹ
Amope Onibata ni oun maa n se idanilẹkọ fun awọn obinrin ati ẹlẹgbẹjẹgbẹ lọfẹ fun ọsẹ meji tabi ju bẹẹ lọ lati se iwuri fun wsn nipa isẹ bata sise.
Àwọn ìtàn mánigbàgbé tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí:
Akẹkọjade fasiti naa wa rọ awọn obi lati jẹ kawọn ọmọ wọn kọ isẹ ọwọ mọ iwe, ki wọn si tun se iwuri fun wọn lori isẹ ti wọn ba yan laayo naa.
Imo ESN-Soldiers Crisis: Gómìnà Uzodinma kéde kónílé ó gbélé ní Orlu
Oríṣun àwòrán, Other
Awọn ọmọ ikọ alaabo Eastern Security Network, ESN atawọn ọmọogun Naijiria gbe ina woju ara wọn nilu Orlu ni ipinlẹ Imo, nigba ti eruku rẹ yoo si fi rolẹ, ẹmi eeyan ti bọ, ọpọlọpọ lo si tun fara ṣese.
Eyi lo mu ki gomina ipinlẹ naa, Hope Uzodinma gbe aṣẹ konile o gbele kalẹ laarin agogo mẹfa owurọ si mẹfa irọlẹ, kaakiri gbogbo ijọba ibilẹ to wa lagbegbe Orlu.
Awọn agbegbe ti ọrọ naa kan ni Orlu, Orsu, Oru East, Oru West, Ideato North, Ideato South, Njaba, Isu, Nwangele ati Nkwerre.
Eyi n waye lẹyin ti fidio wahala to ṣẹlẹ laarin awọn ọmọ ẹgbẹ agbebọn ESN naa atawọn agbofinro lu igboro.
Gomina Uzodinma ṣalaye ninu atẹjade kan pe, alaafia ti pada jọba lagbegbe Orlu bayii lẹyin ti wọn ko awọn agbofinro lọ sibẹ.
Oríṣun àwòrán, Other
Oniruru iroyin lo n tẹ ileeṣẹ BBC lọwọ lori ohun gan to fa wahala naa; bi awọn kan ṣe n sọ pe  laarin awọn ọmọ ẹgbẹ IPOB atawọn ologun ni laasigbo naa ti waye.
Amọ awọn eeyan miran n sọ pe awọn ole lo n ṣọṣẹ.
Gomina ipinlẹ naa ti ke sawọn agbofinro lati ṣawari awọn to wa nidi rukerudo naa.
Sunday Igboho fulani ultimatum: Àwọn ará Kebbi àti Zamfara ló n jínígbé ní Oke Ogun- Serik
Bi wahala naa ṣe bẹrẹ:
Awọn ileeṣẹ iroyin abẹle kan ṣalaye pe, lọjọ Ẹti ni itaporogan ibọn yinyin ti kọkọ bẹrẹ laarin awọn ologun atawọn ọmọ ikọ Eastern Security Network [ESN] ti Nnamdi Kanu gbe kalẹ laipẹ yii.
Iroyin tun sọ pe ilu Okporo lagbegbe Orlu ni wahala naa ti bẹ silẹ, ko si din ni ile marun un, to fi mọ awọn ṣọ̀ọṣi
Blessed Holy Trinity Sabbath Mission, ni ijọba ibilẹ Orlu, ti wọn dana sun.
Bakan naa, ni iro ibon tun dun lakọlakọ lagbegbe Bank Road, Orlu lọjọ Aje,
ti ipaya si n jọba lagbegbe naa bayii.
Ibrahim Attahiru: Àjọṣepọ̀ wò ló wà láàrin ọgagun tuntun Attahiru, Buratai àti Shekau?
Oríṣun àwòrán, AFP
Lara awọn ọgagun ileeṣẹ ologun Naijiria tuntun ti aarẹ Buhari yan sipo, ọkan wa lara wọn tawọn eeyan n ran ọrọ rẹ lẹnu.
Ẹni taa n wi yi ni ọgagun Ibrahim Attahiru.
Ṣaaju iyansipo rẹ, oun ni adari ikọ ọwọ keji ọmọ ogun ilẹ wa (82 Division) ni ileeṣẹ ologun Naijiria.
Amọ loju opo ayelujara, awọn eeyan ko dakẹ lori ọrọ rẹ paapa ibaṣepọ ati ohun to ti waye sẹyin laarin rẹ ati ọga to gba ipo lọwọ rẹ Tukur Buratai.
Lọdun 2017 wọn yan sipo lati koju ikọ Boko Haram gẹgẹ bi adari Operation Lafiya Dole, ti wọn fi n gbogun ti ikọ mujẹ mujẹ Boko Haram.
''Ri wi pe o mu oku tabi aaye Shekau wa laarin ogoji ọjọ''
Aṣẹ yii ni ọgagun Tukur Buratai pa fun ọgagun Attahiru ni ọdun 2017 to yan an sipo adari ikọ idoju ija kọ Boko Haram naa.
Oríṣun àwòrán, @HQNigerianArmy
Awọn ologun ti kọkọ se eto abo kogberegbe Python dance ati Crocodile Smiles
Iyansipo yii ko so eso rere fun Attahiru nitori asiko to gba iṣẹ yi ni Boko Haram wa bẹrẹ si ni sooro ju ti tẹlẹ lọ.
Lara awọn nkan ti Boko Haram da lara ni pe, wọn ṣigun lọ si olu ilu ipinlẹ Borno, Maiduguri.
Lasiko taa n wi yii, Boko Haram pa eeyan aadọta ni Mọṣalaṣi loṣu Kọkanla ọdun 2017.
Oríṣun àwòrán, State house
Losu Keje ọdun 2017 bakan naa ti Attahiru wa lori ipo, awọn eeyan to le ni ogoji padanu ẹmi wọn lasiko tawọn ọmọ ogun n gbiyanju lati doola awọn ti Boko Haram ji gbe.
Lara awọn to ba iṣẹlẹ yii lọ ni awọn ọmọ ogun ati awọn ikọ to n ṣe iwadi nipa pipọn epo rọbi lagbegbe Borno.
Ko tan sibẹ, iṣọwọ lo awọn to de ado oloro mọra ati yiyin ado oloro lu awọn ọmọ ogun lasiko ti Attahiru wa lori oye peleke si ju ti tẹlẹ lọ.
Eyi to jẹ pabanbari ọrọ yii ni pe, Attahiru ko ri olori ikọ agbesunmọmi Shekau mu titi ti gbedeke ti ọga rẹ Tukur Buratai fun fi pe.
Amọ awọn kan woye pe iṣẹ ti wọn gbe le lọwọ naa jẹ eyi ti yoo ṣoro lati ṣe nitori awọn to ṣaaju rẹ naa ko ri Shekau mu.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ọmọ ogun mẹjẹ lati orilẹẹde Naijiria ati Cameroon ni wọn padanu ẹmi wọn ninu ikọlu naa
Nicholas Rogers ni ọgagun to gba ipo naa lọwọ rẹ nigba ti wọn yọ kuro.
Ninu ọrọ idagbere rẹ, ọgagun Attahiru sọ pe awọn ribi pa awọn ọgagun Boko Haram marun un ati awọn ọmọ ogun rẹ aadọta .
Nigba ti wọn yọ kuro, ileeṣẹ ologun ko sọ idi ti wọn fi yọ sugbọn wọn gbe kuro lati lọ di ipo mii mu, ti wọn ko kọkọ sọ ipo to jẹ nigba naa.
Pẹlu ohun to ti waye sẹyin pẹlu ọgagun Attahiru, ọga rẹ tẹlẹ Tukur Buratai ati olori ikọ Boko Haram Abubakar Shekau, ibeere tawọn eeyan beere ni pe ṣe yoo ribi dẹkun Boko Haram?
Igba diẹ lo ku ti ijọba aarẹ Buhari yoo lo lori oye nitori naa awọn eeyan ti n sọ pe o le maa ribi ṣe iṣẹ daada depo pe yoo dẹkun Boko Haram.
Sunday Igboho: OPC fẹ́ k'awọn oríadé Yorùbá parí aáwọ̀ láàrín Igboho àti Seyi Makinde
Oríṣun àwòrán, Facebook/Seyi makinde
Yoruba ni agba kii wa lọja, ki ori ọmọ tuntun wọ
Eyi lo mu ki ẹgbẹ apapọ ọmọ Oodua, OPC fi n kesi awọn lọbalọba ilẹ Yoruba pe ki wọn wa ọna lati pari aawọ to n waye laarin Gomina Seyi Makinde ati Sunday Igboho.
Arọwa naa ni OPC, ẹka tipinlẹ Oyo fi sita fun awọn akọroyin lẹyin ipade wọn kan to waye nilu Ibadan.
Alaga ẹgbẹ OPC ni ipinlẹ Oyo, Rotimi Olumo ni ''o ṣe pataki lati wa wọrọkọ fi ṣada pẹtu aawọ naa, paapa lasiko yii tilẹ Yoruba n koju ipenija aabo lọwọ awọn darandaran Fulani''
Oríṣun àwòrán, OPC
Olumo ni ṣiṣe atunto eto aabo ṣe pataki ati pe idunkoko mọ Igboho ko le seso rere nitori eyi kii ṣe ọna abayọ si ọrọ to wa nilẹ naa.
''Abẹwo Igboho si Igangan jẹ igbesẹ to tọ, a ko si gbọdọ fi da wahala silẹ laarin rẹ ati aarẹ Ọnakakanfo ilẹ Yoruba''
O fi kun pe ''Sunday Igboho ti ṣe iṣẹ ribiribi lati mu alaafia ba ilẹ Yoruba, awọn lọbalọba wa ni lati bẹnu atẹ lu iwa aburu ọwọ awọn Fulani, wọn ko si gbọdọ jẹ ki wọn bori wa''
Sunday Igboho: Fulani kò leè dúró, táa bá lo ohun ta jogún lọ́dọ̀ àwọ̀n bàbá wa
Bakan naa ni Olumo bẹnu atẹ lu bawọn kan ti ṣe lọ fina si ile Igboho to wa ni agbegbe Soka.
O wa kesi awọn alaṣẹ lati ri wipe gbogbo awọn to mọ nipa iṣẹlẹ ọhun foju wina ofin.
Sunday Igboho: Lóòtọ́ọ́ ní Bola Tinubu fún mi ní ₦2m láti máṣe dá sí ìbò Mimiko l‘Ondo
Oloye Sunday Adeyemo, ti ọpọ eeyan mọ si Sunday Igboho ti salaye nipa ajọsepọ to ni pẹlu asaaju ẹgbẹ oselu APC, Oloye Bola Ahmed Tinubu.
Igboho, lasiko to n kopa lori eto kan lori ayelujara ti agba akọroyin, Dele Momodu se agbatẹru rẹ, lo ti salaye nipa ohun to da oun ati Tinubu pọ.
Igboho ni lootọ ni oun lọ sepade pọ pẹlu Tinubu nile rẹ to wa ni Bourdillion nilu Eko nitori Sẹnetọ Rashidi Adewolu Ladoja to jẹ baba fun oun lo pasẹ pe ki oun lọ.
Ajijagbara fun ilẹ Yoruba naa ni lasiko ti eto idibo gomina fẹ waye nipinlẹ Ondo, ti Olusegun Mimiko ti kopa ninu rẹ, ni isẹlẹ naa waye.
O salaye pe lasiko ipade naa ni Tinubu sọ fun mi pe n ko gbọdọ se atilẹyin fun ẹgbẹ oselu PDP lasiko eto idibo naa nitori iwa aidaa ti wọn hu si Ladoja, to jẹ baba fun oun.
"Igboho ni ""N kò gbà owó lọwọ Tinubu rí àmọ́ o fún mi ní miliọnu meji naira lasiko abẹwo mi naa,pe kí n fi ra epo sì moto."
"Iya ti PDP fi jẹ ladoja ní ko jẹ ki n sisẹ fun PDP, mo sì ṣe ohun tí Tinubu fe ki n se lasiko naa."""
Igboho, lasiko to n salaye iru agbara to ni sọ pe lootọ ni agbara wa nilẹ Yoruba, amọ awọn alaisootọ kan lo n mu ebu ẹyin ba a.
"Yoruba ni oogun lọwọ. Onirọ tí pọ ni kò jẹ ka naani nnkan ta ni. Ologun kii se ìkà báwọn Musulumi ati Kristiẹni tí lérò rẹ.
Ọlọ́run dá èwe àti egbò, Ọlọrun lo máa ń fún èèyàn, tí èèyàn kò bá ti sí lo."
Nigba to n salaye iru ajọsepọ to ni pẹlu Rashidi Ladoja, Igboho ni baba oun lo jẹ, tori ọdọ rẹ ni oun de si lẹyin ti ogun Modakeke ati Ife pari, ninu eyi ti oun ti kopa.
"Lootọ ni n kii ba oloselu se amọ mo ba awọn mẹta kan se pupọ. Ladoja, bàbà dáadáa ni, mo fẹran wọn, kìí yẹ àdéhùn.
A jọ dúró tì ara wa. Mo tẹ́lẹ̀ Lam Adesina fún ọdún kan, àti Ladoja. Mo tún bá Oyinlola ṣe ni Osun."
Nigba to n dahun ibeere lori ibasepọ rẹ pẹlu gomina ipinlẹ Oyo, Enginia Seyi Makinde ati idi ti aarin wọn ko fi gun, Igboho ni eyi ko ri bẹẹ rara.
"Èmi àti Makinde, ibasepọ  wá dán moran. Ladoja ni mo n tẹle. Ibi tí kò ba lọ, n kii lọ. Makinde lo ba mi sí ilé mi tó jọna.
Ó tún fún mi ní ẹrọ amunawa alagbara 500KVA lati gbe mi larugẹ ni adugbo ti mo n gbe, bẹẹ ni Ladoja lo pasẹ fun wa pe ka dibo fún Seyi
Makinde, ta si sisẹ fún wọn lọjọ idibo.
Èmi kii se gìrì mọ oloselu miran lẹyin Ladoja. Ń ko dalẹ rẹ rí, ohun ti ko bá lọwọ sì, èmi kii se.
Ọpọ lo fi owó lọ mi àmọ́ mo kò ọ, n ko le kúrò lẹyin Ladoja bo tilẹ jẹ pe a ko se oselu mọ."
Oloye Sunday Igboho tun mẹnuba bi aarin oun ati Aarẹ Ọna Kakanfo tilẹ Yoruba, Iba Gani Adams ti ri lasiko yii.
O ni kò sí nkankan bíi ìjà laarin oun àti Gani Adams, awọn si jọ ń ṣiṣẹ ohun tó ń ṣẹlẹ̀ yìí ni.
O fikun pe Gani Adams gan ti ke sita lori bawọn ọdaran kan laarin awọn Fulani se n huwa ika nilẹ Yoruba, eyi ti ko ba oun naa lara mu rara.
Òun náà tí sọrọ tako ìwà àwọn darandaran yìí, a si dijọ n sisẹ pọ ni, ko si ija rara laarin wa.
Lori ajọsepọ rẹ pẹlu ajijagbara fun ilẹ Igbo, Nnamdi Kanu, Sunday Igboho salaye pe oun kò mọ Nnamdi Kanu rí rara, bẹẹ ni ko si ajọsepọ kankan laarin awọn.
"Mo kọ ila soju, ọmọ Yoruba ni mi, mo maa n dọbalẹ ki awọn iya ati baba mi ni, èdè àti àṣà emi ati Kanu kò papọ rara.
Koda, ako sọrọ si ara wa ri, kò sì sí ajọseps kankan pẹlu emi ati Kanu rara.
Lakota, Igboho tun leri leka pe oun si duro lori ipinnu oun pe awọn ọdaran Fulani gbọdọ fi ilẹ Yoiruba silẹ ni, ki alaafia le jọba, ki oun to sinmi.
Sunday Igboho: Gani Adams yòǹbó àwọn gómìnà Yorùbá lórí ìpìnnu ìpàdé wọn pẹ̀lú darandaran
Oríṣun àwòrán, Iba Gani Adams
Aarẹ ọna Kakanfo nilẹ Yoruba, Oloye Gani Adams tun ti sọrọ nipa awọn isẹlẹ to n waye lẹnu lọọlọ yii nilẹ Kaarọ Oojire.
Adams, lasiko to n kopa lori eto tẹlifisan kan nilu Eko salaye pe awa ọmọ Yoruba la n se ara wa nitori bi ko ba si ole ile, ti ita ko le wa ja.
O ni o ti foju han pe awọn eeyan kan laarin iran Yoruba lo n lẹdi apo pọ mọ awọn ọdaran kan laarin Fulani darandaran lati maa huwa ika to gogo yii.
Iwadii mi laarin awọn fijilante fihan peara awa Yoruba kan n fọwọ sowọpọ pẹlu awọn ọdaran Fulani lati maa ji awọn eeyan gbe gba owo lẹkun iwọ oorun guusu Naijiria."
Awọn eeyan wa lo ko ida mẹẹdọgbọn si ọgbọn laarin awọn ọdaran to n dunkooko mọ alaafia ilẹ Yoruba
Sunday Igboho fulani ultimatum: Àwọn ará Kebbi àti Zamfara ló n jínígbé ní Oke Ogun- Serik
"Nigba ta fi ọrọ wa awọn ọdaran Fulani ti ọwọ tẹ lagbegbe Ilesa lẹnu wo, a ri pe ọmọ Yoruba lo n bawọn se ounjẹ, bẹẹ si ni Yoruba lo n fun wsn ni iroyin nipa ẹni ti wọn yoo ji gbe."""
Aarẹ, nigba to n sọrọ lori igbesẹ ti ajijagbara Sunday Igboho gbe nilu Igangan, salaye pe, Igboho ko bun oun gbọ rara ko to lọ silu Igangan nibi to ti fun awọn Fulani ni gbedeke ọjọ meje lati ko aasa wọn nilẹ Yoruba.
Amọ o ni yoo nira lati bu Igboho lori igbesẹ to gbe naa nitori awọn eeyan ibẹ to n wa ominira, lo kesi pe ko wa gba awọn silẹ lọwọ awọn ọdaran Fulani naa.
Ọdun 2013 ni emi ati Igboho ti foju kanra kẹyin, a ko fi bẹẹ sunmọ ara wa, bi o tilẹ jẹ pe n ko fara mọ igbesẹ to gbe amọ yoo soro ki ẹnikẹni to bu lori igbesẹ naa, tori Yoruba n poungbẹ fun ominira.
Nigba to n sọrọ lori ikede ti ọga ọlọpaa pata nilẹ wa, Adamu fun Kọmisana ọlọpaa nipinlẹ Oyo, lati lọ gbe Sunday Igboho wa silu Abuja, Adams ni ọrọ pọ nibẹ.
Sunday Igboho: Fulani kò leè dúró, táa bá lo ohun ta jogún lọ́dọ̀ àwọ̀n bàbá wa
"Kii se Igboho nikan ni wọn fẹ gbe si ahamọ, awọn agbofinro gan n foju si emi naa lara lati gbe mi, emi ni ẹni akọkọ ti wọn fẹ gbe nitori ọrọ oselu.
Idi ree ti mo fi nilati sọra mi, bẹẹ si ni awọn oloselu kan ti tọwọ bọ ọrọ to nii se pẹlu Sunday Igboho yii.
Adams fikun pe awọn eeyan to bu ẹnu atẹ lu wa lọdun 2015, ni wsn wa n lo Sunday Igboho bayii lati ba mi lorukọ jẹ, mo si fi ohun gbogbo ti mo ni si ewu fun ilẹ Yoruba."
"Bawo ni Sunday Igboho yoo se lo iwa akikanju rẹ lati ba isẹ ti eeyan kan ti se fun ọdun mejidinlọgbọn jẹ? Yoruba maa n ba ti akikanju ati akọni wsn jẹ lẹyin o rẹyin ni."""
Wayi o, Oloye Gani Adams ti se sadankata si awọn gomina nilẹ Yoruba lori ohun ti wọn fẹnu ko le lori nibi ipade ti wọn se pẹlu awọn darandaran.
Atẹjade kan ti akọwe iroyin fun Adams, Kehinde Aderemi fisita lo sisọ loju ọrọ yii.
Aarẹ ni igbesẹ awọn gomina naa ni yoo mu adinku ba ipaya to wa nilẹ, ti yoo si wa ojutu laelae si eto aabo ti ko fara rọ lẹkun yii.
O fikun pe o yẹ ki gbogbo eeyan gbaruku ti ikọ Amotekun bayii lati pese aabo nilẹ Yoruba nitori ẹkun guusu Naijiria lagbara pupọ ju awsn ẹkun miran ni Naijiria lọ.
O wa koro oju si igbesẹ awọn eeyan kan lati sọ ikọ naa ni suna buruku, ki wọn si foju tẹnbẹlu aayan awọn gomina ilẹ Yoruba lori ikọ alaabo naa.
Sunday Igboho: N kò fẹ́ oyè ọ̀gá àgbà páta fún ikọ̀ Amotekun nílẹ̀ Yorùbá
Aarẹ Gani Adams ti bu ẹnu atẹ lu bi awọn ọbayejẹ kan se lọ kan ina lu ile Sunday Igboho mọjumọ ọjọ Isẹgun, to si ni igbesẹ naa jẹ ara ọna lati da omi tutu si ajijagbara naa lọkan.
"O se ni laanu pe awọn alagbara kan ko dunnu si ohun to n waye lẹkun iwọ oorun guusu Naijiria, isẹlẹ ina naa lo si n fidi aifararọ eto aabo mulẹ.
Yoo si dara ki ijọba tanna wadi awọn eeyan to wa nidi isẹlẹ yii, ki ọwọja wahala yii ma baa peleke si.
Sunday Igboho: N kò fẹ́ oyè ọ̀gá àgbà páta fún ikọ̀ Amotekun nílẹ̀ Yorùbá
Nigba to n fesi lori ahesọ ọrọ naa fun awọn akọroyin, ti BBC Yoruba wa lara wọn, Sunday Igboho ni oun ko fẹ ipo oludari patapata fun ikọ Amotekun yika ilẹ Yoruba, ti wọn n yọ ọ naa.
O ni oun to jẹ oun logun bayii ni bi awọn ọdaran Fulani yoo se fi ilẹ Yoruba silẹ, ti alaafia yoo si jọba pada.
Sunday Igboho: Ọlọ́run lọ́wọ́ sí bí mo ṣe lọ dojú kọ apààyàn Fulani ní Ibarapa
Oríṣun àwòrán, Instagram/Sunday Igboho
Ajijgbara ọmọ ilẹ Yoruba nni, Oloye Sunday Adeyemo, ti sps eeyan mọ si Sunday Igboho ti leri leka pe awọn onisẹ ibi laarin awọn Fulani nipinlẹ Ogun ti rugi oyin.
Igboho, ninu fidio miran to lu ori ayelujara pa kede pe oun yoo le awọn onisẹ ibi Fulani naa jinna rere nipinlẹ Ogun.
O ni ariwo isẹ ibi awọn ọdaran darandarn nipinlẹ Ogun ti de etigbọ oun, oun si ti setan lati dahun si igbe ẹbẹ awsn ọmọ Yoruba to wa nipinlẹ naa.
Bẹẹ ba gbagbe, ariwo sọ lẹnu ọjọ mẹta yii nigba ti awọn sọja lọ na awọn agbẹ lawọn abule kan nipinlẹ Ogun lori ẹsun pe wọn ko gba awọn darandaran laaye lati da ẹran jẹ ni agbegbe naa.
Sunday Igboho: N kò fẹ́ oyè ọ̀gá àgbà páta fún ikọ̀ Amotekun nílẹ̀ Yorùbá
Nigba to n sọrọ lori isẹlẹ naa, Sunday Igboho ni asiko ti to ti Ọlọrun fẹ tu awọn Yoruba silẹ lọwọ ide awọn onisẹ laabi laarin awọn darandaran naa.
O si yẹ ko ye awọn eeyan pe lilọ ti mo lọ si agbegbe Ibarapa lati lọ kilọ fawọn onisẹ ibi Fulani naa ni Ọlọrun lọwọ si.
Iya to n jẹ awọn eeyan ni agbegbe Ibarapa naa ti pọ ju, eyi to le gongo pẹlu iku Ọmọwe Aborode, isẹlẹ yii si lo tu asiri awọn isẹlẹ buruku to n waye nibẹ."
Sunday Igboho fulani ultimatum: Àwọn ará Kebbi àti Zamfara ló n jínígbé ní Oke Ogun- Serik
"Igboho tẹsiwaju pe ""pẹlu aṣẹ Ọlọrun ọba, awọn isoro apaayan Fulani nipinlẹ Ogun naa yoo yanju."
"Gbogbo awọn ọdaran Fulani to ba wa loke Ogun ni ko maa mura mi silẹ, mo n bọ kankan."""
Ajafẹtọ ẹni naa wa gbarata lori bi awọn oloselu se n pagi dina ijagudu rẹ lati gba awọn iran Yoruba silẹ lọwọ inira, eyi toun n se pẹlu ootọ inu.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
''Ṣe ẹ ri iwe ipẹjọ wa lori awọn ọmọ ologun to fiya jẹ awọn agbẹ wa ni ijọba ibilẹ ariwa Yewa?''
''Rara a ko ri iwe ipẹjọ kankan.''
Ọrọ fakinfa to n waye ree laarin ijọba ipinlẹ Ogun ati awọn oriade ijọba ibilẹ ariwa Yewa.
Eyi ko si sẹyin iwe ifehonuhan ti awọn ọba kọ pe ko tẹ awọn lọrun bi awọn ọmọ ogun ilẹ Naijiria kan ṣe fiya jẹ awọn agbẹ.
Bi a ko ba gbagbe, laipẹ yii ni iroyin gbode pe awọn ọmọogun orileede Naijiria kan fiya jẹ awọn agbẹ lagbegbe Yewa, nitori awọn agbẹ naa kọ lati jẹ ki awọn darandaran Fulani fi maalu wọn jẹko.
Oríṣun àwòrán, Twitter
Ọba Eselu ti ilu Eselu Oba Akintunde Akinyemi naa si wa lara awọn oriade to kọ iwe ifẹhonuhan si ileesẹ ọlọpaa, ologun ati ijọba ipinlẹ Ogun.
Amọ ṣa, oluranlọwọ Gomina ipinlẹ Ogun lori ọrọ ipolongo, Remmy Hazzan ti salaye pe awọn ko ti ri iwe ihonu han yi gba.
Hazzan fikun ọrọ rẹ pe isẹlẹ́ naa ko ṣokunkun si ijọba ati pe awọn ti n gbe igbeṣẹ lati yanju rẹ.
''A ko ti ri iwe ipẹjọ naa gba ṣugbọn a mọ wi pe iru nnkan bayi n waye''
Nigba tawọn akọroyin beere lọwọ rẹ pe, ki ni igbesẹ ti ijọba n gbe lọwọ o ni ''iwadii ṣi n lọ lọwọ ki gbogbo awọn ti ko ba ti fi iwe ranṣẹ ki wọn ṣe bẹ.''
Sunday Igboho fulani ultimatum: Àwọn ará Kebbi àti Zamfara ló n jínígbé ní Oke Ogun- Serik
O ṣalaye pe Gomina yoo ṣe iwadii ọrọ́ naa ati pe oun to rọrun lati ṣe ni ''ki Gomina pe awọn ọga ọmọogun to wa ni bareeke Alamala, ki wọn ṣe iwadii iṣẹlẹ yii''
Amọ ileeṣẹ ọlọpaa ipinlẹ Ogun ti sọ yanya pe oun ti ri iwe ifẹhonu han naa gba ni tawọn.
Sunday Igboho: Gani Adams ní ọ̀ràn tí Igboho bá dá, aráàlú ló dá a
Ifọrọwerọ  pẹlu Gani Adams lori ọrọ Sunday Igboho
Iba Gani Adams ti da si awọn awuyewuye to n su yọ lori igbesẹ ti ajijagbara kan fun ilẹ Yoruba, Sunday Igboho gbe lati gbogun ti awọn ọdaran laarin Fulani darandaran.
Ninu ifọrọwerọ to ṣe pẹlu BBC Yoruba, Gani Adams ni awọn onimọ ofin to ni nkan ti Sunday Igboho ṣe tako ofin, ni lati beere ibeere kan.
Ibeere to ni o yẹ ki wọn beere ni pe, ki lo de ti awọn agbofinro ko fi mu awọn ọdaran laarin awọn Fulani to tapa sofin, ti Igboho fi doju ija kọ wọn.
Aarẹ Ọna kakanfo ni nitori iya to ti jẹ awọn Yoruba ''ko si ẹni to le da Igboho lẹbi nkan to ṣe''
''Awọn to ti pa Faborode, to pa eeyan to to aadọta ni Oke Ogun ati Ibarapa laarin ọdun mẹfa, ṣe nkan ti wọn ṣe ko tako ẹtọ ẹda ọmọniyan bi?
Gani Adams ni koda, bi eeyan ba tako nkan ti Sunday Igboho n ṣe, iru ẹni bẹẹ yoo jẹbi ilẹ Yoruba.
Sunday Igboho fulani ultimatum: Àwọn ará Kebbi àti Zamfara ló n jínígbé ní Oke Ogun- Serik
O ṣalaye pe, lootọ kii ṣe pe oun ati Sunday Igboho ti sọrọ ṣaaju ko to gbe gbogbo igbesẹ to n gbe, sugbọn ohunkohun ti ko ba a ṣe, ẹtọ Yoruba lo n ja fun.
''Lootọ aburo wa Sunday Igboho akikanju eeyan ni, bo ṣe n sọ wi pe aarẹ mọ nipa rẹ, lootọ ẹni to ba jẹ asiwaju lo maa n mọ nipa nkan.''
''Nigba tawa naa bẹrẹ, ta si kere, a maa n da ọran si awọn baba wa ninu ẹgbẹ Afẹnifẹre lọrun ni. Bi Igboho ba da nnkan silẹ, ọrun wa lo da si gẹgẹ bi agba''
Ni idahun si ibeere pe, ki lo de ti ko fi lewaju awọn to n ja fẹtọ Yoruba?
Gani Adams ni aarẹ Ọna Kakanfo kii dede ṣaaju ogun bi kii ṣe pe yoo ti ran awọn ọmọlẹyin rẹ ṣaaju igba naa.
O ni bi ọrọ ba di wi pe ipa awọn ti aarẹ ran lọ ko ba le ka nkan to wa nilẹ, igba naa ni aarẹ yoo to wa kan si awọn Ọba Yoruba, ko to le bọ sita lati koju ogun.
O pẹ ki Buhari to yan awọn olori ileeṣẹ ologun tuntun
Aarẹ Ọna Kakanfo sọ pe lootọ o pẹ ki aarẹ Buhari to yọ awọn ti ara ilu ti n ke pe ki o yọ nipo, ṣugbọn o pẹ ya ju rara lọ.
O ni ipenija aabo to ba Naijiria kọja ọrọ Fulani darandaran nikan nitori naa, awọn ti wọn gbe sipo yii gbọdọ mura siṣẹ.
Iba sọ pe ki Naijiria to le ri ifọkanbalẹ, ohun ti awọn to wa lori oye gbọdọ ṣe ni ki wọn ṣe atunto orileede Naijiria, eyi taa mọ si Restructuring.
O ni ti a ba ṣe atunto yii, taa si pada si eto ijọba ẹlẹkunjẹkun bi atẹyinwa, a o le ni awọn ẹka ijọba ti yoo mu idagbasoke ba agbeegbe kọọkan.
Ifọrọwerọ pẹlu Gani Adams lori ọrọ Sunday Igboho
COVID-19 Health Protection Regulations 2021: Ìjìyà ẹ̀wọ̀n àti owó ìtanràn ń dúró de ẹni tó bá tàpá sófin
Oríṣun àwòrán, Facebook/Seyi Makinde
Aarẹ Muhammadu Buhari fi buwọlu aba ofin eto ilera to n pese aabo lori arun Coronavirus tọdun 2021 nilu Abuja.
Bi o tilẹ jẹ pe ko si ilana to tuntun ninu ofin naa nitori ọpọ ilana to wa ninu rẹ lawọn eeyan ti n mu lo amọ atilẹyin ofin ti wa bayiii lati foju ẹni to ba tẹ ofin naa loju baile ẹjọ.
Gẹgẹ bi ofin isera ẹni naa ti salaye ni ori kẹrinlelọgbọn rẹ, ẹnikẹni to ba tasẹ agẹrẹ si ofin naa yoo san owo itanran tabi ko ri ẹwọn he tabi ko jiya mejeeji.
Ofin naa tun mẹnuba asa tita kete sira ẹni, eyi ti gbogbo eeyan awujọ gbọdọ tẹle, wiwọ iboju, fifọ ọwọ loore koore, ko si jọwọ ara rẹ lati jẹ ki wọn se ayẹwo bi ara rẹ se gbona si.
Oríṣun àwòrán, @MBuhari
Bakan naa ni ofin yii ni ero to gbọdọ pejọ sinu ibudo kan ju aadọta lọ ayafi awọn ibudo ijọsin, bẹẹ si ni ero ibudo ijọsin naa ko gbọdọ gba ju ero idaji iye to yẹ ko lọ gba lọ.
Bakan naa ni ofin yii ro awọn ile ẹkọ, ile ifowopamọ atawọn ibudo ijọsin lagbara lati fidi ofin naa mulẹ, eyi ti yoo dena arun Covid-19
Ko tan sibẹ o, ẹsẹ nla ni fun ẹnikẹni to ba tapa si ofin yii, to si ro awọn agbofinro lagbara lati gbe iru ẹni bẹẹ, ko le foju wina iya ẹsẹ rẹ.
Ijiya ẹsẹ iru ẹni bẹẹ ni pe yoo san owo itanran tabi ko fi ẹwọn osu mẹfa jura tabi ko se mejeeji papọ.
Transparency International: Nàíjíríà wà nípò tó burú jùlọ nínú ìwà àjẹbánu láti ọdún méjì sẹ́yìn
Oríṣun àwòrán, @MBuhari
Orilẹ-ede Naijiria ja walẹ síi ninu awọn orilẹ-ede ti iwa ibajẹ ti pọ julọ lagbaye.
Gẹgẹ bi atẹjade ti ajọ Transparency International fi sita, Naijiria lo wa ni ipo keji ninu awon orilẹ-ede ti iwa ibajẹ ti pọju lapa iwọ- oorun ilẹ Afrika.
Ajọ naa ṣalaye pe atẹjade ọhun fihan pe iwa ibajẹ ti buru si ni Naijiria ju ti atẹyinwa lọ.
Ajọ Transparency International ni ipo ti Naijiria wa bayii lo buru julọ laarin ọdun meji sí asiko yii.
Orilẹ-ede Guinea Bissau ni iwa jẹgudu-jẹra pọ sí julọ ni ẹkun ìwọ̀-oòrùn ilẹ Adulawọ.
Ilorin Conjoined Twins: Àwọn òbí ìbejì tó lẹ̀pọ̀ ní ọ̀kàn àwọn bàjẹ́ láti rí ibèjì wọn tó
Naijiria ti wa ni ipo 149 bayii ninu orilẹ-ede 183 ti ajọ Transparency International ṣe agbeyẹwo wọn.
Orileede Sudan lo buru julọ ninu iwa ibajẹ nilẹ Afrika.
Somalia lo wa ni ipo keji nigba ti orilẹ-ede South Sudan ṣe ipo kẹta.
Amọ, orilẹ-ede Seychelles lo gba ipo kinni ninu awọn orilẹ-ede to ṣe daadaa julọ nilẹ Adulawọ.
Amope Onibata: Kìí ṣe gbogbo ọkùnrin ló gbà kí ń ṣe bàtà fún àwọn
Ẹwẹ, Aarẹ Muhammadu Buhari ti sọ pe irọ nla ni iroyin ti ajọ Transparency International gbe jade nipa orilẹ-ede Naijiria.
Oluranlọwọ fun aarẹ lori ọrọ iroyin, Garba Shehu lo fọrọ naa lede loju opo Twitter rẹ.
Oríṣun àwòrán, @GarShehu
Shehu ṣalaye pe lai ṣe ani-ani, ijọba Aarẹ Buhari n ṣe aṣeyọri lori akitiyan lati gbogun ti iwa ibajẹ ni Naijiria.
Iroyin ti ajọ Transparency International gbe jade kudiẹ kaato, ati pe niṣe lo yẹ ki wọn gboriyin fun Buhari lẹyin to ti dẹkun iwa ibajẹ laarin awọn oṣiṣẹ ọba, Shehu lo sọ bẹẹ.
Oríṣun àwòrán, Wole Soyinka
Akọni onkọwe nni, Ọjọgbọn Wole Soyinka kede pe ijọba Aarẹ Muhammadu Buhari n pin orilẹede Naijiria si yẹlẹyẹlẹ pẹlu ilana to n gba se ijọba rẹ.
Ọjọgbọn Soyinka sọrọ naa lori ẹrọ amohunmaworan kan nilu Eko l'Ọjọru.
Laisi ani àní, orilẹede Naijiria ti pin yẹlẹyẹlẹ, ijọba to wa lode yii lo si faa, Soyinka lo sọ bẹẹ.
Ọjọgbọn Soyinka wa di ẹbi gbogbo isẹlẹ yii ru ijọba Buhari nitori bi ijọba rẹ ṣe n ṣegbe lẹyin awọn ẹya kan ju awọn kan lọ.
"Soyinka ni ijọba ẹlẹnu meji ni ijọba to wa lode, ""ohun to ba ṣẹlẹ tabi ẹni to ba ṣẹlẹ si lo maa sọ bi ijọba Buhari yoo ṣe woo."""
Oríṣun àwòrán, Wole Soyinka
"Soyinka sọ pe ọpọ awọn ọrọ to n jade lati ileeṣẹ aarẹ buru jai, ""ọrọ imọtara ẹni nìkan ni, koda o yẹ ki oju gba awọn to n sọ iru ọrọ bẹẹ ti, o si ti yẹ ki wọn dawọn duro lẹnu iṣẹ wọn tipẹ."""
Ọjọgbọn Soyinka ni ko si ẹni to ni igbagbọ ninu ijọba yii mọ.
O ṣeni laanu pe ọkan lara ohun ti ijọba to wa lode yoo fi silẹ lọ ni yii, Soyinka lo woye bẹẹ.
Ọjọgbọn Soyinka ni ijọba Buhari ko gbogun ti iwa ibajẹ kankan mọ, o ni iwa ibajẹ ti gbalẹ debi pe awọn ileẹjọ ko tete dajọ mọ.
Sunday Igboho: Fulani kò leè dúró, táa bá lo ohun ta jogún lọ́dọ̀ àwọ̀n bàbá wa
Ọpọ eeyan lo yẹ ko ti dero ẹwọn ti ijọba yii ko baa tii maa kaarẹ lori igbogun ti iwa ibajẹ ni, Soyinka lo sọ bẹẹ.
Soyinka ni ọrọ ajọ EFCC ti oun n ṣe atilẹyin fun lati igba ti Nuhu Ribadu ti jẹ alága rẹ, naa ko ye oun mọ.
Ẹwẹ, ẹgbẹ ọmọ Yoruba, Afenifere ati ẹgbẹ to n ri si ọrọ awọn eeyan agbegbe Niger Delta,  PANDEF, ti kin ọrọ ti Ọjọgbọn Wole Soyinka sọ lẹyin.
Agbẹnusọ fun ẹgbẹ Afenifere, Yinka Odumakin ni otitọ lọrọ tí Ọjọgbọn Soyinka sọ pẹlu awọn akiyesi rẹ naa.
Odumakin ni baṣu baṣu ni Aarẹ Buhari n ṣe ìjọba orilẹ-ede Naijiria.
Sunday Igboho fulani ultimatum: Àwọn ará Kebbi àti Zamfara ló n jínígbé ní Oke Ogun- Serik
O ni ohun to ti ni loju ni pe, ijọba Buhari lo ṣe okunfa ede-aiyede ẹlẹyamẹya to n lọ lọwọ lorilẹede Naijiria bayii nipa ṣiṣegbe lẹyin awọn eeyan kan.
Bakan naa ni agbẹnusọ ẹgbẹ PANDEF, Ọgbẹni Ken Robinson kin ọrọ Soyinka lẹyin.
Ọgbẹni Robinson ni lootọọ ni pe ijọba Buhari ti pin Naijiria yẹlẹyẹlẹ eleyi to si ti fa ikunsinu bayii.
Ọpọ ọmọ Naijiria lo da bi alejo to n ṣatipo nilẹ abinibi wọn, ẹya ati ẹsin ni ijọba fi n pin ipo, Robinson lo sọ bẹẹ.
Pangolin Covid-19: Ẹ wo ẹranko tó ṣeéṣe kó ní ǹkan ṣe pẹ̀lú à[rùn Coronavirus!
O ni yatọ si awọn olori ileeṣẹ ọmogun ti Buhari ṣẹṣẹ yan sipo, awọn eeyan lati apakan orileede Naijiria lo wa nipo olori awọn ọmọ-ogun tẹlẹ.
Robinson ni eyi lo jẹ ki ọpọ gbagbọ pe Naijiria ti pin yẹlẹyẹlẹ ju igba ti ogun abẹle bẹ silẹ lọ.
Ilorin Conjoined Twins: Àwọn òbí ìbejì tó lẹ̀pọ̀ ní ọ̀kàn àwọn bàjẹ́ láti rí ibèjì wọn tó
Ohun ayọ ati idunnu ni ọmọ bibi jẹ, gbogbo obi ati ẹbi lo si maa n fi oju sọna lati ki ọmọ tuntun kaabọ saye ni kete ti alaboyun ba ti loyun.
Amọ eyi ko ri bẹẹ fun arabinrin Tawakalitu Ahmed ati ọkọ rẹ nilu Ilorin, ẹni ti ọba oke fi ibeji lanti-lanti ta lọrẹ.
Idi ni pe awọn ibeji naa lẹ pọ ni lati igba aya lọ soke nigba to bi wọn, bi o tilẹ jẹ pe ayẹwo to se ninu oyun ko fihan pe awọn ibeji to wa ninu rẹ ti lẹpọ.
Nigba to n ba BBC Yoruba sọrọ lori ohun to la kọja ninu oyun ati lẹyin to bi awọn ibeji naa tan, Tawakalitu ni ibanujẹ nla lo gba ọkan oun lati ri pe awọn ọmọ naa ko pe lara.
O ni ọpọ ọrọ ti ko dara ni awọn eeyan ti sọ nipa awọn ọmọ oun, ti wn si gba iya mi nimọran lati fi oogun pa wọn nitori abami ọmọ ni wọn
O ni isẹ abẹ to jẹ aseyọri ti wọn se fun awọn ibeji naa nile iwosan ẹkọsẹ isegun fasiti Ilorin lo tun mu ayọ pada si ọkan oun.
Bakan naa, awọn dokita to sisẹ abẹ yii ba BBC Yoruba sọrọ lori ọna ti wọn gba ati irinsẹ ti wọn lo lati ya awọn ibeji naa, ninu isẹ abẹ oni wakati meje to jẹ aseyọri.
Àwọn ìtàn mánigbàgbé tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí:
Ohun ayọ to tun wa nibẹ ni pe ile iwosan ẹkọsẹ isegun naa ti gba awọn obi awọn ibeji naa sẹnu isẹ, ki wọn le ri owo tsju awọn ọmọ naa.
Mike Sonko: Gbogbo dúkìá Gómìnà àná náà ló jẹ́ wúrà
Oríṣun àwòrán, Instagram/mike.sonko
Yoruba ni ohun to ba wu olowo, lo n fi owo rẹ se, ara to ba si wu olowo, lo le fi owo rẹ da.
Bi igbe aye ọkunrin kan Mike Sonko se ri ree, ẹni to nifẹ wura puọ, ọpọ ohun alumọni rẹ si lo jẹ kikida goolu pọnbele.
Sonko, ti inagijẹ rẹ n jẹ Sonkoree, jẹ ọdọmọde olowo lati orilẹede Kenya, bakan naa lo si tun jẹ oloselu to gbajumọ bii isana ẹlẹta.
Ẹni ọdun marundinlaadọta ni Sonko, to si jẹ gomina keji ti yoo dari ilu Nairobi amọ ile asofin agba ilk naa yọ nipo gomina lori ẹsun iwa ọdaran ati asemase.
Oríṣun àwòrán, Instagram/Mike Sonko
Bi o tilẹ jẹ pe ọkunrin yii lo ni owo rẹ amọ ọpọ eeyan ni ẹnu maa n ya nipa awọn dukia to jẹ kikida goolu olowo iyebiye to maa n ra.
Wọn ni isẹ, osi ati aini gogo nilẹ Afirika ati ni orilẹede rẹ pẹlu amọ ifẹ wura lo gba ookan aya rẹ.
Oríṣun àwòrán, Instagram/Mike Sonko
Mike Sonko nifẹ wura, koda ọkọ ayọkẹlẹ rẹ gan ko gbẹyin
Oríṣun àwòrán, Instagram/Mike Sonko
Gbogbo inu ọọfisi Sonko gan, kikida goolu ni
Oríṣun àwòrán, Instagram/Mike Sonko
Olowo ni yoo ku re, wura dara , o rẹwa ni ọọfisi Sonko
Oríṣun àwòrán, Instagram/Mike Sonko
Ta lo le sọ pe wura ko rẹwa
Oríṣun àwòrán, Instagram/Mike Sonko
Kii se obinrin nikan ni ọṣọ wura dara lara wọn, o dara lara ọkunrin pẹlu, Sonko lo fidi eyi mulẹ pẹlu ẹṣọ wura to rẹwa
Oríṣun àwòrán, Instagram/Mike Sonko
Bi Ọba Oke ba ti fi ọkan ẹda balẹ, ẹrin ni yoo gba ẹnu rẹ
Oríṣun àwòrán, Instagram/Mike Sonko
Ọpa to gbe asia orilẹede soke ni ọọfice Sonko gan, wura pọnbele ni
Oríṣun àwòrán, Instagram/Mike Sonko
Ibi a ba jaye de ree o, eyi tun kasiara, Waini Sono, kiki wura ni igo rẹ
Oríṣun àwòrán, Instagram/Mike Sonko
Awọn ẹsọ ẹsin ti Sondo fi se ẹsọ ninu ọọfisi rẹ gan, goolu ni
Ibadan Violence: Bí ìkọlù jàǹdùkú sí àgọ ọlọ́pàá Mapo ní Ibadan ṣe wáyé rèé
Oríṣun àwòrán, @PoliceNG
Iroyin to tẹ wa lọwọ lati ilu Ibadan sọ pe, awọn afurasi janduku kan ti ṣe ikọlu sawọn ọlọpaa nitori bi wọn se mu awọn afurasi meji ti wọn lo n da omi alaafia ilu ru.
A gbọ pe ikọlu naa bẹrẹ lagbegbe Odo-Osun lọjọbọ, ti o si tan de agọ ọlọpaa to wa ni Mapo.
Eeyan meji  ku ninu iṣẹlẹ naa gẹgẹ bi iroyin to tẹ wa lọwọ ti wi.
Lọjọbọ ni awọn ọlọpaa mu awọn janduku meji kan ladugbo Odo-Osun nitosi Mapo.
Bi awọn akẹgbẹ wọn ṣe ri pe ọwọ ti tẹ wọn, ni wọn gbiyanju lati fipa tu wọn silẹ lọwọ awọn ọlọpaa.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Amọ ṣa, ọlọpaa ṣina bolẹ fun wọn ni agbegbe Odo-Osun ti eeyan kan si ku nibẹ.
Lẹyin ikọlu ti Odo-Osun yii, awọn janduku taa n wi yi tun ṣigun lọ si agọ ọlọpaa to wa ni Mapo, lati fẹhonu han lori eeyan wọn kan ti o ku.
Ninu wọdu-wọdu to waye nibẹ, awọn ọlọpaa tun yinbọn lati daabo bo agọ wọn, eeyan kan tun fara gbọta to si gba ibẹ ku.
Ilorin Conjoined Twins: Àwọn òbí ìbejì tó lẹ̀pọ̀ ní ọ̀kàn àwọn bàjẹ́ láti rí ibèjì wọn tó
Alukoro ọlọpaa ni ipinlẹ Oyo, Olugbenga Fadeyi fidi iṣẹlẹ yii mulẹ fawọn akọroyin ninu atẹjade kan to fi sita.
O ni ''lẹyin tawọn ọlọpaa mu awọn janduku meji kan, arakunrin kan ti wọn n pe orukọ rẹ ni ''Packaging'' lewaju awọn janduku mii to to ọgbọn,
lati ṣigun bo agọ ọlọpaa, ki wọn le tu akẹẹgbẹ wọn silẹ''
Transparency International: Wo ẹjọ́ àjẹbánu márùn-ún tó ṣeéṣe kó fí Nàìjíríà sí ipò kejì lórí àtẹ ìwà àjẹbánu
Ko jẹ tuntun mọ wi pe ajọ Transparency International to n risi ọrọ iṣedodo ninu ijọba, gbe orukọ Naijiria jade gẹgẹ bi orileede keji lẹkun iwọ oorun ilẹ Afrika, ti iwa ajẹbanu ti gbilẹ julọ.
Iroyin yii jẹ eyi ti ko dun mọ ijọba aarẹ Muhammadu Buhari ninu nitori pe ọkan lara opo pataki iṣejọba rẹ ni lati doju ija kọ iwa ajẹbanu.
Eyi si lo mu agbẹnusọ fun aarẹ, Garba Shehu tutọ soke foju gba gidi pe ko tọ bi wọn ṣe gbe orukọ Naijiria jade ni ipo keji awọn orilẹede alajẹbanu ni iwọ oorun Afirika.
Idi si ree ti BBC Yoruba fi se akojọpọ awọn ẹjọ ajẹbanu to milẹ titi ni Naijiria, ti ijọba ti ṣe lọdun 2020 pẹlu awọn to fẹsun kan pe, wọn lu owo ijọba ni ponpo.
O si seese ko jẹ pe awọn ẹjọ kamilaya nidi iwa ajẹbanu naa, lo mu ki ajọ TI se odiwọn Naijiria bi orilẹede keji to kundun iwọn ajẹbanu ni iwọ oorun Afirika.
Maina ati ẹsun sise owo tole ni biliọnu meji naira basubasu:
Abdulrasheed Maina to jẹ alaga igbimọ atunto ọrọ owo ifẹyinti ni Naijiria, ni wọn fi ẹsun pe o lu biliọnu meji owo awọn osisẹ fẹyinti ni ponpo.
Ẹjọ rẹ yii lọdun 2020 gba orisirisi ọna yọ debi pe, Sẹnẹtọ kan to gba oniduro Maina, iyẹn Senẹtọ Ali Ndume jawọ kuro ninu ẹjọ rẹ nigba to sa mọ ile ẹjọ lọwọ.
Ati Maina ati ọmọ rẹ, Faisal ni ile ẹjọ fiwe sita pe ki awọn agbofinro mu wọn wa siwaju adajọ.
Lẹyin ọpọ atotonu, wọn mu Maina wa lati orileede Niger to sa lọ, to si tun wa pada bẹrẹ si jẹjọ ẹsun ti wọn fi kan an.
Daniel Pondei ati iwadii ajẹbanu ogoji biliọnu naira owo NDDC:
Saaju ki o to daku loju gbogbo ọmọ Naijiria to n wo tẹlifisan, ọpọ eeyan ni ko fẹ ẹ gbọ orukọ Daniel Pondei ri.
Amọ nigba ti wọn bẹrẹ si ni beere bo ti ṣe ṣakoso owo ajọ to n se akoso agbegbe Niger Delta, NDDC, niwaju igbimọ iwadii kan nile aṣoju-ṣofin Naijiria to si ṣadede daku, gbogbo eeyan lo mọ.
Oríṣun àwòrán, @nassnigeria
Lootọ lo pada ṣalaye pe, oun ni ipenija ilera ni ṣugbọn ọpọ lo ri bo ti ṣe daku gẹgẹ bi ọgbọn ẹwẹ lati mase dahun ibeere ti awọn aṣofin n beere lọwọ rẹ.
Owo to to ogoji biliọnu Naira ni igbimọ naa n ṣe iwadii bi ajọ NDDC ṣe naa laarin ibẹrẹ ọdun 2020.
Titi di igba ta n ṣe akojọ iroyin yii, wọn ko ti ri owo naa yanju
Orji Uzor Kalu n jẹjọ biliọnu meje naira:
Ajọ to n gbogun ti iwa ajẹbanu EFCC ti n ba Sẹnẹtọ Orji Uzor Kalu ṣẹjọ ọjọ ti pẹ, lori pe o ṣe owo ọba to to biliọnu meje naira baṣubasu.
Ẹsun mọkandinlogoji ni wọn fikan an, ti ile ẹjọ si ni ko maa lọ ṣẹwọn ọdun mejila lọdun 2019.
Oríṣun àwòrán, TWITTER/@OUKTWEETS
Ẹjọ yii ni wọn fa titi wọ ọdun 2020, ti ile ẹjọ to ga julọ ni Naijiria si pada gbe idajọ lelẹ pe, Uzor Kalu ati awọn mii ti wọn fẹsun kan, ko jẹbi.
EFCC tapa si idajọ naa, ti wọn si ni awọn yoo tubọ bẹrẹ igbẹjọ tuntun lori ọrọ Uzor Kalu.
Amọ ṣa, ba ti ṣe n sọrọ yii, Uzor Kalu jẹ aṣofin agba, to si n ba iṣẹ rẹ lọ nile aṣofin l‘Abuja.
Muhammed Adoke ati ẹjọ ajẹbanu $1.1 billion lori epo Malabu:
Ẹsun onipele meje ni wọn fi kan Minisita feto idajọ ati agbẹjọro agba Naijiria tẹlẹ, Mohammed Adoke.
Ko si sẹyin pe wọn lo gba abẹtẹlẹ, ki wọn ba le buwọlu idunadura ọrọ owo epo rọbi taa mọ si 'Malabu Oil deal.''
Oríṣun àwòrán, EFCC/Twitter
Ninu ẹsun ti wọn fi kan, wọn sọ pe o gba abẹtẹlẹ to to ọọdunrun miliọn Naira.
Saaju ni wọn ti bẹrẹ ẹjọ yii, ti adajọ si faaye gba Adoke lati lọ si Dubai fun ayẹwo ara rẹ.
Awọn ọlọpaa ọtẹlẹmuyẹ agbaye, Interpol mu ni Dubai ti wọn si da pada wa si Naijiria ni oṣu Kejila ọdun 2019.
Wọn ko ribi ṣẹjọ yii pupọ lọdun 2020 nitori arun Covid-19 ṣugbọn o wa lara awọn ẹjọ ti Naijiria ṣe, to da lori ajẹbanu to milẹ titi.
Nollywood: Wo àkójọpọ̀ ohun tó wáyé lágbo àwọn òṣèré tíátà lọ́sẹ̀ yìí
Oríṣun àwòrán, Instagram/bobrisky222
Oniruuru awọn isẹlẹ nla nla lo waye ni agbo awọn osere tiata lọsẹ yii ti ko yẹ kẹ padanu rẹ.
Bi awọn isẹlẹ kan se dun mọ ni ninu, ni awọn kan ba ni lkan jẹ, se tibi tire la da ile aye.
Awọn akojọpọ isẹlẹ to waye lagbo tiata lọsẹ yii re ni sisẹ n tẹle.
Oríṣun àwòrán, Instagram/mrlatin1510
Ori lo mọ iṣẹ aṣela laye. Bolaji Amusan ti ọpọ mọ si Mr Latin ati Odunlade Adekola lọ si ilu oyinbo niluu Vienna lorilẹede Austria nibi ayẹyẹ kanifa aṣọ Adire.
Mr Latin lo fi fọto oun ati Adekola nibi ti wọn ti wọ aṣọ Adire nibi ayẹyẹ ọhun niluu Vienna si ori ẹrọ Instagram.
"MR Latin tiẹ sọ loju opo Instagram rẹ pe ""ẹ o tii ri nkan kan"", eyi to tumọ si pe wọn sẹsẹ n mu ẹyẹ bọ lapo ni."
Oríṣun àwòrán, Instagram/bobrisky222
"Ori arabinrin kan lo ma ti sọre bayii lẹyin to ya ""tattoo"" Okuneye Olanrewaju Idris, ti ọpọ mọ si Bobrisky si ara rẹ."
"Bobrisky funra rẹ lo fi fọto obinrin naa, to jẹ ọkan lara awọn ololufẹ rẹ si oju opo Instagram rẹ pẹlu ""tattoo"" to ya si ẹyin rẹ."
Bobrisky wa ṣeleri lati ṣe ohun mere-mere fun arabinrin naa.
O ṣeleri lati fun obinrin ọhún l'ẹbun miliọnu kan naira, ra foonu to ba fẹ fun un ati pe, oun maa gbe arabinrin naa rinrin ajo afẹ lọ si Dubai.
Dokita fun Kemi Afolabi ni oogun oorun lati fara nisinmi lẹyin ayẹyẹ isile rẹ:
Oríṣun àwòrán, Instagram/kemiafolabiadesipe
Lẹyin to ṣe ayẹyẹ iṣile tan, oṣere tiata Yoruba, Kemi Afolabi wa ni igbele nibi ti o ti n sinmi.
O ni awọn dokita lo sọ foun pe oun nilo lati sinmi nile tori ilera ara oun.
Kemi ni oun ko mọ pe awọn dokita oun fi oogun orun sinu abẹrẹ ti wọn fún oun.
Oríṣun àwòrán, Nstagram/mukarayofficial
Iku doro, iku ṣeka, iku ti mu Lofty Eyiwumi Ray to jẹ aburo gbajugbaja oṣere Mukaddam Eyiwumi Ray ti ọpọ mọ sí Muka Ray lọ.
Loju opo Instagram rẹ ni Muka Ray ti sọ nipa iku aburo rẹ obinrin yii.
"Ibeere ""ki lo de, ki lo ṣẹlẹ"" ni Muka Ray n beere pẹlu ẹdun ọkan lori oju opo Instagram rẹ."
"Bakan naa lo fi ọrọ bii ""sun re o,  o daarọ si ori Instagram rẹ eyi to fi dagbere fun aburo rẹ to ṣe aláìsi."
Oríṣun àwòrán, Nstagram/mukarayofficial
Jude Chukwuka: Wò ó bí oríkì àwọn ìlú Yorùbá ṣe yọ̀ lẹ́nu ọmọ Igbo jú ọmọ onílùú lọ
Jude Chukwuka, tii se ọmọ Igbo, amọ to gbọ ede Yoruba tun ti gbe tuntun de.
Lọtẹ yii, Oríkì Ooni, Alaafin, Eko àti Ọlọ́fàmọjọ̀ ni Chukwuka fi n panu, eyi to yọ lẹnu rẹ ju tawọn ọmọ onilu lọ.
Chukwuka ninu fidio yii ki ilu Ile Ife, Oyo, Eko ati ọba wọn, bakan naa lo ki awọn ọmọ Ọlọfamọjọ titi, ti ori eeyan fi wu.
Iyalẹnu si ni yoo jẹ fun ojulowo ọmọ Yoruba ti ko mọ oriki ilu tabi ọba alade kankan, pe ọmọ ẹya Igbo tun mọ awọn oriki Yoruba ju ọmọ Kaarọ Oojire lọ.
Àwọn ìtàn mánigbàgbé tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí:
Olagunsoye Oyinlola: A bẹ Obasanjo lásìkò ìbò ààrẹ 2015 ni kó tó gbà láti ti Buhari lẹ́yìn
Oríṣun àwòrán, Other
Gomina ana nipinlẹ Osun, Ọmọọba Olagunsoye Oyinlola ti salaye lẹkunrẹrẹ nipa awọn isẹlẹ to n waye lagbo oselu orilẹede Naijiria.
Oyinlola, lasiko to n ba akọroyin iwe iroyin Punch sọrọ tun mẹnuba bi aarẹ ana, Oloye Olusegun Obasanjo, se pagidina erongba Bola Ahmed Tinubu lati jẹ igbakeji aarẹ Muhammadu Buhari.
O fikun pe ẹbẹ pọ ki Obasanjo to gba lati ti Buhari lẹyin pe ko dije fun ipo aarẹ lọdun 2015 lẹyin to tako isejọba Goodluck Jonathan.
Gomina ologun tẹlẹ nipinlẹ Eko naa fikun pe adehun ti wa saaju ibo 2015 pe laarin Buhari ati Tinubu pe ọkan yoo se aarọ Naijiria, ti ekeji yoo si se igbakeji rẹ, amọ adehun naa ko han si gbogbo ọmọ ẹgbẹ.
Aremu: Eré ìtàn nípa ìbí, àti jéèyàn pẹ̀lú ìpèníjà Olusegun Aremu Obasanjo
Oyinlola ni erongba awọn mejeeji yii lo n da ariyanjiyan silẹ ninu ẹgbẹ oselu APC nitori musulumi lawọn oludije mejeeji naa, eyi to fẹ gba awọn Kristiẹni sẹyin.
Oríṣun àwòrán, Olagunsoye Oyinlola
O ni ti kii ba se pe Obasanjo yari, ẹgbẹ oselu APC ko ba fa Buhari ati Tinubu kalẹ gẹgẹ bi oludije fun ipo aarẹ ati igbakeji rẹ, ko ba si nira fun wọn lati yẹ aga mọ Jonathan nidi.
Gomina alagbada nipinlẹ Osun naa tẹsiwaju pe, ọpẹlọpẹ Bukola Saraki, Ibikunle Amosun, Bola Tinubu, Kashim, Imam ati oun lo lọ ka Obasanjọ mọle nilu Ota ni deede aago meje aarọ pe ko ti Buhari lẹyin lati dije.
Obasanjo: Atiku kìí se Áńgẹ́lì, àmọ́ yóò se dáadáa ní ìlọ́po méjì ju Buhari lọ
Bakan naa lo ni Obasanjo salaye pe fun awọn lọjọ naa lọhun lori idi to fi tako Buhari lati dije, eyi to wa n fi oju han sita bayi, nitori bo se sọ, bẹẹ naa lo n sẹ bayii.
"O ni Obasanjọ sọ pe ""Buhari ti mo mọ yoo se daada ninu ọrọ to ba jẹ mọ isẹ ologun, amọ lẹyin eyi, Buhari ko mọ ohunkohun rara mọ, boya ni ẹka ọrọ aje ni tabi tọrọ ilẹ okeere."
Jude Chukwuka: Wò ó bí oríkì àwọn ìlú Yorùbá ṣe yọ̀ lẹ́nu ọmọ Igbo jú ọmọ onílùú lọ
Sunday Igboho: Wo àwọn èèkàn ìlú tó ń gbóṣùbá fún Òòṣà pé ó kú ọmọ ṣe
Oríṣun àwòrán, Instagram/SundayIgboho
Yoruba ni ta ba ri ẹni to seun, ẹ jẹ ka ki pe o seun nitori ku isẹ, lo n mu ori onisẹ ya, Yinni yinni, kẹni si le se omiran ni.
Ọpọ ọmọ Yoruba lo ti n dide nile wọn lati lọ ki ajijagbara kan nilẹ Kaarọ Oojire, Sunday Igboho ku isẹ takuntakun.
Bẹẹ ba tii gbagbe, Sunday Igboho lo lọ silu Igangan ni ọsẹ kan sẹyin lati lọ fawọn ọdaran Fulani lagbegbe Ibarapa ni gbedeke ọjọ meje, pe ki wọn ko aasa wọn lagbegbe naa.
Isẹlẹ yii lo n ja rainrain yika ilẹ wa, bi awọn eeyan kan si se n kọrin re ki Igboho, ni awọn miran ni o n se ofin lọwọ ara rẹ.
Sugbọn awọn ọmọ Yoruba kan ko duro lori ayelujara nikan, amọ wọn morile ile Sunday Igboho lati fi atilẹyin wọn han fun lori igbesẹ akin to gbe naa.
Sunday Igboho fulani ultimatum: Àwọn ará Kebbi àti Zamfara ló n jínígbé ní Oke Ogun- Serik
Yoruba sa ni aja to ba lẹni lẹyin, nii pa ọbọ.
Eyi ko si tun le sẹyin bi awọn janduku ẹda kan ti ẹnikẹni ko mọ, se lọ sọ ina si ile Sunday Igboho ni oru ọjọ Aje si Isẹgun.
Ọpọ eeyan yika Naijiria si lo dide lati tabuku iwa laabi naa, ti wọn lo tako ofin, o si wa lati da omi tutu si ọkan ajijagbara naa ni.
BBC Yoruba wa se akojọpọ awọn ọmọ Yoruba to lọ ki Sunday Igboho nile rẹ ati awọn to pe lori foonu pe o ku ọmọ se, to fi mọ awọn to fi ọrọ iwuri ransẹ si.
Oríṣun àwòrán, Facebook/King (Dr) Saheed Osupa Akorede﻿
Ni owurọ Ọjọru, ọjọ Kẹtadinlọgbọn osu Kinni ọdun 2021, eyiun ọjọ keji ti awọn eeyan kan sọ ina sile Sunday Igboho, ni agba akọrin Fuji, Saheed Osupa se abẹwo sile rẹ.
Osupa, to ko awọn alatilẹyin rẹ kan lẹyin, lo ba Igboho ni alejo nile rẹ tuntun, to n gbe ni adugbo Soka nilu Ibadan.
Gbajumọ akọrin Fuji naa, tii se ọmọ bibi ilu Ibadan lo ti kọrin lọpọ igba fi kọrin re ki Sunday Igboho eyi to si n ja rain lori ayelujara.
Gẹgẹ bi fidio kan ti Saheed Osupa fi soju opo Facebook rẹ ti safihan rẹ, bi akọrin Fuji naa soju kan Sunday Iogboho lo n ki i ni mẹsan mẹwa.
"Lara awọn oriki to si fi pe Igboho ni ""Sanpọnna Oodua, Ẹkun, ọkọ oke, tawọn to duro ti ajijagbara naa si n ki Osupa kaabọ sinu ile naa."
Lẹyin eyi, ni Sunday Igboho ati Sahee Osupa wa wọnu yara igbalejo nla kan lọ lati tẹ sọrọ eyi ti ko han fun araye.
Oríṣun àwòrán, Facebook/Sen Rilwan Adesoji Akanbi
Sẹnetọ tẹlẹ to soju ẹkun idibo guusu Oyo, Rilwan Adesoji Akanbi naa ti se ago onile sinu ile Sunday Igboho, lati ba kẹdun fun ile rẹ to jona, to si tun se sadankata si lori igbesẹ akin to gbe nilu Igangan.
Sẹnetọ naa lo kede pẹlu aworan loju opo Facebook rẹ pe oun ti lọ ki Sunday Igboho nile rẹ lori isẹ aksni to se, ti Igboho naa si tẹle wa sile pada.
Oríṣun àwòrán, Facebook/Sen Rilwan Adesoji Akanbi
Akanbi, tii se Ọkanlọmọ tilẹ Ibadan wa yonbo Igboho pe o mu alaafia jọba pada lẹkun iwọ oorun guusu Naijiria lai naani idunkooko iku ati dukia rẹ ti wọn jo nina.
Asofin Sina Peller:
Lara awọn eekan ọmọ Oodua miran to yonbo isẹ akikanju ti Igboho se ni Sina Peller, tii se asofin to n soju ẹkun idibo Iseyin, Itesiwaju, Iwajowa ati Kajola nipinlẹ Oyo nile asoju-sofin ilẹ wa.
Sina, to jẹ gbajumọ alafẹ nilu Eko, nii tun se ọmọ bibi gbajugbaja pidan-pidan nni, Ọjọgbọn Abiola Peller to ti di oloogbe.
Oríṣun àwòrán, Instagram/shinapeller
Bakan naa ni lo yẹ ko ye wa pe Sina Peller jẹ ọmọ bibi agbegbe Oke Ogun ti Sunday Igboho naa ti wa bi o tilẹ jẹ pe ilu wọn lo se ọtọọtọ.
Sunday Igboho wa lati ilu Igboho ni ijọba ibilẹ Oorelope nigba ti Sina Peller wa lati ilu Iseyin, nijọba ibilẹ Iseyin.
Loju opo Instagram rẹ, Peller sọrọ lori oniruuru awuyewuye to suyọ nipa igbesẹ ti Sunday Igboho gbe nilu Igangan, to si ni inu oun dun si ajijagbara naa.
"O ni Igboho ni ohùn tawọn mẹkunnu gba sọrọ nipa iya tawọn ọdaran darandaran fi n jẹ wọn, to si n ṣa ni mẹsan-mẹwa pe ""Igboho OOṣa."""
Oríṣun àwòrán, Instagram/shinapeller
"Igboho Oosa yẹ bi jagunjagun, mo si ki pupọ fun iwa akọni, iwuri ati akikanju rẹ pẹlu ipa to ko lati mu adinku ba iwa ọdaran lagbegbe rẹ.
Ko si aniani pe Igboho ti jẹ ki gbogbo aye mọ nipa ipenija eto aabo to n koju ẹkun iwọ oorun guusu Naijiria bayii nitori iwa ika awọn ọdaran darandaran."
Asoju-sofin naa ni Igboho ti kọ itan to dara fun ara rẹ, itan ko si ni gbagbe ipa to ko lati sọrọ sita lasiko ti eto aabo mẹhẹ.
O wa rọ awọn ọmọ Naijria lati fọwọ sowọpọ, ki wọn si wa ni irẹpọ lati tako awọn ọta to n dide si wọn lẹka eto aabo.
Ko tan sibẹ o, lara awọn eekan ọmọ ilẹ Yoruba miran to ti pe Igboho lori foonu lati ki ku isẹ takuntakun ni ,awọn agba oselu, oriade atawọn gbajumọ miran.
Lara awọn oriade to ti se awa lẹyin rẹ fun Igboho, gẹgẹ bi onitọsun ti darukọ wọn ninu fidio kan to n ja rain-rain lori ayelujara ni Ooni, Alaafin, Olubadan, Awujalẹ, Eleko ati bẹẹ bẹẹ lọ.
Bakan lo ni awọn oloselu bii Femi Fani Kayode ati Ayodele Fayose ti ransẹ ikinilaya si oun, ti Aarẹ Ọna Kakanfo Gani Adams naa ko si gbẹyin ninu awọn to n se atilẹyin fun.
Kwara accident: Èèyàn mẹ́tàdínlógún(17) kú nínú ìjàmbá ọkọ̀ bọ́ọ̀sì lópòpóónà Jebba, ẹnìkan mórí bọ́
Oríṣun àwòrán, Kwara Fire Service
Agba adura ni Yoruba maa n gba pe a o ni rin lọjọ ti ebi n pa ọna.
Eeyan mẹtadinlogun lo jona raurau ninu ijamba ọkọ ero to ṣẹlẹ lopopona Bode-Saadu si ilu Jebba nipinlẹ Kwara lọjọ Abamẹta.
Awakọ ero Toyota naa ni a gbọ pe ko le dari ọkọ ọkọ naa mọ lẹyin to ti gbiyanju lati ya ọkọ akẹru to ko ata ati ọkọ ajagbe kan to wa niwaju rẹ.
Eleyi lo jẹ ki ọkọ bọọsi Toyota naa lọ fori sọ ọkọ ajagbe mii to n bọ lati ọna Jebba, lẹyin naa ni ina sọ!
Loju ẹsẹ naa ni eeyan mẹtadinlogun gbẹmi mi nibi ijamba ọhun ṣugbọn ori ko ẹnikan yọ nibẹ lai farapa rara.
Agbẹnusọ ileeṣẹ panapana ipinlẹ Kwara, Ọgbẹni Hassan hakeem Adekunle lo fidi iṣẹlẹ ọhun mulẹ ninu atẹjade kan to ṣọwọ sawọn akọroyin.
Oríṣun àwòrán, Kwara State Fire Service
Ọgbẹni Adekunle gbadura pe ki Eleduwa tu awọn ẹbi awọn eeyan to padanu ẹmi wọn ninu.
Ọga agba ileeṣẹ panpana ipinlẹ Kwara, CFO Falade Olumuyiwa John rọ awọn awakọ lati maa tẹẹ jẹjẹ nitori ẹmi o laarọ.
Dubai citizenship: Báyìí ni o ṣe lè di ọmọ onílùú ní Dubai pẹ̀lú òfin tuntun orílẹ́èdè U.A.E.
Oríṣun àwòrán, Twitter/Sheikh Mohammed
Orilẹede United Arab Emirates yoo bẹrẹ si ni maa fawọn alejo ni iwe igbelu fun igba akọkọ ninu itan ilẹ naa.
Amọ awọn isọri eeyan kan to le ṣe anfaani funh orilẹede naa ni ijọba pinnu lati maa fun ni iwe igbelu.
Igbakeji aarẹ ilẹ UAE to tun jẹ olori ilu Dubai, Sheikh Mohammed bin Rashid al Maktoum lo fọrọ yii lede lori ẹrọ ayelujara Twitter lọjọ Abamẹta.
Rashid al Maktoum ṣalaye pe ijọba orilẹede UAE ti pinnu lati maa fun awọn akọṣẹ-mọṣẹ, atawọn ti Eleduwa fun lẹbun ara ọtọ ni iwe igbeluu.
Awọn onimọ sayẹnsi, awọn onimọ ẹrọ, onkọwe, awọn oṣere atawọn ẹbi wọn naa yoo lanfaani si iwe igbeluu orilẹede UAE.
Oríṣun àwòrán, Twitter/Sheikh Mohammed
Adari ilu Dubai ni igbimọ alaṣẹ orilẹede UAE, ileẹjọ abẹle Emiri atawọn igbimọ alaṣẹ mii ni yoo maa yan awọn to ba kun oju oṣunwọn lati gba iwe igbeluu.
Bakan naa, awọn to ba gba iwe igbeluu UAE yoo lanfaani lati maa jẹ ọmọ orilẹede abinibi wọn.
Ninu oṣu kọkanla ọdun 2020 ni ijọba ilẹ UAE kede pe oun yoo maa fawọn alejo to ba ti kawe gba oye ọmọwe ni fasiti ni fisa ọdun mẹwaa.
Fisa naa wa fun awọn to ba  kẹkọọ gboye lawọn ile iwe giga fasiti ti orilẹede UAE ba ni ajọṣepọ pẹlu wọn.
Awọn dokita oniṣegun oyinbo to ba tin gbe orilẹede UAE naa lanfaani lati gba irufẹ fisa yii.
Pangolin Covid-19: Ẹ wo ẹranko tó ṣeéṣe kó ní ǹkan ṣe pẹ̀lú à[rùn Coronavirus!
Sunday Igboho: Òfin kóńlé-ó-gbélé gbòde n'Ibarapa lórí ẹ̀rù pé Fulani le k'ógun wá lẹ́yìn àbẹ̀wò Igboho
Ibẹru-bojo gbalẹ niluu Igangan lagbegbe Ibarapa nipinlẹ Oyo lẹyin ikọlu to waye laarin ajijagbara Sunday Adeyemo ti ọpọ mọ si Sunday Igboho atawọn Fulani lagbegbe ọhun.
Koda awọn olori agbegbe naa ti kede ofin konle-o-gbele lati aṣaalẹ ti idaji aarọ.
Eyi wa lara awọn igbesẹ lati dena awọn Fulani to le fẹ pada wa gbẹsan lẹyin ti ikọlu pẹlu Igboho.
Ti ẹ ko ba gbagbe, Igboho pẹlu ero lẹyin yabo ibugbe awọn Fulani niluu Igangan lẹyin to fun wọn lọjọ meje lati fi Ibarapa silẹ.
Lati igba naa lẹru ti n bawọn ara ilu Igangan pe awọn Fulani le gbeja wa ko wọn.
Pangolin Covid-19: Ẹ wo ẹranko tó ṣeéṣe kó ní ǹkan ṣe pẹ̀lú à[rùn Coronavirus!
Awọn eeyan agbegbe naa kepe ijọba lati ṣe iwadii Seriki Fulani ipinlẹ Oyo, Abdulkadir Saliu lori ẹsun ijinigbe atawọn ẹsun iwa ọdaran mii ti wọn fi kan an
Oludasilẹ ẹgbẹ to n ri si idagbasoke ile Igangan, Ọgbẹni Oladokun Oladiran sọ fawọn akọroyin pe awọn eeyan agbegbe naa ṣe ofin konle-o-gbele nitori awọn ko ni igbagbọ ninu eto abo ti ijọba pese fawọn.
Ọgbẹni Oladiran ṣalaye pe awọn ko ti ri awọn ẹṣọ Amotekun igba ti Gomina Seyi Makinde kede pe oun ti ran si agbegbe naa.
O rọ Makinde pe ki o ṣe abẹwo si agbegbe Ibarapa lati fi oju ara rẹ ri ohun to n ṣẹlẹ gan an nibẹ pẹlu awọn Fulani darandran.
Ọgbẹni Oladiran ṣalaye siwaju sii pe awọn Fulani si wa lawọn agbegbe bii Ile Bamogba ati AUD niluu Igangan lai si wahala kankan.
Lawal Ayankemi Oluwatoyin: Mo kọ̀ láti máa tọrọ owó nítorí ojú mi tó fọ́, iṣẹ́ ló wù mí
''Ṣugbọn ohun tawọn eeyan ilu Igangan ko fẹ ni awọn Fulani kan to n huwa ọdaran.
Japanese Woman: ''Èmi àti òkú ìyá mí ni a jọ ń gbé fún ọdún mẹ́wàá ''
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ileeṣẹ ọlọpaa lorilẹede Japan ti fi panpẹ ofin mu obinrin to gbe oku iya rẹ si inu ile ninu ẹrọ amuohuntutu fun ọdun mẹwaa.
Arabinrin Yomi Yoshino to jẹ ẹni ọdun mejidinlaadọta ni o sọ wi pe oun ba oku iya oun ninu ile ti wọn jọ n gbe, lo ba tii mọ inu ẹrọ amuohuntutu.
O ni idi ti oun fi ṣe bẹẹ ni pe oun ko fẹ ko kuro ninu ile ti awọn jọ n gbe ni Tokyo.
Ninu ile itura kan ni ilu Chiba to sunmo Tokyo ni wọn ti fi panpẹ ọba mu arabinrin to gbe oku iya rẹ sinu ẹrọ amohuntuntun naa.
Oríṣun àwòrán, others
Ikọ ọlọpaa ni ko si oju apa kankan lara oku to ti gan to wa ninu ẹrọamohuntutu naa.
Bakan naa ni ijọba sọ wi pe awọn ko lee sọ igba ti arabinrin naa ti ku tabi iru iku to pa a.
Ikọ ọlọpaa ni iwadii fihan pe ọmọbinrin naa sun oku iya rẹ ki, ko to le e gba inu amuohun tutu to gbe oku naa si.
Mckinley Erves di ẹni tọ ń ríran rí aàwọ̀ nípasẹ̀ ìrànlọ́wọ́ ọ̀rẹ́ rẹ̀
Ibadan Violence: Ṣé lóòtọ́ ní àwọn jàǹdùkú jó ìlé 200 àti ọ̀kọ́ 29 ní Ibadan?
Oríṣun àwòrán, AFP
Laipẹ yii ni iroyin fi lede wi pe awọn janduku ti sọ ina si ile to le ni igba, ti wọn si jo ọkọ ayọkẹlẹ to le ni ogun ni ilu Ibadan, ni ipinlẹ Oyo.
Agbegbe Odo-Osun/Ita Baale/Aderogba ni ilu Ibadan ni iroyin naa sọ wi pe iṣẹlẹ naa ti waye.
Amọ, ileeṣẹ ọlọpaa ti fi lede wi pe ko si ohun to jọ bẹẹ to waye, ati wi pe awọn oniroyin  ẹlẹjẹ lo gbe iroyin naa.
Ninu atẹjade ti alukoro ọlọpaa nipinlẹ Oyo, Olugbenga Fadeyi fi lede lo ti sọ wi pe ọwọ awọn tẹ janduku mẹfa to ṣọṣẹ ni agbegbe Labiran ni Ọgbọnjọ, Osu Kini, ọdun 2021.
Fadeyi ni ohun to ṣẹlẹ ni pe awọn janduku to wa ni agbegbe naa jade sita ni Ọjọ Kọkandinlọgbọn, Oṣu Kinni, ọdun 2021 lati ṣekọlu si awọn ile itaja to wa ni agbegbe naa, ti wọn si dana si oju kan nibi ti wọn pagọ si.
Mckinley Erves di ẹni tọ ń ríran rí aàwọ̀ nípasẹ̀ ìrànlọ́wọ́ ọ̀rẹ́ rẹ̀
O ni ile kan ati ileesẹ itaja ni wọn kọlu, ti eyi si jasi ipe gbajawiri ti wọn pe awọn ọlọpaa lati pese alaafia si agbegbe naa.
Awọn janduku naa jade ni agbegbe Aderogba ni asalẹ ti wọn si kọlu agbegbe Bayerunka ati Ogbori Efon ni ilu Ibadan.
''Awọn ọlọpaa ati ikọ Amọtẹkun ni wọn ran lọ si agbegbe naa, ki wọn to ri awọn kan mu, ti wọn si pa ina ti wọn da si agbegbe naa.''
Eleyii mu ki awọn janduku naa sa kuro ni agbegbe naa, ti alaafia si ti jọba.
Alukoro ọlọpaa naa fikun pe awọn ti bẹrẹ si ti tọpasẹ awọn janduku to ku, ki awọn le fi panpẹ ọba mu wọn, ki wọn si gbe wọn lọ si ileẹjọ.
Lawal Ayankemi Oluwatoyin: Mo kọ̀ láti máa tọrọ owó nítorí ojú mi tó fọ́, iṣẹ́ ló wù mí
Iroyin to tẹ wa lọwọ lati ilu Ibadan sọ pe, awọn afurasi janduku kan ti ṣe ikọlu sawọn ọlọpaa nitori bi wọn se mu awọn afurasi meji ti wọn lo n da omi alaafia ilu ru.
Oríṣun àwòrán, @PoliceNG
A gbọ pe ikọlu naa bẹrẹ lagbegbe Odo-Osun lọjọbọ, ti o si tan de agọ ọlọpaa to wa ni Mapo.
Eeyan meji  ku ninu iṣẹlẹ naa gẹgẹ bi iroyin to tẹ wa lọwọ ti wi.
Lọjọbọ ni awọn ọlọpaa mu awọn janduku meji kan ladugbo Odo-Osun nitosi Mapo.
Bi awọn akẹgbẹ wọn ṣe ri pe ọwọ ti tẹ wọn, ni wọn gbiyanju lati fipa tu wọn silẹ lọwọ awọn ọlọpaa.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Amọ ṣa, ọlọpaa ṣina bolẹ fun wọn ni agbegbe Odo-Osun ti eeyan kan si ku nibẹ.
Lẹyin ikọlu ti Odo-Osun yii, awọn janduku taa n wi yi tun ṣigun lọ si agọ ọlọpaa to wa ni Mapo, lati fẹhonu han lori eeyan wọn kan ti o ku.
Ninu wọdu-wọdu to waye nibẹ, awọn ọlọpaa tun yinbọn lati daabo bo agọ wọn, eeyan kan tun fara gbọta to si gba ibẹ ku.
Ilorin Conjoined Twins: Àwọn òbí ìbejì tó lẹ̀pọ̀ ní ọ̀kàn àwọn bàjẹ́ láti rí ibèjì wọn tó
Alukoro ọlọpaa ni ipinlẹ Oyo, Olugbenga Fadeyi fidi iṣẹlẹ yii mulẹ fawọn akọroyin ninu atẹjade kan to fi sita.
O ni ''lẹyin tawọn ọlọpaa mu awọn janduku meji kan, arakunrin kan ti wọn n pe orukọ rẹ ni ''Packaging'' lewaju awọn janduku mii to to ọgbọn,
lati ṣigun bo agọ ọlọpaa, ki wọn le tu akẹẹgbẹ wọn silẹ''
LASTMA Yesufa: Àwọn dókítà gbìyànjú lórí ojú mi ṣùgbọ́n...
Tolulope Adeleke Aire: Mo wòye pé àwọn ọkùnrin Nàìjíríà kò fi bẹ́ẹ̀ mọ̀ nípa ìtọ́jú ọmọ tuntun
Tolulopa Adeleke Aire ṣalaye idi to fi gbe eto itọju ikoko kalẹ fun awọn baba ọmọ tuntun.
Eyin alaboyun, kii ṣe ẹyin nikan ni ẹ le da ọmọ yin tọ o.
Tọkọtaya ti wọn jọ fun ara wọn loyun naa ni ki wọn jọ tọju ikoko naa.
Ona abayọ si iṣoro aini oluranlọwọ ni Noọsi Tolulọpẹ Adeleke Aire n kọ awọn ọkunrin.
Akọṣẹmọṣẹ nọọsi ni Naijiria ati ni Ilẹ United Kingdom ni Tolulope Adeleke Aire to n kọ awọn ọkunrin ni Naijiria lati tun ero wọn pa nipa riran iyawo wọn lọwọ lati tọju ikoko.
O n kọ wọn nipa igbẹbi, itọju alaboyun ati ẹni to ṣẹṣẹ bimọ tuntun sọwọ.
Abdullahi, Ẹni ọdún 52 rí ẹ̀wọ̀n he nítorí pé ó jí fóònù méjì gbé ní Abeokuta
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ileẹjọ Majisireti nipinlẹ Ogun ti ran arakunrin ẹni ọdun mejilelaadọta lọ si ẹwọn oṣu mẹta nitori o ji ẹrọ ilewo meji ni ilu Abẹokuta.
Lasiko ti o ba wa ni ẹwọn yii ni yoo ma ṣiṣẹ ilu ni agbegbe agọ ọlọpaa Adigbe ni ilu Abẹokuta to jẹ olu ilu ipinlẹ Ogun.
Arakunrin Abdullahi ti wọn ko fi adirẹsi rẹ si ita ni Adajọ ni wi pe o jẹbi ẹsun iwa ole.
Adajọ Majisreti, Dehinde Dipeolu lo ran arakunrin Abdullahi lọ si ẹwọn naa lẹyin to jẹwọ wi pe lootọ ni oun jale, to si bẹ ileẹjọ wi pe oun ko ni ṣe bẹẹ mọ.
Lasiko ti igbẹjọ naa n lọ lọwọ ni agbẹjọrọ Lawrence Olu-Balogun ni Ọjọ Kọkandinlogun, Osu Kini ni arakunrin naa jale ni agbegbe Panseke ni Abeokuta ni ipinlẹ Ogun.
Lawrence ni  Abdullahi wọ sọọbu meji ni agbegbe naa ni bi ti wọn ti n ṣiṣẹ ẹrọ kọmputa ati ileeṣẹ ti wọn ti n ran aṣọ ni agbegbe naa.
Tolulope Adeleke Aire: Mo wòye pé àwọn ọkùnrin Nàìjíríà kò fi bẹ́ẹ̀ mọ̀ nípa ìtọ́jú ọmọ tu
Lẹyin yo wọle tan lo ba ṣe bi ẹni pe o fẹ ki wọn ba oun ṣe iṣẹ, amọ ohun ini wọn lo ko lọ.
''Abdullahi wọ sọọbu Ogundipe, to si sọ wi pe ohun fẹ ṣe I.D kaadi , amọ nigba ti Ogundipe n ba awọn onibara miran sọrọ lọwọ, lo mu foomu rẹ ti iye owo rẹ jẹ N54,000, to si yọ lọ.''
''Lẹyin naa lo lọ si sọọbu Arakunrin Olorunmade, to si sọ wi pe oun fẹ ran aṣọ, amọ o ri i wi pe ko si ẹni to kọju si oun, o si ji foonu miran nibẹ ti iye owo rẹ jẹ N42,000''
Adajọ lasiko to n ka idajọ rẹ ni wi pe iwa ole jija tako ofin ipinlẹ Ogun, iyẹn section 390 (9) ti criminal code laws ti ọdun 2006, ni ipinlẹ Ogun.
Lẹyin naa lo ni ki ọkunrin to jale naa, Abdullahi ni ko lọ sin ilu fun oṣu mẹta nipa titun ayika ṣe, ko ma gba awọn ibi to dọti ko si maa ko idọti oju popo ni Adigbe.
LASTMA Yesufa: Àwọn dókítà gbìyànjú lórí ojú mi ṣùgbọ́n...
Cash grant: Ìjọba àpapọ̀ bẹ̀rẹ̀ sísan N20,000 owó ìrànwọ́ fáwọn obìnrin igbèríko l'Ogun
Oríṣun àwòrán, Twitter/Federal Ministry of Humanitarian Affairs
Ijọba apapọ ti bẹrẹ si ni san owo iranwọ ẹgbẹrun lọna ogun naira(N20,000) fawọn obinrin ẹgbẹrun mẹta ati abọ(3500) to wa ni igberiko nipinlẹ Ogun.
Ijọba ibilẹ ogun to wa ni ipinlẹ naa lawọn obinrin ọhun ti wa.
Minisita fun ileeṣẹ ijọba to n ri si ṣiṣe iranwọ fun araalu ati idasoke awọn eeyan, Hajiya Sadiya Faruq lo fi eto naa lọlẹ niluu Abeokuta lopin ọsẹ to lọ.
Hajiya Faruq ti akọwe agba ileeṣẹ ijọba naa, Bashir Alkali ṣoju nibi ayẹyẹ ọhun ṣalaye pe eto naa wa fun fifa awọn ti ko rọwọ họri soke.
O ni ijọba Aarẹ Muhammadu Buhari ti n ṣeranwọ fawọn talaka lati ibẹrẹ ijọba rẹ, bo tilẹ jẹ pe idojukọ pọ fun ijọba rẹ.
Minisita ni dindin iṣẹ ku lawujọ ti di eto ti gbogbo awọn ijọba orilẹede agbaye n ṣe bayii.
''Eyi lo mu ki Aarẹ Buhari ṣe agbekalẹ eto iranwọ fawọn eeyan,  National Social Investment Programme (NSIP) lati le din oṣi ku ni Naijiria,'' minisita lo sọ bẹẹ.
Hayiya Faruq ni eto NSIP ti ni ipa to dara laye awọn ọmọ Naijiria lati igba to ti bẹrẹ lọdun 2016.
Minisita sọ pe akọsilẹ fihan pe miliọnu mejila eeyan lo ti jẹ anfaani eto ọhun lati igba to ti bẹrẹ ni Naijira.
O ni bakan naa ni ijọba tun n san ẹgbẹrun marun naira fawọn eeyan bi miliọnu kan ti wọn ko rọwọ họri lawujọ.
Hajiya Faruq fikun ọrọ rẹ pe awọn olokoowo kekeke naa ti jẹ anfaani ẹyawo labẹ ijọba Aarẹ Muhammadu Buhari.
Fulani herders: Ṣé lóòtọ́ọ́ láwọn Fulani tún ṣá aráàlú Igangan méjì ládàá nínú ilé wọn?
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Iroyin to tẹ wa lọwọ lati ilu Igangan lagbegbe Ibarapa nipinlẹ Oyo sọ pe awọn afurasi Fulani darandaran ṣa Ọgbẹni Adekola Adeyemo, ẹni ọdun marunlelọgọta lori.
Bakan naa ni a tun gbọ pe awọn Fulani ọhun tun ṣa Jamiu Saedu, ẹni ọgbọn ọdun ladaa lori.
Iroyin sọ pe awọn mejeeji n sun lọwọ ninu ile wọn nigba ti awọn Fulani ọhun lọ kawọn mọle.
Eekan ilu Igangan kan, ọgbẹni Taiwo Adeagbo sọ fawọn akọroyin pe awọn eeyan mejeeji ti n wa nile iwosan nibi ti wọn ti n gba itọju bayii.
Ọgbẹni Adeagbo fikun ọrọ rẹ pe ẹjọ naa ti de ọdọ awọn ọlọpaa fun iwadii.
Ẹwẹ, awọn araalu ilu Kajola ati Gbagba ni ijọba ibilẹ Ayete lagbegbe Ibarapa nipinlẹ Oyo ni a gbọ pe wọn ti fi ilu wọn silẹ bayii.
Awọn araalu ọhun sọ fawọn akọroyin pe Fulani kan ti orukọ rẹ n jẹ, Iskilu Wakil lawọn sọ fun pe ko fi ori ilẹ to wa silẹ nitori ko ra ilẹ naa lọwọ ẹnikan kan.
Eleyi ni iroyin sọ pe o bi Wakil ninu ti o si bẹrẹ si ni leri pe oun ni oriṣiiriṣii ija oloro lakata oun.
Lawal Ayankemi Oluwatoyin: Mo kọ̀ láti máa tọrọ owó nítorí ojú mi tó fọ́, iṣẹ́ ló wù mí
Asawo ti Ayete, Oba Emmanuel Okeniyi ṣalaye pe ọpọ awọn agbẹ lo ki fi oko wọn silẹ lọ lori ẹru pe Wakil le wa ṣe wọn ni ijamba.
Oba Okeniyi sọ pe lootọọ ni Gomina Seyi Makinde ipinlẹ ti ran awọn ẹṣẹ Amotekun wa si Ayete, ṣugbọn o ni awọn ẹṣọ naa ko tii lọ sawọn ilu to wa ni Ayete.
Ẹnikan to ko fẹ ki a darukọ rẹ ṣalaye pe niṣe ni Wakil atawọn ọmọọṣẹ rẹ lọ di ọna to lọ si awọn ilu meji yii to si sọ pe oun ṣetan lati yinbọn fun araalu to ba sun mọ ibẹ.
Agbẹnusọ ileeṣẹ ọlọpaa ipinlẹ Oyo, Olugbenga Fadeyi ṣalaye fun BBC Yoruba pe awọn agbofinro ti wa kaakiri agbegbe Ibarapa lati ri pe ko si ẹni to ṣe nkan to tapa si ofin.
Ọgbẹni Fadeyi ni ko si ewu fawọn araalu to wa lagbegbe Ibarapa.
Bakan naa lo sọ pe ileeṣẹ ọlọpaa ti bẹrẹ iwadii lori iṣẹlẹ awọn afursai Fulani ti wọn ni wọn ṣa awọn araalu ilu ladaa.
Pangolin Covid-19: Ẹ wo ẹranko tó ṣeéṣe kó ní ǹkan ṣe pẹ̀lú à[rùn Coronavirus!
Driving offence: Àjọ FRSC kìlọ̀ f'áwọn awakọ̀ tó máa tẹ fóònù lórí ìrin ní ìpínlẹ̀ Eko.
Oríṣun àwòrán, FRSC
Ajọ ẹṣọ oju popo ti kilọ fawọn awakọ to maa n tẹ foonu lori irin nipinlẹ Eko pe ki wọn so ewe agbejẹ mọwọ.
Ọga ajọ FRSC nipinlẹ Eko, CC Olusegun Ogungbemide lo sọrọ ikilọ yii ninu atẹjade kan ti ajọ naa fi sita lọjọ Aiku.
Ogungbemide ni gbogbo awọn ẹṣọ lo ti wa lojufo bayii lati maa mu ẹnikẹni ti aje iru iwa ba ṣi mọ lori.
Ọga ajọ FRSC ni awọn ẹṣọ oju popo ko le laju silẹ ki wọn maa wo awọn to n tapa si ofin ọkọ wiwa popo ki wọn maa ṣe ohun to lodi sofin.
''Gbogbo awakọ ni ofin oju popo wa fun, eyi lo yẹ ki wọn ṣe awọn nkan ti ko le ge ẹmi wọn kuru lojiji,'' Ogungbemide ṣalaye.
Lawal Ayankemi Oluwatoyin: Mo kọ̀ láti máa tọrọ owó nítorí ojú mi tó fọ́, iṣẹ́ ló wù mí
Ọga ajọ FRSC nipinlẹ Eko ṣalaye pe o wa ninu ofin irina pe awakọ kankan ko gbọdọ lo foonu lọna kọna nigba ti o ba wa lori irin.
O ni bakan naa ni ofin ọhun tun sọ pe olukọni ni ọkọ wiwa gan an ko gbọdọ pe ẹnikẹni lori foonu tabi gba ipe.
Pangolin Covid-19: Ẹ wo ẹranko tó ṣeéṣe kó ní ǹkan ṣe pẹ̀lú à[rùn Coronavirus!
Ogungbemide ni awọn ofin naa ree lẹyọkọọkan:
Ọga ajọ FRSC nipinlẹ Eko ṣalaye pe fun anfaani ''ara wa ni gbogbo awọn ofin yii wa fun.''
Ogungbemide ni ọpọ awakọ lo ṣagbako iku ojiji lori titẹ foonu nigba ti wọn n wakọ.
Mckinley Erves di ẹni tọ ń ríran rí aàwọ̀ nípasẹ̀ ìrànlọ́wọ́ ọ̀rẹ́ rẹ̀
Big breast: Damilola Adegboro, Oluwaseun Amoo, Remi Fatolu: Ẹlòmíì ń fi irú ọyàn wa tọrọ
Ariwo ọyàn ńlá ló máa ń tẹ̀lẹ́ mi ní gbogbo 'bus stop'- Damilola Tosin Adegboro
Leyin iforowanilenuwo BBC pẹlu Remi Fatolu, ọpọ obinrin miran to lọyan naa tún ti jáde sita sọrọ soke nipa idẹyẹsi ti oju wọn n ri.
Damilola Oluwatosin Adegboro ati Oluwaseun Amoo jade sita wa sọ idẹyẹsi ti awọn n koju nitori ọyan aya wọn bo ṣe tobi to.
Oluwatosin ni orin Ọlọmurọrọ maa wolẹ ni awọn kan gana an ma n kọ fun oun ni eyi to jẹ orin aalọ apagbe to ṣafihan obinrin to lọyan.
Remi Fatolu ni inu oun dun pe oun ṣe ifọrọwanilẹnuwo naa pelu BBC nitori pe nkan yi pada pẹlu oju ti awọn eeyan fi n wo oun ni awujọ.Remilekun Fatolu bú sẹ́kún fún ohun tó ti pàdánù láyé torí ọyàn ńla rẹ̀.
Tosin Adegboro ni oju onidọti ni ọpọ ọkunrin fi n wo awọn to lọyan, ṣugbọn irọ ni eyi.
Ọpọ ọkunrin lo wu lati maa fẹ awa ti a ni ọyan nla ṣugbọn wọn ko fẹ gbe wa silẹ bii iyawo- Oluwatosin Adegboro.
Awọn obinrin miran maa n bẹbé pe ki n fun awọn ni diẹ lara ọyan mi ni, ọyan naa ti su mi.
Wọn mẹnuba awọn ipenija ti wọn n ri lawujọ ati eebu lọdọ awọn obinrin miran lori ọyan nla wọn.
Tosin ni ọpọ igba ni oju maa n ti oun nitori ọyan nla naa.
Mi ò kí ń fẹ́ ya fọ́tò tabi ki n jade kuro nile nitori eèbú nipa ọyan nla ti mo ni- Tosin Adegboro
Ọpọ maa n jẹ ko dabi pe iwọ lo da ara ẹ pẹlu ọyan nla tabi ohun to wu eeyan ni.
Remi Fatolu gab awọn obinrin to ni ipenija yii nimọran lati jade sita sórọ ki wọn si gab kadara ki ara wọn le fuyẹ.
Oluwaseun Amoo ni ki awọn eeyna dẹkun idẹyẹsi obinrin to ba ni ọyan nla nitori pe ko rọrun rara.
Oluwatosin Adegboro ni ko wu ẹni to ni ọyan nla naa bẹẹ nitori pe oun kọ lo da ara rẹ ati pe ọrọ awọn eeyan maa n fa ironu ati ibanujẹ ti eeyan ko ba ṣọra.
2nd wave Covid-19 in Nigeria: Ìjọba ìpínlẹ̀ Eko ti f'òfin de ìpéjọpọ̀ tó bá ju àádọ́ta (50) èèyàn lọ torí coronavirus
Oríṣun àwòrán, Twitter/Babajide Sanwo-Olu
Bi ina ko ba tan laṣọ, ẹjẹ kii tan leekanna lọrọ ajakalẹ arun covid-19 da bayii nipinlẹ Eko.
Lẹyin ti arun naa n fi ojoojumọ pọ si ni Naijiria papaa julọ nipinlẹ Eko, Gomina Babajide Sanwo-Olu ti kede pe ijọba ti fofin de ipejọpọ to ba ti ju aadọta eeyan lọ bayii kaakiri ipinlẹ naa.
Sanwo-Olu fọrọ yii lede ninu atẹjade kan to fi sita lọjọ Aiku.
Amọ, gomina ṣalaye ninu atẹjade ọhun pe ofin naa ko kan awọn ile ijọsin nipinlẹ Eko ti ijọba ti sọ fun tẹlẹ pe ki wọn ma ju idaji awọn olujọsin to n maa n jọsin tẹlẹ lọ ninu gbọngan ti wọn n lo.
''Inu ijọba ipinlẹ Eko ko dun si bi ọpọ eeyan ti n tapa si ilana ati dena ajakalẹ coronavirus,'' Sanwo-Olu lo bẹẹ.
Big breast: Oluwatosin Adegboro, Oluwaseun Amoo, Remi Fatolu: Ẹlòmíì ń fi irú ọyàn wa tọrọ
Gomina Sanwo-Olu sọ pe ọpọ awọn eeyan to ni gbọngan ayẹyẹ lo ti n tapa si awọn alakalẹ ofin lori ati dena covid-19.
''Eyi ni lati kilọ gbogbo awọn to ba n ṣe iruẹ lati ki ọwọ ọmọ wọn bọṣọ, bi bẹẹ kọ, wọn o fi oju wina ofin,'' Sanwo-Olu kilọ.
Mckinley Erves di ẹni tọ ń ríran rí aàwọ̀ nípasẹ̀ ìrànlọ́wọ́ ọ̀rẹ́ rẹ̀
Sanwo-ọlu ṣalaye pe ''gẹgẹ bi ofin ti Aarẹ Muhammadu Buhari buwọlu, ẹnikẹni ti aje iwa ibajẹ yii ba ṣi mọ lori yoo san owo itanran tabi ko ṣẹwọn oṣu mẹfa tabi ko ṣewọn ko si tun sanwo itanran.
Oríṣun àwòrán, Babajide Sanwo-Olu
Gomina ni gbogbo olugbe ipinlẹ Eko lo gbọdọ maa tẹle alakalẹ ati dena ajakalẹ arun coronavirus bayii.
Tolulope Adeleke Aire: Mo wòye pé àwọn ọkùnrin Nàìjíríà kò fi bẹ́ẹ̀ mọ̀ nípa ìtọ́jú ọmọ tu
Alleged threat to life: Ọmọ ọdún mẹ́tàdínlógún (17) káwọ́ sẹ́yìn rojọ́ lórí ẹ̀sùn ìdúnkookò láti gbẹ̀mí ìyá rẹ̀''
Oríṣun àwòrán, @others
Ija kò dọlà, orúkọ lo n sọ ni
Ọmọkunrin kan, Quadri Taiwo ti dero ileẹjọ niluu Eko lori ẹsun pe o n dunkoko lati gbẹmi iya rẹ.
Taiwo ẹni ọdun mẹtadinlogun kawọ sẹyin rojọ nileẹjọ majisireeti ni Ikeja lọjọ Aje ọjọ kinni, oṣu keji, ọdun 2021 yii.
Ileeṣẹ ọlọpaa ipinlẹ Eko fẹsun kan Taiwo pe o n dunkoko lati gbẹmi iya rẹ ati pe o n fa wahala eyi to lodi si ofin ipinlẹ naa.
Amọ, Taiwo sọ fun ileẹjọ pe oun ko jẹbi ẹsun ti wọn fi kan oun.
Olupẹjọ ASP Kehinde Ajayi ṣalaye fun ileẹjọ pe Taiwo oṣu kọkanla ọdun 2020 ni iṣẹlẹ ọhun ṣẹlẹ ni opopona Balogun lagbegbe Orile-Agege.
Ajayi ni Taiwo dunkoko mọ iya rẹ, arabinrin Mojisola Taiwo lẹyin ede-ai-ede laarin awọn mejeeji.
Akomolede ati Asa Ondo: Wo ìdí tí Yorùbá ṣe ń lo Ìjàpá ni olú ẹ̀dá ìtàn Àlọ́ Àpagbé- Oyelo
Bakan naa ni ASP Ajayi sọ pe Taiwo ko gba alaafia laaye lẹyin to fi oriṣii atẹjiṣẹ eebu si iya rẹ.
''Lẹyin iwadii ti a ṣe ni a to fi ọwọ ofin mu Taiwo,'' ASP Ajayi ṣalaye.
Tolulope Adeleke Aire: Mo wòye pé àwọn ọkùnrin Nàìjíríà kò fi bẹ́ẹ̀ mọ̀ nípa ìtọ́jú ọmọ tu
Adajọ majisireeti, Arabinrin A.O. Ajibade gba beeli N50,000 fun Taiwo pẹlu oniduro kan.
O sun ẹjọ naa siwaju titi di ọjọ kọkanla, oṣu keji.
Big breast: Oluwatosin Adegboro, Oluwaseun Amoo, Remi Fatolu: Ẹlòmíì ń fi irú ọyàn wa tọrọ
Sunday Igboho Ogun trip vs Fulani: Mó wá sí ìpínlẹ̀ Ogun láti lé àwọn Fulani ajínigbé dànù lórí ilẹ̀ Yorùbá
Sunday Igboho: 'Ǹkan tÍ Sunday Igboho Ṣe ní Ibarapa tún ti ṣelẹ̀ ní ìpínlẹ̀ Ogun'
Adari egbe Miyetti Allah ni ile Yoruba, Muhammed Kabir Labar ni nkan tÍ Sunday Igboho Ṣe ní Ibarapa tún ti ṣelẹ̀ ní ìpínlẹ̀ Ogun
Kabir Labar  lo so bee fun BBC Yoruba.
Labar fẹsun kan Sunday Igboho pe bi o ṣe ṣẹlẹ lẹyin ti o kuro ni Igangan naa tun ti ṣẹlẹ ní Ogun.
Wọn dana sun ile Seriki ni agbegbe Ijọba ibilẹ Igbowa, ni ipinlẹ Ogun.
Oríṣun àwòrán, Facebook/Africa Eyes
Ìjọba ìpínlẹ̀ Ogun kọ́ ló pé Sunday Igboho, ó kàn wá fúnra rẹ ni- Kọ̀míṣọ̀nná Ogun
Kọsmiṣọnna fun ifitonileti ni ipinlẹ Ogun, Abdulwaheed Odusile ti ni ki awọn eeyan mẹnu kuro lori koko pe Gomina Dapo Abiodun lo ranse pe Suinday Igboho.
Odusile fi atẹjade naa sita ni Abeokuta to jẹ olu ilu ipinle Ogun lẹyin ti Sunday Adeyemi wa si ipinlẹ Ogun wa kilọ iwa buruku fawon Fulani ajinigbe.
Kọmiṣọnna salaye ohun to ṣẹlẹ pe, Remi Hazzan to jẹ olubadamọran fun gomina Dapo Abiodun lori ibaraenisoro ni awọn kan dori ọrọ rẹ kodo.
Akomolede ati Asa Ondo: Wo ìdí tí Yorùbá ṣe ń lo Ìjàpá ni olú ẹ̀dá ìtàn Àlọ́ Àpagbé- Oyelo
O ni wọn yi ọrọ Hazzan ninu ifọrọwanilẹnuwo kan to ṣe ṣaaju ki Sunday Adeyemo ti ọpọ n pe ni Sunday Igboho to wa si Yewa nirọlẹ ana.
Odusilẹ ni nitootọ ni Hazzan ni ijọba Dapọ Abiodun yoo fọwọsopọ pẹlu awọn ti ọrọ kan ninu ile ati ni ia lati rii pe eto aabo wa fun awọn eniyan ipinlẹ Ogun ṣugbọn ko darukọ pe Sunday Igboho ni wọn n ranṣẹ pe.
O ni rioyin pe ijọba ranṣẹ pe Oloye sunday Igboho lati wa daabo bo awọn eeyan ipinlẹ Ogun jẹ irọ.
Odusilẹ ni ijọba gomina Dapo Abiodun n ko gbogbo eeyan mọra, ko dẹyẹ si ẹnikẹni ati pe ko si ẹni ti ko le fọwọsowọpọ pẹlu fun idagbasoke ati eto aabo ipinlẹ Ogun.
Oríṣun àwòrán, Facebook/Africa Eyes
Ki lo ti kọkọ ṣẹlẹ sẹyin?
Mó wá sí ìpínlẹ̀ Ogun láti lé àwọn Fulani ajínigbé dànù lórí ilẹ̀ Yorùbá- Sunday Igboho
Iroyin to tẹ wa lọwọ lati ipinlẹ Ogun sọ pe gbajugbaja ajijagbara ilẹ Yoruba, Sunday Adeyemo ti ọpọ mọ si Sunday Igboho ti gunlẹ si ipinlẹ Ogun lati kọju ija sawọn janduku Fulani to n huwa ọdaran nibẹ.
Ohun iroyin to tẹ wa lọwọ sọ pe aarọ ọjọ Aje, ọjọ kinini, oṣu keji ni Igboho fi ilu Ibadan silẹ lọ si ipinlẹ Ogun.
Tolulope Adeleke Aire: Mo wòye pé àwọn ọkùnrin Nàìjíríà kò fi bẹ́ẹ̀ mọ̀ nípa ìtọ́jú ọmọ tu
''A o ba awọn agbaagba ni Yewa ṣe ipade pọ, a si ti wa ni ilẹ Yewa bayii,'' Ọgbẹni Akinpelu ṣalaye.
Fidio kan lori ayelujara ṣe afihan Igboho fun ra rẹ nibi to ti n ba awọn ọmọ ipinlẹ sọrọ ni Ilu Ọja Ọdan.
''Ipinlẹ Ogun ni mo wa bayii, mo wa gba awọn ọmọ Yoruba silẹ lọwọ awọn Fulani ajinigbe, awọn Fulani to fi ipa bawọn obinrin lopọ,'' Igboho sọrọ soke.
Igboho tun ni ''a ko fẹ Fulani ajinigbe mọ lori ilẹ baba wa, o to gẹẹ bayii.''
''O ya ẹ jẹ ki a wọ inu igbo Idua lọ bayii lati lọ pade awọn Fulani to n ji awọn Yoruba gbe.
Ọkan lara awọn ọmọlẹyin Igboho, Ọgbẹni Sina Akinpẹlu to ba BBC Yoruba sọrọ ṣalaye pe Igboho atawọn ọmọlẹyin rẹ gbera lọ si ipinlẹ lati kilọ fawọn Fulani lati so ewe agbejẹ mọwọ bi bẹẹ kọ, wọn o jẹ iyan wọn niṣu.
Ọgbẹni Akinpelu ṣalaye pe ko si ẹni to ranṣẹ pe Igboho atawọn ọmọlẹyin ni pato,
O ni Igboho atawọn to kọwọ rin pẹlu rẹ fi ọrọ naa to awọn lọbalọba leti pe awọn n bọ wa si ipinlẹ Ogun.
Big breast: Oluwatosin Adegboro, Oluwaseun Amoo, Remi Fatolu: Ẹlòmíì ń fi irú ọyàn wa tọrọ
''A o ba awọn agbaagba ni Yewa ṣe ipade pọ, a si ti wa ni ilẹ Yewa bayii,'' Ọgbẹni Akinpelu ṣalaye.
Akinpelu sọ pe awọn yoo ranṣẹ si awọn Fulani to wa ni Yewa pe lati kilọ fun wọn pe wọn o gbọdọ na ọba alade kankan tabi fiya jẹ ọmọ Yoruba mọ, lai jẹ bẹ, wọn gbọdọ ko ẹru wọn ki wọn si ipinlẹ Ogun silẹ.
Oríṣun àwòrán, Facebook/Africa Eyes
''A o mọ iye ọjọ ti a maa lo ni Yewa lori ọrọ awọn Fulani yii, gbogbo awọn ọmọ Yoruba to nifẹ si ohun ti a n ṣe lo wa lẹyin wa,'' Ọgbẹni Akinpẹlu lo sọ bẹẹ.
Akinpelu fikun ọrọ rẹ pe awọn ranṣẹ si Gomina Abiodun wi pe awọn n bọ ṣugbọn gomina ko tii fesi.
''Amọ, a ko le duro ki gomina fesi kawọn ti wọn yoo fi pa awọn eeyan wa tan,'' Akinpelu ṣalaye.
Oríṣun àwòrán, Facebook/Africa Eyes
Ṣaaju akoko yii ni oludamọran pataki fun Gomina Abiodun ipinlẹ Ogun, Remmy Hazzan sọ pe ẹnikẹni to ba le ṣe iranwọ lori eto abo to mẹhẹ l'Ogun, ijọba yoo gbaruku tii.
Hazzan ni kii ṣe Igboho nikan, ẹnikẹni to ba le wa ojutu si ipenija ti ipinlẹ Ogun ni lori eto abo ni ijọba yoo ṣe atilẹyin fun un.
Oríṣun àwòrán, Facebook/Africa Eyes
Laipẹ yii ni iroyin kan gbori ayelujara pa pe awọn olugbe agbegbe ijọba ibilẹ ariwa Yewa ke gbajare pe awọn sọja to tẹle awọn Fulani darandaran kan to ko ẹran jẹ oko ni Yewa fiya jẹ awọn.
Tony Momoh: Mínísítà ètò ìròyìn nígbà kan rí jáde láyé lẹ́ni ọdún mọ́kànlélọ́gọ́rin
Oríṣun àwòrán, Twitter/Atiku Abubakar
Minisita eto iroyin ati aṣa tẹlẹ ri lorilẹede Naijiria Tony Momoh ti jade laye lẹni ọdun mọkanlelọgọrin.
Awọn to sun mọ oloogbe naa lo sọ nipa iku rẹ fawọn akọroyin.
Wọn ni nile rẹ to wa niluu Abuja ni minisita eto iroyin tẹlẹ ti jẹ Ọlọrun nipe.
Ọpọ awọn eekan ilu atawọn olosẹlu lo ti ṣedaro Ọgbẹni Momoh.
Igbakeji aarẹ orilẹede Naijiria tẹlẹ ri, Atiku Abubakar ṣapejuwe Momoh gẹgẹ bi eniyan to dara.
Atiku fọrọ ikẹdun ranṣẹ si idile Momoh nigba to gbadura pe ki Eleduwa tẹ ẹ si afẹfẹ rere.
Momoh di ipo minisita eto iroyin ati aṣa mu laarin ọdun 1986 si 1990 lasiko ijọba ologun Ibrahim Babangida.
NIN registration: Ìjọba Nàìjíríà ti sún ọjọ́ ìforúkọsílẹ káàdi ìbánisọ̀rọ̀ síwájú síi
Oríṣun àwòrán, others
Ijọba Naijiria ti kede laarọ oni ọjọ Iṣẹgun, ọjọ keji, oṣu keji, ọdun 2021 pe wọn ti fi kun asiko iforukọsilẹ ti wọn kede tẹlẹ.
Eto iforukọsilẹ yii ni lati ni idanimọ gbogbo awọn to n lo kaadi ipe ori foonu ni Naijiria.
Ọsẹ mẹjọ ni ijọba Naijiria fi kun gbendeke naa ki op le tubọ rọrun sii fawọn eniyan Naijiria lati le forukọsilẹ paapaa lasiko ajakalẹ arun coronavirus yii.
Saaju ni ijọba ti kede ọjọ kesan an, oṣu keji tẹlẹ ki wọn to sun un di oṣu kẹrin bayii.
Oludari ẹka gbogboogbo ni ileeṣẹ ijọba to n mojuto eto iforukọsilẹ naa Nigerian Communications Commission, Ikechukwu Adinde, lo fi ọrọ naa sita.
Akomolede ati Asa Ondo: Wo ìdí tí Yorùbá ṣe ń lo Ìjàpá ni olú ẹ̀dá ìtàn Àlọ́ Àpagbé- Oyelo
Adinde ṣalaye pe o di dandan ki wọn fi asiko kun igba iforukọsilẹ naa nitori pe awọn eeyan n kun lori ero to pọ nibudo iforukọsilẹ ati awọn kudiẹ kudiẹ mii to nilo asiko sii lati yanju ni irọrun fun awọn oluforukọsilẹ.
Big breast: Oluwatosin Adegboro, Oluwaseun Amoo, Remi Fatolu: Ẹlòmíì ń fi irú ọyàn wa tọrọ
Isa Patami to jẹ minista ileeṣẹ ijọba apapọ lori ona ibaraẹnisọrọ naa ṣalaye nipa bo ṣe ṣe pataki lati fi kun asiko naa.
Patami sọ eyi di mimọ lasiko to n ṣe ipade pẹlu ikọ to n mojuto ọrọ itankalẹ ajakalẹ arun Coronavirus lọjọ kinni, oṣu yii.
US Mission in Nigeria: Ilẹ̀ Amerika nílò olùkọ́ èdè Yorùbá, wo bí o ti lè forúkọ sílẹ̀ níbí
Oríṣun àwòrán, Twitter/Joe Biden
Ileeṣẹ aṣoju ijọba ilẹ Amerika lorilẹede Naijiria ti kede pe orilẹede Amẹrika nilo awọn olukọ ede Yoruba ati Hausa ni U.S.A.
Ẹka ileeṣẹ aṣoju ijọba Amẹrika to n ri si ọrọ iroyin sọ pe aye ti ṣi silẹ fawọn ọmọ Naijiria to ba kun oju oṣunwọn lati kọ ede ati aṣa Yoruba pẹlu Hausa lawọn ileewe giga fasiti l'Amẹrika lati fi orukọ silẹ fun eto naa.
Ọjọ kinni oṣu keji ọdun 2021 yii ni aye ṣi silẹ fawọn eeyan lati maa forukọ silẹ fun eto naa.
Ọjọ kinni oṣu kẹfa ọdun ni eto iforukọ silẹ fun eto naa yoo wa sopin.
Ẹka ileeṣẹ aṣoju ijọba Amẹrika to n ri si ọrọ ede ilẹ okeere, ''Foreign Language Teaching Assistant Programme (FLTA)'' lo gbe ikede ọhun jade.
Ajọ FLTA ni eto naa wa lati fawọn ọdọ olukọ ilẹ okeere lati wa kọ awọn akẹkọọ l'Amẹrika ni ede ati aṣa Yoruba.
Akomolede ati Asa Ondo: Wo ìdí tí Yorùbá ṣe ń lo Ìjàpá ni olú ẹ̀dá ìtàn Àlọ́ Àpagbé- Oyelo
Ajọ naa tun ṣlaaye pe eto yii yoo fawọn to ba nifẹ si eto ọhun lati kẹkọọ sii ipa iṣẹ olukọni.
Ajọ FLTA tun ni eto ọhun yoo tun jẹ ki oye ede oyinbo ye wọn sii, ati pe wọn yoo tun lanfaani lati mọ nipa aṣa ilẹ Amẹrika.
Oríṣun àwòrán, Twitter/US Mission in Nigeria
Yatọ si ẹkọ mii ti wọn yoo lanfaani lati kọ, awọn to ba pegede fun eto ọhun yoo maa kopa ninu itakurọsọ lori ede Yoruba ati Hausa.
Wọn yoo tun lanfaani lati kopa ninu ifọrọwerọ lori aṣa ati ede ti wọn ba n kọ.
Oju opo yii(https://apply.iie.org/FLTA2021) ni o ti le forukọ silẹ lati lọ kọ ede Yoruba tabi Hausa l'Amerika.
Kiriji war (1877-1893), Ibadan, Ekiti, Ijesa: Ìkónilẹ́rú ilẹ̀ Yorùbá ló parí Ogun Kiriji
Oríṣun àwòrán, Old Naija
Yoruba bọ, wọn ni ti ọmọ ko ba ba itan, yoo ba arọba nitori arọba gan an ni baba itan.
Eyi lo difa fun itan bi ogun Kiriji ṣe waye, ohun to ṣe okunfa rẹ, iye ọdun ti wọn fi ja ogun naa ati bi o ṣe pari.
Ogun Kiriji ti ọpọ tun mọ si ogun Ekiti parapọ jẹ ogun to waye laarin ilu Ibadan ati Ekiti pẹlu Ijesha.
Gẹgẹ bí Latosa ṣe ṣalaye,  ogun Kiriji lo kẹyin gbogbo ogun nilẹ Yoruba,  ati pe ogun naa lo pẹ julọ ninu gbogbo ogun to ṣẹlẹ nilẹ Yoruba.
Ki lo ṣe okunfa ogun Kiriji?
Ṣe ẹ mọ pe ti ko ba nidi, obinrin kii jẹ ikumolu.
Ogun Kiriji bẹ silẹ nitori awọn ofin ati ilana didari awọn eeyan ti Ibadan gbe kalẹ nitori ipa to ko ninu ogun ilu Osogbo ọdun 1840 ati iṣẹgun rẹ ninu ogun Ijaye.
Iṣẹgun yii lo pokiki Ibadan gẹgẹ bí ilu akin ti yoo rọpo ijọba abaṣẹ wa Oyo Ile to wo lulẹ.
World Cancer Day: Mo pàdánù ọkọ àti ọ̀rẹ́ bí mo ṣe ni 'Cancer'- Iwalade Adebimpe Adetunji
Ibadan ti fi idi ijọba rẹ mulẹ kaakiri ilẹ Yoruba to fi de Ekiti ati Ijesha.Ṣugbọn Ekiti ati Ijesha tako igbesẹ yii nitori wọn ko ri Ibadan gẹgẹ bi ilu alagbara ilẹ Yoruba.
Ohun to ṣe okunfa ogun Kiriji gan an ni bi awọn aṣoju ilu Ibadan ṣe n huwa ọdaran lawọn ilu.
Itan sọ pe niiṣe ni wọn n dunkoko mọ awọn ọdọ, koda wọn tun n fi ipa bawọn obinrin lopọ.
Eleyi lo mu ki awọn  eeyan Ekiti ati Ijesha ṣekupa ọpọ ninu wọn ti wọn si doju ija kọ Ibadan.
Bayii lawọn ilu mii nilẹ Yoruba naa da si ogun ọhún.
Akomolede ati Asa Ondo: Wo ìdí tí Yorùbá ṣe ń lo Ìjàpá ni olú ẹ̀dá ìtàn Àlọ́ Àpagbé- Oyelo
Ewo ni wọ́n n pè ní ogun Jalumi to waye lọd\un 1878?
Egba ati Ijebu ṣegbe lẹyin Ekiti ati Ijesha.
Wọn si doju ija ko Ibadan lati Guusu.
Nigba ti awon ọmoogun Ekiti ati Ijesha pẹlu atilẹyin awọn Fulani gbogun ti Ibadan lati apa Ariwa.Lọna marun un ọtọọtọ ni Ibadan nikan ti jagun.
Lọjọ kinni, oṣu kọkanla, ọdun 1878 ni Ibadan kọlu awọn ọmọogun Ekiti, Ijesha at'awọn Fulani Ilorin lapa Ariwa ibi to di ipinle Osun lonii.
Ibadan si ṣẹgun gbogbo wọn.
Eyi ni wọn n pe ni ogun Jalumi ọdun 1878 tabi Ogun Ikirun.
Oríṣun àwòrán, Old Naija
Kini o kọkọ fa ija laarin Modakeke ati Ile Ife?
Ogun Kiriji naa lo ta epo si aawọ to wa laarin Ife at'awọn ara Oyo to wa niluu Modakeke ti wọn ṣe atilẹyin fun Ibadan.
Modakeke pada bori Ifẹ pẹlu iranlọwọ Ibadan.
Ìtanijí lórí BBC Yorùbá: Odú Iwori Obara bá wa sọ̀rọ̀ lórí ìfaradà tó pọ̀
Kini idi ti wọn fi sọ ogun naa ni ogun Kiriji?
O ṣe pataki lati mọ pe oruko Kiriji ti wọn n pe ogun naa niṣe pẹlu bi ohun ija oloro ti wọn fi jaa.
Bi ohun ija ti awọn ọmọogun Ekiti ati Ijesha n lo labẹ alaṣẹ ọgagun wọn, Ogedengbe ṣe n dun bi àrá nigba naa lo faa.
Awọn ohun ija oloro yii lo ran Ekiti ati Ijesha lọwọ ninu ogun Kiriji.
Ba wo ni ogun Kiriji ṣe pari?
Ogun Kiriji tẹsiwaju fun ọpọ ọdun ki Gomina Carter lati ilu oyinbo to gbiyanju lati pẹtu sija náà lọdun 1886.
Ṣugbọn ogun naa ko pari to fi di ọdun 1892 nigba ti ilẹ Gẹẹsi de si Ijebu pẹlu ibọn to lagbara.
Lọdun 1893 ni Gomina Carter fi ipa pari ija ọhún.
Bí àlááfíà yóò ṣe wà láàrin Fulani àti Yorùbá ni Ooni bá lọ sọ́dọ̀ Buhari- Ààfin Ile Ife
Itan sọ pe gomina f'ẹsẹ rin lati ilu Eko lọ si ibudo awọn ọmọogun Ibadan ati Ekiti pẹlu Ijesha ni Igbajo ati Okemesi.
Nibẹ lo si ti sọ fawọn ọmoogun naa pe ki wọn pada sile.
Lẹyin naa ni wọn jọ buwọlu iwe adehun kan eleyii to sọ ilẹ alagbara ilẹ Yoruba di ọkan lara awọn ẹkun ti ijọba ilẹ Gẹẹsi ko lẹru lapa Iwọ-oorun ilẹ Afirika.
Police brutality: Tola ní inú òun kò bá dùn tí wọ́n bá le fi àwọn ọlọ́pàá tó lù òun jófin yàtọ̀ sí 5m tí wọ́n fẹ́ fún òun
Oríṣun àwòrán, Twitter/Abiodun Sonaike
Ileẹjọ giga niluu Osogbo ti dajọ pe ki ileeṣẹ ọlọpaa san miliọnu marun naira fun ọmọbinrin kan, Tola Azeez lẹyin ti awọn ọlọpaa fiya jẹ ẹ lasiko kole-o-gbele arun coronavirus.
Azeez niwaju ile rẹ lawọn ọlọpaa kan ṣadeedee ri, ti wọn si lu u lalu bami lai ṣẹṣẹ kan.
Fidio bi wọn ṣe lu u nilu bara gba ori ayelujara kan lọdun to lọ.
Tola ni oun ni lati fi ilu ti oun n gbe nigba naa silẹ lati lọ tọju ara oun niluu ibo mii.
O ṣalaye pe ṣaaju iṣẹlẹ naa, oun jẹ ẹnikan ti kii fẹ kawọn eeyan ṣaaba mọ nipa oun to n ṣẹlẹ si oun.
Ṣugbọn o ni inu oun dun pe ileẹjọ ni ki wọn fun oun ni miliọnu marun un.
Amọ o ni inu oun ko ba dun si ti wọn ba le fi ọlọpaa to fiya jẹ oun jofin ko lo jẹ arikọgbọn fawọn mii to ba hu iru iwa bẹẹ.
Oba Abdul-Rauf Olayiwola Adedeji II : Wo ohun tó yẹ kí o mọ̀ nípa Akirun ti Ìlú Ìkìrun tó wàjà
Oríṣun àwòrán, Tkbeshi Online
Ijọba ipinlẹ Osun lo kede loju opo Twitter rẹ pe Akirun ilu Ikirun, Oba AbdulRauf Olawale Adedeji waja lalẹ Ọjọru
Ijọba Osun ṣalaye loju opo Twitter rẹ pe ni bii ago mọkanla alẹ Ọjọru ti Oba Adedeji dagbere faye.
Ko si ẹni to le sọ pato ohun to ṣekupa Akirun ilu Ikirun lẹni ọdun mejidinlọgọrin.
Ohun ti a gbọ ni pe Akirun ṣe aisan diẹ ki Ẹlẹmi to gba a lalẹ Ọjọru.
Bi ọgbọn ọdun sẹyin ni Oba Adedeji  gori itẹ baba rẹ nilu Ikirun.
World Cancer Day: Mo pàdánù ọkọ àti ọ̀rẹ́ bí mo ṣe ni 'Cancer'- Iwalade Adebimpe Adetunji
Ọpọ eeyan lo ṣapejuwe Oba Adedeji to jẹ oṣiṣẹ banki tẹlẹ ki o to jọba pe musulumi ododo ni.
Ogunna gbongbo ẹgbẹ musulumi nii ṣe nilu Ikirun ati ni ipinlẹ Osun lapapọ nigba aye rẹ.
Ọdun 2002 ni Oba Adedeji lọ si ilẹ mimọ ni ilu Mecca.
Oríṣun àwòrán, Google
Oun ni baba iṣalẹ ẹgbẹ musulumi Ibadu-Rahman Society ati Anwar-Ul-Islam niluu Ibadan nigba aye rẹ.
Oba Adedeji lo ọrọ rẹ Eledua yọnda fun un lati ṣe iranwọn fawọn ti ko rọwọ họri lawujọ.
Big breast: Oluwatosin Adegboro, Oluwaseun Amoo, Remi Fatolu: Ẹlòmíì ń fi irú ọyàn wa tọrọ
Ìròyìn Yàjóyàjó -'Akirun ti Ìlú Ìkìrun,Oba Abdul-Rauf Olayiwola Adedeji II   ti wàjà
Ọba Akirun ti Ikirun, Oba Abdul-Rauf Olayiwola Adedeji II ti jade laye.
Eni ọdun  mejidinlọgọrin ni ọba ni ipinlẹ Osun naa ki wọn to jade laye.
Akomolede ati Asa Ondo: Wo ìdí tí Yorùbá ṣe ń lo Ìjàpá ni olú ẹ̀dá ìtàn Àlọ́ Àpagbé- Oyelo
Mohammed Adamu: Ẹ wo ìgbà mẹ́rin tí Ààrẹ Buhari ti tàpá sí ìlànà òfin orílẹ̀-èdè Nàíjíríà
Oríṣun àwòrán, Twitter/Buhari
Ọpọlọpọ igba ni Aarẹ orilẹ-ede Naijiria, Muhammadu Buhari ti rekọja ofin orilẹede Naijiria nipa titẹ oju ofin mọle.
Eleyii to ṣẹlẹ laipẹ yii ti awọn agba agbẹjọrọ lorilẹede Naijiria,SAN ti bu ẹnu atẹ lu bi aarẹ Buhari ṣe fi oṣu mẹta kun iye ọjọ ti Ọga Agba ọlọpaa, Muhammed Adamu yoo lo nipo ki o to fẹyinti lẹnu iṣẹ.
Ọjọ Ajẹ, Ọjọ Kini, Oṣu Keji lo yẹ ki Ọga Adamu fẹyinti lẹyin to wọ iṣẹ ni ọdun 1986, to si ṣiṣẹ ọba fun ọdun marundinlọgbọn.
Eyi ni akojọpọ igba mẹrin ti aarẹ Buhari ti tẹ oju ofin Naijiria mọlẹ;
1) Yiyọ olootu idajọ lorile-ede Naijiria, Adajọ Walter Onoghen kuro ni ipo
Ni Ọjọ Karundinlọgbọn, Ọdun 2019 ni aarẹ Buhari paṣẹ ki Olootu idajọ lorile-ede Naijiria, Adajọ Walter Onoghen lọ rọkun nilẹ lori ẹsun magomago ti wọn fi kan an.
Oríṣun àwòrán, Google
Ọpọlọpọ ọmọ Naijiria lo bu ẹnu atẹ lu igbesẹ aarẹ Buhari yii nitori ko ba ofin orilẹ-ede Naijiria mu.
Labẹ ofin, ẹka iṣejọba aarẹ ko lagbara lori ẹka idajọ nitori wọn da duro ni ọtọọtọ ni abẹ ofin Naijiria.
Amọ, awọn miran tilẹ ri igbesẹ aarẹ naa ni i ṣe pẹlu idibo gbogboogbo ti o waye ni ọdun 2019, ti wọn ri Onnoghen gẹgẹ bi ẹni ti yoo dena ẹto idajọ, amọ ako le e fi idi ọrọ naa mulẹ.
Ìtanijí lórí BBC Yorùbá: Odú Iwori Obara bá wa sọ̀rọ̀ lórí ìfaradà tó pọ̀
2) Rira ọkọ ofurufu Tucano lai gba aṣẹ lọwọ Ile Igbimọ Asofin
Ni Osu kẹrin, ọdun 2018 ni aarẹ Buhari ra ọkọ ofurufu Tucano fun ikọ ọmọogun Naijiria ni iye owo to le ni irinwo miliọnu dọla owo ilẹ okeere ($496 million).
Eleyii ni aarẹ ṣe lai gba aṣẹ ile Igbimọ Aṣofin Naijiria to si tako ofin ọdun 1999 ni orilẹ-ede Naijiria.
Oríṣun àwòrán, Google
Ofin naa sọ wi pe aarẹ Buhari ko gbọdọ na owo ninu apo ijọba lai gba aṣẹ lọwọ Ile Igbimọ Asofin lorilẹ-ede Naijiria.
Ofin naa tun fi idi ẹ mulẹ wi pe o ni iru nkan ti ijọba le e lo owo lati apo isuna le lori to tọna labẹ ofin.
Amọ, aarẹ Buhari ko tẹlẹ ofin yii, to si ra ọkọ Tucano laigba aṣẹ ọun.
World Cancer Day: Mo pàdánù ọkọ àti ọ̀rẹ́ bí mo ṣe ni 'Cancer'- Iwalade Adebimpe Adetunji
3) Atimọle Colonel Sambo Dasuki lẹyin ti ileẹjọ ti gba beeli rẹ
Ọpọlọpọ igba ni aarẹ Buhari ti kọ eti ikun si aṣẹ ileẹjọ lori ipejọ ti ijọba ba pe mọ ọmọ Naijiria.
Ileẹjọ giga ni ilu Abuja lo paṣẹ ni ọdun 2015 pe ki wọn fun Dasuki ni aṣẹ lati lọ si oke okun fun ọṣẹ mẹta lati gba eto iwosan to peye ni oke okun.
Oríṣun àwòrán, Google
Ijọba aarẹ Buhari kọ lati bọw fun ofin ti wọn ko si gba beeli rẹ.
Ni ọdun 2016 naa ni ileẹjọ ilẹ Afrika, Ecowas paṣẹ ki wọn gba beeli rẹ, ki ijọba apapọ si san owo itanran miliọnu marundinlogun naira fun dasuki.
Bakan naa ni ọdun 2018 ni ileẹjọ tun paṣẹ bẹẹ, ti ijọba si kọ lati tẹle aṣẹ naa ti ileẹjọ pa.
Akomolede ati Asa Ondo: Wo ìdí tí Yorùbá ṣe ń lo Ìjàpá ni olú ẹ̀dá ìtàn Àlọ́ Àpagbé- Oyelo
4) Atimolẹ El-Zakzaky lẹyin ti ileẹjọ ti gba beeli rẹ
Adari ẹgbẹ Shite lorilẹ-ede Naijiria, El-Zakzaky ti wa ni atimọle ijọba lati ọdun mẹta lẹyin ti ikọ ọmọogun Naijiria pa awọn eniyan ni ojude.
Iyawo rẹ ati awọn ẹbi rẹ wa ni ara awọn ti wọn pa, to fi mọ ile rẹ ti wọn jo.
Lẹyin gbogbo itu ti awọn ikọ ọmọogun ṣe fun El-Zakzaky yii ni ijọba tun tii mọlẹ.
Ni ọdun 2016 ni ileẹjọ giga ni ilu Abuja paṣẹ ki wọn fi silẹ nitori ijọba lo tẹ ẹtọ rẹ mọlẹ.
Amọ, titi di asiko yii ni El-Zakzaky ṣi wa ni atimọle awọn ajọ ọtẹlẹmuyẹ DSS, ti oun ati iyawo rẹ si ti lugbadi arun Coronavirus ni atimọle.
Oríṣun àwòrán, Twitter/Buhari
Buhari ní kí ọ̀gá ọlọ́pàá Adamu tó yẹ kó fẹ̀yìntì máa báṣẹ́ lọ
Aarẹ Muhammadu Buhari ti sọ pe ki ọga ọlọpaa Naijiria, Mohammed Adamu to yẹ ko ti fẹyin ti bayii maa baṣẹ lọ fun oṣu mẹta sii.
Oríṣun àwòrán, @Bashir Ahmad
Aarẹ Buhari ni eyi yoo ṣeranwọ fun iyansipo ọga ọlọpaa tuntun.
Minisita to n ri si ọrọ awọn ọlọpaa Mohammad Dingyadi lo fidi ọrọ yii fawọn akọroyin nile iṣẹ ijọba niluu Abuja.
Oríṣun àwòrán, NTA
Ẹwẹ, Aarẹ Buhari tun fi orukọ awọn olori ileeṣẹ ologun ti wọn ṣẹṣẹ fẹyinti, Abayomi Olonisakin (Rtd ), Lt Gen Tukur Buratai (Rtd), Vice Admiral Ibok-Ete Ibas (Rtd), Air Marshal Sadique Abubakar (Rtd) ati Air Vice Marshal Mohammed S Usman (Rtd), si ile aṣofin agba l'Abuja fun ipo aṣoju Naijiria nilẹ okeere.
Cancer: Àṣe ara mi ni iso ti n run gbogbo bí mo ṣe n ṣèrànwọ́ lórí jẹjẹrẹ
Bí àlááfíà yóò ṣe wà láàrin Fulani àti Yorùbá ni Ooni bá lọ sọ́dọ̀ Buhari- Ààfin Ile Ife
Aafin Ile Ife ti ṣalaye idi abajọ ti Ooni Ile Ife, Oba Adeyeye Enitan Ogunwusi fi ṣabẹwo si Aarẹ Muhammadu Buhari lori aawọ to wa laarin awọn Fulani atawọn agbẹ nilẹ Yoruba.
Agbẹnusọ fun Ooni, Moses Olafare sọ fun BBC Yoruba pe Ooni sọ fun Buhari lati wa nkan ṣe si ọrọ awọn Fulani kan to huwa ọdaran nilẹ Yoruba ni.
Ọgbẹni Olafare fikun ọrọ rẹ pe Ooni gbọingbọin ni Kabiyesi wa lẹyin Sunday Igboho, amọ ọba laye gbọdọ pẹtu si ija ni nitori ko si ọba to maa fẹ ki ilu tu mọ ọ lori.
Ọlafare ko ṣai kilọ fun Igboho pe ki ijimere rẹ ṣogi gun, ko maa ba gun igi aladi.
Marriage breakup: Iléẹjọ́ tú ìgbéyàwó ọdún méje ká lórí ẹ̀sùn ìfiraẹni-sílẹ̀
Oríṣun àwòrán, others
Ileẹjọ agbegbe kan ni Kubwa niluu Abuja ti tu igbeyawo ọdun meje ka lori ẹsun ifiraẹni silẹ.
Igbayawo laarin Abubakar ati iyawo rẹ Zainab Ozigi  fori sanpọn lẹyin Zainab sọ fun ileẹjọ pe ki wọn tu awọn kan nitori ọkọ oun ti pa oun ti fun ọdun mẹta.
Ninu idajọ rẹ, Adajọ Muhammad Adamu tu igbeyawo ọhun ka amọ o kilọ fun Zainab pe ki o duro fun oṣu mẹta ki o to fẹ ọkọ miiran.
Zainab sọ fun ileẹjọ pe labẹ ofin eṣin musulumi loun ti fẹ Abubakar eyi ti Eledua fi ọmọ kan jinki awọn papọ.
Abubakar naa gba pe ki ileẹjọ tu igbeyawo awọn ka.
World Cancer Day: Mo pàdánù ọkọ àti ọ̀rẹ́ bí mo ṣe ni 'Cancer'- Iwalade Adebimpe Adetunji
Ṣugbọn o ṣalaye pe oun ko fi Zainab silẹ fun ọdun mẹta gẹgẹ bi o ṣe sọ fun ileẹjọ.
''Mo sọ fun iyawo mi pe ki o fi Abuja silẹ wa ba mi nipinlẹ Ogun, ṣugbọn o kọ jalẹ,'' Abubakar ṣalaye.
O ni oun naa ko fẹ ni ajọṣepọ pẹlu Zainab mọ nitori ifẹ oun ti yọ lọkan rẹ.
Sunday Igboho vs Fulani: Mí ò nílò ìrànlọ́wọ́ owó lọ́wọ́ ẹnikẹ́ni láti ilẹ̀ òkèrè
Ajìjàgbara ilẹ̀ Yorùbá, Sunday Adeyemo, ti gbogbo ènìyàn mọ̀ si Sunday Igboho ni ọkan oun ko mi rara ninu ijagbara lati gba iran Yoruba silẹ lọwọ awọn to pe ni apaayan Fulani darandaran bo tilẹ jẹ pe o ni ẹru n ba awọn mọlẹbi oun.
Esi yii jade lẹyin ti ti awọn kan ti ẹnikẹni ko mọ ṣi bo ọkan lara ile Sunday Igboho ni Ibadan ti wọn si jo o nina, Sunday ni ẹda alaye kankan ko lee pa oun afi Ọlọrun Ọba.
Lásìkò ìfọ̀rọ̀wérọ̀ pẹ̀lú ìwé ìròyìn Punch ló ti ṣíṣọ lójú eegún ọ̀rọ̀ pé, òun kò bèrè fún ìrànwọ́ owó láti ọwa ẹnikẹ́ni.
Emi o bẹru ohunkohun tabi ẹnikẹni o, afi Ọlọrun. Ọlọrun lo ni ilẹ oun si ni adari gbogbo ọkan. Ko si ẹda alaye kankan to lee pami torinaa mi o le bẹru eeyan ẹlẹ́ran ara.
"Ninu iroyin naa, Igboho ni awọn ọmọ oun ti n pe oun ti wọn si n rọ ọ pe ko jawọ. ""Gbogbo igba ni wọn n ki mi nilọ""."
Iyawo mi naa wa ninu idamu ọkan nitori ijijagbara mi ṣugbn mo ni lati ṣe eyi fun itusilẹ awọn eeyan mi. Amọ emi naa ni ibanujẹ tori ihuwasi ti wn n ṣe si awọn eeyan mi.
Amọ Sunday ni ija yii wa fun didara gbogbo eeyan ni torii pe bi oun ba lọ tan ki wọn ma baa ṣe ẹru.
Igboho tún ṣíṣọ lójú eegún lórí ìròyìn tó n jà ràìràìn nígboro pé, Sunday Igboho ń pe fún ẹ̀bùn owó láti túbọ̀ ran ìràn Yorùbá lọ́wọ́.
"Ṣáájú ni àwọn míràn tilẹ̀ sọ pé, ọ̀rọ̀ Sunday Igboho wà lára ìdí tí wọ́n fi fòfinde ètò káràkátà ""Cryptocurrency"" láti dènà mọ́ àwọn tó fẹ́ fi owó rànṣẹ́ sí i láti òkè òkun."
Amope Onibata: Kìí ṣe gbogbo ọkùnrin ló gbà kí ń ṣe bàtà fún àwọn
"Nínú ọ̀rọ̀ rẹ̀, ""mí kò nílò irú owó yẹ̀n àti pé kò sí ǹkan tó jọ bẹ́ẹ̀"""
"Ó ní owó àti ọlà tí òun ni kò ṣèyìn ìdókoowò nínú epo rọ̀bì àti afẹ́fẹ́ gáàsì, ""bákan náà ni mò ń ta mọ́tò""."
Mí ò pínu láti lọ́ sínú òṣèlú gẹ́gẹ́ bi àwọn kan ṣe n sọ pẹ̀lú, bákan náà ni mí ò ṣe ǹkan ti mò ń ṣe nítori kí n le di ìlúmọ̀ọ̀ká.
Asìkò wo ni ìpàdé Sunday Igboho àti Pásítọ̀ Tunde Bakare?
Nínú ọ̀rọ̀ rẹ̀, Sunday Igoho ni lóòtọ́ ni pásítọ̀ Tunde Bakare ránṣẹ́ pe òun sùgbọ́n, òun yóò jẹ́ ìpè rẹ̀ ní àsìkò tó bá ti rsrun
Kókó ọ̀rọ̀ ti a ó maa sọ náà ni bi aláfíà àti ìrọ̀rùn yóò sẹ de bá ẹ̀yà Yorùbá
Bótill jẹ́ pé , ojójúnmọ̀ ni àwọn ọmọ mi àti ìyàwó mi ń rawọ́ ẹ̀bẹ̀ sí mi lójoojúmọ́ láti má ja ìjà yiìí mọ́, sùgbọ́n ó pọndandan kí n ṣe láti le tú ìrà Yoruba sílẹ̀ lọ́wọ́ àwọn aninilára.
Níwọ̀n ìgbà tí àwọn tó yẹ kí wọ́n mójútó ọ̀rọ̀ náà bá ti n  káwọ́ gbera, mó ni ojúṣe láti ṣe fún àǹfàní ará ìlú.
"Ẹ jẹ́ kí n sàlàyé kí ọ̀rọ̀ le tán nílẹ̀. ""Nígbà tí mo dé Eruwa, mó lọ fi ara mi hàn lágọ̀ọ́ ọlọ́pàá, mò sì sọ ǹkan ti mo bá wá si àdúgbò náà, adáriu ẹka ilé iṣẹ́ ọlọ́pàá náà sì gbà láti tẹ̀lẹ́ wá lọ."
Nígbà tí a de Igangan, à tún bá àwọn 'ọlọ́pàá operation Burst' a lọ sínú ]ilú náà rán pẹ́ asì pada lẹ́sẹ̀kẹsẹ̀ láti lọ sọ fún àwọn ọlọ́pà''a.
Ìbéérè mi ni pé, ṣe ọ̀gá ọlọ́pàá yóà máa wò wá kí a lọ má dáná sun ilé Seriki? Sé ọlọ́pàá Operation Burst yóò jk kí a lọ tí a bá dáná sun ilé Seriki?
Kò sí nkan tó jọ bẹ́ẹ̀ nígbà tí a wà níbẹ̀ nítorí náà àwa kọ́ ni a dáná sun ilé Seriki Fulani.
Sunday Igboho wa gba gbogbo ọmọ Kárọ̀-oojíre nímọ̀ràn pé kí wọ́n wà ní ìṣọ̀kàn kí wọ́n sìmì ọ̀rọ̀ òṣèlú ṣíṣe lórí ǹkan tó niṣe pẹlú igbésí ayé àwọn ènìyàn.
Ó rọ àwọn oríadé gbogbo, awọn ọdọ́ àti adarí láti fọwọ́sowọ́pọ̀ ki wọ́n sì máa fi ohùn kan sọ̀rọ̀.
Sunday Igboho vs Fulani: Seriki ní dúkìá tó tó N500m lòun pàdánú. àmọ́ òun fẹ́ láti padà sí Igangan
Seriki Fulani ìlú Igangan, lagbegbe Ibarapa nipinlẹ Oyo, Abdulkadri Saliu ti ṣalaye ohun to ṣẹlẹ nigba ti ajijagbara ilẹ Yoruba, Sunday Igboho atawọn ero lẹyin rẹ ṣe ni Igangan lẹyin to sọ fun wọn pe ki wọn fi ilẹ ipinlẹ Oyo silẹ.
Seriki ṣalaye pe owo maalu to le ni miliọnu kan naira  jona mọle labẹ bẹẹdi oun.
''Dukia mi to wa nilu ile jona, ile fulati mẹrin lo jona ati kọju simi ki n kọju siọ ti mo kọkọ kọ jona,'' Seriki ṣalaye.
O ni ''maalu igba maalu le meje ni mi o ri bayii, ṣugbọn n ko le lọ wa wọn lọwọ yii, koda mo gbọ pe awọn kan ti wa n  ji maalu mi lọ.
Lọrọ kan, dukia mi to bajẹ to ẹẹdẹgbẹta miliọnu ti ko ba ju bayẹn lọ,'' Seriki Saliu lo sọ bẹẹ.
World Cancer Day: Mo pàdánù ọkọ àti ọ̀rẹ́ bí mo ṣe ni 'Cancer'- Iwalade Adebimpe Adetunji
Seriki Saliu ni Fulani ti wọn n jigbe ju Yoruba ti wọn jigbe ni Ibarapa lọ.
O tun ṣalaye pe ''emi gan an ni mo maa mu ẹjọ awọn Fulani lọ si agọ awọn ọlọpaa.
Akure incest Momoh Usman case: Láti ẹni ọdún mẹ́tàlà ni Bàbá mi ti ń ba mi sùn- Fatimah Us
Nitori naa, ko si bi mo ti le jẹ baba isalẹ fawọn Fulani,'' Seriki Saliu lo sọ bẹẹ.
''Mo fẹ pada si ilu Igangan ti wọn ba gba mi laaye, bo tilẹ jẹ pe aburo mi tawọn mẹrin mii lo ba ba iṣẹlẹ ọhun lọ,'' Seriki ṣalaye.
Akomolede ati Asa Ondo: Wo ìdí tí Yorùbá ṣe ń lo Ìjàpá ni olú ẹ̀dá ìtàn Àlọ́ Àpagbé- Oyelo
Sunday Igboho vs Fulani, Gofundme: ''Ìrọ ní ò, N51.8million kọ́ ní àwọn Naijiria dá fún Sunday Igboho, N4milion ní''
Agbẹnusọ fun Sunday Igboho ti ni lootọ ni awọn ọmọ Naijiria ṣi aṣunwọn owo ''Gofundme'' fun Sunday Igboho; amọ kii ṣe N51.8million.
Eyi ko ṣẹyin iroyin to n ja ranyin nilẹ pe awọn ọmọ Naijiria to wa ni ilẹ okeere ti fi iye to le ni miliọnu mọkanlelaadọta naira sinu asunwọn naa bayii.
Iroyin ni laarin wakati mẹẹdoguin ti wọn ṣi asunwọn naa ni owo yii ti wọ inu rẹ.
Awọn ọmọ Naijiria ti okeere naa n da owo naa lati fi ra ọkọ fun Sunday Igboho lati fi le awọn Fulani darandaran to n pa awọn eniyan kakiri kuro ni ilẹ Yoruba.
Maureen Badejọ to ṣe alagbatẹru rẹ ni awọn ri iye owo to to £9, 450 (N4.8m) laarin wakati mejidinlogun.
Amọ, Ọkan lara awọn ọmọlẹyin Igboho, to ba BBC Yoruba sọrọ ṣugbọn ti ko fẹ ka da orukọ rẹ ni pe iye owo ti wọn ti kojo ko i tii to iye owo ti awọn eniyan n sọ wi pe awọn ri gba,
Bí àlááfíà yóò ṣe wà láàrin Fulani àti Yorùbá ni Ooni bá lọ sọ́dọ̀ Buhari- Ààfin Ile Ife
O fidi ẹ mulẹ pe lootọ ni wọn ṣi apo owo ''Gofundme'' fun Sunday Igboho.
Bakan naa si ni O fikun un pe ẹgbẹ awọn ọmọ Yoruba kan ni ilẹ okeere lo gbẹ igbesẹ naa ti wọn si ti ri miliọnu mẹrin naa laarin wakati mẹẹdogun ti wọn ṣi aṣunwọn owo naa.
Laipẹ yii ni Igboho atawọn ọmọlẹyin rẹ gbera lọ si ipinlẹ Ọyọ ati Ogun lati kilọ fawọn Fulani ki wọn so ewe agbejẹ mọwọ bi bẹẹ kọ, wọn o jẹ iyan wọn niṣu.
Wọn ni Sunday Igboho gunlẹ si awọn ipinlẹ yii nigba to lọ sibẹ lati kọju ija sawọn janduku Fulani to n huwa ọdaran nibẹ.
Ohun iroyin to tẹ wa lọwọ sọ pe aarọ ọjọ Aje, ọjọ kinini, oṣu keji ni Igboho fi ilu Ibadan silẹ lọ si ipinlẹ Ogun.
Adari egbe Miyetti Allah ni ile Yoruba, Muhammed Kabir Labar ni nkan tÍ Sunday Igboho ṣe ní Ibarapa tún ti ṣelẹ̀ ní ìpínlẹ̀ Ogun.
Amọ lara awọn Naijiria ti bu ẹnu atẹ lu igbesẹ Sunday Igboho to fi mọ ọmọ gbajugbaja olorin K1,Dami Ayinde Marshal to sọ oko ọrọ si awọn ọmọ Naijiria to n da owo jọ fun Sunday Igboho.
Akomolede ati Asa Ondo: Wo ìdí tí Yorùbá ṣe ń lo Ìjàpá ni olú ẹ̀dá ìtàn Àlọ́ Àpagbé- Oyelo
ASUU 2021 strike: Àwọn akẹ́kọ̀ọ́ UI ní ìyanṣẹ́lódì àwọn òṣìṣẹ́ fásítì ń ṣe àkọ́bá tó pọ̀ fáwọn
Ẹgbẹ awọn olukọ agba ni awọn ile ẹkọ giga fasiti to n bẹ loriẹede yii labẹ asia SSANU ati awọn oṣiṣẹ ti ki i ṣe olukọ, NASU ti bẹrẹ iyanṣẹlodi lonii.
Ọkan lara awọn aṣoju ẹgbẹ oṣiṣẹ naa ni fasiti ilẹ Ibadan, Wale Akinrẹmi ba BBC Yoruba sọrọ ninu ọgba ile ẹkọ naa l'ọjọ Ẹti.
O ni ikuna ijọba apapọ lori awọn owo ati ajẹmọnu ti wọn jẹ ẹgbẹ oṣiṣẹ naa lo fa iyanṣẹlodi ti wọn gunle.
Bakan naa ni Akinrẹmi fi idi ọrọ mulẹ wi pe ẹgbẹ oṣiṣẹ naa ko ni gbaa laabọ ti ijọba ba kọ lati wọn ọn kun.
O ni atunṣe gbudọ waye lori gbogbo ẹtọ ti wọn n beere fun bẹrẹ lati ori afikun owo oṣu awọn oṣiṣẹ, ẹdinwo apo aṣuwọn IPPIS, owo oṣiṣẹ fẹyinti ati bẹẹbẹẹ lọ, ki iyanṣẹlodi naa to le wa si opin.
Ìtanijí lórí BBC Yorùbá: Odú Iwori Obara bá wa sọ̀rọ̀ lórí ìfaradà tó pọ̀
Pupọ ninu awọn eeyan to wa ninu ọgba ile ẹkọ naa lasiko ti a ṣe abẹwo sibẹ lo jẹ akẹkọọ to wa ni opin eto ẹkọ ati awọn to ti kẹkọọ pari ti wọn n mura lati lọ ṣe agunbanirọ.
Lara wọn ti o ba wa sọrọ ṣe alaye wi pe awọn iyanṣẹlodi to n waye ni lemọlemọ ni awọn ile ẹkọ giga to n bẹ lorilẹede yii lo n ṣe akoba ti o pọ fun itẹsiwaju aye awọn akẹkọọ.
Akomolede ati Asa Ondo: Wo ìdí tí Yorùbá ṣe ń lo Ìjàpá ni olú ẹ̀dá ìtàn Àlọ́ Àpagbé- Oyelo
Wọn fi kun ọrọ wọn wi pe oun ti wa ni opin eto ẹkọ, nnkan to si ku ni ki igbimọ ile ẹkọ giga fasiti ilẹ Ibadan buwọ lu esi idanwo ti wọn ṣe.
Eyi  ni yoo fun wọn le lanfani lati lọ sin ilẹ baba wọn gẹgẹ bi i agunbanirọ, ṣugbọn iyanṣẹlodi to n lọ lọwọ bayii ti bẹgi dina igbesẹ naa.
Bakan naa ni wọn parọwa si ijọba apapọ lati ri si ọrọ awọn ẹgbẹ oṣiṣẹ naa ki itẹsiwaju le de ba awọn akẹkọọ.
World Cancer Day: Mo pàdánù ọkọ àti ọ̀rẹ́ bí mo ṣe ni 'Cancer'- Iwalade Adebimpe Adetunji
Ọjọ kejilelogun, oṣu keji ọdun yii lo yẹ ki awọn akẹkọọ fasiti ile Ibadan wọle pada sẹnu ẹkọ wọn gẹgẹ bi i awọn alakoso ile ẹkọ naa ṣe kede rẹ  tẹlẹri.
Sugbọn o ṣeeṣe ki ẹto ẹkọ foju wina awọn idiwọ kan tabi omii ti awọn ẹgbẹ oṣiṣẹ to bẹrẹ iyanṣẹ lodi lonii ba kọ lati pada sẹnu iṣẹ wọn.
Bí àlááfíà yóò ṣe wà láàrin Fulani àti Yorùbá ni Ooni bá lọ sọ́dọ̀ Buhari- Ààfin Ile Ife
Port Harcourt Sextuplet: Joyce ní ọjọ́ tí òun bímọ lòun mọ̀ pé oyún ìbẹfà ló wà nínú òun
Oríṣun àwòrán, Bright Akhimien
Ẹ ku ọwọ lomi lo yẹ ki a maa ki tọkọ-taya Joyce ati Bright Akhimien ti Eledua ti fi odindi ọmọ mẹfa ta lọrẹ lẹẹkan ṣoso.
Lẹyin ọdun meje ti Joyce, ẹni ọdun mọkandinlogoji ati ọkọ rẹ, DSP Bright Akhimien ti wọn wa lati ipinlẹ Edo ni Olodumare to da wọn lohun.
Ọkunrin mẹrin ati obinrin meji lawọn ọmọ naa ti wọn bi lọjọ kejila, oṣu kinni, ọdun 2021 niluu Port Harcourt nipinlẹ Rivers.
Joyce ni oun ko mọ pe ọmọ mẹfa loun yoo bi lẹẹkan naa lẹyin ti dokita sọ fun oun pe ọmọ to pọ lo wa ninu oun.
O ni: ''Ọjọ ti mo bi awọn ọmọ naa lawọn nọọsi bẹrẹ si ni ka wọn ti wọn si ri i pe mẹfa lawọn ọmọ naa,'' Joyce ṣalaye.
Akure incest Momoh Usman case: Láti ẹni ọdún mẹ́tàlà ni Bàbá mi ti ń ba mi sùn- Fatimah Us
''O ṣoro fun mi lati mọ iye ọmọ to wa ninu mi nigba naa tori nigba kuu gba ti a ba lọ si ayẹwo ni awọn ọmọ naa maa n bo ara wọn mọlẹ.
Eleyi to maa n jẹ ko nira lati mọ iye ọmọ to wa ninu mi,'' Joyce lo sọ bẹẹ.
Joyce ṣalaye pe inu oun dun debi pe oun ko mọ ohun ti oun tiẹ le sọ gan an.
O ni ''iyalẹnu lo jẹ fun mi bi Eleduwa ṣe n ṣiṣẹ rẹ pẹlu ọmọ mẹfa ti Ọba oke fi jinki emi ati idile mi.''
Bo tilẹ jẹ pe wọn padanu ọkan lara awọn obinrin to wa ninu awọn naa, wọn si n dupẹ lọwọ Ọlọrun fun ẹbun pataki yii.
Oríṣun àwòrán, Bright Akhimien
''Niṣe ni mo n bi ara mi leere pe ṣe emi naa ree, lẹyin gbogbo ohun ti oju mi ti ri fun ọdun meje.
Emi naa ni mo wa di ẹni to n ka ọmọ ni meni meji, omije ayọ lo n jabọ loju mi bi mo ti n yin Ọlọrun pe O ranti mi,'' Joyce lo sọ fawọn akọroyin bẹẹ.
Ọjọ kọkanla, oṣu kinni, ọdun 2014 ni Joyce ati Bright ṣe igbeyawo ti wọn si gbadura fun ere idi igbeyawo.
Ojoojumọ ni mo n yin Olorun logo nibi to sin mi de.
Lẹyin ọdun kan ti wọn ṣe igbeyawo ni Joyce bi ọmọkunrin kan, ṣugbọn lẹyin ọjọ kan ti ọmọ naa de ile aye lo pada.
Joyce ni lati igba naa, oun ko loyun lati aarọ di alẹ ri, bẹẹ ni oun ko loyun ki oyun naa wa bajẹ.
Cancer: Àṣe ara mi ni iso ti n run gbogbo bí mo ṣe n ṣèrànwọ́ lórí jẹjẹrẹ
O ni ọkọ oun gbaruku ti oun lasiko tawọn fi n wo oju Ọlọrun, ṣugbọn awọn ẹbi lo beere ni gbogbo igba.
''Ọjọ kan wa ti mo lọ ki ẹnikan to bimọ ni abule, nibi ti mo ti fẹ gbe ọmọ ni iya rẹ kọ fun mi lati gbe e, o dun mi gan na, koda mo sunkun nigba ti mo dele.
Arabinrin Akhimien ṣalaye pe alakọkọ ti oun ṣe eto ati loyun pẹlu ilana IVF naa ni oun bimọ yii.
''Niṣe ni a wa owo lati ṣe IVF nitori owo rẹ pọ gan an, ṣugbọn Ọlọrun gbọ adura wa, ẹkan ti a ṣe naa ni a si bimọ.
Bright, baba ibẹfa naa sọ fawọn akọroyin pe oun ko tiẹ fi ọkan si nigba ti iyawo oun sọ pe oun ti loyun nitori oun ko fẹ nkan to maa ba oun ninu jẹ.
World Cancer Day: Mo pàdánù ọkọ àti ọ̀rẹ́ bí mo ṣe ni 'Cancer'- Iwalade Adebimpe Adetunji
''Oṣu kinni kọja, oṣu keji, nigba ti o di oṣu kẹta ni a bẹrẹ si ni gbagbọ pe Ọlọrun ti da wa lohun,'' Bright ṣalaye.
O dupẹ lọwọ Eleduwa pe O ranti awọn fun ni ẹbun pataki ọmọ mẹfa lẹẹkan ṣoṣo.
Ondo killing: Ta ló pa ẹbí olùrànlọ́wọ́ Gómìnà Rotinmi Akeredolu sórí oko rẹ̀ l'Ondo?
Oríṣun àwòrán, Facebook/Rotimi Akeredolu Aketi
Iroyin kan ti n ja rain-rain lori ayelujara pe awọn afurasi Fulani darandaran ti ṣekupa ẹbi oluranlọwọ Gomina Rotinmi Akeredolu ipinlẹ Ondo lori ọrọ iroyin, Gani Muhammed Ajowa sori oko rẹ.
Ọgbẹni Dayo Ibiye ni oluranlọwọ Akeredolu sọ loju opo Facebook pe awọn afurasi Fulani ti pa ninu oko rẹ to wa ni Ajowa.
O sọ loju opo rẹ bayii pe ''Dayo Ibiye, ọkunrin niọ, ṣugbọn bi wọn ṣe ri ọ mu lo ya mi lẹnu.''
Ṣugbọn Kọmiṣọnna ọlọpaa ipinlẹ Ondo, Bolaji Salami  sọ fun BBC Yoruba pe ko si ẹni to le sọ bo ya awọn Fulani darandaran lo pa Ibiye bayii.
Ọgbẹni Salami ṣalaye pe apa wa lara oku oloogbe naa ṣugbọn iwadii n lọ lọwọ lati mọ ohun to ṣe okunfa iku Ọgbẹni Abiye gan an.
Akomolede ati Asa Ondo: Wo ìdí tí Yorùbá ṣe ń lo Ìjàpá ni olú ẹ̀dá ìtàn Àlọ́ Àpagbé- Oyelo
''O le jẹ pe ija lo ṣẹlẹ laarin ọkunrin atawọn agbẹ mii, amọ iwadii si lọ lọwọ lori ohun to ṣe okunfa iku ọkunrin gan an,'' ọga ọlọpaa lo sọ bẹẹ.
Ọgbẹni Salami fikun ọrọ rẹ pe iyawo oloogbe naa lo fi to awọn ọlọpaa leti lẹyin ti wọn o ri Abiye ko pada wale lati oko.
Ọga ọlọpaa Ondo sọ pe awọn agbofinro ti wa ni agbegbe oko ti iṣẹlẹ ọhun ti ṣẹlẹ, wọn si ti gbe oku ọkunrin naa lọ si ile igboku si.
Big breast: Oluwatosin Adegboro, Oluwaseun Amoo, Remi Fatolu: Ẹlòmíì ń fi irú ọyàn wa tọrọ
Atiku àti Davido sọ̀rọ̀ sókè nípa bí ìjọba Buhari ṣé ti àkáúntì ''cryptocurrency'' pa
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Eti yin to gbọ alọ nipa ikede ijọba apapọ Naijria lati ti akaunti awọn to n ṣe karakata owo Crptocurrency yẹ ki o gbọ abọ.
Idi ree ti a fi ni ka mu tọ yin wa ohun tawọn ọmọ Naijriria ti n sọ nipa ikede yi.
Tolori tẹlẹmu lo ti n da si ọrọ. Ninu awọn to gbaujumọ taa le tọka si ni igbakeji aarẹ ana, Atiku Abubakar.
Atiku to jẹ gbajugbaja onisowo to si ni ọpọ ileeṣẹ sọ pe nkan ti Naijria nilo lasiko yi ni pipese iṣẹ lati le jẹ ki ọrọ aje burẹkẹ si.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Asiko yi kọ lo yẹ ki ijọba fofin de karakata ti yoo maa jẹ ki owo wọle si ẹka ọrọ aje wa ni ohun ti Atiku sọ.
O ṣalaye pe ''o ṣeeṣe ki ijọba mojuto cryptocurrency yi ati bi owo ti se n wọle si Naijiria lai se akoba fun aabo orileede wa.Eyi ṣuwọn ju ki wọn ti i pa lọ''
O tẹsiwaju pe ''awọn ọdọ Naijiria n koju inira airiṣe nitori naa o y ki ijọba pese iṣẹ lati le jẹ ki ẹka ọrọ aje gbooro si''
Ẹwẹ awọn ọmọ Naijiria mii ti n da si ọrọ yi.
Ninu wọn ni arakunrin Osasu Obayiuwana to sọ pe aini igbagbọ ninu eto ọrọ aje banki apapọ Naijiri lo mu kawọn eeyan ya sidi Cryptocurrency.
Oríṣun àwòrán, Twitter
Gbajugbaja olorin takasufe Naijiria Davido naa da si ọrọ yi.
Loju opo rẹ ni Twitter, OBO ni oun ṣẹṣẹ n gbero lati darapọ mọ owo crypto ni ki ikede ijọba apapọ yi to jade.
Ọrọ yi gẹgẹ bi o ṣe sọ fun awọn eeyan miliọnu mẹjọ to n tẹle loju opo rẹ jẹ iyalẹnu
Oríṣun àwòrán, @Davido
Awọn mii to tun sọrọ ati ohun ti wọn wi ree:
Oríṣun àwòrán, @obyezeks
Oríṣun àwòrán, @segalink
Gbogbo ẹyin to n ṣe kata kara owo ''cryptocurrency''  ni Naijiria, ẹ jawọ nbẹ tori o lodi sofin orilẹede yii.
Banki apapọ ni Naijiria CBN ti paṣẹ fun gbogbo ile ifowopamọ lorilẹede Najiria lati gbe apo ikowosi awọn eeyan to ba n ṣe kata kara owo  'cryptocurrency'' ti pa.
Koda CBN paṣẹ fawṣon ile ifowopamọ lati ṣe awari gbogbo awọn onibara wọn to ni apo ikowosi fun owo ''crypo'' ki wọn si ti wọn pa lẹsẹ kẹsẹ.
CBN ṣalaye ninu atẹjade kan to fi sita ti ọga ẹka to n ṣe amojuto ni banki naa, Bello Hassan buwọlu pe kilọ fawọn ile ifowopamọ ni Naijiria ewu to wa ninu kiko owo ''crypo'' si banki wọn.
Banki CBN sọ ninu atẹjade ọhun pe ile ifowopamọ kankan ko gbọdọ ni ohun kohun ṣe pẹlu kata kara mọ bayii.
Banki CBN sọ ninu atẹjade ọhun pe ẹnikẹni to ba tapa si ikede yii yoo foju win ofin.
Big breast: Oluwatosin Adegboro, Oluwaseun Amoo, Remi Fatolu: Ẹlòmíì ń fi irú ọyàn wa tọrọ
Ẹwẹ, ọgọọrọ ọmọ Naijiria lo ti bu ẹnu atẹ lu igbesẹ banki apapọ Najiria.
Awọn ilumọọka lori ayelujara bii Shehu Sani, Reno Omokri, Ben Murray-Bruce, Omoyele Sowore, Debo Macaroni, DJ Switch ati awọn mii lo koro oju si igbesẹ ijọba.
Amotekun attack: Àwọn jàndùkú ṣá ẹ̀ṣọ́ Amotekun àti ọlọ́pàá ní àdá àti àáké n'Ibadan
Oríṣun àwòrán, Twitter/Oyo State Government
Awọn janduku kọlu awọn ẹṣọ alaabo Amotekun ni ijọba ibilẹ Ona Ara ni ipinlẹ Oyo.
Ẹgbẹ awọn onile ni agbegbe Odeyale lo pe awọn agbofinro fun iranwọ lẹyin ikọlu awọn janduku lagbegbe naa.
Alakoso ẹṣọ Amotekun ni ijọba Ona Ara, Ọgbẹni Adelakun ṣalaye pe awọn janduku fi aake ati ada ṣa ẹṣọ Amotekun mẹrin ti wọn si farapa yanayana.
Ọgbẹni Adelakun sọ pe mẹrin ninu awọn ẹṣọ Amotekun ni wọn wa nile iwosan UCH nibi ti wọn ti n gba itọju.
O ni iṣẹ iwadii si n lọ lọwọ lori iṣẹlẹ to ṣẹlẹ naa.
World Cancer Day: Mo pàdánù ọkọ àti ọ̀rẹ́ bí mo ṣe ni 'Cancer'- Iwalade Adebimpe Adetunji
Abuja accidents: Àjọ FRSC ní ọ̀kànlélúgba èèyàn(201) ló dèrò ọ̀run nínú ìjàmbá ọkọ̀ l'Abuja
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Olukọ kan ati akẹkọ soso ni ori ko yọ ninu ijamba mọto naa
Ijamba ọkọ mẹrindinlẹgbẹrun(994) lo ṣẹlẹ ni olu ilu orilẹede Naijiria, Abuja ni ọdun 2020 to lọ.
Ọga ajọ ẹṣọ oju popo, FRSC, Ọgbẹni Gora Wobin lo fidi ọrọ yii mulẹ fawọn akọroyin niluu Abuja.
Ọgbẹni Wobin ṣalaye pe iye ijamba ọkọ to ṣẹlẹ lasiko tawọn ṣe agbeyẹwo rẹ fihan pe nọmba ijamba to ṣẹlẹ ti dinku si ti ọdun 2019.
Ọga ajọ FRSC ni ijamba ọkọ mejilelogoji le lẹgbẹrun lo ṣẹlẹ lọdun 2019.
''Ẹgbẹrun kan ati okoo le lugba le mẹta awọn ọkọ to ni ijamba niluj Abuja, nigba ti ojilelugba eeayan le mẹjọ(248) lo ku niluu Abuja,'' ọga ajọ FRSC lo sọ bẹẹ.
Bí àlááfíà yóò ṣe wà láàrin Fulani àti Yorùbá ni Ooni bá lọ sọ́dọ̀ Buhari- Ààfin Ile Ife
Ọga FRSC Abuja ni eeyan sọ pe eeyan mọkalelugba(201) lo ku ninu ijamba ijamba ọkọ lọdun 2020.
''Iye awọn to farapa naa dinku lọdun 2020 si ọdun 2019, eeyan 1,728 lo farapa ninu ijamba ọkọ ni 2020 nigba ti 2,385 ṣeṣe lọdun 2019.
Eeyan 2, 603 lo mori bọ ninu ijamba ọkọ lọdun 2020, nigba ti ori ko 3,375 eeyan yọ ni 2019.
Ọgbẹni Wobin sọ pe ere asapajude, ẹru adiju, taya fifọ, yiya ọkọ mii lọna aitọ ati aifọkan si ọkọ wiwa lawọn nkan to maa n ṣe okunfa ijamba ọkọ.
Akure incest Momoh Usman case: Láti ẹni ọdún mẹ́tàlà ni Bàbá mi ti ń ba mi sùn- Fatimah Us
Yollywood: Mo Adebimpe gba omijé lójú Lateef Adedimeji, ayẹyẹ ọjọ́ ìbí da Saheed Balogun àti Fathia Wiliams pọ̀
Oríṣun àwòrán, Instagram
Ọrọ ifẹ, bi adanwo ni. Eyi lo difa fun oṣere tiata Yoruba to bu sẹkun ayo. Kinni idi abajọ?
Gbogbo rẹ la o ṣalaye fun yin ni ẹkunrẹrẹ lai ṣẹ ọkan kan ku.
Saheed Balogun ati aya rẹ tẹlẹ, Fathia Willaims ṣe ọjọ ibi ni ọjọ kan naa laarin ọsẹ yii.
Wọnyii ni awọn iṣẹlẹ to ṣẹlẹ lagbo osẹre Yoruba lọsẹ yii.
Mo'bimpe gba omijé lójú Adedimeji
Gbajugbaja oṣere taita, Lateef Adedimeji ya agbado ha sawọn ololufẹ ere Yoruba lẹnu lẹyin to da omi loju poro poro.
Ki lo le mu Adedimeji bu omi loju gan an?
Ọrẹbinrin rẹ, Mo'bimpe Oyebade lo ya a lẹnu  pẹlu ẹbun iyebiye ṣaaju ọjọ ibi rẹ.
Eyi lo mu ki lateef bu sẹkun ayọ
Oríṣun àwòrán, Instagram/Mo'Bimpe Adebade
Fathia ati Saheed Balogun
Yoruba maa n sọ pe owo ti ọmọ ba ti wọ, okuta ti wọọ.
Otitọ ni pe Fathia ati Saheed Balogun ti kọ ara wọn silẹ gẹgẹ lọkọ laya bo tilẹ jẹ pe wọn bimọ fun ara wọn.
Akure incest Momoh Usman case: Láti ẹni ọdún mẹ́tàlà ni Bàbá mi ti ń ba mi sùn- Fatimah Us
Amọ, ohun kan to maa n pa awọn mejeeji pọ lọdọọdun ni ayẹyẹ ọjọ ibi wọn.
Ọjọ karun un, oṣu keji, ọdun 2021 yii lawọn mejeeji tun ṣe ọjọ ibi wọn.
Oríṣun àwòrán, Instagram/Fathia Balogun
Toyin Abraham
Ilumọọka oṣere tiata, Toyin Abraham ti di wolii obinrin.
Ninu fidio kan ti Toyin fi si oju opo Instagram rẹ lo ti ṣiwaju adura fawọn obinrin ti ko ti si nile ọkọ.
Bí àlááfíà yóò ṣe wà láàrin Fulani àti Yorùbá ni Ooni bá lọ sọ́dọ̀ Buhari- Ààfin Ile Ife
Toyin sọ ninu adura naa pe ibi kibi ti wọn ko ba ni pade ọkọ wọn, ki awọn ma lọ sibẹ.
Toyin ni ki awọn obinrin ti ko ba ti lọ sile ọkọ ye ṣakọ si awọn ọkunrimọ.
World Cancer Day: Mo pàdánù ọkọ àti ọ̀rẹ́ bí mo ṣe ni 'Cancer'- Iwalade Adebimpe Adetunji
Dele Odule
Agbaọjẹ oṣere Dele Odule ṣe ilanilọyẹ lori rọba idabobo fun ibalopọ ni tirẹ tori arun.
Ọgbẹni Odule sọ pe o maa n ti ọpọ eeyan loju lati beere fun rọba idaabobo nile itaja tabi ile ita oogun.
O fi ara rẹ ṣe apejuwe ẹni ti o fẹ ra rọba idaabo bo ṣugbọn ti ko le darukọ ohun to fẹ ra gan an.
Lowe lowe lo Odule fi n beere fun rọba idaabo bo lọwọ ọmọ to n taja.
Ṣugbọn ọrọ Odule ko gba ibi kan ye ọmọbinrin olutaja ọhun nitori ko sọ oju abẹ nikoo.
Cancer: Àṣe ara mi ni iso ti n run gbogbo bí mo ṣe n ṣèrànwọ́ lórí jẹjẹrẹ
Seyi Makinde: Kí ni wọ́n sọ nípa ètò ààbò lójú òpó Whatsapp PDP Oyo tí Gómìnà fí bínú kúrò níbẹ?
Aigbọraẹniye to n waye ninu ẹgbẹ oṣelu PDP ni ipinlẹ Oyotun ti gbọna mii yọ pẹlu bi Gomina Seyt Makinde ṣe fi ibinu kuro loju opo Whatsapp ẹgbẹ naa.
Igbesẹ Gomina yi ko sẹyin bi akọwe ipolongo ẹgbẹ PDP ni Oyo, Akeem Olatunji ṣe pin fọnran fidio kan nibi tawọn kan ti ni ki Gomina wa wọrọkọ fi ṣada nipa eto aabo.
Fọnran yi gẹgẹ bi a ti ṣe gbọ ni Olatunji fi ibeere kin lẹyin to si ni ''gbogbo eeyan lo ti ri fidio yi to si yẹ kawọn alaṣẹ fesi si''
Oríṣun àwòrán, livetimes.ng
Ọrọ yi la gbọ pe o bi Gomina ninu to si mu ko ṣapejuwe awọn to wa nidi fidio naa bi ''omugọ.''
Ninu aworan oju opo Whatsapp(Screenshot) to fi ọrọ ti wọn ni Gomina kọ, niṣe lo ni  ''kii ṣe gbogbo ọrọ tawọn omugọ ba sọ lo yẹ ki ijọba fesi si''
Lẹyin ọrọ yi ni Gomina tun beere pe ki lo de ti ọrọ kan to niṣe pẹlu iforukọsilẹ ẹgbẹ APC ṣe wa loju opo PDP.
Ko pẹ ti o beere ọrọ yi ni Gomina ba yọ ara rẹ kuro loju opo Whatsapp ẹgbẹ naa.
Iriwisi ọtọọtọ lo tẹle igbesẹ Gomina yi ta si gbọ pe bawọn kan ti se n bẹnu atẹ lu pe ko fẹ gbọ ootọ lawọn mii fibinu kuro lori opo naa lati fi ṣatilẹyin fun un.
Ninu awọn ọmọ ẹgbẹ to fi oju opo Whatsapp lẹ pẹlu Gomina Makinde ni Basa Sarumi, Akeem Olatunji, Bisi Ilaka, Hon Agboworin, Hon Dare Adeleke, Hon. Yinka Adeniyi ati Hon Kehinde Akande.
Ìpèsè iṣẹ́ ló yẹ kí ìjọba gbájú mọọ́, kìí ṣe ''cryptocurrency''- Atiku
Irú ìkọlù wo ló ń wáyé ní Osun tí ìjọba fi kéde òfin kónílé-ó-gbélé 24 hours?
Pánsá ò fúnra! Ọ̀rọ̀ Fúlàní darandaran àti àgbẹ̀ yìí, hmmn, abúrú ńlá kan ń kanlẹ̀kùn - Soyinka
Ileeṣẹ BBC gbiyanju lati pe ago alaga ẹgbẹ PDP ni ipinlẹ Oyo ko fesi sọrọ yi ṣugbọn ko gbe ago rẹ.
Bẹẹ naa la o ri ọrọ gbọ lati ọdọ alukoro ẹgbẹ PDP Akeem Olatunji ti wọn ni o da oju opo Whatsapp yi silẹ.
Nigerian cryptocurrency: Àwọn orílè-èdè bí China, India, Iran náà ti fi òfin de owó Crypto
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ọjọ Ẹti ni banki apapọ Naijiria pasẹ pe banki kankan ko gbọdọ ṣe katakara owo ori ayelujara, Crypto (Dogecoin, Bitcoin, ati Ethereum) mọ. Ọpọlọpọ awuyewuye lo si ti n waye lori àṣẹ naa jakejado Naijiria. Awọn ileesẹ iroyin kan ni Naijiria sọ pe nitori ikilọ ti ileesẹ ọtẹlẹmuyẹ ilẹ America, FBI, fun banki apapọ Naijiria ni wọn fi fofin de Crypto.
Ko sẹyin bi onijibiti to n lo owó Crypto lati ko ọpọlọpọ miliọnu Dọla ilẹ America ti wọn ko jọ lọna aitọ lati àwọn orilẹ-ede kan ati America, wò Naijiria, ni banki apapọ naa se pàṣẹ. Sugbọn ṣa, kii ṣe orilẹ-ede Naijiria nikan lo ti fi ofin de owo Crypto.
Ọmọ Yahoo tú àṣírí ara rẹ̀ fún, bí wọ́n ṣe ń ṣe é BBC Yorùbá
Ninu oṣu Kẹsàn-án, ọdun 2017 ni China bẹrẹ igbesẹ lati fi ofin de pasipaarọ Bitcoin lorilẹ-ede naa. Awọn ilu bi Beijing ati Shanghai lo si ti bẹrẹ.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ofin naa jẹ ara igbesẹ ijọba China lati mu adinku ba ewu to wa fun eto owó nina lorilẹ-ede naa. Banki apapọ China fi ikilọ sita lori itakun agbaye kan to gbe kalẹ pe awọn eeyan kan n lo owo Crypto lati hu iwa ọdaran bi katakara oogun oloro, fayawọ, kiko owo pamọ lọna aitọ, ati ikowojọ ti ko ba ofin mu.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Wọn ni àwọn onijibiti le ma a lo lati gbọ bukaata igbesunmọmi, kiko owo pamọ lọna ti ko ba ofin mu, ati bẹẹ bẹẹ lọ. Koda lọdun 2019, awọn alasẹ ni Iran gbẹsẹ le ẹgbẹrun kan irin'ṣẹ iwakusa Bitcoin, to jẹ ti ileesẹ meji to ti ko igba wọle, nitori pe ina ijọba ti wọn n lo ti pọ ju
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ninu oṣu Kẹrin, ọdun 2018, banki apapọ India kede pe ofin ti de rira tabi tita owo Crypto. Koda, oṣu mẹta ni Reserve Bank of India, fun awọn banki naa lati fi opin si okoowo naa.Eeyan bi miliọnu marun-un lo n lo owo Crypto ni India lasiko naa.
Ọjọ kẹrinlelogun, oṣu Kejila, ọdun 2017 ni banki apapọ Bangladesh fi ofin de lilo owo Bitcoin. Ninu atẹjade kan to fi sita lo ti sọ pe nina owo naa le fa titapa si ofin to de gbigbọ bukaata igbesunmọmi ati kiko owo pamọ lọna ti ko ba ofin mu.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ninu oṣu Kọkanla, ọdun 2017 ni iroyin jade pe banki apapọ ati ileesẹ to n ri si pasipaarọ owo ilẹ okeere ni Morocco ti fofin de nina owó Crypto. Ati pe ijiya nla ni fun ẹnikẹni to ba gba owó lati  ilẹ okeere tabi san owó silẹ okeere lai lo àwọn ajọ ti ijọba fi àṣẹ fun, tabi gba owo ilẹ okeere ti ko si ninu akọsilẹ Bank Al-Maghrib.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Wọn ni ewu nla ni fun awọn to n na owo naa, nitori pe owo naa ṣe e lo lati ṣe katakara oogun oloro, nkan ijagun ati owo itusilẹ fun ẹni ti wọn ba ji gbe.
Ọdun 2019 ni banki apapọ ati ileesẹ ijọba Uganda to n mojuto ọrọ owo nina kilọ fun awọn eeyan pe ki wọn o ma a na owo Crypto nitori pe ijọba ko tẹ́wọ́ gba a. Ijọba sọ pe ọpọlọpọ owó Crypto ni ko ni atilẹyin ijọba tabi eto adojutofo.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Bakan naa ni ileesẹ naa sọ pe ko si aabo fun awọn to n na owo naa ni Uganda, ti ohunkohun ba sẹlẹ si owo wọn.
Bakan naa ni banki apapọ Zambia, kilọ fun awọn eniyan orilẹ-ede naa ninu oṣu Kẹwaa, ọdun 2018 lori nina owó Crypto, to si ran wọn létí pe kii ṣe owó to ṣe itẹwọgba lorilẹ-ede naa. Lara ewu ìwà ọdaran ti banki naa sọ pe o rọ mọ nina owó naa ni kiko owó pamọ lọna ti ko tọ ọ, jibiti, ati gbigbọ bukaata awọn agbesunmọmi. Pẹlu àṣẹ ti banki apapọ Naijiria pa yii, ọpọlọpọ miliọnu Dọla owó Crypto ni yoo ha si Naijiria, to jẹ orilẹ-ede kejì ti okoowo Bitcoin pọ si julọ l'agbaye. Bitcoin to le ni ẹgbẹrun lọna ọgọta ni awọn ọmọ Naijiria ti fi dokoowo lati ọdun 2015.
Sotitobire Update: Agbẹjọ́rò Pásítọ̀ Alfa Babatunde láwọn ṣetán láti yí ìdájọ padà nilé ẹjọ́ Kòtẹ́milọ́rùn
Awọn agbẹjọro to n soju Pasitọ Alfa Bataunde ti ijọ Sotitobirẹ ti n ṣalaye fawọn akọroyin bi wọn yoo ti ṣe yi idajọ rẹ pada.
Ile ẹjọ Kotẹmilọrun to wa nilu Akure ni igbẹjọ Sotitobirẹ tuntun yi ti n gbera sọ lati yi idajọ ile ẹjọ giga to dajọ ẹwọn gbere fun Pasitọ Bababtunde.
Losu Kẹwa ọdun to kọja ni ile ẹjọ gbe idajọ kalẹ lori ẹsun pe Pasitọ Babatunde mọ si bi ọmọ ọdun kan Gold Kolawole ti ṣe di awati nile ijọsin rẹ loṣu Kọkanla ọdun 2019.
Ìdájọ́ òdòdò ló fẹsẹ̀ múlẹ̀ lórí ọ̀rọ̀ Pásítọ̀ Sotitobire - Agbẹjọ́rò fún ìjọba
Pasitọ Babatunde ati awọn eeyan marun un mii lo gba idajọ lẹyin igbẹjọ oloṣu mẹwa to waye laarin oṣu Kini ati Oṣu Kẹwa 2020.
Agbẹjọro agba Gboyega Awomọlọ ni o lewaju awọn to ṣoju Pasitọ Babatunde ti arabinrin Bola Joel Ogundadegbe ati John Dada Joshua soju ijọba.
Wo ìgbé àyé ìyá àti ọmọbìnrin tó ń fi iṣẹ́ aṣẹ́wó jẹun
Ninu ọrọ rẹ Awomolo gba iyọnda ile ẹjọ lati fi iwe mẹta sọwọ eyi ti o fẹ fi tako agbara ile ẹjọ to gbẹjọ Sotitobirẹ ati aikajuoṣunwọn iwadii ajọ ọtẹlẹmuyẹ DSS.
Iwe mẹta yi la gbọ pe awọn agbẹjọro  ijọba  to ṣẹjọ Sotitobirẹ niwaju ile ẹjọ giga lẹyin ti awọn ikọ ọtẹlẹmuyẹ mu Pasito Babtunde ko tako.
Adajọ to n gbẹjọ ọhun Rita Nosakhare Pemu ni awọn funj awọn agbẹjọro Sotitobire ni ọjọ mọkanla lati ṣatunto gbogbo iwe ti wọn ba fẹ kọ wa siwaju ile ẹjọ.
Lasiko ti wọn n ba awọn akọroyin sọrọ, agbẹjọro Pasito Babatunde ọgbẹni Awomolo sọ fawọn akọroyin pe gbogbo ipa lawọn yoo ṣa lati ri pe Pasitọ naa gba itusilẹ.
Bẹẹ naa ni agbẹjọro ijọba arabinrin  Ogundadegbe ni wamuwamu lawọn ti gbaradi lati ṣẹjọ naa niwaju adajọ.
Wolii Babatunde ati awọn ti wọn jijọ fẹsun kan ko yọju sile ẹjọ amọ iwadii wa fi han pe o ti kọwe lati yọju sawọn igbẹjọ mi ti yoo waye lẹyin toni.
Woli Sotitobire tún yọjú! Ó ní ilé ẹjọ́ Kòtẹ́milọ́rùn yáá lónìí láti tún ẹjọ́ dá
Lẹyin oṣu mẹta ti wọn dajọ pe o jẹbi ẹsun gbigbimọpọ ti ọmọde kan, Gold Kolawole fi poora ni ijọ rẹ ninu oṣu kọkanla ọdun 2019, nkan mii ti wu jade bayii o.
Atẹjade kan ti o jẹ pe BBC Yoruba nikan ni anfani lati foju ganni rẹ ti fihan pe igbẹjọ mii lorii Woli Sotitobire yoo tun bẹrẹ lonii, ọjọ kẹjọ oṣu keji ọdun 2021.
Ọjọ ti pẹ ti awọn alatilẹyin ati ololufẹ oludasilẹ ijọ Sotitobire Praising Chapel ni ilu Akure, Woli Babatunde Alfa ti n foju sọna fun ohun ti yoo pada ṣẹlẹ lori idajọ rẹ.
Wo ìgbé àyé ìyá àti ọmọbìnrin tó ń fi iṣẹ́ aṣẹ́wó jẹun
Sotitobire: Ọkọ mi kò mọ̀ Jegede PDP rí, kódà kò fa ẹnikẹ́ni kalẹ̀ dípò Akeredolu- Bisola
Boya o ti n wa sopin ni o, boya o tun n tẹsiwaju ni o, ọrọ tun ti yipada bayi pẹlu bi Pasitọ naa ṣe pinu lati gba ile ẹjọ kotẹmilọrun lọ lati sọ pe ko tọ bi ile ẹjọ giga ṣe fi oun sẹwọn gbere.
Gẹgẹ bi aridaju ti a ni lọwọ, agbẹjọro agba Naijiria meji, Oloye Gboyega ati iyawo rẹ, Victoria ni yoo dari agbẹjọro mẹfa mii lati koju aridaju ti Pasitọ naa sọ pe oun ni pẹlu awọn olukọ ọmọde marun mii ni ijọ rẹ ti wọn jọ n foju wina ofin lẹwọn.
Awọn atẹjade naa fihan wipe wọn ti kọkọ pe ẹjọ kotẹmilọrun ninu oṣu kọkanla ọdun 2020 pẹlu ẹri marun ti wọn ni, bakan naa wọn tun fi ipẹjọ mii ṣọwọ pẹlu ẹri mejila ni ọjọ kejila oṣu kejila dun 2020.
Woli Alfa sọ pe adajọ to kọkọ da ẹjọ ti wọn fi ju oun sẹwọn ṣe ohun aitọ nile ẹjọ nitori wipe ile ẹjọ ko ni aṣẹ lati gbọ ẹjọ naa bẹẹ si lo ni ajọ ọtẹlẹmuyẹ naa ko ni agabara kankan lati maa tọpinpin ati ṣewadii ọrọ to yẹ ki ọlọpaa mojuto.
Nibayii, wọn ti da ọjọ Aje, ọjọ kẹjọ oṣu keji ọdun 2021 lati gbọ ẹjọ rẹ ni ile ẹjọ kotẹmilọrun ti ilu Akure.
Iwadii tun fihan pe awọn tọrọ kan koda to fi mọ ile iṣe to n ri si eto idajọ lo ti mọ nipa igbesẹ tuntun yii ti wn si ti gbaradi lati bẹrẹ igbẹjọ lakọtun lori ẹjọ yii to jẹ ọkan pataki ninu iwe itan eto idajọ ipinlẹ Ondo.
Ijọ Sotitobire Praising Chapel ti Woli Babatunde Alfa Babatunde jẹ oludasilẹ ati alakoso fun jẹ ijọ ti ero ti maa n wọ ju niluu Akure ko to wa di pe o kagbako iṣẹlẹ aburu yii nigba ti Gold Kolawole, ọmọ ọdun kan nigba naa lọhun dede poora lasiko ti isin n lọ lọwọ ninu oṣu kọkanla ọdun 2019.
Lẹyin eyi ni awọn agbofinro ọtẹlẹmuyẹ DSS lọ gbe Wolii naa ti wọn si wọ ọ lọ ile ẹjọ majisireeti ni Akure to tun wa di ero ile ẹjọ giga nibi ti wọn ti da ẹjọ fun un lori ẹsun gboogi meji to da lorii ijọmọgbe ati igbimọpọ ati lilọwọ ninu ijọmọgbe.
Nkan bii oṣu mẹwaa gbako laarin oṣu Sẹẹrẹ si oṣu Ọwara ọdun 2020 ni fa ki n fa ẹjọ naa waye ti idajọ sọ pe Woli Sotitobire atawọn olukọ ọmọde marun jẹbi ẹsun ti wọn fi kan wọn, wn si ran wn lọ si ẹwọn gberee labẹ idajọ Adajọ Olusegun Odusola ni ibamu pẹlu aṣẹ ẹri ti ẹjọ ti adajọ agba tẹlẹri ni Ondo, Adekola Olawoye dari.
Ondo nurse protest: Ó tó gẹ́ẹ́, ẹ bá wa bẹ àwọn mọ̀lẹ́bí àti aláìsàn ní FMC Owo, kí wọ́n yé fìyà jẹ àwa nọ́ọ̀sì.
Oríṣun àwòrán, Facebook/max.collinsjnr
Awọn oṣiṣẹ ilera nọọsi ni ile iwosan ijọba apapọ FMC Ọwọ, ni ipinlẹ Ondo, ti ke gbajare lori bawọn alaisan ati mọlẹbi wọn ṣe n fiya jẹ wọn.
Ọrọ yi mu ki wọn ṣe iwọde alalaafia lati fi ifẹhonu wọn han lori ọrọ yi.
Ifiyajẹni ti wọn lawọn koju kẹyin leleyi to ni ṣe pẹlu bi awọn mọlẹbi arakunrin kan to gbẹmi mi se lu awọn nọọsi meji kan laludaku lọjọ Aiku.
A gbọ pe ẹsẹ kan aye ẹsẹ kan ọrun larakunrin naa wa nigba ti wọn fi gbe de ile iwosan ti gbogbo igbiyanju awọn oṣiṣẹ ilera lati doola ẹmi rẹ si ja si pabo.
Awọn mọlẹbi arakunrin naa ti wọn pe orukọ rẹ ni Mojoyinoluwa Adelu lati Ilara Mokin fa ibinu yọ nitori iku rẹ ti wọn si lu awọn nọọsi meji yi lalaubami.
Ọkan lara awọn nọọsi yi, Olayinka Bankole, to ba akọroyin sọrọ lati ori ibusun rẹ ni ile iwosan  ni iya to jẹ awọn kii ṣe kekere,
Seyi Makinde; Ilé iwosan kan ṣoṣo tó wà ní  Idí-Iroko /Adewole tí bàjẹ́ pátápátá.
O ni pẹlu pe awọn sa asala fẹmi awọn  wọ inu ile igbọnsẹ, niṣe ni awọn mọlẹbia oloogbe naa wọ awọn jade ti wọn si da bantẹ iya fawọn.
Olayinka ni awọn eeyan meji kan gbe oun soke ti wọn si jan oun mọlẹ ki awọn to ku si fọwọ kun wọn lati maa na oun.
''Niṣe la sa wọ ile igbọnsẹ,wọn tẹle wa debẹ, wọn si wọ wa sita.Awọn obinrin meji kan ninu wọn fọ mi mọlẹ, wọn si bẹrẹ si ni lumi''
Lasiko iwọde awọn nọọsi yi ọga agba ile iwosan naa dokita Liasu Ahmed sọ pe iwadii ti bẹrẹ lori ọrọ yi ati pe awọn yoo fawọn to ba mọ nipa iṣẹlẹ yi le ọlọpaa lọwọ.
Learning Yoruba: Akọmọlédè àti Àṣà Yorùbá gbé oríkì yẹ̀wò
Laye atijọ to si tun n ṣẹlẹ titi di oni, eeyan le da gbogbo ti apo rẹ silẹ bi o ba gbọ ti oriki rẹ n lọ to si n wọ ọ lakinyẹmi ara.
Aṣa àti iṣe ilẹ kaaro o jiire ni Oriki. Ewi alohun ti ko ṣee fọwọ rọ sẹyin ni pẹlu.
Yatọ fun ki a kan maa fọ girama lati ṣalaye itumọ oriki, ko si eeyan ti o gbọ oriki rẹ ti ori rẹ ko ni wu.
Amọ ṣe ẹ mọ wipe kii ṣe eeyan tabi ilu nikan lo ni oriki?
Iran ni oriki, Oriṣa ni, ẹranko gan ni oriki.
Ni ti orukọ eeyan nikan gaan o pin si meji. O lee jẹ oriki abisọ tabi amutọrunwa.
Oriki pọn aṣa Yoruba le pupọ pupọ, agbe aṣa ga si ni. Kkoda ẹ lee ri aṣa ati iṣe ilu kan ninu oriki wọn.
Ohun ti ẹ ko gbọ ri nipa eeyan kan tabi ilu lee ṣuyọ sii yin nigba ti ẹ ba farabalẹ gbọ awọn ọrọ oriki rẹ.
Yoruba Film: Nígbà tí ǹkan aburú bá ṣẹlẹ̀, àwọn olólùfẹ́ gaan ló máa sọ̀rọ̀ - Ronke Oshodi Oke
Oríṣun àwòrán, Ronke Oshodi
Bi awọn ololufẹ gbajugbaja oṣere, Ronke Anthony-Ojo ti gbogbo eeyan mọ si Ronke Oshodi Oke ṣe n faraya lori ayelujara lori pe o padanu lara ọyan rẹ to tobi ti di ranto.
BBC Yoruba kan si ilumọọka oṣere yii lati mọ iha ti oun funrarẹ kọ si ọrọ ti awọn eeyan n sọ lori ayelujara.
"''Mo kan ""slim down"" naa ni o, ko si babara nibẹ, ṣe ẹ mọ wipe nkan ti eeyan fẹ yatọ si nkan ti o n wu ẹlomiran lara eeyan.''"
50 Year old Ajayi Folashade: Mo ti kọ́kọ́ dán an wò ní 80s àmọ́, ó kàn ṣáà ń wù mi náà ni
Lootọ awọn eeyan gba pe ko saburu ninu pe o jo lara ṣugbọn ohun to n ka wọn lara ni wipe abusi Edumare nla iyẹn ọyan ti o ni to si n wu awọn ololufẹ rẹ mii ninu ere to tun jo lo n ka wọn lara.
"Ronke Oshodi Oke ni ""ọra ti pọju ninu ọyan yẹn ni, ati lara. Ṣe ẹ mọ wipe eeyan ti n dagba, awọn nkan mii si wa to yẹ keeyan tete mojuto.''"
"O ni ''Nigba ti eeyan ba maa fi sunmọ ẹni aadọta ọdun, awọn nkan mii o ni ṣee ko mọ"""
Ó dára kí obìnrin níṣẹ́ lọ́wọ́ - Toyin Lawani
Tori naa ni Ronke Oshodi Oke ṣe ni oun yan lati gbe igbesẹ yii. O ni o ti pẹ toun ti fẹ jo lara amọ ti oun n wo wipe haa ṣe oun yoo wa padanu ọyan yii ni.
O kan jẹ asiko yii ni awọn eeyan ṣẹṣẹ ri i ni. Latinu oṣu kẹfa ni mo ti bẹrẹ ilana jijo lara yii ṣugbọn ẹyin ololuf mi ṣẹṣẹ n ri i ni.
Ṣe jijo lara yii sọ Ronke di alaisan ni?
"Ronke Ojo jẹ ko di mimọ pe fun ilera ara oun ni nkan ti oun ṣe yii. ""Nigba ti nkan aburu ba ṣẹlẹ si eeyan tori iru nkan bayii, awọn ololufẹ yẹn gaan lo maa kọkọ sọrọ""."
Nigba ti a bi Ronke pe ki ni iyatọ laarin igba ti o ni yan nla ati asiko yii ti ara rẹ ti jo, Ronke ni awọn ara ile lo ro wipe nkan yipada ti wọn n pariwo.
Ni temi, ko si iyatọ kankan ninu nkan ti mo ṣe nisisiyii. Koda bi mo ba wo ara mi ninu ile, mi o ri i wipe nkankan lọ lara mi. Ọra lasan lo wa nibẹ ti wọn si yọ kuro.
Ronke Oshodi Oke jẹ ko ye BBC Yoruba wipe nkan to ṣe pataki to si wu oun loun ṣe amọ oun ko ṣaisan rara bi awn kan ṣe n ro.
Iru kọmu wo ni Ronke Ojo n wọ bayii to yatọ si igba to ni ọyan nla?
Ko si iyatọ ninu kọmu ti mo n wọ nisisiyi ati ti tẹlẹ. Ọrọ yii gan ya akọroyin BBC Yoruba lẹnu amọ gẹgẹ bi obinrin, loot o ṣeeṣe ki ibi ara ti eeyan n so okun kọmu mọ ma fibẹẹ yatọ.
Iyatọ to wa ni wipe 110kg ni gbogbo sisanra mi tẹlẹ amọ nibayii, mo ti di nkan bii 87kg. Mo si nifẹẹ rẹ bẹẹ.
Ki ni imọran Ronke fun awọn ololufẹ to ka lara pe ọyan rẹ jo?
Ẹbẹ ni Ronkẹ fi bẹẹ pe ki awọn ololufẹ oun to ba binu ma binu si oun rara nitori wipe tori ilera oun loun ṣe ṣe e.
Ẹ ba mi bẹ awọn ololufẹ mi ki wọn wa nkan mii wo lara mi ju yan yii lọ.
Ronke ni tẹlẹ kii fi bẹẹ ṣe tori ọyan ni awọn akẹgbẹ oun ṣe n pe oun si ere ati awọn ipa ti oun ko nitorinaa ki awọn ololuf oun ma fi tiyẹn ṣe rara.
Gorilla glue Girl: Ọmọ Ghana, Dr Michael Obeng rí irun Tessica olórí gúlúù fọ̀ pẹ̀lú iṣẹ́ abẹ
Oríṣun àwòrán, MICHAEL K. OBENG FACEBOOK
Arabinrin to fi 'Gorilla Glue' lẹ irun ori rẹ ti pada ri ọna abayọ, lẹyin oṣu kan to fi jagun titi ti ko rii ṣe.
Ẹni ogun ọdun naa gbera lati ilu Louisiana lọ si Los Angeles ni Ọjọru, lati ri dokita kan to jẹ ọmọ orilẹ-ede Ghana ati America, Dokita Michael Obeng, fun ọna abayọ.
Laipẹ yii ni Tessica Brown di gbajugbaja lori ayelujara lasiko to fi fidio kan sita nitori iṣoro to n koju.
Diẹ lo ku ko pe oṣu kan nigba naa, to ti ṣeeṣi fi 'gorilla glue' ti wọn fi n lẹ igi, ati awọn nkan mii to l'agbara, lẹ irun rẹ.
Gbogbo igbiyanju rẹ lati fi ọṣẹ ati omi fọ ọ danu lo jasi ofo. Bẹẹni ko ri ọna abayọ nileewosan.
Oríṣun àwòrán, im_d_ollady/TWITTER
Ṣugbọn ori rẹ gbe e pade alawo ire, nigba ti Dokita Obeng kan si i pe oun yoo ṣe itọju rẹ lọfẹẹ.
Dokita naa ṣe iṣẹ abẹ si irun rẹ, lati yọ 'gorilla glue naa kuro.
Iroyin sọ pe wakati mẹrin ni isẹ abẹ naa fi waye, ati pe bi ẹgbẹrun mejila Dọla ni Tessica i ba san, ka ni dokita naa fẹ ẹ gba owo.
Iru eniyan wo wa  ni Dokita Michael Obeng to gba Tenessa ninu iṣoro rẹ?
Ìròyìn ayọ̀ ló jẹ́ fún Tessica tó fi 'glue' lẹ irun  pọ̀ nígbà tó rí ẹlẹ́yinjú àánú Dókítà tó fẹ́ ṣe iṣẹ́ abẹ orí fún un
Ori ti ko ọmọbinrin Jessica Brown yọ o, lẹyin to ri dokita ti yoo ṣe iṣẹ abẹ fun un nitori ''glue' to fi lẹ ori rẹ, ti ko ṣi lẹyin oṣu kan.
Jessica Brown ni ọrọ rẹ gba ori ayelujara kan nitori o lo ''gorilla adhesive glue'' Lai kii ṣe 'hair spray' lati fi lẹ irun rẹ.
Amọ Dokita Micheal Obeng ti wọn bi lorilẹede Ghana, amọ to n ṣiṣẹ ni Amerika, ti ni oun yoo ṣiṣẹ abẹ fun un ni ọfẹ ti irun naa yoo fi ṣi.
Ọmọbinrin naa lo 'glue' hun ki irun rẹ ba le duro si oju kan lati bi oṣu kan sẹyin, ti o si ti sa gbogbo ipa rẹ lati ṣi 'glue' ọhun kuro ni ori, amọ ko ṣi rara lẹyin to ti fọ  nigba mẹẹdogun.
50 Year old Ajayi Folashade: Mo ti kọ́kọ́ dán an wò ní 80s àmọ́, ó kàn ṣáà ń wù mi náà ni
'Glue' ti omobinrin yii fi si ori ni won ma fi n le 'tiles' inu ile ati baluwe ati lati ko koi le.
''E gba mi o, iru mi ko kuro ni oju kan o, mo ti fo o bi igba marundinlogun, amo o le pa sibe ni''
Aṃọ, Dokita Obeng ni aanu ọmọbinrin Jessica naa ṣe oun nigba ti oun gbọ iriri rẹ.
Oríṣun àwòrán, Dr Micheal Obeng/Instagram
Dr Micheal Obeng
Dokita naa ni awon yoo wa ṣe iṣẹ abẹ fun un, ti wọn yoo si kun un lorun ki o ma ba a jẹ irora.
Dokita to jẹ asaraloge naa ni awọn yoo lo 'chemical' lati fi fọ ori naa.
Iru iṣẹ abẹ yii yẹ ko naa ni iye owo ẹgbẹrun mejila dọla owo ilẹ okeere, amọ dokita naa ni ọfẹ ni oun yoo se e fun un.
Ogbontagiri Dokita ni Obeng gege bi a ṣe rika ni oju opo rẹ lori ayelujara, ti o si tun da ileeṣẹ eto ọfẹ ti n kọ awọn eniyan ni iṣẹ abẹ ṣiṣe araloge, ti wọn pe orukọ rẹ ni 'Restoring Emotional Stability Through Outstanding Reconstructive Efforts (Restore).'
"Arabinrin kan to n gbe nilu Louisiana ti deero ileewosan lẹyin to ṣe e ṣi fi eroja ti wọn fi n lẹ nkan pọ ""Gorilla Glue spray adhesive' si irun orí rẹ dipo jẹẹli irun."
Ibẹrẹ oṣu Keji ni iroyin ìṣòro to doju kọ Tessica Brown jáde si ori ayelujara.
O sọ ninu iroyin naa pe oun ti n gbe irun ti oun ṣe kiri lati bi oṣu kan, nitori pe oun se àṣìṣe nipa lilo 'glue' ti ko yẹ ki oun lo lasiko ti eyi to ma n lo tán.
O sọ lori ayelujara Instagram pe igba mẹẹdogun ni oun ti fọ irun orí oun, sugbọn eroja naa ko kuro.
Ohun táa mọ̀ nípa àpò àsùwọ̀n owó Sunday Igboho tí ariwo ta pé ìjọba gbẹ́sẹ̀ lé
Ǹkan márùn ún tó yẹ kí o mọ̀ nípa NIN àti BVN
Àsìkò yìí la gbúdọ̀ pa jíjẹ́ ọ̀ta ara ẹni tì lẹ fi rí mi ní ìpàdé pẹ̀lú APC - Femi Fani Kayode
Ṣé o mọ oríkì ìlú ara rẹ tó olùkọ́ yìí tó dántọ́ lẹ́nu rẹ̀ bíi ọmọ ìlú rẹ?
Oríṣun àwòrán, im_d_ollady
Gẹgẹ bi akọsilẹ to wa ni itakun agbaye Gorilla Glue, omi ko le ṣi danu, wọn si saba ma n fi lẹ taisi iléèwẹ̀, igi mọ ilẹ inu ile, ati àjà ile.
Eroja acetone tabi isopropyl alcohol lo le ṣí i.
Ileesẹ to n ṣe 'glue' naa si ti ba Arabinrin Brown daro lori Twitter, nigba ti wọn gbọ nkan to ṣẹlẹ si.
Ọjọ Satide ni Brown fi fọto ara rẹ si ori Instagram rẹ @im_d_ollady lasiko to lọ si ileewosan St. Bernard Parish Hospital ni Chalmette, Louisiana, lati ṣi eroja naa danu.
O rọ àwọn eeyan lati ma a gbadura fun lati la wahala yii kọjá, ati pe ki o ma padanu irun rẹ.
À ṣé ara mi ni isó tí ń rùn, tí èmi náà ń ṣépè fún ẹni tí Jamiu Azeez ń sọ - Mama Ereko
Ọba tó wàjà àmọ́ tí òkú rẹ̀ gbúdọ̀ jókòó sórí ìtẹ́ ṣáájú ìsìnkú
Ọlọ́pàá dá ọkùnrin méjì tó ń ní ìbálòpọ̀ ọkùnrin sọ́kùnrin padà sí ìlú abínibí wọn
Wo ìgbé àyé ìyá àti ọmọbìnrin tó ń fi iṣẹ́ aṣẹ́wó jẹun
Oríṣun àwòrán, im_d_ollady/TWITTER
Ileesẹ to n ṣe 'glue ' naa sọ pe àrà ọtọ ni nkan to ṣẹlẹ si Arabinrin Tessica, ati pe eroja to lo kii ṣe fun irun.
"Wọn ni ""eroja ti a n ṣe kii ṣe fun irun, nitori pe o ma n lẹ nkan pọ titi lai ni. O le gbiyanju lati rẹ irun naa si inu omi to lọwọọrọ, omi ọsẹ tabi ki o fi alcohol pa irun naa."
Titi di asiko yii, Arabinrin Tessica ṣi wa ninu ìṣòro rẹ.
Iroyin TMZ ti ẹ sọ pe o n gbeero lati gbe ẹjọ naa lọ sile ẹjọ, nitori pe ohun ti ileesẹ naa sọ pe ko ṣe ko tán ìṣòro rẹ.
Awọn to sunmọ obinrin naa sọ pe wakati mejilelogun lo lo ni ileewosan.
Ẹ wa kọ́ bí wọ́n ṣe ń sin máàlù lọ́nà ìgbàlódé lọ́dọ̀ èmi àti Kwam1  - Oluwo
Ọ̀rá lásán ló wà nínú ọ̀yàn mi tó jò, ẹ̀yin olólùfẹ́ mi, ẹ wá ǹkàn míì wò lára mi - Ronke Oshodi Oke
Oríṣun àwòrán, im_d_ollady/TWITTER
Nise ni eroja acetone ti awọn oṣiṣẹ eto ilera fi si ipakọ rẹ n bo awọ ori rẹ.
O mu ki 'glue' naa rọ, sugbọn ṣe lo tun sare le pada.
Ni bayii, Tessica ti n tọrọ owo fun iwosan rẹ, o si ti ri ẹgbẹrun mẹsan Dọla ($9,000) ko jọ.
Ileesẹ GC sọ pe awọn kọ eewọ si ara gbogbo ọjà wọn, pe iṣẹ titi lai lo ma n ṣe.
Sugbọn, a gbọ pe Tessica ro pe ko sewu ti oun ba lo o, nitori pe gbogbonise ni.
Ikọ̀ Gómìnà Borno, Zulum kàgbákò ìjàmbá ọkọ̀ lójú pópó
Oríṣun àwòrán, @Mohamme17292289
Ikọ Gomina Babagana Zulum ti ipinlẹ Borno ti kagbako ijamba ọkọ lasiko irinajo kan.
A gbọ pe nigba ti o n dari bọ lati irinajo ni Mafa si Maiduguri ni iṣẹlẹ yi waye.
BBC ri gbọ lẹnu awọn to kọwọn rin pẹlu Gomina pe taya ọkọ kan lara ọkọ  ikọ Gomina lo fọ ti eeyan mẹta si ku ninu ijamba naa.
Ni kete ti a ba ri aridaju nipa iṣẹlẹ naa ju bo ti ṣe wa yi lọ, a o maa fi to yin leti
A n ṣe akojọpọ iroyin lọwọ...
Itan Manigbagbe: Oba Asanike Yefusu Oloyede, Olubadan tó gbóyà, aláwàdà, tó tún kún fún ọgbọ́n
Oríṣun àwòrán, The Cable
Ọba Yesufu Oloyede Asanikẹ ni Olubadan kẹtadinlogoji to jẹ niluu Ibadan.
Idile Asanikẹ ni adugbo Idi-Aro lo ti wa.
Gbajumọ oniṣowoo koko ni Ọba Asanikẹ.
Lati ọdun 1947 si lo ti n dari ilu lẹyin ti wọn fi jẹ Mọgaji agboole Asanikẹ.
Lọdun 1957, Oloyede asanikẹ di oloye laafin Olubadan, nigba ti Ọba I.B Akinyẹle  fi joye.
Diẹdiẹ si lo gun akasọ oye, titi to fi di Olubadan ni ọjọ kẹrin, oṣu Keji, ọdun 1983.
Abẹ́rẹ́ àjẹsára Covid-19 ń yí àwọn èèyàn sí oníbálòpọ̀ akọsákọ àti abosábo - Alfa Abbas
'Sunday Igboho dáná sun àwòrán bàbá wà kódà ó tún yìnbọn sókè nígbà tó wà sí ilé wà ní Eggua'
Ta ló ṣekúpa akẹ́kọ̀ọ́ iléèwé Poly Rufus Giwa tí wọ́n ṣá pa
Ohun táa mọ̀ nípa ibọn tó ró kùlà kùlà ní Obalende
50 Year old Ajayi Folashade: Mo ti kọ́kọ́ dán an wò ní 80s àmọ́, ó kàn ṣáà ń wù mi náà ni
Oríṣun àwòrán, Facebook/Hrh Oba Yesufu Oloyede-Asanike I
Ọdun mẹwaa ni Asanikẹ lo lori oye Olubadan. Ọpọlọpọ si ni ko gbagbọ pe yoo lo to iye ọdun naa, nitori pe o ti di arugbo kujọ-kujọ ko to o jẹ ọba.
Sugbọn lai fi ti ọjọ ori ati ipo ilera rẹ ṣe, itan sọ pe ọba to kun fun ọgbọn, imọ, igboya, iwoye, ati alawada ni.
Bakan naa lo jẹ pe kii rẹrin, ti kii si bẹru lati sọrọ.
Lara awọn 'ọrọ akin' ti itan sọ pe Asanikẹ sọ ni asiko ti aarẹ ologun, oloogbe Sani Abacha ṣe abẹwo si aafin rẹ.
Eeyan nla, to ga, to sigbọnlẹ, ti oju rẹ n yọ ina,  ni kabiesi n reti, amọ iyalẹnu lo jẹ fun lati ri pe Abacha ko ri bẹẹ.
"Asanikẹ ko le pa iyalẹnu rẹ mọra, lo ba dahun pe ""Abacha, a so o ju bayi lọ!''"
Abacha paapaa bu si ẹrin.
Adebisi Idikan: Òun ló gba Ìbàdàn sílẹ̀ lọ́wọ́ ìyà owó orí sísan
Ẹru ẹnikẹni kii ba a, to fi mọ awọn ọmọ ologun.
Koda, gomina ologun kan fi ẹsun kan-an pe saara lo n fi òyè ṣe nilu Ibadan.
"Inu bi Asanikẹ debi pe pẹlu ibinu lo fi sọ pe ki gomina naa ko gbe ẹnu rẹ dakẹ. O ni ""ọba ni gomina laaye rẹ, ọba ni emi naa laaye mi."
Ọrọ naa waye lẹyin ti Ọba Asanikẹ fi M.K.O Abiola, to jẹ ọmọ bibi ilẹ Ẹgba, jẹ oye Bashorun ilẹ Ibadan.
Oríṣun àwòrán, Facebook/Hrh Oba Yesufu Oloyede-Asanike I
Ọba Asanikẹ ati MKO Abiola
Ọpọlọpọ ọmọ bibi ilẹ Ibadan lo binu si ifinijoye naa, nitori wọn gbagbọ pe ọmọ ilu nikan ni oye naa tọ si.
Itan sọ pe Ọba Asanikẹ ni Olubadan to fi eeyan joye ju lọ, lai fi ẹya ti ẹni naa ti wa ṣe ni Naijiria.
Awọn kan ti ẹ gbagbọ pe o ma n ta oye fun ẹnikẹni to ba ti le san owo fun.
Oríṣun àwòrán, Twitter/ @yoruba history
Asanike ati Oba Adeniji Adele ti ilu Eko, ati Alake ti Ẹ̀gba,ati Ọ̀ba Ademolalọ̀dun 1950
Lara awọn ọmọ ilẹ okeere ti Asanikẹ fi joye ni ọmọ orilẹ-ede Lebanon, I-MUDAH to jẹ oniṣowo ni ọja Gbagi.
Oye Baba Laje ilu Ibadan ni Ọba Yesufu Asanikẹ fi jẹ.
Lori ọrọ ifinijoye yii naa, itan sọ pe awọn oloye rẹ kan ti inu n bi ko ara wọn jọ lẹyin ija kabiesi ati gomina ologun naa.
Wọn lọ si aafin Asanikẹ, wọn si sọ fun pe ko si oye kankan mọ ninu akọsilẹ lati fun ẹnikẹni.
"Niṣe ni Asanikẹ tun sare fun wọn ni esi pe ""oye tan, oye naa ni""."
Ó pé ogún ọdun tí MKO Abiọla jáde láyé
Oyè Ibadan kò sí fún títà - Otun Olubadan, Lekan Balogun
A kò ní fi adé wa sílẹ̀ nítorí Olubadan - Àwọn Ọba 27
Ìsọkúsọ ni Olúbàdàn ń sọ, àwa la lè yọ́ lóyè. òun kò le è yọ́ wá - Lekan Balogun
Lọdun 1983, laipẹ si igba to jẹ ọba ni eto idibo waye. Ija oṣelu si waye laarin gomina to wa ni ipo, Oloogbe Bola Ige ti ẹgbẹ oṣelu UPN, ati oludije ẹgbk oṣelu NPN, Dokita Ọmọlolu Olunlọyọ.
Olunlọyọ lo wọle, botilẹ jẹ pe awọn eeyan fi ẹsun kan pe magomago waye ninu idibo naa.
Ọrọ naa di ti ile ẹjọ. Asanikẹ paapa lọ si iwaju igbimọ to n gbọ ẹsun idibo naa lati ṣe atilẹyin fun Olunlọyọ to jẹ ọmọ ilu Ibadan.
"Gbangba lo ti sọ pe ""ọmọ wa ni, ẹ jẹ o se"", lai fi ṣe pe ilu Ibadan ni Bọla Ige gbe dagba, to ti n ṣe iṣẹ amofin, to tun fẹ ọmọ ilu Ibadan ni iyawo."
Ọkan lara awọn iṣẹlẹ to tun jẹ manigbagbe lasiko ti Ọba Oloyede Asanikẹ wa nipo ni asiko ti awọn adigunjale kan wọ aafin rẹ, ti wọn si yọ awọn taya ati ẹya ara ọkọ lara awọn ọkọ ayọkẹlẹ Olubadan.
Oríṣun àwòrán, Facebook/ Hrh Oba Yesufu Oloyede-Asanike I
Kiakia ni ọwọ awọn oṣiṣẹ alaabo l'aafin tẹ digunjale yii.
Pẹlu idinnu ati iwuri si ni awọn oṣiṣẹ alaabo naa fi ko awọn ole lọ siwaju kabiesi lati fi han pe awọn ṣe iṣẹ takun-takun.
"Amọ, iyalẹnu lo jẹ nigba ti Kabiesi tu awọn ole naa silẹ, to si fun awọn alaabo ni esi pe ""mi o ran yin pe kẹ ẹ sọ mọto, iyawo mi ni mo ni ẹ sọ""."
Ìtàn ayé Ọba Seriki Abass ti Badagry, tó ní aya 128, ọmọ 144
Irú èpè wo ni Aláàfin Aolẹ ṣẹ́ fún ìran Yorùbá?
Ìtàn rèé nípa bí Ogbomoso ṣe pa ọba wọn ní ọdùn tó ti pẹ́ díẹ̀ sẹ́yìn
Ìgbà mẹ́jọ tí ọ̀rọ̀ Oluwo di ariwo nígboro láàrín ọdún márùn ún rẹ̀ lóyè
Àlàyé rèé lórí bí wọ́n ṣe mú mi lẹ́rú ní 1837 - Ajayi Crowther
Itan sọ pe Ọba Asanikẹ ko fi inu tan ọkan lara awọn olori rẹ to fẹra, eyi si lo mu ko gba awọn ẹsọ alaabo lati ma a tẹle kiri. Boya o n yan ale.
Gẹẹgẹ lo ma n gbe awọn obinrin.
Iṣẹlẹ manigbagbe mii tun ni lasiko ti awọn ọmọ ilẹ Afrika kan to tun jẹ ọmọ ilẹ America ṣe abẹwo si aafin rẹ.
"Gẹgẹ bi iṣe rẹ, Olubadan tun ta omi oge si arẹwa obinrin kan nipa si sọ pe ""Oo le lọ""."
Itan sọ pe ẹru ba ọmọbinrin naa to ro pe Kabiesi ti fi ofin mu oun ni. Kia lo fi igbe ta, ki Kabiesi fun'ra rẹ to o mọ pe awada ti oun ṣe ti l'agbara ju.
Oríṣun àwòrán, Facebook/Hrh Oba Yesufu Oloyede-Asanike I
Ọba Asanikẹ ati ọ̀kan lara awọn olori rẹ
"O tọrọ aforiji, o si sọ fun pe ""mo fi n ba ọ sie ni""."
Yatọ si awọn nkan wọn yii, Ọba Asanikẹ ni Olubadan akọkọ to gbe ninu aafin igbalode ni Ọja Ọba, nilu Ibadan.
O lo ipo rẹ lati wa ilọsiwaju ilẹ Ibadan ati awọn ọmọ ilu.
O pese iranwọ fun awọn to fẹ ẹ wọ ileewe giga, ati awọn to n wa iṣẹ lara wọn.
Ọjọ kẹrinlelogun, oṣu Kejila, ọdun 1993 lo waja.
Farmers-Herders clash: Amotekun Ondo mú àwọn afurasí daran-daran tó já wọ oko olóko pẹ̀lú màálù
Oríṣun àwòrán, @news360info
Ọjọ Iṣẹgun ni iroyin jade pe ọwọ awọn oṣiṣẹ ajọ alabo Amọtẹkun nipinlẹ Ondo tẹ daran-daran Fulani meji ati awọn maalu wọn nijọba ibilẹ Ifedore nipinlẹ Ondo.
Awọn afurasi naa ni iroyin sọ pe wọn fi ẹran ọsin wọn ba irugbin jẹ ni oko awọn agbẹ kan ni agbegbe naa.
Bakan naa ni wọn tun fi ẹsun kan wọn pe wọn kọju ija si awọn oṣiṣẹ Amọtẹkun to fẹ fi ofin mu wọn.
Iṣẹlẹ yii waye lẹyin ọsẹ bii meji ti gomina ipinlẹ Ondo, Rotimi Akeredolu kede ofin to de dida ẹran ọsin ni oru, ati laarin ilu ati ojupopo.
Bakan naa ni gomina tun paṣẹ fun awọn daran-daran lati kuro ni awọn igbo iyasọtọ nipinlẹ naa.
Lasiko to ba BBC Yoruba sọrọ, Oludari ajọ Amọtẹkun nipinlẹ Ondo, Adeleye Adetunji sọ pe lootọ ni ọwọ awọn tẹ daran-daran meji, ati awọn maalu wọn fun pe wọn ba irugbin jẹ ni oko oloko.
Ṣugbọn ṣa, Alaga ẹgbẹ awọn daran-daran, Miyetti Allah, Alhaji Garuba Bello, sọ pe oun ko tii gbọ nipa iṣẹlẹ naa.
Lati oṣu Kinni, ọdun 2020 ni ọrọ awọn Fulani daran-daran ati awọn agbẹ tun ti n fa wahala ni ilẹ Yoruba.
Paapaa lẹyin ti gbajugbaja ajijagbara, Sunday Adeyemo, ti awọn eeyan mọ si Sunday Igboho, fun awọn Fulani daran-daran ni gbedeke ọjọ meje lati fi ilẹ Yoruba silẹ.
Sunday Igboho fulani ultimatum: Àwọn ará Kebbi àti Zamfara ló n jínígbé ní Oke Ogun- Serik
Ọrọ yii fa rogbodiyan lasiko ti Igboho lọ si agbegbe Oke Ogun nipinlẹ Ọyọ, nibi ti awọn janduku kan ti kọlu Seriki Fulani nilu Igangan lẹyin abẹwo Sunday Igboho.
Herders-Farmers clash: Kí oníkálùkù máa lọ ní ìlọ tiẹ̀, a ò fẹ́ Seriki Fulani ní ìlú mọ́-Akọ̀wé àgbẹ̀ Igangan
Ipetuṣaawọ ọrọ laarin Fulani ati awọn agbe Yoruba ni Ibarapa paapa ni ilu Igangan ko ṣebi ẹni pe yoo yanju laipẹ yi.
Idi  ni pe awọn tọrọ kan, iyen awọn Yoruba ati awọn Fulani ko ṣetan lati joko yanju ọrọ yi ni tubu n nubi.
Ninu ifọrọwerọ to waye lori ikanni BBC akọwe awọn agbẹ ni Igangan alagba Taiwo Adeagbo sọ pe alejo lawọn Fulani ati pe wọn fi oko jijẹ kalẹ ti wọn si bẹrẹ si ni pa awọn eeyan.
O mu ẹri wa nipa awọn iwe ẹhonu toun ti kọ lati fẹsun kan Seriki Fulani lori gbogbo aṣemasẹ to n ṣe lagbegbe Igangan.
Ninu alaye rẹ, alagba Adeagbo sọ pe Seriki Fulani kii ṣe  ẹni to faye gba alaafia nilu nipa awọn nkan orisirisi to n kọ sinu iwe iroyin
''Saliu Seriki kọ iwe si ijọba ipinlẹ Oyo lai ṣe pe ẹnikankan n pa maalu rẹ''
''Bakan naa nigba ti BBC lọ ba fun ifọrọwerọ o ṣalaye pe maalu oun le si ni ọdọọdun ni.Ṣe ẹyin naa ri gbogbo irọ to n pa? Awọn n ri oko wọn da ṣugbọn awa agbẹ Yoruba ko ri oko tiwa da''
Adeagbo ni gbogbo atotonu yoo wu ki Seriki Fulani ati awọn ọmọ rẹ le wi, ohun to ṣe koko ni pe ara ilu ko fẹ wọn nilu mọ.
Awọn ara ilu ko le ni ka ma gbe ni Igangan mọ
Ninu esi si gbogbo awọn ẹsun ti Adeagbo fi kan baba rẹ, ọmọ Seriki Fulani, Ibrahim Salihu sọ pe ẹtaanu lo n mu ki awọn Yoruba maa tako igbelu Fulani ni Igangan.
O ni ko si ootọ ninu ọrọ ti Adeagbo sọ pe Seriki Fulani n pe awọn Fulani wa lati ilẹ Niger to si n fipa gba maalu wọn.
Sunday Igboho fulani ultimatum: Àwọn ará Kebbi àti Zamfara ló n jínígbé ní Oke Ogun- Serik
Arakunrin Fulani ni aigbede ara eni ni orisun ija pelu agbe
Ibrahim bẹnu atẹ lu gbogbo akawe ti Adeagbo muwa to si ni Adeagbo gaan kii ṣe ọmọ ilu Igangan nitori naa ko le sọ nipa itan Igangan tabi ko ni oun gbẹnu awọn agbẹ sọrọ.
Lori ẹsun pe awọn Fulani n gbe ibọn AK47 kaakiri, Ibrahim fesi pe :
''Bi a ba ni ibọn lọwọ, ṣe awọn to wa ṣigun ba wa nile, a ko ni ti ṣina ibọn lati daabo bo ara wa ni?''
Nipa iku Ọmọwe Abọrọde ti wọn pa ni Igangan Ibrahim ni oun ko jiyan pe kii ṣe Fulani lo pa ṣugbọn iku rẹ jọ bi iṣẹlẹ awọn agbenipa nitori ọrọ oṣelu ni.
O ṣalaye pe Aborọde jẹ ẹni to sunmọ awọn Fulani paapa mọlẹbi Seriki Fulani nitori naa iroyin to gbode pe wọn pa Aborode nigba to wa fẹjọ sun Seriki pe awọn Fulani fẹran jẹ oko rẹ kii ṣe ootọ.
Nigbẹyin gbẹyin ifọrọwanilẹnuwo, BBC beere boya wọn le wa na abayọ lati le jijọ maa gbe pọ ni irẹpọ.
Ninu esi tirẹ Alagba Adeagbo sọ pe ko si ṣiṣe ko si aiṣe, gbogbo ara ilu ni ko fẹ ri Seriki Fiulani ati awọnb ọmọ ẹ nilu mọ.
Amọ ṣa Ibrahim ni ara ilu kole sọ pe kawọn ma gbe ilu mọ lopin igba ti ofin Naijiria  faaye gba ki ọmọ Naijriia maa gbe ibi to ba wu lopin igba to ba ti jẹ ọmọ ilẹ naa.
Adamu Suleiman sọ pe lootọ lawọn ati Yoruba jijọ n gbe ibọn kaakiri
Bi ẹ baa n sọrọ pe awa Fulani n gbebọn kiri, lootọ ni ṣugbọn awọn Yoruba naa n gbe ibon tiwọn naa ka.
Ọrọ yi ni BBC gbọ lati ẹnu ọkan lara awọn darandaran to wa nilẹ Yoruba.
Adamu Suleiman to ba BBC sọrọ fidi ọrọ mulẹ pe lootọ lawọn n gbe ibọn kaakiri ṣugbọn ati awọn ati awọn agbẹ lo n gbe ibọn kiri titi ti ijọba yoo fi yanju wahala to wa nilẹ.
Ọmọ Seriki Fulani ilu Eggua ni ijọba ibilẹ Yewa nipinlẹ Ogun yi sọ pe ile oun wa lara ile tawọn janduku dana sun laipẹ yi ni Eggua.
O ni ijọba kii gbe igbesẹ to yẹ lati dẹkun ikọlu to n waye yi nitori awọn ọlọpaa ko ni irinṣẹ to kaju osunwọn.
Lori ọrọ awọn janduku to wa dana sun ile wọn ni Eggua, Suleiman ni ''Nigba ti Sunday Igboho de ilke wa, o ni ki wọn dana sun, o gbe aworan baba mi wọn sọ ina si, wọn yinbọn. Ohun gaan alara gbe ibọn to si yin soke''
Sueliman tẹsiwaju pe ''ara Seriki ko ya, o wa ni ile iwosan bi mo ṣe n ba yin sọrọ. O n gba itọju nitori ohun to ṣẹlẹ ko iporuru ọkan ba''
Bẹẹ naa ni Suleiman sọ pe oun ti n gbe ni Eggua lati kekere ni.
O ni awọn mọlẹbi Seriki to aadọta to wa nibẹ ati pe lọdun 1985 ni wọn bi oun si Eggua.
O ṣalaye ibasepọ to wa laarin awọn agbẹ ati darandaran latẹyinwa.
''Ti agbe ba ri darandaran wọn maa n sọ fun wọn ki wọn ma da ẹran wọ inu oko, awa naa si maa n gbọ si wọn lẹnu''
Saaju asiko yi lawọn eeyan ti n sọrọ pe awọn darandaran maa n gbe ibọn rin kaakiri nilẹ kaarọ o jiire ṣugbọn ko si Fulani to sọ pe lootọ ni.
Bí àlááfíà yóò ṣe wà láàrin Fulani àti Yorùbá ni Ooni bá lọ sọ́dọ̀ Buhari- Ààfin Ile Ife
Bi a ti ṣe n gbiyanju lati gbọrọ lẹnu awọn ti ọrọ yi kan, nibẹ la ti rin gẹrẹ wọ abule Asa ni ijọba ibilẹ Iselu Yewa ni ariwa ipinlẹ Ogun.
A gbọ pe awọn darandaran ṣe ikọlu sawọn eeyan nibẹ.
Nibẹ la ti pade arabinrin kan to ṣalaye fun wa pe awọn darandaran pa ọmọ kan ṣoṣo ti oun bi.
Arakunrin kan naa sọ fun wa pe wọn ṣa oun lada lori ati ọwọ ti wọn si ge ika oun sọnu.
A tun ri arakunrin kan ti oun naa ṣalaye pe awọn darandaran da ọgbẹ si oun lara pẹlu ada.
Ọja to wa labule yi ko rẹni na nitori ibẹru pe awọn darandaran yi yoo wa ṣe ikọlu si wọn.
Arakunrin Mathew Fakambi sọ fun BBC bi awọn darandaran yi ṣe kọlu ile itaja oun ti wọn si jin ọja gbe nibẹ.
Arabinrin yi sọ pe awọn darnadaran pa ọmọ kan ṣoṣo toun bi
"Lọjọ taa n wi yi, mo lọ si Oja Odan lati lọ tun ẹrọ amunawa gẹnẹretọ ṣe. Bi mo ṣe n pada bọ ni mo ri tawọn eeyan sa kaakiri''
''Nigba ti  mo beere pe ki lo ṣẹlẹ, wọn ni awọn Fulani lo n le awọn''
O ṣalaye pe awọn to kogun wa ba awọn yi gbe awọn agbofinro lọwọ ti wọn si n yinbọn ti wọn si n fọ ṣọọbu awọn.
Herdsmen invade Soyinka House: Ṣé lóòtọ́ làwọn darandaran tasẹ̀ àgẹrẹ wọ ọgbà Soyinka?
Ileeṣẹ ọlọpaa ipinlẹ Ogun ti fesi si iroyin to gbode kan pe awọn daandaran Fulani ṣigun lọ ba ọjọgbọn Wole Soyinka nile rẹ.
Alukoro ọlọpaa Abimbola Oyeyemi ṣalaye pe ko si ootọ ninu fọnran fidio kan ti eeyan kan ti n sọ pe awọn darandaran ti yabo ile Soyinka .
Ninu alaye rẹ o ni niṣe ni Wole Soyinka pade darandarasn kan to ni oun n wa maalu rẹ́ to sọnu ti Soyinka si sọ fun pe kio gbe awọn maluuu rẹ kuro ni agbegbe ile rẹ.
O ni ọga ọlọpaa agọ ọlọpaa to wa ni agbegbe Kemta Estate gbọ si ọrọ yi to si ni ki ẹni to ni maalu naa yọju si agọ ọlọpaa lati wa ṣalaye bi ọrọ se ri.
Oyeyemi ni o jẹ iyalẹnu pe awọn ri fọnran fidio to gbori ayelujarea kan ti awọn eeyan si n gbe iroyin ẹlẹjẹ pe awọn Fulani ṣigun lọ si ile Soyinka lati lọ doju ija kọ.
Gẹgẹ bo ti ṣe sọ, ko si ohun to jọ wi pe wọn yabo ile Soyinka tabi pe wọn ba dukia rẹ jẹ.
Kọmisana ọlọpaa ninu atẹjade naa tẹsiwaju lati kan si ibi ti iṣẹlẹ naa ti waye.
Edward Awolowo sọ pe yatọ si pe oun ba ẹni to ni maalu naa Kazeem Soriola sọrọ, oun wadi ọrọ lẹnu Fulani to n ba daa maalu ti awọn si ti fidi ododo mulẹ.
Ileeṣẹ ọlọpaa wa rọ awọn ọmọ Naijiria lati yago fun iroyin ayederu eyi to le da wahala silẹ lawujọ.
Obalende Shooting: Ìkọlù láàrin àjọ NURTW ní agbègbè Obalende dá wàhálà sílẹ̀
Oríṣun àwòrán, OTHERS
A gbọ wipe eeyan mẹfa ni  ọwọ ti tẹ to lọwọ ninu iro ibọn yinyin to da gbogbo adugbo Obalende ru ni ọjọ kọkanla oṣu keji ọdun 2021.
Ileeṣẹ Ọlọ́paa ipinlẹ Eko ti kawọ iṣẹlẹ naa ko ti ohun gbogbo si ti n lọ deede bo ṣe wa tẹlẹ ni Obalende, ipinlẹ Eko.
Ninu iwadii lati gbọ wipe ikọlu kọgba naa waye laarin awọn ẹgbẹ awakọ agbegbe naa ṣugbọn ko si ẹmi kankan to ṣofo.
Ẹwẹ awọn afurasi ti ọwọ tẹ, wọn ti fi panpẹ ọba mu wọn wọn si ti ko wọn le ọlọpaa lọwọ.
Kọmiṣana ọlọpaa ipinlẹ Eko, CP HAkeem Odumosu ti kilọ pe awọn ko ni faaye gba igbesẹ ti ko ba ofin mu rara ni ipinlẹ naa.
Gẹgẹ bo ṣe  tẹ wa lọwọ, iroyin n gba ori ayelujara kan pe iro ibọn n dun ni agbegbe Obalende ni ipinlẹ Eko.
Lasiko iṣẹlẹ naa, wọn afurasi to n yin ibọn ko ye ẹnikẹni amọ awọn fidio to han kaakiri oju opo ayelura fihan bi awọn eeyan ṣe n sa wọdi wọdi kiri.
Awọn eeyan ti bẹrẹ si ni fi ikilọ sita pe ẹ dakun bi ẹ ba n lọ si Obalende, tabi agbegbe Ikoyi, ẹ pada sẹyin toripe awọn agbero n ja ti ko si tii si agbofinro kankan to yọju."
Oríṣun àwòrán, OTHERS
50 Year old Ajayi Folashade: Mo ti kọ́kọ́ dán an wò ní 80s àmọ́, ó kàn ṣáà ń wù mi náà ni
"Ẹwẹ, ileeṣẹ Ọlọpaa ipinlẹ Eko ti fi ọrọ sita lori ayelujara pe ""igbakeji ọlọpaa atawọn ikọ wa ti wa nilẹ lati koju iṣẹlẹ naa. Ẹ ṣeun ti ẹ kan si wa""."
A n ṣe akojọpọ iroyin lọwọ...
Chief Lateef Jakande: Ètò ìsìnkú gómìnà alágbádá àkọ́kọ́ ti ìpínlẹ̀ Eko
Eto isinku gomina ijọba alagbada akọkọ ti ipinlẹ Eko ti n waye.
Lara awọ́n eekan ilu to peju sibi eto isinku yii ni gomina ana ipinlẹ Ogun, Ibikunle Amosun, igbakeji gomina ipinlẹ Eko, Obafemi Hamzat atawọn eeyan jankan jankan mii nipinlẹ Eko ati lawọn ipinlẹ mii.
Awọn imaamu nla nla ninu ẹ́sin musulumi peju sibẹ lati gba adura ikẹyin fun un.
Imaamu agba Ilupeju ataawọn aafaa ibẹ wa lara awọn to ṣe adura nibi eto isin ikẹhin fun oloogbe.
Akewi kan to mọ gidi nipa oloogbe kẹnu b ewi ti ori awọn si n wu nitori pe o j eeyan to sunmọ Alhaji Jakande gan.
Ninu ewi rẹ lo ti n sọ iru eeyan ti oloogbe jẹ ati awn nkan rere rere to ṣe nigba aye rẹ to bẹẹ tawọn eeyan bẹrẹ si ni na an lowo.
Ni 1981, mo ṣe awo fun wọn, mo sọ fun wọ́n nipa awọ́n iṣẹ́ Jakande...
Eto isinku yii n lọ lọ́wọ́ lori ayelujara Zoom fun anfani awọn ti ofin ko gba laye lati lọ si ibi itẹ oloogbe.
Bi o ba fẹ wo eto isinku naa bo ṣe n lọ lọwọ tẹ oju opo isalẹ yii:
Linkhttp://bit.ly/BurialCeremonyOfAlhajiLateefJakande
Gẹgẹ bo ṣe tẹ wa lọwọ, Alhaji Lateef Jakande jẹ Ọlọrun nipe lowurọ oni Ọjọbọ, ọjọ kọkanla oṣu keji ọdun 2021 lẹni ọdun 91.
Ọkan lara awọn ọmọ oloogbe Deji Jakande lo fi aridaju iroyin yii hande.
Bakan naa, Gomina Babajide Sanwoolu ti ipinlẹ Eko ti fi ọrọ idaro sita nipa baba Jakande. O yin in gẹgẹ bi adari to laami laaka ati oniroyin to ṣee gbagbọ nigba aye rẹ.
Nigba ti BBC Yoruba kan si Kọmisana fun eto ipolongo ati ọgbọn inu ni ipinlẹ Eko, o jẹ ko di mimọ pe eekan ti ko ṣee gbagbe ni oloogbe Jakande nipinlẹ Eko, nilẹ Yoruba ati ni Naijiria lapapọ.
Ọgbẹni Gbenga Omotosho fi yeni pe gẹgẹ bii gomina akọkọ ni ijọba alagbada fun ipinlẹ Eko ti o dẹ ṣe e daadaa to bẹẹ to jẹ pe orukọ rẹ ko le parẹ laelae.
Ẹni to jẹ pe gomina wa lonii, Babajide Sanwoolu n gbedi fun ni oloogbe Jakande. Nipa eto ileewe, ibagbepọ araalu, irina ati gbogbo bo ṣe ṣe ijọba rẹ, ohun to ṣe ko lee parẹ laelae ni.
Omotosho ni ọfọ nla ni nkan to ṣẹlẹ jẹ fun ipinlẹ Eko amọ inu awọn dun pe baba ṣe nkan rere ti wọn lee ranti rẹ fun.
Oloogbe Jakande lo wa pẹlu baba Awolowo nigba aye wọn ni. Bakan naa gbogbo nkan ti baba Jakande ṣe nigba aye tirẹ naa ni wọn n gbosuba fun.
O fi kun un pe oloogbe Jakande tun gbiyanju lati maa ri i daju pe ẹkọ ti iran Yoruba nilo di nini ki gbogbo Yoruba baa le ṣe ara wọn ni oṣuṣu ọwọ.
50 Year old Ajayi Folashade: Mo ti kọ́kọ́ dán an wò ní 80s àmọ́, ó kàn ṣáà ń wù mi náà ni
Covid-19 Vs Homosexual: Alfa Abbas Tabrizian ń wáàsù kí àwọn alátìlẹ́yìn rẹ̀ má gba abẹ́rẹ́ Covid-19
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Adari ẹsin Islam kan Alfa Ayatollah Abbas Tabrizian ti fi ọrọ sita pe abẹrẹ ajẹsara Covid-19 tawọn eeyan n gba lee sọ wọn di ẹni to fẹran ibalopọ akọsakọ tabi abosabo.
Ninu iwe iroyin Jerusalem Post, Alfa Tabrizian sọ loju opo Telegram rẹ to si ti ni awọn to n tẹle e to le ni igba miliọnu pe aburu ti abẹrẹ ajẹsara yii le ṣe ree.
Amọ ko fi ẹri pataki kankan han to fi gbe ọrọ rẹ lẹyin.
 Ẹ ma sun mọ awọn to ti gba abẹrẹ ajẹsara Covid-19. Wọn ti yipada si onibalopọ akọsakọ ati abosabo.
Iroyin sọ pe aafaa yii ni akọsilẹ itan ki o saba maa sọ ọrọ itako nipa awọn oogun oyinbo.
50 Year old Ajayi Folashade: Mo ti kọ́kọ́ dán an wò ní 80s àmọ́, ó kàn ṣáà ń wù mi náà ni
Bẹẹ naa ni awọn ọrọ to sọ laipẹ yii ti fa iriwisi ọtọọtọ ti awọn eeyan si n gbiyanju ati dẹru ba awọn eeyan ki wọn ma ṣe gba abẹrẹ ajẹsara.
Awọn ijọba orilẹede kaakiri si n fi aridaju han fun gbogbo agbaye pe ko si ewu kankan ninu gbigba abẹrẹ ajẹsara yii.
"Ayatollah Abbas Tabrizian to jẹ araa Iran maa n gbe ara rẹ gẹgẹ bii ""Baba awọn onimọ iṣegun ẹsin Islam"" to si n fihan pe awọn oogun ti ẹsin ti pa oju awọn oogun ti oyinbo da si eyi ti ko wulo."
Ni ọdun  to kọja ni fidio kan tan ka lori ayelujara to ṣafihan bi Tabrizian n sọ ina si iwe imọ iṣegun oyinbo kan to n jẹ Harrison's Manual of Medicine ọkan lara iwee Harrison's Principles of Internal Medicine to jẹ iwe pataki kan tawọn oniṣegun oyinbo maa n lo.
Ara ilẹ Iran kan to lodi si awọn nkan yii, Sheina Vojoudi sọ fun iwe iroyin Jerusalem Post pe erongba Tabrizian ni lati maa tan ọrọ ase ka lati maa dẹru sọkan awọn eeyan ki wọn ma gba abẹrẹ ajẹsara naa.
Bii ti awọn mii, gbogbo kudiẹ kudiẹ to ba yọju lara ọrọ abẹrẹ ajẹsara Covid-19 ni Tabrizian n yi mọ ọrọ ibalopọ.
Oun kọ ni yoo kọkọ jẹ adari ẹsin to n sọ pe abẹrẹ ajẹsara Covid-19 m fa ibalopọ akọsakọ ati abosabo.
Oniwaasu kan naa nibẹrẹ ọdun yii sọ fun awọn ọmọlẹyin rẹ pe wọn ma gba abẹrẹ ajẹsara naa tori o lee sọ wọn di akọsakọ
Lọdun to kọja, pasitọ to jẹ eeyan ti aarẹ tẹlẹ ni Amẹrika, Trump fẹran, Rick Wiles fesi si ọrọ iku agbẹjọro onibalopọ akọsakọ kan to ko arun Covid pe idajọ Ọlọrunlo wa sori rẹ ati pe ajalu mla kan n bọ.
Ẹwẹ, ninu oṣu kọkanla oniwaasu ori tẹlẹfisan to lodii si ibalopọ akọsakọ ati abosabo to si ni aisan Covid-19 nii ṣe pẹlu aṣẹwo ati gbigbe igbe aye ẹṣẹ ni oun funrarẹ ku latari kiko arun Covid-19 yii kan naa.
EndSARS: Àwọn ọ̀dọ́ tẹ̀ ẹ́ pa, àmọ́ wo ìkílọ̀ Ìjọba àpapọ̀, Ọlọ̀pàá àti Gómìnà Sanwoolu
Oríṣun àwòrán, Reuters
Ijọba apapọ orilẹede Naijiria ti ki awọn ọdọ to n gbero lati ṣe iwọde ni ẹnu ibode Lekki nilọ pe ki wọn ma dan an wo.
Minisita iroyin, Lai Mohammed to ṣekilọ yii kẹnu bọ ọrọ nigba to n ba awọn oniroyin sọrọ l'Ọjọbọ niluu Abuja to si ni awọn ọmọ Naijiria lẹtọ lati ṣewọde amọ iwa ipa lorukọ iwọde lawọn ko ni gba.
Mohammed ni pẹlu irori, o ṣeeṣe ki awọn janduku ja iwde ti awn kan n gberoo ko waye lọjọ Satide ọjọ kẹtala ọdun 2021 ni ibode Lekki.
Amọ ṣe ni awọn ọdọ naa labẹ akoso #EndSARS  kọjalẹ ti wọn ni dandan ni awọn yoo ṣe iwọde ọhun.
Ẹwẹ, ẹgbẹ mii labẹ akoso #DefendLagos naa ti sọ ṣaaju wipe awọn naa yoo ṣe iwọde tiwọn lodi si ti awọn oni EndSARS.
Ijọba apapọ Naijiria naa ti wa kilọ fun awọn to wa labẹ akoso #OccupyLekkiprotest pe ki wọn dẹyin lẹyin nkan ti wọn fẹ ṣe.
50 Year old Ajayi Folashade: Mo ti kọ́kọ́ dán an wò ní 80s àmọ́, ó kàn ṣáà ń wù mi náà ni
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Bakan naa, ijọba ipinlẹ Eko tun kilọ fun awọn ti igun #Occupy Lekkiprotest ki wọn jawọ pe awọn ko ni gba ki wọn sa sabẹ iwọde lati da ilu ru.
Ijọba Eko tun ni awọn ko ni faaye gba biba nkan ini ati dida ẹmi awọn eeyan legbodo mọ nipinlẹ naa.
Bi ẹ ko ba gbagbe, ọrọ iwọde EndSARS gangan bẹrẹ ninu oṣu kẹwa ọdun 2020 niwaju olu ileeṣẹ ọlọpaa ipinlẹ Eko.
Lọjọ keji ọjọ yii ni iwọde naa tan de awọn ilu mii ni Naijiria bii Abuja, Benin, Abeokuta, Port Harcourt.
Ọjọ ti ọrọ bọ sori gangan to di eyi ti ẹnikẹni lagbaye ko lee gbagbe ni ogunjọ oṣu kẹwa ọdun 2020 nigba ti iṣi awọn ọmọ ogun sọja sṣina ibọn bolẹ si awọn oluwọde ni ibode Lekki ti iroyin si gbode kan pe wọn pa ọpọlọpọ eniyan.
Ohun to wa wu apa keji yii jade ni igba ti igbimọ to n gbẹjọ aṣemaṣe awọn ọlọpaa ni ipinlẹ Eko paṣẹ pe ile iṣẹ to ni Lekki toll gatae lanfani lati pada gbajọba ibẹ, lawọn ọdọ ba tun yari.
Farmers vs Herders: Ìjọba tí kò ṣe ojúṣe rẹ̀ ló mú káwọn Fulani máa gbé ìbọn AK47 kiri
Oríṣun àwòrán, Bala Mohammed Facebook
Gomina ipinlẹ Bauchi, Bala Mohammed ti sọ idi ti awọn Fulani ko ni le ṣe lalai maa gbe ibọn AK-47 kaakiri.
O fidi ọrọ yi mulẹ lasiko to n sọrọ nibi apero awọn akọroyin to waye ni olu ilu Bauchi.
Mohammed ni idi t'ọpọ awọn darandaran fi n gbe ibọn ni lati daabo bo ẹmi ara rẹ ninu igbo lọwọ awọn ẹranko ati ajimaalu gbe.
Bala ni ko yẹ ki awọn ọmọ Naijiria maa sọ gbogbo eeyan ẹya kan di alaburu nitori iwa tawọn kan baa n hu ninu wọn.
O ni ijọba to kuna lati daabo bo awọndarandaran lo mu ki wọn maa gbe ibọn fun aabo ẹmi wọn.
Lẹnu lọọlọ ọrọ wahala ija laarin awọn darandaran ati agbẹ jẹ eleyi to mu iriwisi ọtọọtọ wa.
Ninu awọn to sọrọ nipa iṣẹlẹ yi ni Gomina ipinlẹ Benue, Samuel Ortom to ni aarẹ Buhari n ṣe bi igba pe aarẹ awọn Fulani nikan nii ṣe.
Lasiko apero awọn oniroyin yi, Bala Mohammed bẹnu atẹ lu Ortom pe o wa lara awọn to n fi gbolohun rẹ da ija ẹlẹyamẹya silẹ.
''A ti ri nkan tawọn  Gomina akẹgbẹ wa n sọ ni iwọ oorun Guusu Naijira ati awọn to wa ni Guusu Guusu Naijiria. Wọn kuna pẹlu ọrọ wọn''
O ni ''ṣugbọn ẹni to kuna ju ni Gomina Ortom Benue to da gbogbo wahala yi silẹ.Bi ẹ ko ba faye gba awọn eya mi, ṣebi awa naa n faye gba awọn eeyan yin lọdọ wa?''
Loju opo Twitter niṣe lawọn eeyan n sọrọ labẹ akorio ọrọ AK-47.
Sẹnẹtọ nigba kan ri Shehu Sani ni bi igba pe eeyan n faye gba ki eeyan maa hu iwa aburu ni ọrọ Gomina yi jẹ
Ray Isah no tiẹ sọ pe ko wulẹ yẹ ki a ma jiyan lori ọrọ yi. Ki ẹya kọọkan kuku maa gbe ibọn kiri
Ṣugbọn ninuirori tirẹ Seidu Idris ni  ọna gbogi ree fawọn Fulani lati daabo bo ara wọn
Lekki Toll Gate, End Sars Protest: Mr Macaroni ti sọ̀rọ̀sókè fún ìjọba Nàìjíríà lẹ́yìn tó ti àtìmọ́lé dé
Oríṣun àwòrán, others
Awon mọlẹbi mi ki mi nilọ, emi ni ko gbọ́- Mr Macaroni.
Debo Adedayo to jẹ adẹrin poṣonu ti ọpọ mọ si Mr Macaroni lo ti sọrọ soke lẹyin ti ori koo yọ latimọle awọn ọlọpaa lẹyin iwọde ni Lekki Tollgate ni ana.
Mr Macaroni ni ọpẹlọpẹ awọn ọmọ Naijiria to pariwo sita boya wọn ko ba ti gbagbe oun.
O tun fi soju opo twitter ayelujara pe ijọba Naijiria lo kuna lati pese aabo to yẹ fun ara ilu, koda o ni ko si ẹya Hausa tabi Igbo tabi iran kankan to ṣe oun bikoṣe ijọba Naijiria.
Debo Adedayo gba pe ọkan naa ni iran Igbo, Yoruba ati Hausa ti wọn jọ jẹ ọrẹ ara wọn
Oríṣun àwòrán, Debo Mac/ BBC
N100, 000 ni Mr Macaroni àtàwọn tó kù tí wọ́n mú ní Lekki Tollgate san
Wọ́n ti gba béélì Mr Macaroni àti àwọn olùwọ́de kan tí ọlọ́pàá mú ní Lekki Toll Gate
Wọn ti yọnda diẹ lara awọn oluwọde ti wọn mu ni Lekki Toll gate lọjọ Satide.
Oríṣun àwòrán, @omoyelesowore
Ẹgbẹrun lọna ọgọrun un naira ni ile iṣẹ iroyin abẹle TVC ni wọn san ni owo beeli ẹnikọọkan.
Ogoji eniyan ni awọn ọlọpaa ko nibi iwode Lekki tollgate naa.
Gbajugbaja alawada, Debo Macaroni ati awọn mii wa lara awọn eeyan to ti gba ominira.
Ẹsun iditẹ, dida alaafia ilu ru ati titapa si ilana Covid-19 ni wọn fi kan wọn.
Bí àlááfíà yóò ṣe wà láàrin Fulani àti Yorùbá ni Ooni bá lọ sọ́dọ̀ Buhari- Ààfin Ile Ife
Ọkan lara awọn agbẹjọro to n ṣagbatẹru iwọde ENDSARS, @Mochievous lo fi ikede naa sita loju opo Twitter rẹ.
Lara awọn nkan ti wọn yoo nilo lati gba beeli wọn ni oniduro kọọkan, ẹgbẹrun lọna ọgọrun Naira ati esi ayẹwo aarun Covid-19.
Amọ ṣa, ọjọ keji, oṣun Kẹta ni igbẹjọ yoo waye lori ọrọ wọn.
Ajimuna ni ikọ BBC fi ṣe ti wọn ji gbera lọ si ibode Lekki Toll gate nibi ti awọn ọdọ ti fẹ ṣe iwọde.
Ọkan lara awọn ọdọ to wa nibẹ ti awọn ọlọpaa ko ni papamọra wọ inu ọkọ wọn n pariwo sọrọ soke pe ẹtọ oun loun n ja fun.
Damilare Adenola to jẹ ẹni ọdun mẹrinlelogun sọ pe jẹjẹ oun loun duro ti oun n woran ti awọn ọlọpaa si wa mu oun.
Ajimuna ni ikọ BBC fi ṣe ti wọn ji gbera lọ si ibode Lekki Toll gate nibi ti awọn ọdọ ti fẹ ṣe iwọde.
Akure incest Momoh Usman case: Láti ẹni ọdún mẹ́tàlà ni Bàbá mi ti ń ba mi sùn- Fatimah Us
Awọn ọlpaa kogberegbe ti duro wamu si ẹnu ibode Lekki Toll Gate lati kọdi eyikeyi oluwọde to ba fẹ ṣewọde ENDSARS mii ni ipinlẹ Eko.
Lalẹ ọjọ Ẹti ti ikọ BBC kan si 'Lekki Toll Gate Admiralty Plaza' niṣe lakọroyin wa ri awọn ọlọpaa na ti wọn dira ogun.
Saaju ni Yinka Egbeyemi to jẹ alukoro ọlọpaa ti lewaju awọn ikọ ọlọpaa naa lati ṣafihan wamuwamu la duro kaakiri agbegbe Obalende, Ikoyo, Jakande Roundabout ati awọn aaye mi ni Eti Osa Lagos Island.
O ni awọn ṣe bẹ lati dena eyikeyi iwa daran to ba fẹ waye nibẹ.
Ẹwẹ ileeṣẹ to n ṣakoso ibode Lekki Toll Gate lo n rawọ ẹbẹ sawọn to fẹ ṣewọde lọla.
Ileeṣẹ naa ni wọn ti ba ibode naa jẹ tẹlẹ bi wọn ba si tun iwọde mii ṣe, ọgbẹ ọkan ni yoo jẹ fawọn mọlẹbi ti iṣẹlẹ naa fọwọkan lẹmi tẹlẹ.
Shasa market Ibadan: Wo nkan tí a mọ̀ nípa wàhálà tó mú ẹ̀mí ẹnìkan lọ ní Shasa nílùú Ibadan
Oríṣun àwòrán, Twitter/@Ifemosu Michael Adewale
Ìjọba ìpínlẹ̀ Ọyọ ti ti ọjà Ṣaṣa nítorí rògbòdìyàn tó n wáyé níbẹ̀ láti ọjọ́ Ẹtì
Eeyan kan gbẹmi mi ninu ija to waye ni ọja Shasa nilu Ibadan lọjọ Ẹti.
Agbẹnusọ ileeṣẹ ọlọpaa nipinlẹ, sọ fun BBC Yoruba pe ẹni naa ku lasiko ti awọn janduku kọju ija si ara wọn.
Oríṣun àwòrán, Police
Ṣugbọn ṣa, iroyin to n lọ ni pe ija n waye laarin awọn eeyan to jẹ ẹya Yoruba ati Hausa ninu ọja naa.
BBC Yoruba gbọ wi pe ija naa bẹrẹ laarin ọkunrin sobata kan to jẹ Hausa, ati ọkunrin kan to jẹ ẹya Yoruba, eyi to pada yọri si iku ẹni to jẹ Hausa.
Bakan naa ni awọn fidio to n lọ lori ayelujara n sọ pe awọn eeyan ẹya Hausa ti n kọju ija si awọn to n gbe ni agbegbe Shasa lati ọjọ Ẹti ti ọrọ naa ti waye.
Ti wọn si n ba dukia, ile ati ọkọ wọn jẹ.
Amọ ninu ọrọ rẹ, Agbẹnusọ ọlọpaa sọ pe kii sẹ ija ẹlẹyamẹya.
"O ni ""ija naa kii sẹ ti ẹlẹyamẹya, laarin awọn ọmọ janduku to n wa ọna atijẹ ni."
Ẹ̀yin olórin ẹ̀mí tó ń bóra, lo èékáná gígùn, oò yàtọ̀ sí aṣẹ́wó hòtẹ́ẹ̀lì tí wọ́n ń gbé bíi súùtì Pepper Menti - Bola Are
Eeyan kan si kú nipaṣẹ bẹẹ.
O fikun pe awọn ọlọpaa ati eleto aabo miran ti wa ni agbegbe naa, ti alaafia si ti n jọba diẹdiẹ.
Akure incest Momoh Usman case: Láti ẹni ọdún mẹ́tàlà ni Bàbá mi ti ń ba mi sùn- Fatimah Us
Lori iṣẹlẹ yii bakan naa, gomina ipinlẹ ọyọ, Seyi Makinde ti kede pe ki ọja Shasa p di titi pa.
Isede yoo si ma a waye laarin aago mẹfa irọlẹ si meje owurọ titi di asiko ti ijọba ba gbẹsẹ kuro lori ofin naa.
50 Year old Ajayi Folashade: Mo ti kọ́kọ́ dán an wò ní 80s àmọ́, ó kàn ṣáà ń wù mi náà ni
Ronke Odusanya: Àwọn olólùfẹ́ Ronke Odusanya Ìdídowó ti ń fọnmú lórí àṣẹ àyẹ̀wò DNA tí iléẹjọ́ pa lórí ọmọ tó bí fún Saheed
Oríṣun àwòrán, Instagram/ronkeodusanya
Ile ẹjọ Majistreti kan nilu Eko ni iroyin sọ pe o ti paṣẹ pe ki wọn lọ ṣe ayẹwo tani baba ọmọ, iyẹn DNA test fun ọmọbinrin ti eekan oṣere Ronkẹ Odusanya ti ọpọ mọ si ididowo bi fun ọkọ rẹ.
Gẹgẹ bi awọn iroyin iwe iroyin abẹle kan ṣe gbe, adajọ Majistreti M. O. Tanimọla paṣẹ naa larin ọsẹ to kọja nigba ti wọn gbe ẹjọ naa wa siwaju rẹ.
Ọlanrewaju Saheed to jẹ ọkọ Ronkẹ Odusanya rọ ile ẹjọ naa lati paṣẹ fun ayẹwo DNA naa lati mọ boya lootọ oun ni baba ọmọ naa nitori oun n funra pe irin ẹsẹ iyawo oun ko mọ.
Gẹgẹ bi a ṣe gbọ, agbẹjọro fun Ronkẹ ididowo ko ba a jiyan lori rẹ, nitori oun naa gba bẹẹ pe ki wọn ṣe ayẹwo naa.
Bayii ti ile ẹjọ naa si gba lati ṣe atọna ayẹwo ọhun ni ileewosan ti wọn ko ni darukọ nibi ti wọn yoo si ti fi esi rẹ ṣọwọ si ile ẹjọ naa taara.
Ọdun kan ati oṣu diẹ sẹyin ni Ronkẹ Odusanya bi ọmọbinrin rẹ nileewosan kan loke okun.
Oríṣun àwòrán, Instagram/ronkeodusanya
Amọ bayii awọn ololufẹ elere itage naa ti n fọnmu lori rẹ.
"@hotyjay ni ""Ọmọ jọ ẹ bayii o si tun n wa ayẹwo DNA? O dara o, ohun oju rẹ n wa, yoo rii o."""
"@Studedsavage ni tirẹ kọ pe "" Ọmọ ti mo rii yii jọ baba rẹ bi imumu ni o."
"O fẹ fi iwọnba owo to ku ti Ronkẹ ko tii gba ṣofo leyi o."""
"@kxngrivo ni tirẹ kọ wi pe, ""O san ni kiakiao, mo ti ri ọkunrin kan to jẹ wi pe mẹrin ninu awọn ọmọ rẹ ni kii ṣe tirẹ."
Bẹẹ, eyi to kere ju ninu wọn, ọmọ ọdun mejidinlọgbọn ni. bawo ni baba ẹni ọdun marundinlaadọrin tun aye rẹ to o.
"Yara tete ṣe e bayii o arakunrin mi."""
"@marigoldconcepts, "" ka maa wulẹ bopo lọle olooro lori ayẹwo DNA o, ẹda baba rẹ ni ọmọdebinrin yii o"""
Ẹ̀yin olórin ẹ̀mí tó ń bóra, lo èékáná gígùn, oò yàtọ̀ sí aṣẹ́wó hòtẹ́ẹ̀lì tí wọ́n ń gbé bíi súùtì Pepper Menti - Bola Are
What is Valentine?: Ẹ wo bí àwọn gbajúmọ̀, òṣèré ṣe ṣe àyájọ́ Ọjọ́ Valentine
Oríṣun àwòrán, Instagram
Ibeere nla yii ni Mercy Aigbe beere loju opo ayelujara.
Gbajugbaja osere Yoruba naa ni Ṣé ìyàwó ilé tàbí àlè níta ló yé kí ọkùnrin lo 'Valentine' rẹ̀ pẹ̀lú?
Idahun si ibeere yii si ṣotọọtọ loju opo ayelujara lati ana to ti beere rẹ
Bi awọn kan ṣe n sọ pe iyawo to wa ninu ile lo yẹ ki eeyan ba sami ayajọ ololufẹ naa ni awọn miran n sọ pe ale ni ita lo maa gbadun ju.
Ọpọlọpọ awọn ololufẹ lo ma n farahan lati ṣe ayajọ Ọjọ Ololufẹ, Valentine's day ti wọn yoo si fi ifẹ han si ara wọn.
Aṣọ pupa si ni ọpọlọpọ eniyan ma n wọ ni ọjọ naa lati fi ifẹ han si ara wọn.
Awọn gbajumọ lawujọ to fi mọ awọn oṣere ko gbẹyin nibẹ lọdun yii lati fi ifẹ han si ara wọn, pẹlu asọ alaranbara ti wọn fi ṣe ara wọn lọsọ.
Ẹ wo aworan awọn gbajugbaja ti wọn fi si oju opo Instagram wọn gẹgẹ bi wọn ṣe ṣe ayajọ ọjọ ọlọlufẹ ti ọdun yii.
Oríṣun àwòrán, Instagram/Ninalowo
Gbajugbaja Osere, Ninalowo ki iyawo rẹ ati awọn ololufẹ rẹ ku ayajọ ọjọ Valentine.
Oríṣun àwòrán, Instagram/@tokemakinwa
Gbajumọ sọrọsọrọ, Toke Makinwa ni ọjọ gbogbo ni Valentine fun ohun.
Ìdí tí wọn kii fi jẹ́ kí obìnrin jẹ Ọ̀ọ̀ni ni Ile Ife
Ìjọba Nàìjíríà tó yé kó pèsè aàbò ló kùnà lẹ́nú ojúṣe wọn- Mr Macaroni lẹ́yìn tó ti àtìmọ́lé dé
Ìjà tó wáyé ní Sasa ní Ibadan kìí ṣe ti ẹlẹ́yàmẹ̀yà-  Agbẹnusọ ọlọ́pàá
Wo ojú àwọn tí ọwọ́ tẹ̀ níbi ìkọlù NURTW ní Obalende
Abẹ́rẹ́ àjẹsára Covid-19 ń yí àwọn èèyàn sí oníbálòpọ̀ akọsákọ àti abosábo - Alfa Abbas
Tó bá jẹ́ pé à ń gbé AK47, ìgbà táwọn àgbẹ̀ dáná sun ilé wa, ṣé aò ti ní pa wọ́n dànù? -Ọmọ Seriki Fulani
Oríṣun àwòrán, Instagram/@iyaboojofespris
Iyabo Ojo re e to n ki awọn ololufẹ rẹ ku ayajọ Ọjọ Valentine.
Ẹ wo bí àwọn gbajúmọ̀, òṣèré ṣe ṣe àyájọ́ Ọjọ́ Valentine
Oríṣun àwòrán, Nkechi Blessing
Oni ọjọ ibi Nkechi Blessing, ọpọlọpọ eniyan lo si ti n kii ku ọjọ ibi.
Oríṣun àwòrán, Instagram/@iniedo
Osere Ini Edo ni ki awọn ololufẹ rẹ pin ifẹ kari ni ọjọ Valentine yii.
Oríṣun àwòrán, Instagram/Simi
Akọrin to gbajumọ, Simi ki awọn ololufẹ rẹ ku ọdun Valentine to fi mọ ọkọ rẹ, Adekunle Gold ati ọmọ rẹ.
Oríṣun àwòrán, Instagram/@realomosexy
Gbajugbaja Osere, Omotola Jalade ki awọn ọlọlufẹ ku ayajọ ọdun Valentine pẹlu akọle pe obinrin ni mi ni gbogbo ọna.
Wo ǹkan márùn ún tí ọ̀pọ̀ èèyàn kò fẹ́ ní 'Valentine' 2021
Mọ̀ síi nípa àwọn ohun tó lè mú kí èèyàn tètè ní irun funfun lórí láì tíì di arúgbó
É dẹ́kun ìjà ẹlẹ́yàmẹ̀yà ní Shasha, èyí kò sí nínú àṣà ìran Yorùbá- Akeredolu
Gómìnà Borno fi ọkọ̀ àti N13.9m dá Dókítà Akinbode lọ́lá fún ìṣẹ́ takuntakun ní iléèwòsàn ìjọba ní Borno
Ṣé lóòtọ́ ni iléẹjọ́ pàṣẹ àyẹ̀wò DNA fún ọmọ Ronke Odusanya Ìdídowó, nítorí àwọn olólùfẹ́ rẹ̀ ti ń fọnmú?
Oríṣun àwòrán, Instagram/ Mercy Aigbe
Gbajugbaja Osere Yoruba, Mercy Aigbe ki awọn ololufẹ rẹ ku ọdun Valentine pẹlu ọrọ wi pe talo yẹ ki ọkunrin lo ọjọ Valentine pẹlu, ṣe iyawo ile rẹ ni atbi ale?
Ayajọ ololufẹ miran tun wọle de wẹrẹ.
Ọsẹ ifẹ ni ọsẹ ayajọ ololufẹ jẹ ti o si maa n kun fun ọpọlọpọ idunu ati ireti fun awọn eeyan.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Oniruuru eto lawọn eeyan ti maa n la kalẹ fun paripari ọsẹ naa to jẹ  ọjọ kẹrinla oṣu keji ọdun 2021.
Amọṣa oniruuru ọna ati anfani lo wa lati fi ifẹ han fun ololufẹ rẹ.
Sise akanṣe ounjẹ, fifi asiko silẹ lati ba ololufẹ ẹni ṣere pọ, akanṣe apejẹ tabi ipagọ, ẹbun ati bẹẹbẹẹlọ kun ara rẹ.
Eyi ni diẹ lara awọn ọrọ ikini ati atẹjiṣẹ, aworan ati bẹẹ bẹẹ lọ ti o lee fi mu inu ololufẹ rẹ dun ni ayajọ ololufẹ.
Mo ni ifẹ rẹ loni, lọla ati titi aye, ṣugbọn mo fẹ fi ifẹ pupọ sii han fun ọ lọjọ ti oni yii. A ku ajọyọ ayajọ Valentine ololufẹ mii.
Ẹ̀yin olórin ẹ̀mí tó ń bóra, lo èékáná gígùn, oò yàtọ̀ sí aṣẹ́wó hòtẹ́ẹ̀lì tí wọ́n ń gbé bíi súùtì Pepper Menti - Bola Are
Oni ni ọjọ ti a ya sọtọ fun wa lati gbadun ara wa ki a si ni ifẹ ara wa. Mo fẹ ṣe ayajọ Valentine yii ni ara ọtọ gẹgẹ bi iwọ pẹlu ṣe jẹ ara ọtọ fun mi. A ku ajọyọ ayajọ Valentine ololufẹ mii.
 Iwọ ni ala mi to dun julọ, igba ti o ko ba si si pẹlu mi lo maa n jasi igba ẹru to le juls fun mi. N ko lee duro lati tun fi oju kan ọ ololufẹ mi. A ku ajọyọ ayajọ Valentine ololufẹ mii.
 Iwọ ni afojusun kan ṣoṣo ti mo ni laye. Mo fẹ nifẹ rẹ, mo fẹ tun nifẹ rẹ sii ni gbogbo ọjọ. A ku ajọyọ ayajọ Valentine ololufẹ mii.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Oniruuru itan lo ti bi ayajọ Valentine ṣe ṣẹ wa lẹyin .  diẹ lara rẹ niwọnyii.
Gẹgẹ bi iwe aṣeranwọ lori itan akọsilẹ, Britannica ṣe sọ, ninu ọdun ilẹ Romu kan ti wọn n pe ni ajọdun Lupercalia, eyi ti wọn maa n ṣe ni aarin oṣu keji ọdun ni ayajọ Valentine ti ṣẹ jade wa.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Lasiko ajọdun naa, wọn maa n so obinrin ati ọkunrin pọ nipasẹ tẹtẹ oriire kan ti wọn maa n ṣe. Igbagbọ ọpọ ni pe Poopu Gelasius kinni lo yi ajọdun naa pada si ayajọ Valentine ki o to di bii ọdun pupọ sẹyin ti wọn wa bẹrẹ si ni n ṣe ajọyọ ifẹ lọjọ naa.
Bawo ni Itan Valentine ṣe bẹrẹ?
Awọn itan miran tilẹ tun sọ pe o da lori eeyan kan ti orukọ rẹ n jẹ Valentine.
Awọn kan tilẹ ni wọn fi ọjọ naa sọ orukọ St. Valentine ti Terni to jẹ Biṣọbu.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
"Itan miran dẹ tun sọ wi pe ọjọ naa gba orukọ rẹ lati ara alufa kan to n jẹ Valentine, ẹni ti wọn ni o figbakan ri fi lẹta ranṣẹ si ọmọbinrin wọda ẹwọn to wa to si pe akori lẹta naa ni ""from your Valentine"" to tumọ si, ""lati ọdọ Valentine rẹ."""
Bí àlááfíà yóò ṣe wà láàrin Fulani àti Yorùbá ni Ooni bá lọ sọ́dọ̀ Buhari- Ààfin Ile Ife
Lọdun 270 CE ni olori ilu Romu Emperor Claudius II Gothicus pa nitori ẹsin rẹ.
O ṣeeṣe ki awọn mejeeji yii jẹ ọkan naa, gẹgẹ bi iwe Britannica ṣe sọ.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Borno Dr Isa Akinbode: Gómìnà Zulum ti Borno fún Dókítà Akinbode ní àmì ẹ̀yẹ fún ìṣẹ́ takuntakun ní iléèwòsàn ìjọba
Oríṣun àwòrán, Borno State Government
Gomina ipinlẹ Borno, Ọjọgbọn Babagana Umara Zulum ti fi ọkọ tuntun ati iye owo to le ni miliọnu mẹtala da dokita Isa Akinbode lọla.
Gomina Zulum dupẹ lọwọ rẹ fun iṣẹ takuntakun to ṣe nigba to wa ni ẹnu iṣẹ ijọba gẹgẹ bi dokita.
O ni ọpọlọpọ awọn eniyan lo sa kuro ni agbegbe Mongono lasiko ikọlu ikọ Boko Haram si agbegbe naa, amọ dokita naa duro digbidigbi.
Dokita Isa Akinbode si pẹlu awọn eniyan ti ikọ Boko Haram ji gbe, amọ ti wọn fi silẹ.
Ọdun mejilelogun ni Dokita Akinbode fi ṣiṣẹ ni ileewosan gbogboogbo ti Mongono, nipinlẹ Borno.
Oríṣun àwòrán, Borno state Government
Gomina ipinlẹ Borno ni o ṣe pataki ki awọn da dokita naa lọl nitori o sin araalu ati orilẹede rẹ pẹlu gbogbo ipa rẹ.
Bakan naa ni wọn fun ọmọbinrin Dokita Akinbode ni iṣẹ lẹṣẹkẹsẹ, ti wọn si tun ṣeleri lati san owo oṣu fun dokita naa fun gbogbo ọdun to fi ṣiṣẹ ijọba pẹlu ajẹmọnu rẹ.
Gomina ọhun rọ awọn ọmọ Dokita Akinbode lati tọju baba wọn nitori alaanu eniyan lojẹ ni gbogbo ọjọ to fi ṣiṣẹ.
Oríṣun àwòrán, Borno State Government
Dokita Akinbode lo wa lati ipinlẹ Ogun, amọ o lọ si fasiti ipinlẹ Maiduguri to si durọ si ipinlẹ ọhun lati igba naa titi ti o fi fẹyinti lẹyin ọdun mejilelogun.
Oríṣun àwòrán, Borno State Government
Ikọ Boko Haram ti wa nipinlẹ Borno lati bi ọdun mẹwaa ṣẹyin, ti wọn si ti fi ọpọlọpọ ẹmi ṣofo lati igba ti wọn ti n ṣe ikọlu si agbegbe naa.
Bí àlááfíà yóò ṣe wà láàrin Fulani àti Yorùbá ni Ooni bá lọ sọ́dọ̀ Buhari- Ààfin Ile Ife
Shasha crisis aftermath: Alága àwọn òntàjà lóun pàdánù N20m níbi ìjà tó ṣẹlẹ̀
Oríṣun àwòrán, Arakunrin akeredolu/twitter
Ọpọ ẹmi ati dukia ni iroyin sọ pe o ṣofo nibi ija to waye lọja Sasha n'Ibadan nipinlẹ Oyo.
Koda, iroyin ni pe alaga ẹgbẹ awọn ontaja lọja naa, STA, Alhaji Usman Nyako ṣalaye pe oun padanu owo to le ni ogun miliọnu naira nibi ikọlu náà ni ijọba ibilẹ Akinyẹle.
Alhaji Nyako to ti jẹ alaga awọn ontaja lọja Sasha fun ọdun mẹta bayii sọ pe oun ko ni pada si ọja naa bi wọn ba tiẹ yanju aawọ ọhun tan tori ohun ti oju oun ri lasiko aawọ naa.
Oniṣowo Nyako ni owo to le ni miliọnu mẹwaa naira loun pa ninu ṣọọbu oun lọjọ ti iṣẹlẹ ọhun ṣẹlẹ.
Ile mi, awọn ọkọ ti mo ni at'awọn ọkọ akẹru mi ni wọn dáná sun, Nyako ṣalaye.
Femi Falana, Endsars: Awolowo kò fáààyè gba kí èèyàn máa yàgò fún Màálù nígboro
Alhaji Nyako to sọ pe aṣọ  toun wọ jade nile lo wa lara oun lọjọ náà gboṣuba fún ijọba ipinlẹ Kano fún ẹgbẹrun lọna ọgọrun naira owo iranwọ to fún ìgbà eeyan to jẹ ọmọ bibi ipinle naa ti iṣẹlẹ ọja Shasha ṣakoba fun.
Ọpọ eeyan ni wọn ṣekupa loju mi, nitori naa mi o le pada sibẹ mọ, Nyako lo sọ bẹẹ.
O ni iwa aisotitọ awọn eeyan kan lo ṣe okunfa rogbodiyan naa.
Oríṣun àwòrán, Arakunrin akeredolu/twitter
Alhaji Nyako rọ gbogbo ẹka ijọba lati dide iranwọ fún gbogbo àwọn tí iṣẹlẹ ọhún ṣe akoba fún.
Oniṣowo mii, Kabiru Tambuwal ṣalaye pe miliọnu kan naira loun padanu ninu rogbodiyan ọja Shasha.
Ata ni mo n ta, awọn ọrẹ mi wa lara awọn to ku nigba ti ọpọ ti ori ko yọ ti pada si ilu Kano, Tambuwal ṣalaye.
Oun naa sọ wí pe oun o le pada si ọja Shasha mọ.
Oríṣun àwòrán, @WhistleTimes
Gómìnà ìpínlẹ̀ Kano ṣèrànwọ́ ₦18.5m fún àwọn ọmọ ìpínlẹ̀ rẹ̀ tó faragbá nínú rògbòdìyàn tó wáyé ní Sasa
Ganduje ṣe ìrànlọ́wọ́ fún àwọn ọmọ bíbí ìlú Kano 185 pẹ̀lú ₦18.5m
Gomina Abdullahi Ganduje ti ipinlẹ Kano ti gbe owo to le ni milliọnu mẹjidinlogun naira kalẹ fun awọn ọmọ bibi ilu Kanọ marunlelọgọsan (185) ti wọn padanu nnkan ini wọn sinu rogbodiyan to ṣẹlẹ ni ọja Ṣaṣa nilu Ibadan.
Oladele Ogbeyemi Albert: Irin tí mò ń lò máa ń bá mi sọ̀rọ̀ nínú ẹ̀mí kí ń tó gbẹ́ wọn sóh
Alhaji Garba Mohammed, kọmiṣọnna fun iroyin nipinlẹ Kano to le iwaju awọn aṣoju ijọba ipinlẹ naa lo fun ọkọọkan ninu awọn eeyan naa ni ẹgbẹrun lọna ọgọrun un naira l'ọjọ Iṣẹgun nilu Ibadan.
Lara awọn to tun ṣoju ijọba ipinlẹ Kano nibi ipejọpọ naa ni Alhaji Ibrahim Muktar to jẹ kọmiṣọna fun karakata ati idokowo, ati Alhaji Sanusi Muhammed to jẹ kọmisana fun eto ẹkọ.
Mohammed ṣe alaye pe gomina ipinlẹ Kano lo paa laṣẹ fun wọn lati ṣe abẹwo si awọn ọmọ bibi ipinlẹ naa ki wọn le ri i bi nnkan ṣe n lọ fun wọn ati ọna ti ijọba lẹ gba ran wọn lọwọ.
"O ni, ""Awọn eeyan bi i marunlelọgọsan an lo fara gba nibi iṣẹlẹ buruku naa, a ti ṣe iṣiro wa, eyii lo si mu ki a fun ọkọọkan wọn ni ẹgbẹrun lọna ọgọrun naira."
A o ṣe awari awọn to ti rinrin ajo lọ si Kano ninu wọn, bakan naa ni a o fi ọrọ naa to gomina leti lori bi a o ṣe ri awọn eeyan naa ti a o si fun wọn ni owo ti wọn.
Shasha Crisis in Ibadan: Gbọ́ ohun tó ṣokùnfà ìjà láàrin Aláboyún, soo bàtà àti Hausa alá
O tẹsiwaju pe awọn aṣoju ijọba ipinlẹ Kano ti ba awọn eeyan ti ọrọ naa kan sọrọ, wọn si ti gbọ alaye lori irora ati awọn ipenija wọn gẹgẹ bi wọn ṣe ṣeleri wi pe awọn yoo fi ọrọ naa to gomina ipinlẹ Ọyọ, Onimọẹrọ Ṣeyi Makinde leti.
Kọmiṣọnna naa pe fun ifọwọsọwọpọ laarin awọn gomina ati awọn ajọ eleto aabo, gẹgẹ bi o ṣe n fi idunnu han wi pe kan yoo tun waye nipinlẹ Ogun lori eto aabo.
Oríṣun àwòrán, @TrueNewsNG
Ọga agba ileeṣẹ ọlọpaa ni Naijiria, Mohammed Adamu ti paṣẹ pe ki wọn fi ikọ awọn agbofinro kan to dantọ ṣowọ si ipinlẹ Oyo lẹyin rogbodiyan to waye ni ọja Sasa to wa niluu Ibadan.
Ninu atẹjade kan ti agbẹnusọ ileeṣe naa, Frank Mba fi lede, o ni lara awọn ẹka agbofinro ti wọn n ran lọ si ipinlẹ naa ni awọn akọṣẹmọṣẹ lati ẹka ti wọn ti n fimu finlẹ, awọn ọlọpaa kogberegbe, pẹlu ẹlikọpita kan.
Atẹjade ọhun ṣalaye pe ojuṣe ikọ naa ni lati da alaafia pada si ipinlẹ Oyo, ki wọn si pana ija ẹlẹyamẹya to n jo nibẹ.
"Gẹgẹ bo ṣe sọ, o ni ""igbakeji adari ileeṣẹ ọlọpaa, DIG David Folawiyo ni yoo dari ikọ naa, ti yoo si ṣiṣẹ papo pẹlu gbogbo awọn ti ọrọ kan lati da alaafia pada si ipinlẹ Oyo."""
Adamu wa fi da awọn eeyan ilu loju pe ileeṣẹ ọlọpaa yoo sa gbogbo ipa rẹ lati ri daju pe ko si rogbodoyan kankan mọ nipinlẹ Oyo ati kaakiri Naijiria.
Lẹyin naa lo ke si gbogbo olugbe ipinlẹ Oyo atawọn ọmọ Naijiria miran lati fọwọsowọpọ pẹlu awọn agbofinro ki alaafia le jọba laarin ilu.
Ṣaaju ni gomina ipinlẹ ọhun, Seyi Makinde, ati ojugba rẹ nipinlẹ Ondo, Rotimi Akeredolu ti kọkọ ṣabẹwo si ọja naa lọna ati wa ojutu si rogboyan to bẹ silẹ larin ẹya Hausa ati Yoruba ninu ọja ọhun.
Oríṣun àwòrán, Arakunrin akeredolu/twitter
Gomina ipinlẹ Ọyọ ni igbesẹ arẹmọlẹkun yoo waye fawọn eeyan to padanu dukia ati ọrọ aje wọn sinu wahala to bẹ silẹ lọja Sasa lopin ọsẹ to kọja.
Bakan naa ni gomina ipinlẹ Ondo, Rotimi Akeredolu pẹlu rs awọn eeyan lati ṣe ọpọlọpọ suuru nitori fifi waduwadu bi ilu ṣe ri mọ ibagbepọ awọn ataladugbo wọn lee ba ọpọlọpọ nnkan jẹ.
Gomina Makinde pẹlu Akeredolu sọrọ yii nigba tawọn mejeeji kọwọrin lọ si ọja Ṣaṣa lati foju ganni ọwọja wahala naa.
Akomolede ati Asa lori BBC: Olùkọ́ Bolanle Adekanmi kọ́ wa nípa oríṣíi Àròkọ Yorùbá tó wà
Gomina Makinde ni lootọ iwe ofin orilẹede Naijiria fi aye silẹ fun gbogbo ọmọ orilẹede Naijiria lati gbe ni ibikibi to ba wu wọn lorilẹede Naijiria, sibẹ eeyan bẹẹ gbọdọ tẹle ofin ati aṣa irufẹ agbegbe bẹẹ.
Bi awọn janduku ba fẹ lo anfani bi ilu ṣe ri lati da rogbodiyan silẹ, a ko ni faaye rẹ silẹ. Mo ti pe ipade laarin awọn aṣiwaju igun mejeeji lati lee wọna abayọ lori iṣẹlẹ naa
Gomina ipinlẹ Ọyọ fi kun un pe aṣẹ konile o gbele to wa nilẹ nibẹ yoo ṣi maa wa lọ nigba ti o si tun rọ awọn agbofinro lati jawe sobi lori ojuṣe mimojuto abo lagbegbe naa.
Ninu ọrọ tirẹ, gomina Akeredolu rọ gbogbo awọn igun ti ọrọ kan lati sinmẹdọ.
"A mọ pe ibinu wa lọkan awọn eeyan nilẹyii lọwọ ṣugbọn ẹ jẹ ka ṣe suuru. Lootọ iṣoro kan tabi omiran lee wa ṣugbọn otitọ ibẹ ni pe ọmọ iya ni gbogbo wa."""
Lọjọ Ẹti ni ina wahala sọ ni ọja Sasa nilu Ibadan. Oniruru alaye lo ti n waye lori ohun to ṣokunfa rogbodiyan
Oríṣun àwòrán, Presidency/twitter
Aarẹ Buhari ti bu ẹnu atẹ lu oniruuru ikọlu to n waye lorilẹede Naijiria.
O ni asiko to fun awọn olori ijọ ẹsin atawọn ọbalaye, awọn gomina atawọn aṣiwaju oloṣelu miran gbogbo lati fọwọsowọpọ pẹlu ijsba apapọ lọna ati lee ri daju pe ko si ipinya ẹlẹsinjẹsin tabi ẹlẹyamẹya lawọn ilu to wa labẹ akoso wọn.
Ijọba wa ṣetan lati daabo bo gbogbo ẹsin ati ẹya lorilẹede Naijiria bi o ti wu ki wọn mọ ni iye, ni ibamu pẹlu ilakalẹ iwe ofin Naijiria. A ko ni faye silẹ fun ẹya tabi ẹsin kan lati bẹrẹ si nii gbin ẹso wahala ati ikorira sawọn miran.
Lori iro: Ká ni àwọn Òbí mi gbà fún mí, èmi àti Sunny Ade  á jọ máa 'Compete- Baba Lórí ir
Kò ju nǹkan bíi wákàtí mẹ̀ta tí a kúrò níbẹ̀ tí wọ́n tún pa èèyàn mẹ́ta - Alukoro ọlọ́pàá
Regent, youngest king: Ọbalayé tó kéré jùlọ nílẹ̀ Yorùbá, Oloyede Akinghare gbadé nípínlẹ̀ Ondo
Lẹyin ọdun mẹta ti baba rẹ, Adeyẹmọ Adeyẹọba waja, Ọmọọba Oloyede gun ori itẹ gẹgẹ bii Kabiyesi Arujale Ojima ti ilu Okelusẹ ni ijọba ibilẹ Ọsẹ, ni ipinlẹ Ondo.
Laarin ọdun 2012 si 2019 ni Ọba Adeyẹmọ Adeyẹọba fi wa lori itẹ ki wọn to gbe ade le ọmọ rẹ ọkunrin, Ọba Oloyede Akinghare keji, to jẹ ọmọ ọdun mẹtadinlogun lori.
Gomina Rotimi Akeredolu gbe Ọpa aṣẹ oye fun Ọba Oloyede.
Ọba Oloyede Akinghare II ni yoo jẹ Oba karundinlaadọta ti yoo jẹ ni ilu Okelusẹ lẹyin ti awọn to tẹ ilu naa do gbera kuro ni ilu Ifẹ pẹlawọn  akẹgbẹ rẹ to tẹ ilu Ọwọ ati Benin do.
Oye idile ni oye ọba ni ilu Okelusẹ akọbi ọmọ ọkunrin ọba to ba wa lori itẹ si ni o maa n joye naa.
Oun si ni abigbẹyin baba rẹ nitori o ni awọn ẹgbọn mẹta to jẹ obinrinbi o tilẹ jẹ pe.
Ọjọ karundinlogun, oṣu karun, Ọdun 2003 ni wọn bi Kabiyesi Ọba Akinghare, iwe karun un girama lo si wa bayii nillewe kan nilu Arigidi Akoko.
Gẹgẹ bi ohun ti awọn onitan n sọ, Kabiyesi Akinghare ni ọba laye ti ọjọ ori rẹ kere julọ ni ilẹ Yoruba.
'500 level'' ni mo wà nígbà tí mo di adélé Ọba'
Sexually transmitted diseases: Kọ́ńdọ́mù 587 mílíọ̀nù lọmọ Nàìjíríà ń lò lọ́dún
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Iwadii kan ti ajọ Aids Healthcare center gbe jade ni ifọwọsowọpọ pẹlu ajọ to n gbogun ti ajakalẹ arun AIDS, NACA ati NOIPolls ti fihan pe ọrinlelẹẹdẹgbẹta o le meje rọba idaabobo condom lawọn ọmọ orilẹede Naijiria n lo lọdun.
Amọṣa iwadi naa tun jẹ ko di mimọ pe bilisnu kan o le aadọja miliọnu rọba idaabobo kọndọọmu lorilẹ-ede Naijiria nilo lọdọọdun lati lee dẹkun ọwọja arun ibalopọ lorilẹede Naijiria.
Awọn ajọ naa tun fi idi iwadii wọn mulẹ peiye alafo to wa laarin iye to wa nilẹ ati iye ti orilẹede yii nilo jẹ ọtalelẹẹdẹgbẹta ati mẹrin, 564.
Oladele Ogbeyemi Albert: Irin tí mò ń lò máa ń bá mi sọ̀rọ̀ nínú ẹ̀mí kí ń tó gbẹ́ wọn sóh
Iwadii ijinlẹ naa tun sọ ọ di mimọ pe awọn eeyan ẹkun aringbungbun ariwa (North Central), aringbungbun guusu (South-south) ati ariwa gusu (South east) orilẹede Naijiria lo n lo kọndọmu julọ.
Bakan naa lo tun fi kun un pe awọn ọkunrin n lo kọndọmu ju awọn obinrin lọ.
Lori iro: Ká ni àwọn Òbí mi gbà fún mí, èmi àti Sunny Ade  á jọ máa 'Compete- Baba Lórí ir
GSS Kagara abduction news update: Ìròyìn òfegè ni pé a ti rí àwọn akẹ́kọ̀ọ́ Government Science College, Kagara gbà padà
Gomina ipinlẹ Niger, Alhaji Abubakar Sani Bello ti sọ pe irọ ni iroyin to n jade pe awọn to ji awọn akẹkọọ gbe ti fi wọn silẹ.
Wọn ni irọ ni iroyin naa nitori pe iroyin ofege ni.
Gomina Sani Bello sọ pe titi di asiko yii wọn ko tii ri awọn akẹkọọ naa gba.
O ni awọn ṣi n gbiyanju lati wa awọn akẹkọọ naa ri ni.
Gomina naa salaye fun BBC pe Sheik Ahmad Gumi to jẹ gbajugbaja alfa ni oun ti sepade pẹlu awọn janduku kan lori ọrọ awọn ti wọn ji gbe nile ẹkọ Government Science College  ni Kangara ni ipinlẹ Niger.
Sheik naa ni kii ṣe awon to ji awọn ọmọ gbe gangan ni oun pade bi awọn ileeṣẹ iroyin kan ṣe n sọ kiri.
Femi Falana, Endsars: Awolowo kò fáààyè gba kí èèyàn máa yàgò fún Màálù nígboro
Ṣugbọn awọn janduku naa ṣelelri lati ran wọn lọwọ wa awọn akkọọ naa ri.
Ati pe awọn mọ awọn to ji awọn ọmọ naa gbe, ki wọn le tete fi wọn silẹ.
Oríṣun àwòrán, @Nigeria Army
Mínístà, Kọ̀wé fipò rẹ sílẹ̀ tàbí kí o dákẹ́ tí ò kó bá wá àwọn akẹ́kọ̀ọ́ tó sọnù- ọmọ Nàìjíríà
Awọn ọmọ Naijiria yari lori ayelujara nitori ọrọ ẹnu minista tuntutn ti aarẹ Buhari ṣẹṣẹ yan sipo gẹgẹ bi Minsita eto aabo Naijiria.
Èrò àwọn ọmọ Nàìjíríà ṣọ̀tọ̀ọ̀tọ̀ lórí àṣẹ Mínístà ètò aàbò
Ogagun fẹyin ti agba Bashir Magashi lo sọ fun awọn ara abule kan pe ki wọn gbeja ara wọn kuro lọwọ awọn oniṣẹ ibi to n dunkooko mọ wọn nibẹ.
Bakan naa lo tun ṣapejuwe awọn to ji awọn akẹkọọ Kagara ni ipinlẹ Niger ni aarin gbungbun Naijira gẹgẹ bii alailagbara ti kii ṣe akọni to le koju awọn eeyan to duro bi akọni.
O ni ki awọn eeyan Naijiria pese aabo to peye nibikibi ti wọn ba wa ki wọn si di oju lalakan fi n ṣọri fun ara wọn.
Lẹyin to sọrọ yii ni awọn ọmọ Naijira faraya lori ayelujara pe ko kuku kọwe fipo rẹ silẹ tabi ko gbẹnu rẹ dakẹ ti ko ba nkan to kan fun oun gẹgẹ bii minista eto aabo.
Oladele Ogbeyemi Albert: Irin tí mò ń lò máa ń bá mi sọ̀rọ̀ nínú ẹ̀mí kí ń tó gbẹ́ wọn sóh
Awọn miran ni ko ma lo ẹṣọ aabo awọn eleto aabo to n ṣo Minista funra rẹ to ba da ara rẹ loju
Awọn miran bii Kayode Ogundamisi ni eyi ti fihan pe ko si eto aabo kankan fun ara Naijria rara
Oríṣun àwòrán, @Senate
Buhari kéde ìlú kò fararọ lásìkò yìí- Ilé Igbimọ̀ Aṣofin Nàìjíríà
Wọ́n ti tilẹ̀kùn gbogbo ilé ẹ̀kọ́ níjọba ìbílẹ̀ Rafi, Munya, Mariga àti Shiroro pa ní ìpínlẹ̀ Niger
Ile igbimọ Aṣofin agba ni Abuja ti kede pe ki Aarẹ Muhammadu Buhari kede ilu kofararọ bayii ni Naijiria.
Shasha Crisis in Ibadan: Gbọ́ ohun tó ṣokùnfà ìjà láàrin Aláboyún, soo bàtà àti Hausa alá
Wọn ni o to gẹ ọmọ Leffi ni ibi ọrọ ipenija eto aabo de duro bayii kaakiri ipinlẹ Naijiria.
Awọn ọmọ ile kede yii lẹyin ti awọn oniṣẹ ibi kan kọlu ile ẹkọ Government Science School, Kagara, ni ipinlẹ Niger, ni aarin gbungbun Naijiria.
Wọn ni ki Aarẹ tẹlẹ aba ti igbimọ tẹẹkoto lori ipenija eto aabo Naijiria tile igbimọ Aṣofin fẹnuko le lori lọjọ kẹtadinlogun, oṣu kétam ọdun 2020.
Oríṣun àwòrán, Reuters
Wasu daga cikin daliban sun tsere
Akẹ́kọ̀ọ́ 27, òṣìṣẹ́ méjì àti mọ̀lẹ́bí méjìlá ni àwọ́n agbébọn jí gbé ní ìpínlẹ̀ Niger
Gomina ipinlẹ Niger, Abubakar Sani ti sọ pe awọn akẹkọọ mẹtadinlọgbọn, oṣiṣẹ ileewe meji atawọn mọlẹbi mejila ni awọn agbebọn kan ji gbe nipinlẹ naa.
Sani lo ṣi aṣọ loju eegun lori iye awọn eeyan naa nibi ipade awọn akọroyin kan to waye ni Minna.
Gẹgẹ bo ṣe sọ, awọn akẹkọọ ọhun jẹ ọmọ ile iwe Government Science School, to wa ni Kagara, ṣugbọn apapọ iye eeyan to ti dawati bayii je mọkanlelogoji.
Ààrẹ Muhammadu Buhari ti pàṣe kí àwọn ológun ṣàwárí àwọn èèyàn náà ní kíákíá
Gomina naa ṣalaye pe awọn agbebọn ọhun tun yinbọn pa ọkan lara awọn akẹkọọ naa.
Bo tilẹ jẹ pe Sani sọ pe ijọba oun ko ni san owo itusilẹ kankan fun awọn ajinigbe naa, ṣugbọn o ti paṣẹ pe ki wọn ti gbogbo ileewe ti awọn akẹkọọ n gbe pa nipinlẹ ọhun.
Ẹwẹ, Aarẹ Muhammadu Buhari ti bu ẹnu atẹ lu iṣẹlẹ ijinigbe naa ninu atẹjade kan ti amugbalẹgbẹ rẹ  lori ọrọ iroyin ati ipolongo, Garba Shehu fi ṣọwọ si awọn akọroyin.
Akomolede ati Asa lori BBC: Olùkọ́ Bolanle Adekanmi kọ́ wa nípa oríṣíi Àròkọ Yorùbá tó wà
Buhari ni oun ti paṣẹ fun awọn ọlọpaa atawọn ọmọ ogun lati wa gbogbo ọna lati ṣawari awọn ọmọ ile iwe ọhun.
O sọ pe ijọba ohun yoo ṣe iranwọ to yẹ fun awọn oṣiṣẹ eto abo lati ri pe opin de ba gbogbo ophun to jọ mọ iṣẹrubalu ati ijinigbe ni Naijiria.
Gómìnà ìpínlẹ̀ Kano ṣèrànwọ́ ₦18.5m fún àwọn ọmọ ìpínlẹ̀ rẹ̀ tó faragbá nínú rògbòdìyàn tó wáyé ní Sasa
Kíní ìtumọ̀ àyájọ́ Ọ̀jọ ''Ash Wednesday' tó wáyé lóní?
Níléèwé girama GSS Kagara, àwọn agbébọn pa akẹ́kọ̀ọ́, jí ọ̀pọ̀ akẹ̀kọ̀ọ́ míràn àti olùkọ́ gbé ní Niger
Wo ohun 10 tó yẹ́ kó mọ̀ nípà Ọ̀gà EFCC, Abdulrasheed Bawa tí ààrẹ̀ Buhari yàn
Wo àwọn ohun méje tó yẹ kí o mọ̀ nípa Ngozi Okonjo-Iwealla àti ọkọ rẹ̀ Ikemba
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Awọn agbébọn pa akẹ́kọ̀ọ́ kan, jí ọ̀pọ̀ akẹ̀kọ̀ọ́ gírama àti olùkọ́ gbé níléèwé girama GSS Kagara ní Niger
Awọn agbebọn tun ti ya bo ileewe girama kan ni ipinlẹ Niger nibi ti wọn ti yinbọn pa akẹkọọ kan ti wọn si tun ji ọpọ awọn akẹkọọ ati olukọ gbe.
Iroyin lati awọn ileeṣẹ iroyin abẹle kan fi idi rẹ mulẹ pe ileewe Government Science School Kagara ni ipinlẹ Niger ni awọn agbebọn naa kọlu.
Ẹ̀yin olórin ẹ̀mí tó ń bóra, lo èékáná gígùn, oò yàtọ̀ sí aṣẹ́wó hòtẹ́ẹ̀lì tí wọ́n ń gbé bíi súùtì Pepper Menti - Bola Are
Iroyin naa ṣalaye pe ni nnkan bii agogo meji oru ni awọn agbebọn naa ya wọ ileewe naa pẹlu aṣọ ileewe naa lara wọn.
Awọn alaṣẹ ijọba ipinlẹ Niger ṣalaye pe awọn ko tii le fi idi iye awọn akẹkọọ tabi oluks ti wọn ji gbe mulẹ.
Amọṣa awọn orisun iroyin kan ṣalaye pe niwọn igba to jẹ pe iye awọn akẹkọs to wa nilewe naa to ẹgbẹrun kan iye awọn akẹkọọ ati olukọ ti wọn ji gbe naa lee pọ diẹ.
Lori iro: Ká ni àwọn Òbí mi gbà fún mí, èmi àti Sunny Ade  á jọ máa 'Compete- Baba Lórí ir
Gẹgẹ bi awọn orisun iroyin miran ṣe fi idi rẹ mulẹ, awọn kan lara awọn akẹkọs naa ti sa asala kuro lọwọ awọn ajinigbe naa.
Nibayii, wọn ṣi n ka iye awọn akẹkọs to ku ki wọn to lee mọ ni pato iye awọn akẹkọọ ati olukọ ti wọn ji gbe.
Awọn alaṣẹ ko tii fi iroyin sita lori iṣẹlẹ ijinigbe naa.
Gbọnmọgbọnmọ awọn agbebọn to n kọlu ileewe girama lati ji awọn akẹkọọ gbe kii ṣe iroyin tuntun mọ lorilẹede Naijiria paapaa lagbegbe oke ọya orilẹede Naijiria.
Ni oṣu kejila, ọdun 2020 lawọn agbebọn ji ọdunrun akẹkọọ gbe nileewe girama Kankara Secondary school ni ipinlẹ Katsina eleyi to fa ọpọ ọrọ latawọn orilẹede agbaye gbogbo.
Ọwọ́ tẹ Sani fọganaisa tó fipá pọ́ ọ̀dọ́mọbìnrin ọdún 15 pa ní Gombe
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ọwọ ti tẹ Sani Sale, fọganaisa, ọmọ ọdun mejidinlogoji kan ni ipinlẹ Yobe to sa nle lẹyin to fipa ba  ọmọbinrin ọmọ ọdun marundinlogun kan lo pọtọmọbinrin naa si ku si yara rẹ.
Ilu Gadaka ni ijọba ibilẹ Fika ni ipinlẹ Yobe ni iṣẹlẹ naa ti ṣẹlẹ.
Gẹgẹ bi awọn ọlọpaa ṣe sọ, ni ọjọ kẹwaa, oṣu keji, ọdun 2021 ni ọmọdebinrin naa kiri akara lọ sigboro ṣugbọn ti awọn obi rẹ ko si ri i ko pada wale mọ titi ti ilẹ ọjọ naa fi ṣu.
Akomolede ati Asa lori BBC: Olùkọ́ Bolanle Adekanmi kọ́ wa nípa oríṣíi Àròkọ Yorùbá tó wà
Nigba ti ilẹ ọjọ keji mọ  ni wọn ri oku rẹ ninu yara Sani Sale.
Ni kete ti aje ọrọ naa ṣi mọọ lori lo ti na papa bora lọ si ipinlẹ Gombe nibi ti ọwọ ọlọpaa ti pada wa tẹ ẹ.
Oríṣun àwòrán, vvv
Shasha Crisis in Ibadan: Gbọ́ ohun tó ṣokùnfà ìjà láàrin Aláboyún, soo bàtà àti Hausa alá
Barcelona vs PSG: Messi fi àbàrá kékeré gba ńlá lọ́wọ́ Mbappe ni Nou Camp
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Igba laa ni, ẹnikan o lo ile aye gbo.
Ohun lo difa fun ọdọmọde agbabọọlu PSG, Kylian Mbappe to rọ agbaọjẹ agbabọọlu Barcelona, Lionel Messi loye.
Goolu mẹta ọtọtọ ni Mbappe gba sawọn Barcelona nigba ti PSG pokọ iya fun Barcelona nile wọn ni ipele ẹlẹni-mẹrindinlogun idije UEFA Champions League lalẹ ọjọ Iṣẹgun.
Ṣe ẹ mọ pe akọda oro ko da bi adagbẹyin.
Messi lo kọkọ gba pẹnariti wọle PSG lai mọ pe o kọ lẹta si iya ni.
Ṣugbọn goolu mẹrin ni Mbappe ati Moise Kean fi da pada lẹyin ti wọn lu Barca mọlẹ bi aṣọ ofi pẹlu ami ayo mẹrin sí ẹyọkan.
Lori iro: Ká ni àwọn Òbí mi gbà fún mí, èmi àti Sunny Ade  á jọ máa 'Compete- Baba Lórí ir
Iti ọgẹdẹ ti ko to ohun ti a n yọ ada si ni PSG fi ọrọ Barcelona ṣe ni Nou Camp tori elege ara PSG, Neymar gan an ko lanfaani lati kopa ninu ifẹsẹwọnsẹ ọhún lẹyin to ti fi ẹsẹ ṣeṣe tẹlẹ.
O ṣeeṣe ki Neymar kopa ninu ipele keji ifẹsẹwọnṣẹ ọhun ti yoo waye logunjo, oṣu kẹta ọdun yìí niluu Paris.
Akomolede ati Asa lori BBC: Olùkọ́ Bolanle Adekanmi kọ́ wa nípa oríṣíi Àròkọ Yorùbá tó wà
Sasa crisis, MURIC: Ó yẹ kí ìjọba sanwó gbà mábínú fún darandaran àtàwọn àgbẹ̀ tó faragbá nínú rògbòdòdìyàn Sasa
Oríṣun àwòrán, Gertty
Ẹgbẹ ajafẹtọ awọn Musulumi, MURIC, ti rọ ijọpa apapọ lati fofin de awọn Fulani darandaran to n gbe ibọn Ak-47 rin laarin ilu.
Adari ẹgbẹ naa, Ọjọgbọn Ishaq Akintola lo fi ọrọ naa lede ninu atẹjade kan to fi ṣowọ si awọn akọroyin lori rogbodiyan to waye laarin awọn ẹya Hausa ati Yoruba lagbegbe Sasa, niluu Ibadan.
MURIC sọ pe irufẹ ija bẹẹ kii ṣe ohun to bojumu ati pe ija ẹlẹyamẹya kii bimọ ire.
Akintola rọ Aarẹ Muhammadu Buhari lori ọna to le gba lati dẹkun irufẹ iṣẹlẹ bẹẹ lọjọ iwaju.
Lakọkọ, o ni o yẹ ki ijọba san owo gba mabinu fun gbogbo awọn agbẹ ti maluu ti jẹ nnkan ere oko wọn tabi ti wọn ba oko wọn kẹ.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Akintola sọ siwaju si pe o ye ki ijọba tun fun awọn Fulani to ba ni ẹri aridaju pe wọn padanu maluu wọn ninu iṣẹlẹ naa lowo to jọju.
Ko tan sibẹ, Akintola tun rọ ijọba apapọ lati pese owo gọbọi fun awọn darandaran ki wọn le fi irufẹ owo bẹẹ kọ awọn ile ti awọn maluu naa yoo maa gbe.
O ni eyi yoo jẹ lọna ati pana ija laarin awọn agbẹ atawọn darandaran.
Atẹjade naa tẹsiwaju pe o yẹ ki ijọba apapọ fofin de bi awọn darandaran ṣe maa n ko maluu kiri laarin igboro.
Pe eyi yoo jẹ gẹgẹ bi ọna kan gboogi lati lati yanju ija lemọlemọ laarin awọn Fulani ọhun atawọn agbẹ ni Naijiria.
Shasha Crisis in Ibadan: Gbọ́ ohun tó ṣokùnfà ìjà láàrin Aláboyún, soo bàtà àti Hausa alá
Akintola pari ọrọ rẹ pe o yẹ ki ile asọfin agba  ṣe agbeyẹwo ofin to lodi si sisọ ọrọ ikorira lori ayelujara, o ni awọn ọrọ ikorira lo tunbọ da kun rogbodiyan to waye ni Sasa.
Lẹyin naa lo ke si ijọba ipinlẹ Oyo lati ṣe iwadii ohun to bi rogbodiyan naa, ko si fi gbogbo awọn ti aje ọrọ na ba ṣi mọ ori jofin.
Texas weather: Ìjì òtútù pa èèyàn 21 ní Amẹ́ríkà, ẹgbẹ̀lẹ́gbẹ̀ míràn ń dojúkọ ìṣoro àìsíná ẹ̀lẹ́ńtíríkì
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Iji nla kan to la gusu orilẹ-ede Amẹrika kọja ti ran eeyan mọkanlelogun lọ sọrun, o si ti gba anfani ina mọnamọna lọwọ ọkẹ aimoye miliọnu awọn eeyan nibẹ.
Ko sina ni ilu Texas pẹlu bi awọn olugbe ibẹ ṣe n wa ina lati fi seto ooru fun ara wọn.
Ọpọ awọn olugbe ipinlẹ naa lo n pariwo pe awọn ko ri iru otutu bayii ri.
Ohun ti awọn onimọ nipa oju ọjọ sọ ni pe o ṣeeṣe ki oju ọjọ ri bi o ṣe ri yii titi di opin ọsẹ yii.
Nitori iji otutu yii, awọn eeyan ti ku ni Texas, Louisiana, Kentucky, North Carolina ati Missouri.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ajọ to n mojuto ọrọ nipa oju ọjọ ni orilẹ-ede Amẹrika ti ṣalaye pe iye awọn ọmọ orilẹ-ede naa to wa labẹ ijamba iji otutu bayii le ni aadọjọ miliọnu.
Iji otutu naa tilẹ tun de Mexico nibi ti omilẹgbẹ awọn eeyan ko ti ri ina mọnamọna to ja geere lo.
Oladele Ogbeyemi Albert: Irin tí mò ń lò máa ń bá mi sọ̀rọ̀ nínú ẹ̀mí kí ń tó gbẹ́ wọn sóh
Gẹgẹ bi iroyin lati orilẹ-ede naa ṣe sọ, pupọ awọn to ku lo jẹ wi pe afẹfẹ oloro Carbon monoxide lo pa wọn nibi ti wọn ti tan mọto wọn silẹ ninu ile lati lee fi dooru mu ara wọn.
Bakan naa lawọn miran tun kagbako iku nipasẹ ijamba mọto.
Awọn majẹ-o-bajẹ nibẹ ti n kọminu pe eyi lee fa ọpọlọpọ wahala fun ilera ilu.
Bii miliọnu mẹrin eeyan ni Texas ni ko ri ina mọnamọna lo, awọn bii miliọnu kan ati aabọ miran si tun kun wọn ninu iriri ati iṣoro yii ni Houston.
Akomolede ati Asa lori BBC: Olùkọ́ Bolanle Adekanmi kọ́ wa nípa oríṣíi Àròkọ Yorùbá tó wà
Court ban on Oyo park Managers: Mukaila Auxilliary ní Àìṣàtìpó rí ló ń da 'Ejiogbe' láàmú, tó fi ń ta ko ìṣèjọba òun
Lọjọru ni ile ẹjọ giga ipinlẹ Ọyọ paṣẹ pe ki wọgile iṣẹ awọn alakoso ibudokọ nipinlẹ Ọyọ, PMS ti gomina Ṣeyi Makinde fi lọlẹ.
Gomina Makinde gbe iks naa kalẹ ni ọdun 2020 lẹyin to gbẹsẹ le ẹgbẹ awakọ ero, NURTW nipinlẹ Ọyọ
Ninu ifọrọwerọ rẹ pẹlu BBC News Yoruba, alaga igbimọ amuṣẹya lori gbigbowo ode lawọn idikọ gbogbo ni ipinlẹ Ọyọ, PMS, Alhaji Mukaila. ti ọpọ mọ si Auxilliary ti sọrọsoke.
Ọ ṣalaye pe eremọde lasan ni idajọ naa.
Ati pe aidoju kọ ina ti oun atawọn ọmọlẹyin oun ti dojukọ lẹnu iṣẹ ọmọ ẹgbẹ ọlọkọ ero, Alhaji Abideen Olajide ti ọpọ mọ si Ejiogbe ko tii doju kọọ rara.
Alhaji Mukaila ṣalaye pe ijọba to wa lode ti gbe gbogbo igbesẹ to yẹ lati pẹtu si aawọ laarin ẹgbẹ awọn ọlọkọ ero ṣugbọn ti oloye Ejiogbe faake kọri.
O ni gbogbo aye lo mọ pe ijọba to ba wa lode lo n sọ ẹni ti wọn ba fẹ ko dari ẹgbẹ ọlọkọ ero.
O ni oun loun n ṣiṣẹ fun ẹgbẹ oṣelu to n ṣejọba ni ipinlẹ Ọyọ nitori naa, 'asiko oun lo de yii'
Oladele Ogbeyemi Albert: Irin tí mò ń lò máa ń bá mi sọ̀rọ̀ nínú ẹ̀mí kí ń tó gbẹ́ wọn sóh
"Auxilliary ni ẹnikẹni ninu awọn igun to n tako iṣejọba oun ni ẹgbẹ ọlọkọ ero lee darapọ mọ oun lati lee wa bi jijẹ mimu wọn yoo ṣe maa jade ""ṣugbọn ko si idi fun ipinya nitori karinkapọ yiyẹ nii yẹ ni."""
Ninu idajọ rẹ lori ẹjọ rẹ, Onidajọ M. A. Adegbola ṣalaye pe owo ti ko tọna ni awọn alakoso ti gomina Ṣeyi Makinde yan si ipo n gba lọwọ awọn awakọ.
O fi kun ọrọ rẹ wi pe ijọba ibilẹ nikan lo lẹtọ lati yan iru awọn alakoso bẹẹ, ni ibamu pẹlu ofin orilẹ-ede yii.
Orlu crisis video: Ohun tí a mọ̀ nípa fídíò tó lu ayélujára pa rèé
Ṣé lóòtó ni ilé-iṣẹ́ ológun gbé hẹlikópítà ìjagun lọ si Orlu ní ìpínlẹ̀ Imo?
Iwadii BBC lori iroyin to sọ pe ileeṣẹ ologun orile-ede Naijiria n fi baalu ijagun hẹlikopita yin ado oloro si ilu Orlu fihan pe otitọ ni ileeṣẹ ologun gbe hẹlikopita lọ si Orlu nipinlẹ Imo.
Ni bi ọsẹ mẹta sẹyin lawọn janduku kan ṣekupa awọn eeyan ti wọn sì tun dana sun ọpọ ile níbẹ.
Oju opo Twitter ati Instagram ni Naijiria n gbona giri giri pẹlu iroyin pe ileeṣẹ ologun n yin ado oloro ni Orlu ti wọn si tun n mawọn ẹṣọ alaabo apa ila oorun Naijiria, Eastern Security Network (ESN).
Oriṣiiruṣii fidio lori Twitter lo n ṣafihan bi baalu hẹlikopita ṣe n fo kaakiri ilu Orlu.
Iro ibọn n dun nínu ọkan lara fidio to lu ayelujara pa bi hẹlikopita ṣe n fo.
"Bakan naa ni ọkunrin kan n pariwo ""ha! Jesu Kristi o! Kilode tawọn eeyan yii fi n kaakiri... Jesu ẹ wo ibọn. Ha!...ẹ jẹ ki onikaluku sare wọ ile o."""
Oladele Ogbeyemi Albert: Irin tí mò ń lò máa ń bá mi sọ̀rọ̀ nínú ẹ̀mí kí ń tó gbẹ́ wọn sóh
BBC ko le sọ ni pato igba ti wọn ya fidio ọhun tawọn eeyan n pin lori ayelujara.
Amọ, alukoro ileeṣẹ ọlọpaa ipinlẹ Imo, Orlando Ikeokwu sọ fun BBC pe oun o mọ ohun kan nipa fidio naa.
Lori iro: Ká ni àwọn Òbí mi gbà fún mí, èmi àti Sunny Ade  á jọ máa 'Compete- Baba Lórí ir
Ọpọ eeyan lo ti n pe mi ti wọn si n beere ohun to n ṣẹlẹ ni Orlu, ṣugbọn ohun ti mo mọ ni pe ko si rogbodiyan kankan ni Orlu, alaafia ni gbogbo eeyan wa ni Orlu, Ọgbẹni Ikeokwu ṣalaye.
Odz Chioma to sọrọ lati ilu Orlu ṣalaye pe ko si rogbodiyan kankan lagbegbe oun.
Chioma sọ pe lootọọ lawọn ologun duro wamu wamu kaakiri ilu Orlu ṣugbọn wọn o ṣe idiwọ fun ẹnikẹni.
Awọn eeyan mii to tun sọrọ lati Orlu ṣalaye pe awọn gbọ iro ibọn lagbegbe Okporo, awọn si tun ri awọn sọja ṣugbọn ko si rogbodiyan kankan.
Awọn miran tun sọ pe agbegbe Uli ati Orsu lawọn ti gbọ iro ibọn, àmọ́ kò de agbegbe awọn.
Akomolede ati Asa lori BBC: Olùkọ́ Bolanle Adekanmi kọ́ wa nípa oríṣíi Àròkọ Yorùbá tó wà
Kinni ileeṣẹ ologun sọ?
Alukoro ileeṣẹ ologun 34, Artillery Brigade to wa ni Obinze, Owerri, Babatunde Zubairu sọ pe lootọọ lawọn gbe baalu hẹlikopita lọ si Orlu amọ awọn omogun awọn o dunkoko mọ ẹnikẹni.
Ọgbẹni Zubairu ni ileeṣẹ ologun gbe Igbesẹ yii nitori ohun ti wọn gbọ.
Abdullahi Dikko Inde: Wo ẹ̀sùn ìwà àjẹbánu tí wọn fi kan ọ̀gá àgbà ilé-iṣẹ́ aṣọ́bodè tó kú
Oríṣun àwòrán, @Preseidency
Ọ̀gá àgbà ilé-iṣẹ́ aṣọ́bodè(Customs) tẹ́lẹ̀ tó kú tí wọ́n fẹ̀sùn kíkó ẹgbẹ̀lẹ́gbẹ̀ bílíọ̀nù jẹ kan
Ọpọ eeyan lo n ṣe idaro ọga agba ileeṣẹ aṣọbode orilẹ ede Naijiria tẹlẹ, Abdullahi Dikko Inde to jade laye.
Koda Igbakeji Aarẹ Naijiria nigba kan ri, Atiku  Abubakar darapọ mawọn to n ṣedaro Inde to ku l'Ọjọbọ, ọjọ kejidinlogun oṣu keji ọdun 2021 yii.
Dikko Inde jade laye lẹni ọdun mọkanlelọgọta gẹgẹ bi ileeṣẹ aṣọbobe Naijiria ti ṣalaye.
Oríṣun àwòrán, @NigeriaCustom
Iroyin kan tiẹ sọ pe Inde papoda nile iwosan kan niluu Abuja nibi to ti n gba itọju lẹyin ti o ṣaarẹ.
Ẹwẹ, ọga agba ileeṣẹ aṣọbode Naijiria n jẹjọ lọwọ lori ẹsun iwa ajẹbanu ṣáájú iku rẹ.
Lara ẹsun ti wọn fi kan an ni pe o ko ẹgbẹlẹgbẹ biliọnu owo naira to jẹ owo ijọba jẹ nigba to wa lori aleefa gẹgẹ bi ọga agba ileeṣẹ aṣọbode Naijiria.
Ajọ ICPC to n gbogun ti iwa ibajẹ lawujọ lo kọkọ gbe Inde lọ si ileẹjọ lori iwa ajẹbanu.
Lẹyin naa ni ajọ EFCC gba ọkọ bọginni mẹtadinlogun lọwọ Dikko nibi to ko wọn sì nile rẹ ni Kaduna lọdun 2017.
Femi Falana, Endsars: Awolowo kò fáààyè gba kí èèyàn máa yàgò fún Màálù nígboro
Ṣugbọn lọdun 2019, adajọ Nnamdi Dimgba ileẹjọ giga niluu Abuja pàṣẹ pe ki ajọ EFCC da ẹjọ ti o pe Inde duro lẹyin ti minisita eto idajọ, Abubakar Malami ati Inde buwọlu iwe adehun lati pari ẹjọ ọhún.
Iroyin kan sọ pe Dikko da biliọnu kan ati abọ pada fun ijọba lara owo to ko jẹ ni wọn pè e.
Oladele Ogbeyemi Albert: Irin tí mò ń lò máa ń bá mi sọ̀rọ̀ nínú ẹ̀mí kí ń tó gbẹ́ wọn sóh
Amọ, loṣu keji, ọdun 2020, ileẹjọ giga ijọba apapọ kan l'Abuja tun paṣẹ pe ki wọn lọ gbe Inde pada nitori ko wá sí ile ẹjọ mọ.
Ṣugbọn agbẹjọro rẹ, Solomon Akuma fi iwe ẹri  ile iwosan hàn pe Inde n ṣe aisan ni ko jẹ ko lanfaani lati wa sile ẹjọ.
Agbẹjọro Inde tun sọ pe o wa nile iwosan niluu London nibi to ti n gba itọju.
Lori iro: Ká ni àwọn Òbí mi gbà fún mí, èmi àti Sunny Ade  á jọ máa 'Compete- Baba Lórí ir
Funmi Martins: Sir Shina Peters dúpẹ́ lọ́wọ́ àwọn abiyamọ ayé lórí ọ̀rọ̀ ọmọ tí Funmi Martins bí kó tó kú
Oríṣun àwòrán, Instagram/sir shinapeters
Gbajugbaja olorin Juju, Sir Shina Peters ti dupẹ lọwọ awọn abiyamọ aye fun ifẹ ati itara wọn lori ọrọ ọmọ ti oloogbe oṣere Funmi Martins bi ki o to papoda.
Bakan naa ni Ọgbẹni Peters tun dupẹ lọwọ ileeṣẹ iroyin ori ayelujara kan, Gistloverupdate to gbe ọrọ naa jade.
''Gbogbo ẹyin abiamọ aye ti ẹ da si ọrọ Damilare, mo ki yin fun ifẹ ti ẹ ni si mi,'' Shina Peters sọrọ yii ninu fidio kan to fi sori ayelujara.
Ẹwẹ, iwadii tuntun taa tun ri nipa iku oloogbe Gunmi Martins ree:
Olorin Juju naa sọ pe ''ti eeyan ba mọ inu ro, a mọ ọpẹ da,'' idi niyii ti oun fi dupẹ lọwọ gbogbo awọn to da si ọrọ naa.
Ọgbẹni Peters tun ṣeleri pe oun ko ni ja wọn abiyamọ to da si ọrọ naa kulẹ.
Amọ, Ọgbẹni Peters ko ṣai ṣalaye pe ọrọ pọ ninu iwe kọbọ lori ọrọ naa.
Ṣugbọn akọrin Juju ọhun sọ pe oun o ṣetan lati tu iṣu de isalẹ koko lori ọrọ naa.
Ọ̀pọ̀ èèyàn lórí ayélujára dá Shina Peters lẹ́bi lórí ọ̀rọ̀ ọmọ tí Funmi Martins bí kó tó kú
Ori ayelujara si n gbona giri giri lori ọrọ gbajugbaja akọrin Juju, Sir Shina Peters ti wọn fẹsun kan pe ko nanii ọmọkunrin kan ti oṣere tiata tẹlẹ to ti di oloogbe bayii Funmi Martins bi fun un.
Ileeṣẹ iroyin ori ayelujara kan, Gistloverupdate lo fọrọ naa soju opo Instagram ati Twitter rẹ.
Oríṣun àwòrán, Instagram/Sir Shina Peters
Gistloverupdate ṣalaye pe olorin Juju Sina Peters ko beere ọmọkunrin yii, Damilare lati igba ti mama rẹ Funmi ti jade laye.
Ṣé o nífẹ̀ẹ́ láti kọ èdè ẹ̀yà Nàìjíríà míì ní kíákíá?
Gistloverupdate tun sọ pe Shina ti pe fun ayẹwo DNA lori ọmọ naa lati mọ daju bo ya oun lo ni ọmọ naa.
Gistliverupdate tun bu ẹnu atẹ lu ọrọ to ni Shina sọ pe kawọn eeyan maa da owo iranwọ fun ọmọ naa mọ.
Mother tongue day 2021, Akomolede, YSAN: A ti parí iṣẹ́ lórí èdè ìperí Meta-Language Yorùb
Ọpọ eeyan lori ayelujara lo koro oju si ọrọ yii, koda niṣe ni wọn n di ẹbi ọrọ naa ru ọgbẹni Peters.
Abidemi Adumeta SHina Peters kii ṣe ẹni ti eeyan le gbagbọ, o ni kawọn eeyan maa dawo iranwọ lọ fun Damilare.
Dada Margaret sọ ni tẹ pe Sina ko ni ohun kan to fẹ ṣe fun Damilare bii ti wulẹ ko mọ.
Oríṣun àwòrán, Instagram/gistloverupdate
Thereallaurel_norman sọ pe ọmọkunrin naa ti di ilumọọka ni, Shina ko ni beere fun ayẹwo DNA.
O ni Shina ko beere fun ayẹwo DNA lori Clarence Peters nitori ọmọ naa ti ṣoriire.
UNSUB App: Ṣé ó mọ́ ẹni tí wọ́n ti fipá bá lòpọ̀ rí tó ń fẹ́ ìdájọ́ òdodo?-Olajide Abiose
Biola Abiola tiẹ ni ọmọ naa ko nilo ayẹwo DNA kankan tori o jọ Shina ju.
Abiola ni o maa nira fun ọmọkin yii lati dariji Shina Peters ti esi ayẹwo DNA ọhun ba jade.
Oríṣun àwòrán, Instagram/gistloverupdate
Mo pàdánù owó tó lé ní N20m lọ́jà Shasha, mi ò padà síbẹ́ mọ́- Alhaji Nyako
Ṣé lóòtó ni ilé-iṣẹ́ ológun gbé hẹlikópítà ìjagun lọ si Orlu ní ìpínlẹ̀ Imo?
Irọ́ ni o, mí o fẹ̀ Lateef Adedemeji- Oyin Elebuibọn pẹ̀lú omijé ojú
Ọ̀gá àgbà ilé-iṣẹ́ aṣọ́bodè (Customs) tẹ́lẹ̀ tó kú tí wọ́n fẹ̀sùn kíkó ẹgbẹ̀lẹ́gbẹ̀ bílíọ̀nù jẹ kan
Oríṣun àwòrán, Instagram/gistloverupdate
Princess Ebunoluwa Olujobi woye ni tiẹ pe ohun to mu Shina Peters lati beere fun ayẹwo DNA fun Damilare fihan pe oun ati oloogbe Martins jọ ni ajọṣepọ.
@Akinluvmore ni iwa ainitiju gbaa ni Shina Peters n hu.
O ni o yẹ ki oju gba a ti papaa julọ lẹyin ti wọn fi jẹ oye biṣọọbu tan ni ijọ Kerubu ati Serafu.
Gbajugbaja oṣere tiata, Mide Martins ni awọn mi ti i ẹ n bu wi pe o yẹ ko le tọju ọmọkunrin ti mama bi kẹyin ki o to jade laye.
Femi Falana, Endsars: Awolowo kò fáààyè gba kí èèyàn máa yàgò fún Màálù nígboro
Wọn ni Eledua ti kẹ Mide de bi pe o yẹ ki o le ṣe iranwọ fun Damilare.
Oladele Ogbeyemi Albert: Irin tí mò ń lò máa ń bá mi sọ̀rọ̀ nínú ẹ̀mí kí ń tó gbẹ́ wọn sóh
Kagara abduction: Lai Mohammed ní ìjọba ò sanwó fáwọn ajínigbé láti fi àwọn akẹ́kọ̀ọ́ iléèwé Kagara sílẹ̀
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Faabada! Ijọba ko ni san owo kankan fawọn agbebọn ajinigbe to ji awọn akẹkọọ ati oṣiṣẹ ileewe girama Government Science College ilu kagara nipinlẹ Niger lọ,
Minisita eto iroyin ati aṣa, Lai Mohammed lo sọrọ lori ileeṣẹ ẹrọ amohunmaworan Channels.
Iroyin kan tu lu ayelujara pa pe ijọba apapọ ti san owo gọbọi fawọn ajinigbe lati fi awọn ọmọ akẹkọọ atawọn oṣiṣẹ ileewe ti wọn jigbe silẹ.
Amọ, nigba to n sọrọ lori eto kan lori Channels lọjọ Abamẹta, Mohammed ni irọ ni pe ijọba ti sanwo itanran fawọn ajinigbe.
Minisita ni oriṣiiriṣii ọna ni ijọba n gba lati rii pe awọn akẹkọọ atawọn oṣiṣẹ ileewe Kagara ti wọn jigbe gba ominira.
Ọgbẹni Mohammed sọ pe ọjọ kan kọ ni gbogbo nkan de ibi to de yii, bakan naa ni kii ṣe ọjọ kan ni gbogbo nkan maa pada bọ sipo.
Femi Falana, Endsars: Awolowo kò fáààyè gba kí èèyàn máa yàgò fún Màálù nígboro
''Ijọba ko ni gba iwa ọdaran kankan laaye lorilẹede Naijiria, ati pe ijọba fẹ ṣe iwadii ohun to ṣe okunfa iwa ọdaran tawọn eeyan kan hu lawujọ.
Laipẹ yii ni mo lọ si ilu Minna pẹlu awọn minisita mii to fi mọ ọga agba ọlọpaa ni Naijiria  lati ṣe iwadii lori ọrọ iṣẹlẹ ijinigbe ileewe girama Kagara.
Mother tongue day 2021, Akomolede, YSAN: A ti parí iṣẹ́ lórí èdè ìperí Meta-Language Yorùb
Mo le fi da yin loju pe ijọba n ṣiṣẹ takuntakun lori ọrọ naa,'' Mohammed lo sọ bẹẹ.
Ẹwẹ, Gomina ipinlẹ Niger, Abubakar Bello paṣẹ l'Ọjọru pe ki wọn gbe gbogbo ileewe tipa lagbegbe tawọn ajinigbe ti n ṣọṣẹ nipinlẹ naa.
Oladele Ogbeyemi Albert: Irin tí mò ń lò máa ń bá mi sọ̀rọ̀ nínú ẹ̀mí kí ń tó gbẹ́ wọn sóh
Ile igbimọ aṣofin l'Abuja naa ti sọ fun Aarẹ Muhammadu Buhari pe ki o kede nkan o fara rọ lori ọrọ eto abo ni Naijiria.
Ṣaaju iṣẹlẹ yii awọn ajinigbe kan yabo ileewe girama to wa ni Kankara, nipinlẹ Katsina nibi ti wọn ji awọn akẹkọọ to le ni ọdunun un gbe lọ.
Badagry Historical Wells: Omi inú kànga Wawú ló ń kó ọpọlọ àwọn ẹrú lọ
Ọkùnrin kan, Enoch Adamu gún olólùfẹ́ rẹ̀, Ashini Hosea lọ́bẹ lórí N85,000 lẹ́yìn tó kọ̀ láti ṣèyàwó pẹ̀lú rẹ̀
Aawọ to wa laarin ọkunrin kan, Enoch Adamu  ati ololufẹ rẹ tẹlẹ ri, Ashini Hosea bẹyin yọ lẹyin ti ọkunrin yii fa ọbẹ yọ nile ẹjọ ti o si bẹrẹ si ni gun obinrin naa.
Igbesẹ ileẹjọ to n ri si ẹsun ọdaran niluu Yola, ipinlẹ Adamawa to yi adehun to wa laarin ọkunrin naa ati ololufẹ rẹ pe obinrin naa gbọdọ san ẹgbẹrun marunlelọgọrin fun un lẹyin to sọ pe oun ko fẹ ẹ mọ.
Adamu gbe Ashini lọ sile ẹjọ lori adehun owo to wa laarin wọn pe yoo san fun un.
O fẹ gba gbogbo owo to ni oun ti na lori Ashini lati igba ti wọn ti n ba ọrọ ifẹ wọn bọ ki Ashini to sọ pe oun ko ṣe mọ.
Owo ori gan an wa lara owo ti Adamu fẹ gba pada lọwọ Ashini.
Oladele Ogbeyemi Albert: Irin tí mò ń lò máa ń bá mi sọ̀rọ̀ nínú ẹ̀mí kí ń tó gbẹ́ wọn sóh
Ṣugbọn ileẹjọ wọgile adehun lati san owo naa pada fun Adamu.
Wọn gbe Ashini digba digba lọ si ile iwosan fun itọju nigba ti wọn ju Adamu si atimọle.
Mother tongue day 2021, Akomolede, YSAN: A ti parí iṣẹ́ lórí èdè ìperí Meta-Language Yorùb
Ẹni ti ọrọ naa ṣoju rẹ ṣalaye pe ileẹjọ ti kọkọ sun igbẹjọ ọhun si Ọjọbọ ọjọ kejidinlogun oṣu keji ọdun 2021 lati jiroro lori owo ti Adamu n beere.
Ṣugbọn o ni ọrọ naa bẹyin yọ lẹyin ti agbẹjọro Ashini rọ ileẹjọ lati wọgile owo ti Adamu n beere fun nitori koro oju si ohun ti Adamu n beere fun.
UNSUB App: Ṣé ó mọ́ ẹni tí wọ́n ti fipá bá lòpọ̀ rí tó ń fẹ́ ìdájọ́ òdodo?-Olajide Abiose
Ẹni ti ọrọ ṣoju rẹ ni eyi gan an lo fa sababi iṣẹlẹ igunnilọbẹ nile ẹjọ.
Ẹwẹ, alukoro ileeṣẹ ọlọpaa ipinlẹ Yobe, DSP Sulieman Nguroje fidi rẹ mulẹ pe Adamu ti wa ni akolo awọn ọlọpaa.
Bakan naa ni Nguroje sọ pe Ashini si wa laaye, koda o fikun un pe Adamu tun gun awọn mẹrin miran lọbẹ ti wọn si farapa.
Femi Falana, Endsars: Awolowo kò fáààyè gba kí èèyàn máa yàgò fún Màálù nígboro
Women, Pregnancy complications: Wo oríṣìí àrùn méjọ to máa ń ṣáábà mú aláboyún
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Oríṣìí àrùn mẹ́jọ tó máa ń ṣáábà mú aláboyún rèéAdura gbogbo obinrin to ba ṣẹṣẹ ṣe igbeyawo naa ni pe ki wọn fi inu ṣoyun fẹyin gbọmọ pọn.
Ṣugbọn ọpọ ni ko mọ awọn irora to wa ninu ipo oloyun.
Dokita onimọ nipa obinrin ati ọmọde, Dokita Joseph Ayinde ṣalaye pe o ṣe pataki ki awọn eeyan mọ nipa awọn arun ọhun.
Wọnyii ni awọn arun oriṣii mẹjọ to máa n ṣaaba ṣe alaboyun:
1. Àrùn iba:
Dokita Ayinde ni arun iba jẹ ọkan lara arun to maa n ṣaaba ṣe awọn alaboyun.
O ṣọ pe awọn ti oyun wọn ko tii ju bi oṣu mẹta lọ ní arun maa yọ lẹnu.
O rọ awọn alaboyun lati maa sun ninu nẹẹti ki ẹfọn maa le jẹ wọn eyi to maa n fa iba.
US Vice President:Ẹ wo ìtàn obìnrin àkọ́kọ́ tí yóò jẹ igbákejì Ààrẹ ilẹ́ Amẹrika?
2. Arun Anemia:
Dokita Ayinde ni arun yii naa wọ pọ pẹlu awọn oloyun.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ohun ti arun yii tumọ si ni pe awọn alaboyun maa n ni ẹjẹ ruru nitori wọn nilo ẹjẹ to pọ pẹlu bi wọn ti sanra.
Ọna abayọ ni kí alaboyun jẹ ounjẹ to dara ko sí tun lo awọn rẹ bi folic acid deedee.
'Bí aya bá kọ ọkọ rẹ̀ silẹ̀, kó wà láì lọ́kọ̀'
3. Ẹjẹ ruru:
Dokita Ayinde ṣalaye pe ọpọ oloyun lo maa n ni arun ẹjẹ ruru nitori awọn ati ọmọ to wa ninu wọn lo jọ n pin ẹjẹ lo.
Oríṣun àwòrán, @Alhassan
Amọ, dokita naa ṣalaye pe awọn obinrin to ba ti to ọdun mẹrindinlọgbọn lọ soke ni wọn máa n ṣaaba larun yii.
Ọna abayọ ni ṣiṣe ayẹwo nigba gbogbo lati mọ boya ifunpa lọ soke.
Ọkùnrin tó fẹ́ fipábámilòpọ̀ fín ǹkan sí mi lójú ló ṣe rọ́nà wọlé sí mi lára
4. Arun itọ ṣuga:
Dokita Ayinde ni ipo oloyun le fa arun itọ ṣuga .
Bakan naa ni dokita ọhun tun sọ pe oloyun le jogun arun itọ ṣuga lati ọdọ awọn obi rẹ.
Ìgbésí ayé àwọn ọmọdébìnrin wọ̀nyìí di ọ̀tun láti 2008
Itọ atọju, eebi ati aigbọran daadaa lawọn àpẹẹrẹ tawọn oloyun to ba larun naa maa n ri.
Dokita ni ọna abayọ ni pe ki alaboyun maa ri dokita rẹ deedee fun itọju to peye.
Mother tongue day 2021, Akomolede, YSAN: A ti parí iṣẹ́ lórí èdè ìperí Meta-Language Yorùb
5. Arun arunmọleegun
Dokita Ayinde ni arun arunmọleegun maa yọ ọpọ oloyun lẹnu.
O ni lilo oogun folic acid lọna abayọ, bi bẹẹ kọ, arun yii le gbẹmi alaboyun.
Ọ̀pọ̀ òṣìṣẹ́ elétò ìlera ló ti n lo tọ̀nà ìgbàlódé láti fiṣe àkọsílẹ̀
6. Arun ọkan
Awọn oloyun tun maa n larun ọkan.
Dokita Ayinde sọ pe ipo oloyun tun maa n jẹ ki eeyan ni arun ọkan.
Isinmi lẹnu iṣẹ, riri dokita deedee ati yiyẹ ifunpa wo  lọna abayọ.
Oladele Ogbeyemi Albert: Irin tí mò ń lò máa ń bá mi sọ̀rọ̀ nínú ẹ̀mí kí ń tó gbẹ́ wọn sóh
7. Arun varicose ori iṣan:
Dokita Ayinde ni irufẹ arun ori iṣan yii ko ṣaaba wọ pọ laarin awọn aboyun.
Dokita ni oloyun le dena arun yii nipa sisun silẹ ati nina ẹsẹ soke.
Femi Falana, Endsars: Awolowo kò fáààyè gba kí èèyàn máa yàgò fún Màálù nígboro
8. Ẹsẹ wiwu ati eebi:
Dokita Ayinde sọ pe ẹsẹ ọpọ oloyun maa n wu, bakan naa lawọn oloyun mii tun maa n ṣaaba bi.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ṣugbọn Ayinde ni eyi kii ṣaaba ṣakoba fun wọn.
Lakotan, Dokita onimọ nipa awọn obinrin ati ọmọde ṣọ pe o dara ki obinrin bimọ ni ọjọ ori ti ko ju ọdun marundinlogoji lọ tori awọn arun to maa n ṣe oloyun niiṣe pẹlu ọjọ ori wọn.
UNSUB App: Ṣé ó mọ́ ẹni tí wọ́n ti fipá bá lòpọ̀ rí tó ń fẹ́ ìdájọ́ òdodo?-Olajide Abiose
Ọkùnrin ẹni ọdún 73 sá kúrò nílé lẹ́yìn tí ìyàwó rẹ̀ lóyín ìbẹta
Oríṣun àwòrán,  @legitngnews
Obinrin ẹni ọdun mẹrinlelọgbọn yii ko lero pe oju oun yoo ri iru nnkan bayii nigba to gba lati ṣe iyawo Pili Shaban ni nnkan bii ọdun mẹrindilogun sẹyin.
Igbesi aye Zawadi Mussa Ntaliligwa bẹrẹ si n dori kodo lẹyin ti ọkọ rẹ sa kuro nile ni kete to gbọ pe ọmọ mẹta lo wa ninu oyun inu rẹ.
Ṣaaju ni obiunrin naa ti kọkọ bi ọmọ marun un tẹlẹ ki oyun ibẹta ọhun to de.
Gẹgẹ bii nnkan to sọ fun awọn akọroyin, ọkọ rẹ naa sa kuro nile laarin oṣu Karun un ọdun 2020, iyẹn lasiko ti ọwọja ajakalẹ arun Covid-19 kọkọ fi gbogbo agbaye logbologbo, ti ọpọ orilẹ-ede si wa ni igbele.
"O ni ""ibẹta ni mo bi loṣu kinni ọdun yii, awọn meji jẹ ọkunrin, ti eyii to kẹyin si jẹ obinrin."""
Oríṣun àwòrán, @legitngnews
Obinrin naa to n gbe lagbegbe ila oorun Tanzania ni inu oṣi ati iṣẹ ni oun n gbe lati igba ti ọkọ oun to jẹ ẹni ọdun mẹtalelaadọrin ti fi oun silẹ pẹlu ọmọ mẹjọ lati maa tọju.
Mother tongue day 2021, Akomolede, YSAN: A ti parí iṣẹ́ lórí èdè ìperí Meta-Language Yorùb
Ni bayii, o ni awọn alabagbe lo n da owo jọ nigba miran ti oun atawọn ọmọ naa fi n jẹun, koda, o ni oṣi naa pọ to bẹẹ ti oun padanu ọkan lara awọn ibẹta ọhun ninu oṣu Kẹji ọdun yii.
"Nigba to n ṣalaye lori ohun pato to mu ọkọ kẹru ara rẹ jade kuro nile, o ni ""mo gbagbọ o ko kuro nile nitori o ti mọ pe oyun naa maa na wa ni owo to pọ."""
UNSUB App: Ṣé ó mọ́ ẹni tí wọ́n ti fipá bá lòpọ̀ rí tó ń fẹ́ ìdájọ́ òdodo?-Olajide Abiose
A ko ni ija kankan lati nnkanbii ọdun mẹrindinlogun ti fẹ ara wa titi di igba ti mo ni oyun ọhun ko to kuro nile, to si ko gbogbo dukia wa, ati awọn aṣọ mi gan pẹlu.
O ṣalaye pe lati igba ti ọkọ naa ti salọ, iṣẹ agbaṣẹ pẹlu iṣẹ ọmọ ọdọ ni oun n ṣe ki awọn naa to le jẹun lọpọ igba.
Zawadi pari ọrọ rẹ pe oun ko binu si ọkunrin naa bo tilẹ jẹ pe o fi oun silẹ lọ, bakan naa lo sọ pe oun ṣetan lati dariji to ba pinnu lati pada wa sile.
Badagry Historical Wells: Omi inú kànga Wawú ló ń kó ọpọlọ àwọn ẹrú lọ
Lẹyin naa lo rọ awọn ọkunri lati maṣẹ kọ ojuṣẹ wọn ninu ile gẹgẹ baale lai ro bi nnkan ṣe le to lawujọ.
Femi Falana, Endsars: Awolowo kò fáààyè gba kí èèyàn máa yàgò fún Màálù nígboro
Benin Republic: Ìjọba sọ̀rọ̀ lórí ìròyin tó ní Benin fẹ́ di ọ̀kan lára àwọn ìpínlẹ̀ Nàìjíríà
Oríṣun àwòrán, Twitter/Government of Nigeria
Ọpọ ọmọ Naijiria lo sọ ero wọn boya wọn fẹ ki orilẹede Benin Republic di ọkan lara awọn ipinlẹ to wa lorilẹede yii.
Niṣe lori ayelujara gbona giri giri lẹyin ti ọgọọrọ eeyan n gba ọrọ naa bi ẹni n gba igba ọti lori Twitter ati Facebook lọjọ Satide.
Iroyin kan lo kọkọ sọ pe minisita ọrọ ilẹ okeere, Geoffrey Onyeama ṣalaye pe Aarẹ orilẹede Benin, Patrice Talon sọ erongba rẹ pe awọn ṣetan lati di ipinlẹ kẹtadinlogoji ni Naijiria.
Amọ, awọn Naijiria sọ ti inu wọn lori Twitter ati Facebook lori ọrọ naa.
Ọpọ eeyan lo sọ pe kaka ki kiniun ṣe akapo ẹkun, ki onikaluku maa ṣe ọdẹ tiẹ lọọtọọ.
Wọn ni ọrọ Naijiria gan an ti too gbọ, wọn sọ pe ki orilẹede Benin wa laye rẹ.
Sẹnẹtọ Shehu Sani atawọn ọmọ Najiria mii faramọ pe ki Benin Republic darapọ mọ Naijiria.
Ṣugbọn Sani ṣe ikilọ pe ẹnikẹni ko gbọdọ tumọ ohun to n ṣẹlẹ lọwọlọwọ ni Naijiria lede Faranse fun awọn eeyan Benin.
Ẹka ileeṣẹ ijọba orilẹede Naijiria to n ri si ọrọ ilẹ okeere ti fesi pe ko si ohun to jọ bẹẹ pe Benin Republic fẹ di ipinlẹ kẹtadinlogoji ni Naijiria.
Ninu atẹjade to fi sita loju opo Twitter rẹ, ilẹẹṣẹ ijọba naa ni orilẹede Naijiria ko ni erongba lati sọ Benin di ọkan lara ipinlẹ ni Naijiria.
Ijọba sọ ninu atẹjade ọhun pe awọn kan lo ṣi ọrọ ti minisita ọrọ ilẹ okeere sọ gbọ.
Atẹjade ọhun ṣalaye pe ohun ti Ọgbẹni Onyeama sọ ni pe Aarẹ Muhammadu Buhari ati aarẹ Benin fẹ ki ajọṣepọ to wa laarin Naijiria ati Benin tun dan mọran sii.
Fight against corruption: Ọ̀rọ̀ Satguru Maharaj ji sí àwọn olóṣèlú Nàìjíríà lórí ìwà àjẹbánu
Oríṣun àwòrán, Instagram/Bashir Ahamad
Oludasilẹ ijọ One Love Family, Satguru Maharaj ji ti ja gudugbẹ ọrọ lulẹ lori ọrọ igbogun ti iwa ajẹbanu lorilẹede Naijiria.
Guru Maharaj ji woye pe asiko ti to fawọn oloṣelu lati maa ṣe ibura lọna ẹsin abalaye nigba ti wọn ba n ṣe ifilọlẹ ijọba wọn.
O ni bibura pẹlu Ogun, Sango ati Ifa lo le jẹ ki iwa ajẹbanu to gbode kan ni Naijiria di ohun igbagbe.
Guru Maharaj ji sọrọ yii nibi apero kan to da lori awọn iṣẹlẹ to n ṣakoba fun gbogbo agbaye ni lọọlọ yii lọjọ Abamẹta.
''Awọn eeyan n bura pẹlu Bibeli ati Quoran, ṣugbọn wọn n kowo ilu jẹ, ohun kan ko si ṣẹlẹ si wọn.
Iwa ọdaran yii si ti ṣe akoba nla fun ọpọ idile ati ileeṣẹ.
Amọ, to ba jẹ pe Ogun tabi Sango ni wọn fi n bura ni, ọpọ eeyan ni ko ni maa kowo ilu jẹ,'' Guru Maharaj ji lo woye bẹẹ.
Ẹ̀yin olórin ẹ̀mí tó ń bóra, lo èékáná gígùn, oò yàtọ̀ sí aṣẹ́wó hòtẹ́ẹ̀lì tí wọ́n ń gbé bíi súùtì Pepper Menti - Bola Are
Olori ijọ One Love Family ni awọn eeyan ti fi orisun silẹ nibi ti gbogbo nkan ti bẹrẹ ati ibi ti otitọ ati ododo wa.
O rọ ijọba lati gbe ọrọ ibura pẹlu Ogun, Sango ati Ifa wo, o ni ọna kan gboogi tawọn ''baba wa'' gbe kalẹ niyii lati maa wa ojutu si ohunkohun to ba ruju.
Guru Maharaj ji fikun ọrọ rẹ pe ibura lọna ẹsin ibilẹ yoo jẹ ki awọn olori maa ṣe ijọba daradara nitori ibẹru ibinu Ogun tabi Sango yoo wa lọkan wọn.
O ni ''a nilo nkan ti yoo maa ka wa lọwọ kọ lori iwa ibajẹ lawujọ.''
Airforce Plane crash in Abuja: Iléeṣé ológùn ti ń sìnkú àwọn akọni tó bá ìjàmbá ọkọ̀ Bàálù lọ ní Abuja
Oríṣun àwòrán, Channels
Ẹkun ko ṣee pa mora ni ibi itẹ oku National Military Cemetery ni Abuja nibi ti ile iṣẹ ologun Naijiria ti n si oku awọn meje to papoda ninu baalu to ja lọjọ Aiku.
Awọn Sagẹnti naa wa lara awọn to wa ninu ọkọ baalu Beechcraft King Air 350 ti ile iṣẹ ogun ofurufu eyi to ja ni ilu Bassa ti ko jina si papakọ ofurufu Nnamdi Azikwe ti Abuja lasiko ti wọn lọ fun iṣẹ ogun kan Lara awọn to wa nibi eto isinku naa ni Minisita eto abo, Bashir Magashi, awọn ọga awọn ologun mii ti ọga awọn ọmọ ogun alaabo, Major General Lucky Irabor dari.
Ọkọ mi bá àwọn ọmọ wa sọ̀rọ̀ lágo kan kó tó wọ bàálù tó já, àmọ háà! - Ìyàwó Olasunkanmi Olawunmi
Awọn mọlẹbi awọn oloogbe naa wa nibi itẹ oku nibi ti ko ti si oju ẹni kankan to gbẹ tabi da furu ayafi pẹlu omije tori awọn ẹni ire to lọ.
Awọn ọmọ ologun meje to ku ninu ijamba ọkọ ofurufu ni Ọjọ Isinmi yoo wọ ka ilẹ sun ni Ọjọbọ, Ọjọ Karundinlọgbọn, Oṣu Keji , ọdun 2021.
Ileeṣẹ ọmọogun ofurufu ni Naijiria lo fi iroyin yii lede ni Ọjọọru lasiko ti wọn n ba awọn oniroyin sọrọ.
Ni itẹ awọn akọni ti orilẹede Naijiria ni wọn n sin awọn meje ọhun si ni agbegbe Lugbe, lọna Airport Road, ni ilu Abuja.
'Tí mi ò bá rí ògùn rà fún ọmọ mi, á máa gé ara rẹ̀ jẹ tí ẹ̀jẹ̀ yóò máa ṣàn'
Ọkọ ofurufu, Beechcraft King Air B350i ti wọn wa naa lo taku looju ofurufu, to si da ijamba ọkọ to pa gbogbo awọn to wa ninu ọkọ ofurufu ọhun.
Awọn akọni to ku ọhun ni ọmọogun Haruna Gadzama, ọmọogun Henry Piyo, ọmọogun Micheal Okpara, ọmọogun Bassey Etim, ọmọogun Olasunkanmi Olawunmi, ọmọogun Ugochukwu Oluka ati ọmọogun Adewale Johnson.
Oríṣun àwòrán, icirnigeria
Ọpọlọpọ ọmọ Naijiria jake jado lo kẹrora awọn akọni ti wọn ku iku gbigbona naa.
Bakan naa ni Adari Ikọ Ọmọogun Ofurufu ni Naijiria, Air Vice Marshal Isiaka Amao ti pe fun iwadii lori iṣẹlẹ naa.
Ọgagun naa fikun wi pe awọn ọmọogun ti wọn ku naa ṣẹṣẹ kuro ni ilu Minna, ni ipinlẹ Niger nibi ti wọn ti lọ ṣewadii lori ọna ati doola ẹmi awọn
akẹkọọ mejilelogoji ati awọn olukọ ti awọn aginigbe ko lọ kuro ni ileewe wọn ni Government Science College, Kagara, ipinlẹ Niger lasiko ti wọn ṣe ikọlu sibẹ.
Oríṣun àwòrán, @wyrelessng
O ṣoju mi koro kan ti sọ pe atukọ baalu ileeṣẹ ologun ofurufu to ja lulẹ niluu Abuja gbiyanju ki iṣẹlẹ naa ma waye ṣugbọn omi pọ ju ọka lọ fun un.
Nigba to n ba BBC sọrọ, o ni oju oun gan ni baalu naa ṣe ja lulẹ ti ina si ṣẹyọ lara rẹ.
"O ṣalaye pe ""mo ri bi baalu naa ṣe n tiraka ko ma ja lulẹ nitori atukọ rẹ gbiyanju lati pada si papakọ ofurufu ṣugbọn o papa ja naa ni."""
Lẹyin ti baalu naa ja tan ni ina ati eefin ṣọ lara rẹ.
Obinrin ọhun sọ siwaju si pe, ṣe ni omi bẹrẹ si n bọ loju oun ti oun si n kigbe ikunlẹ abiyamọ lẹyin iṣẹlẹ naa.
Gẹgẹ bii ohun ileeṣẹ ologun sọ ṣaaju, ẹmi meje lo ba iṣẹlẹ naa lọ.
Ki lo ti ṣẹlẹ ṣẹyin?
Oríṣun àwòrán, @bellokambra1
Ọọfisi alukoro ileeṣẹ ologun ofurufu Naijiria ti kede pe eeyan meje lo dero ọrun lẹyin ti baalu ileeṣẹ naa kan ja niluu Abuja lọjọ Aiku.
Alukoro ileeṣẹ ọhun, Air Vice Marshal Ibikunle Daramola lo fidi iroyin naa mulẹ loju opo Twitter rẹ.
"O ni ""A fẹ fidi rẹ mulẹ pe lootọ ni baalu ileeṣẹ ọmọ ogun ofurufu Beechcraft KingAir B350i ja lasiko to n pada si Abuja lẹyin ti ẹnjini rẹ kọṣẹ."""
Awọn oṣiṣẹ pajawiri ti wa nibi ti iṣẹlẹ naa ti ṣẹ, ṣugbọn o ṣeni laanu pe eeyan meje lo ba iṣẹlẹ naa lọ.
Ibikunle fi kun pe, ọga agba ileeṣẹ ọhun, Air Vice Marshal IO Amao ti paṣẹ ki wọn bẹrẹ iwadii lori ohun to ṣokunfa iṣẹlẹ naa ni kankan.
Lẹyin naa lo rọ awọn eeyan ilu lati ṣe suru nitori awọn yoo tu iṣu de isalẹ ikoko iṣẹlẹ naa laipẹ.
Ẹwẹ, ẹnikan ti iṣẹlẹ naa ṣoju rẹ ti ba BBC sọrọ lori ohun to ṣẹlẹ ki baalu naa to ja.
Nkechi Ugochukwu to n gbe lagbegbe ibi ti iṣẹlẹ naa ti ṣẹ sọ pe inu yara ni oun ti gbọ ariwo nla kan.
"O ni ""ko jẹ tuntun pe mo maa n gbọ iro awọn ọkọ ofurufu ninu yara mi ti wọn ba n kọja, ṣugbọn ariwo eyii yatọ."""
O ṣlaye pe awọn eeyan korajọ lẹyin ti baalu naa ja tan ṣugbọn wọn ko foju ri ẹnikankan to ru la, o fi kun pe ọkọ ofurufu ologun ni.
Ki lo tin ṣẹlẹ sẹyin?
Oríṣun àwòrán, @mobilisingniger
Ọkọ ofurufu ileeṣẹ ọmọ ogun kan, King Air 350, ti ja lulẹ niluu Abuja.
Iroyin ni atukọ baalu na ti kọkọ ke gbajare pe ọkan lara irinṣẹ rẹ ti kọṣẹ nigba to n fo bọ lati Minna.
Minisita to n ri si eto irinna ọkọ ofurufu ni Naijiria, Hadi Sirika ti fidii iroyin naa mulẹ loju opo Twitter rẹ.
Sirika ni iṣẹlẹ naa jẹ eyii to buru jọjọ.
Farmers-herdsmen crisis: Fayemi ní fifi òfin de dída máàlù kiri kò lè dẹ́kun àawọ̀ láàrin àwọn àgbẹ̀ àti darandaran
Oríṣun àwòrán, Facebook/Kayode Fayemi
Gomina ipinlẹ Ekiti to tun jẹ alaga ẹgbẹ awọn gomina ni Naijiria, Ọmọwe Kayode Fayemi ti ni fifi ofin de dida maalu kaakiri kọ ni ojutu si aawọ to n ṣẹlẹ laarin awọn darandaran atawọn agbẹ ni Naijiria.
Ọmọwe Fayemi sọrọ yii lori eto kan lọjọ Aiku lori amohunmaworan Channels niluu Eko.
Fayemi sọ pe fifi ofin de dida maalu kaakiri lai wa bi awọn darandaran yoo ṣe maa ko ẹran wọn jẹ oko ko ni fopin si wahala to n bẹ silẹ laarin awọn agbẹ atawọn darandaran.
''Gbogbo gomina lo ṣe adehun lati wa ọna ti awọn darandaran yoo fi maa tọju maalu wọn lai pa ẹnikan kan lara.
A ni lati wo bi a ṣe le tẹle eto sinsin ẹranko lọna igbalode yala nipa kikọ ọgba fun wọn ati pipese ọna mii lati maa fun wọn lounjẹ,'' Fayemi ṣalaye.
Gomina Fayemi tun sọ pe gbogbo nkan yii ko le ṣẹlẹ lọjọ kan tori aawọ naa ti n ṣẹlẹ fun ọjọ pipẹ.
Fayemi ni diẹ diẹ ni ofin ki awọn darandaran ma ma da maalu kaakiri yoo fi mulẹ ti awọn ọlọsin ẹran yoo si bẹrẹ si ni kọ gba fawọn ẹran wọn.
Bakan naa ni Fayemi tun fikun ọrọ rẹ pe ijọba gbọdọ ṣe iranwọ fawọn ọlọsin ẹran gẹgẹ bi wọn ṣe n ran awọn agbẹ onirẹsi ati awọn to n gbin ẹgẹ lọwọ.
Gomina ipinlẹ Ekiti tun sọ pe ai tete da ṣheria fawọn darandaran to tasẹ agẹrẹ lo jẹ ki awọn ma sọ pe ipinlẹ Ekiti n ṣegbe lẹyin awọn darandaran.
Gẹ́gẹ́ bí àṣà, mo ti mọ̀ tipẹ́ pé mo máa jẹ ọba Akinghare II -  Oba Oloyede
Ifon chiefs vs Police: Iléeṣẹ́ ọlọ́pàá ní òun kò pe àwọn olóyè Ifon nítorí màálù tó kú
Oríṣun àwòrán, AFP/Getty Images
Ileeṣẹ ọlọpaa Najiria ti sọ pe awọn o ranṣẹ pe awọn oloye ilu Ifon ni ipinlẹ Ondo lati wa sọ tẹnu wọn lori iṣẹ iwadii ti awọn ọlọpaa n ṣe lasan ni.
Awọn oloye ọhun ti kọkọ ke gbajare pe ileeṣẹ ọlọpaa ranṣẹ pe awọn wa si ilu Abuja nitori maalu ọkunrin kan ti orukọ rẹ n jẹ Abdullahi.
Amọ, aṣoju ileeṣẹ ọlọpaa to ba BBC Yoruba lati ilu Abuja, DSP Ibrahim Agu ṣalaye pe ileeṣẹ ọlọpaa kan fẹ gbọ tẹnu wọn lasan ni.
Ileeṣẹ ọlọpaa ti kọkọ fi atẹjade kan jade sita pe ki Oloye Olaniyi Olotu to jẹ akọwe igbimọ awọn oloye ili Ifo, Oloye Olijewu, Saliu Omotosho, Oloye Ekon and Oluode ilu Ifon wa ni tẹnu wọn.
Ileeṣẹ ọlọpaa ni awọn fẹ fi ọrọ wa wọn lẹnu wo lori ẹsun igbimọ pọ lati huwa ọdaran, idunkoko mọ ẹmi ẹni ati igbiyanju lati jinigbe.
Nigba ti o n fesi si ọrọ naa, alukoro fun ileeṣẹ ọlọpaa nipinlẹ Ondo, Tee-Leo Ikoro rọ awọn oloye naa lati yọju sawọn ọlọpaa niluu Abuja.
Ọgbẹni Ikoro ṣalaye pe bi ileeṣẹ ọlọpaa ti ranṣẹ pe wọn ko tumọ si pe ọdarab ni wọn.
O yẹ ki wọn lọ wi tẹnu wọn lori ọrọ naa ki wọn si gbagbe rẹ.
Ọgbẹni Ikoro sọ pe ko si ohun ti awọn ọlọpaa fẹ fi wọn ṣe ju pe wọn fẹ fi ọrọ wa wọn lẹnu wo.
Awọn oloye naa tiẹ sọ pe ileeṣẹ ọlọpaa ko tii ri ohun kan ṣe lori ọrọ ọba ilu, Oba Israel Adeusi ti wọn sọ pe awọn agbebọn kan ṣeku pa.
Ṣugbọn awọn ọlọpaa n pe awọn wa si ilu Abuja lori ọrọ maalu kan to ku.
Amọ, alukoro ileeṣẹ ọlọpaa Ondo ṣalaye pe oun ko mọ ohun kan nipa iṣẹlẹ maalu to ku, o ni ọsẹ to lọ ni ọga ọlọpaa DPO ilu pe oun lori ọrọ naa.
Ikoro fidi rẹ mulẹ pe ileeṣẹ ọlọpaa si n ṣe iwadii lori iṣẹlẹ iṣekupani oba ilu Ifon.
Oba Oloyede Akinghare youngest king: SS2 ni mo wà bàyíí, kí n tó dàgbà, mo máa ṣe ǹkan gidi sí ìlú
Lati ẹnu ọna afin ni ipele ipele ati isọri isọri awọn eeyan agbaye ti n ko okiki Ọba tuntun to gori itẹ gẹ́gẹ́ bi ọdọ.
Ọba Oloyede Akinghare lo gba ade gẹgẹ bi ọba to kere julọ nilẹ Yoruba.
BBC Yoruba lọ ṣe Kaabiyesi rẹ ni aafin Ọba Oloyede nilu Okelusẹ gẹgẹ bi Ọbalayé tó kéré jùlọ nílẹ̀ Yorùbá, Oloyede Akinghare tó gbadé .
Lootọ, o ṣeeṣe ki iru eyi ti waye ri lawọn ẹya orilẹede Naijiria mii ṣugbọn ko wọpọ, nilẹ Yoruba, ipinlẹ Ondo ni Ọba to kere julọ ti kọkọ ṣẹ wa.
Oloyede Akinghare gun ori itẹ gẹgẹ bii Kabiyesi Arujale Ojima ti ilu Okelusẹ ni ijọba ibilẹ Ọsẹ, ni ipinlẹ Ondo.
Lẹyin ọdun mẹta ti baba rẹ waja lo gori itẹ.
Oríṣun àwòrán, Yetunde Olugbenga
To fi mọ awọn ọmọ ileewe rẹ lo wa tilu tifọn ti wọn n yẹ ọba wọn si.
Gẹgẹ bi ọkan lara oun ti a mubọ, Ọba Oloyede ṣi wa lẹnu ẹkọ rẹ, o ni ipo ti oun wa ko fa idiwọ kankan fun ẹkọ oun.
Oríṣun àwòrán, Oba Oloyede Akinghare
Ọlọrun maa ran wa lọwọ, nkan ti mo ba ti sọ naa ni ilu maa tẹle ti wọn maa gba bẹẹ́.
Ẹwẹ, Kabiyesi Akinghare ni ko tii si ọrọ fifẹ iyawo lọrọ oun o!
Rochas Okorocha in court: Kí ló gbé Rochas Okorocha dé ilé ẹjọ́?
Oríṣun àwòrán, BBC Igbo
Iroyin ti jade pe o ṣeeṣe ki gomina ipinlẹ Imo, Rochas Okorocha tẹlẹ foju ba ile ẹjọ.
Alukoro ọlọpaa ipinlẹ Imo, Ikeowo Orlando sọ fun BBC pe lootọ ni awọn fi panpẹ ofin Sẹnetọ Rochas ni ọjọ kọkanlelogun oṣu keji lẹyin to fi tipatipa lọ ibi dukia kan.
Okorocha to n ṣoju ẹkun Imo West nile igbimọ aṣofin agba naa ni gomina ipinlẹ ọhun laarin ọdun 2011 si 2019.
Gẹ́gẹ́ bi Orlando ṣe sọ ọ, ijọba to wa lori alefa lọwọlọwọ gbe agbegbe kan Royal Spring Palms apartment ti pa ṣugbọn wọn ni Rochas ja wọ ibẹ.
Ẹ̀jẹ̀ mi ni Damilare, ṣé ẹ lè dá abúrò mi padà fún mí? Mo ṣèlérí láti tọ́jú rẹ̀ - Mide-Funmi Martins
Fifi òfin de dída máàlù kiri kò lè dẹ́kun àawọ̀ láàrin àwọn àgbẹ̀ àti darandaran àyàfi... - Fayemi
Gẹ́gẹ́ bí àṣà, mo ti mọ̀ tipẹ́ pé mo máa jẹ ọba Akinghare II -  Oba Oloyede
Eleyi mu ki ọpọlọpọ aṣoju ijọba atawọn ọdọ ilu Owerri korajọ ti wahala si bẹ silẹ laarin igun mejeji ti ọrọ ti ṣẹlẹ.
A pe Sẹnetọ Rochas Okorocha si ileeṣẹ wa lati wa sọrọ ohun to m nipa fifi ipa ja wọ inu ọgba naa.
Ṣaaju, ijọba ipinl Imo gbe Royal Palm Estate ti pa eyi to jẹ ohun ini kan ti wọn lọ mọ Nkechi Okorocha to jẹ iyawo Sẹnetọ Rochas lẹsẹ eyi to wa ni agbegbe Akachi ni olu ilu Owerri.
Gẹgẹ bi atẹjade kan ti agbẹnusọ fun  Sẹnet Rochas fi sita, Sam Onwuemeodo sọ pe ijọba ipinlẹ Imo dari awọn janduku ati ọlọpaa lati ile ijọba lati lọ kọlu gomina tẹlẹ.
O ni wọn ba gbogbo ọkọ to n tẹle e jẹ. O tun fi kun un pe wọn kọlu awọn oluranlọwọ rẹ amọ Rochas ko awọn eeyan tirẹ lọ ja ilẹkun ti wọn si wọ ile naa.
Ẹwẹ, ijọba ipinlẹ Imo ti ni awọn ko lọwọ si iṣẹlẹ yii.
Ẹ̀yin olórin ẹ̀mí tó ń bóra, lo èékáná gígùn, oò yàtọ̀ sí aṣẹ́wó hòtẹ́ẹ̀lì tí wọ́n ń gbé bíi súùtì Pepper Menti - Bola Are
Oluranlọwọ ti gomina Uzodinma, Oguike Nwachukwu sọ pe ijọba gbe ile naa ti torii pe ẹru ole ni.
O ni nigba ti Rochas si ko awọn janduku lọ ja ilẹkun, ojuṣe ọlọpaa ni lati rii daju pe awọn eeyan tẹle ofin ilu.
Sheik Ahmad Gumi: Ẹ wo èsì tó fún iléeṣẹ́ ọmọogun Nàìjíríà lórí ẹ̀sùn kòbákùngbé
Sheik Gumi
Gbajugbaja ẹlẹsin Musulumi ati apẹtusaawọ, Sheik Ahmad Gumi ti fesi si ọrọ ti ileeṣẹ ọmọogun Naijiria fi lede lati ki i nilọ.
Sheik Ahmad Gumi lo fi lede wipe ọrọ ẹsin ati ẹlẹyamẹya ti n da rogbodiyan silẹ laarin awọn ọmọogun Naijiria.
Lẹyin to sọ ọrọ naa ni Ileeṣẹ Ọmọogun Naijiria wa fun un lesi wipe ko ṣe diẹdiẹ pẹlu awọn ọrọ to n sọ laisi eri to daju.
Amọ, ninu iforowanilẹnuwo ti ileeṣẹ BBC ṣe pẹlu Gumi lo ti ni awọn ileeṣẹ ọmọogun Naijiria ko gbọ ohun ye daradara ni, ati wipe oun ko sọ ọrọ odi si wọn.
Bí ìjọba, ọlọ́pàá, ológun, Amotekun ò bá le gbà wá, àwa mú Wakili láti gba ìran Yorùbá sílẹ̀ ni - OPC
Wakili jiyàn ọ̀rọ̀, ó ní òun kò mọ ohunkohun nípa ìṣekúpani tó ń wáyé n'Ibarapa méjèèje
Ìkúnlẹ̀ Abiyamọ ò! Báwo láwọn ọmọ kékèéké méjìla ṣé kú s'odò lẹ́ẹ̀kàn náà?
Wakili tẹẹ rí yẹn kìí ṣe ẹran rírọ̀, ó ń díbọ́n ní o - Iba Gani Adams
Gumi ni ọrọ ẹlẹsinjẹsin ti oun n sọ waye laarin ọdun 2010 si 2015 ti kii si ṣe ni isinyii mọ.
''Awọn to n ṣe akoso ileeṣẹ ọmọogun Naijiria ni igbayen ni mo n ba sọrọ kii ṣe ni isinyii''
Bakan naa ni onimọ nipa ẹsin Islam naa ni oun ni ajọsepọ to dan mọran pẹlu ileeṣẹ ọmọogun Naijiria ti ko si ede aiyede laarin wọn.
Sheik Gumi tun bu ẹnu atẹ lu awọn ileeṣẹ oniroyin ti wọn n gbe iroyin ẹlẹjẹ, ni ko jẹ ki ọrọ awọn eniyan ye ara wọn.
Ọmọogun Naijiria tẹlẹri ni Sheik Gumi ko to di wi pe o jagun fẹyinti gẹgẹ bi dokita ni ikọ ọmọogun.
Amọ, Ileeṣẹ ọmọogun Naijiria ni ko si iwa ẹlẹyamẹya tabi ẹlẹsinmẹsin ni ileeṣẹ ̣omọogun Naijiria nitori naa ki Gumi ṣọ ara ṣe pẹlu ọrọ ẹnu rẹ.
Sheik Gumi lo di ilumọọka lẹyin ti o dunadura pẹlu awọn agbebọn to ji awọn ọmọ ileewe gbe ni agbegbe Ariwa orilẹede Naijiria.
Wa wo èré èyí tó yẹ fún àárọ̀ kùtù àti èyi tó wà fún òṣúpá
Onimọ nipa ẹsin musulumi Sheikh Ahmad Gumi ti sọ pe awọn agbebọn ajinigbe ki saaba yinbọn pa eeyan.
Sheikh Gumi ṣalaye pe owo lo jẹ ki wọn maa ji awọn eeyan gbe kii ṣe nkan mii.
Sheikh Gumi tun sọ pe awọn janduku ajinigbe yii le fi awọn eeyan ti wọn ba jigbe pamọ si akata wọn titi ti wọn yoo fi ri owo gba lori wọn.
Oríṣun àwòrán, Facebook/Dr Ahmad Abubakar Mahmud Gumi
Bakan naa ni onimọ nipa ẹsin musulumi sọ pe awọn janduku ajinigbe yii gan an maa n lepa alaafia.
Sheikh ni awọn ajinigbe ṣetan lati gbe ibọn wọn silẹ ti ijọba ba le ni ifọrọwerọ pẹlu wọn.
O fikun ọrọ rẹ pe ija ẹlẹya mẹya lawọn ajinigbe Fulani ọhun ja.
Sheikh Gumi ni inu awọn Fulani darandaran ko dun si awọn eeyan yoku to wa ni igboro.
50 Year old Ajayi Folashade: Mo ti kọ́kọ́ dán an wò ní 80s àmọ́, ó kàn ṣáà ń wù mi náà ni
''Nitorinaa, bi ilu ṣe ri lo mu ki awọn eeyan di janduku ajinigbe, kii ṣe ohun ti wọn fẹ finu fẹdọ ṣe,'' Sheikh lo sọ bẹẹ.
O tun ṣalaye pe janduku ajinigbe yii ko wa lati ilẹ okeere, ọmọ orilẹede Naijiria ni wọn.
''Ohun ti mo mọ ni pe lilo awọn ologun kii ṣe ojutu si ọrọ awọn janduku agbebọn yii, ifikunlukun pẹlu wọn lo le ṣee,'' Sheikh ṣalaye.
Sheikh tun fikun ọrọ rẹ pe awọn agbebọn ajinigbe yii kii ṣe Boko Haram.
Amọ o kilọ pe ijọba ni lati wa nkan ṣe si ọrọ wọn ki Boko Haram maa le wọ ọrọ naa.
Sex benefits: Ǹjẹ́ o mọ̀ pé ìbálọ̀pọ̀ pẹ̀lú aya tàbí ọkọ rẹ lè jẹ́ kí o dàbí ọmọdé?
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Dokita onimọ sayẹnsi nipa ihuwa ẹda ati ọpọlọ eeyan kan to jẹ ọmọ orilẹede Scotland ti sọ ninu awọn iwadii to ṣe wipe nini ibalopọ gbigbona maa n jẹ ki ara eeyan da bi ara ọmọde.
Dokita David Weeks ati onkọwe nipa sayẹnsi, Jamie James ṣe ifọrọwerọ pẹlu eeyan marundinlọgọrun lorilẹede Scotland ti oju wọn kere ju ọjọ ori wọn lọ.
Dokita Weeks ati onkọwe James fẹnu ko pe ibalopọ ti wọn ti ni sẹyin ni aṣiri bi wọn ṣe kere ju ọjọ ori wọn lọ loju.
Dokita Weeks sọ ninu esi iwadii rẹ pe oju lọkọ laya to ba n ni ibalopọ lẹẹmẹta laarin ọsẹ maa fi bi ọdun mẹwaa kere ju ọjọ ori wọn lọ.
''Igbadun to wa ninu ibalopọ jẹ ọkan gbogi lara ohun to le jẹ ki eeyan kere loju ju ọjọ ori rẹ lọ,'' Dokita Weeks ṣalaye.
O ni ọpọ awọn ilumọọka ti oju wọn n dan ju ọjọ ori wọn lọ lo n gbadun ibasun pẹlu ọkọ tabi iyawo wọn.
Dokita Weeks ṣalaye pe ọpọ lọkọ laya lo n jẹ anfaani nla yii to wa ninu ibalopọ.
''Ibasun ni igbadun to gbojigan julọ, ohun lo si maa n fa wiwa awọn kẹmika kan lasiko ibasun eyi to maa n ṣe ara loore,'' Dokita Weeks lo sọ bẹẹ.
Weeks ni ṣiṣe ere idaraya lo kọkọ ṣe pataki lati jẹ ki eeyan kere ju ọjọ ori rẹ lọ, lẹyin naa lo ku ibasun.
Tóò bá fún ọkùnrinn lóúnjẹ́ tóo tẹ́ kiní yẹn sílẹ̀ fún un dáadáa... - Yinka TNT
Iwadii Dokita Weeks tun fihan pe awọn ti oju wọn ba ri bi ọmọde maa n ni igboya, ori wọn si maa n pe pere pere.
O sọ ninu iṣẹ iwadii rẹ pe awọn iwa to maa n mu kawọn eeyan tete gbo ni siga mimu, wahala ṣiṣe ati wiwa ninu oorun.
Amọ, Dokita Weeks sọ pe ibalopọ laarin lọkọ laya lo ni iru anfaani gidi yii ninu.
O ni kii ṣe awọn eeyan to ba n ni ibalopọ pẹlu irufẹ ẹnikẹni ti wọn ba kan ri nita.
Insurgency: Àdó olóró ẹgbẹ́ agbésùnmọ̀mí sekú pa èèyàn mẹ́wàá ní Maiduguri
Oríṣun àwòrán, NIGERIAN AIR FORCE HQ
Iroyin to n tẹ wa lọwọ lati ilu Maiduguri nipinlẹ Borno sọ pe ọpọ eeyan ni ẹgbẹ agbesunmọni kan ti ran lọ si ọrun alakeji lẹyin ti wọn yin ado oloro si olu-ilu ipinlẹ naa lọjọ Iṣẹgun.
O ṣoju mi koro kan sọ pe awọn ọmọkunrin mẹsan ni ado oloro ṣeku pa nibi ti wọn ti n gba bọọlu lagbegbe Gwange niluu Maiduguri.
Akọroyin kan, Ali Chiroma to n gbe ni Maiduguri naa fidi rẹ mulẹ pe eeyan mẹrin ni ado oloro pa lagbegbe oun ni Adam Kolo.
Iroyin kan tun sọ pe eeyan mẹwaa ni ado oloro ṣeku pa nibi iṣẹlẹ naa niluu Maiduguri.
''Nibi ti ado oloro sọlẹ si ko jina si ile wa, gbogbo awọn to farapa ni wọn ti ko lọ sile iwosan ẹkọṣẹ iṣegun fasiti Maiduguri, UMTH,'' Ciroma lo ṣalaye bẹẹ.
O fikun ọrọ rẹ pe agbegbe Gwange ati Adam Kolo ti ko jina si aafin Shehu ilu Borno ni iṣẹlẹ naa ti rinlẹ julọ.
'Tí mi ò bá rí ògùn rà fún ọmọ mi, á máa gé ara rẹ̀ jẹ tí ẹ̀jẹ̀ yóò máa ṣàn'
Awọn olugbe ilu Maiduguri kan sọ pe awọn agbesunmọmi naa gbiyanju lati ya wọ inu ilu naa lẹyin ti wọn yin ado oloro akọkọ.
Ṣugbọn ko ṣeeṣe fun wọn lẹyin ti wọn kọju ija si wọn.
Gomina ipinlẹ Borno, Babagana Zulum ṣe abẹwo sawọn to n gba itọju nile iwosan UMTH ni Maiduguri.
Ko si ẹgbẹ agbesumọmi to tii sọ pe awọn lo wa nidi iṣẹlẹ ọhun, amọ ilu Maiduguri ni Boko haram ti bẹrẹ.
Ibẹ si ni iroyin sọ pe wọn ti n fi ẹmi eeyan bii ẹgbẹrun mẹrindinlogoji ṣofo lati ọdun 2009 ti eeyan bi miliọnu meji si ti di alai nile lori lapa ila oorun ariwa Naijiria.
Kagara school kidnap: Onímọ̀ tako Fayemi tó ní àfi kí ìjọba má báwọn jàndùkù ajínigbé sọ̀rọ̀
Oríṣun àwòrán, Facebook/Sheikh Ahmad Gumi
Nibi ti ọrọ awọn janduku agbebọn to n ji awọn eeyan gbe kaakiri Naijiria de bayii, afaimọ ki awọn alaṣẹ ijọba ma ni ifọrọwerọ pẹlu awọn janduku ọhun.
Alaga ẹgbẹ awọn gomina ni Naijiria to tun jẹ gomina ipinlẹ Ekiti lo sọrọ yii nigba toun atawọn akẹgbẹ rẹ ṣabẹwo si Gomina Sani Bello ipinlẹ Niger lori iṣẹlẹ ijinigbe awọn akẹkọọ ileewe girama Kagara nipinlẹ naa.
Ọjọru ọjọ kẹrindinlogun oṣu keji ọdun 2021 lawọn agbebọn yabo ile ẹkọ ọhun ni ijọba ibilẹ Rafi nibi ti wọn ti ji akẹkọọ mẹtadinlọgbọn ati oṣiṣẹ ile ẹkọ naa mẹẹdogun gbe lọ.
Ninu ọrọ rẹ, Fayemi pe fun ibaṣepọ to dan mọran laarin awọn oṣiṣẹ eleto abo lati le koju awọn ipenija eto abo ni Naijiria.
Gomina Fayemi sọ pe o sẹ pataki lati wa ọna miiran lati dẹkun iṣoro eto abo lorilẹede Naijiria yatọ si ohun tawọn ileeṣẹ ologun n ṣe.
O ni idi eyi lo fi ṣe pataki lati ba awọn janduku agbebọn sọrọ lati dẹkun ijinigbe.
Fayemi ṣalaye pe ina ti jo dori koko bayii lori ọrọ eto abo to mẹhẹ, eyi lo si fi ṣe pataki lati wa gbogbo ọna ti ''a le fi yanju iṣoro eto abo ni Naijiria.''
Gomina ipinlẹ Ekiti sọ pe biba awọn janduku agbebọn yii sọrọ wa lara awọn ọna lati wa ojutu si iṣoro eto abo.
O ni lẹyin naa, o tun ṣe koko lati ṣe iwadii lori ohun to ṣe okunfa iwa ọdaran ati ijinigbe to n ṣẹlẹ kaakiri bayii.
'Tí mi ò bá rí ògùn rà fún ọmọ mi, á máa gé ara rẹ̀ jẹ tí ẹ̀jẹ̀ yóò máa ṣàn'
Gomina ipinlẹ Niger ki Fayemi ati awọn akẹgbẹ rẹ to ṣabẹwo si i, bakan naa lo sọ pe asiko ti to fun ijọba apapọ lati wa nkan ṣe si ọrọ eto abo to mẹhẹ ni Naijiria.
Ṣugbọn onimọ nipa ọrọ eto abo, Ọgbẹni Richard Amuwa sọ fun BBC Yoruba pe igbesẹ lati ba awọn janduku agbebọn sọrọ buru jai.
O ni ti ijọba ba fi le ba awọn janduku ajinigbe sọrọ, eyi yoo fawọn iru janduku bẹẹ lati ṣẹyọ lawọn orilẹede Naijiria mii.
Ọgbẹni Amuwa sọ pe ọrọ eto abo ti di nkan mii ni Naijiria bayii nitori ko si ibi ti abo wa mọ ni Naijiria.
O ni ojutu si ọrọ abo to mẹhẹ ni ọlọpaa ipinlẹ, o ni ohun to yẹ ki awọn gomina maa ja fun ni eleyi kii ṣe ifọrọwerọ pẹlu awọn janduku.
2023 elections: Àwọn lọ́balọ́ba Ekiti ní Fayemi kójú òṣùnwọ̀n láti jẹ ààrẹ Nàìjíríà lọ́dún 2023
Oríṣun àwòrán, Facebook/Kayode Fayemi
Ẹgbẹ lọbalọba ni ipinlẹ Ekiti ti buwọlu Gomina Kayode Fayemi fun idibo aarẹ ọdun 2023 ni orilẹede Naijiria.
Awọn ọba alaye ọhun fẹnu ko nibi ipade ti wọn ṣe ni Ado-Ekiti lọjọ kẹrinlelogun oṣu keji pe Fayemi lo to gbangba sun lọyẹ lati tukọ orilẹede Najiria.
Awọn ọba alaye sọ pe awọn yoo gbe igbimọ kan dide eyi ti yoo rọ Fayemi lati dije fun ipo aarẹ ninu idibo gbogbogbo ọdun 2023 ni Naijiria.
Ọkọ mi bá àwọn ọmọ wa sọ̀rọ̀ lágo kan kó tó wọ bàálù tó já, àmọ háà! - Ìyàwó Olasunkanmi Olawunmi
"Awọn lọbalọba Ekiti sọrọ yii di mimọ lẹyin ti wọn gbọrọ lẹnu ẹgbẹ kan ti akori rẹ n jẹ ""Our Belief Project"" ti Ọgbẹni Aloba Abejide ṣe agbatẹru rẹ."
Ọgbẹni Abejide lo kọkọ rọ awọn ọba alaye naa lati ba gomina ipinlẹ Ekiti sọrọ pe ko kede erongba rẹ lati dupo aarẹ lọdun 2023 ni kiakia.
Alaga awọn igbimọ lọbalọba ipinlẹ Ekiti, Alawe ti Ilawe-Ekiti, Ọba Adebanji Ajibade Alabi Afuntade Kinni sọ pe eeyan bi Fayemi ti ori rẹ pe ti o si ni okun lo le dari Naijiria bayii pẹlu oriṣiiriṣii iṣoro to n koju orilẹede yii bayii.
''Fayemi wa lara awọn to doju ija kọ awọn ologun lati rii pe Naijiria pada si ijọba awarawa.
50 Year old Ajayi Folashade: Mo ti kọ́kọ́ dán an wò ní 80s àmọ́, ó kàn ṣáà ń wù mi náà ni
Bakan naa Fayemi tun ti gboye ni fasiti lori ogun, nitorinaa oun lo le wa ojutu si eto abo to mẹhẹ ni Naijiria to ba le di aarẹ lọdunm 2023, Alawe lo sọ bẹẹ.
Oba Afuntade Kinni fikun ọrọ rẹ pe o ti to asiko ki ọmọbibi Ekiti naa jẹ aarẹ orilẹede Naijiria lẹyin ti wọn ti ran awọn ẹya mii lọwọlọwọ lati doke.
Alawe ni Sultan ilu Sokokto Abubakar S'aad ati Gomina Nasir El-Rufai ipinlẹ Kaduna gan an ti sọ tẹlẹ pe awọn ni igbagbọ ninu Fayemi.
Oba alaye naa rọ gbogbo awọn oloṣelu nipinlẹ Ekiti lati gbaruku ti Fayemi lọdun 2023.
Death penalty for rapists: Wo ìpínlẹ̀ tó ṣẹ̀ṣẹ̀ buwọ́lu ìdájọ́ ikú f'ẹ́nikẹ́ni tó fipá báàyàn lòpọ̀
Oríṣun àwòrán, AFP
Iku lere ẹṣẹ bayii fun ẹnikẹni to ba fipa baayan lopọ ni ipinlẹ Jigawa bayii.
Gomina Muhammad Badaru ipinlẹ Jigawa lo buwọlu ofin idajọ iku fun ẹnikẹni to ba fipa baayan lopọ to si tun ko arun HIV/AIDS ran an bayii.
Koda ẹni ti wọn ba fipa ba lopọ gan yoo gba ẹgbẹrun lọna ẹẹdẹgbẹta naira owo gba mabinu.
Ọkọ mi bá àwọn ọmọ wa sọ̀rọ̀ lágo kan kó tó wọ bàálù tó já, àmọ háà! - Ìyàwó Olasunkanmi Olawunmi
Ile igbimọ aṣofin ipinlẹ naa lo kọkọ gbe abadofin ọhun lọ siwaju gomina lẹyin ti gbogbo ile ti buwọlu tan an.
Nigba to n buwọlu ofin naa, Gomina Badaru lu adajọ agba to tun jẹ kọmiṣọnna eto idajọ nipinlẹ naa, Musa Aliyu ati igbimọ Ulamas lọgọ ẹnu fun aṣeyọri ofin ọhun.
Gomina ni oun buwọlu ofin naa lẹyin tawọn igbimọ Ulamas fi da oun loju pe ofin naa ko tako ofin Islam ati aṣa awọn eeyan ipinlẹ Jigawa.
Ofin Sharia ni yoo bori ti o ba da bi ẹni pe ofin tuntun yii fẹ tako ofin ẹsin Islam.
Ẹwẹ, alaga igbimọ Ulamas, Bashir-Ahmad ṣalaye pe awọn ṣe agbeyẹwo ofin tuntun naa, o si wa ni ibamu pẹlu ofin ẹsin islam.
Ọkunrin naa gbe oriyin fun gomina fun igbagbọ to ni ninu igbimọ Ulamas lati ṣiṣẹ lori ofin naa.
Ofin tuntun ọhun tun sọ pe idajọ ẹwọn gbere ni yoo maa wa fun ẹnikẹni to ba da kẹmika bi ''acid'' si ara ẹni ti wọn ba fipa ba lopọ lara.
Plane crash in Abuja: Bàbá ṣì wà, ìyá wà, ìyàwó àtàwọn ọmọ ló kúnlẹ̀ yìí
Iya to bi Olasunkanmi kẹnu bọ ọrọ toun ti omije loju. Ko si ẹni le rẹ ara wọn lẹkun ninu ile tori ati iyawo atiya, ati baba, ẹgbọn aburo to fi mọ awọn ọmọ lo n jẹ ọla pe Olasunkanmi n ṣiṣẹ nileeṣẹ ologun Naijiria.
Olootọ ti ẹ o le gbe ẹjọ ẹlẹjọ wa ba ni Olasukanmi, ọkọ mi o fawọn  ọmọ ẹ ṣere, ko fi emi gan funra mi ṣere.
Omolola Olasunkanmi to jẹ aya ọkan lara awọn ọmọ ologun to ba ijamba baalu to ja ni ẹba papakọ ofurufu Abuja bara jẹ gidi gan nigba ti BBC Yoruba ba wọn lalejo.
Oríṣun àwòrán, NAF
Iyawo rẹ ni aaro rẹ kan n ṣe awọn ọmọ ni wọn dẹ ni ki awọn pe e lori foonu.
"Ololufẹ mi, A ti fẹ gbera, baalu wa ti fẹ gbera, o ti fẹ gbera, o daa, ẹ o gunlẹ layọ o""."
Omolola ni ọrọ ti oun gbọ kẹyin lẹnu ọkọ ohun niyẹn lẹyin ti awọn de lati ṣọọṣi lọjọ naa ti iku mu u lọ.
Olasunkanmi lo n gbọ gbogbo bukata, temi ni ki n ṣa a ti tọju awọn ọmọ, ko si iṣẹ kankan ti mo n ṣe.
Kii ṣe aya nikan ni Olasunkanmi fi silẹ lọ, ọmọ ọdun mẹsan, mẹfa koda ọmọ ọdun kan ṣoṣo wa lara wọn.
Oríṣun àwòrán, NAF
Iya Olasunkanmi ṣi wa laye, oun naa bara jẹ. Iyawo ni igba ti ko ba ti si ẹni ti yoo sanwo ile ti wọn n gbe nibo ni ki oun ti bẹrẹ.
"Iyawo ni titi de owo ""Pampers ọmọ ni Olasunkanmi n fi ranṣẹ. Tori naa, iku rẹ ṣi alafo silẹ gidi gan."
Oríṣun àwòrán, NAF
Covid-19 herbal medicine: Ooni ṣe ìfilọ́lẹ̀ òògùn ìbílẹ̀ coronavirus
Oríṣun àwòrán, Ooni Palace
Bi orilẹede Naijiria ṣe ti n reti abẹrẹ ajẹsara coronavirus, Arole Oduduwa, Ooni Ile Ife, Oba Adeyeye Enitan Ogunwusi Ojaja II ti ṣe ifilọlẹ oogun ibilẹ to le gbogun ti coronavirus atawọn arun mii ninu agọ ara.
Eto naa waye ni aafin Ile Ife nipasẹ ajọ Herbal Remedies International ti Ooni jẹ alaga rẹ pẹlu ajoṣepọ gbajugbaja oniṣegun ibilẹ, Dokita Akintunde Ayeni to jẹ oludari ati alakoso ilẹeṣẹ oogun ibilẹ YEMKEM International LTD.
Awọn ti wọn ṣẹṣẹ ṣe ifilọlẹ rẹ naa ni Verozil to n gbogun ti arun karun to ba fẹ wọ agọ ara, Bitter Leaf Capsule, eyi to n ṣiṣẹ ẹjẹ ruru ati itọ ṣuga.
Awọn oogun mii ti wọn ṣẹṣẹ fi lọlẹ ni Vision Pro to n gbogun ti arun oju ati Rio Capsule eleyi to n ṣiṣẹ fun arun aile ṣe deedee ọkunrin pẹlu aya rẹ.
Nigba ti o ba awọn akọroyin sọrọ, Oba Ogunwusi sọ pe ko yẹ ki orilẹede Naijiria tun maa ko oogun wọle lati ilẹ okeere mọ pẹlu bi Eleduwa ti fi ewe ati egbo jinki wa nilẹ Afirika ati Naijiria papaa julọ.
Ooni sọ pe ajọ eleto ilera lagbaaye , WHO gan an fidi rẹ mulẹ pe orilẹede Naijiria ni awọn egbo to wulo fun ṣiṣe abẹrẹ fun wiwo ọpọlọlọpọ arun.
Ọkọ mi bá àwọn ọmọ wa sọ̀rọ̀ lágo kan kó tó wọ bàálù tó já, àmọ háà! - Ìyàwó Olasunkanmi Olawunmi
Oríṣun àwòrán, Ooni Palace
''A ko maa da eto yii ṣe lasan, inu mi dun lati sọ fun yin pe abadofin kan wa nile aṣofin agba l'Abuja bayii to da lori lilo oogun ibilẹ ni Naijiria,'' Ooni ṣalaye.
Oba Ogunwusi ṣalaye pe abadofin ọhun ni yoo maa ṣe amujoto lilo oogun ibilẹ ni Naijiria.
Ooni fikun ọrọ rẹ pe ileeṣẹ YEMKEM lo to gbangba sun lọyẹ nipa pipo oogun ibilẹ lẹyin to ti n ṣiṣẹ naa fun bii ogoji ọdun.
Oríṣun àwòrán, Ooni palace
''Lati oṣu kẹsan ọdun 2020 ni ajọ NAFDAC ti buwọlu oogun naa, ṣugbọn mo ni a gbọdọ pakeeji oogun naa daadaa ko to jade,'' Ooni lo sọ bẹẹ.
Ooni sọ pe ẹgbẹẹgbẹrun alarun coronavirus lo ti lo oogun yii ti wọn si ti ri iwosan lọwọ arun naa.
Ooni fikun ọrọ rẹ pe ohun to kan ni lati gba ẹgbẹrun lọna ọgọrun ọdọ ṣiṣẹ bayii lẹyin ti oogun naa ti jade tan.
Ẹwẹ, oludamọran agba si Aarẹ Muhammadu Buhari lori ọrọ ipese iṣẹ, Ọgbẹni Afolabi Imoukhuede to wa nibi ifilọlẹ naa gboṣuba fun Ooni fun iṣẹ takun takun to ṣe lori oogun naa.
Zamfara abduction: Ìjọba ìpínlẹ̀ Zamfara ní irọ́ ni ìròyìn tó sọ pé àwọn ti rí àwọn akẹ́kọ̀ọ́ náà padà
Oríṣun àwòrán, Reuters
Ijọba ipinlẹ Zamafara ti kede pe awọn agbebọn to ji awọn akẹkọọbinrin ile ẹkọ Government Girls Science Secondary School, Jangebe, gbe ko tii tu awọn akẹkọọ naa silẹ.
Ṣaaju ni iroyin kan ti kọkọ gbode lọsan ọjọ Aiku pe wọn ti tu awọn ọdọbinrin naa silẹ, ati pe wọn ti wa ni ikawọ ijọba.
Ninu atẹjade kan ti agbẹnusọ gomina Bello Muhammad Matawalle, Jamilu Ilyasu Magaji fi sọwọ si BBC, o ni irọ nla gbaa ni iroyin naa.
Irọ́ ni o! A kò tíì rí àwọn akẹ́kọ̀ọ́bìnrin tó lé ní 300 tí wọ́n jí gbé ní GGSS Jangebe - Ìjọba Zamfara
"Magaji ni ""lati ọjọ Ẹti ti wọn ti ji awọn akẹkọọ naa gbe, gomina ati gbogbo awọn alabaṣiṣẹ rẹ ko tii sinmi nitori akitiyan lati wa awọn akẹkọọ naa ri."""
O ṣeni laanu pe awọn kan ti ko mọ ohun to n lọ le lọ gbe iroyin jade pe a ti ṣawari awọn akẹkọọ naa.
Magaji sọ pe irufẹ iroyin ti ko ni gbongbo bayii le ṣakoba fun akitiyan awọn ẹṣọ alabo to n wa awọn ọmọ naa, ati pe o le mu ibanujẹ ọkan ba awọn obi awọn akẹkọọ ọhun.
O pari atẹjade naa pe ijọba ipinlẹ Zamfara yoo bun awọn ọmọ Naijiria gbọ ni kete ti wọn ba ti ṣawari awọn akẹkọọ ọhun.
Ǹjẹ́ ẹ mọ̀ pé ìròyìn Kayeefi akọnilẹ́nu hààà ṣẹlẹ̀ ní Ibarapa méjèèjè nígbà ìkọlù Fulani?
Lalẹ ọjọ Ẹti, iroyin jade wipe akẹkọbinrin meje ninu awọn ọọdunrun o le mtadinlogun ti awọn ajinigbe ji gbe ti bọ mọ wọn lọwọ.
Awọn araalu ti ipadabọ wọn ṣoju wọn sọfun awọn oiroyin pe wọn ti pada sinu ilu wọn funrawọn gẹgẹ bi wọn ṣe ni awọn kan dede wa ọna awọn lati pada sile nigba ti wọn n rin kiri ninu igbo aginju ti awọn ajinigbe gbe wọn lọ.
Gẹgẹ bi oṣojumikoro naa ṣe sọ, o ni awọn ọmọ naa ni awọn mii naa ti sa ti wọn yoo si to pada sile.
Lẹyin ti iroyin ijinigbe yii tan ka gbogbo agbaye ti awọn ajọ ati orilẹede agbaye si ti n da si i ti wọn ti n fi ọrọ ranṣẹ si Naijiria, gomina ipinlẹ Zamfara ti paṣẹ pe ki wọn gbe gbogbo ileewe oniyara akẹkọọ ti pa ni Zamfara.
Bakan naa ni ọlọpaa ipinlẹ naa ni awọn ti bẹrẹ igbesẹ lati ri aridaju idoola awọn akẹkọbinrin naa.
Francis Olusola Alao: Wọ́n ti ti ọ̀rọ̀ òṣèlú bọ ọ̀rs Sunday Igboho, ṣùgbọ́n..- Oba Olugbọn
Iroyin to ṣẹṣẹ n jade sita sọ pe awọn ajinigbepawo tun ti ṣọṣẹ ijinigbe ni ilu Jangebe ipinlẹ Zamfara.
Akẹkọọbinrin ni wọn tun ji gbe lọtẹ yii, wọn o si kere niye rara. Ṣaaju, iye ti wọn kọkọ sọ ni pe ọọdunrun ọmọbinrin ni wọn ti ji gbe.
Ko tii si aridaju kankan nipa awọn to ji awọn akẹkọ naa gbe bẹẹ si ni ko sẹni to mọ ibi ti wọn gbe wọn lọ.
Ẹwẹ, awọn ti ile iṣẹ iroyin BBC ba sọrọ sọ pe o daju wipe o le lọọdunrun awọn ọmọbinrin naa ti wọn jigbe nileewe ni Zamfara.
Ǹjẹ́ ẹ mọ̀ pé ìròyìn Kayeefi akọnilẹ́nu hààà ṣẹlẹ̀ ní Ibarapa méjèèjè nígbà ìkọlù Fulani?
Baba ọkan lara awọn akẹkọ naa ati olukọ ni ileewe naa sọ fun BBC pe lootọ ni o ṣẹlẹ.
Oṣojumikoro sọ nigba ti wọ́n fi ka iye awọn ọmọ ile iwe naa to ku nilẹ ni wọn ri i pe irinwo lawọn ti wọn ko ri.
Ileeṣẹ iroyin News Agency of Nigeria naa royin rẹ pe Kọmisọna eto abo nibẹ, Abubakar Dauran sọ pe ọgọgọrun awọn ọmọ ileewe ni awọn agbebọn ti ji gbe l ṣugbn ti ko sọ iye wọn pato ni tirẹ.
Eyi waye ni ko pẹ ti akitiyan ṣi n lọ lọwọ lati doola awọn akẹkọọ Kangara ti wọn ṣẹṣẹ ji gbe lọsẹ to kọja.
Ọkọ mi bá àwọn ọmọ wa sọ̀rọ̀ lágo kan kó tó wọ bàálù tó já, àmọ háà! - Ìyàwó Olasunkanmi Olawunmi
Kabiru Sani ti wọn ji aburo rẹ mẹta gbe sọ fun BBC pe awọn agbebọn naa yabo ileewe ọhun wọn si ko gbogbo awọn ẹṣọ alaabo ni papamọra ki wọn to ri awọn akẹkọọ naa gbe.
"Gẹgẹ bo ṣe sọ, ""o ju ọọdunrun le aadọrin awọn obinrin ti wọn ji gbe ti awọn ọmọbinrin naa si wa lati ipinlẹ ọtọọtọ bii Kaduna, Sokoto, Kano, Jigawa ati Kebbi""."
"Bi wọn ṣe de, wọn yi ileewe naa kaati gbogbo ibi ti wọn mọ pe awọn ẹṣọ alaabo wa wọn si kọlu ẹnu ibode ileewe, ẹṣ kan dide o si yinbọn amọ nigba to ri i pe agbara rẹ ju toun lọ, o sa lọ. Bi wọn ṣe rọna wọ yara awọn akẹkọbinrin naa ti wọn si n ji wọn ko.
PDP Reconciliation: Bukola Saraki ṣe ìpàdé pẹ̀lú gómínà Seyi Makinde, Ayo Fayose lórí ọ̀rọ̀ adarí ẹgbẹ́ PDP
Oríṣun àwòrán, Twitter/Saraki
Aarẹ ile igbimọ asofin tẹlẹri, Bukọla Saraki ti ṣe ipade pọ pẹlu gomina ipinlẹ Ekiti ati gomina ipinlẹ Oyo, Seyi Makinde lori ọna ati mu ilọsiwaju ba ẹgbẹ oṣelu PDP.
Saraki lo fi iroyin naa lede loju opo ikansiraẹni Twitter rẹ.
O ni lọna ati mu idagbasoke ba ẹgbẹ oṣelu PDP, oun ṣe ipade pẹlu Fayoṣe ni ọsẹ to kọja.
Bakan naa ni Saraki fikun wi pe ni Ọjọ Ẹti, oṣẹ yii ni oun ṣe ipade pọ pẹlu Makinde ti ipinlẹ Oyo.
O ni oun gbe igbesẹ naa lati ma a gbọ lati ẹnu awọn adari lọna ati dẹku aigbọra ẹniye ni ẹgbẹ oṣelu naa.
Oríṣun àwòrán, Twitter/Saraki
''Inu mi dun lati gbọ ọrọ lẹnu awọn alẹnulọrọ ni ẹgbẹ oṣelu PDP''
''Awọn mejeeji ni wọn ṣetan lati ri wi pe ẹgbẹ oṣelu PDP ni agbara si ni orilẹede Naijiria''
Ẹgbẹ oṣelu PDP n koju idojukọ lori ẹni ti yoo jẹ asaaju ẹgbẹ oṣelu naa saaju idibo gbogboogbo ọdun 2023.
Ni ọpọ igba ni Fayose ti kọ lati ri Seyi Makinde gẹgẹ bi asaaju ni ẹgbẹ oṣelu PDP.
Fayose ni baba isalẹ ni oun jẹ fun Makinde ninu iṣẹ oṣelu, eleyii ti Makinde kọ lati gbe ori fun un.
Ayinla Omowura: Bí ikú Ayinla Omowura ṣe mi gbogbo ìlú àti ìjọba tìtì rèé látẹnu àwọn ọmọ
Igi nla ni Ayinla Omowura lagbo awọn olorin Yoruba koda bi wọn da gbogbo olorin Naijiria pọ, Ayinla jẹ ọkan gboogi lara wọn.
Lai takurọsọ, Ayinla Omowura jẹ ọkan lara awọn ojulowo olorin ọmọ Yoruba lati igba ti orilẹede Naijiria ti gba ominira lọwọ awọn oyinbo amunisin.
Ẹwẹ, iku rẹ kii ṣe ohun ti eeyan maa n fẹ diju lati sọ toripe iroyin rẹ ba ni lọkan jẹ pupọ lo rọ mọ iku rẹ.
Awọn ọmọ ollogbe naa gba BBC Yoruba lalejo ni ile wọn nilu Abeokuta nibi ti wọn ti ṣalaye  bi iku baba wọn ṣe gba gbogbo ilu kan ati ohun ti oju wọn ri lẹyin iku baba wọn.
Ileewe ni a wa ti a ti dede gbọ iroyin pe gbogbo igboro daru ti wọn si kede konileogbele nitori  wipe Ayinla Omowura papode""."
Haruna Ayinla Omowura to jẹ ọmọ bibi inu Oloogbe, lo sọ eyi fun BBC Yoruba. O ni wọn sọ̀ fun oun ipe igo ni wọn ti gba oloogbe lori nigba ti wọn yoo si fi dele, baba ti ku.
O ti to ogoji ọdun gbako sẹyin bayii ti Ayinla Omowura ku ṣugbọn ti ohun rẹ ṣi n kan tantan leti awọn eeyan nipa ẹbun orin ti Ọlọrun tun fun ọkan lara awọn ọmọ rẹ.
Eyi lo fun Haruna Ayinla Omowura ni igboye lati sọ pe awọn to n kọ Fuji ti wọn ni Fuji ni Oba orin pe kii ṣe Apala, ko ni oye rẹ to tori Fuji naa ni wọn lee kọ wọn o le ri Apala kọ rara.
Students abduction, Kagara GSC Students: Ọ̀pọ̀ akẹ́kọ̀ọ́ láwọn ò padà lọ sílé ẹ̀kọ́ wọn mọ́ torí ohun tí ojú wọn rí lákàtà ajínigbé
Oríṣun àwòrán, Twitter/Governor Niger
Iroyin ko to amojuba lẹnu awọn akẹkọọ ile ẹkọ girama ilu Kagara nipinlẹ Niger to ṣẹṣẹ gbominira lọwọ awọn ajinigbe lọjọ Abamẹta ọjọ kẹtadinlọgbọn oṣu keji ọdun 2021.
Gomina ipinlẹ Niger, Abubakar Sani Bello lo tẹwọ gba awọn akẹkọọ atawọn oṣiṣẹ ile ẹkọ naa ti gbogbo wọn jẹ mejildinlogoji.
Ọkan lara awọn akẹkọọ naa Abubakar Sidi, ọmọ ogun ọdun to wa ni kilaasi SS3 ṣalaye pe awọn janduku ajinigbe ọhun fiya jẹ awọn nipasẹ iṣẹ ti obi ẹni kọọkan awọn n ṣe.
''Wọn ko fun wọn lounjẹ lati ago kan ọsan to fi di oru ki wọn to pada fun wa lounjẹ.
Lẹyin ti wọn fun wa lounjẹ tan, wọn bẹrẹ si ni sọ fun wa pe ki awọn ti baba wọn ba jẹ ọlọpaa ati sọja bọ sita, eyi lo maa sọ iru iya ti wọn maa fi jẹ wọn,'' Sidi ṣalaye.
Regent Ondo: Láti 1978 tí Bàbá mi ti jẹ Oba ni mo ti ms pé máà jẹ adelé- Magaret Omonije I
Akẹkọọ miran, Suleiman Lawal toun naa wa ni kilaasi SS3 ṣalaye pe ''awọn ajinigbe fiya jẹ wa debi pe n ko ro pe mo le pada si ilẹ ẹkọ wa mọ.''
Awọn akẹkọọbinrin to wa lara awọn akẹkọọ naa ko tiẹ le sọrọ rara fun ẹru to si wa lara wọn.
Oríṣun àwòrán, Twitter/Governor Niger
Ọpọ awọn obi to ba awọn akọroyin naa sọ pe awọn le maa jẹ ki awọn ọmọ awọn pada si ile ẹkọ naa mọ.
Arabinrin  Elizabeth Jonathan to jẹ ọkan lara awọn obi awọn akẹkọọ ti wọn jigbe ni oun ko le sun fun ọjọ mọkanla tawọn akẹkọọ naa fi wa lakata awọn ajinigbe.
Femi Falana, Endsars: Awolowo kò fáààyè gba kí èèyàn máa yàgò fún Màálù nígboro
''Ayọ mi kun wi pe ọmọ mi ti kuro lọwọ awọn ajinigbe, ko ni pada si ile ẹkọ naa mọ,'' Arabinrin Jonathan lo sọ bẹẹ.
Ẹwẹ, Gomina Bello ipinlẹ Niger ti kede pe ijọba n gbero lati gbe awọn ile ẹkọ tawọn akẹkọọ n sun ti pa.
Mother tongue day 2021, Akomolede, YSAN: A ti parí iṣẹ́ lórí èdè ìperí Meta-Language Yorùb
Gomina ipinlẹ Niger sọ pe gbogbo eeyan mejidinlogoji ti wọn jigbe ni wọn ti gba itọju nile iwosan.
Gomina Bello fikun ọrọ rẹ pe ọkan lara awọn akẹkọọ mẹtalelogun to ṣẹṣẹ gbomina lọwọ awọn ajinigbe si tun wa nile iwosan tori ailera rẹ.
Badagry Historical Wells: Omi inú kànga Wawú ló ń kó ọpọlọ àwọn ẹrú lọ
LGBTQI in Ghana: Ààrẹ Ghana yarí pé ìjọba òun kọ́ ní yóò buwọ́lu ìgbéyàwó akọ sákọ àti abo sábo
Oríṣun àwòrán, AFP
Aarẹ Nana Akufo-Addo orilẹede Ghana ti sọ pe ijọba oun ko ni buwọlu igbeyawo akọ sakọ ati abo sabo.
Aarẹ Akufo-Addo sọ pe ti igbeyawo akọ sakọ ati abo sabo yoo ba tiẹ waye ni Ghana, kii ṣe labẹ ijọba oun.
Aarẹ sọrọ yii nibi ayẹyẹ ifinjoye biṣọọbu keji ijọ Angilika St Michael's ati All Angel's to wa ni Asante Mampong.
''Mo ti sọ tẹlẹ, ṣugbọn mo tun fẹ sọ ọ lẹkan sii pe kii ṣe lasiko ijọba Aarẹ Nana Addo Dankwah Akufo-Addo ni agbekalẹ ofin igbeyawo akọ sakọ ati abo sabo yoo ti waye,'' Aarẹ Nana-Akufo lo sọ bẹẹ.
Aarẹ Ghana ni ọpọ eeyan ati oriṣiiriṣii ajọ lo fẹ ki ijọba oun sọrọ lori iha to kọ si igbeyawo akọ sakọ ati abo sabo.
Femi Falana, Endsars: Awolowo kò fáààyè gba kí èèyàn máa yàgò fún Màálù nígboro
Ọrọ lori bo ya ijọba yoo buwọlu igbeyawo akọ sabọ ati abo sabo lorilẹede Ghana ti n ja ran-in-ran-in lori ayelujara laarin awọn ọmọ orilẹede naa lẹni ọjọ mẹta yii.
Badagry Historical Wells: Omi inú kànga Wawú ló ń kó ọpọlọ àwọn ẹrú lọ
Ọrọ yii bẹrẹ lẹyin ti ijọgba gbe ile to da bi ọfiisi ẹgbẹ awọn akọ sakọ ati abo sabo ti wọn ṣẹṣẹ kọ ni Ghana tipa.
Mother tongue day 2021, Akomolede, YSAN: A ti parí iṣẹ́ lórí èdè ìperí Meta-Language Yorùb
Lọsẹ to lọ ni ileeṣẹ ọlọpaa yabo ile ọhun ti wọn si gbe tipa niluu Accra, eyi ti ọpọ eeyan ni Ghana koro oju si.
Oladele Ogbeyemi Albert: Irin tí mò ń lò máa ń bá mi sọ̀rọ̀ nínú ẹ̀mí kí ń tó gbẹ́ wọn sóh
Sunday Igboho: Agbejọ́rò Ozekhome ní Igboho ní láti gbàṣẹ ìdáàbòbò iléẹjọ́ káwọn ọlapáá má ba à lè mú u
Oríṣun àwòrán, Instagram/Sunday Igboho
Lẹyin ti awọn ọlọpaa gbiyanju lati fi ọwọ ofin mu ajijagbara ilẹ Yoruba, Sunday Adeyemo ti ọpọ mọ si Sunday Igboho, ọpọ eeyan ti n jade satilẹyin fun un.
Lara wọn ni gbajugbaja agbẹjọro, Mike Ozekhome (SAN) ti oun naa ti rọ Igboho lati gba aṣẹ idaabobo nile ẹjọ ki awọn ọlọpaa ma ba a le dunkooko lati fi ọwọ ofin mu un mọ.
Ozekhome sọrọ yii ninu atẹjade kan to fi sita lọjọ Abamẹta ninu eyi to ti bu ẹnu atẹ lu igbiyanju awọn agbofinro to fẹ mu Igboho niluu Ibadan.
''Igboho ni ẹtọ labẹ ofin lati beere aṣẹ idaabobo nile ẹjọ ki awọn ọlọpaa tabi awọn ẹṣọ alaabo ma le dunkoko mọ ọ mọ,'' Ozekhime lo woye bẹẹ.
''Ileẹjọ yoo fun Igboho ni iru aṣẹ bẹẹ nitori ko si ẹri to daju pe o ṣe ohun to tapa si ofin.
Agbẹjọro agba naa ni awọn agbofinro le ranṣẹ pe Igboho ti wọn ba ni ẹri to daju pe o ti ṣẹ si ofin.
Femi Falana, Endsars: Awolowo kò fáààyè gba kí èèyàn máa yàgò fún Màálù nígboro
Ẹwẹ. ẹgbẹ ọmọ Oduduwa ni ipinlẹ Minnesota lorilẹede Amẹrika ti kilọ pe eera kan ko gbọdọ rin Igboho nitori o n sọrọ tako awọn daran daran to n huwa ọdaran nilẹ Yoruba.
Aarẹ ẹgbẹ ọhun, pasitọ Goke Odujole ṣalaye pe aṣiṣe nla ni yoo jẹ ti ijọba ba fi le mu Igboho.
O ni Igboho n ṣoju awọn Yoruba ni, kii ṣe pe o n da iṣẹ ara rẹ jẹ pẹlu nkna ti o n ṣe.
Oríṣun àwòrán, Instagram/Sunday Igboho
''Ọpọ ọmọ Yoruba ni inu wọn ko dun pẹlu bi eto abo ti mẹhẹ, ti iwa ijinigbe ati ifipa banilopọ sẹ di meji eepinni nilẹ Yoruba bayii,'' alufaa Odujole lo sọ bẹẹ.
O ni ti ijọba ba le mu Igboho, ọpọ ọdọ mii to le ju Igboho lọ yoo tun dide.
Oladele Ogbeyemi Albert: Irin tí mò ń lò máa ń bá mi sọ̀rọ̀ nínú ẹ̀mí kí ń tó gbẹ́ wọn sóh
Ọgbẹni Odujole ni eto abo ti mẹhẹ debi pe awọn eeyan lo n pese abo fun ara wọn kii ṣe ijọba mọ
O rọ ijọba lati fi ọwọ ofin mu awọn to pa Olufọn ilu Ifon ati Ọmọwe Fatai Aborode ni Ibarapa nipinlẹ Oyo.
Badagry Historical Wells: Omi inú kànga Wawú ló ń kó ọpọlọ àwọn ẹrú lọ
Zamfara kidnapping: A ti bẹ̀rẹ̀ ìgbésẹ̀ ètò aà[bò míràn tó máa fi ará ìlú lọ́kàn balẹ̀- Hadi Sirika
Oríṣun àwòrán, @Sirika
Minista fun ọrọ ofurufu ni Naijiria, Hadi Sirika ti bu ẹnu ẹ̀tẹ́ lu iwa awọn agbebọn ni Naijiria.
O ni bi wọn ṣe ji awọn akẹkọọbinrin ti Jangebe yii gbe ni wọn kan fẹ fi tabuku aarẹ Buhari ati iṣẹjọba rẹ ni.
Ijọba apapọ ni Naijiria mẹnuba awọn igbesẹ akọtun lati mojuto ọrọ eto aabo ni Naijiria.
Ijọba ni oun ṣetan lati tubọ daabo bo awọn ọmọde ni pato.
Awọn igbese naa ni i ṣe pẹlu ajọsepọ pẹlu awon illeṣẹ ijọba, awọn ara ilu nibi ti iwa ibi yii pọ si, awọn akọṣẹmọṣẹ ninu eto aabo.
Bakan naa ni wọn yoo tun gbajumọ rira awọn ohun eelo ijagun, ohun eelo ikọni ati idanilẹkọ awọn oṣiṣẹ eleto aabo.
Hadi Sirika salaye eyi fun awọn akoroyin lẹyin ipade rẹ pẹlu aarẹ Muhammadu Buhari lataari abẹwo rẹ si ipinlẹ Zamfara.
Francis Olusola Alao: Wọ́n ti ti ọ̀rọ̀ òṣèlú bọ ọ̀rs Sunday Igboho, ṣùgbọ́n..- Oba Olugbọn
Lọjọ Abamẹta to kọja ni Hadi Sirika ṣaju awọn ikọ kan lọ si ipinlẹ Zamfara.
Bakan naa nijọba paṣẹ fun awọn ajọ ẹṣọ ara ilu Nigerian Security and Civil Defence Corps (NSCDC) lati tubọ ri si eto aabo awọn akẹkọọ.
Àwọn ajínigbé fìyà jẹ́ wa lọ́nà igbó tí wọ́n kó wa lọ- Akẹ́kọ̀ọ́bìnrin GSS Zamfara:
Àwọn ajínigbé ní àwọn á yìnbọn pa wá tí a kò bá tètè rín nínú igbó-Akẹ́kọ̀ọ́bìnrin GSS Zamfara
Awọn Ajinigbe fiya jẹwa lọna nigba ti wọn n gbe wa lọ si inu aginju-Akẹ́kọ̀ọ́bìnrin GSS Zamfara
Oríṣun àwòrán, @Zamfara Govt
Koda. Wọn tilẹ ni awọn yoo yinbọn pawa, ti a ko ba rin kiakia lọna igborere ọhun.
Awọn ọmọbinrin ileewe GSS Jangebe ni Zamfara lo sọ iriri wọn lọwọ awọn agbegbn to jiwọn gbe.
Awọn ọmọ yii royin ohun ti oju wọn ri to fun ijọba Zamfara lẹyin ti wọn doola ẹmi wọn.
Bakan naa ni Aarẹ Buhari ni iriri awọn ọmọbinrin to fẹrẹ tọ ọọdunrun naa kọja keremi
Ọjọ Keji, Oṣu Kẹta ni ijọba ipinlẹ Zamfara kede itusilẹ wọn lọwọ awọn ajinigbe.
Ayekofẹnifọrọ:  Ó yá, ẹ fi àmì sórí ọ̀rọ̀ náà.
A kò san owó ìtanràn kankan látí gba àwọn akẹ́kọ̀ọ́bìnrin yìí- Gomina Zamfara
Àwọn akẹ́kọ̀ọ́bìnrin ilé ẹ̀kọ́ GSS ní ìpínlẹ̀ Zamfara ti gbòmìnira lọ́wọ́ àwọn ajínígbé
Gomina ipinlẹ Zamfara, Bello Matawalle ti sọ fun BBC pe ijọba oun ko san owo itanran kankan lati gba awọn akẹkọọbinrin ti awọn ajinigbe ji gbe naa pada.
#EndSars Ogbomoso: Èmí kò ní kí wọ́n pa ọlọ́pàá tó pa Isisaka, ṣùgbọ́n...- Ramota, Iya Isi
O ni awọn kan jọ ni ajọsọpọ pẹlu awọn ajinigbe naa ni.
Bakan naa ni gomina naa fidiẹ mulẹ pe gbogbo awọn akẹkọọ naa lo ti gba ominira ati pe inu oun dun fun ominira awọn ọmọbinrin 279 naa.
Akomolede àti Aṣa:  Olùkọ́ Olajide láti Ẹdẹ ló ṣàlàyé nípa Awẹ́ Gbólóhùn fún wa ní kíkún
Gẹgẹ bi o ti hande pe awọn alaṣẹ orilẹ-ede Naijiria kii gba lọpọ igba pe wọn san owo itanran fun awọn ajinigbe.
Lọjọ Eti to kọja ni awọn agbebọn kọlu ile ẹkọ GSS Jangebe lati ṣọṣẹ yii.
Oríṣun àwòrán, Twitter
Àwọn akẹ́kọ̀ọ́bìnrin 279 ti ilé ẹ̀kọ́ GSS ní ìpínlẹ̀ Zamfara ti gbòmìnira lọ́wọ́ àwọn ajínígbé
Awọn akẹkọọbinrin ti wọn jigbe ni agbegbe Jangebe ni ipinlẹ Zamfara ni wọn ti gba ominira bayii
Kọmiṣọnna fun eto aabo abẹle ni ipinle Zamfara fidiẹ mulẹ fun BBC.
Femi Falana, Endsars: Awolowo kò fáààyè gba kí èèyàn máa yàgò fún Màálù nígboro
O ni awọn akẹkọbinrin 279 to jẹ ọkan dinlọgọrin o le ni igba ni awọn ti ri gba pada bayii.
Koda awọn akẹkọbinrin naa ti wa ni Gusau to jẹ olu ilu ipinlẹ Zamfara.
Olusegun Obasanjo: Ọmú ìyá mi ti mo fi ń mùkọ ni kekere ló jẹ ki ń lókun
Kọmisọnna ọrọ abẹlẹ naa tun fidiẹ mulẹ fun BBC pe kii ṣe ọmọ 317 to jẹ mẹtadinlogun le ni ọọdunrun ti wọn kọkọ ni awọn ajinigbe gbe ni wọn ji gbe.
O ni ko si ọmọbinrin kankan mọ ni akata awọn ajinigbe naa mọ.
O ni gomina yoo ba wọn sọrọ laarọ oni.
Mother tongue day 2021, Akomolede, YSAN: A ti parí iṣẹ́ lórí èdè ìperí Meta-Language Yorùb
Lọjọ Eti ni wọn ji awọn ọmọ naa gbe ni agbegbe Jangebe ni ipinlẹ Zamfara to wa ni ariwa Naijiria.
A ko le fidiẹ mulẹ boya wọn san owo itanran tabi bẹẹkọ.
BBC Yoruba yoo maa mu ẹkunrẹrẹ iroyin ọhun wa fun un yin bo ba ṣe n lọ....
Coronavirus after one year in Nigeria: Níbo ni ọ̀rọ̀ Covid 19 dé dúró ní Nàìjíríà?
Divorce case: Ọkùnrin kan sọ fún iléẹjọ́ láti tú ìgbéyàwó rẹ̀ ká, torí ìyàwó rẹ̀ máa ń gbá a létí
Oríṣun àwòrán, AFP
Ọkunrin kan to jẹ oṣiṣẹ ijọba, Ọgbẹni Oyeniyi Oyedepo sọ fun ileẹjọ agbegbe to wa ni Mapo niluu Ibadan pe ki wọn tu igbeyawo ọdun mẹrinla laarin oun ati iyawo oun ka.
Idi abajọ ni pe Ọgbẹni Oyedepo ṣalaye fun ileẹjọ pe niṣe ni iyawo oun, Iyabo ma n digbaju ru oun nigba kugba toun ba ti ba awọn ọmọ mẹrin ti Eledua fi jinki awọn wi.
''Iyabo ti da igbeyawo ru pata pata, alaigbọran obinrin ni, bẹẹ ni ko si bọwọ fun mi rara,'' Oyedepo lo sọ bẹẹ.
Iyawo rẹ naa to jẹ oniṣowo ni faramọ wi pe ki ileẹjọ tu igbeyawo awọn ka.
Iyabo ni onidọti n ọkọ oun, kii tun ara ṣe lẹyin to ba tọju awọn ẹranko to n sin tan ninu ile.
Femi Falana, Endsars: Awolowo kò fáààyè gba kí èèyàn máa yàgò fún Màálù nígboro
''Otitọ ni mo gba eti ẹ ṣugbọn nitori o lu mi, o si ni ki n kuro nile oun ni mo fi ṣe bẹẹ,'' Iyabo ṣalaye.
Iyabo fikun ọrọ rẹ pe Oyedepo tun n ṣe ṣina, nitori naa oun ko ni ifẹ rẹ mọ.
Badagry Historical Wells: Omi inú kànga Wawú ló ń kó ọpọlọ àwọn ẹrú lọ
Aarẹ ileẹjọ ọhun, Oloye Ademola Odunade woye pe igbeyawo naa si le duro tawọn mejeeji ba ni suuru.
Aarẹ Odunade ranṣẹ pe awọn ẹbi ọkọ ati iyawo lati da si ọrọ naa.
Mother tongue day 2021, Akomolede, YSAN: A ti parí iṣẹ́ lórí èdè ìperí Meta-Language Yorùb
Ileẹjọ ti sun igbẹjọ naa siwaju di ọjọ kẹrindinlogun, oṣu kẹrin, ọdun 2021 yii.
Regent Ondo: Láti 1978 tí Bàbá mi ti jẹ Oba ni mo ti ms pé máà jẹ adelé- Magaret Omonije I
Ondo Nurses'strike: Nítorí 'áfúsá', àwọn nọ́ọ̀sì bẹ̀rẹ̀ ìyanṣẹ́lódì l'Ondo gba àsanpé owó oṣù wọn
Oríṣun àwòrán, thenewstrack.com.ng
Awọn nọọsi ati oṣiṣẹ agbẹbi ni ipinlẹ Ondo ti bẹrẹ iyanṣẹlodi onikilọ ọlọjọ mẹta lati fi fa ijọba ipinlẹ naa leti lori sisan abọ owo osu fawọn.
Ẹgbẹ awọn nọọsi ati agbẹbi lorilẹ-ede Naijiria, (NANNM) ẹka ti ipinlẹ Ondo bẹrẹ iyanṣẹlodi lọjọ Aje, ọjọ kinni, oṣu kẹta, ọdun 2021.
Gẹgẹ bi ohun tawọn igbimọ adari ẹgbẹ naa fi sita pe awọn n ja fun, sisa asanpe owo oṣu wọn dipo aabọ eyi ti gomina ipinlẹ naa ni ki wọn maa san fawọn oṣiṣẹ pẹlu bibẹrẹ ilana owo osu tuntun fawọn nọọsi lẹka nijọba ibilẹ wa lara ohun ti wọn n beere fun.
Francis Olusola Alao: Wọ́n ti ti ọ̀rọ̀ òṣèlú bọ ọ̀rs Sunday Igboho, ṣùgbọ́n..- Oba Olugbọn
Ṣaaju ni awọn ọmọ ẹgbẹ oṣiṣẹ nọọsi ati agbẹbi naa ti kọkọ fun ijọba ni gbendeke ojọ meje lati fi yanju ibeere wọn naa ṣugbọn ti ko si igbesẹ to yanranti latọdọ ijọba.
Femi Falana, Endsars: Awolowo kò fáààyè gba kí èèyàn máa yàgò fún Màálù nígboro
Lasiko ti BBC News Yoruba gbiyanju ati kan si alaga ẹgbẹ naa ni ipinlẹ Ondo, ohun ti a gbọ ni pe ijọba atawọn ẹgbẹ oṣiṣẹ lẹka ilera wa ninu ipade kan eleyi ti ko ṣai nii ṣe pẹlu rukerudo iyanṣẹlodi lẹka ilera ni ipinlẹ Ondo.
Mother tongue day 2021, Akomolede, YSAN: A ti parí iṣẹ́ lórí èdè ìperí Meta-Language Yorùb
Sunday Igboho: Àwọn ọmọ ogun, ọ̀tẹlẹ̀múyẹ́ DSS àtawọn òṣìṣẹ́ NSCDC ló dá mi lọ́nà
Oríṣun àwòrán, sundayigbohonews
Oloye Sunday Adeyemo, ti ọpọ mọ si Sunday Igboho ti sọ pe igbiyanju ajọ ọtẹlẹmuyẹ ijọba apapọ, DSS, lati mu ohun ni ọna marose Ibadan si Eko jẹ akitiyan lati pa ohun.
Ajijagbara naa ni oun bọ asọ oun lẹyin ti ọkan lara awọn ọtẹmuyẹ naa lọ aṣo naa mọ oun lọrun.
Igboho lo ṣi aṣọ loju eegun ọrọ naa ninu ifọrọwerọ kan pẹlu ọgbẹni Reuben Abati lori eto kan lori redio.
"O ṣalaye pe ""idi ti mo ṣe bọ aṣo mi ni pe ọkan lara awọn DSS yẹn di aṣo naa mu, mo si bọ, ti mo si fi le lọwọ."""
Wọn bẹrẹ si n yinbọn nigba ti a bẹrẹ si n fa ọrọ naa, koda ohun itiju ni gbogbo ohun to ṣẹlẹ yẹn jẹ fun mi.
Oríṣun àwòrán, Oyo insight
Igboho tẹsiwaju pe ẹni iyi ni oun, ọmọ Yoruba si ni oun pẹlu, o ni ẹtọ awọn ọmọ Yoruba ni oun n ja fun, nitori naa ko yẹn ki wọn wu iru iwa bẹẹ si oun.
Francis Olusola Alao: Wọ́n ti ti ọ̀rọ̀ òṣèlú bọ ọ̀rs Sunday Igboho, ṣùgbọ́n..- Oba Olugbọn
"Sunday Igboho ni ""Oniṣowo ni mi mo si n san owo ori fun ijọba loorekoore, ṣe o bojumu ki n maa lọ laarin igboro ki awọn kan si gbiyanju lati pa mi?"
Fun kinni? Kilode ti wọn ṣe fẹ gbẹmi mi?
Ajafẹọmọniyan naa sọ siwaju si pe eto abo Naijiria ti mẹhẹ nitori bi awọn ọdaran darandaran ṣe n pa awọn eeyan ti wọn si n fi ipa ba awọn obinrin lajọṣepọ ṣugbọn ijọba ko ri nnkankan ṣe si.
O ni kaka ki ijọba da seria fun apaayan atawọn ajinigbe ni Naijiria, ni ṣe lo n fun wọn lowo to si n dun mọhurumọhuru mọ awọn awọn eeyan ilu ti ko ṣẹ.
Igboho ni akojọpọ awọn ọmọ ogun, ikọ ọtẹlẹmuyẹ DSS atawọn ẹṣọ NSCDC lo gbiyanju lati mu oun, to ko si ọlọpaa ninu wọn.
Bo tilẹ jẹ ajọ DSS ti sọ pe awọn ko mọwọ mẹsẹ ninu ẹsun ti Igboho fi kan awọn, ọpọ awọn ọmọ Naijiria bii ẹgbẹ Afẹnifẹre ati ati agba ọjẹ ninu imọ ofin, Femi Falana lo ti bu ẹnu ẹtẹ lu igbeṣẹ naa.
Okiki Sunday igboho milẹ titi kaakiri agbaye ni ibẹrẹ ọdun yii lẹyin to fun awọn Fulani kan ni gbedeke ọjọ meje lati fi ilu Igangan silẹ lẹyin ti ọpọ eeyan ti fi ẹsun ipaniyan ati ijinigbe kan wọn.
Femi Falana, Endsars: Awolowo kò fáààyè gba kí èèyàn máa yàgò fún Màálù nígboro
Prof Edwin Ijeoma: Ọ̀jọ̀gbọ́n Ijeoma ní òun kìí ṣeọmọ Nàìjíríà mọ́, South Africa tó yàn dípò bá tún lée jáde
Oríṣun àwòrán, Premium times
Ọjọgbọn ọmọ Naijiria kan ti oruks rẹ n jẹ Edwin Ijeoma kọ ipakọ si orilẹede Naijiria lọdun 1998 pẹlu ileri pe oun kii ṣe ọmọ orilẹ-ede Naijiria mọ,o si gba iwe ọmọ onilẹ ti orilẹede South Africa.
Amọṣa, nnkan ti ba ibomiran yọ fun bayii ti ọrọ rẹ si ti di ti ko gbele ko gbeta bii ti ilẹkun aganrandi.
Orilẹede South Africa to gba gẹgẹ bi orilẹede rẹ ti lee jade bayii, wọn si ti fa iwe ijọmọonilẹ rẹ ya.
Ẹsun ti wọn fi kan an ni pe o se igbeyawo alarede pẹlu obinrin ọmọ orilẹ-ede South Africa kan nigba to mọ pe oun ni iyawo alarede miran.
Gẹgẹ bi awọn iwe iroyin abẹle kan ni orilẹ-ede naa ṣe sọ, ọdun 1998 ni Ọjọgbọn Ijeoma de sorilẹ-ede South Africa lati Naijiria lati kẹkẹ ni fasiti Pretoria.
Wọn ni ọgbọn ẹwẹ ṣiṣe igbeyawo alarede pẹlu obinrin kan lorilẹ-ede naa lo fi gba iwe igbelu ati ijọmọ onilẹ to gba.
Akomolede àti Aṣa:  Olùkọ́ Olajide láti Ẹdẹ ló ṣàlàyé nípa Awẹ́ Gbólóhùn fún wa ní kíkún
Ni ọdun 2005 lo di ọmọ onilẹ ki o to kọ iyawo rẹ to jẹ ọmọ orilẹede South Africa silẹ lọdun 2007 nitori aile bimọ wọn.
Lẹyin eyi ni wọn ni obinrin kan ti orukọ rẹ n jẹ Anne Tomo darapọ mọ lorilẹ-ede South Africa.
Femi Falana, Endsars: Awolowo kò fáààyè gba kí èèyàn máa yàgò fún Màálù nígboro
Wọn si ṣakiyesi ninu ọkan lara awọn iwe ti arabinrin naa fi ṣọwọ si ileeṣẹ ijọba orilẹ-ede naa lori ọrọ iwe igbelu fihan pe oun ati ọjọgbọn naa ti ṣe igbeyawo lọdun 1993.
Eleyii to mu ki ileeṣẹ ijọba orilẹede naa o fidi rẹ mulẹ pe o ṣe igbeyawo alarede pẹlu obinrin meji ọtọọtọ.
Oríṣun àwòrán, facebook/ ijeoma edwin
Wọn ni nigba ti wọn bi Ọjọgbọn Edwin Ijeoma leere nigba to n beere fun iwe ijọmọ onilẹ lorilẹ-ede naa pe ṣe o ni mọlẹbi kankan lorilẹ-ede Naijiria, ohun to sọ ni pe aburo oun ni Anne Ijeoma, kii ṣe iyawo.
Awọn alaṣẹ lorilẹorilẹ-ede South Africa woye pe ọgbọn ati gba iwe igbelu ati ọmọ onilẹ ni Ọjọgbọn Ijeoma da to fi gbe ọmọ ilẹ South Africa to kọ silẹ niyawo.
Regent Ondo: Láti 1978 tí Bàbá mi ti jẹ Oba ni mo ti ms pé máà jẹ adelé- Magaret Omonije I
Nibayii, wọn ti fa iwe igbelu ati iwe ọmọ onilẹ rẹ ya.
Ẹwẹ fasiti Fort Hare nibi ti Ọjọgbọn Edwin Ijeoma ti n ṣiṣẹ ni lati ọdun to kọja ni wọn ti paṣẹ ko lọ rọọkun nile fun awọn iwa aṣemaṣe kan to hu.
Francis Olusola Alao: Wọ́n ti ti ọ̀rọ̀ òṣèlú bọ ọ̀rs Sunday Igboho, ṣùgbọ́n..- Oba Olugbọn
Agbẹnusọ fun fasiti naa, Tandi Maputa ṣalaye fun Premium Times pe ọjọ kẹrindinlogun, oṣu kẹwaa, ọdun 2020 ni wọn ti ni ko lọ rọọkun nile.
Ati pe iwadii lori iwa aitọ to hu naa ṣi n lọ ati pe o kan ṣe kongẹ asiko ti ọbẹ ileeṣẹ ọrọ abẹle lorilẹede naa baa niru ni.
Bola Tinubu: BolaTinubu kò tíì rí ìwé ìpè gbà látọ̀dọ̀ EFCC lórí dúkìá rẹ̀
Oríṣun àwòrán, Pm parrot
Tinubu ko ṣe nnkan etufu to lee maa kiyesi sẹyinkule si lori ọrọ ajọ EFCC ti wọn ni o fẹ wa gbe.
Ọrọ yii ni ọkan lara awọn itẹlẹ idi rẹ ti ko lee rii ti ṣalaye fun BBC News Yoruba nigba ti a pe lati beere ohun to bayiwa pẹlu iroyin to n kaakiri pe awsn oṣiṣẹ ajọ EFCC ti n gbradi lati fi panpaẹ ofin gbe agba oṣelu lẹgbẹ oṣelu APC naa.
Iroyin to n lọ kaakiri ni pe ajọ EFCC tun ti n gbero lati tun iwadii ṣe lori dukia agba oṣelu naa.
Ohun ti iroyin abẹle n sọ ni pe ajọ EFCC tun ti tun iwe kọ si ajọ to n ṣeto dukia awsn to dipo ilu mu, CCB pe ko fi iwe akọsilẹ dukia Asiwaju Bọla Tinubu ranṣẹ si wọn.
Ohun ti a gbọ lati igun oloye Tinubu ni pe iroyin to n lọ kaakiri naa ṣe awọn naa ni kayeefi nitori pe awọn gan ko tii ri iwe ipe tabi ohunkohun to jọ mọ ajọ EFCC gba.
Wọn ni ohun ti awọn eeyan n ri loju ewe iroyin lawọn naa n ri bayii.
Wọn ni ko tii si ẹnikẹni to kan si Aṣiwaju Bola Ahmed Tinubu lori ohunkohun latọdọ tabi nipa EFCC.
No-fly zone: Garba Shehu ṣàlàyé ìdí tí Aàrẹ Buhari ṣe kéde pé kí ọkọ̀ òfurufú má fò ní Zamfara mọ́
Oríṣun àwòrán, others
Lọjọ Iṣẹgun ni aarẹ Muhammadu Buhari kede pe ki ọkọ ofurufu ma fo mọ lori afẹfẹ ni ipinlẹ Zamfara.
O ni oun gbe igbesẹ yii lati mojuto eto aabo ẹkun naa.
Francis Olusola Alao: Wọ́n ti ti ọ̀rọ̀ òṣèlú bọ ọ̀rs Sunday Igboho, ṣùgbọ́n..- Oba Olugbọn
"Kini itumọ 'No-Fly Zone"" ?"
Eyi ni ikede nipa agbegbe kan ti ijọba ma paṣẹ waa le lori pe wọn ko ni le fo lori rẹ.
Eyi ja si pe ọkọ ofurufu kankan ko ni le gba ibẹ koja ni igba gbendeke asiko naa.
Awọn ologun lo maa n ni agbara lori irufẹ agbegbe bayii.
Wọn ko ni faaye gba gbogbo ọkọ ofurufu yoowu ko jẹ lati fo nibẹ.
Iru agbegbe yii maa n saaba jẹ nigba ogun tabi ti ilu tabi agbegbe naa ko ba fararọ.
Garba Shehu ṣàlàyé ìdí tí Aàrẹ Buhari ṣe kéde pé kí ọkọ̀ òfurufú má fò ní Zamfara mọ́
Olubadamọran si aarẹ Buhari lori eto iroyin, Garba Shehu ti ṣalaye idi ti Buhari fi kede pe ọkọ ofurufu ko gbọdọ fo mọ ni Zamfara.
O ni ọpọlọpọ ọkọ ofurufu aladani ni awọn kan fi maa n ko ẹru iwakusa kuro ni agbegbe yii.
Olusegun Obasanjo: Ọmú ìyá mi ti mo fi ń mùkọ ni kekere ló jẹ ki ń lókun
Koda, O ni wọn n lo ọkọ ofurufu wọnyii lati fi ko nkan ogun ati ohun eelo iṣọṣẹ bii ibọn.
Garba Shehu tun ni wọn n fi ọkọ ofurufu aladani yii ti wọn tun fi n ji goolu ko lọ si Dubai lati ipinlẹ Zamfara.
Se iru rẹ ti ṣẹlẹ ri ni Naijiria?
Saaju asiko yii ni Olubadamọran fun eto aabo ni Naijiria nigba kan ri, Ogagun agba to ti fẹyinti Babagana Monguro kede iru ikede yii.
O ni eyi ko ṣẹyin alami ti ijọba igba naa gbọ alami pe awọn kan fẹ ṣọṣẹ ni eyi ti wọn fi kede nigba naa.
Akomolede àti Aṣa:  Olùkọ́ Olajide láti Ẹdẹ ló ṣàlàyé nípa Awẹ́ Gbólóhùn fún wa ní kíkún
Lọdun 2017 ni Baba=gana Munguno kede pe ọkọ ofurufu kankan ko gbọdọ fo kọja ni Abuja nigba naa.
Koda, o tun ti ilekun papakọ ofurufu Abuja nigba naa pa.
Oríṣun àwòrán, @Presidency
Kò sí ìwakùsà àti ìrìnàjò ọkọ̀ òfurufú mọ́ ní ìpínlẹ̀ Zamfara- Aàrẹ Buhari
Aarẹ Muhammadu Buhari ti fofin de irinajo ọkọ ofurufu ni ipinlẹ Zamfara nitori ipo ti eto abo ipinlẹ naa wa lasiko yii.
Oríṣun àwòrán, Nig Govt
Bẹẹ naa ni Aarẹ Buhari tun gbẹsẹle gbogbo ohun to jọ mọ iwakusa ni ipinlẹ ọhun.
Olubadamọran fu Aarẹ lori eto abo, ajagunfẹyinti Babagana Monguno lo fin ọrọ naa lede lẹyij ipade awọn adari ijọba to waye nile ijọba apapọ niluu Abuja.
Eyii n tumọ si pe baalu ileeṣẹ awọn ọmọ ogun nikan lo lẹtọ labẹ ofin lati fo ni ofurufu ipijlẹ naa.
Ọgagun Monguno sọ pe oju awọn wa lara gbogbo awọn ti kii ṣe oṣiṣẹ ologun nipinlẹ naa, ati pe gbogbo ohun ti yoo gba ni awọn yoo fun ki alaafia le pada si agbegbe naa.
#EndSars Ogbomoso: Èmí kò ní kí wọ́n pa ọlọ́pàá tó pa Isisaka, ṣùgbọ́n...- Ramota, Iya Isi
O sọ siwaju si pe gbogbo awọn ileeṣẹ ijọba apapọ to n ṣiṣẹ ifimufinlẹ lo ti gbaradi lati ri pe awọn kọlọrọsi kankan ko sọ Naijiria sinu idamu.
Gẹgẹ bo ṣe sọ, Aarẹ Muhammadu Buhari ti paṣẹ fun awọn ọga agba ileeṣẹ ọmọ ogun lati gba iṣakoso gbogbo awọn agbegbe ti awọn oniṣẹ ibi ti n ṣọṣẹ.
Oríṣun àwòrán, Bashir ahmad/twitter
Àwọn aṣòfin àgbà buwọ́lu orúkọ àwọn olórí ológun tuntun
Service chiefs: Àwọn aṣòfin àgbà buwọ́lu orúkọ àwọn olórí ológun tuntun
Ileegbimọ aṣofin agba lorilẹede Naijiria ti buwọlu orukọ awọn ọga agba ileeṣẹ ologun tuntun ni Naijiria.
Wọn buwọlu orukọ wọn lẹyin ti igbimọ tẹẹkoto nile naa gbe wọn kalẹ pe wọn ti wẹ yan kainkain lati jẹ aṣaaju fun awọn ẹka ileeṣẹ ọmọ ogun lorilẹede Naijiria.
Ni Ọjọru to kọja ni aarẹ ile naa, Sẹnetọ Ahmad Lawan gbe iwe ti aarẹ kọ lati fi orukọ wọn ṣọwọ si awọn aṣofin agba ka iwaju ile naa to si fun igbimọ tẹẹkoto lori aabo ni ile naa ni gbendeke ọsẹ meji lati fi ṣe ayẹwo wọn fun igbọwọle.
Regent Ondo: Láti 1978 tí Bàbá mi ti jẹ Oba ni mo ti ms pé máà jẹ adelé- Magaret Omonije I
Awọn olori ileeṣẹ ologun tuntun naa niwọnyii:
Ọgagun agba (Major General) Lucky Eluonye Onyenuchea lrabor - Ọgagun agba patapata
Ọgagun agba (Major General) Ibrahim Attahiru - Olori ileeṣẹ ọmọogun oriilẹ.
Femi Falana, Endsars: Awolowo kò fáààyè gba kí èèyàn máa yàgò fún Màálù nígboro
Ọgagun agba oju omi (Rear Admiral) Awwal Zubairu Gambo- Olori ileeṣẹ ọmọogun ojuomi.
Ọgagun agba ofurufu (Air Vice Marshal) Isiaka O. Amao- Olori ileeṣẹ ọmọogun ofurufu.
Sẹnetọ Lawan to jẹ aarẹ ile aṣofin agba ke sawọn olori ileeṣẹ ologun naa lati tubo kara masiki gbigbogun ti igbesunmọmi ki wọn si jẹ awọn ibuba wọn run.
Chimamanda Adichie: Bábá, ìyá Chimaamanda Adichie jáde láyé láàrín ọdún kan, kíló ṣẹlẹ̀?
Oríṣun àwòrán, Google
Chimamanda Ngozi Adichie n ṣe daro awọn obi rẹ ti wn jade laye laarin ọdun kan.
Oṣu Kẹfa, ọdun 2020 ni baba rẹ, James Adichie jade laye lẹni ọdun mẹtadinladọrun ni ileewosan to ti n gba itọju lẹyin to ṣe aisan.
Bakan naa ni iya rẹ, ẹni ọdun mẹjidinlọgọrin naa fi aye silẹ lairotẹlẹ ni Ọjọ Kini, Oṣu Kẹta, ọdun 2021, lẹyin oṣu mẹsan ti ọkọ rẹ fi ayẹ silẹ.
Oríṣun àwòrán, Instagram/ChimamandaAdichie
Awọn ẹbi naa n ṣedaro iya ọmọ naa ati ọkọ rẹ to fi aye silẹ.
Awọn ọmọ Adichie to gbẹyin baba ati iya wọn ni Ijeoma, Uchenna, Chuks, Okechukwu, Chimamanda ati Kenechukwu pẹlu ọpọlọpọ ọmọ-ọmọ.
Amọ awọn ẹbi ko i tii sọ igba ti wọn yoo sin iya ọmọ to papoda naa.
Chimamanda Adichie jẹ ọkan lara awọn onkowe gboogi lati ilẹ Afrika to si jẹ ẹya Igbo, lorilẹede Naijiria.
Ajafẹtọ ọmọbinrin ni Adichie, to si ti gba ami ẹyẹ lọpọlọpọ fun iṣẹ ribiribi ti iwe rẹ n ṣe ni awujọ.
Ọmọ ipinlẹ Anambra ni,amọ ti wọn bi si ilu Enugu.
Akomolede ati Asa lori BBC: Olùkọ́ Kikelomo  Ogunboye tan ìmalẹ̀ sí ìwà olè ọ̀gá ọlọ́pàá
Baba Adichie lo gbe ile ogbajugbaja onkọwe, Chinua Achebe pẹlu awọn ọmọ rẹ mẹfa.
Awọn eniyan tilẹ sọ wi pe o ṣeeṣẹ ki ifẹ Chimamanda fun iwe ati iṣẹ rẹ gẹgẹ bi onkọwe niiṣe pẹlu ile Achebe ti wọn gbe naa.
Francis Olusola Alao: Wọ́n ti ti ọ̀rọ̀ òṣèlú bọ ọ̀rs Sunday Igboho, ṣùgbọ́n..- Oba Olugbọn
Nigerian Labour Congress: Ewú ńbẹ! tí ìjọba ìpínlẹ̀ bá sàkóso gbèndéke owó oṣù òṣìṣẹ́,wọ́n ò ní san N30,000, N10,000 ní wọ́n má á san
Ẹgbẹ awọn oṣiṣẹ ni Naijiria ti ni awọn yoo bẹrẹ ifẹhọnu tako igbese awọn asofin lati gbe aṣẹ gbedeke owo oṣu oṣiṣẹ kuro ni ọdọ ijọpa apapọ lọ si abẹ aṣẹ ipinlẹ.
Eyi ko ṣẹyin abadofin ti ile aṣofin n da aba lati gbe aṣẹ kuro ni abẹ ijọba apapọ lọ si abẹ aṣẹ ijọba ipinlẹ wọn, ti wọn n pe ni ''Exclusive List to Concurrent List''.
Alaga ẹgbẹ awọn oṣiṣẹ, Ayuba Wabba ni iwa ijẹkujẹ awọn oloṣelu lo mu ki wọn fẹ fi iya jẹ awọn oṣiṣẹ ni Naijiria.
Wabba ni awọn ijọba ipinlẹ yoo san owo perete fun awọn oṣiṣẹ wọn ti wọn ba gba wọn laaye lati ma a san owo oṣu oṣiṣẹ.
''Abẹ ofin agbaye ni o wa wi pe ijọba apapọ ni yoo ma a ṣeto gbendeke owo osu awọn oṣiṣẹ kii ṣe ijọba ipinlẹ''
#EndSars Ogbomoso: Èmí kò ní kí wọ́n pa ọlọ́pàá tó pa Isisaka, ṣùgbọ́n...- Ramota, Iya Isi
'Wabba ni: 'Nitori naa, a ko ni gba ki awọn aṣofin rẹ wa jẹ nitori iwa ijẹkujẹ ati ifiyajẹ ara ilu ti wọn ma n ṣe''
''Labẹ ofin Naijiria, owo kan naa ni awọn oloṣelu ti wọn n yan si ipọ n gba lai wo ọrọ ajẹ tabi awọn alakalẹ miran''
Olusegun Obasanjo: Ọmú ìyá mi ti mo fi ń mùkọ ni kekere ló jẹ ki ń lókun
Ni afikun, adari ajọ naa ni: ''Kilode to wa jẹ ọrọ awọn oṣiṣẹ to yẹ ko pọn dandan fun wọn ni wọn yoo wa ma a dinku''
''Nitori ti a ba fi awọn ipinlẹ silẹ ki wọn ma a pa aṣẹ lori gbendeke owo osu oṣiṣẹ, awọn miran ko ni san 30,000 naira gẹgẹ bi gbendeke, 10,000 naira ni wọn yoo maa san.''
Wabba ni: ''Nitori naa ni a gbọdọ tako abadofin naa nitori ipinya ni wọn fẹ mu ba awọn oṣiṣẹ, bi awọn oṣelu ṣe n pin awọn eniyan nipa ẹsin ati ẹya ni Naijiria''
Bakan naa ni Alaga ẹgbẹ awọn oṣiṣẹ, Ayuba fikun wi pe ni Ọjọọru, ọṣẹ to n bọ ni awọn yoo bẹrẹ ifẹhọnuhan kaakiri awọn ipinlẹ ni orilẹ-ede Naijiria ni awọn ile aṣofin kaakiri Niajiria ati ile Asofin ni ilu Abuja.
Akomolede àti Aṣa:  Olùkọ́ Olajide láti Ẹdẹ ló ṣàlàyé nípa Awẹ́ Gbólóhùn fún wa ní kíkún
Omoyele Sowore: Ìpakájà, Ìrọ́kẹ́, Ode àti àwọn ǹkan míràn tó fọnrere òòtọ́ inú Babaláwo- Fagbenle Adedayo, Agesin Adimula Ila Orangun
Oríṣun àwòrán, The guradian Nigeria
Bí ẹ ṣe lè dá babaláwo tòótọ́ àti òfégè mọ̀ rèé
Ẹ̀yin tí ẹ ń pariwo babaláwo tẹ̀lé Sowore lọ sílé ẹjọ́, bí ẹ ṣe lè dá babaláwo mọ̀ rèé
Ni ọjọ Iṣẹgun ti eekan ajafẹtọ, Ọmọyẹle Ṣoworẹ lọ si ile ẹjọ, arameeri iran lo waye nigba ti eeyan kan ninu aṣọ ti o kun fun owo ẹyọ ti wọn ta sii lara tẹle wọ ile ẹjọ.
Imurasi arakunrin naa fa ọpọ ariyanjiyan ati gbọyisọyi lori iru ẹni gan an ti arakunrin naa jẹ.
Eyi lo mu ki BBC News Yoruba tọ awọn agba onimọ lọ lori ọna ti a fi lee da Babalawo mọ.
Ninu ọrọ to sọ, Baba Agẹṣin Adimula ti ilu Ila Ọrangun, Oloye Fagbenle Adedayọ ṣalaye pe lati igba iwaṣẹ, bẹrẹ lati ori Ọrunmila to jẹ Babalawo akọkọ ni awọn babalawo ti ni ilana imura wọn.
#EndSars Ogbomoso: Èmí kò ní kí wọ́n pa ọlọ́pàá tó pa Isisaka, ṣùgbọ́n...- Ramota, Iya Isi
Ipakaja:
Gẹgẹ bi o ṣe sọ, ko si aṣọ ti Ọrunmila ko lee wọ, to ba ji, o lee wọ aṣọ pupa, to ba ji o le wọ aṣọ dudu, ṣugbọn aṣọ funfun ati aṣọ alaro ni ọrunmila to jẹ Babalawo akọkọ maa n saba wọ ju.
Amọṣa ohun ti a fi maa n daa mọ gẹgẹ bi Orunmila ni pe yoo pa kaja.
Oríṣun àwòrán, facebook/ifayemi elebuibon
Pipa kaja tumọ si riro aṣọ nla ti a wa so ọwọ rẹ si ibi ejika kan. Apẹrẹ pipa kaja ni bi Kabiyesi Ọọniriṣa ṣe maa n mura.
Babalawo to ba jẹ onifa maa pakaja aṣọ bi o ti le wu ki aṣọ to wọ o ri. Aṣọ to ba wu babalawo lo lee wọ si isalẹ, ṣugbọn ohun kan ti ko gbọdọ maa ṣe ni pipakaja sori aṣọ bẹẹ.
Akomolede àti Aṣa:  Olùkọ́ Olajide láti Ẹdẹ ló ṣàlàyé nípa Awẹ́ Gbólóhùn fún wa ní kíkún
Ohun idanimọ akọkọ fun awọn alawo ni pe bi o ti le wu ki aṣọ ti wọn ba wọ o ri, o gbọdọ da aṣọ bora lati pa kaja.
Oríṣun àwòrán, facebook Ifayemi elebuibon
Lẹyin ti babalawo ba ti pakaja rẹ tan, o gbọdọ mu irọkẹ dani.
Ki ni ohun ti Yoruba n pe ni irọkẹ? Irọkẹ ni igi kekere kan bayii ti wọn maa n sin. Igba miran si wa ti wọn si maa n lo eyin erin atawọn igi kan ni igbo ti awọn agba mọ.
Irọkẹ yii ni babalawo maa fi n lu oju ọpọn ifa kere-kere ti wọn ba ti n da ifa tabi ki ifa lọwọ.
Oríṣun àwòrán, Others
ilẹkẹ iṣẹmbaye kan
Ode:
Ohun miran ti a fi n da babalawo mọ ni iduro ni ode ifa. Babalawo gbọdọ ni ode ifa lọwọ.
Gẹgẹ bi Oloye Fagbenle Adedayọ, Agẹsin Adimula ilu Ila Ọrangun ṣe sọ, ode ifa yii da bi iyun tabi ilẹkẹ ti o maa n ni awọ eweko (green) ati awọ ilẹ (brown). Ode yii ni wọn maa n so mọ ọwọ.
Francis Olusola Alao: Wọ́n ti ti ọ̀rọ̀ òṣèlú bọ ọ̀rs Sunday Igboho, ṣùgbọ́n..- Oba Olugbọn
Gẹgẹ bi ẹsẹ ifa ṣe sọ, ode yii duro fun iwalaaye ẹda lori ilẹ. Idi niyi ti o fi yan awọ eweko ati awọ ilẹ.
Agẹṣin Adimula ilu Ila Ọrangun ṣalaye pe kii ṣe ọpa ti a sin nii fi eniyan han bi babalawo, gẹgẹ bi ọpọ ti maa n rii ninu awọn sinima agbelewo gbogbo.
O ni babalawo yoo mura daadaa gẹgẹ bi o ti yẹ, kii ṣe aṣọ ti wọn ko ogun si yannayanna lawọn babalawo maa n wọ.
Oríṣun àwòrán, facebook/Ifayemi Elebuibon
"Agesin Adimula ni: ""Awọn to n wọ aṣọ ogun, awọn la n pe ni oniṣegun"""
Bakan naa lo fi kun un pe babalawo kii di irun ori rẹ, oniṣegun ati ọlọya lo maa n di irun ori wọn.
"Bi babalawo ba fa ori tan wọn le da irun kekere kan silẹ ni aarin ori ti wọn n pe ni aso ifa lawọn iha ibikan nilẹ Yoruba
Olusegun Obasanjo: Ọmú ìyá mi ti mo fi ń mùkọ ni kekere ló jẹ ki ń lókun
Ohun to ba fi le yatọ si eyi, (kii ṣe babalawo) gbogbo awọn baba ti a ni ẹ o ri bẹẹ nitori pe wọn kii ṣe oniṣegun."
"Gbogbo ohun ti a ba fẹ sọ inu ifa lo ti n jade. Ifa o ki n di nnkan mọra, ọrọ ni Ifa"""
Oríṣun àwòrán, @Sowore
Ẹni to tẹlẹ mi lọ sile ẹjọ ti aye n pariwo kii ṣe Babablawo bikoṣe arakunrin to wa ṣatilẹyin fun mi- Sowore.
Bo ṣe wu eeyan lo ṣe le mura lọ sile ẹjọ lati ṣatilẹyin fun mi ni ọrọ ti Sowore kọkọ fi fesi ibeere irufẹ ẹni ti arakunrin naa jẹ.
Omoyele Sowore to n jẹjọ nile ẹjọ ni Abuja ti ba BBC sọrọ lori akọni to wa lẹyin rẹ nibi igbẹjọ ni ana.
Oludari ikọ #Revolution now, Omoyele Sowore to dije dupo aarẹ ni Naijriia lọdun 2019 ti sọrọsoke.
O salaye nipa arakunrin kan to tẹlẹ e lọsile ẹjọ ni Abuja ni ana.
Francis Olusola Alao: Wọ́n ti ti ọ̀rọ̀ òṣèlú bọ ọ̀rs Sunday Igboho, ṣùgbọ́n..- Oba Olugbọn
Omoyele Sowore ni ọkunrin naa kii ṣe babalawo tabi onisegun rara.
Koda, o ni ki ṣe alafọṣẹ bi awọn kan ṣe n sọ kiri lori ayelujara.
#EndSars Ogbomoso: Èmí kò ní kí wọ́n pa ọlọ́pàá tó pa Isisaka, ṣùgbọ́n...- Ramota, Iya Isi
Sowore ni arakunrin naa jẹ akọni ọmọ ilẹ Adulawọ to ṣafihan igbagbọ rẹ ninu imura rẹ.
O ni eyi ko si tako ofin ilẹ Naijiria nitori pe bi o ba ṣe wu ni ni a n ṣe imale ẹni ati imura ẹni.
Omoyele Sowori to jẹ oludasile ile isẹ iroyin Sahara Reporters ni idi ti arakunrin naa fi mura bẹẹ ni pe o kan fẹ fi han awọn eniyan kan ti wọn maa n tabuku imura ibilẹ ni.
Olusegun Obasanjo: Ọmú ìyá mi ti mo fi ń mùkọ ni kekere ló jẹ ki ń lókun
O ni awọn aṣa imura ati igbagbọ ilẹ wa kan ni ẹsin ajoji ati imura atọhunrinwa ti gbọn dani lọwọ wa ni eyi ti ko yẹ ko ri bẹẹ.
Sowore sọ fun BBC pe ọkunrin naa wa ṣe atilẹyin fun oun gẹgẹ bii akọni ẹlẹru ni.
Oríṣun àwòrán, @Aisha
Ati pe Bi Pasitọ ati Aafa ati Wooli eeyan ṣe le wa pese iranlọwọ atilẹyin fun un lasiko iṣoro naa ni ọkunrin naa wa ṣe fun oun.
NURTW Ondo: Ọ̀pọ̀ èrò ní Akure fi ayọ́ hàn bí Aketi ṣe ni kí NURTW lọ sinmi
Lati igba ti wọn ti yọ sile ẹjọ ni awọn eeyan ti n sọ oriṣiriṣi nipa imura arakunrin naa.
Akomolede àti Aṣa:  Olùkọ́ Olajide láti Ẹdẹ ló ṣàlàyé nípa Awẹ́ Gbólóhùn fún wa ní kíkún
Yoruba-Fulani crisis: Ọlọrun má jẹ́ kí a jẹ́ gbèsè lókù báyìí tí a kò kó ọjá lọ sílẹ̀ Yorùbá mọ́- Hausa Oníṣòwò
Oríṣun àwòrán, others
Awọn ẹgbẹ olounjẹ ati ẹlẹran ọsin ni Naijiria lati ariwa ti amọ si AUFCDN n tẹsiwaju ninu iyanṣẹlodi wọn.
Egbe yii ti apeja orukọ wọn n jẹ: Amalgamated Union of Foodstuff and Cattle Dealers of Nigeria (AUFCDN) ni wọn kede pe ohun gbogbo ti gba ọpọ bayii nilẹ Hausa.
Gbogbo awọn agbẹ ti ọrọ kan ni apa ariwa Naijiria ti wọn ti n ko ohun eelo ọbẹ bii ata, tomati, alubọsa, iresi ati bẹẹ bẹẹ lọ ti n pariwo gbese..A ò ní kó oúnjẹ lọ sílẹ̀ Yorùbá láì jẹ́ pé ààbò wà fáwọn Fulani níbẹ̀- Miyetti Allah
Wọn ni ọpọ ti ko ni ere rara ni awọn fi n ta nkan ọbẹ bayii ki wọn ma baa bajẹ mọ ori igba ati inu oko awọn.
Awọn miran ni ọrọ naa ko le tii aynju bayii laisi awọn igbesẹ kan;
Koda, ọpọ eeyan lo ti fidi ẹ mulẹ pe ọpọ ni apẹrẹ Tomati ati rodo bayii ni awọn ipinlẹ to wa ni ariwa ati ni Abuja to jẹ olu ilu Naijiria.
Eyi ko ṣẹyin bi awọn kan ṣe lọ di opopona ti wọn n gba ko nkan oko wọle wa si iwọ oorun guusu Naijiria lati ariwa
Olusegun Obasanjo: Ọmú ìyá mi ti mo fi ń mùkọ ni kekere ló jẹ ki ń lókun
Ọpọ awọn eeyan lori ayelujara lo ṣalaye pe ohun to ṣokunfa gbese ọlọpọ yanturu ni ariwa yii ko ṣẹyin pe awọn ata ti pọ ju nibẹ nitori pe wọn ko ri wọn ko lọ si awọn ipinlẹ ilẹ Yoruba ati Igbo.
Bẹẹ awọn eeyan ti n sọrọ lori ayelujara:
Bawo ni ọmọ ṣe sọri lọja ilẹ Yoruba ati Igbo bayii?
Ni iṣọ ẹlẹran ìso ni ọja Alaba ni ipinlẹ Eko ni owo ẹran agbo ti di ilọpọ mẹta bayii.
Akọroyin BBC to lọ sibẹ ni koda, niṣẹ ni gbogbo ọja naa da waiwai ti ero ko si pọ rara.
Francis Olusola Alao: Wọ́n ti ti ọ̀rọ̀ òṣèlú bọ ọ̀rs Sunday Igboho, ṣùgbọ́n..- Oba Olugbọn
O ni bẹẹ si ni gbogbo ẹran ọsin ati awọn nkan miran gbowo lori jọjọ.
Mallam Tanimu Bulama to jẹ Waziri alaba Rago ṣlaye fun BBC pe: Eran agbo ti wọn n ta ni N30, 000 tẹlẹ ti di N95,000 bayii nitori pe Niger ati ilẹ Sudan gba ilẹ Hausa ni awọn n gab ko ẹran wọle ju.
Ero awọn Yoruba to n ra ọja ọwon naa yatọ bayii:
Mallam Umar to tun ba BBC sọrọ ṣalaye pe ironu ti ba ọpọ awon agbẹ ati Oniṣowo ni ariwa Naijiria nitori pe nkan ti n bajé si ori igba wọn.
O ni bayii awọn ti n ta tomati apẹrẹ ti wọn n ta ni N2,100 tẹlẹ ni N800 nitori pe wọn ti n bajẹ.
Oríṣun àwòrán, @Awal Ahmad
Se lootọ ni wọn n ko ọja pamọ?
Awọn miran ni awọn ọlọja nilẹ Yoruba n ko ọja pamọ nitori pe ọja mii ko de lati ilẹ Hausa.
Sugbọn Emir ọja Alaba, Alhaji Umaru Goggo ni irọ ni eyi.
O parọwa pe asiko ti to ki wọn fopin si aṣẹ ma ko ọja wọle lati ariwa yii.
O ni o n ṣakoba fun ati Hausa ati Yoruba ati Igbo ni bayii.
Koda, Emir naa ke si aarẹ Naijiria lati wa ojutu si iṣoro yii ki nkan ma lọ bajẹ tan.
NURTW Ondo: Ọ̀pọ̀ èrò ní Akure fi ayọ́ hàn bí Aketi ṣe ni kí NURTW lọ sinmi
Sunday Igboho: Igboho láṣẹ lábẹ́ òfin Nàìjíríà láti bọ ohun tó wù ú nígbà tó wù ú- Yinka Oyebode
Oríṣun àwòrán, FACEBOOK
Ijọba ipinlẹ Ekiti ti ni awọn gbọ wi pe eekan ọm Yoruba, Sunday Igboho lọ si igbo Ire-Ekiti lati lọ bọ Ogun.
''Lọ́ọ̀tọ́ ní Sunday Igboho wá sí igbó Ire-Ekiti láti bọ Ogun lákáyé! ''
Akọwe eto iroyin fun gomina ipinlẹ Ekiti, Yinka Oyebode lo sọ bẹẹ fun BBC Yoruba lẹyin fidio to jade lori ayelujara,to safihan Sunday Igboho ninu igbo Ire-Ekiti.
Arakunrin Oyebode ni Igboho laṣẹ ni abẹ ofin lati lọ si ibikibi to ba wu u nitori ọmọ orilẹede Naijiria ni, to si le e ṣe ẹsin to ba wu u.
Akọwe Ekiti ni: 'Amọ agbegbe Ire-Ekiti fun ibi ti awọn eniyan gbagbọ nipa bibọ Ogun, nitori naa a gbọ wi pe oun nbọ nibẹ''
''Oun ti o lọ ṣe nipe o lọ darapọ mọ awọn ẹlẹsin ibilẹ lati lọ bọ Ogun gẹgẹ bi igbagbọ rẹ''
Bone setting: Adimula Kehinde Akinfenwa ṣàlàyé nípa irúfẹ́ ẹranko tí wọ́n fi ń to eegun èy
Saaju ni fidio kan ti ja ranyin lori ayelujara nibi ti awọn eniyan ti tu yaya sita lati ki Sunday Igboho kaabọ ni agbegbe wọn.
Lẹyin naa ni wọn lọ si ojubọ Ogun lati lọ ṣe adura ati iṣẹṣe.
Awọn ero lo pejọ naa wa ni ibi ojubọ Ogun naa lati oru titi di owurọ lati rubọ ati lati ṣe adura.
Awọn eniyan ti wọn n sọrọ ninu fidio naa sọ wi pe awọn ara agbegbe Ire-Ekiti gba ni alejo wa si agbegbe wọn.
Ti wọn si fun un ni ọpa aṣẹ ti Ogun lo nigba aye  rẹ lati fi jagun.
Awọn ẹlẹsin ibilẹ gbagbọ wi pe ilu Ire-Ekiti ni Ogun wọlẹ si, ti wọn si ma n lọ si ojubọ rẹ lati bọ ọ ni orekoore.
Bakan naa ni wọn n yin ibọn kalukalu lati fi bọ Ogun gẹgẹ bi iṣe wọn lasiko ti wọn ba n bọ orisa naa.
Eekan ọmọ Yoruba ni, Sunday Adeyẹmọ ti ọpọ mọ si Sunday Igboho ti ṣeleri ati da sẹria to ba yẹ fun awọn oloṣelu ọmọ ilẹ Yoruba to ba gbiyanju ati darapọ mọ idije ipo aarẹ Naijiria lọdun 2023.
Oríṣun àwòrán, Others
Igboho to sọ eleyii nigba to n ba ọpọ ero kan sọrọ̀ nibi eto kan laipẹ yii.
"O ṣalaye pe, dipo ki awọn oloṣelu ẹya Yoruba o maa gbaruku ti ipe fun ijijangbara ilẹ Yoruba, ipolongo lati dije fun ipo aarẹ ni wọn n le kaakiri."""
O ni oun o ni gba kawọn oloṣelu ilẹ Yoruba kan laaye lati dije nitori oun ṣetan lati gbẹmi wọn ki idibo naa gan to waye.
Bakan naa lo tun rọ awọn agbagba ilẹ Yoruba lati dide fun ijijagbara ilẹ Yoruba.
Olusegun Obasanjo: Ọmú ìyá mi ti mo fi ń mùkọ ni kekere ló jẹ ki ń lókun
Ninu ọrọ rẹ, o ni imọtara-ẹni-nikan lo n ba awọn oloṣelu ilẹ Yoruba ja ti wọn fi n polongo fun ilepa ara wọn lati di aarẹ.
O ni oun yoo ba wọn ja bi  wọn ba gbero rẹ.
NURTW Ondo: Ọ̀pọ̀ èrò ní Akure fi ayọ́ hàn bí Aketi ṣe ni kí NURTW lọ sinmi
Bakan naa ni Igboho tun ke sawọn ọdọ lati lọ ṣe oogun abẹnugọngọ lati lee fi gbeja ara wọn lasiko ipenija to n bọ lọna.
Akomolede àti Aṣa:  Olùkọ́ Olajide láti Ẹdẹ ló ṣàlàyé nípa Awẹ́ Gbólóhùn fún wa ní kíkún
"Oyinkansola Elebuibon: Wọ́n ṣa mi ní àdá lọ́pọ̀ ìgbà, ṣùgbọ́n kò wọlé sí mi lára nítorí ""Science?"""
Oríṣun àwòrán, oyinelebuibon
Oyinkansola Elebuibon, to jẹ ọkan lara awọn ọmọ Araba awo ilu Oṣogbo, Ifayemi Elebuibon, ti sọ pe oun iba ti jẹ Ọlọrun nipe bi kii ba ṣe ọpẹlọpẹ ajẹsara.
Oyinkansola lo fi ọrọ naa lede ninu ifọrọwerọ kan pẹlu BBC Yoruba.
Gẹgẹ bo ṣe ṣọ, awọn janduku kan ṣaa ni ada lọpọ igba, ṣugbọn ada naa ko wọle si lara.
Wo ohun tí Professor Peller wí tó kó bá a gẹ́gẹ́ bí ìyàwó rẹ̀, Lady Peller ṣe tú u síta
Ṣaaju ni Oyinkansola ti kọkọ sọ ninu ifọrọwerọ naa pe ilẹ Amẹrika ni oun fi ṣebugbe bayii nitori awọn iṣẹlẹ to kan ṣẹlẹ si i nilu u Ibadan lọdun 2019.
Iṣẹlẹ naa jẹ eyii to gbomi loju Oyinkansọla, koda, bintin bayii lo ku ki omi bọ loju rẹ lasikọ to n ṣalaye ọrọ naa fun BBC Yoruba.
Sunday Igboho latest: Sunday Igboho kò gba 'Award'ti a fún un ní Ogo Yorùbá nítorí inú rẹ̀
"Oyinkansola ni ""Alẹ ọjọ kan lẹyin ti mo ti ode ere de ni awọn kan wa da emi atawọn ọmọ to n gbe pẹlu mi mọle, wọn gba owo ati awọn nnkan miran lọwọ wa."""
Ṣugbọn nigba to ya, wọn ni ki n wọle sinu yara, mo si ṣe bẹẹ, lẹyin ti wọn ko awọn ẹgba ọrun tan ni wọn ba ni ki n dubulẹ sori ibusun ti mo si kọ.
"Ninu alaye rẹ, o sọ siwaju si pe ""Lẹyin ti mo bọ lọwọ wọn tan ninu ile ni mo ba ni ki n jade lẹnu ilẹkun nla to wọ inu ile ni mo to ranti pe mo ti ti ilẹkun naa pa."""
Oríṣun àwòrán, oyinelebuibon
Bi awọn eeyan yii ṣe jade simi niyẹn ti wọn si bẹrẹ si n ṣa mi ladaa, ṣugbọn ko wọle, o kan fi apa diẹ simi lara ni.
"O ṣalaye pe ""ọpẹlọpẹ 'science' ni ko jẹ ki ada naa wọle simi lara, n o ba ti gba ibẹ lọ."""
"Ṣugbọn nigba ti atọkun BBC Yoruba bere pe ki lo n jẹ ""science"" ti Oyinkansola n sọ, lo ṣi aṣọ loju eegun pe oogun abẹnu gọngọ ni oun n poe ni 'science.'"
Oríṣun àwòrán, oyinelebuibon
Yatọ si eyii, Oyinkansola tun sọrọ nipa bi ere ori itage ṣe jẹ ajogun ba fun oun, ati bi ko ṣe ti oun loju lati jẹ onigabgbọ ninu ẹsin adayeba ilẹ Yoruba, paapaa Ifa Olokun asọrọ dayọ.
#EndSars Ogbomoso: Èmí kò ní kí wọ́n pa ọlọ́pàá tó pa Isisaka, ṣùgbọ́n...- Ramota, Iya Isi
Oyinkansola sọ pe lara afojusun oun fun ọjọ iwaju ni pe yoo wu oun lati gbe aṣa Yoruna ga ju bo ṣe wa lasiko yii lọ.
Nipa ibasẹpọ to wa laarin oun ati oṣere tiata kan ti irawọ rẹ n tan lọwọ yii, ti awọn kan sọ pe awọn mejeji ni ibasẹpọ, ati pe gbajumọ oṣere naa lo gbe lọ silẹ Amẹrika, Oyinkansola sọ pe ko si ohun to jọ bẹẹ rara.
Francis Olusola Alao: Wọ́n ti ti ọ̀rọ̀ òṣèlú bọ ọ̀rs Sunday Igboho, ṣùgbọ́n..- Oba Olugbọn
Fulani-Yoruba Crisis: Àwọn oníṣòwò Hausa ti ń kó ọjà wọlé padà- Aminu Alaba Rago
Oríṣun àwòrán, others
BBC ti fidiẹ mulẹ pe awọn ọja ounjẹ ti pada n wọle bayii lati ariwa Naijiria wa si Iwọ oorun guusu ati ila oorun guusu.
Saaju ni awọn Ẹgbẹ Amalgamated Union of Foodstuff and Cattle Dealers of Nigeria (AUFCDN) ti kọkọ gunle iyanṣẹlodi Ọlọrun má jẹ́ kí a jẹ́ gbèsè lókù báyìí tí a kò kó ọjá lọ sílẹ̀ Yorùbá mọ́- Hausa Oníṣòwò
Iyanṣẹlodi yii mu nkan bajẹ lori igba ati ninu ọkọ awọn oniṣowo Hausa ni eyi to jẹ ki awọn eeyan Yoruba ma ra ounjẹ bii Tomati, alubosa, Ewa, Agbo ati bẹẹ bẹẹ lọ lowo gọbọi.
Lẹyin ipade loriṣiiriṣii ni wón wọgile iyanṣẹlodii naa lẹyin ti wọn fẹnuko lori awọn nkan kọọkan.
Alaga ẹgbẹ Amalgamated Union of Foodstuff and Cattle Dealers of Nigeria (AUFCDN), ẹka Alaba Rago, Alhaji Aminu lo fidiẹ mulẹ fun BBC pe ọja ti n wọle si ipinlẹ Eko atawọn ipinlẹ to kù.
O ni gbogbo awọn ọkọ akẹru ati tirela ti wón da duro tẹlẹ ni oju ọna ni ipinlẹ Kwara ati Niger ni awọn ti ri ti wọn ti n kọja wọle bayii.
Gbogbo ọja to ha si opopona tẹlẹ ti wọ awọn ipinlẹ ile Igbo ati ti ilẹ Yoruba.
Saaju ni awọn oniṣowo Hausa ti a ba sọrọ ti fi aidunnu han lori awọn nkan ti wọn padanu tẹlẹ.
Wọn ni awọn nkan ti awọn naa padanu ka wọn lara ṣugbọn aabo ẹmi ati dukia koowa lo jẹ gbogbo eeyan logun
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ìjà ti parí, a ti gbà láti má a gbé ounjẹ wá sí ilẹ̀ Yoruba padà'- Hausa-Fulani Ọlọ́jà
Egbe awọn agbẹ olounjẹ lati Ariwa orilẹ-ede Naijiria pẹlu awọn Fulani darandaran (AUFCDN) ti gbegile iyanṣẹlodi ti wọn gunle.
Fulani-Yoruba Crisis: Oba Soun ló fí mi jẹ ọba Sabo ni Ogbomọṣọ- Alh Haruna Bala Abdulsala
Ẹgbẹ Amalgamated Union of Foodstuff and Cattle Dealers of Nigeria (AUFCDN) naa ni awọn yoo bẹrẹ si ni gbe ounjẹ pada wa si Iwọ oorun orilẹ-ede Naijiria lasiko ipade pẹlu ijọba apapọ ti Gomina ipinlẹ Kogi, Yahaya Bello ṣe aṣoju fun ni ilu Abuja.
Ninu ọrọ tirẹ, gomina ipinlẹ Kogi, Yahaya Bello bẹ ẹgbẹ naa ki wọn fi opin si iyanṣẹlodi wọn, ti awọn yoo si ri daju pe gbogbo nkan ti wọn bere fun ni ijọba a fi fun wọn.
Gomina Bello ni gbogbo eniyan ni iyanṣẹlodi naa ta ba nitori awọn ọmọ Naijiria n la ọpọlọpọ idojukọ kọja nitori nkan to le, nitori naa ki wọn ma tun dakun iṣoro naa.
#EndSars Ogbomoso: Èmí kò ní kí wọ́n pa ọlọ́pàá tó pa Isisaka, ṣùgbọ́n...- Ramota, Iya Isi
Aarẹ ẹgbẹ AUFCDN, Muhammed Tahir ni awọn gbe igbeṣẹ naa nitori ijọba gba lati san iye owo to le ni biliọnu mẹrin naira fun awọn fun gbogbo awọn nkan ti wọn padanu lasiko ija laarin awọn ẹya ni Naijiria.
Tahir ni ijọba ṣeleri lati ri pe aabo to daju wa fun wọn loju ọna ti wọn ba n gbe ounjẹ bọ lati Ariwa ati opin si bi wọn ṣe n gba owo gọbọi ni ọwọ wọn ni oju ọna.
''Inu wa dun nitori gbogbo nkan ti a bere fun ni ijọba gba lati ṣe fun wa.''
Olusegun Obasanjo: Ọmú ìyá mi ti mo fi ń mùkọ ni kekere ló jẹ ki ń lókun
Tahir ni: ''Nitori ijọba ti Gomina Bello ṣoju fun bẹ wa wi pe awọn yoo ṣe ohun to tọ, ni awọn ṣe gbegile iyanṣẹlodi ọhun''
''Ijọba si ṣeleri lati pese aabo to tọ fun awọn ọlọja lati ariwa lati le ṣe iṣẹ wọn ni ọna to tọ''
Bakan naa ni Minisita tẹlẹri fun ọrọ irinna ofurufu, Femi Fani Kayode ni Sunday Igboho ti fi da oun loju wi pe awọn Hausa-Fulani ko ni dojukọ ija ẹlẹyamẹya mọ.
Amọ, o kesi ijọba apapọ lati pese aabo to tọ fun awọn agbẹ naa ni ilẹ Yoruba nitori awọn Fulani darandaran to n pa awọn eniyan ninu igbo ijọba.
Akomolede àti Aṣa:  Olùkọ́ Olajide láti Ẹdẹ ló ṣàlàyé nípa Awẹ́ Gbólóhùn fún wa ní kíkún
Zamfara kidnapping, Shooting: Àwọn Agbébọn ti dáná sún agbègbè Maru nípinlẹ̀ Zamfara, wọ́n tún jí èèyàn tó lé lọ́gọ́ta gbé lọ
Oríṣun àwòrán, @Nigeria Army
Awọn olugbe agbegbe Ruwan Tofa nijọba ibilẹ Maru ni ipinlẹ Zamfara ti ko sọwọ awọn agbebọn bayii.
Iroyin to n tẹ wa lọwọ sọ pe niṣe ni awọn agbebọn kan deedee yabo abule yiii ti wọn si sọna si inu rẹ.
Bayii, wọn ni ilaji abule naa ti jona tan pẹlu ọpọlọpọ dukia lo ti ṣofo danu.
"Eyi n waye lataari iṣoro ijinigbe to n pọ sii nibẹ ni eyi ti  o mu ki aarẹ Buhari kede ""No-Fly Zone"" nibẹ lẹyin ti wọn ji awọn akẹkọọbinrin 279 gbe.Wo ohun tí Ńo-Fly Zone' túmọ̀ sí,"
Awọn olugbe agbegbe Ruwan Tofa ti sa asala kuro ninu abule naa ni Zamfara bayii.
Wọn ṣalaye fun awọn  akọroyin pe lati ọdun to kọja ni awọn ti n la iṣoro eto aabo kọja ninu eyi ti wọn ti jo awọn ọkọ ayọkẹlẹ wọn, ile itaja wọn, ile ati awọn dukia to pọ.
Wọn ni o le ni eeyna ọgọta ti wọn ti ko salọ kuro ni abule naa bayii.
Francis Olusola Alao: Wọ́n ti ti ọ̀rọ̀ òṣèlú bọ ọ̀rs Sunday Igboho, ṣùgbọ́n..- Oba Olugbọn
Awọn ọmọ wẹwẹ, awọn Obinrin lo pọ ti wọn le ni ọgọta ti wọn ti dawati bayii.
Okunrin kan, Maigari ni iyawo oun merin ati awọn ọmọ lo ti dawati bayii.
Enikan naa tun sun pe eeyan mẹẹdogun lo ti sọnu ninu ile ti oun.
Wọn ni ẹẹmeji ni wọn pe awọn agbofinro ṣugbọn nigba ti a ko ri ẹṣọ alaabo kankan la ṣe sa asala fun ẹmi wa.
Nigba ti BBC kan si ileṣẹ ọlọpaa ni Zamfara ṣugbọn a ko ri nkankan di mu, a ko dẹ ri ẹnikankan ba wa yanayana ọrọ naa.
Fulani-Yoruba Crisis: Oba Soun ló fí mi jẹ ọba Sabo ni Ogbomọṣọ- Alh Haruna Bala Abdulsala
Saaju ni awọn agbebọn tunti ji awọn ọmọ kan gbe ni Runka nipinlẹ Katsina,
Ara ilu Runka ni pe wọn ji akẹkọọ mẹta gbe ni ọjọ Iṣẹgun to kọja.
Wọn ni wọn ji awọn akẹkọọ yii gbe nigba ti wọn n bọ lati ile ẹkọ lo sile Obi wọn.
Oríṣun àwòrán, @Zamfara Govt
Wọ́n tún yìnbọn níbi àpèjẹ 'Ẹ káàbọ̀' tí wọ́n ṣe fáwọn akẹ́kọ̀ọ́bìnrin Zamfara lẹ́yìn àṣẹ Buhari
Wọ́n tún yìnbọn níbi àpèjẹ 'Ẹ káàbọ̀' tí wọ́n ṣe fáwọn akẹ́kọ̀ọ́bìnrin Zamfara lẹ́yìn àṣẹ Buhari
"Lẹyin ti aarẹ Muhammadu Buhari kede pe ipinlẹ Zamfara ti di "" No-Fly Zone"" Wo ohun tí Ńo-Fly Zone' túmọ̀ sí, eruku tun sọ lala nibẹ."
Niṣẹ ni nkan bẹyin yọ nibi apejẹ ẹ kaabọ pada sile ti wọn ṣeto fawon akẹkọọbinrin ile ẹkọ GSS Jangebe.
Iroyin ti a gbọ nipe ija bẹ silẹ nigab ti awọn alaṣẹ ipinlẹ Zamfara lọ ko awọn ọmọ naa fun Obi wọn nibi apejẹ naa.
Awọn ara ilu Jangebe kan sọ fun BBC pe wahala bẹ silẹ nigba ti awọn ara abule bẹrẹ si ni sọ awọn alaṣẹ ni okuta lasiko ti wọn de lati da awọn akẹkọọbinrin naa pada fun awọn Obi wọn.
Eni ti ọrọ naa ṣoju ẹ sọ fun BBC pe o kere tan eniyan mẹta ni awọn ọmọ ogun ilẹ to wa nibẹ yinbọn fun.
O ni bi awọn ara ilu ṣe n sọ awọn alaṣẹ to tẹlẹ awon ọmọ naa wa loko ni awọn ṣọja ṣina bolẹ nibẹ.
Olusegun Obasanjo: Ọmú ìyá mi ti mo fi ń mùkọ ni kekere ló jẹ ki ń lókun
A ko tii le sọ boya ẹnikẹni ku ninu iṣẹlẹ naa tabi bẹẹkọ titi di asiko yii.
Lọjọ Eti to kọja ni wọn ji awọn akẹkọọbinrin yii gbe ti wọn si tu wọn silẹ lẹyin ti ijọba ni wọn gbiyanju pupọ.
Francis Olusola Alao: Wọ́n ti ti ọ̀rọ̀ òṣèlú bọ ọ̀rs Sunday Igboho, ṣùgbọ́n..- Oba Olugbọn
Awọn akẹkọọbinrin 279 yii ti wa lọdọ ijọba ipinlẹ Zamfara nile ijọba ni Gusau to jẹ olu ilu Zamfara lati ọjọ Isẹgun ti ijọba kede pe wọn ti ri wọn gba pada.
Nile ijọba ni wọn ni wọn ti n gba itọju ki wọn to fẹ da wọn pada sọdọ Obi wọn to fi di iṣu ata yanyan.
Oríṣun àwòrán, Others
Ni kéte lẹyin ti ijọba ri awọn akẹkọọbinrin yii gab pada ni Aarẹ Buhari kede pe ki ọkọ ofurufu kanakan ma rin mọ ni Zamfara.
#EndSars Ogbomoso: Èmí kò ní kí wọ́n pa ọlọ́pàá tó pa Isisaka, ṣùgbọ́n...- Ramota, Iya Isi
Garba Shehu ṣalaye idi ti ijọba Buhari fi paṣẹ yii fun BBC pe o nii ṣe pẹlu awọn oniṣẹ ibi to n fi ọkọ ofuirufu aladani ji goolu ijọba wà lọ si Dubai.Wo ohun tí Ńo-Fly Zone' túmọ̀ sí
Koda, O ni eto aabo ẹkun ariwa yii ti gba amojuto ati awọn igbesẹ aṣẹ lati le daabo bo awọn ara ilu ibẹ.
Akomolede àti Aṣa:  Olùkọ́ Olajide láti Ẹdẹ ló ṣàlàyé nípa Awẹ́ Gbólóhùn fún wa ní kíkún
Congo gold mountain: Àwọn ará abúlé kan ṣàwàrì àlùmọ́ọ́nì gòólù ní wọ́n bá kígbe síta ní Ọlọ̀pàá bá yi wọn ká!
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ọpọlọpọ nkan ni awọn eeyan ti n sọ lori ayelujara nipa iṣẹlẹ yii to waye ni orilẹ-ede Congo.
Ni DR Congo ni awọn ara abule kan ti ṣẹgi ọla laimọ rara pe ọla naa ti n ba awọn gbe lati ọdun to ti pe wa.
Ki lo ṣẹlẹ gangan ni Birava ni DR Congo?
Saaju ni awọn eniyan abule Birava to jẹ iwọn kilomita marundinlogoji si ariwa ẹkun Bukavu ni aarin gbungbun ilu South-Kivu ni ẹkun kan naa.
Byode Malenga to jẹ akọroyin BBC ni DR Congo ṣalaye pe labule ni wọn ti deedee rii pe goolu wa ninu iyẹpe ori oke kan nibẹ.
Leyin ti awọn eeyan abule yii ri goolu yii, ni wọn bẹrẹ si ni fọọ ninu omi to si di goolu to dara.
Ni kete ti wọn rii ni ọpọ ero rọ lọ si ori oke naa ti wọn si bẹrẹ si ni gbọn iyẹpẹ ori oke naa ti onikaluku si lọ n fọ goolu jade nibẹ ti wọn n di ọlọla.
Ko pẹ lẹyin naa ni awọn kan fi si ori ayelujara ohun to n ṣẹlẹ ti koowa si di ero ibẹ ti wọn si n pin in kaakiri lori ayelujara.
Fulani-Yoruba Crisis: Oba Soun ló fí mi jẹ ọba Sabo ni Ogbomọṣọ- Alh Haruna Bala Abdulsala
Kini Ijọba DR Congo ti wa ṣe bayii?
Ni kete ti iroyin naa tẹ ijọba DR Congo lọwọ ni wọn ti ran awọn agbofinro kọja lọ sibẹ pe ki wọn lo mojuto ori oke naa ti goolu wa.
Koda, iroyin ni ijọba ti da awọn agbofinro sita lati lọ maa gba awọn goolu ti awọn eeyan mii ti ko ni abule naa pada.
Orilẹ-ede DR Congo jẹ ọkan lara awọn orilẹ-ede ilẹ Adulawọ to ni awọn ohun alumọọni pupọ bii goolu, ati awọn nkan miran.
Oríṣun àwòrán, @Ahmad
Akoroyin BBC, Malenga ṣalaye pe kii ṣe awọn awakusa nikan loju wọn hande ninu fidio naa to jade lori ayelujara.
Malenga ni lati opin ọsẹ to kọja ni iṣẹlẹ naa ti bẹrẹ, ki fọnran fidio naa to jade lẹyin naa.
Wọn ni goolu to to ida 60 ninu 100 si ida 90 ninu 100.
Olusegun Obasanjo: Ọmú ìyá mi ti mo fi ń mùkọ ni kekere ló jẹ ki ń lókun
Fulani herdsmen: Oba Soun ló fí mi jẹ ọba Sabo ni Ogbomọṣọ- Alh Haruna Bala Abdulsala
Bi ọgọrun un ọdun sẹyin ni Baba baba wa jẹ ọba Sabo akọkọ ni Ogbomoso- Oba Sabo Haruna
Olorun ló di ìran Yorùbá, Hausa àti Igbo papọ̀- Oba Sabo ní Ogbomoso
BBC ṣabẹwo si Alahaji Haruna Bala Abdulsalami to n dari Sabo ni Ogbomoso nipinlẹ Oyo ni guusu Iwọ oorun Naijriia.
Oba Sabo yii sọ itan bi awọn baba nla rẹ ṣe de Ogbomọsọ ki wọn to jẹ Oba nibẹ.
O ṣalaye ipa pataki ti Oba Soun Ogbomoso ko ninu sisọ oun di ọba ni Sabo.
Oba Sabo ni Oba soun sọ pe ki oun maa dari gbogbo ẹya eeyan to ba ti n gbe ni Sabo ni Ogbomọṣo.
Bakan naa ni Oba Haruna Bala Abdulsalami sọ fun BBC Yoruba pe ewe lo n daabo bo ẹkọ ni ọrọ Hausa ati Yoruba.
O ṣakawe pe bi Yoruba ṣe pọ nilẹ Hausa ti wọn ko si fẹ wale mọ naa ni Hausa pọ nibi to ti ṣori rẹ.
Koda, O ni Yoruba ni iyawo oun gan an.
Oba Haruna Bala Abdulsalami ni ija Fulani, Hausa ati Yoruba ko jẹ tuntun rara.
Nitori pe o ti wa tipẹtipẹ.
O ni ẹya Fulani fẹ fi gbogbo ọna gbe ogo ẹya wọn ga ni.
ENDSARS: Báwo ní Ọba Rilwan tí ìlú Eko ṣe ní $2 million àti N17 million sí inú àfin rẹ̀?
Oríṣun àwòrán, Twitter
Ibeere ti awọn eniyan n bi Oba Rilwan lori ẹrọ ayelujara ni wi pe bawọ ni ọba ṣe ni iye owo to to Miliọnu meji dọla owo ilẹ okeere ati miliọnu mẹtadinlogun naira si inu afin rẹ.
Eyi ko ṣẹyin ẹsun ti Ọba ilu Eko, Rilwan Akiolu fikan awn ọdọ Endsars wi pe wọn ji owo ohun ninu afin nigba ifẹhọnuhan Endsars.
Oba Akiolu sọ ọrọ yii lasiko ti wọn ṣi haalu, Glover Memorial Hal, ni agbegbe Custom street, ni Lagos Island, ti wọn jo lasiko ifẹhọnuhan Endsars.
Oba Akiolu ni ti awọn eniyan ba mọ ipalara to wa nipa  jiji owo ọba ni, wọn o ni ṣe e, amọ ohun ko ni sepe fun wọn.
Lara awọn ọdọ n kesi Ajọ to n gbogun ti iwa ibajẹ lawujọ lati ṣewadii bi ọba ṣe ni iye owo to to bẹẹ si ile.
Amọ, awọn miran ni awọn ọba ni ilẹ Yoruba ma n ni ọrọ nitori iru eniyan ti wọn jẹ lawujọ, ati wi pe Oba Rilwan ko lo lowo ju laarin awọn ọba ni ilẹ Yoruba.
Amọ Deji ti ilu Akure, Ọba Aladetoyinbo ni awọn ọba ko ni owo bẹẹ ni wọn ko ni agbara mọ bi ti atẹyinwa, a ti wi pe orukọ nikan ni wọn ni.
Fulani-Yoruba Crisis: Oba Soun ló fí mi jẹ ọba Sabo ni Ogbomọṣọ- Alh Haruna Bala Abdulsala
MC Oluomo: Baba tó dàbí MC Oluomo láyé yìí kòsí, ẹni tó bá ní, ó ní ohun gbogbo- Ọmọ MC Oluọmọ
Oríṣun àwòrán, Instagram
Ọmọ MC Oluomo ti sapejuwe Baba rẹ, Musiliu Ayinde Adesanya ti inagijẹ rẹ n jẹ MC Oluomo gẹgẹ bi ẹni to mu iwuri ba oun ni gbogbo ọna.
Ni Oju opo ikansiraẹni Instagram ni o ti sọ ọrọ iwuri nipa baba rẹ.
O ni ọdun marun un ṣẹyin ni MC Oluomo pe awọn ọmọ si ijoko to si sọ iriri rẹ fun wọn nipa bi oun ṣe di ẹni ti oun da loni.
MC oluomo ni oun ti ṣe gbogbo ohun to yẹ ki oun ṣe lori wọn gẹgẹ bi baba, ti oun ko si jẹ wọn ni gbese mọ.
''Ohun ti mo jẹ yin ni eto ẹkọ, eleyii ti mo si ti fun yin gẹgẹ bi ọmọ,ti ọpọ yin si ti kẹkọ jade''
Fulani-Yoruba Crisis: Oba Soun ló fí mi jẹ ọba Sabo ni Ogbomọṣọ- Alh Haruna Bala Abdulsala
M C Oluọmọ ni: ''E lo ẹkọ yin ati fi di eniyan nla ni ẹyinwa ọla, ki e si le e daduro fun ara yin laiwo oju baba yin''
''Nitori mi o ni ile tabi ilẹ ti ẹ fẹjogun lati ọwọ mi, mo ti fun un yin ni ogun to yẹ fun yin''
Oríṣun àwòrán, Instagram
Inu mi dun pe mo jẹ ọmọ Adesanya, iyẹn MC Oluomo, bi o tilẹ jẹpe ọpọlọpọ eniyan lo ma n sọrọ abuku si baba mi''
''Eniyan nla ni to n gbadura, to si ni ifẹ awọn ọmọ rẹ daradara.''
''Ẹni to ba ni MC Oluomo ni baba, ni ohun gbogbo.''
O ni ohun to ba wu awọn eeyna ki wọn maa sọ laidara nipa baba oun MC Olu ọmọ
Oríṣun àwòrán, Google
Musiliu Ayinde ti inagijẹ rẹ jẹ MC Oluomo ni Alaga ẹgbẹ awọn awakọ NURTW ni ipinlẹ Eko.
Olusegun Obasanjo: Ọmú ìyá mi ti mo fi ń mùkọ ni kekere ló jẹ ki ń lókun
Ojọ Kẹrinla, Ọdun 1975 ni wọn bi MC Oluomo to si fẹ iyawo mẹrin ati ọmọ mẹsan.
"Laipẹ yii ni o kọ iwe to sọ nipa igbeaye rẹ, to si pe orukọ rẹ ni iṣẹ mi fun ọmọniyan, ""My Service to Humanity""."
Akomolede àti Aṣa:  Olùkọ́ Olajide láti Ẹdẹ ló ṣàlàyé nípa Awẹ́ Gbólóhùn fún wa ní kíkún
Sadiq Daba biography: Àwọn ohun tó yẹ kí o mọ̀ nípa Sadiq Daba 'Inspector Waziri' nínú sinimá October 1 tó jáde láyé rèé
Oríṣun àwòrán, Premium times
Gbajumọ oṣere ni Sadiq Abubakar Daba ti ọpọ mọ si Sadiq Daba. Akọṣẹmọṣẹ igbohunsafẹfẹ si tun ni pẹlu.
Bi o tilẹ jẹ pe ọmọ ilu Kano ni, Ilu Freetown lorilẹede Sierra Leone lo gbe dagba ki o to pada si orilẹede Naijiria nigba to pe ọmọ ọdun marundinlogun.
Ileewe St Edwards Secondary school ni ilu Freetown lo lọ fun ẹkọ girama ki o to lọ gba iwe  ẹri imọ ijinlẹ ni fasiti Ahmadu Bello University ni ilu Zaria.
"Daba ṣiṣẹ gẹgẹ bi agbohunsafẹfẹ ni ileeṣẹ mohunmaworan apapọ Naijiria, NTA ki o to bẹrẹ si ni mu iṣẹ ere sinima ati itage mọ iṣẹ rẹ ni nnkan bii ogoji ọdun o le diẹ sẹyin pẹlu ere ọlọsọọsẹ ni "" Cockcrow at dawn"""
Fulani-Yoruba Crisis: Oba Soun ló fí mi jẹ ọba Sabo ni Ogbomọṣọ- Alh Haruna Bala Abdulsala
Ni ọdun 2017 ni Daba kede pe oun ti ni aisan jẹjẹrẹ inu ẹjẹ ati jẹjẹrẹ inu koropọn ọmọ ọkunrin.
Lasiko yii, ọpọ awọn eekan ọmọ Naijiria ni wọn dide iranwọ owo fun un nigba naa.
Ni ọjọ kẹta, oṣu kẹta ọdun 2021 ni Sadiq Abubakar Daba dagbere faye ni ileewosan kan ni ilu Eko.
Olusegun Obasanjo: Ọmú ìyá mi ti mo fi ń mùkọ ni kekere ló jẹ ki ń lókun
"Buhari on Zamfara: Buhari ni káwọn agbófinró ó yìnbọn fáwọn tó ń gbé ìbọn AK-47, àwọn ọmọ Nàìjíríà ń pariwo ""lórí irọ́"""
Oríṣun àwòrán, Tweeter/@MBuhari
Aarẹ Muhammadu Buhari ti  paṣẹ pe ki awọn agbofinro o maa yinbọn si ẹnikẹni ti wsn ba ba ibọn atamatase AK-47 lọwọ rẹ.
Eyi wa lara awọn igbesẹ tuntun ti aarẹ orilẹede Naijiria, Muhammadu Buhari n gbe lati dẹkun gbọnmọgbọnmọ iwa ijinigbe, ati ikogunjalu to n waye loirlẹede Naijiria.
Agbẹnusọ fun aarẹ, Garba Shehu ni ijọba apapọ ti wa gba bayii lati fi irin koju irin lori wahala to n fojojums gogo bayii lawọn ipinlẹ bii Zamfara atawọn ipinlẹ miran lẹkun ariwa orilẹede Naijiria.
Aarẹ ti pasẹ fawọn agbofinro lati wọ gbogbo awọn igbo to jẹ ibuba awọn oniṣẹ ibi naa lọ ki wọn si le wọn jade, ki wọn si doju ibọn kọ ẹnikẹni ti wọn ba ri nibẹ pẹlu awọn ohun ija oloro bii  AK-47.
Francis Olusola Alao: Wọ́n ti ti ọ̀rọ̀ òṣèlú bọ ọ̀rs Sunday Igboho, ṣùgbọ́n..- Oba Olugbọn
Shehu Garba tun jẹ ko di mimọ pe idi ti aarẹ Buhari fi paṣẹ pe ko gbọdọ si baluu kan ti yoo tun fo mọ nipinlẹ Zamfara.
O ni eyi ko ṣẹyin lẹyin iwadii awọn ọtẹlẹmuyẹ to fihan pe awọn baluu aladani kan n fo wọ ipinlẹ naa lati ko nnkan ijagun oloro fawọn apanilẹkunjaye naa.
Sugbọn awọn ọmọ Naijiria ti n fi ero wọn han lori eyi ti ero wọn si ṣe ọtọọtọ lori rẹ.
Oríṣun àwòrán, facebook/screenshot
Fulani-Yoruba Crisis: Oba Soun ló fí mi jẹ ọba Sabo ni Ogbomọṣọ- Alh Haruna Bala Abdulsala
Bi awọn kan ṣe n bi aarẹ leere boya o ti ṣeto awọn ohun ija to lee koju eyi tawọn sbayejẹ yii n ko dani, fawọn agbofinro lawsn miran n pariwo  pe ileri bẹẹ kii n fi ẹsẹ mulẹ.
Ninu ọrọ tirẹ loju opo BBC News Yoruba  ni facebook,
Oríṣun àwòrán, Screenshot/facebook
Olusegun Obasanjo: Ọmú ìyá mi ti mo fi ń mùkọ ni kekere ló jẹ ki ń lókun
Prophet Muyideen Kasali: Ìjà ti parí láàrín wòlíì Kasali àti Bunmi Olasehinde tó jẹ́ ìyàwó rẹ̀ àkọ́kọ́
Oríṣun àwòrán, @DailyPostNGR
Gbajugbaja ajihinrere ati Wolii, Muyideen Kasali ati iyawo rẹ aarọ, Bunmi Olasehinde ti pari ija to wa laarin wọn.
Gẹgẹ bii ohun ti Wolii naa sọ, ọdun mẹta gbako ni tọkọtaya ọhun fi tuka ki ija to pari.
Tọkọtaya naa fi ẹri ifẹ wọn han ni gbagede isọji ita gbangba kan, nibi ti Wolii Kasali ti pe obinrin naa jade si ori aga iwaasu, to si fi ọwọ kọ ni ọrun.
"Lẹyin naa ni Kasali sọ fun obinrin naa pe ""ṣe o mọ pe mo ni ifẹ rẹ gidi"" ti obinrin ọhun si fesi pe oun naa nifẹ Wolii Kasali."
"Kasali wa sọ fun obinrin naa pe ""oo ni ṣe bẹẹ mọ abi?"" iyawo rẹ ọhun si fesi pe ""mi o ni ṣe bẹẹ mọ, ẹyin naa o ni ṣe bẹẹ mọ."""
Oríṣun àwòrán, Jingle Hobama TV
Inu idunnu ati ayọ ni awọn ololufẹ mejeji ọhun fi pari ija wọn loju gbogbo awọn eeyan to peju sibi ipade naa, ti wọn si tun fi ẹnu ko ara wọn lẹnu.
Ki lo ti kọkọ ṣẹlẹ?
Bi ẹ ko ba gbagbe, ṣaaju ni Wolii Kasali ti kọkọ sọ oriṣiriṣi ọrọ nipa iyawo rẹ naa lẹyin ti aarin wọn daru.
Wòlíì Kasali sọrọ nípa awuyewuye pé o lè ìyàwó rẹ̀ jáde nílé
Lara awọn awọn ohun to sọ ninu ifọrọwerọ pẹlu BBC Yoruba ni bi ija ṣe waye laarin wọn, ohun to ṣokunfa ija naa ati bi oun ṣe ni iyawo keji.
Lẹyin ija to waye laarin awọn mejeeji ni Kasali fẹ iyawo miran, iyẹn orekelẹwa, Dolapo Awosika.
Woli Kasali: Angẹli mi ni orékelẹ́wà Dọlapo Awoṣika
Nigba to n sọrọ ṣaaju nipa iyawo rẹ keji ọhun, Kasali sọ pe oun fẹran iyawo oun akọkọ, iyẹn Bunmi ti wọn ṣẹṣẹ pari ija yii, ati pe kii ṣe oogun ni oun fi de Dolapo mọlẹ gẹgẹ bii ahesọ ọrọ ti awọn kan n gbe kiri.
Nipa Dolapo naa, Kasali ni o jẹ ẹni ti Ọlọrun ran si oun, oun ko si le ju angẹli oun nu.
Fulani-Yoruba Crisis: Oba Soun ló fí mi jẹ ọba Sabo ni Ogbomọṣọ- Alh Haruna Bala Abdulsala
Lẹyinorẹyin, ija ti pari laarin Wolii Kasali ati aya rẹ akọkọ.
Pupọ awọn ololufẹ Wolii naa lo si ti n ki awọn mejeeji ku oriire igbesẹ tuntun ti wọn ṣẹṣẹ gbe ọhun.
Bo tillẹ jẹ pe afọju ni Wolii Kasali, ti wọn si bi i sinu idile Musulumi, ṣugbọn wọn ko bii gẹgẹ bii afọju, o si jẹ ọkan gboogi lara awọn Wolii ti ọpọ eeyan gbagbọ pe agbara Ọlọrun n bẹ pẹlu rẹ lasiko yii.
Francis Olusola Alao: Wọ́n ti ti ọ̀rọ̀ òṣèlú bọ ọ̀rs Sunday Igboho, ṣùgbọ́n..- Oba Olugbọn
Sasa market ibadan: Èèyàn méje dèrò àtìmọ́lé nítorí rògbòdìyàn wáyé nílùú Ibadan
Oríṣun àwòrán, Arakunrin akeredolu/twitter
Ile ẹjọ Majistreeti Iyaganku tọ n bẹ nilu Ibadan ti paṣẹ l'Ọjọbọ pe ki wọn sọ awọn ọkunrin meje kan si atimọle Abolongo to n bẹ l'Ọyọ lorii ẹsun ṣiṣẹ dukiya lofo ati iṣekupani lasiko rogbodiyan to waye ninu ọja Ṣaṣa.
Ileeṣẹ ọlọpaa gbe Tajudeen Oladunni, ẹni aadọta ọdun; Saburi Lawal, ẹni ọdun mẹtadinlogoji; Ojo Joshua, ẹni ọdun mẹẹdọgbọn; Adekunle Olanrewaju, ẹni ọdun mejidinlogoji.
Pẹlu Olagunju James, ẹni ọdun mẹrinlelogoji; Rasaq Yahya, ẹni ọdun mejilelọgbọn ati Olaide Olawuyi, to jẹ ẹni ogun ọdun lọ si ile ẹjọ lori ẹsun mẹfa ọtọọtọ to da lori i iditẹ, ṣiṣe dukiya lofo ati iṣekupani.
Fulani-Yoruba Crisis: Oba Soun ló fí mi jẹ ọba Sabo ni Ogbomọṣọ- Alh Haruna Bala Abdulsala
Adajọ I.O Osho ko gba ẹbẹ awọn afurasi naa lati gbe ẹjọ naa lọ sile ẹjọ mii.
O paṣẹ pe ki ileeṣẹ ọlọpaa da iwe ipẹjọ wọn pada si ọọfisi awọn agbefọba nipinlẹ Ọyọ fun amọran to peye lori ẹjọ naa.
Oríṣun àwòrán, Arakunrin akeredolu/twitter
Arabinrin Osho wa sun igbẹjọ ọhun siwaju di ọjọ kọkanla, oṣu Karun un, ọdun ti a wa yii.
Saaju ni agbẹjọro fun ijọba, Foluke Oladosu ti kọkọ sọ fun ile ẹjọ naa pe awọn afurasi naa lẹ idi apo pọ lati ṣiṣẹ laabi.
Ọladoṣu ni l'ọjọ kejila, oṣu Keji, ọdun yii, ni nnkan bi i aago mẹwa owurọ ni awọn afurasi ọhun ṣekupa Arakunrin Adeola Shakirudeen lẹyin ti wọn luu bi i ejo aijẹ.
Bakan naa ni ileeṣẹ ọlọpaa fi ẹsun kan awọn eeyan naa pe awọn afurasi ọhun tun ṣekupa awọn eeyan mọkanlelọgbọn miran.
Femi Falana, Endsars: Awolowo kò fáààyè gba kí èèyàn máa yàgò fún Màálù nígboro
Wọn fi kun ọrọ wọn pe awọn afurasi naa dana sun ile meji kan to jẹ ti Arakunrin Adelabu Ibrahim, ti wọn si fi dukiya ti o to bi i aadọta milliọnu naira ṣofo.
Ileeṣẹ ọlọpaa tẹsiwaju wi pe, awọn afurasi naa tun dana sun ile kan to jẹ ti Osuolale Akindele, ti wọn si ba dukiya ti o to ogun milliọnu naira jẹ.
Ileeṣẹ ọlọpaa ṣe alaye pe awọn ẹsun naa tako agbekale ofin ọdun 2000, eyii to n risi iwa ọdaran nipinlẹ Ọyọ.
#EndSars Ogbomoso: Èmí kò ní kí wọ́n pa ọlọ́pàá tó pa Isisaka, ṣùgbọ́n...- Ramota, Iya Isi
Kalashnikov AK-47: Ohun mẹ́fà tó yẹ kí o mọ̀ nípa ìbọn AK-47 rèé
Oríṣun àwòrán, Getty Images
O ti to nnkan bii ọjọ mẹta sẹyin ti ọpọ ọmọ Naijiria ti n ke gbajare si ijọba apapọ lati gba wọn lọwọ awọn Fulani darandaran to n gbe ibọn Ak-47 rin kaakiri.
Lara awọn ẹsun ti awọn eeyan fi kan awọn Fulani ọhun ni pe wọn n jinigbe, ti wọn si n gba owo itusilẹ lọwọ awọn eeyan.
Ọpọ awọn ọmọ Naijiria lo n bu ẹnu ẹtẹ lu Aarẹ Muhammamdu Buhari pe ko gbe igbesẹ kankan nipa ọrọ naa.
Koda, awọn kan tilẹ sọ pe Aarẹ ko sọrọ nitori pe oun ni baba isalẹ ẹgbẹ awọn darandaran, iyẹn Miyetti Allah.
Eredi ree ti ọkan lara awọn agbẹnusọ Buhari, Garba Shehu, fi sọ fun BBC pe Aarẹ ti paṣe pe ki awọn ọmọ ogun yinbo fun ẹnikẹni ti wọn ba ka ibọn Ak-47 naa mọ lọwọ.
Shehu sọ pe aṣẹ ọhun jẹ ọkan lara awọn ọna ti ijọba apapọ fẹ gba lati kapa iwa ọdaran ati ijinigbe ni Naijiria.
Ṣugbọn irufẹ ibọn wo gan an ni wọn n pe ni Ak-47 yii?
Eyi ni ibeere ti ọpọ n beere lori ayelujara ni eyi to jẹ ki BBC ṣe iwadii lori ibọn naa.
Francis Olusola Alao: Wọ́n ti ti ọ̀rọ̀ òṣèlú bọ ọ̀rs Sunday Igboho, ṣùgbọ́n..- Oba Olugbọn
Awọn ohun marun un to yẹ ki o mọ nipa ibọn AK-47 ree\:
Orukọ ibọn naa:
Orukọ ẹni to ṣe ibọn Ak-47 ni Mikhail Kalashnikov, ọmọ orilẹ-ede Rusia si ni ọkunrin naa.
Wọn ti n lo ibọn Ak-47 lati ọdun 1948 titi di akoko yii.
Orukọ ibọn naa gangan ni Avtomat Kalashnikova, ti awọn kan si n pe ni Kalashnikov.
Fulani-Yoruba Crisis: Oba Soun ló fí mi jẹ ọba Sabo ni Ogbomọṣọ- Alh Haruna Bala Abdulsala
Awọn to n lo AK-47
Lara awọn orilẹ-ede ti awọn ọmọ ogun wọn n lo ibọn AK-47 ni: Hungary, India, Indonesia, Iran, Iraq, Israel,  Lebanon lai yọ ileeṣẹ ọlọpaa Naijiria silẹ pẹlu.
Ṣe AK-47 ba ofin mu?
Ọrọ yii da lori orilẹ-ede ti eeyan ti n lo ibọn naa.
Labẹ ofin Naijiria, o lodi si ofin ki eeyan ti kii ṣe agbofinro tabi ọmọ ogun maa gbe ibọn AK-47 kiri.
Ki eeyan to le maa gbe ibọn AK-47 lọwọ, o ni lati gba aṣẹ lọwọ ijọba, ṣugbọn ọpọ lo n ra ibọna naa ni ọna aitọ kaakiri agbaye.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ọta melo ni Ak-47 le gbe lẹẹkan ṣoṣo?
Gẹgẹ bii iwadii ti ileeṣẹ iroyin military.com ṣe, ibọn AK-47 le yin ọta ẹgbẹta laarin iṣẹju aaya.
Olusegun Obasanjo: Ọmú ìyá mi ti mo fi ń mùkọ ni kekere ló jẹ ki ń lókun
Bawo ni ibọn yii ṣe buru to?
Awọn onimọ nipa ohun ija oloro sọ pe AK-47 ni ibọn to buru ju, to si le tete gbẹmi eeyan ju ti awọn ologun tii ṣe.
Gẹgẹ bii nnkan ti awọn onimọ nipa eto ilera sọ, ọta ibọn naa kan ṣoṣo le ba ẹya ara eeyan jẹ, o si tun lagbara lati mu ẹmi lọ ni iṣẹju aaya.
Sugbọn nigba miran, eyii da lori ibi ti ibọn naa ba ti ba eeyan ati bi ẹni to yi ibọn ọhun ba ṣe jina tabi sun mọ eeyan si.
Kilode ti ibọn yii ṣe gbajumọ lọwọ awọn agbesumọmi?
Ibọn naa rọrun lati gbe ka.
Eeyan ko si nilo lati kọ ẹkọ rẹpẹtẹ ko to le mọ bi wọn ṣe n yinbọn AK-47, idi ree to ṣe wọnpọ lọwọ awọn aṣẹrubalu tabi agbesumọmi.
Francis Olusola Alao: Wọ́n ti ti ọ̀rọ̀ òṣèlú bọ ọ̀rs Sunday Igboho, ṣùgbọ́n..- Oba Olugbọn
AK-47 nilẹ Amẹrika
Gẹgẹ bii itan ṣe sọ, o to ọdun 1950 ki ileeṣẹ ọmọ ogun Amẹrika to mọ nipa ibọn AK-47.
Bo tilẹ jẹ pe awọn ọmọ ogun ilẹ Anmẹrika kii ṣa baa lo ibọn Ak-47 yii, pupọ ninu awọn ọmọ ogun naa lo ni imọ nipa lilo rẹ.
South-Africa Crocodiles: A ti rí Ọọ̀nì ''crocodile'' 27 nínú àwọn tó sálọ, ẹ̀yin ará ìlú, ẹ ṣọ́ra
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ijọba orilẹede South-Africa ti kede wi pe awọn ṣi n wa awọn ọọni to sakuro ni ibi ti wọn ti n ṣin wọn ni agbegbe Western Cape Province, lorilẹede naa.
Awọn alaṣẹ ni awọn ti ri mẹtadinlọgbọn ninu awọn ooni naa, amọ awọn ko mọ iye awọn to ku ti wọn ṣi n wa.
Awọn ooni naa ni wọn sa kuro ni agbegbe gba ogiri kan to ya lulẹ ni ibi ti wọn ti n sin wọn ni Bonnievale, ti wọn si wọ inu omi Breede River.
Ijọba si ti kilọ fun awọn araalu lati ṣọra fun awọn ọọni ti wọn ba ri ni agbegbe wọn.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
''Awọn ọọni yii lewu, ẹranko igbo ni wọn, bi o tilẹ jẹpe ojukan ni wọn ti sin wọn.
''Awọn eniyan gbọdọ ṣọra fun agbegbe naa, titi ti wọn yoo fi ri awọn to ku gbe''.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ọjọọru, Ọjọ Kẹta, Oṣu Kẹta ni awọn ọọni naa ti wọn gun to iwọn mita kan abọ 1.5m (4ft 11in) sa kuro nibi ti wn ko wọn si.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ileeṣẹ ọlọpaa ti gbe ikọ kan kalẹ lati sawari awọn ọọni naa, ki wọn si gbe wọn si inu awọn ni eti omi CapeNature naa.
Bone setting: Adimula Kehinde Akinfenwa ṣàlàyé nípa irúfẹ́ ẹranko tí wọ́n fi ń to eegun èya ara èèyàn
A kò lé sọ pé kí wọ́n má to eegun pẹ̀lú ewé àti egbò mọ́ nítorií pé ó ń ṣiṣẹ́- Ojọgbọn Adebukola Ositelu
Oloye Adimula Kehinde Akinfẹnwa jẹ ọkan lara awọn oniṣegun ibilẹ to n to eegun to ba kan tabi to ba yẹ.
BBC ṣabẹwo lati mọ sii nipa ọna ti wọn n gba lọna ibile lati to eegun.
Oludari ileeṣẹ Adimula Olofin Orthopaedic Home Clinic yii sọ nipa ewe aato ati egungun ẹranko ati ohùn ti wọn n pe pẹlu awọn nkan mii ti wọn fi n jẹ ki egungun pada si aaye rẹ.
Kini iyatọ ti wọn fi n to eegun lọna ibilẹ ati tile iwosan igbalode isinyi?
BBC ba awọn alaisan ti wọn n to eegun wọn lọna ibilẹ sọrọ lori iriri wọn.
Lara wọn ni Abimbola ti eegun ọwọ rẹ kan nigba to n gba bọọlu ati Ogbeni Ogunjide Femi ti eegun rẹ kan nibi ijamba ọkọ.
Ogunjide Femi sọ ohun toju rẹ ti ri nipa iṣẹ abẹ ati itọju miran to ti gba.
Oloye Kehinde Akinfenwa Topatosẹ sọ nipa irufẹ ẹranko ti wọn n lo eegun rẹ fi to ti eeyan ati awọn ẹya ara to yẹ ni lilo fi ṣe ọṣẹ, ipara tabi oogun.
Dokita Adedamola Dada to jẹ Oniṣegun oyinbo naa ba BBC sọrọ lori iṣẹ egungun tito lọna igbalode tile iwosan.
O sọ pataki yiya fọto eegun to kan ṣaaju gbigba itọju kankan.
Onisegun Oyinbo Dada gba awọn eeyan nimọran lati ṣọra fun ewu lilọ kiri lai de ile iwosan ti eegun ẹni ba kan nitori pe o maa n jẹ ki iṣoro titun eegun naa ṣe pọ sii ni.
Bakan naa ni BBC tun kan si Ọjọgbọn Adebukọla Ositelu to jẹ alaga ajọ to n risi ọrọ awọn oniṣegun ibilẹ ni ipinlẹ Eko.
Ojọgbọn Adebukola Ositelu sọ ipa ti eto iṣegun ibilẹ n ko ninu ilera awọn eeyan Naijiria pe a ko le yọ wọn sẹyin.
O menuba ohun to ku ni ṣiṣe fun idagbasoke ona ilana itọju mejeeji ni Naijiria.
Pẹlu irufẹ ajọṣepọ to yẹ ko wa laarin awọn mejeeji.
Produced by Oyeyemi Mustapha
LASTMA, Alleged impersonation: Àjọ LASTMA ní ó ṣòro púpọ̀ láti mọ ayédèrú òṣìṣẹ́ àjọ náà l'Eko
Oríṣun àwòrán, Facebook/LASTMA
O nira gan an lati mọ awọn oṣiṣẹ ajọ LASTMA to jẹ ayederu yatọ si awọn t jẹ ojulowo.
Agbẹnusọ fun ajọ LASTMA nipinlẹ Eko, Olumide Filade lo fidi ọrọ yii mulẹ fun BBC Yoruba.
Ọgbẹni Filade sọ pe awọn ayederu oṣiṣẹ LASTMA maa n ṣi kiri lati agbegbe kan si omiran lo jẹ ko nira lati mu wọn Ọwọ́ pálábá ayédèrú òṣìṣẹ́ LASTMA ségi ní Mushin ní ìpínlẹ̀ Eko.
Ogbeni Falade ni: ayederu oṣiṣẹ LASTMA, Shakiru Agbaje ti ọwọ palaba rẹ segi di minu nitori awọn eeyan adugbo Mushin to ta ajọ naa lolobo.
O ni iṣẹ iwadii lo ṣe iranwọ ti ajọ LASTMA fi ri Ọgbẹni Agbaje mu.
Bone setting: Adimula Kehinde Akinfenwa ṣàlàyé nípa irúfẹ́ ẹranko tí wọ́n fi ń to eegun èy
Agbẹnusọ LASTMA sọ pe iwadii si n lọ lọwọ lori Agbaje ti wọn mọ.
Ọgbẹni Filade ṣalaye pe ọrọ naa ti dọdọ awọn ọlọpaa bayii nirori o niṣe pẹlu iwa ọdaran.
Sunday Igboho latest: Sunday Igboho kò gba 'Award'ti a fún un ní Ogo Yorùbá nítorí inú rẹ̀
Ogbeni Falade ni: ''LASTMA gba aṣọ lọwọ Agbaje lẹyin ti wọn da a duro lẹnu iṣẹ, ṣugbọn ọpọ iru wọn maa n ran aṣọ mii lati huwa ọdaran ni,'' agbẹnusọ LASTMA lo sọ bẹẹ.
O ni bawọn ti wọn ba ti da duro lẹnu iṣẹ ọlọpaa ati ologun ṣe maa n ran aṣọ lati maa lu awọn eeyan ni jibiti lawọn ti LASTMA naa ba duro maa n ṣe.
Ọwọ́ pálábá ayédèrú òṣìṣẹ́ LASTMA ségi ní Mushin ní ìpínlẹ̀ Eko
Ọwọ palaba ayederu oṣiṣẹ ẹṣọ oju popo LASTMA kan, Shakiru Agbaje, niluu Eko segi lẹyin ti ajọ naa fi ọwọ ofin mu un.
Ni agbegbe Mushin ni wọn ti gba Ọgbẹni Agbaje to ti figba kan ṣiṣẹ pẹlu ajọ LASTMA ṣugbọn ti wọn ti da duro lẹnu iṣẹ lati ọdun mẹsan an sẹyin mu.
Oríṣun àwòrán, Facebook/LASTMA
Nigba to n ṣalaye bi ajọ LASTMA ṣe gba ọkunrin naa mu, ọga agba LASTMA nipinlẹ Eko, Ọgbẹni Olajide Oduyoye sọ pe ajọ LASTMA da ọkunrin ọhun duro lẹnu iṣẹ lori o lo ayederu iwe ẹri ati pe o tun lu jibiti.
Oduyoye ni o ti pẹ ti Ọgbẹni Agbaje ti n dunkoko mawọn awakọ lagbegbe Mushin ti o si n huwa ọdaran nibi ti o ti n pe ara rẹ ni oṣiṣẹ LASTMA.
Ọga agba LASTMA ni oriṣiiriṣii iwa ọdaran ti Agbaje hu sawọn awakọ lagbegbe Mushin ti ba orukọ ajọ naa jẹ.
LASTMA Yesufa: Àwọn dókítà gbìyànjú lórí ojú mi ṣùgbọ́n...
O ni gbogbo awọn ti LASTMA ti da duro lẹnu iṣẹ ṣugbọn ti wọn si tun n wọ aṣọ LASTMA kiri lati huwa bajẹ lọwọ yoo tẹ.
Ọga agba LASTMA rọ awọn araalu lati maa wo orukọ awọn oṣiṣẹ LASTMA to ba dawọn duro tabi ni itakurọsọ pẹlu wọn.
Ọgbẹni Oduyoye rọ awọn awakọ lati pa gbogbo ofin irinna ipinlẹ mọ ti wọn ba n wakọ loju popo.
Ọga agba LASTMA naa sọ pe ajọ naa yoo fi to araalu leti iru ijiya to tọ si Agbaje lẹyin ti iṣẹ iwadii ba pari lori ọrọ naa.
Francis Olusola Alao: Wọ́n ti ti ọ̀rọ̀ òṣèlú bọ ọ̀rs Sunday Igboho, ṣùgbọ́n..- Oba Olugbọn
Takoradi girls: Iléẹjọ́ ti pàṣẹ pé kí wọ́n yẹgi fún ọmọ Nàìjíríà méjì tó mọ̀ nípa ikú àwọn ọmọbìnrin Ghana mẹ́rin
Oríṣun àwòrán, Ghana Police
Ariwo pọ lẹyin ti awọn ọmọbinrin yi di awati ni ọdun 2018
Awọn ọmọ Naijiria meji kan ni wọn ti ni ki wọn yẹgi fun ni Ghana bi wọn ba kọ lati tako idajọ ile ẹjọ lẹyin ọgbọn ọjọ.
Ile ẹjọ giga to wa ni Sekondi ni idajọ yi ti ṣaaju waye pe ki wọn yẹgi fun Samuel Udoetuk Wills ati John Oji lori awọn ọmọbinrin Takoradi kan ti wọn di awati.
Adajọ Richard Adjei-Frimpong ti ile ẹjọ Kotẹmilọrun tubọ fẹsẹ idajọ ile ẹjọ rinlẹ lọjọ Karun un, oṣu Kẹta, ọdun 2021.
Igbimọ adajọ ẹlẹnimeje to gbe idajọ yi kalẹ ni awọn arakunrin yi jẹbi ijinigbe ati iṣekupani awọn ọmọbinrin Takoradi mẹrin naa.
Wo ohun tí Professor Peller wí tó kó bá a gẹ́gẹ́ bí ìyàwó rẹ̀, Lady Peller ṣe tú u síta
Bawo ni ọrọ yii ṣe ṣẹlẹ?
Iṣẹlẹ bi awọn ọmọbinrin yi ṣe di awati ni Takoradi kan araalu lominu pupọ lẹyin tawọn obi wọn fẹjọ sun lagọ ọlọpaa pe awọn n wa wọn.
Niṣe ni iwọde bẹrẹ ti awọn ileeṣẹ iroyin Ghana naa si m'ọrọ yi bẹnu lati le ri wi pe awọn ọmọ ti wọn jigbe wọn yi di awati.
Oríṣun àwòrán, Ghana Police
Samuel Udoetuk Wills and John Oji
Lẹyin ọpọ iwadii awọn ọlọpaa ri eegun awọn ọmọ yi ninu 'soak-away'.
Ayẹwo ti wọn ṣe nipa DNA fi han pe loṣu Kẹwaa, ọdun 2020 pe aṣẹku eegun yi jẹ ti awọn ọmọbinrin ti wọn n wa ọhun.
Bone setting: Adimula Kehinde Akinfenwa ṣàlàyé nípa irúfẹ́ ẹranko tí wọ́n fi ń to eegun èy
Osun Kidnap rescue: Àwọn ọlọ́pàá dóòlà ẹ̀mí arìnrìnàjò méje tí wọ́n jígbé ní Ibokun
Oríṣun àwòrán, AFP
Ìgbà àkọ́kọ́ kọ́ nìyí tí irú ìṣẹ̀lẹ̀ bẹ̀ yòó wáyé
Ileeṣẹ ọlọpaa nipinlẹ Osun ti kede pe awọn ti ribi doola arinrinajo meje lọwọ awọn ajinigbe.
Alukoro ileeṣẹ naa Yemisi Opalola lo lede ọrọ fun ileeṣẹ BBC ninu atẹjade kan lọjọ Abamẹta.
O ni awọn doola ẹmi awọn arinrinajo naa nipa ajọsepọ pẹlu awọn ẹsọ alaabo mii.
Yemisi ṣalaye pe loju ọna Ibokun / Osogbo lawọn ajinigbe wọn yi ti jin awọn arinrinajo naa gbe lọjọ Iṣẹgun.
Lasiko ikọlu yi, a gbọ pe eeyan kan ku ti awọn meji si farapa lasiko ti awọn ajinigbe yi ṣe ikọlu si wọn labule Ajebandele ni ijọba ibilẹ Ibokun.
Oba Sunday Oyediran ṣàlàyé kíkún nípa ìṣẹ̀ṣe, ìgbàgbọ́ àti ẹ̀sìn tí kò dí ará wọn lọ́wọ́
Agbofinro Yemisi ko sọ boya awọn ri awọn ajinigbe ọhun mu ṣugbọn o ni niṣe ni wọn tu awọn arinrinajo naa silẹ nigba ti awọn fungun mọ wọn.
O tẹsiwaju pe awọn ti wọn doola ko ni pẹ darapọ mọ mọlẹbi wọn.
Orisabunmi, Ibidapọ-Obe, Akin Olugbade, Martins Kuye, Lateef Jakande: Àwọn eèkàn ọmọ Yorùbá tó ti jáde láyé lọ́dún 2021 nìkan
Oríṣun àwòrán, others
Wo àwọn eèkàn ọmọ Yorùbá tó ti jáde láyé lọ́dún 2021 nìkan
Ọdun to ti mu ọpọlọpọ la oriṣiriṣi nnkan kọja ni ọdun 2021 jẹ bi o tilẹ jẹ pe ko tii ju ọsu mẹta lọ ti ọdun naa bẹrẹ.
Ọpọlọpọ to ku ni iku wọn ko ṣẹyin ajakalẹ arun COVID-19 ti awọn miran si tun ku iku miran yala nitori ọjọ ogbo, ikọlu awọn agbebọn darandaran, ijamba ọkọ tabi awọn aisan miran.
Eyi ni akọsilẹ awọn orukọ awọn eekan ọmọ Yoruba to ti di araalẹ laarin oṣu mẹta akọkọ lọdun 2021.
Oríṣun àwòrán, @Ibidapo-Obe
1.Ọjọgbọn Ibidapọ-Obe:
Purofẹsọ Ibidapọ-Obe ni giwa faisiti ilu Eko, UNILAG tẹlẹ.
Bakan naa lo tun fi igbakan ri jẹ giwa fun fasiti Alex Ekwueme Federal University ni ilu Ndufu-Alike.
Bone setting: Adimula Kehinde Akinfenwa ṣàlàyé nípa irúfẹ́ ẹranko tí wọ́n fi ń to eegun èy
Ọjọgbọn  Oyewusi Ibidapo-Obe jade laye ni ọjọ kẹta, oṣu kini, ọdun 2021.
Ohun ti araye gbọ ni pe aarun COVID-19 lo ṣokunfa iku rẹ.
Iyalẹnu nla ni iku rẹ jẹ fun ọpọlọpọ awọn eeyan paapaajulọ lagbo ẹkọ lorilẹede Naijiria ati lagbaye.
Oríṣun àwòrán, @Orisabunmi
2. Arabinrin Folake Aremu (Orisabunmi):
Eekan elere itage ati sinima ni arabinrin Folake Aremu ti ọpọlọpọ mọ si Orisabunmi.
Ọjọ karun un, oṣu kini ọdun 2021 ni Oriṣabunmi jade laye.
Fulani-Yoruba Crisis: Oba Soun ló fí mi jẹ ọba Sabo ni Ogbomọṣọ- Alh Haruna Bala Abdulsala
Iku rẹ si fẹ afẹfẹ ibanujẹ nlanla si agbo awọn oṣere tiata.
Ọmọ ilu Olla ni ipinlẹ  Kwara ni Oriṣabunmi, ẹni õgọta ọdun si ni nigba to jade laye.
Lẹyin oṣu mẹrin ti ọkọ rẹ tẹlẹ, Jimoh Aliu jade laye ni iku mu oun pẹlu lọ.
Oríṣun àwòrán, @Folabi Olumide
3. Ọjọgbọn Folabi Olumide:
Ọjọgbọn Folabi Olumide ni giwa akọkọ fun fasiti ipinlẹ Eko, LASU, ọjọ Ẹti ọjọ kẹjọ oṣu kini ni wọn ju awà silẹ.
Aisan ranpẹ lo muu lọ si alakeji lẹni ọdun mọkanlelọgọrin.
4. Aare Boluwatife Akin-Olugbade:
Aare Boluwatife Akin-Olugbade ni Aare Ona Kakanfo ti Owu nilu Abẹokuta.
Lagbaye ni wọn ti mọ si ọkan gboogi lara awọn to nifẹ ọkọ Rolls-Royce julọ.
Oríṣun àwòrán, @Akin-Olugbade
Ọjọ kẹrinla, oṣu kini, ọdun 2021 ni ajakalẹ arun COVID-19 wọle mu u lọ.
Amofin to kọṣẹmọsẹ gboye ọmọwe ninu imọ ofin nipa ileeṣẹ ni ni fasiti Cambridge.
Ọkọ Rolls Royce mẹwaa ni oun nikan niti owo rẹ n lọ si ẹgbẹlẹgbẹ biliọnu naira.
Ẹni ọdun mẹrinlelọgọta ni ki ọlọjọ to de.
5. Martins Kuye:
Martins Kuyẹ fi igbakanri jẹ minisita fun ọrọ iṣuna lorilẹede Naijiria.
Eekan ẹgbẹ oṣelu PDP si ni pẹlu ki o to jadelaye ni ọjọ kẹtadinlogun oṣu kini ọdun 2021.
Onimọ nipa ibagnepọ ẹda( socioloist) ati ọrọ aje (economist) ni.
Igba meji ọtọtọ lo si gbiyanju ati di gomina ipinlẹ Ogun ṣugbọn ti ko bọ si ki ọlọjọ to de.
Oríṣun àwòrán, @Martins Kuye
6. Alhaji Lateef Jakande:
Gomina tẹlẹ fun ipinlẹ Eko, Lateef Jakande jade laye ni ọjọ kọkanla oṣu keji ọdun 2021.
Ẹni ọdun mọkanlelaadọrun ni Baba kekere nigba to jade laye.
Sunday Igboho latest: Sunday Igboho kò gba 'Award'ti a fún un ní Ogo Yorùbá nítorí inú rẹ̀
Akọroyin to dantọ ni ki o to di gomina ipinlẹ Eko laarin ọdun 1979 si 1983.
Nigba to ya, o di minisita fun iṣẹ ode labẹ iṣejọba Ọgagun Sani Abacha laarin ọdun 1993 si 1998.
Fulani-Yoruba Crisis: Oba Soun ló fí mi jẹ ọba Sabo ni Ogbomọṣọ- Alh Haruna Bala Abdulsala
Akute NNPC Fire Incidence 2021: Iná ń jó lọ́wọ́ ní Akute nitòsí Berger báyìí
Awọn panapana ipinlẹ Eko ti de sibẹ ni kopẹ ti awọn ara Akute ranṣẹ pe wọn.
Wọn si ti pa ina naa to ṣẹyọ ni Akute ni idaji oni.
Àwọn panápaná ti pa iná tó ṣẹ́yọ nídàjí òní nílé epo NNPC ní Akute nitòsí Berger báyìí
Iroyin to n tẹ wa lọwọ ni pe ina n jo bayii ni Akute ni ipinlẹ Ogun nitosi Berger.
Bone setting: Adimula Kehinde Akinfenwa ṣàlàyé nípa irúfẹ́ ẹranko tí wọ́n fi ń to eegun èy
Iná ń jó lọ́wọ́ ní Akute nitòsí Berger báyìí
Iroyin to n tẹ wa lọwọ ni pe ina n jo bayii ni Akute ni ipinlẹ Ogun nitosi Berger.
Arakunrin Tolu ti iṣẹlẹ naa ṣoju rẹ ṣalaye pe ina naa deede sọ nile epo NNPC to wa lẹgbẹ Ajayi Farm Bus stop ni Akute.
O ni ọkọ agbepo kan kan fẹ ja epo sinu agba nile epo naa ni ina deede ṣẹyọ.
O ni wọn gbiyanju lati fi apa ina Fire Extinguisher pa ina na sugbọn ẹpa ko boro mọ.
Ina naa ti ran opo ina ati waya rẹ ti epo rọbi sti ti da sinu gọta ni eyi ti ina naa n gba ran kakiri.
Bayii ọpọ awọn eeyan ti n gbiyanju lati pa ina naa lara awọn ile kọọkan ni Akute.
Wọn ti n pe awọn panapana bayii ni agbegbe Akute.
BBC yoo maa mu gbogbo bo ba ṣe n lọ wa fun un yin loju opo yii
Professor Peller: Lọjọ ti Professor Peller gé mi sí méjì lójú ìdán, ó gbìyànjú, ó láàgùn, ṣùgbọn ... - Lady Peller
Iyawo gbajugbaja ọlọwọ idan ti gbogbo agbaye mọ, Professor Peller ni Lady Peller bẹẹ naa si ni oun ni alabaṣiṣẹpọ rẹ.
"Oun funrarẹ sọ fun BBC Yoruba pe ""mo ba Professor Peller ṣiṣẹ́ dáadáa, opidan ni Professor Peller, opidan lemi naa, iṣẹ taa dẹ n ṣe niyẹn""."
Lọjọ ti gbajugbaja olorin Afro ọmọ Naijiria, Fela Anikulapo Kuti ku naa ni iroyin tun kan nigboro pe Professor Peller ti di oloogbe.
Alhaja Silifat Abiola Peller ti gbogbo eniyan mọ si Lady Peller ṣalaye ọ̀rọ̀ lori ọjọ buruku ti Eṣu gbomi mu eyi ti Professor Peller n lo iyawo rẹ lọwọ lati pidan toti baba ge e si meji amọ ti ko tete ri i da pada wa saye.
Iṣẹlẹ ọjọ naa mu ki awọn eeyan to wa wo iran lẹyin igba naa ti Professor Peller bọ sori itage lati pidan pe Lady Peller lawọn fẹ ri toripe wọn ko ri aaye rẹ lati igba ti opidan ọkọ rẹ ti ge e si meji lori itage.
Ọrọ̀ kunlẹ ti Lady Peller sọ fun akọroyin BBC Yoruba lori ọpọlọpọ ohun to n ru awọn eeyan ati oluworan ọjọ naa loju titi di oni.
"Lady Peller sọ fun araye gbọ́ pe ""Musulumi gidi lemi, Musulumi gidi ni ọkọ mi"" pẹlu bi wọn ṣe n pidan to."
"O ni Ọlọrun mọ pe oun fẹ pe e si Aljana naa lo fi jẹ ko wa lori irun Sujud to fi jade laye ti awọn to ṣọ ọ fi ri i pa tori o jẹwọ igba ti kii si ogun kankan lara oun pe ""igba tu mo ba n kirun fun ọlọrun mi ni""."
Israel Adesanya fìdí rẹmi lọ́wọ́ Blachowicz ní ìdíje UFC259
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Abẹsẹkubiojo ọmọ Naijiria Israel Adesanya ko ribi jẹwọ ara rẹ bi ọmọ Akin pẹlu bo ti ṣe padanu anfaani lati ni igbanu ẹyẹ, bẹliti meji lẹẹkan ṣoṣo ninu idije UFC259.
O kuna pẹlu bi alatako rẹ Jan Blachowicz ṣe fidi rẹ janlẹ ninu ija wọn to waye ni Las Vegas lọjọ Aiku.
Ninu abala marun un ija naa, awọn adajọ sọ pe Blachowicz lẹni to ṣe daada julọ pẹlu awọn ẹsẹ to rọ bo Adesanya.
Ni bayi, Blachowicz  ṣi yi di bẹliti light heavyweight rẹ mu ti Adesanya naa si duro lẹgbẹ kẹjẹbu rẹ tii ṣe middleweight.
Ninu ọrọ rẹ to sọ lẹyin ija naa, Adesanya ni ko saburu nibi ifidirẹmi naa nitori igbiyanju loun gba lati fi itan lelẹ.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
O ni lootọ ni Blachowicz tobi ju oun lọ ati pe o yẹ ki oun ṣapa ju bi oun ti ṣe ṣe lọ.
Igba akọkọ ree ti abẹsẹkubiojo naa yoo fidirẹmi lọwọ awọn alatako rẹ ninu idije UFC.
Awọn ololufẹ Adesanya kan sara si pẹlu bo ti ṣe koju Blachowicz to tobi ju lọ.
Amar_23 ninu ọrọ rẹ ni ko saburu bi Izzy ti ṣe fidirẹmi nitori o gbiyanju lati sun siwaju kuro ni ipele to wa
Chisanga Malata ni akinkanju ni Adesanya ti o si yẹ kawọn eeyan gboṣuba kaare fun un.
Wo ohun tí Professor Peller wí tó kó bá a gẹ́gẹ́ bí ìyàwó rẹ̀, Lady Peller ṣe tú u síta
Kwara Hijab Crisis: Ìjọbá ńi akẹ́kọ̀ọ́bìnrin Mùṣùlùmí le lo ìbòrí gẹ́gẹ́ bó ṣe ń wáyé l‘Eko, Osun, Oyo
Ijọba ipinlẹ Kwara ti kede pe kawọn ileewe mẹwa to gbe ti pa tẹlẹ nitori aawọ lilo Hijab di sisi pada.
Atẹjade kan tijọba fisita lo sisọ loju ọrọ yii pẹlu afikun pe bi ijọba se fọwọsi ilana pe akẹkọọbinrin to ba nifẹ lati lo Hijab lawọn ileẹkọ ijọba le lo yoo mu ki alaafia jọba, ti ibagbepọ alaafia yoo si wa.
Igbesẹ alaafia ta gbe yii yoo mu ibọwọfunraẹni, agbọye ati alaafia pada sawọn ileẹkọ, paapaa niwọn igba ti ẹkun ariwa Naijiria ati ọpọ ipinlẹ lẹkun iwọ oorun guusu bii Eko, Osun, Ekiti ati Oyo ti fara mọ pe kawọn akẹkọbinrin maa lo Hijab.
"Nibayii tawọn akẹkọ n wọle pada si kilaasi, ijọba n sakiyesi isoro ti ọpọ awọn akẹkọjade to fẹ sedanwo WAEC n koju.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
A si ti pasẹ pe kawọn ile ẹkọ ti wọn ti pa tẹlẹ naa maa se afikun lẹsinni wakati meji fawọn akẹkọjade naa lẹyin ti akoko eto ẹkọ ba pari lojoojumọ, tijọba yoo si tun pese ipanu fun wọn."
Ijọba ipinlẹ Kwara wa gbosuba fawọn asaaju Kristiẹni ati Musulumi fun agbọye wọn ati aayan lati jẹ ki alaafia jọba lagbegbe wọn lati ọsẹ diẹ sẹyin ti rogbodiyan naa ti bẹrẹ.
Gbogbo àwọn ti ọ̀rọ̀ kan nípìnlẹ̀ Kwwara lo ti n sọ ìwòyè wọ́n lórí rúkèrúdò tó n wáye ní ìpínlẹ̀ Kwara
Sáájú ni égbẹ́ ọmọlẹ́yìn Kriténi ti sọ èrò wọ́n, bákan náà ni BBC Yoruba bá akọwé ẹgbẹ́ IEDPU nílùú Ilorin sọ̀rọ̀
Lásìkò tó n bá wá sọ̀rọ̀ ó sàlàyé pé ìgbésẹ̀ ìjọba tọ̀nà ó sì bá òfin mú, nítorí pé kò sí ǹkan tó tako òfin nínú ǹkan to ti n wáyé tẹ́lẹ̀.
O ní gbogbo eniyan lo ni ẹtọ lati peju si ibikibi ninu awujọ gẹ́gẹ́ bi ofin se sọ.
Ẹtọ ọmọ Musulumi ni lati lo Hijab nítori ilana lati sin ẹsin to wú wọ́n jẹ́ ọkan lara ẹtọ ọmọniyan, bákan náà ni wọ́n le wọ irú asọ to bá wù wọ́n.
Ọjọgbọn Oba Abdulhamid salaye pe ti eniyan ba ti wa ni iru ẹtọ yii, gbogbo ibi to ba ti jẹ ìta gbpangba ni, wọn lẹtọ lati wọ ibẹ̀.
Àwọn ilé iwé yìí owó ori ni wọn fi n san owo àwọn olùkọ tó wà nibẹ, nítori naa nkan ijọba ni. Ọ̀rọ̀ Hijab kìí se ǹkan tuntun n\itori náà kò yẹ kí ó jẹ́ ǹkan ti yóò maa dí ọja ọla àwọn ọmọ lọ́wọ́
Oríṣun àwòrán, IEDPU
"Ẹlẹ́sìn méjèèjì ló ti jọ n gbé pọ̀ lálàfíà láti ẹ̀yìn wá tí kò sì sí wàhálà, láyèé ti ọ̀pọ̀ ń sáré láti gbé àwọn ǹkan mere mere ṣe yìí kìí ṣe ọ̀rọ̀ ẹsin ló yẹ lásìkò yìí"""
Ọ̀jọ̀gban náà ni kò pé kí ẹlẹ́sìn ọ̀tọ̀ọ̀tọ máa dá wà pàápàá jùlọ ni àwọn ilé iwé, ó sọ èyí nítorí àwọn tó n sọ pé ki àwọn tó bá jk musùlùmí máa lọ sí ilé ìwé tí Musulumi bá dá síll kí àwọn Kiristẹ́nì sì má lọ sí ibi tí wọ́n.
Ó ní ó ṣe pàtàkì kí àwọn ọmọ náà mọ bi à ti 'se n gbépọ̀ láti àsìkò yìí kìí ṣe ìgbà ti wọ́n bá dàgbà tan ni wan yóò ṣẹ̀ṣẹ̀ wá máa gbìyànjú láti bárawọn ṣe.  A ni ǹkan ti a fẹ́ kọ́ lọ́dọ̀ ara wa.
Ọ̀rẹ́ tímọ́tímọ́ ọmọ mi Janet ni orúkọ rẹ̀, emi funra mi a ma bá pé ó sì má n wá sí ilé wa  bí ó ṣe yẹ kí o rí níyẹ̀n.
Ó  wá sàlàyé pé, tí àwọn kristẹni bá le gba àwọn ilé ìwé yìí padà lọ́wọ́ ìjọba, ìgbà yẹ ni yóò se gbọ́ nítorí wọ́n le gbé òfin kalẹ̀. Sùgbọ́n títí dí àsìkò yìí, àti ìjọba apapọ àti tí ìpínlẹ̀ kò sí ẹni tó dáhun láti dá ilé ìwé padà fún wọ́n.
IEDPU jẹ́ ẹgbẹ́ ìtẹ̀síwájú àti ìdàgbàsókè , ibásepọ àti ìrẹ́pọ̀ ọmọ bíbí ìlú Ilorin to wà ni ìjọba ìbílẹ̀ márùn ní ìpínlẹ̀ Kwara.
Ẹgbẹ ọmọlẹyin Kristi ni ipinlẹ Kwara ti fesi si bi awọn ọmọ ẹgbẹ naa kan se pejọ si ileewe ti ijọba Kwara sọ pe ko wa ni titi pa nitori wahala wiwọ Hijab.
CAN sọ pe ko si ohun to buru ti ẹnikẹni ba fi ẹhonu han lori lilo Hijab paapa lawọn ileewe Kristẹni nitori ofin faye gba iwọde.
Ẹgbẹ naa sọ pe lopin igba ti ko ba ti mu ija wa ko saburu nibẹ.  Ọkan lara awọn ọmọ ẹgbẹ naa to ba BBC Yoruba sọrọ lo fidi ọrọ yi mulẹ.
Aposteeli Sina Ibiyemi to jẹ oludari eto ofin f'ẹgbẹ CAN Kwara ṣalaye pe awọn ko ni ki eeyan kankan ma ṣẹsin tirẹ.
O ni awọn ko ṣẹṣẹ bẹrẹ si ni fa ọrọ yi ati pe nkan meji pere lawọn fẹ.
Akọkọ, ki ijọba Kwara da ileewe ti wọn gba lọwọ awọn pada ki awọn eeyan si maa lo Hijab nileewe awọn.
''Awọn eeyan kan lo fẹ funkun mọ Gomina ki wọn fi le fofin lilo Hijab lawọn ileewe rinlẹ mọ wa lori.''
O tẹsiwaju pe bi ijọba ti ṣe ti awọn ileewe yi pa, alaafia ni wọn wa ṣugbọn ki wọn ṣe ohun to ba tọ ki alaafia le jọba.
Ibiyemi tẹsiwaju pe olu ilu ipinlẹ Kwara kii ṣe ti ẹnikan nitori naa ko yẹ ki awọn kan maa jẹ gaba lori awọn araalu to ku.
''Ijọba ni lati sayẹwo ẹtọ gbogbo eeyan nipinlẹ yi, ẹnikẹni to ba fẹ ki awọn ọmọ wọn lo Hijab nileewe, ki wọn gbe wọn lọ si Mọdirasa tabi awọn ileewe ti musulumi ba da ni''
Akọroyin BBC to kaakiri awọn ileewe ti ijọba tipa jabọ pe titi pa lawọn ileewe naa wa.
Yatọ si ni ileewe Baptist Secondary School ti awọn kan ti dana sun taya, pupọ awọn ileewe yi ni o wa ni titi pa ti ko si si wahala kankan.
Ijọba ipinlẹ Kwara ti kede pe awọn ileẹkọ ti wọn gbe ti pa nitori wahala lilo Hijab yoo ṣi wa bẹẹ nitori aabo.
Ileeṣẹ eto ẹkọ ipinlẹ naa lo fi atẹjade sita lọjọ Aiku.
Ninu atẹjade ọhun ti arabinrin Kemi Adeosun to jẹ akọwe agba buwọlu, wọn ni awọn gbe igbesẹ naa nitori aabo.
Wo ohun tí Professor Peller wí tó kó bá a gẹ́gẹ́ bí ìyàwó rẹ̀, Lady Peller ṣe tú u síta
Lọjọ Aje tii ṣe ọjọ Kẹjọ oṣu Kẹta lo yẹ ki wọn ṣi awọn ileewe girama mẹwaa yi pada.
Wahala ọrọ Hijab yi ti n rugbo bọ o to ọjọ mẹta ki ijọba to wa kede pe ki wọn ti awọn ileewe mẹwaa kan ti awọn Kristẹni sọ pe awọn lawọn n ṣe akoso wọn.
Mina la voilée, olorin to tun jẹ ajafẹtọ obinri
Lọjọ kọkandilogun Osu keji ni wọn gbe aṣẹ yi jade nitori iwọde tawọn akẹkọọ ati ẹgbẹ musulumi kan ṣe pe awọn alakoso ileewe naa ko jẹ ki awọn ọmọbinrin lo Hijab.
Awọn ileewe ti wọn ti pa naa wa bẹẹ ti ijọba si gbe igbimọ kan kalẹ lati ṣagbeyẹwo ọrọ naa.
Ababọ igbimọ naa ni pe ijọba paṣẹ pe awọn ọmọ musulumi lẹtọ lati lo Hijab ni eyikeyi ileewe nipinlẹ naa.
Ọrọ yi ko dun mọ ẹgbẹ awọn ọmọlẹyin Kristi CAN ti wọn si leri pe awọn ko ni gba ki awọn ọmọ musulumi wọ Hijab nile ẹkọ wọn.
Kaakiri loju opo Whatsapp ati loju opo ayelujara awọn ikọ mejeeji, musulumi ati Kristẹni ti n leri leka  pe awọn ko ni gba.
Pẹlu ohun ti ijọba wa ṣe yi, o daju pe wọn ko fẹ ki wahala bẹ silẹ nigba ti wọn ba ṣi awọn ileewe yi pada ni wọn fi ni ki wọn ṣi wa ni titi pa.
Apam beach: Ọlọ́pàá ní àwọn ríbi dóòlà ọmọdé méjì ṣugbọn méjìlá bá odò lọ̀ ní Ghana
Oríṣun àwòrán, Adom News
Alukoro ọlọpaa DSP Irene Oppong ni Cape Coast sọ pe awọn gbẹsun kan lati ọdọ Kwame Akono ni nkan bi ago mẹjọ alẹ kọja.
Ileeṣẹ ọlọpaa ti bẹrẹ iwadii lori ohun to ṣokunfa iku awọn ọmọde mejila to lọ wẹ lodo Apam Beach lagbegbe aarin gbungbun ilẹ naa  lorileede Ghana.
Iṣẹlẹ yi waye lọjọ Kẹjọ oṣu Kẹta ọdun yii.
Ninu atẹjade ti ileeṣẹ ọlọpaa agbegbe naa fi sita, wọn ni ''wọn gbe oku awọn ọmọde mejila ọhun jade lodo ti wọn si doola ẹmi awọn meji''
Wakili tẹẹ rí yẹn kìí ṣe ẹran rírọ̀, ó ń díbọ́n ní o - Iba Gani Adams
Ninu ọrọ rẹ, Akono sọ pe ibatan rẹ Joshua Annor ẹni ọdun mẹẹdogun ti bodo lọ lasiko to lọ gba bọọlu lẹgbẹ odo pẹlu awọn ọrẹ rẹ.
Niṣe latẹjade naa sọ pe awọn ọlọpaa sare lọ sibẹ lati lọ mọ ohun to ṣẹlẹ.
''Ori ba wa ṣe e, a ribi doola Simon Dadzie ọmọọdun mẹẹdogun ati Godfred Appretsie ọmọọdun mẹrinla ti wọn si n gba itọju nile iwosan''
Yemen Water Child: Ọmọdé 44 ni Sọ́jà pa, tí 100 míì sì kú látọwọ́ ohun ìjà olóró
O tẹsiwaju pe awọn pada ribi yọ oku mejila mii lodo ti ọjọ ori awọn ọmọ naa si jẹ bi ọdun mẹrinla si mẹtadinlogun lwourọ ọjọ Aje. Obinrin meji wa ninu wọn.
Bẹẹ ni awọn ọlọpaa sọ pe iwadii ṣi n tẹsiwaju lati mọ ohun to ṣẹlẹ ni pato.
Igbiyanju ṣi n tẹsiwaju lati ṣawari awọn miran to ba ṣi wa ninu omi naa.
Wa wo èré èyí tó yẹ fún àárọ̀ kùtù àti èyi tó wà fún òṣúpá
Iroyin to n tẹwa lọwọ ti a ko ridi rẹ fi mul sọ pe o top awọn ọmọde ogun to gba ọna ẹburu lọ wẹ lodo naa.
Awọn araadugbo sọ pe nitori ilana Covid-19 to wa nita awọn ọmọ yi y jade lati lọ wẹ lodo ni nitori ko si igbalaye lati wẹ nibẹ.
Wọn nitori ọna ti wọn gba yi ni wọn ko fi tete mọ pe wọn ko si odo titi di ọjọ Aje lati ọjọ Aiku ti wọn ti lọ.
Ko daju bi awọn agbofinro ko ṣe mọ pe awọn ọmọ yi yọ gb'ọna  ẹburu lati lọ we lodo.
Wakili Arrest: Iléeṣẹ́ ọlọ́pàá ti tú àwọn ọmọ ẹgbẹ́ OPC tó mú Wakili sílẹ̀
Oríṣun àwòrán, Facebook/OPC Diary
Awọn ọmọ ẹgbẹ OPC mẹta ti ileeṣẹ ọlọpaa ti mọle lori ẹsun wi pe wọn mu Wakili ti gba itusilẹ kuro ni agọ ọlọpaa lẹyin ti wọn gba oniduro wọn.Wọn kuro ni atimọlẹ ọlọpaa to n bẹ ni Iyaganku nilu Ibadan ni nnkan bi i aago mẹfa irọlẹ ku ogun iṣẹju l'ọjọ Iṣẹgun.
Itusilẹ naa ko se lẹyin igbesẹ ijọba ipinlẹ Ọyọ ati Aarẹ Ọna Kakanfo ilẹ Yoruba, Iba Gani Adams.
"Adari OPC nipinlẹ Ọyọ, Arakunrin Rotimi Oguntunde ti gbogbo eeyan mọ si ""Olumọ"", alamọran pataki si gomina ipinlẹ Ọyọ lori i aṣa ati irinajo igbafẹ, Hon. Ademola Akeem Ige ati agbẹjọro fun OPC lo tẹwọgba awọn ọmọ ẹgbẹ naa."
Iroyin to n tẹ wa lọwọ sọ pe ileeṣẹ ọlọpaa ti gbe awọn ọmọ ẹgbẹ OPC ti wọn mu ogbontagi Fulani daran daradaran, Isikilu Wakili lọ si ilu Abuja.
Iroyin ti a gbọ ni pe ọkan lara awọn oludamọran fun Aarẹ Muhammadu Buhari lo paṣẹ pe ki wọn gbe awọn eeyan naa wa si ilu Abuja.
Awọn ọmọ ẹgbẹ OPC naa wa lara awọn ẹṣọ to ṣiṣẹ pọ mu Wakili lagbegbe Ibarapa nipinlẹ Oyo.
Bí ìjọba, ọlọ́pàá, ológun, Amotekun ò bá le gbà wá, àwa mú Wakili láti gba ìran Yorùbá sílẹ̀ ni - OPC
Amọ, agbẹnusọ fun ileeṣẹ ọlọpaa nipinlẹ Oyo, Olugbenga Fadeyi sọ fun BBC Yoruba pe awọn ọmọ ẹgbẹ OPC naa si wa ni ẹka awọn ọtẹlẹmuyẹ ni Iyaganku niluu Ibadan.
Ẹsun ifipabanilopọ, ijinigbe ati ipaniyan ni wọn awọn eeyan Ibarapa fi kan Wakili ki ọwọ OPC to tẹ ẹ.
Oríṣun àwòrán, OPC
Ẹwẹ, Aarẹ Onakakanfo ilẹ Yoruba, Iba Gani Adams bu ẹnu atẹ lu bi ileeṣẹ ọlọpaa ṣe ju awọn ọmọ ẹgbẹ OPC to wa labẹ rẹ si atimọle.
O ni iranwọ lasan ni awọn OPC ṣe fun ileeṣẹ ọlọpaa lori ati wa ojutu si eto abo to mẹhẹ kaakiri ipinlẹ Oyo.
Gani Adams ṣalaye ọdaran pọnbele ni Wakili, o ni o kan n dibọn lasan ni fawọn ọlọpaa.
Wa wo èré èyí tó yẹ fún àárọ̀ kùtù àti èyi tó wà fún òṣúpá
James Ibori: Ìjọba UK yóò dá bílíọ̀nù méjì(N2b) owó tí Ibori kó pamọ́ padà sí Nàìjíríà
Oríṣun àwòrán, Metropolitan Police
Ijọba orilẹede UK ti ṣeleri lati da owo to le ni biliọnu meji naira(2,206,888,400) lara owo ti gomina ipinlẹ Delta tẹlẹ ri, James Ibori ji ko pamọ si orilẹede naa pada si Naijiria.
Gomina ipinlẹ Delta tẹlẹ ri jẹbi ẹsun ikowo pamọ silẹ okeere lọna aitọ ti wọn fi kan an lọdun 2012.
Owo to le ni biliọnu mejidinlọgbọn ni wọn fẹsun kan Ibori pe o ji ko lọ silẹ okeere lati Delta.
Awọn alaṣẹ orilẹede Uk ṣalaye pe igba akọkọ ree ti ti orilẹede Gẹeṣi yoo da owo ti wọn ri gba lati ọwọ ọdaran pada si Naijiria.
Ọdun 2016 ni Naijiria ati ijọba ilẹ Gẹẹsi kọwọ bọ iwe adehun ninu eyi ti ijọba UK ti ṣeleri lati maa da owo tawọn ọmọ Naijiria ba ji ko wa si orilẹede naa pada si Naijiria.
Ọjọ Iṣẹgun, ọjọ kẹsan an oṣu kẹta ọdun 2021 ni aṣoju ijọba orilẹede UK ati Naijiria tu buwọlu iwe adehun mii pe Naijiria gbọdọ lo owo naa fun ipese ohun amayedẹrun.
Bakan naa ni wọn tun jọ ṣe adehun pe ijọba yoo lo lara owo lati pari ọna ilu Eko si Ibadan ati Abuja si ilu Kano to fi mọ afara Niger keji ti iṣẹ n lọ lori rẹ lọwọ.
Ta ni James Ibori?
James Ibori ni gomina ipinlẹ Delta nigba kan ri.
Ṣaaju ni Ibori gbe ni orilẹede UK ni bii ogoji ọdun sẹyin nibi to ti ṣiṣẹ gẹgẹ bi akọwe owo nile itaja ti wọn n pe ni  DIY store niluu London.
Ibori jẹbi ẹsun ole jija nibi to ti n ṣiṣẹ ni London lọdun 1991.
Lẹyin naa lo pada si Naijiria ti o si bẹrẹ si ni ṣe oṣelu.
Ibori di gomina ipinlẹ Delta lọdun 1999, nibẹ lo ti bẹrẹ si ni ko owo ipinlẹ naa lọ si ilẹ okeere.
Ileeṣẹ ọlọpaa bẹrẹ si ni ṣe iwadii Ibori lọdun 2005 nigba ti o fẹ ra baalu agberapa ti tara rẹ.
Ọdun 2012 ni wọn fi ẹsun jibiti onikoko mẹwaa kan an to le ni biliọnu mejidinlọgbọn ṣugbọn wọn fi silẹ lọdun 2016.
Covid-19 Vaccines: Sanwo-Olu ní ìpínlẹ̀ Eko yóò bẹ̀rẹ̀ sí ní máa fáwọn èèyàn lábẹ́rẹ́ àjẹsára láìpẹ́
Oríṣun àwòrán, facebook/okikionline
Ninu awọn to ti ri abẹrẹ naa gba la ti ri ipinlẹ bi Eko ti ọwọja arun naa ti peleke ju lọ.
Ipinlẹ Eko ri abẹrẹ 507,000 Astra-Zeneca gba labẹ eto abẹrẹ ajẹsara ọfẹ  ti Covax ṣeto.
Ni nkan bi ago marun un aarọ ọjọ Iṣẹgun ni abẹrẹ naa balẹ si papakọ ofurufu Murtala Muhammed nilu Eko.
Oríṣun àwòrán, Facebook/Babajide Sanwo-Olu
Abẹrẹ ajẹsara Oxford-AstraZeneca ti balẹ bagẹ si ipinlẹ Eko lọjọ Iṣẹgun, ọjọ keṣan an oṣu kẹta ọdun 2021 yii.
Gomina Babajide Sanwo-Olu kede loju opo Twitter rẹ pe oun ti gba agbẹrẹ ajẹsara coronavirus lati ọwọ ijọba apapọ.
Sanwo-Olu ni idunnu lo jẹ fun oun pe abẹrẹ naa ti wọ ipinlẹ Eko.
Gomina ipinlẹ Eko ṣalaye pe gbogbo ilana ati fawọn olugbe ipinlẹ ni abẹrẹ ọhun ni ijọba yoo tẹ le.
Sanwo-Olu ko ṣai rọ awọn olugbe ipinlẹ Eko lati maa tẹle ilana ati gbogun ti ajakalẹ arun covid-19 nipa wiwọ ibomu, fifọwọ ni gbogbo igba ati tita kete si ara ẹni.
Ijọba ipinlẹ Ogun lo kọkọ gba abẹrẹ naa lọjọ Aje ki o to de si ipinlẹ Eko lọjọ Iṣẹgun.
Ajọ eleto ilera lagbaaye, WHO lo ṣagbatẹru abẹrẹ naa labẹ eto COVAX.
Ni ipinlẹ Kwara awọn naa gba abẹrẹ wọn lalẹ ọjọ Iṣẹgun.
Oxford AstraZeneca Vaccine naa balẹ̀ bagẹ si papakọ ofurufu ilu Ilorin ni nkan bii ago mẹjọ abọ alẹ ọjọ Isẹgun nibi ti ikọ ti ijọba ipinlẹ yan ti tẹwọ gba a  labẹ idari akọwe agba ileeṣẹ eto ilera ipinlẹ naa.
Oríṣun àwòrán, facebook/okikionline
Ijọba ipinlẹ Ondo naa ti tẹwọ gba abẹrẹ ajẹsara Covid-19 to le ni ẹgbẹrun marunlelaadọrin abọ (75,570).
Alẹ ọjọ Iṣẹgun lo balẹ si papakọ ofurufu ipinlẹ naa ti awọn oṣiṣẹ eleto ilera alabọde ipinlẹ naa si tẹwọ gba a.
Oríṣun àwòrán, facebook/okikionline
Lowurọ Ọjọru ni ipinlẹ Ekiti naa darapọ mọ awọn ipinlẹ akẹgbẹ rẹ to ti gba abẹrẹ ajẹsara Covid-19.
Loju opo Twitter gomina ipinlẹ naa lo ti hande pe Gomina Fayemi ati igbakeji rẹ Otunba Bisi Egbeyemi ni yoo maa dari awọn ara ipinlẹ naa lati tẹwọ gba a nita gbangba.
Oríṣun àwòrán, Dapo Abiodun
Ijọba ipinlẹ Ogun ti gba abẹrẹ ajẹsara ẹgbẹrun lọna aadọta lati dena itankalẹ aarun Coronavirus ni ipinlẹ Ogun.
Gomina ipinlẹ Ogun, Dapo Abiodun ni ileeṣẹ ijọba to ti gba abẹrẹ ajẹsara naa wọle ni awọn ṣi n reti ẹgbẹrun lọna aadọta miran.
Gomina naa ni awọn yoo tẹlẹ ilana aṣẹ Ajọ to n risi eto ilera awọn ọmọ Naijiria lati pin awọn abẹrẹ ajẹsara naa fun awọn eniyan to yẹ ki o gba a.
Bakan naa ni gomina naa fikun wi pe awọn ti ṣe ilana awọn ileewosan gbogboogbo, aladani kaakiri ipinlẹ naa to fi mọ ijọba ibilẹ ti yoo pin awọn abẹrẹ ajẹsara naa.
Saaju ni gomina naa ti ni awọn eleto ilera, awọn agbalagba ni yoo kọkọ gba abẹrẹ ajẹsara naa gẹgẹ bi aṣẹ Ajọ NPHCDA.
Gomina Abiodun ni abẹrẹ ajẹsara naa mu ọna abayọ de si igbeaye awọn eniyan ti arun Coronavirus daru lati bi Oṣu mẹtala sẹyin.
'A o kọkọ gba abẹrẹ ajẹsara akọkọ, a tun wa gba eleekeji ti yoo mu ki eroja ara to n gbogun ti arun jipepe si'.
Amọ, gomina ipinlẹ Ogun ni awọn yoo ṣi ma a tẹle awọn ilana ofin to de arun Coronavirus, nitori abẹrẹ aarun Coronavirus ko ni jẹ ki arun naa ni agbara lara awọn eniyan.
Ipinlẹ Ogun ni wọn ti kọkọ kede arun Coronavirus ni Naijiria, lẹyin ti arakunrin ọmọ ilẹ Italy de si Naijiria ni Ọjọ Kẹtadinlọgbọn, Oṣu Keji, ọdun 2020.
Iyatọ iye abẹrẹ tawọn ipinlẹ kọọkan n gba ko sẹyin bi ọwọja arun naa ba ti ṣe peleke si ni ipinlẹ kọọkan.
Labala labala ni wọn yoo maa pin abẹrẹ yi to siṣe wi pe lọpọ igba, awọn oṣiṣẹ ilera, agbalagba ati awọn eekan ijọba lo ti n kọkọ gba abẹrẹ naa.
Fawọn araalu mii to ba fẹ gba ijọba ti ṣeto iforukọsilẹ loju opo ayelujara.
Miliionu mẹrin abẹrẹ ajẹsara yi ni Naijiria kọkọ ri gba labẹ eto abẹrẹ ọfẹ ti igbimọ COVAX ṣe fawọn orileede agbaye.Kwara, Eko, Osun ati Nassarawa, awọn ipinlẹ to ti ri abẹrẹ Covid-19 gba
Oríṣun àwòrán, facebook/okikionline
Iskilu Wakili arrested: Ṣé èèyàn máa ń gba ìran ẹ̀ sílẹ̀ kó di ogun ní? - Oyo OPC
Adari ẹgbẹ Oodua Progressive Congress ni ipinlẹ Oyo labẹ isakoso Aarẹ Ọna Kakanfo ilẹ Yoruba Iba Gani Adams, Comrade Rotimi Olumo ba BBC Yoruba sọrọ nilu Ibadan lati fesi si bi wọn ṣe fi panpẹ ofin ko awọn ọmọ ẹgbẹ wọn si atimọle torii pe wọn mu ogbontarigi Fulani to jẹ afurasi apaayan, Iskilu Wakili.
Rotimi ni ajoji nikan lo lee ma mọ ipenija aisi aabo to n doju kọ ẹkun Guusu Ila Oorun Naijiria.
Àwọn ọmọ OPC tó mú Wakili ṣì wà ní Iyakangu n'Ibadan, wọn ò tìí lọ sí Abuja - Ọlọ́pàá Oyo
Wo nkan tó yẹ kí o mọ̀ nípa Iskilu Wakili, afurasí Balógun Fulani tí OPC mú ní Ayetẹ ìpínlẹ̀ Ọyọ
Wakili jiyàn ọ̀rọ̀, ó ní òun kò mọ ohunkohun nípa ìṣekúpani tó ń wáyé n'Ibarapa méjèèje
Wakili tẹẹ rí yẹn kìí ṣe ẹran rírọ̀, ó ń díbọ́n ní o - Iba Gani Adams
O ni ogun ni nkan to n ja awọn ilu Ibarapa mejeeje toripe iṣoro ti wọn doju kọ yatọ si ohun ti awọn ilu igboro n dojukọ.
Bi ijọba o ba le gba wa, ti ọlọpaa o le mu u, awọn Amotekun lọ ibẹ wọn o ri Wakili mu...
"Rotimi ni awọn ọdọ ilu wa pawọpọ pẹlu ẹgbẹ oṣelu OPC lati wọ inu igbo naa lati le Wakili kuro ti wọn si ri i mu amọ o ni ""o ba ni lọkan jẹ pe ọlọpaa tun wa n mu awọn ọmọ wa""."
Rotimi ni oun soju gbogbo ọmọ Yoruba lati sọ fun ijọba pe ki wọn tu awọn ọmọ OPC to ṣe akitiyan lati gba iran wọn silẹ ki wọn maa lọ ile wọn.
Sheik Gumi fèsì padà sí iléeṣẹ́ ọmọogun Nàìjíríà tó kì í nílọ̀ lórí ọ̀rọ̀ kòbákùngbé
Ìkúnlẹ̀ Abiyamọ ò! Báwo láwọn ọmọ kékèéké méjìla ṣé kú s'odò lẹ́ẹ̀kàn náà?
Jemila Bio Ibrahim: Àìmọye ìgbà ni mo ti bó lẹ́sẹ̀ ṣùgbọ́n bí ẹṣin bá dá ni mọ́'lẹ̀...
Ibẹru yẹn nikan lẹ maa gbe kuro lọkan yin tẹẹ ba fẹ gun ẹṣin.
"Jemila Bio Ibrahim jẹ ọkan lara awọn ọmọ ẹgbẹ ""Emirates Equestrians Club"" eyi to tumọ si awọn to n gun ẹṣin gba afẹ ni ilu Ilorin."
Ninu fọnran yii, o di mimọ pe iye owo ẹṣin kuro ni keremi koda lawọn orilẹede to ti ni iyi, ẹṣin mii to miliọnu lọna aadọrin naira (70m). Abdulzeez Olayinka Oniyangi ni:
"Ẹṣin mii wa to jẹ 70m, taa ba n sọrọ Argentine Horses, amọ nibi, ẹ lee ri bii 400,0000, 600,000, itọju rẹ ni pataki.
Ẹgbẹ yii gba pe ọna idaraya kan ni gigun ẹṣin nitorinaa wọn n fẹ obinrin sii.
Violence against Women: Wo iye obìnrin lágbàáye tó ń kojú ìwà ipá, àti ohun tó ń ṣokùnfà ẹ̀?
Oríṣun àwòrán, PA Media
Iwadii ti Ajọ eto ilera lagbaye, WHO gbe jade ti fihan pe ida mẹta awọn obinrin lagbaye lo n koju iwa ipa ni igba kan tabi omiran ni igba aye wọn.
Iwadii yii safihan iwa ipa to lagbara julọ ti awọn obinrin n koju lati ọdun 2000 si 2018, to si fihan pe iwa ipa pọsi lasiko aarun Coronavirus.
''Iwa ipa ti peleke si ti ẹgbẹlẹgbẹ miliọnu awọn obinrin ṣi n koju rẹ ni ojoojumọ''.
Wo obìnrin kanṣoso láàrin àwọ́n ọkunrin agunẹṣin gbafẹ́ nílùú Ilorin àmọ́ tọ́kàn rẹ̀ yii
''Ida mẹrin awọn obinrin laaarin ọdun marundinlogun si ọdun mẹrinlelogun ni awọn ọrẹkunrin wọn ti fi ipa kan hu iwa ipa si.''
''iwa ipa ti awọn obinrin n koju yii si wọpo laarin awọn eniyan to wa ni Iwọ Guusu Asia ati Ilẹ Afrika, to fi mọ agbegbe  Oceania.
Onimọ nipa ẹtọ awọn obinrin, Dokita Mairo Mandara ni iwadii naa ko jọ oun loju nitori gẹgẹ bi dokita, oun mọ awọn obinrin ti wọn n koju ọpọlọpọ idojukọ ninu igbeyawo wọn.
O ni iwa ipa si obinrin ti wọpọ ni awujọ ti ko si niiṣe pẹlu ede, ẹya , ẹsin tabi talika ati ọlọrọ, gbogbo eniyan ni wọn n hu iwa ipa si obinrin.
Wakili tẹẹ rí yẹn kìí ṣe ẹran rírọ̀, ó ń díbọ́n ní o - Iba Gani Adams
''Lasiko aarun Coronavirus yii, ifipabanilopọ ti pọsi to fi mọ awọn ọmọde.''
''Ọpọlọpọ awọn obinrin ti ko mọ wi pe awọn obi awọn ọkọ wọn ti hu iwa ipa si wọn nigba ti wọn wa ni ọmọde, ti wa bẹrẹ si ni hu iru iwa naa si wọn.''
Dokita Mandara ni bi o tilẹ jẹpe awọn obinrin ni ifarada, amọ wọn ko le e ni igbagbọ ninu ọkunrin to ba ti hu iwa ipa si wọn.
Bakan ni o parọwa si awọn ọkunrin lati bẹru Ọlọrun, ki wọn si ranti pe ti wọn ba fi iya jẹ awọn obinrin, obinrin ni iya wọn, obinrin si ni awọn ọmọ wọn nitori awọn ọmọ naa yoo dagba.
Wa wo èré èyí tó yẹ fún àárọ̀ kùtù àti èyi tó wà fún òṣúpá
Nigerian Labour Congress: Diẹ rèé nínú àwòrán ìwọ́de àwọn ọmọ ẹgbẹ́ òṣìṣẹ́ Nàìjíríà ní Abuja, Eko àti Ibadan
Ohun tawọn oṣiṣẹ lawọn fẹ ni pe ki ile aṣofin ma gbe aṣẹ sisan owo oṣu kuro ni abẹ ijọba apapọ lọ si abẹ aṣẹ ijọba ipinlẹ.
Iwọde ni Abuja
Iwọde ẹgbẹ oṣiṣẹ
Iwọde ni Abuja
Iwọde ẹgbẹ oṣiṣẹ
Awọn ọmọ ẹgbẹ NLC nilu Ibadan naa tu yaya jade lati ṣe iwọde
Ohun tawọn oṣiṣẹ lawọn fẹ ni pe ki ile aṣofin ma gbe aṣẹ sisan owo oṣu kuro ni abẹ ijọba apapọ lọ si abẹ aṣẹ ijọba ipinlẹ
NLC sọ pe ti wọn ba gbe aṣẹ yi kuro labẹ aṣẹ ijọba apapọ, awọn ipinlẹ le maa san iye to ba wu wọn foṣiṣẹ
Aarẹ awọn oṣiṣẹ Ayuba Waaba ni ailanu ara ilu loju lo mu ki awọn aṣofin fẹ gbe igbesẹ yi
Nilu Eko ti o jẹ olu ilu ọrọ aje Naijiria awọn oṣiṣẹ gba oju titi lati se iwọde
Iwọde ni ilu Abuja
Ọrọ owo oṣu to kere julọ lorileede Naijiria jẹ eleyi ti o fọwọ kan ọpọ oṣiṣẹ lẹmi
Sikiru Ayinde Barrister's son: Báwo ni Barry Jhay se kó sí gbaga ọlọ́pàá?
Oríṣun àwòrán, BArry Jhay
Gbajugbaja olorin Barry Jhay to tun jẹ ọmọ agba ọjẹ olorin Yoruba ni Naijria, oloogbe Alhaji Ayinde Barrister ni ọlọpaa ṣẹṣẹ mu laipẹ yii lori ẹsun iku ọga ileeṣẹ to n gbe awọn awo orin rẹ sita, Babatunde Oyerinde Abiodun ti ọpọ mọ si Kashy.
Iroyin ni wọn fi ẹsun kan pe ilumọọka olorin naa wa ni orilẹede Ghana lati lọ ṣe awọn orin kan ati lati ba ọga ileeṣẹ orin rẹ sọ ọ̀rọ̀ katakara.
Ṣaaju ọjọ ti arakunrin naa papoda, a gbọ pe o fun Barry Jhay ni ẹbun ago ọwọ nla ti iye owo rẹ to miliọnu mẹsan naira eyi ti olorin naa fi buga ninu fidio kan to fi sita loju opo instagram rẹ.
Oríṣun àwòrán, Barry Jhay
Wo obìnrin kanṣoso láàrin àwọ́n ọkunrin agunẹṣin gbafẹ́ nílùú Ilorin àmọ́ tọ́kàn rẹ̀ yii
Ninu fidio naa, eeyan lee gbọ ti Barry Jhay n sọ pe bi mo ṣe darapọ mọ ẹgbẹ yẹn niyẹn"" ti Kashy naa sin n sọrọ labẹlẹ pe ""Mo nifẹ rẹ ọmọ iya""."
"Awọn awuyewuye to n lọ lode fihan pe o ti pẹ ti Kashy ti jẹ eegun ẹyin nipa ẹnawo fun iṣẹ orin kikọ Barry latori eyi to sọ ọ di ilumọka gangan lọdun 2018, ""Aiye""."
Beeyan ba si wo oju opo instagram Barry Jhay ati Kashy daadaa, eeyan o ri i pe irẹpọ gidi lo wa laarin awọn mejeeji.
Bi Kashy ba tilẹ fẹ jọ ẹni ti ko fẹran awọn itakun ayelujara, o ṣi pọn olorin naa le kẹyin lọjọ kẹtala oṣu keji ọdun 2021 tii ṣe ọjọ ibi Barry Jhay.
Ohun to jẹ kayefi ni wipe, nigba diẹ ṣaaju ki Kashy to ku, iroyin sọ pe Barry Jhay fi fidio kan hande nibi to ti n pọ ẹjẹ lẹnu.
Oríṣun àwòrán, BarryJhay
"Wo bi arakunrin yii ṣe n lu mi. Mi o ṣe nkankan o. Mo n ka orin silẹ ni ọkunrin yii si bẹrẹ si ni lu mi bayii. Igba to ya lo pe orukọ ẹni naa ti ẹnikẹni ko mọ ni ""Jew""."
Awọn ọmọ ẹlẹgbẹ okunkun lo maa n saba lo orukọ yẹn fun awọn ti kii ṣe ọmọ ẹgbẹ́ rara. Nigba mii o maa n tumọ si pe wọn n pe ẹni bẹ́ẹ́ ni ikoko tabi ojo ati bẹ́ẹ̀ bẹ́ẹ̀ lọ.
Gbogbo iru eyi lo mu ki iroyin to n gbode kan di eyi ti wọn gbagbọ pe o ṣeeṣe ko jẹ pe ẹgbẹ okunkun kan ni orilẹede Ghana lo ṣe ikọlu si i.
Kii ṣe ajoji laarin awọn oṣere ati olorin ki wọn maa ni aawọ lori ọrọ owo ati ni ọpọ igba, ibaṣepọ laarin wọn maa n fẹ́rẹ́ẹ̀ fori ṣanpọn.
Wakili tẹẹ rí yẹn kìí ṣe ẹran rírọ̀, ó ń díbọ́n ní o - Iba Gani Adams
Iroyin kan fi sita pe Barry Jhay ati Kashy ni ija lori awọn ọrọ katakara kan.
Bi ẹ ba ranti, ajọ EFCC mu Kashy lọdun 2020 lori ẹsun jibiti ori ayelujara. Ọrọ latẹnu awọn kan to sunmọ ọ pẹti pẹti sọ pe iṣẹlẹ pẹlu ajọ EFCC pa a lara debi to kan an lẹmi eyi to mu ko bẹrẹ si ni lo oogun ni orilẹede ti ofin wn lodi si i.
Ẹwẹ, ohun tawọn eeyan n ran mẹnu nita gbangba lati igba naa ni pe ṣe Barry jhay lo fa iku ọga rẹ ni? Abi ṣe o ran awọn ọmọ ẹgbẹ okunkun lati fiya jẹ Kashy? Abi ṣe iporuru ọkan lo fa sababi bi Kashy ṣe gba ẹmi ara rẹ ni?
Eyi ati ọpọ ibeere ni ileeṣẹ ọlọpaa Ghana ni ireti lati ṣi aṣọ loju wọn ninu igbesẹ iwadi ti wọn n ṣe lọ́wọ́lọ́wọ́.
Sunday Igboho: ''Ọlọ́pàá tó bá yìnbọn pa àgbẹ̀ nílẹ̀ Yorùbá yóò kábàmọ́ọ̀, àwọn tó ń gbé AK-47 ni Buhari ní kí ẹ pa''
Oríṣun àwòrán, Nigeria police/Sunday Igboho
Gbajugbaja ajijagbara ilẹ Yoruba, Ọgbẹni Sunday Adeyemo ti ọpọ mọ si Sunday Igboho ti kilọ fawọn ọtẹlẹmuyẹ. awọn ọlọpaa atawọn ẹṣọ eleto abo mii lati rọra ṣe lori aṣẹ ti Aarẹ Muhammadu Buhari pa pe kawọn ẹṣọ alaabo maa yinbọn
Laipẹ yii ni Buhari paṣẹ fawọn ẹṣọ eleto abo lati yinbọn fun ẹnikẹni ti wọn ba ri ibọn AK-47 lọwọ rẹ ninu igbo.
Ṣugbọn Igboho sọ ninu fidio kan to fi lede lori ayelujara pe ki awọn ẹṣọ eleto abo maa lọ ṣeeṣi mu awọn agbẹ tabi ọde to n lo ibọn sakabula nilẹ Yoruba.
Ọgbẹni Adeyemo ṣalaye pe ibọn AK-47 yatọ si iru ibọn tawọn agbẹ n gbe kọpa lọ si oko nilẹ Yoruba.
O kilọ fawọn ẹṣọ eleto abo lati maa yinbọn fawọn agbẹ ti wọn fi ibọn sakabula ṣora lorukọ wi pe wọn n gbe ibọn AK-47 kiri ninu igbo.
''Sheikh Gumi ti sọ ibi tawọn janduku to n lo ibọn AK-47 wa ninu igbo, nibẹ lo yẹ kawọn ẹṣọ eleto lọ.
Ki wọn maa tiẹ gbero lati yọ awọn ọdẹ ati awọn agbẹ to n lo ibọn lẹnu rara,'' Igboho lo sọ bẹẹ.
Ọgbẹni Igboho ni inu oun dun si aṣẹ ti Buhari pa lori ọrọ awọn to n gbe ibọn AK-47 kiri ninu igbo, o ni ariwo ti oun atawọn eeyan kan n pa nipa awọn darandaran to n gbebọn kiri ti n so eso rere niyẹn.
Igboho rọ awọn agbofinro lati jẹ iṣẹ ti Buhari ran wọn lai beṣu bẹgba.
O ni ẹnikẹni to ṣeeṣi pa ọlọdẹ tabi agbẹ to n gbebọn sakabula lọ si oko fun iṣọra ara rẹ yoo kabamọ.
Igboho ni lorukọ gbogbo ọmọ ilẹ Yoruba lapaapọ ni oun n jiṣẹ naa fawọn eṣọ eleto abo.
Covid-19 vaccines: Gómìnà Gboyega Oyetọla, aya rẹ̀ Kafayat gba abẹ́rẹ́ àjẹsára COVID-19 ní ìpínlẹ̀ Ọṣun
Oríṣun àwòrán, Osun State Government
Gomina Gboyega Oyetọla ti ipinlẹ Ọṣun ati iyawo rẹ Kafayat ti gba abẹrẹ ajẹsara COVID-19 nilu Osogbo.
Dokita agba nileekọṣẹ iṣegun oyinbo ti fasiti ipinlẹ Õṣun, Ọjọgbọn Peter Ọlaitan lo gba abẹrẹ naa fun gomina Oyetọla ati iyawo rẹ.
Ni alẹ ọjọ Iṣẹgun ni awọn alaṣẹ ijọba nipinlẹ Osun tẹwọ gba awọn ipin abẹrẹ ajẹsara naa ti wọn fi ṣọwọ sii.
Bakan naa ni igbakeji gomina ipinlẹ Ọṣun, Benedict Alabi at'awọn ọmọ ignimọ iṣejọba ipinlẹ naa pẹlu gba a.
Ipin ẹgbẹrun mẹrinlelọgota ati ojilelugba (64,240) abẹrẹ ajẹsara COVID-19 AstraZeneca  ni wọn pin kan ipinlẹ naa.
Oríṣun àwòrán, Osun State Government
Ṣaaju gbigba abẹrẹ ajẹsara naa fun gomina Oyetọla ni wọn ti kọkọ gba a fawọn oṣiṣẹ eleto ilera nibẹ gẹgẹ bi ilana ti ajọ ilera alabọde lorilẹede Naijiria,  National Primary Health Care Development Agency gbe kalẹ.
Ninu ọrọ rẹ, gomina Oyetọla ṣalaye pe ohun pinnu lati wa lara awọn ipele akọkọ ti yoo gba abẹrẹ naa ni ipinlẹ ọhun lati le fun awọn eeyan ipinlẹ Ọṣun ni idaniloju pe ko sewu pẹlu gbigba abẹrẹ ajẹsara COVID-19 naa.
O wa rọ awọn olugbe ipinlẹ naa lati karamasiki idaabobo ara wọn lọwọ ajakalẹ arun naa nipa titẹle awọn ilana ti awọn onimọ ilera gbe kalẹ.
Akeredolu pẹlu gba abẹrẹ COVID-19, O ni karaalu yago fun gbọyisọyi nipa abẹrẹ ajẹsara COVID-19
Ni ipinlẹ Ondo, gomina Rotimi Akeredolu pẹlu gba abẹrẹ ajẹsara COVID-19 nilu  Akurẹ, to si tun gba awọn eeyan ipinlẹ naa niyanju pe ki wọn yẹra fun iroyin gbọyisọyi nipa abẹrẹ ajẹsara COVID-19.
Gẹgẹ bi o ṣe sọ, ko sewu kankan nipa abẹrẹ ajẹsara naa.
Oríṣun àwòrán, Ondo State Government
Igbakeji rẹ, Lucky Ayedatiwa, at'awọn lọbalọba bii Osewawe tilu Ondo, Oba Dr. Victor Kiladejo, Deji ilu Akurẹ, Oba Aladetoyinbo Ogunlade Aladelusi pẹlu gba abẹrẹ ajẹsara naa nilu Akurẹ.
Ẹgbẹrun mẹtalelaadọrin ati ọrinlelẹẹdẹgbẹta o din mẹwaa (73,570) ni ipin to kan ipinlẹ Ondo lat'ọdọ ijọba apapọ lọjọ Iṣẹgun, ọjọ kẹsan oṣu kẹta ọdun 2021.
Rape of minors: Ẹni bá rí i kó sọ o, Ìjọba ń wá ẹni dún 45 tó fipá bá ọmọ ọdún méje lòpọ̀
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ile aṣofin nipinlẹ Bauchi ti gbe igbimọ dide lati ṣawari ọkunrin ẹni ọdun marundinlaadọta to fi ipa ba ọmọ ọdun meje lopọ.
Awọn aṣofin kan ni ileeṣẹ ọlọpaa ti gba beeli ọkunrin naa lẹyin ti wọn fi panpẹ ọba gbe.
Agbegbe ijọba ibilẹ Faggo ni Shira ni iṣẹlẹ naa ti waye.
Ọkan lara awọn aṣofin to gbe ọrọ naa ka ile aṣofin ni ki ileeṣẹ ọlọpaa ni kiakia wa ọkunrin yii jade lai fi akoko ṣofo.
O ni ọkunrin agbalagba naa ba ọmọbinrin naa lopọ lẹyin to dunkoko mọ ọ wi pe oun yoo pa a.
Bakan naa lo fi da awọn oniroyin loju wi pe awọn yoo ri wi pe ijọba fi ọkunrin oun jofin.
O ni awọn yoo ṣewadii ni ijọba ibilẹ Shira ati ileeṣẹ ọlọpaa ni agbegbe naa ibi ti wọn de duro lori bi wọn ṣe fi panpẹ ọba mu ọkunrin naa.
Amọ, nibayii awọn aṣofin naa ni awọn ko mọ ibi ti ọkunrin naa salọ, sugbọn awọn fi n da awọn araalu loju wi pe arakunrin oun ko ni lo lai jẹ iya ẹsẹ rẹ.
Ijọba ipinlẹ Bauchi ni ifipabanilọpọ ti wọpọ nipinlẹ naa, ti wọn si ti fi ofin de iru iwa bẹẹ ni ipinlẹ ọhun.
Ẹwọn ogun ni ijọba yoo fun ẹnikẹni ti wọn ba fi idi rẹ mulẹ pe o fi ipa ba obinrin lopọ.
Wo obìnrin kanṣoso láàrin àwọ́n ọkunrin agunẹṣin gbafẹ́ nílùú Ilorin àmọ́ tọ́kàn rẹ̀ yii
Kehinde Ayooloa: Aya kọmíṣọ́nà ọ̀rọ̀ agbègbè ìpínlẹ̀ Oyo tẹ́lẹ̀, Oluwakemi Ayoola ti jáde láyé
Oríṣun àwòrán, Facebook/Kehinde Ayoola
Arabirnin Oluwakemi Ayoola, to jẹ aya kọmiṣọna fun ọrọ agbegbe nipinlẹ Oyo tẹlẹ, Kehinde Ayoola ti jade laye.
Iṣẹlẹ naa waye lẹyin nnkan bii oṣu mẹwaa ti ọkọ rẹ ọhun ti kọkọ fi aye silẹ.
Oluwakemi jẹ ọjọgbọn ni ẹka eto imọ nipa ọrọ agbẹ ni fasiti Obafemi Awolowo to wa ni Ile Ife, bakan naa lo tun jẹ oluwadii pẹlu ajọ IAR&T, eyii to wa ni Apata, niluu Ibadan.
Iroyin ni oloogbe naa ti kọkọ n ṣaisan tẹlẹ ki ọlọjọ to de, ṣugbọn aisan naa lagbara sii lẹyin ti ọkọ rẹ jade laye lasiko to n ṣiṣẹ gẹgẹ bii kọmiṣọna ninu ijọba Amojuẹrọ Seyi Makinde to wa lori alefa ijọba ipinlẹ Oyo.
Ọjọ kẹrinla, oṣu Karun un, ọdun 2020 ni ọkọ oloogbe naa fi aye silẹ, iyẹn lasiko to ku ọsẹ meji ki wọn ṣe ayẹyẹ ọdun kan gomina Makinde lori alefa.
Ọpọ awọn ẹbi, ọrẹ ati alabaṣiṣẹ lo ti bẹrẹ si n daro oloogbe ọhun.
Osun bank robbery: Ọlọ́pàá ní àwọn olè jí N600,000 nínú ATM l'Osun, àmọ́ àwọn ọlọ́pàá ti lé wọn wọ inú igbó
Oríṣun àwòrán, Agunbe Voice
Ọrọ ti jẹyọ lati ọdọ ileeṣẹ ọlọpaa nipinlẹ Osun lori awọn eeyan meji to padanu ẹmi wọn nigba tawọn ole yabo ile ifowopamọ kan ni Okuku.
Alukoro ọlọpaa arabinrin Yemisi Opalola to ba BBC sọrọ ni ọkunrin ọlọlkada kan ati baba agbalagba to ni ipenija arun ọpọlọ lawọn ole naa pa.
Awọn eeyan meji ni wọn yinbọn pa.Wọn sọ fun wa pe baba agbalagba alagana kan ati ọlọkada ni wọn pa''
Yemisi tẹsiwaju pe kọmisana ọlọpaa ipinlẹ Osun Olawale Olokode ti ni kawọn agbofinro ṣe awari awọn ole naa laifasiko ṣofo.
Ilu Okuku ni ilu Gomina tẹlẹri Olagunsoye Oyinlola.
Oríṣun àwòrán, OTHER
Ileeṣẹ ọlọpaa ipinlẹ Osun ti ṣalaye fun BBC Yoruba awọn adigunjale to yabo ile ifowopamọ WEMA ati Micro Finance niluu Okuku ko ri awọn banki naa wọ.
Agbẹnusọ ileeṣẹ ọlọpaa fun ipinlẹ Osun, Yemisi Opalola sọ pe owo to to ẹgbẹrun lọna ẹgbẹta naira ni wọn ri ko ninu ẹrọ igbowo(ATM machine) lẹyin ti wọn ko raye wọle nitori banki naa ti pari iṣẹ ti awọn oṣiṣẹ si ti lọ sile.
Alukoro ileeṣẹ ọlọpaa ni oṣiṣẹ banki WEMA kan ti ko tii lọọle lawọn janduku naa ni ko ṣi ẹrọ ATM fun wọn nibi ti wọn ti ji owo naa ko lọ.
Mo bẹ̀rẹ̀ ẹ̀ṣẹ̀ jijà ní ọmọ ọdún méjì, inú mi dùn pé bàbá mi fi mí sí ọ̀nà ẹ̀ṣẹ̀ jíjà - Tijani Azeez
''Awọn adigunjale naa fẹsẹ fẹẹ lẹyin ti wọn ri awọn ọlọpaa to n bọ lati ọọkan.
Ẹwẹ, Kọmiṣọnna ọlọpaa ipinlẹ Osun fun ra rẹ lo ṣaaju awọn ọlọpaa kogberegbe lọ bawọn ọdaran naa.
Amọ, awọn ọlọpaa ti le awọn ole naa wọn inu igbo lọ pẹlu igbagbọ pe, wọn si le ri wọn mu nibẹ,'' Opalola lo sọ bẹẹ.
Àwọn adigunjalè yabo báńkì l'Osun, ọ̀gá ọlọ́pàá kojú wọn pẹ̀lú àwọn ọlọ́pàá kògbérègbéè
Iroyin to n tẹ wa lọwọ lati ipinlẹ Osun lo sọ pe awọn adigunjale ti yabo ile ifowopamọ kan niluu Okuku nipinlẹ Osun lọsan Ọjọbọ.
Agbẹnusọ fun ileeṣẹ ọlọpaa ipinlẹ Osun to ba BBC Yoruba sọrọ, Yemisi Opaola lo fidi ọrọ yii mulẹ.
Oríṣun àwòrán, OTHER
Agbẹnusọ ọlọpaa ṣalaye pe Kọmiṣọnna ọlọpaa ipinlẹ Osun fun ra rẹ lo ṣaaju awọn ọlọpaa kogberegbe lọ si banki naa lati mu awọn ọdaran ọhun.
Yorùbá films: Iya Rainbow di ònílé tuntun, ilé méjì ni wọ́n fi ta á lọ́rẹ
Oríṣun àwòrán, Iya Rainbow
Agba osere Yoruba, Idowu Phillips, ti ọpọ eeyan mọ si Iya Rainbow tun ti di onile tuntun.Ọsẹ to kọja ni osere naa kede loju opo Instagram rẹ pe ileesẹ kan lo fi ile fulaati meji ta oun lọ rẹ ni agbegbe Mowe, nipinlẹ Ogun.Koda, o ni wọn tun fi orukọ oun sọ opopona kan ninu esiteeti aladani naa.
Prophet Shittu Adeniyi: Ẹni tó bá ń tọrọ agbe, kìí jẹ́ èèyàn ní mo ṣe tẹ́pa mọ́ṣẹ́
Yoruba ni bi ẹmi ba wa, ireti n bẹ, ẹda ko si ni aropin.
Eyi ni imọran ojisẹ Ọlọrun kan to ni ipenija oju, Wolii Shittu Adeniyi, ti ọpọ eeyan mọ si Wolii Oluwalogbon, lasiko to n ba BBC Yoruba sọrọ lori awọn ohun to n la kọja ati iriri to ni nile aye.
Ninu ọrọ rẹ, Wolii Oluwalogbon ni oun padanu oju oun lẹyin osu mẹta ti iyawo oun jade laye lọjọ to bi ọmọ tuntun.
Nibayii, ojisẹ Ọlọrun naa ti fẹ iyawo miran, bi awọn ọmọ, o n kọrin, se ọsin ẹja, to si tun n ya fiimu pẹlu.
Wolii Shittu Adeniyi wa rawọ ẹbẹ sawọn eeyan to ni ipenija ara bii tiẹ lati mase sọ ireti nu, tabi ro ara wọn pin.
Bakan naa lko rọ wọn lati gbara le agbe sise nitori ipo ti wọn wa, amọ ki wọn wa isẹ oojọ kan se nitori o ni ẹni to ba n se agbe jẹun, kii jẹ eeyan gidi laye.
Àwọn ìtàn mánigbàgbé tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí:
Bola Tinubu: Kókó ọ̀rọ̀ mẹ́wàá tí Asiwaju sọ rèé lórí aáwọ̀ darandaran àti agbẹ̀
Oríṣun àwòrán, @AsiwajuTinubu
Yoruba ni aisi nibẹ, ni aibawọn da si, agba kii si wa lọja, ki ori ọmọ tuntun wọ.
Eyi lo mu ki asaaju ẹgbẹ oselu APC nilẹ yii, Asiwaju Bola Ahmed Tinubu fi sọrọ soke lori aawọ to n waye yika Naijiria nipa ọsẹ tawọn ọdaran darandaran n se.
Ninu atẹjade kan to fisita lọjọ abamẹta, Tinubu ni aawọ yii ti n gbọna ọtun yọ, to si gbe imọran kalẹ pe ki wọn sọ awọn ilẹ ilu ti wọn ko lo di ibudo ọsin ẹran.
O ni a le mọ odi yika awọn ilẹ ti a ko lo bayii lati haaya rẹ fawọn darandaran fun sinsin ẹran ni owo ti ko gunpa, eyiun awọn to ba fi orukọ silẹ.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
"Tinubu ni ""Imọran oun yoo jẹ kawọn darandaran le joko sisẹ wọn pẹlu pipa ere nla wọle ti wọn ba fi ilẹ ti a ko lo haaya fun wọn lowo pọọku."
Amọ eyi ko wa lati fiya jẹ awọn darandaran amọ owo iforukọsilẹ ti wọn ba san yoo jẹ kawọn naa ni owo idokowo lori isẹ naa ni, eyi yoo si fopin si ariyanjiyan to n waye lori fifun awọn darandaran ni ilẹ
Gani Adams: Fulani kọ́ ni ìṣòro ètò ààbò tó mẹ́hẹ nílẹ̀ Yorùbá, àwọn èèyàn wa ni
Oríṣun àwòrán, Facebook/Seyi Makinde
Lori ọrọ eto aabo to mẹhẹ nilẹ Yoruba, awọn Fulani kọ ni ìṣòro wá.
Eyi ni ọrọ ti Aarẹ Ọna Kakanfo ilẹ Yoruba, Iba Gani Adams sọ nibi ipade apero ilẹ Yoruba to waye nilu Ibadan, ipinlẹ Ọyọ, ni Ọjọbọ.
Ipade apero naa lo jẹ idasilẹ ẹgbẹ kan, South-West Security Stakeholders, lati ọwọ Gani Adams.
Ẹgbẹ naa ti yoo jẹ akojọpọ oriṣiriṣi ẹgbẹ nilẹ Yoruba, igbimọ lọba-lọba, ẹgbẹ OPC, Agbẹkọya, Sọludẹrọ, àwọn ọdẹ, fijilante àti awọn ẹgbẹ mii.
Ẹgbẹ naa ni yoo ma mojuto eto abo ilẹ Yoruba.
Ifọrọwerọ  pẹlu Gani Adams lori ọrọ Sunday Igboho
Nigba to n ṣorọ, Iba Adams sọ pe ibanujẹ ni bi wọn ṣe ko awọn ọmọ ẹgbẹ OPC to mu Iskilu Wakili, olori Fulani ni ilẹ̀ Ibarapa, lọ sile ẹjọ.
Bakan naa  ni awọn eeyan mii to sọrọ níbi ipade naa koro oju si awọn iṣẹlẹ ijinigbe, ifipabanilopọ, ipaniyan, ati biba ọkọ ati eto ọrọ aje àwọn eeyan jẹ nilẹ Yoruba.
Lara wọn ni Akọwe Agba fun igbimọ agbaagba ilẹ Yoruba, Ọmọwe Kunle Olajide to sọ pe ibi ọ̀wọ̀ ni awọn aginju to wa ni ilẹ Yoruba.
Iba Gani Adams: Bẹ́ẹ gbé màláíkà kan lọ sí Aso Rock, kò lè ṣàṣeyọrí
O fikun pe ẹ̀yà Yoruba ko ni i fun ẹnikẹni ni nkankan lara awọn aginju rẹ fun.
Adams wa kilọ pe ko yẹ ko jẹ pe awọn eeyan perete ni yoo ma a mojuto ọrọ abo.
"O ni ""ti a ko ba tete mojuto ọrọ abo to mẹhẹ nilẹ Yoruba, o ṣe e ṣe ki o buru si i.'"
O fi ẹsun kan pe awọn adari ẹ̀yà Yoruba kan fi aarun Covid-19 ṣe awawi, lati má a kopa níbi ipade naa.
 Lati igba ti mo ti di Aarẹ Ọna Kakanfo, oriṣiriṣi ojúṣe lo wa ni ọrùn mi, sugbọn ọpọ eeyan si n beere pe, ki ni mo n ṣe lori ọrọ aabo nilẹ Yoruba.
Farmers Herders Crisis: Rẹ́rẹ́ rún, ẹ̀mí àti dúkìá ṣòfò lágbègbè Ariwa Yewa
O tẹsiwaju pe ọpọlọpọ awọn ọmọ Yoruba to wa ni ipo agbára, lo ti gbagbe orisun wọn.
Fun ẹyin ti ẹ n beere pe ki ni mo n ṣe lori ọrọ abo, ẹyọ kan lára agbára ti mo ni, ni mo lo laarin ọsẹ meji, ti ilẹ mì titi.
O ṣalaye pe laarin ọsẹ meji pere ni awọn ọmọlẹyin òun wọ inu aginjù, ti wọn si mu igbakeji Iskilu Wakili, ati awọn mẹta mii ti wọn fa le ọlọpaa lọwọ.
" Oṣù kan ni a fi n sọ ìwọlé ati ijade Wakili, ko to o di pe ọwọ tẹ ẹ, ati awọn mẹta míì ni Ibarapa.
Wakili tẹẹ rí yẹn kìí ṣe ẹran rírọ̀, ó ń díbọ́n ní o - Iba Gani Adams
Bi wọn ṣe fi ẹsun ipaniyan, didana sun dukia, ati di darapọ mọ ẹgbẹ ti ko ba ofin mu, kan àwọn to mu Wakili nile ẹjọ yẹ ko mu ẹ̀yà Yoruba ronu."
Wọn gbe igbesẹ lati ṣọ eto aabo nilẹ Yoruba di alailagbara ni.
 Sugbọn ṣa, awọn eeyan wa gan-an ni ìṣòro wa, kii ṣe Fulani, nitori mo gbọ pe awọn ọmọ Yoruba kan jẹ ọdalẹ.
Nibi ipade naa ni awọn to sọrọ ti rọ àwọn gomina nilẹ Yoruba, lati ṣe igbelarugẹ fun eto ọgbin àti nkan ọsin.
Wọn ni eyi yoo fi opin si bi ilẹ Yoruba ṣe n gbojule Ariwa Naijiria fun oúnjẹ.
Saaju la ti mu iroyin wa pe Aarẹ Ọna Kakanfo nilẹ Yoruba, Oloye Gani Adams tun ti sọrọ soke nipa eto aabo to mẹhẹ nilẹ Yoruba atawọn ọna abayọ si.
Oloye Adams, lasiko to n fọwọ werọ pẹlu iwe iroyin Vanguard tun mẹnuba ọpọ ipenija eto aabo tilẹ Yoruba n koju ati ewu to wa nibẹ fun iran yii.
Aarẹ ni lọwọ lọwọ bayii, awọn janduku kan lati apa oke Ọya wa lawọn agbegbe kan nilẹ Yoruba, paapaa nilu Owo, ni abule Iwuse, tawọn baalu kekeke si maa n wa ja ibọn fun wọn.
"Sẹ mọ pe ijọba ipinlẹ Ondo ati awọn eeyan ilu Owo ko le wọ inu igbo naa lati lọ koju wọn. Bakan naa ni awọn janduku yii naa n wa goolu wa lọna aitọ nilu Ilesa laisi ẹni ti yoo yẹ wọn lọwọ wo.
Koda, awọn ọdaran yii lo n wa ohun alumọọni wa nilu Igangan lọna aitọ, eyi to jẹ ki Wakili atawọn ọmọ ogun rẹ ni owo tabua lọwọ lati fi ra ohun ija oloro, ti wọn fi tun n ji eeyan gbe."
Oloye Adams fikun pe bakan naa nilu Irawo Ile ati Idere, wọn n wakusa lọwọ nibẹ lọna ti ko bofin mu, awọn ohun alumọọni ti iran to n bọ si nilo ree lati se aye wọn.
O ni ko si ọmọ Yoruba to le lọ sapa Oke Oya lati wa kusa wọn nibẹ lai fa wahala, ti ọpọ eeyan to le ni ọgọrin si ti sa kuro lawọn abule to wa ni agbegbe Ibarapa nitori ọsẹ awọn janduku yii.
Gani Adams wa rọ awọn ọmọ Yoruba to n gbode gba fawọn janduku lati ronu piwada ki wọn si fọwọ sowọpọ fun isọkan ati irẹpọ ilẹ Yoruba.
O fikun pe ti wọn ba kọ lati ronu piwada, awọn yoo bẹ awọn alalẹ nilẹ Yoruba si wọn ni, pe ki wọn se wọn bi ọsẹ ti n soju.
Gani Adams ni ọpọ awọn ọdaran Fulani yii mọọmọ n sediwọ fun awọn agbẹ lati gbin ire oko tabi kore wọn ni nitori ki wọn le maa ko ounjẹ wa si ilẹ Yoruba lati apa oke ọya ni
Ni ojoojumọ, miliọnu mejilelogun naira ni awọn eeyan apa oke ọya to n ko ounjẹ wa silẹ Yoruba n pa lọ sile, eyi si wọn ko se fẹ ka seto ọgbin ni aseye.
Nipa orin ibilẹ Yoruba to sẹsẹ jade, Aarẹ ni Oloye Obafemi Awolowo lo kọ orin naa silẹ, ko to ku, o si yẹ ki gbogbo ipinlẹ nilẹ Yoruba tẹwọ gba a.
O wa rọ awọn ipinlẹ to wa nilẹ Yoruba lati tẹwọgba orin ibilẹ Yoruba tuntun ti wọn sẹsẹ gbe jade.
Orin ibilẹ wa naa lagbara pupọ, o n fun ni ni iwuri, imuyangan gẹgẹ bi ọmọ Yoruba, tawọn ọdọ wa nile iwe ba si n kọ, yoo fun wọn ni iwuri gẹgẹ bii ogo alawọ dudu.
Nigba to n sọrọ lori awọn ọba alaye, aarẹ Gani Adams ni lootọ ni ominu n kọ oun lori bi awọn ọba alaye nilẹ Yoruba se bu ẹẹkẹ diwọ lori ikọlu awọn ọdaran darandaran.
Prophet Shittu Adeniyi: Ẹni tó bá ń tọrọ agbe, kìí jẹ́ èèyàn ní mo ṣe tẹ́pa mọ́ṣẹ́
O ni oun mọ pe diẹ lara awọn ọba alaye yii ni wọn fi tipa gbe le wa lori, ti wọn si n fun wa ni wahala se ams idajọ ọba, ọwọ eledumare lo wa.
Awọn eeyan to n tako wa laarin ẹya Yoruba ni isoro wa nitori awọn kan wa ti wọn n jowu wa, ti wọn si n sisẹ tako aseyọri wa.
O wa rọ awọn eeyan lati mase maa tabuku wọn lori aye amọ se la mọ baa se maa fi ara da fun wọn nitori awọn Fulani gan kii yaju si ọba tiwọn, ko si bi wọn se le buru to.
Gani Adams: Irọ́ ni wọn ń pa, mi ò sálọ sí France nítorí ìwọ́de
Idi ree ti mo fi n wọ asọ funfun, de fila Abeti Aja:
Bakan naa ni Aarẹ Gani Adams ti sisọ loju rẹ pe kii se pe oun wa ninu ẹgbẹ awo kan ni oun se maa n wọ asọ funfun, gẹgẹ bi awọn eeyan kan se lero.
"Amọ o ni ""Ohun ti ayanmọ mi fẹ ni asọ funfun ti mo n wọ nitori ki ẹsin to gba ọpọ nnkan lọwọ wa, akọsẹjaye wa lati mọ ohun ti isẹda ọmọ tuntun yoo jẹ."
"Idile Musulumi ni wọn ti bi mi, ti ko si seese fun wọn lati beere akọsẹjaye mi amọ lasiko ti mo n se ẹgbẹ ọmọ Oduduwa, OPC, ọpọ ibi ti mo n lọ ni wọn ti salaye fun mi pe asọ tuntun ni ki n maa wọ."""
Wakili tẹẹ rí yẹn kìí ṣe ẹran rírọ̀, ó ń díbọ́n ní o - Iba Gani Adams
Aarẹ Ọna Kakanfo fikun pe lati ọdun 2000 ni wọn ti n sọ ọrọ yii fun oun ams oun ko ja kunra, ti igbe aye oun ko si fi bẹẹ ni iyipada rere.
O ni nigba to di ọdun 2004 ni oun pinnu lọjọ kan, ti oun si ra asọ funfun bii ọgbọn, oun gbe fun aransọ lati ran, to fi mọ awọtẹlẹ oun si lo n funfun pẹlu lati igba naa.
Awọn asọ to le ni igba lo wa ninu kọbọọdu asọ mi ti kii se funfun, mo si bẹrẹ si pin fawọn ọmọ ẹyin mi lọjọ naa, lati igba naa ni mo ti n wọ asọ funfun.
Aarẹ ni bakan naa fila gọbi ni oun maa n de sori tẹlẹ, to si maa n yun oun lori tabi fun oun ni ẹfọri amọ baba kan lo yọ si oun loju oorun pe ki oun bẹrẹ si ni de abeti aja.
O ni lati igba naa ni oun ti n de fila abeti aja ti aye mọ oun mọ, eyi si ni oun ro pe yoo jẹ ẹkọ fun awọn iran to n bọ.
SERAP: À fẹ́ kílé ẹjọ́ pàṣẹ fún Buhari láti máṣe yá owó aráàlú tó wà ní báǹkì
Oríṣun àwòrán, @MBuhari
Ajọ to n ja fun ẹtọ ọmọniyan nidi ọrọ aje ati ijiyin isẹ iriju ẹni, SERAP, tun ti wọ aarẹ Muhammadu Buhari lọ sile ẹjọ giga tijọba apapọ to wa nilu Abuja.
Igbesẹ naa ni Serap ni oun fẹ fi da ijọba lọwọkọ lati mase ya owo ninu apo asunwọn awọn ọmọ Naijiria ti wọn ko lo fun igba pipẹ, lawọn banki gbogbo nilẹ wa.
Owo naa, ti wọn lo to biliọnu lọna marundinlẹẹdẹgbẹwa (N895m) , tun wa lara awọn owo ipin idokowo tawọn araalu ko beere fun.
Ajọ Serap ni igbesẹ ijọba naa lodi sofin to si tun tako ofin to wa fun eto isuna ọdun 2020.
Ajọ Serap wa n rọ ileeẹjọ naa lati pasẹ pe ijọba ati aarẹ Buhari ko gbọdọ  gba awọn owo naa tabi ya ninu rẹ, ko si tun gbọdọ tọwọ bọ owo awọn ọmọ Naijiria naa tabi gbe kuro ninu apo asuwọn owo ti wọn ko pamọ si.
Adebunmi Adeyeye: Mo jẹ gbèsè gbọ́múléláńtà, ìdí iṣẹ́ kabúkabú ni mo ti ri san
Ajọ ajafẹtọ ẹni naa ni bi o tilẹ jẹ pe ọrọ aje Naijiria n saisan lojoojumọ, ti adinku si n ba owo to n wọle fun lojoojumọ, sibẹ awọn adari wa labẹ ijọba apapọ ati lawọn ipinlẹ to fi mọ awọn asofin ko mu adinku ba ilana bi wọn se n nawo.
O ni awọn ọmọ Naijiria ti ori n ta julọ nitori inakuna wọn ọhun naa tun ni ijọba fẹ lọ ya ninu owo wọn.
Sunday Igboho: Ẹ gbàgbé Gẹ̀ẹ́sì, ọpọlọ mi pé ju tàwọn tó kàwé lọ
Oríṣun àwòrán, Ooni, Sunday Igboho ati Alaafin
Ilumọọka ajafẹtọ iran Yoruba, Oloye Sunday Igboho, tun ti yọ suti ete sawọn eeyan to n kẹgan rẹ pe ko kawe debi to ni apẹrẹ.
Sunday Igboho, lasiko to n bawọn ololufẹ rẹ sọrọ lọjọ Aiku lo fesi pada fawọn ọmọ Yoruba to ni ko kawe to nnkan.
Igboho ni awọn ọmọ Yoruba kan lo n kẹgan oun pe oun ko yẹ ni ẹni ti yoo lewaju iran Yoruba nidi ijijagbara nitori pe oun ko gbọ ede oyinbo bo se yẹ.
Oríṣun àwòrán, Instagram/Sunday Igboho
"Igboho ni ""Wọn ni n ko kawe, ti n ko si le ja fun iran Yoruba, amọ alaimskan ni wọn, ti ko ni laakaye."""
Ajafẹtọ ọmọniyan naa ni ọpọlọ toun ju tawọn eeyan to n pẹgan oun lọ, bi o tilẹ jẹ pe oun ko kawe to wọn.
Igboho ni ilẹ Yoruba ni oun n ja fun, ko si si ohun to kan ohun ninu sisọ ede Gẹẹsi nitori bi aarẹ Amẹrika yoo ba ba oun sọrọ, ede abinibi oun ni oun yoo fi baa sọrọ.
Asiko yii lo si bẹrẹ si ni sọ ede Gẹẹsi, tawọn alatilẹyin rẹ si n sa ni mẹsan-mẹwa.
Sunday Igboho: Fulani kò leè dúró, táa bá lo ohun ta jogún lọ́dọ̀ àwọ̀n bàbá wa
Ko si ohunkohun ti mo fẹ gba lọwọ ẹni to pe ara rẹ ni ọjọgbọn fasiti, nitori gbogbo awọn ti wọn ni awọn gbọ eebo yii, iru wọn lo n se isẹ asọna lẹnu ọna ile mi.
"Ila ẹẹkẹ mi ni iwe ẹri pe mo jẹ ojulowo ọmọ Yoruba ti ko ni abula, ti ilẹ Yoruba ba si ni ominira tan, ede abinibi la mu lskunkundun.
Ede oyinbo ti wsn n gbe larugẹ yoo si jẹntẹdi, eyi ti ko ni wulo mọ rara."
Bakan naa ninu ifọrọwerọ ọhun ni oloye Sunday Igboho tun ti sisọ loju rẹ pe oun ko ni lero rara lati jẹ Aarẹ Ọna Kakanfo nilẹ Yoruba.
Igboho salaye pe oye to ga julọ, ti gbogbo agbaye fi mọ oun ni Igboho, Ọlọrun Ọba si lo fun oun.
Adebunmi Adeyeye: Mo jẹ gbèsè gbọ́múléláńtà, ìdí iṣẹ́ kabúkabú ni mo ti ri san
"Ko si oye tẹ le fun mi laye yii, lai pe Igboho mọ, aye ko le mọ pe emi lẹ n sọrọ rẹ.
N ko nilo oye aarẹ ọna kakanfo kankan mọ lẹyin Igboho ti Ọlọrun fun mi."
Sunday Igboho tun ti fidi rẹ mulẹ pe awọn ọba alaye ilẹ Yoruba ti wa lẹyin oun gbaa gbaa gbaa nidi ijijagbara fun ilẹ Yoruba.
"Igboho ni ""Iku Baba Yeye, alasẹ ekeji orisa lo n sọrọ lọwọ bi mo se n sọrọ yii, nitori o wa pẹlu wa."
Koda, Oonirisa Ọjaja Adeyeye Enitan Ogunwusi gan wa pẹlu wa, to fi mọ Awujale, Olugbon, Olu Ilaro atawọn ọba yoku ni agbegbe Oke Ogun to fi mọ Olukere.
Akomolede àti Asa:  Mọ̀ si nípa àṣà ìsọmọlórúkọ́ nílẹ̀ Yorùbá àti ìtumọ̀ orúkọ̀ fún ìkókó
Igboho ni awọn ọba alaye naa ti n sọ fun aarẹ Muhammadu Buhari pe ti ko ba sọra, o seese ko jẹ awọn ọba ilẹ Yoruba ni yoo siwaju ijijagbara yii gkgẹ bo se waye laye atijs ti ọba maa n siwaju ogun.
"Koda, gbogbo awọn kabiyesi ti kọ lẹta si Buhari lori ọrọ awọn apaayan Fulani pe funra awọn ni awọn yoo sigun, eyi to fi skan wa balẹ pe a ni baba to n ti wa lẹyin.'
Oríṣun àwòrán, Sunday Igboho/Instagram
Ilumọọka ajijagbara ọmọ Yoruba nni, Oloye Sunday Adeyemo, ti ọpọ eeyan mọ si Sunday Igboho, tun ti salaye lori bi irinajo rẹ silu Ayete lọjọru to kọja se ri.
Igboho, lasiko to n bawọn ọmọlẹyin rẹ atawọn araalu sọrọ lori ayelujara lọjọ Aiku lo ti salaye nipa irinajo rẹ ọhun.
Igboho ni  irinajo mi silu Ayete so eso rere pupọ, ti ọwọ oun si dẹ nidi sise awari awọn afurasi ọdaran darandaran amọ mo kọ lati kọkọ gbe sori ayelujara ni."
"Awọn agbaagba Yoruba ti ba wa wi pe eeyan kii fi gbogbo ẹnu sọrọ, gbogbo asọ kọ la a saa loorun, a si ti gbọ, tori naa ni n ko se kọkọ gbe fidio sita nigba ti mo n lọ."""
Sunday Igboho: Ẹ fi Ògún búra fún wa láti jà fún ilẹ̀ Yorùbá láì gbé Amotekun sábẹ́ ìjọba
O fikun pe diẹ ni fidio ati iroyin tawọn araalu gbọ nipa irinajo naa, kii si se gbogbo ohun ti oun ba n se, ni oun yoo maa gbe sori ayelujara mọ.
Igboho ni nigba toun di ilu Ayete de, ni oun to se fidio sita nipa awọn isẹ ribiribi ti oun se lati pe alaafia pada silu naa.
Fidio ti mo gbe diẹ sita nipa ohun ta se nilu Ayete ni yoo jẹ kawọn eeyan mọ pe kii se ẹnu lasan ni oun fi n se ijijagbara fun ilẹ Yoruba, tabi pe a ti lọ sinmi tabi jami lori rẹ.
Sunday Igboho ni o di igba ti iran Yoruba ba de ilẹ ileri, toun ri pe alaafia ti wa, ki oun to sinmi nidi ijijagbara naa.
Bakan naa lo ni oun si n jẹ mọsa ọrọ awọn ọdaran Fulani ni eteeti lọwọ ni, oun ko tii bo loju gangan amọ laipẹ ni oun yoo bo loju torotoro, ti Yoruba yoo si de ilẹ ileri.
Ajijagbara ọmọ ilẹ Yoruba naa wa fi ọwọ sọya pe awọn ọdọ tawọn n jija gbara fun ilẹ Yoruba lasiko yii, ni yoo gba ominira fun ilẹ Yoruba, kii si se iran to n bọ.
"Awọn ọmọ wa kọ ni yoo gba ominira fun iran Yoruba, awa ọdọ yii ni. Ẹ gbagbe pe a se aseti lori rẹ, ta si gbe le awọn ọmọ wa lọwọ.
Adebunmi Adeyeye: Mo jẹ gbèsè gbọ́múléláńtà, ìdí iṣẹ́ kabúkabú ni mo ti ri san
Ọlọrun lo ti mi sita lati wa sisẹ yii, ko si oun ti mo fẹ, ti Ọlọrun ko fun mi, ko si yẹ ko jẹ iru emi ni yoo ma sisẹ ijijagbara yii, amọ Ọlọrun lo ran mi."
Ninu eto ibanisọrọ naa ni Igboho tun ti kesi awọn ọmọ Yoruba lati fun sokoto wọn ko le, nitori ko si ọrọ pe a n boju wẹyin mọ.
O fikun pe ko si ohunkohun kankan to le dun mọhurumshuru mọ wa mọ.
Prophet Shittu Adeniyi: Ẹni tó bá ń tọrọ agbe, kìí jẹ́ èèyàn ní mo ṣe tẹ́pa mọ́ṣẹ́
"Sheik Gumi mọ ibi ti awọn ajinigbe agbebọn wa, to si n beere pe ki ijọba darijin wọn. Amọ awa ta n fẹ alaafia fun Yoruba lẹ n ko, tẹ fẹ gbe sahamọ, ko le seese.Yoruba, ẹ fun sokoto yin ko le, a ko boju wẹyin mọ
Sunday Igboho: Olùkówójọ gbọnmú fún agbẹnusọ Igboho tó ní ₦2.5m kìí ṣe bàbàrà fún owó oúnjẹ
Oríṣun àwòrán, Sunday Igboho
Awuyewuye ti n waye lori owo kan ti iye rẹ to miliọnu meji abọ naira ti awọn eeyan da lati ṣagbatẹru ijijagbara ti Oloye Sunday Igboho n ja fun ilẹ Yoruba.
Gẹgẹ bii ohun ti a gbọ, awọn eeyan da owo naa si ikawọ arabinrin kan ti orukọ rẹ n jẹ Maureen Badejọ, to si yẹ ki Maureen fi owo ọhun ṣowọ si Oloye Igboho.
Wahala bẹ silẹ lẹyin ti Maureen sọ pe oun fi owo naa ṣọwọ si Olayomi Koiki, ti ọpọ mọ si Koiki Media, to jẹ agbẹnusọ ajijagbara naa.
Iroyin naa ni lẹyin ti Koiki gba owo naa tan, ko fidi rẹ mulẹ fun Maureen pe owo naa ti de ikawọ oun fun nnkan bi ọsẹ meji.
Oríṣun àwòrán, @ThePentecostNG
Ko pẹ si asiko yii ti awuyewuye bẹrẹ si n waye lori owo naa, ti wọn pe ni owo ounjẹ.
Idi ree ti Muareen fi ṣe fidio kan, nibi to ti kesi Koiki lati wa sọ boya o ti gba owo naa tabi ko tii gba.
Bo tilẹ jẹ pe ibeere ọhun ati gbagede eto ti Muareen ti beere nipa owo naa ko dun mọ Koiki ninu, o fesi pe lootọ ni oun gba owo ọhun gẹgẹ bii owo ounjẹ.
Gẹgẹ bii ohun ti Maureen sọ, o ni oun n reti ki Koiki kede pe oun ti gba owo naa, ki awọn eeyan to da owo ọhun le mọ bo ṣe n lọ.
Nigba ti Maureen n beere lọwọ rẹ, idi ti ko ṣe fi ohun ransẹ pe oun ti gba owo naa lẹyin ọsẹ meji, ni Koiki ba dahun pe owo ounjẹ lasan ni N2.5 miliọnu, ati pe kii ṣe nnkan babara nitori awọn eeyan ti da owo to ju bẹẹ lọ fun ijagbara ọhun.
Akomolede àti Asa:  Mọ̀ si nípa àṣà ìsọmọlórúkọ́ nílẹ̀ Yorùbá àti ìtumọ̀ orúkọ̀ fún ìkókó
Ọrọ ti Koiki sọ yii, pe owo na ko jẹ tuntun ati nnkan babara lobi Muareen ninu, to bẹẹ ti awọn mejeji fi n ta ohun sira wọn.
Lẹyin naa ni Maureen ni ki Koiki fi ori eto oun silẹ.
Gbas gbos to waye laarin Maureen ati Koiki ti wa mu ki obinrin naa ke si ileeṣẹ GoFundMe lati da gbogbo owo to gba lọwọ ara ilu to nifẹ lati ṣagbatẹru ijijagbara ti Sunday Igboho n ṣe, pada fun wọn.
Ti ẹ ko ba gbagbe, oṣu diẹ sẹyin ni Ololye Sunday Igboho kede Koiki Media gẹgẹ bii ojulowo agbẹnusọ oun, lẹyin ti awọn kan bẹrẹ si ni ṣi oriṣiri oju opo lorukọ rẹ.
Adebunmi Adeyeye: Mo jẹ gbèsè gbọ́múléláńtà, ìdí iṣẹ́ kabúkabú ni mo ti ri san
Oríṣun àwòrán, Sunday Igboho Instagram
Awuye wuye ti n waye lori owo iranwọ fun isẹ ijijagbara ti wọn da fun Oloye Sunday Igboho, tii se ajijagbara kan fun iran Yoruba.
Idi ni pe Igboho ti kede fun araye pe oun ko gba owo kankan to to ogoji miliọnu naira tawọn eeyan kan n pariwo pe wọn ko fun oun.
Igboho, ninu fidio kan to ti bawọn araalu atawọn ọmọlẹyin rẹ sọrọ lọjọ Aiku ni ọrọ yii ti jẹyọ.
O ni Owo ti wọn ni wọn da fun mi, pe wọn gbe ogoji miliọnu naira fun mi, n ko gba owo kankan lọwọ ẹnikẹni."
Sunday Igboho: Fulani kò leè dúró, táa bá lo ohun ta jogún lọ́dọ̀ àwọ̀n bàbá wa
"Miliọnu mẹfa ati aabọ naira (N6.5m) pere lo tẹ mi lọwọ. Awọn ti mo sọrọ wọn jade ninu fidio ti mo se nikan lo fun mi lowo naa, mo si kede rẹ nigba naa."""
"Ajijagbara ọmọ Yoruba naa fikun pe ""owo rẹpẹtẹ ti wọn da fun Maureen, a ko ri gba, gbogbo ẹnu ni mo fi sọ."
Awọn eeyan kan fọkan si pe mo gba ogoji miliọnu naira, amọ n ko ri gba. Madam Maureen naa ni oun ko ri owo naa gba.
"O ni GoFundme ko gbe owo naa kalẹ, n ko si sọ ohunkohun, tori owo naa kọ la n na."""
Sunday Igboho: Ẹ fi Ògún búra fún wa láti jà fún ilẹ̀ Yorùbá láì gbé Amotekun sábẹ́ ìjọba
Sunday Igboho ni ojoojumọ ni awọn n dana pẹlu awọn ọmọlẹyin oun, tawọn n jẹun, da epo sinu ọkọ tawọn n gbe kiri.
Amọ o fikun pe yiyọ ẹkun oun lori ọrọ naa, ti ojo kọ rara.
Ibeere to wa n gba ẹnu ọpọ eeyan ni pe nibo ni owo tuulu yii wa nigba ti ko de ọdọ Sunday Igboho?
Adebunmi Adeyeye: Mo jẹ gbèsè gbọ́múléláńtà, ìdí iṣẹ́ kabúkabú ni mo ti ri san
Sugbọn lẹyin ọjọ kan ti Sunday Igboho sọrọ yii lori ayelujara, ni gbajumọ kan nipa ohun to n lọ lawujọ, Kayode Ogundamisi fi ikede kan soju opo Twitter rẹ nipa owo naa ni aarọ ọjọ Aje oni.
Ninu ikede naa ni Ogundamisi ti salaye pe obinrin kan, Maureen Badejo, ti wọn fi ẹsun ikowojẹ kan, ti kọwe si ajọ GoFundMe pe ko da owo to din diẹ ni miliọnu mẹtadinlaadọta pọun (£46,933) pada.
Oríṣun àwòrán, @ogundamisi
Owo iranwọ yii, to ni wọn ko jọ fun Sunday Igboho lo ni ki ajọ naa da pada fun awọn eeyan to da owo naa.
Nibayii, BBC Yoruba ti n gbe igbesẹ lati ba Maureen Badejo sọrọ lori isẹlẹ yii lati mọ ibi ti ọrọ owo owo iranwọ naa de duro ati bi owo naa se rin.
Bo ba se lọ si, a maa mu iroyin ọhun wa fun yin.
Fake Lemonade in Kano: Ọwọ́ ìjọba tẹ èèyàn mẹ́rin lórí títa ayédèrú ohun mímu tó ń pààyàn
Ajọ to n daabo bo ẹtọ araalu nipinlẹ Kano ṣọ pe, ọwọ ti tẹ eeyan mẹrin to ta ayederu ohun mímu fun awọn eeyan nipinlẹ naa.
Iroyin sọ pe ṣe ni awọn to mu ohun mimu naa bẹrẹ si ni bì, ti wọn si n tọ ẹ̀jẹ̀ lẹyin ti wọn mu u tan.
Ọga agba fun ajọ naa, Baffa Dan Agundi sọ fun BBC pe, ninu ile kan ti wọn ko ti i kọ tan nijọba ibilẹ Munjibir, ni ọwọ ti tẹ àwọn eeyan mẹrin naa.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí:
O ni apo to to ẹẹdẹgbẹta ni wọn fi di awọn nkan mimu naa, ti ọjọ ti lọ lori wọn, àti awọn nkan mii to lewu fun eeyan lati jẹ.
"Ọgbẹni Baffa sọ pe ""ojúṣe ẹni to jẹ olori ninu awọn ti ọwọ wa tẹ ni lati ko awọn nkan mimu to jẹ ayederu, ati eyi ti ọjọ ti lọ lori wọn, wa fun awọn to ku."
 Koda, diẹ lara awọn nkan ti a ba nibẹ ko jọ nkan mimu. 
O ni ọwọ tẹ awọn afurasi naa nipasẹ iwadii, lẹyin ti awọn eeyan kan sọ pe ọjà Singha ati Bakin Asibiti, nilu Kano, ni awọn ti ra nkan mimu naa.
Bakan naa ni ileesẹ ijọba to wa fun eto ilera nipinlẹ Kano sọ pe lootọ ni eeyan mẹrin kú, lẹyin ti wọn mu àwọn nkan mimu naa.
Akomolede àti Asa:  Mọ̀ si nípa àṣà ìsọmọlórúkọ́ nílẹ̀ Yorùbá àti ìtumọ̀ orúkọ̀ fún ìkókó
Dokita Bashir Lawal, ti ileewosan Abdullahi Wase sọ pe aisan Lassa Fever ni awọn kọkọ ro pe o n ṣe awọn eeyan naa, nigba ti wọn gbe wọn de ileewosan rẹ.
O ni sugbọn, awọn pada mọ pe kii ṣe Lassa.
Eeyan meji lo ku si ileewosan, meji ku si ile wọn, eeyan bi i 189 si n gba itọju lọwọ ni ileewosan ọtọọtọ nilu Kano.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Iroyin to n tẹ wa lọwọ ni yajoyajo sọ pe awọn agbebọn tun ti ji awọn akẹkọọ ile ẹkọ alakọbẹrẹ Rema, nijọba ibilẹ Birnin Gwari nipinlẹ Kaduna gbe lọ.
Bakna naa la gbọ pe awọn olukọ awọn akẹkọọ yii gan wa lara awọn eeyan tawọn agbebọn naa ji gbe lọ.
Ọsan ọjọ Aje ni isẹlẹ naa waye.
Kọmisana feto aabo ati ọrọ abẹle nipinlẹ Kaduna, Samuel Aruwan lo fidi isẹlẹ naa mulẹ ninu atẹjade kan to fisita fawọn akọroyin.
Awọn alasẹ ko si ti le sọ pato iye akẹkọọ ati olukọ tawọn agbebọn naa ji ko lọ.
Adebunmi Adeyeye: Mo jẹ gbèsè gbọ́múléláńtà, ìdí iṣẹ́ kabúkabú ni mo ti ri san
Ọba alaye kan to kọ lati darukọ rẹ naa fidi isẹlẹ yii mulẹ fun BBC.
Bẹẹ ba si gbagbe, alẹ ọjọ Satide ni awọn agbebọn yii tun gbinyanju lati kọlu ile ẹkọ girama Ikara , ti wọn si gbinyanju lati ji awọn akẹkọọ ibẹ gbe.
Ọba alaye naa ni awọn akẹkọọ ọọdunrun ati meje ni wọn doola wọn lọwọ awọn ajinigbe naa.
A o maa mu ẹkunrẹrẹ iroyin naa wa fun yin laipẹ.
Niger Attack: Ìjọ̀ba kéde ọjọ́ mẹ́ta láti dárò àwọn èèyàn tó jáláìsí nínú ìkọlù náà
Oríṣun àwòrán, Getty Images
O kere tan, eeyan mejidinlọgọta ti jade laye lorilẹede Niger lasiko ti ikọ agbebọna kan kọlu awọn agbegbe to paala pẹlu orilẹede Mali.
Awọn agbebọn naa lo sina ibọn bolẹ sara ọkọ mẹrin to n ko awọn ero pada lati ọja lagbegbe Tillaberi.
Lọwọlọwọ bayii, ko si ikọ adunkoomọni kankan to tii jade sita pe oun lo wa nidi ikọlu naa.
Amọ sa, ikọ ajijagbara meji lo n ba orilẹede Niger soro bayii, ọkan ninu wọn lo wa niwọ oorun orilẹede naa lẹba ilẹ Mali ati Burkina Faso.
Ikọ ajijagbara keji lo wa ni ila oorun guusu ilẹ Niger nibi to ti paala pẹlu orilẹede wa Naijiria.
"Atẹjade kan ti ijọba ilẹ Niger ka sita lori mohunmaworan ilẹ naa salaye pe ""ọpọ agbebọn to dimọra, ti ẹnikẹni ko si damọ lo kọlu ọkọ mẹrin to n ko ero bọ lati ọja Banibangou pada wa si abule Chinedogar ati Darey-Daye."
"Lẹyin ikọlu wọn, eeyan mejidinlọgọta lo jade laye, ọkan fara pa, ti ọpọ ounjẹ onihoro si sofo danu, bakan naa ni wọn jo ọpọ ọkọ nina, ti wọn si tun gba ọkọ meji sọdọ."""
Ijọba Niger wa kede ọjọ mẹta fun idaro awọn eeyan to jalaisi lorilẹede naa lati ipasẹ ikọlu ọhun, bẹrẹ lati oni Ọjọru.
Akomolede àti Asa:  Mọ̀ si nípa àṣà ìsọmọlórúkọ́ nílẹ̀ Yorùbá àti ìtumọ̀ orúkọ̀ fún ìkókó
Atẹjade naa wa rọ awọn araalu lati maa fi oju sọri pupọ, ki wọn si maa sọrọ sita pẹlu ipinnu ọkan lati tako iwa ọdaran ni gbogbo ọna.
Oríṣun àwòrán, @NigeriainfoFM
Ijọba apapọ ti ke si awọn ọmọ Naijiria lati fi ọwọ gidi mu eto abo ara wọn gẹgẹ bii ọna kan gboogi lati fopin si awọn ikọlu to n waye si awọn akẹkọọ.
Minisita abẹle fun eto ẹkọ, Chukwuemeka Nwajiuba lo sọ ọrọ naa ninu ifọrọwerọ kan pẹlu awọn akọroyin lọjọ Aje, nibi to ti sọ pe ko ṣeeṣe ki ijọba dabo bo gbogbo ile ẹkọ to wa ni Naijiria.
Gẹgẹ bo ṣe sọ, ijọba apapọ ti sọ fun awọn ile ẹkọ lati maa fi gbogbo ohun to jọ mọ ọrọ abo to awọn agbofinro leti.
Ninu ifọrọwerọ ọhun, ni wọn ti beere lọwọ minisita naa pe, ki ni ohun gan pato ti ijọba n ṣe lati dabo bo awọn ile ẹkọ lọwọ awọn janduku to n kọlu wọn lemọlemọ.
Akomolede àti Asa:  Mọ̀ si nípa àṣà ìsọmọlórúkọ́ nílẹ̀ Yorùbá àti ìtumọ̀ orúkọ̀ fún ìkókó
"O ni ""eto aabo ṣe pataki lootọ, o si jẹ ohun to jẹ awọn araalu logun, ṣugbọn ijọba ko le daabo bo gbogbo ile."""
Oju ni alakan fi n ṣori, nitori naa ni a ṣe sọ fun awọn ile ẹkọ nibikibi ti wọn ba wa pe, ti wọn ba kofiri ohun to le ṣakoba fun ẹmi ati dukia wọn, ki wọn tete fi to awọn agbofinro leti.
Nwajiuba sọ pe gbogbo ile ẹkọ to wa n Naijiria, yala ti ijọba ni tabi ti aladani, lo ni odi, ṣugbọn eyii ko da nnkan ti awọn awọn eeyan naa ko ba le maa ṣọ ara wọn.
"O ni ""o yẹ ki awọn eeyan maa ṣọ ara wọn, ki wọn si mu eto aabo wọn lọkunkundun, bẹẹ si ni ki wọn tete maa ke sawọn agbofinro ti wọn ba kofiri ohun to le fi wọn sinu ewu."""
Adebunmi Adeyeye: Mo jẹ gbèsè gbọ́múléláńtà, ìdí iṣẹ́ kabúkabú ni mo ti ri san
Ẹwẹ, ijọba ipinlẹ Kaduna ti sọ pe awọn olukọ mẹta pere ni awọn janduku kan ji gbe nile ẹkọ alakọbẹrẹ UBE to wa ni Magajin, iyẹn ni ijọba ibilẹ Brinin Gwari, nipinlẹ naa.
Kọmiṣọna to n ri si eto abo abẹlẹ, Samuel Aruwan sọ nibi ipade awọn akọroyin kan pe awọn janduku ọhun ko ri akẹkọọ kankan gbe lọ.
O ti to ọjọ mẹta kan ti awọn ajinigbe ti kọju si awọn akẹkọọ, paapaa labegbe oke ọya, eyii to ti fa ibẹru si ọkan ọpọ obi ati akẹkọọ lati lọ sile ẹkọ.
Oríṣun àwòrán, Olabisi Onabanjo University
Awọn janduku agbebọn ti ji awọn akẹkọọbinrin meji fasiti Olabisi Onabajo to wa ni niluu Ayetoro, ni ijọba ibilẹ Ariwa Yewa nipinlẹ Ogun.
Agbẹnusọ fu ileeṣẹ ọlọpaa ipinlẹ Ogun, Abimbola Oyeyemi sọ fun BBC Yoruba pe, ni bii ago mẹsan abọ alẹ ọjọ Aiku ọjọ kẹrinla oṣu kẹta ọdun 2021 yii ni wọn ji awọn akẹkọọ naa gbe nigba ti wọn n pada si ile wọn.
Ọgbẹni Oyeyemi ṣalaye pe aaya bẹ silẹ, o bẹ sare ni ileeṣẹ ọlọpaa ipinlẹ Ogun fi ṣe nitori iṣẹ iwadii ti bẹrẹ ni pẹru lati awọn akẹkọọ naa ri.
''Ọga ọlọpaa ilu Ayetoro gan an lo dari akitiyan ileeṣẹ ọlọpaa lati wa awọn akẹkọnbinrin naa rii.
Awọn ọlọpaa kogberegbe naa ti bẹrẹ iṣẹ iwadii lori iṣẹlẹ ọhun, a si gbagbọ pe a o ri awọn akẹkọọ naa laipẹ,'' agbẹnusọ ọlọpaa ṣalaye.
Nigba ti BBC Yoruba beere bo ya otitọ ni pe awọn agbebọn ọhun n beere fun aadọta miliọnu owo naira lati fi awọn akẹkọọ naa silẹ, Ọgbẹni Oyeyemi ni oun ko ni fẹ sọrọ lori rẹ.
O ni ọrọ lori owofun awọn ajinigbe le ṣakoba fun iwadii ileeṣẹ ọlọpaa to n lọ lọwọ lori iṣẹlẹ naa.
Insecurity in Yorubaland: Ọba Tejuosho ní àwọn tó ṣe àpérò àpapọ̀ ọmọ Oodua yẹ kò pe gbogbo oríadé sí ìpàdé
Oríṣun àwòrán, OPC
Ipade apapọ awọn ọmọ Kootu Oojire waye nilu Ibadan ni Ọjọru nilu Ibadan ti se olu ilu ipinlẹ Oyo, lati jiroro lori eto aabo to mẹhẹ ati awọn ipenija mioi to n koju iran Yoruba.
Ọpọ awọn eekanlu nilẹ Yoruba lo bawọn peju sibi ipade naa ninu eyi ta ti ri Alagba Banji Akitoye, Oloye Sunday Igboho ati bẹẹ bẹẹ lọ.
Sugbọn ọpọ eeyan lo n beere pe ki lo de tawọn ọba alaye kankan nilẹ Yoruba ko fi bawọn peju sibi ipade naa niwọn igba to jẹ pe eto aabo to mẹhẹ yii, awọn gan lo gberu julọ.
Idi ree ti BBC Yoruba fi tọ awọn ọba alaye kan lọ lati sewadi ohun to faa, tawọn ori ade ko se bawọn peju sibi ipade apapọ ọmọ Yoruba naa.
Oríṣun àwòrán, Facebook/Seyi makinde
Nigba to ba BBC sọrọ, Ọba Adetokunbọ Gbadegẹsin Okikiọla Tejuosho, Adabọnyin Ẹkùn Akọkọ, to jẹ ọba ìlú Orile-Kenta, nijọba ibilẹ Ọdẹda, nipinlẹ Ogun, sọ pe ninu iwe iroyin ni oun ti gbọ́ nipa ipade naa.
Ọba Tejuosho ni o dabi pe kii ṣe gbogbo ọba ilẹ Yoruba ni wọn pe si ibi ipade apero to waye nilu Ibadan naa, eyi to da lori eto aabo to mẹhẹ.
"O ni ""awọn ọba kan ti wọn gbagbọ pe awọn lo di ilẹ Yoruba ni wọn maa n pe si ipade, kii si ṣe emi ni ma a tako nkan ti wọn ba sọ nibẹ ni orúkọ gbogbo ọmọ Yoruba."""
Farmers Herders Crisis: Rẹ́rẹ́ rún, ẹ̀mí àti dúkìá ṣòfò lágbègbè Ariwa Yewa
Lori ọrọ idasilẹ orilẹ-ede Yoruba, Ọba Tejuosho sọ pe oun faramọ àbájade ipade naa, to ba ti jẹ pe yoo mu idagbasoke ati ọna abayọ si ipenija eto aabo ba ilẹ Yoruba.
Sugbọn, o ni o gbọdọ gba ọna to yẹ, ti ko ni i fa itajẹsilẹ tabi ogun.
Ẹwẹ, Ọba tejuosho tun ti kesi ijọba apapọ lati fọwọsowọpọ pẹlu awọn ọdẹ ibilẹ, fijilante, OPC ati Amotekun fun ipese eto aabo to peye.
Ọba alaye naa parọwa yii lasiko to n dunnu si bi awọn akẹkọọ fasiti Olabisi Onabanjo meji se ri idande gba lọwọ awọn ajinigbe.
Oriade naa ni awọn alaabo ibilẹ n sisẹ kara lati gba awọn ọmọ Yoruba to wa ni igbekun silẹ, to si tun tọkasi iyanju wọn lati ri pe tu Alhaji Lookman Onabanjo, tii se onisowo kan ti wọn ji gbe laipẹ yii silẹ.
Oríṣun àwòrán, Facebook/Seyi Makinde
O wa se apejuwe awọn ajinigbe naa gẹgẹ bii ẹni ibi ti ko lẹkọọ, eyi ti awujọ kankan ko le fara da nilẹ Yoruba.
Ọba Tejuosho wa gbarata lori pe ko sibi to ni aabo mọ ni tibu tooro ilẹ Yoruba, to si sapejuwe iwa ijinigbe gẹgẹ bii iwa ọdaran to wuwo pupọ.
Bakan naa lo rọ awọn araalu lati maa fi oju sọri nitori ipese aabo to peye jẹ ojuse gbogbo wa.
Oríṣun àwòrán, Amotekun Oyo state
Agba kii wa lọja, ki ori ọmọ tuntun wọ, eyi lo mu ki ẹgbẹ Afenifere Renewal Group ARG tun se n ronu jinlẹ lori eto aabo to mẹhẹ ni Naijiria.
Idi si ree ti wọn tun se n kesi awọn gomina to wa lẹkun iwọ oorun Naijiria lati san sokoto wọn ko le ńidi ipese eto aabo to peye fun ipinlẹ wọn.
Ẹgbẹ Afenifere ni ohun taa ba ni, laa naani, o si yẹ kawọn gomina kogiri mọ igbesẹ riro ikọ alaabo Amotekun lagbara, ki wahala to de.
Ẹ pese awọn ohun ija fun wọn, to fi mọ awọn ohun eelo ti wọn nilo ati owo pelu orukọ rere, ki wsn le kaato lati koju ipenija eto aabo to ba suyọ nibikibi lẹkun yii.
Adebunmi Adeyeye: Mo jẹ gbèsè gbọ́múléláńtà, ìdí iṣẹ́ kabúkabú ni mo ti ri san
Bakan naa ni wọn gba awọn gomina nimọran lati sawari ohun eelo labẹle, ti wsn yoo fi ro awọn eeyan wọn lagbara nidi didaabo bo ẹkun yii, kipo gbigbe ara le ileesẹ ọlọpa apapọ.
Nigba to n gbarata lori asa ijinigbe to n di lemọlemọ ni Naijiria, asaaju ẹgbẹ ARG, Olawale Osun ni ko yẹ kawọn gomina sun asunpiye, oju si lo yẹ ki alakan wọn maa fi sọri bayii.
Wo ohun tí Professor Peller wí tó kó bá a gẹ́gẹ́ bí ìyàwó rẹ̀, Lady Peller ṣe tú u síta
O yẹ ko ti ye awọn gomina lẹkun iwọ oorun Naijiria bayii pe ẹyin ni aabo awọn eeyan ipinlẹ yin gberu, ẹ lọ gbaju mọ.
Oríṣun àwòrán, Facebook/OPC diary
Ileeṣẹ ọlọpaa ipinlẹ Oyo ti sọ pe ohun ti bẹrẹ iṣẹ iwadii lori ọga Fulani, Iskilu Wakili atawọn eeyan rẹ meji ti wọn fọwọ ofin mu.
Ninu atẹjade kan ti alukoro ileeṣẹ ọlọpaa ipinlẹ Oyo, CSP Fadeyi Olugbenga, Anipr fi sita lọjọ Aje, ileeṣẹ ọlọpaa ni awọn ọlọpaa ọtẹlẹmuyẹ to wa ni Iyakangu ti bẹrẹ iṣẹ lori ọrọ awọn Fulani ọhun.
Ileeṣẹ ọlọpaa wa rọ awọn to ba ni ẹri to daju lori ẹsun ijinigbe atawọn ẹsun mii ti wọn fi kan Wakili atawọn eeyan rẹ pe ki wọn mu awọn ẹri naa wa.
Ileeṣẹ ọlọpaa sọ ninu atẹjade naa wi pe awọn ẹri yii yoo ṣe iranwọ lori ati mọ otitọ lori ọrọ naa.
Ọga ọlọpaa ipinlẹ Oyo tun sọ ninu atẹjade naa pe irọ lawọn kan n gbe kiri pe ileeṣẹ ọlọpaa ju awọn to mu ẹjọ awọn Fulani darandaran lagbegbe Ibarapa si atimọle.
Bakan naa lo sọ pe irọ ni pe ileeṣẹ ọlọpaa gbowo ki wọn to fun wọn ni beeli.
Ọga ọlọpaaa Oyo ni iru awọn eeyan to n gbe irufẹ iroyin bayii n tabuku iṣẹ riniribi tawọn ọlọpaa n ṣe nipinlẹ naa.
Ọga ọlọpaa ni ileeṣẹ ọlọpaa Oyo ṣetan lati ṣiṣẹ pọ pẹlu awọn araalu ti wọn ba ni ohun kan tabi omiran to le ṣe iranwọn lori ọrọ abo nipinlẹ Oyo.
Oxford AstraZeneca - Ìjọba àpapọ̀ ní kò séwu nípa abẹ́rẹ́ àjẹsára
Oríṣun àwòrán, Prof Akin Abayomi
Yoruba ni eeyan kii daradara ko ma ku sibi kan, bẹẹ si ni a kii waye, ka ma ni arun kan lara.
Bẹẹ lọrọ fẹ ẹ ri pẹlu abẹrẹ ajẹsara Oxford AstraZeneca to wa lati dena arun Coronavirus, eyi ti wọn ti ko wọ orilẹede Naijiria bayii.
Lọwọ lọwọ bayii, ko din ni eeyan ẹgbẹrun mẹjọ to ti gba abẹrẹ ajẹsara naa nilẹ wa, gẹgẹ bi igbimọ amusẹya lori arun Coronavirus se wi.
Amọ sa, ajọ naa ni ipinlẹ Kogi nikan ni ẹnikẹni ko ti gba abẹrẹ naa nitori bi isẹ atunse se n lọ lọwọ lori ẹrọ amunkan tutu rẹ, ti wsn yoo ko abẹrẹ naa pamọ si.
Oríṣun àwòrán, EPA
Amọ nibayii, Kọmisana feto ilera nipinlẹ Eko, Akin Abayomi ti sisọ loju rẹ pe awọn ewu kan wa to rọ mọ gbigba abẹrẹ ajẹsara AstraZeneca naa.
Dokita Abayomi ni lootọ ko si ohunkohun to se oun ni ọjọ akọkọ ti oun gba abẹrẹ ajẹsara naa amọ lọjọ keji ni ori n fọ oun, ti ara si tun n ro oun pẹlu.
"Lọjọ keji ni otutu n mu mi, ara n ro mi, ti oju ibi ti mo ti gba abẹrẹ naa si n dun mi amọ mo lo oogun ara riro, mo sere idaraya, ti mo si lọ sun.
Nigba ti mo taji, se ni ara mi le koko, ti mo si wa daada."
Kaakiri agbaye, awọn orilẹede kan ti n fofin de gbigba abẹrẹ ajẹsara naa nitori abajade rẹ lara awọn eeyan kan ti wọn lo n mu ki ẹjẹ wọn di.
Akomolede àti Asa:  Mọ̀ si nípa àṣà ìsọmọlórúkọ́ nílẹ̀ Yorùbá àti ìtumọ̀ orúkọ̀ fún ìkókó
Lọwọ lọwọ, orilẹede Spain, Germany, France, Italy ati Holland naa ti darapọ mọ awọn orilẹede to ti dawọ duro lori fifun awọn eeyan wọn ni abẹrẹ naa.
Ohun ti wọn lo sokunfa igbesẹ wọn ọhun ni bi ẹjẹ awọn eeyan kan se n di.
Amọ ajọ eleto ilera lagbaye WHO ti kede pe kawọn eeyan mase dẹkun gbigba abẹrẹ ajẹsara naa nitori ko si ewu ninu rẹ.
WHO ni ko si ẹri kankan to daju nipa aleebu ti wọn ni abẹrẹ ajẹsara naa ni, eyi to ni se pẹlu ewu ẹjẹ didi.
Adebunmi Adeyeye: Mo jẹ gbèsè gbọ́múléláńtà, ìdí iṣẹ́ kabúkabú ni mo ti ri san
Nibayii, ijọba apapọ ti fọwọ gbaya fawọn araalu pe ko si ewu kankan nidi gbigba abẹrẹ naa.
Dokita Shuaib Faisal, tii se akọwe apapọ fun ajọ eleto ilera alabọde ni Naijiria lo fọwọ gbaya bẹẹ pẹlu afikun pe, tori abẹrẹ ajẹsara Oxford AstraZeneca jẹ olowo pọọku, ko tumọ si pe ko pegede to.
Apam Beach Drowning: Wọ́n ti sin òkú àwọn akẹ́kọ̀ọ́ mẹ́ẹ̀dógún náà lápapọ̀
Bi eeyan ba jẹ ori ahun, yoo sọkun to ba gbọ iroyin nipa iku awọn akẹkọ bii ogun, ti wọn ls luwẹ ni eti okun Apam lọjọ Aiku, ọjọ Keje osu Kẹta ọdun 2021.
Ileesẹ ọlọpaa nilẹ Ghana ti wa fidi rẹ mulẹ pe awọn ti ri oku mẹtala lara awọn akẹkọ naa to ku sinu okun ti wọn ti n luwẹ letikun Apam lọjọ Aje, ọjọ Kẹjọ osu Kẹta.
Atẹjade kan ti ileesẹ ọlọpaa ni Ghana fisita salaye pe meji ninu awọn akẹkọ naa ni wọn ri laaye leti okun ọhun, nigba ti wọn ri oku akẹkọọ mejila.
Ọga ọlọpaa Irene Oppong to wa ni ẹka to n gbọ ọrọ araalu nilu Cape Coast ni ọkunrin kan, Kwame Akono lo mu ẹsun nipa isẹlẹ naa tọ oun wa.
"Deede aago mẹsan ku ogun isẹju ni ọkunrin naamu ẹsun tọ wa wa pe ọmọ ẹgbọn oun, Joshua Annor, tii se ọmọ ọdun mẹẹdogun lo lọ gba bọọlu leti okun, to si ri sinu rẹ pẹlu awọn ọmọ miran.
Idi niyi ta fi tete morile eti okun naa pẹlu ikọ ti yoo wa awọn ọmọ naa jade, Ọlọrun si ba wa se, a ri Simon Dadzie, ọmọ ọdun mẹẹdogun ati Gogffrey Apperetsie, ọmọ ọdun mẹrinla yọ laaye."
Oppong fikun pe awọn akẹkọ mejeeji yii lawọn tete gbe lọ sile iwosan ijọ Aguda ti Luke fun itọju to yẹ.
Akomolede àti Asa:  Mọ̀ si nípa àṣà ìsọmọlórúkọ́ nílẹ̀ Yorùbá àti ìtumọ̀ orúkọ̀ fún ìkókó
O ni awọn oku awọn akẹkọọ tawọn ri ni aarọ ọjọ Aje ni ọjọ ori wọn wa laarin ọdun mẹrinla si mẹtadinlogun, ti oku ọmọbinrin meji si wa laarin wọn.
O ni awọn oku awọn ọmọbinrin mejeeji naa lawọn gbe lọ sile igbokusi to wa nile iwosan fun ayẹwo to yẹ, ti iwadi si ti n lọ lọwọ lati mọ iru iku to pa awọn akẹkọ naa.
Adebunmi Adeyeye: Mo jẹ gbèsè gbọ́múléláńtà, ìdí iṣẹ́ kabúkabú ni mo ti ri san
Amọ sa, wọn ti sin oku awọn akẹkọ mẹtala ọhun lapapọ loni ọjọ Isẹgun, kutu hai si lawọn mọlẹbi wọn ti de sile iwosan katoliki Luke nibi ti wọn gbe oku awọn ọmọ naa si.
Dino Melaye: Mo jẹ́ afọ́jú tẹ́lẹ̀, àmọ́ mo ti ríran pé wọn gba wa ni bí Buhari ṣe di ààrẹ
Oríṣun àwòrán, Dino Melaye/Instagram
Asofin agba tẹlẹ nile asofin apapọ ilẹ wa, Sẹnatọ Dino Melaye ti n tọrọ aforrijin lọwọ Ọlọrun lori atilẹyin to se fun aarẹ Muhammadu Buhari lati wọle ibo lọdun 2015.
Melaye, lasiko to n kopa lori eto kan lori mohunmaworan Channels lọjọ Ẹti, eyi to gbe ẹda rẹ soju opo Instagram rẹ, lo ti tọrọ aforijin bẹẹ.
"Melaye wa se apejuwe bi Buhari se di aarẹ Naijiria gẹgẹ bii ""iwa jibiti ati gbajuẹ to tii buru julọ nilẹ Afirika"", to si ni kawọn eeyan gbagbe gbogbo ohun tawọn fi tan wọn jẹ lasiko ipolongo ibo naa."
Asofin tẹlẹ naa ni ijọba Buhari ti ja awọn ọmọ Naijiria kulẹ ni gbogbo ọna, bẹrẹ lati ori eto aabo to mẹhẹ titi de ori aisi ipese awọn ohun eelo amayedẹrun.
Oríṣun àwòrán, Dino Melaye/Instagram
"Mo tọrọ aforijin lọwọ Ọlọrun ọga ogo to ga julọ, ẹni to da ọrun ati aye ati lọwọ awọn ọmọ Naijiria lori bi mo se ti Buhari lẹyin lati de ipo aarẹ.
Bawo ni eeyan se le wa ninu ẹgbẹ oselu kan tabi sugba aarẹ pẹlu gbogbo  isẹlẹ to n waye lọwọlọwọ ni Naijiria?
Nitori naa, mo kabamọ gidigidi pe mo ti i lẹyin nitori wọn lu wa ni jibiti ni."
Ogbomoso Quitdruplets: Ọ̀kan nínú àwọn ìbarùn-ún jáde láyé lọ́jọ́ karùn-ún
Bakan naa ni asofin agba tẹlẹ naa wa koro oju si bi ijọba apapọ se buwọ lu pe ki wọn fi biliọnu lọna meji ati ọgọrun miliọnu naira (N2.1m) se oju ọna kilomita kansoso lati Kano si Abuja.
A o ranti pe Dino Melaye lo n soju ẹkun idibo iwọ oorun Kogi nile asofin agba ilẹ wa tẹlẹ ko to di pe o fidi rẹmi ninu atundi ibo to waye.
Oríṣun àwòrán, Ekiti state Government
Ijọba apapọ Naijiria ti ke sawọn ipinlẹ gbogbo ni Naijiria lati daabo bo awọn igbo ọba wọn nitori awọn ajinigbe.
Asẹ yii lo wa nitori bi awọn ọdaran darandaran ati ajinigbe se n lo igbo sba lati fori pamọ sisẹ laabi wọn.
Akọwe ijọba apapọ, Boss Mustapha lo pasẹ bẹẹ nibi ipade awọn akọwe ijọba to waye fun saa akọkọ lọdun yii nilu Abuja.
Mustapha ni ijọba apapọ yoo ro awọn igbo ọba rẹ mẹtadinlogun to wa jakejado Naijiria lagbara lati gbaa lọwọ awọn afurasi ọdaran.
"Gbogbo wa la mọ pe a nilo awọn igbo ọba wa atawọn agbegbe min taa ya sọtọ fun iwulo isẹ ti wọn wa fun, paapaa fun pasi paarọ owo naira wa si tilẹ okeere.
Bed Wetting: Tolulope Joseph ní ò lé ní ogún ọdún tí òun fi tọ̀ sílé kí ìwòsàn tó dé
Bakan naa lawọn igbo ọba yii tun jẹ orisun ipese isẹ oojọ fawọn eeyan, to si tun maa n pese awọn eroja asaraloore fun ilẹ to lọra ati ipese ounjẹ lọpọ yanturu"
Nitori naa, mo wa n pe awọn ijọba ipinlẹ nija lati bẹrẹ si ni gbe igbesẹ fun idaabo bo awọn igbo yii ti akoso rẹ wa nikawọ wọn.
Oríṣun àwòrán, Reuters
A ṣe agba adura ni awọn Yoruba maa n gba pe a o ni rin lọjọ ebi n pọna.
Ọkunrin kan ẹni ọdun marunlelogoji, Olasunkanmi Fagbemi ti ṣalaye fun igbimọ to n gbẹjọ iwa ọdaran ọlọpaa nipa bi ibọn ọlọpaa ṣe tun un da, ti ko si le fun obinrin loyun lati igba naa.
Fagbemi ni oun n rinrin ajo lọ si ilu Ibadan lọjọ kejidinlogun oṣu kẹjọ ọdun 2010, lawọn ọlọpaa kan da ọkọ ero ti oun wọ duro.
''Awakọ ero ti mo wa ninu rẹ fun awọn ọlọpaa naa ni ọgọrun un naira, lẹyin naa lawọn ọlọpaa ni ki o paaki sẹgbẹ daadaa, ko le gba ṣenji rẹ.
Oríṣun àwòrán, @PoliceNG
Awakọ naa bọ silẹ ninu ọkọ lati gba ọgọrin naira ṣenji rẹ, nibi ti a ti n duro ninu ọkọ ni ọlọpaa kan ti yinbọn sinu ọkọ ti mo wa nibẹ.
"Ibọn naa ba mi lọrun, ọta ibọn ọhun tun lọ sinu egungun ẹyin mi.
Awọn ọlọpaa naa fẹsẹ fẹẹ lẹyin ti wọn ri ohun to ṣẹlẹ,'' Fagbemi ṣalaye.
Fagbemi ni awakọ ero naa lo gbe oun lọ si ile iwosan UCH niluu Ibadan nibi ti wọn ti ṣiṣẹ abẹ foun lati yọ ọta ibọn ninu eegun ẹyin oun lẹyin ọjọ kẹrin.
Adebunmi Adeyeye: Mo jẹ gbèsè gbọ́múléláńtà, ìdí iṣẹ́ kabúkabú ni mo ti ri san
''Mo ti kọ iwe ipẹjọ laimoye igba si awọn alaṣẹ atawọn oriṣiiriṣii ọga ọlọpaa nipinlẹ Ogun, amọ wọn o ṣe nkankan lori ọrọ naa lati bi ọdun mẹwaa sẹyin bayii,'' Fagbemi lo sọ bẹẹ.
Fagbemi ni nkan ko rọrun fun oun mọ lati igba ti iṣẹlẹ naa ti waye nitori oun ti naa ẹgbẹlẹgbẹ miliọnu lati tọju ara oun.
Koda, o ni oun ti rinrin ajo lọ si orilẹede India fun itọju ara oun.
Bakan naa ni Fagbemi sọ pe oun ti ta dukia ati ohun ini oun lori ati tọju ara oun.
Akomolede àti Asa:  Mọ̀ si nípa àṣà ìsọmọlórúkọ́ nílẹ̀ Yorùbá àti ìtumọ̀ orúkọ̀ fún ìkókó
''Mo n gbero lati gbeyawo nigba ti iṣẹlẹ yii ṣẹlẹ si mi, wọn si ti sọ fun mi nile iwosan pe n ko le ba obinrin sun loyun tori ailera mi ayafi nipasẹ IVF loku,'' Fagbemi lo sọ bẹẹ.
Ẹwẹ, alaga igbimọ oluwadii naa, Adajọ Solomon Olugbemi sọ pe igbimọ ọhun yoo kọ lẹta si ọga ọlọpaa ipinlẹ Ogun, lati mu ẹri to daju wa pe otitọ ni iṣẹlẹ ọhun ṣẹlẹ.
Iskilu Wakili: Wakili àtàwọn méjì míì dèrò ẹ̀wọ̀n lẹ́yìn tí wọ́n fẹ̀sùn ìpànìyàn, ìjínigbé àti olè kàn wọ́n
Oríṣun àwòrán, Facebook/OPC Diary
Ileeṣẹ ọlọpaa ipinlẹ Oyo ti fẹsun ipaniyan, ijinigbe ati ẹsun ole kan  Fulani darandaran, Iskilu Abdullahi Wakili ti ọpọ sọ pe o da agbegbe Ibarapa nipinlẹ Oyo ru.
Ileẹjọ majisireeti to wa ni agbegbe Iyaganku niluu Ibadan lọjọ Iṣẹgun paṣẹ pe ki wọn ju Wakili ati ọmọkunrin rẹ meji, Samaila, 27 ati Aliyu Manu si atimọle.
Ẹsun onikoko mẹfa ni ileeṣẹ ọlọpaa fi kan Wakili atawọn ọmọ rẹ mejeeji.
Adajọ Majisireeti, Emmanuel Idowu ko gbọ ẹbẹ ti awọn afurasi naa n bẹ pe ileẹjọ Majisireeti ko lagbara lati ṣe igbẹjọ ọhun.
Adajọ paṣẹ rara lai beṣu bẹgba pe ki wọn gbe wọn ju si atimọle.
Adajọ sun igbẹjọ naa si ọjọ kẹtadinlogun oṣu karun un ọdun 2021 yii.
Laipẹ yii ni awọn ọmọ ẹgbẹ OPC mu Wakili lagbegbe Ibarapa nipinlẹ Oyo ti wọn si le awọn ọlọpaa lọwọ.
Seyi Makinde: Tí aráàlú bá kọ̀ mí bíi gómìnà, ẹ̀rù kò bà mí láti fipò sílẹ̀
Oríṣun àwòrán, Facebook/Seyi Makinde
Gomina ipinlẹ Oyo, Onimọ ẹrọ Seyi Makinde ti kede pe ko le tu iru kan lara oun, ti oun ba kuna lati bori ibo fun saa keji.
Makinde lo ti kuna fun igba mẹta ọtọọtọ to tiraka lati di ibo gomina ipinlẹ Oyo  eyi to waye lọdun 2007, 2011 ati 2015.
Gomina Makinde lo sisọ loju ọrọ yii nibi ipade awọn alẹnulọrọ lori eto aabo ilẹ Yoruba to waye ni gbọngan Mapo nilu Ibadan lọjọru.
O tun fikun pe oun setan lati kuro lori aleefa tawọn araalu ba ni ki oun maa lọ, ru ko si ba oun lati fi ipo gomina silẹ.
Ti awọn eeyan ipinlẹ Oyo ba ni ki n kuro ni ọọfisi gẹgẹ bii gomina ipinlẹ Oyo, n ko ni ro ni ẹẹmeji, ki n to kuro nitori ojoojumọ ni mo n gbe baagi mi lọ si ọọfisi lati ile."""
Oríṣun àwòrán, Facebook/Seyi Makinde
Bakan naa ni gomina Makinde ni oun ko ni baba isalẹ ninu oselu, Ọlọrun si lo sọ oun di gomina, kii se ẹda alaaye kankan.
"Ọlọrun nikan ni mo bẹru, n ko bẹru ẹda alaaye kankan, ko si si bi ẹda kan se ni agbara to, emi ko le e bẹru rẹ.
Mo dije fun ipo gomina lọdun 2007,2011 ati 2015, ti mo si ja kulẹ amọ nigba ti Ọlọrun ni akoko to lati sọ mi di gomina, o gbe mi de ipo naa."
"Makinde ni oun ko ni abẹrẹ ni ọọfisi ti oun le boju wo lẹyin, ti ilọ ba ti ya, oun ti setan."""
O fikun pe ijọba oun ti n pese aabo to peye lati daabo bo ẹmi ati dukia, ti ijọba oun yoo si tun se amulo awọn ara ita lẹka eto aabo rẹ.
Farmers Herders Crisis: Rẹ́rẹ́ rún, ẹ̀mí àti dúkìá ṣòfò lágbègbè Ariwa Yewa
Nitori ipo ti mo wa, awọn ohun ti mo n ri, ẹyin ko le ri i, mo si n seleri pe ma maa se ipinnu nibamu pẹlu ifẹ araalu ni.
O wa sisọ loju rẹ pe nibi ipade eto aabo to kọja, oun da aawọ silẹ nitori pe eto aabo to mẹhẹ ti kọja ka maa fi ẹnu pa a lasan.
O ni awọn eeyan ti ko ba si lara awọn osisẹ ikọ alaabo Amotekun le lọ di ara ikọ ọdẹ ibilẹ Soludero tabi Fijilante gẹgẹ bi ara ọna lati fi ara wọn silẹ fun isẹ aabo ilu.
Oríṣun àwòrán, Facebook/Seyi Makinde
Saaju la ti sọ fun yin pe awọn eeyan meji ọtọọtọ ni awọn agbebọn ji gbe l'ọjọ Aje ni ibudo ti wọn ti n fọ okuta kan to n bẹ nilu Ibadan.
Ọkan ninu awọn eeyan meji naa jẹ oṣiṣẹ ileeṣẹ abanikọle, RCC ti ẹnikeji si jẹ oṣiṣẹ ile ifowopamọ Polaris.
Ijinigbe naa ṣẹlẹ lasiko ti awọn agbebọn yawọ ibudo ti wọn ti n fọ okuta(Binu Quarry) to n bẹ ni ilu Dalli lopopona Ibadan si Ijẹbu-Ode lati gbe awọn eeyan meji naa.
Iroyin fi idi ẹ mulẹ wi pe wọn ti fi ọrọ naa to awọn ọlọpaa agbegbe Idi Ayunrẹ leti nilu Ibadan.
Ijinigbe yii waye lẹyin oṣu diẹ ti awọn agbebọn yawọ ibudo ti wọn ti n fọ okuta kan ni agbegbe ijọba ibilẹ Akinyẹle, ti wọn si ji awọn oṣiṣẹ kan gbe lọ.
Alukoro ajọ ọlọpaa nipinlẹ Ọyọ, Arakunrin Olugbenga Fadeyi fi idi iṣẹlẹ naa mulẹ.
L'ọjọ Iṣẹgun ni Fadeyi ṣe alaye wi pe ileeṣẹ ọlọpaa ti n sa gbogbo ipa lati ri i daju wi pe awọn eeyan naa gba ominira.
Funke Olakunrin: Ilé ẹjọ́ sún ìgbẹ́jọ́ ikú ọmọ Fasoranti sí oṣù kẹrin àti ìkarùn ún
Oríṣun àwòrán, @EyeinAfrica
Ikọ akọṣẹmọṣẹ ẹṣọ alaabo Force CID ati SWAT ti fi ṣikun ofin mu awọn eeyan marun un miran, ti wọn fẹsun kan pe wọn lọwọ ninu iku ọmọ adari ana fẹgbẹ Afẹnifẹre, Reuben Fasoranti, iyẹn Funke Olakunrin.
Iroyin naa di mimọ lasiko ti igbẹjọ awọn afurasi ti ọwọ kọkọ tẹ ṣaju n tẹsiwaju, nile ẹjọ giga to wa niluu Akure, eyi ti adajọ Bode Adegbehinde n dari rẹ.
Ẹjọ naa ni idaduro ranpẹ lẹyin ti agbẹjọro ijọba, Grace Olowoporoku sọ fun ile ẹjọ naa pe, ọwọ ti tẹ awọn afurasi miran lori ẹsun kan naa.
Ṣaaju ni awọn agbofinro ti kọkọ mu awọn mẹrin kan lori ẹsun ipaniyan naa, ti wọn si ti n kawọ pọnyin rojọ niwaju adajọ.
Wọn ko wọn lọ siwaju adajọ lori ẹsun mẹta ọtọọtọ, igbimọditẹ lati paayan, ipaniyan ati ijinigbe.
Oríṣun àwòrán, @RipplesNG
Ẹjọ ọhun ti wa niwaju adajọ lati oṣu Kẹjọ ọdun 2020, ṣugbọn ti ọwọ ti tẹ awọn afurasi marun un miran, iye eeyan to n jẹjọ lori iku arabinrin naa ti wa di mẹsan an.
Ọlọpaa to n ṣewadii ọrọ naa sọ pe, wọn lọ mu awọn marun un ọhun lẹyin ti orukọ wọn n jẹyọ nigba gbogbo lasiko ti igbẹjọ naa n lọwọ.
Grace Olowoporoku ti beere pe ki wọn sun ẹjọ naa siwaju, ki aye le wa lati ṣewadii awọn afurasi tuntun naa finni-finni.
Akomolede àti Asa:  Mọ̀ si nípa àṣà ìsọmọlórúkọ́ nílẹ̀ Yorùbá àti ìtumọ̀ orúkọ̀ fún ìkókó
Adajọ to n gbọ ẹjọ ọhun, Bode Adegbehingbe ti sun ẹjọ naa siwaju titi di ọjọ kẹtadinlọgbọn, ọjọ kọkandilọgbọn, ọgbọn ọjọ oṣu Kẹrin ati ọjọ karun un, osu Karun un, ọdun 2021.
Ti ẹ ko ba gbabe, oṣu Keje, ọdun 2019 ni awọn afurasi naa ṣekupa Funke Olakunrin loju ọna marosẹ Ore si Eko.
Adebunmi Adeyeye: Mo jẹ gbèsè gbọ́múléláńtà, ìdí iṣẹ́ kabúkabú ni mo ti ri san
Barry Jhay: Àgbẹjọ́rò ní irúfẹ́ ìṣẹ̀lẹ̀ yìí náà wáyé sí Ayinde Barrister tí wọn ló pa èèyàn lẹ́yìn egúngún
Oríṣun àwòrán, Instagram/therealbarryjhay
Adura to yẹ ki onikaluku maa gba ki o to jade nile ni pe, ki Ọlọrun maa jẹ ki a ri alakoba.
Ọgbẹni Temitope Salami to jẹ agbẹjọro Oluwakayode Junior Balogun, ọmọ oloogbe akọrin Fuji, Alhaji Sikiru Ayinde Barrister ti ọpọ awọn ololufẹ rẹ mọ si Barry Jhay lo sọrọ yii lori ohun to ṣẹlẹ si i nipa iku ọrẹ rẹ, Kashy Godson niluu Accra lorilẹede Ghana.
Agbẹjọro Salami ni bi ọrọ Barry Jhay ṣe ri gan an niyii nipa bi awọn ọlọpaa orilẹede Ghana ṣe mu un gẹgẹ bi ọkan lara awọn afurasi ti wọn fọrọ wa lẹnu wo nipa iku Kashy.
Ọgbẹni Salami ṣalaye pe, Barry Jhay ko mọwọ, ko mẹsẹ nipa iku Kashy, atipe ọrẹ rẹ timọ timọ ni Kashy jẹ fun un.
Agbẹjoro Salami tun ṣalaye pe, ileeṣẹ ọlọpaa orilẹede Ghana ko figba kan fẹsun kan Barry Jhay pe o mọ nipa iku Kashy.
Oríṣun àwòrán, Barry Jhay
O ni wọn kan fọrọ wa a lẹnu wo lasan ni, kii ṣe Barry Jhay nikan, awọn ọlọpaa tun fọrọ wa eeyan mẹrin miran lẹnu wo ninu iṣẹ iwadii wọn.
"Asọdun awọn eeyan lasan lawọn kan n gbe kiri pe Barry Jhay lọwọ ninu iku Kashy.
Lọjọ ti iṣẹlẹ ọhun ṣẹlẹ, ọtọ ni yara ti Barry Jhay wa, nigba ti Kashy ati ọrẹbinrin rẹ naa wa ninu yara mii.
'Mi ò sí ni Ghana àmọ̀ ó dá wa lójú pé Ghana jẹ́ ìlú tó máa ń lo òfin wọn dáadáa, Barry Jhay máa bọ́'
Lojiji ni ọrẹbinrin Kashy sare lọ ba Barry Jhay ninu yara to wa pe oun ko mọ bi Kashy n ṣe mọ.
Barry Jhay ba sare lọ wo Kashy, ṣugbọn nigba to de ibi ti Kashy wa, ija ni Kashy gbe koju Barry Jhay ,ti o si bẹrẹ si ni lẹ nkan mọ an,'' agbẹjọro ṣalaye.
Ọgbẹni Salami ni nigba ti ọrọ ri bayii ni Barry Jhay sare kuro lọdọ Kashy pẹlu ẹjẹ lẹnu, lẹyin to ti ṣeeṣe, ti o ṣi lọ sọ fawọn agbofinro ni isalẹ nipa ohun to n sẹlẹ si Kashy.
Agbẹjọro Salami sọ pe leyin bi iṣẹju mẹwaa ti Barry Jhay sa kuro ni yara Kashy, ni Kashy jabọ lati ori oke kẹrin silẹ, ti o si gbabẹ di oloogbe.
Farmers Herders Crisis: Rẹ́rẹ́ rún, ẹ̀mí àti dúkìá ṣòfò lágbègbè Ariwa Yewa
''Kamẹra CCTV lo fi otitọ han pe Barry Jhay ko lọwọ ninu iku Kashy niluu Accra.
Awọn ọlọpaa ati ẹgbọn Kashy ati emi fun ra mi, ni a jọ wo kamẹra CCTV nibi ti a ti ri bi Kashy ṣe ku.
Ti ko ba si kamẹra CCTV ni, ko ba le diẹ lati fidi rẹ mulẹ pe Barry Jhay ko mọ ohun kan nipa iku Kashy.
Ayẹwo oku Kashy naa tun fihan pe, Barry Jhay ko lọwọ ninu iku ọrẹ ati ọga rẹ to di oloogbe.
Nibayii, ọkan Barry Jhay bajẹ lori iṣẹlẹ yii nitori ọrẹ kori o sun ni oun ati Kashy jẹ.
Koda, Kashy fun Barry Jhay lẹbun ago ni bii ọjọ meji si ọjọ ti o jade laye,'' agbẹjọro Salami lo ṣalaye bẹẹ.
Ẹwẹ, agbẹjọro Salami sọ pe iru nkan to ṣẹlẹ si Barry Jhay ti ṣẹlẹ si oloogbe Ayinde Barrister lọdun 1974.
O ni wọn tiran mọ Barrister lọrun pe oun lo pa ẹni to ku lẹyin egungun kan ṣugbọn ododo pada foju han ni igbẹyin gbẹyin.
Ọgbẹni Salami ni lẹyin naa ni Barrister ṣe awo kan to pe akọle rẹ ni ''Okiki'' jade.
Farmers Herders Crisis: Rẹ́rẹ́ rún, ẹ̀mí àti dúkìá ṣòfò lágbègbè Ariwa Yewa
Yoruba ni iroyin ko to afojuba, ẹni to ba de ibẹ nikan lo le sọ, iroyin okeere si ree, bi ko ba dinkan, yoo le ọkan.
Eyi lo mu ki BBC Yoruba balẹ sagbegbe Ariwa Yewa nipinlẹ Ogun to paala ilẹ pẹlu orilẹede Benin.
Lẹnu lọọlọ yii ni ẹnu n kun agbegbe naa nipa ọsẹ nla tawọn ọdaran Fulani n se fun wọn eyi to ti sọ agbegbe naa di ahoro, tawọn eeyan si n sa asala fun ẹmi wọn.
Lasiko abẹwo wa naa silu Igborọ, Iselu, asa ati bẹẹ bẹẹ lọ, ẹnu ko gba iroyin nipa ọpọ ile, mọto, dukia ati ire oko to bajẹ lasiko awọn ikọlu naa.
Ikọ BBC Yoruba ba awọn olugbe agbegbe naa sọrọ, to fi mọ asoju Fulani, ta si tun kan si ijọba ipinlẹ Ogun lati mọ aayan to n se lati pinwọ ikọlu naa.
Osugbo: Elebuibon ní awo ni yóò ṣìnkú ọba tó ṣètùtù kó tó dépò, kìí ṣe Alfa tàbí Pásítọ̀
Oríṣun àwòrán, Oro Festival
Araba Awo tilu Osogbo, Oloye Ifayemi Elebuibon ti salaye fun BBC Yoruba nipa ohun to rọ mọ ọba jijẹ, ẹsin to n se ati ilana sinsin oku rẹ.
Elebuibon salaye awọn ọrọ yii lasiko to n ba BBC sọrọ nipa bi awọn ẹgbẹ awo Osugbo se lọ fi tipa gbe oku ọba to waja.
Saaju la ti mu iroyin wa fun yin nipa bi ẹgbẹ awo Osugbo se fi tipa gbe oku ọba kan pamọ nilẹ Ijebu.
Iroyin naa ni awọn mọlẹbi ọba naa ni ko fẹ ki wọn sin baba wọn nilana ẹsin ibilẹ eyi to mu ki wọn gba ile ẹjọ lọ.
Oríṣun àwòrán, Oro Festivals
Nigba to n dahun ibeere lori ẹni to lẹtọ lati sin oku ọba to ba waja, Elebuibon ni kii se mọlẹbi lo lẹtọ lati sin oku ọba rara.
O ni niwọn igba ti ọba kan ba ti gori itẹ, o ti di ti gbogbo aye, oku rẹ si ti di ti araalu ati gbogbo eeyan.
Oku ọba to ba waja kii se ti mọlẹbi mọ, awọn to lẹtọ lati sin oku rẹ naa lo lọ gbe oku naa pamọ."
"Boya ọba ko wa sọ fawọn mọlẹbi rẹ tẹlẹ ni pe oun ti se oro, lo mu ki wọn pe awọn Osugbo lẹjọ."""
Araba Awo ilu Osogbo fikun pe ọba kọba to ba jẹ kii se ti mọlẹbi rẹ mọ, wọn ko si lẹtọ mọ lati pasẹ lori isinku rẹ.
Wakili tẹẹ rí yẹn kìí ṣe ẹran rírọ̀, ó ń díbọ́n ní o - Iba Gani Adams
Ọpọ igba ni isẹlẹ ti waye saaju nipa awuyewuye to maa n waye nidi ilana sinsin oku ọba to ba waja.
Bakan naa nirufẹ isẹlẹ yii waye saaju nilu Abeokuta nigba ti mọlẹbi Alake tilẹ Ẹgba tẹlẹ, ọba Lipede waja faake kọri fawọn ọmọ ẹgbẹ Ogboni.
Wọn ni Kabiyesi naa ti sọ asọtẹlẹ saaju pe ilana Kristiẹni ni ki wọn fi sin oun, nitori oun ti di ọmọlẹyin Kristi tootọ, ki oun to tẹri gbasọ.
Nigba to n sọrọ lori asa ki awọn ọba kan maa sọ asọtẹlẹ fawọn mọlẹbi wọn lori ọna ti wọn fẹ ki wọn gba sin wọn, Elebuibon ni eyi ko tọna.
"Yoo dara ki ẹni to ba fẹ ki wọn sin oun nilana ẹsin igbalode Kristiẹni abi Musulumi ma kuku wulẹ jọba rara.
Ki wọn to fi ọba jẹ, o ni oro ti wọn yoo se, ti ọba ba si tun ku, o ni oro ti wọn yoo se pẹlu. Ẹni to ba wa jẹ Kristiẹni abi Musulumi, ẹ ma wulẹ jọba.
Ẹ fun ẹni to setan lati se isẹse laaye lati jọba, ka le yago fun awuyewuye ti ko tọna."
Wo obìnrin kanṣoso láàrin àwọ́n ọkunrin agunẹṣin gbafẹ́ nílùú Ilorin àmọ́ tọ́kàn rẹ̀ yii
Araba Awo, lasiko to n salaye awọn ewu to rọ mọ ilana sinsin ọba ni ilana ẹsin igbalode salaye pe ewu n bẹ loko longẹ fun oku ọba to ba waja naa.
"Oku ọba ti wọn ko ba fi etutu tabi isẹse sin yoo ni idiwọ nla lẹnu irinajo rẹ. Awọn ara ilẹ to yẹ ko ba pade ni yoo nira fun lati ri, eyi to lewu pupọ.
Bakan naa, iru ọba to waja yii ko pese ọna to tọ silẹ fun ẹlomiran to fẹ jẹ ọba lẹyin rẹ, eyi naa si lee mu idiwọ nla lọwọ.
O yẹ ki wọn se bi wọn se n se lati igba iwasẹ, ko le ri bo se yẹ ko ri, bi bẹẹ kọ, o lewu."
Bone setting: Adimula Kehinde Akinfenwa ṣàlàyé nípa irúfẹ́ ẹranko tí wọ́n fi ń to eegun èy
Oloye Ifayemi Elebuibon wa rọ ile ẹjọ lati bọwọ fun asa ati isẹse agbegbe kọọkan nilẹ Airika ati ba se n gbe igbe aye wa.
"Ilẹ alawọ dudu Afirika la wa, adajọ gbọdọ bojuwo eyi. Bi eeyan kan ba ni oun n se Musulumi, kii sa se ilẹ Arab ni wọn ti bi.
Bakan naa, ẹni to ba ni oun n se Kristiẹni, kii se ilẹ Jerusalem ni wọn ti bi, bi wọn ti n se ni ilẹ Jerusalem ati Arab yatọ si tilẹ Afirika."
Oríṣun àwòrán, Daily Trust
Ta lo ni ẹtọ lati sin oku ọba alaye to ba waja, ẹgbẹ awo to n dari ilu lo gbọdọ sin ọba ni ilana ibilẹ ni abi mọlẹbi ọba?
Bakan naa, ilana isinku wo lo yẹ ki wọn fi sin oku ọba, se ilana ẹsin ti ọba ba n sin ni abi ilana isẹse to gba jọba ninu ilu?
Ohun aburu wo lo le sẹlẹ ti wọn ko ba sin ọba nilana ẹsin ibilẹ, ti wọn si sin nilana ẹsin Kristiẹni abi ti Musulumi?
Awọn ibeere yii ati ọpọ miran lo n tawọ tasẹ ninu awọn ọmọ Yoruba to gbọ nipa isẹlẹ kan to waye nilu Aba Ayepe.
Gẹgẹ bi iwe iroyin Daily Trust ti jabọ rẹ, awọn ọmọ ẹgbẹ awo Osugbo lo fi tipa gbe oku Alaye-Aba tilu Aba Ayepe kuro nibi ti awọn mọlẹbi tọju oku ọba naa pamọ si.
Oríṣun àwòrán, Daily Trust
Ọjọ Kejilelogunosu Kinni ọdun 2021 ni Ọba Rauf Adebayo Raji-Suleimon, Alaye-Aba tilu Aba Ayepe, dara pọ mọ awọn baba nla rẹ, tawọn mọlẹbi rẹ ko si fẹ sin nilana ẹsin ibilẹ.
Ọna lati daaabo bo isẹse lo mu kawọn ọmọ ẹgbẹ awo Osugbo ya wọ ibi ti oku naa wa, ti wsn si lọ gbe pamọ nilana ẹsin ibilẹ, eyi to bi awọn mọlẹbi ori ade to di oloogbe naa ninu.
Ọrọ di isu ata yanan-yanan, tawọn mọlẹbi ọba si wọ ẹgbẹ Osugbo lọ sile ẹjọ pe wọn tako ẹtọ tawọn ni lati fun baba awọn ni ẹyẹ ikẹyin nilana ẹsin Musulumi.
Awọn mọlẹbi ọba naa ni Mususlumi ododo ni ọba naa ko to waja, o si yẹ ki wọn sin ori ade naa nilana ẹsin Islam ni.
Ẹjọ naa si lo pe awọn eeyan mẹẹdogun wa sile ẹjọ lati jẹjọ, awọn si lo jẹ ọmọ ẹgbẹ awo Osugbo nilẹ Ijebu nigbati igbimọ afọbajẹ tilẹ Ijebu lapapọ jẹ Olujẹjọ kẹrindinlogun.
Mọlẹbi ọba naa wa n beere miliọnu lọna aadọta naira gẹgẹ bii owo gba ma binu fun bi ẹgbẹ awo Osugbo se tẹ ẹtọ wọn mọlẹ ati ti ọba to waja pẹlu.
Farmers Herders Crisis: Rẹ́rẹ́ rún, ẹ̀mí àti dúkìá ṣòfò lágbègbè Ariwa Yewa
Amọ nigba ti awọn ọmọ ẹgbẹ Osugbo ọhun n yọju sile ẹjọ to n gbọ ẹjọ naa nilu Abeokuta lati wa jẹjọ, se ni awọn ẹgbẹ awo naa wọnu gbọngan ile ẹjọ pẹlu asọ awo.
Bakan naa ni wọn n kọ orin isẹse to jọ mọ ẹgbẹ awo wọn, eyi ti wọn fi n tako ẹjọ naa ti idile ọba to waja pe wọn.
Adajọ ti wa sun igbẹjọ siwaju di ọjọ Kẹrindinlsgbọn osu Kẹrin ọdun 2021.
New Minimum Wage: NLC ní bí àtúntò yóò bá bá owó oṣù òṣìṣẹ́, ọ̀dọ́ gómìnà àti aṣòfin ní yóò ti bẹ̀rẹ̀
Oríṣun àwòrán, @NLC
Awọn olori ẹgbẹ osisẹ ni Naijiria ti bẹnu atẹ lu awọn to dipo aṣẹ mu lori bi wọn se fẹ sagbekalẹ abadofin kan, ti yoo gbe akoso owo osu to kere julọ ni Naijiria kuro labẹ akoso ijọba apapọ sọdọ awọn ijọba ipinlẹ.
Aarẹ ẹgbẹ osisẹ ni Naijria Ayuba Waaba lo fi ọrọ yii lede lasiko ipade kan pẹlu awọn olori ile asojusofin Naijiria lọjọ Isegun.
Lasiko ipade yii, Waba ni oun to ba da fun Taiye, o di dandan ka le se bẹẹ fun Kehinde naa, tori eyi, ki atunto naa bẹrẹ lati ọdọ awọn asofin ilẹ yii.
Waaba kọwọrin nibi ipade yii pẹlu awọn olori ẹgbẹ osisẹ mii bi ti Trade Union Congress, ọgbẹni Quadri Olaleye.
O sọ pe: ''A setan lati fẹsẹ ipinu wa rinlẹ. Bi a ba fẹ se atunto owo osu, mo lero pe lọdọ awọn to dipo ijọba mu lo yẹ ko ti bẹrẹ.
Oríṣun àwòrán, @NLC
Nigba ti wọn satunyẹwo owo osu pẹlu ida aadọta lọdun 211, atunto ida ẹgbẹrin ni wọn mu ba owo osu awọn to dipo mu ni ijọba''
''Nitori naa, to ba se pe a n wo boya ijọba ni agbara lati san owo yii, ibi to yẹ ki a ti bẹrẹ niyẹn.
Owo osu to kere julọ la wa n beere fun, to si se wi pe awọn kan ti n gba owo to ga julọ''
Lọwọ-lọwọ bayi, ajọ to n mojuto owo osu awọn Gomina ni ipinlẹ Naijiria ko se ipinya kankan lori owo osu Gomina, lori agbara ati iye owo to n wọle fun wọn.
Farmers Herders Crisis: Rẹ́rẹ́ rún, ẹ̀mí àti dúkìá ṣòfò lágbègbè Ariwa Yewa
Gbogbo Gomina patapata, gẹgẹ bi Waaba se salaye, lo n gba iye owo kan naa.
Bẹẹ lo ni ko si iyatọ ninu owo awọn kọmisana ati awọn olori ile asofin.
Fun idi eyi, o ni ki wọn mase jẹ ki awọn ipinlẹ kan maa san owo to kere julọ fun awọn osisẹ, kawọn mii si ma san an rara.
Nibi ipade naa ni olori ile asojusofin Naijiria, Femi Gbajabiamila ati awọn olori ile mii wa, to fi mọ ẹni to sagbekalẹ abadofin yii nile asofin asoju, Garba Datti Muhammad.
Akomolede àti Asa:  Mọ̀ si nípa àṣà ìsọmọlórúkọ́ nílẹ̀ Yorùbá àti ìtumọ̀ orúkọ̀ fún ìkókó
Eni to sagbekalẹ abadofin yii ti sọ niwaju ile lọjọ Kẹtalelogun osu Keji pe, ofin naa yoo gba ijọba apapọ ati ijọba ipinlẹ laaye lati dunadura nipa iye owo osu to ba wu wọn ni ibamu pẹlu ominira ti ofin ilẹ yii se fun wọn.
Sugbọn Waba sọ pe lawọn orileede mii to ti goke agba, ijọba apapọ lo si lasẹ lori iye owo osu to kere julọ fawọn osisẹ.
Gbajabiamila, ninu esi lori ọrọ yii ni awọn asofin lẹtọ lati fi abadofin sọwọ sile.
O wa rọ awọn ẹgbẹ osisẹ lati jiroro pẹlu awọn asoju wọn tabi ki wọn wa sọ tọkan wọn nigba ti ile ba pe araalu lati wa da si abadofin naa.
Adebunmi Adeyeye: Mo jẹ gbèsè gbọ́múléláńtà, ìdí iṣẹ́ kabúkabú ni mo ti ri san
O ni wọn tun le lo anfaani ileesẹ iroyin lati sọ ẹdun ọkan wọn.
O ni ki ile to gbe igbesẹ lori ọrọ yii, awọn yoo sagbeyẹwo rẹ daada lati le buwọlu ofin ti yoo se araalu, paapa awọn osisẹ Naijiria lanfaani.
Ki lo kan El-Rufai ninu ọrọ to wa nilẹ yi?
Awọn ẹgbẹ osisẹ ti fẹsun kan Gomina ipinlẹ Kaduna Nasir El Rufai pe oun ati awọn akẹgbẹ rẹ kan ni igi wọrọkọ to n tako abadofin yii.
Prophet Shittu Adeniyi: Ẹni tó bá ń tọrọ agbe, kìí jẹ́ èèyàn ní mo ṣe tẹ́pa mọ́ṣẹ́
Wọn fi ẹsun naa kan ninu iwe kan ti wọn fi sọwọ si ile asofin lasiko ipade pẹlu awọn olori ile.
Gẹgẹ bi wọn ti wi, aridaju wa pe Gomina Nasir Elrufai ati awọn Gomina mii lo n sagbatẹru abadofin.
Bi a ko ba gbagbe, asofin to mu aba yii wa, Garba Datti Mohammad, n soju ẹkun Sabora Gat tipinlẹ Kaduna nile asojusofin Naijiria.
Amọ Gomina El Rufai ko ti fesi si ẹsun ti wọn fi kan an yii.
Astrazeneca Vaccine: Ìjọba Osun àti Ogun fi orúkọ ibùdo ìlera fún gbígba abẹ́rẹ́ àjẹsára pamọ́
Oríṣun àwòrán, Nigerian Government
Lẹyin ti ijọba apapọ tẹwọ gba abẹrẹ ajẹsara Covid-19 ti AstraZeneca ṣe, labẹ eto Covax, wọn ti pin abẹrẹ ọhun kaakiri awọn ipinlẹ Naijiria.
Gẹgẹ bi eto naa ṣe lọ, awọn oṣiṣẹ eto ilera atawọn alaisan Covid-19 ni yoo kọkọ gba abẹrẹ naa, ko to kan awọn eeyan ilu miran.
Ṣaaju ni Aarẹ Muhammadu ti gba abẹrẹ tirẹ loju awọn ọmọ Naijiria, lati fi ọkan wọn balẹ pe ko si ewu ninu gbigba abẹrẹ ajẹsara ọhun.
Ṣugbọn ọpọ eeyan lo ti n woye ibi ti wọn ti le gba abẹrẹ naa lagbegbe to sun mọ wọn.
Oríṣun àwòrán, @Reuters
Ipinlẹ Eko
Kọmiṣọna eto ilera ipinlẹ Eko, Akin Abayomi kede lọjọ Iṣẹgun pe ibudo ilera mejidinlaadọrun un, 88, ni wọn ti le gba abẹrẹ naa l'Eko.
Awọn ibudo naa to gbe soju opo Twitter rẹ ree:
Lara awọn ile iwosan ti wọn ti le gba abẹrẹ ọhun ni ile iwosan awọn ọlọpaa ati ọmọ ogun wa.
Ipinlẹ Ogun
Ile iwosan mẹtadinlaadọfa, 107,  ni awọjn eeyan ipinlẹ Ogun ti le gba abẹrẹ ajẹsara Covid-19, ṣugbọn wọn ko tii fi adirẹsi awọn ileewosan naa lede.
Awọn oṣiṣẹ eto ilera nikan ni wọn ṣi n fun labẹrẹ naa lọwọ yii.
Gẹgẹ bii nkan ti kọmiṣọna eto iroyin ipinlẹ naa, dokita Tomi Coker sọ fun BBC Yoruba, wọn yoo jẹ ki awọn eeyan ilu mọ ibi ti wọn ti le gba abẹrẹ naa, ti wọn ba ko abala keji rẹ wọle.
Farmers Herders Crisis: Rẹ́rẹ́ rún, ẹ̀mí àti dúkìá ṣòfò lágbègbè Ariwa Yewa
"O ni ""ko ni bojumu ka fi adirẹsi ibi ti awọn araalu ti le gba abẹrẹ naa sita, ṣugbọn ka má fun wọn nitori awọn oṣiṣẹ eto ilera nikan ni a n fun lọwọ, idi ree ti a ṣe fi orukọ awọn ileewosan naa pamọ lasiko yii."""
Coker pari ọrọ rẹ pe, o kere tan, ileewosan marun nun ni awọn eeyan ti le gba abẹrẹ naa nipinlẹ Ogun.
Ipinlẹ Osun
Kọmiṣọna eto ilera ipinlẹ Osun, Olasunkanmi Isamotu sọ fun BBC Yoruba pe, ileewosan mẹtadinlọgọrun, 97, ni awọn eeyan ti le gba abẹrẹ Covid-19 ni ipinlẹ ọhun.
Ṣugbọn ko si aṣọ loju adirẹsi awọn ile iwosan naa fun BBC Yoruba lasiko yii.
Nigerian Drone Maker: Roqeeb Aderogba ní ìgbà mẹ́fà l‘òun kùnà láti ṣe dírónù, kó tó yege
Ohun to ba n wu ni, nii pọ lọla ẹni, ologun ẹru ku, asọ rẹ jẹ ọkansoso, smọ ti yoo ba si jẹ asamu, kekere ni yoo ti maa jẹ ẹnu samusamu.
Lati igba ewe ni Roqeeb Aderogba ti maa n sewadi ninu ara rẹ pe bawo lo seese fun baalu lati maa fo lai naani bo se tobi si.
Igba yii si ni ọmọde naa ti pinnu pe imọ ẹrọ nipa baalu sise ni oun yoo lọ kọ ti oun ba dagba nile ẹkọ fasiti.
Lẹyin ti ọpọ igbiyanju rẹ lati wọ ile ẹkọ fasiti kan lorilẹede India kuna, nibi to ti fẹ lọ kọ ẹkọ nipa sise baalu, Roqeeb ba gba fasiti Ladoke Akintola, LAUTECH nilu Ogbomoso lọ.
Lautech si lo ti n kọ ẹkọ nipa imọ ẹrọ Chemical Engineering.
Amọ ipele eto ẹkọ ọlọdun kẹta lo wa to fi tun kuro nibẹ, to si lọ bẹrẹ eto ẹkọ nipa kikọ nipa baalu sise nile ẹkọ fasiti ipinlẹ Kwara.
Àwọn ìtàn mánigbàgbé tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí:
Lọwọ lọwọ bayii, Roqeeb ti se baalu kekere ayaworan dironu, taa mọ si Drone, lẹyin igba to ti kuna fun igba mẹfa ọtọọtọ lati se e.
Roqeeb Aderogba ba BBC Yoruba sọrọ nipa iriri rẹ naa, to si se afihan awọn baalu kekere to ti se.
Insecurity in Yorubaland: Olugbon ní àwọn ọba ṣetán láti ti olóòtọ́ọ́ oníṣẹ̀ṣé lẹ́yìn lórí ìpèsè àbò
Oríṣun àwòrán, @tostvnetwork
Olugbon ti Orile Igbon ni ẹkun Ogbomoso, Ọba Francis Olusola Alao ti fesi si ọrọ awọn oniṣẹṣe to sọ pe awọn lagbara lati wa ojutu si eto abo to mẹhẹ nilẹ Yoruba.
Nigba to n ba BBC Yoruba sọrọ, Olugbon sọ pe iṣẹsẹ lagba lotitọọ, amọ opurọ lo pọ ninu awọn onisẹse, olootọ aarin wọn ṣọwọn.
''Mi o sọ pe awọn to n sọ otitọ ninu wọn ko si o, amọ bi awọn awọn aafa ati wolii eke ṣe pọ kaakiri, naa lo wa laarin awọn oniṣẹse pẹlu.''
Ọba Olusola Alao ni ọpọ eeyan kan n fẹ ki awọn akọroyin maa gba ọrọ lẹnu wọn lasan ni.
''Ti awọn oniṣẹṣe ba fẹ fi otitọ ṣe e, ti wọn ba le wa ojutu si eto aabo to mẹhẹ nilẹ Yoruba, awa lọbalọba maa ti wọn lẹyin''.
Nigerian Drone Maker: Roqeeb Aderogba ní ìgbà mẹ́fà l‘òun kùnà láti ṣe dírónù, kó tó yege
Oju gba mi ti fawọn onisẹse to se ayẹta ti
Kabiyesi ni ohun to maa n kọ oun lominu nipa ọrọ awọn oniṣẹṣe ni pe awọn to n fi otitọ ṣe e ko pọ rara.
Olugbon fi awọn kan to pe ara wọn ni ọmọ ẹgbẹ Agbekoya, ti wọn sọ pe awọn ni oogun ayẹta ibọn ṣe apẹẹrẹ.
''Lẹyin ti wọn pe ọfọ tan si ewurẹ kan lara ni wọn da ibọn bo, ṣugbọn ọta ibọn fa ewurẹ naa ya pẹrẹ pẹrẹ ni.
''Oju gba wọn ti, wọn ni lati maa sọ fun mi pe, awọn ti dan oogun naa wo kawọn to wa,'' Olugbo ṣalaye.
Farmers Herders Crisis: Rẹ́rẹ́ rún, ẹ̀mí àti dúkìá ṣòfò lágbègbè Ariwa Yewa
Ẹwẹ, Onpetu Ijeru, Ọba Sunday Oyediran ti sọ pe adura ni ojutu si eto abo to mẹhẹ nilẹ Yoruba ati kaakiri orilẹede Naijiria.
Kabiyesi ni ko si ohun ti agbara Ọlọrun ko ka.
Onpetu ni ko si ohun to buru nibi ọrọ ti awọn oniṣẹṣe sọ pe awọn lagbara lati wa ojutu si ọrọ eto abo to mẹhẹ nilẹ Yoruba.
Kabiyesi ni ''ẹni to lagbara ko ni lọ sori redio tabi sọ fawọn akọroyin pe oun lagbara bi awọn oniṣẹṣe ti n ṣe.''
Nipa ọrọ ẹsin tawọn oniṣẹṣe sọ pe o n mu ifasẹyin ba ilẹ Yoruba, Onpetu ni ẹsin lo mu idagbasoke ba ilẹ Yoruba.
Kabiyesi ni ẹsin lo mu oriṣiiriṣii nkan amayedẹrun wa si ilẹ Yoruba ati orilẹede Naijiria.
Wakili tẹẹ rí yẹn kìí ṣe ẹran rírọ̀, ó ń díbọ́n ní o - Iba Gani Adams
A kọ òrìṣà babańlá wa sílẹ̀ ló jẹ́ kí ọ̀daràn darandaran máa pa wá bí ẹ̀fọn - Àwọn Oníṣẹ̀ṣe
Ni bayii ti oniruru ẹgbẹ ti n wa ọna abayọ si eto abo to mẹhẹ ni Naijiria, awọn ẹlẹsin ibilẹ ti sọrọ lori igbaradi wọn lati fopin si ipaniyan, ijinigbe ati gbogbo iwa ọdaran nilẹ Yoruba.
Lara awọn ipinlẹ ti ọrọ naa kan bii iṣan ọrun ni ipinlẹ Ogun, nibi ti wọn ti n koju iṣoro ija laarin awọn agbẹ atawọn Fulani darandaran, to n fi ibọn AK-47 da maalu.
N ṣe lo da bii pe gbogbo bi awọn eeyan ṣe n lọgun inira ti awọn ọdaran Fulani ọhun n fun wọn to, ijọba apapọ ko ka ọrọ naa kun.
Eyi lo fa ti oriṣiriṣi ẹgbẹ ati ẹya ni Naijiria fi n sọ pe ti ijọba ko ba le daabo bo wọn, awọn yoo daabo bo ara awọn.
Eredi ree ti awọn adari awọn ẹlẹsin ibilẹ nipinlẹ Ogun naa fi sọ pe awọn ní ọna abayọ lọwọ si eto abo naa to mẹhẹ, paapaa nilẹ Yoruba.
Oríṣun àwòrán, Oro Festival
Nigba to n ba awọn akọroyin sọrọ niluu Abeokuta, Olu Iṣẹṣe ti ipinlẹ Ogun, Ọmọwe Ifarotimi Adifagbola sọ pe oriṣiriṣi awọn oriṣa lo wa ti awọn le ke pe lati daabo bo iran Yoruba.
Adifagbola ni o ṣeni laanu pe, awọn ẹlẹsin ibilẹ naa ti ṣina lẹyin ti wọn gbe ara le ẹsin atọhunrinwa, ti wọn si kọ ẹsin awọn babanla wọn silẹ.
"Gẹgẹ bo ṣe sọ, ""awọn to n gbe ẹsin ẹlẹsin lori ti fa wa ṣẹyin gidi gan, a ti kọ awọn oriṣa awọn babanla wa silẹ ọjọ ti pẹ, eyi si lo jẹ ki awọn ọdaran darandaran yii maa pa wa bi ẹni pa ẹfọn."""
Wo ohun tí Professor Peller wí tó kó bá a gẹ́gẹ́ bí ìyàwó rẹ̀, Lady Peller ṣe tú u síta
Bo tilẹ jẹ pe awọn kan n sọ pe a ko si loju ogun, irọ ni o, oju ogun ni a wa. A si ni lati ke pe awọn oriṣa awọn babanla wa, ti mo si ni igbagbọ pe wọn jẹ wa ni oo.
"Nigba to n da si ọrọ naa, Ọba Iṣegun ti Obada, Oloye Ololade Sunday ṣalaye pe ""ko si ọdaran darandaran kankan ti yoo le da wahala silẹ nilẹ Yoruba ti wọn ba gba  awọn ẹlẹsin ibilẹ laaye lati doju ija kọ wọn."""
Sunday ni awọn agbegbe ti awọn janduku ọhun le maa dojukọ ni awọn ibi ti wọn ko ti bọwọ fun ẹsin abalaye ati aṣa.
Bone setting: Adimula Kehinde Akinfenwa ṣàlàyé nípa irúfẹ́ ẹranko tí wọ́n fi ń to eegun èy
O ni ko le ṣeeṣe ki Oloye Sunday Igboho maa jijagbara fun ilẹ Yoruba ti ko ba ni agbara iṣẹṣe lọwọ.
Ẹwẹ, Ololade pari ọrọ rẹ pe, yoo ṣoro lati ṣe awọn oro kan lai si ifọwọsowọpọ ijọba nibẹ, nitori awọn nikan lo ní aṣẹ lati kede konile-o-gbele lasiko irufẹ oro bẹẹ.
Sunday Igboho: Àsìkò ti tó, ẹ̀yin ọmọ Yoruba tó ń bẹ lókè ọya, ẹ máa padà bọ̀ nílé
Oloye Sunday Adeyemo, ti ọpọ mọ si Sunday Igboho ti ke si gbogbo ọmọ Yoruba to wa loke ọya lati pada wale nitori ile ti to lọ, ati pe asiko ti to lati da orilẹ-ede to jẹ ti ọmọ Yoruba silẹ.
Igboho lo sọ ọrọ naa nibi ipade kan ti Ọjọgbọn Banji Akintoye, to jẹ aṣiwaju nilẹ Yoruba naa wa.
O ṣalaye pe ko si nnkankan to n jẹ iṣọkan Naijiria mọ lẹyin ti eto abo ilẹ Yoruba mẹhẹ, ti ijọba apapọ ko si ri ohun kankan ṣe nipa rẹ.
Bakan naa lo tun ṣalaye pe oun atawọn ikọ oun ti ṣetan lati koju awọn ọdaran Fulani lọna ati le wọn kuro ni gbogbo ilẹ Yoruba patapa.
"Gẹgẹ bo ṣe sọ, ""a o lọ ṣi awọn ẹnu ibode wa ti ijọba apapọ ti pa, a o si ṣigbogbo rẹ ki ounjẹ le maa wọle."""
A kii ṣe ara Naijiria mọ, ọlọpaa ti wọn ba bi daa, ko da wa lọna tabi ko gbiyanju lati mu ẹnikẹni ninu wa, igba yẹn ni wọn yoo mọ pe ẹnu Yoruba ko.
Igboho sọ pe ko si anfani kankan ti ẹya Yoruba n ri ninu Naijiria gẹgẹ bii orilẹ-ede nitori gbogbo ipo to ṣe pataki ninu ijọba to wa lode yii ni Hausa n ṣakoso.
O pari ọrọ rẹ pe digbi ni oun wa lẹyin awọn agbagba Yoruba lori igbesẹ wọn lati gba ominira kuro ni Naijiria.
Nigerian Drone Maker: Roqeeb Aderogba ní ìgbà mẹ́fà l‘òun kùnà láti ṣe dírónù, kó tó yege
A ko fẹ Fulani mọ nilẹ Yoruba, a fẹ́ maa se akoso ara wa funra wa ni.
Igbe ti ajijagbara ọmọ Yoruba, Sunday Adeyemo, ti ọpọ eeyan mọ si Sunday Igboho fi bọ ẹnu niyii, nibi ipade apapọ ọmọ Yoruba.
Igboho, ẹni to gbarata lori eto aabo to mẹhẹ nilẹ Yoruba ati bi awọn ọdaran darandaran kan se n pa ọmọ Yoruba tun ni ''ogun ka maa le su, ka maa le tọ nitori aibalẹ ọkan nilẹ Yoruba ti to gẹ.''
''Kilode gan an? A n rin, ọkan wa ko balẹ, ka ma le sun, ka ma le tọ, a n gbe inu ile wa, ọkan wa ko balẹ, Ki lo de? ṣe ẹru ni wa ni?
Gbogbo awọn to di ipo olori mu ni ibudokọ ọkọ oju-omi Tincan Island ati ibudokọ ọkọ oju-omi yoku to wa niluu Eko, Fulani ni wọn, a ko fẹ wọn mọ.''
A n lọ si awọn ẹnu ibode Yoruba silẹ ki ounjẹ le wọle ni irọrun
Igboho ni bakan naa lọmọ ṣori lawọn ibode Naijiria to wa nilẹ Yoruba, o fi ibode Idi Iroko ṣe apẹẹrẹ nibi ti Fulani ti jẹ ọga agba ileeṣẹ aṣọbode.
''Awa ọmọ Yoruba ni lati ṣe ipade bi awọn ibode wa yoo ṣe di ṣiṣi, ki irẹsi atawọn nkan mii le maa wọle ni irọrun,'' Igboho lo sọ bẹẹ.
Ajijagbara ọmọ Yoruba ni ''o ti to gẹ, gbogbo ibode wa ni ijọba apapọ ti gbe tipa, a si n fi asiko yii sọ fun wọn pe a ko si labẹ wọn mọ.''
"Igboho ni ''awa gan an ti ṣetan fun gbogbo ohun ti ijọba ba fẹ ṣe fun wa, mo n gba ẹnu gbogbo ọmọ Yoruba ni o."""
Farmers Herders Crisis: Rẹ́rẹ́ rún, ẹ̀mí àti dúkìá ṣòfò lágbègbè Ariwa Yewa
Ajijagbara naa wa fi ọwọ gbaya pe isọkan ati irẹpọ wa laarin awọn ọmọ Yoruba, ko si si iyapa mọ laarin wọn.
"Igboho ni ""awọn eeyan kan le maa sọ pe ẹnu Yoruba ko ko, ẹ maa fọkan si rara, ti ẹ ba fẹ mọ boya ẹnu wa ko tabi ko ko, ẹ fi ọwọ kan ẹnikẹni ninu wa.''"
Bakan naa ni Sunday Igboho fi da gbogbo ọmọ Yoruba loju pe gba gba gba lawọn ọba alaye nilẹ Yoruba n bẹ lẹyin oun fun iwa ijijagbara ti oun n se.
Igboho sọ pe ''gbogbo ọba alaye ilẹ Yoruba lo wa lẹyin wa, ọba to ba wa ni oun ko si lẹyin wa, ki o lọ ṣe fidio lori ayelujara ki a ri, ko ni di ọjọ keji.''
Wakili tẹẹ rí yẹn kìí ṣe ẹran rírọ̀, ó ń díbọ́n ní o - Iba Gani Adams
Ajijagbara ilẹ Yoruba naa wa ke pe awọn ọmọ Yoruba to wa lapa oke ọya Naijiria pe ki wọn maa bọ wale.
Igboho ni imọran ti oun ni, ni oun n gba awọn ọmọ Yoruba to wa loke ọya naa pe ile to lọ.
"Ẹ maa bọ nile o, iya to n jẹ wa ti to gẹ, asiko ti to, ile ti ya, ẹ jẹ ka se ara wa ni ọkan soso.
''Asiko ti to, ile ti ya, ẹ jẹ ki a ṣe ara wa ni ọkan,'' Igboho lo sọ bẹẹ.
John Magufuli: Ọ̀pọ̀ ọmọ ilẹ̀ Tanzania ni Magufuli mú àyípadà rere bá orílẹ́èdè náà
Bi a ku laa dere, eeyan o sunwọn laaye. Awọn ọmọ orilẹede Tanzania ti n ṣe idaro Aarẹ John Magufuli to papoda lẹni ọdun mọkanlelọgọta.
Ọpọ eeyan nilẹ naa fẹran Magufuli, wọn gbagbọ pe iṣẹ ribi ribi lo ṣe nipa gbigbe ogun ti iwa ajẹbanu.
Onwoye kan, Atilio Tagailile tiẹ sọ pe ọga ni Magufuli pẹlu ohun to ṣe lẹyin to di aarẹ orilẹede Tanzania titi o fi ku.
Wọn dibo yan John Magufuli gẹgẹ bi Aarẹ karun un Tanzania lọdun 2015.
Katakata ''bulldozer'' ni wọn n pe e wọn gboriyin fun Magufuli fun bi o ti gbogun ti iwa ajẹbanu ati inakuna ijọba lorilẹede naa.
Magufuli ni arun jẹjẹrẹ ni iwa ajẹbanu eyi to nilo ki ijọba fi ọwọ lile mu.
Bed Wetting: Tolulope Joseph ní ò lé ní ogún ọdún tí òun fi tọ̀ sílé kí ìwòsàn tó dé
Iwa ki ọmọ maa tọ sile kii se ohun ajeji nilẹ Yoruba eyi to maa n ba obi ati iru ọmọ bẹẹ ninu jẹ lai tete ri ọna abayọ si aisan naa.
Ohun to sẹlẹ si Tolulope Joseph ree ẹni to n tọ sile titi di ẹni ọdun marundinlọgbọn.
Nigba to n salaye ọpọ idẹyẹsi ati idojuti to dojukọ nitori aisan tọle-tọle, Tolulope ni ọpọ asa abalaye ni oun tẹle lati wa ojutu si aisan naa.
O ni oun maa n kunlẹ lati bẹ ọlọ ata ni alẹ, to fi mọ opo ina, ti oun yoo si tun tọ sinu ẹyin ina, ki oun ma baa tọ sile loru.
Amọ o ni pabo ni gbogbo awọn igbesẹ naa ja si titi di iwa ti oun ls ka nipa aisan naa lori ayelujara ti wọn n pe ni Enuresisi.
Àwọn ìtàn mánigbàgbé tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí:
Tolulope, to n sinru ilu lọwọ bayii ni ọna abayọ toun ri nipa ohun to n fa aisan tọletọle, ti oun si wa ojutu si, lo mu ki oun kọ iwe jade lati tọ awọn eeyan miran sọna.
A ṣe fidio yii pẹlu ifọwọsọpọ pẹlu Oyeyemi Gbenga-Mustapha.
Fatai Aborode: Bàbá olóògbé ní kò sí ẹni tí kò le bẹ Fulani lọ́wẹ̀ láti ṣiṣẹ́ ibi
Oríṣun àwòrán, Facebook/Fatai Aborode
Alhaji Lasisi Folorunso Aborode, to jẹ baba Ọmọwe Fatai Aborode, tun ti ṣalaye siwaju sii lori iku to pa Ọmọwe Fatai Aborode.
Ọmọwe Fatai Aborode lawọn janduku agbebọn kan ṣekupa niluu Igangan lagbegbe Ibarapa nipinlẹ Oyo.
Baba Aborode, lasiko to n ba BBC Yoruba sọrọ salaye pe eekan ọmọ ẹgbẹ oṣelu PDP lagbegbe Ibarapa, Alagba Olawuwo tawọn ọlọpaa fẹsun kan pe o lọwọ ninu iku ọmọ oun, lo maa n tako ọmọ oun tẹlẹ lagbo oṣelu lati ọjọ pipẹ.
Lori ahesọ ọrọ kan to n ja rain pe awọn afurasi Fulani darandran lo ṣeku pa Ọmọwe Aborode, baba oloogbe ni ko si ẹni ti ko le bẹ awọn Fulani niṣẹ, lati ṣeeyan nibi.
Bed Wetting: Tolulope Joseph ní ò lé ní ogún ọdún tí òun fi tọ̀ sílé kí ìwòsàn tó dé
''Olawuwo tako Ọmọwe Aborode nigba ti wọn jọ wa ninu ẹgbẹ oṣelu PDP, asiko naa ni wọn fi Aborode jẹ oye alakoso ẹgbẹ oṣelu PDP ni Ibarapa.
Olawuwo sọ pe Aborode kere, ẹni to lo ọdun mẹẹdogun niluu Oyinbo ko too gba oye Ọmọwe, o ni ko le ṣiṣẹ yẹn.
Ṣugbọn ẹgbẹ PDP ni Ọmọwe Aborode koju osunwọn fun ipo ti wọn fun un, ati igba naa ni wọn ti gbogun ti i."
Farmers Herders Crisis: Rẹ́rẹ́ rún, ẹ̀mí àti dúkìá ṣòfò lágbègbè Ariwa Yewa
Alhaji Aborode ni idi ree ti Aborode ṣe fi PDP silẹ nigba naa niyẹn, amọ ọrẹ rẹ kan, Remi Oseni lo bẹ ẹ pe ko pada sinu ẹgbẹ naa.
Alhaji Aborode tun sọ pe akọwe fun ọmọ oun naa tun gbabọde fun un lori ọrọ iku rẹ.
Ọ́lọ́pàá gbé èèkàn PDP l'Oyo lọ ileẹjọ́ lórí ikú Fatai Aborode
Ileesẹ ọlọpaa ipinlẹ Oyo ti fidi rẹ mulẹ pe ọwọ ti tẹ eekan ọmọ ẹgbẹ oselu PDP kan lagbegbe Ibarapa nipinlẹ Oyo lori iku Fatai Aborode.
Oluwarẹ ni alagba Olawuwo, tii se gbajumọ oloselu kan nilu Igangan.
Nigba to n ba BBC Yoruba sọrọ lowurọ ọjọ Ẹti, agbẹnusọ fun ileesẹ ọlọpaa ipinlẹ Oyo, Olugbenga Fadeyi sisọ loju rẹ pe, wọn ti gbe alagba Olawuwo lọ sile ẹjọ lori ẹsun pe o lọwọ ninu iku agbẹ ati oloselu naa lagbegbe Ibarapa.
Fadeyi ni lọwọlọwọ bayii, wọn ti fi eekan ọmọ ẹgbẹ oselu PDP naa sahamọ ninu ọgba ẹwọn titi ti igbẹjọ yoo fi pari lori ẹsun ipaniyan ti wọn fi kan-an.
Ǹjẹ́ ẹ mọ̀ pé ìròyìn Kayeefi akọnilẹ́nu hààà ṣẹlẹ̀ ní Ibarapa méjèèjè nígbà ìkọlù Fulani?
Wọn ti fi to mi leti pe awọn ẹsun kan wa ti wọn fi kan alagba Olawuwo nipa iku oloogbe naa, a si ti gbe lọ sile ẹjọ, amọ adajọ ti ni ka fi pamọ sinu ọgba ẹwọn titi ti igbẹjọ yoo fi pari.
Iroyin kan ni awọn ọmọ ẹgbẹ oselu PDP ti n lọ ki alagba Olawuwo naa ni ileesẹ ọlọpaa to n dena iwa ijinigbe to wa ni Dugbe, nilu Ibadan.
Bẹẹ ba gbagbe, Ọmọwe Fatai Aborode jẹ ọmọ ẹgbẹ oselu PDP nilu Igangan lagbegbe Ibarapa, to si tun jẹ agbẹ alada nla to ni ọpọ eeka oko to fi gbin eso kasu.
Bed Wetting: Tolulope Joseph ní ò lé ní ogún ọdún tí òun fi tọ̀ sílé kí ìwòsàn tó dé
Ọjọ Ẹti, ọjọ Kọkanla osu Kejila ọdun 2020 ni awọn agbebọn kan da Aborode to tilu eebo wa dale isẹ silẹ, lọna ni aago marun irọlẹ lasiko to n pada lọ sile latinu oko rẹ.
Ahesọ ọrọ kan lo ti n ja rain nilẹ pe awọn afurasi ọdaran Fulani kan lo sekupa ọmọwe naa.
Iku Ọmọwe yi si lo bi ajijagbara fun ilẹ Yoruba, Oloye Sunday Igboho ninu, to fi lọ fun Seriki Fulani nilu Igangan ni gbedeke ọjọ meje lati ko aasa rẹ kuro nilu naa.
Nigerian Drone Maker: Roqeeb Aderogba ní ìgbà mẹ́fà l‘òun kùnà láti ṣe dírónù, kó tó yege
Isẹlẹ yii si lo n fa awuyewuye lọwọ, ti ko tii tan nilẹ.
A o ranti pe gomina ipinlẹ Oyo, Seyi Makinde gan kede nigba kan pe wọn ti fi to oun leti pe iku Fatai Aborode ni ohun se pẹlu ọrọ oselu.
Samia Suluhu Hassan: Ikú ààrẹ Magufuli sọ igbákejì rẹ̀ di ààrẹ obìnrin àkọ́kọ́ ní orílẹ̀èdè náà
Oríṣun àwòrán, AFP
Irọlẹ Ọjọbọ ni isẹ kan Samia Suluhu Hassan, lati tufọ iku aarẹ orilẹ-ede Tanzania, John Magufuli, gẹgẹ bi igbakeji rẹ.
Ni bayii, o ti gba ipo Magufuli gẹgẹ bi aarẹ.
Ọdun 2015 ni wọn kọkọ dibo yan an sipo igbakeji fun Aarẹ Magufuli, wọn si tun jọ wọle fun saa keji lọdun 2020.
Gẹgẹ bi òfin orilẹ-ede Tanzania ṣe laa kalẹ, oun ni yoo pari saa ọlọdun marun naa.
Oun nikan si ni yoo jẹ adari to jẹ obìnrin nilẹ Africa, lọwọlọwọ.
Mama Samia ni wọn ma n pe ẹni ọdun mọkanlelọgọta ọhun - ninu àṣà orilẹ-ede Tanzania, eyi tumọ si pe ẹni ọ̀wọ̀, ti wọn n pọnle ni, kii ṣe pe wọn n fi oju kéré rẹ gẹgẹ bi obìnrin.
Magufuli mú àyípadà rere bá orílẹ́èdè Tanzania- Ònwòye
Iyalẹnu ni iyansipo rẹ lati dije pẹlu Magufuli  jẹ ni ọdun 2015, nitori pe ọpọlọpọ awọn àgbà oloṣelu lo wa ninu ẹgbẹ oṣelu Chama Cha Mapinduzi (CCM), to ti wa ni ipo isakoso lati ọdun 1961.
Ọdun 2000 ni wọn kọkọ yan si ipo àṣẹ, sugbọn lọdun 2014, o di ilumọọka kaakiri orilẹ-ede Tanzania, nigba to di igbakeji alaga igbimọ aṣofin to kọ ofin tuntun.
Ọna to ma n gba mojuto rogbodiyan to ba waye ninu igbimọ, ati ibawi to ma n fun awọn ọmọ igbimọ to ma n sọrọ dáadáa, mu ki o gbayi pupọ.
Iyatọ pupọ lo wa laarin iru eeyan to jẹ, ati ti ọga rẹ, Aarẹ Magufuli.
Oríṣun àwòrán, AFP
Bi Magufuli ṣe jẹ ẹni ti ko gba gbẹrẹ, ti kii si tiju ẹnikẹni, tabi sọ ìhà to ba kọ si nkan, ara Samia balẹ̀ pupọ, o si má n ro arojinlẹ daada.
Bakan naa lo tun jẹ eleti gbaroye, to si ni igbagbọ ninu sise nkan ni ilana to yẹ.
"Ọmọ ile aṣofin kan, January Makamba, to ba a ṣíṣẹ ri ni ọfiisi Igbakeji Aarẹ, ti sọ ri pe ""Samia ni oloṣelu ti wọn fi oju di julọ ni Tanzania""."
"O ni ""mo ti sakiyesi bo ṣe n sisẹ, bo ṣe ma n gbe igbesẹ ati ìpamọ́ra rẹ daadaa. O koju oṣuwọn lati jẹ adari""."
Sugbọn gbogbo amuyẹ yii ko ti i safihan bi yoo ṣe le ṣe ilana ìṣàkóso. Eyi to ṣe koko ni pe boya yoo tẹsiwaju pẹlu ọwọ yẹpẹrẹ ti asiwaju rẹ fi mu ọrọ coronavirus.
Sunday Igboho: Farounbi ní Igboho kò ní gbòǹgbò ìpìlẹ tó fi ń jà, àmọ Kanu àti Dokubo ni
Oniruuru ẹgbẹ ajijagbara lo wa ni ẹkun kọọkan lorilẹede Naijiria, ti wọn n ja fun alaafia, irọrun ati igbayegbadun ẹkun ti wọn ti wa.
Lara wọn la ti ri ikọ ajijagbara MEND, IPOB, MASSOB, OPC ati bẹẹ bẹẹ lọ ti wọn n wa idẹrun agbegbe wọn.
Ohun kan soso tawọn ikọ ajijagbara naa si n ja fun ni ibaradọgba nidi pinpin ohun alumọọni ilẹ yii laarin awọn ẹkun to wa ni Naijiria.
Ni ẹkun ariwa Naijiria, ẹgbẹ Arewa wa to n gbẹnu sọrọ fun ẹkun naa, amọ ko fi bẹẹ si ikọ ajijagbara to n ja fun irọrun wọn.
Oríṣun àwòrán, Asari Dokubo
Ẹgbẹ apapọ awọn eeyan agbegbe Niger-Delta, MENd, lo n pariwo fun idẹrun awọn eeyan agbegbe naa.
Lara awọn adari wọn ni Asari Dokubo, ẹni to fi Naijiria logbologbo lasiko kan, to si n fọ awọn ọpa epo rọbi tii se orisun ọrọ aje wa.
Eredi ijijagbara rẹ ni pe agbegbe Niger Delta ti oun ti wa ni epo rọbi ti Naijiria n ta sodo si julọ, to si n mu owo wa fun orilẹede yii.
Sugbọn o ni o se ni laanu pe agbegbe naa ni isẹ, iya ati osi ti n bawọn finra julọ, tijọba ko si pese awọn ohun eelo amayedẹrun to yẹ nibẹ, amọ ti awọn ẹkun yoku n gbadun owo epo to n wa lati ọdọ awọn.
Amọ lẹyin o rẹyin ni ijọba apapọ joko se ipade pẹlu wọn, o n fun awọn ajijagbara naa ni owo iranwọ losoosu, to si ran ọpọ wọn ni ile ẹkọ labẹle ati ni oke okun.
Amọ laipẹ yii ni Asari Dokubo tun jade sita lati kede pe agbegbe Niger Delta ti darapọ mọ orilẹede Biafra, ti awọn si ti yapa kuro nilẹ wa Naijiri.
Oríṣun àwòrán, Nnamdi Kanu
Nnamdi Kanu lo da ẹgbẹ IPOB silẹ, afojusun rẹ si ni lati ya agbegbe ila oorun ariwa kuro lara orilẹede Naijiria.
Kanu yii lo kede lakoko kan pe orilẹede Naijiria ti yapa kuro ni Naijiria amọ awọn agbofinro lọ si ẹkun naa lati lọ tako igbesẹ yii.
Koda, ẹgbẹ IPOB ti se asia, orin ibilẹ ati owo kọrẹnsi ti wọn yoo maa na ni orilẹede Biafra tuntun to ni oun da silẹ, to si tun ni awọn ọmọ ogun pẹlu.
Ajijagbara fun ilẹ Yoruba ni wọn n pe Sunday Igboho, laipẹ yii si lo bọ sita lati tako bi awọn afurasi ọdaran Fulani se n pa awọn ẹya Yoruba.
Atako yii lo mu ko kede ni ọjọ kejidinlogun osu kẹta ọdun 2021 pe ilẹ Yoruba to wa lẹkun iwọ oorun guusu kii se ara Naijiria mọ.
Ikede rẹ yii lo ti n fa awuyewuye yika orilẹede Naijiria, idi si ree ti BBC Yoruba fi se iyatọ ati afiwe to wa laarin awọn ajijagbara mẹtẹẹta yii.
Kò sí ìgbà kankan tí Yorùbá jókòó pé ki Igboho  lọ kéde ìyapa kúrò ní Nàíjíríà
Nigba to n sọrọ lori eleyi, Ọmọwe Yemi Farounbi tii se asoju tẹlẹ fun ilẹ Naijiria si orilẹede Phillipines sọ pe iya to n jẹ awọn eeyan wọn lo n ta awọn eeyan naa lara.
Amọ o ni Nnamdi Kanu ati asari Dokubo ni wọn ni pepele tabi ipilẹ ti wọn fi n ja pẹlu ijsba, eyi ta le pe ni ẹgbẹ ajijagbara amọ Sunday Igboho ko ni.
Ogbomoso Quitdruplets: Ọ̀kan nínú àwọn ìbarùn-ún jáde láyé lọ́jọ́ karùn-ún
O fikun pe awọn eeyan agbegbe Niger Delta ri Dokubo bii asaaju wọn, ti ẹya Igbo naa si ri Kanu bii olori ikọ ajijagbara wọn sugbọn Igboho ko ni ẹgbẹ to fi n jija gbara, debi pe wọn yoo mọ ni asaaju.
"Aṣiwaju awọn eeyan agbegbe Niger Delta ni Asari Dokubo jẹ, ṣugbọn emi o ro pe Sunday Igboho ti de iru ipo bẹẹ nilẹ Yoruba.
Lootọ ni Igboho ṣe gudugudu meje lati daabo bo awọn ara ilu Ibarapa, ṣugbọn pe o ti di alakoso fun Yoruba gẹgẹ bii Asari ṣe jẹ fun ẹgbẹ MEND nigbayẹn, ati Kanu fun ẹgbẹ IPOB, Igboho ko tii de iru ipo bẹẹ."""
Bed Wetting: Tolulope Joseph ní ò lé ní ogún ọdún tí òun fi tọ̀ sílé kí ìwòsàn tó dé
Farounbi ni o ṣoro lati fi ohun ti Sunday Igboho n ṣe we ohun ti Asari Dokubo n ṣe, bo tilẹ jẹ pe awọn eeyan Dokubo naa ti sọ pe awọn ko ran ni iṣẹ lati ko wọn mọ ilẹ Biafra.
Farounbi ṣalaye siwaju pe, Nnamdi kanu ti ni gbongbo to duro le pẹlu awọn eeyan rẹ, bẹẹ naa ni Asari Dokubo, ṣugbọn Sunday Igboho ko ni irufẹ gbongbo bẹẹ.
Ikọ wo Sunday Igboho yoo ni ohun n ja fun? Abi awọn wo gan lo ran nisẹ pe ko lọ ko ẹya Yoruba kuro ni Naijiria? Se APC ni abi PDP, Afenifere ni abi ẹgbẹ agbaagba Yoruba?
Nigerian Drone Maker: Roqeeb Aderogba ní ìgbà mẹ́fà l‘òun kùnà láti ṣe dírónù, kó tó yege
Kanu gbọ eebo lati ja fun iran rẹ amọ Igboho ko le sọ gẹẹsi dan mọran:
Yatọ si eyi, awọn ọmọ Yoruba kan lo ti woye pe Nnamdi Kanu lo ka iwe, to si le soju iran rẹ niwaju awujọ agbaye pẹ́lu ede oyinbo to yanranti, amọ̀ Sunday Igboho ko kawe, ti ko si le sọ̀ Gẹẹsi to nnkan.
Awọn eeyan yi lo wa n beere pe se iru ẹni ti eebo rẹ ko kunju iwọn yii ni yoo gbẹnu iran Yoruba sọrọ, ti rogbodiyan to n se ba de oju ọgbagade.
Farmers Herders Crisis: Rẹ́rẹ́ rún, ẹ̀mí àti dúkìá ṣòfò lágbègbè Ariwa Yewa
Afiwe mii ti awọn eeyan tun se akiyesi nipa awọn ajijagbara yii ni pe mọlẹbi awọn mẹtẹẹta ko si ni orilẹede Naijiria tabi gbe ni ẹkun wọn ti wọn n ja fun.
Nnamdi Kanu ni aya ati ọmọ rẹ wa loke okun, Asari Dokubo ni awọ̀n okoowo ati ẹbi rẹ wa ni ilẹ olominira Benin to mule ti wa nigba ti awọn ọmọ ati aya Sunday Igboho naa wa lorilẹede Amẹrika.
Oríṣun àwòrán, Instagram/Sunday Igboho
Amofin kan lorilẹede Naijiria ti fi oju ofin wo ikede ti Sunday Igboho se ni Ọjọru, nibi to ti ni ẹkun iwọ oorun kii se ara orilẹede Naijiria mọ.
Amofin Stephen Ajibola James, lasiko to n ba BBC Yoruba sọrọ salaye pe ta ba fi oju ofin wo o, ete lati ja ijọba gba ni ikede ti Igboho se ọhun.
James ni Igboho ko ni agbara lati kede pe apa ibikan ti yapa kuro lorilẹede Naijiria, ikede rẹ yii si lo wa lati mu ki awọn ọmọ Naijiria ni ikunsinu si ara wọn.
"Ile igbimọ asofin apapọ nikan lo ni agbara lati kede iyapa agbegbe kan lẹyin tawọn ọmọ Naijiria ba ti dibo pe awọn fara mọ pe ki ẹya kan yapa kuro lara Naijiria.
Oríṣun àwòrán, Instagram/Sunday Igboho
Bi wọn ti se ree lasiko ti orilẹede Cameroon fẹ yapa kuro lorilẹede Naijiria, bakan naa lasiko ti agbegbe Bakassi naa fẹ kuro, awọn eeyan si sọ ohun ti wọn fẹ.
Eeyan kan ko le dede wa jade lati kede iyapa agbegbe kan lai jẹ pe onitọun jẹ asofin, Sunday Igboho kan sọ tiẹ lasan ni, ọrọ rẹ ko ni itumọ kankan, sajẹ lasan ni."
Amofin James tẹsiwaju pe, gbogbo nnkan lo ni eto lati tẹle nitori awọn nnkan kan lo so gbogbo ẹkun to wa ni Naijiria papọ, kii se ọrọ ẹnu la fi se, ọrọ ẹnu lasan ko si le ya wa.
Farmers Herders Crisis: Rẹ́rẹ́ rún, ẹ̀mí àti dúkìá ṣòfò lágbègbè Ariwa Yewa
Amofin James salaye pe, Sunday Igboho ti sẹ si ofin ete lati ditẹ gbajọba, ẹsẹ nla si ni labẹ ofin, ijọba si le gbe lati jẹjọ.
Bakan naa, Igboho tun dete lati mase jẹ ki inu awọn ọmọ Naijiria dun si ijọba to wa nita nitori iru ikede to se , ẹnu rẹ ko gba a.
"Ma a rọ ijọba lati maa wo Igboho niran, ki wọn ma si gbe si ahamọ rara lọna ati dena akọtun rogbodiyan to le fẹ tidi gbigbe rẹ yọ nilẹ Yoruba.
Ki ijọba sa ri ihalẹ Sunday Igboho bii ẹni to n pala sẹnu, ofuutu fẹẹtẹ, aasa ti ko ni kanun, nitori ti wọn ba gbe, wọn yoo kan jẹ ko dabi akọni ajijagbara ni."
Awọn agbaagba kan nilẹ Yoruba kan ti n fi erongba wọn han lori ikede ti Oloye Sunday Igboho se pe ilẹ Yoruba ko si lara Naijiria mọ.
Bakan naa ni Igboho tun kede pe akoko ti to ki ẹya Yoruba da wa gẹgẹ bii orilẹ-ede to ti gba ominira, eyi to ti n da awuyewuye silẹ yika apapọ orilẹede Naijiria.
Lara awọn eeyan to woye igbesẹ ti Igboho gbe yii ni aṣoju tẹlẹ fun Naijiria ni orilẹede Philipines, Ọmọwe Yemi Farounbi.
Farounbi ni erongba Sunday Igboho lasan lo fi lede nitori ko si ibi ti gbogbo Yoruba ti jokoo lati yan ẹnikẹni pe ko lọ da orilẹede Oduduwa silẹ.
Bed Wetting: Tolulope Joseph ní ò lé ní ogún ọdún tí òun fi tọ̀ sílé kí ìwòsàn tó dé
Gẹgẹ bo ṣe sọ, ki ẹya kan to le yapa lati da orilẹede tiwọn silẹ, oriṣiriṣi ipade ni yoo waye, pẹlu ijiroro lori bi wọn ṣe le da orilẹede naa silẹ pẹlu ifọwọsowọpọ ajọ agbaye, UN.
"O ni ""lootọ inu Yoruba bajẹ si ohun to n ṣẹlẹ ni Naijiria, ko si igba kankan ti awọn agba joko Yoruba lati yan ẹnikẹni lati ṣoju wọn nipa dida orilẹ-ede tuntun silẹ."""
"Ara lasan lo n ta Sunday Igboho nipa bi orilẹede Naijiria se bajẹ to, ṣugbọn emi o ro pe bi ara ṣe n ta eeyan lo yẹ ko gbe ọrọ naa kalẹ, o yẹ ko fi suuru mu ẹkọ gbigbona.
Nigerian Drone Maker: Roqeeb Aderogba ní ìgbà mẹ́fà l‘òun kùnà láti ṣe dírónù, kó tó yege
Bi eeyan ba si fi ẹkọ gbigbona, ahọn rẹ ni yoo jo, abi se a ti ni olori fun orilẹede Oduduwa ti wọn n polongo ni? Se wọn ti ni eto aabo fun ilu naa ni?
Se wọn ti ni ilana fun eto ijọba awa ara wa fun orilẹede Oduduwa ni? Awọn igbesẹ kan maa n wa ki eeyan to se iru nnkan bẹyẹn."
O fikun pe, ọrọ ilẹ yii gbọdọ kọkọ dun gbogbo wa bakan naa, ka jọ fẹnu ko bakan naa, ka le mọ igbesẹ ta jọ gbe bakan naa, Igboho ko ba se suuru ki gbogbo wa jọ fẹnu ko na lori yiyapa kuro ni Naijiria.
Jimoh Odutola: Gbajúmọ̀ olókoòwò tó n sọ àlòkù táyà di tuntun ní Afíríkà
Oríṣun àwòrán, Yoruba history /twitter
Ọkan pataki ni Jimoh Odutola lara awọn to kọkọ dá ileesẹ silẹ ni Naijiria, ati awọn oníṣòwò to lami-laaka.
Ilu Ijebu-Ode ni wọn bi Jimoh si, oun si ni aburo gbajugbaja onisowo to tun jẹ ẹlẹyinju aanu, Oloye Timothy Adeola Odutola.
Jimoh ko lọ si ileewe rara, koda ọmọ ọdun mejila lo ti bẹrẹ isẹ aje ni ṣíṣe.
O bẹrẹ isẹ gẹgẹ bi ọmọ ọdọ ati ọmọ ikọsẹ lọdọ oníṣòwò maalu, Alhaji Abdul-Kareem Otupa.
Àwọn ìtàn mánigbàgbé tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí:
Sugbọn, òpin de ba irinajo rẹ nibẹ ni ọdun 1918 nitori ajakalẹ aarun to waye ni agbaye ni ọdun naa.
Nigba to pe ọmọ ọdun mẹrindinlogun, o bẹrẹ isẹ aṣọ tita pẹlu Pọun mẹfa, ti ọkọ iya rẹ,  Sanni Bilesanmi, fún.
Oríṣun àwòrán, Yoruba history /twitter
Ọkunrin yii ni iya Jimoh fẹ, lẹyin ti baba rẹ di oloogbe. Lọdun 1927, Jimoh tun gba ọna mii yọ nidi okoowo ṣíṣe.
O bẹrẹ si ni ṣe owo eto irinna ọkọ. Bakan naa, lọdun 1929, o fi owo katakara kòkó kun isẹ rẹ.
Ìtàn sọ pe o ṣe àṣeyọrí pupọ nidi isẹ yii, nitori pe otitọ inu lo fi n ṣe okoowo rẹ.
Sugbọn ṣa, ifasẹyin kan de ba lasiko ti oun ati ẹ̀gbọ́n rẹ, Adeola Odutola, jọ da òwò pọ.
Itan sọ pe iya wọn lo fi dandan mu àwọn mejeeji ni ọdun 1932, lati jọ ṣe òwò pọ. Saaju asiko naa, akọwe ile ẹjọ ni Adeola, o si tun n ṣe okoowo keekeeke.
O kéré sí Number! 'Àwa ológún ò fi ara wa wọ́lẹ̀ tó bẹ́ẹ̀ láti máa ṣe alamí lórí irú ẹ Sunday Igboho'
Àlàyé rèé lórí bí Gómìnà Ortom Benue ṣé bọ̀ lọ́wọ́ àwọn agbébọn
Taooma: Ìbáṣepọ̀ mi pẹ̀lú àwọn òbí mi yàtọ̀ sí bí mó ṣé n polongo nínú fídíò mi
Oríṣun àwòrán, Yoruba history /twitter
Okoowo karakata èrè oko si ilẹ okeere, aṣọ hihun, ati iwakusa goolu ni wọn n ṣe.
Àmọ́, kii dun ko pọ ni ọrọ ajọsepọ wọn jẹ. Lọdun 1948, ajọsepọ wọn fi ori sanpọn, ti wọn si tuka.
Àmọ́, wọn di orogun òwò. Awọn mejeeji lo si pada di alaseyọri ni ọna ti wọn rìn.
Lọdun 1950, o da ileesẹ J. A Odutọla and Company Limited silẹ. Abẹ ileesẹ naa si ni gbogbo okoowo rẹ wa.
Lẹyin ọdun mẹrin, o da ileesẹ West African Tyre Retreading and Company Ltd silẹ.
Bed Wetting: Tolulope Joseph ní ò lé ní ogún ọdún tí òun fi tọ̀ sílé kí ìwòsàn tó dé
Ileesẹ naa ni akọkọ iru rẹ ni ilẹ Africa. Ohun ti ileesẹ naa ma n ṣe ni pe o ma n sọ aloku taya tabi eyi ti ko dara mọ di tuntun.
Ileesẹ naa gbooro debi pe ijọba orilẹ-ede Ghana ati Kenya ránṣẹ́ pe Jimoh Odutola, lati wa a da iru rẹ silẹ ni orilẹ-ede wọn.
Àṣeyọrí Odutola ko tán sibẹ o. Oun kan naa tun ni ẹni akọkọ to da ileesẹ ti wọn ti n ṣe timutimu (foam) onirọba silẹ lọdun 1958, ati eyi ti wọn n fi ike ṣe ni ọdun 1960.
Nigba ti yoo fi di ọdun 1951, o ti ṣi ọfiisi kan si ilu Oldham, United Kingdom. Lọdun 1967, o gba iwe ẹri apọnle gẹgẹ bi ọmọ Africa to kọkọ lọ si North Pole.
Nigerian Drone Maker: Roqeeb Aderogba ní ìgbà mẹ́fà l‘òun kùnà láti ṣe dírónù, kó tó yege
Ni ọdun naa bakan naa lo tun di ọmọ Afirika akọkọ to wọ baalu Lufthansa lati ilu Tokyo ni orilẹ-ede Japan, lọ si Alaska lorilẹ-ede America, ati Alaska lọ si Copenhagen.
Bo tilẹ jẹ pe Jimoh Odutọla ko kawe, o ri daju pe gbogbo ọmọ mẹrinlelogun to bi kawe debi to wu wọn.
Lara awọn ọmọ rẹ ni Ọjọgbọn Ebun Clark, Ọjọgbọn akọkọ ninu imọ ere ori itage ni Nigeria. Oun si ni iyawo gbajugbaja onkọwe, Ọjọgbọn J. P Clark.
Ẹlẹyinju aanu ni Alhaji Jimoh Odutọla. O kọ ileewe girama kan ati ile ẹ̀kọ́ Kuraani ní ìlú Ijẹbu-Ode.
Bakan naa lo ṣe ojupopo oni maili mẹsan lati ìlú Irogbo si Iperindo ni Ilesha.
Oríṣun àwòrán, Yoruba history /twitter
Lara oore aritọkasi to tun ṣe ni bo ṣe kọ ibusun igba fun ileesẹ ologun nilu Ibadan lati ṣe atilẹyin fun ijọba Naijiria lasiko ogun Biafra.
O pe ẹni ọdun marunlelọgọrun ko to o kú ni ọdun 2010.
Titi di oni, orúkọ rẹ ni wọn fi sọ opopona naa kan ni ọjà Ogunpa/Dugbẹ nilu Ibadan.
Bakan naa ni ipinlẹ Eko, wọn fi orukọ rẹ sọ adugbo kan ni agbegbe Surulere.
Albinism: Èèmọ̀ rèé o! Kí ló lè mú kí àfín 114 di àwátì?
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ajọ ajafẹtọ ọmọniyan lapa gusu ilẹ Afirika ti sọ pe ọpọ awọn afin lo si n tun di awati lorilẹede Mozambique di akoko yii.
Ajọ naa ṣalaye pe ẹjọ to niṣe pẹlu awọn afin to di awati le ni marunlelaadọta to wa nile ẹjọ bayii.
Ajọ ajafẹtọ naa sọ pe o kere tan, afin mẹrinlelaadọfa lo ti di awati ni ọdun bii meje sẹyin.
Awọn eeyan kan maa n pa awọn afin lapa ila oorun ati gusu Afirika.
Igbagbọ awọn eeyan ni pe wọn maa n lo ẹya ara afin fun oogun owo ati oogun ifẹ.
Ajọ to n ri si ẹtọ ọmọniyan ni Mozambique, CNDH ṣe agbekalẹ ijiroro kan niluu Maputo lati fọrọ jomitoro ọrọ lori iwa idẹyeṣi tawọn afin bi ẹgbẹrun lọna ogun n doju kọ.
Sheila Massuque to n ṣiṣẹ pẹlu ajọ CNDH ṣalaye pe ọpọ afin lawọn ẹbi wọn ti kọ silẹ nigba ti awọn mii ti ṣagbako iku ojiji.
Ileeṣẹ ijọba to n ri si ọrọ eto idajọ sọ pe ijọba n gbiyanju lati daabo bo awọn afin.
Awọn afin to wa lorilẹede Mozambique sọ awọn ile iwosan maa n dẹyẹ si awọn lasiko ajakalẹ arun coronavirus.
Wọn ni ọpọ igba ni wọn maa n da awọn pada.
Gani Adams: Gbogbo gómìnà Yorùbá ni mo kọ̀wé sí láti bá ṣèpàdé
Oríṣun àwòrán, Twitter/Seyi Makinde
Ni itẹsiwaju ọna ati wa ojutu si awọn ipenija to n koju ilẹ Yoruba, Aarẹ Ọna Kakanfo Gani Adams ati Gomina Seyi Makinde ti dijọ ṣepade pọ nilu Ibadan.
Ipade yi ti wọn ṣe ni bonkẹlẹ la gbọ pe o da lori ọrọ aabo ati ọrọ aje ilẹ kaarọ o jiire.
Atẹjade lati ọdọ agbẹnusọ feto iroyin fun gomina Seyi Makinde, Ọgbẹni Taiwo Adisa sọ pe aarẹ Gani Adams lo kọwe si gbogbo awọn Gomina ipinlẹ Yoruba lati beere fun ipade lori ọrọ aje ati aabo.''
Gani Adams ninu ọrọ rẹ si ni ''Inu mi si dun pe wọn jẹ mi ni o''
Iba tẹsiwaju pe ''mo ṣepade pẹlu Gomina Ekiti ni ọjọ meji sẹyin, nibayi mo n ṣe ipade pẹlu Gomina Oyo''
Oríṣun àwòrán, Facebook/Seyi Makinde
O ni o ṣe pataki kawọn fikunlukun lori ọrọ iṣẹ agbẹ ati pe, awọn Gomina mejeeji ti sọ ọna tawọn yoo fi mu idagbasoke ba iṣẹ agbẹ, paapa fawọn aladani.
''Mo fẹ fi da wọn loju pe awa naa yoo kopa tiwa lati ri pe a mọ awọn to fẹ dowo pọ pẹlu wọn wa''
Iba Gani Adams tun fikun ọrọ rẹ pe, ati awọn ati ijọba Oyo, ibi kanna lawọn jijọ n foju sun lori mimu alaafia ba ara ilu.
Ogbomoso Quitdruplets: Ọ̀kan nínú àwọn ìbarùn-ún jáde láyé lọ́jọ́ karùn-ún
O ni pẹlu ibi ti ọrọ de yii, awọn ọmọ Yoruba ko gbọdọ sun asunpiye, o si yẹ ki wọn pawọpọ lori ọrọ aabo ilẹ wọn eyi to ni ojuṣe gbogbo ọmọ Yoruba nii ṣe.
Kò sí ìgbà kankan tí Yorùbá jókòó pé ki Igboho lọ kéde ìyapa kúrò ní Nàíjíríà
Ogbomoso Quintuplets: Ọ̀kan nínú àwọn ìbarùn-ún jáde láyé lọ́jọ́ karùn-ún
Isẹ Oluwa, awamaridi ni nitori ọna rẹ, ko si ẹni to ye tabi ẹni to mọ, bo si se wu Oluwa lo n se ọla.
Nibi ti awọn eeyan kan ti n fi ojoojumọ sunkun si Ọlọrun lọrun fun ẹbun ọmọ, ni Ọba Oke ti fi ibarun ta idile Idowu ati Funmilayo Oluwadara lọrẹ.
Awọn tọkọ-taya yii lo ti kọkọ bi ọmọ marun tẹlẹ, ki oore ibarun tun to wọle de, ti iya wọn si bi wọn wọọrọwọ lai se isẹ abẹ.
Nigba ti tọkọtaya Oluwadara n ba BBC Yoruba sọrọ nilu Ogbomoso, wọn ni ibẹta ni dokita kọkọ ni oun yoo bi, ki ibarun to wa, ọkunrin kan ati obinrin mẹrin.
Ni ọjọ karun tawọn ọms naa dele aye la gbọ pe ọkunrin kan soso laarin awọn ibarun naa jade laye.
Tọkọ-taya naa ti wọn jẹ alagbaro, ni ko ti wa ri owo ile iwosan san lati maa lọ sile, bi o tilk jẹ pe dokita ti yọnda wọn.
Wọn wa n bẹbẹ fun iranwọ owo lọdọ awọn ẹlẹyinju aanu, lati sanwo ile iwosan ati fun itọju awọn ọmọ mẹrin to ku pẹlu awọn ẹgbọn wọn nitori ọna abayọ.
Sunday Igboho: Afurasí mẹ́rin tí wọn ló ń dọdẹ Majasọla nílé rẹ̀ ní Soka, bọ́ sí àhàmọ ọlọ́pàá
Oríṣun àwòrán, Facebook/Koiki Media
Ilumọọka ajafẹtọ ilẹ Yoruba, Oloye Sunday Igboho ni ọwọ rẹ ti tẹ awọn eeyan meji ti wọn wọ asọ ologun ati eeyan meji mii ti wọn jẹ araalu.
Sunday Igboho ni ọwọ oun tẹ awọn eeyan mẹrẹẹrin naa lori ẹsun pe wọn n sọ oun lọwọ lẹsẹ kiri ni deede aago kan ọsan ọjọ Ẹti.
Fidio kan ti agbẹnusọ fun Sunday Igboho, Olayomi Koiki fisita lasiko ti isẹlẹ naa n waye loju opo Facebook rẹ, ni isẹlẹ ti foju han.
Ninu fidio naa, ni awọn eeyan mẹrẹẹrin naa ti kunlẹ, tawọn alatilẹyin Igboho si n da 'sẹria' fun wọn.
Amọ awọn afurasi ologun naa ni awọn n gun ọkada lọ si ibi kan ti awọn n lọ ni, awọn ko si mọ ibẹ, nigba ti awọn ri awọn araalu meji naa ti wọn n ja, ti awọn si duro lati la wọn.
Oríṣun àwòrán, Facebook/Koiki Media
Awọn eeyan ti irisi wọn naa jọ ti ologun naa ni Igboho wa fẹsun kan pe ijọba lo ran wọn lati maa dọdẹ ile oun to wa ni adugbo Soka nilu Ibadan.
Bakan naa lo ni igbesẹ ijọba naa lo seese ko wa lati gbe oun sahamọ nitori ikede ti oun se ni Ọjọru pe ilẹ Yoruba kii se ara Naijiria mọ.
Oríṣun àwòrán, Facebook/Koiki Media
Igboho wa se apejuwe awọn eeyan meji to jẹ araalu laarin awọn afurasi mẹrẹẹrin bii ọmọ ale Yoruba.
O ni ti kii ba se bẹẹ, wọn ko ba ti ran wọn lati wa maa ṣọ oun kiri, ti oun si n seleri lati pari wọn.
Oríṣun àwòrán, Facebook/Koiki Media
"Ẹ́ lọ sọfun ẹni to ran yin si mi pe o kere gan, tẹ ba tiẹ wa fẹ se were, kii se ọdọ mi lo yẹ kẹ se si. Gbogbo ẹyin ọmọ ale Yoruba yii, ni maa pari yin.
Ti kii ba se ohun ti mo gbe lọwọ ni, ati ki ilẹ Yoruba ma bajẹ, iru yin kere si mi."
Amọ iroyin kan ni Sunday Igboho ni ki awọn eeyan oun mase fiya jẹ awọn afurasi naa, to si ti fa wọn le ọlọpaa lọwọ.
Ninu fidio naa ni Olayomi Koiki ti salaye pe, idunkooko si Sunday Igboho ti n lagbara bayii.
Oríṣun àwòrán, Facebook/Koiki Media
O wa n beere pe ki ni awọn ologun n wa lori ọkada ni agbegbe Soka, nigba to jẹ pe Alakia ni ibudo ologun wọn wa.
O wa ke si ijọba apapọ lati sọra se nipa irufẹ awọn eeyan to n ran lati maa sọ ile Sunday Igboho.
Wayi o, BBC Yoruba gbiyanju lati ba agbẹnusọ fun ileesẹ ọlọpaa ipinlẹ Oyo, Olugbenga Fadeyi sọrọ lati fidi isẹlẹ yii mulẹ, amọ ko gbe ipe rẹ lori aago
Kaduna killings: Gómìnà El-Rufai kẹ́dùn pẹ̀lú ẹbí àwọn tó kú
Oríṣun àwòrán, @HQNigerianArmy
Awọn janduku agbebọn tun ti ṣekupa eeyan mẹtala ninu ikọlu mii to waye ni ijọba ibilẹ Zangon Kataf, Kauru ati Chikun nipinlẹ Kaduna.
Kọmiṣọna fun ọrọ abẹle ati ọrọ aabo nipinlẹ Kaduna, Samuel Aruwan ṣalaye pe, ileeṣẹ ologun ti fidi ọrọ naa mulẹ.
Gẹgẹ bi iroyin ti a gbọ, awọn janduku naa kọlu Irmiya Godwin ati aburo rẹ, lẹyin ti wọn de lati oko wọn to wa ni ijọba ibilẹ Zango Kataf.
Wọn ṣekupa Godwin, amọ aburo rẹ mori bọ, o si sa asala fun ẹmi rẹ.
Bakan naa lawọn janduku ọhun tun kọlu abule Kizachi ni ijọba ibilẹ Kauru nibi ti wọn ti pa eeyan mẹwaa, ti eeyan mẹrin si farapa.
Oríṣun àwòrán, Andrwe Akyalla
Ile mẹrindinlọgọta ati alupupu mẹrindinlogun ni wọn dana sun, koda wọn tun sọ ina si aba ti awọn eeyan abule naa ko ere oko si.
Orukọ awọn tawọn janduku ọhun pa gẹgẹ bi iroyin ti a gbọ ṣe sọ ni Esther Bulus ati ọmọ rẹ ti ko ju ọdun kan lọ, Maria Bulus, Lami Bulus, Aliyu Bulus.
Awọn yoku ni Monday Joseph, Geje Abuba, Wakili Filibus, Yakubu Ali, Dije Waziri ati Joseph Ibrahim.
Cecilia Aku, Yakubu Idi, Godiya Saleh, Moses Adamu ni awọn eeyan to ṣeeṣe ninu ikọlu naa, wọn n gba itọju lọwọ nile iwosan bayii.
Ogbomoso Quitdruplets: Ọ̀kan nínú àwọn ìbarùn-ún jáde láyé lọ́jọ́ karùn-ún
Bakan naa, awọn agbebọn ṣekupa Duza Bamaiyi ni abule Masaka ni ijọba ibilẹ Chikun, nibi ti eeyan meji ti farapa.
Wọn tun pa Zakka Pada ni abule Kurmin ni ijọba ibilẹ Chikun kan naa.
Ẹwẹ, gomina Nasir El-Rufai ti kẹdun pẹlu awọn ẹbi oloogbe, o si gbadura pe ki Eleduwa tẹ wọn si afẹfẹ rere.
Nyesom Wike: Lẹ́yìn Ọlọ́run, èmi ló tún kàn fún Rotimi Amaechi torí èmi ló sọ ọ́ di gómìnà
Oríṣun àwòrán, Facebook/Rivers State Government
Gomina ipinlẹ Rivers, Nyesom Wike ti sọ pe, oun ko le fi ẹgbẹ oṣelu PDP silẹ laelae lọ darapọ mọ APC.
Ninu ifọrọwerọ pẹlu BBC, Wike sọ pe kikuro ninu ẹgbẹ PDP dabi ẹni pe oun ni fi ẹgbẹ to ni arun iba silẹ, lati lọ si APC to ni arun jẹjẹrẹ.
Wike ni ohunkohun ti kii ba ṣẹlẹ, mimi kan ko le mi oun ninu ẹgbẹ oṣelu PDP.
Gomina Wike tun fesi lori ọrọ ti gomina ipinlẹ Rivers tẹlẹ, Rotimi Amaechi sọ pe oṣiṣẹ oun nii ṣe tẹlẹ.
Wike ni ''emi lo ku lẹyin Ọlọrun fun Amaechi, nitori emi ni Ọlọrun lo fun un lati wọle gẹgẹ bi gomina ipinlẹ Rivers.
Ogbomoso Quitdruplets: Ọ̀kan nínú àwọn ìbarùn-ún jáde láyé lọ́jọ́ karùn-ún
Emi naa ni Amaechi wa n sọ pe oṣiṣẹ rẹ ni mo jẹ tẹlẹ, mo ni fọnran aworan ti Amaechi ti sọ ni ṣọọṣi pe, lẹyin Ọlọrun, emi lo tun kan fun un.''
Gomina Wike ni oun gan an ni oun sọ Amaechi di gomina Rivers lai si ani ani kankan nibẹ.
''O ni oṣiṣẹ oun ni mo jẹ, ṣugbọn emi naa ni mo n fi ẹyin rẹ gbalẹ lagbo oṣelu.
Ṣugbọn ẹgbẹ oṣelu rẹ APC fidi rẹmi ninu ibo aarẹ ati ibo ile igbimọ aṣofin l'Abuja.
Bed Wetting: Tolulope Joseph ní ò lé ní ogún ọdún tí òun fi tọ̀ sílé kí ìwòsàn tó dé
O tun sọ pe, n ko le se gomina laelae, amọ oju rẹ naa lo ṣe ti mo fi wọle ibo gomina lẹẹmeji ọtọtọ.
Emi funra mi ni mo sọ pe ipo adari awọn oṣiṣẹ ni mo fẹ nigba ti Amaechi jẹ gomina ipinlẹ Rivers,'' Wike lo sọ bẹẹ.
Gomina ni ile ẹjọ ati igbimọ to n gbẹjọ ẹsun ṣiṣe owo ilu kumọ kumọ lo fidi rẹ mulẹ pe Amaechi jẹbi ẹsun iwa ajẹbanu.
Amaechi lo ta ileeṣẹ afẹfẹ gaasi ipinlẹ Rivers fun ọdunrun miliiọnu le mẹjọ owo dọla.
Báyìí lórí ṣé ko mi yọ lọ́wọ́ àwọn agbébọn - Gómìnà Samuel Ortom
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Gomina ipinlẹ Benue Samuel Ortom ti fidi ọrọ mulẹ pe lootọ lawọn agbebọn ṣe ikọlu si oun logunjọ oṣu Kẹta.
Gomina naa sọ pe awọn agbebọn  ti wọn doju ija kọ awọn ẹsọ rẹ wọ aṣọ dudu ti wọn si to mẹẹdogun
O ni awọn agbebọn yi fẹ ran oun lọ si ọrun aremabọ ni nitori o to kilomita meji ti awọn fi sa fun wọn
Lasiko to n ba awọn akọroyin sọrọ ni Ortom tu kẹkẹ ọrọ silẹ ṣapejuwe awọn agbebọn yi gẹgẹ bi darandaran to si ni bi awọn mẹẹdogun wọn ni wọn tọ ipasẹ oun de eti odo toun ti n fẹsẹ rin.
Gomina Ortom jẹ eeyan kan to n bẹnu atẹ lu ihuwasi awọn darandaran to jẹ ipenija aabo ni Naijiria lẹnu ọjọ mẹta yii.
Ṣaaju lo ti sọ fun BBC ninu ifọrọwerọ kan laipẹ yi pe awọn ẹgbẹ darandaran yi tako ofin ti oun ko si faramọ iṣesi wọn.
Bakan naa lo kesi ijọba lati fi iru ọwọ to fi mu awọn ẹgbẹ mii bi ti IPOB ati ESN ti ijọba ni awọn wọgile mu ẹgbẹ Miyetti Allah awọn darandaran.
Taooma: Ìbáṣepọ̀ mi pẹ̀lú àwọn òbí mi yàtọ̀ sí bí mó ṣé n polongo nínú fídíò mi
Ekiti by-election: INEC ní èèyàn mẹ́ta kú, ọlọ́pàá ní kò rí bẹ́ẹ̀, PDP fapajánú
Oríṣun àwòrán, Facebook/KayodeFayemi/Ayodele Fayose
Iwọ lo lẹbi emi kọ lorin tawọn alẹnulọrọ paapa ninu ẹgbẹ oṣelu APC ati PDP n fi bẹnu lori laasigbo to waye nibi idibo atundi ijọba ibilẹ to waye ni Ekiti.
Lọjọ Abamẹta niṣe ni ajọ eleto idibo INEC wọgile eto idibo naa to si sọ pe eeyan mẹta ku ti agunbanirọ kan ati ọlọpaa kan naa si farapa.
Ayodele Fayose to jẹ eekan ninu ẹgbẹ PDP sọ pe iṣẹlẹ yi yoo maa ja awọn aṣebi ninu nitori pe wọn ṣeku pa awọn eeyan wọn nitori idibo sile aṣofin ipinlẹ lasan.
Ninu ọrọ to fi soju opo rẹ ni Twitter, Fayose ṣalaye pe ohun to ṣẹlẹ ni Omuo Ekiti ko ju pe ijọba fun ara rẹ n ṣagbatẹru iwa agbesunmọmi lati fi doju ija kọ ara ilu.
O ni nigba ti wọn ri pe ewe ti fẹ sunko ti ara ilu o si fẹran wọn mọ ni wọn fi n dunkoko mọ ara ilu.
''Pipa awọn alaiṣẹ nitori wọọdu marun un ninu idibo atundi ijọba ibilẹ jẹ iwa to buru jai to si doju ti ni.
''Mo ro pe a ti kọja iru iwa ẹranko yi ni Ekiti paapa lọwọ yi ti ijọba n koju ipenija aabo eleyi ti wọn ko rojutu si''
Bi Fayose ṣe n tutọ soke foju gba lawọn ajọ eleto idibo Naijiria INEC naa n sọ pe awọn ti so eto idibo yi rọ.
Wọn ni ti awọn ba tẹsiwaju lati ṣeto idibo yi yoo da bi gba pe awọn n gbe lẹyin iwa ibajẹ ni.
Oríṣun àwòrán, Twitter/Inec
Festus Okoye to jẹ Kọmisana ajọ naa to n mojuto ọrọ idanilẹ oludibo to  buwọlu atẹjade yi ni awọn agbofinro ti bẹrẹ iwadii lori ọrọ yi.
Nigba ti iroyin yi kọkọ lu sita ti BBC Yoruba kan si alukoro ọlọpaa Ekiti  ASP Abutu Sunday sọ pe ko si ẹni to kú.
O sọ ninu atẹjade to fi ranṣẹ si BBC pe eeyan mẹfa lo kan farapa nibi iṣẹlẹ naa.
Lara wọn si ni ọlọpaa meji, agunbanirọ kan, ati araalu mẹta wa.
O ṣalaye pe gbogbo wọn ti n gba itọju nileewosan gbogboogbo to wa ni Ikọle-Ekiti.
Bakan naa lo sọ pe ọwọ ti tẹ afurasi mẹta lori iṣẹlẹ naa.
"O ni ""Kọmisanna ọlọpaa nipinlẹ Ekiti n fi da awọn araalu loju pe ileeṣẹ ọlọpaa yoo ri daju pe awọn to lọwọ si iṣẹlẹ naa foju wina ofin. O si tun rọ gbogbo eniyan lati fi ọkan balẹ."""
Fayemi ba mọlẹbi kẹdun, o ni awọn to huiwa yi ko ni lọ laijiya
Ẹwẹ Gomina Kayode Fayemi ninu ọrọ tirẹ nipa iṣẹlẹ yi sọ pe ijọba yoo ri pe gbogbo awọn to mọ si ipaniyan yi yoo foju wina ofin.
Ninu atẹjade ti agbẹnusọ rẹ Yinka Oyebode fi sita, o ni ijọba ba mọlẹbi awọn to farapa ati awọn to ku kẹdun.
Asofin agba to n ṣoju Ekiti ni ẹkun Guusu ipinlẹ naa Senator Biodun Olujimi sọ pe ori lo ko oun yọ nibi iṣẹlẹ yi.
Olujimi to jẹ ọmọ Omuo Ekiti sọ pe ọpẹlọpẹ awọn alatilẹyin loun  fi moribọ nigba tawọn agbebọn ṣigun bo awọn oludibo ni ibudo idibo rẹ to wa ni ward 7,Unit 007.
Oríṣun àwòrán, Facebook/Biodun Olujimi
Atundi ibo yi to waye lọjọ Abamẹta jẹ eleyi ti INEC ṣeto lati dibo yan ẹlomii ti yoo gba ipo aṣofin oloogbe Juwa Adegbuyi ti ẹgbẹ oṣelu APC to di ipo naa mu tẹlẹ.
Ko ju wakati meji ti wọn bẹrẹ idibo tawọn agbegbọn ṣigun de tọrọ si di boo lọ o yago mi ni Omuo.
Iwadii ṣi n tẹsiwaju botilẹ jẹ wi pe awọn ẹgbẹ oṣelu PDP n naka aleebu si ẹgbẹ APC pe awọn janduku wọn lo wa da idibo naa ru.
Kabiyesi Kidnapped: Olorí Oba Imope ní ẹbí kábíyèsí kò ní N200M tíáwọ́n ajínigbé ń béèrè
Oríṣun àwòrán, Oba Tajudeen Omotayo
Oju Ọlọrun laa n wo nitori ipa wa ko ka iye owo ti wọn ni ka mu wa kawọn to le tu Kabiyesi silẹ.
Ọrọ ti Olori Omotayo Adesola fọ lesi ree nigba ti akọroyin BBC Yoruba tun pe wọn lori ago lati mọ boya wọn gburo Kabiyesi.
Lati ọjọ Abamẹta lawọn ajinigbepawo ti gbe Kabiiyesi ti wọn si ni ki mọlẹbi wọn mu igba miliọnu Naira wa.
''Wọn pe wa laarọ yi ti wọn si ni ṣe a ti ri owo naa. Mo sọ fun wọn pe ko tii pe''
Olori ni iporuru ọkan ti de ba awọn mọlẹbi bayi nitori awọn ko mọ iru ipo ti Kabiyesi wa.
Nigba taa beere lọwọ wọn boya wọn ti gburo awọn ọlọpaa lori iṣẹlẹ yi, wọn ni awọn ọlọpaa wa kaakiri ilu ṣugbọn awọn ko le sọ boya wọn ti ri awọn ajinigbe naa.
Nigba ti BBC Yoruba ba agbẹnusọ ọlọpaa ipinlẹ Ogun Abimbola Oyeyemi sọrọ kẹyin, o ni awọn ikọ ọtẹlẹmuye n gbiyanju lati ṣawari Kabiyesi
Lẹnu lọọlọ yi, iwa ijinigbe ti wa gbilẹ ni Naijiria ti ko si fẹ yọ apa kankan lorileede naa silẹ.
Oríṣun àwòrán, Nigeria presidency
Olori Omotayo Adesola, Oba Tajudeen Omotayo ilu Imope tawọn afurasi ajinigbe Fulani gbe lọjọ Abamẹta ti rawọ ẹbẹ sawọn ajinigbe naa pe ki wọn fiye denu, ki wọn tu kabiyesi silẹ.
Olori Adesola ni ẹbi kabiyesi ko ni igba miliọnu naira tawọn ajinigbepawo n beere fun ki wọn to le tu kabiyesi silẹ.
Olori ṣalaye fun BBC Yoruba pe awọn ajinigbe naa fi foonu kabiyesi pe lati ba ẹbi sọrọ.
''Awọn ajinigbe naa n sọ ede Pidgin oyinbo pẹlu kabiyesi, ohun ti kabiyesi sọ ni pe ki a lọ wa owo nla wa kawọn ajinigbe le fi wọn silẹ.
Nigba ti mo beere pe elo ni ki a lọ wa, kabiyesi ni bii igba miliọnu naira ni o,'' Olori lo sọ bẹẹ.
Olori ṣalaye pe ''a o lowo kankan o, ki wọn ṣaanu wa, ati pe awọn ọmọ kabiyesi ṣi kere.''
''Awọn ọlọpaa sọ fun wa pe awọn ajinigbe naa ṣi wa pẹlu kabiyesi ninu igbo lagbegbe Imope, wọn o tii kuro lagbegbe.
Koda awọn ajinigbe ọhun yinbọn mọ ọkan lara awọn ọlọde to bẹ sinu igbo ti wọn gbe kabiyesi lọ lẹsẹ.
Ẹni naa wa nile iwosan nibi to ti n gba itọju lọwọ bayii,'' Olori ṣalaye.
Olori naa tun ke pe ijọba ipinlẹ Ogun lati ṣe iranwọ lori ati gba ominira lọwọ awọn ajinigbe.
Bakan naa. ọkan lara ẹbi kabiyesi, Jide Abiodun Adebanjo naa rawọn ẹbẹ sawọn janduku ajinigbe naa wi pe ki wọn fi kabiyesi silẹ.
Ọgbẹni Adebanjo ni ko si ibi ti ẹbi kabiyesi ti fẹ ri ọgọrun tabi igba miliọnu naira.
Ọgbẹni Adebanjo ni ẹbẹ naa ni ẹbi kabiyesi n bẹ pe ki awọn ajinigbe ọhun mu owo naa walẹ.
Ajínigbé jí Oba Imope gbé ní Ogun, wọ́n pa olódẹ tó fẹ dóòlà Kábíyèsí, N200M ni wọ́n ń béèrè
Awọn ajinigbepawo ti tun ṣoro pẹlu bi wọn ti ṣe ji ọba alade mii gbe nilẹ Yoruba.
Lọjọ Abamẹta ni wọn ji Oba Tajudeen Omotayo, Oba tilẹ Imope gbe lagbegbe ijẹbu Igbo ni ipinlẹ Ogun.
Ẹkunrẹrẹ iroyin nipa iṣẹlẹ naa ko tii tẹwa lọwọ ṣugbọn awọn to sunmọ oriade naa ni nkan bi ago mọkanla lo gbera kuro laafin la ti lọ si Ijebu Ode ninu ọkọ ayọkẹlẹ rẹ.
Awọn ajinigbepawo naa la gbọ pe wọn da Ori Ade ọhun lọna ni agbegbe Okeeri ni Imope ti wọn si ji Kabiyesi gbe lọ.
Wọn fi ọkọ ti Ọba gbe jade silẹ loju ọna.
Mọlẹbi Oba ọhun kan to ba BBC sọrọ ni lẹyin igba tawọn ajinigbe naa gbe ọba sa lọ, wọn kan si iyawo rẹ  lati mu igba miliọnu Naira wa lowo idoola.
Lẹyin idunadura wọn lawọn yoo gba ọgọrun miliọnu Naira.
Gẹ́gẹ́ bí àṣà, mo ti mọ̀ tipẹ́ pé mo máa jẹ ọba Akinghare II -  Oba Oloyede
Bẹẹ la tun gbọ pe awọn ọlọde kan yabo igbo to yi ilu naa ka lati doola Ọba.
Ababọ rẹ nipe awọn ajinigbe yi yinbọn pa ọkan lara awọn ọdẹ ọhun.
Titi di ba ṣe n ṣakojọ iroyin yi, wọn ko ti ri ọba naa.
Alukoro ileeṣẹ ọlọpaa nipinlẹ Ogun  Ararakunrin Abimbola Oyeyemi fidi iṣẹlẹ yi mulẹ fun BBC to si ni ikọ ọtẹlẹ́muyẹ ọlọpaa ti bẹrẹ iwadii lori ọrọ naa.
Nipa ti pe awọn ajinigbe yi pa ọlọde kan Oyeyemi ni oun ko mọ si.
Bẹẹ naa lo sọ pe awọmn ko ti gburo pe awọn ajinigbe naa beere owo idoola lọdọ mọlẹbi.
Sunday Igboho: Iléeṣẹ́ ológun Nàìjíríà dá èsì padà sí Sunday Igboho tó kó ọmọ ogun sí àhámọ́
Oríṣun àwòrán, Defence Headquatres,Sunday Igboho
Ileeṣẹ ologun orilẹede Naijniria ti da esi pada si iwa ti gbajugbaja ajafẹtọ ẹya Yoruba, Sunday Adeyemo ti gbogbo eeyan mọ si Sunday Igboho hu si awọn ọmọ ogun kan.
Wọn fi atẹjade kan sita eyi ti adele oludari ileeṣẹ ologun alaabo, Brigadier General BE Onyeuko fọwọ si pe awọn ri fidio to gbalẹ kan lori ayelujara ati kaakiri awọn ileeṣẹ iroyin to ni Sunday Igboho mu awọn Sọja si ahamọ torii pe o ni wn n ṣe alami lori oun.
Ṣaaju ni Sunday Igboho ni ọwọ oun tẹ awọn eeyan mẹrẹẹrin naa lori ẹsun pe wọn n sọ oun lọwọ lẹsẹ kiri ni deede aago kan ọsan ọjọ Ẹti.
Oríṣun àwòrán, Sunday Igboho
Ogbomoso Quitdruplets: Ọ̀kan nínú àwọn ìbarùn-ún jáde láyé lọ́jọ́ karùn-ún
Afurasi Sọja ni ileeṣẹ ologun pe awọn ọmọ ogun ti ọwọ sunday Igboho tẹ yii ninu atẹjade wọn leyi ti wọn ṣalaye pe ninu fidio naa, wọn fi ẹsun kan wọn pe ijọba lo ran wọn lati lọ ṣe alami layika ile Sunday Igboho to wa ni agbegbe Soka ni Ibadan, ipinlẹ Oyo.
"Bakan naa, wọn ṣapejuwe sunday Igboho gẹgẹ bii ""ẹni to n pe ara rẹ ni ajijagbara ilẹ Yoruba"" pe o fẹsun kan pe gbogbo ohun tawọn afurasi Sọja naa n ṣe ni atilẹyin ijọba apapọ eyi to jẹ nitori ọrọ rẹ to sọ pe iran Yoruba kii ṣe ara orilẹede Naijiria mọ."
Oríṣun àwòrán, Nigerian Defence Headquartres
Oríṣun àwòrán, Nigerian Defence Headquartres
Ẹwẹ, atẹjade naa sọ pe ileeṣẹ ologun ko raye biba Sunday Igboho tabi awọn isọngbe rẹ ṣe fa ki n fa ọrọ kankan ṣugbọn o kan ṣe pataki lati jẹ ki awọn eeyan mọ iha ti awọn kọ si iṣẹlẹ yii gangan.
Adele oludari ileeṣẹ ogun naa ni awọn fẹ fi hande pe ileeṣẹ ogun Naijiria mọ iṣẹ wọn de oju ami pẹlu oniruuru ipo to yẹ lati ri i pe aabo to daju wa ni orilẹede Naijiria tori naa ikọ ologun ko lee fi ara wọn wọlẹ
de bi pe iru Sunday Igboho to jẹ afurasi kaakiri ilu.
"Bakan naa wọn jẹ ko di mimọ pe ileeṣẹ ologun ni ofin ti wọn n tẹle ninu ṣiṣe iṣẹ wọn ati to n tọ awọn oṣiṣẹ wọn sọna ""torinaa ko ṣeeṣe ki ọmọ ogun to wa lẹnu iṣẹ to yẹ ki wọn maa ṣe lati hu iru iwa ti Sunday Igboho atawọn eeyan rẹ n fẹsun kan pe wọn hu""."
"Fun idi eyi ni ileeṣẹ ologun ṣe ni ""ki alaye wa lee ye yin daadaa lori ọrọ yii lai ṣe iyemeji, ""ibẹrẹ iwadi taa ṣe fihan pe ọkan lara afurasi sọja naa kii ṣe ọmọ ogun Naijiria, o kan dibọn bii ologun ni""."
Ẹwẹ, wọn ni oṣoju mi koro ti awọn nigbagbọ ninu ẹ ti tu aṣiri fawọn pe awọn isọngbe Sunday Igboho gbá tẹle awọn kan lẹyin nigba ti ọkada to gbe ẹni to n dibọn ọhun ati ologun kan kọlu wọn.
"Lẹsẹkẹsẹ ni wọn mu awọn mejeeji ti wọn si ko wọn lọ si ""ile ti wọn pe ni ti sunday Igboho"" ni Soka ṣaaju Toll gate Ibadan, nibẹ si ni wọn ti fi orukọ awn to n ṣe alami pe wọn""."
Awọn ologun ni iwadii ṣi n tẹsiwaju labẹ akoso ileeṣẹ ogun oriilẹ ati ti oju ofurufu lati tu aṣiri ohun to ṣẹlẹ gangan lọjọ naa.
Ni wọn ba fi ikilọ sita pe ki awọn eeyan tabi ẹgbẹ jawọ ninu tita epo si aṣọ ala ileeṣẹ ologun Naijiria nipa wiwọ wọn lọna kan tabi omiran sinu awọn ọrọ pẹpẹpẹ ti ko kan wọn tori irinajo oṣelu ti wọn tori awọn ko ni fi aaye gba iru iwa bẹẹ rara ati rara. Bakan naa, wọn ni ẹnikẹni lee pin iroyin ti a kọ yii kaakiri awọn oju opo ayelujara wọn ki gbogbo agbaye le mọ.
Sunday Igboho: Mi ò lè ṣe àkọlù sí bàbá mi Alake nítorí wọ́n jẹ́ ọ̀kan nínú àwọn èèyan tí a kò fọwọ́ rọ́ sẹ́yìn nílẹ̀ Yoruba
Oríṣun àwòrán, @TheReal_Hafeez
"Gbajugbaja ajafẹtọ ilẹ Yoruba, Oloye Sunday Adeyẹmọ, ti gbogbo eeyan mọ si ""Sunday Igboho"" ti ṣalaye pe oun ko le ri awọn agbaagba fin, ki a tọ sọ pe awọn Ọba alade nilẹ Yoruba."
Ọrọ yii ni ẹsi ti Igboho fọ lori ẹsun ti awọn eeyan kan fi kan an wi pe o n gbero lati ṣe ikọlu si aafin Alake nilu Abẹokuta.
O ni ki ẹnikẹni ma ṣe ṣi oun gbọ nitori ko si ninu aṣa oun lati maa ri awọn agbalagba ati Ọba alade ilẹ Yoruba fin, nitori a ko gbudọ fi ọwọ yẹpẹrẹ mu aṣa ilẹ wa.
"Ninu atẹjade to fi ranṣẹ si awọn oniroyin lati ọwọ alamọran rẹ lori iroyin, Dapo Salami, Igboho ni, ""Emi Sunday Igboho, mi o le ri awọn agbaagba ati Ọba ilẹ Yoruba fin."""
Oríṣun àwòrán, @TheNationNews
Baba ni Alake jẹ si mi, o si jẹ ẹnikan ti mo bu iyi fun gan an. Mi o le ṣe ikọlu si baba mi nitori wọn jẹ ọkan ninu awọn eeyan ti a ko le fi ọwọ rọ sẹyin ninu ẹya Yoruba.
Mo si mọ wi pe baba naa yoo ṣe atilẹyin fun wa lati de ibi ilepa wa.
Atẹjade naa ṣalaye ni kikun pe ko si otitọ kankan ninu ẹsun ti wọn fi kan oun wi pe Igboho n gbero lati ṣe ikọlu si aafin Alake ti ilẹ Ẹgba, Ọba Adedọtun Arẹmu Gbadebọ.
Sunday Igboho rọ gbogbo eeyan lati kọ eti ọgbọin si awọn iroyin to n tọka rẹ wi pe oun n gbero lati ri agbalagba kan tabi Ọba alade fin, nitori ifojusun gbogbo ilẹ Yoruba ni lati da duro.
Omi iké kan, l'èèyàn kan lè mu f'ọ́jọ́ mẹ́ta láì ro ti ekòló inú rẹ̀ - Ìlú Elega, Kwara
Oríṣun àwòrán, Alake of Egba land
Alake ti ilẹ Egba, Oba Adedokun Aremu Gbadebo Okukenu kẹrin ti fi ọrọ lede pe ohun ti awọn iwe iroyin kan to lorukọ lorilẹede Naijiria n gbe nipa iha ti oun kọ si Sunday Igboho lori ọrọ Oduduwa Republic ko ri bi wọn ṣe n kọ ọ rara.
Ninu atẹjade kan ti agbẹnusọ fun Kabiyesi fi sita, Oloye Zents Kunle Sowumi to jẹ Baba Tayese ti ilẹ Egba ṣalaye pe awọn iwe iroyin kan n kọ iroyin kiri pe lasiko ti ẹgbẹ awọn awakọ Naijiria, NTREAN ṣe abẹwo si aafin Ake ni Abeokuta ni oun kẹnu ọrọ si ajafẹtọ ilẹ Yoruba, Sunday igboho lori ọna ti iran n tọ bayii.
Kabiyesi n fẹ lati fi to gbogbo eeyan leti wipe iru ọrọ bayii ko jẹ jade rara nigba ti NTREAN wa bẹ afin mi wo mo si fẹ ki gbogbo ara Egba ati ilẹ Yoruba kọ eti ikun si iru iroyin bayii eyi tawọn iwe iroyin Punch,  Sahara Reporters atawọn mii n gbe.
Kabiyesi ni iṣẹ̀ awọn ọta Egba leyii lori ohun to jẹ pe awọn baba nla baba wọn gan duro fun latayedaye nigba ti Lisabi Agbogbo Akala ja fitafita lati gba ilẹ Egba lọwọ ijọba Oyo.
"Atẹjade naa ni ""bi Kabiyesi ba tilẹ wa fẹ sọrọ si iru nkan to ṣe pataki si imọlara awọn eeyan rẹ, kii ṣe ni iru apejọpọ pẹlu ẹgbẹ awọn awakọ ni yoo ti sọ ọ""."
Oríṣun àwòrán, Zents Oyekunle Sowumi
O ni Kabiyesi yoo kọkọ tọ awọn igbimọ alaṣẹ ilẹ Egba lọ, awọn Ogboni to fi mọ awọn oriṣa atawọn alalẹ ilẹ gbogbo ni ilana aṣa ilẹ Egba ko to ṣe iru nkan bẹẹ.
Alake ti Egba wa n rọ gbogbo ara Egba nile ati lẹ́yìn odi pe ki wọn mọ ọmọ ẹni ti wọn n ṣe paapaa nipa pe ki wọn ma gbagbe itan wọn ki wọn si kọ eti ọgbọin si awọn alahesọ tabi ileeṣẹ iroyin to ba ri Ọba Alake ti ilẹ Egba fin lọna ti wọn n gba kọ iroyin wọn.
Taooma: Ìbáṣepọ̀ mi pẹ̀lú àwọn òbí mi yàtọ̀ sí bí mó ṣé n polongo nínú fídíò mi
Sunday Igboho: ''Ẹ ó ríjà oba, tí ẹ bá gbìyànjú láti fọ́wọ́ kan Sunday Igboho''
Oríṣun àwòrán, Instagram/Sunday Igboho
Ajijagbara ilẹ Yoruba, Ọgbẹni Sunday Adeyemo ti ọpọ mọ si Sunday Igboho tun ti kilọ fawọn to ba n gbero lati mu un.
Nigba ti Igboho ṣe abẹwo si Oba ilu Oke-Iho lagbegbe Oke Ogun nipinlẹ Oyo, Oba Rafiu Osuolale Mustapha,  Igboho sọ pe Alaafin Oyo, Oba Lamidi Olayiwola Adeyemi duro gbọin-gbọin lẹyin ohun.
Igboho sọ ninu fido kan to fi sori Facebook pe ''nigba tawọn ijọba Naijiria lọ ba Alaafin wi pe ko fa Sunday Igboho le wọn lọwọ, o ni ko ṣeeṣe bẹẹ.
Alaafin ni Sunday Igboho ti ẹ n wo yẹn, mẹwaa ni, eleyi ti ẹ n ri yẹn to n kaakiri kii ṣe Sunday Igboho tori pe oun mọ an dele dele.
Nitoripe awọn baba toun atawọn baba tiẹ jọ ṣe pọ ni.
Ti ẹ ba si gbiyanju lati fọwọ kan Sunday Igboho, igba naa lẹ o rija ọba, Alaafin lo sọ bẹẹ.
Alaafin lo kọkọ kọ lẹta si Buhari pe o to gẹẹ nipa ọrọ awọn Fulani nipinlẹ Oyo,'' Igboho lo sọ bẹẹ.
Sunday Igboho ko ṣai sọ fun Oba Mustapha pe oun ṣetan lati le awọn Fulani kuro lori ilẹ Oke-Iho ti Kabiyesi ba fẹ bẹẹ.
Igboho tun sọ fun Kabiyesi nipa erongba rẹ lori bi iran Yoruba yoo ti yapa kuro lara Naijiria.
Ajijagbara Igboho ni yiyapa iran Yoruba kuro lara Naijiria ti ṣeeṣe na.
Ninu ọrọ tirẹ, Oba Mustapha Adeitan Keji gbadura pe fun Igboho pe didaduro iran Yoruba yoo ṣeeṣe.
Herdsmen Crisis: A kò ní f'ayé gbà darandaran tí kò bá forúkọsílẹ̀ láàrin ọsẹ̀ méjì l'Ekiti
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Awon ọmọ ẹgbẹ Ekitiparapo ni ipinlẹ Eko ati ẹgbẹ Ekitipanupo ti wọn jẹ meji laarin gbajumọ ẹgbẹ fun ọmọ Ekiti nilu okeere tí sọ wipe ki Gomina Kayode Fayemi sọra lori ọrọ awon daandaran pẹlu titẹwọ gba eto sisin ẹranko ti ijọba apapọ ṣeto, iyẹn National Livestock Transformation Programme.
Awon oludari fun awọn ọmọ Ekiti nilu okeere sọrọ yii lẹyin ti BBC News Yoruba kọ iroyin wipe ijọba ipinlẹ Ekiti fi ikilọ sita fawọn darandaran ati agbẹ ni ipinlẹ naa lati forukọsilẹ laarin ọsẹ mẹji bi bẹẹ kọ oju ọdaran lawọn yoo fi wo wọn.
Iroyin ọhun sọ wipe ijoba Ekiti ṣalaye eto iforukọsilẹ bi oṣe ṣe pataki ki awọn baa le mọ onka awọn agbẹ ati darandaran.
Kí ló wá nínú àbádòfin pínpín omi àti àwọn ǹkan inú omi tó ń mú awuyewuye wa?
CAN: Samson ni ọrọ awọn ajinigbe ti gba àpérò ní Naijiria
Ninu atẹjade ti Aarẹ Ekitiparapo Lagos, Dare Ojo ati Olori awọn Ekitipanupo Roundtable Initiative, Alagba Gabriel Akinyemi fun awọn ọmọ Ekiti to wa nilu okeere sọ wipe igbesẹ naa jẹ ohun ifiyesi lori itewọgba eto naa lati ọwọ ipinle ọhun jẹ ohun iyalẹnu lati fi ilẹ fun awọn darandaran fun jijẹko.
"Atẹjade naa tun sọ wipe ""A ṣe akiyesi pe Ijọpa apapọ ni ọdun meji sẹyin ti ṣe agbekalẹ RUGA, eyiti o tun wa ni orukọ iyipada si National Livestock Transformation Programme pẹlu awọn ete kan naa fun pipin ilẹ fun awọn darandaran latara idii jijẹ ati ibugbe""."
"Ojó ati Akinyemi sọ pe: ""Nitori abajade jijẹ ti ailaabo nipasẹ awọn darandaran ni ipinlẹ naa, o jẹ aibalẹ ọkan pe ijọba ipinlẹ naa le ronu awọn darandaran ibi ipamọ ọja ni ipinlẹ naa."
A o ranti wipe, ni ọjọ kẹrindinlọgbọn osu kinni, iroyin jade pe awọn darandaran run oko ọgbọn miliọnu 235 ti ọpọlọpọ miliọnu Naira ti o jẹ ti awọn ọmọ ẹgbẹ ti agbado awọn alagbata ati awọn onija ọja.
Ba kan naa, ni ọjọ kẹrindinlogun, oṣu kinni, awọn darandaran  pa alaboyun kan ni Ijọba agbegbe Ido / Osi; awọn darandaran pa awọn agbẹ meji ni oṣu Kẹta ọjọ keje ni Isaba-Ekiti.
"Atẹjade naa tun sọ wipe, ""iku miiran ni igbasilẹ to waye ni opopona Ikere- Iju ni oṣu kẹta ọjọ kẹtala, laarin ọpọlọpọ awọn iṣẹlẹ miiran. Awọn opopona ti o so Aramoko si Ijero, Ikere si Iju ati awọn ipade Ita-Ore ti di awọn ibi ole jija bayii. O ni ""ọpọlọpọ awọn eniyan ko le wa si ile nitori iberu awọn ajinigbe""."
Ijọba ipinlẹ Ekiti ti fi ikilọ sita fawọn darandaran ati agbẹ ni ipinlẹ naa lati forukọsilẹ laarin ọsẹ mẹji  bi bẹẹ kọ oju ọdaran lawọn yoo fi wo wọn.
Ikilọ yi n waye lẹyin ti gbedeke ọsẹ meji ti wọn ṣaaju fun wọn tẹlẹ dopin.
Anfaani ọsẹ meji tuntun yi yoo bẹrẹ lati ọjọ Aje,ọjọ kejilelogun oṣu Kẹta.
Kọmisana feto iṣẹ agbẹ ati ipese ounjẹ Olabode Adetoyi ninu atẹjade to fi sita ni Ekiti sọ pe eto iforukọsilẹ yi di dandan kawọn baa le mọ ounka awọn agbẹ ati darandaran.
Bakan naa lo ni awọn n seto yi ki alaafia baa le jọba laarin awọn ikọ agbe ati darandaran lọna ti mu opin ba ija lemọlemọ to n waye laarin wọn.
O ni eleyi  si tun wa ni ibamu pẹlu eto ayipada iṣẹ sisisn ẹranko tiijọba apapọ ṣeto, iyẹn National Livestock Transformation Programme.
Oríṣun àwòrán, Kayode Fayemi/Facebook
Oluranlọwọ pataki si Gomina Kayode Fayemi lori ọrọ aabo,Ọgagun Ebenezer Ogundana, to si tun jẹ alaga igbimọ ipẹtusaawọ agbẹ ati darandaran naa tẹnu bọrọ yi.
Ninu atẹjade to fi sita , o ni ẹnikẹni ti ko ba forukọsilẹ oju ọdaran lawọn yoo fi wo.
O ni irufẹ awọn eeyan bẹ, awọn yoo paṣẹ fun wọn lati fi ipinlẹ awọn silẹ ni.
Lakotan, adari ileeṣẹ iyipada ati atunto  ọjọgbọn Mobolaji Aluko sọ fun ileesẹ iroyin NAN pe ọfẹ lawọn yoo pin kaadi idanimọ fawọn agbẹ ati darandaranto ba forukọ silẹ.
Sunday Ighoho kéde àwọn ọ̀daràn Fulani mẹ́ta tó ṣàkọlù sílé ìyá rẹ̀, ọwọ́ tẹ ọ̀kan, méjì na pápá bora
Oríṣun àwòrán, @247NNU
Gbajugbaja ajijagbara, Sunday Adeyemo, ti ọpọ mọ si Sunday Igboho ti kede pe awọn ọdaran Fulani mẹta kan ti ṣakọlu sile iya oun to wa niluu Igboho, nipinlẹ Oyo.
Igboho ni ọwọ tẹ ọkan lara awọn afurasi naa, wọn si ti faa le ileeṣẹ ọlọpaa lọwọ, nigba ti awọn meji to ku na papa bora.
Nigba ti BBC Yoruba kan si alukoro ileeṣẹ ọlọpaa ipinlẹ Oyo, Olugbenga Fadeyi, o ni lootọ ni afura kan ti wa ni ahamọ awọn, iwadii si ti bẹrẹ lati mọ okodoro iṣẹlẹ ọhun.
Ẹwẹ, minisita ileeṣẹ to n ri si eto irinna ọkọ ofurufu tẹlẹri, ti awọn eeyan tun n wo gẹgẹ bii alatilẹyin Sunday Igboho, Femi Fani-Kayode naa tun kede ọrọ naa loju opo Twitter rẹ.
"O ni ""mo ṣẹṣẹ ba Sunday Igboho sọrọ tan ni, o si sọ fun mi pe ọwọ tẹ awọn Fulani meji to jẹ ọmọ ilẹ okeere nile iya oun to wa ni Igboho, nipinlẹ Oyo."""
Afojusun awọn Fulani naa ni lati ṣakọlu si iya agba ọhun, ọkan ninu wọn sa asala ṣugbọn ẹnikeji rẹ ti wa ni gbaga ọlọpaa.
Lẹyin naa lo fi oju afurasi naa lede loju opo ọhun.
Ṣaaju ni agbẹnusọ fun Ighoho, Olayomi Koiki ti kọkọ kede iroyin naa, to si sọ pe iṣẹlẹ ọhun waye ni nnkan bii aago mẹjọ alẹ ku iṣẹju diẹ.
Omi iké kan, l'èèyàn kan lè mu f'ọ́jọ́ mẹ́ta láì ro ti ekòló inú rẹ̀ - Ìlú Elega, Kwara
Ti ẹ ko ba gbabgbe, Sunday Igboho ati awọn ẹmẹwa rẹ ti kọkọ kede pe awọn mu awọn eeyan meji kan, ti ọkan jẹ ọmọ ogun, to si fẹsun kan awọn eeyan naa ope wọn wa ṣe ami oun.
Ṣugbọn ko pẹ si asiko naa ti ileeṣẹ ologun fesi pe eni tim wọn mu ninu aṣọ ṣọja kii ṣe oṣiṣẹ ileeṣẹ ọmọ ogun.
Bed Wetting: Tolulope Joseph ní ò lé ní ogún ọdún tí òun fi tọ̀ sílé kí ìwòsàn tó dé
Ibarapa: Àwọn ọ̀dọ́ ṣe ìwọ́de lọọọ́físì Seyi Makinde lẹ́yìn tí ọlọ́pàá ti àwọn ọmọ ẹgbẹ́ OPC tó mú Wakili mọ́lé
Awọn ọdọ kan ti ya bo ọọfisi ijọba ipinlẹ Oyo to wa ni Agodi, niluu Ibadan, lati fi aidunu wọn lede nitori ipaniyan to n waye nipinlẹ ọhun, paapaa lagbegbe Ibarapa, Oke-Ogun atawọn agbegbe miran.
Bẹẹ ni awọn ọdọ ọhun tun n ṣefẹhonuhan lodi si bi ileeṣẹ ọlọpaa ipinlẹ Oyo ṣe ti awọn ọmọ ẹgbẹ OPC mẹta kan mọle lẹyin ti ile ẹjọ kan paṣẹ pe ki wọn ṣe bẹẹ.
Awọn ọmọ ẹgbẹ OPC naa wa lara awọn ikọ to fi panpẹ ọba mu Iskilu Wakili, ti wọn fẹsun kan pe o n ṣagbatẹru ijinigbe ati ipaniyan niluu Ibarapa.
Ṣaaju ni ileeṣẹ ọlọpaa ipinlẹ Oyo ti kọkọ ti awọn ọmọ ẹgbẹ OPC naa mọle, ti wọn si fi ẹsun ipaniyan ati didana sun dukia lọna aitọ kan wọn, ki wọn to ni ki wọn logba diẹ ninu ọgba ẹwọn ki iwadii le tẹsiwaju.
Awọn olufẹhonuhan ọhun, ti ọpọ ninu wọn wa lati Ibarapa ya bo ọọfii ijọba ọhun, ti wọn si n kọrin pe ko si abo kankan fun awọn eeyan awọn pẹlu oriṣiriṣi akọle lọwọ.
Ọkan lara awọn to ṣagbatẹru iwọde na, Oladiran Oladokun sọ fun awọn akọrọrin pe bi awọn ọlọpaa ṣe ti awọn ọmọ ẹgbẹ OPC naa mọle n ṣafihan pe awọn ọlọpaa ko nilo iranlọwọ awọn eeyan ilu lati mu awọn ọdaran lawujọ.
Omi iké kan, l'èèyàn kan lè mu f'ọ́jọ́ mẹ́ta láì ro ti ekòló inú rẹ̀ - Ìlú Elega, Kwara
Oladokun ṣalaye pe Wakili da awọn eyan Ibarapa laamu pupọ, bo tilẹ jẹ pe awọn ọlọpaa kọ lati mu, awọn ọlọpaa ọhun tun n fiya jẹ awọn ọmọ ẹgbẹ OPC to mu afurasi naa.
"Gẹgẹ bo ṣe sọ, ""a wa nibi lati ṣe ifẹhonuhan lodi si bi awọn awọn agbofinro ṣe mu awọn ọmọ ẹgbẹ OPC mẹta to mu Wakili to n da agbegbe Kajola, Ayete atawọn agbegbe miran laamu,ti wọn si tun ti wọn mọle."""
Won Ṣawari Wakili, wọn si fi panpẹ ofin mu, ṣugbọn awọn ọlọpaa ti wọn mọle, eyii jẹ ohun to buru jai, to tun n ṣafihan fun awọn eeyan ilu pe ko yẹ ki wọn maa ran ileeṣẹ ọlọpaa lọwọ lati mu awọn ọdaran.
Bed Wetting: Tolulope Joseph ní ò lé ní ogún ọdún tí òun fi tọ̀ sílé kí ìwòsàn tó dé
UITH Mortuary Announcement: Ìyàtọ̀ tó wà láàrín òkú Mọ́ṣúárì aládàáni àti ti ìjọba rèé - Òṣìṣẹ́ Mọ́ṣúárì
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Oludari ni Ile iṣẹ igbokupamọsi aladani kan ni ipinlẹ Eko ti ni iwa ki awọn eeyan maa pa oku ti si Mọṣuari ko wọpọ ni ọdọ awọn bii ti ijọba.
Eyi waye lẹyin ti ile igbokupamọsi ti Fasiti ilu Ilorin fi ikede kan sita pe awọn ko ri aye gbe oku tuntun si mọ torinaa ki awọn to ti gbe oku sibẹ fun ọjọ pipẹ wa gbe oku wọn kuro.
BBC Yoruba kan si ọkan lara awọn ọga ileeṣẹ igbokupamọsi ti aladani kan ni ilu Eko, Ọgbẹni Deinde Harrison to n ṣiṣẹ pẹlu Ebony Funerals ni awọn o ki n kọ oku kankan niwọn igba ti owo ba ti n wọle.
Bo tilẹ jẹ pe nigba miran ti aaye ba kun, a o sọ fun ẹbi naa pe ko saye mọ ṣugbọn awọn eeyan kii wa pa oku ti si ọdọ tiwa bii ti Mọṣuari ijọba.
O ni awọn eeyan gbudọ kọkọ san asan silẹ owo na, to ba si wa di pe owo naa ti fẹ tan, wọn a pe wọn lati wa fi kun owo wọn.
Lootọ gbogbo Mọṣuari lo ni iye aye ti wn n lo fi gbe oku si bi aye naa ba si ti kun, ko si ṣiṣe afi ki wọn kọ oku ti wọn ba gbe wa.
"Kódà wọ́n lè fí òkú sílẹ̀, kí owó ṣáa ti máa wọle bi wọn ba ti n san owo itọju, awọn lo maa sọ asiko ti wọn fẹ wa gbe oku wọn.
Ọgbẹni Deinde ṣalaye pe ni ọpọ igba awọn to ba gbe oku lọ si Mọṣuari ijọba maa n foju wo o pe ṣebi ti ijọba ni.
Awọn oku mii ti wọn kan ri he ni titi tabi ti ẹjọ wa lori ẹ le wa nibẹ fun odidi oṣu mẹfa, idi ti ẹlomiran fi n ṣe bẹẹ le jẹ ọrọ owo to bẹẹ to jẹ pe awọn gan o tii ri owo jẹun, wọn a kan pa oku naa ti sibẹ ni""."
Eyi ati ọpọlọpọ idi ni Ọgbẹni Deinde ni o wọpọ ni awọn ile igbokupamọsi ti ijọba to bẹẹ to jẹ wipe awọn eeyan mii o tilẹ ni yọju mọ tori awọn to gbe wọn wa o ki n ṣe mọlẹbi wọn.
"Wo àwọn ọ̀rọ̀ tó ki pọ́pọ́ tí Lateef Adedimeji fi kọrin ọjọ́ ìbí 23 fún Adebimpe Oyebade ""Onítèmi"""
Sùkẹ̀! Ọ̀rọ̀ òṣèlú ni gbogbo ẹ tí Akeredolu ṣe tako ìdásílẹ̀ Oduduwa Nation - Banji Akintoye
Ẹ̀yà Yorùbá ti fara ṣiṣẹ́ púpọ̀ fún Naijiria, nítorí nàá à kò le déèdé sọ pé a fẹ́ kúrò - Àgbààgbà Yorùbá
Deinde ṣalaye wipe wọn gbudọ fi kẹmika rọ ọ lara daadaa bi wọn ba ti gbe e wa yala ni ti ijọba ni o tabi ti aladani.
"Bi wọn ba embalm"" oku lai sanwo, o kan maa wa nibẹ lasan ni fun ọjọ pipẹ, awọn to ni Mọṣuari ni yoo pofo tori ojoojumọ ni wọn nilo ina lati ma jẹ ki oku bajẹ""."
Bakan naa o ni awọn to n ṣiṣẹ ni Mọṣuari yoo ṣaa gba owo, bo tilẹ jẹ ti ijọba, o ni owo naa ni wọn fi ṣe atunṣe ibẹ.
Oku o gbudọ 'decompose'  ko gbudọ bajẹ to ba tile bajẹ, awọn oloku naa lo maa fẹ gbe wọn lọ ile ẹjọ tabi fa wahala.
Ọgbẹni Deinde ni kii ṣe pe o wu awọn Moṣuari naa lati ni ẹbi lara o ṣugbọn owo ni wọn fi n ṣe gbogbo iṣẹ nibẹ.
Koda o ni ninu oku marun ti wọn ba gbe wa nibẹ, ọfẹ lawọn n gba ẹyọkan nibẹ.
Ẹwẹ, iye owo ti Deinde ni ọpọ ile igbokupamọsi aladani n gba fun ọjọ kan jẹ ẹgbẹrun kan eyi to si jẹ pe ti ijọba kere jọjọ si tiwọn.
Àwọn ọ̀rọ̀ Yorùbá kan wà tí ẹ kò lè lò pọ̀ mọ́ ara wọn, àwn ọ̀rọ̀ tẹ́ẹ lè fi rọ́pò rèé
Oba Tajudeen Omotayo ti Imope gbà ìtúsíẹ̀ lọ́dọ̀ ajínigbé amò wọ́n gba owó wọ́n tún fìyà jẹ ẹ́
Oríṣun àwòrán, Oba Tajudeen Omotayo
Kabiyesi Ọba Tajudeen Omotayo, ori ade ti ilu Imope ti gba itusilẹ lọdọ awọn ajinigbe ṣugbọn ko ba ọfẹ de.
Olori Omotayo Adesola iyawo Kabiyesi to fidi ọrọ yi mulẹ fun ileeṣe BBC sọ pe lalẹ ọjọ Iṣegun ni Kabiyesi de ati pe awọn san owo idoola ẹmi.
Ninu alaye ti wọn ṣe olori ni lootọ ni Kabiyesi gba itusilẹ ṣugbọn awọn ajinigbe yi fi iya jẹ wọn ki wọn to tu wọn silẹ.
Yatọ si iya ti wọn fi jẹ Kabiyesi  o ni wọn tun bere owo idoola ọgọrun miliọnu Naira lọwọ awọn amọ gbogbo ohun tawọn ri ko jọ ni wọn gba.
''Wahala wa o, Kabiyesi o le da rin bi wọn ṣe de. Wọn na wọn gaan koda ile iwosan ni wọn wa bayi''
O fi kun pe owo tawọn ṣa jọ pada pe perepere ki awọn ajinigbe naa to pada tu Kabiyesi silẹ
''Wọn gba owo lọ. Wọn gba owo naa to pe. Wọn gba owo lọ''
Lati ọjọ Abamẹta  to kọja lawọn ajinigbepawo ti gbe Kabiyesi ti wọn si ni ki mọlẹbi wọn mu igba miliọnu Naira wa.
Lẹyin idunadura wọn ni ki wọn mu ọgọrun miliọnu Naira wa.
Ọlọpaa lawọn ko mọ si boya mọlẹbi san owo idoola fun ajinigbe
Agbẹnusọ ileeṣẹ ọlọpaa nipinlẹ Ogun arakunrin Abimbola Oyeyemi  sọ pe lootọ ni wọn tu Kabiyesi silẹ ati pe awọn lawọn ṣe to itusilẹ rẹ.
Oyeyemi ni ọga ọlọpaa iyẹn Kọmisana ipinlẹ Ogun fun ara rẹ ko dakẹ lori itusilẹ Oba ki wọn to pada gba idande.
Nigba ti BBC beere boya awọn ọlọpaa doju ija kọ awọn ajinigbe naa ni ki wọn to tu Kabiyesi silẹ, o ni ''a ko le tu aṣiri baa ti ṣe n ṣiṣẹ wa''.
Bakan naa lo sọ pe ohun ko le dahun si ibeere nipa boya awọn ajinigbe naa gba owo lọdọ mọlẹbi Kabiyesi.
O ni ohun to ṣe pataki ni pe awọn ti doola ẹmi ẹni ti wọn jigbe ati pe iṣẹ ṣi ku tawọn yoo ṣe lẹyin igba yi.
''Nitori pe a ti ribi doola ẹni ti wọn jigbe ko tunmọ si pe a ko ni ṣapa lati wa awọn to hu iwa yii.''
''Arọwa wa si awọn mọlẹbi kàn ni pe ki wọn ma ṣe san owo idoola fawọn ọdaran wọnyii mọ''.
Penis size by Dr Shanna Swan: Kí ló ń fa kí ǹkan ọmọkùnrin yorò?
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Onimọ Sayẹnsi nipa ọrọ ayika ti fi hande pe nkan ọmọ ọkunrin eeyan maa n yoro ti awọn agbegbe rẹ ko si ni ṣara jọ nitori ti ayika eeyan.
"Dokita Shanna Swan sọ ninu iwe tuntun rẹ to kọ ti akọle rẹ n jẹ ""Count Down"" sọ pe ọmọ eniyan n doju kọ iṣoro iloyun ati ibimọ latari kẹmika kan ti wọn n pe ni ""phthalates"" to n fa ki wọn bi ọmọ ikoko pẹlu nkan kunrin tabi obinrin ti ko ṣara jọ daadaa."
Ninu iwe naa, arabinrin Shanna ṣagbeyẹwo bi wọn ṣe n fi ọwọ yẹpẹrẹ mu iye atọ ọmọkunrin to n jade eyi to maa ṣakoba fun idagbasoke ilana ibimọ ọkunrin ati obinrin to si n ko ọjọ iwaju sinu ewu.
Latari idọti ayika nkan ọmọkunrin tabi obinrin yii, awọn ọmọ ti wọn n bi ti nkan ọmọkunrin wọn kere ti n pọ sii.
'Èmi àti ìyàwó mi ti ń gbé pọ̀ nínú ìgbéyàwó wa fún 60 years', ẹ wá kọ́ ẹ̀kọ́ lẹ́nu àgbà méjì
Bí Oduduwa Republic bá bẹ̀rẹ̀, a ò ní ṣe aburú fún àwọn tó takò wá, ìlànà ààtẹ̀lé rèé - Banji Akintoye
Iwadi Dokita Swan fihan gẹgẹ bi wọn ṣe fi awọn ekute ṣe ayẹwo kẹmika phthalate ọhun ti wọn si rii pe nigba ti wọn fi ṣi ara ọmọ oyun inu wọn si kẹmika naa, o da bii pe wọn yoo bi awọn ọmọ naa pẹlu nkan ọmọ ọkunrin konkolo.
O wadii pe awọn ikoko ọkunrin ti ara wọn ba ni nkan ṣe pẹlu phthalates ninu oyun maa n ni awọn nkan to rọ mọ nkan ọmọkunrin kukuru.
Kẹmika naa ni iṣẹ to n ṣe ni awọn ileeṣẹ ti wọn fi n mu ki ike rọba fẹlẹ sii ṣugbọn Dokita Swan ni awọn kẹmika naa ti n wọ inu awọn nkan iṣere ati ounjẹ to si n ṣakoba fun idagbasoke eeyan.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Phthalates jẹ akojọpọ awọn kẹmika ti wọn fi ṣe nkan elo pupọ bii iṣere ọmọde, nkan ti wọn n lẹ mọlẹ, lẹ m ogiri, ọṣẹ, ọili, nkan iko ounjẹ si, awn nkan ilera, apo ẹjẹ ati bẹẹ bẹẹ lọ.
Wọn maa n lo o ninu awọn oun elo aṣaraloge bii kẹmika ti wọn fi n nu eekana, iparun, ipa abiya lẹ́yìn fifa irun ibẹ, ọṣẹ iwẹ, ọṣẹ ifọrun, lọfinda ati bẹẹ lọ.
Wọn maa n lo o lati mu polyvinyl chloride, iyẹn ike rọba ti wọn si tun nlo bii amu nkan yọ ninu awọn ipara.
Ninu akọsilẹ iwe kan ti awọn onimọ Sayẹnsi tun fi si ori ayelujara  Medical news website, wọn ṣalaye awọn idi mii to fi le mu nkan ọmọ ọkunrin kere sii.
Báa ṣe lọ́pọlọ tó, ẹnu Yorùbá ò kò, ọgbọ́n táa gbúdọ̀ dá rèé - Ìpàdé àgbààgbà Yorùbá n'Ibadan
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ki nkan ọmọkunrin maa kere wọpọ paapaa bi awọn ọkunrin ba ṣe n dagba si ṣugbọn awọn idi mii naa wa to le fi yoro.
Bi ọkunrin ba ṣe n dagba sii, awọn nkan ọlọra to wa ninu ara wn a maa ṣa ara jọ ninu awọn nkan to maa n pin ẹjẹ kaakiri ara yoo si mu ki eyi dinku.
eleyi maa mu ki awọn sẹẹli iṣan ara to wa nibi ohun to n mu nkan ọmọ ọkunrin le bẹrẹ si ni ṣaarẹ. Awọn tuubu to n mu nkan ọmọkunrin le maa ṣiṣẹ karakara ti ẹjẹ ba n wọ ibẹ daadaa torinaa bi ẹjẹ naa ba ti dinku, o tumọ si pe nkan ọkunrin naa ko ni maa fibẹẹ le ni gbogbo igba.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ipa ti sisanra n ko paapaa ni agbegbe ikùn jẹ pabanbari fun ọpọlọpọ awọn ọkunrin bi wọn ba ṣe n dagba.
Bo til jẹ pe nkan ọmọkunrin le fara han bii kekere nitori sisanra, amọ o le ma yoro. idi ti yoo fi jọ pe o kere ni pe ara ogiri ikun ni ibẹrẹ nkan ọmọkunrin wa bi ikun ba si ti n tobi sii, yoo fa nkan ọmọkunrin naa sinu. Bi eeyan ba wa jo lara, nkan ọmọkunrin rẹ yoo pada bọ sipo ati bo ṣe tobi si tẹlẹ.
Iwadii kan ninu Journal of Impotence Research fihan pe bi ọkunrin ba ni aisan jẹjẹrẹ abẹ, ti wọn si fẹ ṣe iṣẹ abẹ eyi ti wọn n pe ni radical prostatectomy, o lee ni iriri ki nkan ọmọkunrin rẹ kere
Awọn oogun kan wa to lee fa ki nkan ọmọkunrin kere. Awọn oogun bii Adderall ti wọn maa n lo fun ẹni ti iṣe féfé rẹ ba ti kọja ala, bakan naa awọn oogun to n wo iporuru ọkan san, oogun to n wo arun ọpọlọ san atawọn oogun mii ti dokita ba pe fun itọju abẹ wiwu.
Ni ọdun 1998, fasiti oniṣegun ti Boston ṣe ayẹwo nkan awọn ọkunrin igba to dide duro tandi. Abajade ayẹwo naa fihan pe, awọn to n mu siga, ti nkan ọmọkunrin wọn ba dide, o maa n kuru ju ti ẹni ti ko mu siga lọ.
Idi si ni pe kẹmika to n jade lasiko ti wọn ba n fa siga simu lee ṣe ọna ti ẹjọ n gba lọ inu nkan ọmọ ọkunrin leṣe. O si lee dena ki ẹjẹ kun inu nkan ọmọkunrin naa eyi ti yoo fi dide.
Lai wo ti miu ara ya ati ipa to n ko ninu ọpọlọ, bi ohun to n pin ẹjẹ kiri ba ti bajẹ, nkan ọmọkunrin ko le duro ko si ni le tandi.
Leah Sharibu bímọ kò bímọ, òhun tí ìwádìí fihàn rèé nipa akẹ́kọ̀ọ́ Dapchi táwọn agbébọn jígbé
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Leah Sharibu ti bimọ mii lahamọ to wa?
O da wa loju pe ibeere yi lo wa lọkan yi nipa akẹkọọ ileewe Dapchi tawọn Boko Haram ji gbe lati oṣu Keji ọdun 2018.
Lori iroyin to gbode yi, BBC kan si baba to bi ọmọbinrin akẹkọọ yi, Nathan Sharibu to si sọ nipa ohun to mọ boya lootọ ni Leah ti  bimọ keji ni ahamọ Boko Haram.
Ka ti bi pẹlẹbẹ mu ọọlẹ jẹ.
Lọjọ Iṣẹgun, ajọ ajafẹtọmọniyan kan to wa ni orileede Amẹrika n kẹdun bi wọn ti ṣe pa Leah Sharibu ti si ahamọ awọn Boko Haram latijọyi.
O ni akikanju ọmọbinrin ẹlẹsin Kristẹni yi ni iroyin tẹ awọn lọwọ pe o ti bimọ ẹlẹkeeji si ahamọ.
Ojojumọ n'inu awọn ẹbi n bajẹ lori ikọlu Dapchi
BBC ko ribi fidi ọrọ yi mulẹ boya lootọ lo ṣẹlẹ bẹẹ amọ a kan si baba to bi Leah Sharibu, Nathan Sharibu.
Pẹlu ibanujẹ ọkan o sọ fun wa nirọlẹ Ọjọru pe ''Ahesọ ni ọrọ naa''.
O sọ pe oun ko ti gbọ nkankan nip ape ọmọ rẹ bi ọmọ lahamọ awọn agbesunmọmi yi.
O ni lati igba ti wọn ti ji Leah gbe, oun ko gbọ nkankan lati ọdọ rẹ ati awọn to jiigbe.
Oríṣun àwòrán, Twitter
Arakunrin Nathan tẹsiwaju pe lọpọ igba lawọn ijọba apapọ ti ṣeleri fun oun pe awọn yoo doola ọmọ rẹ kuro lahamọ to wa.
''Mo ti parọwa si wọn lọpọ igba ṣugbọn titi di asiko yi pabo lo ja si. Mio ti ẹ wa mọ nkan ti mole sọ fun wọn mọ.''
Orisirisi iroyin lo gbode nipa Leah Sharibu lati igba ti wọn ti ji i gbe ni ọdun 2018.
Ni oṣu kini awọn ileeṣẹ iwe iroyin Naijiria kan sọ pe Leah loyun fun ọgagun Boko Harm kan ti eyiun si ti ti gbe ekuro ni Naijiria.
Lọjọ Kọkandilogun oṣu Keji 2018 ni awọn Boko Harm ji Leah ati awọn akẹgbẹ rẹ obinrin mi gbe nileẹkọ Dapchi towa ni Yobe.
Lẹyin igba naa ni ijọba apapọ ri bi doola awọn ọmọbinrin yi ṣugbọn wọn kọ lati fi Leah silẹ nitori pe o ni oun ko ni yi ẹsin oun pada di musulumi.
Loṣu Kẹjọ ọdun 2019, ijọba Naijiria sọ pe Leah ṣi wa laaye. Nigba taa n wi yi, agbẹnusọ aarẹ Buhari, Garba Shehu ni ọjọ ko ni simi ayafi ti wọn ba ri Leah da pada wa sile.
Bola Tinubu: Ọ̀pọ̀ ní ìpolongo ìbò 2023 ni Tinubu ń ṣe pẹ̀lú ₦50m tó fàwọn oníṣòwò Katsina
Oríṣun àwòrán, Facebook/Bola Tinubu
Oriṣiiriṣii ọna lawọn eeyan fi wo igbesẹ eekan ẹgbẹ oṣelu APC, Bola Ahmed Tinubu to gbe aadọta miliọnu naira fawọn oniṣowo ti ṣọọbu wọn jona ni ipinlẹ Katsina .
Eleyii jẹ owo iranwọ fawọn ontaja naa to ti padunu dukia iyebiye ninu ijamba ina to ṣẹlẹ.
Awọn kan sọ lori ayelujara pe aluwala ologbo, ọgbọn ati ko ẹran jẹ naa ni gbogbo rẹ.
Eleyii tumọ si pe owo ti Tinubu gbe kalẹ niṣe pẹlu ipolongo oṣelu ṣaaju ibo aarẹ ọdun 2023.
Omooba Adejuyigbe Isaiah TaiyeTaiwo lori ikanni BBC Yoruba ni Facebook pe ko si ibi ti Tinubu n lọ ninu ibo 2023 to ba tiẹ dije fun ipo aarẹ gan an.
O beere wi pe elo ni Tinubu kede gẹgẹ bi owo iranwọ fawọn to ku nibi iṣẹlẹ Lekki Tollgate lọdun 2020?
Ọgbẹni Taiwo tiẹ lọ si inu iwe mimọ lori ọrọ naa lẹyin to sọ pe ''gbogbo aisododo, ẹsẹ ni.''
Ọgbẹni Joseph Olatunji ati Folakemi Oyeyipo ni ti wọn sọ pe ohun to da Tinubu atawọn oniṣowo katsina pọ naa ni yoo tu wọn ka.
Awọn tiẹ n beere lọwọ Tinubu wi pe kilode ti ko ṣe iranwọ owo fawọn oniṣowo ọjọ Ṣasha niluu Ibadan ti awọn padanu ọja wọn lẹyin rogbodiyan to waye nibẹ.
Bosede Comfort Ilesanmi naa sọ pe kinni Tinubu ṣe fawọn eeyan Yewa ipinlẹ Ogun ti wọn lọ ṣatipo lorilẹede Benin Republic lẹyin ikọlu awọn Fulani.
Amọ, ero Kamal Kamaldeen tayọ ni tiẹ, oun gbagbọ pe Tinubu yoo jẹ aarẹ orilẹede Naijiria laṣẹ Edumare lọdun 2023.
Ẹwẹ, ṣaaju ni iroyin kan ti kọkọ sọ pe Tinubu ṣe abẹwo si ipinlẹ Katsina laarọ Ọjọru, nibi to ti parọwa si awọn oniṣowo naa lati maṣe ba ọkan jẹ lori iṣẹlẹ ọhun.
Ọpọ ọja lo jona ninu iṣẹlẹ naa, eyii to mu ki ijọba ipinlẹ ọhun gbe iwadii dide lati mọ ohun to ṣokunfa ina naa.
Yoruba artists: Wo àwọn òṣèré tó ti bímọ lọ́dún 2021 tí a wà yìí
Oríṣun àwòrán, Instagram
Ẹ ku owo lomi ni Yoruba maa n ki awọn ti Eleduwa ba ṣẹṣẹ fi ọmọ ta lọrẹ.
Bayii gan an ni wọn ṣe n ki awọn oṣere tiata kan lẹyin ti Ọba oke ti fi ọmọ jinki wọn.
Wọnyii ni awọn oṣere ti Ọlọrun Oba fi ọmọ tuntun jojolo ta lọrẹ ninu ọdun 2021 ti a wa yii.
Bukunmi Oluwasina
Lọjọ kẹrin oṣu kẹta ọdun 2021 ni oṣere tiata, Bukunmi Oluwasina kede loju opo Instagram rẹ pe Ọlọrun ti fi ọmọ ta oun lọrẹ.
Oṣu kẹsan an ọdun 2020 ni Bukunmi di aya lọọdẹ ẹni bi ọkan rẹ ti wọn ti jọ n fẹra tipẹ.
Bukunmi fi oriṣiiriṣii fọto igba to fi wa ninu oyun si oju opo Instagram rẹ.
Koda, o tun fi fidio kan eyi ti o fi kọ orin fun ọmọ jojolo ti Eleduwa fi ta a lọrẹ naa.
O tun sọ loju opo Instagram rẹ pe, ninu ohun gbogbo ti oun ti fọwọ kan laye, ko si eyi to da bi ọmọ naa.
Biola Adekunle
Oṣere tiata, Biola Adekunle ati ọkọ rẹ tun ri ẹbun ọmọ tuntun jojolo mii gba lọwọ Eledua ninu oṣu keji ọdun 2021.
Biola kede lori ayelujara pe Ọlọrun tun ti fi ọmọbinrin jinki idile oun.
Ọdun 2014 ni Biola ṣe igbeyawo, ṣugbọn o ni idaduro fun ọdun marun ki o to bimọ.
Ọmọ keji ti Ọlọrun yoo fi ta oun ati ọkọ rẹ lọrẹ ree.
Adesuwa Wellington-Etomi
Oṣere tiata, Adesuwa Wellington-Etomi ati ọkọ rẹ, Banky Wellington ti ọpọ mọ si Banky W naa di ọlọmọ loṣu keji ọdun 2021.
Adesuwa ati Banky W lo kede ọmọ naa lẹyin ti wọn fi fọto sori oju opo Instagram wọn.
Adesua sọ pe ''Ọlọrun agbaye, o lagbara, lọsẹ mẹrin to kọja, mo gba ẹbun iyebiye julọ- ọmọkunrin wa.''
Banky W ni tirẹ ki iyawo rẹ ku ọjọ ibi ati ewu ọmọ ti Ọlọrun fi ta wọn lọrẹ.
Olorin takasufe, Banky W ni ọrọ ẹnu lasan ko le sọ bi inu oun ti dun to nitori Eledua ti sọ ẹgan awọn di ogo.
Kemi Lala Akindoju
Oṣere tiata, Kemi Lala Akindoju naa dawọọ idunnu ọmọ tuntun jojolo loṣu keji ọdun 2021 pẹlu ọkọ rẹ, Gbubemi Fregene.
Kemi ko beṣu bẹgba, oju opo Twitter rẹ lo fi fọto ọmọ si nibi to ti sọ pe ọmọkunrin ni ọmọ ọhun.
Oṣere naa tun kọ orukọ ọmọ naa sori oju opo Twitter rẹ pe Adéoreòfé Toritseju Chukwuebuka Fregene ni ọmọ naa yoo maa jẹ.
Loju opo Instagram rẹ, Kemi fi orin bọ ẹnu pe ti oun ba tiẹ lẹgbẹrun ahọn, ko le to lati yin Oluwa.
Benin artefacts: Germany ń gbèrò láti dá ère 530 ìlú Benin tí wọ́n jí padà sí Nàìjíríà
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Orilẹede Germany ti bẹrẹ si ni gbero lati da awọn ere iṣẹnbaye ilu Benin to wa nilẹ naa pada si Naijiria.
Igbimọ kan lorilẹede Germany lo fidi ọrọ yii mulẹ fawọn akọroyin ni Ọjọru, ọjọ kẹrinlelogun oṣu kẹta ọdun 2023.
Lasiko ijọba amunilẹru ilẹ Gẹẹsi ni wọn ji awọn ere naa lati ijọba Benin lọ si Germany.
Awọn ere yii si ti wa nile nnkan iṣẹnbaye pamọ si lati igba ti wọn ti ko wọn lọ si oke okun ni ilu Berlin tii ṣe olu ilu orilẹede Germany.
Awọn alakoṣo ibi iko nnkan iṣẹnbaye naa si lo fẹnu ko pe awọn yoo da awọn ere idẹ ilu Benin pada si ibi ti wọn ti ko wọn wa.
Ninu atẹjade kan ti wọn fi sita, igbimọ naa sọ pe ifọrọjọmi toro ọrọ ti n lọ pẹlu awọn orilẹede ti wọn ti gbe awọn ere kan wa si orilẹede Germany lati da wọn pada.
Minisita ọrọ ilẹ okeere ni Germany, Heiko Maas sọ pe ọna kan lati ṣe ododo nipa itan ikonilẹru ni dida awọn ere ọhun pada.
''Nipa awọn ere idẹ ilu Benin, a ti n ba awọn aṣoju orilẹede Naijiria ni Germany sọrọ, Maas lo sọ bẹẹ.''
Okoo le lẹẹdẹgbẹta nnkan iṣẹnbaye ilu Benin le mẹwaa(530) lo wa nile ikon nkan si to wa ni ilu Berlin.
Yoruba artists: Ṣé Yomi Fabiyi ti rí ìfẹ́ míràn ni lẹ́yìn tó kọ ìyàwó rẹ̀ òyìnbó tẹ́lẹ̀ sílẹ̀?
Oríṣun àwòrán, Instagram/realyomi Fabiyi
Oriṣiiriṣii nkan lo ṣẹlẹ lagbo awọn oṣere tiata Yoruba lọsẹ yii.
Lara awọn nkan to ṣẹlẹ lagbo oṣere yii, meji lami laaka ninu wọn.
Wọnyii ni awọn oriṣiiriṣii to ṣẹlẹ lagbo awọn osẹre tiata lọsẹ yii.
Yomi Fabiyi
Oríṣun àwòrán, Yomi Fabiyi
Ṣe ẹ mọ pe ọrọ ifẹ bi adanwo ni. Fidio kan ti gbajugbaja oṣere tiata, Yomi Fabiyi fi sita ti jẹ ki awọn eeyan maa beere ibeere.
Fidio naa ṣe afihan rẹ pẹlu orekelẹwa obinrin kan nibi ti awọn mejeeji ti n fẹnu ko ara wọn lẹnu.
Ọgbẹni Fabiyi gan an kọ awọn ọrọ ifẹ sori fidio naa loju opo Instagram rẹ.
"Fabiyi ni ''ti mo ba nifẹ rẹ, mo gbọdọ fẹnu ko ẹ ni ẹrẹkẹ. Ọrọ ifẹ maa n sọ mi di alailagbara""."
Yomi tun sọrọ lori fido mii to fi soju opo Instagram rẹ pe oun ati ọrẹbinrin oun n lọ si gbọngan idaraya.
O tun sọ lori fidio naa pe pe kawọn eeyan wo oluranlọwọ oun, eyun-un ni ọmọ pupa roboto kan to wa lẹgbẹ rẹ ninu mọto.
Ẹwẹ, ọpọ awọn akẹgbẹ re lo n ki ku oriire igbeyawo bo tilẹ jẹ pe ko sọ fun ẹnikan pe o ti ṣe igbeyawo.
Oríṣun àwòrán, Yomi Fabiyi
Oríṣun àwòrán, Yomi Fabiyi
Fabiyi kede lori ayelujara lọdun 2016 pe oun ti kọ iyawo oun oyinbo ọmọ ilẹ Gẹẹsi, Fran silẹ.
Iya Awero
Oríṣun àwòrán, Gboyega Akosile
Iya Awero fẹ́rẹ̀ẹ́ bú sẹ́kún níbí tó ti tẹ́wọ́ gba ẹ̀bùn ilé tuntun
Gbajugbaja oṣere fiimu Yoruba, Lanre Hassan ti ọpọlọpọ mọ si Mama Awero di onile lairo tẹlẹ.
Bawo lo ti ṣẹlẹ? Gomina Babajide Sanwo-Olu ipinlẹ Eko lo fi ile oniyara mẹta ta Iya Awero lọrẹ.
Arabinrin Hassan fi idunu rẹ han si gomina ipinlẹ Eko pẹlu oriṣiiriṣii ọrọ iwuri.
Mi o mọ ohun ti mo le sọ, o ṣi n ya mi lẹnu ṣugbọn inu mi dun lonii, mi o ni le sọ pupọ. Mo dupẹ pupọ lọwọ yin gomina mi.
Bayii ni Iya Awero ṣe fi idunnu rẹ han si Gomina Sanwo-Olu.
Adebimpe Oyebade
Ilumọọka oṣerebinrin Adebimpe Oyebade ṣe ọjọ ibi, ori ayelujara mi titi.
O ni oun fẹ maa jẹ ẹni to n fi ipo adari to dara han siwaju sii bi oun ṣe n ṣe latẹyin wa.
Mo_bimpe fi ọrọ dupẹ fun bi awọn ololufẹ rẹ ṣe tu yaya lati ki i ku ọjọ ibi rẹ.
Ori itage mi ni ile aye yii jẹ mo si ti fi gbogbo ipa mi ko ipa gidi latyin wa. Mo gbadura lati tẹsiwaju ninu ṣiṣe afihan ipo ẹni nla to n dari siwaju sii.
Bakan naa ni akẹgbẹ rẹ ti ọpọ maa n pe ni ọkọ rẹ, Lateef Adedimeji ṣe tẹ ẹ si rẹpẹtẹ.
Niṣe lo n ki i ni mẹsan an mẹwaa.
Femi Adebayo Salami
Gbajugbaja oṣere tiata, Femi Adebayo Salami ṣe iranti igba ti o lẹpọ pẹlu baba rẹ Adebayo Salami lagbo ogege ṣiṣe.
Asọ aran to ṣiṣẹ si lọrun ni Femi wọn ninu fọto ti oun ati baba rẹ wa ninu rẹ wọ.
Ọgbẹ Salami gan an fun ra rẹ ro dẹdẹ, bẹẹ lo kan dudu ninu aṣọ oke alanbara to wọ pẹlu ọpọ lọwọ.
Lai ṣe ani-ani, awọn mejeeji rẹwa lọkunrin ninu aṣọ ti wọn wọ.
INEC: Lẹyìn tí ọ̀jọ̀gbọ́n fásítì tó yí èsì ìbò Sẹnẹto Akpabio f‘ẹ̀wọ̀n jura, kí ló kàn fará yoku?
Oríṣun àwòrán, Google
Oju opo Twitter ti n gbana jẹ lori iroyin pe  wọn ti dajọ ẹwọn fun ọjọgbọn to yiwe esi ibo ti  Sẹnẹtọ Godswill Akpabio kopa ninu rẹ lọdun 2019.
Iroyin yi lu sita lỌjọbọ pe ọjọgbọn Peter Ogban ti fasiti Uyo yoo fi aṣọ penpe roko ọba nitori yiyi iwe esi idbo .
Labẹ ofin INEC ẹwọn ọdun mẹta lo wa fun ẹnikẹni to ba jẹ adari idibo to mọọmọ yi iwe tabi abajade ibo.
Ko si owo itanran kankan lori ẹsun yi bi kii ṣe pe ki onitoun ṣẹwọn.
Loju opo Twitter awọn eeyan ti n sọrọ lori idajọ yi ti wọn si n beere pe ki wa ni yoo ṣẹlẹ si ẹni to jẹ anfaani wuruwuru ibo yi botilẹ jẹ wi pe ko pada jawe olubori.
Die ree ninu ọrọ wọn yi.
Oríṣun àwòrán, TWITTER
Oríṣun àwòrán, Twitter
Oríṣun àwòrán, TWITTER
Lopin igba ti ko ti si ẹri to ṣafihan ilẹdiapopọ laarin Ọjọgbọn naa a ti Ṣẹnẹtọ Akpabio eyi to sunmọ ko ṣẹlẹ ni pe Ọjọgbọn yi yoo da jẹ iya rẹ ni.
Ka ni pe makaruru ibo yi gbe Akpabio wọlẹ ni a o ba tiẹ maa sọ pe ki wọn gbe ipo rẹ fun ẹni ti wọn jijọ dije dupo amọ ọrọ ko ri bẹẹ.
INEC ki ba maa ba Ọjọgbọn to yiwe idibo fun Akpabio ṣẹjọ ṣugbọn ọjọgbọn yi fun ara rẹ lo ni ki agbẹjọro rẹ kan si INEC pe ki wọn maa ṣe ni koun wa jabọ eto idibo to yi.
Oun nikan kan ni INEC pe ti awọn mii ninu wọn naa si kọ lati wa jabọ esi idibo.
Abalọ ababọ, INEC pinu lati gbe ọjọgbọn yi lọ si ileẹjọ ti adajọ si pada dajọ ẹwọn oṣu mẹrindinlogoji fun.
Ninu gbogbo ohun to ṣẹlẹ yi,  o fi n han pe ireti wa fawọn to n beere idajọ to yẹ fun ẹnikẹni toba ṣe makaruru eto idibo.
JAMB news 2021: Ìdí tí NIN rẹ fi ṣe pàtàkì láti forúkọsílẹ̀ fún ìdánwò JAMB rèé
Oríṣun àwòrán, Prof. Ishaq Oloyede
Oludari ajọ to n ri si idanwo aṣewọle iwe giga JAMB, Ọjọgbọn Ishaq Oloyede ti ṣalaye pe idi ti ajọ naa fi paṣẹ pe ki awọn aṣedanwo maa lo nọmba idanimọ NIN fun iforukọsilẹ ni lati dẹkun magomago idanwo.
Ọgbẹni Oloyede sọ eyi lasiko ipade ori ayelujara kan to ṣe plu alakoso ibudo idanwo ori ẹrọ ayarabiaṣa (Computer Based Test) pe aṣẹ lilo nọmba NIN lọdun yii wa latọdọ minisita eto ẹkọ, Adamu Adamu ati pe idi mii ni lati bojuwo ọrọ abo lorilede Naijiria.
Eyi ko waye lasiko idanwo JAMB ti ọdun 2020.
Ẹ kò nílò nọ́mbà ìdánimọ̀ NIN fún ìdánwò àṣewọlé ọdún 2020 - JAMB
ICPC fi panpẹ́ ọba mú ọ̀gá àgbà Jamb tẹ́lẹ̀ rí
Ohun tí Ọlọ́pàá mọ̀ nípa bóyá Agbébọn jí ọmọ ìjọ RCCG mẹ́jọ tó ń lọ jèrè ọkàn gbé rèé!
'Èmi àti ìyàwó mi ti ń gbé pọ̀ nínú ìgbéyàwó wa fún 60 years', ẹ wá kọ́ ẹ̀kọ́ lẹ́nu àgbà méjì
Nitori abo ni. Fun ipele tiwa yii, yoo ṣeranwọ lati lodi si biba eeyan kọ idanwo amọ idi ti wọn gbojule ju ni ipenija aabo lorilẹede Naijiria a si mọ pe ọpọlọpọ iṣoro taa ni lo ni ṣe pẹlu iṣoro idanimọ tori ao le da gbogbo araalu mọ...
JAMB ti kede pe ọjọ kẹjọ oṣu kẹrin ni wọn da fun iforukọsilẹ idanwo tdun yii wn si ni yoo pari ni ọjọ kẹẹdogun oṣu karun ọdun 2021.
Oríṣun àwòrán, Pulse
Oloyede sọ nibi ipade ọhun pe awọn aṣedanwo gbudọ lo siimu to si n ṣiṣẹ ti wn o si tii lo ri ṣaaju akoko iforukọsilẹ wọn.
O fi kun un pe ajọ JAMB n ba minisita to n ri si ibanisọrọ ṣepade lati fun awọn ni aṣ idariji fun ida ogun aṣedanwo ti ko ba ni siimu.
"Kii ṣe gbogbo aṣedanwo ni ko ni siimu, ida ọgọrin lo ti nọmba wọn, torinaa a n sọrọ ida ogun bayii taa ba si ri anfani ati gba aṣ idariji yii latọdọ minisita, ao rii daju pe awọn eeyan tẹle ofin tori ijọba ti ni gbogbo nkan yii ni o le ṣamojuto aabo fun gbogbo wa.
Ajọ JAMB loju opo Twitter wọn kede pe ẹgbrun mẹta abọ Naira (N3,500) ni owo idoruksilẹ ati ẹẹdẹgbẹta naira (N500) fun awọn iwe to yẹ ni kika fun idanwo naa.
Lagos one-day governor: Gómìnà Sanwo-Olu gba pẹ̀lú gómìna ọlọ́jọ́ kan fún ìpínlẹ̀ Eko dámọ̀ràn lórí ìdàgbàsókè ètò ẹ̀kọ́
Oríṣun àwòrán, Twitter/ babajide sanwo-olu
Gomina Babajide Sanwo-Olu ti ipinlẹ Eko ti gba gomina tuntun fun ipinlẹ naa, Omidan Ẹniọla Ajala lalejo lọfisi rẹ.
Omidan Ẹniọla Ajala ni gomina ọlọjọ kan fun ipinlẹ Eko lẹyin to gbegba oroke nibi idije 'Ta n mọ ọ?' New Era Spelling Bee Competition fawọn akẹkọọ ileewe girama ni ipinlẹ naa.
Lasiko  ipade rẹ pẹlu Omidan Ajala atawọn ọmọ igbimọ iṣejọba rẹ, gomina Sanwo-Olu ni idagbasoke eto Ẹkọ ko ni rẹyin ninu eto idagbasoke isọdọtun ti iṣejọba oun gbe kari eyi to pe ni 'THEMES agenda'
Oríṣun àwòrán, Lagos state Government
'Èmi àti ìyàwó mi ti ń gbé pọ̀ nínú ìgbéyàwó wa fún 60 years', láì sí ìṣòro'
O ni ijọba ipinlẹ Eko yoo tubọ maa rii daju pe ayika ikẹkọ ni ipinlẹ naa tubọ ṣi n mu ki eto ẹkọ o dun un kọ fawọn akẹkọọ.
O wa kan sara si omidan Ajala fun ijafafa, iṣọkan akin ati iduro ṣinṣin rẹ pẹlu amọran pe oun atawọn ọmọ igbimọ rẹ ko gbọdọ faye gba igbesẹ ṣiṣe akoso ipinlẹ Eko fun ọjọ kan lati ko si wọn lori to bẹẹ ti wọn yoo fi yẹsẹ kuro lojuna idagbasoke ẹkọ wọn.
Oríṣun àwòrán, Twitter/ babajide sanwo-olu
Omidan Ẹniọla Ajala to jẹ gomina ọjọ kan ni ipinlẹ Eko fun ọdun 2021 jẹ akẹkọọ ileewe girama Lafiaji Senior High school, Lagos Island.
Awọn ọmọ igbimọ rẹ yooku ni Grace Ikhariale lati ileewe girama TinCan Island Senior High School, Tolu , to jẹ igbakeji gomina; Oluwatosin Akinbọdewa lati Iworo Ajido Senior Secondary School, Badagry ni olori ile aṣofin; Eunice Adedọtun lati Agbẹdẹ Senior School Ikorodu ni kọmiṣọna eto ẹkọ, ti Ekene Ezeunala lati Meiran Community High school jẹ alaga igbimọ tẹlekoto lori eto ẹkọ nile aṣofin ipinlẹ naa.
Ninu ọrọ rẹ lasiko to fi n lewaju ipade ọlọsọọsẹ ti igbimọ iṣakoso ijọba ipinlẹ Eko, gomina ọlọjọ kan ni ipinlẹ Eko fun ọdun 2021, omidan Ẹniọla Ajala dupẹ pupọ lọwọ gomina ipinlẹ Eko, Babajide Sanwo-Olu fun ọla, ẹyẹ ati iyi to bu fun awọn akẹkọọ to bori nibi idije 'Ta n mọ ọ?' naa.
Oríṣun àwòrán, Twitter/ babajide sanwo-olu
Bakan naa lo gboriyin fun gomina Sanwo-Olu lori bi o ṣe moju to ọrọ ajakalẹ arun COVID-19 ni ipinlẹ naa, to si rọ awọn akẹkọọ lati maa foju si ẹkọ wọn ki wọn lee bori awọn ipenija gbogbo ni ọna wọn.
Bakan naa ni 'gomina' Ẹniọla Ajala ke si gomina Sanwo-Olu pe ko tubọ pese awọn ohun elo amayedẹrun lawọn ileewe tawọn akẹkọọ to bori idije naa ti jade wa to si tun rọ ijọba lati ṣeto ẹbun to jọju fun awọn obi oun, to gboriyin fun pẹlu bi wọn ṣe tọ ọ ni ọna gbogbo to yẹ.
Fuel price hike: Àjọ elépo rọ̀bì, NNPC ní kó sáyé fífi owó kún owó epo bẹntiró báyìí
Oríṣun àwòrán, others
Ajọ elepo rọbi lorilẹede Naijiria, NNPC ti rọ awọn eeyan orilẹede Naijiria lati lọ fi ọkan wọn balẹ na o nitori ko si ohun kan to tii yẹ, tabi sun owo ori epo bẹntiro kuro ni iye to wa tẹlẹ.
Ajọ NNPC ni ijiroro ati ifikuluku n lọ lọwọ pẹlu awọn ẹgbẹ oṣiṣẹ atawọn alẹnulọrọ lẹka naa, o si di igba ti eyi ba pari ki igbesẹ kankan to lee waye.
Ninu ọrọ to ba awọn oniroyin sọ ni ilu Abuja, adari ẹka alukoro ni ajọ naa, Ọmọwe Kennie Ọbatẹru ṣalaye pe lọwọ yii ajọ naa lo n fori rọ wahala ati ẹru kiko epo rọbi wọle sorilẹede Naijiria lati lee rii daju pe ohun amuṣagbara wa forilẹede Naijiria.
Ọmọwe Ọbatẹru ni ko si ohun to jọ fifi owo le iye ti wọn n ta epo bẹntiro tẹlẹ nitori ifikuluku to ṣi n lọ lọwọ naa ati pe wọn ti ṣeto bi iye epo tawọn araalu yoo nilo ni anito ati aniṣẹku yoo ṣe wa larọwọto lorilẹede Naijiria.
Báa ṣe lọ́pọlọ tó, ẹnu Yorùbá ò kò, ọgbọ́n táa gbúdọ̀ dá rèé - Ìpàdé àgbààgbà Yorùbá n'Ibadan
Ajọ NNPC wa rọ awọn ileepo to n da aṣẹ ara wọn pa nipa fifi kun iye owo epo bẹntiro lati lọ simọdọ ki wọn maa si da alaafia ẹka epo rọbi lorilẹede Naijiria ru.
Bakan naa lo rọ awọn ọntaja epo atawọn onimọto tabi ọlọkada pe ni ki wọn ye ko tabi ra epo pamọ to  ni ireti pe yoo wọn sii laipẹ.
RCCG members kidnap: Ọlọ́pàá ní àwọn kò gbọ́ ohun kan nípa bó yá àwọn agbébọn jí ọmọ ìjọ RCCG mẹ́jọ
Oríṣun àwòrán, Facebook/Eje Faraday
Ileeṣẹ ọlọpaa ipinlẹ Kaduna ti sọ pe ko si ohun to jọ iroyin to lu ori ayelujara pe awọn agbebọn ajinigbe tun ti ji ọmọ ijọ Redeemed Christian Church of God(RCCG) mẹjọ gbe lọ.
Iroyin naa to gbalẹ kan lori ayelujara sọ pe awọn eeyan ti wọn jigbe naa jẹ ọmọ ijọ RCCG ti ẹkun Trinity Sanctuary niluu Kaduna.
Iroyin naa sọ pe iṣẹlẹ yii ṣẹlẹ lọjọ Ẹti nigba tawọn ọmọ ijọ RCCG ọhun n rinrin ajo lopona Kachia nibi ti wọn ti n lọ fun eto kan.
Ọgbẹni Eje Faraday lo fọrọ naa lede loju opo Facebook rẹ ni bii ago meje ọjọ Ẹti.
Ọgbẹni Faraday sọ loju opo Facebook rẹ pe gbogbo ero to wa ninu ọkọ bọọsi tawọn ọmọ ijọ RCCG naa wa ni wọn jigbe lọ tan.
Ẹnikan to tun jẹ oṣiṣẹ ijọ RCCG sọ fun iwe iroyin Punch pe awọn ọmọ ijọ naa n lọ fun eto ijere ọkan fun Ọlọrun nigba ti iṣẹlẹ ọhun ṣẹlẹ.
O ni awọn agbebọn naa ni ki wọn kuro ninu bọọsi ti wọn wa pe ki wọn wọ eleyii tawọn gbe wa.
Ṣugbọn agbẹnusọ fun ileeṣẹ ọlọpaa to ba BBC Yoruba sọrọ, ASP Muhammad Jalige ṣalaye pe ko si ohun to jọ bẹẹ.
''Lati ọjọ Ẹti ọjẹ kẹrindinlọgbọn oṣu Kẹta lawọn akoroyin ti n pe mi ni mẹsan mẹwaa lori iroyin ijinigbe ni Kaduna.
Ko si ẹni to mọ ohun kan nipa iṣẹlẹ ijinigbe awọn ọmọ ijọ RCCG kankan ni Kaduna.
Ohun to ya mi lẹnu ni pe ipinlẹ Eko nikan lawọn akọroyin ti n pe mi."
Alukoro ọlọpaa naa ni akọroyin to wa ni Kaduna ati apa ariwa orilẹede Naijiria ko pe oun, ki lode to fi jẹ pe lati ilu Eko nikan ni wọn ti n pe oun.
"Amọ, ti ileeṣẹ ọlọpaa ba gbọ ohun kan nipa iṣẹlẹ yii, n o jẹ ki ẹ gbọ,'' ASP Jalige lo ṣalaye bẹẹ.
Ijọ Redeem Christian Church of God jẹ ijọ nla to si ni ẹka kaakiri orilẹede Naijiria. Iya ijọ naa kalẹ si Ebute Mẹta ni ilu Eko.
Buhari Medical Tourism: Kí lẹ̀ ń bú ààrẹ fún nígbà tọ́pọ́ òṣìṣẹ́ ìlera ń ṣe owó ìṣúná wọn báṣubàṣu
Oríṣun àwòrán, Twitter
Agbẹjọro ati ajafẹtọ ọmọniyan, Kayode Ajulọ ti bu ẹnu atẹ lu awọn ti wọn n sọrọ odi si aarẹ Buhari nitori pe o lọ si ilu London lati lọ gba itọju.
Ajulọ ni aarẹ Buhari ni aṣẹ labẹ ofin ọdun 1999 ni Naijiria lati jade tabi wọle si orilẹede Naijiria, to fi mọ ilẹ okeere lati lọ gba itọju.
O fikun pe, aarẹ Buhari yoo ti ro o daadaa ki o to tẹsiwaju lati sọ fun awọn ọmọ Naijiria wi pe oun fẹ lọ isinmi ọṣẹ meji lati gba itọju fun ara rẹ lai pa irọ fun awọn ọmọ Naijiria.
''Ti aarẹ Buhari ba ni oun lọ fun ọlide, ta lo le e da duro tabi oun fẹ lọ ṣepade pẹlu eniyan kan ni Ilu Ọba?''
''Amọ o sọ otitọ fun awọn ọmọ Naijiria, nitori naa ko yẹ ki wọn bu ẹnu atẹ lu.''
Akomolede àti Asa: Ìyàtọ̀ tó wà láàrin ìlànà ìpolówó ọjà láyé àtijọ́ àti òde òní
Bakan naa lo ni ofin orilẹede Naijiria ko le e kan ni ipa fun ẹnikẹni lati duro si orilẹede rẹ lati gba iwosan ti o ba ni anfaani ati ọre ọfẹ lati lọ gba eto iwosan to peye.
Ajulọ fikun un pe eto ilera lorilẹede Naijiria ti dẹnukọlẹ to fi mọ eto ẹko ati eto irinna lorilẹede Naijiria.
''Amọ kii ṣe ijọba nikan lo jẹbi bi ohun gbogbo ṣe dẹnukọlẹ nitori lọpọ igba ni awọn adari eto ilera ko le e sọ pato bi wọn ṣe n ṣe owo ti ijọba n fun ẹka naa.
Onpetu Ijeru: Akala ní torí Aláàfin kò ṣúgbàá òun fún sáà kejì, ló ṣe ní kí pín ipò alága
Lori awọn dokita ti wọn fẹ gunle iyanṣelodi,atunṣe gbọdọ ba ẹka naa, ki awọn alaṣẹ si naani ẹmi awọn eniyan ati oṣiṣẹ wọn.
Aarẹ Buhari to lọ fun isinmi oloṣẹ meji naa ni yoo pada si Naijiria ni ọsẹ keji, Osu Kẹrin, ọdun 2021.
Igba akọkọ kọ ni yii ti aarẹ orilẹede Naijiria, Muhammadu Buhari yoo lọ si Ilẹ Gẹẹsi lati lọ gba eto ilera to peye.
Oríṣun àwòrán, Instagram/Bashir Ahmad
Eleyii ko ṣẹyin ikede ijọba apapọ pe Aarẹ orilẹede Naijiria, Muhammadu Buhari n lọ si ilu London lati lọ gba itọju fun isinmi ọlọsẹ-meji.
Ileeṣẹ ijọba ni Ọjọ Iṣẹgun, Ọgbọnjọ Oṣu Kẹta, ọdun 2021 ni aarẹ Buhari yoo ma a rin irinajo naa.
Wọn yii ni igba mẹ́fà ti Aarẹ Buhari lọ gba itọju nilẹ okeere
Ọjọ karun un oṣu keji, ọdun 2016
Ni bi oṣu mẹjọ to bẹrẹ ijọba gẹgẹ bi aarẹ orilẹede Naijiria, Aarẹ Buhari rinrin ajo lọ si ilu London lọjọ karun un oṣu keji ọdun 2016.
Atẹjade lati ileeṣẹ ijọba ṣalaye pe ọrọ ara Buhari lo mu gunle irinajo naa.
O pada si Naijiria lati irinajo naa lọjọ kẹwaa oṣu keji ọdun 2016.
Ọjọ kọkandinlogun oṣu kinni, ọdun 2017
Aarẹ Buhari mori le ilẹ Gẹẹsi lọjọ kọkandinlogun oṣu kinni, ọdun 2017.
Ileeṣẹ aarẹ sọ pe itọju ara rẹ lo mu ki aarẹ Buhari gunle irinajo ọhun si ilu Oba.
Ọjọ kẹwaa oṣu kẹta ọdun 2017 ni Buhari pada si Naijiria lẹyin to lo ọjọ mọkanlelaadọta lorilẹede UK.
Ọjọ kọkanlelogun oṣu kẹsan an, ọdun 2017
Ọjọ kọkanlelogun oṣu kẹsan an ọdun 2017 ni Aarẹ Buhari gbera lati ilu London lọ si orilẹede Amẹrika.
Aarẹ rinrin ajo naa lati lọ gba itọju fun agọ ara rẹ.
Ọjọ mẹrin ni Buhari lo nilẹ Amẹrika ko to pada si ilu Abuja lọjọ kẹẹdọgbvọn oṣu kẹsan an ọdun 2017 .
Ọjọ kẹsan an oṣu kẹrin, ọdun 2018
Buhari fi orilẹede Naijiria silẹ lọ si ilẹ Gẹẹsi lọjọ kẹsan an oṣu kẹrin ọdun 2018.
Ọjọ mẹtala gbako ni Buhari nilẹ Uk ki o to pada wale lọjọ kọkanlelogun oṣu kẹsan an ọdun 2018.
Ijọba ni isinmi ọlọdọọdun ni Aarẹ Buhari lọ fun nilẹ Gẹẹsi.
Buhari kopa ninu ipade awọn orilẹede to gbominira lati ọdọ ilẹ Gẹẹsi, bakan naa lo ṣe ipade pẹlu Olootu ijọba ilẹ Gẹẹsi Theresa May nigba naa.
Ọjọ kẹjọ oṣu karun un ọdun 2018
Aarẹ Buhari tun gbera lọ si ilẹ Uk lọjọ kẹjọ oṣu karun un ọdun 2018.
Iroyin to jade lati ileeṣẹ ṣalaye pe itọju ara lo mu ki Buhari rinrin ajo lọ si ilẹ okeere.
Ọjọ kọkanla oṣu karun ọdun 2018 ni Buhari pada si Naijiria lẹyin to gba itọju tan niluu London.
Aarẹ orilẹede Naijiria, Muhammadu Buhari n lọ si ilu London lati lọ gba itọju fun isinmi ọlọsẹ-meji.
Ileeṣẹ ijọba fikun pe aarẹ yoo pada si orilẹede Naijiria ni Ọsẹ keji ni Oṣu Kẹrin, ọdun 2021.
Oríṣun àwòrán, Twitter/Bashir Ahmad
Ijọba apapọ ti kede pe Aarẹ orilẹede Naijiria, Muhammadu Buhari n lọ si ilu London lati lọ gba itọju fun isinmi ọlọsẹ-meji.
Ileeṣẹ ijọba loju opo Twitter wọn ni Ọjọ Iṣẹgun, Ọgbọnjọ Oṣu Kẹta, ọdun 2021 ni aarẹ Buhari yoo ma a rin irinajo naa.
Amọ ki aarẹ Buhari to kuro ni ilu Abuja, yoo kọkọ ṣe ipade pẹlu awọn adari ikọ ọmọogun Naijiria.
Lẹyin naa ni aarẹ yoo tẹsiwaju irinajo rẹ si Ilẹ Gẹẹsi fun ọṣẹ meji.
Ileeṣẹ ijọba fikun pe aarẹ yoo pada si orilẹede Naijiria ni Ọsẹ keji ni Oṣu Kẹrin, ọdun 2021.
Amọ, ẹgbẹ awọn dokita lorilẹede Naijiria,NARD ti fariga wi pe awọn yoo bẹrẹ iyanṣẹlodi alaini gbedeke bẹrẹ lati Ọjọ Kini, Oṣu Kẹrin, ọdun 2021.
Lara ẹsun ti wọn fi kan ijọba ni wi pe wọn kọ lati mu ileri wọn ṣe lasiko ti wọn ba wọn ṣepade titi di asiko yii.
Bakan naa ni wọn fẹsun kan ijọba wi pe wọn kọ lati ṣetọju awọn ẹbi ati ara ti awọn dokita ti wọn ku tori arun Coronavirus.
Akomolede àti Asa: Ìyàtọ̀ tó wà láàrin ìlànà ìpolówó ọjà láyé àtijọ́ àti òde òní
Nibayii, ẹgbẹ awọn dokita lorilẹede Naijiria ti ni awọn ko ni yi ọkan wọn pada nitori ijọba kọ lati mu adehun wọn ṣẹ titi di asiko yii.
Amọ Minisita fun iṣẹ ati igbanisiṣẹ, Festus Keyamo ti rọ awọn dokita naa lati gbegile iyanṣẹlodi ọun nitori ijọba ti gbe igbese lati ṣe ipade pẹlu wọn.
Oríṣun àwòrán, @ProfOsinbajo
Igbakeji aarẹ, Yemi Osinbajo ti gba awọn to n polongo pe ki Naijiria tuka, lati tun ero ara wọn pa.
Iroyin sọ pe nibi eto idanilẹkọ to waye fun ọjọ ibi Bola Tinubu, ni Osinbajo ti sọ ọrọ naa.
Osinbajo sọ pe ti Naijiria ba tuka, o ṣe e ṣe ki awọn arinrinajo o nilo iwe irinna ki wọn o to le wọ awọn ilu bi Kano.
O fi ọrọ naa ṣakawe pe, ka ni Naijiria ti pin ni, gbogbo awọn to wa nibi idanilẹkọ naa ni i ba nilo fisa ki wọn o to o le wa.
Ninu iroyin mii, Minisita igbokegbodo ọkọ ni Naijiria, Rotimi Amaechi ti sọ pe pinpin tabi atunto Naijiria kọ ni yoo mu igbayegbadun wa fawọn ọmọ orilẹede yii.
Amaechi ni awọn to n kọminu lori ọjọ iwaju orilẹede Naijiria n ṣe bẹẹ nitori ifẹ ti wọn ni si orilẹede wọn.
Amọ, Amaechi sọ pe atunto tabi pinpin Naijiria kọ ni yoo jẹ ki nnkan ṣẹnu 're fawọn ọmọ orilẹede Naijiria.
Minisita igbokegbodo ọkọ sọ pe ko dara ki awọn eeyan maa sọ pe iṣẹ ati oṣi ti pọ sii lasiko ijọba Aarẹ Muhammadu Buhari ju ijọba Goodluck Jonathan to wa lori oye tẹlẹ lọ.
Amaechi ni kii ṣe asọdun pe lati ori awọn ijọba to ti ṣe ki Buhari to gori oye ni iṣẹ ati oṣi ti n gbilẹ bọ ki Buhari too de.
Minisita ni ati igba ti Naijiria ti pada si ijọba ologun ni iṣẹ ati oṣi ti bẹrẹ si ni ba ọpọ eeyan finra ni Naijiria.
''Gbogbo wa ni a nifẹ orilẹede wa Naijiria, ti a si n fẹ ki orilẹede naa dun un gbe fun gbogbo eeyan.
'Èmi àti ìyàwó mi ti ń gbé pọ̀ nínú ìgbéyàwó wa fún 60 years', ẹ wá kọ́ ẹ̀kọ́ lẹ́nu àgbà méjì
Amọ, erongba wa lati jẹ ki Naijiria dara ju ero awọn kan ti wọn fẹ ki orilẹede yii pin lọ.
Atunto tabi yiyapa Naijiria kọ lo maa mu inu awọn ọmọ orilẹede yii dun,'' Amaechi ṣalaye.
O ni wiwa ni iṣọkan lo le mu igbayegbadun wa fawọn ọmọ Naijiria.
Minisita igbokegbodo ọkọ ko ṣai fidi rẹ mulẹ pe ko si igba tawọn eeyan ti ebi n pa ko ni doju Naijiria bolẹ ti iṣẹ ati oṣi ba si n pọ sii.
Buhari: Ó dára kí Orílẹ̀èdè Naijiria wa ní ìṣọ̀kan jú kí a pínyà lọ
Oríṣun àwòrán, Twitter
Aarẹ orilẹede Naijiria, Muhammadu Buhari ti ni iṣọkan ati ibagbepọ gẹgẹ bi orilẹede kan lo dara fun orilẹede Naijiria, kii ṣe ituka.
Buhari sọ eyi lasiko ijiroro ọlọdọọdun ti wọn fi sọri ọjọ ibi asiwaju ẹgbẹ oṣelu APC, Bola Ahmed Tinubu, ti wọn ṣe lori ẹrọ ayelujara ati ni gbọngan ileeṣẹ ijọba ni ipinlẹ Kano.
Aarẹ Buhari to sọrọ lori ayelujara lati Aso Rock ni ilu Abuja ni, Tinubu jẹ ẹnikan pato to ja fun iṣọkan ati alaafia Naijiria lati wa ni orilẹede kan.
''Tinubu ko ipa ribiribi lati ri wi pe ayajọ Ọjọ June 12 duro lailai lorilẹede Naijiria lati ṣeranti MKO Abiola ati ipa to ko nipa iṣejọba alagbada ni Naijiria''
''Bakan naa ni Tinubu ṣe daradara lasiko to jẹ gomina ipinlẹ Eko ni ọdun 1999 si ọdun 2007.''
Oríṣun àwòrán, Twitter
O ni ijọba gbọdọ ri wi pe awọn ohun alumọni Naijiria kari awọn eniyan nile-loko, ki ọkan awọn ọmọ Naijiria balẹ ni gbogbo ibi ti wọn ba wa.
Bakan naa ni aarẹ fikun wi pe iṣẹ ti oun yan laayo ti fun oun ni ore ofẹ lati kaakiri gbọgbọ Naijiria, eleyii to fihan oun wi pe iṣọkan ati alaafia lo le mu orilẹede Naijiria goke agba.
''Ogun abẹle to waye ni ọdun 1967 si 1970 ti mo kopa ninu rẹ, ti ọpọlọpọ ologun ku to fi mọ awọn ọmọde, agbalagbala, ọkunrin, obinrin, nitori naa ogun kii ṣe ọna abayọ si iṣoro Niajiria."
Akomolede àti Asa: Ìyàtọ̀ tó wà láàrin ìlànà ìpolówó ọjà láyé àtijọ́ àti òde òní
Ninu ọrọ tirẹ, Tinubu rọ ijọba aarẹ Buhari lati pese iṣẹ fun awọn ọdọ ti wọn pọ bi yanrin ni Naijiria, to si jẹ wi pe ida mẹtalelọgbọn ninu wọn nikan lo ni iṣẹ lọwọ.
Oríṣun àwòrán, @TheBolaATinubu
Fidio kan to n ja rainrain lori ayelujara lo se afihan asaaju ẹgbẹ oselu APC, Asiwaju Bola Ahmed Tinubu to fẹ yọ subu.
Tinubu lo wa nilu Kaduna lọjọ Abamẹta nibi idanilẹkọ ọlọdọọdun ti wọn fi sọri Ọlọla Ahmadu Bello, ikọkanla iru rẹ, to waye ni Gbọngan Arewa.
Gẹgẹ bi fidio naa ti se afihan rẹ, Jagaban tilu Eko n wọnu ile bọ, o si wa laarin ọpọ eeyan lori pepele ti wọn se fun awọn ọlọla, lasiko ti isẹlẹ naa waye.
Tinubu, ẹni to n ki awọn alejo to wa lori tabili ọlọla naa, ni ẹsẹ rẹ sadede yọ, to si fẹ subu.
Ọpẹlọpẹ awọn ẹsọ alaabo to rọgba yi ka, ti wọn si tete dii mu, ko ma baa subu sori ilẹ.
Covid-19: Wo ìròyìn òfegè mẹ́jọ táwọn adarí ẹ̀sìn ń sọ nípa àbẹ́rẹ́ àjẹsára Coronavirus
Amọ sa, ero awọn eeyan kan se ọtọọtọ lori isẹlẹ bi ẹsẹ Tinubu se yọ nibi idanilẹkọ ọlọdọọdun naa.
Bi awọn eeyan kan se ni isẹlẹ naa kii se tuntun, ko si ni ọwọ aye ninu rara nitori ko si ẹni ti ko le subu.
Amọ awọn eeyan miran lero tiwọn ni agba ti de si gomina ana nipinlẹ Eko naa, ti ilera ara rẹ si ti jẹ ti agba, idi si ree ti ẹsẹ rẹ fi yọ subu.
Ni ti agba oselu kan lẹkun ariwa Naijiria, Sẹnatọ Shehu Sani, lowe lowe ni ọrọ rẹ gẹgẹ bi imọran fun asiwaju Bola Tinubu loju opo Twitter rẹ.
Oríṣun àwòrán, @ShehuSani
"Sani ni "" Iwọ Jagaban, mọ iwọn ara rẹ, wọn yoo maa rẹrin si ọ tabi ba ọ sọrọ kẹlẹkẹlẹ lati gbe ọ lọ sori oke Sinai, amọ wọn yoo ju ọ silẹ, wọn yoo si mu ko ri sinu odo Euphrates."""
Ọrọ ti Sani sọ yii si ni awọn eeyan to sọrọ le lori n gba bii ẹni gba igba ọti.
Wo kókó ọ̀rọ̀ mẹ́wàá tí Bola Tinubu sọ ní Kaduna
Oríṣun àwòrán, @TheBolaATinubu
Saaju la ti mu iroyin wa fun yin pe asaaju ẹgbẹ oselu APC, Asiwaju Bola Ahmed Tinubu ti tako gomina ipinlẹ Plateau, Simon Lalong, pe ki ẹka isejọba mẹtẹẹta se adinku owona wọn ni kiamọsa.
Gẹgẹ bi Lalong ti wi nibi eto ti Tinubu bawọn peju si nilu Kaduna, bi adinku ba ba owona ijọba, owo yoo wa lati gbọ bukata lawọn ẹka eto idagbasoke to se koko, eyi to jẹ ipenija fun Naijiria.
Amọ nigba to n sọrọ lọjọ Abamẹta nibi idanilẹkọ ọlọdọọdunti wọn fi sọri Ahmadu Bello, ikọkanla iru rẹ, nibi ti gomina Plateau naa wa, Tinubu ni ọrọ ko ri bi Lalong se woye rẹ.
'Èmi àti ìyàwó mi ti ń gbé pọ̀ nínú ìgbéyàwó wa fún 60 years', ẹ wá kọ́ ẹ̀kọ́ lẹ́nu àgbà méjì
Asaju ẹgbẹ oselu APC naa ni o yẹ kawọn ọmọ Naijiria tako ero pe owona ijọba ko mu eso rere kankan jade, to si lewu fun ọrọ aje orilẹede yii.
Tinubu ni o seese lootọ ki ijọba maa na inakuna tabi ko lo owo naa feto idagbosoke to yẹ, bẹẹ si ni ẹka eto aladani to n sọ owo na, ko tumọ si pe o n kopa gidi si agbega ọrọ aje.
O wa salaye pe o yẹ ki ijọba maa pese owona to jọju fawọn isẹ akanse ti yoo pese isẹ ati idagbasoke fun ilẹ wa.
'Pẹ̀lú gbogbo ìrìnàjò Dubai mi, ẹ̀sẹ̀ gígún ní Nàìjíríà láti pàdé èèyàn ńlá ńlá tó lè ra àwòrán wa ṣe pàtàkì'
Yatọ si eyi, ọpọ ọrọ ni oloye Tinubu sọ nibi ipade naa, akekuru awọn ọrọ naa ree:
Koko ohun mẹsan mii ti Tinubu sọ ni Kaduna:
Viral Audio on Begging: Àwọn alágbe ń fapá jánú pé aráàlú kórira àwọn torí àhesọ ọ̀rọ̀
Oríṣun àwòrán, Abdullahi Tafa
Yoruba ni tẹni ba dakẹ, ti ara rẹ maa n ba dakẹ ni nitori ẹnu ẹni la fi n kọ mejẹ.
Eyi lo mu ki awọn onibaara to wa ni agbegbe Ọja Ọba nilu Ibadan se figbe bọnu pe okuta ti ba ọja awọn eyi tii se agbe sise.
Ọpọ awọn eeyan apa oke ọya lo kun ilu Ibadan, tii se olu ilu ipinlẹ Oyo dẹnu lati wa se agbe, ti wsn si wọpọ lawọn agbegbe bii Sabo, Ọjọọ, Ọja Ọba, Mọkọla, Sasa ati bẹẹ bẹẹ lọ.
Gẹgẹ bi iwe iroyin Vanguard ti wi, Ọjọbọ lawọn alagbe yii, ti wọn fẹẹ to ọọdunrun niye, bẹrẹ si ni fi ẹhonu han pe awọn eeyan ko fi bẹẹ se aanu fun awọn mọ.
Wọn ni agbara kaka ni awọn fi n mu ọwọ lọ sẹnu lasiko yii nitori fọnran kan to gbode pe awọn alagbe maa n ta owo baara fawọn to n fi se etutu ọla.
Oríṣun àwòrán, Abdullahi Tafa
Bẹẹ ba gbagbe, laipẹ yii la mu iroyin to wa nisalẹ yii wa fun yin nipa bawọn gbajumọ kan ni awujọ se pinnu pe awọn ko ni fun awọn onibara lowo mọ.
Idi ni bi fọnran ohun obinrin alagbe kan se gba ori ayelujara laipẹ yii, nibi to ti n tu asiri bi wọn se n parọ se agbe, ti wọn yoo si tun ta owo ti wọn ba ri kojọ fawọn eeyan kan.
Obinrin naa ni owo ọhun ni awọn eeyan to ba ra a lọwọ awọn maa fi n se etutu ọla, aṣiki ẹnikẹni to ba si fun awọn ni owo agbe naa yoo maa lọ silẹ ni.
Oríṣun àwòrán, Abdullahi Tafa
Nigba to sọrọ lorukọ awọn alagbe naa, Abubakar Abdullahi, tii se Seriki Hausawa lagbegbe Ọja Aba ni awọn eeyan ti bẹrẹ si ni ikorira nla sawọn alagbe bayii.
"Iroyin to gbode kan pe awọn alagbe maa n ta owo baara ti wọn ba ri gba lati ọdọ awọn alaanu fun awọn eeyan ti yoo fi owo naa se etutu ọla, kii se otitọ rara.
Ahesọ ọrọ yii si lo ti mu okuta ba agbe sise nitori ọpọ eeyan awujọ ni ko fẹ ri awọn alagbe soju mọ lasiko yi.
Blighted Ovum: Obìnrin kan sọ ohun tójú rẹ̀ rí nígbà tí oyún bàjẹ́ lára rẹ̀ ní ẹ̀ẹ̀mẹta
Ohun ta mọ ni pe awọn ontaja, onikiri ọja atawọn awakọ ero maa n wa sẹ owo beba odidi si wẹwẹ lọdọ awọn alagbe yii, paapaa lọdọ awọn arọ, ati afọju.
Abdullahi wa kede pe o se pataki ki awọn wẹ orukọ awọn alagbe mọ ninu ẹsaun yii, tori awọn ko mọwọ, mẹsẹ ninu rẹ.
Oríṣun àwòrán, Access24
Saaju la ti mu iroyin wa fun yin pe fọnran ohun arabinrin alagbe kan to fi iṣẹ bara ọdun mẹwaa kọ ile mẹrin, ra ọkọ mẹta, ti n lọ kaakiri lori ayelujara, to si gbalẹ kan.
Arabinrin naa to pe orukọ ara rẹ ni Simbiatu Mopelola ṣalaye ninu ifọrọwerọ akasilẹ naa pe, ẹni ọdun mọkanlelaadọta ni oun ati pe ọmọ oun meji lo wa loke okun, ti oun si ni awọn eeyan mejila to n ba oun ṣiṣẹ.
Arabinrin naa, ti iroyin sọ pe o ti wa ni ahamọ awọn ọlọpaa fi kun un pe, gbogbo owo ti awọn eeyan ba fun awọn gẹgẹ bii baara, ni awọn tun maa n tun ta.
O ni awọn Alfa, Woli atawọn gbajumọ kan to fẹ ja ewe sobi etutu ọla wọn lo maa n ra awọn owo baara ti awọn ba pa naa, eleyi to ni o n fa sababi ifasẹyin fun ọpọ awọn ẹlẹyinju aanu to ba wa ninu awọn to fun onibaara lowo naa.
Nibayii, awọn ọmọ orilẹede Naijiria ti n sọ si ọrọ naa, koda awọn eekan ilu pẹlu ko gbẹyin.
Oríṣun àwòrán, Screenshot
Paul Play Dairo, ọmọ agba oṣere juju ni, IK Dairo lo kọkọ gbe ọrọ sita lori rẹ nigba to fi ọrọ naa soju opo ikansiraẹni Facebook rẹ.
Dairo ni pe  obinrin ẹni ọdun mọkanlelaadọta kọ ile mẹrin, ra mọto mẹta, o ran ọmọ nilẹ okeere ninu owo iṣẹ bara ọdun mẹwaa to ṣe."""
Ọpọ awọn to da si ọrọ naa loju opo facebook Paul Play Dairo ni wọn ke ibosi ara adugbo, ti wọn si ni pe awọn ti pinnu lati dẹkun ṣiṣe aanu fun awọn onibara mọ.
Oríṣun àwòrán, facebook/paul dairo/daddy freeze
Nibayii naa, gbajugbaja agbohunsafẹfẹ nni, Daddy freeze ni tirẹ ni nṣe ni ara oun n gbọn lati igba ti oun ti gbọ fọnran ohun akasilẹ naa, nitori o mu ẹru oore ṣiṣe fun onibara ba oun.
Oríṣun àwòrán, Screenshot
Haaa ni iṣẹlẹ naa n ṣe ọpọlọpọ loju opo ayelujara awọn mejeeji yii bayii, to si seese ki isẹlẹ naa da omi tutu sookan aya awọn araalu lati maa se oore fun onibaara.
Sunday Igboho: Àwọn èèyàn kan ní mò ń fi ètò ìjìjàgbara kó owó jọ láti lu jìbìtì
Gbajugbaja ajijagbara fun ilẹ Yoruba, Oloye Sunday Adeyemo Igboho ti faraya fun awọn eeyan to n pe ni onijibi ati gbajuẹ.
Igboho lasiko to n kopa lori eto kan ti agbẹnusọ rẹ, Olayomi Koiki se atọkun rẹ, nibi to ti n ba obinrin ilẹ okeere kan sọrọ, lo ti fara ya bẹẹ.
Ajijagbara  ọmọ ilẹ Yoruba naa ni eti oun ti kun pupọ nipa awọn eeyan to n sọ oun ni suna buruku pe onijibiti ni oun.
O ni awọn eeyan naa ni wọn n fi ẹnu ibajẹ kun eto ijijagbara ti oun n se pe oun fi n ko owo jọ ni, eto to buru jai.
Igboho ni Ọlọrun gba adura oun daadaa, ti kii se kekere pẹlu.
Igboho Ultimatum to Fulani: Ẹni bá mọ Sunday Igboho kó bá wa bẹ̀ẹ́ o,
"Eeyan nla ni mi ti Ọlọrun kẹ pupọ, ti ẹnikẹni ko si le jade wa pe mo lu oun ni jibiti owo lati de ipo nla ti mo wa loni.
A jade sita lati daabo bo awọn eeyan wa, ti awọn eeyan kan si ni nitori owo la fi n se e, ẹ jọọ, iru owo wo niyẹn.
Lọpọ igba ni mo maa n sọ pe ki ni ere mi ninu ijijagbara naa, titi debi pe awọn eeyan yoo maa naka aleebu si mi pe mo n lu awọn ni jibiti ni."
Igboho tun wa fọwọ sọya pe, gbajumọ onisowo ọlọjọ pipẹ ni oun, ti oun si ri taje se lai se kekere. Orukọ ileesẹ oun si ni Adeson International Concept Limited.
Ifọrọwerọ  pẹlu Gani Adams lori ọrọ Sunday Igboho
O fikun pe oun ni oludari agba fun ileesẹ elepo rọbi ati afẹfẹ idana gaasi naa, kii si se akoko yii ni oun da ileesẹ naa silẹ, ọjọ ti pẹ.
Sunday Igboho tun mẹnuba pe ijọba apapọ gan sewadi oun nigba ti wọn ri owo tuulu to wa ninu apo asunwọn owo oun nile ifowopamọ, ti wsn si gbẹsẹ le.
Amọ o ni ofo ọjọ keji ọja naa ni iwadi wọn ọhun ja si, ti wọn si pada kan saara si oun nitori wọn ri daju pe onisowo to lami laaka ni oun, isalẹ owo toun ko si lẹgbin.
Kò sí ìgbà kankan tí Yorùbá jókòó pé ki Igboho  lọ kéde ìyapa kúrò ní Nàíjíríà
Awọn eeyan kan wa n pe emi ni onijibiti, wọn n sọ orisirisi ọrọ kobakungbe pe mo fẹ lu awọn eeyan ni jibiti ni.
Bakan naa ni Igboho lo akoko eto naa lati tọrọ aforijin lọwọ awọn oriade ti wọn sọ pe awọn n yaju si tabi tabuku wọn.
O ni ki gbogbo awọn ọba alaye ti wọn ba ti sọrọ abuku si mase binu nitori a le bu ọba lẹyin, amọ ta ba de iwaju rẹ, a sọ pe a ko sọ bẹẹ.
"A ko yaju si awọn oriade wa, a kan n ke si wọn lati dide se ojuse wọn, nitori ẹtọ wa ni lati pe wọn, ara lo si n ta wa nipa eto aabo to mẹhẹ naa.
Ko gba ẹnu ọmọ ko ni ki iya oun pa idi mọ, nitori naa, ki wọn darijin wa ta ba yaju si wọn."
Covid-19: Wo ìròyìn òfegè mẹ́jọ táwọn adarí ẹ̀sìn ń sọ nípa àbẹ́rẹ́ àjẹsára Coronavirus
Ajijagbara naa wa fidi rẹ mulẹ pe, asiko ijijagbara fun ilẹ Oodua ti to nitori to ba ya awọn ọmọ kekeke yoo died lati gbeja ara wọn.
O ni awọn ọmọde naa yoo ja fun ẹtọ wọn, ti Ọba Oke yoo si ran wọn lọwọ lati gbeja wọn, idi si niyi ta fi gbọdọ dide.
O wa dupẹ lọwọ awọn ọmọ Yoruba to wa loke okun fun atilẹyin wọn fun eto ijijagbara to n se, to si ni akoko ti to bayii lati tako iwa isekupani, ijinigbe ati ifipabanilopọ.
Oríṣun àwòrán, koiki media
Eekan ọmọ Yoruba nni, Sunday Adeyẹmọ ti ọpọ eeyan mọ si Sunday Igboho, ti ṣalaye pe oun ko mọ adura gba bẹẹni oun o fi ọjọkan ri dupẹ lọwọ Ọlọrun fun oore ana.
Amọṣa, o ni oun mọ daju pe adura ọpọ awọn eeyan Ọlọrun bi awọn Alfa n gba pupọ lori oun, ni oun fi n se aseyọri.
Oloye Sunday Igboho ṣalaye ọrọ yii nigba to n sọrọ nibi eto Malud Nabiy kan to waye nilu Ido Ọṣun ni ipinlẹ Ọṣun.
Sunday Igboho ni ajogunba ni oogun abẹnugọngọ jẹ fun oun nitori ọwọ baba oun ni oun ti jogun rẹ ṣugbọn oun ko dara pọ mọ ẹgbẹ awo kankan.
Oríṣun àwòrán, koiki media
O fi kun un pe, lati kekere ni oun ti sunmọ awọn Alfaa, ti oun si mọ pe pupọ wọn lo ni ifẹ oun daradara, bẹẹ ni adura wọn ni gbogbo igba n gba lori oun.
"Igboho ni ""Aya mi tubọ di lati maa jijagbara tori adura awọn aafa n gba lori mi. Lati kekere ni mo ti sunmọ awọn Alfa bi n ko tilẹ mọ adura gba."""
Sunday Igboho wa ranti isẹlẹ kan to waye lopopona Ibadan silu Eko, lasiko ti awọn osisẹ ọtẹlẹmuyẹ DSS fẹ gbe ni tipatipa lasiko to n lọ silu Eko, amọ ti ori ko yọ.
Oríṣun àwòrán, Koiki Media
Asaaju ajijagbara naa mu wa siranti pe ọjọ Jimoh ni ọjọ ti isẹlẹ naa waye, adura ti awọn Alfa si gba fun oun lọjọ naa, lo ko oun yọ.
"Awọn osisẹ DSS to le ni ọgọta, ti gbogbo wọn gbe ibọn lọwọ, lo sẹburu mi lọjọ naa, ti wọn si ti wa baalu kekere ẹlikopita kalẹ, lati di mi ni apanyaka lọ silu Abuja.
Amọ mo kan pasẹ fun wọn pe ki wọn maa lọ, ni gbogbo wọn ba tuka, mo mọ pe adura tawọn Alfa gba fun mi lọjọ Jimoh naa lo gba lori mi."
"Igboho ni ""alaigbọn ẹda  ni yoo sọ pe ko si Alfa lẹyin wa, inu awọn Alfa si n dun pe adura awọn n gba lori wa."""
Covid-19: Wo ìròyìn òfegè mẹ́jọ táwọn adarí ẹ̀sìn ń sọ nípa àbẹ́rẹ́ àjẹsára Coronavirus
O wa fi ọwọ gbaya pe ni iwoyi ọdun ti n bọ, ilẹ Yoruba yoo ti wa ni ominira lasiko ọdun Nabiyy Maolud, tawọn ọba alaye yoo si pejọ lati se ayẹyẹ ominira ilẹ Yoruba lasiko naa.
Oloye Sunday Igboho tun jẹ ko di mimọ pe, ohun ti oun n ja fun, gẹgẹ bi idagbasoke, aabo ati alaafia ni ilẹ Yoruba n tẹsiwaju nitori atilẹyin awọn iranṣẹ Ọlọrun gbogbo ti wọn n fi adura ran oun lọwọ.
O ni ohun to n waye nilẹ Yoruba ko sẹlẹ ri, imọsi Ọlọrun ati tawọn Alfa, lo si jẹ ki oun maa se ohun ti mo n se.
Oríṣun àwòrán, Koiki Media
Awọn Alfa to wa nibi eto naa wa kan sara sii fun ọkan akin rẹ ati ifaraẹni jin fun idagbasoke ilẹ Yoruba paapaa julọ didide tako awọn ọdaran darandaran to n ji ọpọ gbe nilẹ Yoruba, ti wọn si tun ti sọ ọpọ di ero ọrun.
Ebenezer Obey and Simi: Commander ní akọrin tó ní tálẹ́ǹtì ni Simi, òun ní ìrírí tó dára pẹ̀lú rẹ̀
Oríṣun àwòrán, Instagram/Simply Simi
Awọn Yoruba maa n sọ pe bi okete ba dagba tan, ọmu ọmọ rẹ lo maa n mu.
Bayii lọrọ ri pẹlu gbajugbaja olorin Juju, Oloye Ebenezer Obey Fabiyi ti ọpọ maa n pe ni Chief Commander pẹlu olorin takasufe, Simisola ti ọpọ mọ si Simi.
Simi ṣe ẹda ọkan lara orin ti Obey ti kọ, ti akọle rẹ n jẹ ''Aimasiko'', eyi ti awọn mejeeji di jọ kọ papọ.
Nigba ti o ba awọn akọroyin sọrọ, Obey Commander ni iriri to dara ni kikọ orin awo ''Aimasiko'' papọ pẹlu Simi.
''Bi ọmọ ni Simi ati Adekunle Gold, ọkọ rẹ jẹ si mi.
'Èmi àti ìyàwó mi ti ń gbé pọ̀ nínú ìgbéyàwó wa fún 60 years', ẹ wá kọ́ ẹ̀kọ́ lẹ́nu àgbà méjì
Simi jẹ olorin to ni talẹnti gan an, o ṣe ẹda ọkan lara awọn awo orin, ''Aimasiko'' lẹyin to gba iyọnda lati ọdọ mi.
Lẹyin naa ni emi ati Simi jọ kọ orin naa papọ, eleyii to dun un gbọ leti.'' Ebenezer lo ṣalaye bẹẹ.
Agbaọjẹ olorin Juju naa ni onirẹlẹ ni Simi, atipe olorin ti ko ṣe fi ọwọ rọ sẹyin loun ati ọkọ rẹ, Adekunle Gold.
Ebenezer Obey ko ṣai sọrọ nipa Burna Boy ati Wizkid ti wọn gba ami ẹyẹ agbaye Grammy ninu orin kikọ.
Covid-19: Wo ìròyìn òfegè mẹ́jọ táwọn adarí ẹ̀sìn ń sọ nípa àbẹ́rẹ́ àjẹsára Coronavirus
''Idunnu lo jẹ fun mi pe Burna Boy ati Wizkid pada gba ami ẹyẹ Grammy, oriire nla ni,'' Obey lo sọ bẹẹ.
Chief Commander, ti yoo pe ẹni ọdun mọkandinlọgọrin lọjọ kẹta oṣu kẹrin sọ pe gbogbo iyoku aye oun, Ọlọrun oba loun yoo fi sin.
Obey ni igba mẹrin ọtọtọ lawọn eeyan kan ti tufọ oun lai tii ku, nitori naa, ''mo ni lati maa yin Ọba oke to da mi si.
Ati pe jijẹ olorin fun ọgọta ọdun to lati maa yin Eleduwa to fun mi ni ore ọfẹ,'' Chief Commander lo ṣalaye bẹẹ.
Miscarriage paid leave: Owó àti ìsinmi tí ìjọba yóò fún ọ rèé, tí oyún bá bàjẹ́ tàbí bímọ kú
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ko si ani-ani pe obinrin ti oyun ba bajẹ lara rẹ tabi ti o ba bimọ ku nilo itọju ati imulọkanle.
Eyi lo mi ki ile aṣofin orilẹede New Zealand buwọlu agbekalẹ ofin kan fawọn obinrin ti wọn ba bimọ ku tabi tabi ti oyun bajẹ lara wọn.
Labẹ ofin yii, awọn oṣiṣẹ ti iru nnkan yii ba ṣẹlẹ si yoo lanfaani lati gba isinmi ọjọ mẹta lẹnu iṣẹ, ti ijọba tabi awọn to gbawọn ṣiṣẹ si tun gbọdọ fun wọn lowo pẹlu.
Aṣofin ẹgbẹ oṣelu Labour, Ginny Andersen to da aba ofin ọhun ṣalaye pe, ofin naa jẹ ẹtọ awọn ọmọbibi orilẹede New Zealand.
Aṣofin Andersen ni eyi yoo fun awọn ti oyun bajẹ lara wọn ni asiko lati tọju ara wọn, ki wọn to pada sẹnu iṣẹ.
O fikun ọrọ rẹ pe, New Zeland ni orilẹede keji lagbaaye lẹyin India, ti yoo gbe iru ofin yii kalẹ fawọn araalu.
Andersen ni ofin yii yoo fawọn obinrin ni igboya lati gba aaye fun isinmi lẹnu iṣẹ ti oyun ba bajẹ lara wọn tabi ti wọn ba bimọ ku.
Aṣofin naa ni awọn agbaniṣiṣẹ kan maa n fawọn obinrin to ba ni iru iriri bayii ni isinmi lẹnu iṣẹ, ṣugbọn awọn kan kii ṣe bẹẹ eleyii ti ko tọna.
Covid-19: Wo ìròyìn òfegè mẹ́jọ táwọn adarí ẹ̀sìn ń sọ nípa àbẹ́rẹ́ àjẹsára Coronavirus
O ṣalaye pe ofin tuntun yii yoo mu ẹgan tabi oju abuku tawọn kan maa n fi wo awọn ti oyun ba bajẹ lara wọn kuro.
Bakan naa lo sọ pe ofin ọhun yoo tun fawọn obinrin ni igboya lati le maa sọ nipa bibi ọmọ ku tabi oyun bibajẹ lara obinrin.
O ni ofin naa yoo tun fawọn obinrin lanfaani lati beere fun iranwọ nigba ti oyun ba bajẹ lara wọn.
Igbimọ alaṣẹ ijọba New Zealand ni lati buwọlu ofin yii ki o to di amulo nilẹ naa.
Miss Pepeiye: Òṣèré tíátà Yorùbá ṣe ìyàwó pẹ̀lú agbábọ́ọ̀lù Super Eagles Peter Olayinka
Oríṣun àwòrán, Instagram/yetundebarnabas
Ojo ifẹ ti rọ nile agbabọọlu Super Eagles, Peter Olayinka ati oṣere tiata Yoruba kan, Yetunde Barnabas ti ọpọ mọ si Miss Pepeiye, nitori ipa to ko ninu ere Papa Ajasco.
Ọjọ Abamẹta ọjọ kẹtadinlọgbọn oṣu kẹta ọdun 2021 yii ni Olayinka gbe Yetunde ni iyawo.
Iroyin ti a gbọ ni pe, Olayinka pade Yetunde lọdun 2019 ni ọdun kan naa ti o ṣoju ẹgbẹ agbabọọlu Super Eagles Naijiria fun igba akọkọ.
Lati igba naa si ni wọn ti bẹrẹ irinajo ifẹ wọn, ki wọn to di lọkọ laya lọjọ kẹtadinlọgbọn oṣu kẹta.
Lẹyin oṣu mẹta ti Peter dẹnu ifẹ kọ Yetunde ni wọn gbe igbesẹ akọkọ, nipa ṣiṣe mọ mi n mọ ọ pẹlu awọn ẹbi wọn.
Lẹyin naa ni wọn ṣe igbeyawo, ti awọn mejeeji si di lọkọ laya.
Olayinka ati Yetunde ni wọn sọ oriṣiiriṣii ọrọ ifẹ loju opo Instagram wọn, lẹyin ti wọn so wọn pọ tan.
Yetunde sọ loju opo Instagram rẹ pe ''o ṣe ti o fihan mi pe ifẹ otitọ ṣi wa.
Eyi gan an lo jẹ ki n gbe igbesẹ lati jẹ tirẹ titi aye mi.''
Olayinka ni tiẹ sọ lori Instagram pe ''mo le maa mọ ọrọ to yẹ ki n lo lati fi idunnu mi han ati iru ibukun to rọgba yi mi ka lẹyin ti o wọn inu aye mi.
Ṣugbọn mo ṣa fẹ ki o mọ pe mo nifẹ rẹ pẹlu gbogbo ohun to wa ninu mi, ati pe irinajo ti a bẹrẹ yii, titi laelae ni.''
Lẹyin ti wọn so awọn mejeeji pọ tan ni tọkọ taya fi ijo bẹẹ ti wọn si jọ sọdi rukẹ.
Bola Tinubu: Ojú ọjọ́ ti kò dára ṣèdíwọ́ fáwọn èèkànlú láti bá Asiwaju ṣe ọjọ́ ìbí ní Kano
Oríṣun àwòrán, @akandeoj
Yoruba ni riro ni ti eniyan amọ sise ni ti Ọlọrun nitori ko si ẹda to mọ ọla.
Bẹẹ ni ọrọ ri nibi eto idanilẹkọ ọlọdọọdun, ikejila iru rẹ, ti wọn gbe kalẹ lati sami ọjọ ibi asaaju ẹgbẹ oselu APC, Asiwaju Bola Tinubu nilu Kano.
Idi ni pe ọpọ awọn eeyan jankan jankan to yẹ ko peju sibi ayẹyẹ naa ni ko le lọ nitori oju ọjọ ti ko dara.
Oju ọjọ to mẹhẹ naa lo se idiwọ fun baalu wọn lati fo lọ silu Kano nibi ti idanilẹkọ ọjọ ibi naa ti n waye.
Onpetu Ijeru: Akala ní torí Aláàfin kò ṣúgbàá òun fún sáà kejì, ló ṣe ní kí pín ipò alága
Lara awọn eekanlu ti oju ọjọ sediwọ fun lati peju sibi ayẹyẹ naa ni igbakeji aarẹ Yemi Osinbajo, Minisita fọrọ abẹle, Rauf Aregbesola ati olori ile asojusofin nilẹ wa, Femi Gbajabiamila.
Awọn yoku ni akọwe fun ijọba apapọ Naijiria, Boss Mustapha, Minisita feto iroyin ati asa, Lai Muhammed atawsn eeyan jankan jankan miran.
Nigba to n fidi isẹlẹ yii mulẹ ni oju opo Twitter rẹ, agbẹnusọ fun igbakeji aarẹ, Laolu Akande kede pe ori ayelujara ni aarẹ ati igbakeji rẹ yoo ti wo eto naa.
Oríṣun àwòrán, @akandeoj
O ni aarọ yii lo yẹ ki Yemi Osinbajo tẹ baalu leti lọ silu Kano fun idanilẹkọ ti wọn fi sọri ọjọ ibi kọkandinlaadọrin Asiwaju Bola Tinubu.
Amọ Akande tẹsiwaju pe oju ọjọ ti ko dara lo se idiwọ fun igbakeji aarẹ lati peju sibi eto naa.
Oríṣun àwòrán, @MBuhari
Ileesẹ aarẹ Naijiria ti sọrọ lori ọrọ kan to gba igboro kan pe owo Naira ilẹ wa yoo ba owo Dọla kan dọgba ni kete ti Muhammmadu Buhari ba gba akoso.
Ọrọ yii ni awọn eeyan kan sọ pe Buhari fi se ileri lasiko ipolongo ibo rẹ lọdun 2015.
Amọ nigba to n fesi lori ọrọ ọhun, Oludamọran fun aarẹ Buhari feto iroyin, Femi Adesina salaye pe aarẹ ko figba kankan seleri bẹẹ fawọn ọmọ Naijiria.
Adesina, lasiko to n kopa lori eto ori tẹlifisan kan nilu Eko fikun pe ayederu ati iroyin eke ni ọrọ bẹẹ, ko waye ri .
Iru ọrọ bayii ko waye ri. Ayederu iroyin ni, ti ko le see se.
Onpetu Ijeru: Akala ní torí Aláàfin kò ṣúgbàá òun fún sáà kejì, ló ṣe ní kí pín ipò alága
Bẹẹ ba gbagbe, o ti to ọjọ mẹta tawọn eeyan kan ti n ni aarẹ Buhari niran nipa awọn ileri to se lasiko eto ipolongo ibo rẹ lọdun 2015.
Ileri pe Buhari ni Naira kan yoo fi ẹgbẹ kẹgbẹ pẹlu Dọla kan lọdun 2015 si ni wọn n gba bii ẹni gba igba ọti lawọn oju opo ayelujara gbogbo.
Lọwọlọwọ bayii, lẹyin ti aarẹ Buhari ti lo ọdun mẹfa lori aleefa, ọrinlenirinwo naira ni wọn fi n se pasipaarọ fun dọla kan bayii.
'Òde ìnáwó làwọn èèyàn ma ń rò bí wọ́n bá rí Ankara, ìgbà tí wọ́n rí i lára àga tí mo ṣe, ẹnu wọn ò padé mọ́'
Idi si ree ti awọn ọmọ Naijiria fi n lọgun pe isẹlẹ naa tako ileri ti aarẹ Buhari se fun awọn lọdun 2015 to fẹ dije.
Oríṣun àwòrán, Twitter/Haramain Sharifain
Ina ṣẹyọ lẹgbẹ mọṣalaaṣi Anabi Mohammad ni Medina ni orilẹede Saudi Arabia.
Oriṣiiriṣii fidio to lu ori opo Twitter pa ṣe afihan bi ina ọhun ṣe n jo ile kan, to wa lẹgbẹ mọṣalaaṣi Anabi ti eefi ṣi gbalẹ nibẹ.
Ko si ẹni to kọkọ mọ ohun to ṣe okunfa iṣẹlẹ ọhun.
Amọ, wọn ti pada pa ina ọhun to n jo bi ina sufuru tẹlẹ.
Haramain Sharifain to fi awọn fidio naa lede loju opo Twitter rẹ sọ pe, kete tawọn oṣiṣẹ alaabo Civil Defence de ibi iṣẹlẹ naa ni wọn pana ọhun.
Gbogbo bi iṣẹlẹ naa ti waye kawọn panapana to de lo wa ninu fidio ti Sharifain fi soju opo Twitter rẹ.
Japesa: N kò fẹ́ da àwọn olólùfẹ́ mi láàmú ni mo ṣe ra pósí fún ìpalẹ̀mọ́ ìsìnkú mi
Oríṣun àwòrán, Instagram/japesakenya
Ẹnu ko gba iroyin lori ayelujara ni ọjọ Satide nigba ti ọdọmọde akọrin kan sadede ra posi ara rẹ.
Akọrin ọhun, to gbajumọ bii isana ẹlẹẹta lorilẹede Kenya, lo sadede kede loju opo ibadọrẹ Instagram rẹ pe oun ti ra posi ti wọn yoo fi sin oun, ti oun ba jade laye.
Akọrin yii, ti orukọ rẹ n jẹ Phillip Ptaroba Okoyo, ti ọpọ eeyan ni Kenya mọ si Japesa ni oun gbe igbesẹ ọhun ni ipalẹmọ fun eto isinku oun.
"Papesa kọ soju opo Instagram rẹ pe ""Mo sẹsẹ ra posi kan fun isinku ara mi ni, nitori n ko fẹ yọ ẹyin ololufẹ mi lẹnu, ti mo ba ku tan."""
Oríṣun àwòrán, Instagram/japesakenya
Bakan naa ni aworan ti Japesa gbe sita naa se afihan rẹ to ba posi ọhun ya fọto, ki aye le ri pe otitọ ni ọrọ rẹ.
Ikede yii lo ba awọn ololufẹ rẹ lojiji, ti wọn si n fesi pada fun pe ko sọra se nipa ọrọ ẹnu rẹ nitori ahọn lewu.
Awọn ọpọ lo n kọminu pe ki lo le sẹlẹ, ti ọdọmọde akọrin yoo fi maa ra posi ara rẹ.
Onpetu Ijeru: Akala ní torí Aláàfin kò ṣúgbàá òun fún sáà kejì, ló ṣe ní kí pín ipò alága
Sugbọn lero tawọn eeyan miran, posi ti Japesa ra gan jẹ olowo pọọku, ti ko wọn rara, eyi to fara han pe wọn kan n ba sere lori ikede rẹ yii ni.
Oríṣun àwòrán, PIUS UTOMI EKPEI
Ẹgbẹ awọn dokita nileewosan agba gbogbo lorilẹede Naijiria, NARD ti kede pe, awọn yoo bẹrẹ iyanṣẹlodi ni Ọjọbọ ọsẹ yii.
Nard wa yan pe ayafi ti ijọba apapọ ba gbe igbesẹ kanmọnkia lori ibeere wọn nikan ni ẹrọ iyansẹlodi naa.
Igbimọ akoso agba fẹgbẹ awọn dokita, NEC ti buwọlu itẹsiwaju iyanṣẹlodi naa, nibi ipade wọn to waye nileewosan nla apapọ orilẹede Naijiria nilu Abuja.
Gẹgẹ bi atẹjade kan ti wọn fi sita lẹyin ipade naa ṣe sọ, ọrọ aisan owo oṣu fun wọn jẹ koko ninu ohun to n fa iyanṣẹlodi naa.
Wọn ni yatọ si pe ijọba n jẹ awọn dokita naa ni owo oṣu mẹta, ọpọ awọn dokita naa ni wọn tun nkoju ipenija owo oṣu ṣaaju eyi kaakiri awọn ileewosan, paapaajulọ awọn ileewosan nlanla to jẹ tijọba ipinlẹ.
Oríṣun àwòrán, NARD
Fun apẹrẹ, ọpọlọpọ awọn dokita naa, labẹ eto GIFMIS ni wọn ko tii ri owo oṣu wọn gba fun oṣu mẹrin bayii.
Ni ileekọṣẹ iṣegun bii ABSUTJH, ogun oṣu lawọn dokita nibẹ ko tii fi gba owo oṣu bayii, ni ileewosan IMSUT, wọn ko tii gba owo oṣu tiwọn naa pẹlu.
Yahoo Boys Akute-Alagbole: Iléeṣé ọlọ́pàá Ogun ní kò sí ẹnikẹ́ni tó fi ìṣẹ̀lẹ̀ náà tó òhun létí
Oríṣun àwòrán, EFCC
Laipẹ yii ni iroyin kan gba oju opo ibanidọrẹ Twitter pe awọn ọdọ bii aadọta ti jade laye lẹyin ti wọn ti ibi apejẹ ọjọ ibi kan de.
Gẹgẹ bi ẹnikan to gbe iroyin naa soju opo ayelujara rẹ ti wi, ọdọmọde gbajuẹ kan, tawọn eeyan n pe ni Yahoo Boy lo se apejẹ ọjọ ibi rẹ, to si kesi awọn ọrẹ rẹ naa, lati wa ba yọ.
Isẹlẹ naa ti wọn lo waye ni adugbo Alagbole Akute nipinlẹ Ogun lo sọ pe awọn ọdọ bii aadọta to bawọn peju sibi isẹlẹ naa lo ti tẹri gbasọ lairotẹlẹ.
Nigba ti wọn n fesi si iroyin ọhun, ẹnikan to pe ara rẹ ni Yusuff Yinka Rilwan naa fọwọ gbaya pe lootọ ni isẹlẹ naa waye.
Koda, Yusuff ni aladugbo oun kan padanu ọrẹ, ọmọ rẹ meji, bakan naa lo ni ọkunrin kan ni opopona ti oun n gbe naa bawọn peju sibi apejẹ ọhun.
Oríṣun àwòrán, @pelumiAwotedu
O fikun pe ọkunrin naa ati ọrẹ rẹ mẹrin lo sọ ẹmi wọn nu sinu isẹlẹ naa, awọn eeyan to si ku mọ oun ti oun mọ ree lai le sọ awọn ti oun ko mọ, to ba isẹlẹ naa lọ.
O ni won ti ka to ọgbọn eeyan to ti jade laye bayii lati ipasẹ isẹlẹ naa, ti wọn si tun n ka oku awọn eeyan to lọ sibi apejẹ ọhun siwaju.
Koda, iroyin naa ni ẹni to se apejẹ ọjọ ibi gan pẹlu ti dagbere faye.
Ọpọ eeyan to gbọ nipa isẹlẹ yii lo n para poro lori ayelujara, ti wọn si ni o see se ko jẹ pe wọn fi awọn eeyan yii se etutu ni.
Oríṣun àwòrán, @Ysquare_R
Sugbọn lero tawọn eeyan miran, iku awọn ọdọ yii le wa lati ipasẹ majele ti wọ́n jẹ nibi apejẹ naa, paapaa nigba to jẹ pe ẹni to n se ọjọ ibi naa ti ku pẹlu.
Isẹlẹ akanilaya ta gbọ yii lo mu wa maa finnu finlẹ pe se lootọ ni lo waye bi abi agbelẹrọ lori ayelujara lasan ni.
Nigba to n ba BBC Yoruba sọrọ nipa isẹlẹ naa, ẹnikan to pe orukọ ara rẹ Samuel sọ fun BBC Yoruba pe iroyin naa kii se ojulowo tan.
O ni lootọ ni awọn gende mẹrin kan to sun sile itura ni adugbo Alagbole naa jade laye lẹyin ti wọn ti apejẹ kan de.
Samuel ni eeyan mẹrin pere ni oun mọ to ku sile itura, amọ bi awọn eeyan kan se wa n kede pe eeyan to ku to aadọta jẹ kayeefi.
Onpetu Ijeru: Akala ní torí Aláàfin kò ṣúgbàá òun fún sáà kejì, ló ṣe ní kí pín ipò alága
O ni ọrọ okeere, bi ko ba le ọkan yoo dinkan ni, ọpọ eeyan ti oju rẹ ko to ọrọ si lo maa n kede rẹ lori ayelujara.
"O see se ko jẹ pe majele wa ninu ounjẹ ti wọn jẹ laimọ amọ ko si ẹni to le fidi rẹ mulẹ pe wọn fi wọn se etutu ni.'
Ninu iyanju wa lati ti idi otitọ mulẹ, BBC Yoruba ba alukoro fun ileesẹ ọlọ̀paa nipinlẹ Ogun, Abimbola Oyeyemi sọrọ lori isẹlẹ yii.
Nigba to n sọ ohun to mọ lori isẹlẹ yii, Oyeyemi ni irọ to jinna sootọ ni ikede naa nitori gbogbo ọna lawọn ti finmu finlẹ lati ri arigbamu lori isẹlẹ yii amọ ko si ohun to jọọ.
'Èmi àti ìyàwó mi ti ń gbé pọ̀ nínú ìgbéyàwó wa fún 60 years', ẹ wá kọ́ ẹ̀kọ́ lẹ́nu àgbà méjì
Irọ̀ nla patapata ni isẹlẹ naa, ko si ẹnikẹni to jalaisi lẹyin ti wọn ti ibi apejẹ de, debi pe eeyan aadọta ku."
"A gbe igbesẹ lati se awari isẹlẹ naa amọ irọ ni, koda, ko si ẹnikẹni to tọ ọlọpaa wa pe nnkan bayi waye."""
Oríṣun àwòrán, others
Ko din ni eeyan mẹta to jade laye nigba ti ẹgbẹ okunkun meji koju ara wọn lowurọ ọjọ Aiku nilu Oṣogbo.
Awọn eeyan mẹta naa ni awọn agbofinro fidi rẹ mulẹ pe wọn jẹ ọkan lara awọn ọmọ ẹgbẹ okunkun to n gbe ina woju ara wọn naa.
Ẹgbẹ okunkun Ẹyẹ ati Aiye ni awọn ẹgbẹ okunkun mejeeji ti ọrọ kan, afẹmọjumọ lati nnkan bi agogo mẹjọ owurọ si ni iroyin sọ pe wọn ti bẹrẹ wahala wọn.
Onpetu Ijeru: Akala ní torí Aláàfin kò ṣúgbàá òun fún sáà kejì, ló ṣe ní kí pín ipò alága
Agbegbe Kọlawọle ni ilu Oṣogbo si ni rogbodiyan ẹlẹgbẹ okunkun naa ti waye, eyi to to ọpọlọpọ wakati.
Agbegbe Kọlawọle, Alie ati Ọbalende ni iroyin sọ pe wọn ti pa awọn ọmọ ẹgbẹ okunkun mẹta naa, ti ọpọlọpọ miran si farapa yanayana.
Awọn nnkan ija oloro bii ibọn, ada igo, aake, ọbẹ ati apola igi lawọn ọmọ ẹgbẹ okunkun naa fi koju ara wọn.
Báa ṣe lọ́pọlọ tó, ẹnu Yorùbá ò kò, ọgbọ́n táa gbúdọ̀ dá rèé - Ìpàdé àgbààgbà Yorùbá n'Ibadan
Ọrọ ẹgbẹ okunkun ati wahala wọn ti wa di lemọlemọ bayii ni ipinlẹ Ọṣun paapaa ilu Oṣogbo, lati nnkan bii ọdun mẹrin sẹyin bayii.
Alukoro ileeṣẹ ọlọpaa ipinlẹ Oṣun, Yemisi Opalola to fi idi iṣẹlẹ naa mulẹ ṣalaye pe, ileeṣẹ ọlọpaa ti gbe oku to ku lọ sileewosan nla UNIOSUN, ti wọn si ti bẹrẹ iwadii pẹlu.
Bola Tinubu: Buhari gba 50m ọ̀dọ́ síṣẹ́ ológun láti pèsè iṣẹ́ àti kojú ìwà ọ̀daràn
Oríṣun àwòrán, The Presidency
Yoruba ni ti a ba le ewure titi, to fi kan ogiri, to ba fi yiju pada, yoo bu olowo rẹ jẹ ni.
Idi ree ti asaaju ẹgbẹ oselu APC nilẹ yii, Asiwaju Bola Ahmed Tinubu fi n lọgun tantan fun ijọba aarẹ Buhari pe aawẹ gbigba lojoojums ti su awọn ọmọ Naijiria.
Tinubu ke gbajare bẹẹ nibi idanilẹkọ ọlọdọọdun ti wọn fi sọri ọjọ ibi ọdun kọkandinlaadọrin rẹ, ikejila iru rẹ, to waye nilu Kano lọjọ Aje.
Akori idanilẹkọ naa ni 'Okun to so wa pọ ni ọrọ ajọni wa ati pataki ajọsepọ apapọ fun idagbasoke ati iserere'.
Tinubu ni akoko yii kii se akoko sọwona tabi se ọrọ aje ni koko wọn le, akoko to yẹ ka pese oniruuru anfaani ree.
Akomolede àti Asa: Ìyàtọ̀ tó wà láàrin ìlànà ìpolówó ọjà láyé àtijọ́ àti òde òní
"Bi orilẹede Amẹrika ba n na owo gọbọi lai wo ẹyin wo, ti wọn si tun n beere owo si fun ipese awọn ohun eelo amayedẹrun ati ipese isẹ.
Ki wa lo de ti ẹyin yoo fi ni ka maa gba aawẹ nigba ti ida mẹtalelọgbọn awọn ọdọ ninu ọgọrun ko ni isẹ lọwọ."
Tinubu fikun pe ọjọ pẹ tawọn ọmọ Naijiria ti n gbaawẹ, bẹẹ si ni airisẹse lo sokunfa iwa idunkookomọni ati ijinigbe atawọn iwa ọdaran miran.
Báa ṣe lọ́pọlọ tó, ẹnu Yorùbá ò kò, ọgbọ́n táa gbúdọ̀ dá rèé - Ìpàdé àgbààgbà Yorùbá n'Ibadan
O wa rọ ijọba apapọ lati gba awọn ọdọ to to aadọta miliọnu sisẹ ologun, ki a le koju iwa itajẹsilẹ, idunkooko mọni atawọn iwa miran to n dunkokoo mọ eto aabo wa.
Ọrọ to ti ẹnu Kọla Ologbodiyan, akọwe ipolongo fun ẹgbẹ oṣelu PDP lorilẹede Naijiria jade niyi nigba to fi n ba BBC News Yoruba sọrọ.
Ologbondiyan lo salaye lori bi nnkan ṣe n lọ si lagbo oṣelu orilẹede Naijiria ati igbesẹ ti ẹgbẹ oṣelu naa n gbe lati ṣe koriya fawọn ọdọ ati lati pa ina gbogbo aawọ lagbo rẹ.
O ni gbogbo aṣiwaju ati ọmọlẹyin gbogbo ninu ẹgbẹ oṣelu naa lo mọ pe ikọsẹ nlanla ni bi ẹgbẹ oṣelu APC ṣe gbajọba ni Naijiria.
Onpetu Ijeru: Akala ní torí Aláàfin kò ṣúgbàá òun fún sáà kejì, ló ṣe ní kí pín ipò alága
Bẹẹ lo tun mẹnuba iriri awọn ọmọ orilẹede Naijiria lati igba ti iṣejọba ẹgbẹ oṣelu APC ti bẹrẹ lọdun 2015.
Ọgbẹni Kọla Ologbodiyan ni ohun ti ẹgbẹ oṣelu APC tawọn ọmọ Naijiria 'gbe wa lati wa ṣeranwọ fun wọn' da silẹ gan, ju eyi ti araalu ti n kọminu le lori lati iṣaaju.
O ni ẹgbẹ oṣelu APC wa lati wa gba agbara ni lai ni imọ ati dari ilu, ṣugbọn ni ipadabọ PDP, araalu yoo mọ pe wọn ti lọ kọ ọgbọn wa.
Oríṣun àwòrán, Pdp
O wa ṣalaye pe, ẹgbẹ oṣelu PDP ti n ṣe agbeyẹwo bi adinku ṣe lee de ba iye owo ti awọn ọdọ yoo maa ra fọọmu idije ẹgbẹ oṣelu naa.
Ṣaaju eto idibo apapọ ọdun 2019, miliọnu mejila naira (N12 million) lawọn to dije fun ipo aarẹ lẹgbẹ oṣelu PDP san.
Awọn to dije fun ipo gomina ipinlẹ san miliọnu mẹfa naira (N6 million), awọn to dije fun ile aṣofin apapọ san miliọnu mẹta abọ Naira (N3.5 million naira) ile asofin ipinlẹ san ẹgbẹrun lọna ẹgbẹta naira (N600, 000).
'Èmi àti ìyàwó mi ti ń gbé pọ̀ nínú ìgbéyàwó wa fún 60 years', ẹ wá kọ́ ẹ̀kọ́ lẹ́nu àgbà méjì
Agbẹnusọ fun ẹgbẹ oṣelu PDP naa ni, ara awọn igbesẹ tuntun ti awọn n gbero le lori ni riri daju pe owo fifi ifẹ han lati dije nikan lawọn ọdọ n san, gẹgẹ bi wọn ṣe ṣe fawọn obinrin.
O ni gbogbo igbesẹ wọnyii lo ṣi wa labẹ ijiroro lawọn ẹka gbogbo lẹgbẹ oṣelu naa.
Oduduwa Republic: Oba Yoruba Bauchi ní wíwọ ara wọn Yorùbá àti Hausa kò ní kí Yorùbá má ya kúrò ní Nàìjíríà
Oríṣun àwòrán, Amani
Oba Yoruba ni Bauchi, Alhaji Tirimisiyu Adegoke ti fesi si ọrọ ọmọ ẹgbẹ Yoruba, Yoruba welfare group (YWG) to sọ pe awọn ko fẹ Oduduwa Republic.
Oba Yoruba Bauchi sọ pe lootọọ ni Hausa ati Yoruba ti wọ inu ara wọn, amọ iyẹn ko ni ki Yoruba maa yapa kuro lara orilẹede Naijiria.
Oba Adegoke ni ti Yoruba ba maa lọ, wọn ni lati joko pẹlu awọn Hausa ki wọn jọ sọ asọyepọ lọna ti ko ni fa ija.
''Ogun ni emi ko fẹ, ti aṣoyepọ ba le waye, Yoruba ni lati fi ọgbọn ṣe ọrọ naa ko maa ba mu wahala dani.
Onpetu Ijeru: Akala ní torí Aláàfin kò ṣúgbàá òun fún sáà kejì, ló ṣe ní kí pín ipò alága
Otitọ ni pe ọpọ Hausa ti fẹ Yoruba ni iyawo, awọn Yoruba naa ti fẹ Hausa, a ti wọ ara ra ṣugbọn a gbọdọ sọ asọyepọ,'' Oba Adegoke lo sọ bẹẹ.
Oba Yoruba Bauchi ko ṣai sọ pe oun ko mọ ohun kan nipa ẹgbẹ Yoruba YWG ti wọn sọrọ yii gan an.
O fikun ọrọ rẹ pe, ko si ọba Yoruba ni Kaduna ti ẹgbẹ YWG ti bawọn akọroyin sọrọ.
Sunday Igboho, àwa Yorùbá lókè Ọya kò wálé, a kò fẹ́ Oduduwa Republic - YWG
Oríṣun àwòrán, Abdulhakeem Adegoke Facebook
Ẹgbẹ ọmọ Yoruba nipinlẹ mọkandinlogun to wa lapa ariwa orilẹede Naijiria, Yoruba welfare group (YWG) ti sọ pe awọn ko faramọ yiyapa kuro lara Naijiria, lati da Oduduwa Republic silẹ.
Nibi ipade awọn akọroyin to waye lọjọ Aiku niluu Kaduna, aarẹ ẹgbẹ YWG, Abdulhakeem Adegoke sọ pe, awọn Yoruba to wa nilẹ Hausa ko fẹ orilẹede mii lẹyin orilẹede Naijiria.
Ọgbẹni Adegoke ṣalaye pe, awọn Hausa ti gbawọn Yoruba tọwọ tẹsẹ lati igba tawọn ti n jọ n gbe papọ.
''A n sọrọ gẹgẹ bi aṣoju gbogbo ọmọ Yoruba to wa ni ipinlẹ mọkandinlogun nilẹ loke Oya pe, ọmọ Naijiria ni wa, a ko si si lara awọn to n beere fun Oduduwa Nation.
Bed Wetting: Tolulope Joseph ní ò lé ní ogún ọdún tí òun fi tọ̀ sílé kí ìwòsàn tó dé
Awọn Yoruba atawọn Hausa ti wọ inu ara wa wọn, awọn baba nla wa nilẹ Yoruba ti wa nilẹ Hausa fun bii igba ọdun.
Ọpọ ninu wa lo ti fẹ awọn Hausa gẹgẹ ọkọ tabi iyawo, bakan naa lawọn Hausa ti fẹ Yoruba.
Ati pe, okoowo wa nilẹ Hausa ju tiriliọnu marun un lọ, gbogbo awa Yoruba ti a wa nilẹ Hausa si tun ju ipinlẹ mẹta nilẹ Yoruba lọ.
Nitori naa, a ko le lọ darapọ mawọn ti ko bikita nipa ẹmi ati dukia wa lasiko yii,'' Ọgbẹni Adegoke lo ṣalaye bẹẹ.
Eekan ilẹ Yoruba, Ọjọgbọn Banji Akintoye ati ajijagbara Sunday Adeyemo, ti ọpọ mọ si Sunday Igboho wa lara awọn aṣaaju to n beere fun yiyapa Yoruba kuro lara Naijiria lati da Oduduwa Nation silẹ.
Kashimawo Laloko: Gbajúgbajà akọ́nimọ̀ọ́gbá eré bọ́ọ̀lù Laloko tó ṣàwárí Mikel Obi àti Osaze dágbére fáyé
Oríṣun àwòrán, NFF
Iku ṣeka, iku doro. Iku ti mu ọga agba tẹrẹ ri ni ajọ to n ri si ere bọọlu afẹsẹgba lorilẹede Naijiria, NFF, Kashimawo Laloko lọ.
Ọkan lara awọn ọmọkunrin rẹ, Adewale lo kede pe ile iwosan Sacred Hearts Catholic Hospital niluu Abeokuta ni Laloko ku si lọjọ Aiku lẹni ọdun mẹrindinlọgọrin.
Yatọ si wi pe, Laloko kii fọwọ sori ahọn sọ, o ṣiṣẹ takun takun lati mu ilọsiwaju ba gbajugbaja ileeṣẹ ikọni ni bọọlu afẹsẹgba Pepsi Football Academy.
Ọpọ awọn agbabọọlu to di ilumọọka lonii lo jade lati Pepsi Football Academy.
Awọn agbabọọlu bii Mikel Obi, Osaze Odemwingie, Soga Sambo, Elderson Echejile, Joseph Akpala ati Yinka Adedeji ati bẹẹ bẹẹ lọ lo jade ni Pepsi Academy.
Koda Laloko ṣe akọnimọọgba ẹgbẹ agbabọọlu orilẹede Gambia nigba aye rẹ.
Awọn ẹbi ti kede pe wọn yoo sin Laloko to jẹ Olori Parakoyi ilu Egba si ile rẹ to wa lagbegbe Gbonagun niluu Abeokuta.
Akomolede àti Asa: Ìyàtọ̀ tó wà láàrin ìlànà ìpolówó ọjà láyé àtijọ́ àti òde òní
Ipolowo ọja ni agunmu owo, gẹgẹ bi Yoruba se maa n sọ.
Bẹẹ si ni ọja tabi isẹ ti eeyan ko ba polowo rẹ yoo di okuta ni, idi si ree ti ilana ipolowo ọja nilana adayeba kii fi se ohun amusere.
Lori eto Akomolede ati Asa lọsẹ yii, olukọ wa, Olayinka aya Olorunyolemi tile ẹkọ girama St Louis nilu Akure kọ wa nipa ipolowo ọja nilẹ Yoruba.
Bakan naa lo mẹnuba awọn ọna ara ta maa n gba polowo ọja ati isẹ laye atijọ, bẹẹ lo tun mẹnuba oniruuru awọn ọja to wa bii ọja owurọ, ọsan ati alẹ.
Àwọn ìtàn mánigbàgbé tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí:
Ẹ wa nnkan fidi le lati wa kẹkọ ilana ipolowo ọja nilana abalaye lori eto yii, ẹ ku ikalẹ.
Ooduwa Republic: Gani àwọn alálẹ̀ yóò gbe wá, tá bá fi òtítọ̀ jà fún òmìnira
Oríṣun àwòrán, Gani Adams
Yoruba ni ọwọ ọmọde ko to pẹpẹ, tawọn agba naa ko si wọ keregbe nitori ọmọde gbọn, agba gbọn la fi da ilẹ ifẹ.
Eyi lo mu ki Aarẹ Ọna Kakanfo nilẹ Yoruba, Iba Gani Adams se n mu da awọn ọmọ Yoruba loju nipa awọn ilana ti wn yoo lo lati gba ominira fun ilẹ Yoruba.
Adams ni awọ̀n ọ̀mọ Yoruba naa ni Ọlọrun yoo lo lati gba ominira ọhun , bawọn to wa ninu ile se ni ipa ti wọn yoo ko, naa lawọn ọmọ Yoruba to wa loke okun yoo ko ipa ti wọn naa.
Gani Adams, lasiko to n kopa lori eto ileesẹ wa BBC Yoruba, tun salaye pe isọri meji ni awọn eeyan pin si, ero wa, bẹẹ naa si ni awọn eeyan wa.
O ni awọn alagbara ọmọ Yoruba wa lawọn orilẹede kaakiri awọn ilu oyinbo to pọ, ti wọn mọ eeyan nla nla ati ninu ajọ isọkan agbaye, United Nations.
Atunto Naijiria la n fẹ - Aarẹ Onakakanfo, Gani Adams
A ni awọn ọmọwe kaakiri ti ọwọja wọn na kaakiri agbaye, koda, awọn miran wa laarin wọn ti wn ko ni kan ilẹkun, ki wọn to wọle tọ Biden, tii se aarẹ orilẹede Amẹrika.
O ni gbogbo wọn ni wọn setan lati ja fun ominira ilẹ Yoruba lai lo ọta ibọn, o fikun pe ati ero, ati eeyan ni yoo wulo fun ominira Yoruba, nigba ti akoko ba to.
O wa laa kalẹ pe ọrọ sise girigiri lori ayelujara kọ ni ọrọ gbigba ominira ta n wi yii, kii si se ọrọ ariwo tabi ọrọ Gani Adams tabi ọrọ Sunday Igboho.
Pure Water Lylon Art: Adejoke ní ohun èlò ta fi ọ̀rá ṣe ń ní àlòpẹ́, kìí tètè jẹ
Iba rọ gbogbo ìràn Yorùbá láti ja ìjàgbara láti gba òmìnira, kí wọ́n yé fi òṣèlú ṣe òhunkóhun, pàápàá jùlọ àwọn tó wà ní òkè òkun.
Aarẹ Gani Adams wa rọ awọn ọba alaye nilẹ Yoruba atawọn eeyan to n tako iyapa kuro ni Naijiria lati ronu wo lẹẹmeji, nitori o le lẹyin, bi oku iya jọjọ.
"Ẹ jẹ ka se otitọ, ka se ara wa ni ọkan soso, ka si fi imọ se ọkan, kawọn alalẹ le gbe wa, ka nifẹ ara wa, ka si mase gba abọde fun iran Yoruba.
Ẹ ma se abosi, ka si ranti iran to n bọ, ẹgbẹ ẹya Yoruba ti pọ ju, tawọn kan si n da nnkan ru, ko si yẹ ka jẹ ki owo tabi oselu da aarin wa ru nitori owo yoo tan, oselu yoo lọ amọ alajọbi ni yoo ku."
Nigba to n dahun ibeere pe nibo ni ipinlẹ Kogi ati Kwara yoo wa, ti ẹkun iwọ oorun guusu Naijiria ba yapa, Gani Adams ni bi igi ba wo lu igi, ti oke rẹ la kọkọ re kuro.
O ni ẹkun iwọ oorun yoo kọkọ gba ara rẹ silẹ lọwọ iya na, ko to wa mọ ọna ti yoo gba ko awọn eeyan rẹ to n bẹ ni Kwara ati Kogi naa kuro.
A ni ka kọkọ ko ara wa kuro ni ọfin ta jin si yii na, ka to wa maa ko awọn eeyan wa to wa kaakiri mọra, a kọkọ le ẹyọrọ jinna na, ka to pada wa fi abọ fun adiẹ.
Ifọrọwerọ  pẹlu Gani Adams lori ọrọ Sunday Igboho
Ààrẹ ọ̀nà Kankanfo gbogbo ilẹ̀ Yorùbá, Iba Gbaniyu Ige Adams tí kéde pé ómó Yorùbá kò ni tá ẹ̀jẹ̀ sílẹ̀ tábi já ogun kankan títí ọwọ́ wọn yóò fi tèkudà.
Iba Gani Adams sọ èyí lásìkò tó ń ṣe ìfọ̀rọ̀wérọ̀ pẹ̀lú BBC News Yorùbá lórí ọ̀rọ̀ Oduduwa Republic tí àwọn ọmọ káàrọ̀-ò-jíire ń pè fún.
Ó ní kí ìjọba má halẹ̀ ogun mọ́ ẹnikẹni, ńiwọ̀n ìgbà tí ilẹ̀ gbogbo ẹ̀yà Yorùbá kò ti wọ inú ilẹ̀ ẹ̀yà míràn, kò sí ǹkan tó le fa ìjà láàrín Yòrùbá àti ẹ̀yà míràn.
Ó ní gbogbo Fulani nilẹ̀ Yorùbá lé dúró sọdọ wa níwọ̀n ìgbà tí wọ́n kò bá gba àbọ̀dè fún ẹ̀yà Yorùbá, àwọn Yorùbá tó bá sì wà ní ilẹ̀ Hausa le dúró síbẹ̀ láì padà wálé.
Ilẹ Fulani wa ni Sokoto lọhun, Kaduna ni ẹnu aala Middle Belt, ilẹ Yoruba ko wọ inu ilẹ ẹya miran rara, nitori naa, ko le si ija rara.
Wakili tẹẹ rí yẹn kìí ṣe ẹran rírọ̀, ó ń díbọ́n ní o - Iba Gani Adams
Gani Adams wa kede fun awọn eeyan to n bẹru pe ogun le waye nitori iyapa pe, ki wọn mase fi ogun halẹ mọ wa rara.
"Ko le si ogun kankan, bẹẹ ni ko si ọrọ pe a gba fisa ka to wọ ilu Kano, irọ ni, se a n gba fisa wọ Ghana ni? Ẹkun iwọ oorun Afirika ni gbogbo wa wa.
Ọdun mẹfa la fi ja ogun June 12 lai ta ọta ibọn kankan, titi ti akoso ijọba apapọ fi bọ si ọwọ ọmọ Yoruba, nitori naa, ọrọ ogun jija ko le waye."
"Amọ to ba jẹ ogun naa ni yoo yanju rẹ, ẹru ko ba mi nitori mo setan lati tẹle iran Yoruba nibi kibi to ba n lọ, n ko ni gbabọde fun ilẹ Yoruba."""
Oríṣun àwòrán, kwam1_official/Instagram
Lórí orin ti K1 kọ ránṣẹ́ pé kí Iba Adams jẹ́ kí ọmọ Yorùbá de ipò ààrẹ Nàìjíríà náà, Gani Adams ni olórin ni Wasiu Ayinde ti gbogbo ènìyàn mọ̀ sí K1, àwọn alágbára sì ló má n rán irú wọ́n níṣẹ́.
Ẹni awa naa maa n ba pade loju agbo, ta maa n nawo fun ni Wasiu Ayinde, awọn olorin si ni Yoruba maa n pe ni alagbe.
Ààrẹ ọ̀nà Kakanfò ní ọ̀pọ̀ ìgbà alágbé ni àwọn olórín, fèrè tí àwọn alágbára bá sì fọn sí wọ́n lẹ́nu, ni wọ́n máa n fọn síta.
"Emí kìí ṣe alágbára, òjíṣẹ́ ni mi, agbára má n gun àwọn alágbára, wọ́n a sì má subú, sùgbọ́n òjíṣẹ́ máá n tẹti si ohùn ọlọ́rún ni láti ṣiṣẹ́ ìlú.
Ohun Ọlọrun ati tawọn to nile aye ni emi yoo tẹle, kii se ohun ti awọn alagbara ba ran awọn alagbe si mi."
Missing Alpha Jet: Ayédèrú fídíò ni Boko Haram fi léde lórí ọkọ̀ òfúrufú ọmọgun Alpha Jet tó pòórá -NAF
Oríṣun àwòrán, NAF
Awọn onimọ nipa eto abo ti sọrọ lori baalu ileeṣẹ ọmọ ogun ofurufu to poora ni Maiduguri, eyii ti ikọ ẹgbẹ agbesumọmi Boko Haram sọ pe awọn lo jaa bọ.
Ninu atẹjada kan ti ileesẹ ọmọ ogun fi lede, wọn ni ofege ni fidio ti Boko Haram gbe jade lori bi wọn ṣe ja baalu naa bọ.
Wọn ni ko si ootọ kankan ninu fidio naa, ati pe ki awọn ọmọ Naijiria ma ṣe ka fidio naa si.
Ṣaaju ni ileeṣẹ ọmọ ogun ofurufu, NAF, ti kọkọ kede pe baalu naa, to ni nọmba idanimọ NAF 745 ti poora, ati pe iwadii ti bẹrẹ lati mọ bo ṣe rin.
Onimọ kan nipa eto abo, Audu Bulama Bukarti to n ṣe iwadii nipa eto abo l'Afrika sọ fun BBC pe, fidio ti Boko Haram gbe jade ko le jẹ otitọ nitori bi wọn ṣe ge fidio naa nigba mẹta ọtọtọ.
Onimọ naa wa ni o ṣeeṣe ki Boko Haram mọ ibi ti baalu naa ja si, ki wọn si tete de agbegbe naa lati ya fidio rẹ lasiko ti awọn ọmọ ologun ṣi n wa lọwọ.
Pure Water Lylon Art: Adejoke ní ohun èlò ta fi ọ̀rá ṣe ń ní àlòpẹ́, kìí tètè jẹ
Audu fi kun pe ewu n bẹ loko longẹ Naijiria to ba jẹ pe lootọ, ọkọ baalu ti ileeṣẹ ologun n wa ni eyii ti Boko Haram sọ pe awọn ja lulẹ.
"O fi kun pe ""ko ni jẹ iyalẹnu to ba jẹ pe Boko Haram lo ja balu naa bọ nitori misaili kan ti ikọ naa yin loṣu to kọja balẹ si aarin ilu Maiduguri, eyii to mu ẹmi eeyan mẹrindilogun lọ, lara awọn ti ọmọ wẹwẹ mẹsan an wa."""
O pari ọrọ rẹ pe ijọba Naijiria ni lati gba pe awọn ọmọ ẹgbẹgun Boko Haram ni ohun ija oloro lọwọ, ki ijọba si ṣe ohun to yẹ lati ri pe awọn ọmọ ogun rẹ naa ni ohun ija to lagbara lati koju awọn ọmọ ogun Boko Haram ọhun.
Ki lo ti ṣẹlẹ sẹyin?
Oríṣun àwòrán, NAF
Ilé iṣẹ́ ọmọ ogun ojú òfurufú ti ni ìwòyé ìwádìí àwọn fi hàn pé, ọkọ̀ òfurufú Alpha Jet (NAF475) tó pòórá kúrò lójú ìwòràn ilé iṣẹ́ náà, seese ko ti ja lulẹ.
Awọn ọmọ ikọ̀ ologun ojú òfurufú méjì lo wà nínú ọkọ ofurufu naa eyi to poora loju ofurufu lọjọru.
Kò sí àrídájú ǹkan tí ó fa ìṣẹ̀lẹ̀ yìí  tàbi ibi tí àwọn ologun méjì náà já sí.
Awọn awakọ̀ òfurufú náà ni Ọgagun ofurufu John Abolarinwa àti Ebiakpo Chapele.
Adarí ìpolongo àti ọ̀rọ̀ tó n lọ fún ilé iṣé ọmọ ogun ofurufu, Edward Gabkwet, lo sisọ loju ọrọ naa ninu àtẹ̀jáde kan to fisita.
O sàlàyé pé, gbogbo àwọn ikọ ọmọ ogun, tó fí mọ́ àwọn ọmọ ogun orí ilẹ̀, ló n ṣaayan lọ́wọ́lọ́wọ́ bayii lati ṣe àwárí àti ìdóòlà ẹ́mí àwọn ènìyàn náà.
Wọ́n fi kún pé, pẹ̀lú bi ǹkan ṣe lọ yìí, kò sí ǹkan ti kò le ṣẹlẹ̀ sùgbọ́n àwọn ni ìrètí pé ó yẹ kí wọ́n rí àwọn méjì náà láti dóòlà wọn.
Oríṣun àwòrán, NAF
Ọ̀sán ọjọ́bọ ọjọ́ kíní, oṣù kẹrin ọdún 2021 ni NAF kéde pé àwọn kò rí Alpha Jet mọ́ láti aago márún kọjá ìṣẹ́jú mẹ́jọ lọ́jọ́rú.
Ondo Cow Death: Ọba Akungba ní Fulani tó ni màálù tó kú níkan ló mọ omi tí wọn mu
Alale ilu Akungba Akoko, Oba Isaac Adeyeye, Ajimo kẹta ti tẹnumọ pe, ko si ẹni to lee sọ pato ohun to ṣekupa awọn maluu to ku lojiji ni ilu Akungba.
Ọba Adeyeye lo sọ bẹẹ fun BBC Yoruba lasiko to n fi idi rẹ mulẹ pe lootọ ni iṣẹlẹ naa waye.
Saaju ni ileesẹ ọlọpaa ipinlẹ Ondo ti sọ fun BBC lọjọ Isẹgun pe iwadii ti fihan pe, omi kan to seese ko ni majele ninu ni awọn maalu to ku naa mu, amọ iwadii si n tẹsiwaju.
O ni nitori iṣẹlẹ naa ko ṣoju ẹnikẹni ayafi awọn darandaran to mọ ibi ti wọn rin si lati lọ da ẹran wọn, lo le e sọ iru omi ati koriko ti awọn ẹran maalu naa jẹ.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Àrá abàmì kan ṣe ikú pa màálù tó lé lógún
''Omi to dara lo wa ni Akungba ati agbegbe ti iṣẹlẹ naa ti ṣẹlẹ, a si ti tun wo awọn omi naa, ẹja wa ninu rẹ to n ṣere, nitori naa, kii ṣe omi inu ilu ni wọn mu.''
Alalẹ ilu Akungba fikun pe ni kete ti oun gbọ nipa iṣẹlẹ naa, ni oun paṣẹ fun ẹni to ni maluu naa pe ko ma titori owo ti yoo padanu, maa ta oku ẹran fun awọn eniyan o.
''Kiakia naa ni mo kan si ijọba ibilẹ ati ijọba ipinlẹ lati fi iṣẹlẹ naa to wọn leti''
Onpetu Ijeru: Akala ní torí Aláàfin kò ṣúgbàá òun fún sáà kejì, ló ṣe ní kí pín ipò alága
''Awọn eleto ilera ijọba ibilẹ si ti wa sibẹ, wọn si ti lọ sin awọn maluu naa.''
''Ki wọn to lọ sin wọn, wọn kọkọ quarantine ibi ti iṣẹlẹ ti ṣẹlẹ, ti wọn si da 'chemical' si wọn lara, ki wọn to lọ sin wọn''
''Mo si tun kilọ fun awọn eniyan lati ṣọra fun ẹran maalu jijẹ lasiko yii nitori nkan to le pa malu ọgbọn lẹẹkan naa, le pa ọmọ eniyan.''
Oríṣun àwòrán, @todays_echo
Igbo oro ni ori oke Ọwa ni ara ti san pa awọn malu naa
Alale ilu Akungba Akoko, Oba Isaac Adeyeye, Ajimo III ni ọlọpaa ṣi n ṣewadii iṣẹlẹ naa lọwọ, amọ awọn eniyan ṣi gbọdọ yẹra fun ẹran namọ lasiko yii.
Igba akọkọ kọ niyi ti maluu ti ko din ni ọgbọn maluu yoo ṣa dede ku lagbegbe Akungba ni ipinlẹ Ondo.
Ọba ilu Akungba Akoko, Oba Isaac Sunday Adeyeye, Ajimo III, ti fi ikilọ sita fun awọn eniyan ara agbegbe naa lati ṣọra fun ẹran maalu jijẹ lasiko yii ki wọn ma ba jẹ oku ẹran.
Eyi ko ṣẹyin iṣẹlẹ arameriri to ṣẹlẹ ni ijọba ibilẹ naa, nigba ti maluu to le ni ọgbọn fo sanlẹ ku ni agbegbe naa.
Ọba Adeyeye ni awọn ti kilọ fun awọn alapata lagbegbe naa lati maṣe ta awọn oku ẹran naa nitori ilera awọn eniyan.
Bakan naa ni o fikun pe, alapata kankan ti wọn ba gbamu to n ta oku ẹran yoo foju wina ofin.
Oríṣun àwòrán, OTHERS
''O ṣeeṣe ki awọn ẹran to ku naa jẹ koriko to ni majẹle nigba ti wọn n ko wọn da kiri.''
''Nitori naa mo ti paṣẹ pe ki ẹnikẹni maṣe ta oku ẹran maalu naa nitori ko tilẹ tii si ẹni to mọ nkan to ṣekupa wọn''
''Awọn maalu naa sadede fo sanlẹ ku ni nitori o le e jẹ omi ti wọn mu ''
Ọba ilu Akungba naa fikun pe awọn ti kesi awọn eleto ilẹra ni ijọba ibilẹ naa lati wa ṣewadii iṣẹlẹ, ki wọn si gbe igbesẹ to yẹ.
Blighted Ovum: Obìnrin kan sọ ohun tójú rẹ̀ rí nígbà tí oyún bàjẹ́ lára rẹ̀ ní ẹ̀ẹ̀mẹta
Ni aago mẹjọ, alẹ Ọjọ Aje ni wọn ni iṣẹlẹ naa ṣẹ lagbegbe Ibaka ni ilu naa.
Bi ẹ ko ba ni gbagbe, irufẹ iṣẹlẹ yii naa ti waye ni ilu Ijarẹ ati ilu Ikarẹ Akoko ni ipinlẹ Ondo kan naa ni ọdun 2019.
Oríṣun àwòrán, @todays_echo
Igbo oro ni ori oke Ọwa ni ara ti san pa awọn malu naa
Ariwo ki ree, emi lo tun ba eyi wa lo gba igboro kan niluu Akugba Akoko ni ipinlẹ Ondo lojumọ ọjọ Iṣẹgun nigba ti iroyin kan sigboro pe ko din ni ọgbọn maluu lo ti ṣa dede ku lagbegbe kan ni ilu naa.
Bi ẹ ko ba ni gbagbe, ilu Akungba ni fasiti Adekunle Ajasin, AAUA fikalẹ si.
Ni alẹ ọjọ Aje ni wọn ni iṣẹlẹ naa ṣẹ lagbegbe Ibaka ni ilu naa.
Bi ẹ ko ba ni gbagbe, irufẹ iṣẹlẹ yii naa ti ṣẹlẹ ni ilu Ijarẹ ati ilu Ikarẹ Akoko ni ipinlẹ Ondo kan naa ni ọdun 2019.
Akomolede àti Asa: Ìyàtọ̀ tó wà láàrin ìlànà ìpolówó ọjà láyé àtijọ́ àti òde òní
Ileeṣẹ ọlọpaa ni ipinlẹ Ondo fi idi rẹ mulẹ pe lootọ ni iṣẹlẹ naa ṣẹlẹ ati pe iwadii ti n lọ lori rẹ.
Ninu ọrọ to ba BBC News Yoruba sọ, alukoro ileeṣẹ ọlọpaa, ASP TEE-LEO IKORO ṣalaye pe, gẹgẹ bi ohun to tẹ awọn lọwọ, awọn maluu naa ku lẹyin ti wọn mu ninu orisun omi kan naa.
Alukoro ileeṣẹ ọlọpaa ni ipinlẹ Ondo naa ni, ohun to ru awọn loju ti awọn n wadi lati ri idahun si bayii, ni lati mọ boya majele wa ninu omi naa ni tabi nnkan miran lo ṣe awọn maluu naa.
NIN Registration: Ẹ̀wọ̀n ọdún mẹ́rìnlá ló ń bẹ nílẹ̀ fún àwọn tí kò ní nọ́mbà ìbánimọ̀ NIN ní Nàìjíríà
Oríṣun àwòrán, Nimc
Ijọba apapọ ti fi lelẹ pe ọmọ Naijiria ti ko ba ti ni nọmba idanimọ apapọ orilẹede Naijiria, NIN yoo fi ẹwọn ọdun mẹrinla jora.
Minisita eto ibaraẹnisọrọ ati ọrọ aje igbalode, Ọmọwe Isa Ali Pantami lo sọ eleyi di mimọ lẹyin ipade ọlọsọọsẹ awọn minisita pẹlawọn oniroyin nilu Abuja.
Ọmọwe  Patami ṣalaye pe lọwọ yii, o le ni miliọnu mọkalelaadọta ọmọ Naijiria to ti forukọilẹ fun nọmba NIN wọn.
O ni gẹgẹ bi ofin to ti NIN lẹyin lorilẹede Naijiria,yatọ si ẹwọn ọdun mẹrinla, ẹnikẹni to ba kuna ati gba nọmba naa ko ni lẹtọ ati anfani si awọn ohun amayedẹrun ijọba ati eto banki ati eto ibanisọrọ.
O ni numba Idanimọ naa ko ṣee ti ọwọ makaruru bọ bi tii ikaniyan sẹnsọ.
O fi kun un pe ọgọsan o le mẹsan an miliọnu kaadi ibanisọrọ SIM lawọn eeyan ti ṣeto iforukọsilẹ fun lorilẹede Naijiria ninu eyi to jẹ pe aadọjọ miliọnu ninu wọn nikan ni ilana iforukọsilẹ awọn to ni wọn jina denu; ti awọn yooku ko si ni ilana iforukọsilẹ to jina denu.
Oríṣun àwòrán, Nimc
Ile ẹjọ giga kan to jẹ ti ijọba apapọ nilu Eko, ti fofin de ijọba apapọ Naijiria, lati má fi ofin de awọn siimu ti wọn ko ba so pọ mọ NIN titi oṣu Kẹrin.
Ọdun 2020 ni ileesẹ ìjọba to n mojuto eto ibaraẹni sọrọ, pàṣẹ fun awọn ileesẹ ibaraẹni sọrọ pe ki wọn o gbẹsẹ le irú awọn siimu bẹ ẹ.
Gbedeke ọjọ kẹfà, oṣu Kẹrin ti ijọba pa láṣẹ si ti mu ki ọpọ eeyan o ma a yabo awọn ibudo iforukọ silẹ lai naani aarun Covid-19.
Sugbọn ṣa, ẹnikan to ti fi igba kan jẹ igbakeji aarẹ ẹgbẹ awọn agbẹjọro ni Naijiria, Monday Ubani, pe ẹjọ pe ki ilé ẹjọ́ fi ofin de ileesẹ ìjọba naa lati má fi ofin de awọn siimu ti wọn ko sọ pọ mọ nọmba idanimọ NIN.
Oríṣun àwòrán, Nimc
Awọn to pe lẹjọ ni ijọba apapọ, Agbẹjọro Agba Naijiria, ileesẹ NCC ati Minisita fun eto ibaraẹni sọrọ.
Ubani sọ ninu iwe ìpéjọ rẹ pe yatọ si pe àṣẹ naa yoo mu inira ba oun, o ni o tun jẹ ọna lati fi ẹtọ ti oun ni lati ni dukia ati lati sọrọ bo ṣe wu oun, dun un.
O ni eyi tako agbekalẹ ofin ọdun 1999. Bakan naa lo fẹ ki ile ẹjọ fi ọjọ kún gbedeke naa.
Ninu idajọ to ṣe lori ẹjọ naa lọjọ kẹtalelogun, oṣu Kẹta, ọdun 2021, Onidajọ M. A Onuetenu pàṣẹ pe ki ijọba fi oṣu meji kún gbedeke naa.
Blighted Ovum: Obìnrin kan sọ ohun tójú rẹ̀ rí nígbà tí oyún bàjẹ́ lára rẹ̀ ní ẹ̀ẹ̀mẹta
Oṣu meji naa si bẹrẹ lati ọjọ idajọ.
Ile ẹjọ ti wa sọ pe ìnira, ati fifi ẹtọ ẹni dun ni, ni gbedeke ọjọ kẹfa, oṣu Kẹrin yoo jẹ fun awọn ọmọ Naijiria.
Bakan naa ni idajọ naa tun sọ pe gbedeke naa yoo fi araalu sinu ewu aarun Covid-19 nibi ti wọn ba ti n kora jọ pọ̀ nitori pe wọn fẹ ẹ fi orukọ silẹ fun NIN.
Ile ẹjọ si ti kọ lẹta si Minisita eto idajọ, to tun jẹ agbẹjọro agba, Abubakar Malami, lati pasẹ fun gbogbo ileesẹ ti ọrọ kan, pe ki wọn o tẹle idajọ naa.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Laipẹ yii ni iroyin n ja ranyin-ranyin pe awọn alaṣẹ ijọba ni Bayelsa ti fun awọn darandaran Fulani ni gbedeke ọjọ mẹrinla, lati ko aasa wọn kuro ni ipinlẹ naa, ki wọn gba oko ibomiran lọ.
Iroyin yii milẹ diẹ nitori igba akọkọ niyi ti irufẹ aṣẹ bẹẹ yoo jade lawọn agbegbe ti kii ṣe ilẹ Yoruba.
Awọn ijọba ipinlẹ kan atawọn ajijagbara kan ni ilẹ Yoruba lo n gbe igbesẹ lati le awọn darandaran Fulani kuro ni ilẹ Yoruba, tabi mojuto igbokegbodo wọn.
Ohun ti iroyin to kọkọ jade naa sọ ni pe ijọba ipinlẹ Bayelsa ti fun awọn daranadaran fulani to wa ni ipinlẹ naa ni ọsẹ meji lati fi kuro nibẹ nitori gbọnmọgbọnmọ wahala ati ijinigbe to n wọ tọ wọn lẹyin ni ipinlẹ naa.
Akomolede àti Asa: Ìyàtọ̀ tó wà láàrin ìlànà ìpolówó ọjà láyé àtijọ́ àti òde òní
Amọṣa, nigba ti BBC News yoo kan si awọn alaṣẹ ijọba ipinlẹ naa, wọn ni bẹẹ kọ lọrọ ri o. ṣugbọn iroyin naa tun fẹ fara jọ ootọ diẹ.
Kọmiṣọna eto ọgbin ati ohun alumọni ni ipinlẹ Bayelsa, David Alagoa ṣalaye pe, igbimọ to n mojuto akoso ohun ọsin ni ipinlẹ naa, ṣe ipade pẹlawọn adari ẹgbẹ Miyetti Allah, MACBAN.
O ni ijọba atawọn adari ẹgbẹ naa ti fimọ ṣọkan pe wọn yoo ni awọn aṣayan agbegbe tawọn darandaran Fulani yoo maa ko maluu wọn jẹ si.
Ogbomoso Quitdruplets: Ọ̀kan nínú àwọn ìbarùn-ún jáde láyé lọ́jọ́ karùn-ún
O ni wọn fi imọ ṣọkan lori idi ti awọn darandaran fi ni lati kuro ni ipinlẹ naa.
Ohun ti wọn wa fohun si ni pe, ki wọn maa lọ sawọn agbegbe ijẹko ti oyinbo n pe ni Ranching.
FIFA 2022 World cup qualifiers: Japan wọ́ Mongolia nílẹ̀ gẹrẹrẹrẹ pẹ̀lú góòlù mẹ́rìnlá sí òdo
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Aṣe airijinna lairi abuke ọkẹrẹ, bẹẹsi ni  aileja nii jẹ ojude baba mi o de ihin.
Owe mejeeji yii lo wa si ise nibi ifẹsẹwọnsẹ tani yoo kopa ni idije ife ẹyẹ agbaye World cup tọdun 2022.
Boya ka kọkọ beere lọwọ yin pe ki lẹ o ṣe bi ẹ ba gbọ pe ninu ifẹsẹwọnsẹ bọọlu kan, orilẹede kan ni Afrika na iks Super Eagles pẹlu goolu mẹrinla si odo?
Hmmm...bi ọrọ ṣe ri niyi nigba ti orilẹede Mongolia gba Japan lalejo.
Nṣe ni Japan sọ ara wọn di alejo ọran mọ Mongolia lọwọ ti wọn si na wọn pẹlu goolu mẹrinla si odo.
Takumi Minamino,  Agbabọọlu Liverpool ti wọn ya Southampton fun saa liigi Premiership to n lọ lọwọ nilẹ Gẹẹsi  wa lara awọn to gba goolu si awọn ninu ifẹsẹwọnsẹ naa.
Goolu mẹta ni Yuya Osako to n gba bọọlu jẹun ni Werder Bremen gba wọle ni tirẹ.
Awọn agbabọọlu Japan to tun gba bọọlu sinu awọn ni Sho Inagaki (meji), Junya Ito (meji), Kyogo Furuhashi (meji), Daichi Kamada, Hidemasa Morita Takuma Asano ti  Khash Erdene Tuyaa, agbabọọlu Mongolia naa gba ọkan si ile ara rẹ.
Ogbomoso Quitdruplets: Ọ̀kan nínú àwọn ìbarùn-ún jáde láyé lọ́jọ́ karùn-ún
Pẹlu esi ifẹsẹwọnsẹ yii, orilẹede Japan yoo kogoja lati kopa nibi idije ife ẹyẹ agbaye tọdun 2022 bi wọn ba lee fagba han orilẹede Myanmar.
Ilu Chiba, lorilẹede Japan ni ifẹsẹwọnsẹ naa ti waye lẹyin ti ofin isede to wa nilẹ lorilẹede Mongolia mu ki ifẹsẹwọnsẹ naa o ma lee waye ni orilẹede naa.
Ni ọjọ Aje ni  orilẹede Canada ti kọkọ naa orilẹede Caynan Islands pẹlu ami ayo mọkanla si odo.
Orilẹede Mongolia wa ni ipo aadọwa (190) ninu atẹ igbelewọn awọn orilẹede to n gba bọọlu lagbaye labẹ ajọ FIFA.
Buhari: Ẹ mú gbogbo àwọn ajínigbé àtàwọn onígbọ̀wọ́ wọn balẹ̀ ní kíákíá
Oríṣun àwòrán, @NigeriaGov
Aarẹ Muhammadu Buhari ti paṣẹ fun awọn ọga ileeṣẹ ọmọ ogun ni Naijiria lati palẹ awọn janduku, ajinigbe atawọn to n ṣagbatẹru wọn mọ ni kankan.
Buhari lo paṣẹ ọhun lasiko to n ṣepade pẹlu awọn ọga ileeṣẹ ologun atawọn agbofinro naa nile ijọba niluu Abuja.
O ni eyii ti awọn janduku ati ajinigbe naa ṣe ninu dida eto abo Naijiria laamu ti to, ki awọn ọgagun si fopin si iṣẹ wọn ni kiakia.
Lẹyin ipade naa ni olubadamọran pataki fun Aarẹ lori eto abo, Babagana Monguno jabọ ipade ọhun fun awọn akọroyin.
Oríṣun àwòrán, @NigeriaGov
Monguno ni Aarẹ ti paṣẹ fun awọn adari ileeṣẹ ologun naa pe, ki wọn bẹrẹ iṣẹ lori aṣẹ ti oun ti pa ṣaaju  ninu oṣu Keji pe, oun ti gbẹsẹle irinajo ọkọ ofurufu ati iwakusa nipinlẹ Zamfara.
"O ni ""lori ọrọ ijinigbe atawọn janduku loke ọya, aarẹ ti sọ pe oun fẹ ki a fi ẹnu rẹ jona lẹsẹkẹsẹ."""
Aarẹ sọ fun wa kedere pe oun n fẹ ki a fi oju awọn onigbọwọ awọn janduku ati ajinigbe naa lede, ki a le da alaafia pada si awọn agbegbe naa.
Oríṣun àwòrán, @NigeriaGov
O fikun pe Aarẹ ko ni gba ko jẹ pe awọn janduku ni yoo maa ṣakoso awọn agbegbe kan ni Naijiria, eyii tii ṣe ilu to lọba, to tun ni ijoye.
Monguno ṣalaye pe Aarẹ ti ṣe tan lati pese gbogbo ohun ija fun awọn awọn ọmọ lati koju awọn ọdaran to n da Naijiria laamu.
"O pari ọrọ rẹ pe ""Aarẹ ti paṣẹ pe ki a lo gbogbo agbara wa lati mu gbogbo awọn jaduku atawọn ajinigbe naa balẹ lai yọ awọn to n ṣagbatẹru wọn silẹ."""
Akomolede àti Asa: Ìyàtọ̀ tó wà láàrin ìlànà ìpolówó ọjà láyé àtijọ́ àti òde òní
Ipade peu awọn ọga ologun naa lo waye ṣaaju ki Aarẹ Muhammadu Buhari to tẹkọ leti lọ silẹ Gẹẹsi, nibi ti yoo ti lọ gba itọju.
Ṣaaju ni amugbalẹgbẹ Aarẹ lori ọrọ to n lọ Femi Adesina ti kọkọ kede irinajo naa, nibi to ti sọ pe Aarẹ yoo pada si Naijiria ninu ọsẹ Keji, ọsu Kẹrin.
CCT Tribunal: Alága CCT fèsì lórí fídíò kan tó ṣàfihàn bó ṣe ń fìyà jẹ ẹsọ kan
Oríṣun àwòrán, Screenshot
Alaga igbimọ onidajọ  to n gbọ ẹsun asemase nidi ihuwasi osisẹ ọba atawọn to dipo oselu mu, Code of Conduct Tribunal, Adajọ Danladi Umar ti fesi lori fidio kan to gbode eyi to se afihan rẹ.
Fidio naa, to ti gba ori ayelujara kan,  lo safihan Umar to fa ibinu yọ nile itaja igbalode kan ti wọn n pe ni Banex to wa ladugbo Wuse keji nilu Abuja nibi to ti n lu ẹsọ alaabo ile itaja naa.
Umar lo lu ipa si ẹsọ alaabo ọhun, ko to di pe wọn gba ọkunrin naa mu, tawọn ọlọpaa si gbe ju sinu ọkọ wọn.
Amọ nigba to n fesi lori fidio ifiyajẹni naa, Umar ni ẹsọ ibudo itaja naa lo yaju si oun, to si n halẹ mọ oun.
Oríṣun àwòrán, NTA
Atẹjade kan ti agbẹnusọ fun igbimọ olugbẹjọ CCT, Ibraheem Al-Hazzan fisita lori isẹlẹ naa lo sisọ loju ọrọ Umar yii.
Ohun to jẹ yọ ni pe Umar ati ẹsọ alaabo naa ni wsn dijọ n tahun sira wọn ni ibudo igbọkọsi to wa nile itaja naa lọjọ Aje, eyi to papa di ija.
Umar la gbọ pe o lọ sile itaja igbalode Banex lọjọ Aje lati lọ tun ẹrọ ibaraẹnisọrọ rẹ to bajẹ se nibẹ.
Ni kete to si de ibudo itaja naa, ni awakọ rẹ gbe ọkọ si aaye kan to sofo nibudo igbọkọsi ile itaja ọhun.
Amọ ẹsọ to wa lọọkan nibudo naa tete pariwo pe ki wọn mase gbe ọkọ wọn gunlẹ si aaye to sofo naa.
Sugbọn se ni alaga igbimọ olugbẹjọ CCT naa yari pe awakọ oun ko gbọdọ gbe ọkọ naa kuro ni aaye to wa naa.
Nigba to n salaye bi isẹlẹ naa se waye, Al-Hassan ni aawọ naa bẹrẹ nigba ti ẹsọ ile itaja naa ko le se alaye to yẹ lori idi ti Alaga CCT ko fi gbọdọ gbe ọkọ rẹ duro ni aaye to sofo naa.
"Bi o tilẹ jẹ pe alaga CCT naa ko sọ iru eeyan to jẹ fun, amọ ẹsọ naa yaju si pupọ, to si ni oun yoo se alaga awọn bii ọsẹ tii se oju, ti ko ba gbe ọkọ rẹ kuro nibẹ.
To ba jẹ pe ọga wa lọ sile itaja naa ni lati fa wahala tabi dunkoko mọ ẹnikẹni gẹgẹ bi awọn eeyan kan se n sọ, yoo lọ sibẹ bii ọlọla ni pẹlu awọn ẹsọ alaabo rẹ."
Blighted Ovum: Obìnrin kan sọ ohun tójú rẹ̀ rí nígbà tí oyún bàjẹ́ lára rẹ̀ ní ẹ̀ẹ̀mẹta
"Amọ Umar nikan lo lọ pẹlu aburo rẹ ọkunrin, ọlọpa to si han ninu fidio naa, kii se ikọ ọlọpa fun alaga igbimọ CCT."""
O ni ọlọpaa naa lo n sisẹ ni agbegbe ti ibudo itaja naa wa, ẹni to kọkọ da si aawọ naa, ko to di pe awọn ikọ ọlọpaa lati agọ ọlọpaa Maitama de sibẹ.
"Se ni awọn ikọ janduku kan to wa ninu ile itaja naa bẹrk si ju ada ati ohun ija oloro mọ ọkọ ọga Umar, eyi to mu ọgbẹ ba ni ọmọ ika ọwọ rẹ kan.
Koda, mọto rẹ bajẹ, ti wọn si fọ digi iwaju ọkọ naa."
Oduduwa Nation: Femi Falana ní ọ̀nà láti pọ́n aráàlú lójú ni ìpè fún ìyapa Nàíjíríà
Ogbontarigi agbejọro agba ni Naijiria, Femi Falana, ti sọ pe elero kukuru ni awọn to n polongo pe ki Naijiria o pín si ẹlẹyamẹya. Ninu ifọrọwanilẹnu kan to ṣe pẹlu ileesẹ iroyin abẹle kan, Root TV, ni Falana ti sọ pe orilẹ-ede Naijiria ni awọn aláwọ̀ dúdú pọ si julọ ni agbaye.
O fikun pe o yẹ́ ka se gbogbo ohun to ba yẹ́ lati ri daju pe orilẹ́ede Naijiria duro re ni, ọpọ to si n beere fun ipinya Naijiria nilana ẹlẹyamẹya ni ko ni oju inu.
"Agba amofin naa fikun pe ọna lati lo anfaani ifiyajẹni, lilọ ni lọwọ gba, to wa ninu isejọba Naijiria, fun ominira ara wọn ni wọn n wa. ""Ko si ẹnikẹni ninu wọn to n gbero eto ẹ̀kọ́ to dara tabi ọrọ aje ti yoo pin ọrọ̀ kari, ni orilẹ-ede ti wọn fẹ ẹ da silẹ."
Oríṣun àwòrán, Sunday Igboho
"Oun to jẹ wọn lógún ni lati ni ominira ti yoo fi aaye gba wọn láti tẹsiwaju ninu pipọn araalu lójú. Eyi ti ko le ṣe e ṣe."" O beere pe njẹ awọn eeyan to n kede orilẹ-ede tuntun lori ayelujara ti gbọ́ èrò awọn araalu lati mọ boya wọn fẹ ya kuro ni ara Naijiria. "" Ko si ẹnikẹni to beere. """
O ni awọ̀n eeyan kan ji lọjọ kan ni wọn kede pe a n lọ kuro lara Naijiria, lọ sibo? O yẹ ka kọkọ wa ojutu si aini idagbasoke Naijiria na.
Kò sí ìgbà kankan tí Yorùbá jókòó pé ki Igboho  lọ kéde ìyapa kúrò ní Nàíjíríà
Femi Falana wa woye pe ọ̀pọ̀ isoro tawọ̀n eeyan kan n lọ̀gun pe gẹgẹ bii awawi lati ya kuro lara Naijiria lo jẹ isẹ́ ọwọ awọn eeyan, afọwọfa ẹda ni.
O fikun pe ko ohun to le, ti ko ni dẹ, ka sa ni suuru nitori awọn isoro to ni ojutu ni awọ̀n eeyan kan mu lọwọ lati maa polongo iyapa Naijiria.O ṣalaye pe nkan to ṣe koko ni lati wa ọna abayọ si awọn ìṣòro ti orile-ede Naijiria ni.
Jaiye Kuti: Ọ̀pọ̀ ìgbà ni mò n fi ẹ̀rín bo omijé mọ́lẹ̀ láti bo àṣírí ara mi
Oríṣun àwòrán, jayeola_monje/ Instagram
Yoruba ni onikaluku abi tiẹ lara, gbogbo asọ si kọ laa sa ninu oorun nitori asọ lo bo asiri isoro ẹda.
Bẹẹ lọrọ ri fun gbajugbaja oṣerebinrin kan ninu tiata Yoruba, Jaiye Kuti, ẹni to sọ pe ọpọlọpọ igba ni oun n fi ẹ̀rín bo omijé oju oun mọ́lẹ̀.
Ninu ọrọ kan to kọ sori ayelujara Instagram rẹ, arẹwà oṣerebinrin naa sọ pe lootọ ni oun ma n rẹrin ni gbogbo igba, àmọ́ ko tumọ si pe inu òun maa n dùn ni igba gbogbo.
Mo ma n wa ninu awọn ipò to ma n mu mi sunkun lọpọ igba nitori mo n la awọn iriri kan kọja to maa n jẹ ki omije da silẹ loju mi.
Oríṣun àwòrán, jayeola_monje/ Instagram
 Ẹni to jade wa lati inu iriri to ṣòro lati gbagbọ ni mi, sugbọn imoore nikan lo gbe mi ro nitori ẹni to ba ni ọkan ọpẹ nikan lo ni ọrọ̀.
Gbajugbaja oṣere naa ṣalaye pe, ọpọlọpọ igba ni oun ti kuna, to si ma n jẹ ìnira fun oun lati dìde pada.
O ni nkan ẹyọ kan ṣoṣo ti oun ma n se lasiko naa ni ki oun sọ omijé di oúnjẹ.
O ni bo tilẹ jẹ pe oun n sisẹ takuntakun lati tọju ẹbí oun, ati lati ṣe iranlọwọ fun awọn eeyan niwọnba ti agbara oun ká, sibẹsibẹ, òun n sunkun.
Blighted Ovum: Obìnrin kan sọ ohun tójú rẹ̀ rí nígbà tí oyún bàjẹ́ lára rẹ̀ ní ẹ̀ẹ̀mẹta
O gba awọn ololufẹ rẹ ni imọran láti mọ riri, ki wọn si gbádùn gbogbo anfaani ti wọn ba ri gba, nitori pe to ba di ọjọ iwaju, wọn o ri pe nkan nla ni, to si se babara pupọ.
O ni oun dupẹ lọwọ gbogbo àwọn to ti ni ipa lori ayé òun, fun ifẹ ati atilẹyin wọn lọna kan abi omiran.
Herdsmen Attack: Adebanjo ní àwọn ọ̀dọ́ ní ìjọba ń fìyà jẹ pẹ̀lú àìkáátò rẹ̀
Oríṣun àwòrán, Twitter
Adari kan ninu ẹgbẹ ọmọ Yoruba Afenifere, Oloye Ayo Adebanjo ni ọpọlọpọ awọn ọdọ ajijagbara bii Sunday Igboho ati Nnamdi Kanu ni yoo dide ti ijọba apapọ ko ba ṣe oun to yẹ.
Baba Adebanjọ ni iṣekupani ojojumọ ti pọju lorilẹede Naijiria, ni awọn ọdọ ṣe n dide lati gba ara wọn la.
O ni awọn ọdọ ni ijọba n koju pẹlu aikaato eto akoso rẹ, nitori naa, wọn ko le e da wọn duro.
''Ọjọ ti pẹ ta ti n pariwo ki ijọba ṣe atunto orilẹede Naijiria, amọ wọn kọ eti ikun si ọrọ wa.
O yẹ ko ye ijọba pe o n fi ina si ibinu awọn ọdọ ni Naijiria nitori pe o kọ lati ṣe atunto orilẹede Naijiria.
Kò sí ìgbà kankan tí Yorùbá jókòó pé ki Igboho  lọ kéde ìyapa kúrò ní Nàíjíríà
Ijọba yẹ ko fun awọn ẹkun to wa ni Naijiria laaye lati ṣakoso ohun ini wọn funra wọn ni''
Bakan naa ni ẹgbẹ awọn ẹya igbo, Nigeria Patriotic Youth Against Corruption and transparency, ni awọn ko ni gba fun awọn Fulani darandaran lati wa si ilẹ awọn, ki wọn si ma a jẹ awọn eniyan wọn ni iya.
Adari ẹgbẹ naa, Oloye Emmanuel Iwuayanwu ni awọn adari ni ilẹ igbo yoo dide lati gbogun ti ipaniyan awọn ẹbi ati ara awọn ni ilẹ Igbo, paapaa ni ipinlẹ Ebonyi.
''Nkan buburu lo n ṣẹlẹ ni Naijiria, o buru jai ki awon Fulani darandaran ma a pa eniyan kaakiri lai si pe wọn ti ọwọ ọmọ wọn bọ aṣọ.''
Cattle Ranching: Ẹ wo Fulani darandaran to tako àṣà dída màálù kiri lójú pópó
''Nibayii awọn ọdọ lati ipinlẹ mẹtadinlogun lorilẹede Naijiria ti kesi awọn darandaran to n paniyan, ki wọn kuro ni agbegbe naa ni kiakia lai wọ ẹyin.''
Bakan naa ni wọn kilọ fun ijọba lati jawọ igbeṣẹ fifi panpẹ mu awọn ọdọ to n ja fun ẹya wọn bii Alhaji Asari Dokubo, Sunday Igboho ati Nnamdi Kanu.
Ọpọlọpọ awọn eniyan lo sọrọ tako iṣekupani to n waye ni Guusu orilẹede Naijiria lati ọwọ awọn afurasi Fulani darandaran.
Gomina ipinlẹ Ebonyi, David Umahi ọwọ awọn ti tẹ awọn afurasi darandaran to ṣekọlu awọn ijọba ibilẹ bii mẹrin ni ipinlẹ naa.
Gomina Umahi lo sọ ọrọ yii lasiko to ṣe abẹwọ si ibi ti iṣẹlẹ naa ti waye ni ijọba ibilẹ Nkalaha, Obegu, Umuhuali ati Amaezu.
Umahi ni awọn marundinlogun lo ku ninu ikọlu naa.
''A ti ri awọn to sekọlu si awọn eniyan ijọba ipinlẹ yii, ti a si ti ri awọn to ran wọn ni iṣẹ''
''Mo si ti bẹrẹ si ni ba awn eniyan sọrọ ti iṣẹlẹ naa ṣe ijamba fun, ati ki awọn eniyan ma gbe ija ara wọn ja.''
''Ibanujẹ ọkan lo jẹfun mi pẹlu iṣẹlẹ to waye ni Ebọnyi ati bi awọn darandaran to wa nmi agbegbe naa ṣe sa asala fun ẹmi wọn, ki awọn eniyan ma ba a pa wọn''.
Gomina ipinlẹ Ebonyi ni ti iṣẹlẹ ikọlu awọn Fulani darandaran yii ba tẹsiwaju kaakiri orilẹede Naijiria, o le da ogun abẹle.
Ẹni ti iṣẹlẹ naa ṣoju rẹ ni awọn agbegbọn naa kọlu pẹlu ikọ ati ada ti wọn si fi ọbẹ le awọn eniyan kuro nibẹ.
O tun fikun wi pe wọn pa alfa ijọ Methodist to wa nibẹ, ti wọn si ko ọpọlọpọ dukia awọn eniyan lọ nibẹ.
Amọ, ijọba bu ẹnu atẹ lu bi awọn eniyan ṣe fiyajẹ awọn afurasi ti wọn ri lagbagbe naa, jungle justice lai fi idi rẹ mulẹ pe awọn gan an lo ṣiṣẹ ibi ọhun.
Gomina ipinlẹ Ebonyi, David Umahi ni iwadii ṣin tẹsiwaju lori iṣẹlẹ naa.
Oríṣun àwòrán, DIANAIME UKO
Nnkan ko fi gbogbo ara rọgbọ ni ijọba ibilẹ Essien Udim ni ipinlẹ Akwa Ibom, lẹyin ti awọn agbebọn kan lọ kọlu awọn ọkọ ọlọpaa atawọn ologun to n mojuto eto abo nibẹ.
Awọn agbebọn naa ti wọn to aadọta ni iye ni wọn ni wọn n tako alaga ijọba ibilẹ naa, ti wọn si tipa bẹẹ kọlu awọn ọlọpaa ati ọmọ ogun ti wọn ko lọ si ibẹ lati pẹtu si awọ.
Gẹgẹ bi iroyin ṣe sọ, ọga ọlọpaa kan ti orukọ rẹ n jẹ Benedict Okoh Ajide atawọn ọlọpaa miran ni awọn agbebọn naa pa ni owurọ ọjọ Iṣẹgun ọgbọn ọjọ oṣu kẹta ọdun 2021.
Oríṣun àwòrán, DIANAIME UKO
Ohun ti BBC News gbọ nibẹ ni pe, awọn agbebọn naa jo ile ọga ọlọpaa, CSP Ajide, koda ọta ibọn ba eeyan kan to n kọja ls ni tirẹ to si gba  ibẹ ku.
Bakan naa ni wọn tun da ina sun awọn ọkọ Hilux kan, wọnṣe awọn ọlọpaa miran leṣe bi o tilẹ jẹ pe a ko lee sọ iye wọn.
Ni nnkan bii ọsẹ mẹrin sẹyin, awọn agbebọn kan kọlu agọ ọlọpaa kan ti wọn si da ina sun apakan agọ ọlọpaa naa titi kan awọn aloku ọkọ kan ti wọn wa kalẹ si ọgba agọ ọlọpaa naa.
Ikọlu yii lo mu ki ijọba ipinlẹ Akwa Ibom fofin de lilo alupupu ọkada tabi kẹkẹ marwa nibẹ lọjọ kẹrindinlọgbọn oṣu kẹta ọdun 2021.
Ijọba ibilẹ Essien Udim atawọn ijọba ibilẹ meji miran ni aṣẹ naa kan, laarin agogo mẹfa irọlẹ si meje aarọ lati dẹkun iwa ọdaran nibẹ.
Ni bi a ṣe n sọrọ yii, ileeṣẹ ọlọpaa ni ipinlẹ Akwa Ibom ko tii sọ ohunkohun lori iṣẹlẹ naa.
Buhari: PDP àtàwọn àjọ míì figbe ta lórí èsì ìwádìí Amẹ́ríkà nípa ìjọba Buhari
Oríṣun àwòrán, Other
Orilẹ-ede Amẹrika ti fẹsun kan ijọba Aarẹ Muhammadu Buhari pe iwa ajẹbanu ti pọju labẹ ijọba rẹ.
Bakanna ni Amerika sọ pe ijọba Buhari ko faye gba ẹtọ ọmọniyan lati sọrọ lawujọ papaa julọ lọdun 2020.
Ilẹ Amerika sọrọ yii ninu esi iwadii rẹ lori ẹtọ ọmọniyan lorilẹede Naijiria lọdun 2020.
Orilẹ-ede Amẹrika sọ ninu atẹjade ọhun pe iwa ibajẹ pọ kaakiri labẹ ijọba Buhari to fi mọ ẹka eto idajọ ati eto abo.
Ninu eleyi to tako igbesẹ ijọba to wa lode lati gbogun ti iwa ajẹbanu, ẹka ijọba ilẹ Amerika to n ri si ọrọ ilẹ okeere sọ pe ẹsun iwa ibajẹ ni ijọba lọdun 2020 pọju.
'Èmi àti ìyàwó mi ti ń gbé pọ̀ nínú ìgbéyàwó wa fún 60 years', ẹ wá kọ́ ẹ̀kọ́ lẹ́nu àgbà méjì
Orilẹ-ede Amẹrika fi iwadii ati bi wọn ti fi ọwọ ofin mu alaga ajọ EFCC to n gbogun ti iwa ibajẹ, Ibrahim Magu lori ẹsun iwa ajẹbanu ṣe àpẹẹrẹ.
Amerika tun sọ ninu atẹjade naa pe ọpọ ẹjọ iwa ibajẹ ni ko tii niyanju ni Naijiria nitori bi wọn ṣe n fi falẹ.
Bakanna ni orilẹ-ede Amẹrika fẹsun kan ijọba Buhari pe o n dunkoko mawọn akọroyin lẹnu iṣẹ wọn.
Atẹjade naa ṣalaye pe awọn oloṣelu n lo awọn ẹṣọ eleto abo lati huwa ipa s'awọn akọroyin to n ṣiṣẹ lori titẹ ẹtọ.
Bí Oduduwa Republic bá bẹ̀rẹ̀, a ò ní ṣe aburú fún àwọn tó takò wá, ìlànà ààtẹ̀lé rèé - Banji Akintoye
Koda, atẹjade ọhun sọ pe awọn akọroyin kan ṣagbako iku ojiji lẹnu iṣẹ wọn ni Naijiria lọdun 2020.
Ẹwẹ, ẹgbẹ oṣelu alatako PDP ati aarẹ ajọ to n ri si ẹrọ ọmọniyan tẹlẹ rí, Malachy Ugwumadu ti dẹnu bo ijọba Buhari lori atẹjade naa.
Akọwe iroyin fun ẹgbẹ oṣelu PDP, Kola Ologbondiyan ni otitọ ni orile-ede Amerika sọ ninu atẹjade to fi sita lori ijọba Aarẹ Buhari.
"Gbogbo eeyan lo mọ pe ijọba Buhari lo tẹ ẹtọ ọmọniyan mọlẹ julọ.
Omi iké kan, l'èèyàn kan lè mu f'ọ́jọ́ mẹ́ta láì ro ti ekòló inú rẹ̀ - Ìlú Elega, Kwara
Koda, titẹ ẹtọ ọmọniyan mọlẹ labẹ ijọba Buhari buru ju ti ijọba ologun Sani Abacha, Ologbondiyan lo sọ bẹẹ."
Oludasilẹ ajọ to n ri si ọrọ ijọba awaarawa, Ariyo-Dare Atoye ni atẹjade orilẹ ede Amẹrika ṣapejuwe bi iwa ibajẹ ṣe gbilẹ to ni ijọba Buhari.
Oríṣun àwòrán, EPA
Orilẹede Amẹrika ti kede pe ọpọ awọn iroyin tawọn ileesẹ iroyin labẹle ati lagbaye kọ nipa pe ibọn yinyin sawọn oluwọde waye lẹnu ibode Lekki, ni oun ko le fi idi rẹ mulẹ.
Bẹẹ ba gbagbe, ogunjọ osu Kẹwa ọdun 2020 ni iroyin gbode pe awọn ọmọ ologun kan lọ yinbọn mọ awọn ọdọ to n se iwọde ENDSars lẹnu iloro Lekki, ti ọpọ si gbẹmi mi.
Ilẹ Amẹrika fi ero rẹ yii han ninu ikede abọ iwadi rẹ lori awọn ẹsun ti ẹgbẹ ajafẹtọ ọmọniyan fi kan ijọba Naijiria ati ileesẹ ologun ilẹ wa.
Atẹjade ọhun, ti wọn fisita lọjọ Isẹgun lo tẹnumọ pe awọn iroyin to jade nipa oku to sun lẹnu iloro Lekki lasiko ENDSars ko de ọdọ oun titi ti ọdun 2020 fi pari.
Oríṣun àwòrán, EPA
"Ajọ Ajafẹtọ ẹni Amnesty kede pe eeyan mẹwa lo jalaisi lasiko ikọlu naa amọ ijọba Naijiria tako iroyin ọhun, bẹẹ si ni ko si ẹgbẹ miran to fidi ootọ ọrọ mulẹ nipa rẹ.
Eeyan meji pere ni ijọba lo jade laye nipa isẹlẹ ọhun, oku kan ti wọn ri lẹnu iloro Lekki naa lo safihan pe o la wahala kọja, nigba ti oku keji ti wọn ri ni agbegbe kan nigboro Eko, ni ọgbẹ ọta ibọn lara.
Blighted Ovum: Obìnrin kan sọ ohun tójú rẹ̀ rí nígbà tí oyún bàjẹ́ lára rẹ̀ ní ẹ̀ẹ̀mẹta
Nigba ti ọdun fi pari, igbimọ olugbẹjọ ẹsun ifiyajẹni ti wọn fi kan awọn ọlọpaa to n joko nilu Eko si n gbọ ẹsun latẹnu awọn ti ọrọ naa kan, ti iwadi lori ipaniyan Lekki si n tẹsiwaju."
Eyo Festival: Wo ohun tó yẹ kò mọ̀ nípa ọdún tí takọ-tabo kò ti gbọdọ̀ wọ bàta tabí mu sìgá
Oríṣun àwòrán, Wikipedia
Ilu kọọkan to wa nilẹ Yoruba lo ni ami idamọ tiẹ, ati awọn ọdun ibilẹ ti wọn n se, eyi ti wọn maa n ki oriki wọn mọ.
Bi Orò se wa nilẹ Ijẹbu, ti Olóòlú wa ni Ibadan, naa ni ọdun Ẹyọ wa nilu Eko.
Ẹyọ yii, ti wọn tun n pe ni Adamu Orisa, gẹgẹ ba se ri ka latara akojọpọ iroyin nipa rẹ loju opo Wikipedia, lo jẹ ọdun ibilẹ pataki, tawọn ọmọ bibi ilu Eko kii fi sere rara.
Àwọn ìtàn mánigbàgbé tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí:
Amọ lojumọ to mọ loni, wọn ti gbe ọdun naa larugẹ debi pe o ti di apeyawawo, ti wọn fi n se irinajo afẹ, eyi to n mu owo wọle wa fun ilẹ wa.
Ẹyọ lo tumọ si awọn onijo ti wọn n wọ asọ ibilẹ to yatọ, wọn yoo bori lati oke delẹ bii eegun pẹlu asọ funfun, wọn yoo de ate tabi akẹtẹ sori, ti wọn yoo si ma jo kiri pẹlu ọpa lọwọ lasiko ọdun.
A le ni ọdun Ẹyọ yii lo jẹ ohun ti awọn ẹgbẹ awo nilu Eko n se agbatẹru rẹ, ọgbẹri ko si le mọ nipa rẹ.
Laye ijọun, awọn Ẹyọ ni wọn maa n sin ọba tabi oloye pataki to ba waja lọ si itẹ, ti wọn si tun maa n se ayẹyẹ fun ọba tuntun to ba gun ori itẹ.
Oríṣun àwòrán, Wikipedia
Ere ẹyọ yii lo dun wo, to si n se afihan asa ilẹ adulawọ, eyi ta le fi we ajọdun asa to maa n waye nilẹ Brazil.
Yatọ si ọdun Ẹyọ awọn ọdun mii wa tawọn eeyan Eko a maa se bi  ọdun Egungun Awoo Ode, Oko aje ati ọdun Oya.
Amọ lara awọn ohun idanimọ ti ilu Eko fi di ilumọọka ni ọrọ aje to burẹkẹ nibẹ.
Itan fi ye wa pe awọ̀n Ẹ́yọ̀ akọ̀kọ̀ lo jade to lọ̀wọ̀ọ̀wọ̀ nilu Eko ni ogunjọ osu keji ọ̀dun 1854  ni erekusu Eko, ni agbegbe Iga Iduganran.
Wọ̀n si se ọ̀dun Ẹ́yọ̀ yii lati se ayẹ́yẹ́ fun igbe aye Ọ́ba Akitoye tilu Eko ni.
Amọ̀ itan salaye pe ilu Iperu nipinlẹ Ogun ni Ẹyọ ti wa, ibẹ si ni orirun rẹ.
Pupọ eeyan nipinlẹ Eko lo gbọnju ba ọdun Ẹyọ pẹlu ọdun mii bi ọdun Igunnu tawọn babanla wọn maa n se.
Oríṣun àwòrán, Wikipedia
Orisi Iga Ẹyọ to wa ni Eko ati Orukọ idile ti wọn n soju
Iga Ẹyọ to wa lati Iperu Akesan la le pin awọn idile to n gbe si marun, eyi ti wọn fi n sọri orisi Ẹyọ to wa nilu Eko. Awọn si ni iwọnyi:
Gẹgẹ bi itan se fi ye wa, Oba Eko nigba naa lọhun, Oba Akinsemoyin lo tọ Ẹyọ lọ, ki aburo rẹ Erelu Kuti baa le ri ọmọ bi.
Erelu Kuti pada ri ọmọ bi, to si se wipe awọn arọmọdọmọ rẹ ni wọn n jẹ alẹnulọrọ lori awọn to n jẹ Ọba ni Eko titi di oni.
Itan tun sọ fun wa pe, adugbo Oke Ipa to sun mọ agbegbe Glover ni Ikoyi, ni wọn ti kọkọ se ọdun Ẹyọ ni igba naa lọhun.
Oríṣun àwòrán, Wikipedia
Ilana bi wọn ti n se ọdun Ẹyọ nilu Eko
Oke Ipa ni ibi tawọn ọba ati oloye maa n rinrin ajo ọlọjọ mẹta lọ lati le pejọ wo ere Ẹyọ.
Diẹ diẹ ere Ẹyọ di alarinrin ti wọn si n mu iyipada ba sise ere naa bi ọdun se n gun ori ọdun.
Lọpọ igba ti ọba ba waja ni wọn a maa se ere Ẹyọ tabi ni igba ti ọba mi ba gun ori apere.
Lode oni, wọn a maa se ere Ẹyọ lati fi se apọnle eekan ilu Eko to ba papoda tabi ti awọn alejo pataki kankan ba wa sabẹwo si ipinlẹ Eko.
Wọn a maa saba pari pọpọnsinsin Ẹyọ yii gbọngan nla Tafawa Balewa Square ni Ilu Eko.
Bẹẹ naa ni awọn Ẹyọ a tun maa kopa ninu ajọdun asa ti awọn alakoso ipinlẹ Eko ba seto, Arts and Culture Festival.
Oríṣun àwòrán, Wikipedia
Bakan naa ni ipinlẹ Eko maa n gbe Ẹyọ lọ kopa ninu idije asa ati ibilẹ ni Naijiria, National Arts and Culture Festival
Ohun kan to se koko ni pe ere Adimu Orisa yii ko le ma waye ni Eko ti Ọba Eko ba waja.
Fawọn mọlẹbi to ba fẹ fi ere Ẹyọ se ayẹsi eeyan wọn pataki  to papọda, o di dandan ki wọn kan si Akinsiku ilu Eko, to jẹ olori awọn ẹyọ fun iyọnda rẹ kawọn elere Ẹyọ to jade sita.
Lẹyin ti wọn ba ti mu awọn nkan etutu ati ẹbun to yẹ wa, ẹyin igba naa ni wọn to le da ọjọ ti Ẹyọ yoo jade sere .
Lọjọ ajọdun Ẹyọ, nise ni wọn maa n di gbogbo oju ọna ni erekusu Eko.
Lati oju ọna afara Carter Bridge titi de Tinubu Square, awọn alajọdun yii maa n di oju ọna naa ni.
Lati ibẹ ni wọn yoo ti wọ lọ si Iga Idunganran,  ikorita Tafawa Balewa ni wọn si maa n pari gbogbo eto wọn si.
'Èmi àti ìyàwó mi ti ń gbé pọ̀ nínú ìgbéyàwó wa fún 60 years', ẹ wá kọ́ ẹ̀kọ́ lẹ́nu àgbà méjì
Ọsẹ kan saaju ki ajọdun naa to waye, awọn Ẹyọ agba maa n na ọpa sita fun gbogbo eeyan lati foju ri. Eyi tumọ si pe ọsẹ to n bọ ni wọn yoo jade Eyọ.
"Lowurọ ọjọ ajọdun""Orisa Oniko""  maa n jade lati wọ gbogbo aburu to wa ninu ilu danu."
Awọn ikọ mẹrẹẹrin Ẹyọ maa n to jade lọọkọọkan laarin ọjọ Aje si ọjọbọ. Awọn ikọ naa ni (Laba (Red), Oniko (yellow), Ologede (Green) ati Eyọ Agere (Purple)
Lẹnu ọjọ mẹta yii, wọn kii se ọdun Ẹyọ bii ti atẹyinwa mọ nilu Eko.
Akọsilẹ taa ri ni pe lọdun 2017 ni wọn ti se Ẹyọ kẹyin ni Eko, boya ọna lati dena iwa jagidijagan si ni eyi fi ri bẹẹ.
Nitori naa pupọ eeyan ni ko ni ranti Adamu Orisa ati pọpọsinsin ti o maa n ba ajọdun yii wa nipinlẹ Eko.
Chris Oyakhilome: £125,000 ní owó ìtanràn tí Tẹlifísàn Loveworld yóò san fún ìwà arúfin
Oríṣun àwòrán, pastorchris.oyakhilome Instagram
Ajọ to n se akoso eto igbohunsafẹfẹ nilẹ United Kingdom ti kesi ileesẹ mohunmaworan pasitọ kan ni Naijiria, Chris Oyaklome lati sanwo itanran.
Ileesẹ mohunmaworan naa, Loveworld Television Network, ni wọn ni ko san owo itanran ẹgbẹrun lọna marundinlaadoje pọnun 125,00.
Ẹsẹ ti wọn ka si ọrun ileesẹ agbohunsafẹfẹ naa ni pe o gbe eto kan sita lori ọrọ ẹsin, ninu eyi ti wọn ti n sọ awọn ofege iroyin nipa arun Coronavirus lai daabo bo awọn onworan wọn.
Ajọ naa ni igba keji ree laarin ọdun tileesẹ naa yoo tako ofin to rọ mọ gbigbe ojulowo iroyin lai ni abula sori afẹfẹ, eyi to n tako iroyin gidi nipa arun Coronavirus.
A ri awọn iwa riru ofin yii bii eyi to gbopọn pupọ ati iwa asise mase to n foju han lọpọ igba eyi to mu ka ta ileesẹ igbohunsafẹfẹ naa loji owo.
Bed Wetting: Tolulope Joseph ní ò lé ní ogún ọdún tí òun fi tọ̀ sílé kí ìwòsàn tó dé
Ileesẹ ijọ UK to n sakoto awọn ileesẹ igbohunsafẹfẹ naa ni oun to n kọ oun lominu ni pe igba akọkọ kọ ree tileesẹ amohunmaworan Loveworld yoo tasẹ agẹrẹ si ofin awọn.
O ni irufẹ iwa arufin naa ti kọkọ waye lọdun 2020, tileesẹ tẹlifisan Loveworld si fi ọwọ gbaya pe oun yoo mu ibọwọ fun ofin lọkunkundun lai se bẹẹ.
Muyiwa Ademola: Ẹ forí jìn mí, àpàrá lásán tí mo dá nípa òṣèlú ṣíṣe ti gbọ̀nà míì yọ
Oríṣun àwòrán, Instagram/authenticmuy
Muyiwa Ademola, ti ọpọ eeyan mọ si Muyi Authentic ti sọ pe, iṣẹ tiata ni iṣẹ ti ori ran oun ati pe oun ko nifẹ si oṣelu ṣiṣe.
Ademola lo sọ ọrọ naa loju opo Instagram rẹ, lẹyin to ti kọkọ kede saaju nipa ipinu rẹ lati darapọ mọ oṣelu sise.
Ninu ikede to kọkọ gbe jade lọjọ kinni, oṣu Kẹrin lo ti sọ pe oun ti bẹrẹ oṣelu, ati pe oun yoo du ipo sẹnatọ ninu idibo gbogbo gboo ti yoo waye lọdun 2023.
Ṣugbọn o ti wa sọ pe apara lasan ni ọrọ oun akọkọ nipa sise oṣelu.
"O ni ""Apara ti mo da yii ti n gbọna mii yọ o, mo kan ni ki n ṣere diẹ ni, ṣugbọn mo ni lati tọrọ aforoji lọwọ ẹyin ololufẹ mi."""
Oríṣun àwòrán, Instagram/authenticmuy
"Muyi Authentic sọ pe, oriṣiriṣi ipe ni oun gba lati ọdọ awọn ololufẹ oun kaakiri Naijiria titi de ilu Abuja lori ọrọ pe oun ti di oloṣelu, ṣugbọn o ni ""April Fool"" lasan ni ikede ọhun."
O sọ siwaju si pe, apara ti oun da naa, jẹ ki oun mọ si nipa ifẹ ti awọn eeyan ni si oun ati irufẹ oju ti ọpọ eeyan fi wo ọrọ oṣelu ni Naijiria.
"O ni ""bi awọn kan ṣe n ṣọ pe awọn wa lẹyin mi digbi bii ike, lawọn mii n sọ pe ki n ma ba wọn lọwọ si ọrọ oṣelu Naijiria fun idi kan tabi omiran."""
Muyiwa ni oun tun kọ ẹkọ tuntun miran nipa awọn eeyan ilu ti oun n gbe lori, nipa bi wọn ko ṣe lee ti oun lẹyin to ba tilẹ jẹ pe lootọ ni oun fẹ gbegba oṣelu.
Oríṣun àwòrán, Instagram/authenticmuy
"Ọmọ Ademola sọ pe ""o jẹ ohun iyalẹnu fun mi pe awọn eeyan ilu ti mo ti ka gbogbo iwe aye mi, ti mo kọle si, ti mo n gbe, ti mo si tun ti n ṣiṣẹ ko ti mi lẹyin ninu ọrọ oṣelu yii, to ba tilẹ jẹ pe lootọ ni mo fẹ ṣe oṣelu."""
Lẹyin naa lo tọrọ aforiji lọwọ awọn ololufe rẹ fun apara ọhun, o si tun fidi rẹ mulẹ pe, iṣẹ tiata ni iṣẹ ti ori ran oun.
Ẹwẹ, April Fool ni apara ti awọn eeyan maa n da ni gbogbo ọjọ kinni, oṣu Kẹrin, ọdọdun, fun ẹfẹ tabi ere ṣiṣe.
Cattle Ranching: Ẹ wo Fulani darandaran to tako àṣà dída màálù kiri lójú pópó
Ṣugbọn ọpọ lo ti n bu ẹnu ẹtẹ lu apara naa nitori irufẹ atubọtan to maa n gbẹyin awọn apara miran.
Iroyin ni ọpọ eeyan lo ti dero ileewosan lẹyin ti wọn daku nitori apara April Fool, ti ẉon ro pe o jẹ ootọ.
Oríṣun àwòrán, Instagram/authenticmuy
Gbogbo ẹda lo maa n gbero lati de ibi giga, ti ẹda kii si sinmi titi yoo fi de ibi ọla rẹ.
Bẹẹ ni ọrọ ri pẹlu ilumọọka osere tiata nni, Muyiwa Ademola, ti ọpọ eeyan mọ si Muyi Authentic.
Muyiwa Ademola lo kede loju opo instagram rẹ pe oun ti setan lati dara pọ mọ agbo oselu ilẹ wa, ti oun yoo si gbegbe ibo lọdun 2023.
Ademola ni oun yoo sinmi fun igba diẹ naa fun ere tiata, ti oun yoo si kọju mọ oselu sise gẹgẹ bo se wa ninu erongba oun lati ọjọ pipẹ wa.
Oríṣun àwòrán, Instagram/authenticmuy
Bakan naa ni ilumọọka osere tiata naa ni oun ti pinnu lati dije fun ipo asofin agba ta mọ si Sẹnetọ ninu idibo gbogbo gboo lọdun 2023.
"Ademola ni ""Isisẹ sin ọmọniyan ni owo ile to san pe o n gbe ile aye, gẹgẹ bi Muhammed Ali ti wi. Lẹyin o rẹyin, mo ti wa n jade sita bayii lati sisẹ sin orilẹede mi atawọn eeyan mi."
Mo n yẹba diẹ na fun isẹ tiata sise lati dije fun ipo Sẹnetọ, ki Ọlọrun ran mi lọwọ.
Ademola ni ilu Ibadan ni oun tẹdo si, fun ọdun mẹtadinlaadọta amọ ọmọ ọba ni oun ni ididle ọba kan nilu Abeokuta nipinlẹ Ogun.
Oríṣun àwòrán, Instagram/authenticmuy
Gbajumọ osere tiata naa wa n beere lọwọ awọn ololufẹ rẹ pe nibo ni wọn lero tabi ti wọn le gba oun nimọran lati dije fun ipo naa.
O ni se ilu Ibadan lo yẹ ki oun ti dije ni abi Abeokuta tii se ilu abinibi oun.
Bẹẹ ba si gbagbe, Ademola lo ti kọkọ beere lọwọ awọn ololufẹ rẹ pe ki wọn sọ orukọ musulumi oun nitori oun ni orukọ abisọ to jẹ ti ẹsin Islam.
Báa ṣe lọ́pọlọ tó, ẹnu Yorùbá ò kò, ọgbọ́n táa gbúdọ̀ dá rèé - Ìpàdé àgbààgbà Yorùbá n'Ibadan
Osere tiata naa sisọ loju rẹ pe ọmọ bibi ilu Ilorin ni iya oun, ti baba oun si sọ oun ni Muyiwa Ademola Stephen amọ wọn fun oun ni orukọ Mususlumi.
Oduduwa Nation: Gani Adams ní àìmọ ìtàn ló ń mú kí Oluwo máa tako ìpè fún ìyapa Nàìjíríà
Aarẹ Ọna Kakanfo fun ilẹ Yoruba, Iba Gani Adams ti ranṣẹ si Oluwo ti Ilu Iwo, lori bo ṣe n ta ko ọrọ idaduro ilẹ Yoruba, o ni ko lọ ranti  pe bi wọn ba ran ọmọ ni iṣẹ ẹru, a fi tọmọ jẹ ẹ.
Iba Gani Adams sọ ọrọ yii ninu ifọrọwerọ rẹ pẹlu BBC News Yoruba lọjọbọ.
O ni pẹlu bi ọrọ abo, eto ẹkọ, ilera ati igbayegbadun araalu ṣe ri ni Naijiria bayii, ilẹ Yoruba ko lee tẹsiwaju ati maa sinru nibi to yẹ ko ti lẹnu.
Gani Adams ni lootọ oun ko lee yọ ẹrẹkẹ ṣuti tabi eebu si ọba kankan ni ilẹ Yoruba, ṣugbọn o wa rọ awọn ọba Yoruba lati fi ara wọn sipo ọwọ, ki wọn si maa tẹ sibi tawọn ọmọ Yoruba ba tẹ si.
Oluwo ṣẹṣẹ jẹ Ọba ni, ko mọ itan Yoruba lo fi n ṣe gbogbo ohun to n ṣe lori oye, ko mọ pe ọba ti ko ba se ifẹ araalu maa n kabamọ gbẹyin ni.
Oluwo, tí wọ́n bá rán ọmọ níṣẹ́ ẹrú, kó fi t'ọmọ jẹ - Gani Adams
O ni awọn iroyin to n lọ kaakiri n fihan pe, awọn ọbalaye nilẹ Yoruba naa n lọwọ ninu wahala naa pẹlu bi ọpọlọpọ wọn ṣe n gba maluu ati ẹran ọsin miran lati dakẹ lori iwa ibajẹ awọn Fulani darandaran.
Adams ni eyi gan n kun ara ohun to n fun awọn ọbayejẹ ọdaran darandaran naa lanfani ati tẹsiwaju ninu iwa aitọ wọn.
Iba Gani Adams ṣalaye pe, lootọ awọn ọba alaye kan ti ngba ohun ti ko tọ bi abẹtẹlẹ, amọ kii ṣe gbogbo ọba lo jẹ ọbẹ, ja epo si aya , sugbọn igbesẹ ti n lọ lati mu atunṣe ba iha naa.
Bí Oduduwa Republic bá bẹ̀rẹ̀, a ò ní ṣe aburú fún àwọn tó takò wá, ìlànà ààtẹ̀lé rèé - Banji Akintoye
O tun ke sawọn eekanlu, ọbalaye ati ilumọọka ilẹ Yoruba ti ko ba nifẹ si idaduro ilẹ Yoruba lati dakẹ jẹjẹ titi ayeraye, ki wọn maa ba a foju wina ibinu awọn ọmọ Yoruba.
Ẹwẹ, Iba Gani Adams ṣalaye pe, ihuwasi awọn agbofinro pẹlu ko ran ilakaka araalu lati dẹkun ipenija abo ni ilẹ Yoruba lọwọ.
Nigba to n mẹnu ba bi ọlọpaa ṣe fi mẹta ninu awọn ọmọ ẹgbẹ OPC si ahamọ, lẹyin ti wọn fi panpẹ mu Wakili, afurasi Fulani ti wọn ni o n da awọn eeyan oke Ogun laamu, gẹgẹ bi apẹrẹ,.
Iba Adams ni awọn agbofinro ko fẹ fi ọwọ sowọpọ pẹlu araalu lati dẹkun ipenija eto aabo naa.
O ni bi awọn ọbalaye, agbofinro ati alaga ijọba ibilẹ ba le e fọwọsowọpọ pẹlu awọn araalu ati ẹgbẹ gbogbo to yẹ, ipenija abo yoo dẹkun ni kiakia.
Oríṣun àwòrán, Gani Adams
Aarẹ Ọna Kakanfo tilẹ Yoruba, Iba Gani Adams tun ti sọrọ lori ipo ti eto aabo ilẹ Yoruba wa, to si ni arwo aabo to mẹhẹ ti dinku pupọ.
O ni lootọ ni ewu si n waye lawọn agbegbe kan amọ aabo ti n gbopọn lawọn agbegbe kan yatọ si bo se n waye ni osu mẹta si mẹfa sẹyin.
O ni pẹlu ajọsepọ awọn ẹlẹgbẹjẹgbẹ atawọn eeyan kan to n se ipade loore koore lori eto aabo yii, o ti n so eso rere.
"A ti kọ lẹta si gbogbo ọba nilẹ Yoruba, ti mo si fi ọwọ si lẹta naa eyi tawọn ọlọdẹ ati OPC fi ọwọ si pe ki wọn maa fi idunkooko to ba wa ni agbegbe wọn ransẹ.
Atunto Naijiria la n fẹ - Aarẹ Onakakanfo, Gani Adams
O ni ọrọ eto aabo kii se ọrọ ariwo, amọ o yẹ ka bi awọn agbofinro wa pe se wọn setan pe ki aabo wa ni Naijiria
Awọn agbofinro wa to n se ijamba feto aabo lo mu ki awọn eeyan maa fun idasilẹ Oduduwa, sugbọn ti wọn ba fọwọsowọpọ pẹlu araalu, eto aabo to mẹhẹ yoo dohun itan."
Lori idasilẹ orilẹede Yoruba, Gani Adams ni Íbi ti Yoruba ba ti n lọ ni mo n lọ, ohun ti wọn ba fẹ, ni mo fẹ. Amọ o yẹ ki a beere pe nibo lawọn ọba atawọn oloselu wa n lọ nitori emi gan fẹ orilẹede Oduduwa.
Wakili tẹẹ rí yẹn kìí ṣe ẹran rírọ̀, ó ń díbọ́n ní o - Iba Gani Adams
"Awọn ọjọgbọn kaakiri agbaye ni Odududwa Republic ni awọn n fẹ. Laelae n ko ni jẹ ọta Yoruba, a si ti se ipade lori ayelujara, to si foju han pe Oduduwa Republic ni awọn eeyan wa n fẹ."""
Laarin ọdun mẹwa, ọrọ aje Yoruba yoo ru gọgọ, nitori Ọlọrun fun wa ni ọpọlọ pipe, ti idagbasoke nla gidi yoo si wa fun ilẹ Yoruba.
Iwa ijiyin isẹ iriju ẹni yoo pada sinu ilana isejọba wa, ti eto aabo to gbopọn yoo si wa nigba ti iwa ajẹbanu yoo dinku
Tẹlẹtẹlẹ, ko si ole jija nilẹ Yoruba amọ ọdun 1975 ni idigunjale bẹrẹ, eyi ti yoo dinku pupọ, ti orilẹede Yoruba ba wa.
Nigba to n sọrọ lori awọn eeyan wa to wa loke ọya, Adams ni ka to gba orilẹede oodua, ko nilo kawọn eeyan wa loke ọya wa sile tabi kawọn ẹya miran kuro nilẹ Yoruba.
O fikun pe ohun to le mu akude wọ agbekalẹ orilẹede Oodua ni aala ilẹ amọ o ni Ọlọrun ti se eyi funra rẹ nitori aala wa ti wa tipẹ.
Kò sí ìgbà kankan tí Yorùbá jókòó pé ki Igboho  lọ kéde ìyapa kúrò ní Nàíjíríà
Aarẹ ni dandan kọ ni ki ogun waye, ka to pin kuro ni Naijiria, a le joko sori tabili, ka si pin Naijiria si wẹwẹ
O pe mi ki n jẹ ọrẹ iran mi ju ọrẹ awọn aninilara lọ
Iba Gani Adams wa fọwọ jaya pe oun ko ni tako nnkan ti Yoruba ba n fẹ nitori ẹni to ba n se ọta ilu maa n ge ika jẹ gbẹyin ni.
O wa rọ awọn ọba alaye nilẹ Yoruba lati fọwọsowọpọ pẹlu iran Yoruba lati ri daju pe ohun ti wọn n pohungbẹ tẹ wọn lọwọ.
Bakan naa lo ni oun ko ni sọrọ abuku si ọba kankan amọ o yẹ kawọn ọba naa tete maa se ohun tawọn eeyan wọn ba n fẹ.
Lori eto aabo, Adams ni inu ọgba ẹwọn ni onikaluku wa nitori eto aabo to mẹhẹ.
O ni wọn ran Kọmisana ọlọpaa wa sipinlẹ Oyo ni, ki ọga ọlọpaa patapata tete gbe kuro
Igbesẹ gbigbe awọn
Doctors strike: Awọn Dokita 'NARD' da iṣẹ silẹ lati bere ẹtọ wọn lọwọ ijọba
Lonii ni ẹgbẹ awọn Dokita nile iwosan nla to jẹ tijọba, 'National Association of Resident Doctors of Nigeria', NARD jakejado orilẹede Naijiria gunlẹ iyanṣẹlodi lẹyin gbogbo ipade ti wọn ṣe pẹlu ijọba apapọ.
Awọn aṣoju ẹgbẹ naa ṣe alaye wi pe ikuna ijọba apapọ lori i gbogbo adẹhun ti o ṣe fun awọn Dokita naa lo ṣe okunfa iyanṣẹlodi ti wọn gunle.
Wọn ni gbedeke ti wọn fun ijọba tẹlẹri lati dahun awọn ibeere wọn ni ọjọ kọkanlelọgbọn oṣu kẹta ọdun, ṣugbọn ọjọ naa ti rekọja lọ lai gbọ nnkan kan lati ọdọ ijọba.
Lara awọn nnkan ti awọn Dokita naa n beere fun ni pe ki ijọba san gbogbo owo oṣu ati ajẹmọnu wọn, atungbeyẹwo owo iṣẹlẹ pajawiri kuro ni ẹgbẹrun marun un naira ti o wa bayii, sisan ajẹmọnu owo itọju aarun COVID-19
ati awọn ajẹmọnu to ni i ṣe pẹlu awọn ile ẹkọ giga ti o jẹ ti ijọba.Awọn Dokita ti o jẹ ọmọ ẹgbẹ naa nile iwosan UCH ilẹ Ibadan naa darapọ mọ awọn akẹgbẹ jakejado orilẹede Naijiria ninu iyanṣẹlodi to bẹrẹ lonii.
BBC Yoruba ṣe abẹwọ si ile iwosan nla fasiti ilẹ Ibadan, UCH lowurọ oni, paroparo sini ọfisi awọn Dokita naa da.
Botilẹ jẹ wi pe pupọ ninu awọn alaisan to n bẹ ninu ọgba ile iwosan naa ko ti i ni imọlara iyanṣẹlodi naa, ohun ti o ṣeeṣe ni pe ki wọn bẹrẹ sini ke irora bi iyanṣẹlodi naa ba pẹ ju botiyẹ lọ.
Adari ẹgbẹ Dokita nile Iwosan UCH, Dr Zakariyau Temitope Hussein ṣe alaye fun akọroyin wa wi pe iyanṣẹlodi ti o bẹrẹ lonii ko ti i ni ọjọ ti yoo pari nitori ki iyanṣẹlodi naa to bẹrẹ ni ijọba ti mọ gbogbo ohun ti wọn n beere
fun lati ọdun kan sẹyin.
"O ni, ""Nile le iwosan UCH nikan, awọn Dokita ti ijọba jẹ lowo to ọọdunrunlelaadọrin(370). Nitori wọn naa ni a fi n ṣe iyanṣẹlodi""."
O ni ọjọ ti ijọba ba da wọn lohun gbogbo nnkan ti wọn n beere fun ki iyanṣẹlodi naa to wa si opin.
Awọn nnkan ti awọn alakoso ẹgbẹ awọn Dokita naa fi ẹnu ko lati beere fun ni;
Ki gbogbo owo ati ajẹmọnu ti ijọba jẹ awọn ọmọ ẹgbẹ naa di sisan,  atungbeyẹwo owo iṣẹlẹ pajawiri and sisan owo itọju aarun COVID-19 sisan ajẹmọnu ọdun 2014-2016.
Ekiti Assembly election violence: Omijé ẹkún ṣàn níbi ìsìnkú sájẹ́ǹtì ọlọ́pàá táwọn tọ́ọ̀gì òṣèlú pa l'Ekiti
Wọn ti sin oku obinrin ọlọpaa ti awọn janduku ṣekupa lasiko atundi ibo sile aṣofin to waye ni ipinlẹ Ekiti lọjọ Satide to kọja.
Arabinrin ọlọpaa naa ti orukọ rẹ n jẹ Bukọla Ọlawoye-Ogundeji wa lara awọn eeyam mẹrin tawọn janduku oṣelu pa lasiko atundi ibo naa ni Omuo Ekiti.
Ile rẹ ni ilu Ikẹrẹ Ekiti ni wọn sin in si.
Ọkọ rẹ, Ignatius Ogundeji ati ẹgbọn rẹ, lalekan Ọlawoye daro iku rẹ ti wọn si rọ ileeṣẹ ọlọpaa lati ṣe eto to ts fun itọju ati amojuto ẹkọ awọn ọmọ ti oloogbe naa fi silẹ.
Arabinrin Alice Ẹlẹmọṣọ to mu bi iya pẹlu Ọmọlayọ Ọlawoye to jẹ iya rẹ gangan ṣalaye pẹlu omije loju pe olu smọ awsn ni wọn padanu naa.
Kọmiṣọna ọlọpaa ni ipinlẹ Ekiti, Tunde Mobayo ranṣẹ si ibi isinku naa pẹlu ileri pe  ileeṣẹ ọlọpaa ati ijsba ipinlẹ Ekiti yoo kede awsn ẹtọ to wa nikalẹ fun awọn ọms oloogbe naa atawọn obi rẹ.
ọmọ ọdun mẹtalelọgbọn ni arabinrin ọlọpaa Bukọla Ọlawoye-Ogundeji, Sajẹnti si ni ipo rẹ ki o to pade iku rẹ lsiko to lọ mojuto eto idibo si ile aṣofin ipinlẹ naa ni ogunjọ oṣu kẹta ọdun 2021.
Sunday Igboho: Àwọn ìkọlù sí mi, ilé àti ìyá mi fihàn pé àwọn kan ń dọdẹ mi
Oríṣun àwòrán, sunday_igboho1/Instagram
Eruku ariwo to sọ lana lori bi ajijagbara ọmọ Yoruba nni, Oloye Sunday Igboho se gba iwe ipe lati ọdọ ọga ọlọpa ni ọjọbọ, ko tii lọ silẹ rara.
Koda, ọpọ eeyan lo si n para poro lori isẹlẹ naa, ati ewu ti wọn lo see se ko wa fun ẹmi ajijagbara naa.
Amọ nigba to n salaye lori idi to fi kọ lati gba iwe ipe naa, to ni awọn gende ọlọpaa mẹẹdogun mu wa sile ohun, Sunday Igboho ni ọrọ naa gbero ni.
Agbẹnusọ fun Igboho, Olayomi Koiki salaye pe iriri to ti waye lati ẹyin wa nilẹ Naijiria lo mu ki awọn ẹsọ ajijagbara naa kọ lati gba lẹta ipe ọhun.
Sunday Igboho latest: Sunday Igboho kò gba 'Award'ti a fún un ní Ogo Yorùbá nítorí inú rẹ̀
Bẹẹ ba gbagbe, lẹta ni wọn wọn mu wa sile Dele Giwa lọdun 1986, to di bọnbu to bu kẹu, eyi to ran gbajumọ akọroyin naa sọrun ọsangangan.
Bakan naa lo fikun pe awọn isẹlẹ afunilara to n waye ni ayika ajijagbara naa to fura si pe wọn n dọdẹ rẹ loju mejeeji.
Abi ki ni ka ti sọ ti ina ti awọn ọbayejẹ kan sọ si ile Igboho ladugbo Soka nilu Ibadan losu diẹ sẹyin, tawọn osisẹ alaabo to wa ninu asọ Khaki naa si tun da lọna lasiko to n lọ silu Eko.
Pure Water Lylon Art: Adejoke ní ohun èlò ta fi ọ̀rá ṣe ń ní àlòpẹ́, kìí tètè jẹ
"Ko tan sibẹ, Koiki fikun pe awọn afurasi Fulani kan tun kọlu ile Sunday Igboho lọsẹ diẹ sẹyin, tawọn gende kan to wọ asọ ologun naa si tun wa tọpinpin ile rẹ."""
Koiki ni oye lagba n wo, ifura si ni oogun agba, tawọn gende agbofinro ba wa tun mu lẹta wa lati ọdọ ọga agba ọlapaa, eyi to mu ifura lọwọ.
Oríṣun àwòrán, Instagram/SundayIgboho
Ajijangbara ati ajafẹtọmọniyan, Sunday Igboho ti ke gbajare si awọn araalu pe ijọba Naijiria n gbiyanju lati fi panpẹ ofin mu oun ni bonkẹlẹ.
Agbẹnusọ fun Sunday Igboho, Olayomi Koiki lo fi ọrọ naa lede ninu atẹjade kan to fisita loju opo Facebook rẹ.
"Koiki ni ""a fẹ fi to gbogbo araye atawọn ọmọ Naijiria leti pe, ọga agba ọlọpaa fi lẹta kan ranṣẹ si Sunday Igboho, ṣugbọn awọn ẹsọ alabo rẹ kọ lati gba lẹta naa."""
O fikun pe Ọjọbọ, Ọjọ Kini, Osu Kẹrin, ọdun 2021 ni wọn mu lẹta naa wa sile Igboho lati ipasẹ ileesẹ igbalode afiweransẹ DHL.
Agbẹnusọ fun Igboho tun salaye pe, awọn ọkunrin mẹfa kan ti wọn pe ara wọn ni ọlọpaa ṣugbọn ti wọn ko wọ aṣọ isẹ, atawọn mẹsan an miran
gunlẹ sile Igboho ni deede aago mẹta ọsan Ọjọbọ naa.
Oríṣun àwòrán, Koiki Media
"Koiki ni mọto Corolla  ni wọn gbe wa sile ajafẹtọ ilu naa, ti wọn si sọ fawọn ẹsọ ile naa pe awọn fẹ ri oloye igboho."""
Koiki ṣalaye pe awọn gende ọhun sọ pe ọdọ ọga agba fun ileeṣẹ ọlọpaa Najiria ni awọn ti wa pẹlu lẹta kan lọwọ wọn, ti wọn kọ orukọ Sunday Igboho si lara.
Wọn ni ọga agba ọlọpaa lo ni kawọn fun ni lẹta naa amọ sibẹ ikọ alaabo Sunday Igboho ko tẹwọ gba lẹta ọhun.
Agbẹnusọ fun ajijagbara naa wa n beere ninu atẹjade naa pe Sunday Igboho yoo nifẹ lati mọ idi ti ọga agba yanyan fun ileeṣẹ ọlọpaa yoo ṣe fi iwe pe oun.
Igboho ni ti wọn ba tilẹ fẹ fi iwe pe oun gan, o yẹ ki wọn kọkọ fi iwe pe gbogbo awọn janduku ajinigbe atawọn ọmọ ẹgbẹ Boko Haram, to n da
alaafia Naijiria laamu lati ọjọ yii wa.
Sunday Igboho fulani ultimatum: Àwọn ará Kebbi àti Zamfara ló n jínígbé ní Oke Ogun- Serik
Igboho fi kun pe, ti ọga agba ileeṣẹ ọlọpaa ba fẹ ri, n ṣe lo yẹ ko kede nita gbangba dipo ko maa fiwe ipe ranṣẹ si oun nikọkọ.
Koiki pari ọrọ rẹ pe, fifi lẹta ranṣẹ si Igboho ko jẹ itẹwọgba awọn rara, nitori pe, bẹẹ ni ijọba Naijiria ṣe fi lẹta ranṣẹ si ọmọ Yoruba kan ri ni ọpọ
ọdun sẹyin, iyẹn Dele Giwa, eyii to mu ẹmi rẹ lọ.
siluu Eko, lagbegbe Guru Maraji, ṣugbọn ti wọn mu ofo.
Good Friday: Kí ló jẹ́ kí wọ́n máa pe ọjọ́ tí wọ́n kan Jésù mọ́ igi agbelebu ní ọjọ́ rere?
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ọdún Ajinde yìí ni àwon ọmọlẹyìn Kristi jakejado àgbáyé máa n ṣe ìrántí ikú ati ajinde Jesu Kristi.
Ni ibẹrẹ pẹpẹ ẹṣin Kristẹni, awọn onigbagbọ máa n ya ọjọ náà sọtọ gẹgẹ bíi ọjọ ibanujẹ, ọjọ ọfọ, ọjọ ironupiwada ati ọjọ awẹ.
Ọjọ yii si ni wọn maa n pe ni ọjọ Ẹ́ti rere lode oni, koda, ọpọ Kristiẹni kii jẹ ohun abẹmi to jẹ ẹlẹjẹ ni iru ayajọ oni lati sami ati iya nla iku Jesu lori igi agbelebu.
Fun ọdun 2021, oni yii, tíì ṣe ọjọ Keji, oṣù Kẹrin ni ọjọ Ẹti rere fun ọdun yii bọ si, ti wọn n pe ni Good Friday.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Bó tilẹ jẹ pé ọjọ ọfọ ati ìbànújẹ ni ọjọ náà jẹ ninu itan ẹṣin onígbàgbọ, amọ ọjọ náà ló jẹ òpin ọsẹ to se pataki julọ ninu itan Kristẹni.
Ọsẹ yii ni wọn maa n pe ni ọsẹ ikaanu fun ijiya ati iku Jesu Kristi.
Ìgbàgbọ àwọn Kristẹni ni pé, ọjọ Ẹtì náà ni Jesu ku lórí igi agbelebu, to sí ko ẹsẹ gbogbo araye lọ, ko to di pe o ji dide pada ni ọjọ kẹta.
Cattle Ranching: Ẹ wo Fulani darandaran to tako àṣà dída màálù kiri lójú pópó
Ṣugbọn ki lo de ti wọn fi n pé ọjọ náà ni Good Friday, ìyẹn ọjọ Ẹtì rere, dipo ọjọ ibanujẹ ti ọjọ náà jẹ?
Àlùfáà Mike Schmitz ni lootọ lo jẹ ọjọ ibanujẹ, ṣugbọn ni ida keji ẹwẹ, ọjọ ayọ ni ọjọ náà nítorí pé ọjọ ọhun gan ni Jésù ko ẹsẹ arayé lọ lori igi agbelebu.
O ni awọn onígbàgbọ́ máa n ri ọjọ náà bíi ọjọ ti Ọlọrun ko ẹsẹ arayé lọ, to si dari ẹsẹ jin gbogbo èèyàn labẹ ore ọfẹ Jesu.
Bed Wetting: Tolulope Joseph ní ò lé ní ogún ọdún tí òun fi tọ̀ sílé kí ìwòsàn tó dé
Àlùfáà náà parí ọrọ rẹ pé, agbelebu nìkan ni idahun sí gbogbo ìbéèrè awọn Kristẹni lórí gbogbo ìṣòro tí wọn bá gbé tọ Ọlọrun wa.
Eredi ree ti ọjọ Good Friday yii se jẹ ọjọ ayọ fun onígbàgbọ bo tilẹ jẹ pé ọjọ burúkú ni ọjọ náà nínú ìtàn ẹṣin Kristẹni káàkiri àgbáyé.
BBC Yoruba wa n ki awọn ọmọlẹyin Kristi lagbaye ku ọdun ọjọ Ẹti rere, ta si n gbadura pe a se pupọ rẹ nile aye.
Sunday Igboho: YCE ní ọ̀pọ̀ ìgbà ní Miyetti Allah sọ̀rọ̀ àbùkù, tí kò sẹ́ni tó gbé wọn
Oríṣun àwòrán, TWITTER
Sunday Igboho ke gbajare sita pe gende mẹẹdogun mu iwe wa sile oun pe Ọga ọlọpaa fẹ ri oun.
Ẹgbẹ agbaagba nilẹ Yoruba, YCE ti fi atilẹyin wọn han si bi ajijagbara ati ajafẹtọ ẹni nni, Sunday Igboho ṣe kọ lati tẹwọ gba iwe ipe ti ọga agba ọlọpaa fi n pe e wa si Abuja.
Akọwe agba fẹgbẹ YCE, Dokita Kunle Olajide lo fi atilẹyin rẹ han wipe, o dara bi Igboho ṣe kọ ipe naa, nitori ejo lọwọ ninu.
Olajide ni Igboho lasẹ lati mase tẹwọ gba iru lẹta bẹẹ lọwọ awọn ti ọga agba ọlọpaa fi ran nitori  bi nkan ṣe ri lorilẹede Naijiria.
''O buru jai ki Ọga agba ọlọpaa fi iwe pe Igboho lati ilu Ibadan wa si ilu Abuja pẹlu bi oju ọna ṣe ri lorilẹede Naijiria.
Sunday Igboho latest: Sunday Igboho kò gba 'Award'ti a fún un ní Ogo Yorùbá nítorí inú rẹ̀
"''Ti awọn ọlọpaa ba ni ibeere fun Igboho, awọn ọga ọlọpaa to wa ni ilu Ibadan le ṣoju Ọga ọlọpaa, lai si wi pe wọn rin irinajo lọ si ilu Abuja."""
Akọwe ẹgbẹ awọn agbaagba ni ilẹ Yoruba naa ni ki ọga agba ọlọpaa tẹle ilana awọn ọlọpaa nitori o ni awọn kọmiṣọna ni abẹ rẹ, to le ṣiṣẹ fun un ni ilu Ibadan lai de Abuja.
''Nitori to ba jẹ emi naa, n ko ni gba lẹta ọhun, nitori a ti ri awọn to gba lẹta saaju ri, to jẹ ado oloro to bu gbamu lo wa ninu rẹ''
''O tilẹ lewu ki eniyan gbera lati ilu Ibadan lọ si ilu Abuja pẹlu bi awọn oju ọna ṣe lewu lati gba lasiko yii.''
Pure Water Lylon Art: Adejoke ní ohun èlò ta fi ọ̀rá ṣe ń ní àlòpẹ́, kìí tètè jẹ
Bakan naa lo kesi ẹka eto aabo lorilẹede Naijiria lati ṣiṣẹ wọn bi iṣẹ, ki wọn ye e fari apa kan, da apa kan si ni idi iṣẹ wọn.
Kunle Olajide fikun wi pe, ọpọ igba ni ẹgbẹ awọn Fulani darandaran, Miyetti Alah ti n sọrọ kubakugbe lori afẹfẹ, ti ko si si ẹni to fi iwe pe wọn, ki wọn wa jẹjọ.
Oríṣun àwòrán, femi fani Kayode
Awọn ọmọ Yoruba kan ti n fesi lori iwe ipe ti ọga agba ọlọpaa fi ransẹ si ile Oloye Sunday Igboho lọjọbọ.
Sunday Igboho lo pariwo sita pe awọn eeyan kan, ti wọn pe ara wọn ni ọlọpaa, mu iwe kan wa si ile oun.
O ni awọn gende mẹẹdogun to wa sile oun naa sọ pe ọga agba ọlọpaa lorilẹede Naijiria lo n pe oun.
Amọ nigba to n fesi lori isẹlẹ yii, Minisita feto irinna ofurufu tẹlẹ, Fẹmi Fani Kayode ke si ijọba apapọ pe ko ṣe pẹlẹ lori ọrọ Sunday Igboho.
Oríṣun àwòrán, femi fani-kayode
Fani-Kayode, ẹni to se ikilọ naa loju opo Twitter rẹ ni ko ni dara ki ijọba apapọ fi ọwọ ara rẹ da wahala ti ko ni lee pari silẹ.
Fani Kayọde ṣalaye pe, o daju pe awọn eekan ọmọ Yoruba kan to woye pe, okiki ati ọla ti Sunday Igboho n ni lojoojumọ, ti fẹ bori tiwọn, lo wa nidi ọrọ yii.
O ni awọn ọmọ Yoruba naa, ti wọn ri pe irawọ Igboho ti fẹ bo irawọ tiwọn mọle ni wọn n ko si ijọba aarẹ Buhari ninu pe ko fi panpẹ ofin gbe Sunday Igboho.
Oríṣun àwòrán, @realFFK
...fifi papnpẹ ofin gbe Igboho ko lee ran awọn eeyan wọnyi lọwọ ninu ilepa oṣelu wọn. Yoo kan tun tubọ jẹ ko ṣoro fun wọn lati mu erongba oṣelu ti wọn ni ṣẹ ni.
O fi kun pe ni ilẹ to mọ loni yii, oun ko lero pe Sunday Igboho tii ṣe ohunkohun to tapa si ofin orilẹede Naijiria.
Ohun kan to ṣe naa ko ju wi pe o duro fun erongba ati ilepa awọn ọmọ Yoruba to le ni aadọrin miliọnu.
Oríṣun àwòrán, @realFFK
O ni Igboho ni ọpọ ọmọ Kaarọ oojire n wo gẹgẹ bii akinkanju ilẹ Yoruba, lẹyin Oduduwa to tẹ ilẹ naa gan do.
Oloye Fẹmi Fani Kayọde wa ke si ijọba aarẹ Buhari pe, dipo wiwa ọna ati mu Igboho tabi ṣeku paa, o yẹ ki wọn wa ọna ati joko baa jiroro lori ohun to n ja fun ni.
O ni erongba rẹ naa ko si sẹyin didẹkun gulegule awọn ọdaran darandaran Fulani to n da hilahilo silẹ lẹkun ilẹ Yoruba.
Oríṣun àwòrán, @realFFK
"Maa sọ ọ lẹẹkan yii pe, ohun kan to fẹ ti igi bọ oju alaafia ati iduro ṣinṣin orilẹede Naijiria loni yii ni bi awọn eeyan kan
Ni ijọba Buhari ṣe n gbero lati pa, tabi fi panpaẹ ofin mu ọrẹ mi ati eeyan mi, Oloye Sunday Adeyẹmo, ti ọpọ mọ si Sunday Igboho."
Pure Water Lylon Art: Adejoke ní ohun èlò ta fi ọ̀rá ṣe ń ní àlòpẹ́, kìí tètè jẹ
Ori lo mọ isẹ asela, bẹẹ si ni atẹlẹwọ ẹni kii tan ni jẹ.
Adejoke Lasisi ree, ẹni ti isẹ ọọfisi wu lati se amọ to pada n fi isẹ ọwọ bu okele sẹnu lai wa isẹ sarafinni kiri mọ.
Adejoke, ẹni to n fi aloku ọra Pure Water atawọn aloku asọ se asọ oke eyi to n lo lati se baagi, bata, ẹni atẹẹka ati bẹẹ bẹẹ lọ, ba BBC Yoruba sọrọ nipa ohun to gbe de idi isẹ yii.
Inu isẹ asọ oke tita ni wọn bi Adejoke si amọ o ni oun korira idọti ni oun se ronu nnkan ta le fi aloku ọra ati asọ se.
Bakan naa lo ni ọpọ anfaani lo wa ninu awọn eroja ti oun n se jade nitori o maa n ni alopẹ, ti kii si tete bajẹ nitori eroja ọra funra rẹ kii jẹ mọlẹ.
Adejoke fikun pe, amulo aloku ọra yii lati fi se ohunmere-mere n pese isẹ oojọ, yoo si tun n mu ki ọrọ aje Naijiria ru gọgọ si tawọn eeyan ba le tẹwọgba.
Àwọn ìtàn mánigbàgbé tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí:
O tẹsiwaju pe ti aaye ba si silẹ lati maa ko eroja ti wọn fi aloku ọra se lọ soke okun fun tita, pasipaarọ owo Naira wa si owo ilẹ okeere yoo tun lowura si.
Yinka Odumakin: Wo àwọn ohun tó yẹ kí o mọ̀ nípa agbẹnusọ Afenifere tó dolóògbé
Oríṣun àwòrán, dapo Abiodun
Aarọ ọjọ kẹta, oṣu Kẹrin, ọdun 2021 ni iroyin gbode pe ọkan ninu awọn asaaju ẹgbẹ ọmọ bibi ilẹ Yoruba, Oloye Yinka Odumakin ti dagbere faye.
Odumakin, nigba aye rẹ ni agbẹnusọ fun ẹgbẹ Afenifere, to n sọrọ lorukọ ẹya Yoruba lori awọn isẹlẹ to n waye nilẹ wa.
Lati igba ti iroyin naa ti jade ni ọpọ awọn eekan ilu atawọn oloṣelu ti bẹrẹ si n fi ọrọ ẹdun lede lori iku akọni ọhun.
Awọn ohun to yẹ ki o mọ nipa Yinka Odumakin ree.
Ki lo ti ṣẹlẹ sẹyin?
Oríṣun àwòrán, Joe Odumakin
Yoruba ni bi ọdẹ ba ku, ọdẹ ni yoo se oro lẹyin ọdẹ, ba si ku la dere, eeyan ko sunwọn laaye.
Ọpọ ọmọ ilẹ kaarọ oojire lo ti n sedaro iku agba ọmọ Yoruba to jade laye, Oloye Yinka Odumakin.
Ile iwosan ẹkọsẹ isegun fasiti ipinlẹ Eko, LASUTH ni Odumakin dakẹ si lasiko aisan ranpẹ to se e.
Gẹgẹ ba se gbọ, ẹka ile iwosan naa, ti wọn ti n tọju awọn eeyan to ni arun Coronavirus ni Odumakin mi kanlẹ si ni idaji ọjọ Abamẹta.
Oríṣun àwòrán, Joe Odumakin
Nigba to n fi idi iku ọrọ rẹ mulẹ fawọn akọroyin, aya oloogbe naa, Ọmọwe Joe Odumakin ni manigbagbe ni iku oloogbe naa jẹ fun oun.
Ọkan lara ẹya ara mi lo lọ yii.
Nigba tawọn naa n se idaro ẹni rere to lọ, Ọjọgbọn Banji Akitoye sọ fun BBC Yoruba pe akikanju ọmọ Yoruba lo papoda yii, igi nla lo da nigbo.
"Lero ti akọwe fun ẹgbẹ agbaagba ilẹ Yoruba, YCE, Dokita Kunle Olajide ni ""Iku doro, erin wo, igi da, Ajanaku sun bi oke, ẹni re lọ."""
Dokita Olajide ni alafo nla ni iku Odumakin yoo fi silẹ ninu iran Yoruba nitori ipa akikanju to ko fun ilọsiwaju iran rẹ lasiko to wa loke eepẹ.
Akọwe ẹgbẹ agbaagba fun ilẹ Yoruba naa wa gbadura pe ki ọba oke tẹ Odumakin si afẹfẹ rere.
Pure Water Lylon Art: Adejoke ní ohun èlò ta fi ọ̀rá ṣe ń ní àlòpẹ́, kìí tètè jẹ
Bakan naa niakọwe ẹgbẹ Afenifere, Basorun Sehinde Arogbofa se apejuwe iku Odumakin bii adanu nla fun ẹgbẹ naa ati orilẹede Naijiria lapapọ.
Arogbọfa ni iku Odumakin ba oun lojiji, to si jẹ ẹsẹ nla to ba oun lairotẹlẹ nitori ẹni to sun mọ oun bii isan ọrun ni.
"Yinka ko ba ma lọ lasiko yii nitori ọlọpọlọ pipe ẹda ni, to si maa n mu awọn aba to kun fun ọgbọn wa, isẹlẹ yii ba mi ninu jẹ pupọ.
Arogbofa wa gbadura pe ki Ọlọrun tẹ oloogbe Yinka Odumakin si afẹfẹ rere.
Iroyin to n tẹ wa lọwọ ni yajoyajo ti ni ọkan ninu awọn asaaju ẹgbẹ ọmọ bibi ilẹ Yoruba, Oloye Yinka Odumakin ti dagbere faye.
Odumakin, nigba aye rẹ ni agbẹnusọ fun ẹgbẹ Afenifere, to n sọrọ lorukọ ẹya Yoruba lori awọn isẹlẹ to n waye nilẹ wa.
Nigba to n fi idi iku oloogbe naa mulẹ fun BBc Yoruba, Ọjọgbọn Banji Akintoye, tii se ọkan lara agbaagba ilẹ Yoruba sọ pe igi nla lo da nigbo Naijiria.
Yinka Odumakin si ni ọkọ gbajumọ ajafẹtọ ẹni lobinrin, Comrade Joe Odumakin.Iku doro, iku sika, iku ti mu ẹni re lọ.
A o maa mu ẹkunrẹrẹ iroyin nipa itan igbe aye ati iku oloogbe Yinka Odumakin wa fun yin laipẹ.
Toyin Abraham: Ìyálàyá gbogbo yin, mo mọ àwọn olólùfẹ́ mi tí wọn ń gba tèmi
Oríṣun àwòrán, toyin_abraham/Instagram
Yoruba ni arẹmaja kan ko si, ajamarẹ ni ko sunwọn nitori ahọn ati ẹnu maa n ja.
Bẹẹ ni ọrọ ri pẹlu gbajumọ osere tiata lobinrin kan, Toyin Abraham ati ololufẹ rẹ kan, ti wọn n tahun si ara wọn.
Bakan naa ni awọn mejeeji n sọ oko ọrọ sira wọn eyi to n ya ọpọ eeyan lẹnu pe ki lo le to eyi.
Fiimu kan ti Niyi Akinmolayan gbe jade, ninu eyi ti Toyin Abraham kopa ninu rẹ lo fa ibẹrẹ aawọ naa.
Bẹẹ ba gbagbe, o ti ti ọjọ mẹta kan, ti Toyin ti n pariwo sinima naa lori ayelujara pe yoo jade, eyi to pe akori rẹ ni 'Prophetess'.
Ni kete ti sinima naa jade, lawọn eeyan ti n tu jade lọ sile sinima lati lọ wo fiimu naa, eyi to n mu ki awọn olootu sinima naa ri taje se, to fi mọ Toyin funra rẹ.
Amọ ni kete ti sinima naa jade, ni ọkunrin kan ti wọn n pe ni Cinema Pointer,ẹni to gbajumọ nidi ka gbọn sinima wo yẹbẹyẹbẹ, ka si se agbeyẹwo bo se dara si, sọ ero rẹ nipa fiimu ọhun.
Lero ti Cinema Pointer, o ni agbeẹwo fiimu Prophetess ti oun se fihan pe Kii se fiimu ti oun le ni ki awọn eeyan lọ wo rara."
"Sinima naa ri rudurudu, to si kun fun ariwo lasan. Sinima Prophetess yii lo jẹ sinima oni wakati kan ati isẹju mẹrinlelogun to jẹ radarada."""
Oríṣun àwòrán, toyin_abraham/Instagram
Ni kete ti Toyin Abraham ka agbeyẹwo ati ariwisi Cinema Pointer ni ibinu gba oju rẹ, to si fesi pada fun onitọhun pẹlu ara gbigbona.
"Mo le fọwọ gbaya pe eeyan kan to n sisẹ lagbo tiata ni ọ, ẹni to korira mi nitori ọwọ mi n lọ soke, ti o ko si lagbara lati da mi duro.
Gbogbo sinima ti mo ba ti kopa tabi gbe jade lo maa n bu ẹnu atẹ lu. Boya o ro pe emi lo gbe sinima Prophetess jade, amọ emi kọ lo ni, mo kan kopa ninu rẹ ni."
Toyin tẹsiwaju pe oun ni awọn ololufẹ toun ati agbo awọn to n ra ọja oun, oun si maa n fun wọn ni ohun ti wọn n fẹ.
Se o mọ pe kii se wasa pe ki eeyan pa owo to to miliọnu lọna aadoje naira lasiko iwọde ENDSars ati igbele Coronavirus, ki n si tun ẹni osere tiata akọkọ fun aimọye ọsẹ loju mohunmaworan Neflix?
Oríṣun àwòrán, cinemapointer/Instagram
Toyin wa la Cinima Pointer loye pe ọrọ to da lori ohun to n sẹlẹ lorilẹede Naijiria ni sinima Prophetess da le lori, to si wa fawọn ọmọ Naijiria, eyi ti ọmọ Naijiria se jade, ti inu rẹ ko si dun si.
"Cinema Pointer abi ẹnikẹni to wu ko jẹ tabi iru ẹni yoowu to ran ọ, mo fi ẹ silẹ ki ẹri ọkan rẹ maa jẹ ọ. N ko si ni fun s ni riba, gẹgẹ bi awọn eeyan yoku se n fun ọ, nitori naa, maa sọ isọkusọ to ba wu ọ sita, ki Ọlọrun se idajọ rẹ.
To ba wa jẹ pe lootọ lo fẹ ki n gba ariwisi rẹ gbọ, fi oju rẹ sita, jẹ ki n mọ ọ, ka jọ roju ara wa."
Ọrọ naa ko tii balẹ ti Cinema Pointer naa fi fesi pada fun Toyin pe ko mase se giragira nitori pe o pa aadoje miliọny naira lasiko igbele Coronavirus.
Oríṣun àwòrán, cinemapointer/Instagram
O ni sebi eeyan ni akẹẹgbẹ rẹ, Funke Akindele to pa ọtalelẹgbẹta (650m) lasiko naa, ti ko si pariwo, eelo wa ni aadoje miliọnu naira ti Toyin n sakọ si.
Ọpọ eeyan lo ti n fesi lori aawọ to n waye laarin awọn mejeeji naa, ti wọn si ni o yẹ ki Toyin le ni ara lati gba ariwisi si lati ọdọ awọn ololufẹ rẹ, nigba ti awọn miran sọ pe agbeyẹwo Cinema Pointer lori sinima Prophetess fi si apakan, ti ko si jẹ ojulowo.
Amọ nigba ti Toyin Abraham yoo fesi pada fun wọ, iyalaya gbogbo yin lo fi fesi pada.
Don Jazzy wife: Ìgbéyàwó mi túká nítorí iṣẹ́ orin ni mò ń fi gbogbo àkókò mi fún
Oríṣun àwòrán, donjazzy
Gbajugbaja olorin ọmọ Naijiiria, Don Jazzy ti ṣalaye pe bo ṣe ṣegbeyawo ni nnkan bii ọdun mejidinlogunsẹyin ṣugbọn ti igbeyawo naa tuka.
Don Jazzy lo sọ ọrọ naa loju opo Instagram rẹ, nibi to ti sọ pe ọmọ ogun ọdun pere ni oun lasiko naa ki oun ati iyawo oun ọhun to pinya nigba ti oun wa ni ọmọ ọdun mejilelogun.
Nigba to n sọrọ lori bo ṣe ṣẹlẹ, oludari ileeṣẹ Marvin Records naa ṣalaye pe ifẹ ti oun ni si iṣẹ orin lo da ifẹ oun ati iyawo oun, Michelle Jackson, to n fi ilẹ Gẹẹsi ṣebugbe ru.
Oríṣun àwòrán, donjazzy
"O ni ""fun ọpọ igba lawọn eeyan ti maa n bere lọwọ mi pe igba wo gan ni mo fẹ gbe iyawo, ṣugbọn ootọ ibẹ ni pe mo ṣe igbayawo ni nkan bii ọdun mejidinlogun ṣeyin nigba ti mi mo wa lọmọ ogun ọdun pere."""
Mo gbe ọrẹ mi atata, Michelle niyawo, o si larinrin, ṣugbọn mo fi ayọ fọ nitori iṣẹ orin ni mo n fi gbogbo akoko mi gbọ.
Don Jazzy ni ituka igbeyawo ọhun dun oun pupọ, ati pe oun ṣi ni ifẹ si orin kikọ, nitori naa oun ko ṣetan lati ṣe igbeyawo miran eyii ti yoo tun tuka nitori bi oun ṣe n fi gbogbo akoko oun gbọ ti iṣẹ orin.
O ni bo tilẹ jẹ pe oun ko fẹran lati maa ṣorọ nipa ọrọ ifẹ oun ni gbangba, ṣugbọn oun sọrọ naa jade lẹyin ti oun wo ifọrọwerọ kan, Bounce, ti Ebuka wa ninu rẹ.
Ọpọ awọn ololufẹ Don Jazzy lo ti n fi erongba wọn lede lori aṣo to ṣi loju eegun yii.
Muhammadu Buhari: Ọ̀pọ̀ ọmọ Naijiria ló ń jìyà nítorí ìwà àjẹbánu tó wà ní ẹ̀ka ètò ìlera - SERAP
Oríṣun àwòrán, @TheresaTekenah
Ajọ to n ja fun ẹtọ ọmọniyan nidi ọrọ aje ati ijiyin isẹ iriju ẹni, SERAP, ti pe Aarẹ Muhhamadu Buhari lẹjọ lori ikuna rẹ lati ṣe iwadii owo to le ni biliọnu mẹta abọ naira ti wọn la kalẹ fun ẹka eto ilera to poora.
SERAP ni owo naa ti iye rẹ jẹ ₦3,836,685,213.13 ni wọn la kalẹ fun ileeṣẹ to n ri si eto ilera, awọn ile iwosan ijọba, awọn ile ẹkọ ẹkọṣẹ iṣegun ati ajọ to n mojuto lilo ati akoso ounjẹ ati oogun ni Naijiria, NAFDAC.
Ninu atẹjade kan ti ajọ naa fi lede, eyii ti igbakeji adari rẹ, Kolawole Oluwadare buwọlu, o ni awọn n pe Aarẹ lẹjọ lẹyin ti abajade iwadii ti ọọfisi akapo agba Naijiri ṣe fi han pe owo naa ti poora.
Ipẹjọ yii lo n waye lẹyin ti ẹgbẹ awọn dokita ni Naijiria gunle iyanṣelodi lori owo oṣu ti ijọba jẹ wọn, awọn ajẹmọnu to yẹ ki wọn gba lasiko ajakalẹ arun Covid-19, atawọn ajẹmọnu miran.
SERAP n fẹ ki ile ẹjọ kan an nipa fun Aarẹ Buhari lati ṣe iwadii bi owo naa ṣe rin.
Oríṣun àwòrán, @festusdada1
Bakan naa ni SERAP tun n fẹ ki ijọba apapọ ṣe ọfintoto iwa ajẹbanu ti wọn sọ pe o n waye lawọn ile iwosan ijọba, awọn ile ẹkọ ẹkọṣẹ iṣegun ati ni ajọ NAFDAC.
Mobile Wash: iṣẹ́ fífọ́ mọ́tò tà ni mó yàn láààyò- Slay Mama
Ajọ naa sọ pe awọn ọmọ Naijiria ti ko rọwọ họri n jiya nitori iwa ajẹbanu to sodo si ẹka eto ilera.
Wọn ko tii sọ ọjọ ti igbẹjọ naa yoo bẹrẹ.
Bi ẹ ko ba gbagbe, Aarẹ Muhammadu Buhari wa niluu London nibi to ti lọ gba itọju.
Ọpọ ọmọ Naijiria lo si ti n fi erongba wọn lede lori ipinnu Aarẹ lati lọ ṣayẹwo ara rẹ niluu London lasiko ti awọn dokita gunle iyanṣelodi ni Naijiria.
Pure Water Lylon Art: Adejoke ní ohun èlò ta fi ọ̀rá ṣe ń ní àlòpẹ́, kìí tètè jẹ
Olusegun Obasanjo àti Sheikh Gumi ṣe ìpaàdé lórí ètò àbò Naijiria tó mẹ́hẹ l'Abeokuta
Oríṣun àwòrán, OOPL
Aarẹ Naijiria tẹlẹ, Olusegun Obasanjo ati gbajugbaja ẹlẹsin Musulumi Sheikh Ahmad Gumi ti ke si ijọba apapọ lati ṣe agbekalẹ ile ẹjọ pataki ti yoo maa gbọ ẹjọ awọn janduku, awọn ajinigbe atawọn to n lo ibọn lai gba aṣẹ.
Wọn tun sọ pe ki ijọba ṣe atunsẹ igbeaye awọn ọdaran ti wọn ba  ronupiwada, ki wọn si fun wọn ni ẹkọ ati iṣẹ ti wọn yoo maa ṣe dipo iwa ọdaran.
Obasanjo ati Gumi lo fi ọrọ naa lede ninu atẹjade ti awọn mejeji buwọlu lẹyin ipade ti wọn ṣe nile Obasanjo to wa niluu Abeokuta.
Ninu atẹjade naa to ni koko mọkanlelogun ni wọn tun ti rọ ijọba apapọ lati fi ọrọ eto abo Naijiria to mẹhẹ to ajọ ilẹ Afrika leti iyẹn, ECOWAS.
Obasanjo ki Gumi fun akitiyan rẹ lori eto abo loye ọya, bẹẹ naa ni Gumi gbe oṣuba kara fun Aarẹ tẹlẹri ọhun fun awọn ipa to ti sa sẹyin ki Naijiria le dara.
Oríṣun àwòrán, oopl
Bakan naa ni wọn tun gba ijọba ni imọran lati maa dabo bo awọn amí to ba n fi ọrọ awọn ajanduku naa to ijọba leti, ko si tun maa ṣe iwuri fun wọn.
"Lara awọn koko naa ni ""ki ijọba maa fi iya to tọ jẹ awọn ọdaju ọdaran, ko ma si fi oju aanu wo gbogbo awọn to n gbe ibọn kiri lai gba aṣẹ to yẹ."""
Àṣírí ìdí tí ìjínigbé fi ń ṣẹlẹ̀ ní Nàìjíríà ló tú nínú fídíò yìí
Ki ijọba tun ṣe agbekalẹ awọn ile ẹjọ pataki ti yoo maa gbọ ẹjọ awọn janduku, ajinigbe, awọn to n gba owo itusilẹ lọwọ ẹbi awọn ti wọn ji gbe, atawọn to n gbe ibọn kiri lọna aitọ.
Oríṣun àwòrán, oopl
Atẹjade naa pari pẹlu imọran pe ojuṣe gbogbo ọmọ Naijiria ni eto abo jẹ.
Lẹyin naa lo ni awọn memeji ti fẹnuko lati wa ọna abayọ si eto abo Naijiria to mẹhẹ, ati pe Sheik Gumi ti fi iwe pe Obasanjo lati bẹ ilu Kaduna wo lati tẹsiwaju ninu ijiroro wọn.
Pure Water Lylon Art: Adejoke ní ohun èlò ta fi ọ̀rá ṣe ń ní àlòpẹ́, kìí tètè jẹ
Owerri prison break: Àwọn agbébọn kan ti dáná sun ọgbà ẹ̀wọ̀n ní Imo, èèyàn kan dèrò ọ̀run
Ileeṣẹ ọlọpaa ti sọ pe awọn ọmọ ẹgbẹ to n ja fun idasilẹ orilẹ-ede Biafra (IPOB), ati ikọ alaabo ni ẹkun Ila oorun, ESN, lo ṣe ikọlu si ọgba ẹwọn nilu Owerri lọjọ Aje.
Ọga Agba ọlọpaa, Mohammed Adamu sọ pe awọn ọmọ ẹgbẹ IPOB ati ESN to ṣe ikọlu naa pọ , to si jẹ pe awsn nkan ijagun igbalode ati abugbamu ni wọn ko lọ si ibi iṣẹlẹ naa.
"Ninu atẹjade kan ti agbẹnusọ ileeṣẹ ọlọpaa, Frank Mba fi sita ni Mohammed ti sọ pe ""igbiyanju awọn agbebọn naa lati wọ ibi ti awọn ọlọpaa n ko awọn nkan ijagun si ni olu ileeṣẹ ọlọpaa lo ja si ofo, nitpri pe awọn ọlọpaa to wa lẹnu iṣẹ ko gba fun wọn""."
O ni digbi ni ibudo naa wa, ti ko si si ọlọpaa kankan to ku sinu iṣẹlẹ naa yatọ si kọnstebu ọlọpaa kan ti ọta ibọn ba ni ejika.
Amọ ninu iroyin mii, adele Ọga Agba ni ajọ to n mojuto ọgba ẹwọn ni Naijiria, ẹka ti ipinlẹ Imo, John Mrabure sọ pe ẹlẹwọn 1,844, ni awọn agbebọn naa tu silẹ.
"Agbẹnusọ ajọ ọgba ẹwọn to jẹ ti ijọba apapọ, Francis Enobere, to fi atẹjade naa sita sọ pe ""ni nkan bi aago meji oru ọjọ Aje, ọjọ karun-un, oṣu Kẹrin, ọdun 2021, ni awọn agbebọn naa wọ inu ọgba naa, ti wọn si fi nkan abugbamu fs awọn ọfiisi to wa nibẹ."
Iroyin to n tẹ wa lọwọ bayii sọ pe eeyan kan ti dero ọrun lẹyin ti awọn agbebọn kọlu ọgba ẹwọn kan niluu Oweri, nipinlẹ Imo.
Gẹgẹ bii ohun ti a gbọ, iṣẹlẹ naa waye lorumọju, ko si ṣeni to tii le sọ boya ẹlẹwọn kankan ti salọ.
Awọn fidio kan to wa loju opo ikansiraẹni lori ayelujara ṣafihan bi iro ibọn ṣe n dun kẹukẹu.
A ko tii le sọ ni pato awọn to wa nidii akọlu naa, gbogbo akitiyan wa lati kan si ileeṣẹ ọlọpaa ipinlẹ ọhun lo ja si pabo.
Ẹwẹ, akọroyin BBC to wa ni ilu naa lọwọ yii jabọ pe wọn ti yibọn pa ẹlẹwọn kan lasiko to n gbiyanju lati salọ.
A ṣi n ṣe akojọpọ iroyin yii lọwọ, a oo maa fi to yin leti bo ba ṣe n lọ.
Antonio Oladeinde Fernandez: Ìtàn ìgbé ayé ọmọ Naijiria to ni ọkọ̀ òfúrufú mẹ́fà àti owó ní báǹkì láwọn orílẹ̀-ède méje
Oríṣun àwòrán, @solotufe
Oloye Antonio Oladeinde Fernandez jẹ ọkan pataki ninu awọn baba olowo orilẹ-ede Naijiria ati ọkan lara awọn eyan to lowo julọ nilẹ adulawọ nigbaa aye rẹ.
O ni owo to bẹẹ gẹ, to fi ni ọkọ ofurufu mẹfa funra rẹ, o ra ile awodamiẹnu kan lorilẹ-ede France ti Napoleon Bonaparte ti gbe ri, koda, to ba fẹ jẹun nile ounjẹ, niṣe ni wọn maa n ni ki gbogbo awọn to ba wa nibẹ jade fun un.
Torí àti ṣe Kòkò irin, bí mo ṣe máa ǹ fara yá iná nìyìí - Amokoko Saki
Ibẹrẹ pẹpẹ rẹ ati bo ṣe di olowo
Wọn bi Fernandez bi ọjọ kejila, oṣu Kẹjọ, ọdun 1929 niluu Eko sinu idile tọkọ-taya Julia Fernandex ati Canut Fernandez.
Orukọ Fernandenz wa lati iran awọn ẹru ti wọn gba ominira lọwọ orilẹ-ede Brazil, Portuguese si ni ede wọn.
Gẹgẹ bi itan aye rẹ ṣe lọ, awọn obi rẹ ko lowo lọwọ, bo tilẹ jẹ pe wọn ko ṣagbe jẹun, eyii lo mu ko gbiyanju lati ni owo lọwọ.
O kawe lawọn ile ẹkọ kan niluu Eko bii CMS Grammar School, Saint Gregory ati Holy Cross.
Oríṣun àwòrán, @DeleMomodu
Nigba to wa ni ọmọ ọdun mejidinlogun lo gba ilu Amẹrika lọ, ilẹ naa san an lẹyin to bẹrẹ iṣẹ epo rọbi, larin ọdun meji pere lo di olowo gọbọi.
Iroyin ni Fernadez bẹrẹ si n pa biliọnu lẹyin to ra ida aadọta ileeṣẹ Petor Inett to n wa epo ni eti okun orilẹ-ede Angola.
Bo tilẹ jẹ pe kii ṣaba bẹ Naijiria wo, Fernandez ni awọn ile niluu Kano, awọn ile alaja pupọ niluu Eko, atawọn ile miran lawọn orilẹ-ede bii Scotland, France, Belgium ati ilẹ Gẹẹsi.
Bẹẹ lo tun ni obitibiti owo nile ifowopamọ lawọn ilu bii Cayman Islands, France, Switzerland, Irealand, Hong Kong, Scotland ati ile Amẹrika.
'Bí ojú ọ̀nà agbàrá òjò tí ijọba ṣe n'IIorin ṣe ń pa àwọn ọmọ iléèwé wa rèé! Ẹ sàánú wa'
Fernandez ati oṣelu
Nigaba to di ọdun 1982 ni Fernandez darapọ mọ oṣelu, o si ṣiṣẹ pẹlu ijọba orilẹ-ede Angola gẹgẹ bii olubadamọrann pataki fun ijọba ilẹ naa.
Ni ọdun 1984, wọn yan an gẹgẹ bii aṣoju ajọ iṣokan agbaye, UN, lati orilẹ-ede Mozambique.
Ọdun 1992 ni wọn yan an gẹgẹ bii olubadamọran pataki si Aarẹ Mozabique, o si di ipo naa mu fun ọdun meji gbako ko to tun ti di aṣoju ijọba Dahomey Republic lọdun naa lọhun.
Oríṣun àwòrán, @DeleMomodu
Idile rẹ
Orukọ iyawo akọfẹ rẹ ni Barbara to jẹ ọmọ bibi ilẹ Amẹrika, wọn si jọ gbe papọ gẹgẹ bii tọkọtaya fun ọdun marunlelogun.
Lẹyin naa lo gbe ọmọ ọba Abiola Dosumu, ti ilu Eko niyawo, ṣugbọn igbeyawo naa tuka, o si kan an nipa fun obinrin naa lati dẹkun ati maa lo orikọ idile oun lawujọ.
Iyawo rẹ kẹta ni Duke Fernandez ṣugbọn aarin wọn daru lọdun 2003.
Lẹyin ti igbeyawo ọhun fori sọgi ni ile ẹjọ kan an nipa fun Fernandez lati maa san ẹgbẹrun marundinlọgọrin pọun fun obinrin ọhun loṣoṣu.
Iyawo to fẹ kẹyin ni ọmọ Ọba Halima Maude lati ipinlẹ Kano, oun ni wọn si jọ wa gẹgẹ bii tọkọ-taya titi di akoko to papoda.
Ẹsin abalaye
Gẹgẹ bii awọn onkọtan nipa igbeaye rẹ sẹ sọ, ẹsin ibilẹ ni Oloye Antonio Deinde Fernandez ṣe ko to fi aye silẹ, koda agba ọjẹ ni ninu ẹgbẹ Ogboni.
"Awọn eeyan kan ri gẹgẹ bii ẹni iyi nilẹ Yoruba, gbolohun ọrọ ti wọn si mọọ si ni ""agutan meji kii mu omi ninu koto kan naa."""
Oríṣun àwòrán, inlandtown
Ẹkọ
Lara awọn ẹkọ ti awọn ọdọ aye ode oni le ri kọ ninu igbeaye Fernandez ni pe ko ni ṣe iru ipo ti eeyan ba wa nile aye, o si le yi kadara rẹ pada si rere.
Bakan naa ni igbe aye rẹ ṣafihan pe ẹnikẹni to ba mura siṣẹ rẹ le la bopẹ boya.
Fernandez ni owo to bẹẹ to fi ọpọ dukia silẹ fun awọn ọmọ to fi silẹ saye lọ.
Ọjọ kinni, oṣu Kẹsan an, ọdun 2015 ni Fernandez dagbere faye niluu Brussels, lorilẹ-ede Belgium.
Muhammadu Buhari London travel: Ìdí tí àwọn ọmọ Naijiria ṣe fẹ̀hónúhàn lòdì sí ìrìnàjò Buhari sí London
Oríṣun àwòrán, @Adamsyyoladauda
Awọn alatilẹyin aarẹ Buhari naa ti farahan lati jẹ karaye mọ pe aarẹ Buhari kii ṣe eeyan buruku.
Lẹ́yìn tí àwọn ọmọ Nàìjíríà kan ṣe ìfẹ̀hónúhàn níwájú Abuja House, ibi tí Ààrẹ Buhari dé sí ní ìlú London, tí wọ́n sì sọ pé kó padà sílé, ni àwọn ọmọ Nàìjíríà míì náà  wá ṣe ìwọ́de pé àwọn wà lẹ́yìn Ààrẹ náà.
Aarẹ Buhari lo tẹkọ ofurufu leti lọjọ diẹ sẹyin lati lọ fun isinmi ti yoo fi tọju ara rẹ ni London.
Asọtẹ́lẹ̀ ikú Yinka Odumakin ti jáde sí wa tẹ́lẹ̀, ẹbí gbàdúrà, àmọ́...- Jacob Odumakin
Ojú wa rí, a ṣe IVF, oyún ìbeji bàjẹ́ kí á tó di ọlọ́mọ láyé - Adesua àti Banky W
Ọlọ́pàá fọhùn pé ẹgbẹ́ IPOB ni àwọn agbébọn tú ẹlẹ́wọ̀n 1,844 sílẹ̀ ní ọgbà ẹ̀wọ̀n Owerri
Amọ eyi waye ni kete ti awọn dokita lorilẹede Naijiria gun le iyanṣẹlodi nitori aisa owo oṣu wọn deede.
Bi iṣẹlẹ meji yii ṣe ṣe kongẹ ara wọn lo mu awọn ọmọ Naijria faraya ti wọn si n ṣe iwọde tako irinajo aarẹ si ilu London.
Amọ, amugbalẹgbẹ Aarẹ tẹlẹri Goodluck Jonathan, iyẹn Reno Omokri n gbe ọ̀rọ̀ sita pe Ọmọwe Philip[Idaewo to dari iwọde adura fun aarẹ Buhari kii ṣe ajoji ati pe bi oluranlọwọ aarẹ Buhari ṣe juwe rẹ gẹgẹ bi olufọkansin ọmọ Naijiria ko tọ.
O fi si oju opo Twitter rẹ pe Philip Idaewor yii naa ni alaga ẹgbẹ oṣelu  APC niluu London torinaa ẹyin aarẹ Buhari lo wa tẹlẹ.
Oríṣun àwòrán, Reno Omokri
Awọn ọmọ Naijiria kan to n fi ilu London ṣebugbe ti bẹrẹ ifẹhonuhan lodi si bi Aarẹ Muhamadu Buhari ṣe lọ si ilu naa fun ayẹwo.
Ifẹhonuhan ọhun ti wọn kọ lati dẹwọ rẹ ni wọn fi n fa Aarẹ Buhari leti pe ko pada si Naijiria to ba fẹ ṣe ayẹwo ara rẹ.
Ọjọru to kọja yii ni amugbalẹgbẹ Aarẹ Naijiria tẹlẹ, Goodluck Jonathan, iyẹn Reno Omokri tẹkọ ofurufu leti lọ siluu London lati bẹrẹ ifẹhonuhan naa, eyii ti ko tii dẹwọ rẹ lati igba naa wa.
Ṣugbọn ki lo fa iwọde naa gan?
Iwọde ọ́hun bẹrẹ nitori iyanṣelodi awọn dokita ni Naijiria, eyii to bẹrẹ lọjọ kinni, oṣu Kẹrin, ọdun yii.
Awọn dokita ni Naijiria daṣẹ silẹ lọna ati bere awọn ẹtọ kan lọwọ ijọba apapọ bii owo oṣu to jẹ wọn atawọn ajẹmọnu kan to yẹ ki wọn gba lasiko ajakalẹ arun Covid-19.
Oríṣun àwòrán, Reno Omokri
Lati le fi aidunu wọn han si Aarẹ lori bo ṣe lọ gba itọju ni London lasiko ti awọn dokita wa ni iyanṣelodi ni Naijiria, Omokri ko awọn eeyan kan sọdi lati ṣe iwọde niwaju ile ijọba Naijiria ti Aarẹ Buhari wa ni London.
Jimoh Ológì déé! Ọ̀mọ̀wé ní kílàsì fásitì, ológì nílé
"Ninu atẹjade kan to fi lede loju opo Twitter rẹ, Omokri ni ""ti awọn dokita nilẹ Gẹẹṣi ba n gunle iyanṣelodi, sẹ Aarẹ Bahari yoo to ẹni to n lọ sibẹ fun ayẹwo?"""
Oríṣun àwòrán, Twitter/ Reno Omokri
Nigba ti ikọ BBC ṣabẹwo sile ijọba Naijiria ni London, ọkan lara awọn olufẹhonuhan naa ni ko dun mọ oun ninu bi Aarẹ Buhari ati ẹbi rẹ kii ṣe gba itọju ni Naijiria.
O ni Buhari kọ lati kọ ile iwosan to yanranti si Naijiria lati igba to ti gori oye lọdun 2015, ṣugbọn o nifẹ si ati maa lọ gba itọju ni London, eyii ti ko yẹ ko ri bẹẹ.
Ẹlomiran ni iye owo ti Buhari yoo na fun itọju ara rẹ ni London to wa kii ṣe owo kekere, ati pe kii ṣe iru owo to yẹ ki ijọba Naijiria maa na lasiko yii niyẹn.
Iye igba ti Buhari ti lọ silẹ Gẹẹsi fun itọju
Buhari lọ siluu London laarin ọjọ kẹfa si ọjọ kọkandinlogun ọdun 2016 lati gba itọju.
O tun ṣayẹwo siluu London larin ọjọ keje si ọjọ kẹtala, oṣu Kẹjọ, ọdun 2017 fun ayẹwo, iyẹn lasiko ti wọn sọ pe eku gba ile ijọba apapọ, Aso Rock, to wa niluu Abuja.
Àṣírí ìdí tí ìjínigbé fi ń ṣẹlẹ̀ ní Nàìjíríà ló tú nínú fídíò yìí
Lọdun 2018, Buhari lo ọjọ mẹwaa ni London laarin ọjọ kẹjọ si ọjọ kejidinlogun lati ri awọn dokita.
Lẹyin na lo tun bẹ ilẹ Gẹẹṣi wo larin ọjọ keji si ọjọ kẹtadinlogun, ọdun 2019, ṣugbọn a ko le sọ boya ayẹwo lo lọ fun lasiko naa.
Oríṣun àwòrán, Reno Omokri/Twitter
Ẹwẹ, ijọba Naijiria ko tii ṣo ohun kankan lori ifẹhonuhan naa lati igba to ti bẹrẹ.
Mobile Wash: iṣẹ́ fífọ́ mọ́tò tà ni mó yàn láààyò- Slay Mama
Usman Alkali Baba biography: Nígbà tí Adamu ń ṣiṣẹ́ lọ́wọ́ ní Owerri, Ààrẹ Buhari yan Alkali ní adélé Ọ̀gá Ọlọ́pàá tuntun
Oríṣun àwòrán, The cable ng
Iroyin to n tẹ wa lọwọ ni wipe aar Muhammadu Buhari ti yan igbakeji ọga ọlọpaa Usman Alkali Baba gẹgẹ bi adele ọga ọlọpaa tuntun.
Eyi n waye gẹgẹ bi Muhammed Adamu to jẹ ọga awọn ọlọpaa ni Naijiria n mojuto iṣẹlẹ ikọlu to waye ni ọgba ẹwọn ipinlẹ Owerri.
Minisita foro olọpaa, Maigari Dingyadi lo kede igbesẹ tuntun ti aarẹ ṣẹṣẹ gbe naa.
Ọdun 1963 ni wọn bi Alkali Baba Usman ni ipinlẹ Yobe.
O kawe gboye ni Fasiti Bayero to wa nilu Kano, ati Fasiti ilu Maiduguri.
Ọdun 1988 lo darapọ mọ ileeṣẹ ọlọpaa ti o si goke lati oye ASP di kọmiṣọna ọlọpaa mi ọjọ kẹtadinlọgbọn ọdun 2013.
Ṣaaju iyansipo rẹ gẹgẹ bi Adele Ọga Agba ọlọpaa, oun ni oludari ẹka ileeṣẹ ọlọpaa ọtẹlẹmuyẹ ati iwadii iwa ọdaran..
'Bí ojú ọ̀nà agbàrá òjò tí ijọba ṣe n'IIorin ṣe ń pa àwọn ọmọ iléèwé wa rèé! Ẹ sàánú wa'
Gbogbo awọn eto ẹkọṣẹ gbogbo ro yẹ fun oye kọọkan to gba lo ṣe lori awọn isẹ iwadii, igbesumọmi ati kikoju iwa ọdaran gbogbo to fi mọ amojuto lilọ bibọ ọkọ.
O jẹ ọkan lara awọn ọmọ ẹgbẹ ajọ ọlọpaa lagbayebeeni o tun jẹ ọkan lara awọn akẹkọọ jade nileekọṣẹ omo-ogun lagbaye International War College.
O figba kan ri jẹ igbakeji kọmiṣọna ọlọpaa ni ipinlẹ Kaduna ati Abuja.
Alkali Usman yoo maa gbaṣẹ lẹyẹ-o-ṣọka lọwọ ọga agba olopaa, Mohammed Adamu to n fi ipo naa silẹ bayii.
Ni osu keji ọdun 2021 lo ti yẹ ki Mohammed Adamu o fi ipo naa silẹ, ṣugbọn Aarẹ Buhari fi kun iye ọjọ rẹ lori oye nigba naa
A o maa mu ẹkunrẹrẹ iroyin naa wa fun yin bo ba ṣe nlọ.
Adesua Etomi àti Banky W ṣàlàyé ohun tí ojú wọ́n rí kí wọ́n tó bímọ
Oríṣun àwòrán, Instagram/adesuaetomi
Gbajugbaja oṣere, Adesua Etomi ati ọkọ rẹ to jẹ olorin, Banky jẹri ni ṣọọṣi pe oju awọn ri ki awọn to di ọlọmọ laye.
Wọn ni awọn ṣe eto ati bimọ ti wọn n pe ni IVF, koda wọn ni Adesua loyun ibeji ṣugbọn oyun naa bajẹ mọ ọn lara.
Adesua ṣalaye pe oun loyun ibeji lẹyin tawọn ṣe IVF tan, awọn ọmọ naa si n dagba, koda wọn maa n ru ninu oun.
Ṣugbọn ''lọjọ kan ti a lọ fun ayẹwo nile iwosan ni dokita sọ fun mi pe awọn ọmọ naa ko mi mọ ninu mi.
Dokita sọ fun wa pe a gbọdọ ko oyun to ti bajẹ ọhun kuro ninu mi lai fi akoko ṣofo.
Emi ati Banky pinnu lati gbadura pe ki awọn mọ le maa mi pada ṣugbọn ọwọ ti bọ si ori,'' Adesua lo sọ bẹẹ.
Banky W ni asiko naa lagbara pupọ foun ati iyawo ouj nitori ibanujẹ nla ni iṣẹlẹ naa jẹ fawọn mejeeji.
''Mo ranti pe mo mu Adesua lọ si oke lẹyin ti wọn ko inu rẹ tan, mo di i lọwọ mu lori aga nibi ti awa mejeeji ti sunkun.
Igbiyanju IVF nigba keji ko tiẹ ṣiṣẹ rara, awọn dokita ni ile ọmọ Adesua ko wa bo ṣe yẹ ko wa ati pe atọ Banky W naa ko ṣe daadaa mọ,'' Banky W ṣalaye.
Lẹyin naa lawọn mejeeji pinnu lati maa lo oogun kankan mọ, ti wọn si fi igbagbọ sinu Eledua lori ati bimọ laye.
Adesua ranti pe wẹrẹ ni Ọlọrun ṣe e fawọn lọdun 2020 nigba ti awọn ko tiẹ ro rara.
Oba oke pada fi ọmọkunrin lanti lanti jinki idile naa eyi ti wọn pe orukọ rẹ ni Zaiah.
Adesua ni awọn pinnu lati sọ iriri awọn nitori ọpọ obinrin lo n la iru nkan bayii kọja ti wọn ko si le sọrọ sita.
Yinka Odumakin: Ẹbi akọwe iroyin ẹgbẹ Afenifere to di oloogbe kede eto isinku rẹ
Oríṣun àwòrán, Joe Odumakin
Ẹbi akọwe iroyin ẹgbẹ Afenifere to di oloogbe, Yinka Odumakin ti kede eto isinku rẹ.
Iyawo oloogbe naa, Ọmọwe Joe Okei-Odumakin lo kede eto isinku ọkọ rẹ ninu atẹjade kan to fi sita.
Ọmọwe Okei-Odumakin ni ọjọ mẹta ni eto isinku naa yoo fi waye.
Aya oloogbe naa ṣalaye pe, Ọjọbọ ọjọ kejilelogun oṣu kẹrin ni eto orin imọyi fun oloogbe naa yoo waye ni ọgba ẹkọsẹ ọlọpaa, Police College, Ikeja, lati ago mọkanla aarọ si mẹrin irọlẹ.
Ọjọ Ẹti, ọjọ kẹtalelogun oṣu kẹrin ni wọn yóò gbe oku oloogbe naa lọ si ilu abinibi rẹ ni Moro, ni ijọba ibilẹ Ariwa Ife, ipinlẹ Ọsun.
Female Car Painter: Èmi ní obìnrin àkọ́kọ́ tí yóò máa ṣiṣẹ́ akunmọ́tò ní Ibadan
Aya oloogbe ni eto orin idagbere yoo fun oloogbe naa yoo waye ni ileewe girama ijọ Anglican ni Origbo ni ago marun un irọlẹ, pẹlu afikun pe eto titan abẹla lo kan lẹyin orin kikọ.
Ọjọ Abamẹta ọjọ kẹrinlelogun ni wọn yoo tẹ oku nitẹ ẹyẹ, ki awọn eeyan le ri i fun igba ikẹyin.
Ago mẹwaa aarọ Sátidé yii naa ni eto isin ikẹyin fun oloogbe Yinka Odumakin yóò waye, lẹyin naa ni iyoku ara rẹ yoo wọ kaa ilẹ lọ.
Oríṣun àwòrán, Twitter/Omoyele Sowore
Iku ko da ọjọ, arun ko da oṣu, bẹẹ ni ko si ẹni to ri ti ọlọjọ ṣe bi o ba ti de.
Ọpọ eeyan to fi mọ awọn eekan lagbo oṣelu lo ti n ṣe idaro ajijagbara Yinka Odumakin to dagbere faye.
Ẹni ọdun mẹrindinlọgọta ni Odumakin ki o to fi aye ẹṣẹ yii silẹ.
Amọ, ẹgbọn oloogbe naa, Pasitọ Jacob Odumakin sọ fawọn akọroyin pe iran iku Yinka Odumakin ti jade tẹlẹ.
Pasitọ naa ṣalaye pe asọtẹlẹ to jade sọ pe kawọn gbadura ki igi tutu maa wo nigba ti igi gbigbẹ si duro.
Ẹgbọn oloogbe naa ṣalaye pe Yinka Odumakin ni igi tutu duro fun nigba ti baba rẹ to ti pe ọdun marundinlọgọfa si jẹ igi gbigbẹ.
O ni ẹbi ko bẹsu bẹgba lẹyin ti asọtẹlẹ yii jade lawọn bẹrẹ si ni gbadura.
Amọ pasitọ Jacob ni ẹlẹmi pada gba a nitori ko si ẹni to ti ti ọlọjọ ṣe.
O ni ibanujẹ nla ni iku Yinka jẹ fun idile awọn papaa julọ rẹ to di darugbo.
Arun coronavirus ni a gbọ pe o pada ṣeku pa Odumakin lẹyin ti ko le mi mọ daadaa.
Ẹgbọn oloogbe ọhun tun sọ pe ẹgbẹ Afenifere ti sọ pe awọn lawọn yoo ṣe oku Odamakin to jẹ akọwe ẹgbẹ Yoruba naa.
Ẹ padà wá o ẹ̀yin ẹlẹ́wọ̀n, ẹni tó bá wá wọ́ọ́rọ́wọ́ yóò rí ìdáríjì, ẹni tí kò bá wá ... - Aregbesola
Ariwo sọọ! Àwọn agbébọn jí ọkọ, ìyàwó àtàwọn ọmọ wọn gbé l'Ondo
Tinubu ló lè ṣeé lọ́dún 2023, Pa Fasoranti àti Oba Osemawe Ondo sọ̀rọ̀ sókè
'Bí ojú ọ̀nà agbàrá òjò tí ijọba ṣe n'IIorin ṣe ń pa àwọn ọmọ iléèwé wa rèé! Ẹ sàánú wa'
Owerri jailbreak: Àwọn agbébọn tún kọlu Àgọ́ Ọlọ́pàá míì
Agọ Ọlọpaa Mbieri to wa ni agbegbe ijọba ibilẹ Mbaitoli tun ni tuntun ti a gbọ tẹlẹ pe wọn ṣe ikọlu si.
Eyi ni yoo jẹ agọ ọlọpaa ikeje ti awọn janduku kọlu ni ipinlẹ Imo laarin oṣu kini ọdun yii si oṣu kẹrin, lara rẹ si ni ikọlu si olu ileeṣẹ ọlọpaa to wa ni ipinlẹ Imo lọjọ Aje.
Gẹgẹ bi awọn ti ọrọ naa ṣoju wọn ṣe sọ ọ, awọn agbebọn ba agọ ọlọpaa naa jẹ ti wọn si tu awọn afurasi ọdaran to wa nibẹ silẹ.
Iroyin sọ pe alẹ Ọjọru ni wọn tun yabo ibẹ pẹlu awọn ohun ija nla nla lai tii to wakati mẹrinlelogun ti awọn kan ṣẹṣẹ kọlu agọ ọlọpaa ti Ehime Mbano ti wọn si jo o ni ina.
Bii ọlọpaa meji ni a gbọ pe wn ṣe leṣe ti iroyin si ni wọn ti ji eeyan kan gbe lọ.
Ọlọpaa ipinlẹ Imo lo fidi ọr naa mulẹ pe lootọ ni wọn tun kọlu agọ mii.
Ẹwẹ, agbẹnusọ ileeṣẹ ọlọpaa Imo ni awọn ribi kapaa awọn to ṣe ikọlu naa o si ni awọn afurasi kan ti wa ni ahamọ ọlọpaa.
Awọn agbebọn kan ti dana sun olu ileeṣẹ ọlọpaa to wa ni ijọba ibilẹ Ehime Mbano, nipinlẹ Imo.
Ikọlu yii waye lẹyin ọjọ kan ti awọn agbebọn kan kọlu ọgba ẹwọn to wa ni ilu Owerri, ati olu ileeṣẹ ọlọpaa to wa ni ipinlẹ Imo.
Lasiko ikọlu naa ni wọn tu ẹlẹwọn 1,884 silẹ, ti wọn si tun dana sun ọkọ to le ni aadọta ni olu ileeṣẹ ọlọpaa.
Ikọlu ti ọjọ Iṣẹgun waye lẹyin wakati diẹ ti Igbakeji Aarẹ Naijiria, Yẹmi Ọṣinbajo, Ọga Agba fun ileeṣẹ ọlọpaa ti wọn ṣẹṣẹ yọ nipo, Mohammed Adama, ati awọn olori ijọba mii ṣe abẹwo si ilu Owerri nitori ikọlu to waye lọjọ Aje.
Iroyin sọ pe gbogbo awọn afurasi ọdaran to wa ni ahamọ ni agọ ọlọpaa naa ni awọn agbebọn ọhun tu silẹ, ko to o di pe wọn dana sun un.
Ọkan lara awọn to n gbe ni agbegbe naa sọ fun BBC Pidgin pe titi di aago meje abọ alẹ ni iro ibọn n dun.
Ileeṣẹ ọgba ẹwọn ni Naijiria ti sọ pe awọn ẹlẹwọn to wa ni ọgba ẹwọn niluu Owerri ko to ẹgbẹrun meji bi ajọ Amnesty International ṣe sọ.
Ajọ Amnesty International ti sọ tẹlẹ pe ọgba ẹwọn tawọn agbebọn kọlu ni ilu Owerri eyi to mu kawọn ẹlẹwọn salọ ko yẹ ko gba ju ẹlẹwọn 548 lọ.
Ajọ naa sọ pe ẹlẹwọn 2,156 lo wa ninu ọgba ẹwọn naa nigba tawọn agbebọn kọlu ọgba ẹwọn ọhun.
Nigba ti o n ba BBC Yoruba sọrọ, agbẹnusọ fun ileeṣẹ ọgba ẹwọn ni Naijiria, Francis Osagiede Enobore ṣalaye pe kii ṣe ẹlẹwọn 2,156 lo wa ninu ọgba ẹwọn naa nigba ti iṣẹlẹ ọhun ṣẹlẹ.
Ọgbẹni  Enobore ni ẹlẹwọn 1,881 lo wa lọgba ẹwọn ki iṣẹlẹ naa to waye.
''Bo tilẹ jẹ pe awọn ẹlẹwọn to wa lọgba ẹwọn ilu Owerri ju iye awọn to yẹ ko wa nibẹ lọ, amọ ọrọ ko ri bi ajọ Amnesty Insternational ṣe sọ,'' Ọgbẹni Enobore lo sọ bẹẹ.
Ọgbẹni Enobore sọ pe ọpọ eeyan to wa lẹwọn lo yẹ ki wọn ti gba idajọ kuro lẹwọn ṣugbọn ọpọ ninu wọn ni ko lowo lati gba agbẹjọro ti yoo ṣoju wọn.
O fikun ọrọ rẹ pe kii ṣe ọgba ẹwọn ilu Owerri nikan lawọn ẹlẹwọn ti pọju lọgba ẹwọn, o ni kaakiri ilu nla nla ni Naijiria ni.
Enobore kepe awọn agbẹjọro ẹlẹyinju aanu lati ṣoju awọn ẹlẹwọn ti ko rọwọ họri lati ṣoju wọn nile ẹjọ ki awọn to wa lẹwọn le dinku.
Bakan naa lo fidi rẹ mulẹ pe iṣẹ n lọ lọwọ lori kikọ ọgba ẹwọn to tobi ti yoo gba awọn ẹlẹwọn to pọ kaakiri Naijiria.
Àwọn èdè abẹ́ ahọ́n tóo lè fi sọ̀rọ̀ rèé láì tú àṣírí ọ̀rọ̀ rẹ áyé
Resident doctors strike in Nigeria: Ẹgbẹ́ àwọn dókítà àti ìjọba tako ara wọn l'Oyo lórí ìyanṣẹ́lódì
Oríṣun àwòrán, @BBCAfrica
Ẹgbẹ awọn dokita ipinlẹ Oyo ti sọ pe ko si ootọ ninu  ọrọ kan ti ijọba ipinlẹ naa n sọ pe awọn ko daṣẹ silẹ.
Ṣaaju ni kọmiṣọna fun eto ilera ipinlẹ ọhun, Bashir Bello ti kọkọ sọ fun BBC Yoruba pe awọn dokita ipinlẹ ọhun ko gunle iyanṣẹlodi kankan .
Bello sọ pe gbogbo ohun ti awọn dokita n bere lọwọ ijọba ipinlẹ Oyo ni ijọba  naa n ṣe fun wọn, eyii to mu ki ajọṣepọ to wa laarin wọn gun rege.
O ṣalaye pe nitori naa ni awọn dokita naa ko ṣe darapọ mọ awọn akẹgbẹ wọn to n daṣẹsile ni Naijiria.
"Gẹgẹ bo ṣe sọ, ""eto ilera ṣe patakli si ijọba to wa lode yii, nitori naa ko si dokitan kankan nipinlẹ Oyo to daṣẹsilẹ, a si n tọju awọn iba perete to n ṣiṣẹ lawọn ile iwosan ijọba."""
Lasiko ajakalẹ arun Corona yii gan, obitibiti owo ni gomina ipinlẹ Oyo la kalẹ fun ile iwosan UCH, eyii to n ṣafihan awọn anfani ti awọn eeyan n jẹ lara ijọba, nitori naa ni wọn ko ṣe ni eredi kankan lati da iṣẹ silẹ.
Ṣugbọn nigba ti BBC Yoruba kan si Aarẹ ẹgbẹ awọn dokita nile iwosan ijọba apapọ to wa niluu Ibadan, UCH, dokita Zakariyau Temitope Hussein ni irọ pata ni ọrọ ti ijọba sọ nitori awọn wa ni iyanṣẹlodi.
Hussein sọ pe awọn ti yanṣelodi gẹgẹ bi awọn akẹgbẹ awọn kaakiri Naijiria, bo tilẹ jẹ pe ẹgbẹ awọn dokita miran n ṣiṣẹ lọ lọwọ.
"O ni ""awa resident doctors ti daṣẹ silẹ o, ṣugbọn awọn dokita miran ti wọn n pe ni 'consultants' ṣi wa lawọn ile iwosan."""
Àwọn èdè abẹ́ ahọ́n tóo lè fi sọ̀rọ̀ rèé láì tú àṣírí ọ̀rọ̀ rẹ áyé
"Hussein sọ siwaju sii pe ""awọn ọmọ ẹgbẹ wa ni UCH ati ile iwosan to wa ni LAUTECH ti yanṣelodi, emi o mọ ohun ti kọmiṣọna fun eto ilera n sọrọ nipa rẹ."""
Ẹgbẹ awọn dokita naa gunle iyanṣẹlodi  kaakiri Naijiria lẹyin ti wọn fẹsun kan ijọba apapọ pe o n fi awọn ẹtọ wọn dun wọn.
Bakan naa ni wọn tun n bere awọn ajẹmọnu kan to yẹ ki ijọba fun wọn lasiko ajakalẹ arun Covid-19, ṣugbọn wọn ni ijọba kọ etin ọgbọin si awọn ibere wọn.
Jimoh Ológì déé! Ọ̀mọ̀wé ní kílàsì fásitì, ológì nílé
ASUP gbé àgádágodo sẹ́nu ọ̀nà àwọn ilé ẹ̀kọ́ gbogbonìṣde ní Naijiria
Oríṣun àwòrán, @justeventsonlin
Ẹgbẹ awọn olukọ ile ẹkọ gbogboniṣe, ASUP, ti gunle iyanṣelodi ọlọjọ gbọọrọ lati bere fun atunto bi ijọba ṣe n san owo oṣu wọn.
Gẹgẹ bi ohun ti ẹgbẹ naa sọ, iyanṣelodi ọhun ti bẹrẹ lonii ọjọ Iṣegun, ọjọ kẹfa, oṣu Kẹrin, ọdun 2021.
ASUP kede iyanṣelodi naa lẹyin ipade ti wọn ṣe pẹlu awọn aṣoju ijọba apapọ niluu Abuja.
Yatọ si atunto bi ijọba ṣe maa n san owo wọn ti wọn n bere fun, ASUP tun sọ pe ki ijọba san owo to jẹ awọn olukọ lawọn ile ẹkọ gbogboniṣe lawọn ipinlẹ kan ni Naijiria.
Wọn tun fi ẹsun kan ijọba pe o kọ lati san owo oṣu mẹwaa to jẹ awọn oṣiṣẹ wọn lẹyin to buwọlu owo oṣu tuntun to kere ju fun awọn oṣiṣẹ.
Oríṣun àwòrán, @justeventsonlin
ASUP ni iyanṣelodi ọhun ṣe pataki lasiko yii, paapaa niwọn igba ti ijọba apapọ ti kọ lati mu awọn ileri to ṣe fun awọn ṣẹ.
Àwọn èdè abẹ́ ahọ́n tóo lè fi sọ̀rọ̀ rèé láì tú àṣírí ọ̀rọ̀ rẹ áyé
Arẹ apapọ ẹgbẹ naa, Anderson Ezeibe ni, bo tilẹ jẹ pe awọn yoo ṣi maa ba ijọba apapọ jiroro, ko si ohun ti yoo da iyanṣelodi ọhun duro ayafi ti ijọba ba da awọn lohun.
Bi ẹ ko ba gbagbe, ko pẹ ti ẹgbẹ awọn oṣiṣẹ fasiti, ASUU, wọgile iyanṣẹlodi ti awọn naa gunle lẹyin oṣu mẹsan an gbako.
Ẹwẹ, ẹgbẹ awọn oṣiṣẹ ile ẹjọ, JUSUN, ati ẹgbẹ awọn dokita naa ti bẹrẹ iyanṣẹlodi.
Jimoh Ológì déé! Ọ̀mọ̀wé ní kílàsì fásitì, ológì nílé
Aminat Idris, aláboyún oṣù mẹ́jọ tó fi Taekwondo dára ní ìdíje National Sports Festival ni Edo
Oríṣun àwòrán, legit ng
A fi bi idan ori itage ni nigba ti arabinrin alaboyun kan, ti oyun inu rẹ ti pe oṣu mẹjọ, Aminat Idris bori ninu idije Taekwando nibi idije ere idaray gbogboogbo to n lọ lọwọ nipinlẹ Edo.
Obinrin naa to jẹ aṣoju ipinlẹ Eko nibi idije naa kopa ninu ẹka Taekwando ti wọn n pe ni Poomsae.
Poomsae ninu ere idaraya taekwando jẹ ṣiṣe afihan gbogbo ẹka taekwando (ẹṣẹ, iduro, ìpá ati bẹẹbẹẹ lọ) ni ṣiṣẹ n tẹle, lai ṣe aṣiṣe kankan.
Sekinat Quadri ọmọ ọdun meje ajẹsẹ to fẹ dabi Anthony Joshua
Ninu fidio kan to gba ori ayelujara Twitter, a ri Aminat to n pa oriṣiriṣi itú ninu idije ijakadi naa.
Oun ati akẹẹgbẹ rẹ kan, Arowora Roqeeb ti wọn jọ n ṣoju ipinlẹ Eko, lo jọ da ara naa.
Yatọ si pe o gba ami ẹyẹ goolu fun ipinlẹ Eko, Aminat tun gba ami ẹyẹ bàbà ati ìdẹ ni ẹka ti awọn obinrin ati gẹgẹ bi olukopa.
Eyi si mu ko jẹ ọkanlara awọn elere idaraya to gba ami ẹyẹ julọ nibi idije naa.
Igba akọkọ kọ re e ti Aminat Idrees gba ami ẹyẹ ninu idije Taekwondo.
Lọdun 2018, ami ẹyẹ idẹ lo gba nibi idije ere idaraya gbogboogbo ni Naijiria.
Oríṣun àwòrán, lagos state government/twitter
Amọ ṣa, bi awọn kan ṣe n gboriyin fun, ni awọn miran n bu ẹnu ẹtẹ lu u pe idije naa lewu fun ipo to wa gẹgẹ bi alaboyun.
Yoruba film celebrities: Ìdí tí mo fi ṣe ìgbéyàwó ìdákọ́nkọ́ - Sotayo Gaga
Oríṣun àwòrán, Sotayo Gaga
Gbajugbaja oṣere tiata Tayo Sobola ti fi idi rẹ mulẹ erongba rẹ to fi ṣe iyawo idakọnkọ.
Ni nkan bi oṣu melo kan sẹyin ni gbogbo awọn ololufẹ oṣere naa n kọ haa lẹyin ti wọn ri foto oṣere yii lori ayelujara instagram rẹ. Nigba ti awọn kan n ki ku orire ni awọn miiran n sọ pe awo sinima to fẹ gbe jade ni.
Kí nìdí tí gbajúgbajà òṣèré Sotayo Gaga ṣègbéyàwó bóńkẹ́lẹ́?
Mo ti ní ìyàwó àfẹ́sọ́nà, ayẹyẹ ìgbeyàwó mi ń bọ̀ láìpẹ́ - Lateef Adedimeji
Arapa re gangan sọ̀rọ̀ nípa ìrìnàjò ìpè rẹ̀ tuntun
Wo àwọn Ọ̀gá Àgbà Ọlọ́pàá tó ti jẹ́ látọdún 1999
Kí ló lè ṣekúpa olùkọ́ fásitì Adekunle Ajasin tẹ́lẹ̀ tó dákẹ́ sínú mọ́tò rẹ̀ yìí?
Oríṣun àwòrán, Sotayo Gaga
Sugbọn ninu ifọrọwerọ pẹlu iwe iroyin kan ni Sotayo ti fi idi ọrọ naa mulẹ pe lootọ ni oun ṣe igbeyawo ati pe o ti to ọdun meje sẹyin ni oun ti mọ ọ.
"O ní, ""mo ti ṣe igbeyawo, ọkọ mi kii si ṣe oni tiata. O ti ṣe diẹ ti mo ti ṣe iyawo. Mo ti mọ ọkọ mi fun ọdun meje ki a to ṣe igbeyawo. Ti ẹ ba mọ mi, ẹ mọ pe mi kii gbe ọrọ ara mi sita."
Mo ti wa pẹlu ọkọ mi lati ọdun meje sẹyin. Irubọ ni ọrọ igbeyawo.
"Mo n ka nkan miiran lori awọn iwe iroyin ayelujara mo si rẹrin: gbogbo ibi ti wọn ba fẹ ni wọn le tan an ka de, mi o nifẹ lati maa gbe nkan to ba kan mi si aaye ara mi, nitori rẹ ni mo se fi igbeyawo mi ṣe idakọnkọ.
Kii ṣe ọdun yii ni mo ṣe igbeyawo, mo kan ṣẹṣẹ fi fọto igbeyawo mi sita ni oṣu diẹ sẹyin ni."
Àwọn nkan tó yẹ kí o mọ̀ nípa adelé Ọ̀gá Àgbà ọlọ́pàá ti Buhari ṣẹ̀ṣẹ̀ yàn
Àrà kìí tán nílé alárà! Aláboyún oṣù mẹ́jọ, Aminat Idris borí nínú ìdíje Taekwondo
Asọtẹ́lẹ̀ ikú Yinka Odumakin ti jáde sí wa tẹ́lẹ̀, ẹbí gbàdúrà, àmọ́...- Jacob Odumakin
Oríṣun àwòrán, Sotayo Gaga
Àwọn òbìnrin tó ń ya fọ́tò ìhòhò ara wọn níwájú ilé kó sí gbaga ọlọ́pàá!Gbajugbaja oṣere naa, to tun jẹ oniṣowo aṣọ fidirẹ mulẹ pe lootọ ni oun ko kopa ninu awọn Sinima pupọ lati bi ọjọ mẹta sẹyin nitori pe oun n di asiko yii moju to ọrọ aṣọ ti mo n ta ni, eyi ti mo ṣẹṣẹ ṣi ẹka kan  si  Abuja.
"O ni ""asiko wa dun gbogbo nkan, mo si ni igbagbọ pe gbogbo nkan ri eniyan ba fẹ ṣe eniyan gbọdọ wa asiko fun."
Fun emi, ọpọ lo n fi atẹjiṣẹ ranṣẹ pe awọn o ri mi ninu sinima mọ, nigba miiran eeyan a ma fi iṣẹ silẹ lati wa owo. Igba miiran wa ti mo ma n fẹ lati ṣe sinima, gbigbo ẹni to ba si pe mi fun ere lasiko naa, mo n da wọn lohun, mo si le ṣe sinima meji si mẹta.
Igba miran si wa ti mi o le ṣe sinima, ki n sọ ootọ iṣẹ aṣọ ti mo n ṣe o maa n gba asiko gidi afi ti ko ba si adojusun. Mo ṣi sọọbu tuntun kan ni Abuja, ibẹ naa si ni ile mi wa nitori ibẹ ni awọn alabara mi pọ si. Ni bayii iṣẹ aṣọ ni mo gbajumọ bi mo ṣe n ta ni mo n ra Mo ti ni oju ti awọn eniyan n fẹ ninu sinima, ti mo ba di silẹ diẹ lati lọ ṣowo, igbkuugba ti mo ba pada de ko ai eni ti yoo mọ pe mo fi igba kan kuro.
Ti mo ba ri ọwọ nilẹ ni mo n ṣe sinima bayii.
Bola Tinubu: Èèkàn Afenifere àtàwọn ọba l'Ondo kéde àtìlẹ́yìn wọn fún Tinubu fún ìbò ààrẹ 2023
Oríṣun àwòrán, Twitter/Babajide Sanwo-Olu
Olori ẹgbẹ ọmọ Yoruba, Afenifere tẹlẹ, Pa Reuben Fasoranti ti kede atilẹyin rẹ fun Aṣiwaju Bola Tinubu lati di aarẹ orilẹede Naijiria lọdun 2023.
Pa Fasoranti sọrọ yii nigba tawọn ẹgbẹ to n ṣe ipolongo fun Tinubu lapa iwọ oorun gusu ni Naijiria, South West Agenda for Asiwaju Bola Ahmed Tinubu (SWAGA 23) ṣe abẹwo si i nile rẹ niluu Akure.
Baba Fasoranti ni ''Tinubu koju osunwọn lati tukọ orilẹede Naijiria pẹlu oriṣiiriṣii nkan to ti gbe ṣe lati ẹyin wa.''
''Tinubu to gbangbaa sun lọyẹ lati jẹ aarẹ Naijiria lọdun 2023.
Mo fọwọ sii, mo si gbadura pe ki Eleduwa gbọ adura rẹ nitori to ba de ipo naa tan, gbogbo ohun ti a n fẹ ni yoo ṣe,'' Pa Fasoranti lo ṣalaye bẹẹ.
Baba Fasoranti sọ pe ti Tinubu ba fi le di aarẹ Naijiria, gbogbo erongba ẹgbẹ Afenifere lori ọrọ atunto Naijiria ni yoo di mimuṣẹ.
''Lai si ani-ani kankan nibẹ, Tinubu lo le ṣee lọdun 2023, mo mọ Tinubu daadaa.
Tinubu ko ni ja awọn ọmọ Naijiria kulẹ ti o ba de ipo aarẹ lọdun 2023, Fasoranti ṣalaye.
Ìdí tí mo fi ṣe ìgbéyàwó ìdákọ́nkọ́ - Sotayo Gaga
Ẹgbẹ́ àwọn òṣìṣẹ́ ilé ẹ̀kọ́ gbogbonìṣe, ASUP gùnlé ìyanṣẹ́lódì àìlópin
Àwọn agbébọn tún dáná sun àgọ́ ọlọ́pàá ní Imo, wọ́n tú àwọn tó wà ní àhámọ́ sílẹ̀
Alakoṣo ẹgbẹ SWAGA 23, Dayo Adeyeye kepe awọn ọmọ ilẹ Yoruba lati fohun ṣọkan, ki wọn si gbaruku ti Tinubu fun ibo aarẹ lọdun 2023.
O ni ọna kan gboogi ti ọmọ Yoruba le fi jẹ aarẹ Naijiria lọdun 2023 ni pe ki onikalulu lapa iwọ oorun gusu Naijiria gbaruku ti Tinubu.
Ẹwẹ, Osemawe Ondo, Oba Victor Kiladejo ati Abodi Ikale, Oba George Faduyile naa ni Tinubu lo le ṣee ti yoo fi yanju lọdun 2023.
Wọn ni ilẹ Yoruba le gbaruku ti lati dupo aarẹ ninu eto idibo gbogbogbo ọdun 2023.
Kaduna killings: Àwọn jàndùkú pa èèyàn mẹ́jọ, wọ́n tún jí ọ̀pọ̀ gbé lọ ní Kaduna
Oríṣun àwòrán, Twitter/Kaduna Government
O kere tan, eeyan mẹjọ lawọn agbebọn ṣekupa lọjọ Iṣẹgun nigba tawọn eeyan mii si farapa yanyana ninu ikọlu tuntun to waye nipinlẹ Kaduna.
Kọmiṣọnna fun ọrọ abo abẹle nipinlẹ Kaduna, Samuel Aruwan ṣalaye pe awọn agbebọn ọhun di oju ọna lẹba abule Kadanye lagbegbe Kajuru.
Ọgbẹni Aruwan sọ pe nibẹ ni wọn ti dabọn bo ọkọ bọọsi akero kan ati ọkọ akẹru to ko igi idanam wọn si yinbọn pa eeyan marun un lẹsẹ kẹsẹ.
Awọn kan tiẹ sọ pe wọn tun ji ọpọ eeyan gbe ninu iṣẹlẹ naa.
Bakan naa ni
Kọmiṣọnna fun ọrọ abo abẹle nipinlẹ Kaduna ṣalaye pe ni abule Akilbu ati Inlowo lagbegbe Kachia lawọn agbebọn ti yinbọn pa awọn eeyan mii.
Bakan naa lo sọ pe ọgọsan maalu ni wọn tun jigbe lọ ni gaa awọn darandaran to wa lagbegbe naa.
Ọgbẹni Aruwan tun fidi rẹ mulẹ pe awọn ọlọpaa dena ikọlu mii ti ko ba tun waye loju ọna Kaduna si Birni Gwari lagbegbe Buruku.
Awọn ọlọpaa yabo ibi tawọn agbebọn ọhun ti fẹ ṣọṣẹ nibi ti wọn ti doju ija kọ ara wọn ti awọn janduku naa si fẹsẹ fẹ.
Eeyan meji, Fahad Lawal ati Usman Shehu ni wọn doola nibẹ, awọn mejeeji si n gba itọju nile iwosan bayii.
'Bí ojú ọ̀nà agbàrá òjò tí ijọba ṣe n'IIorin ṣe ń pa àwọn ọmọ iléèwé wa rèé! Ẹ sàánú wa'
Dangote, Adenuga àti Rabiu pọ̀ síi pẹ̀lú $5.7bn - Forbes
Oríṣun àwòrán, Instagram/femiotedola
Ọrọ̀ awọn bilonia to jẹ ọmọ orilẹede Naijiria tun ti pọ sii pẹlu biliọnu mẹfa owo dọla din diẹ laarin ọdun kan sẹyin.
Iwe iroyin Forbes lo gbe iroyin naa jade pe ninu atẹjade awọn bilonia fun ọdun 2021.
Atẹjade ti Forbes gbe jade lọjọ Iṣẹgun fihan pe Aliko Dangote to jẹ oludari ati ọga agba ileeṣẹ Dangote naa si lo lowo julọ nilẹ Afirika.
Mẹrinla lara awọn bilonia agbaye ọhun lo wa lati ilẹ Afirika.
Ni bayii, dukia ati ọrọ Dangote ti di $11.5bn lati $8.3bn to wa lọdun 2020.
Dangote bilonia to wa ni ipo kọkanlelọgọsan lori tabili awọn eeyan to lọrọ julọ ni gbogbo agbaye.
Ọrọ ati dukia alaga ileeṣẹ ẹrọ ibaraẹnisọrọ Globacom ati ile epo rọbi Conoil Plc, Mike Adenuga naa le si lati $5.6bn lọdun 2020 si $6.1bn bayii.
Adenuga lẹni to lowo julọ ṣikeji lorilẹede Naijiria, amọ ipo karun un lo wa nilẹ Afirika nigba to wa ni ipo oji le ni irinwo 440 lagbaaye.
Oludasilẹ ileeṣẹ BUA Group, Abdulsamad Rabiu naa gberu sii pẹlu ọrọ rẹ.
Ohun ini rẹ ti di $4.9bn bayii lati $2.9bn to wa lọdun 2020.
Marun un ninu awọn bilonia lati ilẹ Afirika ti iwe iroyin Forbes gbe jade lo wa lati orilẹede South Africa.
Marun un miran wa lati orilẹede Egypt, nigba ti ẹyọkan jẹ ọmọ bibi orilẹede Algeria.
Ẹwẹ, oludasilẹ ileeṣẹ Amazon, Jeff Bezos si ni ẹni to lowo julọ lagbaaye pẹlu $177bn.
Ọgbẹni Bezos ti wa ni ipo kinni bayii fun ọdun mẹrin gbako.
Ẹ padà wá o ẹ̀yin ẹlẹ́wọ̀n, ẹni tó bá wá wọ́ọ́rọ́wọ́ yóò rí ìdáríjì, ẹni tí kò bá wá ... - Aregbesola
Ariwo sọọ! Àwọn agbébọn jí ọkọ, ìyàwó àtàwọn ọmọ wọn gbé l'Ondo
"Sotayo Gaga bẹ́ ""speaker"" ọdún tó ti ṣegbéyàwó àti ohuin tó fi pamọ́"
'Bí ojú ọ̀nà agbàrá òjò tí ijọba ṣe n'IIorin ṣe ń pa àwọn ọmọ iléèwé wa rèé! Ẹ sàánú wa'
Traditional Rulers Attack: Ọba David Oyewumi ti gba òmìnira lọ́wọ́ àwọn ajínigbé ní Ekiti
Oríṣun àwòrán, @insightlinkstv
Idunu ṣubu  lu ayọ nipinlẹ Ekiti lẹyin ti ọba Ilemeso-Ekiti, Ọba David Oyewumi gba ominira lọwọ awọn ajinigbe.
Ọsẹ to kọja ni awọn ajinigbe naa kan lu aafin rẹ ni nnkan bii aago mẹjọ abọ aṣalẹ, ti wọn si ji i gbe lọ.
Agbẹnusọ ileeṣẹ ọlọpaa ipinlẹ Ekiti, sọ fun BBC Yoruba pe ori ade naa ti bọ lọwọ awọn ajinigbe ọhun, o si ti pada sile lọdọ awọn ẹbi rẹ.
"Agbenusọ ọlọpaa naa ni: ""Mo fẹ sọ fun un yin pe awọn ajinigbe naa ti tu Kabiesi silẹ, o si ti pada silẹ lọdọ awọn mọlẹbi rẹ."""
Wọn tu u silẹ lẹyin ti awọn akọṣẹmọṣẹ ọlọpaa kan lu inu igbo ti wọn gbe e lọ lati doola rẹ lọwọ awọn ajinigbe ọhun.
Ṣaaju ni iroyin kan ti kọkọ gbode pe awọn ajinigbe ọhun beere ogun miliọnu naira gẹgẹ bii owo itusilẹ lọwọ awọn ẹbi rẹ.
Akomolede ati Aṣa lori BBC Yoruba: Ẹ̀yà Ara Ifọ̀ ní olùkọ́ Adedokun kọ́ wa
Ṣugbọn Abutu sọ fun BBC pe ko si ohun to jọ bẹẹ, ati pe ileeṣẹ ọlọpaa ko le fidi rẹ mulẹ boya awọn ẹbi ọba alaye naa san owo itusilẹ kankan.
Wọn ji ori ade naa gbe ninu aafin rẹ l'Ọjọbọ lẹyin ti awọn ajinigbe ọhun kọlu aafin rẹ, ti wọn si fo ogiri wọle.
Iṣẹlẹ naa waye ni nnkan bii ọsẹ kan si asiko ti ọba Elewu ti Ewu-Ekiti, Ọba Adetutu Ajayi, ti kọkọ jajabọ lọwọ awọn kan ti wọn gbiyanju lati ji oun naa gbe.
Ọpọ awọn ọmọ Yoruba kaakiri orilẹ-ede naijiria lo bu ẹnu ẹtẹ lu iṣẹlẹ naa pe o jẹ ohun itiju pe awọn ajinigbe gboju-gboya lati wọ inu aafin lọ lati ji odidi ọba gbe.
aaaaaaaaaaaaaaa
Yoruba ni iku to n pa ojugba ẹni, owe lo n pa fun ni, bi atẹgun ba si ti n gbe kẹtẹpẹ ogi, ayafi ki onilafun ma se afira.
Ọba David Oyewumi, to jẹ Obadu ti Ilemeso-Ekiti, ni awọn ajijigbe ji gbe ninu aafin rẹ to wa ni ijọba ibilẹ Oye, nipinle Ekiti.
Oríṣun àwòrán, @DailyPostNGR
Awọn ajinigbe naa fo iganna wọ inu aafin kabiesi, wọn si bẹrẹ si n yinbọ soke ki wọn to ji gbe lọ.
Iṣẹlẹ yii lo n waye ni nnkan bii ọsẹ kan si asiko ti ọba Elewu ti Ewu-Ekiti, Ọba Adetutu Ajayi, bọ lọwọ awọn kan ti wọn gbiyanju lati ji oun naa gbe.
Oṣojumikoro kan sọ pe awọn ajinigbe naa lu ori ade ọhun atawọn ẹbi rẹ ninu aafin, ki wọn to gbe salọ.
"O ni ""inu aafin baba ni wọn ti gbe wọn lọ, awọn eeyan bii mẹrin fo ogiri wọle, ti wọn si n beere pe, baba da, baba da… eyi to n ṣafihan pe baba gan ni wọn wa wa."
Sunday Igboho: Fulani kò leè dúró, táa bá lo ohun ta jogún lọ́dọ̀ àwọ̀n bàbá wa
"Ni kete ti wọn ri baba bayii ni wọn gbe wọn salọ."""
Ọpọ awọn olugbe ilu naa to jẹ agbẹ, lo ti bẹrẹ si n sa kuro nibẹ nitori ibẹru awọn ajinigbe.
Nigba to n fi idi isẹlẹ naa mulẹ fun BBC Yoruba, Alaga igbimọ lọbalọba nipinlẹ Ekiti, Ọba Adebanji Ajibade Alabi, tii ṣe Alawe ti ilu Ilawe-Ekiti ni iṣẹlẹ naa jẹ eyii to buru jai o si ba awọn lọkan jẹ gidi.
"O ni ""awa gẹgẹ bii ọba, ati gbe igbesẹ lori iṣẹlẹ naa, nitori ni kete ti a gbọ ni mo ke si ileeṣẹ ọlọpaa, awọn fijilante atawọn ikọ Amọtẹkun lati wọ inu igbo ti wọn gbe ọba naa lọ, lati wa a ri."""
Ọba Ajibade Alabi sọ pe, o jẹ ohun ti eti ko gbọ ri ki awọn ajinigbe maa farapamọ sinu igbo ki wọn si gboju gboya lati wọ inu aafin lati ji odidi ori gbe.
"Gẹgẹ bo ṣe sọ, ""awọn Amọtekun n gbiyanju nitori awọn lo maa n wọnu igbo lọ lati lọ ṣọfintoto awọn ajinigbe, nitori naa, o yẹ ki ijọba ti wọn lẹyin, ki ijọba si pese irinṣẹ igbalode fun wọn lati ṣiṣẹ wọn."""
Sunday Igboho fulani ultimatum: Àwọn ará Kebbi àti Zamfara ló n jínígbé ní Oke Ogun- Serik
O rọ ileeṣẹ ọlọpaa lati fọwọsowọpọ pẹlu awọn ẹṣọ alabo miran bii ileeṣẹ ologun, awọn fijilante  ati ọlọdẹ ilu lai yọ Amọtekun silẹ, lati wọ inu ogbo lọ lati le gbogbo awọn ajinigbeto wa nibẹ jade.
Ọba Alabi ni itiju nla ni fun ilu pe awọn ajinigbe wọ inu aafin, ti wọn si ji ọba wọn gbe lọ lai si idiwọ kankan.
Bo tilẹ jẹ pe o mẹnuba ikọlu ti awọn eeyan kan ṣe si ọba Ewu lọna ilu Ayetoro, alaga igbimọ awọn lọbalọba Ekiti naa ni iṣẹlẹ yii ni igba akọkọ ti wọn yoo ji ọba gbe ni ipinlẹ Ekiti.
Ni ti awọn igbesẹ ti awọn lọbalọba n gbe nipinlẹ Ekiti lati dabo bo ara wọn atawọn eeyan ilu, Ọba Ajibade Alabi ni ipade ti n lọ lọwọ laarin awọn lọbalọba naa, ti oun ko fẹ mẹnuba.
Female Car Painter: Èmi ní obìnrin àkọ́kọ́ tí yóò máa ṣiṣẹ́ akunmọ́tò ní Ibadan
Nigba ti BBC Yoruba kan si alukoro ileeṣẹ ọlọpaa ipinlẹ Ekiti, ASP Sunday Abutu, o ni lootọ ni iṣẹlẹ naa waye, awọn si ti ran awọn akọṣẹmọṣẹ ọtẹlẹmuyẹ sinu igbo naa lati ṣawari kabiesi ọhun.
Abutu ni iṣẹ ti n lọ lọwọ lati ṣawari oriade naa, awọn yoo si doola kabiesi ọhun laipẹ.
O pari ọrọ rẹ pe, titi di akoko ti oun fi n ba BBC sọrọ, awọn ajijigbe naa ko tii beere owo itusilẹ kankan lọwọ awọn mọlẹbi ori ade ti wọn ji gbe ọhun.
Oríṣun àwòrán, NigerianArmyHQ
Awọn ikọlu to n waye nilẹ Naijiria lemọ lemọ yii ti di Egbirin ọtẹ, baa se npa ọkan ni omii n ru.
Idi ni pe oriade kan nipinlẹ Ekiti, ẹni tii se ọkan lara awọn oriade pataki nipinlẹ naa, to tun jẹ Elewu tilu Ewu Ekiti, Ọba Adetutu Ajayi ni awọn gende agbebọn kan tun ti kọlu.
Awọn gende agbebọn naa kọlu oriade yii lasiko to n ti ilu Ayetoro Ekiti to mule ti ilu rẹ bọ, se ni wọn si rọjo ọta ibọn si ara ọkọ ayọkẹlẹ rẹ.
Ọba naa, to fi ara gba ọgbẹ ọta ibọn lori ko yọ lọwọ iku ojiji, to si ti n gba itọju nile iwosan aladani kan nilu Ado Ekiti.
Torí àti ṣe Kòkò irin, bí mo ṣe máa ǹ fara yá iná nìyìí - Amokoko Saki
A gbọ pe ẹsẹ, ọwọ ati ikun ni oriade naa ti fara gba ọgbẹ ọta ibọn, to si wa lẹsẹ kan aye, ẹsẹ kan ọrun bayii.
Agbẹnusọ fun ileesẹ ọlọpaa nipinlẹ Ekiti, Sunday Abutu ti wa fidi isẹlẹ naa mulẹ, to si n fi ika hanu pe isẹlẹ naa waye lai naani pe awọn ọlọpaa n paraaro ipinlẹ naa lati de ikọlu awọn ọdaran.
Oríṣun àwòrán, @DailyPostNGR
Ara mee riri, mo rori ologbo latẹ. Awọn ẹbi Ọgbẹni Olisa Ibrahim iyawo atawọn ọmọ wọn mẹta ti sọ ohun ti oju wọn lakata awọn agbebọn to ji wọn gbe nipinlẹ Ondo.
Ẹbi naa ti wọn jigbe lopopona Ajowa si Ayere kabba ṣalaye pe lara awọn nnkan tawọn ajinigbe ọhun beere fun ni ounjẹ to dun, ọti waini ati ẹran suya yatọ si owo.
Ẹbi Ọgbẹni Ibrahim to n pada lọ si ibugbe wọn niluu Abuja lẹyin ọdun Ajinde lawọn ajinigbe ọhun kọkọ beere fun miliọnu mẹwaa owo itusilẹ lẹyin ti wọn gbe wọn lọ tan.
Gbogbo wọn lo pada si ilu Ajowa-Akoko lẹyin ti wọn gba ominira tan lọwọ awọn agbebọn ajinigbe.
Ohun ti a gbọ ni pe wọn san owo kan ki wọn to fi wọn silẹ, ṣugbọn ileeṣẹ ọlọpaa ko le fidi rẹ mulẹ.
Niṣe lawọn eeyan n tu yaya lọ si ile wọn nibi ti wọn ti n ki wọn ku oriire pe aja to rele ẹkun to bọ, ki ki i ku ewu.
Ipinlẹ Ondo yii naa wọn ti ji pasaitọ Fredrick Aramuwa gbe ti wọn si ṣekupa lẹyin ti a gbọ pe awọn ẹbi san owo gọbọi fawọn kọlọnbiti ẹda ọhun.
Ariwo sọọ! Àwọn agbébọn jí ọkọ, ìyàwó àtàwọn ọmọ wọn gbé l'Ondo
Awọn agbebọn kan ti ji idile ẹlẹni marun un gbe niluu Ajowa-Akoko, ni ijọba ibilẹ Ariwa-Iwọ-oorun Akoko ni ipinlẹ Ondo.
Iroyin ni awọn eeyan naa n rinrinajo lọ si Abuja lati Ajowa-Akoko, nibi ti wọn ti lọ ṣe ọdun Ajinde ki awọn ajinigbe ọhun to ka wọn mọ abala kan ti ko dara loju ọna naa.
Gẹgẹ bii ohun ti a gbọ, wọn ji olori ẹbi naa, Ibrahim Olusa plẹlu iyawo atawọn ọmọ rẹ gbe loju ibọn laarin Ajowa-Akoko si Ayere ni ipinlẹ Kogi, wọn si ko gbogbo wọn lọ sinu igbo kijikiji.
Wọn ni awọn ajinigbe naa ti kan si ẹbi awọn ti wọn ti je gbe lati bere miliọnu mẹwaa naira owo itusilẹ wọn.
Isẹlẹ naa si ti mu iporuru ba ọkan awọn eeyan ilu ọhun.
'Bí ojú ọ̀nà agbàrá òjò tí ijọba ṣe n'IIorin ṣe ń pa àwọn ọmọ iléèwé wa rèé! Ẹ sàánú wa'
Ọkan lara awọn adari ilu naa, to tun jẹ alaga igbijmọ adari Ajowa-Akoko ana, Ajayi bakare to fidi iṣẹlẹ naa mulẹ sọ pe ijinigbe ati idigunjale n peleke sii lagbegbe nitori ọna ti ko dara ni iha ipinle Kogi.
Bakare wa ke si ijọba lati tun ọna naa ṣe ni kiakia lati le ṣadinku iwa ọdaran lagbegbe ọhun.
Àwọn èdè abẹ́ ahọ́n tóo lè fi sọ̀rọ̀ rèé láì tú àṣírí ọ̀rọ̀ rẹ áyé
Buhari driver: Kò sẹ́ni tó lè ní kí Buhari má gba ìtọ́jú nílẹ̀ òkèèrè - Amúgbálẹ́egbẹ́ Ààrẹ
Oríṣun àwòrán, Femi Adesina
Amugbalẹgbẹ Aarẹ Muhammadu Buhari lori oju opo ikansiraẹni lori ayelujara, Lauretta Onochie ti sọ pe Aarẹ lẹtọọ lati maa lọ gba itọju loke okun.
Onochie lo sọrọ naa ninu atẹjade kan loju opo Twitter rẹ lasiko to n fesi si bi awọn ọmọ Naijiria kan ṣe n bu ẹnu ẹtẹ lu Aare Buahri pe o lọ gba itọju loke okun lasiko ti awọn dokita daṣẹsilẹ ni Naijiria.
Ṣaaju ni ọpọ ọmọ Naijiria ti kọkọ bu ẹnu atẹ lu Buhari pe idi ti ko ṣe le gba itọju ni Naijiria ni pe o kọ lati tun ẹka eto ilera ṣe, koda awọn kan ṣe ifẹhonuhan niluu London pẹlu.
Lẹyin to de sile ijọba niluu London lawọn eeyan kan ti bẹrẹ ifẹhonuhan, ti wọn si n sọ pe ko pada si Naijiria lati tunṣẹ.
Nigba to n da si ọrọ naa, Onochie sọ pe ko sẹni to le ni ki Buhari ma kan si awọn dokita to n ti n ṣetọju rẹ lati nnkan bii ogoji ọdun sẹyin.
"O ni ""Aarẹ Buhari yoo tun lọ ṣe ayẹwo miran loke okun to ba di ọdun to n bọ, awọn eeyan yoo si tun pariwo ẹnu lasan naa ni."""
'Bí ojú ọ̀nà agbàrá òjò tí ijọba ṣe n'IIorin ṣe ń pa àwọn ọmọ iléèwé wa rèé! Ẹ sàánú wa'
O lọ fun ayẹwo lọdun 2017, 2018, 2019 ati 2020 ki Corona to de, ariwo ẹnu yii kan naa lawọn pa nigba naa.
Oríṣun àwòrán, Lauretta Onochie
Amugbalẹgbẹ Aarẹ naa fi kun pe ko si ọkunri ti yoo gba ki gẹrigẹ miran gẹ irun fun oun nitori gẹrigẹri rẹ ko si ni tosi.
"Lauretta fi kun pe ""to ba wu Aarẹ lati lọ fun ayẹwo miran lọdun 2022 ati 2023, yoo lọ nitori ọwọ rẹ lo wa."""
Onochie pari ọrọ rẹ pe kaakiri agbaye lawọn eeyan ti maa n tẹkọ leti lati lọ ṣayẹwo lọdọ awọn dokita wọn, nitori naa, ariwo lasan lawọn eeyan n pa, ati pe ariwo naa ko le di Aarẹ lọwọ lati ri olutọju rẹ.
Àwọn èdè abẹ́ ahọ́n tóo lè fi sọ̀rọ̀ rèé láì tú àṣírí ọ̀rọ̀ rẹ áyé
When can I get the Covid vaccine: Ó ṣeéṣe kí ìjọba Naijiria dáwọ́ gbígbà abẹrẹ Covid-19 dúró kí abala kejì tó dé
Oríṣun àwòrán, @naijapremiumgst
Awọn alaṣẹ eto ilera ni Naijiria ti sọ pe awọn yoo dawọ fifun awọn eeyan labẹrẹ ajẹsara Covid-19 ti Osford-Astrazeneca ṣe duro ti awọn eeyan ba ti gba idaji abẹrẹ to wa ni ikawọ wọn.
Minisita abẹlẹ fun eto ilera, Olurunnimbe Mamora sọ fun awọn akọroyin pe awọn ko le sọ ni pato akoko ti abala keji abẹrẹ naa yoo de.
Nitori naa ni wọn yoo ṣe da gbiba rẹ duro ki awọn to ti gba abẹrẹ naa ṣaaju le gba nigba keji.
Ti ẹ ko ba gbagbe, igba meji ọtọtọ ni awọn eeyan yoo ni lati gba abẹrẹ naa fun abo to peye.
Gẹgẹ bi ohun ti Mamora sọ, ijọba yoo dawọ gbiga rẹ duro ki abẹrẹ naa ma baa tan nilẹ ki awọn to ti gba abala kinni le ri gba lẹẹkan si, paapaa ni bayii ti wọn ko mọ akoko ti abala keji rẹ yoo de.
Oríṣun àwòrán, @MowliidHaji
Atẹjade kan lati ileeṣẹ to n ri si eto ilera alabọde fi han pe nnkan bii miliọnu kan eeyan lo ti gba abẹrẹ naa ni Naijiria fun igba akọkọ.
'Bí ojú ọ̀nà agbàrá òjò tí ijọba ṣe n'IIorin ṣe ń pa àwọn ọmọ iléèwé wa rèé! Ẹ sàánú wa'
Awọn eleto ilera ni wọn kọkọ fun labẹrẹ ọhun nigba ti wọn ko wọ Naijiria loṣu Keji ọdun yii.
Ẹwẹ, ijọba Naijiria ti bẹrẹ si n ṣayẹwo abẹrẹ ajẹsara meji miran ti awọn onimọ ijinlẹ rẹ ṣe.
Nnkan bii 162,000 eeyan lo ti fara kasa Coronavirus ni Naijiria, ẹgbẹrun meji eeyan o le diẹ si ti ba arun naa lọ.
Jimoh Ológì déé! Ọ̀mọ̀wé ní kílàsì fásitì, ológì nílé
Suzzanne Wenger: Obìnrin òyìnbó tó mọ ojú òrìṣà Osun ju ọmọ Yorùbá lọ
Oríṣun àwòrán, ARTouch
Ni ilẹ kaarọ oojiire, ẹsin ibilẹ tabi iṣẹṣe rinlẹ lati atijọ, ohun si lo jẹ ẹsin abalaye tawọn baba nla wa tẹwọgba lati fi maa sin Olodumare.
Amọ, nigba ti awọn oyinbo alawọ funfun de, ẹya Yoruba fi ẹsin abalaye silẹ, ti wọn si tẹwọgba ẹsin Kristiẹni ati ti Musulumi.
Ẹtahoro ọmọ Yoruba lo ku to n gbe awọn orisa abalaye ga, ti wọn si n se ẹsin ibilẹ.
Àwọn ìtàn mánigbàgbé tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí:
Idi si ree to se jẹ ohun iyalẹnu lati ri obinrin oyinbo to n kara mọ aasiki ẹsin ibilẹ ju awa alawọ dudu gan an lọ.
Orukọ obinrin naa ni Suzzane Wenger, to wa lati ilu oyinbo, ti kii si fi ọkankan ninu awọn orisa ilẹ Yoruba sere.
Gẹgẹ bi oju opo Wikipedia to wa lori itakun agbaye ti slaye, ipa kekere kọ ni Suzzane Wenger, ti ọpọ mọ si Adunni Olorisa ko, lati ri pe ẹsin abalaye wa ko parun nilẹ Yoruba.
Adunni Olorisa jẹ agbẹgilere, to si maa n fi igi da ara to ba wu, eyi to mu ko rọrun fun lati gbẹ ere nipa oniruuru orisa to wa nilẹ Yoruba.
Bi itan aye obinrin naa si se lọ ree ati ipa manigbagbe to ko nidi agbega asa ati orisa ilẹ Kaarọ Oojire
Oríṣun àwòrán, ARTouch
Ọjọ Kẹrin, osu keje, ọdun 1915 ni wọn bi Suzzanne Wenger sile aye, lasiko ogun agbaye akọkọ.
Ilu Graz, lorilẹ-ede Guusu Austria si ni wọn bi obinrin naa si, sinu idile ẹlẹsin Kristẹni, amọ, o nifẹ gbogbo ohun to ba jẹ ti isẹda tabi adayeba.
Eyi lo mu ki Suzzanne lọ kọ nipa isẹ ọna, paapaa ba se n gbẹ igi ni ere, to si lọ yika awọn ilu nla nla lati mọ nipa isẹ naa, to si tun n ta awọn ọja to ba fi igi se.
Nitori ifẹ si isẹ ọna to ni, lara awọn ilẹ to ti sisẹ ọna naa ni Vienna, Italy, Switzerland ati Paris, lorilẹ-ede Faranse.
Ilu Paris si ni Suzzanne wa, to fi se alabapade ọkọ rẹ akọkọ, Ulli Beier ẹni to sẹsẹ ri isẹ olukọ lọgba fasiti Ibadan.
Ulli Bier ati Suzzanne Wenger se igbeyawo nilu London lọdun 1949, eyi to mu ko rọrun fun wọn lati dijọ wa silẹ Naijiria bii tọkọ taya.
Nigba to di ọdun 1950, awọn tọkọ-taya yii lọ tẹdo silu Ede nitori wọn n wa ayika to kun fun ohun isẹda lati maa gbe.
Bawo ni Suzzanne Wenger se gba ẹsin iṣẹṣe?
Suzzanne Wenger ko saadede tẹwọ gba orisa ibilẹ amọ aisan nla kan lo deede gbe  e ṣanlẹ laarin ọdun kan ti oun ati ọkọ rẹ wọ Naijiria, ti wọn si tẹdo si ilu Ibadan.
Lọ́dun 1950 yii ni arun ikọ ife da a wolẹ, bẹẹ ni ko si dokita oyinbo kankan larọwọto lati se itọju rẹ, to si n ku lọ bi ọjọ ti n gori ọjọ.
Asiko yii ni awọn olorisa dide, ti wọn si n se itọju obinrin yii pẹlu agbo, egboogi, ewe ati egbo titi ti ara rẹ fi da, to si bọ lọwọ arun asekupani naa.
Lati igba naa, ni Suzzanne ti fi aye rẹ fun awọn orisa, ti ko si boju wẹyin mọ, bẹẹ lo si mu ẹsin bibọ orisa ni ọkunkundun, to si gba a gbọ titi di ọjọ iku rẹ.
Oríṣun àwòrán, ARTouch
Asiko yii si lo salabapade orisa Obatala ati Alagemo, to si nifẹ pupọ si ọna ti wọn n gba bọ awọn orisa yii ati gbogbo ohun to jẹ mọ.
Bi o tilẹ jẹ pe Suzzanne ko gbọ ede Yoruba, sibẹ eyi ko se idiwọ fun un lati maa kọ nipa ilana irubọ ati etutu awọn orisa yii, to si di ọrẹ awọn olorisa naa.
Suzzanne yi orukọ rẹ pada kuro ni ti oyinbo, awọn olorisa si sọ ọ ni orukọ abisọ nilana ẹsin abalaye.
Orukọ rẹ tuntun ni Iwinfunmi Adunni Olorisa, Ọba Samuel Adeleye Adenle, Ataoja tilu Osogbo si lo fun un ni orukọ naa.
Oríṣun àwòrán, NAvigator Film
Adunni ati ọkọ rẹ tun lọ silu Osogbo lati tẹdo si, ibẹ si ni wọn ti tuka gẹgẹ bi tọkọ-taya.
Obinrin oyinbo naa n tẹsiwaju pẹlu orisa bibọ, to si n kọ ẹkọ lojoojumọ nipa ilana ẹsin abalaye.
Adunni tun dan igbeyawo wo lẹẹkan si, to si tun se igbeyawo pẹlu ọkọ keji, tii se onilu ibilẹ lọdun 1959.
Orukọ onilu naa ni Oloye Ayansola Oniru Alarape, toun naa ti di oloogbe bayii.
Amọ igbeyawo naa ko tun tọjọ, ti wọn fi tuka, ti Adunni si da wa titi opin aye rẹ lai sopo fẹ ọkọ kankan mọ, amọ to fi awọn orisa se ọkọ.
Wo itan omi gbigbona ati tutu ni Ikọgosi Ekiti
Adunni ko tẹwọ gba orisa kan soso ni pato amọ o gba ilana ẹsin ibilẹ, gbogbo ọna si lo n gba gbe awọn ẹsin abalaye yii larugẹ.
Oniruuru ere ni Adunni fi igi gbẹ lati safihan awọn orisa ilẹ Yoruba, to si n fi owo, ara ati isẹ ọwọ gbe oẹsin abalaye tilẹ Yoruba larugẹ.
Gbogbo awọn ẹlẹsin Kristiẹni ati ti Musulumi lo n se ariwisi si obinrin oyinbo yii pe se lo tun n se agbende ati agbega iwa ibọrisa, eyi to ti n lọ sokun igbagbe.
Amọ, gbogbo ariwisi wọn ni ko tu irun kankan lara Adunni, to si n tẹsiwaju lati maa fọn rere pe ajọsepọ wa laarin awọn ẹsin mẹtẹẹta, ko si iyatọ.
Olumo Rock: Òrìṣà Igùn lọba ọ̀pọ̀ òrìṣà tó wà lábẹ́ Olúmọ tó ń dáhùn àdúrà
Awọn ohun meremere ti Adunni Olorisa se nidi agbega osiṣa nigba aye rẹ
Ikorodu cult crisis:A máa gbé Orò síta lọ́jọ́kọ́jọ́ tí ìjà ẹgbẹ́ òkùnkùn bá tún ṣẹlẹ̀- Àwọ
Kíni ìdí ti àwọn ọmọ ogun fi n ṣọ́ àwọn Imaam ni Mecca?
Mọ̀ sií i nípa Oba Yesufu Asanike , Olubadan tí kìí fi ọ̀rọ̀ sí abẹ́ ahọ́n sọ kódà níwájú sọ́jà
Irú ẹ̀dá wo ni Lamidi Adeyemi? Aláàfin tó rí ìbẹ̀rẹ̀ àti opin sáà gómìnà mọ́kànlélógún l‘Oyo
August Agboola Brownie, ọmọ Yorùbá tí wọ́n n wárí fún ní Poland
Akomolede àti Asa: Kí ni Ìjálá láàrin àwọn ewì alohùn àti bí wọ́n ṣe ń sun-ún?
Yemi Farounbi: Yorùbá yóò dáàbò bo ara rẹ́, bí ìjọ́ba bá kùnà láti ràgà bò wọ́n
aaaaaaaaaaaaaaa
Aadọta ọdun gbako ni Adunni Olorisa lo pẹlu iran Yoruba ko to filẹ bora.
Ọjọ ni ọjọ Aje, ọjọ kejila, osu Kinni, ọdun 2009, ti Aduuni Olorisa dakẹ, to si ki aye pe o digbose se nile iwosan Aguda ti Fatimah to wa nilu Osogbo.
Gbogbo ọmọ mẹẹdogun ti obinrin oyinbo tọ yii si gba tọ ọ lo wa ni ẹba ibusun rẹ lasiko to mi kanlẹ.
Lara awọn ọmọ ti Adunni gba tọ ni Yinka Davies Okundaye ti ọpọ eeyan mọ si Nikky Afirikana, ẹni toun naa gbajumọ nidi isẹ ọna ati asọ Adire sise.
hhhhhh
Ọmọ ọdun mẹfa ni Yinka wa nigba to di ọmọ orukan, ti Adunni si gba lati ma a tọju rẹ gẹgẹ bii ọmọ bibi inu rẹ.
Ko si to jade laye ni Adunni ti fi ọrọ silẹ pe wọn ko gbọdọ gbe oku oun sinu yinyin ni ibudo igbokusi tabi se inawo alarinrin lati se oku oun.
Ọpọ eeyan to si gbọ nipa iku akikanju obinrin iya olorisa yii lo ni kii se pe o ku, o sun ni lati di ọkan lara orisa ti iran Yoruba ko ni le gbagbe laelae.
Bakan naa ni awọn ọmọ rẹ fidi rẹ mulẹ pe lootọ ni wọn sin Adunni nilana ẹsin isẹse amọ ko si ẹni to ge ẹya ara rẹ kankan, lodi si ahesọ ọrọ tawọn kan n sọ kiri.
Female Car Painter: Èmi ní obìnrin àkọ́kọ́ tí yóò máa ṣiṣẹ́ akunmọ́tò ní Ibadan
Adunni Olorisa ti waye, o si ti lọ mọ ipa manigbagbe to ko nidi agbega asa ilẹ Yoruba ko le parẹ laelae.
Lara awọn ẹkọ naa ni pe ko yẹ ka maa fi ọwọ rọ oun adayeba wa sẹyin nitori ọmọ ale nii fi ọwọ osi juwe ile baba rẹ.
Bakan naa ni itan igbe aye Adunni kọ wa pe ka maa se anu nipa gbigbe ori awọn ọmọde sori soke boya ọba oke fun wa ni ọmọ abi bẹẹ kọ.
Itan yii tun kọ wa pe ka maa se amulo awọn ohun isẹse wa bii egboogi, agbo, ewe ati egbo nitori iwulo tiwọn naa wa, eyi to ti n lọ sokun igbagbe bayii.
Itan Omi Erin
Usman Alkali Baba: Ó yẹ kí ìjọba bẹ̀rẹ̀ owó oṣù tuntun f'áwọn ọlọ́pàá gẹ́gẹ́ bíi ìlérí wọn lásìkò ìwọ́de EndSARS
Oríṣun àwòrán, @Gidi_Traffic
Awọn ọmọ Naijiria kan ti sọ pe kii ṣe pipaarọ ọga agba ileeṣẹ ọlọpaa lo le tun eto abo Naijiria to mẹhẹ ṣe, bikoṣe ki ijọba pese awọn ohun to yẹ fun awọn ọlọpaa, bii owo oṣu to niye lori, ile gigbe, ilera to dara, ati bẹẹbẹẹ lọ.
Nigba to n sọrọ lori ireti awọn ara ilu lori iyansipo adele ọga agba tuntun fun ileeṣẹ ọlọpaa, Usman Alkali Baba, ajijagbara kan, Kunle Wizeman Ajayi sọ pe aisi abo ounjẹ ati iṣẹ lo fa eto abo to mẹhẹ ni Naijiria.
O ni ti awọn eeyan ko ba jẹun kanu, ti wọn ko si ni iṣẹ gidi lọwọ, ko sẹni ti yoo le sun ninu ile rẹ.
Ajayi sọ pe ọrọ ti ọga agba tuntun ileeṣẹ ọlọpaa naa sọ pe oun yoo mu atunṣe nla ba ileeṣe ọlọpaa naa ni gbogbo awọn to ṣiwaju rẹ maa n sọ lai si iyatọ to dantọ ti wọn maa n mu wa.
"Gẹgẹ bo ṣe sọ, ""oun ti a fẹ gbọ ni pe ki ijọba sọ pe awọn ti n san owo oṣu tuntun fun awọn ọlọpaa gẹgẹ bii ileri ti wọn ṣe fu awọn ọdọ lasiko iwọde #EndSARS."""
Oríṣun àwòrán, Presidency
"Kunle Ajayi ni ""ibere to yẹ ki awọn ọmọ Naijiria bere lọwọ ọga agba  ileeṣẹ ọlọpaa tuntun ni pe, ṣe wọn ti ko awọn ọlọpaa onijẹkujẹ to n tọrọ owo loju popo kuro nibẹ?"""
'Bí ojú ọ̀nà agbàrá òjò tí ijọba ṣe n'IIorin ṣe ń pa àwọn ọmọ iléèwé wa rèé! Ẹ sàánú wa'
Ṣe ki n ṣe awọn ọlọpaa funra wọn lo n fi owo ara wọn ra aṣọ iṣẹ si ọrun ara wọn.
Ajijagbara naa ni o di igba ti ijọba ba ka awọn ọlọpaa si eeyan pataki, ki wọn maa tọju wọn daadaa ki awọn eeyan naa to le mura siṣẹ.
O pari ọrọ rẹ pe ọga agba tuntun ti wọn ṣẹṣẹ yan ko le ṣe aṣeyọri ti wọn ko ba ṣetọju awọn ọlọpaa to wa labẹ rẹ to n ṣo awọn eeyan ilu.
O fi kun pe ijọba apapọ tun gbọdọ pese iṣẹ atawọn ohun amayedẹrun fun awọn ọdọ ti ko niṣẹ lọwọ ti wọn ba n fẹ ayipada rere nipa ti eto abo Naijiria.
Àwọn èdè abẹ́ ahọ́n tóo lè fi sọ̀rọ̀ rèé láì tú àṣírí ọ̀rọ̀ rẹ áyé
Kii ṣe iroyin mọ pe Aarẹ Muhammadu Buhari ti yan Usman Alkali Baba gegebi adele oga agba olopaa tuntun ni Naijiria.
Ohun ti ọpọ n sọ bayii naa ni awọn ipenija marun un to ga ju ti Alkali Baba yoo maa dojukọ lori ipo tuntun naa.
Asiko iyansipo ọga agba ọlọpaa Usman Alkali Baba bọ si asiko ti ipenija ọrọ abo lorilẹede Naijiria n peleke sii.
Ojojumọ ni iṣẹlẹ ijinigbe iṣigun ji maluu, ikọlu laarin agbẹ atawọn darandaran pẹlu ikolu awọn ileeṣẹ ọlọpaa ati ọgba ẹwọn ni ipinlẹ Imo lẹnu lọwọlọwọ yii.
Oríṣun àwòrán, Presidency
Eekan majẹobajẹ kan lori ọrọ abo lorilẹede Naijiria atawọn agbegbe aṣalẹ ilẹ Afrika, Mallam Kaniru Adamu yannana awọn ipenija marun un ti oga ọlọpaa tuntun, Usman Alkali Baba yoo koju.
1. Mimu atunṣe ba ajọṣepọ laarin olopaa ati araalu
Ọpọ aigbọraẹniye ati aini igbẹkẹle ninu ọlọpaa lo wa laarin awọn araalu eyi to nii ṣe pẹlu awọn iṣẹlẹ atẹyinwa pẹlu bi awọn ọlọpaa kan ti sẹ fi iya jẹ alaiṣẹ tabi fi ẹtọ araalu dun wọn at'awọn iwa ritẹ ẹtọ araalu mọlẹ.
Ọga ọlọpaa tuntun yii gbọdọ gbe igbesẹ to loorin lori mimu.atunṣe ba eyi.
O gbọdọ gbe igbesẹ atunto to yanranti laarin ileesẹ ọlọpaa ki araalu lee mọ pe omi tuntun ti ru ẹja tu tun ti wọ inu rẹ.
Bi a ko ba ni gbagbe iwode EndSARS to waye lọdun to kọja ninu eyi tawọn ọmọ orilẹede Naijiria, paapaajulọ awọn ọdọ ti tu sita lati fi ẹhonu wọn han lori iwa familete n tutọ tawọn ọlpọpaa kan n hu.
Oríṣun àwòrán, Presidency
2. Bakan naa lo tun gbọdọ mojuto igbayegbadun awọn ọlọpaa abẹ rẹ paapaa lori owo oṣu wọn, ayika ti wọn ti n ṣiṣẹ, awọn owo ajẹmọnu gbogbo to tọ si wọn nitori nnkan o ṣe ẹnure fawọn ọlọpaa.
Ọpọ si n woo pe oṣeese ko jẹ idi ti pupọ ninu wọn fin hu iwa kotọ kaakiri.
Bi a ba fẹ ki ọlọpaa o duro daadaa, igbeaye wọn naa gbọdọ duro daadaa.
3. Ipese awọn ohun ija to ku oju iwọn.
O gbọdọ ṣe amulo ẹdawo idagbasoke ileeṣẹ ọlọpaa, Government'sTrust fund lati fi pese awọn ohun ija to yẹ.fawọn ọlọpaa lati fi ṣe iṣẹ wọn bi o ti tọ ati bo ti yẹ.
4. Dida iyi ọlọpaa pada.
Yoo ni lati ji giri ṣiṣẹ si dida ogo ati ọla iṣẹ ọlọpaa laorilẹede Naijiria pada.
Eyi yoo lee mu ki wọn le ṣe iṣẹ wọn ni ibamu pẹlu ilakalẹ iwe ofin orilẹede Naijiria ki wọn si lee pese abo to yẹ labẹle.
Lọwọ ti a wa bayii, eniyan fẹrẹ lee sọ pe awọn ologun lo n ṣe.iṣẹ ọlọpa lorilẹede Naijiria bayii.
Nitoeinaa, ọga agba tuntun fun ileeṣẹ ọlọpaa ni Naijiria gbọdọ da ogo ati ọla pada si iṣẹ ọlọpaa lẹyẹ o ṣọka.
Eyi ni yoo fun ijọba ni ifọkanbalẹ lati da wọn da iṣẹ abo abẹle laipe awọn ṣọja sii.
'Bí ojú ọ̀nà agbàrá òjò tí ijọba ṣe n'IIorin ṣe ń pa àwọn ọmọ iléèwé wa rèé! Ẹ sàánú wa'
5. Gbigba ọpọlọpọ eniyan si iṣẹ ọlọpaa.
Ọga ọlọpaa tuntun, Usman Alkali Baba gbọdọ rii daju pe iye ọlọpaa to to lati mojuto abo Naijiria ni wọn gba sí iṣẹ.
Nitori ọpọlọpọ ileeṣẹ alaabo lo n ṣe awọn iṣẹ to fara pẹ iṣẹ ọlọpaa bii ajọ ẹṣọ oju popo ati ajọ abo ara ẹni labo ilu (civil defence) pẹlu.
Nitorinaa, ipenija kan to tun wa fun un ni lati wa ọna ati mu ki ajọṣepọ to dan mọran waye laarin awọn ẹka ileeṣẹ alaabo wọnyi.
Lakotan, Mallam Kabiru Adamu ṣalaye pe bi awọn ileeṣẹ alabo wọnyi ba lee pa dukuu aarin wọn ti si ẹgbẹ kan naa, ki wọn si fọwọsowọpọ, ohun ija nla ni iṣọkan wọn yoo jẹ lati koju awọn ipenija abo lorilẹede Naijiria.
National Sports Festival: Ìjọba àpapọ̀ ní kò sí ohun tó jọ pé ìdíje náà yóò párí l'Ọ́jọ́bọ̀
Oríṣun àwòrán, Twitter/National Sports Festival
Ijọba apapọ ti sọ pe idije oriṣiiriṣii ere idaraya, National Sports Festival to n lọ lọwọ nipinlẹ Edo ko ni wa sopin lojiji lonii Ọjọbọ mọ.
Ọrọ yii jade lẹyin ti igbimọ abẹnu lori idije naa, LOC ti kọkọ kede pe idije naa yoo pari lọsan Ọjọbọ nitori aisowo.
Ṣugbọn igbakeji oludari ọrọ iroyin ni ileeṣẹ ijọba to n ri si ọrọ ere idaraya ati idagbasoke awọn ọdọ, Ramon Balogun lo fidi ọrọ naa mulẹ ninu atẹjade to fi sita l'Ọjọbọ.
O ṣalaye ninu atẹjade ọhun pe ẹka ijọba to n ṣakoso ere idaraya ati ajọ MOC to n ṣiṣẹ lori agbekalẹ idije naa ko gbọ ohun kan nipa ọrọ ti igbimọ LOC ipinlẹ Edo sọ pe idije naa ko ni le tẹsiwaju mọ.
Atẹjade naa ṣalaye pe ko si ipade kankan tabi apero kan lori ati da idije naa duro.
Ọgbẹni Balogun sọ pe Minisita ere idaraya, Sunday Dare, akọwe agba ileeṣẹ to n ri si ọrọ ere idaraya atawọn lọgalọga lo wa ni Benin fun idije National Sports Festival.
O ṣalaye pe ojuṣe ipinlẹ Edo tabi igbimọ LOC ni lati fi to wọn leti ti ipenija kan tabi omiran ba wa lori idije to n lọ lọwọ.
Igbakeji oludari ọrọ iroyin ni ileeṣẹ ijọba to n ri si ọrọ ere idaraya ati idagbasoke awọn ọdọ tun sọ pe ipinlẹ Edo tiẹ beere iranwọ owo lori ati gbalejo idije ọhun lẹyin ti ijọba sun un siwaju nitori ajakalẹ arun covid-19.
Ọgbẹni Balogun ni ileeṣẹ ijọba to n ri si ere idaraya ti gbe ọrọ naa de iwaju ijọba apapọ, o si yẹ ki owo iranwọ naa jade laipẹ.
Ẹwẹ, alakoso ọrọ iroyin lori idije National Sports Festival to n lọ lọwọ nipinlẹ Edo, Ebomhiana Musa lo sọ lalẹ Ọjọru pe igbesẹ lati da idije naa duro waye nibi ipade ti igbimọ LOC ṣe eleyii ti igbakeji gomina ipinlẹ Edo, Philip Shaibu wa nibẹ.
O sọ pe igbimọ LOC gbe igbesẹ yii nitori ijọba apapọ ko tii mu ileri iranwọ owo to ṣe fun ipinlẹ Edo ṣẹ lẹyin ti wọn ti kọkọ sun idije naa siwaju tẹlẹ.
O kere tan ẹgbẹrun mẹjọ awọn elere idaraya lo n kopa ninu idije National Sports Festival to n lọ lọwọ nipinlẹ Edo.
Adekunle Ajasin lecturer: Ó jọ bí ẹni pé ṣe ni alàgbà Olatunde Adegbuyi fọwọ́ rọrí kú - Iléeṣẹ́ ọlọ́pàá Ondo
Ileeṣẹ ọlọpaa ipinlẹ Ondo ti sọ pe iwadii ti bẹrẹ lori iku to pa olukọ fasiti Adekunle Ajasin tẹlẹ, Ọjọgbọn Olatunde Adegbuyi, ti wọn ba oku rẹ ninu ọkọ rẹ.
Alukoro ileeṣẹ naa nipinlẹ Ondo, Tee-Leo Ikoro lo fidi ọrọ naa mule fun BBC Yoruba.
Ikoro sọ pe lootọ ni awọn ọlọpaa le fidi rẹ mulẹ pe ọkunrin naa ku sinu ọkọ rẹ niluu Akungba-Akoko.
"O ni ""nigba ti awọn ọlọpaa de ibi ti iṣẹlẹ naa ti ṣẹlẹ, wọn rii pe o ti ku sinu ọkọ ayọkẹlẹ rẹ."""
Lẹyin ti wọn rii ni wọn si gbe oku naa lọ sile iwosan, ko si ami kankan lara rẹ pe boya ṣe ni wọn pa oloogbe ọhun.
Gẹgẹ bi alukoro ileeṣẹ naa ṣe sọ, awọn ko tii le sọ ohun to ṣokunfa iku ọkunrin naa titi di igba ti awọn dokita yoo fi esi iwadii ti wọn n ṣe lede ṣugbọn o jọ bi ẹni pe ejo ko lọwọ ninu iku rẹ.
Ọpọ ẹbi, ọrẹ, atawọn akẹkọọ oloogbe naa nigba kan ri lo ti bẹrẹ si n kẹdun iku rẹ.
Lara awọn eeyan naa ni Alade Olugbenga to sọ pe oun maa n gbadun kilaasi oloogbe naa ni ẹka imọ Geology lasiko ti oun jẹ akẹkọọ labẹ rẹ.
O ni ko si igba ti oun kii gbadun kilaasi rẹ lati igba ti oun ti wa ni ipele kinni titi de ipele kẹrin ni fasiti ọhun.
Oríṣun àwòrán, @globalextra
Wọn ti ri oku olukọ fasiti Adekunle Ajasin, AAUA, tẹlẹri kan, Olatunde Adegbuyi ninu ọkọ rẹ niluu Akungba-Akoko.
Awọn to ri oloogbe naa, to ti fi igba kan jẹ olukọ ni ẹka imọ Earth Science ko to di oloogbe sọ pe alaafia lo wa ki iṣẹlẹ na to waye.
Iroyin ni wọn ri oku oloogbe ọhun ninu ọkọ ayọkẹlẹ rẹ lagbegbe Permanent Site niluu Akungba.
"Ẹnikan ti ọrọ naa ṣoju rẹ sọ fun awọn akọroyin pe ""eeyan kan to n kọja lọ lo ri okunrin naa ninu ọkọ rẹ to dori kodo lai mi ara."""
Ẹni naa lo ke gbajare si awọn eeyan adugbo ki wọn ti ri pe o ti dakẹ.
'Òde ìnáwó làwọn èèyàn ma ń rò bí wọ́n bá rí Ankara, ìgbà tí wọ́n rí i lára àga tí mo ṣe, ẹnu wọn ò padé mọ́'
Ko ṣeni to tii le sọ ohun to ṣokunfa iku oloogbe naa titi di akoko ti a fi n ko iryin yii jọ.
Alukoro fasiti Adekunle Ajasin, Victor Askinpelumi lo fidi iroyin naa mulẹ fun BBC Yoruba.
Ọpọ awọn ololufẹ oloogbe ọhun atawọn to ti fi igba kan jẹ akẹkọọ rẹ lo ti bẹrẹ si n ṣedaro rẹ lori ayelujara.
'Bí ojú ọ̀nà agbàrá òjò tí ijọba ṣe n'IIorin ṣe ń pa àwọn ọmọ iléèwé wa rèé! Ẹ sàánú wa'
Man sets girlfriend ablaze: Saka dáná sun 'ààlè' rẹ̀ tọmọ-tọmọ n'Ibadan, òun nàá tún jóná kú
Oríṣun àwòrán, other
Iroyin kan to tẹ wa lọwọ ni pe ọkunrin kan, Ahmed Saka, ti dana sun ara rẹ ati olulufẹ rẹ nigba kan, Mutiat Oladele ati ọmọ meji nilu Ibadan.
Iroyin sọ pe niṣe ni Saka lọ ọ dana sun ile Arabinrin Mutiat, to jẹ aale rẹ, nitori pe obinrin naa fi opin si ọrọ ifẹ to wa laarin wọn.
A gbọ pe obinrin naa ati meji ninu ọmọ rẹ lo ku nitori iṣẹlẹ naa.
Bakan naa ni iroyin sọ pe ọkunrin naa pada ku, ti awọn ọmọ Mutiat mẹtayooku si di eero ileewosan nitori ifarapa ti wọn ni.
Alẹ Ọjọru ni iṣẹlẹ naa waye ni agbegbe Shogoye, ni Idi-Arẹrẹ, nilu Ibadan.
Akọroyin BBC nilu Ibadan sọ pe lootọ ni iṣẹlẹ naa waye.
Lara iroyin to n lọ ni pe Saka ati Mutiat n yan ara wọn lale ṣaaju iṣẹlẹ yii.
Amọ, Mutiat sọ pe oun ko ṣe mọ, eyi to mi ki Saka o dun kooko pe oun yoo pa ara oun, yoo si tun pa Mutiat.
Gbogbo igbiyanju wa lati ba alukoro ileeṣẹ ọlọpaa ipinlẹ Ọyọ, Olugbenga Fadeyi sọrọ lori iṣẹlẹ naa titi di asiko ti a jabọ iroyin yii, ni ko so eso rere.
Prince Philip, Duke of Edinburgh ti dágbére fáyé lẹ́ni ọdún 99
Arẹmọ Phillip to jẹ ọkọ Ọbabinrin Elizabeth to ti wa lori aisan ti dagbere faye lẹni ọdun mọkandilọgọrun, gẹgẹ bi aafin Buckingham ṣe kede.
"Aafin Buckingham sọ pe: ""Pẹlu ọkan ibanujẹ ni Ọbabinrin fi kede iku ọkọ rẹ, Ọlọlajulọ Phillip to jẹ Duke ti Edinburgh."
Ọlọlajulọ dagbere faye ni wọọrọwọ ni Windsor Castle.
Duke ti Edinburgh, to jẹ ọkọ Ọbabinrin to pẹ laye julọ ninu itan ilẹ Gẹẹsi pada si Windsor lọjọ kẹrindinlogun oṣu Kẹta lati ile iwosan to ti n gba itọju.
Nigba to n sọrọ ni ibugbe rẹ ni Downing Street, olootu ijọba Boris Johnson sọ pe Duke ''jẹ iwuri ninu igbesi aye ọpọ awọn ọdọ''.
"O gbiyanju lati ṣatọna idile ọlọla ilẹ Gẹẹsi lati le ri wi pe ọ jẹ ogunagbongbo  to mu igbeaye alaafia ba awọn eeyan ilẹ naa''
Oríṣun àwòrán, Reuters
Wọn gbe aworan ikede iku Duke siwaju Buckingham Palace
Ẹwẹ, Justin Welby, to jẹ  the Archbishop ilu  Canterbury, sọ pe Duke ko yẹ , bẹẹ ni ko gbo lati gbe bukata awọn ẹlomiran ni pataki dipo tiẹ to si mu ki eyi jẹ awokọṣe igbe aye Kristẹni nipa isin ara ilu''"
Wọn fa aṣia iwaju Buckingham Palace wa si aarin ti wọn si gbe aamin ikede siwaju ẹnu ọna aafin naa lẹyin ikede iku Arẹmọ.
Niṣe lawọn eeyan gbe ododo orisirisi wa siwaju aafin ni idaro iku rẹ ti ọgọrọ eeyan naa si kan si aafin Windsor lati ṣe ikẹdun ẹni to lọ.
Oríṣun àwòrán, Reuters
Awọn eeyan gbe ododo ikẹdun siwaju Buckingham Palace
Akọroyin BBC, Nicholas Witchel sọ pe o jẹ ''asiko ibanujẹ ọkan forileeede naa'' paapa julọ fun Ọmọbabinrin to padanu ọkọ rẹ ti wọn jijọ ti wa papọ lati nkan bi mẹtalelaadọrin-pupọ wa ni ko tilẹ wa laye pẹ to asiko yi''
"O ni Arẹmọ  Philip ti ""ko ipa ribiribi ninu aṣeyọri ọmọbabinrin lori itẹ'' to si ṣe apejuwe Arẹmọ gẹgẹ bi ''ẹni ti ko mikan ninu igbagbọ pataki iṣẹ ti ọmọbabinrin n ṣe to si gbaruku ti digbi''"
"O fi kun pe ""Pataki idurosinsin ibaṣepọ awọn mejeeji ati igbeyawo wọn lo jẹ ki ọmọbabinrin ṣe aṣeyọri to ṣe lori oye''"
Oríṣun àwòrán,  Tim Graham/PA
O le ni ọgọta ọdun ti Duke fi wa lẹgbẹ ọmọbabinrin gẹgẹ bi ọkọ rẹ eyi to mu jẹ ọkọ ọmọbabinrin to pẹ laye julọ lọdun 2009
Arẹmọ fẹ Ọmọba Elizabeth lọdun 1947, ọdun marun ko to di Ọba oun si ni ọba to pẹ ju ninu itan ilẹ Britain.
Ninu oṣu kẹta, Duke ti Edinburgh kuro ni ileewosan lẹyin odidi oṣu kan fun iwosan.
O n gba itọju latari idamu ọkan to ti n ba finra tẹ́lẹ̀ nileewosan mii ni Londo - St Bartholomew's.
Oríṣun àwòrán, Reuters
Wọn fa aṣia iwaju Buckingham Palace wa si aarin
Aremo Phillip ati Ọbabinrin ni ọmọ mẹrin, ọmọ-mọ mẹjọ ati ọmọ-ọmọ-ọmọ mẹwa.
Akọbi ọmọkunrin wọn, Arẹmọ Whales, Prince Charles ni wọn bi lọdun 1948, lẹyin naa ni wọn bi aburo rẹ obinrin, Ọmọbabinrin Anne, lọdun 1950, Duke ti York, Ọmọba Andrew lọdun 1960 ati Earl ti Wessex, Arẹmọ Edward lọdun 1964.
Wọn bí Arẹmọ Phillip ni Greek island ti Corfu ni ọjọ kẹwa oṣu kẹfa ọdun 1921.
Baba rẹ Arẹmọ Andrew ti Breece ati Denmark jẹ ọmọ ọba kekere ti Ọba George I ti Hellenes.
Benin Bronze sculptures: Ṣọ́ọ̀ṣì Church of England fẹ́ dá ère idẹ Benin méjì padà sí Nàìjíríà
Oríṣun àwòrán, Woolley and Wallis
Ara kii tan nile alara. Adifa fun ile ijọsin Church of England to fẹ da ere idẹ meji ilu Benin pada si Naijiria.
Ṣọọṣi naa ni ẹbun ni wọn fi awọn ere naa ṣe fawọn lorilẹede Naijiria ni bii ogoji ọdun sẹyin.
Church of England wa lara awọn ajọ to fẹ da awọn ere Naijiria ti ilẹ Gẹẹsi gbe lọ si Yuropu pada.
O ti le ni ọgọrun ọdun ọdun ti ilẹ Gẹẹsi fi tipa ko awọn ere yii lati Naijiria lọ si ilẹ Yuropu laye ijọba amunilẹru.
Koda wọn tun ta pupọ lara awọn ere naa sawọn ile iko nkan isẹnbaye si kaakiri ilẹ Yuropu.
Laipẹ yii lawọn alaṣẹ ile iko nkan isẹnbaye si niluu Berlin lorilẹede Germany pinnu lati da ọpọ ere ti gbe lati Naijiria pada.
Ijọba Benin wa lara awọn to gbogun to fija pẹta pẹlu awọn oyinbo akonilẹru nigba ti wọn fẹ ko orilẹede Naijiria lẹrin laye igba naa.
Benin naa si ni ọpọlọpọ nkan isẹnbaye pọ si lati aye atijọ titi di asiko yii.
Ere ilu Benin kan tiẹ wa ti wọn ta ni owo to le ni miliọnu marun naira(5,215,984,000) tii ṣe £10m.
Torí àti ṣe Kòkò irin, bí mo ṣe máa ǹ fara yá iná nìyìí - Amokoko Saki
Hijab Crisis: Elebuibon ní àwọn ẹlẹ́sìn ìbílẹ̀ náà fẹ́ káwọn ọmọ wọn máa wọ ìlẹ̀kẹ̀ lọ sílé ìwé
Oríṣun àwòrán, Instagram/Ifayemi Elebuibon
Araba ilu Osogbo, Oloye Yemi Elebuibon t i sọ pe awọn ẹlẹsin ibilẹ naa fẹ ki awọn ọmọ awọn naa maa wọ ilẹkẹ lọ si ile ẹkọ.
Laipẹ yii ni ija bẹ silẹ niluu Ilorin lori awọn akẹkọọ musulumi tawọn alaṣẹ ileewe girama kristẹni ko gba laaye lati maa wọ Hijaabu wa si ileewe.
Awọn alaṣẹ ileewe naa naa yari pe ilana ẹsin kristẹni lawọn fi da awọn ile ẹkọ ọhun silẹ.
Fun idi eyi, wọn gbagbọ pe ko yẹ ki awọn akẹkọọ musulumi maa wọ hijaabu wa si iru ile ẹkọ bẹẹ.
Amọ, awọn musulumi ni ijọba ipinlẹ Kwara ti gba awọn ile ẹkọ yii lọwọ awọn ijọ kristẹni to dawọn silẹ.
Nitori naa, awọn musulumi sọ pe o yẹ kawọn ọmọ awọn to jẹ akẹkọọ lawọn iru ileewe bẹẹ lanfaani lati maa wọ hijaabu.
Nigba ti o n ba BBC Yoruba sọrọ, Elebuibon ni awọn ẹlẹsin abalaye naa lẹtọ labẹ ofin gẹgẹ bi awọn ẹlẹsin musulumi ati kristẹni.
''Ko lẹtọ ko jẹ pe ki wọn maa sọ fawọn ọmọ oniṣẹṣe pe ki wọn maa bọ ilẹkẹ to wa lọwọ wọn.
Awa o  ni kawọn ọmọ musulumi maa wọ hijaabu, a o ni kawọn ọmọ kristẹni maa mu ilẹkẹ ''Rosary'' ni, ṣugbọn ki wọn jẹ ki awa naa ṣe ti wa.
Ki wọn jẹ ki onifa bọ Ifa, ki ọlọṣun bọ Osun, ki olodu bọ Odu, ki aye ba le dara,''Elebuibon ṣalaye.
Agba babalawo naa fikun ọrọ rẹ gbogbo ẹsin mẹtẹẹta loyẹ ki ijọba fun laaye lati ṣe ẹsin wọn lai ṣegbe fẹni kan.
Elebuibon ni ''ooṣa lo ni gbogbo ilẹkẹ ti a ni nilẹ Yoruba.
Ilẹkẹ otutu ọpọn ni wọn maa n fi dawọn oniṣẹṣe mọ, awọn oni Sango le mu irọkẹ lọwọ.''
Elebuibon ni o jẹ iyalẹnu pe nnkan ti ara wa ni kii wu wa.
Araba ilu Osogbo sọ pe awọn musulumi atawọn kristẹni to bara wọn lori ọrọ wiwọ hijaabu, ai si ifẹ lo n fa iru iṣẹlẹ bẹẹ.
Elebuibon rọ awọn kristẹni ati musulumi papaa julọ niluu Ilorin pe ki wọn lọ wa imọ nipa ẹsin miiran nitori ko yẹ ki ẹsin fa ija rara.
Agba babalawo naa ṣalaye pe awọn oniṣẹṣe yoo gbe aba naa lọ si iwaju ijọba lati ṣe agbekalẹ ofin ti yoo fawọn oniṣẹṣe naa lanfaani lati maa ṣe ẹsin gẹgẹ bi wọn ṣe fẹ.
Has JAMB registration been postponed: Wo ọjọ́ tí ìforúkọsílẹ̀ ìdánwò àṣewọlé JAMB yóò bẹ̀rẹ̀
Oríṣun àwòrán, @KarmaPresh
Ajọ to n ri si idanwo aṣewọle iwe giga ni Naijiria, JAMB, ti kede pe iforukọsilẹ idanwọ aṣewọle si awọn awọn fasiti ọdun 2021 ko ni bẹrẹ lọjọ kẹjọ, oṣu Kẹrin yii.
Ninu ifọrọwerọ pẹlu agbẹnusọ ajọ naa, Fabian Benjamine, o ni JAMB ṣi n ṣe awọn eto kan lọwọ eyii ti ko jẹ ko ṣeeṣẹ lati bẹrẹ iforukọsilẹ naa lọjọ kẹjọ.
"Gẹgẹ bo ṣe sọ fun BBC, ""ohun ti a ṣe ni pe, a gbero lati bẹrẹ iforukọsilẹ naa lọjọ kẹjọ, oṣu Kẹrin, ṣugbọn kii ṣe ikede ti a fi sita niyẹn."""
Benjamine sọ pe ikede ti wọn ba fi lede nikan lo le sọ ni pato akoko ti iforukọsilẹ ọhun yoo bẹrẹ.
O fikun pe awọn n ṣe awọn eto kan lọwọ ti yoo mu ki iforukọsilẹ naa rọrun, awọn ko si tii pari rẹ.
Alukoro ajọ naa ṣo siwaju si pe lara awọn eto tuntun ti wọn ṣẹṣẹ fi kun iforukọsilẹ naa ni nọmba idanimọ NIN.
Torí àti ṣe Kòkò irin, bí mo ṣe máa ǹ fara yá iná nìyìí - Amokoko Saki
O ṣalaye pe nọmba idanimọ NIN ọhun yoo mu ko rọrun fun awọn lati gba awọn alaye nipa awọn to fẹ ṣe idanwo naa lọwọ ijọba apapọ
O ni idi ree ti wọn ko tii ṣe bẹrẹ iforukọsilẹ naa, ki awọn to fẹ forukọsilẹ ma baa maa sa kiri nitori ọrọ NIN.
"Nigba ti akọroyin BBC bere akoko ti iforukọsilẹ naa yoo bẹrẹ ni pato, o fesi pe ""ọsẹ to n bọ ṣe pataki, ko si ohun ti yoo di wa lọwọ lati ma bẹrẹ lọsẹ to n bọ."""
'Bí ojú ọ̀nà agbàrá òjò tí ijọba ṣe n'IIorin ṣe ń pa àwọn ọmọ iléèwé wa rèé! Ẹ sàánú wa'
Prince Phillip: Ìgbé ayé Ọmọba Phillip nínú àwòrán
Wọn bi Duke ti Edinburgh ni Greek island ti Corfu ni ọjọ kẹwa oṣu kẹfa ọdun 1921. Awọn iran rẹ jẹ idile oye lati Denmark, Germany, Russia ati Britain.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Arẹmọ Philip ni ọmọkunrin kanṣoṣo ti Ọmọba Prince Andrew ti Greece ati Ọmọbabinrin Alice ti Battenberg bi.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Arẹmọ bẹrẹ ileewe ni France ni ileewe MacJannet American school ni St Cloud oun si niyi pẹlu awọn akẹgbẹ rẹ nileewe. Ọmọ ọdun meje lo lo lọ gbe pẹlu awọn mọlẹbi rẹẹ Mountbatten ni England, nibi to ti ka ileewe to ṣaaju alakọbẹrẹ.
Oríṣun àwòrán, PA
Oríṣun àwòrán, PA
Oríṣun àwòrán, PA
Nigba ti oun ati Ọmọbabinrin Elizabeth bẹrẹ - July 1947...
Oríṣun àwòrán, PA
Bẹ́ẹ̀ si ni wọn ṣegbeyawo ni ogunjọ oṣu kọkanla ọdun kan naa
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ọbabinrin Elizabeth ati Duke ti Edinburgh lọjọdiẹṣaaju ọjọ to gbọ iroyin pe baba rẹ ti ku
Oríṣun àwòrán, PA
Arẹmọ n ṣe ere idaraya Polo
Oríṣun àwòrán, PA
Arẹmọ tun fẹran ko maa gba bọọlu Cricket
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Arẹmọ Phillip kọwọ rin pẹlu Ọbabinrin Elizabeth lọ si India lọdun 1961.
The duke and Queen had four children, (from left) Edward, Andrew, Anne and Charles, pictured here in the 1960s.
Oríṣun àwòrán, PA
Arẹmọ Phillip pẹlu Ọbabinrin Elizabeth ṣe ibẹwo si oko kan lati ṣe ayẹyẹ igbeyawo wọn
Oríṣun àwòrán, PA
Arẹmọ Phillip ati Ọbabinrin Elizabeth nigbato n ṣe ayẹyẹ ọjọ ibi ọdun mẹẹdọgbọn
Oríṣun àwòrán, PA
Arẹmọ Phillip pẹlu Ọbabinrin Elizabeth
Oríṣun àwòrán, PA
Oṣu kẹjọ ọdun 1979 nigba ti ọmọ ẹgbọn/aburo baba rẹ ku
Oríṣun àwòrán, PA
Arẹmọ fẹran awọn ẹranko ati nkan ti Ọlọrun da pupọ
Oríṣun àwòrán, PA
In 1985 the Duke of Edinburgh was surrounded by his family, including the young princes William and Harry, as they gathered to watch a flypast over Buckingham Palace after Trooping the Colour.
Oríṣun àwòrán, PA
Lọdun 1996 Duke kọwọrin pẹlu aarẹ South African President Nelson Mandela lọ fun yiyan bi ologun awọn ẹlẹṣin lọjọ ibẹwo akọkọ rẹ si Britain.
Oríṣun àwòrán, PA
Arẹmọ Phillip gbaruku ti Ọbabinrin fun o le ni ọgọta ọdun iṣejọba rẹ to fi mọ igba to pe ẹni aadọta ọdun lọdun 2002
Oríṣun àwòrán, PA
Duke ti Edinburgh nibi ami ẹyẹ Duke of Edinburgh
Oríṣun àwòrán, PA
Duke tẹsiwaju lati maa ṣe idije ere ẹṣin koda titi di igba ogbo rẹ. Ọkan ree ni Sandringham lọdun 2005.
Oríṣun àwòrán, AFP
Igbeyawo ọmọ-ọmọ Arẹmọ Phillip, Ọmọba Prince Williams pẹlu Catherine Middleton lọdun 2011.
Oríṣun àwòrán, AFP
Lẹyin oṣu mejila, o fihan pe ṣaka ni ara Duke ti Edinburgh ṣi da
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Arẹmọ Phillip àti ọmọbabinrin Anne lẹyin ti ara Duke ti ya
Oríṣun àwòrán, PA Media
June 2013 ni ṣọọṣi kan ni Westminster Abbey lati ṣe ayẹyẹ iwuye ọgọta ọdun ti Ọbabinrin pe lori oye
Oríṣun àwòrán, PA Media
Lẹyin to ṣi ibudo ọsin ati igbafẹ awọn Erin, Duke ti Edinburgh kede pẹ̀lú atilẹyin Ọbabinrin pe oun ko ni farahan ni eto itagbangba kankan mọ lẹni ọdun marundinlọgọrun to pe
Oríṣun àwòrán, PA Media
Ọbabinrin Elizabeth ati Arẹmọ Phillip
Oríṣun àwòrán, PA Media
Dke ni ọkọ Ọbabinrin to pẹ laye ju ninu itan ilẹ Britain
Prince Philip: Wọ́n yìbọn sókè káàkiri Ilẹ̀ Gẹ́ẹ̀sì láti ṣẹ̀yẹ Duke ti Edinburgh
Oríṣun àwòrán, Reuters
Awọn ọmọogun ikọ ibudo Woolwich Barracks to yin ibọn lasiko igbeyawo Ọbabinrin Elizabeth ati Ọmọbakunrin Philip ni ọdun 1947, ati ni ọdun 1953 to jẹ ọba naa yin ibọn lati ṣe ẹyẹ ikẹyin Duke ti Edinburgh
Ayẹyẹ ṣì ń tẹ̀síwájú fún ìsìnkú ọmọọba Philip tó jẹ́ Duke ti Edinburgh nípa bí wọ́n yóò ṣe yìnbọn sókè kákìkiri ilẹ̀ gẹ̀ẹ́sì, ní Gibralter ati lori ọkọ̀ ìjà ojú omi.
Awọn ikọ ọmọogun wọ ibomu dudu lati yin ibọn ẹyẹ ikẹyin ni Hillsborough.
Ọmọọba Philip, tó jẹ́ ọkọ ọbabinrin ilẹ̀ gẹ̀ẹ̀sí Elizabeth kejì fún ọdún mẹ́tàléláàdọ́rin kú ní ọjọ́ Eti, ọjọ́ kẹsàn, oṣù kẹrin ọdún 2021.
Oríṣun àwòrán, PA Media
Awọn eniyan pejọ lati wo bi wọn ṣe n yin ibọn naa.
Philip ẹni ọdún mọ́kàndínlọ́gọ́rùn ni ó ṣe ìjọba ni inú ìtàn ọba  ilẹ̀ Gẹ̀ẹ̀sí.
Awọn ikọ ọmọọgun to n ṣiṣẹ ninu ile ọba pejọ lati bẹri fun Duke ti Edinburgh pẹlu idake iṣẹju meji.
Àwọn ọmọogun yóò yin ìbọn mọ́kanlélógójì láàrín ìṣẹ́jú kan látimaago mejìlà ọsan ni ìlú London, Edinburgh, Cardiff, àti Belfast, gẹ́gẹ́ bi ilé iṣẹ́ ààbò ilẹ̀ gẹ̀ẹ̀sì ṣe sọ.
Oríṣun àwòrán, EPA
Ni orilẹede Australia, wọn so 'flag' orilẹede naa walẹ lati ṣe ayẹyẹ ikẹyin fun Duke ti Edinburgh.
"Awọn ọmọ ogun ojú omi fún ilé óba to fi mọ HMS Diamond ati HMS Montrose náà yóò yìnbọn ìkíni fún ayẹyẹ Duke to ṣiṣẹ́ gẹ́gẹ́ bi ọmọ ogun ojú omi lásìkò ogun àgbáyé ẹlẹkejì tó sì gba ipò oye gíga ""Lord High Admiral"""
Awọn to n fi òdòdó sí wáju ilé ọba ni Winsdor Castle
Ìbọn yìnyin yìí ni yóò waye loju iworan yin lórí ayélijara tí o si ṣe pàtàkì ki àwọn olùgbé ilẹ̀ gẹ̀ẹ̀sì máa wòó láti ilé.
Prince Philip: Ìsìn ìrántí wáyé fún Duke ti Edinburgh níjọ Canterbury Cathedral
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ayẹyẹ ìsìn ìrántí wáyé lónìí fún Duke ti Edinburgh ní ilé ìjọsin Canterbury Cathedral, bi ilẹ̀ gẹ̀ẹ́sì ṣe wà nínú ọ̀fọ̀ ikú ọmọọba Philip.
Bísọ́ọ̀bù Canterbury Justin Welby, ni wọn ni ó ṣeeṣe ko ṣètò ìsìnkú lọ́jọ́ sátide tó n bọ̀.
Aṣojú ìjọba ilẹ̀ gẹ̀ẹ́sì nígbà kán rí Sir John Mayor, tó jẹ́ ọ̀rẹ́ Duke ní òun ni ìgbágbọ́ pé àwọn ènìyàn yóò gba ọbabinrin láàyè láti ṣọ̀fọ̀.
Nínú ìfọ̀rọ̀wánilẹ́nuwò pẹ̀lú Andrew Marr , ó sàlàyé pé jíjẹ́ olórí ìlú jẹ́ ipo àdáwà fúnra rẹ̀, Duke tó tún jẹ́ aláfọ̀rọ̀lọ̀ rẹ̀ ló tún wá lọ yìí.
Àrẹ̀mọ Phillip padòdà lẹ́ni ọdún 99
Bó tilẹ̀ jẹ́ pé Prince Philip ti lọ síbẹ̀, ọbabinrin kò le gbàgbé rẹ̀ yóò túbọ̀ dàbí pé wọ́n jọ jòkó sẹ́gbẹ́ ará wọn.
Sir John yìí bákan náà ni alábojútó Duke ti Cambridge ati ti Sussex lẹ́yìn ti ìyá wọ́n kú, ó ni òun ni ìgbàgbọ́ pé, àwọn arákùnrin rẹ̀ tókù yóò lo àsìkò yìí, láti fi pari gbogbo aáwọ̀ tó wà láàrín wọn.
Oríṣun àwòrán, PA Media
Eto isinku naa yoo waye ninu ijọ George ni Afin Windsor
Ile ọba ni Ilẹ Gẹẹsi ti fi alakalẹ lede bi etò ìsìnkú ọmọọba Philip tó jẹ́ ọkọ Ọbabirin Elizabeth ẹlẹ́ẹ̀kejì yoo ṣe lọ ni Ọjọ kẹtadinlogun, Osu Kẹrin, ọdun 2021
Ẹni ọdún mọ́kàndílọ́gọ́rùn ní Duke ti Edinburgh, Philip to dagbere fun aye ni Ọjọ kẹsan, Osu Kẹrin, ọdun 2021.
Gbogbo bí ètò òkú yóò ṣe lọ ni wọn ti sọ di mímọ̀ pẹ̀lú ayẹyẹ ránpẹ́ , yàtọ̀ sí irú àyẹyẹ ńla tí wọ́n máa ń ṣe tí ọbá bá kú.
Awọn ẹbi nikan yoo wa ni ibi ayẹyẹ isinku naa, nitori isinku ile ọba ni, kii ṣe ti Ilẹ Gẹẹsi.
Aado mẹta(15:00 BST) ni isinku naa yoo bẹrẹ ti wọn yoo si ṣe afihan rẹ jakejado agbaye ni ori ẹrọ amohunmaworan.
Awọn ẹbi ati ara ni isinku naa yoo safihan akikanju ọkunrin ti ọmọọbakunrin naa jẹ nigba aye rẹ.
Bakan naa ni Ọbabinrin Elizabeth ti buwolu eto isinku naa.
Bi eto isinku naa yoo ṣe lọ niyii;
Kíni ǹkan tó kù báyìí?
Ìjọba Ilẹ̀ Gẹ̀ẹ́sì ti kéde pé àsíá orílẹ̀-èdè náà yóò wá sílẹ̀ ni gbogbo àwọn ilé isẹ́ ìjọba jákèjádò láti aago mẹ́jọ lẹ́yin ọjọ́ keji ìsìnkú.
Oríṣun àwòrán, EPA
Láti buyì fún ọmọọba Philip, àwọn ẹgbẹ́ òṣèlú méjì to gbajúgbajà jùlọ ni ilẹ̀ gẹ̀ẹ̀sí Scotland àti Wales ti dáwọ́ ìpolongo ìbò tí ó yẹ kó wáyé ni oṣù tó n bọ̀ duro.
Ilé aṣòfin  yóò jòkó lọ́jọ́ Ajé láti ṣe ìkíní ìkẹyìn fún Duke ti Edinburgh.
Ètò gbèdékè tí wọ́n gbé lé ará ilú láti maa péjú síbi ti ọ̀pọ̀ ènìyàn to ti wa nilẹ ni wọ́n ti ṣe àwọn àtúnṣe sí ni àwọn ọjọ́ tó kù fẹ̀r kí ayẹyé ètò ìsìnkú wáyé àti ni àsìkò ayẹyẹ ìsìkú gan.
Wọ́n ti gba àwọn ará ìlú nímọ̀ràn láti má pejú síbi ayẹyé ìsìnkú náà gẹ́gẹ́ bi àjọ tó n mójú to ètò ààbò ṣe sọ.
Bákan náà ni ilé ọba ti rọ àwọn ará ìlú láti ma fi òdòdó kankan sí ilé ọba, bí kò ṣe ki wọ́n lọ má a fún àwọn ọmọ aláìní ni ẹ̀bùn lórúkọ Duke ti Edinburgh. Wọ́n fi kun pé wọ́n le fi ìwé ìkíni wọ́n ránṣe lórí  iwé ìkíni to wa lórí ayélujára
"Gẹ́gẹ́ bi ètò ti ó yé kí ó wáyé lẹ́yìn ikú ọmọọba Duke èyí ti àpèjẹ́ rẹ̀ jẹ́ ""Forth Bridge"" ẹgbẹgbẹrun àwọn ènìyàn ló yé kí ó péjú sí London àti Winsdor, tí àwọn míràn pẹ̀lú yóò wá ọ̀ọ̀kán dúró sí kí wọ́n le ni ànfàni láti wo bí àwọn ológun yóò ṣe gbé òkú."
Ọgọ́rùn àwọn ọmọ ogun pẹ̀lú ni yoo tò sí òpópónà láti bu ọlá fún Duke.
Sùgbọ́n láti ìgbà tí ọ̀rọ̀ àjàkálẹ̀ ààrùn yìí ti bẹ̀rẹ̀, àwọn tó n ṣagbátẹrù ètò náà tí n ṣiṣẹ́ lórí  ọ̀nà bi kò 'se ni sí èrò púpọ̀ níbi ayhẹyẹ òkú náà.
Ní báyìí Ọbabinrin ń rọ bi àyípada yóò ṣe bá ètò ayẹyẹ ìsìnkú pàápàá jùlọ lórí ìkìlọ ìjọba àti ètò ìjìnà síra ẹni.
Ìgbàgbọ́ ni pé wọ́n yóò gbé òkú ọmọọba Philip sí ibusọ̀ kékeré lọ sí St George's Chapel fún ètò ìsìnkú lọ́jọ́ ìsìnkú.
OPC: Àwọn àgbà ilẹ̀ Yoruba ní OPC àti Boko Haram kò jọra, kí wọn má fi ewúrẹ́ wé ẹkùn
Oríṣun àwòrán, OPC
Awọn agbagba ilẹ Yoruba kan ti sọ pe, bi ẹni fi ewurẹ we ẹkun ni ki eeyan maa fi ẹgbẹ OPC we ẹgbẹ agbesumọmi Boko Haram jẹ, nitori wọn ko jọ ara wọn.
Ṣaaju ni olórí àwọn ọmọ ogun Naijiria tẹlẹ, Abdulrahman Dambazau ti kọkọ sọ pe ọkan naa ni ẹgbẹ IPOB, OPC ati Boko Haram nitori afojusun awọn ẹgbẹ naa ni lati da ogun abẹle silẹ ni Naijiria.
Nigba to n ba BBC Yoruba sọrọ, Ọmọwe Taye Ayorinde to jẹ alaga ẹgbẹ Yoruba World Assembly sọ pe, agbesumọmi gan ni Dambazau funra rẹ fun afiwe to ṣe ninu ọrọ to sọ.
Ayorinde ni ko yẹ ki ẹni to jẹ ologun maa fi OPC we Boko Haram nitori awọn eeyan to n bọwọ fun ofin ni awọn ọmọ ẹgbẹ OPC jẹ.
"O ni ""Nigba miran eeyan a maa ba ọrọ agọ nibi ti yoo ti ro pe oun yoo ba ọrọ ọgbọn, bawo ni eeyan ṣe maa fi ewurẹ we ẹkun?"""
Oríṣun àwòrán, Taye Ayorinde
Awọn ọmọ wa lo wa ninu ẹgbẹ OPC, ṣugbọn ni ti Boko Haram, awọn Dambazau yii lo mọ awọn to wa nibẹ nitori awọn naa lo lo wọn lasiko eto idibo.
Ayorinde ṣalaye pe ko mu ọgbọn dani ki eeyan maa fi OPC to n ṣiṣẹ abo we awọn Boko Haram to n wu iwa ipaniyan ati ijinigbe.
Ẹwẹ, Alagba Sehinde Arogbofa naa da si ọrọ ọhun nigba to sọ fun BBC pe, iyatọ gedegbe lo wa laarin ẹgbẹ OPC ati Boko Haram.
O ni ilu Kano ni ẹni to da ikọ agbesumọmi Boko Haram ti bẹrẹ, ki wọn to le lọ ilu Maiduguri nibi to ti gbilẹ.
Oríṣun àwòrán, Sehinde Arogbofa
Arogbofa ṣalaye pe, Boko Haram lodi si iwe kika ati iwa ọlaju, ṣugbọn OPC ko ṣe bẹẹ, niṣe ni wọn n ja fun igbala awọn ti wọn n fi iya jẹ lawujọ.
O tẹsiwaju pe iwa jagidijagan pẹlu ibọn ni awọn Boko Haram fi n ṣọṣẹ, ko si ṣe ṣafiwe awọn OPC to jẹ pe awọn ọmọwe lo da ẹgbẹ ti wọn silẹ.
"Alagba naa fi kun pe ""Boko Haram atawọn ti ko fẹ itẹsiwaju Naijiria lo jọ n ṣiṣẹ papọ, ṣugbọn niṣe ni OPC n wa ilọsiwaju Naijiria."""
"Arogbofa pari ọrọ rẹ pe ""awọn ẹlẹsin Musulumi lo kun ẹgbẹ Boko Haram nigba ti OPC ko ni nnkan ṣe pẹlu ẹsin, idi ree ti awọn Musuli, Kristeni atawọn ẹlẹsin abalaye ṣe wa nibẹ."""
Female Car Painter: Èmi ní obìnrin àkọ́kọ́ tí yóò máa ṣiṣẹ́ akunmọ́tò ní Ibadan
"O ni ""eyii ti ẹ ni Dambazau sọ yẹn kii ṣe ara ẹ o, ko sọ daa o, ẹ o le fi aja we ẹkun o."""
Ẹwẹ, onimọ nipa eto abo kan, Arákùnrin Akin Adeyi sọ pe Dambazau ko ni imọ lo jẹ ko maa fi OPC we Boko Haram nitori wọn jina si ara wọn.
Gẹgẹ bo ṣe sọ, ara iṣoro ti Naijiria ni niyẹn nitori wọn ko sọ oju abẹ niko.
Adeyi sọ pe idojuti nla ni ọrọ naa jẹ fun Dambazu gẹgẹ bii ologun ati ipo to di mu ni Naijiria nitori ibi ti OPC ati Boko Haram ti n bọ ati iwa wọn kii ṣe ọkan naa.
Oríṣun àwòrán, United States Africa Command
Ẹgbẹ awọn dokita lorileede Naijira ti so iyanṣẹlodi ti wọn gunle rọ lẹyin ọjọ mẹwaa.
Dokita  Uyilawa Okhuaihesuyi, tii se aarẹ ẹgbẹ awọn Dokita lo fidi ọrọ yi mulẹ fawọn akọroyin.
O ni ''ni nkan bi wakati kan sẹyin (lọjọ Abamẹta) la so iyanṣẹlodi naa rọ ni idahun si ẹbẹ awọn ọmọ Naijiria.''
O tẹsiwaju pe ''ijọba ti dahun sawọn ibeere kọọkan ninu ohun taa beere lọdọ wọn''
Ṣaaju ni ijọba Naijriia ti buwọlu iwe adehun kan pẹlu awọn ẹgbẹ dokita Naijira-igba keji ree ti wọn yoo buwlu iwe adehun laarin  ọsẹ meji.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Awọn Dokita ati awọn osise ilera miran ko gba dede iye owo kannáà.
Ninu ifọrọwanilẹnuwo kan, Minisita feto igbaniṣiṣẹ ni Naijiria, Dokita Chris Ngige sọ pe ''ipade taa ṣe lọjọ Abameta waye ki a baa le ṣe atunse si adehun taa kọkọ buwọlu pẹlu awọn Dokita''
O ni nitori eleyi awọn ti gbe igbimọ ẹlẹni marun un kan kalẹ, ti yoo mojuto awọn oṣiṣẹ ti ọrọ yii kan, taa si fun wọn ni ọjọ mẹta lati gbe orukọ wọn jade.
Lọjọ kinni oṣu Kẹrin lawọn ẹgbẹ dokita wọn yi gunle iyanṣẹlodi.
Cattle Ranching: Ẹ wo Fulani darandaran to tako àṣà dída màálù kiri lójú pópó
Ohun ti ẹgbẹ naa n beere lọwọ ijọba pọ, to fi mọ pe ki ijọba san owo oṣu ti wọn jẹ awọn dokita lai da ẹnikankan si.
Wọn tun beere fun afikun ida aadọta lori iye owo ajẹmọnu gbogbo oṣiṣẹ ilera, to fi mọ sisan gbese owo moriya iṣẹ Covid-19 fawọn to n ṣiṣẹ ni ile iwosan ipinlẹ to fi mọ awọn nkan miran.
Oduduwa Nation: Kunle Olajide ní kìí ṣe gbogbo ọmọ Yorùbá ló fara mọ ìyapa Nàíjíríà
Oríṣun àwòrán, sundayigboho_usa_fans/Instagram
Ọkan pataki lara ẹgbẹ igbimọ agbaagba Yoruba, YCE, Dokita Kunle Olajide ti koro oju si bi ọga ileẹkọ girama mẹta se faaye gba ipolongo idasilẹ orilẹ-ede Oduduwa nileewe wọn.
Olajide ni o yẹ ki ẹnikẹni to fẹ ẹ lọ bá àwọn akẹkọọ sọrọ ninu ọgba ileẹkọ wọn, gba àṣẹ lọwọ ijọba ipinlẹ to n sakoso nipinlẹ naa.
O ni nkan ti awọn Ọga agba ileewe mẹtẹẹta naa ṣe ko boju mu to.
Awọn ọmọ keekeeke ni awọn akẹkọọ naa, ko yẹ ki a ma a gbe ìtọ́ni lori titako ijọba de ọdọ wọn rara. Ko gbọdọ ri bẹ ẹ.
O ni oun faramọ nkan ti ijọba ipinlẹ Osun ṣe fun awọn ọga ileewe naa.
Oríṣun àwòrán, sundayigboho_usa_fans/Instagram
O ṣalaye pe ohun gbogbo ti awọn eeyan to n polongo idasilẹ orilẹ-ede Yoruba ba se gbọdọ ba ofin Naijiria mu, nitori pe abẹ isakoso Naijiria ni wọn si wa.
O ni ẹnikẹni ko ti i le fi ọwọ sọya pe gbogbo ọmọ Yoruba lo fẹ ẹ ya kuro lara Naijiria.
"Awọn ọmọ wa si wa ni ijọba, a ko ṣa le sọ pe wọn kii ṣe ọmọ wa mọ. A ni lati fi suuru ṣe nkan.
Slain Ekiti Police woman: Ìyá rẹ̀ ní àìrìṣẹ́ṣe ló mú kí Bukola Olawoye gba iṣẹ́ ọlọ́pàá
Se bi Yemi Osinbajo, tii se ọmọ Yoruba si ni gbakeji aarẹ, se a wa ni kii se ọmọ wa mọ nitori pe a fẹ gba orilẹede Oduduwa."
Dokita Olajide wa rọ awọn eeyan to n polongo fun iyapa orilẹede Naijiria naa lati mase maa tẹ ofin loju nitori ta ba n sunkun, a maa n riran.
Ijọba ipinlẹ Osun ti ṣalaye idi ti wọn fi ni ki awọn adari ileewe girama mẹta lọ rọọkun nile nitori pe wọn jẹ kawọn to n polongo idasilẹ orileede Oduduwa wọ ileewe lai gbaṣẹ.
Kọmisana feto ẹkọ ni ipinlẹ naa, Folorosunso  Oladoyin Bamiṣaiye ṣalaye fun BBC Yoruba pe, ṣe lawọn ọga ileẹkọ naa kuna ninu ojuṣe wọn nipa didaabo bo awọn ọmọ to wa ni ikapa wọn.
O ni gẹgẹ bi eleto ẹkọ, awọn ko ni atako si ki awọn eeyan sọ ero ọkan wọn ṣugbọn nigba ti eleyi ba ti n tasẹ agẹrẹ si ẹtọ ati aabo awọn akẹkọọ, o di dandan kawọn gbe igbesẹ.
Bamiṣaiye ni ojuṣe awọn oludari ileewe ni lati fi to awọn ọga wọn leti, yala ki awọn to wọ inu ileewe to wọle tabi kete ti wọn ba ti jade nibẹ.
''A gbọ lootọ pe awọn to wọ awọn ileewe wọnyi dira wa ṣugbọn bi wọn ba tiẹ fi tipa mu awọn oludari yii nigba ti wọn wọle, ṣe ko yẹ ki wọn sọ bun wa gbọ nigba ti wọn lọ tan?''
Oríṣun àwòrán, Google
''Ti apa ọga agba ile ẹkọ ko ba ka wọn lati da wọn duro, o le sọ fawọn akẹkọọ pe ki wọn tuka maa lọ si ile wọn. Amọ titi ti a fi kọ lẹta si awọn oludari ileẹkọ yii lọjọ keji, wọn ko sọ nkankan fun wa''
Kọmisana naa fi kun ọrọ rẹ pe, awọn to wa ni Abuja ati Amẹrika lo kọkọ fi fidio bawọn olupolongo yii ti ṣe wọ inu ileewe ranṣẹ si oun.
Nigba ti BBC beere lọwọ rẹ pe, ki ni igbesẹ ti ijọba gbe lati dẹkun iru iṣẹlẹ yii lọjọ iwaju, o ni awọn ti fi iwe ikilọ ranṣẹ sawọn oludari ile ẹkọ to ku pe, bi wọn ba faye gba ẹnikẹni ti ko gbasẹ lati wọ ileewe, wọn yoo foju wina ofin.
Egbejila Fish Village: Àwọn ọlọ́sìn ẹja ní àwọn fi iṣẹ́ báńkì sílẹ̀ wá ṣe ọ̀sìn ẹja ni
'Nibi ọrọ de yii, ipe fun ituka orileede ni wọn n kigbe rẹ, bi adari ileewe kankan ba si faye gba wọn tabi ẹlọmiran wọle lai gba iyọnda, ajọ ọtẹlẹmuyẹ DSS ni wọn yoo ba lẹjọ''
Ijọba ipinlẹ Osun ti pàṣẹ fun awọn ọga ileewe girama mẹta, lati fi isẹ silẹ fun igba diẹ.
Ẹsun ti ijọba fi kan àwọn eniyan naa ni pe, wọn faaye gba ẹgbẹ kan to n polongo idasilẹ orilẹ-ede Oduduwa, lati ba awọn akẹkọọ wọn sọrọ.
Awọn iwe iroyin abẹle sọ pe ni ibẹrẹ ọsẹ yii, ni awọn eeyan kan lọ si awọn ileewe mẹta ni ilu Irẹsi, nijọba ibilẹ Boluwaduro, nipinlẹ Osun, lati ba awọn akẹkọọ ibẹ sọrọ.
Iroyin sọ pe ẹgbẹ naa sọ fun awọn akẹkọọ naa pe, ki wọn o kọ orilẹ-ede Naijiria silẹ, ki wọn o si beere fun orilẹ-ede Oduduwa.
Sugbọn ṣa, ijọba ipinlẹ Osun ti sọ pe oun ko mọ nipa abẹwo awọn eniyan naa.
Oríṣun àwòrán, Koiki Media
Kọmisana fun eto ẹkọ nipinlẹ Osun, Ọgbẹni Folorunsho Bamisayemi sọ ninu atẹjade kan pe, isejọba Gomina Gboyega Oyetola ko mọ nipa abẹwo naa.
Bakan naa lo ni oun ko fun ẹgbẹ naa ni àṣẹ lati ba awọn akẹkọọ ileewe ijọba sọrọ nipa iyapa Naijiria.
"Ọgbẹni Bamisayemi sọ pe ""ijọba ipinlẹ Osun ko fi igba kankan fi ọwọ si ki ẹgbẹ kankan o ba awọn akẹkọọ ileewe rẹ sọrọ nipa ọrọ ti 'a mọ pe o le fa wahala, to si le ba isọkan jẹ ni orilẹ-ede wa""."
"Gẹgẹ bi orilẹ-ede Naijiria, a ni igbagbọ ninu àlá rẹ. A si rọ gbogbo ọmọ Naijiria, lati gbadura, ki wọn si ṣiṣẹ́ fun iduro ṣinṣin rẹ.
Oríṣun àwòrán, Koiki Media
Ki awọn Ọga ileewe to gba iru ẹgbẹ naa laaye ninu ọgba ileewe wa o mura lati doju kọ ijiya fun nkan ti wọn ṣe."
Bakan naa ninu ọrọ ti ẹ naa, Oludamọran pataki fun Gomina Oyetola lori eto ẹkọ, Ọgbẹni Jamiu Olawumi sọ pe, o ṣeni laanu pe awọn eeyan buruku kan n lọ kaakiri, lati ma gbin èròkerò si ọkan àwọn ọmọde nitori wọn mọ pe wọn ko ti i gbọn daadaa.
O kilọ fun iru awọn ẹgbẹ́ bẹ ẹ lati jina si awọn ileewe nipinlẹ Ọsun.
Bí Oduduwa Republic bá bẹ̀rẹ̀, a ò ní ṣe aburú fún àwọn tó takò wá, ìlànà ààtẹ̀lé rèé - Banji Akintoye
Oríṣun àwòrán, thecitypulsenews
Awọn olori ẹya Yoruba kan ti n fesi si ọrọ to jade lati ọdọ awọn ẹgbẹ awọn eeyan apa ariwa Naijiria kan, to ni pe awọn yọnu si atunto Naijiria ṣugbọn awọn ko nifẹ si pinpin ipo aarẹ lẹlẹkunjẹkun, ta mọ si zoning.
Oloye Olusola Ebiseni, gẹgẹ bi iwe iroyin Vanguard ti ṣe sọ, wa lara awọn olori Yoruba to sọ ero ọkan wan nipa ọrọ to jade lati ọdọ awọn olori eeyan apa oke ọya.
Ebiseni ni n ṣe lawọn ọmọ Yoruba dorikodo bii adan, tawọn n wo iṣe ẹyẹ awọn ẹgbẹ ariwa yii nitori wọn ko ṣẹṣẹ maa sọ iru ọrọ bayi.
Ninu ọrọ tirẹ alagba Samuel Adeleye to jẹ aarẹ tẹlẹ ri fun ẹgbẹ agbaagba Yoruba, YCE sọ pe, to ba ṣe pe lootọ lawọn ẹgbẹ eeyan Ariwa fẹ atunto  ni, ''wọn yoo ri iyọnu ara ilu''.
Afẹnifẹre ni ọrọ atunto lawọ́n tori ẹ yan Atiku laayo
Bakan naa ni  ọmọwe Yemi Faroumbi, to figba kan jẹ aṣoju Naijiria si Philippines ni, ko si aarẹ kankan to le ṣe aṣeyọri pẹlu bi iwe ofin Naijiria ti ṣe wa yii.
Lẹnu ọjọ mẹta yii lawọn ẹya Yoruba ti n lewaju ipe lati se atunto Naijiria lọna ti agbara yoo fi dinku lọwọ ijọba apapọ, lọ si ọdọ ijọba ipinlẹ kọọkan.
Pẹlu bẹẹ, ọpọ ti n sọ pe ki awọn ijọba ipinlẹ naa lagbara lori ileeṣẹ ọlọpaa to wa labẹ akoso ijọba apapọ.
Àrẹ̀mọ Phillip padòdà lẹ́ni ọdún 99
Lakotan, ohun tawọn to n sọrọ atunto yii n fẹ, ni ki ijọba apapọ ju ọwọ awọn ojuṣe kọọkan silẹ fun ijọba ipinlẹ, lati le pa owo wọle si bo tilẹ jẹ pe wọn yoo maa san owo ori fun ijọba apapọ.
Alaafin: Ọba Adeyemi kọ̀ ilé alárinrin méjì fún Ayaba Folashade ati Omowunmi
Oríṣun àwòrán, olori_omoh_one/Instagram
O ti foju han gbangba pe kii se olori kansoso ni Alaafin tilu Oyo, Ọba Lamidi Olayiwola Adeyemi Kẹta fun ni ẹbun ile alarinrin.
Ọjọ Aiku la mu iroyin wa fun yin pe Kabiyesi naa fun Olori Memunat Omowunmi ni ẹbun ile alarinrin kan nilu Ibadan.
Amọ olori keji, Aishat Folasade toun naa gba ẹbun ile alarinrin mii naa ti kede sita loju opo ibanidọrẹpọ rẹ pe oriire naa kan oun.
Nigba to n sọrọ loju opo Instagram rẹ, Olori Folasade n dupẹ lọwọ Ọlọrun fun ẹbun naa, to si n ki ara rẹ ku oriire ati ibukun to ri gba.
Oríṣun àwòrán, ayaba_folashade
"Lotitọ, aafin suuru ni ile yii. Ọlọrun dara si mi, mo si n dupẹ lọwọ Kabiyesi pe o jẹ ọkọ daradara.
Mo ki ara mi ku oriire, mo si gba adura pe ki Ọlọrun tubọ maa bukun fun mi siwaju si.
Emi ni iya onile tuntun lọwọlọwọ laarin igboro."
Iroyin ohun to n lọ fi ye ni pe kori-kosun ni Olori Folashade ati Olori Omowunmi, ti ajọsepọ to dan mọran si wa ni aarin awọn mejeeji.
Ankoo asọ ni wọn maa n wọ lọ sode nigba gbogbo, ti wọn si maa n dijọ ya aworan papọ lori ayelujara lati fi han araye pe ọrẹ gidi ni awọn laafin Oyo.
Bakan naa ni Olori Omowunmi fidi rẹ mulẹ pe kii se oun nikan ni oun gba ẹbun ile alarinrin yii, nitori ọrọ to sẹsẹ kọ soju opo Instagram rẹ lo sisọ loju eyi.
Olori Omowunmi mi oun ati Olori Folashade ko sẹsẹ maa pe ara awọn ni oloriire julọ laarin awọn obinrin.
Female Car Painter: Èmi ní obìnrin àkọ́kọ́ tí yóò máa ṣiṣẹ́ akunmọ́tò ní Ibadan
"A ko mọ pe yoo sẹ nibẹrẹ amọ agbara to wa ninu ahọn ta fi n sọrọ, ti jẹ ki ọrọ naa wa si imusẹ.
Emi ati olori oloriire keji, Ayaba Folashade wa n dupẹ pupọ lọwọ baba ati ọkọ wa, Ọba Lamidi Olayiwola Adeyemi Kẹta fun ẹbun naa.
Kii se pe ẹbun naa yẹ fun wa, a kan ri aanu gba ni. Ọkan imoore wa ko si to lai jẹ pe a dupẹ lọwọ awọn Ayaba yoku  pe wọn ko ni ri ibanujẹ laye wọn."
Ile mejeeji ti Alaafin kọ yii fun awọn olori mejeeji lo wa ni ẹgbẹ ara wọn, to si jẹ aworan ati ọda kannaa.
Koda, ọjọ Satide ni wọn si ile mejeeji, tawsn Olori Omowunmi ati Ayaba Folasade si wọn asọ ankoo lati si ile wọn.
Oríṣun àwòrán, olori_omoh_one/Instagram
Idunnu ti subu lu ayọ ni aafin Oyo bayii nitori bi Alaafin tilu Oyo, Ọba Lamidi Olayiwola Adeyemi Kẹta se kọ ile fun ọkan lara awọn olori rẹ, Ayaba Memunat Omowunmi Adeyemi.
Ayẹyẹ isile naa si lo waye ni ọjọ Satide, ọjọ Kẹwa osu Kẹrin ọdun 2021.
Gẹgẹ bi ayaba oloriire naa ti kọ soju opo Instagram rẹ, o foju han pe ilu Ibadan ni ile alaja kan , to jẹ ọna meji naa wa.
Aworan ti Olori Omowunmi fi sita fihan pe ile alaja kan wa niwaju, omiran tun wa lẹyin, ti wọn si kọ wọn ni irufẹ aworan kan naa.
Ile alarinrin naa lo pe ni 'Palace of Patience' eyi to tumọ si Aafin Suuru.
Koda, ọda kan naa ni wọn fi kun awọn ile naa, to si ni aburada fun aaye igbọkọsi lọna igbalode niwaju ile, bẹẹ ni wọn mọ ogiri yi ile ọhun ka.
Oríṣun àwòrán, olori_omoh_one/Instagram
Bakan naa ni aworan ile yii fihan pe adugbo to jẹ oju ni gbese nilu Ibadan ni ile naa wa, koda, o dabi ẹnipe adugbo Bodija nilu Ibadan ni.
Koda, Alaafin funra rẹ, ati awọn eeyan jankan jankan ti wọn fi iwe pe, lo wa si ile ọhun.
Yoruba ni Yinni Yinni, kẹni le se omii ni, eyi si lo mu ki Olori Omowunmi maa ki ọkọ rẹ, Alaafin ni mẹsan mẹsan mẹwa fun inawo rẹ lori ile naa.
Olori Memunat Omowunmi salaye loju opo Instagram naa, wa ki ara rẹ ku oriire fun ẹbun ile alarinrin ti ọkọ oun, fun oun bii ẹbun.
Oríṣun àwòrán, olori_omoh_one/Instagram
"Mo gba ẹbun ile lọwọ ọba, tii se ọkọ mi, oni yii, (ọjọ Satide) si ni ayẹyẹ isile naa. Mo dupẹ lọwọ gbogbo awọn to wa ba mi yọ.
Pẹlu ẹmi irẹlẹ ati ọwọ, ni mo fi n mọ riri ọkọ mi, baba awọn ọmọ mi fun ohun gbogbo to ti n se fun mi.
N ko le dupẹ lọwọ rẹ tan, nitori atilẹyin rẹ nigba gbogbo ko lonka, ,o si gbadura pe ki Ọlọrun fun wọn ni ilera pipe, ki wọn tun le se fun mi ju bẹẹ lọ."
Bakan naa ni Olori iya onile tuntun yii, tun mọ riri awọn eeyan to wa ba yọ ayọ ile tuntun naa.
Oríṣun àwòrán, olori_omoh_one/Instagram
"Ohun rere ko ni wọn ninu ile gbogbo wa, mo si gba adura pe  ayọ laa maa ba ara wa yọ."""
Nibi ayẹyẹ awẹjẹwẹmu naa si ni ọpọ eeyan ti jẹ ajẹyo, ti wọn si tun fi ijo sara.
Gbogbo awọn ololufẹ Olori Memunat Omowunmi Adeyemi si lo ti wa n ki ku oriire ẹbun ile tuntun naa, ti wọn si n gbadura pe ẹmi rẹ yoo lo.
Insecurity in Lagos: Ìṣọ́ òru ní obìnrin náà ti ń bọ̀, kó tó kàgbákò ìkọlù
Oríṣun àwòrán, @followlasg
Àwọn jàndùkú kan gún ìyá ọlọ́mọ mẹ́ta, Oluwakemi Odugbesan pa ni agbegbe Oduntan ladugbo Ketu nípìnlẹ̀ Eko lọ́jọ́ Satide.
Wọ́n pa arábinrin náà lásìkò tí wọ́n fẹ́ jí fóònù  àti báàgì àpamọ́wọ́ rẹ̀.
Obìnrin ẹni ọdun mọ́kànlélógójì náà ni wọ́n pàdé lásìkò tó n bọ̀ láti ilé ìjọsin tó lọ fún iṣọ́ òòru ni aago mẹ́fà ìdájí ọjọ́ náà.
Gẹ́gẹ́ bi ìròyìn ṣe sọ, agbegbe Oduntan ni arábìrín náà ń gbé ó sì tí fẹ́ẹ̀ dé ẹnu ọ̀nà ilé rẹ̀ nigbati isẹlẹ naa waye.
Lẹ́yìn ti wọ́n ṣe iṣẹ́ ibi náà tán, ọ̀kan nínú àwọn ọdaran ọ̀hún ló fi fóònu Oluwakemi pe ìyá rẹ̀, láti sọ ǹkan ti wọn se fun ọmọ rẹ.
Torí àti ṣe Kòkò irin, bí mo ṣe máa ǹ fara yá iná nìyìí - Amokoko Saki
Ẹni ti ọ̀rọ̀ náà ṣe ojú rẹ̀ ṣàlàyé pé, Oluwakemi tó jẹ́ àkọ́bi nínú ọmọ marun ti ìyá rẹ̀ bi, ni wọ́n gún ni ni àyà lẹ́ẹ̀mẹ̀ta .
Wọ́n sáré gbe lọ sí ilé ìwòsàn Azir ni opópónà Oduntan, sùgbọ́n ó pada gbé ẹmi mi nítorí pé ẹjẹ̀ tó ṣòfò lara rẹ ti pọ̀jù.
Àwọn ẹbi olóògbé tí mú ẹjọ́ náà lọ sí agọ́ ọlọ́pàá tó wà ni Ketu.
Ọjọ́ ìbí ọkọ Oluwakemi ni wọ́n pa á, ọ̀sẹ péréte ló kù kí tọkọtaya Odugbesan lọ tẹ̀dó si orílẹ̀-èdè Canada, kí wọ́n to dá ẹmi rẹ̀ légbodò.
Àrẹ̀mọ Phillip padòdà lẹ́ni ọdún 99
Gbogbo Ketu àti agbègbè rẹ̀ ló ti wà nínú ìbẹ̀rù bojo láti ìgbà tí ìṣẹ̀lẹ̀ náà ti ṣẹ́.
Láti ńkan bi ọ̀sẹ̀ díẹ̀ sẹyin báyìí, ó kéré tán, ènìyàn mẹ́wàá ni àwọn janduku ti kojú ni oríta agbegbe náà ni ìdáji tàbi alẹ́.
Ronke Oshodi Oke: Ronke Oshodi Oke ṣe ìdárò ọmọ rẹ̀ tó di olóògbé
Oríṣun àwòrán, Ronke oshodioke
Ọmọ mi ọ̀wọ́n, àkọ́bi mi, ọ̀rẹ́ mi àti gbogbo ǹkan ti mo ni, Oluwabunmi Akinleye ọdun kẹwàá rèé tí o ti fi mi sílẹ̀
Èyí ni ọ̀rọ̀ idaro ti gbajúgbajà òṣèré tiata, Ronke Ojo tí gbogbo ènìyàn mọ̀ sí Ronke Oshodi Oke kọ nipa ọmọ rẹ̀ tó di olóògbé.
Ronke Ojo ló gbé fótò ọmọ rẹ̀ síta pé, ó ti le ni ọdún mẹ́wàá tí ikú ti wọle mú àkọ́bí òun lọ.
Láti àsìkò yìí ni ọ̀pọ̀ àwọn olọ́lùfẹ́ Ronke Ojo ti fọ́n sórí ayélujára láti ba kẹ́dun ikú ọmọ rẹ̀ tó d'olóògbé.
Bó tilẹ̀ jẹ́ pé Ronke Oshodi Oke kò sọ ǹkan tó ṣokùnfa ikú ọmọ náà, sùgbọ́n ìwé ìròyìn kan sọ pé àìsàn jẹjẹrẹ inu egungun ló paá.
Oríṣun àwòrán, Ronald Grant
Ẹni kan tó fẹ́ ká forúkọ bo òun láṣírí sọ pé, ẹni ọdún mọ́kàdínlọ́gbọ̀n ni Bunmi lásìkò tó papò dà, tó si máa n ṣe bi amúgbálẹ́gbẹ̀ẹ́ fún Ronke Ojo lásìkò náà.
Ìròyìn náà fi kun pé, tí ènìyàn bá ri bi ọmọbinrin náà ṣe sún mọ́ òṣèré náà tó, ọ̀pọ̀ ni yóò rò pé, ọmọ tàbi àbúrò rẹ̀ ni lóòtọ́.
Wọn ni ní ǹkan bi ọdún mọ́kànlá sẹ́yìn ni Bunmi ni ààrun jẹjẹrẹ inú egungun, èyí sì ló mú kí ọ̀pọ̀ àwọn òṣèré tíátà lásìkò náà bẹ̀rẹ̀ ìpolongo láti kówó jọ fún, kí wọn le gba ẹ̀mí rẹ̀ là.
Oríṣun àwòrán, ronkeoshodioke/Instagram
Àṣẹ̀yìn wá àṣẹ̀yìn bọ̀, Bunmi ko rí ìjà náà jà lájàyè, tó sì gbé ẹ̀mí mì lọjọ kọ̀kanlá oṣù kẹrin ọdún 2011 ni ilé ìwòsàn UCH Ibadan, níbi tó ti ń gba ìtọ́jú.
Ọ̀pọ̀ àwọn olólùfẹ́ Ronke Ojo ló n ṣeléde lẹ́yìn ọmọ náà, díẹ̀ lára ìkíni wọn rèé.
Oríṣun àwòrán, Ronke oshodi
Oríṣun àwòrán, Ronke Oshodi oke
Oríṣun àwòrán, Ronke Oshodi oke
Foluke Daramola: Toyosi Adesanya sọ òkò ọ̀rọ̀ sáwọn tó ń pe eléré tíátà ní aṣẹ́wó
Lórí ọ̀rọ̀ ìbanilórúkọ jẹ́ tí Foluke Daramola fí ké gbàjare lójú òpó instagram rẹ̀ láìpẹ́ yìí, ọ̀kan nínú àwọn gbájúgbajà òṣèré tíátà míràn tún ti bọ́ síta lórí ọ̀rọ̀ náà.
Toyosi Adesanya, gbajumọ osere mii to bọ sita naa ni gbogbo ẹni ti ìṣesí Foluke bá n bí nínú, kí wọ́n lọ wá ǹkan ṣe si.
Toyosi sọ̀rọ̀ yìí lójú òpó instagram Foluke Daramola, gẹ́gẹ́ bí ọ̀kan nínú àdarí ẹgbẹ́ Tampan.
O ni gẹ́gẹ́ bi ìṣẹ́ tí àwọn gbà, kò di dandan nígbà ti àwọn àgbà ẹgbẹ́ bá dí olóògbé, kí àwọn tó ṣe ojúṣe tó yẹ fun wọn.
Toyosi ni ìgbésẹ̀ Foluke Daramola ni láti mú inú àwọn ènìyàn náà dùn lásìkò tí wọ́n wà láyé, à ti pé àwọn kìí ṣe oore tí wọ́n yóò lọ máa pòréré rẹ̀ lórí ayélujára.
Gbajúgbajà òṣèré náà ni láti bi ọdún mẹ́tàdínlọ́gbọ̀n ṣẹyìn ni àwọn tí máa n ran ara àwọn lọ́wọ́, tó bá kù díẹ̀ káàtó fún ọmọ ẹgbẹ́.
Ṣe o di ìgbà tí àwọn àgbà yìí bá kú tán, kí a tó tọ́jú wọ́n ni, ǹkan tí a bá lẹ́nu iṣẹ́ nígbà tí a bẹ̀rẹ̀ ni à ń ṣe
Ó ní òun rọ àwọn olólùfẹ́ àti olùwòràn eré títà, láti máṣe mú ǹkan ṣú àwọn nitori awọn n gbìyànjú láti ṣe oore, o ni bákan náà ni ọ̀pọ̀ àwọn mííràn nínú agboolé tíátà pẹlu n se oore.
"Toyosi wa kesi awọn eeyan to n sọrọ odi nipa Foluke pe ""tí ìwọ́ bá tilẹ̀ ti ro ara rẹ pín pé o ko lè jẹ́ ènìyàn mọ́, ṣe o mọ iye ọdún tí àwa ti lò, kí a tó ní orúkọ tí a ni lónìí ni?"
Akomolede àti Asa: Kí ni Ìjálá láàrin àwọn ewì alohùn àti bí wọ́n ṣe ń sun-ún?
"Àìmọye ènìyàn ló ti ni orúkọ jùwá lọ lásìkò tí à ti bẹ̀rẹ̀ àti àwọn ti a ti lọrúkọ jùlọ láti ìgbà tí a ti bẹ̀rẹ̀  yìí."""
"Toyosi ni òun ni Foluke Daramola yan gẹ́gẹ́ bi akọ̀wé ẹgbẹ́ ajọ náà nígba to ṣe ìdásìlẹ̀ rẹ̀ lọ́dún 2019, àpò ara rẹ̀ sì ló tí mú owó tó fi n ràn àwọn arúgbó náà lọ́wọ́"""
 Tí ìwọ́ bá ni àgbàlagbà tàbi òbí nílé rẹ, tí o kọ̀ láti tọ́jú wọ́n, ṣe ó túmọ̀ sí pé kí ẹlòmíràn máṣe tọ́jú tirẹ̀ ní? Gbogbo ẹ̀yin tí inú ń bi, ẹ lọ gbà fún ẹni ti Ọlọ́run yọ́nú sí.
Bakan naa ni Toyosi ke si awọn obinrin to n pe awọn osere tiata lobinrin ni asẹwo, lati bọ sita wa sọ boya ọkọ to gbe wọn sile lo ja ibale wọn.
N kò ṣàánú mọ́ fáwọn àgbà òṣèré torí ìrọ́ tẹ pa mọ́ mi
Oríṣun àwòrán, Foluke Daramola
Gbajugbajà òṣèré tíátà Yorùbá, Foluke Daramola tí rọ ará ìlú láti kọ etí ọ̀gbọin sí àhesọ ọ̀rọ̀ kan tó n lọ pe, òun ń fí owó tí àwọn ènìyàn dá fún ètò ẹlẹyinjú àànú tí òun ṣe, se ìtọ́jú ara oùn.
Foluke Daramola ni kàkà bẹ́ẹ̀, iṣẹ́ owó tí òun ṣe ni òun ń lò láti ṣe ìtọ́jú àwọn arúgbó osere tiata tí òun máa n fún lówó.
Sáájú ni ọkàn nínú àwọn alátẹ̀lé rẹ̀ lórí ayélujára Instagram rẹ, tí kọ ǹkan sí abẹ ọ̀rọ̀ kan tí Foluke fi síta eyi to ni:
Gẹ́gẹ́ bí nǹkan ti òun rí lórí ayelujara pé  kí òṣèré náà ṣe ǹkan tọ yẹ lórí ọ̀rọ̀ owó náà tí kò bá fẹ́ kú, bákan náà ló tún kọ pé, Foluke já ọkọ ọlọ́kọ gba ni.
Oríṣun àwòrán, Foluke Daramola
Sùgbọ́n nínú ìdáhùn Foluke Daramola lo ti bẹ̀nu àtẹ lu ọ̀rọ̀ tí ẹni náà sọ tó si ṣẹ́ èpè lé pé lé nítorí pé òun bá òun lórùkọ jẹ́ ni.
Bákan náà ni òṣèré náà tún fi ìdí rẹ́ múlẹ̀ pé, òun kìí gba owó lọ́wọ́ ẹnikẹ́ni láti ran ajọ ẹlẹyinjú àǹù tí òn dásílẹ̀ lọ́wọ́ gẹ́gẹ́ bi ẹni náà ṣe sọ bíkò ṣe pé, òógùn ojú òun ni òun ń ná fún wọ́n.
Bákan náà lo ké sí ẹnikẹni tó bá ni ẹri tó dájú kí o gbe wá sí ìtà gbangba  kí wọn ye wá sí abẹ́ àkọlé òun láti wá kọ ìkọkúkọ.
Èló gan ni mó n fún àwọn arúgbó yìí gan, 5000, 10000 tí kò bá jẹ́ bẹ́ẹ̀ kí iná ọlọrun sọ̀kalẹ̀ lé ẹni náà lórí
"Fún ìgbà ìkẹyín mó fẹ́ kí àlàyé yìí ye olúkúlùkù "" Mi  kìí gba owó lọ́wọ́ ẹnikẹ́ni láti ṣe iṣẹ́ tí mo yàn layò láti má ràn àwọn arúgbó Nollywood lọ́wọ́."
Owó ara mí ni mo fí n ṣe e, àwọn ti wọn ni mó ni ibi tí mo ti n gba owó, tí wọn sì ni ẹ̀rí, kí wọ́n bọ si gbangba láti wá sọ ọ.
Oríṣun àwòrán, Foluke Daramola
"Bí kò bá sì tí sí ẹri, ẹ yé e wá si ojú òpó instagram mi láti kọ ìkọkukọ, kí ìbínú Ọlọ́run tó rọ̀ lé yín lórí."""
"Osere tiata naa fikun pe "" Ọpọ igba ni wọn ti n sọ ahesọ ọrọ nipa isẹ aanu toun n se, to si ni oun ti oun nifẹ lati se ni isẹ aanu naa fawọn agbaagba osere tiata, ti oun ko si da owo kankan si apo ara oun."""
Bakan naa lo sẹ lori iroyin kan to ni awọn olootu ere tiata meji ba oun ni ajọsepọ ni ibudo ere, ki wọn le fun oun ni ipa lati ko ninu ere wọn.
Female Car Painter: Èmi ní obìnrin àkọ́kọ́ tí yóò máa ṣiṣẹ́ akunmọ́tò ní Ibadan
Epe pọ ti Foluke Daramola sẹ, ti a ko le kọ sita , amọ to pa fidio naa rẹ loju opo rẹ, eyi to fi n fi ẹhonu han sawọn eeyan to n pa irọ mọ pe o gba owo lọwọ awọn eeyan kan, ti wọn si tun ni o n se sina pẹlu awọn olootu ere tiata.
Bodija Plank Market: Iná tún ṣẹ́ wọ ìsọ̀ pákó ni Bodija ìlú Ibadan
Oríṣun àwòrán, oyo insight
Ìsọ pákó tó jẹ́ gbájúgbajà ní ìlú Ibadan tí múná, gẹ́gẹ́ bi ìròyìn ṣe sọ
Nínú fọ́nran kan to n lọ lójú òpó twitter ni àwọn ènìyàn ti fi ìdí rẹ̀ múlẹ̀, bákan náà ni àwọn tó ni sọ́ọ̀bù nínú ọjọ́ náà tí wọ́n sì bá òṣìṣẹ́ BBC Yoruba sọ̀rọ̀ sàlàyé pé, iná náà kọjá sísọ.
Akomolede àti Asa: Kí ni Ìjálá láàrin àwọn ewì alohùn àti bí wọ́n ṣe ń sun-ún?
Nínú fọ́nran ọ̀hún bákan náà ni a ri àwọn ara àdúgbò tí wan ń sá kíjokíjo ti wọ́n sì n pè fún ìrànwọ́ àwọn panápaná.
Láipẹ̀ yìí ni ìsọ̀ páàtì ọkọ̀ jónà ti ọ̀pọ̀ àwọn olùtajà agbègbè náà sí n ka òfò wọ́n lọ́wọ́ ki èyí tún tó wáye
Lai Mohammed: Ìgbà márùn ùn ọtọ́ọ̀tọ̀ rèé tí ọ̀rọ̀ mínísítà fétò ìròyìn bí ọmọ Nàìjíríà nínú
Oríṣun àwòrán, @Shakapostng
Odu ni Minisita feto ibaraalu sọrọ ni Naijiria, Lai Mohammed, kii ṣe aimọ fawọn ọmọ Naijiria.
Yatọ si pe isẹ rẹ gba ki gbogbo ọmọ Naijiria mọ ọ bii ẹni mọ owo, sibẹ, lọpọ  igba to ba sọrọ, awọn araalu ki i fẹ́ gbọ ọrọ rẹ.
Yala nitori pe wọn maa n ni ọrọ rẹ jinna sootọ ni tabi pe awọn ko tilẹ nigbagbọ ninu ijọba Naijiria.
O ṣeese kẹ ti gbọ pe Lai Muhammed ni awọn akọroyin to n fẹnu tẹnbẹlu Naijiria, lo ṣokunfa bi alaṣẹ Twitter, Jack Dorsey ṣe gbe olu ileeṣẹ rẹ ni Afrika lọ si Ghana dipo Naijiria.
Awuyewuye ọrọ yii ko ti tan nilẹ ṣugbọn ka fi eleyi ṣe iranti fun ara wa ni, nipa awọn igba marun un miran tọrọ Lai Mohammed mu inu bi awọn ọmọ Naijiria.
Diẹ ree ninu wọn:
Lai Mohammed ni ki Big Brother Naija kogba sile tori Covid-19
Lọdun 2020 ileeṣẹ iroyin kan ni Naijiria gbe iroyin jade pe, Minisita Lai Mohammed paṣẹ fun  adele adari ajọ to n sakoto eto igbohunsafẹfẹ ni Naijiria, Armstrong Idachaba.
Wọn ni Muhammed pasẹ fun Idachaba pe ko kọwe si awọn eleto ere idaraya Big Brother Africa, lati kogba sile.
Muhammed, ggẹ bi wn se sọ ni o ṣeeṣe ki awọn eeyan ko arun Covid-19 lori eto naa.
Ọrọ naa ko dun mọ awọn eeyan Naijiria ninu, paapa awọn ọdọ, ti wọn ni Lai Muhammed fẹ gba ohun to n mu inu awọn dun lọwọ awọn ni.
Eto aabo munadoko labẹ aarẹ Buhari
Ni osu kinni lọdun 2021, lasiko to n ba awọn akọroyin sọrọ, ni Lai Muhammed kede pe eto aabo munadoko labẹ isejọba Muhammadu Buhari ju tawọn ijba to ti kọja lọ.
Lai sọ pe ka fi ẹgan kun, ka tun yọ tẹgan kuro, eto aabo ni Naijiria munadoko labẹ aarẹ Buhari ju igba ti ijọba ti tẹlẹ, PDP, wa lori oye lọ.
Ayodele Fayose, to jẹ eekan ninu ẹgbẹ PDP wa lara awọn to faraya lori ọrọ yii, ti ọpọ ọmọ Naijiria si kin lẹyin lati gboju agan si Lai Muhammed.
Lasiko to n ba awọn akọroyin sọrọ, naa tun ni Minisita feto iroyin ati asa sọ pe ko yẹ kawọn ọmọ Naijiria bara ajẹ nitori alekun owo eroja epo rọbi.
Lai Mohammed ni ifaraya awọn ọmọ Naijiria lori alekun owo epo kii ṣe oun to yẹ nitori bi owo epo ṣe n lọ soke, naa lo tun n wa silẹ, ko si yẹ ki wọn binu.
Muhammed ni ti owo epo rọbi ba walẹ, o di dandan kawọn araalu san owo kekere lowo epo nitori naa ko yẹ ki wọn maa fa ibinu yọ lori rẹ.
Bed Wetting: Tolulope Joseph ní ò lé ní ogún ọdún tí òun fi tọ̀ sílé kí ìwòsàn tó dé
Ko si ijọba kankan to ni ifẹ ara ilu lọkan ti yoo faaye gba ki awọn eeyan maa sọrọ ikorira, ki wọn si tun maa pin iroyin eke lori itakun agbaye.
Diẹ ree lara ọrọ ti Minisita sọ nipa abadofin iṣakoso ẹrọ ayelujara tawọn ọmọ Naijiria fi yari mọ lọwọ.
Loṣu Kọkanla ọdun 2019 lo fi ọrọ yii lede, to si tun fi akawe awọn orileede mii lagbaye to n sakoso bi awọn eeyan wọn ṣe n lo ẹrọ ayelujara.
Ninu awọn orileede to darukọ ni Singapore, China, South Korea, ati bẹẹ bẹẹ lọ.
Oríṣun àwòrán, Twitter
Minisita feto iroyin ni Naijiria, Alhaji Lai Mohammed ti da si awuyewuye lori bi ileesẹ Twitter ṣe gbe ọọfisi rẹ ni Afrika lọ si Ghana dipo Naijiria.
Lọjọ Aje ni ọga ileeṣẹ Twitter, Jack Dorsey kede pe awọn ti ṣetan lati si ọfisi si ilẹ Afrika, ti olu ileeṣẹ naa yoo si tẹdo si orileede Ghana.
Kete ti o fi ikede yii sita lawọn ọmọ Naijriia ti n sọ ariwisi nipa igbesẹ yii, tawọn kan si ni Naijiria lo yẹ ko gbe ileesẹ naa wa dipo Ghana.
Alaye tawọn ọmọ Naijiria fi kin ọrọ wọn lẹyin ni pe, Naijiria tobi ju Ghana lọ pẹlu awọn idi miran.
Lai Mohammed naa wa salaye idi ti ọrọ naa fi ri bẹẹ nigba to n ba awọn akọroyin sọrọ l‘Ọjọbọ.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
O ni ohun to yẹ ni pe ki Twitter gbe olu ileeṣẹ rẹ ni Afrika wa si Naijiria ''nitori nkan bi eeyan miliọnu marundinlọgbọn lo n lo Twitter ni Naijiria, ti
wọn ko si ju miliọnu mẹjọ lọ ni Ghana''
''Lai si iye meji, kii ṣe nitori ọrọ aje lo fi tori rẹ gbe igbesẹ yi''
Lai Muhammed ni Twitter lẹtọ lati gbe olu ileeṣẹ rẹ lọ si ibikibi to ba wu u.
"Minisita wa fi ọrọ kun eleyi ti o sọ pe ""Mo lero pe eleyi yoo jẹ ẹkọ fawọn ọmọ Naijiria.''"
Lai ni ''Nkan ti oju eeyan maa n ri ree, ti o ba ta orileede rẹ lọpọ nitori ọpọlọpọ igba lawọn eeyan ma n sọ asọdun lori ipenija to n koju Naijiria.''
O tẹsiwaju pe ''ko si igba teleyi foju han bi asiko iwọde ENDSARS nibi tawọn akọroyin ti n jijadu laarin ara wọn lori ẹni ti yoo ṣapejuwe Naijiria
gẹgẹ bi ọrun apaadi ti awọn eeyan ko gbọdọ wa sibẹ.''
Slain Ekiti Police woman: Ìyá rẹ̀ ní àìrìṣẹ́ṣe ló mú kí Bukola Olawoye gba iṣẹ́ ọlọ́pàá
O ni oun dupẹ lọdọ Ọlọrun pe orileede Amẹrika fọ Naijiria mọ pe ko si eeyan kankan to ku ninu iṣẹlẹ Lekki Toll Gate.
Minisita naa pari ọrọ rẹ pẹlu amọran sawọn ọmọ Naijiria lati nifẹ ilẹ wọn lọkan.
O  ni ''bi o ba ba ile ara rẹ jẹ, nibo lo ku ti wa a gbe?''
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ilé iṣẹ́ Twitter tó fi ilẹ̀ ilẹ̀ Amerika ṣe ibùdó ti yàn orílẹ̀ -èdè Ghana gẹ́gẹ́ ofíisì rẹ̀ túntun ni afirika, sùgbọ́n ọpọ ọmọ Naijiria lo n beere pe kí ló mú wọn yan Ghana láàyò gan?
"Lọ́jọ́ Ajé òṣẹ̀ yìí ní Jack Dorsey fi léde lórí twitter pé, ""Twitter ti balẹ̀ bàgẹ sí ilẹ̀ adúláwọ̀. Ghana ẹ seun o àti @NAkufoAddo""."
Eyi si lo dabi ni pe ileesẹ Twiitter fi n kéde agbekalẹ ọọfisi rẹ akọkọ ni Afirika.
Kí ọ̀gà àgbà pátápátá fun ileesẹ Twitter tó le kọ èyí sí ojú òpó twitter rẹ̀, tó sì tún ṣe àbẹ̀wò sí orílẹ̀èdè Ghana ni ọdún 2019, eyi fi han pé ìjọba Ghana wà lẹ́yìn ilé iṣẹ́ náà gbáágbágbá.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Àsìkò yìí bákan náà tó sàbẹ̀wò sí Ghana ni Dorsey ń ṣe àbẹ̀wò káàkiri awọn orílẹ̀-èdè to wa nilẹ̀ Afrika, bákan náà ló sì sọ pé, òun fẹ wá gbé ilẹ̀ adúiláwọ̀ fún oṣù mẹ́ta sí mẹ́fà.
Amọ o ni òun kò ti mọ ibi ti òun yóò gbé ni Afrika. Sùgbọ́n ó jọ bi ẹni pé gbogbo ètò ló ti tò lati tẹdo si Ghana, ni ọ̀gá àgbà twitter ṣe kọ sórí twitter fúnra rẹ̀.
Ààfàní rèé fún Dorsey láti gbé, ki o sí kópa nínú si agbega ètò ìmọ̀ ẹ̀rọ ni ilẹ̀ adúláwọ̀, kó jẹ́ pé Ghana náà ló wà, eyi yóò jẹ́ ìwúrí fún ọ̀pọ̀ ọmọ aláwọ̀ dúdú nilẹ̀ Afíríkà.
Abẹ̀wọ sojú òpó Twitter fi han pé ààyè mẹ́sàn ló ṣí sílẹ̀ fún ìṣẹ́ níbẹ̀ Sàbẹ̀wò sí ojú òpó wọ́n níbí
Wayi o, ìdùnnú súbú lu ayọ ni ìròyìn náà fún àwọn olùgbé Ghana, tó fí mọ ààrẹ Ilẹ̀ Ghana, Nana Akufo-Addo, tó sàkàwé ìgbésẹ̀ náà bíi èyí tó dára, sùgbọ́n ọ̀rọ̀ ṣe ọ̀tọ̀ọ̀tọ lọ́dọ̀ àwọn ọmọ Nàìjíríà.
Bí àwọn ọmọ Nàìjíríà kan ṣe n gbarata pé orílẹ̀-èdè Nàìjíríà ni ọọ́fíísì túntun ileesẹ Twitter naa tọ́ sí, ni àwọn míràn gbà pé ijọbaNàìjíríà àti ètò ààbò tó mẹ́hẹ, kò lé jẹ́ kí irú ilé iṣẹ́ bẹ́ẹ̀ wá tẹ̀dó sí Nàìjíríà.
"Ó kọ́ pé, "" Ìfọkànbalẹ̀ tí a ni láti gbé ilé iṣẹ́ wa sí Ghana jẹ́ ìròyìn ayọ, ìjọba Ghana fi tayọ̀tayọ̀ gba ìkéde náà, ó sì ni ìbáṣepọ̀ wọn yóò dán mọ́rán."
Kíní ìdí ti Twitter fi yan Ghana Láàyò?
Ó lè jẹ́ pé nítórí Ghan a máa gbárùkù tí òwò
Gẹ́gẹ́ bi ìwádìí Bánkì àgbáyé kan tó jáde ni ọdún 2019, ipò 118 ní Ghana wà lára àwọn orílẹ̀-èdè tí o rọrun láti ṣe òwò lẹ́gbẹ̀ orílẹ̀-èdè Nàìjíríà, tó wà nípò 131.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ìtùmọ̀ èyí ni pé, ẹni tó jẹ́ ipò àkọ́kọ́ ni òwò dùn ṣe jù níbẹ̀, ìpò tí orílẹ̀-èdè Nàìjíríà wà túmọ̀ sí pé kò rọ̀rùn rárá lati se owo lorilẹede rẹ.
Sùgbọ́n gẹ́gẹ́ bí ọ̀gá yìí ṣe sọ, òun yàn orílẹ̀-èdè Ghana nítori pé ètò ìjọba àwa arawa ń rú gọ̀gọ̀ níbẹ̀.
Bákan náà lo ni wọ́n faramọ́ òmìnirà láti sọ èrò ọkàn ẹni lórí ayélujára, pàápàá jùlọ lórí ayélujára èyí tí twitter ń pè fún.
Akomolede àti Asa: Kí ni Ìjálá láàrin àwọn ewì alohùn àti bí wọ́n ṣe ń sun-ún?
"Bákan náà ni twitter tún sọ àwọn ìdí míràn tí wọ́n fi yan Ghana láàyò bí i eto ajọsepọ okoowo lai ni owo ori ọja ninu, taa mọ si ""African Continental Free Trade Zone """
Ilé iṣẹ́ twitter ni ẹka ilé iṣẹ́ rẹ méjìlélọ́gbọ̀n ni orílẹ̀-èdè mọ́kàndínlógún.
Davido: Ó fún Yinka Ayefele ní ₦1m, tó sì tún fẹ́ ran ẹ́ni tó fẹ́ pa ara rẹ̀ lọ́wọ́
Oríṣun àwòrán, davido/Instagram
Se ni ori ayelujara n gbona lopin ọsẹ nitori awọn isẹ aanu kan ti ilumọọka akọrin taka n sufe nni, David Adeleke, ti ọpọ eeyan mọ si Davido se.
Se ni ojo owo yanturu rọ fun gbajumọ olorin Tungba, Yinka Ayefele lagbo ode ere kan ti Davido yọju si, to si na miliọnu kan naira fun bii owo imọri.
Ayẹyẹ inawo kan to waye nilu Abẹokuta nibi ti Yinka Ayefele ti sere loju agbo, ni Davido yọju si.
Nigba to gbe fidio naa soju opo Instagram rẹ, Ayefele mọ riri ẹbun owo ti Davido fun naa, to si ni oun dupẹ fun iyi ati ẹyẹ to se fun oun.
Lasiko ti Davido de iwaju Ayefele, ni Akọrin Tungba naa mu orin bọnu, eyi to jẹ ọkan lara orin Davido to gbajumọ.
Oríṣun àwòrán, yinkaayefele/Instagram
Bi Ayefele si se n pariwo 'Ẹ ma da mi duro, emi lọmọ baba olowo...' ni Davido na owo naa si, to si tun bẹrẹ si ni fi ẹsẹ rajo.
Amọ nigba to ya, ni Davido gan gba ẹrọ amohunbugbẹnu, eyiun Maikirofoonu lọwọ Ayefele, to si n kọrin sẹlẹru agbo, agbara agbo, ni Ọsun fi n wẹ ọmọ rẹ, ki dokita to de.
Orin bii orisi mẹta ni Davido kọ loju agbo naa, to fi mọ alowo ma jaye, ẹyin lẹ mọ, tawọn eeyan oju agbo si n fi ẹsẹ rajo.
Amọ se ni Ayefele naa n na owo pada fun Davido, tọrọ naa si dabi olowo pade olowo.
Ninu fidio naa si lo ti fi oju han pe gbajumọ akọrin Fuji naa, Pasuma wa loju agbo yii, toun naa si n kọrin ki Davido ni mẹsan mẹwa.
Oríṣun àwòrán, yinkaayefele/Instagram
Davido, ti ko lo ju isẹju marun lọ loju agbo naa, wa di mọ Ayefele, to si di mọ ọ, ko to kuro loju agbo naa.
Bakan naa lopin ọsẹ yii, lara isẹ aanu mii ti Davido tun se ni bo se ke si awọn eeyan lati ba oun wa ọkunrin kan to fẹ gbẹmi ara rẹ.
Ọkunrin naa, to gbe oogun asekupani to fẹ lo soju opo Instagram rẹ,  lo wa kọ ọrọ sabẹ aworan oogun naa pe ko si ẹnikẹni to bikita nipa oun.
Ni kete ti Davido si foju gan ni ọrọ naa ati bi ọkunrin yii, ti oju opo ibanidọrẹ rẹ ni Instagram jẹ @rjlawal se setan lati gbẹmi ara rk, lo ba fesi pada fun.
Oríṣun àwòrán, rjlawal/Instagram
"Davido ni ""Arakunrin mi, Ọlọrun bikita fun ọ..., n ko mọ ọ ni ojukoroju amọ mo setan lati ran ọ lọwọ... Ẹ jọwọ, ẹ ba mi kan si ọkunrin naa, pe mo n wa lati seranwọ fun."""
Igbesẹ Davido yii si lo mu ki ọpọ eeyan maa kọrin rere kii, ti wsn si n gbe osuba randẹ fun pe eeyan rere ni, oloju aanu si ni pẹlu.
Ọpọ eeyan lo wa ki Davido lẹyin, ti wsn si n rawọ ẹbẹ si Lawal pe ko mase gbiyanju lati da ẹmi ara rẹ legbodo.
Amọ titi di akoko yii, ọkunrin naa ko tii yọju sita lati wa beere iranwọ ti Davido seleri lati se fun.
June 12 Annulment: Obasanjọ ní àwọn tí kò gbé ìjọba lè MKO lọ́wọ́ ṣé bẹ́ẹ̀ nítorí ẹtáànú ní
Oríṣun àwòrán, The Premier News
Aarẹ orileede Naijiria tẹlẹri Olusegun Obasanjo ti sọrọ lori bi wọn se wọgile ibo aarẹ ti Moshood Kashimawo Olawale Abiola jawe olubori ninu rẹ, loṣu Kẹfa ọdun 1993.
Obasanjo woye bẹẹ lasiko ayẹyẹ ifami ẹyẹ dani lọla to waye ni Abeokuta labẹ asia ẹgbẹ awọn ọmọ ẹgba nipinlẹ Ogun.
Aarẹ ana ni Naijiria naa, ti wọn dijọ da lọla pẹlu MKO Abiola salaye pe, ẹtaanu ni ko jẹ ki wọn gbe ipo naa fun Abiola.
O ni bi bẹẹ kọ, ko ba jẹ pe ọmọ ẹgba mẹta ni yoo di ipo aarẹ mu ninu akọsilẹ Naijiria .
Bó tilẹ̀ jẹ́ pé wọn ní gbájúgbajà oníwàásù Nàìjírìá kan tí sọ tẹ́lẹ̀ pé kí Abíola má díje fún ìdìbò tẹ́lẹ̀.
Nibi ayẹyẹ ifamiẹyẹ danilọla naa ni Obasanjo ti wa ṣapejuwe MKO gẹgẹ bi akẹẹgbẹ rẹ nile iwe girama.
Abiola ati Obasanjo jijọ lọ si ile ẹkọ girama Baptist Boys High School nilu Abeokuta nigba ewe wọn.
Yatọ si Obasanjo, Ernest Shonekan to jẹ olori ijọba fidihẹ ni Naijiria naa de ipo aarẹ, bo tilẹ jẹ pe fun igba diẹ lo fi lo ipo naa.
''Mo fẹ dupẹ lọwọ ẹgbẹ Abeokuta Club fun ọla ti wọn fi da mi lọla yii ati iyi ti wọn ra fun akẹgbẹ mii, MKO Abiola.''
''Kabiyesi Alake sọrọ nipa rẹ, ṣẹ si mọ pe bi eeyan ba gba ife lẹẹmẹta, o di ti onitọun niyẹn. Bi kii ba ṣe ẹtaanu, Abeokuta ko ba ti ni aarẹ lẹẹmẹẹta bayi''
Female Car Painter: Èmi ní obìnrin àkọ́kọ́ tí yóò máa ṣiṣẹ́ akunmọ́tò ní Ibadan
Ọrọ ti Obasanjo sọ yii ṣebi ẹni tako oju tawọn eeyan fi n wo ibaṣepọ to wa laarin oun ati MKO nigba aye rẹ, paapa awọn mọlẹbi MKO to ri Obasanjo gẹgẹ bi ẹni ti ko fẹran MKO.
Lọpọ igba ninu ifọrọwerọ wọn pẹlu awọn akọroyin, lawọn mọlẹbi oloogbe ti ni Obasanjo ko gbiyanju to lati bu iyi fun Abiola lasiko to wa lori oye gẹgẹ bi aarẹ.
Ọrọ yii tun jẹyọ bi ere bi ere lasiko ti ijọba Muhammadu Buhari yẹ Abiola si, nipa fifi orukọ papa iṣere nla Abuja peri rẹ, ti wọn si tun sọ June 12 ni ayajọ oṣelu awarawa ni Naijiria nitori rẹ.
Sunday igboho: Ẹgbẹ́ Fulani fárígá pé kí wọn dá Seriki padà sí Igangan pẹ̀lú owó ìtanràn
Ẹgbẹ awọn ọmọ bibi Fulani kan, Gan Allah Fulani Developmet Association,GADFAN, ti kesi ijọba Naijiria, lati san owo itanran fun Seriki Fulani ti wọn si nipo pada kuro nilu Igangan.
Bẹẹ ni wọn sọ pe ki ijọba fofin mu Sunday Igboho, to ṣagbatẹru ikọlu si Seriki, eyiun Alhaji Salihu Abdulkadir nilu Igangan.
Ẹgbẹ GADFAN fi ọrọ yii lede lasiko ti wọn ṣe abẹwo si Seriki Abdulkadir lọjọ Abamẹta ni ilu Ilorin, nibi toun ati mọlẹbi rẹ fori pamọ si.
Alaga ẹgbẹ naa Sulaiman Yakubu ati akọwe, Ibrahim Abdulahi sọ ninu atẹjade to tẹ BBC lọwọ pe, ki ijọba fi ọlọpaa mu Sunday Igboho, ko si foju wina ofin ni kiakia.
Igboho Ultimatum to Fulani: Ẹni bá mọ Sunday Igboho kó bá wa bẹ̀ẹ́ o,
''O ya wa lẹnu pe titi di ba ṣe n sọrọ yii, fanda-fanda ni Igboho n rin kaakiri bi igba pe nkankan ko tiẹ ṣẹlẹ''
''Nitori naa ẹgbẹ GADFAN n kesi ijọba apapọ ati ijọba ipinlẹ Oyo, lati ri pe wọn se deede pẹlu Alhaji Seriki ati awọn eeyan rẹ nipa mimu Igboho. ''
Wọn fi kun pe ki ijọba ri pe wọn tara san owo gba ma binu fun awọn to padanu dukia, ki wọn si jẹ ki wọn pada si ile wọn lalaafia nilu Igangan.
Kò sí ìgbà kankan tí Yorùbá jókòó pé ki Igboho  lọ kéde ìyapa kúrò ní Nàíjíríà
Atẹjade naa sọ bakan naa pe, ikọlu tawọn eeyan Igboho ṣe si ile Seriki ni Igangan lo mu ko padanu ''dukia ati awọn nkan ọsin ti owo rẹ wọ ẹẹdẹgbẹta miliọnu Naira''
Ẹgbẹ naa sọ pe, awọn yoo lo gbogbo ọna labẹ ofin lati ri pe awọn gba ẹtọ Seriki fun.
Wọn ni ''a ti n ba awọn agbẹjọrọ sọrọ, ti a ko si ni pẹ gbe ọrọ lọ si ile ẹjọ ti ijọba ko ba ṣe nkankan si''
Oríṣun àwòrán, GADFAN
Female Car Painter: Modupe ní Ọkùnrin máa ń dẹnu ìfẹ́ kọ òun tàbí fi òun ṣe yẹ̀yẹ́ torí ó jẹ́ obìnrin tó ń kun mọ́tò lọ́dà
Ohun ti ọkunrin le se, awsn obinrin le se ju bẹẹ lọ ni Yoruba maa n sọ.
Bo si se ri ree pẹlu obinrin kan, Modupe Olagunju, ẹni to yan isẹ kikun mọto ni ọda laayo, to si jẹ obinrin akọkọ ti yoo maa sisẹ naa nilu Ibadan.
Nigba to n ba BBC Yoruba sọrọ, Modupe ni iya oun lo pọn ni dandan fun oun lati kọ isẹ naa nigba ti oun si wa nile ẹkọ girama, eyi toun fi n jẹun lonii.
O salaye pe ọpọ ipenija ni oun ba pade lẹnu isẹ naa nitori awọn ọkunrin kan maa n dẹnu ifẹ kọ oun, ki wọn to gbe isẹ fun oun tabi ki wọn maa se yẹyẹ pe oun n sisẹ ọkunrin.
Bakan naa lo fikun pe sọọbu oun nikan da jona nigba ti oun bẹrẹ isẹ naa, eyi to da omi tutu si oun lọkan, tawọn ọkunrin kii si fẹ ki oun gba isọ sọdọ wọn.
Àwọn ìtàn mánigbàgbé tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí:
Modupe Olagunju wa gba awọn obinrin nimọran lati kọ isẹ ọwọ mọ ẹkọ iwe, ki wọn si tun bẹrẹ nibi kekere, ki wọn ma baa se ju agbara wọn lọ.
Ebube Agu: Àwọn gómìnà Igbo ṣàgbékalẹ̀ ikọ̀ ẹ̀ṣọ́ aláàbò tuntun
Oríṣun àwòrán, Ft. Dj Benkraft
"Awọn gomina ni Guusu ila oorun Naijiria ti korajọ lati ṣagbekalẹ ikọ alabo kan ti wọn pe orukọ rẹ ni ""Ebube Agu"" lọna ati gbogun ti iwa ọdaran to n peleke sii lagbegbe naa."
Alaga ẹgbẹ awọn gomina ọhun, Dave Umahi lo kede agbekalẹ ikọ naa lẹyin ipade kan ti oun atawọn akẹgbẹ rẹ ṣe niluu Imo.
Gẹgẹ bo ṣe sọ, olu ọọfisi ikọ naa yoo wa ni ipinlẹ  Enugu.
Ninu atẹjade to fi lede lẹyin ipade naa, Umahi sọ pe ikọ ọhun yoo tun maa dari iṣẹ awọn fijilante agbegbe naa.
"O ni ""lẹyin ipade pẹlu awọn gimina atawọn ti ọrọ kan nipa ti eto abo ni iha Guusu ila oorun Naijiria, a ti fẹnuko lati gbogun ti iwa ọdaran ati iwa iṣẹrubalu ni Naijiria, paapaa lagbegbe wa."""
Bẹẹni a tun bu ẹnu atẹ lu bi awọn ọdaran kan ṣe n dana sun agọ awọn ọlọpaa ati ọgba ẹwọn, ti wọn si n tu awọn ẹlẹwọn silẹ.
Umahi fi kun pe digbi ni gbogbo ipinlẹ marun to wa ni iha Guusu ila oorun Naijiria wa lẹyin ijọba apapọ lori eto abo, ati pe gbogbo igbesẹ ti ijọba apapọ ba fẹ gbe lati kọju ija si awọn ọdaran lawọn yoo tẹle.
O ṣalaye pe gbogbo awọn oloṣelu nilẹ igbo ti fẹnuko lati fi imọ ṣọkan lori awọn aṣẹrubalu, wọn si ti pinnu lati kọju ija si awọn eeyan naa labẹ asia kan naa.
Awọn gomina ọhun tun ke si ọga agba ileeṣẹ ọlọpaa lati gba awọn kọmiṣọna ọlọpaa laaye lati maa ṣiṣẹ wọn  bo ṣe tọ ati bo ṣe yẹ dipo ko maa ran awọn eeyan kan wa lati Abuja lati maa bẹ iṣẹ wọn wo.
Female Car Painter: Èmi ní obìnrin àkọ́kọ́ tí yóò máa ṣiṣẹ́ akunmọ́tò ní Ibadan
Wọn tun fẹnuko pe awọn ti gbẹsẹle bi awọn daradaran ṣe maa n da ẹran kaakiri aarin ilu.
Atẹjade naa pari pe ki ibaṣepọ to dan mọran wa laarin awọn  agbẹ atawọn to n si maalu.
Ọpọ awọn ọmọ Naijiria lo ti bẹrẹ si n fi erongba wọn lede lori ikede ikọ ẹṣọ alabo tuntun naa.
Mary Daniel: Ìjọba ìpínlẹ̀ Eko ní obìnrin ẹlẹ́sẹ̀ kan náà yóò wà ní ìkáwọ́ òun títí tí yóò fi bẹ̀rẹ̀ òwò
Oríṣun àwòrán, Screen Shot
Ijọba ipinlẹ Eko ti sọ pe oun yoo bojuto bi Mary Daniel, obinrin to n ta omi ninu sunkẹrẹ-fakẹrẹ ọkọ lagbegbe Oshodi, yoo ṣe maa gbe igbe aye to dara lati akoko yii lọ.Igbesẹ yii lo n waye lẹyin ti awọn ẹlẹyinju aanu lawujọ bẹrẹ si n fi owo ṣọwọ si obinrin naa, ni kete ti aworan rẹ fa ori ayelujara ya.Anu rẹ ṣe ọpọ ọmọ Naijria lasiko to ba awọn akọroyin sọrọ, lori ohun to ti la kọja lati igba to ti padanu ẹsẹ rẹ kan ninu ijamba ọkọ lọdun 2006.
Lẹyin ti ọrọ Mary jade sigboro ni olubadamọran Pataki si gomina ipinlẹ Eko lori ọrọ araalu, Aderemi Adebowale sọrọ sita nipa obinrin naa.
O ni ijọba ipinlẹ Eko ti mu arabinrin ọhun sọdọ, titi ti wọn yoo fi ṣeto bi awọn yoo ṣe gba ile fun, ati bi wọn yoo ṣe tọ sọna lori owo ti yoo maa ṣe.
Oríṣun àwòrán, Screen Shot
"Adebowale, lasiko to n ba iwe iroyin Punch sọrọ ni ""mo gbọ nipa Mary lọjọ Aje nigba ti awọn oloṣelu meji kan mu wa si ọdọ mi pẹlu kaadi ATM rẹ."
"Wọn ni o yẹ ki a daabo bo nitori iye owo to n wọle sinu apo rẹ ni banki.""""Mo ti ke si kọmiṣọna to n ri si ọrọ awọn ọdọ, a o fi Mary pamọ si ile kan lagbegbe Ikorodu fun nnkan bii ọsẹ kan, titi ti a o fi wa ile fun.""Adebowale pari ọrọ rẹ pe, oun yoo maa ṣe itọju ati alamọna rẹ, oun yoo si ri daju pe o di olugbe ilu Eko tootọ."
Oríṣun àwòrán, Screen Shot
Lara awọn eeyan to ti fi owo ṣọwọ si Mary ni oludije sipo gomina nipinle Imo tẹlẹ, Uche Nwosu, to fun ni ẹgbẹrun lọna ẹẹdẹgbẹta naira.
Awọn ọrẹ Nwosu naa tun ṣeleri iye owo yii bakan naa gẹgẹ bii ẹbun fun Mary Daniel.
Saaju lati ti mu iroyin wa fun yin pe nkan bii ọjọ melo kan sẹyin ni aworan obinrin to n ta omi inu ọra pẹlu ẹsẹ kan fa ori ayelujara ya, ti ọpọ si n kaanu rẹ.
Gẹgẹ bii ohun to sọ fun awọn akọrọyin niluu Eko, obinrin ọhun ti orukọ abisọ rẹ n jẹ Mary Daniel sọ pe, iṣẹ agbẹjọro lo wu oun lati ṣe lati kekere, ṣugbọn ijamba ọkọ lo sọ oun di ẹlẹsẹ kan.
Mary ṣalaye pe oun nikan lo moribọ ninu gbogbo awọn to wa ninu ọkọ ti ijamba ọhun ti ṣẹlẹ lọdun 2006.
"O ni ""ọdun 2006 ni mo ni ijamba ọkọ nigba ti emi atawọn obi mi n rinrinajo lọ si abule wa, ọmọ ọdun mẹwaa ni mi lasiko naa, emi nikan ni mo ru ijamba ọkọ naa la nitori awọn eeyan marundinlogun to ku ba a lọ."""
Oríṣun àwòrán, Screen Shot
Mary tẹsiwaju pe, awọn eeyan ke si iya-iya oun lori aago lẹyin ijamba ọkọ ọhun, ṣugbọn ki wọn to foju ganni ara wọn, wọn ti ge ẹsẹ oun kan, bii bẹ kọ, o ṣeeṣe ki oun naa ba iṣẹlẹ naa lọ.
"Lẹyin ọdun mẹwaa, ni Mary tẹkọ leti lọ si iluu Onitsha, nibi to ti bẹrẹ si n ta omi inu ọra ti ọpọ mọ si ""pure water"" pẹlu ẹsẹ kan."
Ilu Onitsha yii lo wa ti iya-iya rẹ naa ti ke si pe wọn ti ba ri ọkọ, ṣugbọn ere ifẹ oun ati ọkọ naa ko lọ titi nitori ọkunrin ọhun kọ lati tọju rẹ, koda ọkunrin naa tun lu ni jibiti owo pẹlu.
"Nigba to n ṣalaye bi ere ifẹ wọn ṣe dopin, o ni ""lẹyin ti mo loyun tan ni ọkọ mi yi iwa pada, emi ni mo n da nikan gbọ bukata bi mo ṣe n jẹun pẹlu oyun inu mi."""
Ko pẹ si asiko naa ni mo tẹkọ leti lọ si ilu Asaba, nibi ti mo ti n ta omi inu ọra pẹlu ẹsẹ kan yii naa, mo gbiyanju lati gba ile, lẹyin naa ni mo ke si ọkọ mi lati maa gbe pẹlu mi ko to di pe mo bi ọmọ.
Oríṣun àwòrán, Screen Shot
"Ko pẹ si asiko yii ni mo ri oloju anu kan to fi N500,000 ta mi lọrẹ, ṣugbọn bi ọkọ mi ṣe ko firi owo naa, lo ko ẹrọ ibaraẹnisọrọ mi ati kaadi ATM mi, to si gba gbogbo owo naa ku ẹgbẹrun meji pere."""
Mary sọ pe oun ko tii foju gan ni ọkunrin naa lati igba to ti gbe oun lowo salọ.
Akanda ẹda naa pari ọrọ rẹ pe, yoo wu oun lati fi iṣẹ omi inu ọra tita silẹ ti oun ba ri oluranlọwọ, ati pe iṣẹ aranṣọ lo wu oun lati ṣe niwọn igba to jẹ pe oun ko nilo ẹsẹ meji lati ranṣọ.
Lẹyin ti aworan abarapa naa gbajumọ tan lori ayelujara, ni awọn ẹlẹyinju anu kan bẹrẹ si n ko owo jọ fun Mary lati fi seranwọ fun.
Female Car Painter: Èmi ní obìnrin àkọ́kọ́ tí yóò máa ṣiṣẹ́ akunmọ́tò ní Ibadan
Lara awọn to fi owo ṣeranlọwọ fun obinrin ọhun ni akọwe ijọba ipinlẹ Imo tẹlẹ, Ugwumba Uche Nwosu, to fun ni sọwedowo miliọnu kan naira.
Titi di akoko ti a nko iroyin yii jọ, awọn ẹlẹyinju anu kan si n gbiyanju lati ṣe iranlọwọ fun
Squash: Dele Oladejo ní eré ìdáráyá náà yóò pèsè iṣẹ́ àti owó fáráàlú
Ni orilẹede Naijiria, ọpọ eeyan ni ko mọ nipa ere idaraya miran mọ yatọ si ere bọọlu, eyi to lokiki yika aye.
"Ọpọ eeyan ni ko si mọ pe ere idaraya ẹlẹyin ti wọn n gba mọ iganna, ""Squash"",  jẹ ọkan gboogi lara awọn ọna ti awọn orilẹede to ti goke agba l'agbaye fi n se agbega eto ilera ati ọrọ aje wọn."
Bo tilẹ jẹ wi pe ere idaraya naa ko ti i fi bẹẹ wọ pọ ni orilẹede Naijiria, amọ awọn akọṣẹmọṣẹ nipa ere idaraya Squash kan ti ṣe alaye fun BBC Yoruba wi pe, orisun ọrọ ati ilera pipe ni ere idaraya naa, ti a ba le kọ ibi ara si i.
Agba ọjẹ ninu ere idaraya naa, Dokita Oludele Oladejo ṣe alaye wi pe ijọba gbọdọ wa ọna lati gbe ere idaraya naa larugẹ nitori pe o le ṣe anfani to pọ fun ọrọ aje aladani ati fun orilẹede l'apapọ.
Dele Ọladejo si lo se agbatẹru idije Squash nilu Ibadan laipẹ yii fawọn ọjẹ wẹwẹ elere idaraya naa ti ọjọ ori wọn wa laarin ọdun mẹtala si mẹtadinlogun.
"Dokita onisegun oyinbo naa ni, ""Ere idaraya Squash jẹ eto ọrọ aje lọna tiẹ nitori pe fun awọn to n gba a, iṣẹ aṣejere ati aṣelowo ni."
Awọn ti yoo ma a mojuto akoso ere idaraya naa, iṣẹ lo jẹ fun awọn yẹn pẹlu.
"Ijọba gan yoo maa gba owo ori lọwọ awọn oṣiṣẹ tabi lọwọ awọn to n gba Squash, to ba di ere idaraya nla""."
"Oladejo ni ere bọọlu ti wọn n gba mọ iganna yii, iyẹn ""Squash"" ki i ṣe ere idaraya lasan nitori ojulowo iṣẹ oojọ to n fun ni lokun, to si tun le mu ọpọlọpọ owo wọle ni."
O parọwa si awọn obi ati ijọba lati fun awọn ọmọ lanfani kikopa ninu ere idaraya naa nitori pupọ ọmọde ni yoo fakọyọ, ti wọn ba fun wọn ni anfani lati se ere idaraya naa.
"O fi kun ọrọ rẹ pe ""ijọba ni lati wa ọna to fi jẹ pe gbogbo awọn ere idaraya wọnyii ni yoo jẹ gboogi ohun ti wọn n na owo le."
"Bakan naa ni ki wọn fi anfani silẹ fun awọn akọṣẹmọṣẹ to n kọ ọmọ nipa awọn ere yii lati lọ kọọ nibi ti o yẹ, nitori pe ere ti o wa nibẹ kọja nnkan ti a ro""."
Lẹyin idije ere idaraya Squash to waye ni ibudo igbafẹ Recreation Club nilu Ibadan naa ni wọn ti pin oniruuru ẹbun fawọn ọmọ to fakọyọ lọkunrin ati lobinrin, ninu idije naa.
Female Car Painter: Èmi ní obìnrin àkọ́kọ́ tí yóò máa ṣiṣẹ́ akunmọ́tò ní Ibadan
Bakan naa ni ọmọkunrin meji, ti wọn jẹ ọmọ iya kan naa gba ẹbun ẹkọ ọfẹ titi de ile ẹkọ giga fasiti eyi ti apapọ awọn elere idaraya Squash to wa nibudo igbafẹ Recreation Club nilu Ibadan se agbatẹru rẹ.
Isa Patami: Mínísítà fèsì sí ìròyìn tó ní ó wà lára àwọn bàbá ìsàlẹ̀ Boko Haram àti Al-Qaeda
Oríṣun àwòrán, @DrIsaPantami
Minisita fun ileeṣẹ ijọba to n ri eto ibaraẹnisọrọ ni Naijiria, Isa Pantami ti fesi si iroyin kan to sọ pe, orilẹ-ede Amẹrika kede rẹ gẹgẹ bi ọkan lara awọn baba isalẹ ẹgbẹ agbesunmomi Boko Haram.
Pantami sọ loju opo Twitter rẹ pe, ile iṣẹ iroyin to gbe iroyin ọhun jade yoo foju ba ileẹjọ fún ibanilorukọ jẹ.
Laarọ ọjọ Aje ni iroyin naa lu ori ayelujara pa pe, Amerika darukọ minisita eto ibaraẹnisọrọ gẹgẹ bi ọkan lara awọn to n ṣe onigbọwọ ẹgbẹ agbesunmomi.
Iroyin kan tiẹ ṣalaye pe, ẹka ileeṣẹ ọtẹlẹmuyẹ ilẹ Amerika sọ pe ki Pantami to de ipo minisita, lo ti jẹjẹ lati maa ṣe atilẹyin fún ẹgbẹ Al-Qaeda.
Iwe iroyin naa tun sọ pe, Pantami ni ibaṣepọ pẹlu olori akọkọ fun ikọ Boko Haram, Mohammed Yusuf at'awọn olori ẹgbẹ Abu Quatada Al-Filistini ati Al-Qaeda.
Oríṣun àwòrán, NigeriaArmyHQ
Amọ, minisita naa ni fun bi ọdun mẹẹdogun loun ti n ṣe idanilẹkọ tako awọn alakatakiti ẹsin.
Pantami ni lori ọrọ lilo kaadi idanimọ NIN lati fi koju eto abo to mẹhẹ, o ni ijọba ko ni boju w'ẹyin.
Ẹwẹ, iwadii fihan pe orukọ Pantami ko si ninu awọn orukọ awọn to niṣe pẹlu ẹgbẹ agbesunmomi ti awon ọlọpaa FBI fi lede.
Agbẹnusọ fun minisita feto ibaraẹnisọrọ naa, Uwa Suleiman sọ fun BBC pe, iwe iroyin to gbe iroyin naa jade fẹ fi ba minisita lórúkọ jẹ lasan ni.
Suleiman ni onimọ nipa ẹsin Islam ni Pantami, o sí kẹkọọ kaakiri orilẹ-ede agbaye to fi de orilẹ-ede Saudi Arabia.
Female Car Painter: Èmi ní obìnrin àkọ́kọ́ tí yóò máa ṣiṣẹ́ akunmọ́tò ní Ibadan
O ṣalaye pe koko miran to fihan pe Pantami ko mọ ohun kan nipa awọn ẹgbẹ agbesunmomi ni fidio ti olori Boko Haram Abubakar Shekau ṣe ninu eyi to ti sọ pe Pantami wa lara awọn eeyan ti oun fẹ pa.
O ni Shekau sọ ninu fidio ọhun lọdun 2020 pe Pantami lọ darapọ mọ ijọba bo tilẹ jẹ pe onimọ nipa ẹsin musulumi ni.
Akomolede àti Asa: Kí ni Ìjálá láàrin àwọn ewì alohùn àti bí wọ́n ṣe ń sun-ún?
Ki ni Yoruba n pe ni Ijala, irufẹ awọn eeyan wo lo n sun, asiko wo ni wọn n sun ati pe bawo ni wọn se n sun Ijala?
Lọsẹ yii lori eto Akomolede ati Asa lori BBC Yoruba, Arabinrin Modupe aya Azzez, tii se olukọ ile ẹkọ girama Akure kọ wa nipa Ijala sisun.
Ninu alaye rẹ, aya Azeez ni Ijala jẹ ere awọn ọdẹ , to si sọ nipa iyatọ to wa laarin Ijala ati Iremoje, eyi tawọn ọdẹ maa n sun lasiko ti ọkan ninu wọn ba ku.
Bakan naa la tun kọ nipa ọna tawọn ọdẹ maa n gba lo Ijala lati fi ki ara wọn, se abẹwo sira wọn ati awọn itan nipa Ijala to ti waye ri.
Bakan naa ni olukọ ede Yoruba naa tun kọ wa nipa awọn aseyọri awọn ọdẹ to ti waye sẹyin lati ipasẹ Ijala ati oriki awọn ẹranko nla nla tawọn ọdẹ ti pa ninu igbo.
Ẹ fara balẹ lati kọ ẹkọ toni lori eto yii nipa Ijala sisun.
Iya Ife: Said Balogun, Kemi Afolabi àtàwọn òṣèré míràn ń ṣèdárò Iya Ife tó fayé sílẹ̀
Oríṣun àwòrán, bukysmart/Instagram
Ẹgbẹ awọn oṣere tiata ni Naijiria tun ti n ṣọfọ lẹyin ọjọ diẹ ti agba oṣere nni, Orisabunmi jade laye.
Ẹgbẹ awọn oṣere tiata Yoruba ti kede iku Ashabi Ayantunde, ti ọpọ eeyan mọ si Iya Ife.
Iya Ife jẹ ọkan gboogi lara awọn oṣere tiata Yoruba to dantọ to si mọ ere ṣiṣe, ede Ile Ife si lo maa n sọ ninu ere tiata.
Gẹgẹ bii ohun ti agbọ, obinrin naa dagbere faye laarin wakati diẹ to yẹ ko ṣe ayẹyẹ ọjọ ibi rẹ.
Lara awọn akẹgbẹ rẹ nidii iṣẹ tiata to kede iku rẹ sọ pe, o jẹ ohun ibanujẹ gidi fun awọn ẹbi atawọn akẹgbẹ rẹ nidi iṣẹ ọhun.
Nigba ti Bukky Smart n ṣedaro rẹ loju opo Instagram rẹ, o ni bi iya ni Iya Ife jẹ si oun, lẹyin naa lo gbadura pe ki Ọlọrun dari ẹṣẹ rẹ jin, ko si tun tẹ si afẹfẹ rere.
Oríṣun àwòrán, bukysmart/Instagram
Oṣere miran to tun kẹdun iku rẹ ni Adigun to sọ pe nnkan bii aago mẹta oru ni oun ṣi n ki oloogbe ọhun ku oriire ọjọ ibi rẹ lai mọ pe ọlọjọ ti de.
Ọpọ awọn gbajumọ oṣere miran lo ti bẹrẹ si n kẹdun iku Iya Ife lori ayelujara.
Lara awọn oṣere naa  ni, Saidi Balogun, Damola Olatunji, Kemi Afolabi, ati bẹẹ bẹẹ lọ.
Oríṣun àwòrán, bukysmart/Instagram
Kemi Afolabi ni iya naa maa n fi ifẹ nla han si oun, to so maa n pariwo ọmọ ti wọn n sọ nigbakuugba to ba ri oun loko ere tiata.
Titi di akoko ti a n ko iroyin yii jọ, ko sẹni to le sọ ni pato ohun to ṣokunfa iku oṣere naa.
A gbadura pe ki Ọlọrun tẹ si afẹfẹ rere.
Oríṣun àwòrán, bukysmart/Instagram
Lateef Adedimeji: Mo ri iṣẹ́ Ọlọ́run, omijé gbọ̀n mí, mo sì rí ìdí tí ọpẹ́ fi tọ́ sí mi
Oríṣun àwòrán, adedimejilateef/Instagram
Yoruba ni ẹda to ba mọ inu ro, yoo mọ ọpẹ du nitori ẹni to ba ri isẹ Ọlọrun yoo fi ọpẹ fun Eledua.
Ọpọ isẹ Ọba Oke si la n ri ni ojoojumọ ti a ko ka kun ayafi igba to ba kan wa gangan.
Bẹẹ si ni ọpọ akanda ẹda to yi wa ka ni a ko ti ara wọn yin Ọlọrun logo, ayafi ta ba ri itọni lati se bẹẹ.
Boya itọni yii gan ni gbajumọ osere tiata Yoruba kan, Lateef Adedimeji ri, ti omije fi bọ loju rẹ, to si bẹrẹ si ni fi ọpẹ fun ọba oke.
Nigba to n salaye ohun to mu omije jade loju rẹ naa, agba osere tiata naa ni oun ronu jinlẹ lori ipo tawọn ẹda to ni ipenija oju wa ni.
Adedimeji, ẹni to salaye ohun to foju kan lasiko to sabẹwo sile ẹkọ awọn akanda ẹda to ni ipenija oju loju opo Instagram rẹ, ni ẹru Ọlọrun ba oun.
Oríṣun àwòrán, adedimejilateef/Instagram
"Mo ri ẹwa awọn isẹda Ọlọrun lonii lẹkunrẹrẹ, pẹlu omije loju, mo si ri didi to fi yẹ ki n maa dupẹ lọwọ adaniwaye.
Ọlọrun lagbara, to si maa n mu ki ẹnu ya ẹda pẹlu awọn ohun iyanu to n se, ọna rẹ si yatọ si ti eniyan patapata.
Loni ni mo jami lori aayan mi lati ni oye nipa iru ẹda ti Ọlọrun jẹ, eyi kii se isẹ mi lati mọ, ki oun sa maa jẹ Ọlọrun, ki emi si maa jẹ ẹda ọwọ rẹ."
Adedimeji, ẹni to fi fidio abẹwo to se sile ẹkọ awọn akanda ẹda to ni ipenija oju naa soju opo Instagram rẹ, wa fi ẹmi imoore rẹ han si Ọlọrun fun ipo to wa.
Mo gbadun akoko ti mo lo pẹlu awọn akẹkọọ to ni ipenija oju nile ẹkọ Bethesda, wọn ko ni mọra pupọ.
Ko si ọna miran ti yoo dara ti mo fi le lo akoko mi ju ki n wa pẹlu awọn akanda ẹda yii lọ, awọn eeyan yii ni ẹyin n pe ni afọju amọ mo n pe wọn ni Oju Ọlọrun.
"Awọn eeyan yii ko le ri mi bii ẹlẹran ara amọ wọn so pọ mọ ẹmi mi ju ọna kan lọ, Ọlọrun fi ẹbun ọwọ to lagbara jinki wọn ati ẹmi to yanranti."""
Adedimeji tẹsiwaju pe lati isẹju akọkọ ti oun de ọdọ wọn, titi di akoko ti oun fi wọn silẹ, se ni ayọ ati okun wa lara wọn.
Oríṣun àwòrán, adedimejilateef/Instagram
O ni bi o tilẹ jẹ pe oun ti kuro lọdọ wọn, sibẹ ẹmi oun ko kuro nibẹ, to si n rọ awọn ololufẹ rẹ lati maa sabẹwo sawọn akanda ẹda naa.
"Ohun ti mo n salaye yoo tete ye yin tẹ ba n bẹ awọn eeyan yii wo, lati akoko yii lọ, maa sọ abẹwo mi sile awọn eeyan to ni ipenija oju naa di ajọdun ọdọọdun.
Wọn ko ni da wa mọ, wọn yoo si maa ri mi ni oore koore ju ti tẹlẹ lọ."
Adedimeji ni ipa sise bii afọju ti oun ko ninu ere ti oun se nile ẹkọ awọn afọju naa jẹ ki oun mọ si nipa ohun tawọn eeyan to ni ipenija oju n la kọja.
Akomolede àti Asa: Kí ni Ìjálá láàrin àwọn ewì alohùn àti bí wọ́n ṣe ń sun-ún?
Osere tiata naa wa rọ awọn eeyan to ba n la ipo to nira kọja lati ni ọkan akin, ki wọn si maa ranti pe alaanu ni Ọlọrun.
"Ọlọrun yoo farahan yin lasiko ti ẹ ko nireti rẹ, ẹ sa maa fi ẹmi imoore yin han si, kẹ si maa dupẹ lọwọ rẹ.
Bi ẹmi ba wa, ireti n bẹ, ẹ mase sọ ireti nu nitori ile aye yii rẹwa pupọ, Ọlọrun si dara.
Ramadan Kareem: Wo nǹkan márùn ún tó ṣe kókó àti èèwọ̀ fún aláàwẹ̀
Oríṣun àwòrán, Anadolu Agency
Oṣu apọnle fawọn Musulumi, oṣu Ramadan mii ti tun de.
Lorileede Naijiria ati lawọn orileede mii lagbaye, aawẹ Ramadan ti gbera sọ lẹyin ikede lọdọ awọn olori musulumi.
Ninu oṣu yii, awọn musulumi maa n pa ẹnu ati abẹ mọ lati owurọ kutu titi di igba ti oorun yoo fi wọ.
Sultan ilu Sokoto, Abubakar Saad to jẹ olori musulumi ni Naijiiria lo kede ibẹrẹ aawẹ tọdun yi.
Bayii ti aawẹ ti wa bẹrẹ, ki lawọn nkan marun un to yẹ ki musulumi ṣe lati le gbadun awẹ naa bo ti ṣe yẹ.
RAMADAN: Onímọ̀ ẹ̀sin sọ nípa isẹ́ láádá àti làádà
Lootọ, awẹ ni nnkan ṣe pẹlu ki eeyan maa ṣe mu tabi jẹun ṣugbọn awọn onimọ sọ pe, ti alaawẹ ba fẹ gbadun awẹ, o di dandan ko mu omi daada.
Lasiko ti eeyan ba n jẹ saari tabi lasiko iṣinu, omi mumu yoo jẹ ki awọn ẹya inu ara eeyan ṣe iṣẹ bo ti ṣe yẹ lasiko to ba n gba awẹ.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Omi amuju naa ko daa, ki a ma gbagbe pe niwọntunwọnsi lo yẹ ki a ṣe nkan.
Jẹ awọn ounjẹ to n fun ara lokun, ko si yago fun iyọ pupọ
Bi o ba di asiko saari jijẹ, amọran fawọn alaawẹ ni pe ki wọn jẹ ounjẹ ti yoo fun ara lokun.
Yatọ si eleyi, wọn ni ki iru ounjẹ naa jẹ eleyi ti yoo tete da lara wọn ki wọn si mase jẹ ki iyọ pọ ninu rẹ.
Àwẹ Ramandan; Àwọn ouńjẹ tí a fi ń já àwẹ̀
Bi eeyan ba n jẹun, ko jẹ ni iwọntun wọnsi, ko ma jẹ ounjẹ pupọ nitori eleyi le ṣe akoba fun ara
Iye wakati ti alaawẹ yoo fi gba aawẹ ko yẹ ko ju wakati mejila si mẹtala lọ.
Bi eeyan ko ba lo akoko yii daada, yoo dabi pe gbogbo ọjọ lo fi n gba awẹ ni
Ri  wi pe o ṣeto awọn iṣẹ ati iṣẹ laada lasiko awẹ bi kike alukurani, gbigbọ waasi ati wiwa pẹlu mọlẹbi rẹ.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Bo ba di looru to yẹ ko ji fun Tahajjud naa, la asiko to ba fẹ fi ji kalẹ, ki o ba le ni eto.
Ri wi pe o ṣun daadaa
Oorun a maa jẹ ki ara bọ sipo pada lẹyin ti eeyan ba ṣe wahala.
Pupọ alawẹ ni kii sun daada, ti eleyi si maa mu ki irẹwẹsi kan maa ba wọn.
Oríṣun àwòrán, Others
Bi o ba ri pe o pari gbogbo iṣẹ to y ki o ṣe ti asiko si wa fun ẹ, tara  nara silẹ ko sun ki alaafia ba le ba ara rẹ.
Yiyago fun ounjẹ ati omi mimu to fi mọ ṣiṣọ gbolohun to ba n jade lẹnu alaawẹ jẹ ọna kan gbogi ti alawẹ gbọdọ mojuto.
Irọ pipa, isọkusọ, sisọ ọrọ karimi wa lara awọn ọna ti alaawẹ le fi padanu oore to wa ninu awẹ gbigba.
Lati le dena eleyi, awọn onimọ ẹsin ni ki awọn musulumi sọ ọrọ ẹnu wọn ati iwa wọn.
Awọ nkan marun un toyẹ ki alaawẹ yago fun:
Oyo kidnap: Ọlọ́pàá, fijilanté àti ọdẹ ìbílẹ̀ bẹ́ sínú igbó, wọn gba obìnrin mẹ́ta lọ́wọ́ ajínigbé
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ileeṣẹ ọlọpaa ipinlẹ Oyo ti kede itusilẹ obinrin mẹta tawọn ajinigbe pawo gbe lọjọ Aje.
Agbegbe Onipe lopopona Ijebu-ode si Idi-Ayunre ni ijọba ibilẹ Oluyole, ni awọn obinrin naa ti ko sọwọ awọn ajinigbe ọhun.
Alukoro ileeṣẹ ọlọpaa nipinlẹ Oyo, Adewale Osifeso sọ ninu atẹjade to fi sita pe, iwadii awọn ọlọpaa pẹlu iranwọ awọn ọlọdẹ ati fijilante lo jẹ ki awọn obinrin naa ba ominira.
DSP Osifeso ṣalaye pe awọn ọlọdẹ ati fijilante lo bẹ sinu igbo pẹlu awọn ọlọpaa lati ṣe awari awọn obinrin naa.
Alukoro ileeṣẹ ọlọpaa ni awọn obinrin ọhun, Temitope Okeowo, Abosede Adebayo ati Bola Ogunrinde ti lọ si ile wọn pada, lẹyin ti wọn ṣayẹwo ara wọn tan.
Yemi Farounbi: Yorùbá yóò dáàbò bo ara rẹ́, bí ìjọ́ba bá kùnà láti ràgà bò wọ́n
DSP Osifeso ni iṣẹ ṣi n lọ lati rii pe ọwọ ọlọpaa tẹ awọn agbebọn ajinigbe pawo naa.
Ẹwẹ, kọmiṣọnna ọlọpaa nipinlẹ Oyo, Ngozi Onadeko ti wa rọ awọn eeyan ipinlẹ Oyo lati maa ṣiṣẹ pọ pẹlu ileeṣẹ ọlọpaa, nipa tita awọn ọlọpaa lolobo lori iwa awọn ọdaran lagbegbe wọn.
Ọga ọlọpaa ipinlẹ Oyo ni ileeṣẹ ọlọpaa ko ni kaarẹ nipa didaabo bo awọn eeyan ipinlẹ naa.
Kí ló pa òkú mẹ́jọ tí wọ́n bẹ́ lórí ní Calabar?
Aye fẹlẹ, oriṣiiriṣii iṣẹlẹ lo n ṣẹlẹ ni duniyan.
Lọjọ Iṣẹgun ni iroyin kan jade pe awọn kan ṣadeedee ri oku eeyan mẹjọ ti wọn ti bẹ ori wọn ninu koto ti wọn da wọn sì, lẹnu ọna abawọle silu Calabar, nipinlẹ Cross River.
Aworan yii kii se eyi to sẹlẹ ni Calabar
Agbẹnusọ ajọ ẹṣọ eleto abo NSCDC to ba BBC sọrọ, Solomon Eremi ṣalaye pe, lootọọ ni awọn ri oku eeyan mẹjọ, to ti n jẹra ni abawọlu Calabar.
Ọgbẹni Eremi ni awọn eeyan kan lo tawọn lolobo pe, awọn n gboorun oku eeyan nibi kan.
O ni lẹyin naa ni ajọ NSCDC ṣe awari ibi ti awọn oku naa ti n run.
Torí àti ṣe Kòkò irin, bí mo ṣe máa ǹ fara yá iná nìyìí - Amokoko Saki
Ọgbẹni Eremi ni a ran àwon ẹṣọ pẹlu ibọn, lati lọ wo ohun to ṣẹlẹ gan an níbẹ."
Oku eeyan mẹjọ ni wọn bá nibẹ, ọkunrin ni meje ninu wọn nigba ti ẹnikan jẹ obinrin.
"Ọkan lara wọn si tutu sibẹ."""
Agbẹnusọ NSCDC ni awọn ko le sọ pato bi wọn ṣe ku, tabi iru eeyan ti wọn jẹ.
Amọ, o ni ajọ NSCDC n ṣiṣẹ pọ pẹlu ileeṣẹ ẹka eto ilera ati ayika ijoba ipinlẹ Cross River, lati ko awọn oku naa kuro nibi ti wọn wa nitori wọn ti n jẹra.
Egbejila Fish Village: Àwọn ọlọ́sìn ẹja ní àwọn fi iṣẹ́ báńkì sílẹ̀ wá ṣe ọ̀sìn ẹja ni
Ẹwẹ, awọn ara adugbo ti awọn oku naa wa tiẹ sọ pe, mẹẹdogun ni oku eeyan to wa nibẹ ti wọn si ti ge ori wọn pẹlu.
Awọn agbẹ to n bọ lati oko, ni awọn ara adugbo ni wọn ri awọn oku eeyan naa.
Wọn ni ibi ti iṣẹlẹ ọhun ti ṣẹlẹ ko jina si ibi t'awọn ọlọpaa ti maa n duro lopopona Calabar si Odukpani.
Awọn ara adugbo ni wọn ti pada ko awọn oku ọhun kuro lagbegbe naa.
Ko fẹ si ojumọ kan ti yoo mọ lorilẹede Naijiria bayii, ti araalu ko ni gbọ iroyin pe eeyan kan tabi meji tun ti ko si panpẹ awọn aṣebi ati ajinigbe.
Eyi taa tun gbọ laipẹ yii ni eleyi to ṣẹlẹ ni agbegbe Onipe ni Ibadan lọjọ Aje, nibi ti wọn ti ji obinrin mẹta gbe.
Ọkan ninu awọn obinrin yii, Bola Ogunrinde la gbọ pe o jẹ ọmọogun Naijira.
Awọn meji to ku, Temitope Okeowo ati arabinrin Abosede Adebayo jẹ oṣiṣẹ ilera nile iwosan gbogboniṣe Ijebu Igbo.
Gẹgẹ bi iwe iroyin The nation ti wi, awọn ọkunrin meji kan lo fi to awọn ọlọpaa Idi Ayunre leti pe, awọn ajinigbe ti gbe awọn obinrin naa.
Fulani Kidnapping: Owó púpọ̀ la san kí wọ́n tó fi mi sílẹ̀
Alukoro ọlọpaa nipinlẹ Oyo, Adewale Osifesọ sọ pe awọn n gbiyanju pẹlu ikọ fijilante lati ri pe wọn doola awọn arabinrin yii.
Yatọ si iṣẹlẹ ti ipinlẹ Oyo yii, a tun gbọ pe awọn ajinigbe yinbọn pa Inspẹkitọ ọlọpaa kan, Ambi John ni Abuja. nigba to gbiyanju lati doju ija kọ awọn ajinigbe.
Iṣẹlẹ naa to waye ni adugbo Angwan-Zegele-Zuba ni Abuja, la gbọ pe awọn ajinigbe naa pada gbe eeyan meji salọ, ti ọlọpaa kan ati fijilante kan si fara gbọta.
Egbejila Fish Village: Àwọn ọlọ́sìn ẹja ní àwọn fi iṣẹ́ báńkì sílẹ̀ wá ṣe ọ̀sìn ẹja ni
Awọn mejeeji wa ni ile iwosan nibi ti wọn ti n gba itọju lọwọ.
Yusuf Mariam, to jẹ alukoro ọlọpaa ni Abuja naa ti fidi isẹlẹ naa mulẹ, o ni awọn ti n tọ pinpin awọn ajinigbe naa lati le doola awọn to ko si pampẹ wọn.
Chibok Girls: Kà nípa àwọn ìjínigbé akẹ́kọ̀ọ́ míràn tó wáyé ní Nàìjíríà lẹ́yìn ti Chibok
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Inu ibanujẹ lọpọ awọn obi ọmọ Obìnrin Chibok wa
O ti pe ọdun meje bayi ti ijinigbe awọn akẹkọbinrin ile iwe girama Chibok ni ipinlẹ Borno ti waye.
Ọjọ naa ree bi ana loju awọn ti ko padanu ọmọ, ṣugbọn lọdọ awọn obi ati mọlẹbi awọn to ọmọ to dawati, ibanujẹ ojojumọ ni wọn n ba sun, ba ji.
Bo tilẹ jẹ wi pe pupọ ninu awọn akẹkọọ ọrinlenigbadinkan (279) ti wọn ji gbe, lo ti ribi sa mọ awọn ajinigbe lọwọ tabi ti ijọba doola wọn, amọ o si le ni ọgọrun akẹkọọ to wa ninu ide Boko Haram.
Ninu atẹjade kan ti Amnesty International fi sita lori ọrọ  yii, wọn bẹnu atẹ lu ijọba Naijiria.
Wọn ni o ṣe ni laanu pe aimọye akẹkọọ Naijiria lo di awati nitori ijọba ko ri bi ojuṣe wọn lati daabo bo wọn.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
ọmọ Chibok
Laarin oṣu Kejila ọdun 2020 si oṣu Kẹta ọdun 2021, wọn ti kede ijinigbe lawọn ileewe marun un to kere tan lẹkun ariwa Naijria.
Ifoya ijinigbe mii gẹgẹ bi Amnesty International ti ṣe sọ, ti mu ki wọn ti awọn ileewe bii ẹgbẹta miran pa lagbegbe ọhun.
Amnesty ni ko si ijiya fawọn ikọ Boko Haram to ji awọn ọmọ gbe, bẹẹ si ni awọn alaṣẹ kuna lọpọ igba lati daabo bo awọn ileẹkọ toun ti iṣẹlẹ ijinigbe nibẹ.
Lori ọrọ ijinigbe yii, a ni ki a ṣagbeyẹwo awọn ijinigbe akẹkọọ mii to waye lẹyin ti Chibok.
Nilu Kankara lawọn ajingbe ti jin akẹkọọ to le ni ọọdunrun gbe lọjọ Kọkanla oṣu Kejila ọdun 2020.
Awọn akẹkọkunrin wọn yi pada gba itusilẹ ṣugbọn wahala ati iporuru ọkan to ko ba awọn obi ati araalu kọja afẹnusọ.
Iṣẹlẹ yi mu ki awọn ijọba Kano, Zamfara,Jigawa ati Katsina gbe ilkun awọn ileewe ti pa ni kiakia.
Laarin awọn janduku ati ikọ Boko Haram, niṣe ni wọn n ṣe fakinfa pe awọn lawọn ji awọn akẹkọọ naa gbe.
Ipinlẹ Niger ni ileewe yi naa wa ni owurọ kutu lawọn ajinigbe si gbe awọn akẹkọọ nibẹ lọj Ktadinlogun oṣu Keji 2021.
Oṣu kan lẹyin iṣẹlẹ Kankara ni ti Kagara waye awọn agbebọn lo si ji awọn akẹkọọ yi gbe.
Oríṣun àwòrán, Twitter/Governor Niger
Lọjọ Kẹtadinlọgbọn oṣu Keji ni wọn gba itusilẹ.
Ileewe meji ni awọn agbebọn ṣe ikọlu si ni ipinlẹ Kaduna nibi ti Gomina Nasir El Rufai ti n ṣe akoso to fi mọ Federal College of Forestry Mechanization nibi ti wọn ti gbe akẹkọọ ọgbọn.
Ni ọjọ Kọkanla oṣu Kẹta ni wọn ji wọn gbe.Ibi ti wọn ti ji wọn ko si jina si ileeṣẹ awọn ọmọogun Naijiria.
Ohun oju ri to!
Kete tawọn ajinigbe yi gbe awọn akẹkọọ naa ni wn fi fọnran fidio sita nibi ti wọn ti n fi iya jẹ awọn akẹkọọ naa.
Gẹgẹ bi iroyin to tẹwa lọwọ, nkan bi mẹtala awọn akẹkọọ yi lo ti ribi gba itusilẹ tawọn iyoku si yi wa ni ahamọ.
Awọn eyi ti a  kọ yi nikan kọ lo ṣẹlẹ ṣugbọn eyi taa ye gba wa lati kọ ree.
Titi di baa ṣe n kọ iroyin yi, awọn akẹkọọ Chibok to ku si wa ni ahamọ.
Egbejila Fish Village: Ọlọ́sìn ẹja ní àìríṣẹ́ṣe ló mú káwọn sin ẹja àmọ́ ijọba Kwara ko jẹ káwọn rimu mi.
Isẹ agbẹ ni isẹ ilẹ wa, ẹni ti ko ba sisẹ, yoo jale
Eyi lo mu ki awọn ọdọ kan nilu Ilorin se fi isẹ banki silẹ, maa dawọle isẹ ọsin ẹja, lsna ati mu agbega ba isẹ naa.
Nigba ti wọn n ba BBC Yoruba sọrọ, awọn ọdọ naa ti wọn da abule ọsin ẹja silẹ ni agbegbe Egbejila, ni eti bebe odo Asa nilu Ilorin salaye pe ohun to mu wọn dawọle isẹ naa.
Àwọn ìtàn mánigbàgbé tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí:
Bakan naa ni wọn salaye ipenija to wa niwaju wọn, paapaa bi ijọba Kwara se ni ki wọn ko ọsin ẹja wọn kuro lagbegbe naa nitori ọsin ẹja naa n ba omi Asa jẹ.
BBC Yoruba tun ba ijọba Kwara naa sọrọ lori ohun to ri lọbẹ, to fi wa iru sọwọ lati le awọn ọlọsin ẹja ọhun kuro ni abule ti wọn wa.
Abọ iwadii wa ree nipa bi abule ọsin ẹja ni Asa se gbooro si, awọn anfaani to wa nidi isẹ naa ati ipenija to n ba wọn finra.
Abiola Ajimobi: PDP ti fèsì padà fún Muideen Bello pé owó ló máa ń sọ bí wáàsí rẹ yóò ṣe rí
Oríṣun àwòrán, Sheikh Muhydeen Ajani Bello/Seyi Makinde Facebook
Ẹgbẹ oṣelu PDP nipinlẹ Oyo ti ṣapejuwe ọrọ ti Sheik Muyideen Bello sọ nipa ijọba PDP ipinlẹ Oyo labẹ Gomina Seyi Makinde, gẹgẹ bi ọrọ to kudiẹ kaato.
PDP sọ ninu atẹjade to fi sita pe, gbogbo ọrọ ti Sheik Bello sọ tako ijọba Makinde lo tako ilana ẹsin islam ati awẹ Ramadan to n lọ lọwọ.
Bakan naa ni ẹgbẹ oselu naa ni gbogbo ohun ti Sheik Bello sọ ni ko wa ni ibamu pẹlu ipese ohun eelo amayedẹru ti ijọba Makinde ti pese fun araalu nipinlẹ Oyo.
PDP ni Sheik Bello kuna lati sọrọ soke nipa wahala awọn ẹlẹgbẹ okunkun One Million Boys ni ipinlẹ Oyo ati bi awọn agbalagba to ti fẹyinti lẹnu iṣẹ, ṣe n to lati gba owo ifẹhinti wọn labẹ ijọba APC to wa lori oye ki PDP to gba ijọba.
Oríṣun àwòrán, Sheikh Muhydeen Ajani Bello/Facebook
PDP sọ ninu atẹjade naa pe oju aye ni Sheik Bello n ṣe nibi waasi iranti Gomina Abiola Ajimobi to ti sọrọ tako PDP, wọn ni o n sọrọ lati tẹ awọn to pe sibi waasi naa lọrun ni.
Ẹgbẹ oṣelu PDP ni awọn eeyan ipinlẹ Oyo ko ba fẹ lati gbọ ọrọ Ọlọrun ti yoo ṣe wọn lanfaani ju bi Sheik naa ti tabuku ijọba PDP to wa lode bayii lọ.
PDP ni awọn eeyan ti Sheik Bello n tabuku ijọba Gomina Makinde loju wọn naa lo dibo fún PDP ti wọn si le APC lọ.
Slain Ekiti Police woman: Ìyá rẹ̀ ní àìrìṣẹ́ṣe ló mú kí Bukola Olawoye gba iṣẹ́ ọlọ́pàá
PDP sọ pe waasi to niiṣe pẹlu ifẹ, alaafia ati otitọ lo yẹ ki Sheik Bello maa ṣe lati tu awọn eeyan ninu nitori ohun ti wọn n la kọja lọwọ lorilẹede Naijiria.
Ẹgbẹ naa ni oju awọn ọmọ Naijiria ti ri to pẹlu bi eto aabo ṣe mẹhe lati igba ti ẹgbẹ oṣelu APC ti bẹrẹ sí ni tukọ orilẹ-ede Naijiria.
Oríṣun àwòrán, Seyi Makinde Facebook
Saaju la ti mu iroyin wa fun yin pe ijọba ipinlẹ Oyo ti ke si onimọ nipa ẹsin Islam kan, Sheik Muideen Bello lati gbe agbada oselu wọ, to ba nifẹ lati se oselu, dipo ko maa da asọ ẹsin boju kiri lati se oselu.
Akọwe gomina ipinlẹ Oyo feto iroyin, Taiwo Adisa lo fesi pada bẹẹ fun onimọ ẹsin naa lori esi to fọ pe ko si idagbasoke kankan nipinlẹ Oyo.
Sheik Bello lo kede nibi waasi awẹ Ramadan ọlọdọọdun ti wọn fi n se iranti oloogbe Abiola Ajimobi pe, ni kete ti gomina ana naa ti kuro nipo, ni eto idagbasoke ti duro.
Waasi ọlọdọọdun naa, akọkọ iru rẹ, lo waye ni mọsalasi Ajimobi, Oke Ado Ibadan nibi ti ọpọlọpọ awọn ọrẹ ati ojulumọ Abiola Ajimobi, to di oloogbe lọdun to kọja, lo wa nibi idanilẹkọọ naa.
Sheikh naa to gbe waasi rẹ kalẹ lori pe ko si nkan ti ko ni èrè lọdọ Allah, sọ pe, ko si nkan aritọkasi kankan ninu isejọba to wa nipinlẹ Ọyọ lọwọ lọwọ.
"Nigba to n fi ipaya rẹ han lori eto aabo to mẹhẹ nipinlẹ Oyo, Bello sọ pe ko ti i si ayipada kankan nilu Ibadan. O ni ""a ko le rin bo ṣe wu wa mọ""."
O ni, o yẹ ki awọn eeyan bẹru Ọlọhun, ki wọn o si gbọran si awọn Wòlíì lẹnu.
Mo n sọ fun yin pe nkan ti a ba ṣe ni àwọn eeyan yoo sọ. Ogún rere ni Ajimobi fi silẹ. 
O ni ipele pé 'wọn ṣi n gbaradi ni wọn wa, a ti pada si ipele igbaradi. A ko le gbagbe Lam Adesina àti Abiola Ajimobi (àwọn mejeeji to ti di oloogbe bayii).
Oríṣun àwòrán, Seyi Makinde Facebook
Amọ nigba to n fun Bello lesi ọrọ yii, Adisa ni onimọ ẹsin Islam naa kii se olugbe ipinlẹ Oyo, nitori naa, ko le mọ nipa aseyọri gidi ti gomina Makinde ti se lori aleefa.
"Afọju gan mọ pe aseyọri wa nipinlẹ Oyo lati ọwọ gomina Seyi Makinde, ti ajọ to n se odiwọn akọsilẹ nipa ọrọ aje Naijiria, NBS naa si fidi eyi mulẹ.
Ida mẹrindinlọgbọn ninu ọgọrun ni ajọ NBS fi kede pe idagbasoke ati ọrọ aje ipinlẹ Oyo ru gọgọ si lasiko ijọba Seyi Makinde."
"Awa sa kọ ni ajọ NBS wa labẹ rẹ, abẹ ijọba apapọ ni, nitori naa ohun ti Sheik Bello sọ ko ni itumọ."""
Oríṣun àwòrán, Seyi Makinde Facebook
Bakan naa ni Adisa tẹsiwaju pe ijọba Seyi Makinde n tun ohun to ti bajẹ, to ba nilẹ se ni amọ ko maa pariwo kiri pe nnkan ti bajẹ.
O wa tọkasi oju ọna Moniya si Ilu Iseyin, ti ijọba Makinde sẹsẹ se, to si n bi Bello leere pe se ko gba ibẹ kọja lẹnu lọọlọ yii ni lati mọ ni agbega to ba ọna naa.
"Wakati mẹrin ni wọn fi n rin lati Ibadan lọ si Iseyin tẹlẹ ki Makinde to gori aleefa, amọ nibayii, isẹju marundinlaadọta pe ni wọn fi n rin ọna naa bayii.
Oju ọna Onipepeye ati Akobo naa wa nibẹ, ti ijọba Seyi Makinde ti pari rẹ, to si ti dun rin."
Egbejila Fish Village: Àwọn ọlọ́sìn ẹja ní àwọn fi iṣẹ́ báńkì sílẹ̀ wá ṣe ọ̀sìn ẹja ni
Akọwe gomina Makinde feto iroyin tun salaye pe lara awọn agbasẹse ti Ajimobi gbe isẹ fun, amọ ti ko sisẹ naa lo si jẹ ijọba ipinlẹ Oyo ni owo bii irinwo biliọnu naira.
Adisa wa n gba Muideen Bello nimọran lati gbe agbada oselu wọ, ko si ye fi ẹsin boju, lati maa se oselu.
Oríṣun àwòrán, CCII
Ọjọ Iṣẹgun ni iroyin jade kaakiri ori ayelujara pe gomina ipinlẹ Imo tẹlẹ, Rochas Okorocha ti wa ni akata ajọ to n gbogun ti iwa ibajẹ ni Naijiria, EFCC nilu Abuja.
Ọọfisi rẹ to wa nilu Abuja ni EFCC ti nawọ mu Okorocha lori ẹsun pe o n gbe owo tuulu lọ soke okun, tawọn iroyin kan si ni wọn ti fi si ahamọ.
Bakan naa ni agbẹnusọ fun ajọ EFCC, Wilson Uwujaren fidi iroyin naa mulẹ pe awọn osisẹ ajọ naa ti gbe Okorocha.
Nigba toun naa n fidi isẹlẹ yii mulẹ, Oludamọran pataki fun Senetọ Okorocha, Sam Onwuemeodo, sọ pe ko si nkan to buru ninu bi ajọ EFCC se pe Okorocha si ọọfisi wọn.
Oríṣun àwòrán, CCII
Ọgbẹni Onwuemeodo ṣalaye pe lẹyin ti Rochas fi ipo gomina ipinlẹ Imo silẹ ni ọdun 2019, ni ijọba ipinlẹ naa kọ iwe ẹsun nipa rẹ si ajọ EFCC.
"O ni ""EFCC ṣe iwadii lori ayelujara awọn ẹsun naa, o si ti gbe ọrọ lọ si oriṣiriṣi ile ẹjọ ni Naijiria."
 Ti EFCC ba wa a ránṣẹ pe Okorocha fun awọn àlàyé lori awọn ọrọ to wa nile ẹjọ, ko si nkan to buru nibẹ, paapaa bi ajọ naa ṣe ṣẹṣẹ ni Alaga tuntun. 
O ni isẹ ajọ naa lo n ṣe, ati pe Okorocha yoo ma a fọwọsowọpọ pẹlu rẹ gẹgẹ bi ọmọ Naijiria rere.
Egbejila Fish Village: Àwọn ọlọ́sìn ẹja ní àwọn fi iṣẹ́ báńkì sílẹ̀ wá ṣe ọ̀sìn ẹja ni
Igba akọkọ kọ re e ti EFCC yoo ránṣẹ pe e. Wọn n pe e, o si da wọn lohun.
Àmọ́ ṣa, ó ni awọn yoo ma a wo boya ajọ EFCC yoo jawọ ninu awọn ẹjọ naa, tabi yoo tẹsiwaju pẹlu wọn nile ẹjọ.
Chibok Girls: Lẹ́yìn ọdún méje tí wọn gbé àwọn akẹ́kọ̀ọ́, owó ààbò fún iléèwé wọlẹ̀
Oríṣun àwòrán, AFP
Ọpọlọpọ ijinigbe lo ti waye lọdun yii
Lasiko ijinigbe akẹkọọ ọlọpọ yanturu to waye lọdun 2014 ni Chibok, tii ṣe ọdún meje sẹyin, ìjọba ilẹ gẹẹsi ṣe agbekalẹ ẹgbẹlẹgbẹ miliọnu dọla pẹlu atilẹyin asoju ijọba ilẹ gẹẹsi nigba naa, lati daabo bo awọn akẹkọọ nile iwe.
Baalu lo balẹ bagẹ silu Chibok ninu oṣu kẹta ọdun 2015, Okonjo Iweala tó jẹ mínísítà ètò ìsúna àti olori ajọ eleto katakara WTO báyii, lo bọ silẹ ninu baalu ọhun.
Ọpọ awọn obi ti wọn ji ọmọ wọn gbe ati awọ olori ilu si n duro wamuwamu lati kii kabọ.
O lọ si Chibok lati ṣe agbekalẹ okuta akọkọ fun atunṣe awọn ile ẹkọ ijọba ti awọn Boko Haram ti bajẹ lálẹ́ ọjọ buruku eṣu gbomin mu naa, tii se ọjọ kẹrinla, oṣu kẹrin ọdun 2014.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Okonjo Iweala se agbekalẹ okuta ipinle akọkọ fun atunṣe ile ẹkọ Chibok lọdun 2015
Abẹwo Okonjo Iweala yii jẹ ọkan lara igbesẹ to waye, lẹyin ti awọn ijọba ilẹ okere da si ọrọ ijinigbe awọn ọmọ to din diẹ ni ọọdunrun (276) lati ọwọ awọn agbesumọmí alakatakiti ẹsin ni Chibok lọdun 2014.
Ọpọ awọn ilu ati orilẹede lo n lo 'hastag' #BringBackOurGirls, ti olori ijọba ilẹ gẹẹsi tẹlẹri, Gordon Brown si ṣe agbatẹru ikowojọ ọgbọn milọnu dọla.
Owo ọhun si to bi mílọnu mejilelogun pọun fun aabo awọn akẹkọọ nile iwe, awọn ajọ kan labẹ isọkan agbaye, ijọba Naijiria ati awọn aladani kan, lo pese owo naa.
"Ẹẹdẹgbẹta ile iwe ni a o daabo bo: awọn yara ikẹkọọ tuntun yoo wa; a o mọ odi yi ile iwe ka, bakan naa ni a o gba awọn ọlọdẹ.
Oríṣun àwòrán, Borno state govenment
Erongba wọn ni pe, awọn akẹkọọ ko ni ni ifọkanbalẹ nikan ti wọn ba n lọ si ile ẹkọ, sugbọn ayika to duro re lati le kọ ẹkọ ati lati ni idagbasoke yoo wa gẹgẹ bi Gordon Brown ṣe sọ ninu oṣu karun ọdun 2014"
Mọrain-mọrain lọrọ naa dun lẹnu rẹ, ọdun meje ree, ko si aabo nile iwe ẹẹdẹgbẹta, wọn ko kọ kilaasi tuntun miran.
Titipa ni ile ẹkọ Chibok si wa
Saaju ni awọn aṣeyọri kan wa, bi wọn ṣe ṣe agbekalẹ awọn kilaasi fun awọn akẹkọ nibudo awọn ti ko ri ile gbe nitori ogun Boko haram.
Bakan naa ni wọn pese nkan ikawe fun awọn ọmọ, sugbọn ko ju ọdun meji lọ ti gbogbo eto yii fi doju de pẹlu ipolongo iside rẹ to waye nilu Abuja.
Awọn iṣẹlẹ ijinigbe ni awọn ile ẹkọ ni iha ariwa laipẹ yii fihan bi ijóba Naijiria ṣe kuna lati gbe awọn eto ijọba to le daabo bo awọn akẹkọọ nile iwe.
Titi di oni, ọmọ to din diẹ ni aadọfa lo sì wa ni ahamọ Boko haram lara awọn ti wọn ji ko ni Chibok.
Bakan naa, ọgbọn ninu awọn ile ẹkọ ti wọn pinu lati kọkọ fi bẹrẹ aabo nile ẹkọ, ni wọn ko tun kọ titi di oni yii.
Bo tilẹ jẹ pé, wọn kọ awọn kilaasi kọọkan lẹyin ti Ngozi Okonjo-Iweala ṣe abẹwo si Chibok, sùgbọ́n awọn adari ilu naa ni wọn ko kọ daadaa.
Iṣẹ ajanbaku ni, gbogbo atẹgun to ba ti fẹ bayii, lo n ba apakan tabi omiran ile naa jẹ. Ojoojumọ lo n wo titi di oni yii, ko si ẹni to lo kilaasi naa.
Allan Manasseh agbẹnusọ ilu Chibok lo sọ bẹẹ fun BBC.
Ẹwẹ, àwọn ọmọogun lo n kọ kilaasi to wa nibẹ bayìí pẹlu iranlọwọ ijọba ipinlẹ Borno, lẹyin ti Gomina Babagana Zulum ṣabẹwo si ile iwe naa ni oṣu kọkanla ọdun to kọja, ti nkan to foju ri si ba a lọkan jẹ.
Ọgbẹni Brown, tii se asoju eto ẹkọ ninu ajọ isọkan agbaye sọ fun BBC ninu atẹjade kan pe, pẹlu gbogbo ijinigbe to tun waye yii, oun ti ṣe ipade pẹlu mínísíta ètò isuna Naijiria ni ọdun 2020.
O ni afojusun ipade naa ni lati gbiyanju, ko gbaruku ti eto idaabo to peye fawọn ile ẹkọ.
Titi di asiko yii, ofiisi rẹ ko dahun ibeere bi wọn ṣe na ọgbọn miliọnu dọla ti wọn ko jọ lọjọsi, nítori gbogbo owo naa, ijọba Naijiria ni wọn ko fun.
Oríṣun àwòrán, Ijoba ipinle Borno
Fọtọ inu oṣu kọkanla ọdun 2020 to ṣe afihan Kolaasi ti afẹfẹ ti ṣi orule rẹ lọaa
Ètò ẹkọ girama agba, onikilaasi kinni (SSI) kuna ni ọdun 2016, eyiun ọdun kan lẹyin ti íjọba ana kuro lori oye ni Naijiria.
Goodluck Jonathan lo wa nijọba nigba ti wọn ji awọn ọmọ naa gbe, ti wọ́n si ṣe agbekalẹ eto ẹkọ SSI sùgbọ́n ààrẹ Muhammadu Buhari gba ijọba lọwọ rẹ.
Ajọ isọkan agbaye ati awọn miran to fẹ ṣe agbekalẹ owo sọ pe, ìjọba Naijiria kii yọju si ipade deede ati pe, awọn eto iṣejọba aarẹ Buhari di ọpọ nkan lọwọ, ti wọ́n si pada yọ ipese owo naa kúro ninu eto wọn.
Ninu atẹjade kan lati ile iṣẹ ilẹ gẹẹsi, o di ẹbi ru ijọba aarẹ Buhari pe oun ló fi nkan falẹ lati tẹle eto aabo fun ile ẹkọ.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Gani Adams: Akẹ́kọ̀ọ́ tó bá fẹ́ wọ iléẹ̀kọ́ gíga nílẹ̀ Yorùbá gbọdọ̀ yege nínú èdè abínibí
Oríṣun àwòrán, Nigerian Canadian agency
Aarẹ Ọna kakanfo tilẹ Yoruba, Gani Adams ti kesi awọn gomina to wa lawọn ipinlẹ mẹfẹẹfa nilẹ Yoruba lati sọ ẹkọ ede Yoruba di ọranyan.
Ede Yoruba yii ni Adams ni o gbọdọ jẹ dandan fawọn akẹkọọ lati yege ninu rẹ, ki wọn to le gba wọn wọle sawọn ile ẹkọ giga to jẹ tawọn ipinlẹ nilẹ Yoruba.
Aarẹ Ọna Kakanfo ni igbesẹ yii ni yoo daabo bo ede abinibi wa ko ma lọ sokun igbagbe laipe ọjọ.
Aarẹ Gani Adams gbe imọran yii kalẹ lasiko ajọdun asa ibilẹ to maa n waye lọdọọdun nipinlẹ Oyo eyi ti wọn pe ni Ọdun asa ibilẹ fun igbafẹ ti Omi tuntun.
Ifọrọwerọ  pẹlu Gani Adams lori ọrọ Sunday Igboho
Ọdun ibilẹ naa, ti wọn pe akori rẹ ni 'Asa wa...Ipilẹ wa' nileesẹ eto iroyin, asa ati igbafẹ nipinlẹ Oyo se agbatẹru rẹ eyi to waye ni gbọngan asa ibilẹ, loke Mokola nilu Ibadan.
Aarẹ Gani Adams fikun pe asa ni nnkan se pẹlu asọ ti ẹya kan ba n wọ, ede ti wọn n sọ lẹnu ati ọpọ ohun to nii se pẹlu ẹya naa.
"Gẹgẹ ba se n mu ede Gẹẹsi ati isiro lawọn ile ẹkọ ni ọranyan, naa lo yẹ ka fi ede Yoruba se ọranyan ki akẹkọọ to wọle ẹkọ giga lawọn ipinlẹ.
Eyi yoo sewuri fawọn akẹkọọ iran yii lati mọ ede abinibi wa lati ile ẹkọ alakọbẹrẹ titi de girama, ki wọn to ri aaye wọle ẹkọ giga.
'Bí ojú ọ̀nà agbàrá òjò tí ijọba ṣe n'IIorin ṣe ń pa àwọn ọmọ iléèwé wa rèé! Ẹ sàánú wa'
Koko ohun to yẹ ka fi sinu ilana eto ẹkọ ree, ede Yoruba gbọdọ jẹ dandan ninu rẹ, awọn olukọ to n kọ ede Yoruba kan si gbọdọ mu isẹ wọn lọkunkundun pẹlu.
Gani Adams wa gbawọn gomina ipinlẹ nilẹ Yoruba lati bẹrẹ si ni gba awọn olukọ ede Yoruba sisẹ lati se iwuri fawọn ogo wẹẹrẹ ati ọdọ wa.
O fikun pe awọn obi ko ni akoko to pọ lati lo pẹlu ọmọ ninu ile,ọpọ iwa tawọn ọmọ wa si n hu ni wsn kọ lati ọdọ awọn ọdọ wọn.
Egbejila Fish Village: Àwọn ọlọ́sìn ẹja ní àwọn fi iṣẹ́ báńkì sílẹ̀ wá ṣe ọ̀sìn ẹja ni
Mo wa n rọ awọn gomina wa lati sọ ede Yoruba di ọranyan fun gbogbo akẹkọọ to ba fẹ wọ ile ẹkọ gigalaarin ọdun mẹta si akoko yii."""
Biola Adebayo: Oríṣiríṣi ọjà ni mo kiri ní kékeré, síbẹ̀ mí ò rí owó wọ Fáṣítì
Oríṣun àwòrán, biolabayo1/Instagram
Yoruba bọ, wọn ni oju kii pọ́n iṣin ko ma là, bi ẹkun si pẹ titi di alẹ kan, ayọ n bọ ni owurọ.
Bẹẹ gan-an ni ọrọ ri fun gbajugbaja oṣerebinrin, Biola Adebayo nigba to n seranti ọpọ ipenija to la kọja, ko to jẹ eeyan nile aye.
Osere naa to ranti igbe aye rẹ àtẹ̀yìnwá gẹgẹ bi ọmọ atẹrọ̀fọ̀ dide ni orisirisi nkan ni oun kiri bii ọja lasiko ijagudu lati se rere nile aye.
Aworan kan ti Biola fi si ori ayelujara Instagram rẹ, lo mu ko ranti awọn asiko ti nkan nira fun nigba ewe rẹ.
Ninu aworan naa, to ya nibi kan to ti n ṣe eré ti a o ti i mọ orúkọ rẹ, ni Biola ti n kiri búrẹ́dì.
Oríṣun àwòrán, biolabayo1/Instagram
"O ni ""aworan yii mu mi ranti igbe aye mi ni ibẹrẹ pẹpẹ. Oriṣiriṣi nkan ni mo kiri gẹgẹ bi ọdọmọbinrin, sugbọn búrẹ́dì tita ni awọn eeyan fi mọ òun."
O ni oun kiri burẹdi naa titi di igba ti oun di ọlọmọge ni, to si gba oun to ọdún meje, ki oun to wọ fasiti.
Ko tan sibẹ o, arẹwà oṣerebinrin naa to ti lami-laaka ninu iṣẹ sinima ṣíṣe sọ pe ẹẹmẹrin ọ̀tọ̀ọ̀tọ̀ ni oun ni anfaani lati kekọọ ni fasiti, sugbọn ìṣòro aisi owo ja oun kulẹ.
Biola Adebayo to dupẹ lọwọ Ọlọ́run fun ibi ti igbeaye rẹ duro de bayii sọ pe kii ṣe iwe ẹ̀rí akọkọ nikan ni oun ni, o ni oun tun ti gba iwe ẹri 'masters' keji.
Egbejila Fish Village: Àwọn ọlọ́sìn ẹja ní àwọn fi iṣẹ́ báńkì sílẹ̀ wá ṣe ọ̀sìn ẹja ni
Asiko naa kii ṣe nkan to rọrùn rara, àmọ́ mi o ti itori rẹ má nifẹ Ọlọ́run, bẹ ẹ ni mo si ni ireti. Ki n ma parọ, Ọlọ́run dára si mi lọpọlọpọ.
O fikun ọrọ rẹ pe, lootọ òun ko ti i de ipele to wu oun, àmọ́ oun ko si ni ipele ti oun wa tẹlẹ mọ.
Biola sọ pe gbogbo ẹpisteli ọrọ ti oun kọ waye lati le ṣe iwuri fun awọn eeyan pe, ki wọn o ma ṣe sọ ireti nu.
" Ohunkóhun to wu ki o ma a la kọjá, ma sọ ireti nu lori ilepa rẹ. O ni idi ti o fi n la asiko naa kọjá.
Ìwọ ṣa ma a gbadura, fi Ọlọ́run ṣáájú, ja fafa, tẹra mọ isẹ rẹ, ki o si ni afojusun. Imọlẹ rẹ yoo tàn laipẹ."
Odeda Oko Kidnap: Ìyá ọmọ tó sọnù ní ajínigbé ni òun kò gbọdọ̀ sọ iyé owó ìtúsílẹ̀ tí wọn gbà
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Wọ́n ti ri ọmọkùnrin, ẹni ọdún mẹtàlá ti  ìròyìn rẹ jáde pé àwọn ajínigbé ji lọ́jọ́ Sátide, lásìkò tí òun àti ìyá rẹ̀ fẹ́ wọle ní ǹkan bi aago mẹ́sàn alẹ́ lagbègbè Obada ni ìpínlẹ̀ Ogun.
Nínú ìfọ̀rọ̀wánilẹ̀nu wò ti BBC ṣe pẹ̀lú ẹbi ọmọde yìí, iya rẹ́ ta fi orukọ bo ni asiri sàlàyé pé, gbogbo ẹ̀bẹ̀ tí àwọn bẹ̀ àwọn ajínigbé láti gba ẹgbẹ̀rún lọ́nà ààdọ́ta Náírà, pàbó ló já sí.
Ọkan nínú àwọn ẹbi ọmọ náà ṣàlàyé pé, gbogbo ọ̀nà ni àwọn ti wá owó jáde láti rí ṣàjọ, ti àwọn ajínígbé náà sì kìlọ pé, tí owó òn kò bá pé, àwọn yóò gba ẹmi ọmọ wọn.
Ìyá ọmọ náà pẹ̀lú sàlàyé pé, nínú àlàyé tí ọmọ òun ṣe nígbà tó délé, ló tí sọ fún àwọn pé, àwọn ajinigbé náà fi ye òun pé, tí àwọn obi òun bá kọ làti gbé owó wá, àwọn yóò máa mú òun lọ, tí àwọn yóò sì kọ ọ bi yóò se máa yìnbọn.
Akomolede àti Asa: Kí ni Ìjálá láàrin àwọn ewì alohùn àti bí wọ́n ṣe ń sun-ún?
Ó ní ọmọ náà ṣàlàyé pé, wọ́n fún òun lónjẹ lásìkò tó tọ́ bó tilẹ̀ jẹ́ pé òun kọ̀ láti jẹ òunjẹ náà, sùgbọ́n gbogbo ǹnkan tí ó n ṣẹlẹ nínú ilé ni òun ń rí ni ibi ti òun wà lọ́dọ̀ àwọn ajínigbe naa.
Àwọn ẹbi ọmọ náà ni ìmọ̀ràn ọlọ́pàá lásìkò tí ọ̀rọ̀ yìí ṣẹlẹ̀ ni pé, àwọn kò gbọ̀dọ̀ san owó kankan, pé wọ́n yóò gbé ọmọ náà sílẹ̀.
Sùgbọ́n o ni nígbà ti àwọn ri bi ọ̀rọ̀ náà ṣe n lọ, ni àwọn fí lọ wa owó naa.
Wọ́n ni àwọn ri gbogbo bi a ṣe n bá ọlọ́pàá sọ̀rọ̀ àti iroyin gbogbo, wipe kí a múra sí bóyá a kò fẹ́ rí ọmọ wa mọ́, ìgbà tó dí àná ni wọ́n pada fí ọmọ naa sílẹ̀ pẹlú owó ìtúsílẹ̀.
"Wọ́n túbọ̀ kìlọ̀ fún wá pé a kò gbọdọ̀ sọ iye owó ìtúsílẹ̀ tí a san."""
Female Car Painter: Èmi ní obìnrin àkọ́kọ́ tí yóò máa ṣiṣẹ́ akunmọ́tò ní Ibadan
Ìyá ọmọ náà ni àti sọ́ọ̀bù ni àwọn ti dé lálẹ́ ọjọ́ Sátide, ti òun sì ni kí ọmọ náà bọ́ sílẹ̀ nínú ọkọ̀ láti lọ ṣí géètì fún òun láti wọlé.
Amọ o ni àwọn agbébọ̀n náà, ti wọn sin awọn dele ti mú ọmọ, ọjọ́ kejì ni wọ́n tó pé láti bèèrè fún owó ìtúsílẹ̀ tii se àádọ́ta míliọ̀nù Nàírà lẹ́yìn ọ̀pọ̀lọpọ̀ ẹ̀bẹ̀, wọ́n já owó naa wá sílẹ̀.
Títí dí àsìkò yìí, kò sí ẹni ti a funra sí pé ó le ṣe irú ǹnkan náà, nítòrí míníra àti omi tutu ni mó n tà, tẹ̀kún-tẹkun ni mo fi ń bẹ̀ wọ́n sùgbọ́n wọn kò gbọ́ ẹbẹ, a fi ìgbà tí a san owó.
Ọmọ náà sọ pé méjì nínú àwọn ajinigbe naa ló gbọ́ èdè Yorùbá sùgbọ́n Fulani ni wọ́n, àti pé, gbogbo àwọn tó n wá sí ilé ni òun ń ri lọ́dọ̀ wọ́n lọ́hun, sùgbọ́n òun kò lè sọ̀rọ̀.
Egbejila Fish Village: Àwọn ọlọ́sìn ẹja ní àwọn fi iṣẹ́ báńkì sílẹ̀ wá ṣe ọ̀sìn ẹja ni
"Ọmọ náà ni àsìkò tí àwọ́n wà nínú igbó, kí màmá òun tó gbé owó de ni àwọn ajínígbén yìí ti ṣètò ìbn wọ́n kálẹ̀, tí àwọn ọlọ́pàá pẹ̀lú sì jẹ́rìí si pé, ìbọ̀n tó lágbaára ló wà lọ́wọ́ àwọn ọ̀daran náà.
Lẹ́yìn ò rẹ̀yin tí a gbé owó sílẹ̀ ni wọ́n fi ọmọ náà sílẹ̀.
Nigeria Cash Crunch: Ọ̀dá owó n bá ìjóba àpapọ̀ fíra, àwọn gómìnà Yorùbá ní kò sí gìrì
Oríṣun àwòrán, AFP
Àwọn aṣojú ìjọba ni ìhà ìwọ̀-òòrùn Gúúsù Nàìjiríà ti ni, lábẹ́ àkóso bótiwùkórí, àwọn kò le jẹ òṣìṣẹ́ lówó oṣù kankan.
Ọ̀rọ̀ yìí kò ṣẹ̀yin bí àwọn aṣojú ìjọba àpapọ̀ méjì kan ṣe ké gbàjare pé, orílẹ̀-èdè yìí nílò ìrànwọ́ owó ní wàrànṣesà, láti pese ohun eelo amáyédérun fún ara ìlú.
Bó tílẹ̀ jẹ́ pé mínísítà fún ètò ìsúná Zainab Ahmed bẹnu atẹ́ lu ọ̀rọ̀ tí gómìnà ìpínlẹ̀ Edo sọ pé, ìjọba apapọ̀ lọ tẹ́ owó tó tó ọgọ́ta bílíọ̀nù nàìrà lósù tó kọja.
Gomina Godwin Obaseki ni owo ti wn tẹ ọhun lo jẹ kí wọ́n ri owó ajẹmọ́nú ìpínlẹ̀ olosoosu awọn ijọba ipinlẹ pín fún wọ́n.
Amọ Ahmed sọ pé ìjọba kan nílò láti mú àlékún bá owó àpawọlé fún ìjọba.
Ìdí rèé tí BBC Yorùbá ṣe bá àwọn tí ọ̀rọ̀ kan ni ìjọba ìpínlẹ̀ sọ̀rọ̀, lórí ìgbáradì wọ́n bí owó ajẹmọ́nú olóṣooṣù láti ọ̀dọ̀ ìjọba àpapọ̀ kò bá wọlé lásìkò tó yẹ.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Àkọ̀wé ìròyìn fun gómìnà nípínlẹ̀ Oyo, Taiwo Adisa sàlàyé pé láti ìgbà ti gómìnà Seyi Makinde ti gorí àléfà, idá mẹ́rìndílọ́gbọ̀n ní ètò ọ̀rọ̀ ajé fi rú gọ́gọ́ sí, fún ìdí èyí tipẹ́ tipẹ́ ni ìjọba ìpínlẹ̀ Oyo ti wa wọ̀rọ̀kọ̀ fi sàdá nipa ọda owo naa.
Ó ní ètò ọ̀rọ̀ Aje jẹ́ ọ̀kan pàtàkì nínú àfojúsùn onígunmẹ́rìn Gómínà  Makinde, nítorí náà ni àwọn ṣe tí n gbé ẹ̀ru wiwo naa láti ilẹ̀.
O ni bí owó ìjọba kò bá tilẹ̀ wọlé, ìpínlẹ̀ Oyo ko le jẹ gbèsè.
Adisa ni tó bá ṣe díẹ̀ sí, owó tí ìjọba àpapọ bá ń sàn yóò kan dà bi àfikún owó ni, nítorí lọ́wọ́ báyìí, ìjọba ń sapa láti jẹ́ ki ètò ọ̀rọ̀ ajé rú gọ́gọ́ sí ni, nípa dídí àwọn ọ̀nà tí owó ìjọba ń gbà sòfò.
Kótó dí pe ọdún mẹ́rìn yìí yoo fẹnu kọ́lẹ̀, ìdá ọgọ́ta iyé owó tí ìjọba ìpínlẹ̀ Oyo nílò ni yóò maa pèsè fún ara rẹ."
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Bákan náà ni kọ́mísọ̀nà ọ̀rọ̀ tó n lọ ní ìpińlẹ̀ Eko Gbenga Omotosho náà sàlàyé pé láti ilẹ̀ ní gbogbo ènìyàn ti mọ̀ pé ìpínlẹ̀ Eko kìí fí owó ìjọba apapọ̀ ṣe gbogbo ǹkan mère mère ti wọ́n ń rí ni ìpińlẹ̀ Eko.
Ó ni àfojú sùn Eko ni láti dàbi àwọn orílẹ̀-èdè tó ti tójúbọ́ ni àgbáyé nítori náà, wọ́n n lo owo orí ara ilú láti ṣe iṣẹ́ ribiribi ti wọ́n n ṣe, tí ọ̀pọ̀ ko si gbẹ́yìn nínú owó orí sísan.
Omotosho ni oníruurú ètò ni ìjọba n se láti mú ǹkan dẹ̀run fún àwọn èlétò-ọ̀rọ̀ ajé tó bá fẹ́ dá ilé iṣẹ́ sílẹ̀, èyí sí n jẹ́ kí ètò ọ̀rọ̀ ajé gbòòrò sí ni ìpínlẹ̀ Eko.
Egbejila Fish Village: Àwọn ọlọ́sìn ẹja ní àwọn fi iṣẹ́ báńkì sílẹ̀ wá ṣe ọ̀sìn ẹja ni
Oore ọfẹ Ọlọrun nijọba Osun fi n gbera tẹlẹ, ẹru ko ba wa:
Bákan náà ni ọ̀rọ̀ rí ní ìpínlẹ̀ Osun gẹ́gẹ́ bí akọ̀wé ìròyìn Gómìnà  Ismail Omipidan ṣe sọ.
O ni láti ìgbà ti gómìnà Adegboyega Oyetola ti gorí oyè láti ọdún méjì sẹ́yìn, kò sí owó kan tó dàbí alárà tó n wá láti ọ̀dọ̀ ìjọba àpapọ̀.
Ní oṣù míràn wọ́n kìí fí owó kankan ránṣẹ́ sí ìpínlẹ̀ Osun, èyí sì tí jẹ́ kí a sán sòkòtò wa le láti ilẹ̀, a kìí dúró de owó láti ọ̀dọ̀ ìjọba àpapọ̀.
"Omipidan ni ""nítorí ìdí èyí ni a ṣe mú ètò ọ̀rọ̀ ajé, ibi ìgbáfẹ́, wíwa kùsà, àti iṣẹ́ ọ̀gbìn ni ọ̀kúnkúndùn."""
O sàlàyé pé ìpińlẹ̀ Osun yàtọ̀ gédégédé sí àwọn ìpínlẹ̀ tó kù láti ẹ̀yin wá, oré ọ̀fẹ́ Ọlọ́run si ni ìjọba fí n gbéra, nítori náà kò sí ǹkan tó lé ṣẹ̀lẹ̀ tí ẹ̀rù yóò bá ìpińlẹ̀ Osun.
Buhari Trip to London: Ǹkan mẹ́rin tó ṣẹ̀lẹ̀ nígbà tí Buhari rín ìrìnàjò lọ London
Oríṣun àwòrán, Buhari Sallau
Ní ọ̀gbọ̀n ọjọ́ oṣù kẹta ọdún 2021 ni ilé ṣẹ́ ààrẹ kéde pé ààrẹ Muhammadu Buhari yóò rìn ìrìnàjò lọ sókè òkùn láti lọ sínmi.
Ọ̀pọ̀ ọmọ Nàìjíríà ló n fàpa jánú pé láti ìgbà tí ààrẹ Muhammadu Buhari ti gori oye, lo ti n rin ìrìn àjò lọ sí ilẹ̀ òkèrè láti lọ gba ìtọ́jú.
Amọ lasiko ti aarẹ Buhari fi lọ gba itọju nilu London naa, ọpọ isẹlẹ lo waye ni Naijiria, marun ninu wọn ree:
Ǹkan márùn-ùn tó ṣẹlẹ̀ ní Nàìjíríà lásìkò tí Buhari kò sí nílé
Oríṣun àwòrán, NMA
Ní kété tí àarẹ Buhari rìnrìnàjò ni àwọn dókítà ni Nàìjíríà gùnlé ìyànṣẹ́lódì nítorí ìjọba kọ̀ láti san owó oṣù wọn.
Àwọn  ǹkan míràn tí wọ́n tún pè fún ni pé kí ìjọba san gbogbo owó tí wọ́n ti jẹ àwọn sẹ́yìn.
Èyí nìkàn kọ́, àwọn owó ààbò nítorí ewu tó bá de bá wọn lẹ́nu iṣẹ́ ni wọn tun n beere fun pẹlu.
Ẹgbẹ́ awọn dókítà náà sàlàyé pé, àwọn tun fẹ ki ijọba san awọn ajẹsilẹ owó àjẹmọ́nú fàwọn dókítà tó ṣiṣẹ́ lásìkò igbele arun Convid-19, pàápàá jùlọ, àwọn ilé ìwòsàn tí ìjọba ìpínlẹ̀.
Agbebọn kọlu ileesẹ ọlọpaa ati ọgba ẹwọn ni Imo, ẹlẹwọn bii ẹgbẹrun meji sa lọ
Ní ọjọ́ keje oṣù kẹrin ọdún 2021, ọjọ́ kẹjọ tí ààrẹ Buhari ti wà ni ilẹ̀ gẹ̀ẹ́sì, ni àwọn agbébọ̀n lọ ṣe ìkọlù sí ọgbà ẹ̀wọ̀n tó wà ni Imo.
Ìròyìn fi ìdí rẹ̀ múlẹ̀ pé àwọn ọ̀daràn toto ojilelẹgbẹsan ati mẹrin (1,844) ló sá kúrò lọ́gbà ẹ̀wọ̀n.
Àwọn tó ṣe ìkọlu sí ọ̀gbà ẹ̀wọ̀n yìí bákan náà ló tún ṣe ìkọlu sí àgọ́ ọlọ́pàá, lẹ́yin èyí ni gómìnà fi ìpè kóníléògbélé síta láti aago mẹ́wàá alẹ́ sí aago mẹ́fà ìdájí.
Ààrẹ Muhammadu Buhari fi ohùn ránṣẹ́ sílé pé kí gbogbo àwọn ẹ̀sọ́ elétò ààbò ní ìpínlẹ̀ Imo àti gbogbo ẹ̀sọ elétò ààbò ni ẹkùn náà lépa àwọn ọdaràn tó kọlu ọgbà ẹwọ̀n àti ilé iṣẹ́ ọlọ́pàá ọhun.
Oríṣun àwòrán, PoliceNG
Lásìkò tí ààrẹ Buhari rìnrìn àjò lọ sí ilẹ̀ gẹ̀ẹ́sì bákan náà, ló yan ọ̀gá àgbà ọlọ́pàá tuntun, Baba Alkali, tó sí gbé iṣẹ́ túntun le lọ́wọ́ láti fójú àwọn ọdaran hàn.
Èyí tún mú kí àwọn ènìyàn máa kọ hàà nítórí sáájú ni ààrẹ Buhari ti fí oṣù mẹ́tà kún àsìkò ti ọga ọlọpa to wa nipo nigba naa, Adamu.
Amọ nigba ti Buhari de ilu oyinbo lo tun pasẹ pe ki wọn yan ẹlomiran rọpo Adamu lẹsẹsẹkẹ.
Ìyàlẹ́nú ló jẹ́ pé, ibi àbẹ̀wò iṣẹ̀lẹ̀ ikọ̀lù sí ọgbà ẹ̀wọn àti àgọ ọlọ́pàá ni Adamu wa, nígbà tí ààrẹ Muhammadu Buhari yọ níṣẹ́.
Lẹ́yìn tí ààrẹ Buhari lọ ìrìn àjò ni àwọn gómìnà ẹkùn South-East ṣe àgbékalẹ̀ Ebube Agu gẹ́gẹ́ bí ẹ̀sọ alaabò fun ẹkùn wọ́n
Àwọn gómiǹà náà tó péjọ láti ṣe ifilọ́lẹ̀ ẹgbẹ́ náà ni Gómínà ti Abia, Okezuo Ikpeazu ati ti Anambra, Willie Obiano.
Awọn gomina yoku ni ti Enugu, Ifeanyi Ugwuanyi; Ebonyi, Dave Umahi àti Hope Uzodimma tó gbàlejò wọ́n ni Imo.
Fete Gede: Wo àwọn èèyàn tó ń jí àwọn òkú láti bèèrè ààbò ẹ̀mí
Oríṣun àwòrán, Travel Noire
Airin jinna, lai ri abuke ọkẹrẹ, t'eeyan ba rin jinna, yoo ri ẹja to yarọ ninu ibu.
Awọn eeyan kan ma ree, ti wọn maa n ba oku sọrọ lọdọọdun fun aabo ẹmi, owo, ọmọ ati fawọn ipese nnkan miran.
Ọdun awọn to ti ku ti wọn maa n pe ni Fete Gede, jẹ ọkan lara ayẹyẹ to ṣe pataki julọ fawọn ẹlẹsin ibilẹ to n lo oogun dudu, ti wọn n pe ni Voodoo.
Àwọn ìtàn mánigbàgbé tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí:
Ayẹyẹ ọhun to maa n waye lọdọọdun, ni wọn ti maa n ṣe ajọyọ lori awọn ẹmi airi, awọn to wa lajule ọrun at'awọn oku lorilẹede.
Oríṣun àwòrán, Travel Noire
Ọdun naa ti wọn maa n ṣe lọjọ meji akọkọ ninu oṣu kọkanla, lawọn eeyan maa n lo lati wa agbara, abo ati ibaṣepọ ọtun pẹlu awọn oku.
Ọpọ eeyan lo maa n lo asiko yii lati ba awọn eeyan wọn to ti ku sọrọ, awọn ti wọn jọ ni asọti ọrọ papọ ki iku to mu wọn lọ.
N ṣe ni ẹmi awọn oku maa n ba le awọn eeyan lori nibi ajọdun naa.
Awọn ẹlẹsin ibilẹ to n lo oogun dudu Voodoo, to jẹ ọkan lara awọn ẹsin to ti wa nilẹ Afirika tipẹ, lo ni ajọdun yii.
Oríṣun àwòrán, Travel Noire
Ọpọ ninu awọn eeyan to n se ajọdun awọn oku yii, lo wa lati orilẹ-ede Benin, awọn mii wa lati iran Yoruba ni Naijiria, awọn kan lati Ghana, nigba ti awọn mii lati ẹkun ijọba Kongo.
Koda, awọn ẹlẹsin Kristẹni gan an maa n darapọ mawọn to n ṣe ajọdun yii lorilẹede Haiti.
Orilẹ-ede Haiti ni ẹsin yii ti bẹrẹ ati apa ilẹ Caribbean, nibi tawọn eeyan ti wọn ko lẹru lati iwọ oorun Afirika wa.
Fun ọpọ ọdun bayii, ẹsin Voodoo ti dapọ mọ ẹsin Kristẹni ati Musulumi.
Ajọdun Fete Gede bẹrẹ pẹlu awọn to maa n mura bi ẹmi airi ti wọn maa n pe ni Loas.
Oríṣun àwòrán, Travel Noire
Awọn mii maa n wọ aṣọ funfun, ti wọn o si maa jo lọ si oju saare ti wọn n sin oku, si pẹlu ẹbun ti wọn fẹ fun awọn oku.
Bakan naa ni wọn maa n gbe ounjẹ dani fawọn oku fun aabo wọn lori awọn alaaye.
Ajọdun yii maa n gba okun ati agbara awn to ba n se e nitori ẹmi awọn oku maa n gun wọn, ti ẹmi awọn oku naa yoo si dabi ti alaaye.
Ajọ̀dun awọn oku yii lo maa n se pẹki n pẹki pẹlu ayajọ ọjọ awọn oku ninu ẹsin Kristiẹni, ti wọn n pe ni All Saints Day.
Oríṣun àwòrán, Travel Noire
Wọn tun maa n fi ajọdun yii ṣe iranti Papa Gede, ẹni ti wọn gbagbọ pe oun lo kọkọ ku, ti o sí ṣaaju awọn oku miiran lọ si ilẹ tuntun tii ṣe ibugbe awọn oku.
Wọn tun maa n fi oríṣìíríṣìí nkan pa ara wọn to fi mọ fifi ata soju ara wọn, nigba ti akoko wọn ba to lati fawọn oku ni ẹbun.
Awọn eeyan tun maa n lo ajọdun Fete Gede lati beere fun owo, ẹmi gigun, ọmọ ati abo lọwọ awọn ẹmi airi.
Oduduwa Nation: Ọlọ́pàá dá ìwọ́de fún ìyapa Nàíjíríà dúrò fún ìgbà díẹ̀ ní Sagamu
Oríṣun àwòrán, Screen Shot
Awọn ọlọpaa to wa nilu Sagamu da iwọde ita gbangba tawọn eeyan to n polongo Oduduwa Nation n se nilu naa duro fun igba diẹ ni ọjọ Ẹti.
Olayomi Koiki, tii se agbẹnusọ fun asaaju ajijagbara to n polongo orilẹede Oduduwa, Sunday Igboho, lo kede isẹlẹ yii loju opo Facebook rẹ.
Koiki, to n gbe iwọde naa bo se n waye, lo jẹ ki awọn eeyan to n wo iwọde naa loju opo Facebook rẹ gbọ nipa iro ibọn to n dun nibi iwọde naa.
Iwọde ọhun lo ti kọkọ waye ni ọja kan to gbajumọ nilu Sagamu lati ta awọn eeyan ji nipa orilẹede Oduduwa ti wọn n fẹ ko jẹ dida silẹ.
Oríṣun àwòrán, Screen Shot
Awọn iyalọja to si n tẹti si ipolongo idasilẹ orilẹede Yoruba naa ni inu wọn n dun lati gbọ ọrọ awọn olupolongo ọhun, bi wọn se n salaye fun wọn nipa ipo ti Naijiria wa.
Koda, awọn iyalọja to bawọn eeyan naa lo sọrọ ni wọn fi ero wọn han pe awọn n fẹ ki orilẹede tuntun naa wa si imusẹ laisi rogbodiyan kankan.
Amọ bi awọn olupolongo naa se de iwaju agọ ọlọpaa to wa ni Sagamu, ni awọn ọlọpaa to wa nibẹ tu jade ni ọgọọrọ, ti wọn si n yinbọn soke.
Oríṣun àwòrán, Screen Shot
Isẹlẹ yii lo mu ki awọn oluwọde yii sọkalẹ kuro ninu awọn ọkọ ti wọn n gbe kiri lati se iwọde, ti wọn si fi ẹsẹ rin lọ ba awọn ọlọpaa naa.
Wọn ba wọn sọrọ alaafia, ti wọn si salaye pe awọn ko ba ti ija wa, iwọde ẹ̀rọ̀ ni awọn n se, eyi ti ko le ni ọwọ rogbodiyan ninu, eyi tawọn n se fun idasilẹ orilẹede tuntun.
Yemi Farounbi: Yorùbá yóò dáàbò bo ara rẹ́, bí ìjọ́ba bá kùnà láti ràgà bò wọ́n
Awọn ọlọpaa naa wa rọ awọn oluwọde naa lati se iwọde wọn ni pẹlẹ putu, ti awọn mejeeji si jọ sere ati awada, ki wọn to pinya.
Oduduwa Nation: Olùwọ́de ní ètò ààbò tí Makinde pèsè, ló mú ki ìwọ́de Ibadan lọ wọ́ọ́rọ́
Awọn eeyan to n seto ipolongo fun idasilẹ orilẹede Oduduwa ti gbosuba kare fun gomina ipinlẹ Oyo, Seyi Makinde lori atilẹyin rẹ.
Nigba to n ki gomina Makinde pe o seun, agbẹnusọ fun Sunday Igboho, Olayomi Koiki ni awọn n m riri ipese eto aabo peye to pese fawọn oluwọde Oduduwa Nation.
Koiki, to kede bẹẹ loju opo Facebook rẹ, Koiki ni awọn n kede fun araye pe gomina ipinlẹ Oyo ti seto gbogbo eto to yẹ lati jẹ ki alaafia jọba lasiko iwọde naa.
"Gomina ipinlẹ Oyo lo se atilẹyin fun iwọde Oduduwa Nation nipa ipese eto aabo to peye, lati ri daju pe ẹnikni ko da iwọde alaafia naa ru.
Oríṣun àwòrán, Koiki Media
Atilẹyin gomina Makinde yii lo fi n da wa loju pe ipolongo alaafia naa yoo lọ laisi rogbodiyan kankan."
Awọn oluwọde naa wa mọ riri atilẹyin gomina Seyi Makinde fun aseyọri iwọde alagbara to waye lọjọ Abamẹta naa.
Oríṣun àwòrán, Koiki Media
Saaju la ti mu iroyin wa fun yin pe pitimu ni agbegbe Mapo ati Oja Oba nilu Ibadan kun ni idaji ọjọ Abamẹta fun awọn ọlọpaa to n gbarodan.
Agbegbe yii si ni iwọde naa ti gberasọ, bẹẹ ni awọn agbofinro yii tun wa kaakiri awọn agbegbe to se koko nilu Ibadan lati ri daju pe alaafia jọba lasiko iwọde naa.
O ti to ọjọ mẹta bayii ti ariwo ti gba ilẹ kan pe iwọde alagbara nla kan yoo waye nilu Ibadan, tii se olu ilu ipinlẹ Oyo lonii ọjọ Abamẹta.
Awọn eeyan to n polongo idasilẹ orilẹede Oduduwa si ni wọn n se agbatẹru iwọde naa, eyi ti wọn ni yoo waye ni gbọngan Mapo.
Aago mẹsan owurọ ọjọ Satide si ni wọn ni iwọde naa yoo bẹrẹ ni Mapo, ti wọn yoo si maa lọ yika ilu Ibadan lati ba awọn eeyan sọrọ.
Bẹẹ ni irọkẹkẹ nipa iwọde naa ti gbode, ti ọpọ eeyan si n woye pe se iwọde naa yoo waye laisi rogbodiyan bi.
Amọ nigba ti BBC Yoruba gunlẹ si gbọngan Mapo ni aago to yẹ ki iwọde waye, a ko tii kofiri awọn eeyan to se agbatẹru iwọde naa.
Titi di akoko yii ta n nko iroyin yii jọ, ko ti i si ẹnikan kan ninu wọn to yọju.
Koda, awọn agbofinro ti oju wọn ko rẹrin rara lo ti de Mapo lati idaji, ti wọn si fọn ka gbogbo agbegbe Oja Oba.
Nigba ti BBC Yoruba se iwadii lọwọ ọkan lara awọn to se agbatẹru iwọde naa lori aago lati mọ ohun to n da wọn duro, o ni inu ile lawọn si wa bayii.
Ohun ti ko han si wa ni boya wọn n reti ki awon ẹsọ alaabo kuro ni agbegbe naa, ki iwọde to bẹrẹ, amọ lọwọ lọwọ bayii, awọn agbofinro ti sọ agadagodo si ẹnu ọna Mapo.
Yemi Farounbi: Yorùbá yóò dáàbò bo ara rẹ́, bí ìjọ́ba bá kùnà láti ràgà bò wọ́n
Ojogbon Banji Akintoye ati Sunday Igboho wa lara awon to yẹ ko le iwaju iwọde naa.
Slain Ekiti Police woman: Ìyá rẹ̀ ní àìrìṣẹ́ṣe ló mú kí Bukola Olawoye gba iṣẹ́ ọlọ́pàá
Adura ti ẹda kọọkan maa n gba ni pe ohun ta jẹ la n wa, ka ma pade ohun ti yoo jẹ wa.
Amọ adura yii ko gba rara fun obinrin ọlọpaa kan nipinlẹ Ekiti to lọ sẹnu isẹ lọjọ ti wọn n se atundi ibo sile asoju sofin ilẹ wa.
Obinrin ọlọpaa naa, Sajẹnti Bukola Olawoye lo bawọn sisẹ agbofinro lọjọ Satide, Ogunjọ osu Kẹta ọdun 2021 nibi atundi ibo ẹkun Ila oorun Ekiti sile asoju sofin.
Bukola ni ọta ibọn ba lasiko ti rogbodiyan gbode nibi atundi ibo naa, to si jade laye lọjọ Keji nile iwosan to ti n gba itọju, eyi to mu ki wọn so eto idibo naa rọ.
BBC Yoruba fẹsẹ kan de ile oloogbe Olawoye, lati mọ bi adanu obinrin ọlọpaa naa se ri lara wọn.
Nigba ti wọn n ba wa sọrọ,  iya ati alagbatọ obinrin naa ni airisẹse lo mu ki Bukola lọ gba isẹ ọlọpaa, ti oun si ri iran iku rẹ ni kete ti wọn yinbọn mọ.
Wọn wa n bẹ ijọba lati se awari ẹni to yinbọn mọ obinrin naa, tii se ẹni ọdun mẹtalelọgbọn, to si fi ọmọ meji silẹ saye lọ.
Kọmisana ọlọpaa nipinlẹ Ekiti naa ni oun ri isẹlẹ naa bii eyi to wu Ọlọrun nitori gbogbo eto to yẹ ni awọn se lati dena rogbodiyan lasiko ibo naa.
Kano Killer Juice: Ìjọba Eko, Osun, Katsina, Cross River àti Sokoto figbe ta lẹ́yìn tí ẹlẹ́rindòdò gbẹ̀mí èèyàn mẹ́wàá
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ijọba ipinle Kano ti kede pe, eeyan mẹwaa ti dero ọrun, ti awọn irinwo miran si ti dero ile iwosan, lẹyin ti wọn mu ẹlẹrindodo kan ti wọn ko darukọ rẹ.
Ṣaaju ni ijọba ipinlẹ naa ti kọkọ sọ pe ẹlẹrindodo yii kan naa gba ẹmi eeyan mẹta, to si sọ eeyan mẹtalelọgọjọ dero ile iwosan.
Kọmiṣọna eto ilera ipinlẹ ọhun, Aminu Tsanyawa, sọ ninu fidio kan ti wọn fi ṣọwọ si awọn akọroyin pe, ninu awọn irinwo to wa nile iwosan, nnkan bi aadọta lo n gba itọju lọwọ lori aisan to jọ mọ kindinrin.
Bi ijọba Kano ṣe n lọgun pe ki awọn eeyan ṣọra fun ẹlẹrindodo naa, awọn ijọba ipinlẹ Eko, Katsina, Cross River, Sokoto ati Osun naa ti n kilọ fun awọn eeyan ipinlẹ awọn lati ṣọra fun mimu oniruru ẹlẹrindodo.
Oríṣun àwòrán, Kano State Government
Bo tilẹ jẹ pe wọn ni ki awọn eeyan ma foya, wọn ki wọn nilọ lati maa wo ọjọ ori ẹlẹrindodo ki wọn to maa mu.
Nibi ipade awọn akọroyin kan to waye niluu Kano lọjọ kẹrindinlogun, oṣu kẹta, Aminu Tsanyawa sọ fun awọn eeyan pe aisan naa ti tan de ijọba ibilẹ mẹtala.
Ileeṣẹ eto ilera ipinlẹ naa sọ pe lara awọn ami ti awọn to lugbadi aisan ọhun n fi han ni itọ pipọn, iba ati oju pipọn.
Lẹyin naa ni wọn rọ awọn eeyan naa lati sọra fun irufẹ ẹlẹrindodo ti wọn yoo maa mu, paapaa lasiko Ramadan yii.
"Iwadii ti ajọ NAFDAC ṣe fi han pe lara awọn eroja ti wọn fi po ẹlẹrindodo naa ni ""Hyroxylamine"" wa,  eyi ti wọn ni awọn agbesumọmi maa n lo lati fi ṣọṣẹ."
Cattle Ranching: Ẹ wo Fulani darandaran to tako àṣà dída màálù kiri lójú pópó
NAFDAC fi kun pe ọwọ ti tẹ awọn to wa nidii ileeṣẹ to n po ẹlẹrindodo naa, iwadii si ti bẹrẹ.
Ẹwẹ, ijọba ipinlẹ Eko ti kilọ fun awọn eeyan ipinlẹ rẹ lati maa wo ọjọ ori ẹlẹrindodo ki wọn to maa mu.
Kọmiṣọna fun ọrọ to n lọ, Gbenga Omotoso sọ fun awọn akọroyin pe ki awọn araalu ma ṣe mu ẹlẹrindodo ti ko ba gba ontẹ ajọ NAFDAC.
Nigba to n sọrọ lori ẹlẹrindodo to n ṣekupa awọn eeyan ni Kano, Omotoso sọ pe awọn ko ni gba ki ẹnikẹni ta ẹlẹrindodo naa nipinlẹ oun.
Ni ipinlẹ Osun, olubadamọran pataki si gomina Gboyega Oyetola, Siji Olamiju ti kilọ fun awọn araalu lati sọra fun mimu ẹlẹrindodo ti wọn ko ba mọ daadaa.
Slain Ekiti Police woman: Ìyá rẹ̀ ní àìrìṣẹ́ṣe ló mú kí Bukola Olawoye gba iṣẹ́ ọlọ́pàá
O sọ pe o rọrun lati ko ẹlẹrindodo to n paayan ni Kano wọ ipinlẹ Osun nitori bi awọn eeyan oke ọya ṣe pọ ni ipinlẹ naa, nitori naa oju ni alakan fi n ṣọri.
"Olamiju ni ""a ti gbọ nipa ẹlẹrindodo ti NAFDAC sọ pe o n pa awọn eeyan ni Kano, a fẹ fi akoko yii rọ awọn ọmọ Naijiria, paapaa awọn eeyan ipinlẹ Osun lati maa sọra fun ẹlẹrindodo ti wọn ko ba mọ daada lasiko awẹ yii."""
O pari ọrọ rẹ pe iṣẹ ti bẹrẹ pẹlu ajọṣepọ NAFDAC lati ṣawari ẹlẹrindodo naa, ki wọn le ko kuro nipinlẹ Osun to ba jẹ pe o ti wa lori igba.
Bolanle Ninalowo: Azeez ní súná mi àmọ́ ìrírí ayé kan ló sọ mi di Krístẹ́nì
Oríṣun àwòrán, iamnino_b/Instagram
Yoruba ni iriri aye kii ti ni titi, ko ti ni pa, ọgbọn naa ni yoo fi kọ ni.
Bẹẹ si ni bi iriri aye ba de ba ẹ́da kan, awọn ọ̀na ti yoo gba yọ kuro nibẹ ni yoo maa wa lasiko naa, ki ọkan rẹ le balẹ.
Ohun to sẹlẹ ree pẹlu gbajugbaja oṣere tiata Yoruba kan, Bolanle Ninalowo, ẹni to ṣalaye idi to ṣe fi ẹsin Islam silẹ di ọmọlẹyin Kristi.
Ninalowo sọrọ yii ninu ifọrọwerọ kan to se lori ẹrọ Instagram.
Gẹgẹ bo ti salaye, idile musulumi gidi ni wọn bi Ninalowo si, amọ o ṣalaye pe oun yipada sí Kristẹni nitori iriri kan ti ko dara ti oun ni.
Ninalowo ti orukọ musulumi rẹ n jẹ Azeez sọ pe, awọn obi oun, to fi mọ awọn ẹbi ti wọn jẹ musulumi, ko le gba oun nigba ti iṣoro de.
'Òṣìṣẹ́ Bánkì ni mí l'Amẹ́ríkà kí n tó bẹ̀rẹ̀ Tíátà'
Gbajumọ oṣere naa ni iwe mimọ Bibeli nikan lo gba oun ninu iṣoro naa, eyi ti ko salaye rẹ faraye.
O ni lati igba naa, ni oun ti n ka Bibeli nigba gbogbo, ti oun si di ọmọlẹyin Kristi bi o tilẹ jẹ pe oun kii lọ sile ijọsin rara lati jọsin.
Ni kete ti mo gba bibeli mu, o di iwe to n tọ mi sọna ni igbesi aye mi lati igba naa, Ninalowo lo sọ bẹẹ.
Arẹwa ọkunrin oṣere naa ni, oun ko le gbagbe bi oun ti ri ojutuu sí iṣoro ti o n ba oun finra nigba naa ninu Bibeli.
Oríṣun àwòrán, iamnino_b/Instagram
Ninalowo sọ pe ẹẹkan pere ni oun bawọn jọsin ni sọọsi ri sugbọn o salaye pe ojoojumọ ni oun maa n ka Bibeli ni akaye.
Slain Ekiti Police woman: Ìyá rẹ̀ ní àìrìṣẹ́ṣe ló mú kí Bukola Olawoye gba iṣẹ́ ọlọ́pàá
Bola Tinubu: Mo gbóṣùbà fáwọn tó ń pín ìrẹsì fún mẹ̀kúnnù pẹ̀lú àwòrán mi
Oríṣun àwòrán, Twitter/Arise Nigeran Youth
Eekan ẹgbẹ oṣelu APC, Asiwaju Bola Tinubu ti sọ pe, oun kọ loun n pin irẹsi fawọn eeyan lapa ariwa orilẹede Naijiria ninu awẹ Ramadan to n lọ lọwọ yii.
Tinubu sọrọ yii ninu atẹjade kan to fisita lati ipasẹ oluranlọwọ rẹ feto iroyin, Tunde Rahman.
Laipẹ yii ni aworan apo irẹsi ti wọn ya Tinubu si lara lu ori ayelujara pa, ti ahesọ ọrọ naa si ni Tinubu lo n pin irẹsi naa lẹkun ariwa naa.
Tinubu ṣalaye ninu atẹjade naa pe lootọọ ni oun ri aworan apo irẹsi ti wọn ya oju oun si lara lori ayelujara, ṣugbọn oun kọ lo wa nidi rẹ.
Yemi Farounbi: Yorùbá yóò dáàbò bo ara rẹ́, bí ìjọ́ba bá kùnà láti ràgà bò wọ́n
Ẹwẹ, Tinubu gboṣuba fawọn ẹlẹyinju aanu to n pin irẹsi lasiko aawẹ yii.
O ni iwa ifẹ ati ififuni tawọn eeyan naa fihan lasiko Ramadan yii dara pupọ.
Ọpọ lo gbagbọ pe Tinubu n fi pinpin irẹsi lapa ariwa Naijiria ṣe ipolongo ṣaaju ibo aarẹ ọdun 2023 ni.
Sotayo Sobola: N kò le ṣeré farakinra pẹ̀lú ọkùnrin mọ́ lẹ́yìn ìgbeyàwó
Oríṣun àwòrán, Instagram/sotayogaga
Iyawo dun lọsingin, ọkọ tun mi gbe. Ọkan gboogi ni iran Yoruba jẹ ninu awọn to maa n bu ọla fun awọn to ba gbeyawo tabi re ile ọkọ.
Eyi lo difa fun gbajugba arẹwa oṣere tiata Yoruba, Tayo Sobola, ti ọpọ mọ si Sotayo Gaga, to sọ pe awọn eeyan n fun oun ni apọnle lẹyin ti oun ṣe igbeyawo tan ju ti tẹlẹ lọ.
Lẹyin to ṣe igbawo bonkẹlẹ tan, Sotayo ni ile ọkọ dun, o si larinrin pẹlu.
Arẹwa oṣere tiata Yoruba sọ pe ọdun meje loun fi ṣe ọrẹ pẹlu ọkọ oun ko to di pe awọn ṣe igbeyawo.
O ni lootọọ ni pe ko le ṣalai maa si idojukọ ninu igbeyawo, amọ Sotayo ni oun ati ọkọ oun dagba to lati wa ojutuu si idojukọ to ba wa.
''Igba tuntun mii ni igbeyawo jẹ fun emi ati ọkọ mi, a ṣi ti n rinrin ajo naa lọ diẹ diẹ,'' Sotayo lo sọ bẹẹ.
Nigba to n sọrọ nipa ayipada to ti ba ipa ti o maa n ko ninu ere lẹyin to ṣe igbeyawo tan, Sotayo ni oun ti semẹdọ nipa ṣiṣe awọn ere ti yoo mu ki oun farakinra ju pẹlu ọkunrin ninu ere bayii.
O ni bo tilẹ jẹ pe, ọkọ oun mọ pe iṣẹ tiata ni iṣẹ oun ki awọn to fẹra, oun naa ko ni ko ipa ti inu ọkọ oun ko le dun si ninu ere.
Yemi Farounbi: Yorùbá yóò dáàbò bo ara rẹ́, bí ìjọ́ba bá kùnà láti ràgà bò wọ́n
Sotayo ti wọn ṣẹṣẹ fi joye Sarauniya (Yeye) Uke Kingdom nipinlẹ Nasarawa sọ pe, o gbọdọ ni awọn nkan ti aafin Uke ri lara oun ki wọn to fun oun loye naa.
''Emir Uke gangan an sọ fun mi pe ibeji baba oun lo jẹ oye naa kẹyin, lẹyin naa ni wọn fi oye yii da oun lọla.
Wọn gbọdọ ri mi gẹgẹ bi awokọsẹ rere fawọn obinrin ni Nasarawa ki wọn to fun mi loye yii,'' Sotayo ṣalaye.
Secret Cult: Ọjọ́ orí àwọn akẹ́kọ̀ọ́ náà wà láàrin ọdún 14 sí 18
Oríṣun àwòrán, @GreaterLagosNG
Ileeṣẹ ọlọpaa ipinlẹ Eko ti fi ṣikun ofin mu awọn  ọdọ mẹrin kan, ti wọn fẹsun kan pe wọn jẹ ọmọ ẹgbẹ okunkun.
Wọn ni awọn afurasi naa tẹkọ leti lọ si ipinlẹ Eko lati Ogun lati ṣakọlu si awọn ọmọ ẹgbẹ okunkun miran, to wa lawọn ile iwe girama kan lagbegbe Akinyele ati Alakukọ.
Gẹgẹ bii atẹjade ti alukoro ileeṣẹ ọlọpaa ipinlẹ Eko, Muyiwa Adejobi fi lede, o ni awọn afurasi ọhun jẹ ọdọ ti ọjọ ori wọn ko ju ọdun mẹrinla si mejidinlogun lọ.
Adejobi sọ pe meji lara awọn ọdọkunrin naa jẹ akẹkọọ ile ẹkọ girama Odewale Community High School to wa ni Ijoko, nipinlẹ Ogun.
Yemi Farounbi: Yorùbá yóò dáàbò bo ara rẹ́, bí ìjọ́ba bá kùnà láti ràgà bò wọ́n
Nigba ti awọn meji to ku jẹ akẹkọọ ile ẹkọ Tunik Internation School, to wa ni Dalemo Alakuko.
Atẹjade naa tẹsiwaju pe ni kete ti awọn agbofinro gbọ pe awọn ọmọ ẹgbẹ okunkun naa n mura lati kọlu awọn orogun wọn nile iwe miran ni wọn tọpaṣe wọn lọ.
Lara awọn ohun ija ti wọn ri lọwọ awọn afurasi naa ni ada, egboogi oloro, ati oriṣiriṣi oogun abẹnu gọngọ.
Slain Ekiti Police woman: Ìyá rẹ̀ ní àìrìṣẹ́ṣe ló mú kí Bukola Olawoye gba iṣẹ́ ọlọ́pàá
Ẹwẹ, kọmiṣona ọlọpaa ipinlẹ Eko, Hakeem Odumosu ti pasẹ pe ki wọn ko awọn afurasi naa lọ si agọ wọn to wa ni Ikeja.
Lẹyin naa lo ni ki wọn bẹrẹ iwadii ni kikun ati ọna lati fi ṣikun ofin mu awọn ọmọ ẹgbẹ okunkun to jẹ orogun wọn, ti wọn n gbiyanju lati ṣakọlu si.
Prince Philip: Ọkọ ọbabìnrin ilẹ̀ Gẹ̀ẹ́sí àtàwọn ẹbí rẹ̀ ti ṣe ẹ̀yẹ ìkẹyìn fún Duke ti Edinburgh
Oríṣun àwòrán, PA Media
Ọbabinrin ilẹ Gẹẹsi atawọn ẹbi rẹ ti ṣe ẹyẹ ikẹyin fun ọkọ rẹ, Duke ti Edinburgh ni Windsor Castle.
Iba eeyan perete, to fi mọ awọn ẹbi atawọn ọmọ oloogbe mẹrin, eyii ti William ati Harry wa lara wọn ni wọn tẹlẹ posi ti wọn gbe oloogbe ọhun si.
Lẹyin naa ni wọn gbe posi ọhun wọ ile ijọsin St. George to wa ni Windsor Castle lori ọkọ ayọkẹlẹ land Rover.
Ni dede aago mẹta ọsan ni wọn ṣe idakẹjẹ oniṣeju kan kaakiri ilẹ Gẹẹsi.
Bo tilẹ jẹ gbagede Windsor Castle ni wọn ti ṣe eto isinkun naa, wọn ko gba ọpọ ero laye nibẹ tabi lawọn ile miran to jẹ ti ori ade ilẹ Gẹẹsi.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Mẹsan an ninu awọn mọlebi ori ade lo tẹlẹ posi Prince Philip, to fi mọ awọn ọmọọba, Anne, Charles, Edward pẹlu Andrew.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Duke ti Cambridge ati ọmọ ọba Harry kọwọrin pẹlu ibatan wọn, Peter Philips.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Vice Admiral Sir Timothy Laurence ati the Earl ti Snowdon na ko gbẹyin nibẹ.
Oríṣun àwòrán, PA Media
Ki wọn to ṣe idakẹjẹ oni iṣẹju kan ni ọkọ ọbabinri Elizabeth de, to si lo pade Biṣọọbu agba ti Canterbury.
Oríṣun àwòrán, PA Media
Oríṣun àwòrán, Reuters
Oríṣun àwòrán, Reuters
Oríṣun àwòrán, AFP
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ọpọ ero lo wo bi eto isinku naa ṣe lọ lati okeere.
Oríṣun àwòrán, Reuters
Oríṣun àwòrán, PA Media
Awọn ọmọ ogun yinbọn soke bi wọn ṣe n gbe oku Prince Philip wọ inu ile ijọsin St. George.
Oríṣun àwòrán, PA Media
Awọn eeyan ilu gbiyanju lati peju sibẹ ṣugbọn wọn ko gba ọpọ ero laaye nitori ilana itakete siraẹni.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Oríṣun àwòrán, Mary Evans Picture Library
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Oríṣun àwòrán, Reuters
Oríṣun àwòrán, PA Media
Oríṣun àwòrán, Reuters
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Eniola Badmus: Gbajúgbajà òṣèré tíátà di aṣojú LAWMA ní ìpínlẹ̀ Eko
Oríṣun àwòrán, Instagram/Eniola Badmus
Gbajugbaja oṣere tiata, Eniola Badmus ti di aṣjoju ajọ LAWMA to n ri si gbigba ipinlẹ Eko mọ.
Eniola fi oriṣiiriṣii fọto bi wọn ṣe sọ di aṣoju ajọ LAWMA soju opo Instagram rẹ.
Gbajugbaja oṣere naa ṣalaye pe aṣọ ti oun wọ lọ si ibi ayẹyẹ  ''Headies award'' lo sun oun de bi ibi ire bayii.
''Ori ayelujara mi titi lori aṣọ ti Eniola wọ lọ si ibi ami ẹyẹ Headies Award niluu Eko, ọpọ lo sọ pe mo da bi oṣiṣẹ LAWMA pẹlu aṣọ ti mo wọ lọ si ibi ayẹyẹ naa.
Mo gbagbọ pe ifẹ tawọn eeyan ni si mi lo jẹ ki wọn sọ pe mo dabi oṣiṣẹ LAWMA to n ko idọti loju titi.
Ṣugbọn ọrọ ti wọn sọ ni bii oṣu meji sẹyin bayii ti ja si oriire fun mi.
Nkan iwuri lo jẹ fun mi pe mo ti di aṣoju ajọ LAWMA nipinlẹ Eko.
Mo ṣetan lati lo ẹbun ti Eledua fun mi lati ṣiṣẹ pọ pẹlu ajọ LAWMA,'' Eniola ṣalaye.
Eniola dupẹ lọwọ ijọba ipinlẹ Eko fun anfaani ti wọn fun mi lati ṣiṣẹ pọ gbe ipinlẹ Eko ga si.
O tun dupẹ lọwọ awọn ololufẹ rẹ bakan naa, o rọ wọn lati ṣiṣẹ pọ pẹlu ijọba gbe ipinlẹ Eko ga si.
Eniola ti darapọ mọ Woli Arole, Bolanle Ninalowo ati Tobi Bakre gẹgẹ bi awọn oṣere to jẹ aṣoju ajọ LAWMA nipinlẹ Eko.
Ọkọ àti ìyàwó sọ àsọtẹ́lẹ̀ tani yóò wọlé nínú PDP tàbí APC
Covid-19 vaccine: Ẹ má dán abẹ́rẹ́ Covid-19 wò lára mi, mi ò gbà! Mi kìí ṣe ẹmọ́ òyìnbó- David Oyedepo
Oríṣun àwòrán, facebook/David Oyedepo
Oludasilẹ ijọ Living Faith ti ọpọ mọ si Winners Chapel, Biṣọọbu David Oyedepo tun ti sọ pe oun ko ni gbabẹrẹ ajẹsara covid-19.
Biṣọọbu Oyedepo ni oun ko ni tọrọ aforiji lọwọ ẹnikẹni nitori oun kọ lati gbabẹrẹ ajẹsara ajakalẹ arun coronavirus.
Biṣọọbu naa sọrọ yii nibi eto adura ijọ naa to waye lọjọ Abamẹta ọjọ kẹtadinlogun oṣu kẹrin ọdun 2021 yii.
Pasitọ Oyedepo ni oun kii ṣe ẹmọ oyinbo ti wọn le dan abẹrẹ coronavirus wo lara rẹ.
Oludasilẹ ijọ Winners Chapel tun sọ pe abẹrẹ Oxford/Astra Zeneca ti ijọba n fun awọn ọmọ Naijiria lodi si ofin.
Oyedepo ni ''ọrọ ajakalẹ arun coronavirus ti daru mọ gbogbo agbaye loju, ṣugbọn ninu ijọ Ọlọrun ni ojutuu si arun naa wa.''
David Oyedepo ni: ''Mi o o ri bi ti wọn ti n fi ipa fun eeyan abẹrẹ. Mi kii ṣe agbẹjọro ṣugbọn mo ro pe ko tọna.
O kan le wa ṣadeedee wa si ile mi lati fun mi labẹrẹ lai ranṣẹ si ọ tẹlẹ.'
A kii ṣe ẹmọ oyinbo ni Naijiria, itanjẹ lasan ni ọrọ abẹrẹ yii,'' Oyedepo lo sọ bẹẹ.
hhhhhh
Oṣu kẹta, ọdun 2021 yii ni orilẹede Naijiria gba abẹrẹ Oxford/Astra Zeneca to le ni miliọnu mẹta.
Eeyan to le ni miliọnu kan lo ti gba abẹrẹ ọhun bayii ni Naijiria.
Eeyan to le ni ẹgbẹrun lọna ọjọ, 160,000 lo ti lugbadi arun covid-19 ni Najiria, nigba ti ẹgbẹrun meji meji ninu wọn ti ba arun naa lọ.
Seyi Makinde and BCOS staff quaters: Ṣé lóòtọ́ọ́ ni Makinde ní fẹ́ wó iléègbé àwọn òṣìṣẹ́ BCOS ní Ibadan?
Oríṣun àwòrán, Facebook/Seyi Makinde
Iroyin to n tẹ wa lọwọ lati olu ilu ipinlẹ Oyo sọ pe Gomina Seyi Makinde ti paṣẹ pe ki wọn wo ileegbe awọn oṣiṣẹ ileeṣẹ iroyin BCOS to wa ni agbegbe Basorun niluu Ibadan.
Ọjọ Aiku, ọjọ kejidinlogun, oṣu kẹrin ni a gbọ pe ijọba Makinde fẹ da ile naa wo.
Ko si ẹni to le sọ pato ohun ti ijọba fẹ fi ilẹ naa ṣe ti wọn ba wo ile to wa lori rẹ tan.
Amọ, awọn kan sọ pe ijọba fẹ fi ilẹ to wa layinka ileegbe awọn oṣiṣẹ BCOS ati ilẹ ti ileegbe wọn lori rẹ kọ ile gbigbe nla ni.
Iroyin kan tiẹ sọ pe agbaṣeṣe ti ijọba gbe iṣẹ ile wiwo ọhun le lọwọ ti ko katakata lọ sibẹ, ki wọn bẹrẹ iṣẹ loku.
Slain Ekiti Police woman: Ìyá rẹ̀ ní àìrìṣẹ́ṣe ló mú kí Bukola Olawoye gba iṣẹ́ ọlọ́pàá
Oṣiṣẹ BCOS kan to ba awọn akọroyin sọrọ ṣugbọn ti ko darukọ ara rẹ ni ijọba ko fawọn olugbe ile naa ni iwe lati kuro nile ọhun.
O ni iṣoro airilegbe ni yoo lawọn oṣiṣẹ naa yoo doju kọ ti ijọba ba wo ileegbe wọn nitori wọn ko lowo lati gba ile to dara lagbegbe Basorun ti BCOS wa.
hhhhhh
Ẹwẹ, igbimọ alaṣẹ ileeṣẹ igbohun safẹfẹ BCOS ti sọ pe iru funfun balau ni iroyin to lu ori ayelujara pe ijọba ipinlẹ Oyo wo ileegbe awọn oṣiṣẹ BCOS.
Ninu atẹjade ọhun ti ọga agba BCOS buwọlu, alaga ileeṣẹ igbohun safẹfẹ. Ọmọba Dotun Oyelade, sọ pe loorekoore ni igbimọ alaṣẹ BCOS maa n sọ erongba ijọba lori ile ti wọn n gbe fun wọn.
Ọmọba Oyelade ni igbimọ alaṣẹ ileeṣẹ iroyin naa ko ni jẹ ki igbesẹ kankan ti ijọba ba fẹ gbe pa awọn oṣiṣẹ BCOS lara.
Ọga agba naa rọ awọn oṣiṣẹ BCOS atawọn ẹgbẹ oṣiṣẹ lẹka-jẹka lati maa ka iroyin naa kun.
Egbejila Fish Village: Àwọn ọlọ́sìn ẹja ní àwọn fi iṣẹ́ báńkì sílẹ̀ wá ṣe ọ̀sìn ẹja ni
Amọ, o ṣalaye pe asọyepọ yoo waye pẹlu awọn oṣiṣẹ lori ileegbe nla ti ijọba n gbero lati kọ sori ilẹ to wa lẹgbẹ ileegbe awọn oṣiṣẹ BCOS ti ijọba ti gba tipẹ.
Ninu ọrọ tiẹ, akọwe iroyin fun gomina ipinlẹ Oyo, Taiwo Adisa sọ fun BBC Yoruba pe ko si otitọ kankan ninu iroyin naa.
''Ijọba ko fẹ wo ileegbe BCOS ni Ibadan, ilẹ ti ijọba ti gba tipẹ lẹgbẹ ileegbe BCOS ni ijọba fẹ kọ ileegbe nla le lori.
Taiwo Adisa tun ni: Ohun ti ijọba tun fẹ ṣe ni pe ki wọn tun awọn ileegbe awọn oṣiṣẹ BCOS ti ko dara loju to ṣe ki ibẹ le ba maa wu awọn ti ijọba ba fẹ ta ilẹ tabi ile tuntun fun.
Ijọba fẹ ṣe eyi nitori nibẹ lawọn eeyan maa gba kọja lọ si ibi ileegbe nla tuntun ti ijọba fẹ kọ,'' Ọgbẹni Adisa ṣalaye.
Female Car Painter: Èmi ní obìnrin àkọ́kọ́ tí yóò máa ṣiṣẹ́ akunmọ́tò ní Ibadan
Ijọba Oloye Obafemi Awolowo lo ya ilẹ ti wọn kọ ileegbe naa si lori, ṣugbọn ijọba ologun labẹ alaṣẹ Col. David Jemibewon lo kọ ile naa.
Awọn gomina to ti jẹ tẹlẹ nipinlẹ Oyo ti gbiyanju lati lo ilẹ ti ileegbe awọn oṣiṣẹ BCOS wa lori rẹ. amọ igbesẹ naa ko kẹsẹ jari.
Ọkọ àti ìyàwó sọ àsọtẹ́lẹ̀ tani yóò wọlé nínú PDP tàbí APC
T.B Joshua Synagogue church: Youtube lé T.B Joshua kúro, Facebook nàá tún pàrokò sí i
Oríṣun àwòrán, TB Joshua Ministries
Egbinrin ọtẹ, ba ṣe n pakan, nikan n ru ni ọrọ di fun oludasilẹ ijọ Synagogue, Wooli TB Joshua, pẹlu bi awọn alaṣẹ ẹrọ ayelujara ṣe n ja a kuro loju opo wọn.
Ọjọ diẹ ni ẹrọ ayelujara ti awọn eeyan ti ma n wo fidio, Youtube pa oju opo Joshua rẹ lọdọ wọn, lẹyin ti wọn fi ẹsun kan pe o sọ ọrọ ikorira.
Iyalẹnu lo tun jẹ lẹyin ọjọ diẹ, ti iroyin jade pe awọn alaṣẹ oju opo ayelujara mii, Facebook, naa tun ti le e kuro loju opo wọn.
Iroyin sọ pe Joshua sọ ọrọ tako oju opo Facebook, lẹyin ti fidio kan ṣafihan rẹ nibi to ti n le ẹmi ibalopọ ọkunrin si ọkunrin jade lara awọn eeyan.
Amọ ṣa, oju opo ijọ Synagogue lori Facebook, ti wọn pe ni Prophet TB Joshua Ministries, ṣi wa.
Eeyan to le ni miliọnu marun-un lo wa loju opo naa.
hhhhhh
Nkan ti Facebook ṣe ni pe wọn yọ gbogbo awọn fidio iṣẹ itusilẹ kuro lọwọ 'ẹmi obinrin', to fi sita, kuro ni oju opo naa.
Ileeṣẹ Facebook sọ pe awọn ko ni i gba ki ẹnikẹni o ma a gbogun ti awọn eeyan nitori iru ibalopọ ti wọn n ni.
Iroyin sọ pe ọpọlọpọ fidio lo wa ni ori ayelujara Youtube ijọ naa, eyi to ṣafihan bi TB Joshua ṣe n le ẹmi ibalopọ ọkunrin si ọkunrin, ati ti obinrin si obinrin, kuro lara awọn eeyan.
Wahala bẹrẹ fun Joshua lẹyin ti ajọ kan, Open Democracy kọ iwe ẹsun si awọn alaṣẹ oju opo naa, lori iru fidio ti Joshua n fi si ibẹ, boya o ba ofin oju opo wọn mu.
Amọ o, ijọ naa ti sọ loju opo Facebook rẹ pe oun kii sọ ọrọ idẹyẹsi tabi ikorira.
TB Joshua funra rẹ ti fesi si awọn iṣẹlẹ yii.
Ninu ọrọ to kọ si ori ayelujara Twitter rẹ, o fi fidio kan sibẹ to ni nirtori rẹ ni awọn alaṣẹ Youtube ṣe ja oun kuro loju opo wọn.
"Ninu fidio naa, wooli naa sọ pe ""ọkunrin kan wa ninu eto isin to n lọ lọwọ, to ni ẹmi ọkunrin ninu, ọkunrin ni ọ, ṣugbọn o ko mọ bi nkan yii ṣe ṣẹlẹ si ọ."
O wu ọ lati fẹ obinrin niyawo, sugbọn mi ọkunrin n yọ ọ lẹnu, o ko si le ran ara rẹ lọwọ..., oya ma a jade bọ fun itusilẹ.
Slain Ekiti Police woman: Ìyá rẹ̀ ní àìrìṣẹ́ṣe ló mú kí Bukola Olawoye gba iṣẹ́ ọlọ́pàá
Lẹyin ọrọ ti Joshua sọ yii, ni ọkunrin kan jade sita laarin ero pe lootọ ni ẹmi kan ma n sọ fun oun pe ọkunrin ni ki oun o ma a fi ara mọ.
O ni o ti le ni ogun ọdun ti wahala naa ti bẹrẹ ninu aye oun.
O ṣalaye pe oriṣiriṣi nkan ni oun ma n ṣe lati fa oju wọn mọra, amọ ti wọn ko ba gba t'oun, o ma n dabi pe ki oun ba ẹranko ni ibalopọ.
Female Car Painter: Èmi ní obìnrin àkọ́kọ́ tí yóò máa ṣiṣẹ́ akunmọ́tò ní Ibadan
Ijọ Synagogue sọ pe ifẹ Ọlọrun ni awsn n pin fun gbogbo eniyan lori Emmanuel TV, lai wo ẹya tabi ẹsin wọn ṣe.
A ni ibaṣepọ to dara pẹlu Youtube, igbagbọ wa si ni pe wọn kanju gbe igbesẹ naa.
Egbejila Fish Village: Àwọn ọlọ́sìn ẹja ní àwọn fi iṣẹ́ báńkì sílẹ̀ wá ṣe ọ̀sìn ẹja ni
European Super League: Arsenal, Man United, Man City, Real Madrid, Barcelona fẹ́ dá ìdíje líìgì tuntun sílẹ̀ ní Yúróòpù
Ni ọjọ Aiku ni iroyin kan gbode lagbe ere bọọlu lagbaye, papaa julọ nilẹ Yuropu pe awọn eekan ẹgbẹ agbabọọlu kan ti fẹ yapa.
Wọn ni wọn fẹ lọ da liigi agba tuntun silẹ nilẹ Yuroopu eyi ti wọn pe ni European Super league.
Iroyin naa burẹkẹ sii pẹlu bi awọn agba ọjẹ ẹgbẹ agbabọọlu mẹfa lati liigi Premiership ni ilẹ Gẹẹsi ṣe kede ati darapọ mọ liigi tuntun naa.
Awọn ẹgbẹ agbabọọlu mẹfa naa ni Arsenal, Chelsea, Manchester city, Manchester United, Liverpool ati Tottenham.
Ni oṣu kẹwaa, ọdun to kọja ni igbesẹ kọkọ bẹrẹ pẹlu ijiroro to lọwọ ileeṣẹ iṣuna kan ti orukọ rẹ n jẹ JP Morgan ninu.
Koko apero naa ni lati gbe idije kan kalẹ lati rọpo idije Champions League ni ilẹ Yuroopu ti owo ori rẹ yoo si to biliọnu mẹfa o le ẹgbẹta miliọnu pọun.
Ajọ UEFA gbe igbesẹ lati gbe idije Champions League tuntun pẹlu awọn ẹgbẹ agbabọọlu mẹrindinlogoji.
Eyi n waye pẹlu awọn atunṣe tuntun ti wọn gbero lati kede lọjọ Aje, ọjọ kọkandinlogun oṣu kẹrin.
aaaaaaaaaaaaaaa
Kini erongba wọn fun liigi tuntun yii?
Ero wọn ni pe eyi yoo wawọ erongba idije Super league tuntun naa bọlẹ ṣugbọn ko dabi ẹni pe awọn atunto naa de agbeji ara agba ọjẹ ẹgbẹ agbabọọlu mejila to wa nidi idasilẹ liigi agba tuntun naa.
Oríṣun àwòrán, uefa
Arsenal, Chelsea, Liverpool, Manchester United, Manchester City ati Tottenham wa lara awọn ẹgbẹ agbabọọlu mejila to ti buwọlu idasilẹ liigi tuntun naa.
Awọn ẹgbẹ agbabọọlu liigi Premiership ti ilẹ Gẹẹsi naa yoo dara pọ mọ awọn ẹgbẹ agbabọọlu bii AC Milan, Athletico Madrid, Barcelona, Inter Milan, Juventus ati Real Madrid fun idasilẹ ẹgbẹ agbabọọlu naa.
Ajọ idasilẹ liigi tuntun ọhun ti wọn pe ni European Super league, ESL ni awọn ẹgbẹ agbabọọlu naa ti gba lati da liigi naa silẹ ti ifẹsẹwọnsẹ wọn yoo si maa waye ni aarin ọsẹ.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Kini yoo ṣẹlẹ lẹyin idasilẹ naa?
Amọṣa wọn yoo ṣi maa tẹsiwaju lati kopa ninu idije liigi orilẹede ọkọọkan wọn.
O ni liigi tuntun naa yoo bẹrẹ ni kanmọkia ti aaye rẹ ba ti yọ ati pe wọn n reti awọn ẹgbẹ agbabọọlu mẹta miran lati darapọ laipẹ.
Bakan naa ni wọn tun n gbero ati da idije tawọn ẹgbẹ agbabọọlu obinrin silẹ pẹlu.
Oríṣun àwòrán, Reuters
Liigi agba ọjẹ ilẹ Yuroopu naa, European Super league, ESL yoo fi aaye silẹ fun ẹgbẹ agbabọọlu ogun lati kopa.
Egbẹ agbabọọlu mejila ti wa nikalẹ, pẹlu mẹta miran ti wọn n reti ṣugbọn ti wọn ko tii darukọ wọn, atawọn marun miran ti yoo maa kopa pẹlu bi wọn ba ṣe kogoja si lọdọọdun.
Isọri meji ni wọn yoo pin wọn si pẹlu ẹgbẹ agbabọọlu mẹwaa-mẹwaa ni isọri kọọkan lati maa figagbaga bẹrẹ lati oṣu kẹjọ ọdọọdun.
hhhhhh
Awọn mẹta to ba moke ni ọkọọkan isọri naa yoo wọle fun ipele kọta faina.
Ipele yii ti awọn ẹgbẹ agbabọọlu to ba wa ni ipo kẹrin ati ikarun lawọn isọri mejeeji yoo tun forikori lati mu meji  ti yoo daraps mọ awọn mẹfa akọkọ ni ipele kọta faina.
Lati ibẹ lọ ifẹsẹwọnsẹ rẹ yoo farajọ ti idije Champions League to wa nilẹ bayii.
Ajọ iṣakoso ESL ni owo ti yoo maa wọle yoo gbe pẹẹli ju ti Champions league lọ, eyi to tumọ si owo pupọ si fawọn ẹgbẹ agbabọọlu to nkopa.
Oríṣun àwòrán, uefa/twitter
Ajọ to n ṣakoso ere bọọlu nilẹ Yuroopu, ajọ to n ṣamojuto bọọlu liigi premiership nilẹ Gẹẹsi pẹlu olotu ijsba ilẹ Gẹẹsi, Boris Johnson wa lara awọn to ti bu ẹnu atẹ lu igbesẹ naa.
"Ajọ UEFA ni oun yoo lo ""gbogbo ọna to ba yẹ"" lati fi dawọ igbesẹ naa duro."
Bẹẹni iroyin n jẹ ko di mimọ pe inu awọn eekan lagbo iṣakoso ere bọọlu ni UEFA ko dun si igbesẹ naa.
"Olotu ijọba ilẹ Gẹẹsi, Boris Johnson ni igbesẹ naa yoo ""ṣe akoba fun ere bọọlu"" ati pe ijọba ilẹ Gẹẹsi yoo ṣe atilẹyin fun awọn alaṣẹ ere bọọlu ""ninu igbesẹ gbogbo ti wọn ba fẹ gbe"""
"O fi kun un pe ""Gbogbo awọn ẹgbẹ agbabọọlu ti ọrọ kan gbọdọ jẹjọ niwaju awọn ololufẹ wọn ati gbogbo ololufẹ ere bọọlu lagbaye ki wọn to tun gbe igbesẹ yoowu lori rẹ."""
Oríṣun àwòrán, uefa
"Aarẹ ẹgbẹ agbabọọlu Real Madrid, Florentino Perez, to jẹ alaga akọkọ fun ajọ liigi bọọlu ni Yuroopu, ESL ṣalaye pe idije tuntun naa ""yoo ṣe iranwọ fun ere bọọlu lẹka gbogbo."""
"Alaga ẹgbẹ agbabọọlu Juventus Andrea Agnelli ṣalaye pe awọn ẹgbẹ agbabọọlu mejila naa"" parapọ lasiko to ṣe pataki yii lati mu ayipada ba ere bọọlu ni ilẹ Yuroopu, lati gbe ẹsẹ ere idaraya ti a fẹran le pepele to dara fun ọjọ iwaju."""
Alaga ẹgbẹ agbabọọlu Manchester United, Joel Glazer ni yoo jẹ igbakeji  liigi tuntun naa.
"O ni: ""Liigi Super League yoo ṣina tuntun fun ere bọọlu nilẹ Yuroopu, nipa ṣiṣeto idije ti ko lẹlẹgbẹ lagbaye, pẹlu afikun owo fun idagbasoke ere bọọlu."""
Rivers state local government elections: PDP gba gbogbo ipò alága káńsù àti káńsélọ̀ ní ìdìbò ìjọba ìbílẹ̀ Rivers
Ẹgbẹ oṣelu Peoples Democratic Party, PDP ti jawe olubori ipo alaga kansu mẹtalelgun nibi idibo ijọba ibilẹ to waye ni ipinlẹ Rivers lopin ọṣẹ to kọja.
Alaga ajọ eleto idibo ipinlẹ Rivers, RSIEC, Adajọfẹyinti George Omereji kede awọn alaga tuntun ati kansilọ fawọn ijọba ibilẹ mẹtalelogun to wa ni ipinlẹ naa.
Bakan naa lo si ṣalaye fun gbogbo wọn pe ki wọn rii daju pe wọn ko akoyawọ, ki wọn si fọwọsowọpọ pẹlu awọn to fidirẹmi ninu idibo naa lati ṣiṣẹ sin araalu fun idagbasoke ijọba ibilẹ wọn.
"O ni: ""Ọkan naa ni awọn to jawe olubori atawọn to fidirẹmi nitori ẹbi kan naa ni yin, lẹyin idibo yii ẹ fun ara yin ni ọwọ to yẹ ki ẹ si jumọ ṣe iṣẹ pọ fun idagbasoke ipinlẹ Rivers."""
Amọṣa, awọn ẹgbẹ oṣelu kan ti n fi iru na igba yangan lori esi idibo ijọba ibilẹ to waye ni ipinlẹ Rivers ti wọn si ti n pe fun wiwọgile esi idibo naa.
hhhhhh
Ẹgbẹ oṣelu African Action Alliance, AAC to wa lara awọn ẹgbẹ oṣelu to n pe fun wiwọgile esi idibo ijọba ibilẹ naa tọka si idibo naa gẹgẹ bi iwọsi nlanla fun eto iṣejọba tiwantiwa.
Atẹjade kan ti alaga ẹgbẹ oṣelu AAC ni ipinlẹ Rivers, Progress Ogbokuma Aselemi fọwọsi rọ ijọba apapọ lati wọgile ajọ eleto idibo tipinlẹ lorilẹ-ede Naijiria.
O ni pe nitori wọn ti sọ iyi ati aiṣegbe pẹlu ojuṣe iṣakoso eto idibo nu.
Bakan naa ni ẹgbẹ oṣelu Social Democratic Party, SDP pẹlu tun ti pe fun wiwọgile idibo naa.
Wọn pe fun atundi ibo sijọba ibilẹ nipinlẹ Rivers amọṣa labẹ iṣakoso alaga tuntun fi ajọ to n ṣamojuto idibo nipinlẹ naa.
Yemi Farounbi: Yorùbá yóò dáàbò bo ara rẹ́, bí ìjọ́ba bá kùnà láti ràgà bò wọ́n
Mounrinho: Tottenham gbaṣẹ́ lọ́wọ́ Mourinho gẹ́gẹ́ bí akọ́nimọ̀ọ́gbá ikọ̀ rẹ̀
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Awọn alaṣẹ ẹgbẹ agbabọọlu Tottenham ti gba iṣẹ lọwọ Jose Mourinho gẹgẹbi akọnimọọgba ikọ naa lẹyin ọdun kan ati oṣu marun un.
Ni oṣu kọkanla ọdun 2019 ni wọn yan  Mourinho lati rọpo Mauricio Pochettino gẹgẹ bi akọnimọọgba ikọ Spurs to si gbe e lọ si ipo kẹfa lori atẹ liigi Premiership fun saa to kọja.
Lọwọ yii ipo keje ni wọn wa lori atẹ liigi fun saa liigi tọdun 20220/2021 to n lọ lọwọ, lẹyin ti wọn ri ami meji mu ninu ifẹsẹwọnsẹ mẹta ti wọn gba sẹyin ti wọn si tun ti jabọ ninu idije Europa loṣu kẹta ọdun 2021.
Spurs yoo maa koju Manchester city ni aṣekagbaidije Carabao ni ọjọ karundinlọgbọn oṣu kẹrin, ọdun 2021.
ẹgbẹ agbabọọlu Tottenham wa lara awọn ẹgbẹ agbabọọlu to n darapọ mọ idije liigi tuntun nilẹ Yuroopu.
hhhhhh
Bakan naa ni wọn tun yọ awọn alabaṣiṣẹ pọ Mourinho Joao Sacramento, Nuno Santos, Carlos Lalin ati Giovanni Cerra.
"Daniel Levy, alaga ẹgbẹ agbabọọlu Tottenhan ṣapejuwe Mourinho gẹgẹ bi ""akọṣẹmọṣẹ to  fi ifaẹnijin han paapaa lasiko ajakalẹ arun COVID-19"""
aaaaaaaaaaaaaaa
Ifẹsẹwọnsẹ mẹwaa ni Mourinho ati ikọ Tottenham rẹ ti fidirẹmi ni liigi yii, eleyi to si jẹ igba akọkọ rẹ lati igba to ti gba iṣẹ akọnimọọgba rẹ.
Ifẹsẹwọnsẹ pẹlu Everton to waye lọjọ Ẹti ni ikẹyin fun Mourinho gẹgẹbi akọnimọọgba Everton, ọmi oni goolu mejimeji ni wọn si ta.
Agbabọọlu Tottenham tẹlẹ, Ryan Mason to n mojuto awọn ọjẹwẹwẹ agbabọọlu ikọ naa ni yoo gba iṣakoso eto igbaradi awọn agbabọọlu ikọ naa lọjọ Aje.
Islam, Sheik Taofeeq Akewugbagold: Tó bá kó ìyàwó jọ tóò tọ́jú wọn, o ó jẹ ìgbẹ́ àti ìtọ̀ ìdájí láìmọ̀
Ọgbà wèrè àti ilé aṣẹ́wó nilé ẹni tí kò lówó tó tún fẹ́ ìyàwómẹ́rin- Sheik Akewugbagold
Sheik Akewugbagold ṣalaye pe: Iyawo kan ni dandan fun ọkunrin ninu ẹsin Islam.
Bakan naa ni aafa yii ni ko si nkan to buru ninu Islam pe ọkunrin kan fẹ iyawo meji si mẹrin lọjọ kan ṣoṣo.
Aafa ni 'Kọndisọn' lo gbe  iyawo pupọ fifẹ jade ninu ẹsin Islam.
Sheik Akeugbagold ni pe: Owó nini lo ṣe pataki julọ lati fẹ iyawo mẹrin ninun Islam ati agbara lati ba wọn sun bi o ṣe yẹ lasiko
Oríṣun àwòrán, @Akehugbagold
Sheik Akehugbagold nipa iyawo mẹrin ninu Islam
Sheik Akewugbagold ni pe nini iyawo meji si mẹrin ko ba ẹsin jẹ ninu Islam ṣugbon ofin mọkanla lo gbọdọ tẹlẹ ninu sharia ki o ma ba jébi.
O ni Anabi ko faaye gba ṣiṣe 'Fadá' rara ninu Islam
Ati pe o san, lati ni iyawo pupọ ju iyawo kan nile pẹlu àlè pupọ nigboro.
Wo idi ti Olorun ṣe faaye gba iyawo mẹrin ninu Islam ninu ifọrọwerọ pẹlu Sheik Akewugbagold yii lẹkunrẹrẹ.
Ṣe o mọ pe o maa ni 'Stroke' ti o ba ku ti o ko ba ṣe deede laarin awọn iyawo mẹrin ti o fẹ sile?
Ikere-Ekiti cult clash: Èèyàn mẹ́fà kú nínú ìjà ẹgbẹ́ òkùnkùn, ọ̀rọ̀ di ẹni orí yọ ó dilé ní Ikẹrẹ-Ekiti
Èèyàn mẹ́fà kú nínú ìjà ẹgbẹ́ òkùnkùn , ọ̀rọ̀ di ẹni orí yọ ó dilé ní Ikẹrẹ-Ekiti
Ọrọ di bo o lọ, yago fun mi nilu Ikẹrẹ-Ekiti, nipinlẹ Ekiti, lọjọ Isinmi, lasiko ti ija ṣẹlẹ laarin awọn ọmọ ẹgbẹ okunkun.
Iroyin ta a gbọ ni pe alẹ ọjọ Satide ni wahala naa ti bẹrẹ nigba ti awọn ọmọ ẹgbẹ okunkun kan yinbọn pa ọkunrin kan ti wọn pe ni Ojuale.
A gbọ pe nitosi Gbọngan ilu naa to wa ni agbegbe Odo Oja ni wọn ti yinbọn pa Ojuale, ti iroyin sọ pe ọmọ ẹgbẹ okunkun ni oun naa.
Awọn iwe iroyin abẹle sọ pe botilẹ jẹ pe ọmọ ilu Ikẹrẹ ni Ojuale, ṣugbọn ilu Port Harcourt lo n gbe.
aaaaaaaaaaaaaaa
Ayẹyẹ igbeyawo ọrẹ rẹ kan la gbọ pe o wa fun, ki awọn ọmọ ẹgbẹ okunkun to o yinbọn pa.
Ko pẹ lẹyin ti wọn pa Ojuale, ni awọn ọmọ ẹgbẹ rẹ naa tu jade pẹlu oriṣiriṣi nkan ija oloro, ti wọn si bẹrẹ si ni kọju ija si awọn olugbe ni agbegbe naa.
"Bẹẹ ni wọn n yin ibọn lakọlakọ, eyi to mu ki awọn araalu o sa asala fun ẹmi wọn.
Nigba to fidi iṣẹlẹ naa mulẹ fun BBC, agbẹnusọ ileeṣẹ ọlọpaa nipinlẹ Ekiti, Sunday Abutu sọ pe lootọ ni iṣẹlẹ naa waye.
O ni ṣugbọn, ọwọ ti tẹ afurasi 45 lori iṣẹlẹ naa, ti wọn si ti wa ni agọ ọlọpaa.
hhhhhh
Bakan naa lo sọ pe awọn ọlọpaa ṣi wa ni agbegbe naa lati tẹsiwaju pẹlu eto aabo titi ti alaafia yoo fi jọba.
A gbọ pe awọn ara ilu Ikẹrẹ ti bẹ ijọba ipinlẹ Ekiti, lati tọpinpin bi ija laarin awọn ẹgbẹ okunkun ṣe n waye nigba gbogbo ninu ilu naa.
Lori eyi, Abutu sọ pe lootọ ni, ti ileeṣẹ ọlọpaa si ti mu awọn ọmọ ẹlẹgbẹ okunkun kan, ṣaaju ikọlu to tun waye ni ọjọ Satide.
Ninu iṣẹlẹ to waye lọjọ Satide mọju ọjọ Aiku yii, iroyin ti ao ti le fidirẹmulẹ sọ pe ko din ni eeyan mẹfa to kú.
Naira Marley: Ṣé o fẹ́ lọ sí ọ̀run rere? Wo bí Naira Marley yóò ṣe bá ọ bẹ̀bẹ̀ kí ó tó wọlé
Oríṣun àwòrán, Instagram/@nairamarley
Gbajugbaja akọrin, Azeez Fashola ti ọpọ mọ si Naira Marley ti sọ pe oun ni yoo kọkọ wọ ọrun, tako igbagbọ awọn eeyan kan.
Ninu fidio kan to fi si ori ayelujara Instagram rẹ lo ti sọ pe oun ko ni nkankan ṣe pẹlu ọrun apadi, nitori pe oorun to n mu ni aye gan-an ju ti ina jaanamọ lọ.
O ni aanu oun ṣe awọn eeyan to ma n sọ pe ẹnikan lo ma a kọkọ lọ si ọrun apadi.
O ni emi ati Ọlọrun mọ ibi ti a di ibaṣepọ wa si. Aanu ẹ ṣe mi."""
Naira Marley sọ pe oun lo ma a ba awọn eeyan naa bẹbẹ ni ẹnu ọna ọrun, ki wọn o to o le wọle.
Bi mo ṣe ma a bayin bẹbẹ niyẹn lẹnu ibode ọrun pe Ọlọrun, ẹ jọ ẹ jẹ ki eleyi wọle. Mo mọ eleyi ri, Mallam ni, ẹ jẹ ko wọle. Bi mo ṣe ma bayin bẹbẹ niyẹn.
Akọrin naa to fi lawani bo ori lo wa ninu ọkọ pẹlu awọn kan to ṣe e sẹ ko jẹ isọmọgbe rẹ, ti ọkan lara wọn si mu tẹsibiyu dani.
Lati igba ti awẹ Ramadan ti ọdun 2021 ti bẹrẹ lo dabi ẹni pe gbajugbaja akọrin naa n kọ awọn ọrs ẹsin lori ayelujara.
aaaaaaaaaaaaaaa
Ninu ọrọ kan to kọkọ fi si ori ayelujara rẹ ni ọjọ kẹrinla, oṣu Kẹrin, Naira Marley ṣe atupalẹ ati itọni lori bi awọn musulumi ṣe le ka Kuraani tan laarin ọgbọn ọjọ ti Ramadan yoo fi waye.
Ọpọ eeyan si lo jẹ iyalẹnu fun pe iru awọn ọrọ 'iwa mimọ' bẹẹ le jade lẹnu Marley, ti awọn eeyan kan gbagbọ pe ẹlẹṣẹ ni.
Eyi ko ṣẹyin iru awọn orin ati aṣa to ma n da, eyi ti awọn eeyan ti tọka si ni ọpọ igba pe ko bojumu.
hhhhhh
Yoruba Nation: Ẹni tó máa kú ko kú, ẹni tó máa kù ko kù, ẹ jẹ́ ká jà fún ominira - Ọba Adetokunbo Tejuosoho
Oríṣun àwòrán, Adetokunbo Tejuosho
Ori ade kan ti sọ pe awọn eeyan bi oun ko nibi kankan lati salọ, ṣugbọn awọn ti ṣetan lati fi ẹmi wọn lelẹ ki ilẹ Yoruba le gba ominira lọwọ awọn to n ni aye wọn lara.
Ọba Adetokunbo Tejuosoho, Olu Orile Kemta lo sọ ọrọ naa ninu ifọrọwerọ kan pẹlu BBC Yoruba ni idahun si ọrọ minisita fun eto iroyin ati aṣa, Lai Mohammed.
Ṣaaju ni Lai Mohammed ti kọkọ sọ pe ti gbogbo awọn to n lọgun Yoruba Nation ni yoo salọ ti ọrọ naa ba bẹyin yọ.
Ṣugbọn Ọba Orile kemta ti fesi pe ko si ohun to jọ bẹẹ, koda o ni awọn eeyan kan tilẹ ti n salọ kuro ni Naijiria tẹlẹ nitori bi gbogbo nnkan ṣe ri, paapaa nipa ti eto abo to mẹhẹ.
"O ni ""Ẹnu ọjọ mẹta yii ni awọn kan ji odidi Ọba kan gbe nipinlẹ Ekiti, iyẹn nigba ti wọn ti kọkọ gbiyanju lati ji Ọba mii gbe ṣaaju."""
Oríṣun àwòrán, Adetokunbo Tejuosho
Bo tilẹ jẹ pe baba ni Lai Mohammed jẹ, igbagbọ temi ni pe o yẹ ko gbiyanju lati pẹtu si awọn eeyan ninu ni, kii ṣe ko maa sọ pe awọn kan yoo salọ.
"Tejusosho tẹsiwaju pe ""Awọn ajinigbe n wọ inu aafin lati ji ori odidi ade gbe, ẹ wa sọ pe ki awọn ajijagbara ma sọrọ... Nibo la n salọ gan, ẹni to maa kú ko kú, ẹni to maa kù ko kù, ẹ jẹ ka  ja fun ominira!"""
aaaaaaaaaaaaaaa
Tejuosho ni bi ọrọ ọhun ṣe n lọ yii, awọn ara ilu ti n ni igbagbọ ninu awọn eeyan bi Sunday Igboho ju igbagbọ ti wọn ni ninu ijọba lọ.
Gẹgẹ bo ṣe sọ, o ni lootọ ni pe ijọba to wa lode jogun ba awọn iṣoro to wa ni Naijiria, ṣugbọn nigba ti wọn n ṣe ipolongo ibo, ileri ayipada 'change' ni wọn ṣe fun awọn eeyan ilu.
Idi si ree ti awọn araalu ṣe ni igbagbọ ninu wọn ṣaaju.
Kò sí ìgbà kankan tí Yorùbá jókòó pé ki Igboho  lọ kéde ìyapa kúrò ní Nàíjíríà
Oba yii fi kun un pe o yẹ ki ijọba pe ipade apero, ki gbogbo ẹya to wa ni Naijiria sọ ohun ti wọn n fẹ ki wọn si ṣe atunto, bi bẹẹ kọ, ki onikaluku maa lọ ni ilọ tirẹ.
Ni ti pe maa jo lọ mo n wo ẹyin rẹ ni ọrọ awọn to n pe fun ominira ilẹ Yoruba, Ọba Tejuosho ni ko ri bẹẹ nitori awọn to ni ifẹ awọn aaralu lọkan lo n pe fun ominira.
"O ṣalaye pe ""Ko si ẹni to n gbadura fun ogun, ṣugbọn ti a ko ba fẹ ogun, o yẹ ki a yanju ogun abẹle to n ja wa, ki a si ṣẹ atunto."""
Kii ṣe ẹbi awọn to n pe fun ipinya, ṣugbọn wọn gbe igbesẹ naa nitori wọn ti sun kan ogiri.
Ọba Tejuosho paro ọrọ rẹ pe oun ko gbadura fun wahala, ṣugbọn ti ọrọ naa ba gbọna mii yọ, oun  ko ni ibi kankan ti oun yoo salọ lodi si ọrọ ti Lai Mohammed sọ nipa awọn to n pe fun iyapa.
Yemi Farounbi: Yorùbá yóò dáàbò bo ara rẹ́, bí ìjọ́ba bá kùnà láti ràgà bò wọ́n
#PantamiMustResign, Isa Pantami: Àwọn ọmọ Naijiria ń fẹ́ ìyọnípò mínístà fún ọ̀nà ìbáraẹnisọ̀rọ̀ nítorí ọ̀rọ̀ tó sọ nípa àwọn agbésùnmọ̀mí
Oríṣun àwòrán, @NewsWireNGR
Ọpọ ọmọ Naijiria lo ti bẹrẹ si n pe fun ikọwefiposilẹ minisita fun ọna ibaraẹnisọrọ, Isa Pantami lori ayelujara pẹlu ami #PantamiMustResign.
Igbesẹ naa ko ṣẹyin ẹsun ti wọn fi kan pe o n sọrọ atilẹyin fun ẹgbẹ agbesunmọmi bii Al-Qaeda ati Taliban.
hhhhhh
Ṣaaju ni ileeṣẹ iroyin ori ayelujara kan ti kọkọ jabọ pe ijọba ilẹ Amẹrika ti fi orukọ Pantami sara awọn eeyan ti wọn n ṣọ loju-lẹsẹ nitori pe o n ṣe atilẹyin fun awọn agbẹsunmọmi, ṣugbọn ilesẹ iroyin naa ti yi ohun pada.
Pantami ti ṣe awọn waasi kan lawọn ọdun diẹ sẹyin, nibi ti wọn ni o ti sọrọ atilẹyin fun ikọ agbesunmọmi Al-Qaeda ati Taliban, eyii to da rogbodiyan silẹ lori ayeluja.
Ọrọ naa mu ki ọpọ awọn ọmọ Naijiria sọ pe ko kọwe fi ipo silẹ tabi ki Aarẹ Muhammadu gba iṣẹ lọwọ rẹ, nigba ti awọn eeyan miran si sọ pe Pantami ko ṣe si ofin kankan.
Pantami funra rẹ, to jẹ onimọ nipa ẹsin Musulumi ti fesi pe oun ko ni nkankan ṣe pẹlu ẹgbẹ agbesunmọmi kankan.
Yatọ si awọn ọmọ Naijiria to n lọgun pe ki wọn gba iṣẹ lọwọ Pantami lojo opo Twitter, eeyan kan gboogi to n jẹ ọrọ naa lẹnu ni Reno Omokri, to jẹ amugbalẹgbẹ Aarẹ ana, Goodluck Ebele Jonathan.
Oríṣun àwòrán, @Living__death
Bi ẹ ko ba gbagbe, Omokri yii lo lewaju awọn ọmọ Naijiria kan to n ṣe ifẹhonuhan niwaju ile ijọba Naijiria ni London lasiko ti Aarẹ Muhammadu Buhari lọ ṣayẹwo ilera ara rẹ lọsẹ diẹ sẹyin.
Yatọ si Omokri, ẹgbẹ oṣelu PDP naa ti sọ pe ki minisita naa kọwe fi ipo silẹ lori ọrọ ọhun.
aaaaaaaaaaaaaaa
PDP sọ ninu atẹjade kan pe ominu n kọ awọn nitori ipo ti Pantami wa ni Naijiria, ati pe ewu n bẹ loko longẹ to ba jẹ pe lootọ ni o n ṣe atilẹyin fun ẹgbẹ agbesunmọmi.
PDP tun sọ pe iroyin nipa awọn araalu to wa ni ikawọ Pantami nipasẹ eto iforukọsilẹ nọmba idanimọ NIN ko jẹ ki awọn ni igbagbọ ninu rẹ mọ, nitori naa o yẹ ko fi ipo silẹ lẹyin ti awọn araalu ti sọ pe ko ṣe bẹẹ.
Ẹwẹ, ibeere ti ọpọ eeyan n bere bayii ni pe, ṣe Pantami yoo kọwe fipo silẹ ni tabi Aarẹ Muhammadu Buahri yoo fi ọwọ osi juwe ile fun un tabi yoo maa wo o niran?.
Ko si ẹni to tii le sọ ohun to le ṣẹlẹ.
Slain Ekiti Police woman: Ìyá rẹ̀ ní àìrìṣẹ́ṣe ló mú kí Bukola Olawoye gba iṣẹ́ ọlọ́pàá
Ebenezer Obey: Ìdí iṣẹ́ agbẹjọ́rò tàbí dókítà ni mo rò pé mo ti máa ṣe oríire
Oríṣun àwòrán, @THEWILLNG
Agbabọje akọrin juju, Ebenezer Obey Fabiyi ti tẹnu bọọrọ lori idi ti iya rẹ ko fi fẹ ko ya sidi orin kikọ.
O ni iya to bi oun lọmọ ko fi tọkantọkan ro wi pe oun yoo se isẹ orin nisẹ asela.
Ninu alaye ti ilumọọka akọrin yi se fun ileeṣẹ iroyin abẹle Punch, o sọ pe dipo isẹ olorin isẹ dokita tabi agbẹjọro ni iya oun nifẹ si ki oun se.
Ko kuku si ẹni to mọ irinajo ẹda, nitori naa lo fi da bi ẹni pe iya Chief Commander fi maa n sọ fun tọsan-toru pe ko sinmi lati maa lu ilu kaakiri, ko si gbajumọ ẹkọ la ti le di dokita tabi agbẹjọro.
Nise ni mama mi maa n sọ pe, ṣe iwọ ko fẹ soriire laye ni?
Oríṣun àwòrán, @Go247B
Bi o ba kọju mọ ẹkọ rẹ, ti o si di agbẹjọro se o mọ pe awọn eeyan yoo maa pe mi ni iya lawyer ni?
"Obey tun sọ pe mama oun yoo tun beere pe ""ṣe iwọ ko nifẹ si ko ma wa ọkọ ayọkẹlẹ ni?''"
aaaaaaaaaaaaaaa
O tẹsiwaju pe mama ko mọ ni ati pe oun ko da wọn lẹbi rara.
''Ṣugbọn  nigba ti wọn ri pe isẹ orin yi lọna mi ati pe nnkan ti mo fẹ se niyẹn, wọn fi mi silẹ laaye ara mi.''
Ohun to n fa ifoya fun iya Ebenezer Obey gẹgẹ bi ohun to sọ ko sẹyin igbagbọ tawọn eeyan ni pe awọn olorin a maa mu siga, wọn a si maa mu ọti.
Lati le jẹ ki ọkan mama rẹ balẹ, Ebenezer Obey sọ pe oun ṣe ileri lati yago fun gbogbo nkan ti mama oun ko nifẹ si.
Amọran ti wọn gba mi yi jẹ ojulowo amọran nitori nigba ti mo de oju agbami orin kikọ, gbogbo awọn nkan wọn yi ni mo ba pade.
''Pẹlu ogo lọdọ Ọlọrun mo ṣe ileri lati yago fawọn iwakiwa yi, mo si dupe pe mo se ileri yi notori ohun lo jẹ ki n yan kin yanju lonii niyẹn.''
hhhhhh
Ìjọba Katsina yóò bẹ̀rẹ̀ sí ń fi ajá ṣọ́ àwọn ilé ẹ̀kọ́ láti kojú àwọn ajínigbé
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ijọba ipinlẹ Katsina ti sọ pe awọn yoo bẹrẹ si n fi aja ṣo awọn ile ẹkọ ti awọn akẹkọọ n gbe nipinlẹ naa.
Kọmiṣonna fun eto ẹkọ ipinlẹ ọhun, Badamasi Lawal Chiranci sọ fun BBC pe ijọba ipinlẹ naa ti pese 580 miliọnu ti wọn yoo fi kọ ogiri yii awọn ile ẹkọ naa ka.
O fi kun pe wọn yoo tun lo lara owo ọhun lati ra awọn aja lọna ati koju eto abo to mẹhẹ.
Chiranci ṣalaye pe awọn aja naa yoo maa ta awọn agbofinro lolobo ni gbogbo igba ti nnkan ko ba fẹ ṣẹnu ire nipa ti eto abo.
"Gẹgẹ bo ṣe sọ ""Ti awọn aja naa ba ti kofiri ohunkohun to le ṣakoba fun eto abo, wọn yoo tete ta awọn agbofinro lolobo, eyii ti yoo wulo fun gbogbo araalu."""
aaaaaaaaaaaaaaa
Kọmiṣọnna naa fikun pe awọn yoo tun ṣe idanilẹkọọ fun awọn akẹkọ lori ọna ti wọn yoo fi da awọn janduku mọ, ki wọn le maa tete ke si awọn ọlọpaa.
O pari ọrọ rẹ pe, iṣẹlẹ ijinigbe to waye ni Katsina kiba ma ti waye to ba jẹ pe awọn akẹkọọ mọ bi wọn ṣe le bojuto eto abo ara wọn.
Slain Ekiti Police woman: Ìyá rẹ̀ ní àìrìṣẹ́ṣe ló mú kí Bukola Olawoye gba iṣẹ́ ọlọ́pàá
Ondo Election tribunal judgment: Ilé ẹjọ́ kótẹ́milọ́rùn ló kù, dídùn lọsàn á sò- Ondo PDP
Oríṣun àwòrán, @Jegede
Lẹyin idajọ ileẹjọ to gbọ ẹjọ eto idibo to waye ni ipinlẹ Ondo loṣu kẹwa ọdun to kọja ni ẹgbẹ oṣelu PDP ti ni pe ko tan sibẹ.
PDP ti Eyitayo Jegede dije dupo gomina labẹ rẹ ti sọrọ soke wi pe ile ẹjọ kotẹmilọrun ni awọn n lọ bayii nitori idajọ naa ku diẹ kaato.
Ninu atẹjade ti akọwe ẹgbẹ naa nipinle Ondo, Kennedy Ikantu Peretei fi sita ni wọ́n ti sọ pe PDP mọ pe iroyin ayọ ni wọn a ba bọ nibẹ.
Budo Ikoko water problem: Ìyàwó wa ti sá lọ kúrò ní Asa nítorí àìsí omi- Alhaji Sunmonu
PDP ni igbagbọ ẹgbẹ naa ni pe ko si ẹni to le tẹ ofin ọdun 1999 Naijiria mọlẹ lọna aitọ.
Bakan naa ni wọn tun rọ awọn ọmọ ẹgbẹ wọn lati ni suuru nitori adun lo maa gbẹyin ewuro ẹjọ Jegede gẹgẹ bii gomina ipinlẹ Ondo.
Oríṣun àwòrán, Eyitayo jegede/twitter
Iléẹjọ́ da ẹjọ́ Jegede, olùdíje PDP l'Ondo nù, Ó ní Akeredolu ni gómìnà
Ile ẹjọ to n gbọ awuyewuye kotẹmilọrun esi idibo gomina ni ipinlẹ Ondo ti fontẹ lu Rotimi Akeredolu gẹgẹ bi ẹni taraalu dibo yan sipo gomina nipinlẹ Ondo.
Iléẹjọ́ da ẹjọ́ Jegede, olùdíje PDP nù, Ó ní Akeredolu ni gómìnà tárá Ondo dìbò yaǹ.
Akomolede ati Aṣa lori BBC Yoruba: Ẹ̀yà Ara Ifọ̀ ní olùkọ́ Adedokun kọ́ wa
Ninu idajọ to gbe kalẹ loni, onidajọ Umar Abubakar to lewaju awọn adajọ mẹta to gbọ ẹjọ naa wọgile ẹjọ ti Jẹgẹdẹ pe lori pe awọn ko laṣẹ labẹ ofin lati gbọ ohun to fẹ ki wọn da ẹjọ le.
Ile ẹjọ naa ni ohun ti Eyitayọ Jẹgẹdẹ gbe wa siwaju ile ẹjọ naa kii ṣe ohun ti wọn lee yọ ṣuti ete si nitori ọrọ abẹnu laarin abẹ orule ẹgbẹ oṣelu kan ni ko kan ile ẹjọ rara.
Ile ẹjọ naa ni ẹgbẹ oṣelu APC fa Oluwarotimi Akeredolu ati igbakeji rẹ, Lucky Aiyedatiwa kalẹ gẹgẹ bi ọmọ oye fun ipo gomina.
O ni eyi wa ni ibamu pẹlu ilakalẹ abala kẹtadinlọgọsan iwe ofin Naijiria ati abala ikọkanlelọgbọn iwe ofin eto idibo lorilẹede Naijiria.
Onidajọ Abubakar ni iwe ofin idibo ko la kalẹ pe ẹni bayi ni pato ni ki wọn gbe orukọ oludije ibo le lọwọ ati pe kẹnu maa gbofo ni ti guguru ni bi alaga ba tẹwọ gbaa.
Oríṣun àwòrán, Others
Gẹgẹ bi o ṣe jẹ oni ọjọ Iṣẹgun, ogunjọ, oṣu kẹrin, ọdun 2021 lawọn Adajọ ile ẹjọ to n gbọ awuyewuye esi idibo gomina ni ipinlẹ Ondo mu fun idajọ lori ẹjọ ti oludije ẹgbẹ oṣelu PDP Eyitayọ Jẹgẹdẹ pe tako esi idibo to gbe Rotimi Akeredolu ti ẹgbẹ oṣelu APC gẹgẹ bi gomina ipinlẹ Ondo.
Amọṣa, ile ẹjọ naa ti ni ori ayelujara 'zoom' ni wọn yoo ti gbe idajọ naa kalẹ.
hhhhhh
Eyi ni pe ko si ẹnikẹni ti yoo wa ninu ile ẹjọ lati gbọ idajọ naa, ori ayelujara ikansira ẹni zoom ni gbogbo awọn ti ọrs kan ninu ẹjọ naa yoo ti feti ko idajọ naa.
Gẹgẹ bi ohun ti a gbọ, igbesẹ naa waye latari iyanṣẹlodi awọn oṣiṣẹ ẹka eto idajọ lorilẹede Naijiria to n lọ lọwọ lati ja fun ominira iṣuna fun ẹka eto idajọ lorilẹede Naijiria.
Eto idibo sipo gomina ni ipinlẹ Ondo ti waye koda, wọn ti bura fun Rotimi Akeredolu gẹgẹ bi gomina nibẹ.
Amọṣa, loni ni ile ẹjọ yoo sọ bi ọmọ yoo ṣe ṣori lori aga gomina ni ipinlẹ naa laarin gomina Rotimi Akeredolu ti ẹgbẹ oṣelu APC ati Eyitayo Jẹgẹdẹ ti ẹgbẹ oṣelu PDP.
Oríṣun àwòrán, Eyitayo jegede/twitter
Eyitayọ Jẹgẹdẹ gbe Rotimi Akeredolu lọ sile ẹjọ lẹyin ti ajọ INEC kede esi idibo naa ni ọjọ kọkanla, oṣu kẹwaa, ọdun 2020.
Nibẹ ni o si ti n rọ ile ẹjọ to n gbọ awuyewuye esi idibo ni ipinlẹ naa lati wọgile ikede INEC naa ki o si kede oun Jẹgẹdẹ gẹgẹ bii gomina ti araalu dibo yan ni ipinlẹ Ondo.
Kini o le ṣẹlẹ nibi idajọ ti yoo waye lonii ni Ondo?
Pẹlu idajọ ti yoo waye loni, ọna mẹta lọrọ naa lee jasi:
Yala ki ile ẹjọ naa ni ki Gomina Rotimi Akeredolu o tẹsiwaju gẹgẹ bi gomina, tabi ko wọgile ibo naa ko kede atundi ibo.
Ohun kẹta ti ile ẹjọ naa lee pa laṣẹ ni ki o kede Jẹgẹdẹ gẹgẹ bi gomina.
Eyi yoo wu ko jẹ nibẹ, Ọjọ Iṣẹgun ogunjọ, oṣu kẹrin, ọdun 2021 yoo ni ami ninu eto idibo ipinlẹ Ondo.
Ni ọsẹ to kọja ọjọ kẹtalelogun, oṣu kẹrin, ọdun 2021 ni ile ẹjọ fi idajọ rẹ si lori ẹjọ naa ṣugbọn o dabi ẹni pe ayipada ti de ba eyi.
aaaaaaaaaaaaaaa
Nollywood, Yollywood: Tayo Sobola tí ọ̀pọ̀ mọ̀ sí Ṣótáyọ̀ Gaga ní wọ́n ti fi Òun jẹ ìyá Ọba ní Nasarawa
Oríṣun àwòrán, Sotayogaga/instagram
Ọpọ awọn ololufẹ gbajugbaja oṣere tiata Yoruba ni, Tayọ Sobọla ti ọpọ mọ si Ṣotayọ Gaga ni ko lee pa idunnu wọn mọra bayii.
Eyi ko ṣeyin igba ti eekan oṣere sinima naa kede loju opo Instagram rẹ ni ọjọ diẹ sẹyin pe wọn ti fi oun jẹ Iya oba ni ilu Uke ni  ipinlẹ Nasarawa.
Sotayo Gaga ni Emir ti ilu Uke, Abdullah Hassan lo fi oun jẹ oye tuntun naa ni aafin rẹ.
Sotayo ni lede Hausa, orukọ oye naa ni Sarauniya to tumọ si iya ọba.
Igbesẹ nla lọpọ awọn ololufẹ rẹ ri eyi si nitori pe gẹgẹ bi awọn kan ninu wọn ṣe sọ ninu idahun wọn si atẹjade rẹ naa, o fihan pe awọn ara oke ọya pẹlu n gbadun iṣẹ ọwọ rẹ, wọn si mọ riri rẹ pẹlu.
hhhhhh
Lara awọn to wa nibi ayẹyẹ naa ni Ambasadọ Sadiq Ibrahim atawọn eekan ọmọ ilu naa.
Oríṣun àwòrán, Tsotayogaga/instagram/screenshot
Akomolede ati Aṣa lori BBC Yoruba: Ẹ̀yà Ara Ifọ̀ ní olùkọ́ Adedokun kọ́ wa
Insecurity in Nigeria: Wo àwọn ìkọlù àgọ́ ọlọ́pàá tó ti wáyé lẹ́kùn àríwá gúúsù Nàìjíríà ní lọ́wọ́ yì
Oríṣun àwòrán, Ebonyi police
Lẹnu lọwọlọwọ yii gbọnmọgbọnmọ ikọlu awọn agbebọn sawọn agọ ọlọpaa lẹkun ila oorun gusu orilẹede Naijiria n kọ ọpọlọpọ lominu paapaajulọ awọn alaṣẹ eto abo lorilẹede Naijiria.
Amọṣa, iṣẹlẹ naa ti wa di lemọlemọ to si n mu ki ọpọ awọn olugbe naa o maa kọrin araba tunra mu, odo n gbarere.
Eyi ni ṣisẹ n tẹle bi awọn ikọlu naa ti ṣe waye laarin oṣu mẹfa titi di asiko ti a fi n ko iroyin yii jọ :
Eyi waye ni ọjọ kẹjọ oṣu kini, ọdun 2021 ninu eyi ti awọn ọlọpaa mẹta ti padanu ẹmi wọn.
Agọ ọlọpaa to wa ni ilu Onueeke ni ijọba ibilẹ Ezza south ni ipinlẹ naa ni wọn kọlu.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ni ọjọ kini oṣu keji ọdun 2021 leyi waye to si mu ẹmi ọlọpaa kan lọ.
Agọ ọlọpaa to wa ni Omoba ni Ijọba ibilẹ Isiala Ngwa south leyi ti waye.
Ni ọjọ kẹrin, oṣu keji ọdun 2021, awọn agbebọn kan tun kọlu agọ ọlọpaa ni Isu ni Onitsha Isu nibiti wọn ti jo agọ ọlọpaa kan bolẹ.
Ni ọjọ karun un oṣu keji, ọdun 202, awọn agbebọn kan tun kọlu agọ ọlọpaa kan ni Umulowo nijọba ibilẹ Obowo nibi ti wọn ti pa ọlọpaa meji.
Oríṣun àwòrán, Ebonyi police
Ọjọ kẹtalelogun, oṣu keji yii kan naa, awọn agbebọn yii tun ṣe ọṣẹ nipinlẹ Abia nibi ti wọn ti pa ọlọpaa meji lagọ ọlọpaa to wa ni Abayi ni ilu Aba.
Nigba to di ọjọ karundinlọgbọn, oṣu keji ọdun 2021, Aboh Mbaise ni wọn gbe iṣẹ ibi wọn lọ ni ipinlẹ Imo nibi ti wọn ti dana sun odindi agọ ọlọpaa kan bolẹ.
Awọn oniṣẹ ibi yii tẹsiwaju ni ipinlẹ Imo ni ọjọ kẹsan an, oṣu kẹta nigba ti wọn tun kọlu agọ ọlọpaa kan ni Ihitte-Uboma ti wọn si jo agọ ọlọpa to wa nipa.
Lọjọ kejidinlogun oṣu kẹta, ọdun 2021, wọn tun ṣekupa ọlọpaa kan ni ibudo ayẹwo ọkọ tawọn ọlọpaa gbe kalẹ ni Neni nijọba ibilẹ Anaocha.
Lọjọ kọkandinlogun oṣu kẹta ọdun 2021, awọn agbebọn tun pa ọlọpaa kan nigba ti wọn kọlu agọ ọlọpaa Ekwulobia ni Nanka ni ipinlẹ naa.
Oríṣun àwòrán, other
Ipinlẹ Abia ni wọn tun gbe iṣẹ laabi wọn lọ ni ọjọ kejilelogun oṣu kẹta ọdun 2021 nigba ti wọn kọlu agọ ọlọpaa ni Abiriba, iyẹn ni ijọba ibilẹ Ọhafia.
ọlọpaa mẹta ni wọn pa lasiko ikọlu naa.
Akomolede ati Aṣa lori BBC Yoruba: Ẹ̀yà Ara Ifọ̀ ní olùkọ́ Adedokun kọ́ wa
Lọjọ kẹsan an, oṣu kẹrin, ọdun 2021, awọn agbebọn kan tun kọlu agọ ọlọpaa ni Ukpo ni ipinlẹ Anambra.
Eyi waye  nigba tawọn agbebọn naa ya wọ olu ileeṣẹ ẹkun kẹtala ileeṣẹ ọlọpaa ni ipinlẹ naa ni nnkan bi agogo mẹrin.
Sugbọn iroyin sọ pe awọn ọlọpaa da wọn lọwọ duro ki wọn to le ṣe ọṣẹ ju bi o ti yẹ lọ.
Awọn ọlọpaa ni awọn agbebọn naa ko ri ibọn ọlọpaa ko salọ lasiko ikọlu naa
Awọn iroyin abẹle kan sọ pe wọn pa ọlọpaa meji lasiko ikọlu naa.
Oríṣun àwòrán, other
Ni ọjọ kẹsan an, oṣu kẹrin, ọdun 2021 yii kan naa awọn agbebọn tun kọlu agọ ọlọpaa ni Ozokoli, nijọba ibilẹ Bende nipinlẹ Abia.
Lasiko ikọlu wọn naa, wọn tu awọn ti wọn wa lahamọ ọlọpaa ni agọ naa silẹ ti wọn si dana sun ile ọkọ atawọn dukia miran to jẹ ti ọlọpaa nibẹ.
aaaaaaaaaaaaaaa
"Nibi ti ọrọ de duro bayii, ko si ẹni lee sọ ni pato iye ọlọpaa to ti ku sọwọ ikọlu awọn agbebọn yii ṣugbọn gbogbo igba ti ikọlu yii ba n waye ni ileeṣẹ ọlọpaa n fi da araalu loju ""pe ko si apaniyan kan ti yoo lọ laijiya"""
Ọpọlọpọ igba ni wọn si ti fi ẹsun kan awọn ọmọ ẹgbẹ ajijangbara IPOB pe awọn lo wa nidi ikọlu naa, ṣugbọn IPOB ti ni awọn ko mọwọ-mẹsẹ nipa awọn ikọlu buruku naa.
hhhhhh
Idriss Deby: Àwọn ológun ní Chad ní Ààrẹ Idriss Deby kú lọ́wọ́ ọta ìbọn tó faragbà
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Idriss Deby, Aàrẹ orílẹ̀-èdè Chad jáde láyé!
Iroyin to n jade latọdọ awọn ologun orilẹ-ede Chad n sọ pe Aarẹ Idris Deby ti orilẹede naa ti jade laye.
Awọn alaṣẹ ologun lorilẹede Chad ni Aarẹ Deby ku latari ọgbẹ ọta ibọn to gba lasiko ti wọn n koju awọn ọmọogun ọlọtẹ to ṣigun wọ olu ilu orilẹede naa, N'Djamena.
Ireti wa pe aarẹ Deby yoo wọle saa kẹfa gẹgẹ bi aarẹ orilẹede naa lẹyin idibo aarẹ to waye nibẹ lọjọ kọkanla oṣu kẹrin ọdun yii.
Kini o ti ṣẹlẹ tẹlẹ?
Idriss Deby jẹ aarẹ ti o ditẹ gbajọba ni orilẹ-ede Chad.
Ọpọ igba si ni wọn ti gbiyanju lati ditẹ gbajọba lọwọ rẹ ṣugbọn to n ja si pabo ni orilẹ-ede Chad nilẹ Adulawọ.
Loṣu kẹrin ọdun 2011 ni Idriss Debby di aare ilẹ Chad lẹẹkẹrin nigba ti awọn ẹgbẹ alatako kọ lati kopa ninu idibo naa gẹgẹ bi wọn ṣe ṣe lọdun 2006.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Lọdun 2008 nijọba waa ko pẹlu awọn ọmọ ogun alatako ninu ikọlu to gbona ni chad nigba naa.
Koda lọdun 2013 nijọba Idriss Deby ni oun ti fopin si iditẹ gbajọba lati ọdọ awọn eekan ninu iṣẹ ologun.
Tani Idriss Derby?
A bi Idriss Deby ni Fada ni ila oorun Chad lọdun 1952.
O jẹ akọṣẹmọṣẹ ọmọ ogun ilẹ nibi to ti ran Hissen Habre lọwọ si Goukouki Queddei lọdun 1982.
Lọdun 1989 lo sa lọ si orilẹ-ede Sudan lẹyin ti wọn fẹsun iditẹgbajọba kan an.
Lọdun kan lẹyin eyi ni Patriotic Salvation Movement le Ọgbẹni Habre lọ lọdun naa.
hhhhhh
Ọdun 1991 ni wọn kede Ogbeni Idriss Deby gẹgẹ bii Aarẹ ile Chad.
Lọdun 1996 ni Deby tun dibo gbajọba de ipo aarẹ alagbada labẹ akoso ẹgbẹ oṣelu alasopọ.
Lẹyin eyi ni wọn tun dibo yan an lọdun 2001, ati 2005 ni eyi to fi lọ fun saa kẹta lẹyin ayipada ọdun 2005.
Lọdun 2013 ni amnesty International se akọsilẹ kan pe Idriss Deby n fiya jẹ awọn to ba n bu ẹnu ẹ̀tẹ́ lu iṣejọba rẹ ni Chad ati pe ko mu awọn ileri tuntun to n ṣe ṣe fun ara ilu lati bọwọ fun ẹtọ ọmọniyan to ṣe lọdun 1990 to gori aleefa.
Deby Idriss gbogun ti awọn oniṣẹ ibi agbesunmọmi pupọ.
O ṣiṣẹ pẹlu awọn orilẹ-ede to sunmọ Chad bii Niger, Nigeria, Cameroun, Mali ati bẹẹ bẹẹ lọ.
Oun lo n lewaju ninu esi idibo ti wọn n ka lọwọ ni orilẹ-ede Chad nibi ti wọn ni o ti ni ida ọgọrin bayii ṣaaju iku rẹ.
Eyi tumọ si pe ki wọn kede rẹ lo n duro de
aaaaaaaaaaaaaaa
Iru iku wo lo pa Idriss Deby?
Awọn ọmọ ilẹ Chad sọ pe lasiko ogun ni aarẹ Idriss Deby ṣubu loju ija.
Lasiko yii ni awọn ọmọ ogun ilẹ Chad n gbogunti awọn ọmọ ogun alatako to ti dana ija ni olu ilu Chad ni N'Djamena
Eto idibo ti wọn ṣe lọjọ kọkanla, oṣu kẹrin, ọdun yii ni wọn ti n reti pe Idriss Deby ni yoo bori idibo naa ti yoo si gori aleefa aarẹ Chad lẹẹkẹfa.
Akomolede ati Aṣa lori BBC Yoruba: Ẹ̀yà Ara Ifọ̀ ní olùkọ́ Adedokun kọ́ wa
Kini a n pe ni ẹya ara ifọ?
Eto Akomolede ati Asa lori BBC Yoruba toni ti jade nibi ti a ti n gbe ẹya ara ti a n lo fun iro ede pipe wo.
Arabinrin Adedokun Ronke ni olukọ wa lati ile ẹkọ Emmanuel Agboola Baptist Grammar School, Kajola ni Ogbomoso ni ipinlẹ Oyo.
Kini a n pe ni iro aikunyun ati iro akunyun?
Kini pataki eyin oke, ahọn ati komookun nigba ti eeyan ba n sọrọ?
Kọ sii nipa ẹya ara ti a n lo fun iro ede pipe nigba ti a ba nṣafọ.
Awọn ẹya ara wo ni a le fi oju ri?
Awọn wo ni a ko le fojuri to si ṣe pataki fun iro ede pipe?
Olukọ Adedokun Ronke tun ṣalaye kikun lori awọn afipe asunsi ati akanmọlé
Mọ sii nipa iro akunyun ati iro aikunyun.
Autonomy for Judiciary: Àwọn Gomina ṣetán láti yọwọ́ kúrò nínú sísan owó oṣù àwọn aṣòfin ìpínlẹ̀ àti Adájọ́- Fayemi
Oríṣun àwòrán, Getty/kayode fayemi
Ogunjọ, oṣu Karun-un, ọdun 2020 ni Aarẹ Muhammadu Buhari buwọlu ofin ti yoo fun awọn ile aṣofin ipinlẹ, ati ẹka eto idajọ ni awọn ipinlẹ ni ominira lati da duro ninu eto inawo wọn.
Igbesẹ Aarẹ ko ṣẹyin atunsẹ to waye si abala ofin naa ninu iwe ofin ọdun 1999.
Ọpọlọpọ awọn gomina ipinlẹ lo fi aidunnu wọn han lori igbesẹ naa, eyi to mu ki Aarẹ ṣe ipade kan pẹlu wọn lo ri ayelujara.
Bakan naa ni aarẹ da sisọ ofin naa di aṣẹ ijọba duro, titi ti Agbẹjọro Agba Naijiria  yoo fi ṣe ipade pẹlu awọn gomina lati yanju ibẹru ti wọn n ba ni lori igbesẹ aarẹ.
Amọ, ni ọjọ kọkandinlogun, oṣu Kẹrin, ọdun 2021, ẹgbẹ awọn gomina ni Naijiria kede pe awọn ti fi ara mọ ofin yii.Àwọn Gomina ṣetán láti yọwọ́ kúrò nínú sísan owó oṣù àwọn aṣòfin ìpínlẹ̀ àti Adájọ́- Fayemi
Ikede wọn waye lẹyin ti awọn oṣiṣẹ ile ẹjọ ati awọn agbẹjọro bẹrẹ iwọde ati iyanṣẹlodi lori ọrọ naa.
Àwọn ọmọ ẹgbẹ́ PDP fẹ̀hónúhàn nílé ẹjọ́ gíga jùlọ
Ṣaaju ki Aarẹ Buhari to o pa aṣẹ naa, awọn gomina ipinlẹ lo ma n sọ iye owo ti wọn yoo fun awọn ẹka ijọba yooku, to fi mọ yiyọnda owo naa fun wọn.
O ma n farahan ninu aba owo isuna ti wọn n gbe lọ siwaju awọn aṣofin ipinlẹ.
Eyi mu ki awọn gomina o ni aṣẹ ati agbara lori ẹka eto idajọ ati awọn aṣofin.
Gẹgẹ bi alaye ti ileeṣẹ amofin Lori Niji Oni & Co ṣe lori ofin tuntun yii ni ori ayelujara rẹ, nijioni.com, Aarẹ ti paṣẹ pe ki Oluṣiro owo Agba fun Naijiria, o ma a yọ lara owo to tọ si ipinlẹ ti ko ba ti tẹle aṣẹ tuntun yii, ki owo naa to tẹ wọn lọwọ.
Awọn ipinlẹ gbọdọ fi si inu ofin eto isuna wọn pe ominira wa fun ẹka idajọ ati aṣofin, lati ṣeto isuna funra wọn. Awọn ti ko ba ni ofin yii tẹlẹ gbọdọ fi kun ofin wọn.
Akomolede ati Aṣa lori BBC Yoruba: Ẹ̀yà Ara Ifọ̀ ní olùkọ́ Adedokun kọ́ wa
1) Aṣẹ aarẹ fihan pe Oluṣiro owo Agba nipasẹ aṣẹ aarẹ, tabi eyi ti Agbẹjọro agba ba pa, le fọwọ si i pe ki wọn o yọ lara owo to n lọ si apo ijọba ipinlẹ to ba kuna lati yọnda owo to tọ si ẹka idajọ ati ile aṣofin ipinlẹ rẹ, ni ibamu pẹlu Abala ofin 121 (3) ti Naijiria fun ọdun 1999.
2) Aṣẹ tuntun yii tun fi lelẹ pe ẹka to n dari ijọba 'executive' ko gbọdọ ṣe aba eto isuna fun ẹka idajọ mọ:
a)O ni igbimọ mii fun owo isuna ni yoo ma ṣe e , ti yoo si tun mojuto bi wọn ṣe n na.
b) Ẹka eto idajọ ni ipinlẹ kọọkan ni yoo yan igbimọ rẹ fun eto iṣuna, amojuto ati nina owo iṣuna rẹ.
c) Awọn ti yoo si wa ninu igbimọ naa ni Adajọ Agba ni ipinlẹ naa (Alaga), Aarẹ ile ẹjọ Sharia/ile ẹjọ ibilẹ, eeyan meji lati inu ajọ to n dari ẹka eto idajọ (Adajọ Agba ni yoo yan wọn lẹyin to ba jiroro pẹlu awọn ọmọ igbimọ to kù).
d) Akọwe ile ẹjọ giga ipinlẹ ni yoo jẹ Akọwe igbimọ yii.
aaaaaaaaaaaaaaa
a)Ti igbimọ naa ba ti tẹwọ gba àbá owo isuna fun lọdọọdun, yoo ranṣẹ pe awọn Oluṣiro owo ni ile ẹjọ kọọkan tabi ẹlẹgbẹjẹgbẹ ni ẹka eto idajọ, lati wa ṣalaye lori aba isuna wọn.
b) aba isuna naa yoo da lori awọn ilana ti igbimọ to wa fun isuna ba fun awọn ile ẹjọ ati ẹlẹgbẹjẹgbẹ ni ẹka eto idajọ. Eyi ni wọn o si gbe lọ si iwaju awọn aṣofin ipinlẹ.
c) ti ijọba ba ti yọnda owo isuna naa,  igbimọ yii yoo ma ranṣẹ si ọfiisi ti wọn ti n ṣeto owo isuna, boya ni oṣooṣu tabi asiko to ba pinnu, pe ko yọnda owo fun oṣu naa tabi oṣu mẹta.
Ibeere wọn yii ni Oluṣiro owo Agba ni ipinlẹ yoo fi aṣẹ si pe ki wọn o yọnda owo fun awọn oludari nile ẹjọ ati ẹlẹgbẹjẹgbẹ ni ẹka eto idajọ, ni ibamu pẹlu ofin to de eto isuna.
Ilana ti ijọba ipinlẹ n gba ṣe akọsilẹ, eto agbekalẹ owo iṣuna tẹlẹ naa ni ẹka eto idajọ ati aṣofin yoo tẹle.
Oríṣun àwòrán, others
Ijọba ti ni ki awọn adajọ ati aṣofin ni ipinlẹ fi ọkan balẹ nitori awọn gomina ti ṣetan lati jẹ ki wọn da duro lori owo osu wọn.
Gomina ipinlẹ Ekiti ati Alaga ẹgbẹ awọn gomina lorilẹede Naijiria, Kayode Fayemi lo kede rẹ lẹyin ipade ni ile ijọ,ba ni ilu Abuja
Oríṣun àwòrán, @Fayemi
Fayemi ni ko si otitọ ninu iroyin pe awọn gomina ipinlẹ tako aba ki awọn aṣofin daduro lai si iranwọ ijọba ipinlẹ ati eto idajọ ni ipinlẹ naa pẹlu.
O ni ori ọwọ kan naa ni awọn Abẹ̣ṇ̣ugan ile igbimo aṣofin ipinlẹ ati awọn adajọ wa pẹlu gomina.
Amọ, gomina ipinlẹ Ekiti, Kayode Fayemi ko sọ ni ẹkun rẹrẹ bi idaduro awọn ẹka iṣejọba mejeeji naa yoo ṣe lọ.
''Inu mi dun wi pe olori awọn oṣiṣẹ aarẹ Buhari, Ibrahim Gambari ti bẹrẹ igbese ti yoo tẹ gbogbo awọn ti ọrọ naa kan lọrun.''
''A ko tii le sọ ọjọ gan an ti idaduro ẹka aṣofin ati idajọ yoo bẹrẹ ni pẹrẹwu, amọ inu oṣu to n bọ ni.''
hhhhhh
Bakan naa ni Fayemi wa kesi awọn adajo to gunle iyanṣelodi lati jọwọ pada si ẹnu iṣẹ wọn fun itẹsiwaju orilẹede Naijiria.
O ni awọn adajọ yẹ ki wọn woo ṣe bayii nibi ti ọrọ de duro, nitori awọn gomina ipinlẹ kaakiri Naijria lo ti gbe igbeṣẹ akọni lati ri pe wọn ko fi eto wọn dun wọn.
Ọjọ Kẹfa, Oṣu Kẹrin ni ẹgbẹ awọn oṣiṣe ni ẹka eto idajọ ni Naijiria, JUSUN gunle iyanṣelodi lati bere fun ẹto to fun wọn ni aṣẹ lati daduro nitori bi ijọba ipinlẹ ṣe n fi owo ajẹmọnu wọn dun wọn.
Police rescue: Àwọn ọlọ́pàá ti dóòlà ọmọbìnrin tí àwọn òbí rẹ̀ so mọ́lẹ̀ fún ọdún 10
Oríṣun àwòrán, KANO POLICE COMMAND
Ileeṣẹ ọlọpaa nipinlẹ Kano ti doola ẹmi ọmọ ọdun marundinlogun kan ti awọn obi rẹ somọlẹ bii ẹran fun ọdun mẹwaa.
Ileeṣẹ ọlọpaa sọ pe lati igba ti Aisha Jubril ti wa ni ọmọ ọdun marun un ni wọn ti somọlẹ si inu ile.
Kọmisọnna ọlọpaa ni kete ti iroyin ipo ti ọmọ naa wa tẹ awọn leti ni awọn ọlọpaa ti sigun lọ sibẹ lati lọ doola ẹmi rẹ.
Awọn ọlọpaa ni irisi ọmọ naa fihan pe ko jẹun, bẹẹ si ni ko ri itọju to peye nitori ibi ti wọn ti mọlẹ si kun fun idọti.
Nibayii, Aisha  ti wa ni ileewosan Murtala Mohammed nilu Kano, nibi to ti n gba itọju.
Akomolede ati Aṣa lori BBC Yoruba: Ẹ̀yà Ara Ifọ̀ ní olùkọ́ Adedokun kọ́ wa
Bakan naa ni iya Aisha, Rabi Mohammed, ti wa ni panpẹ ọ̣lọpaa , ti baba rẹ si ti salọ.
Nkan bi ọdun to kọja ni iru iṣẹlẹ bayii peleke si ni ilu Kano, ti awọn alabojuto yoo ma a so ọmọ mọlẹ bi ẹran.
Amọ, iyalẹnu lo jẹ nitori awọn obi Aisha to da ẹjẹ le e lori ni o fi iya jẹ ẹ.
Ileeṣẹ ọlọpaa ni iwadii ti bẹrẹ lori iṣẹlẹ naa, ti awọn si ti gbe ẹjọ naa lọ si ẹka to n risi iwa ọdaran, ti yoo si ṣeeṣe ki wọn fi oju ba ile ẹjọ.
hhhhhh
Ọwọ́ NDLEA tẹ akẹ́kọ̀ọ́ fásitì tó n ta 'cookies' tí wọ́n fi oògùn olóro ṣe fún àwọn ọmọ́de
Oríṣun àwòrán, Ndlea nigeria
Ajọ to n gbogun ti lilo egboogi oloro ni Naijiria, NDLEA ti mu ọmọbinrin kan ati ọrẹkunrin rẹ, fun pe wọn n ta bisikiti ti wọn fi egboogi oloro ṣe fun awọn ọmọde nilu Abuja.
Ninu atẹjade ti ajọ NDLEA fi sita loju opo Twitter rẹ lo ti sọ pe ọwọ tẹ Rhoda Agboje.
Rhoda jẹ akẹkọọ fasiti, ati ọrẹkunrin rẹ, Ifeanyi Nwankwo, pe wọn n fi egboogi oloro pelo bisikiiti ti wọn n ta fun awọn ọmọ ileewe ati awọn eeyan mi laarin ilu, ti ko mọ iru iṣẹ ti wọn n ṣe.
aaaaaaaaaaaaaaa
Gẹgẹ bi ajọ naa ṣe sọ, aṣiri ikọ naa tu u, lẹyin ti ọwọ tẹ Rhoda t'ohun ti bisikiti naa mẹrin lọwọ rẹ lọjọ Aiku, ọjọ kejidinlogun, oṣu Kẹrin, ọdun 2021.
Agbegbe NNPC Cooperative Estate ni Gaduwa, nilu Abuja, ni ọwọ ti tẹ ẹ lẹyin ti awọn kan fi ẹjọ rẹ sun pe o fun ọmọde kan ni bisikiiti naa jẹ.
Iroyin sọ pe ọmọdebinrin naa bẹrẹ si ni ṣe were-were, ko le sun, bẹẹ lo n sọrọ bi ẹni to ni aarun ọpọlọ nitori oró bisikiiti naa lara rẹ.
Lasiko ti awọn oṣiṣẹ ajọ NDLEA n fi ọrọ wa Rhoda l'ẹnu wo lo jẹwọ pe oun ati ọrẹ rẹ kan ni wọn jọ n ṣe bisikiiti naa.
Oríṣun àwòrán, Ndlea nigeria
Ọwọ tẹ Rhoda Agboje ati ọrẹkunrin rẹ, Ifeanyi Nwankwo ti ọwọ NDLEA
Ẹgbẹrun kan aabọ Naira si ni wọn ma n ta ẹyọ mẹta rẹ.
Iwadii ti wọn ṣe si ile ọrẹkunrin rẹ lo mu ki wọn o ri igba bisikiiti naa ti wọn fi egboogi oloro ṣe.
Bakan naa ni wọn ba awọn irinṣẹ ti wọn fi n ṣe e.
Akomolede ati Aṣa lori BBC Yoruba: Ẹ̀yà Ara Ifọ̀ ní olùkọ́ Adedokun kọ́ wa
Afurasi naa sọ pe oun ma n ta a ni ibi ariya, fun awọn araalu ti ko mọ nkan ti wọn fi ṣe e, to fi mọ awọn ọmọ ileewe.
Bakan naa lo ma n gbe fun awọn ile itaja ati ile ijo gẹgẹ bi alagbata rẹ.
hhhhhh
Idriss Deby: Wo kókó méje nípa Mahamat Kaka Deby tò gba ipò Ààrẹ fìdíhẹ tuntun ní Chad
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Lẹyin iṣekupani aarẹ Idriss Deby to n tukọ orilẹ-ede Chad lanaa ni wọn yan ọmọ rẹ Mahamat Kaka Idriss Deby sipo aarẹ nibẹ.
Lati igba ti iroyin iyansipo rẹ si ti jade ni gbogbo eeyan ti n fẹ mọ sii nipa arẹ fidihẹ to n dele naa.
Tani Mahamat Idriss Deby Itno to di aarẹ tuntun ilẹ Chad lẹyin iṣekupani baba rẹ?
Ileeṣẹ ologun Chad ti fi lede pe Mahamat Idriss Deby Itno ni yoo  di aarẹ tuntun ilẹ Chad, lẹyin ti baba rẹ, Idriss Deby Itno di oloogbe.
Idriss Deby to jẹ baba aarẹ tuntun naa ni o ti wa ni ijọba fun ọgbọn ọdun, ki o to ba ogun lọ nibi ikọlu to waye lorilẹ-ede naa.
Budo Ikoko water problem: Ìyàwó wa ti sá lọ kúrò ní Asa nítorí àìsí omi- Alhaji Sunmonu
Wo koko meje to ṣe pataki nipa aarẹ tuntun naa, Mahamat kaka Deby:
•Mahamat Idriss Deby to jẹ ogagun yoo di ipo baba rẹ mu fun oṣu mejidinlogun.
•Ọdun 1983 si 1984 ni wọn bi Mahamat Idriss Deby, to si jẹ ẹni ọdun mejidinlogoji si ẹni ọdun mẹtadinlogoji.
•Orilẹ-ede Faranse lo ti lọ kọ iṣẹ ologun lẹyin to lo ile ẹkọ alakọbẹrẹ ni orilẹ-ede Chad.
Ọwọ́ NDLEA tẹ akẹ́kọ̀ọ́ fásitì tó n ta 'cookies' tí wọ́n fi oògùn olóro ṣe fún àwọn ọmọ́de
Olufon ti ilu Ifon-Orolu, Ọba Almarouf Adekunle Magbagbeola ti wàjà
Àwọn ọlọ́pàá ti dóòlà ọmọbìnrin tí àwọn òbí rẹ̀ so mọ́lẹ̀ fún ọdún 10
Wo àtúpalẹ̀ nkan tí òmìnira tí àwọn gómìnà fi ọwọ́ sí fún ẹ̀ka ìdájọ́ Naijiria túmọ̀ sí
Ṣé lóòtọ́ ni Sotayo Gaga ti di ìyá Ọba nílẹ̀ Hausa?
Kí ni ìdí tí àwọn ọmọ Naijiria ṣe fẹ́ kí Isa Pantami kọ̀wé fi ipò sílẹ̀?
•Ni ọdun 2013 ni wọn yan an gẹgẹ bi igbakeji adari ikọ ọmọogun ilẹ Chad to pegede julọ (Chadian Special Forces).
•Ki baba rẹ to ku, o ṣiṣẹ gẹgẹ bi igbakeji adari ikọ ọmọogun ilẹ Chad lasiko ogun abẹlẹ ariwa ilẹ Mali.
•Bakan naa o ṣiṣẹ gẹgẹ bi Alaga ajọ to n risi gbigbe ijọba ologun silẹ ni Chad.
Akomolede ati Aṣa lori BBC Yoruba: Ẹ̀yà Ara Ifọ̀ ní olùkọ́ Adedokun kọ́ wa
•Lasiko ti ọgagun Kaka wa ni ipo aarẹ tuntun yii, o yẹ ki Abẹnugan Ile Igbimọ Asofin orilẹede naa pe fun idibo sipo aarẹ, eleyii ti Kaka ko ni kopa nibẹ.
Aare Idriss Deby to papoda naa je okan gboogi ninu awon to ja fitafita tako iko Boko Haram ni agbegbe Chad nigba aye re.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Wọ́n ti kéde ọmọ Ààrẹ Chad tẹ́lẹ̀, Kaka Deby gẹ̀gẹ́ bíi Ààrẹ fìdíhẹ tuntun
Ileeṣẹ ọmọ ogun orilẹ-ede Chad ti kede ọgagun Mahamat Idriss Deby, to jẹ ọmọ Aarẹ Idriss Deby to papopda gẹgẹ bii dari igbimọ ọmọ ogun ti yoo maa dari orilẹ-ede naa fun saa yii.
Ikede yii lo waye lẹyin iku Aarẹ Idriss Deby ọhun lẹyin to fara gba ọta ibọn loju ija pẹlu awọn ọmọ ologun ọlọtẹ.
Wọn sọ pe ọgagun Mahamat Kaka ni yoo tukọ orilẹ-ede naa gẹgẹ bii Aarẹ fidihẹ fun ọdun kan abọ.
Kini o n ṣẹlẹ̀ ní Chad lẹ́yìn ikú Idriss Deby?
Ki wọn to kede ipo tuntun yii, ọgagun Kaka ni alaga igbimọ to n ri si ayipada ijọba ologun ni Chad.
Onimọ nipa eto oṣelu kan, Ọjọgbọn Evariste Ngarlem Toldé ṣalaye fun BBC pe, o lodi si ofin orilẹ-ede Chad bi wọn ṣe kede ọmọ Idriss Deby gẹge bii olori lẹyin iku baba rẹ.
aaaaaaaaaaaaaaa
Ṣaaju ji wọn ti kọkọ kede konile-o-gbele lorilẹ-ede naa lẹyin iku Aarẹ Deby, igbele naa yoo si maa bẹrẹ lati aago mẹfa irọlẹ si marun un owurọ.
Idriss Deby ni Aarẹ Chad lati ọdun 1990 titi di ọdun 2021 to dagbere faye.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ijọba orilẹ-ede Chad ti kede ofin konile-o-gbele lẹyin iku Aarẹ ana, Idriss Deby Ta ni Idriss Deby tí kò bá tún gorí àlééfà ipò aarẹ Chad lẹ́ẹ̀kẹfà tó wá ṣaláìsí yìí?
Konile-o-gbele alailọjọ naa yoo bẹrẹ lati aago mẹfa irọlẹ si marun u owurọ, bakan naa ni ọkọ ofurufu kankan ko ni jade tabi wọle si orilẹ-ede naa fun saa yii.Ẹlẹ́wọ̀n 44 kú sọ́gbà ẹ̀wọ̀n nítorí ooru tó mú púpọ̀
Deby jade laye lẹyin to fara gba ọta ibọn lasiko to n koju awọn ọmọogun ọlọtẹ to ṣigun wọ olu ilu orilẹede naa, N'Djamena.
Ọjọ kọkanla oṣu yii ni awọn ọmọ ogun ọlọtẹ naa bẹrẹ si n ṣakọlu lemọlemọ lẹyin idibo sipo Aarẹ ti wọn di, eyii ti abajade rẹ n fi han pe Deby ni yoo gori alefa fun saa kẹfa.
Idriss Deby jẹ aarẹ ti o ditẹ gbajọba ni orilẹ-ede Chad.
hhhhhh
Ọpọ igba si ni wọn ti gbiyanju lati ditẹ gbajọba lọwọ rẹ ṣugbọn to n ja si pabo ni orilẹ-ede Chad nilẹ Adulawọ.
Loṣu kẹrin, ọdun 2011 ni Idriss Debby di aare ilẹ Chad lẹẹkẹrin nigba ti awọn ẹgbẹ alatako kọ lati kopa ninu idibo naa gẹgẹ bi wọn ṣe ṣe lọdun 2006.
George Floyd: Ilé ẹjọ́ ni Derek Chauvin jẹ̀bi ẹ̀sùn mẹ́tẹ̀ẹ̀ta tí wọ́n fi kàn án lórí ikú Floyd
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ile ẹjọ ti gbe idajọ kalẹ pe ọlọpaa to kunlẹ le oloogbe George Floyd lọrun to fi ku lọdun 2020, iyẹn  ọgbẹni Derek Chauvin, jẹbi ẹsun ipaniyan mẹtẹẹta ti wọn fi kan an.
Amọṣa, yoo to ọsẹ mẹjọ si asiko yii ki wọn to ran an lọ si ẹwọn bi o tilẹ jẹ wi pe ahamọ awọn ọlọpaa ni yoo wa titi di igba naa.
Ọlọpaa ni Derek Chauvin ni ipinlẹ Minnesota lorilẹ-ede Amẹrika ti fidio kan ti ọdọbinrin kan ti orukọ rẹ n jẹ Darnella ya lasiko ti Derek fi gbe orunkun le ọkunrin alawọdudu kan ti orukọ rẹ n jẹ George Floyd lọrun nigba ti wọn fẹ fi panpẹ ofin mu.
"Fidio yii lo di ilu mọọka lori ayelujara ti gbogbo agbaye fi kọminu lori iwa kotọ awọn ọlọpaa si araalu paapaa awọn Adulawọ nibẹ, eleyi to bi iwọde ""Black lives matter"""
Ni ọjọ Iṣẹgun lawọn igbimọ oludajọ nile ẹjọ to gbọ ẹsun ti wọn fi kan ọlọpaa naa, Derek Chauvin gbe ero wọn sita lori ẹsun naa ti wọn si ni pe o jẹbi ẹsun naa.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Aarẹ Biden ati igbakeji rẹ Kamala Harris wa lara awọn aṣiwaju lagbaye ti wọn kọkọ sọrọ lori idajọ naa.
Biden ni idajọ naa ko to o, o fihan pe omi ṣi n bẹ lamu fawọn adari lorilẹ-ede Amẹrika. O ni wọn ni lati dẹkun iwa ẹlẹyamẹya lẹka gbogbo lorilẹ-ede Amẹrika.
"Biden ni ""a o le e dawọ duro nibi ti a de yii,"" ti oun ati igbakeji rẹ si, Kamala Harris si ṣalaye pe iwa ẹlẹyamẹya lẹkajẹka gbogbo to ti n waye ninu itan orilẹ-ede Amẹrika jẹ ""abawọn lara ẹmi orilẹ-ede wa""."
Bakan naa ni Aarẹ Joe Biden, aya rẹ, pẹlu igbakeji rẹ Kamala Harris tun pe ẹbi oloogbe Floyd ni kete ti idajọ naa jade ti wọn si ki wọn ku irọju.
Koda, wọn tun ṣe ileri pe igbesẹ yoo tọ idajọ naa lẹyin fun ayipada to yẹ lori ọrọ ẹlẹyamẹya nilẹ Amẹrika lati rii pe iku ẹni wọn ko ja si asan.
Oríṣun àwòrán, Reuters
Boris Johnson, olootu ijọba ilẹ Gẹẹsi
Ninu ọrọ tirẹ, olootu ijọba ilẹ Gẹẹsi, Boris Johnson wa lara awọn olori orilẹ-ede lagbaye to kọkọ sọrọ lori idajọ naa.
Boris Johnson, loju opo Twitter rẹ, kan sara si idajọ naa.
Iku Floyd bami ninu jẹ gidi, inu mi si dun si idajọ naa.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ẹwẹ, eekan ajafẹtọ ọmọniyan lorilẹ-ede Amẹrika, alagba Al Sharpton tọka si idajọ naa gẹgẹ bi akoko imọlẹ laarin kurukuru ọjọ.
Loni, a le e nu omije wa nu kuro ki a si tun mura ija fun ọjọ miran
Oríṣun àwòrán, Reuters
Bakan naa ni alagba Sharpton ṣeranti awọn alawọdudu gbogbo ti wọn ku latọwọ awọn ọlọpaa alawọfunfun.
O si ran awọn ajafẹtọ bii tirẹ leti nibi ipade adura kan lẹyin idajọ naa pe isinku Daunte Wright, ọmọ ogun ọdun tawọn ọlọpaa yinbọn pa lọsẹ to kọja ku ọjọ meji pere.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Barack Obama ati aya rẹ Michelle pẹlu ti sọrọ lori idajọ naa.
"Ninu atẹjade kan ti wọn fi sita, awọn mejeeji ni ""ohun to tọna ni ilu Minneeapolis ṣe"" ati pe ""igbesẹ to yẹ loju ọna ilọsiwaju"" ni."
Oríṣun àwòrán, Reuters
Nigba wo ni Dereck Chauvin yo bẹrẹ gbigba ijiya rẹ?
Nibayii ni wọn ti gbe idajọ rẹ kalẹ, yoo to bii ọsẹ mẹjọ ki wọn to gbe ijiya rẹ sita.
Amọṣa, niwọn to jẹ wi pe ko fi jẹ pe ko ni akọsilẹ iwa ọdaran kankan sẹyin, ilakalẹ ofin ni ipinlẹ Minnesota fihan pe o le e lọ si ẹwọn ọdun mejila.
Awọn olupẹjọ lee gbe awijare kalẹ niwaju ile ẹjọ naa pe ki wọn fun un ni ẹwọn to to ogoji ọdun iyẹn bi onidajọ Peter Cahill to n gbọ ẹjọ naa ba wo o pe ọran rẹ le pupọ.
Black lives Matter: Ọmọ Naijiria sọ ìrírí rẹ̀ lọ́wọ́ àwọn ọlọ́pàá nílẹ̀ Amerika.
Ni kete ti wọn gbe idajọ kalẹ ni ariwo ayọ lo gbode ni gbagede ile ẹjọ naa ti awọn eeyan kaakiri orilẹ-ede Amẹrika ti wọn ti peju lati mọ bi idajọ naa yoo ṣe lọ si n fo fayọ pe idajọ ododo fidi mulẹ lori iṣẹlẹ iku Floyd.
Oríṣun àwòrán, Reuters
OAU Ile Ife: Àwọn nǹkan tó ka akẹ́kọ̀ọ́ fásitì OAU Ile Ife, Emmanuel Adedeji láya ló mú kó gbẹ̀mí ara rẹ̀
Oríṣun àwòrán, other
Iroyin jade lọjọ Iṣẹgun pe akẹkọọ onipele keji ẹka eto ẹkọ nipa iṣakoso ati iṣiro owo ni fasiti Ọbafẹmi Awolọwọ, OAU ni ilu Ile Ifẹ ni ipinlẹ Ọṣun ti gba ẹmi ara rẹ.
Akẹkọọ naa ti wọn pe orukọ rẹ ni Emmanuel Adedeji gba ẹmi ara rẹ lẹyin ti wọn ni o gbe oku apakokoro jẹ.
Ninu ifọrọwerọ rẹ pẹlu BBC News Yoruba, alukoro ileewe fasiti OAU, Ọgbẹni Abiọdun Ọlarewaju ṣalaye pe lootọ ni iṣẹlẹ naa ṣẹlẹ ati pe o ṣeeṣe ki o jẹ pe nnkan kan lo ka ọmọdekunrin naa laya to fi igbesẹ naa.
Alukoro naa fi kun un pe lootọ awọn alaṣẹ ileewe naa ko lee sọ boya ẹkọ rẹ ni, nitori pe ko si akọsilẹ kankan to fihan pe o ni iṣoro lẹnu ẹkọ rẹ tabi maaki to n gba'
Koda, o ni  o lee jẹ ohun to n lọ layika rẹ to yatọ si eto ẹkọ.
Gẹgẹ bi Alukoro naa ṣe tun ṣalaye siwaju pe awọn alaṣẹ ileewe naa ti ranṣẹ si awọn obi rẹ ti wọn si ti bawọn kẹdun lori iku ọmọ wọn.
Budo Ikoko water problem: Ìyàwó wa ti sá lọ kúrò ní Asa nítorí àìsí omi- Alhaji Sunmonu
O ni akẹkọọ naa ni abigbẹyin awọn obi rẹ, baba rẹ ti ku, bẹlni iya ati ẹgbọn rẹ ni wọn n tọọ.
Alukoro fasiti OAU naa wa rọ araalu lati maa gba awọn ọdọ to ba wa layika wọn lamọran lori ifarada ati ibi gbogbo to wa ninu ire laye ati layika wọn.
aaaaaaaaaaaaaaa
Kaduna student kidnapping: Gómìnà El-Rufai sọ pé owó ìdóòlà yóò túbọ̀ ṣe ìwúrí fún àwọn ọ̀daràn
Oríṣun àwòrán, Twitter@elrufai
Gomina Nasir El-Rufai ti ipinlẹ Kaduna ti sọ pe ijọba oun ko ni i san owo kankan fun awọn agbebọn to n ṣoro nipinlẹ naa.
El-Rufai sọ eyi gẹgẹ bi esi nipa bi awọn eeyan kan ṣe n pín fidio to ti sọ fun ijọba aarẹ Naijiria nigba kan, Goodluck Jonathan, pe ko san owo fun itusilẹ àwọn akẹkọọ Chibok ti Boko Haram gbe lọdun 2014.
Laarin bi oṣu kan ni awọn janduku ti kọlu àwọn ileewe giga ni ipinlẹ Kaduna, ti wọn si ti pa marun-un lára àwọn akẹkọọ to wa ni ahamọ wọn.
Ọsan ọjọ Iṣẹgun si ni awọn agbebọn tun fi fidio kan si ori ayelujara, nibi ti wọn ti ṣe afihan àwọn akẹkọọ ileewe imọ ọgbin kan nipinlẹ naa ti wọn jigbe ninu oṣu Kẹta.
Oludamọran fun Gomina El-Rufai lori eto ibaraẹni sọrọ, to fi atẹjade sita lorukọ gomina, Muyiwa Adekeye sọ pe awọn iṣẹlẹ ijinigbe to n waye lasiko yii yatọ si ti ọdun 2014.
O ni igbesẹ owó sísan, ijiroro, idunadura ati aforijin ti ijọba ń ṣe fún awọn janduku kan n fun wọn ni agbara ati igboya si ni lati tẹsiwaju ninu iṣẹ ibi.
Oríṣun àwòrán, Greenfield University
"Ti nkan ba ṣe n yi pada, naa lo ṣe koko ki ayipada ba igbesẹ ti eeyan ba fẹ ẹ gbé fun ọna abayọ.
 Nitori naa, imọran ti eeyan kan (gomina) mu wa ni ọpọlọpọ ọdún sẹyin, ko le jẹ ọna abayọ si wahala nla to ti bẹrẹ lati ọdun 2014, botiwu ki wọn o pin fidio naa kiri to."""
"O ni ""pe awọn ọdaran di wa ni gogongo mú, ko tumọ si pe ka fun wọn ni owo ti wọn o tun fi ma a gbe isẹ ọwọ wọn lárugẹ.""O ṣalaye pe diẹ ni igbesẹ ti ijọba ipinlẹ Kaduna le gbe, nitori pe abẹ ìṣàkóso ijọba apapọ ni àwọn ileesẹ eto aabo wa."
Sugbọn ṣa, Gomina El-Rufai sọ pe awọn ti n jiroro pẹlu ijọba apapọ lori ọna abayọ.
Bakan naa lo sọ pe ijọba kẹdun ijinigbe àwọn akẹkọọ náà, ati iku àwọn ti wọn ti pa lara wọn.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Wọn tun ti ri oku meji lara awọn akẹkọọ Fasiti Greenfield, ti awọn agbebọn ji gbe nipinlẹ Kaduna lọsẹ to kọja.
Ninu ikede ti ijọba ipinlẹ Kaduna fi sita lọjọ Aje, ọjọ kẹrindinlọgbọn, oṣu Kẹrin, wọn ni wọn ti gbe oku mejeeji lọ si mọsuari, ti wọn si tun ti sọ fun awọn alasẹ fasiti naa.
Ọjọ diẹ sẹyin ni wọn kọkọ ri oku mẹta lára àwọn akẹkọọ naa ni abule kan nipinlẹ Kaduna.
Kọmisanna fun eto aabo abẹle nibẹ, Samuel Aruwan sọ pe ibanujẹ ni isẹ ibi ọwọ àwọn eeyan naa jẹ fun Gomina Nasir El-Rufai.
Ibanujẹ ni ikọlu si awọn akẹkọọ ti ko mọ nkankan, lasiko ti wọn n kekọọ wọn fun ọjọ ọ̀la to dara.
Bakan naa ni ijọba ti ránṣẹ ibanikẹdun si ẹbí àwọn akẹkọọ naa.
Oríṣun àwòrán, Greenfield University
Mẹta lara awọn akẹkọọ fasiti Greenfield ti awọn agbebọn kan ji gbe ni ipinlẹ Kaduna ti dero ọrun.
Awọn akẹkọọ naa wa lara awọn akẹkọọ ti awọn agbebọn ji gbe ni fasiti aladani naa to wa loju ọna marosẹ Kaduna si Abuja loru ọjọ Iṣẹgun.
Nigba to n fidi iroyin naa mulẹ fun awọn akọroyin, kọmiṣọna fun eto abo ati ọrọ abẹle ni Kaduna, Samuel Aruwan sọ pe wọn ti ko oku awọn akẹkọọ naa lọ sile igbokusi.
O ni wọn ri oku awọn ekẹkọọ naa ni abule Kwanan Bature, iyẹn lagbegbe ti ko fi bẹẹ jina si fasiti ọhun.
Ọjọ Iṣẹgun ọsẹ yii lawọn agbebọn kan ṣadede kọlu fasiti naa ni Kasarami, lẹba oju ọna marosẹ Kaduna si Abuja, ti wọn si ji awọn akẹkọọ kan gbe lọ.
Oṣojumikoro kan sọ fun awọn akọroyin pe awọn agbebọn naa ya bo fasiti ọhun, ti wọn si ṣina ibọn bolẹ, ki wọn to ji awọn akẹkọọ naa gbe lọ.
Ikorodu cult crisis:A máa gbé Orò síta lọ́jọ́kọ́jọ́ tí ìjà ẹgbẹ́ òkùnkùn bá tún ṣẹlẹ̀- Àwọ
Awọn eeyan to n gbe lagbegbe fasiti ọhun sọ pe ile ẹkọ naa, ti gbogbo awọn akẹkọọ rẹ ko ju bii ogoji ko ni eto abo to peye, wọn ni eredi ree to fi rọrun fun awọn agbebọn naa lati kọlu fasiti ọhun.
Ẹnu ọjọ mẹta yii ni awọn agbebọn bẹrẹ si n ṣakọlu lemọ-lemọ ni ipinlẹ Kaduna, ti wọn si sọ oju da awọn akẹkọọ.
aaaaaaaaaaaaaaa
Ki lo ti ṣẹlẹ sẹyin?
Awọn alaṣẹ ijọba ipinlẹ Kaduna lapa iwọ oorun ariwa orilẹ-ede Naijiria ti fidi rẹ mulẹ fun BBC pe awọn agbebọn ti ṣigun wọn fasiti GreeFiel University, ileẹkọ fasiti aladani kan nipinlẹ naa ti wọn si ji ọpọ awọn akẹkọọ ko lọ.
Awọn ọlọpaa pẹlu ni awọn agbebọn naa ya wọ Ileewe giga fasiti naa ti o wa lagbegbe opopona Kaduna si Abuja ni aṣalẹ ọjọ Iṣẹgun ogunjọ oṣu kẹrin ọdun 2021.
Alukoro ileeṣẹ ọlọpaa ni ipinlẹ Kaduna Mohammed Jalige ṣalaye pe ni bi a ṣe n sọrọ yii, awọn ọlọpaa ko tii le sọ ni pato iye awọn akẹkọs ti wọn ko lọ tabi ibi ti wọn ko wọn gba.
"O ni ""awọn ọlọpaa ti wa lọgba ileewe naa bayii awọn si ti n beere fun iwe iforukọ silẹ awọn akẹkọọ nibẹ lati lee mọ iye awọn akẹkọọ ti awọn agbebọn naa jigbe salọ"""
Inu yara awọn akẹkọọ naa ni wọn ti ji wọn gbe, okunrin ati obinrin pẹlu.
Akomolede ati Aṣa lori BBC Yoruba: Ẹ̀yà Ara Ifọ̀ ní olùkọ́ Adedokun kọ́ wa
Baby placenta: Ṣé lóòtọ́ọ́ làwọn kan máa ń fi ibi ọmọ ṣe oògùn?
Oríṣun àwòrán, Science Photo Library
Baba ọmọ lo maa n gbe olubi ọmọ ni kere ti ọmọ ba ti bọ lara iya ọmọ tan.
Olubi ọmọ tawọn kan maa n pe ni ibi ọmọ jẹ ohun to ṣe pataki laarin oriṣiiriṣii ẹya lorilẹ-ede Naijiria.
Dokita Joseph Akinde to jẹ onimọ nipa itọju awọn alaboyun ṣalaye pe igbagbọ wa ninu aṣa lasan ni ohun ti ọpọ maa n sọ nipa ibi ọmọ.
Dokita Akinde sọ pe awọn kan tiẹ ni igbagbọ wi pe ibi ọmọ niiṣe pẹlu ayanmọ ọmọ naa laye.
''Igbagbọ wọn ni pe ohun kohun ti ẹnikẹni ba ṣe pẹlu ibi ọmọ ni ohun ṣe pẹlu ohun ti ọmọ naa yoo da laye.
Ṣugbọn a ko le fidi eleyi mulẹ ninu iṣẹ iṣegun tabi ninu imọ ijinlẹ sayẹnsi, igbagbọ ninu aṣa lasan ni,'' Dokita Akinde ṣalaye.
Budo Ikoko water problem: Ìyàwó wa ti sá lọ kúrò ní Asa nítorí àìsí omi- Alhaji Sunmonu
Awọn dokita onimọ nipa itọju obinrin naa sọ pe dokita ti ko ri ibi ọmọ gbe fun baba ọmọ ti wọ gau.
Wọn ni ọpọ awọn dokita ni wọn ti dunkoko mọ lori ibi ọmọ, koda wọn sọ pe awọn eeyan maa n gbe dokita lọ si ileẹjọ lori órọ ibi ọmọ.
Amọ, Dokita Akinde ṣalaye pe aṣa lasan an ni gbogbo rẹ, ko ni ohun kan ṣe pẹlu sayẹnsi.
''Awọn eeyan kan maa n bo olubi ọmọ mọlẹ, igbagbọ wọn ni pe ibi kibi ti ọmọ naa ba wa, o gbọdọ de ibi ti wọn ri ibi rẹ mọ lọjọ kan.
aaaaaaaaaaaaaaa
Awọn mii tun gbagbọ pe wọn maa n fi olubi ọmọ ṣe oogun, di niyii ti wọn maa fi n gbaa lati ile iwosan.
Mo ranti ni bii ọdun diẹ sẹyin bi ẹbi obinrin kan kan to bimọ si ile iwosan ijọba ṣe dunkoko mọ dotika to gbẹbi fun obinrin naa nitori ko mọ ibi ti ibi ọmọ wa.
hhhhhh
Niṣe lawọn ẹbi naa lọ sọ fawọn akọroyin pe dokita naa ti ta olubi ọmọ awọn, o si ti ta ayanmọ rẹ laye,'' Dokita Akinde lo sọ bẹẹ.
Alaga ẹgbẹ awọn dokita oniṣegun oyinbo nipinlẹ Cross River, Dokita Innocent Abang naa kin ọrọ Ọgbẹni Akinde lẹyin.
Dokita Abang ni ọpọ lo gbagbọ pe ibi ti wọn ba ri ibi ọmọ si ni ayanmọ rẹ wa.
Dokita sọ pe awọn tiẹ maa n gbin igi agbọn sori ibi ti wọn ba ri ibi ọmọ si, ''wọn gbagbọ pe bi igi naa ṣe n dagba ni ọmọ naa yoo maa dagba.''
Akomolede ati Aṣa lori BBC Yoruba: Ẹ̀yà Ara Ifọ̀ ní olùkọ́ Adedokun kọ́ wa
Joe Ligon: Ẹlẹ́wọ̀n tó pẹ́ lọ́gbà ẹ̀wọ̀n jùlọ ní Amerika gba ìtúsílẹ̀ lẹ́yìn ọdún 68 lẹ́wọ̀n
Oríṣun àwòrán, BRADLEY S BRIDGE
Lẹyin ọdun mejidinlaadọrin, Joe Ligon to jẹ ẹni to pẹ ju lẹwọn ninu itan orileede Amẹrika ti gba itusilẹ.
Nigba to wa ni ọdun mẹẹdogun ni wọn ran lẹwọn lori ẹsun pe oun ati awọn akẹgbẹ rẹ kan kopa ninu idigunjale ati ikọlu sawọn ọmuti kan eyi to kangun si pe eeyan meji padanu ẹmi wọn lọdun 1953.
Itan baba to fi ọdọ wọ ẹwọn yi jẹ eleyi to se eeyan ni kayefi nitori titi di igba to fi jade lẹwọn, ni se lo n sọ pe oun ko jẹbi ẹsun ti wọn fi kan an.
Ewọn gbere ti wọn fi si jẹ eleyi ti ko fun un laanfaani lati tọrọ aforijin titi di ọdun 2017.
Ni soki gbogbo awọn to mọ ko to di ero ẹwọn lo ti fẹẹ ku tan tabi ti wọn ti dagba debi pe wọn ko da ara wọn mọ mọ.
Ọpẹlọpẹ agbẹjọro rẹ to sipe fun niwaju adajọ ti wọn fi tu silẹ ni osu keji ọdun 2021 yi, Joe ko ba ma ti kuro lẹwọn titi di ba ti se n sọrọ yi.
O ti kuro lẹwọn bayi, sugbọn o ba BBC sọrọ nipa iriri rẹ nigba to wa lẹwọn ati afojusun rẹ bayi to ti gba ominira.
aaaaaaaaaaaaaaa
Ma da si nkan ti ko kan ẹ bo ba fẹ gbe igbe aye alafiaa.
Koko kan pataki ti Joe n tẹnumọ ni pe lati igba kekere loun ti da nikan wa.
Kọda,  o sọ pe ni nigba ti oun wa lẹwọn, bi igba ti oun si n tẹsiwaju pẹlu idanikanwa lo ri.
"Iranlọwọ lo jẹ fawọn eeyan bi temi ti wọn fẹ da wa.
Iru eeyan bẹẹ ni mo jẹ ati pe kete ti mo ti wọ inu ẹwọn ti wọn tilẹkun mọ mi, nise ni mo di eti mi si gbogbo nkan to n lọ layika.
Lẹẹkọọkan wọn gba wa laaye lati gbọ redio tabi ka wo ẹrọ amounmaworan.
Awọn nkan wọnyi lo di ọrẹ timọtimọ fun mi lẹwọn''.
Oríṣun àwòrán, BRADLEY S BRIDGE
Bi eeyan ba sọ pe Ligon yiwa pada si daada nigba to wa lẹwọn, a ko jina sootọ.
Iwa sise jẹẹjẹ yi ni ko jẹ ki o ko si wahala ti igbe aye rẹ ninu ẹwọn ko si mu inira wa ju ti tẹgbẹ lọ.
O ni nise loun fi ọdun mejidinlaadọrin toun lo lẹwọn lati fi kọ ẹkọ pataki nipa ki eeyan mama da si nkan ti ko kan an.
Nigba tasiko to ti wọn yoo tu silẹ lẹwọn,ko tiẹ nii lara rara wi pe ko si ẹnikankan to wa lati wa pade rẹ.
Budo Ikoko water problem: Ìyàwó wa ti sá lọ kúrò ní Asa nítorí àìsí omi- Alhaji Sunmonu
Joe ni oun ko wa ọrẹ kankan nitori oun mọọmọ pinuu bẹẹ ni.
''Nigba ta wa lẹwọn, a ko ni ọrẹ pupọ, bẹẹ la o ni ọrẹ nita naa.Mi o tiẹ ki n lo gbolohun ''ọrẹ''
lati sapejuwe ẹnikankan.Ọpọ lo pe eeyan lọrẹ ti o si jasi aburu fun wọn.''
O salaye pe  ''ni temi a le jijọ jẹ alabasepọ tabi akegbẹ sugbọn mi o mu ẹnikankan nimu ọrẹ''
Bawo le se di ero ẹwọn?
Bi a ba wo igba ewe Ligon, a o ri pe lati igba naa lo ti bẹrẹ si ni danikan wa.
Ni ilu Birmingham ni Alabama to dagba si, ko ni ọrẹ kankan nibẹ.
Ọpọ igba awọn mọlẹbi rẹ nikan  lo maa n ba sepọ ti wọn a si maa tẹti gbọ iwaasu lati ẹnu baba to bi baba rẹ ni ile ijọsin to wa nibẹ.
Oríṣun àwòrán, PENNSYLVANIA DEPARTMENT OF CORRECTIONS
Ni igba to di ọmọ ọdun mẹtala, a ti oun ati mama rẹ to n sisẹ nọọsi ati baba rẹ to n sisẹ mọkaliiki ati awọn aburo rẹ, wọn ko lọ si agbegbe guusu Philadelphia.
Ileewe nira fun un ti ko si mọ bi wọn se n kọ tabi ka iwe. Ko mọ ere idaraya kankan se ko si ni ọrẹ ti eeyan n ba se pọ.
Aini ọrẹ rẹ yi  lo n ba lọ titi di  irọlẹ ọjọ ti wọn lọ daran pẹlu awọn kan lọdun 1953.
Ninu awọn ti wọn jijọ kora wọn lo digun jale lọjọ taa n wi yi, ko si ẹnikankan to mọ ninu wọn.
Awọn to kan  pade ladugbo ti wọn jijọ se ikọlu si awọn ọmuti kan ni ọlọpaa ko wọn papọ.
Abalọ ababọ, awọn ọlọpaa ko oun ati awọn ọrẹ rẹ ti wọn si fẹsun ipaniyan kan.
Ọrọ di ile ẹjọ nibi ti adajọ ti ni ki wọn ran lẹwọn gbere lẹni ọdun mẹẹdogun.
Ipinlẹ Pennsylvannia  ti wọn ti ran lẹwọn jẹ ọkan ninu awọn ipinlẹ mẹfa ti  wọn kii dari ji awọn ti o ba gba idajọ ẹwọn gbere.
Eyi lo mu ki o gba kamu idajọ lori ẹsun onigun meji ti wọn fi kan to si kọri si ẹwọn lai rojọ.
Oríṣun àwòrán, H. ARMSTRONG ROBERTS/CLASSICSTOCK
Koda ko tiẹ mọ iye ẹwọn ọdun ti wọn ran lọjọ naa lọhun.
Bayi to ti wa kuro lẹwọn, ki lo kan?
Igbiyanju agbẹjọro rẹ lo mu ki Ligon pada ri itusilẹ lẹwọn.
Bo tilẹ jẹ wi pe anfaani wa fun lati pe ẹjọ kotẹmilọrun sugbọn ainimọ se akoba fun ti o si pẹ lẹwọn ju bo ti se yẹ lọ.
Nigba ti yoo fi jade lẹwọn lọjọ kọkanla osu keji ọdun 2021,nise ni o dabi iranran loju rẹ.
''O dabi ẹni pe wọn tun mi bi ni,nitori gbogbo nkan lo dabi tuntun loju mi''.
''Mo wo awọn ọkọ tuntun,mo wo ile ti wọn gbe misi ati awọn ile onigogoro to yi wa ka.
Gbogbo rẹ lo yatọ loju mi sugbọn o ti n mọra diẹ diẹ''
Ajọ ẹlẹyinju aanu kan lo n se iranwọ fun bayi ati le gbegbe aye alaafia lẹyin to jade lẹwọn.
Akomolede ati Aṣa lori BBC Yoruba: Ẹ̀yà Ara Ifọ̀ ní olùkọ́ Adedokun kọ́ wa
Bobrisky 2021 Ramadan: Wo ìdí tí Bobrisky kò fi kópa nínú àwẹ̀ Ramadan tó ń lọ lọ́wọ́
Oríṣun àwòrán, Instagram/Bobrisky
Ko ṣeku ko ṣẹyẹ nipa aṣọ obinrin ati ọkunrin wiwọ, Okuneye Idris Olanrewaju ti ọpọ mọ si Bobrisky ti ṣalaye idi ti ko fi kopa ninu awẹ Ramadan to n lọ lọwọ.
Bobrisky sọ loju opo Instagram rẹ pe nkan oṣu oun ni ko foun laye lati gba awẹ awọn musulumi to n lọ lọwọ.
''Awọn eeyan ti n bi mi leere bo ya mo n gba awẹ, ṣugbọn mo n dawọn lohun pe mo n ṣe nkan oṣu mi lọwọ.
Gẹgẹ bi ẹsẹ mọ, awẹ awọn obinrin kii pe,'' Bobrisky lo sọ bẹẹ lori ẹrọ Instagram.
Ẹwẹ, ero awọn eeyan ṣe ọtọtọtọ lori gudugbẹ ọrọ ti Bobrisky ja lulẹ loju opo Instagram rẹ.
Iyalẹnu lọrọ yii jẹ fawọn ololufẹ Bobrisky kan ti wọn ka ọrọ to fi lede loju opo Instagram rẹ.
aaaaaaaaaaaaaaa
Oloribecca ni tẹ sọ pe ọrọ ti Bobrisky sọ fẹ mu oun daku rangbọndan nigba ti awọn kan bu si ẹrin gbagada.
Oríṣun àwòrán, Instagram/bobrisky222
hhhhhh
Oríṣun àwòrán, Instagram/Bobrisky
Ogebaby ni tiẹ beere lọwọ Bobrisky pe ṣe nkan oṣu rẹ ko mu inira wa fun un.
Annabelle bu si ẹrin gbagada ni tiẹ, o ni Bobrisky ko ni fi ẹrin pa oun niluu Eko.
Akomolede ati Aṣa lori BBC Yoruba: Ẹ̀yà Ara Ifọ̀ ní olùkọ́ Adedokun kọ́ wa
Abija: Mo fẹ́ pokùnso torí ìjákulẹ̀ tí Ajileye fún mi, ọpẹ́ tọ́ọ́gì kan tó bá mi sọ̀rọ̀
Oríṣun àwòrán, Screen Shot
Yoruba ni ogun ọmọde ko le sere pe ogun ọdun, ọgbọn agba ko si le se asaro pe ọgbọn osu, arẹmaja kankan ko si rara, ajamarẹ ni ko sunwọn.
Bẹẹ ni ọrọ ri pẹlu agba osere kan to gbajumọ ninu ere tiata lede Yoruba, Alhaji Tajudeen Oyewole, ti ọpọ eeyan mọ si Abija ati ọga rẹ, Alhaji Yekeen Ajileye.
Abija lo jẹ ọmọ isẹ fun Olaleye, to si maa n ko ipa to tọju ninu awọn ere ti ọga rẹ naa ba se bii Koto Aye, Koto Ọrun, Ọpa Aje ati bẹẹ bẹẹ lọ.
'Iṣẹ wá burẹkẹ síi tórí Covid-19, owó ńlá ló wà nínú dídáná sun òkú, ìsìnkú  Zoom, Live streaming'
Nigba to n salaye ohun to mu oun kuro ninu ẹgbẹ osere Ajileye ki onitọun to di oloogbe, Abija sọrọ yanya ninu fido kan to gba ori ayelujara kan ti ileesẹ Mohunmaworan Ojopagogo gbe jade.
Abija ni awọn osere tiata kan lo wa ba ọga oun pe ki oun wa ba awọn kopa ninu ere kan, ti wọn si san gbogbo owo ti ọga oun beere lori oun fun.
O ni sugbọn ọga oun wa fi gbedeke kan le pe, oun ati Fadeyi Oloro ko gbọdọ kopa papọ ninu ere naa sugbọn ọrọ yiwọ nigba ti awọn de Eko, nibi ti ere naa ti n waye.
Ṣé ẹ léró pé ọmọ mi ṣì lè padà wá bá mi láàyè báyìí? Òbí akẹ́kọ̀ọ́ Kaduna"
Abìjà: Bàbá mi fi iṣẹ́ ọdẹ ti ń pa lémi lọ́wọ́ ni nítorí babaláwo ni
"Nigba ti mo de Eko, awọn to ni ere naa gbe emi ati Fadeyi Oloro papọ, ta si dijọ kopa tori n ko le pada sẹyin mọ pe n ko se mọ.
Ọga mi gan ko kọkọ ka ọrọ yii kun nibẹrẹ nigba to gbọ pe emi ati Oloro ti koju ara wa ninu ere naa, afi igba ti ọkan lara awọn iyawo rẹ mu lọ wo ere naa l'Eko, nigba ti sinima naa jade.
Ẹsin obinrin ni ọga mi gun, bo si se jade kuro ni gbọngan sinima naa ni oju rẹ ti pọn nigba to ri omilẹgbẹ ero to wa wo sinima yii.
O dabi pe oun naa ti n gbero tẹlẹ lati gbe emi ati Fadeyi Oloro papọ ninu ere, tawọn yẹn si ti siwaju rẹ se bẹẹ."
Tóò bá fẹ́ràn àti máa pọ́n ọ̀rọ̀ tàbí èèyàn lé, ẹ̀kọ́ ráńpẹ́ yìí yóò wúlò fún ọ
Abija ni oun bẹ ọga oun titi, tawọn agbaagba elere naa si pe awọn joko lati pari aawọ naa amọ ọga oun ko gba, to si kọ lati fi ori jin oun.
O fikun pe nigba to ya, awọn kan ni awọn fẹ ran awọn osere Ajileye lọ si Mecca, ti orukọ oun si wa lara wọn.
O ni akoko ti awọn fẹ se adura Mecca yii ni oun gbọ pe oun ko ni ba awọn yoku lọ si Mecca naa tori Ajileye ti fi orukọ ẹnikan to pe ni Musibau rọpo oun.
"Ẹsẹ kan soso ti ọga mi sẹ mi ree, o dun mi pupọ, koda, o dun ẹlẹda mi, nitori ko sọ fun mi nibẹrẹ pe n ko ni lọ.
hhhhhh
Iya ati ẹgbọn mi ti wa ba mi nilu Eko lati Osogbo ni ọjọ ti mo da pe maa se adura Mecca, bi mo si se fẹ maa salaye fun wọn nipa ohun to sẹlẹ, ẹkun ni mo bu si.
Iya mi fẹ lọ ba Ajileye amọ mo ni ko ma lọ, ti oun ati ẹgbọn mi si pada si Osogbo pẹlu ibanujẹ.
Ọjọ kẹta ni mo mu okun pe mo fẹ pokunso, amọ mo pade tọọgi kan to fi ohun ọmọ ita ba mi sọrọ pe se opin aye de ni, ti eeyan ko ba lọ si Mecca."
Abija tẹ́siwaju pe bakan naa ni ọrọ ri nigba to yẹ ki oun lọ si ilu London, ti iwe irinna Passport oun si lo ọdun marun lọwọ eeyan kan, koda, o ni o bajẹ sọwọ ẹni naa.
Wùnmí Toríọlá: Toyin Abraham kìí se ọ̀gá mi nínú tíátà
Abija ni bi ọdun mẹta sẹyin ni oun se aisan kan to lagbara, koda gbogbo aye lo gbọ nipa rẹ amọ ni kete ti ara oun n bọ pada sipo, ni ọna la fun oun.
"Redio Ayefele ni Ilumọọka Presenter ti pe mi fun ifọrọwanilẹnuwo, to si fi owo ọkọ ransẹ si mi amọ mo na owo naa jẹun ni, ti n ko si ka ipe rẹ si.
O tun pe mi lẹẹkeji, to si tun fi ẹgbẹrun marun naira ransẹ bii owo ọkọ, ti mo si lọ. Lẹyin eto naa ni obinrin kan ti wọn pe no Alhaja Keromylee pe mi.
O fun mi ni ẹgbẹrun lọna aadọta naira, to si tun leri lati ran mi lọ si Mecca nigba to gbọ pe n kii se Alhaji."
Abija salaye pe oun ko ka ileri naa si, ti oun ko si fi ọkan si tabi sọ fun ẹnikẹni pe oun fẹ lọ si Mecca\.
O ni koda, oun ko sọ fun iyawo oun nile titi di igba ti wọn ni kawọn wa fun idanilẹkọ ati gbigba ẹru tawọn n ko lọ.
Asiko yii mni mo ke si aya mi, ta si jọ lọ sibi idanilẹkọ naa, ibẹ si lo ti mọ pe mo fẹ lọ Mecca eyi to fa ija nla, diẹ si lo ku ki aarin wa daru.
Bọlanle Ninalowo: Ọ̀rẹ́ lásán àti olóore mi ni Mercy Aigbe
Abija tun tẹsiwaju ninu ọrọ rẹ pe nigba ti oun de Mecca, ni Alfa kan to mọ oun ati Ajileye sọ fun oun pe ibẹ ni ọga oun ti tọrọ lọwọ Ọlọrun pe ko gba gbogbo oore to se fun oun.
"A se ẹsẹ ti mo sẹ Ajileye, o gbe de Mecca. Alfa kan sọ fun mi pe nibiyi ni ọga mi ti gbadura si Ọlọrun pe gbogbo oun ti Ọlọrun se fun mi lati ara oun, eyi to n dun mi ninu, ni ki Ọlọrun gba lọwọ mi.
Alfa naa ni isẹ kan soso ti ọga mi se ni Mecca ree lọdun naa, ti ko si ba wọn kopa ninu isẹ yoku mọ titi to fi pada wale."
Mo n wayawo - Falz ti kigbe fun awọn ololufẹ rẹ
Alhaji Tajudeen Oyewole tun mẹnuba ohun ti oju rẹ ri lọdun 2007 lasiko to ni ijamba mọto, eyi to da gunlẹ fun ọdun meji ati aabọ.
"Location ni mo ti n bọ, nibi ta ti lọ ya fiimu mi ti akọle rẹ n jẹ Ibinu Abija, mo ko ijamba ọkọ nigba ta n pada sile, ti ẹsẹ mi si da.
Ọdun meji aabọ ni mo lo nilẹ lẹ, lai le rin tori ẹsẹ mi ti da. Sinima Ibinu Abija naa ko si tii jade titi di oni, mo sẹsẹ tun fẹ gbe sita ni."
BBC gbalejo ọmọ Ibadan
Alhaji Tajudeen Oyewole wa kede pe oun ati ọga oun pari aawọ aarin awọn, ko to di pe o jẹ Ọlọrun nipe.
O ni oun ti dari gbogbo ẹsẹ ti ọga oun sẹ oun jin in, ti awọn si pada rẹ pada.
"Ajileye pada pe mi lati wa kopa ninu fiimu rẹ ko to jade laye, ti n ko si ka ẹsẹ kankan si lrun, nitori pe ẹgbọn lo jẹ si mi, ta si sun mọ ara wa pẹki pẹki.
Bí àwọn gbájúẹ̀ ṣe lu ìyá ẹni ọdún 90 ní jìbìtì $32 mílíọ́nù dọ́là rèé
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Awọn gbajuẹ kan ti wọn dibọn gẹgẹ bi alaṣẹ lati orilẹ-ede China ti lu iya arugbo ẹni aadọrun ọdun kan ni jibiti owo to to miliọnu mejilelọgbọn dọla owo ilẹ Amẹrika
Awọn ọlọpaa ni Hongkong ṣalaye pe awọn ọdaran naa yoo maa mura bi awọn oṣiṣẹ alaabo ilu to n ṣe iwadi awọn iwa ọdaran kan ni China lati ṣiṣẹ ibi wọn.
Awọn gbajuẹ naa sọ fun mama arugbo ọhun pe eeyan kan ti ji orukọ rẹ to si n lo o ni China.
Wọn ni ko san owo sinu aṣuwọn banki ni igba mọkanla laarin oṣu kẹjọ si oṣu kini ọdun yii fun wọn lati lee fi dọdẹ ẹni to n ji orukọ rẹ lo naa.
Ni bayii, ọwọ awọn ọlọpaa ti tẹ ọdọkunrin ọmọ ọdun mọkandinlogun kan ti wọn gba beeli rẹ.
Budo Ikoko water problem: Ìyàwó wa ti sá lọ kúrò ní Asa nítorí àìsí omi- Alhaji Sunmonu
Awọn ileeṣẹ iroyin ni HongKong gbe e sita pe oṣu kẹjọ, ọdun to kọja ni wọn kọkọ kan si obinrin naa.
Wọn dibọn bii pe oṣiṣẹ lati orilẹ-ede China ni awọn ki wọn to wa lọ fun iya naa ni foonu ibanisọrọ kan pe oun ni ko maa fi pe awọn nigbakugba to ba fẹ pe wọn.
hhhhhh
Ara awọn ọmọ ọdọ iya arugbo naa lo pariwo sita fun awọn ọmọ rẹ nipa awọn iwa kotọ tawọn eeyan, ti wọn ro pe oṣiṣẹ alaabo latọdọ ijọba, naa n hu.
Iya agba naa ko gbe pẹlu awọn mọlẹbi rẹ ṣugbọn o ni ọpọlọpọ awọn oṣiṣẹ bi ọmọọdọ to n baa ṣiṣẹ ni ile rẹ to wa ni ọkan lara awọn ibugbe awọn to rijajẹ lawujọ ni Hong Kong.
Akomolede ati Aṣa lori BBC Yoruba: Ẹ̀yà Ara Ifọ̀ ní olùkọ́ Adedokun kọ́ wa
Android phone app malware: Ìwádìí fihàn pé àwọn 'App' kan ń ṣe àkóbá fún ọ̀pọ̀lọpọ̀ fóònù ní Nàìjíríà
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Iwadii ijinlẹ kan lorilẹ-ede Naijiria ti fihan pe ọpọlọpọ awọn foonu android lorilẹede Naijiria lo ni awọn eroja ajẹnirun.
Iwadii naa ni ileeṣẹ imọẹrọ nipa  foonu ibanisọrọ kan torukọ rẹ n jẹ Upstream gbe sita lẹyin to ṣe ayẹwo ẹgbẹrun lọna irinwo o le marundinlogun idunadura lori foonu ibanisọrọ.
Iwadii naa gba wọn ni oṣu mẹta gbako, eredi rẹ si ni lati ṣiṣọ loju eegun iwa jibiti to waye lasiko igbele ajakalẹ arun coronavirus ni Naijiria, paapaa julọ laarin oṣu kọkanla, ọdun 2020 si oṣu kini, ọdun 2021.
Pupọ awọn eroja ajẹnirun ori foonu wọnyii lo n waye yala nitori atunto eto ori foonu (Changing settings) to lee mu ọpọlọpọ ewu dani debi jiji awọn kọkọrọ makan (Password) atawọn iroyin ara ẹni (personal data) ti a ba fi pamọ sori foonu ẹni.
Budo Ikoko water problem: Ìyàwó wa ti sá lọ kúrò ní Asa nítorí àìsí omi- Alhaji Sunmonu
Iwadii naa fiyeni pe nnkan bii ọrinlelẹẹdẹgbẹta o din mẹrin (576) eroja imọ ẹrọ ori foonu (apps and software programms) lo wa lorilẹ-ede Naijiria bayii.
Ileeṣẹ Upstream gbe iwadii naa jade ni ifọwọsowọpọ pẹlu ẹka iwadii abo igbalode ti wọn n pe ni Secure D.
aaaaaaaaaaaaaaa
Wọn ni pupọ awọn eroja yii lo jẹ wi pe ku ori akoto ọja ayelujara Playstore fawọn foonu to n lo Android operating system.
Abajade iwadii naa wa n yọju rẹ sita pe awọn eroja ori foonu marun kan wa ti nnkan ori wọn fẹ suuru bii XOS Launcher, HiOS Launcher, Phoenix Browser, AHA Games ati Cobo Launcher Easily DIY Theme.
Ṣaṣa ni foonu Android ti wọn n ta lorilẹ-ede Naijiria lode oni ti kii si awọn eroja ajẹnirun ori foonu wọn lori wọn.
Fuel scarcity: NNPC ní kò sí ọ̀wọ́n-gógó epo bẹntiró núlùú Abuja
Ko si ohun to jọ pe epo wọn  nilu Abuja.
Esi tawọn alasẹ ileesẹ ipọnpo orileede Naijiria,NNPC, n sọ re ni itako iroyin to gbode pe awọn araalu tun ti bẹrẹ si ni to f'epo ni Abuja.
Iroyin to kaakiri ni pe pupọ awọn ileepo ni ko ta epo fawọn ọlọkọ ati pe awọn to n ta gan an nise ni awọn eeyan to nibẹ bi ẹni gba saara lọjọ Isẹgun.
Ninu awọn to ba BBC sọrọ ni ọjọ Aje ni awọn fasiko sofo pupọ nitori  tito fun epo.
Awọn kan sọ pe o to wakati mẹjọ tawọn fi to lati le ra epo bẹntiroo.
Budo Ikoko water problem: Ìyàwó wa ti sá lọ kúrò ní Asa nítorí àìsí omi- Alhaji Sunmonu
Ọlọkọ ero takisi ti a baa sọrọ ni awọn ko risẹ se dipo tawọn yoo ti ẹ mu owo lọ ba mọlẹbi.
Ila tito fun epo to gun wọn yi ko sẹyin ọrọ ihalẹ to wa lati ọdọ awọn ẹgbẹ awakọ tanka epo to ni awọn yoo gunle iyansẹlodi lọjọ Aje.
Sugbọn lẹyin igba ti ọga agba ileesẹ NNPC Mele Kyari ba wọn sọrọ, wọn wọgile idasẹsilẹ naa.
Bakan naa ni Kyari kede pe ijọba ko ni fi owo kun owo epo losu  to n bọ tii se osu Karun ọdun.
Kyari ni biba ni epo wa nilẹ nitorinaa ko yẹ kawọn eeyan maa fi ibẹrubojo sare ra epo.
Akomolede ati Aṣa lori BBC Yoruba: Ẹ̀yà Ara Ifọ̀ ní olùkọ́ Adedokun kọ́ wa
Cement price hike: Aṣòfin képe ìjọba láti wá ńkan ṣe sí ọ̀wọ́n-gógó símẹ́ntì ní Nàìjíríà
Oríṣun àwòrán, Facebook/Aliko Dangote
Ile igbimọ aṣofin agba niluu Abuja ti bẹrẹ igbesẹ lati mu adinku ba ọwọn-gogo simẹnti ikọle lorilẹede Naijiria.
Ile rọ ijọba apapọ lati lati ṣe agbekalẹ ofin ti yoo fun ọpọ lanfaani lati maa ṣe owo simẹnti ki adinku le ba ọwọn-gogo rẹ.
Ile ni ipese ohun amayedẹrun tabi owo iranwọ ti yoo fawọn oniṣowo simẹnti lanfaani lati maa taa fawọn eeyan.
Sẹnẹtọ Ashiru Oyelola Yisa atawọn akẹgbẹ rẹ marun un lo da aba naa eleyi ti gbogbvo ile jiroro le lori.
Sẹnẹtọ Muhammad Enagi Bima; Adelere Adeyemi Oriolowo; Samuel Egwu; Kabiru Gaya ati Michael Nnachi lawọn sẹnẹtọ marun un mii to ṣe agbekalẹ aba ọhun.
Budo Ikoko water problem: Ìyàwó wa ti sá lọ kúrò ní Asa nítorí àìsí omi- Alhaji Sunmonu
Sẹnẹtọ Yisa sọ ninu ọrọ rẹ pe simẹnti wa lara ohun elo ikọle ti orilẹede Naijiria ni yanturu.
'''Bi simẹnti ṣe di N3, 800 lati N2, 600 n jẹ ki iṣẹ ikọle tabi ọna ṣiṣe maa wọlẹ, bakan naa lo n ṣakoba fawọn oṣiṣẹ.
Akomolede ati Aṣa lori BBC Yoruba: Ẹ̀yà Ara Ifọ̀ ní olùkọ́ Adedokun kọ́ wa
Ileeṣẹ simẹnti mẹta pere, Dangote Cement (60.6%); Lafarge Africa Plc (21.8 %) ati BUA Group (17.6%) lo n ta simẹnti ni Naijiria.
Eyi gan an  lo jẹ ki wọn maa gbowo lee lori ni o ṣe wu wọn,'' Sẹnẹtọ Yisa lo sọ bẹẹ.
aaaaaaaaaaaaaaa
Sẹnẹtọ Yisa ni ''o yẹ ki o kọ gbogbo wa lominu pe ọwọn-gogo simẹnti pẹlu aiṣowo yoo jẹ ki ayederu ohun elo ikọle pọ, yoo si tun jẹ ki ọpọ iṣẹ di aṣepati.''
Ile fẹnu ko, o si kepe ijọba apapọ lati pese ẹyawo i ko ni gara fawọn oniṣowo simẹnti ni Naijiria ki owo simẹnti le walẹ ki awọn ọmọ Naijiria le maa ra.
NAF Killing: A ti gbé ìwàdìí dìde láti mọ òkodoro ọ̀rọ̀ nípa ìṣẹ̀lẹ̀ náà
Oríṣun àwòrán, @NigAirForce
Baalu ileeṣẹ ọmọ ogun ofurufu, NAF, ti ṣeku pa ogun lara awọn ọmọ ologun to n doju ija kọ ikọ agbesumọmi Boko Haram ni ipinlẹ Borno.
Iroyin naa ni ọkọ ofurufu naa ṣeṣi sọ ado oloro lu awọn jagunjagun to wa ni iha rẹ, ti nnkan bii ogun lara awọn ṣọja naa si dagbere faye.
Ṣaaju ni wọn ti kọkọ ke si awọn ọmọ ogun naa lati doju ija kọ awọn ọmọ ogun agbesumọmi Boko Haram ti ikọ Islamic State n ṣatilẹyin fun.
Igbesẹ naa waye lasiko ti wọn n ṣakọlu si agbegbe Mainok to jẹ olu ijọba ibilẹ Kaga, nipinlẹ naa.
Awọn agbesumọmi ọhun kọlu agbegbe naa pẹlu ọkọ ti wọn gbe ibọn le lori bii marundinlogun, wọn si tun dana sun ibi ti awọn ọmọ ogun tẹdo si.
Oríṣun àwòrán, @NigAirForce
Gẹgẹ bii ohun ti a gbọ, awọn ọmọ ogun to lọ ṣatilẹyin fun awọn akẹgbẹ wọn, ni NAF sọ ado oloro le lori.
Iṣẹlẹ naa ti mu ki ọpọ ọmọ Naijiria koro oju si ileeṣẹ ologun, ti wọn si n fi erongba wọn lede lori ayelujara lori iṣẹlẹ naa.
Lasiko ti ileeṣẹ ọmọ ogun ofurufu n da si ọrọ naa, bo tilẹ jẹ pe wọn ko sẹ pe iṣẹlẹ naa ko waye, ṣugbọn wọn ni awọn ti bẹrẹ iwadii lori rẹ.
Wọn ni awọn yoo si bun gbogbo ọmọ Naijiria gbọ laipẹ lori abajade iwadii wọn.
Akomolede ati Aṣa: Kọ́ ẹ̀kọ́ si nípa ààlọ́ nílẹ̀ Yorùbá
Wọn ni Ileeṣẹ NAF ti gbọ nipa iroyin to sọ pe ileeṣẹ ọmọ ogun ofurufu ṣekupa ogun lara awọn ọmọ ogun rẹ, a ti gbe iwadii dide lori iroyin naa, a oo si jẹ ki gbogbo araalu mọ abajade iwadii wa."""
Ẹwẹ, pupọ awọn ọmọ Naijiria lo n yọ suti ete si ileeṣẹ naa lori iṣẹlẹ ọhun.
Oríṣun àwòrán, @iamlordraiden
Bi awọn kan ṣe n sọ pe wọn mọọmọ pa awọn ọmọogun naa ni, lawọn kan n sọ pe yoo dara ki awọn ni suuru de abajade iwadii ti ileesẹ ologun ofurufu fẹ se.
Ẹ wo diẹ lara awọn nnkan mii ti awọn eeyan n sọ loju opo Twitter:
Oríṣun àwòrán, @seunoye04
Oríṣun àwòrán, AFC
Wọn ti sin oku awọn eeyan mọkanlelaadọta ti awọn agbebọn ṣekupa ni ipinlẹ Zamfara l'Ọjọbọ
Ẹnikan ti ọrọ ṣoju naa rẹ sọ fun BBC pe ẹkun Magami ni wọn ti ṣekupa awọn eeyan naa lawọn abule kan.
Awọn agbebọn ọhun dabọn bo awọn eeyan nigba ti awọn kan fẹ doola wọn.
Iroyin kan sọ pe awọn eeyan si n sa asala fun ẹmi wọn lẹkun Magami lẹyin iṣẹlẹ iṣekupani naa.
Awọn ti ọrọ ṣoju wọn ṣalaye pe ogun eeyan ni wọn pa ni abule Ruwan Dawa, mẹwaa ni Kangon Fari Mana.
Budo Ikoko water problem: Ìyàwó wa ti sá lọ kúrò ní Asa nítorí àìsí omi- Alhaji Sunmonu
Mẹfa ni wọn pa ni abule ni Madaba, mẹfa naa ni Wealth, ẹyọkan ni Kogo, ati ẹyọkan ni Ayaya ati ẹyọkan ni Rairai.
Ẹnikan sọ pe awọn janduku naa n yinbọn ni abule Kangon Fari Mana fun bii wakati meje.
Ọjọ keji lawọn eeyan abule Yar Doka to pada si ibugbe wọn lẹyin ikọlu awọn agbebọn naa.
Aarọ Ọjọbọ ni wọn sin eeyan mẹwa ti wọn sẹkupa ni abule Kangon Fari Mana.
aaaaaaaaaaaaaaa
Awọn eeyan abule naa ni aisi awọn ẹṣọ eleto abo n fi iya jẹ awọn.
Ẹwẹ, ileeṣẹ ọlọpaa ipinlẹ Zamfara ti ṣalaye pe awọn ti ko awọn ẹṣọ ranṣẹ si ẹkun naa.
Awọn ara abule naa ni awọn ko le tun ara awọn oku eeyan awọn ṣe nitori awọn n bẹru pe awọn janduku naa le pada wa.
Eeyan mọkanla ni wọn gbe lọ si ile iwosan ijọba ni Magami nibi ti wọn ti n gba itọju.
hhhhhh
Ada Jesus death: Ṣé òtítọ́ ni pé ikú apanilẹ́ẹ̀rín Ada Jesus lọ́wọ́ ayé nínú?
Oríṣun àwòrán, Ada Jesus
Harrison Gwamnishu to jẹ olutọju adẹrinpoṣonu to jade laye, Mmesoma Mercy Obi ti awọn eeyan mọ si Ada ti kede pe iku to pa a ko lọwọ aye ninu.
O ṣalaye wi pe aisan to ti n ṣe e fun ọjọ pipẹ lo gba ẹmi apanilẹrin naa.
Gwamnishu sọrọ yii laarọ Ọjọbọ lẹyin ti iku Ada Jesus ya awọn eeyan lẹnu ni Ọjọru.
Ki o to di wi pe olutọju Ada Jesus ba a pade, ailera rẹ ti wọ ọ lara gan an debi pe ko le da sọrọ daadaa mọ.
Gwamnishu sọ fun BBC pe iku ati ọdọ Ọlọrun lo pa Ada Jesus.
''Iru iku to pa Ada Jesus to fi ọmọ saye lọ jẹ iru iku to maa ṣaaba pa ọpọ eeyan.
Budo Ikoko water problem: Ìyàwó wa ti sá lọ kúrò ní Asa nítorí àìsí omi- Alhaji Sunmonu
Ada ko ba ti ku to jẹ wi pe wọn tete gbe lọ si ile iwosan ni ṣugbọn aisan naa ti wọ ọ lara pupọ, wọn dokita gan an fidi rẹ mulẹ bẹẹ.
Ara rẹ ti n balẹ diẹ diẹ nigba ti wọn gbe e wa si ibudo itọju awọn to larun kindinrin.
Koda, ọpọ eeyan eeyan lo ti dawo iranwọ fun itọju Ada Jesus ṣugbọn o ṣeni laanu pe o pada ku,'' Gwamnishu ṣalaye.
Gwamnishu sọ pe oun atawọn eeyan kan ti bẹrẹ si ni ba ile iwosan Fortis sọrọ niluu Mumbai lorilẹede India lori ati gbe Ada Jesus lọ fun itọju arun kindinrin.
O ni awọn fẹ ki o gbadun diẹ ki awọn to gbe e lọ si India lati ṣiṣẹ abẹ ipaarọ kindinrin rẹ ki ẹlẹmi to pada gba a.
hhhhhh
Gwamnishu fikun ọrọ rẹ pe awọn eeyan kan tiẹ n bẹbẹ lati da owo iranwọ fun itọju Ada Jesus, ṣugbọn gbogbo rẹ ti tan bayii.
Olutọju Ada Jesus sọ pe lootọọ ni adẹrinpoṣonu naa ti ku, ṣugbọn awọn ẹbi rẹ si nilo iranlọwọ awọn eeyan.
Gwamnishu ni ''Ada Jesus fi ọmọ silẹ saye lọ, ọmọ naa si nilo iranwọlọwọ awọn eeyan.
O tun tan imọlẹ si ọrọ kan tawọn eeyan kan n sọ pe ko beere iranwọ owo fun itọju Ada lori ẹrọ ayelujara.
Gwamnishu ni owo kọ ni iṣoro lori ailera Ada Jesus nitori Onimọ ẹrọ Marksman Chinedu Ijiomah ṣetan lati fi miliọnu mẹwaa silẹ fun itọju rẹ.
Akomolede ati Aṣa lori BBC Yoruba: Ẹ̀yà Ara Ifọ̀ ní olùkọ́ Adedokun kọ́ wa
Amotekun ìpínlẹ̀ Ondo ti ń wá àwọn òṣìṣẹ́ ojú ọ̀nà mẹ́ta tí wọ́n jí gbé lágbègbè Akoko
Oríṣun àwòrán, Rotimi Akeredolu Aketi
Ikọ amọtẹkun ipinlẹ Ondo ti sọ pe awọn ti kan sinu igbo lati ṣawari awọn oṣiṣẹ oju ọna mẹta ti awọn ajinigbe ji gbe lopopona Ikaramu si Akunnu Akoko.
Adari ikọ naa ni ipinlẹ Ondo, Adeleye Olusanyero lo fidi ọrọ naa mulẹ fun BBC Yoruba ninu ifọrọwerọ kan.
"O ni ""Ootọ ni pe wọn ji awọn eeyan mẹta to n ṣiṣẹ oju ọna marosẹ Ikaramu si Akunnu-Akoko gbe, ṣugbọn a ti kan lu inu igbo ti wọn gbe wọn lọ lati ṣawari wọn."""
Bo tilẹ jẹ pe ko darukọ ileeṣẹ ti awọn eeyan mẹta naa n ṣiṣẹ fun, o ni wọn kii ṣe oṣiṣẹ ileeṣẹ to n tu ọna ṣe fun ijọba ipinlẹ Ondo.
Oríṣun àwòrán, Seyi Makinde
Adeleye ṣo siwaju si pe oun ko le sọ boya awọn ajinigbe ọhun ti kan si ẹbi awọn ti wọn ji gbe lati bere fun owo itusilẹ kankan, ṣugbọn awọn ti n ṣiṣẹ takuntakun ninu igbo naa lati ṣawari awọn eeyan ọhun.
Lori ipo ti iṣẹ oju ọna naa wa lẹyin ti wọn ji awọn oṣiṣẹ naa gbe tan, Adeleye sọ pe iṣe naa ko duro, nitori ikọ alabo Amotekun ti bẹrẹ si n pese abo to peye fun awọn oṣiṣẹ to ku, wọn si ti pada sẹnu iṣẹ wọn.
Budo Ikoko water problem: Ìyàwó wa ti sá lọ kúrò ní Asa nítorí àìsí omi- Alhaji Sunmonu
Iroyin sọ pe ọjọ Iṣẹgun ni wọn ji awọn eeyan naa gbe ni nnkan bii aago mẹfa irọlẹ, iṣẹlẹ ijinigbe ọhun si ti mu ibẹrubojo ba ọpọ olugbe ilu naa.
Ẹwẹ, alukoro ileeṣẹ ọlọpaa ipinlẹ ọhun, Tee-Leo Ikoro sọ pe awọn ti n ṣiṣẹ lati ti daju pe awọn eeyan naa bọ lọwọ awọn ajinigbe naa lai farapa.
Iṣẹlẹ ijinigbe naa lo n waye lẹyin ọjọ diẹ ti Ọba Auga, iyẹn Alauga ti ilu Auga-Akoko, Ọba Samuel Agunloye rọ gomina ipinlẹ Ondo, Rotimi Akeredolu lati fi awọn ẹṣọ alaabo ṣowọ si agbegbe naa nitori eto abo to mẹhẹ.
aaaaaaaaaaaaaaa
Ṣaaju ni Akeredolu ti kọkọ ṣeleri fun awọn eeyan ọhun pe oun yoo ṣe aṣepari opopona Akunnu si Ikaramu ati Oke Agbe Akoko, eyii to sọ pe awọn ijọba to ṣaaju rẹ ti kọ silẹ lati nnkan bii ọdun mejidinlogun.
hhhhhh
Children replacing their fathers as presidents in Africa: Wo àwọn olórí orílè-èdè ilẹ̀ Áfíríkà mẹ́fà tó rọ́pò òbí wọn gẹ́gẹ́ bí ààrẹ.
Kò ṣẹlẹ̀ rí kan kò wáyé nípa pé ọmọ ń rọ́pò òbí rẹ nínú ètò isèjọba nípa ètò òṣèlú tàbí isèjọba lọ́balọ́ba lágbàyéé.
Ṣùgbọ́n, ọ̀pọ̀ àwọn orílẹ̀-èdè ilẹ̀ adúláwọ̀ tí n sọ ètò isèjọba di nkan ti ọmọ lè jogún lọ́wọ́ àwọn òbí rẹ̀ tàbí àwọn babáńlá rẹ̀.
Ológun Mahamat Idriss Déby to jẹ́ ọmọ ààrẹ orileede Chad, Idriss Déby ni wọ́n búra wọlé fún lọ́jọ́ Ìṣẹ́gun lẹ́yìn ikú bàbá rẹ tó farapa lójú ogun to sì gba ibẹ kú.
Yàtọ̀ sí orile-ede Chad, ọ̀pọ̀ àwọn orileede ilẹ̀ Áfíríkà mìíran ló ti yan àwọn ọmọ olórí orile-ede to di olóògbé tàbí tó kọ̀wé fipò sílẹ̀ jẹ ààrẹ bótilẹ̀ jẹ́ pé èyí kò sí nínú Ìwé òfin orile-ede wọn tàbí bá òfin mu.
Èyí ni àwọn olórí orílè-èdè tó gba oyè òbí wọn:
Orílẹ̀ èdè Democratic Republic of Congo ni Joseph Kabila ti jẹ ààrẹ láti inú oṣù kini, odun 2001, titi di oṣù kini, ọdún 2019
Lẹ́yìn ọjọ́ Mẹ́wàá tí awọn agbanipa pa bàbá rẹ̀, Laurent-Désiré Kabila ló gorí àlééfà
A bí Joseph ni ọjọ́ kẹrin, oṣù kẹfà, ọdún 1971, ni ẹkùn Sud-Kivu, ni ìdílé ológun àti olóṣèlú.
Kabila tó jẹ́ ọmọ-ọmọ alákatakítí ni orileede Congo, Laurent Kabila dàgbà o si kàwé ni orile-ede Tanzania.
Ó jẹ́ ọ̀kan lára àwọn alákatakítí tó ń gbógun ti ìjọba ti wọ́n sì ran bàbá rẹ̀ lọ́wọ́ láti yọ ààrẹ Mobutu Sese Seko ti Zaire níjọba lọ́dún 1997
Lẹ́yìn tí Laurent di ààrẹ ló dá orúkọ orílè-èdè náà padà sí Democratic Republic of Congo, Ó rán Joseph lọ sí China láti lọ ní ìmọ̀ kún ìmọ̀ nínú iṣẹ́ ológun.
Bi ó ṣe padà dé ní wọ́n fi jẹ olórí àwọn ọmọ ogun orílè-èdè náà.
Ni ọdún 1998 ni Laurent Kabila bẹ̀rẹ̀ si ni bẹnu ìwà kò sí ẹni tó le mú mi àti ìgbésùmọ̀mí, èyí lo sì mu kí ọ̀pọ̀ àwọn orílè-èdè Áfíríkà rán àwọn ọmọ Ogun wọn lọ síbẹ̀.
Lẹ́yìn tí àwọn agbanipa mú ààrẹ Laurent kúrò lọ́nà, wọ́n yan Joseph gẹ́gẹ́ bí ààrẹ tuntun ni ọjọ́ kẹrìndínlógbọ̀n, oṣù kíní, ọdún 2001.
Budo Ikoko water problem: Ìyàwó wa ti sá lọ kúrò ní Asa nítorí àìsí omi- Alhaji Sunmonu
Ọ̀pọ̀ ogún tó ní ìlapa ló ti ṣẹlẹ̀ sí orílè-èdè náà tí nkan sì ti bajẹ́ nítorí wọn kò ní ìjọba tó yanrantí àti Ogun ojoojúmọ́
Bi ó tilẹ̀ jẹ́ pé Kabila gbìyànjú láti dá àlàáfíà padà sí orílè-èdè naa, síbẹ̀ o ni ìdojúkọ pẹ̀lú àwọn ẹgbẹ́ alátakò.
Kabila sì n gbìyànjú láti mú ìṣọ̀kan bá orílè-èdè naa, lẹ́yìn tí o ṣe àtúngbéyẹ̀wò ìwé òfin orílè-èdè naa lọ́dún 2002 ti wọ́n sì gba ọ̀pọ̀ ẹgbẹ́ òṣèlú láàyè láti díje dupò ààrẹ lẹ́yìn ogójì ọdún tí irú rẹ̀ kò tíì ṣẹlẹ̀.
Kabila jáwé olúborí, tó sì fi ẹ̀yìn alátakò rẹ̀ Jean-Pierre Bemba janlẹ̀ nínú oṣù Kẹ̀wá ọdún 2006.
Ni ọdún 2008, Kabila buwọ́lu ìwé àlàáfíà pẹ̀lú ẹgbẹ́ alákatakítí ogún tó n bá orílè-èdè náà jà, àdéhùn náà padà forísọ́npọ́n lẹ́yìn tí àwọn kan tún padà sí orí omi.
A bí ààrẹ Faure Essozimna Gnassingbé Eyadéma ni ọjọ́ kẹfa, oṣù kẹfà, ọdún 1966, ó jẹ́ olóṣèlú tó sì ti di ààrẹ láti ọdún 2005.
Kí ó tó di ààrẹ Togo, bàbá rẹ̀ ààrẹ Gnassingbé Eyadéma, tí fún ni oyè mínísítà láti 2003 sí 2005.
Nígbà tí ààrẹ Eyadéma kú ni ọdún 2005 Gnassingbé ni wọ́n sáré yàn bí ààrẹ tuntun láti gbárùkù ti àwọn ológun.
Ọ̀rọ̀ lórí bóyá òfin orílè-èdè náà fàyè gba irú ǹkan bẹ́ẹ̀ fi Gnassingbé sábẹ́ wàhálà púpọ̀, bákan náà ló jáwé olúborí nínú ìdíje ààrẹ ni ọjọ́ kẹrìndínlógún, oṣù kẹrin, ọdún 2005, wọ́n sì búra wọlé fún gẹ́gẹ́ bí ààrẹ.
Wọ́n tún Gnassingbé yan ni ọdún 2010, àwọn ẹgbẹ́ alátakò yarí pé kò ní sí àtúndì ìbò, èyí sí jẹ kí ọ̀pọ̀ ẹ̀mí ṣòfò tí ọ̀pọ̀ sá kúrò ní ibùgbé wọn.
Tsohon shugaban kasar Togo Faure Gnassingbé
Ààrẹ tuntun ti Chad, Mahamat Idriss Déby, jẹ́ ológun ti kò tíì pé ọmọ ogójì ọdún ló gbà ipò bàbá rẹ̀, ààrẹ Idriss Deby Itno tó kú ní ogúnjọ́, oṣù kẹrin, ọdún 2021.
Ọdún 1983 ni a bí Mahamat Idriss Déby gẹ́gẹ́ bí ọkàn nínú ọmọ Idriss Déby tó dolóògbé
Ọ̀pọ̀ ló máa ń pè é ni Mahamat Kaka nítorí ìyá àwọn òbí rẹ̀ ló tọ̀ọ.
Lásìkò tí bàbá rẹ̀ kú, òun ni olórí àwọn ẹ̀sọ́ ààbò ààrẹ gẹ́gẹ́ bí akọ̀ròyìn BBC tó wà ni Chad ṣe sọ.
Bákan ni o ti kópa nínú onírúurú Ogun.
Ni ọdún 2009, Mahamat Idriss Deby ti jagun lorisirisi ni Am Dam tí òun ati ẹbi rẹ̀ Timan Erdimi to tún jẹ́ ẹbí ààrẹ Eastern Chad.
aaaaaaaaaaaaaaa
Ààrẹ Ali Bongo Ondimba jẹ́ ọmọ ààrẹ Gabon, Omar Bongo, tó jẹ ààrẹ láti ọdún 1967 títí o fí kú ní ọdún 2009.
Ààrẹ Gabon ni ààrẹ kẹta láti Oṣù kẹwàá, ọdún 2009, lẹ́yìn tí bàbá rẹ̀ kú
A bí ni Gabon ni inú oṣù kejì, Odun 1959 sí ìdílé Ali Bongo tí ọ̀pọ̀ mọ̀ sí Alain Bernard Bongo ni agbègbè Congo-Brazzaville.
Ọdún mẹ́jọ ni nígbà tí bàbá rẹ̀ di ààrẹ ni ọdún 1967, asọ̀tàn orílè-èdè France François Gaulme sọ fun BBC.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ayé ààrẹ Ali Bongo kún fún ílà-ílo pàápàá jùlọ nígbà tó wà ní ọ̀dọ́kùnrin.
Kódà láti ìgbà tí wọ́n tí bí ní wọ́n tí máa n sọ̀rọ̀ ahesọ pé wọ́n gbáàtọ́ ni lati ìhà gúúsù ìlà-oòrùn Nàìjíríà lásìkò ogún abẹ́lé
Àwọn mìíràn ríi gẹ́gẹ́ oluṣègbè fábo tí ó sì fẹ́ran epo rọ̀ọ̀bì orílè-èdè Gabon
Àìsàn to daa wólẹ̀ ni ọdún dïẹ̀ sẹ́yìn jẹ́ èyí tó ń kọ orílè-èdè náà lóminú, ìdìtẹ̀gbàjọba tí àwọn ọmọ ogún ṣe pẹ̀lú f'ori sánpọ́n.
Ìdí tí wọ́n fi fẹ́ dìtẹ̀ gbà jọba ni pé àwọn fẹ́ dá orílè-èdè náà padà sí bí ó ṣe yẹ kí ó wà lẹ́yìn ìdìbò odun 2016, tí o mú ìtàjẹ̀ silẹ̀ àti wàhálà dání.
Ọba Muhammed Bin Sidi Alaouite ti Morocco ni a bi ni ọjọ́ kọkànlélógun, Oṣù Kẹjọ, ọdún 1963, ni Rabat tíì ṣe olu ilu Morocco.
O gorí àlééfà ni ọjọ́ kẹtàlélógun, oṣù keje odun 1999, lẹ́yìn tí bàbá rẹ̀, Ọba Hassan Keji kú.
Ni kété tó gorí àlééfà ló kéde lórí amohunmaworan pé òun yóò gbógun ti, òsì, ìwà àjẹbánu bákan náà ni òun yóò pèsè isẹ àti lati mú kí ètò fifaaye gba ẹ̀tọ́ ọmọ nìyàn búrẹ́kẹ síi.
hhhhhh
Ẹ̀wẹ̀ àwọn àyípadà yìí bi àwọn alákatakítí ẹṣin Islam kan nínú.
Nínú oṣù kejì ọdún 2000, o ṣe àgbékalẹ̀ òfin ìdílé mìíràn, èyí tó fi ààyè gba ìrọkunsápá obìnrin.
Nínú oṣù Kejìlá ọdún 2020, Oba Mohammed kẹfà gba láti tún ìbáṣepọ̀ pẹ̀lú orílè-èdè Israel lábẹ́ àdéhùn tí ìjọba ilẹ̀ Amẹrika yóò fi ṣe ni túmọ̀ nílẹ̀ Africa labẹ àkóso Morocco.
Ọba Mswati III (Makhosetive) jẹ́ ọmọ ọba Sobhuza II ti ọkan nínú àwọn ìyàwó rẹ̀, Ntfombi Tfwala bí.
A bí ní ọjọ́ Kọkàndínlógún oṣù kẹrin, ọdún 1968 ni Manzini.
Ó jẹ́ ọmọ òye Mswati kẹta ni Ingwenyama tí o sì padà di ọba ni Swaziland ni ọjọ́ karùn-úndínlọ́gbọ̀n 1986, lẹ́ni ọdún méjìdínlógún, òun sì ni ọba tí ó kéré jùlọ lágbàyé lásìkò náà
Ọba Sobhuza kejì kú ní ọjọ́ kokanlelogun, inú oṣù kẹjọ, ọdún 1982, ti ọmọ ọba Makhosetive sì di empirọ̀ tuntun.
Akomolede ati Aṣa lori BBC Yoruba: Ẹ̀yà Ara Ifọ̀ ní olùkọ́ Adedokun kọ́ wa
Baba Ijesha: TAMPAN ní ìbànújẹ́ ọkàn ni pé ọ̀kan lára ọmọ ẹgbẹ́ òun hùwà ìdójútini
Àwọn ọmọ ẹgbẹ́ eré orí itàgẹ́ ẹ̀ka ti TAMPAN, ti fi ẹ̀dún ọkàn wọn hàn lórí bí wọn ṣe ni ìjákulẹ̀ ọkàn tó nígbà tí wọ́n gbọ́ nípa ẹ̀sùn tí wọn fi kan ọ̀kan lára ọmọ ẹgbẹ́ náà kan, Olarewwaju James, ti gbogbo ènìyàn mọ̀ sí Baba Ijesha.
Tampan ni oun ri bii ojuse oun lati bu ẹnu atẹ lu iwa biba ọmọde lopọ ti Baba Ijesha jẹ́wọ́ pe oun se, gẹgẹ bi awọn ọlọpaa se fidi rẹ mulẹ.
Nínú àtẹ̀jáde kan tí adari ìwádìí fun ẹgbẹ́ náà, Yemi Amodu fọwọ́ sí, TAMPAN fí kún pé, ǹkan ìdójútini gbá à ni, tí ó sì pọ̀ndandan pé kí ẹgbẹ́ tàbùkù ẹni tó hu irú ìwà ìkà bẹ́ẹ̀ sí ọmọdé.
"Pẹ̀lú bí ọ̀rọ̀ yìí ṣe jẹ́ ǹkan ẹlẹgẹ́, tí ó sì wà lábẹ̀ ìwádìí pẹ̀lú, síbẹ̀ TAMPAN fi yé gbogbo àgbáyé pé, òun kò lè sí lẹ́yìn irú ìwà ìbàjẹ́ bẹ́ẹ̀ nítórí pé àwọn gan ni oní wàásù tó n sọ̀rọ̀ lòdì sí irú ǹkan báyìí.
Oríṣun àwòrán, tampanglobal/Instagram
 Gẹ́gẹ́ bí ẹgbẹ́ a mọ ìwà, ìṣesí àti ìhùwà sí àwọn ènìyàn wà gẹ́gẹ́ bi oníwàásù."
Nítorí náà, a kò ní kùnà láti ran ìjọba lọ́wọ́ láti ri dájú pé irú ìwà báyìí dí òhun ìgbàgbé láwùjọ wa
Ẹgbẹ́ tún bá ẹbi ọmọ tí ọ̀rọ̀ yìí ṣẹ̀lẹ̀ sí kẹ́dùn, wọ́n sì rọ gbogbo òbí lápapọ̀ láti máa fún àwọn ọmọ wọn ni àànfàni láti sàlàyé ara wọ́n láì bẹ̀rù tí ìrú nǹkan yìí bá ṣẹ̀lẹ̀ sí wọ́n, kí àwọn ẹni ibi bẹ́ẹ̀ má bá ri ibi sá sí nínú àwùjọ wa.
Hisham Wadan: Ìlanilọ́yẹ̀ nípa àrùn ojú ló mú mi ṣe fíìmù Lost in London
"Lákotan ẹgbẹ́ Tampan ni oun dúro fún ìwà jíjẹ ọmọlúwàbí láwùjọ atí àlátẹ̀lé òfin nígbogbo ìgbà.
Oríṣun àwòrán, Baba Ijesha Instagram/Rotimi Makinde Facebook
Ọrọ isẹlẹ to waye nipa gbajumọ osere tiata kan, Olanrewaju James ti n fa oniruuru awuyewuye miran lori ayelujara.
Ọkan lara rẹ ni ti gbajumọ osere miran, Rotimi Makinde, ti ko fi bẹẹ se ere tiata mọ amọ to jẹ asoju sofin tẹlẹ nile asofin agba ilẹ wa, to soju ẹkun idibo Ife.
Makinde lo bọ soju opo Facebook rẹ, to si n rọ awọn araalu to n bu ẹni atẹ lu iwa ti baba Ijesa hu pe ki wọn se suuru, ki wọn jẹ ki idajọ ileẹjọ waye na.
O ni o yẹ kawọn eeyan tiẹ kọminu tabi siyemeji nipa ẹsun biba ọmọde lopọ ti wọn fi kan baba Ijesa,titi ti ileẹjọ to n gbọ ẹjọ naa ba kede pe afurasi naa jẹbi ẹsun naa.
Oríṣun àwòrán, Rotimi Makinde Facebook
Mo mọ pe wọn fi ẹsun kan pe o sẹ si ẹsun ti wọn fi kan... abi se ẹsẹ ni ki eeyan jẹ gbajumọ osere tiata ni, ẹ jẹ ka ni suuru, ka si fi ifẹ han si."
Lootọ la n bu ẹnu atẹ lu iwakiwa ni awujọ amọ ẹ dẹkun sise idajọ lọwọ ara yin lori ẹsun biba ọmọde sun ti wọn fi kan afurasi naa.
O dabi ẹni pe ọpọ wa gan la ti ni ninu tẹlẹ lati mu Baba Ijesa walẹ ko to di akoko yii. Iwa ọdaran ko dara amọ iwa kikan afurasi mọ agbelebu gan jẹ iwa ọdaran.
"...Lootọ la le se aanu ọmọde ti wọn lo fara gba iwa naa."""
Oríṣun àwòrán, Rotimi Makinde Facebook
Ohun ti Rotimi Makinde kọ soju opo Facebook rẹ ree, ti ọpọ eeyan fi gba ya, ti wọn si n kọ kobakungbe ọrọ si abẹ ọrọ rẹ.
Bi o tilẹ jẹ pe Makinde ti yọ ọrọ naa kuro loju opo Facebook rẹ amọ sibẹ ko dẹkun lati maa tako iwa idalẹbi tawọn eeyan n hu, tawọn onitọun naa si n da lohun pada.
Koda, Makinde tun kọ ọrọ miran pe ẹja goolu ko ni ibi to le sa pamọ si, ki aye ma rii, to si se adura pe ki Ọba Oke mase jẹ ka di ẹni ilẹlẹ lasiko iporogan.
Oríṣun àwòrán, Rotimi Makinde Facebook
O ni oun ko fi igba kankan fara mọ ohun ti wọn ni Baba Ijesa se, to si ni ki ẹni ti inu ba n bi lori ọrọ ohun lọ di ina mu.
Ọrọ yii naa lo fun n mu esi to gbona jade lati ẹnu awọn ololufẹ Rotimi Makinde lori ayelujara naa, ti ọpọ wọn si n sọ fun asoju-sofin tẹlẹ naa pe afurasi ti jẹwọ ẹsun ti wọn fi kan.\Wọn ni ọrọkọrọ ni Makinde n sọ lẹnu, ti wọn si ni oun gan buru ju baba Ijesa lọ.
Oríṣun àwòrán, @OlofofoMusic
Saaju la ti sọ fun yin pe ileeṣẹ ọlọpaa ipinlẹ Eko ti kede pe awọn ti fi ṣikun ofin mu gbajugbaja oṣere tiata Yoruba, Olanrewaju James, ti ọpọ awọn ololufẹ rẹ mọ si Baba Ijesha.
Ninu atẹjade kan ti alukoro ileeṣẹ naa, Muyiwa Adejobi fi sọwọ si BBC Yoruba, o ni awọn mu Baba Ijesha lori ẹsun pe o ba ọmọ ọdun mẹrinla ni ibalopọ.
"Atẹjade naa ni ""Ileeṣẹ ọloọpaa ipinlẹ Eko ti fi ṣikun ofin mu Olanrewaju James, ẹni ọdun mejidinlaadọta, ti awọn eeyan mọ si Baba Ijesha lori ẹsun pe o ba ọmọ ọdun mẹrinla lopọ."""
Obinrin kan ti orukọ rẹ n jẹ Princess Adekola Adekanya lo fi ọrọ naa to ile iṣẹ wa to wa ni Sabo leti lọjọ kọkandinlogin, oṣu Kẹrin, ọdun 2021.
Adejobi tẹsiwaju ninu atẹjade naa pe iwadii ti awọn ṣe fi han pe afurasi naa ti n ba ọmọ ọhun ni ibalopọ lati akoko to wa ni ọmọ ọdun meje.
aaaaaaaaaaaaaaa
"O ni ""Afurasi naa jẹwọ pe lootọ ni oun ṣe ẹṣun ti wọn fi kan oun."""
Adejọbi fi kun pe ẹrọ ayaworan CCTV to wa ninu ile ti iṣẹlẹ naa ti waye tun ka afurasi naa silẹ.
Ẹwẹ, kọmiṣọna ọlọpaa ipinlẹ Eko, Hakeem Odumosu ti paṣẹ pe ki iwadii bẹrẹ lori iṣẹlẹ naa, o si ṣeleri pe idajọ odo ni yoo tẹle iwadii ọhun.
Gbogbo akitiyan lati kan si oṣere naa tabi awọn ojugba rẹ nidii iṣẹ tiata lo ja si pabo.
hhhhhh
Àwọn ajínigbé kò jí ẹnikẹ́ni gbé lágbègbè Igboọra sí Eruwa - Ọlọ́pàá Ọyọ
Oríṣun àwòrán, @seyiamakinde
Kọmiṣọna ọlọpaa n'ipinlẹ Ọyọ, Ngozi Onadeko ti ṣe alaye pe irọ lasan lo wa nidi iroyin to n ja rainain pe awọn eeyan mẹẹdọgbọn bọ si ọwọ awọn ajinigbe laarin wakati mẹrinlelogun ni agbegbe Ibarapa.
Onadeko to ba awọn oniroyin sọrọ l'Ọjọbọ ni olu ileeṣẹ ọlọpaa to n bẹ ni agbegbe Ẹlẹyẹle, niluu Ibadan fi kun ọrọ rẹ pe irọ ti o jina si otitọ ni iroyin naa.
O ni iroyin naa to ileeṣẹ ọlọpaa lọwọ lowurọ Ọjọbọ wi pe awọn agbegbọn ji awọn eeyan kan gbe ni agbegbe Eruwa, pẹlu alaye wi pe ofintoto ti ileeṣẹ ọlọpaa ṣe lo fi idi ọrọ mulẹ wi pe irọ lasan ni iroyin naa.
Saaju ni iroyin gba ode kan lọsan Ọjọbọ wi pe awọn agbebọn ṣe ikọlu si ọkọ akero kan, ti wọn si ji awọn ero ọkọ mẹrindinlogun lọ l'opopona Igboọra si Eruwa.
Bakan naa ni iroyin mi i tun sọ pe awọn agbebọn tun ji eeyan meje mi i l'Ọjọru.
Botilẹ jẹ pe arakunrin kan ti wọn pe orukọ rẹ ni Ọladiran Ọladokun ni agbegbe Ibarapa sọ wi pe lootọ ni iṣẹlẹ naa waye.
Budo Ikoko water problem: Ìyàwó wa ti sá lọ kúrò ní Asa nítorí àìsí omi- Alhaji Sunmonu
Ẹwẹ, kọmiṣọna ọlọpaa ni oun ṣe ipade pẹlu awọn ọga agba ajọ ọlọpaa ni agbegbe Igboọra ati Ibarapa, wọn si ni iru iṣẹlẹ bẹẹ ko waye rara.
Nibayii, Kọmiṣọna ọlọpaa n'ipinlẹ Ọyọ ti parọwa si awọn olugbe agbegbe naa ati ipinlẹ Ọyọ lapapọ lati maa lọ si ẹnu iṣẹ wọn lai bẹru ati lai foya, gẹgẹ bi o ṣe n parọwa si wọn lati maa ta ileeṣẹ ọlọpaa ni olobo ki eto aabo le fi ẹsẹ mulẹ si i n'ipinlẹ naa.
aaaaaaaaaaaaaaa
EKSU Ekiti workers crisis: Àwọn aláṣẹ ilé ẹ̀kọ́ EKSU ti ní kí wọ́n gbé ilé ẹ̀kọ́ náà tì pa
Àwọn aláṣẹ ilé ẹ̀kọ́ fasiti Ekiti, tí ní kí wọ́n gbé ilé ẹ̀kọ́ náà tì  pa lóní wàràǹsesà.
Bákan náà ni ìgbìmọ̀ aláṣẹ ọ̀hún tún ni òun kò fọ̀wọ́ sí ẹgbẹ́ akẹ́kọ̀ọ́ kankan ni il'é ìwé náà tó fi mọ́, ASUU, NASU, SSANU, NAAT.
Àtéjáde tó jẹyọ láti ọwọ́ agbẹnusọ ilé ìwé náà Bode Olofinmaugun ló fẹ̀sùn kan pé òun fura pé àwọn kan dìde láti da ètò ẹ̀kọ́ rú ni ilé ìwé náà tí wọ́n sì ń fi ẹ̀mí àti dúkíà àwọn ènìyàn sínú ewu láti bi ọ̀sẹ̀ kan sẹ́yìn.
Ẹ̀wẹ̀, ó rọ gbogbo akẹ́kọ̀ọ́ láti kúrò nílé ẹ̀kọ́ ní kíákíá.
Sáájú ni ìpàdé laáárìn àwọn ìgbìms olórí ẹgbẹ́ òsìṣẹ́ ilé ẹ̀ka náà àti àwọn ìgbìmọ́ aláṣẹ ilé ẹ̀kọ́ náà forí sọ́pọ́n, bí àwọn asójú ẹgbẹ́ tó wá fún ìpàdé náà ṣe bínú jáde kúrò nínú ìpàdé ọ̀hún bí wọ́n ṣe kọ̀ látiṣe ǹkan tí wọ́n ń bèèrè fún.
aaaaaaaaaaaaaaa
Ìròyìn tún fi yé ni pé, àwọn èèkàn mííràn tó tí bá gómìnà ṣe ìpàdé pẹ̀lú bínú jáde nínú ìpàdé náà nítórí bi gómìnà ṣe fi ààké kọ́rí lórí ọ̀rọ̀ náà tó sì ks láti ṣe ǹkan tí wọ́n ń fẹ́, lára rẹ̀ ní owó oṣù mẹ́tà tí wọ́n jẹ lọ́dún 2019, owó oṣù mẹ́rìnlá tí wọ́n yọ nínú owó oṣù ati owó ìfẹ̀yìn tì.
Budo Ikoko water problem: Ìyàwó wa ti sá lọ kúrò ní Asa nítorí àìsí omi- Alhaji Sunmonu
Àwọn olórí òṣìṣẹ́ ní ilé ìwé náà lásìkò tí wọ́n ń bá àwọn oníròyìn sọ̀rọ̀ jẹ́jẹ̀ẹ́ pé àwọn kò ní sinmi ìfẹ̀hónú hàn títí tí ìjọba yóò fi ṣe ǹkan tí àwọ́n ń fẹ́.
Bákan náà ní wan bu ẹnu àtẹ́ lu ìgbìmọ̀ aláṣẹ ilé ẹ̀kọ́ náà tí kò le san àwọn owó tí wọ́n yọ nínú owó oṣù pàda láti ọdún 2018.
Àtẹ̀jádé ìjọba apapọ̀ lórí ọ̀rọ̀ Pantami fihàn pé wọ́n ń káànú ìgbésùnmọ̀nmí- PDP
Ẹjọ́ ń bẹ lọ́run fún gbogbo ẹ̀yin tí kò wàásù fáwọn tó ń tẹ lé yín lórí Instagram àti Facebook- Mike Bamiloye
Olólùfẹ́ Naira Marley kọ sẹ́nu tírélà nítorí ₦500 tó fẹ́ gbà lọ́wọ́ rẹ̀
Adunni Olorisa, obìnrin òyìnbó tó di ìyàwó òrìṣà nílẹ̀ Yorùbá títí di ọjọ́ ogbó
Àwọn agbébọn ti pa mẹ́ta nínú àwọn akẹ́kọ̀ọ́ fásitì Greenfield tí wọ́n jí gbé ní Kaduna
‘Jí foonu ọkọ rẹ̀ wò, kóo fi ẹ̀wọ̀n jura’
Oríṣun àwòrán, Roundoffnews
Nnkan ko rọgbọ ni saa yii ni fasiti ipinlẹ Ekiti, EKSU pẹlu gbọnmọgbọnmọ wahala oṣiṣẹ nibẹ.
Lọwọ yii awọn oṣiṣẹ fasiti ipinlẹ Ekiti ko tii jami lori iyanṣẹlodi ati iwọde ti wọn n gunle nibẹ lati beere fun awọn ajẹẹlẹ owo oṣu wọn kan eyi ti awọn alaṣẹ ẹgbẹ oṣiṣẹ nibẹ ni awọn n beere fun.
Ẹnu iloro ọgba fasiti naa to yẹ ko jẹ abawọle sinu awujọ ikẹkọọ ni wọn ti sọ di ibudo igbafẹ nibi ti wọn ti gba awọn onilu ti wọn si n jo.
Oniruuru orin ọtẹ ati eebu lo n gbode nibẹ ti wọn n kọ tako ijọba ipinlẹ naa atawọn alaṣẹ fasiti ọhun, ti awọn oṣiṣẹ naa si n jo lati wọde fun ajẹẹlẹ owo oṣu ati ajẹmọnu gbogbo ti wọn n beere fun.
Iwọde wọn yii ko jẹ ki ohunkohun tabi ẹnikẹni wọle tabi jade lẹnu iloro ileewe naa to si ti mu ki ẹkọ kikọ.
aaaaaaaaaaaaaaa
Ọkan lara awọn oṣiṣẹ fasiti naa, Ọgbẹni Azeez Aguda to ba awọn oniroyin abẹle kan sọrọ  ṣalaye pe ohun ti wọn n ja fun ni sisan ajẹẹlẹ owo oṣu wọn fun oṣu  ikeje, ikẹjọ ati ikẹsan ọdun 2018.
Wọn tun n beere fun dida owo alajẹṣẹku kọpuretifu ati owo ifẹyinti wọn pada, igbayegbadun awọn oṣiṣẹ ati dida awọn oṣiṣẹ ti wọn ys niṣẹ pada.
Akomolede ati Aṣa lori BBC Yoruba: Ẹ̀yà Ara Ifọ̀ ní olùkọ́ Adedokun kọ́ wa
Ondo crime: Happiness tó fọ́gi mọ́ orogún rẹ̀, Blessing Emmanuel lórí tó fi kú l'Ondo ti wà láhámọ́ ọlọ́pàá
Oríṣun àwòrán, Thenewstrack.com.ng
Arabinrin Nanko Happiness ni iyale ti Napre Blessing si jẹ iyawo nile arakunrin Emmanuel.
Ọrọ kan lo ṣe bi ọrọ laarin awọn tiyale tiyawo mejeeji yi to fa ija laarin wọn
Kọmiṣọnna ọlọpaa ni ipinlẹ Ondo, Bọlaji Salami to ṣe afihan arabinrin Happiness pẹlawọn afurasi ọdaran kan lolu ileeṣẹ ọlọpaa ni lu Akurẹ sọrọ ilẹ kun.
O ṣalaye pe ọjọ keje oṣu, kẹrin ọdun 2021 ni iṣẹlẹ naa waye lagbegbe Sunshine Garden Estate, Ọda nilu Akurẹ.
Ikorodu cult crisis:A máa gbé Orò síta lọ́jọ́kọ́jọ́ tí ìjà ẹgbẹ́ òkùnkùn bá tún ṣẹlẹ̀- Àwọ
O fi kun pe Happiness to jẹ iyale yọgi to fi lu iyawo rẹ Blessing lori lasiko ija naa.
Igba ti eyi ko tẹẹ lọrun lo ba tun mu ọkọ iroko ti iyawo rẹ naa to sha lori ati ni ara eleyi ti wọn ni o ṣokunfa iku rẹ.
Nollywood Yoruba: Ẹjọ́ ń bẹ lọ́run fún gbogbo ẹ̀yin tí kò wàásù fáwọn tó ń tẹ lé yín lórí Instagram àti Facebook- Mike Bamiloye
Oríṣun àwòrán, Mount Zion
Gbajugbaja ajinhinrere ninu ere ori itage Kristẹni,  Mike Bamiloye ti kilọ fawọn eeyan ti ko sọrọ Ọlọrun fun awọn to tẹ le wọn loju opo Facebook ati Instagram.Bamiloye ni gbogbo awọn ti ko ri nkan gidi fawọn ololufẹ wọn ju awọn nkan ti ko tọ ati nkan amunidẹṣẹ ni yoo jiyin lọjọ idajọ niwaju Eledua Oṣere naa ni ọrọ kọta dọtii ni ọpọ ilumọọka maa n bawọn ololufẹ wọn sọ lori Instagram àti Facebook.
"Bamiloye sọ pe niṣe lo yẹ ki wọn maa jẹ ki awọn to n tẹ le maa pongbẹ lati gbọ ọrọ iye.Oṣere Bamiloye ni ""anfaani nla ti ẹ o jiyin lọjọ idajọ ni ẹ n sọnu.""O ni ko si ohun to dabi k'awọn eeyan maa fi ọrọ Ọlọrun bọ ọgọọrọ eeyan to n tẹ le wọn loju opo ayelujara Instagram ati Facebook."
hhhhhh
Oṣere yii ti maa n sọ nipa igbe aye ododo nigba kugba loju opo ayelujara rẹ.Bamiloye ni oludasilẹ gbajugbaja ileeṣẹ oṣere Kristẹni, Mount Zion Films eleyi to ti gbe oriṣiiriṣii ere jade.
Oríṣun àwòrán, Screenshot
Gbajumọ oṣere tiata Yoruba, Kẹmi Afọlabi ti sọọ di mimọ pe ojojo n ṣe ogun ara ogun oun ko le bayii ati pe idubulẹ aisan loun wa lọwọ yii.
Kẹmi Afọlabi fi to awọn ololufẹ leti lori ikanni ikansiraẹni  ayelujara rẹ.
Kemi ṣalaye pe oṣu kejila, ọdun 2020 loun lọ sode iṣẹ tiata kẹyin nitori aisan naa ti ko darukọ rẹ.
Amọṣa, o dupẹ lọwọ Ọlọrun fun didasi ẹmi rẹ to si n sọ fawọn ololufẹ rẹ pe oun maa jẹri ọpẹ laipẹ.
Ikorodu cult crisis:A máa gbé Orò síta lọ́jọ́kọ́jọ́ tí ìjà ẹgbẹ́ òkùnkùn bá tún ṣẹlẹ̀- Àwọ
iṣẹ ti mo gbakẹyin ni #Disẹmb2020 niyi n ko le lọ si ode tiata kankan lọdun #2021 nitori ailera ara mi.
aaaaaaaaaaaaaaa
Idriss Déby Itno funeral pictures: Wo bí ètò ìsìnkú Aàrẹ Chad àná, Idris Deby ṣe ń lọ
Oríṣun àwòrán, AFP
Awọn ọmọ ogun ge posi Aa[re Deby pẹlu asia orilẹ-ede naa
Eto isinku Aarẹ orilẹ-ede Chad ana, Idris Deby ti n lọ lọwọ.
Ṣaaju ni awọn olori ẹgbẹgun ọlọtẹ ti kọkọ dukoko mọ awọn adari ijọba ilẹ okeere to fẹ peju sibi eto isinku naa lati maṣe yọju.
Ogunjo, oṣu Kẹrin, ọdun 2021 ni Deby jade laye lẹyin to fara gbọta ibọn loju ija pẹlu awọn ọmọ ogun ọlotẹ.
Ẹni ọdun mejidinlaadọrin ni Deby ko to jade laye.
Oríṣun àwòrán, AFP
Ọmọ Aarẹ ana naa, Gen Mahamat Déby Itno,ti wọn ṣẹṣẹ gbe ijọba naa le lọwọ
Aarẹ mali ati Guinea ti kalẹ sibi ti eto isinku naa yoo ti waye.
Oríṣun àwòrán, Reuters
Aarẹ Niger Mohamed Bazoum (L), Aarẹ France Emmanuel Macron ati Mauritania Mohamed Ould Cheikh El Ghazouanipade nibi eto isinku naa
Aarẹ orilẹ-ede France, Emmanuel Macro ti ṣetan lati tẹkọ leti lọ si Ndjamena bo tilẹ jẹ pe awọn ọmọ ogun ọlọtẹ ti kilọ fun awọn adari orilẹ-ede miran lati maṣe yọju sibi eto isinkun ọhun.
Oríṣun àwòrán, EPA
Awọn ọmọ ololgun ti wa nikalẹ
Oríṣun àwòrán, EPA
Awọn eeyan ilu naa ko gbẹyuin nibẹ
Ọdun 2016 ni Deby jawe olubori ninu eto idibo to gbe wọle fun saa karun un.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Aarẹ ana ni Chad, Idriss Déby Itno
Ọdun 2018 ni ile igbimọ aṣofin orilẹ-ede naa ṣe agbeyẹwo ofun wọn, eyii to faye gba Deby lati dije fun saa kẹfa.
hhhhhh
Seyi Makinde: Ìjọba Oyo ní ètò fún àwọn òṣíṣẹ́ BCOS kó tó bẹ̀rẹ̀ sí ń wó iiléègbé wọn - Alága iléeṣẹ́ náà
Ọpọlọpọ awuyewuye lo rọ mọ ileigbe awọn oṣiṣẹ ileeṣẹ igbohunsafẹfẹ ipinlẹ Ọyọ, BCOS, lẹnu ọjọ melo kan si asiko yii.
Bi iroyin kan ṣe n sọ wi pe Gomina Ṣeyi Makinde dede ko awọn katakata wọn inu ọgba ileeṣẹ naa lai sọ fun wọn tẹlẹ ni iroyin mi i tun sọ wi pe awọn alakoso ileeṣẹ naa mọ si igbesẹ naa.
BBC Yoruba ṣe abẹwo si ileeṣẹ naa ni owuro ọjọ Ẹti, a si ri i daju wi pe ijọba ipinlẹ Ọyọ ti bẹrẹ si ni wo awọn ile kan to jẹ ileegbe awọn oṣiṣẹ BCOS.
Alaga ileeṣẹ igbohunsafẹfẹ ipinlẹ Ọyọ, BCOS, Alagba Dọtun Oyelade ṣe alaye fun akọroyin wa pe, o to bi i ipade mẹrin ọtọọtọ ti wọn ba awọn olori oṣiṣẹ labẹ aburada RATTAWU  ati NUJ ṣe, lẹyin eleyii ti ijọba ipinlẹ Ọyọ tun ba wọn ṣe ipade pọ bi i ẹmeeji si ẹmẹẹta lori ọrọ naa.
"Oyelade ni, ""Eyii to jẹ okodoro ọrọ ni wi pe ijọba fẹ lo awọn aye to ṣẹku lẹyin ọdọ wa ni."""
Ijọba naa lo kuku ni ilẹ, wọn fẹ lo o lati fi ṣe agbekalẹ ile akọta ti Oyinbo n pe ni Estate, ijọba wa pa idi apo pọ pẹlu ẹnikan ti yoo gbe owo silẹ ti yoo si kọ ọ.
Ikorodu cult crisis:A máa gbé Orò síta lọ́jọ́kọ́jọ́ tí ìjà ẹgbẹ́ òkùnkùn bá tún ṣẹlẹ̀- Àwọ
O fi kun ọrọ rẹ pe ijọba ipinlẹ Ọyọ yoo fi ọwọsọwọpọ pẹlu ile iṣẹ adani naa ti akanṣe iṣẹ naa yoo fi yọri ti wọn a si ta a.
Alaga ileeṣẹ naa tẹsiwaju pe pupọ ninu awọn ileigbe awọn oṣiṣẹ naa lo ti di ile atijọ ti ko si dun un wo lọju mọ.
"O ni, ""Wọn ti gbo si ara, igbo ti bo wọn, paanu mii ti ja, ferese omii ko si nibẹ mọ, ẹ o le mọ pe eeyan n gbe ibẹ."""
O ni awọn ti parọwa si ijọba lati ma wo gbogbo ileigbe naa nitori pupọ ninu awọn oṣiṣẹ naa lo n ṣiṣẹ mọju.
Oyelade ni ijọba ti yọnda awọn aaye kan fun iru awọn oṣiṣẹ bẹẹ, bakan naa ni wọn yọnda mọṣalaṣi ati ṣọọṣi to fi mọ gbọngan awọn oṣiṣẹ fẹyinti.
O tẹsiwaju pe ijọba to wa lode ki i ṣe ijọba ika, eyii lo mu ki wọn fun awọn oṣiṣẹ to n gbe ile naa ni oṣu mẹta lati wa ile mii, bẹẹ sini ijọba yoo fun gbogbo wọn ni owo ile ọdun kan.
Oyelade ni ko si olugbe kankan ninu awọn ile ti ijọba ti bẹrẹ sini wo bayii.
O pari ọrọ rẹ pe awọn ile ti ko si ẹnikẹni ninu rẹ ni ijọba kọkọ bẹrẹ sini wo l'Ọjọbọ.
Budo Ikoko water problem: Ìyàwó wa ti sá lọ kúrò ní Asa nítorí àìsí omi- Alhaji Sunmonu
Naira Marley fi ìfẹ́ hàn sí àwọn olólùfẹ́ rẹ̀ lójú pópó, àwọn méjì kó sẹ́nu tírélà
Oríṣun àwòrán, Naira Marley
Ori ko ọkan lara awọn ololufẹ gbajugbaja olorin takasufe, Naira Marley, yọ lọwọ iku ojiji lagbegbe Ajah, niluu Eko.
Fidio kan to n milẹ titi loju opo ikansiraẹni lori ayelujara lo ṣafihan bi iṣẹlẹ naa ṣe waye.
Ninu fidio naa ni Naira Marley ti ṣi ferese ọkọ ayọkẹlẹ to wa ninu rẹ, to si n na owo jade si awọn ololufẹ rẹ lori popo.
"Bo tilẹ jẹ pe ọkọ ti Naira Marley wa ninu rẹ wa lori ere, awọn ololufẹ rẹ ọhun n kii ni mẹsan an mẹwaa, ti wọn si n pariwo ""Marley, o pọ, o pọ."""
Awọn kan lara awọn eeyan naa wa lori alupupu, ti awọn alupuipu naa si  n sare tete tẹle ọkọ Naira Marley lori ere.
Oríṣun àwòrán, NAira marley
Nigba ti Naira Marley na N500 jade si awọn meji kan lara awọn eeyan naa to wa lori alupupu, ti wọn si gba owo naa tan ni wọn ya bara sẹnu ọkọ ajagbe kan.
Ni kete ti wọn ko si ẹnu ọkọ ajagbe  naa tan ni Naira Marley ke gbajare si dẹrẹba ọkọ ajagba naa, to si n ke si pe ko rifaasi.
hhhhhh
Gẹgẹ bii ohun to wa ninu fidio naa, awọn mejeji to wa lori alupupu naa ko farapa, ẹmi ẹnikẹni ko si ba iṣẹlẹ naa lọ.
Ikorodu cult crisis:A máa gbé Orò síta lọ́jọ́kọ́jọ́ tí ìjà ẹgbẹ́ òkùnkùn bá tún ṣẹlẹ̀- Àwọ
Bo tilẹ jẹ pe ori ko awọn eeyan naa yọ, iṣeju aaya perete si iṣẹlẹ naa ni ẹlomiran tun n ki Naira mMarley ni mẹsan an mẹwa ki oun naa le ri owo gba lọwọ olorin ọhun.
"Lasiko to fi fido ọhun soju opo Instagram rẹ, Naira Marley sọ pe ""Diẹ lo ku ki arakunrin yẹn padanu ẹsẹ rẹ."""
Ọpọ awọn to wo fidio naa lo ti bẹrẹ si n fi erongba wọn lede lori iṣẹlẹ ọhun.
Bi awọn kan ṣe n kan sara si naira Marley fun aajo ololufẹ rẹ to ṣe, lawọn mii n sọ pe iṣẹ ati iya to wa lode le mu ki odidi gende fi ẹmi ara wewu nitori ₦500 pere.
Akomolede ati Aṣa lori BBC Yoruba: Ẹ̀yà Ara Ifọ̀ ní olùkọ́ Adedokun kọ́ wa
Ramadan Fast 2021: Pásítọ̀ pín ounjẹ iṣínu àwẹ̀ fún àwọn Músùlùmí
Oríṣun àwòrán, Channels
Bísọ̀ọ̀bù àgbà nígbà kan rí nílùú Abuja, John Onaiyekan tí pín ounjẹ́ tó lé ni igba fún àwọn músùlùmí bí ẹgbẹ̀rún méjì ní mọ́sálásí Al-Habibiyah ní agbègbè Guzape nìlùú Abuja tíí ṣe olúùlú orílẹ̀ èdè Nàìjíríà
Lásìkò tí wọ́n péjọ láti ṣinu ààwẹ̀ ní òun àti àwọn onígbàgbọ́ míírà sàbẹ̀wò sí mọ́sálásí náà.
Ilé iṣẹ́ ìròyìn Channels gbé àwọn fótò bí Bísọ̀ọ̀bù àgbà ọ̀ún ṣe ń pín ounjẹ náà fún àwọn mùsùlùmí láti ṣínu.
Oríṣun àwòrán, Channels
Gẹ́gẹ́ bí ó ṣe sọ lásìkò tó n pín, ó ṣàlàyé pé Ọlọ́rùn fẹ́ràn kí krìstẹ́nì fi ìfẹ́ hán nítòrí ìfẹ́ ni òun fúnra rẹ̀, àti pé àwọn ń ṣe èyí láti jẹ́ kí àláfíà kó jọba láàárín krìsẹ́ní àti Musulumi.
Nínú ọ̀rọ̀ rẹ̀, Imaamu Mọ́sálásí Al- Habibyyah Fuad Adeyemi sọ pé, ǹkan tí adarí krìtẹ́nì ṣe yìí fi hàn pé ẹ̀sìn méjèèjì lé jọ́ jùmọ̀ gbé pọ̀ gẹ́gẹ́ bí ọ̀rẹ́ àti ni ìgbé àlàfíà.
Oríṣun àwòrán, Channels
Argentina Transport Minister: Ọkọ̀ Mínísítà tàkìtì nínú ìjàmbá ọkọ̀ tó wáyé lásìkò ìjì líle
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Iku omi lo n pomuwẹ,iku ogun lo n pa akikanju, iku oge si ni Yoruba ni a maa pa arẹwa.
Ni orileede Argentina iku to fẹ jọmọ awọn eyi taa sọ ṣaaju yi ṣebẹ pa Minisita feto irina,Mario Meoni, ti o padanu ẹmi rẹ ninu ijamba oju popo.
Iroyin to tẹwa lọwọ sọ pe o kagbako iku ninu ijamba ọkọ lọjọ Ẹti lẹyin abẹwo si ilu Rosario.
Gẹgẹ baa ṣe gbọ, lasiko iji lile kan ni ọkọ rẹ takiti ti o si ṣokunfa iku rẹ.
Atẹjade lati ileeṣẹ iroyin aarẹ nilẹ naa ni oun nikan lo wa ninu ọkọ nigba ti iṣẹlẹ yi waye.
Koda a gbọ pe o ṣẹṣẹ fi ọrọ si oju opo Twitter rẹ pe oun ṣabẹwo  pẹlu  aarẹ Alberto Fernandez si agbegbe Santa Fe.
Lasiko abẹwo yi, o ni awọn buwọlu iwe adehun lori ibudokọ ẹru ọkọ oju omi, reluwee ati awọn ohun amayedẹrun miran.
Iroyin iku rẹ ti mu ki awọn alabaṣiṣẹpọ rẹ maa kẹdun iku rẹ ti ọpọ si ṣapejuwe rẹ gẹgẹ bi eeyan daa.
Ọ 1965 ni wọn bi nilu Ascencion nibi towa pada ti jẹ oye Mayor laarin ọdun 2003 si 2015.
O fi iyawo ati ọmọ meji saye lọ.
Suspected Ritualist: Ki láwọn gende méjì n ṣé ní ibojì òkú pẹlú orí gbígbẹ ní Kaduna
Oríṣun àwòrán, Daily Trust
Ọwọ palaba awọn alaburu meji kan ti segi ni Kaduna lẹyin ti awọn ọlọpaa ka wọn mọ plu ori oku .
Alukoro ọlọpaa ipinlẹ naa ASP Muhammad Jalige lo fi ọrọ yi to awọn akọroyin leti ninu atẹjade kan gẹgẹ bi ileeṣẹ iroyin Daily Trust ti ṣe sọ.
Jalige sọ pe lọjọ Kẹtalelogun ni awn gba ipe ẹgba wa kan lati ọdọ ọga agọ ọlọpaa to wa ni Kakuri.
DPO agọ ọlọpaa naa sọ pe niṣe lawọn kan fi to awọn leti  ni nkan bi ago mọkanla alẹ pe pe awọn olubi kan wa nibi iboji oku Musulumi to wa ni Kudenden.
Nigba ta wọn ọlọpaa yoo fi de ibẹ, wọn ka awọn ọkunrin meji kan mọ pẹlu ọkọ ati ori oku.
Awọn mejeeji jijọ n gbe ni adirẹsi Zaki Close, Kabala West, Kaduna.
Jalige sọ pe awọn ṣi n tẹsiwaju pẹlu iwadii lati mọ pato nkan ti wọn n ṣe nibẹ pẹlu ori oku.
O wa rọ araalu lati tete fio to awọn ọlọpaa leti bi wọn ba kẹfin ẹnikankan to n hu iwa aida
Oduduwa Republic Agitators: Bí Oyetola ṣe lé ọ̀gá iléèwé mẹ́tẹ́ẹ̀ta jẹ́ àfihàn ìwà ìkórira sí wa
Oríṣun àwòrán, Koiki Media
Ẹgbẹ apapọ awọn eeyan to n beere fun idasilẹ orilẹede Yoruba, labẹ aburada Oduduwa Republic Agitators (ORA), ti sọrọ soke lori isẹlẹ to waye nipinlẹ Osun laipẹ yii.
Bẹẹ ba gbagbe, ijọba Osun pasẹ pe ki ọga ileẹkọ giram mẹta lọ rọọkun nile na nitori bi awọn eeyan to n beere fun iyapa orilẹede Naijiria se wọnu ọgba ileewe wọn lati fa oju awọn akẹkọọ ibẹ mọra.
Amọ nigba to n sọ ero rẹ lori isẹlẹ yii, ẹgbẹ ORA ni oun yoo seto atako alagbara nipinlẹ Osun lori igbesẹ ijọba naa nitori iya to fi jẹ awọn ọga ilẹẹkọ naa.
Atẹjade kan ti aarẹ ẹgbẹ agbaye fun Oduduwa Republic Agitators Worldwide  (ORA), Segun Damilola Olaniyan  fisita lo sisọ loju ọrọ naa.
Oríṣun àwòrán, ODUDUWA REPUBLIC AGITATORS/Facebook
Ẹgbẹ ORA ni bi gomina ipinlẹ Osun, Adegboyega Oyetola se ni ki awọn ọga ileẹkọ mẹtẹẹta naa lọ rọọkun nile fihan pe o korira awọn eeyan to n ja fun orilẹede tuntun naa.
Bakan naa ni wọn leri leka pe loore koore ni awọn yoo maa fi ẹhonu han lori isẹlẹ naa titi ti gomina Oyetola yoo fi da ọga ileẹkọ mẹtẹẹta naa pada.
"A ri igbesẹ gomina Osun gẹgẹ bii iwa ikorira si awọn eeyan to n polongo fun idasilẹ orilẹede Yoruba, a si tako igbesẹ odi to gbe naa pẹlu iwọde alagbara.
Bí Oduduwa Republic bá bẹ̀rẹ̀, a ò ní ṣe aburú fún àwọn tó takò wá, ìlànà ààtẹ̀lé rèé - Banji Akintoye
Awọn ọga ileẹkọ naa gbe igbesẹ naa tori ẹtọ ti wọn ni labẹ ofin lati seto ipolongo  ni ayika naa.
Gbogbo ọba alaye ati agba ijoye nipinlẹ Osun la fun ni atẹjade yii, ki a le fi isẹlẹ yii to wọn leti."
Ẹgbẹ ORA tẹsiwaju pe oun ti ri daju pe ilẹ Yoruba nikan ni awọn asaaju oselu kii se atilẹyin fun ifẹ araalu nitori ifẹ tara wọn.
Báa ṣe lọ́pọlọ tó, ẹnu Yorùbá ò kò, ọgbọ́n táa gbúdọ̀ dá rèé - Ìpàdé àgbààgbà Yorùbá n'Ibadan
Ẹgbẹ naa ni oun lero pe gomina naa yoo se afihan iwa ọmọluabi nipa yiyi igbesẹ rẹ pada ki awọn ọga ileewe mẹtẹẹta le pada si ẹnu isẹ ni kiakia.
Ẹgbẹ ORA ni ti gomina Oyetola ba gbe igbesẹ naa, eyi to tubọ mu ki ifẹ tawọn ni si ru gọgọ si nitori baba ati arakunrin awọn lo jẹ.
Hisham Wadan: Ìlanilọ́yẹ̀ nípa àrùn ojú ló mú mi ṣe fíìmù Lost in London
Insecurity in Nigeria: Èèyàn bíi àádọ́ta kú ikú òjijì lọ́jọ́ Ajé láti ọwọ́ agbébọ̀n
Oríṣun àwòrán, @HQNigerianArmy
Ọjọ Aje to kun fun ẹjẹ ni ọjọ ana, nigba tawọn agbebọn sọsẹ, ti wọn si n pa eeyan kiri yika orilẹede Naijiria.
Se ni ilẹ mu ẹjẹ nipinlẹ Rivers, Kebbi, Anambra, Borno, Ebonyi ati Imo.
Koda rogbodiyan tun waye nilu Eko, ti ẹmi awọn eeyan miran si tun bọ.
Lapapọ, o le ni aadọta eeyan to jade laye lairotẹlẹ yika Naijiria ti akọsilẹ wa fun, lati ọwọ awọn agbebọn.
Sọja marun lo ku nipinlẹ Rivers, ọlọpaa mẹfa ni Imo, eeyan mọkanla ni Kebii, marun ni Eko ati mẹsan ni Anambra.
Bakan naa, sọja mẹfa miran ku ni Borno, meji ni Imo nigba ti awọn akẹkọọ meji lara awọn ti wọn ji gbe ni fasiti Greenfield naa jalaisi.
Akomolede ati Aṣa: Kọ́ ẹ̀kọ́ si nípa ààlọ́ nílẹ̀ Yorùbá
Ileesẹ ọlọpa nipinlẹ Kebbi ti fidi rẹ mulẹ pe awọn agbebọn ti pa ọga agba ọlọpaa kan ati osisẹ ọlọpaa mẹjọ pẹlu fijilante meji.
Awọn eeyan mọkanla naa lo jade laye lasiko ti awọn ati agbebọn doju ibọn kọ ara wọn lọjọ Aiku.
Osisẹ alarina fun ileesẹ ọlọpa, Nafiu Abubakar sọ fun ileesẹ akoroyinjọ ilẹ wa, NAN pe deede aago meji abọ ọsan ni isẹlẹ naa sẹlẹ.
Awọn agbebọn naa lo doju ija kọ agbegbe Dankolo, Sakaba, Makuku, Dokar Kambari ati Kurmin Hodo ti gbogbo wọn wa nijọba ibilẹ Sakaba.
Bakan naa, ileesẹ ọlọpaa ni awọn agbebọn naa ko fi ara re lọ sile pẹlu lasiko ija naa.
Olugbon of Igbon: ‘Rubber Stamp’ làwọn aṣòfin àpapọ̀, wọn kò ṣojú aráàlú
"Olugbe kan ni agbegbe naa, Salisu Adamu sọ funleesẹ NAN pe ""Wọn pa ọga ọlọpaa Jimoh Abdullahi. Awọn ọlọpaa mii ati osisẹ fijilante meji mii."
"Ẹ jọọ a nilo adura, eeyan meje mii ni wọn tun pa ni abule Inana."""
O tun sisọ loju rẹ pe awọn agbebọn naa tun ko ẹgbẹlẹgbẹ maalu lọ ni awọn abule naa.
Se ni wọn n yinbọn soke laibikita eyi to mu ki awọn ara abule naa sa asala fun ẹmi wọn kaakiri.
Ẹnikan tiẹ tun fidi rẹ mulẹ pe ọpọ ọlọpaa lo tun di awati lẹyin ikọlu naa.
Oríṣun àwòrán, Screen shot
Ẹgbẹ ajafẹtọmọniyan kan, Human Rights Writers Association of Nigeria, HURIWA, ti di ẹbi ikọlu awọn agbesumọmi si awọn ile ijọsin Kristẹni ni Kaduna ru Aarẹ Muhammadu Buhari.
HURIWA sọ pe bi ijọba Buhari ṣe kọ lati jawe lọ gbele ẹ fun minisita eto ibaraẹnisọrọ, Isa Pantami, lo sokunfa isẹlẹ naa.
Ẹgbẹ ajafẹtọẹni naa ni lẹyin ti Pantami jẹwọ pe lootọ ni oun ti fi igba kan ṣe atilẹyin fun awọn ẹgbẹ agbesumọmi bii Al-Qaeda ati Taliban, Buhari ko se ohunkohun si.
Huriwa ni eyi lo ki awọn agbesumọmi Naijiria laya lati maa kọlu awọn ile ijọsi bo ṣe wu wọn.
Ninu atẹjade kan ti HURIWA fi sọwọ si awọn akọroyin, eyii to tẹ BBC lọwọ lo ti sọ bẹẹ.
O ni iwa ti Aarẹ Buhari wu ọhun n ṣapẹrẹ fun awọn agbesumọmi naa, lati maa ṣe ohun to wu wọn, ti ohunkohun ko si ni ti ẹyin rẹ jade.
Ikọlu ti awọn agbesumọni naa ṣe si awọn Kristẹni kẹyin ni eyii to waye lọjọ Aiku nile ijọsin kan ni abule Manini Tasha, ni ipinlẹ Kaduna, nibi ti wọn ti pa dokita kan, ti ọpọ ọmọ ile ijọsin naa si farapa.
Gẹgẹ bii ohun ti oṣojumi koro kan sọ, nnkan bii aago mẹsan an owurọ ni awọn agbesumọni naa kọlu ile ijọsin ọhun lasiko ti isin n lọ lọwọ.
Ikorodu cult crisis:A máa gbé Orò síta lọ́jọ́kọ́jọ́ tí ìjà ẹgbẹ́ òkùnkùn bá tún ṣẹlẹ̀- Àwọ
O ni wọn ṣina ibọn bolẹ, eyii to mu ki isin daru, ti wọn si pa dokita kan to n ṣiṣẹ fun ileeṣẹ to n ri si eto ilera.
HARIWA ti wa ke si awọn ọmọ Naijiria lati rọ ijọba ilẹ Amẹrika, Canada ati ilẹ Gẹẹsi lati kede ijọba Aarẹ Muhammadu Buhari bii eyii to n ṣatilẹyin fun ẹgbẹ agbesumọmi Al-Qaeda and Taliban.
O tun ni ki awọn ọmọ Naijiria kan an nipa fun awọn adari ijọba lagbaye lati ri ijọba Aarẹ Muhammadu Buhari gẹgẹ bii eyii to n faye gba ipakupa awọn eeyan ilu lati ọwọ awọn Fulani darandaran atawọn alakakiti ẹsin Musulumi.
aaaaaaaaaaaaaaa
"HARIWA ni ""Igbagbọ wa ni pe Aarẹ Muhammadu Buhari ko le dẹwọ iṣekupani awọn ọmọ Naijiria nitori oun funra rẹ n ṣatilẹyin fun wọn, awọn adari ijọba lagbaye nikan lo le gba awọn ọmọ Naijiria silẹ, ti wọn si le dawọ ogun abẹle to n bọ ni Naijiria duro."""
Ẹwẹ, ẹgbẹ awọn ọmọlẹyin Kristi ni Naijiria, CAN, ẹka ti ipinlẹ Kaduna ti bu ẹnu ẹtẹ lu ikọlu awọn Kristẹni ni Kaduna.
Ninu atẹjade kan ti akọwe ẹgbẹ naa, Caleb Ma'aji fi ṣọwọ si awọn akọroyin, o ni o jẹ ohun ibanujẹ pe awọn ọmọ ẹgbẹ agbesumọmi n kọlu awọn ile ijọsin lai si idaduro Kankan.
Budo Ikoko water problem: Ìyàwó wa ti sá lọ kúrò ní Asa nítorí àìsí omi- Alhaji Sunmonu
"CAN ni ""Ki ni ẹsẹ awọn ọmọ ilu yii gan to fi jẹ pe awọn agbesumọmi ni ominira ati abo ju awọn ọmọ ilu ti ko lẹṣẹ lọ?"""
Lẹyin naa ni CAN ke pe awọn ẹṣọ alabo lati tu awọn ti awọn agbesumọmi naa ji gbe silẹ ni kankan, wọn si tun ke si ijọba apapọ lati ji giri si ojuṣe rẹ loi eto abo dipo eyii to fi n pariwo ẹnu lasan.
Oríṣun àwòrán, Twitter/GovKaduna
Ijọba ipinlẹ Kaduna ti fidi ọrọ mule pe awọn agbebọn kan ti ya wọ ile ijọsin kan nilu Kaduna, ti wọn si pa eeyan kan.
Samuel Aruwan Kọmisana feto aabo abẹle ni Kaduna sọ pe ille ijọsin naa wa ni ijọba ibile Chukun.
O ni  lootọ ni ikọlu waye lowurọ ọjọ Aiku lasiko tawọn Kristẹni n jọsin ni abule Manini ni ijọba ibilẹ Chikun.
O ni ni nkan bi ago mẹsan abọ aarọ lawọn agbofinro kan si ile ijọsin Haske Baptist Church nibi ti wọ n ti ri pe awọn agbebọn pa olujọsin kan.
Dokita Zechariah Dogonyaro lorukọ rẹ si n jẹ.
Yatọ si dokita ti wọn pa, wọn tun gbe awọn olujọsin mẹrin salọ.
Sheu Mainika to jẹ olugbe adugbo naa la tun gbọ pe o farapa.
Aruwan ninu atẹjade yi tun fidi ọrọ mulẹ pe awọn agbebọn tun ṣe ikọlu sawọn abule mii ni ijọba ibilẹ Birnin Gwari ti wọn si pa eeyan mẹfa.
Ẹwẹ, awọn agbebọn miran gẹgẹ bi Aruwan ṣe salaye tun pa arabinrin kan,Rahila Dauda ni abule Amfu ni Kachia bakan naa.
Oríṣun àwòrán, AFP
Ìgbà àkọ́kọ́ kọ́ nìyí tí irú ìṣẹ̀lẹ̀ bẹ̀ yòó wáyé
Gomina El Rufai bẹnu atẹ lu iṣẹlẹ wọnyi to si ba awọn ara ile ijọsin ti ikọlu yi ti waye kẹdun.
Agbegbe Chukun jẹ ibi tawọn agbebọn janduku ti n ṣoro bii agbọn, ti gbogbo igbiyanju awọn ara adugbo lati dẹkun rẹ si ja si pabo.
Laipẹ yi ni wọn ri oku awọn akẹkọọ ileewe fasiti Greenfield mẹta kan ti awọn ajinigbe gbe ni ijọba ibilẹ yii bakna naa.
Nileewe taa n wi yi, awọn agbebọn ji awọn akẹkọọ gbe lalẹ ọjọ Iṣẹgun lẹyin ti wọn pa ọlọdẹ ileewe naa.
Folajimi Olubunmi-Adewole: Àwọn òbí rẹ̀ ní adóòlá ẹ̀mí kò ṣaáyan tó láti dóòlà ọmọ náà ló fa ikú rẹ̀
Oríṣun àwòrán, Screen Shot/SkyNews
Folajimi Olubunmi-Adewole: Àwọn adóòlá ẹ̀mí kò gbìyànjú tó láti dóòlà ọmọ wa lásìkò tó ń dóòlà ẹlòmíràn - Obi Jimi
Awọn ẹbi ọdọkunrin kan to ku lẹyin to kan lu odo River Thames niluu London, lati doola ẹmi obinrin kan to ko sinu odo naa ṣaaju, ti di ẹbi iku rẹ ru awọn tó wa oku rẹ ninu odo ọhun.
Won ni o ṣeéṣe kí ọmọ wọn ṣi wa láàyè, to ba jẹ pé wọn fi kun ìgbìyànjú wọn lati tete se awari rẹ ni.
Ọdọkunrin náà ti orukọ rẹ n jẹ Folajimi Olubunmi-Adewole, ti ọpọ eeyan mọ sí Jimi, n bọ lati ibi isẹ rẹ lasiko to ri obinrin kan to re bọ sínú odò náà.
Idi ree ti Jimi àti ẹlòmíràn kan lu odo ọhún lati doola obinrin naa ni nnkan bíi aago méjìlá òru.
Oríṣun àwòrán, Screen Shot/SkyNews
Lẹyin o rẹyin, ileeṣẹ to n ri sí ètò àbò orí omi ati ẹka ileeṣẹ ọlọpaa to n ri sí ọrọ ori omi, doola obinrin naa sugbọn Jimi di awati.
Aago mẹfa aarọ ọjọ keji ni ọlọpaa sọ pé wọn tó ri oku ẹnikan to fara jọ ọmọ ogun ọdún náà.
Ṣugbọn baba oloogbe naa, Michael Adewole ati iya rẹ Olasunkanmi Adewole, ti n pé fún idajọ òdodo lori iku ọmọ wọn.
"Ìyá ọmọ náà sọ fún àwọn akọroyin pẹlu omije loju pe ""Ni ṣe ni ọmọ mi n gbiyanju lati gba ẹmi ẹlòmíràn la, nitori naa ìdájọ òdodo ni mo fẹ."""
Oríṣun àwòrán, Screen Shot/SkyNews
Baba rẹ sọ pé èèyàn dáadáa ni ọmọ oun, oniwa tutu sí ni pẹlu, bẹẹ ni ọpọ èèyàn lórí ayelujara ti n kan sara si oloogbe ọhun gẹgẹ bíi akínkanjú èèyàn.
Lara àwọn tó gboriyin fún Jimi ni Mayor ti ilu London, Sadiq Khan, ẹni to sọ pe ọmọ gidi ni fún ọkàn akin to ni.
Baba ọmọ náà ni igbiyanju awọn ọlọpaa lati kan lu omi lati ṣawari ọmọ oun ko to, ko to dakẹ sinu omi.
Oríṣun àwòrán, Screen Shot/SkyNews
Ṣugbọn awọn adoola ẹmi sọ fún àwọn akọroyin pe, awon sa ipa wọn lati ṣawari rẹ loru ọjọ ti iṣẹlẹ naa waye ṣugbọn awọn kò ri.
Wọn ní nígbà tó di aago kan kọjá ogun iṣẹju loru, ni wọn dẹkun wiwa rẹ ki wọn tó rí oku rẹ laarọ ọjọ keji.
Oríṣun àwòrán, Nigeria Police
Inspẹkitọ ọlọpaa to yinbọn pa arakunrin kan Jelili Bakare ni ile igbafẹ Quilox ni ipinlẹ Eko ni wọn ti gba aṣọ lọrun rẹ.
Ileeṣẹ ọlọpaa ipinlẹ Eko lo fi ikede yi sita ninu atẹjade kan ti  Muyiwa Adejobi alukoro ọlọpaa buwọlu.
O ni Komisana ọlọpaa ni Eko Hakeenm Odumosu ni awọn ko ni faaye gba iru iwa bayi laarin awọn agbofinro.
Lọjọ Kejidinlogun oṣu Kẹta ọdun yi ni Inspẹkitọ Jonathan Kompani yinbọn pa Jelili Bakare gbajumọ oniṣowo ni adugbo Lekki.
Gẹgẹ bi iroyin to jade, niṣe ni ọta ibọn ba Jelili ni aaye igbafẹ Quilox nigba tawọn ọlọpaa to wa ni Thera Peace Estate Sangotedo ṣadede bẹrẹ si ni yinbọn.
Inspẹkitọ Jonathan ati Jelila n fa ọrọ mọ arawọn lọwọ nitori pe Jonathan ni oun fẹ tu ara Jelilil wo ṣugbọn ti Jelili ni oun ko ni gba.
Lasiko iṣẹlẹ yi, wọn sọ pe Inspekitọ Jonathan ti mọti yo ti ko si bikita ẹnikẹni ti ọta ibọn rẹ baa le ba.
Eyi kii ṣe igba akọkọ ti awọn ọlọpaa yoo yinbọn pa araalu ti ariwo si ti pọ nigboro pe ki awọn ọga ọlọpaa ma ṣe foju fo aṣiṣe yi mọ.
Ohun to kan bayi ni pe Jonathan yoo foju ba ile ẹjọ.
Olusegun Obasanjo: Nàìjíríà yóò ṣẹ́gun ìpèníjà àbò tó mẹ́hẹ láìpẹ́
Oríṣun àwòrán, Obasanjo
Aarẹ nigbakanri lorilẹede Naijiria, Oloye Oluṣẹgun Ọbasanjọ ti fi da awọn ọmọ Naijiria loju pe, gbọnmọ-gbọnmọ abo to mẹhẹ bayii yoo di itan laipẹ.
Ọbasanjọ ṣalaye pe ẹpọn agbo ni ọrọ Naijiria ati ipenija abo to n koju rẹ lọwọ bayii; O ni mimi lo n mi, ko le jabọ.
O ni bo pẹ bo ya imọlẹ yoo tan, ti idẹrun yoo si de pẹlu gbogbo itajẹsilẹ to n waye yii.
Oloye Ọbasanjọ ni digbi ni igbagbọ oun duro pe orilẹede Naijiria yoo ṣẹgun ipenija abo to mẹhẹ to n ba a finra lọwọ.
Nibi eto ifẹyinti fun Biṣọbu agba ijọ onitẹbọmi lorilẹede Naijiria, Nigeria Baptist Convention, Ẹniọwọ Samuel Ayọkunle lagba oṣelu naa ti sọ eyi.
Oloye Olusẹgun Obasanjo ni bopẹ boya, orilẹede Naijiria yoo bori awọn iṣoro rẹ gbogbo.
Aarẹ Naijiria nigbakanri naa wa fi kun pe igbagbọ oun ko figbakan yẹ ninu orilẹede, oun si yi ri oye pe ohun gbogbo to le koko bayii m bọ wa dẹrọ laipẹ.
Oríṣun àwòrán, Obasanjo
Ààrẹ tẹ́lẹ̀ ní Nàìjíríà, Olusegun Obasanjo sọ pé òun kò ri gbọ́ pé àwọn ènìyàn kán kígbe pé àwọn fẹ́ ìpinyà orílẹ̀-èdè Nàìjíríà.
Bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé àwọn IPOB àti àwọn tó n bèèrè fún orílẹ̀-èdè Oduduwa wà lára àwọn tó n pè fún ìpinyà Nàìjíríà, sùgbọ́n ààrẹ àná ní òun kò mọ̀.
Lásìkò tó n ṣe ìfọ̀rọ̀wérọ̀ pẹ̀lú àwọn oníròyìn ní Sokoto, ni Obasanjo ti dáhùn ìbèérè tí akọròyìn kan bi i láti sọ sí ọ̀rọ̀ ìpinyà ti àwọn ọmọ Nàìjíríà kan ń pè fún.
"Nínú ìdáhùn rẹ̀, ààrẹ àná ní "" ìpinyà? mí o gbọ́ ǹkankan nípa ìpínyà tàbí pé àwọn kán ń pè fún un ni Nàìjíríà."""
Obasanjo ti rìnrìnajo lọ sí Sokoto láti ọjọ́ Satide, níbi to tí lọ ṣe ìfilọlẹ̀ afárá olókè towo rẹ tó bílíọ̀nù mẹ́ta àti mílíọ̀nù lọ́nà irinwó nàìrà, tó sì tún sàbẹ̀wò sí àwọn iṣẹ́ àkànṣe mííràn ní ìpínlẹ̀ náà.
Olugbon of Igbon: ‘Rubber Stamp’ làwọn aṣòfin àpapọ̀, wọn kò ṣojú aráàlú
Olugbon tile Igbon, Ọba Francis Olusola Alao ti kede pe oun n siyemeji nipa aarẹ Buhari to wa nipo nitori kii se Buhari toun mọ lọdun 1983 ree.
Kabiyesi, ẹni to woye ọrọ yii lasiko to n fọrọwerọ pẹlu BBC Yoruba tun woye pe awọn asofin agba ko lọ soju araalu, wọn kan wa nibẹ bii fidi hẹẹ ni.
Ọba Alao ni agbara ti pọ ju lọdọ ijọba apapọ, o si yẹ ki gbogbo ẹya to wa ni Naijiria joko lati wa bi atunto yoo se ba orilẹede yii.
Bakan naa tun ni oriade yii ke si gomina Seyi Makinde tipinlẹ Oyo lati tubọ tẹmpẹlẹ mọ ipese eto aabo to pegede bi o tilk jẹ pe o n gbinyanju.
O ni aidangajia ijọba apapọ nidi ipese eto aabo to peye lo mu kawọn ijọba ipinlẹ nilẹ Yoruba da ikọ alaabo Amotekun silẹ, o si ni awọn naa n gbinyanju.
Àwọn ìtàn mánigbàgbé tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí:
Ọrọ pọ ti Olugbon ba BBC Yoruba sọ, ẹ sa wa nnkan fidi le lati gbadun fidio yii.
Sunday Igboho: Aago kan ààbọ̀ òru ní àwọn agbébọn gúnlẹ̀ láti sun ilé mi
Oríṣun àwòrán, Sunday Igboho/Instagram
Iroyin to n tẹ wa lọwọ ni yajo yajo ti kede pe awọn agbebọn kan ya bo ile ajijagbara fun ilẹ Yoruba, oloye Sunday Adeyemo, ti ọpọ eeyan mọ si Sunday Igboho.
Iroyin naa fikun pe se ni iro ibọn n dun lakọ lakọ niwaju ile Sunday Igboho ni oru mọ̀ju ọjọ Aje, ti gbogbo agbegbe Soka, ti ile ajijagbara naa wa, ko si fara rọ̀ laajin oru.
Nigba to n fi idi isẹlẹ naa mulẹ fun BBC Yoruba, agbẹnusọ fun Igboho lorilẹede Naijiria, Dapo Salami salaye pe deede aago kan oru ni awọn eeyan naa gunlẹ sinu ile naa.
Salami ni awọn alatilẹyin Sunday Igboho to wa ninu ile pẹlu rẹ gbena woju awọn eeyan to wa se ikọlu naa, ti wọn si le wọn danu.
" A ko le sọ iye eeyan to wa loru mọju lati wa kọlu ile Sunday Igboho amọ wọn pọ, ti a ko si tun mọ iru awọn eeyan to fi oru boju wa.
Olugbon of Igbon: ‘Rubber Stamp’ làwọn aṣòfin àpapọ̀, wọn kò ṣojú aráàlú
A ko mọ boya janduku ni wọn tabi ọmọ ologun sugbọn wọn wa pẹlu ọpọ kẹẹgi pẹtiroolu, o si foju han pe wọn wa lati sun ile mọ Igboho lori ni.
Ọpẹlọpẹ awọn ọmọ ẹyin igboho to tako awọn eeyan yii lati sisẹ laabi wọn, ti wọn si fi ẹsẹ fẹ.
Dapọ Salami wa fi ọwọ gbaya pe ko si ohunkohun to se ajijagbara fun ilẹ Yoruba naa, saka ni ara rẹ da.
Iyabo Ojo: Ẹ yé ṣe àwáwí fún bàbá Ijesha torí pé ó jẹ́ gbajúmọ̀, ohun tí kò dáa, kò dáa
Ero awọn osere gbajumọ osere tiata meji lobinrin ti se ọtọọtọ lori isẹlẹ to waye si ọkan lara wọn lọkunrin, James Omiyinka Olanrewaju.
Olanrewaju, ti ọpọ eeyan mọ si baba Ijesha ni ọwọ ọlọpaa tẹ pe o n ba ọmọ ọdun mẹrinla kan lopọ, eyi to ti n se lati igba ti ọmọdebinrin naa wa ni ọmọ ọdun meje.
Ọlọpaa ni lootọ ni osere tiata naa si ti jẹwọ pe bẹẹ ni awọn ẹsun ti wsn fi kan oun ri.
Amọ nigba ti wọn n sọ ero wọn lori isẹlẹ yii ati iha tawọn araalu kọ si, awọn osere tiata meji lobinrin, Iyabo Ojo ati Foluke Daramola ni ero wọn se ọtọọtọ nipa isẹlẹ naa.
Lero ti Iyabo Ojo, o ke si awọn akẹgbẹ rẹ pe ki wọn dẹkun lati maa ṣe awawi fun afurasi naa.
Olugbon of Igbon: ‘Rubber Stamp’ làwọn aṣòfin àpapọ̀, wọn kò ṣojú aráàlú
Ninu fidio kan to fi lede loju opo Instagram rẹ, Iyabo Ojo ni ohun ti ko dara, ko ni orukọ meji to yẹ ka pe e, biko se aidaa.
O ni Mo ti ri oriṣiriṣi awọn akọle kan lori ayelujara, nibi ti awọn eeyan ti n da si ọrọ Baba Ijesha, bi awọn kan ṣe n sọ pe ṣe ni wọn ko ba a, lawọn mii n sọ pe ki a ma tii ṣe idajọ rẹ, ki a duro ki awọn agbofinro ati ile ẹjọ ṣe iṣẹ wọn."""
Imọran mi si awọn akẹgbẹ mi ni pe, ki wọn ma ṣe wa awawi kankan fun Baba Ijesha nitori iru iṣẹlẹ bayii ni awọn eeyan kan fi maa n wu iwa ifipabanilopọ, ti wọn a si mu jẹ nitori ẹni ti ọrọ naa kan jẹ gbajumọ lawujọ.
Gẹgẹ bi Iyabo Ojo ṣe sọ, awọn eeyan maa n wa awawi fun awọn afipabanilopọ ṣugbọn ko si awawi kankan fun ẹnikẹni to ba fi ipa ba eeyan lopọ.
Iyabo to sọrọ pẹlu ibinu sọ pe, afipabanilopọ ko ni orukọ meji bi ko ṣe afipabinilopọ, paapaa ẹni to n ba ọmọ kekere lopọ.
"Bo tilẹ jẹ o ni oun ko ṣe idajọ Baba Ijesha ṣugbọn o ni ""Mo ti gbọ ohun to ṣẹlẹ, o ti n ba ọmọ naa lopọ lati bii lọdun meje sẹyin gẹgẹ bii ọmọ naa ṣe sọ."
"Lẹyin naa ni wọn fiwe pe wa sile wọn, ti wọn si dẹ ọdẹ fun pẹlu ẹrọ ayaworan CCTV, o si ko si pampẹ ti wọn dẹ silẹ fun."""
Iyabo Ojo sọ pe, ko sẹni to tii le sọ ibi ti ọrọ naa yoo yọri si titi di igba ti iwadii yoo pari, ti ile ẹjọ yoo si ṣe idajọ rẹ.
Amọ o ni ki ẹnikẹni maṣe beere pe ki wọn fi fidio bo ṣe ba ọmọ naa ni ibalopọ lede fun gbogbo agbaye lati wo, nitori ko dara fun ọjọ iwaju ọmọ naa.
Oríṣun àwòrán, iyaboojofespris/Instagram
O ni ki ẹnikẹni mase ṣegbe lẹyin Baba Ijesha nitori pe o jẹ gbajumọ oṣere, bẹẹ naa lo ni oun koro oju si iwa ti afurasi naa wu, ki ọwọ palaba rẹ to segi.
Iyabo Ojo ni inu maa n bi oun ti awọn eeyan ba n sọ pe o ṣeeṣe ko jẹ pe akoba lasan ni wọn fi iṣẹlẹ naa ṣe fun Baba Ijesha.
Lẹyin naa lo fi epe banu wi pe oju ẹnikẹni to ba ti Baba Ijesha lẹyin yoo ri irufẹ ohun ti oju ọmọ ọdun mẹrinla ti wọn ni o fi ipa ba lopọ ri.
Gbajumọ oṣere naa ṣalaye pe ko yẹ ki ẹni to ba n ni ibalopọ pẹlu awọn ọjẹwẹwẹ maa gbe laarin ilu pẹlu awọn eeyan mii nitori arun ọpọloọ n ba irufẹ ẹni bẹẹ ja.
Iyabọ Ojo pari ọrọ rẹ pe ẹjọ kii ṣe ti ẹni, ka ma mọọ da, nitori naa ki awọn akẹgbẹ ohun nidi iṣẹ tiata duro de idajọ ile ẹjọ lori ọrọ naa, sugbọn ki wọn dẹkun ati maa ṣegbe lẹyin ohun ti ko tọ.
hhhhhh
Ẹwẹ, oṣere tiata Yoruba miran, Foluke Daramola naa ti sọ erongba tirẹ lori iṣelẹ naa.
Foluke ni lootọ ni oun gbọ nipa iṣẹlẹ naa ṣugbọn ẹgbẹ oṣere tiata ti oun wa ko tii ṣe iwadii tiwọn.
"Gẹgẹ bo ṣe sọ ""Idi ti a ko ṣe tii sọrọ lori iṣẹlẹ naa ni pe ileeṣẹ ọlọpaa ni ẹrọ CCTV ka iṣẹelẹ naa silẹ, ṣugbọn ko si ẹni to tii foju ganni fidio naa ati pe ẹnikẹni ninu ẹgbẹ oṣere tiata ko tii wo."""
A ko tii gbọ lati ẹnu ẹni ti ọrọ naa kan tabi lati ẹni aṣoju rẹ kankan.
Oríṣun àwòrán, folukedaramolasalako/Instagram
Foluke ṣalaye pe nigba ti wọn fi ẹsun gbigbe oogun oloro kan agba oṣere, Baba Suwe lọpọ ọdun sẹyin, ọpọ araalu lo bẹrẹ si n ṣedajọ Baba Suwe lẹyin ti ajọ NDLEA sọ pe o ya idi oogun oloro mẹrindinogun lagọ wọn ṣugbọn ti ko si ẹri kanka  lati fi ẹsun naa lẹyin.
O ni ko yẹ ki ọkankan ninu awọn ọmọ oṣere tiata bẹrẹ si n ṣe idajọ Baba Ijesha nigba ti ile ẹjọ ko tii ṣedajọ tirẹ.
O fi kun pe ọpọ ojuṣe lo wa lori awọn gbajumọ oṣere, nitori naa ki awọn akẹgbẹ oun  ṣe mẹdọ lori iṣẹlẹ naa titi ti awọn agbofinro yoo fi pari iṣẹ wọn.
Foluke pari ọrọ rẹ pe, ọrọ ifipabanilopọ kii ṣe ohun ti eeyan le fi ọwọ yẹpẹrẹmu, lai ro ti irufẹ ẹni ti wọn fi ẹsun naa kan.
Oríṣun àwòrán, folukedaramolasalako/Instagram
Lẹyin naa lo gbadura fun gboggbo awọn ti ọrọ naa kan ki Ọlọrun tu wọn ninu, to si sọ pe ki awọn eeyan duro lati ri fọnra bi ọrọ naa ṣe ṣẹlẹ ki wọn to bẹrẹ si n ṣedajọ lọwọ ara wọn.
Bi ẹ ko ba gbagbe, Iyabo Ojo ati Foluke Daramola yii ni awọn kan ti fi ipa ba lopọ ri, iriri naa kii si ṣe eyii to dara gẹgẹ bi wọn ṣe sọ ṣaaju.
Ọsẹ to kọja ni Baba Ijesha ko si gbaga ọlọpaa lori ẹsun ibalopọ ọmọ ọdun mẹrinla, ti wọn si sọ pe o jẹwọ pe lootọ ni ouns ̣e si ẹsun ọhun.
Sunday Igboho: Àwọn èèkàn ọmọ Yorùbá fárígá lórí ìkọlù ìgbà gbogbo sílé ajìjàgbara
Oríṣun àwòrán, sunday_igboho1
Awọn agbaagba nilẹ Yoruba, awọn lọbalọba, to fi mọ awọn ẹgbẹ ọmọ Yoruba, ti bẹrẹ si fesi lori ikọlu si ile ajijagbara fun ilẹ Yoruba, oloye Sunday Adeyemo, ti ọpọ eeyan mọ si Sunday Igboho.
Agbenusọ fun Sunday Igboho, Dapo Salami lo sọ fun BBC Yoruba pe ni oru Ọjọ Aje, ni nkan bii aago kan oru, ni awọn agbebọn wa si ile Sunday Igboho, ti wọn si bẹrẹ si ni yin ibọn.
Salami ni ọpẹlọpẹ awọn eniyan to wa ninu ile Igboho lo dojukọ awọn agbebọn naa, ti wọn si bori wọn.
Amọ, iṣẹlẹ naa ti mu ki awọn ẹgbẹ ọmọ Yoruba ati awọn ọba alaye kesi ijọba lati wa wọrọkọ fi ṣe ada lori ikọlu lemọlemọ si ile Sunday Igboho.
Ẹgbẹ Yoruba Welfare Group ti ni ọmọ ale ilẹ Yoruba ni yoo fi idunnu han si ikọlu ti awọn agbegbọn n ṣe si Sunday Igboho, ni ilu Ibadan ni lemọlemọ.
Oríṣun àwòrán, Yoruba Welfare Group
Alaga ẹgbẹ YWG naa, Comrade Abdulhakeem Adegoke Alawuje lo fi ero ẹgb naa han bẹẹ lasiko to n ba BBC Yoruba sọrọ pẹlu afikun pe ibatan ni Sunday Igboho jẹ si oun gẹgẹ bi ọmọ Yoruba.
Comrade Alawuje ni ijọba ko ni ere kankan nipa ṣiṣe ikọlu si ile Sunday Igboho, nitori naa, ki wọn ṣe iwadii ni ẹkunrẹrẹ nipa awọn to wa ni idi iṣẹlẹ naa.
O ni ilẹ Yoruba kii ṣe ibi ti awọn eniyan ti le ma a digun abẹle si ara wọn.
''Ti ijọba ba ni ẹsun ti wọn fi kan Sunday Igboho, ki wọn tẹlẹ ofin orilẹede Naijiria, kii ṣe ikọlu sii ni oorekoore''
''Bakan naa, ti a ba ri ọmọ ale Yoruba to n gba abọde fun Sunday Igboho, o ku ẹni naa ati ẹlẹda rẹ.''
Sunday Igboho fulani ultimatum: Àwọn ará Kebbi àti Zamfara ló n jínígbé ní Oke Ogun- Serik
''Nitori ojulowo ọmọ Naijiria gbọdọ ṣe atilẹyin fun Sunday Igboho, nitori awọn ni oun ja fun un.''
Ẹgbẹ Yoruba Welfare Group naa ni ijọba ko ba ri iwadii naa ṣe ni kulẹkulẹ, awọn alalẹ ilẹ Yoruba ni yoo ṣe idajọ awọn to n ṣekọlu si Sunday Igboho.
Kii ṣe Sunday Igboho nikan ni wọn n ṣe ikọlu si, gbogbo ọmọ Naijiria ni - Ọkẹrẹ Saki
Ọkẹrẹ tilu Shaki ni agbegbe Okeogun, nipinlẹ Oyo, Oba Khalid Olabisi Oyeniyi ti ni eto aabo to mẹhẹ lorilẹede Naijiria lo fa ikọlu lemọlemọ si ile Sunday Igboho.
Ọba Oyeniyi ni ko si ọkan ẹnikẹni to balẹ mọ ni Naijiria, nitori ikọlu ati ijinigbe to gbode kan ni Naijiria.
Oríṣun àwòrán, H.R.M Oba Khalid Olabisi the Okere of Saki Land
Kabiyesi to n rin irinajo lọwọ ni, n ṣe ni ẹmi oun gbe soke, ti ko si le e sinmi bayii titi oun yoo fi de ibi ti oun n lọ.
O ni o ba ni lọkan jẹ nitori wi pe ko si ẹni to lero wi pe iru iṣẹlẹ bayii le ma a waye ni Naijiria.
Ọkẹrẹ wa parọwa si ijọba lati kesi Ajọ Isọkan agbaye lati wa ran wọn lọwọ lori eto aabo to dẹnukọlẹ tan ni Naijiria, nitori agbara ijọba orilẹede yii ko ka ohun to wa ni ilẹ mọ.
Ti eto aabo ba ti mẹhẹ, ko si nkan ti ko le ṣẹlẹ - Ọba Onilala
Onilala tilu Lanlate, Oba Sunday Oladejo, ni o ṣeni laanu wi pe wọn tun lọ ṣekọlu si ile Sunday Igboho.
Amọ, Kabiyesi Oladejo ni awọn lọbalọba ko i tii le sọ pupọ lori iṣẹlẹ naa nitori iwadii ṣi n lọ lọwọ lori iṣẹlẹ ọhun.
Oríṣun àwòrán, Ọba Sunday Oladejo, Onilala of Lanlate
Ọba Oladejọ ni eto aabo, paapaa ni ipinlẹ Oyo ti dẹnukọlẹ patapata, ti apa ijọba ko si ka a mọ.
O ni iru iṣẹlẹ to waye si Sunday Igboho ko ni ye ma a waye, nitori ti eto aabo ko ba ti gbe pẹẹli soke, oriṣiriṣi nkan ni yoo ma a ṣẹlẹ.
Iru ejo lẹ n fa lọwọ pẹlu ikọlu lemọlemọ si Sunday Igboho- Ẹgbẹ Ilana Ọmọ Odua
Akọwe Ẹgbẹ Ilana Ọmọ Odua, Opeoluwa George Akinola ti bu ẹnu atẹ lu ikọlu ti awọn agbebọn kan ṣe si Sunday Igboho.
Opeoluwa George Akinola ni Sunday Igboho ko ṣe ibi kankan si ẹnikẹni, bẹẹ si ni ko ba ti eniyan jẹ.
O ni ilẹ Yoruba ati ominira awọn ọmọ Oodua ni Sunday Igboho n ja fun.
Oríṣun àwòrán, Facebook
Bakan naa ni o beere ni ọwọ ijọba wi pe, ki ni wọn n dun koko mọ Sunday Igboho si, ati wi pe ki ni wọn wa a fun?
O fikun wi pe awọn to n ṣekọlu si Sunday Igboho n fa ejo lẹsẹ ni o, ti wọn ko ba fẹ ri wahala ati rogbodiyan.
Channels TV: SERAP ní òun yóò wọ́ NBC relé ẹjọ́ torí pàṣán tó fi na iléeṣẹ́ ìròyìn
Oríṣun àwòrán, Channels TV
Ẹgbẹ awọn olootu iwe iroyin ni Naijiria, NGE, ẹgbẹ ajafẹtọọmọniyan, SERAP ati ẹgbẹ oṣelu PDP ti bu ẹnu atẹ lu ileeṣẹ to n ri si eto igbohunsafẹfẹ ni Naijiria, NBC, lẹyin to fofin de ileeṣẹ Iroyin Channels.
NGE sọ pe awọn ko fọwọ si bi NBC ṣe n dunkoko mọ ileeṣẹ tẹlifiṣan Channels lẹyin to ṣe ifọrọwerọ pẹlu agbẹnusọ ẹgbẹ IPOB, iyẹn ọgbẹni Emmanuel Powerful lọjọ Aiku.
"Eto naa to waye lori ẹrọ ibaraẹnisọrọ lori amohunmaworan Channels ko dun mọ ijọba ninu tori awọn ọrọ kan ti alejo naa sọ lori eto ""Politics Today."""
Eyi si lo mu ki ileesẹ NBC fi iwe ranṣẹ si ileeṣẹ tẹlifiṣan naa, to si ni ki wọn da eto naa duro fun igba diẹ.
Oríṣun àwòrán, nbcgovng
Ninu atẹjade kan to fi ṣọwọ si awọn akọroyin, ẹgbẹ NGE sọ pe awọn ileeṣẹ iroyin ko ni le ṣe iṣẹ wọn bi iṣẹ, ti ijọba to wa lode ba n dunkoko mọ wọn.
Ẹgbẹ naa ni digbi ni awọn wa lẹyin Channels bi ike, awọn ko si ni gba ki ijọba to wa lode yii gbin ẹru si ọkan awọn ileeṣẹ iroyin ni Naijiria.
Lẹyin naa lo ṣalaye pe, ijọba to wa lode yii n se oju ṣaaju nitori ko na awọn ileeṣẹ iroyin kan to gbe iroyin nipa ifọrọwerọ ati ipade ẹlẹsin Musulumi, Sheikh Gumi pẹlu awọn  janduku to n da alaafia Naijiria ru ni paṣan.
Olugbon of Igbon: ‘Rubber Stamp’ làwọn aṣòfin àpapọ̀, wọn kò ṣojú aráàlú
Ni ti SERAP, wọn ni ki ijọba apapọ ati NBC yi ipinnu wọn pada lori igbesẹ ti wọn gbe lati fi iya jẹ ileeṣẹ iroyin Channels, ati owo itanran miliọnu marun un naira ti wọn ni ki ileeṣẹ naa san.
"Ninu atẹjade kan ti adari rẹ, Kolawole Oluwadare buwọlu, SERAP ni ""Idaduro ileeṣẹ iroyin Channels lodi si ofin, ko si lẹsẹ nilẹ."
"A fẹ ki ijọba ati NBC pa igbesẹ naa da ni kankan, bi bẹẹ kọ a o lọ sile ẹjọ lẹyin wakati mejidinlaadọta."""
O ni igbesẹ yii n ṣafihan pe, ijọba to wa lode ko fẹ ki awọn ileeṣẹ iroyin ṣe iṣẹ wọn gẹgẹ bii ofin ṣe gba wọn laaye.
Akomolede ati Aṣa: Kọ́ ẹ̀kọ́ si nípa ààlọ́ nílẹ̀ Yorùbá
Ẹwẹ, ẹgbẹ oṣelu PDP ti juwe igbesẹ ti ajọ NBC gbe lori ileeṣẹ iroyin Channels gẹgẹ bii eyii to bani lọkan jẹ.
"PDP sọ ninu atẹjade kan pe ""Igbesẹ yii jẹ eyii to le da kun wahala to wa nilẹ ni Naijiria, paapaa lasiko ti a wa yii, nitori naa a rọ ijọba lati tun ọrọ naa gbe yẹwo."""
Lori eto ileesẹ Channels ni agbẹnusọ fun ẹgbẹ IPOB ti ijọba ti fofin de, fẹsun kan ileeṣẹ ologun pe wọn pa ọkan lara awọn adari ẹgbẹ ọhun lọna aitọ loju ọna abule rẹ, ti wọn si parọ fun awọn araalu bi ọrọ iku ọhun ṣe jẹ.
Igbesẹ ileeṣẹ naa, paapaa ọrọ ti Emmanuel Powerful sọ lori eto naa, si ni ko dun mọ ijọba apapọ ninu.
Ọpọ awọn ọmọ Naijiria lo ti bẹrẹ fi n fi erongba wọn lede lori bi NBC ṣe na ileeṣẹ iroyin naa ni paṣan, lẹyin ifọrọwerọ ọhun.
Oríṣun àwòrán, Punch Newspapers
Ariwo yago fadugbo Iyana Iba ati Volks lo gba ori Twitter kan lọsan ọjọ Aje.
Eyi ko si sẹyin wahala to bẹ silẹ laarin awọn ọmọ ẹgbẹ ọlọkọ ero NURTW ati awọn ọlọkada lagbegbe Iyana Iba.
Gẹgẹ bi iroyin ta gbọ, ija yii ko sẹyin bi awọn ọmọ ẹgbẹ ọlọkọ ṣe fẹ ja iwe fawọn ọlọkada kan ni agbegbe iyana Iba ni Ojoo.
O soju mi koro kan ti o pe rorukọ ara rẹ ni Ibrahim sọ fun akọroyin pe nkan bi ago mẹjọ aarọ ni wahala yii ti bẹrẹ.
''Ikọlu laarin awọn ọmọ ẹgbẹ NURTW ati awọn ọlọkada lo da ki ni yii silẹ. O ti tan de Alkaba Rago to fi mọ ibudo iwọkọ Volks''
Akure okada attack: Ọlọ́kadà tí àwọn afunrasí darandaran ṣá ní
O ṣalaye pe awọn eeyan to wa nibẹ n sa asala fẹmi ara wọn nigba ti awọn ọlọkada naa doju ija kọ awọn ẹgbẹ NURTW .
Loju opo Twitter, n ṣe ni orisirisi fọnran fidio gbode nibi tawọn eeyan ti n sare asala kuro nibi wahala naa.
Ninu awọn fidio naa si ni wn ti ni ẹmi kan ti bọ sinu wahala naa.
Ekiti Election: Ẹgbẹ́ awakọ̀ Ekiti pa ìjọba dà lẹ́yìn tí wọ́n kéde Fayẹmi
Ninu ọrọ rẹ, alukoro ọlọpaa nipinlẹ Eko, Muyiwa Adejobi ni alaafia ti pada si agbegbe naa lẹyin rogbodiyan ọhun.
O ni awọn agbofinro ti wa nibẹ ṣugbọn ija to waye ko ni se pẹlu ẹlẹyamẹya rara gẹgẹ bi awọn eeyan kan se n gbe ahesọ ọrọ yii kiri.
O ni ki araalu maṣe jaya ati pe laipẹ awọn yoo sọrọ lẹkunrẹrẹ nipa ohun to waye, eyi to bi laasigbo naa.
Alaafin: Àwọn ẹlẹ́yinjú àánú ń kówó jọ fún olorì Alaafin Oyo, Damilola láti fi gba ilé
Oríṣun àwòrán, officialqueen_dami
O dabi ẹni pe asiko yii ko dara lori bi Olori Damilola se kuro ni aafin Oyo, ti ara ko si rọ okun fun.
Gẹgẹ bi iroyin to n ja lori ayelujara, a gbọ pe Olori Damilola ti lọ ba ọrẹ rẹ kan pe ko saanu oun nitori apo oun gbẹ.
Lọwọlọwọ bayii, a gbọ pe ilu Eko ni Olori Damilola sa wa, ti wọn si ti n se eto ikowojọ fun lati ri pe o ri nnkan dimu.
Koda, se ni wọn fi ọrọ ti Olori Damilola sọ nipa ipo inira to n la kọja naa soju opo ayelujara nibi ti iya rẹ gan ti n sọkun.
Bakan naa ni wọn tun fi atẹjisẹ ti Damilola fi ransẹ si ọrẹ rẹ naa sori ayelujara nibi to ti n sọ fun onitọun pe oun sẹsẹ gunlẹ silu Eko ni.
Damilola ni ko si ibi kankan ti oun fẹ sun ni alẹ ọjọ naa, ti oun si nilo lati fi ori ha ibi kan di ọjọ keji.
Oríṣun àwòrán, Gistlovers
O ni Kabiyesi sọ fun oun pe ki oun kuro ni aafin nitori oun ko fẹ ri oun, to si ni ki wọn ti ilegbe mi.
Aanu Olori naa si lo se awọn eeyan to ka iroyin naa, ti wọn si n da owo jọ fun Olori Damilola, ki aye le tubọ rọrun fun nilu Eko.
Ni idaji oni ti wọn gbe iroyin naa sita, owo ti wọn n da jọ fun Olori Damilola ti le ni ẹgbẹrun lọna ẹgbẹrin naira (₦857,000)
Bẹẹ ba gbagbe, saaju la ti mu iroyin wa fun yin pe Olori Damilola ti kuro ni aafin Oyo nitori ọrẹ rẹ kan to gba sile nigba ti onitọun ni isoro.
Oríṣun àwòrán, Gistlover
Amọ lẹyin o rẹyin, ọrẹ yii ti di aayo Alaafin, ti Olori Damilola si faake kọri pe obinrin naa, to pe orukọ rẹ ni Abebi, ko le ba oun se orogun.
Idi si niyi to se ni wọn le oun jade ni aafin Oyo ni aajin oru, to si sa lọ silu Eko lati lọ bẹrẹ igbe aye tuntun.
Oríṣun àwòrán, officialqueen_dami/nstagram
Saaju la ti fi to yin leti pe iroyin to gba ori ayelujara kan ti salaye bi Olori Damilola se ko jade ni aafin Oyo.
Gẹgẹ bi ọrẹ Olori Damilola kan ti salaye lori ayelujara, olo ẹlẹjẹ tutu kan tii se ọrẹ fun Olori naa, ni baba ṣẹṣẹ ri lati fi se ayaba.
Ẹyin naa ni boo lo ṣe jẹ? Ẹ jẹ ki a bu yin gbọ bo ṣe jẹ gẹgẹ bi itakurọsọ to waye laarin olori Damilọla ati ọrẹ rẹ, eyi to n bẹ lori gbajugba oju opo ayelujara Instagram kan.
Ọrọ naa la gbọ pe o bẹrẹ nigba ti ọmọbinrin kan ti wọn ni olori Damilọla pe orukọ rẹ ni Abẹbi lati ilu Ibadan, kan si olori Damilọla pe iṣẹ n ṣẹ oun, oun si nilo iranlọwọ ayaba naa, ki jijẹ ati mimu lee di irọrun.
Oríṣun àwòrán, officialqueen_dami/nstagram
Ohun ti a gbọ ni pe olori Damilọla gba, o si pe Abẹbi yii lati wa maa baa da si owo aṣọ adirẹ to n ṣe.
Lẹyin eyi ni a gbọ pe ọwọ kan ọwọ, ẹsẹ kan ẹsẹ laarin Kabiyesi alaafin ati Abebi Ibadan, lo ba fi eyi ti Alaafin Ọyọ ati Abebi Ibadan jumọ di wọlewọde, titi ti o fi di aayo baba.
Igba ti wọn ni Kabiyesi n gbero ati kuku wa gbe Abẹbi ọrẹ olori Damilọla niṣulọka, ni olori Damilọla ba fariga pe Kabiyesi ko lee maa gun ori oun, ko tun maa gun ori ọrẹ oun.
Itan Ilu gangan
Eyi, gẹgẹ bi oju opo ikansira ẹni Instagram ti Olori Damilọla ba sọrọ ṣe sọ, lo faa ti Kabiyesi Alaafin fi ni ki Olori Damilọla maa lọ kuro laafin.
Lasiko ti iroyin yii fi n jade, aafin ọyọ ko tii sọ ohunkohun lori iṣẹlẹ yii.
Ni odun meji sẹyin ni Olori Damilọla di ayaba laafin Oyo.
Gẹgẹ bi a ṣe gbọ, wọn ti le iya olori Damilọla at'awọn mọlẹbi rẹ kuro laafin Ọyọ.
Ogbomoso: Ẹbọ ọkùnrin àti obìnrin tí kò ní ìbálòpọ̀ rí ni wọ́n rú dènà ogun Fulani
Koda gẹgẹ bi ọrọ inu atẹranṣẹ ti Olori Damilọla fi ranṣẹ to fi ke gbajare sita, o ni ọkan lara awọn iransẹ kabiyesi ni wọn ran pe ko da ẹru oun sita.
Oríṣun àwòrán, officialqueendamifanpage/Instagram
Iroyin to n lọ nigboro bayii, ta ni ka gbe si yin leti ni pe Olori Damilola, tii se ọkan lara awọn 'Ẹlẹ Daddy', Oxygen ti Alaafin ìlú Ọyọ, Ọba Lamidi Olayiwola Adeyemi Kẹta fi n mi, tun ti kuro ni aafin.
Bẹẹ ni oniruuru awọn ileesẹ iroyin ori ayelujara lo ti n gbe iroyin sita lati alẹ ọjọ Aiku pe olori Damilọla naa ti fi aafin silẹ.
Igba akọkọ si kọ re e ti iroyin yoo sọ pe Damilọla ti kuro ni aafin.
Ẹ o ranti pe lasiko ti iroyin jade ni ọdun 2020 pe Olori Aanu kuro ni aafin, naa la gbọ pe Damilọla naa tẹlẹ. sugbọn wọn ni o sa pada si aafin.
Iroyin ti ẹ sọ lasiko naa pe aarin oru ni awọn mejeeji fi aafin silẹ.
Sugbọn ni asiko yii, a ko ti i mọ nkan to ṣe e ṣe ko le Olori Damilọla kuro ni aafin, tabi asiko to kuro, tabi ibi to lọ.
Iroyin pe Olori Damilọla ti ko jade kuro ni aafin si lo jade sori ayelujara lẹyin ọjọ diẹ ti Ọba Adeyemi kọ ilé awosifila fun meji lara awọn olori rẹ.
Awọn olori to gba ẹbun ile naa ni Ayaba Memunat ati Folashade, to pe ni Aafin Suuru, ‚Palace of Patience'.
Alaafin: Olori Aanu Adeyemi ṣàlàyé ìdí tó ṣe gẹ́ Oba Lamidi Adeyemi ti ìlú Oyo
Ṣe o wa a ṣe e ṣe ko jẹ igbesẹ ti Alaafin gbé lo mu Damilola kuro ni aafin?A ko le sọ amọ nigba to ba ya, gbogbo rẹ yoo fi oju han sita fun araye.
Sugbọn iwadii wa fihan pe, ko si aworan Ọba Adeyemi kankan mọ ni oju opo ibanidọrẹ Instagram Olori Damilola, kikida aworan oun ati ọmọ rẹ nikan si lo wa nibẹ.
Ta ba si wo ohun to ti sẹlẹ lati ẹyin wa, lasiko ti awọn olori to saaju ko kuro ni aafin, se ni wọn n yọ fọto ti wọn ya pẹlu Alaafin kuro loju opo ayelujara wọn.
Bakan naa la tun ri pe Olori Damilola ko wọ ilẹkẹ si ọrun ati ọwọ gẹgẹ bo se maa n wọ ọ tẹlẹ bii ayaba.
Akomolede ati Aṣa: Kọ́ ẹ̀kọ́ si nípa ààlọ́ nílẹ̀ Yorùbá
Olori Damilọla ni ayaba to kere ju ni aafin ìlú Ọyọ, ki iroyin tun to gbe ni oṣu diẹ sẹyin pe, Iku Baba Yeye, Alasẹ ikeji Orisa tun ti fẹ òló ẹlẹ́jẹ tutu mii lati ilẹ Igbo.
Chioma ni wọn pe orukọ ayaba tuntun naa.
Iwadii wa si fihan pe, gbogbo àwọn olori Alaafin to n lo ayelujara Instagram, ni Chioma n ba dọọrẹ papọ, to si ma n kọ ọrọ si abẹ àwọn aworan tabi fidio ti wọn ba fi sibẹ.
hhhhhh
Tẹ o ba gbagbe, ọdun to kọja ni meji lara awọn olori ni aafin Oyo, Ayaba Badirat Ajoke ati Aanu, kuro ni aafin laarin oṣu diẹ si ara wọn.
Iroyin sọ nigba naa pe, Badirat ni ajọsepọ pẹlu gbajugbaja olorin Fuji, Wasiu Ayinde K1, ni wọn fi le e kuro ni aafin, ti Olori Badra si sẹ lori ẹsun naa.
Ni ti Aanu, a ko mọ pato nnkan to le kuro ni aafin Iku Baba Yeye.
Bẹẹ ba gbagbe, nigba ti awọn olori mejeeji kọkọ ko kuro ni aafin Oyo, ere ni, awada ni, irọ ni, kii se ootọ, ni awọn eeyan n sọ.
aaaaaaaaaaaaaaa
Bẹẹ si ni atẹjade kankan ko si jade sita lati aafin Oyo nipa isẹlẹ naa fun awọn akọroyin, kii ootọ ọrọ to pada fidi mulẹ pe awọn Olori naa ti rin jinna si aafin Oyo lootọ.
Olori Aanu lo si fi ẹsun kan Alaafin loju opo Instagram rẹ pe oriade naa n lepa ẹ̀mí oun nitori pe oun sá kuro ni aafin, eyi to fidi ọrọ mulẹ pe o ti kọ Alaafin silẹ.
Igba yii si lo to ye gbogbo eeyan pe lootọ ni Olori Aanu naa ti ko kuro ni Aafin Oyo.
Olugbon of Igbon: ‘Rubber Stamp’ làwọn aṣòfin àpapọ̀, wọn kò ṣojú aráàlú
Nibayii, okoowo aṣọ ni olori Badirat ati Aanu n ṣe nilu Eko bayii, to si ti fidi mulẹ pe wọn ti di ayaba ana ni aafin Oyo.
Yoruba ni ti ko ba si ina, eefin ko le ru sita, bi ootọ wa ni ayaba Damilola naa ti kuro ni aafin abi irọ ni, laipẹ, laijinna, ẹri yoo jade.
US Consulate: Ojú lálákàn fí n ṣọ́ri l‘Eko báyìí, wo ìlànà tó tẹ̀lé fún ààbò ẹ̀mí rẹ
Ilé iṣẹ́ asoju ilẹ́ Amẹrika ni Nàìjíríà ti gbé atẹjáde kan sita lori bó ṣe yẹ kí àwọn ènìyàn máa rìn ní ìlú Eko, kí wọ́n má bá bọ́ sọ́wọ́ àwọn ọdaran.
Nínú àtẹjáde náà ni ilé iṣẹ́ ilẹ̀ Amerika ti ni àwọn ti gbúro àwọn ìgárá ọlọ́sà nípìnlẹ̀ Eko pàápàá jùlọ ni agbegbe Ikoyi àti Victorial Island, ti wọn ti n se ọsẹ julọ.
Bakan naa lo fikun pe ọwọ ti iwa idigunjale ati alọnilọwọgba se n pelkeke si nilu Eko gba ifura, ti ọpọ awọn onisẹ ibi naa si maa n fọ digi ọkọ lati ja araalu lole ojukoroju.
Atẹjade naa salaye pe se ni awọn ọlọkada maa n yọ tẹle awọn mọto ti wọn ba fẹ ja lole loju popo, titi ti awakọ naa yoo fi duro lasiko ti ina to n dari ọkọ ba ni ko duro, ti wọn yoo si raye ja onitọun lole dukia rẹ.
Ileesẹ asoju ijọba ilẹ Amẹrika ni Naijiria tun tẹsiwaju pe yatọ si pe awọn isẹlẹ idigunjale naa maa n waye ni aaji, loru dudu, amọ sibẹ, ọpọ irufẹ isẹlẹ naa tun waye ni ọsan gangan.
Oríṣun àwòrán, Screenshot
Atjade naa wa rọ awọn araalu, paapaa awọn ajeji lati ilẹ Amẹrika lati maa fi oju sọri nitori awọn isẹlẹ idigunjale ọhun maa n mu ẹmi lọ nigba miran.
Ìlànà ààbò mẹ́wàá tó ṣe kókó fún olùgbé ìlu Eko:
Akomolede ati Aṣa: Kọ́ ẹ̀kọ́ si nípa ààlọ́ nílẹ̀ Yorùbá
Ki lo bọ sodo, ti ko ro tomu? Abẹrẹ ni o.
Eyi jẹ ọkan lara awọn aalọ apamọ to wa nilẹ Yoruba, ti a maa fi n kọ awọn ọmọde ati agba.
Gẹgẹ bi olukọ wa, Nike aya Bankole ti salaye, ọpọlọ ẹni to ba mọ aalọ maa n ji pepe, ti yoo si seranwọ fun ọmọde lati ja fafa.
Bakan naa. Lori eto Akomolede ati Asa lọsẹ yii, olukọ wa tun sọ nipa itan bi aalọ se bẹrẹ, orisi aalọ to wa, itumọ wọn ati ohun ta n lo aalọ fun.
Ẹ wa nnkan fidi le lati kọ ẹkọ siwaju nipa aalọ, kẹ le fi imọ kun imọ yin.
Àwọn ìtàn mánigbàgbé tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí:
Funke Etti: Mo gbádùn ẹ̀sìn Islam nígbà kan rí, ṣùgbọ́n mo ti di ọmọlẹ́yìn Kristi báyìí
Oríṣun àwòrán, iamfunkeetti/nstagram
Gbajugbaja oṣere tiata Yoruba lobinrin, Funke Etti ti ṣalaye bo ṣe pa ẹsin da, lati Musulumi si Kristẹni.
Funke Etti sọ pe oun gba ẹsin Kristẹni ninu ijọ Irapada, RCCG, ni nnkan bii ọdun mejila sẹyin.
Oṣere naa ni, bo tilẹ jẹ pe oun gbadun akoko oun gẹgẹ bii Musulumi ṣugbọn oun yipada di Kristẹni nigba ti akoko to.
"O ni ""Mo wa ni olu ijọ RCCG lọjọ naa lọhun nigba ti olori ijọ naa, pasitọ E.A. Adeboye pari iwaasu rẹ, to si kede pe ki gbogbo awọn to ba fẹ fi aye wọn fun Jesu maa bọ niwaju, mo si ṣe bẹẹ."""
Lẹyin ti mo jade siwaju tan ni mo tọrọ idariji ẹṣẹ mi, ti mo si di atunbi lọwọ kan naa.
hhhhhh
Funke ṣalaye pe ẹlẹsin Musulumi ni baba oun, ti iya oun si jẹ ọmọlẹyin Kristi, ṣugbọn ko si eyikeyi ninu awọn mejeji to fi ipa mu oun lati ṣe ẹsin tirẹ.
O ni oun funra oun loun yan ẹsin ti oun n ṣe lati ilẹ wa.
"O ni ""Nigba ti mo jẹ Musulumi, mo maa n gbadura nigba marun un lojumọ, mo si tun maa n gba aawẹ ni akoko to yẹ, eyii to jẹ ohun ti mo gbadun."""
Femi Adebayo: Ẹyin ọ̀dọ́, ẹ káàbọ̀ ságbo ilé Tíátà
O wa pari ọrọ rẹ pe, ni bayii ti oun ti di ọmọlẹyin Kristi, gbogbo ohun ti awọn Kristẹni n ṣe ni oun naa n ba wọn ṣe.
Baba Ijesha: Iyabo Ojo àti àwọn obìnrin kan ń ṣèwọ́de tako ìtúsílẹ̀ afurasí náà
Gbajumọ osere tiata lobinrin, Iyabo Ojo, ẹni to n gbara ta lori ọrọ Baba Ijesha ati ọmọde ti wọn lo fi tipa ba lopọ, ti mu ileri rẹ sẹ.
Iyabo, to n leri leka ninu fidio kan to se loju opo Instagram rẹ lalẹ Ọjọru, lo ni ohun yoo ba ọrọ ẹsun ti wọn fi kan Baba Ijesha de opin, ti idajọ ododo yoo si wa.
Iyabo, ẹni to ni kede pe awọn eeyan kan n saayan lati yọ baba Ijesha latimọle ọlọpaa lọjọ Ẹti, wa fọwọ gbaya pe oun ko ni gba ki wọn tu afurasi naa silẹ.
Lọna ati mu ileri rẹ sẹ, Iyabo ti wa gba agọ ọlọpaa Panti lọ nilu Eko lati lọ fi ẹhonu rẹ han pe wọn ko gbọdọ tu Baba Ijesha silẹ ni ahamọ.
Iyabo, ẹni to kọwọ rin pẹlu awọn obinrin kan ti ọpọ wọn jẹ osere tiata bakan naa, ni wọ́n n ke fata fata niwaju agọ ọlọpaa naa pe wọn ko gbọdọ tu Baba Ijesha silẹ.
"Ọrọ eyi kii se ọrọ eeyan kan mọ, o ti di ọrọ gbogbo abiyamọ. Ko si ibi ti a n lọ, ibi ti a maa wa ni eleyi.
Gbogbo wa la bimọ, bawo ni agbalagba ọkunrin yoo se maa ba ọmọkekere lopọ, a ni gba. Ta lo fẹ́ fi silẹ, nibo lo fẹ wọ, gbogbo wa la bimọ."
Titi di akoko ta n ko iroyin yii jọ, Iyabo ati awọn akẹẹgbẹ rẹ naa si wa niwaju agọ ọlọpaa Panti nilu Eko nibi ti wọn ti n fi ẹhonu han.
Oríṣun àwòrán, legemiami/Instagram
Yoruba ni ti ọrọ ba se n pẹ nilẹ, naa ni yoo maa gbọn si.
Bẹẹ ni ọrọ ẹsun ifipa ba ọmọde lopọ ti wọn fi kan gbajumọ osere tiata kan, James Olanrewaju Omiyinka, ti ọpọ eeyan mọ si Baba Ijesha ri.
Idi ni pe oniruuru ọrọ lo ti n jẹyọ lẹyin ti iroyin naa jade sita, tawọn akẹẹgbẹ rẹ ninu isẹ tiata atawọn araalu si ti n sọ oniruuru ero wọn nipa isẹlẹ naa.
Lara wọn ni gbajumọ osere tiata lọkunrin kan, ti gbogbo eeyan mọ si Legemiami, to sọrọ nipa ẹsun ti wọn fi kan Baba Ijesha.
Lege, ẹni to fi ọrọ naa sita loju opo Instagram rẹ lasiko ti iroyin jade nipa rẹ ni ko dara bi awọn eeyan kan se n da baba Ijesha lẹbi lori ẹsun naa saaju idajọ ileẹjọ.
Lege ni lootọ ni wọn fi ẹsun kan gbajumọ osere naa pe o fipa ba ọmọde lopọ, amọ wọn ko se afihan fidio bi Baba Ijesha ti n hu iwa ibajẹ naa.
Oríṣun àwòrán, legemiami/Instagram
"Se ile kanna abi adugbo kanna ni wọn jọ n gbe ni, lo se rọrun fun lati ba ọmọ naa lopọ lati ọmọ ọdun meje, ko ye mi.
Awọn akẹẹgbẹ mi kan ti n jade, ti wọn si n sọrọ nipa isẹlẹ naa eyi to n fun awọn eeyan kan lọrọ sọ, ti wọn si n sọrọ buruku nipa agbo isẹ tiata Nollywood, ẹka ti Yoruba.
To ba jẹ pe bẹẹ ni, ika to ba sẹ ni ọba n ge, bi o tilẹ jẹ pe oun ko se atilẹyin fun ohun ti baba Ijesha se."
Legemaimi wa n beere pe ki ni awọn osere fiimu Yoruba se fun awọn eeyan to n bu awọn osere tiata lede Yoruba, se awọn lo sẹ wọn ni?
O ni ko si idaniloju pe Baba Ijesha hu iwa naa, yoo si dara ki wọn ni suuru ki ileẹjọ dajọ naa, ki wọn to maa tanuku awọn osere.
Osere tiata naa wa jẹjẹ pe awokọse rere ni oun maa jẹ fawọn ololufẹ oun, oun ko si le fara mọ iwa ifipa banilopọ.
Amọ awọn ọrọ to Legemiami sọ yii ti bọ si apo ibinu awọn eeyan kan, ti wọn si ti bọ sori ayelujara lati maa naka aleebu si osere tiata naa.
Ọpọ awọn obinrin si lo n naka aleebu si pe ọwọ oun gan ko mọ nipa iru ẹsun ti wọn fi kan Baba Ijesha, nitori naa lo se n gbe lẹyin rẹ.
Awọn miran kan tiẹ tun fi ẹsun gbajuẹ kan, eyi tawọn ileesẹ iroyin ayelujara kan n gbe soju opo wọn.
hhhhhh
Koda, oju opo ayelujara ti kun nipa orisirisi iroyin nipa awọn osere tiata kan lede Yoruba, ti wọn n naka aleebu si pe wọn n hu iru iwa ti baba Ijesha hu, eyi ti awa ko ni darukọ wọn.
Awọn ẹsun naa pọ to bẹẹ gẹẹ ti osere tiata yii fi tun bọ sori ayelujara lati maa bẹ awọn obinrin pe ki wọn tu eekanna lẹyin ọrun oun.
Legemiami ni kawọn obinrin to n pa irọ mọ oun nitori ero ohun nipa ọrọ baba Ijesha jọọ dari jin oun, oun ko ni se bẹẹ mọ.
"O ni ""Nibi ta ba de yii, o daa bayii, mo bẹ ẹyin obinrin patapata pe ki ẹ dari jin mi, n ko ni se bẹẹ mọ."
N ko fara mọ nnkan ti ko dara, mo kan ni ọrọ naa ko ri bẹẹ ni amọ ẹ dari jin mi.
"Nnkan ti n ko se ni wọn ti fi n kan mi bayii, ẹ dakun ẹ dari jin mi. Ẹ ko ni ri ibi, ẹ ko ni sofo tabi sunkun ọmọ"""
Ọrọ wa di ibẹru obinrin ni ipilẹsẹ ọgbọn fun Legemiami, to si n rawọ rasẹ si gbogbo obinrin pe ki wọn fori jin oun.
Ramadan: Àwọn tí kìí ṣe Mùsùlùmí sọ àǹfààní tí wọ́n n jẹ látara awẹ gbígbà
Pe aawẹ Ramadan n lọ lọwọ kii ṣe iroyin tuntun, sugbọn nkan kan to jẹ iyalẹnu ni pe awọn eeyan kan ti kii ṣe ẹlẹ́sìn Musulumi naa n gba awẹ naa.
Eyi gan-an lo difa fun awọn kan ti kii ṣe ẹlẹ́sìn Musulumi lorilẹ-ede Sri Lanka, àmọ́ ti wọn n gba awẹ Ramadan nitori oore to n ṣe fun wọn.
Ẹsin Buddha lo gbajumọ julọ ni Sri Lanka, lẹyin naa ni ẹsin Katoliiki ati Musilimu.
Nitori naa lo ṣe jẹ iyalẹnu nigba ti ọdọmọkunrin oloṣelu kan lorilẹ-ede naa, kede pe oun n gba awẹ Ramadan.
Rehan Jayawickreme ko jẹun ọ̀sán lati ọjọ kẹrinla, oṣu Kẹrin ti Ramadan ti bẹrẹ, bẹ́ẹ̀ si ni ko mu.
What causes coronavirus: Akeugbagold sọ àṣírí ohun ti àrùn coronavirus ń dá lárá f
Nkan miran to tun jẹ ki igbesẹ rẹ jẹ iyalẹnu ni pe, ọpọlọpọ eeyan ni kii fi oju're wo àwọn musulumi ni Sri Lanka.
Eyi ko sẹyin bi awọn alakatakiti ẹṣin islam ṣe kọlu àwọn sọọsi lasiko ọdún Ajinde lọdun meji sẹyin.
Ikọlu naa mu ẹ̀mí eeyan lọ, ti awọn kan si tun farapa.
Yatọ si eyi, ọjọ gan-an ti awọn eeyan Sinhala ati Tamil n ṣe ayẹyẹ ibẹrẹ ọdun tuntun, naa ni Ramadan maa n bẹrẹ.
RAMADAN: Onímọ̀ ẹ̀sin sọ nípa isẹ́ láádá àti làádà
Rehan Jayawickreme sọ pe oun gba awẹ naa lati ṣe atilẹyin fun awọn musulumi nitori bi awọn eeyan ṣe n dẹyẹ si wọn nitori ikọlu to waye ọhun.
Jayawickreme nikan kọ ni ẹlẹ́sìn miran to n gba awẹ Ramadan ni Sri Lanka.
Marianne David, akọroyin kan to n gbe ni olu ilu Sri Lanka, Colombo sọ pe, oun naa ma n gba awẹ Ramadan.
Ramadan:ọmọ ọdún mẹ́wàá sọ ìrírí rẹ̀ pẹlú Àwẹ̀
O ni awẹ naa ma n fun oun ni ifọkanbalẹ, aanu, alaafia ati ìmọ̀, to si tun ma n kọ ni ẹkọ nípa ìtọrẹ aanu, paapaa fun awọn ti ebi ń pa.
Ọpọlọpọ eeyan si lo ti n bu ẹnu ẹtẹ lu Jayawickreme pé, nitori ìbò lo ṣe n ṣe iṣe musulumi.
Àmọ́, oun naa dahun pe, kii ṣe pe oun fẹ di ẹlẹ́sìn Islam. O ni oun n ṣe nitori pe oun korira idẹyẹsi.
Nadyne Parr to jẹ Kristẹni lati ilẹ America paapa sọ pe oun kii fi Ramadan ṣeré.
Ogbomoso: Ẹbọ ọkùnrin àti obìnrin tí kò ní ìbálòpọ̀ rí ni wọ́n rú dènà ogun Fulani
Ilu Michigan ni Parr ti n sisẹ olukọ ati Onkọwe.
O ni ifọwọsowọpọ ti Ramadan maa n fi si aarin oriṣiriṣi ẹ̀sìn ati àṣà, lo jẹ iwuri fun oun.
Ati pe asiko naa ma n mu oun sunmọ Ọlọ́run si.
Oluwo: Kí làwọn obìnrin ń wá kiri, tí wọn ń sanwó láti fẹ́ ọkùnrin
Oríṣun àwòrán, oluwo
Oluwo ti ilu Iwo, Ọba Abdulrasheed Adewale Akanbi, Ilufemiloye Telu 1, ti kilọ fun awọn obinrin lori ẹrọ ayelujara lati ṣọra fun awọn ayederu eniyan ti wọn n fi orukọ rẹ gba owo lọwọ awọn obinrin.
Eyi ko ṣẹyin ẹsun ti Oluwo fi kan awọn obinrin kan to n wa si aafin, lati wa fi ẹjọ awọn gbajuẹ ti wọn n lu wọn ni jibiti lori oju opo Facebook sun.
Oluwo ni lori Facebook ni wọn ti n lu awọn obinrin naa ni jibiti owo, ti oun ko si si lori Facebook, yatọ si oju opo Instagram.
Kabiyesi ni awọn gbajuẹ naa  ṣi 'personal page' lori Facebook ti wọn ti n lu awọn obinrin yii ni jibiti, pẹlu ileri pe Oluwo yoo fi wọn ṣe aya.
Oluwo Divorce: ko si ẹni ti kò mọ pé ọmọ ilẹ̀ òkèrè ni mó fi ṣe aya
''Emi o wa iyawo o, mo ni ẹni ti mo n fẹ, obinrin to ba n wa ọkọ, ko wa lọ si iwaju
Awọn ti wọn n wa si aafin n sọ wi pe wọn n gba owo ọti ni ọwọ awọn lati fi ṣe etutu lati fi fẹ wọn.
A kii ṣe etutu ni ilu Iwo, a ki n bọ orisa ni aafin ti wa, nitori naa irọ lasan ni''
Oluwo ti ilu Iwọ ni obinrin to wa si aafin ni wọn gba 17,500 Naira ni ọwọ oun, wi pe wọn fẹ fi ra ọti lati fi ṣe etutu.
''Ki ni awọn obinrin yii n wa kiri, ti wọn n san owo lati fi fẹ ọkunrin.
Ikorodu cult crisis:A máa gbé Orò síta lọ́jọ́kọ́jọ́ tí ìjà ẹgbẹ́ òkùnkùn bá tún ṣẹlẹ̀- Àwọ
Ẹni to ba n wa ọkọ, ko wa si aafin lati wa wo o boya Oluwo ko ni aya, amọ mi o si lori igba mọ, laipẹ ni ma a ṣe afihan ayaba tuntun.
''Mo ti ni iyawo ti temi, ẹni to ni oruka to wa ni ọwọ Oluwo ti gba a, mi o fẹ iyawo ori ayelujara.
''Nitori ọpọ ti n wa si aafin, ọkan ni 92,000 ni oun san nitori oun fẹ fẹ Oluwo, ko si lori atẹ o''
''Nigba wo ni aye di radarada to jẹ wi pe obinrin ni yoo ma a san owo lati fẹ ọkunrin, eleyii ko bojumu rara.''
Budo Ikoko water problem: Ìyàwó wa ti sá lọ kúrò ní Asa nítorí àìsí omi- Alhaji Sunmonu
Bakan naa ni Oluwo ṣeleri wi pe laipẹ laijina, awọn ti wọn ba n ṣe iru rẹ yoo foju wina ofin nitori awọn ti fi ọrọ naa to awọn ọlọpaa leti.
Ti ẹ ko ba gbagbe, laipẹ yii ni wọn fẹsun kan ọba kan ni ipinlẹ Ogun wi pe o lu awọn obinrin ni jibiti lori ayelujara, eleyii to ṣeleri igbeyawo fun wọn.
Oríṣun àwòrán, Facebook/emperortelu1
Oye to kan ara Iwo ni Yoruba a maa sọ, wọn ni bo pẹ boya yoo kan ara Ẹdẹ.
Boya nitori ki iru nkan to ṣẹlẹ si oriade kan nilẹ yi laipẹ, maa ba a ṣẹlẹ si, lo mu ki Oluwo ilu Iwo, Oba Abdulrasheed Adewale Akanbi Telu Kinni, se maa lọgun pe, oun ko wa iyawo.
Ninu atẹjade kan to fi sọwọ sawọn oniroyin ni Oluwo ti lọgun bẹẹ.
Oba Abdulrasheed Akanbi ni pẹlu bi awọn kan se n ko sọwọ gbajuẹ, paapaa bi awọn obinrin to fẹ fẹ oun ṣe n pọ si, oun ni lati sọ faraye pe oun ko wa iyawo rara.
Oluwo ni ẹnikẹni to ba ko sọwọ awọn gbajuẹ yii ṣe bẹẹ fun ori ara rẹ ni, o ni oun kọ loun n kọ ẹnu ifẹ si wọn loju opo ayelujara.
Akomolede ati Aṣa: Kọ́ ẹ̀kọ́ si nípa ààlọ́ nílẹ̀ Yorùbá
''Eti wa ti kun pe awọn gbajuẹ wọnyii ti ṣi oju opo lorukọ Oluwo, ti awọn obinrin ṣi n kopa ninu etutu orisi nitori pe wọn fẹ di Olori''
O tẹsiwaju pe, awọn obilẹjẹ ẹda yii fẹ ba Oluwo lorukọ jẹ ni, nitori naa, oun n fi to araalu leti pe, Oluwo ko ni oju opo kankan lori Facebook yatọ si ti tẹlẹ.
Bakan naa lo kede pe oun ti fi ọrọ naa to ileesẹ ọlọpaa leti.
Olugbon of Igbon: ‘Rubber Stamp’ làwọn aṣòfin àpapọ̀, wọn kò ṣojú aráàlú
O wa kilọ pe ẹnikẹni to ba ko sọwọ awọn gbajuẹ naa ko ni nkankan ṣe pẹlu Oluwo.
Bẹẹ ba gbagbe, ko si Olori kankan lọọdẹ Kabiyesi Oluwo titi di akoko yii, lẹyin ti Olori Channel tii se ayaba kẹru kuro laafin, ni nkan bi ọdun kan sẹyin.
Ogbomoso: Ẹbọ ọkùnrin àti obìnrin tí kò ní ìbálòpọ̀ rí ni wọ́n rú láti dènà ogun Fulani
Yoruba ni agba ko ni tan lorilẹ, bi ọmọde ko ba si ba itan, yoo ba arọba, tii se baba itan
Ọpọ eeyan lo ti n gbọ itan pe ogun ko ja ja ja, ko ko ilu Ogbomoso ri, ti adugbo kan si wa nilu naa, ti wọn n pe ni Ogun o jalu.
Amọ bawo ni ilu Ogbomoso ti see, ti ogun ko fi ri ilu naa ko? Ọna lati wadi okodoro ọrọ lo mu ki BBC Yoruba tẹkọ leti lọ silu naa.
Nibẹ si ni Ọmọọba Olawuyi Oyelayo Itabiyi ti salaye bi olori Fulani, Alfa Alimi se gbinyanju lati ko ogun ja Ogbomoso amọ ti ko ri se.
Ọmọọba Itabiyi ni ẹẹmẹta ni Fulani Alfa Alimi wa si Ogbomoso laye Oba Toyeje Akanni Abaya Oluoyo.
Bakan naa lo tun salaye iru ẹbọ ti wọn ru lati dena ogun Fulani to pa Aarẹ Ọna Kakanfo Afonja nilu Ilorin,  ko mase wọ ilu Ogbomoso.
Àwọn ìtàn mánigbàgbé tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí:
Baba agba naa ni ọkunrin ti ko mọ obinrin ati obinrin ti ko mọ ọkunrin ni wọn fi ru ẹbọ naa.
Ọrọ pọ ti baba Itabiyi ba BBC Yoruba sọ, ẹ maa gbọ ninu fidio yii.
Biafra: Ẹgbẹ́ 52 lókè ọya ní ààbò tó mẹ́hẹ ń kọ olórí pípé ọmọ Nàíjíríà lóminú
Agbarijọpọ ẹgbẹ oke oya mejilelaadọta kan, CNG ti rawọ ẹbẹ si ijọba Naijiria ati ajọ iṣọkan agbaye, lori bi idasilẹ orilẹede Biafra yoo ṣe d'ohun fun awọn ẹya Igbo.
Ẹgbẹ CNG tun na ika alebu si ẹgbẹ ajijagbara idasilẹ orilẹede Biafra, IPOB pe o ti n sọ ara rẹ di ẹgbẹ alakatakiti to n da wahala silẹ, to si tun n doju ogun koju Naijiria, eleyi to ni ko dara to.
Amọ ẹgbẹ naa tun tọka si ileri ati ọrọ aarẹ Mohammadu Buhari gẹgẹ bi ileri ori ahọn ati ihalẹ lasanlasan.
CNG ni ko din ni ọtalelẹẹdẹgbẹrun ati mẹwaa, 970 awọn akẹẹkọ ti awọn ajinigbepawo ti ji gbe lapa oke ọya laarin oṣu kejila ọdun 2020 si oṣu kẹrin ọdun 2021.
Wọn ni ọpọlọpọ awọn akẹkọọ yii lo ṣi wa ni ahamọ awọn ajinigbe yii, ti wọn si ti pa ọpọ ninu wọn.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Agbẹnusọ fun ẹgbẹ CNG naa Abdulazeez Suleiman, ninu atẹjade kan ni ko si igba kan ri ninu itan Naijiria to jẹ pe awọn janduku, ọdaran ati ajinigbe lo gba iṣakoso apa oke ọya bi ti ijọba Buhari yii.
O ni awọn ajọ agbaye gbogbo tun ni lati dìde si bi eto abo lorilẹede Naijiria ṣe ti wa dojuru bayii, bi ẹsẹ telọ.
O fi kun pe paapaajulọ awọn orilẹede bi ilẹ Gẹẹsi ni lati dide, gegebi ajọṣepọ rẹ pẹlu Naijiria, lati rii daju pe ijọba n se ojuse to yẹ lori idaabobo awọn eeyan orilẹede Naijiria.
Ogbomoso: Ẹbọ ọkùnrin àti obìnrin tí kò ní ìbálòpọ̀ rí ni wọ́n rú dènà ogun Fulani
O ni ki awọn orilẹede agbaye mase gbagbe pe bi nnkan ba daru lorilẹede Naijiria, yoo da omi alaafia Afirika naa ru pẹlu.
Smart Adeyemi: Bí àwọn agbebọn ṣe ń pa ọ̀gọ̀ọ̀rọ̀ ọmọ Nàìjíríà ló pa mí lẹ́kún
Oríṣun àwòrán, @SenSmartAdeyemi
Sẹnetọ Smart Adeyẹmi ti ṣalaye pe bi ipaniyan ṣe di tọrọ fọnkale ni Naijiria lọwọlọwọ bayii, eyi to ni o gba omije loju oun lasiko ti oun fi n sọrọ nibi ijoko ile aṣofin agba lọjọ Iṣẹgun.
Sẹnetọ Adeyẹmi to bu omije soju lasiko to n da ṣi ọrọ wahala eto aabo to mẹhẹ ni Naijiria, eyi ti ile gbe yẹwo ni, irufẹ ipaniyan to n waye bayii ni Naijiria ko fẹẹ ni ẹlẹgbẹ, lati igba ti wọn ti tẹẹ do.
Ninu ọrọ to ba BBC News Yoruba sọ, Sẹnetọ Adeyẹmi woye pe laijẹ pe Naijiria n jagun lọwọ, iye ẹmi to n padanu lorilẹede yii kọja eyi ti awọn aṣiwaju gbọdọ mojuto.
Lori itaporogan to waye laarin oun ati akẹgbẹ rẹ, Sẹnetọ Rẹmi Tinubu, lori pe ọrọ rẹ dabi ọrọ alatako, Sẹnetọ Adeyẹmi ni ọrọ to wa nilẹ bayii ti kuro ni ọrọ ẹlẹgbẹjẹgbẹ, ti gbogbo awọn aṣofin si gbọdọ jigiri lori rẹ.
Oríṣun àwòrán, @HQNigerianArmy
O ni oun ko lee sọ san an pe ijọba aarẹ Buhari ti ja araalu kulẹ nitoripe awọn nnkan ti wọn ṣe to dara pẹlu wa.
Sugbọn o ni koko agbekalẹ iṣejọba fun araalu, eyi to jẹ aabo ẹmi ati dukia ni ijọba Buhari ti ja kulẹ, ti o si nilo ki o ji giri wa nnkan ṣe si.
Sẹnetọ Adeyẹmi to nṣe oju ẹkun idibo apapọ iwọ-oorun Kogi (Kogi West) ni lootọ Buhari lee jẹri sii pe oun wa lara awọn aṣofin to n fi igba gbogbo tii lẹyin.
Ogbomoso: Ẹbọ ọkùnrin àti obìnrin tí kò ní ìbálòpọ̀ rí ni wọ́n rú dènà ogun Fulani
Amọ o ni sibẹ, nibi ti hilahilo ọrọ aabo de bayii, awọn aṣiwaju ko gbọdọ fi ọrọ naa ṣe egbo ile nitori iye ẹmi to n ṣofo ni Naijiria bayii pakasọ.
Oríṣun àwòrán, @RemiTinubu
Saaju la ti mu iroyin wa fun yin pe, orukọ Remi Tinubu lo leke tente lori ayelujara lorilẹede Naijiria ni owurọ Ọjọọru, lẹyin ti fidio kan safihan gbolohun ti Remi Tinubu sọ lori eto aabo to mẹhẹ ni Naijiria.
Sẹnetọ to n soju ẹkun idibo Iwọ oorun ipinlẹ Kogi, Smart Adeyemi lo n fi itara sọrọ lori eto aabo to ti dẹnukọlẹ ni Naijiria, o ni ki pe ki aarẹ Buhari o wa nkan ṣe si ni kiakia.
Lasiko ti Adeyemi n sọrọ lọwọ ni Remi Tinubu, to n ṣoju ẹkun aarin gbungun ipinlẹ Eko, nile Igbimọ Aṣofin agba ọhun sọ wi pe, lo n bi akẹẹgbẹ rẹ naa pe se o si wa ninu ẹgbẹ oselu PDP ni?
Bakan naa ni Remi tun n Adeyemi pe se aguntan to da asọ ikooko bora ni? Ọrọ rẹ yii si lo bi ọpọlọpọ ọmọ Naijiria ninu.
Senato Sani Musa lo ke gbare pẹlu aba to gbe sita pe awọn agbesunmọmi Boko Haram ti gbakoso ijọba ibilẹ mẹta ni ipinlẹ Niger, ti wọn si ti gbe asia wọn soke sibẹ lati jẹ olori le awọn eniyan lori.
Lasiko yii ni Sẹnatọ Smart Adeyemi dide, to si fi itara sọrọ wi pe eto aabo lorilẹede Naijiria ti dẹnukọlẹ patapata.
Ninu ọrọ rẹ, Adeyemi, ẹni to n fi omije sọrọ ni o ṣeni laanu wi pe, awọn eniyan paapaa ijọba, n fi ọwọ yẹpẹrẹ mu eto aabo to ti dẹnukọlẹ kaakiri nitori ọpọ ọmọ Naijiria ni ẹmi wọn ti sọnu sinu ijamba ikọlu kaakiri.
''Nigba kan ri, mo le tẹ ọkọ leti lati ibi ti mo wa lọ si Maiduguri lai si wahala, amọ ọrọ ko ri bẹẹ mọ, ko si ọkan ẹni to balẹ lati wa ọkọ lati ilu kan si omiran''
''Aarẹ! Ina njo lori papa lorilẹede Naijiria, asiko si ti to lati sọ ododo ọrọ lai fi ti ọrọ oṣelu bọ ọ, nitori ọpọ ẹ̣mi lo n sọnu kaakiri ẹya ati ẹkun Naijiria''
''Ẹ kesi awọn orilẹede lagbaye lati wa ran wa lọwọ, ki ẹ fi ti igberaga silẹ, nitori apa ẹnikẹni ni Naijiria ko ka ọrọ to wa nilẹ yii mọ''
Lasiko ti Sẹnatọ Adeyemi n fi itara sọrọ lọwọ lori eto aabo naa, ti omije si n bọ loju rẹ, ni fidio safihan Remi Tinubu to n sọrọ labẹlẹ.
Ninu ọrọ to sọ, Remi Tinubu ni ''Ṣe ọmọ ẹgbẹ oṣelu PDP ni ẹ ni? Abi ikooko to wọ aṣọ aguntan ni iwọ n ṣe ni?
Amọ, Smart Adeyemi ko tilẹ fun Remi Tinubu lesi, to si bẹrẹ si sọrọ fitafita pe, asiko ti to lati beere iranwọ ni oke okun lori eto aabo, nitori ẹgbẹlẹgbẹ biliọnu Naira ni ijọba ti na, ti ko si si aṣeyọri kankan.
Akomolede ati Aṣa: Kọ́ ẹ̀kọ́ si nípa ààlọ́ nílẹ̀ Yorùbá
Loju ọpọ Twitter ni awọn ọmọ Naijiria ti fi ero wọn han si itakurosọ to waye ni Ile Igbimọ Asofin Agba naa ni Ọjọ Iṣẹgun.
Ọpọlọpọ awọn to sọrọ ni, ko yẹ ki Remi Tinubu ti ọrọ oṣelu bo ọrọ eto aabo to mẹhẹ kaakiri ẹkun Naijiria, ati wi pe iwa buruku gba a ni arabinrin naa wu.
Awọn miran ni Remi Tinubu pẹlu iwa rẹ ko le e jẹ iyawo aarẹ lorilẹede Naijiria, ti ọkọ rẹ ba dije dupo ni ọdun 2023, nitori wọn ko ni dibo fun un.
Olugbon of Igbon: ‘Rubber Stamp’ làwọn aṣòfin àpapọ̀, wọn kò ṣojú aráàlú
Bakan naa ni awọn miran ni Remi Tinubu gbọdọ bẹbẹ, ko si tọrọ aforiji lọwọ awọn ọmọ Naijiria, nitori ọrọ aibikita to sọ nipa bi ẹ̣mi awọ̣n ọmọ Naijiria ṣe n sọfo lojoojumọ nitori eto aabo ti ko muna doko.
Bi o tilẹ jẹ pe ọkan gboogi ninu ẹgbẹ oṣelu APC, Asiwaju Bola Ahmed Tinubu to jẹ ọkọ Remi Tinubu ko tii sọ ni gbangba pe, oun yoo dije dupo aarẹ ni ọdun 2023, ọpọlọpọ eniyan lo n sọ wi pe arakunrin ọhun ti n gbe igbesẹ to jọ bẹẹ.
Baba Ijesha: Princess ní ojoojúmọ́ ni Ijesha ń tọ̀rọ̀ ìdáríjìn lọ́wọ́ òun ní àgọ́ ọlọ́pàá
Arabinrin Damilola Adekoya, tii se adẹrinposonu, ti ọpọ eeyan mọ si Princess, ti ke si gbogbo araalu pe ẹnikẹni ti Baba Ijesha ba ni ajọsepọ aitọ pẹlu ọmọ rẹ, wa fi to oun leti.
Princess, lasiko to n salaye bi gbajumọ osere naa se yaju si ọmọ rẹ nidi ajọsepọ laitọ, wa kesi awọn obi tabi alagbatọ to ba mọ pe Baba Ijesha ti ni ibalopọ aitọ pẹlu ọmọ oun ri tabi ti aburo rẹ, ko wa sọ fun oun.
Princess, ẹni to salaye pe oun fi inu wenu, oun wa jẹ iwọ, tun gba awọn obi nimọran lati mase jẹri ẹnikẹni lati da ọmọ wọn da.
Bakan naa lo tun gba awọn obi to ba ni ẹsun lori Baba Ijesha niyanju lati lọ̀ si agọ ọlọpaa to wa ni Panti, ki wọn lọ fi ẹjọ sun nitori ibẹ ni baba Ijesha wa.
Princess tun sisọ loju rẹ fun araye pe ojoojumọ ni oun n yọju si agọ ọlọpaa Panti nilu Eko, nibi ti wọn ti Baba Ijesha mọ, ti ọkunrin naa si maa n rawọ ẹbẹ si oun pe ki oun jọọ, dari jin oun.
Akeugbagold
O ni awọn ọlọ̀paa si n se iwadi rẹ lọwọ, to si ti jẹwọ pe ko si irọ ninu ẹsun ti wọn fi kan.
"Baba Ijesha ni oun ko hu iru iwa yii ri fun ọmọde kanakan ayafi ọmọ mi, amọ bawo ni mo se fẹ mọ pe otitọ lo n sọ.
Se iru ohun to yẹ ki Baba Ijesha fi san oore ti mo se fun ree, haa, eeyan ma le o."
Alaye ti n jẹyọ lori ẹsun ifipa ba ọmọde lopọ ti wọn fi kan gbajumọ osere tiata Yoruba kan, Olanrewaju James Omiyinka, ti ọpọ mọ si Baba Ijesha.
Obinrin kan to jẹ gbajugbaja adẹrinposonu to jẹ alagbatọ ọmọdebinrin ti wọn fi ẹsun kan Baba Ijesha ba lopọ, ti wa soju opo ayelujara Instagram rẹ, lati sọ fun araye nipa bi isẹlẹ naa se waye.
Adẹrinposonu naa to n jẹ Princess Comedian lo n fi omije nla sọ bi isẹlẹ naa se ba a lọkan jẹ to ati bo se waye.
Obinrin naa, ẹni to koro oju si bi awọn eeyan kan se n da lẹbi, tun salaye pe kii se gbogbo igba ni Baba Ijesha n wa ba ọmọ naa lopọ fun odidi ọdun meje.
O ni ẹẹkan pere lo wa sile oun ni ọdun meje sẹyin, to si se ọmọ naa bi ọsẹ ti n soju.
Princess ni lati igba ti isẹlẹ naa ti waye ni ọdun meje sẹyin, ni ara ti n fu oun pe nnkan ti yatọ lara ọmọ naa, to si ti n kuna gidi nipa ẹkọ rẹ.
O ni ọpọ ẹbi lo n da oun lẹbi pe oun ni atẹnumọ ju amọ oun mọ pe nnkan ti yipada lara ọmọ naa.
Obinrin adẹrinposonu naa ni awọn obi to wa ladugbo oun lo gba ki awọn ọmọ wọn wa maa gbe ni ọdọ oun, ti wọn si fi awọn ọmọ naa se oun laanu.
O fikun pe mẹfa ni awọn ọmọ ti oun gba tọ, ọkunrin mẹta ati obinrin mẹta.
Princess ni Baba Ijesha lo wa ba oun pe oun ni isoro nipa ẹkọ rẹ, o ni oun n fẹ iranlọwọ lati wọ ileẹkọ fasiti, ti oun si fi si lẹsinni.
Obinrin naa tun salaye pe nigba keji ti baba Ijesha wa lẹyin ọdun meje wa se pẹki akoko ti anti oun wa wo oun, ti oun si fẹ sin jade nigba ti onitọun n lọ sile.
O ni oun sọkalẹ lati lọ si geeti fun, ti oun ko si lo ju isẹju mẹta si mẹrin lọ nisalẹ, amọ oun ko mọ pe nnkan ti sẹlẹ.
"Baba Ijesha tun pada wa ni ọjọ keji lati mọ boya ọmọ naa ti sọ ohun to sẹlẹ fun gbogbo ile. Ọmọ naa ni Ijesha sọ pe ki oun kalọ sidi mọto oun lati wa gbe eso ti oun ra wọle.
Amọ nigba ti wọn de isalẹ lo tun ba ọmọ naa se isekuse lẹẹkeji, lati igba naa ni ko ti wa sile mi mọ amọ nigba to ba nilo iranlọwọ, o maa n pe mi.
Lọjọ kan ni mo sọ fun pe ki lo de to se n sa fun mi, o nilo iranlọwọ, o si joko sile, se emi ni ki n wa ko owo fun ọ ninu ile ni.
Ni ọsẹ keji ti isẹlẹ naa waye, ni awọn alasẹ ileẹkọ ọmọ naa pe mi pe ki n yọju sawọn pe ọmọ naa n joko sori ọkunrin to jẹ ẹgbọn rẹ, to si n rin idi mọ ni itan."
"Onigbagbọ gidi ni awọn obi ọmọ naa, ti wọn si ro pe ogun ẹmi lo n ja ọmọ ọdun meje naa, koda n ki gba ki wọn wo iwokuwo lori tẹlifisan."""
Princess ni ijakulẹ ti ọmọ naa tun n ni ninu ẹkọ rẹ, ko jẹ ki ara oun balẹ nitori wọn fi ọmọ naa rẹ oun lẹkun ni.
Ogbomoso: Ẹbọ ọkùnrin àti obìnrin tí kò ní ìbálòpọ̀ rí ni wọ́n rú dènà ogun Fulani
O ni ọrẹ oun lo ba ọmọ naa sọrọ lati mọ idi ti isesi rẹ se yipada lẹyin ọdun meje ti isẹlẹ naa waye, ti ọmọ naa si jẹwọ oun to wa laarin rẹ ati baba Ijesha, ti otutu si mu oun.
Idi ree ti mo se ni ki baba Ijesha yọju si mi, ti emi ati mama mi si ti mura silẹ pe a maa bi  nipa ọrọ naa, ko sọ otitọ.
"A wa seto ẹrọ ayaworan CCTV, ta si ni ki gbogbo eeyan to wa ninu ile jade lọ. Nigba to de, o ri awọn to wa se CCTV naa, mo sọ fun pe awọn osisẹ DSTV ni wọn, mo fẹ sin wọn jade.
Ni kete ta jade lo bẹrẹ si ni wa inu ile kiri lati ri pe ko si eeyan kankan ninu ile tabi pe a fi kamẹra sinu ile.
Ẹ ri bi eeyan se buru to. N ko tiẹ le maa salaye awọn nnkan to se nitori a n wo bo se n se lori foonu wa.
O wa mu ọmọ naa lọ sile idana nitori pe o mọ pe ko le si ẹrọ ayaworan nibẹ."
hhhhhh
Obinrin naa wa koro oju si awọn eeyan to n sọ oun ti wọn ko mọ lori ọrọ yii lati sọra nipa isẹlẹ naa.
Princess ni to ba wu awọn eeyan, ki wọn halẹ mọ oun, ohun to daju ni pe idajọ ododo yoo waye lori ẹsun toun fi kan baba Ijesha.
"To ba wu yin, ẹ lọ dena de mi, idajọ yoo waye. Se nitori pe Baba Ijẹsha jẹ osere tiata Yoruba lẹ se n gbe lẹyin rẹ?
Ko si ọmọde to yẹ ki ẹnikẹni fi tipa ba lopọ, ko dara rara.
Baba Ijesha: Iyabo Ojo ní bí wọn bá tú afurasí náà sílẹ̀, òun yóò da padà sí àtìmọ́lé
Gbajumọ osere tiata, Iyabo Ojo ti ke gbàjare si awọn ọmọ Nàijíríà, láti gbáruku ti ọ̀rọ̀ ọmọ tí Bàbá Ijesha se iwa ibajẹ pẹlu rẹ, kí ìyà  má jẹ Damilola Adekoya, ti gbogbo eniyan mọ̀ sí Princess Comedian gbé.
Nínú fídíò kan tó ṣe loju òpó instagram rẹ lalẹ ọjọru lo ti n kígbe pé, awọn ti gbọ pé àwọn kan fẹ gba ọ̀nà ẹburu yọ Baba Ijesha kuro ni àhámọ́ ọlọpaa.
Ó ní tí wọ́n bá tú Baba Ijesha sílẹ̀, òun tìkara òun yóò tun gbé lọ sí ẹ̀wọn pada àti pe ó pọn dandan ki wọ́n ṣe idajọ́ fún nílé ẹjọ.
Iyabo Ojo ni pẹ̀lú gbogbo nǹkan ti òun ti fi ojú ohun ri nipa nǹkan ti baba Ijesha ṣe si ọmọde naa, nínú fọ́nran aworan ti Princess fún òun láànfàni láti wo, ijiya to tọ gbọdọ wa fun afurasi naa.
 Tí wọ́n bá fi Baba Ijesha silẹ̀, a ó tún mú"" Gbogbo obi ni yóò dide láti gbèjà Princess lórí ọ̀rọ̀ tó wà nílẹ̀ yìí."
Oríṣun àwòrán, babaijesha/Instagram
Iyabo Ojo ni òun ń kede lórí fọ́nran náà, láti pe gbogbo àwọn tó n pete pèrò láti yọ Bàbá Ijesha kuro nínú ipò tó wà lọ́wọ́lọ́wọ́ bayii, pe ki wọn mase dan wo rara.
Gbajúgbajà òṣèrè náà ní kò sí bí ó ti wù kó pẹ́ tó kí àwọn òṣìṣẹ́ ilé ẹjọ́ to n wosẹ niran bayii to wọle, ó si di dandan kí àwọn ọlọpaa gbe lọ sí ilé ẹjọ́.
Ó ni gbogbo àwọn eléré tíatà tí n pe òun láti jámi lórí ọ̀rọ̀ yìí sùgbọ́n orí òtítọ́ ni òun dúró lé, ìdájọ́ òdodo si ni òun wà.
Iyabo Ojo wá ké pe Gómìnà ìpínlẹ̀ Eko àti Iyawo rẹ̀ pẹlu gbogbo àwọn bọ̀rọ̀kìní láwùjọ, láti dá sí ọ̀rọ̀ yìí, ki wọn si gba ìdájọ́ fún ọmọ náà.
Ọrọ ẹsun ifipa ba ọmọde lopọ ti wọn fi kan gbajumọ osere tiata lede Yoruba, ti ọpọ mọ si Baba Ijesha, tun ti n fa wahala miran lagbo tiata.
Idi ni pe oniruuru awọn osere tiata yii ni wọn n sọ ero wọn sori ayelujra lori isẹlẹ naa, tawọn miran si n kọju ija nla sira wọn.
Bi awọn osere tiata kan se gba pe o yẹ kawọn osere yoku se atilẹyin fun baba Ijesha ni, ti ko si yẹ ki wọn ti i maa se idajọ rẹ.
Ni awọn miran n gbara ta pe, osere tiata ti wọn fi ẹsun kan naa ti jẹwọ fun ọlọpaa nipa ẹsun yii, ti wọn si n bu ẹnu atẹ lu igbesẹ rẹ naa.
Bẹẹ ba gbagbe, a ti kọkọ mu iroyin wa fun yin nipa bi osere tiata lede Yoruba meji, Iyabo Ojo ati Foluke Daramola se n ta ko ara wọn lori isẹlẹ yii.
Bakan naa ni awọn gbajumọ osere tiata Yoruba lọkunrin meji, Legemiami ati Yomi Fabiyi naa ti sọrọ nipa isẹlẹ yii, eyi to ti n fa awuyewuye.
Yomi Fabiyi, ninu ọrọ rẹ to gbe sori ayelujara Instagram rẹ, lo ti n tako awọn akẹẹgbẹ rẹ to ti sọrs saaju nipa Baba Ijesha , paapa awọn to n yọ suti ete si pe ki wọn sọra se.
Awọn ọrọ rẹ naa lo dabi eyi to n tako awọn ohun ti Iyabo Ojo ti sọ saaju lori ẹsun ti wsn fi kan Baba Ijesha.
Oríṣun àwòrán, realyomifabiyi/Instagram
"Igba ti mo maa n ri awọn akẹẹgbẹ mi ki wọn jade sita lati sọrọ, nigba ti wọn ba fẹ bu ẹnu atẹ lu akẹẹgbẹ wọn kan to jin si koto tabi to wa ninu wahala.
Wọn gbagbọ pe ko si ẹnikẹni to le se ohunkohun fun wọn, o si yẹ ki wọn maa ranti pe Ọlọrun n bẹ o."
Ọrọ naa lo bọ si apo ibinu Iyabo Ojo, ti oun ati Yomi Fabiyi si jọ n fi atẹjisẹ sọwọ si ara wọn lori Whatsapp.
Amọ nigba to ya, Yomi gbe ọrọ naa soju opo Instagram rẹ, to si tun bi Iyabo ninu, ti onitọun si pada fun Yomi ni oko ọrọ pe oun lo n fi ọrọ to kọ naa ba wi.
Oríṣun àwòrán, realyomifabiyi/Instagram
Ninu esi rẹ, Iyabo ni Yomi n fi owe pe oun ni onidọti ati alaye dojuru, ti ko si le jẹ oun lo n ba wi laelae.
O wa ke si Yomi Fabiyi lati lọ wadi otitọ ọrọ nipa ohun ti Baba Ijesha se ni agọ ọlọpaa to wa ni Panti nilu Eko tabi ko lọ bi Princess, iya ọmọ naa.
"Yomi Fabiyi, to ba fẹ ba eeyan lorukọ jẹ, kii se iru emi lo mẹnuba. Bi ọrọ ba se jẹ ni mo maa n sọ, emi kii se asajẹ ma sẹ, ẹ ma jẹ ka maa pọn jẹbẹ ni akisa.
Amọ se ni Yomi Fabiyi naa tun fesi pada fun Iyabo Ojo pe ko le jẹ oun lo n ba mi, boya oun ati Baba Ijesha lo ni asamọ to n pa.
Oríṣun àwòrán, iyaboojofespris/Instagram
Igi imu jinna sori. Asọ ti wọn ba ba lara egungun temi, temi lo n se. N ko ni ba ọ maa gba ọrọ bii ẹni gba igba ọti nitori mo ni iyi ati apọnle ju bayẹn lọ."""
Lẹyin naa lo ba lọ se fidio kan soju opo Instagram rẹ, eyi to fi n fesi ọrọ pada ransẹ si Iyabo Ojo
Ọrọ naa ko tan rara ninu Iyabo Ojo lori esi ti Yomi Fabiyi fọ fun pada ninu fidio to se, toun naa si jade lọ se fidio mii pada loju opo Instagram rẹ lati rọ ojo epe le Yomi Fabiyi lori.
Yomi Fabiyi, jade sita ki n sọ ọrọ si ẹ lori live fidio yii, o dabi ẹni pe ori rẹ ti yin. Iwọ ni o lawọn nnka ju mi lọ, sebi iwọ ni ọmọ isẹ baba Suwe.
Iyabo ni ojoojumọ ni Yomi Fabiyi maa n lọgun Baba Suwe tori pe o se oore fun.
Yomi, ori rẹ ti daru, ori rẹ ti yin. O ni ka ma sare se ipinnu, iwọ gan lo n ba aye Baba Ijesha jẹ. Mo ti ransẹ si ninu ẹwọn to wa pẹlu.
"Iyabo ni Yomi lo maa n jẹ ki awọn osere yoku maa sọ ohun to wu wọn."""
Iyabo, ẹni to n fi ibinu sọrọ lori fidio naa ni ọrọ ti iru awọn Yomi n sọ lo mu ki awọn osere yoku maa se atilẹyin fun iwa ti Baba Ijesha hu.
"Yomi Fabiyi, o n fi ara rẹ we mi, to ba ni asọ to mi, o ko le ni akisa to mi nitori nigba ti mo n jijagudu lati ko ọrọ mi jọ, nibo ni iwọ wa.
O n kọ oyinbo ofo ati isọnu, to ba jẹ ọmọ rẹ ni Baba Ijesha se iru rẹ fun, se o  maa ni o fẹ wo fidio. Emi ya were gan ni, abi olori... ni ẹ ni?"
Iyabo Ojo wa n leri leka pe Yomi Fabiyi ko ni le wọ ilu oyinbo, ti ko ba sọra, tori ohun yoo ba na tan bii owo, ti wọn yoo si fontẹ lu orukọ rẹ.
"Ẹni to ba n se atilẹyin fun afipabanilopọ, afipabanilopọ ni oun naa. Mo kuro ninu awọn to le maa fi tayin ati awọn olori... ti wọn n satilẹyin fun ọ, tẹ jọ n ba ọmọde lopọ.
Mo ti wo fidio bi Baba Ijesha se yaju si ọmọdebinrin naa, o si foju han pe baba Ijesha jẹbi ẹsun naa bajẹbajẹ, ti wọn ba fi silẹ, maa tun da pada sẹwọn.
Iyabo Ojo ni ọmọ ọdun meje si mẹjọ ni ọkunrin kọkọ bami sere oge, ti n ko si le sọ fun iya mi. Mo si ri ibi ti Baba Ijesha ti n ti ọwọ bọ ọmọde naa nidi.
To ba se emi ni ọrọ ọmọ yii sẹlẹ si, boya si ọmọ mi ni tabi ọmọ ọmọ mi, maa se aye onitọun basubasu, mo si n kilọ fun gbogbo ẹyin tẹ n se bẹẹ lati sọra."
O wa n fọwọ ta Yomi Fabiyi laya pe to ba to bẹẹ, ko yọju si atimole ti Baba Ijesha wa ni Panti, ti wọn ko ba ni ti mọle.
"O ni ""Yomi Fabiyi, mo ni ẹ lọkan tori ọmọde ti ọrọ naa kan, abi bawo ni ọrọ Baba Suwe to gbe oogun oloro Cocaine se papọ mọ ti ọmọde ti baba Ijesha n la.'"
Ogbomoso: Ẹbọ ọkùnrin àti obìnrin tí kò ní ìbálòpọ̀ rí ni wọ́n rú dènà ogun Fulani
Iyabo Ojo tun wọn epe miran jolẹ lori Baba Ijesha ati awọn eeyan to n tii lẹyin, to si tun kede pe oun ti da duro, ti oun si ti fi agbo tiata Yoruba wọn silẹ.
Florence Ajimobi: Ohun tí n kò lérò ni mo bá lẹ́yìn tí a kúrò ní ìjọba - Florence Ajimobi
Oríṣun àwòrán, florenceajimobi/Instagram
Aya gomina ipinlẹ Oyo tẹlẹ ri, Florence Ajimobi ti salaye pe idakeji ohun ti oun ko gbaradi fun lati koju loun ba pade, lẹyin ti oun ati ọkọ oun kuro ni ijọba tan.
Arabinrin Ajimobi sọrọ yii nibi iṣinu awẹ pẹlu awọn alaṣẹ ẹgbẹ akọroyin, NUJ ati NAWOJ nipinlẹ Oyo, eyi to waye nile rẹ niluu Ibadan.
Aya Ajimobi ni oun ti gbaradi ni kete tawọn kuro lori aga aleefa, lati ni iriri ikorira ati iwa ọdalẹ lati ọdọ awọn eeyan.
Ṣugbọn aya gomina ana ipinlẹ Oyo sọ pe, n ṣe lawọn eeyan n gbe oun gẹgẹ, ti wọn si n fi ifẹ han si oun nibi kibi ti oun ba lọ, lẹyin ti awọn kuro nipo tan.
"Awọn eeyan n fi ifẹ han si mi, eleyi to ya mi lẹnu, mo dupẹ lọwọ Ọlọrun fun eyi.
Oríṣun àwòrán, florenceajimobi/Instagram
N ṣe lọpọlọpọ eeyan duro gidigba lẹyin mi, n ko pe gẹgẹ bii eeyan nitori mo maa n ṣe aṣiṣe.
O ṣeeṣe ki n ti ṣe aṣiṣe nigba ti mo fi jẹ aya gomina ipinlẹ Oyo, sugbọn mo fẹ ki ẹ mọ pe n ko mọọ mọ ṣe awọn aṣiṣe ti mo ba ti ṣe nigba naa.
Ati pe ko si ẹni to pe nitori eeyan ni gbogbo wa, Ajimobi lo sọ bẹẹ."
Nigba to n sọ nipa ọkọ rẹ to di oloogbe ni bii oṣu mẹwa sẹyin, aya Ajimobi ni oun tun wa nífẹẹ Abiola Ajimobi si lẹyin to ti ku, ju igba aye rẹ lọ.
O ni oun ko mọ iyi ọpọlọpọ ohun ti Ajimobi n ṣe gẹgẹbi olori ile nigba aye rẹ amọ asiko yii gan an loun ṣẹṣẹ mọ riri gbogbo ohun ti to n ṣe nigba aye rẹ.
aaaaaaaaaaaaaaa
"Mo si máa n sọ fawọn ọmọ mi pe akinkanju ọkunrin ni baba wọn.
Ko tii pe ọdun kan ti Iku mu ọkọ mi lọ, ṣugbọn n ṣe ni mo n ṣafẹri rẹ ni gbogbo igba.
Mo n sọ nipa ẹni ti mo ba gbe fun ogoji ọdun, ti ko figba kan ṣaroye ri. Mi o gbọ ko ṣe aroye ri,'' aya gomina ipinlẹ Oyo tẹlẹ ṣalaye.
O ni Ajimobi n gbe gbogbo ẹru idile awọn lai ṣaroye fun ẹnikan.
Aya Ajimobi ni ko rọrun lati jẹ ọmọkunrin ni tootọọ. Ti mo ba tun ayé wa, mo si maa fẹ lati wa ni obinrin lẹẹkan sii."
Budo Ikoko water problem: Ìyàwó wa ti sá lọ kúrò ní Asa nítorí àìsí omi- Alhaji Sunmonu
Mo si tun maa fẹ lati jẹ aya Ajimobi ni iye igba ti a ba jọ pada wa si ayé nitori kò sí ọkunrin bii Ajimobi.
"Oninu rere ni Ajimobi, olootọọ eeyan si ni, n ko le gbagbe rẹ laelae,"" aya gomina ipinlẹ Oyo tẹlẹ lo sọ bẹẹ."
Mary Daniel: Ìjọba Eko ní ẹbi obìnrin náà ni àwọn fàá lé lọ́wọ́, tí wọn kò sì gbẹ́sẹ̀ lé N25m owó ìranwọ́ rẹ̀
Oríṣun àwòrán, Lagos State Government
Ijọba ipinlẹ Eko ti kede pe irọ to jinna sootọ ni iroyin kan to gba ori ayelujara kan pe wọn ti fa Mary Daniel, obinrin ẹlẹsẹ kan to n ta omi loju popo, le ọlọpaa lọwọ.
Ni irọlẹ Ọjọru ni iroyin kan gbalẹ pe obinrin ẹlẹsẹ kan naa, tawọn eeyan seto ikowojọ fun laipẹ yii, tijọba Eko si siju aanu wo, ni irọ wa ninu ọrọ rẹ, ti wọn si ti fa le ọlọpaa lọwọ.
Iroyin naa ni Mary pa irọ pe oun ko ni baba ati iya laye, ti wọn si ti jalaisi ninu ijamba ọkọ ti ẹsẹ rẹ ti da amọ ti wọn sawari rẹ pe baba rẹ wa laye.
Bakan naa ni ahesọ iroyin naa ni kii se inu ijamba ọkọ ni ẹsẹ Mary ti ge bikose pe wọn bi mọ bẹẹ ni lati igba to ti de ile aye.
Wọn tun ni awọn eeyan kan to seranwọ fun Mary lati gbe ọrọ rẹ de ori ayelujara ti n dunkooko mọ pe awọn fk gba ipin awọn ninu miliọnu mẹẹdọgbọn naira ti awọn alaanu ko jọ fun bii owo iranwọ.
Oríṣun àwòrán, Screen Shot
Ọna lati fi idi ootọ ọrọ mulẹ lo mu ki BBC Yoruba pe ijọba ipinlẹ Eko lati mọ boya lootọ ni awọn ahesọ ọrọ to n lọ lori ayelujara naa.
Nigba to n tako awọn ahesọ iroyin yii, Kọmisana feto iroyin nipinlẹ Eko, Ọgbẹni Gbenga Omotoso salaye pe ko si ootọ kankan ninu iroyin to n lọ lori ayelujara nipa obinrin naa.
Omotoso ni ijọba Eko tẹwọgba Mary ni ọjọ Kẹtala osu Kẹrin ọdun 2021 lasiko ti ariwo rẹ gba ori ayelujara, ti awọn eeyan si ti ko miliọnu mẹtala naira jọ fun bii owo iranwọ.
O ni lọwọ lọwọ bayii, owo tawọn eeyan fi se Mary laanu ti le ni miliọnu mẹẹdọgbọn naira lasiko to de ọdọ ijọba ipinlẹ Eko.
"Ijọba Eko gba itọju Mary, ta si ri pe aabo to peye wa fun.Ni Ọjọru la wa gbe igbimọ kan kalẹ ninu eyi ti awọn ọlọpaa wa pẹlu ileesẹ to n seto idẹrun araalu.
Oríṣun àwòrán, Lagos State Government
Bakan naa la pe ẹgbẹ awọn ọmọ bibi ẹya Igala to n gbe nilu Eko, nibi ti Mary ti wa, ta si fa obinrin ẹlẹsẹ kan naa le wọn lọwọ fun itọju.
A ko fẹ ki obinrin naa bọ sọwọ awọn gbajuẹ to le fẹ gba owo to ri kojọ lọwọ rẹ ni a se gbe igbesẹ yii."
Kọmisana feto iroyin nipinlẹ Eko fikun pe, wọn ti pasẹ fun awọn ẹya Igala naa lati ri daju pe wọn lo owo ọhun lati gba ilegbe fun obinrin ẹlẹsẹ kan naa.
Bakan naa ni Ijọba Eko tun pasẹ pe ki wọn si tun si ibudo itaja igbalode ti Mary nifẹ lati si fun gẹgẹ bii okoowo to fẹ dawọle ati isẹ oojọ.
"A tun sọ fun awọn araalu obinrin naa pe ilu Eko la fẹ ki Mary maa gbe, ko si dokowo si nitori ilu Eko lo ti ri gbogbo owo to ri kojọ naa.
Squash: Dele Oladejo ní iṣẹ́ ńlá ni eré ìdárayá Squash, olówó àti akọni ẹ̀dá ló ń gbá a
Eyi si fidi rẹ mulẹ pe Eko jẹ ibi ti eeyan ti n se oriire nitori pe o tun jẹ ilu to ko tonile talejo mọra."
Ijọba Eko wa kede pe Mary Daniels ko si ni agọ ọlọpaa fun iwadi kankan tabi pe asiri tu pe o parọ, bẹẹ ni wọn ko maa sewadi rẹ nitori pe baba rẹ wa nile aye.
Bẹẹ ba gbagbe, laipẹ yii ni ori ayelujara kun fun iroyin obinrin naa, ti ọpọ eeyan si n da owo jọ fun lati saanu rẹ.
Arabinrin to ge lẹsẹ naa ṣalaye, nigba t'awọn oniroyin n f'ọrọ waa lẹnu wo nigba ti iroyin rẹ jade pe, salaye pe inu ijamba mọto to gbẹmi gbogbo awọn ero inu ọkọ naa, loun ti padanu ẹsẹ oun kan.
O ni inu ijamba mọto yii kan naa lawọn obi oun mejeji ku si.
Nigba ti fọto rẹ nibi to ti n kiri omi pure water ni Osodi nilu Eko, bọ sigboro aye lọsẹ diẹ sẹyin, ọpọlọpọ ẹlẹyinju aanu ni Naijiria ati loke okun ni wọn dide iranwọ fun.
Ogbomoso: Ẹbọ ọkùnrin àti obìnrin tí kò ní ìbálòpọ̀ rí ni wọ́n rú dènà ogun Fulani
O ṣalaye ninu iforowerọ kan pe ọmọ orukan loun ati pe oun loun n da gbe bukata ọmọ kan ti oun bi ati iya agba oun.
O tun figbakan mu ẹnu le iroyin nipa bi nnkan ṣe le koko fun oun, to fi di wi pe oun ni lati fi ileewe silẹ bọ si igboro lati ta omi inu ike, ki oun ati ọmọ pẹlu iya agba oun lee jẹun.
Laipẹ yii si ni wọn ṣe ẹyẹ ọjọ ibi fun arabinrin naa pẹlu oniruru aworan, akara oyinbo ati bẹẹ bẹẹ lọ.
Fulani-Herders Crisis: Ọlọ́pàá ní Amotekun, OPC àti Fijilanté ló rí àwọn afurasí náà mú
Oríṣun àwòrán, Amotekun
Ikọ alaabo nilẹ Yoruba, Amọtẹkun ti fi oju awọn afurasi ọdaran mẹfa, ti ọwọ wọn tẹ ni ipinlẹ Ọyọ han si gbangba.
Ninu atẹjade ti Adari ikọ Amọtẹkun nipinlẹ Oyo, ọgagun Olayinka Olayanju fi lede ni, ijọba ibilẹ Kajọla nipinlẹ Oyo lọwọ ti tẹ awọn afurasi ọdaran naa, ti wọn jẹ agbebọn darandaran.
Olayanju ni ajọṣepọ awọn ikọ eleto aabo labẹle bi awọn vigilante ati awọn ọmọ ẹgbẹ OPC lo ṣiṣẹ pọ, ti ọwọ fi tẹ awọn agbebọn lasiko ti wọn n ṣe iwọde ka.
O ni owurọ kutu Ọjọ kọkandinlọgbọn, Oṣu Kẹrin, ni ọwọ tẹ awọn agbebọn naa ni ijọba ibilẹ Kajọla ni ibi ti wọn ti gbe igi di opopona ti awọn eniyan n gba kọja.
Oríṣun àwòrán, Amotekun
Ikọ Amọtẹkun ni bi o tilẹ jepe wọn gbiyanju lati sa mọ awọn lọwọ, awọn ri wọn gbamu lẹyin ti wọn le  wọn wọ inu igbo lọ.
Orukọ awọn afurasi agbebọn to jẹ Fulani naa ni Awali Atine, Ibrahim Abu, Shuaib Balau, Ibrahim Musa, Abdullah Masika ati Umar Aliu Masika.
Awọn afurasi agbebọn naa ni wọn n ṣọṣẹ ni agbegbe Okeho-Ilua ati Okeho-Iṣẹyin, nipinlẹ Oyo.
Ikọ Amọtẹkun ni awọn afurasi agbebọn yii ni ma n ṣiṣẹ gẹgẹ bi Fulani darandaran ni ọsan, ti wọn a si dena da awọn eniyan ni oru.
Olugbon of Igbon: ‘Rubber Stamp’ làwọn aṣòfin àpapọ̀, wọn kò ṣojú aráàlú
Lasiko ti wọn ri wọn gbamu, maalu to le ni ọgọsan ni wọn gba ni ọwọ wọn pẹlu ohun ija oloro ni oriṣiriṣi ati iye owo to to #268, 470.00.
Ikọ Amọtẹku  naa fikun pe awọn tun ri awọn afurasi agbebọn marun un miran ni apa ila oorun Saki, ti awọn si ti fa wọn le ikọ ọlọpaa lọwọ.
Bakan naa ni ikọ Amọtẹkun naa wa rọ awọn araalu lati ran awọn lọwọ nipa fifi iroyin ti yoo ran iwadii lọwọ fi to awọn leti.
Baba Ijesha: Fídíò tí Iyabo Ojo gbé jádé lo ṣàfihàn Ijesha tó ń bẹ̀bẹ̀
Oríṣun àwòrán, Baba Ijesha
Ọrọ ẹsun ti wọn fi kan baba Ijesha ti n gba ọna miran yọ bayii nitori Iyabo Ojo, gbajumọ osere tiata kan ti gbe fidio kan jade ninu eyi ti Baba Ijesha wa.
Ninu fọnran aworan naa ni Baba Ijesha ti joko silẹ, to si n bẹbẹ pe ki wọn dari jin oun.
Fidio naa ti Iyabo Ojo gbe soju opo Instagram rẹ lo se afihan Baba Ijesha to n sọ pe ki wọn dari jin oun nitori isẹ esu ni.
Baba Ijesha, ti awọn eeyan kan n fi ọrọ wa lẹnu wo, to fi mọ iya ọmọ naa, lo n salaye ohun to ri lọbẹ, to fi wa iru sọwọ.
Ninu fidio naa ni iya ọmọ, Princess ti yari, to si fẹ lu Baba Ijesha amọ ti awọn eeyan n bẹ lati mase se bẹẹ.
Baba Ijesha, ninu fidio naa lo salaye pe oun ni ogun idile, eyi to han si Princess funra rẹ, ti isẹlẹ naa ko si le se ẹyin ogun to n ja oun.
"Lootọ ni mo se ohun ti ko dara, ẹ jọọ, ẹ dari jin mi tori Ọlọrun, mo mọ pe mo sẹ, mo se nnkan ti ko dara, ma wo temi, jọọ mo bẹbẹ ni.
Oju ko ni tiẹ, jọọ, ko yẹ ki n se eleyi si ọ, n ko mọ ohun to se mi, mo si le pa ara mi."
Nigba ti Princess, iya ọmọ n bi Baba Ijesha pe ki lo de to se wa nawọ̀ ere si ọmọ ọdun meje, to tun pada wa se bẹẹ ni igba keji, baba Ijesha ko ri ohunkohun sọ, o sa kan n bẹbẹ ni.
Lẹyin o rẹyin ni wọn wa mu Baba Ijesha lọ si agọ ọlọpaa lori ẹsun naa.
Amọ nitori pe ẹjọ naa ti de ile ẹjọ, to si ti di ọrọ ofin, ileesẹ BBC ko le se afihan fọnran aworan naa loju opo wa.
Baba Ijesha: Ìjọba ìpínlẹ̀ Eko fi ẹ̀sùn mẹ́rin kan Ijesha, ẹ̀wọ̀n gbére wà nínú ìjìyà ẹ̀ṣẹ̀ náà
Oríṣun àwòrán, babaijesha
Ijọba ipinlẹ Eko ti kede pe oun ti gbọ nipa ẹsun ifipa ba ọmọde lopọ ti wọn fi kan gbajumọ oṣere kan, Baba Ijesha, ati pe oun ti ṣetan lati ṣe ẹjọ rẹ.
Ninu atẹjade ti ileeṣẹ to n ri si ẹsun ifibanilopọ fi lede, eyii to tẹ BBC Yoruba lọwọ, ni wọn ti kede bẹẹ.
"Ikede naa ni ""A fẹ fi akoko yii sọ fun gbogbo araalu pe, ileeṣẹ ijọba ipinlẹ Eko to n ri si ẹsun ifibanilopọ ati iwa ipa ninu ile, ti bẹrẹ iṣẹ lori ẹsun ti wọn fi kan Baba Ijesa, a si ti n ba awọn to fẹsun kan an sọrọ."""
A fẹ ki ẹyin eeyan ilu mọ pe wọn ti fi ẹda iwe ẹsun rẹ ṣọwọ si ẹka to n ṣe ẹjọ awọn araalu, DPP, fun imọran to tọ labẹ ofin.
Lẹyin naa ni wọn ṣalaye awọn ẹsun naa lẹsẹṣẹ ati ijiya to wa fun awọn ẹsun ọhun labẹ ofin ijọba ipinlẹ Eko.
Oríṣun àwòrán, princesscomedian
Ileeṣẹ naa ni awọn ni igbagbọ to dantọ ninu ẹka eto idajọ ipinlẹ Eko lati ri daju pe gbogbo awọn ti ọrọ naa kan yoo ri idajọ ododo gba.
Ikorodu cult crisis:A máa gbé Orò síta lọ́jọ́kọ́jọ́ tí ìjà ẹgbẹ́ òkùnkùn bá tún ṣẹlẹ̀- Àwọ
Lẹyin naa ni wọn sọ pe, ijọba ipinlẹ Eko ko faye gba gbogbo iwa to jọ ifipabanilopọ ati iwa ipa si obinrin tabi ọkunrin ni ipinlẹ naa.
Ọjọ kejilelogun, oṣu Kẹrin, ọdun yii ni ileeṣẹ ọlọpaa ipinlẹ Eko sọ fun BBC ninu atẹjade kan pe, afurasi naa ti wa ni ahamọ.
Igbesẹ naa waye lẹyin ti Damilola Adesanya, ti ọpọ mọ si Princess Comedian fi ẹjọ rẹ sun ni agọ ọlọpaa to wa ni Sabo nilu Eko
Ọpọ awọn ọmọ Naijiria ati awọn akẹgbẹ rẹ nidi iṣẹ tiata ni wọn ti bẹrẹ si n fi erongba wọn lede lori iṣẹlẹ naa.
Ki lo ti ṣẹlẹ sẹyin?
Oríṣun àwòrán, saidibalogun/Babaijesha Instagram
Ọrọ awuyewuye to n lọ lọwọ lori ẹsun biba ọmọde lopọ ti wọn fi kan gbajumọ osere, Baba Ijesha, tun ti sun kan gbajugbaja osere miran, Saidi Balogun.
Idi ni pe ọpọ awọn eeyan to n tako gbigba beeli Baba Ijesha ni ahamọ ọlọpa, lo ti n pariwo awọn osere tiata lọkunrin kan pe awọn lo wa nidi igbesẹ lati tu Baba Ijesha silẹ.
Lara awọn ọkunrin ti wọn n lọ ọrọ naa mọ lọrun ni Yomi Fabiyi ati Saidi Balogun pẹlu awọn osere tiata lọkunrin miran ti ko tii sọrọ lori awuyewuye naa.
Amọ nigba to n takun ero awọn eeyan to ni oun n se atilẹyin fun Baba Ijesha, Saidi Balogun ni oun ko fara mọ iwa ifipabanilopọ rara ati rara.
Saidi, ẹni to se fidio kan soju opo Instagram rẹ lori ọrọ naa ni, oun korira asa ifipabanilopọ fun obinrin agbalagba, ka to wa sọ hihu iwa yii si ọmọde ti ko mọ ọtun yatọ si osi.
"Mo korira iwa nina ọwọ ere oke si ọmọge, n ko si se ri. N ko de agọ ọlọpaa Panti ri laye mi, bẹẹ ni n ko tii ba Baba Ijesha sọrọ rara lati igba to ti wa ni ahamọ.
Ki wa lo de ti maa fi sọ fawọn ọlọpaa pe ki wọn fi silẹ, ki lo de ti maa fi se bẹẹ. Ẹ jọọ, se ẹ mọọmọ n ditẹ lati ba orukọ mi jẹ, kẹ fi le mu mi walẹ ni abi bawo?"
Saidi Balogun fikun pe oun ko se atilẹyin rara fun iru iwa bẹẹ, amọ oun dakẹ lai sọrọ nipa isẹlẹ naa nitori pe oun fẹ ki ofun sisẹ rẹ ni lai si idiwọ.
Helen Paul sọ idi tó fi gba orúkọ ní kékere
Se emi nikan ni osere tiata ti ko tii sọrọ lori isẹlẹ yii ni? Ninu ẹgbẹ bii ọgbọn, eeyan kan abi meji pere lo tii sọrọ, ki wa lo de tẹ se n pariwo mi.
Bakan naa ni Saidi ni oun fi gbogbo ara se atilẹyin fun ohun tawọn obinrin n se lori ọrọ yii, oun ki wọn, oun si yin wọn pẹlu.
Amọ o ni ohun n bẹ wọn ni pe ki wọn mase mu orukọ oun bọnu lori ọrọ naa, ki wọn dakun, fi ohun silẹ.
Oríṣun àwòrán, Instagram/realyomifabiyi
Gbajumọ osere tiata Yoruba, Yọmi Fabiyi ti fesi lori bi awọn eeyan kan se n naka aleebu si pe o n satilẹyin fun Baba Ijesha.
Baba Ijesha ni osere tiata Yoruba ti wọn fi ẹsun kan pe o nawọ ere oge si ọmọdebinrin ọmọ ọdun mẹrinla, tii se ọmọ adẹrinposonu kan, Princess.
Oniruuru ọrọ si ni Yomi Fabiyi ti kọ soju opo Instagram rẹ lati igba ti isẹlẹ naa ti waye, eyi to fi n sekilọ pe ki araye mase tii da baba Ijesha lẹbi, titi ti ileẹjọ yoo fi gbe idajọ kalẹ lori ọrọ naa.
Ọrọ Fabiyi yii lo bọ sapo ibinu awọn ọmọ Naijiria, to fi mọ awọn akẹẹgbẹ rẹ bii Iyabo Ojo ati Mercy Aigbe, ti eruku si n yọ lori ayelujara nipa iha ti Yomi Fabiyi kọ si ọrọ Baba Ijesha naa.
Nigba to n ba BBC Yoruba sọrọ lori isẹlẹ yii, Fabiyi sọ pe gba-gba-gba loun duro lẹyin Baba Ijẹsha to wa lahamọ ọlọpaa bayii .
Oríṣun àwòrán, realyomifabiyi/Instagram
O ni afurasi naa lẹtọ si igbẹjọ ati idajọ ododo labẹ ẹtọ ọmọniyan, ko si yẹ kawọn eeyan tii maa se idajọ rẹ, titi ti ileẹjọ yoo fi kede idajọ rẹ.
Yọmi Fabiyi salaye pe, oun ko figbakan ti iwa ibajẹ, irufẹ eyi ti wọn n fẹsun rẹ kan Baba Ijesha, lẹyin.
O ni ṣugbọn ohun ti oun n ja fun ni pe ki awọn eeyan to n ṣe idajọ rẹ lori ayelujara o ranti pe labẹ ẹtọ omoniyan lagbaye, afurasi ko tii di ọdaran ayafi igba ti adajọ ba sọ pe o jẹbi ẹsun ti wọn fi kan an.
Nipa bẹẹ, o ni gbogbo awọn ti n pariwo lori ayejara pe kawọn ọlọpaa mase gba beeli Baba Ijesha kan n pala lẹnu lasan ni.
"Labẹ ofin Baba Ijesha lẹtọ si beeli, bi wọn ba si fun un, ofin lo fun, kii ṣe oun Yọmi Fabiyi.
Ara oun to n fa awujọ sẹyin ni aibọwọ fun ẹtọ ọmọniyan ati pe, idajọ ori ayelujara ti ọpọ awọn to n da si iṣẹlẹ naa n ṣe, ko le ran orilẹede yii lọwọ."
Lori itahunsiraẹni to n waye laarin rẹ ati Iyabọ Ojo lori ikanni ayelujara, Yomi Fabiyi ni oun mọ gbajumo osere naa si eeyan daadaa.
Amọ o ni sibẹ, igbagbọ oun ṣi ni pe agbẹjọ ẹnikan da, agba oṣika ni, oun ko si ni yẹsẹ kuro lori ero oun naa.
hhhhhh
Ni kutu hai oorọ Ọjọbọ ni iroyin miran tun jade sori ayelujara nibi ti obinrin kan ti n fi sun kan Yomi Fabiyi pe oun naa fẹ fipa ba oun lopọ nigba kan ri.
Gẹgẹ bi obinrin naa to kede ọrọ yii soju opo Instagram rẹ, actoryohan ti wi, iru ẹyẹ ni ẹyẹ n wọ tọ lẹyin, ni ọrọ Yomi Fabiyi ati Baba Ijesha, ta si ni eesi yoo gbe, bi ko se elegbo.
Obinrin naa, ẹni to koro oju si iha ti Fabiyi kọ si ero Iyabo Ojo, lo tẹsiwaju lati maa salaye ohun to sẹlẹ si lọdun 2016, to si ni diẹ lo ku ki Fabiyi fipa ba oun lopọ.
"Mo fẹ se ere itage, mo si kan si Yomi Fabiyi nipa rẹ, o ni ki n san ẹgbẹrun lọna marundinlogoji naira lati fi gba fọọmu bii ọmọ ẹgbẹ tiata rẹ.
Mo san ẹgbẹrun mẹẹdọgbọn ninu rẹ, to si ni ki n wa pade oun nibi ti wọn ti n se ere. Igba ti mo de ibẹ, lo tun ni ọọfisi ni fọọmu naa wa, to si ni ki n kalọ si ọọfisi oun.
Amọ ile rẹ ni adugbo Ogolonto nilu Ikorodu lo gbe mi lọ, o fun mi ni fọọmu lati kọ nnkan nipa mi sibẹ. Ibi ti mo ti n se bẹẹ lọwọ, lo ti jade ni ihooho wa ba mi, to si n na nnkan ọkunrin rẹ si mi."
Obinrin naa ni oun sa kuro ninu ile naa, ti oun si ni oun ko le sun ti nitori ere, o wa ni ko fi owo oun ransẹ si oun.
Nigba to n sọ ero rẹ lori iroyin naa, Fabiyi ni irọ to jinna sootọ ni ẹsun obinrin naa, ti ọrọ naa ba si da loju, ko lọ fi ẹjọ oun sun ọlọpaa.
Ogbomoso: Ẹbọ ọkùnrin àti obìnrin tí kò ní ìbálòpọ̀ rí ni wọ́n rú dènà ogun Fulani
Bakan naa lo tun woye pe awọn obinrin kan kundun ki wọn maa pa irọ mọ ọkunrin, oun si le duro osu kan lai ri obinrin, bi obinrin ko ba si gba fun oun, kii se dandan.
"Ẹ ba sa oogun si mi, titi ti opin aye yoo fi de, n ko le fi ipa ba obinrin lopọ laelae, ti ọrọ naa ba si da obinrin naa loju, ko  gba agọ ọlọpaa lọ.
Maa eran obinrin naa ni ẹwọn, ti n ko si ni gbọ ẹbẹ lasiko naa, nitori irọ nla lo pa mọ mi."
Eye Bank in Lagos: Ibùdó ìtọ́jú ojú ní kẹ fi ẹyinjú yín sílẹ̀ tẹ bá kú, àwọn kìí fojú ṣe ètùtù tàbí rúbọ
Oniruuru arun ẹfọju lo wa ti ko han si awọn eeyan, eyi to si yẹ ka da ara wa lẹkọ le lori.
Awọn eroja kan wa ninu oju ti a mọ si Conias, orisirisi nnkan si lo le fa a, ki awọn eroja naa da isẹ silẹ.
Aisisẹ wọn si le fa ipenija oju tabi ki oju naa fọ patapata, idi si ree ti BBC Yoruba fi lọ si ibudo ise oju pamọ lọjọ si to wa nilu Eko, to maa n fun awọn eeyan ti oju wọn ti fọ ni oju mii.
Amọ o se ni laanu pe ọpọ eeyan ni ko setan lati sugba ibudo yii, ti wọn kii si tọwọ bọ iwe lati fi oju wọn silẹ lẹyin ti wọn ba ku tan.
Mosunmade aya Faderin, tii se onimọ nipa itọju oju salaye fun wa nipa awọn eroja oju wọnyii, to si ni ti ọlọjọ ba de, oju nikan lo kọkọ maa yọ laarin ọjọ mẹta.
Amọ tawọn eeyan ba ti fun onimọ isegun ni asẹ lati tete yọ oju alaisi naa laarin ọjọ kan to ku, wọn yoo se itọju rẹ fun iwulo ẹlomiran.
Eyi si lo ni yoo mu ki awọn eeyan to ni ipenija oju, ti ko si riran mọ, le ri aanu gba lati riran pada.
Bakan naa ni ọkunrin kan, Emma Akana salaye fun wa nipa isẹ abẹ oju to se nigba ti ko le riran mọ, amọ to riran pada lẹyin ti wọn fun ni oju ẹlomiran.
Aya Faderin wa n rawọ ẹbẹ pe ki awọn alaye wa fun ile iwosan lasẹ lati yọ oju wọn lẹyin ti wọn ba ku tan fun iwulo ẹlomiran.
O fikun pe awọn kii fi oju naa se ẹbọ abi etutu gẹgẹ bi awọn eeyan kan se lero.
Baba Ijesha: Iléèṣẹ́ ọlọ́pàá ní wọ́n le gba béèlì ẹ̀ṣùn bíbá ọmọdé tage àmọ́ wọn kìí gba béèlì bíbá ọmọdé lòpọ̀
Ileesẹ ọlọpaa nipinlẹ Eko ti kede pe oun ko ni gba beeli gbajumọ osere tiata ti wọn fẹsun kan pe o fi tipa ba ọmọ ọdun mẹrinla lopọ, ti ọpọ eeyan mọ si Baba Ijesha.
Kọmisana fun ileesẹ ọlọpa nipinlẹ Eko, Akeem Odumosu lo kede bẹẹ lasiko ipade akọroyin to se ni olu ileesẹ ọlọpaa ipinlẹ Eko lọjọ Ẹti.
Odumosu, ẹni to sọrọ lori iwọde tawọn ajafẹtọ ẹni kan se wa sọdọ rẹ lati tako beeli Baba Ijesha tun ni, ẹsun meji ni wọn fi kan afurasi naa, idi si niyi ti yoo si se wa ni ahamọ ọlọpaa.
"Ẹsun akọkọ ni pe o ba ọmọ kekere lopọ lasiko ti ko tọ ati nibi ti ko tọ, ẹẹkeji nipe o n fi ọwọ kan ọmọde naa laigba asẹ lọwọ awọn obi rẹ.
A ri wipe nipa ẹsun keji yẹn, gbogbo iwadi ti a ṣe lo ti fi idi ẹ mulẹ wipe, o sẹ si ẹsun ti wọn fi kan sugbọn à ń duro ki ile ẹjọ sísẹ, ka le gbe lọ si ile ẹjọ.
Ẹsun nina ọwọ ere oge si ọmọde ta mọ si Sexual Assault ni wọn le fun afurasi ẹsun naa ni beeli amọ ẹsun ifipa ba ọmọde lopọ, eyiun Defilement ni wọn kii gba oniduro rẹ fun afurasi nipinlẹ Eko."
Kọmisana ọlọpaa ni Eko fikun pe, Ile ẹjọ nikan lo le fi idi rẹ mu lẹ pe lootọ ni Baba Ijesha jẹbi tabi bẹẹ kọ, amọ isẹ tiwa ni ka se iwadii, ka si fi oju afurasi naa ba ile ẹjọ.
"A ti ri ẹri to dani loju wipe Baba Ijesha ṣe nkan to yẹ ko ṣe labẹ ofin sugbon a kò ti fi silẹ.
À ti gbe iwe ẹjọ rẹ (Case file) lọ si ileeṣẹ ijọba to wa nipa ọrọ ofin (Justice ministry) lati ba wa fi oju ofin woo.
Nkan ti àwọn ọlọpaa ń duro de niyẹn, esi ti wọn ba fun wa labẹ ofin ni yoo ṣokunfa igbesẹ ọlọpaa sugbọn esikesi ti wọn ba fun wa, ọlọpaa yoo jẹki àwọn araalu mọ.
Emi gẹgẹ bi ẹnikan bi Ọga ọlọpaa ipinlẹ Eko, n ko ti ni kiwọn fi silẹ o, o si wa ni ahamọ ti wọn fi si"
Ọga ọlọpaa tun sọ wipe, ẹsun ti wọn le gba iduro eeyan ni ẹsun ti Baba Ijesha sẹ sugbọn ti wọn ba gba iduro afurasi lori rẹ, ko tumọ si wipe ẹsun ti wọn fi kan ti pari tabi pe o ti jare ẹsun ti wọn fi kan.
Ofin keji tun ni wipe afurasi ti wọn gba iduro rẹ lori iru ẹsun yii, ṣe eyi ko ni koba iwadi ti ọlọpaa ń se lọ, ti o ba jasi wipe yoo sakoba fun iwadi naa, agbara wa labẹ ofin lati mase gba iduro ẹni bẹẹ.
Odumosu wa mọ riri awọn ajafẹtọ ẹni to n se iwọde naa fun ọgbọn agba ti wọn lo lasiko iwọde wọn, to si ni ahesọ ọrọ ni pe wọn fẹ fun Baba Ijesha ni beeli.
"Ko si ẹni to n dunkooko mọ wa lati tu Baba Ijesha silẹ, bẹẹ ni ko si ẹni to n wa eekanna mọ mi lọrun bii Kọmisana ọlọpaa.
N ko le se ohun ti n ko ni awijare fun labẹ ofin, emi funra ara mi si ni mo n se amojuto gbogbo ẹsun to ba jẹ mọ iwa iyajusini laarin takọ-tabo."
Saaju la ti sọ fun yin pe, iroyin to n tẹ wa lọwọ bayii ti salaye pe iwọde alagbara kan yoo waye ni aarọ oni ọjọ Ẹti nilu Eko, lati ta ko gbigba beeli Baba Ijesha.
Baba Ijesha ni gbajumọ osere tiata ti wọn fẹsun kan pe o nawọ ere oge si ọmọde ọmọ ọdun mẹrinla kan laipẹ yii, to si wa ni ahamọ ọlọpaa ni agbegbe Panti nilu Eko.
Afurasi yii ni iroyin kan sọ pe wọn yoo gba beeli rẹ, ti yoo si maa lọ sile lati maa lọ koju ileẹjọ to ba ya, ti ahesọ iroyin kan si ni, fidio fìdí rẹ múlẹ pe lootọọ ni Baba Ijesha ba ọmọdebinrin naa ni ajọṣepọ tipa tipa.
Amọ iroyin to n tẹ wa lọwọ bayii ti salaye pe awọn ẹgbẹ ajafẹtọ ọmọniyan lorisirisi ati awọn obinrin to jẹ abiyamọ ti n gbaradi lati tako igbesẹ gbigba beeli Baba Ijesha naa.
Nigba to n ba BBC Yoruba sọrọ lori iwọ̀de alagbara to n bọ naa, agbẹjọro ati ajafẹtọ awọn obinrin, Oluwatoyin Ojo sọ pe ileeṣẹ ọlọpaa ni oun ko le sọ pe awọn ko le fidi rẹ mulẹ pe Baba Ijesha jẹbi ẹsun ti wọn fi kan an.
Oríṣun àwòrán, @d_lowla
Ajafẹtọ ẹni naa ṣalaye pe ọmọdebinrin yii sọ pe Baba Ijesha ba oun lajọṣepọ nigba toun wa ni ọmọ ọdun meje, pẹlu afikun pe Baba Ijesha tun ki kọkọrọ bọ oun loju ara.
Bakanna ni Baba Ijesha fun ra rẹ jẹwọ pe lootọọ loun fipa ba ọmọdebinrin yii to n gbe lọdọ adẹrinpoṣonu, Princess lọpọ.
"Lẹyin ti ẹrọ CCTV tu aṣiri bi Baba Ijesha tun ṣe fipa ba ọmọ naa ni ajọṣepọ tàn nígbà to pe ọmọ ọdun mẹrinla, n ṣe lo n bẹbẹ fún aforiji pe iṣẹ Esu ni.
Ati pe ile iwosan fidi rẹ mulẹ pe, ẹnikan ti fipa ba ọmọde naa lopọ lẹyin ayẹwo ti wọn ṣe fún ọmọ ọhun.
Ogbomoso: Ẹbọ ọkùnrin àti obìnrin tí kò ní ìbálòpọ̀ rí ni wọ́n rú dènà ogun Fulani
Ko gba ibi kan ye mi ohun to mu kawọn ọlọpaa sọ pe ko si ẹri to daju pe lootọọ ni Baba Ijesha fipa ba ọmọ naa lopọ, ajafẹtọ awọn obinrin ṣalaye."
Agbẹjọro naa sọ pe idi ni yii toun at'awọn ọmọ Naijiria kan fi fẹ ṣe iwọde lọ sọdọ awọn ọlọpaa lori ọrọ naa ni aarọ ọjọ Ẹti.
Ajafẹtọ awọn obinrin yii ko ṣai mẹnu ba ipa ti iyanṣẹlodi awọn oṣiṣẹ eto idajọ le ni lori ọrọ naa .
O ni lootọọ ni eeyan ko gbọdọ lo ju ọjọ kan lọ ni atimọle, ti wọn ba fi ẹsun ti wọn le gba beeli rẹ kan an.
Olugbon of Igbon: ‘Rubber Stamp’ làwọn aṣòfin àpapọ̀, wọn kò ṣojú aráàlú
Agbẹjọro naa ṣalaye pe eeyan ko gbọdọ lo ju ọjọ meji ni atimọle lọ ti ileẹjọ ba jina labẹ ofin orile-ede Naijiria.
O ṣalaye pe ileẹjọ lo le sọ bo ya Baba Ijesha jẹbi ẹsun ti wọn fi kan an tabi ko jẹbi.
O ni ti tawọn ọlọpaa ni lati gbe ẹsun ti wọn ba mu wa fún wọn lọ sí ilé ẹjọ.
Bẹẹ ba gbagbe, ọpọ awọn obinrin to jẹ osere tiata ati iya ọmọ ti ọrọ kan, Princess ni wọn se iwọde kan l‘Ọjọbọ ni agọ ọlọpaa Panti, lati tako gbigba beeli baba Ijesha.
Oduduwa Nation: Àwọn ọlọ́pàá bíi 200 ló dènà dè wá níbi tí a ti fẹ́ ṣe ìwọ́de l'Abeokuta - Ilana Omo Oodua
Oríṣun àwòrán, Ìlànà Ọmọ Oòduà International Facebook
Ẹgbẹ to n ja fun ominira ilẹ Yoruba, Ilana Ọmọ Oodua ti sọ pe ileeṣẹ ọlọpaa ipinlẹ Ogun ti fi sikun ofin mu eeyan marundinlọgbọn ti wọn n ṣe iwọde niluu Abeokuta.
Ninu atẹjada kan ti akọwe ẹgbẹ naa, Maxwell Adeleye buwọlu, eyii to fi ṣọwọ si BBC lo ti kede bẹẹ.
O ni nnkan bii igba ọlọpaa lo yii awọn eeyan naa ka ki wọn to fi ofin mu wọn l'Abeokuta.
"Gẹgẹ bo ṣe sọ ""A fẹ ki gbogbo eeyan mọ pe ileeṣẹ ọlọpaa ipinlẹ Ogun ti fi panpẹ ofin mu marundinlọgbọn ninu awọn eeyan wa lasiko ti wọn gbaradi lati bẹrẹ iwọde fun ominira ilẹ Yoruba."""
A si fẹ jẹ ko wa ni akọsilẹ pe awọn eeyan naa ko tapa si ofin kankan, ni ṣe ni wọn n ṣe ohun to tọ si wọn gẹgẹ bii ẹtọ wọn labẹ ofin lati ja fun ominira ati lati korajọ pọ gẹgẹ bii ofin ṣe la a kalẹ.
O ni awọn gẹgẹ bii ọmọ ẹgbẹ Ilana Ọmọ Oodua kii ṣe oni jagidijagan, nitori naa, awọn n ke si ijọba lati tu awọn eeyan naa silẹ ni kankan, bi bẹẹ kọ awọn yoo gbenu woju ẹkun ileeṣẹ ọlọpaa kaakiri ilẹ Yoruba.
Ẹgbẹ naa tun ke si gomina ipinlẹ Ogun, Ọmọba Dapo Abiodun ko ma ṣe gba awọn kan laye lati lo ipinlẹ rẹ lati fi ti tẹ ẹtọ awọn ọmọ Yoruba loju.
Iroyin ni iwaju aafin Alake ti ilu Ẹgba ni awọn ọlọpaa naa ti ko awọn oluwọde ọhun sinu ọkọ Black Mariac ti wọn gbe wa.
Ṣaaju ni ileeṣẹ ọlọpaa ipinlẹ Ogun ti kọkọ ki awọn oluwọde naa nilọ pe wọn ko gbọdọ gunle iwọde naa, bi bẹẹ kọ, awọn eeyan naa yoo foju wina ofin.
Ṣugbọn awọn ọmọ ẹgbẹ naa fesi pada pe ti ọlọpaa ni wọn n wi nitori awọn yoo tẹsiwaju pẹlu iwọde naa.
Oríṣun àwòrán, Ìlànà Ọmọ Oòduà International Facebook
Ọrọ iwọde ti awọn ajijagbara to n fẹ orilẹede Yoruba, eyi ti ileesẹ ọlọpaa nipinlẹ Ogun wọgile ti n fa awuyewuye bayii.
Idi ni pe awọn ẹlẹgbẹjẹgbẹ lorisirisi lo ti n leri leka pe bi ọlọpa ba fẹ, bi wọn si kọ, ohun to ni ki awọn mase yẹn, awọn yoo se, se isu atẹnumọran kii jona.
Ọjọbọ ni ileesẹ ọlọpaa nipinlẹ Ogun fi atẹjade kan sita pe oun ti wọgile iwọde tawọn ajijagbara fẹ se nilu Abeokuta lati beere fun idasilẹ orilẹede Yoruba.
Amọ Ẹgbẹ Ilana ọmọ Oodua, IOO, ninu atẹjade kan to fisita ati lasiko to n ba BBC Yoruba sọrọ kede pe, gbogbo agbara ti awọn ajijagbara naa ni lawọn yoo fi tako awọn ọlọpaa nilu Abeokuta loni.
Atẹjade naa ti akọwe ẹgbẹ, Maxwell Adeyemi Adeleye fọwọsi, tun kesi awọn ẹlẹgbẹjẹgbẹ lorisirisi lati maa bọ nilu Abeokuta lọjọ Satide oni lati wa tọpinpin bi iwọde naa yoo se lọ.
Oríṣun àwòrán, Ìlànà Ọmọ Oòduà International Facebook
Lara awọn ẹgbẹ to kesi ni ẹgbẹ awọn akọroyin lobinrin ati lọkunrin, ẹgbẹ ajafẹtọẹni Huriwa, Serap, CDHR, ẹgbẹ awọn agbẹjọro atawọn ẹgbẹ miran.
Ẹgbẹ Ilana Ọmọ Yoruba naa ni ileesẹ ọlọpaa kede ogun si ẹtọ ọmọ Yoruba lati korajọ se iwọde alafia ni, pẹlu bo se ni oun wọgile iwọde naa.
Ẹgbẹ IOO naa wa n fewe ọmọ mọ ileesẹ ọlọpaa leti pe, gbogbo ohun to ba gba nilana ofin ati lọdọ awujọ agbaye, ni awọn yoo fun to ba, to ba fi gbe igbesẹ lati da iwọde naa duro.
Bí Oduduwa Republic bá bẹ̀rẹ̀, a ò ní ṣe aburú fún àwọn tó takò wá, ìlànà ààtẹ̀lé rèé - Banji Akintoye
Ẹgbẹ IOO, ti alagba Banji Akitoye n ko sodi  wa n ke tantan sileesẹ ọlọpaa ipinlẹ Ogun pe oun yoo se iwọde naa lọni gẹgẹ bo se wa ni akọsilẹ nitori wọn ko ni agbara labẹ ofin lati da awọn duro.
Ọlọpaa ko le da wa duro, a se iwọde Yoruba Nation l‘Abeokuta lọjọ Satide
Oríṣun àwòrán, Oduduwa Grand Alliance For Independence
Awọn ẹlẹgbẹjẹgbẹ ati awọn eekan nilẹ Yoruba, ti bu ẹnu atẹ lu igbesẹ ileeṣẹ ọlọpaa nipinlẹ Ogun lati tako iwode Yoruba Nation ti yoo waye ni ilu Abeokuta lọla.
Ninu atẹjade ti ileeṣẹ ọlọpaa fi lede ni wọn ti fi ẹsun kan awọn ti wọn n ṣe iwode lati beere fun idasilẹ orilẹede ilẹ Yoruba wi pe wọn n da alaafia ipinlẹ Ogun ru.
Agbẹnusọ fun ileeṣẹ ọlọpaa ni igba mẹrin ni wọn ti ṣe iwode naa laarin osu kan, ti o si mu wahala ati ipalara dani fun awọn eniyan ara ipinlẹ Ogun.
Amọ, Banji Akintoye to jẹ agba ọjẹ nilẹ Yoruba ati adari ẹgbẹ ọmọ Yoruba, Ilana ọmọ Yoruba ni, ko si otitọ kankan ninu ọrọ ti ileeṣẹ ọlọpaa sọ.
Akitoye ni awọn ni aṣẹ labẹ ofin orilẹede Naijiria lati ja fun ẹtọ awọn nipa ṣiṣe iwọde lai fa wahala.
Bakan naa ni ẹgbẹ Oodua People's Congress ni dandan iwọde naa yoo waye ni Satide, Ọjọ Kinni, Osu Karun un, ọdun 2021.
Ẹgbẹ Oodua people's Congress OPC, ti ni ko si ohunkohun ti o le da awọn duro iwọde ni ipinlẹ Ogun ni Ọjọ Satide.
Oríṣun àwòrán, OPC
Agbẹnusọ fun ẹgbẹ OPC, Shina Akinpelu ni oun ni igbagbọ pe ko to di asalẹ, ileeṣẹ ọlọpaa ati awọn adari yoo ti wa ojutu si ọrọ naa.
''Ọlọpaa yẹ ko fun wa ni 'caution paper' ti a tọ wọ bọ pe ko ni si wahala nitori awọn onijagidijagan to ba fẹ lo iwọde naa lati da wahala silẹ.
''Wọn fẹ sọ wa di ẹranko ni, a ko ni gba fun wọn lati da wa pada si igba ''Abacha must go'', amọ ti wọn ba fẹ wahala wọn yoo ri.''
Bakan naa ni ẹgbẹ OPC ni ti ileeṣẹ ọlọpaa ba ṣiṣẹ pọ pẹlu awọn, ohun gbogbo a lọ ni irọwọrọṣẹ.
Ọlọpaa yẹ ko pese aabo fun wa lasiko iwọde, kii ṣe ko halẹ mọ wa - Ilana Ọmọ Yoruba
Ẹgbẹ Ilana ọmọ Yoruba ti ni ko si ẹnikẹni to lee da awọn duro lati ṣe iwọde lati pe fun orilẹede ilẹ Yoruba.
Lasiko ti Akọwe Ẹgbẹ Ilana Ọmọ Odua, Opeoluwa George Akinola n ba BBC News Yoruba sọrọ, o ni awọn ni aṣẹ gẹgẹ bi ọmọ Yoruba lati ṣe iwode.
Oríṣun àwòrán, Facebook
''Ẹni kankan ko laṣẹ lati ni ki a ma rin ni ilẹ wa nitori ilu wa lawa, a ma rin, a ma yan fanda nitori a kii ṣe onijagidijagan nitori naa ko ni si wahala''
''A ṣe ni Ibadan ko si wahala, nitori naa a ma ṣe ni Abeokuta lai si wahala''
Ọlọpaa ipinlẹ Ogun yẹ ki wọn pese eto aabo fun wa nitori a ko gbe ibọn ati ada lati sewọde, a fẹ ba awọn araalu sọrọ lori nkan ti a fẹ''
Ẹgbẹ Ilana Ọmọ Yoruba fikun wi pe ọmọluwabi ni awọn, nitori naa ki ileeṣẹ ọlọpaa ma da wahala silẹ.
A kii ṣe o ni jagidijadan, a ko ni fi tipatipa ṣe iwọde ni Ogun - Banji Akinoye
Banji Akitoye to jẹ adari ẹgbẹ Ilana Ọmọ Yoruba ti ni awọn yoo tiraka lati ba ileeṣẹ ọlọpaa jiroro, ki ilẹ Ọjọ Satide to mọ.
Oríṣun àwòrán, OTHERS
Amọ, o ni ti ileeṣẹ ọlọpaa ba tẹnumọ pe dandan wọn ko gbọdọ ṣe iwọde naa, ko ni waye.
Banji Akintoye fikun wi pe, kii ṣe tipatipa ni Yoruba gbọdọ duro ni Naijiria nitori naa ni awọn ṣe n pe fun Yoruba Nation nitori iṣekupani ojojumọ yii gbọdọ dopin.
''A ti wi pe kii ṣe ẹṣẹ pe awọn ko ṣe Naijiria mọ, ki onikaluku lọ nilọ tirẹ''
Bakan naa ni Akintoye ni awọn to wa si iwode to waye ni Ibadan le ni miliọnu meji, ti ko si si rogbodiyan kankan.
Oríṣun àwòrán, Oduduwa Grand Alliance For Independence
Saaju la ti mu iroyin wa fun yin pe, o dabi pe nnkan ti n pakasọ fun awọn eeyan to n beere fun idasilẹ orilẹede Yoruba lori iwọde ti wọn n gbero lati se nipinlẹ Ogun ni ọla ọjọ Satide.
Idi ni pe ileesẹ ọlọpaa nipinlẹ Ogun ti faake kọri lati gba awọn oluwọde naa laaye lati wa se iwọde wọn, ti wọn si rọ wsn lati jami lori iwọde ọhun.
Atẹjade kan ti agbẹnusọ fun ileesẹ ọlọpaa nipinlẹ Ogun, Abimbola Oyeyemi fisita l'Ọjọbọ lori ọrọ yii salaye pe awọn iwọde ti awọn ẹgbẹ yii ti se latẹyinwa lo n fa sunkẹrẹ fakẹrẹ yika ipinlẹ naa.
Bakan naa ni ileesẹ ọlspa sọ pe iwọde ọhun tun le sokunfa rogbodiyan nipinlẹ naa, tawọn ọmọ isọta yoo si ja iwọde naa gba lati da araalu laamu.
"Bẹẹ ba gbagbe, awọn ikọ to n polongo fun idasilẹ orilẹede Yoruba se iwọde lọjọ Kọkanlelogun osu kẹta ọdun yii nilu Isara Remo, ti wọn si di awọn opopona, eyi to mu lilọ-bibọ ọkọ pakasọ.
Irufẹ iwọde yii naa tun waye nilu Sagamu lọjọ Kẹrindinlogun osu Kẹrin yii, ti wọn si fẹ doju ija kọ agọ ọlọpaa to wa nilu naa lainidi.
Tun wẹ, wọn tun se iwọde miran ni Ajuwọn lọjọ kẹẹdọgbọn osu yii bakan naa, ti wọn si n pin awọn iwe to n ru eeyan ninu.
Bẹẹ ni wọn n lẹ oko mọ awọn ọlọpaa ati ileesẹ agbofinro miran."
Atẹjade naa ni ikọ yii lo tun n beere lati se iwọde fun igba kẹrin lọla ọjọ kinni osu karun ọdun yii nilu Abeokuta, eyi ti yoo jẹ ikẹrin iru rẹ ni sisẹ n tẹle.
Olugbon of Igbon: ‘Rubber Stamp’ làwọn aṣòfin àpapọ̀, wọn kò ṣojú aráàlú
Ileesẹ ọlọpaa ni o maa n nira fawọn lati ka awọn janduku to ba jẹ asawọ laarin awọn oluwọde lọwọko ni awọn iwọde to ti waye saaju, ti wọn si maa n da omi alaafia ilu ru.
"Amọ a ko le kawọ gbera kawọn eeyan kan maa mu awọn araalu yoku lọwọ sẹyin pẹlu ihuwasi wọn, eyi to tun n dunkooko mọ isọkan Naijiria.
Ta ba si sọra, o seese ki ipinlẹ Ogun bọ sinu irora ati ipayinkeke to n ti idi irufẹ iwọde bẹẹ waye ni awọn ipinlẹ miran ti wọn ti gba wọn laaye.
Yemi Farounbi: Yorùbá yóò dáàbò bo ara rẹ́, bí ìjọ́ba bá kùnà láti ràgà bò wọ́n
Ileesẹ ọlọpa nipinlẹ Ogun wa n rọ awọn asaaju ikọ to n pe fun idasilẹ Oduduwa lati jami lori erongba wọn lati se iwọde miran nibikibi yika ipinlẹ naa.
10 Streets In Ilorin: Oke Kura, Ita Ogunbọ, Ita Kudimoh jẹ́ ara orúkọ àdúgbò tó níí ṣe pẹ̀lú ìjà Oyo àti Ilorin
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ilu Ilorin wa lara awọn ilu ilẹ Yoruba to lamilaaka, ti itan idasilẹ rẹ si nii se pẹlu ilẹ Kaarọ ojire.
Ilorin jẹ ilu kan to kun fun itan ati iriri bi awọn Yoruba ati awọn ẹya miran bii Fulani, Bariba, Tapa atawọn ẹya miran lapa Oke Ọya, se ni ajọsepọ, eyi to bi irẹpọ oniruuru aṣa ti ko si iru afiwe rẹ nilẹ Yoruba kankan.
Itan ilu Ilorin pọ debi pe ti a ba ni ka maa sọ labẹ apilẹkọ yii, a ko ni le e pari rẹ, amọ a le se agbeyẹwo awọn orukọ adugbo to jẹ manigbagbe nilu Ilorin to n safihan ibasepọ Oyo ati Ilorin laye atijọ.
Awọn adugbo naa ree:
Nigba ti Alaafin Oluewu ti ilu Oyo kogun ja Ilorin ni ọdun 1835, ọkan lara awọn jagunjagun to dara pọ mọ awọn ọmọ ogun Oyo ni Woru Kura.
Kura ni orukọ inagijẹ rẹ, ti eleyi si tumọ si Ìkookò (Hyena) lede Hausa.
Jagunjagun yii jẹ ẹya Baruba ti a si mọ si Sona Kpera.
Wọn fi adugbo Oke Kura sọri rẹ nitori pe ibẹ ni ọwọ awọn ọmọ ogun Ilorin ti tẹ.
Oke Kura gba orukọ rẹ lẹyin iṣẹlẹ yii ati pe, ni Oke Kura ni wọn ti ṣekupa Sona Kpera.
Bi awọn eeyan ko ba fẹ pe orukọ adugbo yii ni Oke Kura, wọn a tun maa pe ni Ode Olohunmamuwa nitori ọgba ẹwọn to wa nibẹ.
'Fulani Ilorin l'ọkọ mi'
Ita Ogunbo/Ita Kudimoh
Orukọ awọn adugbo mejeeji yii naa ni ohun ṣe pẹlu ogun ti Oyo ko ja Ilorin lọsun 1835, eyi ta mẹnu ba saaju.
Itumọ orukọ adugbo Ita Ogunbọ, ninu alaye tawọn onimọ nipa itan Ilorin ṣe fun wa, pin si ọna meji.
Akọkọ ibẹ ni pe lasiko ogun yii, adugbo ibi ti oogun tawọn ọmọ ogun wọn ti jabọ, ni wọn fi sọri adugbo yii.
O tumọ si pe ''Ita ti oogun ti bọ'' ni kukuru, Ita Ogunbọ.
Alaye ẹlẹẹkeji ni pe adugbo yii ni ibi ti wọn ti n bọ ''Ogun'' ṣugbọn itan eleyi ko gbalẹ to alakọkọ.
Ìjọba AbdulRazaq ti wólé aláànúú wa ní Ilorin
Ita Kudimoh
Adugbo Ita Kudimoh, gẹgẹ bi itan ti a ri ka ninu iwe alagba LAK Jimoh, naa ni ohun ṣe pẹlu ogun ti a n ba ọrọ rẹ bọ.
Ita Kudimoh ko jina si Ita Ogunbo, nibi ni iku di awọn ọmọ ogun Oyo to wa kogun ja Ilorin mọ.
Ita ti iku di wọn mọ"". Ita Ẹgba"
Adugbo yii ni ibi ti awọn eeyan Ẹgba to n gbe nilu Ilorin tẹdo si.
Titi di oni, agboole kan wa ti wọn n pe ni Ile Ẹgba, ti eleyi si fi han pe orisirisi ẹya Yoruba lo wa nilu Ilorin.
Yatọ si orukọ agboole Ile Ẹgba yii, awọn agboole mii naa bi Agboole Ologbomoṣọ, Agboole Baba Offa ati awọn agboole mii, ti orisun wọn jẹ ti ilẹ Yoruba wa ni Ilorin.
Geri Alimi/Garin Alimi
Yoo ṣoro ki eeyan maa bọ lati Eko tabi Ibadan wa si Ilorin, ko ma kọja niwaju opopona tabi adugbo taa n pe ni Geri Alimi.
Geri Alimi jẹ adugbo ikini kaabọ si ilu Ilorin ni kete ti eeyan ba ti n wọ inu ilu bọ.
Ṣugbọn orukọ Geri Alimi ti wọn fi sọ adugbọ yii jẹ ilumọọka ni Ilorin, paapa bi a ba wo itan bi awọn Fulani ti ṣe tẹdo ni ilu naa.
Adugbo yii si ni Alimi tẹdo si, ẹni tii se Fulani to gba Ilorin lọwọ Aarẹ Ọna Kakanfo, Afonja.
Oríṣun àwòrán, Xultan Visuals
Geri Alimi tumọ si ilu Alimi tabi ilu onimọ.
Adugbo yii si ni awọn Fulani musulumi labẹ idari Sheikh Salih Janta, tawọn onitan a maa pe ni Alimi tẹdo si, lati maa ṣiṣẹ Daawah tabi iwaasu wọn.
Loni bi a ba pe Geri Alimi, ile iwosan to wa nibẹ ti wọn n pe orukọ rẹ naa ni Geri Alimi Hospital, lọpọ a maa ranti.
Nibi yii ni ijọba ṣe flyover ẹyọ kan ṣoṣo to wa nilu Ilorin si.
Ile ifiweranṣẹ Post Office to wa niwaju ibẹ ni wọn fi sọ orukọ adugbo yii.
Lara nkan tawọn eeyan si mọ Post Office si ni pe, awọn to n ta ọja lẹgbẹ oju irin reluwe ko jina sibẹ, ati pe o jẹ gẹgẹ bi ọna tawọn elero ọkọ to n gbe ilu bi Offa ati Oshogbo ti maa n gbe ero.
Bi awọn eeyan ba si n ṣe iwọde, Post Offfice wa lara ibi ti wọn maa n pejọ si nitori pe awọn eeyan a maa pade nibi lọpọ igba.
Oríṣun àwòrán, Gobir Foundation
Adugbo yii ni gbajugbaja onimọ ẹsin Islam Solagberu ati awọn eeyan rẹ tẹdo si nigba ti wọn fi wa si Ilorin.
Yatọ si pe Solagberu jẹ alufaa, o tun jẹ onisowo.
Saaju ki Alfa Alimi to de silu Ilorin, wọn ka Okesuna gẹgẹ bi agbegbe to wa lẹyin ilu ti wọn n pe ni Ilorin gan.
Loni awọn to n ta ọja ati awọn Hausa lo wa ni adugbo naa loni.
Ileewe alakọbẹrẹ akọkọ ni Kwara ta mọ si Okesuna Primary School wa ni adugbo yii.
Ọdun 1915 ni wọn da ileewe naa silẹ ni wọọdu Zango to wa labẹ ijọba ibilẹ iwọọrun Ilorin.
Ninu awọn eekan ilu Ilorin to kẹkọ jade ni ileewe naa ni Mallam Muhammadu Ajeigbe Gobir(1900-1960), Waziri ilu Ilorin akọkọ.
Aarin gbungbun Ilorin nibi ti awọn eeyan mọ si Oke Male ni adugbo taa n pe ni Pakata wa.
Opopona rẹ, Pakata Road si bẹrẹ lati Oja Oba titi to fi de ''Roundabout'' Pakata.
Adugbo Pakata lamilaaka laarin awọn eeyan Ilorin nitori awọn eeyan jankan jankan ọmọ bibi ilu Ilorin to wa lati ibẹ.
Adugbo Pakata ni wọn ti bi oṣere tiata ilumọọka nii, Adebayo Salami, tawọn eeyan mọ si ọga Bello.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Lagbo oṣelu, awọn ilumọọka bi S.B Pakata ati awọn alfa onimọ bi Sheikh Ghali Alaaya wa lati adugbo Pakata.
Adugbo Pakata naa ni wọn da Ileewe alakọbẹrẹ keji ni Kwara si lẹyin ti Okesuna, iyẹn Pakata Elementary School.
Bi eeyan ba fẹ lọ si adugbo bi Alore, Adeta, Ita Nmo ati Oloje to fi mọ Ogidi ati Oko Olowo, o le gba Pakata de ibẹ.
Opopona Taiwo nilu Ilorin kan, Ilorin kan ni.
Bi eeyan ba si ti wọ inu ilu naa, ni yoo ti ri pe ọna yii yatọ nipa titi rẹ ati awọn ile itaja to wa lapa ọtun ati osi rẹ.
Wọn fi orukọ opopona Taiwo road sọri ọgagun Ibrahim Taiwo, to jẹ alakoso ipinlẹ naa lasiko ijọba ologun ọdun 1975-1976.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Bi a ko ba gbagbe, lasiko ifitẹgbajọba ni wọn pa Ibrahim Taiwo ati ọgagun Murtala Mohammed to jẹ olori ologun Naijiria nigba naa.
Ni iranti rẹ ni wọn fi sọ opopona yii ni Taiwo Road.
"Ṣaaju igba naa ""Oyo Bye-Pass"" ni a ri akọsilẹ pe wọn n pe adugbo yii."
Orukọ meji ni adugbo Unity Road n jẹ.
Lọkan awọn araalu, Unity Road ni wọn mọ opopona ọhun si ṣugbọn lakọsilẹ lọdọ ijọba, Wahab Folawiyo lorukọ rẹ n jẹ.
Eyikeyi ti ẹ ba darukọ fawọn awakọ, ko si eyi ti wọn ko mọ.
Oríṣun àwòrán, Ilorin Info
Opopona Unity bẹrẹ lati iyana tawọn adari ọkọ Traffic Warden wa ni Taiwo ki a to maa lọ si Taiwo Isale.
Loju ọna yii laa ti ri ileeṣẹ awọn panapana ati ile inaju taa mọ si Amusement Park.
Lopopona Unity bakan naa, awọn ile ijọsin bi ECWA naa wa, ti awọn ile itaja naa si wa nibẹ.
Genesis: Ariwo sọ lórí bí ìjọ Mùsùlùmí ṣe pe wòlíì sí òru Lailatul Quadir
Oríṣun àwòrán, Suphian Opeyemi Sodiq/Facebook
Yoruba ni ẹsin ko fa ija, bo ba se wu ni laa se ẹsin ẹni.
Amọ eyi ko ri bẹẹ pẹlu isẹlẹ kan to n waye lori ayelujara eyi tawọn eeyan n gba bii ẹni gba igba igba ọti, ti wọn si n tutọ si ara wọn loju lori ọrọ ẹsin.
Ohun to sokunfa isẹlẹ yii ni ti ijọ ẹsin Islam kan, Ahbaab li-Islam pẹlu ajọsepọ Markazu Ahbaab Uloomudeen to fẹ se isin oru abiyi taa mọ si lailatul Quadir.
Ijọ naa ti Fadheelatul Ustaz Alhaji Habeebulah se alakoso rẹ, lo wa ladugbo Iju Ishaga nilu Eko, ti isin oru abiyi naa yoo si waye ni ọjọ Keje osu karun taa wa yii, laago mẹwa owurọ.
Oríṣun àwòrán, Suphian Opeyemi Sodiq/Facebook
Amọ ohun to wa jẹ iyalẹnu fawọn ọmọ Naijiria to ri iwe ipe ti wọn fisita fawọn alejo, ni bi wọn se ni Wolii ati Ojisẹ Ọlọrun Oladele Ogundipe, ti ọpọ eeyan mọ si Wolii Genesis, ni alejo pataki nibi eto naa.
Iwe ipe yii ni Suphian Opeyemi Sodiq fi soju opo Facebook rẹ.
Bẹẹ ba gbagbe, awuyewuye waye laipẹ yii nipa Wolii Genesis ati ẹsun ti obinrin kan fi kan pe o gba owo lọwọ oun lati fi ra ilẹ amọ ti ko ri owo ati ilẹ.
Ọrọ yii lo di tile ẹjọ, ti wolii Genesi si lo osu meje lọgba ẹwọn, ki wọn to gba beeli rẹ laipẹ yii.
Haa, ki ni eleyi si lo n gba ẹnu ọpọ eeyan lori ayelujara to ri iwe ipe naa.
Oríṣun àwòrán, Al-Mudeer Ar-Rashādy Oladele/Facebook
Ọpọ ọmọ Naijiria to si fesi lori isẹlẹ naa lo koro oju si igbesẹ pipe wolii wa sibi isin musulumi nigba ti awọn eeyan miran ni ko si ohun to buru ninu rẹ.
Ni ero awọn ọmọ Naijiria to da si ọrọ naa, wọn ni igbesẹ naa tako ẹsin Islam pupọ, nitori oru abiyi ni ọwọ ju ọwọ ti wọn fi mu yii lọ.
Koda, Rashady Oladele lero tiẹ ni se lo yẹ ki wọn fi iya to jopin jẹ ẹni to se iru eyi, ti awọn miran si lero pe tori owo ni wọn se hu iwa naa.
Oríṣun àwòrán, Ibitoye Farian/Facebook
Elegushi Romance Fraud: Ọwọ́ tẹ abánikunlé tó fi orúkọ Ọba Elegushi lu obìnrin kan ní jìbìtì ₦51m
Oríṣun àwòrán, @PoliceNG
Afurasi meji to fi orukọ ọba Elegushi nipinlẹ Eko lu eeyan ni jibiti, ti wa ni ahamọ ọlọpaa
Ileesẹ ọlọpaa nipinlẹ Eko ti ṣa fihan ọkùnrin kan, Moses Olaitan ati ẹnikeji rẹ, Segun Omoshola fun ẹsun pe wọn fi orukọ ọba Elegushi lu jibiti.
Iroyin sọ pe nise ni àwọn eniyan naa n pe ara wọn ni Ọba Saheed Elegushi fun obinrin kan ti wọn pade lori ayelujara Facebook, titi wọn fi lu u ni jibiti miliọnu marundinlọgọta naira.
Ọga Agba ọlọpaa nipinlẹ Eko, Hakeem Odumosu sọ lasiko to fi ojú awọn afurasi naa han ni olu ileesẹ ọlọpaa to wa ni Ikeja pe, lẹyin ti wọn fi ẹjọ wọn sùn nileesẹ ọlọpaa, lẹyin oṣu mẹta tí wọn da ọ̀ràn naa, ni ọwọ awọn ọtẹlẹmuyẹ tẹ Segun ati Olaitan.
Olugbon of Igbon: ‘Rubber Stamp’ làwọn aṣòfin àpapọ̀, wọn kò ṣojú aráàlú
Ọkan lara awọn afurasi naa, Olaitan sọ pe oun fi orukọ ọba naa ṣi oju opo ibanidọrẹ lori Facebook, ti oun si bẹrẹ si ni fi àwọn aworan rẹ sibẹ lati fa oju awọn to n wa ọkọ mọ́ra.
Nipasẹ bẹẹ si ni obinrin ti wọn lu ni jibiti fi bọ si panpẹ wọn.
Olaitan ṣalaye pe, obìnrin naa ba oun sọrọ lori Facebook pe oun fẹ ẹ fẹ ọba ni ọkọ.
"Mo sọ fun pe to ba fẹ ẹ fẹ ọba, o gbọdọ ṣe àwọn nkan ibilẹ diẹ, o si gba lati ṣe bẹ ẹ.
 O sọ fun mi pe ki n fi nọmba apo asunwọn banki mi ránṣẹ si oun, sugbọn mi o ni. Eyi si lo mu mi fi ọrọ lọ Segun, to wa nọmba akanti ta fi gba owo naa."""
Olaitan sọ pe miliọnu meji aabọ Naira ni wọn san fun oun, ati pe nígbà ti ọwọ tẹ ẹ, ni oun to mọ pe miliọnu mọkanlelaadọta ni obinrin naa san.
aaaaaaaaaaaaaaa
O sọ pe nọ́mbà foonu oun ni awọn ọlọpaa tọpinpin rẹ, ti ọwọ fi tẹ oun lasiko ti oun n palẹmọ fun ayẹyẹ ọjọ ibi oun.
Ni ti Segun to wa akanti ti wọn fi gba owo naa, o sọ pe lootọ ni oun mu lọ si ọdọ awọn to pese akanti naa.
Sugbọn o ni miliọnu mẹta aabọ Naira ni wọn fun oun, iyalẹnu si lo jẹ fun oun nigba ti awọn ọlọpaa sọ pe miliọnu mọkanlelaadọta Naira ni obìnrin naa fi ránṣẹ.
Bẹẹ ba gbagbe laipẹ yii ni Oluwo tilu Iwo, Ọba Abdulrasheed Adewale Akanbi naa figbe bọnu pe, awọn eeyan kan n gba awọn obinrin to nifẹ lati di ayaba ni aafin oun lori Facebook pẹlu orukọ oun.
Baba Ijesha: Iyabo Ojo fèsì fún Bukky Black, Ó ní ọ̀rọ̀ rírùn ló sọ, ìtìjú ńlá ló jẹ́ fún ìran obìnrin àti ìyá
Oríṣun àwòrán, Instagram/iyaboojofepris/buckkyblack28
Ọrọ ti ẹsun aṣemaṣe ti wọn fi kan gbajumọ oṣere tiata, Baba Ijẹsha yoo da silẹ lawujọ awọn oṣere Yoruba yoo fẹẹ domiru diẹ o.
Nibayii, iyabọ ojo ti fesi si eekan oṣere miran, Bukky Black  to sọ pe ko si bi Baba Ijesha ṣe lee ṣe ohun ti wọn pe o ṣe naa nitori ninu ọrọ rẹ ẹṣin  inu iwe ni Baba Ijẹsha ti ko lee ta.
Iyabọ Ojo ni iyalẹnu nla lo jẹ fun oun pe Bukky Black to jẹ agbablagba ninu owo ere tiata lee sọ ọrọ naa ati pe itiju nla lo jẹ fun iran obinrin atawọn iya lagbaye.
Iyabọ Ojo ninu fidio kan to fi sita lori ayelujara ṣalaye pe kii ṣe ohun to boju mu pe Bukky Black fẹ ki wọn boo mọle nitori pe o jẹ ọrẹ rẹ.
O ni bi Bukky Black ba n sọ pe oun ko ri Baba Ijẹsha pẹlu obinrin ri, a jẹ pe Bukky Black ko ranti pe Baba Ijesha ti ni iyawo ri to si tun ti bimọ ri.
Akẹgbẹ wa kan ti ṣe aṣemaṣe o si yẹ ko foju wina ofin lori rẹ ki awọn to ku lee fi kọgbọn.
Oríṣun àwòrán, buckkyblack28/Instagram
Awuyewuye miran tun ti bẹ silẹ lori ẹsun asemase pẹlu ọmọ ọdun mẹrinla ti wsn fi kan Baba Ijesha, tii se agbajumọ oesere tiata.
Lọtẹ yii, obinrin mii to jẹ gbajugbaja osere tiata ti ọpọ eeyan mọ si Bukky Black ti wa dojukọ akẹẹgbẹ rẹ ninu isẹ tiata bakan naa, Iyabo Ojo, lori ipa to n ko lori ọrọ Baba Ijesha.
Bukky Black ninu fidio kan to se sita lajọ Ẹti lo ti n salaye pe oun mọ Baba Ijesha bii ẹni mọ owo nitori ẹyin ile oun lo n gbe ni Ikorodu nilu Eko.
Black, ẹni to ni ohun kii saba da si ohun to n sẹlẹ lawujọ ni ohun to sẹlẹ si Baba Ijesha ba oun lọkan jẹ, ti oun ko si le sun.
O ni gẹgẹ bi ohun ti mọ osere tiata naa, o jẹ ẹni ti kii yara mọ obinrin ti ko si kundun lati maa ko obinrin kiri.
"Baba Ijesha ko fi bẹẹ fẹran obinrin ti mo si maa n bi pe se o ni nnkan ọmọkunrin sa, o kan maa n se bii okobo ni.
N ko mọ Ijesha pẹlu ọrẹbinrin kankan, bii ẹni ti ko ni nnkan obinrin lo maa n se."
Bukky Black ni oun ti ohun ri ninu isẹlẹ naa ni pe ki eeyan ye ko isoro rẹ lọ si ọrọ ọrẹ amọ ka maa ke pe Ọlọrun , ẹni to n dahun adura.
Gẹgẹ bo se wi, isẹlẹ baba Ijesha naa dabi pe wọn n se sinima ni, wọn sẹẹti Baba Ijesha ni, bi ere itage lo si jọ loju oun.
hhhhhh
"Fidio ti Iyabo Ojo gbe sita, mo wo ni aimọye igba, to si dabi ẹni pe wsn n sere sinima ni. O dabi ẹni pe awọn ere ti Baba Ijesha ti se tẹlẹ ni wọn n sọrọ le lori.
Abi bawo ni isẹlẹ kan yoo se waye ni ọdun meje sẹyin, ti ẹ ko ri ẹni naa mu, tẹ wa pe sibi kan lati sẹẹti rẹ, ti yoo si ko sọwọ.
Amọ o se mi laanu bi ọpọ eeyan se maa n sọrọ lorisirisi lasiko ti nnkan wa waye lori ayelujara, onikaluku yoo si maa sọrọ saa.
Bi nnkan ba sẹlẹ si ẹda, atunse lo yẹ ka maa wa, kii se ka maa baa jẹ. Iwọ to wa lori ilẹ alaaye, to ni laari, to n mi, to n se daada, to ni laari, to ro pe o ti debi to n lọ."
To wa ri ẹni ti isoro kan, to mura pe o maa ba tiẹ jẹ ni, Oluwa lo maa ba ti onitọun jẹ nitori ti ẹni to de la ri, a ko mọ ti ẹni to n bọ.
Ikorodu cult crisis:A máa gbé Orò síta lọ́jọ́kọ́jọ́ tí ìjà ẹgbẹ́ òkùnkùn bá tún ṣẹlẹ̀- Àwọ
"Gbogbo ẹnikẹni to ba si ni oun yoo maa da isoro ẹlomiran, ẹnikẹni ta bi ninu obinrin, Ọlọrun maa ba ti onitsun jẹ ni."""
Bukky Black wa kesi Iyabo Ojo pe ọga rẹ ni Baba Ijesha jẹ ninu ere tiata, ti awọn ara ita ba si n tako baba Ijesha, ko yẹ ko jẹ Iyabo Ojo ni yoo se bẹẹ.
"Iyabo Ojo, jẹ ki n sọ fun ẹ, ko yẹ ko post fidio yẹn, tabi ko ko awọn ọrẹ rẹ lọ sagọ ọlọpaa pe ti wsn ba fi Baba Ijesha silẹ, o maa pa sibi ni.
Ẹ lọ pa, kẹ wa maa gbe orilẹ alaaye, atunse lo yk kẹ maa wa, Ọlọrun ma fi isoro wa bu wa. Amọ to ba jẹ pe o ku ni ,ẹ maa ls sin, ẹ wa maa sunkun kiri.
Ẹ ma jẹ ka maa dakun isoro ara wa, atunse lo yẹ ka maa wa, ẹ ma jẹ ka maa da kun nitori ti kaluku si maa de baa.
Olugbon of Igbon: ‘Rubber Stamp’ làwọn aṣòfin àpapọ̀, wọn kò ṣojú aráàlú
Iwa ti ikọọ́kan yin n hu labẹ ile ju bayii lọ, gbogbo wa ni ẹlẹsẹ, ẹni ti ilẹ ba mọ ba ni barawo."
Bakan naa ni Bukky Black n beere pe ki lo de ti wọn sẹẹti Baba Ijesha up lẹyin ọdun meje to ti se nnkan ti wọn lo se saaju.
O ni isoro ti wọn mọ pe Baba Ijesha ni ni wọn sisẹ le lori.
Kidnapping in Kwara: Gómìnà Kwara kó ṣọ́jà wọ ibùba àwọn ajínigbé l‘Ekiti, Oke-Ero
Oríṣun àwòrán, kwara state government
Gẹgẹ bi ara ọna ati dẹkun eto abo to mẹhẹ ati ọwọja ijinigbepawo ni ipinlẹ Kwara, ijọba ipinlẹ naa ti ko awọn ọmọ ogun wọ awọn ibuba ajinigbe kaakiri agbegbe ijọba ibilẹ Ekiti ati Oke Ero ni ipinlẹ naa.
Gẹgẹ bi awọn iroyin abẹle to n jade ni ipinlẹ naa ṣe sọ, ọpọ awọn iṣẹlẹ ijinigbepawo lo n waye lagbegbe naa nitori awọn ajinigbepawo ti sọ ara wọn di ẹrujẹjẹ nibẹ, tara ile ko lee roko, ti ero ọna ko si lee wale mọ.
Oríṣun àwòrán, kwara state government
Ijọba ipinlẹ ipinlẹ Kwara ni gbogbo ipa lawọn yoo sa, lati rii pe eto abo to mẹhẹ, paapaa julọ ọwọja ijinigbepawo jẹ rodo lọ mumi nibẹ.
Oríṣun àwòrán, kwara state government
O ni eyi yoo seese nipa fifi ọwọ sowọpọ pẹlawọn ajọ alaabo gbogbo to ba yẹ, lati le gbogbo iwa to ba n tigi bọ oju alaafia ipinlẹ Kwara atawọn eeyan rẹ lugbẹ.
Oríṣun àwòrán, kwara state government
Oríṣun àwòrán, kwara state government
Oríṣun àwòrán, kwara state government
Oríṣun àwòrán, kwara state government
Oríṣun àwòrán, kwara state government
Ibadan Customs raid: Àṣẹ ti jáde kí Iléeṣẹ́ aṣọ́bodè dá gbogbo ìrẹsì tí wọ́n kó padà
Oríṣun àwòrán, others
Igbimọ alabẹṣekele to n ri si ẹtọmọniyan nile igbimọ aṣofin orilẹede yii ti kesi ileeṣẹ aṣọbode lati da awọn apo irẹsi ati owo ti iroyin sọ wi pe awọn oṣiṣẹ ajọ naa ko ni awọn ilẹ itaja kan ni Ọja'ba ilu Ibadan pada.
Lopin ọṣẹ ti o kọja ni iroyin gbode kan wi pe awọn oṣiṣẹ aṣọbode yawọ ọja naa ti wọn si fi tirela mẹjọ ko apo iresi ati owo ti wọn ri ni awọn ṣọọbu kan lọ.
Igbesẹ naa si waye lẹyin ọsẹ diẹ ti wọn ko ọpọlọpọ irẹsi lọ l'oru mọju ninu ọja Bodija nilu Ibadan.
Iṣẹlẹ yii lo mu ki Sẹnetọ Teslim Folarin to n ṣoju aarin gbungbun Ọyọ nile igbimọ aṣofin ti Sẹnetọ Kola Balogun fi ẹhonu han lori iwa ti ileeṣẹ aṣọbode n hu.
L'ọjọ Iṣẹgun ni aarẹ ile igbimọ aṣofin Ọmọwe Ahmad Lawan tọka ẹsun ti igbimọ alabẹṣekele naa fi kan ileeṣẹ aṣọbode lori i titapa si ẹtọmọniyan, ti o si koro oju si igbesẹ naa gẹgẹ bi i ohun ti ko jẹ itẹwọgba.
Lẹyin eleyii ni igbimọ naa paṣẹ fun alakoso ileeṣẹ aṣọbode, Hameed Ali ti oluranlọwọ rẹ, Garba Mohammed ṣoju fun lati ri i daju wi pe gbogbo nnkan ti wọn ko lo di dida pada laarin ọṣẹ meji.
'Iṣẹ wá burẹkẹ síi tórí Covid-19, owó ńlá ló wà nínú dídáná sun òkú, ìsìnkú  Zoom, Live streaming'
Bakan naa ni igbimọ naa paṣẹ wi pe ki gbogbo ṣọọbu ti wọn ti pa di ṣiṣi pada, gẹgẹ bi wọn ṣe n da awọn owo ti wọn ko lọ pada.
Awọn aṣoju igbimọ naa pa ẹnu pọ sọ wi pe igbesẹ ileeṣẹ aṣọbode ko bojumu pẹlu alaye wi pe o tako ilana antẹlẹ ajọ naa ti aarẹ tẹlẹri, Oloye Olusegun Obasanjo buwọlu ni ọdun 2007.
Ilana antẹlẹ naa fi idi ẹ mulẹ wi pe ogoji kilomita ni ayika ibode ni awọn oṣiṣẹ ajọ naa ti ni ẹtọ lati gbẹsẹ le ẹru ofin.
Ni nnkan bi i aago meji oru ọjọ Abamẹta ni awọn oṣiṣẹ aṣọbode orilẹede Naijiria yawọ Ọja'ba nilu Ibadan ti wọn si fi tirela ko ọpọlọpọ apo irẹsi lọ.
Iṣẹlẹ yii waye lẹyin oṣu kan ti wọn yawọ ọja Bodija l'oru ti wọn si ko ọpọlọpọ apo irẹsi lọ.
"Alukoro ileeṣẹ aṣọbode ni agbegbe Ọyọ ati Ọṣun, Kayode Wey fi idi iṣẹlẹ naa mulẹ, ṣugbọn o ṣe alaye wi pe ẹka ileeṣẹ naa to jẹ ti ijọba apapọ, ""Federal Operation Unit (FOU) Zone A"" lo yawọ ọja naa.O fi kun ọrọ rẹ wi pe awọn oṣiṣẹ yii kan naa lo ko irẹsi ni ọja Bodija."
Ẹni ti o jẹ alukoro fun ilẹẹṣẹ aṣọbode fun ijọba apapọ, FOU, Arakunrin Theophilus Duniya naa fi idi iṣẹlẹ naa mulẹ.
Ninu ọrọ ti o ba awọn oniroyin sọ lori ẹrọ ibanisọrọ, Duniya ni ileeṣẹ aṣọbode ni agbara lati gbe igbesẹ naa, paapaa julọ nitori pe ijọba ti gbẹsẹ le kiko irẹsi wọ Naijiria lati ilẹ okere ki ipẹsẹ rẹsi le gberu si i labẹnu.
O fi kun ọrọ rẹ pe ẹru ofin ni irẹsi ti ẹnikẹni ba ko wọle lati ilẹ okere. Eyii lo si fun ile iṣẹ aṣọbode ni agbara lati yawọ ibikibi ki wọn si ko ẹru ofin jade.Lara awọn ontaja ti wọn ko ọja wọn lọ gbarata wi pe lati ọwọ awọn ẹya Hausa ni awọn ti ra pupọ awọn irẹsi ti awọn n ta n'Ibadan.
Wọn ni bi igba ti ileeṣẹ aṣọbode kan doju le wọn ni awọn ọja wọn ti wọn n ko ni lemọlemọ. Wọn fi kun ọrọ wọn wi pe iru igbesẹ bẹẹ ki i waye ni ilẹ Hausa ti wọn ti n ko irẹsi naa wọle.Wọn parọwa si ijọba lati ja fun gbeja wọn ja lori ọrọ naa.
Iniobong Umoren story: Ìjọba Akwa Ibom pè fún ìdájọ́ òdodo lórí ìwádìí ikú ọ̀dọ̀bìnrin tó dàwátì tórí ó ń wá iṣẹ́
Oríṣun àwòrán, Twitter
Ijọba ipinlẹ Akwa Ibom ti fi aidunnu wọn han lori iroyin iku Iniobong Umoren to ku lẹyin ti afurasi kan, Uduak Frank Akpan jii gbe to fi ipa baa lo ko to tun gbẹmi rẹ.
Gomina ipinlẹ Akwa Ibom to dupẹ lọwọ awọn ọlọpaa fun fifi panpẹ ofin mu arakunrin naa ṣalaye pe ijọba ti kan sawọn ọlọpaa ni ipinlẹ ọhun lati rii daju pe afurasi naa foju wina ofin bi o ti tọ ati bi o ti yẹ.
O ni ijọba ipinlẹ Akwa Ibom ba awọn ẹbi oloogbe naa kẹdun ọmọ wọn to ku to si fi kun un pe ohun ti ijọba n lepa ni ipinlẹ naa ni alaafia ati abo fun tonile talejo to n gbe nibẹ.
Ọrọ ti ijọba ipinlẹ naa sọ yii n waye lẹyin ti awọn ọlọpaa ti kọkọ kede pe ọwọ awọn ti tẹ Uduak Frank Akpan, ọmọ ogun ọdun kan ti wọn fura si pe oun lo ji Iniobong gbe, to fipa baa lo pọ to si tun pa a.
Oríṣun àwòrán, Twitter/Happiness Activist
Ileeṣẹ ọlọpaa ipinlẹ Akwa Ibom ti fi panpẹ ofin mu afurasi ayederu agbanisiṣẹ kan to fipa ba arabinrin to n wa iṣẹ lo pọ to tun pa a ni agbegbe Airport Road, ilu Uyo.
Iroyin to gbode kan ni pe Umoren n wa iṣẹ lori ayelujara ni l'Ọjọbọ ọsẹ to kọja ni Akpan ba fi ọgbọn fi iṣẹ ayederu kan lọ ọ to si fun un ni adirẹsi ọfiisi rẹ.
Ẹwẹ, ko pẹ to fi ọrọ ori foonu ranṣẹ si ọrẹ rẹ Umoh Uduak pe oun n lọ fun ifọrọwanilẹnuwo ni adirẹsi ti wọn fi ranṣẹ ni foonu rẹ ko lọ mọ.
Ni Uduak ba figbe ta lorii Twitter, o ni oun ngbọ ti ọrẹ oun n kigbe ninu ọrọ ori foonu oniṣẹju aaya kan pere to fi ranṣẹ si oun to si ni pabo ni igbiyanju oun lati ri i ba sọrọ n ja si.
Ọjọ́ mẹta péré lo ní báyìí láti ṣe àyẹ̀wò Covid19 ṣáájú ìrìnàjò wá sí Nàìjíríà!
Wo ìdí tí ìjọba Naijiria ṣe fòfin de gbogbo arìnrìnàjò láti India, Brazil àti Turkey
Bola Tinubu: Ọlọrun kò ní gbà kí Naijiria tún la ogun abẹ́lé míràn kọjá
'Àwọn òbí mi gbé mi jù sílẹ̀ nítorí pé mo jẹ́ àfín'
'Bàbá, orúkọ yín rèé nínú ìwé òṣìṣẹ́fẹ̀yìntì Nàìjíríà tó ti kú, kí 'ló ṣẹ́lẹ̀?'
Igba naa lo bẹrẹ #FindHinnyHumoren lori ayelujara ti wọn si fi oju Akpan ati adirẹsi rẹ hande.
Pẹlu Hashtag ti wn n pin lori ayelujara ni wọn fi ṣawari ibi ti o n gbe. Kete to mọ pe wọn ti n wa oun ni iroyin sọ pe afurasi ọhun ti na papa bora.
Bakan naa, iroyin ni wn bo oku arabinrin naa mọlẹ labẹ iho ti ko jin rara lẹyin ti wọn fẹsun kan pe akpan fipa ba a lopọ to tun pa a.
Ileeṣẹ Ọlọpaa wa fesi loju opo Twitter tiwọn @PoliceNG ti wọn ni ọwọ ti t afurasi meji lori ọrọ naa.
"Wọn ni ""ikọ ọlọpaa Akwa Ibom to n gbogun ti iwa ijinigbe ti kara bọ iwadii. Ọwọ ti tẹ eeyan meji, a o si maa fun yin ni  ẹkunrẹrẹ iroyin bo ba ṣe n yọju."
Alukoro Ọlọpaa ipinlẹ naa, Odiko Macdon lo fihan ninu ọrọ rẹ pe afurasi naa jẹwọ pe oun fipa ba a lo pọ oun si pa a.
Atjade ileeṣẹ ọlọpaa ipinlẹ naa ka bayii pe: Ileeṣẹ Ọlọpaa Akwa Ibom ti mu Ọgbẹni Uduak Frank Akpan ẹni ogun ọdun fun ẹsun ijinigbe ati ipaniyan to ṣe si Arabinrin Iniobong Umoren.
Ileeṣẹ ọlọpaa ni awọn ti wu oku Iniobong Umoren, akẹkọjade to wa iṣẹ lọ ti awọn agbenipa kan si gba ẹmi rẹ.
Ninu ọrọ to ba awọn oniroyin kan sọ, alukoro ileeṣẹ ọlọpaa ni ipinlẹ Akwa Ibom, Odiko MacDon ṣalaye pe wọn ti mu afurasi kan lori iku rẹ, o si ti jẹwọ .
O ni afurasi naa lo mu wọn lọ si ibi ti wọn da erupẹ bo oku ọdọbinrin naa sii.
O fi kun un pe wọn ti gbe oku ọmọbinrin naa lọ sile igbokusi kan lati lee ṣe awọn ayẹwo gbogbo to yẹ eyi ti yoo tubọ ran awọn ọlọpaa lọwọ ninu iwadii wọn.
Wọn ni afurasi naa fipa ba ọmọbinrin ọhun lopọ, o si tun fi iya jẹ.
Oríṣun àwòrán, Twitter
Wọn ti pa ọrẹ mi o, wọn dẹ tun ti sin ọrẹ mi
Ariwo ti arabinrin kan @UmohUduak labẹ apejẹ orukọ 'Happiness Activist' fi sita loju opo twitter ree.
Happiness Activist ti kọkọ pariwo sita lọjọ diẹ sẹyin pe ọrẹ oun kan to lọ fun ifọrọwanilẹnuwo fun igbanisiṣẹ lagbegbe Airpot road ni Akwa Ibom di awati.
Ẹyin eeyan mi, ọrẹ mi @HinyHumoren ti wọ inu wahala o si nilo iranlọwọ wa...ṣaaju loni lo sọ fun mi pe oun lọ fun ifọrọwanilẹnuwo fun igbanisiṣẹ lagbegbe Airpot road  eyi to jina si ile rẹ.
Nigba ti yoo fi di owurọ ọjọ Aiku, ọjọ keji oṣu karun un ọdun 2021 ni 'Happiness Activist'ba tun bọ sori Twitter lati kede pe wọn ti pa ọrẹ oun o bẹẹ ni wọn si tun da erupẹ bo o mọlẹ.
"Ninu ọrọ to ba BBC News sọ arabinrin @UmohUduak to sọrọ pẹlu ẹkun ṣalaye pe ""wọn ti pa ọrẹ mi o, wọn ti sin ọrẹ mi"""
"Alukoro fun ileeṣẹ ọlọpaa ni ipinlẹ Akwa Ibom, Odiko MacDon ṣalaye fun BBC pe ""a ti n pari iwadii lori rẹ, atẹjade yoo jade nipa rẹ laipẹ"". Iniobong Umoren, ọmọbinrin to sọnu lọjọ diẹ sẹyin lẹyin to tọ ipasẹ iṣẹ kan ti wọn fun un lati ipinlẹ Akwa Ibom lọ ti jade laye."
'Wọ́n fipá bá mi lòpọ̀ toyúntoyún títí tí mo pàdánú ọmọ náà, wọ́n jù mi sílẹ̀ níhòhò'
Aṣe agba adura ni awọn Yoruba maa n ṣe pe bi a ṣe n wa ohun ti a o jẹ lọ, ki a maa pade ohun ti yoo jẹ wa.
Ọmọbinrin kan, Iniobong Hiny Umoren to wa lati ipinlẹ Akwa Ibom to n wa iṣẹ lo ti di awati bayii.
Awọn ẹbi ati ọrẹ ọmọbinrin naa ko dakẹ rara lori ayelujara papaa julọ lori ẹrọ Twitter ati Facebook lati igba ti Iniobong ti di awati.
Oríṣun àwòrán, Twitter/Happiness Activist
#FindHinyHumoren lo gbori ẹrọ Twitter eleyi tawọn eeyan lo le lẹgbẹrun lọna ọgọfa n sọrọ le lori.
Ọpọ eeyan lo n beere lori Twitter pe nibo ni ọmọbinrin naa le wa lati ọjọ yii.
Ẹwẹ, ileeṣẹ ọlọpaa ipinlẹ Akwa Ibom ti kede pe ohun ti fọwọ ofin mu eeyan lori bi Iniubong ṣe di awati.
Happiness Activist @UmohUduak1 to jẹ ọmọbinrin naa sọ loju opo Twitter rẹ pe Hiny sọ fun pe oun n lọ fun ifọrọwanilẹnu wo fun iṣẹ nigba ti awọn rira kẹyin.
Uduak ṣalaye pe oun fi fọnran kan ṣọwọ si Hiny lori ẹrọ Whatsapp, lẹyin naa loun pe lori ago bo ya o fẹ ba oun sọrọ.
Ṣugbọn Uduak ni ohun ẹkun ọrẹ oun ni oun gbọ nibi to ti n kigbe pe kawọn eeyan gba oun.
Hiny ti kọkọ sọ loju opo Twitter rẹ pe oun n wa iṣẹ eleyii ti ọpọ eeyan si gba a ni imọran lori ibi ti o ti le wa iṣẹ lọ.
Ọpọ lo ti gbadura pe ki Hiny pada wale fun ra rẹ laaye lẹyin to ti di awati lati Ọjọbọ, ọjọ kọkandinlọgbọn oṣu kẹrin.
Insecurity in Nigeria: Fayemi ní ìṣẹ̀lẹ̀ àwọn agbésùnmọ̀mí bíì Boko Haram ti dínkù lásìkò ìjọba Buhari
Oríṣun àwòrán, Twitter/Muhammadu Buhari
Laisi ani ani, awọn agbesunmọmi bii Boko Haram ko ṣọṣẹ mọ bi ti tẹlẹ lati igba ti Aarẹ Muhammadu Buhari ti gori oye lọdun 2015.
Alaga ẹgbẹ awọn gomina ni Naijiria to tun jẹ gomina ipinlẹ Ekiti, Kayode Fayemi lo maa sọrọ yii lori eto kan niluu Eko lọjọ Abamẹta .
Fayemi ni ọpọ le maa gbagbọ, amọ o da oun loju pe igbesunmọmi ti dinku lasiko ijọba Muhammadu Buhari.
Gomina Fayemi pe ijọba APC ṣi niṣẹ lati ṣe lori eto abo to mẹhẹ ni Naijiria, amọ o durọ ilọsiwaju wa lori eto to niiṣe pẹlu igbesunmọmi.
Fayemi ni ''otitọ ni pe ijọba APC ṣe ọpọlọpọ ileri lọdun 2015 ki a to dori ijọba.
Eyi ti ọpọ eeyan fi fẹran wa ni ileri lati fi ọmọniyan ṣe ijọba ti a ba gori aleefa.
Ṣugbọn lati igba ti Buhari ti jẹ aarẹ orilẹede Naijiria, a ko gbọ ki awọn agbesunmọmi maa yin bọmbu bi wọn ti n yin tẹlẹ mọ.
Ti ẹ o ba gbagbe, ki APC to dori oye, wọn yi ado oloro si ile ajọ iṣọkan agbaye, UN niluu Abuja.
Bakan naa ni wọn tun yin bọmbu lawọn ṣọọṣi kan, ilu Abuja ko tiẹ ṣe lọ nigba naa.
Ṣugbọn gbogbo rẹ lo ti lọọlẹ laarin ọdun mẹrin akọkọ ijọba Buhari.''
Fayemi ni iṣoro igbesunmọmi tun ṣẹyọ nitori bi ohun ija oloro ti di tọrọ fọn kale ni Naijiria bayii.
Lizzy Anjorin: Ayọ̀ abara tín-tín! Lizzy Anjorin bímọ sí orílẹ́èdè Amẹrika
Oríṣun àwòrán, Instagram/Lizzyanjorin
Ayọ abara tintin, gbajugbaja oṣere ati oniṣowo Lizzy Anjorin ti bi ọmọ tuntun lantilanti.
Lizzy fi fidio ti ounj ati ọkọ rẹ ti n dọwẹkẹ nigba to wa ninu oyun si oju opo Instagram rẹ.
''Oba aṣekan maku tun ti ṣe e, O maa n wo ọkan dajọ.
Ki i dajọ pẹlu ohun ti awọn eeyan ba n sọ nipa eeyan, oba pakanmire ti pa ẹgan mi rẹ patapata.
Lizzy ni ''ẹ darapọ mọ wa lati ṣajọyọ ore ti Ọlọrun ṣe fun wa.
Ọlọrun tun ti bu kun wa lẹẹkan sii, iyin ni gbogbo rẹ ja si, ALIHAMDULILLAH.
Ọjọ kinni oṣu karun un ọdun 2021 niluu Miami nipinlẹ Florida lorilẹede Amerika lo ti ṣẹlẹ.''
Lizzy ko sọ bo ya ọkunrin tabi obinrin ni ọmọ ti Eleduwa fi jinki oun ati ọkọ rẹ naa.
Bo tilẹ jẹ pe ọmọ akọkọ ti Lizzy yoo bi fun ọkọ rẹ to ṣeṣẹ fẹ niyii, o ti ni ọmọ kan to ti dagba tẹlẹ.
Baba Ijesha: Iyabo Ojo, Esabod, Davido lápá kan, Yomi Fabiyi, Bukky Black lápá kejì lórí ọ̀rọ̀ Baba Ijesha
Kii ṣe iroyin mọ pe gbajumọ oṣere Baba Ijesha n foju wina ofin lọwọ bayii lori ẹsun aṣemaṣe pẹlu ọmọdebinrin ọmọ ọdun mẹrinla kan to jẹ ọmọ agbatọ fun gbajumọ alawada obinrin ni ti gbogbo aye mọ si Princess.
Lẹyin ti iroyin aṣemaṣe naa lu si agbami iroyin agbaye ni awọn eekan lawujọ gbogbo ti n sọrọ lori iṣẹlẹ naa. Bi awọn kan ṣe n bu ẹnu atẹ lu iwa yii lawọn miran n pe fun suuru ti awọn kan si n gbẹri gbajumọ oṣere naa jẹ pe ko lee ṣe nnkan to jọ bẹẹ; kodan awọn miran tilẹ n pe okobo ni ko leeta putu rara.
Oríṣun àwòrán, Iyabo ojo
Ni kete ti iroyin aṣemaṣe yii jade, lara awọn ti ko yee lọgun tantantan ni Iyabọ Ojo wa.
Koda o ti ṣee de ibi pe awọn eeyan kan lori ayelujara ti n pariwo pe aṣeju rẹ pọ abi boya o ni nnkan miran to wa bi dukuu laarin oun ati Baba Ijesha.
Amọṣa, Iyabọ Ojo ti ni ko si nnkan to wa laarin oun tabi ẹsan ti oun fẹ gba ju pe gẹgẹ bi obinrin, asiko to lati dide fun idaabobo awọn ọmọbinrin lawujọ nitori pe ọgbẹ ọkan ti ọpọ n gbe kiri lori awọn aṣemaṣe igba atijọ pọ pupọ lawujọ lode oni.
Oríṣun àwòrán, Esabod
Ninu ọrọ tirẹ, ilumọka asọrọgbayi lori ayelujara ni, Esther Aboderin ti ọpọ mọ si Esabod ni tirẹ ṣalaye pe ko ya oun lẹnu pupọ ju nitori Baba Ijesha ti fi irufẹ nnkan bẹẹ lọ oun pẹlu.
Ninu eto kan to ṣe loju opo Instagram rẹ, Esabod ni igbesẹ to ba tọ ni ki wọn gbe lori ọrọ naa.
Oríṣun àwòrán, davido
Ọrọ yii tilẹ fa ibinu yọ fun Davido lori gbajumọ oṣere miran, Yomi Fabiyi.
Loju opo Instagram rẹ ni Davido fi fọto Fabiyi si to si kọ ọrọ kobakungbe kan sibẹ pẹlu.
'Wọ́n ti pa ọ̀rẹ́ mi o, wọ́n ti sín in'! Ọ̀rẹ́ Iniobong Umoren tó dàwátì ní Akwa Ibom pariwo síta
Orí yọ ẹ́ o Baba Ijesha tí mi ò rí fídíò èpè tí wọ́n ní ò ń ṣẹ́, ǹkan tí mi ò bá ṣe fún ẹ... - Iyabo Ojo
Buhari, wá nǹkan ṣe sí ètò àbò tó mẹ́hẹ ní Naijiria kó tó pẹ́ jù - Alaafin, Ooni
'Wọ́n fipá bá mi lòpọ̀ toyúntoyún títí tí mo pàdánú ọmọ náà, wọ́n jù mi sílẹ̀ níhòhò'
Oríṣun àwòrán, Mercy aigbe
Mercy Aigbe ni tirẹ ni inu to n bi oun kọja afẹnusọ.
Ki Ọlọrun fiya jẹ gbogbo awọn to n gbe lẹyin Ijesha...Boya ẹ fẹ tabi ẹ kọ, idajọ ododo yoo waye! Ọlọrun maa dabo bo awọn ọmọ wa o ki o si maa ba wa tu aṣiri awọn ọdaran wọnyii.
Oríṣun àwòrán, femi adebayo
Gbajumọ oṣere naa ni oun duro lẹyin Princess ati ọmọdebinrin ọdun mẹrinla naa lai yẹsẹ.
Oríṣun àwòrán, Muyiwa ademola
Muyiwa Authentic ni idi ki idajọ ododo fẹsẹ mulẹ loun wa o gbogbo awọn to ba ṣebi si gbọdọ foju wina ofin.
Oríṣun àwòrán, yomi fabiyi
Lara awọn ti ohun wọn ga ju lẹyin Baba Ijesha ni Yọmi Fabiyi wa.
Yọmi ni ko yẹ ki awọn eeyan ṣe idajọ gbajumọ oṣere naa lori ayelujara lai tii wo fidio bo ṣe ṣe ohun ti wọn pe o ṣe naa.
Eleyi fa ọpọlọpọ eebu ati ọrọ tako gbajumọ oṣere yii.
Oríṣun àwòrán, foluke daramola
Foluke Daramola ni ki wọn ye se idajọ Baba Ijesha bi wọn ti se fun Baba Suwe.
O ni ko yẹ ki ọkankan ninu awọn ọmọ oṣere tiata bẹrẹ si n ṣe idajọ Baba Ijesha nigba ti ile ẹjọ ko tii ṣedajọ tirẹ.
O fi kun un pe ọpọ ojuṣe lo wa lori awọn gbajumọ oṣere, nitori naa ki awọn akẹgbẹ oun ṣe mẹdọ lori iṣẹlẹ naa titi ti awọn agbofinro yoo fi pari iṣẹ wọn.
Foluke pari ọrọ rẹ pe, ọrọ ifipabanilopọ kii ṣe ohun ti eeyan le fi ọwọ yẹpẹrẹ mu, lai ro ti irufẹ ẹni ti wọn fi ẹsun naa kan.
Oríṣun àwòrán, Bukky black
Lara awọn oṣere to gbe sẹyin Baba Ijesha ni Bukky Black wa.
Gbajumọ oṣere tiata naa to ni ẹyin ile oun ni baba Ijesha kọ ile si ṣalaye pe oun ko gbagbọ pe Baba Ijesha lee ṣe debi ti yoo maa ṣe aṣemaṣe pẹlu ọmọdebinrin kankan.
Isa Pantami: Ilé aṣòfin àgbà l'Abuja ní kò sí ẹ̀rí tó dájú láti yọ Pantami nípò mínísítà
Oríṣun àwòrán, Facebook/Isa Pantami
Ile aṣofin agba orilẹede Naijiria niluu Abuja ti sọ pe ko si ẹri to daju ti awọn le lo lati da minisita ẹrọ ibaraẹnisọrọ ati ọrọ aje, Isa Pantami duro lẹnu iṣẹ.
Ọpọ ọmọ Naijiria lo ti n ke pe ijọba Aarẹ Muhammadu Buhari lati fun Pantami ni iwe gbele ẹ lori ẹsun pe o ṣe atilẹyin fun awọn ẹgbẹ agbesunmọmi.
Koda, fọnran ọrọ ti wọn ni Pantami sọ lati ṣe atilẹyin fawọn ẹgbẹ agbesunmọmi ti lu ori ayelujara pe.
Awọn kan tiẹ tun da ile aṣofin agba niluu Abuja lẹbi pe wọn ko ṣiṣẹ wọn bii iṣẹ nigba ti wọn ṣe ayẹwo awọn orukọ awọn eeyan ti Buhari fi ranṣẹ sile fun ipo minisita.
Ṣugbọn nigba to n ba awọn akọroyin sọrọ, alaga igbimọ eto iroyin nile, Ọmọwe Ajibola Basiru sọ pe ile aṣofin ko lẹbi lori bi o ṣe buwọlu iyansipo Pantami gẹgẹ bi minisita.
Ọmọwe Basiru ṣalaye ko si ẹni to mu ẹjọ tabi ẹsun kankan wa lati tako iyansipo Pantami lasiko ti ile n ṣayẹwo awọn orukọ ti Buhari fi ṣowọ sawọn aṣofin.
''A ko ṣe ohun to lodin sofin, ko si ajọ eleto abo kankan to sọ ohun kan nipa Pantami to le mu wa maa buwọlu iyansipo rẹ lasiko ti a n ṣe ayẹwo rẹ to fi di asiko yii.
Awọn sẹnẹtọ ko lagbara lati yọ minisita nipo, a kan le ṣe ayẹwo lasan an ni pẹlu ohun ti a ba mọ nipa awọn ti aarẹ fẹ yan sipo minisita.
Aarẹ nikan lo lagbara lati yan minisita si ipo, oun naa lo si lagbara lati yọ minisita to ba yan si ipo kuro nipo.
A ko le titori ohun tawọn eeyan n sọ lori ayelujara lati gbe igbesẹ kan tabi omiran,'' Sẹnẹtọ Basiru ṣalaye.
Alaga igbimọ eto iroyin nile aṣofin agba sọ pe ko si ẹni to le tọka si ibi ti ofin ti sọ pe ile le yọ Pantami nipo ninu gbogbo awọn to n sọrọ lori ayelujara.
O ṣalaye pe Pantami ko tapa si ofin Naijiria lọna kọna, notiri idi eyi lawọn aṣofin ko le fi yọ nipo.
Èèmọ̀ wọ̀lú! Àwọn jàndùkú agbébọn pa kọmíṣọ́nnà àti ọlọ́pàá, wọ́n dáná sun àgọ́ ọlọ́pàá
Oríṣun àwòrán, Twitter/Kogi Facts
Ọrọ eto abo to mẹhẹ ni orilẹede Naijiria ti wa di ojukeji bayii.
Awọn agbebọn lo maa tun ti ṣekupa kọmiṣọnna to n ri si owo awọn oṣiṣẹ fẹyinti nipinlẹ Kogi, Adebayo Solomon.
Lọjọ Abamẹta lawọn kọlọnbiti ẹda ọhun yinbọn fun Solomon ninu ọkọ rẹ nigba to n rinrin ajo lati ilu Ilorin si Kabba.
Wọn ti gbe oku kọmiṣọnna naa lọ si ile igbokusi ijọ ECWA to wa niluu Egbe.
Bakan naa ni a gbọ pe wọn tun ti ji alaga ijọba ilẹ ila oorun Yagba nipinlẹ naa, Pius Kolawole gbe lọ.
Ọga ọlọpaa ipinlẹ Kogi, Ayuba Ede ti sọ pe ileeṣẹ ọlọpaa ti bẹrẹ iwadii lori iṣẹlẹ ọhun.
Wọn ko tii ri alaga kansu ila ooru Yagba ti wọn jigbe lọ di akoko ti a kọ iroyin yii.
Awọn agbebọn pa ọlọpaa lẹyin ikọlu si agọ ọlọpaa ni Ebonyi
Ẹwẹ, iroyin to tẹ wa lọwọ lati ipinlẹ Ebonyi sọ pe awọn janduku agbebọn kọlu agọ ọlọpaa Abaomege to wa ni ijọba ibilẹ Onicha nipinlẹ naa.
Gẹgẹ bi iroyin ti a gbọ ṣe sọ, alẹ ọjọ Abamẹta lawọn kọlọnbiti ẹda naa ṣe ikọlu si agọ ọlọpaa ọhun nibi ti wọn dabọn bolẹ.
Koda, ọlọpaa kan ba iṣẹlẹ naa lọ ti omiran si farapa gẹgẹ bi ohun ti a gbọ.
Kọmiṣọnaa fun eto abo, Stanley Emegha lo fidi iṣẹlẹ yii mulẹ fun BBC.
Nigeria bound travelers : Ọjọ́ mẹta sí asiko ìrìnàjò rẹ sí Nàìjíríà ni o gbọdọ̀ ṣe àyẹ̀wò Covid19
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ijọba orile-ede Naijiria ti din asiko ti esi ayẹwo Covid le gbe ọ da, ti o ba fẹ rinrin ajo si Naijiria lati ọjọ mẹrin si ọjọ mẹta.
Eyi tumọ si pe ti o ba fẹ rin irinajo si Nàìjíríà, to ba ku ọjọ mẹta lati gbera ni o to le ṣe ayẹwo aarun Covid-19.
Ṣaaju asiko yii, ọjọ mẹrin ni o maa n jẹ, Ṣugbọn o ti di ọjọ mẹta ninu atejade tí jọba fi sita lọjọ Aiku.
Akọwe agba fun Ijọba apapọ Naijiria, Boss Mustapha wipe ayewo PCR to ba ti ju ọjọ mẹta lọ ki eniyan to rin irin ajo wa si Naijiria ko ni jẹ itẹwọgba mọ.
Akọwe Ijọba to tun jẹ alaga igbimọ amusẹse lori Covid-19 tun sọ pe ọmọ Naijiria to ti sabẹwo si India, Brazil, Italy tabi Orile-ede kan to n fi oju wina aarun Covid-19 lọpọ bayii tabi ti iku Covid pọ nibẹ yoo ni lati ṣe ayẹwo Covid-19 wọn to ba ku ọla ti wọn yoo rinrin ajo.
O kede pe ijiya ẹsẹ fáànì owo $3,500 lori arinrinajo kọọkan fun ile ìṣe ọkọ ofurufu to ba ru ofin naa, wọn ko si ni gba ẹni tii kii se ọmọ Naijiria laaye lati wọ orile-ede yii rara.
"A rọ awọn ọmọ Naijiria lati yago fun irinajo ti ko se pataki lọ si oko okun, paapaa julọ awọn orileede ti aarun Covid-19 n peleke si nibẹ.
'Bàbá, orúkọ yín rèé nínú ìwé òṣìṣẹ́fẹ̀yìntì Nàìjíríà tó ti kú, kí 'ló ṣẹ́lẹ̀?'
Awọn ọmọ Naijiria ati awọn alejo to ni iwe igbelu sugbọn to ti rin irin ajo lọ si Brazil India tabi Turkey laarin ọjọ mẹrinla sẹyin ki wọn to wa si Naijiria yoo duro du  iyasọtọ fun ọjọ meje ni ibi ti ijọba fọwọsi ni kete ti wọn ba ti wọ orileede yii, ọlọdani si ni yoo san owo to rọ mọ."
Ẹnikẹni to ba wọ orileede Naijiria lati ibikíbi gbọdọ wa ni igbele ọjọ meje ti o ba de ibi ti o n lọ, bakan naa ni o gbọdọ ṣe ayẹwo Covid19 lẹyin ọjọ keje ni awọn ile ayẹwo ti ijọba fọwọsi.
Akọwe ijọba ni awọn gbe igbesẹ yii lati da abo bo orileede yii nitori bi aarun naa se n peleke si ti o si fa iku ọwọọwọ ni awọn orileede kan.
Xue Li gbajúmọ̀ aṣẹ̀ṣọ́ oge ṣàlàyé bí àwọn òbí rẹ̀ ṣe gbé e jù sílẹ̀ nítorí pé ó jẹ́ àfín
Oríṣun àwòrán, @LUXVISUALSTORYTELLERS
Awọn agba bọ wọn ni afin kii wọja ki tajatẹran o maa mọ bẹẹni oniruuru igbagbọ lawọn eeyan ni nipa wọn eleyi ti o maa n mu ipalara ba wọn lọpọ igba.
Ni ilẹ Yoruba nikan kọ lawọn afin ti n foju wina oniruru ipenija. O dabi ẹni pe bi wọn ṣe n ṣe nilẹ yii naa ni wọn n ṣe nilẹ miran.
Nigba ti Xueli wa lọmọde, awọn obi rẹ lọ ju u silẹ nile awọn ọmọ alainiya kan.
Nigba to pe ọmọ ọdun mẹrindinlogun lo ti di ilumọọka loju ewe awọn iwe iroyin atigbadegba lori oge ṣiṣe bii Vogue ti o si di aṣoju fun ọpọ eekan ileeṣẹ aṣaraloge ati ẹṣọ oun ẹgba ọwọ ati ọrun.
Lorilẹede China awọn eeyan kan a maa fi oju wo awọn afin gẹgẹ bi egun.
Amọṣa nitoripe o da yatọ, Xueli rawọ le iṣẹ aṣaraloge.
Xue Li ni orukọ apejẹ tawọn oṣiṣẹ ile awọn ọmọ alainiya naa fun un. ni ede Chine Xue tumọ si yinyin, Li si tumọ si ẹwa.
Oríṣun àwòrán, BIEL CAPLLONCH
Nigba to pe ọmọ ọdun mẹta ni wọn gba a tọ to si lọ bẹrẹ si ni gbe pelu obinrin alagbatọ rẹ ati ọmọ rẹ.
O ni alagbatọ oun ko yi orukọ ti wọn fun un pada ati pe o fẹ ki oun maa ranti orilẹede China to jẹ orirun oun.
"Nigba ti wọn bi mi, ijọba orilẹede China gbe ofin ifetosọmọbibi kalẹ lori eeyan kan ṣoṣo ni idile kan.
To ba tun wa lọ jẹ afin lọmọ too bi, ọran kan niyẹn lọtọ.
Oríṣun àwòrán, JET VAN GAAL
Ọpọlọpọ awọn ọmọ bii temi ni wọn ti gbe ju sọnu, wọn ti ti ọpọlọpọ wọn mọle, tabi ki wọn di ẹni ẹgan bi wọn ba lọ sileewe.
Lawọn agbegbe kan nilẹ Afirika, wọn a maa pa wọn tabi ge ẹya ara wọn.
Awọn ajẹ ati alafọṣẹ a maa fi egungun wọn ṣoogun nitoripe awọn eeyan nigbagbọ pe o n wo aisan san, ṣugbọn irọ nla ni eyi, igbagbọ odi lasọn ni.
Ori ko emi yọ pe wọn kan lọ gbe mi ju silẹ lasan ni. awọn obi to bi mi ko tilẹ fi ijuwe kankan silẹ ti mo le fi mọ ọjọ ibi.
Oríṣun àwòrán, REINY BOURGONJE
Amọṣa ni ọdun kan sẹyin awọn dokita ya aworan ọwọ mi lati fi mọ iye ọdun ti mo le to wọn si sọ pe o ṣeeṣe ki n jẹ ọmọ ọdun marundinlogun.
Nigba ti mo pe ọmọ ọdun mẹrinla ni mo ti bẹrẹ si ni ṣe aṣoju ipolongo oja fun awọn ileeṣẹ to n ṣe ẹṣọ ati ẹgba ọwọ ati ọrun.
Iya mi kan si eeyan kan to n ran aṣọ ni ilu Hong Kong.
O ni ọmọ ọkunrin to ni arun kan, o wa fẹ ran awọn aṣọ kan ti yoo maa bo aṣiri rẹ ti awọn eeyan ko fi ni maa wo ẹnu rẹ nigba gbogbo.
Oríṣun àwòrán, KURT GEIGER
O beere boya mo nifẹ si kikopa nibi eto ipatẹ aṣọ oge to fẹ ṣe ni Hong Kong.
Mo fẹran didadarapọ mọọ gidigidi.
Lẹyin rẹ ni mo gba ipe fun fọto yiya kan ninu eyi ti a ti ri Brock Elbank ti oun naa pe mi fun fọto yiya ni ileeṣẹ rẹ to wa ni ilu London
O gbe fọto naa si ori oju opo ayelujara rẹ.
'Bàbá, orúkọ yín rèé nínú ìwé òṣìṣẹ́fẹ̀yìntì Nàìjíríà tó ti kú, kí 'ló ṣẹ́lẹ̀?'
Lẹyin naa ni ileeṣẹ Zebedee Talent naa pe mi lati beere boya mo fẹ lati ba wọn ṣiṣẹ gẹgẹ bi ara ilakaka wọn lati rii pe awọn akanda naa lẹnu lawujọ ileeṣẹ ẹṣọ oun ẹgba ọwọ ati ọrun.
Wọn fi ọkan lara awọn fọto ti Brock ya fun mi sinu iwe iroyin atigbadegba kan lorilẹede Italy ti orukọ rẹ n jẹ Vogue loṣu kẹfa ọdun 2019 pẹlu fọto Lana del Rey ni iwaju iwe iroyin atigbadegba naa.
Lakọkọ mi o mọ iye to wọle si apo iwe iroyin atigbadegba naa ṣugbọn o pẹ ki n to mọ idi tinu awọn eeayn fi  n dun si mi nigba naa.
Oríṣun àwòrán, ROB JANSEN
Ni awujọ ileeṣẹ aṣaraloge didayatọ jẹ ibukun lọna kan to si n ṣi ilẹkun fun mi lati ta awọn eeyan ji nipa awọn afin.
Lọpọ igba fọto angẹli tabi oku ni wọn saba maa n fi awọn afin ya lawujọ ẹṣọ oun ẹgba ọwọ ati ọrun. Eleyi si maa n bi mi ninu lọpọlọpọ.
Eleyi si ri bẹẹ laarin awujọ tabi aṣa to n ṣeku pa awọn afin lawọn orilẹede bii Tanzania ati Malawi.
Oríṣun àwòrán, ANNE WEIDINGER
Mo fẹ ki awọn ọdọmọde yoku to jẹ afin-tabi akanda tabi idayatọ miran- o mọ pe awọn naa lee ṣe e, wọn lee da ohun gbogbo ti wọn ni lọkan lati da.
Fun emi o, bi  awa kan ṣe yatọ si awọn kan, lawọn ti a yatọ si naa yatọ si awọn kan.
Mo fẹran ere idaraya ati gigun nnkan.
Awọn eeyan lee maa sọ pe o ko lee ṣe, ṣugbọn iwọ gbiyanju rẹ, waa ri pe o le ṣe. "
Strip club visit: Tíṣà mu ọtí yó ló bá kó àwọn ọmọ kíláàsì lọ ilé ijó oníhòhò
Oríṣun àwòrán, Ethan Miller
Wọn ti le olukọ imọ ẹkọ ẹrọ kọmputa ni ileewe kan to dẹru ba awọn akẹkọ nigba to mu ọti yo to si ko gbogbo wọn lọ si ile ijo awọn onihoho.
"Iwa ti Ọgbẹni Richard Glenn hu ""ko jẹ itẹwọgbà"" rara. Wọn ti le e lọ sile kuro ni Longridge Towers School ni ilana ofin ileewe naa. Ko si ni ba wọn ṣiṣẹ fun odidi ọdun mẹta."
Ẹni ọdun marunlelaadọta ni Ọgbẹni Glenn to si gba pe oun jẹbi iwa aidaa to hu si awọn ọmọde eyi ti wọn fi le e danu.
Ni ileewe to ti n kọni yii, owo ileewe ọmọ kan to £4,850 (N2,756,433.48) ni saa kan.
Igbimọ to n koju iwa aṣemaṣe kan gbọ wipe o jẹ́ ọkan lara awọn adari to ko awọn ọdun mẹrindinlogun si ogun ninu irinajo igbafẹ ẹkọ lọ si Costa Rica lọjọ karun oṣu keje ọdun 2019.
Iroyin ni o yẹ ko wa nibẹ titi di ọjọ kejidinlọgbọn oṣu kan naa ṣugbọn lẹyin ọjọ mẹfa, awọn alakoso eto naa le e kuro tori ihuwasi rẹ.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Awọn ihuwasi rẹ lasiko naa niyii:
Igbimọ aṣewadii ni o fi diẹ lara awọn akẹkọọ naa to wa ni ikawọ rẹ sinu ewu.
"O fi kun un pe ""ko sohun to jọ mọ ọrọ ija tabi ete ibalopọ"" ninu kiko awọn akẹkọ naa lọ si ile ijo ti wọn ti maa gbe ara wọn le itan jo amọ Ọgbẹni Glenn ni ko boju mu o si lodi si ofin bi ko ṣe le ko ara rẹ ni ijanu."
'Bàbá, orúkọ yín rèé nínú ìwé òṣìṣẹ́fẹ̀yìntì Nàìjíríà tó ti kú, kí 'ló ṣẹ́lẹ̀?'
O ni oun ko le rantiohun to ṣẹlẹ gan tori bi oun ṣe ti yo. Wọn fi aworan awọn ọpọlọpọ tikẹẹti ọti to ra ni ile ijo ọ̀hún han igbimọ, wọn si ni o tẹ awọn lọrun pe ihuwasi rẹ lodii gbaa si ohun to tọ si akọṣẹmọṣẹ.
"Igbimọ ni ""ọpọlọpọ igba ni Ọgbẹni Glenn n ta gọọgọọ̀ labẹ akoso ọti torinaa ko si anfani to lee fi ṣe bi eeyan gidi tabi ṣe ggẹb bi obi ti iwulo rẹ ba yọju."
Bẹẹ si ni orilẹede ajoji lawọn ọmọ to wa ni ikawọ rẹ yii wa nibi oju ọlọmọ ko too ti wọn si dara le e fun itọsọna ati abo wọn.
Mr Glenn jẹ akọṣẹmọṣẹ olukọni ati adari irinajo ti wn ni ireti pe yoo ṣe eto ti wọn lọ fun daadaa lai si ewu to si yẹ ko mọ iwa hihuwasi rẹ.
Lẹyin to ba ti lo ọdun mẹta ijiya rẹ nile tan, Ọgbẹni Glenn yoo nilo lati ṣẹṣẹ kọ iwe ranṣẹ pe ki wọn gbe ote ọhun kuro, igbimọ alakoso aṣemaṣe lo sọ bẹẹ.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Boko Haram: Iléeṣẹ́ ọlọ́pàá ní òun fẹ́ lo ẹṣin àti Ọ̀kadà láti ṣọ́ ìlú Abuja
Ileesẹ ọlọ́pàá nilu Abuja tí kéde pé òun yóò fi àwọn òṣìṣẹ́ rẹ̀ tó ń lo Okada àti ẹṣin ránṣẹ́ si àárín ìlú náà láti finmu finlẹ nípa àwọn ọ̀daràn.Atẹjade kan tí ọga ọlọpaa nilu Abuja, Mariam Yusuf fi síta lo sísọ loju ọrọ yii O fikún pé àwọn òṣìṣẹ́ náà yóò wọ àwọn agbègbè ìgbèríko lọ níbi táwọn ọ̀daràn fi le ṣe ibùba, tí mọto sì má le wọnú ìbẹ.
Ọ̀gá àgbà ọlọ́pàá ni Abuja gbé igbesẹ náà lẹ́yìn tí ìròyìn ayélujára kan kéde pé ikọ Boko Haram ti kọlù agbègbè kan nilu náà.Àmọ́ ikọ ọmọ ogun alajumọse feto ààbò nilu náà tí ni irọ ni ìròyìn náà.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Yusuf ni ìdí rèé táwọn òṣìṣẹ́ agbófinró náà yóò fi wa ẹṣin àti ọkada láti máa tọpinpin ojú pópó àtàwọn ẹsẹkuku laarin ìlú náà.Ileesẹ ọlọpaa náà wá ń rọ àwọn aráàlú Abuja láti ṣe suuru nítorí kò ní sí ewu.
Oríṣun àwòrán, DSS
Ile ișẹ ọtẹlẹmuyẹ ni awọn ko ni fi oju Ire wo ẹgbẹ kankan labẹ ahesọ pe awọn n ja ijagbara eyi ti yoo maa da omi alafia ilu ru.
Ile ișẹ DSS fidi ọrọ yii mulẹ lọjọ Aiku ninu atejade kan ti wọn ti bẹnu atẹ lu awọn kọlọrọsi kan ti wọn n dunkoko mọ ijọba pe awọn n fẹ ipinya, eyi to si n da ifọwọsowọpọ Naijiria ru.
Eyi ti o jẹyọ laipẹ yii ni ti awọn adari ijoba Naijiria nigba kan sẹyin naa ti wọn n pe fun ayipada ijọba to wa lori alefa lọna ti ko tọ ti o si ni ki gbogbo ara ilu gbe igbesẹ.
"Eyi fi han pe eredi ti ẹni naa fi n se e ni lati da wahala silẹ ni Naijiria.
O ṣeni laanu pe ọpọ awọn to n pe fun nkan wọnyii jẹ ẹni a n buyi fun ni awujọ, ti o si yẹ ki wọn wa nidi otitọ ati igbelarugẹ orileede ati lati ma jẹ ki imọ taraẹni nìkan ba ilọsiwaju orileede yii jẹ, ọrọ DSS re."
Ile ișẹ naa fi kun un pe awọn ri gbogbo ọna ti wọn gba lati darapọ mọ awọn miran to wa ni ilẹ okere lati ko wahala ba Naijiria.
O ran wọn leti pe bi o tilẹ jẹ pe Ijoba awaarawa fi aaye gba ki awọn eniyan le sọ ero ọkan wọn, ko fi aaye gba ki awọn eniyan maa sọ isokusọ to le ko ba eto aabo orileede.
 Nitori idi eyi, awọn eniyan ati ẹgbẹ oni imọ taraẹni nikan ni a kilọ fun lati jina si awọn iwa yii ti o le da alaafia ati isopọ ilu ru.
Awọn gbajugbaja lawujọ ni lati sọra ṣe ki wọn si kora wọn ni ijanu lati ma sọ ọrọ ti yoo da wahala silẹ lawujọ, gẹgẹ bi atẹjade naa se sọ.
Laipe yii ni ile ișẹ ọtẹlẹmuyẹ pe awọn kan fun iforowanilẹnuwo sugbọn ti wọn sọ pe asigbọ ọrọ ni, nigba ti ẹlomiran sọ pe kii ṣe nkan ti awọn sọ ni awọn eniyan n tumọ.
Awọn ikilọ ile ișẹ ọtẹlẹmuyẹ yii jẹyọ latari bi orileede Naijiria se n koju eto aabo to mẹhẹ, ijingbe, ipaniyan, Idigunjale, ìgbésùmọ̀mí ati kikogun ja awọn eleto aabo jakejado Naijiria.
'Bàbá, orúkọ yín rèé nínú ìwé òṣìṣẹ́fẹ̀yìntì Nàìjíríà tó ti kú, kí 'ló ṣẹ́lẹ̀?'
Nana Agradaa: Ìyá aláwo sogún-dogójì tó di oníwàásù ọ̀sàn gangan
Oríṣun àwòrán, other
Nana Agradaa sọ pe Ajihinrere Patricia Oduro Koranteng ni orukọ oun tuntun
Ere ni, awada ni, ko jẹ ri bẹẹ ni ọpọlọpọ eeyan n sọ lẹyin ti gbajugbaja Iya alawo kan to gbojugboya, kede pe oun ko ṣoogun mọ, ti oun si ti gbe agogo igbala bayii.
Mama Alawo naa, to jẹ gbajugbaja lorilẹ-ede Ghana, Nana Agradaa lo kede ayipada naa, lẹyin ti awọn ọlọpaa gba beeli rẹ ni ọsẹ to kọja.
Ẹsun ti wọn fi kan Agradaa ni pe o ni ileeṣẹ amohunmaworan meji ti ko ni iwe aṣẹ ijọba.
Amọ, itusilẹ rẹ kii ṣe ọfẹ, nitori pe ẹgbẹrun lọna ẹẹdẹgbẹta GHc, tii se owo orilẹ-ede Ghana lo san gẹgẹ bi owo itanran.
"Ṣugbọn tako ẹsun ti ileeṣẹ ọlọpaa fi kan-an, ọpọ eeyan lo gbagbọ pe awọn ọlọpaa mu iya alawo naa nitori pe o n polowo oogun abẹnu-gọngọ ""sika gari"", to n sogun di ogoji."
Àwọn to n bá ẹlẹkun sunkún ní Ghana
Ori amohunmaworan Thunder TV ati Ice TV to da silẹ lo ti maa n ṣe afihan bo ṣe n ṣe etutu ati irubọ, to si ma n sọ pe awọn oriṣa oun le sọ owo di ilọpo meji.
Eyi gan-an lo mu ki o jẹ iyalẹnu fun ọpọlọpọ eniyan nigba ti Mama Alawo naa deedee pẹyinda lẹyin awọn oriṣa rẹ, lẹyin to bọ lọwọ ọlọpaa, to si n sọ pe oun ti di atunbi.
Ṣugbọn, awọn eeyan kan lori ayelujara gbagbọ pe, ikede to ṣe le jẹ ọgbọn ẹwẹ lati fi ẹsin Kristiẹni boju, ko si tẹsiwaju pẹlu oogun sogun di ogoji to n ṣe.
Bakan naa ni Mama Alawo naa tun tọrọ aforiji lọwọ awọn eeyan ti igbesẹ rẹ gẹgẹ bi alawo ba ni ipa ti ko dara ninu igbe aye wọn.
Oloye Ìdòwú Olukunle so pe babalawo lo le mo òun ti ọ̀sándòru yóò já sí fun ara ilu.
Nana Agradaa sọ pe Ajihinrere Patricia Oduro Koranteng ni orukọ oun tuntun
Yatọ si pe o yẹyẹ awọn oriṣa rẹ ni gbangba, Agradaa tun sọ pe oun yoo ranṣẹ pe awọn pasitọ lati pa awọn osiṣa to wa ni ojubọ rẹ run.
Greenfield Students Kidnap: Ajínigbé ní òun yóò pa àwọn akẹ́kọ̀ọ́ yókù lái sí owó lónìí
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Awọn ajinigbe to ko awọn akẹkọọ fasiti Greenfield ni Kaduna si ahamọ ti leri lati pa awọn akẹkọọ to ku lọdọ wọn, bi wọn ko ba san owo idoola ẹmi ti wọn beere.
O kere tan eeyan mẹtalelogun to fi mọ awọn olukọ ileewe fasiti aladani to wa lopopona Kaduna si Abuja, ni wọn ji gbe logunjọ osu Kẹrin ọdun yii.
Saaju asiko yii, lawọn ajinigbe naa ti mu ileri wọn sẹ pẹlu bi wọn ti se pa awọn akẹkọọ marun un ninu awọn ti wọn ji gbe.
Ẹwẹ olori awọn janduku ajinigbe naa, Sani Jalingo to ba ileesẹ iroyin ẹka Hausa Voice of Amẹrika sọrọ ni, owo idoola ẹmi ọgọrun miliọnu dọla ati alupupu mẹwaa lawọn n beere fun.
'Bàbá, orúkọ yín rèé nínú ìwé òṣìṣẹ́fẹ̀yìntì Nàìjíríà tó ti kú, kí 'ló ṣẹ́lẹ̀?'
Jalingo, ti inagijẹ rẹ n jẹ 'Baleri' ni bi ijọba ba kọ lati da awọn lohun lọjọ Isẹgun iyẹn ọla, awọn yoo pa awọn akẹkọọ to ku to wa ni ahamọ lọdọ awọn.
O tẹnumọ pe bi ijọba ba kọ etikun si awọn, n se ni awọn yoo fi ọkọ tirela ko oku awọn akẹkọọ naa wa sigboro.
O ni akẹkọọ mẹtadinlogun, ninu eyi ta ti ri obinrin mẹẹdogun ati ọkunrin meji lo wa ni ahamọ.
Jalingo ni awọn obi awọn akẹkọọ to ku ti san owo miliọnu marundinlọgọta fawọn.
Oríṣun àwòrán, Greenfield University
Lẹyin ti wọn ji awọn akẹkọọ yii gbe, lawọn ajinigbe naa ti kan si awọn obi awọn ọmọ ọhun, ti wọn si ti beere fun ẹgbẹrin miliọnu Naira owo idoola ẹmi.
Jalingo ni awọn ko tiẹ wa beere fun ẹgbẹta miliọnu dọla mọ bi kii se ọgọrun miliọnu Naira lati ọdọ ijọba bayi.
Amọ o se ni laanu pe wọn pa awọn marun un ninu awọn akẹkọọ wọn yii lẹyin igba naa.
Titi di asiko yii, ijọba Kaduna ko ti yi ipinu rẹ pada pe awọn ko ni san owo idoola ẹmi fawọn ajinigbe naa.
Toyosi Adesanya: Ohun tó ṣẹlẹ̀, gbogbo wa ló kàn àmọ́ ṣe ni à ǹ fọ aṣọ ìdọ̀tí wa níta gbangba,
Oríṣun àwòrán, adesanyatoyosi_ileyemi/nstagram
Ọrọ ẹsun ti wọn fi kan gbajumọ osere tiata Yoruba, ti ọpọ eeyan mọ si Baba Ijesha ti n fun awọn oniruuru ẹgbẹ osere tiata lanfaani lati maa sọrọ soke.
Ọpọ awọn osere tiata yii to ti sọrọ saaju bii Iyabo Ojo, Yomi Fabiyi, Foluke Daramola, Bukky Black, Mr Latin ati Saheed Balogun, ni wọn n gbena woju ara wọn lori isẹlẹ naa.
Amọ awọn osere tiata miran to tun sẹsẹ sọrọ sita lori isẹlẹ naa ni Toyosi Adesanya ati Laide Bakare.
'Iṣẹ wá burẹkẹ síi tórí Covid-19, owó ńlá ló wà nínú dídáná sun òkú, ìsìnkú  Zoom, Live streaming'
Awọn osere tiata mejeeji naa ni wọn gbe fidio kan soju opo Instagram wọn lati da si ohun to n waye lagbo tiata naa.
hhhhhh
Toyosi Adesanya, to gbẹnu sọrọ lorukọ awọn mejeeji salaye ọrọ pọ ninu awọn ti awọn fẹ sọ sugbọn awọn ko le sọrọ, ti wọn ba lọ bulọọku awọn.
Toyosi ni tawọn pọ ju lagbo tiata Yoruba, ohun to sẹlẹ ti sẹlẹ amọ se ni awọn tun n fọ asọ idọti awọn nita gbangba, ti onikaluku wa n sọ ohun to wu lori isẹlẹ to waye.
"Awọn to ni ka se afọmọ agbo tiata wa ko parọ rara, pe awọn osere ti ko dantọ ti pọ ju, pe awọn to n ba agbo wa jẹ ti pọ ju, se wọn parọ ni.
O ti wa debi pe o yẹ ki gbogbo wa ronu bayii nitori agbo tiata Yoruba kii se ohun amurele mọ, ki awa ta ni orukọ lati agbo ere tiata Yoruba si mọ ara wa.
Wọn wa n pe awa ni Yeyebrity, ẹ jọọ se bi awọn asiwaju wa se se e ree ni bii ọgbọn ọdun sẹyin, ti awọn kan si ni awọn gbọdọ sọrọ pẹlu tipatipa.
Toyosi ni o dabi ẹni pe awọn ko mọ bi nnkan to sẹlẹ naa se wuwo si eyi to seese ko ba agbo tiata Yoruba jẹ patapata, awọn ti wọn si bajẹ laarin awọn gan mọ pe awọn bajẹ.
Wùnmí Toríọlá: Toyin Abraham kìí se ọ̀gá mi nínú tíátà
O wa fara ya lori awọn eeyan ti kii jade taara ta lati sọrọ amọ ti wọn maa n sa pamọ sabẹ ọrọ mii tawọn eeyan kan ba sọ sita lati maa ju oko ọrọ miran.
Idile nla kan soso lo yẹ ka jẹ. Nnkan to sẹlẹ yii ba wa gidi nitori ẹni to ba ni idanilẹkọ gidi nipa isẹ tiata yoo mọ pe o ba wa nitori bi awọn asiwaju ti se kọ ree."
Ojoojumọ ni idarudapọ n waye, to si yẹ ka kọkọ bọ ni ogun onijẹsa de yii naa, ka to wa maa wa ọna abayọ nitori ohun to ba se ọrẹ rẹ, se ọ pẹlu.
Bọlanle Ninalowo: Ọ̀rẹ́ lásán àti olóore mi ni Mercy Aigbe
"Oju ti ọrẹ mi, oju ko ti mi, oluwarẹ ko ni ojuti ni, nitori nnkan to se Ijesha, nnkan to se gbogbo wa ni. Ko wa yẹ ki ẹnikẹnni maa wa ohun ti ko sẹlẹ jade."""
Toyosi Adesanya fikun pe ko yẹ ki gbogbo awọn osere tiata to n gba ọrọ Baba Ijesha mọ ara wọn lọwọ bii ẹni gba igba ọti de debi pe awọn onworan awọn ni yoo maa gba awọn nimọran.
Amọ o ni eyi ti n ri bẹẹ nitori awọn ko serious, ko si si ifọwọsowọpọ laarin ara wọn, to si n beere pe se ọna abayọ si isẹlẹ to waye, eyi ti ko dara ree?
"Kii se ọna abayọ ree rara ni a n se yii nitori o ti n di nnkan miran, yoo si dara ki a maa sọrọ pẹlu ọpọlọ pipe nitori a ni ẹgbẹ ati asaaju.
Mama Rainbow: iṣẹ́ tíátà kò ta sánsán mọ́ bíi ti ayé àtijọ́
A ti wa n ba debi pe wọn ti n bi wa pe ki ni pataki ẹgbẹ wa gan? Ẹ saanu wa, ẹ ma jẹ ko bajẹ, a ko ni ọna miran ta fi n jẹun, ẹ jẹ ka pe aaro ati ọdọfin inu wa."
Toyosi ni nnkan to sẹlẹ, nnkan buruku ni, kaka ki awọn si pe ara awọn jọ, n se ni awọn tun n ja, to si rọ awọn abiyamọ to n ja lori ọrọ yii, pe ki wọn se diẹdiẹ.
Bakan naa lo rọ wọn pe ki awọn mase ta ara awọn nu nitori eyi ko le se awọn ni anfaani.
Yoruba Adverb: Ẹ̀kọ́ ráńpẹ́ yìí nípa Ọ̀rọ̀ Àpọ́nlé yóò wúlò fún ọ
Itumọ yekeyeke Ọrọ Apọnle ati bi ẹ ṣe le lo o, awọn apẹrẹ ọrọ apnle ti ẹ le fi kun awọn ọrọ iṣe (Verb) ninu gbolohun ni alaye rẹ jade daadaa ninu kilaasi Akomolede ati Aṣa Yoruba toni.
Ọgbẹni Moses Olayiwola to jẹ olukọ wa lati ileewe Smith International Baptrist Academy ni ilu Ogbomoso farabalẹ la aye awọn ọdọ.
Eyi jẹ anfani fun ẹnikẹni to ba fẹran lati maa lo awọn afikun ọrọ ninu gbolohun rẹ fun apọnle ṣiṣe.
Niger State Attack: Àwọn agbébọn tún ti jí ènìyàn tó lé ní 100 gbé lọ
Oríṣun àwòrán, other
Awọn olugbe ipinlẹ Niger ti kegbare pe awọn agbebọn ti ṣekọlu si ilu awọn, ti wọn si pa ọpọlọpọ eniyan pẹlu awọn eniyan to le ni ọgọrun ti wọn tun jigbe lọ.
Eyi ko ṣẹyin ikede gomina ipinlẹ Niger, Abubakar Bello to ni awọn ikọ agbẹsunmọmi Boko Haram ti ṣigun bo ipinlẹ awọn.
Awọn ilu ti wọn ṣekọlu si naa ni Shadadi, ni ijọba ibilẹ Mariga, ti awọn ti iṣẹlẹ naa ṣoju wọn ni o le ni ẹgbẹrun eniyan to ti sakuro ni agbegbe naa.
Wo ọjọ́ gangan tí Pásítọ̀ Dare Adeboye ti jáde láyé, ẹgbẹ́ àwọn ọmọ Pásítọ̀ RCCG kéde
NECO gbé èsì ìdánwò ọdún 2020 jáde!
Ganiyu fẹ́ na pápá bora lẹ́yìn tó gún ìya ìyàwó rẹ̀ lọ́bẹ pa lọ́sàán àwẹ, ọwọ́ bá tẹ̀ ẹ́
'Iṣẹ wá burẹkẹ síi tórí Covid-19, owó ńlá ló wà nínú dídáná sun òkú, ìsìnkú  Zoom, Live streaming'
Awọn ara ilu Shadadi ni awọn ti awọn agbebọn naa pa ni Ọjọru le ni ọgọrun, amọ ijọba ipinlẹ Niger ni iye awọn eniyan to ku ati eyi ti wọn jigbe lọ ko to ọgọrun un eniyan.
Ẹlomiran ti ọrọ naa ṣoju rẹ ni awọn agbebọn naa wa sibẹ ni ọgọọrọ, ti wọn si bẹrẹ si ni yinbọn, ti eniyan mẹjọ ku lẹsẹkẹsẹ, ti mẹrin si farapa.
Nibayii, awọn eniyan ti n sakuro ni agbegbe naa lọ si ilu Kontagora to sun mọ wọn lati sa asala fun ẹmi wọn.
Ijọba ipinlẹ Niger ni awọn si n ṣe akojọpọ orukọ awọn eniyan to lugbadi iṣẹlẹ naa ni, ki ijọba apapọ le ṣeranwọ fun wọn lati koju eto aabo to dẹnukọlẹ nibẹ.
Titi di asiko yii, ko ti i si idaniloju pe awọn ikọ agbẹsunmọmi Boko Haram lo ṣe ikọlu naa tabi awọn ọdaran agbebọn lo pa awọn eniyan ni ipinlẹ Niger.
Omije ẹkun, ohun aro, orin ẹhonu lo gbode lasiko ti awọn obi, alagbatọ atawọn ajafẹtọ wọde lọ sile aṣofin apapọ Naijiria nilu Abuja lati pe fun igbesẹ kanmọnkia latọdọ ijọba lori itusilẹ awọn akẹkọọ ileewe ẹkọṣẹ imọ nipa akoso igbodidi, Federal College of Forestry Mechanization, Kaduna.
Ọkan ninu awọn obi awọn akẹkọọ ti wọn ji gbe naa ti o pe orukọ ara rẹ ni Rabi Magaji Zakariya, ni kii ṣe ohun to rọrun rara ati pe inira ti ẹbi oun n dojukọ lori iṣẹlẹ naa ko kere rara.
O ni gbogbo oun ti awọn n ri ni wahala ti awọn akẹkọọ naa n dojukọ lori ayelujara, ko si ẹni to ri igbesẹ ti ijọba n gbe lori rẹ.
O ni opo ni oun ati pe ọdun tokọja lo yẹ ki ọmọ oun ti kẹkọjade ni ileewe naa kani pe ajakalẹ arun COVID-19 ko gbaye kan ni.
Arabinrin Zakariyani Ọjọbọ ni yoo pe oṣu meji gbako ti awọn akẹkọọ naa ti wa ni ahamọ awọn ajinigbe naa.
Ọmọ mi ko leeyan niwaju tabi lẹyin lẹyin emi yii. Mo wo iwaju mo wo ẹyin mi o le jẹun, mi o ri ọmọ mi. Bi mo ṣe n pe orukọ rẹ to ko da mi lohun... Ẹ jọọ ṣe ẹ ro pe maa tun lee fi oju kan ọmọ mi mọ bayii? Arabinrin Zakariya pariwo pẹlu ẹkun.
Arakunrin kan ti ọmọ rẹ pẹlu wa lara awọn akẹkọọ ti wọn ji gbe ṣalaye fun BBC pe ẹẹdẹgbẹta miliọnu naira (N500, 000,000) ni awọn ajinigbe naa n beere fun.
O ni igba ti ijọba ti kọ lati dunadura pẹlawọn ajinigbe naa lo mu ki awọn gbe ẹbẹ awọn wa siwaju awọn aṣofin apapọ lati gba ọrọ wọn ro.
Arabinrin Hellen Sunday Hai ti oun pẹlu jẹ obi ni tirẹ ṣalaye pe awọn o ni ọrọ meji lati sọ ju kawọn rawọ ẹbẹ si ijọba lati ba awọn yẹ gbogbo ọna to ba yẹ fun itusilẹ awọn ọmọ wọn.
Ọkan ninu awọn akẹkọọ naa ti ori ko yọ lẹyin ti wọn ji wọn gbe ṣalaye pe lilu pọ lasiko ti oun fi wa lahamọ awọn ajinigbe naa.
O ni awọn ọkunrin lo lọ n pọn omi nigba ti awọn obinrin aarin wọn n dana ounjẹ fun wọn. Bakan naa lo fi kun pe awọn kan ninu awọn ajinigbe naa gbiyanju lati fipa ba ọkan ninu awọn akẹkọọ naa to jẹ obinrin lo pọ ki ọkan ninu wọn.
Pẹlu bi jiji awọn akẹkọọ gbe ni ipinlẹ Kaduna ti ṣe di eyi ti gbogbo agbaye n ko aya soke sii bayii, awọn obi ati alagbatọ awọn akẹkọọ ileewe giga fun ẹkọ nipa akoso igbo, Federal College of Forestry mechanisation ti bẹrẹ iwọde ni ilu Abuja loni.
Gẹgẹ bi iroyin to tẹ ileeṣẹ BBC lọwọ, awọn obi ati alagbatọ awọn akẹkọọ ti wọn ji gbe naa ni awọn n wọde lọ si ileegbimọ aṣofin apapọ orilẹede Naijiria to wa nilu Abuja lati pe fun igbesẹ kanmọnkia lori itusilẹ awọn akẹkọọ naa.
Ni oṣu kẹta ọdun 2021 lawọn agbebọn kan ya wọ ileewe naa to wa lagbegbe Mando ni ilu Kaduna nibi ti wọn ti ji ọgbọn akẹkọọ ti ẹnikẹni ko si mọ  ibi ti wọn ko wọn lọ.
Lẹyin eyi ni awọn agbebọn naa beere fun owo itusilẹ lori awọn akẹkọọ naa eleyi ti ijọba ipinlẹ Kaduna ni awọn ko lee san owo itusilẹ fun awọn ajinigbe.
Gomina ipinlẹ Kaduna, Nasir El-Rufai ṣalaye nigba to n fesi lori ijinigbe to gogo ni ipinlẹ naa pe sisan owo itusilẹ fawọn ajinigbe di eewọ labẹ iṣakoso oun.
Tóò bá fẹ́ràn àti máa pọ́n ọ̀rọ̀ tàbí èèyàn lé, ẹ̀kọ́ ráńpẹ́ yìí yóò wúlò fún ọ
Ibarapa security: Agbébọn tú alápatà mẹ́ta tí wọ́n jí gbé sílẹ̀ lẹ́yìn tí wọ́n gba ẹgbẹ̀lẹ́gbẹ̀ owó
Oríṣun àwòrán, other
Awọn agbebọn tun ti ṣọṣẹ lagbegbe Ibarapa ni ipinlẹ Ọyọ nibi ti wọn ti ji awọn eeyan gbe.
Iroyin sọ pe agbegbe Idi pẹ nitosi Igangan ni wọn ti ṣọṣẹ lọtẹ yii.
Ninu ọrọ to ba BBC News Yoruba sọ, akọwe awọn agbẹ ni Ibarapa,  Ọgbẹni Taiwo Adeagbo ṣalaye pe alapata ni awọn mẹta ti wọn ji gbe naa ati pe wọn tan wọn pe ki wọn wa ra malu ni owo pọọku ni ki wọn to kugiri si wọn jiwọn gbe loju ibọn.
Akọwe awọn agbẹ ni Ibarapa naa kede orukọ awọn ti wọn ji gbe naa gẹgẹ bii Ọlagunju Gafari ti inagijẹ rẹ n jẹ Soka, Jimoh Kabiru ti inagijẹ rẹ n jẹ Ọmọ Iya ati Fasasi Kareem lati idile ọba Asawo ni ilu Ayetẹ.
O fi kun pe ni ọjọ Aje, ọjọ kẹta oṣu kẹrin ọdun 2021 ni wọn tu wọn silẹ lẹyin ti wọn gba owo ẹgbẹlẹbẹ lọwọ wọn.
Ni ọjọ Aiku ọjọ kẹta oṣu kẹrin ọdun 2021 ni wọn ji awọn eeyan naa gbe.
Ogun rape: Bàbá ọdún 52 fi ipá bá ọmọ rẹ̀ ọdún mẹ́wàá lòpọ̀
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ọkunrin kan, Kayode Adeniyi ẹni ọdun mejilelaadọta tim ko si gba ọlọpaa lọri ẹsun pe o fipa ba ọmọbinrin rẹ lopọ.
Agbẹnusọ ileeṣẹ ọlọpaa ipinlẹ Ogun, Abimbola Oyeyemi, sọ ninu atẹjade kan to fi sita pe ọwọ tẹ ọkunrin naa lẹyin tawọn kan mu ẹjọ rẹ wa si agọ ọlọpaa to wa lagbegbe Agbado.
Ẹgbọn mọmọ ọmọdebinrin naa to jẹ ọmọ ọdun mẹwaa lo mu ẹjọ naa lọ si agọ ọlọpaa.
Ẹgbọn mọmọ ọmọdebinrin naa ṣalaye fawọn ọlọpaa pe baba ọmọbinrin ọhun fi ipa mu un wọle nibi to ti fi pilo di i lẹnu ki o to fi ipa ba a lopọ.
Lẹyin naa ni a gbọ pe DPO, CSP Kehinde Kuranga ran awọn ọlọpaa lọ sibẹ nibi ti wọn ti fi ọwọ ofin mu ọkunrin naa.
Agbẹnusọ fun ileeṣẹ ọlọpaa ṣalaye siwaju si Ọgbẹni Adeniyi jẹwọ pe lootọọ loun fi ipa ba ọmọ naa lopọ.
O ni ọkunrin naa jẹwọ ọbẹ loun fi ṣẹru ba ọmọdebinrin ọhun latii rii pe oun ba ni sun ni tipa.
Ọgbẹni Oyeyemi sọ pe iwadii fihan pe ọkunrin naa ti maa n fipa bawọn ọmọbinrin mẹta lopọ ki ọwọ palaba rẹ to segi bayii.
Ẹwẹ, kọmiṣọnna ọlọpaa ipinlẹ Ogun, Edward Ajogun ti paṣẹ pe ki ajọ to n ri si ọrọ ẹbi tẹwọgba ẹjọ naa.
Kaduna Forestry Students Kidnapping: Àwọn akẹ́kọ̀ọ́ sọ ìrírí wọn ní àhámọ́ ajínigbé fún ọjọ́ 56
Oríṣun àwòrán, Valentina Shekara
Idunnu subu lu ayọ fun awọn mọlẹbi ati ara awọn akẹkọọ mẹtadinlọgbọn lati ileewe Federal College of Forestry Mechanisation, Kaduna to jajabọ lọwọ awọn ajinigbe lẹyin ọjọ mẹrindinlọgọta ni ahamọ.
Amọ iriri wọn ni panpẹ ajinigbe buru jai, to jẹ wi pe niṣe ni wọn bu ṣẹkun lati sọ ohun ti oju wọn ri.
Nkan bi aago mẹta ọsan ni ariwọ sọ ni papa ibudokọ okọ ofurufu ni ilu Kaduba, ti awọn eniyan si fo fun ayọ lati ri awọn ọmọ wọn.
Ọkan lara awọn akẹkọọ naa to sọ iriri rẹ, Sarah Sunday  ni awọn lọ si ọrun apaadi bọ ni pẹlu ohun to ṣẹlẹ si wọn.
''Wọn ko gba ki ẹnikẹni bu omi sara tabi lọ si baluwẹ ni ahamọ ọhun.''
Oríṣun àwòrán, Valentina Shekara
''Amọ wọn ko lu wa tabi pa ẹnikẹni ninu wa, ọ̀jọ kini ti a ti de bẹ ni wọn ti lu wa, ti wọn si ṣe fidio wa.''
''Bakan naa ni a o jẹun, ti a si rin rin rin ninu igbo aginju. Lẹyin ti awọn ọkunrin ba lọ pọn omi wa fun wa ni a o fi se ounjẹ Tuwo pẹlu Miyan kuka tabi Tuwo pẹlu Ila gbigbẹ''
''Igba kan pere la jẹ irẹsi ati spaghetti naa ni ahamọ awọn ajinigbe naa.''
Akẹkọbinrin miran to tun sọ iriri rẹ, Zakariya Mogaji ni awọn ohun to ṣẹlẹ si awọn gbẹnutan, ti wọn si fi iya jẹ awọn loriṣiriṣi.
Oríṣun àwòrán, Valentina Shekara
Arabinrin Magaji ni oun ko gbero iru nkan to ṣẹlẹ si oun fun ọta oun kankan nitori ko ṣee fi ẹnu sọ.
''Awọn ajinigbe yii nilo adura pe ki Ọlọrun fi ọwọ tọ wọn lọkan, amọ ni ti temi, mo ti dariji wọn.''
Oríṣun àwòrán, Valentina Shekara
Ninu ọrọ tirẹ, kọmisọnna ọlọpaa nipinlẹ Kaduna, Umar Muri ni awọn akẹkọọ to gba itusilẹ naa ti ṣe ayẹwo ara wọn finifini ni ileewosan, ti wọn si ni anfaani lati darapọ pẹlu awọn obi wọn.
Bakan naa ni o rọ wọn wi pe ki wọn ma jẹ ki iṣẹlẹ yii di wọn lọwọ ati pada si ileewe lati tẹpa mọ eto ẹkọ wọn.
Awọn akẹkọọ mẹtadinlọgbọn to gba itusilẹ naa wa lara awọn mẹtadinlogoji ti wọn jigbe ni nkan bi oṣu meji sẹyin ni ileewe wọn.
Awọn akẹkọọ mẹtadinlọgbọn lati ileewe giga Federal College of Forestry ni Afaka, Kaduna ti gba itusilẹ lọwọ awọn ajinigbe.
Ileeṣẹ iroyin Daily Trust fi idi iṣẹlẹ naa mulẹ nigba ti wọn ba ọkan lara awọn to ṣe oniduro awọn ti wọn tu silẹ naa sọrọ.
Iroyin naa ni gbajugbaja oniwaasu Islam,  Sheikh Ahmed Gumi pẹlu iranwọ aarẹ orilẹede Naijiria tẹlẹ, Olusegun Obasanjo lo se eto bi awọn akẹkọọ naa ṣe gba itusilẹ.
Awọn akẹkọọ mẹtadinlọgbọn to gba itusilẹ naa wa lara awọn mẹtadinlogoji ti wọn jigbe ni nkan bi oṣu meji sẹyin ni ileewe wọn.
India Corona scourge: Àlàyé rèé lórí ohun tó ń fa bí kòkòrò COVID-19 India ṣe búrẹ̀kẹ̀
Iroyin ni awọn mẹwaa  ni awọn agbebọn naa kọkọ tu silẹ, lẹyin ti awọn obi ati alaṣẹ ileewe san owo ẹmi awọn ọmọ naa.
Awọn agbebọn naa kọkọ beere owo to to ẹẹdẹgbẹ miliọnu lọwọ ijọba ipinlẹ Kaduna, ki wọn to fi awọn ọmọ naa silẹ.
Amọ ijọba kọ lati duna dura pẹlu wọn, pẹlu ileri wi pe pipa lo tọ si wọn.
Gbajumọ olori ẹsin musulumi kan lorilẹede Naijiria, Ahmad Gumi ni awọn agbebọn Boko Haram lo ji awọn akẹkọọ fasiti Greenfield nilu Kaduna gbe.
O ṣalaye lori eto ileeṣẹ mohunmaworan AIT pe ọrọ ijinigbe awọn akẹkọọ naa ti n dojuru bi ẹsẹ telọ.
Ni ọjọ kejidinlogun oṣu kẹrin ọdun 2021 lawọn agbebọn ji ọpọlọpọ awọn akẹkọọ gbe nileewe fasiti Greenfield ni ilu Kaduna.
Oríṣun àwòrán, other
Wọn ti pa lara awọn ọmọ naa ti wọn si tun n lerileka pe bi ijọba ko ba ko owo itusilẹ ọgọrun miliọnu naira wa pẹlu ọkada tuntun mẹwaa, pipa lawọn yoo pa awọn akẹkọọ to ku.
Alfaa Gumi ni awọn agbebọn Bokoharam naa ti n wọnu awọn agbebọn to n ji eeyan gbe kaakiri lorilẹede Naijiria bayii.
Ọrọ naa ti n dojuru gidigidi bayii nitori awọn kan naa ti n lọwọ sii; Boko Haram ti n wọnu ọrọ yii bayii. Awọn gan ni wọn ji awọn akẹkọọ fasiti Greenfield gbe. Ọrọ orun ko si mọ bayii afi ka tete gbe igbesẹ lori rẹ ni kiakia.
O wa rọ banki apapọ orilẹede Naijiria lati san owo ti wọn beere fun naa.
O woye pe lootọ owo to gọbọi ni ọgọrun miliọnu naira ti wọn n beere fun ṣugbọn ko si owo to pọ ju lati san fun ẹmi awọn akẹkọọ naa
Opeyemi Ayeola ní àṣìlò ògùn ibà ku díẹ̀ kó rán òun lọ sọ́run alákeji láìpé ọjọ́
Oríṣun àwòrán, instagram/Screenshot
Se wọn ni iku ti yoo ba pa ni, to ba ṣi ni ni fila o yẹ ka dupẹ.
Gbajumọ oṣere, Ọpẹyẹmi Ayeọla ti ke si gbogbo awọn ololufẹ rẹ ki wọn ba oun dupẹ lọwọ Ọlọrun pẹlu bi ori ṣe ko oun yọ lọwọ iku.
Ọpẹyẹmi Ayeọla ṣalaye lori ikanni ayelujara rẹ pe ori lo ko oun yọ lọwọ aṣilo ogun ati pe bi kii ba ṣe Ọlọrun ni, aṣilo ogun ko ba ti ran oun lọ sọrun alakeji.
O wa rọ awọn eeyan lati maa ka awọn iwe ikilọ ati atọna to wa lara ogun gbogbo ti wọn ba ra.
O ni eyi fẹrẹ gba ẹmi oun laipẹ yii.
"o ṣalaye pe: ""ni ọjọ meji sẹyin mo wa ni ibudo yiya sinima kan ni mo ba sọ fawọn akẹgbẹ mi pe o fẹ ṣe bi ẹni tẹ mi diẹ."
"Gbogbo wọn ba woye pe boya iba ni, gẹgẹ bi gbogbo wa naa ṣe maa n funrawa ṣapejuwe ohun to n ṣe wa lai ri dokita."""
Oríṣun àwòrán, Instagram/opeyemi ayeola
Gbajumọ oṣere naa ni oun lọ si ile itaja ogun kan nigba ti oun pari iṣẹ. O ni oun fẹran Gari gidigidi, loun ba mu Gari ki oun to lo ọwọ akọkọ ogun naa lai ka awọn ọrọ atọna nipa ogun naa to wa lara iwe pelebe ti wọn fi si i lara.
O ni bi oun ṣe lo ọwọ keji ogun naa ni ọjọ Iṣẹgun loun ba gbera kọri si ọna Ikorodu lati ile oun ni ipinlẹ Ogun fun iṣẹ laimọ pe ara ohun to maa n farahan nipa ogun naa ni oyi atawọn nnkan miran koda eeyan lee daku.
'Iṣẹ wá burẹkẹ síi tórí Covid-19, owó ńlá ló wà nínú dídáná sun òkú, ìsìnkú  Zoom, Live streaming'
Lai fọrọ gun igba meji ọtọọtọ ni mo daku ni ibi iṣẹ ki wọn to gbe mi de ile iwosan. Koda ni ile iwosan mo tun daku lẹẹkan ki awọn dokita to ri mi.
O ni ileewosan ni wọn ti jẹ koun mọ pe oun ko ni aisan Iba gan an ti oun lo ogun fun, ki oun to tun wa lo ogun naa lai ka iwe atọnisọna to wa lara rẹ.
India Corona scourge: Àlàyé rèé lórí ohun tó ń fa bí kòkòrò COVID-19 India ṣe búrẹ̀kẹ̀
Lẹnu lọọlọ yii ni okiki gbalẹ pe ọwọja arun Coronavirus ti legba kan ju ọrin lọ ni orilẹede India.
Laarin osu kan, o si le ni miliọnu marun eeyan to ti lugbadi kokoro arun naa, idi si ree ti ileesẹ BBC se tanna wadi ohun to fa itankalẹ arun naa lẹnu lọọlọ yii ni India.
Iwadii BBC ti wa fidi rẹ mulẹ pe bi awọn eeyan se seraro lori awọn ilana to n dena itankalẹ arun Covid-19 lo fa sababi.
Bakan naa la tun fidi rẹ mulẹ pe oniruuru ẹya arun Coronavirus lo ti su yọ ni India, to si rọrun fun lati tete ran ẹlomiran.
Iwadii tun fidi rẹ mulẹ pe ẹya arun naa to wa lati ilẹ United Kingdom UK lo pọ ju awọn ẹya arun Covid-19 miran lọ.
Koda, aaye ko fẹ si mọ lati sin awọn oku to n jade laye lati ipasẹ arun naa bayii.
Mbaka missing: Father Ejike Mbaka ti ṣí aṣọ lójú àwọn tó sọ ọ́ dàwátì
Oríṣun àwòrán, other
Gbajumọ oluṣọaguntan ijọ aguda nipinlẹ Enugu, Ẹniọwọ Ejike Mbaka ti ọpọ mọ si Fada Mbaka ti ṣalaye awọn to wa nidi bo ṣe di awati fun ọjọ meji.
Nigba to n ba awọn olujọsin ijọ rẹ sọrọ nileejọsin Adoration ministries ni Umuchigbo Nike nilu Enugu, Fada Mbaka ṣalaye pe awọn alaṣẹ daosisi ijọ Aguda nilu Enugu lo wa nidi bi oun ṣe dawati.
O ni Bisọbu agba ijọ aguda nibẹ lo pe oun sibi ipade kan, ibẹ si ni wọn ti fi oun si abẹ ahamọ.
O ni ara ẹsun ti wọn ka si oun lẹsẹ̀ ni pe oun gbadura fun Nnamdi Kanu, aṣiwaju ẹgbẹ agbesunmọmi IPOB.
Gẹgẹ bi o ṣe sọ fawọn ọmọ ijọ rẹ, ọgbọn ọjọ ni wọn gbero lati fi fi oun si ahamọ ki o to di pe awọn ọmọ ijọ rẹ pariwo sita ti wọn fi tu oun silẹ.
Fada Mbaka ṣalaye pe oun ti wọn sọ fun oun ni pe oun yoo wa lahamọ fun oṣu kan fun oun lati gbadura ki oun si ṣe aṣaro lori iṣe oun.
"O ni oun rọ wọn lati fun oun laaye lati ba awọn eeyan ijọ oun sọrọ ki oun si ti ilẹkun ileejọsin naa ""ṣugbọn wọn ni rara, ẹ gbami laaye lati ṣe isin oni fun awọn olujọsin ijọ mi, mi o tilẹ ni sọ fun wọn pe mo wa labẹ ibawi, wọn ni rara. Maa kan sọ fawọn ọmọ ijọ mi ni pe mo n lọ fun adura ọlọgbọn ọjọ, a o pada wa gbogbo wa yoo si bọwọ fun gbogbo nnkan ti wọn ba sọ, wọn ni rara"""
India Corona scourge: Àlàyé rèé lórí ohun tó ń fa bí kòkòrò COVID-19 India ṣe búrẹ̀kẹ̀
O ni oun tilẹ bẹ wọn pe ki wọn gbe iranṣẹ Ọlọrun miran lọ si ijọ naa, sibẹ wọn kọ ni.
Ni Ọjọru ni okiki kan nigba tawọn ọmọ ijọ Adoration ministries ti Fada Mbaka n ṣe oluṣọaguntan fun wọde nilu Enugu ti wọn si n pariwo pe ki wọn ba awọn wa Fada Mbaka ti wọn ji gbe.
Ninu ọrọ rẹ, Fada Mbaka ni awọn oṣiṣẹ ileeṣẹ agbofinro DSS kọ lo gbe oun gẹgẹ bi awọn eeyan kan ṣe ro.
Wọn ti ri ojiṣẹ Ọlọrun, Fr Ejike Mbaka.
Ṣaaju ni iroyin jade pe alufaa naa to ni ijọ Adoration Ministry nilu Enugu ti di awati fun bi ọjọ meji.
Iṣẹlẹ yii n waye lẹyin ọjọ diẹ ti Mbaka pe ki Aarẹ Muhammadu Buhari fi ipo silẹ nitori bi eto aabo ṣe ri ni Naijiria.
Oríṣun àwòrán, Adoration ministry enugu
Bi iroyin ṣe jade pe wọn ko ri Mbaka, ni awọn alatilẹyin rẹ ti tu jade fun iwọde lọ si ile Olori alufaa ijọ Aguda nilu Enugu.
Botilẹ jẹ pe a ko ti i le sọ nkankan nipa bi alufaa naa ṣe pada si ilu tabi ibi to ti n bọ, tilu-tifọn, tijo tayọ ni awọn eeyan fi pade rẹ.
Awọn to wa ni ayika alufaa naa sọ pe o ti le ni ọjọ meji ti awọn ti ri Mbaka gbẹyin.
A gbọ pe o dagbere fun to sunmọ pe pun n lọ si ile Alufaa Agba ijọ Katoliliiki ni ẹkun Enugu, ṣugbọn wọn ko ri i lati igba naa.
Fr Mbaka kọ ẹ̀yìn sí Buhari nítorí kò rí nǹkan jẹ lábẹ́ rẹ̀ - Iléeṣẹ́ Ààrẹ
Fr Mbaka, ọmọ ìjọ rẹ̀ kọ̀lu akọ̀ròyìn BBC, wọ́n lù wọ́n ní àlùdojúbolẹ̀
Lasiko ti BBC ṣe abẹwo si inu ọgba ijọ rẹ, Adoration Ministry, niṣe ni eero pe jọ sibẹ, ti wọn si n beere pe nibo ni Father Mbaka wa.
Ṣugbọn, BBC ko ti i le sọ ni pato boya wọn ji alufaa naa gbe lọ ni, boya o farapamọ ni tabi wa ni ọdọ awọn agbofinro.
Bakan naa ni awọn alaṣẹ ijọ Aguda nilu Enugu sọ pe awọn ko ti i gbọ nipa iṣẹlẹ naa.
Alufaa kan to sunmọ Mbaka naa sọ pe oun ko gbọ nipa didi awati rẹ, ṣugbọn ko gbe ipe oun si ori ẹrọ ibanisọrọ rẹ.
Iṣẹlẹ yii si ti mu ki awọn ọmọ ijọ rẹ bẹrẹ iwọde.
Queen Salawa Abeni Waka Queen àti ohun mẹ́wàá tíó yẹ kí o mọ̀ nípa rẹ̀
Oríṣun àwòrán, Instagram/salawa abeni
Queen Salawa Abeni bẹrẹ iṣẹ orin gẹgẹ bi iṣẹ aje lati igba to ti wa ni ọdun mẹwaa, o kan lọ ba ọkan lara awọn asaaju ninu iṣẹ gbigbe orin jade nilu Eko o si bẹbẹ pe ko jẹ ki oun kọ orin ki wọn ri nkan ti oun le se.
Sugbọn wọn ko fun un ni anfaani nitori wọn foju ọmọkekere wo o ati pe ko si nnkan to ni laari kan ti o le se.
Ko pẹ si asiko naa ni agbaọjẹ abanigbe orin jade yii ba a nibi kan ni agbegbe Ẹpẹ nibi ti o ti n fi orin da awọn eniyan laraya ti ero si pe biba sibẹ.
Lọgan lo gbe e lọ lati gba orin rẹ silẹ, lati igba yii ni wọn ti bẹrẹ si ni tọ sọna gẹgẹ bi ọkan ninu awọn gbajugbaja olorin to lamilaaka ni Naijiria.
Èmi àti Kolington kò fẹ́ra padà o, ọba Wákà kò fẹ́ ọba Fuji mọ́ - Salawa Abeni
Inú káàdì ìránti tí mo rí he ní mó tí rí fọ́tò ìhòhò Salawa, mó kàn fẹ́ gbà owó díẹ̀ ni- Afurasí
Ó pé ọdún mẹ́wàá tí Barrister kú; wo ǹkan tó yẹ láti mọ̀ nípa rẹ̀ gẹ́gẹ́ bíi olórin, tẹ̀wé-tẹ̀wé, akọ̀wé àti sọ́jà
Èmi kò gbé pọ̀ pẹ̀lú Kollington Ayinla àmọ́ ọjà t'ọ́mọ ti wọ̀ lọ̀rọ̀ àwa méjééjì - Salawa Abẹni
Lasiko kan sẹyin ni Waka Queen ṣe aisan, ọpọ lo si ti ro pe aisan ọhun ni yoo mu opin ba gbajugbaja naa, ṣugbọn, o ru u la.
Pẹlu iranlọwọ awọn ọmọ Naijiria ati ijọba ipinlẹ Eko, Tinubu, Fashola ati Ambode ni Salawa ni Ọlọrun lo fun oun, o bọ lọwọ aisan rọparọsẹ to kọlu u to si ti n ṣe daada lati igba naa.
Oríṣun àwòrán, Instagram/salawa abeni
Lẹyin eyi lo tun ba BBC Yoruba sọrọ lori igbesi aye rẹ ninu iṣẹ orin.
Awọn nnkan mẹwaa ti o yẹ ki o mọ nipa Salawa Abeni ree, akikanju obinrin to nigbagbọ ninu ara rẹ pe oun le ṣe daada pẹlu atilẹyin awọn obi rẹ.
1. Salawa Abeni bẹrẹ orin kikọ lati ọmọ ọdun mẹsan sugbọn o sọ di iṣẹ aṣela lati wa ounjẹ oojọ ni igba to pe ọmọ ọdun mẹwaa.
2. O gbe awo orin akọkọ jade ni ọdun 1976 to pe akọle rẹ ni General Muritala Ramat Muhammed labẹ asia Leader Records.
Eré orí ìtàgé kọ́ ni pé Baba Ijesha ń tẹ ọmọ lára, ẹ yé gbè sẹ́yìn mi lọ́nà àìtọ́ - Yomi Fabiyi
Ṣé lóòtọ́ ni Fr Ejike Mbaka ti di àwátì? Ẹ wo ǹkan tí a mọ̀ nípa rẹ̀
'Iṣẹ wá burẹkẹ síi tórí Covid-19, owó ńlá ló wà nínú dídáná sun òkú, ìsìnkú  Zoom, Live streaming'
3.  Oun ni obinrin akọkọ to gbe orin jade to si ta kasẹẹti to le ni miliọnu kan ni Naijiria, orin akọkọ to se jade ni pẹlu.
4.  Nigba ti o wa ni ọdun mẹrindilogun, Salawa Abeni da ẹgbẹ orin kalẹ to pe ni The Waka Modernisers lọdun 1977.
Oríṣun àwòrán, Instagram/salawa abeni
5.  Leader Records lo wa lati ọdun 1976 si ọdun 1985, o si ṣe agbekalẹ orin mẹrinla laarin asiko naa.
6. O figba kan fẹ gbajugbaja olorin, Alhaji Killington Ayinla ti gbogbo eniyan mọ si Kollington ti wọn si bi awọn ọmọ lara wọn ni Sheriff ati Okikiola. Bakan naa lo padanu ọmọ kan ri, eyi to bi fun Lati Adepoju.
7.  O darapọ mọ rẹkọọdu Kollington lasiko ti wọn n fẹ ara wọn laarin ọdun 1986 titi di 1994 nigba  ti wọn tuka.
8. Labẹ Kollinton Records, awo orin mẹwaa lo gbe jade.
9. Ọdun 1992 ni Alaafin Oyo, Oba Lamidi Adeyemi fun ni oye Waka Queen orin.
Oríṣun àwòrán, Instagram/salawa abeni
10. Ọkan ninu ọmọ ti Salawa bi fun Kollington Ayinla, Sheriff tọpasẹ awọn obi rẹ  bi oun naa ṣe n kọ orin taka sufe pẹlu orukọ Big Sheriff.
Oun ati Waka Queen ṣe atunkọ orin rẹ Gentle Lady ni mi.
Shebaby: Àwọn Eléégún ní òṣèré yóò kú láàrin ọjọ́ méje
Oríṣun àwòrán, Seyi Ariyo Shebaby Instagram
Yoruba ni ẹnikan kii gbọ ọjọ iku rẹ ko dakẹ, eeyan ko si le mọ ọjọ to maa ku, ki inu rẹ dun.
Idi ree ti gbajumọ osere tiata lobinrin kan, Seyi Ariyo, ti ọpọ eeyan mọ si Shebaby se bu sẹkun, to si n figbe ta.
Ariyo, ẹni to bu sẹkun ninu fidio kan to gbe soju opo ayelujara Instagram rẹ salaye pe fiimu kan ni oun ya, eyi to fẹ fa iku ojiji ba oun bayii.
Ariyo ẹni to n ke si gbogbo ọmọ Naijiria pe ki wọn gba oun, salaye pe fiimu kan to pe akori rẹ ni Asiri Pẹpẹ ni oun ya lọsẹ to kọja.
"Mo dẹ lo eegun ninu sinima naa, eegun ba osere kan sun ninu ere naa, eeyan kan wa lo foonu rẹ lati ya aworan ọwọ ibi ti egungun ti ba obinrin naa sun.
Ẹni to ya aworan naa wa gbe fidio ibi ti eegun ti n ba onitọun sun sori ayelujara ni awọn eleegun ba ri, wọn ti bẹrẹ si ba mi fa wahala lati ọsẹ to kọja.
Awọn Eleegun ti wa n dunkooko mọ mi pe maa ku laarin ọjọ meje, ẹ jọọ, ẹ gba mi, ẹ ma jẹ ki n ku, mo ti ran gbogbo awọn eeyan si wọn, wọn gbọ ni o."
Nollywood: Bẹbẹ ń lọ ní ibùdó yíya sinimá Àgbésọrísùn
Shebaby wa n rawọ ẹbẹ pe ki awọn Eleegun dari jin oun nitori oun ko tapa si isẹse, amọ ki wọn fori jin oun, oun ko ni se bẹẹ mọ.
"N ko ni foju tẹmbẹlu asa ajogunba wa laelae, mo se sinima Asiri Pepe lati la awọn eeyan lọyẹ lori ohun to n sẹlẹ ninu ẹsin, eyi to kọja ohun to n waye lori pẹpẹ.
Paapaa julọ, mo tun salaye ewu to wa ninu bi awọn eeyan kan se maa n foju tabuku ẹsin isẹse wa nilẹ Afirika.
Yomi Fabiyi ló ni ki òun àti ìyàwó rẹ̀ yàgò fún ra wọn
Shebaby wa fi ọwọ sọya pe bi sinima naa ba jade, awọn eeyan gan yoo ri funra wọn pe  oun ko se sinima naa lati ta ẹrẹ si asa ajogunba wa.
Bola Tinubu: Femi Kuti ní kí APC àti Tinubu yọ àmì ìdámọ̀ wọn kúrò lára èròjà ìbò
Oríṣun àwòrán, Femi Kuti/ Bola Tinubu Twitter
Ẹbi gbajumọ akọrin nni, Fela Anikulapo Kuti ti yari fun asaaju ẹgbẹ oselu APC ati gomina tẹlẹ nipinlẹ Eko, Asiwaju Bola Ahmed Tinubu.
Koko ohun to fa sababi aawọ naa ko se lẹyin eto idibo aarẹ to n bọ lọdun 2023 ninu eyi ti awọn eeyan kan n sọ kiri pe oloselu naa fẹ kopa ninu rẹ.
Ẹgbẹ oselu APC lo gbe ọrọ atawọn aworan eroja ipolongo ibo fun Asiwaju Bola Tinubu soju opo Twitter rẹ, eyi ti wọn kọ 'Africana Jagaban' si lara.
'Ẹ kálọ sí ìlú mi'... Ètò ńlá tó bẹ̀ sílẹ̀ kìjà lórí BBC Yorùbá
Olori ẹbi ati Dawodu Fela, Femi Kuti ti wa pariwo si oju opo Twitter rẹ pe oun ri awọn eroja ipolongo ibo naa ti ẹgbẹ APC gbe sita bii T-Shirt, ti wọn lo orukọ idamọ awọn.
Oríṣun àwòrán, @Femiakuti
Femi ni lara awọn eroja ipolongo ibo naa ni wọn ti ri ọrọ 'Africana Jagaban', bẹẹ si ni orukọ Africana yii ọpọ eeyan mọ Fela Anikulapo mọ.
Femi Kuti wa n ke si awọn ọmọ ẹgbẹ oselu APC ati Asiwaju Tinubu funra rẹ pe ki wọn yọ orukọ Africana naa kuro lara eroja ipolongo ibo ti wọn n pin kiri.
O salaye pe orukọ idamọ ẹbi Fela ni Africana naa, ẹgbẹ oselu APC si n tẹ ẹtọ awọn mọlẹ nipa lilo orukọ nnaa lai gba asẹ lọdọ ẹbi awọn.
Oríṣun àwòrán, @Femiakuti
Gbajumọ akọrin Afro Beats naa ni yoo dara ki ẹgbẹ oselu APC tete pa awọn ohun to kọ ati aworan to gbe soju opo Twitter rẹ rẹ ko to di nnkan mii.
Ẹbi wa  ko fara mọ ẹgbẹ oselu kankan lorilẹede Naijiria tabi loke okun. A n se ayẹwo bi nnkan yii se n lọ finnifinni."
Irú ẹ̀dá wo ni Fẹla Jẹ́?
Tẹ ba si kuna lati tẹle ibeere wa, a jẹ pe a ko ni nnkan miran ta se ju pe ka tẹle ilana ofin to wa larọwọ to wa.
Amọ lọwọlọwọ bayii, ẹgbẹ oselu APC ti gbọ imọran ti Femi Kuti gba wọn, to si ti gbe awọn aworan eroja ipolongo ibo naa kuro loju opo Twitter rẹ.
Oríṣun àwòrán, @Femiakuti
Oduduwa Nation: Ẹgbẹ ọmọ Yorùbá YAF ṣèwọ́de tako ìyapa Nàíjíríà
Oríṣun àwòrán, The Nation
Se ni ohun gbogbo pakasọ nilu Ado-Ekiti l‘Ọjọbọ nigba ti ẹgbẹ ọmọ bibi ilẹ Yoruba kan, Yoruba Appraisal Forum, YAF, se iwọde tako ipinya Naijiria.
Deedee aago mẹsan owurọ ni iwọde na ti bẹrẹ, ti wọn si korajọ pọ si gbagede Adekunle Fajuyi, nibi ti wọn ti gbera lati bẹrẹ iwọde yika ilu Ado Ekiti.
Lara awọn eeyan to se iwọde naa la ti ri awọn ọlọkada, ẹgbẹ ọdọ lorisirisi  ati ẹgbẹ awọn ọlọkọ ero ti wọn gbe oniruuru akọle lọwọ.
'Ẹ kálọ sí ìlú mi'... Ètò ńlá tó bẹ̀ sílẹ̀ kìjà lórí BBC Yorùbá
Ohun to wa ninqu akọle naa ni ‘A gbagbọ ninu orilẹede Naijiria to wa ni ọkan soso, Orilẹede Naijiria se koko, ẹ jẹ ka jọ wa papọ ka si nifẹ ara wa.‘
Bakan naa ni awọn akọle miran sọ pe ‘ko si ba se le duro bii orilẹede lai si isọkan, ikan omi ni wa ni ẹyọ kọkan amọ okun nla ni wa ta ba wa papọ.‘
Oríṣun àwòrán, The Nation
Alakoso fun ẹgbẹ YAF, Adesina Animashaun, lasiko to n ba awọn oluwọde naa sọrọ tako Sunday Igboho ati bo se n pe fun iyapa Naijiria.
O wa sapejuwe iwa naa gẹgẹ bii eyi to fẹ gba akoso ijọba orilẹede yii, ti ko si tun safihan ẹni to ni ifẹ ilẹ baba rẹ.
Bakan naa ni Animashaun tun koro oju sawọn igbesẹ Nnamdi Kanu ati ẹgbẹ rẹ, IPOB, lati pin orilẹede yii niya, ati iwa ipaniyan ati idaluru ti wọn n se nitori ipe fun iyapa.
Oríṣun àwòrán, The Nation
Ẹgbẹ YAF wa ke si awọn oriade nilẹ Yoruba lati mase gba Nnamdi Kanu laaye pe ko tọwọ bọ ọpọlọ wọn tabi bọ si aarin wọn nitori ẹri to daju ti fihan pe rogbodiyan lo fẹ da silẹ.
"Ẹ ma jẹ ka sọ Naijiria da bi orilẹede Somalia se da nitori ogun abẹle, n ko tiẹ fẹ ni iriri ogun jija titi aye mi nitori a mọ nnkan ta padanu lasiko iwọde EndSARS to kọja.
Awa bii ọmọ ẹgbẹ Yoruba Appraisal Forum, a n fi ikilọ sita pe a ko ni gba ki ẹlẹgbẹjgbẹ tabi ẹnikẹni sọ ẹkun iwọ oorun Naijiria di ibudo ogun."
Kò sí ìgbà kankan tí Yorùbá jókòó pé ki Igboho  lọ kéde ìyapa kúrò ní Nàíjíríà
Ẹgbẹ YAF wa n ke si ileesẹ ọlọpaa, awọn ọtẹlẹmuyẹ DSS, awọn ologun atawọn ileesẹ agbofinro gbogbo lati ji giri si ojuse wọn, ki wọn si da awọn ajijagbara to n wa iyapa Naijiria lẹkun.
New Minimum Wage: Aráàlú fẹ́ kíjọba dín owó olóṣèlú kù dípò owó oṣù òṣìṣẹ́
Oríṣun àwòrán, NLC
Awọn ọmọ Naijiria fesi lori ẹrọ ayelujara lori igbesẹ ijọba lati din owo oṣu oṣiṣẹ ku lori ọrọ aje to dẹnukọlẹ
Igbe ilu o fararọ ni awọn eniyan nke ni Naijiria pẹlu ariwo pe ki ijọba wa nkan ṣe si ọwọngogo owo ounjẹ, ko ma si gbero lati din owo oṣu oṣiṣẹ, ti ko to nkankan ku.
Ọrọ yii ati bẹẹ bẹẹ lọ ni awọn eniyan n fi ranṣẹ ni oju opo ikansiraẹni Facebook lati fi aidunnu wọn han si ijọba to wa lode yii lori bi nkan ko ṣe fararọ fun awọn eniyan.
Ijọba orileede Naijiria lo kede wi pe awọn n gbero lati din owo oṣu oṣiṣe ku nitori ọrọ aje ti dẹnukọle patapata ni Naijiria.
Oba Sunday Oyediran ṣàlàyé kíkún nípa ìṣẹ̀ṣe, ìgbàgbọ́ àti ẹ̀sìn tí kò dí ará wọn lọ́wọ́
Amọ, ẹgbẹ oṣiṣẹ ni Naijiria to fi mọ awọn araalu lo fi lede wi pe, ko gbọdọ si ohun to jọ bẹẹ, afi ti ijọba ba fẹ din owo oṣu awọn oloṣelu ku.
Adeniji Olugbenga to sọrọ loju opo BBC News Yoruba ni owo awọn aṣofin ni Naijiria ju ti awọn oṣiṣẹ lọ ni ọna igba.
O ni nitori idi eyi, ki ijọba din owo oṣu wọn ku, ki wọn fi ti awọn oṣiṣẹ silẹ nitori owo ọhun ko to ra nkankan pẹlu ọwọngogo owo ounjẹ.
Francis Olusola Alao: Wọ́n ti ti ọ̀rọ̀ òṣèlú bọ ọ̀rs Sunday Igboho, ṣùgbọ́n..- Oba Olugbọn
Bolaji Abdullateef ni ijọba fẹ sọ awọn oṣiṣẹ to ti talaka tẹlẹ di ekute  sọọṣi ti ko tilẹ lee fi owo ra nkankan mọ ni ọja, nitori gbogbo rẹ ti dojuru patapata.
Ninu ọrọ tirẹ, Oko Oro Wumi beere pe se ni asiko ti gbogbo nkan wọn gogo yii ni ijọba n gbero lati din owo oṣu ku, nigba to si jẹ pe owo ori awọn oṣiṣẹ yii ni awọn adari Naijiria n na lai ṣiṣẹ fun un.
Adenike Ireoluwa Amoo ni owo oṣu ti awọn oṣiṣẹ n gba lọwọlọwọ ni Naijiria ko ka nkankan ati pe aanu Ọlọrun ni wọn fi n gbera, ti ọpọlọpọ oṣiṣẹ si ti di onigbese tan.
hhhhhh
Pẹlu ibinu ni Olakunle Timothy Orokunbi fi sọ wi pe ki ijọba lọ din owo oṣu ti gomina kọọkan n gba ku pẹlu owo mọto wọn.
Bakan naa lo ni owo aṣọ ti wọn n wọ, owo ijoko ile awọn aṣofin ati owo oṣu awọn minisita ni ki ijọba lọ dinku, kii ṣe ti awọn oṣiṣẹ.
Amọ, arakunrin Olatunde Awe O'Connell ni ki ijọba Naijiria ṣe ohun gbogbo ti wọn ba le ṣe lati ri wi pe ọrọ aje to dẹnukọlẹ bọ si ipo pada ni Naijiria.
Dare Adeboye: Ọjọ́ Ìṣẹ́gun ní olóògbé yóò wọ káà ilẹ̀ ṣùn ní Redemption Camp
Oríṣun àwòrán, Pst Dee
Idile Baba Enoch Adejare Adeboye to sẹsẹ padanu ọkan lara ọmọkunrin rẹ, Pasitọ Dare Adeboye, ti sọrọ sita fun igba akọkọ lẹyin isẹlẹ ibanujẹ naa.
Atẹjade kan ti mọlẹbi naa fisita lọjọ Ẹti, eyi ti Pasitọ Leke Adeboye fọwọsi lo dupẹ lọwọ gbogbo eeyan fun ibanikẹdun wọn.
Bakan naa lo tun salaye ilana bi iku oloogbe naa yoo se lọ.
"Leke Adeboye ni ""Pẹlu ẹmi imoore la fi n mọ riri yin bẹ se duro ti ẹbi wa lasiko idanwo yii, amọ a tu ara wa ninu pe ọmọ wa ọwọn pada lọ sile ni lati lọ sinmi lọdọ baba ati ẹlẹda rẹ."
Oríṣun àwòrán, Pst  Dee
Igboya wa lo fidi mulẹ ninu igbe aye ifiraẹnijin ati aimọ tara ẹni nikan ti ọmọ wa gbe ninu Jesu Kristi, Olugbala wa.
"Adura wa ni pe ki gbogbo wa dijọ pade nile ologo lorukọ Jesu."""
Bakan naa ni ẹbi Adeboye tun salaye ilana ti eto isinku oloogbe naa yoo gba waye.
'Ẹ kálọ sí ìlú mi'... Ètò ńlá tó bẹ̀ sílẹ̀ kìjà lórí BBC Yorùbá
Bi eto isisnku Dare Adeboye yoo se lọ ree:
Akanse isin yoo waye ninu ijọ Redeem, City of David Youth Church to wa ni Eket nipinlẹ Akwa Ibom nibi ti oloogbe naa ti jẹ ojisẹ Ọlọrun, to si ku si.
Akanse isin orin idupẹ ati ọrọ imọyi nipa oloogbe yoo waye ni ijọ Redeem, House of Favour to wa ni Redemption Camp nilu Eko.
Isin idagbere yoo waye ni aago mẹwa owurọ ni ibudo awọn ọdọ, Youth Centre, to wa ni Redemption Camp ni Mowe, nipinlẹ Ogun.
Lẹyin naa ni wọn yoo sin oloogbe Dare Adeboye si ibẹ.
Idaho School Shooting; Ọmọ ọdún mọ́kànlá yìnbọn mọ́ èèyàn mẹ́ta níléèwé
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ọmọdebinrin kan tii se ọmọ ọdun mọkanla si mejila ni iroyin lo yinbọn lu awọn akẹgbẹ rẹ meji ni ileewe ati tisa ni ipinlẹ Idaho, lorilẹede Amẹrika.
Ileeṣẹ ọlọpaa nipinlẹ naa ni ọmọdebinrin ti wọn ko darukọ rẹ ọhun wa ni ipele kẹfa ni ileewe alakọbẹrẹ.
Ọmọdebinrin ọhun lo mu ibọn lọ si ileewe Idaho Middle School to si ṣina bolẹ.
Eniyan mẹta to faragba ninu iṣẹlẹ naa ni awọn alaṣẹ sọ wi pe wọn ko ku, amọ wọn farapa.
Ọpẹlọpẹ olukọ obinrin miran lo jijakadi pẹlu ọmọdebinrin naa, to si gba ibọn lọwọ rẹ, ki awọn ọlọpaa to de lati fi panpẹ si lọwọ.
Ko tii han si ẹnikẹni idi ti ọmọ naa fi yinbọn lu akẹgbẹ ati olukọ rẹ.
Awọn ti iṣẹlẹ naa ṣoju wọn ni n ṣe ni ọmọdebinrin naa yọ ibọn kuro ninu baagi to gbe pọn, to si bẹrẹ si yin ibọn leralera ninu ileewe naa ati ita.
Bẹẹ si ni wọn bẹrẹ si ni gbọ ariwo kikan kikan lẹyin ti awọn to faragba ninu iṣẹlẹ naa ṣiṣe.
Adari ileewe naa, Chad Martin ni ibanujẹ ọkan ni iṣẹlẹ to waye ni ileewe wọn jẹ fun gbogbo awọn ti ọrọ naa kan, amọ wọn dupẹ pe ko mu ẹmi ẹnikẹni lọ.
'Ẹ kálọ sí ìlú mi'... Ètò ńlá tó bẹ̀ sílẹ̀ kìjà lórí BBC Yorùbá
Bakan naa ni wọn ti paṣẹ lati ti ileewe naa pa ni Ọjọ Ẹti, amọ awọn olubadamọran yoo wa ni ikalẹ lati ba awọn akẹkọọ sọrọ.
Ileeṣẹ ọtẹlẹmuyẹ lorilẹede Amerika, FBI ati ọlọpaa abẹlẹ ni iwadii ti bẹrẹ ni pẹrẹwu lori iṣẹlẹ naa.
Dare Adeboye news: Ìdílé Pásítọ̀ Dare, ọmọ́ Pásítọ̀ Adeboye fẹ́ dá wà lásìkò yìí
Oríṣun àwòrán, thehgservice
Ijọ Irapada iyẹn Redeem Christian Church of God ti kede pe kii ṣe Covid-19 to wa lode lo mu ẹmi Pasitọ Dare Adeboye, ọmọ oludari ijọ naa lọ.
"Ninu atẹjade ti ẹka ijọ naa to nmojuto eto ipagọ adura oloṣooṣu, ""the holyghost service"" fi sita ni aridaju yii ti wa."
Atẹjade ọhun sọ imọlara ẹbi ati ijọ RCCG nipa iṣẹlẹ yii, igbe aye rere oloogbe ati imulọkanle wipe awọn ati Dare Adeboye yoo pade lẹsẹ Jesu Kristi lọrun nibi ti ko si inira mọ.
Ohun tí ìyàwó Adeboye ṣe ní ìgbà akọkọ tó fojú hàn lẹ́yìn ikú ọmọ wọn Dare
Àwọn ǹkan tí o kò gbọ́ rí nípa Dare Adeboye tó kú
Oríṣun àwòrán, psfrccgofficial
Atẹ̀ade naa tun tọrọ̀ gafara lọwọ awọn eeyan lati da wa lasiko idaro ti wọn wa.
O wu mọlẹbi lati da wa lasiko yii a si gbadura pe Ọlrun yoo wa pẹlu yin bi ẹ ṣe gbọ ibeere ẹbẹ wa yii.
Àwọn agbébọn tún ti jí àwọn akẹ́kọ̀ọ́ míì gbé ní ìpínlẹ̀ Abia
Ọmọ Nàíjíríà sọ̀kò ọ̀rọ̀ síjọba lórí èròǹgbà láti dín owó oṣù òṣìṣẹ́ kù
'Ẹ kálọ sí ìlú mi'... Ètò ńlá tó bẹ̀ sílẹ̀ kìjà lórí BBC Yorùbá
Oríṣun àwòrán, thehgservice
"Lopin atẹjade naa ni wn kọ gadagba pe "" a fẹ ki gbogbo eeyan mọ wipe iku yii ko ni nkankan ẹ pẹlu aisan Covid-19 rara""."
Apapọ ẹgbẹ awọn ọmọ Pasitọ ni ijọ Redeemed Christian Church of God ti fi ikede sita ọjọ ti Oluwadamilare Temitayo Adeboye jade laye amọ ti ko tete han fun gbogbo eeyan.
"Loju opo Twitter wọn ni wọn ti fi atẹjade sita to sọ pe ""pẹlu ọkan wuwo la fi kede ipapoda ọmọ wa, ẹgbọn wa, ọkọ ati baba wa, Oluwadamilare Temitayo Adeboye to lọ ba Ọlọrun ni ọjọ Iṣẹgun ọjọ kẹrin oṣu karun ọdun 2021""."
Atẹjade naa ka wipe igbe aye rẹ jẹ igbe aye rere gẹgẹ bo ṣe sin Ọlọrun lai kaarẹ, to n fun ni tp si n dari lai si ifoya.
Bo tilẹ jẹ pe iroyin yii fi wa gidi gan, a duro lori Jesu Kristi ninu ẹni ti a ni idaniloju pe a o pade nibi ti ko si inira.
Oríṣun àwòrán, Pastor Dee
Ọ̀rọ̀ Leke Adeboye, aburo oloogbe
A mú olódodo lọ́ ṣáájú ọjọ́ ibi...
Ni owurọ kutukutu oni ni abigbẹyin oludari ijọ RCCG, Pasitọ Leke Adeboye fi ọrọ sita lati inu iwe owe inu bibeli eyi to lọ mọ iroyin to n jade lori ayelujara pe ẹgbọn rẹ, Pasitọ Dare Adeboye ti jade laye.
Ọpọlọpọ ero lo ti n wọ loju opo Facebook Leke lori ọrọ to fi sita yii ti wọn si ti n ba idile Adeboye ati ijọ RCCG kẹdun.
Pasitọ Leke ati Dare Adeboye jọ jẹ ọmọ gbajugbaja Pasitọ ati oludari ijọ Redeemed Christian Church of God, Pasitọ Enoch Adejare Adeboye.
Leke Adeboye to tun jẹ oluranlọwọ agba fun oludasilẹ ijọnaa fi ẹsẹ bibeli, Iwe Isaiah 57:1  si oju opo rẹ eyi to sọ pe:
"Olódodo ṣègbé kò sí ẹnìkan tí ó rò ó lọ́kàn ara rẹ̀;
a mú àwọn ẹni mímọ́ lọ, kò sì ṣí ẹni tó yé pé
a ti mú àwọn olódodo lọ láti yọ wọ́n kúrò nínú ibi."
Oríṣun àwòrán, Leke Adeboye
Bo tilẹ jẹ pe ko tii si mọlẹbi kankan to jade wa fi orukọ oloogbe naa sita lori ohun to ṣẹlẹ, kẹtikẹti lero n wọ lati ba Pasitọ Leke Adeboye kẹdun lori ayelujara.
Oríṣun àwòrán, Leke Adeboye
Oríṣun àwòrán, Leke Adeboye
Oríṣun àwòrán, Leke Adeboye
Iroyin naa tẹ wa lọwọ ni yajoyajo pe Pasitọ Dare Adeboye to jẹ ọmọ oludari ijọ Redeemed Christian Church of God, Pasitọ Adejare Adeboye ti jade laye.
Ọkan lara awọn Pasitọ agba ijọ RCCG to tun jẹ eeyan to ṣee fọkan tan ni ijọ naa sọ fun BBC Yoruba pe lootọ ni awọn ti gbọ iroyin naa.
Eekan miiran ti a tun kan si jẹ ko di mimọ pe oun ko fẹ ki awọn oniroyin maa gbe iroyin ti ko jẹ ootọ nipa iṣẹlẹ yii.
Amọ o fi aridaju ọrọ naa mulẹ fun BBC Yoruba pe lootọ ni Pasitọ Dare dagbere faye.
Oríṣun àwòrán, Leke Adeboye
Ẹwẹ, o ni adura ni ki gbogbo eeyan maa gba fun mọlẹbi Adeboye ki wọn ri itunu ati okun Ọlọrun.
O ni dajudaju ki ọsẹ yii to kanlẹ, mọlẹbi yoo fi ọrọ ẹbi sita nipa rẹ.
Ẹwẹ, o tẹ ẹ mọ akọroyin BBC leti wipe irọ patapata gbaa ni iroyin ti awọn kan n gbe pe aisan Covid-19 tàbí ijamba ọkọ lo ṣokunfa iku oloogbe.
Ki gbogbo eeyan kọ eti ikun si iroyin to n sọ pe iku Covid-19 tabi ijamba ọkọ lo pa Pasitọ Dare.
Pasitọ Dare jẹ ọkan lara awọn Pasitọ agba fun ẹka ijọ awọn ọdọ RCCG ni ilu Abuja ti iroyin si sọ pe oun lo waasu ni ijọ rẹ lọjọ isinmi to kọja yii.
NECO result 2020: Akẹ́kọ̀ọ́ 26, 277 ló pegedé ní ìdánwò NECO ọdún 2020 tó jáde
Oríṣun àwòrán, other
Fun awọn akẹkọọ to joko ṣedanwo NECO oṣu kọkanla ọdun to kọja, esi idanwo aṣekagba naa ti jade.
Ajọ NECO kede esi idanwo naa lowurọ Ọjọbọ ti wọn si ni laarin ẹgbẹrun mẹrindinlọgbọn ati ọrinlelugba o din mẹta (26,277) akẹkọọ ninu ẹgbẹrun mọkandinlogoji o le ẹẹdẹgbẹta ati mẹta (39, 503) akẹkọọ to jọko ṣe idanwo naa lo yege ninu imọ ẹkọ marun ninu eyi ti ẹkọ ede oyinbo ati iṣiro wa.
Ninu atẹjade kan ti akọwe agba ajọ NECO, Ọjọgbọn Godswill Obioma fi sita lolu ileeṣẹ ajọ idanwo naa to wa ni ilu Minna ni ipinlẹ Niger, ẹgbẹrun mọkanlelogoji ati ọtalerinwo o din ẹyọkan lawọn akẹkọọ to forukọsilẹ fun idanwo naa, ẹgbẹrun mọkandinlogoji o le ẹẹdẹgbẹta ati mẹta (39, 503) akẹkọọ lo joko ṣe idanwo ọhun.
O ni ẹgbẹrun mẹfa ati ọtalerinwo o le marun ni iṣẹlẹ aṣemaṣe to waye lasiko idanwo naa eleyi to kere si ẹgbẹ mẹtadinlogun o le mẹrin ni ọdun 2019.
Security: Ọba Okemesi ní ọwọ́ yẹpẹrẹ tọ́mọ Yorùbá fi mú àṣà ló jẹ́ kí àwọn ajínigbé máa gbé ọba láàfin
Oríṣun àwòrán, okemesi Ekiti
Bi ẹ ba ri ọba ilẹ Yoruba ti awọn agbebọn n ji gbe tabi pa, iru ọba bẹẹ ko bọwọ fun iṣẹṣe ilẹ Ooodua ni.
Owa Ooye ti ilu Okemesi Ekiti Oba Gbadebo Adedeji lo sọ eyi nigba to fi n tẹpẹlẹ mọ lilo awọn nkan amusagbara isẹnbaye Yoruba lati koju ipenija aabo to n koju Naijiria.
Owa Ooye ti ilu Okemesi Ekiti ni iru awọn nkan amuyẹ wọn yi le koju ijinigbe ati awọn iwa ọdaran mii to gbogo lawujo.
'Ẹ kálọ sí ìlú mi'... Ètò ńlá tó bẹ̀ sílẹ̀ kìjà lórí BBC Yorùbá
Lasiko to n ba awọn akọroyin sọrọ saaju ifilọlẹ eto ajọdun asa Okemesi Cultural Festival tọdun yi ni ọba naa salaye pe kani awọn ọba alade ko fi ọwọ yẹpẹrẹ mu asa wọn ni, awọn ajinigbe ko ba ma ribi maa nawọ gan wọn laafin wọn.
O ni bi wọn ba lo awọn nkan amusagbara yi bo ti se yẹ ni, ko le si ajinigbe tabi awọn janduku kankan to le se ikọlu si wọn tabi agbegbe wọn.
Oowa Oye naa ni lawọn orileede mii, asa jẹ ohun amuyangan ti awọn eeyan fi n pa owo wọle sugbọn , ọrọ ko ri bẹ ni Naijiria.
Oríṣun àwòrán, PAlace of the ooni of ife
''Ikọlu tawọn agbebọn n se si ori ade ti n peleke lẹnu ọjọ mẹta yi.Bawo lawọn janduku yoo ti se maa se ikọlu sawọn Kabiyesi ti wọn yoo maa pa wọn bi ẹni pa adiẹ?''
''Mo ni igbagbọ pe bi a ba fi ẹsẹ ile tọ ọrọ yi, gbogbo rẹ ni yoo niyanju''.
Ohun tí ìyàwó Adeboye ṣe ní ìgbà akọkọ tó fojú hàn lẹ́yìn ikú ọmọ wọn Dare
Àwọn ẹni ibi kan ń wá gbogbo ọ̀nà láti tú orílẹ̀èdè Nàíjíríà ká - Ààrẹ́ Buhari
'Tééyàn bá kú a lè yọ yọ ojú yẹn tẹ́ẹ bá gbà wá láyé, a lè dá a sí fún ẹlòmíràn'
Kabiyesi tẹsiwaju pe laye atijọ ti awọn eeyan maa n kogun ja ara wọn, o ni bi awọn Yoruba se n jagun.
O ni ''awọn eeyan kan ko ni igbagbọ si isẹsẹ wa mọ nitori awọn ẹsin tuntun to yẹpẹrẹ agbara awọn babanla wa''
Koda o ni awọn Kabiyesi kan a maa sọ pe awọn ko le se irọra lati fi daabo bo ara wọn.
O ni iwa yi jẹ iwa ti ko bojumu.
Oríṣun àwòrán, PAlace of the ooni of ife
''Awa ni olusọ asa wa, a kii se ẹni to n fi asa wa rare nilẹ.Ki lo de ta fi n sa kuro nidi asa wa?''
Lẹnu ọjọ mẹta yi ni ilẹ Yoruba ati lawọn aaye miran ni Naijiria, ijingbe paapa tawọn oriade ko jẹ nkan tuntun mọ.
Ni ipinlẹ Ekiti, awọn ajinigbe ti se ikọlu sawọn ọba kan ti wọn si ti ji awọn kan pe to fi mọ awọn mii to padanu ẹmi wọn lọwọ awọn olubi wọn yi.
Pupọ araalu lo ti n kesi ijọba lati wa wọrọkọ fi sada lori ọrọ yi nitori inu ibẹrubojo lawọn araalu ati awọn lọbalọba naa n gbe.
Mile 12: Èèyàn kan kú nínú ìjà tó n wáyé ní Mile 12 láti bíi ọ̀sẹ̀ kan
Oríṣun àwòrán, Twitter/@Mr_JAGs
Awọn ọlọpaa to lọ ọ pẹtu si ija ni adugbo Mile 12
Ọrọ di bo o lọ, yago fun mi ni agbegbe Mile 12 nipinlẹ Eko nitori ija igboro to n waye laarin awọn janduku.
Iroyin to jade si ori ayelujara ni ọsan Ọjọbọ ni pe niṣe ni awọn janduku n kọlu awọn eeyan, ti wọn si n ba dukia jẹ.
Ija yii ni ẹlẹẹkeji ti yoo waye ni adugbo naa laarin ọjọ mẹta.
A gbọ pe ni adugbo Gengere ni agbegbe Mile 12 ni ija naa ti n waye. Eyi to mu ki kọmisanna ọlọpaa nipinlẹ Eko, Hakeem Odumosu paṣẹ pe ki awọn ọlọpaa mu eeyan mẹtala to jẹ olori awọn ẹgbẹ to n ja.
Àwọn jàndùkú ṣá ẹ̀ṣọ́ Amotekun àti ọlọ́pàá ní àdá àti àáké n'Ibadan
Ganiyu fẹ́ na pápá bora lẹ́yìn tó gún ìya ìyàwó rẹ̀ lọ́bẹ pa lọ́sàán àwẹ, ọwọ́ bá tẹ̀ ẹ́
Ọjọ́ 30 ni wọ́n fẹ́ fi gbé mi pamọ́, ariwo ọmọ ìjọ ló jẹ́ kí wọ́n tú mi sílẹ̀ - Father Mbaka
Ìjínigbé àti ìdigunjalè kò sí ní ìkáwọ́ ìjọba àpapọ̀ - Lai Mohammed
Gẹgẹ bi atẹjade ti agbẹnusọ gomina Sanwo-Olu ti ipinlẹ Eko, Gboyega Akosile fi sita, ọgbọnjọ, oṣu Kẹrin ni wahala ti bẹrẹ.
O ni iwadii ileeṣẹ ọlọpaa fihan pe awọn janduku bẹrẹ wahala lẹyin ti wọn fi ẹsun kan olori igbimọ eto aabo ni adugbo Gengere, Alhaji Alidu Mohammed, pe o fi abuku kan Anọbi Mohammed, to si tun sọ ọrọ odi si.
Oríṣun àwòrán, Twitter/@mr_jags
Bayii ni awọn ọlọpaa ṣe duro wamuwamu lati pana ija igboro to waye ni Mile 12 ni opin ọsẹ to kọja
Ibinu si ọrọ to sọ ni awọn janduku fi ya sita, ti wọn si dana sun ọkọ ayọkẹlẹ rẹ meji, wọn tun kọlu ọkan lara awọn ile rẹ.
Bakan naa ni wọn dana sun ile ile kekere kan to jẹ ti ẹlomii, Alhaji Mamuda.
Yatọ si eyi, iṣẹlẹ naa mu ẹmi eeyan kan, Papa Mohammed, lẹyin ti wọn fi nkan gun ni ọjọ naa. Ọjọ kinni, oṣu Karun-un si lo dagbere faye nileewosan.
Nibayii, a ko ti i le sọ boya ija to bẹrẹ lati ọgbọnjọ, oṣu Kẹrin lo tun fa ti ọsan oni, tabi nkan mii.
Awọn oṣiṣẹ alaabo si ti de si ibẹ lati mu ki alaafia jọba.
Kairo Oshodi Market Fire: LASEMA tọ́ka pé ejò lọ́wọ́ nínú lórí ìṣẹ̀lẹ̀ iná tó ba dúkìá jẹ́
Oríṣun àwòrán, LASEMA
Ajọ to n risi isẹlẹ pajawiri nipinlẹ Eko,  LASEMA ti sọ pe ejo lọwọ ninu  ijamba ina to sakoba fun ọpọ dukia ni ọja alasọ Kairo ni Oshodi l'Ọjọbọ.
Ninu atẹjade kan ti ọga ajọ naa, Dokita Olufemi Damilola Oke-Osanyintolu fi sọwọ si BBC Yoruba, o ni awọn ṣi n se iwadii lọwọ ṣugbọn ninu nkan ti awọn ri, o dabi ẹni pe awọn kan yin ado oloro kekeeke kan to seese ki o sokunfa ina to jo ọja naa.
Ko si eeyan kankan to ba isẹlẹ naa lọ ati pe lọwọ lọwọ bayi, wọn ti n bu omi si ina lati mu ki agbegbe ọhun tutu diẹ.
'Ẹ kálọ sí ìlú mi'... Ètò ńlá tó bẹ̀ sílẹ̀ kìjà lórí BBC Yorùbá
Àwọn agbébọn tún ti jí àwọn akẹ́kọ̀ọ́ míì gbé ní ìpínlẹ̀ Abia
Ọmọ Nàíjíríà sọ̀kò ọ̀rọ̀ síjọba lórí èròǹgbà láti dín owó oṣù òṣìṣẹ́ kù
Ikú Dare Adeboye kò ní ǹkankan ṣe pẹ̀lú Covid-19, a bẹ̀bẹ̀ láti dá wà lákòókò yìí - Ẹbi Adeboye
Àwọn ǹkan tí o kò gbọ́ rí nípa Dare Adeboye tó kú
Oríṣun àwòrán, LASEMA
Dokita Olufemi Damilola Oke-Osanyintolu ni awọn ti fi ọrọ yi to awọn agbofinro leti ti wọn si ti bẹrẹ iwadii lati tusu di isalẹ koko ohun to sokunfa ina naa.
Ohun taa si mọ nipa ijamba ina yi
Nkan bi ago mẹjọ alẹ ọjọbọ ni ina yi bẹrẹ to si sakoba fawọn sọọbu to wa nibi ti wọn ti n ta asọ lọja naa.
Ohun to sokunfa ina naa ko daju sugbọn awọn dukia ti iye owo rẹ wọ ẹgbẹgbẹrun miliọnu Naira lo sakoba fun.
Ṣé o mọ àwọn òrìṣà ìṣẹ̀mbáyé méje tó di ilẹ̀ gbogbo àgbáyé mú?
'Iṣẹ wá burẹkẹ síi tórí Covid-19, owó ńlá ló wà nínú dídáná sun òkú, ìsìnkú  Zoom, Live streaming'
Oríṣun àwòrán, LASEMA
Pupọ awọn ile itaja ti wọn sọ agadagodo si ni ina yi ti bẹrẹ to si gbalẹ laipẹ.
O gba awọn osisẹ pajawiri, ọlọpaa ati panapana lọpọ asiko ki wọn to ri ina yi pa.
Pupọ awọn olutaja lo ti palẹmọ lọ sile nigba ti ina naa yoo fi bẹrẹ.
Ko si eeyan kankan ti akọsilẹ wa pe o ba ijamba ina yi lọ.
Abia state university news: Àwọn agbébọn ti jí àwọn akẹ́kọ̀ọ́ ABSU gbé ní Abia
Oríṣun àwòrán, @megaiconmagg
Afi bii ina to n ran, lẹyin ọjọ kan ṣoṣo ti awọn akẹkọọ to wa ni ahamọ ajingbe ni Kaduna moribọ, awọn agbebọn kan tun ti ji awọn akẹkọọ mii gbe ni ipinlẹ Abia.
Ninu atẹjade kan ti kọmiṣọna eto iroyin ipinlẹ naa, John Kalu, fi lede, o ni wọn ji awọn akẹkọọ naa, ti awọn ko tii mọ iye wọn gbe ni opopona Okigwe si Uturu.
"O ni ""gẹgẹ bii iroyin to tẹ wa lọwọ, awọn akẹkọọ naa n rinrinajo ninu ọkọ korope lati ilu Okigwe si Uturu laarin aago meje si mẹjọ alẹ ki wọn to ṣagbako awọn agbebọn ọhun lẹba igbo kan, ti wọn si ko awọn akẹkọọ naa lọ pẹlu awọn arinrinajo miran."""
Meji ninu awọn akẹkọọ naa moribọ ṣugbọn awọn to ku ṣi wa ni ahamọ awọn ajinigbe ti ko si sẹni to lẹ sọ ibi ti wọn wa.
Kalu fi kun un pe awọn n ṣiṣẹ papọ pẹlu ifọwọsowọpọ ijọba ipinlẹ Imo atawọn ẹṣọ alaabo ni ipinlẹ mejeji lati doola ẹmi awọn akẹkọọ ọhun.
Lẹyin naa lo rọ awọn akẹkọọ ati oṣiṣẹ fasiti naa lati fi ọkan wọn balẹ nitori awọn yoo rii daju pe wọn doola awọn akẹkọọ naa lai ku ẹnikan.
Ẹwẹ, ileeṣẹ ọlọpaa ipinlẹ ọhun ti sọ pe awọn ti bẹrẹ igbesẹ ti awọn akẹkọọ naa yoo fi di riri pada ni kankan.
Bi ẹ ko ba gbabe, ẹnu oṣu diẹ sẹyin ni ijinigbe awọn akẹkọọ di tọrọfọnkalẹ ni Naijiria, paapaa lagbegbe oke ọya.
Lọjọ kọkanla oṣu Kẹta ọdun yii, wọn ji akẹkọọ mọkandinlogoji gbe ni  Federal College of Forestry Mechanization, to wa ni Afaka, ni ipinlẹ Kaduna.
Nigba to di ogunjọ oṣu to kọja, wọn tun ji awọn akẹkọọ fasiti Greenfield gbe ni Kaduna yii kan naa.
Yatọ si Kaduna, wọn ti ji oniruru akẹkọọ mii gbe lawọn ipinlẹ bii Benue, Plateau, Katsina ati Zamfara.
'Iṣẹ wá burẹkẹ síi tórí Covid-19, owó ńlá ló wà nínú dídáná sun òkú, ìsìnkú  Zoom, Live streaming'
Akure Oloyemekun: Ṣé ẹ ti gbọ́ nípa Ua Agbeto rí níbí tí ìtọ̀ kìí rùn bó bá ṣe pọ̀ tó?
Ṣé ẹ ti gbọ awọn itan kankakanka nipa iṣẹdalẹ ilu Akurẹ?
BBC Yoruba ba eeyan ilu Akure rinrinajo lọ si ilu nla naa koda to fi mọ awọn kọrọ ilu Akure.
A ni ifọrọwerọ pẹlu Deji, Ọba ilu Akure to sọ idi ti gbogbo Ọba ilu Akurẹ fi n jẹ Déjì lái ṣe Alakurẹ.
Ọna kan wa ninu aafin Deji Akure to ṣe pataki leyi to jẹ wipe ẹẹkan ṣoṣo ni Kabiyesi lee gba ibẹ ni igbesi aye rẹ to jẹ pe igba to ba ṣẹṣẹ jba ti wọn a mu u wọ inu aafin.
Ṣe ẹ tun ti gbọ nipa ibi iṣẹmbaye to n jẹ Ua Agbetọ nibi ti ẹ o le gbọ oorun itọ kankan ko si bi ọgọọrọ eeyan ba ṣe tọ sibẹ to.
Ẹ ba wa kalọ ninu fidio yii si awọn ibi kọlọfin ati ibi gbangba ilu nla nni, Akurẹ.
Hadiza Bala Usman: Kí ló dé tí Buhari ní kí olùdarí NPA lọ rọọ́kun nílé?
Oríṣun àwòrán, Twitter/Hadiza Bala Usman
Ojumọ kan ara kan.Ni ijọba aarẹ Buhari orileede Naijiria ara ki tan nile alara.
Eyi to gbode bayi tawọn eeyan n jẹ lẹnu ni ikede to jade lati ọdọ agbẹnusọ aarẹ pe ki oludari ileesẹ to n mojuto ẹru to n gba ibudokọ ọkọ oju omi wọ Naijiria,NPA lọ rọọkun nile.
Garba Shehu ninu atẹjade taa n wi yi ni aarẹ ti buwọlu aba ti Minisita feto irina Rotimi Amaechi da lori idasilẹ igbimọ iwadii ti yoo tọ pinpin akoso ileesẹ yi labẹ akoso Hadiza Bala Usman.
Yatọ si eyi, atẹjade naa ni aarẹ pasẹ ki Hadiza lo rọọkun nile lopin igba ti iwadii yoo fi waye.
"Ọgbẹni Mohammed Koko  ni yoo maa dele nipo naa lasiko iwadii yi.''
Pẹlu atẹjade yi, a ko ri pato nkan ti wọn fi n tori rẹ tọ pinpin ileesẹ yi amọ awa naa fimu finlẹ diẹ la ba ni ka tan imọlẹ si awọn nkankan nipa Hadiza Bala Usman ti o seese ki ẹ maa mọ.
Die ree nipa ohun to yẹ ki ẹ mọ nipa
Lagbo Oselu
O jẹ oloselu to ti bẹrẹ si ni sisẹ gẹgẹ bi alasẹ ileesẹ NPA lati ọdun 2016.
Saaju igba naa lọdun 1999 o lo ọdun kan ni ajọ to n mojuto idagbasoke ijọba awarawa ni Zaria gẹgẹ bi olukọsẹ.
Lẹyin igba naa ni o sisẹ pẹlu ẹka ijọba ti wọn n pe ni BPE laarin osu Kẹfa ọdun 2000 titi di 2004.
Laarin Osu kẹwa 2004 si osu Kini ọdun 2008 o di ipo oluranlọwọ pataki si Minisita lori amojuto ise akansẹ ni Abuja labẹ ajọ UNDP
O dije dupo asoju ẹkun idibo Musawa/Matazu gẹgẹ bi oludije labẹ asia ẹgbẹ oselu APC lọdun 2011 sugbọn o fidirẹmi.
Lẹyin igba naa lo dara pọ mọ ẹgbẹ ti ko ni se pẹlu ijọba to n gbaju mọ isakoso orileede Naijiria bo ti se yẹ taa mọ si Good Governance Group for Nigeria.
Laarin 2011 si 2015 lo fi ba wọn sisẹ
Ipolongo Bring Back Our Girls
Oun ati Aisha Yesufu ni wọn jijọ da ipolongo  Bring Back Our Girls kalẹ lọdun  2014
Wọn da ikọ yi silẹ lẹyin ijingbe awọn akẹkọbinrin Chibok lati le pe fun idoola awọn akẹkọbinrin wọn yi.
Pẹlu awọn oluwọde miran wọn fi ohun wọn polongo nipa awọn akẹkọbinrin yi.
Nibẹ lọpọ eeyan ni Naijiria ti mọ ẹni ti wọn n pe ni Hadiza Baala ati Aisha Yesufu.
Koda nigba to gba ipo gẹgẹ bi oludari NPA o si n kopa ninu awọn eto Bring back our Girls nipa sise eto ipade laarin ijọba Naijiria ati awọn obi awọn akẹkọọ ti wọn ji gbe yi.
O darapọ mọ BBOG lati se iwọde lọdun 2016.
Ibasepọ rẹ pẹlu Gomina El Rufai
Wọlewọde loun ati Gomina ipinlẹ Kaduna Nasir El Rufai.
Ibasepọ wọn yi si ti bẹrẹ lati igba ti o  ti sisẹ labẹ rẹ gẹgẹ bi ọga agba ileesẹ BPE lasiko ijọba Olusegun Obasanjo.
Eyi lo mu ki pupọ awọn eeyan maa ni El Rufai fi forukọ rẹ sọwọ gẹgẹ bi oludari ileesẹ NPA.
Koda El Rufai yan si ipo olori awọn osisẹ ile ijọba lẹyin to jaweolubori ninu idibo Gomina ni ọdun 2015.
Oun ni obinrin akọkọ ti wọn yoo yan si ipo yi ninu akọsilẹ ipinlẹ Kaduna.
Idile lọbalọba lo ti wa
Hadiza wa lati ile ọlọba awọn Fulani Sullubawa ti wọn ti n jọba ni Katsina lati ọjọ to ti pẹ.
Baba to bi Ọjọgbọn Bala Usman ni ọmọọmọ Emir Katsina Muhammadu Dikko.
Bakan naa baba to bi iya baba rẹ rẹ ni o jẹ Emir kẹwaaa ti elyi naa si mu ki oun gaan wa lati idile ọlọba.
Ilumọọka ni Baba to bi
Baba Hadiza Bala Usman,oloogbe Ọjọgbọn Bala Usman figba kan jẹ ọkan lara awọn eekan to wa lati ariwa Naijiria.
Ọjọgbọn onimọ ẹkọ itan yi lọpọ sapejuwe rẹ gẹgẹ bi alakatakiti to se pe ọpọ ọrọ rẹ́ a maa tako ijọba to wa lode nigba naa.
O figba kan sisẹ gẹgẹ bi akọwe ijọba Kaduna lasiko ijọba Balarabe Musa ni saa keji ijọba awarawa ni Naijiria.
O fẹ oludamọran si aarẹ
Tanimu Bala Kurfi ni ọkọ ti Hadiza Bala Usman fẹ tẹlẹ to si jẹ oludamọran si aarẹ Naijiria tẹlẹ Umaru Musa Yar Adua.
Gẹgẹ bi wọn ti se lorukọ ni mọlẹbi Hadiza, bẹẹ naa ni orukọ mọlẹbi Tanimu jẹ eyi ti ọpọ mọ ni Naijiria ti ọkọ rẹ si di orisi ipo mu ni Naijiria.
Awọn mejeeji bimọ ọkunrin meji ki wọn to pinya.
Aarẹ Buhari yan Hadiza sipo oludari ileesẹ NPA ni osu Kẹfa ọdun 2016.
Ọpọlọpọ awuyewuye lo ba iyansipo yi wa nitori awọn kan sọ pe ko kaju osunwọn lati di ipo naa mu.
Makinde vs Algon: Iléẹjọ́ ní bí Makinde ṣe lé àwọn alága APC l'Oyo lọ lòdì sófin
Oríṣun àwòrán, Facebook/Seyi Makinde
Ileẹjọ to ga julọ lorilẹede Naijiria ti dajọ pe igbesẹ Gomina Seyi Makinde ipinlẹ Oyo lati le awọn alaga ati kansilọ ijọba ibilẹ nipinlẹ Oyo lọ lodi sofin.
Ileẹjọ tun ni igbesẹ Makinde lati fi awọn alaga fidihẹ rọpo awọn alaga naa lodi si ofin pẹlu.
Ẹgbẹ awọn oṣiṣẹ ijọba ibilẹ nipinlẹ Oyo, ALGON gbe ijọba ipinlẹ Oyo lọ si ileẹjọ to ga julọ lẹyin ti ileẹjọ kotẹmilọrun buwọlu igbesẹ Makinde to da wọn duro lẹnu iṣẹ.
Ọjọ kọkandinlọgbọn oṣu karun un ọdun 2019 ni Gomina Makinde dawọn alaga atawọn kansilọ naa duro.
Amọ, ileẹjọ to ga julọ paṣẹ pe ijọba ipinlẹ Oyo gbọdọ san gbogbo owo oṣu ati ajẹmọnu awọn alaga kansu naa fun wọn patapata.
Ileẹjọ sọ ninu idajọ rẹ pe owo naa gbọdọ jẹ sisan titi oṣu kẹjọ, bi bẹẹ kọọ afojudi ileẹjọ ni ọrọ naa yoo jẹ.
Bakan naa ni ileẹjọ paṣẹ pe ki Makinde san ogun miliọnu naira nitori iwa aitọ to hu nipa lile awọn alaga atawọn kansilọ ẹgbẹ oṣelu APC lọ.
Ọdun 2018 ni wọn dibo yan awọn alaga atawọn kansilọ naa ki Makinde to dawọn duro lọdun 2019.
Wo ǹkan méje tó yẹ kí o mọ̀ nipa Mama Taraba tó jáde láyé lẹ́ni ọdún 61
Oríṣun àwòrán, Aisha Al Hassan
Iku ko dọjọ, arun ko doṣu, minisita ọrọ awọn obinrin tẹlẹ, Aisha Jummai Al-Hassan ti ọpọ mọ si Mama Taraba ti jade laye.
Iroyin to tẹ wa lọwọ ni yajo yajo sọ pe ilu Cairo lorilẹede Egypt ni Mama Taraba ku si.
Ẹni ọdun mọkanlelọgọta ni minisita ọrọ obinrin tẹlẹ i ṣe ki ọlọjọ to de.
Ohun meje to yẹ ki o mọ nipa Aisha Jummai Al-Hassan niyii
1. A bi Aisha Jummai Al-Hassan ti ọpọ mọ si Mama Taraba ni ọjọ kẹrindinlogun oṣu kẹsan an lọdun 1959 niluu Jalingo nipinlẹ Taraba.
2. Mama Taraba ni obinrin akọkọ to jẹ kọmiṣọnaa eto idajọ ati agbẹjọro agba nipinlẹ Taraba.
Oun naa tun ni obinrin akọkọ ti wọn yan gẹgẹ bi akọwe igbimọ eto idajọ l'Abuja lọdun 2003.
3. Ọdun 2015 ni Aarẹ Muhammadu Buhari yan an sipo minisita lẹyin to wọle ibo gbogbo tan.
4. Mama Taraba kọwe fipo silẹ gẹgẹ bi minisita lọjọ kẹtadinlọgbọn oṣu keje ọdun 2018 lẹyin ti igbimọ to n ṣayẹwo awọn oludije fẹgbẹ APC yọ ọ kuro ninu awọn to dije ninu ibo abẹnu fun ipo gomina lọdun 2019.
5. Ẹgbẹ oṣelu UDP gba Mama Taraba tọwọ tẹsẹ gẹgẹ bi oludipe fun ipo gomina nipinlẹ Taraba lẹti oludije kan yẹba fun un.
6. Wọn fun  Aisha Al-Hassan ni inagijẹ ''Mama Taraba'' nitori ipa ribi ribi to n ko ninu eto osẹlu ipinlẹ Taraba.
7. Minisita ọrọ obinrin tẹlẹ ṣe atilẹyin fun ajọ to n ri si ere bọọlu ipinlẹ Taraba nigba aye rẹ.
BBC Yollywood Roundup: Wo àkójọpọ̀ ìròyìn lágbo òṣèré tíátà Yorùbá lọ́sẹ̀ yii
Oríṣun àwòrán, INSTAGRAM/SALAWA ABENI
Nnkan ayọ waye lọpọlọpọ lagbo oṣere tiata Yoruba lọsẹ yii.
Bi awọn kan se n se ọjọ ibi, bimọ tuntun, ni ẹlomiran ranti iku iya rẹ nigba ti awọn gbajumọ osere miran n gba ọrọ Baba ijesha mọ ara wọn lọwọ bi ẹni gba igba ọti.
BBC Yoruba ti wa se akojọpọ awọn isẹlẹ to waye lagbo awọn osere tiata lọsẹ yii, diẹ lara rẹ ree.
Gbajumọ oṣere, Bukunmi Oluwaṣina le ọdun kan loke eepẹ ni ọjọ Keje oṣu Karun, ọpọlọpọ awọn oṣere ẹgbẹ rẹ lo si n kii ku oriire.
Bukunmi fi sita loju opo rẹ pe, nnkan ti oun beere lọwọ Ọlọrun lasiko ọjọ ibi oun lọdun 2020, lo ti ṣe fun oun.
O ni oun ati ọkọ oun beere fun asọkalẹ anfani oyun ti oun ni nigba naay, ti Ọlọrun si ṣe e ni wẹrẹ.
Nibayii ọpọ awọn akẹẹgbẹ rẹ lagbo amuludun ni wọn ti n kii ku oriire naa.
Fẹmi adebayọ, Woli agba, Kunle Afod, Tawa Ajisefini, Wunmi Ajiboye, pẹlu Wumi Toriọla titi kan Mr Macaroni ati bẹẹ bẹẹ lọ ni wọn ti kii ku oriire.
Oríṣun àwòrán, Screenshot
Oríṣun àwòrán, Screenshot
Oríṣun àwòrán, Screenshot
Oríṣun àwòrán, Screenshot
Oríṣun àwòrán, Screenshot
Oríṣun àwòrán, Screenshot
Oríṣun àwòrán, INSTAGRAM/LIZZYANJORIN
Ni ọjọ kini oṣu karun ọdun 2021 ni Lizzy Anjọrin ati ọkọ rẹ gbalejo ọmọ tuntun.
Lizzy fi fidio ti ounj ati ọkọ rẹ ti n dọwẹkẹ nigba to wa ninu oyun si oju opo Instagram rẹ.
''Oba aṣekan maku tun ti ṣe e, O maa n wo ọkan dajọ.
Ki i dajọ pẹlu ohun ti awọn eeyan ba n sọ nipa eeyan, oba pakanmire ti pa ẹgan mi rẹ patapata.
Lizzy ni ''ẹ darapọ mọ wa lati ṣajọyọ oore ti Ọlọrun ṣe fun wa.
Ọlọrun tun ti bukun wa lẹẹkan sii, iyin ni gbogbo rẹ ja si, ALIHAMDULILLAH.
Ọjọ kinni oṣu karun un ọdun 2021 niluu Miami nipinlẹ Florida lorilẹede Amerika lo ti ṣẹlẹ.''
Lizzy ko sọ bo ya ọkunrin tabi obinrin ni ọmọ ti Eleduwa fi jinki oun ati ọkọ rẹ naa.
Oríṣun àwòrán, Instagram/ninalowo
Ọjọ keje oṣu kẹfa naa ni ọjọ ibi gbajumọ oṣere tiata, Bọlanle Ninalowo, ti ọpọ eeyan tun maa n pe ni Makanaki.
Ninalowo kede ọjọ ibi rẹ pẹlu fidio kan ti oun ati iyawo rẹ ti n fẹnuko ara wọn lẹnu loju opo Instagram rẹ.
Awọn agba oṣere bii Allwell Adedamola, Ajibọla Alabi Pauma, Iteledicon, Bukunmi Oluwasina ati bẹẹbẹẹ lọ ni wọn ti kii ku oriire ọjọ ibi rẹ.
Oríṣun àwòrán, Screenshot
Oríṣun àwòrán, Screenshot
Oríṣun àwòrán, Screenshot
Oríṣun àwòrán, Screenshot
Gbajumọ oṣere ni Funmi Martin ki o to jade laye.
Ọjọ kẹfa oṣu karun un ọdun 2002 ni Funmi Martin jade laye lasiko aisan ranpẹ.
Ni ọjọ kẹfa oṣu karun ọdun 2021 lo pe ọdun mọkandinlogun ti oloogbe naa ti re ibi agba a re.
Ọmọ rẹ Mide Martins, ti oun pẹlu jẹ gbajugbaja oṣere tiata naa fi iranti iya rẹ sita loju opo  instagram rẹ:
DIDUN DIDUN NI IRANTI OLODODO"
Maa sun lookan aya ẹlẹda rẹ
Anikẹ Florence Funmi Martins Abiamọ tootọ
Aye yii fẹran rẹ ṣugbọn Ọlọrun fẹran rẹ ju wa lọ
"Maa simi ANIKE IYA NI WURA MI"""
Oríṣun àwòrán, INSTAGRAM/SALAWA ABENI
Ọkan lara awọn eekan manigbagbe olorin ni Waka Queen, Abẹni Salawa.
Ọjọ karun un oṣu karun un ọdun 2021 ni Salawa Abẹni pe ẹni ọgọta ọdun.
Lara awọn eekan to si kọrin ki, ti wọn si tun kii ni 'Ọganla Fuji' Wasiu Alabi Pasuma wa.
Ninu fidio kan ti Salawa Abẹni fi si oju opo Instagram rẹ, ni Pasuma ti ṣe afihan ara rẹ ni ile Salawa nibi to ti n kọrin kii ku ọdun ti Salawa naa si n jo.
Chinese rocket: Orí omi Indian Ocean ni wọ́n ti ri àjákù Rọ́kẹ̀ẹ̀tì China tó já náà
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Rọkẹẹti China
Iléeṣẹ iroyin India ti kede pe wọn ti ri ajaku rọkẹẹti China ti aye n pariwo pe o fẹ ja naa.
Wọn ni ori omi Indian Ocean ni wọn ti rii nigba to pada ja si aye.
A dupẹ pe rọkẹẹti yii ko pada ja si aarin ilu  nibi ti aye ti n bẹru ipalara pupọ.
Ṣaaju ki o to ja ni awọn onimọ onwoye lati ilẹ Amerika ati Yuroopu ti n woye ibi ti yoo kangu si ni agbaye.
Wọn ni wọn ti n gbiyanju lati pa run ko to tun di pe ageku ejo rẹ pada wa saye lọjọ Aiku to kọja ni Beijing ni China
Kini o ti ṣẹlẹ ṣaaju?
Chinese tú Rọ́kẹ́ẹ̀tì ńlá sílẹ̀ tí yóò tó balẹ̀ s'áyé - Eko, New York àtàwọn ìlú míì ló leè jábọ́ sí
Lagos, New York wà lára àwọn ìlú tí wọ́n dárúkọ pé ó leè tẹ́rí gba Rọ́kẹ́ẹ̀tì China tó wà lójú ọ̀run
Ọkan lara awọn Rọkẹẹti nla orilẹede China ni wọn n reti ko bọ sori ilẹ aye nitori idi kan ti wọn ṣalaye pe airibi ṣamojuto irina rẹ.
Trade by Barter, Rivers: Mọ̀ síi nípa ọjà ní Esuk Mba, níbití o ti lè fi iṣu gba edé, epo
Ni iwọn toonu mejidinlogun, ọkan lara awọn Rọkẹẹti to tobi ju fun ọpọlọpọ ọdun ni iwadii fihan pe o fẹ ṣi ọna yii.
Ilẹ Amẹrika sọ lọjọ Iṣẹgun pe awọn n woye ọna ti Rọkẹẹti naa ngba bọ ṣugbọn wọn ko ni erongba lati da ibọn bo o.
"A ni ireti pe yoo balẹ si ibi ti ko ti ni pa ẹnikẹni lara, akọwe ileeṣẹ abo l'Amẹrika, Lloyd Austin lo sọ bẹẹ. ""Ireti wa pe boya ninu ko balẹ sinu omi nla tabi iru ibi bayii kan naa""."
Oniruuru awọn akọṣẹmọṣẹ to n wo inu ofurufu n tọka si ọwọ irọlẹ tabi alẹ jọ Abamẹta tabi owurọ kutu ọjọ Aiku gẹgẹ bi akoko to ṣeeṣe ko balẹ.
Amọ, iru awọn iwoye bayii lee ma ri bẹẹ nigba miran.
"Ọjọ kọkandinlọgbọn oṣu kẹrin gangan ni Rọkẹẹti ""elliptical orbit"" ti iwọn ibi to wa bayii to 160km si 375km ga ju aye lọ ṣugbọn to ti n kuna bayii."
'Tééyàn bá kú a lè yọ yọ ojú yẹn tẹ́ẹ bá gbà wá láyé, a lè dá a sí fún ẹlòmíràn'
Kí ni yoo ṣẹlẹ bi Rọkẹẹti yii ba balẹ si aye?
Gbogbo ọkọ lo yẹ ko fẹrẹẹ jona raurau nigba to ba fi gunlẹ latinu afẹfẹ, bo tilẹ jẹ pe o maa n ṣeeṣe ki o ni awọn irin to lee yọ́ lara atawọ́n afaragbaya mii ti yio fi ye bibalẹ rẹ.
Pe o ṣeeṣe ki apa kan tabi omiran lara ara rọkẹẹti ti yoo tuka ta ba eeyan ko fi bẹẹ ri bẹẹ, nitoripe ọp aaye lori aye lo jẹ omi nla ati pe apa ibi ti yoo balẹ si kii fibẹ jẹ ibi ti awọn eeyan n gbe.
Oríṣun àwòrán, Twitter/The Aerospace Corporation
Ki ni China sọ?
china ti fariga pe awọn eeyan n sọ pe awọn ko naani mimoju to iru nkan nla bayii to ṣina.
Awọn eeyan n gbe iroyin oniruuru ijamba ti iṣẹlẹ yii le ṣẹlẹ.
Ẹw, loju opo ayelujara orilede naa, wn ti ṣapejuwe awọn iroyin to n kari aye pe wọn kan n pọn n lasan ni. Ni tiwọn, wọn woye pe Rọkẹẹti naa ṣeeṣe ko balẹ sinu omi nla nla kan.
Unknown gunmen: Ǹkan dé o! Àwọn jàndùkú tún yìnbọn pa ọlọ́pàá méje
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Awọn janduku agbebọn tun ti yinbọn pa awọn ọlọpaa mẹfa lẹnu iṣẹ wọn nipinlẹ Rivers lalẹ ọjọ Ẹti, ọjọ keje oṣu karun ọdun 2021.
Ninu atẹjade ti agbẹnusọ ileeṣẹ ọlọpaa ipinlẹ Rivers, SP Nnamdi Omoni fi sita, o ni bi ago mẹjọ abọ alẹ ni iṣẹlẹ ọhun ṣẹlẹ.
O ṣalaye ninu atẹjade naa pe ọkọ Hilux lawọn agbebọn naa fi ṣe iṣẹ laabi ti wọn ṣe lọjọ Ẹti.
Awọn ọlọpaa to wa lori afara Choba lawọn agbebọn naa kọkọ kọlu nibi ti wọn ti pa ọlọpaa meji ti wọn si tun dana sun ọkọ ọkan lara awọn ọlọpaa ọhun.
Awọn agbebọn naa tun gbera lọ si agọ ọlọpaa to wa ni Rumuji nibi ti wọn tun ti pa ọlọpaa meji mi ti wọn si tun dana sun ọkọ awọn ọlọpaa.
Nnamdi sọ ninu atẹjade naa pe awọn agbofinro naa kọju ija sawọn agbebọn ọhun nigba ti wọn de eyi to mi ki meji lara wọn gbẹmi mi.
Oríṣun àwòrán, Rivers State Police
Bakan naa ni wọn tun kọlu agọ ọlọpaa to wa ni Elimgbu, bo tilẹ jẹ pe wọn ba awọn ọlọpaa naa nile.
Awọn ọlọpaa kọju ija sawọn janduku agbebọn ọhun, ṣugbọn mẹta ninu awọn ọlọpaa lo ba iṣẹlẹ naa lọ.
Awọn agbebọn naa ko ri ọkọ Hilux ti wọn gbe wa pada gbe lọ, ọkọ Sienna ti wọn ji gba lọwọ ẹnikan ni wọn gbe lọ.
Agbẹnusọ ileeṣẹ ọlọpaa sọ pe awọn agbebọn naa fara gbọta yana yana eyi to da apa si wọn lara.
Oríṣun àwòrán, Rivers State Police
Wọn tun gbe Sienna naa silẹ nigba tawọn ọlọpaa ko pada lẹyin wọn, bayii ni wọn ṣe na papa bora pẹlu apa ọta ibọn lara wọn.
Ẹwẹ, wọn ti gbe oku awọn ọlọpaa to ṣubu loju ogun lọ si mọsuari, nigbati ọga ọlọpaa ipinlẹ Rivers, Eboka Friday sẹleri pe ileeṣẹ ọlọpaa yoo ṣe awari awọn kọlọnbiti ẹda naa.
Ileeṣẹ ọlọpaa wa rọ awọn araalu lati fi to awọn ọlọpaa leti ti wọn ba ri ẹnikẹni pẹlu apa ibọn lara wọn.
Ademola Adeleke: Sẹ́nẹ́tọ̀ Ademola Adeleke kẹ́kọ̀ọ́ gboyè ní fásítì l'Amerika
Oríṣun àwòrán, Instagram/Ademola Adeleke
Njẹ ẹ ranti sẹnẹtọ onijo? Eyiun ni, Ademola Adeleke to jẹ oludije fun ipo gomina ninu idibo gomina ipinlẹ Osun lọdun 2018.
Sẹnẹtọ Adeleke ti kawe gboye ni fasiti lorilẹede Amerika lopin ọsẹ yii.
Ademola to jẹ aburo baba olorin takasufe, Davido ro dẹdẹ, bẹẹ lo kan dudu nibi ayẹyẹ ikẹkọjade ni fasiti to ti gboye l'Amerika.
Sẹnẹtọ onijo ko ṣai fi idunnu rẹ han loju opo Instagram rẹ.
Oludije fun ipo gomina labẹ asia ẹgbẹ oṣelu PDP nipinlẹ Osun lọsun 2018 kọọ soju opo Instagram rẹ pe Ọlọrun dara ni gbogbo igba.
Ọrẹ, ojulumọ ati ẹbi to fi mọ ẹgbọn Sẹnẹtọ onijo, Adedeji Adeleke ati ọmọkunrin rẹ, BRed lo wa nibi ayẹyẹ ikẹkọọjade naa lorilẹede Amerika.
Ẹwẹ, idile atawọn ọrẹ fi ẹsẹ ra ijo lati ba Ọgbẹni Ademola yọ lori aṣeyọri rẹ.
Koda, ẹgbẹ rẹ Adedeji naa ko gbẹyin, bakan naa ni Ademola fun ra n mi lẹgbẹ.
Yomi Fabiyi kési àwọn olólùfẹ́ òtítọ́ láti jáde fún ìwọ́de fún Baba Ijẹsha ni Panti
Oríṣun àwòrán, others
Yomi Fabiyi ko ti i dakẹ lori ipinnu rẹ ja fitafita fun itusilẹ akẹgbẹ rẹ, Baba Ijẹsha kuro ni ahamọ ọlọpaa.
Ninu ọrọ to tun kọ si oju opo Instagram rẹ ni ọjọ Aje, Fabiyi sọ pe oun ko ni i duro de ẹnikẹni ki oun to o bẹrẹ iwọde ti oun kede.
Fabiyi to fi ibinu han ninu ọrọ naa sọ pe inu n bi oun nitori pe ọrọ Baba Ijẹsha kan oun.
O ni ọkunrin kan bi i igba ni oun.
"Ẹnikẹni to ba mọ pe ọrọ yii kan oun, to si nifẹ lati ṣe atilẹyin fun nkan to tọ, le darapọ mọ mi.
Ti o ba si lero pe nkan to tọ ni fifi eeyan si atimọle lọna ti ko ba ofin mu, tabi o ro pe ko le kan ọ, ọmọ, baba tabi iya rẹ, ma gbiyanju lati darapọ."""
Bakan naa ni Ọgbẹni Fabiyi kilọ fun awọn oṣiṣẹ ilu ati awọn olori ti ìbò gbe wọle, lati ma jẹ ki ifẹ inu wọn tabi eero ọkan wọn nipa nkan to ṣẹlẹ, ṣe idiwọ fun iṣẹ wọn tabi ofin ilu.
Akomolede ati Aṣa lori BBC Yoruba: Wo díẹ̀ nípa àbùdá Olodumare- Iyabo Ayinde
Fabiyi ni asiko ti nkan to dara ba ṣẹlẹ ni Naijiria ma n fi ara rẹ we America, ṣugbọn to ba ti nii ṣe pẹlu ẹtọ ọmọniyan, 'a ko gbọdọ fi Naijiria we America rara.
Ẹ jẹ ki ofin ko ṣe iṣẹ rẹ, ko si daabo bo ẹtọ gbogbo eniyan.
Fabiyi tun fi kun ọrọ rẹ pe lootọ ni awọn oṣiṣẹ ile ẹjọ wa ni iyanṣẹlodi, amọ ṣe atimọle ni Baba Ijẹsha yoo wa , koda ti iyanṣẹlodi naa ba pe ọdun kan?
Gbajugbaja oṣere ori itage Yoruba, Iyabo Ojo ti sọ oriṣiiriṣii ọrọ iwuri nipa adẹrinpoṣonu, Damilola Adekoya ti ọpọ mọ si Princess.
Iyabo wa lara awọn to n ja fita fita lati rii pe akẹgbẹ rẹ ninu ere tiata, Olarenwaju James ti awọn eeyan mọ si Baba Ijesha foju wina ofin lori ẹsun ifipabanilopọ ti wọn kan an.
Laipẹ yii iroyin kan jade ninu eyi ti wọn ti fẹsun kan Baba Ijesha o fi ipa ba ọmọbinrin Princess lopọ.
Ṣugbọn lọjọ ibi Princess, Iyabo ki i ni mẹsan an mẹwaa loju opo Instagram rẹ.
O ni anfaani lo jẹ fun oun lati ba Princess pade ati lati mọ ọ sii daadaa.
'Tééyàn bá kú a lè yọ yọ ojú yẹn tẹ́ẹ bá gbà wá láyé, a lè dá a sí fún ẹlòmíràn'
Iyabo ni obinrin to ṣe e fi yangan ni adẹrinpoṣonu Princess, ati wi pe ayanmọ lo mu ki awọn mejeeji pade ara awọn.
''Ero wa jọ ara wọn, bakan ni a jọ nifẹ awọn ọmọde.
Alara tí Ilara Epe: Òjò gbọ́dọ̀ rọ̀ lásìkò ọdún Ẹlẹ́gba ni ìlú Epe- Oba Olufolarin Ogunsan
Mo mọ pe asiko to lagbara ni asiko jẹ fun ọ, ṣugbọn mo rọ ẹ pe ki o pakiti mọri.
Laipẹ lai jina, gbogbo rẹ ni yoo di afisẹyin ti egun n fi aṣọ,'' Iyabo lo sọ bẹẹ.
Iyabo ni ''mo nifẹ rẹ gan an ọrẹ mi atata. Isu ọmọ a jina fun wa je.''
Trade by Barter, Rivers: Mọ̀ síi nípa ọjà ní Esuk Mba, níbití o ti lè fi iṣu gba edé, epo
End of Ramadan, Id-el-fitr: Ajọ NSCIA ní ààwẹ̀ Ramadan ṣì tẹ̀síwájú dí Ọjọ́ọ̀rú, a kọ̀ tíì rí òṣùpá
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Sultan ti ilu Sokoto ti sọrọ labẹ asia ajọ ẹgbẹ Musulumi ni Naijiria, Alhaji Muhammad Sa'ad Abubakar  wi pe aawẹ Ramadan ṣi tẹsiwaju di Ọjọ Kẹtala, Oṣu Karun un, ọdun 2021.
Eyi ko ṣẹyin bi Ajọ Supreme Council for Islamic Affairs (NSCIA) ṣe ni awọn ko i tii ri oṣupa ti yoo fi ipari aawẹ Ramadan han.
Ninu Atẹjade ti wọn fi sita naa ni Ọjọọru naa ni aawẹ yoo di ọgbọn ọjọ ti wọn ti bẹrẹ.
Nitori naa, itunu aawẹ yoo waye ni Ọjọ kẹtala, Oṣu Karun un, ọdun 2021, eyi to jẹ Ọjọ Kini, Oṣu Shawaal, 1442 ninu Calender awọn Musulumi.
Ajọ awọn Musulumi naa gbadura fun awọn Musulumi pe wọn ṣe fi alaafia ati ayọ ṣe ọdun itunu aawẹ naa.
Saaju ni Ajọ NSCIA ṣalaye pe ti wọn ba ri oṣu tuntun lalẹ ọjọ Iṣẹgun, Ọjọru ni Sultan yoo bawọn akọroyin sọrọ tii ṣe ọjọ kinni oṣu Shawwal.
Bakan naa ni ijọba apapọ kede ọjọ meji gẹgẹ bi ọjọ isinmi fun awọn oṣiṣẹ lati ṣe ayẹyẹ ọdun itunu aawẹ.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ijọba apapọ ti kede Ọjọru ọjọ kejila ati Ọjọbọ, ọjọ kẹtala ọjọ kẹtala gẹgẹbi ọjọ isinmi lẹnu iṣẹ ni Naijiria.
Minisita f'ọrọ abẹrẹ, Raif Arẹgbẹṣọla kede eyi nigba to n ki awọn Musulumi ku oriire ipari awẹ osu Ramadan.
Bakan naa lo ke sawọn ileeṣẹ agbofinro ati ikọ alaabo gbogbo lati jẹ akinkanju ki wọn si dẹkun wahala abo to n koju Naijiria.
O fi kun un pe ijọba Aarẹ Muhammadu Buhari ṣetan lat dẹkun iwa ipa ati ọdaran gbogbo lati lee mu alaafia to jọju wọ Naijiria.
Sultan Sokoto ní káwọn mùsùlùmí wojú ọ̀run fún oṣù tuntun láti parí àwẹ̀
Sultan ilu Sokoto, Amir-ul Mu'mineen Naijiria, Alhaji Muhammad Sa'ad Abubakar ti sọ fawọn musulumi kaakiri orilẹede Naijiria lati wo oju ọrun lọju Iṣẹgun fun ipari awẹ.
Akomolede ati Aṣa lori BBC Yoruba: Wo díẹ̀ nípa àbùdá Olodumare- Iyabo Ayinde
Ọjọ Iṣẹgun yii tii ṣe ọjọ kọkanla oṣu karun un ọdun 2021 lo jẹ oṣu kẹwaa ninu ilana kalẹnda ẹsin islam.
Ti o ba ṣẹlẹ pe oṣu tuntun ko jade lọjẹ Iṣẹgun, awẹ ṣi maa pari lọjọ naa ti ọdun Sallah yoo si tẹlee l'Ọjọru tii ṣe ọjọ kejila oṣu karun un.
Ninu atẹjade ti ajọ NSCIA to n ri si ọrọ ẹsin islam ni Naijiria fi sita, igbakeji akọwe agba ajọ naa, Ọjọgbọn Salisu Shehu kepe awọn musulumi lati feti si awọn ilana lori ipari awẹ.
Trade by Barter, Rivers: Mọ̀ síi nípa ọjà ní Esuk Mba, níbití o ti lè fi iṣu gba edé, epo
O ṣalaye ninu atẹjade naa pe ajọ to n ri si wiwa oṣu tuntun ti rọ Sultan pe ọjọ Iṣẹgun ni kawọn musulumi wa lojufo fun oṣu Shawwal to tumọ si ipari awẹ.
Ajọ NSCIA ṣalaye pe ti wọn ba ri oṣu tuntun lalẹ ọjọ Iṣẹgun, Ọjọru ni Sultan yoo bawọn akọroyin sọrọ tii ṣe ọjọ kinni oṣu Shawwal.
Ọjọgbọn Shehu ni ''ṣugbọn ti wọn ko ba fi le ri oṣu tuntun lọjọ Iṣẹgun, ajẹ wi pe Ọjọ lo maa jẹ ọjọ kinni, oṣu Shawwal niyẹn.'
O ni fun idi eyi, gbogbvo musulumi ni lati maa wo oju ọrun fun oṣu tuntun gẹgẹ bi Amir-ul Mu'mineen Naijiria ṣe sọ.
Bakan naa ni atẹjade ọhun sọ pe ajọ NSCIA labẹ alaṣẹ aarẹ ẹgbẹ naa, Alh. Muhammad Sa'ad Abubakar, CFR, n ki gbogbo mumuni ati mumina ododo ku ọdun itunu awẹ ṣaaju akoko naa.
Ẹgbẹ naa gbadura pe Allah yoo san onikaluku ni ẹsan rere.
'Tééyàn bá kú a lè yọ yọ ojú yẹn tẹ́ẹ bá gbà wá láyé, a lè dá a sí fún ẹlòmíràn'
African Idols: Kí ló lè mú kí àlùfáà ìjọ Aguda máa kó ère ìṣẹ̀nbáyé pamọ́?
Eewọ! A kii ri aja ni mọṣalaaṣi. Ẹ gbọ na, ki lo kan alufaa ijọ Aguda pẹlu awọn ere iṣẹnbaye?
Bẹẹ laa bi ni o. Ilumọọka alufaa ijọ Aguda kan nilẹ awọn Ibo, Rev Fr Paul Obayi lo n ko awọn ere iṣẹnbaye pamọ o.
Kini idi abajọ ti Rev Fr Obayi fi n ko ere pamọ nigba ti ki i ṣe olooṣa?
Rev Fr Obayi ni oun n ko awọn ere iṣẹnbaye yii pamọ si ile ikonkan iṣẹnbaye oamọ si kawọn ọmọde to m bọ lẹyin wa ọla le lanfaani lati ri wọn.
Alufaa Obayi ni tawọn iran to n bọ lẹyin wa ọla ko ba ri awọn ere yii, wọn ko ni mọ itan iran ẹya Ibo.
''Mi o mọ idi tawọn alufaa atawọn ile ijọsin fi n dan sun awọn ere atawọn oriṣa ilẹ Ibo?''
Akomolede ati Aṣa lori BBC Yoruba: Wo díẹ̀ nípa àbùdá Olodumare- Iyabo Ayinde
Ibeere ti alufaa Obayi beere niyii nigba to ba awọn akọroyin sọrọ.
''Ọpọ ere iṣẹmbaye Igboukwu lawọn oloe ti jigbe lọ.
Ki lo n ṣẹlẹ bayii nipa ooṣa to wa nilẹ Ozalla?''
Ara awọn ibeere ti Rev Fr Obayi n beere niyii.
Ọpọ ere ati ooṣa iṣẹnbaye ni awọn to fi ẹsin abalaye silẹ di ọmọ lẹyin Kristi ti dana sun lẹyin ti wọn di onigbagbọ tan.
Amọ, Rev Fr Obayi n kaakiri ilẹ Ibo lati ko awọn ere iṣẹnbaye to ba ti gbọ pe wọn fẹ dan sun pamọ.
Koda, o mu awọn akọroyin lọ si awọn ojubọ to ti ko ọpọ ere ati ooṣa iṣẹnbaye to ti ko pamọ bayii.
Alara tí Ilara Epe: Òjò gbọ́dọ̀ rọ̀ lásìkò ọdún Ẹlẹ́gba ni ìlú Epe- Oba Olufolarin Ogunsan
Lizzy Anjorin: Wo orúkọ mẹ́rìnlá tí Lizzy Anjorin sọ ọmọ rẹ̀
Oríṣun àwòrán, Instagram/Lizzy Anjorin
Ẹbun pataki ni ọmọ bibi, o to bẹẹ ka ki iya aburo ku ewu.
Oṣerebinrin tiata Yoruba, Lizzy Anjorin ti n dawọ idunnu ọmọ tuntun jojolo ti Eledua fi ta a lọrẹ.
Lizzy ti n ki Ọlọrun ni mẹsan an mẹwaa lati igba ti o ti bi ọmọ naa lorilẹede Amerika.
Oriṣiiriṣii orin ati oriṣiiriṣii aworan oun ati ọkọ rẹ ni Lizzy ti fi si oju opo Instagram lati igba ti o ti bi ọmọ naa.
Lizzy ko le ṣa lai maa sọ pe Ọlọrun ọba sọ ẹgan oun di ogo nipa ọmọ tuntun to fi ta oun lọrẹ Mo gbé ìgbésẹ̀ láti ṣẹ́ oyún ọmọ mi tuntun, ọkọ mi nàá sì faramọ́ nítorí pé...
Lẹyin to ti sọ awọn oun ti o la kọja lati asiko ti oyun duro si i lara titi ti o fi bi ọmọ naa tan, Lizzy tun ti fi ọrukọ ọmọ naa soju opo Instagram rẹ bayii.
Lizzy bẹrẹ nipa kiki gbogbo awọn abiyamọ aye ku ajayọ ọjọ iya to waye lọjọ kẹsan an oṣu karun un ọdun 2021 yii.
Lẹyin naa lo bẹrẹ si ni ka orukọ ọmọ rẹ ni ọkọọkan ejeeji to fi pe mẹrinla.
Lizzy ni orukọ ọmọ naa niwọn yii:
1. OBA* ASETAN MAKU
2. OBA OKE *PEGANMIRE*
.
3. OBA OKE FAYE *YEMI*
Trade by Barter, Rivers: Mọ̀ síi nípa ọjà ní Esuk Mba, níbití o ti lè fi iṣu gba edé, epo
.
4. OBA OKE *SEYIFUNMITAN*
.
5. OBA OKE FADUN *KAYOMI*
.
6. OBA OKE SORO MI *DAYO* NIWAJU ARONIPIN
.
7. *ADEWEPOMOLA*
.
8. *FLORIDA *
.
'Tééyàn bá kú a lè yọ yọ ojú yẹn tẹ́ẹ bá gbà wá láyé, a lè dá a sí fún ẹlòmíràn'
9. *OKIKI* WOLE *OLA*
10. *SEMAWON*
.
11. *MENDO*
.
12. *FARYAT*
Orukọ ikoko to ku ni:
13. *ABEBI*
14. *LAWAL*
Lẹyin to darukọ mẹrinla yii tan lo tun wa rọ awọn eeyan lati ba oun fi orukọ mẹwaa kun awọn eyi ti oun ti sọ.
Dare Adeboye, #PDee àti #NotTodaySatan, I'm not leaving God: Ẹ wo bí Leke Adeboye, àwọn ọ̀dọ́ ìjọ RCCG ṣe gẹ irun wọn láti bú ọlá fún olóògbé Dare Adeboye
Oríṣun àwòrán, Instagram/PDEE
Gbogbo eto lo ti bẹrẹ fun eto isinku oloogbẹ, Pasitọ Dare Adeboye to jẹ ọmọkunrin ikeji Pasitọ Enoch Adeboye to jẹ adari ijọ Redeem Christian Church of God lagbaye.
Ọjọ Kọkanla, Oṣu Karun un ni yoo wọ kaa ilẹ sun, amọ lati Ọjọ Aiku ọṣẹ naa ni ayẹyẹ ikẹyin loriṣiriṣi ti bẹrẹ fun un pẹlu awọn ọdọ ijọ naa ti wọn gẹ irun ori wọn lati ṣe ẹyẹ ikẹyin fun oloogbe naa.
Pẹlu Hashtag #PDee ati #NotTodaySatan, I'm not leaving God, ni wọn n lo lati fi aworan wọn sita pẹlu bi wọn fa irun wọn lori ayelujara.
''Awọn ọrọ akọle ti wọn ko si be ni pe'' A o bẹru iku mọ, iye ayeraye ni tiwa ni aye ati ni orun ti n bọ. Kikuro ninu ara mu mi wa pẹlu Oluwa ninu ẹmi''
''Ki emi wa laye ni lati wa ninu Kristi, ki emi si ku jẹ ere nitori iye ayeraye ni - Phillippians 1:21.''
Oríṣun àwòrán, Instagram/PDEE
Ẹni akọkọ to kọkọ gẹ irun rẹ ni aburo oloogbe naa, Leke Adeboye ki  awọn ọmọlẹyin Kristi ninu ijọ naa kaakiri agbaye to bere lati ma a ṣe gẹgẹ bi Leke ṣe n ṣe.
Ninu fidio to fi lede lo ti sọ wi pe iṣe wọn ni lati bu ọla fun ẹni to ba jẹ akinkanju ọkunrin to jẹ ọdọ ninu Kristi, to si ja fitafita fun ọrọ Ọlọrun ki o to rekọja kuro ni aye.
'Iṣẹ wá burẹkẹ síi tórí Covid-19, owó ńlá ló wà nínú dídáná sun òkú, ìsìnkú  Zoom, Live streaming'
Ọpọlọpọ eniyan lo si ti bẹrẹ si ni fesi si irun gigẹ naa lati bu ọla fun ẹni to doloogbe.
Ọpọ sọ wi pe kii ṣe ọna igbagbọ lati gẹ irun nitori oloogbe to kọja lọ nigba ti awọn miran ni o dara bẹẹ nitori ẹni ọdun mejilelogoji ni Dare ko to di oloogbe.
Oríṣun àwòrán, others
Ọjọ kẹfa, oṣu Karun un, ọdun 2021 ni iroyin iku pasitọ Dare Adeboye fa ori ayelujara ya.
Iroyin iku rẹ da omi tutu si ọkan gbogbo eeyan, paapaa awọn ọmọ ijọ Redeemed Christian Church, RCCG, ni Naijiria ati loke okun.
Dare Adeboye nigba aye rẹ jẹ ọkan lara awọn ọmọ alufa agba, to tun jẹ adari ijọ RCCG kaakiri agbaye, pasitọ Enoch Adejare Adeboye.
Wọn bi Dare Adeboye ni ọjọ kẹsan an, oṣu Kẹfa, ọdun 1979.
Dare jẹ olukọ awọn ọdọ, o jẹ ẹnikan to ko awọn eeyan mọra, o si tun jẹ ọkan pataki lara awọn ọdọ to lẹnu lọrọ ati ilumọka ninu ijọ RCCG.
"Orukọ ti ọpọ awọn ọdọ ninu ijọ irapada maa n pe ni ""Pastor Dee tabi PD""."
Oba Olufolarin Ogunsan Alara tí Ilara Epe: Òjò gbọ́dọ̀ rọ̀ lásìkò ọdún Ẹlẹ́gba ni ìlú Epe
Mo gbọdọ sadura fun Kilajolu lẹyin to ba na mi tan lasiko ọdun Ẹ̀bì ni Ilara Ẹpẹ-  Kabiesi Alara ti ilu Ilara Ẹpẹ nipinlẹ Eko.
Oba Olufolarin Ogunsanwo to jẹ Alara ti ilu Ilara ni Ẹpẹ ni ipinlẹ Eko ni guusu iwọ oorun Naijiria gba BBC Yoruba lalejo.
Kabiesi ṣalaye itan ilu Ilara ati pataki oye ọba ilu naa lati igba iwaṣẹ.
Oba Alara salaye kikun nipa ọdun Ẹbi ati eegun Kilajolu ti wọn maa n fi kẹyin ọdun naa.
Eegun Kilajolu yii ni yoo kọkọ na Kabiesi Ilarqa lẹgba.
Lẹyin naa ni Kabiesi a ṣadura fun eegun naa ki o to le jade lọ maa na awọn ara ilu Ilara  ni Epe ni ọrẹ.
Kabiesi Olufolarin Ogunsanwo ni iṣẹ agbẹ ati iṣẹ apẹja ni a mọ awọn eniyan Ilu Ilara Epe mọ lati igab iwaṣẹ ni eyi ti wọn ṣi n ṣe titi di oni.
Oba ni leyin ti oun ba ti ṣadura fun Kilajolu tan ni yoo wa bẹrẹ si ni gabdura fun ilu Epe ati Naijiria lapapọ.
Ondo kidnap: Amotekun Ondo ju afurasí ajínigbé mẹ́rin s'átìmọ́lé, dóòlà àwọn tí wọ́n jígbé
Oríṣun àwòrán, Amotekun Ondo
Ọjọ gbogbo ni ti ole, ọjọ kan bayii ni ti oloun.
Ẹṣọ Amotekun ipinlẹ Ondo lo ti fi ọwọ ofin mu awọn afurasi ajinigbe mẹrin niluu Akure.
Ọga agba Amotekun nipinlẹ Ondo to ba BBC Yoruba sọrọ, Oloye Adetunji Adeleye ṣalaye pe oju ọna Akure si Oda lawọn afurasi ọhun ti ji awọn eeyan gbe lọ.
Oloye Adeleye sọ pe ẹṣọ Amotekun doola awọn eeyan tawọn afurasi ọhun jigbe lọ.
Ọga agba Amotekun ni ileeṣẹ ọlọpaa naa ṣiṣẹ pọ pẹlu awọn ẹṣọ Amotekun lati ri pe ọwọ tẹ awọn afurasi naa.
''Lẹsẹkẹsẹ ti iṣẹlẹ ọhun ṣẹlẹ ni a fi ọrọ naa to ileeṣẹ ọlọpaa ati ajọ ọtẹlẹmuyẹ DSS ipinlẹ Ondo.
Alara tí Ilara Epe: Òjò gbọ́dọ̀ rọ̀ lásìkò ọdún Ẹlẹ́gba ni ìlú Epe- Oba Olufolarin Ogunsan
Gbogbo ẹṣọ eleto abo nipinlẹ Ondo ni a jọ ṣiṣẹ papọ lori ati mu awọn afurasi naa,'' Oloye Adeleye ṣalaye.
O fikun ọrọ rẹ pe awọn afurasi mẹrin naa si wa ni atimọle ẹṣọ Amotekun nigba ti iwadii ṣi n lọ lọwọ.
Trade by Barter, Rivers: Mọ̀ síi nípa ọjà ní Esuk Mba, níbití o ti lè fi iṣu gba edé, epo
Oloye Adeleye ni o ṣeeṣe ko jẹ wi pe lati atimọle ẹṣọ Amotekun lawọn afurasi naa yoo gba lọ sile ẹjọ.
Amọ, o sọ pe iwadii ṣi n lọ lọwọ, ati pe abajade iwadii lo maa sọ bo ya awọn maa fawọn afurasi naa lọ sọdọ awọn ọlọpaa.
Covid-19 in Nigeria: Ìjọba dá òfin kónlé-ó-gbélé lórí àjàkálẹ̀ àrùn covid-19 padà
Oríṣun àwòrán, Twitter/NCDC
Ijọba apapọ orilẹede Naijiria ti da ofin konle-o-gbele pada lori ati dena ajakalẹ arun coronavirus.
Ọkan lara awọn oludari igbimọ PTF to n ri si ati dena ajakalẹ arun naa ni Naijiria, Dokita Mukhtar Mohammed lo fọrọ yii lede lọjọ Aje.
O ṣalaye pe ijọba ti da ofin konle-o-gbele to wa tẹlẹ laarin ago mejila alẹ si ago mẹrin aarọ pada kaakiri gbogbo ipinlẹ to wa ni Naijiria.
Bakan naa lo ṣalaye pe lati alẹ ọjọ Iṣẹgun, gbogbo ile ijo, gbọngan idaraya yoo di titi pa.
O tun fikun ọrọ rẹ pe ipejọpọ awọn eeyan ko gbọdọ ju aadọta lọ mọ lati asiko yii lọ
''Ẹnikẹni ti ko ba wọ ibomu ko ni lanfaani lati wọ ileeṣẹ ijọba kankan.
Lori ayelujara ni ipade awọn ileeṣẹ ijọba yoo ti maa waye bayii.
Alara tí Ilara Epe: Òjò gbọ́dọ̀ rọ̀ lásìkò ọdún Ẹlẹ́gba ni ìlú Epe- Oba Olufolarin Ogunsan
Awọn ti o ṣe pataki fun lati rinrin ajo lọ si oke okun nikan lo yẹ ki wọn rinrin ajo lọ si ilẹ okeere bayii,'' Dokita Mohammed lo ṣalaye bẹẹ.
Amọ, o sọ pe awọn eeyan yoo ṣi maa lanfaani lati rinrin ajo lati ipinlẹ kan si omiran kaakiri Naijiria.
Dare Adeboye burial: Pásítọ̀ Adeboye bẹ̀bẹ̀ fún àdúrà fún ìdílé rẹ̀ àti ẹbí olóògbé Dare Adeboye
Oríṣun àwòrán, @pdee
Oludari ijọ Redeem(RCCG), Pasitọ Enoch Adejare Adeboye ti bẹbẹ adura fun idile rẹ nigba to n sọrọ nibi eto isinku ọmọkunrin rẹ, Pasitọ Dare Adeboye to d'oloogbe.
Baba Adeboye sọrọ lori ẹrọ amohunmaworan nibi eto isinku naa to wa ni ọgba ''Redeem camp'' to wa ni opopona ilu Eko si Ibadan.
Alufaa Adeboye sọ pe ikku ko mọ ọmọde, bẹẹ ni ko mọ agba nitori bi ọmọde ṣe n ku naa ni awọn agbalagba n ku.
''Iku ko niiṣe pẹlu ọjọ ori eeyan, ṣugbọn ẹ dẹkun lati maa gbadura fun mi.
Ẹ maa gbadura fun iyawo mi, ẹ maa ranti aya oloogbe atawọn ọmọ rẹ naa ninu adura yin.
Oríṣun àwòrán, @Dare Adeboye
Eleyii to ju gbogbo rẹ lọ ni pe e maa gbadura fun ara yin ki ẹyin naa le pari irinajo yin laye yii daradara,'' Pasitọ Adeboye lo sọ bẹẹ.
Baba Adeboye ṣalaye pe ko si ọna ti aye yii fi le da bi ọrun laelae.
''Mo mọ ohun ti mo n sọ nipa rẹ tori pe mo rii fun ra mi.
Akomolede ati Aṣa lori BBC Yoruba: Wo díẹ̀ nípa àbùdá Olodumare- Iyabo Ayinde
Ti ẹ ba ri mi ti mo n ṣiṣẹ takuntakun fun Oluwa, nitori mo mọ pe ere mi n duro de mi lọrun ni.
Mo rọ yin wi pe ki ẹ tẹsiwaju ninu ereeje igbagbọ.
Ohun ti mo mọ nipe iyanu nla ti iru rẹ ti aye ko tii ri ri yoo ṣẹlẹ ninu aye yin laipẹ,'' Pasitọ Adeboye lo sọ bẹẹ.
Baba Adeboye tun sọ pe oun yoo tubọ tẹra mọ ọrọ awọn ọdọ ninu ijọ RCCG ju ti atẹyinwa lọ.
Oríṣun àwòrán, BBC/screenshot
Àwọn àwòrán láti ibi ètò ìsìnkú olóògbé Dare Adeboye ni Redemption Camp
Eto isinku oloogbe Dare Adeboye, to jẹ ọmọ kẹta to tun duro fun ọmọkunrin keji adari ijọ Redeemed Christian Church of God, RCCG, Pasito Enoch Adejare Adeboye ti bẹrẹ.
Bayii ni awọn eeyan ṣe pejọ sibi ti ayẹyẹ isinku naa yoo ti waye
Gbogbo ẹbi, ara ọrẹ ati ojulumọ ni ireti wa pe wọn yoo peju pesẹ sibi isin naa loni ọjọ Iṣẹgun, ọjọ kọkanla, oṣu karun un, ọdun 2021.
Pẹlu Hashtag #PDee ati #NotTodaySatan, I'm not leaving God, ni wọn n lo lati fi aworan wọn sita pẹlu bi wọn fa irun wọn lori ayelujara.
Lana ni wọn ti kọkọ ṣe isin idagbere ni ile ijosin House of Favour ni Redemption Camp ni Mowe ni ipinlẹ Ogun.
Eyi si waye leyin isin iyẹ oloogbe si to kọkọ waye ni ọjọ Aiku nil ipinlẹ Akwa Ibom ti oloogbe ti ṣiṣẹ iranṣẹ gbẹyin ki ọlọjọ to de.
Awọn ọmọ ogun igbala naa ko gbẹhin nibi eto naa. Tilu-tifọn ni wọn fi gbe oku Dare Adeboye lọ si ibi ti isinku yoo ti waye
Ọjọ Isẹgun ọjọ Kọkanla osu Karun ọdun 2021:
Isin idagbere yoo waye ni aago mẹwa owurọ ni ibudo awọn ọdọ, Youth Centre, to wa ni Redemption Camp ni Mowe, nipinlẹ Ogun.
Lẹyin naa ni wọn yoo sin oloogbe Dare Adeboye si ibẹ.
Oríṣun àwòrán, @PDEE
Lẹyin isin fun oloogbe ni RCCG House of Favour ni Redemption Camp ni Mowe ni ipinlẹ Ogun laarọ oni ni wọn yoo gbe ara oloogbe Oluwadamilare Temitayo Adeboye lọ si itẹ̀ oku ni Redemption Camp.
Nibẹ ni wọn yoo ti fi eruku fun eruku ati iyẹpẹ fun iyẹpẹ ti wọn yoo si fi ara naa silẹ lọ.
Iyawo kan, Temiloluwa ati ọmọ mẹta, Oluwatise, IreOluwa, ati Araoluwa lo gbẹyin oloogbe naa yatọ si Obi, ẹgbọn, aburo, ara ati ọrẹ.
Trade by Barter, Rivers: Mọ̀ síi nípa ọjà ní Esuk Mba, níbití o ti lè fi iṣu gba edé, epo
Aso Rock robbery: Àwọn ìgbà tí adigunjalé ti yabo àwọn ilé ìjọba rí
Oríṣun àwòrán, Presidency
Eleyi ṣẹlẹ ni orilẹede Naijiria lọdun 2019 lẹyin ti awọn adigunle ja wọ inu ọfiisi igbakeji olori oṣiṣẹ gomina Bayelsa tẹlẹ, Seriake Dickson lati ji owo.
Ebizi Brown to jẹ igbakeji olori oṣiṣẹ nigba naa nipinlẹ Bayelsa ni awọn adigunjale ọhun ja wọ inu ọfiisi oun.
Wọn si ji owo ti iye rẹ jẹ miliọnu mẹta abọ nigba naa, arabinrin Brown lo fidi ọrọ yii mulẹ fun ileeṣẹ amohunmaworan Channels lasiko naa.
Agbẹnusọ ọlọpaa ipinlẹ Bayelsa nigba naa tun fi ẹnu kun un pe ootọ lo ṣẹlẹ.
Awọn ọlọpaa ṣafikun ọrọ pe awọn janduku ọhun ba ilẹkun to wọ ọfiisi arabinrin Brown jẹ lati le ri ọna wọle wọn si tun ba apoti ikowo pamọsi to wa ninu ọfiisi naa lati le ji owo.
Ikú kò m'ọmọdé, kò màgbà, ẹ gbàdúrà fún ìdílé mi àti aya pẹ̀lú ọmọ olóògbé- Pásítọ̀ Adeboye
Ìjọba àpapọ̀ kéde Òjọ́rú àti Ọjọ́bọ gẹ́gẹ́ bi ísinmi lẹ́nu iṣẹ́
Ìnú ìpayà, ìbẹ̀rú ní a wà nítorí a kò tíì gburò Pásítọ̀ Ìjọ Deeper Life tí wọ́n jígbẹ lọ ni ìlú Akure- Ẹbí
Àwọn ọmọ Naijiria yóò rí akitiyan ìjọba láti yanjú ètò àbò tó mẹ́hẹ láìpẹ́ - Lai Mohammed
Ẹni tó bá ní láàkàyè, a mọ ẹ̀tọ́ ọmọnìyàn, àwà ti kọ lẹ́tà, èsì t'Ọ́lọ́pàá sì fún wa rèé - Yomi Fabiyi
Ikọlu Aafin Buckingham lọdun 1982
Eyi jẹ iṣẹlẹ ti awọn ara Britain ko le gbagbe laye laye lẹyin ti arakunrin kan ti wọn n pe ni Michael Fargan ri ọna wọ inu aafin naa.
Koda Fargan ribi wọ inu yara Ọlọla julọ, Ọbabinrin Elizabeth keji.
Gẹgẹ bi iroyin BBC ṣe sọ ọ, Fargan ẹni ọdun mejilelọgbọn naa lasiko ọhun fo fẹnsi wọle, o tọ inu oju iho paipu titi to fi de inu yara Ọbabinrin Elizabeth, ẹnikankan ko si ri i.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ofolongo ẹsẹ ni baba ọlọmọ marun adigunjale naa fi bọ mọ gbogbo awọn ẹṣọ ile ọba lọwọ to fi mọ gbogbo irinṣẹ alariwo to yẹ ko tu u fo titi to fi wọ yara Ọbabinrin.
Nigba to wọ inu iyẹwu rẹ, o ni ko fun ohun ni siga, Ọba ba pariwo ni ọkan ninu ẹṣọ ba bu u so titi ti awọn ọlọpaa fi gba a mu.
Eleyi waye lọdun 2007 nigba ti igara ọlọsa, Obadiah Marius ati ọrẹbinrin rẹ kọlu inu ojule nọmba aadọrin ninu iloro Whitehall ni London.
Ile yii sunmọ ile ijọba Olootu ilẹ Gẹẹsi ati ibi ti aọn aṣofin ilẹ UK ti n ṣepade.
Awọn ololufẹ meji naa wa ọgbọn lati wọ inu ibi ipade awọn aṣofin lai gba ọna to yẹ ki wọn ti yẹ wọn wo rara.
Koda, wọn tun gba ouna ibode oni irin to yẹ ko maa da abo bo  Olootu lọwọ awọn agbe ado oloro.
Nigba to ya, ọwọ awọn ọlọpaa tẹ Obadiah ati ọrẹbinrin rẹ ti wọn si fi ẹsun to lagbara kan wọn labẹ ofin ilẹ United Kingdom.
Bí àwọn adigunjalè ṣe gbìyànjú láti fọ́ ile olórí àwọn òṣìṣẹ́ lọ́fíìsì ààrẹ.
Oríṣun àwòrán, @statehouse
Awọn adigunjale kan ti gbiyanju lati wọ ile Ọjọgbọn Ibrahim Gambari, ẹni to jẹ olori awọn oṣiṣẹ lakata aarẹ Buhari.
Ileeṣẹ aarẹ fi idi rẹ mule ninu atẹjade kan loju opo Twitter.
Iroyin sọ pe awọn alọkolohunkigbe naa wọ ile olori awọn to n ba aarẹ Buhari ṣiṣẹ, ṣugbọn ileeṣẹ aarẹ ni ko si ohun to jọ ati pe awọn ole naa ko ri aye wọle.
Oríṣun àwòrán, Tweet
Garba Shehu to jẹ amugbalẹgbẹ fun aarẹ lori ọrọ iroyin ati ipolongo ṣalaye lori Twitter pe ko si giri nitoripe awọn ole naa ko raye wọ ile Ọjọgbọn Gambari.
"Olori awọn oṣiṣẹ to n ṣiṣẹ lọfiisi aarẹ, Ọjọgbọn Gambari ti fidi rẹ mulẹ pe awọn oponu eeyan kan yi gbiyanju lati fipa wọ ile oun ni nnkan bii agogo mẹta owurọ yii (ọjọ Aje)  ṣugbọn wọn ko rii ṣe.
 Ọjọgbọn Gambari, ti ile rẹ wa ni opopona to kangun si ile aarẹ  Aso Rock Villa, ti wa fi ọkan awọn eeyan balẹ pe ko sewu."","
Alara tí Ilara Epe: Òjò gbọ́dọ̀ rọ̀ lásìkò ọdún Ẹlẹ́gba ni ìlú Epe- Oba Olufolarin Ogunsan
David Oyedepo: Ẹnikẹ́ni kò lẹ́tọ̀ọ́ láti fipá mú mi gbabẹ́rẹ́ àjẹsára Covid-19 - Oyedepo
Oríṣun àwòrán, @Oyedepo
Ẹ ò lè rí Covid-19 nínú ìjọ mi, ẹ má fi abẹ́rẹ́ rẹ̀ lọ̀ mí - Oyedepo
Oludasilẹ ijọ Living Faith kaakiri agbaye, Biṣọọbu David Oyedepo ti sọ pe iwalaaye Ọlọrun nilẹ Afrika ni ko jẹ ki arun Coronavirus gbẹmi ọpọ eeyan gẹgẹ bii awọn onimọ kan ṣe sọ ṣaaju.
Alufa naa lo sọ ọrọ ọhun lasiko to n waasu nibi isin idupẹ ajọdun ogoji ọdun ti wọn da ijọ naa silẹ.
"Oyedepo ni ""Awọn onimọ sayẹnsi kan sọ pe arun Corona yoo pa awọn eeyan nilẹ Afrika to bẹ ti ko ni si aye lati sin oku awọn eeyan naa si."""
Ṣugbọn Ọlọrun doju ti wọn nitori Afrika ni iye eeyan to kere julọ ti Corona pa wa.
Baba Oyedepo ni ko si ẹni to le fi ipa mu ẹnikẹni gba abẹrẹ ajẹsara Covid-19.
Akomolede ati Aṣa lori BBC Yoruba: Wo díẹ̀ nípa àbùdá Olodumare- Iyabo Ayinde
"Oyedepo sọ pe ""Ko si ẹnikẹni tabi alaṣẹ kankan to le fi ipa mu yin lati gba abẹrẹ ajẹsara kankan."""
Ẹ wo bi ero ṣe pọ nibi yii, ṣe ẹ gburo arun Corona kankan nibi…?
Alufa ọhun ṣalaye pe iwalaaye Ọlọrun ni ko jẹ ki awọn lugbadi Covid-19 gẹgẹ bii asọtẹlẹ awọn onimọ sayẹnsi ṣaaju.
O ni ko si ẹnikẹni to le fi ipa mu oun lati gba abẹrẹ nitori oun ko mọ erongba awọn alaṣẹ ti wọn fi n lọgun abẹrẹ naa, o si fi kun pe oun mọ pe wọn ko ni erongba rere fun awọn araalu.
Alufa ọhun ni ko bojumu ki wọn ki wọn kan an nipa fun eeyan lati gba abẹrẹ naa, tabi ki wọn fi ọwọ osi juwe ile fun eeyan nitori pe o kọ lati gba abẹrẹ ajẹsara Covid-19.
Oyedepo pari ọrọ rẹ pe eeyan kii ṣe ẹranko, nitori naa ko yẹ ki wọn dan abẹrẹ kankan wo lara awọn eeyan labẹ asia arun Coronavirus.
Alara tí Ilara Epe: Òjò gbọ́dọ̀ rọ̀ lásìkò ọdún Ẹlẹ́gba ni ìlú Epe- Oba Olufolarin Ogunsan
Biṣọọbu Oyedepo jẹ ọkan gboogi lara awọn ojiṣẹ Ọlọrun ni Naijiria to maa n sọ erongba wọn jade, ti wọn ko si gbagbọ pe arun Coronavirus le ṣe wọn ni ohunkohun.
Bi ẹ ko ba gbagbe, ṣaaju ni ijọba ilẹ Gẹẹsi ti kọkọ na alufa kan ti oun naa jẹ ọmọ Naijiria ni paṣan, iyẹn pasitọ Chris Oyakhilome lẹyin to waasu tako Covid-19 ati abẹrẹ ajẹsara ti wọn po lati koju ajakalẹ arun naa.
Insecurity in Nigeria: Àwọn gómìnà ẹkùn Gúúsù fòfin de dída màálù ní gbangba
Oríṣun àwòrán, Dapo Abiodun MFR
Awọn gomina ilẹ Yoruba, ilẹ Ibo ati awọn ẹkun Niger Delta ti ke si Aarẹ Muhammadu Buhari lati b'awọn ọmọ Naijiria sọrọ lori eto abo to ti polukurumusu ni Naijiria bayii.
Awọn mẹtadinlogun lapa gusu orilẹede Naijiria kede ọrọ naa lẹyin ipade ti wọn ṣe lọjọ Iṣẹgun ninu Asaba, nipinlẹ Delta.
Koko mejila lawọn gomina naa fẹnu ko si eleyii ti alaga wọn, Gomina Rotimi Akeredolu ipinlẹ Ondo ka jade.
Awọn gomina naa sọ pe awọn eeyan apa gusu Naijiria ṣi n wa iṣọkan orilẹede yii niwọn igba ti ododo, aiṣegbe lẹyin ẹnikan ati alaafia ba ti wa laarin awọn ọmọ Naijiria.
Awọn ẹkun gusu ko ṣai fi aidunnu wọn han lori eto abo to mẹhẹ bayii.
''A ṣe akiyesi pe awọn darandarn, awọn ọdaran atawọn janduku to n wa si ẹkun gusu ni Naijiria ti ṣakoba fun eto abo awọn eeyan wa.
Eku ko ke bi eku mọ, bẹẹ ni ẹyẹ ko ke bi ẹyẹ mọ, awọn eeyan ko le gbe ni alaafia mọ.
Gbọgbo nkan yii lo si ti ṣokunfa ọwọngogo ounjẹ bayii.
Fun idi eyi, a ti fofin de dida maalu kiri ni gbangba kaakiri apa gusu Naijiria,'' Akeredolu lo sọ bẹẹ ninu atẹjade to fi sita.
Akeredolu ni ''a tun fẹnuko pe ijọba ni lati gbe igbesẹ ni kiakia lati lati ṣe atunto Naijiria lori ọrọ ọlọpaa ipinlẹ atawọn atunto ileeṣẹ ijọba kan.
A tun fẹ ijọba apapọ ṣe agbekalẹ ifọrọwerọ pẹlu awọn ọmọ Naijiria lati le sọ ohun to n kọ wọn lominu gan an.
Ijọba tun gbọdọ tun ero rẹ pa lori ofin konle-o-gbele to da pada tori ajakalẹ arun covid-19 nitori akoba to le ṣe fun ọrọ aje.
Manchester United vs Leicester: Leicester City ṣẹ́ṣó ìyà fún Man United, Man City gba ife ẹ̀yẹ Premier League ti sáà yìí
Oríṣun àwòrán, Twitter/Kevin de Bruyne
Ẹgbẹ agbabọọlu Manchester City ti gba ife ẹyẹ Premier League fun saa bọọlu yii.
Man City gba ife naa lẹyin ti Leicestrer City lu Man U mọle pẹlu ami ayo meji sẹyọkan lọjọ Iṣẹgun.
Ami ayo mẹwaa ni Man City fi n ṣiwaju United ninu eyi ti wọn si ni ifẹsẹwọnsẹ mẹta pere to ku ti wọn yoo gba ti saa yii yoo fi pari.
Igba kẹta ti Man City yoo gba ife ẹyẹ Premier League ree laarin ọdun mẹrin ti Pep Guardiola ti di akọnimọọgba wọn.
International Nurses Day 2021: Wo ìpèníjà àti àǹfàní inú iṣẹ́ nọ́ọ̀sì- Adetokunbo Shaba
Bi ayajọ awọn nọọsi ṣe n lọ lagbaaye, Ọgbẹni Adetokunbo Shaba ti sọ pe gbogbo eeyan kọ lo le ṣe iṣẹ nọọsi.
Shaba to jẹ agba nọọsi ti lo ogoji ọdun lẹnu iṣẹ nọọsi.
O ni ati obinrin ati ọkunrin lo n ṣiṣẹ nọọsi nitori gbogbo eeyan ni aisan maa n ṣe.
Ọgbẹni Shaba sọ pe ijọba ko tii gbiyanju to fawọn nọọsi ki ọkan wọn le balẹ lẹnu iṣẹ.
O ṣalaye pe ijọba ni lati ṣeto to mọyan lori nipa owo oṣu awọn nọọsi, ohun elo iṣẹ, omi ati ina ati bẹẹ bẹẹ lọ.
Ọgbẹni Shaba sọ pe nọọsi kan lo yẹ ko wa fun eeyan ni Naijiria gẹgẹ bi o ti ri kaakiri agbaye.
Baba Ijesha: Ohun tí a mọ̀ rèé lórí ìròyìn tó jáde pé Iyabo Ojo ti bẹ Yomi Fabiyi padà
Oríṣun àwòrán, Instagram/Iyabo Ojo
Iroyin to gbode kan nsiyi ni pe Iyabo Ojo, ti bẹ Yomi Fabiyi to n ja fun ẹtọ Baba Ijesha ni Panti.
Ṣaaju ni Iyabo Ojo ati Yomi Fabiyi ti n sọrọ sira wọn nitori ọrọ ẹsun ṣiṣe ọmọde jakujaku ti wọn fi kan Olarewaju Omiyinka ni agọ ọlọpaa ni Panti.
Lati bi ọjọ diẹ sẹyin, ni Fabiyi ti n fọnrere lori ayelujara pe Iyabo ati Princess ti leri lati pa Baba Ijẹsha, to ba fi kuro ni ahamọ ọlọpaa.
Ṣugbọn ninu ọrọ kan to kọ si ori Instagram rẹ ni owurọ Ọjọbọ, Ọgbẹni Fabiyi sọ pe Iyabọ ti bẹ oun lori ayelujara Whatsapp.
Botilẹ jẹ pe Fabiyi fi awọn aworan kan sita, to ni o jẹ akọsilẹ ọrọ laarin oun ati Iyabọ.
Ninu aworan naa lo ti han pe 'Iyabo' sọ pe oun ko darukọ Yọmi ninu fidio oun, gbogbo awọn akẹẹgbẹ oun ni oun n ba wi.Kí ló mú Yomi Fabiyi àti Iyabo Ojo máa sá aṣọ ìdọ̀tí ara wọn síta?
Ko pẹ ti eyi jade sita, ni Iyabọ naa fesi, to ni kii ṣe ọrọ̀ nipa ẹbẹ ti oun bẹ nikan lo yẹ ki Yomi fi sita faye ri.
Ansoogun jagunjagun Iresa Adu Ogbomoso tó máa ń bínú gba ẹbọ- Oloye James Olawale
Iyabo ba kuku lọ ya fọto gboogbo ọrọ wọn lori Whatssap si ori ayelujara rẹ to si ni oun ko ba Yomi ta eyin rara, ki gbogbo aye wo awọn ọrọ to jẹyọ laarin awọn mejeji ni kọkọ.
Labẹ awọn aworan naa lo tun kọ ọrọ si pe o ya oun l'ẹnu pe Fabiyi ṣi n sọ isọkusọ nipa ọmọ ti wọn ni Baba Ijẹsha ba lopọ, lẹyin to pari ija pẹlu oun.
Fabiyi sọ pe Iyabọ ti jẹwọ, to si tun bẹbẹ fun bo ṣe mu ki awọn eeyan o bú oun lori ayelujara.
Yoruba bọ wọn ni a n j'Ekuru ọrọ ko tan lawo, iwọ tun n gbọn ọwọ rẹ sii. lo difa fun ọrọ ẹsun ti wọn fi kan gbajugbaja oṣere apanilẹrin Olanrewaju Omiyinka ti ọpọ mọ si Baba Ijesha lori ifipabọmọde lo.
Amọ kaka ki ewe agbọn dẹ lori  ọrọ yii niṣe lo n pele sii loju ati lọkan awọn eeyan torii bi awọn akẹgbẹ Baba Ijesha meji ṣe gbe ọrọ naa ka ori ti wọn si n gba a bi ẹni n gba igba ọti.
Bẹẹ gan-an ni ọrọ ri laarin oṣere Nollywood meji, Yomi Fabiyi ati Iyabọ Ojo.
Oríṣun àwòrán, Instagram/yomi fabiyi/iyabo ojo
Eyi ko ṣẹyin ija ori ayelujara to ti n waye laarin awọn mejeeji lati bi ọsẹ mẹta ti ọwọ titẹ akẹẹgbẹ wọn, Omiyinka James Baba Ijesha, fun ẹsun ifipabanilopọ.
Ọjọru ni Iyabo Ojo tun fi lẹta kan sita lori ayelujara, eyi to ṣafihan pe o ti pe Yọmi ni ẹjọ fun ẹsun ibanilorukọ jẹ.
Miliọnu lọna ọgọrun Naira si lo sọ pe oun yoo gba lọwọ Yọmi gẹgẹ bi owo itanran.
International Nurses Day 2021: Wo ìpèníjà àti àǹfàní inú iṣk nọ́ọ̀sì- Adetokunbo Shaba
Kí ló mú Yomi Fabiyi àti Iyabo Ojo máa sá aṣọ ìdọ̀tí ara wọn síta?
Iyabo Ojo àti  Yomi Fabiyi tú ara wọn fó  lórí ọ̀rọ̀ ọlọ́rọ̀
Fabiyi ni  oun n tiraka lati ko ara oun ni ijanu, ki oun ma ba kọlu Iyabọ Ojo.
"Iyabọ, mo fẹran rẹ pupọ, mo si n tiraka lati ko ara mi ni ijanu, ki n ma kọlu ọ.
Ti mo ba gba ẹ mu, wa a ri were."""
Ọgbẹni Fabiyi ṣalaye pe ẹjẹ apapọ ọkunrin ati obinrin ni oun, eyi to sọ oun di akanda ẹda.
O ni ki Iyabọ o ma ṣe jẹ ki ẹnikẹni ti i, nitori pe to ba kọja aaye rẹ, oun yoo pa oju da si.
"Yomi ti pe akọle sinima tuntun to fẹ gbe jade ni ""Ọkọ Iyabọ"" to si ni awọn to ba gbagbọ pe oun le ṣe e ki wọn o bẹrẹ si ni rọ owo wọle si asunwọn owo oun."
Akomolede ati Aṣa lori BBC Yoruba: Wo díẹ̀ nípa àbùdá Olodumare- Iyabo Ayinde
Yoruba maa n gbadura pe ki Eledua maa jẹ ki wọn fi ọrọ lọrọ gba wa lẹnu.
Awuyewuye lori ọrọ osẹre tiata Yoruba, James Olanrewaju Omiyinka ti ọpọ mọ si Baba Ijesha ko ti tan sibẹ o.
Ti ẹ ko ba gbagbe, ero awọn akẹgbẹ Baba Ijesha sọtọtọ lati ti ọrọ naa ti ṣẹlẹ.
Eyi lo mu ki Iyabo Ojo ati Yomi Fabiyi tako ara wọn lori ọrọ naa.
Bi Iyabo ṣe duro lori ẹsẹ rẹ pe idajọ ododo gbọdọ waye lori ọrọ naa ni Yomi naa n sọ pe ki awọn eeyan maa tii da Baba Ijesha lẹjọ.
Koda, Yomi tun ṣe iwọde pẹlu awọn eeyan kan l'Ọjọru lati tako bi awọn ọlọpaa ko ṣe ti gba ki wọn gba beeli Baba Ijesha ni ahamọ to wa.
Ṣugbọn tuntun lori ọrọ naa bayii ni pe Iyabo ti gbe Yomi lọ si ileẹjọ lori ẹsun ibanilorukọ jẹ.
Ninu iwe ipẹjọ ti agbẹjọro Iyabo fi ṣọwọ si Yomi, o ṣalaye nibẹ pe Yomi gbọdọ tọrọ aforijin.
Bakan naa ni agbẹjọro Iyabo sọ pe Yomi ni lati san owo itanran fun awọn ọrọ kobakungbe ti o sọ si Iyabo.
Agbẹjọro Iyabo tun sọ pe Yomi n gbe beba ti orukọ Iyabo wa nibẹ pẹlu oriṣiiriṣii ẹsun to fi kan Iyabo.
Agbẹjọro Iyabo ni gbogbo ẹsun ti Yomi fi kan Iyabo, ko si otitọ kankan ninu rẹ.
O ni arosọ, irọ ati eke ni gbogbo ohun ti Yomi n sọ lati le ba orukọ Iyabo jẹ ni gbogbo rẹ.
Yomi naa gbe soju opo Instagram rẹ pe Iyabo Ojo ati Princess ṣeleri pe awọn yoo pa Baba Ijesha ti wọn ba gba beeli rẹ
Baba Ijesha si wa ni atimọle awọn ọlọpaa niluu Eko lori ẹsun ifipabanilopọ pẹlu ọmọdebinrin adẹrinpoṣonu, Princess.
Eid Al Fitri Public holidays: Wo àwọn ìpínlẹ̀ tó kéde àfikún ọjọ́ ìsinmi ọdún ìtúnu awẹ̀ síi
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Awọn ipinlẹ kan lorilẹ-ede Naijiria ti ṣafikun ọjọ isinmi fun ọdun itunu aawẹ Ramadan ti 2021 siwaju sii.
Awọn ipinlẹ naa fi oni ọjọ Eti, ọjọ kẹrinla, oṣu karun un kun ọjọ meji ti ijọba apapọ kọkọ kede tẹlẹ, iyẹn ọjọru, ọjọ kejila ati ọjọbọ, ọjọ kẹtala, oṣu karun un.
Gomian ipinlẹ Kano, Abdulahi Ganduje lo kọkọ kede pe oun ti fi ọjọ Eti kun isinmi awọn eniyan ipinlẹ naa ni eyi ti wọn yoo fi fi ọjọ mẹta sami ayẹyẹ ipari awẹ Ramadan tọdun 2021.
Ogbeni Muhammed Garba Shehu to jẹ kọmiṣọnna ifitonileti ati iroyin gbogbo fun ipinlẹ Kano lo kọkọ fi eyi sita.
International Nurses Day 2021: Wo ìpèníjà àti àǹfàní inú iṣk nọ́ọ̀sì- Adetokunbo Shaba
Lẹyin naa ni ijọba ipinlẹ Jigawa naa kede itẹsiwaju isinmi pe ki ti ipinlẹ naa di ọjọ mẹta.
Hussaini Ali Kila to jẹ olori awọn oṣiṣẹ ni ipinlẹ Jigawa lo fi atẹjade sita lati kede isinmi ọjọ Eti kun eyi ti ijọba apapọ kede tẹlẹ.
Ansoogun jagunjagun Iresa Adu Ogbomoso tó máa ń bínú gba ẹbọ- Oloye James Olawale
Wọ́n ti kírun ọdún ìtúnu àwẹ̀ n'Ibadan
L'Ọjọru ni Imam agba ilẹ Ibadan, Sheikh AbdulGaniyu Abubakry Agbotomokekere le iwaju irun itunu awẹ ni gbagede Yidi to n bẹ ni gbegbe Agodi nilu Ibadan.
Igbakeji gomina ipinlẹ Ọyọ, Rauf Olaniyan ati Olubadan ilẹ Ibadan, Oba Saliu Adetunji wa lara awọn eeyan pataki to pejupesẹ sibi irun naa.
Adura yii waye t'oun ti bi ajọ to n mojuto ọrọ ẹsin Islam lorilẹede Naijiria, 'Nigerian Supreme Council for Islamic Affairs (NSCIA)' ṣe paa laṣẹ wi pe ki awẹ Ramadan tẹsiwaju nitori osupa Shawal ko yọ ni alẹ ana.
Aṣẹ yii lo mu ki awẹ di ọgbọn.
Ọrọ kan ti wọn fi lede loju ọpọ ikansiraẹni Facebook Sheik Agbotomokekere lana lo kede rẹ wi pe awẹ Ramadan ti pari l'ọjọ Iṣẹgun, ọdun itunu awẹ yoo si waye l'Ọjọru.
Gẹgẹ bi ileri ti o ṣe, Sheik Agbotomokekere le iwaju awọn Musulumi kan lọ si Yidi, ṣugbọn pupọ ninu awọn adari ẹsin bi i Aarẹ Musulumi ilẹ Yoruba, Edo ati ipinlẹ Delta, Alhaji Dawud Makanjuola Akinola De-Damak, gomina tẹlẹri nipinlẹ Ọyọ, Oloye Rashidi Ladoja ati awọn mii ko si nibi ipejọpọ naa.
Bo tilẹ jẹ wi pe awọn eeyan pọ nibi ipejọpọ naa, onka awọn to kirun ọdun itunu awẹ nibẹ ko to iye awọn to n wa tẹlẹri. Iredi sini wi pe awọn eeyan kan ṣi gba awẹ titi di oni.
Eleyii ki i ṣe igba akọkọ ti iru igbese yii yoo waye, asaaju ẹsin yii kede iru igbese yii ni ọdun mẹta sẹyin, botilẹ jẹ wi pe awọn alaṣẹ ni o yẹ ki awẹ tẹsiwaju.
Eid-el-Fitri security: Ọ̀gá àgbà ọlọ́pàá ní Nàìjíríà pàṣẹ ki wọn kó ọ̀pọ̀ ọlọ́pàá síta fún ìtúnu àwẹ̀
Oríṣun àwòrán, @Nigeria Police
Ọga agba ọlọpaa lorilẹ-ede Naijiria, Alkali Usman Baba ti paṣẹ ti paṣẹ pe ki wọn da ọlọpaa sita kaakiri Naijiria lọpọ yanturu lọna ati mu ki okun abo o tubọ gbopọn lasiko itunu awẹ to wa lode.
Ninu ọrọ ti alukoro apapọ ileeṣẹ ọlọpaa, Frank Mba fi sita, ọga agba ọlọpaa ni Naijiria ti kan si gbogbo awọn amugbalẹgbẹ rẹ, awọn kọmiṣọnna ọlọpaa ni ipinlẹ pẹlu awọn lọgalọga lẹka ileeṣẹ ọlọpaa lati gbe igbesẹ gbogbo to ba yẹ fun idaabobo bo araalu lasiko ọdun yii.
Ọga ọlọpaa Usman Baba nilootọ ọrọ abo ti dagun lorilẹede Naijiria sibẹ kii ṣe ohun to kọja bibori.
Bakan naa lo tun fọkan awọn ọmọ Naijiria balẹ pe ileesẹ ọlọpaa labẹ idari oun ko ni ja wọn ni tan mọnnn nipa ririi daju pe ojuutu wa si ọrọ abo to mẹhẹ ni Naijiria.
Ansoogun jagunjagun Iresa Adu Ogbomoso tó máa ń bínú gba ẹbọ- Oloye James Olawale
O wa ro awọn ọmọ Naijiria lati fọwọsowọpọ pẹl'awọn ọlọpaa lọna ati tu aṣiri gbogbo awọn oniṣẹ ibi lawujọ pẹlu ibuba wọn.
Lori ipele kẹrin ilana igbogun ti ajakalẹ arun COVID-19 ni Naijiria, iyẹn Level-4 protocol ti ijọba apapọ ṣẹsẹ kede.
Ọga agba ọlọpaa lorilẹ-ede Naijiria naa rọ awọn ọga ọlọpaa ni ipinlẹ lati ṣiṣẹ tọ ilana tuntun naa lẹyin nipa ririi dajupe awọn eeyan ni ipinlẹ koOwa wọn tẹlẹ ilana ti ijọba apapọ gbe kalẹ lati dena ajakalẹ
COVID-19 lẹẹkan sii ni Nigeria.
Akomolede ati Aṣa lori BBC Yoruba: Wo díẹ̀ nípa àbùdá Olodumare- Iyabo Ayinde
Student commits suicide: Ṣé lóòtọ́ọ́ ni akẹ́kọ̀ọ́ fásítì Akungba gbẹ̀mí ara rẹ̀?
Oríṣun àwòrán, others
Iroyin to lu ori ayelujara ni pe akẹkọọ nipa eto oṣelu ni fasiti ipinlẹ, ni ipinlẹ Ondo to wa niluu Akungba Akoko, Feranmi Fasunle Omowunmi.
Feranmi ti nọmba igbaniwọle rẹ si ile ẹkọ naa jẹ 180503006 ni iroyin sọ pe o mu oogun peku peku lati pa ara rẹ l'Ọjọru.
Ko si ẹni to le sọ pato ohun to ṣe okunfa iku ọdọmọbinrin naa ṣugbọn awọn kan sọ pe o ṣeeṣe ki o gbẹmi ara rẹ lẹyin ti ibaṣepọ rẹ pẹlu ọrẹkunrin rẹ fori ṣanpọn.
Ṣugbọn awọn ọrẹ to sun mọ ṣalaye fawọn akọroyin pe irọ nla lọrọ naa nitori awọn ko mọ ọ mọ ọkunrin kankan lati igba to ti wọle si ile ẹkọ naa.
Iroyin sọ pe awọn ọrẹ Feranmi lo ri pe o ti mu oogun ti o si n pọkaka iku ninu ile rẹ.
Lati ibẹ ni wọn ti gbe e lọ si ile iwosan fun itọju awọn eleru ti sun igi.
International Nurses Day 2021: Wo ìpèníjà àti àǹfàní inú iṣk nọ́ọ̀sì- Adetokunbo Shaba
A gbọ wi pe awọn obi rẹ wa nile iwosan nibi ti o ti pada gbẹmi mi.
Awọn alaṣẹ ile ẹkọ naa ṣalaye pe otitọ ni iṣẹlẹ ọhun ṣẹlẹ, amọ ko si ẹni to le sọ pe ohun to faa to fi pa ara rẹ gan na niyii.
Nigba ti BBC Yoruba ba ileeṣẹ ọlọpaa ipinlẹ Ondo sọrọ, agbẹnusọ ileeṣẹ ọlọpaa, Teo Ikoro sọ pe awọn naa ti ka nipa iṣẹlẹ ọhun lori ayelujara.
Ansoogun jagunjagun Iresa Adu Ogbomoso tó máa ń bínú gba ẹbọ- Oloye James Olawale
Ṣugbọn Ọgbẹni IKoro ṣalaye ko si ẹni ti o tii mu ọrọ naa wa sọdọ awọn ọlọpaa.
Ọgbẹni Ikoro ni ileeṣẹ ko le mu ẹnikẹni ti eeyan ba gba ẹmi ara rẹ.
O ni ileeṣẹ ọlọpaa le bẹrẹ iwadii ti awọn ẹbi ẹni to ba p ara ba fu ra si ẹnikan pe oun lo wa ni idi rẹ loku.
Eid al-fitr 2021: Àwọn míì ṣọdún ìtúnu àwẹ̀ lónìí Ọjọ́bọ̀ n'Ibadan lẹ́yìn táwọn kan kírun lánàá
Oríṣun àwòrán, Other
Ọpọlọpọ awọn eekan ninu ọṣelu ati awọn Musulumi to gba awẹ di ọgbọn ọjọ lo pejupesẹ si awọn ọkanojọkan Yidi nilu Ibadan ati jakejado ipinlẹ Ọyọ lati ṣe ajọyọ ọdun itunu awẹ lonii.
Oríṣun àwòrán, Other
Lara awọn eeyan pataki to kopa nibi irun ọdun itunu awẹ ni Mọṣalaṣi nla to n bẹ ninu ọgba fasiti ilẹ Ibadan ni Gomina tẹlẹri nipinlẹ Ọyọ, Sẹnetọ Rasheed Ladoja, Sẹnetọ aarin gbungbun Ọyọ, Teslim Folarin.
Kí ló mú Yomi Fabiyi àti Iyabo Ojo máa sá aṣọ ìdọ̀tí ara wọn síta?
Lẹ́yìn ìwọ́de Yomi Fabiyi, ọlọ́pàá sọ ìdí tí wọ́n kò fi gba béélì Baba Ijẹsha, àti ìgbà tó ṣe é ṣe kí wọ́n ó fi sílẹ̀
Wọ́n ti kírun ọdún ìtúnu àwẹ̀ n'Ibadan
Oríṣun àwòrán, Other
Sẹnetọ agbegbe ariwa Ọyọ, Abdulfatai Buhari, Kọmisana tẹlẹri fun ọrọ ayika nipinlẹ Ọyọ, Oloye Lowo Obisesan ati bẹẹ bẹẹ lọ.
Oríṣun àwòrán, Other
Irun ọdun itunu awẹ waye lonii lẹyin ti Imam agba ilẹ Ibadan, Sheik Agbọtọmọkekere ko awọn Musulumi  kan ṣodi n'Ibadan lati ṣe adua itunu awẹ l'Ọjọru.
Botilẹ jẹ wi pe irun naa waye ni Yidi to n bẹ ni agbegbe Agodi nilu Ibadan, awọn eeyan to kopa nibẹ ko pọ tọ iye awọn eeyan to kirun ọdun itunu.
Wọnyii ni aworan bi ọdun itunu awẹ ṣe lọ ni ilu Ibadan.
Oríṣun àwòrán, Other
Oríṣun àwòrán, Other
Oríṣun àwòrán, Other
Oríṣun àwòrán, Other
Oríṣun àwòrán, Other
Ondo kidnap: Fowokemi Ogedengbe, ọmọ Pasitọ Deeper Life tí wọ́n jígbé l'Ondo ní àwọn ajínigbé kò tíì pe àwọn
Awọn ẹbi ati ara Pasitọ ijọ Deeper Life ti wọn jigbe lọ ni ilu Akure, Otamayomi Ogedengbe ni awọn ko i tii gbọ ohun kankan lati ọdọ awọn janduku to ji i gbe lọ.
Iroyin to lo ori ayelujara ni pe awọn ajinigbe ọhun beere fun ọgbọn miliọnu naira lalẹ Ọjọru nigba ti wọn pe ẹbi pasitọ naa.
Iroyin mii tiẹ sọ pe awọn janduku ajinigbe pawo naa sọ pe owo itusilẹ naa ko gbọdọ din ni ọgbọn miliọnu.
Ṣugbọn ọmọbinrin pasitọ naa, Fowokemi Ogedengbe sọ fun BBC Yoruba pe irọ funfun balau ni iroyin tawọn kan n gbe kiri.
Fowokemi ṣalaye pe ẹbi pasitọ Deeper Life ọhun ko ti gbọ lati ọdọ awọn ajinigbe titi di akoko yii.
Ansoogun jagunjagun Iresa Adu Ogbomoso tó máa ń bínú gba ẹbọ- Oloye James Olawale
Ọmọ baba naa ni: ''A ko mọ ibi ti awọn to kọ iroyin pe wọn ti tu u silẹ ti gbó iroyin naa.
Bi emi ṣe rii ka lori ayelujara niyẹn, amọ ko si otitọ kan ninu iroyin naa.
International Nurses Day 2021: Wo ìpèníjà àti àǹfàní inú iṣk nọ́ọ̀sì- Adetokunbo Shaba
A ko mọ ibi ti baba mi wa bayii nitori awọn ajinigbe naa ko tii pe wa,'' Fowokemi lo ṣalaye bẹẹ.
O rọ awọn eeyan lati maa fi adura ran idile awọn lọwọ wi pe ki awọn janduku ajinigbe naa le fi olori ile wọn silẹ.
Ọmọbinrin Pasitọ Ogedengbe, Fowokẹmi ni inu ipaya ati ibẹru ni awọn wa nitori awọn ajinigbe naa ko tii kan si wọn.
O ni baba oun ni ilera to si ni awọn oogun ti oun lo ni ojoojumọ, amọ lati igba ti wọn ti jigbe lọ yii awọn ko gbọ nkankan.
Ọjọ Kẹwaa, Oṣu Karun un ni wọn ji pasitọ Godwin Mayomi Ogedengbe lẹyin to pari isin ninu ile ijọsin rẹ ni nkan bi aago mẹsan an alẹ.
Akomolede ati Aṣa lori BBC Yoruba: Wo díẹ̀ nípa àbùdá Olodumare- Iyabo Ayinde
Oduduwa Nation: Ẹ̀yìn tí ẹ̀ ń pè fún Yoruba Nation, òpè ní yín, ẹ kò ní ìmọ̀ - Ladoja
Oríṣun àwòrán, Twitter
Gomina ipinlẹ Ọyọ tẹlẹ, Rasheed Ladọja ti kilọ fun awọn to n beere fun idadurọ orilẹede Yoruba, Oduduwa Nation lati jawọ nitori ibẹrẹ ogun ni yoo jẹ.
Ladọja lo sọrọ nibi adura Eid lasiko ọdun Ramada ni ilu Ibadan.
Ninu ọrọ rẹ, Ladọja ni ibeerẹ ogun ni ọpọlọpọ eniyan ma n mọ, wọn ki n mọ opin rẹ.
O fikun wipe awọn to n beere fun Oduduwa Nation ko mọ itunu rẹ ati ohun ti yoo jasi fun awọn eniyan.
''Ko si ẹni to mọ bi ogun to bẹ silẹ ni Syria ṣe bẹrẹ, ti wọn si ti wa lẹnu rẹ fun ọpọlọpọ ọdun bayii lai tii si ọna abayọ si ogun naa, ti ọpọlọpọ ẹmi si ti ba iṣẹlẹ naa lọ''
''Adura to yẹ ki a maa gba ni wi pe ki Ọlọrun fun wa ni adari to dara lorilẹede Naijiria''.
Ansoogun jagunjagun Iresa Adu Ogbomoso tó máa ń bínú gba ẹbọ- Oloye James Olawale
Ladoja ni: ''Nigba miran Ọlọrun si le e fun wa ni awn adari ti ko dara lati koju awọn ipenija kọọkan, to ba jẹ igbayi ni a fẹ yapa kuro ni ara Naijiria, o yẹ ki a ro o daadaa pẹlu agbekalẹ to danmọran''.
''Ati wi pe ta lo sọ fun yin wi pe awọn ara ẹya Ariwa naa fẹ duro pẹlu Naijiria, awọn Guusu naa wa nibẹ ti wọn fẹ lọ, amọ suuru ni gbogbo rẹ gba''.
Oríṣun àwòrán, Twitter
Bakan naa ninu ọrọ rẹ ni Rasheed Ladọja ti kesi awọn darandaran lorilẹede Naijiria pe iṣe wọn ko ba ti igbalode mu mọ kaakiri agbaye.
Ladọja ni ko si ibi ti wọn ti n da ẹran kaakiri igboro, ti wọn si n ba oko oloko jẹ.
Ladọja ni opin gbọdọ deba dida ẹran kaakiri igboro nitori ipaniyan to n mu dani loore-koore.
O gboriyin fun  awọn gomina kaakiri ipinlẹ ni Naijiria to ti sọ di ofin pe ko gbọdọ si dida ẹran kaakiri igboro mọ ni ipinlẹ wọn.
Amọ, o ni awọn gomina naa gbọdọ ri daju pe awọn eniyan n tẹle ofin naa, nipa fifi idi rẹ mulẹ ni awọn igberiko naa.
International Nurses Day 2021: Wo ìpèníjà àti àǹfàní inú iṣk nọ́ọ̀sì- Adetokunbo Shaba
ICPC ń wá ọkọ ọmọ Buhari àtàwọn méjì míì lórí ṣíṣe $65,000,000 kúmọ kùmọ
Oríṣun àwòrán, ICPC/Screenshot
Ajọ ICPC to n gbogun ti iwa ajẹbanu atawọn iwa ọdran mii ti kede pe awọn n wa ọkọ ọmọ Aarẹ Muhammadu Buhari, Gimba Yau Kumo,atawọn meji mii lori ẹsun iṣowo ilu kumọ kumọ.
Ẹsun ti ajọ naa fi kan wọn ni pe wọn na miliọnu marunlelọgọta owo dọla baṣu baṣu.
Ọdun 2016 ni Ọgbẹni Yau Kumo ti ICPC n wa yii ṣe igbeyawo pẹlu ọmọbinrin keji Aarẹ Buhari.
ICPC ni ajọ to ri si iwa ajẹbanu tawọn oṣiṣẹ ọba ba hu lẹnu iṣẹ.
Gẹgẹ bi atẹjade ti ajọ naa fi soju opo alatagba wọn, ICPC ni Tarry Rufus, Bola Ogunsola ati Yau Kumo lawọn n wa bayii.
Ẹsun ti wọn kan wọn niṣe pẹlu iwa ajẹbanu lori owo ileegbe awọn oṣiṣẹ.
Oríṣun àwòrán, ICPC
Eto ti ijọba apapọ gbe kalẹ ni eto ileegbe ti ko ni gara fawọn fawọn oṣiṣẹ.
Ilu Daura to jẹ ile Aarẹ Buhari ni Yau kumo ti ṣe igbeyawo pẹlu Fatima to jẹ ọmọbinrin Buhari.
Yau Kumo  ni ọga agba banki ayanilowo kọle ti ijọba apapọ tẹlẹ, banki lo si n ṣamojuto owo tawọn oṣiṣẹ n da fun ileegbe.
Iniubong Umoren: Àwọn ọlọ́pàá fojú afurasí to ṣekúpa Iniubong Umoren tó ń wá iṣẹ́ hàn
Ọjọ ti a ba ku laa dere, eniyan o sunwọn laaye.
Lẹyin ti wọn sin oku Iniubong Umoren ti wọn ṣekupa nibi to ti wa iṣẹ lọ nipinlẹ Akwa Ibom tan, ileeṣẹ ọlọpaa ipinlẹ naa tiu ṣafihan afurasi to sẹkupa a, Akpan 'Frank' Uduak.
Ọga agba ọlọpaa nipinlẹ Akwa Ibom, Andrew Amiengheme ṣalaye pe awọn ọlọpaa fi oju Akpan han nitori ahesọ ọrọ to n lọ kaakiri lori ayelujara pe o ti ku si ahamọ awọn ọlọpaa.
''Awọn tiẹ sọ pe o ti gbẹmi ara rẹ ni ahamọ ọlọpaa, awọn ni ṣokoto to wọ lo fi pa ara rẹ.
Mi o mọ ibi ti afurasi to wa ni ahamọ yoo ti fi ṣokoto to wọ gbẹmi ara rẹ.
Ọpọlọpọ eeyan lo ti pe mi lori ago lati beere bo ya awọn ọlọpaa fẹ tọ oju ẹjọ naa mọlẹ ni.
Idi niyii ti a fi pe apero awọn akọroyin ki onikaluku le fi oju ara wọn ri i pe o si wa ni atimọle ọlọpaa,'' ọga ọlọpaa ṣalaye.
Kọmiṣọnna ọlọpaa ipinlẹ Akwa Ibom ni o ṣeni laanu pe ayelujara to yẹ kawọn eeyan maa lo lati ran awọn ọlọpaa lọwọ ni wọn fi tabuku ọlọpaa.
O ni ẹjọ ti wọn kọkọ mu wa ni ẹjọ ijinigbe eleyii tawọn ọlọpaa ṣi bẹrẹ iṣẹ lori rẹ ni kiakia.
Ọga ọlọpaa Amiengheme tun ṣalaye pe DPO agọ ọlọpaa Uruan tawọn kan sọ pe o lọwọ ninu iṣẹlẹ naa ko mọ ohun kan nipa rẹ.
O ni DPO naa kan darapọ mọ ẹbi Frank lati ri pe o pada wale lati ilu Oron to sa lọ ni.
Kọmiṣọnna ọlọpaa ipinlẹ Akwa Ibom ni iwadii ṣi n lọ lọwọ lori iṣẹlẹ naa niwọn igba ti ọrọ naa ko tii de ileẹjọ.
#PantamiMustGo: Ajàfẹ́tọ́, Aisha Yesufu sọ ìdí tí kò fi lè so nọ́mbà fóònù rẹ̀ mọ́ nọ́mbà ìdánimọ̀ àpapọ̀ Nàìjíríà, NIN
Oríṣun àwòrán, Twitter/ aisha shehu
Ajafẹtọ ọmọniyan ni, Arabinrin Aisha Yesufu ti sọ pe ko sohun to jọọ o.
O ni oun ko le e so nọmba idanimọ apapọ ilẹẹ Naijiria, NIN mọ nọmba ibanisọrọ oun layelaye gẹgẹ bi ijọba apapọ Naijiria ṣe n fọnrere rẹ bayii.
"Aisha Yesufu ni, siso oju opo numba ibanisọrọ oun mọ nọmba idanimọ apapọ NIN ""yoo mu ki awọn iroyin to ṣe koko nipa oun wa ni ikawọ awọn elegbe ati alabaṣiṣẹpọ awọn agbesunmọmi"" lorilẹ-ede Naijiria."
Aisha fi eleyi han loju opo Twitter rẹ nigba ti oun naa n da si ọrọ kan to n ja loju opo Twitter labẹ koko ọrọ #PantiMustGo.
Nibẹ ni awọn ero ori Twitter kan ti n pe fun iyọkuro nipo minisita fun ibanisọrọ lorilẹ-ede Naijiria, Isa Pantami.
"Ẹ jẹ ki n sọ ọ laifọtape pe, emi ko lee so nọmba idanimọ apapọ ilẹẹ Naijiria, NIN mọ nọmba ibanisọrọ mi o!
O san ki n kuku maa ni ẹrọ ibanisọrọ rara ju ki n finufindọ ko awọn iroyin to ṣe koko nipa oun wa ni ikawọ awọn elegbe ati alabaṣiṣẹpọ awọn agbesunmọmi #PantamiMustGo"
Ipe fun iyọkuro nipo minisita fun ibanisọrọ lorilẹ-ede Naijiria, Isa Pantami n jo bi ina ẹrun lori ayelujara.
Eyi ko ṣehin nitori ọrọ iwasu kan to gbe kalẹ lawọn ọdun diẹ sẹyin ninu eyi to ti n ṣe atilẹyin fun awọn ẹgbẹ agbesunmọmi bii Al-Qaeda ati Taliban.
Amọṣa ileeṣẹ arẹ ti sọ pe ko sọrọ lori rẹ nitori nigba ti minisita Pantami sọ ọrọ yii ọmọde lo n ṣe e, o si ti yipada lasiko yii.
Ansoogun jagunjagun Iresa Adu Ogbomoso tó máa ń bínú gba ẹbọ- Oloye James Olawale
Osun state: Èèyàn márùn ún kó sí gbaga ọlọ́pàá lórí ikú ẹ̀ni ọdún 42 kan l'Ẹ́dẹ
Oríṣun àwòrán, other
Ọwọ awọn ọlọpaa ni ipinlẹ Ọṣun ti tẹ awọn afurasi ọdaran marun un kanlori iku ẹni ọdun mejilelogoji kan ti orukọ rẹ n jẹ Wakili Ọlayiwọla ni agbegbe Arulogun ni ilu Ẹdẹ l'Ọjọbọ.
Gẹgẹ bi awn eeyan ti iṣẹlẹ naa ṣoju wọn ṣe sọ, awọn janduku kan ti wọn to ọgbọn ni iye kslu ile oloogbe naa ti wọn si rọ ojo ibọn lee.
Ileeṣẹ ọlọpaa, ninu atẹjade kan ti alukoro ọlọpaa ni ipinlẹ naa, Yẹmisi Ọpalọla fi sita awọn eeyan meji kagbako iku ojiji lọwọ awọn janduku naa ti wọn si ti gbe oku wọn si ile igbokupamọsi.
Iganmu shanty demolition: Oníṣẹ́ ibi pọ̀ tó ń ṣọṣẹ́ lábẹ́ afárá Iganmu yìí ti pẹ́ ṣùgbọ́n.
Bakan naa ni wọn ni wọn ka awọn ohun ija oloro bi ibọn oloju kan, ibọn ṣakabula kan, ọta ibọn mẹjọ, aake, ada, ogun abẹnugọngọ ati alupupu marun.
Awọn iroyin abẹle tun fi kun un pe awọn afurasi ọdaran naa tun da ina sun  ọkọ ayọkẹlẹ Toyota corola to jẹ ti ọkunrin naa.
India, Coronavirus: Ìtọ́jú aláìsàn ló jẹ́ mi lógún nítorí ètò ìlera wa mẹ́hẹ- Nọ́ọ̀sì Kama
Yoruba Nation: Kókó mẹ́ta tí Sunday Igboho sọ nípa ìbo 2023 níbi ìwọ́de l‘Osogbo
Oloye Sunday Adeyẹmọ ti ọpọ mọ si Sunday Igboho, ti ṣalaye fun awọn to n kigbe fun idasilẹ orilẹede Yoruba, Yoruba Nation, pe oun atawọn ẹlẹgbẹ oun ko ni gba eto idibo laaye mọ ni ilẹ Yoruba, titi di igba ti ẹkun naa ba gba ominira rẹ.
Lọjọ Satide ni Igboho sọrọ yii lasiko to fi n ba awọn to n pe fun idasilẹ orilẹede Yoruba sọrọ nibi iwọde itagbangba kan to waye nilu Osogbo.
Igboho tun rọ awọn ọmọlẹyin rẹ lati dẹkun nina ika aleebu si awọn gomina ipinlẹ lẹkun iwọ oorun guusu Naijiria nitoripe gbogbo wọn lo duro lẹyin ipe ti wọn n ja fun.
O ni nitori ibẹru pe ki ijọba apapọ o ma gbẹsẹ le owo ipin oṣooṣu to n kan ijọba ipinlẹ wọn, ni wọn ṣe ṣe ẹnu ni mẹnumọ.
'Ẹ kálọ sí ìlú mi'... Ètò ńlá tó bẹ̀ sílẹ̀ kìjà lórí BBC Yorùbá
Bakan naa lo bu ẹnu atẹ lu bi awọn oṣiṣẹ aṣọbode kan ṣe yinbọn pa awọn olugbe ilu Isẹyin kan lọjọ diẹ sẹyin.
O fikun pe asiko to fun ijọba lati fopin si ipẹjọ awọn ọmọ ẹgbẹ OPC to mu Isikilu Wakili, afurasi ti wọn fi ẹsun ọpọlọpọ iṣẹlẹ ijinigbe kan ni ilu Igangan ati agbegbe rẹ.
O fi kun pe aifi panpẹ ofin gbe awọn ọdaran darandaran to n da wahala silẹ, ti mu ki aya tubọ ko wọn lati maa hu awọn iwa kotọ kaakiri orilẹede Naijiria.
Ẹwẹ, fidio kan tun fara han lori ayelujara lẹyin iwọde naa, eyi to ṣafihan bi awọn ọmọlẹyin Sunday Igboho ṣe mu eeyan kan ti wọn fura si pe oṣiṣẹ ileeṣẹ ọtẹlẹmuyẹ DSS ni.
Face Transplant: DiMeo ṣùn lásìkò tó n wa ọkọ̀ lálẹ́, ló bá jóná nígbà tí ọkọ̀ gbiná
Arakunrin naa to pe ara rẹ ni Idowu Ọlayinka ṣalaye ninu fidio naa pe, ijọba apapọ loun n ba ṣiṣẹ ati pe ọfiisi awọn ni wọn ti ni ki oun lọ mu nọmba ọkan lara awọn ọkọ to n tẹle Sunday Igboho.
Ileeṣẹ DSS ko tii sọ ohunkohun boya lootọ tabi irọ ni arakunrin naa jẹ ara awọn oṣiṣẹ rẹ.
Oloye Sunday Igboho ati ogunlọgọ awọn eeyan to n ja fun ominira ilẹ Yoruba, Yoruba Nation, ti ṣe iwọde niluu Osogbo, to jẹ olu ilu ipinlẹ Osun.
"Awọn oluwọde naa to bẹrẹ iwọde ọhun laarọ ọjọ Abamẹta gbe oniruru kaadi lọwọ ti wọn kọ awọn akọle kan si bii ""A fẹ ominira"" ati ""Ọmọ Yoruba ile ya"" ati bẹẹbẹẹ lọ."
Wọn bẹrẹ iwọde naa lati agbegbe Ogo-Oluwa, titi de Olaiya, Freedom Park, Old Garage atawọn agbegbe mii to ṣe pataki niluu Osogbo.
Nigba to n sọrọ nibi iwọde naa, Sunday Igboho sọ pe asiko ti to ki ilẹ Yoruba bọ lọwọ awọn amunisin to n pa awọn eeyan ilẹ rẹ lai bikita.
Ọgọọrọ awọn agbofinro lo peju sibi iwọde naa lati pese eto abo to peye.
Lara awọn agbofinro to peju sibi iwọde ọhun ni awọn oṣiṣẹ ọtẹlẹmuyẹ DSS, ileeṣẹ ọlọpaa, awọn oṣiṣẹ abo araẹni labo ilu, awọn ọlọde ilu, ati bẹẹ beẹ lọ.
Irufẹ iwọde bẹẹ ti kọkọ waye ni ilu Ibadan, ni ipinlẹ Oyo ati ilu Abeokuta nipinlẹ Ogun.
Awọn onigbọwọ iwọde ọhun ti ṣeleri pe awọn yoo geb iwọde naa de ipinlẹ Ondo ati Ekiti laipẹ.
Ki lo ti ṣẹlẹ ṣeyin?
Awọn igun ọmọ Yoruba to n beere fun idasilẹ orilẹede Yoruba, Yoruba nation pade ni ilu Oṣogbo tii ṣe olu ilu Ipinlẹ Ọṣun loni.
Iwọde wọn ọhun to waye fun ọpọlọpọ wakati da lilọ bibọ ọkọ duro ni ilu Osogbo.
Gbogbo bi wọn ti n wọde ni wọn n kọrin ijagbara ati ẹhonu lori ipenija ti wọn woye pe o nkoju iran ọmọ Yoruba ni orilẹede Naijiria.
lati ipinlẹ Kogi, Kwara, Eko, Ọyọ, Ogun, Ondo, Ekiti ati Ọṣun lawọn oluwọde naa ti wa
Ọpọlọpọ awọn to sọrọ nibi iwọde naa ni wọn ni bi nnkan ṣe ri lorilẹede Naijiria bayii, nnkan ko rọgbọ, bẹẹni ohun ẹya gbogbo to so Naijiria pọ ko ṣọkan.
Wọn fi kun un pe ipe fun idasilẹ orilẹede Yoruba kii ṣe eyi ti o la wahala, jagidijagan lilo ibọn tabi ohun ija oloro dani rara.
Iganmu shanty demolition: Oníṣẹ́ ibi pọ̀ tó ń ṣọṣẹ́ lábẹ́ afárá Iganmu yìí ti pẹ́ ṣùgbọ́n.
India, Coronavirus: Ìtọ́jú aláìsàn ló jẹ́ mi lógún nítorí ètò ìlera wa mẹ́hẹ- Nọ́ọ̀sì Kama
Wọ́n rò pé mo ya wèrè ni Saudi lẹ́yìn ikú ọkọ mi
India, Coronavirus: Ìtọ́jú aláìsàn ló jẹ́ mi lógún nítorí ètò ìlera wa mẹ́hẹ- Nọ́ọ̀sì Kamala Nepali
Kamala Nepali ba BBC sọrọ lori nkan to jẹ ki oun pinnu lati maa tọju alaisan coronavirus lẹyin ti oun naa kagbako ẹ.
Kamala jẹ ọkan lara awọn nọọsi to n tọju awọn alaisan Coronavirus.
Nepali sọ bi oun funra oun ṣe ni ajakalẹ arun coronavirus ki o to yee bọ ti o si gbadun.
Kamala salaye kikun nipa bi oun ṣe pinnu lati maa ṣetọju awọn alaisan Covid 19 nitori pe oun mọ bi o ṣe n ri lara lati wa ni ẹsẹ kan aye ati ẹsẹ kan ọrun.
Nọọsi ẹni ọdun merinlelogun yii yanana ni kikun lori ohun ti itọju alaisan Covid 19 le gba lọwọ olutọju rẹ.
Deji Akure and Ondo Government: Irọ́ ni pé ìjọba fòfin dè mí láti yan àwọn Baálẹ̀ nílùú Akure- Ọba Aladetoyinbo Aladelusi
Oríṣun àwòrán, @Ojuasha
Deji ti ilu Akure, Ọba Aladetoyinbo Ogunlade Aladelusi ti sọ pe oun ni aṣẹ lati maa yan awọn Olu ati Baalẹ ni ariwa ati guusu Akure tako ọrọ ti ijọba ipinlẹ naa sọ pe ko ni irufẹ agbara bẹẹ.
Akọwe oriade naa, Adeyeye Michael, lo sọ ọrọ na ninu atẹjade kan to fi ṣọwọ si awọn akọroyin.
"Atẹjade naa ni ""Deji ti ilu Akure ti ri awọn iroyin kan to n lọ ninu awọn iwe iroyin pe ijọba ipinlẹ Ondo ti fofin de e lati yan awọn oloye ati Baalẹ."""
A fẹ ki o ye gbogbo eeyan pe irọ pata ni awọn iroyin naa ati pe awọn to kọ irufẹ iroyin bẹẹ gbe igbesẹ ọhun lọna ati ṣi awọn araalu lọna ni.
Wọn ni bo tilẹ jẹ pe awọn gba lẹta kan lati ọọfisi ileeṣẹ ijọba ipinlẹ Ondo to n ri si ọrọ ijọba ibilẹ ati oye jijẹ lori ọrọ naa to ti wa nile ẹjọ tẹlẹ, ile ẹjọ ti da ẹjọ naa nu.
Oríṣun àwòrán, @DailyPostNGR
Atẹjade ọhun ni lati igba iwasẹ ni Deji ti jẹ alaṣẹ lori ilẹ Akure ati awọn ilu kereje to wa ni agbegbe rẹ, Deji si ni ẹni to maa n yan awọn oloye ati Baalẹ lori awọn ilu naa.
Alara tí Ilara Epe: Òjò gbọ́dọ̀ rọ̀ lásìkò ọdún Ẹlẹ́gba ni ìlú Epe- Oba Olufolarin Ogunsan
Bo tilẹ pe awọn Baalẹ kan ti kọkọ gbe Deji lọ ile ẹjọ lori iṣẹlẹ to jọ mọ ọrọ oye jijẹ naa ṣaaju, atẹjade ọhun ni ile ẹjọ ti da ẹjọ naa nu, Deji si ni alaṣẹ lori gbogbo ilẹ Akure.
India, Coronavirus: Ìtọ́jú aláìsàn ló jẹ́ mi lógún nítorí ètò ìlera wa mẹ́hẹ- Nọ́ọ̀sì Kama
Ọjọ kẹtala, oṣu Karun un, ọdun yii ni iroyin kan gbode pe ijọba ipinlẹ Ondo ti paṣẹ fun Deji ti ilu Akure lati jawọ kuro ninu yiyan awọn Baalẹ.
Lara awọn ilu ti iroyin naa sọ pe Deji ko laṣẹ lati yan Baalẹ rẹ ni Ago Sonibare ni Ala/Ajagbusi, Eleyewo, Ago-Ajapada ni igbo Ofosu, Ago Tedibomi ni Ala/Ajagbusi, Agunla to wa ni Ayede-Ogbese, Ilado/Elemo ati ilu Isinigbo.
Iganmu shanty demolition: Oníṣẹ́ ibi pọ̀ tó ń ṣọṣẹ́ lábẹ́ afárá Iganmu yìí ti pẹ́ ṣùgbọ́n.
Iléeṣẹ́ ọlọ́pàá dóòlà ọmọ oṣù kan tí wọ́n gbé e sọnù l'Eko
Oríṣun àwòrán, Muyiwa Adejobi
Ileeṣẹ ọlọpaa ipinlẹ Eko ti doola ẹmi ọmọ oṣu kan ti wọn gbe ju si ẹba ọna nipinlẹ naa.
Ninu atẹjade kan ti alukoro ileeṣẹ ọhun, Muyiwa Adejobi fi ṣọwọ si BBC Yoruba, o ni wọn ri ọmọ jojolo naa ni orita ti ile epo Odun-Ade wa, iyẹn ni ibudokọ Orile.
Gẹgẹ bo ṣe sọ, awọn eeyan kan to n kọja lẹba ọna ọhun lo ke si awọn agbofinro ni ẹka Orile lati wa wo ọmọ naa, lẹyin naa ni wọn gbe ọmọ ọhun lọ si ẹka ileeṣẹ ọlọpaa to n ri si ọrọ awọn obinrin, eyii to wa ni Ikeja.
Kọmiṣọna ọlọpaa ipinlẹ Eko, Hakeem Odumosu ti foju ganni ọmọ naa, o si ti paṣẹ pe ki wọn fun ni itọju to peye.
Kii ṣe igba akọkọ ree ti awọn eeyan ilu yoo gbe ọmọ sọnu nilu Eko ninu ọdun yii.
Iganmu shanty demolition: Oníṣẹ́ ibi pọ̀ tó ń ṣọṣẹ́ lábẹ́ afárá Iganmu yìí ti pẹ́ ṣùgbọ́n.
Lọjọ karundinlogun, oṣu Kẹta ọdun ti a wa yii,  oninure kan pe akiyesi ileeṣẹ ọlọpaa si ọmọ kan ti wọn gbe sọnu lagbegbe Oko Oba, niluu Eko.
Ninu oṣu Kẹta kan naa ni wọn ri oku ọmọ jojolo miran lẹba ile iwosan Ayinke, to wa ni opopona papakọ ọkọ ofurufu, ni Ikeja niluu Eko yii kan naa.
Odumosu ti wa ṣeleri pe oun atawọn alabaṣiṣẹ oun yoo fọ ilu Eko mọ kuro lọwọ awọn iwa bii ki eeyan maa gbe ọmọ sọnu.
'Tééyàn bá kú a lè yọ yọ ojú yẹn tẹ́ẹ bá gbà wá láyé, a lè dá a sí fún ẹlòmíràn'
Face Transplant: DiMeo ṣùn lásìkò tó n wa ọkọ̀ lálẹ́, ló bá jóná nígbà tí ọkọ̀ gbiná
Awọn agba bọ, wọn ni ireti si n bẹ fun igi ta bẹ lori, nitori bo pẹ, bo ya, igi yoo pada ruwe.
Bẹẹ ni ọrọ ri pẹlu ọmọ orilẹede Amẹrika kan, Joseph DiMeo to jona nigba ti ọkọ rẹ sadede gbina lasiko to sun lọ nigba to n wa ọkọ naa lalẹ.
Ete, ọwọ ati Oju Joseph lo jona, to si nira fun lati maa wo digi lati mọ bi aworan rẹ se ri.
Amọ awọn ẹbi rẹ seto fun lati sisẹ abẹ lẹyin osu mẹjọ ti isẹlẹ naa waye, tawsn dokita ogoje si se isẹ abẹ naa fun wakatai mẹtalelogun ni igba mẹta ọtọọtọ.
Igba kẹta ni aseyọri to wa lati paarọ ọwọ, oju ati ete Joseph to jona, to si pada di eeyan to see wo.
Nigba to n ba BBC sọrọ, Joseph DiMeo ni ohun to wu ohun bayii ni lati wa ni ominira toun naa, ki oun si le da duro bii awọn eeyan yoku lati gbara le ẹnikẹni.
Àwọn ìtàn mánigbàgbé tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí:
O si fi ẹmi imoore rẹ han si awọn ẹbi rẹ naa ti wọn duro tii nigba isoro.
Yoruba Nation: YAF ní gbàjarè Banji Akitoye lé ṣàkóbá fún Yorùbá tó bá jẹ́ irọ́
Oríṣun àwòrán, Yoruba Appraisal Forum
Awọn ọmọ ẹgbẹ Yoruba Appraisal Forum, YAP, ti ke si awọn agbofinro, lati ṣe ọfintoto ọrọ ti aṣaaju ẹgbẹ Ilana ọmọ Yoruba, Ọjọgbọn Banji Akintoye sọ.
Alagba Akitoye ni wọn lo sọ pe awọn agbesumọmi ti n mura lati kọlu Guusu iwọ-oorun Naijiria.
Adari ẹgbẹ YAF naa, Adeshina Animashaun lo sọ ọrọ naa lẹyin ipade kan ti wọn ṣe niluu Eko.
Animasahun ni iwe ti Akintoye kọ nipa ikọlu awọn ẹgbẹ agbesumọmi nilẹ Yoruba le da wahala silẹ, ti ko ba si ootọ kanka ninu ọrọ ọhun.
Ṣaaju ni iroyin kan ti kọkọ sọ pe baba Akintoye kọ lẹta si awọn gomina ilẹ Yoruba lori ikọlu naa to ṣeeṣe ko waye.
Yemi Farounbi: Yorùbá yóò dáàbò bo ara rẹ́, bí ìjọ́ba bá kùnà láti ràgà bò wọ́n
Ninu lẹta ọhun ni Akintoye ti sọ pe awọn ẹgbẹ agbesumọmi ti n mura lati kọlu gbogbo ilẹ Yoruba, lọna ati ṣakoba fun eto ọrọ aje agbegbe naa.
"Animashaun sọ fun awọn kọroyin pe ""O yẹ ka wo lẹta Akintoye daadaa nitori atilẹyin rẹ fun iyapa Yoruba kuro lara Naijiria."""
O ṣeeṣe ki Akintoye mọ ọpọ ohun ti awa araalu to ku ko mọ.
"O tẹsiwaju pe ""O yẹ ki awọn agbofinro fi ọrọ wa Akintoye lẹnu wo nitori irufẹ ọrọ to sọ pẹlu awọn ọmọlẹyin rẹ to n pe fun iyapa Naijiria."""
Bí Oduduwa Republic bá bẹ̀rẹ̀, a ò ní ṣe aburú fún àwọn tó takò wá, ìlànà ààtẹ̀lé rèé - Banji Akintoye
Animashaun ni ki awọn ọdọ sọra fun awọn eeyan to n pe fun iyapa Naijiria, ki wọn ma baa maa ja ija ti ko tọ eyii to le mu ki wọn ṣẹ si ofin.
"O ni ""Awọn ọdọ ni lati ṣọra gidi fun awọn ti yoo maa pe wọn lati darapọ mọ ẹgbẹ agbesumọmi labẹ asia pe wọn n jija ominira."""
Adari YAF naa wa rọ ijọba apapọ atawọn gomina ni iha Guusu iwọ-oorun Naijiria lati pese eto abo to peye ni gbogbo ipinlẹ mẹfa to wa lagbegbe ọhun.
Ansoogun jagunjagun Iresa Adu Ogbomoso tó máa ń bínú gba ẹbọ- Oloye James Olawale
O ni eyi lọna ati kapa awọn janduku to n gbero lati da omi alaafia agbegbe naa ru.
Lẹyin naa lo rọ awọn ọdọ ilẹ Yoruba lati gbogun ti iwa iṣẹrubalu ati gbogbo ipe fun ijijagbara ti awọn kan n lọgun rẹ.
O ni alaafia Naijiria ni ẹgbẹ YAF n fẹ nitori ninu alaafia nikan ni orilẹ-ede ti le ni ilọsiwaju.
Asofin agba to n soju ẹkun idibo aarin gbungbun ipinlẹ Kaduna nile asofin agba kẹjọ to kọja, Sẹnatọ Shehu Sani ti bẹrẹ si fi ọrọ idasilẹ orilẹede Yoruba Nation dapara.
Bẹẹ ba gbagbe, awọn ajijagbara to n beere fun idasilẹ orilẹede Yoruba lati ara orilẹede Naijiria ni wọn se iwọde nilu Osogbo lọjọ Satide.
Nibi iwọde naa to waye ni gbagede Nelson Mandela Freedom Square ni ogunlọgọ awọn ajijagbara naa peju si, to fi mọ asaaju wọn, Sunday Igboho.
Lasiko iwọde ọhun si ni ojo nla kan bẹ silẹ, to si bẹrẹ si ni rọ le awọn oluwọde ọhun lori, eyi ti ko see da duro, ojo yii si lo tu iwọde naa ka.
Idi si ree ti asofin agba naa, Shehu Sani se bọ soju opo Twitter rẹ, to si n fi awọn ajijagbara ọhun se ẹlẹya pe ojo to rọ naa, kii se lasan.
Face Transplant: DiMeo ṣùn lásìkò tó n wa ọkọ̀ lálẹ́, ló bá jóná nígbà tí ọkọ̀ gbiná
Sani ni ojo naa lo n paroko fun awọn ajijagbara ọhun pe ki wọn tun ero wọn pa lori igbesẹ ti wọn n gbe lati pin Naijiria si yẹlẹyẹlẹ.
"Ojo alagbara to rọ lọjọ Satide, eyi to tu awọn oluwọde to n pe fun idasilẹ orilẹede Yoruba ka, jẹ isẹ lati ọdọ Ọlọrun fun wọn.
Isẹ yii lo n paroko pe ki wọn tun ero wọn pa lori igbesẹ ti wọn n gbe, ki wọn si maa sisẹ fun isọkan orilẹede yii.
Erongba lati se agbekalẹ orilẹede fun ẹya tabi ẹsin kan lo jade latinu ọkan ẹlẹyamẹya ti ko ni ifarada fun ibagbepọ alaafia."
Baba Ijesha: Amòfin Ogunlana ní kò tọ́ bí wọn ṣe fi béèlì Omiyinka kọ́ ọrùn ìyanṣẹ́lódì òṣìṣẹ́ iléẹjọ́
Oríṣun àwòrán, Baba Ijesha Instagram/Adesina Ogunlana Facebook
Gbajugbaja agbẹjọro to n ja fun ominira Baba Ijesha, Adesina Ademola Ogunlana ti sọrọ lori iha ti awọn ọlapaa kọ si ọrọ to sọ nipa Baba Ijesha.
Ogunlana, tii se alaga tẹlẹ fun ẹgbẹ awọn agbẹjọro nipinlẹ Eko salaye pe, se ni ẹrin n pa oun nipa bi awọn eeyan naa se n dọgbọn lati tako ofin.
Ogunlana wa fikun pe awọn ọlọpaa ti ni ki oun kọ lẹta si Kọmisana ọlọpaa pe ki wọn fun Baba Ijesha ni beeli kuro ni ahamọ.
"Amọ igbesẹ ti wọn n beere naa ya mi lẹnu nitori ilana ti ko nitumọ lasan ni wsn ni ki n tẹle, ko wulo rara.
Mo si ti sọ fun igbakeji Kọmisana ọlọpaa Adegoke to beere lẹta naa pe se lo n tẹti abala kan ninu ero awọn araalu lori isẹlẹ naa.
Face Transplant: DiMeo ṣùn lásìkò tó n wa ọkọ̀ lálẹ́, ló bá jóná nígbà tí ọkọ̀ gbiná
Mo si sọ fun pe ẹnikẹni to ba jẹ asaaju gbọdọ ni ọkan akin ati igboya lati sọ ati se ohun to tọ nigba gbogbo, ko maa si dabi Pọntu Pilatu to mọ ohun to yẹ ko se lasiko igbẹjọ Jesu, amọ ti ko se e."
Agbẹjọro naa ni Pọntu Pilatu mọ ohun to yẹ ko se amọ se lo n fọ ọwọ rẹ kuro ninu igbẹjọ Jesu, to si jẹ ki wọn kan mọ agbelebu,eyi to fi n tan ara rẹ jẹ.
O ni oun tun sọ fun pe ko lọ ba ọga rẹ pe ki wọn se ohun to yẹ lati se lori ọrọ Baba Ijesha, ki wọn ma si se tẹti si ero araalu lasan.
"Lootọ ni ero araalu se pataki lootọ amọ ko se pataki to ohun to yẹ labẹ ofin ati ohun ti ofin sọ.
O n salaye fun mi pe awọn ri pe afurasi naa se asemase pẹlu ọmọde ni awọn ko fi lee gba beeli rẹ gẹgẹ bi ofin se sọ.
Mo si ni se ofin tipinlẹ Eko lo n sọ, se ofin tipinlẹ Eko ga ju ofin apapọ ilẹ wa lọ ni? rara o, lootọ ni ko ga ju ofin Naijiria lọ."
Amofin Ogunlana ni ọrọ Baba Ijesha kọja boya o ba ọmọde se asemase tabi bẹẹkọ, ohun to wa nilẹ ni pe ka tẹle ohun ti ofin Naijiria sọ lori ọrọ naa.
O ni ọrọ ofin kọja pe boya a fẹran oju Baba Ijesha tabi iwa to hu amọ ohun to yẹ ka wo ni ẹtọ atawọn anfaani ti afurasi naa ni labẹ ofin, ka si tẹle.
O ti foju han gbangba pe se ni wọn n fi ọwọ ọla gba Baba Ijesha loju, ti wọn si n sọ fun pe a tẹ ori rẹ ba, ta si fi ẹtọ rẹ du ọ dipo ka sẹ awọn alagbara to tako ọ.
Agbẹjọro naa ni awọn ti kọ lẹta ọhun, ti awọn si ti fun ọlọpaa Adegoke, ẹni to salaye pe awọn yoo wo boya ileẹjọ yoo sisẹ lọjọ Aje lati gbe Baba Ijesha rele ẹjọ.
Iganmu shanty demolition: Oníṣẹ́ ibi pọ̀ tó ń ṣọṣẹ́ lábẹ́ afárá Iganmu yìí ti pẹ́ ṣùgbọ́n.
"Eyi naa ko tọna rara nitori ko dara bi wọn gbe ẹjọ Baba Ijesha kọ ọrun awọn osisẹ ẹka eto idajọ to n wosẹ niran.
Mo sọ fun pe maa pe oun ati Kọmisana Odumosu lẹjọ, kii se pe mo n dunkooko mọ wọn ni nitori a ti kọja akoko to yẹ ka maa dirẹbẹ fun awọn osisẹ ọba to yẹ ko maa tẹle ofin.
Otitọ ọrọ ree, bi wọn ba si se tete se ohun to tọ, lo se dara si nitori gbogbo eeyan lo yẹ ko maa sọrọ soke lori ifiyajẹni, ko si yẹ ka duro de akoko ti yoo kan wa abi ẹbi wa."
Ogunlana ni ohun tawọn n beere ni pe ki wọn fi Baba Ijesha silẹ nitori awọn osisẹ ẹka eto idajọ ni awọn si n tẹsiwaju pẹlu iyansẹlodi wọn, ti ipade wọn pẹlu ijọba si tun fori sanpọn.
Amofin naa wa n beere pe ti Baba Ijesha ba jẹ ibatan awọn ọlọpaa yii, se wọn yoo se bi wsn ti se yii?
O wa rọ awọn araalu lati maa dagunla si iwa ifiyajẹni, ti wọn yoo si ni bawọn ba ti jiire, abusebuse nitori ori yeye nimogun, ti aisẹ lo pọ.
Beeli ni ẹtọ ẹnikọọkan to ba jẹ afurasi, koda ko si ẹsẹ ti ko yẹ ki wọn mase gba beeli rẹ. Baba Ijesha kọ lo kọ ofin naa.
Wọ́n rò pé mo ya wèrè ni Saudi lẹ́yìn ikú ọkọ mi
Wayi o, amofin Ogunlana tun ti sọrọ lori bi awọn eeyan kan se n sọko ọrọ lu oun lori ayelujara nipa bi oun se n beere ẹtọ ofin fun Baba Ijesha.
O ni igbesẹ wọn naa ko sẹyin igbesẹ ti oun gbe lati lọ wo Baba Ijesha ni ahamọ, ti oun si kọwe pe ki wọn gba beeli rẹ ni ahamọ ọlọpaa.
Bẹẹ ba gbagbe, agbẹjọro naa ati Yomi Fabiyi pẹlu awọn lọya miran ni wsn bẹ Baba Ijesha wo ni ahamọ, ti wọn si n sọ fun awọn ọlọpaa pe o tọ ki wọn gba beeli rẹ.
Amọ lẹyin igbesẹ naa ni agbẹjọro Ogunlana kede loju opo ayelujara Facebook rẹ pe se lawọn eeyan kan n sọko ọrọ si oun fun atilẹyin gbangba ti oun n se fun afurasi naa.
India, Coronavirus: Ìtọ́jú aláìsàn ló jẹ́ mi lógún nítorí ètò ìlera wa mẹ́hẹ- Nọ́ọ̀sì Kama
"Awọn eeyan ni anfaani lati sọ ero ọkan wọn lori awọn iroyin ti oun ba gbe soju opo ibanidọrẹ oun ati fidio pẹlu.
Amọ mo n kilọ fun awọn to ba n sọrọ lori iroyin naa pe wọn yoo gbara gba bọnbu ni ilọpo mẹwa.
Ẹ ba fi ọbẹ ge mi, ma fun yin lesi nitori emi kii se agbẹjọro to n  mu tii lasan, ẹ ro lẹẹmeji, kẹ to maa se ẹnu belebele si mi."
Igisekele: Àwọn àgbà ọ̀jẹ̀ akọrin Fuji ń ṣèdárò Amoo Igisekele tó jáde láyé
Oríṣun àwòrán, Instagram/taofeek igisekele
Eekan akọrin Fuji lorilẹede Naijiria, Alhaji Taofeek Adewale Amọo Igiṣekele ti jade laye.
Igiṣekele ju gbohungbohun silẹ fun igba ikẹyin lorilẹede Amẹrika, lọjọ Satide ni awọn iroyin to jẹyọ lori iku akọrin Fuji naa sọ pe o jade laye.
Awọn iroyin abẹle kan sọ pe aisan iba lo ṣekupa olorin naa.
Alhaji Igiṣekele jẹ ọkan lara awọn gbajugbaja olorin ti ọpọ mọ, koda ọpọ lo mọ ọ gẹgẹ bi ara awọn olorin to wa ni sawawu King Wasiu Ayinde Marshall, KWAM1.
Nigba aye rẹ, oniruuru ipenija lo dojukọ Alhaji Igiṣekele nile ati loke okun. Iroyin kan tilẹ gbe pe laarin ọdun 2012 si 2013, wọn fi ofin de e pe ko gbọdọ wọ ilẹ Gẹẹsi.
Face Transplant: DiMeo ṣùn lásìkò tó n wa ọkọ̀ lálẹ́, ló bá jóná nígbà tí ọkọ̀ gbiná
Amọṣa iroyin naa sọ pe o tẹ oju ofin mọlẹ nigba naa.
Iwe igbelu rẹ nigba naa kii ṣe ọlọjọ gbọọrọ, eleyi to nilo ontẹ igbelu tuntun loorekoore ni, eleyi ti ko si fun un laaye lati pẹ lẹyin odi orilẹede naa ju bo ti ṣe yẹ lọ.
Orilẹede Amẹrika ni Alhaji Igiṣekele tẹdo si, ilu Newark lorilẹ̀ede Amẹrika lo si n gbe titi di ọjọ iku rẹ.
Ọmọ agbole Alagolo lagbegbe Ọjaaba nilu Ibadan ni akọrin Fuji naa.
Ni bayii, ọpọ awọn ololufẹ orin Fuji ni wọn ti n ba awọn olorin naa daro.
Agba olorin miran, Taye Currency lo tufọ iku rẹ loju opo Facebook rẹ. Gẹgẹ bi o ṣe sọ, ohun to ba ni ninu jẹ pupọ ni iku olorin naa.
Lara awọn eekan olorin mii ti wọn ti bọ sita sedaro Igiṣekele ni Saheed Oṣupa wa.
"Ninu atẹjade ti Oṣupa fi soju opo rẹ lo ti ni, ""iku ni opin ohun abẹmi gbogbo, amọ inu Ọlọrun ni itunu wa lori iku arakunrin wa Taofeeq Adewale Amọo Igiṣekele"""
Oríṣun àwòrán, Saheed Osupa Facebook
South Africa Polyandry law: Àwọn aṣòfin ń gbé ìgbésẹ́ lórí òfin tí yóò fààyè gba obìnrin láti ní ọkọ méjì
Oríṣun àwòrán, People daily
Ki lo ṣe bi orilẹede Naijiria ba gbe ofin kan kalẹ pe awọn obinrin le e fẹ ju ọkọ kan lọ, gẹgẹ bi awọn ọkunrin kan ṣe n fẹ ju iyawo kan lọ bayii?
Idi ta fi n beere ibeere yii ni pe oye to kan ara Iwo, le kan ara Ẹdẹ, bẹẹ si ni iku to n pa ojugba ẹni, owe nla lo n pa fun ni.
Lorilẹede South Africa, igbesẹ ti n wa bayii lati gbe ofin kan kalẹ eleyi ti yoo fi aye gba awọn obinrin lati fẹ ju ọkọ kan ṣoṣo lọ.
Eyi wa lara awọn atunṣe tuntun ti wọn fẹ ko de ba ofin igbeyawo lorilẹede naa.
Amọṣa, awọn ẹgbẹ oṣelu kan to fara ti awọn ẹlẹsin gẹgẹ bi oludibo wọn, ti fariga lori eyi.
Face Transplant: DiMeo ṣùn lásìkò tó n wa ọkọ̀ lálẹ́, ló bá jóná nígbà tí ọkọ̀ gbiná
Alaga ẹgbẹ oṣelu Al-Jama-ah, Ganief Hendricks ni, ẹgbẹ oṣelu naa yoo fara mọ awọn iwọde itagbangba lati tako igbesẹ naa.
Eyiun bi aba lori agbekalẹ ofin ti yoo faye gba obinrin lati ni ju ọkọ kan ṣoṣo lọ, eleyi to wa ninu iwe aba ijọba orilẹede naa, ba parada di ofin.
"Gẹgẹ bi ẹgbẹ naa ṣe sọ, ojuṣe ijọba ni lati ""rii daju pe iwa ọmọluwabi jọba lawujọ"""
Igbimọ onidajọ ẹsin musulumi lorilẹede naa, Muslim Judicial Council ṣalaye pe, ajeji ni aṣa ki obirin ni ju ọkọ kan lọ jẹ ninu ẹsin Islam.
Agbẹnusọ fun igbimọ naa, Muneer Abdouroaf ni awọn ko ni lee fọwọsii rara.
Akomolede ati Aṣa lori BBC Yoruba: Wo díẹ̀ nípa àbùdá Olodumare- Iyabo Ayinde
Bakan naa ni aarẹ ẹgbẹ ACDP, Ẹni ọwọ Meshoe MP ṣalaye ni tirẹ pe, bi wọn ba yiri ọrọ naa ni igba igba, awọn ko lee fọwọ si igbesẹ naa.
Agbẹnusọ fun Biṣọọbu agba ijọ Anglican nilu Capetown, Wendy Kelderman sọ wi pe mimẹnu le ọrọ naa lai ti jẹ pe aba naa ti de iwaju igbimọ awọn ijọ Ọlọrun lorilẹede South Africa, yoo fẹ dabi ẹni n ṣiwaju ẹlẹẹdẹ pẹẹdẹ.
Nigba to n gbe iwe aba naa sita, minisita fọrọ abẹle, Ọmọwe Aaron Motsoaledi ni ibẹrẹ ijiroro to ṣe pataki ni eyi jẹ, eyi ti yoo ṣe afọmọ eto igbeyawo lorilẹede South Africa.
Igbesẹ naa wa lati ṣawari awọn ohun to n mu ipaya ba awọn eeyan lori ọrọ igbeyawo, ṣugbọn yoo faye silẹ fun ijiroro lorilẹede South Africa ati loke okun.
Sex Denial: Wo àwọn ìwà to ń hù tí olólùfẹ́ rẹ fi lè fi ìbálòpọ̀ jẹ ọ́ níyà
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ni orilẹede Naijiria, ọpọ ibasepọ tabi igbeyawo lo n fori sanpọn nitori ọrọ ibalopọ.
Ninu ọpọ idile ti ayọ wa tẹlẹ, ni irufẹ ayọ bẹẹ ti dinku nitori awọn idi kan ti wọn ko le ṣalaye fun araye.
Lọpọ igba lo jẹ pe ko si idi miran ti ede aiyede fi n waye laarin ololufẹ, paapaa laarin lọkọ-laya, bikoṣe nipa aisi ibalopọ deede tabi ibalopọ ti ko tẹ ọkọ tabi aya lọrun.
Onkọwe kan nipa ibalopọ laarin tọkọtaya, Tammy Nelson sọ fun iwe iroyin Punch pe o ṣeeṣe ki eeyan wa ninu ibanujẹ, ti ẹnikeji rẹ ba n fi ibalopọ jẹ niya.
Nelson sọ siwaju si pe irufẹ ipo bayii lo jẹ ki ọkọ tabi aya irufẹ ẹni bẹẹ maa lero pe ololufẹ wọn ti ni oju miran sita.
Oríṣun àwòrán, other
Ṣugbọn ki lo le fa ki ọkọ tabi aya maa fi ibalopọ dun ẹnikeji wọn?
Ninu iwadii kan ti ọmọwe naa ṣe, o mẹnuba awọn idi meje ti ololufẹ ẹni le fi maa fi ibalopọ dun ni, awọn idi naa ree:
Ija ojojumọ ati oniruru ariyanjiyan le ṣakoba fun ibalopọ laarin ọkọ tabi aya.
Gẹgẹ bi Nelson ṣe sọ, ololufẹ rẹ le ni ọ sinu eyi to le mu ko ma fẹ ni ibalopọ pẹlu rẹ lasiko ti ija naa ba ṣi n lọ lọwọ.
Ni iru akoko bayii, Nelson gba tọkọ-taya niyanju lati pari aawọ to ba wa laarin wọn, ki wọn to gbiyanju lati ni ibalopọ kankan.
Ko rọrun lati jẹ eeyan nile aye, ẹnikẹni ti ko ba fẹ ṣe ẹru ẹgbẹ rẹ gbọdọ mura si iṣẹ, oju bọrọ ko si ṣe gba ọmọ lọwọ ekurọ.
Wahala jijẹ-mimu le mu ki ibalopọ maa run si awọn ẹlomiran.
Fun apẹrẹ, ẹni to n gbe ni ilu Eko to ti lo ọpọ wakati ninu sunkẹrẹ-fakẹrẹ ọkọ, le ma fẹ ṣe ere ifẹ pẹlu ololufẹ rẹ lẹyin to ba ti de ile tan.
Face Transplant: DiMeo ṣùn lásìkò tó n wa ọkọ̀ lálẹ́, ló bá jóná nígbà tí ọkọ̀ gbiná
Onimọ nipa ibalopọ kan ni ipinlẹ Eko, Chinwe Adeniyi sọ pe o ṣeeṣe ki ololufẹ ẹni kọ ibalopọ lẹyin ti eeyan ba ti bẹrẹ si n hu awọn iwa kan ti ko tẹẹ lọrun.
"Chinwe ni ""Fun apẹrẹ, ti eeyan ba dede di alara kikan, ololufẹ irufẹ ẹni le maa sa fun to ba ti to akoko ibalopọ."""
Awọn onimọ sọ pe ibi ti ibalopọ ti bẹrẹ ni ifẹnukonu, fifi ọwọ kan ara ọkọ tabi aya, ati bẹẹ lọ.
"Gẹgẹ bi ohun ti Nelson sọ ""Awọn nnkan kekeke bii ki ololufẹ fi ọwọ kan ara wọn, ki wọn di ọwọ ara mu lawujọ, ati bẹẹ lọ le tunbọ jẹ ki ifẹ wọn gbilẹ si, yoo si mu ki ibalopọ rọrun."""
Ansoogun jagunjagun Iresa Adu Ogbomoso tó máa ń bínú gba ẹbọ- Oloye James Olawale
Onkọwe kan to tun jẹ onimọ nipa ibalopọ nilẹ Amẹrika, Dawn Michael ni ibalopọ ko gbọdọ jẹ ohun ti eeyan yoo maa ṣe loju kan soso, ni ipo kan ati gẹgẹ bii aṣa adayeba ti laa kalẹ.
O ni tọkọtaya gbọdọ mu ara ọtọ wọ inu ibalopọ wọn ko le ni ina ninu, ki wọn to le gbadun rẹ daadaa.
Dokita naa ni ti tọkọ-taya ba kọ lati ṣe eyii, o le tete sun eyikeyi ninu wọn, ki wọn si maa sunra ki fun ololufẹ wọn.
Oriṣiriṣi ireti lo ṣeeṣe ko waye ṣaaju ibalopọ, ti awọn ireti yii ba ti pọ ju, paapaa fun ọkunrin, o ṣeeṣe ki irufẹ ọkunrin bẹẹ ma le ṣe to bo ṣe lero tabi bo ṣe yẹ.
Nelson ni ti eeyan ba ti n ro bi oun yoo ṣe ṣe daadaa ninu ibalopọ, o ṣeeṣe ki irufẹ ẹni bẹẹ ja ololufẹ rẹ kulẹ.
Awọn onimọ nipa ibalopọ, William Masters ati Virginia Johnson sọ pe eeyan ko nilo lati maa ṣaniyan nipa ibalopọ, o kan ni lati ni ifẹ si ibalopọ nikan ni.
International Nurses Day 2021: Wo ìpèníjà àti àǹfàní inú iṣk nọ́ọ̀sì- Adetokunbo Shaba
Kii ṣe gbogbo eeyan lo nifẹ ibalopọ, awọn miran fẹran ibalopọ bi ounjẹ, bẹẹ si ni awọn miran kọbi ara si.
Bi awọn kan ṣe le ni ibalopọ ojojumọ lawọn mii le wa fun ọpọ ọjọ, ọsẹ tabi lai ni ibalopọ, eyii to le fa iṣoro ninu ile fun tọkọ-taya.
Fun irufẹ awọn ti ko kundun ibalopọ bayii, awọn onimọ sọ pe ki wọn maa sun daadaa, ki awọn jẹ awọn oujẹ to le ṣe ara loore ki wọn si tun maa ṣe ere idaraya dede lọna ati ṣẹgun idojukọ naa.
Baba Ijesha: Ọlọ́pàá kò fún Omiyinka láàyè láti ṣa ikọ̀ agbẹjọ́rò rẹ̀ jọ
Bi ọrọ ba se n pẹ nilẹ, yoo maa gbọn si ni, bayi si ni ọrọ Baba Ijesha da bayii lori ayelujara.
Gbogbo atotonu tawọn ilumọọka si n se lori ẹsun sise asemase pẹlu ọmọde ti wọn fi kan Baba Ijesha, tii se osere tiata, ni ko tii lọ sodo lọ mumi.
Ni ọsan ọjọ Aiku, ni gbajumọ osere tiata nni, Yomi Fabiyi tun gbe fidio miran jade lati tako awọn ọlọpaa lori bi wọn se kọ lati gba beeli Baba Ijesha.
Nigba to n salaye ibi ti ọrọ naa de duro, Fabiyi ni orukọ ti wọn n pe Baba Ijesha pe abọmọdelopọ ni, ko tọ si rara nitori pe ọmọ to wa pẹlu rẹ kii se ọmọde.
Bakan naa lo salaye pe ko si ẹri pe Baba Ijesha ba ọmọ naa sun nitori pe iya ọmọ naa kan sin awọn osisẹ lọ si isalẹ ile rẹ ni.
Ansoogun jagunjagun Iresa Adu Ogbomoso tó máa ń bínú gba ẹbọ- Oloye James Olawale
O fikun pe awọn eeyan kan lo dẹ pakute fun osere tiata naa, ti oun naa si rọ lu u nitori o dabi pe wọn fẹ pa Baba Ijesha ni.
Bakan naa lo salaye pe titi di akoko yii, awọn ọlọpaa ko fi aaye gba afurasi naa lati ko ikọ agbẹjọro rẹ jọ, ko le mọ ohun ti yoo se tabi sọ nile ẹjọ.
O wa n beere pe nigba tawọn ọlọpaa ko fun afurasi naa laaye lati seto nipa awijare rẹ, to ba wa jare nile ẹjọ nkọ?
"Ti wọn ba ti ba ilera rẹ jẹ, ba isẹ ọwọ rẹ jẹ, to fi mọ orukọ ati gbogbo ohun to ni, ki ni yoo sẹlẹ ti adajọ ba da lare nile ẹjọ?
Ofin ilẹ wa gbe kalẹ pe ki wọn fun afurasi nile ẹjọ, koda gan, ẹni to pa eeyan gan ni anfaani si beeli, yoo si dara ki wọn bẹru Ọlọrun.
Ẹ mase joko sori ayelujara lati maa se idajọ ti ko tọ, ẹ kan n lọ silu oyinbo lasan lai kọgbọn nibẹ."
International Nurses Day 2021: Wo ìpèníjà àti àǹfàní inú iṣk nọ́ọ̀sì- Adetokunbo Shaba
"Yomi Fabiyi wa n ke si awọn ọlọpaa lati fi Baba Ijesha silẹ fun oun, ki oun si duro bii oniduro fun nitori ko tiẹ tii mọ iru awọn ẹsun ti wọn fi kan."""
Osere tiata naa fikun pe lasiko ti oun lọ bẹ Baba Ijesha wo ni ahamọ, o ni se lo tako iwọde ti oun fẹ se lati beere fun beeli rẹ.
Amọ o ni oun sọ fun Baba Ijesha pe oun ko se iwọde naa nitori tiẹ nikan, amọ nitori ki oun le ja fun ẹtọ ọmọniyan ni.
Yomi fabiyi ni oun kii se afipabaọmọdelopọ tabi afipabaagbalopọ, to si n sẹ epe fun gbogbo awọn eeyan to n pe ni orukọ buruku yii.
"Idi ti n ko fi sọ oko ọrọ si Iyabo ni pe o ti se awọn ohun to dara fun mi saaju, bẹẹ lo si dide lati sugba mi nigba ti iya mi ku.
Alara tí Ilara Epe: Òjò gbọ́dọ̀ rọ̀ lásìkò ọdún Ẹlẹ́gba ni ìlú Epe- Oba Olufolarin Ogunsan
To ba jẹ ẹlomiran lo dan wo, ẹni ti ko ni orukọ lọdọ mi, yoio tii da mọ, yiyọ ẹkun mi, tojo kọ, n ko si fẹ mọ boya eeyan jẹ ololufẹ mi tabi bẹẹ kọ."
Fabiyi wa n fi ika hanu pe o ya oun lẹnu pe awọn agbaagba ati asaaju to yẹ ko dide lagbo osere tiata lori ọrọ baba Ijesha ko dide rara si ọrọ naa.
PDP governor's meeting: Wo àbájáde ìpàdé àwon Gómínà PDP ní Ibadan
Oríṣun àwòrán, Twitter/seyi makinde
Ohun ti awọn gomina ẹgbẹ oṣelu PDP sọ ree nibi ipade ti wọn ṣe nilu Ibadan.
Apapọ awọn gomina to jẹ ti ẹgbẹ Peoples Democratic Party, PDP ti tọka awọn nnkan marun ọtọọtọ ti yoo mu opin de ba awọn iṣoro to n koju orilẹede Naijira lọwọlọwọ.
L'ọjọ Aje ni mejila ọtọọtọ ninu awọn gomina mẹẹdogun to jẹ ti ẹgbẹ oṣelu PDP lo pejupesẹ si gbọngan nla igbalejo IITA to n bẹ ni opopona Mọniya nilu Ibadan lati ṣe apero lori ọrọ aje ati eto aabo orilẹede Naijiria tofimọ awọn ọrọ to niṣẹ pẹlu ẹgbẹ oṣelu naa.
Lẹyin ipade bonkẹlẹ to waye fun bi i wakati meji, awọn gomina naa fi ohun kan ṣe agbekalẹ abajade ipadae naa:
1. Ipade naa kesi aarẹ orilẹede Naijria lati fi aba ṣọwọ si ile igbimọ aṣofin lati lẹ ṣe atunṣe ofin orilẹede yii ki agbara le to awọn ijọba ipinlẹ lọwọ lori eto aabo nipa ṣiṣe agbekalẹ ọlọpaa agbegbe ati eto aabo mii.
Asẹ́yìn, àwọn ẹbí olóògbé ṣì ń fomijé dárò àwọn tóṣìṣẹ́ 'Custom' yìnbọn pa nílùú Iseyin
2. Wọn parowa si aarẹ lati pe ipade igbimọ ọlọpaa orilẹede Naijira ni kiakia, ninu eleyii ti Aarẹ, awọn Gomina ati awọn alẹnulọrọ mii wa lati jiroro lori awọn ọna abayọ si awọn iṣoro to n koju iṣọkan Naijira, paapaa julọ ọrọ ọlọpaa.
Awọn gomina naa fun ohun ṣọkan pe ileeṣẹ ọlọpaa ṣe pataki ni didaabo bo ijọba awa arawa, nitori idi eyii lo si fi yẹ ki rira nnkan elo, idanilẹkọ ati itọju awọn oṣiṣẹ ajọ naa di nnkan ti ijọba mu lọkunkundun.
3. Bakan naa ni ipade naa gbe lẹyin igbesẹ apapọ awọn Gomina orilẹede Naijiria, awọn Gomina agbegbe Ariwa ati Gusu wi pe ṣiṣẹ idasilẹ ọgba ti maalu ti le maa jẹ oko ni ọna abayọ si wahala awọn agbẹ ati darandaran, pẹlu alaye wi pe Naijiria nilo atunto ki agbara ati ojuṣe le pọ si i lọwọ awọn ijọba ipinlẹ.
Iganmu shanty demolition: Oníṣẹ́ ibi pọ̀ tó ń ṣọṣẹ́ lábẹ́ afárá Iganmu yìí ti pẹ́ ṣùgbọ́n.
4. Ipade naa parọwa si gbogbo ọmọ orilẹede Naijiria lati ṣiṣẹ pọ ninu iṣọkan ati alafia lai si ẹlẹyamẹya, gẹgẹ bi ipade naa ṣe n kesi ẹgbẹ oṣelu APC ti wọn bẹnu atẹ lu gẹgẹ bi ẹgbẹ ti ko kan oju oṣuwọn lati gbe igbesẹ akin ki alafia le jọba lorilẹede yii, ki wọn si kọ ibi ara si agbekalẹ akanṣẹ ati ilana ti yoo ṣe anfani fun iṣọkan orilẹede yii.
5. Ipade naa tun mẹnuba ipe fun ile igbimọ aṣofin lati gbe igbẹsẹ lati lori ofin eto idibo ti yoo ki eto idibo maa lọ ni irọwọrọsẹ lorilẹede yii
Africa Eye: Ahmed Isah rèé tíí ṣe ààrẹ lásán làsàn ní Nàíjíríà tí inú aráàlú dùn sí
Awọn to pejupesẹ sibi ipejọpọ naa ni: Gomina Aminu Waziri Tambuwal ti ipinlẹ Sokoto, Gomina Udom Emmanuel ipinlẹ Akwa Ibom, Gomina Douye Diri ti ipinlẹ Bayelsa,
Gomina Samuel Ortom ti ipinlẹ Benue, Gomina Dr. Ifeanyi Okowa ti ipinlẹ Delta, Gomina Ifeanyi Ugwuanyi ti ipinlẹ Enugu,
Wọ́n rò pé mo ya wèrè ni Saudi lẹ́yìn ikú ọkọ mi
Gomina Nyesom Wike, ti ipinlẹ Rivers, Gomina Oluseyi Abiodun Makinde ti ipinlẹ Oyo,
Gomina Ahmadu Umaru Fintiri ti ipinlẹ Adamawa,
Gomina Godwin Obaseki ti ipinlẹ Edo, Gomina Bala Mohammed ti ipinlẹ Bauchi ati Mahdi Mohdigbakeji Gomina ipinlẹ.
Kini o ti kókó sele?
Àwọn gómìnà ẹgbẹ́ òṣèlú PDP bẹ̀rẹ̀ ìpàdé nílùú Ibadan
Ipade awọn gomina ẹgbẹ oṣelu PDP ti bẹrẹ ni gbọngban nla igbalejo IITA to n bẹ lopopona Moniya nilu Ibadan.
Mejila ninu awọn gomina mẹẹdogun to jẹ ti ẹgbẹ oṣelu PDP ti darapọ mọ ipade naa. Iroyin sọ wi pe awọn kan ṣi n bọ lọna.
Ipadae naa da lori ọrọ aje ati eto aabo orilẹede yii tofimọ awọn ọrọ to niṣẹ pẹlu ẹgbẹ oṣelu PDP.
Lara awọn gomina ti o ti wa nikalẹ ni Dr. Okezie Ikpeazu, gomina ipinlẹ Abia, Hon. Ahmadu Umaru Fintiri ti ipinlẹ Adamawa, Udom Emmanuel
ti ipinlẹ Akwa Ibom, Bala Muhammed ti ipinlẹ Bauchi, Duoye Diri ti ipinlẹ Bayelsa, Dr. Samuel Ortom lati ipinlẹ Benue, Benedict Ayade ti ipinlẹ
Cross River, Dr. Ifeanyi Okowa ti ipinlẹ Delta, Dr. Ifeanyi Ugwuanyi ti ipinlẹ Enugu, Godwin Obaseki ti ipinlẹ Edo, Nyesom Wike ti ipinlẹ
Rivers,Aminu Waziri Tambuwal ti ipinlẹ Sokoto, Darius Ishaku ti ipinlẹ Taraba, Bello Matawalle ti ipinlẹ Zamfara State ati Gomina Ṣeyi Makin ipinlẹ Ọyọ ti o jẹ olugbalejo nibi ipade naa.
Gomina Aminu Waziri Tambuwal ti ipinlẹ Sokoto to jẹ alaga awọn gomina gomina ẹgbẹ oṣelu PDP lo ṣide ipade naa ki wọn to kesi oniroyin lati yẹba fun wọn nibi ipade ni nnkan bi i iṣẹju diẹ si aago meji ọsan.
Ilé iṣẹ BBC wà níkàlẹ̀ láti jábọ̀ àbájáde ìpàdé náà.
Oríṣun àwòrán, Twitter/seyi makinde
Saaju la ti mu iroyin wa fun yin pe awọn gomina ipinlẹ ti ẹgbẹ oṣelu PDP n dari ni Naijiria ti n gunlẹ si ilu Ibadan fun ipade kan, eyi ti wọn pe laarin ara wọn labẹ aburada ẹgbẹ awọn gomina lẹgbẹ oṣelu PDP.
Ipade awọn gomina PDP yii lo n tẹle eyi to ti kọkọ waye saaju losu Kẹrin ọdun 2021 nipinlẹ Benue, ti akori ipade naa si tun da lori ipo ti Naijiria wa.
Bakan naa ni afojusun wọn fun ipade naa, gẹgẹ bi wọn se fi sita, ni ọna ti ẹgbẹ oselu PDP fẹ gba lati jẹ ọna abayọ fawọn ọmọ Naijiria yatọ si ẹgbẹ oselu APC.
Oríṣun àwòrán, Twitter/seyi makinde
Ireti wa pe awọn gomina mẹẹdogun ti wọn dibo yan labẹ ẹgbẹ oselu PDP ni Naijiria ni yoo peju sibi ipade naa.
Lara ohun ti wọn yoo jiroro le lori nibi ipade naa, gẹgẹ bi gomina ipinlẹ Ọyọ, Seyi Makinde ṣe sọ, ni awọn ọrọ to ṣe koko nipa orilẹede Naijiria lapapọ, bii gulegule ọrọ abo to n mẹhẹ ati ọrọ aje to dẹnukọlẹ.
Oríṣun àwòrán, Twitter/seyi makinde
Lara awọn gomina to ti gunlẹ silu Ibadan fun ipade naa ni Gomina Tambuwal ti Sokoto, Samuel Ortom ti Benue, Duoye diri ti Bayelsa, Ifeanyi Ugwuanyi ti Enugu, Ahmadu Umaru Fintiri ti Adamawa.
Bẹẹ ba si gbagbe, nibi ipade akọkọ to waye nilu Markudi naa, ni wọn ti beere fun eto atunto Naijiria ati mimu adinku ba agbara ijọba apapọ.
Oríṣun àwòrán, Twitter/seyi makinde
Awọn ilana yii ni wọn ri bii ọna abayọ lati gba Naijiria lọwọ ogun abẹle miran nitori ọpọ laasigbo to n ba Naijiria finra.
Oríṣun àwòrán, Twitter/seyi makinde
Iseyin Custom Killing: Asẹ́yìn, àwọn ẹbí olóògbé ń fomijé dárò èèyàn tí aṣọ́bodè pa lọ́jọ́ ọdún
Insecurity in Nigeria: Awọn janduku agbébọn tun ti ṣekupa ọlọpaa meji lẹnu iṣẹ ti wọn si tun dáná sun àgọ́ ọlọ́pàá.
Oríṣun àwòrán, other
Awọn janduku agbebọn tun ti ṣekupa ọlọpaa meji lẹnu iṣẹ ti wọn si tun dana sun agọ ọlọ́pàá.
Ni idaji ọjọ Aje, ọjọ kẹtadinlogun oṣu karun ni iṣẹlẹ naa ṣẹlẹ ní àgọ ọlọpaa Ubakala ni ijọba ibilẹ Gusu Umuahia nipinlẹ Abia.
Agbẹnusọ fún ileeṣẹ ọlọpaa ipinlẹ Abia, SP Godfrey Ogbonna lo fidi iṣẹlẹ ọhun mulẹ fawọn akoroyin.
Africa Eye: Ahmed Isah rèé tíí ṣe ààrẹ lásán làsàn ní Nàíjíríà tí inú aráàlú dùn sí
Ogbonna ni bíi ago mejila kọja isẹju mẹwaa loru ni lawọn janduku ọhun de pẹlu ado oloro.
O ni awọn ọlọpaa to lọ kọju ija si wọn gbiyanju agbara wọn, ṣugbọn omi pọ ju ọka lọ.
Ogbonna ni oun ko le sọ ni pato iye t'awọn janduku agbebọn naa jẹ.
Awọn ọlọpaa to f'arapa nibi iṣẹlẹ naa sí wa nile iwosan nibi ti wọn ti n gba itọju.
Ileeṣẹ ọlọpaa ni ọrọ naa ti di ọmọ to ni iya oun ko ni sun bayii, oun naa ko ni foju boorun.
Bi ọjọ marun un sẹyin lawọn ọlọpaa meji lẹyin tawọn agbebọn kọlu ọfiisi wọn ni ijọba ibilẹ Bende nipinlẹ Abia kan naa.
Wọ́n rò pé mo ya wèrè ni Saudi lẹ́yìn ikú ọkọ mi
Ní ọ̀sẹ̀ kan, ẹ̀mí tó lé ní 100 bá ààbò tó mẹ́hẹ lọ ní Nàìjíríà
Èèyàn 100 kú, ajínigbé jí 44 lọ tórí àbò tó mẹ́hẹ ní Nàìjíríà
Ọrọ ipenija abo lorilẹede Naijiria ti di eyi to n ta ba ara ile ati ero ọna bayii.
Ko fẹrẹ si ojumọ kan ti iroyin iwa ipa tabi ijinigbe, ipaniyan ati bẹẹbẹẹ lọ kii waye lorilẹede Naijiria mọ bayii.
Ọrọ naa ti di ti ojumọ kan, ara kan.
Oríṣun àwòrán, other
Eyi gan lo mu ki awọn gomina ipinlẹ to wa lapa gusu orilẹede Naijiria o lọ ree forikori ni ilu Asaba nipinlẹ Delta.
Laarin ọsẹ to kọja nikan, ko din ni ọgọrun eeyan ti wọn pa lorilẹede Naijiria gẹgẹ bi awọn iwe iroyin ti ṣe gbe e sita.
Ẹyin naa ṣe haa, ẹ jẹ ka jijọ woo.
Ọjọ Aiku:
Oríṣun àwòrán, other
Awọn agbebọn kọlu agọ ọlọpaa ni ipinlẹ Akwa Ibom lọsan ọjọ Aiku ni ijọba ibilẹ Abak.
Wọn pa ọlọpaa meji ati maluu mejila.
Bakan naa ni awọn agbebọn tun pa eeyan mẹta nileto kan torukọ rẹ n jẹ Golkofa nipinlẹ Kaduna.
Ẹwẹ, ijọba ipinlẹ naa tun fi idi rẹ mulẹ pe eeyan marun un miran tun ku, ti wọn ṣi n wa eeyan kan miran ninu iṣẹlẹ miran to tun ṣẹlẹ nibẹ.
Ni ipinlẹ Katsina, awọn agbebọn to lọ gbẹsan ni ileto Tsatskiya nijọba ibilẹ Safana ni ipinlẹ Katsina naa tun gbẹmi eeyan mọkanla.
Lọjọ Aje:
Awọn agbebọn pa eeyan mẹta ni ileto kan to wa nijọba ibilẹ Awka ni ipinlẹ Anambra.
"Ọwọ kẹjọ ileeṣẹ ọmọogun orilẹ nipinlẹ Kaduna ni awọn ti pa awọn balogun awọn agbebọn kan pẹlu mejidinlaadọta ọmọ ẹgbẹ wọn lẹkun iwọ oorun ariwa, ninu ikọlu kan ti wọn pe ni ""Operation Tsare Mutane""."
Lowurọ ọjọ Aje yii kan naa, awọn agbebọn ji ogoji awọn olujọsin ti wọn n gba adura oru (Tahajjud) ninu mọsalaṣi kan nijọba ibilẹ Jibia nipinlẹ Katsina.
Bakan naa lawọn agbebọn kan tun kọlu agọ ọlọpaa kan ni Mkpanak ni ijọba ibilẹ Essien Udim ni ipinlẹ Akwa Ibom. Wọn pa ọlọpaa kan.
Lọjọ Aje yii kan naa, awọn ọlọpaa ni ipinlẹ Edo forigbari pẹlu awọn ajinigbe kan, ti wọn si pa mẹta ninu wọn nibi ti wọn ti tu eeyan meje ti wọn jigbe silẹ.
Ọjọ Iṣẹgun:
Oríṣun àwòrán, Twitter/nigeria army
Oluọagutan ijọ Deeper life kan nilu Akurẹ, Pasitọ Ogedengbe Ọtayọmi ko sọwọ awọn ajinigbe.
Iyawo pasitọ naa ni inu ijs ni wọn ti wa ji skọ oun gbe.
Ni ilu Ikaramu Akoko, ni ipinlẹ Ondo kan naa, awọn ajinigbe tun ji agbaẹ meji gbe lọna oko wọn.
Oríṣun àwòrán, Twitter/nigeria army
Awsn agbebọn kan yinbọn pa ọga ọlspaa DSP Abdulqadir Hardo ni ipinlẹ Kebbi
Ileeṣẹ ọmọogun pẹlu fi iwe sita pe awọn koju iks agbebọn Boko Haram ni agbegbe kan nilu Maiduguri.
Mẹsan ninu wọn ni wọn ba ikọlu naa lọ.
Ẹwẹ awọn agbebọn to to ọgọrun niye pẹlu kọ lu agọ ọlọpaa Bende ni ipinlẹ Abia ti wọn si dana sun agọ ọlọpaa naa.
Bakan naa awọn olugbe ilu Mọdakẹkẹ meji lawọn eeyan kan yinbọn pa nileto Alapata.
Oríṣun àwòrán, Twitter/nigeria army
Awọn oṣiṣẹ aṣọbode ṣina ibsn fun awsn onifayawọ laarin igboro, nigba ti ina naa yoo fi rọlẹ araalu mẹrin lo ti di ero ọrun ti ọpọ dukia si bajẹ lọjọ ọdun itunu awẹ.
Ileeṣẹ ologun Naijiria ni awọn pa ọpọlọpọ agbebọn  ati ibuba wọn lawọn aginju kan ni ijọba ibilẹ Chikun ati Birnin Gwari ni ipinlẹ Kaduna.
Awọn ologun ni ko din ni eeyan mẹwaa lasiko ikọlu naa.
Bakan naa, awọn ọlọpaa ni ipinlẹ Akwa Ibom ni eeyan mẹjọ  lo ku lasiko tawọn ẹgbẹ okunkun kan forigbari nijọba ibilẹ Esit Eket.
Awọn janduku pa eeyan meji kan lasiko ti ikọlu kan waye lagbegbe Arulogun nilu Ede
Bakan naa lawọn ọlọpaa ya bo ibuba awọn agbebọn kan nijsba ibilẹ Oyigbo ni ipinlẹ Rivers, mẹrin ninu wọn ati nọọsi obinrin kan ni wọn pa
Asẹ́yìn, àwọn ẹbí olóògbé ṣì ń fomijé dárò àwọn tóṣìṣẹ́ 'Custom' yìnbọn pa nílùú Iseyin
Africa Eye: Ahmed Isah rèé tíí ṣe ààrẹ lásán làsàn ní Nàíjíríà tí inú aráàlú dùn sí
Lojoojumọ ni Ahmed Isah, tii se olootu eto Bẹrẹkẹtẹ maa n ya awọn ọmọ Naijiria lẹnu pẹlu sna to n gba lati gba ẹtọ wọn le wọn lọwọ.
Ọna to n gba lati fidi ẹtọ ọmọniyan le wọn lọwọ yii ni eto rẹ naa to n se lori redio ati tẹlifisan, ti ọpọ eeyan maa n wo.
Ahmed, ti ọpọ eeyan mọ si ‘Ordinary President’, taa mọ si aarẹ lasan lasan ni ọpọ ọmọ Naijiria sọ di orisa nitori bo se n lo agbara rẹ lati gba ẹtọ mẹkunnu fun wọn.
Se lo maa n pe awọn oloselu nija lori afẹfẹ, to fi mọ ileesẹ ọlọpaa to maa n gbe wa siwaju awọn ọmọ Naijiria, eyi si mu ki ọpọ mẹkunnu nifẹ rẹ.
Akọroyin fun ẹka iroyin ọtẹlẹmuyẹ nilẹ Afirika, BBC Africa Eye, eyiun Peter Nkanga tọpinpin Ahmed Isah ati ikọ rẹ fun ọpọlọpọ ọsẹ.
Nibẹ si ni wọn ti sawari rẹ pe lootọ lo le jẹ aarẹ lasan lasan to n yi igbe aye ọpọ eeyan si rere amọ awọn ọna to n gba eyi to n mu awuyewuye lọwọ le mu ewu miran dani.
Atiku Abubakar: Ẹ̀yin gómìnà, ẹ má dúró de ìjọba àpapọ́, kẹ tó wa ojútùú sáwọn ìṣòro Nàíjíríà
Oríṣun àwòrán, Atiku Abubakar Facebook
Igbakeji Aarẹ tẹlẹ ni Naijiria, Atiku Abubakar ti ke si awọn gomina lati ma duro de ijọba apapọ, ki wọn to wa ọna abayọ si oniruru iṣoro to n dojukọ Naijiria.
Bakan naa lo ni ki awọn gomina naa pe ipade apero lati jiroro lori awọn iṣoro Naijiria, ki wọn si wa ojutu si awọn iṣoro naa laarin ara wọn.
Atiku lo sọ ọrọ ọhun ninu atẹjade kan to fi lede loju opo ibadọrẹ Facebook rẹ.
Igbakeji Aarẹ tẹlẹri naa ni, ṣe lo yẹ ki awọn ọmọ Naijiria rere wa ojutu si awọn idojukọ ti Naijiria n koju lai fi ti ẹsin tabi ẹya ṣe.
Oludije sipo Aarẹ labẹ asia ẹgbẹ PDP lọdun 2019 naa sọ siwaju si pe, igbagbọ oun ni pe Naijiria yoo bori gbogbo iṣoro to n dojukọ.
Oríṣun àwòrán, Atiku Abubakar Facebook
"O ni ""Iṣoro ti Naijiria n dojukọ ni pe a n pinya laarin ara wa, yatọ si pe a n pinya nipa ti ẹgbẹ oṣelu ati ẹsin."""
"Mo ti maa n sọ lọpọ igba pe iyatọ to wa laarin wa kii ṣe ni ti Guusu tabi Ariwa, bi ko ṣe nipa awọn eeyan rere atawọn eeyan buburu.
Mo tun ti maa n sọ lọpọ igba pe ọmọ Naijiria pọmbele ni mi, o si yẹ ki a beere lọwọ ara wa, oun to n tumọ si lati jẹ ọmọ Naijiria."
Atiku sọ pe ojulowo ọmọ Naijiria ni ẹni to n bọwọ fun ẹtọ ẹlomiran labẹ ofin, ti ko si fi ti ẹsin tabi ẹya ṣe, to si n wa ilọsiwaju Naijiria pẹlu gbogbo ipa rẹ ni gbogbo igba.
Africa Eye: Ahmed Isah rèé tíí ṣe ààrẹ lásán làsàn ní Nàíjíríà tí inú aráàlú dùn sí
"O ni ọmọ ""Naijiria rere kii da ilu laamu kii si ṣẹruba awọn alabagbe rẹ."""
Titi di nnkan bii ọdun mẹwa sẹyin, ko si ohun to n jẹ ajinigbe-powo nilẹ yii, o si jẹ ohun ti ko fẹ ẹ ṣẹlẹ ri ninu itan orilẹ-ede wa.
Agba oselu naa sọ pe, a ko le tan iṣoro wa to ba jẹ pe bi a ṣe n ronu lati atẹyinwa naa ni a si ṣe n ronu bayii gẹgẹ bii ọrọ ti onimọ ijinlẹ Albert Einstein sọ.
Atiku wa ke si awọn gomina ni Naijiria lati pe ipade apero laarin ara wọn lori ọna ati wa ojutu si ogunlọgọ iṣoro ti Naijiria n dojukọ nitori awọn iṣoro naa yoo pẹ titi ti wọn ba n duro de ijọba apapọ.
Face Transplant: DiMeo ṣùn lásìkò tó n wa ọkọ̀ lálẹ́, ló bá jóná nígbà tí ọkọ̀ gbiná
Lẹyin naa lo ke si gbogbo ọmọ Naijiri lati wa ni iṣọkan ki alaafia le jọba dipo iyapa ti awọn ẹgbẹ kan n pe fun.
Eniola Afeez: Ẹ̀rọ ayàwòrán CCTV ti tú àṣírí ẹni tó ja mi lólè, ẹ bá mi wá a
Oríṣun àwòrán, eniolaafeez/Instagram
Gbajumọ oṣere tiata Yoruba, Eniola Afeez ti fi oju okunrin kan han fun araye, ẹni to fẹsun kan pe o ja oun lole.
Ninu fidio kan ti Afeez fi lede loju opo Instagram rẹ lo ti fi oju ọkunrin naa han fun gbogbo awọn ololufẹ rẹ.
Nigba to n fi oju afurasi naa lede, o ni inu ọọfisi ti awọn ti n ṣiṣẹ ni ọkunrin naa ti ja oun lole.
"O ni ""Ọkunrin ti ẹ n wo yii wa jale ninu ọọfisi wa to wa ni Oluyole lonii, o si ko oniruru ohun eelo olowo iyebiye lọ, agbegbe ti wọn ti foju ganni rẹ kẹyin ni adugbo Mobil, to wa ni Ring Road."""
Aworan CCTV yii n ṣafihan bo ṣe ja wa lole ati bo ṣe salọ, a bẹ ẹnikẹni to ba le sọ bi a ṣe le ri mu, ki wọn pe awọn ẹrọ ibaraẹnisọrọ wa.
Oríṣun àwòrán, eniolaafeez/Instagram
O fi kun pe ẹbun nla wa fun ẹnikẹni to ba le ṣamọna bi ọwọ ṣe le tẹ afurasi ọhun.
Pupọ ninu awọn ololufẹ rẹ lo ti bẹrẹ si n fi erongba wọn lede lori ọna to le fi ri afurasi naa ni kankan.
Eniola Afeez jẹ ọkan pataki lara awọn olupilẹsẹ ati oṣere tiata Yoruba to dantọ.
O ti gba ọpọlọpọ ami ẹyẹ fun iṣẹ ribiribi to ti ṣe nidii iṣẹ naa ti oun ati iyawo rẹ, Esther Kaleyaye jọ n ṣe.
Oríṣun àwòrán, eniolaafeez/Instagram
Asẹ́yìn, àwọn ẹbí olóògbé ṣì ń fomijé dárò àwọn tóṣìṣẹ́ 'Custom' yìnbọn pa nílùú Iseyin
Sunday Igboho: Wo bí àwọn ọmọ Yorùbá ṣe tako ìhàlẹ̀ láti dá ìbò 2023 dúró
Oríṣun àwòrán, Sunday Igboho/Instagram
Ọrọ to ba kọju si ẹnikan, Yoruba ni a maa kọ ẹyin si ẹlomiran bii ilu gangan.
Eyi lo mu ki awọn ọmọ ẹgbẹ Yoruba kan maa tako ọrọ ti Sunday Igboho sọ pe, awọn ajijagbara fun idasilẹ orilẹede Yoruba ko ni jẹ ki idibo waye lawọn ipinlẹ to wa nilẹ Kaarọ oojire lọdun 2023.
Idi ree ti awọn ọmọ Yoruba kan se n fesi si ọrọ naa, ti wọn si n kọju oro si idunkooko si eto idibo gbogbo gboo to ti ẹnu Sunday Igboho jade.
Ninu ifọrọwerọ pẹlu BBC, alagba Abdulhakeem Adegoke Alawuje sọ pe Igboho lẹtọ lati sọ nkan to wu lọkan ṣugbọn ko lagbara lati paṣẹ fun ijọba.
Alawujẹ to jẹ oludasilẹ ẹgbẹ Yoruba Welfare Group fi kun pe, bi Yoruba ko ba dibo, ọna ati dero ẹyin lorilẹede Naijiria ni wọn ba bọ yẹn.
Oríṣun àwòrán, YWG
''Bi ọwọ ẹni ko ba ti tẹ eku ida, a kii beere iku to pa baba ẹni. A ti n pe gbogbo awọn baba wa nilẹ Yoruba ki wọn kesi awọn to n kọrin ọtẹ pe ki wọn tọwọ ọmọ wọn baṣọ.''
O tun sọ pe awọn arijẹ nidi mọdaru lo n pe fun idasilẹ Yoruba Nation ati pe, ko si Ọba Alade nilẹ Yoruba kankan to n gbe lẹyin wọn.
Ọmọde laa fi ṣoogun ogboju ṣugbọn o yẹ ki o fi laakaye ṣe - Niyi Akintola
Ninu ọrọ rẹ agbẹjọro Adeniyi Akintola to fi ilu Ibadan ṣe ibujoko to si tun jẹ ilumọọka oloṣelu, o ni oun ko faramọ ọrọ ti Igboho sọ.
Niyi Akintola ni lootọ ni ofin faye silẹ fun ẹnikẹni lati sọ ero ọkan rẹ gẹgẹ bi Igboho ti ṣe sọ, ṣugbọn ohun gbogbo lo ni aala tiẹ.
O fikun pe Sunday Igboho ko fi laakaye kun eto ijijagbara to n se nitori ọgbọn ju agbara lọ.
''Iru Igboho yẹ ko wa lawujọ, kii sii ṣe gbogbo nkan to ba sọ la le ko danu, ti kii ba ṣe nitori nkan to ṣe awọn ajinigbe, ko ba gbogo ju bayii lọ''
Oríṣun àwòrán, Adeniyi Akintola/Facebook
Amọ o ni Igboho ko gbẹnusọ fun apapọ awọn Yoruba, bakan naa lo ni oun ko faramọ pe ki idibo ma waye lawọn ipinlẹ kaarọ o jiire lọdun 2023.
''Mi o faramọ pe ki o maa si ibo. O si nibẹ, o n beere pe bawo ni wọn ti ṣe pin?''
Nibi iwọde fun idasilẹ orilẹede Yoruba ti Sunday Igboho ati awọn ọmọ Yoruba mii dijọ ṣe ni Osogbo, lo ti sọrọ nipa idibo ọdun 2023.
Asẹ́yìn, àwọn ẹbí olóògbé ṣì ń fomijé dárò àwọn tóṣìṣẹ́ 'Custom' yìnbọn pa nílùú Iseyin
Igboho sọ fawọn to wa nibẹ pe awọn Gomina ipinlẹ ẹkun iwọ oorun Guusu Naijiria nifẹ si ki Yoruba wa ni ominira ṣugbọn ẹru n ba wọn nitori owo oṣooṣu ti wọn n gba lọdọ ijọba apapọ.
O ni yatọ si awọn Gomina, awọn lọbalọba naa wa lẹyin awọn to n pe fun fun idasilẹ orilẹede Yoruba.
Titi di ba ṣe n sọrọ yi, ko ti si Gomina kankantabi Ọba alade Yoruba to jade lati sọ pe awọn wa lyin ipe iyasọtọ Naijiria.
Baba Ijesha: Àkójọpọ̀ ìwádìí wa rèé nípa gbígbá béèlì Olanrewaju Omiyinka
Oríṣun àwòrán, Baba Ijesha/Twitter
Oju opo ayelujara ati tawọn ileeṣẹ iroyin Naijiria kan n gbona janin-janin lọsan ọjọ Aje, lori iroyin kan pe Baba Ijesa to wa ni ahamọ ọlọpaa ti gba itusilẹ.
Lati nkan irọlẹ ọjọ Aiku ni iroyin yii ti kọkọ lu jade sigboro, ti awọn eeyan si n gba bi ẹni gba igba ọti kaakiri.
Idi si niyi ti BBC Yoruba fi n se iwadi pe se lootọ ni wọn ti gba oniduro Olanrewaju James, ti gbogbo eeyan mọ si Baba Ijesa, tabi o si wa ni ahamọ ọlọpaa?
Ọna lati ri okodoro ọrọ nipa ahesọ ọrọ yii lo mu wa pe awọn to sunmọ Baba Ijesa ati awọn agbofinro to fi si ahamọ lori ẹsun aṣemase pẹlu ọmọdebinrin kan.
Africa Eye: Ahmed Isah rèé tíí ṣe ààrẹ lásán làsàn ní Nàíjíríà tí inú aráàlú dùn sí
Yomi Fabiyi - N ko gbọ pe wọn ti gba beeli Baba Ijesha
Ninu awọn to lewaju pe ki wọn tu Baba Ijesa silẹ ni gbajugbaja osere Yomi Fabiyi wa.
Ninu ijagudu rẹ fun idande Baba Ijesha ni ahamọ, Fabiyi ni ofin lo yẹ ka tẹle lori ọrọ Baba Ijesa nitori naa, ko yẹ ki o wa ni ahamọ gbere titi ti wọn yoo fi gbẹjọ rẹ.
Amọ nigba ti BBC Yoruba kan si lori aago rẹ, Fabiyi ni oun ko ti gbọ pe wọn ti gba beeli Baba Ijesa.
O ni ''Bi o ba jẹ pe wọn gba beeli rẹ, ohun to yẹ labẹ ofin naa lo ṣẹlẹ yẹn''
O ni bi awọn eeyan ṣe n gbọ pe wọn tu silẹ loun naa ṣe n gbọ ṣugbọn bi oun ba ri aridaju ọrọ yii, oun yoo fi to wa leti.
Asẹ́yìn, àwọn ẹbí olóògbé ṣì ń fomijé dárò àwọn tóṣìṣẹ́ 'Custom' yìnbọn pa nílùú Iseyin
Alukoro ileeṣẹ Ọlọpaa - N ko gbọ rara pe wọn ti gba beeli Baba Ijesha
Esi Yomi Fabiyi yii si lo mu wa kan si alukoro fun ileesẹ ọlọpaa nipinlẹ Eko lati fidi ootọ ọrọ naa mulẹ.
Nigba to n fesi pada lori atẹjisẹ ta fi ransẹ si, Muyiwa Adejobi tii se Alukoro ọlọpaa ipinlẹ Eko ni oun ko mọ rara boya wọn ti tu afurasi naa silẹ ni ahamọ ọlọpaa.
Amọ sibẹ isẹju- isẹju ni awọn iroyin n kan wa lori ayelujara pe wọn ti gba beeli Baba Ijesha, ti a ko si ri aworan, fidio tabi ẹnikẹni to fidi ọrọ naa mulẹ.
Koda, awọn ololufẹ wa loju opo Facebook BBC Yoruba gan n sọ pe awọn hu gbọ nipa pe wọn ti gba beeli Baba Ijesha sugbọn a ko ri aridaju kankan nipa rẹ.
Niwọn igba ti ileesẹ ti wa kii he ira ti ko mi ọmọ ninu, to ba se jẹ, iwadi si n tẹ siwaju, a maa kan si yin.
Baba Ijesha: Agbẹjọ́rò ṣe gbòsà fún adájọ́ tó fún Baba Ijesha ní béèlì, ọwọ́ ọlọ́pàá lọ̀rọ̀ kù sí
Oríṣun àwòrán, other
Ni ọjọ Aje ni iroyin jade pe wọn ti fi aye beeli gbajumọ oṣere to ko si gbaga ofin lori ẹsun  iwa aṣemaṣe si majesin ti wọn fi kan an, iyẹn Ọgbẹni Omiyinka Ọlanrewaju ti ọpọ mọ si Baba Ijẹsa silẹ.
Gẹgẹ bi iroyin ti a gbọ, lootọ awọn agbẹjọro rẹ ti n gbe igbesẹ fun gbigba beeli rẹ tẹlẹ, ṣugbọn abẹwo igbimọ to n ri si afọmọ awọn ahamọ ọlọpaa ati ọgba ẹwọn ni ipinlẹ Eko pẹlu adajọ Majisireeti agba kan, ni wọn ṣaayan bi aaye gbigba oniduro ṣe yọ fun Baba Ijẹsa labẹ ailera ara rẹ.
"Gẹgẹ bi fidio kan ti ọkan lara awọn agbẹjọro Baba Ijẹṣa, Amofin Adeṣina Ogunyinka gbe sita, o ṣalaye pe ọpẹlọpẹ igboya ati iwa akin Majisireeti agba, Toyin Ogre lo jẹ ki ""Baba Ijesha ri ẹtọ rẹ labẹ ofin gba"""
Amofin Ogunyinka ni awọn ọlọpaa ko kọkọ fi orukọ Baba Ijẹṣa si iwe orukọ awọn ti igbimọ naa fẹ boju wo ọrọ wọn fun beeli labẹ eto afọmọ ahamọ ọlọpaa naa.
Akungba Suicide: Ẹbí, ọ̀rẹ́ àti ọ̀gá iléẹ̀kọ́ sọ̀rọ̀ lórí irú èèyàn tí Feranmi Fasunle jẹ́
Amọ o ni amọṣa adajọ Magisireeti agba naa lo beere pe ki wọn mu Baba Ijẹsa wa ki oun rii.
Igba ti Baba Ijẹsa n jade bọ wa siwaju adajọ Majisireeti agba naa ati ikọ rẹ ni wọn rii pe o n tiro latari oun ti agbẹjọro Baba Ijẹṣa naa ṣalaye pe o jẹ lilu latọwọ awọn ọlọpaa.
Lara awọn ohun ti wọn beere ki wọn to lee gba oniduro rẹ ni oniduro meji ninu eyi ti ọkan gbọdọ jẹ oṣiṣẹ ijọba to wa ni akasọ kẹwaa soke pẹlu mọlẹbi rẹ kan. Bakan naa ni owo beeli ẹgbẹrun lọna ẹẹdẹgbẹta pẹlu gbọdọ wa di sisan.
Oríṣun àwòrán, Adesina Ademola Ogunlana Facebook
O ni ohun to kan bayii ni ki ọlọpaa ṣe ifidimulẹ awọn eto beeli rẹ wọnyi ki Baba Ijẹsa lee pada si ile rẹ.
Amofin Ogunlana tun fi kun pe awọn ikọ agbẹjọro rẹ yoo pese gbogbo ohun ti adajọ Majisireeti Toyin Ogre beere naa fun nidi gbigba beeli Baba Ijesha.
O ni ireti awọn si ni pe ni Ọjọ Iṣẹgun, ọjọ kejidinlogun oṣu kini, ọdun 2021 gbogbo eto lori beeli Baba Ijesa yoo to, yoo si pada sile.
Oríṣun àwòrán, Nollywood
Omiyinka Olanrewaju, bàbà Ìjẹ̀sà ni àwọn agbófinró tí fi ẹ̀sùn kan pé ó se ọmọ ọdun mẹ́rìnlá basu basuỌmọ yìí wà níle apanilerin osonu ni, Damilola Adekoya tí ọ̀pọ̀ mo sì Princess.Àwọn agbófinró ni wọn kò lè fi bàbà Ijesha sílè tẹ́lẹ̀ nítorí pé àwọn ẹ̀ka eto idajọ wá ní iyanselodi
Gbogbo ejọ ni wọn ti sún  síwájú tẹ́lẹ̀ nítorí iyanselodi yìíLosan òní ni ìròyìn jáde pé wọn tí fi bàbà Ìjẹ̀ṣà sílè kúrò ní ahamo ọlọ́pàá
Àwọn Adájọ́ kóòtù ibile yìí ń gbọ́ ejò àwọn èèyàn ti olopaa mú bí ó ti yeÈyí kò seyin àwọn Adájọ́ Majisireeti to n lọ káàkiri àgọ́ ọlọ́pàá ni Ipinle Eko láti mú àdíkù bá àwọn tó wà ni àhámọ́ ni pàntí àti àwọn àgọ́ ọlápàá mííràn.
Nínú ọ̀rọ̀ rẹ̀, agbẹjọ́rò Omiyinka, Adesina Ogunlana sàlàyé pé Májísíréètì náà ló wọ ibi ti Baba Ijesha wà tí àànú ṣì ṣe nítorí pé ìpo ìlera rẹ̀ ṣeni láànú gidi
Agbẹ́jọ́rò náà ni wọ́n bèrè fún oníduro méjì, kí ọ̀kan jẹ́ òṣìṣẹ́ ìjọba tó wà ni ìpele kẹwàá, àti ẹnikeji tó bá jẹ́ ẹbi rẹ̀, Bákan naáà ni wọ́n yóò pèsè ẹgbẹ̀rún lọ́nà ẹ̀dẹ́gbẹ̀ta nítori tí Baba Ijesha ba na pápá bora.
Agbẹ́jọrò náà ni ìlera Baba Ijesha ti mẹ́hẹ gidi, àti pé ẹ̀ṣẹ̀ to ṣẹ kìí ṣe nńkan ti wọ́n ko le gba oníduró fún.
Títí di àsìkò tí à n kọ ìròyìn yìí wọ́n kò tii gba Bàbá Ijesha jáde nítori pé wọ́n kò tíi parí plẹ̀ú gbogbo ètò tí wọ́ yóò fi tu sílẹ̀
O ní àwọn yóò koju ọ̀gá àgbà ọlọ́pàá ìpínlẹ̀ Eko nítori pé wọ́n tẹ ẹtọ́ James Omiyinka mọ́lẹ̀ ni àwọn kò si le faramọ
Ẹ̀wẹ̀ ọ̀pọ̀ ìgbà ni a ti pé agbẹ́nusọ ọlọ́pàá ìpińlẹ̀ Eko Muyiwa Adejobi tó sì sọ fún ilé iṣẹ́ BBC pé kò sí nnkan to ń jẹ́ pe wọ́n ti fi  James Omiyinka silẹ̀, àti pé òun kò mọ ibi ti àwọn ènìyàn tí gbọ́ ìròyìn ti wan ń gbé kiri.
Ọ̀pọ̀ àwọ olọ́lùfẹ́ Baba Ijesha ló ti n dá músò lójú òpó ìkànsíraẹni gbogbo nítori ìtúsílẹ̀ rẹ̀.
Yoruba Nation: Àbọ̀ tí Sunday Igboho mú bọ̀ rèé lẹ́nu àbẹ̀wò rẹ̀ sọ́dọ̀ Guru Maharaji
Oríṣun àwòrán, Screen Shot
Ajijagbara fun idasilẹ́ orilẹede Yoruba, Oloye Sunday Igboho ti se abẹwo sọdọ asaaju ẹsin One Love Family, Sat Guru Maharaji nilu Ibadan.
Igboho, ẹni to ko ọpọ awọn ajijagbara sodi lọ sile asaaju ẹsin naa to wa loju ọna marosẹ Ibadan silu Eko, ni ko si ẹni to mọ idi to fi lọ.
Amọ fidio kan to n ja rain lori ayelujara lo safihan Igboho to n kan saara si Maharaji fun atilẹyin rẹ lori ipe fun idasilẹ orilẹede Yoruba.
Bakan naa lo n rọ asaaju ẹsin naa lati kede atilẹyin rẹ nita gbangba fun ominira orilẹede Yoruba nitori o ni awọn gbadun bo se dugba gbogbo nnkan tawọn n se.
Yemi Farounbi: Yorùbá yóò dáàbò bo ara rẹ́, bí ìjọ́ba bá kùnà láti ràgà bò wọ́n
Nigba to n fesi, Sat Guru Maharaji ni atẹlẹwọ ẹni kii tan ni jẹ, ati pe gbogbo awọn orisa wa, omi , odo, Oluwo, Apena atawọn Ọba wa mọ pe oun duro ti Sunday Igboho.
"Gbogbo awọn igbesẹ to n gbe pe ki iran Yoruba ma subu tabi parẹ, o si da mi loju pe gbogbo orisa ilẹ Yoruba lo duro ti Igboho.
Bi o si se n lọ ni yoo se ohun to yẹ ko se ti ko fi ni si wahala mọ nitori awọn to wa niwaju gan, o ti rẹ wọn."
Alara tí Ilara Epe: Òjò gbọ́dọ̀ rọ̀ lásìkò ọdún Ẹlẹ́gba ni ìlú Epe- Oba Olufolarin Ogunsan
O wa rọ awọn akẹkọọ ati gbogbo araalu lati duro ti Igboho, ki wọn si duro lori otitọ, ka le gba Naijiria la, amọ ti ko ba ri bẹẹ, a jẹ pe oduduwa ti duro niyẹn.
"Guru Maharaji ni ""a ko binu tabi ba ẹnikẹni ja amọ a ko le duro sile ki ebi maa pa wa, ka wa ro pe o digba ta ba de ọrun, ki ara to tu wa, rara, a gbọdọ gba ara wa la.."""
Asaaju ẹsin naa wa kesi awọn gomina nilẹ Yoruba lati maa tọju awọn eeyan to n jija gbara fun ilẹ Yoruba, o ni ko yẹ ki wọn sa gbogbo nnkan si oorun.
'Iṣẹ wá burẹkẹ síi tórí Covid-19, owó ńlá ló wà nínú dídáná sun òkú, ìsìnkú  Zoom, Live streaming'
Ẹ fun wọn ni mọto, bi wọn se n se ni Amẹrika, Japan nuu. Ti wọn ba ri olotitọ, wọn maa n duro ti wọn ni, ẹru ko gbọdọ ba yin. Oduduwa ti de o.
Akungba Suicide: Ẹbí, ọ̀rẹ́ àti ọ̀gá iléẹ̀kọ́ sọ̀rọ̀ lórí irú èèyàn tí Feranmi Fasunle jẹ́
BBC Yoruba fẹsẹ kan ile ẹkọ fasiti Adekunle Ajasin nilu Akungba Akoko lati mọ ohun to pa akẹkọọ kan, Feranmi Fasunle laipẹ yii.
Bẹẹ ba gbagbe, Feranmi naa lo gbe oogun oloro jẹ, to si gba ibẹ re ọrun lọsan gangan.
Nigba ti wọn n ba BBC Yoruba sọrọ, awọn ọrẹ, ẹbi ati ọga ileẹkọ naa sọ pe atunbi pọnnpele ni oloogbe naa, to si maa n waasu Jesu kiri.
Koda, ọkan lara awọn to ba wa sọrọ ni oun lo waasu Jesu fun oun, ti oun fi di atunbi.
Bẹẹ ni wọn sẹ lori ahesọ ọrọ kan to ni akẹkọọ naa gbe majele jẹ nitori ọkunrin to ja silẹ ni.
Wọn fikun pe bi o tilẹ jẹ pe ko si ẹni to mọ idi ti Feranmi fi mu majele yii, sibẹ, awọn mọ pe kii se nitori ọkunrin lo fi se bẹẹ tori awọn ko ri lẹyin ọkunrin kankan ri.
Amọ ohun to sokunkun niwaju eniyan, kedere ni niwaju Ọlọrun Ọba.
Yoruba Nation: Aseyin ní inú ìlú kò dùn, ìwọ́de sì le fa làásìgbò
Asẹyin tilu Iseyin, Ọba Abdulganiy Salau Ologunebi Ajinasẹ Kinni ti ke si awọn eeyan to n pariwo fun idasilẹ orilẹede Yoruba lati mase de ilu Iseyin lasiko yii.
Asẹyin, paroko ọrọ naa ransẹ si asaaju ikọ ajijagbara fun ilẹ Yoruba, Oloye Sunday Igboho ati awọn ikọ rẹ lasiko to n ba akọroyin Punch sọrọ.
Asẹyin ni ilu naa n sọfọ awọn eeyan mẹrin ti awọn asẹbode pa lọwọ, ipo ti wọn si wa bayii ko fara mọ iru iwọde bayii.
O ni iwọde naa lee mu laasigbo dani nitori ara n kan awọn eeyan ilu naa lọwọ tori ọfọ awọn ọmọ wọn ti wọn ku lairotẹlẹ.
"Lootọ ni mo sọ pe wọn ko gbọdọ gbe iwọde Yoruba Nation wa silu Iseyin. Ilu wa ko si ninu idunnu fun iru iwọde bayii.
Asẹ́yìn, àwọn ẹbí olóògbé ṣì ń fomijé dárò àwọn tóṣìṣẹ́ 'Custom' yìnbọn pa nílùú Iseyin
Eyi ko si sẹyin isẹlẹ to waye lọsẹ to kọja."
Bẹẹ ba gbagbe, awọn osisẹ asọbode lo dede yinbọn pa eeyan mẹrin lọjọbọ ọsẹ to kọja, tii se ọjọ ọdun itunu aawẹ.
Isẹlẹ naa si waye lasiko ti awọn asọbode n le awọn onifayawọ to ko irẹsi wọle lọna to lodi sofin.
Baba Ijesha: Princess ní òun yóò borí, ó le má wáyé lójú ẹsẹ̀ àmọ́ ó di dandan
Adẹrinposonu nni, Adekola Adekanla, ti ọpọ eeyan mọ si Princess ti paroko ọrọ ransẹ lori bi Baba Ijesha se ri beeli gba.
Princess, tii se iya ọmọdebinrin ti wọn ni Baba Ijesha ba se asemase, ti wa gbe aworan kan soju opo Instagram rẹ lati paroko ọrọ ransẹ.
Ohun to wa ninu aworan naa ni ọkunrin kan to n fo lọ loju ofurufuru.
"Lara aworan naa ni wọn si kọ ọrọ kan si wipe ""Maa bori, o le maa jẹ loju ẹsẹ amọ o di dandan"""
Bakan naa lo kọ ọrọ si ẹgbẹ akọle naa pe Ọlọrun kii sun, Ọlọrun fẹran ọmọde, ẹ mase ba ọmọde se asemase.
Oríṣun àwòrán, Princesscomedian/Instagram
O tun tẹsiwaju pe ẹ kẹyin si iwa ifipabanilopọ, ẹ sọrọ sita tẹ ba ri ohunkohun.
Ọrọ yii lo kọ ni deede aago mẹwa alẹ ọjọ Isẹgun lẹyin ti iroyin gbalẹ kan pe adajọ ti fontẹ lu pe ki wọn fun Baba Ijesha ni beeli.
Ọpọ awọn ololufẹ adẹrinposonu naa si lo ti n fesi lori ohun ti Princess kọ yii, lati fi lọkan rẹ balẹ pe Ọlọrun wa lori itẹ.
Baba Ijesha: Iyabo Ojo ní òun kò tíi jámi lórí ọ̀rọ̀ ọmọ Princess, òun ṣẹ̀ṣẹ̀ bẹ̀rẹ̀ ni
Oríṣun àwòrán, other
Mo maa n roo tẹlẹ pe ijaba ni iṣoro orilẹede yii ti a n pe ni Naijiria ṣugbọn mo ti rii pe awa ara wa gan an ni iṣoro ara wa.
Ọrọ ti gbajumọ oṣere, Iyabọ Ojo fi bẹrẹ ninu fidio kan to n ja ranyinranyin lori ayelujara ree ninu eyi to ti n fi iha to kọ si beeli ti wọn fun Baba Ijẹṣa han.
Baba Ijesha ni eekan oṣere ti awọn ọlọpaa fi si ahamọ lori ẹsun iwa aṣemaṣe pẹlu majesin, tii se ọmọdebinrin adẹrinposonu nni, Princess.
Ni ọjọ Aje, ọjọ kẹtadinlogun oṣu karun un ọdun 2021 ni adajọ Majisireeti agba kan ṣilẹkun anfani beeli silẹ fun Baba Ijẹṣa lori ọrọ ailera ara rẹ.
Akungba Suicide: Ẹbí, ọ̀rẹ́ àti ọ̀gá iléẹ̀kọ́ sọ̀rọ̀ lórí irú èèyàn tí Feranmi Fasunle jẹ́
Iyabọ Ojo ni o fihan gbangba pe ọpọ ọmọ orilẹede Naijiria ni iwa imọtaraẹnikan ni ironu wọn. Eyi lo si faa ti ọpọ maa fi n de ijọba ti iwa kiko ọrọ ilu si ikawọ arawọn.
O ni oun ko ti jami lori ọrọ ọmọdebinrin ti wọn fẹsun kan baba Ijẹṣa pe o ṣe aṣemaṣe pẹlu.
O fi kun pe bi ọpọ ba ri ohun to ṣẹlẹ si ọmọdebinrin naa gẹgẹ bi eyi ti ko kan wọn
EFCC in Osogbo: EFCC fi ojú àwọn afurasí ọmọ Yahoo tó mú kàwọn ọ̀dọ́ ìlú Osogbo yarí mọ́ wọn lọ́wọ́
Oríṣun àwòrán, Efcc
Ọdọmọdekunrin ẹni ọdun mejilelogun kan to sa kuro niṣẹ ologun wa, lara awọn ọdọ mẹrinlelọgbọn tawọn ẹṣọ EFCC ko, lasiko ti wọn wọ ilu Oṣogbo.
Awọn osisẹ ajọ EFCC naa lo lọ silu Osogbo lati lọ ko awọn afurasi onijibiti, ti ọpọ eeyan mọ si ọmọ Yahoo, lọjọ Aje mọju ọjọ Iṣẹgun.
Bi ẹ ko ba gbagbe, ọrọ kiko awọn ọmọ oni Yahoo naa da wahala silẹ nilu Osogbo fun ọpọlọpọ wakati, lasiko ti awọn ọdọ kan tawọn eeyan fura si pe wọn jẹ onijibiti ori ayelujara ti ọpọ mọ si yahooboys, dana wahala silẹ lawọn agbegbe kan ni igboro ilu Osogbo, bẹrẹ lati afẹmọjumọ ọjọ Iṣẹgun.
Ajọ EFCC ṣalaye loju opo ayelujara rẹ gbogbo pe, awọn ẹṣọ rẹ lati ẹka ileeṣẹ EFCC nilu Ibadan ni wọn lọ fi panpẹ ofin mu ọdọmọkunrin kan ti wọn pe orukọ rẹ ni Adebisi Jamiu.
Oríṣun àwòrán, Efcc
"Bakan naa ni wọn ko awọn miran ti iwadi ọtẹlẹmuyẹ ajọ naa ti fidi rẹ mulẹ pe wọn lọwọ ninu gbigba owo kotọ nipa lilu jibiti ori ayelujara ti wọn n pe ni ""Yahoo-yahoo""."
Awọn yooku ti ajọ EFCC ni ọwọ awọn ẹṣọ awọn tun ba ni Muritala Olaniyi Lateef, Wasiu Olajide, Wasiu Sadiq, Olaniran Abiodun, Ayodeji Tosin, Olaniran Tayo, Oginni Oluwaseun, Oginni Olatunde, Ojuade Oluwafemi and Ibrahim Wande.
Bakan naa ni ọwọ ajọ naa tun tẹ Oladiran Olayinka, Akinjobi Akinwunmi, Abayomi Aderohunmi, Olaoluwa Temitope, Idowu Olawale, Lawrence Taiwo ati Ojo Gbenga.
Oríṣun àwòrán, @officialEFCC
Awọn yoku ni Tiamiyu Farouk, Oladele Seun, Akiniyi Boluwatife, Olaoluwa Mutiu, Olakunle Omolofe, Olalere Samad, Edbadon Johnson, Oketunbi Kayode ati Gbeyide Tomiwa.
Bakan naa ni wọn darukọ Oluwanisola Elmuqsit, Bathlomew John, Ibikunle James, Olamide Oluwaseyi, Yusuf Mohammed, Adebola Ibrahim, ati Ajayi Muyiwa.
Oríṣun àwòrán, TWITTER/SON OF OSUN
Ọkọ marundinlọgbọn tawọn ẹṣọ EFCC gba lọwọ awọn ọdọ ti wọn furasi pe wọn ṣe Yahoo Yahoo l'Osogbo, lawọn ọdọ naa gba pada lọwọ awọn oṣiṣẹ ajọ to n gbogun ti iwa ijẹkujẹ atawọn iwa ọdanran miran ni Naijiria.
Ninu awọn iroyin abẹle to suyọ nilu Osogbo, awọn ọdọ naa fariga pe iwa idukokomọni awọn ẹṣọ EFCC naa ti pọ ju fun awọn lẹnu lọwọlọwọ yii.
"Ni alẹ ọjọ Aje lawọn ẹṣọ ajọ EFCC kan wọlu Osogbo lati fi panpẹ ofin mu awsn eeyan kan ti wọn fura si pe wọn n lọwọ ninu owo jibiti ati gbajuẹ ori ayelujara ti ọpọ mọ si ""Yahoo-yahoo"""
Oríṣun àwòrán, Twitter/son of osun
Awọn akẹgbẹ wọn ṣa ara wọn jọ lati dena de awọn ọdọ naa ni abajade wọn.
Iroyin sọ pe awọn ọdọ naa gba awọn ọkọ ayọkẹlẹ olowo iyebiye ti wọn ko pẹlu awọn afurasi naa pada ki o to di pe wọn da wahala silẹ nilu Osogbo ni gbogbo ọjọ Iṣẹgun.
Oríṣun àwòrán, @jasimania
Oríṣun àwòrán, Twitter/Mayowa Olagunju
Ibẹrubojo lo gbode kan lawọn agbegbe kan lafẹmọjumọ ọjọ Iṣẹgun ni ilu Osogbo ni ipinlẹ Osun.
Awọn ọdọ kan ti ọpọ furasi gẹgẹ bi olowo jibiti ori ayelujara, ti ọpọ mọ si 'Yahoo boys' fariga, ti wọn si da igboro ru nigba tawọn oṣiṣẹ ajọ EFCC kan ba wọn lalejo lati fi panpẹ ofin mu wọn.
Awọn ẹṣọ ajọ EFCC naa ni iroyin sọ pe, wọn foru wọlu Osogbo lati mu awọn afurasi ọmọ yahoo, ki awọn ọdọ kan to da wọn lọna lẹyin ti wọn ti gba ogun ọkọ olowo iyebiye, ti wọn si tun mu awọn afurasi kan.
Gẹgẹ bi a ṣe gbọ awọn ẹṣọ EFCC naa ni lati wa ibi gba fun aabo ẹmi ara wọn.
Awọn ọdọ naa dana si oju popo ni agbegbe Lameco ni olu ilu ipinlẹ Ọṣun naa.
Oríṣun àwòrán, Twitter/mayowa olagunju
"Eeyan kan loju opo Twitter to pe orukọ ara rẹ ni Mayọwa Ọlagunju ṣalaye pe, oru lawọn ẹṣọ ajọ EFCC naa ya wọ agbegbe Adetunji Estate nilu Osogbo, lati ṣa awọn ti wọn fura si pe wọn jẹ ""ọmọ yahoo""."
N ṣe lawọn ọdọ agbegbe naa ba fọn sita, ti wọn si di gbogbo ọna ti awọn ẹṣọ EFCC naa lee gba jade.
"O ni nṣe lawọn 'Ọmọ Yahoo' yari tan patapata, ti wọn si  n pariwo pe ""o to gẹ, iwa ilọnilọwọgba awọn ẹṣọ EFCC buru ju ti ọlọpaa kogberegbe SARS lọ"""
Oríṣun àwòrán, Screenshot
Oluwo Farmers-Herders Summit: Àwọn darandaran ní aráàlú le è jí màálù àwọn torí òfin ìjọba
Aṣoju awọn Fulani darandaran ẹka ti ipinlẹ Ọṣun, ti ra ọwọ ẹbẹ si ijọba apapọ ati awọn alẹnulọrọ lati fun wọn ni anfani diẹ si i, ki ofin to de ẹran dida kaakiri.
Seriki Fulani ni ilu Iwo n'ipinlẹ Ọṣun, Alhaji Mohamadu Oloruntele lo fi ipe naa sita l'ọjọ Iṣẹgun, nibi akanṣe eto apero to waye lori ija awọn darandaran ati awọn agbẹ.
Aafin Oluwo ti ilẹ Iwo, Ọba Abdulrasheed Adewale Akanbi, Telu Kinni ni ipade apero naa si ti waye.
Ninu ọrọ to sọ nibi ipejọpọ naa, Oloruntele ṣalaye pe oye ofin tuntun ti ijọba gbe kalẹ lori kikọ ọgba fun awọn maalu dipo kiko ẹran jẹ kaakiri, ko ti i fi bẹẹ ye awọn darandaran.
Nitori idi eyii lo fi kesi ijọba lati fun wọn ni asiko diẹ si i, ki wọn le gbaradi fun ilana tuntun naa.
Seriki Fulani fikun pe, yoo di irọrun fun awọn darandaran lati tẹle aṣẹ ijọba, lẹyin ti wọn ba ni oye ati idanilẹkọ to peye lori i bi wọn ṣe le tọju awọn nnkan ọsin wọn, lai ko wọn jẹ kaakiri.
O ni ṣugbọn saaju eleyii, awọn darandaran rọ ijọba lati fun wọn ni anfani diẹ si i ki wọn to gbẹsẹ le dida ẹran kaakiri.
Oloruntele tẹsiwaju wi pe, ewu to pọ lo rọ mọ ofin tuntun ti ijọba gbe kalẹ lori i dida ẹran kaakiri.
O ni awọn ara ilu ti ijọba ko bẹ lọwẹ yoo bẹrẹ si ji maalu ti wọn ba ri nigboro gbe, nipasẹ aṣẹ ti ijọba pa lori i dida ẹran kaakiri.
Epe Fish Market: Wá wo oríṣi ẹja tí o rírí lọ́jà ẹja tó tóbi jùlọ ní Nàíjíríà
O ni awọn darandaran yoo dẹkun ati maa da ẹran kaakiri lai pẹ, ṣugbọn ki ijọba ṣe suuru fun wọn diẹ ki wọn fi ọna mi i ti awọn nnkan ọsin wọn yoo maa gba jẹun.
Ẹni ti o jẹ alaga nibi ipade apero naa, to tun jẹ Kọmisana fun eto ọgbin nipinlẹ Ọṣun, Arakunrin Adewole Adedayo ṣalaye pe ko si nnkan to buru ninu ofin tuntun ti ijọba gbekalẹ.
Adedayo ni ofin naa yoo ṣe anfani to pọ fun ọlọsin ẹran, ti awọn maalu to ri itọju to peye ninu ọgba ti wọn kọ fun wọn ni ibamu pẹlu aṣẹ ijọba,yoo si ni alafia.
O tun salaye pe irufẹ awọn maalu inu ọgba bayii maa n sanra ju awọn maalu ti wọn n rin kaakiri inu igbo ati igboro lati wa ounjẹ lọ.
Nipa bẹẹ, o ni awọn ọlọsin maalu ti ni anfani lati bọ awọn nnkan ọsin wọn yo, bẹẹ si ni wọn yoo maa taa ni owo gọboi.
O fi kun ọrọ rẹ wi pe, ijọba yoo ṣe iranlọwọ nipa idanilẹkọ fun awọn darandaran lori agbekalẹ ofin tuntun naa.
Akungba Suicide: Ẹbí, ọ̀rẹ́ àti ọ̀gá iléẹ̀kọ́ sọ̀rọ̀ lórí irú èèyàn tí Feranmi Fasunle jẹ́
Oluwo setan lati seranwọ fun darandaran lori ọgba maalu
Ninu ọrọ tiẹ, olugbalejo agba nibi ipejọpọ naa, Oluwo ti ilẹ Iwo, Ọba Abdulrasheed Akanbi ṣalaye pe awọn agbẹ ati darandaran gbọdọ wa ni iṣọkan ki alafia le jọba.
O ni ọna ti alafia le fi jọba si ni ki awọn darandaran gbọran si aṣẹ ijọba lori i ofin to de dida ẹran kaakiri igboro.
Ọba alade naa wa ṣe ileri lati ṣe iranlọwọ fun awọn darandaran to o ba nilo iranlọwọ lori agbekalẹ awọn ọgba ti maalu yoo ti maa jẹ koriko, dipo kiko wọn jẹ kaakiri ilu.
Awọn Lọbalọba, Baalẹ, ẹgbẹ awọn darandaran, awọn agbẹ, agbofinro ati awọn aṣoju ijọba ipinlẹ Ọṣun wa lara awọn to ba wọn pejupesẹ sibi apero naa.
Saaju la ti sọ fun yin pe ipade apero laarin awọn agbẹ ati Fulani ti bẹrẹ nilu Iwo.
Pẹlu bii olukuluku igun lorilẹede Naijiria ṣe n wa ọna abayọ si gulegule wahala awọn agbẹ olohun ọgbin atawọn Fulani darandaran lo bi ipade apero naa.
Oluwo tilu Iwo Ọba Abdulrasheed Adewale Akanbi si lo gbe igbesẹ gẹgẹ bi ọba alaye, lati mu alaafia wa laarin awọn agbẹ ati darandaran.
Ọba Akanbi ni igbesẹ naa yoo faye silẹ lati gbọ ẹhonu awọn igun gbogbo tọrọ aawọ laarin agbẹ olohun ọgbin ati darandaran kan, paapaajulọ nipinlẹ Ọṣun.
Lasiko ti a fi n ko iroyin yii jọ, awọn eekan gbogbo tọrọ abo ati idagbasoke kan nipinlẹ Osun ni wọn ti peju sibi ipade naa.
Ikọ iroyin BBC Yoruba si ti gunlẹ silu Iwo lati maa mu bi nnkan se n lọ nibẹ wa fun yin nibi ipade apero naa, ẹ maa fi oju sọna lati gbọ ẹkunrẹrẹ iroyin.
Baba Ijesa: Yomi Fabiyi ní àṣeyọrí ńlá ní gbígba béèlì Omiyinka jẹ́
Oríṣun àwòrán, YOMIFABIY/IYABO OJO INSTAGRAM
Nibayii to ku wakati diẹ ki awọn ọlọpaa gba oniduro James Olanrewaju, Baba Ijesa, awọn alatilẹyin rẹ kan ti n ṣọ ero ọkan wọn lori gbigba oniduro rẹ.
Ninu wọn ni Yomi Fabiyi ti oun naa jẹ gbajugbaja oṣere tiata ati alatilẹyin fun Baba Ijesa.
Fabiyi  sọ fun BBC pe nitori pe awọn kan n tapa si ofin Naijiria pe ki wọn fi Ijesa si ahamọ lai ṣe igbẹjọ rẹ, gbigba beeli rẹ yi jẹ aṣeyọri to lamilaka.
O ni ọrọ yii ki ba ma ri bẹẹ ṣugbọn ''ai fun awọn afurasi ni beeli jẹ ọna kan ti wọn fi n pa awọn eeyan lahamọ, ti wọn fi n pa wọn lẹnu mọ, ti wọn si fi n fi ẹtọ dun awọn eeyan''
Oríṣun àwòrán, Instagram
Fabiyi tẹsiwaju pe, awọn ko ni erongba lati ma ṣe ayẹyẹ lori gbigba beeli yii nitori igbẹjọ si wa niwaju ti Baba Ijesha yoo jẹ niwaju adajọ.
Yomi Fabiyi wa fi iyalẹnu rẹ han nipa gbogbo awọn ti wọn n sọ wi pe ki wọn mase fun Ijesa ni beeli.
''Ṣe iyẹn wa tumọ si pe wọn da lare ni? Gbogbo ẹni to ba n hu iru iwa yi, wọn wa lara awọn to n jẹ ki Naijiria maa ni ifasẹyin.''
O wa gba araalu ni imọran lati tẹle ofin Naijiria ki idagbasoke baale ba orileede naa.
Akungba Suicide: Ẹbí, ọ̀rẹ́ àti ọ̀gá iléẹ̀kọ́ sọ̀rọ̀ lórí irú èèyàn tí Feranmi Fasunle jẹ́
''Gbogbo wa la ni ipa la ti ko, ati oniroyin ati araalu,o yẹ ka lọ tun ero wa pa ki a ṣe ohun to tọ''
Lori boya yoo ṣi tẹsiwaju pẹlu atilẹyin fun Baba Ijesa, o ni oun ''ko si lẹyin ki eeyan fi irọ tabi amulumala lati fi ran ẹlomiran lẹwọn''
BBC Yoruba tun ba adẹrinposonu nni, Damilola Adekoya tawọn eeyan mọ si Princess sọrọ, ẹni tii se iya ọmọ ti wọn ni Baba Ijesha se asemase pẹlu rẹ.
Nigba to n ba wa sọrọ, Princess ẹni to mi kanlẹ wa sọ fun wa pe oun ko ni nkankan lati sọ lori ọrọ yii.
Asẹ́yìn, àwọn ẹbí olóògbé ṣì ń fomijé dárò àwọn tóṣìṣẹ́ 'Custom' yìnbọn pa nílùú Iseyin
A tun gbiyanju lati ba agbẹjọro Baba Ijesa naa sọrọ lori igbesẹ ti wọn n  gbe lati yanju gbogbo ohun to nii ṣe pẹlu gbigba oniduro rẹ.
Eeyan kan ti ko darukọ ara rẹ lo gbe ago ipe agbẹjọro Adesina Ogunlana, ti o si ni wọn ko ti le da wa lohun niisinyi.
Ireti wa ni pe wọn yoo pari gbogbo eto gbigba oniduro Baba Ijesa lonii, lẹyin ti ileeṣẹ ọlọpaa ni ko san ẹgbẹrun lọna ẹẹdẹgbẹta Naira fun gbigba oniduro rẹ.
Dapo Abiodun SSA: Ìjọba Ogun júwe ọ̀nà ilé fún amúgbálẹ́gbẹ́ẹ̀ tó ń jẹ́jọ́ ẹ̀ṣùn lílu jìbìtì
Oríṣun àwòrán, Facebook/Abidemi Rufai
Iroyin kan to n tẹwa lọwọ sọ pe amugbalẹgbẹ kan fun Gomina ipinlẹ Ogun, Abidemi Rufai, ti ko si gbaga awọn agbofinro FBI nilẹ Amẹrika.
Eyi ko si sẹyin ẹsun ti wọn fi kan pe o kopa ninu jibiti kan ti wọn fẹ lu ẹka to n pese iranwọ faraalu ti ko niṣẹ lọwọ ni Washington.
Gẹgẹ bi atẹjade ti agbẹjọro agba Tessa Gorman fi sita lorukọ ẹka ipese iranwọ ijọba, ọjọ Ẹti ni wọn mu afurasi naa ni papakọ ofurufu JFK.
Bakan naa ni wọn lo ṣagbatẹru awọn iwa jibiti to fẹ lu ijọba ni gbajuẹ owo to le ni ẹgbẹrun lọna ọtalelọọdunrun din mẹwaa dọla.
Lọjọru ni wọn yoo bẹrẹ igbẹjọ rẹ.
Africa Eye: Ahmed Isah rèé tíí ṣe ààrẹ lásán làsàn ní Nàíjíríà tí inú aráàlú dùn sí
Ẹwẹ, ijọba ipinlẹ Ogun ti sọrọ soke lori isẹlẹ yii, to si ni oun ko tako pe ki afurasi naa foju wina ofin lori ẹsun ti wọn fi kan.
Agbẹnusọ fun Gomina Dapo Abiodun, Kunle Somorin fi to BBC leti pe '' Ipinu ijọba ni pe ki afurasi naa foju wina ofin.
Ẹwẹ, Gomina Abiodun ti paṣẹ pe ki wọn da afurasi naa duro rẹ lẹnu iṣẹ, titi ti yoo fi jẹjọ tan lori ẹsun ti wọn fi kan.
O ni laipẹ, ijọba ipinlẹ Ogun yoo fi atẹjade kan sita lati sọ ipinnu rẹ lori isẹlẹ naa lẹkunrẹrẹ.
Kaduna strike : NLC fòpin sí ìyanṣẹ́lódì Ọlọ́jọ́ mẹ́rin ní Kaduna
Oríṣun àwòrán, El-rufai
Lale oni ojoru yìí ni egbe òṣìṣẹ́ ni Ipinle Kaduna fòpin sí ìyanṣẹ̀lódì tí wọ́n gin lè láti ọjọ́ merin seyinComrade Ayuba Magaji lọ fidie múlè fún BBC pé wọn tí wagbo dekun fún ìyanṣẹ́lódì náà. Wọn fòpin sí iyansẹ́lodi náà lẹ́yìn tí mínísítà ọ̀rọ̀ àwọn òṣìṣẹ́ fún Naijiria, Chris Ngige dá sii
O ni kété tí ilè bá mọ lọ́la ojobo náà ni wọn yóò pàdé mínísítà fún ọ̀rọ̀ òṣìṣẹ́ Ngige Chris ni AbujaComrade Ayuba ni Abuja ni wọ́n yóò ti yanjú gbogbo ọ̀rọ̀ to kú lola
Oríṣun àwòrán, El-Rufai
Àwọn aláṣẹ ìjọba ni ìpínlẹ̀ Kaduna ti pàá láṣẹ fún ilé iṣẹ́ ètò ìlèra láti fún gbogbo àwọn òṣìṣẹ́ nọ́ọ̀sì ilé iṣẹ́ náà ni ìwé lọ rọ́ọkún nílé, pàápàá jùlọ àwọn tó wà ni ipele kẹrinlá sí ìṣàlẹ̀ ti wọ́n sì dàrapọ̀ mọ́ ìfẹ̀hónúhàn tó ń lọ lọ́wọ́.
Oní ló pé ọjọ́ mẹ́ji ti ìyànṣẹ́lódì náà ti bẹ̀rẹ̀.
Ẹgbẹ́ òṣìṣẹ́ Nàìjíríà pè fún ìyànṣẹ́lódí lẹ́yìn ti gómìnà ìpińlẹ̀ náà Nasir El-Rufai yọ àwọn òṣìṣẹ́ ẹgbẹ̀rún méje níṣẹ́ láìrò tẹ́lẹ̀. Wọ́n gùnlé ìyásẹ́lódì ìkìlọ̀ ọlọ́jọ́ márùn, èyí sì tí dí ọ̀pọ̀lọpọ̀ nnkan lọ́wọ́ tó fi mọ́ ọ̀rọ̀ iná mọ̀nàmọ́nà, ọ̀kọ̀ ìrìnà àti ilé ìwòsàn.
Nínú àtẹjáde kan ti agbẹ̀núsọ gọmìnà ìpińlẹ̀ Kaduna Muyiwa Adekeye fọwọ sí ló ti sàlàyé pé pé ìjọba ko ni wẹyin wo lórí dídá àwọn òṣìṣk náà dúró nítorí pé gómìnà ni ìgbàgba pé nnkan to tọnà láti ṣe ni lati ran ipinlẹ naa lọ́wọ́ nipa didaabo bo owo ilu.
Bákan náà lo fi kun pé gbogbo òṣìṣẹ́ Fasiti Kaduna to ba dan iyanṣẹlodi naa wo laṣa ti ko lọ si ibiṣẹ ni oun yọọ niṣẹ, to fi mọ gbogbo àwọn òṣìṣẹ́ ile iṣẹ ijọba gbogbo, ki wọ́n si maa gbe iwe ti wọn fi n kọ orukọ ẹni to ba wa si ibiṣẹ wa si ile ijọba lojoojumọ.
BBC gbiyanju lati ba adari ẹgbẹ NLC sọrọ láti mọ nnkan ti wọn yoo ṣe nitori ọrọ ti gọmina sọ yìí sùgbọn wọn ko gbe aago.
Sanni Ashir to jé olùgbe ipinlẹ Kaduna to ba BBC sọrọ slaye pe ti wọ́n ba le awọn eniyan yii lẹnu iṣẹ ọrọ naa yoo tun buru si ni  paapaa julọ lẹka eto ilera.
Ni Bayii ọpọ ile iwosan lo ti wa ni titi pa, ti awọn eniyan si n gbadura ki wọn pa da si ẹnu iṣẹ ti gomina ba tun wa yọ wọn niṣẹ iṣoro naa yoo pọ si ni. Adura wa ni pe kii gbogbo wahala toi wa nilẹ yii pari kia
Ọjọ kẹta ree ti ko si ina to si ti pe ọjọ meji ti ko si ile epo kankan to n ta epo, eyi si ti mu ki ọpọ awọn ara ilu ko si inu wahala gidi.
Biola Fowosere sàlàyé ìdí tó fi n domilójú pòròpòrò ni ìtà gbangba
Biola Fowosere ti gbogbo ènìyàn mọ̀ sí Ewatomilola Asake ti ke gbàjare sí gbogbo ọmọ Nàìjíríà láti gbà òun lọ́wọ́ àwọn tó n já sọ́sbù rẹ̀ lójoojúmọ.
Ojú òpó Instagram rẹ̀ ló tí ń dòmí lójú pòròpò láti sọ ẹ̀dùn ọkàn rẹ̀.
Lásìkò tó n bá BBC Yorùbá sọ̀rọ̀ ló ti sàlàyé pé ìgbà kẹta rèé tí wọ́n já sọ́ọ̀bù òun, àti pé níwòyí ọdún tó kọjá ni wọ́n já sọ́ọ̀bù tí òun tún gbà.
"Fowosere ni: ""Osù mẹ́ta sẹ̀yin ni mo sí sọ́ọ̀bù yìí tí wọ́n tún wa ji kó yìí"""
"Gbogbo bí wọ́n ṣe n ko, tí mo bá ti lọ sọ fún ọlọ́paàá, wọ́n a wá wòó lẹ́yìn náà mí kò ni gba nǹkan kan"""
 Ní ọdún tó kọjá, wọ́n ji aṣọ tó tó Mílíọ̀nù kan àbọ̀ náírà sùgbọ́n títí dí òní mí o rí nǹkan kan
Face Transplant: DiMeo ṣùn lásìkò tó n wa ọkọ̀ lálẹ́, ló bá jóná nígbà tí ọkọ̀ gbiná
Ó ní àwọn ènìyànn mííràn ní irọ́ ni mò n pa, sùgbọ́n mí o gbàdúrà kí ó ṣẹlẹ̀ sí ẹnikkẹni
Gbájugbajà òṣèrè náà fi kun pé gbogbo ènìyàn tó bá n gbé àgbègbè Iwó ló mọ̀ pé a má n ran àwọn opó lọ́wọ́ ti a wọ́n sì tun máa n rọgunun sápa wọn.
Epe Fish Market: Wá wo oríṣi ẹja tí o rírí lọ́jà ẹja tó tóbi jùlọ ní Nàíjíríà
"Obìnrin náà ni oùn kò rí irú ǹkàn tó ṣẹlẹ̀ ni sọ̀bù òun rí, "" Wọ́n já sọ́ọ̀bù, wọ́n kọ gbogbo ọjà páta, won  gbé ẹrọ amúnáwá rl wọ́n sì tún gbe ẹrọ a mú omi tutu tó ń lò."
" Fridzer ti wọ́n gbé ga to mi lórí ìdúró, #110,000 ni mo ra ni olówónfowósàànú"" èèmèjì ni mo sanwó rẹ̀."""
Ó dúpẹ́ lọ́wọ́ gbogbo àwọn tó n pè, àti àwọn tó n fi àdúrà ran òun lọ́wọ́ àti àwọn tó fi owó ránṣẹ́.
Covid 19 fraud, Dapo Abiodun aid: Wo ǹkan méje tí o kò ma nípa Bidemi Rufai, tó wọ gàu l'Amerika lórí ẹ̀sùn jìbìtì N140m
Oríṣun àwòrán, @Bidemirufai
Wo kókó mẹ́jọ tó yẹ kí o mọ̀ nípa Abidemi Rufai
Lọkọ Aje, ọjọ kẹtadinlogun oṣu karun ọdun 2021 yii ni ẹka eto idajọ orilẹ-ede Amẹrika kede pe oun ti gbe oludamọran Gomina Dapo Abiodun ipinlẹ Ogun, Abidemi Rufai lọ si ileẹjọ lori ẹsun lilu jìbìtì $350,000.
Ọdun 2020 ni Gomina ipinlẹ Ogun yan Rufai sipo ọkan lara awọn oluranlọwọ rẹ.
Ṣugbọn Gomina Abiodun ti jawe gbele ẹ fun Rufai lati igba ti iroyin ọhun ti jade lati Amerika.
Wọnyii ni koko mẹjọ ti o yẹ ki o mọ nipa oluranlọwọ gomina ipinlẹ Ogun ti wọn gbe lọ si ileẹjọ lorilẹede Amerika lori ẹsun jibiti owo.
1. Abidemi Rufai fi igba kan dupo sí ile igbimọ aṣoju-ṣofin l'Abuja lẹkun aarin gbungbun Ijebu labẹ asia ẹgbẹ oṣelu APC.
2. Ọmọ ọdun mejilelogoji ni Rufai í ṣe, o si n gbe ni agbegbe Lekki niluu Eko
Epe Fish Market: Wá wo oríṣi ẹja tí o rírí lọ́jà ẹja tó tóbi jùlọ ní Nàíjíríà
3. Rufai ni iṣẹ kara kata ilẹ ati ile ni oun n ṣe.
Ko da, o ni oun ni oludasilẹ ileeṣẹ Omo Mayodele Educational Foundation to maa n ran awọn ti ko rọwọ họri lawujọ lọwọ.
4. Ọjọ Ẹti tii ṣe ọjọ kẹrinla oṣu karun un ọdun 2021 ni wọn mu Rufai lori ẹsun jibiti owo to to ogoje mílíọ̀nù naira, N140m.
Face Transplant: DiMeo ṣùn lásìkò tó n wa ọkọ̀ lálẹ́, ló bá jóná nígbà tí ọkọ̀ gbiná
5. Gẹgẹ bí ohun tí ẹka eto idajọ orilẹ-ede Amẹrika sọ, laarin oṣu kẹta sì ikẹjọ ọdun 2020 ni Rufai Lu Jibiti owo naa
6. Rufai lo ọpọ awọn olugbe ilẹ Amerika ni Washington bíi ọgọrun lati lù Jibiti ogoje mílíọ̀nù naira owo to yẹ kó ṣanfaani fáwọn ti covid-19 ti ṣakoba iṣẹ wọn.
7. Ọjọ kọkandinlogun oṣu karun ọdun 2021 ni ignẹnọ Rufai bẹrẹ nile ẹjọ.
8. Ti o ba jẹbi awọn ẹsùn tí wọn fi kan an, Rufai le lọ fi aṣọ penpe roko ọba fún ọgbọn ọdun.
Katsina kidnap: Àwọn ajínigbé gbé Adájọ lọ nílé ẹjọ́
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Eemọ lukutu pẹbẹ, ọmọ loyun tan, iya gbe e sita.
Awọn janduku ajinigbe ti gbe Adajọ kan lọ nílé ẹjọ nipinlẹ Katsina.
Agbẹnusọ ileeṣẹ ọlọpaa ipinlẹ Katsina, SP Gambo Isah lo fidi ọrọ naa mulẹ fawọn akọroyin.
SP Isa ni iṣẹlẹ ọhun ṣẹlẹ ni bíi ago mẹta ọsan ninu kootu to wa ni ijọba ibilẹ Safana.
Agbẹnusọ ileeṣẹ ọlọpaa ni oun ko le sọ idi ti Adajọ naa fi lọ sí ileẹjọ lai sí ẹṣọ kankan pẹlu rẹ.
Isah fikun ọrọ rẹ pe gbogbo ileẹjọ lo wa ni titi pa bayii nitori iyanṣẹlodi awọn oṣiṣẹ eto idajọ.
Epe Fish Market: Wá wo oríṣi ẹja tí o rírí lọ́jà ẹja tó tóbi jùlọ ní Nàíjíríà
O ṣalaye pe adajọ naa lọ sí ileẹjọ lati mu nkan nibẹ ni niwọn igba ti awọn oṣiṣẹ ẹka eto idajọ n yanṣẹ lodi lọwọ lọwọ.
O yẹ ki adajọ yii beere fun agbofinro ti yoo tẹ le e lọ síbẹ pẹlu iṣoro eto abo to mẹhẹ ni Naijiria bayii, agbẹnusọ ọlọpaa lo sọ bẹẹ.
O ni ileeṣẹ ti bẹrẹ iwadii lati mọ ohun tó mu ki adajọ naa da lọ sile ẹjọ lai mu agbofinro lẹyin.
Face Transplant: DiMeo ṣùn lásìkò tó n wa ọkọ̀ lálẹ́, ló bá jóná nígbà tí ọkọ̀ gbiná
Lagos sexual offences: Àwọn afurasí afipábánilòpọ̀ 206 wọ gàu l'Eko
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ọjọ gbogbo ni tole, ọjọ kan bayii ni ti oloun gẹgẹ Yoruba ṣe maa n wi.
Ijọba ipinlẹ Eko ti kede pe ọwọ ti tẹ afurasi afipabanilopọ mẹfa le lugba kaakiri ipinlẹ naa.
Kọmiṣọnna eto idajọ to tun jẹ agbẹjọro agba ipinlẹ Eko, Moyosore Onigbanjo lo fidi ọrọ yii mulẹ fawọn akorọyin nileeṣẹ ijọba ni Alausa, Ikeja.
Onigbanjo ṣalaye pe igba eeyan ati mẹfa lawọn ti ẹsun ti wọn kan wọn niiṣe pẹlu ifipabanilopọ ninu ojilelugba eeyan le ẹyọkan ti wọn n ka ọwọ sẹyin rojọ.
Bakan naa ni kọmiṣọnna eto idajọ sọ pe awọn ileẹjọ alagbeka ti ijọba ṣẹṣẹ da silẹ gbọ ẹjọ to le lẹgbẹẹrun lọna ọgọta laarin ọdun kan.
Epe Fish Market: Wá wo oríṣi ẹja tí o rírí lọ́jà ẹja tó tóbi jùlọ ní Nàíjíríà
O ni awọn awakọ to n rin loju ọna bọọsi BRT, awọn to n taja loju titi to fi mọ awọn to n tapa si ofin ati dena itankalẹ arun covid-19 lo ti foju ba ileẹjọ.
Onigbanjo fikun ọrọ rẹ pe ẹjọ to din diẹ ni ẹgbẹrun meji lo wa kaakiri ileẹjọ giga ati ileẹjọ majisreeti to fi mọ awọn afurasi mẹwaa ti wọn lu awọn oṣiṣẹ LASTMA.
Face Transplant: DiMeo ṣùn lásìkò tó n wa ọkọ̀ lálẹ́, ló bá jóná nígbà tí ọkọ̀ gbiná
Kọmiṣọnna eto idajọ tun ṣalaye pe awọn to n taja loju titi, awọn to n ri kaakiri at'awọn ti wọn fẹsun kan lori ọrọ ayika yoo ṣiṣẹ sin ilu fun ijiya ẹṣẹ wọn.
Onigbanjo fi dawọn eeyan ipinlẹ Eko loju pe ijọba yoo maa tẹsiwaju lati maa ba awọn agbofinro ṣiṣẹ lati gbogun ti iwa ibajẹ.
Baba Ijesha: Àwọn ọlọ́paàá àti àwọn agbẹjọ́rò kan ló fẹ́ gba owó, kí wọ́n to fi Omiyinka sílẹ̀
Asaaju ikọ agbẹjọ́rò fun bàbá Ìjẹshà,  Adesina Ogunlana ti ke gbàjàrè pé, ó ti pé ọjọ́ kẹrin báyìí ti wọ́n ti fi Bàbá Ijesha sílẹ̀ láti gba onídurò rẹ̀ sùgbọ́n àwọn ọlọ́paàá kọ̀ láti tu sílẹ̀.
Lásìkò tó ń bá BBC Yorùbá sọ̀rọ̀ lọ́sàn òní ló sàlàyé pé gbogbo ìgbìyànjú òun láti gba Bàbá Ijẹsa sílẹ̀ ni àgọ́ àwọn ọlọ́paàá lo já si pàbo.
Gẹ́gẹ́ bi ó ṣe sọ, àwọn ìlànà tí adájọ́ gbé sílẹ̀ fún ìtúsílẹ̀ Bàbá Ijesa ló rọ̀rùn, gbogbo rẹ̀ si ti wà nílẹ̀.
Sùgbọ́n owó tí wọ́n sọ pé kí ó wà nílẹ̀ fun beeli nítorí ti Baba Ijesha bá sálọ, ni àwọn oníduró yóò san, sùgbọ́n àwọn ọlọ́paàá ni ti àwọn kò bá rí owó náà àwọn ko ni fí sílẹ̀.
Nínú àlàyé rẹ̀, o ní màgòmágo ọlọ́pàá àti apá kan àwọn agbẹ́jọ́rò tó n dúro fún Baba Ijesha, ló n fa ìdádúró.
Down Syndrome Skill centre: Wo bí ọmọ tí ọpọlọ wọn kù díẹ̀ ṣe ń kọ́ iṣẹ́ agẹrun
Ogunlana ni obìnrinn náà kọ́kọ́ fẹ̀sùn kan òun pé kíló de ti òun fi lọ sọ lori ayelujára pé Bàbá Ijesa rù.
Nígbà tí mo de àgọ ọlọ́pàá, mó lọ bá ọlọ́pàá tó n moju to ọ̀rọ̀ Baba Ijesha, Magret Ighodalo to jẹ́ olórí alábòjútó ọrọ to níi ṣe pèlú ọrọ sise obinrin básubàsu.
Ogunlana ni obìnrinn náà kọ́kọ́ fẹ̀sùn kan òun pé, kí ló de ti òun fi lọ sọ lori ayelujára pé Bàbá Ijesa rù, tó sì bá òun jiyàn pé kò rù, bíkòṣe pé nígbà tó dé ọ̀dọ̀ àwọn gan ló sanra si.
Agbẹ́jọ́rò náà ni èyí ló mú òun fèsì pé ó rù, kóda kò tún le rìn dáradára, ó fi kun pé ṣe ni Baba Ijesha ń wo sùù bi ẹni ti wọ́n ti kó láyà jẹ, àfi ìgbà tí òun pariwo mọ pé, ṣe kò mọ òun gẹ́gẹ́ bi agbẹ́jọ́rò rẹ̀ ni?
Epe Fish Market: Wá wo oríṣi ẹja tí o rírí lọ́jà ẹja tó tóbi jùlọ ní Nàíjíríà
"Ọgbẹni Ogunlana ni lẹ́yìn ti òun bèèrè fún fóònù rẹ̀ láti le pe àwọn ẹbi rẹ̀, ki gbogbo èto le bẹ̀rẹ̀ ni Baba Ijesa sọ fun òun pé, fóònù wà lọ́wọ́ ""Madam"" (Magret Ighodalo)."
O ni sùgbọ́n lẹ́yìn tí òun gbìyànjú láti gba fóònù náà ni wọ́n sọ pe ko si ina lórí rẹ, àti pé lẹ́yìn wákàti kan ti wọ́n fi fóònù náà sínú iná, síbẹ̀ wọn ko fún òun ni àànfàní láti ri ẹbi kankan bá sọ̀rọ̀..
Àṣẹ̀yìnwá àṣẹ̀yìn bọ̀, Magret Ighodalo sọ pé Baba Ijesha ni agbẹjọ́rò mííràn, òun si fẹ́ kí wọ́n jọ ma ṣe iṣẹ́ pọ̀ fún Bàbá Ijesa.
" Mó wa ni ṣe o kò mọ̀ mi ni? Ṣe bi ìwọ náà lo fun mi ni nọnba ẹni naa sáájú àsìkò yìí?
Sùgbọ̀n nǹkan tí mo sàkíyèsí ni pe ni pé, wọ́n ti ko baba Ijesa láyà jẹ àti pé, àwọn agbẹ́jọrò kan wa tí wọ́n ti lẹ̀dí àpò pọ̀ mọ́ àwọn ọlọ́pàá lórí ọ̀rọ̀ Baba Ijesa."
Asẹ́yìn, àwọn ẹbí olóògbé ṣì ń fomijé dárò àwọn tóṣìṣẹ́ 'Custom' yìnbọn pa nílùú Iseyin
"Lẹ́yìn ti mo pé agbẹ́jọ́rò náà, ṣe lo jágbe mọ́ mi, tó sì pa fóònù rẹ̀, mo tun padà rán àwọn ọmọ mi pada ní ìrọ̀lẹ́, níbẹ̀ ni wọ́n ti sọ pé ẹ̀ẹ́dẹ́gbẹ̀ta nàìrà tó wà nínú ètò beeli rẹ̀, o di dandan ki wọ́n san."""
Ogunlana sàlàyé pé, owó yìí kìí ṣe fún ṣisan, wọ́n yóò bèèrè fun-un, tí Baba Ijesa ba sálọ ni lẹyin ti wọn ti gba oniduro fun tan.
Sùgbọ́n nnkan ti mo ri ni pe àwọn ọlọ́pàá àti àwọn agbẹjọ́rò kan ni wọ́n jọ n pàdí àpò pọ̀, tí wọ́n si n pé àwọn ènìyàn láti san owó sí àkàntì Baba Ijesa, ki owó náà fi le pé láti pin láàrín ara wọn.
Ansoogun jagunjagun Iresa Adu Ogbomoso tó máa ń bínú gba ẹbọ- Oloye James Olawale
Lọwọ lọwọ bayii, Ogunlana ni awọn ọlọpaa ni owow tawọn eeyan n da jọ lati fi san beeli naa ti to ẹgbẹrun lọna ọọdunrun naira, ₦300,000, o si seese ki wọ̀n fi silẹ, ti owo naa ba pe.
"Emi yari mọ awọn ọlọpaa naa lọwọ ni nigba ti wọn ni ka wa san ẹgbẹrun lọna ẹẹdẹgbẹta owo beeli, iru radarada wo niyẹn, nibo ni wọn ti n sanwo beeli?
Baba Ijesha: Iyabo Ojo ní ìṣẹ̀lẹ̀ yìí ti tú àṣírí báwọn oníwàkòtọ́ ṣe pọ̀ sí ní Nàìjíríà
Oríṣun àwòrán, other
Gbajumọ oṣere tiata, Iyabọ Ojo ti ṣalaye idi to fi lewaju iwọde lọ tako itusilẹ akẹgbẹ rẹ to wa lahamọ ọlọpaa ni Panti nilu Eko.
Iyabọ Ojo ṣalaye ọrọ yii ninu fidio kan tose lati ba awọn ololufẹ rẹ sọ loju opo Instagram rẹ.
Osere tiata lobinrin naa ni saaju asiko yii, ohun ti awọn kan gba lero ni lati gba ẹyinkule tu Baba Ijesha silẹ yala nitoripe o jẹ gbajumọ lawujọ ni tabi ọwọ awọn alagbara ati alẹnulọrọ kan wa lẹyin rẹ nigba naa.
O ni ko sẹni to ni ki Baba Ijẹsha maa wa sile o, ohun ti awọn fẹ ni pe wọn ko gbọdọ tu u silẹ lọna ẹburu, ti araye yoo wa maa beere pe nibo lo wa tabi ta lo gba beeli rẹ, lasiko ti ile ẹjọ ba pada sẹnu iṣẹ ni ipinlẹ Eko.
O jẹ ko di mimọ pe, oun ko lee wẹyin wo lori ọrọ naa nitori pe Baba Ijesha gbọdọ jẹjọ fun iwa aitọ to hu si ọmọdebinrin naa.
Epe Fish Market: Wá wo oríṣi ẹja tí o rírí lọ́jà ẹja tó tóbi jùlọ ní Nàíjíríà
Ohun to mu wa lọ si ọdọ awọn ọlọpaa lakọkọ lati gbe ohun wa soke tako beeli Baba Ijesha ni pe, wọn fẹ tu Baba Ijẹṣha silẹ, ki wọn si fi awuruju pa ina ọrọ naa mọ abẹ aṣọ."
"Awọn ibeere ti a si bi ọlọpaa nigba naa ni pe, ta lo n paṣẹ yii, ki ni awọn ilana ti ofin n beere fun beeli rẹ nigba naa,'ta lo fẹ gba oniduro rẹ amọ ti a ko ri esi kankan."""
Iyabo Ojo ni ohun ti awọn dide fun nigba naa ni pe, bi o ba tilẹ jẹ pe wọn yoo tu Baba Ijesha silẹ, o gbọdọ jẹ ọna to ba ofin mu ni, dipo ọna awuruju to ni wọn kọkọ fẹ fi ṣe nigba naa nitoripe ilumọọka lẹni ti ọrọ kan.
Ohun to ja ju bayii ni pe wọn n tẹle ilana to yẹ dipo ti ọna irọ ti wọn fẹ lo tẹlẹ.
Iyabọ Ojo tun ṣekilọ fun awọn obi ati alagbatọ lati mojuto awọn ọmọ wọn daradara, lati daabo bo wọn lọwọ awọn agbaaya lọkunrin ati lobinrin ti wọn fi iwa ibajẹ fifi ibalopọ kotọ lọ awọn majesin lawujọ.
Akungba Suicide: Ẹbí, ọ̀rẹ́ àti ọ̀gá iléẹ̀kọ́ sọ̀rọ̀ lórí irú èèyàn tí Feranmi Fasunle jẹ́
O ni ọrọ Baba Ijesha naa ti wa fihan bi awọn eeyan to to n hu iwa aṣemaṣe si ọmọde, awọn afipabanilopọ ati oniwa aitọ sawọn ewe, ṣe pọ si lorilẹede Naijiria.
O wa salaye fun gbogbo awọn to n beere pe ṣe oun yoo ṣi ta ile oun, fi ṣe ẹjọ lori ọrọ Baba Ijesha pe, oun ṣetan lati ta ile oun.
Iyabo ni bi wọn ba fẹ ra ile naa nitori pe oniṣowo to fẹran owo loun, oun si setan ati ta ile naa to ba ti jẹ iye to tọna ni wọn ba fẹ raa.
Epe Fish Market: Wá wo oríṣi ẹja tí o rírí lọ́jà ẹja tó tóbi jùlọ ní Nàíjíríà
Yoruba ni ẹni ti ko ba de oko baba ẹlomiran ri, ni yoo ni oko baba toun lo tobi ju.
Bẹẹ ni ọrọ ri ni ọja ẹja ni Epe nibi ti oniruuru ẹja wa, pẹlu orukọ to le ni aadọta.
Lara awọn ẹja to wa nibẹ ni Ọsan, Ekuya, Owere, Ede, Salaporẹ, Kuta, Epiya, Ofan, Safu, Igangan ati bẹẹ bẹẹ lọ.
Koda, ẹnu ko gba iroyin nigba ta foju kan awọn ẹja miran ti ori wọn to ti ọmọ tuntun.
Nigba ti wọn n ba BBC Yoruba sọrọ, ọpọ awọn apẹja yii, ti obinrin wa ninu wọn salaye awọn ipenija ti wọn n koju lẹnu isẹ naa.
Lara rẹ ni owo gege to n gun ori awọn ati ọkọ oju omi ti wọn fi n pa ẹja.
Ẹnu ko gba iroyin, ẹni to ba de ibẹ lo le sọ, ẹ ba wa kalọ silu Epe lati foju gan ni ohun ta n sọ.
Baba Ijesha: Agbẹjọ́rò ní àwọn kan ló dúró pé ojú ló fi ri béélì, ètè rẹ̀ kò ní bà á
Oríṣun àwòrán, babajesa/Instagram
"Ariwo ""nibo ni Baba Ijẹṣa wa? Nibo ni Baba Ijẹṣa wa?"" ni ibeere ti ọpọ n beere lori ayelujara bayii."
Ibeere naa gbalẹ kan lẹyin wakati mejidinlaadọta ti adajọ ile ẹjọ Majisireeti agba kan nipinlẹ Eko, fun gbajumọ oṣere tiata Yoruba, Olanrewaju Omiyinka ti ọpọ mọ si Baba Ijẹṣa ni anfani beeli,
Ibeere si idahun yii ni pe, titi di asiko ti a fi n ko iroyin yii jọ, ahamọ ọlọpaa, ni ẹka ọtẹlẹmuyẹ to wa ni Panti nilu Eko ni Baba Ijesha ṣi wa o.
Ki wa lo sokunfa bi ọrọ yii se ri, ki lo n da Baba Ijesha duro lati lọ sile lẹyin ọjọ meji to gba beeli?
Nigba to n wa idahun si awọn ibeere yii, ti BBC News Yoruba takoto rẹ si, ọkan lara awọn agbẹjọro Baba Ijesha, Amofin Adeshina Ogunlana ṣalaye wi pe, wọn ko tii ri ọrọ beeli rẹ yanju ṣugbọn o ṣeeṣe ki ọsan ko so didun laipẹ.
Epe Fish Market: Wá wo oríṣi ẹja tí o rírí lọ́jà ẹja tó tóbi jùlọ ní Nàíjíríà
Ni bi mo ṣe mọ ati bi mo ṣe wa yii, O (iyẹn Baba Ijesha) ṣi wa nibẹ (Panti)
Nigba ti a beere nipa igba ti o ṣeeṣe ki nnkan bọ soju ọwọ fun agba apanilẹrin naa, Amofin Ogunṣina ni oun a fẹ ki a ṣi ni suuru di irọlẹ Ọjọru lati mọ bi nnkan yoo ṣe lọ si fun.
Bakan naa ni agbẹjọro naa ko ṣalaye nipa ilana gbigba beeli afurasi naa to takoko, ti wọn ko tii ri ọna se amusẹ rẹ fun gbigba beeli afurasi naa.
Amofin Adeshina Ogunṣina wa kọminu lori ilana eto idajọ ati ofin lorilẹede Naijiria.
Africa Eye: Ahmed Isah rèé tíí ṣe ààrẹ lásán làsàn ní Nàíjíríà tí inú aráàlú dùn sí
O ni o ṣeni laanu pe, bi ofin to tọ ṣe wa to lorilẹede Naijiria, awọn to wa ni idi aro ifidimulẹ ofin wọnyi ni ka bẹ, lati ṣe ohun to tọ nigba gbogbo.
"Amofin ni ohun to ku diẹ kaa to ni pe adajọ ni lati dide lọ si ahamọ ọlọpaa ni Panti, lati rii daju pe idajọ ododo wọle tọ Baba Ijẹṣa lọ amọ sibẹsibẹ, o ni awọn kan ṣi duro ni iduro pe 'oju lo fi ri beeli naa, ete rẹ ko ni kan an"""
Ordinary President: Inú mi kò dùn pé mo gbá obìnrin létí lórí afẹ́fẹ́
Gẹgẹ bi baba, inu mi ko dun si bi mo ṣe da igbati bo obinrin lori afẹfẹ.
Gbolohun abamọ to n jade ree lẹnu Ordinary Ahmed Gbajugbaja atọkun eto ajafẹtọmọniyan kan ni ilu Abuja .
Ahmed, ti ọpọ mọ si Ordinary President ṣalaye idi to fi hu iwa yii, to si ni inu oun ko dun si iwa aibọwọ fun ẹtọ ọmọniyan toun hu yii.
Ninu fọnran fidio kan to fi si oju opo Youtube lo ti sọrọ naa ni idahun si ariwo to gbode lẹyin fọnran fidio iwadii BBC, to ṣafihan aṣemaṣe ti ajafẹtọ yi hu si arabinrin kan.
Africa Eye: Ahmed Isah rèé tíí ṣe ààrẹ lásán làsàn ní Nàíjíríà tí inú aráàlú dùn sí
Obinrin yii lo da karosini sori ọmọdebinrin ọmọ ọdun mẹfa lori to si dana sun.
Oludasilẹ ati oludari ileesẹ eto Berekete Family ni lọjọ ti iṣẹlẹ yii waye, o ti rẹ oun gan nitori oun da eeyan to to igba lohun.
''Lọwọ irọlẹ ti a ti pari eto tan, ni wọn ṣẹṣẹ gbe arabinrin naa ati ọmọde to bu kẹrosini si lori wa.
Bi obinrin naa ti ṣe n sọrọ ko ṣe bi ẹni to kabamọ nkan to ṣe rara. Koda awọn eeyan mii to wa nita fẹẹ le maa lu obinrin naa nitori bo ti ṣe n sọrọ.''
Oríṣun àwòrán, Screen Shot
O tẹsiwaju pe ''Aworan fidio ti ẹ ri yẹn, BBC ati Peter Nkanga ati awọn ti wọn jijọ wa ya, wọn kan gbe ibi to wu wọn sita ni .
Mo rọ gbogbo ẹyin alatilẹyin berekete family kaakiri agbaye, kẹ ṣadura pe gbogbo nkan ti BBC ati awọn ti wọn ṣiṣẹ yii ba gba lero, ki ero wọn maa pada si wọn lori.''
O ni ki awọn eeyan fi ọrọ ro ara wọn wo gẹgẹ bi obi, ki wọn to le da oun lẹbi pe oun gba arabinrin kan leti lori afẹfẹ.
Lẹyin naa lo sọ bi oun ti ṣe digbaju ru obinrin naa.
Epe Fish Market: Wá wo oríṣi ẹja tí o rírí lọ́jà ẹja tó tóbi jùlọ ní Nàíjíríà
''Nkan ti mo fẹ wadi lọdọ rẹ ni pe, ta lo sọ fun pe Ajẹ ni ọmọde yi? Iwadii yii ni mo n ṣe ti inu fi bi mi, ti mo fi gba oju ẹ.
Mo tọrọ aforiji, inu mi ko dun si nkan ti mo ṣe yii wi pe mo fọ obinrin leti.
O ni gẹgẹ bi ẹlẹran ara,''mi o ni ọmọ ọkunrin, ọmọ obinrin meji ni mo ni, mo wa fi ọrọ ro ara mi wo, lo mu mi ṣe bẹẹ.
Gbara ti mo da igbati bo arabinrin naa, ni mo bẹrẹ si ni kabamọ nkan ti mo ṣe.
Lara ọrọ ti Ahmed sọ ninu fọnran naa tun ni bo se naka abuku si oniroyin iwadii Peter Nkanga pe awọn ọta oun ati awọn eeyan kan ninu ijọba lo lo o lati wa iṣubu oun.
Asẹ́yìn, àwọn ẹbí olóògbé ṣì ń fomijé dárò àwọn tóṣìṣẹ́ 'Custom' yìnbọn pa nílùú Iseyin
O ṣalaye pe awọn ileeṣẹ ijọba ti ko mojuto ojuse wọn, kii ṣe pe oun n bawọn du ipo, bi kii ṣe pe oun ṣe aanu fawọn mẹkunnu.
Gẹgẹ bo ti ṣe sọ, ka ni wọn n ṣe ojuṣe wọn ni, awọn eeyan ko ni maa wa sori eto lọdọ rẹ.
Lizzy Anjorin: Èmi ń ṣiṣẹ́, obìnrin yìí ń gba owó láti fi ṣe àríyá
Oríṣun àwòrán, Lizzy Anjorin/Instagram
Iroyin nipa osere tiata ati onisowo nni, Lizzy Anjorin ati ọkọ rẹ lo tun n rugbo ni ori ayelujara lọwọ lọwọ bayii.
Eyi ko si sẹyin bi obinrin kan ti wọn pe orukọ rẹ ni Fola Tinubu se n pariwo Lizzy ati ọkọ rẹ, Alhaji Lawal lori ayelujara.
Fola lo kede fawọn akọroyin lori ayelujara pe iya n jẹ oun, ti oun ko si nile lori nitori bi Lizzy Anjorin se gba ọkọ oun, to si bimọ fun.
Bakan naa lo fun wọn ni ohun to gba silẹ nipa itakurọsọ lori foonu laarin ohun ati Alhaji Lawal yii, nibi to ti n beere pe ki onitọun fi owo ransẹ si oun.
Eyi lo mu ki Lizzy wa se fidio kan soju opo Instagram rẹ, to fi n fun obinrin naa lesi pe oun ko ni orogun rara, nitori oun nikan ni iyawo ti ọkọ oun fẹ.
Oríṣun àwòrán, Instagram/ Lizzy Anjorin
Nigba to n sọrọ lori bi obinrin ọlọmọ mẹta naa se ni iya n jẹ oun, Lizzy wa se afihan bi obinrin naa se gba owo to le ni ẹgbẹrun lọna ọọdunrun naira laarin osu Januari nikan.
"Fola, o kan bimọ fun ọkọ mi ni, o kii se iyawo rẹ rara nitori ko ba ọ se igbeyawo tabi so yigi fun ọ.
Laarin osu kinni ọdun si akoko yii, owo to ti gba lọwọ ọkọ mi to miliọnu kan naira, to si tun lọ ba baba onile rẹ pe ko parọ pe o ko tii sanwo ile.
Ti mo ba jẹ eeyan buruku ni, n ko ni jẹ ki ọkọ mi fun ọ ni owo tabi Jeep Exterra ti mo ni ki ọkọ mi gbe fun ọ, bẹẹ ni emi ni mo jẹ ki ọkọ mi gba oyun nigba to loyun."
Epe Fish Market: Wá wo oríṣi ẹja tí o rírí lọ́jà ẹja tó tóbi jùlọ ní Nàíjíríà
Bakan naa tun ni Lizzy se afihan agbasilẹ fọnran ohun itakurọsọ laarin ọkọ rẹ, Lawal ati Baba Onile naa, ti onitsun si n salaye pe obinrin naa lo ni ki oun parọ pe ko tii sanwo ile.
Bakan naa ni Lizzy tako obinrin naa peirọ nla ni aworan to n gbe kiri pe oun se igbeyawo pẹlu ọkọ oun, nitori aworan naa ni wọn ya nigba ti wọn n fi obinrin naa joye.
Lizzy wa n sọ fun obinrin naa pe to ba jẹ pe bi oun se ranti rẹ, naa lo jẹ ki Lawal ranti awọn eeyan to saaju tiẹ naa ni, ko ba ri wọn pe loni.
O fikun pe kii kuku se pe Fola yii nilo owo amọ o mọọmọ se fọnran ohun naa sita lati wọ oun nilẹ ni, ti Ọlọrun yoo si gbe oun leke gbogbo wọn.
Akungba Suicide: Ẹbí, ọ̀rẹ́ àti ọ̀gá iléẹ̀kọ́ sọ̀rọ̀ lórí irú èèyàn tí Feranmi Fasunle jẹ́
Wayi o, Lizzy Anjorin ti sọ fun obinrin ti wọn dijọ n fa surutu naa pe fọọmu fun ayẹwo DNA ti wa nilẹ fun, to si se afihan awọn fọọmu naa.
"Ọmọ mẹta lo sọ fun araye pe o bi fun wa, agbẹjọro yoo pe ọ ni ọjọbọ ọla, to ba lọ se DNA naa, ko to kuro nibẹ, maa fi owo ransẹ si ọ, ko lọ se tara rẹ naa, ko ma baa da bii magomago.
To ba jẹ Lawal lo ni ọmọ mẹtẹẹta, a yanju rẹ amọ to ba jẹ ẹyọ kan tabi meji ni ti Lawal nibẹ, a maa ja."
Africa Eye: Ahmed Isah rèé tíí ṣe ààrẹ lásán làsàn ní Nàíjíríà tí inú aráàlú dùn sí
Nigba to n fesi lori bi awọn eeyan se n yọ suti ete si ọkọ rẹ pe owo osere tiata naa lo n na lai ni isẹ kan pato lọwọ, lizzy salaye pe okoowo jọ pa oun ati ọkọ oun pọ ni.
"Lawal kii se Jigolo, ibudo to ti n ta mọto mẹta lo ni laarin Lekki si Ajah, to si tun ni ileesẹ ti wọn ti n fọ ọkọ.
Lawal n sisẹ takuntakun ni Owode onirin, to si maa n ba wọn ja irin, o maa n sisẹ kara, kii se eeyan buruku, ko si kundun obinrin.
Obinrin mẹrin lo wa nile bii ọmọ ọdọ mi, ko le dẹnu kọ ikankan wọn amọ oju aanu lo fẹ pa Lawal, yoo si dara ki Fola sọ iru eeyan ti lawal jẹ."
Lizzy wa n gba Fola nimọran pe ko ye na owo lori ayẹyẹ to maa n lọ, nitori ibẹ gan lo n na owo le lori.
Lizzy wa n kesi gbogbo awọn eeyan to n sepe fun lori ayelujara pe ayafi ti wọn ba le se ohun ti oun se fun obinrin naa ni erongba wọ̀n ko ni pada da le wọn lori.
Asẹ́yìn, àwọn ẹbí olóògbé ṣì ń fomijé dárò àwọn tóṣìṣẹ́ 'Custom' yìnbọn pa nílùú Iseyin
Lizzy Anjorin wa sisọ loju rẹ pe oun ti fi silẹ ninu akọsilẹ ogun oun pe gbogbo ọmọ ti ọkọ oun ba bi ati ti tiẹ naa, ni wọn maa pin ninu ogun oun.
O ni orukọ awọn ọmọ Fola wa ninu iwe akọsilẹ ogun naa, ati pe ni aduru gbogbo ọmọ ti oun kọ orukọ wọn silẹ lati pin ogun oun, ẹyọ kan soso pere ni ti oun.
O ni eyi fihan pe anfaani ti oun ba ni lati lọ silẹ okeere, ni awọn ọmọ obinrin naa ni pẹlu.
"Emi n sisẹ, amọ Fola n gba owo lati maa lọ si pati.
Down Syndrome Skill centre: Wo bí ọmọ tí ọpọlọ wọn kù díẹ̀ ṣe ń kọ́ iṣẹ́ agẹrun, ọ̀sìn adìẹ̀, ẹja àti aṣọ fífọ̀
Ẹda ko ni aropin, ko si dara ka maa ro eeyan pin nitori ko si ẹni to mọ ohun ti Ọlọrun yoo se.
Ọpọ ọmọ ti ọpọlọ rẹ ko pe to, ti wọn n pe ni aisan Down Syndrome lawọn obi wọn ti pa ti, pẹlu ero pe wọn ko le jẹ eeyan mọ nile aye.
Laipẹ yii si ni BBC Yoruba se fidio kan nibi ti baba kan, Usman Yahaya, to ni ọmọ alarun Down Syndrome yii, Dayo, ti safihan ọmọ rẹ to n kọsẹ ọwọ.
Igbesẹ yii lo wa yii ero ọpọ obi to niru awọn ọmọ bayii pada pe wọn si le se rere nile aye, ti ọpọ wọn si n tọ Baba Dayo lọ pe bawo lo ti see.
Eyi lo mu ki Yahaya da ibudo kan silẹ fawọn ọmọ to ni aisan Down Syndrome, nibi ti wọn ti n kọ isẹ ọwọ bii ọsin adiẹ ati ẹja, irun gigẹ ati asọ fifọ.
Àwọn ìtàn mánigbàgbé tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí:
Nigba to n ba BBC Yoruba sọrọ lori idasilẹ ibudo yii, Yahaya salaye pe o rọrun fawọn ọmọ to ni Down Syndrome lati kọsẹ ọwọ, to si rọ awọn obi lati mase ta wọn nu.
Oyo LG Polls: Alága OYSIEC ní APC fẹ́ sọ òun lẹ́nu nípa ìṣúnsíwájú ìbò tó ń bèèrè fún
Alága OYSIEC ní APC fẹ́ sọ òun lẹ́nu nípa ìṣúnsíwájú ìbò tó ń bèèrè fún
Awọn tọrọ kan nipa idibo ijọba ibilẹ to n bọ lọna nipinlẹ Oyo, ti n tako ara wọn nipa idibo naa ti yoo waye ni ọjọ Satide.
Eyi ko si ṣẹyin bi ẹgbẹ oṣelu APC nipinlẹ Oyo ṣe sọ pe ki ajọ eleto idibo OYSIEC, sun ọjọ idibo siwaju.
Alagba fẹgbẹ APC nipinlẹ Oyo, Oloye Akin Oke ti sọ fun awọn akọroyin ni Ọjọru pe, awọn fẹ isunsiwaju naa ki awọn ọmọ ẹgbẹ awọn le kopa ninu eto idibo naa.
Nigba to n ba BBC Yoruba sọrọ, Oke ni gbogbo eeyan lo mọ wi pe awọn n ṣe ẹjọ lọwọ lasiko to yẹ ki awọn gbaradi feto idibo naa, nitori naa, idibo abẹle ko le waye lasiko igbẹjọ.
Oke ni ọrọ ofin ati ilana ofin lọrọ to wa nilẹ yii tori naa, o yẹ ki ajọ OYSIEC fi igbalaye kalẹ fawọn lati gbaradi de idibo.
ALGON Oyo: Aleshinloye ní ìdájọ́ ilé ẹjọ́ tó ga jùlọ làwọn ń tẹ̀lé, kò sì yẹ kó fa ìjà
''Gẹgẹ bi ẹni to n fẹ alaafia, a kọ iwe si OYSIEC lori idi to fi yẹ ki wọn sun ọjọ ibo siwaju, alaafia ni awa n wa''
O ni amọ o ṣe ni laanu pe ajọ OYSIEC ti adari rẹ jẹ amofin, taku pe awọn yoo tẹsiwaju lati ṣeto idibo naa.
Amọ ṣa, o ni ẹgbẹ awọn yoo ''tẹle gbogbo ilana ofin lati le gba ẹtọ awọn bo ṣe yẹ''
Kini ajọ olominira eleto idibo OYSIEC sọ
Ninu ifọrọwerọ pẹlu alaga ajọ OYSIEC nipinlẹ Oyo, Isiaka Abiola Olagunju, o sọ fun BBC pe bi ẹni pe ẹgbẹ APC fẹ sọ awọn lẹnu ni pẹlu isunsiwaju eto idibo ti wọn n beere fun.
Olagunju ni ọjọ ti pẹ tawọn ti fi to APC leti wi pe idibo yoo waye, ṣugbọn wọn ko tete sọ pe awọn ko ni le kopa lọjọ ti wọn la kalẹ.
''Ni agbara Olorun, a ti se igbaradi, awọn to fẹ gba ohun eelo fun idibo naa ti wa ni ọfisi wa, a si ti gbe ilana jade saaju pe idibo yoo waye lọjọ Satide.''
Oríṣun àwòrán, @seyiamakinde
Oke ni loore koore lawọn n ṣe ipade pẹlu APC ati awọn ẹgbẹ yoku lori eto idibo yii ati pe APC ko foju han pe awọn ko ni kopa ninu idibo.
O tẹsiwaju pe, bawọn tiẹ fẹ sun ọjọ siwaju fun APC, awọn ẹgbẹ oselu mẹtadinlogun to ku ti wọn fẹ kopa ninu idibo ti sọ pe awọn ko le faramọ.
''Ohun ti ofin sọ ko ruju nipa idibo. A ko le tori ẹgbẹ kan, wa maa da awọn ẹgbẹ yoku duro nitori pe wọn lawọn fẹ gbaradi.''
Ohun ti ko ba dun mọ wa ni ki APC kopa, ki ẹsin wọn baa le han si araalu - PDP
Ẹgbẹ Oṣelu PDP naa ti sọ si ọrọ eto idibo ijọba ibilẹ to n mu awuyewuye dani nipinlẹ Oyo.
Akọwe ipolongo fẹgbẹ oselu PDP, onimọ ẹrọ Akeem Olatunji ni ki baa dun mọ awọn, ki APC kopa ninu idibo yii lọjọ Satide.
O ni idi ni pe araalu yoo lanfaani lati ri ẹsin wọn bi wọn ba kopa, ti yoo si han si wọn pe ilu ko fẹ wọn.
Down Syndrome Skill centre: Wo bí ọmọ tí ọpọlọ wọn kù díẹ̀ ṣe ń kọ́ iṣẹ́ agẹrun
''Erongba wọn ni pe wọn yoo ri idajọ ile ẹjọ ra ṣugbọn adajọ ja wọn kulẹ.
Ni bayi ti wọn si ti ri wi pe awọn ko ni le kọ esi idibo bi ti atẹyinwa, lo mu ki wọn ni awọn ko ni kopa''
Olatunji wa gboṣuba kare fun ajọ OYSIEC  lori ipinnu rẹ lati tẹsiwaju pẹlu eto idibo naa, to si ni awọn ni igbagbọ pe idibo ti ko lẹja n bakan ninu ni wọn yoo seto lọjọ Satide.
Oríṣun àwòrán, Ayodeji Aleshinloye
Ẹgbẹ oṣelu APC ti fi ẹsun kan Gomina ipinlẹ Oyo, Seyi Makinde pe o fẹ doju eto oṣelu tiwantiwa bolẹ nipinlẹ Ọyọ.
Ẹgbẹ oṣelu APC tun fẹsun kan gomina Seyi Makinde wipe o lo owo ilu basubasu lati ṣe idibo ti ileẹjọ ti fagile ni awọn ijọba ibilẹ.
Alaga ẹgbẹ oṣelu APC nipinlẹ Ọyọ, Oloye Akin Oke lo sọ bẹẹ nibi apero ẹgbẹ ati awọn akọroyin ti wọn se nilu Ibadan.
Oke ni Gomina Makinde pẹlu ajọṣepọ ajọ eleto idibo nipinlẹ Oyo, OYSIEC n ṣiṣẹ pọ lati doju eto oṣelu tiwantiwa bolẹ nipinlẹ naa.
O salaye pe eyi ri bẹẹ nitori bi wọn fẹ ṣe eto idibo ijọba ibilẹ ni lọjọ Satide ọtunla lai si ẹgbẹ oṣelu APC ninu awọn ti yoo dije dupo.
O ni o ṣe ni laanu wi pe ẹgbẹ oṣelu PDP ati OYSIEC yọ awọn kuro ninu awọn ẹgbẹ ti yoo kopa ninu eto idibo ijọ̣ba ipinlẹ naa.
Epe Fish Market: Wá wo oríṣi ẹja tí o rírí lọ́jà ẹja tó tóbi jùlọ ní Nàíjíríà
''Ẹgbẹ oṣelu APC ni awọn alaga ijọba ibilẹ to bori ninu idibo ijọba ibilẹ to waye ni ọdun 2018 ti wa, ti ileẹjọ si paṣẹ wi pe yiyọ wọn nipo ko ba ofin mu.
Bakan naa ni iye owo ti Ajọ eleto idibo OYSIEC ni ki awọn oludije ma a san , to jẹ N250,000 ati N100,000 lati dije dupo alaga ati councilor ko ba ofin mu.
Igbesẹ ijọba PDP labẹ aṣẹ Makinde yii ko ba ofin mu, nitori naa wọn gbọdọ fi aye silẹ fun awọn ẹgbẹ oṣelu to ku lati ṣe iforukọsilẹ.''
Alaga ẹgbẹ oṣelu APC nipinlẹ Ọyọ naa ni awọn lero wi pe ijọba Makinde yoo tun ero rẹ pa lori idibo ijọba ibilẹ ti yoo waye ni Ọjọ Satide.
Amọ, Oloye Oke ni ti wọn ko ba da eto idibo ijọba ibilẹ naa duro, awọn n gba ileẹjọ lọ.
Wọn wa rọ Adajọ Agba nipinlẹ Ọyọ lati dasi ẹjọ ti wọn pe tako eto idibo ijọba ibilẹ naa, ki idajọ otitọ le jọba ni kiakia.
Ijebu Ode Murder: Ìyàwó tuntun bẹ ọkọ rẹ̀ wò, ní ìyàwó kẹrin bá gún ọkọ pa
Oríṣun àwòrán, Guardian
Ara meeriri, mo ri ori ologbo lori atẹ ni isẹlẹ to waye nilu Ijebu Ode, nipinlẹ Ogun.
Obinrin kan ti wọn pe ni Olanshile Nasirudeen tii se ẹni ọdun mẹtadinlaadọta lo sadede gun ọkọ rẹ ni ọbẹ pa nitori pe o fun obinrin miran loyun.
Agbẹnusọ fun ileesẹ ọlọpaa ipinlẹ Ogun, Abimbola Oyeyemi si ti fidi isẹlẹ naa mulẹ.
Iroyin naa ni obinrin to pa ọkọ rẹ, tii se ẹni ọdun mọkanlelaadọta, ni iyawo kẹrin, tawọn mejeeji si dijọ n sisẹ Alapata ni odo ẹran kan nilu Ijebu Ode.
Obinrin naa lo ri ẹni to loyun fun ọkọ rẹ ni Odo Ẹran, to si bẹrẹ si fi ọrọ wa lẹnu wo lori idi to fi n fẹ ọkọ oun.
Eyi lo fa ariyanjiyan laarin Olanshile ati ọkọ rẹ, ti esu si tapo si ọrọ wọn.
Down Syndrome Skill centre: Wo bí ọmọ tí ọpọlọ wọn kù díẹ̀ ṣe ń kọ́ iṣẹ́ agẹrun
Gẹgẹ bi agbẹnusọ fun ileesẹ ọlọpaa Ogun ti wi, Afurasi apaayan naa mu ọbẹ, to si kun ọkọ rẹ ni ẹyin ẹsẹ rẹ, to si fi ọbẹ ge isan rẹ."
Bi o tilẹ jẹ pe wọn tete gbe ọkunrin naa digbadigba lọ sile iwosan to wa ni arọwọto fun itọju, ti wsn si tun pada gbe lọ sile iwosan ijọba to wa nilu Ijebu Ode amọ ẹpa ko boro mọ.
Ile iwosan ijọba yii ni ẹlẹmi ti gba a nitori ẹjẹ pọ to da lara rẹ.
Idi ree ti Olanshile fi fẹsẹ fẹ nigba to gun ọkọ rẹ ni ọbẹ amọ tawọn osisẹ ọlọpaa tọpasẹ rẹ sibi to fi se buba ladugbo Mobalufon nilu Ijebu Ode.
Ọwọ si tẹ Olanshile nigba ti awọn eeyan kan fi isẹlẹ naa to ọga ọlọpaa to wa ni adugbo Obalende nilu Ijebu Ode leti.
Epe Fish Market: Wá wo oríṣi ẹja tí o rírí lọ́jà ẹja tó tóbi jùlọ ní Nàíjíríà
"Nigba ta fi ọrọ wa obinrin naa, tii se iyawo kẹrin lẹnu wo, o ni ọkọ oun lo kọkọ gba oun leti nitori pe oun bi iyawo rẹ tuntun pe kli lo wa se ni isọ rẹ.
A ti gbe oku oloogbe naa fawọn ẹbi rẹ, ki wọn le sin nilana ẹsin Islam lẹyin ta pari eto ayẹwo ta se fun."
Kọmisana ọlọpaa nipnilẹ Ogun ti wa pasẹ pe ki wọn gbe ẹsun ipaniyan naa lọ si ẹka ọlọpaaọtẹlẹmuyẹ ileesẹ ọlọpaa, ta mọ si CID.
Adebayo Shittu: Ajimobi ló ṣẹ̀ mí, n kò ṣẹ Ajimobi, ipò kan náà la jọ ń wá àmọ́ kò fẹ́ mi ní ìjọba
Oríṣun àwòrán, @adebayoshittuHM
Minisita tẹlẹ fun eto ibaraẹnisọrọ, ti tun se oludije tẹlẹ fun ipo gomina nipinlẹ Oyo, Amofin Adebayo Shittu, ti sọrọ lori bi wọn se yọ nipo Minisita.
Shittu lasiko to n ba BBC Yoruba sọrọ lasiko eto ifọrọwanilẹnuwo kan salaye lori ẹsun aisinru ilu (NYSC) ti wọn fi kan, ati bo se kuro ni ipo minisita.
Shittu ni kii se oun nikan ni oloselu ti ko sinru ilu, ki oun to de ipo oselu nitori gomina ana nipinlẹ Oyo, Abiola Ajimobi gan ko se NYSC, to fi di Sẹnetọ ati gomina.
Bakan naa lo mẹnuba pe, wọn gbe gomina Dapo Abiodun lọ sile ẹjọ lori irufẹ ẹsun aisinru ilu yii, to si jare bọ nitori ofin ti sọ irufẹ iwe ẹri to kere ju, ti oludije fun ipo oselu kan gbọdọ ni.
APC: òfin NYSC ti APC fi mú mi ni wọ́n kò lò fi mú Ajimọbi tí a kò jọ sìnrú ìlú
"O daju pe iwa magomago to waye ninu ẹgbẹ oselu APC lasiko ti Adams Oshiomole jẹ alaga lo mu ko rọrun fawọn ọta mi lati bori mi.
Ki lo de ti wọn fi yọ mi nipo minisita nitori ẹsun pe n ko sinru ilu, se bi Abiola Ajimobi ko se NYSC, to si se gomina ati Sẹnetọ.
Bakan naa, Dapo Abiodun niyẹn, wọn gbe oun naa lọ sile ẹjọ tori ẹsun pe ko sinru ilu, ti wọn ko si tori eyi gba ipo lọwọ rẹ, ofin sa ti sọ iwe ẹri to kere ju fun oludije kan lati ni."
Amofin Shittu, ẹni to tun sisọ loju rẹ pe, oun yoo tun dije fun ipo gomina nipinlẹ Oyo lọdun 2023, wa fi ọwọ sọya pe bi Ọlọrun ba fẹran ipinlẹ Oyo, yoo gba oun laaye lati di gomina.
Oyo LG Polls: OYSIEC ní APC ló yẹ kò bẹ aráàlú lórí àṣìṣe rẹ̀ nípa ìbò ìjọba ìbílẹ̀
Ni kete ti mo pari NYSC ni wọn dibo yan mi sile asofin ipinlẹ Oyo amọ ọrọ naa ti wa nile ẹjọ bayii.
Abiola Ajimobi sẹ mi, tori a dijọ n wa ipo kanna, ko fẹ mi ninu ijọba
Nigba to n sọrọ lori ajọsepọ rẹ pẹlu Abiola Ajimọbi, Adebayo Shittu ni gomina ana naa ti di oloogbe, ko si ni dara ki oun sọ awọn nnkan ti ko ni le fesi le lori.
O ni ipo kan soso ni oun ati Ajimobi dijọ n le, eyi to mu ki awọn mejeeji da bi orogun, oun ko si sẹ Ajimobi amọ Ajimobi sẹ oun.
Minisita tẹlẹ naa fikun pe, oun ati Baba Abiola Ajimobi, eyiun Alhaji Ganiyu Ajimobi ni awọn dijọ wa nile asofin ipinlẹ Oyo lasiko kanna, ti baba naa si mu oun bii ọmọ.
O ni o ya oun lẹnu pe iru ọmọ baba naa lo wa n hu awọn iwa to hu naa si oun.
Down Syndrome Skill centre: Wo bí ọmọ tí ọpọlọ wọn kù díẹ̀ ṣe ń kọ́ iṣẹ́ agẹrun
"Ajimobi mọ pe mo ni iwa ikoraẹninijanu pupọ, ti mo si korira iwa ijẹgaba lori ẹni ati iwa ipa, ti ko si fẹ ki n de ipo ijọba, amọ gbogbo rẹ ti pari bayii.
Wọn ro pe maa ran Ajimobi ni ẹwọn, ti mo ba fi di gomina lẹyin rẹ, ni wọn se gbogun ti mi.
Mo ti se ipade pẹlu opo Ajimobi, ohun to si se koko bayii ni bi a se jẹ ki ipinlẹ Oyo lọ siwaju."
Bakan naa ni amofin Shittu salaye pe oun ati oloogbe Abiola Ajimobi ko pari aawọ to wa ni aarin awọn mejeeji, ko to di pe ọlọjọ de si.
Epe Fish Market: Wá wo oríṣi ẹja tí o rírí lọ́jà ẹja tó tóbi jùlọ ní Nàíjíríà
O fikun pe, o se ni laanu pe awọn agbaagbaa inu ẹgbẹ to yẹ ko pe awọn joko lati pari aawọ naa, ko sọ bẹẹ, eyi ti ko daa to.
"Emi ati Ajimobi pade nile itura kan nilu Eko nigba to ku bii osu mẹrin ko jade laye, ti a si bẹrẹ si fi ara wa se yẹyẹ.
Mo kabamọ pe awa mejeeji ko pari ija aarin wa, ko to jade laye, awọn agbaagba to si yẹ ko ba awa mejeeji pari ija, ni ko se bẹẹ.
Explosion at OBJ Library: Ọ̀kan nínú àwọn méjì tí wọ́n gbe lọ ilé ìwòsàn ti dèrò ọ̀run
Oríṣun àwòrán, @SamuelOmogor
Iroyin to n tẹ wa lọwọ ni yajoyajo ti fi ye ni pe eeyan meji ti dero ile iwosan nigba ti ẹrọ amuletutu, taa mọ si Air Conditioner bu gbamu.
Ọga agba kan nileesẹ naa to fidi isẹlẹ yii mulẹ fun BBC Yoruba salaye pe lootọ ni isẹlẹ naa waye amọ oun ko le sọ boya awọn eeyan meji to fara pa ti ku.
O fikun pe awọn eeyan mejeeji naa lo wa tun ẹrọ amuletutu naa se nigba ti afẹfẹ gaasi inu rẹ bu gbamu, to si se wọn lese.
N ko si nibẹ nigba ti isẹlẹ naa waye, amọ ohun ti wọn sọ fun mi ni pe ọga kan ati ọmọ isẹ rẹ lo wa yẹ awọn ẹrọ AC wa wo."
Nigba to de ibudo kan, lo ri pe ọkan ninu awọn AC naa ni afẹfẹ gaasi rẹ n jo sita, o wa gbiyanjo lati fi ina jo, ko le di oju ibi to ti n jo sita.
Oríṣun àwòrán, Ben Murray Bruce
Boya o n jo lọwọ ni o, tabi igba to n fi gaasi naa sinu AC ni ibugbamu ọhun waye, n ko mọ nnkan to sẹlẹ, ti eyi fi waye.
O fikun pe wọn ti gbe awọn mejeeji lọ sile iwosan fun itọju amọ oun ko le sọ boya wsn si wa laye tabi wọn ti jẹ Ọlọrun nipe.
Baba Ijesha: Adewale Elesho, ààrẹ ANTP sọ̀rọ̀ lórí ìṣẹ̀lẹ̀ Baba Ijesha lẹ́yìn ò rẹyìn
Aarẹ ẹgbẹ awọn oṣere tiata labẹ aṣia ẹgbẹ Association of Nigerian Theater Arts Practictioners, ANTP, Alagba Adewale Ẹlẹshọ, ti ọpọ mọ si Elesho ẹnu n ja waya, naa ti da si ọrọ Baba Ijẹṣa bayii.
Ninu fidio kan to fi sori ayelujara, Elesho ni oun ko fẹ sọrọ lori oun to ṣẹlẹ si Baba Ijẹṣa bikoṣe bi awọn eeyan lawujọ to n pe ohun lọtun losi, lati da si ọrọ naa.
Eleso ni awọn yoo kọkọ le kọlọkọlọ lọ naa, ki awọn to fi abọ sori adiyẹ.
Elesho wa rawọ ẹbẹ si Princess, iya ọmọdebinrin ti wọn fẹsun kan pe Baba Ijesha huwa aṣemaṣe pẹlu rẹ, pe ko jeburẹ lori ọrọ naa, ki o si fi iyedenu nitori pe ọrọ naa ti gbona girigiri ju bi gbogbo awọn eeyan ṣe n sọ lọ.
O ni ki Princess o ro atimaaṣebọ oun ati Baba Ijesha ko fi iyedenu lori ọrọ naa, nitori oju ti ọrẹ mi oju ko timi, onitọun ni ko loju ti niyẹn.
Oríṣun àwòrán, Realyomifabiyi/Instagram
Bakan naa ni gbajumọ oṣere alawada naa tun ke si awọn mọlẹbi ọmọdebinrin naa pe, lootọ ohun to ṣẹlẹ yii ko dun mọ ẹnikẹni ninu ṣugbọn bi a ba ni ka dana sun ejo bo ṣe gun to, afaimọ ka maa da ina sun ile.
"Mo bẹ awọn obi ọmọ ti nnkan ṣẹlẹ si, o jootọ o, ko joo tọ o, wọn ko gbọdọ maa pe eeyan lole, ko tun maa gbe ọmọ ẹran jo.
Ọlọrun nikan lo mọ ohun teeyan ko mọ"
Epe Fish Market: Wá wo oríṣi ẹja tí o rírí lọ́jà ẹja tó tóbi jùlọ ní Nàíjíríà
Lẹyin to rọ gomina Babajide Sanwo-Olu lati bawọn foju sunnukun wo ọrọ naa, aarẹ ẹgbẹ oṣere ANTP naa tun ke sawọn ọlọpaa lati wadi ọrọ naa delẹ daadaa.
O fi kun un pe, iṣẹlẹ naa fihan pe bi ko ti ṣe rọrun to lati ni orukọ rere, lo ṣe rọrun fun orukọ naa lati bajẹ lẹyin aṣemaṣe kan.
Ben Ayade: Mo jẹ́ ọmọlúàbí àti ẹni àpọ́nlé ni mo ṣe lọ sí APC, kìí ṣe ọ̀rọ̀ ẹgbẹ́ òṣèlú
Oríṣun àwòrán, BEN AYADE/FACEBOOK
Gomina ipinlẹ Cross Rivers, Benedict Ayade, ti salaye ohun to mu kuro ninu ẹgbẹ oṣelu PDP lọ si APC.
Gomina Ayade to kede pe oun ti kuro ninu ẹgbẹ alatako PDP lọ si APC to wa lori alefa ni, ki ipinlẹ oun le jẹ anfaani mudunmudun ijọba apapọ loun fi ṣe bẹẹ.
Ayade to ke gbajare ipenija orisirisi ti ipinlẹ rẹ n koju nipa ọrọ owo, ohun amayederun ati airiṣẹse awọn ọdọ tun sọ pe, isipo pada oun yoo mu ki awọn jẹ anfaani lọdọ ijọba apapọ.
O wa gba awọn Gomina akẹgbẹ rẹ miran niyanju, lati pawọpọ pẹlu aarẹ Buhari lati mu idagbasoke ba Naijiria.
"A nilo ki gbogbo awọn Gomina mọ wi pe eyi kii ṣe ọrọ ẹgbẹ oṣelu, jijẹ ọmọluabi ni, jijẹ ẹni apọnle si ni. Ifarajin si afojusun Naijiria naa si laa n sọ''
Aworan Gomina Ayade to kuro ninu ẹgbẹ PDP lọ si APC
Oríṣun àwòrán, Andre Ekeng Inyang
O ni ti gbogbo awọn ba pawọpọ pẹlu aarẹ ẹni ti yoo gba ijọba lyin rẹ lọdun 2023 ko ni ṣe wahala pupọ.
Lọjọbọ yi ni Gomina Ayade kede pe ohun ko ṣẹgbẹ PDP mọ lẹyin ipade bonkẹlẹ kan to ṣe pẹlu awọn Gomina APC mẹfa.
Ninu awọn to wa nibi ipade naa la gbọ pe awọn aṣofin ile asofin agba mii naa wa.
Lara awọn Gomina to ṣabẹwo si nile ijọba la ti ri Gomina ipinlẹ Kebbi, Imo, Yobe, Plateau, Jigawa, ati Ekiti.
Alága OYSIEC ní APC fẹ́ sọ òun lẹ́nu nípa ìṣúnsíwájú ìbò tó ń bèèrè fún
Alimotu Pelewura: Akọni ajìjàgbara obìnrin, ìyálọ́jà àti olóṣèlú tó sun àtìmalé torí owó orí
Oríṣun àwòrán, wikipedia
Ti ọmọ ko ba ba itan, yoo ba arọba nitori arọba gan an ni baba itan.
Eyi lo difa fawọn onkọwe kan ti wọn fi sọ pe, o yẹ ki awọn obinrin to n pe ara wọn ni ajìjàgbara mọ nipa itan awọn akọni obinrin kan, to ti wa saaju wọn.
Eyi ni wọn ni yoo mu ki awọn obinrin yii fi isesi awọn ajijagbara obinrin to ti siwaju, ti wọn ko si ba ilẹ jẹ, se awokọse rere.
Àwọn ìtàn mánigbàgbé tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí:
Mo dúpẹ́ pé ìgbà tí mo wà nínú Jesu ni mo lọ sẹ́wọ̀n, tó bá jẹ́ pé mo wà nínú áyé ni ... - Wòlìí Genesis
Lara awọn akikanju obinrin, ajijagbara ati Oloselu to dantọ̀ ni Iyalọ̀ja akọ̀kọ̀ nilu Eko wa gẹgẹ ba se ko iroyin aye rẹ jọ lati oju opo ayelujara Wikipedia.
Orukọ rẹ ni Oloye Alimotu Pelewura, ẹni to fi gbogbo ọjọ aye rẹ ja fun ẹtọ awọn obinrin papaa julọ niluu Eko.
Oríṣun àwòrán, Wikipedia
A bi Oloye Alimotu Pelewura sí idile olorogun niluu Eko lọdun 1865, oun si ni akọbi awọn ọmọ ti iya rẹ bi.
Pelewura bẹrẹ owo ẹja tita lati igba ewe, ọwọ mọmọ rẹ lo ti jogun ba owo yii niluu Eko nigba naa.
Bo tilẹ jẹ pe Alimotu ko lọ sile iwe, Eledua fi ọpọlọ pipe jinki rẹ.
Ati pe itara to ni lori gbogbo ọrọ to ba nii ṣe pẹlu awọn obinrin jẹ ko ni ẹnu laarin awọn obinrin ẹgbẹ rẹ, ti wọn jọ wa ni ọja.
Ko pẹ ko jinna ni wọn dibo yan Oloye Pelewura gẹgẹ bi Iyalọja lọdun 1910, ti Oba Eshugbami, Eleko ti ilu Eko naa si tun fi joye.
Oyo LG Polls: OYSIEC ní APC ló yẹ kò bẹ aráàlú lórí àṣìṣe rẹ̀ nípa ìbò ìjọba ìbílẹ̀
Pelewura ṣiwaju awọn obinrin lọdun 1932 lati ṣe ifẹhonuhan tako agbekalẹ ofin ijọba akonilẹru ilẹ Gẹẹsi, to ni kawon obinrin maa san owo ori.
Wọn yan Pelewura gẹgẹ bí aṣoju awọn obinrin ninu igbimọ Ilu ti Oba Eko ṣe agbekalẹ rẹ.
Ni nnkan bi ọdun 1935, Pelewura ṣagbatẹru iwọde tako bi wọn ṣe gbe ọja Ereko lọ si agbegbe Oluwole.
Pelewura atawọn obinrin mii gbiyanju lati dena gbigbe ọja naa kuro nibi to wa, eyi to jẹ ki wọn ju sí atimọle.
Awọn obinrin to n ta ọja niluu Eko ṣewọde titi ti ijọba fi tu Pelewura at'awọn obinrin mii latimole silẹ.
Wọ́n rò pé mo ya wèrè ni Saudi lẹ́yìn ikú ọkọ mi
Lọdun 1940, ijọba amunisin ilẹ Gẹẹsi tun ṣe agbekalẹ owo ori tuntun fawọn obinrin ti wọn ba n gba ju aadọta pọun lọ.
Awọn obinrin kii san owo ori tẹlẹ nilẹ Yoruba, eyi jẹ ko ṣe ajeji sí wọn.
Pelewura at'awọn obinrin mii tun dide lati ṣe ifẹhonuhan tako igbesẹ naa tori o jẹ ajeji sí wọn.
Paapaa nitori bi ọrọ aje ṣe dẹnu kọlẹ nigba naa pẹlu airiṣẹ ṣe ọpọ eeyan nitori ogun agbaye to n lọ lọwọ lasiko naa.
Pelewura wọ agbo oṣelu lọdun 1939, o ṣi di ọkan lara ọmọ igbimọ alaṣẹ ẹgbẹ oṣelu NUYD, ẹgbẹ to n ṣe aṣepọ pẹlu ẹgbẹ oṣelu NNDP.
Down Syndrome Skill centre: Wo bí ọmọ tí ọpọlọ wọn kù díẹ̀ ṣe ń kọ́ iṣẹ́ agẹrun
O maa n sọrọ nigba mii gẹgẹ bi olori lasiko ipolongo fawọn oludije ẹgbẹ oṣelu NNDP bo tilẹ jẹ pe awọn obinrin ko lanfaani lati dupo nigba naa.
Pelewura tun jẹ ọkan lara ọmọ ẹgbẹ Nigerian Women's Party, NWP ti oloye Oyinkansola Abayomi da silẹ.
Lasiko ogun agbaye ẹlẹẹkeji lọdun 1941, gbogbo nkan lo wọn gogo nitori ọda ounjẹ.
Èyí mu ki ijọba ṣe agbakalẹ eto lati maa dari iye tawọn eeyan maa ta ọja wọn.
Pelewura at'awọn akẹgbẹ rẹ tako eto naa, wọn ni ko ni jẹki awọn ri ere jẹ to.
Epe Fish Market: Wá wo oríṣi ẹja tí o rírí lọ́jà ẹja tó tóbi jùlọ ní Nàíjíríà
Lọdun 1947 ni wọn fi Pelewura jẹ oye Erelu nitori bi o ṣe n ṣoju awọn obinrin.
Amọ, iku ko dọjọ, arun ko doṣu, igi to tọ kii pẹ nigbo, Pelewura jade laye lọdun 1951.
Ẹgbẹẹgbẹrun eeyan lo peju pesẹ sibi eto isinku rẹ lati ṣe ẹyẹ ikẹyin fun un.
Oyo LG Polls: OYSIEC ní APC ló yẹ kò bẹ aráàlú lórí àṣìṣe rẹ̀ nípa ìbò ìjọba ìbílẹ̀
Awuyewuye to n waye lori eto idibo ijọba ibilẹ ti yoo waye lọjọ Satide ọla nipinlẹ Oyo si n gbona jain jain ni.
Idi ni pe ẹgbẹ oselu APC, to jẹ ẹgbẹ oselu alatako gboogi nipinlẹ Oyo si n figbe ta pe ijọba gbọdọ wọgile eto idibo naa ni, ki oun le ni anfaani lati kopa ninu rẹ.
APC ni ẹjọ ti oun gbe lọ sile ẹjọ lori bi gomina Seyi Makinde se juwe ọna ile fun awọn alaga ijọba ibilẹ ti Abiola Ajimọbi yan sipo, lo mu ki oun ma le se igbaradi fun eto idibo ijọba ibilẹ naa.
Eyi lo mu ki BBC Yoruba tọ awọn alẹnulọrọ lori eto idibo naa lọ lati m,ọ ohun to faa ti awuyewuye naa fi n tẹ siwaju atawọn ọna abayọ si.
Lara awọn to si salaye ẹdun ọkan wọn ati awijare ni Alaga ajọ eleto idibo nipinlẹ Oyo, amofin Isiaka Olagunju, alukoro fun ẹgbẹ oselu PDP, Enjinia Akeem Olatunji ati alaga fun ẹgbẹ awọn alaga ijọba ibilẹ ninu ẹgbẹ APC ti wọn yọ nipo, Ayodeji Abass Aleshiloye.
Alaye ree lori bi awọn eeyan naa se n gba ọrọ idibo ijọba ibilẹ mọ ara wọn lọwọ.
Gani Adams: Ìbátan ní Benin àti Yorùbá, a fẹ́ràn ara wa dénú
Aarẹ Ọna Kakanfo fun ilẹ Yoruba, Oloye Gani Adams, ti gboriyin fun Ọ̣ba ilu Benin, Oba Ewuare II, fun ṣ̣iṣe ayẹyẹ ọdun Ọ̣ranmiyan ni ilu Benin.
Ninu atẹjade ti Gani Adams fi lede lo ti sọ pe, inu oun dun pe Ọba Benin ko fa sẹyin lati fi ajumọṣe to wa ninu itan Yoruba ati ilu Benin han nipa ọdun Ọranmiyan.
O ni ọdun naa ti fi ibaṣepọ to wa laaarin ilẹ Yoruba ati ilu Benin han, ti ko si le si ohunkohun to le ja okun naa.
Gani Adams ni Ọba Ewuare ti fihan pe, itan ko parọ lori bi ilẹ Yoruba ṣe san wa ati bi awọn ara Benin ṣe ṣẹ wa gẹgẹ bi itan ṣe sọ.
''Ninu itan ilẹ Yoruba, Ọranmiyan ni o da ilẹ Ọyọ silẹ, ti awọn pe ni Ọranmiyan to tunmọ si Akin Orun, lẹyin to da ilẹ Ọyọ silẹ tan,  lo si pada wa jẹ ọba kẹfa, iyẹn Ọọni ti Ile Ifẹ.
Oyo LG Polls: OYSIEC ní APC ló yẹ kò bẹ aráàlú lórí àṣìṣe rẹ̀ nípa ìbò ìjọba ìbílẹ̀
Titi di oni, Alaafin ti ilu Ọyọ lo di ipo Ọranmiyan mu ni ilẹ Yoruba, ti awọn ara ilu Ọyọ ati Ọba Lamidi Adeyemi to jẹ Alaafin ti ilu Ọyọ si n ṣe ọdun Ọranmiyan naa ni ọdọọdun.
Ilẹ Yoruba ati ilu Benin ni itan kan naa ati ajọṣepọ kan naa paapaa nipa Ọranmiyan to da ilu mejeeji.
Nitori naa, o pọn dandan fun wa lati ki Ọba Ewuare ku ọdun ati lati gboriyin fun un lori igboya rẹ lati tẹle itan ilu naa"
Epe Fish Market: Wá wo oríṣi ẹja tí o rírí lọ́jà ẹja tó tóbi jùlọ ní Nàíjíríà
Aarẹ Ọna Kakanfo naa wa fikun wi pe ibaṣepọ laarin ilẹ Yoruba ati ilu Benin yoo ma lọ deede, nitori ibatan ni wọn, ti wọn si fẹran ara wọn denu.
Makinde convoy in Ogbomosho: Alao Akala, APC ṣàlàyé bí ọmọ ṣe kú lásìkò ipolongo ìbo l‘ogbomoso
Oríṣun àwòrán, Seyi Makinde/Alao Akala Facebook
Ẹgbẹ oselu APC nipinlẹ Oyo ti fi ẹdun ọkan rẹ han lori isẹlẹ ibanujẹ to waye nigba ti ọkọ kan tẹ ọmọdebinrin kan pa nilu Ogbomoso lọjọbọ.
Isẹlẹ naa ni wọn di ẹbi rẹ ru ọkan lara awọn ọkọ to kọwọrin pẹlu gomina Seyi Makinde lọ seto ipolongo ibo ijọba ibilẹ nilu Ogbomoso amọ ti gomina ti sẹ pe ko ri bẹẹ.
Nigba to n wa safihan bi isẹlẹ naa se ka lara to, ẹgbẹ oselu APC ni o se oun laanu pe gomina Makinde ko tiẹ gbinyanju lati se awari ẹni to se iku pa ọmọdebinrin naa.
Atẹjade kan ti ẹgbẹ APC fisita lori isẹlẹ naa lọjọ Ẹti, eyi ti akọwe ipolongo rẹ, Ọmọọba Ayọbami Adejumọ fisita ni iwa aimọ ojuse ẹni to tii buru julọ ni Makinde hu.
Oríṣun àwòrán, Seyi Makinde Facebook
APC ni ko dara bi gomina Makinde se kọ jalẹ pe kii se ikọ to kọwọrin tẹle oun lẹyin, lọ se ipolongo ibo lo pa ọmọ naa, nigba ti iwadi ti fihan pe, ọkan lara awakọ awọn alatilẹyin gomina to tẹle lọ silu naa, lo huwa ibi yii.
"Ọkan lara awọn to tẹle Seyi Makinde lẹyin, to n wa mọto laibikita lati da ibẹru sọkan aya ara ilu, lo fi ọkọ pa smọdebinrin naa.
Atẹjade naa ni ẹni ti aje iwa ibajẹ yii si mọ lori jẹ ọkan lara ọmọ ẹgbẹ alakoso gareji ọkọ nipinlẹ Oyo, to si tun jẹ ọmọ ẹgbẹ oselu PDP."
Ẹgbẹ oselu APC wa n rọ awọn agbofinro lati se iwadi wọn bo se yẹ lori isẹlẹ naa, ki wọn si ri pe ẹni to pa ọmọ naa gba idajọ to yẹ labẹ ofin.
Epe Fish Market: Wá wo oríṣi ẹja tí o rírí lọ́jà ẹja tó tóbi jùlọ ní Nàíjíríà
Wayi o, Gomina tẹlẹ nipinlẹ Oyo, Oloye Adebayo Alao-Akala ti ke pe gomina ipinlẹ Oyo, Seyi Makinde pe ko wa ẹni to fi ọkọ pa ọmọde kan niluu Ogbomoso.
Alao-Akala sọ ninu atẹjade kan to fi sita lọjọ Ẹti wí pe, ẹnikan lara awọn to kọwọ rin pẹlu Makinde wa si Ogbomoso l'Ọjọbọ lo ṣeku pa ọmọ naa.
Alao-Akala ṣapejuwe iṣẹlẹ naa gẹgẹ bi ohun to ba ni lọkan jẹ, papaa julọ bi baba ọmọdekunrin naa ṣe gbe oku rẹ dani pẹlu ibanujẹ ọkan ati omije loju.
Gomina ipinlẹ Oyo tẹlẹ ni ẹni to pa ọmọdebinrin yii ti ko jẹ ko dagba, gbọdọ foju wina ofin, iru eeyan to wu ti ko ba a jẹ.
Down Syndrome Skill centre: Wo bí ọmọ tí ọpọlọ wọn kù díẹ̀ ṣe ń kọ́ iṣẹ́ agẹrun
Makinde gbọdọ ri pe idajọ ododo waye lori iṣẹlẹ yii lati le jẹ arikọgbọn fawọn awakọ oniwa kuwa, Alao-Akala ṣalaye.
Gomina ipinlẹ Oyo tẹlẹ ni oun mọ irora ti baba ọmọ naa n la kọja bayii lẹyin iṣẹlẹ naa.
Alao-Akala ni gomina ipinlẹ Oyo gbọdọ jẹ ki gbogbo araalu mọ abajade iwadii ti ijọba ba ṣe lori iṣẹlẹ naa.
Oríṣun àwòrán, Twitter/seyi Makinde/other
Ni Ọjọbọ ni iroyin kan jade pe ọkọ kan pa ọmọdebinrin jojolo kan nitosi ibi ti ẹgbẹ oṣelu PDP ti n ṣe ipolongo itagbangba wọn lagbegbe Ọja Igbo nilu Ogbomọṣọ.
Wọn ni ọkan lara awọn ọkọ to kọwọrin pẹlu gomina Seyi Makinde lo seku pa ọmọ ọmọ naa.
Iṣẹlẹ yii fa ọpọ ariwo nibi ipolongo naa eleyii ti gomina ipinlẹ Ọyọ, Seyi Makinde pẹlu peju si.
Iroyin sọ pe awọn mọlẹbi ọmọ naa gbe oku rẹ wa sibi ipolongo itagbangba naa lati beere fun idajọ ododo.
Oniruuru iroyin lo jade nipa bi iṣẹlẹ iku ọmọ naa ṣe waye, bi awọn kan ṣe n sọ pe ọkan lara awọn ọkọ to ba gomina kọwọrin lo ṣeku pa ọmọdebinrin naa.
Oyo LG Polls: OYSIEC ní APC ló yẹ kò bẹ aráàlú lórí àṣìṣe rẹ̀ nípa ìbò ìjọba ìbílẹ̀
Ni awọn eeyan miran n sọ pe o ku diẹ ki ikọ gomina Makinde de ibi ipolongo naa ni iṣẹlẹ ọhun ti waye.
Nigba to n sọrọ lori iṣẹlẹ naa, gomina Seyi Makinde ṣalaye loju opo ayelujara Facebook rẹ pe, ọkọ to pa ọmọdebinrin jojolo naa ko si lara ọkọ to ba oun kọwọrin.
O wa ba awọn ẹbi ọmọde naa kẹdun nipa isẹlẹ laabi yii.
"Mo gbọ iroyin kan pe awọn ọkọ to ba mi kọwọrin pa ọmọdebinrin kan lasiko ti a n lọ si ilu Ogbomọṣọ, loni.
Iwadi wa fihan pe ọkọ eeyan kan ti ẹya rẹ jẹ Toyota Matrix, lo gba ọmọdebinrin yii. Kii ṣe ara ọkọ to ba mi kọwọrin rara."
Oríṣun àwòrán, Screenshot
"Atẹjade kan ti agbẹnusọ fun gomina ipinlẹ Ọyọ, Ọgbẹni Tawo Adisa fi sita tun ṣalaye pe ""Ikọ to ba gomina kọwọrin ti de adugbo Ọja Igbo nibi ti ipolongo itagbangba naa ti waye."
"Koda, wọn ti wọn si ti joko sibi eto naa, igba ti eto ipolongo idibo naa n lọ lọwọ, lawọn eeyan kan ya wọ ibudo ipolongo ibo naa pẹlu oku ọmọde naa."""
Nigba to ṣalaye pe awọn agbofinro ṣi n wa awakọ Toyota Matrix naa, Gomina ipinlẹ Ọyọ rọ awọn eeyan ilu Ogbomọṣọ lati fiyedenu pẹlu idaniloju pe, ijọba yoo tu iṣu de isalẹ ikoko ọrọ naa.
Oshodi Military Crisis: Kí ni ìdí abájọ wàhálà lórí ikú ọmọogun òfúrufú l'Oshodi?
Oríṣun àwòrán, other
Ọpọlọpọ awọn olugbe Oshodi nipinlẹ Eko atawọn to n wọ ọkọ nibẹ ni wọn sa asala fun ẹmi wọn lọjọbọ, lori wahala to bẹ silẹ laarin awọn ọmọogun kan atawọn janduku lagbegbe naa.
Agbegbe Mosafẹjọ ni Oshodi ni iṣẹlẹ naa ti waye.
"Gẹgẹ bi awọn iroyin abẹle kan ṣe sọ, awọn ologun naa ya bo Oshodi ""lati gbẹsan iku ọmọogun ofurufu kan, ti awọn janduku pa lagbegbe naa"""
Ọpọlọpọ ọkọ ero ni wọn bajẹ tawọn awakọ ero si sa fi skọ silẹ, bẹẹ lawọn ọlọja pẹlu juba ehoro ti wọn si fi ṣọọbu wọn silẹ.
Awọn miran sọ pe wọn ri oku ọmọogun naa ni agbegbe naa ti awọn eeyan si fura pe awọn janduku lo gba ẹmi rẹ ki wsn to fi awọn ṣọja naa ṣọwọ sibẹ lati lọ gbe oku rẹ ki wọn si le awọn janduku kuro lagbegbe naa.
Amọṣa ileeṣẹ ọlọpaa ti fi atẹjade kan sita pe awọn ti bẹrẹ si ni wadi ohun gan to fa wahala naa.
Oyo LG Polls: OYSIEC ní APC ló yẹ kò bẹ aráàlú lórí àṣìṣe rẹ̀ nípa ìbò ìjọba ìbílẹ̀
"Alukoro ileeṣẹ ọlọpaa ni ipinlẹ Eko, Muyiwa Adejọbi ṣalaye ninu atẹjade naa pe, "" Ileeṣẹ ọlọpaa ni ipinlẹ Eko gbọ si wahala to waye lagbegbe Capa Park/Mosafẹjọ ni Oshodi loni Ọjọbọ ogunjọ oṣu karun un ọdun 2021 ni agogo meje owurọ. A ti da alaafia pada si agbegbe naa, a si n ṣe iwadii lori rẹ."
"A rọ awọn olugbe ilu Eko lati maa ba iṣẹ wọn ls laisi wahala."""
Yoruba Nation: Aseyin ní òun kò tako ìpè fún Yoruba Nation
Asẹyin ti ilu Isẹyin, Ọba Abdulganiyy Adekunle Salau, Ologunebi-Ajinasẹ Kinni ti ṣalaye pe oun ko figbakankan tako ipe fun idasilẹ orilẹede Yoruba, iyẹn Yoruba Nation.
Atẹjade kan ti Kabiyesi, Asẹyin gbe sita lo ti sọrọ naa lati yannana ọrọ ati aigbọraẹniye to n la kaakiri pe oun ti fofin de Sunday Igboho pe ko gbọdọ gbe iwọde ipe fun Yoruba Nation de ilu Isẹyin.
Kabiyesi Asẹyin ni ohun ti oun sọ fun Sunday Igboho ni pe, bi oju ọjọ ṣe ri pẹlu ọrọ abo ni ilu Isẹyin, gbigbe iwọde bẹẹ kalẹ lewu nitori awọn janduku lee jaa gba bi wọn ṣe ja ti #EndSARS gba.
Asẹ́yìn, àwọn ẹbí olóògbé ṣì ń fomijé dárò àwọn tóṣìṣẹ́ 'Custom' yìnbọn pa nílùú Iseyin
O ni ohun ti oun sọ fun wọn ni pe ki wọn sun iwọde naa, ti wọn fi si ọjọ karun un oṣu kẹfa ọdun 2021 kuro, di ẹyin adura ọjọ kọkanlelogoji awọn eeyan ti oṣiṣẹ aṣọbode pa nilu naa.
Mi o ni pe ki Sunday Igboho maa wa silu Isẹyin, mi o si ni ki iwọde o maa waye nilu Isẹyin ṣugbọn mi o fẹ ko waye bayii nitori ilu Isẹyin ṣi n daro awọn  ọdọ marun un tawọn aṣọbode naa pa.
Asẹyin ni ọmọ oun ni Sunday Igboho gẹgẹ bi ọmọ Oke Ogun to jẹ, nitori naa, ohun ti oun n sọ ni pe iwọde ti Sunday Igboho fẹ ṣe ko lee waye bayii.
NCC IMEI: Irọ́ ni, a kò bèèrè fún nọ́mbà IMEI àwon olùgbé Nàìjíríà- NCC
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Saaju ni iroyin ti jade pe ajo NCC to n mojuto ọ̀na ibaraenisọ̀rọ̀ ni Najiria ti ni ki awon olugbe Naijiria fi nomba International Mobile Equipment Identity (IMEI) to wa lori ẹ̀rọ alagbeka wọn silẹ̀ lati osu keje, ọdun 2021.
Omowe Ikechukwu Adinde to jẹ́ oludari ẹ̀ka ifitonileti ara ilu fun ajo Nigerian Communications Commission ti fi ikede sita pe iroyin to jina si ootọ ni ọ̀rọ̀ naa.
O ni ajọ NCC ko figba kankan beere fun nomba yii lọ́wọ́ awọ́n eeyan ni Naijiria.
O ni gbigba nomba yii waye lati ọ̀dọ̀ awon ẹ̀ka Revised National Identity Policy for SIM Card Registration ti  o jẹ́ ọ̀kan lara awon ajotuntun ti Aare  Buhari da sile lo fi soju opo itakun agbaye.
Oyo LG Polls: OYSIEC ní APC ló yẹ kò bẹ aráàlú lórí àṣìṣe rẹ̀ nípa ìbò ìjọba ìbílẹ̀
O ni ajo yii ti setan lati seto Device Management System (DMS). ni eyi to ma je ki o rorun lati ko awon ayederu nọ́mba kuro nilẹ̀
Ikechukwu ni kete ti eeyan ba ti se iforukosile naa ni ẹ̀rọ naa yoo funra re gbe nomba IMEI iru eni bẹ́ẹ̀ sita lai jẹ́ pe eeyan tun sẹ̀sẹ̀ lọ n seto iforukosilẹ̀ miran
O ni fun idi eyi, ki awon eeyan lo fọkan balẹ̀ pe wọ́n yoo tun lọ to seto iforukosilẹ̀ IMEI
Kí ni IMEI ara fóònù àtí ìwúlò rẹ̀, tí ìjọba fi ń béèrè rẹ̀ lọ́wọ́ aráàlú?
Wo àǹfààní nọ́mbà yìí àti bo ṣe le ṣàwárí rẹ̀ lára fóònù rẹ
Ikede ti ajọ to n risi eto ibaraẹnisọrọ ni Naijiria NCC gbe jade pe ki awọn ọmọ Naijiria fi nọmba IMEI wọn ṣọwọ, jẹ eyi tawọn eeyan n ran lẹnu.
Gẹgẹ bi awọn ikede miran ti wọn gbe jade ṣaaju, paapa nipa siimu ati nọmba NIN, pupọ lo n beere pe ki ni wọn tun fẹ fi nọmba yii ṣe.
Ninu nkan ti wọn sọ pe awọn fẹ fi nọmba naa ṣe ni idena jiji foonu, didaabo bo onibara ileeṣẹ ibaraẹnisọrọ, pipawo wọle fun ijọba ati mimu adinku ba ijinigbe tabi lilo foonu lati fi hu iwa ọdaran.
Bo tilẹ jẹ pe awa ko le gbẹnu wọn sọrọ lori erongba wọn lẹkunrẹrẹ, a gbiyanju lati ṣe iwadii ki gan nipa nọmba yii, ati ipa to n ko ninu eto ibaraẹnisọrọ.
Ninu iwadii wa, awọn koko bii meloo kan jẹ jade, ta lero pe yoo wulo fun mutumuwa.
Diẹ ninu wọn ree:
Itumọ Nọmba IMEI:
Ibi lẹbẹ la a ti mu ọọlẹ jẹ nitori naa, ki a kọkọ ṣe alaye lori itumọ IMEI.
Lede Gẹẹsi, IMEI tunmọ si International Mobile Equipment Identity (IMEI) eyi to tumọ si nọmba idamọ foonu alagbeka kọọkan, ta fi ṣe idanimọ foonu rẹ.
Lara batiri foonu ni wọn maa n tẹ nọmba naa si ṣugbọn bi ẹ ba tẹ nọmba *#06# lori foonu yin, yoo jade soju iran rẹ.
Bi o ṣe lè mọ̀ tí káádì inú ẹ̀rọ ìléwọ rẹ kọ bá sí nínú àkọsílẹ̀
Mẹẹdogun ni nọmba naa jẹ ati pe awọn foonu to ba laaye ibi taa fi siimu si, lo maa n ni nọmba yii.
Bi foonu ba jẹ sim-less, o ṣeeṣe ki o ma ni nọmba yii.
Igbakigba ti eeyan ba pe lori foonu, akọsilẹ a maa wa loju opo ibaraẹnisọrọ nipa nọmba ti eeyan fi pe ati nọmba IMEI foonu to lo.
Koko Pataki nkan ti a n lo nọmba IMEI fun:
Lati le da foonu kọọkan mọ loju opo ibaraẹnisọrọ ni nọmba yii wa fun, nitori pe ọkan ko papọ mọ ekeji.
Ti foonu Tagbaja yatọ si ti Tamẹdun, ko si papọ rara, foonu kọọkan ti eeyan si n lo lo ni nọmba IMEI tiẹ lọkọọkan.
Idaabo bo ni o wa fun ati idanimọ paapa ti foonu ba sọnu tabi ti wọn ba ji foonu gbe.
Tawọn ole ba ji foonu rẹ, IMEI yi ni o le fi da mọ, koda ki wọn yọ siimu rẹ kuro ninu rẹ.
Bi o ba tete fi to ileesẹ ẹrọ ibaraẹnisọrọ leti pe wọn ji foonu rẹ, wọn le ti foonu rẹ pa, ti elomiran ko ni ribi lo, koda ko fi siimu mi sori rẹ.
Bakan naa, awọn agbofinro le lo irinsẹ itọpinpin foonu lati mọ aaye ibi ti foonu rẹ ba wa .
Ni soki, idaabo lọwọ awọn to ba ji foonu gbe ni koko idi  ti nọmba yii fi ṣe pataki.
IMEI ati Ofin orileede nipa ibaraẹnisọrọ:
Nkan ti ijọba sọ nipa ki awọn eeyan fi nọmba IMEI wọn sọwọ sileeṣẹ NCC, nii ṣe pẹlu atunto ilana eto idanimọ iforukọsilẹ siimu, ta mọ si National Identity Policy for SIM Card Registration.
Ninu alaye atẹjade ti wọn fi sita wọn ni awọn fẹ ṣe akojọ nọmba IMEI wọn yii labẹ eto kan ti wọn pe ni Centralised Equipment Identity Register.
Rẹjisita yii ni awọn ileeṣẹ ibaraẹnisọrọ kọọkan yoo maa kan si, lati le mọ IMEI ati awọn iroyin miran nipa eeyan kọọkan to ba ni foonu ni Naijiria.
Iru nnkan bayii kii ṣe tuntun nitori awọn orileede mii bi ilẹ Gẹẹsi, New Zealand, Saudi to fi mọ Latvia ni agbekalẹ ofin to de gbigba ati lilo IMEI.
Koda ni Amẹrika, ijọba wọn figba kan pọn ni dandan pe ki awọn ileeṣẹ ibaraẹnisọrọ leto ti wọn yoo fi maa ti foonu pa, ta mọ si blocklisting service.
IMEI rẹ ṣe yi pada:
Pẹlu gbogbo nkan ta a n sọ lori IMEI yii, njẹ o mọ wi pe o le yi nọmba IMEI rẹ pada?
Bẹẹ ni. Bi eeyan ba ni irinṣẹ to le ṣe nnkan yii, o ṣeeṣe ki o yi nọmba naa pada.
Ni awọn orilẹede bi Amẹrika, ko lodi sofin lati paarọ IMEI ori foonu rẹ lopin igba too ba ti fẹ fi ṣe magomago.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Amọ ni ilẹ Gẹẹsi, piparọ IMEI tabi nini irinṣẹ ti eeyan le fi paarọ IMEI jẹ ohun to lodi sofin lawọn aaye kọọkan.
Ni India, ẹwọn ọdun mẹta ni ofin gbe kalẹ fun ẹnikẹni to ba yi nọmba IMEI pada tabi to n lo IMEI nọmba ayederu.
Yatọ si awọn ileeṣẹ to se foonu, ko si igbalaye fun awọn mii lati yi nọmba naa pada.
A ko le sọ boya eyi tako ofin ni Naijiria lati yi IMEI pada tabi ko tako ofin.
Israel-Palestinian conflict: Ẹ wo bí ìgbé ayé aráàlú ní Gaza ṣe dà lẹ́yìn ìkọlù
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ija nla to waye laarin Gaza ati Israeli ti mu ki Ajọ Iṣọkan Agbaye, UN kede wi pe ti wọn ko ba ṣọra, ogun abẹle ti agbara orilẹede mejeeji ko le e ka, yoo bẹ silẹ nibẹ.
Orilẹede Egypt lo n ṣe akoso Gaza, ki orilẹede Israel to ja ogun lati gba isakoso agbegbe Gaza ni ọdun 1967, amọ Israel yọ ikọ ọmọogun rẹ ati awọn Jew to le ni ẹgbẹrun meje to n gbe nibẹ kuro ni ọdun 2005.
Awọn ajijagbara Hamas lo gba ijọba agbegbe yii lẹyin ti wọn gbajọba lọwọ awọn adari ilẹ Palestine Authority(PA) lasiko ogun to bẹ silẹ ni ọdun 2007.
Lati igba naa ni Israel ati Egypt ti dẹkun bi awọn eniyan ṣe n jade ati wọle ni agbegbe naa, to fi mọ bi ẹru ati awọn ohun ini ṣe n wọle-jade ni agbegbe naa.
Awọn ajijagbara Hamas doju ija kọ Israel ni ọdun 2014 , ti ọpọ ẹmi si lọ si iṣẹlẹ naa, ko to di wi pe ija miran bẹ silẹ ni ọdun 2021.
Oríṣun àwòrán, Reuters
Ki lo fa ija to ṣẹṣẹ waye ni Oṣu Karun, Ọdun 2021?
Ija laarin awọn ajijagbara Hamas ati Israeli bẹrẹ, lẹyin ti awon ara Palestine to n gbe ni East Jerusalem bẹrẹ si ni fa rogbodiyan lori awọn Ilẹ Mimọ to wa ni agbegbe naa.
Awọn ilẹ mimọ naa si lo se iyebiye si awọn Musulumi ati awọn ara Jew to n gbe lagbegbe Gaza.
Ọjọ Kẹwaa, Oṣu Karun un, ni awọn ajijagbara Hamas bẹrẹ si ni ju ado oloro rọkẹẹti, ti wọn fi kilọ fun awọn sọja ilẹ Israel pe ki wọn le awọn eniyan wọn kuro ni agbegbe naa, ko to di wi pe Israel naa bẹrẹ si ni kọju ija si Hamas.
Ikọlu to waye laarin Israel ati Palestine yii si ti ni ipa nla lori awọn eeyan to n gbe lagbegbe Gaza, diẹ lara ipenija ti wọn n koju lati ipasẹ ikọlu naa ree:
Ina ọba ṣọwọn fun awọn ara agbegbe Gaza, ko to di wi pe ija bẹ silẹ laarin Isreal ati Hamas, eyi to wa mu ki ina ọba to ma n wa fun wakati mẹjọ tẹlẹ, ma a wa bayii fun wakati mẹta pere.
Bakan naa ni ẹrọ alupupu ati gẹnẹratọ ti wọn n lo lati fi pese ina ṣọwọn nitori ibode ti Isreal ati Egypt ti mọ awọn ara Gaza, nitori awọn ajijagbara Hamas.
Oríṣun àwòrán, Reuters
Lati igba ti Hamas ti gba isakoso Gaza ni ọdun 2007, ni orilẹede Egypt ti ti ibode pẹlu Gaza.
Ni ọdun to kọja ni wọn tun ti ibode naa nitori ajakalẹ arun Coronavirus to bẹ silẹ kaakiri agbaye.
Ni ọdun 2019, eniyan to to ẹgbẹrun mejidinlọgọrin lo kuro ni Gaza ni ọgọọrọ, ko to di wi pe o bẹrẹ si ni dinku ni bi ọdun to kọja.
Ki ija to bẹ silẹ ni saa yii, wọn n gba Ajọ Iṣọkan Agbaye laaye lati gbe ounjẹ ranṣẹ si awọn eniyan, amọ wọn ko gba ki awọn eniyan kuro ninu ilu naa.
Oríṣun àwòrán, AFP/Getty
Orilẹede Israel ba awọn oju ọna abẹ ilẹ ti Hamas se jẹ
Ida ọgọrin awọn ara Gaza ni wọn nilo iranwọ ounjẹ lojoojumọ nitori iya ati iṣẹ to n ba wọn finra nibẹ.
Idena ti orilẹede Israel ṣe, nipa bo se kọ lati jẹ ki iranwọ de ọdọ awọn ara Gaza, lo ṣokunfa bii awọn eniyan ibẹ ko fi le ṣe kara-kata kankan.
Lọna ati bori idojukọ yii ni Hamas fi gbẹ oju ọna si isalẹ ilẹ, ki ounjẹ ati ohun ija le ma a wọle sibẹ lore-koore.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Gaza jẹ ọkan lara awọn orilẹede to ni awọn araalu to pọju lọ lagbaye, ti wọn si fun ara wọn jọ papọ si ojukan.
Ajọ Iṣọkan Agbaye, UN ni o to awọn ogunlende  bii ẹgbẹrun lọna ẹgbẹta, ti wọn n gbe ni agbegbe Gaza ati awọn ibudo ogunlende mii ni agbegbe naa.
O le ni ẹgbẹrun marun si ẹgbẹrun mẹsan awọn eniyan ti wọn n gbe kilomita kan, eleyii to fẹrẹ to iye eniyan to n gbe ni ilu London.
Amọ, Ajọ UN ni o le ni ogoje ile to wo lasiko ti orilẹede Israel sigun bo Gaza ni ọdun 2014, ti ẹgbẹgbẹrun eniyan si nilo iranwọ ile gbigbe tabi lati tun ile wọn kọ.
Eto ilera ile Gaza ku diẹ kaato nitori idena lati orilẹede Israel ati Egypt ti ko jẹ ki awọn eniyan lẹtọ si eto ilera pipe ni agbegbe naa.
Ajọ Iṣọkan Agbaye,UN  n pese ile iwosan bii mejilelogun fun awọn eniyan, amọ ija laarin ilẹ Israel ati Palestine ti mu ki awọn ile iwosan  yii wo palẹ.
Oríṣun àwòrán, Reuters
Ajọ Eleto Ilera Lagbaye,WHO  ni eyi ti ṣokunfa ki adinku ba fifun awọn eniyan ni abẹrẹ ajẹsara tako aarun Coronavirus to peleke si ni agbegbe naa.
O kere tan miliọnu kan eniyan ni ko ri ounjẹ jẹ lasiko ni Gaza, ti wọn si nilo iranwọ  ni ojoojumọ.
Lore-koore ni wọn n ṣi ibode lati fun awọn ọkọ laaye lati ko ounjẹ wole si agbegbe naa.
O ṣoro fun wọn lati ṣiṣẹ agbẹ  nitori ija pẹlu Israel, bẹẹ si ni wọn ko le e pa ẹja ni odo nitori ala ti wọn ni pẹlu Isreal.
Omi mimu naa ṣọwọn nibẹ nitori omi okun to kun fun iyọ ni wọn ni, ti ko si yẹ fun mimu.
Awọn eniyan agbegbe yii ki n ri omi taara pọn, bi ko ṣe pe igba ti ina ijọba ba wa laarin wakati mẹfa si mẹjọ.
Amọ, ija to waye yii tun ti tubọ mu ifasẹyin ba ina ọba ni Gaza.
Oríṣun àwòrán, Reuters
Ọpọlọpọ awọn ọmọde ni ilu Gaza n lọ si ileewe ti Ajọ Iṣọkan Agbaye, UN da silẹ ni agbegbe naa.
Amọ, awọn ileewe yii ni wọn n lo gẹgẹ bi ibugbe fun awọn ogunlende ti wọn sa kuro nile wọn.
Awọn olotu ilẹ Palestine ni ida mẹrinlelọgọta ile iwe naa ni awọn eniyan ti ma n lọ si ileewe ni arọ ati alẹ.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Gaza pẹlu awọn orilẹede to ni awọn ọdọ to pọjulọ ni agbaye, ti ọpọlọpọ wọn si ju ẹni ọdun marundinlọgbọn lọ.
Amọ, ohun to buru jai nipe ọpọlọpọ wọn ni ko ni iṣẹ lọwọ.
Arun Coronavirus pẹlu ohun to fa akọba ainiṣẹ fun wọn nitori ọpọlọpọ padanu iṣẹ rẹ lasiko ti ajakalẹ aarun naa bẹ silẹ.
Titi di asiko yii, awọn ajijagbara Hamas ti orilẹede Isreal, Amerika, UK, Yuroopu kasi ikọ agbesunmọmi lo n ṣakoso ibẹ.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Olusegun Obasanjo: Àwọn òǹtàjà fi tijó-tìlú pàdé Baba Iyabo lọ́jà òròmọdìẹ
Oríṣun àwòrán, Kehinde Akinyemi
Aarẹ tẹlẹ ni Naijiria, Oloye Olusegun Obasanjo ti ṣeleri iranwọ ile itaja to dara, nigba to ṣe abẹwo sí ọja ti wọn fi orukọ rẹ sọ ni adugbo Oluyole Estate niluu Ibadan.
Obasanjo tun fi da awọn ọlọja loju pe oun yoo gbiyanju lati ri pe wọn rí atilẹyin ijọba gba ninu ọja ọhún.
Se lawọn ontaja tu yaya jade lọ pade baba Iyabo ni ọja ti wọn ti n ta òròmọdìẹ oojọ.
Ọpọ awọn ọlọja naa lo fi ọja wọn silẹ lọ fi ijo ati ilu ki Obasanjo káàbọ̀.
Ninu atẹjade kan ti oluranlọwọ sí aarẹ ana lori ọrọ iroyin, Kehinde Akinyemi fi sita, o ṣalaye pe bíi ago mẹsan an kọja ogun iṣẹju ni Obasanjo balẹ bagẹ sí ọja naa.
Oríṣun àwòrán, Kehinde Akinyemi
O ni awọn oṣiṣẹ Obasanjo lo pe akiyesi rẹ si ọja naa pe, awọn ontaja n lo orukọ rẹ lati mu idagbasoke ba ọja ọhun lati ibẹrẹ pẹpẹ, to fi dé ibi tí o wa lonii.
Eleyii si ti jẹ ki ọja naa di gbajugbaja bayii, bo tilẹ jẹ pe ko si ipilẹ ti ọja naa le duro le lori.
"Ẹ gbe ọja yii silẹ nibi ti ẹ ti n ta, ti ẹ si n ra.
Ohun to kan fún wa lati ṣe bayii ni lati ni ìpìlẹ gidi ti a ko ba fẹ ki wọn le wa kuro nibi.
Ohun ti mo n sọ ni pe, máa ba gomina ipinlẹ Oyo sọrọ pe ki o fun wa nilẹ mii, ti ijọba ko ba le yọnda eyi ti a wa lori rẹ, Obasanjo lo sọ bẹẹ."
Oríṣun àwòrán, Kehinde Akinyemi
Ẹwẹ, olori ẹgbẹ awọn to ta oromọdiẹ oojọ ni Naijiria, Ọgbẹni Olaiya Ogunmoyewa ni abẹwo Obasanjo ti mu ibẹru kuro lọkan awọn ontaja lọja naa.
O ni ohun to ti n gbe awọn ontaja lọkan ni Obasanjo ti wa ojutu si.
Ẹbun fọto nla Obasanjo ni awọn ẹgbẹ ọlọja òròmọdìẹ naa fi mọ riri rẹ.
Oríṣun àwòrán, Olusegun Obasanjo
Aarẹ tẹlẹ ni Naijiria, Oloye Olusegun Obasanjo ti koro oju si iwa kawọn eeyan maa gbe owo atawọn ọrọ aye miran bori iwa otitọ ati isẹ asekara.
Obasanjo ni eyi gan lo n se okunfa ọpọ isoro to n doju kọ orilẹede Naijiria lasiko yii.
Ilu Ibadan ni Obasanjo ti woye ọrọ yii nibi ifilọlẹ ileesẹ adani kan, pẹlu afikun pe a ko le fi iye ile, mọto tabi owo ti eeyan kan ni se odiwọn aseyọri rẹ.
Amọ o ni ipa rere ti iru ẹni bẹẹ ba ko si idagbasoke awujọ to wa, ati iye eeyan to seranwọ lati mu idagbasoke ba igbe aye wọn lo yẹ ka wo.
Oloye Obasanjo wa fikun pe ko si owo kankan, bo ti wu ko pọ to, to le ra ẹri ọkan oun.
Aremu: Eré ìtàn nípa ìbí, àti jéèyàn pẹ̀lú ìpèníjà Olusegun Aremu Obasanjo
"Awọn nnkan ta n mọriri wọn lode oni jẹ ara isoro to n ba wa finra, to mu ki ifẹ owo leke tente.
Nilẹ Yoruba, ifẹ owo kii jẹ wa logun bikose iwa Ọmọluabi, otitọ inu, orukọ rere, ati isẹ asekara.
Amọ nibo ni gbogbo rẹ wa bayii? Se la rọ gbogbo wọn da si ẹgbẹ kan lati maa le owo kiri, nibo si ni iyi ati imọriri wa wa?"
O fikun pe laye ode oni, ẹnikẹni to ba lowo le ra ohunkohun amọ kii se oun nitori owo ti n ra ọpọ ẹri ọkan, to si n beere pe ki ni anfaani ẹni to ba ni gbogbo owo ile aye?
Obasanjo: Buhari ní àìlera lẹ́mìí, lára, àti lọ́kàn.
"Bawo lẹ se fẹ se odieọn aseyọri? Ohun ti aseyọri tumọ si fun emi ni pe ka mu ki ibi kan dara ju ba se baa lọ.
Eyi kii si se bi owo to ni ba se pọ to tabi iye ile to kọ ati ọkọ to ra, amọ o nii se pẹlu ipa to ko lati mu ki ibi kan dara ju bo se baa lọ."
Olusegun Obasanjo: Ọmú ìyá mi ti mo fi ń mùkọ ni kekere ló jẹ ki ń lókun
Military Plane Crash in Ngeria: Ìgbà mẹ́ta rèé tí ìjàmbá ọkọ̀ òfurufú mú ẹ̀mi ológun 20 lọ ní Nàìjíríà
Oríṣun àwòrán, NAF/FACEBOOK
Iṣẹlẹ ijamba ọkọ ofurufu a maa waye lati igba degba kaakiri agbaye.
Orisirisi nkan lo maa n sokunfa ijamba ofurufu yii, bi aṣiṣe lati ọdọ awọn ẹda ọmọniyan tabi ki omiran si jẹ amuwa lati ọdọ Ọlọrun.
Iru iṣẹlẹ bayi ko yọ Naijiria silẹ amọ lẹnu oṣu meloo sira wọn, ijamba ọkọ ofurufu to n waye ti n mu ki awọn eeyan maa beere pe ki gan lo n ṣẹlẹ?
Ijamba ọkọ ofurufu to waye lọjọ Ẹti, nibi ti ọga awọn ọmọ ogun Naijiria, Ọgagun Ibrahim Attahiru ti padanu ẹmi rẹ, lo tun mi ilu titi bayii.
Oun nikan kọ lo ba ijamba yii lọ, awọn ọmọ ogun mẹwaa mii to kọwọrin pẹlu rẹ, naa dagbere fun duniyan.
Oríṣun àwòrán, Twitter
Ki a to maa dahun nkan to ṣokunfa awọn ijamba wọn naa, ẹ jẹ ki a ṣagbeyẹwo awọn igba mẹta ọtọọtọ ti ijamba ọkọ ofurufu ti mu ẹmi awọn ọmọ ogun Naijiria lọ.
Ọjọ Kọkanlelogun oṣu Keji ọdun 2021, ọmọ ogun ofurufu NAF 201 ko agbako
Minsita feto irina ofurufu, Hadi Sirika lo kede iṣẹlẹ yii fun awọn ọmọ Naijiria.
Awọn ọmọ ogun Naijiria meje lo wa ninu baalu King Air B350i (NAF 201) ti o jabọ ni papakọ ofurufu ilu Abuja.
A gbọ pe awọn ọmọ ogun ofurufu naa n lọ si ipinlẹ Niger ni, ki wọn to padanu ẹmi wọn.
Oríṣun àwòrán, NIGERIAN AIRFORCE
Ko pẹ si igba naa, ti ọga ileeṣe ọmọ ogun ofurufu kede pe ki wọn ṣe iwadii ohun to fa ijamba yii.
Titi di ba ṣe n ko iroyin yii jọ, a ko mọ nnkan pato to mu ki baalu naa ja.
Ọkọ ofurufu ologun ti o poora lẹba Maiduguri ni Borno
Lọjọ Kọkanlelọgbọn oṣu Kẹta ni a gbọ ikede pe baalu Alpha Jet to fẹ lọ ṣe iranwọ fawọn ọmọ ogun ni Borno poora.
Ko kọkọ si ẹni to le sọ nkan to ṣẹlẹ si baalu (NAF) Alpha Jet aircraft (NAF475) naa laarin wakati meloo ti iṣẹlẹ yi waye.
Oríṣun àwòrán, NAF/FACEBOOK
Amọ nigba ti yoo fi di ọjọ Keji, ileeṣẹ ọmọ ogun ofurufu kede pe awọn awakọ baalu meji Flight, Lieutenant John Abolarinwa ati Flight Lieutenant Ebiakpo Chapele, lo ba iṣẹlẹ yi lọ.
Ikọ Boko Haram sọ pe awọn lawọn wa nidi ijamba yii ṣugbọn ileeṣẹ ologun ni ọrọ ko ri bẹẹ.
Oríṣun àwòrán, NAF/FACEBOOK
Eleyi ni iṣẹlẹ ijamba ọkọ to ṣẹṣẹ waye, to si mu ki awọn eeyan maa ṣe eemọ ohun to n fa iṣẹlẹ yi leralera.
Ọgagun agba awọn ọmọ Ogun Naijiria, Ibrahim Attahiru to ba iṣẹlẹ yii lọ ṣẹṣẹ gba iṣẹ ko pẹ.
Oun ati awọn ọmọ ogun mẹwaa miran ni wọn kọwọrin ninu ọkọ ofurufu to jabọ ni Kaduna yii.
Ki eledua dẹlẹ fawọn to ti lọ.
America's Newest Chess Master: Tanitoluwa rèé ògbóǹtarìgì ọmọdé aláyò eré Chess tó fi gbọ̀ọ̀rọ́ jẹkà
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Jakejado agbaye lawọn ọmọ Naijiria tọmọde tagba ti n fi itan lelẹ nipa orisirisi igbiyanju wọn.
Ninu wọn la tun ti ri ọdọmdekunrin ọdun mẹwaa kan Tanitoluwa Adewumi to gbegba oroke lati di Chess Master tuntun ni ilu New York lorileede Amẹrika.
Pẹlu aṣeyọri yi, Tanitoluwa fi itan lelẹ gẹgẹ bi ogbontarigi elere ayo Chess ti ọjọ ori rẹ kere julọ ninu itan awọn elere Chess ni Amẹrika.
Nibi idije Fairfield County Chess Club Championship to waye ni ilu Connecticut lọjọ Kini oṣu karun un lo ti pegede.
Àìsàn jẹ́ kí àwọ̀ ara Amida dàbí ara ẹja
O ri ami ẹgbẹrun meji le ni okoolenigba ati meji gba eyi to mu U di ẹni kejidinlọgbọn ti ọjọ ori rẹ kere julọ lati gba ami yIi.
''Inu mi dun pupọ lati jawe olubori ati bi mo ti ṣe gba oye yii. Inu mi dun gaan pe ọwọ mi te oye ti mo n wa yii''.
Lẹyin ọdun mẹta gbako ni o ṣe aṣeyọri yi nitori nkan bi ọdun mẹta syin lo bẹrẹ si ni ta ere Chess.
Nigba ti yoo fi bẹrẹ, oun ati awọn mọlẹbi rẹ n sun ni ile awọn alainile l'Amẹrika ni.
Ohun to ṣokunfa eyi si ni pe wọn sa asala fẹmi wọn kuro ni Naijira nitori idojule ikọ Boko Haram ni Naijiria.
Ni bayi wakati mẹwa si mọkanla lojumọ ni Adewumi fi n ṣe igbaradi ti o si tun maa n raye lati sun fun igba diẹ,
O ti wa jere igbaradi rẹ bayi.
Afojusun Tani ni pe ko jẹ alayo Chess tọjọ ori r kere julọ ti yoo gboye Grandmaster lagbaye.
Ẹni to di ipo naa mu bayi lagbaye a maa jẹ Sergey Karjakin,to gba oye yi lẹni ọdun mejila ati oṣu mẹsan.
Ti Tanitoluwa ba gbaradi to si mura daada, o ṣeeṣe ki o gba oye yi.
Lọwọlọwọ bayi, ọmọ ọdun mẹwaa ati oṣu mẹjọ ni Tanioluwa n ṣe.
Lẹyin ti wọn ko kuro nibi aaye alaini ti wọn wa, o ti kọ iwe itan igbe aye rẹ to pe akọle rẹ ni ''My Name Is Tani . . . and I Believe in Miracles.''
Trevor Noah adẹrinposonu nii ni ireti wa pe yoo gbe ẹda itan naa jade nileeṣẹ sinima rẹ ti ilumọọka onkọtan ere itage to ba wọn  lọwọ ninu  fiimu The Pursuit of Happyness Steven Conrad naa yoo pawọpọ pẹlu wọn.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Oyo LG Polls: Ẹgbẹ́ òṣèlú 17 ń kópa nínú ìbò ìjọba ìbílẹ̀, APC takété
Iroyin sọ wi pe awọn janduku ti da ibo ru ni ijọba ibilẹ Ila-oorun Ibarapa, Ibarapa East Local Government ti o jẹ ijọba ibilẹ adari ile igbimọ aṣofin ipinlẹ Ọyọ, Họnọrebu Adebo Ogundoyin.
Ohun ti o ṣokunfa iwa ipanle naa ni a ko tii fi idiẹ mulẹ ni asiko ti a ko iroyin yii jọ.
Bakan naa ni ajọ eleto idibo ipinlẹ Ọyọ, OYSIEC ti da ọjọ mii fun eto idibo ijọba ibilẹ Ido.
Eyi waye lẹyin ti ajọ naa fagile idibo to waye nibẹ lọjọ kejilelogun, oṣu Karun-un, ọdun 2021, nitori bi ko ṣe si ami idanimọ ẹgbẹ osẹlu ZLP lori iwe idibo.
Ẹ yéé yí òfin àtijọ́ padà bí ọ̀gà, agánrán òfin tuntun la nílò ní Nàìjíríà - PFN
"Ọdún mẹ́ta gbáko ni mo fí ṣé ìgbáradì láti fi di ""National Chess Master"" -Tanitoluwa"
Wo àwọn àwòràn láti ibi ìsìnkú àwọn ọmọ ogun Naijiria tó kú nínú ìjàmbá bàálù ní Kaduna
Àìsàn jẹ́ kí àwọ̀ ara Amida dàbí ara ẹja
Ijọba ibilẹ Ido nikan ni ẹgbẹ oṣelu naa ti ni oludije fun idibo ijọba ibilẹ to waye.
Ọjọ Aiku, ọjọ kẹtalelogun, oṣu Karun-un ni idibo yoo waye ni ijọba ibilẹ naa.
Ṣaaju ni alaga ajọ OYSIEC, Aarẹ Isiaka Olagunju ti tọrọ aforiji pe aṣiṣe lati ọwọ ajọ naa lo fa ifasẹyin naa.
Gẹgẹ bi ohun ti alaga ajọ naa, Aarẹ Abiọla Ọlagunju sọ lori redio Fresh Fm 105.9 nilu Ibadan, o ni igbesẹ naa pọn dandan nitori aisi ami idanimọ ẹgbẹ oṣelu ZLP lori iwe idibo.
Oríṣun àwòrán, others
Ijọba ibilẹ Ido nikan sini ẹgbẹ oṣelu naa ti n dije ninu eto idibo to n lọ lọwọ.
Adari ajọ OYSIEC gba wi pe lootọ ni awọn ṣe aṣiṣẹ lori ọrọ naa pẹlu alaye wi pe oun ati wọn igbimọ to n ṣe akoso ajọ naa yoo gbe igbesẹ ti o tọ.
O ni aṣiṣẹ naa ki i ṣe ohun ti wọn mọọmọ ṣe nitori gbogbo eto ti wọn ṣe tẹlẹ ni lati riidaju wi pe eto idibo naa lọ lai ni aṣiṣe ninu.
Ẹwẹ, botilẹ jẹ wi pe ikede ti waye wi pe ajọ eleto idibo ti wọgile ibo ni ijọba ibilẹ naa, iroyin sọ wi pe ibo ṣi n tẹsiwaju ni ijọba ibilẹ naa titi di asiko yii.
Ijọba ibilẹ mẹtẹẹtalelọgbọn to wa nipinlẹ Oyo ti eto idibo naa ti n waye.
Gẹgẹ bi alaga fun ajọ eleto idibo nipinlẹ Oyo, OYSIEC, Amofin Isiaka Olagunju ti, ajọ naa ko ni segbe si ẹyin ẹgbẹ oselu kankan lasiko eto idibo naa.
Olagunju ni igbaradi to mọyan lori ti wa nilẹ lati ri daju pe eto idibo naa lọ ni alaafia laisi mọkaruru kankan.
O salaye pe ẹgbẹ oselu mẹtadinlogun lo n kopa ninu eto idibo lati yan awọn alaga ati Kanselọ ti yoo maa dari awọn ijọba ipinlẹ to wa nipinlẹ Oyo.
Amọ saaju ni ẹgbẹ oselu APC ti kede pe, oun ko ni kopa ninu eto idibo naa nitori pe oun ko ni aaye lati gbaradi fun idibo ọhun lẹyin ti oun ti ileẹjọ to ga julọ ni Naijiria de lọsẹ kan sẹyin.
Oyo LG Polls: OYSIEC ní APC ló yẹ kò bẹ aráàlú lórí àṣìṣe rẹ̀ nípa ìbò ìjọba ìbílẹ̀
Bakan naa ni ẹgbẹ oselu APC dunkooko lati gbe alaga ajọ OYSIEC ati gomina Seyi Makinde lọ sile ẹjọ, to ba fi tẹsiwaju pẹlu eto idibo naa.
Sugbọn ajọ OYSIEC kede pe onyẹ kankan ko le yẹ eto idibo ọhun, ti oun si n tẹsiwaju nidi rẹ.
Saaju ni gomina ipinlẹ Oyo, Seyi Makinde ti kede pe ko ni si lilọ bibọ ọkọ ati ero lati aago mẹfa aarọ si mẹta ọsanni aarọ ọjọ Satide ti eto idibo naa n waye.
Bakan naa ni wọn kede ana ọjọ Ẹti gẹgẹ bi ọjọ isinmi lẹnu isẹ fun awọn olugbe ipinlẹ Oyo fun igbaradi eto idibo naa.
ALGON Oyo: Aleshinloye ní ìdájọ́ ilé ẹjọ́ tó ga jùlọ làwọn ń tẹ̀lé, kò sì yẹ kó fa ìjà
Nigba ti BBC Yoruba tọpinpin bi eto idibo naa se n lọ si nilu Ibadan, a sawari rẹ pe wọn ti n pin awọn eroja idibo lati idaji ọjọ Satide.
Lati ibi eto idibo si awọn ijọba ibilẹ to n bẹ nipinlẹ Ọyọ. Idibo ti bẹrẹ ni nnkan bi aago mẹwa owurọ ni awon ibudo idibo kan.
Amọ awọn oludibo ko ti i jade ni awọn adugbo mii, bẹẹ si ni awọn kan n reti awọn ohun elo fun idibo ni awọn ikorita kan, ti akọroyin BBC Yoruba ṣe abẹwo si.
Awọn ẹgbẹ oṣelu mẹtadinlogun lo n dije ninu eto idibo naa jakejado awọn ijọba ibilẹ mẹtalelọgbọn to n bẹ nipinlẹ Ọyọ.
Ibrahim Attahiru burial: Alààyè rèé nípa gbèsè tí Tinubusọ pé Nàìjíríà jẹ COAS tó kú nínú ìjàmbá okọ̀ òfurufú
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Agbaọjẹ oloṣelu ni Naijiria Bola Ahmed Tinubu ti pẹlu awọn ọmọ Naijiria to n daro ọga ọmọ ogun Naijiria to padanu ẹmi rẹ ninu ijamba ọkọ ofurufu ni Kaduna.
Tinubu to fi atẹjadẹ kan sita to pe akọle rẹ ni Asiwaju n ṣe idaro Attahiru.
Ninu rẹ o sọ pe ọna kan gboogi lati ranti Attahiru ati awọn mẹwaa to ku ninu ijamba ọkọ ni ki Naijiria bori igbesunmọmi ati awọn ipenija aabo mi.
Gomina nigba kan ri nipinlẹ Eko naa ṣalaye pe''Akikanju ọmọ ogun ni Attahiru ati awọn ti wọn padanu ẹmi wọn to si ṣe pe wọn gbajumọ iṣẹ wọn lati le fi mu afojusun Naijiria gẹgẹ bi orileede wa si imuṣẹ''
O ni iku wọn jẹ ohun to banilọkanjẹ ṣugbọn ''gbese ti a jẹ wọn ni pe ki a san bantẹ wa daada ki a si rii wipe a bori igbesunmọmi ati awọn iwa ipa mii to fẹ bẹgi dina ayanmọ rere ti Naijiria ni.''
Lọjọ Abamẹta ni wọn sinku Ọgagun Attahiru ati awọn mẹwaa mi ti wọn kọwọrin pẹlu rẹ ninu ijamba ọkọ ofurufu to waye ni Kaduna.
Kaakiri si ni ọrọ ikẹdun ti n jade ni iranti awọn akikanju to lọ yii.
Wọn ò bí Baba Ijesha dáa kó sọ pé kò mọ mí rí - Agbẹjọ́rò Adesina Ogunlana
Ẹ yéé yí òfin àtijọ́ padà bí ọ̀gà, agánrán òfin tuntun la nílò ní Nàìjíríà - PFN
"Ọdún mẹ́ta gbáko ni mo fí ṣé ìgbáradì láti fi di ""National Chess Master"" -Tanitoluwa"
Àìsàn jẹ́ kí àwọ̀ ara Amida dàbí ara ẹja
Homosexuality: Nàìjíríà, àtàwọn orílẹ̀èdè tí ìbálòpọ̀ akọsákọ ti lòdì sí òfin rèé
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Oriṣiriṣi ọrọ lo ti n gbode lori awọn onibalopọ abosabo, akọsako, awọn to ni nkan ọma ọkunrin ti wọn tun ni ti obinrin papọ tabi awọn to yi ẹda akọ tabi abo ti wọn wa pada.
Lorilẹede Cameroon, o ti fa ki wọn fi ọwọ ofin mu ọgọọrọ awọn eeyan lọdun yii ni ibamu pẹlu ija fun ẹtọ ọmọniyan.
Koda laipẹ yii, eeyan meji to yiẹda ara wọn pada ni wọn ti ran si ẹwọn ọdun marun lẹyin ti wọn fi ẹsun didan ibalopọ akọsakọ wo.
Orilẹede mọkandinlaadọrin ni ofin wọn lodi si ibalopọ akọsakọ o si fẹrẹẹ to idaji wọn to wa ni Afirika.
Ẹwẹ, lara awọn orilẹede yii ti n gbiyanju lati ma maa pe ibalopọ ẹda kan naa ni iwa to tapa si ofin.
Fun apẹrẹ ninu oṣu keji ọdun yii, aarẹ orilẹede Angola, Joao Lourenco fọwọ si ofin to pada faaye gba  ki awọn eeyan maa ni ibalopọ akọsakọ tabi abosabo to si ni ki awan eeyan yee ṣe idẹyẹsi mọ lori ọrọ to ba ni ṣe pẹlu ibalopọ.
Wo bí ìbálòpọ̀ tó gbóná giri-giri ṣe le ran tọkọtaya lọ́wọ́ láti kojú ìpèníjà
Àwọn òbìnrin tó ń ya fọ́tò ìhòhò ara wọn níwájú ilé kó sí gbaga ọlọ́pàá!
"Òṣèré méjì yìí ń fi ẹ̀wọ̀n runmú tóríi fíìmù ""Ife"" táwọn obìnrin ń bá ara wọn lòpọ̀"
Mo dúpẹ́ pé ìgbà tí mo wà nínú Jesu ni mo lọ sẹ́wọ̀n, tó bá jẹ́ pé mo wà nínú áyé ni ... - Wòlìí Genesis
Gabon naa ṣe bakan naa lori ibalopọ akọsakọ tabi abosabo ti wọn si kede ẹwọn oṣu mẹfa ati faani fun ẹni ti wọn ba gbamu.
Botswana naa ti da ofin naa pada lọdun 2019; Mozambique ati Seychelles ti wọgile ofin to ti ibalopọ ẹda kan naa lọdun diẹ sẹyin.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ni Trinidada ati Tobago, ile ẹjọ kan tun fagile ofin to tako ibalop akọsakọ pe ofin ọhun funrark tako ofin.
Nibẹrẹ ọdun to kọja yii gan ni Singapore da igbesẹ lati ṣe ayida ofin ti yoo tako ibalopọ akọsakọ.
Ẹwẹ lawọn ibi to ku, igbiyanju lati ṣe bẹẹ  ki wan mu ofin yii kuro kuna. Fun apẹrẹ ni Kenya, wọn gbe ẹjọ to tako ibalopọ akọsaka ro daadaa.
Àwọn ọmọ Naijiria n sọ òkò ọ̀rọ̀ sí Buhari àti Osinbajo pé wọn kò lọ sí ìsìnkú Ibrahim Attahiru
Tinubu, Gbajabiamila, Sanwo-Olu gbárùkù tí fífòfin de dída ẹran káàkiri ìgboro
Pé mo gba ìwọ́de lááyè kò túmọ̀ sí pé mo faramọ́ Oduduwa Nation - Akeredolu
TAMPAN pàṣẹ pé 'director' kankan kò gbọdọ̀ pe Nkechi Blessing àti Adams Kehinde sí iṣẹ́ mọ́
Oríṣun àwòrán, AFP
Ọpọlọpọ ofin to sọ ibalopọ akọsakọ di ẹṣẹ bẹrẹ lati igba aye awọn oyinbo amunisin to si jẹ pe lawọn ibi kan, ẹwọn gbọọrọ ni ijiya ẹṣẹ naa.
Lara awọn orilẹede to ni ko ba ofin mu ki ibalopọ akọsakọ wa naa ni ofin to lodi si ibalopọ abosabo.
Amọ apaps ẹgbẹ awọn onibalopọ yii - Gay, Bisexual, Transgender ati Intersex (Ilga) ni ijiya iku gan ni ijiya to wa fun awọn ẹsun yii ni iha Ila Oorun Ariwa Naijiria, ni Brunei, Iran, Mauritania, Saudi ati Yemen.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Baye ba ṣe n yi ka maa ba wọn yi... Orin tawọn eeyan maa n kọ eyi to difa fun pe igba ti n yi lori awan ofin aye atijọ ti wan fi de ibalopọ ẹda kan naa.
Nibayii, orilẹede mejindinlọgbọn lagbaye lo faaye gba ibalopọ ẹda kan naa, ti mẹrinlelọgbọn si ti da a bi ọgbọn faaye gba awan nkan kọọkan to ni ṣe pẹlu ibaṣepọ akọ ati akọ tabi abo ati abo. Ẹgbẹ Ilga sọ bẹẹ.
Ẹkunrẹrẹ akọsilẹ awọn orilẹede ti aaye ko ti gba ibalopọ ẹda kan naa ree:
Afghanistan
Algeria
Antigua & Barbuda
Bangladesh
Barbados
Bhutan
Brunei
Burundi
Cameroon
Chad
Comoros
Cook Islands
Dominica
Egypt
Eritrea
Eswatini
Ethiopia
Gambia
Ghana
Grenada
Guinea
Guyana
Iran
Jamaica
Kenya
Kiribati
Kuwait
Lebanon
Liberia
Libya
Malawi
Malaysia
Maldives
Mauritania
Mauritius
Morocco
Myanmar
Namibia
Nigeria
Occupied Palestinian Territory (Gaza Strip)
Oman
Pakistan
Papua New Guinea
Qatar
Saint Kitts and Nevis
Saint Lucia
Saint Vincent and The Grenadines
Samoa
Saudi Arabia
Senegal
Sierra Leone
Singapore
Solomon Islands
Somalia
South Sudan
Sri Lanka
Sudan
Syria
Tanzania
Togo
Tonga
Tunisia
Turkmenistan
Tuvalu
Uganda
Uzbekistan
Yemen
Zambia
Zimbabwe
Read more from Reality Check
Genesis Global: Bí Ọlọrun ṣe lò mí fún Musiliu tò ti lo ọdún 11 lọgbà ẹwọn ti mo lọ
Wolii Isreal Ogundipe Oladele Israel ti ọpọlọpọ mọ si Genesis ni oun rii daju pe akoko ti wọn wa fi ọ̀lọ́paa gbe ohun jẹ eyi ti awọn to ṣe e to daadaa ni. O sọ ẹkunrẹrẹ idi to fi ro bẹẹ fun BBC yoruba.
"O ṣalaye pe ọgba ẹwọn ti oun lọ ""jẹ ibi ti kii ẹ ibi too ti le jẹ́un to wu ẹ tabi ri iyawo abi ọmọ. O jẹ ibi ti ẹni ti ko ṣẹ ti lee ba ara rẹ boya tori Ọlọpaa ko ṣe ẹjọ daadaa""."
Oríṣun àwòrán, Genesis Global
BBC Yoruba gbera lọ si ile ati ijọ gbajugbaja Wolii ti wọ́n dajọ́ ẹwọn ọdun kan gbako fun amọ ti gbogbo eeyan dede gbọ pe o ti kuro lọgba ẹwọn lai tii lo ọdun meji oloṣu mejila naa pe.
Wolii Genesis ni ṣugbọn ẹni to ba ni Kristi a kan mọọmọ gba fun Ọlọrun ni pẹlu ohun toju rẹ yoo ri lọgba ẹwọn.
Genesis Global: Sáká lara Woli Israel Ogundipe dá, kìí ṣe àìlera ló mú kí wọn fi sílẹ̀ lẹ́wọ̀n
Mo máa ń dédé ṣubú lulẹ̀, tẹ́ẹ bá fi ọwọ kàn mí lásán, kódà lójú ọ̀nà márosẹ̀ - Fatimah Aderounmu
Ṣé o mọ̀ pé o leè rí omira abẹ́ obìnrin míì rà tàbi yọ̀ǹda tìrẹ fún lílò?
'Èmi ọmọ Ikorodu ọ̀ga, ọmọ aṣalẹ̀ jẹ́jẹ! Wo bí àwọn ọmọdé ṣe ń fi Oríkì Yorùbá dábíra ní Children's Day
Ìgboro ayélujára ń gbóná lọ́wọ́lọ́wọ́ mọ́ Remi Tinubu lẹ́yìn tó pe obìnrin kan ní Tọ́ọ̀gì
Oríṣun àwòrán, Genmesis Global
Ẹsun jibiti to to miliọnu mọkanla naira ni wọn fi kan Wolii Genesis eyi to pa ohun ati arabinrin kan, Laide Oni Williams to n gbe ni UK pọ.
Wolii Genesis sọ ohun toju ri ati ohun to ba bọ lati ọgba ẹwọn to lọ bọ tori wọn da a silẹ lẹyin oṣu mẹrin to bẹrẹ ijiya ẹsun naa dipo ọdun kan to yẹ ko lo nibẹ.
Ọrọ naa wa dabi owe kan to sọ pe igba gbogbo ni ọrọ kii ṣi lori alabahun tori bi ọpọlọpọ eeyan ṣe maa n wo awọn iranṣẹ Ọlọrun to ba ti ni iru idojukọ yii.
TAMPAN pàṣẹ pé 'director' kankan kò gbọdọ̀ pe Nkechi Blessing àti Adams Kehinde sí iṣẹ́ mọ́
Pé mo gba ìwọ́de lááyè kò túmọ̀ sí pé mo faramọ́ Oduduwa Nation - Akeredolu
Àwọ̀ ọmọ mi máa ń ṣípẹ̀ẹ́pẹ́ bíi ti ẹja ni, ẹsẹ̀ ń dùn ún kódà, kò tún ríran dáadáa - Ìyá Hameeda
Wo àwọn orílẹ̀èdè tí ìbálòpọ̀ akọsákọ ti lòdì sí òfin
Abuja-Kaduna road: Àwọn olùwọ́de dí òpópónà Abuja sí kaduna lórí ìṣẹ̀lẹ̀ ìjínigbé
Oríṣun àwòrán, Twitter/AustynZOGS
Iroyin ti a n gbọ ni pe awọn olufẹhonuhan ti di ọna mọrosẹ ilu Abuja si Kaduna.
Awọn oluwọde naa yabo oju popo Kaduna si Abuja lati fi ẹhonu han lori iṣẹlẹ ijinigbe to n ṣẹlẹ loju popo naa ni gbogbo igba.
Awọn oluwọde naa sun ọpọ taya lagbegbe Gauraka ​​Tafa.
Eeyan mẹẹdogun ni iroyin sọ pe awọn ajinigbe ṣẹṣẹ gbe tan loju ọna ọhun.
Akọroyin kan tiẹ sọ pe awọn oluwọde tun danu sun awọn agọ ọlọpaa lasiko iwọde naa.
Oriṣiiriṣii fidio ifẹhonuhan ọhun lo lu oju ayelujara pa.
Eto abo ti mẹhẹ bayii kaakiri orilẹede Naijiria pẹlu iṣẹlẹ ijinigbe ati iṣekupani to n ṣẹlẹ.
Yoruba Nation: Banji Akitoye ní àbámọ̀ ni yóò kẹ́yìn ọ̀rọ̀ fáwọn aṣaájú APC nílẹ̀ Oodua
Aarẹ ẹgbẹ Ilana Omo Yoruba, Ọjọgbọn Banji Akitoye ti fewe ọmọ mọ awọn asaaju ẹgbẹ oselu APC leti pe wọn yoo kabamọ bi wọn se takete si idasilẹ orilẹede Yoruba.rilẹ́
Ọjọ Aje ni Akitoye sekilọ yii fawọn asaaju ẹgbẹ oselu APC nilẹ Kaarọ Oojire, ti wọn ni awọn fara mọ pe ki orilẹede Naijiria wa ni ọkansoso, ti wọn si takete si idasilẹ Yoruba Nation.
Nigba to n sọrọ lori ipinnu awọn asaaju naa nibi ipade apero wọn to waye lọjọ Satide, Alaga fun ẹgbẹ Ilana Omo Yoruba naa ni ipinnu ti ko dara ni APC se.
"O ti foju han gbangba pe awọn asaaju APC nilẹ Yoruba naa yoo ge ika jẹ lori ipinnu wọn lati kọ ẹyin si idasilẹ orilẹede Yoruba.
A ti ń fẹ́ Hausa, Ibo, ó sàn ka jọ ṣe é ní tùbí-ǹ-nùbí lórí ọ̀rọ̀ Nàìjíríà ju ìjà ogun lọ - Ọba Alara
Adura mi ni pe nigba ti wọn ba n kabamọ lori ipinnu wọn naa, wọn yoo le ni igboya lati tun ara wọn pe pada si ookan aya awọn ọmọ Yoruba ati ireti wọn."
Bẹẹ ba gbagbe, saaju ni ẹgbẹ Ilana Omo Yoruba ti fesi lori ipinnu awọn asaaju ẹgbẹ APC naa pe itan ko ni sọ ohun to dara nipa wọn.
Oríṣun àwòrán, Facebook/Asiwaju Bola Tinubu
Bi awuyewuye ti n lọ lori ọrọ awọn to n pe fun ki iran Yoruba yapa kuro lara orilẹede Naijiria, awọn ẹgbẹ Ilana Oodua ti kilọ fun eekan ẹgbẹ oṣelu APC, Bola Tinubu.
Ẹgbẹ naa kilọ pe itan ko ni sọ daadaa nipa Aṣiwaju Bola Tinubu atawọn eekan oṣelu nilẹ Yoruba mii ti wọn tako pipe fun Odua Nation.
Lọjọ Aiku to lọ ni Tinubu ati Gomina ipinlẹ Osun tẹlẹ, Oloye Bisi Akande atawọn eekan ẹgbẹ oṣelu APC ṣepade nibi ti wọn tako pipe fun orilẹede iran Yoruba.
Tinubu sọ nibi ipade naa pe oun atawọn to wa nibi ipade naa fọwọ si atunto Naijiria ati fifi ofin de dida maalu kiri ni gbangba.
Ṣugbọn ninu ifọrọwerọ to ṣe pẹlu awọn akoroyin, agbẹnusọ Ilana Oodua, Maxwell Adeleye, sọ o ṣenu pe Tinubu tako pipe fun Odua Nation.
O ṣalaye pe awọn Yoruba ko pe fu ki Naijiria ko daru, amọ wọn fẹ da duro ni eyi to ba ofin ajọ iṣọkan agbaaye  ati iwe ofin orilẹede Naijiria mu.
''Ẹtọ wa ni lati sọ pe a fẹ da duro gẹgẹ bi ẹya Yoruba.
Oun to ba wu Tinubu ati awọn mii ni wọn le maa sọ kiri, ti ẹ ba dibo lori ọrọ yii ni ẹ o mọ pe ọpọ ọmọ ilẹ Yoruba lo fẹ daduro.
O ṣeni laanu pe Oloye Akande naa wa nibi tawọn eeyan kan ti n tako ati da orilẹede Yoruba silẹ,'' Adeleye ṣalaye.
O ni ohun ti ko ye Tinubu ati Akande ni pe lai si awọn eeyan, wọn ko le wa ni ipo aṣaaju ti wọn wa.
Yoruba Nation: Gani Adams ní 'Entertainer ní Igboho àti àgbá òfìfo
Oríṣun àwòrán, Gani Adams and Sunday Igboho
Ọrọ idasilẹ orilẹede Yoruba ti di ija agba meji ati isu ata yan-an yan-an lori ayelujara.
Idi ni pe awọn agbaagba meji nilẹ Yoruba, Aarẹ Ọna Kakanfo Iba Gani Adams ati awọn ajijagbara fun ilẹ Yoruba, Sunday Igboho, ti n sọ oko ọrọ si ara wọn.
Koda, ọrọ yii tun ti ran bi ina inu ojo de ọdọ awọn alatilẹyin asaaju Yoruba mejeeji, ti wọn si n sọko ọrọ buruku si ara wọn.
"'Èmi ọmọ Ikorodu ọ̀ga, ọmọ aṣalẹ̀ jẹ́jẹ! Wo bí àwọn ọmọdé tó ""tuush"" yìí ṣe ń fi oríkì Yorùbá dábíra"
Mo máa ń déédé ṣubú lulẹ̀, tẹ́ẹ bá fi ọwọ kàn mí lásán, kódà lójú ọ̀nà márosẹ̀ - Fatimah
Ìròyìn àyọ̀! Wọ́n tí tú akẹ́kọ̀ọ́ FUNAAB tí wọ́n jígbé sílẹ̀, bí orí ṣe kó o yọ rèé
Gẹgẹ bi awọn fidio to n lọ lori ayelujara, awọn agbaagbaa mejeeji naa ni lo n pe ara wọn ni oniruuru orukọ, ori ọrọ idasilẹ orilẹede Yoruba si ni aawọ wọn naa da le lori.
"Fidio kan to n ja rain lori ayelujara lo se afihan Iba Gani Adams to se apejuwe awọn ajijagbara to n pe fun idasilẹ Orilẹede Yoruba bii Adanilaraya lasan, eyi to pe ni ""Entertainer""."
Gbogbo eeyan lo si mọ pe Sunday Igboho lo n siwaju ipe fun idasilẹ orilẹede Yoruba.
Adams ni oun ni oun kọkọ sawari ikọlu awọn darandaran to n waye lagbegbe Ibarapa naa, ti oun si pariwo fun araye nipa rẹ.
Ọdún 32 ni mo fi ṣiṣẹ́ oko mọ́ ìṣẹ́ tíṣà kí àwọn ọmọ mi le jẹ́ èèyàn, àmọ́ ikú mú Taiwo lọ - Baba Taiwo Asaniyi
A ti ń fẹ́ Hausa, Ibo, ó sàn ka jọ ṣe é ní tùbí-ǹ-nùbí lórí ọ̀rọ̀ Nàìjíríà ju ìjà ogun lọ - Ọba Alara
Amọ o ni se ni 'ajijagbara yii' ko ẹrọ ayaworan Kamẹra lọ sibẹ, to si n se bii ẹni to n da awọn eeyan lara ya.
Iba ni Igboho kii se ajijagbara rara, bi ko se Adanilaraya lasan nitori to ba jẹ pe ajijagbara ni, ko ni maa gbe Kamẹra kiri lati polongo ara rẹ.
Bakan naa lo ni agba ofifo lo maa n pariwo kiri, nitori agba to ni omi ninu kii pariwo rara.
Ninu fidio mii ti agbẹnusọ fun Sunday Igboho, Olayomi Koiki fi soju opo Facebook rẹ, lo se afihan esi ti Sunday Igboho fọ pada lori orukọ Adanilaraya ti Igboho sọ.
Igboho ni isẹ ijijagbara ti oun n se ko wa lati gba ohunkohun lọwọ ẹnikẹni, bi ko se lati gba ominira fun iran Yoruba.
O ni awọn to ni awọn ti n se isẹ ijijagbara yii lati ọjọ pipẹ, ni wọn n gba owo nidi rẹ, ti wọn ko si le sẹ epe pe awọn ko gba owo.
Yemi Farounbi: Yorùbá yóò dáàbò bo ara rẹ́, bí ìjọ́ba bá kùnà láti ràgà bò wọ́n
O ni ọpọ owo ni wọn ti gba, tori owo si ni wọn fi n se isẹ ijijagbara wọn, ọpọ igba si ni oun maa n sẹ epe pe oun ko gba owo lọwọ ẹnikẹni, eyi ti awọn to ni awọn n jija gbara ko le se.
"O yẹ kẹ jẹ ki ori yin pe, kẹ si maa mọ oun ti ẹ maa sọ jade lori ayelujara. Entertainer ni mi lootọ, emi ni Ọlọrun fun.
Iwa ijijagbara mi yii si ni maa fi gba orilẹede Yoruba kuro ni ara Naijiria, agba ofifo tẹ pe mi yii naa ni maa fi gba ominira fun ilẹ Yoruba .
Ti wọn ba to bẹẹ, ki wọn jade lati wa pariwo fun ominira Yoruba, mo mọ pe ko le se bẹẹ nitori to ba se bẹẹ, owo ti awọn araabi gbe fun wọn, wọn yoo beere rẹ pada lọwọ wọn."
Oríṣun àwòrán, Screen Shot
O ni ẹni to pe oun ni Entertainer ti jẹ dodo, ti ko si le sọ ododo. O ni se bi Restructuring ni wọn kọkọ ni awọn n fẹ, ki wọn to wa pada maa beere fun orilẹede Oduduwa.
Ohun ti Sunday Igboho sọ ninu fidio naa ti bọ si apo ibinu Alaga ẹgbẹ oselu OPC nijọba ibilẹ Ikosi Isheri nilu Eko, Alhaji Akeem Omiata.
Ninu fidio kan ti Omiata gbe soju opo Facebook rẹ, lo ti ni Sunday Igboho ko sọ idi gun, to si ti gun igi aladi.
Oríṣun àwòrán, Screen Shot
O ni ọpọ ọrọ ti Sunday Igboho sọ naa ni ko mu laakaye lọwọ, ti awọn to n ti i, si ti tii subu.
"Ẹni to sọrọ si yii kii se ẹgbẹ rẹ, Aarẹ Ọna kakanfo kii se ẹni to maa fi tayin, abi ta lo fi awọn aarẹ to saaju tayin.
Iwọ n fi aarẹ tayin amọ ko le dun mi fun ọ nitori gbogbo awọn ọba lalaye lo ti sọrọ si tan patapata.
Bakan naa lo tun n sọrọ si Baba Adeboye, to n yọ wọn pe ọmọ wọn ku, to ba kawe, se o ko ka ọgbọn inu ni."
Bakan naa tun ni Omiata ni Igboho yoo gba nipa iwa to hu, ti Igboho yoo si mọ pe oun ko jẹ nkankan.
Awọn ọrọ yii si lo n ti n da ori ayelujara laamu bayii.
Francis Olusola Alao: Wọ́n ti ti ọ̀rọ̀ òṣèlú bọ ọ̀rs Sunday Igboho, ṣùgbọ́n..- Oba Olugbọn
Adebayo Adelabu: Florence Ajimobi lẹ́tọ̀ọ́ sí ìdùnú àti ayọ̀ lẹ́yìn iku ọkọ rẹ̀
Oríṣun àwòrán, Screen Shot
Agbaakin Parakoyi ti ilẹ Ibadan, Adebayo Adelabu ti sọrọ lori awuyewuye to n waye lori fidio kan to gba ori ayelujara kan.
Ninu fidio naa, ni oun ati aya gomina tẹlẹ nipinlẹ Oyo, Florence Ajimobi ti dijọ n jijo si orin 'Gbẹ́sẹ̀, Gbe Body Soke' eyi to n ja rainrain lori ayelujara.
Ninu atẹjade kan to fi ṣọwọ si awọn akọroyin, Adelabu sọ pe ko si nnkan babara ninu fidio naa, ṣugbọn awọn kọlọransi ẹda kan kàn mọọmọ fẹ fi fidio naa da wahala silẹ ni.
Adelabu sọ pe inu oun bajẹ lori ọrọ ti awọn eeyan kan n sọ nipa fidio naa, o ni se lo yẹ ki wọn maa ba aya gomina tẹlẹri ọhun yọ, pe o gbẹyin ọkọ rẹ to jẹ Ọlọrun nipe.
"O ni ""Obinrin yii jẹ ẹnikan to duro ti ọkọ rẹ nigba ojo ati igba ẹrun, o si ṣe ọfọ oloogbe ọhun fun nnkan bii ọdun kan gbako."
Oríṣun àwòrán, SScreen Shot
Igbagbọ wa ni pe ẹtọ rẹ ni ki inu rẹ dun lẹẹkan si lẹyin iku ọkọ rẹ.
Ibi ti a ti n jo ijo naa jẹ ipejọpọ ajọyọ kan, ti wọn ṣe fun awọn alakoso ijọba ibilẹ, ALGON, lẹyin ti wọn jawe olubori nile ẹjọ to ga julọ.
"Apejẹ naa si ni awọn alakoso ti wọn dibo yan atawọn eekan ni ijọba ibilẹ naa peju si."""
Adelabu fi kun pe, lẹyin ti wọn fi ẹmi imoore han si Florence Ajimobi fun atilẹyin rẹ fun ALGON, ni wọn ni ko wa ba awọn fi ẹsẹ rajo, ti oun naa si ṣe bẹẹ.
O ni o ṣenu laanu pe ibi to ti n ba oun nikan jo, ni awọn kọlọrọsi ẹda naa gbe sita, ti wọn si n pin lori ayelujara lati tabuku aya gomina tẹlẹri ọhun ati oun alara.
Mo dúpẹ́ pé ìgbà tí mo wà nínú Jesu ni mo lọ sẹ́wọ̀n, tó bá jẹ́ pé mo wà nínú áyé ni ... - Wòlìí Genesis
Agbaakin Parakoyi ti ilẹ Ibadan naa ṣalaye pe, oun ko ri nnkan babara ninu ijo ti aya oloogbe naa jo nitori ko si ẹni ti ko ni ku.
O fikun pe, o ti to nnkan bi ọdun kan ti Abiola Ajimobi jade laye, iyawo rẹ si ti ṣọfọ rẹ bo ṣe tọ ati bo ṣe yẹ.
"O ni ""Sẹnetọ Ajimobi gbe igbe aye to dara, o ni ọjọ lori ko to jade laye, o si foju ganni awọn ọmọ-ọmọ rẹ, nitori naa, ko si ohun to buru ninu ki eeyan dunnu lati ṣe iranti iṣẹ rere to gbele aye ṣe."""
Adelabu pari ọrọ rẹ pe, ki awọn ti ọrọ naa kan maṣe naani ọrọ ti awọn eeyan kan n sọ nipa fidio ọhun lori ayelujara.
Lẹyin naa lo ni pẹlu idunnu ati ayọ ni awọn yoo fi ṣeto iranti ọdun kan ti gomina ipinlẹ Oyo tẹlẹri ọhun, Abiola Ajimobi fi aye silẹ.
Ṣaaju ni awọn kan ti kọkọ n bu ẹnu ẹtẹ lu Florence Ajimobi, lẹyin ti fidio ibi ti oun ati Adelabu ti n jo jade lori ayelujara.
Abiola Ajimobi: Àwọn aṣòfin Naijiria ṣọ̀rọ̀ ìwúrí nípa Ajimobi
"Ninu fidio ọhun ni awọn mejeji ti n jo si orin  ""Gbẹsẹ"" ti ẹni to wa ṣe ere nibi ayẹyẹ naa n kọ."
FUNAAB kidnap: Akẹ́kọ̀ọ́ tí wọ́n gbé lọ ló ń rán ara rẹ̀ nílé ìwé
Oríṣun àwòrán, Eke Isaac
Akẹkọọ fasiti ti wọn ti n kẹkọọ eto ọgbin ni Abeokuta, FUNAAB to wa lahamọ awọ́n ajinigbe ti gba itusilẹ pada.
Akẹkọọ naa, Toyinbo Olayinka wa ni ipele kẹ́rin tii ṣe aṣekagba, wọn ji i gbe lọjọ Abamẹta to kọja ni agbegbe Abule Itoko to to iwọn kilomita mẹwa si ọgba ileewe naa.
Oríṣun àwòrán, Eke Isaac
Alukoro fasiti FUNAAB to kan si BBC,  Kola Adepoju lo sọ aridaju pe wọn ti da a silẹ lalafia lalẹ Ọjọ Aje. Eyi jẹ lẹyin ti awọn akẹgbẹ rẹ ṣe iwọde ninu ileewe.
Ọgbẹni Kola ko sọ boya awọn ajinigbe kan da a silẹ tabi ẹnikẹni san owo idoola rẹ.
Ẹ wo àwọ́n lọ́balọ́ba tó ti ṣàtìlẹ́yìn jíjá fún Oduduwa Nation ní ilẹ̀ yorùbá
Njẹ́ o mọ̀ pé iléèṣẹ́ kan ní UK ti ra orúkọ́ ẹ̀yà Yorùbá tí ẹlòmìí kó fi ní le lò ó?
Ìdí tí àwọn aṣòfin ṣe fẹ fagilé NYSC, ohun táa mọ rèé
Àwọn Ọ̀gágun tó ṣeéṣe kó gba ipò olórí àwọn ọmọogun lẹ́yìn ikú Attahiru nìyìí
Ọdún 32 ni mo fi ṣiṣẹ́ oko mọ́ ìṣẹ́ tíṣà kí àwọn ọmọ mi le jẹ́ èèyàn, àmọ́ ikú mú Taiwo lọ - Baba Taiwo Asaniyi
A ti ń fẹ́ Hausa, Ibo, ó sàn ka jọ ṣe é ní tùbí-ǹ-nùbí lórí ọ̀rọ̀ Nàìjíríà ju ìjà ogun lọ - Ọba Alara
Lai si ipalara, ninu ilera pipe ni wọn tu u silẹ. Ẹkunrẹrẹ lori itusilẹ rẹ ko pọ ati pe gbogbo ẹ wa lọwọ awọn Ọlọpaa ipinlẹ Ogun.
O ni lorukọ awọn alaṣẹ ileewe fasiti naa, awọn dupẹ fun awọn oṣiṣẹ alaabo, atawọn to jẹ ti ijọba ateyi ti kii ṣe tijọba paapaa ileeṣẹ Ọlọpaa Ogun.
Atawọn oniroyin to fi mọ awọn lọbalọba ati gbogbo awọn ti ọrọ̀ kan ni wọ́n ranṣẹ idupẹ si lori itusilẹ akẹkọ naa.
Agbẹnusọ fun Fasiti ti wọn ti n kẹkọọ eto ọgbin, FUNAAB, Adepoju Kola, ti sọ pe akẹkọọ ti ile ẹkọ naa, Olayinka Toyinbo ti awọn ajinigbe gbe lọ kii ṣe agbegbe ile ẹkọ naa ni wọn ti gbe e lọ.
Ọgbẹni Kola ṣalaye pe ni abule kan ti wọn n pe ni Itoko ni ijọba ibilẹ Odeda ni wọn ti gbe Toyinbo lọ nibi to ti n ba ẹnikan ṣiṣẹ ninu oko rẹ.
"''O ṣeni laanu pe akẹkọọ yii lo n ran ara rẹ lọ si ile ẹkọ plu iṣẹ ti o n ṣe""."
Mo dúpẹ́ pé ìgbà tí mo wà nínú Jesu ni mo lọ sẹ́wọ̀n, tó bá jẹ́ pé mo wà nínú áyé ni ... - Wòlìí Genesis
Ati pe lori oko to ti n ṣiṣẹ naa ni o ti n sun ki iṣẹlẹ ọhun to ṣẹlẹ,'' Ọgbẹni Kola ṣalaye.
Lori boya awọn ajinigbe n beere fun owo itusilẹ fun akẹkọọ naa, Kola ni oun ko le sọ ohun kan nipa ọrọ naa.
''A ti fa ọrọ naa le ọlọpaa lọwọ, awọn ọlọpaa yii ṣi ti n ṣiṣẹ takun takun lati ri pe wọn doola akẹkọọ naa lakata awọn ajinigbe.
A ko tiẹ fẹ maa pariwo gan an lori ọrọ yii ki o maa ba ṣakoba akẹkọọ wa to wa lakata awọn ajinigbe.
Àbọ̀ wá bá ni ọ̀rọ̀ Iyabo Ojo àti Yomi Fabiyi lórí ọ̀rọ̀ bàbá Ijẹsha - Damola Olatunji, ẹgbẹ́ TAMPAN
Àwọn Ọ̀gágun tó ṣeéṣe kó gba ipò olórí àwọn ọmọogun lẹ́yìn ikú Attahiru nìyìí
Ọ̀rọ̀ Yorùbá Nation ń fa aáwọ̀ láàrin Gani Adams àti Sunday Igboho
Oríṣun àwòrán, Eke Isaac
Oríṣun àwòrán, Eke Isaac
Awọn akẹkọọ akẹgbẹ rẹ tu yaya jade lati ṣe ifẹhonuhan lori bi wọn ti ji Toyinbo gbe lọ.
Amọ iwọde alaafia ni wọn ṣe, ọdọ awọn ọlọpaa ni wọn ṣe iwọde lọ lati fi ẹhonu wọn han, wọn ko si ba ohun kohun jẹ,'' agbẹnusọ fasiti FUNAAB lo sọ bẹẹ.
Ọjọ Abamẹta ọsẹ to lọ ni wọn gbe Toyinbo lọ ti wọn si n wa di akoko yii.
Ban on open grazing: Akeredolu, yé rí Ààrẹ Buhari fín mọ́; nǹkan tí ààrẹ fẹ́ ni Garba Shehu sọ -BMO
Oríṣun àwòrán, Presidency
Ẹgbẹ kan to n risi ifọnrere Buhari, Buhari Media Organization (BMO) ti ranṣẹ ọrọ si gomina ipinlẹ Ondo, Rotimi Akeredolu lori esi to fọ pada si amugbalẹgbẹ aarẹ Buhari, Garba Shehu.
Wọn ni esi to ranṣẹ fun igbesẹ ti aarẹ Buhari ṣẹṣẹ gbe kalẹ fun didẹkun wahala laarin awọn darandaran ati agbẹ fihan pe ko fi ọwọ fun ọfiisi aarẹ.
Ninu atẹjade kan ti alaga ẹgbẹ naa,  Niyi Akinsiji pẹlu Cassidy Madueke to jẹ akọwe fọwọsi, wọn ni ọrọ ti gomina Akeredolu sọ ku diẹ kaato lori ipinnu ti aarẹ gbe kalẹ lati da awọn igbo ọba pada gẹgẹ bi ara ọna to ṣee mulo dipo kiko maalu jẹko kiri igboro eleyi ti awọn gomina lẹkun gusu orilẹede Naijiria n tako laifi ọna abayọ to tọ silẹ.
Wọn bu ẹnu atẹ lu Gomina Akeredolu fun fifi ọwọ si atẹjade kan eleyi ti wọn ni o fi ọgbọn kọlu aarẹ ati amugbalẹgbẹ rẹ lori ọrọ iroyin, Garba Shehu to kede laipẹ yii nipa igbesẹ ti aarẹ Buhari n gbe lori ọna ati ṣe atunṣe awọn igbo ọba gbogbo.
Mo máa ń déédé ṣubú lulẹ̀, tẹ́ẹ bá fi ọwọ kàn mí lásán, kódà lójú ọ̀nà márosẹ̀ - Fatimah
Ẹgbẹ naa woye pe irufẹ awọn ọrọ to n ti ọdọ gomina ipinlẹ Ondo jade fihan pe ootọ ọrọ ni pe eekan ọmọ Yoruba nni to n ja fun idasilẹ orilẹede Yoruba, Sunday Igboho sọ nigba to wipe gomina Akeredolu wa lara awọn to n ti ipe fun iyapa Yoruba kuro labẹ Naijiria lẹyin sọ.
Ẹgbẹ BMO naa ni awọn lee sọ yanya pe aarẹ lo fọwọsi atẹjade ti Garba Shehu fi sita lori igbesẹ ijọba apapọ lati ṣe agbedide awọn igbo ọba fun sinsin awọn maluu ati pe bi inu gomina Akeredolu ko ba dun si eyi ko bọ si gbangba wa sọ.
Ẹgbẹ to n fonrere Buhari naa, (BMO) wa fi da awọn ọmọ Naijiria loju peigbesẹ aarẹ lati ṣe agbedide awọn igbo ọba naa ko si fun jija ilẹ gba lọwọ ẹnikẹni tabi fifa awọn ilẹ le awọn agbebọn to n fi iṣẹ darandaran boju gẹgẹbi atẹjade ti gomina Akeredolu fọwọsi ṣe sọ.
'Mo fọ kọ́mú, pátá, ògiri ilé lórí 200,000 láìlèfọhùn lórílẹ̀èdè Oman'
Oríṣun àwòrán, Twitter/Garba Shehu
Gomina ipinle Ondo, Rotimi Akeredolu ti bu ẹnu atẹ lu oluranlọwọ Pataki fun Aarẹ Buhari lori ọrọ iroyin, Garba Shehu lori ọrọ to sọ nipa adehun awọn gomina mẹtadinlogun ni Guusu Naijiria pe ko gbọdọ si dida ẹran kaakiri igboro ni Naijiria.
Garba Shehu ninu atẹjade to fi lede wi pe lati ọdọ aarẹ Buhari sọ wi pe ko si ọrọ ninu adehun awọn gomina naa, to si ni pe wọn ko fi ọna abayọ jade si isoro naa.
Amọ gomina Akeredolu ninu atẹjade gba owo oluranlọwọ pataki fun lori awọn iṣẹ pataki, Doyin Odebowale fi lede pẹlu akọle '' 'Mr Garba Shehu: On the trail of an agent provocateur'
Akeredolu ni ẹnikẹni to ba ti n feti si ọrọ ti Garba Shehu n sọ yoo mọ wi pe oun da nkan ṣe ni adabọwọ ara rẹ ni lai gba aṣẹ ni ọwọ aarẹ Muhammadu Buhari, eleyii to fihan wi pe oun lọgun ituka lorilẹede Naijiria.
''O fihan pe o ni awọn miran to n ṣiṣẹ fun yatọ si ilọsiwaju ijọba, eleyii to si fẹ mu ki awọn kan lagbara lori ijọba orilẹede Naijiria''
''Garba gbọdọ sọ awọn to n ṣiṣẹ fun nitori kii ṣe aarẹ Buhari , bi bẹẹ kọ ko salaye idi ti ọrọ Minisita fun eto agbẹ, Alhaji Sabo Nanono, ti wọn yan si ipo, yoo ṣe lagbara ju adehun awọn gomina mẹtadinlogun, ti awọn araalu dibo yan.''
''Garba Shehu ninu ọrọ rẹ ni adehun awọn gomina mẹtadinlogun yii ko ṣe e duro le lori, amọ igbesẹ awọn Fulani darandaran to jẹ ibatan, to paṣẹ wi pe ki wọn kọ ile igbe fun awọn darandaran, ki wọn fun wọn ni omi ati ipese ileewe to fi mọ ileewosan fun wọn lo ṣe e tẹle''.
''Garba fihan pe awọn gomina ko lagbara mọ lori awọn araalu to yan wọn si ipo tabi lori ilẹ wọn, ni ijọba apapọ yoo ṣe ma a gbe igbesẹ tako wọn ni ibi ti wọn jọba le lori.''
Bakan naa ni Gomina Akeredolu wa kilọ gidigidi fun Garba Shehu ati awọn ẹmẹwa rẹ, wi pe ki wọn so ewe agbejẹ mọ ọwọ lori ọrọ awọn Fulani darandaran ni ilẹ Yoruba.
Akeredolu ni nitori pe ijinigbe ati ipaniyan ni ọrekoore gbọdọ dopin at I wi pe awọn ni aṣẹ gẹgẹ bi Gomina ni ipinlẹ awọn lati ripe eto aabo to munadoko wa fun awọn araalu lorilẹede Naijiria.
Gomina ipinlẹ Ondo, Oluwarotimi Akeredolu fikun pe ko si ilẹ kan ninu ilẹ awọn eniyan ni ilẹ Yoruba ti wọn yoo fun awọn Fulani darandaran labẹ akoso bo tilẹ wu ko ri.
Dominic Joshua Ngene: Ọmọ ọdún 21 kó sọ́wọ́ ọlọ́pàá lórí ẹ̀sùn jìbìtì N2bn fún ìdókòwò Bitcoin àti Forex
Oríṣun àwòrán, Dominic Joshua
Ileeṣẹ ọlọpaa ti mu ọga agba ileeṣẹ  Brisk Capital Limited, Dominic Joshua lori ẹsun jibiti owo to le ni biliọnu meji naira.
Ileeṣẹ ọlọpaa ni lara ẹsun ti wọn fi kan Joshua ni pe o dari owo awọn oludokowo lọ si ibo miran.
Awọn ọlọpaa ni lẹyin ti ọpọ eeyan ti mu ẹjọ rẹ wa lawọn ṣe iwadii lori Joshua to jẹ ọmọ ọdun mọkalelogun.
Ileeṣẹ ọlọpaa ni lori ẹrọ ayelujara bii Facebook, Instagram ati Twitter ni Joshua ti maa n ri awọn ti wọn ba n da owo pọ.
Ohun ti wọn ni Joshua n sọ fawọn eeyan ni pe oun maa ba wọn dokowo lori Bitcoin, Forex, ile ati ilẹ tita to fi mọ owo epo rọbi.
Ileeṣẹ ọlọpaa ṣalaye pe Joshua tun maa n sọ fawọn eeyan ere gọbọi bii ida ọgọta ninu ọgorun ni wọn yoo maa ri lori okowo wọn.
Awọn ọlọpaa ni ẹẹdẹẹgbẹta eeyan lo lu ni jibiti owo to le ni biliọnu meji naira ri.
Ninu atẹjade ti kọmiṣọnna ọlọpaa to n ri si ẹsun jibiti lulu, Anderson Bankole fi sita, o kilọ fawọn eeyan lati kiye sara lori okowo ti wọn ba sọ fun wọn pe ere gọbọi lo wa nibẹ.
Ileeṣẹ ọlọpaa ni Joshua yoo foju ba ileẹjọ lẹyin tawọn oṣiṣẹ ẹka eto idajọ ba ti pari iyanṣẹlodi ti wọn gunle lọwọ yii.
Ta ni Dominic Joshua gan an?
Dominic Joshua jẹ ọga agba ileeṣẹ Brisk Capital Limited.
Ọmọbibi ipinlẹ Ebonyi niiṣe, amọ ipinlẹ Akwa Ibom lo fi ṣe ibujoko.
Joshua ninu ọrọ to fi sori ẹrọ ayelujara Linkedin pe oṣiṣẹ banki onimọ nipa okowo ni oun, bẹẹ ni oun si ti ṣiṣẹ naa fun ọdun mẹwaa.
A ko mọ nipa ile ẹkọ to lo, ṣugbọn o sọ pe oun kẹkẹ gboye ni fasiti UNICAL niluu Calabar, ipinlẹ Cross River.
Joshua ṣapejuwe ara rẹ gẹgẹ bi ẹni to n bawọn eeyan dokowo pẹlu owo wọn.
Odu ni Joshua kii ṣe aimọ fun oloko awọn akọroyin, ṣugbọn oun ti ọpọ mọ nipa rẹ ni pe o maa n sọ pe oun maa n ṣe iranwọ fawọn eeyan.
LAgos Snack For Thought: UNICEF ní akẹ́kọ̀ọ́ 229,264 ló kúrò níléẹ̀kọ́
Oríṣun àwòrán, UNICEF
Ìjọba ìpínlẹ̀ Eko ti fìdí ọ̀rọ̀ múlẹ̀ pé òun yóò ṣe àfilọ́lẹ̀ ètò ìsúná òní bílíọ̀nù mọ́kànlá náírà láti máa fún àwọn ọmọ ilé ìwé ni ipanu lasiko ikẹkọọ.
Olùbádámọ̀ràn pàtàkì lórí ìfikùlukù pẹ̀lú ará ìlú nipinlẹ Eko, ọmọọbabirin Aderemi Adebowale lo sọ èyí di mimọ, lásìkò tó ń já bọ̀ àṣeyọrí ọdún méjì ìṣejọba gómìnà Ìpínlẹ̀ Èkó, Babajide Sanwoolu ni Alausa Ikeja.
"Gẹ́gẹ́ bi ó ṣe sọ, ètò ìpèsè ipanu fáwọn akẹ́kọ̀ọ́ tí wọ́n pe àkọlé rè ni ""Snacks for Thought"" yóò seranwọ fún eto oúnjẹ iléèwé tí ìjọba àpapọ̀ gùnlé tẹ́lẹ̀."
Adebowale fikun pe eto ipese ipanu naa lo wá fún àwọn akẹ́kọ̀ọ́ ilé ẹ̀kọ́ alakọbẹrẹ  ipele ikini sì ìkẹta nìkan.
"Ó tún ṣàlàyé pé eto yìí yóò na ìjọba ní bílíọ̀nù mọ́kànlá náírà ""A ni ifọwọ́sọwọ́pọ̀ pelu ilé iṣẹ́ lórí eyi, a sì ti ní ènìyàn irínwó tó ti ṣetán láti ṣe iṣẹ́ fún wa lofẹ̀ẹ́"""
A ti ń fẹ́ Hausa, Ibo, ó sàn ka jọ ṣe é ní tùbí-ǹ-nùbí lórí ọ̀rọ̀ Nàìjíríà ju ìjà ogun lọ - Ọba Alara
Adebowale fi kún pé, ó se pàtàkì láti ṣe èyí kì àwọn lè mú adinku bá bí àwọn ọmọ ṣe ń kúrò ní ilé ìwé ni ìpínlẹ̀ Eko.
O ni èyí ló jẹyọ nínú àbájáde ìwádìí ajọ UNICEF pé awọn akẹkọọ to le ni ẹgbẹrun Okoolerugba o le mẹsan, (229,264) lọ kúrò ní ilé ìwé nipinlẹ Eko lọ́dún 2018.
"Lójúna àti mú adinku bàa iye àwọn akẹkọọ ti yoo duro kawe, a nílò jú owó isuna lásán lọ, àwọn ìrànwọ́ ijoba bí èyí yóò mú ìyàtọ̀ wá nípa fífi ọmọ sì ilé ìwé.
Mo dúpẹ́ pé ìgbà tí mo wà nínú Jesu ni mo lọ sẹ́wọ̀n, tó bá jẹ́ pé mo wà nínú áyé ni ... - Wòlìí Genesis
Bákan náà lo ni igbesẹ naa yóò mú adinku bá ìwà ọ̀daràn láwùjọ."
Military Plane Crash: Opó Alfred Onifade ń ṣèdárò ikú ọkọ rẹ̀ pẹ̀lú ohùn arò
Oríṣun àwòrán, joba_star/Instagram
Adura nla ni pe ki ọba oke jẹ ki tọkọ taya lo ara wọn pẹ, ki wọn ma si tete di opo ọsan gangan.
Jeniffer Olufade, tii se opo ọkan lara awọn awakọ baalu to ba isẹlẹ baalu ologun to ja rin, Alfred Olufade ti n fi itara ati omije se idaro iku ọkọ rẹ.
Olufade, to n fi ohun aro sọrọ loju opo Instagram rẹ salaye pe ọkọ oun ti la ala ni oru mọju Ọjọbo Ogunjọ osu Karun pe baalu oun ja.
Alfred ati Jeniffer, ti wọn se igbeyawo alarinrin ni osu mẹta sẹyin salaye pe aago mẹrin idaji Ọjọbọ naa ni ọkọ oun ji oun loju oorun pe oun la ala abaadi naa.
Oríṣun àwòrán, joba_star/Instagram
"Tibẹru tibẹru lo fi ji mi loju oorun pe o la ala pe baalu rẹ ja nigba tẹ n lọ si Kaduna, o ni se ni ala naa da bi tootọ.
Mo gbadura taratara fun ọ nidaji ọjọ naa, mo si fi ọ lọkan balẹ pe ko ni si ewu, ti mo si tun bi ẹ nipa akọsilẹ ilana ibi tẹ n lọ ati awọn ti o ba kọwọrin.
O sọ fun mi pe Asaniyi, mo si ni ko maa lọ, ko ni si ewu, arinye lo maa rin."
Jeniffer tẹsiwaju pe lootọ ni ọkọ oun lọ si Enugu, Owerrri ati Abuja, ti awọn si dijọ pe ara awọn pẹlu ẹrọ ayaworan fidio, tawọn si sọrọ fun igba pipẹ.
A ti ń fẹ́ Hausa, Ibo, ó sàn ka jọ ṣe é ní tùbí-ǹ-nùbí lórí ọ̀rọ̀ Nàìjíríà ju ìjà ogun lọ - Ọba Alara
"Se ni o sa n rẹrin musẹ ninu  fidio naa, ti n ko si fura pe akoko ikẹyin rẹ niyẹn tabi pe igba ikẹyin to rẹrin si mi ree.
Lẹyin igba naa lo tun fi atẹjisẹ ransẹ pe ẹ n lọ si Kaduna, kia ni ami ara sọ mi, ọkan mi ko balẹ mọ, mo n sare pe ẹ pada fun ọpọ igba, amọ o ko gbe ipe mi.
Mo fẹ bẹ ọ pe ko ma lọ si Kaduna, aya mi bẹrẹ si ja."
Jeniffer tun salaye pe Iyan ati ọbẹ ẹgusi ni ọkọ oun sọ fun oun fẹ jẹ ni ọsan ọjọ naa ti oun ba de lati Kaduna, amọ ikede ọfọ rẹ ni oun gbọ.
Obinrin opo naa wa n beere pe bawo ni oun se fẹ se igbe aye oun, bawo ni oun se fẹ da jẹun lai si ọkọ oun nitori awọn dijọ maa n se ohun gbogbo papọ ni.
Toyin Abraham Vs Lizzy Anjorin: ESABOD dá sí ìjà àwọn méjèéjì, wàhálà míì tún bẹ̀rẹ̀, Iyabo Ojo di Ońlàjà
Ọpọ eeyan lo n ro pe aawọ to wa laarin gbajumọ osere tiata meji, Lizzy Anjorin ati Toyin Abraham ti jẹ rodo, lọ ree mumi ni.
Amọ eyi ko ri bẹẹ rara nitori bi aawọ naa se n pẹ nilẹ si, lo tun n gbọn si, ti awọn oju opo ibanidọrẹ lori ayelujara si n gbona janian janni to ri ija awọn osere meji naa.
Bẹẹ ba gbagbe, ija Toyin ati Lizzy lo fẹ ni bii ọdun meji sẹyin, nigba ti Toyin bimọ, ti Lizzy si ni isọ alagbo lo bimọ si.
"'Èmi ọmọ Ikorodu ọ̀ga, ọmọ aṣalẹ̀ jẹ́jẹ! Wo bí àwọn ọmọdé tó ""tuush"" yìí ṣe ń fi oríkì Yorùbá dábíra"
Mo máa ń déédé ṣubú lulẹ̀, tẹ́ẹ bá fi ọwọ kàn mí lásán, kódà lójú ọ̀nà márosẹ̀ - Fatimah
Ọrọ yii dogun dọdẹ nigba naa, bi awọn eeyan awujọ atawọn gbajumọ kan si se pọn sẹyin Toyin to sẹsẹ bimọ, ni awọn miran pọn sẹyin Lizzy.
Koda, akoko kan tiẹ wa ti agbẹjọro Lizzy kọwe si Toyin Abraham pe ti ko ba sọra, ohun yoo gbe lọ sile ẹjọ.
Ni osu kẹrin ọdun 2021, eyiun bii osu kan sẹyin ni ariwo ayọ jade pe Lizzy Anjorin bimọ tuntun tawọneeyan si n ki ku oriire.
Ko pe ọsẹ meji lẹyin eyi ni obinrin kan, Fola Tinubu kede sita pe iya n jẹ oun atawọn ọmọ oun nitori pe Lizzy gba ọkọ oun, ti ko si jẹ ko tọju oun.
Aanu obinrin naa, to gbe fọnran ohun sita nipa itakurọ oun ati ọkọ rẹ, ti wọn si n koro oju si Lizzy pe ko se daadaa.
Koda, awọn kan ni di ẹbi ru Toyin pe oun lo wa nidi igbesẹ ti obinrin naa gbe yiui, lati ba Lizzy lorukọ jẹ.
Ọpọ awọn eeyan lori ayelujara lo n sẹ epe fun Lizzy, ti wọn si n darukọ Toyin Abraham pe eeyan gidi ni, amọ aburu wa lọwọ Lizzy.
Eebu yii pọ fun Lizzy toun naa fi se fidio sita lati se alaye ohun to waye laarin oun ati obinrin naa pẹlu ọkọ rẹ.
Sugbọn kaka ki wọn dẹyin lẹyin Lizzy, eebu tun n pọ fun ni.
Ọdún 32 ni mo fi ṣiṣẹ́ oko mọ́ ìṣẹ́ tíṣà kí àwọn ọmọ mi le jẹ́ èèyàn, àmọ́ ikú mú Taiwo lọ - Baba Taiwo Asaniyi
Ṣé lóòtọ́ ni àdó olóró búgbàmù ní iléèwé kan ní ìpínlẹ̀ Ebonyi lọ́jọ́ Ìṣẹ́gun?
Ẹ wo àwọ́n lọ́balọ́ba tó ti ṣàtìlẹ́yìn jíjá fún Oduduwa Nation ní ilẹ̀ Yorùbá
'Mo fọ kọ́mú, pátá, ògiri ilé lórí 200,000 láìlèfọhùn lórílẹ̀èdè Oman'
ESABOD da si ija Lizzy ati Toyin, ọrọ di isu ata yanyan
Bi ọpọ eeyan se n fi ẹnu tabuku Lizzy to sẹsẹ bimọ yii, ti wọn si n to sẹyin Toyin, bọ si apo ibinu gbajumọ sọrọsọrọ kan lori ayelujara, Esther Tokunbo Aboderin, ti ọpọ mọ si ESABOD.
Ni irọlẹ oni ọjọ Isẹgun ni ESABOD se fidio kan, to si n sọ kobakungbe ọrọ si Toyin Abraham, ọkọ ati awọn ololufẹ rẹ lori bi wọn se yan Lizzy sọju.
ESABOD sọ ọpọ ọrọ lati gbe sẹyin Lizzy, to si n sọ kobakungbe ọrọ si Toyin, idile rẹ atawọn eeyan to n ti lẹyin.
Koda, o sọrọ debi pe ole, asẹwo ati ẹni ti ko ri owo kọle ni Toyin, ati pe, ko ri ohun kankan sọ lasiko ti ohun beere ohun to fa ija rẹ ati Lizzy ni bii ọdun meji sẹyin.
Koda, ESABOD ni ẹni to n mu oogun oloro ni Toyin, ti ko si gbe nnkan rere se.
Ninu fidio naa, ta n wo loju opo Instagram ESABOD, bo ti n se lọwọ, ni Toyin Abraham pe si, to si bu sẹkun.
Toyin wa fun ESABOD ni gbedeke ọjọ mẹta pe awọn ogun ọrun to n gbe inu oun yoo kan si tori epe to sẹ fun ọmọ ati ọkọ oun.
Toyin ni oun ko mọ idi ọrọ atawọn ẹsun ti ESABOD ati Lizzy fi kan oun nitori oun ko bẹ ẹnikẹni nisẹ lati maa bu Lizzy.
Gbedeke ọjọ mẹta ati ileri ti Toyin se yii bọ sapo ibinu ESABOD, to si ni lẹyin ọjọ mẹta, ti nnkan kan ko ba sẹlẹ, gẹgẹ bi Toyin ti leri, oju rẹ yoo si mabo.
Asiko yii naa ni osere tiata miran, iyabo Ojo foju han ninu fidio naa, to si n bẹ ESABOD pe ọr naa ko ri bẹẹ.
Iyabo wa jẹri Toyin Abraham pe kii se ọmọ buruku rara,m ti oun si ti tẹ ninu ni kọrọ nipa ija oun Lizzy, ti Toyin si ni oun ko mọ ohunkohun nipa rẹ.
Lẹyin ti fidio ESABOD pari tan ni Toyin Abraham naa bẹrẹ fidio tiẹ pẹlu Iyabo Ojo,  to si n da omije loju.
Toyin ni gẹgẹ bii abiyamọ, oun ko le laju silẹ, maa wo ESABOD niran, ko maa fi ọmọ ati ọkọ oun sepe ni oun se leri pe gbogbo epe to sẹ yoo sẹlẹ si obinrin naa laarin ọjọ mẹta.
Nigba ti aawọ naa kọkọ̀ bẹrẹ, ko si ẹni to le sọ pato ohun to faa, amọ a sa ri pe se ni ri ayelujara n gbona laarin awọn ololufẹ awọn osere tiata mejeeji naa.
Awọn ololufẹ Lizzy ni Toyin atawọn ololufẹ́ rẹ ti wọn pe ni Toyin Titans n lo ayederu orukọ lati maa ba Lizzy lorukọ jẹ.
Koda, wọn tun ni Toyin kọ iwe si ilẹ okeere kan ti Lizzy ti lọ ra ọja pe ki wọn yẹ ẹru rẹ wo daadaa, tori o le oogun oloro sinu rẹ.
Bakan naa ni awọn ololufẹ Toyin ni inu Lizzy ko dun si ọmọ ti Toyin bi, lo se n fooro ẹmi rẹ ni kete to bimọ tan.
A ti ń fẹ́ Hausa, Ibo, ó sàn ka jọ ṣe é ní tùbí-ǹ-nùbí lórí ọ̀rọ̀ Nàìjíríà ju ìjà ogun lọ - Ọba Alara
Bi o tilẹ jẹ pe awọn agbaagba awujọ kan ati ninu agbo tiata dide nigba naa lati jẹ́\ki ọrọ naa pari, ta si ro pe o ti ri bẹẹ.
Amọ awọn isẹlẹ akọtun yii lo tun mu ko maa foju han pe ija ọhun sẹsẹ bẹrẹ ni.
James Ibori loot: Ìjọba àpapọ̀ ní òun ti dá £4.2b tó gbà lọ́wọ́ James Ibori padà fún ìpínlẹ̀ Delta
Oríṣun àwòrán, others
Ijọba apapọ ni awọn ti fi owo ti wọn ri gba pada ninu owo ilu ti iye rẹ le ni biliọnu mẹrin poun owo ilẹ Gẹẹsi ṣọwọ pada si ọdọ ijọba ipinlẹ Delta.
Oluṣiro owo agba fun apapọ orilẹede Naijiria, Ahmed Idris lo so sọ bẹẹ. Owo naa poora lapo ijọba lasiko iṣejọba James Ibori gẹgẹ bii gomina ipinlẹ Delta tẹlẹ.
Amofin agba orilẹede Naijiria, Abubakar Malami ti kọkọ sọọ ni oṣu kẹta ọdun yii pe afara keji lori odo River Niger ati opopona Abuja si ilu Kano pẹlu titi marosẹ Eko si Ibadan ni wọn yoo na owo naa le lori dipo ki wọn daa pada si ipinlẹ Delta nibi ti Ibori ti ji.
Nàìjíríà ti rí €4.2m gbà padà nínú owó tí James Ibori gbé- Malami
Ìjọba UK ṣèlérí láti dá bílíọ̀nù méjì(N2b) owó tí Ibori kó jẹ padà sí Nàìjíríà
Akeredolu, yéé rí Ààrẹ Buhari fín mọ́- BMO
Ṣé lóòtọ́ ni àdó olóró búgbàmù ní iléèwé kan ní ìpínlẹ̀ Ebonyi lọ́jọ́ Ìṣẹ́gun?
'Mo fọ kọ́mú, pátá, ògiri ilé lórí 200,000 láìlèfọhùn lórílẹ̀èdè Oman'
Malami sọ ọ nigba naa pe ofin ijọba apapọ ni Ibori tapa si bẹẹni ijọba apaọ lo ṣe ẹjọ ti owo naa fi jade, kii ṣe iipinlẹ.
Amọṣa oluṣiro owo agba lorilẹede Naijiria ṣalaye fun ile aṣoju-ṣofin pe ijọba apapọ gba awọn owo naa lorukọ awọn ijọba ipinlẹ ni.
Oluṣiro owo agba ni Naijiria, Ahmed Idris ṣalaye fun igbimọ tẹẹkoto kan ti ile aṣoju-ṣofin gbe kalẹ pe aṣuwọn ipinlẹ ti wọn ba ti ji owo ni ijọba apapọ maa n da irufẹ owo bẹẹ pada si ni kete ti wọn ba ti gba a.
Ọdún 32 ni mo fi ṣiṣẹ́ oko mọ́ ìṣẹ́ tíṣà kí àwọn ọmọ mi le jẹ́ èèyàn, àmọ́ ikú mú Taiwo lọ - Baba Taiwo Asaniyi
'Ẹ jọ̀wọ́ ẹ bá wá fún àwọn ẹ̀gbọ́n àti àbúrò Taiwo Asaniyi níṣẹ́, òun ló ń bọ́ wọn kó tó kú nínú ìjàmbá bàálù'
Ẹ wo àwọ́n lọ́balọ́ba tó ti ṣàtìlẹ́yìn jíjá fún Oduduwa Nation ní ilẹ̀ Yorùbá
Ìjà Toyin Abraham àti Lizzy Anjorin tún búrẹ́kẹ́
O ni lọtẹ yii o, wọn ti da owo naa pada si aṣuwọn ijọba ipinlẹ Delta nitori lasiko ti James Ibori ṣe gomina nibẹ lo ko owo ti wọn gba naa jẹ.
O ni ijọba apapọ kii jẹ ki iru owo bẹẹ pẹ lọwọ oun nitoripe awọn ipinlẹ tọrọ kan lee gbe lọ si ile ẹjọ.
Ọrọ oluṣiro agba lorilẹede Naijiria yii n waye lẹyin ọsẹ kan ti ijọba apapọ kede pe oun ti gba biliọnu mẹein o le igba miliọnu pọun (£4.2 billion) ti ijọba ilẹ Gẹẹsi gba lọwọ awọn alajọṣepọ Ibori
Fatimah Aderounmu's muscular dystrophy: Bí Ọlọ́run ṣe gbé àdánwó yìí lé mi lọ́wọ́ rèé
Ìgbà tí Dókítà sọ fún mi pé ipò tí mo máa wà títí láé rèé, mò rò pé ayé ti fẹ́ parẹ́.
"Arabinrin Fatimah Aderounmu to jẹ ẹni ọdun mejilelogun ni ipenija aramanda yii n ba finra to maa n mu iṣan eeyan dede rẹwẹsi ti yoo rọ jọ. Awọn oloyinbo n pe aisan naa ni ""muscular dystrophy""."
O maa sabaa ṣakoba fun ọmọde diẹ diẹ lati ẹsẹ tabi nigba mii ko ki wọn ni gbogbo ara kija.
Ọkọ àti ìyàwó ri ọmọ ọdún kan àbọ mọlẹ láàyè lọgànjọ oru, àṣírí tú!
"'Èmi ọmọ Ikorodu ọ̀ga, ọmọ aṣalẹ̀ jẹ́jẹ! Wo bí àwọn ọmọdé tó ""tuush"" yìí ṣe ń fi oríkì Yorùbá dábíra"
Òkùtà wọ agbe ṣíṣe, alágbe kò rí àánú gbà mọ́, ariwo sọ
'Orísúnmibáre ni àìsàn 'Polio' tó kọlù mí ní kékeré'
Akeredolu, yéé rí Ààrẹ Buhari fín mọ́- BMO
Lẹ́yìn ọdún méjì tí iná ìjà tí n jó láàrin wọn, Lizzy Anjorin sọ àwọn ẹ̀ṣẹ̀ tí Toyin Abraham ṣẹ̀ ẹ́
Fatimah ni o maa n mu ara eeyan kaarẹ fun ọpọlọpọ ọjọ, to ba ya yoo pada yi si arun rọpa rọsẹ titi ayeraye.
Titi di oni, awọn onimọ iṣegun oyinbo ko tii ri oogun kankan gbe jade lati koju aisan naa.
Fatimah sọ fun BBC Yoruba pe lati igba ti oun ti wa lọmọ ọdun mọkanla ni Dokita ti kede fun oun pe o ni aisan yii latigba naa lo si ti wa lori aga oni kẹkẹ arọ ti ko si lee gbe ara rẹ.
Nibayii, fatimah ti na 'gbara o ti na 'gboro ninu irir rẹ to si ti da ẹgbẹ kan silẹ lati maa da awọn eeyan lẹkọọ nipa ohun to n jẹ muscular dystrophy to si fi n kowo jọ fun iranwọ awọn to wa ninu iru ipo tirẹ.
Ẹ wo àwọ́n lọ́balọ́ba tó ti ṣàtìlẹ́yìn jíjá fún Oduduwa Nation ní ilẹ̀ Yorùbá
Njẹ́ o mọ̀ pé iléèṣẹ́ kan ní UK ti ra orúkọ́ ẹ̀yà Yorùbá tí ẹlòmìí kó fi ní le lò ó?
Ó ní ìdí tí àwọn òyìnbó tó “Amalgamate” wa ṣe ní ká wà papọ, ẹ tẹ̀ẹ́ jẹ́jẹ́ lórí ìjà fún Oduduwa Nation - Ọba Alara
Ban on Open Grazing: Iléeṣẹ́ ààrẹ ní fífi òfin de ìdaranjẹ̀ nígboro lòdì sófin
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ilé iṣẹ́ ààrẹ Nàìjíríà bẹnu àtẹ́ lu àwọn àbájáde tí àwọn gómìnà Ìpínlẹ̀ to wa lẹkun Gúúsù Naijiria, tí wọn fofinde dídá ẹran ká ní àwọn ìpínlẹ̀ wọn.
Bakan naa ni wọn fi ẹ̀sùn kan pé oselu ni wọn fi ọ̀rọ̀ náà ṣe láti lo agbára wọn.
Èyí jẹyọ nínú àtẹ̀jáde kan ti olùrànlọ́wọ́ pàtàkì àgbà fún ààrẹ Buhari lórí ìpolongo àti eto ìròyìn, Garba Shehu fọwọ́ sí lọ́jọ́ ajé.
Ó ṣàlàyé pé àwọn gómìnà lẹkun Guusu kò wá ojútùú kankan sí ìṣòro àwọn àgbẹ̀ àti darandaran, eyi tó ń dá ojú orileede yìí bolẹ̀ láti ọdún pípẹ́ sẹ́yìn.
Àwọn gómìnà naa, nínú ìpàdé kan tí wọn ṣe ni ìlú Asaba ní Ìpínlẹ̀ Delta, ni wọn dijọ fẹnuko pé àwọn tí fi òfin de asa kí ẹnikẹni máa ko ẹran jẹ́ káàkiri ní Ìpínlẹ̀ àwọn.
'Mo fọ kọ́mú, pátá, ògiri ilé lórí 200,000 láìlèfọhùn lórílẹ̀èdè Oman'
Agbẹjọ́rò àgbà fún Nàìjíríà Abubakar Malami si lo kọkọ naka alebu sì igbesẹ awọn gomina naa.
Ilé iṣẹ́ ààrẹ fìdí rẹ múlẹ̀ pé ọ̀rọ̀ àwọn ènìyàn wọ̀nyí nílò àyẹ̀wò lábẹ́ òfin nítorí pé ó yẹ kí gbogbo ará ìlú ni anfani láti rìn jákèjádò gbogbo ìpínlẹ̀ lai ni ìfòyà.
Ó wa pe akiyesi àwọn ènìyàn sì pe ààrẹ tí fi ìgbà kan buwọ́lu àwọn ọ̀nà àbáyọ sì ọ̀rọ̀ àwọn àgbẹ̀ àti darandaran, kí aawọ wọn lè wá sí òpin.
"Àtẹ̀jáde náà ká báyìí pe: ""Ààrẹ Muhammadu tí ṣàlàyé láti mú òpin dé bá wàhálà láàrin àwọn darandaran àti àwọn àgbẹ̀ àti àwọn ìṣòro mìíràn tó nii ṣe pẹ̀lú darandaran agbebọn tó ń pá ènìyàn kiri."""
A ti ń fẹ́ Hausa, Ibo, ó sàn ka jọ ṣe é ní tùbí-ǹ-nùbí lórí ọ̀rọ̀ Nàìjíríà ju ìjà ogun lọ - Ọba Alara
Ààrẹ tí buwọ́lu àwọn ìlànà kan pàtó láti mú òpin bá hilahilo gẹ́gẹ́ bí Alhaji Sabo Nanono, to jẹ́ mínísíta fún ètò ọ̀gbìn ṣe sọ nínú àbájáde ìwádìí tó ṣe tí o sì gbé fún ààrẹ láti buwọ́lu nínú oṣù kẹrin ọdún.
Igbesẹ yii si waye ṣáájú kí àwọn gómìnà tó lọ máa pàṣẹ fifi ofin de àwọn darandaran nípa bibuwọlu iwe gẹgẹ bi ara ọgbọn òṣèlú láti fi agbára wọn hàn.
Ó hàn gbangba gbangba pé kò sí ọ̀nà àbáyọ tàbí ojútùú tí wọn ṣe sí ọ̀rọ̀ àwọn darandaran, tí wọn ń fi ojoojumọ jajaku akátá láti ìgbà dé ìgbà.
"Ṣùgbọ́n àwọn ará ìlú ni ìhà gúúsù àti ara ìlú jákèjádò Nàìjíríà ni ẹ̀tọ́ láti gbọ́ nípa ọ̀nà àbáyọ tí àwọn olórí wọn tàbí aṣojú se, kii se bí ki wọn wá máa nawọ́ òfin pé ""kii ṣe ìpínlẹ̀ mi."
Mo dúpẹ́ pé ìgbà tí mo wà nínú Jesu ni mo lọ sẹ́wọ̀n, tó bá jẹ́ pé mo wà nínú áyé ni ... - Wòlìí Genesis
Bákan náà ló fi hàn pé nnkan ti wọn n beere fún, mú ìwádìí lọ́wọ́ lábẹ́ òfin ẹ̀tọ́ ọmọniyan ni Nàìjíríà àti ẹ̀tọ́ olúkúlùkù láti rìn sì ibi tó bá wu u ni ìpínlẹ̀ mẹ́rẹ̀rindinlógójì, lai fi ìpínlẹ̀ to tí wá se.
Ṣùgbọ́n ó dùn mọ́ ni pé ìjọba tí gbe ìgbésẹ̀ ṣáájú àsìkò yìí, ààrẹ tí aawọ àwọn àgbẹ̀ àti àwọn darandaran n kọ lominu, ti wá ojuutu sì nípa bibuwọlu pé kí wọn ṣètò ibùjẹ ẹran ní gbogbo ìpínlẹ̀.
Zimbabwean Prostitutes: Olówó nàbì ní bí kò bá sí owó, àwọn ń gba iké àgbàdo àti agolo ẹ̀wà fún ìbálòpọ̀
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Awọn olowo nabi lorilẹede Zimbabwe ni iroyin kan ti sọ pe wọn ti n gba ike agbado ati agolo ẹwa fun ibalopọ.
Ilana pasipaarọ ọja fun ibalopọ yii ni awọn olowo nabi naa n lo ni ẹkun Dema, lorilẹede naa.
Gẹgẹ bi ileesẹ iroyin abẹle kan, New Zimbabwe ti wi, awọn olowo nabi naa lo wa n rawọ ẹbẹ sijọba atawọn onileesẹ nla nla fun owoya ti owo ori rẹ ko gunpa.
"'Èmi ọmọ Ikorodu ọ̀ga, ọmọ aṣalẹ̀ jẹ́jẹ! Wo bí àwọn ọmọdé tó ""tuush"" yìí ṣe ń fi oríkì Yorùbá dábíra"
Owo yii ni wọn ni awọn fẹ maa lo lati fi se okoowo kekeke ti yoo maa mu owo wa, tawọn yoo fi gbọ bukata ẹbi wọn ti ebi n pa.
"Ọkan lara awọn olowo nabi to ba iwe iroyin naa sọrọ ni ""Laye ijọun la maa n gba dọla marun fun oorun alẹ ọjọ kan."
Ìgboro ayélujára ń gbóná lọ́wọ́lọ́wọ́ mọ́ Remi Tinubu lẹ́yìn tó pe obìnrin kan ní Tọ́ọ̀gì
Èèyàn bíi 156 di àwátì bí ọkọ̀ ojú omi ṣe dédé là sí méjì láàrin agbami
Ìdè ọjọ́ pípẹ́ ti já, Villarreal fi Man United ṣe àtẹ̀gùn dé ilẹ̀ ìlérí ní àṣekágbá Europa League
Bangladesh Brothel: Ọ̀pọ̀ àwọn àṣẹ́wó tó wà níbẹ̀ ni wọ́n bí sílé aṣẹ́wó náà
"Lasiko yii, dọla kan pere la n gba, ka le ri owo ra ewebẹ ati tomato ta fi se ounjẹ fun awọn ọmọde ti ebi n pa."""
Bakan ni obinrin olowo nabi naa tun sisọ loju rẹ pe ọmọ mẹta ni oun bi, ti ọkan ninu wọn si wa ni kilaasi kẹrin nile ẹkọ girama.
O fikun pe ọmọ oun naa nilo owo lati fi orukọ silẹ́ fun idanwo asejade nile ẹkọ girama (ZIMSEC) nigba ọmọ keji wa ni kilaasi kinni nile ẹkọ girama.
Uber Lady: Bùkátà pọ̀ lọ́rùn mi ní mo ṣe ń wa taxi akérò
O ni ọmọ oun kẹta lo wa ni kilaasi keje nile ẹkọ alakọbẹrẹ bayii, ti bukata oun lojumọ si n ga soke si.
Mo ti wa n gba ike agbado ati agolo ẹwa gbigbẹ bayii dipo owo fun ibalopọ, nitori ti mo ba ri awọn eroja ounjẹ wọnyi gba, o daju pe awọn ọmọ mi yoo jẹ adalu ẹwa.
Oninabi miran tun salaye pe awọn tiẹ setan lati sisẹ ọmọ ọdọ amọ awọn ara agbegbe naa kii sanwo.
Coffee Painter: Adebukola ní kò sí ìrànwọ́ lẹ́yìn ẹ̀kọ́ girama lòun ṣe ń ya àwòrán
Awọn olowo nabi yii to ba iwe iroyin ọhun sọrọ lo n kopa nibi eto idanilẹkọ kan jẹ ara ọna lati wa adinku si ọwọja kokoro arun HIV atawọn arun mii ta le ko lati ara ibalopọ.
Yoruba Nation: Gani Adams tẹnumọ pé àwọn àjìjàgbara kan tí gba owó lọ́wọ́ olóṣèlú
Ẹgbẹ OPC, igun ti New Era ti ni ki Aarẹ Ọna Kakanfo, Iba Gani Adams darukọ awọn to fẹsun kan pe wọn ti dalẹ ijijagbara fun Yoruba Nation, lara awọn ti wọn jọ korapọ.
Agbẹnusọ fun ẹgbẹ OPC New Era ni orilẹede Naijiria, Shina Akinpelu lasiko to n ba ileeṣẹ iroyin BBC Yoruba sọrọ ni Gani Adams ko kan le e fi ẹsun kan awọn eniyan lai darukọ wọn.
Akinpelu  ni yoo jasi pe irọ n parọ fun irọ ni ọrọ Gani Adams nitori ẹni ti ọrọ ba da loju yoo sọ otitọ, ki wọn le fi oju awọn ẹni ibi han laarin wọn.
King Sunny Ade's son: Ohùn orin bàbá mi nìkan kọ ni l’Ọlọrun fún mi, ijó bíi kòkòrò ni ṣáá
O ni bi o tilẹ jẹ pe awọn naa mọ wi pe kii se gbogbo awọn to n ba awọn rin, lo n ja fun ẹtọ awọn Yoruba nitori awọn oloṣelu naa wa ni aarin awọn.
Oríṣun àwòrán, Elites Media
''Ọga mi ni aarẹ ọna Kakanfọ ni nkan bi ọdun diẹ ṣẹyin, ki n to pada lẹyin rẹ, amọ aarẹ ọna kakanfo mi ni bayii''
''Nitori naa ko si ija laarin Sunday Igboho ati Gani Adams , nkan kan naa ni wọn n ja fun''
''Awọn oloṣelu ati awọn oniroyin ofege lo fẹ da ija silẹ laarin awọn mejeeji, ifẹ ara ilu ni wọn n ja fun ati ki ilẹ Yoruba le e ni ilọsiwaju''
Bakan naa ni agbẹnusọ ẹgbẹ OPC naa kilọ fun awọn oloṣelu wi pe, ti wọn ko ba fẹ ijijagbara fun Yoruba Nation, ki wọn fi owo wọn pamọ.
O ni ko yẹ ki wọn fi owo da awọn ajijagbara lẹkun, nitori idajọ n bọ ni ori wọn.
Shina Akinpelu ni o ti han gbangba pe sasa ni awọn eniyan to fẹran ilẹ Yoruba denudenu, amọ nkan ti wọn fẹ jẹ, ni ko jẹ ki wọn gbadun.
O wa kesi awọn ajijagbara lati tẹsiwaju nitori ọjọ ọla a dara fun ilẹ Yoruba, ti ọwọ wọn yoo si tẹ gbogbo nkan ti wọn ba n wa, to fi mọ ''Oodua Nation''.
Agbẹnusọ fun Aarẹ Ọna Kakanfo fun ilẹ Yoruba, Ọgbẹni Kehinde ti sọ fun BBC Yoruba pe Aarẹ Gani Adams ko ni ko ọrọ rẹ jẹ.
Kehinde ni lootọ lo daju pe awọn ẹni ibi ti wọ aarin awọn ajijagbara fun Yoruba Nation.
O fikun pe Gani Adams ni ẹri to daju nilẹ, ki o to fi ẹsun naa sita lati pe akiyesi awọn eniyan si bo ṣe nlọ.
Bakan naa lo fikun pe, awọn oloṣelu to fẹ du ipo ni ọdun 2023 ni wọn ti bẹrẹ si ni fun awọn eniyan lowo, lati tẹnbẹlu ijijagbara fun Yoruba Nation.
''Ẹ ma gba awọn oloṣelu laaye lati da aarin wa ru nitori wọn ko ni ifẹ araalu, ohun ti wọn yoo jẹ ni wọn n wa kiri.
Ni oju awọn oloṣelu, idibo ọdun 2023 dabi ẹni wi pe ọla ni yoo waye, nitori naa wọn ti n sa gbogbo ipa wọn lati da ijijagbara Yoruba Nation ru.''
O fikun pe ikilọ ni Gani Adams fi lede fun awọn ajijagbara, ki wọn ma fi ọkan tan awọn oloṣelu nitori ọna ati da ijijagbara Yoruba Nation ru ni wọn n wa.
Awọn darandaran ti sekupa ogunlọgọ eniyan lawọn agbegbe kan lorilẹede Naijiria
Saaju la ti mu iroyin wa fun yin pe, Ààrẹ Ọ̀nà Kàkàǹfò fún ilẹ̀ Yorùbá, Iba Gani Adams ni àwọn ogbontarigi olóṣèlú kan ni ìhà gúúsù ìwọ oòrùn, tí rápálá wọ ìjàgbara fun idasilẹ orilẹede Yorùbá.
Ààrẹ Ọ̀nà kakanfo ṣàlàyé pé, ẹ̀tọ́ àwọn ọmọ Yorùbá ni láti pé fún Oodua Republic, ṣùgbọ́n ó ṣàlàyé pé àwọn olóṣèlú kan tí ja gbà, pàápàá jùlọ ni ìhà gúúsù ìwọ̀oorun.
Iba wa nàka àléébù sì àwọn olóṣèlú kan lásìkò ìpàdé àwọn ọmọ ẹgbẹ́ OPC ọlọ́sọ̀ọ̀sẹ̀ tó wáyé ní Ikeja nípìnlẹ̀ Eko.
"'Èmi ọmọ Ikorodu ọ̀ga, ọmọ aṣalẹ̀ jẹ́jẹ! Wo bí àwọn ọmọdé tó ""tuush"" yìí ṣe ń fi oríkì Yorùbá dábíra"
O ní àwọn olóṣèlú ọ̀hún ni a lè pè ní ọ̀dalẹ̀ àwọn ọmọ Yorùbá.
"Gani Adams fikun pe ""ó ṣe ni laanu pé àwọn kan ti pinnu nínú ọkàn wọn láti dá omi tútù sì ọkàn àwọn tó ń jijàgbara."
Ìgboro ayélujára ń gbóná lọ́wọ́lọ́wọ́ mọ́ Remi Tinubu lẹ́yìn tó pe obìnrin kan ní Tọ́ọ̀gì
Èèyàn bíi 156 di àwátì bí ọkọ̀ ojú omi ṣe dédé là sí méjì láàrin agbami
Gani Adams: Ẹniyan ma n ra aye gbe ni
Àwọn nǹkan tó ń ṣẹlẹ̀ láti bí ọ̀sẹ̀ díẹ̀ sẹ́yìn fi hàn pé àwọn alẹ́nulọ́rọ̀ àti àwọn olóṣèlú tí já ìjàgbara náà gbà, ti àṣeyọrí rẹ kò sì dájú mọ.
Ó jẹ́ ọ̀nà láti da omi tútù sí ni lọ́kàn kúrò nínú àfojúsùn tó wà nílẹ̀ tẹ́lẹ̀.
Ṣùgbọ́n mo n sọ báyìí pé ojúlówó ẹ̀tọ́ ni láti bèèrè fún orile-ede ara ẹni, tí a sì ti pinu láti torí rẹ kú, ààrẹ kò ní mú wa lati gba àwọn ènìyàn wá là lọ́wọ́ ìnira.
Ṣùgbọ́n láti jẹ́ kí èyí wá sí ìmúṣẹ, mo lè fi gbogbo ẹnu sọ, pé ó ṣe pàtàkì láti kíyèsí àwọn nǹkan mẹta.
"A gbọ́dọ̀ fi ọgbọ́n inú ṣe é, a gbọ́dọ̀ mọ bí a ó ṣe máa gbọ bí nǹkan ṣe ń lọ láyìíká wá, ń ó fi ìkẹta pam ọ sọ́dọ̀ mi náà."""
Atunto Naijiria la n fẹ - Aarẹ Onakakanfo, Gani Adams
Iba Adams wá sepe fún gbogbo àwọn tí wọn dáná ọ̀tẹ̀ àti ìjà ni ilẹ Yorùbá pàápàá julọ laarin awọn ti wọ́n ń pè fún O'odua Republic.
O fi kún pé ọjọ́ méje gbáko ni òun yóò fi máa ṣépè fun awọn adarugudu silẹ naa.
Major General Farouk Yahaya: Ààrẹ Buhari tí yan olórí ikọ̀ ọmọogun Naijiria tuntun
Oríṣun àwòrán, Defence HQ
Aarẹ orilẹede Naijiria, Muhammadu Buhari ti yan Ọgagaun Major General Forouk Yahaya gẹgẹ bi Adari ikọ awọn ọmọogun ori ilẹ ni Naijiria.
Ninu atẹjade ti ẹka  iroyin ileeṣẹ ọmọogun Naijiria fi lede ni iroyin naa ti han si awọn araalu.
Ọgagun Farouk ni oun dari ikọ awọn ọmọogun Naijiria to n koju ikọ Boko Haram ni ariwa orilẹede Naijiria, ti wọn pe ni HADIN KAI.
Aarẹ Buhari yan adari ikọ tuntun fun awọn ọmọogun Naijiria naa lẹyin ijamba ọkọ ofurufu to mu ẹmi Ọgagun Ibrahim Attahiru lọ ati awọn ọmọogun mẹwaa miran.
Ileeṣẹ ikọ ọmọogun ofurufu naa ni awọn ṣi n ṣe iwadii ijamba ọkọ ofurufu to waye ni tosi papakọ ofurufu to wa ni ilu Kaduna.
Yoruba Nation: Sunday Igboho ní káwọn ajìjàgbara fọwọ́ wọ́nú, kí ọ̀tá máṣe yọ àwọn
Oríṣun àwòrán, Sunday_Igboho1/Instagram
Gbajugbaja ajijagbara fun ilẹ Yoruba, Oloye Sunday Igboho ti kede pe wọn ti sun iwọde fun idasilẹ Yoruba Nation nipinlẹ Ekiti wa sẹyin.
Ọjọ kejila osu Kefa, eyiun June 12 ni Sunday Igboho ati awọn ajijagbara miran to n polongo idasilẹ́ orilẹede Yoruba yẹ ko ya wọ Ado Ekiti fun iwọ̀de naa tẹlẹ, ko to di pe wọn sun siwaju.
Amọ ni bayii, ọjọ Satide, ọjọ Karun osu Kefa ni wọn yoo se iwọde naa, eyi to fi ọsẹ kan din si ọjọ to yẹ ki wọn se iwọde naa tẹlẹ.
King Sunny Ade's son: Ohùn orin bàbá mi nìkan kọ ni l’Ọlọrun fún mi, ijó bíi kòkòrò ni ṣáá
Sunday Igboho, ẹni to kede isunsẹyin iwọde naa loju opo Facebook agbẹnusọ feto iroyin rẹ, Olayomi Koiki, salaye pe o nidi ti igbesẹ naa se waye.
Sunday Igboho: 'Ǹkan tÍ Sunday Igboho Ṣe ní Ibarapa tún ti ṣelẹ̀ ní ìpínlẹ̀ Ogun'
Igboho, ti wọn fi fọnran ohun rẹ ti wọn gba silẹ sita loju opo ikansiraẹni naa, wa rawọ ẹbẹ sawọn eeyan to n binu nitori ọjọ ti wọn yipada naa.
"Ohun to jẹ ka yi ọjọ naa pada si June 5 ni pe iwọde June 12 maa wa ti gbogbo wa maa ti lọ kopa, eyi ti yoo waye nilu Abeokuta.
Idi niyi ti mo fi ni ka ma mu June 12 nitori iwọde n bọ, to dẹ maa ni agbara gan, mo wa fi gbogbo awọn alalẹ bẹ yin kẹ dari jin mi.
Emi ni mo yi ọjọ naa pada si June 5, ẹ ma binu sira wa, ẹ jẹ ka se ara wa lọkan, ori idọbal,ẹ ni mo wa, mo fi Ọlọrun bẹ yin, ka dijọ de ilẹ ileri.
Esu ko ni de si aarin wa, ẹ ma jẹ ki aye yọ wa pe awọn to fẹ gba orilẹede Yoruba, lo n ba ara wọn ja yẹn."
Ifọrọwerọ  pẹlu Gani Adams lori ọrọ Sunday Igboho
O ni igbesẹ naa lo wa lati pana iporuru ọkan to n su yọ nitori iwọde Ekiti,  to si parọwa si awọn ajijagbara naa pe ki wọn se ara wọn ni ọkan.
Igboho fikun pe kii se eeyan kan lo n sisẹ ni ipinlẹ kọọkan, gbogbo wọn lo si se pataki.Ipinlẹ Ekiti kun fun awọn gbajumọ ati ọmọwe, ibẹ si ni Baba wa, Banji Akitoye ti wa.
O ni oun dupẹ pe awọn agbaagba tete pa ina rogbodiyan to fẹ suyọ nipa iwọde naa ni Ekiti, ti Ọlọrun si ti gba akoso ohun gbogbo.
Kò sí ìgbà kankan tí Yorùbá jókòó pé ki Igboho  lọ kéde ìyapa kúrò ní Nàíjíríà
Bakan naa lo ni ko si ẹnikẹni to n ba ara wọn ja, gbogbo wa la n sisẹ papọ fun aseyori iwọde ti yoo waye ni Ekiti lọjọ Karun osu Kẹfa ọdun 2021.
Ronke Oshodi Oke: Àjẹbí ni àwọ̀ pupa mi, omi UK ló mú kí ọmọ ìka mi dúdú
Oríṣun àwòrán, ronkeoshodioke/Instagram
Gbajugbaja oṣere tiata Yoruba, Ronke Oshodi Oke ti pariwo sita pe oun ko bora gẹgẹ bi awọn eeyan kan ṣe n sọ, ti wọn si n tabuku ara oun.
Ronke fìdí ọrọ yii mulẹ ninu fidio kan to fi lede loju opo Instagram rẹ ni aarọ ọjọbọ.
Ronke ni awọn eeyan kan lara awọn ololufẹ oun lo beere pe ki lode ti oun fi n bora nigba to fi aworan ara rẹ kan sita.
King Sunny Ade's son: Ohùn orin bàbá mi nìkan kọ ni l’Ọlọrun fún mi, ijó bíi kòkòrò ni ṣáá
Ilumọọka oṣere naa ni ẹsun tawon eeyan kan fi kan oun pe oun bora nitori ika oun to dudu, ku diẹ kaato nitori ọrọ ko ri bẹ́ẹ̀ rara.
Ronke salaye pe oun sẹsẹ ti ilu Ọba UK de ni, gbogbo eeyan lo si mọ pe omi wọn lagbara pupọ, eyi to yi awọ pupa oun yipada.
Oríṣun àwòrán, ronkeoshodioke/Instagram
Bakan naa lo fikun pe ọmọ ika oun dudu nitori oun n fi omi gbigbona wẹ ni awọn akoko kan, eyi ti ko ba ọmọ pupa lara mu.
"Gbogbo eeyan to mọ mi mọ pe ajẹbi ni awọ pupa ti mo ni nitori awọn obi mi pupa.
Nitori naa lo jẹ ki n ṣe fidio yii lai kun atike tabi tọ nkan kan sí ojú mi, ki ẹ le mọ pe eeyan pupa ni Eledua da mi.
Ṣe ẹ ri ọwọ mi yii to dudu tẹ fi ro pe o da bi ẹni pe mo n bora, omi wọn ni UK ti ko ba mi lara mu lo jẹ ko ri bẹẹ, Ronke ṣalaye."
Ó dára kí obìnrin níṣẹ́ lọ́wọ́ - Toyin Lawani
Ẹwẹ, awọn akẹgbẹ Ronke kan ti sọ fun un pe ko kọ eti ikun sọrọ tawon eeyan kan n sọ nipa rẹ.
Wọn ni ko fi ọrọ naa ṣe ipakọ o gbọ suti, ori ẹlẹgan lo daru, ati pe iwọfa lẹnu, ohun to ba wu ẹlẹnu ni o le fi ẹnu rẹ sọ.
Ghost thief caught in Zimbabwe: Ọwọ́ tẹ ọkùnrin tó n múra bí òkú ọrùn láti ja àwọn èèyàn ní olè
Oríṣun àwòrán, @daddyhope
Yoruba sọ pe ọjọ gbogbo ni ti ole, amọ ọjọ kan ni ti olohun.
Bẹẹ gan ni ọrọ ri fun ọkunrin afurasi ole, alọ kolohun kigbe kan lasiko ti ọwọ tẹ  lẹyin ọjọ pipẹ to ti ma n ja awọn eeyan lole.
Amọ nkan to jẹ iyalẹnu fun gbogbo eniyan ni pe ọna ara, ọna to yanilẹnu ni ọkunrin naa n gba ja ole tiẹ, to bẹẹ ti ọwọ ko fi tẹ ẹ titi di akoko yii.
Awọn ileeṣẹ iroyin ni Zimbabwe sọ pe niṣe ni ọkunrin naa ma n mura bi oku, lati ja awọn eniyan ilu Gutu, ni agbegbe Masvingo, lorilẹ-ede Zimbabwe, to wa ni Ila oorun Africa, lole ninu ile wọn.
Wọn ni ọkunrin hun yoo wọ aṣọ kan ti wọn sẹ bii egungun oku gbigbẹ, eyi ti wọn n pe ni 'skeleton' ni ede Gẹẹsi. Aṣọ naa ma n bo gbogbo ara rẹ lati ori titi de atẹlẹsẹ.
Ṣé lọ́ọ̀tọ̀ ní àkúdááyà wà? ẹ̀ wo ìrírí àwọn tó rí ènìyàn wọn tó kú láàyè
Àìrìjìnà ni àìrábuké ọ̀kẹ́rẹ́, orí ọ̀kadà ni wọ́n ń gbé òku sí lọ mọ́súárì
Àjọ̀dún òkú rèé níbi tí alààyè ti ń tọrọ owó, ọmọ àti ẹ̀mí gígùn lọ́wọ́ ẹ̀mí àìrí
Wo àwọn ìlú tó jẹ́ ẹ̀ṣẹ̀ àti èèwọ̀ ni kí ènìyàn kú níbẹ̀
Àwọn olórí lágbáyé tó ti wọ inú sàréè Ànọ́bi Muhammad rí
King Sunny Ade's son: Ohùn orin bàbá mi nìkan kọ ni l’Ọlọrun fún mi, ijó bíi kòkòrò ni ṣáá
Ṣebi ẹni ija o ba, lo n pe ara rẹ ni ọkunrin.
Ni kete ti 'oku' ọkunrin naa ba ti wọle tọ ẹni to fẹ ja lole, ni onitọhun yoo fi ẹsẹ fẹẹ lai duro wẹyin.
Igbagbọ awọn ti ọkunrin yii ti ja lole ni pe oku gidi lo wọle tọ wọn.
Eyi ṣee ṣe ko ri bẹẹ, nitori igbagbọ to wa nilẹ Afirika ni pe ẹni to ti ku le pada wa si aye lati farahan awọn eniyan rẹ, tabi gba ẹsan lara ẹnikẹni.
Akudaaya ni Yoruba n pe e.
Fayemi dá ọ̀gá ilé ẹ̀kọ́ gíga Health Tech Ijero dúrò lẹ́nu iṣẹ lẹ́yìn tí akẹ́kọ̀ọ́ 100 déèdé di èrò iléèwòsàn
Gìrì àparò lásán ni gbogbo èpè wọn! àwọn tó ń ti Toyin Abraham lẹ́yìn rèé lórí ìjà tó paá pọ́ mọ́ Lizzy Anjorin ati ESABOD
Tó bá dá Gani Adams lójú, kó dárúkọ àwọn ọ̀dàlẹ̀ inú Yoruba Nation - OPC New Era
Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo
Ni kiakia si ni 'oku' naa yoo ko gbogbo nkan to ba wu u ninu ile ẹni naa to ti salọ.
Amọ, okete boru mọ ọ lọwọ, lẹyin ti awọn eeyan kan gbiyanju lati 'ṣe bi ọkunrin', ti wọn si pinnu lati tu 'oku' naa ni aṣọ wo.
Oríṣun àwòrán, @daddyhope
Bayii ni ọkunrin naa ṣe ri lẹyin ti wọn bọ aṣọ oku to fi bo oju
Iyalẹnu si lo jẹ nigba ti wọn ba alaaye eniyan labẹ ẹku.
Gbajugbaja akọroyin kan ni Zimbabwe, Hopewell Chin'ono, to fi iroyin naa sita sọ pe ọwọ ti tẹ afurasi ole naa bayii. O si ti wa ni agọ ọlọpaa.
Maj Gen Faruk Yahaya: Ìdí rèé tí ọ̀gágun 30 fi gbọdọ̀ kọ̀wé fipò sílẹ̀ nítorí ìyànsípò olórí ọmogun tuntun
Oríṣun àwòrán, Twitter/Nigerian army
Yoruba bọ, wọn ni iadlu ni iṣelu. Iroyin to gbalẹ lori ayelujara ni pe ọgagun ọgbọn ninu iṣẹ ologun lo gbọdọ kọwe fipo silẹ nitori olori ọmogun tuntun, Maj. Gen. Frauk Yahaya.
Lẹyin ti olori ọmogun oriilẹ tẹlẹ, Ibrahim Attairu ku ninu iṣẹlẹ baalu ologun to ja niluu Kadana ni Aarẹ Muhammadu Buhari yan Ọgagun Yahaya sipo lati rọpo rẹ.
Lati igba naa ni a ti n gbọ pe awọn ọgagun to ṣaaju Yahaya wọ iṣẹ ologun ni lati yẹba fun un ni bayii to ti di olori ileeṣẹ ọmogun tuntun.
King Sunny Ade's son: Ohùn orin bàbá mi nìkan kọ ni l’Ọlọrun fún mi, ijó bíi kòkòrò ni ṣáá
Ṣugbọn kinni idi ti awọn ọgagun bi ọgbọn fi gbọdọ kuro ninu iṣẹ ologun nitori olori ọmogun ti Buhari ṣẹṣẹ yan sipo?
Ajagun fẹyinti , Rtd Col. Ayo Olaniyan ṣalaye fun BBC Yoruba pe eleyii ki ṣe nkan tuntun ninu iṣẹ ologun.
Ọgagun Olaniyan ni agbẹdọ ni fun awọn ọgagun to ṣaaju Yahaya wọ iṣẹ ologun, wọn ko le gbaṣẹ lọwọ rẹ laelae.
''Idi niyii ti wọn maa fi kuro ninu iṣẹ ologun ti iru nkan bayii ba ti ṣẹlẹ.
Yahaya to jẹ olori ọmogun tuntun ko lẹtọ lati paṣẹ fun awọn ọgagun ti wọn ṣaaju rẹ wọ iṣẹ ologun.
Oríṣun àwòrán, Twitter/Faruk Yahaya
Ṣugbọn nigba mii, ti wọn awọn ọgagun to ṣaaju olori ileeṣẹ ologun ba pọ, ijọbab le gbe wọn lọ si ibo miran ti wọn ko ti ni gbaṣẹ lọwọ olori ileeṣẹ ọmogun.
Ohun to yẹ ki ijọba ṣe ni pe ki wọn gbe awọn ọgagun bẹẹ lọ si ẹka mii ti wọn tun ti le wulo ileeṣẹ ọmogun.
Ijọba ti nawo ribi ribi le wọn lori pẹlu oriṣiiriṣii ileewe ti wọn ti lọ nile ati loke okun.
Idi niyii ti ijọba fi gbọdọ tun ero rẹ pa lori ki awọn ọgagun ninu iṣẹ ologun maa fipo silẹ nigba ti wọn ba yan ẹni to kẹyin wọn wọ iṣẹ ologun sipo,'' Ọgagun Olaniyan ṣalaye.
Ẹwẹ, ọgagun fẹyinti Olaniyan sọ pe ko si bi awọn to ba fẹyinti lẹnu iṣẹ ologun ṣe fẹ ditẹ gbajọba.
''Awọn ọgagun to ti fẹyinti ko le ronu lọ si ibi wi pe ki ditẹ gbajọba nitori wọn  ko si lẹnu iṣẹ ologun mọ.
Awọn nkan ti wọn nilo lati lati ditẹ gbajọba ko si ni ikawọ wọn mọ nitori wọn kuro lẹnu iṣẹ,'' Ọgagun Olaniyan lo ṣalaye bẹẹ.
Diezani Alison-Madueke: Àwọn aṣòfin àti èrò ìwòran yanu sílẹ̀ torí owó tí EFCC rí gbà padà
Oríṣun àwòrán, Efcc
Ajọ to n gbogun ti iwa ajẹbanu atawọn iwa ọdaran to jẹ mọ lorilẹede Naijiria, EFCC, ti kede iye apapọ awọn dukia ile, ẹsọ ara ati goolu, ti wọn ri gba lọwọ minisita tẹlẹ fọrọ epo rọbi, Diezani Alison Madueke.
Madueke, ẹni to jẹ Minisita laye isejọba Goodluck Jonathan to kọja, ni EFCC ri ẹsọ ara to to biliọnu mẹrinla ati miliọnu lọna ọtalenirinwo naira (₦14.460BN) gba pada lọwọ rẹ.
Alaga ajọ EFCC, Abdulrasheed Bawa lo sisọ loju ọrọ yii fun ile asofin tawọn asoju lọjọ Ẹti.
Igbimọ tẹẹkoto nile asofin tawọn asoju lo n joko tọpinpin iye apapọ ohun ti ajọ EFCC ri gba pada lọwọ awọn eeyan ti wọn fi ẹsun ajẹbanu kan.
Se ni awọn asoju-sofin naa atawọn ero iworan to wa nibi ijoko igbimọ naa la ẹnu silẹ, lai le pade mọ nigba ti wọn gbọ ikede ajọ EFCC naa lori dukia Ẹsọ ara ti wọn gba lọwọ Diezani.
Oríṣun àwòrán, Efcc
Bakan naa ni alaga ajọ EFCC tun sọ fun awọn asoju-sofin naa pe apapọ iye owo awọn ile ti wọn ri gba pada lọwọ Diezani to ọgọrin miliọnu dọla ($80M).
Bobrisky: Ọjọ́ ìbí mi ń bọ̀ lọ́nà, ìdí mi sì gbọdọ̀ dúró re, ní mo ṣe fẹ́ ṣiṣẹ́ abẹ náà
Oríṣun àwòrán, Bobrisky222/Instagram
Gbajugbaja ọkunrin to maa n mura bia bo, Idris Okunneye, ti ọpọ eeyan mọ si Bobrisky ti n kọminu lori isẹ abẹ to fẹ se lati mu ki idi rẹ tobi, ko si duro re nilẹ.
Ninu fidio kan to lu ori ayelujara pa lọsan ọjọ Ẹti ni Bobrisky ti kede bẹẹ fun araye nipa isẹ abẹ to fẹ ṣe naa amọ o ni aya oun n ja.
Isẹ abẹ naa ti wọn n pe ni Brazilian butt lift, ni wọn ti maa bu ọra kuro ni awọn ẹya ara kan, bii itan, ikun, isalẹ ẹyin ati gegeru.
Awọn ọra yii ni wọn yoo si ko lọ sinu idi lati jẹ ko tobi si, ti irisi rẹ yoo si tun yatọ lai jẹ pe wọn ri ounkohun sinu rẹ.
Ninu fidio naa ni Bobrisky ti n sọ fun awọn ololufẹ rẹ pe aya n ja, ẹru si n ba oun nipa isẹ naa to ku ọjọ mẹta pere.
Oríṣun àwòrán, bobrisky222/Instagram
"Ẹru n ba mi pupọ nipa isẹ abẹ to ku dẹdẹ ki n se naa nitori irora ti maa jẹ fun ọsẹ melo kan, irora yii le to bẹẹ gẹẹ, ti ko si se fi ẹnu sọ.
Maa ni irora nibi ọmu ati ni gbogbo ara kaakiri amọ mo ti setan lati tẹsiwaju pẹlu isẹ abẹ naa. Maa se e nitori mo ti san gbogbo owo to yẹ fun isẹ abẹ naa.
Mo gbọdọ se ni, maa wọ inu yara isẹ abẹ lọ, ki n si jade pẹlu ara to rẹwa, ọjọ Kọkanlelọgbọn osu Kẹjọ ni ọjọ ibi mi, irisi mi gbọdọ le koko ni."
Bobrisky tẹ siwaju pe, lati ọdun diẹ sẹyin ni oun ti n ro lati se isẹ abẹ naa, ti oun si se asaro pupọ lori rẹ, ki oun to pinnu pe oun yoo se isẹ abẹ yii.
King Sunny Ade's son: Ohùn orin bàbá mi nìkan kọ ni l’Ọlọrun fún mi, ijó bíi kòkòrò ni ṣáá
O ni oun ni owo to towo lati sisẹ abẹ naa, amọ ni kete ti wọn ba ti sisẹ abẹ si igegeru oun, ko le pada si bo se wa tẹlẹ mọ laelae.
O ni idi ree ti oun se n ronu lẹẹmeji nipa isẹ abẹ ọhun amọ lọwọ lọwọ bayii, ko si iyemeji mọ, oun ti pinnu lati se isẹ abẹ naa lọjọ mẹrin oni.
Toyin Abraham: Àwọn èèyàn tó ń rí jẹ ní ìdí mọ̀dàrú ló ń bu pẹtiró sí ìjà tó wà nílẹ̀
Oríṣun àwòrán, Toyin_Abraham/Instagram
Gbajugbaja osere tiata nni, Totin Abraham ti tun sọrọ soke lẹyin aawọ to waye laarin rẹ ati osere Tiata miran, Lizzy Anjorin.
Bẹẹ ba gbagbe, gbajumọ sọrọsọrọ lori ayelujara, Tokunbo Aboderin, ti ọpọ eeyan mọ si ESABOD lo ba wọn pari ija naa lọjọ Isẹgun.
Amọ ni irọlẹ Ọjọbọ ni Toyin tun n wi lele pe, oun ko lọwọ tabi mọ ohunkohun nipa bi ẹnikẹni to ba ni oun n gbeja oun, se n bu ẹnikẹni.
Toyin ni ki wọn mase di ẹbi kankan ru oun ti ẹni to n gbeja oun ba n sepe tabi se ẹẹkẹ eebu.
"Mo ri awọn fidio kan lori ayelujara ninu eyi ti awọn eeyan kan ti wọn ni awọn n gbeja mi ti n sẹ epe fawọn eeyan miran.
Oríṣun àwòrán, Toyin_Abraham/Instagram
Bakan naa, ni wọn si tun n fa awọn ọmọde ti ko ni ẹsẹ lọrun sinu wahala ti wọn n da silẹ.
Ẹ jọwọ n ko fara mọ iru iwa yi ni ọnakọna.
Koda, n ko fi igba kankan ran yin ni iru isẹ bayii ri, ẹ jọwọ, ẹ yọ awọn ọmọde kuro ninu ere itage tẹ n se."
Toyin Abraham tẹsiwaju pe, awọn ọmọde naa yoo dagba, amọ gbogbo hun ti wọn ti sọ nipa wọn ni yoo si wa lori ayelujara, ti ko si le lọ sokun igbagbe laelae.
O fikun pe oun mọ riri ifẹ ati itara awọn eeyan nipa oun amọ ko si awijare kankan lati maa ba ọja ẹlomiran jẹ.
Wùnmí Toríọlá: Toyin Abraham kìí se ọ̀gá mi nínú tíátà
Toyin ni oun fura pe awọn eeyan kan n ri jẹ nidi mọdaru to n waye loore koore naa, nitori fidio ti oun sẹsẹ wo tan fidi eyi mulẹ.
"Mo ri  fidio kan tawọn eeyan kan ti n sẹ epe fun awọn alabasisẹpọ mi kan lagbo tiata atawọn ọmọ wọn.
Eyi ko se dandan, iwa ibi si ni pẹlu, ọna ati jẹ si ni wọn se n bu epo eebo si ere oitage to n lọ lọwọ naa, eyi to ti toju su ni."
Toyin wa n ke si awọn eeyan ti wọn ba ti sọrọ odi si lori ayelujara, pe ki wọn fa ọrọ naa de ibi to lapẹrẹ, ki ẹni to sọrọ odi si wọn naa si sanwo gba ma binu.
King Sunny Ade's son: Ohùn orin bàbá mi nìkan kọ ni l’Ọlọrun fún mi, ijó bíi kòkòrò ni ṣáá
"Ohun ti mo gbero lati maa se ree lati akoko yii lọ, igba ikẹyin si ree ti maa gbe iru ikede yii sita.
Ohun to wa lọkan mi bayi ni bi sinima mi tuntun yoo se jade, mo dupẹ, ẹ se pupọ.
May 29: Àwọn ọmọ Naijiria yóò mọ rírì Ààrẹ Buhari lẹ́yìn tó bá kúrò lórí oyè tán - Ìjọba àpapọ̀
Oríṣun àwòrán, Garba Shehu
Ijọba Naijiria ti sọ pe awọn araalu yoo mọ ipa iṣejọba Aarẹ Muhammadu Buhari lẹyin to ba pari saa rẹ tan lọdun 2023.
Amugbalẹgbẹ Aarẹ lori iroyin ati ipolongo, Femi Adesina lo sọ ọrọ naa ninu atẹjade kan to fi lede lati ṣami si ọdun kẹfa Buhari lori alefa.
O ni o ku ọdun meji ki ijọba yii pari, lagbara Ọlọrun, gbogbo awọn to n bu ẹnu atẹ lu ijọba yii ni yoo ṣi gbe oriyin fun un."""
Gẹgẹ bi Adesina ṣe sọ, ohun ribiribi ti ijọba Buhari ti gbe ṣe ko lonka.
Amugbalẹgbẹ naa mẹnuba awọn akanṣe iṣẹ ti Aarẹ Buhari ti ṣe bii awọn ohun amayedẹrun, idagbosoke igbeaye ọmọniyan atawọn iṣẹ takun-takun mii ni oniruru ẹka.
"Adesina ṣalaye pe ""Lati ori awọn ohun amayederun si eto iṣuna, eto ẹkọ, eto ilera, ere idaraya, gbigbogunti iwa ajẹbanu, ọrọ epo rọbi ati bẹẹ nẹẹ lọ, awọn aṣeyọri wọnyii yẹ ko wu awọn ọmọ Naijiria lori."""
Awọn eeyan kan n sọ pe awọn ko ri nnkankan ti a n ṣe ati pe awọn ko gbọ nipa aṣeyọri kankan, lara awọn aṣeyọri wa ree.
Lẹyin naa lo bẹrẹ si n tọka si awọn nnkan ti ijọba to wa lode yii ti ṣe lẹsẹsẹ.
Democracy day 2021: Kí ni Nàìjíríà ti jèrè lára gbogbo ààrẹ tó ti jẹ látọdún 1999?
Lara awọn nnkan to mẹnuba ni awọn akanṣẹ iṣẹ bii ọkọ oju irin lati Eko si Ibadan, Itakpe si Warri, ati bẹẹ bẹẹ lọ.
O tun mẹnuba awọn atunṣẹ papakọ ọkọ ofurufu bii ti ilu Eko, Abuja, Kano ati Port Harcourt.
Ọpọ awọn ọmọ naijiria lo ti bẹrẹ si fi erongba wọn lede lori atẹjade naa, bi awọn kan ṣe n ki Aarẹ ku iṣẹ takuntakun, lawọn mii n sọ pe nnkan ti bajẹ ju ti igba ti Aarẹ kọkọ gori alefa lọ.
Oríṣun àwòrán, Bashir Ahmad
Oni ọjọ kọkandinlọgbọn oṣu karun un ọdun 2021 lo pe ọdun mẹfa ti Aarẹ Muhammadu Buhari di aarẹ orilẹede Naijiria labẹ ijọba awarawa.
Ẹgbẹ oṣelu PDP lo ti ṣejọba lati ọdun 1999 ti Naijiria ti pada si ijọba awarawa titi di 2015 ti Buhari wọle ibo aarẹ labẹ asia ẹgbẹ oṣelu APC.
Ọjọ kọkandinlọgbọn oṣu karun un ọdun 2015 ni wọn bura wọle fun Buhari gẹgẹ bi aarẹ lẹyin to fẹyin Goodluck Jonathan gbalẹ ninu ibo gbogbogbo ọdun naa.
Buhari tun wọle ẹẹkeji lọdun 2019 nigba ti oludije PDP mii, Atiku Abubakar tun fidi rẹmi ninu ibo aarẹ.
Aarẹ Buhari ṣeleri lati pese eto aabo to mọyan lori ati itaji ọrọ aje Naijiria lẹyin to wọle tan.
Ṣugbọn ero awọn eeyan ṣọtọọtọ lori ijọba Buhari lati bii ọdun mẹfa sẹyin.
Nigba to n sọrọ ni tiẹ, oluranlọwọ aarẹ lori ọrọ iroyin ati ilukoro, Femi Adesina ṣapejuwe Buhari gẹgẹ bi ẹni to ti ṣe aṣeyọri nla laarin ọdun mẹfa to gori aleefa.
Bode George: òòtọ́ ni ìkìlọ̀ Obasanjọ ati Soyinka
Ninu atẹjade ti Adesina fi sita, o ṣalaye pe awọn ti wọn ko ba ni ki ọrọ oṣelu bọ nikan lo le ri aṣeyọri ti Buhari ti ṣe lati ọdun 2015 si akoko yii.
Adesina ni lai ṣe ani-ani ọpọ eeyan to fi mọ awọn alatako gan an ni yoo gboriyin fun Buhari nigba ti ijọba rẹ ba pari lọdun 2023.
O ni ijọba Buhari ti ṣiṣẹ ribiribi lẹka eto ẹkọ, eto inawo, ere idaraya, ileegbe, igbayegbadun araalu ati awọn ẹka mii.
Amọ, awọn ọmọ ẹgbẹ oṣelu to kere julọ nile igbimọ aṣoju-ṣofin niluu Abuja ti sọ pe ijọba Buhari ti kuna fun ọdun mẹfa.
King Sunny Ade's son: Ohùn orin bàbá mi nìkan kọ ni l’Ọlọrun fún mi, ijó bíi kòkòrò ni ṣáá
Awọn aṣofin naa ni ni gbogbo ọna ni ijọba Buhari ko ni ṣe aṣeyọri lati ọdun mẹfa to ti wa lori oye.
''Laye ijọba Buhari ni eto abo mẹhẹ ti ko si ri ojutu sii, iwa ajẹbanu ti pọ sii ni ijọba Buhari, ọrọ aje Naijiria dẹnu kọlẹ, bakan naa ni ẹlẹyamẹya tun pọ sii.
Bi ijọba Buhari ti n ṣe nkan pẹlu igboya ta ni yoo mu mi, bi ko ṣe tẹ le ofin nigba mii, bi wọn ṣe n ṣe èrú ninu ibo, ati bi ijọba APC ṣe n fi ẹtọ awọn araalu dun wọn n kọ wa lominu gẹgẹ bi aṣofin.
Awọn eto ti APC n ṣe labẹ ijọba Buhari ti jẹ ki airi ṣiṣẹ ṣe pọ si, gbogbo nkan lo wọn gogo, owo naira ko ni itumọ kankan mọ.
Orilẹede Naijria ti di ibi ti iṣẹ ati oṣi ti n ba awọn eeyan finra julọ lagbaaye labẹ ijọba Buhari.
Ijọba Buhari ko nilo lati ṣe ayẹyẹ tabi ayajọ ọjọ to de ijọba, ohun ti Buhari nilo ni pe ko fi asiko yii ronu ati wa ojutu si iṣoro to n koju Naijiria lọwọ yii,'' olori ẹgbẹ oṣelu to kere nile, Ndudi Elumelu lo ṣalaye ọrọ yii ninu atẹjade to fi sita.
Adeherself: Adẹ́rìnpòṣónú Cute Abiola ṣe ìyàwó, àmọ́ kìí ṣe pẹ̀lú Adeherself
Oríṣun àwòrán, Adeherself
Iyawo dun lọsingin, ọkọ tun mi gbe. Adẹrinpoṣonu Cute Abiola mori le ilu Ogbomoso lati lọ mu ẹni bi ọkan rẹ fi ṣe aya.
Ọpọ lo ti n sọ tẹlẹ pe Adedamola Adewale ti ọpọ mọ si Adeherself ni Abiola yoo fẹ sile gẹgẹ bi aya rẹ.
Amọ ọrọ ko ri bẹẹ mọ lẹyin ti Abiola gbọna Ogbomoso lọ ṣe igbeyawo pẹlu ọrẹbinrin rẹ ti wọn ti jọ wa tipẹ.
Abiola ati Adeherself maa n ṣaaba fi fọto ara soju opo ayelujara lo jẹ ki ọpọ maa ro wi pe ọrọ ifẹ wa laarin wọn.
Ṣugbọn gbogbo ahesọ ọrọ naa ti di afi sẹyin ti eegun fi aṣọ bayii lẹyin ti Abiola ti di alaya l'Ogbomoso.
Ẹwẹ, Adeherself naa ti sọrọ soke lẹyin ti fọto igbeyawo Abiola gbori ayelujara kan.
Democracy day 2021: Kí ni Nàìjíríà ti jèrè lára gbogbo ààrẹ tó ti jẹ látọdún 1999?
O ni oun ti sọ tẹlẹ pe Abiola ko figba kan dẹnu ifẹ kọ oun ri, ati pe awọn mejeeji ko fẹra ri.
Awọn eeyan ro pe nkan wa laarin wa nitori Abiola fun ra rẹ ko sọ ohun kan lori ọrọ naa.
''Ọrẹ ni emi ati Cute Abiola, ọrẹ naa la o si maa jẹ lẹyin to ti ṣe igbeyawo yii.
Mo ki Abiola ati iyawọ rẹ ku oriire igbeyawo wọn, ṣe awọn eeyan ti wa ri pe iyawo Abiola gangan an ti de bayii,'' Adeherself lo ṣalaye bẹẹ,
Canada ń ṣọ̀fọ̀ lẹ́yìn tí wọ́n rí òkú akẹ́kọ̀ọ́ 215 nílé ẹ̀kọ́ kan
Oríṣun àwòrán, Reuters
Ijọba ilẹ Canada ti sọrọ lẹyin ti wọn ri oku awọn akẹkọọ okòólénígba dín marun (215) nile ẹkọ kan ti wọn ti gbe ti pa.
Adari ijọba orilẹ-ede naa, Justin Trudeau sọ pe iṣẹlẹ naa jẹ eyii to ba ijọba oun ninu jẹ gidi.
Awọn akẹkọọ ti wọn ri oku wọn naa jẹ akẹkọọ Kamloops Indian Residential School to wa lagbegbe British Columbia, eyii ti wọn gbe ti pa lọdun 1978.
Wọn da ile ẹkọ naa silẹ lati kọ awọn eeyan agbegbe ọhun lọna ati gbe igbe ye ọtun lọdun naa lọhun.
Ile ẹkọ naa jẹ eyii ti awọn akẹkọọ n gbe gẹgẹ bii ijọ Katoliiki ṣe ṣagbekalẹ rẹ lọdun 1890, awọn akẹkọọ rẹ si le ni ẹẹdẹgbẹta nigba ti yoo fi di aarin ọdun 1950.
Iroyin ni ẹrọ kan to ṣayẹwo ayika ile ẹkọ naa lo ṣawari oku awọn akẹkọọ ọhun nibi ti wọn sin wọn si ninu ọgba ile ẹkọ naa.
Oríṣun àwòrán, Reuters
Obinrin kan to sọrọ lorukọ awọn aṣoju agbegbe naa, Casimir sọ fun awọn akọroyin pe ko si akọsilẹ kankan pe awọn akẹkọọ naa poora.
"O ni ""Ọmọde ni awọn akẹkọọ naa, koda, ọmọ ọdun mẹta wa lara wọn."""
Democracy day 2021: Kí ni Nàìjíríà ti jèrè lára gbogbo ààrẹ tó ti jẹ látọdún 1999?
Ṣugbọn gẹgẹ bi oun ti a mọ, ko si akọsilẹ kankan pe ẹnikẹni ninu awọn akọkọọ ọhun ti sọnu ṣaaju.
Adari agbegbe Bristish Columbia Lisa Lapointe sọ fun ileeṣẹ iroyin ilẹ Canada, CBC pe, awọn ti gbe iwadii dide lọna ati tu iṣu de isalẹ ikoko iṣẹlẹ naa.
Bode George: òòtọ́ ni ìkìlọ̀ Obasanjọ ati Soyinka
Greenfield University: Àwọn akẹ́kọ̀ọ́ fásitì tí wọ́n jí gbé ní Kaduna ti gba òmìnira
Oríṣun àwòrán, Greefield
Mẹrinla ninu awọn eeyan ti awọn agbebọn ji gbe ni Fasiti Greenfield to wa ni Kaduna ti gba ominira.
Kọmiṣọna eto abo ipinlẹ ọhun, Samuel Aruwan lo fidi ọrọ naa mulẹ fun BBC.
Aruwan sọ pe akẹkọọ mọkanla ati oṣiṣẹ fasiti mẹta ni wọn gba itusilẹ lọwọ ajinigbe ọhun.
Awọn agbebọn naa tu awọn eeyan naa silẹ lọjọ Abamẹta, ọjọ kọkandinlọgbọn, oṣu Karun un, ọdun 2021 loju ọna marosẹ Abuja si Kaduna.
Meji lara awọn awọn obi awọn ọmọ naa sọ fun awọn akọroyin pe ọgọsan (180) miliọnu naira ati alupupu mẹwaa ni awọn ajinigbe naa gba ki wọn to tu awọn ọmọ wọn silẹ.
"Ọkan lara wọn ni ""Ọgọsan an miliọnu naira ni awọn ajijigbe naa gba lọwọ awa obi ki wọn to tu awọn ọmọ wa silẹ."""
Democracy day 2021: Kí ni Nàìjíríà ti jèrè lára gbogbo ààrẹ tó ti jẹ látọdún 1999?
A ko ri iranlọwọ kankan gba lọdọ ijọba lati tu awọn ọmọ wa silẹ, bẹẹ naa ni a ko ri aṣoju ijọba tabi ọlọpaa kankan lati to lọwọ si itusilẹ wọn.
Bi ẹ ko ba gbagbe, ogunjọ, oṣu Kẹrin, ọdun yii ni awọn ajijigbe naa ji awọn aẹkọọ ọhun gbe lẹyin ti wọn kọlu ile ẹkọ wọn.
Ni ọjọ kẹtalelogun, awọn eeyan ilu ri oku mẹta ninu awọn akẹkọọ naa labule Kwanan Bature, eyii ti ko jina sile ẹkọ ọhun.
Bode George: òòtọ́ ni ìkìlọ̀ Obasanjọ ati Soyinka
Ọjọ mẹta lẹyin ti wọn ri oku awọn mẹta naa ni awọn agbebọn naa tu pa meji ninu awọn eeyan naa ti wọn ji gbe.
Ẹwẹ, ọkan lara awọn akẹkọọ naa ti kọkọ gba itusilẹ ṣaaju lẹyin ti awọn obi rẹ san owo itusilẹ fun awọn ajinigbe naa.
Adeherself: Gbogbo ayé ti rí báyìí pé lọkọ láya orí ayélujára lèmi àti Cute Abiola jọ́ ń ṣe
Oríṣun àwòrán, Adeherself
Adedamola Adewale ti ọpọ mọ si Adeherself tun ti sọrọ lori igbeyawo Acute Abiola pẹlu ọrẹbinrin rẹ ọlọjọ pipẹ.
Adeherself fi ọrọ naa soju opo Instagram rẹ nibi to ti sọ pe gbogbo eeyan lo ti ri bayii pe iṣẹ loun ati Cute Abiola n ṣe pẹlu awọn fọto tawọn ti maa n fi sori ayelujara.
''Emi ati Cute Abiola dabi tẹgbọn taburo, ọrẹ kidi si ni ajọ jẹ.
Akẹgbẹ mi ti mo bu iyi fun gidi ni Cute Abiola, gbogbo ohun tawọn eeyan n gbe kiri lori ọrọ naa bayii fihan pe iṣẹ awọn ni ipa gidi lori awọn eeyan ni.
O jẹ ohun iwuri fun mi pe awọn ololufẹ wa n gba awada ti a n ṣe tọwọ tẹsẹ.
Amọ ere lasan ni gbogbo rẹ, kii ṣe wi pe a n fẹ ara wa.
Wọ́n rò pé mo ya wèrè ni Saudi lẹ́yìn ikú ọkọ mi
Irufẹ iṣẹ ti a n ṣe lọwọ lo jẹ ki emi ati Cute Abiola ti a n ṣe ti a ṣe n fi fọto lọkọ laya ara wa sori ayelujara.
Nitori naa, gbogbo awọn to ti n fede fọ lori ọrọ yii, ẹ ṣee.
Simple tricks to identify designer shoes: Ṣe ìwọ lè wọ bàtà #2 mílíọ̀nú
Mo le fi gbogbo ẹnu sọ pe inu mi dun pe emi ati Abiola ṣiṣẹ to jẹ nnkan iwuri,'' Adeherself lo ṣalaye bẹẹ.
India, Coronavirus: Ìtọ́jú aláìsàn ló jẹ́ mi lógún nítorí ètò ìlera wa mẹ́hẹ- Nọ́ọ̀sì Kama
Yoruba Nation agitators: Àwọn ajìjàngbara Yorùbá Nation fipá ṣí bọ́dà Idiroko
Oríṣun àwòrán, Gani Adams and Sunday Igboho
Awọn ajijangbara to n pe fun Yoruba Nation fi ipa ṣi ibode Naijiria si Benin Republic ni Idiroko lọjọ Satide.
Wọn ni ọna ti ṣi pe kawọn eeyan maa ko ounjẹ atawọn nnkan mii wọlu lọpọ yanturu
Amọ, awọn ẹṣọ aṣọbode to n ṣọ ibode naa dawọn lọwọ kọ.
Ọdun  2019 ni ijọba apapọ gbe awọn ibode oriilẹ si Naijiria tipa ti wọn ṣi bẹrẹ si ni ko gbogbo ọja wọle lori omi nikan.
Ninu fidio kan to wa lori ayelujara ni ọkunrin kan ti n yinbọn soke tawọn eeyan to wa nibẹ ṣi n dunnu.
Simple tricks to identify designer shoes: Ṣe ìwọ lè wọ bàtà #2 mílíọ̀nú
Ọpọ lo n sọ ninu fido naa pe kawọn ẹṣọ aṣọbode atawọn sọja wa yinbọn ma wọn ti wọn ba to bẹẹ.
A gbọ wi pe awọn ajijagbara naa ba geeti ibode Idiroko jẹ, ti wọn si n pariwo ''a ti ṣi ibode Idiroko.''
Koda, wọn lu ọkunrin kan to gbiyanju lati ṣe fidio iṣẹlẹ naa pẹlu foonu rẹ laluki.
Agbẹnusọ ileeṣẹ aṣọbode agbegbe Idiroko, Hammed Oloyede to fidi ọrọ naa mulẹ ṣalaye pe awọn ajijangbara Odua Nation ko ṣe ikọlu sawọn ẹṣọ aṣọbode.
Democracy day 2021: Kí ni Nàìjíríà ti jèrè lára gbogbo ààrẹ tó ti jẹ látọdún 1999?
Ọgbẹni Oloyede ni awọn ajijangbara naa kan n ṣe ti wọn ni, o ni ko si iyọnu kankan.
O fikun ọrọ rẹ pe awọn eeyan naa gbiyanju lati kọlu awọn oṣiṣẹ aṣọbode ṣugbọn awọn da wọn lọwọ kọ.
India, Coronavirus: Ìtọ́jú aláìsàn ló jẹ́ mi lógún nítorí ètò ìlera wa mẹ́hẹ- Nọ́ọ̀sì Kama
Biafra Day Celebration, May 30: Àwọn ajìjàngbara Biafra kéde ìsìnmi fáwọn Ibo láti ṣ'àyájọ́ Biafra
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Oni ọgbọnjọ, oṣu karun un, ọdun 2021 lo pe ọdun mẹrinlelaadọta ti oloogbe ọgagun Lt Col. Chukwuemeka Odumegwu Ojukwu kede pe orilẹ-ede Biafra awọn Ibo ti ya kuro lara Naijiria.
Ikede Ojukwu yii lo jẹ ki ogun abẹle bẹ silẹ lọdun 1967, ọdun mẹta gbako ṣi ni wọn fi ja ogun naa.
Eeyan to le lẹgbẹrun lọna ẹẹdẹgbẹta ni ebi ati iṣẹ pa ku ninu ẹya Ibo ninu eyi ti awọn ọmọde ti pọju lọ.
Lati ọdun naa ni ọgbọnjọ, oṣu karun un ti di pataki ninu itan orilẹ-ede Naijiria papaa julọ fawọn ẹya Ibo.
Awọn Ibo naa ko kọkọ ka ọjọ yii kun tẹlẹ, amọ awọn to n pe ifun iyapa Ibo lara Naijiria ti jẹ ki wọn kaa kun bayii.
Lọdọọdun ni awọn ajijigbara fun idaduro ẹya Ibo lara Naijiria maa n sọ fawọn pe ki wọn joko sile lọgbọnjọ oṣu karun lati le fi ṣe ayajọ Biafra.
India, Coronavirus: Ìtọ́jú aláìsàn ló jẹ́ mi lógún nítorí ètò ìlera wa mẹ́hẹ- Nọ́ọ̀sì Kama
Ojukwu gan an ni olori Biafra nitori oun lo kede iyapa Ibo lara Naijiria.
Ilu Nnewi ni Ojukwu ti wa nipinlẹ Anambra ṣugbọn ilu Zungeru nipinlẹ Niger ni wọn bi i si lọdun 1933.
Ọmọ onile ọlọna ni Ojukwu i ṣe, awọn obi rẹ ran an nile iwe debi pe o tun kawe ni fasiti niluu London.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Lẹyin ti o kawe gboye ni fasiti niluu London lo darapọ mọ ileeṣẹ ologun Naijiria.
Ojukwu di gomina ologun apa ila -oorun Naijiria lẹyin tawọn ologun ditẹ gbajọba alagbada lọdun 1966 bo tilẹ jẹ pe ko lọwọ ninu iditẹgbajọba ọhun.
Ko gba pe ọga ni Yakubu Gowon to jẹ aarẹ ologun jẹ fun oun, ati pe o ni Gowon n yan awọn ẹya Ibo jẹ.
Wọ́n rò pé mo ya wèrè ni Saudi lẹ́yìn ikú ọkọ mi
Lẹyin naa lo kede orilẹ-ede Biafra pe ẹya Ibo ṣetan lati yapa kuro ni Naijiria eyi to jẹ ki ogun bẹ silẹ.
Ojukwu lọ ṣatipo lorilẹede Ivory Coast lọdun 1970 lẹyin ti ogun abẹle pari ki ijọba Naijiria to darijin in lọdun 1982.
Ijọba Naijiria gbe Ojukwu lọdun 1983 lẹyin iṣẹlẹ iditẹgbajọba kan, ṣugbọn wọn pada fi i silẹ lọdun 1984.
Ojukwu ko saaba dasi ọrọ oṣelu mọ lati igba naa titi to fi ku lọdun 2011.
Simple tricks to identify designer shoes: Ṣe ìwọ lè wọ bàtà #2 mílíọ̀nú
Ahmed Gulak's death: Àwọn jàndùkú agbébọn ṣekúpa Ahmed Gulak, olùdàmọ́ràn Goodluck Jonathan
Oríṣun àwòrán, Informationng
Awọn janduku agbebọn ti ṣekupa Ahmed Gulak tii ṣe oluranlọwọ aarẹ ana orilẹ-ede Naijiria, Goodluck Jonathan.
Ilu Owerri nipinlẹ Imo ni wọn ti sọ pe wọn yinbọn pa Gulak.
Gulak n rinrin ajo lati Abuja si Owerri lalẹ ọjọ Abamẹta ki o to ṣagbako iku ojiji lọna.
A o maa mu ẹkunrẹrẹ iroyin naa wa fun laipẹ.
Ladipo market fire: Ọjà olówó iyebíye jóná nínú ọjà Ladipo nílùú Eko
Oríṣun àwòrán, LASEMA
Ọpọ ọja olowo iyebiye ti sọnu ninu ijamba ina to dede ṣẹyọ ninu ọja Ladipo, to wa lagbegbe Oshodi niluu Eko.
Inu ibanujẹ ni ọpọ awọn oniṣowo inu ọja naa wa lasiko ti BBC ṣabẹwo sinu ọja ọhun.
Ọja naa jẹ eyii ti wọn ti n ta awọn ẹya ara ọkọ.
Adari ajọ to n ri iṣẹlẹ pajawiri ni ipinlẹ Eko, LASEMA, Olufemi Oke-Osanyintolu sọ fun awọn akọroyin ninu atẹjade kan pe ina ọhun ti ba nnkan jẹ ki awọn oṣiṣẹ awọn to de agbegbe naa.
Oríṣun àwòrán, LASEMA
"O ni ""Lasiko ti a de agbegbe ọhjun, awọn oṣiṣẹ wa ri ile alaja kan ti wọn ti n ta ẹya ara ọkọ, ti ina ti jo."""
Oríṣun àwòrán, LASEMA
Oke-Osanyintolu sọ ṣalaye pe awọnj ko mọ ohun to ṣokunfa ina ọhun ṣugbọn iowadii ti bẹrẹ.
"O ni ""Bo tilẹ jẹ pe awọn oṣiṣẹ pajawiri atawọn panapana ti gunlẹ si agbegbe naa ki ina ọhun ma ba tan de awọn ile miran to yi ọja ọhun ka, a ko tii le sọ ohun to ṣokunfa ina naa."""
Democracy day 2021: Kí ni Nàìjíríà ti jèrè lára gbogbo ààrẹ tó ti jẹ látọdún 1999?
EFCC mú ọmọ Yahoo tó fẹ́ fi Bitcoin ra ọkọ̀ ayọ́kẹ́lẹ́ tí iye rẹ̀ tó 44 mílíọ́nù
Oríṣun àwòrán, @officialEFCC
Ileeṣẹ to n gbogun ti iwa ajẹbanu ni Naijiria, EFCC, ẹka ti ipinlẹ Eko ti kede pe ọwọ awọn ti tẹ afurasi ọmọ Yahoo kan to gbiyanju lati ra ọkọ ayọkẹle SUV ti iye rẹ to miliọnu mẹrinlelogoji pẹlu Bitcoin.
EFCC fẹsun kan afurasi naa, Tobiloba Aramide Ogundiyan pe o yi owo to ri nidi iṣẹ jibiti pada si owo Bitcoin.
"Oṣiṣẹ EFCC  kan to ba awọn akọroyin sọrọ ni ""Ọna ẹburu lo gba ri owo rẹ, o si gbiyanbju lati fi owo naa ra ọkọ ayọkẹlẹ SUV ti iye rẹ to miliọnu mẹrinlelogoji ni ṣọọbu ti wọn ti n ta ọkọ ni Lekki."""
Wọn fi panpẹ ofin mu afurasi ọhun pẹlu awọn meje miran lagbegbe River View Estate to wa ni Lekki fun oniruru ẹsun to jọ mọ lilu jibiti ori ayelujara.
Awọn afurasi mii ti EFCC tun mu ni Samson Alabi Afolabi; Adebayo Dolapo Olumide; Daniel Boluwatife Akinwunmi; Moses Segun; Kelechi Thankgod Felix; Adeleke Godwin Tofunmi ati Adewale Dapo Victor.
EFCC ni wọn ka awọn ohun ìní olowo iyebiye lọwọ wọn bii ẹrọ ilewọ, ẹrọ ayarasbiaṣa alagbeka, oriṣiriṣi ọkọ olowo iyebiye, ẹṣọ ara ati bẹẹ bẹẹ lọ.
Ileeṣẹ naa ni yatọ si jibiti ori ayeluja, awọn afurasi ọhun tun n lu jibiti lọna miran.
Democracy day 2021: Kí ni Nàìjíríà ti jèrè lára gbogbo ààrẹ tó ti jẹ látọdún 1999?
Ahmed Gulak: Ọlọ́pàá ti sọ̀rọ̀ ní kíkún lórí ikú Gulak tó jẹ́ eèkàn tó kúrò ní PDP lọ sí APC
Oríṣun àwòrán, Other
Ileeṣẹ ọlọpaa Naijiria ti ṣalaye sii lori iku Gulak Ahmad to doloogbe lana ọjọ Aiku nipinlẹ Imo ni Ila oorun guusu Naijiria.
Ileeṣẹ ọlọpaa ipinlẹ Imo ni pe awọn Indigenous People of Biafra [IPOB] ati awọn Eastern Security Network [ESN] ni wọn ṣiṣẹ ibi naa.
Ninu atẹjade kan ti alukoro ileeṣẹ ọlọpaa nipinlẹ Imo, Bala Elkana fi sita lo ti sọ ọrọ yii.
Oríṣun àwòrán, @NPF
Bala ni ọlọpaa ti pa eeyan mẹfa to ṣiṣẹ ibi naa ni Imo.
O tun ni awọn pa oniṣẹ ibi mẹrin miran ninu ikọlu to waye ni ijoba ibile Aboh-Mbaise nipinlẹ Imo.
Bala Elkana tun ṣalaye pe awọn oniṣẹ ibi naa n pin alubọsa ni awọn agbofinro pada wọn ti wọn si gbena woju ara wọn.
O ni awakọ Golak lo sọ bi wọn se rin lẹyin iṣẹlẹ naa.
Oríṣun àwòrán, @NPF
Awakọ naa ni oun n gbe Gulak lọ si papakọ ofurufu ni iṣẹlẹ naa waye ni orita Obiangwu ni ijoba ibilẹ Ngorokpala
wọn ti sin Oloogbe Gulak Ahmad nilan ẹsin Musulumi.
Adebayo Murital David: Gbogbo iṣẹ́ tó ń múni là láyé wá láti ọpọlọ ni kìí ṣe agbára
Àwọn ọlọ́pàá rọ̀jò ìbọn lórí àwọn jàndùkú tó ṣekúpa Ahmed Gulak, wọ́n tún gba ìbọn wọn
Iléeṣẹ́ ọlọ́pàá ti mú àwọn jàndùkú tó pa èèkàn ẹgbẹ́ APC
Kọmiṣọnna ọlọpaa Imo, CP Abutu Yaro gboṣuba rabandẹ fawọn ọlọpaa fun iṣẹ takun takun ti wọn ṣe lati ṣawari awọn asekupani naa.
O dabi ẹni pe idajọ kiakia lawọn janduku to ṣekupa Ahmed Gulak tii ṣe oluranlọwọ aarẹ ana orilẹ-ede Naijiria, Goodluck Jonathan gba lẹyin tawọn ọlọpaa ti ran awọn naa lọ si ọrun alakeji.
Oríṣun àwòrán, Gulak
Ileeṣẹ ọlọpaa ipinlẹ Imo ṣalaye ninu atẹjade kan to fi sita lọjọ Aiku pe awọn agbofinro ti ṣawari awọn agbebọn to pa Gulak loju ilu Owerri si Abuja.
Koda awọn ọlọpaa tun gba ibọ AK 47 mẹta, ibọn kekere kan ati ọta ibọn mejilelaadọrun lọwọ wọn.
Bakan naa lawọn ọlọpaa tun gba awọn ọkọ ti wọn fi ṣiṣẹ ibi naa lọwọ wọn.
''Gẹgẹ bi dẹrẹba Gulak to n gbe lọ si papkọ ofurufu nigba ti wọn pa ṣe sọ, awọn agbebọn naa lo ọkọ Toyota Camry 2005, Toyota Sienna 1998, Toyota Hilux ati Lexus RX 330 lati ṣiṣẹ laabi wọn.
O tun sọ fun wa ọna ti awọn janduku ọhun gba lọ lẹyin ti wọn pa Gulak tan.
Simple tricks to identify designer shoes: Ṣe ìwọ lè wọ bàtà #2 mílíọ̀nú
Gbogbo nkan ti a lo niyii lati wa wọn ri de ibi ti wọn wa gan an.
Orita Afor Enyiogugu ni ijọba ibilẹ Aboh-Mbaise ni a ti gba wọn mu, koda wọn n pin alubọsa lati inu ọkọ nla to n bọ lati oke Ọya fawọn eeyan ni a de bẹ.
Bi wọn ṣe ri wọn ni wọn bẹrẹ si ni yinbọn mọ wa, ṣugbọn wọn ba awa ọlọpaa naa nile.
Democracy day 2021: Kí ni Nàìjíríà ti jèrè lára gbogbo ààrẹ tó ti jẹ látọdún 1999?
Awọn janduku mẹfẹẹfa to pa Gulak atawọn akẹgbẹ wọn mẹrin mii lo farapa yanayana,'' ileeṣẹ ọlọpaa ṣalaye.
Kọmiṣọnna ọlọpaa Imo, CP Abutu Yaro gboṣuba rabandẹ fawọn ọlọpaa fun iṣẹ takun takun ti wọn ṣe lati ṣawari awọn asekupani naa.
Awọn janduku agbebọn ti ṣekupa Ahmed Gulak tii ṣe oluranlọwọ aarẹ ana orilẹ-ede Naijiria, Goodluck Jonathan.
Ilu Owerri nipinlẹ Imo ni wọn ti sọ pe wọn yinbọn pa Gulak.
Gulak n rinrin ajo lati Abuja si Owerri lalẹ ọjọ Abamẹta ki o to ṣagbako iku ojiji lọna.
Ibadan killing, Linus Onwuamana: Àwọn jàndùkú agbébọn yìnbọn pa ọkùnrin oníṣòwò kan nílùú Ibadan
Oríṣun àwòrán, other
Ọrọ eto abo to mẹhẹ lorilẹede Naijiria ti n burẹkẹ si, lẹyin tawọn janduku agbebọn tun ṣekupa ọkunrin oniṣowo kan niluu Ibadan.
L'ọjọ Aiku ni ileeṣẹ ọlọpaa ipinlẹ Ọyọ fi idi ọrọ naa mulẹ lori ipapoda Arakunrin Linus Owuamanam, oniṣowo ti awọn agbebọn ti ẹnikẹni ko damọ yinbọn pa.
Iroyin sọ wi pe ni nnkan bi i aago mẹjọ alẹ ọjọ Abamẹta ni awọn olubi ẹda naa gbẹmi Onwuamana.
Oniṣowo naa ni wọn sọ wi pe o n wa ọkọ akẹru kan lọ lopopona Mọkọla si Sango nilu Ibadan lasiko ti o se kongẹ iku ojiji.
Lẹyin ti wọn yinbọn fun un tan, awọn agbebọn naa tun fi nnkan gun un ni aya lati riidaju ko ru ikọlu naa la.
Simple tricks to identify designer shoes: Ṣe ìwọ lè wọ bàtà #2 mílíọ̀nú
Bẹẹ si ni ko si ẹnikẹni ti o mọ ibi ti ẹnikeji to n ba oloogbe rin irinajo lasiko ti iṣẹlẹ naa ṣẹlẹ wa bayii.
Ẹni kan ti o n kọja lọ ti o si ri oloogbe naa ninu agbara ẹjẹ lo fi iṣẹlẹ naa to awọn oṣiṣẹ rẹ leti.
Democracy day 2021: Kí ni Nàìjíríà ti jèrè lára gbogbo ààrẹ tó ti jẹ látọdún 1999?
Insecurity: Amotekun yóò bẹ̀rẹ̀ sí ni káàkiri ibodè nílẹ̀ Yorùbá láti máwọn ọ̀daràn àti ajínigbé- Adetunji adeleye
Ọgagun ọga awọn Amotekun nilẹ Yoruba, Oloye Adetunji Adeleye ti kede pe ọjọ kinni oṣu kẹfa ni ẹṣọ eleto abo naa yoo bẹrẹ si ni maa kaakiri ibode awọn ipinlẹ Yoruba.
Nigba to n ba BBC Yoruba sọrọ, Oloye Adeleye sọ pe awọn gomina ti pese ọkọ tawọn maa lo fun iṣẹ yii.
O tun fikun ọrọ rẹ pe kii ṣe wi pe awọn maa ṣiṣẹ ileeṣẹ aṣọbode.
''Amotekun nikan kọ lo maa ṣiṣẹ yii, awọn ọlọpaa, DSS ati Civil Defence yoo fọwọ sowọpọ pẹlu wa lati le gbogun tawọn adigunle loju popo.
Ṣe ẹ mọ pe idasilẹ Amotekun wa fun iranwọ fawọn agbofinro ni tẹlẹ.
Adebayo Murital David: Gbogbo iṣẹ́ tó ń múni là láyé wá láti ọpọlọ ni kìí ṣe agbára
Ofin to gbe wa kalẹ sọ pe ibi ti apa ba ti n ro wọn ni ki a ti ba wọn gbe e soke.
Awọn eṣọ Amotekun to wa ni ipinlẹ Osun yoo maa ṣiṣẹ pọ pẹlu awọn to wa ni Oyo, awọn ti ipinlẹ Oyo naa yoo gbera lọ si Ondo, bi a o ṣe maa ṣee niyẹn,'' Oloye Adeleye ṣalaye.
Amotekun yóò máa ṣọ́ ibodè àwọn ìpínlẹ̀ Yorùbá láti máwọn ọ̀daràn àti ajínigbé
Gbogbo eto lo ti to bayii fun ẹṣọ alaabo Amotekun lati maa ṣọ ibode awọn ipinlẹ Yoruba.
Igbesẹ yii gbaye lati pese abo to munadoko kaakiri ilẹ kaarọ o jiire.
Ọgagun ẹṣọ Amotekun ipinlẹ Ondo to tun jẹ alaga awọn ọgagun Amoteukun nilẹ Yoruba, Adetunji Adeleye  lo fidi ọrọ yii mulẹ.
Oríṣun àwòrán, Western Nigeria security network
Ọgbẹni Adeleye ni eyi ṣe pataki nitori o maa jẹ ko rọrun lati mu awọn ọdaran to ba sa lati ipinlẹ Yoruba kan si omiran.
Adeleye to sọrọ niluu Akure fidi rẹ mulẹ pe dida ẹranjẹko awọn ti dinku nipinlẹ Ondo bayii.
Democracy day 2021: Kí ni Nàìjíríà ti jèrè lára gbogbo ààrẹ tó ti jẹ látọdún 1999?
O ni awọn darandaran ti bẹrẹ si ni sanwo fawọn agbẹ ti wọn ti da ẹran jẹ oko wọn.
Ọgagun Amotekun naa ni gbogbo opopona to wa kaakiri ilẹ Yoruba lawọn ẹṣọ Amotekun yoo maa ṣọ bayii.
''A fẹ rii pe iṣẹlẹ adigunjale ati ijinigbe dinku lawọn opopona wa nilẹ kaarọ o jiire.
Simple tricks to identify designer shoes: Ṣe ìwọ lè wọ bàtà #2 mílíọ̀nú
A ti ṣe akiyesi pe awọn ibi ti ọna ti bajẹ tawọn awakọ kii ti lanfaani ti sare ni iṣẹlẹ ijinigbe ti maa n saaba ṣẹlẹ.
Bakan naa, a gbọdọ ri wi pe ofin maa dẹran ni gbangba mọ mulẹ kaakiri ilẹ Yoruba.
A ti bẹrẹ si ni mu awọn darandaran to ba dẹran jẹ oko awọn eeyan wa.
Darandaran to ba ti dẹran jẹ oko bayii ti di ọdaran.
Mali Coup: ECOWAS ti fi òfin de àárẹ Mali, wọ́n ní dandan ni kó dá ìjọba alágbádá padà
Oríṣun àwòrán, Reuters
Awọn adari ajọ Ecowas da Mali duro lẹyin iditẹgbajọba to waye nibẹ.
Iditẹgbajọba to waye ni Mali lọsẹ to kọja, ti mu ki ajọ Economic Community of West African States, Ecowas, fi ofin de orilẹ-ede naa.
Iditẹgbajọba naa to sọ Colonel Assimi Goita di aarẹ tuntun, ni ẹlẹẹkeji to waye laarin oṣu mẹ́sàn-án.
Yatọ si fifi ofin de Mali, àwọn adari Ecowas tun sọ pe o gbọdọ yan Olootu ijọba alagbada ni kiakia.
Nibi ipade to waye lori ọrọ Mali ni Ghana lọjọ Aiku, ni wọn ti sọ fún aarẹ ologun tuntun ọhun to n na wa nibi ipade.
Adebayo Murital David: Gbogbo iṣẹ́ tó ń múni là láyé wá láti ọpọlọ ni kìí ṣe agbára
Bakan naa ni wọn tun fẹ ki Colonel Assimi Goita ṣe eto idibo ko to o di oṣu Keji, ọdun to n bọ.
Minisita fun ọrọ ilẹ okeere ni Ghana, Shirley Ayorkor Botchwey sọ fun awọn akọroyin pe o ṣe pataki ki Mali duro daadaa nitori wahala àwọn agbesunmọmi to n waye nibẹ.
Democracy day 2021: Kí ni Nàìjíríà ti jèrè lára gbogbo ààrẹ tó ti jẹ látọdún 1999?
Nitori naa lo ṣe ṣe pataki pe ki wọn o tẹle ilana gbigbe ijọba fun alagbada laarin oṣu mejidinlogun.
Colonel Goita gun ori aga isakoso ijọba lẹyin to pàṣẹ pe ki wọn o mu aarẹ fidihẹ, Bah Ndaw ati Olootu ijọba, Moctar Ouane, lọjọ kẹrinlelogun, oṣu Karun-un.
Omoyele Sowore dèrò ilé ìwòsàn lẹ́yìn tó fara gba ọta gáàsì tajútajú níbi ìwọ́de kan nílùú Abuja
Oríṣun àwòrán, @GuardianNigeria
Ajafẹtọ ati oludije sipo Aarẹ Naijiria lọdun 2019, Omoyele Sowore ti ṣeṣe lẹyin to fara gba ọta gaasi tajutaju lasiko iwọde kan niluu Abuja.
Ṣaaju ni Sowore ati awọn oluwọde kan ti kọkọ korajọ siwaju Unity Fountain laarọ ọjọ Aje lati ṣe ifẹhonuhan lori eto abo to mẹhẹ ni Naijiria.
Bo tilẹ jẹ pe awọn agbofinro kọ lati jẹ ki Sowore ati awọn oluwọde akẹgbẹ rẹ wọle si gbọgan ọhun, ṣugbọn wọ yin gaasi tajutaju lati tu wọn ka.
Ẹnikan ti iṣẹlẹ naa ṣoju rẹ ṣalaye fun awọn akọroyin pe asiko ti ọkan lara awọn ọlọpaa naa yin gaasi ọhun ni ọta rẹ ba Sowore, to si ṣubu lẹsẹ kan naa.
Lẹyin naa ni wọn gbe ajijagbara naa digbadigba lọ sile iwosan fun itọju to peye.
Ninu kan fidio to fi lede loju opo Twitter ati Facebook rẹ, Sowore ṣafihan oju egbo ti ọta naa ti ba a lẹṣẹ, to si n sọ fun awọn alatilẹyin rẹ pe ki wọn má da iwọde ọhun duro.
Adebayo Murital David: Gbogbo iṣẹ́ tó ń múni là láyé wá láti ọpọlọ ni kìí ṣe agbára
Ọpọ awọn ọmọ Naijiria lo ti bẹrẹ si n sọ erongba wọn lede lori iṣẹlẹ naa lori ayelujara.
Lẹyin iṣẹlẹ ọhun ni minisita abẹle fun ọrọ Niger Delta, Festus Keyamo sọ loju opo Twitter rẹ pe ẹnikẹni to ba gba ọna miran lati paarọ ijọba to wa lori oye yatọ si eto idibi ti ṣẹ si ofin.
Keyamo fi kun pe ẹṣẹ iditẹgbajọba ni ki eeyan gba ọna miran ti kii ṣe nipasẹ eto idibo lati da oju ijọba bolẹ.
Ti ẹ ko ba gbagbe, kii ṣe igba akọkọ ree ti Sowore yoo gbiyanju lati gbena woju ẹkun ijọba Naijiria.
Bode George: òòtọ́ ni ìkìlọ̀ Obasanjọ ati Soyinka
Ghana couple buries son alive: Ọkọ àti ìyàwó ri ọmọ ọdún kan àbọ mọlẹ láàyè
Oríṣun àwòrán, Kofi Adjei
Ọwọ Ọlọpaa ti tẹ arakunrin kan ati iyawo rẹ ti wọn mu ni afurasi pe wọn sin ọmọ wọn ọmọ ọdun kan ataabọ laaye ni agbegbe Central Region ni Ghana.
Awọn ti ọrọ naa ṣoju wọn sọ pe ọkọ atiyawo pawọpọ pẹlu oniṣegun ibilẹ kan loru ọganjọ lati sin ọmọ naa.
Abubakar Mohammed to ni iṣẹlẹ naa ṣoju rẹ latinu yara tirẹ sọ pe oun ri awọn mẹtẹẹta nita ti wọn n huwa lodi lodi.
"Bi mo ṣe wa ninu yara, mo ri i pe ọmọ kan wa lejika ọkan lara wọn ... Igba to ya ni mo ri i pe o dabii wipe wọn ti gbe ọmọ naa sin. O sọ eyi fun awọn oniroyin.
Adebayo Murital David: Gbogbo iṣẹ́ tó ń múni là láyé wá láti ọpọlọ ni kìí ṣe agbára
Torinaa, mo lọ fi ọrọ naa to awọn ọlọpaa leti to si jẹ pe lẹyin ti awọn ọlọpaa gbẹ ilẹ naa, a ri i pe lootọ lootọ ni wọn gbe ọmọ naa gbin sinu ilẹ"". Ọgbẹni Abubakar fi kun un."
"Alukoro ileeṣẹ ọlọpaa Central Region, DSP Irene Oppong ṣipaya rẹ pe ""Abubakari fi ọrọ naa to awọn leti ni nkan bii ago mẹta oru."
Lẹsẹkẹsẹ ni ọlọpaa Ghana bọ sigboro ti wọn bẹrẹ si ni wa babalawo naa to ti fẹsẹ fẹẹ.
A ri Paul Adobaw ti wọn mọ si Kojo Okor to jẹ onile rẹ ati obinrin meji ṣugbọn o dabii pe wọn ti pa ọmọ naa lara.
Ọlọpaa mu Paul Adobaw wọn si gbe e lọ si ibi ti iṣẹlẹ ọhun ti wọn si ni ki afurasi naa hu ilẹ ti wọn ti da iyẹpẹ bo nibi ti wọn ti ri ọmọ naa to ti ku, Yaw Adobaw.
Wọn gbe oku ọmọ, lẹyin ti wọn si ṣe ayẹwo kikun, wọn ri i pe ẹjẹ n yọ ni imu ati ẹnu rẹ ki wọn to gbe e lọ si mọṣuari.
Oríṣun àwòrán, Kofi Adjei
Omoyele Sowore dèrò ilé ìwòsàn lẹ́yìn tó fara gba ọta gáàsì tajútajú l'Abuja
Iléeṣẹ́ ọlọ́pàá Nàìjíríà ti kéde pé IPOB àti ESN ló pa Gulak tó kú lánàá
Afurasi ọhun, Paul ti wa ni atimọle ọlọpaa to si n ran wọn lọwọ ninu iwadii ti wọn n ṣe. Ọlọpaa ṣi n wa babalawo to ti na papa bora.
Ileeṣẹ iroyin BBC ko iroyin jọ pe awọn oloye ati agbaagba adugbo naa n ṣe etutu lọwọ lọwọ lati ṣe iwẹnumọ ilẹ tori pe wọn ri ọmọ naa mọlẹ laaye.
Ko tii si aridaju idi kan pato ti lọkọlaya naa fi sin ọmọ wọn laaye ṣugbọn awọn kan sọ pe lẹẹkọọkan ọmọ naa maa n ni abuda agọ ara pe boya torii rẹ si ni wọn ṣe n gbimọ pẹlu babalawo lati pa a.
Iroyin sọ pe idajọ iku ni fun afurasi naa bi ile ẹjọ ba ri i pe o jẹbi ẹsun ti wan fi kan an labẹ iwe ofin ilẹ Ghana toripe afurasi naa lo mọọmọ fa iku ọmọ naa.
Iṣẹlẹ ki wọn maa pa ọmọ toriipe wọn gbagbọ o jẹ ọmọ ẹlẹmikẹmi ko wọpọ ni Ghana ayafi ẹẹkọọkan bii eleyii to si maa n fa idamu si ọkan awọn araalu atipe iwe ofin ọdun 1992 pese fun idaabo bo ẹmi eniyan.
Oro festival in Ikorodu: Idí tí obìrin kò gbọdọ̀ ṣe fi ojú rí Orò rèé
Ọjọ kinni, oṣu Kẹfa, ọdun 2021 ni oro jade niluu Ikorodu, ni ipinlẹ Eko.
Gẹgẹ bii iwadii ti akọrọyin BBC to wa nibi ajọdun naa ṣe, oriṣi Oro meji lo wa nilu Ikorodu, oro kinni ni wọn n pe ni Magbo, eyii to jade lọjọ kinni, oṣu Kẹfa yii.
Oro keji ni wọn n pe Liwe ti yoo jade ni nnkan bii ọsẹ meji si mẹta lẹyin eyii to ṣẹṣẹ jade yii.
Irufẹ eeyan wo lo le foju gan ni Oro?
Gẹgẹ bii ohun ti awọn to wa nidii iṣẹṣe ọhun sọ, gbogbo eeyan lo le foju ganni Oro, ko si yọ onile silẹ tabi alejo, koda ko yọ oyinbo alawọ funfun silẹ pẹlu.
Amọ ṣa o, obinrin kii ri Oro!
Ko si obinrin kankan to gbọdọ jade ni gbogbo asiko ti Oro ba n jade nitori ọkunrin nikan lo le ri oro.
Oba Gbolahan Timson Shomolu Bariga ní 'Restructuring'ti bọ́ aṣọ kò bá Omọyẹ mọ́!
Idi re ti awọn agba ṣe sọ pe, ti obinrin ba foju ri oro, oro a gbe.
Gẹgẹ bii nnkan ti Oloye Ganiyu Taole sọ, ti obinrin alaboyun  ba ṣeeṣi foju ganni Oro, ọmọ irufẹ obinrin bẹẹ le papoda lọjọ ikunlẹ.
Ṣugbọn to ba jẹ obinrin ti ko loyun ni tabi ti ko tii bi ọmọ kankan ri, irufẹ obinrin bẹẹ ko ni ṣe abiyamọ titi ti yoo fi jade laye.
Idi ree ti wọn sẹ maa n ṣe ipolongo pupọ ki asiko ọdun Oro to de ati ki Oro to jade.
Oríṣun àwòrán, other
Ki lo ti ṣẹlẹ sẹyin?
Okunkun birimu, iloro asemọra, ferese atipa, olukuluku ninu iyẹwu. Eyi lohun tawọn obinrin yoo dojukọ lọjọ Iṣẹgun ọjọ kini oṣu kẹfa ọdun 2021 ni ilu Ikorodu.
Idi ni wipe, lọjọ iṣẹgun ni ajọdun oro Magbo yoo waye ni ilu Ikorodu.
Ajọdun Oro jẹ ọkan pataki lra awọn ajọdun iṣẹmbaye ni ilu Ikorodu awọn ọmọ onilẹ to jẹ ọkunrin. Awsn obinrin, ọmọde ati ajeji ko gbọdọ ysju sita ni gbogbo asiko oro naa.
Gẹgẹ bi iṣẹṣe, lasiko ọdun Oro yii obinrin kankan ko gbọdọ jade kuro ni ile rẹ,bẹẹni wọn ko gbọdọ ṣi oju wo awọn ọkunrin awọn ọkunrin to n ṣe atọkun fun Oro naa bi wọn ṣe n lọ lati agbegbe si agbegbe nibẹ.
Igbagbọ awọn eeyan agbegbe naa ni pe obinrin yoowu to ba fi oju ri awọn oloro naa yoo ku ni, tabi ki ohun buruku kan o ṣẹlẹ sii.
"'Èmi ọmọ Ikorodu ọ̀ga, ọmọ aṣalẹ̀ jẹ́jẹ! Wo bí àwọn ọmọdé tó ""tuush"" yìí ṣe ń fi oríkì Yorùbá dábíra"
Ọdun Oro kii ṣe ajeji si iran Yoruba; ọpọlọpọ awọn ilu lo n ṣe ọdun Oro ni ilẹ Yoruba, olukuluku wọn lo si ni ọna ti wọn gba fi n ṣe e.
Oloye Kazeem Adeniyi Roga to jẹ ọkan lara awọn adari ilu ni Ikorodu ṣalaye pe adura ni wọn n fi Oro ṣe lati le aburu lọ kuro ni ilu ati lati mu ki ire o maa wọ tọ awọn eeyan agbegbe naa wa.
Amọṣa arabinrin kan to ti figbakanri gbe  nilu ti wọn ti gbe Oro ri ṣalaye pe eyi ko ri bẹẹ rara.
Adebayo Murital David: Gbogbo iṣẹ́ tó ń múni là láyé wá láti ọpọlọ ni kìí ṣe agbára
Arabinrin Taiwo Yusuf ṣalaye pe to ba jẹ pe bẹẹ lo ṣe ri ni, ki lo de ti awọn ilu to n gbe Oro ṣi n foju wina aburu bii ajakalẹ arun iba eyi to n pa ọmọde ati gbogbo awọn ipaniyan loniranran to n waye.
O ni nṣe ni wọn n fi ọdun Oro naa tẹ ẹtọ awọn obinrin nitoripe awọn obinrin gan an lo n fara gba julọ lasiko ọdun Oro eleyi to lee waye fun bi ọsẹ meji lawọn ilu kan.
"Mo ms obinrin kan to ku sinu ile nitoripe ọkọ rẹ ko lee gbe lọ si ile iwosan nigba ti wahala ṣẹlẹ lori oyun to ni
Ondo: Nítorí ikú ọlọ́pàá, àwọn ọ̀dọ́ lé kábíyèsí jáde láàfin l'Ondo
Oríṣun àwòrán, The news track.com.ng
Awọn ọdọ ilu Itaogbolu ni ijọba ibilẹ Ariwa Akurẹ nipinlẹ Ondo ti le kabiyesi wọn kuro laafin.
Eyi waye lẹyin ti ọlọpaa kan ti orukọ rẹ n jẹ Ayọ Oloyede kagbako iku ninu ijamba ọkọ kan to waye.
Gẹgẹ bi iroyin abẹle to tẹ BBC News Yoruba lọwọ ṣe sọ, awọn ọdọ naa fura pe iku ọlọpaa naa kii ṣe ojulasan.
Bi o tilẹ jẹ pe ibeere ọpọlọpọ ni pe ki lo kan kabiyesi kan iku ọlọpaa to ku ninu ijamba mọto?
Awọn ti iṣẹlẹ naa ṣoju wọn ṣalaye pe awọn ọdọ ilu naa ti inu mbi fi ikanra le kabiyesi Ogbolu tilu ItaOgbolu, Ọba Idowu Fabọrọde kuro laafin lori ẹsun pe o kuna ninu ojuṣe rẹ lati daabo bo awọn ọmọ ilu naa.
Adebayo Murital David: Gbogbo iṣẹ́ tó ń múni là láyé wá láti ọpọlọ ni kìí ṣe agbára
Ọlọpaa naa ti wọn ni o n ṣiṣẹ ni ẹka igbogun ti iwa ẹgbẹ okunkun nileeṣẹ ọlọpaa, Anti-cultism unit to wa nilu Akurẹ wale wa ki iya rẹ gẹgẹ bi awọn ti ọrọ naa ṣoju wọn ṣe sọ. Ipada rẹ si ilu Akurẹ lo ti kagbako ijamba to sọ di ero ọrun.
Awọn ọdọ ilu naa la gbọ pe wọn ni kii ṣe oju lasan ni iku naa ati pe eeyan darandaran ti ọpọlọpọ awọn araalu nifẹ ni oloogbe naa,
COVID-19 in Lagos: Wo ìdí tó fi ṣeéṣe kí ìjọba àpapọ̀ ó kéde àkọ̀tun ìséde n'ipínlẹ̀ Eko
Oríṣun àwòrán, other
Afaimọ ki ijọba apapọ o ma a tun gbe akọtun isede le ipinlẹ Eko lẹyin ti ijọba ipinlẹ naa kede pe awọn eeyan marundinlogoje ti sa kuro ninu ibudo ifiniwọsi fun ayẹwo COVID-19 ti wọn fi wọn si ni ilu Eko.
Awọn eeyan marundinlogoje naa wa lara awọn ero ọtalelẹẹdẹgbẹta ati mẹjọ arinrinajo ti wọn wọ Naijiria latawọn orilẹ-ede ti arun COVID-19 ti n ṣọṣẹ lagbaye to wọ orilẹ-ede Naijiria lẹnu lọwọlọwọ yii.
Awọn orilẹ-ede bii India, Brazil ati Turkey wa lara awọn orilẹ-ede ti awọn eeyan marundinlogoje naa ti wa ki wọn to juba ehoro kuro ni ibudo ifiniwọsi naa.
Kọmiṣọnna feto ilera ni ipinlẹ Eko, Ọjọgbọn Akin Abayọmi ni o ṣepataki kawọn arinrinajo to salọ naa o tete gbe igbesẹ to tọ nipa ilana ti ijọba gbe kalẹ lati dẹkun itankalẹ arun naa.
Ọjọgbọ̀n Abayọmi fi kun pe ninu awọn marundinlogoje naa, mọkandinlọgọfa faake kọri pe awọn ko ni tẹle ilana ifiniwọ fun ayẹwo naa, mẹrindinlogun yooku si ti di awati.
Bakan naa lo ri awọn mọlẹbi awọn ti ọrọ naa kan lati pẹtu si awọn eeyan wọn ninu pe ki wọn pada bi wọn ko ba fẹ ki wọn foju wina ijiya gbogbo to rọ mọọ labẹ
O ni aitẹle ilana yii lee fa idajọ ẹwọn gẹgẹ bi ileegbimọ aṣofin ipinlẹ Eko ṣe gbe ofin kalẹ fun amofinagba rẹ lati tẹle.
Oba Gbolahan Timson Shomolu Bariga ní 'Restructuring'ti bọ́ aṣọ kò bá Omọyẹ mọ́!
Ẹgbẹrun marundinlẹẹdẹgbẹta o le diẹ ni iye ayẹwo arun COVID-19 ti wọn ti ṣe ni ipinlẹ Eko, ẹgbẹrun mọkandinlọgọta  o din diẹ ninu wọn layẹwo fihan pe o laarun naa.
Ninu wọn ẹgbẹrun mẹrinlelaadọta o le diẹ ninu wọn lara wọn ti ya, ọdunrun o le mẹrindinlọgọta lo ku ninu wọn.
Kọmiṣọnna feto ilera ni ipinlẹ Eko naa ṣalaye pe ijọba ipinlẹ Eko ati ajọ irinna ofurufu ni Naijiria, FAAN ti gbe ilana kalẹ ti yoo mu irinajo rọ awọn arinrinajo lọrun.
Eyi yoo jẹ  nipa pipese awọn ile igbafẹ ti wọn fọwọsi tawọn arinrinajo to ṣẹṣẹ wọle lee wọ si fun eto ifiniwọsi fun ayẹwo COVID-19 wọn.
Adebayo Murital David: Gbogbo iṣẹ́ tó ń múni là láyé wá láti ọpọlọ ni kìí ṣe agbára
Ọwọ́ EFCC tẹ ọmọ Yahoo tó fẹ́ ra ọkọ̀ SUV tí iye rẹ̀ tó 44 mílíọ́nù pẹ̀lú Bitcoin
A ti rí ọmọ ilé kéú 11 míì nínú àwón tí agbébọn jí gbé ní ìpínlẹ̀ Niger
Iléeṣẹ́ ọlọ́pàá Nàìjíríà ti kéde pé IPOB àti ESN ló pa Gulak tó kú lánàá
Wo àsìkò tí ìdíje BBNaija lockdown reunion"" yóò bẹ̀rẹ̀"
Omoyele Sowore dèrò ilé ìwòsàn lẹ́yìn tó fara gba ọta gáàsì tajútajú l'Abuja
Adigunjalè ja Ọ̀gá ọlọ́pàá àti ẹni mẹ́ta míràn lólè
Muri Thunder: Àfojúsùn mi ni láti gba Grammy gẹ́gẹ́ bíi olórin Fuji
Oríṣun àwòrán, official_muri_thunder
Gbajugbaja olorin Fuji, Alhaji Muri Alabi Thunder, ti ọpọ mọ si Muri Thunder ti sọ pe ko si ija kankan laarijn oun ati Saheed Osupa.
Muri Thunder lo tu pẹrẹpẹrẹ ọrọ naa lasiko ifọrọwerọ kan pẹlu BBC Yoruba.
Ṣaaju ni ọkan lara awọn ololufẹ olorin Fuji naa ti kọkọ bere loju opo Facebook ileeṣẹ iroyin BBC Yoruba ki eto naa to bẹrẹ nipa ohun to fa ija laarin oun ati Osupa Saheed.
Nigba to n fesi, Muri Thunder sọ pe ọga ati ẹni ti oun n wo loke ni Saheed Osupa jẹ, kii ṣe ẹni ti oun le maa sọrọ abuku si.
Bo tilẹ jẹ ko sẹ nigba ti atọkun eto naa bere lọwọ rẹ nipa ija ti wọn ni o wa laarin oun ati Saheed Osupa ṣaaju.
"O ni ""Ibaṣepọ emi ati King Saheed Osupa gun rege ko si si ija kankan laarin wa."""
Magaret Jimoh: Èrè díẹ̀ ti tó mi níbi oúnjẹ ti mò ń tà- Maggie Rice
Gbogbo ohun ti awọn eeyan n sọ yẹn ti di afiṣeyin ti eegaun n fi aṣọ nitori ọrọ naa ti do ohun igbagbe.
Lasiko to n fẹsi si ohun to ṣẹlẹ to fi sọko ọrọ si Saheed Osupa ninu awon orin rẹ kan.
"Muri Thunder sọ pe ""Kii ṣe pe emi ati Osupa ni ija tẹlẹ, ohun to ṣẹlẹ nigba yẹn, ija gbogbogbo ni."""
Oríṣun àwòrán, official_muri_thunder
Gbajumọ onifuji naa ṣalaye pe gbogbo olorin Fuji lo n kọ orin bu ara wọn lọdun naa lọhun, kii ṣe pe oun mọọmọ sọ oju si Saheed Osupa lara.
Tunde Bakare: Àjọjẹ kò dún bẹ́nìkan kò ní ló fa ìjà S Igboho,bẹ́ẹ̀ ìjọbati gbẹ́rù kọjá orí
Yatọ si ọrọ Saheed Osupa, Muri Thunder tun sọ pe irẹpọ to dan mọran lo wa laarin oun ati gbajugbaja olorin Fuji miran, iyẹn Wasui Alabi Pasuma.
Nigba to n sọrọ lori bi irinajo rẹ ṣe ri nidii iṣẹ orin fuji, Muri Thunder sọ pe wọn bi iṣẹ orin mọ oun ni.
Oba Gbolahan Timson Shomolu Bariga ní 'Restructuring'ti bọ́ aṣọ kò bá Omọyẹ mọ́!
Bo tilẹ jẹ pe o ni oun ko kọ iṣẹ naa lọdọ ẹnikẹni, o ni lara awọn olorin ti oun gbe oṣuba kare fun ni Saheed Osupa, oun si ti ba oniruru olorin ṣiṣẹ papọ.
Ni ti afojusun rẹ fun ọjọ iwaju, Muri Thunder sọ pe yatọ si oniruru ami ẹyẹ ti oun ti gba tẹlẹ, yoo wu oun lati gba ami ẹyẹ Grammy gẹgẹ bii onifuji.
Constitution review: A fẹ́ kí ará ìlú túbọ̀ ráàyè sọ̀rọ̀ nípa ohun tí wọ́n fẹ́ / kò fẹ́ ni- Ajibola Bashir
Oríṣun àwòrán, @Bashir
Kini Ile Igbimọ Asofin Agba fi daa pada fun Akeredolu?
Awọn aṣofin agba naa ti daa pada fun un pe ti ara rẹ lo sọ.
Agbẹnusọ fun ile aṣofin agba, Sẹnetọ Ajibọla Bashiru ni ti ara Akeredolu lo n sọ.
Senetọ Ajibola Bashiru to n ṣoju Osun Central nipinlẹ Osun lo fun un lesi pe ọrọ ko ri bẹẹ.
Agbenusọ naa ni ero ọkan gomina Akeredolu lo fi sita yẹn, awọn ara ilu to ku naa ṣi ni anfani lati sọ ero ti wọn naa.
O tun nilẹyin eyi ni awọn Aṣofin yoo wa joko pẹlu ase lati yọ awọn ero ti ko gbadun da ni ti wọn yoo si mu ero to maa mu ilọsiwaju lo.
Oba Gbolahan Timson Shomolu Bariga ní 'Restructuring'ti bọ́ aṣọ kò bá Omọyẹ mọ́!
Awọn aṣofin agba lorilẹ-ede Naijiria ti fun gomina ipinlẹ Ondo, Rotimi Akeredolu lesi ọrọ rẹ to sọ.
Orọ naa ni pe Akeredolu pe fun wiwọgile ileegbimọ aṣofin apapọ ninu atunṣe iwe ofin orilẹede Naijiria ti awọn aṣofin naa n gbero.
Akeredolu pè fún wíwọ́gilé iléègbìmọ̀ aṣòfin àgbà, àwọn aṣofin àgba ní tẹnu ara rẹ̀ ló ń sọ
Oríṣun àwòrán, twitter/Akeredolu
Akeredolu ninu iwoye rẹ nibi apero finukonu lori atunto iwe ofin naa eyi tawọn aṣoju-ṣofin ṣe nilu Akurẹ ṣalaye pe asiko to fun orilẹ-ede Naijiria lati boju wo bibẹgile eto iṣofin oloju meji ti o n ṣe lọwọ.
Koda, o tun ni ki o si sọọ di ẹyọ kan ninu eyi ti ipinlẹ kọọkan yoo ti ni awọn aṣofin mẹrin lati ṣoju rẹ.
Akeredolu pè fún wíwọ́gilé iléègbìmọ̀ aṣòfin àgbà, àwọn aṣofin àgba ní tẹnu ara rẹ̀ ló ń sọ
Ati pe eredi ipade itagbangba lori atunto iwe ofin Naijiria ni lati gbọ oniruuru ero ọkan araalu lori rẹ.
Amọṣa o, araalu ni yoo papa pinnu ohun ti wọn ba n fẹ ni ilana agbekalẹ abala kẹsan iwe ofin Naijiria ti ọdun 1999.
Adebayo Murital David: Gbogbo iṣẹ́ tó ń múni là láyé wá láti ọpọlọ ni kìí ṣe agbára
Lara awọn ohun ti gomina Akeredolu, ti igbakeji rẹ Lucky Aiyedatiwa ṣoju fun, ṣalaye ni pe iṣẹ aṣofin ko yẹ ko jẹ ajokoti bii ikoko ọbẹ.
Bikoṣe eyi ti awọn aṣofin yoo maa wọle wa ṣe ni atigbadegba.
Bẹẹni ko si yẹ fawọn aṣofin lati gba owo oṣu kankan ti ko han si igbimọ to n pin owo ijọba lorilẹ-ede Naijiria, RMAC
"'Èmi ọmọ Ikorodu ọ̀ga, ọmọ aṣalẹ̀ jẹ́jẹ! Wo bí àwọn ọmọdé tó ""tuush"" yìí ṣe ń fi oríkì Yorùbá dábíra"
FUOYE Sexual harassment: Fásitì FUOYE pàṣẹ lọ rọọ́kún nílé fún lẹ́kṣọ́rà tó ṣe aṣemáṣe pẹ̀lú akẹ́kọ̀ọ́
Oríṣun àwòrán, other
Awọn alaṣẹ Fasiti apapọ nilu Ọyẹ Ekiti, FUOYE ti ni ki olukọ agba kan nibẹ o lọ rọ ọ kun nile lori ẹsun pe o n na ọwọ aṣemaṣe ibalopọ si ọkan lara awọn akẹkọọ ni ileewe naa.
Olukọ naa ti wọn pe orukọ rẹ ni Ọmọwe Mbachaga wa pẹlu ẹka imọ nipa tiata.
Oun ni iroyin nile ẹkọ giga fasiti naa ni wọn ni igbimọ tẹẹkoto ti awọn alaṣẹ ẹka ẹkọ imọ nipa Ọrọ ẹda ati ihuwasi ọmọniyan nileẹkọ giga fasiti naa gbe kalẹ rii pe ọwọ rẹ ko mọ lori awọn ẹsun ti wọn fi kan an.
Atẹjade kan latọdọ awọn alaṣẹ ile ẹkọ naa eyi ti agbẹnusọ fun giwa ibẹ, Foluṣọ Ogunmọdẹde ṣalaye pe ileewe naa ko ni fi aaye gba iwa aitọ.
O ni: bẹẹni oṣiṣẹ koṣiṣẹ to ba ṣe lodi si iwa ọmọluwabi ni ileewe naa bi o ti wulẹ ko mọ yoo foju wina ofin.
Tunde Bakare: Àjọjẹ kò dún bẹ́nìkan kò ní ló fa ìjà S Igboho,bẹ́ẹ̀ ìjọbati gbẹ́rù kọjá orí
Giwa ileẹkọ naa tun fi kun un pe rirọọkun ti wọn ni ki Ọmọwe Mbachaga o lọ rọọkun nile ni lati lee faaye silẹ fun agbekalẹ igbimọ ẹlẹni marun un kan ti wọn yan.
O ni giwa ile ẹkọ naa gbe igbimọ yii kalẹ lati wadii ẹsun ti wọn fi kan an lọna ati lee mọ otitọ gbogbo to rọ mọ.
"'Èmi ọmọ Ikorodu ọ̀ga, ọmọ aṣalẹ̀ jẹ́jẹ! Wo bí àwọn ọmọdé tó ""tuush"" yìí ṣe ń fi oríkì Yorùbá dábíra"
Bakan naa ni Giwa ileewe naa tun paṣẹ fun adari ẹka ẹkọ imọ nipa Ọrọ ẹda ati ihuwasi ọmọniyan nileẹkọ giga fasiti naa lati ṣe iwadii lori irufẹ ẹsun nina ọwọ aṣemaṣe ibalopọ si ọkan lara awọn akẹkọọ ni ileẹkọ naa.
O ni ki wọn tun ṣayẹwo irufẹ ẹsun bẹẹ gbogbo ti wọn tun fi kan olukọni miran ni ẹka ẹkọ naa.
Simple tricks to identify designer shoes: Ṣe ìwọ lè wọ bàtà #2 mílíọ̀nú
Gelede festival: Mọ̀ si i nípa ìtàn eégún Gelede àti pàtàkì eégún náà sí àwọn abiyamọ
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ọpọ awọn ọmọ ilẹ Yoruba aye ode oni lo maa n gbọ ti wọn maa n sọ pe eeyan n jo Gelede, ṣugbọn ọpọ ni ko mọ ohun ti Gelede tumọ si.
Ninu itan ati iṣedalẹ Yoruba, eegun kan lo n jẹ Gelede.
Bo tilẹ jẹ pe Gelede yii ko pin si Naijiria nikan, o tan de awọn orilẹ-ede mii bi Benin ati Togo ti ọpọ ọmọ Yoruba tẹdo si.
Gelede jẹ eegun, wọn a si ma lo eegun naa layajọ ọdun Gelede lati da awọn eeyan laraya, lati kọ wọn lẹkọọ, ati lati mu ki aṣa ilẹ Yoruba gbilẹ sii.
Wọn maa n fi Gelede ṣe ayẹsi awọn obinrin ati iya nilẹ Yoruba, lai yọ awọn oriṣa to jẹ obinri silẹ.
O tun maa n ṣapẹre irufẹ agbara ti awọn obinrin ni nilẹ Yoruba.
Teachers retirement age and years of service: Ìrírí àwọn àgbà olùkọ́ ṣì wúlò fún àwa ọ̀dọ́
Gẹgẹ bii awọn to mọ nipa itan aṣa ilẹ Yoruba ṣe sọ, orisun Gelede so mọ ilu Oyo, Ketu ati Ilobi.
Ninu itan naa, eegun Gelede bẹrẹ pẹlu ọba kan to ti n mura lati waja, ti awọn ọmọkunrin rẹ si n lakaka lati gori itẹ rẹ.
Ọkan lara awọn ọmọkunrin naa, nigba to ti ri pe o ṣeṣe ki oye naa bọ lọwọ oun, lo ba daa bi ọgbọn lati gbẹmi arakunrin rẹ.
Ṣugbọn nigba ti arakunrin rẹ naa gbọ pe ibatan oun  n gbimọ lati gbẹmi oun lo ba da bi ọgbọn to si ṣe iboju kan lati parada ki arakunrin rẹ naa ma baa da mọ.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Gẹgẹ bi itan ọhun ṣe sọ, iboju naa ni wọn n lo fun eegun Gelede laye ode oni.
Ẹsẹ ifa kan tun tan imọlẹ si orisun Gelede, iyẹn bo ṣe tan mọ yemoja.
Lasiko kan ti Yemoja ko tete ri ọmọ bi, o gba ile alawo lọ, alawo naa sọ fun pe ko gbe ẹbọ lọ si orita, ko si maa jo pẹlu ere kekere kan lori rẹ ati ẹgba ni ẹsẹ rẹ.
Adebayo Shittu: Èmi kò ṣẹ Abiola Ajimobi nígbà ayé ẹ, òun ló ṣe mi ṣùgbọ́n.....
Lẹyin to pari irubọ naa tan ni ọmọ ba de, o bi akọbi to jẹ ọkunrin to pe ni Efe, o si tun bi obinrin pẹlu, ti orukẹ rẹ n jẹ Gelede.
Ṣugbọn o ṣeni laanu pe, obinri ti Yemoja bi yii naa ko tete ri ọmọ bi lẹyin igbeyawo rẹ, loun naa ba tun gba ile alawo lọ, alawo naa si sọ fun pe ko gbe ẹbọ, irufẹ eyii ti iya rẹ kọkọ gbe ṣaaju.
Lẹyin to gbe ẹbọ naa tan, iyẹn pẹlu ere kekere kan lori rẹ ati ẹgba ni ẹsẹ rẹ to si n jo ni oun naa to bi ọmọ. Etutu ti Gelede ṣe yii lo bi ijo Gelede.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
"Ẹwẹ, onimọ nipa Gelede kan, to tun jẹ olori Gelede  niluu Eko, oloye Adio Erinfolami sọ fun awọn akọrọyin nigba ọdun Gelede lọdun 2017 pe, ẹmi to wa nidii gelede ni ""iya nla."""
O ṣalaye pe oriṣa naa jẹ onisuuru, o si maa n sọ awọn agan di abiyamọ.
"Gẹgẹ bo ṣe sọ ""Idi ree ti awọn obinrin ti ko ba bimọ ṣe maa n fori balẹ fun Gelede ki wọn le ri ọmọ gbe jo."
Magaret Jimoh: Èrè díẹ̀ ti tó mi níbi oúnjẹ ti mò ń tà- Maggie Rice
Ọkunri ati obinrin lo n ṣe awo Gelede bo tilẹ jẹ pe ọkunrin lo maa n wa labẹ ẹku, ṣugbọn awọn obinrin lo ṣaba maa n pọ ju ninu ẹgbẹ naa.
Awọn kan gbagbọ pe obinrin pọ ninu ẹgbẹ naa nitori ki wọn le tete ri ọmọ bi.
"Olori awo gelede ni wọn n pe ""Iyalaṣẹ,"" oun si lo maa n jẹ alarena laarin oriṣa naa ati awọn eeyan ilu."
Iyalase yii nikan lo ni aṣẹ lati wọ inu ile ti wọn ti n ṣe oro Gelede.
Tunde Bakare: Àjọjẹ kò dún bẹ́nìkan kò ní ló fa ìjà S Igboho,bẹ́ẹ̀ ìjọbati gbẹ́rù kọjá orí
Babalaṣẹ, to jẹ ekeji Iyalaṣẹ ni o maa n ṣakoso gbogbo nnkan atawọn oun elo ti wọn fi n gbe eegun Gelede ọhun.
Abọrẹ lo wa nidii gbogbo ohun to jọ mọ irubọ ati etutu ninu awo Gelede.
Elefe lo n mojuto iboju ti wọn fi n gbeegun Gelede ọhun.
Arugi ati Onilu naa wa lara awọn to wa ninu awo Gelede pẹlu, gbogbo awọn eeyan wọnyii lo ni ojusẹ ti wọn n ṣe.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ọdọdun ni wọn ma n ṣe ọdun Gelede nilẹ Yoruba, ṣugbvọn kii ṣe gbogbo awọn ipinlẹ ti wọn ti  sọ Yoruba ni wọn ti n ṣe ọdun naa.
Eredi ti wọn fi  ṣe ọdun naa ni ki ki ilu le tuba, ko si tuṣẹ, ki ojo rọ lasiko to yẹ ki awọn awọn agbgẹ le ri ti aje ṣe ki iyan ma baa ja laarin ilu.
Wọn maan n lo oriṣiriṣi awọn iboju, pẹlu orin ati ilu ni wọn si maa n ṣe ọdun naa.
Lara awọn ẹku ti wọn fi n gbe egun Gelede ni ti iya to n fun ọmọ lọmu, eyii to n tumọ si ibaṣepọ laarin iya ati ọmọ ikoko.
Ohun kan gboogi to ṣe pataki ninu odun naa ni lati ṣe ayẹsi awọn obinrin, paapaa julọ awọn abiyamọ.
Sex For Grades: UNILAG gba iṣẹ́ lọ́wọ́ Ọ̀jọ̀gbọ́n Boniface Igbeneghu àti Samuel Omoniyi
Oríṣun àwòrán, @jo_alabi
Fasiti ijọba apapọ to wa niluu Eko, UNILAG, ti jawe lọ gbele ẹ fun awọn olukọ meji, Ọjọgbọn Boniface Igbeneghu ati Ọjọgbọn Samuel Omoniyi.
UNILAG gbe igbesẹ naa lẹyin iwadii ti wọn ṣe lẹyin fiimu ti ileeṣẹ iroyin BBC gbe jade, iyẹn sex for grades, eyii to tu aṣiri bi awọn memeji ṣe gbiyanju lati ni ibalopọ pẹlu awọn akẹkọọ lọna ti ko ba ofin mu.
Ninu atẹjade kan ni fasiti ọhun ti kede pe awọn ti da awọn afurasi mejeji naa duro lẹnu iṣẹ.
Africa Eye: Olùkọ́ méjì ní fásitì Eko àti Ghana lùgbàdì ọ̀fíntótó BBC lórí ìwà ìbàjẹ́
"Atẹjade ọhun ni ""Awọn alaṣẹ fasiti yii ti pinnu lati gba iṣẹ lọwọ ọjọgbọn Boniface Igbeneghu to jẹ olukọ ni ẹka imọ ede ilẹ Yuroopu, ati Ọjọgbọn Samuel Omoniyi Oladipo to wa ni ẹka imọ eto ọrọ aje."""
A gbe igbesẹ yii lẹyin ti a ṣe agbeyẹwo iwadii ileeṣẹ iroyin BBC lori ẹsun ibalopọ laarin olukọ si akẹkọọ finifini, nitori naa, ti pinnu lati da awọn afurasi naa duro lẹnu iṣẹ, bẹrẹ lati ọjọ kọkanlelọgbọn, oṣu Karun un, ọdun 2021.
Oríṣun àwòrán, UNILAG
Gẹgẹ bi UNILAG ṣe sọ ninu atẹjade naa, ipinnu wọn lati da awọn eeyan naa duro lẹnu iṣẹ wa ni ibamu pẹlu abala kejidinlogun iwe ofin to gbe fasiti ọhun kalẹ lọdun 1978.
Tunde Bakare: Àjọjẹ kò dún bẹ́nìkan kò ní ló fa ìjà S Igboho,bẹ́ẹ̀ ìjọbati gbẹ́rù kọjá orí
Lẹyin naa ni wọn rọ awọn adari fasiti ọhun lati ṣe agbeyẹwo ofin to rọ mọ iwa ibalopọ lọna aitọ nile ẹkọ naa.
"Ọjọ keje, oṣu Kẹwaa, ọdun 2019 ni ẹka to n ṣe iwadii ijinlẹ nileeṣẹ BBC gbe fiimu ""Sex for grades"" jade lati tu aṣiiri awọn olukọ fasiti ni Najiria ati Ghana to n ba awọn akẹkọọ lopọ lọna aitọ ki wọn le fun wọn ni maaki."
Fiimu ọhun fa ori ayelujara ya, o si tun fun ọpọ awọn akẹkọrinrin ni igboya lati sọrọ sita lori awọn ohun ti oju wọn n ri lọwọ awọn olukọ ni fasiti.
Oba Gbolahan Timson Shomolu Bariga ní 'Restructuring'ti bọ́ aṣọ kò bá Omọyẹ mọ́!
Civil war Tweet: Àwọn ọmọ Nàìjíríà ké sí Twitter pé kó gbé ìdájọ́ Trump lé Ààrẹ Buhari, ṣùgbọ́n Twitter ní kò jọọ́
Oríṣun àwòrán, Twitter/Muhammadu Buhari
Ni Ọjọ Iṣẹgun ni awọn alaṣẹ ikanni ikansiraẹni abẹyẹfo Twitter ti kọkọ yọ ọkan lara awọn atẹranṣẹ ti aarẹ Buhari fi si oju opo rẹ lori ikanni naa, @Mbuhari.
"Aarẹ Buhari gbe atẹjade awọn ọrọ kan to sọ ninu eyi to ti fi ikils ranṣẹ sawọn to fẹ da orilẹede Naijiria ru ti wọn si n dana sun awọn ohun alumsni ajumsni orilẹede Naijiria pe, ""nnkan ariigbọdọ wi kan n bọ lọna fun wọn laipẹ..."""
Aarẹ sọ ọrọ naa lẹyin ijiroro rẹ pẹlu alaga ajọ eleto idibo ni Naijiria, INEC, Ọjọgbọn Mahmood Yakubu lori bawọn eeyan kan ṣe n dana sun awọn ileeṣẹ ati dukia ajọ INEC lawọn agbegbe kan lorilẹede Naijiria.
"Twitter yọ ọkan lara awọn ọrọ to sọ naa nibi to ti sọ pe ""pupọ awọn to n ṣiwa hu bayii kere jọjọ lati mọ ọwọja ifẹmiṣofo to waye lasiko ogun abẹlẹ Naijiria"""
Awa ti a wa loju ogun fun ọgbọn ọdun, ti a fara wina ogun abẹle naa yoo ṣe ohun to tọ siwọn gẹgẹ bi o ṣe tọ si wọn.
Adebayo Shittu: Èmi kò ṣẹ Abiola Ajimobi nígbà ayé ẹ, òun ló ṣe mi ṣùgbọ́n.....
Ileeṣẹ Twitter ni awọn ko lee fofin de aarẹ Buhari pe eegun rẹ ko gbọdọ suyọ lori ikanni naa nitori ni ibamu pẹlu awọn ofin to de lilo ikanni ikansiraẹni naa, Aarẹ Buhari ṣi lanfani ikilọ diẹ sii ki wọn to gbe igi lori ojuopo rẹ
wọn ni ijiya to tọ fun ohun to ṣe bayii naa ni ki wọn yọ abala atẹjade rẹ ti ko ba ofin ikanni naa mu.
Sugbọn Twitter ṣalaye pe bi aarẹ ba n tẹsiwaju lati maa tapa si awọ̀n ofin rẹ awọn yoo kuku gbẹsẹle oju opo rẹ ni o.
Ọpọ ọmọ Naijiria lo ti gbe pẹrẹgi kana pẹlu aarẹ lori atẹjade to fi sita naa ninu eyi ti wọn ti tọka si bo ṣe mẹnuba ogun abẹle ninu atẹjade naa, ninu eyi ti ẹgbẹlẹgbẹ eeyan ti ku gẹgẹ bi pe aarẹ n gbero ati tẹ ẹtọ ọmọniyan mọlẹ.
Oríṣun àwòrán, Twitter
Awọn kan ke si Twitter lati gbegile oju opo Aarẹ Buhari.
"Wọn ni atẹjade ti aarẹ fi sita naa"" fi erongba ati ṣe awọn kan ni ijamba"" han eyi ti wọn ni o tako ofin elo Twitter ti ileeṣẹ ikansiraẹni naa fi silẹ."
Oríṣun àwòrán, Twitter/screenshot
"Lara awọn to ti bs si gbangba lori ọrọ naa ni gomina tẹlẹ ni ipinlẹ Ekiti, Ayọdele Fayoṣe to ni igbesẹ ti Twitter gbe naa fihan pe ""aarẹ Buhari ko lagbara kan to le lo lori ikanni ayelujara"""
Oríṣun àwòrán, Twitter screenshot
"O bere ninu atẹjade tirẹ nibẹ pe, ""igba wo gan ni aarẹ Buhari yoo lo agbara rẹ gẹgẹ bii apaṣẹ waa lati fi oju Twitter ri mabo"" fun yiyọ atẹjade rẹ kuro lori ikanni wọn."
Oríṣun àwòrán, Twitter/screenshot
Awọn ero awọn ọmọ Naijiria miran ree:
Oríṣun àwòrán, Twitter/screenshot
Oríṣun àwòrán, Twitter/screenshot
Security in Nigeria: Alaafin Oyo sọ̀rọ̀ lórí ìṣèjọba tó leè yọ Nàìjíríà kúrò nínú ọ̀fìn tó wà
Oríṣun àwòrán, Alaafin Oba Adeyemi III
Kabiyesi Alaafin ti ilu Ọyọ, Ikubaba yeye, Ọba Lamidi Adeyẹmi kẹta ti sọrọ sita pe ibi ti ọrọ ẹlẹyamẹya ati ẹlẹsinmẹsin de duro bayii lorilẹede Naijiria, ko fẹẹ si iru rẹ ri ninu itan orilẹede Naijiria.
Alaafin Adeyẹmi sọ eyi di mimọ ninu atẹjade kan eyi to fi ranṣẹ sawọn akọroyin l'Ọjọru.
Ikubaba yeye niibi ọrọ gbe de duro lorilẹede Naijiria bayii ti di ayefẹlẹ tobẹ gẹẹ ti  ko si ẹni to lee ni igbagbs ms ninu awọn ileeṣẹ agbofinro gbogbo titi kan ileeṣẹ aṣọbode laiṣegbe.
Amọṣa Kabiyesi Alaafin Ọyọ wa pe fun agbekalẹ ijọba ipin o jupin ti oyinbo n pe ni True Federalism.
O ni irufẹ ijọba bẹẹ yoo fun awọn ipinlẹ lagbara sii.
Adebayo Shittu: Èmi kò ṣẹ Abiola Ajimobi nígbà ayé ẹ, òun ló ṣe mi ṣùgbọ́n.....
Bakan naa lo pe fun eto ibi ko ju ibi lori yiyan awọn eeyan sipo apapọ titi kan awọn ileeṣẹ abo gbogbo.
Kabiyesi laafin ni oun ko lee kawọgbera ti orilẹede Naijiria da wo lulẹ.
Adebayo Murital David: Gbogbo iṣẹ́ tó ń múni là láyé wá láti ọpọlọ ni kìí ṣe agbára
Alaafin Adeyẹmi III ṣalaye pe  eto iṣejọba ibi ko ju ibi Federalism ni ipilẹ ti wọn gbe orilẹede Naijiria .
O ni nibi ipade apero fun iwe ofin lọdun 1959, aba ti Oloye Ọbafẹmi Awolọwọ da, leyin ti olori ẹkun ariwa nigba naa, Sadauna Ahmadu Bello fọwọ si ni gbigbe awọn ẹka bii eto ọgbin, ijọba ibilẹ ati oye jijẹ gbọdọ sọwọ awọn ijọba ẹkun gbogbo leyin to mu ki awọn idagbasoke manigbagbe lee waye nigba naa.
Akure school bus hijacked: Mí kò dá àwọn agbébọn náà mọ̀ ṣùgbọ́n wọn kò bojú- Omolayo Ojo
Ondo school bus hijack: Mí kò dá àwọn agbébọn náà mọ̀ ṣùgbọ́n wọn kò bojú- Omolayo Ojo
Wọn gbe ibọn sori mi pe ki n tẹle wọn ni- Omolayo Ojo to jẹ oluranlọwọ akékọọ ninu bọọsi.
Adari ile ẹkọ Chimola Schools ni wọn ti da gbogbo ọmọ pada ati pe ko si ẹni to sọnu mọ nile iwe naa.
Omolayo ti wọn gbebọn si lori naa ba BBC sọrọ lori bi gbogbo ẹ ṣe ṣẹlẹ.
Bakan na ni kọmiṣọnna Bolaji Salami to n tukọ agbofinro ipinlẹ Ondo naa ba BBC Yoruba sọrọ lori ibi ti igbesẹ wiwa bọọsi ati awọn oniṣẹ ibi naa ri de duro.
A ti rí dírẹ́bà àti olùrànlọ́wọ́ àwọn akẹ́kọ̀ọ́ nínú bọ́ọ̀sì- Adarí ilé ẹ̀kọ́ Chimola Schools, Akure
Irú èyí kò ṣẹlẹ̀ rí nílé ẹ̀kọ́ wa, ṣùgbọ́n a dúpẹ́ pé a rí gbogbo akẹ́kọ̀ọ́- Bolatito Akindemowa
Arabinrin Bolatito Akindemowa to jẹ oludari ile ẹkọ Chimola schools ni Oba Ile Estate ni ilu Akure nibi ti awọn agbebọn ti sọṣẹ ni aarọ yii ti sọrọ sii lori iṣẹlẹ naa.
O salaye pe lasiko ti direba bọọsi to n ṣa awon ọmọ kaakiri  ile wọn n lọ ni nkan bii aago mẹfa abọ owuro oni lo ṣẹlẹ.
Bi a ṣe n sọrọ yii, wọn ti ri direba to wa ọkọ naa ati Omolayo Ojo to jẹ oluranlọwọ awọn akẹkọọ ninu bọọsi naa pada.
Omolayọ Ojo salaye fun BBC Yoruba pe, awọn agbebọn naa gbe oun lọ sinu igbo ni.
O ni: Wọn ja oun sinu igbo naa, wọn si wa ọkọ bọọsi awọn akẹkọọ naa lọ.
Omolayo ni oun rin pada wa si oju titi ti oun si ri awọn alaanu fun pun lowo ọkọ wa si ile ẹkọ pada.
Adari ile ẹkọ naa ni wọn ti fi ọrọ naa to ọlọpaa leti ati pe bọọsi nikan lo ku ti won n wa bayii.
O ni ko si akẹkọọ kanakan to sọnu.
Àwọn ajínigbé ṣọṣẹ́ ní Akure wọ́n kọlu bọ́ọ̀sì iléẹ̀kọ́ kan lọ
Awọn agbebọn kan ti kọlu ọkọ bọọsi ileewe kan lagbegbe Ọba ile Estate  ni ilu Akurẹ.
Gẹgẹ bi iroyin ṣe sọ, awọn agbebọn naa ji eeyan kan gbe ninu awọn oṣiṣẹ to wa pẹlu awọn akẹkọọ naa.
Oríṣun àwòrán, other
Iṣẹlẹ yii ṣẹlẹ ni nnkan bi agogo meje ku iṣẹju diẹ lowurọ Ọjọbọ.
Iroyin fiyeni pe awọn ajinigbe naa ti wọn to mẹjọ niye wa lori alupupu ọkada nigba ti wọn yi bọọsi naa po ti wọn si wọ dẹrẹba ọkọ naa bs silẹ.
Awọn ajinigbe naa wa bọọsi naa ti nọmba idanimọ rẹ jẹ Lagos LSD 853 FJ lọ pẹlu skan lara awọn oṣiṣẹ naa.
Adebayo Shittu: Èmi kò ṣẹ Abiola Ajimobi nígbà ayé ẹ, òun ló ṣe mi ṣùgbọ́n.....
Obasanjo: Obasanjo ní bí àwọn adarí ṣe ń ṣàkóso wa ń pa ìràwọ̀ ọ̀pọ̀ ọmọ Nàìjíríà ọlọpọlọ pípe tó ń dá bírà lágbáyé
Oríṣun àwòrán, other
Aarẹ orilẹede Naijiria nigbakanri, Oloye Oluṣẹgun Ọbasanjọ ti pariwo sita pe ilẹ to n ṣan fun ibanujẹ ati ipayinkeke ni Naijiria bayii dipo wara ati fun oyin.
Oloye Ọbasanjọ ṣalaye wi pe lootọ wara ati oyin ni Eleduwa fi ṣe anfani fun orilẹ-ede yii ṣugbọn awọn aṣiwaju ati adari to n ni ko jẹ ki ileri Eleduwa o ṣẹ mọ orilẹede Naijiria lara.
Oloye Ọbasanjọ woye ọrs yii nibi ayẹyẹ ifilọlẹ iwe kan  ti wọn kọ nipa rẹ eleyi to waye ni gbọngan nla Oluṣẹgun Ọbasanjọ Presidential Library nilu Abẹokuta ipinlẹ Ogun.
O ni gbogbo awọn alẹnulọrọ ninu idagbasoke orilẹ-ede Naijiria ṣi lanfani ati yi kadara buruku yii pada o nitori ko si ẹya, ẹkun tabi ipinlẹ ti eeyan lee de lorilẹede Naijiria ti ko ni ri awọn ọlọpọlọ pipe.
O fi kun un pe pẹlu bi nnkan ṣe ri lorilẹ-ede Naijiria bayii, ko si bi awọn ọmọ Naijiria to jẹ ọlọpọlọ pipe ṣe lee ṣe aṣeyọri nile.
Tunde Bakare: Àjọjẹ kò dún bẹ́nìkan kò ní ló fa ìjà S Igboho,bẹ́ẹ̀ ìjọbati gbẹ́rù kọjá orí
Amọṣa o ni gbogbo agbaye lawọn ọmọ Naijiria ti n ṣe daradara.
Obasanji ni awọn  bii Akin Adeshina to n dari Banki idagbasoke Afirika, ADB; Mohammed Barkindo to n dari ajọ awọn orilẹ-ede elepo rọbi lagbaye, OPEC;
O tun darukọ: Benedict Oramah to n dari banki fun idagbasoke karakata soke okun, Afrexim Bank, Ngozi Okonjo-Iweala to n dari Ajọ karakata lagbaye, WTO ati Amina Mohammed to jẹ igbakeji akọwe agba ajọ iṣọkan agbaye, UN.
Adebayo Shittu: Èmi kò ṣẹ Abiola Ajimobi nígbà ayé ẹ, òun ló ṣe mi ṣùgbọ́n.....
Aarẹ orilẹede tẹlẹ lorilẹede naa ni o yẹ ki awọn to n tukọ orilẹ-ede Naijiria beere idi ti awọn eeyan wọnyi ati omilẹgbẹ awọn ọmọ orilẹ-ede Naijiria miran fi n da bi ẹdun, rọ bi owe lagbaye ṣugbọn ti orilẹ-ede Naijiria fi da bo ṣe da.
O ni o daju pe bi awọn eeyan wọnyi ba wa lorilẹ-ede Naijiria ni, irawọ wọn yoo ti wọmi, iyẹn bi a ba tilẹ le gburo wọn rara.
Sunday Igboho: Bí kò bá sí ìbò láti mọ èrò Yorùbá tó fẹ́ yapa, kò ní sí ìbò òṣèlú ní 2023
Ọjọ Satide ni ilana ọmọ Oodua gbe iwọde ipolongo fun idasilẹ orilẹ-ede Yoruba Nation lọ si ilu Ado-Ekiti, nipinlẹ Ekiti.
Nibi iwọde naa ni Igboho ti sọ pe dandan ni ki idasilẹ orilẹede Yoruba Nation waye, nitori pe aidọgba wa ninu bi ijọba ṣe n pin awọn ọrọ Naijiria, ti wọn si tun ti fi ọwọ rọ ẹya Yoruba sẹyin.
"Igboho to sọrọ ni ede Yoruba sọ pe ""o to gẹ. A gbọdọ duro fun ominira wa, nitori pe a ti jiya to o. Ọmọ Yoruba ni wa, a o si gbọdọ jẹ ẹru nilẹ wa."""
O ni gbogbo nkan to ba gba ni awọn yoo ṣe lati gba Yoruba kuro ni abẹ isinru Fulani, ti yoo si ya kuro lara Naijiria ti yoo ba fi di ipari oṣu Kejila, ọdun 2021.
Sunday Igboho fi ẹsun kan pe gbogbo alumọni ni Naijiria ni, amọ awọn Fulani lo n ṣakoso wọn, ti wọn si tun jẹ olori ileeṣẹ ijọba gbogbo.
Blessing Olajide: Ẹ̀bí akẹ́kọ̀ọ́jáde fásitì Ilorin tí wọn pa ṣàlàyé ikú rẹ̀
O ni gbogbo awọn nkan yii, to fi mọ bi ọpọlọpọ ọdọ to ti kawe tan ko fi ri iṣẹ ṣe, lo mu ki awọn o ma a polongo pe o ti to gẹ ẹ.
Ati pe ti ijọba ko ba fi ṣe idibo lati mọ eero araalu nipa iru Naijiria ti wọn fẹ, ẹya Yoruba ko ni i dibo gbogboogbo lọdun 2023.
O fikun pe ilẹ Yoruba nilo ijọba tiẹ.
"O sọ pe nkan to kan lati ṣe bayii ni pe ""awọn yoo wọ inu igbo lọ lati le awọn darandaran Fulani yii kuro""."
Bakan naa lo sọ nibi iwọde naa, lasiko ti o sabẹwo si aafin Èwí Ado-Ekiti, pe awọn n bọ ni Eko nitori ilẹ baba awọn ni.
Ni nkan bi aago marun irọlẹ ni Sunday Igboho ti ọpọlọpọ eniyan ti n reti nibi iwọde naa de sibẹ pẹlu ọpọ eniyan to n wọ tẹle ni ẹyin.
Ṣaaju ki iwọde naa to bẹrẹ ni awọn eeyan ti pe babi si gbagede Fajuyi Park.
Bakan naa ni wọn ṣe abẹwo si aafin Ewi Ado.
Wamuwamu si ni awọn oṣiṣẹ alaabo Amẹtẹkun, ọlọpaa, FRSC, ati awọ̀n mii duro nibi ti iwọde naa ti fẹ ẹ waye.
Awọn oluwọde ọmọ ilẹ Yoruba labẹ asia to n pe fun idasilẹ Oduduwa Republic ti gunlẹ si ipinlẹ Ekiti fun iwọde.
Eruku ti n sọ lala ni ilu Ado Ekiti, ni igbaradi fun iwọde ipolongo idasilẹ Yoruba Nation.
Igba akọkọ re ti wọn yoo lọ si ipinlẹ naa ṣugbọn wọn ti n kaakiri awọn ipinlẹ mi ṣaaju asiko yi.
Ni nkan bi ọṣẹ meji sẹyin ni irufẹ iwọde bẹẹ waye ni ilu Akure tii ṣe olu ilu ipinlẹ Ondo.
Ko pẹ si igba ti iwọde yi waye ni Gomina Rotimi Akeredolu figbe sita pe ki awọn eeyan sinmi ahesọ pe oun faramọ idasilẹ Oduduwa Nation.
Tunde Bakare: Àjọjẹ kò dún bẹ́nìkan kò ní ló fa ìjà S Igboho,bẹ́ẹ̀ ìjọbati gbẹ́rù kọjá orí
O fọ esi yi ni idahun si ọrọ kan to gbode pe Sunday Adeyemo,Igboho, ni Akeredolu wa lẹyin awọn oluwọde Oduduwa Nation.
Adebayo Shittu: Èmi kò ṣẹ Abiola Ajimobi nígbà ayé ẹ, òun ló ṣe mi ṣùgbọ́n.....
A ko ti mọ nkan ti yoo ṣẹlẹ loni ni ipinlẹ Ekiti ṣugbọn ko ti si ijọba ipinlẹ Yoruba kankan to kọdi iwọde awọn oluwọde Ilana Ọmọ Odua.
Oríṣun àwòrán, Twitter/Kayode Fayemi
Kayode Fayemi to jẹ Gomina ipinlẹ Ekiti  ti wọn n gbe iwọde bọ wa ba ni alaga ẹgbẹ awọn Gomina ni Naijiria.
Lọpọ igba lo ti fi ero ọkan rẹ nipa idasilẹ Oodua Nation han wi pe awọn ti nkan ko rọgbọ fun lo n pe fun ki wọn tu Naijiria ka.
Magaret Jimoh: Èrè díẹ̀ ti tó mi níbi oúnjẹ ti mò ń tà- Maggie Rice
Oduduwa Republic: Abeokuta, Ibadan ,Akure, Osogbo àti àwọn ibòmíràn tí ìwọ́de tí wáyé kọjá
Oríṣun àwòrán, Facebook/Ilana Omo Odua
Ipinlẹ Ekiti ni iwọde awọn to n ja fun idasilẹ orileede Yoruba yoo sodo si lọjọ Abamẹta yi.
Saaju asiko yi, wọn ti se iwọde lawọn ipinlẹ ilẹ kaarọ o jiire miran ni Naijiria.
Lasiko awọn iwọde wọn, niṣe ni awọn alatilẹyin idasilẹ Odua Nation maa n kọ orin ti wọn a si tun gbe asia Yoruba Nation kiri.
Ọrọ iwuri naa a si maa waye paapa lati ẹnu ọkan lara awọn to lewaju ipe yi tii ṣe Sunday Adeyemo ti awọn eeyan mọ si Sunday  Igboho.
Die ree lara awọn iwọde to waye kọja sẹyin ati oun to ṣẹlẹ nibẹ.
Teachers retirement age and years of service: Ìrírí àwọn àgbà olùkọ́ ṣì wúlò fún àwa ọ̀dọ́
Iwọde ipinlẹ Oyo,ero pọ biba niwaju Mapo Hall
Ibadan ni o gbalejo iwọde yi lọjọ Kẹtadinlogun, oṣu Kẹrin ọdun yi.
Bo tilẹ jẹ wipe awọn ọmọ ilana Odua ti kọkọ bẹrẹ iwọde ṣaaju ni ilu Ibarapa eyi to ṣokunfa bi wọn se le Seriki Fulani Igangan nilu.
Nibi iwọde Ibadan ti wọn fi pe fun idasilẹ Oodua Nation, niṣe lawọn ọlọpaa pọ biba ni Ori oke Mapo ṣugbọn ko si ikọlu pẹlu awọn oluwọde.
Oríṣun àwòrán, Facebook/Ilana Omo Odua
Abeokuta: Ilana Ọmọ Odua ni ọlọpaa 200 le dena  de awọn nibi iwọde
Ẹgbẹ to n ja fun ominira ilẹ Yoruba, Ilana Ọmọ Oodua sọ pe ileeṣẹ ọlọpaa ipinlẹ Ogun fi sikun ofin mu eeyan marundinlọgbọn ti wọn  kopa ninu  iwọde yi  niluu Abeokuta.
Tunde Bakare: Àjọjẹ kò dún bẹ́nìkan kò ní ló fa ìjà S Igboho,bẹ́ẹ̀ ìjọbati gbẹ́rù kọjá orí
Ninu atẹjade kan ti akọwe ẹgbẹ naa, Maxwell Adeleye buwọlu, eyii to fi ṣọwọ si BBC lo ti kede bẹẹ.
O ni nnkan bii igba ọlọpaa lo yii awọn eeyan naa ka ki wọn to fi ofin mu wọn l'Abeokuta.
Oríṣun àwòrán, Facebook/Ilana Omo Odua
Iroyin ni iwaju aafin Alake ti ilu Ẹgba ni awọn ọlọpaa naa ti ko awọn oluwọde ọhun sinu ọkọ Black Mariac ti wọn gbe wa.
Ṣaaju ni ileeṣẹ ọlọpaa ipinlẹ Ogun ti kọkọ ki awọn oluwọde naa nilọ pe wọn ko gbọdọ gunle iwọde naa, bi bẹẹ kọ, awọn eeyan naa yoo foju wina ofin.
Ṣugbọn awọn ọmọ ẹgbẹ naa fesi pada pe ti ọlọpaa ni wọn n wi nitori awọn yoo tẹsiwaju pẹlu iwọde naa.
Magaret Jimoh: Èrè díẹ̀ ti tó mi níbi oúnjẹ ti mò ń tà- Maggie Rice
Osogbo,IOO sọ pe ọwọ awọn tẹ ọtẹlẹmuyẹ DSS
Awọn igun ọmọ Yoruba to n beere fun idasilẹ orilẹede Yoruba, Yoruba nation pade ni ilu Oṣogbo tii ṣe olu ilu Ipinlẹ Ọṣun loni.
Iwọde wọn ọhun to waye fun ọpọlọpọ wakati da lilọ bibọ ọkọ duro ni ilu Osogbo.
Gbogbo bi wọn ti n wọde ni wọn n kọrin ijagbara ati ẹhonu lori ipenija ti wọn woye pe o nkoju iran ọmọ Yoruba ni orilẹede Naijiria.
Lati ipinlẹ Kogi, Kwara, Eko, Ọyọ, Ogun, Ondo, Ekiti ati Ọṣun lawọn oluwọde naa ti wa.
Nibi iwọde itagbangba yi awọn iṣẹlẹ manigbagbe kan waye.
Akọkọ ni pe Sunday Igboho sọ pe oun atawọn ẹlẹgbẹ oun ko ni gba eto idibo laaye mọ ni ilẹ Yoruba, titi di igba ti ẹkun naa ba gba ominira rẹ.
Ẹlẹẹkeji ni pe fidio kan tun fara han lori ayelujara lẹyin iwọde naa, eyi to ṣafihan bi awọn ọmọlẹyin Sunday Igboho ṣe mu eeyan kan ti wọn fura si pe oṣiṣẹ ileeṣẹ ọtẹlẹmuyẹ DSS ni.
Ileeṣẹ ọtẹlẹmuye DSS ko fesi si fọnran yi
Adebayo Shittu: Èmi kò ṣẹ Abiola Ajimobi nígbà ayé ẹ, òun ló ṣe mi ṣùgbọ́n.....
Ni ikorita Isikan nilu Akure, ni iwọde naa ti gberasọ, ti awọn oluwọde naa si lọ yika ilu naa lati la awọn araalu lọyẹ nipa pataki idasilẹ orilede Oduduwa.
Akọroyin BBC Yoruba to wa nilu Akure jabọ pe ni irọwọrọsẹ ni iwọde naa n lọ, lai si rogbodiyan kankan.
Oríṣun àwòrán, facebook/oluwarotimi akeredolu aketi
Aṣyinwa aṣẹyinbọ iwọde naa ti Sunday Igboho bawọn kopa, Gomina Rotimi Akeredolu sọ pe oun ko faramọ idasilẹ Oduduwa Nation.
Ọrọ yi to sọ ni idahun si iroyin to gbode pe Sunday Igboho ni Akeredolu wa lẹyin awọn ajijagbara jẹ koko pataki ta ri fa yọ lẹyin iwọde yi.
Akeredolu sọ pe lootọ lohun faaye gba awọn oluwọde ṣugbọn yatọ si ilẹ Yoruba to wa ni Naijiria, ohun ko faramọ idasilẹ orileede Yoruba miran
Olùkọ́ Kano sọ abiyamọ sí ìbànújẹ́, Ó lu akẹ́kọ̀ọ́ ọmọ ọdún mẹ́sàn án pa
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Aworan yi la fi ṣe akawe iya to padanu awọn ọmọ rẹ
Awọn alaṣẹ ni ijọba ibilẹ Fagge ni Kano sọ pe awọn ti ti ileẹ̀kọ́ kan pa lẹyin iroyin to gbode pe olukọ kan lu akẹkọọ kan pa nibẹ.
Awọn obi ọmọ ọdun mẹsan naa Surajo Surajo fẹsun kan olukọ rẹ ni ileẹ̀kọ́ El-Salam Success Academy to wa ni Kurna pe o lu ọmọ wọn pa.
Ileeṣẹ ọlọpaa Kano sọ pe awọn ti mu afurasi tọrọ naa kan.
Hajia Salma to jẹ iya ọmọ ọdun mẹsan an naa sọ fun BBC pe ko si nkankan to ṣe ọmọ oun nigba to lọ sileẹ̀kọ́ lọjọ Iṣẹgun ṣaadede ni wọn kan sọ pe o rẹ ti oun si gbe lọ si ile iwosan.
''Nigba ti mo gbe lọ si ile iwosan awọn dokita ko kọkọ fọwọ kan ti wọn si beere pe ki lo ṣe ọmọdekunrin yi.
Tunde Bakare: Àjọjẹ kò dún bẹ́nìkan kò ní ló fa ìjà S Igboho,bẹ́ẹ̀ ìjọbati gbẹ́rù kọjá orí
Mo sọ fun wọn pe Olukọ rẹ lo sọ pe o n ke irora lo jẹ ki n wa gbe e wa si ọdọ yin.''
''Dokita wa da mi lohun pe awọn ko le ṣe nkankan mọ nitori nise lo n pọ ẹjẹ lẹnu ati imu''
Magaret Jimoh: Èrè díẹ̀ ti tó mi níbi oúnjẹ ti mò ń tà- Maggie Rice
Hajia Salma pada si ile ẹkọ naa nibi ti Olukọ ọhun ti sọ pe oun ko ni le tẹle lọ si ile iwosan.
O ṣalaye pe niṣe lawọn Oluko meji to ku parọwa si pe ko tẹle wi pe ko si nkan ti yoo ṣẹlẹ si.
Nigba ti wọn yoo fi pada de ile iwosan oku ọmọ naa ni wọn ba.
Tunde Bakare: Àjọjẹ kò dún bẹ́nìkan kò ní ló fa ìjà S Igboho,bẹ́ẹ̀ ìjọbati gbẹ́rù kọjá orí
Lẹyin ti o gbo ohun to ṣẹlẹ.Alhaji Muhammad Abdullahi,  to jẹ alaga ijọba ibilẹ Fagge paṣẹ ki wọn ti ileẹ̀kọ́ naa pa lati le jẹ ki iwadii waye.
''Mo ni ki wọn ti ileẹ̀kọ́ naa pa pẹlu bi igboro ti ṣe fẹ daru lori iṣẹlẹ yi tawọn kan si fẹ dana sun ileẹ̀kọ́ naa.
Emi ati awọn agbagba ni ki awọn ọlọpaa lọ sun ileẹ̀kọ́ naa mọjumọ ki awọn eeyan ma ṣe le dana sun''.
Teachers retirement age and years of service: Ìrírí àwọn àgbà olùkọ́ ṣì wúlò fún àwa ọ̀dọ́
Arakunrin Sunday Daniles to jẹ ouldasilẹ ileẹ̀kọ́ naa sọ pe iwadii ti ohun ṣe fihan pe awọn ko mọ nkan to ṣe iku pa ọmọ naa.
O ni awọn n duro de abajade iwadii ọlọpaa lori iṣẹlẹ ọhun.
Farmers-Herders Crisis: Ohun ìbànújẹ́ ló sẹlẹ̀ ní Igangan, ìjọba, ẹ dìde bí o ti yẹ- Oba Lamidi Adeyemi
Oríṣun àwòrán, Others
Oba Adeyemi
Alaafin ti Oyo, Oba Lamidi Adeyemi ti banujẹ́ gidi lori isele isekupani to waye ni ilu Igangan ni ijoba ibile Ariwa Ibarapa ni ipinle Oyo to wa ni guusu Iwo oorun Naijiria.
Laaro ọjọ Aiku ni iroyin ibanuje naa gba igboro kan pe awọn agbebọn kọlu Igangan nibi ti wọn ti sun ọpọlọpọ ile nina ti wọn si pa awọn mii.
Koda, wọn sun aafin Oba Ashi ti ilu Igangan.
Bode Durojaye to jẹ adari ẹka eto ifitonileti fun Aafin Oba Lamidi Adeyemi lo fi atẹjade naa sita.
O ni Kabiesi ni asiko ti to ki ijọba koowa gbajumọ ọna abayọ si i soro eto aaabo yii lẹyẹ o sọka.
Bakan naa lo banuje lori ipo ti ọrọ ẹlẹyamẹya de duro ni Naijiria ni eyi to yẹ ko jẹ agbara orilẹ-ede yii sugbọn ti ko ri bẹẹ.
Snail Slim Soap: Wo ọ̀pọ̀ àǹfààní tó wà nínú lílo ọ̀ṣẹ tí wọn fi omi ìgbín ṣe láti fọ ojú?
Aalfin Oyo gba awọn ẹsọ alaabo lati samulo awon ara ilu ati ọpọlọ pipe awọn iolugbe ileto kọọkan.
Oba Lamidi Adeyemi ni pe laisi eto aabo to mọyan lori, ko le si idagbasoke kankan paapaa ninu eto ọrọ aje.
Kabiesi ni ki ijọba ni ẹka ksskan gbe igbesẹ to kan lati daabo bo awọn ara ilu to n se ijọba le lori.
Tunde Gbadamosi: Kìí ṣe Tinubu ní ipò ààrẹ̀ tọ́ sí, ìgbà wo ní ìtan ajá ń kan lèmọ́mù?
Iroyin to n tẹ wa lọwọ ni agbẹ miran tun ti fara gba ọgbẹ ọta ibọn nilu Idiyan, lẹba ilu Igangan, lagbegbe Ibarapa nipinlẹ Oyo, lati ọwọ afurasi Darandaran.
Gẹgẹ bi iwe iroyin Punch ti salaye, ọkunrin kan tii se ara orilẹede Benin, Kaptain Kaston ni afurasi darandaran yinbọn mọ lẹba oko rẹ.
Ọkunrin agbẹ naa, tii se ẹni ọdun mejidinlọgbọn, ti wọn yinbọn mọ ni ejika, ni wọn tun sa ni oniruuru ọgbẹ ni gbogbo ara.
Ariwo Kaston to n pa pẹlu irora, ni awọn ero ọna to n kọja lọ gbọ, ti wọn si sare gbe digba digba rele iwosan.
Nigba to n fidi isẹlẹ naa mulẹ, oludasilẹ eto idagbasoke fun ilu Igangan, Oladiran Oladokun salaye pe ọjọ Ẹti ni isẹlẹ naa waye.
Adebayo Shittu: Èmi kò ṣẹ Abiola Ajimobi nígbà ayé ẹ, òun ló ṣe mi ṣùgbọ́n.....
Awọn afurasi ọdaran mẹta lo kọlu oloogbe naa lẹba oko rẹ ladugbo Abojukopo nilu Idiyan, ti wọn si sọ fun pe ko gbọdọ kede pe Fulani lo kọlu oun.
Bakan naa ni aburo ọkunrin naa, Pascal Kaston naa ni wọn ti fi isẹlẹ naa to awọn ọlọpaa leti, ti wọn si ti wa sibi isẹlẹ naa lọjọ Ẹti.
"Wọn yinbọn mọ, ti wọn si tun fi ada ṣa. Wọn ko ge ọwọ rẹ amọ ọpọ ọgbẹ wa ni ọwọ rẹ.
O laju nile iwosan laarọ oni, ti ara rẹ si ti n ya diẹdiẹ.
Tunde Bakare: Àjọjẹ kò dún bẹ́nìkan kò ní ló fa ìjà S Igboho,bẹ́ẹ̀ ìjọbati gbẹ́rù kọjá orí
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Awọn eeyan ijọba ibilẹ Dambatta nipinlẹ Kano ti fidirẹmulẹ pe awọn afurasi agbebọn kọlu wọn , ti wọn si gbe ọkunrin oniṣowo kan lọ.
Awọn ti iṣẹlẹ naa ṣoju wọn sọ pe ni nkan bi aago mẹwa aabọ owurọ ni Ọjọbọ ni ilu Kore, to wa ni ijọba ibilẹ naa, ni awọn agbebọn naa wọle, ti wọn si n yinbọn.
Wọn ni ibọn naa ba obinrin kan ati ọmọ rẹ.
Bakan naa ni wọn sọ pe eeyan mẹfa ni wọn tu kọlu .
Botilẹ jẹ pe ko si ẹni to ku, iroyin sọ pe ibọn ba ọmọ kekere kan ni eti.
Awọn olugbe ilu naa sọ pe ko si oṣiṣẹ alaabo kankan to wa ni arọwọto lati doola wọn lasiko ti awọn agbebọn n ṣiṣẹ ọwọ wọn.
Wọn sọ pe ọpọ eeyan ni ẹru ba, ti awọn kan si sa wọ inu igbo lọ.
Teachers retirement age and years of service: Ìrírí àwọn àgbà olùkọ́ ṣì wúlò fún àwa ọ̀dọ́
Alaga ijọba ibilẹ Dambatta, Muhammad Abdullahi Kore sọ pe lootọ ni iṣẹlẹ naa waye, to si sọ pe Emmanuel ni orukọ ẹni ti wọn ji gbe ọhun.
O ni oniṣowo ni ọkunrin naa ni ilu Kore.
Ninu iroyin mii, inu ibanujẹ ati ọfọ ni awọn eniyan ilu Magami ati Mayabaya ni ijọba ibilẹ Gusau nipinlẹ Zamfara wa, lẹyin ti awọn agbebọn kọlu wọn.
Ọjọru ni wọn sọ pe awọn agbebọn naa pa eeyan mẹtadinlogun, ati awọn agbẹ, ko to di pe wọn ko awọn ẹran ọsin wọn lọ.
Magaret Jimoh: Èrè díẹ̀ ti tó mi níbi oúnjẹ ti mò ń tà- Maggie Rice
Ninu oko ni awọn agbẹ naa wa nibi ti wọn ti n ṣiṣẹ, ki ikọlu naa to waye.
Ẹnikan ti ori ko yọ ninu ikọlu naa, amọ ti ko fẹ ki a darukọ rẹ sọ pe awọn ti sin oku eeyan mẹsan-an lara wọn.
Gbogbo igbiyanju BBC lati ba agbẹnusọ ọlọpaa ni ipinlẹ Zamfara sọrọ lo ja si pabo.
Seyi Makinde: Gbígbégilé ojú òpó Twitter yóò ba ọrọ̀ ajé Naijiria jẹ́ ní àgbáyé
Oríṣun àwòrán, Twitter/Seyi Makinde
Gomina ipinlẹ Ọyọ, Seyi Makinde ti bu ẹnu atẹ lu bi ijọba apapọ ṣe ti oju opo ikansiraẹni Twitter kaakiri orilẹede Naijiria.
Ninu atẹjade ti Gomina Makinde fi lede, O ni o pọn dandan lati fi ero rẹ lede lori igbesẹ ijọba Naijiria pẹlu bi wọn ṣe ti oju opo Twitter pa ni Naijiria.
Makinde ni gẹgẹ bi adari, ko yẹ ki ijọba apapọ hu iwa bẹẹ nitori ọrọ ti awọn eniyan n sọ ko ba wọn lara mu.
O ni o yẹ ki ijọba kọkọ fi oju sunnukun wo ipalara ti igbesẹ wọn lati ti oju opo ikansiraẹni Twitter yoo ni lori awọn ọmọ Naijiria.
''O yẹ ki ijọba Naijiria mọ wi pe gbigbegile oju opo Twitter lorilẹede Naijiria yoo fa ifaṣẹyin fun orilẹede Naijiria, eleyii ti yoo mu ki awọn orilẹede lagbaye tẹmbẹlu Naijiria lori ọrọ aje ati ibagbepọ ni awujọ.''
''Oju opo Twitter jẹ gbagede ti awọn ọdọ ati gbogbo awọn ọmọ Naijiria ti n fi ẹhọnu wọn han lati sọrọ nipa ohun ti ko ba tẹ wọn lọrun''
Oríṣun àwòrán, Twitter/Seyi Makinde
''Bakan naa ni awọn ijọba n lo oju opo yii lati ri bi igbesẹ ati eto wọn ṣe ri lara awọn ọmọ Naijiria, eleyii to n mu ki ijọba ṣe atunṣe.''
Gomina ipinlẹ Ọyọ, Seyi Makinde ni o yẹ ki ijọba apapọ mọ nipa ati bi awọn ọdọ ṣe n lo oju opo yii fun ọrọ aje ati igbelarugẹ iṣẹ ọwọ ti wọn yan laayo.
Seyi Makinde ni eto ibanisọrọ igbalode ni oju opo Twitter ti awọn eniyan nilo lati fi pa awọn eniyan sọrọ, bẹẹ si ni awọn ti ko ni ile itaja tabi sọọbu n lo awọn oju opo yii lati ta ọja wọn.
Gomina naa wa kesi ijọba apapọ lati tun ero wọn pa lori igbesẹ naa, ki eto ọrọ aje ma ba a dẹnukọlẹ patapata ni Naijiria.
Snail Slim Soap: Wo ọ̀pọ̀ àǹfààní tó wà nínú lílo ọ̀ṣẹ tí wọn fi omi ìgbín ṣe láti fọ ojú
Ara meeriri ree, a ti ri oju ologbo lori atẹ, paapaa nidi oge sise.
Gẹgẹ bẹẹ se mọ pe awọn obinrin kii fi oge sise sere rara, paapaa nidi ohun ti yoo ba mu ki awọ ara wọn jọlọ, ti oju wọn yoo si gun rege.
Boya eyi lo mu ki ọkunrin kan se iwadii, to si gbe esi iwadi rẹ sita nipa amulo omi ara igbin, ti yoo mu ki oju gun rege.
Ọkunrin onisẹ iwadii naa, Damien Desrocher, tii se ọmọ ọdun mejidinlọgbọn lati ilẹ Faranse jẹ ara eeyan mẹta to n fi omi igbin se ọsẹ ifọju.
Awọn igbin to le ni ẹgbẹrun lọna ọgọta ni Damien n sin, to si tun n gbero lati pese ọsẹ omi igbin bii ẹgbẹrun mẹta lọdun yii.
Nigba to n ba BBC sọrọ, Damien salaye pe awọn kii pa igbin kankan lara lasiko ti wsn ba n yọ omi ara wọn, ti awọn omi igbin naa si wulo fun iwosan.
Àwọn ìtàn mánigbàgbé tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí:
O fikun pe omi ara igbin ni eroja ti wọn n pe ni Collagen ati Elastin, ti kii jẹ ki oju eeyan tete gbo.
Yoruba Nation: Ilana Omo Oodua ní pàbó ní aáyan Aregbesola láti tako ìyapa Nàíjíríà yóò já sí
Oríṣun àwòrán, sunday_igboho1/nstagram
Awọn ọmọ ẹgbẹ Ilana Omo Oodua, to jẹ ọkan pataki lara awọn ẹgbẹ to n pe fun iyapa ilẹ Yoruba kuro lara orilẹ-ede Naijiria ti fun minisita fun ọrọ abẹle, ọgbẹni Rauf Aregbesola lesi, lẹyin to sọrọ abuku saaju si awọn ọmọ ẹgbẹ naa.
Ninu atẹjade kan ti alukoro ẹgbẹ ọhun, Maxwell Adeleye buwọlu, wọn ni Aregbesola kii ṣe ọmọluabi, lo jẹ ko ri adari ẹgbẹ naa fin, iyẹn Ọjọgbọn Banji Akintoye.
Atẹjade naa ni Awa ọmọ ẹgbẹ Ilana Omo Oodua labẹ akoso Ọjọgbọn Banji Akintoye fẹ sọ ni gbangba pe, Aregbesola kii ṣe ọmọlubai lo jẹ ko gboju-gboya lati pe ẹgbẹ baba rẹ ni omugọ."""
Wọn ni gẹgẹ bii minisitia lori ileeṣẹ ijọba to n ri si ọrọ abẹle, o yẹ ki Aregbesola le e bojuto awọn ẹnubode Naijiria, ti awọn atọhunnrinwa darandaran to n da Naijiria laamu, n gba wọle.
Tunde Gbadamosi: Kìí ṣe Tinubu ní ipò ààrẹ̀ tọ́ sí, ìgbà wo ní ìtan ajá ń kan lèmọ́mù?
"Atẹjade ọhun tẹsiwaju pe ""Lẹyin wakati diẹ ti Aregbesola dunkoko mọ ẹya Yoruba tan, ni awọn ọdaran daradaran kọlu Igangan, lagbegbe Ibarapa nipinlẹ Oyo."
"Nibẹ lo ni wọn ti gba ọpọ ẹmi, ti wọn si tun ba ọpọ dukia olowo iyebiye jẹ."""
Titi di akoko yii Aregbesola ko tii fi atẹjade kankan sita lati bu ẹnu ẹtẹ lu ikọlu ọhun.
Ilana Omo Oodua wa n beere lọwọ minsita naa boya oponu ni gbogbo awọn ogunlọgọ eeyan to n darapọ mọ ijijagbara Yoruba Nation lojojumọ.
"Wọn ni ""Ṣe nnkan ti Aregbosola n sọ ni pe oponu ni nnkan bii ẹgbẹrun lọna ogoji eeyan to darapọ mọ iwọde wa niluu Ado Ekiti?"
Tunde Bakare: Àjọjẹ kò dún bẹ́nìkan kò ní ló fa ìjà S Igboho,bẹ́ẹ̀ ìjọbati gbẹ́rù kọjá orí
"Abi awọn ogunlọgọ to darapọ mọ wa nipinlẹ Osun, to jẹ ipinlẹ ti oun funra rẹ ti ṣe ijọba le lori tẹlẹ?"""
Atẹjade naa sọ siwaju si pe, olori pipe ni awọn ọmọ Ilana Omo Oodua, ko si omugọ kankan laarin wọn.
Alukoro ẹgbẹ ọhun ni ẹru Fulani ni Aregbesola, ara lo si n ta a nitori itẹsiwaju to n waye ninu ijijagbara ti awọn n ṣe.
Maxwell pari atẹjade ọhun pe, pabo ni gbogbo akitiyan Aregbesola atawọn to n ṣiṣẹ fun yoo ja si lẹyin o rẹyin nitori ipinnu awọn araaalu lo maa n pada ṣẹ ninu ijọba awarawa.
Oba Gbolahan Timson Shomolu Bariga ní 'Restructuring'ti bọ́ aṣọ kò bá Omọyẹ mọ́!
Bi ẹ ko ba gbagbe, ṣaaju ni Aregbesola ti kọkọ ṣapejuwe awọn to n pe fun idasilẹ orilẹ-ede Yoruba ati Biafra, gẹgẹ bii alamọkan ati omugọ eeyan.
O ni idasilẹ awọn orilẹ-ede ti wọn n pe fun, le yọri si ogun abẹle, eyii ti ko ni tan nilẹ fun nnkan bii aadọta ọdun si asiko yii.
Oríṣun àwòrán, @Gidi_Traffic
Saaju la ti mu iroyin wa fun yin pe, Minisita feto abẹle ni Naijiria, Rauf Aregbesola ti bẹnu atẹ lu awọn to n beere fun idasilẹ orilẹede Yoruba ati Biafra ni Naijiria.
Aregbesola wa ṣe apejuwe awọn ajijagbara yii gẹgẹ bi ''alaimọkan ati omugọ eeyan''
Minisita fọrọ abẹle naa woye ọrọ yii lasiko ayẹyẹ ọjọ ibi rẹ to waye ni Ijebu-jẹsa.
Aregbesola kilọ pe wahala ti wọn n da silẹ yii le yi gbogbo Naijiria ka, to si le da ogun ti yoo ja fun aadọta ọdun silẹ.
O ni ''ikilọ pataki mi fun ẹyin tẹ wa nibi ni ki ẹ mọ pe, omugọ ati alaimọkan lawọn to n pe fun idasilẹ orilẹede Yoruba ati Biafra, ti wọn o si mọ nkan ti ipe naa le bi.
Snail Slim Soap: Wo ọ̀pọ̀ àǹfààní tó wà nínú lílo ọ̀ṣẹ tí wọn fi omi ìgbín ṣe láti fọ ojú?
Idi  ni pe ọla Naijiria lawọn orileede ilẹ okere n wo, ti wọn fi n gboṣuba fun awa alawọdudu lagbaye.
Boya awọn ajijagbara ko mọ pe bi ogun ba fi bẹ silẹ, aadọta ọdun loni, o le ma pari.
Nitori naa o yẹ ki a fi tọkan tọkan daabo bo isọkan wa, lootọ nkan ko ri bo se yẹ amọ mo lero pe iṣejọba bo ti ṣe yẹ lo tọ ki a maa beere dipo ijagbara ki a tu Naijiria ka''
Gomina tẹlẹ nipinlẹ Osun naa fi kun ọrọ rẹ pe, awọn ọmọde ati arugbo ni wahala ogun yoo ṣakoba fun ju lọ, nitori naa, o yẹ ki wọn ro ọrọ yii daada ki wọn to maa lulu ogun ati ọtẹ.
Adebayo Shittu: Èmi kò ṣẹ Abiola Ajimobi nígbà ayé ẹ, òun ló ṣe mi ṣùgbọ́n.....
O tẹnumọ pe ki ẹnikẹni to ba fẹ ogun abẹle silẹ ni Naijiria pa ara rẹ tabi ki irufẹ ẹni naa fi Naijiria silẹ.
''A gbọdọ gbaruku ti Naijiria ni, ori bibẹ kọ loogun ori fifọ''
Igangan Attacks: Ẹgbẹ́ Arewa àti Iba Gani Adams jọ ń fohùn ránsẹ́ síra wọn lórí ọ̀rọ̀ ìsẹ̀lẹ̀ Igangan
Oríṣun àwòrán, Others
Aare Onakakanfo ilẹ Yoruba, Iba Gani Adams ti daa pada pe o togẹ́ lori ọ̀rọ̀ ikọlu awọ Fulani ni ilẹ̀ Yoruba.
Iba Gani Adams sọ̀rọ̀ yii lasiko to n bu ẹnu atẹ ikọlu naa to waye ni Igangan.
O ni pe iṣekupani to wa ye niluu Igangan to wa lagbegbe Ibarapa ni ipinlẹ Oyo, n ṣafihan pe o ṣeeṣe ki ogun bẹ silẹ ni Naijiria laipẹ.
Gani Adams kilọ fun awọn Fulani lati yago fun ilẹ Yoruba, bi bẹẹ kọ, wọn yoo jẹ iyan wọn niṣu.
Ikọlu naa to waye ni afẹmọju ọjọ Isinmi sọ gbogbo awọn olugbe agbegbe Igangan si hilahilo, lẹyin ti awọn afurasi Fulani darandaran ṣekupa ọp eeyan, ti wọn si tun dana sun ọpọ ọkọ ati ile bii ogun
Tunde Gbadamosi: Kìí ṣe Tinubu ní ipò ààrẹ̀ tọ́ sí, ìgbà wo ní ìtan ajá ń kan lèmọ́mù?
Béé, saaju ni ẹgbẹ́ Arewa naa ti fohun ranse si i.
Ẹgbẹ Arewa CNG ti kilọ fun Aarẹ Ọnakakanfo ilẹ Yoruba, Iba Gani Adams pe awọn Yoruba ko gbọdọ gbẹsan iṣẹlẹ ipaniyan to waye niluu Igangan, lagbegbe Ibarapa nipinlẹ Oyo lara awọn Hausa ati Fulani to wa nilẹ Yoruba.
Ẹgbẹ naa sọ pe ikilọ yii ṣe pataki lẹyin ti wọn ni Gani Adams sọ pe awọn eeyan ilẹ Hausa ti kede ogun koju ilẹ nipa iṣẹlẹ ipaniyan to waye niluu Igangan.
Magaret Jimoh: Èrè díẹ̀ ti tó mi níbi oúnjẹ ti mò ń tà- Maggie Rice
Ninu atẹjade kan ti agbẹnusọ ẹgbẹ naa, Abdul-Azeez Sulaiman fi sita, wọn ni awọn ko ni faramọ ikọlu awọn eeyan ilẹ Hausa nilẹ Yoruba.
"O ṣeni laanu pe pẹlu ipo Gani Adams nilẹ Yoruba, o si n tiraka lati fi iwa bi ologun silẹ.
A ri i gẹgẹ bi ohun to buru  jai fún Gani Adams lati sọ pe awọn eeyan ilẹ Hausa lo wa nidi iṣẹlẹ ilu Igangan nigba ti iwadi si n lọ lọwọ lati mọ awọn to ṣiṣẹ naa.
Igbesẹ Gani Adams lati sọrọ yii fihan iru oju tawọn Yoruba fi n wo awọn ẹya Hausa, Sulaiman ṣalaye."
Agbẹnusọ ẹgbẹ CNG fikun ọrọ rẹ pe Gani Adams to n sọ pe awọn eeyan ilẹ Hausa ti kede ogun koju ilẹ Yoruba kan naa lo wa nidi ikọlu awọn alejo niluu Igangan eleyii ti Sunday Igboho ṣe agbatẹru rẹ.
Oríṣun àwòrán, Iba Gani Adams
Ẹgbẹ awọn ara Ariwa orilẹede Naijiria, Pan-Arewa Socio-cultural organization ti kilọ fun Aarẹ Ọna Kakanfo ti Ilẹ Yoruba, Ọtunba Gani Adams, lati ṣọ ọrọ ẹnu rẹ nipa awọn ara oke ọya ti wọn n gbe ni ilẹ Yoruba.
Eyi ko ṣẹyin ọrọ ti Gani Adams sọ lẹyin ti awọn afurasi Fulani darandaran ṣekọlu si ilu Igan
gan nipinlẹ Ọyọ, ti ọpọ ẹmi si ba iṣẹlẹ naa lọ.
Gani Adams ni iṣekupani to wa ye niluu Iganganyii n ṣafihan pe o ṣeeṣe ki ogun bẹ silẹ ni Naijiria laipẹ.
Amọ, ẹgbẹ Arewa ninu ọrọ agbẹnusọ ẹgbẹ naa sọ, Abdul-Azeez Suleiman, o ni awọn fi ikilọ ranṣẹ si Gani Adams pe eera ko gbọdọ rin awọn ara Ariwa to wa ni ilẹ Yoruba nitori iwadii ṣi n lọ lọwọ nipa awọn to ṣekọlu si ilu Igangan naa.
''A ko ni faye gba ikọlu si awọn Hausa kankan ni ilẹ Yoruba nitori wọn n gbẹ nibẹ''
Ayelala Idol: Onímọlẹ̀ ní olúwẹri obìnrin ni òrìṣà náà ló ṣe ń pọn omi sínú ẹlẹ́ṣẹ̀
Suleiman ni o ṣe ni laanu pe Gani Adams to di ipo agba mu ni ilẹ Yoruba lo n sọ ọrọ ogun bi ẹ̀ni pe ko i tii gbagbe lọwọ iṣẹ rẹ gẹgẹ bi ajijagbara eleyii to tako iwa ọmọluwabi.
''Ko yẹ ki Gani Adams dede sọ wi pe awọn ara ile Ariwa to wa ni agbegbe naa, lo ṣe iṣẹ yii lai si aridaju to peye nitori iwadii si n lọ lori iṣẹlẹ naa.''
''Eyi fihan wi pe awọn ara ilẹ Yoruba gẹgẹ bi Gani Adams ṣe fihan, ko fẹran awọn ara ilẹ Hausa to wa laarin wọn nitori wọn ti sare n sọrọ ogun ni ilẹ Yoruba''
Ẹgbẹ awọn ara Ariwa naa ni Gani Adams ko tilẹ ṣewadii ki o to ma a sọrọ ogun nitori nigba ti awọn Sunday Igboho ṣekọlu si Seriki, ko si ẹnikẹni to gbe ija wọn nigba naa.
Oríṣun àwòrán, Monsuru Aderoju
Lẹyin ti iroyin ati aworan iṣẹlẹ naa fa ori ayelujara ya, Gani Adams sọ pe awọn eeyan agbegbe oke ọya n mọọmọ lulu ogun ni.
O ni awọn ara oke ọya naa ti ti tẹ ọka nu iru mọlẹ, akoko si ti to fun awọn ọmọ ilẹ Yoruba lati daabo bo ara wọn, lai boju wo ẹyin.
"Gani Adams ni ""Nigba ti iru nnkan bayii ba n ṣẹlẹ, niṣe lo yẹ ki ẹ dide lati daabo bo ara yin, abi nibo ni awọn ọlọpaa wa lasiko ti awọn janduku yii n pa awọn eeyan wa ni Igangan ?"""
Kò sí ìgbà kankan tí Yorùbá jókòó pé ki Igboho  lọ kéde ìyapa kúrò ní Nàíjíríà
Koda, awọn ọdaran naa ko yọ aafin Asigangan ti ilu Igangan silẹ lasiko ikọlu naa, a si gbọ pe wọn ti gbe ori ade naa lọ.
Aare Ona kakanfo sọ siwaju si pe ọjọ mẹta ṣaaju ikọlu naa ni adari ikọ Amotekun ni ilẹ Yoruba, ajagunfeyinti Kunle Togun ke gbajare pe awọn Fulani darandaran ti ya bo ilẹ Yoruba.
"O ni ""Mo kin ọrọ rẹ lẹyin, mo si pe fun aabo kaakiri ilẹ Yoruba, ṣugbọn bayii ti awọn Fulani kọlu Igangan, mo gbagbọ pe afojusun wọn ni lati da rogbodiyan ati ogun silẹ ni ilẹ Yoruba."""
Gani Adams ni oun ko ni la oju oun silẹ ki awọn ọdaran darandaran maa ta ẹjọ alaiṣẹ silẹ, bii iru eyii ti wọn ṣe ni Igangan.
O ṣalaye pe ni bayii ti awọn eeyan oke ọya ti bẹrẹ si n lu ilu ogun nilẹ Yoruba, oun ko ni dakẹ.
Aare Onakakanfo naa sọ pe eeyan ẹlẹran ara ni awọn ti wọn ge ẹmi wọn kuru ni Igangan, bẹẹ si ni wọn ni ẹbi ati ara pẹlu, ko si yẹ ki iku wọn lọ lasan.
Lẹyin naa lo kilọ fun awọn ọdaran darandaran lati jina rere si ilẹ Yoruba.
O tun ke si awọn ọmọ ẹgbẹ OPC ati awọn gomina ni gbogbo ilẹ Yoruba, lati daabo bo awọn eeyan wọn.
Oríṣun àwòrán, Monsuru Aderoju
Awọn ara ilu Igangan nijọba ibilẹ Ibarapa ti n ke gbajare pẹlu bi awọn afurasi agbebọn ṣe ya wọ ilu naa.
Ninu ikọlu ọhun to waye lalẹ ọjọ Abamẹta ọpọ ile, ọkọ ati aafin Asigangan ilu Igangan ni wọn sọna si.
Eeyan mẹsan ni a gbọ pe wọn pa nigba ti awọn iroyin miran ni iye eeyan to ku fẹrẹ to mejila.
Amọ ṣa ileeṣẹ BBC Yoruba fidi ọrọ mulẹ nipa isẹlẹ naa ati bo se waye.
Gẹgẹ bi igbakeji alaga ẹgbẹ idagbasoke ilu Igangan, arakunrin Azeez Adelere Saminu se wi lasiko to n ba wa sọrọ, deede ago mẹwa abọ alẹ ọjọ Satide lawọn ṣadede bẹrẹ si ni gbọ iro ibọn.
Oríṣun àwòrán, Monsuru Adewumi
''Gbogbo eeyan ko ti sun, ta fi bẹrẹ si ni gbọ iro ibọn. Awọn ọdẹ ilu la kọkọ ro pe wọn n yinbọn soke ṣugbọn a pada ri wi pe awọn Fulani ni.''
Adelere ṣalaye pe lootọ oun ko foju ri awọn agbebọn yii ṣugbọn oun n gbọ ti wọn n sọ ede Fulani nigba ti wọn n ṣe ikọlu sawọn.
''Emi gan ti mo n ba yin sọrọ yii, wọn jo ọkọ mi, aimọye ọkọ ni wọn sun ati ile epo ati ọpọ eeyan lo si ti ku. Eeyan to ku wọn to mẹtala''
Bakan naa lo na ika aleebu si Seriki Fulani, ti Sunday Igboho wa le kuro nilu naa, pe oun lo wa nidi isẹlẹ naa, to si se agbatẹru awọn to wa se ikọlu yii.
Sunday Igboho; Seriki Igangan ní kò sí ẹni tó ran àwọn lọ́wọ́ látí ìgbà ìṣẹ̀lẹ̀ Ibarapa
Ọkan lara awọn ọdọ ilu to ba BBC sọrọ, ti o pe orukọ rẹ ni Monsuru Aderoju naa fidi ọrọ ikọlu yii mulẹ.
O ni aridaju ti oun ri ni pe awọn Fulani lo ṣe ikọlu sawọn nitori awọn araalu naa pa lara awọn to ṣe ikọlu yii, taa si ri pe Fulani ni wọn.
Oríṣun àwòrán, Monsuru Aderoju
Wọn to bi mẹrin ti awa naa pa. Wọn sun ile epo Adolak, wọn sun aafin Ọba naa.''
O ṣalaye pe ilu ko fararọ lọwọ bayi nitori awọn ọdọ ilu ati agbagba ilu ṣi n kaakiri ilu.
Ọna lati wadi ohun gbogbo, ka si di eyi tii se otitọ mu lo mu ki BBC yoruba tun pe Seriki Fulani lori aago, lati mọ boya lootọ, oun lo wa nidi isẹlẹ naa.
Seriki Fulani, Salihu Abdulkadir si ni pupọ awọn eeyan to ba wa BBC sọrọ saaju n naka aleebu si wipe o wa nidi ikọlu yii.
Lọwọlọwọ ilu Ilorin ni o wa, nibi to fori pamọ si lẹyin ti Sunday Igboho le kuro nilu Igangan nibẹrẹ ọdun yii.
Ibrahim, tii se ọmọ Seriki, to ba BBC Yoruba sọrọ ni irọ ni ọrọ tawọn araalu n sọ pe baba oun lo ran awọn Fulani lati lọ kọlu wọn nilu Igangan.
O wa n gbarata pe awọn ko mọwọ-mẹsẹ nipa isẹlẹ naa, to si n beere pe ki ni awọn eeyan tun n fẹ lẹyin ti wọn ti le awọn kuro nilu.
''lẹyin ti wọn ti le wa nilu, ṣe wọn tun fẹ ka kuro nile aye ni?''
Gbogbo igbiyanju BBC Yoruba lati ba Ileeṣẹ ọlọpaa ipinlẹ Oyo sọrọ lori isẹlẹ yii lo ja si pabo.
Idi ni pe alukoro fun ileesẹ Ọlọpaa nipinlẹ Oyo, Adewale Osifeso ko gbe ipe wa lati sọ ohun ti wọn mọ nipa isẹlẹ naa, titi di igba ta fi  n se akojọpọ iroyin yii.
Wakili tẹẹ rí yẹn kìí ṣe ẹran rírọ̀, ó ń díbọ́n ní o - Iba Gani Adams
Kini Gomina Seyi Makinde sọ lori ikọlu yii?
Gomina ipinlẹ Oyo Seyi Makinde naa ti da si ọrọ to wa nilẹ.
O ni oun ti gbọ iroyin buruku nipa ikọlu to waye ni Igangan ati pe oun ti pe awọn ara ilu pe ki wọn fi ọkan balẹ.
O ṣalaye pe awọn agbofinro ti kapa iṣẹlẹ naa.
Lọwọlọwọ, akọwe ẹgbẹ idagbasoke Igangan, Lawal Akeem fi to BBC leti pe, awọn n ṣe ipade pẹlu ọga ọlọpaa agbegbe naa.
TB Joshua biography: Tí kìí bá ṣe rélùwéè tó bàjẹ́ lójú ọ̀nà, iṣẹ́ ológun ní kò bá ṣe
Oríṣun àwòrán, PIUS UTOMI EKPEI
Kii se iroyin mọ pe Wolii Temitope Balogun Joshua ti dagbere faye lẹni ọdun mejidinlọgọta.
Amọ o yẹ ka mọ ohun kan tabi meji nipa oloogbe naa, tii se gbajumọ ojisẹ Ọlọrun kaakiri agbaye.
Ọjọ Kejila osu Kẹfa ọdun 1963 ni wọn bi ojisẹ Ọlọrun naa nilu Arigidi Akoko nipinlẹ Ondo.
Akọsilẹ ta ri ko jọ nipa igbe aye agba wolii naa lori ayelujara loju opo Wikipedia fi han pe ọpọ isẹlẹ manigbagbe lo waye lasiko to n bọ nile aye.
Lara rẹ ni pe osu mẹẹdogun, eyiun ọdun kan ati osu mẹta ni wolii Joshua lo ninu iya rẹ, ki wọn to bii.
Bakan naa ni ori ko ọmọ tuntun jojolo naa yọ lọwọ iku ojiji ni ọjọ keje ti wọn bi nigba ti ibugbamu kan waye ni ibudo iwakusa kan to wa lẹba ile awọn obi rẹ.
Oríṣun àwòrán, TB Joshua Ministries
Se ni ariwo bu gbamu, ti okuta si fọn kan orule ile wọn, amọ ọba oke sọ ọmọ naa, ti ko si fara pa.
Nigba to n rin, TB Joshua bẹrẹ ile ẹkọ alakọbẹrẹ nile ẹkọ St Stephen Anglican nilu rẹ laarin ọdun 1971 si 1977.
Nigba to wa nile iwe girama, pasitọ kekere ni wọn maa n pe Temitope nitori ifẹ to ni si bibeli amọ Joshua ko pari ile ẹkọ girama rẹ.
Oniruuru isẹ ni Joshua se ko to jẹ eeyan laye, lara rẹ ni kiko igbẹ adiẹ nile ọsin adiẹ kan.
Bakan naa lo tun maa n seto ile ẹkọ bibeli fun awọn ọmọde, to si tun maa n lọ sile ẹkọ bibeli lọwọ irọlẹ.
Teachers retirement age and years of service: Ìrírí àwọn àgbà olùkọ́ ṣì wúlò fún àwa ọ̀dọ́
Joshua gbero lati dara pọ mọ ileesẹ ologun amọ erongba rẹ yii lo ja si asan nigba ti ọkọ reluwe to wọ bajẹ lọna, lasiko to n lọ sile ẹkọ awọn ologun.
Nigba to ya lo ri iran ọrun nibi to ti gba ifami ororo yan pe ko da ijọ kan silẹ, eyi to se lọgan, to si pe orukọ ijọ naa ni The Synagogue Church Of All Nations ( SCOAN).
O si le ni olujọsin bii ẹgbẹrun mẹẹdogun to maa n peju sibi isin lọsọọsẹ ninu ijọ naa, ti wọn si maa n wa lati oniruuru orilẹede jakejado agbaye.
Isẹ ami ati iyanu ti TB Joshua se nile aye:
"Oludasilẹ ijọ SCOAN naa lawọn eeyan kan ni o se ọpọ ""isẹ iyanu ojukoroju"" ko to jade laye, ti awọn alawọ dudu ati funfun si maa n ya wa sile ijọsin naa fun adura ati isẹ iyanu."
"Awọn ""isẹ iyanu'ni wọn lo da lori awọn ailera ti ko se wosan loju lasan, to fi mọ ọgbẹ ara, ti wọn si tun ni o wo arun asekupani HIV/AIDS lara awọn eeyan kan."
Magaret Jimoh: Èrè díẹ̀ ti tó mi níbi oúnjẹ ti mò ń tà- Maggie Rice
Bakan naa ni iroyin tun gbalẹ lasiko kan pe Joshua maa n lo omi kan to ti ya si mimọ lati sisẹ iyanu lara awọn eeyan to ni ipenija ara bii awọn arọ, afọju, aditi fun iwosan.
Awọn eeyan miran ni aabo to daju wa fun awọn, ti awọn ba ti lo 'omi iye' ọhun, ti wọn si tun fun awọn ti ko le wa sinu ile ijọsin naa mu.
Koda, lọdun 2013, eeyan mẹrin ni wọn tẹ pa ninu ijọ SCOAN to wa ni Ghana nigba ti isin kan to se nibẹ mu ki ọpọlọpọ ero ya wa, ti inu ijọ naa ko si le gba wọn.
Bakan naa ni ariwo gba ilẹ kan nigba ti Joshua kede pe omi iye oun le wo arun Ebola to n pa eeyan lojiji san.
Tunde Bakare: Àjọjẹ kò dún bẹ́nìkan kò ní ló fa ìjà S Igboho,bẹ́ẹ̀ ìjọbati gbẹ́rù kọjá orí
O wa gbe igo omi iye bii ẹgbẹrun mẹrin ati owo to to ẹgbẹrun lọna aadọta Dọla ransẹ si orilẹede Sierria Leone, ti arun Ebola ti n ba wọn finra.
T.B Joshua: Ọjọ́ ìbí ayọ̀ fún mi àmọ́ ń kò ní lè ṣe ayẹyẹ ọjọ́ ìbí náà
Oríṣun àwòrán, others
Ọjọ Kejila, oṣu Kẹfa, lo yẹ ki Woli Temitope Balogun T.B Joshua ṣe ọjọ ibi ọdun mejidinlọgọta rẹ loke eepẹ.
Ṣugbọn o se ni laanu pe o ku ni ọjọ karun-un, oṣu Kẹfa, ṣaaju ọjọ naa, nigba to ku ọsẹ kan pere ki ọjọ naa ko.
Amọ nkan to tun jẹ iyalẹnu ni pe, wooli naa ti sọ nipa ọjọ ibi rẹ pe oun ko ni ṣe ayẹyẹ kankan ni ọdun yii.
"Ninu fidio kan to jade sori ayelujara lẹyin iku rẹ, Joshua n kọ orin ọjọ ibi fun ara rẹ pe ""Happy Birthday to you...."""
Nibẹ naa lo si ti kede pe oun ko ni i ṣe ayẹyẹ ọjọ ibi kankan ni ọdun yii nitori pe awọn iṣẹlẹ to n waye ni agbaye ko dun mọ oun ninu.
Oríṣun àwòrán, TB Joshua Ministries
"O ni ""ko ni i rọrun fun mi lati ṣe ajọyọ ọjọ ibi mi, nitori pe ọpọ eeyan to fẹ ẹ wa ni wahala ati idaamu to n ṣẹlẹ ni agbaye n ba ninu jẹ."
Ibanujẹ ati ibẹru wọn kan mi. Nitori naa, ẹ jẹ ki a fi ọjọ naa ṣe ọjọ aawẹ ati adura, kẹ ma si gbagbe awọn alaini.
"O ni ""lagbara Ọlọrun, ọpọ ayẹyẹ ọjọ ibi si wa niwaju fun mi ta maa se."""
Blessing Olajide: Ẹ̀bí akẹ́kọ̀ọ́jáde fásitì Ilorin tí wọn pa ṣàlàyé ikú rẹ̀
Bo tilẹ jẹ pe o kọ orin ọjọ ibi fun ara rẹ ninu fidio naa, oloogbe T.B Joshua sọ pe ọpọlọpọ ọjọ ibi lo ṣi wa niwaju lati ṣe.
Nigba aye rẹ, ẹlẹyinju aanu, oloore ati olufifunni ni ọpọ eeyan mọ ọ si, paapaa awọn ololufẹ rẹ.
Nkan yii naa si ni awọn eeyan kan n sọ nipa rẹ lori ayelujara.
Oríṣun àwòrán, Twitter
Unilorin Rape Case: Ẹ̀bí Blessing Olajide tí wọn pa ṣàlàyé ikú rẹ̀
"Awọn obi Blessing ni awọn o fura si nkankan, ko si fi ẹjọ ẹnikankan sun awọn amọ o ni lootọ ni ""a ba iwe pelebe kan ti wọn fi si i lara, wọn kọ 'Unforgiveness from University of Ilorin' wọn tun fi kaadi idanimọ rẹ naa si i lara gẹgẹ bii ọmọ ileewe Unilorin""."
T.B Joshua: ...Àwọn ọmọ ẹ̀yin ń sọ̀fọ̀, ìdá mẹ́ta àǹgẹ́lì Olorun dójútí Lucifa tó lọ- Pasito Chris Okotie
Oríṣun àwòrán, Others
Ibinu nla lati oke wa ti mu  anjonu to n jẹ́ Emmanuel lọ, bẹ́ẹ̀, awọn ọmọ lẹ́yin rẹ́ n sọ̀fọ̀ ipapoda abuku rẹ̀- Pasito Chris Okotie
Pasito Chris Okotie jẹ́ ọ̀kan lara awọn pasito ti won ti sọ̀rọ̀ sita lẹ́yin iku Wolii TB Joshua.
Okotie sọ̀rọ̀ yii lori ero ayelujara ni eyi ti wọ́n ni o wa fun oludasilẹ̀ ijọ Household of God International Ministries.
Ọ̀pọ̀ awon omo Naijiria, lo ti faraya lori ayelujara lori ọ̀rọ̀ Okotie naa.
Won n sọ pe ko kuku si ẹni ti ko ni ku.
Bẹ́ẹ̀, wọ́n ni ọ̀rọ̀ naa ti pọ̀ ju.
Magaret Jimoh: Èrè díẹ̀ ti tó mi níbi oúnjẹ ti mò ń tà- Maggie Rice
Nitooto Chris Okotie ko darukọ kankan ju Emmanuel to fi kun srọ̀ rẹ̀ lọ Sugbọ́n awn eeyan n ni pe o jọ gate, ko jọ gate, o n fi ẹ̀sẹ̀ mejeji tiro ni ọ̀rọ̀ naa jọ.
Awọ́n to n sọ̀rọ̀ loriayelujara ni eyi ko seyin Wolii TB Joshua to ku yii to si je pe Emmanuel naa ni orukọ́ ile ise amohunmaworan re ti ijọ Synagogue Church of All Nations (SCOAN).
Oríṣun àwòrán, rev.chrisokotie/Instagram
Ẹni akọkọ to kọkọ tako TB Joshjua ni Pasitọ Chris Okotie, ti ijọ Household of God, nigba to ṣe apejuwe rẹ gẹgẹ bi iransẹ esu lagbaye, to fẹ da ijọ Ọlọrun ru ni Naijiria.
Okotie ti ko fi igba kan sọ ọrọ TB Joshua ni rere sọ wi pe, o n ṣiṣẹ pẹlu agbara ẹmi okunkun lati sọ agbara ijọ ni Naijiria di okunkun nitori ifẹ esu ni ohun ṣe.
Bakan naa ni Pasitọ naa ko fi ẹhọnu rẹ bo, nigba ti o ri fidio ti Pasitọ Chris Oyakhilome ati TB Joshua ti n gbadura fun arakunrin kan to rọ lapa rọ lẹsẹ.
Tunde Gbadamosi: Kìí ṣe Tinubu ní ipò ààrẹ̀ tọ́ sí, ìgbà wo ní ìtan ajá ń kan lèmọ́mù?
Gbajugbaja akọroyin, Dele Mọmọdu ti fesi lori iku oloogbe T.B Joshua
Dele Momodu ń bèèrè pé ṣe ẹgbẹ́ CAN àtàwọn pásítọ̀ ṣì ń bá olóògbé jà ni lẹ́yìn ikú rẹ̀?
Ṣugbọn yatọ si pe o daro iku wolii naa, ibeere to n beere ni pe ki lo de ti awọn ẹgbẹ ẹlẹsin Kristiẹni ko ti i sọ nkankan nipa iku rẹ.
Oríṣun àwòrán, Others
Lati owurọ ọjọ Aiku ti iroyin iku Joshua ti jade, ni ọpọlọpọ eniyan kaakiri agbaye ti n daro rẹ, ti wọn si n sọ oriṣiriṣi nkan nipa rẹ.
Amọ, akiyesi fihan pe ko si ẹgbẹ ọmọlẹyin Kristi kankan bi Christian Association of Nigeria, CAN, Pentecostal Fellowship of Nigeria, to fi mọ awọn iranṣẹ Ọlọrun to gbajumọ, ko ti i sọ ohunkohun nipa akẹẹgbẹ wọn to lọ.
"Ninu ọrọ kan to kọ si ori ayelujara Instagram rẹ, Momodu sọ pe ""o ga o, pe ko ti i si ọrọ kankan nipa iku TB Joshua lati ọdọ awọn ọmọlẹyin Kristi."
"Se wọn tun ṣi korira rẹ lẹyin to ku ni?""."
Ko nilo ibuwọlu ẹnikẹni... Gbogbo ọkan ni yoo ku.
Magaret Jimoh: Èrè díẹ̀ ti tó mi níbi oúnjẹ ti mò ń tà- Maggie Rice
A ko le sọ idi ti awọn eeyan yii ko ti i sọ ọrọ tabi daro iku wolii naa, tabi iru ibaṣepọ to wa laarin TB Joshua ati ẹgbẹ awọn Kristiẹni nigba to fi wa laye.
Amọ awọn iroyin ti a ko le fidi rẹ mulẹ to n lọ ni pe awọn ẹgbẹ Kristiẹni ati awọn gbajugbaja iranṣẹ Ọlọrun kan ni Naijiria ti sọrọ ri pe, awọn ko le gba T.B Joshua laaye ninu ẹgbẹ awọn.
"Bakan naa ni wọn ni awọn ko ni lọ si ṣọọṣi rẹ fun iṣẹ iranṣẹ ""nitori pe kii ṣe ẹni igbala, bẹẹ ni orisun iṣẹ iyanu to n ṣe ko mọ ọ""."
Tunde Gbadamosi: Kìí ṣe Tinubu ní ipò ààrẹ̀ tọ́ sí, ìgbà wo ní ìtan ajá ń kan lèmọ́mù?
Ọpọ igba ni awuyewuye waye lori iṣẹ iranṣẹ rẹ.
Laipẹ yii ni ileeṣẹ ayelujara Youtube pa oju opo rẹ lọdọ wọn rẹ, nitori fidio kan ti Joshua ti sọ pe oun n wo awọn ọkunrin to n ni ibalopọ pẹlu ọkunrin ẹgbẹ wọn san.
Yatọ si eyi, awọn igba kan wa ti awuyewuye ti waye ri nipa rẹ nitori awọn asọtẹlẹ to sọ ti ko wa si imuṣẹ.
Bakan naa ni lọdun 2014, nigba ti ile kan wó ninu ọgba ile ijọsin Synagogue, to si pa eeyan to le ni ọgọrun.
Pupọ ninu awọn eeyan naa lo wa lati orilẹ-ede South Africa.
Yoruba ni ta ba ku laa dere, eeyan ko sunwọn laaye.
Pasitọ Ijọ Synagogue Church of All Nations, Wolii Temitope Balogun Joshua to dagbere faye ni ọpọ eeyan n kọrin re ki lẹyin iku rẹ pe oloore lọ.
Amọ ni ọpọ igba, ni ọrọ nipa agba wolii naa ti fa awuyewuye, ti wọn si n beere pe ṣe lootọ ni Woli naa jẹ iranṣẹ Ọlọrun?
Lati igba ti Woli TB Joshua ti bẹrẹ iṣẹ gẹgẹ bi eniyan Ọlọrun ni ọpọlọpọ eniyan ti ma n tẹle fun itusilẹ lọwọ ẹmi okunkun, igbala ẹmi wọn ati iṣẹ iyanu.
Kaakiri orilẹede agbaye si ni awọn eniyan ti maa n wa si ile ijọsin rẹ fun igbala ati iwosan, ti ọpọlọpọ ṣi n jẹri si pe agbara rẹ daju.
Amọ ọpọlọpọ awọn pasitọ miran lo ri Joshua nigba aye rẹ, gẹgẹ bi onirọ, to kan n fi orukọ Ọlọrun jẹun ati ẹlẹgbẹ okunkun to n lo agbara ẹmi okunkun ati awọn alawo lati fi ṣe iwosan.
Diẹ lara aero awọn ojisẹ Ọlọrun miran ree nipa TB Joshua lasiko to wa loke eepẹ.
Blessing Olajide: Ẹ̀bí akẹ́kọ̀ọ́jáde fásitì Ilorin tí wọn pa ṣàlàyé ikú rẹ̀
Ohun ti Chris Okotie sọ nigba naa ni pe, o ṣeun ni aanu pe Chris Oyakilhome n ṣepọ pẹlu TB Joshua.
O si tẹnumọ pe ẹlẹgbẹ okunkun ni pasitọ naa, to si bu ẹnu atẹ lu bi wọn ṣe n pe e ni ''Emmanuel'', orukọ ti wọn n pe Jesu Kristi, to jẹ adari gbogbo ijọ Kristẹni lagbaye.
TB Joshua kii ṣe ara wa, ẹlẹgbẹ okunkun ni - Pentecostal Fellowship of Nigeria
Oríṣun àwòrán, PFN
Lasiko ti ẹgbẹ ọmọlẹyin Kristi ni Naijiria, Pentecostal Fellowship of Nigeria dahun si ija laarin TB Joshua ati Chris Okotie, ni wọn sọ wi pe TB Joshua kii ṣe ara awọn ọmọlẹyin Kristi ni Naijiria.
Bisọọbu Mike Okonkwo, to jẹ adari ẹgbẹ Pentecostal Fellowship of Nigeria nigba naa ni TB Joshua kan n farapẹ awọn ọmọlẹyin Kristi ni Naijiria ni, kii ṣe ara wọn rara.
O wa kilọ fun un pe ko ma pe ara rẹ ni ara ijọ Pentecostal lorilẹede Naijiria.
Oríṣun àwòrán, Others
Ninu ọrọ tirẹ, Pasitọ ijọ Revival Assembly Church ni ipinlẹ Eko, Anselm Modubuku ni ko si otitọ ninu ọrọ ti TB Joshua sọ wi pe ati inu iya oun ni oun ti di atunbi, ti o si ti ṣi ọpọlọpọ onigbagbọ ni ọna iye.
Bakan naa ni pasitọ ijọ Word of Life Bible Church, Ayo Oritsejafor ni ilu Warri ni oun ko mọ oun ti awọn ara ilẹ Amẹrika ri lara TB Joshua, ti wọn fi n wọ tẹle nitori oun tikararẹ ko ni ẹni to mọ igba to fi aye rẹ fun Jesu, tabi ta ni pasitọ rẹ.
Oríṣun àwòrán, fACEBOOK/T.B Joshua death
Ara ijọ Synagogue Church of All Nations, to ti tun jẹ ọrẹ timọ timọ si TB Joshua, Oye Ogunwale ni ahesọ ni gbogbo ọrọ ti awọn eniyan miran n sọ nipa rẹ, paapaa awọn pasitọ ni Naijiria.
Ogunwale ni eniyan Ọlọrun ni TB Joshua, ti ko si ni ohun ikọkọ tabi agbara okunkun kankan nitori oun ti mọ lati bi ọdun mẹwaa ṣẹyin.
O ni awọn to n sọrọ rẹ ni aida ni awọn ti ko ri iwosan gba nigba ti wọn lọ si ile ijọsin rẹ, amọ o fi n da awọn eniyan loju wi pe o kere tan, TB Joshua n wo awọn alaisan HIV/Aids bii mẹwaa san ni ọṣẹ kan.
Snail Slim Soap: Wo ọ̀pọ̀ àǹfààní tó wà nínú lílo ọ̀ṣẹ tí wọn fi omi ìgbín ṣe láti fọ ojú?
Ogunwale ni o ṣe ni laanu wi pe ọrọ TB Joshua dabi ti oloye Obafemi Awolowo, to jẹ wi pe lẹyin iku rẹ ni awọn eniyan ṣẹṣẹ rii gẹgẹ bi olori to dara.
O ni igbagbọ ni wọn fi n ri iwosan gba ni ọdọ TB Joshua, amọ ẹni ti ko ba ri idariji gba lati ọdọ Ọlọrun, ko le e ri iwosan gba lọdọ rẹ.
Amọ, awọn miran fi ẹsun kan TB Joshua wi pe, ẹmi okunkun lo fi n ṣe iwosan fun awọn eniyan nitori ti wọn ba ri iwosan gba lẹṣẹkẹṣẹ, aisan naa yoo tun pada pa eniyan bẹẹ ni, laipẹ si ara wọn.
TB Joshua dead: Ikú TB Joshua, Ọmọ Pasitọ Enoch Adeboye, Dare àti àwọn Pásítọ̀ jàǹkàn-jànkàn tí ikú wọn tí mí orílẹ̀èdè Naijiria
Oríṣun àwòrán, Others
Iyalẹnu ati ibanujẹ ọkan ni awọn eniyan fi gbọ iroyin iku gbajugbaja Woli TB Joshua to ni ile ijọsin Synagogue Church of All Nations [SCOAN] to wa ni ilu Eko ni orilẹede Naijiria.
Pasitọ naa jẹ gbajugbaja kaakiri agbaye ti awọn eniyan si ṣe apejuwe rẹ gẹgẹ bi ẹni to o ma n fi fun ni ni ọpọ igba.
Pasitọ naa to ku ni ẹni ọdun mẹtadinlọgọta lo mu jinni-jinni ba gbogbo awọn eniyan lagbaye paapaa awọn orilẹede ni iwọ guusu Naijiria.
Iroyin iku pasitọ naa lo n waye lẹyin oṣu kan ti Dare Adeboye to jẹ ọmọ baba Enoch Adeboye, iyẹn adari ijọ Redeem Christian Church of God lagbaye jade laye.
Akojọpọ awọn pasitọ ti iku wọn ti mi orilẹede Naijiria ni aipẹ yii ree.
Oríṣun àwòrán, PIUS UTOMI EKPEI
Ileesẹ iransẹ TB Joshua ti kede pe oludasilẹ ijọ naa ati agba wolii lorilẹede Naijiria, Temitope Balogun Joshua ti dagbere faye.
Gẹgẹ bi ikede kan ti ileesẹ iransẹ naa ati ijọ Church Of ALl Nations fisita loju opo Facebook rẹ, ana ọjọ Satide, ọjọ karun osu Kẹfa ọdun 2021 ni agba wolii naa mi kanlẹ.
Wolii Joshua, to dele aye ni ọjọ Kejila osu Kẹfa ọdun 1963, lo lo ọdun mejidinlọgọta loke eepẹ, ki ọlọjọ to de.
Wolii Joshua sọrọ lọjọ Satide lasiko ipade to se pẹlu awọn alabasisẹpọ rẹ fun ileesẹ mohunmaworan ijọ rẹ, Emmanuel TV, to si dabi ẹnipe o n sọ asọtẹlẹ nipa iku rẹ.
Ọgọọrọ eniyan ti o pejọ pọ si ijọ rẹ ni Ọjọ Isinmi, Ọjọ Kẹfa, Oṣu Kẹfa lati ṣe ikẹdun iku akọni naa to re ọrun aremabọ.
Oríṣun àwòrán, Leke Adeboye
Apapọ ẹgbẹ awọn ọmọ Pasitọ ni ijọ Redeemed Christian Church of God lo fi kede sita pe Oluwadamilare Temitayo Adeboye ti jade laye.
"Awọn ọdọ ijọ RCCG ni pẹlu ọkan wuwo  ni awọn fi  kede ipapoda ọmọ wọn, ẹgbọn wa, ọkọ ati baba wọn, Oluwadamilare Temitayo Adeboye to lọ ba Ọlọrun ni ọjọ Iṣẹgun ọjọ kẹrin oṣu karun ọdun 2021""."
Atẹjade naa ka wipe igbe aye rẹ jẹ igbe aye rere gẹgẹ bo ṣe sin Ọlọrun lai kaarẹ, to n fun ni. to si n dari lai si ifoya.
Bo tilẹ jẹ pe iroyin yii fi wa gidi gan, a duro lori Jesu Kristi ninu ẹni ti a ni idaniloju pe a o pade nibi ti ko si inira.
Ẹni ọdun mejilelọgoji ni Pasitọ Damilare Adeboye ki o to jẹ kuro laye.
Oríṣun àwòrán, Instagram/gofamint
Pasitọ Elijah Abina, to jẹ adari ijọ Gospel Faith Mission International, GOFAMINT, ti padanu ọmọ rẹ ọkunrin, Emmanuel Folorunso.
Iroyin iku ọmọ Pasitọ Abina jade lẹyin ọjọ diẹ ti ọmọkunrin Pasitọ agba ijọ Redeem, Enoch Adeboye naa jade laye.
Iroyin sọ pe ọjọ kẹrinlelogun, oṣu Kẹrin, ọdun 2021, ni Emmanuel Abina ku nilu Eko.
Eyi to jẹ ọjọ kẹjọ ṣaaju iku ọmọ Adeboye.
Oríṣun àwòrán, Others
Ariwo ati ibanujẹ gbode lorilẹede Naijiria nigba ti iroyin iku pasitọ Ibidun Ighodalo to jẹ́ ọbinrin tó rẹ̀wà jùlọ nígbàkan rí, tó sì tún jẹ́ ìyàwó adarí àti olùdásílẹ̀ ìjọ Trinity House tan jade.
Ibidunni Ighodalo náà kú ní ìdájí  Ọjọ́ àìkú, Ọjọ Kẹrinla, Oṣu Kẹfa, ọdun 2020 ní ìlú Port Harcourt, nípìnlẹ̀ Rivers nibi to ti lọ ṣèrànwọ́ kíkọ́ ibudó ti wọn yóò ti maa tójú àwọn aláàrùn Covid-19 nibẹ.
Nurudeen Lawal  to jẹ adarí Elizabeth R ti Pasitọ Ibidun jẹ oludasilẹ fun, sọ wi pe àwọn kò mọ ǹkan to ṣe ku paa nítori lẹ́yìn ti àwọn pari iṣẹ́ ní  olúkúlùkù wọ yàrá rẹ̀ lọ láti sù, sùgbọ́n nígbà ti ilẹ̀ mọ́ ni ni kò jí mọ.
Ibídùn fí ọkọ àti ìbejì rẹ̀ silẹ̀ sáyé lọ.
Oríṣun àwòrán, Instagram/Celestialonline
Ariwo he lo jade lori ẹrọ ayelujara lẹyin ti ọdọmọde olowo ati oniṣowo ni ipinlẹ Eko, Kayode Badru ku iku ojiji ni ile ijọsin Celestial Church of Christ ni ilu Eko.
Iṣẹlẹ naa ṣẹlẹ ni Ọjọ Aje, Ọjọ Kẹta, Osu Karun un, lasiko to n ṣe eto adura ninu ile ijọsin naa.
Ọkan gboogi ninu awọn agba ni ile ijọsin ti iṣẹlẹ naa ti waye, Imolẹmitan Ojo ni Badru ṣẹ̀ṣẹ de lati Dubai wa si Naijiria lati wa ṣe ayẹyẹ to ti wa pin nkan fun awọn eniyan.
Imọlẹmitan ni ọpẹ́ ní Kayode Badru ń ṣe pẹ̀lú imọlẹ meje ti o fi n ṣe ọpẹ naa ki o to di wi pe nkan yiwọ.
O ni: ''Funrara Kayode Badru lo tan imọlẹ meje to fẹ fi ṣe ọpẹ ni Ọsan Ọjọ Aje naa, ti o fi dupẹ lọwọ Ọlọrun
''Lẹyin naa ni wọn gba imọlẹ meje naa ni ọwọ rẹ, ti wọn si sunmọ kuro ni ọdọ rẹ, ki Woli Ebony to gbadura fun un to si wọn 'perfume' si i lara amọ ko pọju bi o ṣe yẹ lọ''
''Ti ina fi jo Kayode ni ara ko ju iṣẹju aaya ọgbọn, ti ko si to iṣẹju kan ti awọn eniyan to wa nibẹ fi sare digbadigba lọ bu omi ti wọn si pa ina naa''.
Arakunrin Imọlẹmitan tun ṣalaye fun BBC ''nii Ọjọọru ti mo pada lọ si ile iwosan lo wo o, Kayode Badru sọ fun mi pe oun jẹun, o jẹ amala to si mu olomiọsan, amọ Ọjọbọ ni wọn sọ fun mi pe o ti jade laye''.
Oríṣun àwòrán, Facebook/Reinhard Bonnke
Ajíhìnrere àgbáyé Reinhard Bonnke papòdà lẹ́ni ọdún mọ́kàndínlọ́gọ́rin
Iku doro, iku ṣeka, iku ti mu gbajugba ajiyinrere agbaye, Reinhard Bonnke lọ lẹni ọdun mọkandinlọgọrin.
Ninu atẹjade kan ti iyawo rẹ, Annie Bonnke buwọ lu loju opo Facebook rẹ ni wọn ti kede iku ojiṣẹ Ọlọrun yii.
Wọn sọ ninu atẹjade naa pe pẹlu alaafia ni Ọgbẹni Bonnke fi pada lọ ba Ẹlẹdaa rẹ ni ọrun.
Fun ọgọta ọdun sẹyin, Bonnke ṣiṣẹ ajihinrere kaakiri agbaye papaa julọ nilẹ Afirika, o ṣe eto isọji kaakiri awọn orilẹ-ede, ti awọn ọmọlẹyin Kristi ni orilẹede Naijiria si gba tirẹ.
Prince Harry and Meghan: Ọmọbakùnrin Ilẹ̀ Gẹ̀ẹ́sí, Harry àti ìyàwó rẹ̀ bímọ tuntun
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ọmọọbakunrin Harry ati iyawo rẹ Meghan Markle ti polongo ọmọbinrin tuntun jojolo ti wọn ṣẹṣẹ bi.
Ninu atẹjade ti tọkọ-taya naa fi lede ni wọn ti sọ wi pe ni ayọ ati alaafia ni ọmọ awọn keji wọle wẹrẹ fun wọn.
"Atẹjade naa ni orukọ ọmọ tuntun naa ni Lilibet ""Lili"" Diana Mountbatten-Windsor, ti wn bi ni owurọ Ọjọ Kẹrin, Oṣu Kẹfa, ọdun 2021."
Tọkọ-taya fikun wi pe layọ ati alaafia ni iya ati ọmọ wa lọwọlọwọ, ti inu wọn si dun pẹlu iroyin ayọ naa.
Ninu ọrọ rẹ, Ọmọọbakunrin Harry ni idi ti awn fi sọ ọmọ tuntun jojolo naa ni Lilbet ni pe nigba ti Ọbabinrin Elizabeth wa ni kekere o ṣoro fun lati pe orukọ ara rẹ , ti baba rẹ si ma a n pe e ni Lilibet bi oun fun arar rẹ ṣe le pe orukọ ara rẹ.
Oríṣun àwòrán, Misan Harriman/The Duke and Duchess of Sussex
Lati igba naa wa ni wọn ti n Ọbabinrin Elizabeth ni Lilibet, ti ọk rẹ Duke ti Edinburgh to jade laye laipẹ yii naa n pe bẹẹ gẹgẹ bi orukọ to ni ifẹ si.
Bakan naa ni Ọmọọba Harry fikun pe awọn tun sọ orukọ ọmọ naa ni Diana lati fi bu ọla fun iya oun to papoda ninu ijamba ọkọ ni dun 1997, nigba ti Harry wa ni ọmọ ọdun mejila.
Ọmọọbabinrin Charlotte to jẹ ibatan Lili,  to si jẹ ọmọ ẹgbọn Harry naa n jẹ orukọ Diana lati bu ọla fun mama wọn to papoda naa.
Oríṣun àwòrán, Sussexes
Ọjọ Ayajọ ololufẹ lagbaye, Valentines Day ti ọdun 2021 yii ni Ọmọọba Harry ati iyawo rẹ kede pe awọn n reti ọmọ keji jojolo laipẹ.
Babatunde Gbadamosi: Kìí ṣe Tinubu ní ipò ààrẹ̀ tọ́ sí, ìgbà wo ní ìtan ajá ń kan lèmọ́mù?
Yoruba ni agba kii wa lọja, ki ori ọmọ tuntun wọ, agba ti ko si kẹhun sọrọ, yoo kẹ itan sare.
Idi ree ti gbaju gbaja oloselu kan ati onisowo pataki nipinlẹ Eko, Babatunde Gbadamosi fi n ke tantan pe asiko ti to fun ẹya Yoruba lati da duro.
Gbadamọsi, ẹni to ti du ipo gomina fun igba meji nipinlẹ Eko ni gba gba gba ni oun wa lẹyin idasilẹ orilẹede Yoruba lasiko yii, nitori ohun gbogbo ti yiwọ fun orilẹede Naijiria ta wa.
Gbajumọ oloselu naa, to tun sọrọ nipa ero lori eto atunto ti awọn oloselu kan n polongo wa fọwọ gbaya pe ọrọ ti kọja lori rẹ.
O ni ti eto idibo yoo ba tiẹ waye lọdun 2023, laise abosi, ta si fẹ sọ otitọ, ẹya ibo ni ọpọn sun kan lati fa oludije fun ipo aarẹ kalẹ.
Babatunde Gbadamosi wa bu ẹnu atẹ lu erongba asaaju ẹgbẹ oselu APC, Asiwaju Bola Ahmeds Tinubu lati dije fun ipo aarẹ Naijiria lọdun 2023.
O si fi gbogbo ẹnu sọ pe kii se Tinubu ni ipo aarẹ tọ si nitori ko si ba se fẹ pin itan aja, ti yoo kan lemọmu.
Rev Stephen Akinola: Ọmọ bíbí ìlú Igboho níí ṣe àmọ́ tó fi Portharcourt ṣe ibùjókòó
Oríṣun àwòrán, Redemption Ministry
Ọrọ iku ọwọọwọ yii ti wa n toju su awọn eeyan lorilẹede Naijiria nitori bi awọn ọmọde ati agba se n ku.
Ni afẹmọjumọ ọjọ Satide si ọjọ Aiku, ni gbajumọ wolii kan, TB Joshua ki aye pe o digbose, amọ ki ilẹ ọjọ Aiku to su, ni iroyin miran tun gba ilẹ kan pe ojisẹ Ọlọrun miran tun ti jade laye.
Oluwarẹ ni Alufa Stephen Akinola ti ileesẹ iransẹ Redemption Ministry lagbaye, ti ibujoko rẹ wa nilu Portharcourt.
Eto alẹ Suya (Suya Night) ati iji onina (Wind Of Fire) si ni gbogbo eeyan fi mọ ojisẹ Ọlọrun naa.
Idaji ọjọ Aiku, ni tooto asiko ti Wolii TB Joshua jade laye, naa ni Alufa Akinola naa mi kanlẹ nile iwosan kan nilu Abuja.
Gẹgẹ bi ọkan lara ojisẹ Ọlọrun ninu ijọ naa ti fidi rẹ mulẹ fun BBC, gbogbo awọn alufa ijọ naa ni wọn ti kede iku gbajumọ ojisẹ Ọlọrun fun.
Tunde Gbadamosi: Kìí ṣe Tinubu ní ipò ààrẹ̀ tọ́ sí, ìgbà wo ní ìtan ajá ń kan lèmọ́mù?
O fikun pe wọn ti gbe oku oloogbe lọ sibudo igbokusi.
Ọmọ bibi ilu Igboho nipinlẹ Oyo ni Alufa Stephen Akinola, amọ ẹkun ariwa orilẹede Ghana ni wsn bi si.
Alufa Samuel Akinola naa ni baba to bi lọmọ, to si ni aburo mẹsan amọ oun ni abikẹyin awọn obi rẹ.
Amọ wọn padanu baba wọn nigba ti Stephen wa ni ọmọ ọdun mẹtala.
Ile ẹkọ alakọbẹrẹ to wa nilu Damago lẹkun ariwa orilẹede Ghana ni Stephen ti bẹrẹ ẹkọ alakọbẹrẹ nigba to pe ọmọ ọdun mẹrin.
Blessing Olajide: Ẹ̀bí akẹ́kọ̀ọ́jáde fásitì Ilorin tí wọn pa ṣàlàyé ikú rẹ̀
Ọdun 1963 lo setan nile ẹkọ mọda, to si lọ sile ẹkọ girama nilu Tamale. Eyi to pari lọdun 1970.
Ọdun 1971 lo pada de sorilẹede Naijiria, to si n se isẹ olukọ nile ẹkọ alakọbẹrẹ onitẹbọmi to wa nilu Igboho.
Amọ o tẹsiwaju lẹnu ẹkọ rẹ lẹyin to sisẹ ọdun meji, to si lọ sile ẹkọ gbogbonse Poly ni Yaba, lẹyin naa lo wa bẹrẹ isẹ iransẹ.
Igangan Attacks: Ẹ̀yin olóṣèlú, ẹ má fi ìṣẹ̀lẹ̀ ìpànìyàn Igangan dá ìjà ẹlẹ́yàmẹ̀yà sílẹ̀- YWG
Oríṣun àwòrán, Monsuru Aderoju
Ẹgbẹ ọmọ Yoruba, Yoruba Welfare Group (YWG) ti ṣe ìkìlọ fáwọn oloselu.
YWG ni pe ki wọn maa lo iṣẹlẹ ipaniyan to waye niluu Igangan mawọn Yoruba kọlu awọn ẹya miran.
Bi ẹgbẹ YWG ti kẹdun pẹlú àwọn èèyàn Igangan, bẹẹ naa lo rọ awọn oloṣelu lati wa ojutu si iṣẹlẹ laabi ọhun ki wọn sì yago fun ohun to le fa ìjà.
Aarẹ ẹgbẹ YWG lo sọrọ yii nigba to ṣabẹwo sí Asigangan ilu Igangan lati bawọn araalu naa kẹdun.
Ohun ti aarẹ YWG ni lọkan lọrọ tí Ọjọgbọn Banji Akintoye sọ lẹyin ikọlu ọjọ Aiku niluu Igangan pe ijọba apapọ at'awọn Fulani bẹrẹ ogun tako ilẹ Yoruba.
O ni ọrọ naa ri bakan nigba ti Ọjọgbọn Akintoye ti ko ti ṣabẹwo s'ilu Igangan le sọ pe awọn Fulani lo gbimọ pọ kọlu Igangan lọjọ Aiku.
Tunde Gbadamosi: Kìí ṣe Tinubu ní ipò ààrẹ̀ tọ́ sí, ìgbà wo ní ìtan ajá ń kan lèmọ́mù?
"Ọjọgbọn Akintoye ni lati dẹkun fifi ẹmi awọn Yoruba tafala.
Eto abo to múná dóko ni Yoruba nilo bayii ju ọrọ oṣelu lọ.
Asiko ti to fun wa nilẹ Yoruba lati fori kori lori ọna ti le gba wa ojutu si eto abo to mẹhẹ.
O nilo lati ronu ju ohun tawọn ẹṣọ Amotekun le ṣe lọ lori eto abo bayii, aarẹ YWG lo sọ bẹẹ."
"'A rí wàhálà táwọn èèyàn ń kojú nilẹ̀ẹ̀ Yorùbá la ṣe fi ""Amotekun"" fi ọkàn wọn balẹ̀'"
O rọ gbogbo awọn ọmọ Yoruba atata lati fọwọ so wọpọ gbogun ti iṣẹlẹ ijinigbe ati ipaniyan yatọ sí kí wọn kan maa pariwo lori ayelujara lasan.
Ninu ọrọ tiẹ, Asigangan ilu Igangan, Oba AbdulAzeez Adeoye tawọn afurasi Fulani ọhún dana sun aafin rẹ naa kepe Gomina Seyi Makinde ipinlẹ Oyo lati ṣeranwọ fáwọn tó ṣofo dukia wọn ninu ikọlu to waye.
Snail Slim Soap: Wo ọ̀pọ̀ àǹfààní tó wà nínú lílo ọ̀ṣẹ tí wọn fi omi ìgbín ṣe láti fọ ojú?
Ìpànìyàn ní Igangan ń tọ́ Yorùbá níjà, Amotekun alájùmọ̀ṣe ní yóò yanjú rẹ̀ - Akeredolu
Akeredolu àtàwọn Gómìnà Yorùbá fòntẹ̀ lu Amọtẹkun alájùmọ̀ṣe
Awọn Gomina ẹkun iwọ oorun Guusu Naijiria paṣẹ pe ki ikọ Amọtẹkun lẹkun naa bẹrẹ iṣẹ ajọṣepọ.
Aṣẹ tuntun yii ko si sẹyin ikọlu to waye sawọn araalu Igangan ni ijọba ibilẹ Ibarapa ni ipinlẹ Oyo lọjọ Abamẹta.
Ninu akọtun ikọlu naa, awọn ọlọpaa sọ pe eeyan mọkanla lo kagbako iku ojiji lọwọ awọn afurasi agbebọn.
Bẹẹ naa ni wọn dana sun aafin Ọba, awọn ọkọ araalu to fi mọ ile epo kan.
Gomina Rotimi Akeredolu, tii se alaga ẹgbẹ awọn Gomina iwọ oorun Guusu Naijiria lo kede ipinu awọn Gomina naa.
O sọ pe awọn adari ikọ Amọtẹkun ni Oyo, Ondo, Ogun, Osun ati Ekiti lawọn ti sọ fun pe ki wọn fikunlukun, lọna ti wọn yoo fi jijọ ṣiṣẹ pọ.
O wa ṣapejuwe ikọlu to waye ni Igangan gẹgẹ bi ohun to buru jai, to si n tọwọ bọ ni loju lati le wa ija.
Akeredolu tun ke si gbogbo awọn ọmọ Naijiria lati panupọ bẹnu atẹ lu iru iwa yii, eyi to ni o jẹ ikọlu si iwa ọmọluabi ati ibagbepọ alaafia.
''A o ni sinmi titi ti a fi mu ileri wa ṣẹ. O di dandan ki gbogbo awa taa nifẹ alaafia ati ominira koju iwa ẹhanna yi.''
O tẹsiwaju pe ''Ni tiwa, a ti pinu lati daabobo awọn eeyan wa, dukia wọn ati gbogbo ọna jijẹ-mimu wọn lọwọ awọn to n gbogun ti wọn labẹle ati lẹyin odi. Lori eyi, a ko ni yẹ, a ko ni gbọ''
Oríṣun àwòrán, @Amotekun
Lọjọ Kẹsan oṣu Kini ọdun 2020 ni wọn ṣe ifilọlẹ ikọ alaabo Amọtẹkun.
Wọn ṣe agbekalẹ ikọ yii lati koju ipenija aabo to n koju awọn ipinlẹ Yoruba to wa ni ẹkun iwọ oorun Guusu Naijiria.
Lara ojuṣe ikọ yi ni ki wọn koju iwa ọdaran lati ọwọ awọn ọdaran darandaran to n sapamọ sinu igbo lati ṣe ikọlu si araalu.
Awọn ijọba ipinlẹ ti ṣaaju pawọpọ ko ọkọ ati awọn nkan eelo miran jọ fun ikọ naa, ṣugbọn ko pẹ sigba ti wọn bẹrẹ ni Minisita feto idajọ Naijiria, Abubakar Malami ni ikọ naa ko bofin mu.
Tunde Gbadamosi: Kìí ṣe Tinubu ní ipò ààrẹ̀ tọ́ sí, ìgbà wo ní ìtan ajá ń kan lèmọ́mù?
O sọ pe ko si agbarijọpọ ipinlẹ Naijiria kankan to laṣẹ lati ṣe idasilẹ ikọ alaabo ti wọn yatọ si ti ijọba apapọ.
Amọ bayi ti ipenija aabo ti wa fẹju kọja ti tẹlẹ, ohun tara ilu yoo maa beere ni igba ti Amọtẹkun yoo gbera sọ lati le pese aabo to peye fawọn.
Igangan Attacks: Àwọn òbí ń fi ìpaya kó akẹ́kọ̀ọ́ kúrò nílé ẹ̀kọ́ ní Ibarapa torí àkọ́tun ìkọlù
Oríṣun àwòrán, MOnsuru Aderoju
Ọpọ awọn obi ati alagbatọ la gbọ pe wọn ti bẹrẹ si ya bo awọn ile ẹkọ lawọn ilu bii Ayete, Igangan ati Tapa, ni ijọba ibilẹ Ibarapa lati ko awọn ọmọ wọn kuro nitori bi eto aabo agbegbe naa ṣe ri.
Iroyin ni igbesẹ naa ko ṣẹyin ibẹru awọn obi pe o ṣeeṣe ki ikọlu mii waye lawọn ile ẹkọ naa, lẹyin ikọlu to waye ṣaaju ni Igangan lopin ọsẹ ninu eyi ti ọpọ ẹmi ati dukia ti ṣofo.
Ti ẹ ko ba gbagbe, alẹ ọjọ Abamẹta ni awọn afurasi Fulani darandaran ya bo ọkan lara awọn ilu naa, iyẹn Igangan, ti wọn si jo ọpọ ile ati ọkọ lẹyin ti wọn pa awọn eeyan.
Ileeṣẹ ọlọpaa agbegbe naa fidi rẹ mulẹ fun awọn akọroyin pe ko din ni eeyan mọkanla to ba iṣẹlẹ naa lọ.
Elenpe ti Tapa, Oba Oyekanmi Sunday Titiloye sọ fun awọn akọroyin pe, lootọ ni awọn obi ti bẹrẹ si n ko awọn ọmọ wọn kuro nile ẹkọ.
Ayelala Idol: Onímọlẹ̀ ní olúwẹri obìnrin ni òrìṣà náà ló ṣe ń pọn omi sínú ẹlẹ́ṣẹ̀
O ni igbesẹ awọn obi naa ko ṣẹyin ibẹru pe o ṣeeṣe ki awọn ọdaran darandaran tun kọlu ile ẹkọ wọn.
"Ọba Titiloye ṣalaye pe ""A ko le sun titi ti ilẹ fi mọ lẹyin ti a gbọ pe awọn Fulani n gbero lati ṣakọlu si wa, ṣugbọn a ko mọ akoko ti ikọlu naa yoo waye."""
Ko si awọn agbofinro kankan lagbegbe yii, asiko ti a si nilo iranlọwọ ijọba ree.
Ikọlu to waye ni Igangan naa gba omi loju ọpọ awọn ọmọ ilu naa, ọpọ eeyan ni Naijiria si ti bẹrẹ si fi erongba wọn lede lori ikọlu naa.
Farmers Herders Crisis: Rẹ́rẹ́ rún, ẹ̀mí àti dúkìá ṣòfò lágbègbè Ariwa Yewa
Titi di akoko ti a n ko iroyin yii jọ, awọn agbofinro ko tii ri ẹnikẹni gbamu gẹgẹ bii afurasi to wa nidi ikọlu ọhun.
TB Joshua: Ọba Arigidi ní àwọn kò ní ró òkú wòlíì náà torí ó tí sọ àsọtẹ́lẹ̀ tó jẹ mọ́ ikú rẹ̀ sẹ́yìn
Oríṣun àwòrán, others/bbc
Kabiyesi ilu Arigidi Akoko, to jẹ ilu abinibi oloogbe Temitọpẹ Joshua ti sọ pe ifẹ gbogbo ọmọ ilu naa ni pe ki wọn o sin oku gbajugbaja wolii naa sibẹ.
Ninu ọrọ to ba BBC sọ, Zaki ilu Arikidi, Ọba Yisa Olanipekun sọ pe awọn iranṣẹ Ọlọrun nla bi Mose Orimọlade, Ayọdele Babalọla, Samson Ọbadare, ni wọn sin si ilu abinibi wọn.
O ni lootọ awọn ko ti i ba iyawo oloogbe sọrọ, ṣugbọn dandan ni ki wọn o gbe wa sile.
Lori iroyin to n lọ ni ori ayelujara pe awọn ara ilu Arigidi fẹ ẹ wa idi iku to pa Joshua, Ọba sọ pe ko si nkan to jọ iwadii kankan.
"O ni ""ko si idi ti ẹnikẹni fi fẹ ẹ pa, a gba pe o ti pari iṣẹ ti Ọlọrun ran wa si aye lati ṣe ni, paapaa ninu ọrọ to sọ ni ọjọ diẹ sẹyin."
Adebayo Shittu: Èmi kò ṣẹ Abiola Ajimobi nígbà ayé ẹ, òun ló ṣe mi ṣùgbọ́n.....
Ṣugbọn nkan ti a n sọ ni ẹ ba wa gbe oku ẹ wa si Arigidi fun isinku.
O ni ilu naa yoo di ibi ti gbogbo agbaye yoo ma a wa, lati wa gbadura nibi iboji rẹ, ti wn ba sin sibẹ.
O ni lootọ ni iyawo rẹ kii ṣe ọmọ Arigidi, bẹẹ ni awọn ọmọ rẹ ko de ilu Arigidi ri.
"Ti wọn ko ba fi sin si ile, ko si bi awọn ọmọ tabi iyawo rẹ yoo ṣe de ilu wa mọ.
Magaret Jimoh: Èrè díẹ̀ ti tó mi níbi oúnjẹ ti mò ń tà- Maggie Rice
Oun (Joshua) kọ lo ni ara rẹ mọ, awa la ni ọmọ wa. Ọmọ ologo wa ni, ko si gbọdọ sun sita."""
Kabiesi sọ pe nkan ti gbogbo ọmọ ilu fẹ ni oun sọ, ti oun ko si ni i fẹ ki ọrọ ibi ti wọn yoo sin oloogbe si da wahala silẹ.
Oríṣun àwòrán, T.b joshua minisries
Abẹwo si ilu Arigidi, ipinlẹ Ondo, to jẹ ilu abinibi oloogbe Woli T. B Joshua fihan pe, ẹni to dara nita, dara nile ni.
Ọkan lara awọn agbaagba ni agboole rẹ to ba BBC Yoruba sọrọ, Solomon Olotu, sọ pe awọn mọ iku rẹ lara pupọ.
"A ko ti mọ ẹni ti ọlọrun yoo fi rọpo fun wa, nitori pe oun ni imọlẹ ilu yii.
T.B Joshua ti ma n sọ tẹlẹ pe oun yoo ku, oun ni imọlẹ ilu yii, ibanujẹ lo jẹ fun wa pe o papa ku.
Nigba to n tọka si awọn nkan to ṣe fun ilu Arigidi, Olotu naa sọ pe Joshua lo ra ẹrọ amunawa transformer fun ilu naa, to si tun ma n ko ounjẹ fun awọn arugbo ati alaini loore-koore.
Ẹlomiran to tun sọrọ, ọgbẹni Isaac Olumọfẹ sọ pe, oun ati Joshua jọ gbe papọ ni ilu Eko ni, ko to o dipe aisan da oun pada si ilu Arigidi.
O ni owo ti Joshua fun oun lo da oun pada si aye.
Bakan naa ni Oloye mii sọ pe Joshua lo mu ki ọpọlọpọ ọmọ ilu Arigidi da baalu mọ, nitori pe o ti gbe ẹlikọpita wa si ilu ri, to si gbe si ibi ti gbogbo ara ilu ti ni anfaani lati wọ inu rẹ fun igba akọkọ.
Ọba alade ilu naa, Zaki ti Arigidi, Ọba Yisa Olanipekun sọ pe ilu abinibi rẹ ni awọn fẹ ki wọn o wa sin oku rẹ si.
Tunde Gbadamosi: Kìí ṣe Tinubu ní ipò ààrẹ̀ tọ́ sí, ìgbà wo ní ìtan ajá ń kan lèmọ́mù?
Ọkan lara awọn ẹbi oloogbe to ba BBC sọrọ, Arabinrin Bọsẹ Balogun sọ pe, iku rẹ dun oun pupọ, ki Ọlọrun si gba a si afẹfẹ rere.
Baba mi lo jẹ, bo tilẹ jẹ pe aburo lo jẹ fun mi. Amọ o dun mi pe iku mu u lọ ni ọsan gangan."""
TB Joshua: Apostle Paul M.E ti kéde ikú àgbà wòlíì náà láti oṣù kan sẹ́yìn
Oríṣun àwòrán, TB Joshua Ministries
Gẹgẹ bi awọn alasẹ ijọ Synagogue Church of All Nations (SCOAN) se sọ lasiko ti wọn n kede iku oludasilẹ ijọ naa, Wolii TB Joshua, bẹẹ ni ọrọ iku rẹ ri.
Ijọ naa lo kede ni owurọ ọjọ Aiku pe Ọlọrun kii se nnkan, ko ma kọkọ fi han awọn wolii rẹ saaju.
Bakan naa ni ọrọ ri pẹlu Wolii kan, to ti kọkọ sọ asọtẹlẹ ni osu kan sẹyin pe Ọlarun ti setan lati mu Wolii Temitope Balogun Joshua lọ sile ayeraye.
Ninu fidio kan to gba awọn oju opo ayelujara kan, ni ojisẹ Ọlọrun kan Apostle M.E Paul ti n sasọtẹlẹ pe oun ri awọn angẹli, ti wọn wa gbe wolii TB Joshua lọ kuro laye.
"Ọlọrun fi iran igba ikẹyin kan han mi, ẹ tẹti si mi, mo duro silẹ, a si gbe mi lọ si ọrun, ferese ọrun si silẹ fun mi, mo si duro lati boju wo isalẹ ilẹ nile aye.
Oríṣun àwòrán, Paul M.E Ministries
Mo ri awọn angẹli mẹfa ti a ran lati ọrun wa sile aye pe ki wọn lọ gbe wolii Joshua wa, ohun ti mo ri ni mo n sọ.
Awọn angẹli mẹta mu dani ni ọwọ ọtun ati mẹta ni ọwọ osi, ti wọn gbe wolii TB Joshua soke tente, to si mu ife ẹyẹ kan dani."
Wolii Paul ni oun wo ibi ti awọn wolii naa duro si, ti wọn si ya si apa ọtun, oun naa ba woju wo apa ọtun, amọ oun ko ri oju ẹni to joko sori itẹ.
Bakan naa ni Apostle M.E Paul ni oun gbọ ohun Ọlọrun to n sọ fawọn angẹli naa pe ki wọn gba ife ẹyẹ naa lọwọ Wolii Joshua, ki wọn si mu wa fun oun.
Bakan naa lo ni ki wọn mu wolii naa lọ sibi to yẹ fun.
Tunde Gbadamosi: Kìí ṣe Tinubu ní ipò ààrẹ̀ tọ́ sí, ìgbà wo ní ìtan ajá ń kan lèmọ́mù?
"Lọgan ni mo ri awọn agba angẹli to tun ju awọn ti isaaju lọ, ti wọn n duro sẹba itẹ Ọlọrun, wsn wa gba ife ẹyẹ naa lọwọ wolii TB Joshua, ti wọn si gbe lọ siwaju itẹ Ọlọrun.
O ni Oluwa ni ki awọn angẹli yii si gbe wolii si ibi to yẹ ko wa nitori o ti pari ire ije rẹ nile aye.
TB Joshua's death: Ìyàwó TB Joshua sọ bí ọkọ rẹ̀ ṣe kú àti òhun tó fà á
Oríṣun àwòrán, TB Joshua Ministries
Evelyn to jẹ iyawo gbajugbaja Woli Temitope Balogun ti gbogbo eniyan mọ si TB Joshua, ti sọ bi ọkọ rẹ ṣe ku.
Lasiko to n sọrọ, gẹgẹ bi iwe iroyin Daily Post ti sọ, Evelyn ni TB Joshua lo igbẹyin aye rẹ lati fi gbadura fun awọn ara ilẹ India lori ohun ti wọn n la kọja lati igba ti aarun Coronavirus ti bẹ silẹ nibẹ.
O ni Woli naa ni wọn ri ninu ọfisi rẹ to ti ku lẹyin to ṣe isin tan ni irọlẹ ọjọ Satide naa.
Awọn ti wọn sunmọ iyawo oloogbe naa ni Evelyn sọ awọn ọrọ yii lasiko ti awọn eniyan lati ilẹ okeere ba obinrin naa ṣe ipade lẹyin iku ọkọ rẹ.
''Ọkọ mi ṣe iṣẹ rẹ tan ninu igbagbọ nitori wakati mẹta lo fi gbadura, ki o to lọ si isin ori oke, ti ilera ara rẹ si pe samu samu.''
Tunde Bakare: Àjọjẹ kò dún bẹ́nìkan kò ní ló fa ìjà S Igboho,bẹ́ẹ̀ ìjọbati gbẹ́rù kọjá orí
''Ko fi igba kankan fi ami han bi ẹni to n ṣe aisan, ti gbogbo ọrọ rẹ si da le lori gbigba adura fun awọn ara ilẹ India ti aarun covid-19 n ba finra.''
''Ko pẹ si igba yii, ni o wa si yara lati wa wẹ, ti mo si fi silẹ ko lo akoko to nilo lati fi mura, ki isin to bẹrẹ.
''Laipẹ lo jade ninu ile lati lọ waasu laarin isin, to si sọ wi pe ohun gbogbo ni igba ati asiko wa fun, igba ki eniyan wa, ati igba ki eniyan lọ''
''Ọrọ rẹ kun fun ẹmi ati ipaya nitori lọgan to sọ awọn ọrọ yii, naa lo dede kuro ni ile ijọsin to si lọ si inu ile.
Mo duro fun igba diẹ lati wo boya yoo jade, nigba ti n ko gburo rẹ ni mo wọle, ti mo si ba lori ijoko bi ẹni  to dorikodo, amọ ko mọ ara mọ.''
Adebayo Shittu: Èmi kò ṣẹ Abiola Ajimobi nígbà ayé ẹ, òun ló ṣe mi ṣùgbọ́n.....
''Ni kiakia ni mo pe awọn amugbalẹgbẹ rẹ ki wọn ji i, amọ ko si ohun ti wọn le ṣe lasiko naa.''
''Mo gba lootọ wi pe o lọ ba Ọlọrun nile ni nitori o ṣiṣẹ takuntakun nigba ti o wa pẹlu wa, ti opin ọrọ rẹ si awọn eniyan ni lati ''ma a ṣọra, ki wọn si ma a gbadura''.
Ọjọ Karun un, Oṣu Kẹfa, ọdun 2021 ni gbajugbaja Woli agbaye TB Joshua jade laye ni ẹni ọdun mẹtadinlọgọta.
Oyo LG Crisis: ALGON ní Seyi Makinde ń ṣe bíi Baṣọ̀run Gáà, tí kò bọ̀wọ̀ fún òfin
Awọn alaga ijọba ibilẹ ana ni ipinlẹ Oyo, ALGON, ti gomina Seyi Makinde da duro, ti sọ pe gomina ọhun kii ṣe ẹni to n bọwọ fun ofin.
Ayodeji Abass Alesinoye, to jẹ alaga ẹgbẹ ALGON lo sọ ọrọ ọhun ninu ifọrọwerọ kan pẹlu BBC Yoruba, iyẹn lẹyin ti Makinde kọ jalẹ lati san owo awọn alaga naa, eyi ti ile ẹjọ paṣẹ pe ko san fun wọn.
Bi ẹ ko ba gbagbe, asiko ijọba gomina ana, Abiola Ajimobi  ni wọn dibo yan awọn alaga naa, ti wọn jẹ ọmọ ẹgbẹ APC.
Sugbọn lẹyin wakati diẹ ti Makinde de ori oye, lo yọ awọn eeyan ọhun bii jiga lẹyin to ni idibo to gbe wọn wọle ko ba ofin mu.
Ṣugbọn awọn alaga ọhun gbe Makinde lọ sile ẹjọ, ile ẹjọ si ṣe idajọ pe ko san owo oṣu awọn alaga naa fun wọn.
Tunde Gbadamosi: Kìí ṣe Tinubu ní ipò ààrẹ̀ tọ́ sí, ìgbà wo ní ìtan ajá ń kan lèmọ́mù?
Bo tilẹ jẹ pe Makinde ṣetan lati san owo naa ṣaaju ki wọn to lọ sile ẹjọ, ti awọn eeyan ọhun si kọ jalẹ, ni bayii Makinde ti wa fake kọri pe oun ko ni owo kankan san mọ.
O ni ki awọn alaga naa pada silẹ ẹjọ, ki ile ẹjọ ọhun si salaye irufẹ awọn alaga ti oun yoo san owo fun ninu wọn.
Awijare rẹ ni pe alaga ijọba ibilẹ mẹtalelọgbọn ni ofin ilẹ wa mọ pe o wa nipinlẹ Oyo amọ gomina ana, Abiola Ajimobi lo da awọn ijọba ibilẹ onidagbasoke to to marunlelọgbọn silẹ.
Makinde ni ko seese ki oun sanwo fun awọn alaga ijọba ibilẹ ti apapọ wọn jẹ mejidinlaadọrin, nigba ti ofin mọ mẹtalelọgbọn pere ninu wọn.
Teachers retirement age and years of service: Ìrírí àwọn àgbà olùkọ́ ṣì wúlò fún àwa ọ̀dọ́
ALGON ni Makinde n se bii Basọrun Gaa, ti ko si bọwọ fun ile ẹjọ
Lasiko to n ba BBC Yoruba sọrọ, alaga ALGON, Ayodeji Abass Alesinoye ṣalaye pe o ṣeni laanu pe kii ṣe irufẹ gomina Makinde lo yẹ ko maa tapa si ofin.
O ni Gomina yii kan naa ni ile ẹjọ sọ pe oun gan lo jawe olubori ninu eto idibo, ko si sọ pe ile ẹjọ ṣisọ nigba naa lọhun."""
Ṣugbọn bayii Makinde ti n ṣe bii Baṣọrun Gaa ti ko bọwọ fun ofin, o si jẹ ohun iyalẹnu pe Makinde ko bọwọ fun aṣẹ ile ẹjọ.
O ni ni bayii ti ile ẹjọ naa ti fun Makinde di ọjọ keje, oṣu Kẹjọ, ọdun yii, awọn n duro de nnkan ti Makinde yoo ṣe boya yoo kọ lati ma san owo tabi bẹẹ kọ, ti akoko ba to.
"Alesinloye pari ọrọ rẹ pe ""Makinde ko ni ibọwọ fun ofin kankan, ti gbedeke ọjọ ti wọn fun un ba ti pe, oju rẹ yoo ri ohun ti oju awọn ti ko bọwọ fun ofin maa n ri."""
BBC tun kan si akọwe ẹgbẹ APC nipinlẹ Oyo, iyẹn Mojeed Olaoya lati da si ọrọ naa.
Oyo LG Polls: OYSIEC ní APC ló yẹ kò bẹ aráàlú lórí àṣìṣe rẹ̀ nípa ìbò ìjọba ìbílẹ̀
Olaoya sọ pe oun ko ni nnkankan lati sọ lori ọrọ naa ju pe awọn n duro ki gbedeke ọjọ ti ile ẹjọ fun gomina Makinde pe, ki awọn to mọ igbesẹ to kan.
"Gẹgẹ bo ṣe sọ ""Olofin ni awa, a kii kọ dindinrin lọgbọn, a n wo boya yoo ṣe ohun ti ile ẹjọ pa laṣẹ fun tabi bẹẹ kọ, ki a to mọ ohun ti a ṣe lori ọrọ naa."""
Ẹwẹ, nigba ti alaga ẹgbẹ APC ti ọrọ naa kan gbọngbọn, Akin Oke n da si ọrọ ọhun, o ni awọn ko tii ri iwe idajọ naa ṣugbọn oye ni agba n wo.
Akin Oke sọ pe, awọn agba ẹgbẹ ṣi n fi oju ṣunukun wo ọrọ naa titi di igba ti awọn yoo foju gan ni iwe idajọ ati akoko ti ile ẹjọ fun gomina Makinde yoo pe.
Twitter ban, NBC, media agencies: Ẹ̀yin iléesẹ́ ìròyìn gbogbo ní Nàìjíríà, Ẹ dẹ́kun líló 'Twitter' bí bẹ́ẹ̀ kọ́...- NBC
Oríṣun àwòrán, Naijanews.com
Leyin ikede ti ijọba Naijiria ti fopin sin lilo ọna ibaraẹnisọrọ 'Twitter', ajọ to n mojuto ọrọ awọn ileesẹ iroyin gbogbo ni Naijiria, National Broadcasting Commission (NBC) ti fi asẹ mii sita.
Ajọ NBC kede pe lati asiko yii lọ gbogbo ile isẹ iroyin ni Naijiria bii, Redio, Amohunmaworan ati bẹẹ bẹẹ lọ gbọdọ fopin si lilo 'Twitter'bayii.
Ojogbọn Armstrong Idachaba lo fi atẹjade naa sita pe ijọba koro oju si bi awọn ileesẹ iroyin kan ni Naijiria si se n lo 'Twitter'titi di asiko yii.
"Idachaba ni: "" Lataari asẹ ijọba Naijiria, a gba imọran pe ki awọn ileese iroyin ni Naijiria dẹkun lilo 'Twitter'ati lilo o gẹgẹ bii UGC ti wọn fi n yẹ iroyin wọn wo."
Oríṣun àwòrán, NBC
"Abala 2 (1) ninu iwe ofin NBC sọ pe NBC ni agbara lati rii daju pe gbogbo ileesẹ iroyin mu asẹ ijọba se nigba gbogbo ni eyi to maa mu adinku ba iwa ibajẹ ni awujọ wa""."
Tunde Gbadamosi: Kìí ṣe Tinubu ní ipò ààrẹ̀ tọ́ sí, ìgbà wo ní ìtan ajá ń kan lèmọ́mù?
Bakan naa lo menuba abala 5, 6, ati 3 iwe alakalẹ naa to sọ pe ileese iroyin gbọdọ sọra fun lilo ohun eelo iroyin to le fa iyapa, ija tabi asọ ni awujọ.
"Eyi ja si pe ko bojumu to ki ileese iroyin ni Naijiria maa lo ""Twitter' lẹyin ti ijọba ti fofin de wọn."
Snail Slim Soap: Wo ọ̀pọ̀ àǹfààní tó wà nínú lílo ọ̀ṣẹ tí wọn fi omi ìgbín ṣe láti fọ ojú?
Imeko-Afon Attacks: Iléeṣẹ́ ọlọ́pàá Ogun ní ìṣẹ̀lẹ̀ náà jọ ti ìdigunjalè
Kaka ki ewe agbọn dẹ lori iwa isekupani ọlọgọọrọ to n lọ nilẹ Yoruba, ko ko ko lo tun n le si.
Bi awọn agbofinro si se n ge awọn asekupani yii lọwọ, naa ni wọn tun n bọ oruka, ti wọn si n gba ẹmi alaisẹ laibikita.
Ni oru mọju ọjọ Aiku ni iroyin gbalẹ kan pe awọn afurasi darandaran tun ya bo ilu Igangan lagbagbe Ibarapa nipinlẹ Oyo, ti wọn si sekupa eeyan to le ni mọkanla, gẹgẹ bi ọlọpaa ti sọ.
Ni idaji ọjọ Aje ana tun ni iroyin miran gbalẹ kan pe awọn ẹni bii yii tun ti morile ilu Imeko-Afon nipinlẹ Ogun, ti wọn si tun gba ẹmi eeyan mẹta.
Isẹlẹ naa ni iroyin sọ pe o waye ni oru mọju ọjọ Aje bakan naa, ti ọrọ si di boo lọ, ko yago fun mi.
Farmers Herders Crisis: Rẹ́rẹ́ rún, ẹ̀mí àti dúkìá ṣòfò lágbègbè Ariwa Yewa
Gẹgẹ bi awọn eeyan kan ti sọ, wọn ni awọn agbebọn to se ọsẹ nilu Igangan, naa ni wọn tun morile ilu Imeko Afon, ti ko jinna si Igangan, lati paniyan.
Nigba to n fidi isẹlẹ naa mulẹ fun BBC Yoruba, osisẹ kan lara ikọ alaabo alajumọse ni agbegbe Imeko Afon, amọ ti ko fẹ ka darukọ oun ni lootọ ni isekupani naa waye.
Osisẹ agbofinro naa ni awọn arọko ti ọpọ eeyan ti n sisẹ agbẹ bii Gbondoko, Ladugba ati Afon, ti wsn wa nijọba ibilẹ Imeko Afon, ni ikslu naa ti waye.
O fikun pe awọn ko sun mọju lati ri daju pe ohun gbogbo pada bọ sipo lawọn agbegbe naa.
Ayelala Idol: Onímọlẹ̀ ní olúwẹri obìnrin ni òrìṣà náà ló ṣe ń pọn omi sínú ẹlẹ́ṣẹ̀
O si fidi rẹ mulẹ pe ẹmi mẹta lo ba ikọlu naa lọ lawọn abule naa.
"Ẹ wo, gbogbo awọn agbẹ to n sisẹ oko lagbagbe yii ni wọn ti n ko ẹru wọn lati sa kuro nitori ikọlu gbogbo igba to maa n waye nibẹ.
Gbogbo agbegbe naa si lo kan gogo bayii, koda, a ko sun mọju."
Nigba toun naa n fidi isẹlẹ yii mulẹ, osiẹ alarina fun  ileesẹ ọlọpaa ipinlẹ Ogun, Abimbola Oyeyemi ni lootọ lo waye amọ kii se ikslu afurasi darandaran.
Oyeyemi ni isẹlẹ naa lo jẹ ti awọn adigunjale, nitori wọn ja ọkada gba, ti wọn si ji gbe lọ.
Tunde Gbadamosi: Kìí ṣe Tinubu ní ipò ààrẹ̀ tọ́ sí, ìgbà wo ní ìtan ajá ń kan lèmọ́mù?
"Awọn ti wọn kọlu yii jẹ agbẹ lati orilẹede Benini to maa n wa sisẹ oko lorilẹede Naijiria.
Wọn n gun ọkada lọ, ti wọn si bọ sọwọ awọn eeyan to sẹburu wọn, wsn pa wọn, ti wọn si tun gbe awọn ọkada wọn salọ.
A ko mọ boya darandaran ni wọn amọ ikọlu naa fara pẹ isẹlẹ idigunjale nitori wọn ji ọkada gbe lọ.
Kii se igba akọkọ ree ti iru isẹlẹ bayii yoo waye ni agbegbe Imeko-Afon, eyi to n mu ẹmi ọpọ eeyan lọ.
'O kúrò nílé lẹni ọdún mẹ́rìndínlọ́gbọ̀n, lẹyìn ọgọ́ta ọdún ló bá ṣadede yọ sí ìlú padà'
Njẹ ẹyin ti ri ibi ti eeyan ti dawati fun ọgọta ọdun to si ṣadede foju han pada si awọn araale rẹ?
Ọrọ yi da bi fiimu ṣugbọn kii ṣe awada rara.
Ni ilu kan ti wọn n pe ni  Dakatsalle ni ijọba ibilẹ Bebeji ni Kano ni iroyin kayeefi yi ti ṣẹlẹ.
Niṣe ni  wọn tu yaya sita lati wa wo baba agbalagba kan ti o pada wale lẹyin ọgọta ọdun ti o dawati.
Bẹẹ ni, ọgọta ọdun lẹyin ti Mallam Saidu Abdullahi file silẹ lẹni ọdun mẹrindinlọgbọn, ṣadede ni wọn ri to pada wale lagbalagba.
Ki ọrọ yi baa le ye wa daada,ko pẹ si igba ti Naijiria gba ominira ni o file silẹ to si sọ fun akọroyin BBC pe ọkan oun ti n fa ile ṣugbọn oun ko ribi pada wa sile.
Akọroyin BBC Khalifa Shehu Dokaji to ṣabẹwo si idile Saidu jabọ pe awọn ọmọ, mọlẹbi, ọmọọmọ ati awọn alabagbe pe biba lati wa ba wọn yọ pe o pada wa sile.
Ilu Ibadan ni iṣẹ aje gbe Saidu Abdullahi lọ nibi to ti n ṣe owo awusa.
A tun gbọ pe iya rẹ lo gba niyanju lati tọ ẹgbọn baba rẹ kan lọ nigba ti o wa ni ẹni dun mẹrindinlọgbọn.
Wòólì Alfred kú lọ́dún 1964, ó tún padà wà sí ìlú Agelu f'ọ́jọ́ mẹ́rìnlá!
Gẹgẹ bo ti ṣe ṣalaye fun BBC, nigba aye Emir Abdullahi Bayero to jẹ baba baba Emir Kano to wa lori oye lo ni oun ti kuro nile.
Ni igba taa n sọ yi, wọn ko tiẹ ti lala pe wọn yoo da ipinlẹ Kano silẹ rara.
Iṣiro ọdun taa n wi yi jẹ laarin dun 1926-1953.
Pupọ awọn mọlẹbi lo ti sọ ireti nu koda awọn miran ro pe o ti ku ni.
Ohun iyalẹnu kan ni pe ede ẹnu rẹ ko yi pada ati pe arugbo ko ni ko ma mọ ohun to n ṣẹlẹ lawujọ.
Igangan Attacks: Sunday Igboho ní ológun dá òun lọ́nà láti wọnú ìgbó wá afurasí ọdaràn
Oríṣun àwòrán, Screen shot/Koiki Media
Lẹyin ikọlu to waye niluu Igangan lagbegbe Ibarapa nipinlẹ Oyo, ajijagbra to tun jẹ ajafẹtọ ọmọniyan, Oloye Sunday Igboho ti ṣabẹwo siluu ọhun.
Gẹgẹ bii fidio to wa loju opo ayelujara fun agbẹnusọ ajijagbara naa, Olayomi Koiki se sọ, se ni awọn olugbe ilu naa n fo fayọ lasiko ti Igboho balẹ sinu ilu naa tan.
Gẹgẹ bii ohun ti a gbọ, afojusun Igboho ni lati wọ inu igbo kijikiji to wa niluu naa lọ pẹlu erongba lati ṣawari awọn afurasi to ṣiṣe laabi ọhun.
Bo tilẹ jẹ pe kii ṣe igba akọkọ ree ti awọn ọdaran Fulani darandaran yoo ṣekọlu si Igangan, ikọlu to waye kẹyin yii gba omi loju eeyan.
Iroyin ni ko pẹ ti Igboho atawọn ẹmẹwa rẹ gunlẹ sinu ilu naa tan, ti awọn ọmọ ogun naa de.
Oríṣun àwòrán, Screen Shot
Igbagbọ ọpọ eeyan ni pe awọn ọmọ ogun yoo da alaafia pada sinu ilu ọhun.
Ṣugbọn Olayomi Koiki jabọ pe ko din ni ọkọ ayọkẹlẹ mẹwaa ti awọn Ologun naa gbe wa pẹlu erongba lati da Sunday Igboho lọna, ko ma baa wọ inu igbo naa.
Gẹgẹ bo ṣe sọ, awọn ọmọ ogun to lọ Igangan ko fẹ ki Igboho mu awọn afusari to kọlu ilu naa ni.
O ṣalaye pe awọn olugbe ilu ọhun ko gba awọn ọmọ ogun naa laaye lati wọ ilu wọn, eyi to mu wọn da awọn ologun naa pada lẹnu ibode ilu ọhun pẹlu ọgbọn ati awada.
Iroyin naa ni Igboho si wa ninu igbo naa, to n wa awọn afurasi ọdaran to kọlu ilu Iagnagan lọjọ Aje kiri lati mu wọn.
Ti ẹ ko ba gbagbe, oru mọju ọjọ Abamẹta si ọjọ Aiku ni awọn afurasi Fulani darandaran kọlu ilu naa, ti wọn si ṣekupa ọpọ eeyan, bakan naa ni wọn tun jo ọpọ dukia bii ile ati ọkọ.
Ayelala Idol: Onímọlẹ̀ ní olúwẹri obìnrin ni òrìṣà náà ló ṣe ń pọn omi sínú ẹlẹ́ṣẹ̀
Akọroyin BBC to ṣabẹwo si ilu naa lọjọ Aje jabọ pe nnkan ti awọn afurasi naa bajẹ ko lonka.
Lara awọn ibi to foju ganni, ti awọn afurasi naa dana sun ni Aafin Asigangan ti ilu Igangan, to jẹ ori ade ilu naa.
Ti ẹ ba ranti daadaa, agbegbe Ibarapa yii naa ni okiki Sunday Igboho ti kọkọ bẹrẹ si n milẹ titi losu kinni ọdun yii.
Akoko yii, tii se osu kinni ọdun 2021 lo fun awọn Fulani to n gbe lagbagbe ọhun ni gbedeke ọjọ meje, lati fi ibẹ silẹ lẹyin ti wọn fi ẹsun ipaniyan ati ijinigbe kan wọn.
Agbegbe yii naa ni awọn OPC ti fi panpẹ ofin mu arakunrin kan ti wọn n pe ni Iskilu Wakili, ti wọn sọ pe oun ni baba isalẹ fun awọn ọdaran darandaran lagbegbe naa.
Oba Gbolahan Timson Shomolu Bariga ní 'Restructuring'ti bọ́ aṣọ kò bá Omọyẹ mọ́!
Ọpọ awọn alẹnulọrọ lawujọ lo ti bẹrẹ si n bu ẹnu atẹ lu ikọlu naa, to fi mọ awọn eeyan bii gomina ipinlẹ Ondo, Arakunrin Rotimi Akeredolu ati Aarẹ Onakakanfo ilẹ Yoruba, Iba Gani Adams atawọn eeyan mii.
Lẹyin o rẹyin, o ṣe ni laanu pe titi di akoko ti a n ko iroyin yii jọ, awọn agbofinro ko tii ri ẹnikẹni gbamu gẹgẹ afurasi to wa nidi ikọlu ọhun.
Sani Abacha: Àwọn àsìkò tó làmìlaaka nínú ayé olóògbé
Igangan Attacks: Ọdẹ Asọ̀lúdẹ̀rọ́ àti OPC ní ààbò Yorùbá di ojúṣe àwọn bí ààbò ìjọba ṣe kùnà,
Oríṣun àwòrán, Zenger
Yoruba ni ailasọ lọrun paaka, o to apero fun gbogbo ọmọ eriwo, iku to si n pa ojugba ẹni, owe nla lo n pa fun ni.
Awọn isẹlẹ isekupani to n waye lemọ lemọ lẹnu lọọlọ yii ti di irawọ ọsan, to n bawọn agba lẹrun bayii.
Laarin ọjọ mẹta, awọn agbebọn ti kọlu ilu Igangan nibiti ti ọpọ ẹmi ti bọ, ti dukia si bajẹ, bẹẹ naa ni wsn pa ọpọ eeyan ni agbegbe Imeko-Afọn nipinlẹ Ogun.
Ka ma sẹsẹ sọ awọn eeyan ti ọpọ adigunjale, ajinigbe atawọn afinise etutu ọla ti pa, ti awọn iwa ọdaran yii si n tẹsiwaju.
O si dabi ẹni pe apa awọn agbofinro ko fẹ ka awẹn apaniyan yii nitori wọn kii saba ri wọn mu lẹyin ọsẹ ti wọn ba se.
Ayelala Idol: Onímọlẹ̀ ní olúwẹri obìnrin ni òrìṣà náà ló ṣe ń pọn omi sínú ẹlẹ́ṣẹ̀
Idi ree ti ọpọ eeyan fi n lọgun pe nibo ni awọn ọdẹ ibilẹ atawọn eeyan to n pese aabo fun ilẹ Yoruba wa lati pese eto aabo to peye fun wa?
Yoruba sa ni ki agbado to dele aye, nnkan sa ni adiẹ n jẹ, bi a ko ba si ri adan, a le fi oobẹ se ẹbọ.
Ọna lati wa idahun sawọn ibeere araalu yii lo mu BBC Yoruba kan sawọn ọdẹ ibilẹ, ẹgbẹ OPC, Agbekoya atawọn fijilante.
Ohun ta si bi wọn ni pe ki ni wọn n se lati pese eto aabo to gbopọn fun ilẹ Yoruba, ti yoo fi di aiwọ fun awsn ọdaran?
Yoruba sa ni a kii ni ọkọ nilẹ, ka tun maa fi ọwọ ko imi.
Oba Gbolahan Timson Shomolu Bariga ní 'Restructuring'ti bọ́ aṣọ kò bá Omọyẹ mọ́!
Nigba to n dahun ibeere yii, awọn ogboju ọdẹ asọludẹrọ ti sọ pe awọn ti ṣetan lati yanju gbogbo rogbodiyan iṣekupani to n waye lagbegbe Ibarapa ati to eto abo to mẹhẹ kaakiri ilẹ Yoruba.
Alaga ẹgbẹ Ọdẹ Asọludẹro, Alhaji Ajijola Anọbi lo sọ bẹẹ fun BBC Yoruba.
O ni ijọba ipinlẹ Oyo ti gba lati fọwọsowọpọ pẹlu awọn lati lọ pẹtu si wahala naa, koda o ni irọlẹ oni gangan ni awọn n  lọ ilu Igangan.
Ajijola Anobi ni Ara oun ti a n ba ijọba sọ tẹlẹ naa niyẹn ti wọn ko fẹ gbọ, ṣugbọn bayii wọn ti mọ pataki pe ọdẹ lo ni inu igbo."""
Ọdẹ lo n sun ninu igbo, ọdẹ lo ni igbo, a maa n pade awọn anjọnu ati oriṣiri ẹranko ninu igbo ko si si nnkan ti wọn yoo fi wa ṣe.
Tunde Bakare: Àjọjẹ kò dún bẹ́nìkan kò ní ló fa ìjà S Igboho,bẹ́ẹ̀ ìjọbati gbẹ́rù kọjá orí
"Alaga naa ṣalaye siwaju si pe ""O soro lati ko ọlọpaa ti ko wọ inu igbo ri, lati wọ inu igbo, awa ọdẹ ni a mọ gbogbo kọrọkọndu inu igbo."""
O fikun pe kii ṣe ilu Igangan nikan ni awọn yoo ti ṣiṣẹ lasiko yii.
Gẹgẹ bo ṣe sọ, awọn ọdẹ asọludẹrọ ti ṣe ipade pẹlu awọn akẹgbẹ wọn kaakiri ilẹ Yoruba, awọn si ti ṣetan lati da alaafia pada si agbegbe Igangan ati gbogbo  ilẹ Yoruba lapapọ.
Ni ti awọn irinṣẹ ti wọn yoo lo lati fi koju awọn ọdaran darandaran to n da alaafia ilẹ Yoruba laamu, Ajijola Anobi sọ pe yatọ si awọn nnkan abalayeti wọn n lo, ibọn ibilẹ naa wa lọwọ wọn, ibọn naa si tẹ awọn lọrun ju awọn ibọn nla nla ti awọn agbofinron ijọba n gbe kiri.
O pari ọrọ rẹ pe awọn ti ba ibọn atawọn nnkan ija miran to jẹ ti abalaye mulẹ, awọn si gbagbọ pe awọn yoo bori ija naa.
Adebayo Shittu: Èmi kò ṣẹ Abiola Ajimobi nígbà ayé ẹ, òun ló ṣe mi ṣùgbọ́n.....
Ẹwẹ, BBC Yoruba kan si Sina Akinpelu to jẹ agbẹnusọ ẹgbẹ OPC New Era, o ni awọn naa ti bẹrẹ eto lati yanju eto abo to mẹhẹ lagbegbe Ibarapa.
Gẹgẹ bi ohun to sọ fun BBC, nnkan ti wọn kọkọ n ṣe ni lati ṣe iwadii awọn to wa nidii iṣẹlẹ naa nitori o ṣeeṣe ki ejo lọwọ ninu.
Akinpelu fi kun pe, ajọṣepọ to dan mọran lo wa laarin awọn ati ẹgbẹ ọdẹ Asọludẹrọ, ikọ Amotekun atawọn ẹṣọ alaabo miran to jẹ ti ilẹ Yoruba.
O fi kun pe ifọwọsowọpọ to wa laarin awọn ẹgbẹ naa ni ko jẹ ki iṣẹlẹ to waye ni Igangan ju bo ṣe waye lọ.
Magaret Jimoh: Èrè díẹ̀ ti tó mi níbi oúnjẹ ti mò ń tà- Maggie Rice
Bo tilẹ jẹ pe o ni awọn ijọba nilẹ Yoruba ko tii fọwọsowọopọ pẹlu awọn bo ṣe yẹ ko ri, ṣugbọn o ni igbagbọ awọn ni pe ijọba yoo kin awọn lẹyin laipẹ.
Akinpẹlu pari ọrọ rẹ pe, awọn ko ni gba ki awọn Fulani ko ilẹ Yoruba lẹru, bi wọn ṣe ko awọn ẹya kan lẹru lọpọ ọdun sẹyin.
TB Joshua: Ariwo sọ lórí ayélujára nípa Pásítọ̀ tó ní ìṣẹ́gun ńla ni ikú wòlíì náá jẹ́ fún òun
Oríṣun àwòrán, TB Josua Ministries
Yoruba ni ba ku laa dere, eeyan ko sunwọn laaye, ti wọn si maa n koro oju si ki eeyan tabuku ẹni to ba ti ku.
Idi ree ti ọpọ eeyan se ta gba Pasitọ kan lorilẹede Kenya to n fo fayọ nitori wolii TB Joshua jade laye.
Jackson Seyonga, tii se pasitọ agba fun ijọ Christian Life to wa nilu Kampala lo n yọ lori iku wolii naa ninu fidio kan to gba ori ayelujara kan.
Ni kete ti Pasitọ Seyonga gbọ nipa iku Joshua lọjọ Aiku lasiko isin to n lọ lọwọ nile ijọsin rẹ, eyi ti wọ̀n n fi ẹrọ ayaworan ka silẹ, lo n fo fayọ pe eeyan ibi jade laye.
"Wolii TB Joshua ti ku, ẹ ke Haleluyah, alẹ ana lo ku. Se bi mo sọ fun gbogbo yin pe Ọlọrun nikan lo le bori ogun ni orukọ Jesu.
Mo ri iku rẹ bii isẹgun fun mi."
Pasitọ naa wa sọ nipa ọpọ eeyan to ku nibi isẹlẹ ile to wo ninu ijọ Sinagogu lọdun 2014, ninu eyi ti ọpọ ọmọ ilẹ okeere wa nibẹ.
Oríṣun àwòrán, Jackson Seyonga
"O ro pe aye toun se iyebiye ju aye ẹgbẹlẹgbẹ eeyan to ku ninu isẹlẹ naa lọ. Ki lo mu ko ro pe oun le pa ọpọ eeyan tori pe o fẹ se irubọ?
O fikun pe ajẹ nla to n gba ọpọ ẹmi eeyan ni TB Joshua to jade laye naa, ẹsan lo de fun.
Amọ ọpọ eeyan lo ti n fesi lori fidio naa, ti wọn si n sọ oko ọrọ pada si Pasitọ Seyonda fun iwa ẹsẹ to hu naa.
Lara awọn eeyan to si n tako isẹlẹ yii ni Daddy Freeze wa.
Ayelala Idol: Onímọlẹ̀ ní olúwẹri obìnrin ni òrìṣà náà ló ṣe ń pọn omi sínú ẹlẹ́ṣẹ̀
Gbajumọ onwoye kan lori ayelujara, Ifedayo Akinrinde, ti ọpọ eeyan mọ si Daddy Freeze ti wa fesi pada fun ojisẹ Ọlọrun to n yọ iku akẹẹgbẹ rẹ naa.
Ninu fidio miran to gbe sita l;oju opo Instagram rẹ, Daddy Freeze ni se ni ara oun n gbọ lati gbọ pe Kristiẹni le yọ lori iku ẹnikan.
O ni o ti foju han pe ọta nla ni awọn mejeeji loju aye amọ eyi ko fun Pasitọ naa lẹtọ lati maa yọ lori iku ẹlomiran.
Freeze wa tọka si awọn ẹsẹ inu iwe mimọ Bibeli, Iwe Owe ori Kẹrinlelogun ẹsẹ ikẹtadinlogun ati ikejidinlogun, to ni ka mase dunnu si isubu ẹlomiran.
King Sunny Ade's son: Ohùn orin bàbá mi nìkan kọ ni l’Ọlọrun fún mi, ijó bíi kòkòrò ni ṣáá
O ni ọkan oun rẹwẹsi lori fidio naa, ti oun ko si gbagbọ nipa ohun ti eti oun n gbọ.
Kii se iwa ọmọ Ọlọrun lati maa yọ lori iku ọta ẹni, nitori a ko kọ wa bẹẹ."
Igangan Massacre; Orílẹ̀ède 174 káàkiri àgbáyé ní ìwọ́de Yoruba Nation yóò tí wáyé ní June 12
Oríṣun àwòrán, Others
Ọkan lara ẹgbẹ ọmọ Yoruba to gajulọ lagbaye, Yoruba One Voice ti kede pe awọn yoo ṣe iwode kaakiri agbaye ni Ọjọ Ayajọ June 12 lati pe fun idaduro orilẹede Yoruba kuro ni ara Naijiria.
Alaga ẹgbẹ naa, Abilekọ Ọmọladun Orolugbagbe ni ẹgbẹ naa ti pari gbogbo eto ti wọn nilo ki ayẹyẹ naa fi le waye.
Ẹgbẹ Yoruba One Voice fikun kaakiri awọn orilẹede to wa lagbaye to fi mọ orilẹede mẹrinlelaadọsan ni iwode naa yoo ti waye.
Orolugbagbe ni asiko ti to fun gbogbo ọmọ ilẹ Yoruba lati dide ki wọn fi ọwọ sowọpọ pẹlu awọn to n pe fun idaduro orilẹ-ede Yoruba, ki o le ṣeeṣe.
Tunde Gbadamosi: Kìí ṣe Tinubu ní ipò ààrẹ̀ tọ́ sí, ìgbà wo ní ìtan ajá ń kan lèmọ́mù?
Orolugbagbe  fikun pe ko dun mọ awọn ọmọ ilẹ Yoruba kaakiri agbaye ninu pẹlu iṣekupani ọlọgọọrọ to n waye lojoojumọ nibẹ.
''June 12 jẹ ọjọ kan pato ninu itan awọn ọmọ Yoruba ti wọn dibo lati gba ara wọn silẹ lọw ijọba ologun kaakirii Naijiria.
Oríṣun àwòrán, Others
''Nitori naa ni a se fẹ ṣe iwode oun ni ọjọ naa ki gbogbo aye le ri wi pe awọn ọmọ Yoruba to wa lokeere naa fi ọwọ si idaduro ilẹ Yoruba kuro lara Naijiria.''
Ẹgbẹ Yoruba One Voice naa fi ẹhọnu han si ijọba apapọ lori aibikita pẹlu ipaniyan to n waye ni ilẹ Yoruba ati ni orilẹede Naijiria, ti wọn si sapejuwe ti eleyii to n ṣẹlẹ ni ilu Igangan ni ijọba ibilẹ Ibarapa, nipinlẹ Ọyọ.
O fikun wi pe iroyin to tẹ awọn lọwọ ni wi pe awọn ọmọogun Naijiria ti wọn wọ  aṣọ araalu lo hu iwa ọdaran naa, ti ko si si ẹni to le e tọka si wọn wi pe awọn ni wọn ṣiṣẹ naa.
Magaret Jimoh: Èrè díẹ̀ ti tó mi níbi oúnjẹ ti mò ń tà- Maggie Rice
Ẹgbẹ naa ni awọn ko ni igbagbọ ninu orilẹede Naijiria mọ ati ijọba to wa lode yii nitori wọn ko ri nkankan ṣe si ipaniyan, ijinigbe ati ọpọlọpọ iwa ọdaran to n waye lojoojumọ ni Naijiria.
Funmi Aragbaiye: Ọlọ́run ní ohun táwọn olórí wa fẹ́ jẹ ni wọn ń wá ni ìlú kò fi rọgbọ
Ilumọọka akọrin ẹmi nni, Funmi Aragbaiye ti kede pe ọjọ ti pẹ ti Ọlọrun ti fi iran han oun nipa idasilẹ orilẹede Yoruba.
Aragbaiye, lasiko to n ba BBC Yoruba sọrọ salaye pe Ọlọrun sọ fun oun ninu ẹmi pe aisi isọkan laarin iran Yoruba le mu ifasẹyin wa lori idasilẹ orilẹede wọn.
O ni idi ree ti oun se gbe awo orin kan sita nigba naa lati parọwa si iran Yoruba pe ki wọn se ara wọn ni ọkan soso.
Akọrin ẹmi naa tun woye pe ohun ko ri iru asiko ti ilu yoo le bayii ri lati igba ti oun ti de ile aye, eyi to ni ko sẹyin awọn asaaju ilẹ wa ti ko dara.
O fikun pe aye ologun la n pariwo pe ko dara laimọ pe akoko ti yoo buru si wa niwaju lasiko ti oun fi orin ẹmi se isipaya fawọn eeyan ni bii ọgbọn ọdun sẹyin.
O wa salaye pe gbogbo ọmọ Naijiria la ti sẹ, ti iya yii fi pọ, awa si ni ko jẹ ki adura gba lori orilẹede yii.
Àwọn ìtàn mánigbàgbé tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí:
Ajihinrere naa wa woye pe nnkan ko le pada si bo se wa sẹyin mọ ayafi ka maa bẹ Ọlọrun ko mu igba dẹ wa lọrun pada ni.
Igangan Attacks: Sunday Igboho ní àwọn ọba ní gómìnà Makinde ló ní kí áwọn sálọ nígbà tí òun dé Ibarapa
Ajijagbara ati ajafẹtọ ọmọ Yoruba atata, Oloye Sunday Igboho tun ti ṣalaye ohun to ṣẹlẹ nigba to ṣabẹwo si ilu Igangan lẹyin iṣẹlẹ ipaniyan to waye nibẹ laipẹ yii.
Nigba ti o n sọrọ ni aafin Onidio ilu Idio, Igboho beere lọwọ Kabiyesi lati fun oun ni iyọnda lati ṣe igbaradi fawọn ọdọ ki wọn le daabo bo ilu lọwọ awọn janduku agbebọn.
Igboho ṣeleri fun Ọba alaye naa pe iṣẹlẹ ipaniyan to waye laipẹ yii lagbegbe naa, ni yoo ikẹyin iru rẹ lagbegbe naa.
''Nigba ti mo pada wa si Igangan fun igba keji, gbogbo awọn ọba wa lo sa lọ.
Wọn ni gomina lo paṣẹ fawọn pe ki awọn sa lọ, ṣugbọn asiko ti to bayii lati dira fawọn ọdọ ki wọn le maa daabo bo ilu titi ti alaafia yoo fi jọba.
Igangan Attacks: Àkójọpọ̀ àbọ̀ BBC Yorùbá rèé nípa ìṣẹ̀lẹ̀ òfò ẹ̀mí àti dúkìá tó wáyé
Lẹyin ti a ṣẹgun Seriki Saliu tan, awọn Fulani ti a le kuro ni Igangan ati agbegbe rẹ ṣipo pada lọ si ilu Igbo Ora ati Eruwa, awọn eeyan si gba a laaye.
Lati ibẹ ni wọn ti gbimọ pọ lati kogun ja Igangan lẹẹkeji, eleyii ti ko si yẹ ko ri bẹẹ.
Njẹ o yẹ ki awọn eeyan ilu Igbo Ora ati Eruwa tun gba awọn Fulani ti a le kuro ni Igangan si aarin wọn?
O yẹ ki wọn le wọn danu tefe tefe nitori ẹbi ati ara yin wa laarin awọn eeyan Igangan ti wọn n pa ni ipa kupa.
Wọn pa Ọmọwe, Aborode, wọn ji olori ati ọmọba Igbo Ora lọ, bẹẹ kabiyesi ko tun sọrọ.
Teachers retirement age and years of service: Ìrírí àwọn àgbà olùkọ́ ṣì wúlò fún àwa ọ̀dọ́
Awọn Fulani payan ni Igangan, ko si sọja to wa sibẹ, ṣugbọn nigba ti wọn gbọ pe mo n bọ, awọn sọja yabo ilu Igangan,'' Igboho ṣalaye.
Igboho ni awọn sọja wa ni ibode Igangan nigba tawọn Fulani lọ payan nibẹ, wọn ko si lọ sibẹ lati dawọn duro.
Ṣugbọn o ni nigba toun atawọn iṣọmọgbe lọ si Igangan, awọn sọja wa lati dawọn lọwọ kọ.
Gbogbo ọ̀daràn ta lé ní Igangan, Eruwa àti Igboora ní wọn wà, kò sí ìfẹ́ ní Ibarapa - Sunday Igboho
Oríṣun àwòrán, sunday_igboho1
Ajijagbara fun ọmọ Yoruba nni, Oloye Sunday Igboho ti sọrọ lori ikọlu lemọ-lemọ to n waye ni agbegbe Ibarapa nipinlẹ Oyo.
Igboho ni aisi ifẹ ati isọkan laarin awọn ara abule ati awọn oriade to wa lagbegbe Ibarapa, lo mu ki awọn afurasi darandaran maa se aseyọri lati kọlu agbegbe naa loore koore.
Sunday Igboho woye bẹẹ lasiko abẹwo rẹ si aafin Onidio ti Idio, lasiko to lọ si agbegbe Ibarapa lọ wo ọsẹ tawọn afurasi darandaran se si ilu Igangan lọjọ Aiku.
Ninu fọnran aworan kan to bọ sori ayelujara nipa abẹwo Igboho si aafin Onidio naa, lo ti woye pe airin lọwọọwọ nii jẹ ọmọ ejo niya lọrọ awọn eeyan agbegbe Ibarapa, eyi to mu ki ogun naa ja wọn.
O fidi rẹ mulẹ pe abẹwo oun ti sisọ loju rẹ pe ati awọn ara abule, atawọn ọba to wa lawọn abule to n bẹ lagbegbe Ibarapa ni wọn n sa asala fun ẹmi wọn tori ikọlu awọn apaniyan yii.
Tunde Gbadamosi: Kìí ṣe Tinubu ní ipò ààrẹ̀ tọ́ sí, ìgbà wo ní ìtan ajá ń kan lèmọ́mù?
"Mo gbadura pe eyi ni yoo jẹ opin iru isẹlẹ bayii nitori awọn afurasi darandaran yii lo anfaani pe a gba wọn sile ni, lati maa kọlu wa.
Bakan naa ni wọn ri pe ẹnu awọn ara abule atawọn ọba wa lagbegbe yii ko se ọkan, lo jẹ ki iku ita maa pa wọn, ti agbegbe naa si si silẹ fun ikọlu."
Igboho tun sisọ loju rẹ pe ọpọ awọn afurasi apaniyan darandaran ti wọn le kuro nilu Igangan, ni wọn fi ara pamọ silu Igboora ati Eruwa.
O fikun pe lati awọn agbegbe yii si ni awọn apaniyan yii ti n ko ara wọn jọ lati ya wọlu Igangan lati sisẹ ibi, eyi ti ko yẹ ko ri bẹẹ.
"Ni ibẹrẹ pẹpẹ, n ko kọkọ fẹ da si laasigbo to n waye nilu Igangan nitori awọn oriade wọn nibẹ ko setan lati fọwọsowọpọ.
Oba Gbolahan Timson Shomolu Bariga ní 'Restructuring'ti bọ́ aṣọ kò bá Omọyẹ mọ́!
Amọ bi mo se lọ si agbegbe Ibarapa yii lọjọ Aje lo mu ki awọn osisẹ agbofinro tubọ se afikun aayan wọn nilu Igangan.
Wọn ro pe mo tun wa pada fẹ gbẹsan ikọlu ti awọn afurasi darandaran naa se lọjọ Aiku ni."
Sunday Igboho wa koro oju patapata si iwa ipaniyan ati biba dukia jẹ ti awọn onisẹ ibi naa se nilu Igangan.
Bakan naa lo ke si awọn oriade lagbegbe Ibarapa lati fun awọn ọdọ ni idanilẹkọ lori awọn ọna ti wọn fi le daabo awọn abule wọn, ti wọn yoo si maa fi oju sọri bii alakan.
Funmi Aragbaiye: Ọlọ́run ní ohun táwọn olórí wa fẹ́ jẹ ni wọn ń wá
Igangan Attacks: Makinde ní òun ṣetán báyìí láti ró àwọn ọdẹ ìbílẹ̀ àtàwọn míí lágbára
Oríṣun àwòrán, Taiwo Adisa
Lẹyin ọjọ mẹta ti ikọlu waye ni Igangan ni ijọba ibilẹ Ibarapa, Gomina Seyi Makinde ti ṣabẹwo si agbegbe naa.
Abẹwo yii jẹ eleyi ti pupọ araalu ti n reti pe yoo waye, paapa pẹlu iru ijamba to mu ọpọ ẹmi ati dukia lọ ni agbegbe naa.
L'ọjọ Iṣẹgun ti Gomina Ṣeyi Makinde de ilu naa, o kede pe oun yoo sa gbogbo ipa lati daabo bo awọn olugbe ipinlẹ naa.
O fi alaye kun pe  ijọba yoo ṣe ohun gbogbo lati dena iru iṣẹlẹ to waye nilu Igangan ati ni awọn agbegbe mii, lọjọ iwaju.
Oríṣun àwòrán, Taiwo Adisa
Lasiko abẹwo yii, Makinde kan si mọlẹbi awọn eeyan to fi ara gba nibi iṣẹlẹ to waye l'opin ọsẹ to kọja naa.
O ni ijọba yoo ro awọn eleto aabo ibilẹ ni agbara, ki iṣoro eto aabo le di ohun igbagbe nilẹ Ibarapa.
Gomina Makinde nikan kọ lo da ṣe abẹwo yii lọ si agbegbe Ibarapa.
Oríṣun àwòrán, Taiwo Adisa
Lara awọn to kọwọrin pẹlu rẹ ni awọn aṣoju ijọba ipinlẹ Ọyọ, to fi mọ adari ile igbimọ aṣofin ipinlẹ Ọyọ, Hon. Adebo Ogundoyin, ẹni to bẹnu atẹ lu ofo ẹmi  ati dukia lagbegbe naa.O fi kun ọrọ rẹ pe ijọba ti ṣe awari awọn igun to ku diẹ kaato, gẹgẹ bo ṣe n ke si awọn eeyan lati fun ijọba rẹ ni anfani lati mu ki ohun gbogbo tuba, ki o si tuṣẹ bo se wa tẹlẹri, lai si ibẹru.
Oríṣun àwòrán, Taiwo Adisa
Makinde rọ awọn eeyan pe ki wọn ma ṣe idajọ lọwọ ara wọn, dipo bẹẹ, o ni ijọba oun ni ki wọn ba lejọ.
Funmi Aragbaiye: Ọlọ́run ní ohun táwọn olórí wa fẹ́ jẹ ni wọn ń wá
Food and Cattle Union: Á gba ₦4.75bn lọ́wọ́ ìjọba ká tó gbé oúnjẹ síta fún títà
Oríṣun àwòrán, others
Agbarijọpọ ẹgbẹ awọn to n ta ounjẹ ati maalu nilẹ Ariwa Naijiria ti ṣeleri lati dawọ duro lori kiko ounjẹ wa si ẹkun iwọ oorun guusu.
Ẹgbẹ naa sọ pe awọn yoo mu ileri yii ṣẹ laarin ọsẹ mẹta si asiko yii, ti ijọba ba kọ lati ṣe nkan si awọn ohun ti wọn n beere fun.
Alaga ẹgbẹ naa, Muhammed Tahir to ba awọn akọroyin sọrọ lẹyin ipade ẹgbẹ to waye lọjọ Iṣẹgun lo fi ọrọ yii lede.
O ni lati igba ti Gomina ipinlẹ Kogi ti dasi aawọ to wa nilẹ tẹlẹ ni nkan bi ọṣu mẹta sẹyin, awọn ko gbọ ohunkohun mọ lati ọdọ ijọba nipa ohun tawọn beere.
Tunde Gbadamosi: Kìí ṣe Tinubu ní ipò ààrẹ̀ tọ́ sí, ìgbà wo ní ìtan ajá ń kan lèmọ́mù?
Ẹgbẹ awọn ontaja ounjẹ lati ẹkun ariwa naa ni ijọba jẹjẹ lati fun awọn ni owo gba ma binu toto biliọnu mẹrin ati miliọnu lna ọtalẹẹdẹgbẹrin o din mẹwa naira (N4.75bn)
Owo yii ni wọn ni ijba fẹ san lati tu awọn ninu nitori adanu to ba awọn lati ipasẹ ija to waye ni ọja Sasa nilu Ibadan losu kẹta ọdun yii.
Bẹẹ ba gbagbe, ọjọ mẹfa ni wọn fi kọ lati ko ounjẹ wa si guusu Naijiria ni osu kẹta ọdun 2021, ki Gomina Kogi, Yahaya Bello ti ijọba yan lati pari aawọ naa, fi pẹtu si wọn ninu.
Nkan to mu ki ẹgbẹ naa dawọ kiko ounjẹ wa si awọn ipinlẹ Yoruba, ko ṣẹyin ikọlu to waye ni ọja Sasha ni Ibadan.
Wọn fẹsun kan awọn Yoruba pe wọn n ṣeku pa awọn ọmọ ẹgbẹ awọn, ti wọn si tun da wọn lọna lati maa gba owo lọwọ wọn.
Tahiru ṣalaye pe, lẹyin tawọn ṣagbeyẹwo gbogbo ọrọ to wa nilẹ yii, awọn ti pinnu lati se atilẹyin fun awọn ontaja alubọsa to ti dawọ kata kara duro.
O ni ti ijọ́ba ba kọ lati wa wọrọkọ fi ṣada lori ohun tawọn n fẹ lẹyin ọsẹ mẹta awọn yoo gunle iyansẹlodi.
Adebayo Shittu: Èmi kò ṣẹ Abiola Ajimobi nígbà ayé ẹ, òun ló ṣe mi ṣùgbọ́n.....
Pupọ ounjẹ bi ẹwa, agbado ati nnkan elo bi timaati ati ata, lawọn oniṣowo Hausa n ko wa si guusu Naijiria fun tita.
Nigba ti wọn dawọ kiko ounjẹ wa lọjọ mẹfa ninu oṣu Kẹta, n ṣe ni ọwọn gogo ounjẹ waye, ti araalu si n ke irora.
Igangan Attacks: Ohun márùn-ún tí àwọn ọ̀dọ́ fẹ́ bá Makinde sọ rèé
Gomina Seyi Makinde ipinlẹ Oyo ti ni oun gba pe oun jẹbi ikọlu to waye ni ilu Igangan pẹlu ileri pe iru rẹ ko ni waye mọ.
Ero awọn eeyan kan ni pe gomina Makinde ti gba asise rẹ, ti wọn si n gbosuba fun.
Sugbọn inu awọn araalu kan, paapa awọn ọdọ Igangan ko dunnu si Gomina nitori awọn isẹlẹ kan to waye lasiko abẹwo rẹ naa.
Idi si ni wi pe, wọn ni Seyi Makinde ko farabalẹ gbọ ẹdun ọkan awọn lasiko abẹwo rẹ si ilu Igangan lẹyin ikọlu to mu ẹmi eeyan mọkanla lọ.
Lara awọn to ba BBC Yoruba sọrọ lori aidunnu wọn si Gomina ni Monsuru Aderoju, to jẹ ọmọ ilu ati awọn aṣoju ọdọ mii bi Oladiran Oladokun.
TB Joshua: Ṣe ni ọ̀pọ̀ èèyàn ń wa ẹkún mu torí ikú òjijì tó pa wòlíì
Monsuru ni tiẹ sọ pe lootọ ni inu awọn dun si pe Gomina wa lati wa ṣabẹwo sawọn ṣugbọn ko gbọ gbogbo ẹdun ọkan awọn.
Ninu nkan to sọ pe awọn fẹ ni ki gomina ṣe idasilẹ bareke ibudo ọmọ ologun eleyi ti ko ni si awọn ẹya Hausa nibẹ.
Bakan naa lo ni awọn fẹ ki Gomina fi agbara fun awọn ọdẹ fijilante ilu nipa ipese ohun ija lati fi koju awọn to n doju ija kọ wọn.
Ọrọ naa ko fi taratara yatọ si ti alakoso ẹgbẹ idagbasoke ilu Igangan, Igangan Development Advocates tii ṣe Oladiran Oladokun.
Oladiran sọ pe iyalẹnu lo jẹ fawọn pe lẹyin to sọrọ tiẹ tan, Gomina Makinde ko faaye silẹ kawọn tiẹ sọ ohun to n dun wọn lẹmi.
"'Èmi ọmọ Ikorodu ọ̀ga, ọmọ aṣalẹ̀ jẹ́jẹ! Wo bí àwọn ọmọdé tó ""tuush"" yìí ṣe ń fi oríkì Yorùbá dábíra"
O ni ṣaaju asiko yii lawọn ti n ke gbajare pe awọn ti n gbọ fin fin fin pe awọn agbebọn fẹ ṣe ikọlu si Igangan.
''Ka ni pe ọna wa fun wa lati kan si Gomina ni, iru nkan to waye yii ki ba maa ṣẹlẹ.''
''Gomina jinna si wa paapa awa ọdọ, to ṣe pe awa la jẹ bi eti ọba nile ati loko''
Oladokun ṣalaye fun BBC pe, nigba ti Gomina ko duro gbọ ọrọ awọn, awọn yoo fi iwe apilẹkọ ransẹ soju opo Facebook rẹ, boya yoo le de etigbọ rẹ.
Magaret Jimoh: Èrè díẹ̀ ti tó mi níbi oúnjẹ ti mò ń tà- Maggie Rice
Oba Gbolahan Timson Shomolu Bariga ní 'Restructuring'ti bọ́ aṣọ kò bá Omọyẹ mọ́!
Oladokun tubọ kesi Gomina pe ko maṣe fọrọ falẹ lori lilo awọn ọdẹ ibilẹ ati ẹgbẹ fijilante lati koju awọn olubi.
O ṣalaye pe ko si ẹni ti o mọ tibu toro ayika Ibarapa bii awọn ọdẹ yii tori naa, ki wọn ṣatilẹyin fun wọn lati le doju ija kọ awọn to n kogun ja araalu.
Nigeria Passport: Iléeṣẹ́ Immigration bẹ̀rẹ̀ ìlànà tuntun fún gbígba iwé ìrìnna
Oríṣun àwòrán, Nigeria Immigration Service
Ileesẹ to n ri si ìwọlé-wọde ero ati eeyan ni Naijiria, Nigeria Immigration Service, ti kede pe oju opo iforukọ silẹ fun gbigba pasipọọti irinna yoo bẹrẹ isẹ pada ni oru ọjọ kẹjọ, oṣu Kẹfa.
Oludari ileesẹ naa, Muhammad Babandede sọ pe ṣíṣí oju opo naa pada yoo fun awọn eeyan to koju oṣuwọn ni anfaani lati fi orukọ silẹ, ti wọn yoo tun le san owó fun oriṣiriṣi ipele pasipọọti to wa.
Oṣu Karùn-ún ni ileesẹ to n ri si ìwọlé-wọde ero ati eeyan da eto naa duro, ko le ri aaye yanju àwọn iforukọ silẹ to wa nilẹ tẹlẹ.
Bi bẹrẹ ti wọn bẹrẹ pada yii, jẹ ibẹrẹ ilana tuntun fun gbigba pasipọọti.
Bawo ni ilana tuntun fun gbigba Passport yoo ṣe ri?
Ori ayelujara ni ileesẹ Immigration ni iforukọ silẹ ati owo sísan fun gbigba pasipọọti yoo ti ma a waye báyìí.
Awọn to fẹ ẹ gba nilo lati lọ si oju opo naa, nitori pe nibẹ ni wọn yoo ti fi gbogbo àwọn iwe ti wọn nilo silẹ fun ayẹwo.
Lara nkan to tun jẹ tuntun ni pe, aaye ti wa ni oju opo ayelujara naa lati ba oluranlọwọ sọrọ, fun ẹnikẹni to ba ni ipenija lasiko to n fi orukọ silẹ, wọn o si tọ ọ sọna.
Lẹyin ti iforukọ silẹ naa ba yanjú, ẹni to fẹ ẹ gba pasipọọti yoo mu ọjọ ti yoo ṣe ifọrọwanilẹnu wo, ibi to ba wu ú, ati akoko to rọrùn fun.
Ori ayelujara naa ni yoo ti ṣe e.
Funmi Aragbaiye: Ọlọ́run ní ohun táwọn olórí wa fẹ́ jẹ ni wọn ń wá
Ọsẹ mẹfa ni ṣíṣe ati gbigba pasipọọti tuntun, ti yoo si jẹ ọsẹ mẹta fun awọn to ti gba ri, to fẹ pada gba òmíràn.
Lati asiko yii lọ, ileesẹ Immigration ko ni gba ẹnikeni ti ko ba kọkọ fi orukọ silẹ lori ayelujara laaye ni ọfiisi rẹ.
Ori imeeli ati nọmba foonu ti ẹni naa ba kọ lasiko iforukọ silẹ ni wọn o ti sọ fun ti pasipọọti rẹ ba ti wa nilẹ fun gbigba.
Awọn nọmba ibara ẹni sọrọ si ti wa ti awọn to ba ni ipenija le pe fun iranlọwọ.
Ọgbẹni Babandede tun lo anfaani naa lati gba awọn ọmọ Naijiria ni imọran pe ki wọn mase gba ọna ẹ̀bùrú fi orukọ silẹ nitori gbogbo eto naa ti rọrùn bayii.
Teachers retirement age and years of service: Ìrírí àwọn àgbà olùkọ́ ṣì wúlò fún àwa ọ̀dọ́
Bakan lo kilọ fun awọn to n fi gbigba pasipọọti ṣe iṣẹ aje lati dẹ́kun rẹ, ki wọn o ma ba a foju wina ofin.
Ọdun 2019 ni Aarẹ Muhammadu Buhari pàṣẹ pe ileesẹ to n tẹ owó fun Naijiria nikan, lo ni àṣẹ lati ma a tẹ pasipọọti irinna silẹ okeere.
Zamfara Abduction: Agbébọn jí ọ̀pọ̀ èèyàn gbé, tó fi mọ́ ọ̀gọ́ta obìnrin àtàwọn ọmọ wẹ́wẹ́
Oríṣun àwòrán, Nigerian Army
Awọn gende agbebọn ti ya bo ijọba ibilẹ Ruwan Tofa nipinlẹ Zamfara, ti wọn si ji ọpọlapọ eeyan gbe nibẹ.
Ọpọ awọn eeyan ti wọn ji gbe yii lo jẹ obinrin ati ọmọ wẹwẹ ni ọpọ abule ti wọn ya bo lọjọ Isẹgun.
Nigba to n fidi isẹlẹ naa mulẹ fun BBC,  asoju-sofin kan lati ipinlẹ Zamfara sọ pe wọn ji awọn obinrin gbe ni abule Manawa.
O ni wsn pa eeyan mẹrin ni abule Malele ati Randa, ti wọn wa nijọba ibilẹ Maru.
Bakan naa ni asofin Shehu S. Fulani sọ fun BBC pe awọn agbebọn naa tun sọ ina si ọpọ abule.
O fikun pe se ni awọn ọkunrin juba ehoro nigba ti wọn foju gan ni awọn agbebọn naa, ti awọn janduku yii si ko awọn aya atawọn ọmọ wọn.
Funmi Aragbaiye: Ọlọ́run ní ohun táwọn olórí wa fẹ́ jẹ ni wọn ń wá
Bi o tilẹ jẹ pe ko si ẹni to le sọ pato iye eeyan tawọn agbebọn naa mu nigbekun, amọ akọsilẹ fihan pe obinrin to to ọgọta ni wọn ko ri lawọn abule naa.
Iroyin naa fikun pe awọn agbebọn naa n yinbọn soke lakọ-lakọ nigba ti wọn de sibẹ, ti wsn si n sọ ina sawọn ile gbogbo.
Eyi lo mu ki ọpọ eeyan maa sa asala fun ẹmi wọn, amọ awọn obinrin ati ọmọde ti ko le sare daada ni ọwọ agbebọn ba.
Koda, ẹnikan ti isẹlẹ naa soju rẹ ni iyawo oun mẹrẹẹrin ni wọn ji gbe lọ ati awọn ọmọ, ọmọ rẹ, tii se ọmọ ọdun meje nikan ni wọn fi silẹ.
Tunde Bakare: Àjọjẹ kò dún bẹ́nìkan kò ní ló fa ìjà S Igboho,bẹ́ẹ̀ ìjọbati gbẹ́rù kọjá orí
Koda, ọrọ ọhun ko yọ baalẹ awọn abule naa silẹ, to fi mọ awọn idile wọn.
Cannabis Plantation: Akeredolu rọ ìjọba láti tẹ́wọ́ gba ọ̀gbìn igbó ká lè yọ lọ́fìn ọrọ̀ àjé tó mẹ́hẹ
Oríṣun àwòrán, NDLEA/Rotimi Akeredolu
Gomina ipinlẹ Ondo, Arakunrin Rotimi Akeredolu ti rọ ijọba Naijiria lati pa ilana ati èrò atijọ ti, eyi to ni irugbin eṣu ni igbo jẹ.
Akeredolu sọ pe ijọba le ṣe eyi, nipa gbigbe ofin kalẹ fun amojuto ọgbin ati kata-kara igbo.
O ni obitibiti owo ni kata-kara ọgbin igbo yoo mu wọle fun Naijiria, ti yoo si tun jẹ orisun ọrọ aje míì, to ba mojuto daadaa.
Gomina Rotimi Akeredolu gbe imọran yii kalẹ nibi ipade apero kan to waye lori anfaani ati iwulo ọgbin igbo ni Naijiria, eyi to waye nilu Akurẹ lọjọ Aje.
Akeredolu kesi awọn ile aṣofin agba mejeeji ni Naijiria, lati ṣe ọkan akin, ki wọn si ṣe atunse si ofin ajọ to n gbogun ti oogun oloro ni Naijiria, NDLEA, lori lilo igbo.
O ni iwulo ti igbó ni fun eto ilera, pọ ju aleebu rẹ lọ.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ọ̀pọ̀lọpọ̀ló ń fara pamọ́ mu igbò
Gomina Akeredolu sọ pe imọ ijinlẹ ti fihan pe orisun ọrọ aje ni igbo, ti wọn ba se amulo rẹ bo ṣe yẹ.
Nigba to sọrọ lori awuyewuye to n waye lori bo ṣe n polongo pe ọgbin igbo di itẹwọgba, Akeredolu sọ pe oun ko deede ma a polongo.
O ni, irinajo ti oun ati awọn ọmọ igbimọ alasẹ rẹ lọ si orilẹ-ede Thailand ni saa rẹ akọkọ gẹgẹ bi gomina, lo la oun loju si awọn anfaani rẹpẹtẹ to wa lara igbó.
O ni iyalẹnu lọ jẹ fun oun lati ri i ni Thailand pe awọn aginju nla ni ijọba fi n gbin igbo, to si gba awọn to n lo egboogi oloro ni ilokulo tẹlẹ si iṣẹ aje.
O ni kii se pe oun n polongo pe ko di okoowo ti oriṣiriṣi eeyan yoo ma a ṣe, a fi àwọn ti ijọba ba fun ni àṣẹ.
Funmi Aragbaiye: Ọlọ́run ní ohun táwọn olórí wa fẹ́ jẹ ni wọn ń wá
"Awọn oogun ati nkan elo ti wọn fi igbó ṣe wa ni awọn ile itaja ogun ni Naijiria, sugbọn o ṣeni laanu pe ilẹ okeere ni wọn ti n fi owo gọbọi ko wọn wọle.
Nkan ti mo n sọ ni pe ki a fi aaye gba ọgbin igbó, fun lilo awọn ileesẹ to n ṣe oogun oyinbo fun ilera."""
O fi kun ọrọ rẹ pe ipinlẹ Ondo wa lara awọn ibi ti wọn ti ni igbo to dara julọ ni agbaye.
Nigba ti oun naa n ṣorọ, aṣoju ile igbimọ aṣofin níbi ipade apero naa, to tun jẹ agbenusọ ile, Asofin Benjamin Okezie Kalu sọ pe, oun satilẹyin fun erongba Gomina Akeredolu lori sísọ ọgbin igbo di nkan ti ko lodi si ofin ni Naijiria.
Ayelala Idol: Onímọlẹ̀ ní olúwẹri obìnrin ni òrìṣà náà ló ṣe ń pọn omi sínú ẹlẹ́ṣẹ̀
Bakan naa, Alaga igbimọ to wa fun ọrọ ilẹ okeere nile aṣofin, Tolu Akande-Sadipe sọ pe ireti wa pe atunse aba ofin lori awọn oogun oloro, ti wọn ti ṣe agbeyẹwo rẹ fun igba keji yoo mu igba ọtun ba ọgbin igbó fun lilo eto ilera.
TB Joshua: Ṣe ni ọ̀pọ̀ èèyàn ń wa ẹkún mu torí ikú òjijì tó pa wòlíì
Abẹwo BBC si Arigidi Akoko nilu TB Joshua
Igangan Attacks: Àkójọpọ̀ àbọ̀ BBC Yorùbá rèé nípa ìṣẹ̀lẹ̀ òfò ẹ̀mí àti dúkìá tó wáyé
Àkójọpọ̀ àbọ̀ BBC Yorùbá rèé nípa ìṣẹ̀lẹ̀ òfò ẹ̀mí àti dúkìá tó wáyé.
Alakuko/Elega Schools: Aráàlú ní olùkọ̀ọ́ àti akẹ́kọ̀ọ́ ti sá ní kíláàsì tí kò dára
Nibayii ti gbogbo agbaye n gbe eto ẹkọ larugẹ nitori ko si abuja mii lọrun ọpẹ lati de ibi giga, agbegbe meji ree nipinlẹ Kwara, ti akude n ba eto ẹkọ wọn.
Awọn agbegbe naa ni Iyana Alakuko ati Elega ti wọn wa nijọba ibilẹ Asa nipinlẹ Kwara, eyi to to kilomita mẹẹdogun silu Ilorin.
Ileewe kan soso lo wa ni Iyana Alakuko eyi tawọn ọmọ abule naa n lọ amọ awọn yara ikawe to wa nibẹ ko wu oju ri rara.
Ori ilẹ ni awọn olukọ ati akẹkọ n joko si fun eto ẹkọ nitori pe wọn ko ni aga ati tabili ikẹkọ rara.
Koda yara ikawe oni yara meji naa lo wa fun awọn akẹkọọ lati ipele kinni de ikẹfa, ti awọn orule yara ikawe naa si ti lanu kalẹ.
Bakan naa ni ọmọ sori ni abule Elega nibi ti ileewe oni yara ikawe meji to wa nibẹ ti lanu kalẹ, to si ti fẹẹ da wo lulẹ.
Àwọn ìtàn mánigbàgbé tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí:
Koda, ikan ti mu ọpọ orule to gbe awọn kilaasi naa ro eyi to lewu pupọ fun ẹkọ kikọ.
Nigba ti BBC Yoruba se abẹwo si awọn ile ẹkọ to wa ni abule Iyana Alakuko ati Elega, awọn olukọ ati araalu ni ọpọ olukọ ati akẹkọọ ni ko wa sile iwe mọ nitori ewu to wa nibẹ.
Wọn wa n rọ ijọba ipnilẹ Kwara lati dide iranwọ, ki awọn ile ẹkọ naa ma baa dẹnu kọlẹ tan patapata.
Gosiame Sithole: Ìyàwó bímọ mẹ́wàá lẹ́ẹ̀kan ṣoṣo lẹ́yìn tó ti bí ìbejì tẹ́lẹ̀
Oríṣun àwòrán, AFRICAN NEWS AGENCY(ANA)
Iṣẹ Eledumare, awa maridi nio, nitori ko si ẹda kan to ye.
Obìnrin kan lorilẹede South Afrika ma ni Eledua fi ọmọ mẹwaa ta lọrẹ ẹ lẹẹkan ṣoṣo.
Gẹgẹ bí iwe iroyin Daily Mail ṣe sọ, Goaiame Thamara Sithole to jẹ ẹni ọdun mẹtalelọgbọn ti kọkọ bi ibeji tẹlẹ.
Ṣugbọn ni báyìí ọkunrin meje ati obinrin mẹta lawọn ọmọ ti Eledumare ṣẹṣẹ fi ta idile rẹ lọrẹ.
Ọkọ obinrin naa, Tebogo Tsotetsi sọ fáwọn akọroyin pe iṣẹ abẹ ni wọn fi gbẹbi awọn ọmọ naa nile iwosan kan niluu Pretoria lọjọ Aje.
Pabambari rẹ ni pe Tsotetsi ko niiṣe kan lọwọ.
O ni lootọọ ni inu oun dun amọ ominu ṣi n kọ oun bakan naa.
Arabinrin Sithole ṣalaye pe awọn ko loyun lọna Igbalode IVF tabi ọna mii.
Ṣugbọn awọn dokita sọ pe ọna Igbalode IVF at'awọn ọna mii lo le mu ki ọmọ pọ to bayẹn lẹẹkan ṣoṣo.
Tsotetsi to jẹ ọkọ arabinrin naa lo kọkọ sọ fáwọn akọroyin nipa ibi awọn ọmọ mẹwaa ọhún.
Sithole ni awọn dokita kọkọ sọ foun pe ọmọ mẹfa lo wa ninu oun, nigba to ya, ayẹwo scan fihan pe mẹjọ ni.
O ni nigba ti wọn n gbẹbi foun lọwọ ni wọn ri pe mẹwaa láwọn ọmọ to wa ninu oun.
Ibada EFCC arrest: Àjọ EFCC mú àwọn afurasí oníjìbìtì lórí ayélujára àádọ́ta ní Ibadan
Oríṣun àwòrán, EFCC
Ajọ to n mojuto iwa ajẹbanu ni Naijiria, EFCC ẹka ti Ibadan ni ipunlẹ Oyo ti kede eeyan aadọta ti ọwọ wọn tẹ nilu Ibadan.
Lọjọ Eti, ọjọ kẹrin, osu kẹfa, ọdun 2021 ni wọn ko awọn afurasi naa.
Agbegbe Alaro Sango, Agbaje Ijokodo ati Apete Aladura niluu Ibadan ni ọwọ EFCC ti tẹ wọn.
Adari ẹka iroyin ati ifitonileti fun ajọ EFCC, Wilson Uwujaren lo fi orukọ awọn afurasi naa sita bayii.
Wilson ni awọn mẹrinlelọgbọn ninu wọn ni wọn ti fidi ẹsun naa mulẹ̀ fun pe wọn jẹbi.
Tunde Gbadamosi: Kìí ṣe Tinubu ní ipò ààrẹ̀ tọ́ sí, ìgbà wo ní ìtan ajá ń kan lèmọ́mù?
Awọn naa ni: Badmus Abeeb, Ibrahim Ahmed, Adeyemo Babatunde, Abdulrashid Ajagbe, Olajide Okiki Peter, Hassan Yusuf Atanda, Yusuf Olasupo Salaudeen, Bello Ahmed Bamidele, Adewale Damilola Tosin, Kolawole Yusuf Olawale, Nicholas Ferdinand, Keshiro Olanrewaju, Falana Victor Dapo, Abogunrin Emmanuel, Bosun Tomiwa Tunde, Shelter Chibundo, Banjoko Idris, ati Adebayo Akorede.
Oríṣun àwòrán, @EFCC
Awọn to ku ninu wọn ni: Awoyinka Afeez Ayodeji, Afonja Olarenwaju, Akingbade Taofeek, Ezekiel Adekunle, Ganiyu Sodiq, Abioye Abiodun, Ogunbayo Daniel, John Timileyin, Ominiyi Daniel, Adeniyi Idris Sodiq, Joseph James, Adeyemi Segun Oluwaseun, Adeleke Rasheed, Saliu Tomiwa Rasheed, Itoro Edet Ime ati Oseni Nasirudeen.
Ayelala Idol: Onímọlẹ̀ ní olúwẹri obìnrin ni òrìṣà náà ló ṣe ń pọn omi sínú ẹlẹ́ṣẹ̀
Uwujaren ni EFCC ri awọn ẹru ofin gab lọwọ awọn afurasi to ku naa.
Bakan naa  lo ni wọn yoo gbe awọn to ku lọ sile ẹjọ lẹyin ti iwadii ti wọn naa ba ti pari.
Igangan Attacks: Mailafia ní ó yẹ kí Buhari ṣàbẹ̀wò sí Igangan torí ìṣẹ̀lẹ̀ ìpànìyàn
Eruku ifẹhonuhan to n lọ lori isẹlẹ isekupani to waye nilu Igangan nipinlẹ Oyo ko tii rodo, lọ ree mumi.
Lọtẹ yii gbajumọ kan lapa oke ọya ni Naijiria, to tun ti figba kan jẹ igbakeji gomina banki apapọ ilẹ wa, Ọmọwe Obadiah Mailafia lo sọ ero rẹ.
Lasiko to n bawọn akọroyin sọrọ lori isẹlẹ isekupani naa nilu Ibadan, Mailafia ni ẹbi awọn osisẹ agbofinro nipinlẹ Oyo ni isẹlẹ ipaniyan to waye ni Igangan jẹ.
O ni awọn ileesẹ agbofinro labẹ ijọba apapọ ati tipinlẹ lo kuna lati pese aabo to peye ti isẹlẹ ipaniyan naa fi waye.
O ni irufẹ ipenija eto aabo to n koju awọn eeyan ipinlẹ Oyo ko tọ si wọn rara.
"O yẹ ki aarẹ Muhammadu Buhari lọ se abẹwo silu Igangan, ko si ba awọn eeyan ibẹ kẹdun lori isẹlẹ isekupani naa nitori oun lawọn araalu dibo yan.
Igangan Attacks: Àkójọpọ̀ àbọ̀ BBC Yorùbá rèé nípa ìṣẹ̀lẹ̀ òfò ẹ̀mí àti dúkìá tó wáyé
Ọkan wa ko si balẹ pe a le fi ara da iru iwa ipaniyan bayii nitori inu n bi wa, ti ọkan wa si bajẹ lori ipaniyan to waye ni Igangan.
Ọkan lara ojuse ijọba ni ofin ilẹ wa la kalẹ pe ko pese eto aabo to peye fun araalu ati eto igbayegbadun wọn.
Amọ ti ijọba Buhari ko ba se eyi, awọn ọdọ yoo gbakoso, bẹẹ si ni Sunday Igboho atawọn ọmọlẹyin rẹ n duro lati pese aabo to peye fun ara ilu.
Iyoku wa ku sọwọ aarẹ, bi ijọba ko ba ran araalu lọwọ, awọn araalu yoo dide lati ran ara wọn lọwọ."
Ileeṣẹ ọlọpaa ipinlẹ Osun ti sọ pe iwadii n lọ lati fọwọ ofin mu awọn afurasi ẹlẹgbẹ okunkun meji ti ṣokunfa aṣita ibọn to pa ọkunrin kan, ThankGod Olorunwa ni ilu Ilesa, ipinlẹ Osun.
Awọn ẹgbẹ okunkun meji ti ọkunrin kan ti wọn n pe ni Solo ati Bode atawọn akẹgbẹ wọn lati Iwara ni ijọba ibilẹ ila orun Atakunmosa lo fija pẹta ti ibọn fi lọ ba Olorunwa nibi to wa.
Ọmọ ọdun mejidinlọgbọn ni Olorunwa i ṣe ko to fara gbọta aṣita ibọn awọn ẹlẹgbẹ okunkun ni Ilesa.
Sunday Igboho fulani ultimatum: Àwọn ará Kebbi àti Zamfara ló n jínígbé ní Oke Ogun- Serik
Agbẹnusọ ileeṣẹ ọlọpaa ipinlẹ Osun, Yemisi Opalola ṣalaye ninu atẹjade to fi sita wọn ti gbe oku ọkunrin naa si ile iwosan Wesley Guild ni Ilesa.
Opalola ni awọn afurasi ẹlẹgbẹ okunkun naa yoo foju ba ileẹjọ ti ọwọ ba ti tẹ wọn.
Awọn ti iṣẹlẹ ọhun ṣoju wọn ṣalaye pe Olorunwa lọ ra ounjẹ to fẹ jẹ laarọ ni ọta ibọn tawọn ẹlẹgbẹ okunkun naa yin mọ ara wọn lọ ṣeeṣi ba a.
Ohun  ti a tun gbọ ni pe ija laarin ẹlẹgbẹ okunkun Eye ati Afe to ti kọkọ ṣẹlẹ lọjọ Iṣẹgun lo tẹsiwaju ni Ilesa ni Ọjọru.
Nigeria Twitter ban: Iléesẹ́ Twitter ti ń bá ìjọba Nàìjíríà sọ̀rọ̀ papọ̀- Alhaji Lai Mohammed
Oríṣun àwòrán, @Lai Moammed
Iléesẹ Twitter ti setán láti bá ìjọba Nàijíríà sọrọ papọ- Lai Mohammed
Alhaji Ali Mohammed to je minsita fun ifitonileti ati asa ni Naijiria ni pe ileesẹ Twitter ti ijọba Naijiria fofin de lọjọ Eti ti setan lati ba ijọba sọ asọepọ.
Lai Mohammed sọrọ yii fawọn akọroyin nile ijọba lẹyin ti wọn pari ipade igbimọ amusẹse ijọba apapọ.
O ni ileeseẹ lọjọru oni ni ileesẹ Twitter ti kan si ijọba Naijiria lati jọ sọrọ papọ lori ifofin de tijọba se.
Tunde Gbadamosi: Kìí ṣe Tinubu ní ipò ààrẹ̀ tọ́ sí, ìgbà wo ní ìtan ajá ń kan lèmọ́mù?
Lai Mohammed ni ijọba fofin de Twitter nitori idunkooko mọ ni awọn bii IPOB, Kanu Nnamdi ati ipa ti Twitter ko ninu iwọde #EndSARS.
Lai Mohammed tun ni lati isinyii yatọ si Twitter, awọn ileese ọrọ ayelujara bii Facebook, Instagram ma nilo lati forukọ silẹ ni Naijria bayii.
Ayelala Idol: Onímọlẹ̀ ní olúwẹri obìnrin ni òrìṣà náà ló ṣe ń pọn omi sínú ẹlẹ́ṣẹ̀
Lai Mohammed ni ominira lati sọrọ yii wa ni Naijiria nipa se lilo nkan mii yato si Twitter.
Umoja Women‘s Village: Ìlúbìnrin tó gbajúmọ̀, àmọ́ tí kò fi ààyè gba ọkùnrin
Oríṣun àwòrán, Traveller
Yoruba ni airin jinna ni airi abuke ọkẹrẹ, bii eeyan ba rin jinna, yoo de ibi ti wọn ti n fi odo ibulẹ jẹun.
Bẹẹ ni ọrọ ri pẹlu ilu kan, to jẹ kikida obinrin lo n gbe ibẹ amọ ti wọn ko gba ọ̀kunrin kankan laaye lati maa gbe pẹlu wọn.
Orukọ ilu naa ni Umoja, o si jẹ abule kan ni orilẹ-ede Kenya ti oriṣiriṣi àwọn obìnrin to bọ lọwọ ifiyajẹni ọkùnrin n gbe.
Awọn obinrin nikan ni wọn fi aaye gba lati ma a gbe ni Umoja laisi ọkunrin nibẹ.
Oríṣun àwòrán, INSH
Ọdun 1990 ni obìnrin mẹẹdogun kan da abule naa silẹ, lẹyin ti wọn bọ lọwọ  awọn ọmọ ogun ilẹ Gẹẹsi to n fi ipa ba wọn lo pọ.
Diẹ diẹ si ni èrò n pọ si ni abule naa, ti wọn si maa n gba àwọn obinrin to ba wa sa pamọ nitori iwa ipa ninu igbeyawo laaye nibẹ.
Ko yọ àwọn ọmọdebinri naa silẹ, to ba sa kuro ni ilu wọn nitori ki wọn o ma ba fi fun ọkọ.
Bakan naa ni awọn obinrin to ba sa fun abẹ́ dida ati ifipa báni lopọ pẹlu iwa ipa ati ifiyajẹni lọwọ ọkunrin maa n lọ tẹdo si abule naa.
Ẹ̀yà Samburu ni awọn obinrin naa ti wa.
Oríṣun àwòrán, The State
Lara àṣà àwọn eeyan ẹ̀yà naa si ni pe, ko si nkan to buru ninu ki wọn fi ipa ba obinrin lopọ, tabi ki wọn o fi ọmọdebinrin fun ọkọ tabi da abẹ́ fun.
Obìnrin kan ti wọn n pe ni Rebecca Lolosoli, to jẹ ẹ̀yà Samburu, lo jẹ adari àwọn to da abúlé Umoja silẹ.
Lẹyin ti oun fúnra rẹ bọ lọwọ awọn ọkunrin to lu u ni ìlùkulù nitori pe o ni ki wọn da ilu kan ti yoo jẹ ti awọn obinrin nìkan silẹ.
Idi ti wọn fi na Rebecca ni pe ko le jẹ ijiya fun bo ṣe ṣi àwọn obìnrin loju si ẹtọ wọn.
Awọn eeyan ẹ̀yà Samburu jẹ ibatan àwọn ẹ̀yà Maasai, ti wọn si jọ n sọ èdè kan naa.
Teachers retirement age and years of service: Ìrírí àwọn àgbà olùkọ́ ṣì wúlò fún àwa ọ̀dọ́
Ni ẹ̀yà Samburu, awọn ọkunrin lo ma n ṣe ipade apero nípa abule wọn, àmọ́ ti awọn obinrin ma n duro ni ìta ile ibi ti ipade ba ti n waye.
Igba ti wọn ba ni ki obinrin sọrọ nìkan ni wọn gbọdọ sọrọ l'ori ohun to n lọ.
Gẹgẹ bi ìtàn ṣe sọ, ìlú Samburu ni gbogbo àwọn to kọkọ de ilu Umoja ti wa.
Amọ nigba to ya, awọn obinrin ati ọmọdebinrin to gbọ nipa 'aabo' to wa nibẹ bẹrẹ si ni darapọ mọ wọn lati kọ nipa bi wọn ṣe n ṣe òwò.
Awọn eroja asaraloge, ilẹkẹ àti àwọn nkan igbafẹ ni wọn fi n ṣe iṣẹ aje.
Bakan naa ni wọn tun ma n kọ awọn obinrin ati ọmọdebinrin to wa ni awọn abule ẹ̀yà Samburu to yi wọn ka ni ẹkọ.
Magaret Jimoh: Èrè díẹ̀ ti tó mi níbi oúnjẹ ti mò ń tà- Maggie Rice
Awọn idanilẹkọ yii si lo da lori ewu to wa ninu ṣíṣe igbeyawo ni ọmọde, ati abẹ́ dídá fun obinrin.
Nini àwọn ẹ̀gbà ọwọ, ti ọrùn ati awọn eroja isaraloge mii to jẹ oju ni gbese, jẹ àṣeyọrí pataki ni ẹ̀yà Samburu.
Nibi ayẹyẹ kan ti wọn n pe ni 'beading' ni baba ọmọbinrin yoo ti fun ni awọn ẹgba ọrùn, ti baba naa yoo si yan ọkùnrin àgbàlagbà kan to ba jẹ jagunjagun, lati fẹ ọmọ naa ni iyawo.
Ni Samburu, èèwọ̀ ni ki ọmọdebìnrin loyun, se ni wọn yoo pàṣẹ fun ọdọbinrin to ba loyun pe ko ṣẹ, koda ko jẹ pe o ṣe igbeyawo lọmọde.
Idi ni pe ko ni ni okun fun oyun, nitori irora bi ibalopọ ṣe ba ojú ara rẹ jẹ latari ọjọ ori rẹ to kere fun igbeyawo ati apọju ẹjẹ ti yoo da lára rẹ lasiko ìbímọ.
Funmi Aragbaiye: Ọlọ́run ní ohun táwọn olórí wa fẹ́ jẹ ni wọn ń wá
Gẹgẹ bi àṣà wọn nilubinrin yii, eewọ ni fun awọn obinrin naa lati ni ọkọ, àmọ́ wọn le mu ọkunrin wá lati abule mii, ko le fun wọn loyun.
Awọn ọkunrin wọnyii lo n ba wọn mojuto nkan ọsin wọn, ojuṣe kan ṣoṣo ti wọn si ni, ni lati fun awọn obinrin naa loyun.
Nitori pe wọn ko faaye gba ọkùnrin lati gbé pẹlu wọn, ibalopọ naa kii ṣe pẹlu agidi, àmọ́ pẹlu suuru, ki wọn le ma a loyun.
Awọn obinrin to dàgbà lo n se akoso abule Umoja, ti awọn ọdọbinrin wọn si jẹ jagunjagun.
Abule naa paapaa ni ile ẹ̀kọ́ alakọbẹrẹ, gbọ̀ngàn àṣà, ati awọn ibudo fun awọn arìnrìn-àjò igbafẹ to ba wa si Igbo igbafẹ Samburu National reserve.
Awọn arìnrìn-àjò naa ni wọn ma n ta àwọn ilẹkẹ ati ẹṣọ ara ti wọn n ṣe fún.
Buhari in Lagos: Irọ́ ni pé àwọn eèyàn mi nìkan ni mo ń fi sípò adarí ní Nàìjíríà- Muhammadu Buhari
Buhari, Rotimi Amaechi ati awọn eeyan mii lasiko ifilọlẹ naa
Aare Muhammadu Buhari to n tukọ Naijiria lo gbera lati Abuja wa se abẹwo si ilu Eko ni guusu Iwo Oorun Naijiria.
Nibe lo ti kopa ninu eto ifọrọwanilẹnuwo aladase pẹlu ileese Amohunmaworan Arise TV.
Nibi ifọrọwanilẹnuwo yii ni Aare Buhari ti salaye bi oun se n yan awọn eeyan sipo ninu ijọba oun.
Aare ni pe oun kọ lati yan ẹni ti ko koju osuwọn sipo rara.
O ni awọn akọsẹmọsẹ to mọ nkan ti o yẹ ni oun n yan sipo lai naani iran tabi ilu tabi ipinlẹ ti ẹni bẹẹ ti wa ni Naijiria,
Buhari ni o di dandan ki onikaluku sisẹ lati fi amuyẹ han pe oun yẹ nipo ki ijọba to yan iru ẹni bẹẹ sipo.
Idahun yii waye nigba ti wọn beere nipa awọn adari ologun ti Buhari n yan lati ẹya kan nikan.
Oríṣun àwòrán, PRESIDENCY NIGERIA
Orí mi wú pé àkòkò ìjọba mi ní àṣeyọrí reluwé ń wáyé - Buhari
Ibùdókọ̀ reluwé Ekò tó tóbi jùlọ ní West Africa di ṣíṣí
Aarẹ Muhammadu Buhari ti ṣe ifilọlẹ oju ọna reluwe oni kilomita 157, to lọ lati Eko si Ibadan.
Nibi eto naa to waye ni agbegbe ibudokọ reluwe Mobolaji Johnson ni Ebute-Meta, ni ipinlẹ Eko, ni Buhari ti fi idunnu rẹ han lori bi awọn araalu ṣe tẹwọ gba akanṣe iṣẹ naa.
Buhari ni ori oun wu to jẹ pe lasiko ijọba oun ni iru aseyọri bayii n waye ni Naijiria.
Lara awọn eeyan jankanjankan wa nibi ayẹyẹ ifilọlẹ naa ni minisita fun eto irinna, Rotimi Amaechi, minisita fun aṣa ati iroyin, Lai Mohammed ati minisita fun ọrọ ọdọ ati ere idaraya, Sunday Dare.
Awọn yoku ni Olori ile aṣoju-sofin, Femi Gbajabiamila, gomina ipinlẹ Ekiti, Kayode Fayemi, Babajide Sanwo-Olu ti Eko, Seyi Makinde lati Oyo ati Dapo Abiodun lati Ogun.
Buhari, Rotimi Amaechi ati awọn eeyan mii lasiko ifilọlẹ naa
Eto naa ko yọ aṣiwaju ẹgbẹ oṣelu APC, Bola Tinubu, Wole Soyinka ati awọn ẹlẹgbẹjẹgbẹ mii silẹ.
Ọdun 2019 ni Buhari ti ṣe abẹwo si ipinlẹ Eko kẹhin, lasiko to wa a ṣe ifilọlẹ awọn akanṣe iṣẹ kan lasiko ijọba Gomina Akinwumi Ambode.
Alakuko/Elega Schools: Aráàlú ní olùkọ̀ọ́ àti akẹ́kọ̀ọ́ ti sá ní kíláàsì tí kò dára
Loni ni ipinlẹ Eko yoo gbalejo aarẹ orileede Naijiria, Muhammadu Buhari to n bọ wa ṣe abẹwo ọlọjọ kan sipinlẹ naa.
Ninu ikede kan ti ọkan lara awọn amugbalẹgbẹ aarẹ, Bashir Ahmad fi sita loju opo Koo, o ni aarẹ yoo wa ṣe ifilọlẹ reluwe Eko si Ibadan.
Reluwe yii, to wa ni agbegbe Ebutte Meta la gbọ pe wọn bẹrẹ iṣẹ lori rẹ lati ọdun 2017..
Ibudokọ reluwe Mobolaji Johnson yii ni ibudo reluwe to tobi julọ ni iwọ oorun Afrika, to si le gba to ẹgbẹrun mẹfa ero.
Ko si ikede pupọ ti wọn fi to araalu leti nipa abẹwo yii ṣugbọn o ṣeeṣe ki sunkẹrẹ fakẹrẹ ọkọ waye lawọn agbegbe kan Lasiko abẹwo rẹ
Ni Ọjọru ni ọga agba ọlọpaa Naijiria, Alkali Baba Usman ti balẹ si Eko, to si kan si Gomina Babajide Sanwoolu nile ijọba.
Oríṣun àwòrán, Bashir Ahmad
Lasiko abẹwo rẹ to ṣe kẹyin si Eko nigba ijọba Gomina Akinwumi Ambode, ijọba kede isinmi fawọn oṣiṣẹ ki wọn baa le tu yaya jade wa pade aarẹ.
Lọjọ Kẹrinlelogun oṣu Kẹrin ọdun 2019 ni aarẹ Muhammadu Buhari wa silu Eko kẹyin lasiko ayẹyẹ ọjọ ibi asaaju ẹgbẹ oselu APC nni, Asiwaju Bola Ahmed Tinubu.
Oríṣun àwòrán, Facebook/Dapo Abiodun
Ko si ikede isinmi kankan lasiko abẹwo eleyi amọ ibẹru ati inira ti wahala sunkẹrẹ fakẹrẹ ọkọ le ko ba araalu, jẹ eleyi to mumu lọkan awọn eeyan.
Tafa Oloyede: ₦200 ní owó oṣù àkọ́kọ́ mi nìdí iṣẹ́ tíátà, mo sì ní àṣọ mẹ́ta péré
Oríṣun àwòrán, Osun Digital Radio
Bi a ba n darukọ awọn agba ọjẹ ere tiata ni Naijiria loni, yoo ṣoro ki eeyan to le sọ wi pe bawo ni ti Tafa Oloyede ṣe jẹ.
To ba jẹ pe ti ba wọn wo ere bi Olaniyọnu, Folajiyọ,Orogun Adedigba, Iyekan Soja, Teni n teni, Jagun Aso, Ti Oluwa nilẹ apa kini ati apa keji, ẹ o ti ribi ti Tifa ti n da bi ẹdun, to si ti n rọ bi owe.
Gbajugbaja osere tiata Yoruba John Adewuni Adewole ti ọpọ mọ si Tafa, ti n sọrọ nipa iriri rẹ lagbo oṣere.
Ninu fọnran fidio kan ti a ri lori ayelujara, Tafa tu kẹkẹ ọrọ nipa irinajo rẹ silẹ nibẹ, to si sọ pe oun ko ni ju aṣọ mẹta lọ nigba toun bẹrẹ si ni kopa ninu ere ori itage.
Adewuni to jẹ ọmọ bibi ilu Ede sọ pe, igba Naira, ₦200, ni wọn n fun oun gẹgẹ bi owo oṣu nigba toun bẹrẹ ere.
Eegunjobi Omotanbaje Ajobiewe- Èébú ní wọ́n kọ́kọ́ ń bù mí nígbà tí mo bẹ̀rẹ̀ ẹ̀ṣà pípé ní
Nigba ti Tafa fi bẹrẹ si ni ba wọn ṣere, o ni ẹbun amutọrunwa ni ilu lilu ati ijo jijo jẹ fun oun.
Lasiko tawọn oṣere fi n ba awọn alarinjo ṣere kaakiri, ijo jijo orin kikọ tabi ilu lilu jẹ eroja pataki ti oṣere gbọdọ ni.
Igba ta n wi yii nigba tawọn ẹgbẹ ere ori itage bi ti Oyin Adejobi fi jẹ ilumọọka, ṣaaju ki sinima agbelewo to wa gbode.
Tafa sọ pe nigba naa lọhun, oun a maa saba kopa ninu ere ni ileewe girama ati nile ijọsin.
O tẹsiwaju pe nibi toun ti n dara, ni obinrin kan ti gba oun ni imọran lati darapọ mọ ẹgbẹ oṣere wọn ni Osogbo.
'Mo ni baba isalẹ'
"Taibat Oyetunji lorukọ arabinrin yii, to si jẹ iyawo ọga wa Ọlọfaina. Ẹgbẹ oṣere Oyin Adejobi ni wọn ni ki n wa darapọ mọ.
Mo gba lati darapọ mọ wọn. Nibẹ si ni irinajo mi lagbo ere tiata ti bẹrẹ. Apo kan Naira ni owo oṣu mi nigba naa, mi o si ni ju aṣọ mẹta lọ
Bi a ba fẹ ṣere nigba Kootu Aṣipa, emi ni maa kopa to pọ''
Lara awọn ti Oloyede a maa gboṣuba fun ninu awọn oṣere ni Baba Wande.
Idi si ni pe nigba naa lọhun to bẹrẹ iṣẹ ere tiata pẹlu ẹgbẹ Oyin Adejobi, Baba Wande lo jẹ gẹgẹ bi alamojuto ẹgbẹ ti a mọ si ''Manager''
''Ko si igba ti aya mi kii sọ ki, ti mo ba ti ri Baba Wande. Idi si ni pe wọn a maa foju dẹru ba wa, ti a ba wa lori itage.
Ìṣẹ̀lẹ̀ Kàyéèfì: Ìpáǹle tú Abass Owonikoko sí ìhòòhò ayé, kó tó gba kéú lọ́gbà ẹ̀wọ̀n
''Mo kọkọ maa n ro wi pe boya wọn n dẹru ba mi ni ṣugbọn nigba to ya, mo ri wi pe iṣẹ wọn ni wọn n ṣe.''
Ninu awọn ipenija to ni nidi ere tiata, Tafa Oloyede sọ pe ko pọ pupọ.
''Eyi ti mo le pe ni ipenija ni pe, awa ko mọ pe awọn eeyan maa n lowo nidi iṣẹ tiata.''
O ni ifẹ tawọn ni si ere tiata nigba naa lọhun, lo mu ki awọn ṣi wa nidi ere di oni.
O wa gba awọn oṣere miran niyanju lati koju mọ iṣẹ tiata, ki wọn ba le jẹ́ ọrọ idi iṣẹ naa.
Democracy Day: Wo ipa mánigbàgbé Obasanjo, Yar‘adua, Jonathan àti Buhari ní Nàíjíríà
Ọdun miran tun ti de tawọn ọmọ Naijiria n ṣe ayajọ ijọba awarawa Democracy Day.
Lati igba ti Naijiria ti pada si ijọba alagbada ni ọdun 1999 awọn ijọba mẹrin lo ti ṣe akoso ilẹ naa.
Ninu itan, awọn ọmọ Naijria a maa kọ rere awọn kan ninu wọn ti wọn a si tun maa fi idakeji adura ranṣẹ si omiran fun bi wọn ṣe ṣejọba.
Àwọn ìtàn mánigbàgbé tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí:
Ni meni meji, diẹ ree lara awọn nkan manigbagbe ti o so mọ ijọba mẹrẹẹrin to ti jẹ ni Naijiria lati ọdun2009.
Olusegun Obasanjo:
Odu ni Oloye Olusegun Matthew Okikiola Aremu Obasanjo, kii ṣe aimọ foloko lagbo oṣelu Naijiria.
Ṣaaju ki o to bọ aṣọ ologun silẹ lati darapọ mọ oṣelu awarawa, Obasanjo ti  fi igba kan dari Naijiria, to si ko ipa ribiribi nigba ogun abẹle Biafra to ja ni Naijiria.
Ipadabọ ẹbọra Owu si agbo oṣelu waye lẹyin to ṣẹwọn ti iku si tun re kọja lori rẹ labẹ ijọba ologun Sani Abacha.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Oloye Obasanjo gun ori alefa gẹgẹ bi aarẹ Naijiria alagbada lọjọ Kọkandinlọgbọn oṣu Kaarun ọdun 1999.
Lara awọn ipa ati ohun manigbagbe to waye lasiko ijọba Obasanjo la ti ri ka pe :
Kudiẹkudiẹ ijọba rẹ:
Umaru Musa Yar'Adua:
Ọmọ bibi ipinlẹ Katsina ni Yar Adua to si figba kan di ipo Gomina mu ki Olusegun Obasanjo to fa kalẹ lati jẹ aarẹ Naiajiria.
Labẹ aṣia ẹgbẹ oṣelu PDP ni wọn yan lati du ipo aar to si jawe oulbori ninuidibo to waye lọdun 2007.
Nigba ti yoo fi de si ori oye, pupọ awọn eeyan lo n pariwo pe eto idibo to gbe dori alefa ni kọnunkọhọ ninu.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Yar Adua ṣe ohun to ya ara ilu lẹnu nigba to sọ pe oun gba pe lootọ ni eto idibo to gbe oun de ori oye ko yanrantin.
Koda o tun sọ fun awọn alatako lati kọri si ileẹjọ tako esi ibo ti ko ba tẹ wọn lọrun.
Ni itẹsiwaju ipinnu yii, awọn eto ilana ati iyipada de ba eto idibo Naijiria.
Pataki julọ, Yar Adua ṣe agbekalẹ Igbimọ kan labẹ idari Adajọ agba Justice Uwais lati ṣe agbeyẹwo ati atunṣe eto ilana idibo Naijiria.
Oríṣun àwòrán, Facebook
Lara awọn nkan manigbagbe ti igbimọ yi fi lelẹ lo pada wa jẹ gẹgẹ bi itẹlẹ fun eto idibo Naijiria to ti  lalaafia de ibi to ni loni.
Awọn nkan mii to ṣe lasiko rẹ to jẹ manigbagbe ni:
Eeyan ki wa ki o ma ni alebu tiẹ
Ibaṣepọ laarin ijọba Yar Adua ati awọn oloṣelu kan ti ọwọ wọn ko mọ jẹ ohun to mu ki awọn eeyan foju abuku  wo ijọba rẹ.
Apẹrẹ eleyi lo han pẹlu bi ijọba rẹ ṣe dunkoko mọ Nuhu Ribadu titi ti wọn fi yọ nipo ọga agba EFFC ti wọn si fi Farida Waziri rọpo rẹ.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Lakotan, ai ṣe eto igbejọba kalẹ fun igbakeji rẹ Goodluck Jonathan da ọpọ wahala silẹ nigba ti aarẹ de ba a.
Abalọ ababọ, Yar Adua pada ku sori oye lọjọ kaarun oṣu Kaarun ọdun 2010.
Goodluck Ebele Jonathan:
Goodluck Ebele Jonathan wa lara awọn oloṣelu Naijiria ti awọn eeyan a maa juwe bi ẹni itan.
Nigba ti yoo fi de ori oye, pupọ ni ko lero wi pe ipo aarẹ le kan.
Saaju asiko yi, iyọnipo Gomina ti o jẹ igbakeji rẹ Diepreye Alamisegha lo mu ki Jonathan di Gomina ipinlẹ Bayelsa.
Oríṣun àwòrán, TWITTER/GARBA SHEHU
Iru nkan to mu di Gomina tun ṣẹlẹ nigba ti aarẹ Umaru Musa Yar Adua papoda.
Ninu awọn nkan manigbagbe ti ọmọ Naijiria fi maa n ranti ijọba rẹ ni bi o ti ṣe gbe ijọba kalẹ lẹyin to fidirẹmi ninu idibo aarẹ.
Igba akọkọ ree ninu itan Naijiria ti aarẹ to wa lori oye yoo fidirẹmi ninu idibo ṣugbọn o finu fẹdọ gbe ijọba kalẹ fun Muhammadu Buhari to wa lori oye loni.
Awọn nkan iranti to ṣe lasiko ijọba rẹ ree:
Muhammadadu Buhari:
Ọgagun tẹlẹ ri Muhammadu Buhari ni aarẹ to wa lori oye lọwọ lọwọ ni Naijiria.
O di aarẹ lẹyin igba kẹrin to gbiyanju lati dije ipo naa.
Saa keji rẹ lo n lo lọwọ bayi ti orisirisi nkan si ti waye lati igba to de ori oye.
Orin mo de lati wa koju iwa ajẹbanu ati mu alaafia pada ba ilu ni o fi ṣe ipolongo rẹ eyi to mu ko ṣi aga nidi Goodluck Jonathan to wa lori oye.
Nitori pe Buhari ko ti pari lilo ipo rẹ gẹgẹ bi aarẹ, o ṣeeṣe ki a ma le mẹnu ba gbogbo ohun manigbagbe to waye labẹ ijọba rẹ.
Ṣugbọn ni iwọnba ti aye le gba wa, a o ṣapa lati darukọ diẹ nkan to gbeṣe ni saa kini rẹ ati eyi to n ṣe lọwọ
Oríṣun àwòrán, sunday_igboho1/nstagram
Ẹsun kan tawọn araalu n ran lẹnu lori ijọba aarẹ Buhari ni pe o faye gba iwa ẹlẹyamẹya pupọ ti ko si fi tawọn ẹya to ku ṣe ninu iṣejọba rẹ.
Lọpọ igba ni  Ijọba Buhari tako ẹsun yi to si ni pe ọrọ ko ri bẹ.
Bakan naa awọn ọmọ Naijiria ko dunu si bi ijọba Buhari ko ti ṣe mu awọn ileri to ṣe ṣẹ paapa julọ nipa aabo ati ipese ayika alaafia fun araalu.
Wahala ijingbe, ikọlu laarin awọn darandaran ati agbẹ, ifapajanu awọn ajijiagbara ati awọn kudiẹkudiẹ mi tabuku ijọba yi lọdọ araalu.
Oríṣun àwòrán, AFP
Awọn ọmọogun ko sinmi fifigba gbaga pẹlu awọn janduku orisirisi ni Naijiria
Awọn ikunsinu wọn yi pọ debi pe awọn ọdọ Naijiria ṣe iwọde ENDSARS eyi to ṣafihan bi inu wọn ko ti ṣe dun si ijọba paapa awọn agbofinro to n dunkoko mọ araalu.
Lọwọlọwọ, eyi tawọn eeyan kan n ba ijọba fa ni wahala pe awọn f yapa kuro lorileede Naijiria ti elyi si mu ki awọn ẹya bi Yoruba ati Igbo maa ni ki onikaluku maa ṣe tiẹ.
IPOB ni ilẹ Igbo ati Ẹgbẹ awọn ọmọ Yoruba to n pe fun idasilẹ orileede Yoruba lo lewaju awọn ajijagbara to n fi ojojumọ kesi aarẹ ki o tu Naijiria ka kawọn ya sọtọ.
Awọn ipenija yi titi di oni taa n ṣe ajọdun ijọba awarawa ni Naijiria ṣi wa nilẹ.
Bi ijọba Buhari yoo ti ṣe wa tukọ orileede yi lawọn eeyan n wo ki awọn araalu ba le jẹ anfaani ti wọn tori rẹ korajọ ṣe ajọdun Democracy Day.
Olusegun Obasanjo: Àwa ìgbìmọ̀ tó ń wá ire Nàíjíríà ṣèpàdé, àbọ̀ ń bọ̀ láìpẹ́
Oríṣun àwòrán, other
Ọrọ ti jade nipa ipade ti awọn alẹnulọrọ nilẹ yii, ti wọn pe ara wọn ni igbimọ majẹobajẹ to n wa ire Naijiria (Committee for the Goodness of Nigeria) CGN se lọjọbọ.
Awọn eeyan naa, tawọn to jẹ asaaju Naijiria tẹlẹ wa lara wọn, lo se ipade nilu Abuja lati fori ikooko sọdun lori eto aabo Naijiria ati ọna abayọ si.
Lara awọn to peju sibi ipade naa ni Oloye Olusegun Obasanjo, Sultan tilu Sokoto, Muhammad Sa'ad Abubakar, John Cardinal John Onayekan ati Abdulsalami Abubakar.
Àwọn ìtàn mánigbàgbé tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí:
Lọjọbọ lẹyin ipade wọn naa ni agbaagba yii kede pe awọn ko ni ohunkohun sọ nipa ohun ti wọn jiroro le lori nibi ipade naa.
Amọ lọjọ Ẹti, ni oloye Olusegun Obasanjo sọ fawọn akọroyin nilu Abuja pe igbimọ naa ti gbe abọ ipade rẹ sinu iwe, ti yoo si fi ransẹ si aarẹ Muhammadu Buhari.
Igangan Attacks: Àkójọpọ̀ àbọ̀ BBC Yorùbá rèé nípa ìṣẹ̀lẹ̀ òfò ẹ̀mí àti dúkìá tó wáyé
O ni ohun ti ipade awọn da lori ni ọna lati wa ojutu sawọn isoro to n ba Naijiria finra bii eto aabo to mẹhẹ,  ọrọ aje to dagun, igbaye-gbadun araalu ati ilọsiwaju Naijiria.
Awa olori tẹlẹ ni Naijiria, Awọn adajọ agba tẹlẹ, ati awọn oludamọran nipa eto aabo tẹlẹ la wa ninu igbimọ to n wa ire Naijiria."
Bakan naa lawọn ẹlẹgbẹjẹgbẹ osisẹ, olukọ ni fasiti, awọn ẹgbẹ obinrin atawọn eeyan miran wa ninu wa amọ Jonathan, Anyaoku ati Wole Soyinka ko le ba wa pe.
Aarẹ Buhari fesi si iwe wa ta kọ pe a fẹ se ipade naa, to si fesi pada pe ka lọ se, ti abọ ipade naa si jẹ oun logun.
Ogbomoso: Ẹ kálọ sí Ajilete láti mọ àwọn ibùdó tó mú kí ìlú náà yàtọ̀
"A ba ara wa sọ okodoro ọrọ nibẹ nipa bi ọrọ aje ati eto aabo Naijiria se dori kodo, ta si gba pe ọpọ ọrọ la n sọ lai gbe igbesẹ gidi lati ọjọ yii wa."""
Obasanjo ni awọn ko ni fi abajade ipade naa sita titi digba ti awọn ba kọkọ fi abọ ipade naa ransẹ si aarẹ Buhari.
"Amọ a ti pinnu lati mu ayipada ba ohun to n waye tẹlẹ nipa nini igbẹkẹle ninu ara wa, ka si maa gbe igbesẹ tọ ọrọ ta ba sọ.
Laipẹ lẹ si gbọ nipa awọn igbesẹ wa lori abajade ipade ta se."
Lara awọn eeyan miran to tun bawọ̀n peju sibi ipade naa ni Ooni ile Ifẹ́, Oba Adeyeye Enitan Ogunwusi, Etsu ti Nupe, Tunde Fasawe ati Audu Ogbeh.
Aarẹ ana ni Naijiria, Oloye Olusegun Obasanjo ti kesi awsn eeyan to n beere fun iyapa Naijiria lati jami lori ero naa, ki wọn si sisẹ pọ fun isọkan orilẹede yii.
Obasanjo ni ohun to dara gbaa ni ki awọn ẹya to wa ni Naijiria wa ni ọkan soso laisi iyapa, nitori iwa omugọ gbaa ni fun orilẹede yii ko pin yẹlẹyẹlẹ.
Oloye Obasanjo woye ọrọ yii nibi apejẹ lati yan alaga tuntun, Kehinde Isijola fun ẹgbẹ awọn wọnlẹ-wọnlẹ ni Naijiria, ẹka ti ipinlẹ Ogun.
Ibudo iyawe-kawe Oloye Olusegun Obasanjo si ni ayẹyẹ naa ti waye lọjọru.
Aarẹ ana ni Naijiria naa wa gbe imọran kalẹ pe iyi wa ninu ki orilẹede Naijiria wa ni ẹyọ kan soso ju ki ẹya kọọkan da duro lọtọọtọ lọ.
"Ohun ti ko dara rara ni ki Naijiria pin yẹlẹyẹlẹ lasiko yii ti ilẹ Afirika n tiraka lati fidi mulẹ lẹka oselu, ọrọ aje ati igbaye-gbadun ọmọniyan.
Olusegun Obasanjo: Ọmú ìyá mi ti mo fi ń mùkọ ni kekere ló jẹ ki ń lókun
Emi jẹ ẹnikan to nigbagbọ pupọ ninu isọkan Naijiria ti yoo wa ni ọkan soso ni gbogbo ọna, nibi ti ori ọmọ ilẹ yii kọọkan yoo ti wu pe oun ni ipin ninu orilẹede yii."
Obasanjo wa fi orilẹede Pakistan, Yugoslavia ati Sudan se apẹrẹ awọn orilẹede to pin yẹlẹyẹlẹ, amọ ti wọn ko tii ri ojutu sawọn isoro to n ba wọn finra.
O wa salaye pe awa ọmọ Naijiria lo yẹ ka di ẹbi wahala ta n koju lorilẹede yii ru ara wa, dipo ka maa da Ọlọrun lẹbi.
Aremu: Eré ìtàn nípa ìbí, àti jéèyàn pẹ̀lú ìpèníjà Olusegun Aremu Obasanjo
Buhari: Ààrẹ di ẹ̀bi àìrí iṣẹ́ ṣe ru àwọn ọ̀dọ́ Nàìjíríà torí àwọn ìgbésẹ̀ kan tí wọn gbé
Oríṣun àwòrán, The africa report.com
Aarẹ orileede Naijiria, Muhammadu Buhari ti ṣalaye idi ti ọpọ ọdọ Naijiria ko fi ri iṣẹ ṣe, eyi to ni ko sẹyin akoba to waye lasiko iwọde ENDSARS.
Ninu ifọrọwero ti aarẹ ti kopa lori eto akanṣe ileeṣẹ amounmaworan Arise TV ni o ti fi ọrọ yii lede.
Buhari ni awọn ọdọ to kawe gboye rẹpẹtẹ le ma ri iṣẹ nitori iwa ti awọn eeyan kan hu.
O ni ipalara ati biba nkan jẹ to wyae lasiko iwde ENDSARS to lati le awọn to ba fẹ doko owo ni Naijiria kuro.
''Lọ ba eyikeyi Gomina ki o s fun pe ki o fun ẹ ni iṣẹ tabi agbaṣe iṣẹ yoo sọ fun ọ pe ko si aaye.Bẹẹ lọrọ ri lọdọ awọn ijọba ibilẹ naa.''
O ni tori eyi pupọ ọdọ le kawe gboye ṣugbọn wọn le ma ri iṣẹ titi ti wọn yoo fi jade laye.
Àwọn jàndùkú ṣe yabò àwọn olùwọ́de #ENDSARS ní Alausa l'Eko
''Idi ni pe ko si ẹni ti yoo fi owo rẹ doko owo layika ti ko ba si ifọkanbalẹ. Nitori naa ni mo fi sọ fun awọn ọdọ pe ti wọn ba fẹ iṣẹ, ki wọn ṣe pẹlẹ pẹlẹ''
Aarẹ tun tọka si awọn ọkọ akero igba, ti wọn dana sun ni ipinlẹ Eko, eyi ti Gomina Ambode ra .
''Ta ni yoo wa da ileeṣẹ silẹ nigba ti ko ba si ifọkanbalẹ? Ko si.''
Nkan ti mo n sọ yii ko gba ọgbọn pupọ. Ẹ ṣe jẹjẹ, ti alaafia ba wa nilu awọn eeyan yoo wa lati dokowo ti yoo mu iṣẹ wa''
Oríṣun àwòrán, The africa report.com
Oríṣun àwòrán, Muhammadu Buhari/Facebook
Ẹwẹ, Aare Muhammadu Buhari ti ṣe  abẹwo si ilu Eko ni guusu Iwo Oorun Naijiria.
Nibe lo ti kopa ninu eto ifọrọwanilẹnuwo aladase pẹlu ileese Amohunmaworan Arise TV.
"Nibi ifọrọwanilẹnuwo yii ni Aare Buhari ti ni oun kọ lati sọrọ nipa ofin ti ijọba oun fi de ""Twitter"""
Buhari ni oun ko ni dahun ibeere igba ti Twitter yoo bẹrẹ isẹ pada ni Naijiria lasiko naa.
O ni awo mọ sinu, mọ sikun ni oun fi da.
Bakan naa ni Aarẹ Buhari sisọ loju eegun isẹ akanse ti Nigerian Maritime Administration and Safety Agency (NIMASA).
Alakuko/Elega Schools: Aráàlú ní olùkọ̀ọ́ àti akẹ́kọ̀ọ́ ti sá ní kíláàsì tí kò dára
Eyi ti wọ́n pe ni Deep Blue Project.
Awọn miran ti wọn jọ si eto naa ni: Femi Gbajabiamila to jẹ abẹnugan ile igbimọ Asofin ni Abuja, Gomina Sanwo Olu ti ipinle Eko, Gomina ipinlẹ Ekiti, Oyo, Ogun ati igbakeji gomina Ondo.
Bakan naa ni Seneto Gbemisola Saraki, Minista eto irinna ati minista abẹlẹ to n mojuto eto irinna ni Naijiria.
Ọlọ́pàá àti ológun kò ní lójú àánú mọ́ fáwọn abàlújẹ́, ìyàtọ̀ yóò wà - Buhari
Buhari: A má a lo òfin tó ní kí wọn mú màálù tó bá jẹ oko títí tí olówó rẹ̀ yóò fi sanwó
Aarẹ Orilẹede Naijiria, Muhammadu Buhari ti ni ominu n kọ oun nipa ẹkun iwọ oorun ariwa Naijiria , nibi ti awọn eeyan to jẹ ẹya kan naa ti n pa ara wọn.
Aarẹ Buhari woye ọrọ yii lasiko to n kopa lori eto ifọrọwerọ kan pẹlu ileesẹ mohunmaworan kan, to si ni ijọba yoo kan si wọn nibamu pẹlu ede ti wọn gbọ.
"Awọn eeyan yii ti wọn dijọ n sọ ede kanna ni wọn n pa ara wọn, ti wọn si tun n ji maalu ara wọn, ti wọn tun n jo abule ara wọn.
A ti fun awọn ọlọpa atawn ologun ni agbara lati mase loju aanu lawọn ọsẹ diẹ sasiko yii, iyatọ yoo si wa.
Tẹ ba jẹ kawọn eeyan lọ sisẹ ninu oko wọn, ebi yoo pa ilu, tijọba yoo si wọ wahala nla, eyi ti a ko fẹ ko sẹlẹ nitori a ti koju isoro to ga to."
Alakuko/Elega Schools: Aráàlú ní olùkọ̀ọ́ àti akẹ́kọ̀ọ́ ti sá ní kíláàsì tí kò dára
Buhari ni oun ti se ayipada awọn ọga ologun, ta si ba wọn se ipade pọ pẹlu ni aimọye igba.
"A gba wọn laaye lati lọ kaakiri lọ wo ipo ti nnkan wa funra wọn, ta si sọ pe a fẹ ki alaafia wa, ki awsn eeyan le pada sinu oko wọn lati dako.
Amọ a ko pariwo sita pupọ, ki awọn ẹni ibi ma baa mọ, amọ awọn eeyan to wa lẹnu isẹ agbofinro mọ ohun ribiribi ta n se."
Nigba to n sọrọ lori idasilẹ ileesẹ ọlọpaa lawọn ipinlẹ kọọkan, aarẹ Buhari ni oun ti sọ fun awọn gomina pe ki wọn lọ finmu finlẹ labẹle.
Wọn ko le joko kalẹ lẹyin ti wọn ba wọle ibo gomina tan, ki wsn si lero pe emi ni maa ma sisẹ fun wọn, mo ti ran wọn pada.
Nigba to n sọrọ lori bi ẹya kan se n gba ipo giga ju awọn ẹya miran lọ, aarẹ Buhari ni ko yẹ ki wọn maa fi awọn eeyan sipo nitori pe wọn wa lati ẹya kan.
O ni bi eeyan kan ba se dangajia si ni oun maa n wo, bi wọn ba se sisẹ kaakiri si, pẹlu iye ọdun ti wọn fi ni iriri lẹnu isẹ bii ọdun mẹẹdogun si mejidinlogun.
TB Joshua: Ṣe ni ọ̀pọ̀ èèyàn ń wa ẹkún mu torí ikú òjijì tó pa wòlíì
Lori ọrọ bi awọn darandaran se maa n da ẹran kiri loju taye, aarẹ Buhari ni oun ti ni ki wọn wa akọsilẹ ofin ijọba kan jade eyi to n safihan awọn oju ọna maalu ati agbegbe ifiẹran jẹko.
Ofin naa ni pe darandaran ti ẹran rẹ ba jẹ oko oloko, ki wọn mu ẹran naa pamọ, titi ti olowo rẹ yoo fi sanwo oko to jẹ.
O ni awọn darandaran n ko ara wọn nijanu lasiko naa nitori iwọnba ni awọn darandaran to wa, ta si mọ awọn oju ọna ti wọn le gba, o rọrun lati mọ awọn ọna naa.
"Asa ka maa sare wa silu Abuja lo n fa wahala yii. Gomina ipinlẹ Benue si ni mo jẹ ọkan lara wọn amọ n ko jiyan rẹ.
Ohun ti mo n sọ ni pe darandaran ni Naijiria ko legbe ju ọpa lọ amọ awọn eleyi ti n gbe ibọn AK 47.
Awọn Fulani to n wa lati orilẹede Mauritania atawọn agbegbe miran si jọ awọn ọmọ orilẹede yii, eyi to mu ki awọn eeyan maa mu omulomu
Igangan Attacks: Àkójọpọ̀ àbọ̀ BBC Yorùbá rèé nípa ìṣẹ̀lẹ̀ òfò ẹ̀mí àti dúkìá tó wáyé
Nigba to n sọrọ lori ohun to kan to fẹ se to ba kuro nipo aarẹ tan, Muhammadu Buhari ni oun ko pa oko oun ti , oun si setan lati pada sibẹ.
Mo si n sọ fun awọn ọmọ Naijiria pe mo nifẹ lati se daadaa si wọn."
"Lootọ la si nilo ilọsiwaju lẹkun iwọ oorun guusu Naijiria, ila oorun guusu, amọ lọwọlọwọ bayii, ẹkun iwọ oorun ariwa Naijiria lo n kọ mi lominu pupọ nitori ibẹ lo n gbona janin-janin lọwọ."""
Pańpẹ́ ọba mú pàsítọ̀, babaláwo àti àwọn mẹ́ta tí wọ́n ká ara ènìyàn mọ́ lọ́wọ́
Oríṣun àwòrán, thenewstrack.com.ng
Pàsítọ̀ kan ni ìlú Kajola ni ẹ̀ba Osogbo tí ṣe olú ìlú ìpínlẹ̀ Osun, Olagunju Adetunji ni àwọn ọlọ́pàá fi ojú rẹ̀ hàn fáwọn oníròyìn nítorí wọ́n ká ọwọ́ àti ẹsẹ̀ ènìyàn mọ lọ́wọ́.
Yàtọ̀ sí pàsítọ̀ ẹni ogójì ọdún náà, wọ́n tún sàfihàn Rasheed Ajani, Saka Akeem, Abiodun Adetimilehin àti Adewumi Gbadamosi to jẹ́ babaláwo nítorí wọ́n fẹ̀sùn kan pé ó pa ọmọdé kan tí wọ́n pe orúkọ rẹ̀ ni Kehinde nítòsí ilé ìwòsàn ni Osogbo.
Kọmísọ́nà ọlọ́pàá ìpínlẹ̀ Osun, Wale Olokode sọ pé lẹ́yìn tí àwọn ará ìlú tá àwọn lólobó ni àwọn mú àwọn afurasi náà ni agbègbè Oke Ayepe Osogbo  àti Kajola Ijesha.
"Wọn mú àwọn afunrasí pẹ̀lú ọwọ àti ẹsẹ̀ ẹnikan tí wọ́n pé ní Kehinde tó sì ti ń jẹrà, kò sí ẹni tó ti mọ orúkọ bàbá rẹ̀ àti àdúgbò tó ń gbé títí di àsìkò yìí.
Ọwọ́ ọlọ́pàá tẹ afurasí tó gé ojú-ara ọmọdébìnrin ọdún mẹ́fà fún ètùtù ọlà
Wo bí afurasí ọmọ ọdún 16 àti 17 ṣe pa ọmọ ọdún 11 láti fi ṣe ètùtù ọlà
Ọwọ́ ikọ̀ Amọtẹkun ba Mutiu Abdul-Rasheed, afurasí tó ń ta ẹ̀yà ara èèyàn ní Ibadan
Olórí àwọn afunrasí náà, Adewumi Gbadamosi, jẹ́wọ́ pé òun hùwà ìbàjẹ́ náà pẹ̀lú àlàyé pé òun gbé orí olóògbé náà fún Olagunju Adetunji fún ètùtù, gẹ́gẹ́ bí Kọmísọ́nà ọlọ́pàá ṣe sọ.
Gbadamosi sọ fún àwọn oníròyìn pé, òun yin Kehinde ní ìbọn lásìkò tó ń ṣe iṣẹ́ ọdẹ lóru ni Osogbo, ó fi kún pé lẹ́yìn tí òun yín ní ìbọn tán, òun pín ẹ̀yà ara rẹ̀, mú èyí tí oun nílò, tó sì ju èyí tó kù sínú odò.
Baba aláwo tó jẹ́ ẹni àádọ́ta ọdún ṣàlàyé pé òun gbé orí nàá fún Adetunji àti ọ̀rẹ́ rẹ̀ Saka, tí wọ́n tí kàn sí òun tẹ́lẹ̀ láti rán wọn lọ́wọ́ láti ni ọ̀pọ̀ oníbàárà.
Bákan náà ló fi kún pé Ajani tí ó jẹ́ ọlọ́dẹ ran òun lọ́wọ́ láti gbé ọkùnrin tó pá lẹ́yìn tí òun paa tán.
Nigeria'sTwitter ban: Orílẹ̀-èdè Amẹrika pé kí Naijiria fòpin sí fifofinde Twitter.
Oríṣun àwòrán, Getty/other
Orílẹ̀-èdè Amẹrika tí bu ẹnu àtẹ́ lu bí ìjọba Nàìjíríà ṣe fòfinde lilo òpó ikansiraẹni Twitter tí wọ́n sì pàṣẹ láti fi ẹnikẹni tó bá ṣe bẹ́ẹ̀ jófin tó fi mọ́ àwọn ilé iṣẹ́ ìròyìn.
Wọ́n ké sí ìjọba láti ṣe àtúngbéyèwò ìpinnu wọn.
Dídí àwọn ọmọ Nàìjíríà lọ́wọ́ láti kó ìròyìn jọ àti láti sọ èrò ọkàn wọ́n àti nǹkan tí wọn mọ̀ síta kò ní ààyè nínú ètò ìṣèjọba àwa arawa."
Ànfàní láti lè sọ èrò ọkàn ẹni àti  láti mọ̀ nípa ọ̀rọ̀ tó n lọ lórí ayélujára àti láyìíká jẹ́ ìpílẹ̀ fún eto ijoba àwa arawa tó ní ìlọsíwájú ni àwùjọ, agbenusọ ilẹ̀ Amerika Ned Price ló sọ èyí nínú àtẹ̀jáde.
Iléesẹ́ Twitter ti ń bá ìjọba Nàìjíríà sọ̀rọ̀ papọ̀- Alhaji Lai Mohammed
Wo ìlànà tuntun tó tẹ̀lé láti gba ‘Passport’ ní Nàíjíríà
Ìjọba ẹ ṣọ́ra! gbígbégilé ojú òpó Twitter tako ẹ̀tọ́ àwọn ọmọ Naijiria - Gómínà Ṣeyi Makinde
Ẹ̀yin iléesẹ́ ìròyìn gbogbo ní Nàìjíríà, Ẹ dẹ́kun líló 'Twitter' bí bẹ́ẹ̀ kọ́...- NBC
Price fi kún pé àjọ tó ń mójútó ìgbóhùnsáfẹ́fẹ́ (NBC) tí pa á láṣẹ fún àwọn oniroyin ilé iṣẹ́ amóhùmáwòrán àti rẹ́díò láti dẹkùn lilo Twitter.
Orílẹ̀-èdè Nàìjíríà fòfinde Twitter láìsí gbedeke ọjọ́ lẹ́yìn tí ilé iṣẹ́ náà yọ ọ̀rọ̀ kan tí ààrẹ sọ pé ó tẹ òfin Twitter lójú mọ́lẹ̀, pàápàá julọ èyí tí ààrẹ sọ pé èdè tí àwọn tó ń dá ìlú ru gbọ́ ni òun yóò fi bá wọn sọ̀rọ̀.
Lẹyin èyí ni àwọn ilé iṣẹ́ tó ń sagbateru ìbára ẹni sọ̀rọ̀ gbogbo náà gbégidínà lílò rẹ̀ fún àwọn oníbàráà wọn tí ìjọba pẹ̀lú sì tún kesi Twitter àti àwọn òpó ikansiraeni tó kù lọ́jọ́ru pé  kí wọ́n wá gba ìwé àṣẹ láti ṣiṣẹ́ ni Nàìjíríà
Ni báyìí ilé iṣẹ́ Twitter náà tí fi àwọn ènìyàn lọ́kàn balẹ̀ pé àwọn ń sapá lati mú kí àwọn ará ìlú láǹfààní láti túbọ̀ máa lo o.
Ilé iṣẹ́ Twitter àti àjọ ajafẹ́tọ̀ọ́ ọmọnìyàn Amnesty International náà ṣàlàyé pé fifofinde Twitter jẹ́ nǹkan tó jẹ àwọn lógún gidi.
Funmi Awelewa - N kò ní gbà kẹ lò mí tán, kẹ wá já mi jù sílẹ̀ bíi náírà márùn-ún àlòkù
Oríṣun àwòrán, funmiawelewa/Instagram
Ọ̀pọ̀lọpọ̀ àwọn olólùfẹ́ Orijafunmi Awelewa, lọ tí ń janu lójú òpó Instagram láti gbé sẹ́yìn gbajúgbajà òṣèré olólùfẹ́ wọn, tó sọ̀kò ọ̀rọ̀ lu àwọn akẹ́gbẹ́ rẹ̀.
Àwọn akẹẹgbẹ́ rẹ̀ yìí ló ní wọ́n fẹ́ràn láti má sanwó iṣẹ́ tí wọ́n bá bẹ akẹ́gbẹ́ wọ́n láti kópa nínú sinimá agbéléwò.
"Gẹ́gẹ́ bí ó ṣe kọ́ soju òpó instagram rẹ̀,  ""ṣe ẹrí àwọn akẹ́gbẹ́ wa nínú eré tíátà, wọ́n fẹ́ràn láti máa bá àwọn ènìyàn ṣe, tí wọ́n bá rí àǹfààní lọ́dọ̀ ẹni náà ní."
"Ọmọ Iya mi jà f'órí rẹ̀. Awọ́n ènìyàn fẹ́ran láti lo ènìyàn, kì wọn sì já jù sílẹ̀ bí náírà márùn-ún àlòkù"""
Orijafunmi ṣàlàyé pé kí gbogbo àwọn akẹ́gbẹ́ òun gbajumọ nǹkan tí yóò gbé oúnjẹ́ òòjọ́ wá sórí tábìlì wọ́n, nítorí lẹ́yìn ó rẹyìn, àwọn àti ẹbí nìkan ni yóò kojú nnkan tó bá jẹyọ.
Oríṣun àwòrán, funmiawelewa/Instagram
Ó fi kú pé kò sí anfaani kankan nínú kí ènìyàn jẹ́ ìlúmọ̀ọ́ká lai ni kọ́bọ̀ lápò.
Ó wá ké sí àwọn akẹ́gbẹ́ rẹ̀ pé bí wọ́n bá pe oun si iṣẹ́, kí wọ́n ṣetán láti sanwó isẹ́ òun.
Gbajúgbajà òṣèré náà, tí ọ̀pọ̀ mọ̀ sí Morili ni, ọ̀pọ̀ àwọn tó wà lókè kò ṣetán láti fà àwọn tó wà nílẹ̀ sókè, orí ara wọn nìkan ni wọn ń dù.
Ọ̀pọ̀ àwọn olólùfẹ́ rẹ̀ ló ti wá ń kín ọ̀rọ̀ rẹ̀ lẹ́yìn pé, ọ̀rọ̀ Funmi Awelewa jána, àwọn òṣèré tíátà mìíràn pẹ̀lú wà lára àwọn tó gbàrùkù tí nǹkan ti Funmi sọ.
Díẹ̀ lára àwọn tó kín Funmi lẹ́yìn lórí ọ̀rọ̀ náà rèé
Oríṣun àwòrán, funmiawelewa/Instagram
Bobrisky: Ẹyin mi ti lọ, inú ń dùn mí, ìrora yìí pọ̀ jù
Oríṣun àwòrán, Instagram/Bobrisky
Yoruba bọ, wọn ni oju ẹni maa la, a ri iyọnu, tita, riro si la n kọ ila, to ba jinna tan, yoo si di oge.
Bayii gan an lọrọ ṣe ri pẹlu gbajugbaja ọkunrin to maa n mura bii abo, Idris Okunneye, ti ọpọ eeyan mọ si Bobrisky, lori isẹ abẹ to ṣe lati mu ki idi rẹ tobi, ko si duro daadaa nilẹ.
Laipẹ yii si la mu iroyin wa fun yin pe Bobrisky fẹ lọ se ise abẹ idi saaju ọjọ ibi rẹ to si ni oun fẹ maa se idi bala-bala ko to di igba naa.
Nibayii to ti se ise abẹ idi naa nilu Santo Domingo ni lorilẹede Dominican Republic, Bobrisky ti wa n kerora pe iṣẹ abẹ naa ko rọrun rara.
Koda o ni oun ro pe oun ti fẹ ku ni nibi ti iṣẹ abẹ naa dun oun de, ti inu si n kan oun pẹlu.
Bobrisky sọrọ loju opo Snapchat rẹ pe irora ti oun jẹ lasiko iṣẹ abẹ ọhun ko ṣe maa fi ẹnu sọ.
''Ikun mi n dun mi gan an, bakan naa ni ẹyin n ro mi goro go.
Awọn eeyan ti wọn ba ti ṣe iru iṣẹ abẹ bẹẹ ri lo le sọ bi irora to wa nibẹ ṣe pọ to.
Oríṣun àwòrán, Bobrisky/Snapchat
Mo fẹ ki gbogbo irora naa lọ, ki n si pada si igbe aye ti mo n gbe tẹlẹ, ki n to lọ ṣiṣẹ abẹ idi,'' Bobrisky ṣalaye.
Isẹ abẹ yii ti wọn n pe ni 360 Liposuction, ni wọn ti maa n bu ọra kuro ni awọn ẹya ara kan, bii itan, ikun tabi isalẹ ẹyin.
Awọn ọra yii ni wọn yoo si ko lọ sinu idi, lati jẹ ko tobi si.
Oríṣun àwòrán, Bobrisky/Snapchat
Awọn ọra naa bakan naa, ni yoo tun jẹ ki irisi idi tun yatọ lai jẹ pe wọn ri ohunkohun sinu rẹ.
Bobrisky ti sọ tẹlẹ pe oun gbọdọ ṣe iṣẹ abẹ yii lai fọta pe.
''Mo gbọdọ se ni, maa wọ inu yara isẹ abẹ lọ, ki n si jade pẹlu ara to rẹwa.
Ọjọ Kọkanlelọgbọn osu Kẹjọ ni ọjọ ibi mi, mo si fẹ ki irisi mi jẹ oju ni gbese lọjọ naa,'' Bobrisky lo sọ bẹẹ.
Bobrisky fikun ọrọ rẹ pe lati ọdun diẹ sẹyin loun ti n ro lati se isẹ abẹ naa, ki oun to wa pinnu bayii lati ṣee.
Oríṣun àwòrán, Bobrisky/Instagram
Democracy Day: Wo àwọn ààrẹ alágbádá tó ti jẹ ní Nàìjíríà láti ìgbà òmìnira di àkókò yìí
Oríṣun àwòrán, Goodluck Jonathan
Bọmọde o mọ itan, yoo ba arọba nitori arọba gan an ni baba itan.
Ẹyin n woo pé kí lo ba owe yii wa.
Ọrọ to kan yin, to kan mi ni o, ọrọ ijọba awaarawa lorileede Naijiria la n sọ.
Àwọn ìtàn mánigbàgbé tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí:
Lẹyin ijijagbara lọwọ ijọba amunisin ilẹ Gẹẹsi, Naijiria gba ominira lọjọ kinni oṣu kẹwaa ọdun 1960.
Bayii ni ijọba awaarawa ṣe bẹrẹ ni Naijiria eyi to mu ki Nnamdi Azikiwe di aarẹ àkọkọ ninu itan orileede Naijiria ti Alhaji Abubakar Tafawa Balewa si jẹ Olootu ijọba.
Hmmm... Yoruba kare lai!  Wọn ní ile to ba n toro, ọmọ ale ibẹ ni ko tii dagba.
Oríṣun àwòrán, Nigerian Facts and History
Lọjọ kẹẹdogun osu kinni ọdun 1966 lawọn ologun ditẹ gbajọba ninu eyi ti wọn ti ṣekupa Tafawa Balewa at'awọn olori ijoba mii bii Samuel Ladoke Akintola to jẹ olori ijoba ilẹ Yoruba nigba naa.
Ọdun mẹtala gbako ni Naijiria lo loko ẹru ijọba ologun.
Àmọ́, orileede Naijiria pada si ijọba awaarawa lọdun 1979 lẹyin ti Ọgagun Olusegun Obasanjo gbe ijọba fun alagbada ti gbogbo ilu dibo yan, Alhaji Shehu Shagari.
Bayii ni Shagari ṣe di aarẹ abaṣẹ-waa akọkọ lorileede Naijiria.
Oríṣun àwòrán, Shehu Shagari film documentary
Shagari lo ọdun mẹrin fun saa akọkọ, Koda o tun wọlé ẹkeji lọdun 1983.
Àmọ́, awọn ologun tun gbeṣe wọn dé, ọdun 1983 yii naa ni wọn tun fipa gbajọba.
Ọdun mẹwaa ni ijọba ologun tun fi dari orileede Naijiria ki aarẹ fidihẹ Oloye Ernest Shonekan to gori oye lọdun 1993 lẹyin ti Ọgagun Ibrahim Babangida wọgile ibo aarẹ to gbe Moshoodi Kashimawo Olawale Abiola wọlé.
Ṣugbọn oṣu perete bayii ni Oloye Shonekan lo ki Ọgagun Sani Abacha to gbajọba lọwọ rẹ.
Oríṣun àwòrán, Earnest Shonekan
Oju ọmọ Naijiria ri to laye Abacha, ẹyin naa rántí?
Ṣebi ẹ mọ pe ẹni ti Ọlọhun ko le mu, faabada, ko tii da iru eeyan bẹẹ.
Lẹyin ti ijọba Abacha milẹ titi fún ọdun marun gbako, iku wọlé mu ùn lọ lọdun 1998.
Iku Abacha ko maa mu opin ba ijoba ologun ni Naijiria!
Ogagun Abdulsalami Abubakar lori gori aleefa, amọ oun naa lo gbejoba pada falagbada lọdun 1999.
Ṣe ẹ mọ pe, ori ti yoo ba Dade, ko ní ṣá lai d'ade.
Lẹyin ti ori ko o yọ lọgba ẹwọn ti Abacha ju sí, Oloye Olusegun Aremu Obasanjo wọle ibo ààrẹ Naijiria labẹ asia ẹgbẹ oṣelu PDP, o si di aare alagbada lọdun 1999.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Obasanjo lọdun mẹrin akọkọ lori oye.
O tun ṣe bẹ́ẹ̀ wọlé saa keji lọdun 2003 nibi to ti tukọ Naijiria f'ọdun mẹrin mìíràn.
Oloogbe Umaru Musa Yar'adua di ààrẹ orílẹ̀-èdè Nàìjíríà, lẹyin to jawe Olubori ninu ibo aarẹ ọdun 2007, bo tilẹ jẹ pe awuyewuye pọ lori esi ibo ọhún.
Ọpọ ni magomago wa ninu idibo naa.
Ṣugbọn iku ko dọjọ, arun ko doṣu.
Yar'adua ko lo ju ọdun meji lọ lori aleefa.
Ọjọ karun osu karun ọdún 2009 lo jẹ Ọlọrun nipe leyin to ti Irinajo de lati Sáúdí.
Aṣe orukọ ọmọ maa n ro ọmọ ni tootọọ.
Goodluck Jonathan to jẹ igbakeji Yar'adua depo aarẹ lẹyin ti ọga rẹ jẹ Ọlọrun nipe tan.
Oríṣun àwòrán, Facebook/Goodluck Jonathan
Jonathan dije fún ipò ààrẹ ninu ibo ọdún 2011 ninu eyi to ji jawe Olubori labẹ ẹgbẹ oṣelu PDP.
Jonathan gbe ijoba fun Muhammadu Buhari wọọrọwọ lẹyin to jawe Olubori ninu eto idibo ọdun 2015.
Buhari ti dupo ààrẹ tẹlẹ fún igba mẹta ọtọtọ ko to pada wọlé labẹ asia ẹgbẹ oṣelu APC.
"Buhari ṣèlérí ayipada tawọn oloyinbo n pe ni ""change"" lẹgbẹ APC fawọn ọmọ Naijiria."
Oríṣun àwòrán, Muhammadu Buhari
Sai Baba gẹgẹ bi awọn ololufẹ Buhari ṣe máa ń pe tun wọle saa keji lọdun 2019.
Buhari naa lo sí wa lori oye titi di akoko yii.
Ẹyin ọmọ Naijiria nile, loko, lodo ati lẹyin odi, ẹ ku ayajọ ọdun ijọba awaarawa.
Iwaju iwaju lọpa ẹbiti n ree si, Naijiria ko ni rẹyin lasẹ Edumar
June 12: Ọ̀gá àgbà ọlọ́pàá ní Nàìjíríà sọ lórí ìfẹ̀hónúhàn táwọn èèyàn fẹ́ ṣe lásìkò àyájọ́ ìjọba awarawa
Oríṣun àwòrán, Babajide Sanwo-Olu
Ọga ọlọpaa lorilẹede Naijiria, IGP Usman Alkali Baba ti sọrọ lori iwọde tawọn eeyan kan n gbero lati ṣe lọjọ ayajọ ijọba awarawa ni Naijiria lọjọ kejila oṣu kẹfa ọdun 2021 yii, June 12.
Ọga ọlọpaa ni Naijiria rọ awọn araalu lati ṣe ayajọ ijọba awarawa pẹlu alaafia lai da rogbodiyan kankan silẹ.
Ọga ọlọpaa Baba sọrọ yii lasiko abẹwo ọlọjọ mẹta to ṣe si ipinlẹ Eko.
Awọn eeyan kan papa julọ awọn ọdọ ti n gbero lati fi ẹhonu wọn han lori bi nkan ko ṣe fara rọ ni Naijiria.
Eleyii ti mu ki ibẹru bojo gbalẹ kaakiri orilẹede ṣaaju ọjọ iwọde yii.
Koda awọn kan tiẹ n sọ pe afaimọ ki iwọde ọhun maa da bi ti EndSARS to mi ilu titi loṣu kẹwaa ọdun 2020.
Ṣugbọn ọga ọlọpaa sọ pe ọjọ ayọ ati ọjọ idunnu ni June 12 tii ṣe ayajọ ijọba awarawa lorilẹede Naijiria.
O rọ awọn ọmọ Naijiria pe ki wọn yọ ayọ mọ ni wọn ki onikaluku si maa ṣiṣẹ rẹ lai pa ẹlomiran rara.
''Ẹyin olugbe ipinlẹ Eko, ẹ lọ fọkan balẹ, ileeṣẹ ọlọpaa ṣetan lati daabo bo yin bi ẹ ti n ṣe ajọyọ ayajọ ijọba awarawa,'' Baba lo sọ bẹẹ.
Ọga ọlọpaa ni Naijiria tun rọ awọn ọba alaye lati fọwọ sowọpọ pẹlu ileeṣẹ ọlọpaa lori akitiyan ati wa ojutu si eto abo to mẹhẹ ni Naijiria.
Ọga ọlọpaa sọrọ yii nigba to ṣabẹwo si Eleko ti Eko, Oba Rilwan Akiolu niluu Eko.
TCN: Naijiria ti ṣetán láti máa pín iná mọ̀nàmọ́ná sí Niger, Togo, Benin ati Burkina Faso
Oríṣun àwòrán, The Electricity Hub
Awọn orilẹ-ede mẹrin kan ni Afrika; Niger, Togo, Benin ati Burkina Faso ti n gbaradi lati ra ina mọnamọna, tawọn ọmọ Naijiria ko lo.
Alaga ati adari agba ajọ to n ri si ọrọ ina mọnamọna ni iha iwọ-oorun Afrika, WAPP, Sule Abdulaziz lo kede bẹẹ fun awọn akọroyin.
Abdulaziz, to tun jẹ adari ileeṣẹ to n ri si ọrọ ina pinpin ni Naijiria, TCN, sọ pe, awọn orilẹ-ede mẹrin naa n lakaka lati ra ina ọhun labẹ asia ileeṣẹ kan ti wọn ṣẹṣẹ n kọ lọwọ.
"O ṣalaye pe ""Awọn ina ti a o maa ta ni awọn eyi ti wọn ko lo ni Naijiria."""
Awọn ẹrọ ti yoo maa fi ina naa ranṣẹ si wọn yoo maa pese ina ọhun lọna mii fun awọn nikan, nitori naa, kii ṣe lara awọn ina ti awọn ọmọ Naijiria n lo ni a fẹ ko lọ.
Alakuko/Elega Schools: Aráàlú ní olùkọ̀ọ́ àti akẹ́kọ̀ọ́ ti sá ní kíláàsì tí kò dára
Gẹgẹ bo ṣe sọ, Naijiria n reti awọn ẹrọ to n pese ina ti wọn yoo lo lati pin ina bii 330KV lati Naijiria si Niger, Togo, Benin to fi mọ Burkina Faso.
O fi kun pe oju ọna ti wọn gbe ina naa gba yoo gun to n kan bii 875 kilomita.
Abdulaziz fi kun pe awọn ilu kan bii ẹgbẹta ti wọn yoo gbe ina ọhun gba, yoo janfani rẹ nitori awọn naa yoo ri ina lo, kii ṣe pe awọn kan fẹ ko ina lọ silẹ miran nikan ni.
O ni awọn ajọ banki agbaye, ajọ idagbasoke orilẹ-ede France ati banki idagbasoke ilẹ Afrika, AfDB lo n ṣe onigbọwọ eto ọhun.
Abdulaziz ṣalaye pe orilẹ-ede Naijiria ni yoo jẹ anfaani to pọ ju ninu eto naa ,nitori awọn ileeṣẹ apinnaka ni Naijiria ni yoo maa ko ina ọhun lọ s'awọn ilẹ mii.
TB Joshua: Ṣe ni ọ̀pọ̀ èèyàn ń wa ẹkún mu torí ikú òjijì tó pa wòlíì
"O pari ọrọ rẹ pe ""Lati ibẹ lọ, ọpọ owo ni yoo wọle, awọn eeyan ti ko riṣẹ ṣe naa yoo ri nnkan maa fi pa ọwọ pa."""
Ẹwẹ, akọwe agba WAPP, Siengui Appolinaire-Ki sọ pe, iye owo ti iṣẹ naa yoo ba lọ, ko ni din ni $570 miliọnu, ṣugbọn awọn orilẹ-ede tii yoo janfaani iṣẹ naa yoo na ọwọ si iṣẹ ọhun.
O fi kun pe awọn onigbọwọ eto naa yoo na ọwọ si Naijiria atawọn orilẹ-ede ti iṣẹ naa kan kii eto naa le yọri si rere.
Ogbomoso: Wo àwọn ibùdó ìṣẹ̀ǹbáyé tó mú kí ìlú yìí gbajúmọ̀
Yoruba ni ilu ẹni, ni ilu ẹni, ko si si ibi to dabi ibi ta gbe bi ni.
Lori eto Ẹ kalọ si ilu mi ni osu yii, ilu Ogbomoso ni BBC Yoruba balẹ si lati fi oju se mẹrin awọn ibi pataki to jẹ manigbagbe ni ilu naa.
Lẹnu irinajo wa silu Ajilete yii, Ogbomoso ọmọ afogboja, ilu ti wọn ti n jẹ ọka tan, ki wọn to mu ẹkọ yangan, a se alabapade oniruuru ohun amoriwu lọkan o jọkan.
A kan si mọsalasi akọkọ nilu Ogbomoso, ati sọọsi St. David Anglican, akọkọ ti wọn kọ lọdun 1854.
Bakan naa la de aafin ọba Soun tilẹ Ogbomoso ati ibudo ti baba agba n gbe ko to ku, eyiun ijapa to wa ni aafin, to lo ọdun to le ni ọọdunrun laye.
Irinajo wa naa tun gbe wa de ibudo Ogun o jalu, to n se ọwọn iranti pe ogun ko ko ilu Ogbomoso ri.
Àwọn ìtàn mánigbàgbé tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí:
Ẹnu ko gba iroyin, ẹ maa ba wa kalọ silu Ogbomoso loni, lati fi imọ kun imọ yin nipa ilu olokiki naa.
June 12 Democracy Day: Ọ́pọ́ ọmọ Nàíjíríà tó ń ṣèwọ́de ní kí aráàlù ra oúnjẹ sílé
Oríṣun àwòrán, Sunday Igboho_1/Instagram
Gbogbo ilu lo ti n rọ kẹkẹ bayii fun eto isami ayajọ ọjọ isejọba alagbada kẹrin to bẹrẹ lọdun 1999 lorilẹede Naijiria.
Ayajọ ijọba alagbada yii, ni aarẹ Buhari kede lọdun to kọja pe yoo maa waye bayii lọjọ Kejila osu Kẹfa dipo ọjọ Kọkanlelọgbọn osu Karun ọdọọdun to maa n waye tẹlẹ.
Pataki ọjọ Kejila osu Kẹfa naa, taa mọ si June 12 si ni lati bu ọla fun oludije fun ipo aarẹ nigba naa, Oloye MKO Abiola, to jawe olubori ninu ibo naa.
Ibo yii si ni gbogbo agbaye lo jẹ itẹwọgba julọ ninu itan eto idibo lorilẹede Naijiria.
Nibayii ariwo ti n rọ kẹkẹ laarin ilu nipa ayajọ June 12 yii, eyi to ko lọjọ Satide ọla, ti omimi si ti n milẹ pẹlu nipa ayajọ naa.
Idi ni pe oniruuru awọn eeyan to setan lati sami ayajọ naa lo n kede bi sla Satide yoo se ri lorilẹede Naijiria.
Bi awọn ọdọ, ẹgbẹ akẹkọọ, ajafẹtọ ẹni, oloselu, awọn eeyan to n jijagbara fun iyapa Naijiria se n kede eto ti wọn ni, naa ni ijọba n sọ tiẹ.
Ogbomoso: Ẹ kálọ sí Ajilete láti mọ àwọn ibùdó tó mú kí ìlú náà yàtọ̀
Ọna tawọn Ajafẹtọ ẹni, ẹgbẹ Akẹkọọ ati Ajijagbara fẹ gba sami ayajọ June 12.
Ọpọ awọn ẹlẹgbẹjẹgbẹ ajafẹtọ ẹni atawọn ẹgbẹ ọdọ to jẹ akẹkọọ lo ti n figbe bọnu nigboro pe ọjọ Satide ọla yoo ro lasiko ayajọ June 12 yii.
Wọn ni ọjọ naa ni awọn yoo fi se iwọde lati tako ipo ti ko dara ti orilẹede Naijiria wa.
Awọn ikọ to n ja fun idasilẹ orilẹede Yoruba ti kede pe gbogbo ipinlẹ to wa nilẹ Kaarọ Oojiire bii Eko, Oyo, Ogun, Kwara, Ondo, Osun ati Ekiti, ni iwọde yoo ti waye lọjọ Kejila osu Kẹfa.
Ikọ naa wa n rọ awọn gomina to wa nilẹ Yoruba lati fọwọsowọpọ pẹlu awọn ki alaafia le jọba lasiko iwọde naa.
Ikọ naa tun rọ awọn araalu lati ra ounjẹ pamọ sile wọn, ti wọn si ni bi iwọde naa ba se n waye ni Naijiria, naa ni yoo maa waye nilu Oyinbo lorisirisi.
Awọn asaaju ninu ikọ to n pe fun Yoruba Nation, to fi mọ Oloye Sunday Igboho ti wa n ke si gbogbo awọn ajijagbara lati kopa ninu iwọde naa, eyi ti wọn yoo lagbara.
Oríṣun àwòrán, Sunday Asefon Facebook
Ẹgbẹ Akẹkọọ Naijiria ni ko si yatayoto kankan, iwọde nla lawọn yoo fi sami June 12:
Agbarijọpọ ẹgbẹ awọn akẹkọọ lorilẹede yii, NANS si ti fi ikede sita pe June 12 yii ni awọn yoo se iwọde alagbara lati tako eto aabo to mẹhẹ ni Naijiria.
Aarẹ ẹgbẹ NANS lapapọ, Comrade Sunday Asefon ni ko si ohunkohun to wu awọn akẹkọọ lori, ti yoo fi maa fi ayọ sami ayajọ June 12, nigba to jẹ pe ọpọ awọn ọdọ rẹ ni awọn agbebọn ti da ẹmi wsn legbodo.
Asefon, lasiko ipade akọroyin to se wa n ke sawọn akẹkọọ nilẹ Naijiria lati jade sita ni ọjọ June 12 wa se iwọde nitori n ko le wa ku, kii joye ile baba rẹ.
Oríṣun àwòrán, Omoyele Sowore/Facebook
Ọpọ awọn ẹlẹgbẹjẹgbẹ ajijagbara naa ti kede pe awọn ti gbara di fun iwọde nla ti yoo waye ni June 12.
Lara awọn ẹgbẹ ajafẹtọ ẹni naa ni Arise Nigeria ati Revolution Now.
Ẹgbẹ arise Naijiria yii, ti ọpọ wọn jẹ ọdọ si ni ariwo wsn gbode kan lori ayelujara pe June 12 yoo gbona fun iwọde kan tawsn n palẹ rẹ mọ.
Wọn ni O to gẹẹ, awọn ko le dakẹ ku ki ohun gbogbo ni Naijiria si maa bajẹ lasiko awọn, ti wọn si n ke si ijọba lati mura silẹ, nitori awọn n bọ nigboro.
Bakan naa ni ẹgbẹ Revolution Now ti Omoyele Soworẹ ko sodi ti wa n lọgun fun awọn araalu lati ra ounjẹ sile nitori ohun gbogbo yoo pakasọ.
O ni iwọde nla n bọ ni Satide June 12, ti awọn yoo si ti gbogbo ọja, ibudokọ, sọọsi, mọsalasi, ati ile ẹkọ pa ni gbogbo ipinlẹ to wa ni Naijiria.
Soworẹ ninu ikede kan to fi sita loju opo Facebook rẹ ni iwọde yii nikan ni ọna lati jẹ ki ijọba aarẹ Buhari mọ pe o ti kuna.
Alakuko/Elega Schools: Aráàlú ní olùkọ̀ọ́ àti akẹ́kọ̀ọ́ ti sá ní kíláàsì tí kò dára
Ẹ sami ayajọ June 12 lọna alaafia - Ọga agba Ọlọpaa Naijiria
Ọga ọlọpaa ni Naijiria, Usman Alkali Baba ti rọ awọn araalu lati ṣe ayajọ ijọba awarawa pẹlu alaafia lai da rogbodiyan kankan silẹ.
Ọga ọlọpaa Baba sọrọ yii lasiko abẹwo ọlọjọ mẹta to ṣe si ipinlẹ Eko lọjọru.
Ọga ọlọpaa wa rọ awọn ọmọ Naijiria pe ki wọn yọ ayọ mọ ni wọn, ki onikaluku si maa ṣiṣẹ rẹ lai pa ẹlomiran lara.
Nuhu Bamaiyi Poly Kidnap: Agbébọn tún ya bo ilé ẹ̀kọ́ Poly ní Kaduna, wọn jí ọ̀pọ̀ akẹ́kọ̀ọ́ lọ
Oríṣun àwòrán, Nuhu Bamaiyi Polytechnic
O kere tan, akẹkọọ kan ti jade laye nigba ti awọn mẹta miran di awati lasiko ti awọn agbebọn ya bo ile ẹkọ Gbogbonse Polytechnic Nuhu Bamaiyi to wa nipinlẹ Kaduna.
Iroyin naa ni awọn isẹlẹ naa waye ni deede aago mejila aabọ idaji oni ọjọ Ẹti.
Gẹgẹ bi alaga ẹgbẹ awọn olukọ nile ẹkọ naa, Aliyu Musa Kofa ti wi, awọn agbebọn naa yin akẹkọọ meji nibọn, ti wọn si ji mẹta miran lọ ati awọn olukọ.
Igba kẹta ree ti irufẹ isẹlẹ ijinigbe bayii yoo waye laarin ọdun kan lẹyin ti awọn agbebọn naa ji olukọ kan ati ọmọ rẹ meji losu kọkanla ọdun 2020 ninu ọgba ileẹkọ naa.
Kofa ni ọkan lara awọn akẹkọọ naa tawọn agbebọn ọhun yinbọn pa lo jade laye ni aarọ oni.
Ogbomoso: Ẹ kálọ sí Ajilete láti mọ àwọn ibùdó tó mú kí ìlú náà yàtọ̀
Bakan naa lo ni iyawo ọkan lara awọn osisẹ ileẹkọ naa atawọn ọmọ rẹ meji ti gba idande laarọ oni.
Nigba to n fidi isẹlẹ naa mulẹ fun BBC, Kọmisana fọrọ abẹle nipinlẹ Kaduna, Samuel Aruwan ni ijọba yoo kọkọ sewadi ohun to sẹlẹ naa, ki oun to le sọrọ siwaju.
Amọ ọkunrin kan to n gbe nitosi ileẹkọ Gbogbonse naa sọ fun BBC pe ni aajin oru ni oun n gbọ iro ibọn lakọ-lakọ amọ oun kọkọ ro pe ariwo ibọn naa n wa lati ọkan lara ileesẹ ologun to wa nilu Zaria ni.
Bi mo se n gbọ iro ibọn naa, mo ro pe idanilẹkọ ologun lo n lọ lọwọ, aarọ yii ni mo sẹsẹ gbọ nipa ohun to sẹlẹ.
Funmi Aragbaiye: Ọlọ́run ní ohun táwọn olórí wa fẹ́ jẹ ni wọn ń wá
Emmanuel Macron Slap: Damien Tarel to fọ́ ààrẹ France létí, fi ẹ̀wọ̀n jura.
Oríṣun àwòrán, Screen Shot
Ilé ẹjọ́ kan ni ilẹ Faranse tí ni kí ọkùnrin ẹni ọdún mejidinlọ́gbọ̀n kan lọ fi ẹ̀wọ̀n oṣù mẹ́rin jura, lẹ́yìn tó jẹ́wọ́ nílé ẹjọ́ pé òun fọ́ ààrẹ Macron létí ni tòótọ́.
Damien Tarel sọ fún ilé ẹjọ́ pé, òun kò mọ̀ọ́mọ̀ fọ́ ààrẹ létí ṣùgbọ́n adajọ́ ní nǹkan tó mọ̀ọ́mọ̀ ṣe ni, ó sì mú ìwà ipá dání.
Ilé ẹjọ́ tún gbọ́ pé Tarel jẹ̀ ọmọ ẹgbẹ́ alátakò, bákan náà ló sún mọ́ àwọn ọmọ ẹgbẹ́ Yellow-Vest.
Ààrẹ Macron ni wọn kò nílò láti pín ọ̀rọ̀ ìfọ́tí náà yẹ́lẹyẹ̀lẹ, bí kò ṣe pé kí wọ́n mú gbogbo rẹ̀ wà ní iwọntún-wọnsì.
Macron kúrò ilé ìtura ilé ẹ̀kọ̀ kan ni ìhà ìlà oòrùn gúúsù Tain-I'Hermitage, nígbà tí ó sáré lọ kí àwọn ènìyàn tó ń dúró dèé lẹ́yìn irin tí wọ́n fi yí àgbègbè náà ká.
Oríṣun àwòrán, Screen Shot
"Bí Tarel ṣe gbá ààrẹ létí tán, ní àwọn ènìyàn gbọ́ tó ń pariwo ""Montjoie àti Denis! Pẹ̀lú ọ̀rọ̀ bi Macronism"""
Ní kété tí ìṣẹ̀lẹ̀ náà ṣẹ̀ ni ọ̀pọ̀ àwọn olóṣèlú jákèjádò orílẹ̀-èdè France bẹnu àtẹ́ lu nǹkan tó ṣẹlẹ̀ náà.
Kò tó ọdún kan mọ́ tí ìdìbò ààrẹ mìíràn yóò wáyé ní orílẹ̀ èdè France.
Àwọn adájọ́ mẹ́ta sọ́ pé ẹ̀wọ̀n oṣù méjìdínlógún ló tọ́ sí ọkùnrin náà, ṣùgbọ́n wọ́n dá oṣù mẹ́rìnlá nínú rẹ̀ dúró náà àti pé oṣù mẹ́rin rẹ̀ kò bẹ̀rẹ̀ ni kíákíá ṣùgbọ́n tí ó bá ṣẹ ẹ̀sẹ̀ mìíràn ni àwọn yóò mú èyí wá sí lílò.
Ẹnìkejì  to ya àwòrán ìṣẹ̀lẹ̀ náà ń kojú ẹ̀sùn níní ǹkan ìjà lọ́nà aitọ́ lẹ́yìn tí alaṣẹ lábẹ́lé lọ tú ilé rẹ̀. Ìlú kan náà sì ni òun àti Damien Tarel ti wà.
Oríṣun àwòrán, EPA
Ki ni Damien Tarel sọ fún ilé ẹjọ́?
Gẹ́gẹ́ bí ìwé ìròyìn AFP ṣe sọ, olùjẹ́jọ́ náà wá sí ilé ẹjọ́ pẹ̀lú aṣọ aláwọ̀ ewé tó wọ̀ lọ́jọ́ tí wọ́n mú.
Nígbà tí wọ́n bíi ìdí tó fi hu irú ìwà bẹ́ẹ̀, ó sọ fún ilé ẹjọ́ pé, lásìkò tí òun ń dúró de ọ̀rẹ́ òun nínú mọ́tò kí ìṣẹ̀lẹ̀ náà tó wáyé, ní òun ti ronú láti ṣe nǹkan tí àwọn ènìyàn kò ní gbàgbé láyé.
Ó ní òun ti kọ́kọ́ ro o láti lẹ ẹyin mọ, ṣùgbọ́n òun kò tilẹ̀ ro fífọ́ ọ̀gá Macron létí.
"Ṣùgbọ́n mo rí ojú tútù tó lọ, tó sì parọ́ tí gbogbo ènìyàn fi jáde dibò fún bí ààrẹ, èyí ló bomi nínú, bí Tarel ṣe sọ fún ilé ẹjọ́
Ó bẹnu àtẹ́ lu bí ààrẹ ṣe ń ṣe ìjọba, Tarel fi kún pé òun wòye pé ààrẹ wá lára àwọn tó lòdì sí ìdásílẹ̀ gilets jaunes (Yellow Vest) àwọn yìí ló wọ́de ìféhónúhan lásìkò tí Macron ṣẹ̀ṣẹ̀ di ààrẹ,  bí ó ṣe wá simi lọ́kàn ni mo ṣe huwa"" èyí ni Tarel sọ."
Awọn ọ̀rẹ́ Tarel pẹ̀lú sọ pé, kii se ẹni tó nífẹ́ sí òṣèlú rárá.
Òpó ikansiraeni instagram Tarel pẹ̀lú ṣàkàwé rẹ̀ gẹ́gẹ́ bí ayàwòrán àti olólùfẹ́ ìtàn ilẹ̀ Yúróòpù, tó sì gbé àmì àṣà àti ìdá síbẹ̀.
Ogbomoso: Ẹ kálọ sí Ajilete láti mọ àwọn ibùdó tó mú kí ìlú náà yàtọ̀
Kí ni Macron sọ?
Ṣáájú ni ààrẹ Macron tí mójú kúrò níbi ìṣẹ̀lẹ̀ náà pé, kii se nǹkan tí á ń gbé léwọ́, àti pé kò yẹ́ kí wọ́n máa fún àwọn ẹlẹ́mìí ipanle láàyè, láti máa ní ore ọ̀fẹ́ ọ̀rọ̀ tí yoo má gbàsìkò àwùjọ.
Lásìkò to ń bá àwọn oníròyìn sọ̀rọ̀ níbi ayẹyẹ ìpàdé ìlọ́wọ́sí orílè èdè France nínú Ìdíje European football Championship, lo ti sọrọ̀ lórí ìṣẹ̀lẹ̀ náà.
A ti kojú àsìkò kan tí nǹkan lè koko, nígbà tí àwọn gilets jaunes gbé wàhálà de ṣùgbọ́n àwùjọ tí yí padà báyìí loni
Ó fi kún pé òun ti pinu láàyè ara òun, láti gbé ọ̀rọ̀ náà lọ sì ilé ẹjọ́, òun sì ṣetán láti fi gbogbo ọ̀rọ̀ sọwọ́ àwọn adájọ́.
June 12: Iléeṣẹ́ ọlọ́pàá ìpínlẹ̀ Eko láwọn kò mọ ohun kan nípa ìwọ́de láti ṣeàyájọ́ ọ́jọ́ June 12
Oríṣun àwòrán, Babajide Sanwo-Olu
Ileeṣẹ ọlọpaa ipinlẹ Eko ti sọ pe awọn ko mọ ohun kan nipa iwọde tawọn eeyan n sọ lori ayelujara pe yoo waye lọjọ Satide tii ṣe June 12.
Ọjọ kejila oṣu kẹfa naa ni ayajọ ijọba awarawa lorilẹede Naijiria, ọjọ kan naa lawọn kan ti n sọ pe awọn yoo ṣe ifẹhonuhan lori bi ilu ko ṣe fararọ lasiko yii.
Amọ, ninu atẹjade kan ti kọmiṣọnaa ọlọpaa ipinlẹ Eko, CP Hakeem Odumosu fi sita lati ọwọ alukoro ileeṣẹ ọlọpaa, Olumuyiwa Adejobi, o ni awọn ọlọpaa ko gbọ nipa iwọde ọhun.
CP Odumosu ni kawọn olugbe ipinlẹ fi ọkan balẹ, ki wọn si jade lọ si ibi iṣẹ lọjọ Satide nitori eto abo to peye yoo wa fun wọn.
Kọmiṣọnaa ọlọpaa ni ki wọn kọ eti iku si awọn kan to n sọ kaakiri wi pe ki wọn maa jade lọjọ Abamẹta
CP Odumosu to sọ ninu atẹjade naa pe ileeṣẹ ọlọpaa ti ṣe agbekalẹ awọn ọlọpaa ti yoo palẹmọ awọn ọdaran to n jawọn eeyan ipinlẹ Eko lole ninu sunkẹrẹ fakẹrẹ ọkọ loju popo.
Kọmiṣọnna ọlọpaa fawọn agbofinro ọhun ni ọkọ atawọn nkan mii ti wọn nilo lati ṣiṣẹ wọn.
O ṣalaye pe awọn ọlọpaa naa ṣetan lati pese abo to peye lori afara Eko Bridge, Apongbon, Cele, Ijora, Ojota/7up, Mike 12 ati agbegbe Surulere tawọn ọdaran ti n ṣọṣẹ julọ lasiko yii.
''Wámú wámú làwa ọlọ́pàá ń dúró de àwọn tó bá fẹ́ fa wàhálà lọ́jọ́ June 12''
Wamu wamu ni ileeṣẹ ọlọpaa duro ṣaaju iwọde tawọn eeyan kan n gbero lati ṣe lọjọ Abamẹta tii ṣe June 12.
Agbẹnusọ ileeṣẹ ọlọpaa ipinlẹ Osun, SP Yemisi Opalola lo fidi ọrọ yii mulẹ fun BBc Yoruba.
''Kiki ni awọn ọlọpaa wa bi ibọn fawọn to ba fẹ da rogbodiyan silẹ lọjọ June 12 nipinlẹ Osun.
Gbogbo awọn ẹṣọ eleto aabo to fi mọ awọn sọja atawọn ẹṣọ eleto abo mii ni wọn ti parapọ ti wọn si n gbaradi fun iwọde June 12.
Oríṣun àwòrán, Facebook/Nigeria Police Force
Koda awọn ẹṣọ eleto abo ti n wọde kaakiri ilu fun igbaradi ṣaaju ayajọ ijọba awarawa ni Naijiria.
Igbaradi to gbopọn wa nilẹ lati ọdọ awọn oṣiṣẹ eleto abo ṣaaju ọjọ Abamẹta yii.
Awọn ọlọpaa atawọn ẹṣọ eleto abo mii naa mọ nipa gbogbo bo ṣe n lọ nipa ifẹhonuhan tawọn eeyan kan fẹ ṣe.
Ṣugbọn o yẹ ka kọgbọn nipa iwọde EndSARS lọdun 2020 to mu ẹmi lọ,'' agbẹnusọ ileeṣẹ ọlọpaa ṣalaye.
O ni ''kii ṣe pe ṣiṣe iwọde ko tọna labẹ ofin, ṣugbọn mo n fi asiko yii rọ awọn eeyan lati ma jẹ ki nkan bajẹ si ju ti tẹlẹ lọ.
Ọpọ eeyan lo fẹ fi iwọde boju lati wu oriṣiriṣii iwa ọdaran lọjọ June 12.''
Ninu ọrọ tiẹ, alukoro fun ileeṣẹ ọlọpaa ipinlẹ Kwara, Okasanmi Ajayi ti fawọn araalu lọkan balẹ lati ma ṣe foya lori iwọde tawọn eeyan kan n gbero lati ṣe lọjọ June 12.
SP Ajayi sọ pe ileeṣẹ ọlọpaa ṣetan lati daabo bo awọn eeyan lọjọ iwọde naa ati nigba gbogbo.
''Awọn ọlọpaa tun ti gbaradi lonii  kaakiri ipinlẹ Kwara ọjọ Ẹti ṣaaju ayajọ June 12.
Wọn ṣe eyi lati jẹ ki awọn eeyan mọ wi pe ko si ewu loko fun ẹnikan kan lọjọ June 12.
Democarcy Day: Àwọn ọ̀rọ̀ tí Bola Tinubu fi ránṣẹ́ lórí àyájọ́ ìjọba alágbádá rèé
Oríṣun àwòrán, Tinubu
Asíwájú Bola Ahmed Tinubu, to jẹ́ èèkàn nínú ẹgbẹ́ òṣèlú APC ti ní àwọn tó le sọ àwọn ènìyàn di òtòsì àti àláìmọ̀kan, ni àwọn ń bá figagbága.
Bí orílẹ̀-èdè Naijiria ṣe ń ṣe àyájọ́ ìṣèjọba àwa ara wa ni Asiwaju ń ké pe àwọn ọmọ Nàìjíríà láti dúrò tí ètò ìjọba àwa arawa wámúwámu.
Tinubu pe ipe yìí lọjọ́ Eti pẹ̀lú àfikún pé, ètò ìjọba àwa arawa, pẹ̀lú iṣèjọba rere a ma mú ojúùtú bá ìpèníjà tó le ṣúyọ.
Àwọn ìtàn mánigbàgbé tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí:
Bí wọ́n ṣe ya Sinima Ayinla Omowura rèé, BBC Yorùbá  fọ̀rọ̀ wá àwọn òṣèré lẹ́nu wò
Ó ní bí ìdójúkọ ṣe tílẹ̀ pọ̀ tó, tó sì ń kojú olúkúlùkù, síbẹ̀ Nàìjíríà gbọdọ̀ dúró ti ètò ìjọba àwa ara tó múná dóko.
Gómínà ìpínlẹ̀ Eko nígbà kan rí tún rọ Nàìjíríà láti dìde lòdì sí òhunkóhun tó le yí omí àláfíà ètò ìjọba àwa arawa dànù.
Tunde Bakare: Àjọjẹ kò dún bẹ́nìkan kò ní ló fa ìjà S Igboho,bẹ́ẹ̀ ìjọbati gbẹ́rù kọjá orí
Asiwaju rọ wọ́n láti díde lòdì sí ìwà ipá àti jàgídíjàgan àti gbogbo àwọn gbọ́yìsọ̀yí, tí wọ́n ń fi ọ̀rọ̀ ẹnu wọn dá wàhálà sílẹ̀ láàrín àwùjọ Nàìjíríà.
"Àwọn tí á n bá jà ni àwọn tó n sọ ènìyàn di alámọ̀kàn ati òtòsì. A ń ṣe àyájọ ọjọ́ ìṣèjọba àwa arawa kìí ṣe nítórí pé àti rìn jìnà nínú rẹ̀, bí kò ṣe pé kí a ní ìwúrí láti túbọ̀ tẹ̀síwájú.
Nàìjíria sì ni ọ̀nà tó jìn láti lọ, àt ibi gíga láti dé àti láti jọ jùmọ̀ ṣe òhun rere bí orílẹ̀-èdè àti ẹ̀yà èèyàn kan. gẹ́gẹ́ bí ọ̀rọ̀ Tinubu"
Asiwaju ẹgbẹ́ òṣèlú APC náà rọ ọmọ Nàìjíríà láti ránti MKO Abiola, tó ìjáwé olúborí ni June 12, 1993 tí wan sì jí àṣeyọrí rẹ̀ mọ lọ́wọ́.
"Ó ní ""Abiola kò káárẹ̀, sùgbọ́n ó fi ẹ̀mí rẹ̀ lélẹ̀ kí gbogbo ènìyàn báa le jẹ àǹfàní ètò ìjọba àwa-arawa tí wọn gbà lọ́wọ́ rẹ̀."""
Tunde Gbadamosi: Kìí ṣe Tinubu ní ipò ààrẹ̀ tọ́ sí, ìgbà wo ní ìtan ajá ń kan lèmọ́mù?
Tinubu ni láísì ìrúbọ́ tí Abiola ṣe kò ni si àjọtọ̀ June 12 lónìí.
Asiwaju wa rọ gbogbo ọmọ Nàìjíríà láti ránti àwọn ẹlòmíràn tó ti rúbọ láti mú kí ìjọba àwa-arawa wáyé ni Nàìjíríà.
"Ọnà àtàta láti buyì fún ènìyàn kìí ṣe nípa pípé orukọ wọ́n nìkàn, bí kò ṣe nípa kíké pe ẹ̀mí wọ́n àti ìrétí wọ́n nínú ọ̀rọ̀ àti ìṣe wa.
Láti dí onígbàgbọ́ nínú ìjọba àwa-arawa, a kọ́kọ́ gbọdọ jẹ́ ọmọ Nàìjíríà."
Toyin Lawani: Kílódé tí ariwo ìgbéyàwó Toyin ṣe fa orí ayélujara ya?
Oríṣun àwòrán, Tiannahsplace
Toyin Lawani to jẹ́ gbajugbaja onísòwò ṣe ìgbéyàwo lánàá tíi ṣe ọjọ́ kejìlá, oṣù kẹfà ọdún 2021, ayé gbọ́ ọ̀run mọ̀.
Ọ̀pọ̀lọpọ̀ àwọn ohun málegbàgbé ló súyọ níbẹ̀, lára rẹ̀ ní akọlé ti Toyin Abraham gbé jáde lórí ìkànsíraẹni Instaram rẹ̀ pẹ̀lé àkọ́lé lórí fótò Mercy Aigbe àti Iyabo Ojo.
"'Sister Tope Alabi yà mí lẹ́nu gan o pé ""Oniduro mi"" kìí ṣe orin tó yẹ kí ọlọ́run fún mi'"
Láti bíi oṣù díẹ̀ sẹ́yìn ní òkìkí tí ń kàn lórí ayélujára bí Toyin Lawani ṣe ń polongo pé, ìgbéyàwó tí òun fẹ́ ṣe yìí yóò yàtọ̀ sí gbogbo ìgbéyàwó tí àwọn ènìyàn tí ń ṣe láti ẹ̀yìn wá.
Lóòtọ́ ọjọ́ ayẹyẹ àyájọ òmìnira ìjọba àwa-arawa tí àwọn ọmọ Nàìjíríà ń wọ́ lójú pópó láti wọ́de ìfẹ̀hónúhàn lóríi bí ìlú ṣe rí lọjọ́ náà, Toyin Lawani àti olólùfẹ́ rẹ̀ tuntun lo ọjọ́ náà láti bẹ̀rẹ̀ ìrìnàjò ìdílé.
Tani Toyin Lawani?
A bi toyin Lawani ni ọjọ́ kini, oṣù kẹta, ọdun 1982 ní ìpińlẹ̀ Ekiti, O jẹ́ gbájúgbajà jùlọ nínú àwọn aṣe aṣọlọ́ṣọ̀ọ́ ní Nàìjíríà.
Ọmọ gbajugbaja olóṣèlú Olarewaju Lawani tí bàbá rẹ̀ sì ti bá ológun Gowon ṣiṣẹ́ nígbà ayé rẹ̀, tí ìyá rẹ̀ pẹ̀lú Atinuke Babalola sì jẹ́ onísòwò irun ṣíse àti aṣọ títa nílùú Amerika kí ó tó papòdà.
"Alaseyori kọ́ ló ni orin ""Oniduro Mi"", àmọ́ ìdí tí mi ò  ṣe bá a jà pé ó jí orin mi kọ nìyìí - Tolu Adelegan"
"Kí ló fa gbas gbos láàrin Tope Alabi àti Olórin tó kọ ""Oniduro Mi e se""?"
A kò ní ṣe ètò ìsìnkú TB Joshua ní bòńkẹ́lẹ́ - Evelyn Joshua
Israel Adesanya dúró sókè ténté nínú ìjàkadì UFC lẹ́yìn tó fẹ̀ṣẹ́ fọ́ Vettori lẹ́nu
Kìí ṣe Gómìnà Seyi Makinde ló ṣètò ìwọ́de June 12 ní Ibadan kò sì bá wọn kópa -  Taiwo Adisa
Bí wọ́n ṣe ya Sinima Ayinla Omowura rèé, BBC Yorùbá  fọ̀rọ̀ wá àwọn òṣèré lẹ́nu wò
"Oníruuru òwò ní Toyin ń ṣe tí ó sì ti làmìlaaka níbẹ̀. Gẹ́gẹ́ bi gbájúgbàjà òun ṣe sọ, Toyin Lawani ni òun ń ṣe owo tó lé ni ọgbọ̀n lábl Olrùlé kan náà tó pè ni ""Tiannah's Empire""."
Toyin Lawani lọ sí fasiti Unilag níbi tí ó ti ka ìmọ̀ nípa ìròyìn, lẹ́yìn náà ló tún lọ sí fasiti ìlú Eko láti ka imọ èdè òyìnbó láti mú inú bàbá rẹ̀ dùn.
Ní kété tó ṣe èyí tán ló padà síní nǹkan tó yàn láàyò, èyí tí ṣe mímú nǹkan rẹwà, àti ṣíṣe aṣọ lógé.
Oríṣun àwòrán, Tiannahsplace
Báyìí ni ọ̀pọ̀ ń bẹ̀rẹ̀ sí ni gbé iṣẹ́ fún, láti ibẹ̀ lọ ló ti dí ẹni tọ n rán àṣọ fún àwọn èèyàn jánkanjànka àti àwọn ọ̀tọ̀kùlú láwùjọ.
Lábẹ́ òrùlé kan ní Toyin ti ń ṣe ilé ìkọ́ṣẹ́ aṣọ rírán,  ilé òunjẹ́ ìgbàlódé, ilé iṣẹ́ tó n tún ara tò, (SPA) , ilé iṣẹ́ tó n bá ènìyàn gba ìwé ìrìnàjò.
'Nínúu ká ṣe oríire níbí tàbí káa kú'! Àwọn tó ń fẹsẹ̀ rìn sálọ orílẹ̀èdè míì ṣe fídíò ráńṣẹ́ sílé
Toyin Lawani jẹ́ ìyá ọlọ́mọ méjì Tiannah àti Laord Maine fún bàbá méjì.
Ní ọ̀pọ̀ ìgbà Touin Lawani kìí ṣọ̀rọ̀ lórí ìgbéyàwó rẹ̀ àkọ́kọ́, sùgbọ́n ní nǹkan bi ọdún kan sẹ́yìn ló fí sójú òpó Instagram rẹ̀ pé kí àwọn ènìyàn wo bàbá àkọ́bi ọmọ òun.
O ní òun fẹ́ nígbà tí òun wà ní ọmọ ọdún mọ́kàndílógún, àti pé lásìkò náà òun ti ni oríṣi okoòwò márùn tí òun ń ṣe, bákan náà ni òun ń lọ sí ilé ìwé.
Nínú ìfọ̀rọ̀wáni lọ́nuwò kan ni Toyin ti ṣàlàyé bí ọ̀rẹ́ ṣe kó sí òun lọ́kan láti jáwe mí o ṣe ma fún ọkọ́ rẹ̀.
O ní ó máá ń fi ọ̀rọ̀ àbùkù ránṣẹ́ sí òun pé, ìnú ìgbáyàwó tí kò ni ayọ ni òun wà súgbọ́n òun ń ṣe bi ẹni pé inú òun dùn.
Gbogbo èyí ni òun rò papọ̀ tí oùn fi mú ọmọ tí òun bí ní àsìkò tí òun wà ni ọdún mẹ́tàlélógun kúrò nínú ìgbéyàwọ náà láti lọ bẹ̀rẹ̀ ìgbé ayé tuntun.
Ẹ̀wẹ̀, ó ni ọ̀rẹ́ tó gba òun nímọ̀ràn lásìkò náà ń kòjú nǹkan tó ń ṣẹlẹ̀ sí òun nígbà náà báyìí, sùgbọ́n kò kúrò nínú ìgbéyàwó ọ̀hún.
Oríṣun àwòrán, Tiannahsplace
Lẹ́yìn èyí ló ṣe alábàpádé Kensington Womadi tí wọ́n ń pè ni  Lord Trigg tó jẹ́ olórín, Trigg lo bí ọmọ rẹ̀ ọkùnrin fún.
Bí àwọn olólùfẹ́ méjèèjì yìí ṣe túka mú ọ̀pọ̀lọpọ̀ aríwo dáni pẹ̀lú, gẹ́gẹ́ bi ìtàn náà ṣe lọ, Toyin Lawani fi ẹ̀sùn kan pé ifẹ́ owó lásán ni ọmọkunrin náà ní sí òun.
Oríṣun àwòrán, Tiannah
Bákan náà ní àwọnm mííràn sọ pé ọ̀rọ̀ ìhẹ́ tó wà láàrín wọ́n forí sọ́pọ́n nítrorí ìyàtọ ọdún gbọọrọ tó wà láàrín àwọn méjèèjì (Toyin 1982 Triggs 1992).
Nínú ìfọ̀rọ̀wánilẹ́nuwò kan ti Lord Triggs ṣe lo ti sọ pé ọdún mẹ́rìn ni àwọn ti n bá ifẹ́ àwọn bọ̀, kò sí sí òtítọ́ nínú pé, nítorí owó ni òun 'se ń fẹ́ Toyin Lawani.
Oríṣun àwòrán, Tiannah
Sáájú àsìkò yìí ní Toyin Lawani tí sọ fún gbogbo àwọn ènìyàn tó n fí òn ṣe ẹlẹ́yà pé òun bí ọmọ méjì fún bàbá méjì pé, kìí ṣe pé òun wu ònu bẹ́ẹ̀ bíkòṣe pé bí a ṣe kọ ọ́ fún òun ni.
Nínú oṣù kéjì ọdún yìí ní òkìkí kan lórí ayélujára pé Toyin Lawani tún fẹ́ dá ilé ọkọ wò lẹ́ẹ̀kan sí nígbà tí Segun Adebayo tó ṣe ùgbéyàwó pẹ̀lú yìí dá ẹnu ifẹ́ kọọ ní gbangba lọ́jọ́ àyájọ́ olólùfẹ́ ọdún 2021.
Lẹ́yìn èyí ní oníruurú ọ̀rọ̀ bẹ̀rẹ̀ sí ni jáde nípa Toyin Lawani àti ọkọ tuntun tí ó fẹ́ yìí
Sáájú àsìkò yìí àyàwòrán Toyin Lawani ni Segun Adebayo jẹ́ tí ọ̀pọ̀ sì máá n ké gbàjarè lórí àwọn fótò oníhòhò tí Toyin máá ń gbé sórí ayélujára.
Oríṣun àwòrán, Tiannah
Láti àsìkò yìí ní ètò tí bẹ̀rẹ̀ ní pẹrẹwu. Ọ̀pọ̀ àwọn gbájugbajà òṣèré pẹ̀lú ló ń fọ́rere pé ìgbéyàwó náà yóò dùn gbọ́ngbọ́n yóò kan sí.
Toyin tikara rẹ̀ sọ pé pé àwọn àárùn ìyàwó òhún yóò tó àádọ́jọ ènìyàn pọ́lu ọ̀rẹ́ ọkọ méjì.
Bákan náà lo pe àkòrí ètò ìgbéyàwó wan ni #TheArtistAndHisMuse2021
Oríṣun àwòrán, @segun_wealth
Lára àwọn ènìyàn jànkàjànkàn tó péjú síbi àyẹyẹ ìgbéyàwó náà ni Shina Peters, àwọn gbájúgbajà nínú èré tíatá, àwọn àdẹ́rìn pòṣọ́nú àti gbájúmọ̀ láwùjọ.
Lára àwọn nǹkan tó tún jọ àwọn ènìyàn lójú níbi àyẹyẹ náà ni pé, àṣọ aláwọ̀ dúdú ni aṣọ ẹbi tí wọ́n mú níbí ayẹyẹ náà.
Oríṣun àwòrán, Tiannahs
Ìròyìn sọ pé, ọkùnrin tuntun ti Toyin Lawani fẹ́ yìí ni ìyàwó nílé sáájú àsìkò yìí, tí ó sì tí bí ọmọ méjì kí ó tó wá kẹnu ìfẹ́ sí Toyin.
Ọ̀kàn nínú nǹkan tó fí ìdí ọ̀rọ̀ yìí múlẹ̀ ní ọ̀rs kan tí Toyin kọ sójú òpó instagram rẹ̀ níbi tó tí sọ fún aya Segun pé kó lọ jòkó jẹ́ nítori òun lóun ni ọkọ báyìí.
Oríṣun àwòrán, Tunezmediablog
Oríṣun àwòrán, Tunezmediablog
Oríṣun àwòrán, Tunezmediablog
Oríṣun àwòrán, Tunezmediablog
Oríṣun àwòrán, Tunemedikablog
Sááju ọjọ́ ìgbéyàwọ ni wọ́n ti ṣae fọ́ran kan jáde láti fí kí àwọn ènìyàn kú àfójúsọ́nà ìgbéyàwó wọn.
Kò tán síbẹ̀ o, àwọ dúdú ni àkàrà òyìnbó tí Toyin Lawani àti ọkọ rẹ̀ Segun Adebayo lò fún àyẹyẹ ìgbéyàwò wọ́n.
June 12 Democracy Day: Ọmọ Nàìjíríà 10.5M la ti gbọ̀nṣẹ́ gbọ̀nyà kúrò lára wọn - Buhari
Oríṣun àwòrán, Muhammadu Buhari/Facebook
Ninu ọrọ ti aarẹ Muhammadu Buhari ba awọn ọmọ Naijiria sọ ni ayajọ ọjọ ijọba awa ara wa lo ti mẹnu ba a pe ijọba oun gbiyanju gidi lati yọ awọn ọmọ Naijiria kuro ninu iṣẹ.
Gẹgẹ bi Banki agbaye ṣe fi akọsilẹ sita, orilẹede Naijria wa lara awọn ti iye awọn to n jiṣẹ jiya ti pọ ju lagbaye.
Bẹẹ si ni lọdun 2019, Aarẹ Muhammadu Buhari ṣeleri lati rii pe o yọ eeyan ọgọrun miliọnu ọmọ Naijiria kuro ninu iṣẹ laarin ọdun mẹwa.
Bí wọ́n ṣe ya Sinima Ayinla Omowura rèé, BBC Yorùbá  fọ̀rọ̀ wá àwọn òṣèré lẹ́nu wò
"Aarẹ ni iṣẹ ṣi ku lati ṣe ""a si n ṣa gbogbo ipa wa lagbami bi nkan ko ṣe tun to yii ti iye eeyan to wa ni Naijiria si n pọ sii ju iye awọn taa le fun niṣẹ lọ""."
O fi kun un wipe bo tilẹ jẹ pe Covid-19 fi orilẹede Naijiria, awọn ṣi ni afojusun lati yọ eeyan ọgrun miliọnu kuro ninu iṣẹ laarin ọdun mẹwaa.
Aarẹ orilẹede yii, Muhammadu Buhari ti ba awọn ọmọ Naijira sọrọ ni aarọ ọjọ Satide lati ki wọn ku ayajọ ọjọ ijọba awa ara wa to ko naa.
Ninu ọrọ rẹ, Buhari sọ nipa ọpọ aseyọri ti ijọba rẹ ti se lati igba to ti gori aga akoso orilẹede yii ni ọdun mẹfa sẹyin.
Lara awọn aseyọri ti Buhari mẹnuba ni awọn ipese awọn ohun eelo amayedẹrun si tibu tooro orilẹede yii
Àwọn ìtàn mánigbàgbé tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí:
Bobrisky: Ìrora iṣẹ́ abẹ ìdí náà pọ̀ àmọ́ n kò kábàámọ̀ pé mo ṣe é
Oríṣun àwòrán, bobrisky222
Gbajumọ akọ to n mura bii abo, Idris Okunneye, ti ọpọ eeyan mọ si Bobrisky, ti kede pe wọn tun ti gbe oun digba-digba lọ sile iwosan.
Bobrisky, ẹni to kede isẹlẹ laa loju opo Instagram rẹ lọjọ Aje, lo se isẹ abẹ idi nla, ti wọn si fa ọra kuro ni inu ikun rẹ, itan ati igegeru.
Awọn ọra yii ni wọn lẹ mọ ibadi rẹ, ko le tobi si, ti yoo si dabi idi nla ta mọ awọn obinrin mọ.
Bobrisky, ẹni to ti kede saaju pe oun n jẹ irora to lagbara lati ipasẹ isẹ abẹ naa, tun salaye pe wọn ti gbe oun pada lọ sile iwosan lọjọ Satide.
Oríṣun àwòrán, bobrisky222/Instagram
"Wọn tun ti gbe mi digba-digba pada sile iwosan to sun mọ mi ni alẹ ọjọ meji sẹyin nitori irora nla ti mo n jẹ tori isẹ abẹ idi ti mo se.
Amọ n ko kabamọ rara! Laipẹ ni n maa ju idi mi...bi o tilẹ jẹ pe mo ti n reti tẹlẹ pe maa jẹ irora tori isẹ abẹ naa.
Lasiko yii, owo ti maa ma gba yoo lọ soke si, o si yẹ kẹ ri idi mi bayii, o ti tobi daadaa si, ti yoo si maa dawọn eeyan lọrun."
Bakan naa ni Bobrisky tun sisọ loju rẹ pe o kuku nidi ti oun fi n se isẹ abẹ idi naa nitori kii se oju lasan ni oun fi n se.
O salaye pe oun n fara da irora ọhun lati sisẹ abẹ idi yii nitori ololufẹ oun, tii se olowo rẹpẹtẹ ni, ki oun le tubọ maa da lọrun.
Oríṣun àwòrán, bobrisky222/Instagram
Gbajumọ onisowo ipara naa fikun pe eyi yoo tubọ mu ki ololufẹ oun naa tubọ maa na owo rẹpẹtẹ fun oun ni.
Ikede Bobrisky yii si ti n mu kawọn oloufẹ rẹ fesi si ọrọ naa, bi awọn kan si se n ki pe o pẹlẹ, tori irora naa, ni awọn miran n sọ pe o daa bẹẹ fun.
Oríṣun àwòrán, bobrisky222
A ti kọkọ mu iroyin wa fun yin pe, gbajugbaja ọkunrin to maa n mura bii obinrin, Idris Okunneye, ti ọpọ eeyan mọ si Bobrisky, ti sọrọ lori iṣẹ abẹ to lọ ṣe si ibadi rẹ lẹnu ọjọ mẹta yii.
Ṣaaju ni Bobrisky ti kọkọ n wa ẹkun mu loju opo Snapchat rẹ, nibi to ti ṣalaye pe inu irora nla ni oun wa nitori iṣẹ abẹ naa, eyii to mu ki ọpọ awọn ololufẹ rẹ bẹrẹ si n kaanu rẹ.
Ṣugbọn o dabi pe ẹkọ ti n fi oju mumu han fun Bobrisky bayii to tun ti sọrọ loju opo Instagram rẹ, nibi to ti ṣalaye fun awọn ololufẹ rẹ nibi to ba iṣẹ abẹ naa de.
Àwọn ìtàn mánigbàgbé tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí:
Gẹgẹ bo ṣe sọ, ara rẹ ti n da ṣaka lẹyin iṣẹ abẹ naa, awọn irora to farada ṣaaju si ti n dinku.
O ni laipẹ ni oun yoo fi ara oun han fun awọn toun ki wọn le foju ganni ayipada to de ba ibadi rẹ lẹyin iṣẹ abẹ naa.
Oríṣun àwòrán, bobrisky222/Instagram
Ninu atẹjade ọhun lo tun ti fi ẹmi imoore han si ọkan pataki lara awọn ọrẹ to duro tii lasiko ti wọn n ṣiṣẹ abẹ naa.
"O ni ""Mo dupẹ lọwọ ọrẹ mi pataki to duro ti mi lasiko ti mo n ṣiṣẹ abẹ lọwọ, mo mọ pe ifẹ to ni si mi ko ni nnkankan lati ṣe pẹlu owo."
"Sugbọn o jẹ ifẹ atinu ọkan wa. Mo dupẹ lọwọ rẹ fun ibadọrẹpọ rẹ lati nnkan bi ọdun marun un sẹyin wa."""
Àwọn ará ìlú Abiola ní Abẹokuta bá BBC sọ̀rọ̀
Ẹwẹ, lẹsẹ kan naa ni Bobrisky tun bu ẹnu ẹtẹ lu awọn eeyan kan, to fi ẹsun kan pe ifẹ oju lasan ni wọn ni si oun.
Bobrisky ni ọpọ eeyan lo n fẹ ki oun ku lasiko iṣẹ abẹ ti oun ṣe, ṣugbọn awọn eeyan kan naa lo n sọ pe awọn n saaro oun lori ayelujara.
Gẹgẹ bo ṣe sọ, irufẹ awọn eeyan bẹẹ ko ṣe fọkan tan nitori ifẹ oju lasan ni wọn ni si oun.
Oríṣun àwòrán, bobrisky222/Instagram
O wa fi da awọn ololufẹ rẹ loju pe oun ṣi n pada bọ lori ayelujara laipẹ ati pe ipadabọ Abija oun naa yoo lekenka.
O ni inu oun dun pe oun ṣe iṣẹ abẹ ki ara oun le ri bi oun ṣe fẹ ko ri, eyii si mu inu oundun gidi.
Yatọ si iṣẹ abẹ to ṣe, Bobrisky tun sọ pe oun ti ṣetan lati na owo ti iye rẹ ko din ni ẹgbẹrun lọna ogoje naira lori ọkọ ayọkẹlẹ tuntun.
Bakan naa lo tun ṣalaye pe oun yoo ra ile tuntun kan ti iye rẹ to irinwo miliọnu naira.
Gẹgẹ bii ohun to sọ, gbogbo awọn afojusun wọnyi ni yoo mu ṣe titi oṣu Kẹjọ ọdun yii.
Bobrisky pari ọrọ rẹ pe ara ọtọ ni oṣu Kẹjọ naa yo jẹ nitori awọn ohun meremere ti oun ti ni lọkan lati ṣe.
June 12 protest: Ọlọ́pàá yin tíá gaàsì lu àwọn olùwọ́de l'Eko, wọ́n ní ìjà àráàlù
Kọmiṣọna ọlọpaa ipinlẹ Eko, Hakeem Odumosu, ti sọ pe ẹtọ awọn araalu labẹ ofin ni lati ṣe ifẹhonuhan lasiko to ba wu wọn.
O ni ẹtọ awọn gẹgẹ bii agbofinro ni lati fun awọn olufẹhonuhan ni abo to peye lasiko irufẹ iwọde bẹẹ.
Odumosu ṣalaye pe awọn kan to n sun taya laarin oju ọna to lọ si Maryland, ti wọn si kọ lati fi oju ọna ọhun silẹ ni awọn ọlọpaa yin gaasi taju-taju si lọjọ Satide.
"Gẹgẹ bi o ṣe sọ ""Awọn ọmọ mi sọ fun awọ eeyan naa lati ṣi ọna ki awọn to n lọ ibi iṣẹ oojọ wọn le ri aye kọja, ṣugbọn wọn kọ jalẹ."""
Lẹyin ti wọn kọ ni mo ni ko buru, pe ki awọn ọmọ mi fun wọn ni taju-taju diẹ ki wọn le kuro loju lọna nitori ti a ba ni ki a lo ibọn, nnkan mii le ṣẹlẹ.
Ọga ọlọpaa naa sọ pe awọn gbe igbesẹ ọhun ki awọn to n jade lati inu Eko atawọn to n wọ Eko le ri ọna kọja.
Lẹyin naa lo gba awọn oluwọde naa nimọran pe ki wọn maa kọ iwe si ijọba ati ileeṣẹ ọlọpaa lọjọ miran ti wọn ba fẹ ṣe iwọde ki ileeṣẹ ọlọpaa le pese abo to peye fun wọn.
Bi iwọde naa ṣe n lọ niluu Ibadan naa lo n waye ni ipinlẹ Eko, Ondo, Osun, Rivers, ati Abuja.
Hajj 2021 update: Saudi Arabia gbégilé ìrìnàjò Hajj fáwọn ọmọ Nàìjíríà àt'orílẹ̀èdè àgbáyé gbogbo lọ́dún 2021
Oríṣun àwòrán, haramainsharifain.com
Awọn alaṣẹ orilẹede Saudi Arabia ti fofin de awọn arinrinajo silẹ mimọ lati orilẹede Naijiria atawọn orilẹede miran jakejado agbaye pe ko ni si Hajj fun wọn lọdun yii.
Orilẹede Saudi kede rẹ lọjọ Abamẹta pe iwọnba ẹgbẹrun lọna ọgọta ọmọ orilẹede naa ti wọn ti gba abẹẹrẹ ajẹsara COVID-19 wọn pe perepere ni yoo lanfani lati ṣe eto irinajo mimọ Hajj tọdun yii.
Kìí ṣe Gómìnà Seyi Makinde lo ṣètò ìwọ́de June 12 ní Ibadan kò sì bá wọn kópa -  Taiwo Adisa
Ọwọ́ tẹ Kabiru tó ṣá ọ̀rẹ́bìnrin rẹ̀ bí màlúù ní Apomu
Wo ohun tó mú kí àyájọ́ June 12 ṣe pàtàkì fún Nàíjíríà
Bí wọ́n ṣe ya Sinima Ayinla Omowura rèé, BBC Yorùbá  fọ̀rọ̀ wá àwọn òṣèré lẹ́nu wò
Bi ẹ ko ba ni gbagbe, bakan naa lọmọ ṣori ni ọdun to kọja nigba ti ajakalẹ arun COVID-19 gbilẹ lagbaye ti awọn alaṣẹ orilẹede Saudi si se iloro rẹ mọ awọn to n gbero ati rinrinajo Hajj nitori ajakalẹ arun naa.
Oríṣun àwòrán, haramainsharifain.com
Iwọnba bii ẹgbẹrun mẹwaa lawọn to kopa ninu eto irinajo mimọ naa lọdun 2020 eyi to jinna gedegede si nnkan bii miliọnu meji abọ eeyan lọdun 2019.
Eto Hajj tọdun yii, ti yoo waye lopin oṣu keje, ko ni wa fun awọn arinrinajo lati orilẹede miran, bakan naa ni ko si fun ọmọ orilẹede Saudi Arabia ti ọjọ ori rẹ ba ti pe ọdun marundinlaadọrin tabi jubẹ lọ.
June 12 protest: Ọlọ́pàá yin tíá gaàsì lu àwọn olùwọ́de l'Eko, wọ́n ní ìjà àráàlù
Christian Eriksen: Agbábọ́ọ̀lù Denmark, Christian Eriksen, tó dákú lórí pápá ti jí padà níléèwòsàn
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Agbabọọlu orilẹ€de Denmark, Christian Eriksen ti ji saye nileewosan lẹyin to dakun lori papa lasiko ti orilẹede Denmark ati Finland fi n figagbaga lọjọ Satide.
ṣaaju isinmi aarin ifẹsẹwọnsẹ naa ni wọn da a duro lẹyin ti agbabọọlu ẹni ọdun mọkandinlọgbọn naa to n gba bọọlu jẹun fun Inter Milan ṣa dede ṣubu lulẹ.
Kiakia ni alamojuto ifẹsẹwọnsẹ naa, Anthony Taylor ti ke sawọn onimọ iṣegun ki wọn wa fun un ni itọju lori papa.
Ajọ ere bọọlu nilẹ Yuroopu, UEFA sun ifẹsẹwọnsẹ naa siwaju nitori iṣẹlẹ naa ki wọn to tun kede pe ifẹwọnsẹ ọhun yoo waye ni agogo meje abọ alẹ ọjọ Satide kan naa.
"Iks agbabọọlu Finland ti fi atẹjade kan sita pe ""Christian Eriksen ti laju, ilera rẹ si ti duro deede ti wọn si ni awọn n fi ọkan gbadura fun pe ki ara rẹ tete bọ sipo"
June 12 Protest: Ó yẹ kí ọlọ́pàá tọrọ àforíjì lọ́wọ́ àwọn olùwọ́de tí wọ́n mú ní June 12 - Falana
Agbẹjọ́rò àgbà ni Nàìjíríà, Ọ̀gbẹ́ni Femi Falana ti ké sí àwọn ilé iṣẹ́ ọlọ́pàá láti tọrọ àforíjì lọ́wọ́ àwọn olùwọ́de tí wọ́n mú lọ́jọ́ June 12 jákèjádò Nàìjíríà.
Falana ni àwọn ọlọ́pàá tẹ ẹ̀tọ́ àwọn ará ìlú tó fi aayè gbá fífí èrò ẹni hàn mọ́lẹ̀ ní.
" Ó ṣe pàtàkì kí ọlọ́pàá máa bọ̀wọ̀ fún ẹ̀tọ́ ará ìlú. Ó jẹ́ nǹkan tó jìnà sí ìwà ọ̀làjú kí ọlọ́paàá m'Áa lé àwọn olùfẹ̀hóinúhàn tí kò mú nǹkan ìjà lọ́wọ́ lójú pópó bí ọ̀daràn.
Falana fi èrò yìí hàn nínú ìwé aapárò tó fi síta lọ́jọ́ Aikú.
'Sister Tope Alabi yà mí lẹ́nu gan o pé Oniduro mi"" kìí ṣe orin tó yẹ kí ọlọ́run fún mi'"
Bí wọ́n ṣe ya Sinima Ayinla Omowura rèé, BBC Yorùbá  fọ̀rọ̀ wá àwọn òṣèré lẹ́nu wò
Ẹ̀wẹ̀, ọ gbóríyìn fún àwọn olùfẹ̀hónúhàn náà bí wọ́n ṣe hùwà ọmọlúàbí tí wọ́n sì ṣe gbogbo nǹkan tí wọ́n yóò ṣe ni ìrọwọ́rọsẹ̀.
Ọ̀gbẹ́ni Falana bẹ̀nu àtẹ́lu àwáwí àwọn ọlọ́pàá pé àwọn lo tajútaju níbl láti fi dẹ́rùba àwọn jàndùkú kí má ba lé já ìwọ́de náà gbà mọ́ wọ́n lọ́wọ́.
Ajàfẹ́tọ ọmọniyàn náà rọ àwọn olùwọ́de kí wọ́n rIi dájú pé wọ́n ti sọ fún ọlọ́pàá lati gba ìyọ̀nda sáájú àsìkò ìwọ́de gẹ́gẹ́ bí òfin ṣe sọ.
Sáájú ni àgbẹnusọ ọlọ́pàá, Frank Mbba sọ lórí ètò ilé ìròyìn Channels pé àwọn gbé ìgbésẹ̀ láti lo tajútajú láti tú àwọn olùwọde, tó sì fi ìdí rl múlẹ̀ pé, ìgbásẹ̀ náà bá ètò àti ìlànà bí wan ṣe n ṣe lágbàyé mu.
Àwọn ọlọ́paàá fí tajútajú tú àwọn olùwọ́de ká ni Eko àti ìlú Abjua ní ó tilẹ̀ jẹ́ pé àwọn oníròyìn kò rí ohun kóhùn tó farapẹ́ jàgídíjàgàn láàrín àwọn olùwọ́de lásìkò ìwọ́de ki àwọn ọlọ́pàá tó da gbogbo rẹ̀ rú.
Ẹ̀wẹ̀, ọ̀gbẹ́ni Mba sàlàyé pé, nǹkan tó ṣẹ̀lẹ̀ ni Abuja yàtọ àti pé àwọn ni láti lo tájutajú lásìkò tí ìwọ́de ti fẹ́ dá wàháà sílẹ̀ l'Abuja.
Ó ni báyìí ni wọ́n ṣe ń ṣe noi gbogbo àgbáyé, yálà ni Abuja Paris tàbi London. nǹkan ti a le ṣe tí o lé mú wàhálà dáni ni ti ọlọ́pàá bá yin ẹnikan ni ìbọn.
" Mọ fẹ́ fi dá yin lójú bákan náà pé, kò sí ẹnikẹ́ni yálà ni Kwara, Eko, Port Harcout, Kano tabi ni ibikibi tí ó wà ni àtìmọ́lé ọlọ́paàá nítori ìwọ́de June 12.
'Nínúu ká ṣe oríire níbí tàbí káa kú'! Àwọn tó ń fẹsẹ̀ rìn sálọ orílẹ̀èdè míì ṣe fídíò ráńṣẹ́ sílé
Lizzy Anjorin: New York, Atlanta, Chicago àtàwọn ìlú méje míràn l'Ámẹ́ríkà yóò gbàlejò ayẹyẹ ìkómọ ọmọ Lizzy Anjorin
Oríṣun àwòrán, Instagram/lizzy Anjorin
Ẹyin eeyan wa, tẹẹ ba ro wipe ẹ ti wo gẹlẹdẹ opin iran lori ọmọ ti gbajumọ oṣere, Lizzy Anjọrin ati ọkọ rẹ ṣẹṣẹ bii, ẹ gbayi yẹwo, tuntun ni o.
Laipẹ yii, Lizzy Anjọrin ati ọkọ rẹ ki ọmọ wọn akọbi kaabọ ni ilu Florida, lorilẹede Amẹrika.
Nibayii, Lizzy ti fọn fọto ọmọ rẹ naa sori ayelujara bayii pẹlu orukọ rẹ.
Bakan naa ni Lizzy Anjọrin tun tu u sita pe eto ayẹyẹ isọmọlorukọ fun ọmọ oun naa yoo waye lọpọlọpọ awọn ilu nlanla lorilẹede Amẹrika.
O ni apejẹ alaṣọ funfun ni wọn yoo fi isọmọlorukọ ọmọ awọn ṣe ni ilu mẹwaa ọtọọtọ.
O ni ilu New York ni yoo ti bẹrẹ ni ọjọ kẹrin oṣu keje ọdun 2021, yoo yi kan awọn ilu bii Dallas, Atlanta ati Indiana laarin ọjọ kọkanla, ikejidinlogun ati ikarundinlọgbọn oṣu keje naa.
Nigbati Maryland, Houston Texas ati North Carolina yoo waye ọjọ kini, ikẹjọ ati ikarundinlogun oṣu kẹjọ.
Ọjọ  kejilelogun ati ikọkandinlọgbọn oṣu kẹjọ kan naa ni yoo kan awọn ti Minnesota ati California ki wọn to fi adagba rẹ rọ ilu Chicago loṣu kẹsan ọdun yii.
Bí wọ́n ṣe ya Sinima Ayinla Omowura rèé, BBC Yorùbá  fọ̀rọ̀ wá àwọn òṣèré lẹ́nu wò
Igboho and June 12 protests: Sunday Igboho kan sárá sáwọn ọmọ Yorùbá tó wọ́de lọ́jọ́ Sátidé
Oríṣun àwòrán, other
Sunday Igboho ti kan sara sawọn ọmọ Yoruba to jade wọde kaakiri gbogbo agbaye lọjọ Satide fun iwọde June 12 pe wọn ku ifọmọniyan ṣe.
Oloye Sunday Igboho to ṣalaye ninu fidio kan to fi sita lori ayelujara pe inu oun dun daadaa fun bi awọn eeyan ṣe jade fun iwọde naa ṣalaye pe o fihan pe waasimi 'Yoruba Nation' to n lewaju fun ti sunmọle.
Bi o tilẹ jẹ pe ọpọ ero, paapaajulọ awọn ololufẹ Sunday Igboho ni wọn reti pe yoo jade lati lewaju awọn iwọde kọọkan lọjọ Satide, ṣugbọn Sunday Igboho ko si ni eyikeyi awọn iwọde to waye naa kaakiri awọn ipinlẹ Yoruba.
Amọṣa o, Sunday Igboho ko sọ idi ti ko fi si ni eyikeyi awọn iwọde naa.
Euro 2020: England fọ́ Croatia lẹ́nu ní Euro 2020, wo àwọn ohun tó ṣókùnkùn sí ọ nípa rìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ náà
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Goolu kan lati ẹsẹ atamatase agbabọọlu ilẹ Gẹẹsi, Raheem Sterling ni orilẹede England nilo lati fagba han Croatia ni ifẹsẹwọn wọn to waye loni nibi idije Euro 2020 to n lọ lọwọ.
Nigba ti ifẹsẹwọnsẹ naa wọ iṣẹju kẹtadinlọgọta ni Kalving Phillips tẹ paasi si Sterling to si fi suuru gbee sile.
Amọṣa Kalving Phillips lo gba oriyin gẹgẹ bi agbabọọlu to tan bi oorun ninu ifẹsẹwọnsẹ naa pẹlu oniruuru bira to da.
Ninu ọrọ rẹ, akọnimọsgba orilẹede England, Gareth Southgate ni inu oun dun pupọ fun bi awọn agbabọọlu oun ṣe ṣe daradara si ninu ifẹsẹwọnsẹ naa. O ni lootọ yoo mu ẹru wiwo kuro lọrun awọn ṣugbọn eyi ko tumọ si pe awọn ti pegede fun ipele to kan."""
Nibayii, orilẹede Scotland lawọn agbabọọlu England yoo maa koju bayii.
Lọjọ Ẹti ni ifẹsẹwọnsẹ naa yoo waye ni papa iṣire Wembley.
Croatia ni tiwọn yoo maa koju Czeck Republic.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Netanyahu loses post in Israel: Agbára bọ́ lọ́wọ́ Benjamin Netanyahu, Naftali Bennett di olótú ìjọba tuntun ní Israel
Oríṣun àwòrán, Reuters
Olotu ijọba orilẹede Israel, Benjamin Netanyahu ti padanu ipo rẹ gẹgẹ bi olori ijsba orilẹede Israel lẹyin ti wọn dibo nile aṣofin lati gbe ijọba alajumọṣe tuntun wọle nibẹ.
Nibayii, wọn ti bura fun Naftali Bennett gẹgẹ bi olotu ijọba tuntun lorilẹede Israel.
Bennett kede ijọba tuntun naa gẹgẹ bi ijọba ayipada.
Ibo ọgọta si mọkandinlọgọta lawọn agbarijọpọ ẹgbẹ oṣelu alatako to parapọ fi gbe Netanyahu kuro nipo lẹyin ọdun mejila ni ipo naa.
Ọgbẹni Bennett yoo di ipo olotu ijọba orilẹede Israel mu titi di oṣu kẹsan an ọdun 2021 gẹgẹ bi ara eto fun iṣejọba alajumọ pin.
Lẹyin oṣu kẹsan ni yoo gbe agbara fun Yair Lapid, olori ẹgbẹ oṣelu Yesh Atid fun ọdun meji miran.
Ọgbẹni Netanyahu yoo ṣi wa ni ijanu oṣelu lorilẹede naa gẹgẹ bi olori ẹgbẹ oṣelu Likud Party lati di olori ẹgbẹ alatako.
Oríṣun àwòrán, Reuters
Ẹni ọdun mọkandinlaadọta ni Naftali Bennett, o dẹ ti fi igbakanri jẹ olori awọn o ṣiṣẹ labẹ olotu ijọba nigba naa laarin ọdun 2006 si 2008.
O fi ẹgbẹ oṣelu Benjamin Netanyahu silẹ lọ dara pọ mọ ẹgbẹ oṣelu Jewish Home Party.
O di ọmọ ile igbimọ aṣofin labẹ aṣia ẹgbẹ oṣelu naa lẹyin ti wọn bori idibo lọdun 2013.
Gbogbo iṣejọba alajumọṣe lo ti n di ipo minisita mu titi di ọdun 2019 nigba ti ẹgbẹ oṣelu New Right Alliance rẹ ti wọn ṣẹṣẹ da silẹ kuna lati ni ijoko kankan ni ile aṣofin orilẹede naa.
Saaju ko to di oloṣelu, Ọgbẹni Bennett jẹ ologun ati eekan oniṣowo.
"Tope Alabi yà mí lẹ́nu gan o pé ""Oniduro mi"" kìí ṣe orin tó yẹ kí ọlọ́run fún mi - Tolu Adelegan"
Mo sọ fun awọn to n pe mi lati America ati London pe emi o ki n fi agidi wa ogo o.
"BBC Yoruba lọ sile Olorin ẹmi to gba imisi to si tun kọkọ kọ orin ""Oniduro Mi"", Toluwalase Adelegan to fi ilu Akure ṣe ibugbe ti a si bere ọrọ lati tu iṣu de isalẹ koko lori ọrọ ti gbajugbaja olorin, Tope Alabi sọ lori itage ijọ kan to tin ṣe iṣẹ iranṣẹ orin pe ko tọ si olorin naa ko pe Ọlọrun ni Oniduro."
Sister Tope Alabi ya mi lẹnu gan o pe o le sọ pe orin Oniduro Mi kii ṣe orin to yẹ ki Ọlọrun fun eeyan.
Adelegan ni oke lawọn ti maa n wo Tope Alabi pe Ọlọrun lo n fun un ni orin titi rẹ to si wa bọ si gbangba to n sọ pe ko yẹ ki Ọlọrun fun ẹlomiran ni orin.
O kú ogun àjàyé Tope Alabi, odò Jodani lo ṣẹ̀ṣẹ̀ là kọjà yìí o! Àmọ́ rántí pé ... - Mike Bamiloye
"Alaseyori kọ́ ló ni orin ""Oniduro Mi"", àmọ́ ìdí tí mi ò  ṣe bá a jà pé ó jí orin mi kọ nìyìí - Tolu Adelegan"
"Tope Alabi fẹ́ tọ́ Olórin ""Oniduro mi e ṣe"" sọ́nà, bí ọ̀rọ̀ ṣe laná nìyìí"
Wo iye owó tí ìjọba Naijiria ti yá lọ́wọ́ China láti ìgbà tí Ààrẹ Muhammadu Buhari ti gorí àléfà
Jamb ti rọ àwọn akẹ́kọ̀ọ́ láti parí ìforúkọsílẹ̀ lónìí ọjọ́ ìṣẹ́gun
"Awọn eeyan wa n pe lati Londo, America pe ki n lọ wa nkan ṣe si nkan mi, mo si ni emi o ki n fi agidi wa ogo o, Ọlọrun nikan ni ogo mi ati Oniduro temi o""."
Adelegan ni bo tilẹ jẹ pe Tope Alabi ti sọ ọ ni gbangba pe Ọlọrun kii ṣe Oniduro tirẹ to sile ni Oniduro si ibomiran ṣugbọn Oniduro toun ni.
"Lori bi awọn eeyan tilẹ ṣe n ro pe olorin kan ti oun naa ti n di gbajugbaja, Adeyinka Alaseyori lo ni orin naa torii pe o kọ ọ jade, Adelegan ni kii ṣe Alaseyori lo ni orin yẹn, Ọlọrun lo fun oun ti oun si kọ si ori Facebook nigba naa pe Alaseyori kọ lo ni i  amọ "" Oluwa ni pe asiko ko tii to ṣugbọn nigba to di ana, mo gadura titi di bi ago kan kọja, Oluwa sọ fun mi pe ki n gbe igbesẹ tori naa gbogbo ẹyin fans mi ẹ fọkan balẹ""."
Àwọn ọ̀nà kan dí mọ́ mi torípé mo jẹ ọmọ King Sunny Ade yàtọ̀ fún àǹfàní tí mo jẹ - Emperor  Adegeye
"Orin Shanku, Gbese, Já paa, Jesu máa párò lọ, inú Ọlọ́run kò dùn sí i - Bola Are
Mo ti mọ̀ pé mo ṣì máa 'Blow' lọ́jọ́ kan- Bàbá Lórí Irọ́
Yoruba Council of Elders: Ìgbìmọ̀ Àgbààgbà Yorùbá ké sí Ààrẹ Buhari pé kó kọ̀wé fipò sílẹ̀ lórí ipò tí Nàìjíríà wà
Igbimọ awọn agba ilẹ Yoruba ti ke si aarẹ Muhammadu Buhari pe asiko to fun un lati kọwe fi ipo rẹ silẹ.
Akọwe agba fun ẹgbẹ naa, Dokita Kunle Ọlajide ṣalaye eyi ninu ifọrọwerọ kan pẹlu BBC News Yoruba.
Dokita Ọlajide ni nibi ti ọrọ de duro bayii o fihan gbangba pe Aarẹ Buhari ko ni ohun to yẹ lati tukọ orilẹede Naijiria mọ, ko lọ sinmi lo ku.
O ni ohun ti o n damu orilẹede Naijiria bayii ni iwe ofin rẹ ati pe o digba ti atunṣe ba de ba iwe ofin naa ki orilẹede Naijiria to lee toro.
O ni orilẹede Naijiria nilo ki awọn eeyan rẹ parapọ joko ki wọn wa jumọ sọrọ lori irufẹ ofin ti wọn fẹ.
'Nínúu ká ṣe oríire níbí tàbí káa kú'! Àwọn tó ń fẹsẹ̀ rìn sálọ orílẹ̀èdè míì ṣe fídíò ráńṣẹ́ sílé
O sọ pe, Awọn ijọba Ipinle ati awọn alaṣẹ ibile gbọdọ dide ni iṣọkan lati pade Aarẹ ati beere lọwọ rẹ boya a tun fẹ wa ni Nigeria."""
Igbimọ agba Yoruba kọminu lori ikọlu awọn agbebọn darandaran nilẹ Yoruba leyi to ni o buru de odo ikun pe ijsba ko ri ojutu sii.
Tope Alabi, Adeyinka Alaseyori on Oniduromi: Shola Allyson, Lanre Teriba àtàwọn èèkàn míràn sọ̀rọ̀ lórí ohun tí Tope Alabi sọ nípa orin 'Oniduro mi'
Oríṣun àwòrán, Facebook
Afẹfẹ awuyewuye lori ọrọ ti gbajumọ olorin ẹmi, Tọpẹ Alabi sọ nipa orin Oniduro mi ẹ ṣeun ṣi n fẹ kaakiri bayii.
Koda, afẹfẹ naa ti fẹ kan awọn olorin ẹmi atawọn gbajumọ awọlumatẹ bayi lorilẹede Naijiria ati loke okun.
Shola Allyson lo kọkọ bọ sigboro aye lati sọ ero tirẹ lori ọrọ naa leyi to ni o ku diẹ kaa to.
Ninu ọrọ to fi soju opo ayelujara Instagram rẹ, Shola Allyson ni orin ẹmi ti wọn n sọ yii, ti di eyi to ti bukun ọpọlọpọ eeyan kaakiri agbaye, ninu eyi ti oun pẹlu naa ti kọ ẹya orin toun nibẹ.
"'Sister Tope Alabi yà mí lẹ́nu gan o pé ""Oniduro mi"" kìí ṣe orin tó yẹ kí ọlọ́run fún mi'"
"Akọrin ""ifẹ bi eji owurọ"" naa to ni ẹnu Mama Bọla Arẹ loun ti kọkọ gbọ orin naa nilu Akurẹ lọdun diẹ sẹyin, wa kan sara si Adeyinka Alaṣeyọri to sọ sorin naa di gbajugbaja,"
O tun kan saara si Alaseyori  fun bo ṣe mu orin naa wa si etigbọ ọpọlọpọ eeyan, to si ti mu iyanu ba aye wọn pẹlu.
Bakan naa ni akọrin ẹmi miran, Lanre Tẹriba naa ko ṣai da si ọrọ naa.
Nibi ayẹyẹ kan ti Yinka Alaṣeyọri atawọn eekan lawujọ miran wa, ni Lanre Tẹriba ti bu ẹnu atẹ lu ọrọ ti Tọpẹ Alabi sọ naa to si ni ko si idi fun un lati maa bu ẹnu atẹ lu olorin miran.
O ni Tope Alabi gan pẹlu ti fi ọpọlọpọ orukọ miran ṣakawe Ọlọrun, ti ko si si ẹnikẹni to dide takoo.
'Nínúu ká ṣe oríire níbí tàbí káa kú'! Àwọn tó ń fẹsẹ̀ rìn sálọ orílẹ̀èdè míì ṣe fídíò ráńṣẹ́ sílé
Sebi awọn kan lo pe  Ọlọrun ni o wọ kẹmbẹ re ibi ija, ṣe wọn mọ telọ to ran aṣọ Ọlọrun ni...katikati Catastrophy
Ninu ọrọ tirẹ lori eto kan to ṣe loju opo Instagram rẹ lọjọ Aiku, Adeyinka Alaṣeyọri yẹra fun sisọ ọrọ lori iṣẹlẹ naa, eleyi to tun mu ki ọpọlọpọ awọn ololufẹ rẹ tun kan sara sii.
TB Joshua burial: Mo tan àbẹ́là láti fi gbàdúrà fún ẹ̀mí T. B Joshua - Páṣítọ̀ kan ni Israel
Oríṣun àwòrán, others
Pasitọ ìjọ Church of Nativity, nilu Bethlehem lorilẹ-ede Israel, William Ghattas, ti ṣe idaro gbajugbaja wolii, ọmọ Naijiria to ku laipẹ yii, Temitope Joshua, ni ara ọtọ.
Ni ṣe ni pasitọ naa tan abẹla lati fi ṣọ̀fọ̀ akẹẹgbẹ rẹ to lọ.
Ninu ọrọ kan to kọ ni Ọjọru, Pasitọ Ghattas sọ pe oun tan abẹla naa, lati fi gbadura fun oloogbe T. B Joshua ni.
Ọjọ Satide, ọjọ karùn-ún, oṣu Kẹfa, ọdun 2021, ni Joshua ku, lẹni ọdun mẹrindinlọgọta.
William Ghatta, to jẹ alamojuto ìjọ Nativity, ni Bethlehem, tan abẹla naa ni aarin gbùngbùn ilé ìjọsìn naa, nibi ti wọn bi Jesu si, pe ki ẹ̀mí rẹ ko sun re.
Saaju asiko ni sọọsi T. B Joshua, Synagogue Church of All Nations, SCOAN, ti kọkọ kede pe lẹyin ti wolii naa kú àwọn ololufẹ rẹ lori ayelujara Facebook ti lé si pẹlu ẹgbẹrun lọna ẹẹdẹgbẹta, ti ẹgbẹgbẹrun eeyan l'agbaye si n daro ikú rẹ.
Ẹ pàdé olórin Fuji alhaji Besco tó jọ Ayinde Barrister to tún ń kọrin gẹ́lẹ́ bíi tirẹ̀
Wọn ni ọpọ lo ṣe iṣọ oru adura pẹlu titan abẹla, nitori oloogbe ọhun.
"Ọjọ karun-un si ọjọ kọkanla, oṣu Keje, ọdun 2021 ni ìjọ SCOAN kede pe eto ayẹyẹ isinku oloogbe yoo waye """
Baba Ijesha Rape Case: Yomi Fabiyi ní òun nìkàn lòun rí ara òun tó dúró tí Baba Ijesha
Ki lo ti ṣélẹ sẹyin?
Oríṣun àwòrán, others
Ijọ Synagogue Church of All Nations nilu Eko ti kede akoko ati ibi ti wọn yoo sin olusọaguntan wọn to papoda laipẹ yii, Pasitọ Temitọpẹ Balogun Joshua si.
Ninu atẹjade kan eyi ti wọn fi sita lọjọ Aje, wọn ni inu ayika olu ile ijọsin naa to wa nilu Eko ni wọn yoo sin wolii TB Joshua si.
A n gbaradi fun eto isin ọlọsẹ kan ti yoo bẹrẹ ni ọjs karun un si ikọkanla ni iranti igbe aye Wolii TB Joshua.
"Atẹjade naa tun tẹsiwaju pe, ""A o sin si ile ijọsin The Synagogue, Church of All Nations (SCOAN) nilu Eko"""
Ẹni ọdun mẹtadinlọgọta ni Pasitọ TB Joshua ki o to jade laye lọjọ karun un oṣu kẹfa ọdun 2021 nigba to ku ọjọ diẹ si ọjọ ibi rẹ.
TB Joshua: Ṣe ni ọ̀pọ̀ èèyàn ń wa ẹkún mu torí ikú òjijì tó pa wòlíì
Kidnapping in Nigeria: Wo oríadé méje tó kúrò nípò torí ẹ̀ṣùn ìwà ìjínigbé
Oríṣun àwòrán, Facebook
Wahala ipenija aabo to de ba tolori tẹlẹmu lorileede Naijiria ko yọ ẹkun kankan silẹ.
Lawọn ipinlẹ kọọkan, n se ni awọn ijọba n gbogun ti awọn ti wọn ba n lẹdi apo pọ pẹlu awọn ajinigbe naa.
Ọrọ yii le to bẹẹ gẹ debi pe awọn eeyan n naka aleebu si awọn oriade kọọkan, paapaa ni apa Ariwa Naijiria, pe wọn n ba àwọn ajinigbe ṣe papọ.
Ni ipinlẹ Zamfara ati Katsina, ẹsun ijinigbe peleke lodọ awọn oriade, tijọba Zamfara si pàṣẹ pe kí ọba kan to jẹ Oriade onipo gíga, lọ rọọkun nile lọsẹ to kọja nitori pe o ni ohun ṣe pẹlu awọn ajínigbe.
Wonyii si ni orúkọ awọn oriade ti akọsilẹ fi ẹsun kan pe wọn mọ nipa ijinigbe ni apa Ariwa Naijiria:
Oríṣun àwòrán, Zurmi Atiku Abubakar/Facebook
Emir ilu Zurmi Atiku Abubakar ni Oriade ti wọn fẹsun kan pe o mọ nipa ijinigbe to n waye lagbegbe rẹ, tí ìjọba si ni ko lọ rọọkun nile na.
Ṣaaju ni Gomina Bello Matawalle ṣe agbekalẹ igbimọ iwadii kan, ti wọn si fẹnu ko pe ọba yii mọ nipa ijinigbe to  n waye labẹ rẹ.
Igbakeji Gomina Ibrahim Wakkala lo dari igbimọ naa, ti wọn si pasẹ pe ki Oloye Bunun Kanwa, Bello Suleiman máa ṣe akoso ilu.
Àṣẹ lọ rọọkun nile yii ko sẹyin bi awọn ajinigbe ṣe kọlù abule Kadara nibi ti o kere tan, eeyan ọgọrun padanu ẹmi wọn.
Oríṣun àwòrán, Emir Dansadau, Hussaini Umar/Facebook
Emir ilu Dansadau, Hussaini Umar naa wa lara awọn oriade ti wọn pàṣẹ ko lo rọọkun nile ni Zamfara.
Ni ọjọ kini oṣu Kẹfa, Gomina Bello Matawalle ni ko kuro lori apere fún ìgbà die, lori ẹsùn pe o n bawọn janduku agbébọn ṣe.
Dansadau Nasiru Muhammad Sarkin Kudu lo gba ipo rẹ lati máa ṣe akoso ilu.
Gomina Matawalle tun gbe igbimọ kalẹ, ti ọgá àgbà ọlọpaa to ṣiṣẹ feyinti, Mohammad Ibrahim Tsafe dari rẹ.
Igbimọ naa si lo wadii ẹsun ti wọn fi kan oriade ọhun.
Oríṣun àwòrán, Emir Maru, Abubakar Chika/Facebook
Sarkin Maru ni Oriade akọkọ ti ijọba Zamfara yóò yọ kuro lori oye.
Ni oṣù Kẹjọ ọdun 2019, Matawalle yọ Emir Maru, Abubakar Chika lori ẹsun pe o dalẹ awọn araalu nipa lilẹdi apo pọ pẹlu awọn janduku ajinigbe lati ji awọn araalu gbe.
Agbẹnusọ Oriade yii ni, ko si nkan tó jọ bẹẹ, to sì tàkò ẹsun ọhun.
Yatọ sí àwọn Oriade ta ka silẹ yii tun wọn yọ awọn baalẹ kọọkan náà lori ẹsun pe wọn mọ nipa ijinigbe l'agbegbe wọn.
Ninu wọn la ti ri :
Baalẹ abule Kanoma:
Olori Ilu Kanoma ni ijoba ibilẹ Maru ni ipinlẹ Zamfara, Alhaji Lawal Ahmad náà gba aṣẹ lọ rọọkun nile lori ẹsun pe o mọ nipa ijinigbe.
Iwadii ti igbimọ tijọba gbe kalẹ lori ẹsun ijinigbe ti wọn fi kan baalẹ naa, ṣe ṣafihan pe Lawal Ahmad ati Emir Maru, Abubakar Chika n dijọ lẹdi apo pọ gba owo ìdóòlà fun awọn ajinigbe.
Oloye Nasarawa Mailayi, ti orukọ rẹ n je Bello Kiyawa ati  Emir ilu Zurmi, ni won ni ko lọ sinmi nile lori ẹsun pe wọn n ṣiṣẹ pọ pẹlu awọn ajinigbe.
ìjọba ni Emir yii n lẹdi apo pọ pẹlu awọn ajinigbe janduku to buru julọ lagbegbe naa.
Ilu Zurmi wa leti ibode pẹlu Katsina, ti awọn agbébọn ajimaalu sì máa n da wọn láàmú níbẹ.
"'Sister Tope Alabi yà mí lẹ́nu gan o pé ""Oniduro mi"" kìí ṣe orin tó yẹ kí ọlọ́run fún mi'"
Losu kinnin ọdun 2020, ijọba ipinlẹ Zamfara fi ofin de awọn Seriki meji nijọba ibilẹ Bakura ati Zurmi.
Ijọba ni ki Alhaji Bello Garba Kanwa, tii se Seriki abule Kanwa ati Alhaji Muhammad Bello Yusuf, tii se Marafa abule Bakura.
Gẹgẹ bi ijọba ipinlẹZamfara ti wi, o ni oun ni kawọn olori mejeeji lọ rọọkun nile na nitori ẹsun aigbọran ati atako taarata sawọn eto ti ijọba gbe kalẹ.
Awọn ẹsun miran tijọba tun fi kan wọn ni dida si ọrọ oselu, ẹsun ikowojẹ, iwa ajẹbanu ati sise owo ilu basubasu.
Michael Packard: Ọkùnrin kan tó bọ́ sẹnu ẹja àbùùbùtán nínú òkun sọ bí orí ṣe ko yọ
Oríṣun àwòrán, Screen Shot
Michael Packard ti salaye bo se ba ara rẹ lẹnu ẹja abuubutan fun bii aabọ isẹju ni Massachusetts, lorilẹede Amẹrika.
Ẹja abuubutan naa, ti wọn n pe ni Whale, lo pada pọ ọkunrin naa jade lẹnu rẹ, to si jẹ pe orunkun nikan ni ọkunrin naa Packard, fi sese.
Bi o tilẹ jẹ pe iyawo rẹ ti n bẹbẹ pe ki Packard wa isẹ oojọ miran se, amọ o ni oun ko ni lori ero lati fi isẹ bibẹ sinu omi Cape Pod silẹ, eyi to ti n se fun ogoji ọdun.
Ẹja abuubutan yii si lo maa n dagba, ti yoo si gun to mita mẹẹdogun, tii se aadọta ẹsẹ bata.
Bakan naa lo tun maa n tobi to tọọnu mẹrindinlogoji, gẹgẹ bi ajọ to wa fun ẹdawo imọ nipa ẹranko igbẹ ti wi, awọn ẹja yii to ẹgbẹrun lọna ọgọta lagbaye.
Ọjà Mákòókó : Ibẹ̀ ni ọba ẹja wa ní Èkó
Ọgbẹni Packard, tii se ẹni ọdun mẹrindinlọgọta, salaye fun awọn akọroyin pe oun ati awọn akẹẹgbẹ oun gbe ọkọ oju omi awọn ni aarọ ọjọ Ẹti naa nitori oju ọjọ to dara.
O ni awọn tun ni anfaani lati ri ilẹ omi to to ẹsẹ bata ogun.
Packard salaye pe nigba ti oun danu latinu ọkọ oju omi naa, ni oun gbọ ti nnkan lanu gbe oun sẹnu, ti ohun gbogbo si dudu wa loju oun.
Haa, Ọlọrun o, mo ti wa lẹnu ẹja, to si n gbiyanju lati gbe mi mi, O tan bayii, iku lo ku fun mi bayii.
Epe Fish Market: Wá wo oríṣi ẹja tí o rírí lọ́jà ẹja tó tóbi jùlọ ní Nàíjíríà
Se ni Packard bẹrẹ si ni ronu nipa iyawo rẹ ati ọmọ rẹ meji, ọkan jẹ ẹmọ ọdun mẹẹdogun nigba ti ekeji jẹ ọmọ ọdun mejila.
Amọ lojiji, lo pada sori ilẹ pada, to si jade ni ahamọ, to si n mi ori rẹ lugbe-lugbe.
Ibadan Masquerade Festival: Iléeṣẹ́ Ọlọ́pàá ní ọ̀rọ̀ kò rí bẹ́ẹ̀
Oríṣun àwòrán, others
Aarẹ ẹgbẹ awọn ọlọdẹ asọludẹrọ, Alhaji Nureni Ajijọla Anabi ti sọ pe awọn janduku lagbegbe Ọja igbo nilu Ibadan, ti ja ọdun eegun to n lọ lọwọ gba lagbegbe naa.
O ni awọn janduku naa ti sọ ọdun eegun di eyi ti wọn fi n pa eniyan bi ẹni n pẹran, ti wọn si tun n ṣe ọpọlọpọ eeyan leṣe.
AJijola Anabi sọ eyi ninu ifọrọwerọ pẹlu awọn oniroyin kan nilu Ibadan.
Gẹgẹ bi o ṣe sọ, ọdun egungun to n lọ lọwọ jakejado ilu Ibadan ti di ọdun wahala lagbegbe Ọja Igbo ati Ita Ẹgẹ.
Gẹgẹ bi ohun to sọ fun awọn ileeṣẹ iroyin abẹle kan, Alhaji Nureni Ajijọla Anọbi ni awọn janduku lẹyin eegun naa pa eeyan kan, ti wọn si tun da ina sun ile rẹ.
'Ọwọ́ mi ti ń jẹ́rà ká tó mọ̀ pé àfi kí wọ́n tún gé e bí mo bá ṣì fẹ́ máa ṣe iṣẹ́ awakọ̀ lọ'
Amọ ṣa, ileeṣẹ ọlọpaa nipinlẹ Ọyọ ti sọ pe ko si ohun to jọ eyi ati pe, nirọwọ rọsẹ ni ọdun egungun ti ọdun yii n lọ nilu Ibadan.
Ninu atẹjade kan to fi ranṣẹ si BBC Yoruba, alukoro ileeṣẹ ọlọpaa ni ipinlẹ Ọyọ, Adewale Osifeso ni awọn gbe eto ojulalakan fi n ṣọri ati ọtẹlẹmuyẹ kalẹ,
O ni awọn eto naa lo wa lati rii daju pe gbogbo ibi ti wahala lee ti fẹ suyọ ni wọn pa ina rẹ ko to ru.
"'Sister Tope Alabi yà mí lẹ́nu gan o pé ""Oniduro mi"" kìí ṣe orin tó yẹ kí ọlọ́run fún mi'"
"O fi kun un pe, ""gbogbo eleegun ni a ti ṣe ilanilọyẹ fun ṣaaju ọdun egungun naa, ti wọn si tun tọwọ bọwe adehun alaafia lati rii pe ko ni si rukerudo lasiko ọdun naa"""
Ileeṣẹ ọlọpaa ni gbogbo igbesẹ ojulalakan fii ṣọri to yẹ ni awọn ti gbe, ki awọn janduku ma baa sọ ọdun egungun naa di ọdun idana ogun silẹ.
Adeyinka Alaseyori and Tope Alabi: Wòlìí Genesis ní òun ni orin Oniduro Mi wà fún
Oríṣun àwòrán, other
Oluṣọ aguntan agba fun ijọ Celestial Church of Christ, Genesis Global, Ẹniọwọ Israel Ogundipe ti sọ pe ohun ti gbajumọ akọrin ẹmi, Tọpẹ Alabi sọ lori orin Oniduromi ku diẹ kaa to.
"Ẹniọwọ Ogundipẹ ṣalaye ninu fido kan to n lọ kaakiri bayii ninu eyi to ti n kọ orin ""oniduromi ẹ ṣeun"" pe oun gan ni orin naa wa fun, bi awọn eeyan ko ba mọ."
Oniduro mi ni alagbawi mi. O duro fun mi nigba ti ọpọ fi mi silẹ lori ẹjọ ti mo ko si, ti ọpọlọpọ si tun rin jinna si mi nitori pe wọn ko fẹ ki aye mọ wọn mọ mi.
Oluṣọ aguntan ijọ Genesis Global naa wa fi kun un pe, o dara ki Ọlọrun jẹ Oniduro ẹda dipo eniyan ẹlẹran ara.
Emi ni olorin ẹmi naa kọ orin naa fun. Koda nigba ti awọn ile ẹjọ da iṣẹ silẹ, Ọlọrun duro fun mi.
Mo dúpẹ́ pé ìgbà tí mo wà nínú Jesu ni mo lọ sẹ́wọ̀n, tó bá jẹ́ pé mo wà nínú áyé ni ... - Wòlìí Genesis
Laipẹ yii ni awuyewuye hu sita lori ọrọ ti Tọpẹ Alabi sọ ninu fidio kan to ja ranyinranyin kaakiri.
Tope Alabi ni akude wa lori orin naa ati pe ko jẹ jẹ latọwọ Ẹmi mimọ lo ti wa nitori pe Ọlọrun sọ fun oun pe oun kọja Oniduro fun ẹnikẹni.
Lati igba to si ti sọrọ naa, eyi to gba ori ayelujara, ni oniruuru eeyan ti n fesi nipa rẹ, eyi ti ko yọ awọ̀\n gbajumọ awujọ silẹ.
Shrine polling unit: Wo ohun tí INEC fẹ́ ṣe lórí ìbò sípò gómìnà Ekiti àti Osun lọ́dún 2022
Oríṣun àwòrán, Inec
O fẹrẹẹ to ibudo idibo ẹẹdẹgbẹrin abọ o di ọkan ti ajọ eleto idibo INEC ti gbe kuro ni orisiriṣi ibi ti wọn wa kaakiri ipinlẹ Naijiria to fi mọ ilu Abuja.
Alaga Ajọ INEC lorilẹede Naijiria, Ọjọgbọn Mahmood Yakubu ninu ọrọ to sọ ṣalaye pe Ọjọ Satide, Ọjọ Kejidinlogun, Osu Kẹfa, ọdun 2022 ni idibo si ipo gomina yoo waye ni ipinlẹ Ekiti.
Bakan naa nibi eto ọhun, ajọ Eleto idibo, INEC ti kede pe ọdun 2022 ni idibo si lọ gomina yoo waye ni ipinlẹ Osun ati Ipinlẹ Ekiti lorilẹede Naijiria.
Yabuku tun fi kun un pe, oṣu kan lẹyin ti idibo ba waye ni ipinlẹ Ekiti, ni idibo si ipo gomina yoo waye nipinlẹ Osun ni Ọjọ Satide, Ọjọ kẹrindinlogun, Oṣu Keje, ọdun 2022.
Bakan naa ni Ajọ INEC ni awọn ti mu afikun de ba awọn ibudo idibo kaakiri orilẹ̣ede Naijiria lati 119,974 si 176,846.
Alaga ajọ eleto idibo, Ọjọgbọn Mahmood Yakubu lo ṣipaya eyi l'Ọjọbọ nibi iṣide olu ileeṣẹ wọn to wa ni ilu Abuja.
"Yakubu ni ""lẹyin iforikori pẹlu awọn tọrọ kan, ajọ yii ti ṣaṣeyọri lati gbọn ibudo idibo ẹẹdẹgbẹrin abọ o di ọkan kuro lawọn ojubọ irumọlẹ to j ibudo aitọ lati maa dibo."
O ni eyi wa ni ibamu ofin ajọ eleto idibo pe ati ri na lọ dibo nibi to san lai si idiwọ jẹ ẹtọ oludibo ti a gbu mojuto.
Ninu iye ti wọn ri, ibudo idibo 232 ni wọn gbe kuro ni awọn aaye tabi ile to jẹ aladani, 145 lawọn Aafin Ọba, 6 ni Mọṣalaṣi, 21 lati Sọọsi ati mẹsan lati Ojubọ
''A ti gbe awọn ibudo idibo kuro ni awọn agbegbe to jẹ ti aladani bii ṣọọsi, aafin, mọṣalasi ati awọn ile ẹsin abalaye gbogbo''
''Awọn ibudo idibo tuntun ti a ṣẹṣẹ buwọlu naa yoo bẹrẹ iṣẹ lati asiko ibo si ipo gomina ti yoo waye nipinlẹ Anambra ni Ọjọ Kẹfa, Oṣu Kọkanla, ọdun 2021.''
"'Sister Tope Alabi yà mí lẹ́nu gan o pé ""Oniduro mi"" kìí ṣe orin tó yẹ kí ọlọ́run fún mi'"
Ajọ INEC ni awọn n ṣiṣẹ takuntakun kaakiri orilẹede Naijiria lati rii pe idibo n lọ ni irọwọ-rọsẹ lai ni magomago ninu.
Bakan naa ni wọn fi kun pe awọn kede ọjọ idibo sipo gomina ipinlẹ Ekiti ati Osun naa ki awọn ti ọrọ kan le lọ si oju opo ayelujara wọn lati lo wo awọn ilana to wa fun awọn oloṣelu ti yoo kopa ninu idibo naa ni ọdun to n bọ.
Ajo INEC wa parọwa si awon ẹgbẹ oloselu lati ri wi pe wọn ṣakoso idibo abẹlẹ wọn lai si magomago, ki ohun gbogbo si lọ ni pẹle pẹlẹ.
Oríṣun àwòrán, other
Ajọ eleto idibo lorilẹede Naijiria, INEC ti kede sjọ idibo sipo gomina ni ipinlẹ ọṣun ti yoo waye ni ọdun 2022.
Ninu atẹjade kan to fi sita, INEC ni ọjọ kẹrindinlogun oṣu keje ọdun 2022 ni idibo naa yoo waye.
Atẹjade naa ti akọwe ajọ INEC, Rose Orian-Anthony fọwọsi tun sọọ di mimọ pe ọjọ kini oṣu keji ọdun 2022 ni ajọ naa yoo gbe ikede idibo sita lẹyin eyi ti awọn ẹgbẹ oṣelu to ba fẹ kopa lee bẹrẹ si ni gbaradi.
Iyabo Ojo: Alábòsí àti olójúṣàájú ní àwọn akẹẹgbẹ́ mi lágbo tíátà
Oríṣun àwòrán, iyaboojofespris/Instagram
Alabosi ni awọn osere tiata Yoruba, ẹ sọrọ lori Oniduro mi amọ ẹ dakẹ lori ẹni to ba ọmọde sun
Gbajumọ osere tiata, Iyabo Ojo, ko tii sinmi rara lori ọrọ Baba Ijesha ati ẹsun ti wọn fi kan pe o ba ọmọde se asemase.
Lọtẹ yii, awọn agbarijọpọ osere tiata ni Iyabo ta si lọtẹ yii, to si n fẹsun kan wọn pe alabosi paraku ni wọn.
Ninu fidio tuntun ti Iyabo Ojo gbe jade lori ọrọ Baba Ijesha loju opo Instagram rẹ, o ni oun gbọdọ sọ tinu oun fun wọn ni.
Iyabo ojo wa n bi awọn akẹẹgbẹ rẹ pe se wọn sun tẹlẹ ni, ni wọn ko se sọrọ nipa ẹsun asemase ti wọn fi kan ọkan ninu wọn, Baba Ijesha.
"Eyi ti ko kan yin lẹ n da si, gbogbo yin lẹ n bu Tope Alabi pe o ni orin Oniduro Mi ko dara, se o sọ fun yin pe Alaseyori ni oun n ba wi ni.
To ba tiẹ wa jẹ pe oun lo n ba wi lootọ, ewo lo kan yin nibẹ, nitori eyi to kan yin, ẹ ko da si, ẹ mu ohun yin lọ, ẹ sọrọ.
Gbogbo yin lẹ n fi fidio orin sita bayii, amọ eyi to kan yin, ẹ gbe ẹnu dakẹ, ẹ ko beere ọmọ ti nnkan sẹlẹ si tabi Princess iya rẹ."
Iyabo Ojo tun n bi wọn leere pe melo ninu wọn gan lo ti pe Alaseyori lati wa kọrin fun oun bi tabi gbe orin rẹ sita.
O ni oun ko se atilẹyin fun ẹnikẹni ninu wọn, boya Tope ni abi Alaseyori funra rẹ nitori ko si ohun to kan oun nibẹ.
"'Sister Tope Alabi yà mí lẹ́nu gan o pé ""Oniduro mi"" kìí ṣe orin tó yẹ kí ọlọ́run fún mi'"
O ni awọn osere tiata ko duro ti ọmọ ọdun mẹrinla ti wọn se asemase pẹlu rẹ, nitori pe ara wọn lo se amọ se ni wọn n da si ọrọ awọn olorin ẹmi.
"Mo sọ fun yin nigba yẹn pe to ba jẹ ara ita lo se nnkan ti Baba Ijesha se, ẹ ti maa fi ẹhonu han, a ni ẹ kii se eeyan gidi ni agbo osere tiata wa.
Ootọ ọrọ ko ni ka ma sọ ohun, n ko si ni kẹ fẹran mi, gbogbo ẹyin tẹ dakẹ lori ọrọ Baba Ijesha, se o yẹ kẹ sọrọ lori orin Oniduro mi."
O ni sebi eeyan wọn ni Tope Alaseyori, gbogbo wọn se wa n dẹnu bo akọrin naa bayii, to si ni ki wọn sọ ara wọn gidi gan ni, ọrọ to le gidi, wọn ko sọ oju abẹ niko.
"Tẹ ba ti da si ohun ti ko kan yin, ojoojumọ ni emi Iyabo yoo maa jade lati sọrọ si yin. Alabosi ni yin, ẹ kii se eeyan to dara.
'Ọwọ́ mi ti ń jẹ́rà ká tó mọ̀ pé àfi kí wọ́n tún gé e bí mo bá ṣì fẹ́ máa ṣe iṣẹ́ awakọ̀ lọ'
Kii kuku se pe mo korira Alaseyori nitori oun lo wa kọrin lasiko isin idagbere fun iya mi, mo si sun mọ daadaa.
Alaseyori, jọ mase da awọn osere tiata lohun, ti nnkan miran ba se ọ lọla, wọn yoo gbe ẹnu dakẹ ni."
O wa kadi ọrọ rẹ nilẹ pe ki awọn osere tiata naa mase maa da si awọn ọrọ ti ko ba kan wọn.
TB Joshua: Wo nǹkan tó ṣẹlẹ̀ nígbà tí òkú wòlíì yọ sí òṣèrébìnrin, Jaiye Kuti
Oríṣun àwòrán, TB Joshua Ministries and jayeola_monje/Instagram
Gbajugbaja oṣerebinrin, Jaiye Kuti sọ iriri rẹ nipa bi òkú Woli Temitope Joshua ṣe yọ si.
Oṣerebinrin, Jaiye Kuti ni oku oloogbe, Woli Temitope Balogun Joshua, to jẹ oludasilẹ ile ijọsin Synagogue Church of All Nations, yọ si oun lẹyin iku rẹ.
Ninu ọrọ to kọ si ori ayelujara Instagram rẹ, Kuti sọ pe iyalẹnu lo jẹ fun oun pe TB Joshua yọ si oun, bo tilẹ jẹ pe oun ko ri loju koroju ri nigba to wa laye.
Ẹ pàdé olórin Fuji alhaji Besco tó jọ Ayinde Barrister to tún ń kọrin gẹ́lẹ́ bíi tirẹ̀
Ọjọ karun-un, oṣu Kẹfa ni Woli naa jade laye lẹni ọdun mẹtadinlọgọta.
Oṣerebinrin naa sọ pe nise ni ori oun dide jan-in lasiko ti oku TB Joshua yọ si oun, ti oun si ri to rọra kọja lọ jẹjẹ.
Oríṣun àwòrán,  jayeola_monje/Instagram
"Mi o ri ri lojukoroju, sugbọn oku rẹ yọ si mi nigba to ku.
Emi nikan ni mo wa ninu yara mi ni ilu Offa, ti mo deede ri to kọja. Ori mi dide. Nkankan to dara wa nipa ẹ̀mí naa."
"Alaini ni Kristi, sugbọn o bọ́ awọn eniyan, o si n tọju gbogbo eeyan. Bẹẹ ni ìwọTB Joshua naa ṣe fun ọpọlọpọ.
Ẹ pàdé olórin Fuji alhaji Besco tó jọ Ayinde Barrister to tún ń kọrin gẹ́lẹ́ bíi tirẹ̀
Ẹ̀yin olórin ẹ̀mí tó ń bóra, lo èékáná gígùn, oò yàtọ̀ sí aṣẹ́wó hòtẹ́ẹ̀lì tí wọ́n ń gbé bíi súùtì Pepper Menti - Bola Are
Ṣé ìrìnàjò nínú ọkọ̀ Reluwé Ibadan-Lagos-Ogun tuntun bá aráàlù lára mu? Èsì rèé
Eeyan meji ni mo mọ to fi aye wọn fun Jesu ni tootọ nipasẹ rẹ̀."
Jaiye Kuti ni oun gbadura pe ki Ọlọrun tẹ Woli T. B Joshua si afẹfẹ rere.
Bakan naa, nigba to n fesi si awọn ọrọ ti awọn ololufẹ rẹ kọ si abẹ awọn nkan to sọ nípa T. B Joshua, paapaa nipa nkan ti awọn eniyan sọ nipa oloogbe nigba aye rẹ.
Jaiye Kuti sọ pe awọn erokero naa ko yọ oun silẹ. O ni oun naa gbagbọ bi awọn eeyan ṣe sọ pe Joshua kii ṣe iranṣẹ Ọlọrun tootọ.
Gbogbo wa la jẹbi awọn ọrọ naa nípa rẹ, nitori pe a ko ri aridaju nipa iru eniyan to jẹ.
Oserebinrin naa wa n beere pe ta ni eeyan Ọlọrun gan bikose ẹni to se awọn ofin rẹ, to si jẹ pe awọn ojisẹ Ọlọrun nkan wa, to jẹ pe owo ni wọn n wa.
"Wọn ko ni fi ọrọ Ọlọrun gan bọ wa debi pe a mọ ẹni ti Ọlọrun jẹ, okoowo ni wọn n fi ẹsin Kristiẹni se.
Ni Italy, wọn maa fun wa lowo tori pe a wa sile ijọsin, wọn yoo fun wa lowo lati wa sin Ọlọrun ni amọ nibi yii, ohun gbogbo ta ni la fi n sin awọn ojisẹ Ọlọrun."
TB Joshua: Ṣe ni ọ̀pọ̀ èèyàn ń wa ẹkún mu torí ikú òjijì tó pa wòlíì
O fikun pe ọpọ eeyan ni ko mọ ofin orilẹede yii amọ wọn le ka bibeli lori lati ibẹrẹ de opin.
O wa kede pe wọn kan n fi ẹsin tu wa jẹ lasan ni, to si jẹ pe ọtẹ ati tẹmbẹlẹkun lo kun inu ọpọ eeyan to n fi ara rẹ we Kristi.
Tope Alabi, ìyá mi ló jẹ́..., àmọ́ mo fẹ́ ... - Yinka Alaseyori
Oríṣun àwòrán, Tope Alabi, Yinka Alaseyori
"Iroyin to n jade lọwọlọwọ ni pe olorin ẹmi to ti di ilumọka bayii laarin ọjọ mẹta pere, Yinka Alaseyori ti sọrọ soke si bi ogbontarigi olorin Tope Alabi ṣe sọrọ ni gbangba pe ko tọ ki o pe Ọlọrun ni ""Oniduro Mi"". O ti fi ọrọ ranṣẹ si Tope Alabi ati gbogbo eeyan."
Adeyinka Alaseyori kọkọ ṣebi ẹni ti ko fẹ mẹnu ba ọrọ yii rara lati igba to ti ṣẹlẹ gẹgẹ bi ko ṣe ba ile iṣẹ́ iroyin kankan sọrọ lati ọjọ yii ti pada fọhun.
Nibi ti Yinka Alaseyori ti n ṣe isin orin iyin lati ṣaami ayẹyẹ ọjọ ibi rẹ lo ti bẹ gbogbo awọn eeyan lori ọrọ yii.
"Lo ba tun fi adura bọ ẹnu fun gbogbo awọn to n ṣe iṣẹ to jẹ ọna to tọ pe: ""gbogbo ẹyin tẹ n ṣe iṣẹ ọna to tọ to n mu ounjẹ wa sori tabili yin, ẹ o maa lowo sii ni""."
Baba Ijesha Rape Case: Yomi Fabiyi ní òun nìkàn lòun rí ara òun tó dúró tí Baba Ijesha
Àjinigbé pa ọmọ méjì wọ́n ji méjì gbé lọ tí wan jẹ́ ọmọ òbí kan ni Ondo,
Kí ló fa ikú akẹ́kọ̀ọ́ ẹni ọdún 23 yìí tí ọlópàá ba oku rẹ̀ nílé ìtura?
"Alaseyori kọ́ ló ni orin ""Oniduro Mi"", àmọ́ ìdí tí mi ò  ṣe bá a jà pé ó jí orin mi kọ nìyìí - Tolu Adelegan"
Ìjọba Saudi dájọ́ ikú fún ọ̀dọ́ kan lórí ẹ̀ṣẹ̀ tó ṣẹ̀ láti kékéré, ìdí rèé
Nǹkan tí a mọ̀ nípa ìlera Asiwaju Ahmed Tinubu
Ayédèrú òṣìṣẹ́ ìjọba ni Baba Ijesha fà kalẹ́ ló jẹ́ kó ṣì wà láhámọ́ - Ọlọ́pàá
Ṣé ìrìnàjò nínú ọkọ̀ Reluwé Ibadan-Lagos-Ogun tuntun bá aráàlù lára mu? Èsì rèé
Alaṣeyori ni ti oun ba ti ṣe tan nibi eto orin iyin naa, ounjẹ loun n lọ jẹ gẹgẹ bo ṣe ayẹyẹ ọjọ ibi rẹ to jẹ ọjọ kẹrin oṣu kẹfa gangan amọ to ni ko saye lati ṣe ayẹyẹ afi titi di oni ti oun fi ṣe eto orin iyin.
"Lẹyin ọpọlọpọ wakati orin iyin ti akọroyin BBC Yoruba joko ti loju opo ayelujara Adeyinka Alaṣeyori funrarẹ, ti oun ati olorin ẹmi mii Dare Melody kọ lati fi ṣide eto naa, Alaseyori fẹ re si orin alujo tori o ni ""mo fẹ ki ẹ jo amọ mo fẹ fi Ọlọrun bẹ yin..."""
"Alaseyori ni ""mo kọkọ fẹ dupẹ lọwọ gbogbo eeyan kaakiri agbaye, loke okun ati nile nibi fun ifẹ yin. ""Mummy Tope Alabi, iyaa mi ni""."
"O tẹsiwaju pe: ""Iya ni Tope Alabi jẹ si mi, ọna kan tabi omiran si ni gbogbo wa ti jẹ anfani lara awọn orin rẹ... Ẹ jọwọ ẹ jẹ ki alafia jọba""."
Alaseyori ti ijo ati ohun orin didun si ba nile tẹlẹ ti gbogbo ijo wa lara rẹ - lo ba ni kan si orin ati ijo si Ọlọrun ati fun awọn ololufẹ rẹ.
'Ọwọ́ mi ti ń jẹ́rà ká tó mọ̀ pé àfi kí wọ́n tún gé e bí mo bá ṣì fẹ́ máa ṣe iṣẹ́ awakọ̀ lọ'
Yinka Alaseyori ko mẹnu ba idi kankan ti ko fi yẹ ki o kọ orin naa gẹgẹ igun awọn eeyan kan ṣe n ja fun pe kii ṣe ohun gangan ni Ọlọrun fun ni orin naa lati kọ kalẹ.
Iroyin ti a kojọ ati ifọrọwanilẹnuwo BBC Yoruba pẹlu ni ti o gba imisi orin naa gangan, Evangelist Toluwalase Aladelegan fihan pe ọdun 2014 ni Tolu gba imisi orin naa to si tun kọ jade ni ile ito orin pọ.
"'Sister Tope Alabi yà mí lẹ́nu gan o pé ""Oniduro mi"" kìí ṣe orin tó yẹ kí ọlọ́run fún mi'"
Mo rí òkú TB Joshua tó yọ sí mi lẹ́yìn ikú rẹ̀ - Jaiye Kuti
Wòlíì Genesis fèsì lórí ọ̀rọ̀ Tope Alabi nípa orin 'Oniduromi'
Oríṣun àwòrán, Alaseyori
Ẹwẹ, Alaṣeyori to jẹ́ olorin ẹmi to maa n kọ gbogbo orin yala tirẹ ni tabi ti ẹlomiran bi o ba ṣe ni idari kẹnu bọ awọn orin to wu awọn eeyan lori gan. Diẹ lara wọn niyii:
Iṣẹ nla lẹ ṣe laye mi
Ẹyin tẹ fun wa lowo tẹ́ẹ fun wa laṣọ, fun wa ni ipara, ẹ o maa lowo, lọla sii.
Ọlọrun ko da bi eniyan, eeniyan aronipin... Iwo ko lo da mi, iwọ kọ lo bi mi, o si n sọrọ bi Eledumare
Jesus na you big o, Ọga patapata...
Ẹ ṣee aye ọpẹ yọ, mo dupẹ aye ọpẹ pada yọ
N o la agbaye ja, n go si ri bi Ọba...
Oniduro Mi ẹ ṣeun o...
Ẹ̀yin olórin ẹ̀mí tó ń bóra, lo èékáná gígùn, oò yàtọ̀ sí aṣẹ́wó hòtẹ́ẹ̀lì tí wọ́n ń gbé bíi súùtì Pepper Menti - Bola Are
Baba Ijesha case: Iléeṣẹ́ ọlọ́pàá Eko ní àwọn ti yọwọ́ lórí ẹjọ́ Baba Ijesha, àárín òun àti ìjọba lọ̀rọ̀ wà báyìí
Ileeṣẹ ọlọpaa ipinlẹ  Eko ti sọ pe awọn ko mọ ohunkohun nipa ọrọ Baba Ijẹṣa ati igbẹjọ rẹ mọ.
Ninu ọrọ ti wọn ba awọn oniroyin sọ ni gbagede ile ẹjọ Majisireeti ipinlẹ Eko to wa ni agbegbe Yaba, adari ẹka ofin nileeṣẹ ọlọpaa nipinlẹ Eko, Arabinrin Cardoso Yetunde ṣalaye fun awọn akọroyin pe ọlọpaa ti yọwọ kuro ninu ẹjọ Baba Ijẹṣa ati pe ọfiisi adari olupẹjọ DPP nipinlẹ Eko lọrọ ẹjọ Baba Ijẹṣa wa bayii.
Baba Ijesha Rape Case: Yomi Fabiyi ní òun nìkàn lòun rí ara òun tó dúró tí Baba Ijesha
O ni lootọ ni wọn fun Baba Ijesa ni Beeli lasiko iyanṣẹlodi ẹgbẹ awọn oṣiṣẹ ẹka iṣedajọ nigba naa, ṣugbọn nitori awọn gbedeke beeli ti wọn fun un nigba naa ti ko lee mu ṣẹ lo fi jẹ ki wọn gbe e wa sile ẹjọ  Majisireeti lọjọru lati bẹrẹ igbẹjọ rẹ ni pẹrẹu.
O ni lara gbedeke beeli ti wọn fun un ni pe ko fa oṣiṣẹ ijọba to wa ni ipele ikẹrindinlogun kalẹ gẹgẹ bi oniduro eleyi to ni ko ri ṣe.
Ọga ọlọpaa Cardozo ni awọn rii pe ayederu ni ẹni ti awọn agbẹjọro rẹ fa kalẹ gẹgẹ bi oṣiṣẹ ijọba onipele ikẹrindinlogun.
Ẹ pàdé olórin Fuji alhaji Besco tó jọ Ayinde Barrister to tún ń kọrin gẹ́lẹ́ bíi tirẹ̀
"Oṣiṣẹ onipele ikẹrindinlogun ti wọn mu wa, a ni lati mu u tọ olori awọn oṣiṣẹ ijọba nipinlẹ Eko lọ lati lee fidi rẹ mulẹ boya lootọ ni ipele iṣẹ ijọba ti ẹni naa wa.
Olori awọn oṣiṣẹ si fun wa ni esi pe ẹniyẹn kii ṣe oṣiṣẹ."
O ni ọfiisi adari olupẹjọ DPP nipinlẹ Eko ti tẹwọ gba ẹjọ naa lọwọ awọn ọlọpaa ati pe ẹjọ naa kii ṣe ti ọlọpaa mọ, o ti di ẹjọ ijọba.
Lọwọ yii a ti taari ẹjọ naa sọdọ ọfiisi adari olupẹjọ DPP nipinlẹ Eko ko si nnkan to kan ọlọpaa mọ pẹlu ọrọ igbẹjọ Baba Ijesha
Ninu ọrọ rẹ Agbẹjọro fun Baba Ijẹsa, Amofin Kayọde Ọlabiọrẹ ṣalaye pe adajọ Majisireeti to gbọ ẹjọ Baba Ijẹṣa ni oun ko lagbara lati gbọ ẹjọ naa mọ nitori pe ọfiisi adari olupẹjọ DPP nipinlẹ Eko ti sọ niwaju ileẹjọ pe awọn wọn ti pe ẹjọ naa niwaju ile ẹjọ giga ipinlẹ Eko.
Amofin Ọlabiọrẹ ni arọwa wọn lati beere fun beeli ko le gba itusilẹ fun igba diẹ ko bọ si.
'Ọwọ́ mi ti ń jẹ́rà ká tó mọ̀ pé àfi kí wọ́n tún gé e bí mo bá ṣì fẹ́ máa ṣe iṣẹ́ awakọ̀ lọ'
O fi kun un pe gbedeke oṣiṣẹ ijọba onipele ikẹrindinlogun ti wọn fun Baba Ijẹsa lo fa a to ṣi fi wa ni ahamọ ijọba lọwọlọwọ.
Amọṣa o ni ẹbẹ awọn fun ile ẹjs lati tun ọrọ beeli naa yẹwọ foriṣanpọn nitori pe wọn ti pe ẹjọ naa niwaju ile ẹjọ giga.
O ni bi wọn ba gbe ẹjọ naa de iwaju ile ẹjọ giga ipinlẹ Eko ni wọn yoo to tun gbe ẹbẹ fun beeli dide fun Baba Ijẹṣa.
Alberto Sánchez Gómez: Bí ọkùnrin kan ṣe dèrò ẹ̀wọ̀n ọdún 15 lẹ́yìn tó pa ìya rẹ̀ tó sì tún sè é sí ọbẹ̀ jẹ
Oríṣun àwòrán, Spanish police
Arakunrin kan lati ilẹ Spain ti ri ẹwọn ọdun marundinlogun he lẹyin to pa iya rẹ to si tun se e jẹ.
Ọdun 2019 ni ọwọ ọlọpaa tẹ arakunrin Alberto Sánchez Gómez, lẹyin ti wọn ri ẹya ara ni agbegbe ile iya rẹ, ti wọn si tun ba awọn ẹya ara kan ninu ike.
Ileẹjọ ko lati gba ọrọ Sanchez gbọ pe niṣe lo ni arun ọpọlọ lasiko to wu iwa buruku bẹẹ.
Nkan n bẹ! Páṣítọ̀ lu ìyàwó rẹ̀ pa torí pé ó ń yan àlè
Sunday Igboho ní agbébọn tí kò bá kúrò nínú igbó Yorùbá láti ọjọ́ Aje rugi oyin
Iyabo Ojo bẹ̀rẹ̀ ìjà rọ̀fọ̀rọ́fọ̀ pẹ̀lú máníjà rẹ̀ tẹ́lẹ̀ lórí ẹ̀sùn olè jíjà
Wo ikú tó pa Kenneth Kaunda, Ajìjàgbara fún òmìnira Áfíríkà tó gbẹ̀yìn
Baba Ijesha Rape Case: Yomi Fabiyi ní òun nìkàn lòun rí ara òun tó dúró tí Baba Ijesha
Nibayii, ọdun marundinlogun ni yoo lo ni ọgba ẹwọn fun ẹsun ipaniyan pẹlu oṣu marun un miran fun ṣiṣẹ ara oku basubasu.
Bakan naa ni wọn ni ko fun iya rẹ ni ibatan rẹ ni iye owo to to €60,000 ($73,000, £52,000) gẹgẹ bi iye owo itanran.
Oṣu Keji, ọdun to kọja ni ileeṣẹ ọlọpaa jawọ ile Sanches ni agbegbe Madrid, lẹyin ti ọrẹ rẹ kan kegbare nipa  alaafia iya Sanches, iyẹn María Soledad Gómez,ti o ti le ni ọgọta ọdun.
Lasiko igbẹjọ naa ni wọn sọ fun ileẹ̣jọ wi pe niṣe ni Sanchez to jẹ ẹni ọdun mẹrindinlọgbọn yii ọrun iya rẹ pa.
Lẹyin naa ni ọmọkunrin naa ge ẹya ara rẹ yalayala, ti o si se e jẹ fun ọsẹ meji, to si fifun aja rẹ naa.
Ileeṣẹ iroyin ni orilẹede Spain ni awọn to mọ arakunrin Sanches daadaa ni ọpọlọpọ igba lo ti ba iya rẹ ja, ti ọlọpaa si tii mọ ile rẹ pe ko gbọdọ de ọdọ iya rẹ mọ.
"Ẹ jọ̀wọ́ ẹ jẹ́ kí àláfíà jọba lórí orin ""Oniduro Mi"", ìyá ni Tope Alabi jẹ́ sí mi - Adeyinka Alaṣeyori"
Lẹ́yìn ọdún kan tí àwọn ènìyàn ìpínlẹ̀ Borno hó lé lórí, Ààrẹ Buhari ṣe àbẹ̀wò sí Borno
Àwọn agbébọn ti jí àwọn akẹ́kọ̀ọ́ míì gbé lọ ní Kebbi
N5M ni a pàdánù lásìkò tí ìjọba ìpínlẹ̀ Oyo lé wa kùró ní Sabo - Àwọn oníbárà
Ṣé ìrìnàjò nínú ọkọ̀ Reluwé Ibadan-Lagos-Ogun tuntun bá aráàlù lára mu? Èsì rèé
Oyo NURTW-PMS Crisis: Àwọn ọ̀dọ́ fi ẹ̀hónú hàn lọ sọ́dọ̀ Seyi Makinde lórí wàhálà awakọ̀ èrò
Oríṣun àwòrán, Screen Shot
Se ni ọrọ tun di boolọ, koo yago fun mi ni irọlẹ Ọjọru oni ladugbo Iwo Road nilu Ibadan, nigba ti ohun gbogbo dẹnu kọlẹ, ti awọn eeyan si n sa asala fun ẹmi wọn.
Gẹgẹ bi iroyin to n tẹ wa lọwọ ti wi, awọn ọmọ igbimọ to n se akoso gareeji ọkọ, PMS, eyi ti Alhaji Mukaila, ti ọpọ eeyan mọ si Auxilliary ko sodi, ni wọn fija pẹẹta pẹlu awọn ọmọ ẹgbẹ́ awakọ NURTW, tijọba ipinlẹ Oyo ti fi ofin de.
Bi o tilẹ jẹ pe ko tii si ẹni to le sọ ohun to fa isẹlẹ naa, amọ se ni iro ibọn n dun lakọ-lakọ lagbegbe naa, ti ọrọ si di ẹni ori yọ, o dile.
Baba Ijesha Rape Case: Yomi Fabiyi ní òun nìkàn lòun rí ara òun tó dúró tí Baba Ijesha
Gẹgẹ bi ẹnikan ti isẹlẹ naa soju rẹ se salaye fun BBC Yoruba, o ni kawọn to sẹju pẹ, oku meji ti sun nitori isẹlẹ naa.
Bakan naa lo fidi rẹ mulẹ pe se ni awọn igun mejeeji to n kọju ija sira wọn ọhun fọ awọn eroja foonu olowo iyebiye tawọn ontaja n ta nikorita Iwo Road.
Oríṣun àwòrán, Screen Shot
Bẹẹ lo ni wọn ba gbogbo ohun ti wọn fi n patẹ ọja wọn jẹ, ti ekufọ igo si kun ilẹ kaakiri agbegbe naa.
Koda, awọn ọdọ ti inu n bi lori isẹlẹ naa ati ẹmi to ba rin, gbe eeyan kan to fara gba ọgbẹ lasiko ti rogbodiyan naa n waye lọ si ọgba Secretariat nilu Ibadan.
Awọn ọdọ naa ti wọn pọ niye, lo duro siwaju ọọ fisi gomina, ti wọn si n pariwo pe awọn fẹ ki gomina Seyi Makinde wa wo itu tawọn eeyan Auxillary pa ni Iwo Road.
Ẹ̀yin olórin ẹ̀mí tó ń bóra, lo èékáná gígùn, oò yàtọ̀ sí aṣẹ́wó hòtẹ́ẹ̀lì tí wọ́n ń gbé bíi súùtì Pepper Menti - Bola Are
Amọ titi di igba ta fi n ko iroyin yii jọ, Gomina Seyi Makinde ko yọju rara si awọn ọdọ naa.
Wayi o, wọn ti ko awọn ọmọ ikọ digboluja Operation Burst ransẹ si Iwo Road lati da alaafia pada si agbegbe naa.
Nigba ti BBC Yoruba kan si agbẹnusọ fun ileesẹ ọlọpaa ipinlẹ Oyo lati mọ ohun to sokunfa rogbodiyan ọtun yii, wọn ko ti fesi si ibeere wa ta fi ransẹ.
Gani Adams: Ẹ̀yin àjọ àgbáyé, ẹ dìde yanjú wàláhà Nàíjíríà kó tó dojúrú tán
Aarẹ Ọna Kakanfọ Ilẹ Yoruba, Iba Gani Adams ti kọ lẹta si awọn ajọ agbaye, to fi mọ awọn orilẹede ilẹ okeere, lati dasi eto aabo to dẹnukọlẹ ni Naijiria.
Ninu lẹta ti Gani Adams buwọlu fun ara rẹ, lo ti sọ fun awọn ajọ ilẹ okeere yii pe, ti wọn ko ba dasi eto aabo to dẹnukọlẹ ni ilẹ Yoruba yii, yoo ni ipa buruku lori ọrọ aje wọn lorilẹede Naijiria.
"Gani Adams, to pe akọle lẹta naa ni '' Igbesẹ kanmọ n kia lati dawọ iwa isekupani awọn Fulani Darandaran duro nilẹ Yoruba"" ni ohun to pọn dandan ni ki awọn orilẹede wọnyii dasi ọrọ iṣekupani ojojumọ naa."
Awọn ti Gani Adams kọ lẹta naa si ni Akọwe Agba Ajọ Iṣọkan Agbaye, UN, Alaga Ajọ Iṣọkan ilẹ Africa, AU, Ijọba orilẹede Amẹrika, Akọwe ijọba Ilẹ Gẹẹsi, Ajọ iṣọkan Ilẹ Yuroopu ati awọn orilẹede to wa ni abẹ rẹ.
Atunto Naijiria la n fẹ - Aarẹ Onakakanfo, Gani Adams
Awọn orilẹede ati Ajọ to ku ti Gani Adams tun kọ lẹta naa si ni Ajọ Economic Community of West African States (ECOWAS); orilẹede Germany, Canada, Italy, Japan, Holland, Sweden, South Africa, Ghana, Togo Benin Republic ati bẹẹ bẹẹ lọ.
Bakan naa ni Gani Adams bu ẹnu atẹ lu iha ti ijọba apapọ Naijiria kọ si ikọlu awọn darandaran ni ilẹ Yoruba ati bi wọn ko ṣe gbe igbesẹ kankan nipa rẹ.
''Ipaniyan ojojumọ ni Naijiria paapaa ni ilẹ Yoruba ko ni ojutu mọ, ojojumọ ni awọn Fulani darandaran n pa eniyan bi ẹran''
Ti ijọba lawọn orilẹede agbaye ko ba tete dasi iṣẹlẹ to n lọ lọwọ yii, o ṣeeṣe ki ogun abẹle ati ija ẹlẹyamẹya bẹ silẹ kaakiri orilẹede Naijiria.''
Ifọrọwerọ  pẹlu Gani Adams lori ọrọ Sunday Igboho
''Nibayii, ẹgbẹgbẹrun awọn ọmọ Naijiria ni ko le e sun lai foya nitori ipaniyan to n waye kaakiri paapaa ilu Igangan ti wọn ti n paniyan ni ojojumọ''
Gani Adams ni o ṣe ni laanu wi pe ijọba Aarẹ Buhari fi aye gba ipaniyan yii lati tẹsiwaju pẹlu gbolohun ti wọn n sọ wi pe, ko si ẹnikẹni to le e le ẹya kan kuro ni agbegbe kan lorilẹede Naijiria.
Aarẹ Ọna Kakanfo Ilẹ Yoruba naa wa kesi awọn orilẹede lagbaye ati Ajọ naa, lati dasi ọrọ yii ki o to dojuru patapata nitori o ti su awọn eniyan, ti wọn si ti fẹ ma a gbe ohun ija lati daabo bo ara wọn.
Lagos police: Iléeṣẹ́ ọlọ́pàá Eko bẹ̀rẹ̀ ìdánilẹ́kọọ̀ọ́ fún ikọ̀ ATRS tí yòó gba iṣẹ́ ọlọ́ọ̀pá SARS ṣe
Oríṣun àwòrán, lagos police command
Ileeṣẹ ọlọpaa ipinlẹ Eko ti gbe ikọ tuntun kalẹ ti yoo maa gbogun ti idigunjale loju popo ni ipinlẹ Eko.
Orukọ ikọ naa ni Anti Traffic Robbery Squad ti yoo maa gbogun ti idigunjale loju popo paapaa lasiko ti sunkẹrẹ fakẹrẹ ọkọ ba wa.
Kọmiṣọna ọlọpaa ni ipinlẹ Eko, Hakeem Odumoṣu ti paṣẹ pe ki awọn ọlọpaa ikọ naa bẹrẹ idanilẹkọ ati igbaradi.
Kọmiṣọna ọlọpaa Odumoṣu ni laarin oṣu kẹta si asiko yii, ko din ni eeyan mẹtadinlaadoje ti ọwọ ti ba gẹgẹ bi afurasi adigunjale inu sunkẹrẹ-fakẹrẹ nipinlẹ Eko.
O fikun pe ileeṣẹ ọlọpaa ni ipinlẹ Eko ti dide ija si awọn ole to n gba tọwọ oninkan ninu sunkẹrẹ-fakẹrẹ ọkọ.
Baba Ijesha Rape Case: Yomi Fabiyi ní òun nìkàn lòun rí ara òun tó dúró tí Baba Ijesha
Ninu atẹjade kan ti alukoro ileeṣẹ ọlọpaa ni ipinlẹ Eko, Olumuyiwa Adejọbi fi sita, o ni kọmiṣọna ọlọpaa nipinlẹ Eko ti fi aṣẹ sii pe ki idanilẹkọ oloorekoore o maa waye fun awọm ọlọpaa ni ipinlẹ naa.
O ni eyi jẹ ara ọna ati lee jẹ ki wọn wa ni igbaradi fun gbogbo ipenija abo to ba n waye nipinlẹ naa.
Iyabo Ojo and Omo'brish: Kí ló n fa ìjà láàrin ọ̀rẹ́ tímọ́-tímọ́ méjì?
Oríṣun àwòrán, iyaboojofespris/Instagram
Gbajugbaja oṣerebinrin, Iyabo Ojo sọ pe iya oun ni aisan Schizophrenia, to ni i ṣe pẹlu ilera ọpọlọ, ko to o ku ninu oṣu Kọkanla, ọdun to kọja.
Lasiko ti Iyabo ati ọrẹ timọ-timọ, Tosin Abiola, ti ọpọ mọ si Tocyn Omo Brish, n tahun si ara wọn lori ayelujara Instagram ni Iyabo tu asiri naa nipa iya rẹ.
Oṣerebinrin naa fi ẹsun kan Tosin pe o fọwọsowọpọ pẹlu oṣiṣẹ oun nigba kan, lati ba aye òun jẹ.
"Iyabo ni ""awọn eeyan kan ma n wa sinu igbesi aye rẹ lati fi ọ ṣe àtẹ̀gùn fun mimu iwa imọtara ẹni nikan wọn ṣẹ."
Wọn a darapọ mọ ọ, wọn a mọ ìwọlé ati ijade rẹ, wọn a si lo ìṣòro rẹ lati fi ba ti ẹ jẹ, sugbọn o, emi kii ṣe ẹni ti wọn le ba ti ẹ jẹ.
'Ọwọ́ mi ti ń jẹ́rà ká tó mọ̀ pé àfi kí wọ́n tún gé e bí mo bá ṣì fẹ́ máa ṣe iṣẹ́ awakọ̀ lọ'
"O ṣalaye pe lootọ ni mama oun ni aisan ọpọlọ, ""mo tọju rẹ daadaa, mo si nifẹ rẹ pupọ, sugbọn ọpọlọpọ ọdun ni  ìwọ Tosin ma n fi ọgbọn pe mi ni àwọn orúkọ to tumọ si ẹni to ni aarun ọpọlọ."
"Mo kilọ fun ọ lori rẹ, nitori mo ni igbagbọ pe o n fi ọgbọn fi iya mi ṣe yẹyẹ ni."""
Iyabo Ojo sọ pe oun ti ṣetan lati ba ọrẹ òun, Tosin na ọrọ ija naa tan bi owó.
O fi ẹsun kan an pe, lati ọsẹ diẹ ni Tosin ti n sọ òkò eebu si oun, nitori pe oun ko faramọ ibasepọ rẹ pẹlu amugbalẹgbẹ oun nigba kan, Gbemi.
Ẹ̀yin olórin ẹ̀mí tó ń bóra, lo èékáná gígùn, oò yàtọ̀ sí aṣẹ́wó hòtẹ́ẹ̀lì tí wọ́n ń gbé bíi súùtì Pepper Menti - Bola Are
"O le pe ara rẹ ni ọrẹ korikosun mi, ko ma a wa ba ọmọ isẹ ti mo mu bi ọmọ, àmọ́ to fẹ ẹ pa okoowo mi run ṣọrẹ.
Dandan kọ ni ọrẹ, to ba kọjú ija si mi, ma a kọju ìjà si ẹ."
Oríṣun àwòrán, The nation
Gbajumọ oṣere tiata, Iyabọ Ojo ti fẹsun ole jija kan ọkan lara awọn oṣiṣẹ rẹ nigbakan ri, Gbeminiyi Adegbọla .
Adegbọla, gẹgẹ bi iroyin abẹle ṣe sọ, ni oludari ileeṣẹ Fepris Limited, ti Iyabọ Ojo da silẹ.
Lọjọru ni Adegbọla yii bọ soju opo ayelujara Instagram nibi to ti pariwo Iyabọ Ojo sita pe, o fi ẹsun kan oun pe oun lohun fẹ jẹ ileeṣẹ rẹ run.
Ẹ pàdé olórin Fuji alhaji Besco tó jọ Ayinde Barrister to tún ń kọrin gẹ́lẹ́ bíi tirẹ̀
"Adegbọla ni ""O sọ pe mo ji ẹ lowo ko, emi ati iwọ naa mọ pe o ko ni kọbọ lọwọ nigba naa, a kan n ṣe ṣekarimi lasan ni."
Mo gbọ pe wọn ni o mu mi gẹgẹ bi ọmọ, ti mo si ba ileesẹ rẹ jẹ? Huumm, ọmọ kẹ, iya kẹ, ọmọ to maa n lu nita gbangba, to si maa n fi se ẹlẹya loju aye.
Baba Ijesha Rape Case: Yomi Fabiyi ní òun nìkàn lòun rí ara òun tó dúró tí Baba Ijesha
Se ọmọ ti o ko se nnkan daradara fun fun odidi ọdun mẹrinla ti gbogbo wa si mọ nipa bi okoowo yii se lọ, mo si fi gbogbo aye mi sin ọ.
O ni mo gbe owo rẹ, iwọ ati emi si mọ lasiko naa pe o ko ni kọbọ lapo, a kan n se Packaging ni, to si ti di awa kan lẹnu pe a ko gbọdọ tu asiri sita, koda, bi inu n bi wa. Ọlọrun yoo da laarin wa.
O ti le ni ọdun mẹta bayii ti ọrọ yii ti waye amọ o ko jẹ ko tan sibẹ, se nnkan mii wa nibẹ, ti o ko sọ ni?
"Jọọ, fi mi silẹ jare, jẹ ki n gbe aye mi, ko si mu orukọ mi kuro ni ẹnu rẹ."""
Iyabọ Ojo pẹlu bọ sori ayelujara Instagram tirẹ lati fesi si ọrọ Manija rẹ tẹlẹ naa lati fi ẹri ohun ti Adegbọla ji lọwọ rẹ han faye ri.
Ninu ọrọ to kọ, Iyabọ Ojo ni Adegbọla n ko owo ileeṣẹ Fespris Limited lọ sinu aṣuwọn ara rẹ, lẹyin to n fun awọn onibara ileeṣẹ naa ni aṣuwọn ifowopamọsi rẹ, dipo ti ileeṣẹ naa.
Gẹgẹ bi Iyabọ Ojo ṣe sọ, manija rẹ tẹlẹ naa ko da owo naa pada sinu aṣuwọn ileeṣẹ.
O ni nitori iwa ole to ni Adegbọla n hu si ileeṣẹ oun, ni oun fi ti ẹka ileeṣẹ naa mejeeji to wa lagbegbe Ikẹja nilu Eko pa, ti oun si le awọn oṣiṣẹ ibẹ pẹlu ero pe awọn lo n ja oun lole.
O ni nigba ti oun ta gbogbo dukia oun lati fi bẹrẹ ẹka ileeṣẹ naa miran ni agbegbe Lekki Phase 1, ni Manija oun yii tun tẹsiwaju pẹlu jija ileeṣẹ oun lole, ti oun si n lero pe ẹni to ṣee fi ọkan tan ni.
Iyabọ Ojo ni oun jami lori ẹjọ naa tẹlẹ nitori pe iya oun ati iya manija oun naa bẹ oun pe ki oun fiye denu, ki oun si jami lori rẹ.
Ṣé ìrìnàjò nínú ọkọ̀ Reluwé Ibadan-Lagos-Ogun tuntun bá aráàlù lára mu? Èsì rèé
Sunday Igboho: Láti ọjọ́ Ajé lọ, màá bẹ̀rẹ̀ sí ṣa agbébọn jáde nínú igbó Yorùbá
Oríṣun àwòrán, sunday_igboho1
Gbajugbaja ajafẹtọ ọmọniyan nilẹ Yoruba, Oloye Sunday Igboho tun ti ke gbajare fun awọn ọdaran darandaran lati fi ilẹ Yoruba silẹ.
Igboho kede pe bi awọn ọdaran to n paniyan naa ba kọ, oun yoo ri daju pe wọn fin wọn jade kuro ni awọn inu igbo ti wọn sa pamọ si.
Sunday Igboho fi ikilọ yii sita lasiko ifọrọwerọ to se ninu fidio kan to se pẹlu agbẹnusọ rẹ, o fikun pe oun kii kan sọrọ lasan, oun yoo sisẹ tọ ọrọ ti oun ba sọ lẹyin.
Ẹ pàdé olórin Fuji alhaji Besco tó jọ Ayinde Barrister to tún ń kọrin gẹ́lẹ́ bíi tirẹ̀
Bakan naa ni Igboho salaye pe ko si ọrọ anbojuwẹyin mọ lori idasilẹ orilẹede Yoruba, bẹẹ si ni ko si Jubita kankan to le yẹ igbesẹ naa.
O fikun pe ko si gomina kankan nilẹ Yoruba to le fi ọwọ gbaya pe ki iwọde nipa idasilẹ Yoruba Nation mase waye ni ipinlẹ toun nitori gbogbo ọmọ Yoruba lapapọ lo ni ilẹ wọn.
Sunday Igboho: 'Ǹkan tÍ Sunday Igboho Ṣe ní Ibarapa tún ti ṣelẹ̀ ní ìpínlẹ̀ Ogun'
Gbajumọ ajijagbara naa wa sekilọ fawọn ọdaran to n fi inu igbo se asọ bora lati fi ibẹ silẹ, nitori lati akoko yii lọ, oun ko fẹ gbọ pe wọn ji eeyan kankan gbe nilẹ Yoruba.
"Bawo ni eeyan miliọnu mẹfa yoo se maa dari ọmọ Naijiria yoku ti wọn to ọtalerugba o din mẹwa (250m)? Igbeyawo kii se dandan, a ko le ba yin gbe mọ.
Ọkọ igbala ni idasilẹ orilẹede Yoruba jẹ, mo si fẹ ki gbogbo ọmọ Yoruba ko wọnu rẹ, ki wọn si mu ijoko sibẹ."
Nigba to n sọrọ lori isẹ ijijagbara fun ominira ilẹ Yoruba, Sunday Igboho ni ko si ọrọ anbojuwẹyin mọ nipa rẹ.
Bawo la se fẹ pada sẹyin nigba to ku diẹ ka de ibi ta n lọ, awọn ti ko tii dara pọ mọ wa ni ki wọn se bẹẹ lasiko yii nitori ko ni si eto idibo kankan lọdun 2023. Yoruba n ya kuro lara Naijiria.
Kò sí ìgbà kankan tí Yorùbá jókòó pé ki Igboho  lọ kéde ìyapa kúrò ní Nàíjíríà
Sunday Igboho wa rọ awọn ọdọ lati dẹkun sisọ ọrọ abuku sawọn agbaagba nilẹ Yoruba, to fi mọ awọn ọba alaye wa.
"Ẹ jọwọ, ẹ mase maa pe ede ti yoo tabuku awọn agbagba tabi yaju sawọn oriade wa pe wọn ti gba owo. Ẹ ma se bẹẹ.
Koda, ti wọn ba tiẹ ti fun wọn lowo, ara ọrọ ajọni wa ti awọn kan ji ko ni.
Ẹ mase ba awọn agbofinro ja, ẹ jẹ ka se iwọde wa ni alaafia, kẹ si sọ fun aarẹ Buhari pe ti ko ba gbọ ede Yoruba, ẹ sọ fun ni ede Gẹẹsi.
Ẹ wi fun pe awa ko fẹ awọn agbebọn lẹkun wa, isẹ si ti bẹrẹ, lati ọjọ Aje lọ, maa bẹrẹ si ni lọ yika gbogbo igbo nla nla to wa nilẹ Yoruba lati le awọn agbebọn jade.
Mo fẹ ki gbogbo Fulani to wa nilẹ Yoruba ko aasa wọn. Emi funra mi ni maa tọpinpin boya wọn tẹle asẹ naa, emi kii si sọrọ lai ma sisẹ tọọ. Maa jẹwọ ara mi fun wọn, ti mo ba tun gbọ pe wọn ji ẹnikẹni gbe nilẹ Yoruba."""
Sunday Igboho fulani ultimatum: Àwọn ará Kebbi àti Zamfara ló n jínígbé ní Oke Ogun- Serik
Sunday Igboho ni oun yoo sọ fun wọn pe iyatọ wa laarin Yoruba ati darandaran nitori gbogbo awọn ohun ija ti wọn n gbe kiri ni oun yoo gba lọwọ wọn ni ẹrọ wọọrọ.
O ni awọn yoo fẹ afẹfẹ si gbogbo awọn inu igbo  to wa nilẹ Yoruba nitori ti awọn ko ba tete jẹwọ iru eeyan ti Yoruba jẹ fun awọn agbebọn naa, wọn yoo tun maa wa lati gba ilẹ nigba ti orilẹede Yoruba ba da duro.
Ajijagbara fun ilẹ Yoruba naa tun sẹ pe oun ko gba owo lọwọ ẹnikẹni gẹgẹ bi awọn eeyan kan se n sọ kiri.
Tẹ ba mọ ẹni to ba fun mi ni owo pe ki n pa ijaguru fu idasilẹ Yoruba Nation ti, ẹ jade lati sọrọ bayii. Ko si iru owo to le mu ki n dakẹ lati ja fun ominira Yoruba.
"Ẹ ko si le pa mi, ta lẹ pa? Ẹ ju bọnbu si mi abi? Tẹ ba ju bọnbu si mi, maa ran aara si yin. """
'Ọwọ́ mi ti ń jẹ́rà ká tó mọ̀ pé àfi kí wọ́n tún gé e bí mo bá ṣì fẹ́ máa ṣe iṣẹ́ awakọ̀ lọ'
Bakan naa ni Sunday Igboho ni ko si ẹnikẹni to le ji oun gbe, tori oun mọ pe awọn eeyan Yoruba nifẹ oun.
"N ko sọnu o, a ti fẹrẹ de ilẹ ileri, gbogbo awọn to n tẹle mi lọ si iwọde, aabo to daju wa fun yin. Ko si ọlọpaa to le mu yin, ẹtọ wa la n beere, ko si sẹni to le dẹru ba wa lori ilẹ baba wa.
O wa rawọ ẹbẹ silẹ Gẹẹsi ati ajọ isọkan orilẹede agbaye lati seranwọ fun ilẹ Yoruba ki afojusun wọn le jọ.
Kenneth Kaunda: Àárẹ àkọ́kọ́ ní Zambia jáde láyé lẹ́ni ọdún 97
Kenneth Kaunda, Aarẹ akọkọ ni orilẹ-ede Zambia ti jade laye lẹni ọdun mẹtadinlọgọrun.
Yatọ si pe oun ni Aarẹ akọkọ ni Zambia, o jẹ ọkan lara awọn olori nilẹ Africa to ku saye lara awọn to kọjú ija si awọn oyinbo amunisin.
Ọjọ Aje ni wọn gbe Kaunda lọ sileewosan àwọn ologun to wa ni olu ilu orilẹ-ede naa, Lusaka, nitori aisan otutu aya, pneumonia to n se e.
Awọn amugbalẹgbẹ rẹ sọ pe ko ni aarun Covid-19.
Ni nkan bi ọdun 1950, pataki ni Kaunda ko ninu ija ominira fun orilẹ-ede Northern Rhodesia (Namibia) kuro lọwọ ijọba Gẹẹsi.
O si di aarẹ lẹyin ti wọn gba ominira lọdun 1964. Ọpọlọpọ ọdún si lo fi dari orilẹ-ede naa lábẹ́ asia ẹgbẹ oṣelu United National Independence Party (UNIP).
O fi ipo silẹ lọdun 1991 lẹyin to fidi rẹmi ninu idibo gbogbogboo.
Ọmọ rẹ ọkùnrin, Kambarage, to kede iku rẹ loju opo Facebook sọ pe ẹ jẹ ki a gbadura fún""."
"Bakan naa ni aarẹ orilẹ-ede naa, Edgar Lungu sọ pe orilẹ-ede oun n ṣọ̀fọ̀ ""akọni ilẹ Africa tootọ""."
Oríṣun àwòrán, Getty Images
O kọ si oju opo Facebook rẹ pe pẹlu ibanujẹ ni oun fi gba iroyin iku rẹ.
Mo gbadura ni orúkọ gbogbo eniyan orilẹ-ede yii, ati ara mi pe ki ẹbi Kaunda ri itunu gba, bi a ṣe n daro aarẹ akọkọ ati akọni ilẹ Africa tootọ.
Kaunda- ti ọpọ mọ si KK- jẹ ọkan lara awọn to ṣe atilẹyin fun ija ominira àwọn aláwọ̀ dudu ni South Africa.
O tun satilẹyin fun wọn ni Mozambique, to ti di Zimbabwe bayii. Lẹyin ọpọlọpọ ọdún, Kaunda gbájúmọ́ igbogun ti HIV, lẹyin ti aarun Aids pa ìkan lara awọn ọmọ rẹ òkunrin, Masuzyo.
Ọwọ́ ọlọ́pàá tẹ Páṣítọ̀ tó lu ìyàwó rẹ̀ pa, tó tún sin òkú rẹ̀ sílé wọn
Oríṣun àwòrán, Akwa Ibom Police Command
Awọn ọdọ ìlú Ikot Ataku, nijọba ibilẹ Okon-Edet, nipinlẹ Akwa - Ibom kọlu ìjọ Omega World Global Ministry, lẹyin ti iroyin jade pe oludasilẹ ìjọ naa lo pa iyawo rẹ.
Ọwọ́ ileesẹ ọlọpaa ipinlẹ Akwa Ibom tẹ pasitọ naa, Ukachukwu Enoch Christopher, lẹyin ti wọn fi ẹsun kan pe o pa iyawo rẹ, to si tun sin oku rẹ sinu ọgbà ile ti wọn n gbe.
Ninu atẹjade to fi sita, agbenusọ ileesẹ ọlọpaa nipinlẹ naa, Odiko Macdon sọ pe ọjọ kẹrindinlogun, oṣu Kẹfa, ọdun 2021, ni ọwọ tẹ pasitọ, ẹni ọdun mọkandinlaadọta ọhun.
O ni bo tilẹ jẹ pe ọsẹ kan ṣaaju ọjọ naa ni iṣẹlẹ naa waye.
Awọn ọlọpaa sọ pe, èdè aiyede lo waye laarin afurasi naa ati iyawo rẹ, Arabinrin Patience Christopher, lẹyin to fi ẹsun kan obìnrin naa pe o n yan àlè, ati pe oun ni orísun ogun to n ja oun.
Ẹni ogoji ọdun ni Arabinrin Patience, to si bi ọmọ márùn-ún fun pasitọ naa.
Pasitọ naa jewọ pe fun awọn ọlọpaa pe oun lu obìnrin naa pa ni.
Alamojuto ile ti pasitọ naa n gbe, to tun ni sọọsi si, sọ fun BBC pe ọmọ rẹ ọkùnrin keji lo ke gbajare sita pe iya awọn ti di awati.
Nigba ti ẹni naa bẹrẹ iwadii lo ri iboji kekere naa ninu ọgbà ile naa.
Awọn ọlọpaa ti wu oku Patience jade, wọn si ti gbe lọ si mọsuari fun iwadii nkan to pa.
Yoruba Nation: Iléeṣẹ́ aṣọ́bodè ní títìpa ṣì ní ẹnu bodè Idi Iroko wà
Oríṣun àwòrán, Screen Shot
Se ni ibẹru bojo gba ilẹ kan ni agbegbe Idi Iroko nigba ti awọn ọdọ to n beere fun Yoruba Nation ya bo ẹnu Ibode Naijiria si Cotonou to wa nibẹ.
Awọn ọdọ yii ti wọn pọ niye ninu isẹlẹ naa to waye lọjọ Satide, gẹgẹ bi fidio kan to lu oju opo ayelujara ti safihan rẹ, ni wọn n pariwo pe awọn n fẹ idasilẹ Yoruba Nation.
Bakan naa ni wọ̀n si tun n beere pe awọn n fẹ kijọba si ẹnu ibode to ti ti pa silẹ lati ọdun 2019.
"Awọn ọdọ to n fi ẹhonu han naa, lo gbe oniruuru akọle lọwọ, lara ohun ti wọn kọ sinu akọle naa ni pe ""O to gẹẹ, iya yii ti pọ ju, A ko fẹ duro ni Naijiria mọ."""
Bakan naa ni wọn ni Orilẹede Oduduwa ni awọn n fẹ, ti wọn si n to lọwọọwọ lọ si eti ibode Naijiria si Benin, ti wọn si fi agbara si ẹnu geeti to wa nibẹ.
Tunde Gbadamosi: Kìí ṣe Tinubu ní ipò ààrẹ̀ tọ́ sí, ìgbà wo ní ìtan ajá ń kan lèmọ́mù?
Ninu fidio naa ti ko ju ogun isẹju lọ, ni wọn ti ja ibọn gba lọwọ osisẹ asọbode kan to wọ asọ alawọ yẹlo, to n ta ibọn soju afẹfẹ.
Oniruuru ohun lo n jade sita ninu fidio naa, ti wọn si n ke si awọn osisẹ ologun atawọn agbofinro mii lati jade sita wa yin ibọn mọ awọn.
"Awọn ọdọ naa ba ẹnu geeti bode naa jẹ, ti wọn si n pariwo pe ""A ti si ẹnu bode Idi Iroko, ẹyin eeyan, ẹ maa wa ba ọrọ aje yin lọ lẹnu bode naa."""
Lasiko rogbodiyan ọhun, wọn lu ọkunrin kan to n tiraka lati fi foonu rẹ ya isẹlẹ naa.
Funmi Aragbaiye: Ọlọ́run ní ohun táwọn olórí wa fẹ́ jẹ ni wọn ń wá
Ileesẹ asọbode ilẹ wa ti wa fesi pe titipa si ni ẹnu bode Idi Iroko wa, bi o tilẹ jẹ pe lootọ lawọn ọdọ kan gbiyanju lati ja geeti ibẹ.
Agbẹnusọ fun ileesẹ asọbode fun ẹkun kinni, Hammed Oloyede ni nibamu pẹlu asẹ ijọba, ko si ẹni to le si ẹnu ibode naa.
"Lootọ ni awọn ọdọ kan to pe ara wọn ni ajijagbara fun Yoruba Nation wa wa si ẹnu bode Idi Iroko lalẹ Satide amọ ọwọ ka wọn, ti wọn ko si ri bọda naa si.
Ohun gbogbo ti pada bọ sipo bayii, ko si wahala kankan mọ, awọn osisẹ wa si wa lẹnu isẹ wọn wamu-wamu,"
Penis Captivus: Àlàyé rèé lórí bí olólùfẹ́ méjì tó lẹ̀pọ̀ ṣe rí ọ̀nà àbáyọ
Oríṣun àwòrán,  Pai Robins Ogweng Akiiki/Facebook
Kii se igba akọkọ ree ti iroyin yoo maa jade lorilẹede Naijiria nipa ọkunrin ati obinrin to lẹ pọ lasiko ti wọn n se ere ifẹ.
Ọ̀pọ eeyan miran ko gbagbọ pe iru isẹlẹ yii le waye, ti wọn si maa n ro pe ejo lọwọ ninu, ati pe isẹ aye ni.
Lọtẹ yii, ọkunrin kan ni orilẹede Uganda, Pai Robins Ogweng Akiiki ti ke gbajare loju opo Facebook rẹ lọjọru nipa isẹlẹ kan to waye.
Ẹ pàdé olórin Fuji alhaji Besco tó jọ Ayinde Barrister to tún ń kọrin gẹ́lẹ́ bíi tirẹ̀
Gẹgẹ bi ọkunrin naa se wi, se ni ọrọ ọhun da bi ere itage nigba ti ọkunrin kan ha si oju ara obinrin abilekọ kan lasiko ti wọn n sere ifẹ.
Ilu kan ti wọn pe ni Gulu, to wa lẹkun ariwa orilẹede Uganda, ni isẹlẹ naa ti waye.
O kú ogun àjàyé Tope Alabi, odò Jodani lo ṣẹ̀ṣẹ̀ là kọjà yìí o! Àmọ́ rántí pé ... - Mike Bamiloye
Rahmon ń múra láti lọ rí ìyàwó àti ìbèjì tó bí ní US ni wọ́n bá pa á níbi ìjà tó bẹ́ sílẹ̀ ní Iwo road
Àwọn ọlọ́pàá máa ń yọ Baba Ijesha jáde látimọ́lé lálaalẹ́ - Princess
Olùwọ́de EndSARS bímọ tuntun nínú ẹ̀wọ̀n lẹ́yìn tó ti lo oṣù mẹ́jọ ní àhámọ́
Oríṣun àwòrán,  Pai Robins Ogweng Akiiki/Facebook
Gẹgẹ bi ẹni ti isẹlẹ naa soju rẹ, Robins Ogweng Akiiki ti wi, lẹyin ti awọn ololufẹ mejeeji yii ba ara wọn lopọ tan, lo nira fun ọkunrin lati yọ kuro luju ara obinrin naa.
O ni gbogbo igbiyanju awọn mejeeji yii lati pinya lo ja si pabo, idi si ree ti wọn se figbe bọnu ke si ara adugbo pe ki wọn wa gba awọn.
Amọ Robins salaye pe lẹyin o rẹyin ọkọ obinrin naa gbọ nipa isẹlẹ yii, to si wa si ibi ti nnkan ọkunrin miran ti ha sinu oju ara iyawo rẹ.
Ọkọ obinrin yii si lo de, to fi ọwọ si ibadi awọn mejeeji, ti awọn mejeeji si pinya, ti nnkan ọkunrin naa si yọ loju ara obinrin naa.
Ogbomoso: Ẹ kálọ sí Ajilete láti mọ àwọn ibùdó tó mú kí ìlú náà yàtọ̀
Lọwọ lọwọ bayii, awọn mejeeji ti wa ni agọ ọlọpaa, gẹgẹ bi ẹni ti isẹlẹ naa soju rẹ ti wi.
Baba Ijesha Rape Case: Yomi Fabiyi ní òun nìkàn lòun rí ara òun tó dúró tí Baba Ijesha
Ibadan Hoodlums Fracas: Ẹ̀mí OPC méjì bọ́, ọ̀kan wà ní ‘Coma’, wọn jó ọ̀pọ̀ dúkìá
Oríṣun àwòrán, Sikiru Adeyemo
Lẹyin ọjọ kansoso pere ti wahala waye ladugbo Iwo Road nilu Ibadan, eyi to mu ẹmi lọ, rogbodiyan miran tun ti bẹ silẹ nilu naa loru mọju ọjọ Ẹti.
Awọn ọmọ isọta kan ati awọn ọmọ ẹgbẹ OPC la gbọ pe wọn fija pẹẹta nidaji ọjọ Ẹti naa ladugbo inalende si Oopo Yeosa nilu Ibadan.
Koda rogbodiyan yii lo mu ẹmi lọ, ti wọn si jo awọn dukia kan nina pẹlu.
Koda, agbẹnusọ fun ileesẹ ọlọpaa ipinlẹ Oyo, Olawale Osifeso ti fidi isẹlẹ naa mulẹ, amọ ko le sọ iye ẹmi to ba laasigbo naa rin.
Bí ìjọba, ọlọ́pàá, ológun, Amotekun ò bá le gbà wá, àwa mú Wakili láti gba ìran Yorùbá sílẹ̀ ni - OPC
Nigba to n ba BBC Yoruba sọrọ lori rogbodiyan naa, oludari ẹgbẹ OPC nipinlẹ Oyo, igun ti Gani Adams, Rotimi Olumo salaye pe ni bii deede aago mejila oru ni awọn ọmọ isọta wa ka awọn mọ ọọfisi awọn.
O ni tẹlẹ tẹlẹ ni awọn ọmọ isọta naa ti maa n ja awọn eeyan lole ladugbo naa pẹlu ọbẹ, ti alẹ ba ti lẹ ni deede aago mẹwa, ti wọn yoo ja owo gba, to fi mọ foonu ati dukia mii lọwọ awọn eeyan to n rin lọ.
"Ẹni to jẹ olori OPC nibẹ ti lọ fi ẹjọ awọn ọmọ isọta yii sun ni agọ ọlọpaa to wa ni Mokola amọ ohun to fa isẹlẹ akọtun yii ni pe awọn ọmọ isọta naa lọ ji ọkada gbe loru mọju ọjọbọ.
Nigba ti ọkada naa taku lasiko ti wọn n gbe lọ, ti igbiyanju wọn lati mu ko sisẹ si ja si pabo, ni wọn ba sọ ina si, ti wọn si fi silẹ lọ.
Amọ nigba to di idaji ni wọn pada wa lati wa gbe ajoku ọkada naa, ti ọkan lara ọmọ ẹgbẹ OPC si jade si wọn pe ko fi ẹri silẹ pe ẹni to fẹ gbe  ọkada naa lo ni."
Tunde Gbadamosi: Kìí ṣe Tinubu ní ipò ààrẹ̀ tọ́ sí, ìgbà wo ní ìtan ajá ń kan lèmọ́mù?
Olumọ ni bi wahala se bẹrẹ ree o nirọlẹ Ọjọbọ, amọ awọn ọlọpaa ati Operation Burst doola isẹlẹ naa, ti ko fi di wahala.
Amọ o ni nigba to di alẹ, awọn ọmọ isọta naa pada wa lọgọọrọ, ti wọn si wa kọlu ọọfisi OPC to wa nibẹ.
Se ni wọn n yinbọn lakọlakọ mọ awọn eeyan wa, ti wọn si se wọn lese, ẹmi ọmọ ẹgbẹ wa meji lo bọ ninu laasigbo naa.
Bakan naa lo ni ẹni kẹta ti wọn se lese wa lori yooku, yoo ye, ti ko si mọ boya aye ni oun wa, abi ọrun nile iwosan ti wọn gbe lọ.
Olumọ fikun pe awọn ọmọ isọta naa tun jo ọkada kan nina, ti wọn si tun jo odidi ile kan kalẹ lasiko ti wahala naa fọn ina soju.
"Omọ isọta to lewaju awọn ọmọ isọta wa si agbegbe Oopo ni Dare Jalaruru, orukọ awọn ọmọ OPC ti wọn pa ni Akin Aluko, ti ekeji si n jẹ Quassim Omitola.
Ẹnikẹta ti wọn sa lada yanna yanna to wa ni Koma nile iwosan lo n jẹ Opeyemi.
Bakan naa ni wọn sun ile Olodo to jẹ ọmọ ẹgbẹ wa, se ni o raye sa asala fun ẹmi rẹ, bi bẹẹ kọ, ẹmi tiẹ naa ko ba ba isẹlẹ naa rin.
Tunde Bakare: Àjọjẹ kò dún bẹ́nìkan kò ní ló fa ìjà S Igboho,bẹ́ẹ̀ ìjọbati gbẹ́rù kọjá orí
Nigba to n dahun isẹlẹ yii, Rotimi Olumo ni oun ti n ba awọn ọmọ ẹgbẹ oun sọrọ pe ki wọn jẹ ki ijọba gba akoso ọrọ naa.
Emi ati ọga ọlọpaa ti sọrọ, o si ni ki n jẹ ki awọn ọmọ ẹgbẹ wa kuro nibẹ yẹn. Pẹlu idanilẹkọ taa ti fun wọn ti wọn si jẹ ọmọ ẹgbẹ to n gbọ ọrọ si ọga rẹ lẹnu."
O daju pe wọn ko ni pinnu lati gba ẹsan lori ọrọ naa amọ bi awọn ọmọ isọta yii ba tun wa pada kọlu wọn, awọn naa yoo fẹ daabo bo ara wọn.
"Mo wa n rọ awọn ọlọpaa lati lọ gba akoso agbegbe naa, ki eruku wahala ma tun pada ru lẹẹkan si."""
Olumo fikun pe titi di akoko to n ba BBC Yoruba sọrọ̀, awọn ko tii ri gbọ pe ọwọ ọlọpa tẹ ẹnikẹni lori isẹlẹ yii.
Ìtàn ayé Aposteli Timothy Obadare: Afọ́jú oníwàásù tó wo ọ̀pọ̀ sàn lọ́wọ́ àjàkálẹ̀ ìkọ́ ní Iléṣà
Oríṣun àwòrán, Facebook/apostledrtoobadare
Iwaasu Kristẹni lode oni ti kọja iwaasu itagbangba, ori redio tabi lori ẹrọ amohunmaworan.
Lori ayelujara Facebook Twitter ati Instagram, awọn oniwaasu ti n ba awọn eeyan sọrọ Ọlọrun nigbakugba.
Igbiyanju awọn oniwaasu agba to ti ṣaaju ni ilẹ Yoruba lo jẹ bi atọna fun awọn to wa gba iṣẹ naa lọwọ wọn loni.
Ninu awọn ti o fi ẹsẹ iwaasu lelẹ nilẹ Yoruba ni Aposteli Timothy Obadare wa.
Bi ẹ ba ti n gbọ gbolohun ''ogo ni fun Oluwa ni oke orun! mo tun wi leekan si pe... Ogo ni fun Oluwa ni Oke Orun...E jeki a gbadura '' ẹ o ti mọ pe Oniwaasu Timothy Obadare lo n sọrọ yẹn.
Pupọ eeyan lo jẹri sii pe Aposteeli Obadare jẹ oniwaasu to yatọ laarin awọn akẹgbẹ rẹ.
Ohun akọkọ to ṣeni ni eemọ nipa Obadare to jẹ ọmọ bibi ilu Ilesa ni pe o ni ipenija oju.
Ni soki, afọju ti ko rina rara nii ṣe.
Oríṣun àwòrán, Facebook/apostledrtoobadare
Oju ita Obadare to fọ deba lẹyin to lugbadi ajakalẹ aarun Ṣọpọnna nigba to wa lọmọdun mẹfa.
Sibẹ sibẹ, ipenija oju yi ko ni ko ma gbe nkan rere ṣe laye rẹ.
Ọdun 1953 ni Obadare bẹrẹ iṣẹ iwaasu ninu ijọ Aposteli, The  Apostolic Church of Nigeria eyi to fi tọ ipasẹ baba rẹ to jẹ Pasitọ ninu ijọ naa.
Laarin ọdun 1953-1957, o ṣiṣẹ takuntakun nipa iwaasu labẹ ijọ yi.
Mo dúpẹ́ pé ìgbà tí mo wà nínú Jesu ni mo lọ sẹ́wọ̀n, tó bá jẹ́ pé mo wà nínú áyé ni ... - Wòlìí Genesis
A tun ri ka  wipe Aposteli Joseph Ayodele Babalola lo mu Obadare wọ inu ijọ Christ Apostolic Church lọdun 1957.
Ipa ribiribi to ko ninu ijọ yi lo mu ki wn pẹka lawn orileede Afrika mii koda wọn tun pẹka de ilẹ okere.
Obadare pada ya kuro ninu ijọ naa lati lọ da ile ijọsin tirẹ silẹ to pe orukọ rẹ ni World Soul Winning Evangelistic Ministry.
Pupọ awọn iwe akọsilẹ sọ pe ọdun 1930 ni wọn bi Obadare ṣugbọn eyi taa mọ ni pe o bẹrẹ ẹkọ nileẹkọ alakọbẹrẹ Apostolic Church Primary School Ise Ilesa ṣugbọn ko pari ẹkọ nibẹ.
Ninu awọn nkan to ṣeni ni kayefi nipa Obadare ni pe ọpọ eeyan lo jẹri pe awọn ri iwosan gba lọwọ rẹ botilẹ jẹ wi pe Obadare gaan fun ara rẹ ko ribi ṣe nkankan si oju rẹ to fọ.
'Ọwọ́ mi ti ń jẹ́rà ká tó mọ̀ pé àfi kí wọ́n tún gé e bí mo bá ṣì fẹ́ máa ṣe iṣẹ́ awakọ̀ lọ'
Biba lero maa n pe sibi iwaasu ti Obadare maa n ṣe loṣooṣu ti o pe akori rẹ ni Koṣeunti eyi  to bẹrẹ si ni ṣe lọdun 1970.
Koda lori ẹrọ redio, awọn eeyan a maa sare lọ sile lati lọ gbọ iwaasu rẹ nigba naa lọhun.
Wòlíì Kasali sọrọ nípa awuyewuye pé o lè ìyàwó rẹ̀ jáde nílé
Lara awọn itan manigbagbe nipa iṣẹ iyanu ti Obadare maa n ṣe nigba naa leleyi to waye nigba to wa ni kekere.
Gẹgẹ bi a ti ṣe gbọ, Obadare gbagbọ wipe ẹmi mimọ loun le fi gbe iṣẹ Ọlọrun ga.
Nitorinaa, o sọ pe ki mama rẹ ti oun mọ inu iyara nibi to si ti bẹrẹ si ni gba awẹ kikan kikan.
"'Sister Tope Alabi yà mí lẹ́nu gan o pé ""Oniduro mi"" kìí ṣe orin tó yẹ kí ọlọ́run fún mi'"
Nigba to pe ọjọ kaarun to wa ni inu ile, Ọlọrun yọ si. Ni ọjọ Keje to jade sita, a gbọ pe taara ile ijọsin lo gba lọ.
Nibẹ lo ti ṣe iwaasu wakati mẹrin gbako lati ago mẹwaa titi di ago mejila ọsan.
Nibi iwaasu yi la ti gbọ pe eeyan ọọdunrun le ni aadọta ti ri iwosan gba lọwọ  ajakalẹ aarun ikọ to bẹ silẹ nigba taa n wi yi ni ilu Ilesa.
Oríṣun àwòrán, Facebook/apostledrtoobadare
Aposteli Obadare jẹ ilumọọka oniwaasu ti o si ṣe ọpọ irinajo nile ati lẹyin odi.
Ni ọpọ ibi to ti maa n ṣe iwaasu, Obadare a maa fi ọrọ Ọlọrun jagun pẹlu awọn ẹmi okunkun ti a si tun maa ṣe itusilẹ fawọn araalu.
Bí wọ́n ṣe ya Sinima Ayinla Omowura rèé, BBC Yorùbá  fọ̀rọ̀ wá àwọn òṣèré lẹ́nu wò
Lẹyin Aposteli Babalola, ko fẹẹ si oniwaasu ijọ Aposteli to lamilaaka bi Obadare.
Okiki ati igbagbọ tawọn eeyan ni ninu Obadare ṣebi ẹni da wahala di silẹ laarin ijọ CAC ati ijọ rẹ to pe orukọ rẹ ni WOSEM.
Ko si sẹyin bi awọn to ba ti n gbọ iwaasu rẹ ṣe maa n ri ara wọn  gẹgẹ bi ọmọ ijọ WOSEM bo ti lẹ jẹ pe abẹ asia CAC ni Obadare ti bẹrẹ.
Oríṣun àwòrán, Facebook/apostledrtoobadare
Toun ti bẹ,akọsilẹ fi han pe Obadare gba aṣẹ lọdọ awọn aṣaaju CAC ki o to da ijọ rẹ silẹ.
Nigba ti ọlọjọ  yoo fi de ni ọdun 2013, Obadare ti fi ẹsẹ iwaasu lori ẹrọ amounmaworan ati lori redio rinlẹ laarin awọn ẹlẹsin Kristẹni Naijiria.
O jade laye lẹni ọdun mẹtalelọgrin. Obadare fi iyawo kan silẹ lọ ati ọmọ mẹfa ati ọpọ ọmọọmọ.
Ẹ̀yin olórin ẹ̀mí tó ń bóra, lo èékáná gígùn, oò yàtọ̀ sí aṣẹ́wó hòtẹ́ẹ̀lì tí wọ́n ń gbé bíi súùtì Pepper Menti - Bola Are
Kunle Ologundudu: Ìdájọ́ òdodo nìkan ni mò ń bèèrè fún lórí ọ̀rọ̀ Baba Ijesa
Oríṣun àwòrán, @Kunle Ologundudu
Gbajugbaja akewi sọ̀rọ̀ sawon asebajẹ lawujọ paapaa awọn Oloselu ni, Kunle Ologundudu ti ni iku ko si loju oun bayii.
O ni asiko onikaluku yatọ ati pe asiko ti oun ko tii to rara.
Awọn ọmọ Naijiria ti n bẹnu atẹ lu awọn to gbe iroyin ẹlẹjẹ pe gbajugbaja akewi ilẹ Yoruba, Kunle Ologundudu ti kagbako iku lọwọ awọn agbebọn.
Kunle Ologundudu gẹgẹ bi iroyin naa ṣe sọ padanu ẹmi rẹ lọwọ awọn agbebọn niwaju ile rẹ nilu Eko.
Ẹni to kọkọ ke gbajare lori iroyin ofege yi ni ẹni ti ọrọ naa kan-Kunle Ologundudu.
Ọ̀rọ̀ Baba Ijesha tí mo dá sí ló mú kí àwọn tó ń bá a jà ro ikú sí mi- Ologundudu
Kí ló pa Ologundudu àti Baba Ijesha pọ̀ débi pé ìròyìn ikú rẹ̀ gborí ayélujára?
Ninu fọnran fidio kan, o ṣalaye pe ṣadede loun bẹrẹ si ni gba ipe lorisirisi tawọn eeyan si fẹ mọ pe boya lootọ lo kagbako iku.
O ṣalaye pe ọrọ naa ko ṣẹyin bi oun ti ṣe dasi ọrọ awuyewuye to niṣe pẹlu oṣere tiata Yoruba Olanrewaju James taa mọ si Baba Ijesha.
'' Nkan to ṣẹlẹ ni pe ọrọ baba Ijesha ti mo da si lo jẹ ki awọn to n ba ja fẹ maa gbe 'rumours' kiri nipa mi''
Oríṣun àwòrán, Facebook Screenshot/Femi Salako
O ni idi ti wọn fi n ṣe bẹ ni ki irẹwẹsi ọkan le de ba oun lati le ma ja fun ifi idajọ ododo lelẹ.
Ologundudu sọ pe awọn to gbe iroyin yi kaakiri lero wi pe Eko loun wa ṣugbọn oun ko si ni Eko rara.
Ologundudu ni: ''O yẹ ki a yọju sile ẹjọ lori ọrọ Baba Ijesha ṣugbọn mi o raye. Ife ni mo wa.
O ni koda, Ife ni mo wa titi di bi a ṣe n sọrọ yi''
Ninu awọn to kọ ọrọ tako iroyin yi ni Babafemi Ojudu to jẹ oludamọran pataki si aarẹ Buhari lori ọrọ oṣelu.
Ojudu bẹnu atẹ lu iwa yi to si ni iru iṣẹ iroyin kikọ bayi ko bojumu rara.
''Mo ji lowurọ oni lati ka nipa iroyin kan pe Kunle Ologundudu ti ku.Nigba ti maa fi kan si, o ni kokoko lara oun le ati pe lati ago meji oru lawọn eeyan ti n pe oun lori ago''.
Magaret Jimoh: Èrè díẹ̀ ti tó mi níbi oúnjẹ ti mò ń tà- Maggie Rice
Ojudu sọ pe awọn akọroyin ti ko kọṣẹ iroyin yi ti n da wahala sil plu agbelẹkọ iroyin wọn.
Ojudu ṣapejuwe wọn gẹgẹ bi alaburu ẹda ti wn fẹ maa da wahala silẹ lawujọ.
Tunde Bakare: Àjọjẹ kò dún bẹ́nìkan kò ní ló fa ìjà S Igboho,bẹ́ẹ̀ ìjọbati gbẹ́rù kọjá orí
Lakotan, o sọ pe pẹlu nkan to n ṣẹlẹ yi, oun ti wa gba wi pe o yẹ ki wọn fofin de iroyin ayelujara.
''O yẹ ki wọn ṣagbekal ilana bibẹẹkọ, iroyin ayederu le dana sun orileede wa''
Ìjàmbá ṣé ajínigbe tó jí akẹ́kọ̀ọ́ 156 gbé ní ìpínlẹ̀ Niger, èèyàn 15 ṣílẹkùn sá mọ́ wọ́n lọ́wọ́
Oríṣun àwòrán, AFP
Ìgbà àkọ́kọ́ kọ́ nìyí tí irú ìṣẹ̀lẹ̀ bẹ̀ yòó wáyé
Iroyin ayọ leleyi lati ipinlẹ Niger nibi ti eeyan mẹẹdogun kan ti ribi sa mọ awọn ajinigbe lọwọ.
Awọn to ribi bọ yi wa lara awọn eeyan ti wọn ji gbe papọ mọ awọn akẹkọọ mẹrindinlọgọjọ ni ile ẹkọ Salihu Tanko loṣu kaarun ọdun yi ni Tegina.
Iroyin ta ri ka ninu iwe iroyin Naijiria Daily Trust sọ pe lasiko tawọn ajinigbe yi sun lọ lawọn eeyan wọn yi rapala jade ninu ile ti wọn gbe wọn pamọ si ninu igbo.
Ki wọn baa ma ri wọn mu, niṣe ni wọn gba ọna ọtọọta sa lọ.
Ọkan lara awọn to kọkọ pada de Tegina lo ṣalaye bio wọn ṣe moribọ fun awọn araalu.
Lẹyin igba naa ni ijọba ipinlẹ Niger wa gbe igbesẹ lati ṣe itọju ati iranlọwọ fawọn to ribi jajabọ yi.
A gbọ pe ẹni yi wa ni ile iwosan nibi to ti n  gba itọju lọwọ.
Iroyin taa tun gbọ fi kun pe awọn mẹta miran to jajabọ wọ inu ilu Tegina lafẹmọju ọjọ Aiku ti ọkan lara wọn si n gba itọju lọwọ ni ilu Minna.
A ko ribi fidi rẹ mulẹ ṣugbọn wọn ni awọn mii to jajabọ ti wa ni Zaria.
Ohun taa gbọ ni pe igbo kijikiji kan ni Zamfara ni  wọn gbe awọn akẹkọọ ati awọn mii salọ si lẹyin ti wọn ji wọn gbe kuro ni Tegina.
Ṣaaju ni Gomina Niger ti kede pe awọn ribi doola ọmọ ile keu mọkanla ninu awọn ti wọn ji gbe yi.
Lati igba naa, wọn ko ti ribi doola ẹnikankan mọ titi di oni.
Enugu Police Man Shoots Five: Ọlọ́pàá yìnbọn pa èèyàn márùn ún, mẹ́rin míì ń gbà ìtọjú nílé ìwòsàn
Oríṣun àwòrán, ENUGU STATE GOVERNMENT
Gomina ipinlẹ Enugu Ifeanyi Ugwuanyi ti ṣabẹwo sawọn eeyan to farapa ninu iṣẹlẹ ti ọlọpaa ti yinbọn lu awọn araadugbo Golf Estate ni Enugu.
Eeyan mẹrin  lo n gba itọju lọwọ ni ileewosan naa ti Gomina si ti sọ pe ijọba yoo san owo itọju wọn.
Ṣaaju ni Kọmisana ọlọpaa ipinlẹ Enugu ọga ọlọpaa Mohammed Aliyu ti sọ pe ki awọn araalu ran ọlọpaa lọwọ pẹlu iroyin to le tan imọlẹ si iṣẹlẹ ọhun.
End SARS: Kemi jáde níle láti lọ bá mi ra oògùn ni mo gbọ́ pé ọlọ́pàá ti gbée- Ìyá Kemisol
Ninu atẹjade ti alukoro ileeṣẹ ọlọpaa, Daniel Ndukwe fi sita, wọn ni nkan bi ago mẹsan abọ aarọ ọjọ Aiku ni iṣẹlẹ naa waye.
Gẹgẹ bi wọn ṣe sọ, niṣe ni Inspẹkitọ ọlọpaa kan to wa ni Golf Estate ni Enugu ṣina fawọn eeyan ti eeyan marun un si ku ninu iṣẹlẹ yi.
Awọn mẹrin miran to farapa wa ni ile iwosan ilẹ ẹkọṣẹ iṣegun fasiti Enugu, ESUT.
Oríṣun àwòrán, Enugu state government
Ọga ọlọpaa ṣalaye pe awọn ti mu ọlọpaa naa ti o si ti wa ni ahamọ titi tawọn yoo fi pari iwadii.
Wọn ko darukọ ọlọpaa ti ọrọ yi kan tabi ohun to ṣẹlẹ to fi yinbọn lu awọn eeyan.
Oyo State Security Governing Board: Makinde se ìfilọ́lẹ̀ ìgbìmọ̀ àlákòóso Amọtẹkun ó pè fún ìfọ̀wọ́sowọ́pọ̀ aráàlú
Oríṣun àwòrán, OfficialSeyiMakinde
Gomina  ipinlẹ Oyo Seyi Makinde ni ijọba ipinlẹ Oyo yoo ṣiṣọ loju awọn ilana kan lati le koju ipenija aabo to ba ipinlẹ naa.
Lasiko to ṣe ifilọlẹ igbimọ akoso aabo ati igbimọ alakoso ikọ alaabọ Amọtẹkun lo fi ọrọ yi lede.
Lẹnu ọjọ mẹta yi, ipinlẹ Oyo n koju ipenija aabo orisirisi ti o si mu ki awọn eeyan kan maa sọ pe Makinde ko ṣojuṣe rẹ nipa pipese aabo to peye fara ilu.
Gomina Makinde sọ pe pẹlu ifilọlẹ igbimọ wọnyi, araalu yoo ri apẹrẹ wipe ijọba oun n gbe igbesẹ lati mu adinku ba ipenija aabo to koju Oyo.
O ni bẹẹ naa ni ibaṣepọ to mọyan lori yoo waye laarin awọn ikọ ati ileesẹ alaabo eyi ti yoo mu ki aabọ to peye wa lagbegbe naa.
Makinde tun wa parọwa si awọn eekan oṣelu lati yago fun lilo ipenija aabo to n koju Oyo fun ifẹ inu ara wọn.
Oríṣun àwòrán, OfficialSeyiMakinde
O wa rọ awọn araalu lati pawọpọ pẹlu awọn ẹṣọ alaabo lati jẹ ki aabo to jọju wa ni ipinlẹ Oyo.
Ajagunfẹyinti Brigadier General Kunle Togun ni yoo maa jẹ alaga igbimọ alakoso  ẹlẹnimejila Amọtẹkun ọhun.
Life saver car: Ọkọ̀ ayọ́kẹ́lẹ́ yì ti gba ẹ̀mí ọ̀pọ̀ aláboyún àtọmọ ọwọ́ lá ní Jigawa
Igbimọ yi yoo tun ni awọn aṣoju kọọkan lati ileeṣẹ aabo ijọba apapọ,aṣoju kọọkan lati ẹkun idibo mẹtẹtaa.
Bakan naa ni Onpetu ilu Ijero, Oba Sunday Oyediran yoo jẹ aṣoju awọn lọbalọba ninu igbimọ naa.
End SARS: Kemi jáde níle láti lọ bá mi ra oògùn ni mo gbọ́ pé ọlọ́pàá ti gbée- Ìyá Kemisol
Nigeria Twitter Ban: Mínísítà Lai Mohammed fí ìkìlọ tuntun síta lórí àwọn ọmọ Nàìjíríà tó n ló VPN
Minisita feto iroyin lorileede Naijiria Lai Mohammed tun ti da si ọrọ to gbode nipa iwọgile Twitter ni Naijiria.
Eyi to sọ laipẹ yi nii ṣe pẹlu ọrọ lilo VPN to jẹ ọna ẹburu tawọn ọmọ Naijiria fi n lo Twitter lati igba ti ijọba ti fofin de lilo rẹ.
Minisita Lai ṣe ọrọ naa bi ikilọ pe kawọn ọmọ Naijiria jawọ nibi lilo VPN.
"O fi ọrọ yii lede lasiko to n dahun ibeere niwaju igbimọ ile aṣojuṣofin orileede Naijiria eyi to n gbẹjọ lori aṣẹ ""ma lo Twitter"" ti ijọba gbe kalẹ."
Lai Mohammed sọ pe''amọran mi si ẹnikẹni to baa n lo VPN  ni pe ko jawọ nibẹ. Idi ni pe bi o ba lo VPN yoo tu gbogbo aṣiri data yin to fi mọ akoto akanti ifowopamọ yin''.
O ṣalaye pe ''awọn to ba ro wi pe awọn n ṣe Lai Mohammed nipa lilo VPN, ara wọn ni wọn n ṣe''.
Oríṣun àwòrán, others
Aarẹ Naijiria, Muhammadu Buhari ati oludasilẹ Twitter, Jack Dorsey
Ajọ Ecowas ti ka ijọba Naijiria lọwọ ko pe ko gbọdọ fi ofin gbe ẹnikẹni tabi fi iya jẹ wọn nitori pe wọn lo ayeljuara Twitter ni Naijiria.
Ileeṣẹ ẹjọ Ecowas to wa ni Abuja lo pa aṣẹ na lasiko igbẹjọ akọkọ to waye lori ofin to de ayelujara naa lati ọjọ kẹrin, oṣu Kẹfa.
Aṣẹ yii waye lẹyin ti awọn ẹlẹgbẹjkgbẹ kan pe ẹjọ pe ọna lati fi ofin de ominira ọrọ sisọ ni igbesẹ ijọba bo sẹ fi ofin de lilo Twiter.
Ile ẹjọ na sọ pe anfaani  araalu ni si Twitter mu ki o rọrun fun wọn lati le ma sọ ọrọ pẹlu ominira  - ti igbesẹ to ba tako eyi si tumọ si titẹ ẹtọ ọmọniyan loju.
Ẹgbẹ to n ja fun akoyawọ nidi ọrọ aje, Socio-Economic Rights and Accountability Project, SERAP, ati awọn ọmọ Naijiria bi 170 lo pawọpọ , to si lọ si ile ẹjọ naa pe ko paṣẹ pe titẹ ẹtọ ọmọniyan loju ni igbesẹ ijọba Naijiria lori ọrọ Twitter, tumọ si labẹ ofin agbaye.
Kò sí ẹni tí mo fura sí lórí ikú ọkọ mi, àmọ́..- Adebisi aya Titus Ejanla tí wọ́n pa ní Ib
Ijọba fi ofin de lilo oju opo ayelujara Twitter lẹyin ti oju opo naa pa ọrọ kan ti Aarẹ Muhammadu Buhari kọ sibẹ, nitori pe o tako ilana lilo oju opo naa.
Nibi igbẹjọ naa to waye lori ayelujara ni ọjọ Iṣẹgun, agbẹjọro agba to tun jẹ ajafẹtọ ọmọniyan, Femi Falana, to ṣoju awọn ẹlẹgbẹjẹgbẹ naa bẹ ile ẹjọ naa lati fi ofin de ijọba Naijiria pe ko ma mu ẹnikẹni tabi fi iya jẹ wọn labẹ ofin nitoir pe wọn lo Twitter.
End SARS: Kemi jáde níle láti lọ bá mi ra oògùn ni mo gbọ́ pé ọlọ́pàá ti gbée- Ìyá Kemisol
Aawọ laarin orileede Naijiria ati ileeṣẹ ibaraẹnisọrọ oju opo ayelujara Twitter ṣeeṣe ko ni iyanju lai pẹ yi.
Idi ni pe aarẹ Muhammadu  Buhari ti buwọlu ki ijọba Naijiria jiroro pẹlu ileeṣẹ naa.
Ọrọ yi jẹyọ ninu atẹjade kan ti Minisita eto ibaraẹnisọrọ Lai Mohammed fi sita lọjọ Iṣẹgun.
Gẹgẹ bi Segun Adeyemi to n gbẹnusọ fun Minisita Lai ti ṣe sọ, Lai Mohammed ni yoo dari ikọ Naijiria ti yoo jiroro pẹlu Twitter.
Awọn eeyan miran ti yoo kọwọrin pẹlu Minisita lati jiroro ni agbẹjọro agba Naijiria Abubakar Malami, Minista feto ẹrọ ibaraẹnisọrọ ati eto ọrọ ajẹ ayelujara,Issa Ali Pantami.
Fulani attack, Ajowa Ondo: Àwọn Bororo yìí ti kọ́kọ́ ń dàná ní Ajọwa tẹ́lẹ̀, ọmọ mi 5 di
Bẹẹ naa ni Minisita fọr ilẹ okere ati Minisita fọrọ iṣẹ ile ati oju ọna Babatunde Fashola yoo pẹlu igbimọ yi.
Segun Adeyemi fi kun ọrọ rẹ ninu atẹjade naa pe Twitter lo bveere fun ijiroro pẹlu ijọba Naijiria.
Bi a ko ba gbagbe, ijọba Naijiria ti ṣaaju fofin de lilo Twitter nilẹ naa lẹyin ti oju opo naa yọ ọrọ ti aarẹ Buhari kọ.
Alaye ti ijọba ṣe lori igbesẹ yi ni pe iṣẹ Twitter le ṣe akoba fun igbe aaye alaafia ni Naijiria.
End SARS: Kemi jáde níle láti lọ bá mi ra oògùn ni mo gbọ́ pé ọlọ́pàá ti gbée- Ìyá Kemisol
$500, 000 bribe: Farouk Lawan gbà ìdájọ ẹ̀wọ̀n ọdún méje lẹ́yìn ọdún mẹ́sán án tí ẹjọ́ tí wà níwájú adájọ
Farouk Lawan
Ile ẹjọ giga ni olu ilu Naijiria, Abuja ti dajọ ẹwọn ọdun meje fun aṣofin tẹlẹ ri Farouk Lawan.
Idajọ yi ko si ṣẹyin ẹsun pe o fi ipo rẹ gẹgẹ bi alaga igbimọ ile to n ṣe iwadii lori ọrọ ẹkunwo epo rọbi labẹ ijọba igba naa ko owo jẹ.
Adajọ Angela Otaluka fi idajọ yi lelẹ lọjọ Iṣẹgun lẹyin to gbọ awijare gbogbo awọn tọrọ kan ninu ẹjọ naa.
Adajọ sọ pe kii ṣe ọrọ pe wọn fura si Lawan ni ẹjọ to wa nilẹ yi bi kii ṣe pe o  beere fun abẹtẹlẹ miliọnu dọla mẹta to si gba  ẹgbẹrun lọna ẹẹdẹgbẹta dọla.
O ni eronja iwa ajẹbanu n bẹẹ ninu ihuwasi Farouk eyi to han gbangba nitori ko sọ fun awọn agbofinro pe eeyan kan fẹ fi owo wa oju ire lọdọ rẹ.
Ṣaaju ni idajọ fọwọ da awijare ti Farouk mu wa pe ẹjọ naa ti gba asiko pupọ debi pe wọn n gbẹjọ naa fun ọdun mẹsan.
Ajọ to n gbogun ti iwa ajbanu ICPC lo wọ Lawan lọ si ile ẹjọ lẹyin ti fọnran fidio lu sita nibi to ti n gba owo abẹtẹlẹ lọwọ oniṣowo Femi Otedola.
Iwadii Lawan bẹrẹ lọdun 2012 lẹyin ti wọn fi ẹsun kan an wipe o lo ipo rẹ gẹgẹ bi alaga igbimọ iwadii ajẹbanu lori ọrọ kunwo owo epo rọbi ni Naijiria.
Ajẹbanu yi la gbọ nigba naa pe o wọ biliọnu dọla mẹfa.
Lasiko iwadii yi ni wọn fẹsun kan Lawan pe o f gba abẹtẹlẹ miliọnu mẹta dọla lọwọ gbajugbaja olokoowo Femi Otedola.
Iskilu Wakili: Móríyá ní bí iléẹjọ́ ṣe tú àwọn OPC mẹ́tà sílẹ̀ lẹ́yìn tí wọ́n mú Iskilu Wakili tí wọ́n fẹ̀sùn ìwà ọ̀daràn kàn
Oríṣun àwòrán, Others
Adari ẹgbẹ OPC ni ipinlẹ Ọyọ, Rotimi Olumo ti gboriyin fun idajọ otitọ lori awọn ọmọ ẹgbẹ OPC mẹta ti ileeṣẹ ọlọpaa fi si ọgba ẹwọn lati osu mẹta ṣẹyin.
Olumọ to ba BBC News Yoruba sọrọ ni inu awọn dun nitori awọn ọmọ mẹtẹẹta naa n ja fun ilẹ baba wọn ni.
O ni Iskilu Wakili to n ba ilu Ibarapa jẹ pẹlu ọpọlọpọ aṣẹmaṣẹ ti awọn ọmọ ẹgbẹ OPC si fi ẹmi wọn lele ni wọn wa fi si ẹwọn fun oṣu mẹta.
Olumo ni: ''Ati ọlọpaa, soja, Amotẹkun ko si ẹni to ri Wakili mu, awọn ọmọ wọnyii ni wọn ja fitafita fun ilẹ Yoruba.''
''Lẹyin iṣẹlẹ yii ni awọn ọmọ Wakili ati awọn ọmọ Seriki Fulani Igangan pada lọ si ibẹ ti wọn si pa awọn eniyan, to si tun jo ile ọba Igangan pẹlu''.
Peter Fatomilola: Robbery burú ju Yahoo lọ, iṣẹ́ ọpọlọ lọmọ Yahoo fi ń gba owó ìran baba
Adari ẹgbẹ OPC ni ipinlẹ Ọyọ ni Ọjọ Keje, Osu Kẹta, ọdun 2021 ni iṣẹlẹ naa waye ti awọn ọmọ ẹgbẹ OPC fa Wakili le awọn agbofinro ọwọ ni Igbora.
''Ohun ti awọn ọlọpaa sọ fun awọn ọmọ ẹgbẹ OPC naa ni wi pe ki wọn tẹle wọn lọ si olu ileeṣẹ wọn ni Eleyele, Ibadan lati bere ọrọ lọwọ wọn'
'Bi wọnm ṣe fi wọn si atimọle niyen pe eniyan kan ku lasiko rogbodiyan naa, ati wi pe ki wọn wa wi ti ẹnu wọn.'
End SARS: Kemi jáde níle láti lọ bá mi ra oògùn ni mo gbọ́ pé ọlọ́pàá ti gbée- Ìyá Kemisol
'Amọ lẹyin naa wọn tu wọn silẹ ti wọn si gba oniduro wọn nitori ilera ara wọn.'
'Lẹyin ọṣẹ kan ni Kọmiṣọnna ọlọpaa pe ki awọn mẹtẹẹta yoju si wọn nitori wọn ni ibeere fun wọn, amọ lati igba naa ni wọn ti fi wọn si atimọle ni Kọmiṣọnna ọlọpaa si ni o ju agbara ohun lọ lati da wọn silẹ.'
Osu mẹta ni awọn ọmọ ẹgbẹ OPC mẹta naa lo ni ọgba ẹwọn nitori pe wọn mu Wakiti to n hu iwa buruku lagbegbe naa, ti awọn ọmọ rẹ si da ibọn bo wọn lasiko ti wọn lo koju rẹ ni Ibarapa.'
Oríṣun àwòrán, OTHERS
Ẹgbẹ OPC ni ohun to dun awọn julọ ni wi pe awọn lọbalọba kẹyin si awọn nigba ti awọn nilo wọn ju, paapaa awọn ọba Ibarapa mejeeje.
Oluomo ni awọn lọbalọba ni ilẹ Yoruba yẹ ki wọn ke sita lori awọn ọmọ ẹgbẹ OPC ti wọn ti mọle naa nitori awọn ọmọ Yoruba ni wọn n ja fun.
O fikun wi pe awọn ọba yii ma nitori owo osu ti wọn gba lọwọ ijọba ki wọn wa dakẹ lai ṣe ohunkohun si ọrọ eto aabo to dẹnukọlẹ ni ilẹ Yoruba.
'O yẹ ki awọn ọba sọrọ soke pe iṣẹ ilu ni wọn ṣe, wọn da nkankan ṣe fun ara wọn'.
Fulani attack, Ajowa Ondo: Àwọn Bororo yìí ti kọ́kọ́ ń dàná ní Ajọwa tẹ́lẹ̀, ọmọ mi 5 di
'Amọ ki wọn ranti wi pe awọn to le jo aafin ọba Igangan le e ṣekọlu si ẹnikẹni ni ilẹ Yoruba lai wo ti ade ori wọn'
Bakan naa ni ẹgbẹ OPC fikun pe awọn mẹta ti wọn fi silẹ naa ti bẹrẹ si ni gba iwosan to tọ lati igba ti wọn ti gba ominira kuro ni ọgba ẹwọn naa.
Oríṣun àwòrán, Others
Ileẹjọ Magisreti to wa nilu Ibadan nipinlẹ Oyo ti paṣẹ ki wọn tu awọn ọmọ ẹgbẹ OPC mẹta to wa ni ikawọ ọlọpaa silẹ ni kiakia.
Awọn ọmọ ẹgbẹ OPC mẹta naa ni ileeṣẹ ọlọpaa ti mọle lori ẹsun wi pe wọn mu Wakili ti awọn ara Ibarapa ni ipinlẹ Ọyọ fi ẹsun ifipabanilopọ, ijinigbe ati ipaniyan kan.
Awọn mẹtẹẹta naa ti orukọ wọn n jẹ Dauda Kazeem, Awodele Adedigba ati Ramon Hasan ni awọn ọlọpaa ti mọlẹ ni Oṣu Kẹta ọdun yii lẹyin ti wọn tẹ Wakili.
Ẹsun ti ileeṣẹ ọlọpaa fi kan wọn ni wi pe wọn da ina sun ile Wakili, ti ẹmi obinrin kan si lọ si iṣẹlẹ naa
Awọn ọmọ ẹgbẹ OPC wọnyii ni wọn fa Wakili le ọlọpaa ipinlẹ Ọyọ lọwọ, ki ọlọpaa to ṣẹṣẹ wa ti wọn mọle ti wọn si gbe wọn lọ si ileẹjọ.
Kò sí ẹni tí mo fura sí lórí ikú ọkọ mi, àmọ́..- Adebisi aya Titus Ejanla tí wọ́n pa ní Ib
Lasiko ti iṣẹlẹ naa waye ni awọn ọmọ Naijiria bu ẹnu atẹ lu igbeṣẹ ileeṣẹ ọlọpaa ti wọn fẹsun kan pe wọn ti awọn to mu Wakili wa fun ọlọpaa mọle.
Amọ ileẹjọ ni Ọjọ Iṣẹgun paṣẹ wi pe ki wọn fi wọn silẹ, ki wọn ma a lọ ni alaafia, lẹyin ti ileejọ sọ wi pe ko si aridaju kankan lori ẹsun ti wọn fi kan awọn mẹtẹẹta ọhun.
Ẹwẹ, lasiko ti wọn ti awọn ọmọ ẹgbẹ OPC ohun mole ni Aarẹ Onakakanfo ilẹ Yoruba, Iba Gani Adams bu ẹnu atẹ lu bi ileeṣẹ ọlọpaa ṣe ju awọn ọmọ ẹgbẹ OPC to wa labẹ rẹ si atimọle.
Gani Adams ni iranwọ lasan ni awọn OPC ṣe fun ileeṣẹ ọlọpaa lori ati wa ojutu si eto abo to mẹhẹ kaakiri ipinlẹ Oyo.
Gani Adams ṣalaye ọdaran pọnbele ni Wakili, o ni o kan n dibọn lasan ni fawọn ọlọpaa.
Osu mẹta gbako ni awọn mẹtẹẹta lo ni atimole ki ileẹjọ to ṣẹṣẹ tu wọn silẹ lati ma a lọ ni alaafia nitori wọn ko jẹbi ẹsun kankan.
End SARS: Kemi jáde níle láti lọ bá mi ra oògùn ni mo gbọ́ pé ọlọ́pàá ti gbée- Ìyá Kemisol
Ibadan Chief kidnap: Báyìí nì géńdé agbébọn ṣé na'wọ gán Olóyè Tafa àti ìyàwó rẹ́ lásìkò wẹli-wẹli òjò
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Awọn agbebọn tẹnikan ko mọ ti gbe Baalẹ kan ati aya rẹ nilu Ararọmi to n bẹ ni agbegbe Bakatari nilu Ibadan, olu ilu ipinlẹ Ọyọ.
Iroyin sọ wi pe awọn agbebọn naa yawọ ilu Ararọmi ni Bakatari lalẹ ọjọ Iṣẹgun wọn si gbe Baalẹ, Oloye Tafa Apanpa  ati aya rẹ lọ.
Bakatari ti o jẹ ọkan lara awọn ilu to n bẹ ni ijọba ibilẹ Ido wa ni opopona marosẹ Ibadan si Abẹokuta.
Bakan naa lo jẹ ilu to paala laarin ipinlẹ Ogun ati Ọyọ.
Alaye ti awọn olugbe agbegbe naa ṣe ni pe ijinigbe Baalẹ ati aya rẹ waye lalẹ l'ọjọ Iṣẹgun ninu wẹliwẹli ojo to rọ n'Ibadan.
Peter Fatomilola: Robbery burú ju Yahoo lọ, iṣẹ́ ọpọlọ lọmọ Yahoo fi ń gba owó ìran baba
Bakan naa ni wọn fi kun ọrọ wọn wi pe ko si ẹni to mọ ibi ti Oloye naa ati aya  rẹ wa titi di asiko yii.
Kò sí ẹni tí mo fura sí lórí ikú ọkọ mi, àmọ́..- Adebisi aya Titus Ejanla tí wọ́n pa ní Ib
Agbẹnusọ ileeṣẹ ọlọpaa nipinlẹ Ọyọ, Adewale Osifeso fi idi iṣẹlẹ naa mulẹ.
O ni awọn agbofinro ti bẹrẹ iṣẹ iwadi lori ọrọ naa.
Fulani attack, Ajowa Ondo: Àwọn Bororo yìí ti kọ́kọ́ ń dàná ní Ajọwa tẹ́lẹ̀, ọmọ mi 5 di
Bí ó bá ṣè ẹbọ ló gbà, ẹ fín-in kí àlááfíà lè j'ọba ní Oyo- Makinde sọ f'áwọn ẹlẹ́sìn àbáláyé
Oríṣun àwòrán, FACEBOOK/SEYI MAKINDE
Ijọba ipinlẹ Ọyọ ati apapọ ẹgbẹ awọn ẹlẹsin abalaye nipinlẹ naa ti fohunṣọkan lati ṣe amulo agbara iṣẹmbaye lojuna ati fopin si iṣoro eto aabo.Igbesẹ naa jẹ ọkan lara awọn abajade apẹro lori eto aabo ati ibaraẹni gbe ninu alafia to waye l'Ọjọru ni ẹka ileeṣẹ iroyin, aṣa ati irinajo igbafẹ nilu Ibadan.
Kọmisana fun iroyin, aṣa ati irinajo igbafẹ Ọmọwe Wasiu Ọlatunbọsun lo ṣe agbekale ipade naa lorukọ ijọba ipinlẹ Ọyọ.
Oba Sunday Oyediran ṣàlàyé kíkún nípa ìṣẹ̀ṣe, ìgbàgbọ́ àti ẹ̀sìn tí kò dí ará wọn lọ́wọ́
Olatunbosun fi  ayọ ijọba han lori atilẹyin ti awọn ẹlẹsin abalaye n ṣe fun Gomina ipinlẹ Ọyọ lati igba ti o ti gun ori aleefa.
Ọlatunbọsun kede rẹ pe ijọba Ṣeyi Makinde ti gbe igbesẹ lati fun awọn ẹlẹsin abalaye ni ọjọ ti wọn a maa gba isinmi lẹnu iṣẹ gẹgẹ bi awọn ẹlẹsin to ku lati ṣe ọdun wọn.
O ni ilana ofin ati awọn igbesẹ kọọkan lo n ṣe idaduro fun ikede ọjọ naa.
Kọmisana naa kesi awọn ẹlẹsin abalaye naa lati sa gbogbo ipa wọn tofimọ ẹbọ riru ki alafia le jọba nipinlẹ Ọyọ.
"O fi kun ọrọ rẹ wi pe ""a ni lati pada si ilana ti awọn babanla wa fi n yanju iṣoro eto aabo nigba iwasẹ, ki ipinlẹ Ọyọ le tuba ki o si tuṣẹ""."
Peter Fatomilola: Robbery burú ju Yahoo lọ, iṣẹ́ ọpọlọ lọmọ Yahoo fi ń gba owó ìran baba
Oluranlọwọ pataki fun Gomina Ṣeyi Makinde lori iṣakoso, Ẹniọwọ Idowu Ogedengbe to ba wọn pejupesẹ sibi ipade naa kesi awọn ẹlẹsin abalaye lati tẹsiwaju ninu ṣiṣe atilẹyin fun ijọba to n bẹ lode ki iṣẹ idagbasoke le tẹsiwaju.
Aare Isẹṣẹ ipinlẹ Ọyọ, Aare Omikunmi Egbelade, Alaga Aṣa Oriṣa ilẹ Naijiria, Oloye Oke Adejare ati Oba Ela ipinlẹ Ọyọ, Oba Ojebode Awoniran ke si ijọba lati gbe owo kalẹ fun awọn ẹlẹsin mẹta gboogi to n bẹ nipinlẹ Ọyọ fun akanṣe eto adura ati irubọ.
Oríṣun àwòrán, facebook/seyi makinde
Ẹwẹ, bakan naa ni ijọba ṣe ipade pẹlu awọn aṣoju eleegun lori ibara ẹni gbe ninu alaafia ti ijọba Gomina Ṣeyi Makinde n fọn rere rẹ.
Kò sí ẹni tí mo fura sí lórí ikú ọkọ mi, àmọ́..- Adebisi aya Titus Ejanla tí wọ́n pa ní Ib
Baba Ijesha: Iyabo Ojo rí mí fín lórí ọ̀rọ̀ Baba Ijesha, ó pa fóónú mọ́ mí lẹ́nù
Gbajugbaja Oṣere ni Naijiria, Deji Aderemi ti ọpọ eniyan mọ si Ọlọfaina ti bẹ Iyabo Ojo ati awọn miran ti ọrọ kan pe ki wọn dariji Baba Ijesha lori ọrọ ifipabanilopọ ti wọn fi kan an.
Olofaina sọ bẹẹ lasiko to n ba BBC Yoruba sọrọ ni ileẹjọ ti igbẹjọ Baba Ijesha tio waye ni Ọjọbọ.
O ni iru eyi ko ṣẹlẹ ri ni agbo oṣere ki wọn ma a gbe ara wọn lọ si ileẹjọ.
Gbajugbaja oṣere naa fikun wi pe igbiyanju oun lati ba Iyabo Ojo sọrọ lori iṣẹlẹ naa lo jasi pabo, to si sọ fun oun pe ki oun bọ silẹ nibẹ gẹgẹ bi esi to fun oun, ko to di wi pe o pa foonu mọ oun lẹnu.
Bakan naa ni lo fikun pe oun wa lati ilu Ede,nipinlẹ Osun wa si ileẹjọ lati le wo bi ọrọ naa ma jasi.
Ati wi pe ẹgbẹ ti ṣetan lati ba awọn ti ọrọ naa kan wi, amọ ki wọn parapọ jẹ ọkan.
751 unmarked graves found: Bí wọ́n ṣe rí ọ̀pọ̀ sàárè okú nínú ọ̀gbá iléẹ̀kọ́ agbo ilé kan
Oríṣun àwòrán, Reuters
Awọn eeyan ko bata ọmọde jọ lati daro ati lati ṣeranti awọn to ku
Ilu iṣẹmbaye kan ni wọn ti ṣawari awọn saare oku to le ni ẹẹdẹgbẹta abọ ni ori ilẹ ileewe agbo ile Saskatchewan ni Canada.
Ajọ First Nation to nlo awọn darandaran ni Canada ni ohun tuntun yii jẹ eyi ti wọn ṣẹṣẹ gbọ titi di akoko yoo ni Canada.
Eyi ṣẹlẹ lẹyin ti wọn tun ṣẹṣẹ ri oku akẹkọọ igba le mẹẹdogun niru ileewe agbole yii ni Columbia.
"Iná sọọ! Àwọn ọmọdé tó ń kọ́ ìjà ààbò ara ẹni ""Kongfu jó ráúráú"
"Ẹ gbà wa o! Ìwé ìrìnà àti ìwé ìgbélùú wa ní Oman ti ""expire"", wọ́n tún ní Nàìjíríà ti di ibi àìwọ̀"
Ọ̀rọ̀ wo ni Sheikh Gumi sọ tí iléeṣẹ́ ọ̀tẹlẹ̀múyẹ́ DSS ní kó wá ṣàlàyé ara rẹ̀?===
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Sàárè òkú 750 dédé wú jádé níléẹ̀kọ́ agbo-ilé kan, ìlú dàrú!
Ileẹ̀kọ́ Marieval India Residential School ti wọn ti ṣaadede ṣawari awọn iboji oku yii ti wa lati ọdun 1899 titi di 1997 ti wọn ti wa gbe e lọ si ibudo mii ni apa Guusu- Ila Oorun Saskatchewan.
O jẹ ọkan lara awọn ileẹ̀kọ́ to le ni aadoje ti wọn n gbe nibẹ eyi ti ijọba Canada atawọn adari ẹsin pọn ni dandan ni ọọdunrun kọkandinlogun ati ogun tori eredi ati fa awọn ọdọ ilu mọ ile.
Oríṣun àwòrán, Tobias Titz
O to ẹgbẹrun mẹfa ọmọ ileẹ̀kọ́ to ku lasiko ti wọn n lọ awọn ileẹ̀kọ̀ ọhun tori idoju kọ ilera ninu ileẹ̀kọ̀ naa, ọpọ igba ni wọn n ko awọn ọmọ sinu ile ti wọn o kọ daadaa
Bẹẹ, ile naa ti oru gbigbona n ṣe hi-hii ati awọn nkan eelo to kun fun idọti.
Ko tan sibẹ, fifi lilu ati ilọkulọ ibalopọ lọ awọn ọmọ ọlọmọ lo mu ki awọn to ku sa mọ awọn to n dari ileẹ̀kọ́ to fẹ ba wọn lopọ lọwọ.
Fulani attack, Ajowa Ondo: Àwọn Bororo yìí ti kọ́kọ́ ń dàná ní Ajọwa tẹ́lẹ̀, ọmọ mi 5 di
Wọn jẹ ki a ro pe a ko ni ẹmi rara, ọkan lara awọn akẹkọọ to moribọ, Florence Sparvier sọ fun awọn oniroyin l'Ọjọbọ.
Wọn n tẹ wa ri gẹgẹ bi eniyan torinaa a kọ ẹkọ lati ma naani tabi fẹran ara wa.
Peter Fatomilola: Robbery burú ju Yahoo lọ, iṣẹ́ ọpọlọ lọmọ Yahoo fi ń gba owó ìran baba
Loṣu to kọja ni awọn darandaran bẹrẹ si ni lo awọn ohun elo to lee f ilẹ tutu lati fi wa awọn saare ti ko si nigboro ilu yii jade ni Saskatchewan.
"Awọn darandaran naa ṣe apejuwe awari tuntun yii gẹgẹ bi eyi to ba ni lẹru jọjọ to si ja ni laya""."
Kò sí ẹni tí mo fura sí lórí ikú ọkọ mi, àmọ́..- Adebisi aya Titus Ejanla tí wọ́n pa ní Ib
Perry Bellagarde to jẹ oloye agba ile aṣofin wọn ṣapejuwe awari ti wọn ṣee yii gẹgẹ eyi to ba ni lẹru ṣugbọn o ni ko ya oun lẹnu.
Mo ro gbogbo ara Canada lati gbaruku ti ajọ First Nation lasiko ti wọn n koju eyi.
Laarin ọdun 1863 ati 1998, o le ni ẹgbẹrun lọna ogoje ọmọ ilu ti wọn gba lọwọ awọn obi wọn lati ko lọ si awọn ileẹ̀kọ́ naa.
Alhaja Rukayat Batimoluwasi Oniwaka: Orin Wákà la fi ń ṣe Wáàsí, o tó ọdún 70 tí mo tí bẹ̀
Wọn kii saba jẹ ki awọn ọmọ naa sọ ede abinibi wọn tabi dan aṣa wọn wo, ti wọn si n fiya ati ipa jẹ ọpọ ninu wọn.
Akọsilẹ wa fihan lọ̀dun 2008 pe ọpọ awọn ọmọ ni ko pada sọdọ obi wọn tabi ilu wọn.
Fidelis Nweze: Ìjọba ìpínlẹ̀ Ebonyi ní kó sí ootọ nínú ìròyìn pé Kọmísọ̀nàa jíndé
Oríṣun àwòrán, Francis Nwaze
Kọmisana ti awọn eeyan ipinlẹ Ebonyi n yọ pe o ji dide, ijọba ipinlẹ naa sọ pe ko ri bẹẹ.
Niṣe ni ero pọ pitimu ni ile Kọmisana Fidelis Nweze l'Ọjọbọ tawọn eeyan si n fi orin ọpẹ bẹnu pe o ti jinde.
Lọjọ Abamẹta ni ijọba kede pe o jade laye lẹyin ijamba ọkọ kan lọjọ Kọkandinlogun oṣu Kẹfa.
Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo
Ṣaaju iku rẹ, oun ni Kọmisana feto idagbasoke ilu.
Nigba ti akọroyin wa yoo fi de ile rẹ loni, niṣe lawọn eeyan n jo ti wọn si n yọ pe ko ku mọ.
Amọ Fidelis ti wọn gbe digbadigba lọ si ile iwosan Turkish Hospital ni Abuja lọjọ to kan agbako ijamba ọkọ ko si ni ile rẹ bayi.
Laarin oru Ọjọbọ lawọn eeyan gbọ pe o ti jinde ti wọn si fi ijo ati orin ọpẹ bẹnu.
Titi di baa ṣe n sọrọ yii ko sẹni to le sọ pe awọn rii laaye.
Ijọba ipinlẹ Ebonyi ti fesi si iṣẹlẹ yi lasiko ti BBC ba wọn sọrọ.
Agbẹnusọ Gomina David Umahi ṣapejuwe Kọmisana naa gẹgẹ bi ọkan lara awọn Kọmisana to kaju osunwọn ninu ijọba.
O ni awọn ti ṣaaju fi atẹjade kan sita lori iku rẹ koda awọn kede isinmi lẹnu iṣẹ lọjọ Kẹtalelogun oṣu yii lati fi ṣe ayẹsi rẹ.
''Nkan ibanujẹ ni iroyin to tẹ wa lọwọ pe a padanu onimọ ẹrọ wa Fidelis Nweze''
Lalẹ Ọjọru, Gomina David Umahi ṣabẹwo si mọlbi r lati ba wọn kẹdun iku rẹ
Gomina Umahi lasiko abẹwo si mọlẹbi Fidelis Nweze
Oṣe ipinu lati ṣagbatẹru eto ẹkọ awọn ọmọ Kọmisana naa bẹrẹ lati ile ẹkọ alakọbẹrẹ titi de ile iwe Girama.
Ọwọ́ ọlọ́pàá tẹ adigunjalè, afipábánilòpọ̀ 15 l'Ondo
Oríṣun àwòrán, others
Ọmọ ọdún méje ni mo ti ń digunjalè, ogun ìdílé ló fàá, afurasí ṣàlàyé l'Ondo
Ọwọ olopaa nipinlẹ Ondo ti tẹ awọn afurasi ọdaran marundinlogun lori ẹsun idigunjale, fifipa ja alipupu ọkada gba, ati ifipabanilopọ.
Gbenga Kikowo to jẹ ọkan lara awọn afurasi ti wọn mu naa ṣalaye pe lati ọmọ ọdun e loun ti bẹrẹ iwa idigunjale .
Gbenga tun ṣalaye pe ilu Igbaraoke ni oun ti bẹrẹ, bẹẹni ọpọlọpọ igba liun ti lọsi ẹwọn tori rẹ.
O fi kun un pe awọn agbara okunkun idile oun lo faa nitori kii wu oun ki oun jale.
Kò sí ẹni tí mo fura sí lórí ikú ọkọ mi, àmọ́..- Adebisi aya Titus Ejanla tí wọ́n pa ní Ib
Kọmiṣọnna ọlọpaa ni ipinlẹ naa, Ọgbẹni Bọlaji Salami ṣalaye pe kaakiri ipinlẹ naa ni ọwọ ti tẹ awọn afurasi naa.
Kọmiṣọnna ọlọpaa Salami ni agbegbe Oke aro ni ọwọ ọlọpaa ti tẹ Gbenga Kikowo ati akẹgbẹ rẹ ninu iwa aitọ naa.
Oríṣun àwòrán, others
Sheikh Gumi: Irọ́ ni pẹ DSS fi ìwé pè mí tàbí fi ọ̀rọ̀ wá mi lẹ́nu wò
Gbajugbaja ẹlẹsin Islam to fi ilu Kaduna ṣe ibugbe, Sheikh Ahmad Gumi ti sọ pe irọ ni iroyin to tan kalẹ pe ajọ ọtẹlẹmuyẹ DSS fi iwe pe oun fun ifọrọwanilẹnuwo lori ọrọ kan ti oun sọ lodi si ileeṣẹ ologun Naijiria.
Gumi lo sọ ọrọ naa lasiko to n ba awọn akọroyin sọrọ lẹyin isin Jumat ni Kaduna.
O ni ijọba Naijiria mọ si gbogbo akitiyan oun lati ba awọn janduku sọrọ ninu igbo ati pe ko si igba kankan ti oun lọ ba awọn janduku naa sọrọ ti ijọba ko mọ si.
"Sheikh Gumi ni ""Mo fẹ sọ ni gbangba pe ko si ẹnikẹni to fi iwe pe mi tabi fi ṣikun ofin mu mi."""
Ko si igba ti mo ba n lọ sinu igbo lati ba awọn janduku ni ijiroro ti awọn agbofinro kii tẹle mi lọ lati daabo bo mi.
Awọn oṣiṣẹ ajọ ọtẹmuyẹ DSS, awọn lọbalọba atawọn adari awọn Fulani maa n tẹle mi lọ sinu igbo naa, mi o tii da lọ ri.
Ijaw Paternity test: Mọ́ síi nípa ìgbàgbọ́ àwọn Ilaje nípa ọmọ ọkọ àti ọmọ àlè
Gumi sọ siwaju si pe oun ko fi igba kankan sọrọ kobakungbe nipa ileeṣẹ ologun ri ninu ifọrọwerọ lori ẹrọ amohunmaworan.
Gẹgẹ bo ṣe sọ, o ni oun ko fi ẹsun kan ileeṣẹ ọmọ ogun ri lori afẹfẹ.
Ṣaaju ni ọọfisi ajọ ọtẹlẹmuyẹ DSS ti kọkọ sọ pe awọn ti fi iwe pe gbajugbaja ẹlẹsin Musulumi naa.
Agbẹnusọ ajọ ọhun, Peter Afunnaya sọ pe lootọ ni awọn fi iwe pe Gumi nitori ko si ẹni ti awọn ko le fi iwe pe ti ọrọ ba kan irufẹ ẹni bẹẹ.
Bo tilẹ jẹ DSS ko sọ ni pato eredi ti wọn ṣe fi iwe pe Gumi, ṣugbọn awọn eeyan kan ni igbesẹ ọhun ko ṣeyin awọn ọrọ ti Gumi n sọ lori iwa janduku ni Naijiria lẹnu ọjọ mẹta yii.
Fisayo Amodemaja: Nínú eré 'Children Day' ní Sọ́ọ̀ṣì ni Abebi ti bẹ̀rẹ̀ eré ṣisṣe- Bukola
Ki lo ti ṣẹlẹ ṣeyin?
Oríṣun àwòrán, @Gumi
Ileeṣẹ ọtẹlẹmuyẹ orileede Naijiria DSS ti kesi  olori ẹsin Islam kan Sheikh Gumi lati wa ṣalaye ara rẹ lori awọn ọrọ kan to sọ.
Ni  Ọjọbọ ni wọn fiwe pe to si ti yọju si wọn ni ọfisi wọn to wa ni ilu Kaduna .
Ninu ifọrọwanilẹnuwo kan ti agbẹnusọ Sheikh Gumi Tukur Mamu ṣe pẹlu ileeṣẹ iroyin VOA Hausa lo ti fidi ọrọ yi mulẹ.
Tukur sọ pe lootọ ni Gumi dahun si ipe awọn ileeṣẹ ọtẹlẹmuye nitori ifọrọwanilẹnuwo kan to ṣe pẹlu ileeṣẹ iroyin Arise TV.
Ọrọ Gumi to sọ ni idahun si ibeere lori eto naa ni pe awọn ọmọ ogun Naijiria n lẹdi apo pọ pẹlu awọn janduku ajinigbe to n da omi alaafia Naijiria ru.
Nkan ti Gumi sọ yi jẹ nkan ti ko dun mọ ileeṣẹ ọmọ ologun ninu ti wọn si fesi pada pe ọrọ to sọ jẹ eleyi to le da wahgala silẹ to si jẹ ibanilorukọ fawọn.
Ninu atẹjade ti agbẹnusọ ologun Ọgagun Onyeama Nwachukwu buwọlu, o ni awọn ọmọ ologun lo fẹmi wọn lelẹ lati wa awọn akẹkọọ FGC  Yauri ti wọn ji gbe.
Oríṣun àwòrán, Others
O ni lootọ lawọn ko le maa tọrọ aforiji fawọn alaburu ninu ọmọ ologun ṣugbọn awọn ko le faaye gba ki eeyan maa lẹdi apo pọ pẹlu awọn ọta orileede.
Agbẹnusọ Sheikh Gumi sọ pe ileeṣẹ iroyin to gbe ọrọ sita lo yi ọrọ Gumi pada. O ni ninu ifọrọwanilẹnuwo ti Gumi ṣe, ko dẹbi kankan ru ileeṣẹ ologun ninu rẹ.
O wa kesi awọn ileeṣẹ amounmaworan Arise Tv ki wọn satunse ọrọ naa ni kiakia.
Nigerian Cryptocurrency: Báwo ni ilé ẹ̀kọ́ Kano yìí ṣe ń gbà Crypto lọ́wọ́ òbí akẹ́kọ̀ọ́
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Airinjina lai ri abuke ọkẹrẹ!
Ileẹkọ aladani kan ni Kano ti sọ pe awọn ti bẹrẹ si ni gba ki akẹkọọ maa fi Crypto san owo.
Ọga ile ẹkọ naa Sabi'u Musa sọ fun BBC pe awọn gbe igbesẹ nitọri bi ọpọ eeyan ṣe n tẹwọgba owo oju opo ayelujara yii.
Arakunrin Sabi'u fi igbesẹ tuntun yii to awọn akọroyin leti to si ni ileẹkọ New Oxford Science Academy to wa ni  Chiranchi finufẹdọ fẹ ṣe bẹẹ ni.
O ni awọn ko gbe igbesẹ yii lai ṣe pe awọn fi to awọn obi akẹkọọ awọn leti.
"Ohun to mu wa gbe igbesẹ yii ko ṣẹyin bi ọpọ eeyan ṣe n lo irufẹ owo yii lori ayelujara''.
A si dupẹ pe ti ẹ ba wo o daada, ẹ o ri pe awọn orileede bi El-Slavador ti faaye gba lilo cryptocurrency gẹgẹ bi owo fun idunadura''"
Alhaja Rukayat Batimoluwasi Oniwaka: Orin Wákà la fi ń ṣe Wáàsí, o tó ọdún 70 tí mo tí bẹ̀
O tẹsiwaju pe ''Bi a ba wo nkan tawọn onimọ nipa ọrọ aje n sọ, o ṣeese ki Cryptocurrency ti fẹsẹ rinlẹ ni nkan bi ọdun meloo si igba taa wa yii''
Sabi'u  sọ pe idi ree ti o fi yẹ ki Naijiria tete maa gbaradi ki wọn baa ma wa kabamọ.
O ni ''lootọ a o tii gun oke agba laarin awọn orileede to ku ṣugbọn o yẹ ka ṣamulo ilana yii ka baa le ni idagbasoke to yẹ''.
Peter Fatomilola: Robbery burú ju Yahoo lọ, iṣẹ́ ọpọlọ lọmọ Yahoo fi ń gba owó ìran baba
Ko ṣe dandan lati fi Crypto san owo ilewe f'ẹni ti ko ba fẹ
T'ohun ti gbogbo alaye ti Sabi'u ṣe, o ni ko ṣe dandan lati fi Crypto sanwo bi kii ṣe pe o ba wu awọn obi.
''Pupọ awọn obi lo ti sowọpọ pẹlu wa lori igbesẹ yii koda awọn kan wa fi owo Dutch Coin sanwo nibi lana alana yii''.
O tẹsiwaju pe ọkan ninu awọn obi sọ pe inu oun dun si ilana owo sisan yii.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Lori bi wọn ti ṣe n gba san owo naa, Sabi'u  ṣalaye pe niṣe lawọn n pese oju opo akoto owo ileẹkọ naa tawọn obi a si maa san bitcoin wọn sibẹ.
Kii ṣe ka kan maa na owo loju ayelujara la fi n ṣe bi kii ṣe pe ki a maa lo oju opo yi fun idunadura wa.
Ọga ileẹkọ naa fi idunnu rẹ han lori igbesẹ yi to si ni oun nigbagbọ pe laipẹ yi yoo tun gbooro sii.
Kò sí ẹni tí mo fura sí lórí ikú ọkọ mi, àmọ́..- Adebisi aya Titus Ejanla tí wọ́n pa ní Ib
Amọ ṣa ajọ to n mojuto eto pasiparọ owo ni Naijiria Securities and Exchange Commission of Nigeria (SEC) sọ pe awọn ko tii ṣetan lati buwọlu lilo owo yii ni idunadura.
Eyi wa ni ibamu pẹlu ọrọ banki apapọ CBN to ni awọn ko ti ṣetan lati faaye gba lilo owo yii ayafi ti gbogbo eto ba wa ni ṣẹpẹ.
Fulani attack, Ajowa Ondo: Àwọn Bororo yìí ti kọ́kọ́ ń dàná ní Ajọwa tẹ́lẹ̀, ọmọ mi 5 di
Nigerians in Oman: Ìgbe àwọ́n ọmọ Nàìjíríà tó wà ní Oman tú àṣìrí igbèkùn tí wọ́n wà lọ́wọ́lọ́wọ́
Oríṣun àwòrán, Abike Dabiri-Erewa
Nkan bii aadọrun ọmọ Naijria to n gbe ni orilẹede Oman ni awọn ti ko si wahala bayii tori pe wọn ko ribi ṣe atunṣe iwe irina nigba ti iye saa ti ofin fun wọn lanfani lati lo pe paapaa lasiko yii ti orilẹede naa wa labẹ ofin isede latari Covid-19.
Ninu iwadi kan to ṣe pẹlu BBC, Abdulkadir Abdulwahab ni ọpọ awọn gan lo wa ni bebe ki ati padanu iṣẹ ti wọn n ṣe lawọn ileeṣẹ lorilẹede naa tori pe wọn o ni iwe igbelu.
Gẹgẹ bi Abdulkadir ṣe sọ iṣẹlẹ yii ti sọ wọn sinu ọpọlọpọ hila-hilo tori aini iwe igbelu tabi iwe irina ti saa to yẹ ki wọn loo fun ṣi ku lee ko wọn si wahala.
"Iná sọọ! Àwọn ọmọdé tó ń kọ́ ìjà ààbò ara ẹni ""Kongfu jó ráúráú"
Ìjọba orílẹ̀-èdè Oman fòfin de Nàìjíríà àti orílẹ̀-èdè Mẹ́sàn míràn lati má wọ ìlú wọn
Mò ń tọ̀ s'ára ni mo fi gba ara à mi l'óko ẹrú ní Oman
Iyabo Ojo, mẹ́nu kúrò lórí ọ̀rọ̀ Baba Ijesha ní báyìí tí ọ̀rọ̀ ti dé iwájú mi - Adájọ́ Toyin Taiwo
Ọ̀pọ̀ ọmọ Nàìjíríà ń ṣelédè lẹ́yìn Ajimobi, èrò wọn ṣọ̀tọ̀ọ̀tọ̀!
'Mo fọ kọ́mú, pátá, ògiri ilé lórí 200,000 láìlèfọhùn lórílẹ̀èdè Oman'
A n ṣiṣẹ takun takun tori mọlẹbi wa ni, ẹ ran wa lọwọ, a wa ninu wahala o!
O ni ajakalẹ arun Covid-19 ti mu ki iṣoro awọn buru jai sii ati wi pe oniruuru orilẹede lo ni ofin ti wọn gbe kalẹ lati koju  itanka arun naa.
Ọpọ ninu wa lo ro wi pe aaye gba wa lati rinrinajo jade lọhun ka tun pada wọle, bii ka lọ si Najiria ka pada lọ Oman ṣugbọn ni bayii gbogbo ọna lo ti di pa mọ wa.
"O ṣalaye pe Naijiria ti wa lara awọn ibi aiwọ lagbaye. ""Ẹnikẹni to ba si lọ si Naijiria ko lee pada wọ ibi mọ""."
"Amọ, o ni ofin yii ko kan awọn oṣiṣẹ Naijiria to wa ni ileeṣẹ Naijiria lọhun. ""Ko si bibẹgi dina tiwọn lati rinrinajo pada wọ Oman lati maa ṣiṣẹ fun awa ọmọ Naijira""."
Ẹwẹ, ileeṣẹ to n ri si ọrọ awọn ọmọ Naijiria to wa lẹyin odi sọ pe awọn ko mọ rara nipa ohun ti wọn n la kọja nibẹ.
Wo iléẹ̀kọ́ tí wọ́n kò ti fààyè gba akẹ́kọ̀ọ́ láti padà sọ́dọ̀ Òbí tàbí ìlú rẹ̀ lẹ́yìn tó bá parí
Hàà! Akẹ́kọ̀ọ́ UNILAG ẹni ọdún 21 kà bòrò-bòrò pé: Èmi ló pa olówó, ọ̀gá Super TV, Usifo Ataga
Ọ̀rọ̀ wo ni Sheikh Gumi sọ tí iléeṣẹ́ ọ̀tẹlẹ̀múyẹ́ DSS ní kó wá ṣàlàyé ara rẹ̀?
Alukoro ileeṣẹ naa sọ fun BBC pe awọn ti gba ẹsun ti awọn ọmọ Naijiria kan fi ranṣẹ lati Oman.
Ọga agba ajọ naa, Abike Dabiri Erewa ba ọfiisi to n ṣeto iwe irina sọrọ ati minisita to n ri si ọrọ abẹle lori ọrọ iṣoro ti wọn n koju pẹlu erongba lati ran awọn ọmọ Naijiria to n koju iṣoro aini lorilẹede miiran.
Human trafficking: Ààrẹ Buhari, ẹ̀yin gómìnà ìpínlẹ̀ Yorùbá, ẹ rántí wa ní Oman, àwọn ọmọ
Martial arts school fire: Èèyàn 18 tí púpọ̀ nínú wọn jẹ́ ọmọ́dé ló jóná, wo bí ọ̀pọ̀ ọmọdé ṣe tún farapa
Oríṣun àwòrán, ALBERT GONZALEZ FARRAN
O kere tan eeyan mejidinlogun lo ti gbẹmi mi ti awọn bii mẹrindinlogun si farapa yanayana lẹyin ti ina nla ya wọ inu gba ileẹkọ kan ti wọn ti n kọ nipa ija aabo ara ẹni ti oloyinbo n pe ni Martial Arts eyi ti ija Kongfu jẹ ọkan lara wọn.
Ọpọlọpọ awọn to fara gba ninu ijamba ina ọhun ni iroyin ni ọmọde ni wọn ti ọjọ ori wọn wa laarin ọdun meje si mẹrindinlogun ti wọn ngbe ninu ọgba ileẹkọ ti wọn ti nkọ ija yii, iyẹn Shenxing Martial Arts Centre to wa ni ẹkun Henan lorilede China.
Ina yii bu jade lowurọ kutukutu ọjọ Ẹti ti wọn si ti ribi pa , awọn alaṣẹ labẹle lo s eyi ṣugbọn ko han gedegbe ohun to ṣokunfa bi ina naa ṣe bẹrẹ.
Oríṣun àwòrán, FEDERICO SCOPPA
Wo iléẹ̀kọ́ tí wọ́n kò ti fààyè gba akẹ́kọ̀ọ́ láti padà sọ́dọ̀ Òbí tàbí ìlú rẹ̀ lẹ́yìn tó bá parí
'Ìjọba Kwara kàn fẹ́ fi ọ̀rọ̀ Hijab dá ìjà sílẹ̀ láàrin Krìstíẹ́ní àti Mùsùlùmí ni'
Ẹ̀mí àìrí lé àwọn akẹ́kọ̀ọ́ jáde ni ilé ẹ̀kọ́ St Claire's ní Offa
'Tí mi ò bá rí ògùn rà fún ọmọ mi, á máa gé ara rẹ̀ jẹ tí ẹ̀jẹ̀ yóò máa ṣàn'
Irufẹẹ iṣẹlẹ ijamba ina aburu bayii ko ṣẹṣẹ maa ṣẹlẹ ni China eyi to si ni ilana idaabo bo ara ẹni kekeke tabi ti ko kunwọ to.
Gẹgẹ bi atẹjade ijọba Zhengcheng, ijọba ti fi panpẹ ofin mu eeyan to jẹ alakoso ileẹkọ ija naa.
Awọn oṣiṣẹ ijọba sọ fun ileeṣẹ iroyin Beiing Toutiao pe mkan bii akẹkọ mẹrinlelọgbọn to n gbe ninu ọgba ibudo ija naa lo wa nibẹ nigba ti ina ọhun burẹkẹ ni nkan bii ago mẹta akoko tiwọn lọhun.
Lọgan ni wọn ti gbe awọn ọmọ to farapa digba digba lọ sileewosan. Awn obi tawn oniroyin si ba sọrọ sọ pe wọn ko fun awọn ni alaye kankan koda wọn ko tii jẹ́ ki awọn ri awọn ọmọ.
"Ẹ gbà wa o! Ìwé ìrìnà àti ìwé ìgbélùú wa ní Oman ti ""expire"", wọ́n tún ní Nàìjíríà ti di ibi àìwọ̀"
Àwọn adigunjalè kọ lẹ́tà sí adúgbò, wọ́n ni kí ara àdúgbò dá 20m tàbí kí wọ́n ó jàwọ́n lólè
Ọ̀rọ̀ wo ni Sheikh Gumi sọ tí iléeṣẹ́ ọ̀tẹlẹ̀múyẹ́ DSS ní kó wá ṣàlàyé ara rẹ̀?
"Kà nípa ìṣẹ́dá àwọn tí kíní abẹ́ wọn ò dúró tẹ́yin olóyìnbò ń pè ní ""Paedophile"" àmọ́ n'ílànà ìṣẹ̀ṣe"
Oríṣun àwòrán, FEDERICO SCOPPA
Ni Zhenxing, loju ọjọ lawọn ọmọ maa n kọ ẹkọ ija martial arts wọn si tun n gbe nibẹ lalaalẹ. Mi o mọ ohun to ṣokunfa ina naa, ohun ti baba ọmọ ọ̀dun mẹsan kan to moribọ sọ ree.
"Obi mii tun sọ fun ileeṣẹ iroyin Reuters pe ""wọn ko gbogbo iroyin ati alaye pamọ fun eeyan""."
Bi ẹ ba ti n gbọ Shaolin Temple, Ilu Henan ti iṣẹlẹ yii ti ṣẹlẹ lo wa ibẹ si ni wọn mọ gẹgẹ bii ilu ti wọn ti bi imọ ẹkọ ija martial arts ni China nibi ti ọgọọrọ akẹkọ ti n k nipa ija Kongfu.
Oríṣun àwòrán, Cancan Chu
Yoruba Nation Kwara: Àwọn ọ̀dọ́ ìlú Ọ̀ffa fàákékọ́rí lórí ìwọ́de 'Yoruba Nation', wọ́n ní Sunday Igboho bú Ọlọ́fà
"Iwọde ipe fun idasilẹ orilẹede Yoruba ti ọpọ mọ si ""Yoruba Nation"" ti to yẹ ko waye loni nilu Offa foriṣanpọn."
"Awọn to n pe fun idasilẹ orilẹede Yoruba labẹ aṣia ""Yoruba Nation"" ti gunlẹ si ilu Ọffa gẹgẹ bi wọn ti ṣe pinnu rẹ ṣaaju ti wọn si ti bẹrẹ iwọde wọn lati agbegbe Sẹkiteriati ẹgbẹ awọn ọmọ ilu Ọffaa, ODU."
Bi wọn ti n lọ pẹlu oniruuru orin ẹhonu lẹnu wọn ati patako alakọle ti wọn kọ oriṣiriṣi akọle ẹhonu si pẹlu ni awọn agbofinro n wọ tẹle wọn lati rii pe iwọde naa ko jasi rukerudo ni ilu.
Ko pẹ ti iwọde naa bẹrẹ lawọn ọdọ ilu kan ya soju popo lojiji lati da iwọde naa duro eleyi to si fẹ di iṣu ata yan an yan an.
Eyi lo mu ki awọn agbofinro faake kọri pe lọna ati lee dena wahala, iwọde naa ko ni lee tẹsiwaju mọ.
"Awọn ọdọ naa fẹsun kan aṣiwaju awọn ẹgbẹ to n pe fun idasilẹ ""Yoruba Nation"", oloye Sunday Igboho pe o fi ẹnu abuku kan Kabiyesi Ọlọffa ti wọn si ni awọn ko lee la oju awọn silẹ ko maa tabuku Ọbalaye ilu awọn ko si tun fẹ ṣe iwọde ninu ilu bẹẹ."
"Oloye Sunday Igboho tabi ẹnikẹni ninu awọn aṣiwaju ẹgbẹ to n pe fun i""Yoruba Nation"" ko tii sọ ohunkohun lori iṣẹlẹ yii tabi ẹsun ti wọn fi kan Sunday Igboho."
"Iwọde ipe fun idasilẹ orilẹede Yoruba ti ọpọ mọ si ""Yoruba Nation"" ti bẹrẹ ni ilu Ọffa."
Lasiko ti a fi nko iroyin yii jọ awọn to n lewaju ipe fun idaduro ilẹ Yoruba atawọn ọdọ ni ilu Offa ti n ko ara wọn jọ si agbegbe Sẹkiteriati to wa nilu Ọffa nibi ti wọn ti gbera fun iwọde wọn.
Bakan naa lasiko ti a fi nko iroyin naa jọ Oloye Sunday Igboho ko tii darapọ mọ iwọde naa.
Oni ọjọ kẹrindinlogun, oṣu Kẹfa, ọdun 2021 ni iwọde Yoruba Nation yoo waye ni ipinlẹ Kwara.
Iwọde na ti ẹgbẹ Ilana Ọmọ Oodua n ṣe onigbọwọ rẹ ni ireti wa pe yoo waye niluu Offa, ti yoo si bẹrẹ ni aago mẹwaa aarọ lonii ọjọ Abamẹta.
Gẹgẹ bii ohun ti awọn to n ṣagbatẹru iwọde naa sọ, wọn ni awọn ko fẹ ogun tabi itajẹsilẹ, ṣugbọn afojusun awọn ni ki ilẹ Yoruba yapa kuro lara orilẹ-ede Naijiria, ko si da wa laaye ara rẹ gẹgẹ bii orilẹ-ede to ni ominira.
Ṣaaju ni iwọde naa ti kọkọ waye lawọn ilu nla nla bii Osogbo, Ibadan, Akure, Ado Ekiti, ti ireti ṣi wa pe yoo de ilu Eko laipẹ yii.
Lara awọn alẹnulọrọ lawujọ ti awọn eeyan n reti nibi iwọde ọhun ni ajijagbara Oloye Sunday Adeyemo, ti ọpọ mọ si Sunday Igboho.
Lasiko ti agbẹnusọ Igboho, Koiki Media, n kede iwọde ọhun loju opo facebook rẹ, o ni ko si ohun ti yoo yẹ iwọde naa.
Peter Fatomilola: Robbery burú ju Yahoo lọ, iṣẹ́ ọpọlọ lọmọ Yahoo fi ń gba owó ìran baba
O si tun kede fun gbogbo awọn ti yoo yọju sibi iwọde ọhun lati lo ibomu lọna ati bọwọ fun ilana ajakalẹ arun Covid-19 nitori obitibiti ero ti wọn n reti nibẹ.
Ẹwẹ, bo tilẹ jẹ pe ọpọ ọmọ Naijiria lo n ṣatilẹyin fun Yoruba Nation yii, ọpọ awọn mii n sọ pe iyapa kọ ni ọna abayọ si iṣoro ti Naijiria n doju kọ.
Bo tilẹ jẹ pe pupọ awọn ori ade nilẹ Yoruba lo ti ṣo ni gbangba pe digbi lawọn wa lẹyin Yoruba Nation, ṣugbọn awọn ori ade mii bii Oluwo ti ilu Iwo, Ọba Abdulrasheed Adewale Akanbi ni ohun kan ṣoṣo to le gbe Naijiria de ilẹ ileri ni ki gbogbo ẹya to wa ni Naijiria ṣe ara wọn ni oṣuṣu ọwọ.
Fisayo Amodemaja: Nínú eré 'Children Day' ní Sọ́ọ̀ṣì ni Abebi ti bẹ̀rẹ̀ eré ṣisṣe- Bukola
Oyo security: Àwọn agbébọn pa ìyàwò èèkàn olóṣèlú ní Ibadan, ọlọ́pàá ní adigunjalè ní wọ́n
Oríṣun àwòrán, @whatsupibadan
Awọn agbebọn kan ti ṣeku pa arabinrin kan ti orukọ rẹ n jẹ Ọlayẹmi iyawo eekan oloṣelu kan nilu Ibadan, Ọgbẹni Peter Ọdẹtomi lọjọ Ẹti.
Ọgbẹni Ọdẹtomi ti figba kan ri ṣe kọmiṣọnna fun amojuto ijọba ibilẹ ati oye jijẹ ni ipinlẹ Ọyọ lasiko iṣejọba gomina ana nibẹ,
Oloogbe Sẹnetọ Abiọla Ajimọbi to si tun ti figbakan ri jẹ alaga kansu gusu Ogbomọṣọ pẹlu.
Bakan naa ni o tun ti fi igbakanri jẹ oludije fun igbakeji gomina pẹlu Sẹnetọ Ajimọbi lasiko to fi kọkọ du ipo gomina ipinlẹ Ọyọ lọdun 2007.
Kò sí ẹni tí mo fura sí lórí ikú ọkọ mi, àmọ́..- Adebisi aya Titus Ejanla tí wọ́n pa ní Ib
Ninu ile rẹ to wa lagbegbe Akobọ nilu Ibadan ni wọn pa oloogbenaa si.
Ileeṣẹ ọlọpaa ipinlẹ Ọyọ fidi iṣẹlẹ naa mulẹ, ṣugbọn wọn ni awọn adigunjale lo pa iyawo oloṣelu naa lasiko ti wọn fi lọ digun jale nile rẹ lọjọ Ẹti, ọjọ karundinlọgbọn.
Ijaw Paternity test: Mọ́ síi nípa ìgbàgbọ́ àwọn Ilaje nípa ọmọ ọkọ àti ọmọ àlè
White Witches Association: Ẹgbẹ́ àwọn àjẹ́ funfun ní àbò tó mẹ́hẹ lè fọ́ Nàíjíríà sí wẹ́wẹ́, ẹ̀jẹ̀ ti pọ̀jù
Oríṣun àwòrán, others
Ẹgbẹ awọn ajẹ funfun lorilẹede Naijiria, White Witches Association of Nigeria (WWAN) ti ṣekilọ pe o ṣeeṣe ki orilẹede Naijiria pin si mẹrin tabi mẹfa o.
Ẹyin naa mi kanlẹ lori ikede yii abi?
Awọn ajẹ funfun naa ni bi iṣẹlẹ ipaniyan lọtun losi se n waye latọwọ awọn agbesumọmi Boko Haram, atawọn agbebọn to n ṣọṣẹ kaakiri pẹlawọn darandaran Fulani, ko ba tete dopin, ọrọ lee bọ sori fun Naijiria.
Agbẹnusọ fun ẹgbẹ naa nigba kan ri, Dokita Iboi Okhue ṣalaye ninu ipade pẹlu awọn akọroyin lẹyin ipade awọn ajẹ naa to waye nipinlẹ Cross rivers ati Kaduna loṣu keji ati ikẹrin ọdun 2021, lo sisọ loju ọrọ naa.
Peter Fatomilola: Robbery burú ju Yahoo lọ, iṣẹ́ ọpọlọ lọmọ Yahoo fi ń gba owó ìran baba
Afojusun ipade naa ni lati wa ojutu si bi itajẹsilẹ ṣe pọ lorilẹede Naijiria, ti wọn si ni awọn ri aridaju rẹ pe, bi awọn alaṣẹ ko ba tete wa nnkan ṣe si eto aabo to mẹhẹ naa, o ṣeeṣe ki Naijiria o pin si wẹwẹ.
O ni ọrọ abo to mẹhẹ lorilẹede Naijiria bayii n kọ awọn ajẹ lominu bẹẹ ni gbogbo awọn majẹobajẹ lorilẹede Naijiria lo gbọdọ fọwọsowọpọ pẹlu Aarẹ Buhari nitori ajeje ọwọ kan ko lee gbe ẹru dori.
Jeleosinmi Art Centre: Ibùdó yìí ló ń tọ́ ọ̀dọ́ sọ́nà nípa iṣẹ́ ọnà àti àṣà dípò ìwà àìda
Oniruuru awọn ibudo ikẹkọ lo wa paapaa fun awọn ogo wẹẹrẹ, lara rẹ ni ibudo Jeleosinmi tawọn ọmọde ti maa n kọkọ ẹkọ iwe.
Amọ ibudo ikẹkọ Jẹleosinmi ti Abolore Sobayo da silẹ yatọ nitori o n kọ awọn ọdọ ni ede Yoruba ati isẹ ọna lapapọ.
Nigba to n ba BBC Yoruba sọrọ lori idi to fi da ibudo naa silẹ, Sobayo ni ọpọ ọdọ lo n fi ẹsẹ gbalẹ kiri, ti esu si n bẹ wọn nisẹ, lo mu ki oun da ibudo ti wọn yoo ti kọ nipa isẹ ọna ati asa wa silẹ.
O fikun pe ọna lati fi pada fun awujọ ti oun ti jade wa, eyiun Oshodi, lo mu ki oun gbe ibudo jẹleosinmi naa kalẹ sibẹ.
Ni ibudo yii si ni awọn ọdọ ti n kọ nipa oniruuru ara ti wsn le fi isẹ ọna da ati ọpọ ohun to jẹ mọ asa wa nilẹ Yoruba.
Sobayo wa rọ awọn obi lati maa kọkọ fi ede abinibi kọ awọn ọmọ wọn nitori ko si anfaani ninu ki ọmọ wa ma gbọ ede wa.
Àwọn ìtàn mánigbàgbé tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí:
Baba Ijesha: Yomi Fabiyi rọ Iyabo Ojo láti gba àlááfíà láàyè
Oríṣun àwòrán, iyaboojofespris/realyomifabiyi/Instagram
Yoruba ni arẹmaja kankan ko si, amọ ajamarẹ ni ko sunwọn nitori ẹni to ba se ohun to dun mọ ni, le pada se ohun ti yoo dun ni.
Bẹẹ ni ọrọ ri bayii laarin awọn osere tiata meji to n tahun sira wọn lori ọrọ Baba Ijesha, eyiun Yomi Fabiyi ati Iyabo Ojo.
Bẹẹ ba gbegbe, Yomi Fabiyi lo n tako Iyabo Ojo lori awọn igbesẹ ti oserebinrin naa n gbe lori ẹsun asemase ti wsn fi kan Baba Ijesha, lati igba ti isẹlẹ naa ti waye.
Bakan naa ni ileẹjọ ti gba oniduro Baba Ijesha, eyi to tako awọn erongba Iyabo Ojo, ti ọpọ araalu si ti bẹrẹ si yọ suti ete si oserebinrin ọhun
Amọ Yomi Fabiyi ti wa fi ọrọ alaafia ransẹ si Iyabo Ojo pe ko jeburẹ lori ọrọ naa, ko si gba alaafia laaye.
Oríṣun àwòrán, realyomifabiyi/Instagram
Fabiyi, ninu ọrọ tuntun to kọ soju opo Instagram rẹ kede pe oun ti dari jin Iyabo lai naani awọn kobakungbe ọrọ to ti sọ si oun saaju.
Oserekunrin naa ni bi ala ni awọn isẹlẹ to waye lori ọrọ Baba Ijesha naa n se oun, ti oun ko si lero pe oun ati Iyabo Ojo le taporogan sira awọn laelae.
"Eeyan daadaa ni Iyabo Ojo, ọrọ to sẹlẹ si n dun mi bii egbo ninu ọkan mi, n ko fẹ ba ọ ja tabi binu si ọ latinu ọkan mi wa.
Amọ bi ala ni gbogbo bi ọrọ yii se waye n jẹ si mi, jọọ dakun wa alaafia pẹlu ara rẹ ati awọn eeyan miran.
N ko si le sọ pe o kii se eeyan gidi mọ nitori awọn isẹlẹ to waye yii tabi ki n sẹ nipa iru eeyan to jẹ amọ mo ti forijin ọ nipa awọn ọrọ kabiti to sọ si mi."
yyyy
Bakan naa ni Yomi Fabiyi tun gba Iyabo Ojo nimọran lati maa se daadaa siwaju, to si fikun pe oun lero pe awọn imọran naa yoo seso rere ninu rẹ.
Koda, ami ifẹ ni Yomi Fabiyi fi pari ọrọ rẹ si Iyabo Ojo naa.
Bẹẹ ba gbegbe, Iyabo Ojo ti kọkọ se fidio kan saaju pe oun ti dari jin gbogbo awọn eeyan to sẹ oun lori ọrọ Baba Ijesha.
Baba Ijesha: TAMPAN ní Iyabo Ojo, Nkechi Blessing àtàwọn míì tó bá tàbùkù ẹgbẹ́ rugi oyin
Oríṣun àwòrán, iyaboojofespris/nkechiblessingsunday/Instagram
Yoruba ni agba kii wa lọja, ki ori ọmọ tuntun wọ, bẹẹ si ni agba ti ko ba kẹhun sọrọ, afaimọ ko ma kẹ itan sare.
Idi ree ti ẹgbẹ to n sakoso awọn osere tiata lagbo ede Yoruba, TAMPAN, fi n ke tan tan pe se n fi ewe ọmọ mọ awọn ọmọ ẹgbẹ naa kan leti.
Ẹgbẹ TAMPAN atawọn agbaagbaa oludari ere tiata sekilọ yii lasiko ipade akọroyin ti wọn se lọjọ Abamọta.
Ẹgbẹ naa, ti agba osere tiata kan, Jide Kosoko gbẹnu rẹ sọrọ ni lati akoko yii lọ, oun ko ni fara mọ iwa ọyaju lati ọdọ ọmọ bẹ naa mọ.
Ẹgbẹ TAMPAN wa ke si Iyabo Ojo ati Nkechi Blessing, ti wọn jẹ oserebinrin pe ki wọn fopin si iwa ifẹsunkan ni lọna aitọ, eebu ati itabuku ẹni, ti wọn n hu si ẹgbẹ ọhun.
Oríṣun àwòrán, @goldmynetv
"Wọn ti pe akiyesi ẹgbẹ TAMPAN si awọn iwa ibanilorukọjẹ tawọn eeyan kan ti ko ni iwa ikora ẹni nijanu, ti wọn si ro pe awọn ga ju ofin ẹgbẹ lọ, n hu.
A n wo ọpọ iwa itabuku ẹni ti Iyabo Ojo n sọ si ẹgbẹ wa ati agbo osere tiata lapapọ.
Gẹgẹ bi i ara awọn to da isẹ yii silẹ, a ko le kawọ gbera, ka si jẹ ki wọn maa paroko ti ko dara ransẹ si gbogbo aye lai da wọn lẹkun.
Ohun to n sẹlẹ yii ti nipa ti ko dara lori orukọ rere wa, to si le tẹsiwaju lati sakoba fawọn osere tiata ti ko ni sna isẹ aje miran yatọ si ere tiata Yoruba.
Nkechi Blessing naa ti dara pọ mọ iwa buruku yii to n tako ẹgbẹ wa, ta si n sọ pe O to gẹẹ."
Jide Kosoko, gẹgẹ bi ọmọ igbimọ majẹobajẹ fun ẹgbẹ TAMPAN ati agba osere tiata ni ede Yoruba, wa kilọ fun Iyabo Ojo ati Nkechi Blessing atawọn miran to n huwa bii tiwọn.
Peter Fatomilola: Robbery burú ju Yahoo lọ, iṣẹ́ ọpọlọ lọmọ Yahoo fi ń gba owó ìran baba
"Tẹ ba ro pe gbogbo aseyọri yin ati ohun tẹ da loni, kii se lati ipasẹ agbo ere tiata Yoruba ni, o sa yẹ kẹ mọ pe ẹka yii fun yin ni anfaani ati ayika to dara lati di ohun tẹ da lonii.
Abuku si ẹnikan jẹ abuku si gbogbo wa, a si ke si awọn ẹka ẹgbẹ tiata miran lati sugba wa tẹ ba tẹsiwaju lati maa tabuku wa.
A si fi n da yin loju pe tẹ ba tun tapa si ẹgbẹ wa, ẹ ko ni lọ laijiya."
Lara awọn agbaagba elere tiata miran to tun wa nibi ipade akọroyin naa ni Adebayo Salami, ti ọpọ mọ si ọga Bello, Ebun Oloyede, Bolaji Amusan ati Yinka Quadri.
yyyy
Bakan naa ni ẹgbẹ TAMPAN ti fesi si ọrọ kan ti Oloye Aderemi Adedeji, ti wọn tun n pe ni Olofana sọ nipa ọrọ Baba Ijesha.
Olofana lo kede fawọn akọroyin pe ko si agba osere tiata lobinrin kankan ti yoo ni oun de ipo giga lai jẹ pe o ti ni ibalopọ pẹlu eeyan kan ninu ẹgbẹ naa.
Amọ ẹgbẹ TAMPAN, ninu atẹjade kan to fisita kede ni ero agba osere naa kii se ero ẹgbẹ naa rara.
"Ẹgbẹ tiwa kii fara mọ iwa ibalopọ laibikita, bẹẹ ni kii se ara ilana ẹgbẹ wa. Bi agbaagba meji ba gba lati ni nnkan papọ, eyi ko tumọ si pe ohun to n sẹlẹ kaakiri ninu ẹgbẹ tabi agbo osere ni eleyi.
Jeleosinmi Art Centre: Ibùdó yìí ló ń tọ́ ọ̀dọ́ sọ́nà nípa iṣẹ́ ọnà àti àṣà dípò ìwà àìda
Ko si ni akọsilẹ wa pe awọn osere binrin gbọdọ ni ibalopọ pẹlu akẹẹgbẹ lọkunrin tabi awọn ọga wọn, ki wọn to le debi giga ninu ẹgbẹ."
Atẹjade naa wa rọ awọn eeyan to ni iru eyi lero lati yipada nitori asise gbaa ni.
TAMPAN ni awọn ohun to se pataki ki osere tiata kan to de ipo giga ni talẹnti rẹ, idanilẹkọ to gba ati afojusun lati mọ ohun to nwa.
TB Joshua: Láàrin July 5 sí 11 ní ètò ìsìnkú olóògbé náà yóò fi wáyé
Oríṣun àwòrán, TB Joshua Ministries/Instagram
Mọlẹbi oloogbe Wolii TB Joshua to dagbere faye laipẹ yii ti kede ọjọ isinku ati bi ilana isinku oloogbe naa yoo se lọ.
Atẹjade kan ti aya oloogbe TB Joshua, Evelyn fisita lorukọ igbimọ oludari ijọ Synagogue lo sisọ loju ilana isinku naa.
Gẹgẹ bi ilana isinku naa se lọ, bi eto isinku oloogbe TB Joshua ba se n lọ, ni wọn yoo maa se afihan rẹ lori ayelujara ati loju opo Tẹlifisan ijọ naa, Emmanuel TV.
Bi ilana isinku TB Joshua yoo se lọ ree:
Atẹjade ilana isinku naa ni ọjọ karun osu Keje ọdun 2021 ni tito lọwọọwọ pẹlu abẹla yoo waye ni deede aago mẹfa abọ irọlẹ.
Laarin ọjọ meji yii ni isin imọyi fun oloogbe yoo waye, tawọn eeyan yoo si maa sọ ohun ti wọn mọ nipa oloogbe TB Joshua atawọn ohun to gbe ile aye se.
Aago mẹwa aarọ si meje alẹ ni isin imọyi yii yoo waye.
Nigba to ba di ọjọ Keje osu Keje ọdun 2021, ni wọn yoo se isin alẹ orin onigbagbọ ati asalẹ iyin fun oloogbe.
Aago mejila ọsan ni isin naa yoo waye.
Ọjọ Kẹjọ osu Keje ọdun 2021 ni wọn yoo tẹ oku oloogbe TB Joshua naa ni itẹ ẹyẹ .
Aago mọkanla aarọ si marun irọlẹ ni titẹ oloogbe naa nitẹ ẹyẹ yoo fi maa waye.
Oríṣun àwòrán, SCOAN
Ọjọ Kẹsan osu keje ọdun 2021 ni wọn yoo tẹ oku TB Joshua sile ikẹyin, ti wọn yoo si fi ara rẹ fun ilẹ.
Aago mẹwa aarọ ni eto naa yoo maa waye.
Isin idupẹ fun isinku oloogbe TB Joshua yoo waye ni ọjọ Aiku, ọjọ Kọkanla osu Keje ọdun 2021
Deede aago mẹsan si mọkanla aarọ ni isin idupẹ naa yoo maa waye.
Ijọ naa wa kede pe ilu Eko ni wọn yoo ti se gbogbo eto isinku yii, ti wọn yoo si tun sin oloogbe TB Joshua silu Eko bakan naa.
Dino Melaye vs Iyabo Ojo: Sẹ́nétọ̀ ní lórí irọ́ ní ọ̀rọ̀ ìfẹ́ tí wọn ló wà láàrin òun àtàwọn òṣèré tíátà
Oríṣun àwòrán, other
Laipẹ yii ni fidio kan gbode lori ayelujara, ninu eyi ti ohun gbajumọ oṣere tiata ni, Iyabọ Ojo ti n jade bi eyi to wa lori ipe ago, to si n fi gbajumọ Sẹnetọ ati ọmọ jayejaye nni, Dino Melaye ṣepe.
Iyabọ Ojo n sọ ninu fọnran naa pe, Sẹnetọ Melaye n parọ fun awọn ọmọbinrin miran pe ko si ajọṣepọ kankan laarin oun pẹlu rẹ, nigba to si jẹ wi pe adehun ifẹ n bẹ laarin awọn.
Bakan naa lo fi ẹsun kan Dino Melaye ninu fọnran ohun naa pe oloselu naa n sẹ nipa ajọsepọ awọ, fun awọn olulufẹ tuntun to sẹsẹ ni, to si darukọ Omoburty.
Amọṣa, gbajumọ ọmọ jayejaye naa, Sẹnetọ Dino Melaye ti fesi pe ko si ajọṣepọ ifẹ kankan laarin oun ati Iyabọ Ojo tabi Biọdun Okeowo, ti ọpọ mọ si Omoborty.
Awọn oju opo ayelujara kan ti kọkọ gbe sita ṣaaju pe Dino Melaye ati Iyabọ Ojo jijọ n ṣe wọlewọde tẹlẹ, ki oṣere ẹgbẹ rẹ, Ọmọborty to jaa gba mọọ lọwọ.
Oríṣun àwòrán, Screenshot/instagram
Bakan naa ni iroyin sọ pe osere tiata kan Olabisi ọmọ Logbalogba, ti ọmọ kan fun Sẹnetọ Dino Melaye amọ ti onitọun kọ pe ko ri bẹẹ.
"Sẹnetọ Melaye ni ""Lori irọ"" ni gbogbo iroyin naa pẹlu fọnrọn ohun ti Iyabọ Ojo ti n sọ pe irọ ni Dino n pa kiri fawọn obinrin to ba kọ ẹnu ifẹ si pe oun Iyabọ lo n le Dino kiri lati fẹ oun."
O ga oooo. Dino fẹ fẹ A sile, Dino fun B loyun, Dino n ṣe aayan ifẹ pẹlu C, gbogbo rẹ lori irọ ni....haba!!!! Ẹ maa daamu jina, maa fẹyawo laipẹ, koboko ni yoo si fi le gbogbo yin danu. Ẹyin alainiṣẹ gbogbo.
Ọrọ bi edeaiyede kii se lori Dino Melaye.
Fun ọdun mẹwaa ni oun pẹlu Tokunbọ Melaye fi fẹra ni lọkọlaya, ki tirela to gba aarin wọn kọja lẹyin ọmọ mẹta.
Jeleosinmi Art Centre: Ibùdó yìí ló ń tọ́ ọ̀dọ́ sọ́nà nípa iṣẹ́ ọnà àti àṣà dípò ìwà àìda
Olowo of Owo: Bí ìjọba bá ṣe àtúntò tó yẹ, Sunday Igboho yóò fọwọ́sowọ́pọ̀ pẹ̀lú wọn
Olowo tilu Owo, Ọba Ajibade Gbadegesin ti ke si ijọba lati wa nnkan se nipa awọn Fulani to n wa goolu ni Owo.
Ọba Gbadegesin, lasiko ifọrọwerọ rẹ pẹlu BBC Yoruba ni o yẹ ka se akoso Naijiria gẹgẹ ba se fọwọsowọpọ gba ominira.
O ni ohun toju awọn to n pe fun idasilẹ Yoruba Nation ri, lo mu ki wọn maa pariwo fun iyapa Naijiria.
Olowo fikun pe ti ijọba ba se atunto to yẹ, Sunday Igboho yoo dakẹ, ti yoo si fọwọsowọpọ pẹlu ijọba.
Bakan naa lo woye pe ọpẹlọpẹ pe ikọ alaabo Amotekun to ti wa saaju akoko yii, bibẹẹ kọ, Ọlọrun lo mọ ohun ti oju awọn eeyan ipinlẹ Ondo ko ba ri tori eto aawo to mẹhẹ.
Ọba Gbadegesin wa rọ ijọba lati gba eto atunto Naijiria laaye, ki ohun gbogbo le tuba tusẹ.
Niger Delta Avengers: Buhari fèsì pé gbogbo ohun tí NDA ń bèèrè fún, ni òun ti ṣe
Oríṣun àwòrán, AFP
Lẹyin ti wọn sinmi fun bi ọdun mẹta, awọn ajijagbara fun agbegbe Niger Delta, eyiun Niger Delta Avengers (NDA) tun ti gba ọna miran yọ bayii.
Lọtẹ yii, ẹgbẹ Avengers ti ṣe agbekalẹ eto ti wọn pe orukọ rẹ ni 'Operation Humble', eleyii ti wọn fi leri pe awọn yoo fi ba ọrọ aje Naijiria jẹ nipa biba awọn ileeṣẹ epo rọbi to wa lẹkun naa jẹ.
Ninu atẹjade kan ti ẹgbẹ ọhun ti fi sita ni wọn ti ṣalaye pe awọn ṣetan lati ri pe ọrọ aje Naijiria dẹnu kọlẹ.
Koda wọn tun leri pe awọn ṣetan lati da ṣẹria fawọn oloṣelu to n gbimọ pọ pẹlu ijọba apapọ lati fi ẹtọ awọn eeyan ẹkun Niger Delta dun wọn.
Eleyii ṣẹlẹ lẹyin oṣu kan ti olori awọn ajijagbara Niger Delta kan, Ekpemupolo, ti ọpọ mọ si Tompolo, kọ iwe ranṣẹ si ijọba apapọ lati ṣe ifilọlẹ igbimọ to n ri si ọrọ Niger Delta.
Olowo: Bí ìjọba bá ṣe àtúntò tún yẹ, Sunday Igboho yóò fọwọ́sowọ́pọ̀ pẹ̀lú wọn
Tompolo sọ ninu lẹta naa pe ti ijọba ko ba ṣe bẹẹ, awọn ṣetan lati ba awọn ileeṣẹ ifọpo Naijiria to wa lẹkun naa jẹ.
Ọjọ meje pere ni Tompolo fun ijọba lati gbe igbesẹ lọri ọrọ naa.
Ẹgbẹ NDA tun sọ ninu atẹjade to fi sita pe, oun ti sọ fawọn ajijagbara lati pada si inu igbo tawọn irinṣẹ ifọpo wa lẹkun naa.
Ẹwẹ, ijọba apapọ ti fesi si ileri awọn ajijagbara Niger Delta Avengers, wọn ni ko si ọrọ ninu ohun ti ẹgbẹ naa n sọ rara.
Ijọba ni gbogbo ohun ti ẹgbẹ naa n beere fun, ni ijọba ti ṣiṣẹ lori rẹ.
Ninu atẹjade kan ti ileeṣẹ aarẹ fi sita nipasẹ oludamọran fun Aarẹ Muhammadu Buhari lori ọrọ iroyin, Femi Adesina, ijọba ni o jẹ iyalẹnu pe ẹgbẹ NDA n dunkoko mọ ijọba lẹyin ti Buhari ti gbe igbesẹ lori ọpọ ohun ti wọn n beere fun.
Adesina ṣalaye pe ijọba Buhari ti gbe igbesẹ lori atunto ijọba ati idagbasoke ẹkun Niger Delta ti ẹgbẹ NDA n sọ nipa rẹ.
Adesina sọ ninu atẹjade naa pe, Aarẹ Buhari ti ṣepade pọ pẹlu awọn alaṣẹ ẹkun Niger Delta ati ẹgbẹ Ijaw, Ijaw National Congress (INC).
Fuel Scarcity: IPMAN sọ fáwọn ọmọ ẹgbẹ́ rẹ̀ láti daṣẹ́ sílẹ̀ lọ́jọ́ Ìṣẹ́gun
Oríṣun àwòrán, Other
Ọwọn gogo epo bẹntiro tun ti n kan ilẹkun gbọngbọn lorilẹede Naijiria tori bi ẹgbẹ awọn alagbajata epo rọbi, IPMAN se n gbero lati gbe awọn ileepo tipa kaakiri Naijiria.
Nigba to n ba awọn akọroyin sọrọ lọjọ Aiku niluu Jos, agbẹnusọ fun ẹgbẹ IPMAN, Yakubu Suleiman ṣalaye pe, ẹgbẹ naa ti sọ fawọn ọmọ ẹgbẹ lati da iṣẹ silẹ nitori bawọn ọlọpaa ti n dunkoko mọ wọn.
Suleiman ni awọn ọlọpaa tun ṣadede yabo olu ileeṣẹ ẹgbẹ IPMAN lọjọ Ẹti, lori aawọ to n ṣẹlẹ laarin awọn ọmọ ẹgbẹ lori ọrọ ipo olori.
O ṣalaye siwaju si pe, idajọ ileẹjọ to ga julọ ni Naijiria lọdun 2018 sọ pe Ọgbẹni Chinedu Okoronkwo ni aarẹ ẹgbẹ IPMAN, nigba ti Alhaji Danladi Garba Pasali, si jẹ akọwe agba.
Suleiman ni bi awọn ọlọpaa ṣe n tapa si idajọ ileẹjọ yii ko le bi ọmọ rere fun ẹka epo rọbi ni Naijiria.
Olowo: Bí ìjọba bá ṣe àtúntò tún yẹ, Sunday Igboho yóò fọwọ́sowọ́pọ̀ pẹ̀lú wọn
Agbẹnusọ ẹgbẹ IPMAN ni afaimọ ki igbesẹ awọn ọlọpaa yii maa jẹ ki ẹka epo rọbi ni Naijiria dẹnu kọlẹ.
Suleiman ṣalaye pe ọwọn gogo epo ni yoo ṣẹlẹ ti ẹgbẹ IPMAN ba le da iṣẹ silẹ lati ọjọ Iṣẹgun kaakiri orilẹede Naijiria.
O ni ẹgbẹ IPMAN ti n ṣepade kaakiri gbogbo ipinlẹ lati sọ fawọn ọmọ ẹgbẹ wi pe ki wọn da iṣẹ silẹ.
Agbẹnusọ ẹgbẹ IPMAN wa ke si ijọba lati wa nkan ṣe si bi awọn eeyan kan to fi mọ awọn ọlọpaa ṣe n tapa si idajọ ileẹjọ lori ọrọ IPMAN.
O ni ko si igba ti ẹgbẹ naa ko ni gbe awọn ileepo ti pa ti ọga agba ọlọpaa ni Naijiria ko ba wa wọrọkọ fi ṣada lori bawọn ọlọpaa ṣe yabo ile ẹgbẹ IPMAN lori ọrọ ti ileẹjọ ti yanju.
Jeleosinmi Art Centre: Ibùdó yìí ló ń tọ́ ọ̀dọ́ sọ́nà nípa iṣẹ́ ọnà àti àṣà dípò ìwà àìda
Abiola Ajimobi: Florence ní òun máa lọ ń mu kọfí létí ibojì olóògbé láàràárọ̀
Oríṣun àwòrán, Florence Ajimobi
Ọjọ ti a ba ku laa dere, eeyan o ṣunwọn laaye.
Lẹyin ti o pe ọdun kan ti gomina ipinlẹ Oyo tẹlẹ, Abiola Ajimobi jade laye, iyawo rẹ, Florence, ti sọ pe iku ọkọ ti mu oun dẹkun gbigba adura si Ọlọrun.
Florence fidi ọrọ yii mulẹ ninu ọrọ to sọ lasiko ayẹyẹ eto iranti ọdun kan oloogbe naa, bakan naa lo tun kọ awọn ọrọ awunilori nipa bo se nifẹ ọkọ rẹ si ninu iwe eto ti wọn se fun ayẹyẹ naa.
''Lai ṣe ani ani, ko rọrun fun mi rara lati maa gbe lai si ọkọ lati igba ti olowo ori mi ti jade laye.
Oun ni ololufẹ mi, nitori naa, o nira lati tẹsiwaju fun mi ṣugbọn mo gbagbọ pe ayipada yoo wa lọjọ kan.
Oríṣun àwòrán, Screen shot
O ti di aṣa mi lati maa joko si eti iboji rẹ laararọ, ati pe inu mi maa n dun wi pe ọkọ mi nifẹ mi,'' aya Ajimobi ṣalaye.
Ọjọ kẹẹdọgbọn oṣu kẹfa ọdun 2020 ni gomina ipinlẹ Oyo nigba kan ri dagbere faye, o si wọ kaa ilẹ lọ lọjọ kejidinlọgbọn oṣu kẹfa kan naa.
Iyawo Ajimobi ṣalaye pe, oun ati ọkọ oun to ti di oloogbe bayii ko tiẹ sọrọ nipa iku ri ninu irinajo ogoji ọdun ti wọn jọ rin, ki iku to mu un lọ.
''Inu mi dun nigba ti emi ati Biola gbe igbesẹ lọdun 1980 lati ṣe igbeyawo.
Mo le fi gbogbo ẹnu sọ pe emi ati Ajimobi ni ibaṣepọ to dan mọran, ti ẹnikẹni le ni fun ogoji ọdun ti a jọ gbe pọ.
Ṣugbọn iku ko dọjọ, arun ko doṣu, a maa n fi oju ara wa ri ni bi eeyan ṣe n ku, ṣugbọn  a ko tii ni iru iriri bayii fun ra, ko to di igba ti iṣẹlẹ yii ṣẹlẹ.
Oríṣun àwòrán, Screen Shot
Ogunjọ oṣu karun un ọdun 2020 ni ayẹwo fihan pe emi ati ọkọ ni arun coronavirus.
Lẹyin naa ni a ya ara wa sọtọ, ti a si bẹrẹ si ni lo oogun wa nile wa to wa ni Ikoyi niluu Eko gẹgẹ bi awọn dokita ti sọ fun wa.
Mo gbadura kikan kikan, mi o tii gbadura bayẹn ri laye.
Awọn ọmọ atawọn ọrẹ mi naa ko gbẹyin ninu adura gbigba, akoko naa jẹ akoko ẹru ati ireti fun mi.
Mo ni igbagbọ pe Ọlọrun yoo gbọ adura mi, yoo si mu ọkọ mi lara da.
Oríṣun àwòrán, Facebook/Florence Ajimobi
Amọ, lọjọ kẹẹdọgbọn oṣu kẹfa ọdun 2020, iṣẹlẹ nla ṣẹlẹ, iku wọle mu ololufẹ mi lọ.
Nigba naa ni mo mọ pe aye mi ti wa sopin nitori iku ti mu olololufẹ mi to n fun mi lagbara lọ.
Oju ti mi nitori mo ro pe Ọlọrun ti kọ mi silẹ papaa julọ lẹyin ibaṣepọ ti mo ni pẹlu Ọlọrun.
Mi o ko tiẹ mọ bo ya mo fẹ ya were nigba naa ni, koda o wu mi ki emi naa ku ki n le lọ ba Biola ọkọ mi.
Niṣe ni mo kan n wo awọn pasitọ ti wọn wa gbadura nile wa bi fọto nitori mi ko fẹ gbọ ohun ti wọn n sọ nipa Ọlọrun.
Oríṣun àwòrán, Florence Ajimobi
Tori pe Ọlọrun yii kan naa ni mo gbadura si lori ilera ọkọ mi eleyii to pada ku.
Ẹkọ ti mo ti kọ ni pe ti a ba padanu ẹbi, inu wa maa n bajẹ gidi gan an, o maa n dabi ẹni pe Ọlọrun ko si pẹlu wa mọ.
Amọ, Ọlọrun ko fi igba kan fi wa silẹ,'' aya Ajimobi lo sọ bẹẹ.
O ni ko si ẹni to le da bi Ajimobi ọkọ oun laelae nitori o yatọ ni gbogbo ọna.
Osun Masqurade attack: Kayode Esuleke, olórí egúngún to bá àwọn musulumi jà ní Osogbo wà láhámọ́ ọlọ́pàá
Oríṣun àwòrán, Esuleke Omokayode/Facebook
Rogbodiyan to waye laarin awọn ẹlẹsin musulumi ti ijọ Kamorudeen Society Central Mosque ati eleegun nilu Osogbo ni ọjọ Àìkú ti gba ọna miran yọ.
Idi ni pe ileesẹ ọlọpaa ni ipinlẹ Ọṣun ti mu olori awọn eleegun naa, oloye Kayode Eṣuleke si ahamọ.
Gẹgẹ bi iroyin abẹle kan ṣe sọ,  ikọ ọtẹlẹmuyẹ fun ọga agba ọlọpaa, IG Intelligence response Unit, lo ranṣẹ pe oloye Esuleke si ileeṣẹ wọn nilu Osogbo fun ifọrọwanilẹnuwo nibẹ, ti wọn si ti fi si ahamọ.
Glorious Twins: Taiwo àti Kehinde Ekundayo ní ọ̀dọ́ ìyá àgbà ní àwọn ti ẹ̀bún orin kíkọ
Lẹyin rogbodiyan to waye laarin awọn eleegun atawọn ẹlẹsin Musulumi niluu Osogbo, awọn ti ọrọ naa ṣoju wọn ti baba BBC Yoruba sọrọ lori ohun ti oju wọn ri.
Lasiko ti BBC Yoruba ṣabẹwo si agbegbe naa, ọkan lara awọn Musulumi ọhun, Salahudeen Yusuf sọ pe adura ki Naijiria le dara ni awọn n gba lọwọ, ki awọn eleegun naa to kọlu awọn.
"O ni ""Bi a ṣe kirun Aila tan ni awọn eleegun naa n lulu kọja, lẹyin naa ni wọn duro lagbegbe mọṣalaṣi wa."""
Ka to wi ka to fọ, wọn ti bẹrẹ si n sọko si wa, ti wọn si bẹrẹ si n yinbọn si wa.
Ibọn ba baba agbalaga kan lara wa, awọn miran ti ibọn ba ṣi wa nile iwosan LAUTECH bayii nibi ti wọn ti n gba itọju lọwọ.
Obinrin kan lara awọn Musulumi naa tun ṣalaye fun BBC pe, awọn ọlọpaa wa lara awọn elegun naa, ṣugbọn gbogbo akitiyan awọn lati rọ awọn ọlọpaa ọhun lati pana rogbodiyan naa, lo ja si pabo.
O ni awọn ko mura ija, bẹẹ ni awọn ko ba awọn eeyan naa ja nitori adura lawọn n gba, ṣugbọn awọn eleegun naa lo kọlu awọn, ninu eyii ti ẹmi kan ninu wọn ti sọnu.
Ẹwẹ, BBC kan si aṣoju idile awọn eleegun naa, Fasola Esuleke, to si sọ pe eegun idile wọn kii ṣe eegun oni jagidijagan.
Gẹgẹ bo ṣe sọ, awọn elegun naa n kọja lọ lagbegbe ti Mọṣalaṣi ọhun wa ni, ki awọn Musulumi ọhun to tọ ija awọn.
Fasola ni awọn kan n kọja lọ ni, kii ṣe awọn ya lọ ba awọn Musulumi naa.
"O ni ""Igba ti a n bọ ni gbogbo wọn kọlu wa to fi mọ awọn ọmọde to wa lara awọn."""
Wọn ko ada, igo ati okuta to fi mọ ibọn, koda wọn dana silẹ ti wọn si pe awọn yoo sun ẹku eegun.
Nibi ti a ti n du ki wọn ma farakan egungun, ni ọkan lara wọn gbiyanju lati ṣi ẹku egun kuro loju rẹ ṣugbọn egun ọhun salọ.
Fasola tẹsiwaju pe kii ṣe igba akọkọ ree ti awọn Musulumi naa ati olori wọn yoo kọlu awọn.
O fi kun pe pupọ ninu awọn ni wọn ṣe leṣe, koda o ni wọn gun ọmọ kan lara wọn lọbẹ ti ifun rẹ fi tu jade.
Aṣoju eleegun naa pari ọrọ rẹ pe awọn ko gbọ pe ẹnikẹni jade laye lasiko rogbodiyan naa.
Alukoro ileeṣẹ ọlọpaa ipinlẹ Osun, Yemisi Opalola ṣalaye fun BBC pe wọn ti fi ọrọ naa to awọn leto, lootọ si ni ikọlu waye ṣugbọn awọn ko tii le sọ ẹni to kọkọ kọlu ara ninu igun ẹgbẹ.
Opalola ṣalaye pe lootọ ni ẹnikan ba iṣẹlẹ naa lọ ṣugbọn awọn ko tii mọ irufẹ ẹni ti ẹni naa jẹ, nitori awọn mọlẹbi rẹ ko tii wa sọdọ awọn.
O fi kun pe awọn ti fi ṣikun ofin mu awọn eeyan kan, ṣugbọn o ni oun ko tii le sọ ni pato iye eeyan ti awọn ti mu.
Opalola pari ọrọ rẹ pe kii ṣe awọn Fulani lo wa nidi iṣẹlẹ naa, ṣugbọn iwadii ti bẹrẹ lati mọ ohun to ṣokunfa iṣẹlẹ ọhun.
Ki lo ti ṣẹlẹ sẹyin?
Oríṣun àwòrán, World Press
Saaju la ti mu iroyin wa fun yin pe rogbodiyan kan bẹ silẹ nilu Osogbo lọjọ Aiku ana eyi ta gbọ pe o mu ẹmi eeyan kan lọ nigba ti ọpọ eeyan miran sese pupọ.
Bi o tilẹ jẹ pe a ko tii lee fidi ohun to fa wahala yii mulẹ amọ gẹgẹ bi iwe iroyin Osun Defender ti wi, awọn egungun kan to dihamọra pẹlu ohun ija oloro lo fa sababi isẹlẹ naa.
A gbọ pe awọn egungun yii lo ti kọkọ n dun mahuru-mahuru tẹlẹ pẹlu awọn janmọ Mọsalasi kan ti ijọ wọn n jẹ Kamorudeen Islamic Society.
Asiko ti awọn ijọ ẹlẹsin Islam yii, to wa ladugbo Oluode Aranyin nilu Osogbo, si n se adura lọwọ ni wahala ọhun fọnna soju ni deede aago meji abọ ọsan.
Se la gbọ pe awọn egungun yii, to ti kọkọ n paraaro agbegbe ti mọsalasi naa wa, ti wọn n lọ, ti wọn n bọ, ba sadede bẹrẹ si sọ okuta lu awọn to n kirun nibẹ.
Oríṣun àwòrán, Osun Defender
Osun Defender, to ba ọkan lara awọn to fara gbọgbẹ nibi isẹlẹ naa sọrọ, jabọ pe awọn egungun ọhun lo de si adugbo naa pẹlu ikọ ọlọpaa ati Amotekun.
Amọ bawọn ikọ agbofinro naa se fi agbegbe ọhun silẹ, ni awọn egungun naa fa ibọn yọ, ti wọn si n yin lakọ-lakọ.
Asiko ti ibọn yii si n dun, la gbọ pe ibọn ba Baba ijọ Mọsalasi naa, Moshood Salawudeen, to si jade laye loju ẹsẹ.
Nigba to n bawọn akọroyin sọrọ, Imaam Mọsalasi naa, Quyum Yunus ẹni to fidi isẹlẹ naa mulẹ salaye pe, awọn egungun yii lo ni awọn n seto adura fun orilẹede Naijiria tori aabo to mẹhẹ.
Olowo: Bí ìjọba bá ṣe àtúntò tún yẹ, Sunday Igboho yóò fọwọ́sowọ́pọ̀ pẹ̀lú wọn
Ileesẹ ọlọpaa ipinlẹ Osun ko tii sọ ohunkohun lori isẹlẹ yii amọ BBC Yoruba yoo tẹsiwaju lati tanna wadi isẹlẹ yii, ta si mu abọ rẹ wa fun yin laipẹ.
Sunday Igboho: Kò sí ẹni tó ní kí ń má wá sí Eko tàbí pé wọ́n fẹ́ pa mí lásìkò ìwọ́de
Oríṣun àwòrán, sunday_igboho1
Nibayii ti ipalẹmọ fun iwọde Yoruba ti yoo waye nilu Eko lọjọ Satide to n bọ ti doju ọgbagade, awọn eeyan kan ti n kọminu nipa iwọde naa.
Lero tawọn eeyan yii, o seese ki asiwaju kan ninu awọn eeyan to n pe fun idasilẹ orilẹede Yoruba Nation, Oloye Sunday Igboho ma yọju silu Eko fun iwọde naa.
Awọn eeyan naa n kọminu lori idunkoko kan ti wsn ni awsn eeyan kan n se nipinlẹ Eko pe awọn ko fẹ ri awọn oluwọde Yoruba Nation kankan nibẹ.
Amọ nigba to n fesi lori ero awọn eeyan yii, Sunday Igboho ti leri leka pe oun n bọ nilu Eko lọjọ Satide fun iwọde naa.
Igboho ni ẹfọ kii le ẹfọ lawo, ara ilẹ Yoruba ni ilu Eko wa, ko si si ẹni to le ni ki oun ma wa sibẹ.
Sunday Igboho fulani ultimatum: Àwọn ará Kebbi àti Zamfara ló n jínígbé ní Oke Ogun- Serik
Igboho fi ọwọ idaniloju bẹẹ sọya lasiko to n tẹwọgba mọto kan tawọn eeyan kan ra fun iwọde Yoruba Nation.
O kede pe iwọde Yoruba Nation yoo waye gẹgẹ bi wọn se kede rẹ nilu Eko lọjọ Satide, ọjọ Kẹta osu Keje ọdun yii.
"Awọn eeyan kan n pariwo kiri pe ka mase wa silu Eko nitori pe wọn yoo pa wa, irọ nla ni.
Ko si ẹnikẹni to ni ki Igboho mase wa silu Eko, ko si si ẹni to sọ pe oun fẹ pa Sunday Igboho.
Ọmọ Yoruba pọnbele ni mi, ara ilẹ Yoruba si ni ipinlẹ Eko wa, kii se ilẹ Hausa tabi ti ẹya miran.
Olowo: Bí ìjọba bá ṣe àtúntò tún yẹ, Sunday Igboho yóò fọwọ́sowọ́pọ̀ pẹ̀lú wọn
Ẹ mase jẹ ka maa tẹti si gbọyi-sọyi amọ ẹ jẹ ka gbajumọ bi iwọde to n bọ lọna nilu Eko yoo se ri."
Sunday Igboho fikun pe ẹru ko ba oun nipa iwọde naa bi o tilẹ jẹ pe o see see ki ootọ wa ninu ahesọ ọrọ naa.
O ni iwọde alaafia ni awọn n bọ wa se nipinlẹ Eko gẹgẹ bawọn ti se yika awọn ilẹ Yoruba miran, awọn si n seto itaniji ati ilanilọyẹ kiri ni.
O fikun pe awọn ko lọ silu Eko lati lọ da wahala silẹ tabi fa ijangbọn lẹsẹ rara.
Bẹẹ ba gbagbe, gomina ipinlẹ Eko, Babajide Sanwo-Olu ti ni oun ko setan lati gbalejo awọn oluwọde naa nipinlẹ Eko nitori ọkansoso ni orilẹede Naijiria.
Bakan naa nileesẹ ọlọpaa nipinlẹ Eko ti ni awọn oluwọde Yoruba Nation ko tii bun oun gbọ nipa iwọde ti wọn fẹ se ọhun.
Peter Fatomilola: Robbery burú ju Yahoo lọ, iṣẹ́ ọpọlọ lọmọ Yahoo fi ń gba owó ìran baba
Kemisola Ogunniyi: Ọmọ tó bí sọ́gbà ẹ̀wọ̀n ló kọ̀kọ́ gba ẹ̀bùn ẹ̀kọ́ ọ̀fẹ́, kí ti ìyá rẹ̀ tó dé
Lati igba to ti gba itusilẹ nile ẹjọ, se ni idunnu ohun ayọ kan n ṣubu lù ara wọn fún Kemisola Ogunniyi.
Kemisola jẹ akẹkọọ ọmọ ọdun mejidinlogun ti ijọba sọ si ẹwọn pe o kopa ninu iwọde Endsars ni ipinlẹ Ondo.
Eyi taa tun ri gbọ laipẹ yii ni pe obinrin iya ikoko naa ti ri eto ẹkọ ọfẹ gba lọdọ ẹlẹyinju aanu kan.
Agbẹjọro rẹ, Tope Temokun lo fidi ọrọ yi múlẹ fun BBC Yoruba.
O ni ẹni tó ta Kemisola lọọrẹ yii jẹ alaanu, orukọ rẹ si ni Bamidele Omosehin, tii se oludasilẹ Bamidele Omosehin Foundation to sì jẹ ọmọ ipinlẹ Ondo.
Temokun salaye pe bayii, anfaani ẹkọ ọfẹ yii kan sisan owo idanwo Neco ati Idanwo igbaniwọle si yunifasiti ati owó ẹkọ rẹ titi ti yoo fi pari ile ẹkọ giga fasiti.
End SARS: Kemi jáde níle láti lọ bá mi ra oògùn ni mo gbọ́ pé ọlọ́pàá ti gbée- Ìyá Kemisol
Ṣaaju ni ikoko Kemisola ti ṣe orire nipa bi eeyan kan ṣe fún ni anfaani ẹkọ ọfẹ lati ile ẹkọ akọbẹrẹ titi de ile ẹkọ girama.
Anfaani yii n waye lẹyìn osu mẹsan ti awọn agbofinro gbe Kemisola ati awọn oluwọde mii, to kopa ninu iwọde Endsars losu kẹwa odun 2020.
Kemisola ati awọn ti wọn mu la gbọ pe wọn dana sun olu ile ẹgbẹ oṣelu APC ni Akure.
Ọgba ẹwọn Surulere ni ijọba ibilẹ iwo oorun Ondo lo wa, tó sí bimọ si lọjọ kẹrindinlogun osu kẹfa.
Okiki Kemisola kan, t'awọn ọmọ Nàìjíríà sí gbarata pe ko dara bo ṣe bimọ si ẹwọn.
Olowo: Bí ìjọba bá ṣe àtúntò tún yẹ, Sunday Igboho yóò fọwọ́sowọ́pọ̀ pẹ̀lú wọn
Ọrọ Kemisola dayọ ni ọjọ kejilelogun oṣù Kẹfà nigba ti adajọ ile ẹjọ giga gba beeli rẹ.
Ikomọjade fun ọmọ Kemisola waye lẹhin to gba itusilẹ ni ọjọ Kẹtalelogun oṣù Kẹfà ni Akure.
Tunbosun Odunsin: Ẹlẹ́dàá ló fún mi ní tálẹǹtì ẹ̀kún sísun ní ìrọ̀rùn nínú eré tíátà
Gbajugbaja osere tiata kan Olatunbosun Odunsi, ti salaye pe talẹnti ti Ẹlẹda fun oun ni lati maa sọkun ni irọrun ninu ere tiata.
Odunsin, lasiko to n ba BBC Yoruba sọrọ, salaye pe akọsẹmọsẹ osere tiata ni oun, tawọn olootu ati oludari ere si maa n wa oun kiri tori talẹnti ẹkun sisun ti oun ni.
Bakan naa lo salaye akọsẹmọsẹ osere tiata gbọdọ le se ipokipo ti wọn ba fun ninu ere sise, is ti wọn ba si fun oun ni oun maa n se daada.
O ni wọn kii pe oun lati wa se ipo olowo nitori oun ko yọ ikun bii olowo rara amọ sa, wọn maa n pe oun lati ko ipa bii ọlọpaa ati adajọ ninu ere.
Osere tiata naa, ti ọpọ eeyan tun mọ si Paadi Mikailu tun salaye pe oun maa n sọ awọn eeyan ti nnkan ba sẹlẹ si loju aye lati mọ ihuwasi wọn.
O fikun pe iru iwa yii ni oun maa n gbe wọ nigba kiigba ti wsn ba gbe iru ipa bẹẹ fun oun.
Aisha Yesufu: Àbúrò ìyá mí tó ti wà di olùṣọ àgùntàn lóni fojú mí rí mọbo
Oríṣun àwòrán, Aisha Yesufu/Facebook
Yoruba ni oju ẹni maa la, o di dandan ko ri to, bẹẹ ni si ọla ni iyọnu tiẹ.
Bẹẹ ni ọrọ ri nigba ti Aisha Yesufu, to jẹ́ gbajugbaja ajafẹtọ ọminiyan ni Naijiria tẹnu bọ itan igbesi aye rẹ fun awọn akọroyin.
Ninu alaye rẹ, Aisha sọ nipa bi aburo baba rẹ ṣe sọ fún ùn pé kò ni já mọ nkankan laye rẹ.
Ninu ọrọ tó pọ bi igba ti eeyan n kọ episteli to kọ sójú opo ayelujara rẹ, Aisha Yesufu ni ẹni to fi iya jẹ oun ni kekere yii, kii ṣe ara ita si oun rara.
O ni aburo mama oun ẹni naa ṣe ati pe loni bayii, ẹni náà ti di Oniwaasu ọrọ Ọlọrun, ìyẹn ni pé Pasitọ ni.
Tunbosun Odunsin: Ẹlẹ́dàá ló fún mi ní tálẹǹtì ẹ̀kún sísun ní ìrọ̀rùn nínú eré tíátà
"Aburo mama mi yii sọ fun emi ati mama mi nisoju iya to bi mama mi pe, osi ni yoo ta wa ku
O sọ ọpọlọpọ nkan ti o jẹ ọrọ kobakungbe fún wa nígbà naa lọhun, amọ mo ti n gbọ ọpọ ninu rẹ tẹlẹ ṣugbọn ti mi o jẹ sọ fún maami."
"Aisha Yesufu ni ""ọgbẹ ọkàn ni ọrọ naa jẹ nitori o gba omijé loju mama mi"""
"Ẹni táa n wí yií, mama mi lo tọ dagba. Nigba ti yóò ṣe igbeyawo ko ni owo ti yóò fi gba ile, koda ọdọ wa ló n gbe.'
Kunle Olajide, Akọ̀wé ìgbìmọ̀: Ẹ̀yin ọ̀dọ́, ọjọ́ ọ̀la yin kò ṣe e fọ́wọ́ ẹ sọ̀yà, ẹ díde
Nigba to bẹrẹ ilé ẹkọ jeleosinmi, Aisha Yesufu ni awọn obi oun lo fún ọkunrin naa lowo to fi bẹrẹ rẹ.
Ko pẹ, bi nkan ṣe yi pada fún wa niyẹn, ti ati gbọ bukata sí nira fún wa, lọdọ aburo iya mi yii ni mo padà wá lọ gbe.
Níbẹ ni o ti fi iya jẹ mí, to sí n sọ fún mi pé mi o le jẹ eniyan laye."
Ọrọ pọ ti Aisha Yesufu sọ nípa mọlẹbi rẹ yii amọ o ni oun dupe pe ero rẹ kò padà ṣẹ lori oun.
Iskilu Wakili Vs OPC: Àwọn OPC mẹ́ta tó ṣẹ̀ṣẹ̀ gba ìdáǹdè l‘àhámọ́ sọ ohun tójú wọn rí
Oríṣun àwòrán, Facebook/OPC Diary
Awọn ọmọ ẹgbẹ OPC mẹta ni agbegbe Ibarapa ti awọn ọlọpaa mu si ahamọ lasiko ti wọn mu afurasi ọdaran darandaran ni Igangan, Iskilu Wakilu, ti sọrọ nipa ohun ti oju wọn ri.
Orukọ awọn ọmọ ẹgbẹ OPC naa, ti wọn jẹ igun Gani Adams ni Hazzan Raman, Dauda Kazeem ati Awodele Awodigba, ti gbogbo wọn jẹ ọmọ bibi agbegbe Ibarapa.
Awọn akọni mẹtẹẹta naa, ninu fidio kan to jade sori ayelujara salaye pe o ti to ọdun meji ti Wakilu ti bẹrẹ iwa ijinigbe gba owo, ifipabanilopọ ati ipaniyan lagbegbe Ibarapa.
Wọn ni afurasi ọdaran yii ni awọn ọmọ ogun to n sisẹ fun ninu isẹ ibi rẹ yii, ti awọn agbofinro si mọ gbogbo wọn bi isana ẹlẹẹta.
Wọn ni bi awọn ba se n mu awọn ọmọ Wakilu afurasi onisẹ ibi yii, ni awọn ọlọpaa ma n fi wọn silẹ, eyi to mu ki isẹ ibi rẹ maa lekenka siwaju si.
Awọn mẹtẹẹta salaye pe lẹyin ti Sunday Igboho fun awọn ọdaran Fulani ni gbedeke lati ko aasa wọn kuro ni agbegbe Ibarapa, ọpọ wọn lo salọ sinu igbo.
Wọn ni inu igbo yii ni wọn wa, lai le si igboro mọ tabi wọ inu ile wọn pẹlu.
Wakili tẹẹ rí yẹn kìí ṣe ẹran rírọ̀, ó ń díbọ́n ní o - Iba Gani Adams
Ninu ifọrọwerọ naa ni awọn ọmọ ẹgbẹ OPC yii ti salaye pe ọmọ Wakili to wa ni ahamọ pẹlu awọn sọ pe awọn Fulani ti setan lati pa iran Yoruba run ni agbegbe Ibarapa.
Wọn ni se ni ẹnu ya awọn ni ọjọ to sọrọ naa, to si fikun pe Fulani kii dari jin eeyan, o si di dandan ki awọn gbẹsan iwa tawọn Yoruba hu si Fulani.
"Ọmọ Wakili sọ fun wa pe ni ọjọ tawọn ba kọlu Yoruba ni agbegbe Ibarapa, ọrọ naa yoo kọ sisọ.
Inu atimọle si la wa nigba ta gbọ isẹlẹ ipaniyan ọlọgọọrọ to waye nilu Igangan laipẹ yii, ẹnu si ya wa lootọ.
Koda, o sọ fun wa pe awọn Miyetti Allah ti tọwọ bọ ọrọ wa, ti a si gbọdọ fi oju bale ẹjọ dandan."
Wọn fikun pe ori ẹtu ibọn ni awọn eeyan agbegbe Ibarapa joko le, o si yẹ kawọn ọba wa dide si ọrọ yii nitori ogun si n bọ.
"Awọn Fulani ti ni awọn n bọ wa jẹ ilu wa run, a si fẹ kawọn ọba wa jade sita lati ke yanya pe a ko fẹ Fulani mọ ni agbegbe Ibarapa.
To ba jẹ pe bi Sunday Igboho ti kegbe sita, naa ni awọn ọba sugba rẹ, lai jẹ ko sinmi, ti wọn si n gbogun ti awọn Fulani yii, ọrọ ko ba ti yanju.
A si fẹ ki awọn ọba wa sọ fun awọn Fulani to sa lọ silu Igbo Ora pe ki wọn kuro nibẹ, ki alaafia le jọba ni awọn agbegbe yoku to wa ni Ibarapa."
Bí ìjọba, ọlọ́pàá, ológun, Amotekun ò bá le gbà wá, àwa mú Wakili láti gba ìran Yorùbá sílẹ̀ ni - OPC
Awọn akọni ọmọ Oodua yii tun sisọ loju rẹ pe awọn ọmọ Yoruba ti wọn n ko ẹran fun Iskilu Wakilu atawọn darandaran Fulani yoku lati tọju fun wọn lo wa lẹyin awọn afurasi ọdaran naa.
Wọn ni awọn ọmọ Yoruba yii lo maa n pe Wakilu lati se ofofo fun lasiko ti awọn eeyan kan ba fẹ lọ kọ lu ninu igbo to wa, ti yoo si mura silẹ de wọn.
Bakan naa ni wọn fi kun pe awọn agbodegba ọmọ Yoruba naa lo maa n lọ ra eroja ounjẹ, awọn ohun eelo miran pẹlu ohun ija fun Wakilu lasiko to wa ninu igbo to salọ lẹyin abẹwo Sunday Igboho.
"Awọn Yoruba ara wa to jẹ Alapata, lo sofofo fun Wakili pe a n bọ lọjọ ti a lọ mu. Wọn ti gbaradi de wa, ti wọn si n yinbọn mọ wa, lọjọ ti a lọ mu.
Amọ Oodua tẹle wa lọjọ naa ni ọwọ wọn ko se ka wa, koda, awọn baba nla wa ko sun lọjọ naa, wọn gbe wa nija ni, bibẹẹkọ, ọrọ naa ko ba yiwọ."
Igangan Attacks: Àkójọpọ̀ àbọ̀ BBC Yorùbá rèé nípa ìṣẹ̀lẹ̀ òfò ẹ̀mí àti dúkìá tó wáyé
Nigba ti wọn n salaye ọpọ igbesẹ to ti kọkọ waye saaju lati mu afurasi ọdaran naa, awọn akọni ajijagbara naa ni ofo ni gbogbo igbesẹ lati mu n ja si.
Wọn salaye pe awọn apapọ araalu ti kọkọ fun Wakili ni iwe pe ko fi agbegbe naa silẹ, ta mọ si Quit Notice amọ wọn lo fi aake kọri ni.
Wọn ni Wakili sọ fawọn araalu pe ko si baba nla baba ẹni to le le oun kuro ni ibi ti oun wa.
"Saaju ni igbesẹ awọn ọlọpaa lati mu Wakili n ja si pabo nitori bi wọn ba se fẹ mu, ti wọn de ẹnu ọna ile rẹ, ni wọn yoo ni asẹ wa lati oke pe ki awọn fi silẹ.
Nigba to ya nijọba ipinlẹ Oyo fi ikọ Amotekun sọwọ lati mu, ti wọn si kun inu ọkọ nla Hilux bii mẹẹdogun amọ o ku diẹ ki wọn wọnu igbo to wa, ni wọn duro.
Wọn ni awọn tun ti gba order"" pe awọn ko gbọdọ wọnu igbo lọ mu, eyi si lo kọ wa lominu lati lọ mu funra wa."
Sunday Igboho: Seriki Fulani àti ẹbí rẹ̀ gba inú igbó dé ìpínlẹ̀ Ogun
Awọn ọmọ ọgbẹ OPC mẹtẹẹta yii tun salaye pe ẹran ti wọnu egungun, egungun si ti wọnu ẹran, ni ọrọ awọn ọdaran Fulani to wa ni agbegbe Ibarapa.
Wọn ni ọpọ awọn afurasi ọdaran naa ni wọn dara pọ mọ awọn ọdẹ ibilẹ fijilante lati maa sisẹ ibi wọn.
"Wọn n lo isẹ Fijilante naa lati maa ra awọn ohun ija oloro to lagbara, ti wọn si n sọ fun awọn agbofinro to ba bi wọn lọna pe fijilante ni awọn.
Koda, wọn ni Kaadi idanimọ fijilante lagbegbe Ibarapa lọwọ, ti wọn si n fi se isẹ ibi."
Tunbosun Odunsin: Ẹlẹ́dàá ló fún mi ní tálẹǹtì ẹ̀kún sísun ní ìrọ̀rùn nínú eré tíátà
Awọn ọmọ Wakili lo jo ile ati dukia wọn, ti wọn si parọ mọ wa ni ọdọ ọlọpaa pe awa la sisẹ ibi naa:
Awọn OPC naa fikun pe nigba ti awọn mu Wakili de ọdọ ọlọpaa, ni ọmọ rẹ ti awọn ọlọpaa ti n wa lati ọjọ pipẹ wa ba awọn nibẹ.
Wọn ni awọn ọmọ Wakili yii wa fi ẹsun sun awọn ọlọpaa pe awọn ni awọn jo ile ati dukia Wakili, nigba to si jẹ pe funra wọn ni wọn ti dana sun awọn eroja naa.
Atimọle lati wa ridi okodoro ọrọ nigba ti ọmọ Wakili naa sọ fawọn pe awọn huwa naa lati ro ẹjọ mọ awọn lẹsẹ ni nitori awọn kuku mọ pe awọn ko le pada sinu ile awọn to wa laarin ilu mọ.
Wayi o, awọn ọmọ ẹgbẹ OPC mẹtẹẹta naa ti wa leri leka pe awọn ko ni dẹkun gbigbe iran awọn nija bi o tilẹ jẹ pe oju awọn ri ni ahamọ, tawọn si padanu ọpọ nnkan rere lasiko ti awọn wa ni atimọle.
Bakan naa ni wọn sọ iya nla to jẹ awọn mọlẹbi wọn lasiko ti wọn fi wa ni ahamọ ọlọpaa.
Jacob Zuma: Iléẹjọ́ tó gá jùlọ ní South Africa sọ̀ aarẹ́ àná sẹ́wọ̀n oṣù mẹ́ẹ̀dógún
Oríṣun àwòrán, AFP
Ile ẹjọ to ga julọ lorilẹede South Africa ti sọ aarẹ ana lorilẹede Naa, Jacob Zuma si ẹwọn ọdun kan ati osu mẹta.
Ileejẹ to ga julọ ni South Africa naa gbe igbesẹ yii lẹyin ti wọn ti se igbẹjọ aarẹ ana naa, ti wọn si ni o jẹbi ẹsun titẹ asẹ ileejọ loju.
Wọn ni Jacob Zuma fi aake kọri lati yọju siwaju igbimọ olugbẹjọ kan to n tanna wadi ẹsun iwa ajẹbanu ti wọn fi kan nigba to wa nipo aarẹ orilẹede naa.
Ọpọ ẹsun ajẹbanu ni wọn we mọ Zuma lọrun lasiko to wa lori oye, eyi to pari ọdun 2018.
Iroyin kan ni awọn olokoowo nla nla atawọn eekan oloselu lo pawọpọ ditẹ papọ lati tọwọ pọ eto idajọ naa.
Amọ aarẹ ana nilẹ South Afrika naa yọju lẹẹkan soso siwaju igbimọ oluwadi ọhun amọ ti ko yọju sibẹ mọ.
Igbimọ oluwadi naa, ti adajọ Raymond Zondo lewaju rẹ lo rọ ile ẹjọ to ga julọ naa lati da si ọrọ naa amọ a ko mọ boya wọn yoo lọ gbe Zuma nile.
Tunbosun Odunsin: Ẹlẹ́dàá ló fún mi ní tálẹǹtì ẹ̀kún sísun ní ìrọ̀rùn nínú eré tíátà
Ninu igbẹjọ miran, Zuma ti bẹbẹ losu to kọja pe oun ko jẹbi ẹsun iwa ajẹbanu kan ti wọn fi kan ninu igbẹjọ owo to to biliọnu marun dọla to yẹ ki wọn fi ra eroja ijagun lati ọdun 1990 siwaju.
Baba Ijesha: Iya Rainbow ní Princess ń sá ní iléẹjọ́ báyìí lẹ́yìn tọ́rọ̀ di ariwo tán
Oríṣun àwòrán, MAMARAINBOWOFFICIAL
Mama Rainbow ti kopa ninu ere to le ni ẹẹdẹgbẹta
Ọpọ eeyan lo ti n kọminu nipa laasigbo to n waye lagbo osere tiata Yoruba, paapaa bi awọn agba ati ọjẹ wẹwẹ osere se n tako ara wọn lasiko yii.
Gbogbo ede aiyede naa ko si sẹyin ọrọ ẹsun ti wọn fi kan gbajumọ osere tiata kan, Olanrewaju Omiyinka, ti ọpọ mọ si Baba Ijesha pe o se asemase pẹlu ọmọde.
Ọpọ awọn osere tiata si lo ti n gbe oju agan sira wọn lori isẹlẹ yii, bi awọn kan se ni o yẹ kawọn agba osere sọrọ soke lori isẹlẹ naa, ni awọn miran ni ko yẹ bẹẹ.
Ọpọ oṣere tiata bii Yomi Fabiyi lo tako Iyabo Ojo lori ọrọ naa, to si ti fa ede aiyede nla silẹ laarin wọn, to fi mọ Bukky Black, Legemiami ati awọn miran.
Bẹẹ ba gbagbe, ọjọ Aiku ni ẹgbẹ awọn osere tiata TAMPAN kede pe oun ko ni faramọ iwa ọyaju si ẹgbẹ naa latọdọ awọn osere tiata.
Mama Rainbow: iṣẹ́ tíátà kò ta sánsán mọ́ bíi ti ayé àtijọ́
Bakan naa lo ni ki gbajumọ oserebinrin meji, Iyabo Ojo ati Nkechi Blessing lọ rọkun nile na, tori bi wọn se n sọrọ tabuku ẹgbẹ naa.
Amọ Nkechi Blessing lo ti n sọrọ tako igbesẹ naa, to si n gboju agan si agba osere kan, Jide Kosoko, ẹni to jẹ ọkan lara igbimọ majẹobajẹ ẹgbẹ TAMPAN to kede ijiya ẹsẹ oserebinrin mejeeji naa.
Nkechi naa ṣalaye tiẹ pe ẹgbẹ TAMPAN ko lagbara lati da oun duro nitori oun kii ṣe ọmọ ẹgbẹ naa.
Bakan naa lo tun sọ fun agba oṣere Jide Kosoko pe awọn ọmọbinrin rẹ yoo dọwọ boju ti oun ba fi le tu aṣiri rẹ sita.
Amọ Iyabo ni oun ko korira Baba Ijesha bi ko ṣe ẹsun ifipabanilopọ ti wọn fi kan lori ọmọdebinrin adẹrinṣonu, Princess.
Awọn iwa yii lo ti wa n kọ ọpọ eeyan lominu, ti wọn si n beere pe igba wo ni alaafia yoo pada sagbo tiata, ẹka ti Yoruba?
Kunle Olajide, Akọ̀wé ìgbìmọ̀: Ẹ̀yin ọ̀dọ́, ọjọ́ ọ̀la yin kò ṣe e fọ́wọ́ ẹ sọ̀yà, ẹ díde
Idi ree ti BBC Yoruba fi kan si ọkan lara awọn agba ọjẹ oṣere tiata lati mọ igbesẹ ti wọn n gbe, lati pe omi alaafia pada wa sagbo tiata Yoruba.
Nigba to n ba BBC Yoruba sọrọ, Idowu Philips tawọn eeyan mọ si Iya Rainbow ni ọrọ naa ti daru bi ẹsẹ telọ bayii.
''Ki ọrọ yii to delẹ rara, ọjọ mẹrin ni mo fi bẹ Princess wi pe ko maa jẹ ki ọrọ yii di ẹjọ.
Mo bẹ ẹ gan an wi pe ko maa jẹ ki ọrọ yii di ariwo, ẹ wa wo ohun to gbẹyin ọrọ yii bayii.
Baba Ijesha da nisin yii, wọn ṣi i silẹ, iyẹn ni a ṣe n sọ pe ki a tun nkan ṣe niyẹn.
"Baba Ijesha jẹbi, o jare, ki awa kọkọ dide bi ẹgbẹ. Ni sin yii, Princess wa n sa ni ile ẹjọ wi pe ọna wo ni oun le gba lẹyin, ki wọn maa ri oun."""
Tunbosun Odunsin: Ẹlẹ́dàá ló fún mi ní tálẹǹtì ẹ̀kún sísun ní ìrọ̀rùn nínú eré tíátà
Iya Rainbow tẹ́siwaju pe ibẹrẹ ija kọ ni eeyan maa n ro, a n ji lati ro ibi ti ija maa pari si.
O wa gbadura pe ki Ọlọrun fun onikaluku ni omi suuru mu, nitori adura ni ọrọ naa gba bayii.
O ni ti Esu ba ti wọ ṣokoto, o maa n ko sinu awọn ọmọde yẹn ni, ko si si nnkan ti agbalagba maa se nipa rẹ.
Ṣe a fẹ ṣepe fun wọn ni, ṣe a fẹ le wọn ni? Kin lo fẹ gbẹyin rẹ? Eeyan kii leyan nibi ijẹ rẹ. Ẹ maa binu naa ni wọn maa sọ fun wa, ti awa agba yoo si gba a mọra.
Agba osere tiata naa ni ohun to wa nibẹ ni pe Eleduwa naa ni awọn yoo maa bẹ, ko ba awọn yanju ọrọ to wa nilẹ yii.
Baba Ijesha: Ebun Oloyede ní àwọn ọmọ ẹgbẹ TAMPAN ní ẹgbẹ́ fòfin dè láti máṣe bá Iyabo Ojo àti Nkechi Blessing ṣiṣẹ́ papọ̀
Oríṣun àwòrán, NaijaExpress.com
Gbajumọ oṣere tiata Yoruba, Ebun Oloyede, ti ọpọ awọn ololufẹ rẹ mọ si Olaiya Igwe ti sọ pe, ẹgbẹ awọn ko lagbara lati fofin de Nkechi Blessing ati Iyabo Ojo lẹyin ti wọn ri awọn agba ẹgbẹ naa fin.
Olaiya lo ṣiṣọ loju ọrọ naa lori eto kan to ti fọrọ jomitoro ọrọ pẹlu BBC Yoruba.
Igwe ṣalaye pe niwọn igba ti awọn oṣere naa kii tii ṣe ọmọ ẹgbẹ awọn, iyẹn TAMPAN, awọn ko le fofin de wọn lati ma ṣere mọ.
Ṣugbọn o ṣalaye pe ẹgbẹ ọhun ti paṣẹ pe ẹnikẹni ninu awọn ọmọ ẹgbẹ naa ko gbọdọ ba eyikeyi ninu Iyabo Ojo ati Nkechi Blessing da iṣẹ pọ mọ fun saa yii.
"O ni ""Oṣere tiata ni wọn, ṣugbọn wọn kii ṣe ọmọ ẹgbẹ TAMPAN, nitori naa ẹgbẹ wa ko le fofin de awọn memeji."""
Oríṣun àwòrán, @olaiya_igwe01
Ṣugbọn iru emi ti mo n ba yin sọrọ yii atawọn ọmọ ẹgbẹ ti orukọ wọn wa ninu iwe ẹgbẹ wa, ni wọn fofin de lati mase ba Nkechi Blessing ati Iyabo Ojo ṣiṣẹ mọ.
Ṣaaju ni Nkechi ati Iyabo ti kọkọ sọrọ kobakungbe si awọn agba ẹgbẹ TAMPAN loju opo Instagram wọn, lori awọn ọrọ kan to ti ṣẹlẹ ṣaaju, paapaa lori ọrọ baba Ijesha.
Ẹwẹ, ni ti ijiya to wa fun awọn oṣẹre tiata Yoruba to ba tasẹ agẹrẹ, Olaiya sọ pe Aarẹ ẹgbẹ TAMPAN, Bola Amusan, ta tun mọ si Mr Latin, nikan lo le sọ irufẹ ijiya to yẹ fun wọn.
Olaiya sọ pe awọn idanilẹkọ maa n waye ninu ẹgbẹ TAMPAN, nibi ti wọn ti maa n ba awọn oṣere sọrọ lori bo ṣe yẹ ki wọn ṣe maa ṣe lawujọ, ṣugbọn onikaluku ni yoo mọ bi yoo ṣe maa ko ara rẹ ni ijanu.
Loni Ọjọbọ, ọjọ kẹrinlelogun, oṣu Kẹfa, ọdun 2021, ni wọn o tun gbe oṣerekunrin, Olanrewaju Omiyinka, ti ọpọ eeyan mọ si Baba Ijesha, lọ si ile ẹjọ.
Ni ti afojusun rẹ fun ọjọ iwaju, Olaiya sọ pe ere ti oun yoo ṣe kẹyin yoo milẹ titi, koda aye yoo gbọ, ọrun yoo mọ pẹlu.
O ni yoo wu ohun ki sinima naa le wọ ori ẹrọ Ntflix, nibi ti awọn eeyan yoo ti le maa wo kaakiri agbaye, ati pe o ṣeeṣe ko jẹ pe ere naa ni sinima ti oun yoo gbe jade kẹyin.
Lẹyin naa lo gba awọn ololufẹ tiata Yoruba niyanju lati maṣe maa wo awọn aṣemaṣe awọn oṣere, ṣugbọn ki wọn maa wo awọn ere wọn lati kọgbọn ati fun oniruru awokọṣe rere.
Tunbosun Odunsin: Ẹlẹ́dàá ló fún mi ní tálẹǹtì ẹ̀kún sísun ní ìrọ̀rùn nínú eré tíátà
Nnamdi Kanu: Omoyele Sowore ní gbọin-gbọin lòun wà lẹ́yìn Nnamdi Kanu
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Lẹyin ti ijọba apapọ mu olori ẹgbẹ to n jijagbara fun idasilẹ orilẹede Biafra (IPOB), Nnamdi Kanu lọjọ Iṣẹgun, Biṣọọbu ijọ Anglican niluu Enugu, Ẹniọwọ Emmanuel Chukwuma ti sọ pe ipasẹ obinrin ni wọn fi mu.
Ẹniọwọ Chukwuma ni to salaye ọrọ yii fun iwe iroyin Punch, wa lu ijọba lọgọ ẹnu lori bi wọn ṣe mu Kanu pada, lẹyin to sa lọ tẹlẹ nigba ti wọn kọkọ fi ọwọ ofin mu un.
''Nigba to wa ni oke okun, oun lo n lo awọn ọmọ ẹgbẹ IPOB nilẹ Igbo lati maa da rogbodiyan silẹ.
Ọpọ igba ni a kilọ fun un, ṣugbọn ko gbọ si wa lẹnu nigba naa.
Ohun ti awa ro ni pe gẹgẹ bi olori, o yẹ ki Kanu wa sile, ki a si jọ sọ asọyepọ lori ọrọ to wa nilẹ.
#BBCNigeria2019: Nnamdi Kanu sọrọ lórí àwọn oludije PDP àti APC
Kanu ko sọwọ obinrin tawọn ileeṣẹ ọtẹlẹmuyẹ dẹ si i lati ilu London lọ si orilẹede Brazil.
Eleyii fihan pe olori yẹpẹrẹ ni Kanu, bi bẹẹ kọ ọ, ba wo ni obinrin ṣe maa ri ẹ mu ti o ba jẹ olori gidi?
Obinrin lo tan Kanu lati ilu London lọ si orilẹede Brazil, ohun itiju nla ni.
Omoyele Sowore ni gbọin-gbọin lòun wà lẹ́yìn Nnamdi Kanu:
Ninu ọrọ tiẹ, Omoyele Sowore to ṣagbatẹru iwọde RevolutionNow ni gbọin gbọin loun wa lẹyin Kanu.
Sowore ni oun naa ti wa ni ipo ti Kanu wa lọwọ yii ri tẹlẹ.
O ni iru iriri ati idojukọ ti awọn ajijagbara maa n ri ni olori ẹgbẹ IPOB n ri lọwọ bayii.
Glorious Twins: Taiwo àti Kehinde Ekundayo ní ọ̀dọ́ ìyá àgbà ní àwọn ti ẹ̀bún orin kíkọ
Eekan ẹgbẹ Afenifere, Oloye Ayo Adebanjo ti bu ẹnu atẹ lu bi ilẹ okeere ṣe fa Kanu le ijọba Naijiria lọwọ ni tẹ.
Oloye Adebanjo ni ko tọ ki wọn tun fa Kanu le ijọba Naijiria, to jẹ ọta rẹ lọwọ niwọn igba ti wọn ti gba a laaye lati ṣe atipo nibẹ tan.
Adebanjo ni ohun ti ijọba UK ṣe fun Kanu, wọn ti ṣe bẹẹ naa ri fun ẹgbẹ oṣelu Action Group, nigba ti wọn fa Oloye Anthony Enahoro le ijọba Naijiria lọwọ.
Amọ, ilẹ Gẹeṣi ti sọ pe UK kọ ni wọn ti mu Kanu pada gẹgẹ bi iroyin kan ṣe sọ.
Agbẹnusọ fun olu ileeṣẹ ijọba orilẹede UK ni Naijiria, Dean Hurlock, ṣalaye pe kii ṣe UK ni wọn ti mu Kanu ki wọn to da a pada si Naijiria.
Ẹwẹ, ẹgbẹ IPOB ti wa kilọ fun ijọba apapọ pe eera ko gbọdọ ra Kanu ni atimọle ajọ DSS to wa.
Ninu atẹjade to fi sita lọjọ Iṣẹgun, ẹgbẹ naa ni Kanu ko tii jẹbi ẹsun kankan labẹ ofin pẹlu gbogbo ẹsun ti wọn fi kan an.
Ẹgbẹ naa nkan ko gbọdọ ṣe e titi ti igbẹjọ rẹ yoo pari nitori ẹtọ rẹ ni lati wa ni alaafia bi igbẹjọ ṣe n lọ lọwọ.
Oríṣun àwòrán, SCREEN SHOT
Ilé ẹjọ́ ti pàṣẹ kí wọ́n fi Nnamdi Kanu sí àhámọ́ títí di ọjọ́ kẹrìndínlọ́gbọ̀n oṣù tó ń bọ̀
Ọwọ ijọba apapọ orilẹede Naijiria ti tẹ asaaju ikọ to n jija gbara fun ẹya Igbo, Nnamdi Kanu.
Minisita feto idajọ ati agbẹjọro agba ni Naijiria, Abubakar Malami lo fidi isẹlẹ naa mulẹ fawọn akọroyin lọjọ Isẹgun.
Malami ni wọn mu Kanu nilu Ọba to wa, ti wọn si gbe wa sorilẹede yii lọjọ Aiku.
O fikun pe ọwọ tẹ asaaju ajijagbara fun ikọ IPOB naa pẹlu ifọọwọsowọpọ awọn ileesẹ agbofinro lorilẹede Naijiria ati ajọ ọtẹlẹmuyẹ Interpol.
Oríṣun àwòrán, Screen Shot
Bakan naa ni Minisita feto idajọ fikun pe wọn yoo gbe Kanu lọ sile ẹjọ giga tijọba apapọ nilu Abuja lati tẹsiwaju pẹlu ẹjọ to n jẹ tẹlẹ.
Awọn ẹsun naa lo nii se pẹlu iwa idunkoko mọ ni, idaluru, kiko ohun ija oloro jọ lai bofin mu ati akoso awujọ to tako ofin.
Bẹẹ ba gbagbe, osu Kẹrin ọdun 2017 ni wọn gba oniduro Kanu lori awijare pe ara ko da amọ to sa kuro lorilẹede yii.
Lẹyin eyi ni awọn ileesẹ agbofin nilẹ Naijiria kede pe awọn n wa olori ikọ ajijagbara ti ijọba fofin de naa.
Ile ẹjọ giga ilu Abuja lo pasẹ losu kẹta ọdun 2019 pe ki wọn lọ mu asaaju ikọ IPOB, Nnamdi Kanu.
Ẹsun idaluru ni wọn fi kan Kanu nigba naa, to si foju bale ẹjọ.
Kunle Olajide, Akọ̀wé ìgbìmọ̀: Ẹ̀yin ọ̀dọ́, ọjọ́ ọ̀la yin kò ṣe e fọ́wọ́ ẹ sọ̀yà, ẹ díde
Adajọ Binta Nyako wa kede pe oun yoo maa tẹsiwaju pẹlu igbẹjọ Kanu bi o tilẹ jẹ pe o ti kuna lati yọju sile ẹjọ lati ọjọ Kẹẹdọgbọn osu Kẹrin ọdun 2017.
O ni Kanu ko salaye idi ti ko fi yọju sile ẹjọ rara, idi si ree to fi gbe idajọ rẹ le ofin ilẹ wa, abala iwa ọdaran tọdun 2015, ori 352, ẹsẹ kẹrin.
Amọ agbẹjọro fun Nnamdi Kanu, Ifeanyi Ejiofor lo tako ẹbẹ agbẹjọro fun ijọba, Magaji Labaran.
Ejiofor ni ki ile ẹjọ fun oun ni akoko diẹ si lati le salaye idi ti onibara oun ko fi yọju sile ẹjọ amọ ile ẹjọ faake kọri lati gba ẹbẹ rẹ.
Baba Ijesha: Yomi Fabiyi ní ọ̀rọ̀ tí ẹnìkan bá sọ láwùjọ, lá fi mọ̀ irú ẹbí tó ti jáde àti ẹni tó tọ
Oríṣun àwòrán, realyomifabiyi/Instagram
Gbajugbaja osere tiata Yoruba Yomi Fabiyi tun ti n sọ oko ọrọ sawọn eeyan kan loju opo Instagram rẹ.
A ko mọ ẹni to n ba wi tabi idi to fi n sọ ọrọ naa ṣugbọn aroko rẹ naa fara jọ aawọ to gba igboro lori ọrọ oṣere tiata nni, Baba Ijesha.
Lẹnu ọjọ mẹta yii, fa ki n fa ti n waye laarin Yomi Fabiyi ati awọn osere tiata miran lapa, kan to se pe eyi si ti mu ki awọn to jẹ agbagba ẹgbẹ awọn osere tiata dasi ọrọ naa.
Nibi ọrọ to kọ laipẹ yii to si fi soju opo rẹ ni Instagram, Yomi bẹrẹ ọrọ rẹ bi asamọ ati isiti, to sì fi ikilọ pari rẹ.
Yomi ni a mọ ẹni to wo wọn dagba ati idile ti wọn ti jade wa nigba ti  wọn ba n gbe apakan iroyin oju opo ayelujara lati ta fun araye.
O ni bi inu ba n bi eeyan kan nitori idi kan, tabi nkan ti ẹnikan se fun ninu ẹbi, to si n tabuku awọn agbaagba atawọn iran wọn to n bọ.
Loni Ọjọbọ, ọjọ kẹrinlelogun, oṣu Kẹfa, ọdun 2021, ni wọn o tun gbe oṣerekunrin, Olanrewaju Omiyinka, ti ọpọ eeyan mọ si Baba Ijesha, lọ si ile ẹjọ.
Yomi Fabiyi ni iru iwa bayii tumọ si pe iru ẹni bẹẹ ti n tabuku awọn obi rẹ nile, to si n bu wọn pẹlu.
O ni bakan naa si lo ri fun awọn eeyan to n ti iru ẹni bẹẹ lẹyin loju aye ati lori ayelujara.
"Ọmọ adulawọ ni wa, ti eeyan kan ba n fesi, to si n kọja aye rẹ nipa titabuku ipele ti Ọlọrun lo lati gbe onitọhun ga, ajẹ pe wọn ko mọ ohun to tọ niyẹn.
Yatọ si pe ka yẹra fun iru onitọun, ka si maa wo ni ọọkan, o tun se pataki pe ẹsan lati ọdọ Ọlọrun yoo waye."
Yomi Fabiyi fikun pe ko si ẹni ti wọn ko le tan jẹ lori ayelujara, ẹnikẹni si lo le sọrọ lori ohun kan tabi omiran lori ayelujara.
O wa kede pe ohun to daju ni pe ọjọ ọla loyun.
Oríṣun àwòrán, realyomifabiyi/Instagram
O ni bi ọrọ ba ti le diẹ, paapa eyi to jọ mọ iwa ọdaran, ko tọ ki awọn eeyan maa lo ọgbọn inu ti wọn tabi nkan miran to yatọ si ofin, lati fi yanju rẹ.
''Ọtọ ni aaye ile ẹjọ amọ loju opo ayelujara, nkan tawọn eeyan ba n sọ ni wọn maa n fẹ ki araalu tẹle.
Idi ni pe erongba ẹni to kọ ọrọ ni pe o fẹ kawọn eeyan tẹle nkan to ba fẹ ni.''
"O tẹ siwaju pe ""ki awọn eeyan lọ ni arojinlẹ daada, ki wọn si maa ranti pe aabo, alaafia ati ẹtọ ọmọniyan se pataki, ki a to kọ nkankan tabi bawọn se alabapin iroyin kankan loju opo ayelujara.''"
"Ko tan sibẹ, Fabiyi sọ pe ""awọn to n fi aimọkan sọrọ loju opo ayelujara, ibẹ naa lariwo wọn maa n  pin si."""
''Fifi aimọkan han lori ayelujara paapa nigba ti ko ba ti lapa lori nkan ti ofin sọ, ko le kọja oju opo ayelujara''
Tunbosun Odunsin: Ẹlẹ́dàá ló fún mi ní tálẹǹtì ẹ̀kún sísun ní ìrọ̀rùn nínú eré tíátà
Awọn amofin ati adajọ ni imọ nipa ofin, ko si si nkan tẹle se si.
O fi kun ọrọ rẹ pe ti nkan tawọn eeyan ba n sọ lori ayelujara ba ba ofin mu, o se deede fawujọ ni yẹn.
Amọ bi o ba yapa si nkan tofin sọ, ko le yi nkan ti ofin sọ pada.
O wa rọ awọn to n se isiti yii  fun pe ki wọn se ohun to tọ, ki wọn si ri pe awọn tẹle ohun to tọ.
Ọrọ ti Fabiyi sọ pọ ṣugbọn a ko n i le sọ gbogbo ẹ tan.
Mama Rainbow: iṣẹ́ tíátà kò ta sánsán mọ́ bíi ti ayé àtijọ́
Eyi ta kan le fi tọka si ẹni to n ta ọfà ọrọ si ni pé  ọrọ rẹ n waye laipẹ si igba tawọn oserebirin tiata meji kan, Iyabo Ojo ati Nkechi Blessing fesi pada si ààrẹ ẹgbẹ oṣere TAMPAN, Jide Kosoko.
Ninu ọrọ awọn mejeeji, wọn ni awọn ko ni dakẹ lati maa sọ ohun to jẹ otitọ ati ododo paapa nipa ìṣẹlẹ tó kan Baba Ijesha, ti wọn fẹsun kan pe o ṣe aṣemaṣe pẹlu ọmọde.
Auxillary Kidnap Attempt: Akọ̀wé ẹgbẹ́ PMS ní àwọn ọmọ ẹgbẹ́ ọhún ni kò jẹ́ kí wọ́n rí Auxilliary gbé lọ
Oríṣun àwòrán, Facebook/Auxilliary Nation
Akọwe agba fun ajọ to n ri si akoso awọn ibudokọ, Oyo Park Management System (PMS) nipinlẹ Oyo, Comrade Oluwatomiwa Omolewa ti sọrọ lori isẹlẹ kan to waye lọjọ Isẹgun lori alaga ajọ naa.
Omolewa sisọ loju rẹ pe awọn eeyan kan lo wa nidii bi wọn se fẹ ji alaga ajọ PMS, Alhaji Isiaka Lamidi, ti ọpọ mọ si Auxilliary gbe lọ lọjọ Iṣẹgun niluu Ibadan.
Omolewa ṣalaye fawọn akọroyin pe awọn ọmọ ẹgbẹ PMS ni ko jẹ kawọn eeyan ọhun ri Auxilliary gbe lọ ni ọọfisi wọn to wa ni adugbo Podo-New Garage nilu Ibadan
Akọwe ẹgbẹ PMS ni awọn ọmọ ẹgbẹ naa lo gbe ija ko awọn to fẹ mu Auxilliary, nigba ti wọn sọ pe ọga agba ọlọpaa ni Naijiria lo paṣẹ pe kawọn wa mu eekan tẹlẹ ninu ẹgbẹ awakọ ero nipinlẹ Oyo naa.
''O tiẹ ya wa lẹnu pe ko si ọlọpaa kankan lati ipinlẹ Oyo ninu awọn to ni ọga ọlọpaa Naijiria lo ni kawọn wa mu Auxilliary wa.
Auxilliary : Sunday Igboho kìí ṣe ọmọ ìbàdàn, òun gan ló ń dá Ibadan ru
A pada le wọn kuro lẹyin ti wọn ko le fi kaadi idanimọ wọn han pe lootọọ ọlọpaa ni awọn i ṣe,'' Omolewa lo sọ bẹẹ.
Nigba to n dahun ibeere lori boya bi wọn ṣe fẹ mu Auxilliary nii ohun ṣe pẹlu iṣẹlẹ ipaniyan to mu ẹmi Rahmon Azeez atawọn meji mii lọ ni Iwo Road laipẹ yii, Omolewa ni ko si ohun to jọ bẹẹ rara.
Oríṣun àwòrán, The park Management Oyo State/Facebook
O ni ''ileeṣẹ ọlọpaa ti mu awọn afurasi to ṣagbatẹru rogbodiyan ni ikorita Iwo Road naa, ko si ẹnikan ninu awọn afurasi naa ti wọn mu to sọ pe Auxilliary lo ran awọn niṣẹ.''
Akowe ẹgbẹ PMS ni gbogbo awọn to fẹ mu Auxilliary lọna aitọ ni yoo kuna, nitori ẹgbẹ naa ko ni ṣe ohun kan to tapa si ofin orilẹede Naijiria.
Igbiyanju wa lati gbọ tẹnu ileesẹ ọlọpaa nipa isẹlẹ yii ni ko seso rere nitori agbẹnusọ fun ileesẹ ọlọpaa ipnilẹ Oyo ko gbe ipe wa.
Glorious Twins: Taiwo àti Kehinde Ekundayo ní ọ̀dọ́ ìyá àgbà ní àwọn ti ẹ̀bún orin kíkọ
Glorious Twins: Taiwo àti Kehinde Ekundayo ní ọ̀dọ́ ìyá àgbà ní àwọn ti gba ẹ̀bún orin kíkọ
Yoruba ni ọmọ ti yoo ba jẹ asamu, kekere ni yoo ti maa jẹnu samusamu.
Bẹẹ ni ọrọ awọn ọmọ ibeji ologo yii ri, Taiwo Ati Kehinde Ekundayo, ti ọpọ eeayn mọ si Glorious Twins.
Ọmọ ọdun mẹta ni awọn ọmọ mejeeji yii ti bẹrẹ si safihan si orin kikọ amọ wọn ko bẹrẹ si ni kọrin titi di igba ti wọn pe ọmọ ọdun mẹwa.
Nigba ti wọn n ba BBC Yoruba sọrọ, Taiwo ati Kehinde Ekundayo ni ọmọ ẹgbẹ akọrin ni baba ati iya awọn ninu ijọ Celestial kan.
Amọ wọn fikun pe ọdọ mama agba ti awọn gbe, to n lọ sinu ijọ aladura CAC, ni awọn ti mu ẹbun orin kikọ naa.
Bakan naa ni wọn salaye pe awọn ẹsẹ adura orin inu ijọ CAC ni awọn ti maa n ri imisi orin kikọ ti awọn n gbe sita.
Taiwo nifẹ lati di agbẹjọro nigba ti Kehinde fẹ di dokita ti yoo maa gba ẹmi eeyan la.
Awọn ibeji ologo yii ti gbe awo orin jade, ti wọn si ti se ere fun awọn eeyan jankanjankan bii Ọọni tilu ile Ifẹ ati Ọmọọbabinrin Kolade, tii se Iyalaje ilẹ Yoruba.
Nnamdi Kanu: Àwọn àgbà Yorùbá ní ọ̀rọ̀ Sunday Igboho kò papọ̀ mọ́ ti olórí ikọ̀ IPOB
Yoruba ni iku to n pa ojugba ẹni, owe nla lo n pa fun ni.
Idi ree ti awọn eeyan kan nilẹ Yoruba fi n bẹru pe nibayi tijọba apapọ ti gbe Nnamdi Kanu, tii se asaaju ikọ ajijagbara IPOB, o seese ki wọn mu Sunday Igboho naa, to jẹ asaaju awọn eeyan to n pe fun idasilẹ Yoruba Nation.
Amọ awọn eekan ọmọ ilẹ Yoruba kan ti n fesi lori ibẹru yii ati bi ijọba Naijriia se kede pe awọn ti ri Nnamdi Kanu mu.
Nnamdi Kanu ni olori ikọ ajijagbara to n pe fun idasilẹ orileeede awọn ẹya Igbo ti wọn pe ni Biafra.
Olowo: Bí ìjọba bá ṣe àtúntò tún yẹ, Sunday Igboho yóò fọwọ́sowọ́pọ̀ pẹ̀lú wọn
Ninu awọn to ba BBC Yoruba sọrọ ni Ọba Adetokunbo Tejuosho tii se Olu ti Orile Kemta ati Basorun Seinde Arogbofa, to jẹ akọwe fun ẹgbẹ Afenifere.
Ninu ọrọ ti wọn sọ, awọn mejeeji ni bayi ti wọn mu Nanamdi Kanu, ohun to ku ni ko lọ siwaju adajọ lati wi tẹnu rẹ.
Oba Adetokunbo, nigba to n salaye afiwe ati iyatọ to wa laarin eto ipolongo ti Kanu n ṣe fun idasilẹ Biafra pẹlu ti Sunday Igboho to fẹ idasilẹ Oduduwa Nation, oriade naa ni ọrọ awọn mejeeji ko jọ ara wọn.
Ninu iwoye rẹ, Oba Adetokunbo sọ pe ohun gbogbo eeyan lo lẹtọ ifẹhonuhan labẹ ofin Naijiria, yala fun Biafra tabi Oduduwa Nation.
''Ijijagbara Nnamdi Kanu ati Sunday Igboho ko papọ rara, iyatọ wa laarin Kanu ati Igboho.
Peter Fatomilola: Robbery burú ju Yahoo lọ, iṣẹ́ ọpọlọ lọmọ Yahoo fi ń gba owó ìran baba
Idi ni pe ko si ikọlu ni gbogbo ibi ti Igboho ti n ṣe iwọde amọ orisirisi lo ti ṣẹlẹ lọdọ awọn IPOB''
Oriade naa sọ pe awọn ko gbadura ki ogun ṣẹlẹ, bẹẹ si ni awọn ko faramọ ki eeyan maa pe fun ogun.
Bakan naa lo sọ pe wọn ko le mu Sunday Igboho lẹyin ti ọwọ tẹ Nnamdi Kanu bayi nitori wọn ko jọ ara wọn rara.
Amọ nkankan ti Oba Adetokunbo ni o yẹ ki ijọba ṣe ni ki wọn tẹ eti gbọ ikunsinu awọn araalu.
Sehinde Arogbofa ni atunto lo le fopin si ikunsinu araalu:
Ero ti Oba Adetokunbo naa si fara jọ ti Bashorun Sehinde Awogbofa pẹlu.
Awogbofa ninu alaye rẹẹ sọ pe o yẹ ki atunto waye ni Naijiria lati dẹkun aiṣedede to wa laarin awọn ẹya orilẹede yii.
Glorious Twins: Taiwo àti Kehinde Ekundayo ní ọ̀dọ́ ìyá àgbà ní àwọn ti ẹ̀bún orin kíkọ
''N ṣe lo yẹ ka forikori, ka fikunlukun, o si yẹ ki a ṣe atunto nkan nitori bi ohun gbogbo ti ṣe fi sapa kan lo n da wahala silẹ.''
''Bi awọn kan ti ṣe n ro wi pe ẹru ni awọn, ti awọn kan si ri ara wọn bii ọga, lo n da wahala silẹ pupọ.''
Lakotan awọn mejeeji ni o yẹ ki ijọba gbiyanju lati ṣe atunṣe si eyi pẹlu bi araalu ṣe n ke irora.
Wọn ni ki ba maa si gbogbo wahala a fẹ ya sọtọ ti nkan ba lọ bo ti ṣe yẹ.
Ajaawa Mayhem: Alága Káńsù ní ọkùnrin kan tó jẹ́ ọ̀rẹ́ ọlọ́pàá tẹ́lẹ̀, amọ tí ààrin wọn dàrú, ni wọn wá mú lọ́gànjọ́ òru.
Otitọ ọrọ ti n foju han sita nipa bi isẹlẹ ipaniyan to waye nilu Ajaawa, nijọba ibilẹ Ogo Oluwa nipinlẹ Oyo se waye.
Alaga ijọba ibilẹ Ogo Oluwa, to kalẹ si Ajaawa, Hon Oluwaseun Ojo lo salaye ohun to sokunfa isẹlẹ naa lasiko to n ba BBC Yoruba.
Gẹgẹ bi Ojo se wi, ọkunrin kan ti wọn n pe ni Ade Master ni a gbọ pe awọn ọlọpa wa sinu ilu Ajaawa, ti wọ̀n si ni ọga ọlọpa pata nilu Abuja lo fẹ ri.
Ojo ni ọga ọlọpa ni Ajaawa lo fi ọrọ naa to oun leti, to si ni awọn osisẹ ọlọpaa yii ti kọkọ lọ yọju si Kọmisana ọlọpaa ni Ibadan ati ọga ọlọpaa ni ẹkun naa.
O ni deede aago kan oru ni ibọn to n dun lakọ-lakọ sadeede ji gbogbo ilu naa silẹ, ti awọn si ri pe awọn ọlọpaa lati Abuja naa lo n yinbọn kiri.
Soiless Farming: Samson Ogbole ní táwọn irè oko bá fara kan ilẹ̀, ló ń kó àrùn bá wọn
"Wọn ni Ade Master ni wọn wa mu lati Abuja, pe ọga agba ọlọpaa ni ki wọn gbe wa. Bẹẹ ni ọkọ olowo iyebiye nlanla ni ọkunrin naa maa n lo lai se isẹ kankan.
Koda, awọn ọlọpaa gan ko ẹsọ meji fun to maa n tẹle lẹyin, ti wọn si tun fun ni nọmba ọkọ pataki to so mọ ara ọkọ rẹ.
Ade Master yii lo tun n lo ọkọ yafunyafun bii gomina kaakiri, tawọn ẹsọ ẹyin rẹ si maa n yinbọn kaakiri bo se wu wọn.
A ko wa mọ ohun to se fun awọn ọlọpaa, ti wọn ko fi se atilẹyin fun mọ ati idi to se jẹ pe aajin oru ni wọn wa mu."
Alaga ijọba ibilẹ Ogo Oluwa ni se ni awọn ọlọpaa naa kọkọ lọ si ibujoko ijọba ibilẹ naa lori, ti wọn si n yinbọn kiri, ki wọn to mọ pe ọọfisi ni awọn wa.
O fikun pe lẹyin eyi ni wọn wa lọ sile kan, ti wọn si n yinbọn mọ ibẹ, eeyan meji lo ku, ti ọpọlọpọ miran si fara pa.
Ojo salaye pe pẹlu ibẹrubojo ni awọn eeyan ilu naa n gbe bayii, ti ọpọ si ti n sa kuro ninu ilu naa nitoi ọkan wọn ti ko balẹ.
Fisayo Amodemaja: Nínú eré 'Children Day' ní Sọ́ọ̀ṣì ni Abebi ti bẹ̀rẹ̀ eré ṣisṣe- Bukola
"Mo bi ọga ọlọpaa ni Ajaawa pe ki lo de ti wọn fi wa laarin oru lati wa mu afurasi kan, amọ o ni oun ko le dahun ibeere yẹn, amọ o ni ki n lọ bi Kọmisana ọlọpaa.
Ohun gbogbo lo ti doju de laarin ilu, awọn akẹkọọ ko le lọ sile ẹkọ mọ, ti inu fu, aya fu si gbalẹ kan."
Amọ ibeere ti alaga naa sa n beere ni pe, o se jẹ aarin oru ni ọlọpaa wa mu afurasi, to si n yinbọn laibikita, eyi to pa ọpọ eeyan.
Kunle Olajide, Akọ̀wé ìgbìmọ̀: Ẹ̀yin ọ̀dọ́, ọjọ́ ọ̀la yin kò ṣe e fọ́wọ́ ẹ sọ̀yà, ẹ díde
Wayi o, ileesẹ ọlọpaa nipinlẹ Oyo ti tabuku isẹlẹ to waye sawọn osisẹ rẹ eyi ti awọn ọdọ ilu Ajaawa se.
Kọmisana ọlọpaa nipinlẹ Oyo, Ngozi Onadeko lo kede bẹẹ ninu atẹjade kan to fisita, pẹlu afikun pe isẹ iwadi ni awọn ọlọpaa naa lọ se lori isẹlẹ ipaniyan to waye ni Ajaawa, amọ ti awọn ọdọ gbe oju agan si wọn.
Koda, o ni wọn gba awọn irinsẹ ati ohun ija ti awọn ọlọpaa naa ko lọwọ, to si n kọminu lori fifi ẹhonu han sawọn osisẹ ọlọpaa to n sisẹ wọn labẹ ofin.
Ileesẹ ọlọpaa ipinlẹ Oyo wa leri leka pe gbogbo awọn eeyan ti aje iwa idaluru naa ba si mọ lori ni yoo jiya to tọ labẹ ofin.
Oríṣun àwòrán, Anadolu Agency
Se ni ilu Ajaawa gbona jainjain laarọ ọjọ isegun nigba ti awọn eeyan kan ti wọn fura si bii ọlọpaa sadede rọjo ibọn si ile kan.
Eeyan meji lo ti padanu ẹmi wọn tawọn mẹwaa mii si farapa nigba tawọn ọlọpaa kan yabo Ajaawa ni ijọba ibilẹ Ogo Oluwa lọjọ Aje ni ipinlẹ Oyo.
Ko daju ibi tawọn ikọ ọlọpaa yii ti wa ṣugbọn awọn kan ni lati ọọfisi ọga agba Ọlọpaa ni Abuja ni wọn ti wa.
Gẹgẹ bi ohun taa gbọ, awọn eeyan sọ pe nise ni awọn ọlọpaa naa wọ ilu ni nkan bi ago kan oru ninu ọkọ Sienna mẹta ti wọn si bẹrẹ si ni yinbọn lu awọn ile kan.
Nigba to n ba awọn akọroyin sọrọ ni ọjọ Iṣẹgun, alaga ijọba ibilẹ Ogo Oluwa, ti ibujoko rẹ wa ni Ajaawa, Arakunrin Seun Ojo ni awọn ọlọpaa to wa ṣiṣẹ forukọ silẹ lagọ ọlọpaa to wa ni Ajaawa ati ni ọdọ ọga agba ọlọpaa agbegbe naa.
Oríṣun àwòrán, Alaga iba ibilẹ Ajaawa n bawọn akọroyin sọrọ
Eyi jẹ ki a ribi fidi ọrọ mulẹ pe lootọ awọn ọlọpaa lo wa nidi ikọlu yii.
Ninu awọn ti Ojo sọ pe o farakasa iṣẹlẹ yii ni Babalawo Onifa ilu naa Ifaleye Jaiyeola.
O ni awọn ọlọpaa naa gbe oku rẹ, iyawo rẹ ati awakọ rẹ lọwọ lọ.
"Ojo ṣalaye pe "" Laarin oru ni nkan bi ago kan ni a ṣadede gbọ ariwo ẹ gba wa lọdọ awọn araalu Ajaawa latari iro ibọn kikan kikan to gbode lọjọ Kejidinlọgbọn oṣu Kẹfa''"
"Lẹyin ti a ṣe iwaadi, a ribi fidi ọrọ mulẹ pe awọn ọlọpaa doju ibọn kọ awọn ile kan ni Ajaawa lai ni idi kan pato''
O ni ''nkan ti wọn sọ fun wa ni pe lati ọọfisi ọga agba ọlọpaa ni wọn ti ran awọn ikọ to wa ṣiṣẹ yi wa.
Glorious Twins: Taiwo àti Kehinde Ekundayo ní ọ̀dọ́ ìyá àgbà ní àwọn ti ẹ̀bún orin kíkọ
Wọn forukọ silẹ ni agọ ọlọpaa ati lọdọ ọga ọlọpaa agbegbe naa, ti eyi si jẹ aridaju fun wa pe ọlọpaa ni wọn''
O  tẹsiwaju pe ''o  jẹ eemọ fun wa idi tawọn ọlọpaa yoo se ṣigun wọ ilu, ti wọn yoo si maa da ibẹrubojo si ọkan ara ilu lai nidi debi pe ẹmi yoo ṣofo ninu iṣẹlẹ naa''
''Baa ṣe n ba yin sọrọ yii, ati fidi rẹ mulẹ pe eeyan meji ti ku, ti eeyan mẹwaa si farapa''
O ka ọrọ rẹ nilẹ pe awọn ṣi n ṣe akojọ iye eeyan to farapa nitori pe oun ni lati sare wa jabọ nkan to ṣẹlẹ ni Ibadan naa.
Gbogbo igbiyanju BBC Yoruba lati gbọ ti ẹnu ileesẹ ọlọpaa ipinlẹ Oyo lori isẹlẹ yii, lo ja si pabo nitori agbẹnusọ fun ọlọpa ipinlẹ Oyo ko gbe aago ipe wa.
Nnamdi Kanu: Sunday Igboho ní mímú aṣaájú IPOB kò lè dí ìwọ́de Yoruba Nation Eko lọ́wọ́
Oríṣun àwòrán, other
Ọkan gboogi lara awọn to n ja fun idasilẹ orilẹede Yoruba, Oloye Sunday Igboho ti sọ pe bi ọwọ ijọba ṣe tẹ aṣiwaju ipe fun idasilẹ orilẹede Biafra, Mazi Nnamdi Kanu, ko ni idiwọ kankan fun ohun ti oun n ja fun.
Lọjọ Iṣẹgun ni iroyin jade pe ọwọ ijọba ti tẹ Nnamdi Kanu, ti wọn si ti fi si ahamọ lẹyin ti wọn foju rẹ ba ileẹjọ giga apapọ nilu Abuja.
Eyi mu ki ọpọ awọn ololufẹ Sunday Igboho o maa ko aya soke pe, o ṣeeṣe ki ijọba maa gbiyanju ati fi ṣikun ofin gbe Igboho pẹlu.
Amọṣa, Igboho Ooṣa, gẹgẹ bi ọpọlọpọ awọn ololufẹ rẹ ṣe maa n pe e sọ pe, ẹru ko ba oun o ati pe eyi ko ni idiwọ kankan lati ṣe fun iwọde ipe fun 'Yoruba Nation."
Sunday Igboho lo fi ọrọ yii lede lati ẹnu agbẹnusọ rẹ, Olayomi Koiki.
Sunday Igboho: Ẹ fi Ògún búra fún wa láti jà fún ilẹ̀ Yorùbá láì gbé Amotekun sábẹ́ ìjọba
Koda, o ni iwọde naa ti wọn ti seto pe yoo waye ni ilu Eko lọjọ Satide, ọjọ kẹta oṣu Keje ọdun 2021, yoo lọ, gẹgẹ bo se wa ni akọsilẹ.
Bakan naa lo fi kun un pe, gba-gba-gba loun wa lẹyin Nnamdi Kanu ati pe atilẹyin oun ko yẹ gẹrẹ ninu atilẹyin oun fun ipe fun orilẹede Biafra.
Bakan naa ni Igboho ti kede ninu fidio kan to n ja lori ayelujara pe oun ko ni agbara kankan lati ba ijọba apapọ ja tabi ijọba ibilẹ lasan.
O ni Ọlọrun ni yoo ja fun idasilẹ orilẹede Yoruba Nation ati iran Yoruba lapapọ, ki wọn le ya kuro lara Naijiria.
O ni oun ko gbagbọ pe ẹnikẹni n dunkoko lati di awọn ajija gbara naa lọwọ lati wa silu Eko fun iwọde lọjọ Satide to n bọ.
Oríṣun àwòrán, Olayomi Koiki/Facebook
O ni ti eyi ba jẹ otitọ, ki ẹni naa se fidio ara rẹ sita, ko si sọ awọn ọrọ naa, eyi ti yoo jẹ kawọn ri otitọ ọrọ dimu.
Igboho fikun pe awọn ara Eko ti n foju sọna lati gbalejo ikọ Yoruba Nation lọjọ Satide, ti iwọde naa yoo si lọ wọọrọ wọ.
Wayi, Sunday Igboho ti wa rawọ ẹbẹ si ileesẹ ọlọpa nipinlẹ Eko lati pese eto aabo to peye fawọn oluwọde naa nitori gbogbo ọmọ Yoruba lo n fẹ ki iwọde naa waye.
Glorious Twins: Taiwo àti Kehinde Ekundayo ní ọ̀dọ́ ìyá àgbà ní àwọn ti ẹ̀bún orin kíkọ
Baba Ijesha: Femi Adebayo náà dá sí èdè àìyedè tó ń wáyé nínú TAMPAN
Oríṣun àwòrán, femiadebayosalami/Instagram
Ẹgbẹ TAMPAN fi ikilọ ranṣẹ si Iyabo Ojo ati Nkechi Blessing pe ki wọn yeTe ba ẹgbẹ TAMPAN  lorukọ jẹ kaakiri.
Gbajugbaja oṣere Nollywood, Femi Adebayo ti fi ero rẹ lede gẹgẹ bi ọmọ ẹgbẹ awọn oṣere ni Naijiria, TAMPAN, lori awuyewuye to n waye ninu ẹgbẹ naa.
Eyi ko ṣẹyin bi ẹgbẹ TAMPAN ṣe fofin de oṣerebinrin meji, Iyabo Ojo ati Nkechi Blessing lori ipa ti wọn ko lori ọrọ Baba Ijesha ti wọn fẹsun kan pe o ṣe aṣemaṣe pẹlu ọdọmọde kan.
Lasiko ti Femi Adebayo n fi ero rẹ han ninu fidio kan to gbe jade loju opo Instagram rẹ, o sọ wi pe ọrọ naa yoo loju tu laipẹ.
''Gẹgẹ bi ọmọ ẹgbẹ TAMPAN, mọ fẹ fi idi rẹ mulẹ pe ẹgbẹ naa ko ni fi ti ọrọ ẹnu abi irunu da ẹjọ kankan, amọ ẹgbẹ yoo ṣewadii finifini.''
''Ikini ni pe ẹgbẹ TAMPAN ko ni fi aye gba iwa ọdaran tabi iwa ipa kankan ninu ẹgbẹ nitori ohun ti ofin ẹgbẹ dale lori ni ibọwọ fun ara ẹni ati ẹtọ.
Bakan naa ni o jẹ wa logun lati ri pe awọn ọmọ ẹgbẹ ni itẹsiwaju ninu iṣẹ ti wọn yan laayo, ki igbega le ba ẹka oṣere ni Naijiria.
Ikẹta nipe ẹgbẹ ko ni fi aye gba iwakiwa lati ọdọ ẹnikẹni, amọ ọrọ ti wọ inu ara wọn  ninu iṣẹlẹ to waye naa.
Nitori naa, ijiroro ati ibaraẹnisọrọ ti bẹrẹ pẹlu gbogbo awọn ti iṣẹlẹ naa ta ba, a si ni igbagbọ wi pe ohun gbogbo yoo niyanju laipẹ.
Laipẹ yii ni ẹgbẹ TAMPAN fi ikilọ ranṣẹ si Iyabo Ojo ati Nkechi Blessing pe ki wọn ti ọwọ ọmọ wọn bọ aṣọ pẹlu bi wọn ṣe n ba ẹgbẹ TAMPAN  lorukọ jẹ kaakiri.
Glorious Twins: Taiwo àti Kehinde Ekundayo ní ọ̀dọ́ ìyá àgbà ní àwọn ti ẹ̀bún orin kíkọ
Bakan naa ni wọn le Blessing kuro ninu ẹgbẹ fun igba diẹ nitori o ba akẹgbẹ rẹ, Kehinde Adams ja lori ẹrọ ayelujara nitori ọrọ Baba Ijesha kan naa.
Amọ, ẹsun ti won fi kan Iyabo Ojo ni wi pe o sọrọ si awọn  agba oṣere to dakẹ lori ọrọ Baba Ijesha, ti wọn si paṣẹ fun awọn oṣere lati maṣe lo Iyabo Ojo tabi Nkechi Blessing ninu fiimu ti wọn ba fẹ gbe jade.
Baba Ijesha: Lola Alao ní òun àti Iyabo Ojo rán agbẹjọ́rò méjì gbìjà Baba Ijesha àmọ́ ibi ni wọn fi su àwọn
Oríṣun àwòrán, Lola Alao
Awuyewuye lori ọrọ Baba Ijesha lagbo awọn oṣere tiata Yoruba ko ti tan nilẹ patapata pẹlu bi awọn oṣere ṣi tun se n tahun si ara awọn.
Ọkan lara awọn oṣere tiata, Lola Alao naa ti da si ọrọ to n lọ, Bukky Black lo si doju ọrọ tiẹ kọ nitori oko ọrọ ti onitọun sọ si Iyabo Ojo.
Lola tutọ soke o foju gbaa lori fidio ti Bukky Black ṣe eleyii to fi tako Iyabo Ojo lori ọrọ Baba Ijesha.
Lola sọ pe niwaju Ọlọrun ati eniyan, Iyabo ko mọ ohunkohun nipa ọrọ yii rara, o ni oun gan an ni oun pe Iyabo nigba toun gbọ pe awọn ọlọpaa ti mu Baba Ijesha.
''Bukky, ni akọkọ na, mo fẹ ki o mọ pe bi wọn ti gba beeli Baba Ijesha ko tumọ si pe ẹjọ ti pari o.
Soiless Farming: Samson Ogbole ní táwọn irè oko bá fara kan ilẹ̀, ló ń kó àrùn bá wọn
Emi fun ra mi ni mo fi agbẹjọro meji ranṣẹ si Baba Ijesha ni agọ ọlọpaa ti wọn ti i mọ lẹyin ti mo ba Iyabo sọrọ tan.
Ẹ ba mi beere lọwọ Ijesha boya ko ri awọn agbẹjọro meji ti mo fi ranṣẹ si i.
"Iyabo ko korira Ijesha, ohun to ṣẹlẹ gan an ni Iyabo n sọ nitori iru nkan bayii ti ṣẹlẹ si i ri."""
Lola Alao ni oun gan ni oun fi isẹlẹ naa to Yomi Fabiyi ati Iyabo Ojo leti, gẹgẹ bi aburo oun tawọn mejeeji jẹ, ti wọn si dide lati gba Baba Ijesha silẹ nitori awọn lero pe wọn fẹ ba lorukọ jẹ ni.
O ni bi awọn mejeeji si se gbọ ọrọ yii ni wọn dide pe awọn yoo lọ lai jẹ pe ẹnikankan ninu awọn tiẹ mọ ohun ti Baba Ijesha se, to fi de agọ ọlọpaa.
Koda, Lola Alao fidi rẹ mulẹ pe oun n reti Baba Ijesha ko wa ba oun nilu oyinbo ti oun wa lati se sinima kan papọ amọ ti awọn ko ri, to si n ka oun lara pe bawo lo se maa hu iru iwa bayii si oun.
Amọ o ni nigba ti oun pe lati wadi idi ti ko se tii de, ni jẹbẹtẹ gbe ọmọ le oun lọwọ nigba toun gbọ pe o ti wa ni ahamọ ọlọpaa ni Panti.
Koda, Yomi Fabiyi gan bẹrẹ si kọ awọn ọrọ lati gbeja Baba Ijesha, ti oun gan si n se alabapin awọn ọrọ naa loju opo Instagram oun amọ ni kete ti oun mọ idi ọrọ to sẹlẹ, ni oun pa awọn ọrọ naa rẹ.
"Nigba ti Princess fi fidio ranṣẹ, ti emi ati Iyabo wo o tan, ni Iyabo mura pe idajọ ododo gbọdọ ṣẹlẹ lori ọrọ naa.
Bukky, Iyabo ko ba ti sọrọ ti ko ba ṣe fidio ti o fi lede lori ayelujara.
Ṣebi agbalagba ni ẹ, Bukky? Ṣe agbalagba maa n ṣe langbalangba ni?
Bukky, ki ni iwọ ṣe nigba ti wọn mu Baba Ijesha, ṣe bi a jọ wa ni ilu oyinbo ni?
Mo ti n dakẹ lori ọrọ yii tipẹ ṣugbọn ẹri ọkan mi ko jẹ ki n gbadun, jẹjẹ ni Iyabo joko sile rẹ, ẹmi ni mo fi ọrọ Baba Ijesha lọ ọ.
O n dun mi pe emi ni mo ti Iyabo si gbogbo wahala yii.
Awọn adigunjale ti wa sile mi ri ti wọn ji goolu mi atawọn nkan mii, nitori naa ti wọn ba mu ole nibi kan, mo maa n fẹ ki wọn lu daadaa nitori o ti ṣẹlẹ si mi ri.
Glorious Twins: Taiwo àti Kehinde Ekundayo ní ọ̀dọ́ ìyá àgbà ní àwọn ti ẹ̀bún orin kíkọ
Bayi naa si lo maa n ri lara Iyabo to ba gbọ nipa ẹnikan to fi tipa ba obinrin lo pọ."
Lola Alao wa koro oju si bi ọpọ eeyan se n sọrọ si Iyabo Ojo lori ayelujara, to si tun gbara ta lori aarin Yomi Fabiyi ati Iyabo Ojo to ti daru bayii nitori ọrọ Baba Ijesha.
O ni awọn aburo oun mejeeji wa di ọta ara awọn amọ oun mọ pe Ọlọrun yoo ba oun yanju ọrọ naa.
Sunday Igboho: Olugbon ní ìjọba gbọdọ̀ sọ ẹni tó wà ní ìdí ìkọlù ilé Sunday Igboho
Olugbọn ti Orile Igbọn, to tun jẹ igbakeji alaga igbimọ lọbalọba nipinlẹ Oyo, Oba Francis Olusola Alao, ti rọ Oloye Sunday Adeyemo ti ọpọ mọ si Sunday Igboho lati se mẹdọ na, lori iwọde idasilẹ Yoruba Nation ọjọ Satide niluu Eko.
Nigba to n ba BBC Yoruba sọrọ, Kabiyesi Olugbọn ṣalaye pe Igboho atawọn eeyan rẹ gbọdọ sun iwọde naa siwaju pẹlu bi awọn agbebọn ṣe kọlu ile rẹ lagbegbe Soka niluu Ibadan.
Olugbọn rọ Igboho lati bu omi suuru mu diẹ, lati wo ohun to n ṣẹlẹ pẹlu bi wọn ti kọlu ile rẹ nidaji ọjọbọ, ki wọn to tun tẹ siwaju pẹlu iwọde to n bọ niluu Eko.
Ṣugbọn Olugbon ni oun ko sọ pe ki Igboho ma ṣe iwọde tori ṣiṣe ifẹhonuhan ko tapa si ofin orilẹede Naijiria.
Olugbon ni Igboho ko ba ijọba ja pẹlu ifẹhonuhan fun idasilẹ Yoruba ti o n ṣe agbatẹru rẹ.
Soiless Farming: Samson Ogbole ní táwọn irè oko bá fara kan ilẹ̀, ló ń kó àrùn bá wọn
Kabiyesi Olugbon ni ''a gbọdọ kọkọ ṣe iwadii iṣẹlẹ yii bo ya awọn sọja lo ṣe e tabi awọn kọ. To ba jẹ awọn sọja lo ṣee, ẹnikẹni to wu ko le ṣee, ohun to buru jai ni.
Nitori ofin ko sọ fun wa pe Igboho tabi ọmọ Naijiria ko lẹtọ lati ṣe iwọde, ijọba gbọdọ wa idi ohun to ṣẹlẹ yii, ohun ti a n sọ niyẹn pe ko si abo niluu.
Ijọba gbọdọ ṣalaye lati sọ awọn to wa nidi iṣẹlẹ laabi yi, ki wọn si wa nkan ṣe si ọrọ eto aabo to mẹhẹ yii.
Ohun to n ṣẹlẹ yii ko ye mi mọ o, Naijiria ti wa di oju ni alakan fi n ṣọri bayii,'' Olugbon lo woye bẹẹ.
Ninu fidio ti agbẹnusọ fun Igboho, Olayomi Koiki fi soju opo Facebook rẹ, o ni awọn afurasi sọja lo yabo ile ajijagbara nibi to ti sọ pe wọn ṣekupa eeyan meji.
Bakan naa lo ni wọn ba dukia atawọn ọkọ Oloye Igboho jẹ, ti wọn si tun gbe awọn eeyan to wa ninu ile lọ.
Soiless Farming: Samson Ogbole ní táwọn irè oko bá fara kan ilẹ̀, ló ń kó àrùn bá wọn
Ọpọ eeyan lo maa n pa lowe pe ko si ọna abuja ni ọrun ọpẹ, tabi bi a ko ba ri ọkọ, a ko lee de Eko.
Amọ awọn imọ ijinlẹ sayẹnsi ati isẹ iwadi to n jade sita ti n fidi rẹ mulẹ pe ọpọ ọna abuja lo wa, taa fi le se ohunkohun.
Iru rẹ ni ti eto ọgbin, ti ọpọ gba pe inu erupẹ tabi ilẹ nikan ni ọgbin eweko ati ewebẹ pẹlu eso ti lee waye.
Nibayii, awari imọ ijinlẹ ti fidi rẹ mulẹ pe a le se ọgbin ohunkohun lai jẹ pe a lo erupẹ rara.
Ọkunrin kan ree, Samson Ogbole, to n sisẹ ọgbin lai pin wọn sori ilẹ eyi to pe ni Soiless farming tabi Agropolis.
Pẹlu ilana yii, Ogbole n gbin ewebẹ , eweko ati eso sinu tanki omi, ike ipọnmi, ọpa omi ọra ati bẹẹ bẹẹ lọ.
O ni ọpọ arun to maa n yọ ire oko lẹnu lo n wa latinu erupẹ amọ ti awọn ire oko yii ko fara kan ewebẹ, ko ni si aisan.
O wa n lo awọn fulufulu eepo ara irẹsi tutu ati agbado lati pin eweko dipo erupẹ.
Bakan naa lo salaye pe a ko gbọdọ maa pe awọn ewebẹ kan tabi eso pe wọn ni igba ti wọn maa n jade nnitori ilana ọgbin lai lo ajilẹ yii yoo jẹ ka maa ni gbogbo eso, ewebẹ ati eweko yika ọdun.
Àwọn ìtàn mánigbàgbé tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí:
Koda, Samson Ogbole gan n kọ awọn agbẹ nipa ọna ti wọn fi le se amulo ilana ọgbin lai lo erupẹ rara.
Ẹ ba wa kalọ ninu fiudio yii lati mọ bi Ogbole se n sisẹ ọgbin lai lo ilẹ .
Laduni Idowu Giwa-Osagie: Ọ̀rẹ́ Laduni sọ pe ìwúrí ni bí ọ̀rẹ́ òun ṣe di ọlọ́mọ láyé
Oríṣun àwòrán, Punchng
Iho ayọ ati idunnu sọ ni ile arabinrin Ladunni Idowu Giwa-Osagie, lẹyin ti itan aye rẹ ja si pe bi ẹkun pe di alẹ, ayọ nbọ ni owurọ.
Itan Ladunni ti jẹ ki ọpọlọpọ obinrin lori ẹrọ ayelujara, to ṣi n woju Ọlọrun fun ọkọ tabi Ọmọ ati awọn ohun ayọ miran ni igbẹkẹle pe, ko si ohun ti o ṣoro ṣe, ati pe asiko eniyan ko ni kọja rẹ.
Gege bi iroyin to wa loju opo Facebook, Ladun lo pade ọkọ rẹ, Aigbovo-Giwa-Osagie ni ọdun mẹtadinlaadọta o le diẹ.
Ladun ati ọkọ rẹ ṣe igbeyawo lẹyin ọdun kan ti wọn pade ara wọn, eleyii to mu ki arabinrin naa ti di ẹni ọdun mejidinlaadọta.
Oríṣun àwòrán, Punchng
Ko pẹ to ṣe igbeyawo, to ni oyun ni ẹni ọdun mọkandinlaadọta, to si bi ọmọ naa ni Ọjọ Karundinlọgbọn, Oṣu Kẹfa, ọdun 2021, ki o to pe ẹni aadọta ọdun.
Ọmọ tuntun jojolo naa wa ni alaafia pẹlu iya rẹ, ti wọn si sọ orukọ rẹ ni Osarumuwese Oluwaseyitanfunmi Nosakhare.
Ọrẹ Ladunni to fi iroyin naa si oju opo ikansiraẹni Facebook rẹ ni, ọpọlọpọ eniyan lo pejọ si ibi isọmọlorukọ ọmọ tuntun jojolo naa, to waye ni agbegbe Ikẹja, ni ilu Eko.
Ọrẹ Ladunni ni arabinrin naa jẹ ẹni to ni igbagbọ ninu Ọlọrun, to si fi gbogbo ọkan ati adura ni ireti pe asiko tirẹ ṣi n bọ.
"Ṣé o lè gbé orí rẹ lọ sọ́dọ̀ fárífárí alábẹ kó dán bí àwọn tó ní àwọn kò lè lo ""clipper láéláé yìí?"
O ni Ladunni ni ifẹ awọn eniyan pupọ, to si ma n fi ọrọ iyanju ati itunu bọ awọn to ba sun mọ.
Ọrẹ Ladunni wa gba awọn eniyan to n woju Ọlọrun fun ohun ayọ bi eleyii lati maṣe mikan, ki wọn ni igbagbọ ninu Ọlọrun to le ṣe ohun gbogbo ni asiko to yẹ.
Sunday Igboho: Ọwọ́ àwọn afurasí ‘Sọ́jà’ tó kọlu ilé Igboho kò ri mú
Oríṣun àwòrán, Sunday_igboho1/Instagram
Iroyin to n tẹ wa lọwọ ni yajoyajo ni nkan ko fara rọ bayii nile ajijagbara nilẹ Yoruba, Oloye Sunday Adeyemo ti ọpọ mọ si Sunday Ighoho.
Iroyin ti a n gbọ lati ilu Ibadan ni pe awọn ajinigbe yabo ile Igboho to wa ni agbegbe Soka nibi ti wọn ti ji awọn eeyan gbe lọ.
Agbẹnusọ fun Igboho, Olayomi Koiki sọ ninu fidio kan to fi lede loju opo Facebook rẹ ṣalaye pe awọn janduku kan yabo ile Igboho nibi to sọ pe wọn ti pa eeyan.
Koiki ni awọn janduku ọhun tun ji awọn eeyan lọ nile Ighoho to wa ni Soka, ti wọn si ba ọpọ mọto rẹ jẹ.
Lara awọn mọto to sọ pe awọn afurasi janduku naa bajẹ ni ọkọ olowo iyebiye G-Wagon, Prado Jeep atawọn ọkọ miran to wa ninu agbala rẹ
Soiless Farming: Samson Ogbole ní táwọn irè oko bá fara kan ilẹ̀, ló ń kó àrùn bá wọn
Koiki ni awọn afurasi sọja to yabo ile naa ko gbogbo owo to wa ni ile Ighoho lọ. O ni oriṣiiriṣii ọta ibọn lo wa nilẹ tawọn janduku agbebọn ọhun  lo nile Igboho.
Ọpọ eeyan lo ti sọ lori ayelujara lati bu ẹnu atẹ lu iṣẹlẹ naa.
Awọn janduku ọhun wa gbogbo inu ile lati mu Igboho ṣugbọn wọn ko ri Igboho.
Gbogbo awọn to wa ninu ile Igboho ni wọn jigbe lọ to fi mọ awọn to n dana ounjẹ ni ile rẹ to wa ni Soka,'' Koiki ṣalaye.
O ni oriṣiiriṣii ọta ibọn lo wa nilẹ tawọn janduku agbebọn ọhun  lo nile Igboho.
''Awọn janduku ọhun ba gbogbo ọkọ to wa nile Sunday Igboho jẹ patapata.
Olowo: Bí ìjọba bá ṣe àtúntò tún yẹ, Sunday Igboho yóò fọwọ́sowọ́pọ̀ pẹ̀lú wọn
Awọn janduku ọhun wa gbogbo inu ile lati mu Igboho ṣugbọn wọn ko ri Igboho.
Gbogbo awọn to wa ninu ile Igboho ni wọn jigbe lọ to fi mọ awọn to n dana ounjẹ ni ile rẹ to wa ni Soka,'' Koiki ṣalaye.
Koiki fi kun ọrọ rẹ pe ohun ti awọn n gbọ ni pe o ṣeeṣe ki awọn sọja to yabo ile Igboho tun pada wa.
''Mo le sọ pe ijọba orilẹedee Naijiria lo ran awọn sọja wa si ile Sunday Ighoho.
Wọn pa awọn eeyan nibẹ, wọn si ti ko oku awọn eeyan ti wọn pa nile Sunday Igboho lọ.
N ṣe lawọn sọja naa di oju titi pa niwaju ile Igboho, ki wọn to yabo ile rẹ,'' Koiki lo sọ bẹẹ.
Bi iroyin naa ba se n lọ, la maa mu wa fun yin.
El-Rufai: Inú mí dùn bí wọ́n ṣe mú Nnamdi Kanu, yóò kọ́ àwọn yóòkù tí wọ́n fẹ́ pín Naijiria ní ọgbọ́n
Oríṣun àwòrán, Others
Gomina ipinlẹ Kaduna, Nasir El-Rufai ti fesi fun awọn to n bu ẹnu atẹ lu bi ijọba ṣe gbe Nnamdi Kanu pada wa si Niajiria.
Nnamdi Kanu ni ijọba gbe lati ẹyin odi, lati wa jẹjọ ẹsun iditẹ gbajọba ti wọn fi kan an lẹyin to sa kuro ni Naijiria lasiko igbẹjọ rẹ.
El-Rufai lasiko ifọrọwanilẹnuwo pẹlu ileeṣẹ iroyin BBC sọ pe, awọn to n fẹsun kan ijọba apapọ pe wọn ko ri nkan ṣe si ọrọ Boko Haram ati awọn agbẹbọn, amọ ọrọ Nnamdi Kanu ati IPOB lo jẹ wọn logun, ni wọn ko ri ọrọ sọ.
O ni ọrọ Kanu yatọ si ti awọn agbebọn ni ariwa orilẹede Naijiria nitori ''Nnamdi Kanu n pe fun ituka orilẹede Naijiria, ti o si n fa rogbodiyan ati ija ni Naijiria.
O tilẹ pe orilẹede rẹ ni papa awọn ẹranko''.
#BBCNigeria2019: Nnamdi Kanu sọrọ lórí àwọn oludije PDP àti APC
''Eyi yatọ si awọn agbebọn to jẹ wi pe ọrọ aje ni ijinigbe jẹ fun wọn, ti kii ṣe pe wọn gbe ogun ti ijọba pe orilẹede Naijiria gbọdọ tuka.''
''Lakọkọ, inu mi dun pe wọn ri Nnamdi Kanu mu nitori ko naani beeli rẹ , to si ko awọn oniduro rẹ si panpẹ''
''Ekeji ni pe, Kanu fẹ tu orilẹede Naijiria ka, eleyii yoo si kọ awọn to fẹ pin orilẹede Naijiria ni ọgbọn wi pe ki wọn sọ ara ṣe.''
''Rara, rara, rara, bi igba ti ẹ n fi iku we oorun tabi ẹ n pe ọsan ni ''apple'' ni ọrọ Kanu ati awọn agbebọn.''
''Adari ikọ ti ijọba ti pe ni agbesunmọmi ni Kanu, amọ awọn agbebọn ko ni adari pato ti eniyan damọ gẹgẹ bi adari awọn agbebọn wọnyii.''
Ijaw Paternity test: Mọ́ síi nípa ìgbàgbọ́ àwọn Ilaje nípa ọmọ ọkọ àti ọmọ àlè
''Bakan naa ni Kanu joko si ibi kan, to n jaye ọlọba, amọ ijọba Naijiria ti n wa Shekau to jẹ olori awọn ikọ Boko Haram fun ọdun mẹwaa, ti wọn ko ti i ri mu nitori inu aginju lo wa to ti n ja ija tirẹ.''
Gomina ipinlẹ Kaduna, Nasir El-Rufai naa wa kesi ẹnikẹni to ba lero wi pe ọrọ awọn agbebọn ju ti Nnamdi Kanu lọ lati bọ si gbangba pẹlu ẹni to jẹ adari awọn agbebọn to n ji awọn eniyan gbe lorilẹede Naijiria.
Ijọba Ilẹ Gẹẹsi ni oun yoo beere alaye ni ọwọ ijọba Naijiria lori idi to se fi panpẹ ọba mu Nnamdi Kanu, to jẹ adari ikọ IPOB to n pe fun ominira ilẹ Biafra.
Oríṣun àwòrán, Nnamdi Kanu
Adari Ẹka eto iroyin ni ileesẹ asoju Ilẹ Gẹẹsi ni Naijiria, Dean Hurlock lo sọ eyi lasiko ti awọn akọroyin beere igbesẹ ti wọn n gbe lori atimọle Nnamdi Kanu.
Hurlock ni awọn ti bẹrẹ ijiroro pẹlu ijọba Naijiria lati salaye bi wọn ṣe mu Nnamdi Kanu ati wi pe ṣe ọna ti wọn gba mu ba ofin mu.
Kanu to n jẹjọ iditẹ gba ijọba ati igbesunmọmi ni wọn gbe lọ si iwaju Adajọ Binta Nyako ni ileẹjọ Giga ti Ilu Abuja, lẹyin ọjọ meji ti ọwọ tẹ ni ẹyin odi ti wọn si gbe pada wa si Naijiria.
Ilẹ Gẹẹsi ninu atẹjade ti wọn fi lede ni kii ṣe Ilẹ Gẹẹsi ni ijọba Naijiria ti mu Kanu, to jẹ ọmọ Ilẹ Naijiria ati Ilẹ Gẹẹsi.
Ijọba Ilẹ Gẹẹsi fikun pe, igbẹjọ rẹ gbọdọ tẹle ilana ofin lai fi ẹtanu tabi aibọwọ fun ofin ṣe ohunkohun nitori awọn ti bẹrẹ si ni tọpinpin lori iṣẹlẹ naa.
Bakan naa ni wọn fikun pe awọn yoo pese iranwọ,ti igbẹjọ rẹ ba bẹrẹ ni Ọjọ Kẹrindinlọgbọn, Oṣu Keje, ọdun 2021.
Olowo: Bí ìjọba bá ṣe àtúntò tún yẹ, Sunday Igboho yóò fọwọ́sowọ́pọ̀ pẹ̀lú wọn
Amọ, mọlẹbi Kanu to tun jẹ agbẹnusọ ikọ IPOB, Emma Powerful sọ fun awọn oniroyin pe orilẹede Kenya ni awọn otẹlẹmuyẹ ti mu Kanu, ti wọn si gbe wa si Naijiria.
Nibayii, Nnamdi Kanu wa ni atimọle ileeṣẹ ọtẹlẹmuyẹ lorilẹede Naijiria, DSS gẹgẹ bi aṣẹ ilẹ ẹjọ giga ni Naijiria.
Ọdun 2017 lasiko ti igbẹjọ Kanu ṣi n lọ lọwọ lo sakuro ni Naijiria lọ si Ilẹ Gẹẹsi,  nigba ti awọn ọmọogun Naijiria yabo ile obi rẹ ni agbegbe Afaraukwu, nipinlẹ Abia.
Sunday Igboho: Ọmọ odó làwọn agbébọn fi fọ́ ìlẹ̀kùn wọlé gbẹ̀mí, ba dúkìá jẹ́ nílé ajìjàgbara
BBC Yoruba lọ sile Oloye Sunday Igboho to wa ni adugbo Soka, nilu Ibadan ni aarọ Ọjọbọ lati mọ bi ikọlu si ile rẹ se waye.
Bẹẹ ba gbagbe, a ti kọkọ mu iroyin wa fun yin pe awọn afurasi Sọja kan ya bo ile ajijagbara fun ilẹ Yoruba naa ni deede aago kan abọ oru mọju oni.
Nigba ta kan sile naa, a ri pe ọpọ dukia lo bajẹ ninu ile ọhun eyi ti apapọ owo wọn le ni aimọye biliọnu naira.
Bi o tilẹ a ko ri Igboho ninu ile, sibẹ, ko si ẹnikẹni to setan lati sọ ibi ti ajijagbara naa wa, amọ iroyin kan ti ko fi ẹsẹ mulẹ ni se lo sadede poora lasiko ti awọn agbebọn naa de.
A ba awọn eeyan kan ninu ile ọhun, ti wọn si mu wa kaakiri lati foju se mẹrin ọsẹ to waye nibẹ amọ ko si ẹnikẹni to ba wa sọrọ nibẹ.
Ninu irinajo wa yika inu ati agbala ile Sunday Igboho naa, a gbọ itakurọsọ ti awọn eeyan to wa nibẹ n se, ti wọn si n sọ laarin ara wọn pe eeyan marun lo ba isẹlẹ naa rin.
Bakan naa la ri abawọn ẹjẹ ni ọna mẹta ninu ile naa, eyi to fidi rẹ mulẹ pe awọn eeyan fara gbọgbẹ tabi ki ẹmi wọn bọ ninu isẹlẹ naa.
Bakan naa la ri pe ọpọ awọn ferese to wa ninu ile naa, ti wọn jẹ kikida digi ni wọn fọ, ta si ri afọku igo nilẹ Kaakiri pẹlu.
A tun foju ganni awọn aworan lorisirisi ti wsn fọ mọlẹ, ti wọn wo tabili, ti awọn ilẹkun kan si fara han pe wọn fọ wọn.
Koda, a tun ri ọmọ odo kan nilẹ niwaju ile Sunday Igboho, eyi ta gbọ pe awọn agbebọn naa lo lati fọ ilẹkun ẹnu iloro ile wọle, ti wọn si tun fi fọ oju ferese ati ara ile.
Awọn mọto nla nla la ri tawọn ferese wọn ti fọ, to fi mọ awọn ọkọ olowo iyebiye bii G-Wagon, Prado jeep, to fi mọ bọọsi ti wọn tẹ orukọ Yoruba Nation si lara.
Bakan naa la ri awọn aloku ọta ibọn nilẹ niwaju ile naa to wa nilẹ ilẹ.
Awọn eeyan ta ba ninu ile Sunday Igboho naa ni gbogbo awọn eeyan ti wọn n gbe ninu ile ọhun ni awọn afurasi Sọja to wa naa ko lọ, to fi mọ obinrin to n se ounjẹ fun wọn.
Igba akọkọ kọ ree ti ikọlu yoo maa waye sile amọ ibeere ti ọpọ n beere ni pe nibo ni Sunday Igboho wa lasiko ti iklu tii fi n waye.
Sunday Igboho: Ẹgbẹ́ OYC, YWC ní ìwọ́de July 3 yóò wáyé l‘Eko, bó ti wù kẹ kọlu Igboho tó
Ni oru Ọjọbọ ni iroyin sọ pe awọn eeyan kan ti wọn wọ aṣọ ologun ya wọ ile gbajumọ aṣiwaju fun idasilẹ orilẹede Yoruba, Oloye Sunday Adeyẹmọ ti ọpọ mọ si Sunday Igboho.
Iroyin fi idi rẹ mulẹ pe wọn ti ṣe ọpọlọpọ ọṣẹ lasiko ikọlu naa.
Gẹgẹ bi ohun ti akọroyin BBC News Yoruba to lọ sibẹ se fi mulẹ, ọpọlọpọ ọkọ ati dukia miran lo ba lọ. Bakan naa ni ẹjẹ wa lawọn agbegbe kan ni ile naa.
"Pẹlu bi eekan ọmọ Yoruba yii ṣe n gbaradi fun iwọde nla kan ni ilu Eko lọjọ Satide ọjọ kẹta oṣu keje ọdun 2021 fun idasilẹ orilẹede Yoruba ti wọn da pe ni ""Yoruba Nation"", ọpọ lo n woye pe ṣe irufẹ iṣẹlẹ bayii ko ni mu idiwọ ba iwọde naa."
Sunday Igboho: Ẹ fi Ògún búra fún wa láti jà fún ilẹ̀ Yorùbá láì gbé Amotekun sábẹ́ ìjọba
Ninu ọrọ to ba BBC News Yoruba sọ, Comrade Oluyi Akintade Tayọ ti ẹgbẹ oodua Youth Coalition ṣalaye pe, ikọlu lati ibikibi ko lee da iwọde naa duro.
O ni yoo wulẹ tubọ mu ki agbara pọ fun awọn sii ni.
Ọgbẹni Akintade Tayọ ṣe e lalaye pe, inu gbogbo awọn to n ja fun ijijagbara ilẹ Yoruba lo bajẹ si iṣẹlẹ naa ati pe bi awọn to gbe igbesẹ ikọlu naa ba lero pe wọn yoo fi dun kuku laja mọ awọn, ko lee ri bẹẹ rara.
Ko si ibi to gba jọra, ẹni to jẹ Baba fun gbogbo wa, Ọjọgbọn Akintoye ti sọ pe ko si ayipada lori iwọde naa, eyi to fihan pe bi o ti le wu ki atako waye to, ooyẹ kankan ko le yẹ iwọde ilu Eko naa.
Ninu ọrọ tirẹ, eekan ẹgbẹ ajafẹtọ ọmọ Yoruba miran, Dokita Amos Akingba ti ẹgbẹ Yoruba World Congress ṣalaye pe, dipo ki awọn alaṣẹ o tẹti si igbe araalu, ki wọn si wa nnkan ṣe si ẹhonu awọn eeyan amọ ohun to lee tubọ bi idide tako ijọba ati ipe fun ipinya ni wọn n ṣe.
Ninu ọrọ rẹ, o ni kii ṣe ilẹ Yoruba nikan ni ẹhonu yii ti n wa leyi to fihan pe ijọba ni iṣẹ lati ṣe lati tẹti si ẹhonu araalu.
Awọn to sun mọ oloye Sunday Igboho ṣalaye pe yatọ si dukia, ẹmi pẹlu sọnu sinu ikọlu naa.
Sunday Igboho: Sunday Igboho ní àwọn DSS àti ṣọ́jà ló kọlu ilé òun, èèyàn méjì ni wọ́n sì pa
Oloye Sunday Adeyẹmọ ti ọpọ eeyan mọ si Sunday Igboho ti sọ pe awọn oṣiṣẹ DSS ati awọn ologun lo wa nidi iṣẹlẹ ikọlu to waye ni ile rẹ nilu Ibadan loru Ọjọbọ mọju.
Ninu ifọrọwerọ rẹ pẹlu BBC lori bi iṣẹlẹ naa ṣe waye, Oloye Sunday Igboho ni nnkan bii agogo kan abọ ni iṣẹlẹ naa waye ti oun si n gbọ iro ibọn lakọlakọ ti awọn afurasi oṣiṣẹ DSS ati ọmọogun naa si n pariwo oruks oun lati bọ sita.
"Mo yọju loju ferese, mo ri wọn ninu aṣọ DSS ati aṣọ ologun. Mo si wo o pe ki ni mo ṣe ju pe mo ja fun awọn mọlẹbi mi to jẹ Yoruba lati bọ lọwọ awọn agbebọn to n pa wọn to n fipa ba awọn obinrin wọn lo pọ.
Gbogbo iwọde ti mo si n ṣe lo jẹ iwọde alaafia"
Sunday Igboho: Ẹ fi Ògún búra fún wa láti jà fún ilẹ̀ Yorùbá láì gbé Amotekun sábẹ́ ìjọba
Oloye Sunday Igboho ni idi ti oun fi gbe igbesẹ ati ja fun iran Yoruba ni pe ijọba ti kuna ninu ojuṣe rẹ lati daabo bo awọn eeyan ilẹ Yoruba.
O ni oun wa ninu ile lasiko ti awọn agbebọn naa wọ ile oun ati pe eeyan meji ni wọn pa.
Sunday Igboho: Wo ìgbà mẹ́rin tí ìkọlù ti wáyé nílé Sunday Igboho
Lẹyin wakati diẹ ti awọn agbebọn kọlu ile ajijagbara fun iran Yoruba, Oloye Sunday Igboho, ibeere ti ọpọ eeyan n beere ni pe nibo ni ajijagbara naa wa?
A ti sọ fun yin saaju pe awọn eeyan kan to mura bii ọmọ ogun yabo ile Igboho nidaji Ọjọbọ, ti wọn si pa eeyan meji, gẹgẹ bi agbẹnusọ rẹ ti wi.
Abẹwo BBC Yoruba si ile naa si fihan pe ẹjẹ wa nilẹ kaakiri, ti ọpọ dukia si bajẹ.
Bi o tilẹ jẹ pe awọn eeyan ta ba ninu ile naa ko le sọ ibi ti Igboho wa amọ awọn kan ni o ti poora lasiko ti awọn agbbọn naa de sibẹ.
Lẹyin wakati mẹwa ti ikọlu yii ti waye, agbẹnusọ fun Igboho nikan lo n ba araalu sọrọ, ti awọn eeyan si n beere pe ki lo de ti ajijagbara naa ko jade ki awọn ri pe alaafia lo wa.
Sunday Igboho: Ẹ fi Ògún búra fún wa láti jà fún ilẹ̀ Yorùbá láì gbé Amotekun sábẹ́ ìjọba
Koda, awọn eeyan to ba BBC sọrọ ni nigba tawọn amookunsika gan sọ ina si ile Sunday Igboho lalakọkọ, funra rẹ lo jade sita lati ba awọn akọroyin sọrọ.
Wọn wa n beere pe ki lo de lọtẹ yii ti awọn ko fi kofiri rẹ, ti ọpọ si n kaya soke pe se alaafia lo wa.
Lero tawọn eeyan mira, wọn ni se lo yẹ ki Igboho jade sawọn eeyan to wa se ikọlu yii, ko si se wọn bii ọsẹ ti n soju gẹgẹ bo se maa n fi ọwọ gbaya.
Bakan naa ni wọn n para poro pe awọn eeyan to ku ati awọn ti wọn ji gbe lọ, ko ba ti wa ninu ewu, ti Igboho ba fiya to tọ jẹ awọn to wa se ikọlu ọhun.
Igba karun ree ti awọn eeyan kan yoo kọlu ile Sunday Igboho nitori wọn ti kọlu ile rẹ nigba mẹrin sẹyin.
Inu ọdun 2021 ta wa yii nikan si ni awọn ikọlu maraarun naa ti waye saaju.
Igba akọkọ ti ikọlu yoo waye si Sunday Igboho ni akoko to n lọ silu Eko, lati lọ sile Iba Gani Adams.
Opopona Marosẹ Ibadan silu Eko, niwaju ile Guru Maharaji ni awọn osisẹ ọtẹlẹmuyẹ DSS ti da ikọ rẹ duro.
Iroyin to gbalẹ kan nigba naa ni pe awọn DSS naa fẹ gbe Sunday Igboho ni amọ ti awọn onitọun ni ko ri bẹẹ.
Oríṣun àwòrán, Facebook/Koiki Media
Bakan naa ni iroyin gbode pe awọn afurasi Sọja meji wa tọpinpin ile Sunday Igboho amọ ti awọn ọmọ ẹyin rẹ mu wọn mọlẹ.
Awọn afurasi Sọja naa lo wọ asọ ologun ti wọn si n gun ọkada kọja ni ogunjọ osu kẹta ọdun 2021 ti isẹlẹ naa waye.
Amọ awọn afurasi naa ni awọn n lọ jẹjẹ tawọn ni wọn da awọn duro, ti awọn ko si wa se ohunkohun ninu ile naa.
Lẹyin o rẹyin ni wọn fa awọn afurasi naa le ileesẹ ọlọpaa ipinlẹ Oyo lọwọ, ti ileesẹ ologun si fi ikede sita pe awn ko ni pẹlẹngọ lati mu Igboho tawọn ba setan lati se bẹẹ.
Awọn janduku kan la gbọ pe wọn ya bo ile akọkọ ti Sunday Igboho kọ si agbegbe Soka nilu Ibadan, amọ kii se ile yii lo n gbe.
Aimọye dukia lo jona ninu ile naa, ti wọn si tun ni awọn agbebọn ọhun gbe kẹẹgi epo pẹtiroolu wa lati sun ile naa ni.
A gbọ pe ọpẹlọpẹ awọn ọmọ ẹyin Igboho to jade ti wọn, tawọn janduku ọhun to gbe ọkọ bọọsi ati ayọkẹlẹ wa, si sa lọ.
Igba kẹrin ti ariwo yoo sọ pe wọn se ikọlu sile Sunday Igboho ni akoko ti wọn ni awọn osisẹ agbofinro ko ọkọ bọọsi wa lati fun Igboho ni lẹta kan.
Wọn ni ọga agba ọlọpaa nilẹ yii lo fi lẹta naa ransẹ si amọ tawọn ọmọlẹyin Igboho yari lati gba iwe naa.
Tábìlì àmì ẹ̀yẹ Olympic Tokyo 2020
Idije mẹtalelogun ọtọọtọ ati ifigagbaga ojilelọọdunrun o din ẹyọ kan ni yoo waye ninu idije ere idaraya Olympic fọdun 2020.
Ibudo mejilelogoji kaakiri orilẹede Japan ni awọn idije naa yoo ti maa waye.
Oju opo yii ni yoo maa se afihan tabili ami ẹyẹ ti wọn gba, bẹẹ ni yoo maa gbe esi bi idije naa se n lọ si funra ara rẹ lati se afihan iye ami ẹyẹ Wura, baba ati Idẹ ti ikọ elere idaraya kọọkan gba ninu idije naa.
Ami ẹyẹ akọkọ nireti wa pe wọn yoo fun ẹni to jawe olubori lọjọ Kẹrinlelogun osu Keje ọdun 2021.
Bi ikọ kan ti se daadaa si
Sunday Igboho: Wo àwọn èròjà àti orúkọ àwọn èèyàn tí DSS kó nílé Sunday Igboho
Oríṣun àwòrán, sunday_igboho1
Ajọ ọtẹlẹmuyẹ DSS ti ṣalaye lẹkunrẹrẹ idi abajọ ti wọn fi yabo ile ajijagbara ilẹ Yoruba, Oloye Sunday Adeyemo ti ọpọ mọ si Sunday Igboho.
Ajọ DSS ṣalaye ninu atẹjade to fi sita lalẹ Ọjọbọ pe awọn eeyan lo tawọn lolobo pe Igboho ko ibọn ati nkan ijagun pamọ nile rẹ lo jẹ ki awọn yabo ile rẹ.
Ninu atẹjade naa ti agbẹnusọ ajọ ọtẹlẹmuyẹ, Ọmọwe Peter Afunanya fi sita, DSS ni awọn ọmọṣẹ mẹsan an ti wọn gbe ibọn AK-47 lọwọ to wa nile Igboho kọju ibọn sawọn DSS.
Amọ meji ninu awọn ọmọṣẹ Igboho naa tẹri gbaṣọ.
Ọmọwe Afunanya ni ọkan lara awọn DSS lo kan ṣe leṣe ni ọwọ rẹ, o si ti lọ gba itọju nile iwosan.
Ajọ DSS ni lootọọ ni pe awọn mu awọn yoku ti wọn doju ija kọ awọn nile Igboho lọ.
Oríṣun àwòrán, DSS
Lẹyin awọn nkan ti ajọ DSS ko ninu ile Igboho, wọn tun mu eeyan mẹtala ninu ile rẹ lọ si Abuja.
Ọkunrin ni mejila ninu awọn eeyan yii nigba ti ọkan ninu wọn jẹ obinrin.
Orukọ mejila ninu awọn eeyan naa niyii nigba ti iwadii ṣi n lọ lọwọ lori eeyan kẹtala.
i.Abdulateef OFEYAGBE
ii.Amoda BABATUNDE aka Lady K (female)
iii.Tajudeen ERINOYEN
iv.Diakola ADEMOLA
v.Abideen SHITTU
vi.Jamiu NOAH
vii.Ayobami DONALD
viii.Adelabe USMAN
ix.Oluwafelumi KUNLE
x.Raji KAZEEM
xi.Taiwo OPEYEMI and
xii.Bamidele SUNDAY.
DSS nwa  fi asiko yii sọ fawọn ọmọ Naijiria ati gbogbo agbaaye pe, Sunday Igboho atawọn ẹgbẹ rẹ ti wọn jọ n beere fun iyapa orilẹede Yoruba ti ko nkan ija ogun pamọ sile lati maa da ilu ru.
Oríṣun àwòrán, DSS
Awọn ibọn atawọn nkan ijagun ti a ri nile Igboho fihan gbangba nipa erongba Igboho lati kọju ija si ijọba orilẹede Naijiria.
DSS ti n fi asiko yii sọ fawọn gbogbo awọn ileeṣẹ to n ri si iwe igbelu ati kaadi idanimọ pe, Igboho le kan si wọn pe kaadi idanimọ ati iwe igbelu ohun sọnu pe oun fẹ ṣe omiran, ẹ maa da a lohun.
Ajọ DSS tun n sọ fawọn eeyan pe o ṣeeṣe ki marun un ninu ibọn AK-47 ti wọn ri nile Ighoho jẹ awọn ibọn ti awọn ọmọṣẹ rẹ fipa gba lọwọ awọn oṣiṣẹ aṣọbode ni Idi Iroko nipinlẹ Ogun.
Ajọ ọtẹlẹmuyẹ tun fẹ ki awọn araalu mọ pe ija ibọn yinyin sira ẹni to bẹ silẹ nile Igboho fun wakati diẹ lo jẹ ki o ri ọna lati salọ.
Igboho le sa de bi ibi ti o ba wu u bayii, o le ti maa ṣe ikọlu si awọn agbofinro, ṣugbọn bo pẹ bo ya, ọwọ yoo pada tẹ ẹ.
Olowo: Bí ìjọba bá ṣe àtúntò tún yẹ, Sunday Igboho yóò fọwọ́sowọ́pọ̀ pẹ̀lú wọn
Lakotan, ajọ DSS n rọ gbogbo awọn to n ṣatilẹyin fun Igboho lati gba ni imọran pe ki o jọwọ ara rẹ fawọn oṣiṣẹ eleto abo nitori ko si ẹni to ga ju ofin lọ.
Bakan naa, gbogbo awọn eeyan ti DSS mu nile rẹ ni yoo foju ba ile ẹjọ laipẹ,'' Ọmọwe Afunanya lo ṣalaye bẹẹ.
Sunday Igboho: Elebuibon ní kìí ṣe pé ewé sunko fún Sunday Igboho, ìjàmbá làwọn DSS ṣe fún un
Oríṣun àwòrán, Instagram/Sunday Igboho
Oloye Sunday Adeyemo ti ọpọ mọ si Sunday Igboho jẹ ẹnikan ti ọpọ n wo gẹgẹ bi alagbara to kaato lati gbawọn eeyan silẹ lọwọ awọn afiya jẹni.
Idi niyii ti wọn maa fi n pe ni Igboho Oosa, ajijagbara ati ajafẹtọ ọmọniyan.
Eyi gan an lo jẹ ko wa lara awọn to n ṣe agbatẹru iwọde lati pe fun iyapa ati idasilẹ orilẹede Yoruba lara Naijiria.
Ṣé ẹ ti gbọ́ nípa òkú gbígbẹ́ tí wọ́n ṣì bá oyún nínú rẹ̀?
Ṣugbọn kayeefi lo jẹ fun ọpọ ọmọ Naijiria papaa julọ nilẹ Yoruba, bi ajọ ọtẹlẹmuyẹ DSS ṣe raye wọ ile alagbara ajijagbara naa to wa lagbegbe Soka niluu Ibadan loru mọju Ọjọbọ.
Bẹẹ ni ọpọ n beere pe nibo ni Igboho wa, ti ko fi lee koju awọn osisẹ DSS to wa ko awọn ọmọlẹyin rẹ lai bikita fun oogun to ni.
Bakan naa ni wọn ni niwọn igba to jẹ pe alagbara ni Igboho, ko se fi awọn oogun naa raga bo awọn ọmọ lẹyin rẹ, tabi ko ti lo diẹ fun wọn, ti ibọn ko fi ni le ran wọn.
Nipari, awọn ọmọ Yoruba kan wa n beere pe se ewe sunko fun Sunday Igboho ni lasiko tawọn osisẹ DSS fi wa, ni ko se duro koju wọn, ko si se wọn bii ọsẹ ti n soju.
Ọna lati wa idahun sawọn ibeere yii lo mu ka tọ agba alagbara kan nilẹ Yoruba lọ, ẹni to tun jẹ gbajumọ Babalawo ti ko se fi ọwọ rọ sẹyin.
Oríṣun àwòrán, Ifayemi Elebuibon
BBC Yoruba kan si Araba Ilu Osogbo, Ifayemi Elebuibon lati ṣalaye ohun to ṣẹlẹ tawọn ajọ DSS fi rọna wọ ile Igboho, ti wọn si ko bantẹ oogun rẹ atawọn nkan iṣe agbara mii lọ lai si nnkan kan to se wọn.
Elebuibon fesi pe kii ṣe pe ewe sunko fun Igboho, amọ Ijamba lawọn ajọ DSS lọ ṣe fun Igboho nile rẹ nitori ko pe wọn n bọ tẹlẹ.
''To ba jẹ pe Igboho atawọn ọmọlẹyin rẹ ti mura silẹ de wọn ni, ohun ti a n wi yii kọ ni a baa maa wi.
Ṣugbọn ẹni to ṣadeedee ja wọ ile eeyan lai ro ti tẹlẹ, to si bẹrẹ si ni ji nkan eeyan ko.
O da bi igba ti eeyan lọ ba eeyan ni buba ni, ohun to tumọ si ni ilaluri ati ijamba, ati pe bi igba ti eeyan lọ ja eeyan lole ni,'' Elebuibon ṣalaye.
Elebuibon ko ṣai sọ pe ko si igba ti ewe ko le sunko fawọn alagbara papaa julọ ti wọn ko ba kiye sara.
O ni ẹbọ ju oogun lọ tori ẹbọ ni o maa n jẹ ki oogun jẹ ṣugbọn Araba ilu Osogbo ni ojiji lawọn DSS lọ ba Igboho nile.
Peter Fatomilola: Robbery burú ju Yahoo lọ, iṣẹ́ ọpọlọ lọmọ Yahoo fi ń gba owó ìran baba
Lori ọrọ ti ajọ DSS sọ pe Igboho salọ nigba tawọn atawọn ọmọlẹyin rẹ doju ibọn kọ awọn oṣiṣẹ DSS, Elebuibon ni mọja mọsa ni Igboho ṣe kii ṣe pe o fẹ fi awọn ọmọlẹyin rẹ silẹ fun iya jẹ.
Elebuibọn ni ''ologun ti ko ba mọja mọsa, iru wọn lo maa n ba ogun lọ.
Ohun ti a n wi yii kọ ni a ko ba maa wi ti Igboho naa ba koju awọn ajọ DSS to wa ka a mọle ni.''
Elebuibon ko ṣai bu ẹnu atẹ lu bi awọn ajọ ọtẹlẹmuyẹ DSS ti yabo ile Igboho lairo tẹlẹ.
''Ni ilu ọlaju, ohun to yẹ kawọn DSS ṣe ni pe, ṣe lo yẹ ki wọn pe Igboho lori aago wi pe ko wa fun ifọrọwanilẹnu, ko lẹtọọ ki wọn kan ṣadeedee dabọn bolẹ nile rẹ bi wọn ṣe ṣe.
Glorious Twins: Taiwo àti Kehinde Ekundayo ní ọ̀dọ́ ìyá àgbà ní àwọn ti ẹ̀bún orin kíkọ
Bi wọn ṣe maa n ṣe lorilẹede Amerika atawọn orilẹede ọlaju miran niyẹn.
Wọn rọgba yi ẹni naa ka ni titi ti oni tọun yoo fi fi ara rẹ le wọn lọwọ, awa o le kọ wọn niṣẹ wọn ṣugbọn awọn ohun ti awa ti ri lawọn ilu okeere ti awa n gbe niyẹn,'' Elebuibon lo sọ bẹẹ.
Elebuibon ni owe lọrọ bi awọn DSS ṣe yabo ile Igboho n pa fun iran Yoruba pe ki araba tun ra mu, tori odo ti n gbe arere lọ.
Yoruba Nation: Iléeṣẹ́ ọ̀lọ́pàá Eko ní olórí NURTW n‘Ibadan ń bọ̀ wá da ìwọ́de rú l‘Eko láti gbẹ̀san lára Sunday Igboho
Ileesẹ ọlọpaa ipinlẹ Eko ti kede pe iwọde kankan ko gbọdọ waye nipinlẹ Eko labẹ bo ti wu, ko ri.
Kọmisana ọlọpaa l'Eko, Hakeem Odumosu lo fi ikilọ yi lede lasiko to n bawọn akọroyin sọrọ tun fi ewe ọmọ mọ awọn ajijagbara naa leti pe ilu ti yi, orin ti senji.
Odumosu wa n sekilọ fun Sunday Igboho ati alagba Banji Akitoye pe ki wọn ta kete sipinlẹ Eko lori iwọde Yoruba Nation ti wsn n gbero lọjọ Satide.
O ni oun n rọ wọn lati mase yọju soju popo ipinlẹ Eko nitori ifẹ ipinlẹ naa ati ti araalu, bẹẹ si ni ẹnikẹni ti ọwọ ba tẹ pe o se iwọde tabi se agbatẹru rẹ yoo jo palongo labẹ ofin.
"Ipinlẹ Eko ko lee tun foju wina eto aabo to mẹhẹ, idaluru ati idunkooko mọ alafia ilu ta ba wo isẹlẹ buruku to waye ni osu kẹwa ọdun to kọja tori iwọde Endsars.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ọpọ dukia ijọba ati ti araalu lo sofo danu nigba tawọn ọlọpaa fi ẹmi wọn di isẹlẹ naa lọpọlọpọ, eyi to jẹ irubọ to ga julọ.
Ọpọ agọ ọlọpaa ni wọn jo nina, to fi mọ awọn dukia to jẹ ti aladani ọlọpaa kọọkan lasiko iwọde naa, ti ileesẹ ọlọpaa ipinlẹ Eko ko si ti bọ ninu iriri buruku naa.
Nitori naa ni a ko fi ni fi ọwọ ere mu awọn eeyan to n se agbatẹru iwọde naa, ti wọn n sọ pe iwọde alaafia ni awọn fẹ se.
Iru orin yii naa ni awọn oluwọde Endsars mu bọnu amọ ti ọrọ naa pada bu rẹkẹ lẹyin o rẹyin, eyi to mu ẹmi lọ, ti ọpọ dukia si bajẹ."
Ileesẹ ọlọpaa ipinlẹ Eko ni nitori awọn alaye to ti se saaju yii, oun si tun n tẹnumọ pe ẹnikẹni ko gbọdọ wa se iwọde kankan nilu Eko tabi di lilọ bibọ araalu lọwọ lọna ijẹ wọn.
"Odumosu ni ""O ti de si etigbọ mi pe iwọde Yoruba Nation naa yoo waye ni gbagede Gani Fawehinmi ladugbo Ojota nikan."
Amọ awọn eeyan kan ti a ko mọ tun ti n gbero lati se irufẹ iwọde yii bakan naa ni ẹnu iloro Lekki Toll Gate, Ikoyi, Iyana Ipaja, Ikeja, Sururlere, Ikorodu atawọn agbegbe miran ni Eko.
Ta ba fi gba eleyi laaye, ewu nla n bẹ loko longẹ.
Glorious Twins: Taiwo àti Kehinde Ekundayo ní ọ̀dọ́ ìyá àgbà ní àwọn ti ẹ̀bún orin kíkọ
Iwadi awọn osisẹ ọtẹlẹmuyẹ tun ti fidi rẹ mulẹ pe ẹnikan ti wọn n pe ni Eleweomo, to jẹ asaaju ẹgbẹ ọlọkọ ero nilu iBadan ti pari eto gbogbo lati kọlu awọn oluwọde naa.
Eyi ni wọn lo fẹ fi gbẹsan iku ọkan lara awọn ọmọ ẹyin rẹ ti igun Sunday Igboho pa lasiko irufẹ iwọde yii to waye nilu Ibadan lasiko kan.
"Gbogbo akojọpọ ewu to rọ mọ iwọde naa ni ileesẹ ọlọpaa ko fi ni kawọ gbera lati gba awọn ọdaluru yii laaye pe ki wọn da alaafia ipinlẹ Eko ru."""
Kọmisana ọlọpaa nipinlẹ Eko wa rọ awọn eeyan ipnilẹ naa lati maa ba isẹ oojọ wọn lọ nitori awọn ọlọpaa atawọn osisẹ agbofinro miran ti wa kaakiri lati pese aabo to peye fun tonile talejo nipinlẹ Eko.
Olowo: Bí ìjọba bá ṣe àtúntò tún yẹ, Sunday Igboho yóò fọwọ́sowọ́pọ̀ pẹ̀lú wọn
Sunday Igboho: Afenifer ń bèèrè pé ṣé Nàíjíríà ti padà sí sáà oko ẹ̀rú ológun ni?
Ẹgbẹ ọmọ Yoruba lorilẹede Naijiria, Afẹnifẹre ti bu ẹnu atẹ lu ikọlu ti ileeṣẹ ọtẹlẹmuyẹ, DSS ṣe si ile ajijagbara fun ilẹ Yoruba, Sunday Adeyemo, ti ọpọ mọ si Sunday Igboho.
Adele fun Alaga ẹgbẹ Afenifere, Oloye Ayo Adebanjo ni ikọlu ti wọn ṣe si ile Sunday Igboho yii mu ki awọn eniyan ranti nkan ti awọn ọmọ Naijiria la kọja lasiko ijọba Ọgagun Sani Abacha.
Adebanjo ni o ṣe ni laanu pe ikọlu naa fihan bi Naijiria ṣe ti n pada si oko ẹru ati iya aitọ to wọpọ lasiko ijọba Ologun Sani Abacha, ti ẹnikẹni to ba sọrọ tako ijọba yoo foju wina ikọlu lati ọdọ awọn ẹṣọ alaabo.
O fikun pe bi wọn ṣe ṣekọlu si ile Sunday Igboho ko ṣẹyin iṣẹ ijọba apapọ orilẹede Naijiria ati awọn to wa ni ipo adari.
''Awọn ti ọrọ naa ṣoju wọn ni awọn to wa ṣekọlu naa si Sunday Igboho wọ aṣọ awọn ẹṣọ alaabo lorilẹede Naijiria''
''Bakan naa ni aibikita ẹṣọ alaabo lati wa doola ẹmi awọn eniyan nigba ti iṣẹlẹ naa waye fun wakati mẹta, fihan pe awọn ọlọpaa lọwọ ninu iṣẹlẹ naa, nitori agọ ọlọpaa yi agbegbe naa ka.''
''Nitori ko si ọlọpaa kankan to wa sibẹ lati wa koju awọn to ṣekọlu naa, eyi to fihan pe ijọba lọwọ ninu iṣẹlẹ naa''
Ẹgbẹ Afẹnifẹre ni eleyii ko yatọ si nkan to n waye lasiko ijọba Ologun ni Naijiria, bi wọn ṣe n fi iya jẹ awọn eniyan lọna aitọ, ti wọn si n ṣekọlu si ẹni to ba sọrọ tako Abacha.
' A ranti bi wọn ṣe fi iya jẹ awọn ogbontagiri ọmọ Yoruba nigba naa bi Ọgagun Alani Akinrinade, Pa Abraham Adesanya, Pa Alfred Rewane ati bẹẹ bẹẹ lọ.'
Glorious Twins: Taiwo àti Kehinde Ekundayo ní ọ̀dọ́ ìyá àgbà ní àwọn ti ẹ̀bún orin kíkọ
'Iya yii pọ to bẹẹ ti o jasi iku Pa Rewane nigba naa lọhun.'
Ẹgbẹ Afẹnifẹre wa fi asiko yii ke gbajare sita pe, wọn tun ti bẹrẹ si ni ṣe ikọlu si awọn ọmọ Yoruba paapaa awọn to n ja fun ominira ati ẹtọ awọn ọmọ Oduduwa.
Yoruba Nation: Igun Sunday Igboho ní Sátidé ní yóò sọ ẹni tó nìlú Eko láàrin ọmọ Yorùbá àti ọlọ́pàá
Oríṣun àwòrán, Olayomi Koiki
Igun awọn ajijagbara to n tẹle Sunday Igboho lẹyin ti n ke tantan tan pe iwọde Yoruba Nation ti wọn fẹ se nilu Eko yoo waye lọjọ Satide,
Agbẹnusọ fun Sunday Igboho, Olayomi Koiki lo fi ikede yii sita loju opo Facebook rẹ.
Koiki ni lootọ ni ileesẹ ọlọpa nipinlẹ Eko ti fi ikede sita pe oun ko fẹ ri awọn oluwọde Yoruba Nation amọ awọn ajijagbara naa ni lori irọ ni.
Igun Sunday Igboho ni asọrọ sẹ ni awọn, awọn ko si le sọrọ tan ki awọn wa ni awọn ko ni se bẹẹ mọ nitori ọmọ ọkọ ni awọn.
Nitori naa, wọn ni awọn yoo tẹsiwaju pẹlu iwọde Yoruba Nation naa boya Sunday Igboho tẹle awọn tabi ko si nibẹ.
Bẹẹ ba si gbagbe, ẹgbẹ Ilana Omo Oodua labẹ akoso alagba Banji Akitoye naa ti fi atẹjade kan sita ni Ọjọbọ pe awọn yoo tẹsiwaju pẹlu iwọde naa.
Sunday Igboho: Ẹ fi Ògún búra fún wa láti jà fún ilẹ̀ Yorùbá láì gbé Amotekun sábẹ́ ìjọba
"Agbẹnusọ fun Sunday Igboho ni ""Mo gbọ pe Kọmisana Ọlọpaa ni Eko kede pe a ko gbọdọ wa se ikede Yoruba Nation lọjọ Satide, ọjọ Kẹta osu yii."
Ẹ jọọ, ẹ ba wa sọ fawọn ọlọpaa Eko pe a n bọ, a si ti de tan, ki wọn maa reti wa.
Ọjọ naa si la mọ ẹni to ni Eko laarin awọn ọmọ Yoruba ati gomina ipinlẹ Eko, Babajide Sanwo-Olu ati awọn ọlọpaa.
"Ọjọ Satide yii naa la mọ bi ikun lo ni oko, bi pakute ni, a pade ni Eko lọjọ Satide fun iwọde naa, ipade di ọhun."""
"Bakan naa ni agbẹnusọ fun Sunday Igboho ni ""bi gbogbo nnkan yoo ba bajẹ, ko kuku bajẹ lọjọ Satide, o ku sọwọ wọn lati jẹ ka se iwọde pẹlu putu wa tabi bẹẹ kọ."
Sunday Igboho fulani ultimatum: Àwọn ará Kebbi àti Zamfara ló n jínígbé ní Oke Ogun- Serik
"Ninu kẹ jẹ ka se iwọde alaafia tabi da igboro ru, o ku si yin lọwọ, amọ gbogbo ohun to ba sẹlẹ, ileesẹ ọlọpaa Eko ni kẹ mu lori rẹ."""
O wa kede pe aago mẹsan aarọ ni iwọde naa yoo gbera ni gbagede Gani Fawehinmi ladugbo Ojota nilu Eko.
O si rọ gbogbo awsn ajijagbara fun Yoruba Nation lati peju lọpọ yanturu si ibi iwọde naa.
Saaju la ti fi to yin leti pe ileesẹ ọlọpa nipinlẹ Eko ti fi atẹjade kan sita pe oun ko fẹ kofiri awọn ajijagbara naa rara nilu Eko.
Sunday Igboho: Kìí ṣe gbogbo ohun tí DSS kó nílé mi ní wọn pàtẹ rẹ̀, níbo ní góòlù tí wọn kó wà?
Oríṣun àwòrán, DSS
Yoruba ni bi ogun ba jẹ lọ, ọgbọn yoo jẹ bọ.
Agbẹnusọ fun ajijagbara ọmọ Yoruba, Oloye Sunday Igboho ti salaye siwaju nipa ikọlu awọn osisẹ DSS sile ajijagbara naa.
Ninu fidio kan to se loju opo Facebook rẹ Olayomi Koiki sọrọ nipa atẹjade kan ti ileesẹ agbofinro naa fisita lalẹ ọjọbọ ti isẹlẹ naa waye.
Agbẹnusọ Igboho ni Ọlọrun lo saanu fun Sunday Igboho ninu ikọlu naa, kii kuku se pe o mọ se.
O ni awọn DSS yii n wa Igboho kiri lati pa ni amọ Alọrun lo yọ.
"Koda, awọn DSS tun pa ologbo to wa nile Sunday Igboho lọ, ti wọn si ro pe Igboho lo di ologbo lati sa fun wọn, bẹẹ ni wn gbe oku ologbo naa lọ.
Oríṣun àwòrán, DSS
Bakan naa ni agbẹnusọ fun Igboho tun kede pe awọn ko fara mọ eroja ti ileesẹ DSS safihan rẹ pe wọn ko nile Igboho.
O ni kii se eroja perete tawọn osisẹ DSS patẹ rẹ nirọlẹ Ọjọbọ ni ọọfisi wọn nilu Abuja, pe awọn ko nile Igboho lo ri bẹẹ.
Wọn fi ibọn han pe awọn ri AK 47, pump rifle, oogun abẹnu gọngọ, iwe irinna silẹ okeere atawọn ẹrọ ibaraẹnisọrọ ti wọn ko lọ nile Sunday Igboho."
Amọ wọn ko sọ nipa aimọye miliọnu naira ti wọn ko nile Igboho, to fi mọ awọn owo ilẹ okeere bii Pound Sterlings, dollar ati Euro.
Bakana naa ni wọn ko gbogbo ẹsọ goolu olowo iyebiye to wa nile Sunday Igboho lọ, ti wọn si se afihan rẹ mọ awọn ẹru ti wọn patẹ.
Oba Gbolahan Timson Shomolu Bariga ní 'Restructuring'ti bọ́ aṣọ kò bá Omọyẹ mọ́!
Abi ẹyin foju ri awọn ẹsọ ara yii laarin awọn ẹru naa, ohun ti mo ri ni owo beba onidọla kan, haaa, tori Ọlọrun.
Agbẹnusọ fun Sunday Igboho wa n beere pe ki lo de ti awọn oriade nilẹ Yoruba ko fi sọrọ sita lati igba ti isẹlẹ ikọlu sile Sunday Igboho naa ti waye.
Sunday Igboho: Ẹ̀ṣẹ̀ kan ṣoṣo tí olóògbé yìí ṣẹ̀ ni pé ó fẹ́ ìdásílẹ̀ Yoruba Nation
Oríṣun àwòrán, Sunday igboho
Ilumọọka Ajijagbara fun iran Yoruba, Oloye Sunday Igboho ti n ṣọfọ ọkan ninu awọn to jade laye lasiko ikọlu naa.
Isẹlẹ naa waye lẹyin ti ikọ DSS atawọn ikọ agbofinro miran yabo ile Oloye Sunday Igboho lọjọbọ, ti ina ibọn si sọ.
Ileesẹ agbofinro DSS si ti kede pe awọn eeyan meji lawọn pa ni ile eekan ọmọ Yoruba naa, lasiko abẹwo awọn sinu ile naa.
Amọ ninu atẹjade kan to fi sita, Oloye Sunday Igboho rọ awọn ololufẹ rẹ ati gbogbo ọmọ Yoruba lati gbadura fun iyawo atawọn ọmọ ti oloogbe naa fi silẹ saye.
Oríṣun àwòrán, Olayomi Koiki
"Ẹṣẹ kan ṣoṣo to ṣẹ ni pe o n fẹ idasilẹ orilẹede Yoruba.
A gbọdọ ranti awọn eeyan mẹwaa to ṣi wa lahamọ ni Abuja, nibi ti wọn ti fi wọn han gẹgẹ bi ọdaran, sibẹ a n ri awọn agbebọn atawọn Boko Haram to n rin kiri laisi idiwọ ni Naijiria."
Sunday Igboho wa gbadura pe ki Ọlọrun tẹ awọn oloogbe si afẹfẹ rere, ko si tu aya, ọmọ ati ẹbi tawọn oloogbe mejeeji naa fisilẹ saye lọ ninu.
Sunday Igboho: Afenifere Renewal Group ní láì sí ẹ̀rí, yóò nira láti gbàgbọ́ pé ilé Igboho ni DSS ti rí èròjà tó pàtẹ
Oríṣun àwòrán, Instagram/sunday Igboho
Eekan ẹgbẹ Afẹnifẹre Renewal group, Alagba Wale Oshun ti sọrọ soke lori ikọlu DSS si ile Sunday Igboho lọjọbọ.
Ẹgbẹ ARG ní ko si bi ajọ agbofinro DSS ṣe lee lero pe awọn ọmọ Yoruba atawọn ọmọ Naijiria yoo gba ọrọ rẹ gbọ pe ni ile Sunday Igboho ni wọn ti ri awọn ibọn atohun ija oloro ti wọn fi han nilu Abuja.
Ninu Ọrọ kan to ba BBC News Yoruba sọ, Oloye Wale Oshun ṣalaye pe, ajọ DSS gbọdọ mu ẹri to daju jade pe ni ile gbajumọ aṣiwaju ipe fun idasilẹ orilẹede Yoruba, ni wọn ti ri nnkan ijagun naa.
Alagba Oshun tun ṣalaye pe laye olori orilẹede Naijiria tẹlẹ, Ọgagun agba Sani Abacha, bi awọn eeyan ṣe pariwo aibọwọ fun ẹtọ ọmọniyan lasiko naa, sibẹ awọn agbofinro kii fi agidi wọ ile eeyan ti wọn fẹ mu.
Oríṣun àwòrán, DSS
O ni awọn agbofinro yoo kọkọ fi iwe pe onitọun, ki wọn to wa si ile rẹ fun ayẹwo 'bi o ba si nilo ki wọn mu u lọ fun ifọrọwanilẹnuwo, wọn a ṣe bẹẹ'.
O ni ajọ DSS gbọdọ ranti gẹgẹ bi ọmọ Naijiria, Sunday Igboho lanfani si awọn ẹtọ kan ti wọn gbọdọ tẹle, bi wọn ba fẹ wa si ile rẹ fun ohunkohun.
O fi kun un pe, ajọ DSS yoo nilo lati sọ ibi ti wọn ti ri awọn ohun ija oloro ti wọn ni awọn ko ni ile Igboho, afi ti wọn ba fa awọn ẹlẹri sita lati fi gbe ara wọn lẹsẹ pe, lootọ inu ile Igboho ni wọn ti ko wọn sita.
Sunday Igboho: Àwọn ọmọ Yoruba lókè òkun ṣèwọ́de lọ iléeṣẹ́ aṣojú ìjọba Nàìjíríà ní London
Oríṣun àwòrán, Instagram/sunday igboho
Awọn ọmọ Yoruba to wa loke okun ṣe iwọde nileeṣẹ aṣoju ijọba orilẹede Naijiria ni ilẹ Gẹẹsi lọjọ Ẹti.
Iwọde naa da lori bi awọn oṣiṣẹ agbofinro DSS ṣe ya wọ ile eekan ọmọ Yoruba to n pe fun idasilẹ orilẹede Yoruba, Sunday Igboho lọjọbọ.
Oniruru orin ẹhonu lawọn ọmọ Yoruba to ṣe iwọde naa kọ pẹlu awọn patako pelebe-pelebe ti wọn kọ akọle loriṣiriṣi si.
"Lara awọn akọle wọn ni ""Location 419.. #YorubaNationNow, ""Yoruba Nation. No going back"", ""Sunday Igboho is a man of the people"", ""Oduduwa Nation must stand."""
Glorious Twins: Taiwo àti Kehinde Ekundayo ní ọ̀dọ́ ìyá àgbà ní àwọn ti ẹ̀bún orin kíkọ
Awọn oluwọde naa bu ẹnu atẹ lu bi awọn DSS ṣe kọlu ile naa ti wọn si ni eeyan ti ko fẹran wahala ni Sunday Igboho.
Ọkan lara awọn oluwọde naa torukọ rẹ n jẹ Peter Ọladele ṣalaye pe eredi iwọde wọn ni lati fi to awọn alaṣẹ ileeṣẹ aṣoju ijọba Naijiria naa leti peo to gẹẹ.
Ẹ wo awọn iwa ọdaran ti awọn ọdaran darandaran kan n hu kiri; awa o ni dakẹ. Sunday Igboho kii ṣe ọdaran.
"Oluwọde miran, Grace Dada ṣalaye pe ""ki ni Igboho ṣe fun ijọba apapọ? Gumi wa nibẹ to n fidigbodi pẹlu awọn agbebọn, ki lo de ti wọn ko lọ fi panpẹ ofin mu u."
Soiless Farming: Samson Ogbole ní táwọn irè oko bá fara kan ilẹ̀, ló ń kó àrùn bá wọn
Ni Ọjọbọ lawọn oṣiṣẹ DSS atawọn agbofinro kan wọ ile Sunday Igboho ti wọn si pa eeyan meji; bakan naa ni wọn ko oriṣiriṣi nnkan nibẹ.
Baba Ijesha: Iyabo Ojo àti Nkechi Blessing gbà alàáfíà láàyè
Oṣerebinrin, Iyabo Ojo ti tọrọ aforiji lọwọ awọn adari ẹgbẹ awọn oṣere lorilẹede Naijiria, TAMPAN, lori iṣẹlẹ itahunsi ara ẹni to waye laarin wọn.
Iyabo Ojo ni oun ati akẹgbẹ oun Nkechi Blessing Sunday ti tọrọ aforiji lọwọ ẹgbẹ, ki wọn dariji awọn.
Eyi ko ṣẹyin bi ẹgbẹ TAMPAN ṣe paṣẹ fun gbogbo awọn oludari ere ni Nollywood lati kẹyin si oserebinrin mejeeji.
Wọn ni wọn ko gbọdọ kopa ninu ere kankan ti Iyabo Ojo ati Nkechi Blessing ba fẹ gbe yade nitori wọn ba akẹgbẹ wọn ja lori ọrọ Baba Ijesha lori ẹrọ ayelujara.
Ninu ọrọ to kọ si oju opo Instagram rẹ ni Iyabo ti sọ wi pe 'mọ dupẹ lọwọ Esabod, ki agba yin dalẹ, ẹ ku aduroti.'
'Ni akọkọ ni mọ dupe lọwọ Ọlọrun, alaanu to n duro ti emi ati ẹbi mi ni gbogbo igba, gbogbo ọjọ aye mi ni emi yoo fi ma a dupẹ ni ọwọ Ọlọrun.'
'Mọ fẹ fi asiko yii dupẹ lọwọ awọn alatilẹyin mi nitori ifẹ ti wọn ni si mi ati bi wọn ṣe duro ti mi… mi o ni ko iyan yin kere lailai'
'Bakan naa ni mo dupẹ lọwọ ọga mi ati aarẹ ẹgbẹ TAMPAN, Mr Latin, ẹ ṣeun sir.'
'Ẹyin baba wa nla nla, Adebayo Salami, Jide Kosoko, Yinka Quadri, emi ati Nkechi Blessing tọrọ aforiji lọwọ yin, nitori amu yin binu. '
'Agba ni yin, a si bọwọ fun yin, a dupẹ lọwọ yin fun aduroti yin.'
Aarẹ ẹgbẹ awọn oṣere lorilẹede Naijiria, TAMPAN, Bolaji Amusan ti gbogbo eniyan mọ si Mr Latin ti tọrọ idariji lọwọ Iyabo Ojo ati Nkechi Blessing fun ọrọ kubakugbe ti Jide Kosoko sọ si wọn.
Ninu fidio ti Iyabo Ojo fi si oju opo Instagram rẹ ni Mr Latin ti bẹbẹ nitori Jide Kosoko pẹlu ọrọ to sọ lati ba inu wọn jẹ.
Tunbosun Odunsin: Ẹlẹ́dàá ló fún mi ní tálẹǹtì ẹ̀kún sísun ní ìrọ̀rùn nínú eré tíátà
Ọrọ ti Jide Kosoko sọ nipe oun yoo fi iya jẹ Iyabo Ojo, ti oun yoo si di gbogbo ọna mọ ọna ati jeun rẹ.
Amọ, Latin ni eeyan daadaa ni Jide Kosoko to kan sọ ọrọ ibinu lasan ni.
'Ẹni to ba mọ Jide Kosoko yoo jẹri si pe eniyan daadaa ni wọn, nitori naa mo tọrọ aforiji fun ọrọ ti wọn sọ pẹlu ibinu, to si ṣetan lati fa Iyabo Ojo ati Nkechi Blessing mọra.
Bakan naa ni Iyabo Ojo tọrọ aforiji ni ọwọ ẹgbẹ TAMPAN, awọn agbaagba ẹgbẹ to fi mọ Jide Kosoko.
Baba Ijesha: Princess ní òjú gba òun tì fún Iya Rainbow
Gbajugbaja apanilẹrin ati oṣere Nollywood, Princess ti bu ẹnu atẹ lu gbajugbaja oṣere, Idowu Philips ti gbogbo eniyan mọ si Mama Rainbow, lori ọrọ to sọ nipa Baba Ijesha.
Ohun to da ija silẹ laarin  Mama Rainbow ati Princess ni ọrọ ti Mama Rainbow sọ lasiko to n ṣe ifọrọwanilẹnuwọ lori ọrọ Baba Ijesha.
Mama Rainbow ni oun bẹ Princess fun odidi ọjọ mẹrin nigba ti ọrọ Baba Ijesha ṣẹlẹ, pe ko mase jẹ ki ọrọ naa di ariwo.
O ni Princess ko da oun loun nipa ẹbẹ naa, amọ ti ileẹjọ papa gba oniduro Baba Ijesha ni ahamọ lẹyin o rẹyin.
Nigba to n fesi lori ọrọ Mama Rainbow naa ninu fidio ti Princess gbe jade loju ọpọ Instagram rẹ, o salaye bi ọrọ ṣe jẹ laarin oun ati Mama Rainbow nigba ti iṣẹlẹ Baba Ijesha waye.
Mama Rainbow: iṣẹ́ tíátà kò ta sánsán mọ́ bíi ti ayé àtijọ́
'Kii ṣe tuntun mọ pe emi ati awọn ẹbi mi nla ina kọja nitori iṣẹlẹ to waye.
Onikaluku lo ni akọsilẹ tirẹ, amọ mo ṣe fidio yii nitori Mama Rainbow, lẹyin ti mo wo ifọrọwanilẹnu ti wọn ṣe pẹlu ileeṣẹ iroyin BBC Yoruba''
'Oju gba mi ti fun yii nitori ẹ kii ṣe iya rere, inu mi bajẹ nitori mo ri yin gẹgẹ bi iya rere ati ti mo si jẹ ọmọ-ọmọ rere si yin.
'Ẹ sọ wi pe ẹ bẹ mi fun odidi ọjọ mẹrin, ti mi o si gba ẹbẹ yin, pe bayii wọn ti fi Baba Ijesha silẹ.
Amọ ko si otitọ ninu iroyin pe e pe mi ni ẹẹmẹrin, nitori igba kan pere ni ẹ pe mi.'
'Ẹ ni pe ki n lọ fi Baba Ijesha silẹ ni atimọle ọlọpaa, amọ mi o binu nitori agbalagba niyin, ti mọ si sa gbogbo ipa mi lati salaye ọrọ to ṣẹlẹ fun yin.
Ẹ ni Baba Ijesha lo pe yin fun ara rẹ, wi pe ki ẹ bẹ mi nitori oun hu iwa buruku si mi.
Ẹ sọ wi pe ki n fi adirẹsi ile mi ranṣẹ si yin, amọ ẹ ko wa, lẹyin ọjọ kẹta, ẹ tun pe mi lori aago pe ẹ ri pe ọkan mi ko balẹ, pe mo n sun kun, amọ ẹ ko yoju si mi'
Princess to fi ibinu sọrọ ni pe, ka ni ọmọ Mama Rainbow ni iru iṣẹlẹ ọhun ṣẹlẹ si, wọn ko ni ma a ba orukọ oun jẹ kaakiri.'
Princess fikun pe, oun ni igbagbọ pe otitọ ni yoo leke ninu iṣẹlẹ yii ati wi pe ohun gbogbo to sokunkun ni yoo pada han si kedere.
Sunday Igboho: Òògùn ìbílẹ̀ ni mo fi n dáàbò bo ara mi, kìí se ìbọn
Oríṣun àwòrán, sunday_igboho1/Instagram
Gbajugbaja ajafẹtọ ẹni, Oloye Sunday Igboho ti figbe ta pe awọn osisẹ DSS to wa sile oun ko awọn oku awọn eeyan ti wọn pa lọ.
Sunday Igboho ẹni to fi atẹjade kan sita lati ipasẹ agbẹnusọ rẹ, Olayomi Koiki ni irọlẹ ọjọ Ẹti , wa salaye awọn bi ikọlu awọn DSS se waye nile rẹ ati ohun to faa.
Bakan naa ni Igboho mẹnuba pe ilana bi awọn agbofinro se pa awọn oluwọde Endsars logunjọ osu kẹwa, ti wọn si gbe oku wọn lọ, naa ni wọn lo nile oun.
"To ba jẹ pe ijọba Buhari yege lati pa mi ni, wọn ko ba kede pe awọn ko mọ awọn agbebọn to wa sisẹ ibi naa ni.
O si yẹ ki awujọ agbaye mọ pe aayan ti n lọ lati fi tipa mu awọn eeyan ti wọn ko ninu ile mi lati jẹwọ oun ti wọn ko se ni tipa tipa, eyi to le se akoba fun wọn.
Sunday Igboho: Ẹ fi Ògún búra fún wa láti jà fún ilẹ̀ Yorùbá láì gbé Amotekun sábẹ́ ìjọba
Mo wa fẹ ki awujọ agbaye mọ pe ẹni to n bọwọ fun ofin ni mi , mo si n rọ aarẹ Buhari lati rọ awọn agbofinro rẹ, ki wọn dẹkun irọ pipa nipa mi lati ba orukọ mi jẹ."
Igboho ti wa n fọwọ sọya pe oun ko mọ ohunkohun nipa awọn ibọn ti ajọ DSS safihan rẹ pe wọn ko ninu ile oun.
O wa n ke si awujọ agbaye pe ko ye wọn pe o see se ko jẹ inu ibudo iko nnkan ijagun pamọ si to wa ni ọọ̀fisi ajọ DSS ni wọn ti ko awọn ibọn ti wọn safihan rẹ jade.
"Boya awọn agbofinro to ya bo ile mi lo dọgbọn ko awọn ibọn naa wa sibẹ ni tabi ko jẹ pe inu ile ti wọn n ko ohun ija pamọ si ni wọn ti ko awọn ibọn naa jade.
Wọn parọ mọ mi ni, eyi si foju pe idi ti wọn se fi oru mọju wa sile mi ree, ti wọn si ba awọn awọn ẹrọ ayaworan mi jẹ, ki wọn to bẹrẹ isẹ.
Ti ko ba jẹ pe wọn ni ete miran, ki lo de ti wọn ko so ẹrọ ayaworan mọra lati maa ya gbogbo bi wọn ti n sisẹ nile mi, bẹrẹ lati igba ti wọn ti wọle.
O si ti foju han pe pẹlu isesi wọn yii, ijọba Buhari setan lati lo ọnakọna fi pa ẹnu araalu mọ."
Oba Gbolahan Timson Shomolu Bariga ní 'Restructuring'ti bọ́ aṣọ kò bá Omọyẹ mọ́!
Gbajugbaja ajafẹtọ Yoruba naa tun ti sẹ pe oun kọ ni oun ni awọn ibọn ti awọn osisẹ ọtẹlẹmuyẹ DSS se afihan rẹ.
Igboho ni awọn agbofinro naa lo wa sile oun lai mu iwe asẹ lati yẹ ile oun wo wa, gẹgẹ bi ofin ti laa kalẹ, ti wọn si ba awọn dukia oun olowo iyebiye jẹ.
O ni wọn pa awọn eeyan, ti wọn si tun ji ọpọ ohun alumọni ati owo lọ ninu ile oun, eyi ti aworan atawọn fidio rẹ ti wa kaakiri ninu awọn iwe iroyin.
Igboho ni bi aarẹ Buhari se kuna lati dẹkun iwa ọdaran awọn darandaran lo mu ki oun dide lati da si ọrọnaa nitori oun ko ba ti se bẹẹ, ti ijọba ba mọ isẹ rẹ bii isẹ ni.
"Bi mo si se n jija gbara mi ko lọwọ itajẹsilẹ tabi gbigba ẹmi lẹ. Ọna ti mo n gba lati dena iwa ọdaran ni lati le awọn Fulani kuro ni ibuba wọn.
Awọn ileesẹ agbofinro ati ileesẹ aarẹgan si mọ pe n ko tako awọn Fulani to n gbe ni alaafia tabi awọn ẹya miran to wa ni ẹkun iwọ oorun guusu Naijiria."
Sunday Igboho wa fikun pe lẹyin ọpọ iyanju lati fi tipa pa oun lẹnu mọ, amọ ti ko see se, ni wọn wa ri oun bii ewu nla , ti wọn si n dete lati ba oun ni orukọ jẹ.
Sunday Igboho; Irọ́ ńlá ní pé mo wà ní àtímólé DSS, ilé mí ní Ibadan ní mo wà
Oríṣun àwòrán, sunday_igboho1/Instagram
Ajijagbara fun ilẹ Yoruba, Sunday Igboho ti ni ko si otitọ ninu iroyin ẹlẹjẹ to n lọ kaakiri wi pe Ikọ ọtẹlẹmuyẹ DSS ti mu oun si atimọle.
Ninu ifọrọwanilẹnu ti agbẹnusọ rẹ, Olayomi Koiki se fun loju opo Facebook rẹ, ni Sunday Igboho ti bu ẹnu atẹ lu iroyin ẹlẹjẹ ọhun.
Iroyin naa ko si ṣẹyin bi awọn ikọ ọtẹlẹmuye DSS ṣe kọlu ile Sunday Igboho, eyi to mu ẹmi meji lọ, ti ọpọ dukia si bajẹ.
Ninu ọrọ rẹ, Sunday Igboho ni inu ile oun nilu Ibadan ni oun wa, agbofinro kankan ko si wa gbe oun .
''Ẹkaalẹ gbogbo ẹyin ololufẹ mi kaakiri agbalaaye, orukọ mi ni Sunday Igboho, irọ ni pe mo wa ni panpẹ DSS''
Oríṣun àwòrán, Koiki Media
Ọjọ oni jẹ Ọjọ Keji, Osu Keje, ọdun 2021. Mo ti n gbọ iroyin pe DSS ti mu Sunday Igboho, Emi ko si ni Guru o, mo wa ni ile mi ni Ibadan.''
Ibi ti Sunday Igboho pari ọrọ rẹ si niyii, ki Koiki to ma a ba eto rẹ lọ.
Bakan naa ni Sunday Igboho ati awọn alatilẹyin rẹ lori idasilẹ Yoruba Nation ti ni, ko si ohun ti yoo yẹ iwọde ti wọn fẹ ṣe ni ilu Eko ni Ọjọ Kẹta, Osu Keje, ọdun 2021.
Sunday Igboho: Ilana Omo Oodua ní jálajàla tí òkú Adogan rí gan ti DSS lójú, ni wọn ṣe gbé òkú rẹ̀ lọ
Oríṣun àwòrán, Yoruba Nation/Facebook
Awọn ẹlẹgbẹjẹgbẹ nilẹ Yoruba atawọn eekan ajijagbara to n pe fun idasilẹ Yoruba Nation ti n se idaro akọni to lọ laarin wọn.
Ọkunrin naa ti inagijẹ rẹ n jẹ Adogan ni awọn osisẹ agbofinro DSS pa loru Ọjọbọ ti wọn se ikọlu sile gbajumọ ajijagbara fun ilẹ Yoruba, Sunday Igboho.
Adogan la gbọ pe o jẹ ara awọn ọmọlẹyin Sunday Igboho, ti wọn dijọ n jija gudu fun idasilẹ orilẹede Yoruba Nation.
Ọkunrin yii si ni awọn osisẹ DSS lo wa lara awọn eeyan meji ti ẹmi wọn ti ọwọ awọn bọ nile Sunday Igboho nitori pe wọn n di awọn lọwọ lati wọnu ile naa.
Nigba ti wọn n daro oloogbe naa, Ẹgbẹ Ilana Omo Oodua, ti oun naa n jijagbara fun idasilẹ Yoruba Nation kede pe ọta ibọn mejidinlaadọta ni DSS yin mọ Adogan, titi to fi jade laye.
Oríṣun àwòrán, Olayomi Koiki/Facebook
"Atẹjade ti Ifa Dare fisita ni orukọ ẹgbẹ Ilana Omo Oodua loju opo Facebook Olayomi Koiki, tii se agbẹnusọ fun Sunday Igboho ni ""Eyi ni oju akọni ati jagunjagun tootọ."
Orukọ rẹ ni Adogan (PBUH), o gba ọta ibọn mejidinlaadọta sara, to si duro bii akọni Ẹsọ Ikoyi ti ko bẹru ohunkohun.
"Nigba ti ọta ibọn DSS ko ran Adogan, ni wọn ba fi ọmọ odo fọ lori, wọn du bi ẹran titi to fi ku."""
Ẹgbẹ Ilana Omo Yoruba ni Adogan, Majasola Igboho Oosa, ki alaafia ati ibukun Eledua wa pẹlu rẹ, o ti jade kuro lati pada wa ja ni ọjọ miran.
Oríṣun àwòrán, Olayomi Koiki Facebook
Ẹgbẹ naa fikun pe awọn osisẹ DSS se oku Adogan jalajala debi pe oju gan n ti wọn lati fi oku rẹ silẹ, ti wọn si gbe lọ pẹlu wọn.
Ẹgbẹ naa ni se ni ẹjẹ Adogan n ro tẹle awọn DSS lẹyin lati inu yara igbalejo Sunday Igboho titi de olu ileesẹ wọn to wa nilu Abuja.
Ẹgbẹ naa wa n fi ọwọ gbaya pe ko si a n boju wẹyin mọ ninu ọrọ idasilẹ orilẹede Yoruba, ti awọn yoo si se iwọde Yoruba nilu Eko lonii ọjọ Satide.
Saaju ni Sunday Igboho ti kọkọ daro ọmọlẹyin rẹ naa, to si ni ki awọn eeyan maa gbadura fun aya atawọn ọmọ to fi silẹ.
Sunday Igboho: Ọ̀pọ̀ èèyàn jẹ́rìí pé Mùsùlùmí òdodo ni Adogan Oosa, kìí pa irun jẹ
Oríṣun àwòrán, Koiki Media
Yoruba ni iku ogun lo n pa akikanju, iku odo nii pa omuwẹ, iku werewere nii pa obukọ.
Eyi ni ọpọ ọmọ Yoruba fi n sapejuwe ọkunrin kan, Saheed Adigun, ti ọpọ eeyan n pe ni Adogan, to jade laye lasiko ikọlu ti awọn osisẹ DSS se sile Sunday Igboho.
Lẹyin gbogbo hilahilo wahala ikọlu ile ajafẹtọ ọmọniyan fun idasilẹ Yoruba Nation, Sunday Igboho to waye, awọn eeyan ti n kan sara si ọkan lara awọn to fara gbọta naa.
Ṣé ẹ ti gbọ́ nípa òkú gbígbẹ́ tí wọ́n ṣì bá oyún nínú rẹ̀?
Ẹni taa n wi yii, pupọ eeyan ni ko mọ ọ tẹlẹ ko to jade laye, bo tilẹ jẹ wi pe kii jina si ayika ibi ti Sunday Igboho ba wa.
Adogan ooṣa ni inagijẹ rẹ ṣugbọn orukọ abisọ rẹ ni Adigun Saheed.
BBC Yoruba fimu finlẹ nipa rẹ, diẹ ree ninu ohun ta ri loju opo ayelujara nipa oloogbe naa.
Oríṣun àwòrán, Koiki Media
Ọmọ bibi ipinlẹ Osun ni Adigun Saheed taa si gbọ pe lati igba to ti de ọdọ Sunday Igboho, gbọin gbọin lo wa lẹyin rẹ bi ike.
Ilu Osogbo nipinlẹ Osun ni Adigun ti wa, ti ọpọ awọn olubanikẹdun si ti n ya lọ sile rẹ nilu naa, lati lọ daro iku rẹ.
Ohun ta ri aridaju rẹ ni pe musulumi to mu ẹsin rẹ lọkunkundun ni Adigun Saheed.
Gẹgẹ bi ohun taa ri ka nipa rẹ, Saheed Adigun kii pa irun rẹ jẹ ti o si ni igbagbọ pe gbogbo agbara lati ọdọ Allah lo ti wa.
Iroyin kan ti ko fidi mulẹ ni Adogan Oosa wa lori irun nigba ti ikọlu si ile Sunday Igboho waye.
Oríṣun àwòrán, YORUBA NATION
Nipa iru eeyan ti Adogan Oosa jẹ, a ri fọnran fidio kan to ti n kọrin Fuji  ninu ọkọ, eyi to fihan wa pe ololufẹ orin Fuji nii se nigba aye rẹ.
Gẹgẹ bi ọga rẹ, tii ṣe Sunday Igboho, Adogan Oosa naa fẹran orin Wasiu Alabi Pasuma, ti ko si fi ifẹ rẹ pamọ fun.
Ninu fidio kan ti akọrin ,Wasiu Ayinde Onilewura Omo Pasuma to fi ilu Osogbo ṣe ibujoko fi si Instagram rẹ, a ri ti Saheed Adigun n kọ orin Paso.
Olayomi Koiki to jẹ agbẹnusọ Sunday Igboho sọ pe akọni nla lawọn padanu pẹlu iku Adogan Oosa.
Loju opo ayelujara lo fi ikede iku Adigun Oosa si, to si ni ki Eledua dẹ ilẹ fun ẹni to lọ.
Ninu nkan to sọ, a ri aridaju pe Adigun Saheed ni iyawo ati ọmọ ki o to jade laye.
Diẹ ree lara awọn aworan rẹ ti Koiki fi sọwọ.
Oríṣun àwòrán, Koiki Media
Yoruba Nation: Ìrìn padà tẹ fún ìrìn, àwọn aláwo siwájú ìwọ́de láti kojú ọlọ́pàá l‘Eko
Iwọde Yoruba Nation Rally to kọkọ ṣebi ẹni pe ko ni waye nilu Eko ti pada gbera sọ bayi
Ṣugbọn awọn ọlọpaa ati ọmọ ogun ti fi omi ati afẹfẹ tajutaju tu awọn oluwọde naa ka.
Akọroyin wa to jabọ lati ibi iwọde naa nilu Eko sọ pe lọwọ aarọ ti oun debẹ niṣe lawọnb ọlọpaa kun iwaju aaye inaju Gani Fawehinmi ti ko si si oluwọde ni tosi.
Nigba ti yoo fi di nkan bi ago mọkanla ni Kọmisana ọlọpaa ipinlẹ Eko Hakeem Odumosu wa lati ba awọn akọroyin sọrọ.
Bi o ṣe n ba awọn akọroyin sọrọ ni awọn oluwọde naa ba ṣadede ṣi wa, ti wọn si bẹrẹ si ni kọrin lorisirisi pe iya pọ to n jẹ awọn ni Naijiria.
Ariwo Yoruba Nation, Ooṣa ati bẹẹ bẹẹ lọ si lo gbode nibi iwọde naa ti waye, ti awọn oluwọde si n pe fun idasilẹ orilẹede Yoruba kuro lara ni Naijiria.
Ki a to wi ka to fọ, awọn ọlọpaa ti gbe ọkọ nla wọn lati maa fi yin omi si awọn oluwọde ti wọn si tun wọn ka.
Ọwọ ọlọpaa tẹ awọn oluwọde kan ti wọn si gbe wọn si inu ọkọ wọn ti wọn gbe wa.
Bakan naa ni iron ibọn n dun lakọ lakọ
Yoruba Nation: Ọ̀pọ̀ ọmọ Nàíjíríà ló ń fi ìbẹ̀rù hàn lórí ìwọ́de Yoruba Nation tí yóò wáyé ní Eko lónìí
Ọjọ pe, ọjọ ko ti iwọde Yoruba Nation ti ọpọ eeyan ti n fi oju sọna fun yoo waye.
Awọn ajijagbara to n pe fun idasilẹ orilẹede Yoruba Nation si lo n se agbatẹru iwọde naa, ti Oloye Sunday Igboho ati alagba banji Akintoye si n lewaju wọn.
Ọjọ Satide, ọjọ Kẹta osu keje ọdun 2021 ti wọn ti kede saaju pe iwọde naa yoo waye nilu Eko ti wa ko bayii amọ ọpọ eeyan lo ti n kaya soke pe ki ni yoo sẹlẹ loni.
Lati ọjọ ti ikede ti waye pe iwọde naa n bọ nilu Eko, ni awọn oniruuru iroyin ti ko fẹsẹ mulẹ ti n lọ lori ayelujara pe awọn eeyan kan ti n dunkoko lati kọlu awọn oluwọde naa.
Bi o tilẹ jẹ pe awọn oluwọde yii ti n lọgun tẹlẹ pe iwọde alaafia ni awọn n gbe kiri, sibẹ ileesẹ ọlọpaa nipinlẹ Eko ti sepade awọn akọroyin pe oun ko faaye gba iwọde naa lati waye.
Olowo: Bí ìjọba bá ṣe àtúntò tún yẹ, Sunday Igboho yóò fọwọ́sowọ́pọ̀ pẹ̀lú wọn
Gẹgẹ bi Akeem Odumosu, tii se Kọmisana ọlọpaa nipinlẹ Eko se wi, ileesẹ oun ti hu gbọ pe awọn janduku kan ti n palẹmọ lati ja iwọde naa gba mọ awọn ajijagbara Yoruba Nation lọwọ.
O ni oun ko le la oju ohun silẹ, ki wọn da ilu Eko ru mọ oun lori gẹgẹ bo se waye lasiko iwọde Endsars eyi to mu ẹmi lọ, ti ọpọ dukia si tun bajẹ.
Sugbọn awọn ajijagbara naa ti wa fesi pada fun ọga ọlọpaa naa pe bo fẹ, bo kọ awọn n bọ nilu Eko lati wa se iwọde naa lọjọ Satide oni.
Ẹgbẹ Ilana Omo Oodua ti alagba Banji Akitoye ko sodi si ti fi ikede kan sọwọ sawọn akọroyin pe ẹgbẹ naa yoo tẹsiwaju pẹlu iwọde Yoruba Nation lọjọ Satide.
Bakan naa ni igun Sunday Igboho ti kede pe bi ikun lo ni oko ni, bi Pakute ni, ipade di ilu Eko lonii nibi tawọn yoo ti se iwọde.
Kunle Olajide, Akọ̀wé ìgbìmọ̀: Ẹ̀yin ọ̀dọ́, ọjọ́ ọ̀la yin kò ṣe e fọ́wọ́ ẹ sọ̀yà, ẹ díde
Gẹgẹ bi agbẹnusọ fun Sunday Igboho, Olayomi Koiki ti kede loju opo Facebook rẹ, asiko iwọde naa ni gbogbo agbaye yoo mọ ẹni to ni ilu Eko.
O ni aala yoo fi oko ọlẹ han laarin awọn ọlọpaa, Gomina Sanwo-Olu ati awọn ọmọ Yoruba to n bọ wa se iwọde.
Kaakiri ilẹ Yoruba ni awọn ajijagbara naa ti n lọ kaakiri lati se ipolongo fun idasilẹ orilẹede Yoruba Nation naa.
Lara awọn ilu ti wọn ti de ni Ibadan, Abeokuta, Osogbo, Akure, Ado Ekiti, Offa, Ilorin ati bẹẹ bẹẹ lọ
Amọ ibeere ti ọpọ ọmọ Yoruba n beere ni pe se nnkan yoo fara rọ nilu Eko loni, tii awọn ajijagbara naa ba yọju fun iwọde Yoruba Nation?
TB Joshua Burial: Ìjọba ìpínlẹ̀ Eko ní kí ìjọ SCOAN tẹ̀síwájú pẹ̀lú ètò ìṣínkù Wòlí TB Joshua tí yóò bẹ̀rẹ̀ lónìí
Oríṣun àwòrán, Lagos State Government
Ijọba ipinlẹ Eko ti buwọlu eto isinku adari ijọ Synagogue Church of All Nations (SCOAN), Woli TB Joshua to jade laye.
Eyi ko ṣẹyin bii ijọ naa ṣe n reti ọpọlọpọ eniyan kaakiri agbaye ti wọn yoo ma awa si ibi isinku naa lati oni lọ.
Kọmiṣọnna fun eto ilẹra nipinlẹ Eko, Ọjọgbọn Akin Abayomi to saaju awọn to ṣe abẹwọ sibẹ ni idi ti awọn fi lọ sibẹ ni lati ri pe wọn tẹlẹ ilana to de arun Coronavirus.
Abayomi ni awọn n gbiyanju lati ri pe ọwọja ikẹta aarun Coronavirus to n kaakiri awọn orilẹede paapaa India, ko ja de Naijiria.
Oríṣun àwòrán, Lagos State Government
O ni awọn ko fẹ ki arun Coronavirus to ti n rele ni Naijiria tun ru gẹgẹ si oke si nitori iye awọn eniyan to n bọ lati okeere wa si Naijiria.
''A tun fi asiko yii ba ẹbi ati ara oloogbe TB Joshua kẹdun ipapoda ẹni ire to lọ, paapaa ni asiko yii.''
Oríṣun àwòrán, Lagos State Government
''Ohun ti a mọ ni pe orisirisi ọwọja aarun Coronavirus lo n ja kaakiri ni agbaye bayii, amọ a ko fẹ ko wọ ilu Eko.''
''Lẹyin iku T.B Joshua ni gomina ipinlẹ Eko ti paṣẹ pe ki a ṣe abẹwo to yẹ si ile ijọsin naa nitori eniyan nla lo kọja lọ, ti ọpọlọpọ eniyan yoo si pejọ sibẹ.''
Oríṣun àwòrán, Lagos State Government
''Nibayii, gbogbo ẹni to ba n bọ gbọdọ wa ni ipamọ fun ọjọ meje, lẹyin naa ni wọn to le darapọ mọ ayẹyẹ kankan.''
Bakan naa ni kọmisọnna ohun ni gbogbo eto lo ti wa lati ri pe ẹnu ibode Naijiria gbogbo lo wa ni ilana idẹkun arun Coronavirus.
Gẹgẹ bi eto isinku gbajugbaja Wolii agbaye ni ati ati oludari ijọ Synagogue Church of All Nations, Temitope Joshua yoo ṣe bẹrẹ lọsẹ yii, ijọ naa ti kéde ohun to yẹ ni ṣiṣe fun awọn ti yoo wa nibi eto isinku naa.
Oríṣun àwòrán, TB Joshua/instagram
Wọn ni bo tilẹ jẹ pe isin akọkọ ti yoo waye, kii ṣe gbogbo eniyan ni yoo lanfani lati wa nibẹ tori wọn ko ṣe aye silẹ fun gbogbogbo amọ awn ti ko ba si nibẹ lee ba awọn pe lori ayelujara tabi lorii tẹlifisan wọn.
Ninu fidio ti wọn fi sita lori ayelujara ijọ SCOAN lowurọ oni yii kan naa ni wọn ti ki awọn eniyan nilọ pe ki wọn ṣọra fun awọn ọdaran to n dibọn bii ileeṣẹ tẹlifisan Emmanuel tabi ijọ SCOAN lati maa beere owo lọwọ wọn fun eto isin ikẹyin Woli TB Joshua.
Oríṣun àwòrán, TB Joshua/instagram
Ole paraku ni iru awọn bẹẹ! Ẹ ma jẹ ki ẹnikẹni tan yin jẹ, Ọlọ run mọ bo ṣe n sọrọ si ọkan awọn eeyan lati na ọwọ si ohun ti a nilo. A o ran ẹnikẹni, a ko si ni ran ẹnikẹni lai lai.
Ileeṣẹ naa ni awọn ni ọna ti awọn fi n kan si awọn onigbọwọ awọn nipasẹ Emmanuel TV to jẹ agbẹnusọ awọn.
"Lẹyin eyi ni wọn kede ilana bi eto isinku ti yoo bẹrẹ lọla yoo ṣe lọ laarin ọla ọjọ karun titi di ọjọ kọkanla oṣu keje eyi ti wọn n pe akori rẹ ni ""kii ṣe temi, bikoṣe ifẹ Ọlọrun""."
Oríṣun àwòrán, TB Joshua/instagram
Bí ìlànà ìsìnkú TB Joshua yóò ṣe lọ rèé - Mọ̀lẹ́bí kéde
Mo rí òkú TB Joshua tó yọ sí mi lẹ́yìn ikú rẹ̀ - Jaiye Kuti
Mo rí Áńgẹ́lì mẹ́fà tó wá gbé Wòlíì TB Joshua lọ sọ́run - Àlúfáà kan kéde
Wo ohun tí Dele Momodu sọ nípa TB Joshua lẹ́yìn ikú rẹ̀
Ìtàn ayé TB Joshua tó lo ọdún kan àti oṣù mẹ́ta nínú ìyà rẹ̀
Ṣé ẹ ti gbọ́ nípa òkú gbígbẹ́ tí wọ́n ṣì bá oyún nínú rẹ̀?
Ninu ikede naa ni wọn ti ni eto idagbere nipa titan abẹla yoo waye ni ọjọ Aje ọjọ karun oṣu keje. Wọn kede pe ki awọn to n bọ ma gbagbe ati mu abẹla wọn dani.
"Koda wọn ni ""gbogbo ẹni ti ko ba le wa sibi eto naa, o lee tan abẹla ninu ile rẹ gẹgẹ bi ami didarapọ mọ wa lati inu ile lati bu iyi fun iranṣẹ Ọlọrun oloogbe TB Joshua""."
Lọjọ keji eyi ni wọn isin orin idagbere lataarọ yoo waye ninu ijọ SCOAN to wa ni Eko ninu eyi ti ẹ o ti lanfani lati jẹri nipa ohun rere ti Ọlọrun ti lo Wolii naa lati ṣe ninu aye yin.
Isin ti wọn ni aaye rẹ wa ni ṣiṣi fun gbogbo awọn eeyan amọ pẹlu aaye ijoko to lonka ni eyi ti yoo waye l'Ọjọbọ ati ọjọ Ẹti.
Bi  ko ba gbagbe, laip ti ikede iku Wolii Temitope jade ni Ọba ilu ibi rẹ, Arigidi-Akoko ti sọ fun ẹbi pe awọn n f ki wọn wa bu iyi fun ilu awọn nipa sinsin oku rẹ si Arigidi amọ ij pada kede ninu ijọ wn to wa ni Eko ni yoo ti waye.
Nibayii, ijọ Synagogue Church of All Nations ti kede iyawo oloogbe gẹgẹ bi adari tuntun.
Sunday Igboho kọ̀wé sí ìjọba àpapọ̀, o ní dandan kí wọn sàn owó gbà má bínú ₦500m
''Ṣọ́ọ̀bù ìyá rẹ̀ ní Jumoke wá tí ìbọn ọlọ́pàá ti pa lásìkò ìwọ́de Yoruba Nation ní Ojota''
Kò jọ́ọ́! Àṣìṣe kọ́, Ọlọ́pàá mọ̀ọ́mọ̀ pa ọmọ ọdún mẹ́rínlà lásìkò ìwọ́de Yoruba Nation ní Ojota - Femi Falana
Gbogbo ìpilẹ̀sẹ̀ ìṣoro Nàìjíríà ni àtúnyẹ̀wò òfin ta ń ṣe yìí yóò mójútó - Gbajabiamila
Ọkọ̀ òfurufú ọmọ ogun já lulẹ̀, èèyàn 92 ló wà nínú rẹ̀
Wo ohun tó yẹ kí o ṣe sí ojú abẹ́ rẹ, ''vagina'' lẹ́yìn ìbálòpọ̀
Ibadan Gas tanker accident: Báyìí ni ọkọ tó kó afẹ́fẹ́ gáàsì ṣe ṣìnà lọ kọlu àwọn èèyàn n'Ibadan
Oríṣun àwòrán, Instagram/@connectibadan
Eeyan merin otooto lo padanu emi won, ti awon mefa si fi ara pa lojo Aiku ninu ijamba ọkọ kan ni Ibadan.
Loja Bode to n be ni agbegbe Molete ilu Ibadan  lo ti ṣẹlẹ lasiko ti oko ajagbe kan to gbe afefe gaasi padanu ijanu re.
Awon eeyan to wa nibi isele naa se alaye wi pe oko naa to morile ona Gate lati Idi Arere lo jawo inu oja ti o se kolu awon ontaja ati awon eeyan to n koja lọ lopopona.
Pupo ninu awon oja ti won to si ori igba lo pare sinu isele naa.
Adari eso aabo oju popo nipinle Oyo, Arabinrin Chukwurah Uche fi idi oro mule pe awon eeyan mewa lo fi ara gba nibi isele naa.
O ni ijanu oko to da ise sile lo sokunfa ijamba to mu emi eeyan merin lowo.
Omode kan to je okunrin, odo kan to je okunrin ati awon obinrin meji to je  odo.
Uche fi kun oro re pe awon eeyan mefa mii fi ara pa ni orisirisi ona, botile je wi pe osojumikoro kan ti ko fe ki a da oruko oun so fun awon akoroyin pe oku eeyan marun un ni oun si to sun sile.Awon osise panapana ipinle Oyo naa yoju sibi isele naa lati dena ijamba ina. Bakan naa ni awon eso aabo fi ara han lati moju to eto aabo agbegbe naa ati lati se akoso lilobibo oko.
Awọn aworan lati ibi isele jamba ina
Iroyin to n tẹ wa lọwọ sọ pe ọkọ kan to kun fọfọ fun afẹfẹ gaasi ṣi ọna gba to si pa ọpọlọpọ eeyan to wa loju popo ni ọja Bode lagbegbe Molete n'Ibadan.
Gẹgẹ bi awọn to ṣoju wọn ṣe sọ ọ, ọkọ naa bẹrẹ si ni ṣina lati Idi Arere to si yi wọ inu ọja Bode.
Ọkọ Tanka naa sare kọja awọn olutaja awọn kan lara wọn si ku loju ẹsẹ nigba ti ọpọlọpọ farapa.
Ẹni to wa nibi iṣlẹ yii ni oun gba awọn eeyan nimọran lati rin jina si ibi ti iṣẹlẹ yii ti waye tori ọkọ naa lee gbina bi awọn ileeṣẹ panapana ko ba ribi da ọgbọn ẹ.
Awọn oniroyin to wa nibẹ fabọ jẹni pe awọn oṣiṣẹ alaabo atawọn oṣiṣẹ panapana wa nibẹ lati mojuto eto naa.
Titi di akoko ti ako iroyin yii jọ, ko tii si ẹnikẹni to mọ iye eeyan to padanu ẹmi wọn nibi iṣẹlẹ ọhun.
Ṣé ẹ ti gbọ́ nípa òkú gbígbẹ́ tí wọ́n ṣì bá oyún nínú rẹ̀?
Yomi Alliyu SAN: Wo àwọn nkan tó yẹ kí o mọ̀ nípa Yomi Alliyu, agbẹjọ́rò fún Sunday Igboho
Oríṣun àwòrán, others
Yomi Alliyu jẹ agbẹjọro agba ni Naijiria, SAN. Ọdun 2017 lo di agbẹjọro agba.
Ọmọ bibi ilu Ẹdẹ nipinlẹ Osun ni, ṣugbọn ilu Ibadan lo fi ṣe ibugbe to si ti n ṣe iṣẹ agbẹjọro.
Akọsilẹ nipa rẹ lori ayelujara Linkedin fihan pe oṣu Kẹwaa, ọdun 1986 lo ti bẹrẹ iṣẹ gẹgẹ bi amofin ati agbẹjọro.
Ilu Ibadan ni ileeṣẹ agbẹjọro to da silẹ, Chief Yomi Alliyu & Co wa, nibi ti awọn agbẹjọro ati amofin ti n korajọ pọ ṣiṣẹ.
Fasiti ilu Eko,University of Lagos lo ti kawe gboye akọkọ laarin ọdun 1979 si 1980.
"'Oko ni mo wà lọ́nà ""Express"" Ilesha tí àwọn agbébọn yìnbọn bá ẹnu mi tí mò fi dà báyìí'"
Lẹyin naa lo lọ si Obafemi Awolowo University, Ile-Ife, laarin sdun 1980 si 1984.
Wọn gba sinu isẹ amofin ni Nasijiria lọdun 1985.
O lọ si ile ẹkọ girama Olivet Baptist High School, nilu Ọyọ. Yatọ si eyi, o tun lọ si ile ẹkọ girama Gbongan/Ode-Omu Anglican Grammar School, Gbongan nipinlẹ Osun.
Bakan naa lo kawe gboye ninu imọ Notary Public ni ile ẹjọ to ga julọ ni Naijiria.
Oríṣun àwòrán, Facebook/Yomi Alliyu
O gba iwe ẹri nipa imọ Arbitration and Dispute Resolution ni Chartered Institute of Arbitrators
O gba iwe ẹri nipa ofin Civil Law ni fasiti Obafemi Awolowo, Ife.
Gẹgẹ bi akọsilẹ nipa rẹ to wa ni ori ayelujara Linkedin, Yomi Alliyu ti fi igba kan jẹ ọmọ igbimọ oluṣakoso ileeṣẹ agbohunsafẹfẹ ipinlẹ Osun, OSBC, laarin ọdun 1995 si 1998.
Bakan naa lo wa lara ọmọ igbimọ to wadii bi awọn kan sẹ ta awọn irinṣẹ ti wọn n lo ni Asejire Dam ti owo rẹ to 200m nipinlẹ Osun laarin ọdun 1994 si 1995.
O tun di ipo pataki mu ni awọn ileeṣẹ ijọba ipinlẹ Osun bi ileeṣẹ to wa fun ọrọ awọn ijọba ibilẹ; igbimọ to wa fun awọn oṣiṣẹ fẹhinti; igbimọ to n ṣeto yiya awọn oṣiṣẹ ijọba lowo fun ile kikọ (1995 si 1998).
Ẹwẹ, oun ni agbẹjọro to lewaju awọn agbẹjọro to ṣoju ijọba ipinlẹ Oyo nile ẹjọ giga lasiko ti Yinka Ayefele gbe ijọba lọ sile ẹjọ fun pe wọn wo ileeṣẹ rẹ, Music House, to wa ni opopona Challenge nilu Ibadan, lọdun 2018.
Yatọ si pe o jẹ agbẹjọro, iwadii fihan pe o tun jẹ oloṣelu.
Kaduna babies Kidnap: Àwọn agbébọn ṣèkọlù sí iléèwòsàn, wọ́n jí àwọn ọmọọwọ́ gbé
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Awọn agbebọn ti ṣekọlu si ileewosan kan ni ilu Zaria ti wọn si ji awọn ọmọọwọ to wa nibẹ gbe lọ, to fi mọ awọn nọọsi ati awọn ẹṣọ alaabo.
Ileeṣẹ ọlọpaa ni Kaduna ni awọn agbebọn naa ṣekọlu si ọpọlọpọ agbegbe ti awọn eniyan n gbe ni ileewosan National Tuberculosis and Leprosy Hospital ati agọ ọlọpaa to sun mọ ibẹ.
Ileeṣẹ ọlọpaa ni ojiji ni iṣẹlẹ naa  waye, ti o si kọja afẹnusọ, ti eniyan meje sọ ẹmi wọn nu, ti wọn si ji awọn bii mẹwaa gbe lọ.
"'Oko ni mo wà lọ́nà ""Express"" Ilesha tí àwọn agbébọn yìnbọn bá ẹnu mi tí mò fi dà báyìí'"
Wọn ni nise ni awọn agbebọn ni abẹlẹ sina bolẹ ni agọ ọlọpaa ni Zaria.
''Lasiko ti iṣẹlẹ yii n waye lọwọ ni awọn agbebọn miran bẹrẹ si ni yin ibọn ni ileewosan National Tuberculosis and Leprosy centre.''
Oríṣun àwòrán, Getty Images
''Bi o tilẹ jẹpe awọn ọlọpaa bori awọn agbebọn to ṣekọlu si ago ọlọpaa naa, awọn agbebọn gbe awọn ọmọọwọ, awọn nọọsi to fi mọ awọn ẹṣọ alaabo ni ileewosan ọhun.''
''Awọn agbebọn naa si sa wọ inu igbo pẹlu awọn ti wọn jigbe naa''
Awọn ti iṣẹlẹ naa ṣoju wọn ni ọpọ ilu kereje to wa nibẹ ni wọn ṣekọlu si, ti wọn si fi ibọn le awọn araalu kuro nibẹ.
Wọn fikun pe awọn mẹrin ni wọn pa loju ẹṣẹ ninu awọn ti wọn jigbe lasiko iṣẹlẹ naa.
Man gunned in the mouth: Peter Omotoye ní ìbọn nínú ẹnu yìí yí ìgbé ayé òun padà pátápátá
Lasiko ti awọn agbebọn kan dede n ṣọṣẹ ni Alagba Peter Omotoye dede ṣalabapade ibọn ojiji ninu ẹnu rẹ.
Ọmọ Alagba Peter ṣalaye pe ọjọ karundinlọgbọn oṣu kẹta ọdun 2013 ni iṣẹlẹ buruku yii ṣẹlẹ nigba ti baba wa ni oko rẹ to wa lagbegbe ọna marosẹ to lọ si Ibadan.
Bí wọn ṣe jade si oju ọna ni awọn agbebọn jade si wọn ti wọn si yinbọn ba wọn, ẹnu lo bọ si.
Alagba Peter ti ko lee fi ẹnu rẹ sọrọ lati igba naa, ti ko si lee dede jẹun mọ́ tabi mi eemi daadaa ni ikọlu ọhun ti yi gbogbo igbe aye oun ati mọlẹbi rẹ pada.
Iyawo rẹ sọ bi o ṣe ya gbogbo wọn lẹnu nigba ti awọn oṣiṣẹ ileewosan pe wọn pe ki wọn maa bọ.
"Ọmọ naa ni awọn kọ́kọ́ lo oṣu mẹ́ta nileewosan nigba to ṣẹlẹ, koda o ni ""oriṣiriṣi nkan lawọn ti ta fun itọju ẹnu baba wọn."
Ayẹwo CT Scan ti a ṣe ni Ile Ife fihan pe ẹnu ati ahọn ni ibọn naa bajẹ ati pe dokita ni ida mẹta ahọn wọn lo ti bajẹ patapata.
Ọmọ naa ni gbogbo ounjẹ lawọn n fi ẹrọ lọ ko di olomi ki o to lee fi paipu rọba ti wọn gbe si i nimu jẹun tabi lo oogun.
Wole Soyinka: Gbogbo àwọn tó ṣèjọba lẹ́yìn ìjọba ológun ló dá wàhálà tó wà nílẹ̀ yìí sílẹ̀
Àwọn tí yóò gbà ipò Sunday Igboho àti Nnamdi Kanu tí wà nílẹ̀ báyìí.
Ọjọgbọn Wole Soyinka ti sọrọ lori bi nkan ti ṣe n lọ lorileede Naijiria.
Ninu ifọrọwerọ pẹlu ileeṣẹ iroyin BBC, agbaọjẹ onimọ litiresọ yii ni nkan to bajẹ ni Naijiria ko ṣẹṣẹ bẹrẹ lori ijọba yii ṣugbọn ko yẹ ki wọn maa wa nkan ṣe sii.
O ni lati le r'ojutu si awọn ipenija to ba Naijiria, o di dandan ki awọn ọmọ ilẹ naa ṣe apero taa n pe ni Confab.
Soyinka ni eyi nikan ni ọna ti itẹsiwaju ati ijẹ orileede kan le fidi mulẹ ni Naijiria.
BBC Yoruba pada lọ ṣabẹwo si ọja Bode nibi ti ọkọ to kun fọọ fun afẹfẹ gaasi ti dede sina wọ inu ọja to si pa awọn kan.
Lasiko ifọrọwerọ yi, o tun mẹnu ba awọn họwuhọwu to n waye lori ipe fun ipinya Naijiria.
Ni paapa, o sọ ero ọkan rẹ nipa awọn ajafẹtọmọniyan to n pe fun iyapa Naijiria bii ti IPOB ti Nanamdi Kanu n dari rẹ ati ti awọn Ọmọ Oduduwa ti Sunday Igboho n dari.
''Igboho kan gbiyanju lati mu atunṣe ba nkan ti ijọba ti bajẹ ni. A ti ni awọn eeyan mii ti yoo gba ipo Sunday Igboho ati Nnamdi Kanu bi wọn ba ko wọn nilẹ''.
O bẹnu atẹ lu bi ijọba ṣe n fi agbara takuntakun mu awọn eeyan kan bi Nnamdi Kanu ti wọn lo n da alaafia ilu ru ṣugbọn ti wọn ko mura si awọn mii bi Miyetti Allah ati awọn agbebọn darandaran.
Ifọrọwanilẹnuwo pẹlu Ọjogbọn Wọle Soyinka
Soyinka sọ pe awọn darandaran jẹ ẹgbẹ to ni olori ṣugbọn ti ijọba ko gbe igbesẹ to yẹ lati mu awọn olori wọn.
O fi ẹdun ọkan rẹ han bakan naa pẹlu bi ijọba ko ṣe kara mọ aasiki ọrọ awọn ti awọn agbebọn lọ ṣeku pa ni Oke-Ogun.
O ni ọdaran pọnbele lawọn agbebọn wọnyi ti wọn si n fi ojojumọ pọ si.
Ni idahun si ibeere lori bi ijọba ṣe ni awọn n wa awọn to n ṣe onigbọwọ fun Sunday Igboho ati Nnamdi Kanu o ni ko jẹ tuntun.
''Ṣebi nibi la wa ti wọn sọ fun wa pe awọn ti ri awọn to n ṣagbatẹru Boko Haram. Mi o ti ri ki nkankan tẹyin rẹ bọ abi iwọ ti gbọ nkankan ni?''
''Lọkan mi o, o yẹ ki ijọba apapọ tọrọ aforijin lọdọ Igboho ki wọn si ni ko maa lọ lalaafia''.
Lakotan, Soyinka rọ ijọba lati wa wọrọkọ fi ṣada lori awọn ipenija to n koju Naijiria ki o si sọ ododo fawọn ọmọ Naijiria lori iṣejọba wọn.
"'Oko ni mo wà lọ́nà ""Express"" Ilesha tí àwọn agbébọn yìnbọn bá ẹnu mi tí mò fi dà báyìí'"
''Ko si ẹni to n sọ pe gbogbo wahala yi bẹrẹ lasiko ijọba Buhari nitori gbogbo awọn to ṣe ijọba lẹyin ijọba ologun lo da si wahala to wa nilẹ yi.
''Lati igba ti a pada si ijọba alagbada ni awọn olori ti n ṣe aṣise nipa iwa to tako ijọba awarawa. Ninu awọn iwa yi ni bi wọn ṣe n diwọ mọ owo ijọba ibilẹ, ati inakuna owo ijọba.''
Sunday Igboho: Agbekoya ní wàhálà yóò ṣẹlẹ̀ tí Buhari bá mú Igboho, Gani Adams àti Akitoye
Oríṣun àwòrán, Screenshot
Ẹgbẹ ajijagbara nilẹ Yoruba, Agbekoya, ti bu ẹnu atẹ lu ikọlu tawọn ajọ ọtẹlẹmuyẹ DSS ṣe si ile ajafẹtọ ati ajijagbara, Sunday Igboho lagbegbe Soka niluu Ibadan.
Ẹgbẹ Agbekoya wa rọ ijọba apapọ lati semẹdọ lori igbesẹ rẹ lati fi ọwọ ofin mu Igboho at'awọn mii nitori wọn n pe fun iyapapa ẹya Yoruba lara orilẹede Naijiria.
Ẹgbẹ naa ṣe ikilọ yii ninu atẹjade kan to fi sita eleyii ti Jagunmolu Agbekoya ilẹ Yoruba, Kunle Adelakun ti ọpọ mọ si Eruobodo, buwọlu.
Ẹgbẹ Agbekoya ni ohun ti wọn n ja fun wa ni ibamu pẹlu ofin, ati pe ajọ iṣọkan agbaaye, UN gan an fọwọ sii.
"Ijọba gbọdọ tun ero rẹ pa lori igbesẹ lati mu Igboho, Ọjọgbọn Banji Akintoye, Aarẹ Gani Adams ati awọn ti wọn n ja fun Yoruba Nation.
'Oko ni mo wà lọ́nà Express"" Ilesha tí àwọn agbébọn yìnbọn bá ẹnu mi tí mò fi dà báyìí'"
Bi bẹẹ kọọ, rogbodiyan ni ọmọ ti iru igbesẹ bayii maa n bi.
Agbekoya kii gbe ibọn, a o si ni ìbọn AK-47 pẹlu tori a ko ni igbagbọ ninu rẹ.
Ọgbọn ati imọ ti Eledumare fún wa ni agbara wa.
Amọran wà fún Aarẹ Muhammadu Buhari ni pe ki o fi ọgbọn yanju ọrọ to wa nilẹ yii.
Nkan ko tii buru to bayii ri ninu itan Naijiria lati ọdun 1914 ti awọn oyinbo ti da wa pọ.
Awọn araalu lẹtọọ lati sọ ẹdun ọkan wọn tàbí ohun ti wọn n fẹ labẹ ijọba awaarawa.
Ṣé ẹ ti gbọ́ nípa òkú gbígbẹ́ tí wọ́n ṣì bá oyún nínú rẹ̀?
Sí ẹyin olori ẹya Yoruba lagbo oṣelu bíi Asiwaju Bola Tinubu, Oloye Bisi Akande, Ajagun fẹhinti Alani Akinrinade, Oloye Olusegun Obasanjo ati Igbakeji Aarẹ Yemi Osinbajo, ẹ tun ero yin pa.
Awa ẹgbẹ Agbekoya ko ni ṣalai duro gbọingbọin lẹyin araalu.
"Yoruba gbọdọ fi imọ ṣọkan, ati pe ko si ohun to buru ninu ki eeyan maa pe fún idasilẹ Yoruba Nation,"" Agbekoya ṣalaye."
Sunday Igboho: YWG ní káwọn àgbà Yorùbá báwọn ajìjàgbara sọ̀rọ̀ láti dẹkun ìpè fún ìyapa
Ẹgbẹ Yoruba Welfare Group (YWG), ti kesi awọn ọba alaye atawọn asaaju oloselu nilẹ Yoruba lati dide doola aawọ to n waye laarin Sunday Igboho ati eyi to fi n da si  ijọba apapọ.
Ẹgbẹ YWG lọgun bẹẹ ninu atẹjade kan to fisita eyi ti aarẹ ẹgbẹ, Comrade Abdulhakeem Adegoke Alawuje fọwọsi to da lori bi DSS se kọlu ile ajijagbara naa ati bi ijọba apapọ se kede pe oun n wa Sunday Igboho.
Ẹgbẹ naa wa rọ ijọba apapọ lati jẹ ki awọn agbaagba nilẹ Yoruba ba Sunday Igboho atawọn ọmọlẹyin rẹ sọrọ lọna ati jẹ ki alaafia jọ̀ba.
O ni eyi yoo tun fun wọn lanfaani lati dẹkun idunkooko lati da ilu ru nipa bi wọn se n pe fun ominira ilẹ Yoruba kuro lara Naijiria.
"A n rọ awọn eekanlu nilẹ Yoruba lati gbe ọrọ ẹsin tabi oselu ti sẹgbẹ kan, ki wọn si fori jin Sunday Igboho lori awọn ẹsẹ to le sẹ wọn.
'Oko ni mo wà lọ́nà Express"" Ilesha tí àwọn agbébọn yìnbọn bá ẹnu mi tí mò fi dà báyìí'"
Amọ ki wọn dide lati gba oun atawọn alatilẹyin rẹ lọwọ awọn ẹsun ti ijọba apapọ fi kan wọn nitori alaafia ilẹ Yoruba se koko.
"Gẹgẹ bii ajogunba wa, Ololufẹ alaafia ni awa ọmọ Yoruba, a ko si le kuna ninu ojuse yii, paapaa lori ọrọ to nii se pẹ́lu ilẹ baba nla wa."""
YWG ni oun le fi ọwọ sọya pe ẹya Yoruba ko fara mọ iyapa Naijiria, to si n fẹ orilẹede to wa ni isọkan ati alaafia nibi ti idajọ ododo, ibaradọgba, aisegbe sibikan ati isejọba rere yoo ti wa.
Ẹgbẹ naa wa n fi ọwọ sọya pe oun yoo maa kan si awọn asaaju nilẹ Yoruba lati da si ọrọ to wa nilẹ yii, ki wọn si jẹ ki alaafia jọba nilẹ Yoruba.
Southern Governors forum: Ẹgbẹ́ Arewa àtàwọn àgbààgbà Àríwá tako pínpín ipò ààrẹ ní Nàìjíríà
Oríṣun àwòrán, Facebook
Ẹgbẹ Arewa Youth Consultative Forum ati ẹgbẹ awọn agbaagba Ariwa, Northern Elders Forum ti kede pe awọn ko faramọ ọrọ tawọn gomina ẹkun Guusu sọ pe aarẹ orilẹ-ede Naijiria gbọdọ wa lati ẹkun naa.
Aarẹ ẹgbẹ AYCF, Yerima Shettima ati agbẹnusọ fun ẹgbẹ awọn agbaagba, NEF Hakeem Baba Ahmed ko sọrọ ninu ohun tawọn gomina Guusu sọ.
Aarẹ AYCF Shettima ṣalaye pe lati ọdun 1999 ti Naijiria ti pada sí ijọba awaarawa lawọn ẹgbẹ oṣelu ti n pin ipo aarẹ laarin ẹkun Ariwa ati Guusu.
Amọ, Shettima ni eto pinpin ipo aarẹ laarin Ariwa ati Guusu daru lọdun 2011 nigba ti aarẹ ana, Goodluck Jonathan to gori aleefa leyin ti Aarẹ  Umaru Musa Yar'adua ku tan.
Shettima ni dipo ki aarẹ sí wa lati ẹkun Ariwa lẹyin iku Yar'adua, niṣe ni Jonathan dije ninu ibo aarẹ lọdun 2011 nibi ti o sí ti jawe Olubori.
"A ko le jẹ ki ẹnikẹni dunkooko mọ wa ni Oke Oya tabi ki wọn ro pe awọn eeyan ẹkun Ariwa yoo jọwọ ipo aarẹ fún wọn nitori ariwo ti wọn n pa.
Ijọba awaarawa ni a wa, ki onikaluku dije ninu eto idibo gbogbogboo ọdun 2023, Shettima lo sọ bẹẹ."
Ninu ọrọ tirẹ, agbẹnusọ fún ẹgbẹ NEF, Baba Ahmed sọ pe awọn eeyan Ariwa ko ni ki aarẹ ma wa lati ẹkun Guusu ṣugbọn ohun tawọn ko fẹ ni pe ki awọn eeyan perete joko nibi kan ki wọn maa sọ pe aarẹ Naijiria gbọdọ wa lati ẹkun Guusu.
"Awa eeyan Ariwa ko ṣẹṣẹ maa dibo fun Aarẹ lati ẹkun Guusu.
Awa ni a dibo fun Abiola, a dibo fun Obasanjo, bakan naa ni a dibo fun Jonathan.
Nitori naa, ẹnikẹni ko le sọ fun wa pé a gbọdọ dibo ni tipa tipa fún oludije ipo aarẹ lati ẹkun Guusu tabi ki wọn ni ẹ ko gbọdọ dibo fun elomiran yatọ si oludije lati ẹkun Guusu.
Ẹtọ kan naa ni awon eayan Ariwa ni pẹlu awọn ara Guusu, Baba Ahmed lo ṣalaye bẹẹ."
Awọn gomina apa Guusu orilẹ-ede Naijiria fẹnuko lori awọn koko kan lẹyin ti wọn ṣepade pọ tan niluu Eko lọjọ Aje, lori awọn ọrọ to n lọ ní Naijiria.
Ninu atẹjade ti alaga awọn gomina Guusu, Arakunrin Rotimi Akeredolu fi sita, awọn gomina ọhun ṣalaye pe oṣelu aiṣegbe fẹnikan lawọn fọwọ sí.
Eleyii lo jẹ ki wọn fẹnuko pe aarẹ orilẹ-ede Naijiria gbọdọ wa lati apa Guusu nitori o yẹ ki àwọn eeyan Ariwa ati Guusu máa pin ipo aarẹ laarin ẹkun mejeeji ni.
Awọn gomina Guusu tun kede pe iṣọkan Naijiria, ododo, itẹsiwaju ati gbigbe pọ ni alaafia awọn ọmọ Naijiria lo jẹ awọn logun.
"'Oko ni mo wà lọ́nà ""Express"" Ilesha tí àwọn agbébọn yìnbọn bá ẹnu mi tí mò fi dà báyìí'"
Sunday Igboho: Alhaji Fatai ń kírun lọ́wọ́ ni wọ́n ta ní ìbọn, tó sì kú
Oríṣun àwòrán, Olayomi Koiki
Ọjọbọ ọjọ kinni osu Keje ọdun 2021 ni awọn osisẹ ọtẹlẹmuyẹ DSS se ikọlu sile ajijagbara to n pe fun idasilẹ orilẹede Yoruba, Sunday Igboho.
Nibẹ si ni wọn ti jẹwọ pe eeyan meji ni awọn pa ninu ile naa nitori wọn di awọn lọwọ lati sisẹ awọn ninu ile ọhun.
Gẹgẹ bi agbẹnusọ fun Sunday Igboho, Olayomi Koiki ti sọ loju opo Facebook rẹ, orukọ ẹni akọkọ ni Saheed Adisa, ti ọpọ eeyan mọ si Adogan.
Adogan yii si ni wọn ti kọkọ gbe oju rẹ sita fun araye lati se idaro iku rẹ bii akọni ọmọ Yoruba to ja fun ominiran iran rẹ.
Ọpọ eeyan si lo ti n naga lati mọ ẹnikeji ti ẹmi rẹ pọ sinu isẹlẹ naa.
Oríṣun àwòrán, Olayomi Koiki/Instagram
Nibayii, Koiki ti wa bọ soju opo Instagram rẹ lati daro eeyan keji to jalaisi nile Igboho lati ọwọ awọn osisẹ DSS.
Oluwarẹ lo pe ni Alhaji Fatai.
Gẹgẹ bi agbẹnusọ Igboho se wi, Alhaji Fatai yii n kinrun lọwọ ni awọn osisẹ DSS de, ti wọn si ta ni ibọn, eyi to gba ẹmi rẹ.
O wa gbadura pe ki Ọlọrun tẹ oloogbe naa si afẹfẹ rere, ti ọpọ ọmọ Yoruba to da si ọrọ naa si n fi adura sin oku ọrun naa lẹyin.
"'Oko ni mo wà lọ́nà ""Express"" Ilesha tí àwọn agbébọn yìnbọn bá ẹnu mi tí mò fi dà báyìí'"
Sunday Igboho: Falana ní ìkọlù DSS sílé Igboho dàbí ìdìtẹ̀ gbàjọba lóru
Agbẹjọro ati ajafẹtọ ọmọniyan, Femi Falana (SAN) ti bu ẹnu atẹ lu bi ajọ ọtẹlẹmuyẹ DSS ṣe kọlu ile ajijagbara, Oloye Sunday Igboho to wa lagbegbe Soka niluu Ibadan.
Nigba to n sọrọ lori ẹrọ amohunmaworan ileeṣẹ Channels TV, Falana ni igbesẹ ajọ DSS da bí iditẹ-gbajọba to waye lọganjọ oru.
Agbẹjọro agba naa ni ko si ofin Naijiria to faye gba mimu ẹnikẹni ni oru.
"Ikọlu ajọ DSS laago oru sile Igboho jẹ iwa ijọba ologun tawọn ajọ naa jogun ba.
Lai jẹ wí pe eeyan huwa ọdaran loru, kò si ofin to faye gba a, DSS ko l'aṣẹ lati lọ mu ẹnikẹni ni oru.
Ṣé ẹ ti gbọ́ nípa òkú gbígbẹ́ tí wọ́n ṣì bá oyún nínú rẹ̀?
Ohun to tọ ni ki ajọ ọtẹlẹmuyẹ mu iwe aṣẹ to fún wọn lagbara lati ṣe ayẹwo ile Igboho dani, ki wọn to le wọ ile rẹ.
Amọ, kò si ohun to jọ bẹẹ, DSS ko mu iru iwe bẹẹ jade.
Nisin yii, Igboho ni oun ko ni ibọn nile, ṣugbọn DSS ṣe afihan awọn ibọn AK-47 pe awon ri nile rẹ.
Gbogbo nkan bayii ni ko ba ti lojutuu ti DSS ba ti huwa bi ajọ  ọtẹlẹmuyẹ to laju ni, Falana lo ṣalaye bẹẹ."
Agbẹjọro Falana tun sọrọ lori ikede awọn gomina Guusu ọjọ Aje ninu eyi ti wọn ti sọ pe awọn oṣiṣẹ eleto abo gbọdọ maa fi to awọn leti ki wọn to le ṣe ohun kan nipinlẹ awọn.
BBC Yoruba pada lọ ṣabẹwo si ọja Bode nibi ti ọkọ to kun fọọ fun afẹfẹ gaasi ti dede sina wọ inu ọja to si pa awọn kan.
Amọ, Falani ni o ti pẹ ju fun wọn lati sọrọ sita ati pe ṣe igba yii laarọ ti arugbo wọn n sunkun oge.
O ni o buru jai pe ọganjọ oru ni wọn ṣe ikọlu sile Igboho, ti wọn si payan níbẹ, ṣugbọn gomina ipinlẹ Oyo ko mọ.
"Falana ni ""lẹyin bii wakati mejila ni ajọ DSS ṣẹṣẹ sọ pe awọn lawọn wa nidi iṣẹlẹ naa."
"Ẹ lọ ṣe ikọlu sile eeyan, ẹ tun pa eayan meji, gomina ipinlẹ naa ko sí mọ nipa rẹ."""
Falana ni ọrọ naa ko dun gbọ leti.
Lagos Assembly: Wo ìdí tí òfin ilé aṣòfin Eko kò fi le múlẹ̀ lórí ọ́lọ́pàá
Oríṣun àwòrán, LASG
Lọjọ Aje, ọjọ karun un oṣu keje ni ile igbimọ aṣofin ipinlẹ Eko kéde abadofin to wọgile ki awọn ọlọpaa maa ṣafihan awọn afurasi ọdaran lai ti gba idajọ.
Igbakeji olori ile igbimọ aṣofin ipinlẹ Eko, Wasiu Eshilokun-Sanni lo dari ijoko ile nigba ti ile ṣe ikede abadofin ọhun.
Lẹyin ti ile buwọlu abadofin naa ni igbakeji olori ile ni ki akọwe ile fi abadofin naa ranṣẹ si Gomina Babajide Sanwo-Olu lati buwọlu ki o le fi òfin.
Ti gomina ba le buwọluu tan, ofin naa ko ni faye gba awọn ọlọpaa lati ma ṣe afihan awọn afurasi ọdaran mọ niwaju awọn akọroyin.
Ọpọ awọn agbẹjọro lo ti pe fun idaduro asa bi awọn ọlọpaa ṣe maa n ṣafihan awọn afurasi lai ti jẹ pe ileẹjọ ti da wọn lẹbi.
BBC Yoruba pada lọ ṣabẹwo si ọja Bode nibi ti ọkọ to kun fọọ fun afẹfẹ gaasi ti dede sina wọ inu ọja to si pa awọn kan.
Wọn ni ohun ti awọn ọlọpaa n ṣe yii tako ẹtọ ọmọniyan awọn ti wọn pe ni afurasi.
Ṣugbọn agbẹjọro Muktar Kolawole Suleiman ṣalaye pe abadofin ti ile igbimọ aṣofin ìpínlẹ̀ Eko ṣẹṣẹ ṣe, le maa mu opin dé ba bi awọn ọlọpaa ṣe maa n ṣafihan awọn afurasi.
Agbẹjọro Suleiman ni ofin ti ile igbimọ aṣofin ipinlẹ ba ṣe ko le nipa lori ileeṣẹ ọlọpaa.
"Gomina ipinlẹ tabi ile aṣòfin ipinlẹ ko lagbara lori ileeṣẹ ọlọpaa.
Ti o ba wù awọn ọlọpaa ni wọn le tẹle aṣẹ gomina nipinlẹ ti wọn wa, ti o ba sì wu wọn, wọn le maa tẹle aṣẹ gomina tabi ofin ti ile asofin ipinlẹ ba ṣe.
Idi ni pe iwe ofin Naijiria ko fun awọn gomina laṣẹ lori ọlọpaa.
Aarẹ orileede Naijiria tabi aṣoju rẹ lo le pàṣẹ fun ileeṣẹ ọlọpaa, amofin Suleiman lo sọ bẹẹ."
Ṣé ẹ ti gbọ́ nípa òkú gbígbẹ́ tí wọ́n ṣì bá oyún nínú rẹ̀?
Agbẹjọro Suleiman ni ile igbimọ aṣofin agba niluu Abuja nikan lo le ṣofin ti yoo de awọn ọlọpaa lawọn ipinlẹ gbogbo.
O ni ileeṣẹ aarẹ ni ọga ọlọpaa nipinlẹ kọọkan n jiyin fun kii ṣe awọn gomina.
Ajafẹtọ agbẹjọro, Femi  Falana tiẹ ti gbe ajọ EFCC  ati agbẹjọro agba ni Naijiria lọ si ile ẹjọ lori fifi awọn afurasi han ṣáájú igbẹjọ wọn.
Falana ni eyi tapa sofin Naijiria, ati pe o tako ẹsẹ kẹrinlelọgbọn iwe ofin orile-ede Naijiria.
Yomi Fabiyi, Iyabo Ojo kọ́ ló ń wọ́ wálẹ̀ o, ara rẹ̀ gan lò ń wọ́ wálẹ̀ - Femi Branch
Oríṣun àwòrán, Femi Branch, Yomi Fabiyi
"Ọpọlọpọ oṣere ọkunrin lo kọ lati fọhun lori ọrọ fiimu ""Oko Iyabo"" ti Yomi Fabiyi ṣe sita eyi to da wahala silẹ lọwọlọwọ amọ bo ṣe ń gbe ọkan lara wọn ninu bi èébì, Femi Branch ti fibinu sọrọ."
O kọkọ ṣafiwe bi awọn akẹgbẹ wọn kan ṣe maa n fi anfani iṣoro ati ibanujẹ to jẹ ọrọ ọlọrọ fi di eeyan nla labẹ didibọn pe wọn n ṣeranwọ fun ẹni naa.
Ko wu mi lati ṣe fidio yii tori mo mọ pe nkan to n ṣẹlẹ yii gan ni Yomi ti ọrọ yii kan fẹ tẹlẹ - lati fi ibanujẹ awọn eeyan ni igbesoke ko fi ta ọja ara rẹ faraye.
Ṣugbọn Femi Branch ni lootọ nigba toun gbọ pe o n peelo fiimu yii lọwọ oun ro pe yoo daa bi ọgbọn ni ko ma ta ba ẹnikẹni taara amọ o ni Yomi o fi ọpọlọpọ ṣee rara.
Yomi mo ni lati sọ fun ẹ pe nigba ti mo ri gbogbo nkan to wa ninu fiimu Oko Iyabo yẹn, o ri mi lara gidi gan, Bo tilẹ jẹ pe mo mọ pe Iyabo Ojo lo fẹ fi bu, mo ro pe waa ṣi lo ọpọlọ ni ko ma lọ taara amọ o ba mi lojiji pe oo tilẹ ṣe ohunkohun to n mu iṣẹ da yatọ rara, asaan iṣẹ ti ko lọ́pọlọ gbaa lo ṣe jade.
"Ṣé o lè gbé orí rẹ lọ sọ́dọ̀ fárífárí alábẹ kó dán bí àwọn tó ní àwọn kò lè lo ""clipper láéláé yìí?"
Femi tun n fi Ọlọrun bura pe itiju nla ni Yomi jẹ si ẹgbẹ awọn to n ṣe sinima tori o ju ara rẹ silẹ gan ni. O ni Yomi kan n ro pe oun mọ iṣẹ ni amọ ko mọ nkankan rara.
Mo kabamọ pe mo mọ ẹ, lootọ mo kọkọ gbe lẹyin rẹ ni ti pe o n ja fun ki wọn gba ẹtọ onikaluku laaye tori wọn ni ẹtọ lati sọrọ mo gba mo si ro pe waa daa lee nibẹ yẹ ni ṣugbọn o ri mi lara gidigidi lati lẹ sọ pe mo mọ ẹ ri.
O ni o ro pe Iyabo lo fẹ fa walẹ ni amọ ara rẹ (Yomi gangan lo n wọ walẹ). Femi ni ọrọ yii tun wa kan ọmọ ọlọmọ to jẹ ọmọde.
Yomi, oo ma loju ti o, bi mi o ba mọ̀ pe iwọ funrarẹ bimọ ni mi o ba ma... ama boo tilẹ ṣe tun wa bimọ, ko tọ siẹ lati jẹ ẹni ti wọn npe ni baba.
Àwọn agbébọn pa ààrẹ orílẹ̀-èdè Haiti nílé rẹ̀ lóru mọ́jú
Láéláé! A ò faramọ́ àbá àwọn Gómìnà Gúúsù pé ààrẹ Nàìjíríà gbọdọ̀ wá láti ẹkùn wọn lọ́dún 2023 - Ẹgbẹ́ Arewa
Sàdáńkátà! Ẹ̀yin ẹ̀létò ààbò, mo dúpẹ́ lọ́wọ́ yín fún ìkọlù sí ilé Sunday Igboho - Ààrẹ Buhari
"O ni o ya oun lẹ́nu pe yomi le maa fi ilakọja ọmọ kekere ti ko mọ nkankan fi ma ta kaiti ninu fiimu. ""O dẹ n ṣe fiimu yẹn bi nkan ṣe ri gangan, hàà Yomi waa ṣẹwọn o!""."
O ni adajọ̀ ti baba sọ pe ki ẹnikẹni ma sọrọ m nipa rẹ amọ ọrọ yii gaan ni yomi tun wa ṣe sita si fiimu gẹlẹ bi wọn ṣe ni o ri.
Lo ba ni oun n fi ọrọ ranṣẹ si ileeṣẹ Ọlọpaa Naijiria lati fi ofin mu yomi Fabiyi tori ko ye oun nkan ti Yomi gbojule ti ko fi mọ pe oun ti ru ofin ti yoo kan maa ṣe nkan bii pe o le muu jẹ.
O ni ṣe awọn agbẹjọro rẹ o ri akọsilẹ fiimu rẹ ki wọn si gba a nimọran lorii rẹ lori fiimu ailọpọlọ yii.
O ṣẹṣẹ ko panpẹ si ara rẹ lọwọ ni, inu mi dun si ohun ti o ṣe gan.
7/7 Cultism Day: Iléèṣẹ́ ọlọ́pàá fi ìkìlọ̀ síta nítorí àyájọ́ 7/7 táwọn ọmọ ẹgbẹ́ òkùnkùn Aiye fẹ́ ṣe
Oriṣiriṣi ọna ni eto igbani wọle maa n gba ninu awọn ẹgbẹ okunkun
Ileeṣẹ ọlọpaa ipinlẹ Eko ti kilọ fawọn ẹlẹgbẹ okunkun lati ki ọwọ ọmọ wọn bọ aṣọ, lori ayẹyẹ 7/7 ti wọn fẹ ṣe lọjọ keje oṣu keje ọdun 2021 yii.
Atẹjade kan ti ileeṣẹ ọlọpaa ipinlẹ Eko fi sita lati ọwọ agbẹnusọ rẹ, Muyiwa Adejobi, ni awọn agbofinro ti wa lojufo lati fi ọwọ ofin mu ẹnikẹni tó ba ṣe ayẹyẹ naa nipinlẹ Eko.
Ileeṣẹ ọlọpaa ni ẹnikẹni ti wọn ba ko ara wọn jọ lati ṣe ayẹyẹ 7/7 yóò foju wina ofin.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí:
Awọn ọlọpaa ipinlẹ Eko wa kilọ fawọn ẹgbẹ okunkun Neo Black Movement of Africa, ti ọpọ mọ si Black Axe pe, ki wọn mase de ipinlẹ Eko lati ṣe ohun kohun nitori awọn ọlọpaa ko ni gba fún wọn.
Ọga ọlọpaa nipinlẹ Eko, CP Hakeem Odumosu ti wa paṣẹ fawọn ọga ọlọ́pàá agbegbe lati maa kaakiri ipinlẹ Eko lati mu ẹnikẹni to ba n ṣe ayẹyẹ 7/7.
"Ṣé o lè gbé orí rẹ lọ sọ́dọ̀ fárífárí alábẹ kó dán bí àwọn tó ní àwọn kò lè lo ""clipper láéláé yìí?"
Odumosu wa rọ araalu at'awọn obi lati mojuto awọn ọmọ wọn kí wọn maa ba di ọmọ buruku to n darapọ mọ ẹgbẹ okunkun nitori ọlọpaa yoo fi ọwọ ofin mu wọn.
Ileeṣẹ ọlọpaa nipinlẹ Osun ti fi ikede sita fawọn ọmọ ẹgbẹ okunkun to n gbero lati ṣe ayajọ ọjọ ẹgbẹ okunkun nilẹ naa.
Ọjọ yi ti wọn pe ni 7/7 ni ọlọpaa ni ọpọ ikọlu ati itajẹsilẹ ti maa n waye.
Ninu atẹjade ti alukoro ọlọpaa fi sita lorukọ Kọmisana ọlọpaa, Olawale Olokode, wọn ni wamuwamu ni awọn wa lati rii pe iru nkan bẹẹ ko waye.
Ọlọpaa ni iroyin to tẹ awọn lọwọ ni pe awọn ọmọ ẹgbẹ okunkun yii fẹ fi ayajọ yi da omi alaafia ilu ru ṣugbọn awọn ko ni gba fun wọn.
''Kọmisana ti paṣẹ pe ki gbogbo awọn ọga ọlọpaa ati awọn olori ikọ ọlọpaa duro ṣẹpẹ lati koju ẹnikẹni to ba fẹ da ilu ru''
Atẹjade naa tun sọ pe ki awọn obi ati alagbatọ fa ọmọ wọn leti lati yago fun apejo kankan yala ṣaaju lasiko tabi lẹyin ọjọ yi.
Àdá, àáké, ati fila pupa jẹ́ diẹ lara ami idanimọ awọn ẹgbẹ okunkun ni Naijiria
Wọn ni ẹnikẹni to ba kọ eti ikun si ikilọ yi yoo foju wina ofin.
Bẹẹ naa ni ikilọ yi de ọdọ awọn to ni ile itura ati aaye inaju pe ki wọn ma ṣe faaye gba awọn olubi lati lo ọdọ wọn fun iru apejọ to le da omi alaafia ilu ru.
Ipinlẹ Oṣun wa lara awọn ipinlẹ ti ẹgbẹ okunkun ti gbalẹ.
Lai pẹ yi ni a ka iroyin kan pe awọn ọmọ ẹgbẹ okunkun kan ṣa gẹrigẹri kan pa ni ṣọọbu rẹ ladugbo Oke-Ijetu  Oshogo.
Koda alabara gẹrigẹri naa kan to wa nibẹ lasiko ikọlu yi faragbọgbẹ.
Baba Ijesha €50,000 GoFundMe: Àwọn olólùfẹ́ Baba Ìjèsà gbé ìgbà Gofund Me láti fí sàn owó tí yóò fí ṣé ẹjọ́
Oríṣun àwòrán, Baba Ijesha/Twitter
Awọn ololufẹ oṣere tiata Yoruba nii Baba Ijesha ti bẹrẹ si ni da owo jọ lati le fi san owo ti wọn yoo fi ṣẹjọ rẹ.
Ẹsun aṣemaṣe pẹlu ọmọde ni ẹjọ ti wọn fi kan labẹ ofin ipinlẹ Eko.
Lọwọlọwọ bayi, Baba Ijesha ti gba beeli niwaju adajọ ṣugbọn yoo nilo owo ti yoo fi sẹjọ.
Hàà! Yomi wàá ṣẹ̀wọ̀n o! Oò ṣe bí ọlọ́pọlọ rárá, ò kàn ń fi àṣírí Baba Ijesha àti Iyabo Ojo gòkè ni - Femi Branch
Àwọn agbébọn pa ààrẹ orílẹ̀-èdè Haiti nílé rẹ̀ lóru mọ́jú
Ìdí rèé tí àwa lọ́balọ́ba fi dákẹ́ lórí ìṣẹ̀lẹ̀ ìkọlù Sunday Igboho - Oluwo tí Iwo
Láéláé! A ò faramọ́ àbá àwọn Gómìnà Gúúsù pé ààrẹ Nàìjíríà gbọdọ̀ wá láti ẹkùn wọn lọ́dún 2023 - Ẹgbẹ́ Arewa
'Ẹ má sọ pé lọ́balọ́ba kó sọ̀rọ̀ lórí ìkọlù Sunday Igboho, Inú wa kò dún sí ìjọba'
Baba Ijesha Rape Case: Yomi Fabiyi ní òun nìkàn lòun rí ara òun tó dúró tí Baba Ijesha
yyyy
Loju opo Go Fund Me, akọle ipe owo dida fun Baba Ijesha ni wọn pe ni 'Help Olanrewaju Omiyinka with Legal Costs'
Ẹni to si ṣe agbatẹru ipolongo yi ni arakunrin Oladele Matti ti a gbọ pe orileede Ireland lo n gbe.
Matti jẹ oludari ere tiata ti a si ri loju opo r ni Instagram pe o jẹ wọlewọde pẹlu Yomi Fabiyi.
Oríṣun àwòrán, Instagram/OladeleMatti
Ninu ipolongo yi, wọn lawọn nilo €50,000,ṣugbọn iye ti awọn eeyan da ko ti kọja €20 ti wọn ti ri gba.
Nigba ti Baba Ijesha wa sile ẹjọ lori ọrọ beeli rẹ,awọn agbẹjọro agba meji lo tẹle wa ti awọn agbẹjọro mẹtadinlogun mii si kọwọrin pẹlu wọn.
Sunday Igboho: Oluwo tí Iwo ní èébú ni wọ́n bú àwọn lọ́balọ́ba nígbá tí Igboho bẹ̀rẹ̀ ìjìjàgbara.
Oríṣun àwòrán, Instagram/oluwo of iwo land
Oluwo ti ilu Iwo, Ọba AbdulRasheed Akanbi ti ni o ni idi ti awọn lọbalọba fi dakẹ lẹyin ikọlu si ile ajijagbara ẹya Yoruba, Sunday Igboho.
Ọba Akanbi ni kii ṣe wi pe awọn kẹyin si Sunday Igboho nitori ọmọ Yoruba ni, amọ ko gbọ ọrọ si awọn lọbalọlọba lẹnu.
Oluwo ni nigba ti ijijagbara fun Yoruba Nation naa bẹrẹ ni oun ti bẹrẹ si ni lọgun rẹ pe, kii ṣe ọna to yẹ ki wọn gbe e gba ni wọn n gba beere fun idaduro ilẹ Yoruba.
'Ẹ má jẹ́ kí òkú ọmọ mi ráre o ìjọba! Ẹ gbée fún mi kí n lọ sin ín - Ìyá ọmọ ti wọ́n pa ní ìwọ́de Yoruba Nation
Ninu ọrọ tirẹ, Oluwo ni o yẹ ki awọn ajijagbara naa kọkọ wa ba awọn lọbalọba sọrọ lori nkan ti wọn fẹ, ki awọn lọbalọba gbee yẹwo boya nkan to ṣeeṣe ni, ati ọna ti wọn yoo gbee gba.
Amọ, o ni awọn ajijagbara ti Sunday Igboho ṣe adari fun yii n bẹrẹ si ni bu awọn ni, ti awọn araalu naa si n ti wọn lẹyin.
''Wọn gbagbe pe ọba ba lori ohun gbogbo ni, ijọba si laṣẹ lati da abo bo awọn eniyan''.
''Ijọba ko le maa woran ki nkan to ṣẹlẹ lasiko ifẹhọnuhan tako ijiya awọn araalu lọwọ ọlọpaa, ENDSARS tun ṣẹlẹ lorilẹede Naijiria mọ''.
O ni nitori naa iṣẹ ijọba ni wọn n ṣe lati rii pe ko si wahala ni agbegbe kankan.'
''Okun kii ho ruru, ka waa ruru ni ọrọ yii jẹ, a kii ba ijọba ja, a ma n dunadura pẹlu ijọba ni.''
Oríṣun àwòrán, Instagram/oluwo of iwo land
'Ìjámbá Ọ̀kadà ló dédé sọ mi di òdi, ìyàwó tí mo yó ìfẹ́ rẹ̀ náà tún wá jẹ́ odi'
Oluwo ti ilu Iwo, Ọba AbdulRasheed Akanbi fi kun un wipe aanu awọn ti iṣẹlẹ naa mu ẹmi wọn lọ ṣe oun. nitori ara o rọ okun, ara o rọ adiyẹ ni ọrọ Sunday Igboho.
Ọba Akanbi ni ọmọ awọn naa ni Sunday Igboho nitori ọmọ ko lee buru ka fi fun ẹkun pa jẹ nitori baba ni oun jẹ fun Baba Igboho.
Oluwo wa gbadura fun un pe ki Ọlọrun yọ ọ kuro ninu wahala to ko ara rẹ si.
Ticket to Heaven: Ọwọ́ ọlọ́pàá tẹ Pásítọ̀ tó ń ta tíkẹ́ẹ̀tì sí ìjọba ọ̀run ní $500 èèyàn kan
Oríṣun àwòrán, Egypt today
Ara meeriri, mo rí ori olongbo lori atẹ ni iṣẹlẹ kan to waye lorilẹede Zimbabwe laipẹ yii.Pásítọ̀ kan àti aya rẹ ni ọwọ awọn ọlọpaa tẹ pe wọn n gba awọn eeyan lati wa ra tíkẹ́ẹ̀tì sijọba ọrun ni ẹẹdẹgbẹta dọla.Pásítọ̀ Tito Wats lo sọ fun ẹgbẹlẹgbẹ ọmọlẹyin rẹ pe Jesu lo fun oun ni awọn tíkẹ́ẹ̀tì naa, ti wọn yoo lo wọ ọrun rere.
"Ko kan mi ohun tawọn eeyan tabi ọlọpaa n sọ nipa mi, wọn n ṣe inunibini si mi ni tori pe mo n ṣiṣẹ Ọlọrun.Jesu funra rẹ lo yọju si mi, to si ko awọn tíkẹ́ẹ̀tì naa le oun lọwọ, ti wọn jẹ kikida wura.
Ṣé o lè gbé orí rẹ lọ sọ́dọ̀ fárífárí alábẹ kó dán bí àwọn tó ní àwọn kò lè lo clipper láéláé yìí?"
"O ni ki n ta wọn fun awọn eeyan to ba n fẹ igbala.""Iroyin naa ni ẹgbẹlẹgbẹ awọn eeyan lo n fi ẹhonu han tori bi wọn ṣe mu si ahamọ, wọn ni ki ọlọpaa fi silẹ ni.Pásítọ̀ naa ni wọn lo sọ pe goolu pọnbele ni wọn fi ṣe tíkẹ́ẹ̀tì naa, eyi ti yoo pese aaye nijoba ọrun fun ẹnikẹni to ba ni lọwọ."" N ko fẹ mọ ohun ti awọn ọlọpaa n sọ. Goolu pọnbele ni awọn tikẹẹti naa, kii se eyi ti mo ge funra mi, ti mo si fi omi goolu pa lara."
Jesu funra rẹ lo fun mi lẹyin KFC, to si ni ki n lọ ta lati ri owo gba aaye to tobi si. Mo si ti pade ajeji kan to n jẹ Stevie.
O ti wa seleri pe ti mo ba le ko awọn owo naa pap, oun yoo fi baalu kekere rẹ gbe emi ati iyawo mi lọ si aye miran to jẹ kikida eroja Cocaine nikan lo wa nibẹ.
BBC Yoruba pada lọ ṣabẹwo si ọja Bode nibi ti ọkọ to kun fọọ fun afẹfẹ gaasi ti dede sina wọ inu ọja to si pa awọn kan.
Ẹ le fin gbogbo Cocaine to wa nibẹ tẹba fẹ, ọfẹ ni. Ẹ wa ran alaisẹ ni ẹwọn, kẹ wa ri nnkan ti yoo sẹlẹ.
"O yẹ kẹ lọ mu Jesu naa nitori oun lo fun mi ni awọn tikẹẹti onigoolu ọhun lati ta wọn. Mo si setan lati fa Jesu silẹ pẹlu."""
Lara awọn nnkan ti awọn ọlọpaa ba ninu ile wọn ni ẹgbẹrun mẹwa dọla owo beba, awọn ọpa ati ọmọ Anta.
Dilip Kumar: Àgbà ọ̀jẹ̀ òṣèré India kú lẹ́ni ọdún méjìdinlọ́gọ́run
Dilip Kumar, ọ̀kan pàtàkì nínú àwọn tó ń ṣe sinima, to sì gbajúgbajà ni India kú ní Mumbai lẹ́ni ọdún méjìdinlọ́gọ́run
Dilip Kumar àti Saira Bano aya rẹ tí kópa nínú sinimá àgbéléwò India lọ́pọ̀lọpọ̀.
Awọn sinima marunlelogọ́ta láàrin àádọ́ta ọdún lọ tí ṣe, tó sì máa ń kó àwọn ipa tó lágbára gidi.
Ọgbọ́n ọjọ́ oṣù kẹfà ọdún ni wọ́n gbé lọ sí ilé ìwòsàn lẹ́yìn tó sọ pé òun kò lè mi daada.
Fún ìgbà díẹ̀ sí àsìkò yìí, ni ó ti ń ṣe àìsàn, tó sì ti ń lọ sí ilé ìwòsàn bọ̀ ni àìmọye ìgbà.
Ìyàwó rẹ Saira Banu, toun naa jẹ́ òṣèré Nollywood ló fi silẹ lọ, àwọn òṣèré méjèèjì kò bímọ sáyé.
Thackeray àti àwọn gbajúgbajà òṣèré Nollywood, to di mọ Shah Rukh Khan àti Ranbir Kapoor, lo sàbẹ̀wò sí ẹbí Kumar láti lọ bá ẹbi rẹ dárò.
Ọdún 1944 ló kọ́kọ́ ṣe sinimá rẹ, Jwaar Bhata, ṣùgbọ́n ọdún 1949 ni sinima rẹ, Andaz, to gbé jáde di ilúmọ̀ọ́ka.
"Lai dènà pẹnu Dilip Kumar jẹ́ òṣèré tó dára jù lọ tí India ni.
Bó tilẹ̀ jẹ́ pé àwọn òṣèré mìíràn tún wà tó lókìkí julọ, ṣùgbọ́n òun ló dára jù. Gẹ́gẹ́ bí o sẹ sọ fún BBC.
Oríṣun àwòrán, Twitter@NFAIofficial
Ọ̀pọ̀ àwọn sinima to tí ṣe ni, Mela Naya, Daur, GangaJumna, Devdas àti Mughal-e-Azam ti wọn jẹ́ àwọn sinima àrà ọ̀tọ̀ tó jẹ́ kí àwọn olólùfẹ́ rẹ túbọ̀ fẹ́ràn rẹ.
Àwọn sinima mìíràn tí Kumar tí kọ ni Villager, suave urbanite, a Bengali gentleman àti Swashbuckling hero, kí ó tó di àsìkò tó wà lọ ń se sinima to tí ń kópa bii àgbàlagbà ni ọdún 70s, bí Ogbeni Desai ṣe sọ.
Kumar gba ẹ̀bùn àmin ẹ̀yẹ to ga julọ fún sinima, àti àmì ẹ̀yẹ tó ga julọ fún ará ìlú ni India.
Ó fẹ́ Saira Bano lọ́dún 1966, àwọn méjèèjì jọ kọ́pa nínú àwọn sinima to lókìkí lọpọlọpọ ìgbà. Ọdún 1998 ni Kumar tí ṣe sinima Kẹ́yìn.
Ṣé o lè gbé orí rẹ lọ sọ́dọ̀ fárífárí alábẹ kó dán bí àwọn tó ní àwọn kò lè lo clipper láéláé yìí?"
Ọdún 1944 ló kọ́kọ́ ṣe sinimọ́ rẹ Jwaar Bhata, ṣùgbọ́n ọdún 1949 ni sinimọ́ rẹ Andaz t gbé jáde tọ si di ilúmọ̀ọ́ka.
"Lai dènà pẹnu Dilip Kumar jẹ́ òṣèré tó dára jù lọ tí India ni.
Bótilẹ̀ jẹ́ pé àwọn òṣèré mìíràn tún wà tó lókìkí julọ, ṣùgbọ́n òun ló dára jù. Gẹ́gẹ́ bí o sẹ sọ fún BBC
Ọ̀pọ̀ àwọn sinima to tí ṣe ni, Mela Naya, Daur, GangaJumna, Devdas àti Mughal-e-Azam jẹ́ àwọn sinima àrà ọ̀tọ̀ tó jẹ́ kí àwọn olólùfẹ́ rẹ túbọ̀ fẹ́ràn rẹ.
Àwọn sinima mìíràn tí Kumar tí kọ ni Villager, suave urbanite, a Bengali gentleman àti Swashbuckling hero, kí ó tó di àsìkò tó wà lọ ń se sinima to tí ń kópa àgbàlagbà ni ọdún 70s bí Ogbeni Desai ṣe sọ.
Ó gba ẹ̀bùn àmin ẹ̀yẹ to ga julọ fún sinima, àti àmì ẹ̀yẹ tó ga julọ fún ará ìlú ni India.
Ó fẹ́ Saira, Bano lọ́dún 1966, àwọn méjèèjì jọ kọ́pa nínú àwọn sinima ro lókìkí lọpọlọpọ ìgbà. Ọdún 1998 ni Kumar tí ṣe sinima Kẹ́yìn.
Sunday Igboho: Ìkọlù tí ẹ̀ṣọ́ aláàbò ṣe sí Sunday Igboho, Inú wa kò dún sí ìjọba''
Oríṣun àwòrán, Others
Ọba Ẹlẹrinmọ ti Ẹrinmọ Ijẹsha ni ilu Ekiti, Oba (Dr) Michael Ajayi, Arowatawaya II ti ni inu awọn lọbalọba ko dun si iṣẹlẹ ikọlu si Sunday Igboho to waye laipẹ yii.
Oba (Dr) Michael Ajayi, Arowatawaya II lasiko to n ba BBC News Yoruba sọrọ ni nkan to ba ṣẹlẹ si ọmọ Yoruba ẹyọkan, gbogbo wọn ni o ṣẹlẹ si.
O ni awọn lọbalọba ko dakẹ rara, nitori labẹlẹ ni wọn gbe igbeṣẹ lati rii pe opin de ba gbogbo wahala yii.
Ó dùn wá gaan pé wọn kò gbé òkú TB Joshua wá sílé, bó ṣe ọgọ́rùn ún ọdún, a ṣì ń retí - Àwọn ìyàwó ilé
''Mi o ro pe a dakẹ rara, ọmọ ẹni kii buru ka fi fun ẹkun pa jẹ''.
''Nkan to ba ti ba ẹnikan, o ba gbogbo wa naani, inu wa ko dun si''.
Bakan naa ni Ọba Ẹlẹrinmọ ti Ẹrinmọ Ijẹsha ni nkan ti awọn ẹṣọ alaabo pẹlu atilẹyin ijọba apapọ ṣe si Sunday Igboho ko bojumu rara.
'Ìjámbá Ọ̀kadà ló dédé sọ mi di òdi, ìyàwó tí mo yó ìfẹ́ rẹ̀ náà tún wá jẹ́ odi'
Oba Micheal ni awọn ko fi igba kan gbọ pe wọn fi iwe ipe ranṣẹ si Sunday Igboho, wọn kan dede ṣekọlu si ni oru mọju ni.
O ni awọn ni igbagbọ wi pe awọn aṣoju wọn ni ile aṣofin lorilẹede Naijiria naa n ṣiṣẹ takuntakun lati ri pe iya ko jẹ ọmọ ilẹ Yoruba kankan ni ọna aitọ.
Kemi Adeosun NYSC Certificate: Iléẹjọ́ ní Kemi Adeosun kò nílò sabuké láti jẹ mínísítà ní Naijiria
Oríṣun àwòrán, Others
Minisita tẹlẹri fun eto isuna ni Naijiria, Kemi Adeosun ti fesi si aṣẹ ileẹjọ to ni ko jẹbi ẹsun lilo ayederu sabuke ti wọn fi kan an ni ọdun 2018.
Kemi Adeosun ni gbogbo awọn ti wọn tẹ aṣọ oun mẹrẹ pẹlu ẹsun ti wọn fi kan oun ni wọn yoo gburo oun patapata.
Ninu idajọ ile ẹjọ giga ni ilu Abuja ni adajọ ti sọ wi pe ko pọn dandan fun Kemi Adeosun lati sin ilu rẹ fun ọdun kan labẹ asia NYSC, nitori ko yẹ fun ipe naa.
Adajọ Taiwo Taiwo ni Adeosun kii ṣe ọmọ Naijiria nigba to ṣetan ni ile iwe giga, to si pe ẹni ọgbọn ọdun, nitori naa ko nilo sabuke.
Bakan naa ni adajọ naa fikun pe ko nilo lati fi sabuke NYSC han ko to le gba ipo minisita lorilẹede Naijiria.
Ọdun 2018 ni Kemi Adeosun fi ipo rẹ silẹ gẹgẹ bi minisita fun eto iṣuna lẹyin ti wọn fẹsun kan an pe ayederu sabuke lo lo fun NYSC rẹ.
Ninu atẹjade ti Adeosun fi sita oun yoo gbe gbogbo igbeṣẹ to yẹ ni abẹ ofin lati ri wi pe oun ja fun orukọ oun ti wọn bajẹ.
''Mo ti gbọ lati ọdọ awọn agbẹjọro mi pe mi o nilo lati ṣe NYSC ki n to di minisita ni Naijiria, eleyii si ni mo ti n ja fun lati ọjọ yii, amọ mo dupẹ pe ọrọ naa ti ni ojutu.''
''Idajọ naa fihan pe emi lo leke ẹsun ti wọn fi kan mi, eleyii to da ẹru si mi lara fun ọdun mẹta.''
''Aṣeyọri nla ni eleyii jẹ fun mi ati fun awọn ọmọ Naijiria to wa ni oke okun ti wọn n gbero lati wa ṣiṣẹ ilu amọ ti wọn ko ni sabuke NYSC''
Ileẹjọ giga ni ilu Abuja ni Kemi Adeosun ko jẹbi pẹlu ipo to dimu gẹgẹ bi minisita fun ọrọ iṣuna nigba naa nitori ko ṣe NYSC.
Gani Adams on Sunday Igboho: Aláìmọ̀ làwọn tó ní mo lọ Synagogue lọ dárò T.B Joshua dípo lílọ ìwọ́de Yoruba Nation
Oríṣun àwòrán, Iba Gani Adams/Facebook
Aláìmọ̀ làwọn tó ní mo lọ Synagogue lọ dárò T.B Joshua dípo lílọ ìwọ́de Yoruba Nation""."
Aarẹ Ọna Kakanfo Yoruba, Gani Adams ti tutọ soke foju gba lori bawọn kan ṣe ni o pataki isinku T.B Joshua ju kikopa ninu iwọde Yoruba Nation.
Ninu ifọrọwerọ kan to ṣe pẹlu BBC Yoruba lo ti tu kẹkẹ ọrọ yi silẹ.
Iba sọ pe iru ibeere yi ko yẹ ko tiẹ waye rara ati pe awọn to n sọ ọrọ naa jẹ alaimọkan ni.
O woye pe awọn eeyan ṣe le maa sọ pe ṣe oun ti pe tabi kan si Sunday Igboho lati igba ti ajọ DSS ti ṣe ikọlu si ile rẹ to fi wa di pe ibi akọkọ to lọ to han si gobogo araye ni ibi isinku Wolii T.B Joshua.
Ó dùn wá gaan pé wọn kò gbé òkú TB Joshua wá sílé, bó ṣe ọgọ́rùn ún ọdún, a ṣì ń retí - Àwọn ìyàwó ilé
O ni yatọ si pe oun lọ sibẹ lati lọ ṣe idaro eekan ọmọ ilẹ Yoruba to papoda, ọmọ ilu kanna ni oun ati T.B Joshua jẹ.
Lẹnu ọjọ mẹta yi ni ibeere ti nwaye wi pe ki lo de ti Gani Adams ko ṣe lewaju iwọde ati ipolongo Yoruba Nation ti Sunday Igboho ati awọn miran n ṣe agbatẹru rẹ.
Esi ti Gani Adams a si maa fọ si ibeere yi ni pe Aarẹ Ọna Kakanfo kii ṣadede lọ si ode tabi kopa ninu iwọde.
Ifọrọwerọ  pẹlu Gani Adams lori ọrọ Sunday Igboho
Adams ti sọ fun BBC ri wi pe ''Ki ni wọn fi ipo  Aarẹ Ọna Kakanfo pe? ṣe ti mo ba lọ si iwọde ti awọn ọlọpaa ko mi mọ awọn oluwọde, kini ẹ fẹ maa sọ?''
Gani Adams ṣalaye pe bi oun ti ṣe lọ sibi eto isinku T.B Joshua, anfaani pupọ wa nibẹ tawọn eeyan ko mọ paapa nipa amuṣẹ Yoruba Nation ti wọn n ja fun.
O ni nibi isinku yi, awọn eeyan jankan jankan loun yoo pade nibẹ ti wọn si le ṣatilẹyin fun Yoruba Nation bo ba ya.
'OPC ko ṣ'atilẹyin fun Jonathan ni 2015'
''Ṣe ẹ ri ibi isinku ti mo lọ, orisirisi aṣoju orileede ni wọn wa sibẹ. Ninu awọn wọnyi, bo ba di igba taa pade ni awọn ajọ agbaye bi UN, wọn yoo ranti pe a ti jọ sọrọ ri.''
''Nigba taa bi fi sọ fun wọn pe a fẹ idasilẹ Yoruba Republic ko ni jẹ tuntun si wọn nitori a ti jọ pade sọrọ lori rẹ tẹlẹ''
Gani Adams ni kii ṣe pe iwọde tabi ifẹhonuhan naa ko daa lati le polongo idasilẹ Yoruba Nation ṣugbọn ọrọ yi gba ọgbọn ati ooye ti eeyan fii to nkan daada.
O ni gbogbo igbesẹ ti Sunday Igboho n gbe loun mọ si ati pe o ṣe pataki ki awọn ọmọ Yoruba lo orisi ọna lati le ṣamuṣẹ idasilẹ Yoruba Nation ti wọn n ja fun.
Farouk Yahaya: A ti ń rán ọ̀pọ̀ ọ̀daràn lọ sọ́dọ̀ Ọlọ́run láti lọ jẹ́jọ́ ẹ̀ṣẹ̀ wọn - Ólórí iléèṣẹ́ ológun tuntun
Oríṣun àwòrán, The nation
Olori ileeṣẹ ologun Naijiria ti Aarẹ Muhammadu Buhari ṣẹṣẹ bura fun, Ọgagun Farouk Yahaya ti sọ pe awọn n tẹle aṣẹ ti aarẹ pa lati kọju ija si awọn ọdaran jakejado Naijiria.
"Yahaya, lasiko to ba awọn akọroyin sọrọ lẹyin ti Aarẹ Buhari bura fun tan nile ijọba nilu Abuja, sọ pe ọpọlọpọ agbebọn, agbesunmọmi, ati awọn ọdaran miran ni awọn ti ""ran lọ si ọdọ Ọlọrun, lati lọ jẹjọ fun ẹṣẹ wọn""."
Bakan naa lo jẹjẹ pe gbogbo otitọ ati ifọkansin oun yoo wa fun aarẹ, ati orilẹ-ede Naijiria.
O ni oun dupẹ lọwọ aarẹ fun igbẹkẹle to ni ninu oun, to fi yan oun si ipo.
"O sọ pe ""a ti n ṣe aṣeyọri lọpọlọpọ, ao si ma aṣe amulo awọn aṣeyọri naa pẹlu iriri wa lati ṣẹgun."""
"Fun awọn agbebọn ati ọdaran to n fi oju tẹmbẹlu wo eto aabo Naijiria, a ti n tẹle aṣẹ ti aarẹ pa pe ka ba wọn sọrọ ni èdè ti wọn gbọ.
Nkan ti a si n ṣe niyii, debi pe a ti ran ọpọlọpọ wọn si ọdọ Ọlọrun, lati lọ jẹjọ fun ẹsẹ wọn.
Ao si tẹsiwaju lati ma a ṣe bẹ ẹ."""
Nigba ti oun naa n sọrọ, minisita fun eto aabo ni Naijiria, Ọgagun Bashir Magashi sọ pe olori ileeṣẹ ologun naa bẹrẹ iṣẹ rẹ daadaa.
"Ọpọlọpọ ayipada ti wa ninu ilana ti a n gba koju eto aabo, lati igba to ti de ipo. Gbogbo nkan n lọ deedee bo ṣe yẹ.
O da mi loju pe ti a ba n lọ bayii, ko ni i pẹ ti ao fi jade kuro ninu iṣoro igbesunmọmi."""
Ọgagun Magashi sọ pe ko si nkan to buru ninu bi aarẹ ṣe paṣẹ pe ki awọn oṣiṣẹ alaabo ma a ba awọb ọdaran sọrọ ni èdè ti wọn gbọ.
Ko ṣe e ṣe ki a fi aaye gba ọ lati wa laye, ti  o ba ni nkan ijagun lọna ti ko ba ofin mu, nitori pe a le lo nkan ijagun naa lodi si ọ.
TB Joshua burial: Àwọn obìnrin Akoko ní kò sí ọmọbíbí ilẹ̀ náà tó tọ́jú àwọn bíí olóògbé
Oríṣun àwòrán, Tb joshua ministries/facebook
Bi eto isinku Wolii Temitope Balogun Joshua ṣe ti bẹrẹ lati ọjọ Aje, awọn Iyalaje ati Iyalọja ni ilẹ Akoko nipinlẹ Ondo ti pinnu lati ti gbogbo awọn ọja pa ni ọjọ Ẹti.
Ọjọ Ẹti gan-an ni wọn yoo sin oku oloogbe.
Atẹjade lati ọdọ Iyalaje ti ilu Ikarẹ-Akoko, Alhaja Risikat Mohammed sọ pe awọn ṣe bẹẹ lati bu ọla fun ọmọ wọn to ku.
O ni ko si ifarada to tobi ju lati fi yẹ ẹ si fun ifẹ, aanu ati oore to ṣe fun awọn eniyan rẹ nigba to wa laye.
O ni eyi yoo tun fun wọn ni anfaani lati wo bi eto isinku naa ba ṣe n lọ lori ẹrọ amohunmaworan ijọ Synagogue, Emmanuel TV.
Ó dùn wá gaan pé wọn kò gbé òkú TB Joshua wá sílé, bó ṣe ọgọ́rùn ún ọdún, a ṣì ń retí - Àwọn ìyàwó ilé
Ẹlomii, to jẹ olori fun gbogbo awọn obinrin to jẹ oye ni ilẹ Akoko, Oloye Margaret Ebun Oladunni sọ pe ọsẹ ọfọ ni ọsẹ yii jẹ fun ilẹ Akoko.
O ni ko si ọmọ bibi ilẹ naa to ti ku tabi to wa laye, to ṣe itọju awọn eniyan rẹ bi TB Joshua.
Bayii ni ọja ilu Arigidi sẹ ri lasiko ti akọroyin BBC ṣabẹwo si ilu naa.
Sunday Igboho: DSS kò jẹ́ ki mọ̀lẹ́bí tàbí agbẹjọ́rò rí àwọn èèyàn tí wọn ko nílé mi
Oríṣun àwòrán, DSS
Iroyin to n jade lati igun gbajugbaja ajijagbara fun ilẹ Yoruba, Oloye Sunday Igboho ti sisọ loju rẹ nipa ipo ti awọn eeyan ti DSS ko nile rẹ wa.
Agbẹnusọ fun Sunday Igboho, Olayomi Koiki lo sisọ loju ọrọ yii ninu atẹjade kan to ka sita fun araye loju opo Instagram rẹ.
Gẹgẹ bi Koiki ti wi, awọn eeyan mẹwa ti awọn osisẹ DSS ko nile Igboho nilo eto ilera kiamọsa.
'Ẹ má jẹ́ kí òkú ọmọ mi ráre o ìjọba! Ẹ gbée fún mi kí n lọ sin ín - Ìyá ọmọ ti wọ́n pa ní ìwọ́de Yoruba Nation
O ni meji ninu wọn nilo ki wọn de ile iwosan fun itọju nitori ipo ailera to lewu ti wọn wa.
Gẹgẹ bi aworan to si wa loju ayelujara gẹgẹ bi DSS se se afihan rẹ, ọkan lara awọn eeyan ti wọn ko nile Igboho ni ọgbẹ ọta ibọn wa nibi orukun rẹ, eyi to we bandeji mọ.
Agbẹnusọ fun Igboho ni ikọ agbẹjọro fun Sunday Igboho ti yọju si ọọfisi DSS nilu Abuja amọ ti awọn osisẹ agbofinro naa kọ lati jẹ ki wọn ri awọn eeyan to wa ni ahamọ naa.
"Eyi ni lati ke si gbogbo awujọ agbaye nipa bi awọn DSS ko se gba awọn eeyan ti wọn ko nile Sunday Igboho laaye lati ri agbẹjọro wọn.
Eyi tako ẹtọ awọn eeyan ti wọn ba mu si ahamọ tori oselu, ti wọn ko si jẹ ki mọlẹbi ati amofin ri wọn.
Koda, awọn lẹta tawọn agbofin wa fi silẹ ni ọọfisi DSS ni wọn ko sisẹ le lori ti wọn si ni asẹ lati oke wa ni.
Meji ninu awọn eeyan yii lo nilo itọju kiakia, paapaa julẹ, obinrin to maa n seto lori ayelujara ti ọpọ mọ si Lady K."
O tẹsiwaju pe awọn agbofinro yii mọ ipo ailera ti obinrin naa wa, eyi to nilo itọju kiakia amọ wọn kọ eti ikun si.
Ó dùn wá gaan pé wọn kò gbé òkú TB Joshua wá sílé, bó ṣe ọgọ́rùn ún ọdún, a ṣì ń retí - Àwọn ìyàwó ilé
Agbẹnusọ fun Sunday Igboho wa n ke si gbogbo agbaye pe awọn osisẹ DSS lati oke de isalẹ ni ki wn mu bi ohunkohun ba sẹlẹ si ọkankan ninu awọn to wa ni ahamọ naa.
O ni bi awọn osisẹ DSS yii ko se gba awn eeyan naa laaye lati maa jiroro pẹlu awọn agbẹjọro wọn, ti mu ki awọn agbofinro yii gbe igbesẹ kọja agbara ti ofin gbe le wọn lọwọ.
A wa n kesi DSS lati tun ero wọn pa lori bi wọn se n jẹ gaba le awọn eeyan to wa ni ahamọ wọn lori tabi fiya jẹ wọn nitori eyi tako ofin ilẹ wa ti wọn jẹjẹ lati daabo bo.
O wa koro oju si bi wọn se kọlu ile naa ati bi wọn se mu awọn eeyan naa nile Sunday Igboho.
Bẹẹ ba gbagbe, mọlẹbi awọn eeyan ti DSS ko yii se iwọde ni Ọjọru lati fi ẹhonu han lori bi awọn agbofinro naa ko se ko wọn da si ahamọ lai tu wọn si.
'Ìjámbá Ọ̀kadà ló dédé sọ mi di òdi, ìyàwó tí mo yó ìfẹ́ rẹ̀ náà tún wá jẹ́ odi'
Multichoice: Ìjọba gbẹ́sẹ̀ lé àpò àṣùwọn iléeṣẹ́ DSTV àti GO TV torí owó orí
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ijọba apapọ ti gbegi dina apo asunwọn owo ileesẹ Multichoice, to n gbe mohunmaworan DSTV ati GO Tv sita.
Alaye ijọba apapọ ni pe ileesẹ Multichoice n sa fun owo ori sisan, to si tun n lu awọn onibara rẹ ni jibiti.
Ileesẹ to n pawo wọle labẹle labẹ ijọba apapọ FIRS ni owo to to biliọnu mẹrin aabọ Dọla ni ileesẹ South Africa naa jẹ.
'Ẹ má jẹ́ kí òkú ọmọ mi ráre o ìjọba! Ẹ gbée fún mi kí n lọ sin ín - Ìyá ọmọ ti wọ́n pa ní ìwọ́de Yoruba Nation
Gbogbo ẹ̀yin tí ẹ ba orúkọ mi jẹ́ tórí sabuké NYSC mi, mò ń mú ẹyẹ bọ̀ lápò - Kemi Adeosu
Bakan naa ni ajọ FIRS tun na ika aleebu si ileesẹ naa pe o kuna lati dahun si awọn ibeere ti ajọ naa n bi i.
Ó dùn wá gaan pé wọn kò gbé òkú TB Joshua wá sílé, bó ṣe ọgọ́rùn ún ọdún, a ṣì ń retí - Àwọn ìyàwó ilé
FIRS ni bi o tilẹ jẹ pe ida ọgbọn ninu ere ti ileesẹ Multichoice n jẹ lo n wa lati orilẹede Naijiria.
Gẹgẹ bi alaga ileesẹ FIRS, Muhammed Nami ti wi,  sibẹ ileesẹ Multichoice ko fi aaye gba awọn lati yẹ iwe owo ileesẹ naa wo
Amọ ileesẹ naa wa n salaye pe oun n tẹle ofin to de owo ori sisan ni Naijria, ti ifikunlukun si ti n lọ laarin rẹ ati ileesẹ FIRS lati yanju ọrọ naa nitunbi n nubi.
Nibayii, ileesẹ FIRS ti wa pasẹ fun awọn ile ifowopamọ lati seranwọ lati gba owo bii biliọnu mẹrin ati aabọ Dọla pada ninu Triliọnu kan ati aabọ naira  ti ijọba jẹ wọn.
'Ìjámbá Ọ̀kadà ló dédé sọ mi di òdi, ìyàwó tí mo yó ìfẹ́ rẹ̀ náà tún wá jẹ́ odi'
Ileesẹ Multichoice yii lo ni ileesẹ tẹlifisan DSTV ati GOTV to wa lori ayelujara.
Losu kẹfa ọdun 2020 ni awọn asofin lorilẹede Naijiria  bẹrẹ iwadii nipa isọwọsisẹ ileesẹ naa lori bo se n gba owo ni osoosu lọwọ awọn onibara rẹ, boya wọn wo mohunmaworan naa tabi bẹẹ kọ.
Osun Masquerade attack: Ìdìtẹ̀, ìpànìyàn, ìfìyàjẹni wà lára ẹ̀sùn tí wọn fi kan àwọn afurasí náà
Oríṣun àwòrán, Esuleke
Ile ẹjọ majisireti kan nilu Osogbo ti pasẹ ni Ọjọbọ pe ki wọn fi Olori Eleegun, Fashola Esuleke ati Imaamu agba, Kazeem Yunus pẹlu eeyan marun miran si ahamọ.
Eyi ko sẹyin isẹlẹ ikọlu kan to waye ni Mọsalasi Kamarudeen nilu Osogbo laarin awọn Eleegun ati Musulumi, eyi to mu ẹmi olujọsin kan lọ, ti mẹrinla miran si farapa.
Ọjọ Ẹti to kọja, eyiun ọjọ Keji osu Keji ọdun 2021 ni awọn ọlọpaa ti kọkọ fẹ fi oju awọn afurasi naa ba ile ẹjọ amọ Olori Eleegun, Esuleke lo sadede subu, ti wọn ko si le ko wọn lọ sile ẹjọ mọ.
'Ẹ má jẹ́ kí òkú ọmọ mi ráre o ìjọba! Ẹ gbée fún mi kí n lọ sin ín - Ìyá ọmọ ti wọ́n pa ní ìwọ́de Yoruba Nation
Amọ ni Ọjọbọ ni ileesẹ ọlọpaa wọ awọn olujẹjọ meje, eyiun Fashola Esuleke, Kola Adeosun, Idowu Abimbola, Kazeem Yunus, Salawu Jimoh, Alarape Sulaimon Akanbi ati Raimi Saheed lọ sile ẹjọ.
Ẹsun ti wọn si fi kan wọn ni iditẹ, ipaniyan, ifiyajẹni, biba dukia jẹ ati dida alaafia ilu ru.
Ó dùn wá gaan pé wọn kò gbé òkú TB Joshua wá sílé, bó ṣe ọgọ́rùn ún ọdún, a ṣì ń retí - Àwọn ìyàwó ilé
Ọlọpaa agbefọba, Taiwo Adegoke lo kede pe awọn afurasi naa wa nile ẹjọ, ti amofin lati ileesẹ eto idajọ, Moses Faremi si n soju fun ijọba.
Lẹyin eyi ni Adegoke wa bẹ ile ẹjọ pe ko fun oun di la lati gba faili ẹjọ awọn afurasi naa, ki oun si se asaro lori rẹ, ki wọn to tun ko wọn pada wa sile ẹjọ.
"O salaye pe ""Fashola Esuleke, Kola Adeosun ati Idowu Abimbola ni wọn fi ẹsun apaayan kan nigba ti wọn fi ẹsun ifiyajẹni kan Kazeem Yunus, Salawu Jimoh, Alarape Sulaimon Akanbi ati Raimi Saheed."""
Agbẹjọro fun Imaamu agba, Kazeem Odedeji wa rọ ile ẹjọ lati gba Kazeem Yunus, Salawu Jimoh, Alarape Sulaimon Akanbi ati Raimi Saheed lati gbadun oniduro wọn ti agọ ọlọpaa fun wọn.
'Ìjámbá Ọ̀kadà ló dédé sọ mi di òdi, ìyàwó tí mo yó ìfẹ́ rẹ̀ náà tún wá jẹ́ odi'
Amọ agbẹjọro fun awọn Eleegun, Kehinde Abioye ni ile ẹjọ nikan lo le sọ nipa oniduro wọn boya ki wọn si wa ni ahamọ ọlọpaa ni tabi ọgba ẹwọn Ilesa.
Adajọ Majisireti to n gbọ naa, Asimiyu Adebayo wa pasẹ pe ki wọn fi awọn olujẹjọ mejeeje si ahamọ ọlọpaa, to si sun igbẹjọ wọn si ọjọ Aje, ọjọ Kejila osu Keje ọdun 2021.
Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo
TB Joshua's Arigidi-Akoko town: Òkúta tó jábọ́ tí kò pa T.B Joshua ní ìkókó, àwa táa mọ ìt
Ni ilu ibi Wolii Temitope Joshua to di oloogbe ti wọn si n ṣe eto isinku rẹ lọwọ, awọn ara ile rẹ kan ṣi n sọ pe ko dun mọ awọn bi wọn ko ṣe wa sin oku rẹ sile.
Awọn iyawo ile tilẹ ni awọn gbera lọ si Eko lati lọ bere pe bawo ni eto yoo ṣe jẹ ṣugbọn wọn ko jẹ ki awọn ri iyawo Wolii Joshua.
Àdánù láéláé ni fún wa tí wọn kò bá sin òkú T.B Joshua sí ìlú abinibí rẹ̀ - Ọba Arigidi-Akoko
Àwòrán bí ó ṣe ńlọ rèé níbi ìsìnkú TB Joshua lónìí
Wo àwọn gbajúmọ̀, òṣèré tó lọ sí ibi ètò ìsìnkú Temitope Joshua
Ìtàn ayé TB Joshua tó lo ọdún kan àti oṣù mẹ́ta nínú ìyà rẹ̀
Arigidi-Akoko kan gógó torí ikú TB Joshua
'Ẹ má jẹ́ kí òkú ọmọ mi ráre o ìjọba! Ẹ gbée fún mi kí n lọ sin ín - Ìyá ọmọ ti wọ́n pa ní ìwọ́de Yoruba Nation
Amọṣa wọn o ri inu bi, wọn ṣi gbagbọ wipe bi wọn ṣi sin in si ilu eko, bo ba to ọgọrun ọdun, wọn yoo si gbe e wa sile ni ilu ibi rẹ tii ṣe Arigidi-Akoko.
'Ẹ má sọ pé lọ́balọ́ba kó sọ̀rọ̀ lórí ìkọlù Sunday Igboho, Inú wa kò dún sí ìjọba'
Mò ń rán “suit” tó ta lẹ́nu wọ́n sì gba tèmi àti ìyàwó mi gidi nínú iṣẹ télọ - Odi ọkọ àtìyàwó
A ti ń rán ọ̀pọ̀ ọ̀daràn lọ sọ́dọ̀ Ọlọ́run láti lọ jẹ́jọ́ ẹ̀ṣẹ̀ wọn - Ólórí iléèṣẹ́ ológun tuntun
DSS VS Sunday Igboho: O tó gẹ́, Sunday Igboho kọ̀wé sí adájọ kí DSS tú àwọn èèyàn rẹ̀ sílẹ̀
Ajafẹtọ ọmọ Yoruba Oloye Sunday  Adeyemo ti awọn eeyan mọ si Sunday Igboho ti gba ile ẹjọ lọ lati beere fun itusilẹ awọn eeyan rẹ ti ajọ ọtẹlẹmuyẹ DSS mu.
Ni ile rẹ to wa ni adugbo Soka nilu Ibadan ni wọn ti ko awọn eeyan mẹtala lasiko ti wọn ṣe ikọlu si ile rẹ loruganjọ.
Ile ẹjọ giga to wa ni Abuja ni o ti fi iwe ipẹjọ yi lelẹ gẹgẹ bi iwe iroyin Naijiria Punch ṣe jabọ.
Iwe iroyin yi bakan naa sọ pe agbẹjọro Igboho Yomi Aliyyu(SAN) jẹri si ọrọ yi fawọn to si ni lỌjọbọ ni awọn kọ iwe si ile ẹjọ giga Abuja ki wọn pa DSS laṣẹ lati tu awọn eeyan yi silẹ.
Agbẹjọro ọhun ko sọ pato nkan tawọn n beere fun ṣugbọn o sọ fun Punch pe agbẹnusọ Igboho, Olayomi Koiki ti fi atẹjade sita ṣaaju.
Ninu atẹjade yi, o sọ pe Koiki ni awọn ajọ ọtẹlẹmuyẹ ko gba awọn agbẹjọro Igboho laaye lati ri awọn to wa ni ahamọ.
Ni idahun si ibeere nkan ti wn fẹ ṣe lati ri pe wọn gba itusilẹ,Aliyu sọ pe''A ti kọwe sile ẹjọ gigaAbuja nipa gbigba oniduro wọn.Loni la kọ.''
Bi a ko ba gbagbe, ni ọjọ Kini Oṣu Keje ni awọn ajọ ọtẹlẹmuyẹ DSS ṣe ikọlu si ile Igboho.
Lẹyin ikọlu yi, DSS sọ pe lootọ lawọn yinbọn pa eeyan meji to doju ija kọ awọn tawọn si ri ohun ija oloro gbaati pe awọn tu  mu eeyan mẹtala nibẹ.
Igboho ti fesi lati ẹnu agbẹjọro rẹ pe ko si ohun to jọ bẹ.
Sunday Igboho: Ẹgbẹ́ CAN ké gbànjarè sí ìjọba àpapọ̀ Nàìjíríà lórí àwọn Pásítọ̀ tí o wà lọ́wọ́ ajínigbe
Oríṣun àwòrán, OTHERS
Ẹgbẹ ọmọlẹyin Kristi lorileede Naijiria CAN ti bẹnu atẹ lu bi ijọba Naijria ti ṣe n dunkoko mọ ajafẹtọmọniyan ilẹ Yoruba nii, Sunday Igboho.
Ẹgbẹ naa sọrọ yi ninu atẹjade kan ti wọn fi sita lori bi nkan ti ṣe ri ni Naijiria.
CAN sọ pe o ṣeni laanu bi awọn agbofinro ti ṣe n ṣe ikọlu sawọn to n ṣe iwọde alaafia bi Sunday Igboho to si ni bi awọn to n bọ lẹyin ba gbọ iru nkan bayi, yoo jẹ iyalẹnu nla fun wọn.
'Nínú ìran, Olúwa sọ fún mi pé èmi ni màá tẹ̀síwájú nínú iṣẹ́ ìráńṣẹ́ Wòlìí TB Joshua, kàyéfì ti ń ṣẹlẹ̀ nínú ìjọ mi báyìí'
'Ẹ má jẹ́ kí òkú ọmọ mi ráre o ìjọba! Ẹ gbée fún mi kí n lọ sin ín - Ìyá ọmọ ti wọ́n pa ní ìwọ́de Yoruba Nation
Akọwe apapọ ẹgbẹ naa Daramola Bade ni isọkan Naijiria n mi jolojolo bayi pẹlu bi ijọba ṣe n fọwọ yẹpẹrẹ mu awọn ọdaran ati awọn mii to n gbẹnusọ fun wọn.
Akọle atẹjade yi ni wọn pe ni 'Aarẹ Buhari gbọdọ́ doola Pasitọ Popoola DAVID  lọwọ awọn to ji gbe ko si sapa ki Naijiria ma jin si ọfin''
Ninu rẹ, CAN ni ''Araalu ko ni gbagbe ijọba yi lori aile mu ipinu rẹ to ṣe nipa kikoju ipenija aabo ṣẹ ni Naijiria''
Iṣẹ́ ẹmí ẹtan ló bàlemi lasikọ tí mọ so aṣọtẹlẹ̀ pé wọn o wọ ipele aṣekágbá.
Lati le ṣe atunṣe eyi, o ni ''Aarẹ ni lati  yi bo ṣe n ṣe ijọba pada.2023 kii ṣe ohun to pẹ lọ titi.Aarẹ gbọdọ dẹwọ bi awọn ajinigbe ṣe nn ji awọn pasitọ gbe labẹ ijọba rẹ''
CAN tẹsiwaju pe ki aarẹ paṣẹ fun awọn ọga ileeṣẹ ologun ati ọlọpaa lati ṣawari Rev David Popoola ti ijọ Calvary Baptist Church, Kurmin Mashi ni Kaduna State.
Wọn ni awọn ajinigbe gbe Reverend yi lọjọ Iṣẹgun tii ṣe ọjọ Kẹfa Osu Keje 2021.
Ẹgbẹ naa ni awọn rawọ ẹbẹ si ijọba lati ri pe wọn ko pa pasitọ yi bi wọn ṣe pa alaga ijọ Church of the Brethren in Nigeria(EYN) ati alaga ẹgbẹ ọmọlẹyin Kristi ni ijọba ibilẹ Michika ni Adamawa, Rev. Lawan Andimi.
''A ri ijinigbe yi gẹgẹ bi idanwo nla fawọn ọga ileeṣẹ ọmọogun Naijiria paapa ọgagun ọmọ ogun Naijria tuntun Yahaya Farouk ati ọga ọlọpaa Naijiria Usman Alkali Baba nitori gbogbo aye lo n wo bi wọn yoo ti ṣe ṣe iṣẹ wọn.''
CAN fi kun pe ti ijọba Naijiria ba le ṣa gbogbo apa lati mu olori IPOB Nnamdi Kanu,ko yẹ ko le fun wọn lati mu awọn obilẹjẹ to n da omi alaafia Naijiria ru.
Wọn wa parọwa si ijọba ki wọn dide lati koju gbogbo ipenija aabo paapa tawọn ajinigbe ati janduku to fi mọ awọn ọdaran darandaran.
Sunday Igboho: Oluwo kọ lẹ́ta sí Buhari pé òun yóò mú Igboho wá bẹ̀bẹ̀ tí àkókò bá tó
Oríṣun àwòrán, Oluwo of Iwo
Oluwo ti ilu Iwo, Ọba Abdulrasheed Adewale Akanbi, Telu Kinni, ti kọwe si aarẹ Muhammadu Buhari lori ọrọ Ajijagbara fun ilẹ Yoruba nni, Oloye Sunday Igboho.
Ninu ẹda iwe naa ti Oluwo fi sọwọ si BBC Yoruba lo ti salaye pe Igboho bẹrẹ isẹ ijijagbara rẹ gẹgẹ bii olugbeja fun awọn alailagbara ni amọ ilana to n tọ ko ye oun.
Oluwo ni oun ko si lara awọn Ọba to n se atilẹyin fun ijijagbara Sunday Igboho rara bi o tilẹ jẹ pe oun maa n kilọ fun pe ko sọra se nigba ti oun ba gbọ nipa igbesẹ to ba fẹ gbe.
'Nínú ìran, Olúwa sọ fún mi pé èmi ni màá tẹ̀síwájú nínú iṣẹ́ ìráńṣẹ́ Wòlìí TB Joshua, kàyéfì ti ń ṣẹlẹ̀ nínú ìjọ mi báyìí'
O ni Igboho wa si aafin oun lọdun 2018, ti oun si gba ni imọran lori oun to ba wa amọ o kuna lati mọ iyatọ laarin ijijagbara ati kikọju ija si ijọba.
"Nigba to tiẹ ya, se lo n bu gbogbo alẹnulọrọ, to si n fi oniruuru ẹsun kan wọn, emi si ni ẹni akọkọ to ni mo n kọrin fun isọkan Naijiria.
Oríṣun àwòrán, Oluwo of Iwo
Gẹgẹ bi baba, mo dari jin, bẹẹ naa ni mo si n rọ aarẹ wa ni Naijiria lati si oju aanu wo ọmọ rẹ, Sunday Igboho."
Oluwo ni alaimọkan ni Igboho nidi sise akoso awọn nnkan pẹlu ijọba amọ lootọ lo jẹ ẹbun nla fun ilẹ Yoruba.
O ni Igboho ti jẹjẹ bayii lati maa tẹti si awọn agbaagba, ti yoo si maa sọrase lori awọn igbesẹ to ba n gbe lati akoko yii lọ.
"Mo n rọ aarẹ lati seraro lori awọn agbofinro to n lepa Igboho, mo si mọ pe isẹlẹ yii yoo tubọ mu ki okun isọkan Naijiria tubọ yi dain si ni.
Igboho ti jiya pupọ, yoo si jawọ ninu ipe fun iyapa Naijiria to n se, maa mu wa sọdọ yin fun ijiroro alaafia nigba ti akoko ba to."
"Ṣé o lè gbé orí rẹ lọ sọ́dọ̀ fárífárí alábẹ kó dán bí àwọn tó ní àwọn kò lè lo ""clipper láéláé yìí?"
Oluwo fikun pe orilẹede Naijiria ko se e pin lọsan kan, oru kan nitori idi kan tabi oniran atipe, agbara Naijiria ko si ninu oniruuru ede ta jẹ nikan bikose ninu idarijin pẹlu.
O wa mu wa siranti nipa iku to pa MKO Abiola, Ken Saro Wiwa atawọn ajijagbara miran ni ẹkun kọọkan ni Naijiria eyi tawọn ọmọ orilẹede yii ko le tete gbagbe.
Amọ bi ọmọ ko ba tete maa fi itan kọgbọn, baba to ba dara ko ni da ọmọ nu pẹlu omi iwẹ, mo si n sọ eyi, ki aarẹ le mọ pe a wi fun Sunday Igboho to nipa ijijagbara fun idasilẹ orilẹede Yoruba to n se, ko gbọran ni.
'Ìjámbá Ọ̀kadà ló dédé sọ mi di òdi, ìyàwó tí mo yó ìfẹ́ rẹ̀ náà tún wá jẹ́ odi'
Nipari, Oluwo wa kan saara si aarẹ Buhari lori aayan rẹ lati gbogun ti iwa ọdaran, agbebọn, ijinigbe ati bo se mu agbega awọn ohun eelo amayedẹrun nibaada.
Femi Adesina: Kìí ṣe àwọn ọ̀daràn nìkan ló ń gbọ́ èdè Buhari, ẹgbẹ́ alátakò PDP gan ti di akúrẹtẹ̀
Oríṣun àwòrán, Femi Adesina/Facebook
Oludamọran fun aarẹ Muhammadu Buhari lori eto iroyin, Femi Adesina ti kede pe aarẹ ti binu tan si awọn eeyan to n da wahala silẹ lorilẹede yii.
O ni awọn agbebọn, ikọ mujẹmujẹ, ọdaran, ajinigbe atawọn to n pe fun iyapa Naijiria lo ti n kan ni ẹṣẹ, ti gbogbo wọn si ti n gbe imu ẹlẹjẹ kiri bayii.
Femi Adesina woye ọrọ yii ninu ọrọ apilẹkọ rẹ to kọ nipa ipo ti Naijiria wa, eyi to gbe si oju opo Facebook rẹ.
O ni ni kete ti wọn fi okun oye ologun tuntun wọ olori ikọ ọmọ ogun ni Naijiria, Farouk Yahaya, lo ti kede pe gbogbo awọn adarugudu silẹ ni Naijiria ni wn n ran lọ sọdọ Ọlọrun lati lọ dahun awọn iwa ọdaran ti wọn hu.
Oríṣun àwòrán, Femi Adesina/Facebook
Adesina ni ọjọ idajọ yii yoo maa tẹsiwaju titi ti orilẹede Naijira yoo fi di afọmọ lọwọ awọn iwa aidaa gbogbo, eyi to tumọ si ede tuntun ti Buhari n fọ jade.
O salaye pe Buhari tẹti bẹlẹjẹ lati gbọ ẹdun ọkan alaga ajọ eleto idibo nilẹ yii, Ọjọgbọn Mahmoud Yakubu, to n gbarata pe bi wọn ba tẹsiwaju lati maa ba awọn ohun eelo idibo jẹ, yoo lewu fun eto idibo lọjọ iwaju.
"Gẹgẹ bii baba ti idunkooko wa fun ile rẹ yoo ti se, o kaanu awọn to n ba nnkan jẹ lorilẹede yii, to si ni awọn ti awọn jagun abẹle fun ọgbọn osu ko ni maa wo wọn niran, ki wn ba orilẹede yii .
Idi ree to fi ni laipẹ laijinna a ba wọn sọrọ ni ede ti yoo ye wọn."""
"Ede ti Buhari fi n ba awọn abayejẹ yii sọrọ ti wa di gbas-gbos, ti wọn si n pe aarẹ ni Olori ẹka ẹkọ nipa ede ni fasiti."""
Ṣé ẹ ti gbọ́ nípa òkú gbígbẹ́ tí wọ́n ṣì bá oyún nínú rẹ̀?
Bakan naa ni Femi Adesina ni igun kọọkan ni orilẹede yii lo ti wa n gbọ ede Buhari yekeyeke bayii, o ni kii se awọn ọdaran nikan amọ ẹgbẹ oselu alatako PDP pẹlu, ti n gbọ ede aarẹ yekeyeke.
"Ni ẹka oselu, ẹgbẹ PDP ti n di ahoro, ti ko ba si sọra, ẹgbẹ naa yoo di korofo ko to di ọdun 2023, koroba wọn ti n jo, to si n gba omi gidigidi.
Ni osu diẹ si asiko yii, ẹgbẹ oselu kan yoo maa lagbara siwaju ati siwaju, ti omiran yoo si maa di akurẹtẹ ni ojoojumọ, bi ẹgbẹ oselu kẹta ba tiẹ wa, ko le tii ni ipa kankan."
BBC Yoruba pada lọ ṣabẹwo si ọja Bode nibi ti ọkọ to kun fọọ fun afẹfẹ gaasi ti dede sina wọ inu ọja to si pa awọn kan.
Yomi Fabiyi Vs TAMPAN: Òfin tẹ ṣe kò nímọtù, ń kò gba fọ́ọ̀mù yín tẹ́lẹ̀
Oríṣun àwòrán, Realyomifabiyi/Instagram
Yomi Fabiyi, tii se gbajumọ osere tiata ti ẹgbẹ TAMPAN kede pe awọn ti ni ko lọ rọọkun nile nitori fiimu Oko Iyabo to se, ti fesi pada.
Yomi, ẹni to gbe ikede kan sita loju opo Instagram rẹ lori asẹ ti TAMPAN se pe ko yẹba diẹ na ninu ẹgbẹ naa, ti wa ni igbesẹ naa ko tu irun kankan lara oun.
Osere tiata naa ni ọmọ ẹgbẹ ANTP kuku ni oun nibẹrẹ pẹpẹ, to ba si buru tan, oun yoo pada si inu ẹgbẹ naa.
Bi ila ko ba se e gbe, a maa n gbe Ilala. Ẹni to sọ mi nu, lo sọ nnkan gidi nu, ẹni to ri mi he, lo ri nnkan gidi he.
Yomi Fabiyi ni oun ko kuku gba fọọmu tabi fi ọwọ si lati di ọmọ ẹgbẹ TAMPAN tabi dara pọ mọ ẹgbẹ awọn oludari ere.
Oríṣun àwòrán, Realyomifabiyi/Instagram
"Wọn kan ni ki n wa sanwo iforukọsilẹ ni, mo si se bẹẹ amọ n ko fọwọ si iwe kankan lati di ọmọ ẹgbẹ.
Iwe ti ẹ kọ si mi ko tọna rara, ko nitumọ si mi gẹgẹ bi ẹni to n gbe sinima jade.
Ti maa ba tiẹ sọrọ rara, yoo da lori titẹ ẹtọ ọmọniyan loju, ti mo ba si fẹ gbe yin lọ sile ẹjọ, ohun ti eyi yoo da lori ree."
Yomi Fabiyi wa pari ọrọ rẹ pe eeyan kii padanu ohun ti ko ba ni lati ilẹ.
TB Joshua burial: Wọ́n ti sin òkú TB Joshua sí Synagogue! Wo bí ìsìnkú ṣe lọ
Oríṣun àwòrán, Tb joshua ministries
Wọn ti sin oku oludasilẹ ijọ Synagogue Church of All Nations, SCOAN, Wolii Temitope Balogun Joshua.
Ni nkan bi aago mẹta ọsan kọja iṣẹju diẹ ni wọn gbe ara rẹ sinu iboji.
Nibi eto isinku naa to waye ni inu ọgba ijọ rẹ to wa ni adugbo Ikotun nipinlẹ Eko lati ri gomina ipinlẹ Ondo, Rotimi Akeredolu, ati aya Ooni Ile-Ife, Olori Naomi Silekunola Ogunwusi.
Oríṣun àwòrán, Tb joshua ministries
Olori Naomi Adeyeye Ogunwusi, iyawo Ooni Ile-Ife
Ẹwẹ, kọmisanna fun ọrọ abẹle nipinlẹ Eko, Olanrewaju Elegushi lo ṣoju ijọba ipinlẹ Eko nibẹ.
Bakan naa ni Ọba Willard Mswati Gomani lati orilẹede Malawi naa wa.
Eto isin idagbere lo kọkọ waye ninu ṣọọṣi Synagogue, ko to o di pe wọn gbe oku rẹ lọ si ile ikẹhin ti wọn ṣe si abala kan ninu ṣọọṣi naa.
Nigba to n sọrọ nibi isin idagbere, Gomina Rotimi Akeredolu sọ fun awọn eniyan ilu Arigidi to jẹ ilu abinibi oloogbe, lati mase fi oju ọmọ ilu lasan wo o.
Oríṣun àwòrán, Tb joshua ministries
Gomina Rotimi Akeredolu sọ pe eekan agbaye ni TB Joshua
O ni lootọ ni wọn ko sin si ilu Arigidi, amọ eekan agbaye ni.
Bakan naa ni ojiṣẹ Ọlọrun kan to wa nibẹ, Bisọbu Steven Ogedengbe lati ipinlẹ Ondo sọ pe ko si pasitọ to ṣe iṣẹ àmì, to si tun le ẹmi eṣu jade bii TB Joshua.
Bi eto isinku Temitope Joshua ṣe lọ
Nibi isin idagbere to kọkọ waye ninu ṣọọṣi, Gomina Akeredolu lo ka ẹkọ Bibeli akọkọ.
Oríṣun àwòrán, TB joshua ministries/facebook
Serah Joshua, ọkan lara awọn ọmọ oloogbe lo ka ẹkọ Bibeli Kẹta
Bakan naa ni awọn ẹgbẹ akọrin ile ijọba ipinlẹ Ondo kọ orin idaraya.
Awọn akọrin ati awọn agbaagba ijọ, to fi mọ awọn ọmọ oloogbe ati iya wọn, Evelyn, lo yi iboji naa ka nigba ti eto isinku n lọ lọwọ.
Bakan naa, aṣọ funfun balau ati gele funfun ni awọn to kopa nibẹ wọ, ti awọn ẹgbẹ akọrin si fi ọja alawọ pọpu ati goolu kọ ọrun wọn.
Ó dùn wá gaan pé wọn kò gbé òkú TB Joshua wá sílé, bó ṣe ọgọ́rùn ún ọdún, a ṣì ń retí - Àwọn ìyàwó ilé
Alawọ funfun paapaa ni posi ti wọn fi sin.
Iyawo ati awọn ọmọ oloogbe, to fi mọ gomina Akeredolu lo kọkọ bu iyẹpẹ si inu iboji naa, ti wọn si tun ju ododo sinu rẹ.
Lẹyin naa ni awọn akọrin ati awọn alakoso ijọ Synagogue to wa nibẹ.
Glorious Twins: Taiwo àti Kehinde Ekundayo ní ọ̀dọ́ ìyá àgbà ní àwọn ti ẹ̀bún orin kíkọ
Yomi Fabiyi Oko Iyabo: Ẹgbẹ́ TAMPAN ti dá Yomi Fabiyi dúró lẹ́yìn tó gbé fíímù Oko Iyabo jáde
Oríṣun àwòrán, yomi fabiyi
Saaju la ti mu iroyin wa fun yin pe apapọ ẹgbẹ awọn oṣere tiata ni Naijiria, TAMPAN ti fofin de Yomi Fabiyi pe ko lọ rọọkun nile na.
Ninu atẹjade ti ẹgbẹ naa fi sita lọjọ Ẹti lo ti kede pe igbesẹ naa waye nitori iwa abuku ati eyi ti ko ba oju mu gẹgẹ bi oṣere ti Fabiyi hu nipa fiimu Ọkọ Iyabọ to gbe jade laipẹ yii.
Fiimu naa to gbe jade ni ọjọ Aiku to kọja da lori ọrọ ẹsun ifipabanilopọ ti wọn fi kan osẹre miran, Baba Ijesha.
'Nínú ìran, Olúwa sọ fún mi pé èmi ni màá tẹ̀síwájú nínú iṣẹ́ ìráńṣẹ́ Wòlìí TB Joshua, kàyéfì ti ń ṣẹlẹ̀ nínú ìjọ mi báyìí'
TAMPAN sọ pe igbesẹ naa waye lẹyin ti oun gbọ awijare Yomi Fabiyi to jẹ olukọtan, olootu ati oludari fiimu naa, ati oludari keji, Ọgbẹni Dele Matti.
"A ri pe wọn jẹbi hihu iwa ti ko bojumu fun akọṣẹmọṣẹ oni tiata.
Yomi Fabiyi ló ni ki òun àti ìyàwó rẹ̀ yàgò fún ra wọn
Awọn alaṣẹ TAMPAN sọ pe botilẹ jẹ pe Ọgbẹni Fabiyi taku pe ẹtọ oun gẹgẹ bi eniyan, ni lati gbe fiimu jade, eyi ti yoo sọ bi nakn ṣe ri gan-an lori iṣẹlẹ ọrọ Baba Ijesha, wọn ni alajọṣiṣẹpọ rẹ gba pe oun jẹbi, to si kabamọ ipa to ko ninu ṣiṣe fiimu naa.
Ninu atẹjade ti ẹgbẹ naa fi si ori Instagram rẹ ni ikede naa ti jade.
Awọn abajade iwadii ati idajọ ẹgbẹ TAMPAN nipa Yomi Fabiyi:
Ọgbẹni Yomi Fabiyi mọọmọ ṣe fiimu naa lai bọwọ fun ilana to de fiimu ṣiṣe, eyi to tumọ si pe o sẹ isẹ naa pẹlu erongba lati da wahala silẹ laarin ilu.
Ti iṣẹ naa (fiimu) kii ba ti i ṣe ti ile Sinima, ẹnikẹni ko ni ẹtọ lati lo orukọ eeyan ti iṣẹlẹ ṣẹlẹ si ninu fiimu. Nitori naa, iwa aibikita ni bi Fabiyi ṣe lo orukọ, ati awọn iṣẹlẹ to waye loju aye, lai gba aṣẹ lọwọ awọn ti ọrọ kan."
"Ìtàn, agbekalẹ itan, ohùn, ọrọ, akori, orukọ, ati gbogbo nkan to nii sẹ pẹlu fiimu ""Ọkọ Iyabọ"" jẹ awsn nkan to ṣẹlẹ, eleyi to le mu ki ojuṣaaju waye lori ẹjọ naa to ti wa ni ile ẹjọ."
Iwa aibikiti to hu ti tabuku si orukọ ẹgbẹ wa.
Ẹni ti wọn jọ dari ere naa, Ọgbẹni Dele Matti, ti fihan pe oun jẹbi, o ti ronu piwada, a si daa duro fun oṣu mẹta pere.
A paṣẹ ki gbogbo ọmọ ẹgbẹ wa to kopa ninu fiimu naa yọju siwaju igbimọ to wa fun yiyanju aawọ ati ilana isẹ wa, ni ọjọ kẹrinlelogun, oṣu Keje, ọdun2021.
Lakotan, ẹgbẹ TAMPAN sọ pe ẹgbẹ awọn eeyan to jẹ ọmọluabi ni oun, ti ko si ni ṣe atilẹyin fun ohunkohun to ba le da wahala silẹ ni awujọ.
Sunday Igboho: Olùrànlọ́wọ́ Sunday Igboho ní ayédèrú n'ìròyìn tó ní Igboho ṣàbẹ̀wò sí Oluwo
Oríṣun àwòrán, Facabook/Koiki Media
Yoruba bọ, wọn ni eti to ba gbọ alọ, o yẹ ko gbọ abọ.
Ọgbẹni Olayomi Koiki to jẹ oludamọran si Oloye Sunday Adeyemo ti ọpọ mọ si Sunday Igboho ti sọ pe iroyin ofege lasan an ni iroyin kan eleyii to ṣafihan bi Igboho ṣe dọbalẹ niwaju Oluwo ti Ile Iwo, Oba AbdulRasheed Akanbi.
Koiki ṣalaye loju opo Facebook rẹ pe Igboho ko ṣe abẹwo si Oluwo gẹgẹ bi fọto to lu ori ayelujara pa ṣe ṣapejuwe.
Lọjọ Abamẹta, ọjọ kẹsan an, oṣu keje ọdun 2021 yii ni Oluwo fi atẹjade kan sita ninu eyi to ti ṣalaye pe oun ti kọwe ranṣẹ si Aarẹ Muhammadu Buhari pe ko darijin Igboho ki awọn ajọ DSS le dẹyin lẹyin rẹ rẹ.
Ninu ẹda iwe naa ti Oluwo fi sọwọ si BBC Yoruba lo ti salaye pe Igboho bẹrẹ isẹ ijijagbara rẹ gẹgẹ bii olugbeja fun awọn alailagbara ni amọ ilana to n tọ ko ye oun.
Oluwo ni oun ko si lara awọn Ọba to n se atilẹyin fun ijijagbara Sunday Igboho rara bi o tilẹ jẹ pe oun maa n kilọ fun pe ko sọra se nigba ti oun ba gbọ nipa igbesẹ to ba fẹ gbe.
O ni Igboho wa si aafin oun lọdun 2018, ti oun si gba ni imọran lori oun to ba wa amọ o kuna lati mọ iyatọ laarin ijijagbara ati kikọju ija si ijọba.
"Nigba to tiẹ ya, se lo n bu gbogbo alẹnulọrọ, to si n fi oniruuru ẹsun kan wọn, emi si ni ẹni akọkọ to ni mo n kọrin fun isọkan Naijiria.
Gẹgẹ bi baba, mo dari jin, bẹẹ naa ni mo si n rọ aarẹ wa ni Naijiria lati si oju aanu wo ọmọ rẹ, Sunday Igboho."
Oluwo ni alaimọkan ni Igboho nidi sise akoso awọn nnkan pẹlu ijọba amọ lootọ lo jẹ ẹbun nla fun ilẹ Yoruba.
Oba AbdulRasheed Akanbi ni Igboho ti jẹjẹ bayii lati maa tẹti si awọn agbaagba, ti yoo si maa sọrase lori awọn igbesẹ to ba n gbe lati akoko yii lọ.
Amọ, oludamọran Igboho ti sọ pe ko si otitọ kankan ninu iroyin naa.
Noah's Ark replica: Wọ́n dá Ọkọ̀ Noah dúró sí èbúté nítorí pé kò dá pé
Wọn ti tọka si ọkọ oju omi kan to dabi ọkọ Noah, pe ko koju oṣuwọn to lati rin lori òkun.
Koda, wọn ti da a duro sibi ebute to duro si.
Ọdun 2019 ni ọkọ naa, ti wọn ti sọ di ibudo nkan iṣẹnbaye ori omi, de si Ipswich.
Awọn alasẹ to n sa mojuto irinajo ori omi sọ pe ọkọ naa ko le kuro nibẹ nitori pe ko gbadun.
BBC ba awọn to ni ọkọ naa sọrọ.
Miliọnu mẹta Pọun ni wọn ra ọkọ oju omi naa.
Ẹni to ni, Aad Peters, to tun jẹ Olootu ere itage ati tẹlifisan ti kọkọ sọ pe oun fẹ ẹ ṣe nkan ti yoo mu ki oniruuru eniyan rí ọ̀rọ̀ sọ.
Oríṣun àwòrán, Bigship BV
Oriṣiriṣi nkan lo wa ninu 'Ọkọ Noah' ọhun.
Awọn ere onigi to n sapejuwe àwọn ìtàn inu Bibeli, to fi mọ Adamu ati Efa, Kaini ati Abeli. Koda, ti ọgbà Edeni wa nibẹ.
"Agbenusọ fun ajọ to n mojuto irinajo ori omi sọ pe ""o di igba ti wọn ba ṣe àtúnṣe awọn abawọn ara Ọkọ̀ Noah, ko to o le kuro nibẹ."""
Oríṣun àwòrán, Bigship BV
O ni àwọn to ni i si gbọdọ ránṣẹ si awọn oṣiṣẹ ajọ naa lati ṣàyẹ̀wò rẹ pe o ti dara.
Sugbọn, ko sọ àwọn aleebu to wa lara ọkọ naa.
Ọdun 2010 ni Ọgbẹni Peters ra ọkọ naa. Oṣu marun-un si ni awọn akọṣẹmọṣẹ fi sọ ọ di ibudo nkan abalaye 'museum', ti igbagbọ wa pe o to ilaji ọkọ Noah ninu Bibeli
Baba Ijesha: Lẹ́yìn tí a gbọ́ àwíjàre lẹ́nu Dele Matti tó jẹ́ olùdarí eré Ọkọ Iyabọ àti Yomi Fabiyi, a ríi pé wọ́n jẹ̀bi- TAMPAN
Oríṣun àwòrán, @Fabiyi
Gbajugbaja oṣere tiata Yoruba, Yomi Fabiyi ti tun fesi si igbesẹ ẹgbẹ oṣere TAMPAN lori bi wọn ti jawe gbele ẹ fun lori fiimu OKO IYABO to gbe jade.
Ninu atẹjade ti ẹgbẹ naa fi sita lọjọ Ẹti lo ti kede pe igbesẹ naa waye nitori iwa abuku ati eyi ti ko ba oju mu gẹgẹ bi oṣere ti Fabiyi hu nipa fiimu Ọkọ Iyabọ to gbe jade laipẹ yii.
Fiimu naa to gbe jade ni ọjọ Aiku to kọja da lori ọrọ ẹsun ifipabanilopọ ti wọn fi kan osẹre miran, Baba Ijesha.
TAMPAN sọ pe igbesẹ naa waye lẹyin ti oun gbọ awijare Yomi Fabiyi to jẹ olukọtan, olootu ati oludari fiimu naa, ati oludari keji, Ọgbẹni Dele Matti.
"A ri pe wọn jẹbi hihu iwa ti ko bojumu fun akọṣẹmọṣẹ oni tiata.''
Alhaja Rukayat Batimoluwasi Oniwaka: Orin Wákà la fi ń ṣe Wáàsí, o tó ọdún 70 tí mo tí bẹ̀
Amọ, Yomi tutọ soke o tun foju gba a ninu ọrọ to kọ soju opo Instagram rẹ ;ọjọ Abamẹta.
Yomi ṣalaye pe oun ko figba kankan jẹ ọmọ ẹgbẹ TAMPAN, koda oun ko ni kaadi idanimọ ọmọ ẹgbẹ ọhun.
Oríṣun àwòrán, Instagram/Yomi Fabiyi
TAMPAN kò lè ní kí fíìmù OKO IYABO má jáde, mi kìí ṣ'ọmọ ẹgbẹ́ wọn- Yomi Fabiyi
O ni ọpọ awọn gbajugbaja oṣere ni ko ni kaadi idanimọ ẹgbẹ TAMPAN lọwọ ti wọn ṣi n ṣere wọn lọ.
''Ẹgbẹ ANTP ni gbogbo wa jọ wa tẹlẹ, asiko ti to bayii lati pada di ọmọ ẹgbẹ ANTP pada.
O dami loju pe inu oloogbe Ogunde yoo dun si eleyii nibi to wa bayii.
Ẹ bami bi awọn ọmọ ẹgbẹ TAMPAN pe ki wọn fi fọọmu ti mo fi darapọ mọ ẹgbẹ naa sori ayelujara ki awọn eeyan rii ki wọn si le mọ bo ya ọmọ ẹgbẹ ni mi.
Fun idi eyi, iwe lọọ rọkun nle ti wọn kọ si mi, mo ti da a pada fun wọn.
Kò sí ẹni tí mo fura sí lórí ikú ọkọ mi, àmọ́..- Adebisi aya Titus Ejanla tí wọ́n pa ní Ib
Ohun ti gbogbo ẹgbẹ awọn oṣere wa fun ni lati maa ja fawọn ọmọ ẹgbẹ ati lati maa wa igbayegbadun ọmọ ẹgbẹ.
Ẹyin TAMPAN, e bi ara yin leere bo ya ẹ n ṣe awọn nkan yii ninu ẹgbẹ.
Lẹta ti ẹ kọ si mi, n ko tiẹ ri tiyin ro rara, o si dami loju pe ẹ mọ daju wi pe ko si ẹni to le dami duro lati maa ṣe fiimu ti mo n ṣe mọ.
Peter Fatomilola: Robbery burú ju Yahoo lọ, iṣẹ́ ọpọlọ lọmọ Yahoo fi ń gba owó ìran baba
Fiimu to dara ni OKO IYABO, ẹ ko si lagbara lati ṣe ayẹwo rẹ gẹgẹ bi ẹ ṣe sọ ninu lẹta ti ẹ kọ si mi.
Ati pe gbogbo awọn awawi yin lori ilana ati ihuwasi ọmọ ẹgbẹ ko ni itumọ kankan.
Mo fẹ sọ fun yin pe fiimu naa yoo pada jade laipẹ ti akoko ba ti to.
Mo si maa ba awọn agbaagba ẹgbẹ TAMPAN kan sọrọ ki n to gbe igbesẹ to kan,'' Yomi lo ṣalaye bẹẹ.
Fisayo Amodemaja: Nínú eré 'Children Day' ní Sọ́ọ̀ṣì ni Abebi ti bẹ̀rẹ̀ eré ṣisṣe- Bukola
Prophet TB Joshua: Ẹ̀gbọ́n tí TB Joshua fi sílẹ̀ lọ àti gbogbo ìlú kọ̀ láti jáde nílé torí ìsìnkú rẹ̀
Alaanu ni TB Joshua jẹ fun wa ni gbogbo ilu Akoko, TB Joshua lo wa tan imọlẹ fun wa nilu Akoko""."
"Ni agbo ile oloogbe Temitope Joshua ni ilu Arigidi Akoko, lasiko ti wọn n ṣe isinku rẹ ni Eko, BBC Yoruba lọ ṣebẹwo lati mọ bi àwọn mọlẹbi ṣe ń daro ọmọ wọn, baba wọn, ẹgbọn wọn, aburo wn ati ẹni ti wọn pe ni ""oludari aye wọn""."
Gẹgẹ bi Akọbi baba rẹ ṣe sọ, o ni idi ti oun ṣe padanu pupọ tori pe TB Joshua ku ni pe o jẹ aburo si oun.
Àbúrò kẹta mi ni TB Joshua àmọ́ Àrólé ẹbí wa ni, oun lo n tọju wa, oun lo n dari aye wa. O ni mọ lo jẹ fun awọn bẹẹ naa lo si tun jẹ baba fun awọn.
Ẹgbọn rẹ yii ko lee jade sita rara tori ko gbudọ foju gaani bi wọn ṣe n gbee bọ inu saare tori ẹgbọn lo jẹ si oloogbe, aṣa Yoruba si ni pe wọn o ki n sin ọmọde loju agbalagba.
Yatọ fun awọn mọlẹbi rẹ, awọn ara ilu kun fọfọ nilee wọn, gbogbo ọja si ni wọn ti pa.
Iyalọja ilu Arigidi ni oloore ati alaanu ni TB Joshua to fọwọ kan aye gbogbo awọn to wa ni ilu rẹ.
Bakan naa, Kabiyesi ilu Arigidi, Ọba Isa Olanipeku to jẹ Zaki ti ilu Arigidi-Akoko bu ẹnu atẹ lu gbogbo awọn Pasitọ Naijiria to n foju aidaa wo TB Joshua ko lee ṣe to nkan to n ṣe. Kabiyesi ni oun le fi gbogbo ẹnu sọ ọ wipe ko si ọrọ afẹ aye lọrọ rẹ ju ko maa ronu bo ṣe le ran awọn eeyan lọwọ.
EndSARS: Mẹ́ta lára àwọn òkú náà ni wọ́n rí he lágbègbè Lekki Toll Gate
Oríṣun àwòrán, Ken Erics Ugo
Igbimọ oluwadii iwa ipa awọn ọlọpaa si awọn araaalu ni ipinlẹ Eko ti tẹwọ gba esi ayẹwọ oku eeyan mọkandilọgọrun run ti wọn ri he kaakiri ilu Eko lasiko iwọde EndSARS.
Awọn oku naa ti wọn ti wa ni ile igbokupamọsi ni wọn ri he kaakiri ipinlẹ Eko laarin ogunjọ, oṣu Kẹwaa ọdun 2020, si ọjọ kẹtadinlọgbọn, oṣu Kẹwaa, ọdun kan naa.
Onimọ sayensi to n ṣayẹwo ara eeyan, Ọjọgbọn John Obafunwa lo fi esi naa le adari igbimọ ọhun, Adajọ Doris Okwobi lọwọ.
Igbimọ naa gba awọn ẹri ọhun ti wọn ko sinu apo meji wọle lẹyin ti agbẹjọro awọn olufẹhonuhan EndSARS, Adeyinka Olumide-Fusika daba pe ki igbimọ ọhun tẹwọ gba awọn eri naa.
Awọn agbejọro atawọn ọmọ igbimọ naa si faramọ igbeṣe naa pẹlu.
Ṣaaju ni igbimọ naa ti kọkọ fiwe pe Ọjọgbọn Obafunwa lati wa ṣeranwọ fun un lori iwadii rẹ nipa iye ẹmi to sọnu lasiko iwọde EndSARS, paapaa ni iloro Lekki Toll Gate.
Àbúrò mi TB Joshua ló ń darí gbogbo ayé wa bó tilẹ̀ jẹ́ àbúrò kẹta si mi - Àkọ́bí ìdílé TB Joshua
Laisko to kọkọ yọju siwaju igbimọ ọhun lọjọ karun un, oṣu Kẹfa ọdun yii ni igbimọ naa ni ko ko awọn eri naa wa siwaju rẹ.
Eyii to mu ki Ọjọgbọn nipa imọ eto ilera, to tun jẹ olukọ to dantọ nile ẹkọṣẹ iṣẹgun ti fasiti ijọba ipinlẹ Eko, LASU, sọ niwaju igbimọ naa pe lootọ ni awọn ti ṣiṣẹ lara awọn oku mọkandinlaadọrun un ọhun.
Oríṣun àwòrán, BBC Hausa
Gẹgẹ bi ohun ti Ọjọgbọn naa sọ, mẹta lara awọn oku naa ni wọn ri he lagbegbe lekki Toll Gate ti awọn mẹtẹta si jẹ ọkunrin, ṣugbọn awọn ko mọ irufẹ ẹni ti awọn oloogbe naa jẹ.
Ko din ni eeyan mẹrinla to ti fẹsun kan ileeṣẹ ọmọ ogun Naijiria atawọn ọlọpaa pe wọn yinbọn pa ọpọ awọn oluwọde EndSARS lasiko iwọde EndSARS naa.
Wọn fẹsun kan awọn agbofinro ọhun pe ọkẹ aimoye awọn miran lo farapa lasiko ti wọn ṣina ibọn bolẹ fun wọn lasiko ti wọn n ṣewọde lodi si iwa ipa awọn ọlọpaa si araalu.
Ijaw Paternity test: Mọ́ síi nípa ìgbàgbọ́ àwọn Ilaje nípa ọmọ ọkọ àti ọmọ àlè
Bo tilẹ jẹ ileeṣẹ ọmọ ogun sẹ pe awọn ko pa ẹnikẹni lọjọ naa lọhun, ileeṣẹ naa ti kọ lati maa yọju siwaju igbimọ naa bayii, ṣugbọn igbimọ ọhun ṣi n ba iṣẹ rẹ lọ.
'Nínú ìran, Olúwa sọ fún mi pé èmi ni màá tẹ̀síwájú nínú iṣẹ́ ìráńṣẹ́ Wòlìí TB Joshua, kàyéfì ti ń ṣẹlẹ̀ nínú ìjọ mi báyìí'
T.B. Joshua: S.K. Abiara sọ̀rọ̀ nípa ìgbésí-ayé T.B. Joshua níbi ìsìn ìdúpẹ́
Oríṣun àwòrán, TB Joshua Ministries
Bi a ba ku laa dere, eniyan ko sunwọn laaye.
Isin idupẹ waye ni ijọ Synagogue Church of All Nations, SCOAN lẹyin isinku oludasilẹ ijọ naa, TB Joshua.
Lara awọn ojiṣẹ Ọlọrun jankan jankan to wa nibi isin idupẹ ọhun ni Alufa ijọ CAC, S.K. Abiara.
Alufaa Abiara sọ ọrọ idupẹ nipa igbesi aye TB Joshua to di oloogbe lẹni ọdun mejidinlọgọta.
Lopin ọsẹ to lọ ni wọn sin oku oludasilẹ ijọ Synagogue Church of All Nations, SCOAN, Wolii Temitope Balogun Joshua.
Ni nkan bi aago mẹta ọsan kọja iṣẹju diẹ ni wọn gbe ara rẹ sinu iboji.
Nibi eto isinku naa to waye ni inu ọgba ijọ rẹ to wa ni adugbo Ikotun nipinlẹ Eko lati ri gomina ipinlẹ Ondo, Rotimi Akeredolu, ati aya Ooni Ile-Ife, Olori Naomi Silekunola Ogunwusi.
Eto isin idagbere lo kọkọ waye ninu ṣọọṣi Synagogue, ko to o di pe wọn gbe oku rẹ lọ si ile ikẹhin ti wọn ṣe si abala kan ninu ṣọọṣi naa.
Nigba to n sọrọ nibi isin idagbere, Gomina Rotimi Akeredolu sọ fun awọn eniyan ilu Arigidi to jẹ ilu abinibi oloogbe, lati mase fi oju ọmọ ilu lasan wo o.
Bakan naa ni ojiṣẹ Ọlọrun kan to wa nibẹ, Bisọbu Steven Ogedengbe lati ipinlẹ Ondo sọ pe ko si pasitọ to ṣe iṣẹ àmì, to si tun le ẹmi eṣu jade bii TB Joshua.
Ẹgbẹ akọrin ile ijọba ipinlẹ Ondo kọ orin idaraya nibi eto isinku Wolii TB Joshua.
Covid-19 3rd wave: Sanwo-Olu ní ọwọ́jà kẹtàa covid-19 ń kan ìlẹ̀kùn ní ìpínlẹ̀ Eko
Oríṣun àwòrán, @SanwoOlu
Ọwọ́jà kẹtàa covid-19 ń kan ìlẹ̀kùn l'Eko, Sanwo-Olu ké gbàjarè
Lẹyin ti wọn ni itankalẹ arun coronavirus ti n lọọlẹ tẹlẹ nipinlẹ Eko, Gomina Babajide Sanwo-Olu ti ke gbajare pe ọwọja kẹtaa arun naa n kanlẹkun gbọngbọn l'Eko.
Gomina Sanwo-Olu ni awọn ibudo itọju awọn alarun covid-19 tun n kun fọfọ sii lẹnu ọjọ mẹta yii.
Ninu ọrọ gomina lọjọ Aiku, Sanwo-Olu ni akọsilẹ fihan pe arun naa tun ti pọ si pẹlu ida marun un ninu ọgọrun un laarin ọsẹ meji to lọ.
Oríṣun àwòrán, Twitter/jidesanwoolu
Ofin tuntun wo ni Sanwo Olu gbe kalẹ?
Sanwo-Olu afaimọ ki ọwọja coronavirus kẹtaa maa ti de ipinlẹ Eko bayii.
Gomina ṣalaye pe eeyan to le lẹgbẹrun lọna ọgọta eeyan ni akọsilẹ fihan pe o ti lugbadi covid-19 nipinlẹ Eko.
Sanwo-Olu ṣalaye pe ẹgbẹrun marun un le laadọta ninu awọn yii lo ti ri iwosan gba.
Gomina ni ida ilaji eeyna ni aaye wa fun lati jọsin ni gbogbo ile ijọsin lasiko yii.
Peter Fatomilola: Robbery burú ju Yahoo lọ, iṣẹ́ ọpọlọ lọmọ Yahoo fi ń gba owó ìran baba
Ọta le lẹẹdẹgbẹrin le mẹwaa ninu wọn lo si n gba itọju lọwọ.
Sanwo-Olu fikun ọrọ rẹ pe lati inu oṣu kẹtaa ni ọwọja keji covid-19 ti bẹrẹ si ni lọọlẹ nipinlẹ Eko.
''Eyi lo jẹ ki ijọba paṣẹ ṣiṣi awọ ileeṣẹ pada lẹyin ti arun naa ti ṣọṣẹ fun bi ọdun kan sẹyin.
Fisayo Amodemaja: Nínú eré 'Children Day' ní Sọ́ọ̀ṣì ni Abebi ti bẹ̀rẹ̀ eré ṣisṣe- Bukola
Ṣugbọn o ṣeni laanu pe pẹlu iṣẹ aṣekara ati igbiyanju wa lati ri pe covid-19 di ohun igbagbe laarin oṣu mẹta sẹyin, o dabi ẹni pe ọwọja kẹta ti n bẹrẹ bayii.
Lati ibẹrẹ oṣu keje ni a ti ṣe akiyesi pe awọn to n ko arun coronavirus nipinlẹ Eko ti n pọ si.
Àbúrò mi TB Joshua ló ń darí gbogbo ayé wa bó tilẹ̀ jẹ́ àbúrò kẹta si mi - Àkọ́bí ìdílé TB Joshua
Bi awọn eeyan to karun naa laarin ọsẹ kan jẹ ohun to n kọ wa lominu,'' Sanwo-Olu ṣalaye.
Ṣaaju ni ajọ to n gbogun ti ajakalẹ arun ni Naijiria, NCDC kede pe awọn ti ri ẹni to ni irufẹ covid-19 SARS-CoV-2 Delta eleyii ti wọn sọ pe o maa n ran julọ.
TB Joshua Burial: Wolii Synagogue SOAN jẹ́ Akàndá ẹ̀dá- Oba Enitan Ogunwusi, Ooni Ile Ife
Information blackout: Àwọn aṣòfin yọwọ́ nínú àbádòfin tí yóò fòfin de àwọn akọ̀ròyìn lẹ́yìn ìfẹ̀hónúhàn àwọn ilésẹẹ́ ìròyìn
Lẹyin ọjọ  méji ti awọn oniwe iroyin Naijiria ṣe ifẹhonuhan lori abadofin ti wọn ni yoo fofin de awọn akọroyin ni Naijiria, awọn aṣofin ti yọwọ lori abadofin naa.
Igbesẹ yii ko ṣẹyin ifẹhonuhan ti awọn ileeṣẹ iroyin kan ṣe kaakiri Naijiria, paapaa niwaju awọn iwe iroyin to lamilaaka Mi ò lè fọwọ́ sí àbádòfin kankan tí yóò fòfin de iṣẹ́ akọ̀ròyìn- Femi Gbajabiamila
Awọn oniwe iroyin naa sọ pe ifẹhonuhan wọn da lori igbesẹ lati ma jẹ ki ijọba maa fofin de awọn lọna ti ko tọ, eyii ti ko ni jẹ ki wọn le ṣiṣẹ wọn bo ti tọ ati bo ṣe yẹ.
"Ọjọ Aje, ọjọ kejila, oṣu Keje ọdun yii ni awọn iwe iroyin naa bẹrẹ si ni ṣe ifẹhonuhan ọhun niwaju awọn iroyin wọn pẹlu akọle ""Information Blackout."""
Wọn n sọ pe abadofin naa kii ṣe ọna lati fofin de awọn akọroyin nikan, ṣugbọn o tun jẹ ọna lati maa ṣakoso irufẹ iroyin ti awọn eeyan yoo maa ni anfani lati gbọ.
Lara awọn iwe iroyin to kopa ninu ifẹhonuhan ọhun ni Punch, Vanguard ati Guardian wa.
Olagunsoye Oyinlola: Kí Olorun dáríjì wá lórí ọ̀rọ̀ yíi, a ti kùnà ìlérí wa fún ìran Yorùb
Ki lo ti ṣẹlẹ sẹyin?
Oríṣun àwòrán, BBC hausa
Agbẹnusọ ile igbimọ aṣoju-ṣofin, Femi Gbajabiamila ti sọ pe oun ko ni lọwọ si abadofin kan to n gbero lati fofin de awọn akọroyin lẹnu iṣẹ wọn.
Gbajabiamila sọ pe irufẹ abadofin bẹẹ ko le di ofin labẹ iṣakoso oun ninu ile naa.
Ṣaaju ni ẹgbẹ awọn to ni iwe iroyin, NPAN, ẹgbẹ awọn ọga agba nidii iṣẹ iroyin, NGE to fi mọ ẹgbẹ awọn akọroyin ti kọkọ ṣe ifẹhonuhan.
Won ṣe e niwaju awọn iwe iroyin kan lodi si abadofin kan ti yoo maa ṣakoso iṣẹ wọn, eyii to kede owo itanra nnkan bii miliọnu marun un naira fun awọn to ba tapa si ofin naa.
Lara awọn iwe iroyin ni Najiiria to lamilaaka to kopa ninu ifẹhonuhan naa niwaju iwe iroyin wọn ni Punch, Vanguard ati Guardian wa.
Oríṣun àwòrán, vanguard
Gẹgẹ bi ohun ti gbajabiamila sọ, awọn yoo ṣe atunṣe awọn abala to n da wahala silẹ ninu abadofin naa, tabi ki wọn yọ abala naa kuro patapata.
Gbajabiamila lo fi ọrọ naa lede lasiko to n sọrọ nibi ayẹyẹ kan niluu Abuja.
Olagunsoye Oyinlola: Kí Olorun dáríjì wá lórí ọ̀rọ̀ yíi, a ti kùnà ìlérí wa fún ìran Yorùb
O ni oun ti ba ẹni to ṣagbatẹru abadofin naa sọrọ, ati pe oun ti ni ki wọn fi ẹda rẹ ṣọwọ si oun fun ayẹwo.
"Agbẹnusọ ile naa ni ""Emi ko ni wa lara awọn eeyan ti yo ṣofin ti yoo fofi de awọn akọroyin."""
O ni ko yẹ ko si abadofin kankan ti yoo wa siwaju ile, eyii ti afojusun rẹ yoo jẹ lati tẹ ẹtọ awọn akọroyin loju mọlẹ lẹnu iṣẹ wọn.
Gbajabiamila pari ọrọ rẹ pe iyatọ wa laarin abadofin ti yoo fofin de awọn akọroyin ati eyii ti yoo maa ṣakoso iṣẹ wọn.
"Lẹyin naa lo ni ""Emi gẹgẹ bii agbẹnusọ ile ko ni gbe ofin kankan kalẹ ti yoo fofin de awọn akọroyin."
Oduduwa republic: Mo kọ̀ láti kópa nínú ìwọ́de Yoruba Nations rally ni Eko- Iba Gani Adams
Ki lo ti ṣẹlẹ?
Awọn ọmọ Naijiria ṣadeedee ji lọjọ kejila oṣu keje ọdun 2021 ri akori iroyin kan naa lori awọn iwe iroyin.
Ki kuku ṣe aṣiṣe, ohun ti ajọ to n ri si ọrọ iwe iroyin ni Naijiria, Press Organisation [NPO] ti pinnu lati ṣe ni.
Ajọ NPO pe e ni ''Information Blackout'' ti o tumọ si ''aisi iroyin'' lati tako ohun ti wọn sọ pe ijọba n gbero lati ominira ati sọrọ awọn akọroyin ti ijọba fẹ tẹ mẹrẹ.
Awọn gbajugbaja iwe iroyin bii Punch, Vanguard ati Guardian lo kọ ninu iwe iroyin pe ohun ti ijọba fẹ ṣe niyii pẹlu atunṣe ofin NPC ati NBC ni lati tẹ ẹtọ awọn akọroyin.
Ẹgbẹ awọn to ni iwe iroyin, NPAN sọ pe ohun ti ijọba fẹ ṣe pẹlu atunṣe ofin yii lati maa fun awọn akọroyin ni faini N.25m nigba tawọn ileeṣẹ iroyin yoo maa san san faini N5m.
NPAN ni awọn akoroyin tiẹ le ri ẹwọn bi ọdun mẹta he.
Ẹgbẹ NPAN ni ifẹhonuhan awọn ileeṣẹ iwe iroyin yoo tẹsiwaju lọjọ kẹtala oṣu keje.
Ẹgbẹ naa ni lọjọ kẹrinla oṣu keje lawọn iwe iroyin yoo ṣalaye ni kikun idi ti wọn fi tako atunṣe ofin NPC ati NBC naa.
Igbimọ NPO ni ijọba fẹ maa ṣe itọpinpin ohun  tawọn iwe iroyin n gbe sita ni wọn fi fẹ ṣe atunṣe ofin to wa nilẹ ọhun.
Oyo insecurity: Ọ̀gá ọlọ́pàá Oyo ní kò sí ohun tó jọ pé Wakili ń gbèrò láti ṣe ìkọlù sí Ibarapa lọ́jọ́ Ileya
Oríṣun àwòrán, Facebook/Ngozi Onadeko
Kọmiṣọnna ọlọpaa ipinlẹ Oyo, CP Ngozi Onadeko ti ṣalaye fun BBC Yoruba ileeṣẹ ọlọpaa ko gbọ ohun kan to jọ pe Iskilu Wakili pẹlu awọn iṣọmọgbe rẹ n gbero lati ṣe ikọlu si ilu Igangan ati agbegbe Ibarapa nipinlẹ Oyo lasiko ọdun Ileya.
Ẹgbẹ OPC ẹka ti ipinlẹ Oyo lo kọkọ ke gbajare pe Wakili n gbero lati kọlu awọn eeyan Ibarapa lasiko ọdun Ileya.
Alaga OPC nipinlẹ Oyo, Rotimi Olumo sọ fawọn akọroyin pe oun wa pẹlu Aarẹ Onakakanfo, Iba Gani Adams nigba ti o gba ipe pe Wakili fẹ ṣe ikọlu si ilu Igbo Ora, Idere, Tapa, Ayete, ati Igangan lasiko pọpọsinsin ọdun ileya.
Olumo wa rọ awọn eeyan ilu naa lati wa lojufo bi wọn ti n ṣe ọdun Ileya.
Alaga OPC nipinlẹ Oyo fikun ọrọ rẹ pe Aarẹ Gani Adams ti sọ fawọn ọmọ ẹgbẹ OPC nipinlẹ Oyo lati ri pe erongba Wakili atawọn eeyan rẹ ko wa si imuṣẹ.
Kọmureedi Olumo ni OPC ti wa lojufo lati ri pe erongba Wakili ko ni wa si imuṣẹ lagbegbe Ibarapa.
Olumo ṣalaye siwaju si pe nkan to buru jai ni pe awọn ọmọ ẹgbẹ OPC mẹta to mu Wakili dero atimọle ọlọpaa ki wọn to pada fi wọn silẹ.
Alaga OPC tun ke si awọn ọba alade legbegbe Ibarapa lati fẹnuko ki wọn si kọju si awọn Fulani darandaran to n da agbegbe Ibarapa laamu.
Ṣugbọn nigba to n ba BBC Yoruba sọrọ, CP Onadeko ni iroyin naa ko ti dọwọ ileeṣẹ ọlọpaa ipinlẹ Oyo.
Kọmiṣọnna ọlọpaa Oyo ni wamu wamu lawọn ọlọpaa duro lati ri pe awọn janduku to ba fẹ da rogbodiyan silẹ foju wina ofin.
O ni ileeṣẹ ọlọpaa ko figba kankan fi ọrọ abo nipinlẹ Oyo ṣere.
''Ko si ohun to jọ bayẹn lagbegbe Ibarapa nipinlẹ Oyo, awa ọlọpaa gan an wa ni ṣẹpẹ fun ẹnikẹni to ba fẹ huwa ọdaran.
Wo ìlú kan ní Italy tó ṣetán láti fún ọ ní N13.6 mílíọ̀nù tí o bá gbà láti gbé níbẹ̀
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Iroyin ayọ fawọn ọmọ Naijiria to fẹ lọ ṣiṣẹ aje tabi gbe loke okun.
Awọn ọdọ to ba ni owo kan tabi omiran lati ṣe ti wọn si ṣetan lati fi ilu wọn silẹ lọ orilẹede Italy yoo jẹ ẹbun owo tabua.
Ẹkun Calabria lorilẹede Italy ti ṣeleri lati fun ẹnikẹni to ṣetan lati maa gbe abule naa ni owo to le ni miliọnu mẹtala ati aabọ, N13.6m( ($33,000) laarin ọdun mẹta.
Abule Calabria wa ni bebe okun, awọn eeyan ilu naa ko si ju ẹgbẹrun meji lọ.
Pipe awọn eeyan lati wa maa gbe nibẹ jẹ ọkan lara ọna ti ijọba Italy fẹ gba lati jẹ ki eeyan to wa ni ilu naa gberu sii.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Calabria village for South of Italy
Kansilọ ẹkun kan ni Italy, Gianluca Gallo sọ fun CNN pe awọn eeyan to ba ṣetan lati wa maa gbe ilu naa yoo maa gba owo oṣu to to 800-1,000 owo Euro.
O ṣalaye pe wọn yoo gba owo yii fun bi ọdun mẹta tabi ki wọn gba owo naa lati fi da okowo kan tabi ile ọunjẹ tabi oko silẹ.
Amọ, N13.6 million ($33,000) ti wọn fẹ fun awọn eeyan kii ṣe ọfẹ lo ba de o.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Wọn ọna ti o le fi di ẹni amuyẹ fun anfaani yii.
O gbọdọ ṣetan lati bẹrẹ okowo tabi lati ṣiṣẹ nibẹ gẹgẹ bi akọsẹmọṣẹ.
Iru awọn akọṣẹmọṣẹ ti wọn n wa niluu naa ni iwọnyii:
"Thunder strike on Jaipur tower: Bí àrá ṣe sán pa èèyan 16 tó ń ya ""Selfie"" rèé"
Oríṣun àwòrán, NurPhoto
Ara nla to lagbara ti ko sẹni to mọ ibi to ti wọ́ wa ti san pa awọn ọpọlọpọ eeyan ni ilu Jaipur lọjọ isinmi ọsẹ
"Awọn to fo ṣanlẹ ku yii korajọ lati ya fọto ara wọn ti oloyinbo n pe ni ""Selfie"" lode oni eyo to tumọ si wipe ki eeyan kọ oju foonu sira eeyan lati ya a."
Pabanbari ni pe inu ojo ni wọn yan lati ya selfie naa koda wọn tun ko ara wọn jọ lori oke tente ile gogoro kan to jẹ ibi igbafẹ pataki ni Jaipur, orilede India.
Bakan naa ni iroyin tun kan ọpọ awọn mii naa ku lasiko ti ara san ni ipinlẹ Uttar Pradesh ati Madhya Pradesh.
Eeyan to to ẹgbrun meji ni itan sọ pe ara maa n san pa ni India lọdọọdun gẹgẹ bu akọsilẹ.
Ọga Ọlọpaa kan sọ fun awọn oniroyin pe ọpọ ninu awọn to ku lori oke tente ile iṣọ giga naa lo jẹ ọdọ.
Ara san pa eeyan 16 ninu ṣọọṣi ni Rwanda
Kíni ọ̀nà àbáyọ si ọ̀rọ omíyale ni Naijiria?
Àgbàrá òjò gbé alága àdúgbò àti èèyàn méjì mìí lọ nílùú Ibadan
Bàbá ọlọ́mọ méjì kú sínú àgbàrà òjò
Oduduwa republic: Mo kọ̀ láti kópa nínú ìwọ́de Yoruba Nations rally ni Eko- Iba Gani Adams
Awọn mẹtadinlọgbọn lo kora wọn jọ sori oke ile ọhun nigba ti iṣẹlẹ naa ṣẹlẹ ti iroyin si ni awọn kan dede fo bọ silẹ latoke giga nigba ti wọn gburo ara.
Ni ipinlẹ Uttar Pradesh, iroyin o kere tan eeyan mọkanlelogoji ti ọpọ wọn jẹ obinrin ati ọmọde lo fo ṣanlẹ ku tori ara to san.
Jẹjẹ lawọn ọkunrin meji kan n gbatẹgun lab igi kan, loju ẹsẹ ni wọn ku nigba ti ara naa kọ ṣàrà ni ilu Firozabad. Awọn mii naa ku lawọn igun ilu naa mii.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ara
Awọn akọṣẹmọṣẹ ni idi ti iye awn to ku ṣe pọju ni ipinlẹ mejeji ni pe ọpọ eeyan nib lo n ṣiṣẹ nita yala ni ẹka ọgbin tabi awọn to n kọ ile.
Minisita agba ti kede owo gba ma binu fun awọn idile to ni eeyan lara awọn to ku.
Wọ́n o wa tii ri nkankan ni India ni ti ojo rirọ tori pe igba ti ojo maa n ṣe hii hii ju ni laarin oṣu kẹfa si ikẹsan eyi ti ko si tii kasẹ nilẹ.
Akọsilẹ ni iha ipinlẹ southern state of Andhra Pradesh fihan pe ara 36,749 lo lee san laarin wakati mẹtala.
Awọn akọṣẹmọṣẹ si ni o maa n wọpọ lawọn agbegbe ti ewe ibora igi wọn ko nipọ eyi to si n ṣi awọn eniyan si ewu ki ara maa san pa wọn.
Ki ni o le sare ṣe lasiko ti ara ba n san?
Orisun: Royal Society for the Prevention of Accidents
Governor Inuwa Yahaya: Ìjọba Gombe kọ́ iléẹ̀kọ́ sí ẹgbẹ́ àwọn iléeṣẹ́ elétò aàbò láti kojú àwọn ajínigbé
Oríṣun àwòrán, others
Gomina Yahaya ni ijọba oun n kọ awọn ileẹkọ nla nla naa si ẹgbẹ awọn ibudo awọn ẹṣọ alaabo lati dẹkun ijinigbe awọn akẹkọo ̣nipinlẹ naa.
Ijọba ipinlẹ Gombe ni awọn ti bẹrẹ si ni kọ awọn ileẹkọ to ga soke lati le gba ọpọlọpọ awọn akẹkọọ si lati dẹkun ijinigbe ojoojumọ.
Gomina ipinlẹ Gombe, Muhammad Inuwa Yahaya lo sọ bẹẹ ni Ọjọ Aje lasiko to n ṣepade pẹlu adari oṣiṣẹ aarẹ Buhari, Ibrahim Gambari ni ileeṣẹ Aarẹ ni ilu Abuja.
Gomina Yahaya ni ijọba oun n kọ awọn ileẹkọ nla nla naa si ẹgbẹ awọn ibudo awọn ẹṣọ alaabo lati dẹkun ijinigbe awọn akẹkọo ̣nipinlẹ naa.
Bakan naa lo ni ijọba oun gbe igbesẹ naa lẹyin ti wọn ṣewadii ijinigbe ni agbegbe naa, ati ọna abayọ lati da abo bo awọn akẹkọọ nipinlẹ naa.
''A ṣe ayẹwo awọn ileẹkọ wọnyii ati bi awọn ajinigbe ṣe ni anfaani lati wọ ibẹ ati awọn igbesẹ lati koju ipenija wọnyii ni awọn ileẹkọ.''
Oríṣun àwòrán, others
''Lẹyin naa ni a bẹrẹ si ni kọ awọn ileẹkọ nla nla fun awọn akẹkọọ lati le ko wọn jọ pọ sibẹ, paapaa awọn ti awọn ajinigbe ti ṣekọlu si ileẹkọ wọn tẹlẹ, ti ati pada si ileẹkọ si di iṣoro fun wọn.''
Royal Hugs Surprises: Ìyá ẹni ọdún 50 tó dọlọ́mọ láyé fi ìdùnnú hàn bí a ṣe kàn síi- Debor
Gẹgẹ bi ọrọ gomina naa, agbegbe ti ipinlẹ Gombe wa laarin awọn ilu to wa ni ila-oorun ariwa orilẹede Naijiria, mu ki awọn ipenija aisi eto aabo to n ba wọn finra ni awọn agbegbe yii wọnu ilu Gombe.
Olagunsoye Oyinlola: Kí Olorun dáríjì wá lórí ọ̀rọ̀ yíi, a ti kùnà ìlérí wa fún ìran Yorùb
Bakan naa ni Gomina ohun fikun pe awọn n ṣiṣẹ pọ pẹlu awọn lọbalọba, to fi mọ awọn adari ẹsin ki ibaṣepọ to dan mọran le wa laarin awọn araalu.
Oduduwa republic: Mo kọ̀ láti kópa nínú ìwọ́de Yoruba Nations rally ni Eko- Iba Gani Adams
Gomina ipinlẹ Gombe naa ni oun dupẹ pe alaafia jọba nipinlẹ naa ati wi pe awọn araalu gbọ ara wọn ye lai si rogbodiyan tabi wahala kankan.
Traditionalist Oba Ogun: Oba Tejuosho ìlú tí wọn bá ti yọwọ awọn oniṣẹṣe kuro ninu oba jijẹ ko le roju raye
Oríṣun àwòrán, Oba Adetokunbo Tejuoso
Oba Dr Adetokunbo Okikiola Tejuosho, Olu Ile Kenta ti sọ fawọn oniṣẹṣe pe ijọba ko le yọwọ laelae ninu eto ifinijọba gẹgẹ.
Awọn ẹgbẹ oniṣẹṣe ẹka ti ipinlẹ Ogun ti kepe igbimọ aṣofin ipinlẹ naa yọwọ ninu abadofin ti yoo maa ṣakoso awọn lọbalọba nipinlẹ naa.
Amọ nigba to n ba BBC Yoruba sọrọ, Oba Tejuosho ni oniṣẹṣe kọ lo n yan ọba, ijọba lo n ti n yan ọba lati ọjọ to ti pẹ
''Mo bọwọ fawọn oniṣẹṣe, amọ  nkan to yẹ ki ifẹhonuhan da le lori ni pe ki ijọba maa bawọn sọrọ lori ọrọ ọba jijẹ
Kabiesi orile Kemta nipinlẹ Ogun ni: Kii ṣe oni lo ṣẹṣẹ bẹrẹ ti ijọba ti n yan ọba.
O yẹ ki wọn sọ pe ki ijọba maa bun wọn gbọ nipa ọrọ awọn lọbalọba ni, nitori ijọba ko le yọwọ ninu ifinijoye,'' Oba Tejuosho lo sọ bẹẹ.
Oríṣun àwòrán, others
Bakan naa ni Oba alade ọhun tun sọ pe ''ko si bi ijọba ṣe fẹ yọwọ awọn oniṣẹṣe naa ninu eto ifinijọba.
Ibeju Lekki Free Trade Zone: A ti bí ọmọ tó lọ Fásitì tí kò rí iná ọba rí- Olawale Eleto
Ijọba gan an mọ pe awọn etutu wa ti eeyan gbọdọ ṣe ki o to jọba.
Ti wọn ba yọwọ oniṣẹṣe tabi awọn eletutu ninu ọba jijẹ, ilu ko le roju raye.''
Peter Fatomilola: Robbery burú ju Yahoo lọ, iṣẹ́ ọpọlọ lọmọ Yahoo fi ń gba owó ìran baba
Oba Tejuosho tun bu ẹnu atẹ lu awọn eeyan kan to maa pada si ẹsun kristẹni tabi musulumi lẹyin ti wọn ba jọba tan.
O ni ''ẹni to ba jọba ni ṣọọṣi tabi mọṣalaaṣi ko gba ile ijọsin lọ to ti jọba lọ.
Oduduwa republic: Mo kọ̀ láti kópa nínú ìwọ́de Yoruba Nations rally ni Eko- Iba Gani Adams
Kabiesi ni: ke le jọba tan ki o wa sọ pe o di pasitọ tabi aafa.
Iṣẹṣe la n bọ ki awọn ẹsin ajeji to de,'' Oba Tejuosho lo sọ bẹẹ.
Oríṣun àwòrán, Af24news
Àwọn oníṣẹ̀ṣe ń fẹ́ kí ìjọba yọ ọwọ́ nínú Ọba yíyàn ní ìpínlẹ̀ Ogun
Àwọn oníṣẹ̀ṣe ń fẹ́ kí ìjọba yọ ọwọ́ nínú Ọba yíyàn ní ìpínlẹ̀ Ogun
Awọn oniṣẹṣe ni ipinlẹ Ogun ti ke si ile igbimọ aṣofin ipinlẹ naa lati yọwọ rẹ ninu abadofin kan to da lori bi wọn ṣe n yan ọba, awọn baalẹ, oloye atawọn igbimọ lọbalọba nipinlẹ ọhun.
Wọn ni ki awọn aṣofin ọhun dawọ iṣẹ duro lori abadofin naa ti yoo fun ijọba lagbara lati maa ṣakoso bi wọn ṣe  yan ọba nitori kii ṣe iṣẹ wọn.
Agbẹnusọ awọn oniṣẹṣe nipinlẹ ogun, Ifayemi Osunlabi sọ fun awọn akọroyin niluu Abeokuta pe ti abadofin naa ba le di ofin, yoo pa awọn etutu kan ti wọn maa n ṣe fun awọn to ba fẹ jẹ ọba ni ipinlẹ naa rẹ.
Osunlabi sọ pe ẹnikẹni to ba fẹ jẹ ọba ni lati tẹle gbogbo awọn alakalẹ iṣẹṣe to wa nilẹ lati igba iwasẹ wa.
O ni ti wọn ba ṣe aṣeyọri ninu gbigbe ofin naa kalẹ tan, yoo tẹ ẹtọ awọn oniṣẹṣe mọlẹ, o si ṣeeṣe ko da wahala silẹ laarin ilu.
Ẹnikẹni to ba ti jẹ Ọba ti di igbakeji oriṣa, irufẹ ẹni bẹẹ si ni lati tẹle awọn aṣa ati iṣẹṣe kan to ti wa nilẹ tipẹtipẹ.
Olagunsoye Oyinlola: Kí Olorun dáríjì wá lórí ọ̀rọ̀ yíi, a ti kùnà ìlérí wa fún ìran Yorùb
Ifayemi Osunlabi wa ke si awọn aṣofin naa lati dawọ isẹ duro lori abadofin naa ki alaafia le jọba ni ipinlẹ Ogun.
O fi kun pe ofin ọhun yoo da wahala silẹ nipinlẹ Ogun, eyii ti yoo ṣoro lati yanju lọjọ iwaju.
Gẹgẹ bii hun to sọ, ko si ohun to kan awọn aṣofin pẹlu ọrọ iṣẹṣe ati bi wọn ṣe n yan ọba ilu.
O pari ọrọ rẹ pe ọdun to kọja ni wọn kọkọ dabaa ofin naa ṣugbọn awọn oniṣẹṣe tako o, awọn ko si ni gba ki abadofin ọhun di ofin ni igbẹyingbẹyin.
Oduduwa republic: Mo kọ̀ láti kópa nínú ìwọ́de Yoruba Nations rally ni Eko- Iba Gani Adams
Nigeria security, Kaduna Kidnapping: Ó kéré tán, ajínigbé ti pa èèyàn 222 láàrìn oṣù mẹ́ta ní Kaduna- Gomina El Rufai
Oríṣun àwòrán, other
Obinrin mẹsan an ati ọmọde mẹjọ wa ninu awọn ti agbebọn pa nipinlẹ Kaduna.
O kere tan eniyan to le ni igba ti padanu ẹmi wọn laaarin Oṣu Kẹrin si Oṣu Kẹfa, ọdun 2021
Ninu atẹjade ti ijọba ipinlẹ Kaduna fi lede ni wọn ti sọ wi pe eniyan to le ni ẹẹdẹgbẹrin ni awọn ajinigbe ti jigbe lọ nipinlẹ naa.
Ninu atẹjade ti ẹka eto aabo nipinlẹ naa gbe jade ni wọn ti fi lede pe eniyan 239 ninu awọn ti wọn jigbe naa jẹ ọbinrin ti mejilelọgbọn si jẹ ọmọde.
Obinrin mẹsan ati ọmọde mẹjọ wa ninu awọn ti wọn pa.
Peter Fatomilola kìí ṣe agbódegbà Yahoo, Ó ń fẹ́ kí ìjọba, Òbí àti ilé ìjọsìn ṣe ohun tó y
Iye awọn ti wọn farapa ninu ijamba naa le ni igba eniyan (266), ti mejidinlogun ninu wọn si jẹ obinrin ati ọmọde marun un.
Bakan naa ni ifipabanilopo waye ni ipinlẹ ogun kaakiri orilẹede Naijiria, ti mẹtala ninu wọn si jẹ ọmọde.
Ibeju Lekki Free Trade Zone: A ti bí ọmọ tó lọ Fásitì tí kò rí iná ọba rí- Olawale Eleto
Awọn ẹṣọ alaabo ninu atẹjade naa ni awọn gbiyanju lati pa awọn agbebọn mẹtadinlaadọrun, ti awọn si fi panpẹ mu eniyan mẹrinlelogun ninu wọn laarin oṣu mẹta naa.
Olagunsoye Oyinlola: Kí Olorun dáríjì wá lórí ọ̀rọ̀ yíi, a ti kùnà ìlérí wa fún ìran Yorùb
Bakan naa ni wọn ji ẹgbẹrun mẹjọ maluu gbe laarin asiko yii, ti wọn si pa eniyan ẹẹdẹgbẹta laarin Oṣu Kini,ọdun 2021 si Osu kẹta, ọdun 2021.
Ijọba ipinlẹ Kaduna fikun pe ijinigbe yii ti ba ọrọ aje ipinlẹ naa jẹ, ti awọn agbẹ si ti kuro ni oko nitori oro oko wọn ti awọn agbebọn ti bajẹ.
Tunde Gbadamosi: Kìí ṣe Tinubu ní ipò ààrẹ̀ tọ́ sí, ìgbà wo ní ìtan ajá ń kan lèmọ́mù?
Bakan naa ni ijọba ni awọn n tiraka lati koju iṣoro eto aabo to dẹnukọlẹ naa, ti gbogbo igbiyanju wọn si n gberasoke ju ti tẹlẹ lọ.
Ẹwẹ, Ileeṣẹ ọlọpaa nipinlẹ Kaduna ni awọn ẹsọ alaabo amuṣẹya ni awọn ti doola ẹmi akẹkọọ kan ninu awọn mọkanlelọgọfa ti wọn ti gbe lọ.
'Èmi gan máa ń béèrè lọ́wọ́ ara mi pé ta ni Wole Soyinka gangan'
Èèyàn 2,371 ni wọ́n jí gbé, N10biliọnu owó ìtúsílẹ̀ làwọn ajínigbé gbà lóṣù mẹ́fà àkọ́kọ́ ọdún 2021
Àbájáde ìwádìí ní èèyàn 2,371 ni wọ́n jí gbé, N10biliọnu owó ìtúsílẹ̀ làwọn ajínigbé gbà lóṣù mẹ́fà àkọ́kọ́ ọdún 2021
Laarin oṣu kini si ikeje ọdun 2021, ẹgbẹrun meji o le ọdunrun ati mọkanlelaadọrin lawọn eeyan ti awọn ajinigbe ti ji gbe kaakiri awọn ipinlẹ mẹrẹẹrindinlogoji to wa lorilẹ-ede Naijiria.
Oríṣun àwòrán, other
Ajọ aṣewadi nipa ọrọ aje ti orukọ rẹ n jẹ SBM Intelligence lo kede eyi loju opo ayelujara rẹ.
Ajọ naa ni eyi jẹ abajade iwadi kan eyi ti wọn ṣe lori wahala ati ipenija abo lorilẹede Naijiria.
Gẹgẹ bi abajade iwadi naa tun ṣe yọju rẹ sita, ipinlẹ Niger, Katsina ati Kaduna lo n gbegba oroke niti iṣẹlẹ ijinigbe lorilẹ-ede Naijiria.
Nigba ti iwadi naa wa n gbe owo to rọ mọ ijinigbe naa yẹwo, o ni titi di ọgbọn ọjọ oṣu kẹfa ọdun 2021, biliọnu mẹwaa naira lawọn eeyan ti san gẹgẹ bii owo itusilẹ fun awọn eeyan wọn ti wọn ji gbe laarin asiko naa.
Oríṣun àwòrán, @SBM Intelligence
Ilakalẹ abajade iwadi wọn naa tun sọ di mimọ pe losu keji ọdun 2021 nikan eeyan marunlelẹgbẹta (605), ẹẹdẹgbẹta o le mẹrinlelọgbọn ni awọn ajinigbe ji gbe loṣu kẹta, ọtalelọọdunrun o din mẹta ni oṣu marun un.bakan naa lo fi han pe ojilelẹgbẹta ati mẹta 643 ni wọn ji gbe ni ipinlẹ Niger ti wọn si pa mejidinlọgọta.
Tunde Bakare: Àjọjẹ kò dún bẹ́nìkan kò ní ló fa ìjà S Igboho,bẹ́ẹ̀ ìjọbati gbẹ́rù kọjá orí
Okoolelẹẹdẹbẹta o din ẹyọkan (519) ni wọn ji gbe ni Zamfara ti mejilelogun si ku.
Ni ipinlẹ Kaduna ọtalelọdunrun ni wọn ji gbe, mọkanlelogoji leyan to jade laye nipasẹ iṣẹlẹ ijinigbe nibẹ.
Agbekalẹ awọn ipinlẹ yoku niwọnyii: Abia (6), Abuja (50), Adamawa (3), Akwa Ibom (2), Anambra (14), Bauchi (3), Bayelsa (7), Benue (6), Borno (1), Cross River (4), Delta (51), Ebonyi (5), Edo (18), Ekiti (14), Enugu (15).
Bakan naa, ipinlẹ Eko (6), Nasarawa (44), Ogun (26), Ondo (17), Osun (23), Oyo (61), Plateau (10), Rivers (14), Sokoto (10), Taraba (46), ati Yobe (4) Gombe (1), Imo (25), Jigawa (2), Kano (3), Katsina (236), Kebbi (81), Kogi (31) ati Kwara (10).
.
Royal Hugs Surprises: Ìyá ẹni ọdún 50 tó dọlọ́mọ láyé fi ìdùnnú hàn bí a ṣe kàn síi- Debor
Super TV CEO Ataga: Chidinma ò gbudọ̀ kú o sátìmọ́lé Ọlọ́pàá o! Àwọn aṣòfin f'ọ̀rọ̀ ráńṣẹ́ sí Ọ̀gá àgbà Ọlọ́pàá
Oríṣun àwòrán, Usifo Ataga
Ile igbimọ aṣojuṣofin ti fi ọrọ sita pe afurasi ti wọn ni o pa oludari ileeṣẹ Tẹlifisan Super TV, Usifo Ataga ko gbudọ ku si atimọle awọn ọlọpaa Naijiria.
Bakan naa, ile aṣojuṣofin tun ni ki wọn ṣe iwadii ati ayẹwo finifini lori ẹsun naa ki wọn si ma ṣafihan arabinrin Chidinma kiri mọ tabi ki wọn maa gbaa laye lati ba awọn oniroyin sọrọ lori ọrọ ti wọn ṣi n ṣewadii rẹ lọwọ.
"Ile aṣofin ni ki Ọga agba awọn ọlọpaa, Usman Baba ""pe gbogbo awọn ọlọpaa ko ki wọn nilọ pe ko si atunṣe iru iwa ipa yii lori ẹtọ ọmọniyan ati gbigba awọn ti wọn ba fi panpẹ ofin mu laaye lati ba awọn oniroyin sọrọ."
"Wọn n sọ eyi gẹgẹ bi ọkan lara awọn afẹnuko wọn nibi ijoko ile to waye lọjọ Iṣegun lẹyin ti wọn jọ pa ohun pọ lori ọrọ ti wọn lo gba amojuto kiakia ti aṣoju Tolu Akande-Sadipe mu aba rẹ wa to pe akori rẹ ni ""Bi Ọlọpaa ṣe n tẹle ofin ijọba apapọ ati iwadi kikun lori iku oloogbe Ọ̀gbẹ́ni Usifo Ataga."
Gẹgẹ bi awọn aṣofin ṣe sọọ, eyi jẹ lati rii daju pe wọn ṣiṣẹ lori awọn ẹsun mii lọjọ iwaju bi eleyii.
Lafikun, ile aṣojuṣofin ni ọga agba ọlọpaa gbudọ rii daju pe arabinrin Ojukwu ti wọn fẹsun kan ko ku si ahamọ tabi pa ara rẹ nigba to n duro de idajọ rẹ gẹgẹ bo ṣe ti ṣẹlẹ sẹyin lori awọn ẹsun kan to ti kọja.
Ọjọ kẹrinlelogun oṣu kẹfa ọdun 2021 ni ileeṣẹ ọlọpaa Eko ṣafihan oju Chidinma nigba to jẹwọ pe oun lo n gun Ataga ẹni aadọta ọdun naa lọbẹ lọrun pa lẹyin gbọnmi sii omi o to.
Chidinma tun tun eyi sọ ninu ifọrọwanilẹnuwo to ba awọn oniroyin kan sọ.
Ẹwẹ, ninu fidio kan to wa gba ori ayelujara kan lọjọ Aje ni arabinrin Chidinma Ojukwu ti bẹrẹ si ni sọ pe oun kọ loun pa ọga ileeṣẹ Super TV.
Nigba to da aba lọjọ Iṣegun, Aṣofin Akande-Sadipe muu wa si iranti ile pe lati igba ti ọlọpaa ti mu arabinrin Chidinma ni wọn ti n ṣafihan oju rẹ kiri ti wọn si n jẹ ko ba awọn oniroyin sọrọ lori ọrọ to wa di  ohun ti wọn n gba bi ẹni n gba igba ọti lori ayelujara bayii ti awn oniroyin wa brẹ si ni pin ọrọ naa yẹlẹ yẹlẹ.
Gbogbo eleyi naa n ṣẹlẹ pẹlu pẹlu pe ọlọpaa ṣi n ṣe iwadii lọwọ.
Olagunsoye Oyinlola: Kí Olorun dáríjì wá lórí ọ̀rọ̀ yíi, a ti kùnà ìlérí wa fún ìran Yorùb
Ile aṣofin mọ wi pe ofin orilẹede Naijiria ko faaye gba ki ori ayelujara maa sọrọ nipa ẹsun kan nigba ti ile ẹjọ ko ba tii ṣe ipinu rẹ - ko yẹ ki awọn oniroyin maa sọrọ nipa rẹ.
O fi kun un wipe ni abala ikẹrindinlogoji ka ikarun ti iwe ofin Naijiria ti ọdun 1999 ti wọn ti tun ṣe fihan pe gbogbo ẹnikẹni ti ofin ba ti gbe ni wn yoo maa pe ni ko mọwọ ko mẹsẹ titi ti ile ẹjọ yoo fi sọ pe o jẹbi ẹ́un ọhun.
Tori naa wọn ni arabinrin Ojukwu ko tii jẹbi ẹsun to n jẹjọ rẹ lọwọ ko yẹ ki wọn maa foju ọdaran wo o tabi ṣafihan rẹ kiri titi di igba ti iwadii yoo gunrege tori naa ki wọn gba ileeṣẹ laye lati ṣe iṣ wọn.
Buhari meets with senators: Ààrẹ Buhari ń ṣèpàdé pẹ̀lú àwọn sẹ́nétọ̀ 109 lálẹ́ ọjọ́ Iṣẹ́gun
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ààrẹ Muhammadu Buhari yoo sepade lalẹ ọjọ Isẹgun pẹlu awọn seneto Naijiria mokandinlaadota pẹlu jije ounje ale pò nílé ààrẹ l'Abuja.
Ìkede ipàdé yìí tí yóò kó awon asofin ile igbimo asofin agba ati Asoju sofin jade ninu leta ti ile asofin ko eyi ti aare ile asofin agba, Ahmed Lawan ka sì eti igbo gbogbo ile.
Ni ojo ketadinlogbon osu kerin ni awon asofin fẹnuko pe kí adari ile ṣe eto ipade náà láti jo jiroro lori oro abo to n ba Naijiria fúnra.
"Leta naa ka pe ""mo n kọ ìwé yìí láti sí aare ile igbimo asofin agba pe aare Muhammadu Buhari yóò se Ipade pelu awon seneto Naijiria ni ojó Isegun, ojo ketala osu keje odun 2021 ni dede agogo mejo ale."
Ìpàdé yìí ni ìròyìn ni yóò wáyé ní gbongan apeje ni ile aare to wa ni Abuja.
Ẹ o maa ri ẹ́kunrẹrẹ iroyin nipa ipàde naa ka nibi to ba ti waye.
Sunday Igboho: Gani Adams ní àwọn tó yí Igboho ká ló ṣíṣẹ́ pọ̀ pẹ̀lú DSS tó kọlu ilé rẹ̀
Oríṣun àwòrán, Gani Adams ati Sunday Igboho
Aarẹ Ọnakakanfo ilẹ Yoruba, Iba ganu Adams ti sọ pe awọn eeyan to sun mọ Sunday Igboho lo maa jẹ ko rọrun fawọn ajọ ọtẹlẹmuyẹ DSS lati ṣe ikọlu si ile rẹ lagbegbe Soka niluu Ibadan.
Aarẹ ni Ọlọrun n bẹ bi ti atijọ, awọn eeyan ni ko sin Baba bi ti atijọ mọ.
Gani Adams ni oogun si wa nilẹ Yoruba bi ti atijọ, ṣugbọn bi awọn ajijagbara ṣe n ṣe nkan si ara wọn lawọn agbofinro naa n ṣe.
Aarẹ ni awọn ọmọ Yoruba naa lo n ṣe oogun fawọn agbofinro.
''Gẹgẹ bi ohun tawọn eeyan n sọ, ohun ti mo gbọ ni pe babalawo mẹta lo tẹle awọn ajọ DSS lọ ṣe ikọlu si ile Igboho loru.
Ohun ti mo gbọ nio, mi o mọ bo ya otitọ ni tabi irọ.
Oduduwa republic: Mo kọ̀ láti kópa nínú ìwọ́de Yoruba Nations rally ni Eko- Iba Gani Adams
Nigba ti wọn jade tan, ẹnikan tun pe wọn pe ki wọn lọ ko awọn ologbo rẹ.
Wọn ro pe bo ya awọn ologbo yẹn lo fi n ṣe agbara, eyi tumọ si pe awọn to yi Sunday Igboho ka lo maa ṣiṣẹ pọ pẹlu awọn DSS lati mu un.
Wọn tun pa eeyan bii meje nile rẹ ṣugbọn wọn ni meji lawọn pa.
Olagunsoye Oyinlola: Kí Olorun dáríjì wá lórí ọ̀rọ̀ yíi, a ti kùnà ìlérí wa fún ìran Yorùb
Ṣugbọn ati oku ati aye awọn ti wọn pa wọn gbe gbogbo wọn lọ.
Oku awọn adigunjale nikan ni awọn agbofinro lẹtọọ lati gbe lọ kii ṣe okun awọn ajijagbara.
Àbúrò mi TB Joshua ló ń darí gbogbo ayé wa bó tilẹ̀ jẹ́ àbúrò kẹta si mi - Àkọ́bí ìdílé TB Joshua
Ohun to buru pupọ ni, gbogbo awa ọmọ Yoruba ni a bu ẹnu atẹ lu bi ajọ DSS ṣe kọlu ile Sunday Igboho,'' Gani Adams lo ṣalaye bẹẹ.
O ni Igboho tẹlẹ gira gira diẹ pẹlu awọn iwọde to ṣe lori ipe fun idasilẹ Yoruba, amọ agba wa bura bi ewe o ba ṣe ọ ri ni ọrọ Igboho.
Aarẹ ko bẹsu bẹgba lati sọ pe oun si wa lori ẹsẹ oun lori idasilẹ Yoruba Nation.
Royal Hugs Surprises: Ìyá ẹni ọdún 50 tó dọlọ́mọ láyé fi ìdùnnú hàn bí a ṣe kàn síi- Debor
LGBT+ gay men arrested: Ọkùnrin márùn-ún tó jọ ń ṣe kerewà bọ́ sọ́wọ́ Ọlọ́pàá ẹ̀sìn Islam
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ọlọpaa ẹsin Islam ni ipinl Kano ti fi panpẹ ofin mu ọkunrin marun kan ti wọn fi ẹsun kan pe wọn n ni ibalopọ akọsakọ.
Ẹgbẹ ọlọpaa ẹsin Islam ni awọn mu awọn ti wọn furasi naa pe wọn n ba ara wọn lopọ lasiko ti wọn n ṣiṣẹ dọdẹ kiri ni ibi ipamọ kan to wa ni agbegbe Kumbotso lẹyin ti awọn araalu ibẹ fi ẹjọ sun.
Ipinlẹ Kano jẹ ọkan lara awọn ipinlẹ ẹkun Ariwa Naijiria to n lo ofin Islam tabi Sharia papọ mọ ti orilẹede Naijiria.
Ninu ofin mejeji, ibalopọ akọsakọ tabi abosabo lodi si ofin.
Awọn alaṣẹ ni afurasi ni awọn ọkunrin naa pe awọn si n ṣe iwadii lọwọ. Bi wọn ba rii pe wọn jẹbi, wọn lee fi ẹwọn to to ọdun mẹrinla jura ni ilana ofin ilẹ Naijiria.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ni Naijiria, igbesẹ akin lo wade lati fi panpẹ ofin mu awọn to ba n ni ibalopọ ẹ̀dà kan náà eyi ti wọn n pe wọn lawọn orilẹede mii ni LGBT.
Lọdun 2014 ni ijọba tun gbe ofin kan jade ti wọn kede rẹ pe bi obinrin ba n ba ara wọn lopọ tabi ọkunrin lo n ṣe iru ẹ, iwa ọdaran ati arufin gidi ni.
'Èmi gan máa ń béèrè lọ́wọ́ ara mi pé ta ni Wole Soyinka gangan'
Latari eyi, ninu oṣu kẹjọ ọdun 2018, awọn ọlọpaa orilẹede Naijiria mu ọkunrin mẹtadinlọgọta ti wọn jẹ afurasi onibalopọ akọsakọ amọ wọn pada tu wọn silẹ pẹlu beeli.
Olagunsoye Oyinlola: Kí Olorun dáríjì wá lórí ọ̀rọ̀ yíi, a ti kùnà ìlérí wa fún ìran Yorùb
Yoruba movie: Kìí ṣe Iya Esabod tó fẹ máa fi wa pawo lóríi YouTube rẹ ló má máa da ẹgbẹ TAMPAN rú
Oríṣun àwòrán, Google
Gbajugbaja osere onitiata, Olu Olowogemo ti ọpọ mọ sí Mr. Portable ti da fi oko ọrọ ranṣẹ sí gbajugbaja sọrọ sọrọ ori ayelujara, Esther Aboderin to tun n jẹ Esabod lori bo ṣe ni oun(Esabod) gan lo n da aarin awọn oṣere ru.
Portable ni ninu Fidio ti oun kọkọ ṣe jáde, òun o fẹ ki wọn si oun gbọ rárá tori kii ṣe pe oun ni bi ààrẹ ẹgbẹ TAMPAN ìyẹn Mr Latin tori onirẹlẹ ati olufẹ alafia ni latile.
"Amọ ọ ni ""iya to n yeye awọn agbalagba iṣẹ tiwa, Esabod ni mo n bá wi""."
Portable ni oun mọ Latin dáadáa gẹgẹ bí ẹni tó nífẹẹ alafia, o ni apa ibẹ yẹn gangan ni ọta fẹ fi wọlé síi lara. Tori naa ki awọn èèyàn ma ri ààrẹ àwọn gẹgẹ bí ẹni tí kò dára tàbí tí kò mọ ọrọ sọ.
Ojú tí mo fẹ kee fi woo ni wí pé ọnà ibi tí wọn fẹ fi ko ààrẹ mi ni papamora lati le da ọgbọn ba nkan jẹ mọ ọ lọwọ.
Portable ni awọn mọ pe o to oye yẹn jẹ láti ọjọ tí àwọn ti fi je é.
Ṣe ni Portable dari ọrọ rẹ taara lọ sọdọ arabinrin Esther Aboderin (Esabod)  pe ko dẹkun láti máa yẹyẹ awọn agbalagba ẹgbẹ TAMPAN.
Gìrì àparò lásán ni gbogbo èpè wọn! àwọn tó ń ti Toyin Abraham lẹ́yìn rèé lórí ìjà tó paá pọ́ mọ́ Lizzy Anjorin ati ESABOD
Lẹ́yìn ọdún méjì tí iná ìjà tí n jó láàrin wọn, Lizzy Anjorin sọ àwọn ẹ̀ṣẹ̀ tí Toyin Abraham ṣẹ̀ ẹ́
Bí àwọn gbajúmọ̀ ṣe pín rèé lórí ọ̀rọ̀ Baba Ijesha
Ẹ̀ṣọ́ ìyàwó Gómìnà Ekiti Bisi Fayemi bọ́ sọ́wọ́ ọlọ́pàá lórí ẹ̀sùn ìfipábánilòpọ̀ l'Abuja
Àfinra! Ẹ wá máa lọ ilé ẹ̀yin akẹ́kọ̀ọ́ títí di ọjọ́ wájú, a ti ti ìbugbé ilé ẹkọ́ pa torí Covid-19 - Fásitì Unilag
Ti ẹgbẹ wa tabi iṣẹ wa ba ni problem, kii ṣe Iya Esabod tó n wa nkan to máa mu oju òpó YouTube rẹ gboro lati ri ounjẹ jẹ ló má wa máa parí ìjà ẹgbẹ wa.
O ni ti àwọn ba ríi pé ipá àwọn o kaa mọ, awon agbalagba inu ẹgbẹ mọ awọn to ye ki wọn pe lati wa pari aawọ aarin awọn. O ni kii se eeyan tó jẹ pe pipa ni lerin bíi tàwọn loun naa fi ni jẹun ni yóò máa wá pari ija.
Portable ni oun gbọ pé ìyá Esabod maa n ṣepe, o si máa n fún Gbogbo èèyàn lesi tori náà oun n reti èsì lọdọ rẹ.
O koro oju sí bo ṣe ni o ni dótì awọn àgba ẹgbẹ to jẹ pe awọn eeyan bọwọ fún tẹlẹ.
Oríṣun àwòrán, Mr Portable/Mr Latin
Gbajugbaja oṣere tiata Yoruba, Olu Olowogemo Arijan, ti ọpọ eeyan mo si Mr. Portable ti bu ẹnu atẹ lu awọn olori ẹgbẹ awọn oṣere tiata, TAMPAN, lori awuyewuye to n lọ lọwọ ninu ẹgbẹ naa.
O fi kun un pe awọn kan ti sọ iṣẹ́ tíátà di ibi tí wọ́n tí ń polówó iṣẹ́ aṣẹ́wó.
O ni oju gba oun ti fun ẹgbẹ ọhun, paapaa awọn adari wọn bi wọn ko ṣe le yanju awọn rogbodiyan to n ba ẹgbẹ naa finra lasiko yii.
Mr. Portable lo sọ ọrọ naa ninu fidio kan fi ledeloju opo Instagram rẹ.
Gẹgẹ bii ohun to sọ, awọn oṣere jẹ ẹgbẹ kan ti awọn araalu maa n bu iyi fun lawọn asiko kan sẹyin, ṣugbọn ọrọ ko ri bẹẹ mọ bayii.
"O ni ""Awọn eeyan maa n pọn wa le tẹlẹ nitori a maa n mu inu awọn araalu dun, ṣugbọn ẹgbẹ naa ti wa di ẹgbẹ ti awọn kan n ṣoro si abuku si bayii."""
Onikaluku ti n ṣe ohun to wu wọn bayii lai si ọwọ fun awọn agbalagba, ẹyin ti ẹ wa jẹ ọga wa naa ẹ wa jokoo, ẹ wa n wo wa niran.
Gbajumọ osẹre naa bu ẹnu atẹ lu Aarẹ TAMPAN, iyẹn Mr Latin, lori bo ṣe gba lati ṣe ifọrọwerọ pẹlu obinrin kan ti orukọ rẹ n jẹ Esabod lori opo Instagram.
Ibeju Lekki Free Trade Zone: A ti bí ọmọ tó lọ Fásitì tí kò rí iná ọba rí- Olawale Eleto
Obinrin Esabod naa jẹ gbajumọ laye ara rẹ, ṣugbọn ọpọ eeyan ni ko gba tirẹ nitori irufẹ awọn ọrọ kabiti-kabiti to maa n n sọ lori afẹfẹ.
"Mr Portable ni ""Aarẹ ẹgbẹ wa lọ ṣe ifọrọwerọ pẹlu Esabod lati wọ orukọ ẹgbẹ wa nilẹ nibi to ti n tọrọ aforiji ni orukọ Jide Kosoko."""
Oríṣun àwòrán, mrportableharejan
Ninu erongba Mr Portable, ẹgbẹ awọn oṣere lagbara lati da seria fun ọmọ ẹgbẹ to ba tasẹ agẹrẹ lai lọ tọrọ aforiji ni gbangba, paapaa niwaju ẹni ti ki ṣe ọmọ ẹgbẹ naa.
"O ni ""Aarẹ wa n kawọ pọ lati rojọ niwaju Esabod to jẹ pe isọkusọ lo maa n sọ lori ayelujara."""
Ta ni Esabod yii gan... bawo ni ti ẹ ṣe jẹ!
Olagunsoye Oyinlola: Kí Olorun dáríjì wá lórí ọ̀rọ̀ yíi, a ti kùnà ìlérí wa fún ìran Yorùb
Oṣere ọhun ni iṣe gidi ni iṣẹ tiata tẹlẹ, ṣugbọn wọn ti sọ iṣẹ naa di eyii ti wọn fi n polowo iṣẹ aṣẹwo bayii.
Mr. Portable pari ọrọ rẹ pe ko bojumu ki awọn kan maa n yẹyẹ awọn agba oṣere.
Lẹyin naa lo ke si awọn adari ẹgbẹ TAMPAN lati ṣe atunṣe.
Oduduwa republic: Mo kọ̀ láti kópa nínú ìwọ́de Yoruba Nations rally ni Eko- Iba Gani Adams
Buhari Kano visit: Aarẹ Muhammadu Buhari yóò gúnlẹ̀ sí Kano láti fi ìpìlẹ̀ ojú ọna irin lélẹ̀
Oríṣun àwòrán, @Kano Govt
Oju ọna irin tuntun yi ni ireti wa pe yoo tun lọ lati Kaduna si Abuja, ati Abuja si ipinlẹ Eko.
Ipinlẹ Kano jẹ pataki ibi ọrọ aje ni Naijiria, nibi ti awọn eeyan jakejado orilẹ-ede Naijiria ati agbaye ti n ṣe katakara.
Ọjọ ti pẹ ti awọn eeyan kan nipinlẹ naa ti n kùn pé Aarẹ Buhari, ti pa Kano tì lati igba to ti de ipo, botilẹ jẹ  pe awọn ṣe atilẹyin nla fun nigba to du ipo aarẹ.
Àmọ́, awọn kan ti woye pe ipilẹ oju ọna irin ti Buhari fẹ ẹ wá ṣe fihan pe ko gbagbe awọn eniyan ipinlẹ naa.
Okunade Sijuwade: Ìfẹ́ tí Sarun tó súnmọ́ Ooni jù láyé ní sí í ló sọ ọ́ di abọ́bakú- Adeye
Aarẹ Buhari yoo tun sí àwọn akanse isẹ ti Gomina ipinlẹ naa, Abdullahi Umar Ganduje ṣe.
Oríṣun àwòrán, femi Adesina
Oríire ńlá ló jẹ́ fún àwọn ọmọ Naijiria pé orílẹ̀-èdè yìí ṣì wà ní ọ̀kan ṣoṣo- Buhari
Gbogbo agbára mi ni mo máa fi sin Naijiria
Buhari pari ọrọ rẹ pe ajọṣepọ laarin gbogbo ẹka ijọba atawọn araalu nikan lo le mu idagbasoke ba Naijiria.
Oduduwa republic: Mo kọ̀ láti kópa nínú ìwọ́de Yoruba Nations rally ni Eko- Iba Gani Adams
Aarẹ Muhammada Buhari ti sọ pe oriire nla lo jẹ fun awọn ọmọ Naijiria pe orilẹ-ede naa ṣi wa ni ọkan ṣoṣo bo tilẹ jẹ pe o n dojukọ oniruru iṣoro.Ààrẹ Buhari ń ṣèpàdé pẹ̀lú àwọn sẹ́nétọ̀ 109 lálẹ́ ọjọ́ Iṣẹ́gun
Oríṣun àwòrán, @Presidency
Buhari lo sọ ọrọ naa lasiko to n tẹwọgba esi apero kan lori eto abo Naijiria nile aṣoju-ṣofin.
Agbẹnusọ ile naa, Femi Gbajabiamila lo ko awọn akẹgbẹ rẹ kan sọdi lati fi esi naa le Aarẹ lọwọ.
Nigba to n sọrọ, Buhari sọ pe oun ti pinnu lati sin Naijiria pẹlu gbogbo okun ati agbara oun, ati pe eredi ree ti oun fi ṣabẹwo si gbogbo ipinlẹ mẹrindinlogoji to wa ni Naijiria lasiko ipolongo ibo lọdun 2015.
Ẹwẹ, Aarẹ tun ti sọ fun awọn ọmọ ile igbimọ aṣofin agba pe ijọba oun ti ṣetan lati lo gbogbo agbara ti wa ni ikawọ oun lati fopin si eto aabo to mẹhẹ.
Oríṣun àwòrán, Femi adesina
O tun ni oun a fi ṣikun ofin mu gbogbo awọn to wa nidi awọn ikọlu to n waye kaakiri Naijiria.
Aarẹ lo sọ ọrọ naa lasiko wẹjẹ-wẹmu kan pẹlu awọn aṣofin naa nile rẹ niluu Abuja.
Ibeju Lekki Free Trade Zone: A ti bí ọmọ tó lọ Fásitì tí kò rí iná ọba rí- Olawale Eleto
Agbẹnusọ Aarẹ, Femi Adesina sọ ninu atẹjade kan pe eto abo to mẹhẹ, ikọlu awọn janduku, ijinigbe atawọn iwa ọdaran mii ni iṣoro ti ijọba to wa lode yii n dojukọ julọ.
O ni eto abo to mẹhẹ ko gba ijọba laaye lati ṣe awọn ohun amayedẹrun to lọkan ni lati ṣe fun awọn araalu.
"Buhari sọ pe ""Pupọ ninu awọn to n ṣiṣẹ ibi naa n ṣe lati pa owo si apo ara wọn, awọn miii si n ṣe wọn lati fun ijọba ni orukọ buburu."""
Ṣugbọn ko ni ṣe eredi ti wọn fi n da rogbodiyan silẹ laarin ilu, ohun ti a mọ ni pe iwa wọn n mu ifaṣeyin ba orilẹ-ede yii.
Ojuṣe wa gẹgẹ bii ijọba ni lati ri daju pe a ṣe gbogbo ohun to yẹ ninu agbara wa lati jẹ ki wọn foju wina ofin, ki wọn ma si mu oju wa kuro ni awọn afojusun wa gẹgẹ bii ijọba.
Buhari pari ọrọ rẹ pe ajọṣepọ laarin gbogbo ẹka ijọba atawọn araalu nikan lo le mu idagbasoke ba Naijiria.
Olagunsoye Oyinlola: Kí Olorun dáríjì wá lórí ọ̀rọ̀ yíi, a ti kùnà ìlérí wa fún ìran Yorùb
Ladipo Spare parts Market: `ijọba ìpínlẹ̀ Eko ti ti Ọjà Ladipo pa
Awọn alaṣẹ ti ile itaja naa lati tako ifẹhọnuhan to waye ni ọja naa ni Ọjọ Iṣẹgun, Ọjọ Kẹrinla, Oṣu Keje, ọdun 2021.
Awọn alaṣẹ ti ti ọja Ladipo ti wọn ti n ta ẹya ara ọkọ pa ni ipinlẹ Eko, lorilẹede Naijiria.
Awọn ọlọja ni ọja naa lo kọlu awọn soja, amọ ko si ẹni to  le e sọ ohun to fa ija wọn.
Ọkan lara awọn ọlọja nibẹ sọ fun BBC pe ẹmi eniyan kan lọ si iṣẹlẹ naa, ti awọn mẹta to farapa si wa ni ileewosan.
Awọn alaṣẹ ti ile itaja naa lati tako ifẹhọnuhan to waye ni ọja naa ni Ọjọ Iṣẹgun, Ọjọ Kẹrinla, Oṣu Keje, ọdun 2021.
Ọja Ladipo ni ọja kan pato ti wọn ti n ta ẹya ara oko ni ipinlẹ Eko nitori ko si ọkọ to yọnu ni ilu Eko ti kii ṣe ọja Ladipo ni wọn ma n gbe lọ.
Awọn ti ọrọ naa ṣẹlẹ ni oju wọn sọ wi pe ohun to fa ija ni awọn onibara to wa ra ọja ni ibẹ, amọ to wa da pada ni ọjọ keji pe ko dara.
Eleyii ko ba ọlọja naa lara, to si fa ija, eleyii to mu ki onibara naa lo mu awọn soja wa, ti wọn si wa da ibẹ ru.
Iroyin nipe awọn ọmọogun ofurufu lo wa sibẹ lati wa fa rogbodiyan naa.
Titi di asiko yii, ọja naa wa ni titi pa.
Wọ́n ní Ìyá Esabod yẹn ma ń ṣépè, fi òṣèré wọ́lẹ̀, mò ń retí èsì yín sí ọ̀rọ̀ tí mo fi síta yìí - Mr Portable
Àfinra! Ẹ wá máa lọ ilé ẹ̀yin akẹ́kọ̀ọ́ títí di ọjọ́ wájú, a ti ti ìbugbé ilé ẹkọ́ pa torí Covid-19 - Fásitì Unilag
Ẹ̀ṣọ́ ìyàwó Gómìnà Ekiti Bisi Fayemi bọ́ sọ́wọ́ ọlọ́pàá lórí ẹ̀sùn ìfipábánilòpọ̀ l'Abuja
Sunday Igboho, Akintoye àtàwọn míràn fa Buhari, Malami àtàwọn míì lọ síwájú ilé ẹjọ́ àgbáyé ICC
Peter Fatomilola kìí ṣe agbódegbà Yahoo, Ó ń fẹ́ kí ìjọba, Òbí àti ilé ìjọsìn ṣe ohun tó y
Lasiko ti a kọkọ ti a kọkọ ko iroyin yii jọ, awọn eeyan kan ti jade laye nipasẹ iṣẹlẹ ọhun.
Awọn eeyan kan n fi iye awọn to ku si mẹta nigba ti awọn miran n sọ pe marun un ni wọn.
"Gẹgẹ bi oniṣowo kan lọja naa ṣe sọ,  ""Awọn ṣọja kan wa sibi ni wọn si bẹrẹ si ni yinbọn si wa."""
Gẹgẹ bi iroyin tun ṣe fi idi rẹ mulẹ, ọpọlọpọ lo ṣeṣe.
Olagunsoye Oyinlola: Kí Olorun dáríjì wá lórí ọ̀rọ̀ yíi, a ti kùnà ìlérí wa fún ìran Yorùb
Iroyin abẹle fidi rẹ mulẹ pe ija naa bẹẹ silẹ laarin awọn ọmọ ogun ikọ alaabo Operation MESA atawọn janduku kan lagbegbe naa ti wọn n ja tikẹẹti. Eyi lo ṣokunfa bi awọn ọmọ ogun ṣe ṣi ina ibọn bolẹ.
Bakan naa lawọn kan tun sọ pe, oṣiṣẹ ileeṣẹ ọmọogun ofurufu NAF kan lo yinbọn lẹyin edeaiyede kan pẹlu awọn oniṣowo kan nibẹ lori ọja kan to ra.
Ibeju Lekki Free Trade Zone: A ti bí ọmọ tó lọ Fásitì tí kò rí iná ọba rí- Olawale Eleto
Ija bẹ silẹ lọmọ ogun naa ba rasnṣẹ pe awọn akẹgbẹ rẹ.
Amọṣa agbẹnusọ ileeṣẹ ọmọ ogun ofurufu, Ọgagun Edward Gabwet ṣalaye fawọn oniroyin kan pe ipe pajawiri kan lawọn ọmọ ogun ti wọn wa ni ikọ Operation MESA gbọ ti wọn lọ dahun si pe wahala kan bẹ silẹ laarin awọn ọmọ ogun oriilẹ kan ati ajigbese kan.
Oduduwa republic: Mo kọ̀ láti kópa nínú ìwọ́de Yoruba Nations rally ni Eko- Iba Gani Adams
Lọja lawọn oniṣowo kan ti kọlu wọn pẹlu okuta.
Bakan naa lawọn ọmọogun oriilẹ ni iwadi ti nlọ lori iṣẹlẹ naa.
'Èmi gan máa ń béèrè lọ́wọ́ ara mi pé ta ni Wole Soyinka gangan'
Yoruba Nation agitation: Sunday Igboho, Akintoye àtàwọn míràn fa Buhari, Malami àtàwọn míì lọ síwájú ilé ẹjọ́ àgbáyé ICC
Oríṣun àwòrán, other
Adari ẹgbẹ Ilana Ọmọ Oodua Ọjọgbọn Banji Akintoye, aṣiwaju ipe fun idasilẹ orilẹede Yoruba ti pe Buhari lẹjọ.
Akintoye, Sunday Igboho atawọn ẹgbẹ ajijagbara ilẹ Yoruba mọkandinlaadọta ti fọwọsi iwe ẹhonu oloju ewe mẹtadinlọgbọn kan ti wọn gbe tọ ile ẹjọ agbaye, ICC lọ.
Gẹgẹ bi ohun ti iwe iroyin ojoojumọ ilẹ wa ni awọn ri gba gẹgẹ bi iroyin, Amofin Aderẹmi Ọmọjọla lo fi iwe ẹhonu naa ranṣẹ lorukọ wọn.
Ninu iwe ẹhonu naa, wọn fi ẹsun pipa awọn ọmọ Yoruba ni ipinlẹ Ekiti, Ọṣun, Ondo, Ogun, ati ilẹ Okun ni ipinlẹ Kogi ati Kwara kan awọn adari Naijiria kan.
Lara awọn ti wọn pe lẹjọ ni Aarẹ Muhammadu Buhari, minisita feto idajọ Abubakar Malami, olori ileeṣẹ ọmọ ogun oriilẹ tẹlẹ, Tukur Buratai atamọ ọga agba ọlọpaa tẹlẹ bii Ibrahim idris ati Muhammed Adamu.
Oduduwa republic: Mo kọ̀ láti kópa nínú ìwọ́de Yoruba Nations rally ni Eko- Iba Gani Adams
Awon miran ni: Olori ileeṣẹ aṣọbode Hammid Alli, Ọga ọlọpaa Alkali Baba, olori ileeṣẹ ọmọogun ilẹ Farouk Yahaya, olori ileeṣẹ ọmọogun ofurufu tẹlẹ, Sadiq Abubakar,
Oríṣun àwòrán, others
Olagunsoye Oyinlola: Kí Olorun dáríjì wá lórí ọ̀rọ̀ yíi, a ti kùnà ìlérí wa fún ìran Yorùb
Awon mii ni: olori ajọ sifu difẹnsi tẹlẹ Ahmed Audi, ọgaagba ileeṣẹ wọle wọde Naijiria, Mohammed Babandede pẹlu olori ajọ sifu difẹnsi bayii, Abdullahi gana Muhammadu.
'Èmi gan máa ń béèrè lọ́wọ́ ara mi pé ta ni Wole Soyinka gangan'
Iwe ẹhonu naa fi ẹsun kan awọn eeyan naa pe wọn lọwọ si pipa awọn ọmọ ẹgbẹ ajijagbara to pẹjọ naa, wọn si ṣe wọn leṣe.
Nibayii ileẹjọ agbaye ICC ni awọn ti tẹwọ gba iwe ẹhonu naa.
Femi Falana: Ọwọ́ tí Buhari fi mú mú ọ̀rọ̀ Kanu àti Igboho jọ èyí tí wọ́n fi mú olóṣèlú kan lọ́dún 1984
Oríṣun àwòrán, Cool FM 96.9 Kano
Ajafẹtọ ọmọniyan ati agbẹjọro agba, Femi Falana ti sọ pe awọn igbesẹ ti Aarẹ Naiijiria n gbe yoo da Naijiria pada si ọdun 1984, ṣugbọn awọn araalu ko ni gba fun.
Falana lo sọ ọrọ naa nibi ijiroro kan lati sami si ayẹyẹ ọjọ ibi ọdun mẹ́tàdínláàdọ́rùn ún Ọjọgbọn Wole Soyinka loke eepẹ.
Agbẹjọro naa ṣo pe ọwọ ti ijọba Buhari fi mu ọrọ Nnamdi Kanu ati Sunday Igboho farajọ eyii ti wọn lo lati fi ji oloṣelu kan gbe lọdun 1984.
"O ni ""Ko yẹ ki a gba Buhari laaye lati da wa pada si ọdun 1984 bii igba ti wọn gbiyanju lati ji Umaru Diko gbe ni London."""
Wọn ti ji Diko gbe tan lọdun naa lọhun, ṣugbọn ara adugbo kan lo figbe ta lasiko ti wọn n gbe lọ si papakọ ofurufu.
Ibeju Lekki Free Trade Zone: A ti bí ọmọ tó lọ Fásitì tí kò rí iná ọba rí- Olawale Eleto
Falana ṣalaye pe o ṣeeṣe ko jẹ pe ṣe ni wọn kun Nnamdi Kanu loorun ki wọn to gbe wa si Naijiria nitori ijọba Kenya ko le ṣalaye pe awọn finu-findọ fa Kanu le ijọba Naijiria lọwọ.
O ni irọ ni awọn to sọ pe ọna to ba ofin mu ni wọn fi gbe Kanu wa si Naijiria n pa.
Olagunsoye Oyinlola: Kí Olorun dáríjì wá lórí ọ̀rọ̀ yíi, a ti kùnà ìlérí wa fún ìran Yorùb
Ajafẹtọ naa fikun pe eremọde lasan ni awọn to ni ki awọn araalu má ṣe ifẹhonuhna n sẹ nitori ironu awọn ologun lo wa ninu ọpọlọ wọn.
O sọ siwaju si pe Buhari ti gbagbe pe awọn ti gbe Aarẹ Olusegun Obasanjo lọ sile ẹjọ lọdun 2003 ri, lẹyin ti Obasanjo tu iwọde kan ti Buhari ti kopa ka, ti Buhari si jare lati ile ẹjọ ọhun.
O ni ile ẹjọ naa sọ pe ko ba ofin mu ki eeyan kọkọ lọ gba iwe aṣẹ lọwọ ọlọpaa ko to ṣagbatẹru iwọde tabi kopa ninu iwọde kankan, ati pe awọn eeyan to ti gba ominira ko nilo iwe aṣẹ ọlọpaa kankan ki wọn to ṣe iwọde.
Peter Fatomilola: Robbery burú ju Yahoo lọ, iṣẹ́ ọpọlọ lọmọ Yahoo fi ń gba owó ìran baba
Falana ni eredi ree ti awọn fi gbogun ti ile igbimọ aṣofin lati ṣe ofin tuntun kan to sọ pe awọn araalu ko nilo lati fi to ileeṣẹ ọlọpaa leti ki wọn to ṣe iwọde, ayafi ki wọn wa pese eto abo fun wọn, kii ṣe lati gba aṣẹ.
Ekiti rape case: Ẹ̀ṣọ́ ìyàwó Gómìnà Ekiti Bisi Fayemi bọ́ sọ́wọ́ ọlọ́pàá lórí ẹ̀sùn ìfipábánilòpọ̀ l'Abuja
Oríṣun àwòrán, FACEBOOK/KAYODE FAYEMI
Ileeṣẹ ọlọpaa olu ilu orilẹede Naijiria, Abuja ti fi ọwọ sinkun ofin mu ọkan lara awọn ẹṣọ iyawo gomina ipinlẹ Ekiti, Erelu Bisi Fayemi.
Ẹsun ti wọn fi kan ẹṣọ naa ni pe o fipa ba obinrin lopọ niluu Abuja lọjọ karun un oṣu keje.
Kọmiṣọnna eto idajọ ipinlẹ Ekti, Olawale Fapohunda lo fọrọ naa lede loju opo Facebook ipinlẹ Ekiti.
Fapohunda ṣalaye pe ẹka ileeṣẹ ọlọpaa Abuja to n ri si ẹsun iwa ọdaran ti bẹrẹ iwadii lori iṣẹlẹ naa.
Kọmiṣọnna eto idajọ ipinlẹ Ekti sọ pe ipinlẹ Ekiti yoo ṣiṣẹ pọ pẹlu ileeṣẹ ọlọpaa Abuja lori iṣẹ iwadii wọn.
''Ọmọbinrin ti iṣẹlẹ yii ṣẹlẹ si ti n gba itọju ati atilẹyin to nilo bayii.
Bakan naa a ko fẹ ki ẹnikẹni mọ ọmọbinrin naa lati le daabo bo o ki o maa ba di ojuti fun un.
Ijọba Ọmọwe Kayode Fayemi yoo maa tẹsiwaju lati tako iwa ifipabanilopọ nipinlẹ Ekiti.
Amọ, ijọba nilo iranlọwọ awọn araalu lati maa sọrọ soke lori iwa ifipabanilopọ ki ijọba le gbe igbesẹ ni kiakia.
Ajumọṣe gbogbo wa ni ọrọ ti o wa nilẹ yii,'' Fapohunda lo sọ bẹẹ.
Ẹwẹ, ijọba ipinlẹ Ekiti ti gbe eeyan mọkanlelọgọfa lọ si ileẹjọ lori ẹsun ifipabanilopọ.
Kọmiṣọnna eto idajọ ipinlẹ Ekti ni igbẹjọ ti n lọ lọwọ lori awọn ẹsun naa.
O fikun ọrọ rẹ pe awọn eeyan ti ẹbi wọn sẹtan lati gbaruku ti ijọba lori ṣiṣe ẹjọ ni ijọba n ṣe ẹjọ wọn.
Ugieki Asemota: Wọ́n fẹ̀sùn kan Emmanuel pé ó lu ìyàwó rẹ̀ pa nílùú Benin nítórí ó kọ ìbálòpọ̀
Oríṣun àwòrán, OTHER
Ọmọbinrin kan niluu Benin nipinlẹ Edo, Ugieki Asemota, ti dero ọrun ọsan gangan, lẹyin ti ọkọ rẹ, Emmanuel lu u pa nitori ko gba ki o ba ni ibalopọ.
Iwe iroyin Punch jabọ pe ede-ai-yede ṣẹlẹ Emmanuel ati Ugieski lọjọ kejidinlọgbọn oṣu kẹfa to lọ nile wọn to wa ni opopona Abaegbe lagbegbe Evbotubu niluu Benin.
Ohun ti a gbọ ni pe Ugieki wọ yara rẹ lọjọ ti a n wi yii, o si ti ilẹkun mọri ko maa ba si ija laarin oun ati ọkọ rẹ.
Ṣugbọn iroyin sọ pe Emmanuel ni o gbọdọ ṣi ilẹkun, nigba to kọ ti ko ṣi ilẹkun lo bẹrẹ si ni lo aakee lati fi ja ilẹkun mọ lori.
A gbọ pe Ugieki gbiyanju lati gba oju ferese jade nigba to ri pe ọkọ rẹ ti fẹ ja ilẹkun mọ ọn lori.
Amọ, nibi ti o ti n gbiyanju lati gba oju ferese sa lọ ni Emmanuel ti lọ ka a mọ bẹ ti o si bẹrẹ si ni lu u ni alubami titi ti o fi daku.
Victoria Omoruyi to jẹ arabinrin Ugieki ṣalaye pe ile iwosan meji ni ko gba Ugieki nigba ti wọn n gbe e kiri.
Omoruyi ni igbeyawo Ugieki ati Emmanuel kun fun ija ni gbogbo igba ati iwa ipa.
O ṣalaye siwaju sii pe Emmanuel ati Ugieki ti n ja tẹlẹ ṣaaju ọjọ ti iṣẹlẹ naa ṣẹlẹ.
O ni ni gbogbo igba ni ọkọ rẹ maa n lu u ni aluki.
''Ṣugbọn lalẹ ọjọ ti a n wi yii, Emmanuel fẹ ba a ni ibalopọ, amọ Ugieki ni ko maa lọ si yara rẹ jẹjẹ nitori oun ko fẹ wahala.
Amọ ni bi ago mejila oru ni Emmanuel bẹrẹ si ni kan ilẹkun mọ ọn lori ki o to bẹrẹ si ni lo aakee lati jẹ ilẹkun.
Ugieki bẹ Emmanuel nigba ti o n lu pe ẹmi oun ti fẹ bọ, ṣugbọn ko gbó, afigba to lu u debi pe ko le sọrọ mọ.
O gba itọju nile iwosan fun ọjọ dẹ ki o to jẹ Ọlọrun nipe,'' Omoruyi lo ṣalaye bẹẹ.
Agbẹnusọ ileeṣẹ ọlọpaa ipinlẹ Edo, Kontongs Bello to fidi iṣẹlẹ naa mulẹ ṣo pe Emmanuel yoo foju ba ileẹjọ lẹyin ti iwadii ba pari lori iṣẹlẹ ọhun.
Unilag shut down?: Àwọn aláṣẹ Fásitì UNILAG ti ibùgbé àwọn akẹ́kọ̀ọ́ pa torí ọwọ́jà Covid-19
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Awọn alaṣẹ ileewe naa gbe igbesẹ naa lati da abo bo awọn akẹkọọ naa lọwọ ajakalẹ aarun Coronavirus ti ọwọja kẹta ni ipinlẹ Eko.
Awọn alaṣẹ ileẹkọ Fasiti ipinlẹ Eko (UNILAG) ti paṣẹ ki gbogbo awọn akẹkọọ kuro ni ọgba ileẹkọ naa.
Awọn adari ileẹkọ naa ni ki awọn akẹkọọ naa kuro ni yara igbe ileẹkọ naa.
Wọ́n ní Ìyá Esabod yẹn ma ń ṣépè, fi òṣèré wọ́lẹ̀, mò ń retí èsì yín sí ọ̀rọ̀ tí mo fi síta yìí - Mr Portable
'Àṣẹ ni! Gbogbo àgbàlagbà gbúdọ̀ gba abẹ́rẹ́ àjẹsára Covid-19 ṣáájú 31 July'
Vitamin D àti Covid-19: Òótọ́ nípa àṣírí tó wà níbi òògùn yìí fún ìwòsàn Covid
Ṣé ǹkan oṣù rẹ ń dà hìì hìì lẹ́yìn tóó gba abẹ́rẹ́ àjẹsára Covid-19? Ẹ gbọ́ tuntun lẹ́nu àwọn Dókítà
Coronavirus after one year in Nigeria: Níbo ni ọ̀rọ̀ Covid 19 dé dúró ní Nàìjíríà?
Bakan naa ni wọn kede pe awọn akẹkọọ yoo bẹrẹ ẹkọ kikọ lori ẹrọ ayelujara lati Ọjọ Kẹrindinlọgbọn, Oṣu Keje, ọdun 2021.
Awọn alaṣẹ ileewe naa gbe igbesẹ naa lati da abo bo awọn akẹkọọ naa lọwọ ajakalẹ aarun Coronavirus ti ọwọja kẹta ni ipinlẹ Eko.
Bakan naa ni wọn fi lede pe ọpọlọpọ akẹkọọ lọ ti wa ni ileewosan lori aisan to ṣeeṣe ko niiṣe pẹlu aarun Coronavirus.
Ojude Oba festiva 2021: Nítorí ẹ̀dà tuntun COVID-19, Awujale Ijebu Ode, Ọba Adetona wọ́gilé àjọ̀dún Ojude Oba tọdún yìí
Oríṣun àwòrán, other
Awujalẹ ti ilu Ijẹbu, Ọba Sikiru Kayọde Adetọna ti wọgile ajọdun Ojude Ọba ti ọdun yii.
Ninu atẹjade kan ti alamojuto ajọdun naa, Oloye Fassy Yusuf fi sita, bi ajakalẹ ẹda 'Delta variant' arun COVID-19 tun ṣe n gbilẹ sii lo ṣokunfa wiwọgile ajọdun naa.
Atẹjade naa ni kaka ki wọn dẹja tabi gbe awọn eeyan ti yoo peju wa ṣọdun naa nilu Ijẹbu Ode sọwọ ajakalẹ arun naa, yoo dara ki wọn wọgile naa.
Igba keji niyi ti wọn yoo maa wọgile ajọdun Ojude Ọba lati igba to ti bẹrẹ lọpọlọpọ ọdun sẹyin.
Ọjọ meji lẹyin ọdun ileya ni wọn maa n ṣe ajọdun Ojude Ọba.
Atẹjade naa ni bi o tilẹ jẹ pe igbesl naa jẹ eyi ti ko dun mọ Kabiyesi Awujalẹ ninu nitori pataki ọdun naa ninu itan ati igbe aye awọn ọmọ Ijẹbu nile loko ati loke okun, sibẹ Ọbalaye naa n gbadura fun alaafia ati aṣejere awọn ibi gbogbo ti wahala ti n suyọ ati gbogbo Naijiria lapapọ.
Erinjiyan Ekiti: Àjọ̀dún odò Ẹ̀rìn, omi tí wọn kò gbọdọ̀ pa ẹja abàmì inú rẹ̀ wáyé nílùú Erinjiyan
Ọdun Ẹrin ni ilu Ẹrinjiyan ni ipinlẹ Ekiti ni ibi ti wọn ti n kan sara si odo ẹrin ati awọn ẹja iṣẹmbaye inu odo naa.
Gẹgẹ bi itan ti kabiyesi ilu Ẹrinjiyan Ekiti, Ọba Adegoroye Oludaare Ọmọṣeebi, Adegoroye keji ṣe sọ, omi Ẹrin ti wọn n ṣe ajọyọ rẹ yii ni wọn fi ṣe iṣẹdalẹ ilu Ẹrinjiyan.
Omi ẹrin yii si jẹ nnkan pataki ti awọn eeyan ilu naa joko ti.
Gẹgẹ bi itan ṣe sọ awọn abami ẹja kan wa ninu odo naa to jẹ pe ẹnikẹni ko gbọdọ paa. Bi eeyan kan ba paa, ko si bi wọn ṣe lee se to ṣe ni yoo maa luwẹ ninu omi gbigbona ti wọn ba fẹ fi se e.
Olagunsoye Oyinlola: Kí Olorun dáríjì wá lórí ọ̀rọ̀ yíi, a ti kùnà ìlérí wa fún ìran Yorùb
Lasiko ajọdun odo Ẹrin yii lawọn eeyan ti maa wa n beere ohunkohun ti wọn ba n fẹ ti wọn si maa n ni ẹri ọpẹ lori ohun ti wọn ba n beere.
Okunade Sijuwade: Ìfẹ́ tí Sarun tó súnmọ́ Ooni jù láyé ní sí í ló sọ ọ́ di abọ́bakú- Adeye
Gẹgẹ bi Kabiyesi Ọba Adegoroye ṣe sọ, lasiko ajọdun naa wọn a maa din akara ti awọn eeyan yoo maa ṣe wẹjẹwẹmu.
Lasiko ọdun yii naa lawọn ọmọde yoo ṣe ohun ti wọn n pe ni 'Igbo olokun' ti wọn yoo sin awọn akun si ara wọn lọ si idi odo yii. Awọn ọmọ naa yoo wọ inu igbo ti omi yii wa, ẹẹkan lọdun si wọn si maa n wọ igbo naa.
'Èmi gan máa ń béèrè lọ́wọ́ ara mi pé ta ni Wole Soyinka gangan'
Ogun road accidents: Ìjàmbá ọkọ̀ ṣe gbẹ̀mí èèyàn 265 ní ìpínlẹ̀ Ogun
Oríṣun àwòrán, Facebook/FRSC Ogun
O kere tan, ọta le lugba le marun un 265 eeyan lo ti dero ọrun ninu ijamba ọkọ to waye laarin ọdun kan ati oṣu marun un ni ipinlẹ Ogun.
Esi iwadii ti ajọ ẹṣọ oju popo, Traffic Compliance and Enforcement Corps, TRACE ṣalaye pe  eeyan 1,654 lo farapa ninu ijamba ọkọ 1,176 to ṣẹlẹ lati oṣu kinni ọdun 2020 si oṣu karun un ọdun 2021 nipinlẹ Ogun.
Iwadii naa fihan pe eeyan 176 lo gbẹmi mi ninu ijamba ọkọ laarin oṣu kinni si oṣu kejila ọdun 2020.
Eeyan mọkandinlaadọrun lo padanu ẹmi wọn nigba ti ọta le lẹgbẹta le mẹrin farapa ninu ijamba ọkọ laarin oṣu kinni si oṣu karun un ọdun 2021.
171 ọkọ ayọkẹlẹ, 153 bọọsi aladani nigba ti 168 bọọsi ero, 189 ọkọ ero, 101 alupupu, kẹkẹ ẹlẹsẹ mẹta 52, 1555 ọkọ nla ati 169 tirela ni ijamba ọkọ ṣẹlẹ si.
Agbẹnusọ fun ajọ TRACE, Babatunde Akinbiyi ṣalaye pe eeyan 3,021 lo ni ipin ninu awọn ijamba ọkọ ọhun.
Ninu ọdun 2021, ọkunrin mọkadinlọgọrin ati obinrin mẹwaa lo ku laarin oṣu marun un nigba ti ọkunrin 473 ati 191 obinrin lo farapa ninu ijamba ọkọ.
Ọkọ 285 ati 57 alupupu ni ijamba ṣẹlẹ si, ati pe laarin oṣu kinni si ekeji ni awọn eeyan ti ku julọ nigba ti awọn to farapa pọ lati oṣu keji si oṣu karun un.
Ajọ TRACE ati FRSC ni ere asaju lo ṣe okunfa ọpọlọpọ awọn ijamba ọkọ naa.
Wọn iwa kuwa, taya ti ko dara, awọn to n gba ''one way'' ati oju popo to ti bajẹ naa n ṣokunfa ọpọ ijamba ọkọ.
Ẹwẹ, ijọba ti ṣe agbekalẹ eto lati din ijamba ọkọ to n ṣẹlẹ ku loju popo.
Lara awọn ọna ti ijọba fẹ fi ṣe adinku ijamba oju popo ni bi wọn ṣe fi ofin de ọti tita fawọn awakọ.
Major General Huseini Ahmed ti wọ káà ilẹ̀ sùn, ó digbéré!
Oríṣun àwòrán, Army Headquarters
Wọn ti sin oku, Ọgagun agba to jẹ adari ẹka ikojanu ileeṣẹ ọmọ ogun. Wọn sin in si iboji ti awọn ologun to wa ni Abuja.
Awọn agbebọn ti ẹnikẹni ko mọ lo ṣekupa Ọgagun Huseini Ahmed lọjọ kẹẹdogun oṣu keje ọdun 2021 nigba to n rinrinajo laarin opopona Lokoja si Abuja.
Ọga agba awọn ọm ogun oriilẹ, Ọgagun Faruk Yahaya sọ ninu ọrọ rẹ nibi isinku naa pe ọgagun agba naa jẹ atẹpamṣẹ to ṣi mọ iṣẹ rẹ bi ẹni mọ owo.
O ṣapejuwe ọgagun naa loriṣiriṣi ọna ara to fi da yatọ ati ipa ribiribi to ko nileeṣẹ ọmọ ogun nigba to wa laye.
Oríṣun àwòrán, Army Headquarters
Wọn bi Ọgagun Ahmed lọjọ kẹrindinlogun oṣu keji ọdun 1968 nilu Maiduguri. Ijọba ibilẹ Maiduguri lo ti wa ni ipinlẹ Borno.
O lọ sile ẹkọ girama Yelwa ni Makurdi to si wọ ile ẹkọ awọn ọmọ ogun lọdun 1988 ti wọn si fun un ni ipo Regular Combatant Commission lọjọ kẹdọgbọn oṣu kẹsan ọdun 1993.
O jẹ ọkan lara awọn ọlpaa ologun to goke di Ọgagun agba ko to kagbako iku ojiji yii.
Lati mọ riri awọn iṣẹ takun takun to ti ṣe, ọpọlọpọ ami ẹyẹ ni wọn ti fi da Ọgagun Ahmed Huseini lọla loniruuru ipele nileeṣẹ ogun.
Oríṣun àwòrán, Nigeria army hq
Ọ̀gágun àgbà Huseini Ahmed, adarí ẹ̀ka akójanu iléeṣẹ́ ọmọogun oríilẹ̀ ní Nàìjíríà
Awọn agbebọn ti yinbọn pa ọgagun ọmọogun Naijiria kan lasiko to fi n rinrinajo lati ilu Lọkọja lọ si ilu Abuja to jẹ olu ilu Naijiria.
Atẹjade kan ti ile iṣẹ ọmọogun fi sita ṣalaye pe Ọgagun Huseini Ahmed kagbako iku ojiji naa ni alẹ Ọjọbọ nigba ti awọn agbebọn naa kọlu ọkọ rẹ.
Ileeṣẹ ọmọogun oriilẹ ni Naijiria ṣapejuwe iṣẹlẹ naa gẹgẹ bi eyi to banininujẹ lọpọlọpọ, bẹẹ ni wọn ni ko tii si ẹni lee sọ ni pato awọn to wa lẹyin iṣẹlẹ naa ati idi to faa.
Orilẹede Naijiria n ba ipenija ọrọ abo to n ṣe segesege faa lọwọ pẹlu bi awọn ẹgbẹ agbebọn loriṣiriṣi ṣe n rọjo wahala kaakiri tibutoro orilẹede Naijiria.
Opopona ti ọgagun naa rin jẹ skan lara awọn oju opo to ti fi oju wina ikọlu awọn agbebọn wọnyii sẹyin.
Bakan naa ni ko si ẹni lee sọ lọwọ yii boya oun nikan lo wa ninu ọks rẹ lasiko ti iṣẹlẹ naa ṣẹlẹ.
Silas Robotic Engineer: Kò sí ǹkan rere tí ọmọ Nàìjíríà kò lè ṣe
Agbẹnusọ fun ileeṣẹ ọmọ ogun Naijiria, Ọgagun Onyema Nwachukwu ni ọjọ Ẹti ni wọn yoo sin okun Ọgagun agba naa.
Ọkan lara awọn oludari ni olu ileeṣẹ ọmọogun oriilẹ Naijiria nilu Abuja ni Ọgagunagba Hassan, oun si ni akojanu ileeẹ ọmọ ogun oriilẹ ni Naijiria.
NYSC Anthem: Omijé bọ́ lójú alàgbà Adetiran tó kọ orin àkọmọ̀nà NYSC ní Nàìjíríà?
Oríṣun àwòrán, other
Ọmọwe Oluwọle Adetiran ẹni ọdun mẹrinlelaadọta to ṣe agbekalẹ orin akọmọna ajọ agunbanirọ orilẹede Naijiria, NYSC bu gbamu si ẹkun l'Ọjọbọ ti oludari agba ajọ naa, ọgagun Shuaibu Ibrahim bẹl wo ni ile rẹ to wa ni agbegbe Ibafo ni ipinlẹ Ogun.
Ẹ lee maa wo pe ki lo lee faa ti agbalagba fi n bu si ẹkun laarin ọpọ eniyan?
Baba Adetiran to gbe orin naa kalẹ ni ọdun 1984 ni ohun to n pa oun lẹkun ni pe lẹyin ọdun mẹtadinlogoji, wọn ṣi iwe iranti kan oun.
O ṣalaye pe aisan ẹjẹ riru, itọ ṣuga ati jẹjẹrẹ lo n ba oun finra lọwọ bayii
O ni ọdun 1984 ti oun n sinru ilu ni ipinlẹ Ọyọ ni oun ks orin naa.
Ọmọwe Adeniran ko ṣai kan sara si oludari ajọ naa fun ẹyẹ nla to ni o ṣe fun oun pẹlu abẹwo naa.
Ninu ọrọ rẹ, oludari agba fun ajọ NYSC lorilẹede Naijiria, Ọgagun Ibrahim ni ọmọ Naijiria to ṣee fọkansin ni alagba Adetiran ti ẹnikẹni ko lee ko iyan rẹ kere, paapaajulọ ipa rẹ ninu idagbasoke ajọ agunbanirọ orilẹede Naijiria.
WhatsApp: Àwọn èèyàn lè máa lo 'App WhatsApp' láì sí fóònù lọ́wọ́ wọn
Oríṣun àwòrán, Facebook/Whatsapp
Ileesẹ ayelujara WhatsApp ti n dan eto kan wo, eyi ti yoo mu ki awọn eeyan le fi ọrọ ránṣẹ lai lo foonu wọn.
Lọwọ lọwọ, ori foonu nikan ni àṣẹ wa lati lo WhatsApp, to si jẹ pe lai si foonu naa nitosi, ko seese láti lo WhatsApp lori ẹ̀rọ kọmputa.
"Sugbọn, pẹlu eto tuntun yii, awọn to n lo WhatsApp yoo le fi ọrọ ránṣẹ tabi gba ọrọ lati ọdọ ẹlòmíràn ""koda, ki batiri foonu rẹ ti ku""."
Eeyan perete ni yoo kọkọ lo eto tuntun naa, diẹ diẹ si ni wọn o ma a mu gbooro si titi gbogbo eniyan yoo fi le lo o.
Bakan naa ni eto basiri mi, End-to-end encryption, eyi to n pese aabo fun awọn to lo WhatsApp, yoo si sisẹ lori eto tuntun naa.
Iroyin sọ pe ọpọlọpọ miliọnu eeyan lo ti n fẹ eto tuntun yii.
Bawo ni eto tuntun ori WhatsApp yoo se lọ?
Ninu ikede ti wọn fi sita, àwọn amoju ẹ̀rọ nileesẹ Facebook sọ pe ayipada yii nilo ki wọn o tun ero pa lori agbekalẹ WhatsApp.
"Idi ni pe ""smart phone"" ni ọna gboogi ti WhatsApp ti n sisẹ, ohun naa si ni atọna fun awọn ẹrọ to ku bi kọmputa."
Eyi tumọ si pe ọna kan ṣoṣo ni o ti le ṣi WhatsApp silẹ lẹyin foonu rẹ. Ti o ba ṣi ni ibòmíràn, ọna keji yoo pa de fúnra rẹ.
"Eto tuntun yii yoo mu ìṣòro yii kuro.
O ko nilo foonu rẹ lati lo WhatsApp lori kọmputa rẹ."""
Gbogbo ẹrọ, foonu, tabi kọmputa ti o fi n lo WhatsApp ni yoo ni ami idanimọ rẹ, botilẹjẹ pe ẹnikan ṣoṣo lo ni wọn.
Sugbọn, Jake Moore, onimọ nipa eto abo fun ileesẹ Eset to n ṣe 'anti virus' sọ pe iru nkan yii le pagidina eto aabo lori foonu.
O ni ọkọ tabi aya to jẹ oníwà ipa ninu ile tabi ẹni to n sọ eeyan, le lo anfaani naa lati tọ pinpin ẹni ti wọn fẹ ẹ mu, nipa ṣíṣí WhatsApp rẹ lori foonu miran.
O sọ pe o ṣe pataki ki awọn eeyan mọ iye foonu, kọmputa tabi awọn ẹrọ ayarabiasa mii to n lo  WhatsApp wọn.
TB Joshua: Ìjọ Synagogue ní kò sí awuyewuye lórí ẹni tí yóò rọ́pò TB Joshua
Oríṣun àwòrán, TB Joshua MInistries
Ijọ The Synagogue Church of All Nations, SCOAN ti ṣalaye pe iroyin ofege ni iroyin kan to jade ninu iwe iroyin pe awuyewuye n ṣẹlẹ lori ẹni ti yoo gba ipo olori ijọ naa lẹyin ti Wolii TB Joshua ti papoda tan.
Iwe iroyin kan lo kọkọ sọ pe awuyewuye lori ẹni ti yoo rọpo TB Joshua ti bẹ silẹ laarin iyawo oloogbe, Evelyn TB Joshua atawọn ọmọlẹyin wolii to doloogbe naa kan.
Ṣugbọn awọn alaṣẹ ijọ SCOAN sọ ninu atẹjade kan ti wọn sita pe awọn alaparutu kan lo n gbe ayederu iroyin kiri nipa ijọ naa.
Ijọ SCOAN ṣalaye ninu atẹjade ọhun pe ''aya oloogbe Evelyn ṣi n ṣọfọ lọwọ lẹyin ti ọkọ rẹ wọ kaa ilẹ sun tan lọjọ kẹsan oṣu keje ọdun 2021.
Gẹgẹ bi iyawo gidi ati abiamọ, o yẹ kawọn eeyan yẹ ẹ si nipa bibu ọlu fun un ki wọn si maa sọrọ rẹ lasiko yii to si n kẹdun ọkọ rẹ lọwọ.
Evelyn ko ba ẹnikan ja, niṣe lo gbajumọ bi yoo ṣe tẹsiwaju pẹlu iṣẹ ti ọkọ rẹ fi silẹ lọ.
Ọkan ṣoṣo ni gbogbo awọn ọmọ ijọ SCOAN, aya oloogbe Evelyn ko si ni gbolohun asọ pẹlu ẹnikan kan.
A fẹ fi asiko yii sọ fun gbọgbọ eeyan pe, to ba to asiko, a o kede olori tuntun ti yoo rọpo Wolii TB Joshua.
Ẹmi mimọ ni yoo ṣe atọna wa lori ati yan ẹni ti yoo rọpo TB Joshua.
Ṣugbọn lọwọ yii, arabinrin Evelyn lo si n dari gbogbo eto ijọ SCOAN.''
Iyalaje Oodua: Toyin Kolade ṣàlàyé ìdí tí Ooni Ogunwusi ṣe fi jẹ Ìyálájé Oodua fún gbogbo ilẹ̀ Yorùbá lágbáyé
Kaakiri agbaye ni ọrọ Aje ko ti jẹ eyi ti a n fi ọwọ yẹpẹrẹ mu.
Aje ogugunisọ, onisọ iboji.
Gẹgẹ bi itan iṣẹdale, aje lo wa ni idi ki ọmọ ẹda ri na ko ri lo, aje ọhun gan ni alakoso gbogbo karakata lagbaye.
Iyalaje oodua fun gbogbo ọmọ Yoruba kariaye, loye Toyin Kọlade ba BBC News Yoruba sọrọ lori pataki aje, iyatọ rẹ si iyalọja ati bi o ṣe ṣe pataki fun obinrin to ba fẹ ri ti aje ṣe lati maa tẹriba fun ọkọ wọn.
Igangan attacks: Ẹ̀ṣọ́ aṣọ́bodè mẹ́ta àti ọmọ ológun kan farapa níbi ìkọlù kan tó wáyé nílùú Igbó Ọrà -Iléeṣẹ́ aṣọ́bodè
Awọn oṣiṣẹ ẹ̀ṣọ́ aṣọ́bodè  mẹta ati ọmọ ológun kan farapa níbi ìkọlù eléyìí tó wáyé pẹ̀lú àwọn olókoòwo fàyàwọ́ kan lágbègbè Igbo Ora ní Ijọba ìbílẹ̀ Ibarapa, Ipinle Oyo ni nkan bii aago mẹ́jọ alẹ́ ọ́jọ́ Ẹtì Friday ọjọ́
kẹrindínlógún, Oṣu Agẹmọ, ọdún 2021.  Awọn Oṣiṣẹ aṣọ́bodè tí wọ́n farapa ni wọ́n  jẹ́ oṣiṣẹ ẹ̀ka Zone A, Federal Operations Unit, lásìkò tí wọn ń ṣàyẹ̀wò ọkọ̀ gẹ́gẹ́ bí iṣẹ́ wọn lọ́wọ́ ni wọ́n fojú gán-ánni ọkọ akẹ́rù mẹ́jọ tí wọ́n kó àwọn iresi tí kìí ṣe tilẹ̀ yìí wọlé
ṣùgbọ́n tí dírẹ́bà àti àwọn arìnrìn-àjò ọ̀hún bẹ̀rẹ̀ síí dáná ìbọn yá àwọn aṣọ́bodè náà.
Ọ̀kan lára àwọn tí wọ́n ṣe ìkọlù yìí lọta ìbọn bà nígbàtí àwọn tókù sì fẹsẹ̀ fẹ́ẹ papọ̀ pẹ̀lú àwọn ẹrù fàyàwọ́ tí wọ́n gbé.
Lásìkò tísẹ́  iwadii n lọ lọwọ lati fojú àwọn ọ̀daràn yìí ba ilé ẹjọ́, gbogbo awọn oṣiṣẹ aṣọ́bodè àti ọmọ ológun tí wọ́n ṣe ìkọlù sí pẹlu ẹni tí ọta ìbọn bà lórí ti ń gba ìtọ́jú lọ́wọ́ báyìí.
Adelé adarí àgbà àjọ aṣọ́bodè ẹ̀ka ọ̀hún, DC Usman Yahaya, bu ẹnu atẹ lu ikọlu naa bẹ́ẹ̀ lo tẹnumọ́ ipinnu rẹ̀ láti túbọ̀ gbógun ti okoowo fàyàwọ́ láìṣáàrẹ̀.
Gẹ́gẹ́  bí Adelé adarí àgbà àjọ aṣọ́bodè ti sọ, ó pé òun kò ní fìgbà kan jẹ́kí ìrẹ̀wẹ̀sì dé bá òun, pàápàá bí ìkọlù ti ń fojoojumo wáyé sórí àwọn òṣìṣẹ́ aṣọ́bodè láti ọwọ́ àwọn Ọ̀dàràn wọ̀nyí.
Gogogo ni igboro ilu Igboọra kan ati awọn ilu miran lagbegbe Ibarapa lẹyin iṣẹlẹ ikọlu awọn agbebọn to waye nibẹ lalẹ ọjọ Ẹti.
Nigba ti ikọ BBC News Yoruba de ilu naa lowurọ ọjọ Abamẹta ninu ipaya ati ibẹrubojo lawọn olugbe ilu naa wa.
Bakan naa ni ara n kan awọn olugbe ilu Igboọra ati awọn ilu miran lagbegbe Ibarapa lori awọn eeyan ti o padanu ẹmi wọn lasiko ikọlu naa.
Ni bi a ṣe n sọrọ yii, awọn ọdọ ilu naa ti fi ẹhonu han ti ajoku taya ọkọ si kun opopona gbogbo ni ilu naa.
Amọ ṣa awọn agbofinro atawọn ologun ti wa ni ilu naa bayii lati rii daju pe alaafia jọba.
Oríṣun àwòrán, other
Ṣe lootọ ni awọn afurasi agbebọn darandaran Fulani tun ya wọ ilu Igangan ni ipinlẹ Ọyọ lalẹ ọjọ Ẹti?
Eyi ni ibeere to tun gba ẹnu awọn eeyan paapaa awọn ọmọ Yoruba gbogbo lori lẹyin ti iroyin lu si igboro pe ikọlu miran tuntun ti waye ni ilu Igangan.
Awọn iwe iroyin abẹle kan ṣalaye pe awọn araalu naa kan fi to awọn oniroyin leti pe ọks  mẹta ni awọn agbebọn naa gbe wa fi ṣe ọṣẹ ikọlu naa eyi ti ko ju bi iṣẹju mẹwaa lọ.
Awọn iroyin abẹle naa tun jẹ ko di mimọ pe awọn fijilante ilu naa ati awsn ọmọ ẹgbẹ OPC to dide koju awọn agbebọn naa lo da wọn lẹkun ikọlu naa.
Wọn fi kun un pe ilu Igbo Ọra, Igangan ati Ayetẹ ni wọn ti ṣọṣẹ naa.
Bi o tilẹ jẹ wi pe oniruuru iroyin lo n jade nipa iye awọn eeyan to gbẹmi mi lasiko iṣẹlẹ naa, ileeṣẹ ọlọpaa ipinlẹ Ọyọ ko tii fi idi iṣẹẹ naa mulẹ ati boya eeyan kankan jalaisi nipasẹ rẹ.
Igba akọkọ kọ niyi ti iklu awn agbebọn darandaran yoo maa waye ni ilu Igangan ati awọn ilu miran lagbegbe Ibarapa ni ipinlẹ Ọyọ.
Sunday Igboho and Yoruba Nation: Ìjọba àpapọ̀ tún ti kébòsí lórí Sunday Igboho, wọ́n ní ó ń gbìyànjú àti gba pásípọ́tù ìrìnà mírán láti sá ròkè òkun
Oríṣun àwòrán, Sunday igboho/instagram
Ijọba apapọ orilẹede Naijiria ti pariwo sita pe Oloye Sunday Adeniyi Adeyẹmọ ti ọpọ mọ si Sunday Igboho ti n wa ọna lati gba iwe irinna silẹ okeere miran lọna ati lee sa kuro lorilẹede Naijiria.
Ijọba apapọ sọ eleyi di mimọ ninu lẹta kan eyi to tẹ awọn oniroyin lọwọ ti wọn ni ileeṣẹ wọlewọde lorilẹede NAijiria kọ ṣọwọ si oludari agba ileeṣẹ alaabo ọtẹlẹmuyẹ DSS, ọga agba ọlọpaa lorilẹede Naijiria pẹlu ajọ ọtẹlẹmuyẹ NIA.
Wọn ni Sunday Igboho, ẹni to n le iwaju ijijagbara fun idasilẹ orilẹede Yoruba n gbero ati sa ms ofin lọwọ lori ẹsun kiko ohun ija oloro pamọ sile lati da orilẹede Naijiria ru eleyi ti wọn fi kan an lẹyin ti wọn kọlu ile rẹ ni ibẹrẹ oṣu keje ọdun 2021.
Bi o tilẹ jẹ pe Sunday Igboho ti sẹ kanlẹ pe irọ ni gbogbo ẹsun ti wọn fi kan oun, sibẹ awọn ileeṣẹ alaabo ṣi n waa kiri ti ko si si ẹni lee sọ ibi to wa.
Iwe irinna silẹ okeere to jẹ ti Sunday Igboho wa lara awọn ohun ti awọn DSS fi han araye pe awọn ri ko ninu ile rẹ lasiko ikọlu naa.
Ninu lẹta ti o lu si awọn oniroyin abẹle lọwọ yii ni ileeṣẹ wọlewọde tun ti paṣẹ fun gbogbo awọn adari ẹka rẹ gbogbo pe nibikibi ti wọn ba ti kẹẹfin Sunday Igboho nṣe ni ki wọn fi panpẹ ofin gbe e lẹyẹ o ṣọka.
Lagos Magistrate Court: Iléẹjoọ́ feẹ̀sùn kan ìyá 'deacon' pé ó lu ọ̀gá reẹ̀ ní jìbìtì
Oríṣun àwòrán, other
Iya deacon, Olaide Olukanni ti yọju si ileẹjọ lori ẹsun pe o lu jibiti pẹlu orukọ ọga rẹ lati fi lu awọn ara ilu ni jibiti.
Olukanni wa lara awọn mẹfa ti wọn fi ẹsun kan pe o lu jibiti pẹlu ẹsun yiyi iwe ati pipa irọ gba owo, eleyii to le e da alaafia ilu ru.
Amọ, wọn ni wọn ko jẹbi ẹsun ti wọn fi  kan wọn.
Ninu ọrọ ti agbẹjọro Bisi Ogunleye sọ, iya deacon ati awọn to ku lo orukọ ọga rẹ Ẹsan lọna aitọ, lati fi ṣe ayẹwo ile fun ọpọlọpọ awọn eniyan laarin Oṣu Karun, ọdun 2019 si Oṣu Kọkanla, ọdun 2020.
Ogunleye ni iwa jibiti yii lu ofin ipinlẹ Eko, iyẹn section 411, 365 (1), 380 (11) 168 (1)  314 (1) ti ọdun 2015 to koju oro si iwa ọdanran.
Ninu idajọ rẹ, adajọ gba beeli iya deacon ati awọn afurasi bi tirẹ ni iye owo ẹgbẹrun lọna igba ati oniduro wọn.
Iyalaje Oodua: Toyin Kolade ṣàlàyé ìdí tí Ooni Ogunwusi ṣe fi jẹ Ìyálájé Oodua
Bakan naa lo sun igbẹjọ di Ọjọ Kẹrin, Oṣu Kẹjọ, ọdun 2021.
Flying car: Ọkọ̀ tí ń fò, ọ̀nà àbáyọ kan rèé sí ìṣòro 'go slow' lágbègbè rẹ
Imọ ẹrọ ti n goke sii, lara rẹ si ni ọkọ to n fo bi ẹyẹ yii ti wọn ṣẹṣẹ ṣe idanwo rẹ ni ilu Slovakia.
Irufẹ imọ ẹrọ bayii yoo jẹ itura pupọ fun awọn eeyan agbegbe ti sunkẹrẹ fa kẹrẹ ọkọ ti pọ bi ilu Eko lati dẹkun ohun ti awọn eeyan mọ si 'go slow' lọpọlọpọ igba.
Igangan attacks: Gani Adams ní ó tó ọjọ́ mẹ́ta tí OPC ti ń pariwo pé àwọn agbébọn kan ńgbèrò àti kọlu Ibarapa, àwọn agbófinro kò dáhùn ni
Oríṣun àwòrán, other
Aarẹ Ọna Kakanfo ilẹ Yoruba, Iba Gani Adams ti sọrọ lori iṣẹlẹ  to waye ni ilu Iganagan, Igboọra ati agbegbe rẹ eyi to mu ẹmi awọn eeyan ilu naa kan lọ.
Iba Gani Adams ni awọn ọmọ Yoruba ko ni lee kawọgbera mọ maa woran awọn iṣẹlẹ ipaniyan gbogbo to n waye nibẹ yala latọwọ awọn agbebọn tabi awọn oṣiṣẹ agbofinro ilu.
Ninu atẹjade kan eyi to fi sita latọwọ amigbalẹgbẹ rẹ lori ọrọ iroyin, ọgbẹni Kẹhinde Aderẹmi, Iba ni ṣaaju iṣẹlẹ ọjọ Ẹti ni ẹgbẹ OPC ni ipinlẹ Ọyọ ti n ke gbajare pe awọn ti wuu gbọ o pe awọn eeyan kan yoo kọlu awọn agbegbe kan ni Ibarapa ṣugbọn ti awọn ko tii ri igbesẹ to loorin latọdọ ijọba tabi awọn to jẹ agbofinro ni ipinlẹ Ọyọ.
Amọṣa ileeṣẹ aṣọbode (Customs) ti sọ pe ohun to ṣẹlẹ ni ọjọ Ẹti ni ilu Igboọra kii ṣe ikslu awọn agbebọn bi ko ṣe itaporogan laarin awọn oṣiṣẹ aṣọbode atawọn fayawọ to n gbiyanju ati sa mọ ofin lọwọ.
Iyalaje Oodua: Toyin Kolade ṣàlàyé ìdí tí Ooni Ogunwusi ṣe fi jẹ Ìyálájé Oodua
Igangan attacks: Olu ní ìlú Igboora, Igangan, Ayete kìí ṣe ààlà Nàìjíríà, kí aṣọ́bodè dẹ́kun ìpànìyàn níbẹ̀
Oríṣun àwòrán, NCS
Gomina ipinlẹ Ọyọ, Onimọẹrọ Seyi Makinde ti kede pe awọn awọn oṣiṣẹ ileeṣẹ aṣọbode lo kọlu Igangan lọjọ Ẹti, kii ṣe awọn agbebọn.
Gomina Makinde sọ eyi ni ibamu pẹlu ohun ti Olu ti Igboọra, Ọba Jimoh Ọlajide Titiloye ati alaga ijọba ibilẹ Ariwa Ibarapa, Adeoye Adedoyin fi to ikọ ojumi too, ti ipinlẹ Ọyọ gbe kalẹ.
Ọba Jimọh Titiloye ni ṣe ni gbogbo awọn olugbe ilu Igboọra atawọn ilu miran to yii ka n sa kijokijo, ti olukuluku si n fọn lugbẹ lasiko ikọlu naa eleyi to gbẹmi olori awọn ẹṣọ amọtẹkun lagbegbe naa atawọn meji miran.
"A fẹ sọọ ki gbogbo agbaye mọ pe awọn ilu wa, Igboọra, Igangan ati Ayetẹ kii ṣe ilu to wa ni ibode tabi aala orilẹede yii.
Ki lo de tawọn ẹṣọ aṣọbode maa fi wa sọ ilu wọn di ibudo itajẹsilẹ ati ogun?"
Flying car: Ọkọ̀ tí ń fò, ọ̀nà àbáyọ kan rèé sí ìṣòro 'go slow' lágbègbè rẹ
Olori ikọ ti ijọba ran lọ si agbegbe naa, Kọmiṣọna ọlọpaa to ti fẹyinti, Sunday Odukọya ke sawọn eeyan agbegbe naa lati dakundabọ fiyedenu ki wọn ma si ṣe fa wahala.
Odukọya to jẹ amugbalẹgbẹ agba fun gomina Makinde lori ọrọ abo ni, awọn eto abo alajumọṣe laarin awọn fijilante ilu atawọn oṣiṣẹ alaabo bi Amọtẹkun, yoo so eso rere lagbegbe naa.
Funmi Martins‘ Tomb Renovation: Ashabi Olorisha ní òun kò le dúró de Mide Martins fún àríyá tó fẹ́ ṣe lọ́dún tó ń bọ̀
Oríṣun àwòrán, ashabi_olorisha_official/Instagram
Yoruba ni ọrẹ kitikiti, iyekan katakata, lọjọ ti ọrẹ kitikiti ba ku, iyekan katakata ni yoo gbe sin.
Amọ eyi ko ri bẹẹ pẹlu ọrẹminu oloogbe Funmi Martins kan, to gba lati tun iboji rẹ se lẹyin ọdun mọkandinlogun ti oloogbe naa papoda.
Adedola Aderonke, ti ọpọ mọ si Ashabi Olorisha ninu ere tiata ni ọrẹ Funmi Martins naa, amọ orilẹede Amẹrika lo fi se ibujoko bayii, to si gba lati tun iboji ọrẹ rẹ se lẹyin iku rẹ.
Ashabi Olorisha lo gbe fidio kan soju opo Instagram rẹ lati salaye fun awọn eeyan to n sọrọ odi si pe o gbe fidio bo se tun iboji Funmi Martins se sori ayelujara.
O ni oju lo gba oun ti nipa ipo ti iboji Funmi Martins wa lasiko ti oun atawọn eeyan to sun mọ lọ si oju orori rẹ nigba ti wọn n se iranti rẹ laipẹ yii.
"Se ni omije n bọ loju mi nipa ipo ti ko dara ti iboji ọrẹ mi wa lasiko ta lọ se abẹwo si iboji rẹ, ko pẹ lẹyin igba naa ni mo pada si orilẹede Amẹrika.
Koda, ọmọ rẹ ọkunrin gan, Damilare gan bu sẹkun ni leti iboji iya rẹ, idi si ree ti mo se fi owo ransẹ sile lati se itọju iboji naa.
Lootọ ni Mide Martins, ọmọ Funmi Martins ti ni lero lati tun iboji naa se fun ariya iranti ogun ọdun ti mama rẹ jade laye, amọ n ko le duro di asiko yẹn to fẹ se pati, ni mo fi se.
Awọn eeyan kan wa n sọ isọkusọ nipa fidio atunse boji naa ti mo gbe sori ayelujara, emi kii bu eeyan, n ko si fẹ ki ẹnikẹni sun mi kan ogiri."
Osere tiata naa ni nigba ti oun gbe oju ororri Funmi Martins sori ayelujara lasiko ti awọn lọ sibẹ fun iranti ọdun kọkandinlogun to papoda, ọpọ eeyan lo n yọ suti ete lori rẹ.
Oríṣun àwòrán, ashabi_olorisha_official/Instagram
Ashabi Olorisha ni o dun oun bi iboji Funmi Martns se ri yii nitori oun mọ pe lọjọ kan, oun naa yoo lọ sibi ti Funmi Martins lọ.
O wa salaye pe ẹnikẹni to ba nifẹ oloogbe naa, yoo nifẹ ọmọkunrin ti Funmi Martins fi silẹ ni ikoko, eyiun Damilare Isaac Akanbi Peters, ti ko gbọnju mọ iya rẹ.
Oserebinrin naa fikun pe ọmọ naa ko jẹ igbadun iya rara, ọjọ mọkanlelogoji pere ni Damilare fi mu ọmu laya iya rẹ, to si bu sẹkun nigba to de oju orori iya rẹ.
Yomi Fabiyi: Èmí ló mú Bimpe Oyebade dé agbo tíátà àmọ́ ó dà mí
Oríṣun àwòrán, realyomifabiyi/mo_bimpe/Instagram
Gbaju gbaja osere tiata nni, Yomi Fabiyi ti fesi pada lori ẹsun inawọ ifẹ sira ẹni, ti oserebinrin kan fi kan.
Bẹẹ ba gbagbe, a ti mu iroyin wa fun yin nipa bi Adebimpe Oyebade, toun naa jẹ osere tiata, se fi ẹsun kan Yomi Fabiyi pe ko lo oun ninu ere tiata mọ nitori pe oun ko gba, ko ba oun lopọ.
Nibayi, lasiko to n fọrọ werọ pẹlu iwe iroyin Punch, Yomi Fabiyi ni nitori pe oun jẹ osere tiata, ko tumọ si pe oun ko gbọdọ ni ero ifẹ si obinrin.
O ni sebi Bimpe wa bii ara awọn ololufẹ oun ni, ti oun si fun ni ipo asaaju kan ninu ere sinima ti oun n se lọwọ nigba naa.
"Kii se pe mo se idanwo fun lati mọ bi yoo se yege si, bẹẹ ni ko tọ mi wa pe oun fẹ wa kọ isẹ tiata, koda mo ti pari idanwo ohun ti mo n se fawọn to fẹ sisẹ.
Royal Hugs Surprises: Ìyá ẹni ọdún 50 tó dọlọ́mọ láyé fi ìdùnnú hàn bí a ṣe kàn síi- Debor
Amọ mo se iwuri fun nipa fifun ni ipo to lagbara ninu sinima naa ."
Yomi ni ohun to sadede mu ki oun yi iwa pada si oserebinrin naa ni pe oun gan gan lo sẹ oun, koda, o mọ ohun to se si oun pẹlu.
"Gẹgẹ bi ọkunrin, maa ri obinrin ti ọkan mi nifẹ si amọ mo dupẹ pe ko ni mo fi tipa ba oun lopọ, tori ko si ofin to sọ pe mo gbọdọ fun ni ipa lati ko ninu awọn sinima ti mo ba n gbe jade.
Iru ẹtọ wo lo ro pe oun ni gan, to fi maa ro pe o di dandan ki oun ko ipa ninu awọn sinima ti mo n gbe jade, ma si salaye idi to fi sẹ mi."
Yomi ni oun ni oun mu Bimpe Oyebade de agbo osere tiata lọdun 2015, ti oun si jẹ ko kopa ninu sinima oun kan nigba naa.
Amọ ni ọjọ ti wọn pari yiya sinima naa tan, ni Bimpe lọ, ti ko si boju wẹyin mọ lati igba naa, osu Kinni ọdun 2019, eyiun ọdun mẹrin lẹyin naa, ni oun ati ẹ tun to foju kanra.
Okunade Sijuwade: Ìfẹ́ tí Sarun tó súnmọ́ Ooni jù láyé ní sí í ló sọ ọ́ di abọ́bakú- Adeye
"Laarin ọdun mẹrin naa, Bimpe ti ya sinima mẹta ọtọọtọ, n ko mọ oun to wa laarin rẹ ati awọn eeyan to n se onigbọwọ mi, pẹlu alakoso sinima pẹlu awọn ayaworan naa.
Ohun ti mo kan gbọ ni pe o n gba ẹyin lọ seto bi yoo se ya sinima lẹyin mi, iru aya nini wo ree?
Emi ni mo mu Bimpe de agbo tiata nitori mo fẹ ko di ilumọọka oserebinrin. Mo fẹ ko ni isẹ lọwọ amọ ki lo de to n gba ọna ẹburu kaakiri?
Lẹyin o rẹyin, lo wa pe mi pe oun ni isẹ fun mi, mo si sọ fun pe ẹni to gbe isẹ fun gan, ipasẹ mi lo se mọ, ti n ko si gbe isẹ fun onitọun mọ titi laelae."
Yomi Fabiyi wa n gbarata pe gbogbo awọn egungun ẹyin oun lagbo tiata ni Bimpe Oyebade gba mọ oun lọwọ lai fi to oun leti.
O ni to ba jẹ pe o bi oun ni, oun ko ni di lọwọ lati lo wọn, amọ ki lo de to n ji oun ti kii se tiẹ?
Gbajumọ osere naa fikun pe ọpọ nnkan lo tun waye laarin awọn mejeeji amọ to ba fẹ, o le maa yi wọn mọ alaye pe nitori oun ko gba fun oun lati ba oun lopọ ni.
Olagunsoye Oyinlola: Kí Olorun dáríjì wá lórí ọ̀rọ̀ yíi, a ti kùnà ìlérí wa fún ìran Yorùb
"Ki ọkan eeyan fa mọ ẹnikan yatọ si ki eeyan se asemase pẹlu ẹnikan. ẹ le bi Bimpe leere to ba jẹ nawọ ifẹ si mi tabi idakeji rẹ?
N ko kuku kọkọ kofiri rẹ tẹlẹ, oun lo kọkọ kọbi ara si mi. Yatọ si eyi, agbalagba ni awa mejeeji. Ohun to si se pataki ni pe a ko fi tipa tipa se e.
O yẹ ka le la awọn ọdọ lọyẹ pe nini ifẹ si ẹnikan yatọ si sise asemase pẹlu eeyan kan. A n sọrọ nipa sise asemase pẹlu eeyan kan, oun n sọrọ pe mo dẹnu ifẹ kọ oun, se iyẹn mu iwa ori pipe dani?
Insecurity in Oyo: Mogaji Moshood ní àwọn alága ìbílẹ̀ ń fẹ́ kí Makinde ró wọn lágbára láti kojú ètò ààbò
Oríṣun àwòrán, Vanguard
Ọkan lara awọn Mọgaji ilu Ibadan, Mọgaji Moshood ti sọ fún BBC Yoruba pe Gomina Seyi Makinde ko ṣe amulo imọran tawọn Mọgaji fun un, lori ọna lati wa ojutuu si eto abo to mẹhẹ nipinlẹ Oyo.
Mọgaji Moshood ṣalaye pe Makinde fun ra rẹ lo ṣe ipade pọ pẹlu awọn Mọgaji.
Ninu ipade ti a jọ ṣe pọ ni Makinde ti sọ fun wa, lati ko ipa ninu wiwa ojutuu sí ọrọ eto abo nitori awa ni a sun mọ awọn araalu julọ."
Emi gẹgẹ bi ọkan lara awọn Mọgaji ṣepade pọ pẹlu alaga ìjọba ibilẹ meji sí mẹta lori ọrọ naa.
Awọn alaga ti a jọ sọrọ pọ ni ki gomina fawọn laṣẹ, ki awọn le lagbara lati ṣe ohun tí awọn ba fẹ ṣe lori ọrọ abo.
Bakan naa ni awa Mọgaji tun gba Makinde ni imọran wí pe, ki ijọba ro awọn to n da ilu ru lagbara, ki wọn le maa ri nkan ṣe.
Ilorin Cripple Couple: Ọṣẹ ìfabọ́ ni tọkọ-taya tó ní ìpèníjà ẹsẹ̀ ń tà láti bọ́ ọmọ mẹ́ta
A jọ fẹnuko nibi ipade naa pẹlu aṣoju gomina pe, ki a ṣe ipade pọ pẹlu awọn to n ṣe jagidijagan ki a le sọ fun wọn ohun ti ijọba fẹ ṣe fun wọn.
Ohun to ṣẹlẹ pẹlu awọn to da rogbodiyan silẹ ni pe awa ni a ri wọn gẹgẹ ara wa, awọn ko ri wa bẹẹ.
Ṣugbọn awa Mọgaji ko le lọ da ṣe ipade pẹlu awọn eeyan yii lai jẹ pe ijọba ti fún wa ni ohun kan lati fun wọn.
Bẹẹ gẹgẹ ni mo ṣalaye fun gomina, ti wọn si sọ fun mi pe awọn yoo wa nkan ṣe sii.
"Ara awọn imọran ti a fún Makinde niyii, ṣugbọn ijọba rẹ ko mu ọkankan lo nibẹ."" Mọgaji Moshood lo ṣalaye bẹẹ."
Flying car: Ọkọ̀ tí ń fò, ọ̀nà àbáyọ kan rèé sí ìṣòro 'go slow' lágbègbè rẹ
Mọgaji Moshood tun fikun ọrọ rẹ pe, atẹjade ti igbimọ awọn Baalẹ at'awọn Mọgaji fi sita lori eto abo to mẹhẹ,wa lati mu ki gbogbo rẹ le dara naa ni.
Mọgaji Moshood ni awọn ṣetan lati ṣiṣẹ pọ pẹlu Makinde lori ọna ati wa ojutuu si eto abo to mẹhẹ.
"Ti gomina ba ranṣẹ pe wa, a o da a lohun nitori a ko le da a da ọrọ to wa nilẹ yii.
Ṣugbọn awa o lagbara kankan lati ṣe ohun kan, ijọba lo lagbara, agbara si ni eeyan maa fi n ṣe nkan, Mọgaji Moshood lo sọ bẹẹ."
Oríṣun àwòrán, oyo state government
Awọn igbimọ oriade nilẹ Ibadan ti bu ẹnu atẹ lu gomina ipinlẹ Oyo, Seyi Makinde lori ọwọ yẹpẹrẹ, ti wọn lo fi n mu eto aabo nipinlẹ Oyo.
Atẹjade kan ti awọn ọba alaye naa fisita lẹyin ipade wọn tun sisọ loju rẹ pe awọn ọba yii tun koro oju si bi gomina se takete sawọn igbimọ ọba alaye, lati maa da isejọba se.
Ninu awọn ọmọ igbimọ lọba lọba naa, la ti ri awọn olori to di akoso awọn agbegbe kọọkan mu nilu Ibadan, to fi mọ awọn Mọgaji agboole kọọkan ati igbimọ Olubadan.
Awọn ọba alaye naa lo salaye pe gbogbo aayan awọn lati fọrọ werọ pẹlu gomina Makinde lori ipo ti nnkan de duro nilẹ Ibadan, ni ko so eso rere.
Koda, wọn ni awọn tun ti parọwa si Alajia ti Ajia, Ọba Nureni Yusuf pe ko gba gomina nimọran pe ko tun iwa rẹ se.
Ilorin Cripple Couple: Ọṣẹ ìfabọ́ ni tọkọ-taya tó ní ìpèníjà ẹsẹ̀ ń tà láti bọ́ ọmọ mẹ́ta
Nigba to n fidi ọrọ naa mulẹ fun iwe iroyin Punch, Ọba Lekan Balogun tii se Otun Olubadan tilẹ Ibadan, salaye pe lootọ ni gomina jinna sawọn oriade nipinlẹ Oyo.
Ọba Balogun ni igbimọ awọn Ọba alaye naa ko ni ohunkohun ninu lati tako gomina Makinde, ju pe ko ko fi opin si eto aabo to mẹhẹ nilẹ Ibadan lọ.
"Ijọba nikan ko le fopin si eto aabo to mẹhẹ, awọn ọba alaye to sunmọ awọn araalu julọ ni ojuse pataki lati se lati ri daju pe aifararọ aabo di ọrọ itan.
Idi ree ta fi n beere fun ajọsepọ lati ọdọ ijọba, ki wọn le maa ba maa sisẹ tako ara wọn.
Kukah Vs Buhari: Bíṣọ́bù Kukah ní ìfowóṣòfò lásán ní okoòwò tí ẹnikẹ́ni bá ṣe ní Nàíjíríà
Oríṣun àwòrán, other
Ileeṣẹ aarẹ orilẹede Naijiria ti koro oju si ọrọ ti Biṣọbu agba ijọ aguda ni ẹkun Sokoto, ẹniọwọ Matthew Kukah sọ nilẹ Amẹrika.
Mattew Kukah lo ni iṣejọba Aarẹ Muhammadu Buhari ti kuna lati dẹkun ipenija abo to mẹhẹ, eyi to tako ileri to se lọdun 2015.
Biṣọbu Kukah sọrọ naa lasiko to n ṣe idanilẹkọ kan lori bi awọn agbebọn ṣe n dojukọ awọn Kristẹni ni Naijiria, paapaa lagbegbe ariwa. fun ajọ ẹtọ ọmọniyan Tom Lantos Human Rights Commission ni ilu Washington DC.
Atẹjade kan ti amugbalẹgbẹ fun aarẹ lori ọrọ iroyin, Garba Shehu fi sita ni ibanijẹ nla lo jẹ pe Ẹniọwọ Kukah naa lee maa tọ ipasẹ awọn eeyan kan to ni wọn n wa ipo ni ijọba.
Ileeṣẹ aarẹ fi ẹsun kan Biṣọbu Kukah pe o n gbin eso ikorira ati wahala laarin awọn ọmọ Naijiria.
Ilorin Cripple Couple: Ọṣẹ ìfabọ́ ni tọkọ-taya tó ní ìpèníjà ẹsẹ̀ ń tà láti bọ́ ọmọ mẹ́ta
O ni o dun ni lọkan jọjọ pe Ẹniọwọ naa lee maa sọ ọ jade lẹnu pe ifowojona lasan ni idokoowo yowu ti ẹnikẹni ba ṣe lori ohun amuludun bayii laarin orilẹede Naijiria ati Niger.
Ijọba ni irufẹ ohun amuludun bẹẹ to waye laarin orilẹede Naijiria ati Benin Republic ti mu ayipada ba ajọṣepọ ọrọ aje orilẹede mejeeji
Ninu ọrọ rẹ to sọ niwaju awọn aṣofin agba naa, Ẹniọwọ Kukah tọka si bi iwa ijinigbe ṣe n gogo si, ti awọn agbebọn naa si n ko ogun ja ilu, ti wọn si n gba ẹmi lẹnu tọmọde tagba.
O fi kun un pe ọpọ igba ni wọn n ṣe eyi labẹ iboju ẹsin, eyi to ni o to akoko fun awọn musulumi tootọ lati dide ji giri si bi ọrọ ṣe n lọ naa, ki wọn si yọ awọn kanda inu irẹsi wọnyii danu, ki wọn to ba ẹsin jẹ mọ wọn lori.
Olagunsoye Oyinlola: Kí Olorun dáríjì wá lórí ọ̀rọ̀ yíi, a ti kùnà ìlérí wa fún ìran Yorùb
Ileeṣẹ aarẹ ni irọ pata gbaa ni ohun ti alagba Kukah tun sọ pe, ṣe ni awọn kawọ gbera lori bi awọn agbebọn Fulani ṣe n pa awọn agbẹ kiri.
O ni ọwọ iṣejọba Buhari ni ilana akọkọ lori ọrọ awọn agbẹ ati darandaran ti waye lorilẹede Naijiria.
Nigeria Insecurity: Ohun márùn ún tó ń da ètò àbò láàmú ní Nàìjíríà
Oríṣun àwòrán, AFP
Idojukọ nla ni ọrọ ipenija abo to mẹhẹ jẹ fun orilẹede Naijiria.
Ko fẹrẹ si ojumọ kan ti iṣẹlẹ ikọlu, rogbodiyan tabi igbenipa kan kii waye lorilẹede Naijiria bayii.
Ọgbẹni Audu Bulama Bukarti to jẹ agba onimọ nipa eto abo lagbegbe olooru Sahara ni Afirika nibudo iwadii ijinlẹ Tony Blair Institute ṣalaye pe, ọwọja abo to mẹhẹ yii n ṣe akoba lọpọlọpọ fun orilẹede Naijiria.
Pẹlu ọkọọkan awọn ikọlu wọnyii, ẹmi n ṣofo, awọn eeyan n di alaabọ ara, bẹẹ ni igbagbọ ninu eto iṣejọba tiwantiwa ati ninu orilẹede Naijiria n kuru sii lojojumọ."""
Nigba ti Aarẹ Muhammadu Buhari gun aga iṣejọba lọdun 2015, ara ileri to ṣe ni didaabo bo araalu lọwọ awọn agbesunmọmi ati ọdaran gbogbo.
Igangan Attacks: Àkójọpọ̀ àbọ̀ BBC Yorùbá rèé nípa ìṣẹ̀lẹ̀ òfò ẹ̀mí àti dúkìá tó wáyé
Amọṣa o din diẹ ni ọdun meji bayii to ku ki o fi ijọba silẹ lẹyin ọdun mẹfa lai ri ọna abayọ si isoro eto aabo.
Awọn eeyan kan ti woye pe gulegule wahala abo lẹnu lọwọlọwọ yii, lo nii ṣe pẹlu bi iṣẹ ati oṣi ṣe gbilẹ kaakiri orilẹede Naijiria.
Ni bayii, ida mejilelọgbọn abọ awọn ọdọ to wa lorilẹede Naijiria ni ko ni iṣẹ lọwọ.
Eyi ni ipenija marun to n dojukọ abo lorilẹede Naijiria, to si n mu li igbe aye le koko fawọn ọmọ Naijiria lati gbe.
Awọn ipinlẹ ti awọn agbebọn alakatakiti ẹsin ti n ṣọṣẹ
Bi o tilẹ jẹ pe lọdun akọkọ ni Aarẹ Buhari ti kede pe oun ti ṣẹgun awọn agbebọn Boko Haram, amọṣa lọwọ yii O ti yi ohun pada pe ijọba oun n ba ijakulẹ pade lori ati dẹkun  igbesunmọmi eyi to bẹrẹ lẹkun ila oorun ariwa orilẹede Naijiria.
Ẹgbẹ agbebọn Boko Haram ti n gbooro sii lọ sawọn agbegbe tuntun nipa lilo anfani iṣẹ ati aini to gbode lorilẹede Naijiria.
Gẹgẹ bi ajọ iṣọkan agbaye, UN ṣe sọ, titi di opin ọdun 2020,  nnkan bii ẹgbẹrun lọna ọdunrun o le aadọta, 350,000 eeyan lawọn agbebọn Boko Haram ti ran lọ sọrun apapandodo ti wọn si ti sọ  ẹgbẹlẹgbẹ milisnu miran di atipo.
Oríṣun àwòrán, AFP
Ikọlu gbẹmigbẹmi lawọn agbebọn Boko Haram to si n sọ ara rẹ di balogun lawọn agbegbe kan. Bi o ti ṣe n gbowo ori lo n gbowo ilẹ lawọn agbegbe miran. Koda bi a ṣe n kọ iroyin yii, ikọ Boko Haram lo n ṣakoso gbajumọ ọja ẹja agbaye to wa letido Chad bayii.
Laipẹ yii, ikọ kan ti yapa to si fara mọ ikọ agbesumọmi miran Islamic State IS  torukọ rẹ n jẹ Islamic State's West Africa Province, ISWAP ti wọn si ti lagbara ju Boko Haram lọ.
Oniruuru rogbodiyan lo n waye laarin awọn darandaran fulani atawọn agbẹ lorilẹede Naijiria fun ọpọlọpọ ọdun.
Wahala ati ariyanjiyan lori ilẹ ati omi pẹlu papa ijẹko ti di wahalala nla pẹlu ayipada oju ọjs to n waye bayii eyi to n mu ki awọn darandaran o maa rin wa si apa gusu orilẹede Naijiria pẹlu awọn ẹran wọn.
Ọpọ ẹmi lo ti sọnu sinu ikọlu laarin awọn darandaran fulani ati agbẹ lori iwọnba perete aye ijẹko to wa.
Awọn ipinlẹ ti awọn darandaran ati agbẹ ti n fa wahala
Ipinlẹ Benue ni rogbodiyan laarin darandaran ati awọn agbẹ ti buru julọ.
Laipẹ yii, eeyan meje lo ku nigba tawọn agbebọn kan ṣina ibọn bolẹ nibudo kan tawọn eeyan togun le kuro nile wọn wọ si.
Bakan naa lawọn miran ti fi ẹsun ijinigbepawo kan awọn darandaran Fulani pẹlu.
Oríṣun àwòrán, AFP
Wahala ọhun gan ti sun awọn gomina ipinlẹ lati gbẹsẹ le dida malu jẹko ni ita gbangba, eyi si ti fa edeaiyede pẹlu ijọba apapọ.
Ni ọdun 2019, ijọba apapọ gbe eto atunṣe ilana tuntun fun sinsin ẹran ọsin, ti wọn pe ni 10-year National Livestock Transformation Plan kalẹ lati dẹkun rinrinsokesodo awọn ẹran ọsin ati wahala ti wọn n ko sodi. Awọn onwoye ni aini afọkansin, awọn eeyan to tọ ati owo to yẹ lo n di eto naa lọwọ bayii.
Lara awọn ohun to n dẹru ba ọpọlọpọ awọn idile lorilẹede Naijiria bayii ni gulegule ijinigbe, paapaa jiji awọn akẹkọọ gbe nileewe wọn.
O le ni ẹgbẹrun akẹkọs ti awọn agbebọn ti ls ji gbe nileewe wọn laarin oṣu kejila ọdun 2020 si asiko yii. Pupọ ninu wọn lo jẹ pe lẹyin igba ti awọn obi wọn san ẹgbẹlẹgbẹ owo itusilẹ ni wọn to gba ominira.
Awọn agbebọn naa a maa kọlu awọn ileto kekeke lati ji awọn eeyan gbe ti wọn a si tun dana sun ile wọn.
Ọpọlọpọ lo ti sare kuro ni ile wọn nitori wahala awọn agbebọn ajinigbe wọnyi.
Agbegbe iwọ oorun ariwa orilẹ€de Naijiria ni ọṣẹ wọn pọ si julọ. Ni ipinlẹ Zamfara nikan, ẹgbẹrun mẹta eeyan ni wọn ti gbẹmi wọn lati ọdun 2012, ko si tii dẹkun.
Ẹgbẹ ajijagbara kan wa ti wọn n pe ni Indeginous People of Biafra (IPOB) ti n gbena woju awọn agbofinro lorilẹede Naijiria fun ọpọlọpọ igba. IpoB n fẹ ki ẹya Igbo kuro lara orilẹede Naijiria ki wọn si da duro gẹgẹ bi orilẹede tiwọn.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ni ọdun 2014 ni Nnamdi Kanu da ẹgbẹ naa silẹ. Laipẹ yii ni wọn fi panpẹ ofin mu Kanu lati wa jẹjọ ẹsun igbesunmọmi ati iditẹ ms ijọba. Ijakulẹ nla si ni bi o ṣe bọ sọwọ awọn agbofinro ijọba jẹ fun ẹgbẹ IpoB.
Ohun ti IpoB n ja fun kii ṣe tuntun. Ni ọdun1967 ni awọn adari ijọba ẹkun ila oorun Naijiria nigba naa kede ominira kuro lara orilẹede Naijiria, eyi si ṣokunfa ogun abẹle to mu iku ẹgbẹlẹgbẹ eeyan waye nigba naa.
"Aarẹ Buhari ti ṣeleri ati tẹ ẹgbẹ IpoB ri mọlẹ. Loṣu to kọja lo kede loju opo Twitter rẹ ""gbogbo awọn to n ṣi iwa hu loni"" ni a o ba wi ""ni ede ti wọn gbọ"""
Awọn alaṣẹ Twitter yọ atẹjade naa danu loju opo wọn, lori ẹsun pe o tapa si ofin rẹ lẹyin tawọn eeyan kan lori ayelujara pariwo tako aarẹ Buhari lori rẹ. Iṣẹlẹ yii lo ṣokunfa bi ijọba Naijiria ṣe gbe ẹsẹ le oju opo Twitter lorilẹede Naijiria.
Oríṣun àwòrán, AFP
Agbegbe aringbungbun gusi orilẹede Naijiria ni epo rọbi sodo si julọ, ipenija abo nibẹ kii sii ṣe tuntun.
Epo rọbi ni orisun iṣuna fun ijọba orilẹede Naijiria bẹl si lawọn agbegbọn ẹkun naa n kigbe pe fun pipin alekun ere ori epo rọbi kan ẹkun naa.
Wọn ni wiwa epo lẹkun naa lo n da wahala ayika ati agbegbe tawọn eeyan agbegbe naa n koju silẹ.
Fun ọpọlọpọ ọdun lawọn ọdọ agbebọn ẹkun Niger Delta fi wa lọrun ijọba apapọ nipa jiji awọn oṣiṣẹ ileeṣẹ awapo lagbegbe naa gbe ti wọn si n kọlu awọn irinṣẹ iwapo rọbi bii ọpa epo.
Aarẹ orilẹ€de Naijiria tẹlẹ, Umaru Musa Yar'Adua lo gbe igbesẹ idasilẹ eto idariji fawọn agbebọn naa lọdun 2009 eyi to fopin si wahala awọn ọds agbebọn lẹkun Niger Delta.
Amọṣa, lọwọ yii awsn ọdọ agbegbe naa tun ti n lagogo ikilọ pe afaimọ ki awọn ma tun pada soko wahala wọn nibẹ.
Oduduwa republic: Mo kọ̀ láti kópa nínú ìwọ́de Yoruba Nations rally ni Eko- Iba Gani Adams
Sunday Igboho: Páropáro ní iléẹjọ́ dá, tí wọn sì fi àgádágodo ti ẹnu ọ̀nà
Yatọ si ikede to waye lọjọ Aje pe igbẹjọ awọn eeyan ti DSS ko nile Sunday Igboho yoo waye lọjọ Isẹgun, tii se ọjọ ọdun Ileya, amọ ọrọ ko ri bẹẹ mọ.
Nigba ti BBC Yoruba kan sile ẹjọ giga ijọba apapọ to wa nilu Abuja, lati mọ boya lootọ nile ẹjọ naa yoo joko lati gbọ ẹjọ naa, a ri pe paro paro ni ibẹ da.
Koda, a ko ri awọn agbẹjọro, ọlọpaa tabi awọn eeyan kankan to yọju sile ẹjọ naa lati wa mọ ohun ti yoo sẹlẹ.
Koda, agadagodo ni wọn fi ti ẹnu ọna abawọle ile ẹjọ naa, ti gbogbo ọọfisi to wa nibẹ si wa ni titipa.
Bẹẹ ba gbagbe, Adajọ Yomi Aliyu ti kede saaju fun BBC Yoruba pe oun yoo yọju sile ẹjọ naa lonii, boya adajọ joko lati gbọ ẹjọ naa abi bẹkọ.
Oríṣun àwòrán, DSS
Agbẹjọro fun awọn eeyan mejila ti DSS ko nile Sunday Igboho Yomi Aliyu, ti ni igbẹjọ yoo bẹrẹ lori ẹjọ ti wọn pe tako ajọ DSS nile ẹjọ ni ọjọ Isẹgun ọla.
Bẹẹ ba gbegbe, ọla ọjọ Isẹgun ni ọjọ ọdun Ileya, ti ijọba si ti kede pe isinmi ọlọjọ fun awọn ọmọ Naijiria lati gbadun ọdun naa.
Ireti si wa pe awọn osisẹ ile ẹjọ, awọn agbẹjọro atawọn adajọ gan yoo wa lẹnu isinmi fun ọdun Ileya naa.
Nigba to n fidi ọrọ naa mulẹ fun BBC Yoruba, Agbẹjọro Aliyu ni lootọ ni ijọba fi ọjọ igbẹjọ si ọjọ ọdun ileya.
"Iru rẹ ko sẹlẹ ri, a ko wa mọ ohun to le mu ki adajọ ni oun fẹ gbọ ẹjọ naa lọjọ ọdun, to si mọ pe isinmi wa, gbogbo awọn afurasi yii si ni wọn fẹ ko lọ sile ẹjọ.
Oríṣun àwòrán, DSS
Amọ ibeere ni pe awọn wo gan lo fẹ ko awọn afurasi yii de ile ẹjọ.? Awọn ọlọpaa ti yoo ko wọn lọ gan yoo se ọdun nile.
Amọ, a ko tii mọ iru ara ti wọn fẹ da, awa yoo de ile ẹjọ lọla, bi adajọ joko, bi ko joko, awa yoo wa nibẹ.
Awa la pe ijọba apapọ lẹjọ lati tako bi wọn se ti awọn eeyan naa mọle lọna ti ko ba ofin mu, ti wọn ko si jẹ ki awa agbẹjọro wọn ri wọn."
Aliyu ni ohun to tiẹ wa n kọ awọn lominu ni ọrọ obinrin kan soso to wa laarin wọn, o ni wọn ko gba laaye lati paarọ asọ rẹ.
Ilorin Cripple Couple: Ọṣẹ ìfabọ́ ni tọkọ-taya tó ní ìpèníjà ẹsẹ̀ ń tà láti bọ́ ọmọ mẹ́ta
Pata kan soso to wọ si idi ni ọjọ ti wọn mu, naa lo si wa ni idi rẹ, wọn ko jẹ ko paarọ pata tabi asọ.
Aliyu wa fikun pe ohun ti awọn n beere nile ẹjọ ni pe ki adajọ pasẹ pe ki awọn DSS fi oju awọn eeyan mejeejila naa han sita fun wa.
"A fẹ fi oju wa ri wọn lati mọ boya awọn mejeejila si wa laye tabi wọn ti ku, a fẹ mọ."""
Sallah Celebration: Márosẹ̀ Ibadan sí Eko dí pa torí ọdún Iléyá
Tipa tipa lawọn eeyan fi n raye lẹyin tawọn oni kata kara agbo di opopona marosẹ ilu Eko sí Ibadan pa lọjọ Aiku.
Iroyin ti a gbọ ni pe awọn olowo ẹran ọja Kara patẹ ọja wọn soju titi, bi wọn ti n ta ọja fún ọdun Ileya.
Eyi lo si ṣe okunfa sunkẹrẹ fakẹrẹ ọkọ loju popo naa lẹyin ti ọna tawọn ọkọ n gba di ku tooro.
Awọn akọroyin sọ pe sunkẹrẹ fakẹrẹ ọkọ loju ọna awọn to n bọ wa si ilu Eko de agbegbe Alausa nigbati awọn to n jade lati ilu Eko de Olowotedo ni bii ago marun un irọlẹ ọjọ Aiku.
Niṣe lawọn to fẹ ra agbo gbe mọto wọn si ẹgbẹ mejeeji oju titi marọsẹ naa.
Awakọ ero kan, Ramon to n lọ si ilu Ibadan sọ pe iriri to buru jai loun ni loju popo naa.
"Inira lo jẹ fun wa ni bii ọsẹ melo sẹyin bayii.
Amọ, owo ọkọ to ti le sii ni ko jẹ ko dun mi pupọ ju.
Mo ni ireti pe ijọba wa yoo wa nkan ṣe si iṣoro yii nitori o n ṣakoba fun agọ ara wa, awakọ Ramon lo sọ bẹẹ."
Owo ọkọ Eko sí Ibadan ti o jẹ N1,500 sí N2,000 tẹlẹ ti di N3,000 sí N5,000 bayii.
N8,000 ni wọn n wọ ọkọ lati ilu Eko sí Warri bayii eleyii ti wọn n wọ ni N5,500 tẹlẹ.
Ilorin Cripple Couple: Ọṣẹ ìfabọ́ ni tọkọ-taya tó ní ìpèníjà ẹsẹ̀ ń tà láti bọ́ ọmọ mẹ́ta
Ero ọkọ kan to n rinrin ajo bọ lati ilu Akure sí ilu Eko ni lẹyin ti oun lo wakati meji ninu sunkẹrẹ fakẹrẹ ọkọ tan loun gun ọkada lọ si ibi ti oun n lọ.
Onibara ẹran agbo kan lọja Kara sọ pe oun gbe ọkọ oun soju ọna mọrọsẹ tori kò sí aye ti oun le gbe ọkọ oun si ninu ọja naa.
Ẹwẹ, oludamọran pataki si Gomina ipinlẹ Eko lori ọrọ ayika, Ola Oresanya sọ pe ijọba yoo ṣe ìpàdé pẹlu awọn oṣiṣẹ eleto abo lati dari awọn ọlọja ọhun.
''Ọjà ẹran àgbò kò yá bí ti ọdún tó lọ''
Military Plane Crash: Iléeṣẹ́ ológun ní lóòtọ́ọ́ ní agbébọn já bàálù òun lulẹ̀
Oríṣun àwòrán, NAF
Ileesẹ ologun ofurufu ni Naijiria ti doola ẹmi awakọ ofurufu fun ileesẹ ologun oju ofurufu, Abayomi Dairo lọwọ ọta ibọn tawọn adunkookomọni yin mọ baalu ofurufu ologun ti wọn ja walẹ nipinlẹ Zamfara.
Oludari ẹka alarina ati eto iroyin fun ileesẹ ologun ofurufu, Edward Gabkwetto fidi isẹlẹ baalu to ja naa mulẹ lọjọ Aje ni Dairo n pada bọ nibi to ti lọ sisẹ kan laarin aala ilẹ Zamfara si Kaduna, ni wsn kọlu baalu rẹ naa, to si ja lulẹ.
O ni ori ko Dairo yọ nigba to raye kuro ninu baalu naa ko to ja lulẹ, bi awakọ ofurufu naa si se de ilẹ, ni awọn agbebọn naa gba ya a.
"Gabkwet ni "" Ọjọ Aiku, ọjọ Kejidinlogun osu Keje ọdun 2021 ni deede aago kan ku isẹju mẹẹdogun ni isẹlẹ naa waye."
Ọgagun Dairo to wa ọkọ ofurufu naa lo gbogbo idanilẹkọ lati gba ara ẹni silẹ loju ija to ti ni, lati doola ẹmi ara rẹ.
Oríṣun àwòrán, NAF
Bi o tilẹ jẹ pe awọn ikọ adaluru le, ti wọn si da ibọn bo o lati mu ni kete to balẹ amọ o raye sa mọ wọn lọwọ, to si  ribi fara pamọ si titi ti oorun fi wọ.
"Laarin aajin yii ni ọgagun Dairo lo ina ara ẹrọ ibaraẹnisọrọ rẹ lati fi riran, to si raye rin kọja laarin awọn agbegbe tawọn ikọ afẹjẹwẹ naa tẹdo si, titi to fi raye de ibudo ologun, nibi ti wsn ti gba silẹ.
O si yẹ ki gbogbo eeyan mọ pe ni kete ti wọn gbọ iroyin pe baalu ologun kan tun ti ja lulẹ, ni olori ileesẹ ologun ofurufu, Oladayo Amao, ti pasẹ pe ki wọn sa gbogbo aayan to yẹ lati doola awakọ ofurufu naa."
Ilorin Cripple Couple: Ọṣẹ ìfabọ́ ni tọkọ-taya tó ní ìpèníjà ẹsẹ̀ ń tà láti bọ́ ọmọ mẹ́ta
Gani Adams Vs Ogboni: Ààrẹ Ògbóni ní kò tọ́ fún Gani Adams láti máa bú àwọn Ogboni torí ẹrú Aláàfin ni ipò rẹ̀
Oríṣun àwòrán, Others
Aarẹ Ogboni Awise Agbaye, Oba Adeyinka Adisa Sangolade Arinfanlajogun, ti fun Aarẹ Ọna Kakanfọ ilẹ Yoruba, Iba Gani Adams lesi, lori ọrọ to sọ nipa olori awọn ogboni ti wọn mu lasiko iwọde Yoruba Nation to waye ni ipinlẹ Eko.
Ni Ọjọ kẹta, Osu Keje, Ọdun 2021 ni kọmiṣọna ọlọpaa pẹlu ikọ awọn ọlọpaa nipinlẹ Eko fi awọn oluwọde Yoruba Nation ti wọn mu lasiko iwọde wọn ni ilu Eko han, eleyii ti adari ẹgbẹ ogboni kan wa ninu wọn.
Gani Adams, nigba to n ba BBC Yoruba sọrọ lẹyin iṣẹlẹ yii, bu ẹnu atẹ lu adari ẹgbẹ ogboni naa, nitori o ni o jẹ ki awọn ọlọpaa maa ti oun gbọngbọn lasiko iwọde Yoruba Nation.
Gani Adams, ẹni to sọrọ yii lasiko to n salaye idi ti ko fi le bawọn kopa ninu iwọde Yoruba Nation ni ko si ọba alade nilẹ Yoruba to ga ju aarẹ Ọna Kakanfo lọ.
Amọ, Aarẹ Ogboni Awise lasiko ifọrọwanilẹnuwo kan ninu fidio kan to lu ori ayelujara pa, ni ko tọ si Gani Adams lati bu ẹnu atẹ lu awọn ogboni nitori ẹru ati iranṣẹ Alaafin ti Ọyọ ni ipo rẹ, ti kii ṣe ti adari kankan ni gbogbo ilẹ Yoruba.
''Awọn oye miran ni ilẹ Yoruba ju ipo Aarẹ Ọna Kakanfo lọ, to fi mọ awọn oye ti Ọọni ti Ile-Ife ba fun ẹnikẹni, nitori awọn eekan ni ilẹ Yoruba kii jagun, awọn ẹru ati iranṣẹ nikan lo ma n jagun, gẹgẹ bi ipo Aarẹ Ọnakakanfo.
Oduduwa republic: Mo kọ̀ láti kópa nínú ìwọ́de Yoruba Nations rally ni Eko- Iba Gani Adams
Ninu ọrọ rẹ, Ọba Adeyinka ni ko si ẹnikẹni to wa ni ipo kan tabi ni awọn oye ibilẹ kankan, ti ko gba ọdọ awọn Ogboni kọja, nitori naa ko tọ si Gani Adams lati bu ẹnu atẹ lu ẹnikẹni to di ipo naa mu.
''Nitori ẹni ti tirẹ de lamọ, amọ ko si ẹni to mọ igba ti tirẹ naa ma de, ko tọ si Gani Adams lati fi ẹnikẹni ṣe yẹyẹ, nitori oun naa ti ko si ọwọ ijọba ri to si mọ bo ṣe ri.''
''Gani Adams ti kọja aye rẹ, to ba jẹ lootọ lo sọ wi pe ipo oun ju ọpọlọpọ ipo awọn lọbalọba nilẹ Yoruba lọ.''
''Ohun ti n sọ fun Gani Adams ni pe ọba ilu rẹ nikan lo gaju lọ, ko si ọba kankan nilẹ Yoruba ti ipo rẹ ga julọ.''
Oríṣun àwòrán, Others
''Iranṣẹ Alaafin nikan ni Gani Adams jẹ, ati awọn jagunjagun rẹ lo jẹ adari fun, nitori awọn ipo miran gaju tirẹ lọ ni ilẹ Yoruba''
''Ipo ti Ọọni ti Ile-Ife ba fun ẹnikẹni bii  Akogun,' 'Gbonka, ati bẹẹ bẹẹ lọ ju ipo Aarẹ Ọnakakanfo ni ilẹ Yoruba.''
Bakan naa lo ke si awọn lọbalọba ni ilẹ Yoruba lati kesi Gani Adams lati ti ọwọ ọmọ rẹ bọ aṣọ, ko ye sọrọ kubakugbe si awọn asaaju rẹ ati awọn ti wọn kii ṣe irọ.
Zamfara policemen gunned down: Àwọn ọlọ́pàá méje míràn fi ara pá níbí ìkọlù náà lọ́jọ́ Aiku ní Zamfara
Oríṣun àwòrán, Others
Àwọn agbébọn ti pa ọlọ́pàá mẹ́tàlá ní Zamfara- Gomina Zamfara
Emi awọn agbofinro mẹtala lo ba ikólu awọn agbebọn naa rin ti ọpọ ọlọpaa si fara pa yanayana ni Zamfara.
Ijoba Naijiria ti fidié mulẹ pe ẹmi agbofinro mẹtala lo sọnu nibi ikọlu awọn agbebọn to waye ni ariwa iwo oorun ipinle Zamfara ni ariwa Naijiria loke Oya.
Ojo Aiku ni wọn ni awọn agbebọn naa kọlu awọn olopaa nibẹ.
Koda, iroyin naa ni awọn ọlọpaa meje miran fi ara pa yanayana.
Won ni eyi sẹlẹ  leyin ọjọ kan ti awọn agbebọn ji eniyan aadọta gbe ni awọn abule kan ni Zamfara.
Iyalaje Oodua: Toyin Kolade ṣàlàyé ìdí tí Ooni Ogunwusi ṣe fi jẹ Ìyálájé Oodua
Gomina ipinlẹ Zamfara, Ogbeni Bello Matawalle so ninu atẹjade pe: Awọn agbebọn naa ti dẹ panpẹ silẹ de awọn agbofinro naa ni loju ọna abule kan ni ijọba ibilẹ Bungudu.
Awọn agbofinro ni Zamfara salaye pe ipe ijaya kan ni awọn ọlọpaa ti isẹlẹ yii sẹlẹ si gba.
Oríṣun àwòrán, Others
Ti wọn si gbiyanju lati lọ se iranwọ sibẹ ki awọn agbebọn to kọlu wọ́n.
Lọsẹ to kọja ni wọn pa ogagun agba ologun kan ni Abuja.
Lojó kan naa ni wọn tun pa ọmọ ogun mẹrin nibomii ni Naijiria.
Eto aabo Naijiria lo n ko ọpọ lominu bayii.
Philosophy of Ori: Olatunji ní orí ẹni ló ń dúró ti ní lọ́jọ́ ìṣòro àti lójú ikú
Awọn baba nla wa lo maa n pa a lowe pe ori ni a ba bọ, ka fi orisa silẹ nitori ko si orisa to n gbe ni bii ori ẹni.
Wọn a tun ni orisa lo ni ọjọ kan ipọnju, ori ẹni lo ni ọjọ gbogbo.
Sugbọn fun ọpọ ọmọ ilẹ Kaarọ Oojire, o loju ẹni to mọ itumọ ori bibọ, pataki rẹ ati ba se le bọ ori wa, ti yoo fi gbe wa.
Ọna lati mọ iwulo ori bibọ lo mu BBC Yoruba kan si Babalawo kan, Efuwape Olatunji, ẹni to salaye bi a se n bọ ori ati iwulo rẹ fun ẹda kọọkan.
Nigba to n ba BBC Yoruba sọrọ, Baba awo Afuwape ni ori ni ayanmọ ati Ẹlẹda ẹni, ko si yẹ ka wa laye lai bọ.
O ni ori lo n duro ti ẹda lojoojumọ, lasiko isẹlẹ ibi ati ni ọjọ iku ẹni pẹlu.
O wa fi ẹsẹ Ifa kan tọ ọrọ rẹ lẹyin eyi to sọ pataki ori bibọ, to si tun se afihan ọna to yẹ ka gba lati maa bọ ori wa loore koore.
Sunday Igboho Arrest: Reno Omokri ní Buhari ń ràgà bo àwọn ẹ̀yà rẹ̀, tó sì ń lépa àwọn akọni tó ń gbèjà ẹ̀yà tiwọn
Oríṣun àwòrán, sunday_igboho1/Instagram
Amugbalẹgbẹ tẹlẹ fun aarẹ ana, Reno Omokri ti bu ẹnu atẹ lu bi ijọba se mu ajafẹtọ ọmọniyan nilẹ Yoruba, Oloye Sunday Adeyemo, ti ọpọ eeyan mọ si Igboho ni Cotonou, lorilẹede Benin.
Nigba to n sọrọ lori igbesẹ naa loju opo Facebook rẹ, Omokri ni awọn ọmọ Naijiria yoo korajọpọ lati da ohun alumọni wọn jọ lati gbe ajafẹtọ ilu naa lẹyin.
"Omokri ni ""bi wọn se mu Sunday Igboho ni Cotonou ko dara rara, akọni to n ja lati daabo bo awọn eeyan rẹ ni."
A gbọdọ san gbogbo isẹ rere ti Igboho se pada fun nipa kiko awọn ohun alumọni wa papọ lati gbeja rẹ nile ẹjọ.
Buhari ti kọ lati ri awọn ẹbi rẹ to n ja baalu olowo iyebiye to jẹ ti Naijiria lulẹ, bii adunkooko mọni.
Oríṣun àwòrán, Reno Omokri Facebook
Wọn kọkọ pa irọ pe baalu kankan ko ja, amọ nigba ti ori ko awakọ baalu naa yọ, to si ja irọ wọn, ni wọn ba bọ sita lati kede pe lootọ ni baalu ja.
Amọ se ni Buhari n lepa ẹtahoro awọn ọmọ Naijiria to jẹ akọni ti wọn dide lati pin awọn apani darandaran lọwọ isẹ ibi wọn.
"Idi ree ti mo se n duro ti Igboho, kii se pe tori o fẹ pin Naijiria amọ tori pe o dide lati gbeja awọn eeyan rẹ."""
Philosophy of Ori: Olatunji ní orí ẹni ló ń dúró ti ní lọ́jọ́ ìṣòro àti lójú ikú
Imo Police: Pàsítọ̀ tó ń dí ọkọ lọ́wọ́ láti máṣe gun aya rẹ̀ ní ọ̀bẹ, ló gún pa
Oríṣun àwòrán, Gordon Johnson
Yoruba bọ, wọn ni onlaja níí fara gbọgbẹ, ti apọnmilamu si maa n ri eegun nigba mii.
Bayii gan-an lọrọ ṣe rí fun pasitọ ijọ Redeem kan, Thompson Onyekwuru niluu Owerri nibi to ti n la ija laarin ọkọ ati iyawo.
Ileeṣẹ ọlọpaa to fidi iṣẹlẹ ọhún mulẹ sọ pe, ọkunrin kan, Obumneke Onyemechileuzo lo n lu iyawo rẹ, Ogechi ni alubami, ki pasitọ naa to gbiyanju lati lawọn nija.
Agbẹnusọ ileeṣẹ ọlọpaa ipinlẹ Imo, Mike Abattam ṣalaye pe pasitọ n gbiyanju lati ri pe ọkunrin naa ko gun iyawo lọbẹ ni ọkunrin yii fi gun pasitọ lọbẹ, lẹyin to si ṣubu lulẹ gbi.
"Nigba t'awọn ọlọpaa de ibi iṣẹlẹ naa, wọn ba ọkunrin yii nibi to ti n lu aya rẹ lọwọ.
Ti Ọgbẹni Onyemechileuzo ṣe rí awọn ọlọpaa ni o mura ìjà tí o sí gbiyanju lati gun ọlọpaa kan lọbẹ lọrùn.
Lẹyin naa ni awọn ọlọpaa yinbọn fun un lẹsẹ lati le daabo bo ara wọn, Ọgbẹni Abattam ṣalaye."
Philosophy of Ori: Olatunji ní orí ẹni ló ń dúró ti ní lọ́jọ́ ìṣòro àti lójú ikú
Agbẹnusọ ileeṣẹ ọlọpaa ni Onyemechileuzo pada ku lẹyin to ṣeṣe pẹlu ibọn to ba a lẹsẹ.
Ọgbẹni Abattam ṣalaye siwaju sii pe wọn gbe pasitọ ati Ọgbẹni Onyemechileuzo pẹlu aya rẹ lọ sile iwosan, nibi ti awọn dokita ti fìdí rẹ múlẹ pe pasitọ ati ọkunrin naa ti di oloogbe.
O ni iyawo rẹ si n gba itọju lọwọ nile iwosan nigba ti wọn si ti ko awọn oku lọ si mọṣuari.
Agbẹnusọ ileeṣẹ ọlọpaa ni awọn ọlọpaa ti mu ọbẹ ti afurasi naa fi gun pasitọ lọ si agọ ọlọ́pàá.
Ẹwẹ, kọmiṣọnna ọlọpaa ipinlẹ Imo ti paṣẹ pe kawọn ọlọpaa ṣe iwadii kikun lori ohun to ṣokunfa iṣẹlẹ naa.
Bakan naa ni kọmiṣọnna ọlọpaa rọ àwọn araalu lati maa lepa alaafia kí wọn sì maa bọwọ fún ofin.
Iyalaje Oodua: Toyin Kolade ṣàlàyé ìdí tí Ooni Ogunwusi ṣe fi jẹ Ìyálájé Oodua
Sunday Igboho: Ọ̀pọ̀ ‘ẹ̀ṣẹ̀’ tí ajìjàgbara ṣẹ ìjọba rèé, tó fi di ẹni tí wọn ń wá
Oríṣun àwòrán, sunday_igboho1/Instagram
Yoruba ni n ko le wa ku, kii jẹ oye ile baba rẹ, bẹẹ si ni aileja ni jẹ ita baba mi ko de ihin.
Kii se iroyin mọ pe wọn ti mu Oloye Sunday Igboho ni ilu Cotonou lorilẹede Benin, amọ o yẹ ka le ran ara wa leti nipa awọn ohun ti Igboho se, to fi di ẹni ti ijọba apapọ n le kiri.
Ti a ba n sọrọ nipa awọn eeyan to dide lati gbeja ẹya ti wọn ti wa, ọkan soso Ajanaku, tii mi igbo kijikiji ni Oloye Sunday Adeyemo, ti ọpọ eeyan mọ si Igboho.
Idi ni pe lasiko ti ipenija eto aabo gbona jainjain ni agbegbe rẹ, ni Igboho dide lati gbe iran rẹ nija.
Lati igba yii wa si lo ti di ajijagbara ti awọn eeyan n sa tọ lọ lati gbe wọn nija, ko to wa di pe o bẹrẹ si pe fun iyapa Naijiria ati idasilẹ orilẹede Yoruba.
Sunday Igboho: Fulani kò leè dúró, táa bá lo ohun ta jogún lọ́dọ̀ àwọ̀n bàbá wa
Odu ni Sunday Igboho saaju asiko yii, to si ti maa n se atilẹyin fun oloselu bii Rashidi Ladoja ati awọn eeyan miran ti iya n jẹ.
Amọ awọn igbesẹ to gbe ree, to fi ba pao ibinu ijọba Naijiria pada.
Amọ isẹ ijijagbara rẹ yii bẹrẹ nigba to lọ si inu igbo to wa nilu Kishi nipinlẹ Oyo lati wa awọn agbebọn darndaran to fi igbo naa se buba lati jale ati paayan.
Isẹlẹ yii waye ni osu Kẹwa ọdun 2020 to kọja, ti Igboho, awọn ọdẹ ibilẹ, ati fijilante si pawọpọ sisẹ naa, to si ko awọn afurasi ọdaran to ko ninu igbo ọhun le awọn agbofinro lọwọ.
Ni osu kan lẹyin isẹlẹ yii ni Sunday Igboho kede pe ta ba dakẹ, tara ẹni maa n ba ni dakẹ ni, to si ke si awọn ọmọ Yoruba lati jade fun iwọde.
Ọjọ Kinni osu Kẹwa ọdun 2020 ni wsn fi iwọde naa si, eyi ti wọn seto lati waye ni oke okun pẹlu.
Amọ Sunday Igboho ko lọ sigboro ni ọjọ naa lati se iwọde ọhun bi o tilẹ jẹ pe oun ati awọn ọmọlẹyin rẹ duro siwaju ile rẹ lati sọrọ pẹlu asia lọwọ wọn.
Oba Gbolahan Timson Shomolu Bariga ní 'Restructuring'ti bọ́ aṣọ kò bá Omọyẹ mọ́!
Ni ọjọ kẹẹdogun osu Kinni ọdun 2021 ni Sunday Igboho lọ si ilu Igangan lagbegbe Ibarapa, to si ke si awọn Fulani to wa ni agbegbe naa lati ko aasa wọn kuro nibẹ.
O si kede ọjọ meje pe ki wọn fi palẹ ẹru wọn mọ, bibẹẹkọ, oun yoo wa ba wọn nibẹ lati le wọn.
Nigba ti ọjọ pe, o lọ sagbegbe naa lootọ, to si ba awọn eeyan ibẹ sọrọ, amọ ni kete to kuro tan ni idarudapọ waye, ti wọn si jo ile Seriki Fulani ati awọn dukia rẹ.
Bakan naa ni Igboho tun lọ si agbegbe Yewa nipinlẹ Ogun ni ọjọ Kinni osu keji ọdun 2021 lati lọ le awọn afurasi ọdana daranran to n pa awọn eeyan, fipa ba ni lopọ tabi ja awọn araalu ni ole.
Lasiko yii si ni awọn eeyan agbegbe naa n fo fayọ pe alaafia to awsn lọwọ nitori awọn afurasi ọdaran naa ti fi agbegbe awọn silẹ tori abẹwo Igboho.
Koda, wọn ni iroyin Igboho lasan ti to lati da jinnijinni bo awọn afurasi ọdaran naa, ti wsn si n sa kijokijo, ti wsn ba ti gbọ orukọ Igboho.
Tunde Bakare: Àjọjẹ kò dún bẹ́nìkan kò ní ló fa ìjà S Igboho,bẹ́ẹ̀ ìjọbati gbẹ́rù kọjá orí
Lẹyin ti Sunday Igboho sinmi lile awọn ọdaran darandaran, lo ba gunle ipe fun idasilẹ orilẹede Yoruba, eyi to tumọ si iyapa fun orilẹede Naijiria.
Sunday Igboho ati ẹgbẹ Ilana ọmọ Oodua, ti alagba Banji Akitoye n dari rẹ, gbe awọn iwọde yii lọ kaakiri igun mẹrẹẹrin to wa nilẹ Yoruba.
Yatọ si pe iwọde fun Yoruba Nation yii waye lawọn ilu nla nla nilẹ Kaarọ Oojire, ko si ipinlẹ kankan lẹkun iwọ oorun guusu Naijiria, ti iwọde naa ko de rara.
Bẹẹ ni wọn tun n gbe iwọde fun idasilẹ Yoruba Nation lọ sawọn ile ẹkọ, aarin ọja, ibudokọ ati bẹẹ bẹẹ lọ.
Bi ikede fun idasilẹ Yoruba Nation si se n waye ni Naijiria naa ni wọn n se iwọde ni oke okun, eyi to mu ki ikede naa maa gbilẹ lojoojumọ.
Lati igba yii wa si ni Sunday Igboho ti n ri pipọn oju ijọba Naijiria lori ẹsun pe o fẹ da ilu ru, to si n pe fun ituka orilẹede yii.
Bẹẹ ni ọpọ igba ni wọn ti gbiyanju lati mu si ahamọ, nipa lilọ si ile rẹ, ti igbesẹ ijọba si n ja si pabo.
Olagunsoye Oyinlola: Kí Olorun dáríjì wá lórí ọ̀rọ̀ yíi, a ti kùnà ìlérí wa fún ìran Yorùb
Amọ ni ọjọ Kinni osu Keje ọdun 2021, ni awọn osisẹ DSS ya bo ile Sunday Igboho ni ọganjọ oru, wọn pa eeyan nibẹ, ti wọn si ba ọpọ dukia olowo iyebiye jẹ nibẹ.
Koda, wọn ko eeyan mejila kuro ninu ile naa lọ si ọọfisi wọn ni Abuja, ti awọn onitọun si wa ni ahamọ DSS titi di oni.
Lẹyin o rẹyin ni iroyin gbalẹ pe ọwọ ti tẹ Oloye Sunday Igboho nilu Cotonou lorilẹede Benin lasiko to fẹ tẹ baalu leti lọ si orilẹede Germany.
Sunday Igboho Arrest: Ìgbà márùn-ún rèé tí ajìjàgbara bọ́ lọ́wọ́ ìkọlù láti mu
Oríṣun àwòrán, sunday_igboho1/Instagram
Sunday Adeyemo, ti ọpọ eeyan mọ si Igboho lo jẹ asiwaju ajijagbara fun iran Yoruba, to si tun n pe fun idasilẹ orilẹede Yoruba Nation.
Nitori bo se n pe fun iyapa Naijiria yii, ni ijọba se n gbiyanju lati mu si ahamọ, ko si finmu kata ofin nitori ẹsẹ nla ni igbinyanju lati mu iyapa ba orilẹede yii.
Lati igba naa ni Sunday Igboho ti n pariwo pe oniruuru ikọlu lo n waye si ile oun ati lasiko to ba n rin laarin ilu.
Amọ ni alẹ ọjọ Aje, ọjọ Kọkandinlogun osu Keje ọdun 2021, ni iroyin gbalẹ kan pe ọwọ ijọba ti tẹ Sunday Igboho ni ilu Cotonou, lorilẹede Benin.
K ọwọ sinku ijọba to tẹ ajijagbara naa, akoko marun ree ti ariwo ti gbalẹ kan pe ikọlu waye si Igboho pẹlu ete lati mu si ahamọ ijọba.
Igba akọkọ ti ikọlu yoo waye si Sunday Igboho ni akoko to n lọ silu Eko, lati lọ sile Iba Gani Adams.
Opopona Marosẹ Ibadan silu Eko, niwaju ile Guru Maharaji ni awọn osisẹ ọtẹlẹmuyẹ DSS ti da ikọ rẹ duro.
Iroyin to gbalẹ kan nigba naa ni pe awọn DSS naa fẹ gbe Sunday Igboho ni amọ ti awọn onitọun ni ko ri bẹẹ.
Oríṣun àwòrán, Facebook/Koiki Media
Bakan naa ni iroyin gbode pe awọn afurasi Sọja meji wa tọpinpin ile Sunday Igboho amọ ti awọn ọmọ ẹyin rẹ mu wọn mọlẹ.
Awọn afurasi Sọja naa lo wọ asọ ologun ti wọn si n gun ọkada kọja ni ogunjọ osu kẹta ọdun 2021 ti isẹlẹ naa waye.
Amọ awọn afurasi naa ni awọn n lọ jẹjẹ tawọn ni wọn da awọn duro, ti awọn ko si wa se ohunkohun ninu ile naa.
Lẹyin o rẹyin ni wọn fa awọn afurasi naa le ileesẹ ọlọpaa ipinlẹ Oyo lọwọ, ti ileesẹ ologun si fi ikede sita pe awn ko ni pẹlẹngọ lati mu Igboho tawọn ba setan lati se bẹẹ.
Awọn janduku kan la gbọ pe wọn ya bo ile akọkọ ti Sunday Igboho kọ si agbegbe Soka nilu Ibadan, amọ kii se ile yii lo n gbe.
Aimọye dukia lo jona ninu ile naa, ti wọn si tun ni awọn agbebọn ọhun gbe kẹẹgi epo pẹtiroolu wa lati sun ile naa ni.
A gbọ pe ọpẹlọpẹ awọn ọmọ ẹyin Igboho to jade ti wọn, tawọn janduku ọhun to gbe ọkọ bọọsi ati ayọkẹlẹ wa, si sa lọ.
Igba kẹrin ti ariwo yoo sọ pe wọn se ikọlu sile Sunday Igboho ni akoko ti wọn ni awọn osisẹ agbofinro ko ọkọ bọọsi wa lati fun Igboho ni lẹta kan.
Wọn ni ọga agba ọlọpaa nilẹ yii lo fi lẹta naa ransẹ si amọ tawọn ọmọlẹyin Igboho yari lati gba iwe naa.
Nigba to di idaji oru Ọjọbọ, ọ̀jọ̀ Kinni osu Keje ọ̀dun 2021, ni awọn gende agbebọn, ti wọn jẹ osisẹ DSS ya bo ile ajijagbara naa.
Ni ọjọ naa, wọn pa eeyan meji gẹgẹ bi wọn ti kede rẹ, ti wọn si ba ọpọ dukia olowo iyebiye jẹ ninu ile naa amọ wọ ko ri Igboho mu rara.
Bakan naa ni wọn ko eeyan mejila ninu ile naa si ahamọ wọ, ti wọn si tun ko awọn dukia miran lọ si ọọfisi wọn pẹlu.
Lara awọn dukia ọdun ni awọn asọ oogun ibilẹ ti Igboho fi n se isọra, awọn iwe asẹ iwọlu rẹ nilẹ okeere, owo Naira, Euro, Dọla ati pọun, to fi mọ awọn ẹsọ ara ni orisirisi.
Lati akoko naa si ni ijọba ti kede pe awọn n wa Sunday Igboho, ki ọwọ wọn to wa tẹ ni Cotonou, lorilẹede Benin.
Sunday Igboho: Òfin ilẹ̀ adúláwọ̀ kò fún ìjọba láṣẹ́ láti gbé Igboho kúrò ní Cotonou fún ìdí kankan
Oríṣun àwòrán, sunday_igboho1/Instagram
Agbẹjọro fun oloye Sunday Igboho ti sapejuwe bi ikọ ọlọpa INTERPOL se mu onibara rẹ nilu Cotonou lorilẹede Benin bii eyi to ba ni lojiji.
Atẹjade kan ti amofin Yomi Aliyu fi ransẹ si BBC Yoruba lo sisọ loju ọrọ yii pẹlu afikun pe yoo dara ki awọn ọlọpa agbaye INTERPOL mọ nipa igbesẹ tawọn DSS ti kọkọ gbe saaju nipa kikọlu ile Igboho, ti wọn si pa eeyan nibẹ pẹlu biba ọpọ dukia jẹ.
Aliyu ni Awọn DSS ko ri ohunkohun to lodi sofin nile Sunday Igboho amọ wọn pa eeyan meji, ti wọn si gbe oku wọn lọ, ti wọn si ko ibọn meji to jẹ ti ẹsọ Adisa Saheed Olalekan.
Bakan naa lo ni wọn se afihan eeyan mẹtala ti wọn ko nile naa, ti onibara oun si ti ni oun ko mọ ohunkohun nipa awọn ohun ija ti DSS se afihan rẹ pe wọn ko nile oun.
"O ti wa ni akọsilẹ pe awọn ibọn ti DSS patẹ rẹ yii ni DSS ti patẹ rẹ saaju lọdun 2013 ninu isẹlẹ miran, to si wa loju opo Facebook lọdun 2013 bi o tilẹ jẹ pe DSS ti pa a rẹ loju opo ayelujara rẹ.
Sunday Igboho: Fulani kò leè dúró, táa bá lo ohun ta jogún lọ́dọ̀ àwọ̀n bàbá wa
Ọkan lara awọn eeyan ti wọn pa naa, Saheed Adisa Olalekan lo ni ile itaja Oladams Motors, Osogbo, o si wa sile Igboho lati jiroro lori katakara ọkọ ni.
O wa pẹlu ẹsọ ọlọpaa meji, bi o tilẹ jẹ pe awọn ẹsọ ọlọpaa naa ko si lara awọn eeyan ti DSS foju wọn han faraye, ti ibọn wọn meji si wa lara ibọn ti DSS patẹ rẹ."
Agbẹjọro Sunday Igboho wa tọkasi pe adehun to wa laarin orilẹede Naijiria, Togo, Ghana ati orilẹede Benin ko fi ọwọ si pe ki wọn gbe ẹni to n sa lọ tori ọrọ oselu.
O ni ofin ọhun lo sọ pe orilẹede ti ẹni to n sa lọ ba wa le ma fi onitọun silẹ nitori idaduro to wa ninu eto idajọ tabi nitori idẹyẹsi.
Bakan naa lo ni abala ofin ẹtọ ọmọniyan ẹsẹ ogun ninu ofin ilẹ adulawọ ti awọn orilẹede mẹrẹẹrin naa fọwọsi ni gbogbo wọn lo gbọdọ daabo bo ẹtọ fun ijijagbara.
Philosophy of Ori: Olatunji ní orí ẹni ló ń dúró ti ní lọ́jọ́ ìṣòro àti lójú ikú
"Ofin yii lo mu ki Oloye Sunday Igboho jẹ ẹlẹsẹ nidi oselu, ti wọn ko le gbe ni apayanka wale tabi gbe kuro nilẹ Benin Republic fun idi kankan.
Koda, wọn mu aya Sunday Adeyemo, Ropo , tii se ọmọbibi orilẹede Germany pẹlu rẹ ni Cotonou, iru ẹsẹ wo ni oun naa sẹ ti wọn fi mu?"
Amofin Aliyu wa n rọ ijọba orilẹede Benin ati awujọ agbaye, paapaa orilẹede Germany lati dide pinwọ iwa ta ni yoo mu mi tijọba Naijiria n hu.
O ni ki awujọ agbaye kọ lati gba ẹbẹ ijọba lati gbe onibara oun kuro ni Cotonou nitori o ti pe ẹjọ saaju niwaju ileẹjọ agbaye to n gbọ ẹsun iwa ọdaran, ICC.
Sunday Igboho: Olùgbé Benin Republic ní káwọn ọba Yorùbá máa tètè pariwo pé Igboho kò lẹ́ṣẹ̀ lọ́rùn
Oríṣun àwòrán, sunday_igboho/Instagram
Ẹnikan ti ke si awọn ọba alaye nilẹ Yoruba lati tete dide si ọrọ itusilẹ Sunday Igboho, ki ọrọ naa to bọwọ sori.
Ninu fidio kan to jade sori ayelujara ni ọmọ Yoruba kan, Oloye Agbomola Ajirotutu ti n ke gbajare pe awọn ọba Yoruba nilo lati kan si aarẹ orilẹede Benin ni kiamọsa.
Ajirotutu, to n gbe nilu Cotonou salaye pe tawọn oriade nilẹ Yoruba ba se fidio pe eeyan rere ni Igboho, eyi too seranwọ lati ri idande rẹ gba.
O ni lootọ ni oun n se atilẹyin fun idasilẹ Yoruba Nation amọ lori ọrọ Igboho, o kere tan ọba mẹwa gbọdọ jade lati maa fọnrere pe Sunday Igboho ko sẹ rara, iya oselu lo n jẹ.
"Awọn ọba ti ko ba le wa sorilẹede Benin, le se fidio jade laarin ọjọ Isẹgun si Ọjọru pe ki aarẹ orilẹede naa mase da Igboho pada si Naijiria.
Olagunsoye Oyinlola: Kí Olorun dáríjì wá lórí ọ̀rọ̀ yíi, a ti kùnà ìlérí wa fún ìran Yorùb
Ofin Benin lootọ ni ko le gba ijọba Naijiria laaye lati gbe Igboho lọ amọ wọn yoo se iwadi pe iru eeyan wo ni Igboho funra rẹ.
Se ọdaran ti wọn pe lo jẹ ni abi wọn n parọ mọ, amọ ohun ti awọn ọba Yoruba ba sọ bayii pe Igboho kii se eeyan buruku, ajijagbara ni.
Eyi yoo ran Igboho lọwọ pupọ lọdọ ijọba ilẹ Benin lati fi opin si gbogbo isoro to n koju, ti wọn ko si ni fa a kalẹ fun ijọba Naijiria."
Bakan naa ni Ajirotutu ni oun ko fẹ ki ẹmi eeyan lo aarẹ Benin lati tako Sunday Igboho ni se n kigbe pe kawọn agbaagba Yoruba dide, maa pariwo tori abala iwadii nipa Igboho ni Benin wa bayii.
O fikun pe awọn ọba ni orilẹede Benin ti jade sita lati gbe Igboho nija, iyoku wa ku sọwọ awọn Yoruba lati tete dide si ọrọ naa lasiko yii.
Okunade Sijuwade: Ìfẹ́ tí Sarun tó súnmọ́ Ooni jù láyé ní sí í ló sọ ọ́ di abọ́bakú- Adeye
Sunday Igboho: Ooni, Olujinmi, Olugbon, Akin Osuntokun àtàwọn àgbàgbà Yorùbá forí korí
Oríṣun àwòrán, sunday_igboho/Instagram
Ooni Ile Ife àtàwọn èèkàn ilẹ̀ Yorùbá ṣèpàdé ìdákọ́nkọ̀ lórí ọ̀rọ̀ Sunday Igboho
Ooni Ile Ife, Oba Adeyeye Ogunwusi ṣe ipade pọ pẹlu awọn eekan nilẹ Yoruba lori bawọn ọlọpaa ṣe mu Oloye Sunday Adeyemo ti ọpọ mọ sí Sunday Igboho ni Cotonou, orilẹede Benin.
Iroyin sọ pe Sẹnẹtọ Abiodun Olujimi to n ṣoju ẹkun Guusu Ekiti, Ọgbẹni Akin Osuntokun to jẹ oladamọran lori ọrọ oṣelu sí aarẹ Naijiria tẹlẹ rí, Olusegun Obasanjo ati Oludije fun ipo gomina ipinlẹ Eko f'ẹgbẹ PDP, Jimi Agbaje wa nibi ipade idakọnkọ ọhun.
Igbakeji alaga igbimọ awọn lọba lọba ipinlẹ Oyo, Oba Francis Alao, Olugbon ti Orile Igbon ti oun naa wa nibi ipade ọhun ṣalaye pe, awọn ọrọ to ni ṣe pẹlu idagbasoke Naijiria lawọn pe ipade naa fun kawọn to sọrọ lori bi wọn ṣe mu Igboho.
"Ooni lo pe wa si ipade lati sọ asọyepọ lori bi a ṣe le pada maa ṣe nkan ni itubi inubi bi ti tẹlẹ.
Peter Fatomilola kìí ṣe agbódegbà Yahoo, Ó ń fẹ́ kí ìjọba, Òbí àti ilé ìjọsìn ṣe ohun tó y
Ọpọ nkan lo ti bajẹ lorilẹede Naijiria lati bi ọdun melo kan sẹyin ninu eto oṣelu, ọrọ aje at'awọn nkan mii.
A fẹ ṣe atunṣe ọpọ awọn nkan yii.
A ni lati mọ nipa ohun to n lọ lọwọ lorilẹede Naijiria, a maa ba ọpọ eeyan ati oniruuru ẹgbẹ sọrọ lati ri pe nkan pada bọ sipo.
Gbogbo ipinlẹ to wa nilẹ Yoruba ni a mẹnu ba nibi ba ninu ipade naa.
Gbogbo ọba alade ni a maa ba sọrọ nitori asiko ti to lati ṣe atunṣe ohun to ti bajẹ, Olugbon lo sọ bẹẹ."
Amọ wọn ko sọ ohun ti wọn fi ẹnu ọrọ jona le lori nipa isẹlẹ to n waye si Sunday Igboho fun awọn akọroyin.
Alẹ ọjọ Aje ni awọn agbofinro mu Igboho ni papakọ ofurufu Cadjehoun ni Cotonou nibi ti iroyin kan ti sọ pe o ti fẹ rinrin ajo lọ si orileede Germany.
Olagunsoye Oyinlola: Kí Olorun dáríjì wá lórí ọ̀rọ̀ yíi, a ti kùnà ìlérí wa fún ìran Yorùb
Ni bii ọsẹ mẹta sẹyin ni ajọ ọtẹlẹmuyẹ DSS kede pe awọn n wa Igboho lori ẹsun pe o ko ohun ija ogun pamọ sile, amọ o ni ko si ohun to jọ bẹẹ.
Ti ẹ ko ba gbagbe, ijọba apapọ ti paṣẹ fawọn oṣiṣẹ eleto abo lati fọwọ ofin mu Igboho nibi kibi ti wọn ba ti ri i.
Sunday Igboho: Olùwọ́de yoǹbó Ooni lórí ìgbésẹ̀ láti yọ Igboho ní àhámọ̀ àmọ́ rọ Oluwo láti tún èrò rẹ̀ pa
Awọn oluwọde to n pe fun itusilẹ Sunday Igboho to wa ni ahamọ nilu Cotonou, lorilẹede Benin, ti n fi ọrọ ransẹ si Oluwo tilu Iwo lasiko iwọde wọn.
Ọkan lara awọn oluwọde naa, to pe ara rẹ ni Comrade Komolafe, to jẹ ọmọbibi ilu Iwo ni oun dupẹ lọwọ Ooni tilu Ile Ife, Ọba Adeyeye Enitan Ogunwusi, Ọjaja Keji lori awọn igbesẹ to n gbe.
O ni lati igba ti wọn ti mu Sunday Igboho lalẹ ọjọ Aje ni Ooni ko ti sun, to si gbe igbimọ ẹlẹni mọkandinlọgbọn dide lati lọ ja fun itusilẹ Igboho.
"Ooni jẹ ka mọ pe iru wọn lo yẹ nipo oriade tori baba naa jẹ ẹni kan to ni iwa ifiraẹnijin, to si jẹ ka mọ pe gbogbo eeyan Kaarọ Oojire lo jẹ ọmọ bibi inu oun.
Mo wa n gbadura pe ori apere awọn babanla wọn ko ni gbona mọ wọn, bakan naa ni mo si n ke si awọn ọba alaye yoku lati fi ti Ooni se awokọse rere."
Oluwo ilu Iwo ba BBC Yoruba sọrọ lori awuyewuye pẹlu awọn Ọba
Comrade Komolafe wa lo akoko naa lati kesi Oluwo tilu Iwo, Ọba Abdulrasheed Adewale Akanbi, Telu Kinni pe ko maa fura pe awọn eeyan n wo oun.
"O yẹ ki Oluwo mọ pe awọn eeyan n wo ohun, wọn si n gbọ ohun to n sọ. Awọn eeyan kan lo kọkọ lo ori itẹ naa, ti wọn si lo daadaa, ti orukọ wọn ko si parẹ.
Ohun ti Oluwo si n se loni naa, itan lo n kọ, gbogbo ohun tẹ sọ ni Yidi lọjọ ọdun Ileya ana pe ki awọn eeyan kalọ si aafin yin wa lọ jẹun.
Ẹ ni ohun to sẹlẹ si Sunday Igboho ko kan yin, jẹ ka mọ iha tẹ kọ si Igboho, ko si yẹ ko ri bẹẹ rara.
Ti awọn kan ba tiẹ n sọrọ yin laidaa, awa maa n jẹri lẹyin pe ẹ ko le sọ iru rẹ nita gbangba, pe ẹ nifẹ si Sunday Igboho.
Oluwo Divorce: ko si ẹni ti kò mọ pé ọmọ ilẹ̀ òkèrè ni mó fi ṣe aya
A wa n rọ baba wa Akanbi lati yi ohun ti wọn fi n sọrọ pada lati isinsinyii lọ, Ọlọrun ko ni jẹ ki ori itẹ gbona mọ yin o.
Awa ọmọ bibi ilu Iwo ko faramọ ohun tẹ n sọ yẹn, a dẹ n fi asiko yii sọ fun a ko fara mọ ohun ti baba Oluwo n sọ.
Awa kii se ọmọ ale Iwo, ẹ dakun baba wa, ẹ maa fi suuru sọrọ, kẹ si maa gbe gbogbo igbesẹ tẹ ba le gbe lori ọrọ Igboho.
Oluwọde naa wa kasẹ ọrọ rẹ nilẹ pe Sunday Igboho kii se ọdalẹ tabi ọdaran, yoo si dara ki wọn tete fi silẹ.
Oríṣun àwòrán, sunday_igboho/Instagram
Iroyin ti wa tẹ lọwọ pe iwọde alagbara kan yoo waye ni aarọ oni nilu London lori ọrọ Sunday Igboho.
Gẹgẹ bi agbẹnusọ fun Oloye Sunday Igboho, Olayomi Koiki ti kede loju opo Facebook rẹ, awọn ọmọ Naijiria to tẹdo silẹ UK ni yoo korajọpọ fun iwọde naa.
O ni iwọde alagbara naa yoo waye ni ojule kẹwaa, Opopona Downing nilu London, eyi tii se ọọfisi ileesẹ olootu ijọba ilẹ UK, Boris Johnson.
Ẹ jẹ ka ri pe a yọju sibi iwọde naa, ka si maa ranti pe asiko yii nikan la le dide lati ke pe awujọ agbaye nipa ohun to n lọ ni Naijiria."
Wọn ti gbe igbesẹ saaju lati gba ẹmi Sunday Igboho ni ọjọ kinni osu Keje amọ ti ko seese fun ijọba, o si yẹ ko ye wa pe ẹmi rẹ ni wọn n wa.
Iyalaje Oodua: Toyin Kolade ṣàlàyé ìdí tí Ooni Ogunwusi ṣe fi jẹ Ìyálájé Oodua
"Nigba to ti nira fun wọn lati ra Igboho si ọdọ wọn, ohun ti wọn fẹ se bayii ni lati gba ẹmi rẹ."""
Agbẹnusọ fun Igboho ni lati ọjọ ti DSS ti kọlu ile Sunday Igboho ni awọn eeyan ti n jade ni meji mẹta lati se iwọde ni Central London lojoojumọ.
O ni awọn eeyan yii ko ni ki awọn pọ niye, ki wọn to jade, amọ ohun to se pataki ni pe awọn eeyan to n lọ lagbegbe naa n ri wọn.
"Awọn eeyan ti ẹ ko lero kuku n ri wọn, ti wọn si n se akiyesi wọn, ti wọn si n sọ pe ko si ọrọ anbojuwẹyin mọ lori ọrọ Yoruba Nation.
Ori ọrọ Yoruba Nation si la duro le lori. A ko gbọdọ sa sẹyin tabi fi oju pamọ, afigba ta ba gba Yoruba Nation."
O wa rọ awọn ọmọ Yoruba to n gbe nilu ọba lati jade wa kopa ninu iwọde naa.
Peter Fatomilola kìí ṣe agbódegbà Yahoo, Ó ń fẹ́ kí ìjọba, Òbí àti ilé ìjọsìn ṣe ohun tó y
Jumoke Autopsy Report: Èsì àyẹ̀wò ní ìbọn ló pa Jumoke l'Ojota àmọ́ ọlọ́pàá ní àpá ọ̀bẹ wà lára òkú rẹ̀
Oríṣun àwòrán, facebook/ koiki media
"Ayẹwo fihan pe Jumoke Oyeleke ti iroyin sọ pe ọta ibọn pa nibi iwọde fun idasilẹ Yoruba Nation ni Ojota l'Eko gbẹmi mi, lẹyin ti ẹjẹ di si ọkan rẹ eyi t'awọn oloyinbo n pe ni ""hemopericardium."""
Ayẹwo tun fihan pe ọta ibọn bá a ni aya eyi to ṣakoba fun ẹdẹforo rẹ.
Ile iwosan LASUTH lo gbe esi ayẹwo naa jade gẹgẹ Dokita S.S. Soyemi ṣe sọ.
Esi ayẹwo oku Jumoke tun fihan pe laago mọkanla aabọ aarọ ni o jẹ Ọlọrun nipe.
Ṣugbọn ileeṣẹ ọlọpaa Eko sọ pe apa ọbẹ wa lara oku Jumoke eyi to fihan pe o ṣeéṣe ko jẹ pe awọn kan lo gun ùn lọbẹ pa.
Ileeṣẹ ọlọpaa ni ibi ti awọn ti ri oku Jumoke jina si ibi ti iwọde ti n waye.
'Ẹ má jẹ́ kí òkú ọmọ mi ráre o ìjọba! Ẹ gbée fún mi kí n lọ sin ín - Ìyá ọmọ ti wọ́n pa ní ìwọ́de Yoruba Nation
Wọn lẹyin ileepo MRS lọna Maryland lawọn ti ri oku Jumoke ti wọn si we oku naa laṣọ.
Koda wọn ni ẹjẹ ti gbẹ tan lara oku ọhun.
Awọn to wa nibi iwọde naa sọ pe Jumoke ṣagbako iku ojiji dero ọrùn lẹyin tawọn ọlọpaa ṣí aarin awọn olufẹhonuhan lati tu wọn ka lọjọ kẹta oṣu keje.
Wọn ni aṣita ibọn lo gbẹmi lẹnu Jumoke.
Amọ ileeṣẹ ọlọpaa ipinlẹ Eko ni awọn agbofinro to wa nibi iwọde naa ko tilẹ yinbọn rara .
Agbẹnusọ ileeṣẹ ọlọpaa ipinlẹ Eko, Muyiwa Adejobi ṣalaye pe oku Jumoke, ẹni ọdun mẹẹdogbọn fihan pe kii ṣe ọjọ iwọde ọhun lo gbẹmi mi.
Adejobi ni apa to wa lara rẹ ṣe afihan iru iku to pa a.
Agbẹnusọ ileeṣẹ ọlọpaa ni esi ayẹwo ohun to pa Jumoke ti LASUTH gbe jade ko t'ọna.
Silas Robotic Engineer: Kò sí ǹkan rere tí ọmọ Nàìjíríà kò lè ṣe
O ni wọn kan fẹ fi esi naa da ibẹrubojo silẹ ati pe wọn fẹ gbin ibẹru sí ọkan awọn eeyan ipinlẹ Eko ni.
Ẹwẹ, aṣoju ẹbi Jumoke, Ọgbẹni Afolabi Wasiu sọ fawọn akọroyin pe wọn kò ri ọta ninu ara Jumoke.
Ọgbẹni Wasiu ni ayẹwo fihan pe ọta naa jade lara rẹ lẹyin to ba a tan.
O ni ileeṣẹ ko tii fún ẹbi Jumoke labọ iwadii wọn lori iku to pa a.
Ogun Accident: Ọkọ̀ akérò forí sọ ọkọ̀ akólẹ̀, èèyàn mẹ́tàlá kú, míjìlá míì farapa
Oríṣun àwòrán, FRSC
Kowee ke, ko ha ni ọjọru ana nigba ti ọpọ ẹmi bọ ninu isẹlẹ ijamba ọkọ kan to waye lopopona marosẹ Ibadan silu Eko.
Oludari ileesẹ FRSC nipinlẹ Ogun, Ahmed Umar, to fi idi isẹlẹ naa mulẹ salaye pe ere asapajude ati yiya ọkọ silẹ nibi ti ko tọ, lo sokunfa ijamba naa.
Gẹgẹ bo se wi, deede aago mẹrin ku isẹju mẹẹdogun nirọlẹ ni isẹlẹ naa waye, ninu eyi ti eeyan mẹẹdọgbọn ti fara gba, ẹmi mẹtala bọ nigba ti mejila fi ara pa.
Ọkọ bọọsi akero Mazda ti ijamba naa sẹlẹ si, lo jẹ alawọ funfun, ti nọmba rẹ jẹ APP28YE, lo fori sọ ọkọ akolẹ tileesẹ naa n sakoso rẹ, ti ko si ni nọmba kankan lara.
Umar ni wọn ti gbe awọn eeyan to fara pa ninu ijamba ọkọ naa lọ sile iwosan Idera to wa nilu Sagamu fun itọju nigba ti wọn gbe oku awọn alaisi si ibudo igbokusi to wa nile iwosan naa.
Sunday Igboho: Timi Orokoya ní orin Iléyá tí òun kọ lọ́dún 28 sẹ́yìn, ló padà wá ṣẹ báyìí
Bakan naa ni agbẹnusọ fun ajọ to wa fun akoso igboke-gbodo ọkọ loju popo nipinlẹ Ogun, OSTCEC, Babatunde Akinbiyi ni ọmọde mẹrin lo wa ninu awọn eeyan to ba ijamba ọkọ naa rin.
Sunday Igboho: Timi Orokoya ní orin Iléyá tí òun kọ lọ́dún 28 sẹ́yìn, ló padà wá ṣẹ báyìí
Yoruba ni ọrọ agba, bi ko sẹ ni owurọ, yoo sẹ ni ọjọ alẹ.
Bẹẹ ni ọrọ ri pẹlu akọrin ẹmi nni, Timi Orokoya to kọ orin Ileya ni ọdun mejidinlọgbọn sẹyin, ti awọn ọrọ inu orin naa si n sẹ lọwọ lasiko yii.
Nigba to n ba BBC Yoruba sọrọ, Orokoya ni ọpọ ohun orin naa ni awọn ajijagbara to n pe fun Yoruba Nation ti yipada.
O ni ileya ti oun n sọ nigba naa, ni oun fi n pe awọn eeyan pada si ọdọ Ọlọrun ati ijọba ọrun.
Nigba to n sọrọ lori Sunday Igboho, Orokoya ni ohunkohun ko gbọdọ se ajijagbara naa nitori ija ilu lo n gbe.
O wa ke si awọn asaaju ilẹ Yoruba lati dide gbeja Sunday Igboho nitori bi ohun to n beere fun ba dohun tan, kii se oun nikan ni yoo jẹ anfaani rẹ.
Akọrin ẹmi naa ni Alọrun le lo ẹnikẹni lai naani pe boya oogun dundun lo n lo nitori ọpọ awọn ẹlẹsin mii naa n lo dudu yii.
O wa gba ijọba nimọran lati tete wa idahun si ọpọ ohun ti Sunday Igboho n beere, ki alaafia le jọba.
Sunday Igboho: Ó lé yọrí sí ogun, tí ìjọba Naijiria bá fi ìyà jẹ Sunday Igboho bí ọ̀daràn
Oríṣun àwòrán, GANI ADAMS AND SUNDAY IGBOHO
Aarẹ ọna Kakanfo ilẹ Yoruba, Iba Gani Adams ti sọ pe igbiyanju ijọba apapọ Naijiria lati sọ igbesẹ Sunday Igboho di iwa ọdaran, ko ba ilana ijọba awaarawa mu.
Gani Adams sọ ọrọ naa ninu atẹjade ti oluranlọwọ pataki fun lori eto iroyin, Kehinde Aderemi fi sita lorukọ rẹ.
Awn iwe iroyin abẹle jabọ pe Adams ni ibanujẹ lo jẹ fun oun pe ọwọ tẹ Igboho.
Gẹgẹ bo ṣe sọ, o ni erongba ijọba lati ma a kọju ija si awọn ajijagbara ko bojumu, to si le sọ ijọba di ọta araalu.
Nkan to ṣẹlẹ si Igboho n tu aṣiri diẹdiẹ pe ijọba fẹ ẹ ma a fi iya jẹ awọn ajijagbara, eyi to si le sọ ijọba di ijọba aninilara, paapaa lati ọwọ ijọba to de ipo pẹlu ileri ireti to dara ati atilẹyin awọn eniyan Iwọ-Oorun Gusu Naijiria.
"Bakan naa lo ni ki ijọba fi ọwọ suuru mu ọrọ Sunday Igboho, ""nitori pe fifi iya jẹ ẹ, le yọri si ogun""."
"Aṣisẹ nla ni yoo jẹ fun ijọba apapọ, to ba fi le fi iya jẹ awọn ajijagbara fun idasilẹ Yoruba Nation bi ọdaran tabi ọta.
Igboho ni ẹtọ si ominira. Ko si si nkan to buru ninu ko wa aabo lọ si Benin Republic, tabi ilẹ okeere to ba ri i pe ko si aabo fun oun ni Naijiria."""
Ọjọ Aje ni iroyin sọ pe awn ọlọpaa lorilẹ-ede Benin mu Sunday Igboho ati iyawo rẹ, Ropo, ni papakọ ọkọ ofurufu, lasiko ti wọn fẹ wọ baalu lọ si orilẹ-ede Germany.
Sunday Igboho: Ladoja ní bí ìjọba kò bá fi ẹ̀lẹ̀ ṣe, ọ̀pọ̀ ajìjàgbara míì yóò dìde
Gomina tẹlẹri nipinlẹ Oyo, Sẹnetọ Rasidi Adewolu Ladoja ti sọ wi pe, ijọba apapọ lo da awọn ajijagbara bii Sunday Igboho, to n ja fun ilẹ Yoruba ati Nnamdi Kanu to n ja fun idasilẹ orilẹede Biafra silẹ.
Ladoja lo sọ bẹẹ ni ile rẹ lasiko to n ba awọn akọroyin sọrọ lẹyin to gbadura Ileya tan ni ọjọ Iṣẹgun.
O ni ijọba apapọ to kọ lati koju awọn ipenija ijinigbe, ipaniyan awọn araalu kaakiri orilẹede Naijiria, paapaa ilẹ Yoruba lo mu awọn eniyan bi Sunday Igboho di adari fun  awọn eniyan rẹ.
Gomina ipinlẹ Oyo tẹlẹ wa parọwa si ijọba apapọ lati ṣe pẹlẹpẹlẹ pẹlu bi wọn ṣe fi panpẹ ọba mu Sunday Igboho nitori ọpọlọpọ eniyan bii Sunday Igboho ni yoo dide ti ijọba ba fi ọwọ agbara mu awọn ti wọn mu yii.
Travelogue on Abeokuta: Ọmọ ọdún mẹ́ẹ̀dógún yònbó ìbùdó àti èèyàn pàtàkí tó wà ní Abeokuta
Yoruba ni ọmọ ti yoo ba jẹ Asamu, kekere ni yoo ti maa jẹnu samusamu.
Asamu ọmọ si la le pe Grace nitori bo se n jẹnu samusamu lati yonbo ilu abinibi rẹ, Abeokuta, to si salaye yekeyeke nipa awọn ibudo pataki to wa nilu naa.
Lara awọn ibi manigbagbe ti Grace mẹnuba ni Apata Olumo, Aafin Alake tilẹ Egba, Gbọngan ti wọn fi sami ọgọrun ọdun ti wọn tẹ Abeokuta do ati ile ijọsin onigbagbọ akọkọ to wa nilu naa.
Bakan naa ni Grace, tii se ọmọ ọdun mẹẹdogun, tun sọ awọn ibudo igbafẹ atawọn eeyan pataki to jẹ ọmọ bibi ilu Abeokuta.
Ko tan sibẹ, ọmọde yii tun sọ nipa itan bi wọn se da ilu naa silẹ ati awọn eeyan jankanjankan to ti se ribiribi fun agbaye, ti wọn jẹ ọmọ bibi ilu Abeokuta.
Lara awọn to mẹnuba ni Ọjọgbọn Wole Soyinka, Oloye Olusegun Obasanjo, Fela Anikulapo Kuti, Oloye MKO Abiola, Ernest Sonekan ati bẹẹ bẹẹ lọ.
Grace wa ke sawọn onile ati alejo pẹlu awọn eeyan lagbaye to n wa ibi igbafẹ ti wọn fẹ lọ, paapaa awọn ọdọ lati wa silu Abeokuta.
Koda, o fikun pe wọn yoo ge ahọn jẹ ti wọn ba fi ẹnu kan irẹsi Ọfada ati amala Lafun, tii se ounjẹ ibilẹ wọn nilu Abeokuta.
Abuja Cholera Outbreak: Ìjọba ní gbogbo agbègbè tó wà ní Abuja ní Kọ́lẹ́rà dé
Oríṣun àwòrán, Ministry of Health
Iroyin to n tẹ wa lọwọ bayii ti fidi rẹ mulẹ pe arun onigbameji ta ms si Kọlẹra, tun ti gbode ni olu ilu ilẹ wa Abuja.
Oludari ẹka eto ilera araalu fun ilu Abuja, Dokita Sadiq Abdulrahman fidi rẹ mulẹ fun BBC lasiko ifọrọwanilẹnuwo pe eeyan mẹrindinlaadọrin lo ti jade laye lati ipasẹ arun naa.
Bakan naa lo fikun pe ajalu arun Kọlẹra naa ni ọwọja rẹ ti tan de ẹkun mẹfẹẹfa to wa nilu Abuja gẹgẹ bi ayẹwo ti wọn n se fawọn araalu se fidi rẹ mulẹ.
"Lati ọjọ Kinni osu Karun ọdun 2021, la ti n ri ami pe arun yii n bọ, amọ a ko le fidi rẹ mulẹ titi di igba to n mu awọn araalu, ti ayẹwo wa si fidi rẹ mulẹ pe arun onigbameji ni.'
Abdulrahman ni titi di ana Ọjọbọ, ọjọ kejilelogun osu Keje, eeyan bii ọrinlelẹgbẹrin o din meje, 873 , ni awọn le fidi rẹ mulẹ pe o ti ni arun Kọlẹra naa.
Ọwọja arun yii ti tan de gbogbo agbegbe to wa nilu Abuja. Ni agbegbe AMAC, eeyan marundinniirinwo, 395, lo ti ni arun naa nigba ti ojilenirinwoati mẹfa, 246, ni arun ọhun ni agbegbe Gwagwalada."
Travelogue on Abeokuta: Ọmọ ọdún mẹ́ẹ̀dógún yònbó ìbùdó àti èèyàn pàtàkí tó wà ní Abeokuta
Eeyan marunlelaadọjọ, 152 lo ni Kọlẹra ni Bwari, ti eeyan ogoji, 40, si ni ni Kuje nigba ti eeyan mẹtadinlogoji, 37 ni ni Kwali.
"Amọ eeyan mẹta pere lo ni Kọlẹra ni Abaji."""
Dokita naa ni iwadi awọn ti fidi rẹ mulẹ pe ọwọja arun naa n tan kalẹ nitori bawọn eeyan se n pọ si nilu Abuja amọ aayan ti n lọ lati kawọ rẹ ko.
"A ti gbe oniruuru igbimọ kalẹẹ labẹ awọn ileesẹ ti ọrọ ilera yii kan lati gbogun ti arun Kọlẹra nilu Abuja, tawọn osisẹ wa si n lọ kaakiri lati abule si ileto lati sayẹwo omi ti wọn n mu.
Bakan naa lati ti se ifilọlẹ ẹka pajawiri ti yoo maa se itọju awọn alaisan Kọlẹra, gẹgẹ ba se maa n se ti arunkarun kan ba bẹ silẹ."
Rashidi Ladoja: Ẹ jẹ́ kí Bùhárí gbá'pòtí ìbò, bóyá yóò borí
Yomi Fabiyi; N kò lo àpètán orúkọ, ohùn tàbí àwòrán ẹnikẹ́ni nínú fíìmù Oko Iyabo
Oríṣun àwòrán, yomi fabiyi
Ilumọọka osere tiata nni, Yomi Fabiyi, to n lewaju ninu awuyewuye to suyọ lori ẹsun asemase ti wọn fi kan Baba Ijesha, tun ti sọrọ sita.
Yomi, ẹni ti ọpọ eeyan n naka abuku si lori fiimu ọkọ Iyabo to se sita, tun ti gbe fidio miran sita pe ẹnikẹni to ba ro pe fiimu naa tako ẹtọ ọmọniyan le gba ile ẹjọ lọ.
"Osere tiata naa ni oun ko ni da eebu pada fun ọpọ eeyan to n sọ oko ọrọ si oun lori agbejade sinima naa nitori o ni ""kii se gbogbo aja to n gbo, ni eeyan maa n kọbi ara si."""
"Inunibini ko kan ti aimọ iwa wu, nitori naa ni eeyan se gbọdọ gbajumọ ibi to n lọ.
To ba boju wẹyin, to si duro si idi otitọ, nigba to ba ya, wa jare nitori bi irọ ba lọ titi fun ogun ọdun, otitọ yoo le ba ni ọjọ kan.
Travelogue on Abeokuta: Ọmọ ọdún mẹ́ẹ̀dógún yònbó ìbùdó àti èèyàn pàtàkí tó wà ní Abeokuta
Ẹ lọ fa ila si idi ọrọ mi, ọjọ kan n bọ ti awọn to korira rẹ, bu ọrọ tabi sọ ọrọ abuku si ọ, yoo ri daju pe asise nla gbaa ni wọn se.
Yoo ye wọn pe aimọkan lo n da wọn laamu, ẹ yago fun loju opo ayelujara ati loju aye, ko dara rara."
Yomi Fabiyi ni ọpọ eeyan to n sọ oko ọrọ si oun lori fiimu Oko Iyabo ti oun gbe jade ni ko tii wo sinima naa rara, gbogbo eebu ati oko ọrọ ti wọn si n sọ ni wọn ko ni idi lati se bẹẹ.
Osere tiata naa ni gbogbo awọn eeyan to ti wo sinima naa lo n beere pe ki lo de ti ọpọ eeyan se n bu ẹnu atẹ lu sinima yii?
"Eeyan kan le lọ sile ẹjọ lati beere fun idajọ ododo ti wsn ba lo apetan orukọ rẹ ninu ere itage, ohun rẹ tabi aworan rẹ.
Amọ ti onkọtan ati olootu ere ba ti le bọwọ fun awọn nnkan wọnyi, o yẹ ki ẹyin lee le bọwọ fun ninu esi tẹ ba n fọ sita nipa wọn.
Mo ti ya fiimu Oko Iyabo, ki ileẹjọ to kede ọjọ ti yoo maa gbọ ẹjọ Baba Ijesha, bẹẹ si ni itan naa yatọ patapata si ohun to sẹlẹ si Baba Ijesha."
Yomi Fabiyi ni gbogbo aye to wi wo sinima naa lo ri pe ko si ohun ti ko dara rara ninu sinima yii, tabi pe o n se agbega iwa sise asemase pẹlu ọmọde.
O wa pari ọrọ rẹ pe ẹnikẹni ti agbejade sinima naa ko ba dun mọ ninu, tabi pe o tẹ ẹtọ wọn mọlẹ, le gba ile ẹjọ lọ lati gba idajọ.
Sunday Igboho: Bó ṣe bèèrè àtìpó ní Germany, náà ló ń bèèrè nílẹ̀ Benin
Ile ẹjọ orilede Benin Republic ti dá ajijagbara ọmọ Yoruba, Sunday Adeyemo ti ọpọ mọ si Sundayh Igboho padà si ahamọ ọlọpaa, titi di ọjọ Aje ọsẹ to n bọ ti ile ẹjọ yoo tun joko.
Bi o tilẹ jẹ pe Sunday Igboho ti saaju kọwe ẹbẹ lati se atipo ni orilede Germany tẹlẹ, amọ o tun ti n gbiyanju lati se bẹẹ pẹlu ni orílede Benin bayii.
Iroyin to tẹ wa lọwọ fi kun pe, ìgbésẹ yii yoo waye ni àwọn ọsẹ bii melo si asiko yii ati pe o jọ bi eni pe ijọba orilẹede Benin yoo jawọ lori ẹsun pe Sunday Igboho lo iwe irina ayederu ti wọn fi kan.
Asoju àwọn agbẹjọro Oloye Sunday Igboho, Yomi Aliyu naa tun fi kun ninu atẹjade kan pe ko ṣeeṣe ki wọn da Sunday Igboho pada wa si Naijiria.
O ni eyi ko ṣẹyin adehun to ti wa laarin Naijiria ati Benin lọdun 1984 lori dida ẹni ti ijọba n wa pada si Naijiria paapa julọ ẹsun to ba ti ni ọwọ oṣelu ninu bi ti Igboho.
Rashidi Ladoja: Ẹ jẹ́ kí Bùhárí gbá'pòtí ìbò, bóyá yóò borí
Ẹwẹ, lasiko ti wọn mu Igboho, oun ati iyawo rẹ ni wọn mu ni ahamọ, sugbọn ni bayii ile ẹjọ Cour De'appal De Cotonou ti paa lásẹ lọjọbọ pe ki wọn fi Ropo iyawo Igboho silẹ lalafia to ri kop si ẹsun ti wọn fi kan, sugbọn ki Igboho si wa ni ahamọ.
O to wakati mẹfa ti igbẹjọ naa fi waye pẹlu isinmi ranpẹ laarin, sugbọn adajọ ti pasẹ pe ki Igboho wa ni ahamọ titi di asiko igbẹjọ miiran lọsẹ to n bọ.
Gẹgẹ bi iroyin se sọ, ijọba Naijiria ti rọ ìjọba orilede Benin lati fi Igboho si ahamọ titi ti wọn yoo fi pari iwe ẹsun ti wọn fi kan ati bi wọn yoo se fi sọwọ pada si Naijiria.
Wọn ni ésun ti ijọba tun fi kan ni pe, o n sowo ibọn ni Naijiria, ati pe ti ijọba Benin ba tilẹ fi silẹ, o ṣeeṣe ki wọn tun pada mu nitori ẹsun pe o n ṣowo ibọn ti wọn fi kan.
Ninu atẹjade kan adari Ilana Omo Oodua ti ọjọgbọn Akintoye fi sita lo ti ṣalaye pe awawi lasan ti ko fi idi mulẹ ni ẹsun ti ijọba Naijiria fi kan Igboho nitori wọn ko ni ẹri kankan lati gbee lẹsẹ, eyi ko si to nnkan ti Benin yoo fi da Igboho pada si Naijiria.
Seyi Makinde: Ẹ̀yin tẹ́ fẹ́ fi ọ̀rọ̀ ẹ̀sin ba Oyo jẹ́, ẹ ṣọ́ra ṣe
Ẹwẹ Pelumi Ogunlesi to tun jẹ ọkan lara awọn agbẹjọro Igboho ṣalaye pe, ireti wa pe ile ẹjọ Benin yoo da Igboho silẹ, wọn ko si ni daa pada fun ijọba Naijiria lọna aitọ.
"Ẹwẹ, agbẹjọro rẹ miiran, Salami ti sọ saaju fun BBC pe, ""Passport"" Naijiria ati Germany ni wọn ka mọ Igboho lọwọ nigba ti wọn mu nitori naa, ireti wa pe igbẹjọ naa yoo lojutuu laipẹ."
Local Government Elections: Aṣíwájú Bola Tinubu kò dìbò nínú ìbò ìjọba ìbílẹ̀ tó wáyé l'Eko
Oríṣun àwòrán, Asiwaju Bola Tinubu
Fun igba akọkọ ni nkan bi ọdun mẹwaa sẹyin, Aṣiwaju Bola Tinubu ko kopa ninu eto idibo ijọba ibilẹ to waye nipinlẹ Eko lọjọ Abamẹta,ọjọ kẹrinlelogun oṣu keje, ọdun 2021.
Awọn akọroyin rọ lọ si ibudo idibo 047 to wa ni agbegbe Sunday Adigun, Alausa, ni Ikeja nibi ti Tinubu ti maa n dibo.
Amọ, iyalẹnu lo jẹ fawọn akọroyin pe wọn ko ri Tinubu ni ibudo idibo lati wa dibo.
Japan: Ẹ wo arákúnrín tó ń ta ilé àwọn òkú fún àwọn tó ní ìfẹ́ sí
Paro paro ni ibudo idibo naa da pẹlu ẹtaworo awọn oludibo nibẹ nigba ti BBC Yoruba ṣabẹwo sibẹ.
Ni kete tawọn akọroyin gbọ pe Tinubu ko ni jade wa dibo ni wọn kuro ni ibudo idibo naa.
Ko si ẹni to mọ idi ti Tinubu ko fi le kopa ninu eto idibo ijọba ibilẹ ipinlẹ Eko to waye, bo tilẹ jẹ pe awọn kan ni Aṣiwaju ko si ni Naijiria lọwọ yii.
Ohun ti a gbọ ni pe ẹgbẹ oṣelu APC lo jawe olubori ni ibudo idibo Tinubu bo tilẹ jẹ pe oun gan ko si nile lati dibo.
Ẹwẹ, iroyin kan tun sọ pe gomina ipinlẹ Eko tẹlẹ ri meji, Babatunde Fashola ati Akinwunmi Ambode naa ko dibo ni ibudo idibo idibo wọn.
Ètò ìdìbò ìjọba ìbílẹ̀ lọ ní ìrọwọ́-rọsẹ̀ ní ìpínlẹ̀ Ogun- Kọmíṣọ́nnà
Kọmiṣọnna fun ọrọ ijọba ibilẹ ati ọrọ oye jijẹ nipinlẹ Ogun, Afolabi Afuape, ti ṣapejuwe eto idibio ibilẹ to waye nibẹ lọjọ Abamẹta gẹgẹ bi eto to lọ wọọrọ wọ.
Kọmiṣọnna Afuape ni bi o ti yẹ ki eto idibo ri naa ni eto ibo ijọba ibilẹ ipinlẹ Ogun ọjọ Abamẹta ṣe ri.
Kọmiṣọnna naa woye pe awọn oludibo to fi mọ awọn ọmọ ẹgbẹ oṣelu alatako lo huwa bi ọmọluabi ni ibudo idibo.
Onikaluku lo dibo lai si ija tabi fifi ada le awọn eeyan kaakiri lawọn ibudo idibo.
''Imọran mi fawọn ọmọ ipinlẹ Ogun ni lati maa tẹsiwaju ninu ṣiṣe ojuṣe wọn nipa ibo ibo didi.
Ti a ko ba dibo, a ko lẹtọọ lati maa bu ijọba to wa lode pe wọn ko ṣe daadaa.
Akiyesi ikọ BBC Yoruba nibi eto idibo naa fihan pe awọn oludibo ko tu yaya jade lati dibo kaakiriri ipinlẹ Ogun.
Àwọn olùdibò ko jáde dibo ni ipínlẹ̀ Eko, ení tere èjì tere lo n jáde
Bí àwọn ènìyàn ìpínlẹ Eko ṣe ń jade lónìí láti dibo yan alága ìjọba ibílẹ̀ tuntun sí ìjọba ìbílẹ̀ ogun àti LCDA métàdílógóijì, olùjábọ̀ ilé iṣẹ́ BBC Yoruba ni àwọn ènìyàn kà jáde láti wa dibo.
Àwọn elétò ìdìbò tí ṣetan láti bẹ̀rẹ̀ ètò, sùgbọ́n kò sí àwọn olùdibò to yọjú
Ní nǹkan bi aago mẹwaa abọ ti akọròyìn BBC de àwọn Ibudo idibo 004 Opebi ni LCDA  Onigbongbo, kò ti si ètò kan pàtó to n lọ.
Ni àwọn ìhà ibòmíràn nibẹ̀, lẹ́yìn ìforúkọ sílẹ̀ wọ́n ni ki àwọn olùdi[bò pàda wá láti dibo bí o tilẹ̀ jẹ́ pé ènìyàn kan péré náà ló ti jáde wá láti dibo
Díẹ̀ lára àwọn fótò tó ṣe àfihàn bí nǹkan ṣe n lọ níbi ìdìbò tó n wáyé nílùú Eko rèé.
Ko sí òlùdibo kankan ni Ibudo idibo Agege 009
Ko sí òlùdibo kankan ni Ibudo idibo Agege 009
Àwọn asoju ẹgbẹ́ òsèlú àti àwọn elétò ìdìbò ti wà ni ìkàlẹ̀ ni ibudo ìdìbò 011 ni agbègbè Ifako, sùgbọ́n ko si olùdibò
Ibudo idibo 037 ni agbegbe Yaba
Ẹ̀wẹ̀, nǹkan yàtọ díẹ̀ ni ìpínlẹ̀ Ogun àwọn oludibò dílẹ̀ jáde fún ìdìbò yan alága sí ìjọba ìbílẹ̀ ogun tó wa níbẹ̀
Àbẹwò ilé iṣẹ́ BBC Yorùbá sí Wọ́ọ̀dù 7 ibudo idibo 003 & 004 nijọba ibílẹ̀ Abeokuta North fi han pé àwọn ètò ìdìbò tí n gbéra sọ níbẹ̀.
Abeokuta North
Awọn apa kan ninu ẹgbẹ oṣelu Peoples Democratic Party (PDP) ni ipinlẹ Ogun ti ni àwọn ko ni kopa ninu eto idibo si ijọba ibilẹ ti yoo waye ni ipinlẹ naa lonii.
Ipinu yii ko ṣẹyin idajọ ile ẹjọ to ni ki awọn awọn oṣiṣẹ eleto idibo ti ipinlẹ Ogun (OGSIEC) tẹsiwaju lati maa ba eto idibo lọ.
Ile ẹjọ giga ni ilu Abeokuta lo pasẹ pe ki OGSIEC tẹsiwaju lati ṣeto idibo lẹyin ti ọkan ninu awọn ọmọ ẹgbẹ naa Oloye Sikirulai Ogundele pe lodi di OGSIEC.
Sugbọn, nigba ti ile ẹjọ ka igbẹjọ rẹ, Ogundele ni lootọ ni ile ẹjọ ko jiyan pe oun kọ ni olori ẹgbẹ naa ni ipinlẹ Ogun sugbọn o kọ lati da eto idibo duro.
Oloye Ogundele wa pe awọn ọmọ ẹgbé lati ma kopa ninu eto idibo naa.
Ṣé ẹ ti gbọ́ nípa òkú gbígbẹ́ tí wọ́n ṣì bá oyún nínú rẹ̀?
Ninu atéjade to fi sita, lo ti sọ pe awọn ọmọ ẹgbẹ oṣelu PDP ko ni kopa ninu eto idibo naa.
"Atẹjade naa ka bayii: Gbogbo awọn akopa ninu eto idibo to jẹ ọmọ ẹgbẹ, ti wọn ti se ayẹwo fun lati kopa gẹgẹ bi oludije ninu idibo ijoba ibilẹ labẹ ẹgbẹ PDP.
Gbogbo ololufẹ ẹgbẹ ati awọn ti ọrọ kan lati farabalẹ ki wọn si ni igbagbọ ninu idara oun"
Sugbọn oloye miiran ninu ẹgbẹ naa ọmọọba Leke Shittu ṣalayhe pe ẹgbẹ oṣeelu PDP yoo kopa ninu idibo naa nitolri pe awọn to ni ikunsinu laarin ọmọ ẹgbẹ ko le maa paṣẹ nnkan ti gbogbo ọmọ ẹgbẹ yoo ṣe.
O ni OGSIEC ti ṣe nnkan ti o yẹ ki wọn se  nipa ṣiṣe atunto awon ẹgbẹ to yẹ, ti o si rọ awọn ti ko dun mọ lati fọwọwọnu  ki wọn si dibo fun ẹgbẹ wọn.
Alaga OGSIEC Babatunde Osibodu, to fidi ẹjọ ti wọn da si igbo naa mulẹ sọ pe gbogbo aaye ti o yẹ ki awọn ẹgbẹ PDP wa, ni wọn wa fun idibo ti yoo waye lonii.
E jẹ́ ká lọ sí ìlú mi BBC yìí dá lórí Epe ní bi tí eégún ti ń fi ẹgba dá bírà lára Oba
Buhari's visi to Daura: Ẹ má fún mí tabi àwọn olóòṣelú ni ẹ̀bùn kankan mọ́- Buhari sọ fún ọmọ Naijria
Aarẹ Muhammadu Buhari  ti sọ fun awọn ọmọ Naijiria paapaa julọ awọn onisowo, awọn kọngila àwọn àwọn miiran to ri ọwọ fi họri ni Naijiria lati ri pe wọn se iṣẹ iranwọ fun ara ilu.
O ni ki wọn ṣe eyi kaka ki wọ n ma wa onju rere oloselu kiri ati gbigbe ẹbun rabandẹ fun wọn.
Aarẹ Buhari sọ eyi di mimọ lasiko to ṣe abẹwo si Ọba ilu Daura nipinle Katsina Umar Faruk Umar laafin rẹ.
Mi o fẹ ki ẹnikẹni fun  mi ni iwe sọwedowo, ẹ lọ ran awọn ara ilu lọwọ, kaka ti ẹ o fi maa fun awọn oṣiṣẹ ijọbna ni owo abẹtẹlẹ
A o fẹ sọwedowo lọwọ ẹnikẹnitabi ile iṣẹgẹgẹ bi fifi ẹmi imoore han, ẹ jẹ ki wọn lọ ṣe iranwọ fun awọn agbegbe wọn
Aarẹ  ni o wu oun lati maa ṣe abẹwo si ilu Daura lọpọlọpọ, sugbọn owo ti ile iṣẹ aarẹ n na lati ṣe abẹwo ati ọrọ abo jẹ idiwọ sugbọn ọkan oun wa pẹlu awọn eniyan.
" Iṣẹ agbẹ ni a mọ wa si, mo si ni oko ni ilu yii. Mo le maa wa ni ọsẹ mejimeji, ti ko si si ẹni ti o le di mi lọwọ, sugbọn owo ti ile iṣẹ aarẹ n na ti pọ ju.
Sugbọn aarẹ ni o san  lati lo iru owo bẹẹ lati tun ile ẹko ṣe àti lati tun awọn ile iwosan  to wa ṣe.
Aarẹ fi kun pe ore ofẹ Ọlọrun lo gbe orilede Naijiria ro de ibi ti o wa bayii, gẹgẹ bi olri;ede ti o fi odidi ọgbọn osun ja ogun abẹle
Sunday Igboho: Wọ́n sì de Igboho lọ́wọ́ ní àtìmọ́lé ọlọ́pàá ní orílẹ́èdè Benin
Oríṣun àwòrán, Sunday Igboho
Oju ajijagbara ati ajafẹtọ ọmọniyan nilẹ Yoruba, Oloye Sunday Adeyemo(Sunday Igboho) n ri to lọwọ awọn ọlọpaa orilẹede Benin, agbẹjọrọ rẹ, Ibrahim Salami lo sọrọ yii fun BBC Yoruba.
Salami sọ pe bo tilẹ jẹ wi pe ninu atimọle ni wọn ju Igboho si, niṣe lawọn ọlọpaa tun fi ṣẹkẹ ṣẹkẹ si i lọwọ.
O ṣalaye pe pe ọkan lara agbẹjọro marun un to n ṣoju Igboho lorilẹede Benin ni oun jẹ.
''Nigba ti a lọ ṣabẹwo si Igboho ni atimọle ọlọpaa, a ri pe wọn fi ṣẹkẹ ṣẹkẹ si lọwọ, amọ wọn ko lu u, wọn ko si jẹ ẹ niya.
A ṣọ fun awọn agbonfinro wi pe eleyii ko ba ofin orilẹede Benin mu, ṣugbọn wọn ko tii ṣe ohun to yẹ ki wọn ṣe.
Eleyii jẹ ki o nira fun Oloye Igboho lati jẹun ati lati ṣe nkan mii ni atimọle.
Ijọba Naijiria ko tii sọ fun ijọba Benin pe ki wọn ki wọn da Igboho pada si oriẹede Naijiria.
Ohun ti ijọba orilẹede Naijiria sọ fun Benin ni pe Igboho ti lu ofin ni Naijiria wi pe ki wọn mu un nibẹ.
Awọn aṣoju ijọba Naijiria tun sọ fun ile ẹjọ ni Benin pe Igboho ko ibọn pamọ sile eleyii ti o fẹ lo lati pin orilẹede Naijiria.
Wọn tun sọ pe Igboho n lo awọn eeyan lati da ilu ru.
Ijọba Naijiria tun sọ pe Igboho n ṣe fayawọ ibọn.
Mo fẹ sọ fun yin pe Igboho ko tapa si ofin orilẹede Benin, bakan naa wọn ko ka iwe igbelu Benin mọ Igboho lọwọ.
Mo tun fẹ ki ẹ mọ pe papakọ ofurufu ni awọn ọlọpaa ti mu Igboho ati iyawo rẹ lẹyin ti wọn ti ra tikẹẹti tan lati rinrin ajo lọ si orilẹede Germany.
Iyawo Igboho ti gba ominira lọwọ awọn agbofinro ko si si ni atimọle mọ bayii.
Sunday Igboho ń bẹ iléẹjọ́ láti ṣe àtìpò òṣèlú nílẹ̀ Benin
Gbajugbaja ajafẹtọ ọmọniyan, Oloye Sunday Igboho ti n beere pe ki ijọba ilẹ Benin fun oun ni aaye lati fi ori pamọ silu wọn.
Igboho, ẹni ti awọn ọlọpaa ọtẹlẹmuyẹ DSS n wa lorilẹede Naijiria lo tun n koju igbẹjọ lori boya yoo pada sorilẹede Naijiria abi bẹẹkọ.
Oríṣun àwòrán, sunday_igboho/Instagram
Gẹgẹ bi iwe iroyin Punch ti salaye, Igboho pada gba lati beere fun aabo igbelu lọwọ ijọba ilẹ Benin nigba ti awọn ọlọpaa orilẹede Benin mu si ahamọ ni papakọ ofurufu to wa nilu Cotonou lasiko ti oun ati iyawo rẹ n rinrin ajo lọ sorilẹede Germany lọjọ Aje to kọja.
Bi o tilẹ jẹ pe ile ẹjọ ti Igboho ati aya rẹ, Ropo, yọju si nilu Cotonou pasẹ pe ki wọn fi iyawo Igboho silẹ, ko maa lọ sile lai ni gbedeke kankan nidi nitori ko ni ẹjọ lati jẹ, sibẹ wọn ko fi ọkọ silẹ, to si n lo opin ọsẹ ninu ahamọ ọlọpaa kan ni Cotonou.
Rashidi Ladoja: Ẹ jẹ́ kí Bùhárí gbá'pòtí ìbò, bóyá yóò borí
Koko ohun ti wọn si n ba Igboho se ẹjọ le lori ni pe boya wọn yoo fa le ijọba Naijiria lọwọ abi bẹẹkọ, ko le wa koju awọn ẹsun kiko ibọn pamọ tileesẹ DSS fi kan ni Naijiria.
Gẹgẹ ba se gbọ, awọn agbẹjọro Sunday Igboho ti gbe ẹbẹ kan siwaju ile ẹjọ naa, ti wọn si n rọ ọ pe ko fun Igboho laaye lti fori pamọ sorilẹede olominira Benin.
Gbogbo igbesẹ si lo ti n lọ lọwọ bayii lati maa fi ọwọ si awọn iwe to yẹ fun ibeere lọwọ ijọba Benin pe ko gba Igboho laaye lati se atipo oselu lorilẹede naa, dipo ki wọn gbe pada wa si Naijiria.
Travelogue on Abeokuta: Ọmọ ọdún mẹ́ẹ̀dógún yònbó ìbùdó àti èèyàn pàtàkí tó wà ní Abeokuta
Lagos LG Election: Ìbò ìjọba ìbílẹ̀ yóò wáyé l‘Eko lónìí lòdì sí ẹ̀bẹ̀ ẹgbẹ́ òṣèlú mọ́kànlá láti fagi lé e
Loni ọjọ Satide ni eto idibo yoo maa waye lati yan awọn alaga ati Kanselọ sawọn ijọba ibilẹ ati agbegbe idagbasoke to wa jakejado ipinlẹ Eko.
Saaju ni ijọba ti kede pe ko ni si lilọ bibọ awọn ero ati ọkọ lati aago mẹfa aarọ si mẹta ọsan, ti eto idibo naa yoo fi maa waye.
Eto idibo naa yoo seese tori bi ile ẹjọ giga ijọba apapọ to wa ni Ikoyi se kọ lati wọgile eto idibo naa, ti yoo waye lawọn ijọba ibilẹ ati agbegbe onidagbasoke mẹtadinlọgọta to wa nipinlẹ Eko.
Gẹgẹ bi atẹjade kan tijọba ipinlẹ Eko fisita lọjọ Ẹti, awọn ẹgbẹ oselu mọkanla lo n rọ ile ẹjọ giga naa lati wọgile sise eto idibo ọhun.
Adajọ Akintayo Aluko si lo gbọ ẹjọ naa, eyi ti ẹgbẹ oselu Alliance of Social Democrats atawọn mẹwa miran pe ajọ eleto idibo niìnlẹ Eko ati ijọba ipinlẹ naa.
Sunday Igboho: Timi Orokoya ní orin Iléyá tí òun kọ lọ́dún 28 sẹ́yìn, ló padà wá ṣẹ báyìí
Nigba to n gbe idajọ rẹ kalẹ, Adajọ Aluko gba ẹbẹ Agbẹjọro agba ati Kọmisana eto idajọ nipinlẹ Eko, Moyosore Onigbanjo, eyi to gbe kalẹ lorukọ ijọba ipinlẹ Eko.
Adajọ naa ni Ile ẹjọ mi ko ni asẹ lati gbọ ẹjọ naa tabi wọgile eto idibo ijọba ibilẹ ti yoo waye lọjọ Satide."""
Wayi o, Kọmisana ọlọpaa nipinlẹ Eko, Akeem Odumosu ti wa kede pe ileesẹ ọlọpaa ti seto gbogbo to yẹ lati ri daju pe ko si lilọ bibọ ọkọ ati ero jakejado ipinlẹ Eko lọjọ Satide ayafi awọn onisẹ kosemase nikan.
Sunday Igboho: Ẹ fún mi ní ₦500bn lórí dúkìá mi tẹ bàjẹ́ àti títẹ ẹ̀tọ́ mi lójú mọ́lẹ̀
Oríṣun àwòrán, sunday_igboho/Instagram
Ajijagbara fun iran Yoruba, Sunday Igboho ti pe ijọba apapọ lẹjọ lori bawọn osisẹ DSS se ya bo ile rẹ ni Ọjọbọ, ọjọ Kinni osu Keje ọdun yii.
Igboho lo pe awọn ọlọpaa ọtẹlẹmuyẹ DSS ati agbẹjọro agba fun ijọba apapọ, Abubakar Malami lẹjọ lori ikọlu sile rẹ naa.
Ajijagbara naa wa n beere biliọnu lọna ẹẹdẹgbẹta naira lọwọ ijọba lori ọpọ dukia ti DSS bajẹ nile rẹ.
Benin Republic ló bẹ́gi dínà aáyan ìjọba àpapọ̀ láti kù gììrì gbé Igboho wá Naijiria -
Bakan naa lo tun n rọ ile ẹjọ pe ko pasẹ fun ijọba atawọn osisẹ agbofinro rẹ lati bọwọ fun awọn ẹtọ to ni labẹ ofin bii ọmọniyan.
Rashidi Ladoja: Ẹ jẹ́ kí Bùhárí gbá'pòtí ìbò, bóyá yóò borí
Gẹgẹ bi agbẹjọro Igboho ti bẹbẹ ninu iwe ipẹjọ naa, o ni ẹtọ onibara awọn labẹ ofin ọdun 1999m lawọn agbofinro naa ti tẹ loju mọlẹ.
Agba amofin Yomi Aliyu, to n soju fun Sunday Igboho n fẹ ki ileeẹjọ kede pe bawọn agbofinro DSS se ba ọpọ dukia jẹ nile onibara ati bi wọn se ya bo ile naa, lo tẹ ẹtọ rẹ mọlẹ labẹ ofin.
"O ni ""iwa ika, ifiyajẹni ati titẹ ẹtọ ọmọniyan loju mọlẹ ni bi awọn olujẹjọ naa se kọlu ile Sunday Igboho lai sọ iru eeyan ti wọn jẹ."
Koda, wọn ko beere pe ki onibara oun silẹkun fun awọn amọ wọn kan fi ibọn fagidi wọle, ti wọn si pa eeyan meji, to fi mọ baba agbalagba to n kirun lọwọ ninu isọ oru to n se.
"Bakan naa ni wọn tun ba ọpọ dukia jẹ ninu ile naa, to fi mọ awọn ẹranko bii ologbo to n sin ati aja, eyi to tẹ ẹtọ rẹ bii ọmọniyan loju mọlẹ."""
O ni wọn mọọmọ n fi ibọn le kiri lati mu ni oku abi aaye nigba ti ko tii maa kede ogun, lọna ati ja fun ominira Yoruba.
Ilorin Cripple Couple: Ọṣẹ ìfabọ́ ni tọkọ-taya tó ní ìpèníjà ẹsẹ̀ ń tà láti bọ́ ọmọ mẹ́ta
Olupẹjọ naa wa n rọ ileẹjọ lati kede pe ete awọn olupẹjọ ti wọn fi ya bo ile rẹ ni lati di lọwọ ninu ipolongo fun idasilẹ orilẹede Yoruba to n se.
Atẹjade naa, ti amofin Aliyu fisita ni ko si orilẹede kankan to laju ni agbaye, tawọn agbofinro yoo ti fi agidi wọle eeyan kan, ti wọn yoo si pa eeyan tabi ba dukia owo iyebiye jẹ.
Sunday Igboho: Ẹ gbọ́ ohun tí Sanwo-Olu sọ lórí ọ̀rọ̀ Sunday Igboho
Oríṣun àwòrán, Facebook/Babajide Sanwo-Olu
Gomina ipinlẹ Eko, Babajide Sanwo-Olu ti sọrọ lori ohun tawọn gomina ilẹ Yoruba n ṣe lori bi wọn ju Oloye Sunday Adeyemo(Igboho) si atimọle ni ilu Cotonou, lorilẹede Benin.
Ọpọ eeyan lo ti n kọminu pe awọn gomina apa iwọ oorun guusu ko sọ ohun kan loi bi wọn ṣe mu Igboho lorilẹede Benin.
Gomina Sanwo-Olu sọ fawọn akọroyin nibi eto idibo ijọba ibilẹ Eko lọjọ Abamẹta pe iṣẹ n lọ labẹlẹ lori ọrọ Igboho.
Ìdájọ́ jáde! Ilé ẹjọ́ ti ní kí Sunday Igboho ṣì wà ní àhámọ́ ní Cotonou!
Mo fi sánmọ̀ àti ilẹ̀, Mecca àti Medina búra pé Sunday Igboho kò sí nínú ewu níbí - Èèyan Igboho ní Cotonou
Japan: Ẹ wo arákúnrín tó ń ta ilé àwọn òkú fún àwọn tó ní ìfẹ́ sí
''Awọn eeyan n ṣiṣẹ lọ labẹlẹ, ko digba tawọn gomina ba to n sọrọ ni gbangba ki araalu to mọ pe wọn o dakẹ lori ọrọ Igboho.
Asiko yii to le ni akoko yii fun gbogbo wa, ṣugbọn mo fẹ fi da yin loju pe iṣẹ n lọ labẹlẹ.
Nibi ti ọrọ de duro bayii, ko niṣe pẹlu iye awọn akọroyin ti eeyan ba ba sọrọ.
Ohun ti mo mọ ni pe ọpọ eeyan lo n ṣiṣẹ lẹgbẹ lẹgbẹ ati lọlọdanni, ko digba ti wọn ba to sọrọ ni gbangba,'' Sanwo-Olu ṣalaye.
Ọjọ Aje ọjọ kọkandinlogun oṣu keje lawọn agbofinro mu Igboho ni papakọ ofurufu Cadjèhoun niluu Cotonou, lorilẹede Benin.
Oun ati iyawo rẹ, Ropo ni wọn n jọ n rinrin ajo lọ si orilẹede Germany nibi ti wọn ti fẹ wọ baalu laago mẹjọ alẹ ki wọn to mu wọn.
Ṣugbọn awọn gomina ilẹ Yoruba ko ti sọrọ lori iṣẹlẹ ọhun lati ọjọ Aje ti Igboho ti wa ni gbaga ọlọpaa.
Ohun ti ijọba orilẹede Naijiria sọ fun Benin ni pe Igboho ti lu ofin ni Naijiria wi pe ki wọn mu un nibẹ.
Awọn aṣoju ijọba Naijiria tun sọ fun ile ẹjọ ni Benin pe Igboho ko ibọn pamọ sile eleyii ti o fẹ lo lati pin orilẹede Naijiria.
Wọn tun sọ pe Igboho n lo awọn eeyan lati da ilu ru.
Ijọba Naijiria tun sọ pe Igboho n ṣe fayawọ ibọn.
Ṣugbọn ọkan lara awọn agbẹjọro Igboho, Ibrahim Salami to ba BBC Yoruba sọrọ ṣalaye pe ko si otitọ kankan ninu awọn naa.
Sunday Igboho: Ìdí tí agbẹjọ́rò fi ní ó sàn kí Sunday Igboho kú sí Benin ju kí wọ́n dáa padà sí Nàìjíríà lọ
Oríṣun àwòrán, sunday_igboho1
Amofin Ibrahim Salami to jẹ ajijagbara nilẹ Yoruba, Oloye Sunday Adeyemo ti ọpọ mọ si Sunday Igboho ti ṣalaye pe ọna kẹkẹ ni Igboho gba lati Naijiria de orilẹede Benin.
Salami to jẹ Ọjọgbọn ni fasiti kan lorilẹede Benin ni ọna ẹyin ni oun ati iyawo rẹ, Ropo gba de Benin.
Salami sọ pe Igboho ko tapa si ofin kankan ni orilẹede olominira Benin, wọn ko ri iwe igbelu Benin lọwọ rẹ.
Mo fi sánmọ̀ àti ilẹ̀, Mecca àti Medina búra pé Sunday Igboho kò sí nínú ewu níbí - Èèyan Igboho ní Cotonou
''Iwe igbelu orilẹede Naijiria ati Germany ni wọn ba lọwọ Igboho.
Nitori ijọba orilẹede Naijiria ni ijọba Benin fi mu Igboho niluu Cotonou.
Ijọba Naijiria ṣalaye sọ fun ijọba Benin pe Igboho ẹsun mẹta ni Igboho ṣẹ.
Àwọn ẹ̀sùn tí ìjọba Nàìjíríà fi kan Olóyè Sunday Igboho tí wọ́n kà jáde ní Cotonou
Akọkọ ni pe o ko ibọn pamọ sile, o si tun n fi n ṣe fayawọ ibọn.
Wọn tun sọ pe Igboho n lo awọn eeyan lati da ilu ru.
Ẹlẹẹketa ni pe Igboho fẹ pin orilẹede Naijiria si meji tabi mẹta.
Ṣugbọn awọn agbẹjọro Igboho sọ fun ile ẹjọ pe ko si otitọ kankan ninu awọn ẹsun ti wọn fi kan an.
Ohun to ṣe pataki fun awa agbofinro Igboho julọ ni pe a ko fẹ ki wọn gbe Igboho pada si Naijiria.
O tẹ wa lọrun ki Igboho ku si orilẹeee Benin ju ki wọn gbe pada lọ si orilẹede Naijiria lọ.
Pẹlu gbogbo ohun ti ajọ DSS ṣe nile rẹ, bii igba pe a gbe ranṣẹ fun iku ni ti wọn fi le gbe pada si Naijiria.
O san ko ko ku si Benin ju ki wọn lọ pa a bi ẹran lọ ni Naijiria.
Japan: Ẹ wo arákúnrín tó ń ta ilé àwọn òkú fún àwọn tó ní ìfẹ́ sí
Niger school kidnap: Àwọn jàndùkù ajínigbé mú bábá tó gbé owó ìtúsílẹ̀ lọ fáwọn akẹ́kọ̀ọ́ tí wọ́n jígbé mọ́lẹ̀
Oríṣun àwòrán, Reuters
Eemọ lukutu pẹbẹ, awọn janduku ajinigbe ti mu ẹni to gbowo itusilẹ fawọn ọgọrun akẹkọọ ileewe Salihu Tanko Islamic Secondary School niluu Tegina nipinlẹ Niger mọlẹ.
Iroyin sọ pe awọn janduku ọhun ni owo itusilẹ ti ko wa ko pe lo jẹ ki awọn mu un mọlẹ.
Akọroyin BBC, Ishaq Khalid ṣalaye pe awọn obi awọn akẹkọọ naa ti da ẹgbẹẹgbẹrun owo dọla fun itusilẹ awọn akẹkọọ ọhun.
Japan: Ẹ wo arákúnrín tó ń ta ilé àwọn òkú fún àwọn tó ní ìfẹ́ sí
O ti to bi oṣu meji bayii tawọn ajinigbe ti gbe awọn akẹkọọbinrin ati akẹkọọbinrin sa lọ nipinlẹ Niger.
Ọga ile ẹkọ naa sọ pe o yẹ kawọn ajinigbe le tu awọn akẹkọọ naa silẹ lẹyin ti wọn ti gba ẹgbẹrun marunlelaadọrin owo dọla tii ṣe ọgbọn miliọnu naira.
Ṣugbọn o ni ọrọ ti polukuru musu bayii lẹyin ti wọn mu baba to gbowo lọ fun wọn mọlẹ.
Iru nkan bayii ko wọ pọ pẹlu awọn ajinigbe lorilẹede Naijiria.
O ti le ni ẹgbẹrun kan akẹkọọ tawọn ajinigbe ti ji lọ lawọn ile ẹkọ girama ni Naijiria lati oṣu kejila ọdun 2020 di akoko yii.
Ọpọlọpọ wọn lo si wa ni akata awọn ajinigbe pawo yii titi di asiko yii.
Ìyáwó mi ń ké ìrora títí tó fi pàdánú oyún inú rẹ̀ torí aṣemáṣe òsìsẹ́ LASTMA àti ọlọ́pàá - Onyemaechi
Ìgbìmọ̀ ẹlẹ́ni 145 ni yóò ṣe ètò ìgbáyàwó ọmọ ààrẹ Buhari pẹ̀lú ọmọ Emir Bichi
Bethel Baptist kidnap: Àwọn ajínigbé tú 28 nínú akẹ́kọ̀ọ́ 121 Bethel Baptist tí wọ́n jígbé sílẹ̀
Mejidinlọgbọn ninu awọn akẹkọọ mọkanlelọgọfa tawọn ajinigbe gbe lọ lati ile ẹkọ Bethel Baptist loṣu to lọ nipinlẹ Kaduna.
Pẹlu omije loju lawọn obi awọn akẹkọọ naa fi pade ara wọn lẹyin ti wọn ti lo ogunjọ lakata awọn janduku ajinigbe.
Ọkan lara awọn oludasilẹ ile ẹkọ naa, Rev John Joseph Hayab sọ fun BBC pe awọn ajinigbe naa gba lati tu awọn akẹkọọ naa silẹ lẹyin ti wọn jiroro pẹlu obi awọn ọmọ naa.
Amọ ko sọ boya awọn obi awọn akẹkọọ ti wọn jigbe sanwo itusilẹ ki wọn to tu awọn ọmọ naa silẹ.
Ṣugbọn Rev Hayab ni o ṣeeṣe ki awọn obi awọn akẹkọọ ti san owo itusilẹ ki wọn to fi wọn silẹ.
Rev Hayab sọ pe o ti rẹ awọn ọmọ naa nigba tawọn ajinigbe fi wọn silẹ lalẹ ọjọ Abamẹta.
Ni owurọ ọjọ Aiku ni awọn akẹkọọ ọhun lanfaani lati pade awọn obi wọn lẹyin ti wọn ṣe ayẹwo ara fun wọn tan.
Ọjọ karun un oṣu keje ni awọn janduku ajinigbe yabo ile ẹkọ Bethel Baptist nibi ti wọn ti ji awọn akẹkọọ naa gbe lo.
Koda awọn ajinigbe ọhun tun yinbọn pa awọn ẹṣọ eleto abo to n ṣọ ilẹ ẹkọ naa.
Ijọba ipinlẹ Kaduna ko tii sọ ohun kan lori itusilẹ diẹ lara awọn ọmọ ile ẹkọ Bethel Baptist naa.
Àwọn ọba Yorùbá l'órílẹ̀èdè Benin Republic ṣe ìpàdé, ohun tí wọ́n fẹnukò láti ṣe lórí ọ̀rọ̀ Sunday Igboho nìyí
Awọn ọbaalye iran Yoruba lorilẹede Benin Republic ti ipade laafin aladjohoun tilu Adjohoun ni Benin lọjọ Aiku.
Ohun ti ipade wọn naa da le lori ni ọrọ Sunday Adeyẹmọ ti ọpọ mọ si Sunday Igboho.
Lọjọ aje ni oloye Sunday Igboho yoo pada foju ba ile ẹjọ lorilẹede Benin Republic lati mọ boya wọn yoo tuu silẹ ni tabi ki wọn daa pada sorilẹede Naijiria gẹgẹ bi awọn alaṣẹ ijọba.
Lẹyin ipade naa eyi to pari ni nnkan bi agogo meji ọsan orilẹede Naijiria, awọn ọbalaye naa ṣe lalaye fun ikọ BBC News Yoruba to wa nibi ipade naa pe ipade naa wa lati mọ ọna abayọ ati igbesẹ ti awọn yoo gbe lori ọrọ naa ni. Wọn ni ohun ti awọn fi ẹnu ko le lori ni lati kọ iwe si aarẹ orilẹede Benin pẹlu minisita  feto idajọ, minisita fọrọ abẹle ati olori ileegbimọ aṣofin apapọ lorilẹede naa.
Gẹgẹ bi ohun ti wọn sọ, lẹyin ti wọn ba gbe gbogbo igbesẹ wọnyii ni wọn yoo to lanfani ati ba awọn oniroyin sọrọ.
Awọn lọbalọba naa ko ṣalaye fun BBC News Yoruba ohun ti wọn fẹ kọ sinu iwe ti wọn fẹ kọ naa nitori pe gẹgẹ bi wọn ṣe sọ, titu aṣiri ohun ti wọn fẹ fi ranṣẹ si awọn eekan ijọba orilẹede naa lee pagidina ohun ti wọn fẹ gan an.
Ọba Siyan aladjohoun tilu Adjohoun ṣalaye pe awọn ọbalaye naa pẹlu yoo gbiyanju ati ṣe abẹwo sile ijọba orilẹede naa ni ọjọ Aje bi esi iwe awọn naa ko ba tete jade.
Big Brother Naija 2021: Àwọn olùkópa obìnrin darapọ̀ mọ́ ilé ẹlẹ́gbọ́n àgbà BBNaija, ìyàlẹ́nu ńlá ni wọ́n bá pàdé níbẹ̀
Oríṣun àwòrán, BBnaija
Eyi ni aṣigbọ ati aṣitumọ iroyin nipa Sunday Igboho to n lọ laarin awọn oniroyin nilẹ Benin
Awọn olukopa obinrin darapọ mọ ile ẹlẹgbọn agba BBNaija lalẹ ọjọ Aiku bi saa kẹfa eto agbelewo naa ṣe bẹrẹ.
Wo ohun tí àwọn ọba Yorùbá l'órílẹ̀èdè Benin Republic fẹ́ gbé ní ìgbésẹ̀ nítorí Sunday Igboho
'Ó sàn fún wa kí Sunday Igboho kú sí Cotonou ju kí wọ́n dáa padà sí Nàìjíríà lọ'
Isó fààá leè jẹ́ kí ẹ kò Covid-19 níbi tí o ba fún pọ̀! Ẹ fura o!
Pẹ̀lú omijé lójú làwọn òbí akẹ́kọ̀ọ́ 28 Bethel Baptist táwọn ajínigbé tú sílẹ̀ fi pàdé ọmọ wọn
Awọn ọmọbinrin to darapọ ni Angel, Peace, Jackie B, Tega, Arin.
Bakan naa ni Maria, Nini, Princess, Beartrice, Saskay ati Liquorose pẹlu naa wọ ile loni.
Ni ọjọ Abamẹta ni saa kẹfa eto agbelewo naa gbinaya pẹlu ikede awọn olukopa mọkanla to jẹ ọkunrin.
Igba akọkọ si ni yi lori eto naa ti wọn yoo maa kede awọn olukopa skunrin ati obinrin lọtọọtọ.
Oríṣun àwòrán, BBnaija
Amọṣa, iyalẹnu nla lo jẹ fun awọn olukopa obinrin lori eto naa lalẹ ọjọ Aiku ti wọn kede wọn kaabọ sinu ile ẹlẹgbọn agba BBNaija ẹlu bi awọn ọkunrin to ti ṣaaju wọn de inu ile naa ṣe kọ lati fi ariwo ati ays ki wọn kaabọ sinu ile naa.
Ara ere ti awọn ọkunrin fẹ fi ja awọn obinrin naa laya ni eyi.
Amọṣa lẹyin ti wọn kede gbogbo awọn obinrin naa tan lawọn ọkunrin naa ba fo soke lati ki wọn kaabọ.
Sunday Igboho appears in Benin Court: Ìgbẹ́jọ́ ìdákọ́ńkọ́ ni wọ́n ń ṣe fún Sunday Igboho ní Benin Republic lọ́wọ́
Oríṣun àwòrán, OTHERS
Igbẹjọ Sunday Igboho lori ati gba itusilẹ rẹ ti bẹrẹ lorilẹede Benin
Amọṣa idakọnkọ ni igbẹjọ naa n waye
Awọn akọroyin ati ololufẹ rẹ ko lanfani ati wọle.
Ìdájọ́ jáde! Ilé ẹjọ́ ti ní kí Sunday Igboho ṣì wà ní àhámọ́ ní Cotonou!
Oríire ló jẹ́ fún Sunday Igboho bí ọwọ́ òfin kò ṣe bàá ní Nàìjíríà - Femi Falana
Kí ló mú kí ìjọba ìpínlẹ̀ Eko fẹ́ kí adájọ́ fòfin de Yomi Fabiyi nílé ẹjọ́?
Ọmọ Ìjọ Deeper Life Pọ́ńbélé ni ìyà mi àti bàbá mi, mo sì dàgbà síbẹ̀ àmọ́ bíbọ Èṣù ọ̀dàrà lọ́nà tó tọ́ -
Akọroyin BBC Yoruba to wa nibẹ ni awọn agbẹjọro ati iyawo Igboho nikan lo wọle.
Igbẹjọ naa to bẹrẹ ni nnkan bii agogo marun ku iṣẹju diẹ , agogo orilẹede Naijiria ṣi n lọ lọwọ lasiko ti a fi n ko iroyin yii jọ.
Oni loni njẹ ẹni a bẹ lọwẹ lo difa fun bi gbogbo eto yoo ṣe lọ lonii nibi ti adari ẹgbẹ ajijagbara fun orilẹede Oduduwa Republic, Sunday Igboho yoo ti kawọ pọnyin rojọ niwaju adajọ.
Igba akọkọ niyii ti Sunday Adeyemo ti gbogbo eeyan mọ si Igboho yoo farahan niwaju ile ẹjọ ti wọn n gbee lọ lonii.
"Lati ọsẹ to kọja ti wọn ti fi panpẹ ofin mu oun ati iyawo rẹ Ropo ni wọn ti dee lọwọ lẹsẹ si agọ ọlọpaa wọn nibẹ eyi ti wọ́n n pe ni ""brigade criminelle""."
Lati igba naa ni ẹni ọdun mejidinlaadọta yii ti ti eeyan ti gbogbo agbaye tilẹ fẹ mọ tabi ka iroyin nipa rẹ.
Awọn lọba lọba Yoruba ti forikori lori ọna ti wọn yoo gba lati dide iranwọ fun un ni ilu Benin eyi to waye lọjọ Aiku pẹlu atilẹkun mọri ṣe.
Bakan naa, awọn ọmọ Yoruba to wa ni orilẹede Cotonou ti ni awọn ni ireti pe obi ni igbẹjọ naa yoo so ati pe boya wọn lee da Sunday igboho silẹ lonii.
Lori igbẹjọ rẹ yii awọn ẹsun loriṣiriṣi ni wọn fi kan an.
Akọkọ ni pe o ko ibọn pamọ sile, o si tun n fi n ṣe fayawọ ibọn.
Wọn tun sọ pe Igboho n lo awọn eeyan lati da ilu ru.
Ẹlẹẹketa ni pe Igboho fẹ pin orilẹede Naijiria si meji tabi mẹta.
Ṣugbọn awọn agbẹjọro Igboho sọ fun ile ẹjọ pe ko si otitọ kankan ninu awọn ẹsun ti wọn fi kan an.
"Wọn ni ""ohun to ṣe pataki fun awa agbofinro Igboho julọ ni pe a ko fẹ ki wọn gbe Igboho pada si Naijiria"". 'Ó sàn fún wa kí Sunday Igboho kú sí Cotonou ju kí wọ́n dáa padà sí Nàìjíríà lọ'"
Okunrounmu: Ijọba Buhari jẹ ijiya Ọlọrun fun Naijiria
Nnamdi Kanu: Ìgbẹ́jọ́ olórí IPOB Nnamdi Kanu tẹ̀síwájú nílé ẹjọ́ nílùú Abuja
Igbẹjọ ajijagbara to jẹ olori awọn to n ja fun orilẹede Biafra ni iha ẹya Igbo, Nnamdi Kanu si ọj kọkanlelogun oṣu kẹwa ọdun 2021.
Wọn bẹrẹ igbẹjọ naa lowurọ ọjọ Aje nigba ti Nnamdi Kanu ko tilẹ tii de ibẹ.
Nigba ti wọn gbe ẹjọ naa jade, agbẹjọro fun ijọba, M.B. Abubakar fi to ile ẹjọ leti pe wọn ti baba da ọjọ fun ẹjọ naa awọn yoo si tẹsiwaju.
Nigba naa ni agbjọro Nnamdi Kanu, Ifeanyi Ejiofor sọ fun ile ẹjọ naa pe iwe kan wa niwaju ile ẹ́jọ latọdọ onibaara oun ti ile ẹjọ ko tii sọrọ lori rẹ eyi to da lori pe ki wn gbe Kanu kuro ni ahamọ awọn ọtẹlẹmuyẹ DSS lọ si atimọlẹ fun ayipada iwa.
Ilé ẹjọ́ nílùú Eko ti sún ìgbẹ́jọ́ Baba Ijesha sí ọ̀la Ọjọ́ Iṣẹ́gun, wo ohun tó ṣẹlẹ̀
Ìdí tí Olubadan fi rán àwọn asojú lọ sí ìlú Benin fún ìgbẹ́jọ Sunday Adeyemo Igboho
Wo àǹfàní tí wọ́n ṣẹ̀sẹ̀ fún ìyàwó Sunday Igboho ní Cotonou
Adajọ binta Nyako pada fi lede pe wọn ko ni le tẹsiwaju ninu ẹjọ naa lai si Nnamdi Kanu nibẹ to yẹ ko wa wi tẹnu rẹ tori akii fari lẹyin olori.
Adajọ Nyako tun funpe si awọn ajọ ọtẹlẹmuyẹ lati rii pe adari ẹgb IPOB yii yọju si ile ẹj fun igbẹjọ rẹ.
Wọn ti sun ẹjọ naa siwaju di ọjọ kkanlelogun oṣu kẹwaa ọdun 2021 lati tẹsiwaju ninu igbẹjọ naa.
Awọn ẹsun ti wọn fi kan Kanu da lori ifipa doju ijọba orilẹede Naijiria bolẹ.
Ijọba apapọ ti fi ofin de ẹgbẹ IPOB tẹlẹ ni Naijiria pe wọn o gbọdọ ṣe ohun kohun mọ ni Naijiria.
Kanu gbaju gbaja laarin awọn ẹya Igbo, ijọba Naijiria si ti n wa ọna lati fi ọwọ ofin mu un tipẹ ki awọn agbofinro to pada mu un.
Awọn ẹsun ti wọn fi kan Kanu lẹkunrẹrẹ ni ẹsun igbesunmọmi, kiko ohun ijagun pamọ ati ṣiṣe adari ẹgbẹ to tapa si ofin.
Agbẹjọro agba ati minisita eto idajọ ni Naijiria, Abubakar Malami tun fẹsun kan kanu pe o ṣagbatẹru rogbodiyan eyi to mu ẹmi awọn eeyan lọ ti ọpọ dukia si ṣofo.
Kanu ni aṣaaju ẹgbẹ to n pe fun idasilẹ orilẹede Biafra lẹyin aadọta ọdun ti ogun abẹle waye lori ọrọ Biafra ninu eyi ti eeyan to le ni miliọnu kan ti dero ọrun ti ọpọ dukia si bajẹ.
Ni oṣu kẹwaa ọdun 2015 ni ijọba fi ọwọ ofin mu Kanu ti wọn si fi ẹsun kan an.
Amọ, wọn gba beeli Kanu lọdun 2017 ti o si na papa bora kuro ni Naijiria.
Ohun ti Kanu sọ ni pe awọn kan n dunkoko lati gba ẹmi oun.
Ṣugbọn ijọba pada fi ọwọ mu kanu loṣu kẹfa, wọn si da pada si orilẹede Naijiria.
Okunrounmu: Ijọba Buhari jẹ ijiya Ọlọrun fun Naijiria
Sunday Igboho: Wọ́n ti yọ ṣẹ́kẹ́-ṣẹkẹ̀ lọ́wọ́ Igboho, àǹfàní tí wọ́n ṣẹ̀sẹ̀ fún ìyàwó rẹ̀ ní Cotonou rèé
Ẹgbẹ Ilana Omo Oodua ti ṣalaye bi nkan ṣe n lọ lori igbẹjọ Oloye Sunday Adeyemo ti ọpọ mọ si Sunday Igboho.
Ninu atẹjade kan ti alukoro ẹgbẹ naa, Maxwell Adeleye fi sita ni o ti ṣalaye pe awọn ẹṣọ eleto abo ti yọ ṣẹkẹ-ṣẹkẹ kuro lọwọ Igboho bayii.
Wọn ni alẹ ọjọ Abamẹta ni awọn ẹṣọ yọ ma mun gaari kuro lọwọ Igboho.
Mo fi sánmọ̀ àti ilẹ̀, Mecca àti Medina búra pé Sunday Igboho kò sí nínú ewu níbí - Èèyan Igboho ní Cotonou
Ni bayii, wọn ti fun iyawo Igboho, Ropo ni anfaani lati ri ọkọ rẹ ni igba mẹta lojumọ.
Bakan naa, awọn oṣiṣẹ eleto ilera ti ẹgbẹ Ilana Omo Oodua fi ranṣẹ si orilẹede Benin ti ṣe ayẹwo ilera rẹ.
Ilana Omo Oodua tun sọ pe Igboho ko ṣẹ si ofin irina lati orilẹede kan si omiran rara lorilẹede Benin.
Oni ọjọ kẹrindinlọgbọn oṣu keje ni igbẹjọ Igboho yoo tẹsiwaju, o si ṣeeṣe ki ileẹjọ ṣe agbeyẹwo bo ya ki ijọba Benin da a pada si Naijiria.
Ilana Omo Oodua tun rọ awọn ololufẹ Igboho lati ma ṣe lọ si ile ẹjọ ni Benin.
Wọn rọ wọn wi pe ki wọn duro ni Naijiria ki wọn si maa gbadura fun Igboho.
Okunrounmu: Ijọba Buhari jẹ ijiya Ọlọrun fun Naijiria
Ẹgbẹ Ilana Omo Oodua ni o dawọn loju pe Igboho yoo gba ominira lonii nile ẹjọ.
Baba Ijesha in court: Iléẹjọ́ sún ìgbẹ́jọ́ Baba Ijesha di oṣu kẹ́jọ lẹ́yìn tí wọ́n fọ̀rọ̀ wá ọmọ́débìnrin tọ́rọ̀ kàn lẹ́nuwò
Ile ẹjọ to n gbọ ẹjọ aṣemaṣe pẹlu ọmọ kekere ti wọn fi kan gbajumọ oṣere sinima Yoruba, Lanre Omiyinka ti ọpọ mọ si Baba Ijesha ti sun igbẹjs lori ẹjọ naa si ọjọ kọkanla ati ati ikejila oṣu kẹjọ ọdun 2021.
Ninu ile ẹjọ loni, ọmọdebinrin ti ijọba ipinlẹ Eko n pẹjọ pe Baba Ijẹṣa hu iwa aṣemaṣe pẹlu wa nile ẹjọ ti ile ẹjọ si gbọ ti ẹnu rẹ ni idakọnkọ lẹyin ti adajọ ni ki gbogbo awọn ero ati akọroyin to wa ninu ile ẹjọ naa o jade.
Kemi Olunloyo on Sunday Igboho: Mi ò gbè lẹ́yìn Yoruba Nation àmọ́ mo wà lẹ́yìn Sunday Igb
Bakan naa ni ikọ agbẹjọro fun Baba Ijẹsha tun ṣe ifọrọwanilẹnuwo fun Princess to jẹ alagbatọ ọmọdebinrin naa.
Amofin Kayọde Ọlabiran ṣalaye fun awọn oniroyin pe wọn ko tii fi ọrọ wa Baba Ijesha lẹnu wo ninu ile ẹjọ naa bayii.
Baba Ijẹṣa, Princess to jẹ alagbatọ ọmọdebinrin naa ati ọmọdebinrin ti ọrọ kan ni wọn wa ni ile ẹjọ naa loni.
Nibi igbẹjọ gbajugbaja oṣere fiimu Yoruba, Olanrewaju Omiyinka ti ọpọ mọ si Baba Ijesha, adajọ ti gba pe ki ọmọde kan wa jẹri.
Igbẹjọ naa lo n waye ni ile ẹjọ ti wọn ti n gbọ ẹsun aṣemaṣe to lu mọ ibalopọ nilu Eko.
Amọ ṣe ni adajọ le gbogbo awọn to wa nikalẹ nile ẹjọ sita tori pe o ni  ni ibamu pẹlu ofin, ero ko le wa nibẹ bi ẹlẹri to jẹ ọmọde ba wa jẹri.
Ọmọde naa ni wọn ni o ni ohun to lee sọ si iṣẹlẹ to waye yii.
A ń gbóhùn àdúrà sókè ní orílẹ̀èdè 127 lágbàáyé torí àwọn akẹ́kọ̀ọ́ Baptist tí wọ́n jígbé ní Kaduna -Baptist Convention
"Ta ló pa Toheeb ""kunlékunlé"" nílé ọ̀rẹ́ rẹ̀ ní Ikotun?"
Wọ́n ti fi ẹ̀sùn míì kan Sunday Igboho ní ìlú Benin! - Agbẹ́jọ́rò Igboho
Ọmọ Ìjọ Deeper Life Pọ́ńbélé ni ìyà mi àti bàbá mi, mo sì dàgbà síbẹ̀ àmọ́ bíbọ Èṣù ọ̀dàrà lọ́nà tó tọ́ -
Awọn alatilẹyin Baba Ijesha ati Princess Damilola ti tete de si agbegbe ile ẹjọ lati nkan bii ago mẹsan-abọ owurọ.
Lọjọ Aje ni adajọ Oluwatoyin Taiwo sun igbẹjọ naa siwaju lẹyin ti olupẹjọ, oṣere Princess Commedienne ti orukọ rẹ n jẹ Adekola Adekanye kọkọ ṣalaye ẹjọ tirẹ to lodi si ti oṣere akẹgbẹ rẹ to fẹsun kan.
Baba Ijesha ti wọn fi ẹsun mẹfa ọtọọtọ kan lara eyi ti ifipa bani lopọ, fifi ipa fi nkan ọmọkunrin wọ ara obinrin, aṣemaṣe pẹlu ọmọde ati bẹẹ lọ gbogbo eyi ti wọn ni o lodi si abala ofin 259, 135, 261 iwe ofin ipinlẹ Eko ọdun 2011 ati abala 135, 263, 262 ti ofin ipinlẹ Eko ti ọdun 2015.
Oríṣun àwòrán, others
Ijọba ipinlẹ Eko rọ ile ẹjọ to n gbọ ẹjọ Baba Ijẹsha lori ẹsun aṣemaṣe pẹlu ọmọdebinrin kan pe ko fofin de gbajumọ oṣere tiata Yoruba ni, Yọmi Fabiyi pe ko gbọdọ wọ ile ẹjọ naa mọ.
Agbẹjọro fun ijọba lori ẹjọ naa, Amofin Olayinka Adeyẹmi ni Yọmi fabiyi ti huwa kini ile ẹjọ yoo ṣe pẹlu sinima tuntun rẹ 'Ọkọ Iyabọ' to gbe jade.
Gẹgẹ bi o ṣe sọ sinama naa da lori igbẹjọ ile ẹjọ naa to waye lọjọ kẹrinlelogun oṣu kẹfa ọdun 2021 lẹyin ti adajọ ile ẹjọ naa ti paṣẹ pe ki ẹnikẹni o dakẹ ọrọ lori ikanni gbogbo nipa ẹjọ naa.
Ọkan gboogi lara awọn oṣere to gbohun soke lẹyin Baba Ijẹsa ni Yọmi Fabiyi lati igba ti ọrọ ẹsun aṣemaṣe naa ti bẹrẹ.
Mo fi sánmọ̀ àti ilẹ̀, Mecca àti Medina búra pé Sunday Igboho kò sí nínú ewu níbí - Èèyan Igboho ní Cotonou
Agbẹjọro Ijọba ipinlẹ Eko naa ṣalaye fun ile ẹjọ pe gbogbo awọn ọrọ to nii ṣe pẹlu igbẹjọ naa ni Yọmi Fabiyi fi sinu sinama tuntun to ṣẹṣẹ gbe jade naa leyi to ni o tapa si ofin ibọwọ fun ileẹjọ.
Amọṣa agbẹjọro fun Baba Ijẹṣa, Amofin Dada Awoṣika SAN ṣalaye pe ọrọ ko ri bẹẹ rara nitoripe ki igbẹjọ naa to bẹrẹ ni Yọmi Fabiyi ti bẹrẹ iṣẹ lori sinima naa.
Amofin Awoṣika ni oun pẹlu ti wo sinima naa ko si si sna kan to fi gba tako aṣẹ adajọ ile ẹjọ naa.
Ninu ọrọ rẹ, Onidajọ Oluwatoyin Taiwo to n gbọ ẹjọ naa beere boya Yọmi Fabiyi wa ninu ile ẹjọ naa ti wọn si daa lohun pe rara.
Nigba ti agbẹjọro ijọba ni o ṣeeṣe ki awọn aṣoju rẹ o wa nibẹ lati ṣoju rẹ, Onidajọ Taiwo ni ko si bi ile ẹjọ ṣe lee mọ ẹni to wa ṣoju rẹ nile ẹjọ niwọn igba ti ko si ẹnikẹni to kọọ siwaju ori pe awọn n ṣoju fun un.
'N10 la ṣì ń ta Ọṣẹ Aboke látayédáyé! Òòṣà ni àrùn ìgbóná, gbogbo yín lẹ sì níi lára, èèwọ̀ rẹ̀ rèé o'
Ile ẹjọ to n gbẹjọ osẹre tiata Yoruba, James Omiyinka ti ọpọ mọ si Baba Ijesha ti sun igbẹjọ siwaju.
Adajọ Oluwatoyin Taiwo sun igbẹjọ naa si ọjọ kẹtadinlogun oṣu keje ọdun 2021 yii.
Ẹsun ifipabanilopọ lo wa ni ile ẹjọ ti wọn fi kan Baba Ijesha.
Ẹwẹ, adẹrinpoṣonu, Gbenga Adeyinka ba BBC Yoruba sọrọ pe ododo gbọdọ fi oju han lori ọrọ Baba Ijesha.
Adeyinka ni ẹlẹṣẹ ko gbọdọ lọ lai jiya ẹṣẹ rẹ lori ọrọ to wa nilẹ yii.
Oṣere akẹgbẹ rẹ to n tii lẹyin lati ọjọ yii, Yomi Fabiyi ko farahan nile ẹjọ tori ko si ni orilẹede Naijiria lati igba ti ẹgbẹ awọn oṣere TAMPAN ti pee fun ẹjọ ti ko si yọju.
Lara awọn to peju si ile ẹjọ ni gbajugbaja oṣerebinrin to n ti Princess, iya ọmọ ti wọn ni baba Ijesha fẹ fipa ba lopọ lẹyin, Iyabo Ojo amọ o kọ lati ba awọn oniroyin sọrọ.
Bakan naa, awọn mọlẹbi Baba ijesha bii aburo rẹ ati iya iyawo rẹ ṣi duro gba gba tii lẹyin lai mira ti wọn si wa nile ẹjọ.
A o maa mu ẹkunrẹrẹ wa fun un yin.
Yoruba Nation protest: Olùwọ́de 47 nínú àwọn tí ọlọ́pàá kó ní ìwọ́de Yoruba Nation ti gba ìtúsílẹ̀ láhámọ́ ọlọ́pàá
Mẹtadinlaadọta ninu awọn oluwọde mejidinlaadọta ti ọlọpaa mu lasiko iwọde Yoruba Nation to waye lọjọ kẹta oṣu keje ọdun 2021 ti kuro ni ahamọ awọn ọlọpaa bayii lẹyin ti wọn ti mu awọn gbedeke beeli wọn ṣẹ.
Alukoro ẹgbẹ ilana ọmọ Oodua, Maxwell Adelẹyẹ lo sọ eyi di mimọ ninu atẹjade kan to fi sita lalẹ ọjọ Iṣẹgun.
Ile iṣẹ ọlọpaa ipinlẹ Eko ti sọ idi ti o fi gbe awọn oluwọde Yoruba nation mejidinlaadọta lọ si ile ẹjọ.
Nigba ti o ba BBC Yoruba sọrọ, alukoro ileeṣẹ ọlọpaa ipinlẹ Eko, CSP Muyiwa Adejobi ṣalaye pe oriṣiiriṣii ohun ija bii ibọn ati aake ni ọlọpaa ka mọ wọn lọwọ.
Arọ ọjọ Aje lawọn mejulaadọta foju ba ile ẹjọ Majisireeti niluu Eko lori oriṣiiriṣii ẹsun ti wọn fi kan wọn.
Ìdájọ́ jáde! Ilé ẹjọ́ ti ní kí Sunday Igboho ṣì wà ní àhámọ́ ní Cotonou!
Mo fi sánmọ̀ àti ilẹ̀, Mecca àti Medina búra pé Sunday Igboho kò sí nínú ewu níbí - Èèyan Igboho ní Cotonou
CSP Adejobi ni ara ẹsun ti ọlọpaa fi kan wọn ni igbiyanju lati daluru ati kiko ibọn lọwọ lai laṣẹ .
''Koda awọn mii ti a ka ibọn mọ wọn lọwọ sa kuro ninu ọkọ wọn ti wọn si fẹsẹ fẹẹ.
Awọn ẹsun mii ti wọn fi kan awọn eeyan naa ni pipe jọ ni ọna to tapa si ofin ati iwa to le ṣakoba fun alaafia ilu.
Ẹwẹ, atẹjade kan ti ẹgbẹ Ilana Omo oodua fi sita lati ọwọ alukoro ẹgbẹ naa, Maxwell Adeleye sọ pe ileeṣẹ ọlọpaa ti fẹsun kan ọkan lara awọn oluwọde 48 naa, Ọgbẹni Tajudeen Bakare(Olori Ogboni) pe oun ni afurasi to ṣeku pa Jumoke Oyeleke to n ta omi inu ọra(pure water).
Amọṣa, CSP Adejobi ni oun ko le sọ ohun kan lori ọrọ Olori Ogboni nitori oun ko tii ka iwe ipẹjọ naa daadaa.
Ọjọ kẹta oṣu keje ni awọn eeyan naa ṣe iwọde fun idasilẹ orilẹede Yoruba legbegbe Ojota niluu Eko.
Nibi iwọde yii naa ni awọn ọlọpaa ti fi ọwọ ofin mu wọn ki ọrọ naa to de ile ẹjọ.
Sunday Ighoho in Court: Ìdájọ́ jáde! Ilé ẹjọ́ ti ní kí Sunday Igboho ṣì wà ní àhámọ́ ní Cotonou!
Oríṣun àwòrán, OTHERS
Ile ẹjọ to n gbọ ẹjọ Oloye Sunday Adeyẹmọ ti ọpọ mọ si Sunday Igboho ni orilẹ-ede Benin ti paṣẹ pe ki Sunday Igboho kuro ni ibi ti wọn tii mọ lati ọj ti wọn ti fi panpẹ ofin muu.
Idajọ naa jade loru ọganjọ ọjọ Aje ọjọ kẹrindinlọgbọn oṣu keje ti igbẹjọ rẹ bẹrẹ ni orilẹede Benin Republic.
Bi ẹ ko ba gbagbe, ṣaju ni iroyin n tan kaakiri pe wọn de Igboho ni ọwọ ati ẹsẹ ni ahamọ ọlọpaa amọ ni wakati melo kan sẹyin, iyawo rẹ Ropo sọ fun BBC Yoruba pe wọn ti yọ ṣẹkẹ-ṣẹkẹ ọwọ rẹ kuro Wo àǹfàní tí wọ́n ṣẹ̀sẹ̀ fún ìyàwó Sunday Igboho ní Cotonou.
Wọ́n tí lọ́ ẹ̀sùn míì mọ́ Sunday Igboho lẹ́sẹ̀ ní ìlú Benin! - Agbẹ́jọ́rò Igboho
A dúpẹ́ kò sí ọmọ ilé ẹ̀kọ́ Bethel Baptist School tí wọ́n fipa bá lòpọ̀ nígbèkùn ajínígbé - Ààrẹ Baptist
Baba Ijesha: Wọ́n gbé ọmọdé kan wá sílé ẹjọ́ kó wá jẹ́rìí sí ẹ̀sùn Baba Ijesha àti Princess
Ọmọ Ìjọ Deeper Life Pọ́ńbélé ni ìyà mi àti bàbá mi, mo sì dàgbà síbẹ̀ àmọ́ bíbọ Èṣù ọ̀dàrà lọ́nà tó tọ́ -
Ẹwẹ, ile ẹjọ ti dajọ wi pe ki eekan aṣiwaju ipe fun idasilẹ orilẹede Yoruba naa si wa ni ahamọ.
Ahamọ naa ko ni jẹ ibi ipamọ awọn ọlọpaa to wa tẹlẹ eyi ti wọn n pe ni brigade criminelle bikoṣe ibi ipamọ ọgba ẹwọn lati oni lọ.
Eyi tumọ si wipe wọn ṣii nipo kuro nibi to wa lati ibẹrẹ igbẹjọ yii si ibomiran.
Amoṣa titi di asiko ti a n ko iroyin yii jọ, wọn ko tii sọ ẹkunrẹrẹ bi wiwa ni ahamọ rẹ yoo ṣe ri.
Ni ọjọ kọkandinlọgbọn, oṣu keje, ọdun 2021 ni iroyin kan jade sita pe ọwọ awọn agbofinro ti tẹ Sunday Igboho ni orilẹ-ede Benin Republic.
Ijọba orilẹ-ede Naijiria nipasẹ awọn ileeṣẹ agbofinro rẹ, paapaa julọ ileeṣẹ ọtẹlẹmuyẹ DSS ti fi orukọ Igboho sita gẹgẹ bi ẹni ti wọn n wa.
Mo fi sánmọ̀ àti ilẹ̀, Mecca àti Medina búra pé Sunday Igboho kò sí nínú ewu níbí - Èèyan Igboho ní Cotonou
Iroyin si sọ pe lasiko to n gbero lati lọ sorilẹede Germany nibi to ti n gbero lati ṣe atipo ni  wọn mu ni papakọ ofurufu Cardinal Bernardin International  ni ilu Cotonou.
Lati igba naa lo si ti wa ni ahamọ awọn ọlọpaa nibẹ ki wọn to fi iyawo rẹ, Rọpo silẹ lọjọbọ ọsẹ to kọja lẹyin igbẹjọ ile ẹjo kan lorilẹ-ede naa.
Nibayii, a ko tii lee sọ boya awọn agbẹjọro rẹ yoo pe ẹjọ kotẹmilọrun lori idajọ naa.
Sunday Igboho in Benin republic: Ẹ máṣe dágunlá, nǹkan àmúṣagbára ìṣẹ̀mbáyé ilẹ̀ Yorùbá ṣì wà bíi ti àtijọ́ -Ààrẹ ọ̀nà kakanfò Gani Adams
Leṣẹbọ le ṣoogun, baa ti waye paari laari o.
Ọrọ ti Iba Gani Adams, Aarẹ Ọna Kakanfo ilẹ Yoruba fi ṣide ọrọ lori ifọrọwerọ rẹ pẹlu BBC News Yoruba lori boya lootọ nnkan agbara ṣi wa.
Iba Gani Adams ni lootọ awọn nnkan ti a n ri ni ayika wa lee maa mu iyemeji wa ori boya agbara nbẹ tabi booya oogun wa, sibẹ awọn ọmọ Yoruba ṣi nilo lati gbagbọ ninu iṣẹṣe wọn.
O ni kii ṣe pe ko si ohun amuṣagbara Yoruba mọ, ati pe koda nigba iwaṣẹ awọn alagbara n ṣubu pẹlu.
Central Bank Nigeria bans BDCs: Wo ìdí tí báǹkì àpapọ̀ Nàìjíríà CBN fi tilẹ̀kùn mọ́ àwọn tó ń sẹ owó dọ́là, pọ́ùn ní Nàìjíríà
Oríṣun àwòrán, other
Banki apapọ orilẹede Naijiria ti gbẹsẹle tita awọn owo ilẹ okeere fun awọn olokoowo paṣipaarọ owo ilẹ okeere ti ọpọ mọ si Bureau de Change ni Naijiria.
Godwin Emefiele to jẹ gomina agba banki apaps Naijiria lo kede eyi ninu ifọrọwerọ kan pẹlu awọn oniroyin lẹyin ipade igbimọ kokaari lori ilana iṣuna.
O ni iye owo dọla amẹrika ti wọn n ya sọtọ fun awọn olokoowo ṣiṣẹ owo ilẹ okeere naa ko lee yọ mọ.
Emefiele tun ṣalaye pe awọn olokoowo ṣiṣẹ owo ilẹ okeere naa ti sọ ara wọn di ọpa ipọnwo kotọ lorilẹede Naijiria. O ni wọn ti kọ ẹyin si ojuṣe wọn, wọn si ti sọ ara wọn di agbodegba iwa jibiti ati ikowojẹ lorilẹede Naijiria.
Bakan naa lo ni ko si aaye fun iforukọsilẹ awọn olokoowo ṣiṣẹ owo ilẹ okeere tuntun bayi ati pe awọn banki ni yoo maa ṣe ojuṣe ṣiṣẹ owo ilẹ okeere bayii.
O ni awọn banki yoo ni ẹka lawọn banki wọn lati maa ṣẹ owo ilẹ okeere fun araalu.
Ọmọ Ìjọ Deeper Life Pọ́ńbélé ni ìyà mi àti bàbá mi, mo sì dàgbà síbẹ̀ àmọ́ bíbọ Èṣù ọ̀dàrà lọ́nà tó tọ́ -
Police shooting in Osogbo: Ọlọ́pàá MOPOL yìnbọn fún Ọlabomi, ọlọ́kadà nílùú Osogbo
Oríṣun àwòrán, others
Wahala iwọde ti bẹ silẹ ni ilu Oṣogbo tii ṣe olu ilu ipinlẹ Ọṣun.
Ohun ti awọn iroyin abẹle ṣalaye pe o fa eyi ni bi wọn ṣe ni awọn ọlọpaa kan yinbọn pa smọdekunrin kan ti orukọ rẹ n jẹ Saheed Ọlabomi ni agbegbe Oke Onitea nilu Oṣogbo.
Iṣẹlẹ naa la gbọ wi pe o ṣẹlẹ ni nnkan bii agogo marun un ọjọ Iṣẹgun ti wọn si ti gbe ọmọkunrin naa lọ si ileewosan nla LAUTECHTH nilu Oṣogbo kan naa.
Awọn ti ọrọ naa ṣoju wọn ṣalaye pe iṣẹ alupupu gigun ti ọpọ mọ si ọkada ni Ọlabomi n ṣe.
Wọn ni awọn ọlọpaa atawọn awakọ akoyanrin ni wọn n fa wahala ki awọn ọlọpaa to bẹrẹ si nii yinbọn soke lakọlakọ.
Aṣita ibọn ti wọn n yin lakọlakọ naa lo lọ ba Ọlabomi nibi ọrun lori ọkada rẹ.
Ni asiko ti a n ko iroyin yii jọ, gbogbo oju popo lagbegbe naa lawọn ọlọkada atawọn ọdọ ti n fi ẹhonu han ti wọn si n jo taya ọkọ kaakiri awọn agbegbe bii Okefia nilu Osogbo.
Ọmọ Ìjọ Deeper Life Pọ́ńbélé ni ìyà mi àti bàbá mi, mo sì dàgbà síbẹ̀ àmọ́ bíbọ Èṣù ọ̀dàrà lọ́nà tó tọ́ -
Tokyo 2020: Orílẹ́èdè Nàìjíríà kò tíì rí àmì ẹ̀yẹ kankan gbà nínú ìdíje Olympics tó ń lọ
Oríṣun àwòrán, D'Tigers/Nigerian Basketball
Ẹgbẹ agbabọọlu alapẹrẹ Naijiria, D'Tigers tun ti fidi rẹmi ninu ifẹsẹwọnsẹ keji ti wọn gba ninu idije Olympics to n lọ lọwọ niluu Tokyo lorilẹede Japan.
Ẹgbẹ agbabọọlu alapẹrẹ orilẹede Australia lo kọkọ fiya jẹ D'Tigers Naijiria ninu ere bọọlu ti wọn kọkọ.
Ṣugbọn Germany fi ọba lee fun wọn nigba ti wọn ṣe iya airo tẹlẹ fun Naijiria pẹlu ami ayo 99-92.
Germany lo kọkọ ṣiwaju ni ipele akọkọ pẹlu ami ayo 21-24 ki D'Tigers to gbafuja lọwọ wọn ni ipele keji pẹlu ami ayo 29-26.
Ọmi ni awọn mejeeji jọ ta ni ipele keji, ṣugbọn Naijiria fidirẹmi ni ipele kẹrin ere bọọlu alapẹrẹ naa.
D'Tigers ti n lewaju pẹlu ami ayo mọkanla ni ipele kẹta ki wọn to padanu ipo aṣiwaju wọn eyi to mu wọn fidi rẹmi.
Naijiria ati Germany lo fẹyin gbalẹ ninu ere bọọlu alapẹrẹ ti wọn kọkọ kopa ninu rẹ ni idije Tokyo 2020.
Oríṣun àwòrán, D'Tigers/Nigerian Basketball
Nigba ti Austalia fiya jẹ Naijiria, Italy lo pokọ iya fun Germany.
D'Tigers gbọdọ jawe olubori bayii ninu ere bọọlu alapẹrẹ wọn to kẹyin lọjọ Abamẹta ki to le ni ireti lati tẹsiwaju ninu idije Olympics.
Ẹwẹ, agbabọọlu tẹniisi ori tabili, Aruna Quadri naa fidi rẹmi ninu ere ọwọ lori tabili to ṣe pẹlu ninu idije ọlọdanni ni Tokyo 2020.
Ọmọ Brazil, Gustavo Tsuboi lo di ẹru iya le Quadri lori pẹlu ami ayo 4-2 (15-13, 9-11, 6-11, 11-7, 7-11, 6-11).
Ohun to jẹ iyalẹnu ni pe ọga ni Quadri jẹ fun Tsuboi lagbo tẹniisi ori tabili lagbaaye.
Amọ Quadri ni lootọọ ni Tsuboi jẹ si oun ṣugbọn o pegede ju oun lọ ninu ere ọwọ ti awọn jọ ṣe.
Nibayii, orilẹede Naijiria ko tii ri ami ẹyẹ kankan gba ninu idije Toyo 2020 to n lọ lọwọ.
Sunday Igboho: Femi Falani ní Nàìjíríà ní láti kẹ́kọ̀ọ́ lára Benin lóri ọ̀rọ̀ ẹ̀tọ́ ọmọnìyàn
Oríṣun àwòrán, Koiki Media
Ajijagbara ati ajafẹtọ nilẹ Yoruba, Oloye Sunday Adeyemo ti ọpọ mọ si Sunday Igboho ṣi wa ni atimọle amọ kii ṣe ahamọ ọlọpaa lo wa mọ.
Ile ẹjọ lo paṣẹ nibi igbẹjọ rẹ lọjọ Aje pe ki wọn mu Igboho kuro ni atimọle ọlọpaa.
Awọn ikọ agbẹjọro to n ṣoju Igboho ni Cotonou ṣalaye pe ijọba Naijiria ti n gbe baalu agberapa kan kalẹ lati gbe Igboho pada si Naijiria lati wa jẹjọ.
Kemi Olunloyo on Sunday Igboho: Mi ò gbè lẹ́yìn Yoruba Nation àmọ́ mo wà lẹ́yìn Sunday Igb
Mo fi sánmọ̀ àti ilẹ̀, Mecca àti Medina búra pé Sunday Igboho kò sí nínú ewu níbí - Èèyan Igboho ní Cotonou
Ṣugbọn ọrọ Igboho yatọ si ti olori ẹgbẹ IPOB, Nnamdi Kanu nitori ijọba orilẹede olominira Benin da si ọrọ tiẹ.
Adehun ti Naijiria atawọn orilẹede iwọ oorun Afirika bii Togo, Benin ati Ghana jọ ṣe lọdun 1984 ko sọ pe ki wọn jọwọ awọn eeyan ti wọn ba n wa lori ọrọ oṣelu.
Awọn agbẹjọro Igboho sọ pe adehun ati ofin yii daabo bo Igboho.
Oríṣun àwòrán, Koiki Media
Wọn tun sọ pe ofin ajọ ilẹ Afirika, AU faye gba ki eeyan pe fun iyapa lati ara orilẹede kan.
Ati wi pe Naijiria ati Benin wa lara orilẹede mẹẹdogun ọmọ ẹgbẹ ajọ ECOWAS eyi ti alakalẹ oniruuru ofin n dari.
Gẹgẹ bi alakalẹ ofin ECOWAS lori fifi awọn awọn afurasi ọdaran ranṣẹ si orilẹede abinibi wọn, ijọba orilẹede wọn gbọdọ sọ ẹsun ti wọn fi ṣẹ si ofin ki wọn si beere pe ki wọn jọwọ ẹni bẹẹ.
Ile ẹjọ nikan lo le sọ bo ya orilẹede kan yoo jọwọ afurasi ọdaran fun orilẹede abinini wọn.
'N10 la ṣì ń ta Ọṣẹ Aboke látayédáyé! Òòṣà ni àrùn ìgbóná, gbogbo yín lẹ sì níi lára, èèwọ̀ rẹ̀ rèé o'
Ṣe orilẹede Naijiria ti sọ fun Benin lati fi Sunday Igboho ranṣẹ?
Awọn kan ti fẹsun kan ijọba Naijiria pe o n fẹ lo agbara rẹ lati jọ ki Benin da Igboho pada lai fi ọwọ ofin bọ ọrọ naa tabi gbe lọ si ile ẹjọ.
Gbajugbaja agbẹjọro, Femi Falana sọ fun BBC pe ile iṣẹ aṣoju ijọba Naijiria kọ lẹta ranṣẹ si ijọba Benin pe ki wọn jọwọ Igboho fawọn.
Ṣugbọn ijọba ko gbe igbesẹ yii ni ilana ofin, ijọba Naijiria beere lai fi ti ofin ṣe.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Kinni ibaṣepọ to wa laarin Naijiria ati orilẹede Benin?
Ibode da Naijiria ati orilẹede Benin pọ ki ijọba Naijiria to gbe ibode rẹ tipa lọdun 2019.
Naijiria fẹsun kan Benin nigba naa pe o n ṣe fayawọ oriṣiiriṣii nkan ti ko ba ofin mu wọ Naijiria.
Ọrọ ibode ti Naijiria tipa lo mu ki Aarẹ Benin, Patrice Talon ṣe abẹwo si Naijiria lori ọna ati ṣi ibode ọhun pada.
Oríṣun àwòrán, Other
Ibode naa si wa ni titi pa titi di ibẹrẹ ọdun 2021 yii.
Agbẹjọro Falana gbagbọ pe Naijiria ni lati kọ ẹkọ lori igbẹjọ Igboho ni Benin lori ọwọ ti orilẹede naa fi mu ẹtọ ọmọniyan.
Falana ni iyawo Igboho ti wọn mu pẹlu gba ominira ni kiakia lẹyin ti ileẹjọ sọ pe ko ṣẹ si ofin.
Gbajugbaja agbẹjọro naa sọ pe eyi yatọ si ọrọ awọn eeyan mejila ti wọn ko nile Igboho eyi ti wọn tii ko lọ si ile ẹjọ di akoko yii lẹyin ọsẹ diẹ ti wọn ti mu wọn sẹyin.
Ọmọ Ìjọ Deeper Life Pọ́ńbélé ni ìyà mi àti bàbá mi, mo sì dàgbà síbẹ̀ àmọ́ bíbọ Èṣù ọ̀dàrà lọ́nà tó tọ́ -
Sunday Igboho in Benin Republic: Ọ̀gágunfẹ̀yìntì Buratai gúnlẹ̀ sí Benin Republic láti rí Ààrẹ Patrice Talon gẹ́gẹ́ bí aṣojú ìjọba Nàìjíríà
Oríṣun àwòrán, Benin presidency
Olori ileeṣẹ ọmọogun Naijiria nigba kan ri, Tukur Buratai ti farahan niwaju aarẹ orilẹede Benin Republic, Patirce Talon. Ọjọ Iṣẹgun ni eyi waye nile aarẹ Orilẹede naa.
Bi ẹ ko ba gbagbe orilẹede Benin yii kan naa ni eekan ọmọ Yoruba to n lewaju idasilẹ orilẹede Yoruba, Oloye Sunday Adeyẹmọ, ti ọpọ mọ si Sunday Igboho wa bayii to ti n jẹjọ lẹyin to fẹ gba orilẹede naa kọja si orilẹede Gernmany.
Amọṣa kii ṣe tori ọrọ Igboho ni Ọgagunfẹyinti Buratai ṣe lọ si ilẹ Benin Republic, Ọgagunfẹyinti Buratai ni aṣoju ijọba orilẹede Naijiria tuntun si orilẹede Benin. Ni ọjọ Iṣẹgun lo si mu iwe aṣẹ lọ fun aarẹ orilẹede naa, Patrice Talon.
Ilu Cotonou, olu ilu orilẹede Benin ni awọn agbofinro ti mu Sunday Igboho.
Gani Adams agbara
Supreme court judgement on Ondo election: Ilé ẹjọ́ tó ga jùlọ ní Nàìjíríà dá Akeredolu láre lórí ìdìbò gómìnà ìpínlẹ̀ Ondo
Oríṣun àwòrán, others
Ile ẹjọ to ga julọ lorilẹede Naijiria ti gbe are fun gomina Rotimi Akeredolu gẹgẹ bi ẹni ti ilu dibo yan si ipo gomina Ondo.
Lẹyin ti idajọ igbimọ to gbọ ẹhonu esi idibo ipinlẹ Ondo to waye loṣu kẹwaa ọdun 2020, ati ile ẹjọ kotẹmilọrun ti kọkọ gbe are fun Akeredolu gẹgẹ bi olubori idibo naa ni Eyitayọ Jẹgẹdẹ to jẹ oludije fun ẹgbẹ oṣelu PDP ninu idibo sipo gomina ipinlẹ naa gbe ẹjọ kotẹmilọrun lọ siwaju ile ẹjọ to ga julọ ni Naijiria.
Ninu adajọ meje to joko gbọ ẹjọ naa mẹrin ninu wọn lo wọgile ẹjọ kotẹmilọrun ti Jẹgẹdẹ pe nitoripe ko fa gomina ipinlẹ Yobe Mai Mala Buni gẹgẹ bi ara awọn to n pe lẹjọ naa.
Adajọ mẹta yooku ninu eyi ti Onidajọ Mary Peter Odili, Ejembi Eko ati Tijjani Abubakar wa gbe idajọ kalẹ pe Buni ko lẹtọ lati duro gẹgẹ bi adele alaga ẹgbẹ oṣelu APC.
Bakan naa ni wọn tun sọ pe gomina ipinlẹ Yobe naa tapa si abala kẹtalelọgọsan iwe ofin orilẹede Naijiria tọdun 1999.
Bakan naa ni mẹrin ninu awọn adajọ meje to gbọ ẹjọ naa tun fọwọ si idajọ igbimọ to gbọ ẹhonu esi idibo ipinlẹ Ondo to waye loṣu kẹwaa ọdun 2020, ati ile ẹjọ kotẹmilọrun lori ẹjọ naa pe ko lẹsẹ nlẹ.
BBC Africa Eye: BBC ṣe àyẹ̀wò bí ìjẹkújẹ iléeṣẹ́ ológun ṣe ń ṣàkóbá ìdojúkọ ìgbésùnmọ̀mí
Man kills girlfriend in Edo: Ìyá ọlọ́mọ mẹ́rin kagbako ikú lọ́wọ́ ọ̀rẹ́kùnrin rẹ̀ ẹni ọdún 23
Oríṣun àwòrán, other
Iwe iroyin abẹle, The Vanguard, jabọ pe opo ni obìnrin naa, Rosemary Ifeoma, lati ilu Orogun nijọba ibilẹ Ughelli nipinlẹ Delta.
Iroyin sọ pe nise ni Adebayo la igi mọ obìnrin naa, to si ba ni ibalopọ lẹyin naa.
Bakan naa ni iroyin sọ pe o tun fi igi lu ọmọ obinrin naa kan to jẹ ọmọ ọdun mẹtala, ko to o ba iya rẹ lopọ̀, nireti pe ọmọkùnrin naa ti ku.
"Ẹnikan to n gbe ni adugbo naa to ba awọn akọroyin sọrọ ní ""opo ni obìnrin naa to ti bi ọmọ mẹrin, sugbọn abigbẹyin rẹ to jẹ ọmọ ọdún mẹtala nikan lo n gbe pẹlu rẹ."
O ni ìṣòro owo lati sanwo ile to n gbe, eyi si lo mu ko tọrọ aaye lati ma a sun sinu ile kan ti wọn n kọ lọwọ ni adugbo, titi ti yoo fi ri owo kojọ nibi okoowo rẹ lati gba ile.
Ẹni naa fikun pe gbogbo ara adugbo lo mọ pe obìnrin naa ni ọrẹkunrin kan to jẹ birikila, to ma n wa a wa sinu ile naa.
Owurọ kutu ọjọ kẹrindinlogun, oṣu Keje ni ọmọ obìnrin naa sare wa a sọ fun awọn ara adugbo lẹyin to taji, nipa bi afurasi naa ṣe kọlu oun ati iya rẹ loru mọju.
O ni wọn gbe ọmọ naa lọ sileewosan fun itọju. Lẹyin naa si lo mu wọn lọ si ibi ti ti afurasi naa, Adebayo, ti n sisẹ.
Bi Adebayo ṣe ri ọmọ naa lọọkan lo bẹrẹ si ni salọ, ko to o di pe ọwọ tẹ ẹ pẹlu iranlọwọ àwọn ọlọpaa.
Afurasi naa sọ fun awọn ọlọpaa pe oun ko fi igi lu iya ati ọmọ lori.
Ọmọ Ìjọ Deeper Life Pọ́ńbélé ni ìyà mi àti bàbá mi, mo sì dàgbà síbẹ̀ àmọ́ bíbọ Èṣù ọ̀dàrà lọ́nà tó tọ́ -
O ni lootọ ni oun wa si ọdọ wọn, sugbọn ede aiyede waye laarin wọn nitori bi obìnrin naa ṣe fẹ ko ba wa simẹnti lati ṣe nkankan.
"O ni ki n jade kuro ninu ile oun, nigba ti ede aiyede bẹrẹ. Mo si jáde, sugbọn mo ṣìnà nigba ti mo n lọ, eyi to mu ki n tun pada sinu ile naa.
Nigba ti ma a fi de ibẹ, wọn ti ti geeti. Idi niyẹn ti mo fi fo odi ile naa wọle, ti mo si wọ yaara wọn."""
Adebayo ni ọmọ obìnrin naa dunkooko lati fi ọ̀bẹ gun oun.
O wọ inu yaara lọ, o si mu ọ̀bẹ jade. Mo ti i danu, o si fi ori gba ogiri, eyi to mu ko daku.
O ni ibi ti iya ọmọ naa ti n le oun nitori ọmọ rẹ, ti oun si n gbiyanju lati ti i danu, lo ti ṣubú, to si fi ori gbalẹ ti ẹ̀jẹ̀ fi n jade lori rẹ.
O ṣalaye pe oun ko fi igi lu ẹnikẹni lori, tabi ba obinrin naa lo pọ.
Agbenusọ ileesẹ ọlọpaa nipinlẹ Edo, Kontongs Bello sọ fun awọn akọroyin pe wọn o gbe afurasi naa lọ sile ẹjọ, ti iwadii ba ti pari.
Illumminati: Ìbéèrè méjìlá tó yẹ kóo mọ̀ nípa ẹgbẹ́ Illuminati
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Awọn miran ni ẹgbẹ okunkun to fẹ gba gbogbo aye kan ni Illuminati, ti wọn si wa lẹyin ọpọlọpọ ipaniyan ati awọn ohun miran.
Amọ lakọkọ, Iluminati jẹ orukọ ti wọn fun ileeṣẹ kan to n ri si kara-kata ilẹ ati ile, ti wọn da silẹ ni nkan bi igba ọdun o le marundinlaadọta sẹyin labẹ ileeṣẹ Shell.
Amọ orisirisi iroyin ni o wa lori ayelujara nipa ẹgbẹ yii, lai si aridaju to peye.
Kemi Olunloyo on Sunday Igboho: Mi ò gbè lẹ́yìn Yoruba Nation àmọ́ mo wà lẹ́yìn Sunday Igb
Awọn miran ni ẹgbẹ okunkun to fẹ gba gbogbo aye kan ni, ti wọn si wa lẹyin ọpọlọpọ ipaniyan ati awọn ohun miran.
Ẹgbẹ okunkun ni ẹgbẹ ti wọn n pe ni ''The Order of Iluminati'' ti wọn da silẹ ni Bavaria, ni ọdun 1776 si ọdun 1785 ni agbegbe to wa lorilẹede Germany ni aye ode oni.
Emblème des Illuminati de Bavière
O gbọdọ ni atilẹyin gbogbo ọmọ ẹgbẹ to ku, o gbọdọ jẹ ọlọla ati gbajumọ ni awujọ ati laarin ẹbi. Bakan naa ni idagbasoke ninu ẹgbẹ naa jẹ ṣiṣẹ n tele.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Lootọ  ni wọn n ṣe ẹbọ, amọ ko han si gbangba, wọn si ma n lo orukọ idakọnko lati maṣe jẹ ki eniyan mọ awọn to wa ninu ẹgbẹ wọn.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Johann Adam Weishaupt lo bẹrẹ illuminati
Kemi Olunloyo on Sunday Igboho: Wọ́n kí ọwọ́ bọ̀ mí lójú ára, wọ́n fẹ́ fipá bá mi lòpọ̀ lójú títì, mi ò sì kí ń fi bò lórí ayélujára torí...
Wọ́n kí ọwọ́ bọ̀ mí lójú ára, wọ́n fẹ́ fipá bá mi lòpọ̀ lójú títì, mi ò sì kí ń fi bò lórí ayélujára torí...
Orukọ Kemi Olunloyo kii ṣe aimọ fun oloko gbogbo eeyan to ba n tẹle awọn oniroyin ori ayelujara daadaa tori o jẹ eekan laarin wọn.
O jẹ́ eeyan kan ti ẹnu kii ṣi lara rẹ nigba gbogbo tori awọn iroyin kanka kanka to maa n gbe jade. Eyi ko si tu irun kankan lara rẹ tori pe o ni oun mọ nkan ti oun n ṣe.
"Lori ohun to ṣẹlẹ si Sunday Igboho, Olunloyo ni ""Àwọn tó ní ""passport"" orílẹ̀èdè mìí, Igboho àti Kanu ló fẹ́ da Nàìjíríà rú, ẹ má tẹ̀lé wọn o""."
Ọpọlọpọ ọdun ni Kemi Olunloyo ti lo ninu iṣẹ oniroyin aṣewadii to si ni nibayii, iṣẹ oniroyin asọ ero ẹni lo kan fun ohun tori o ti di ọga ninu iṣẹ naa to si ti fi le awọn ọdọ lọwọ lati tẹsiwaju.
Bí ìjọba bá kọ̀ tí kò ṣèdájọ́, tí Ọlọ́pàá kọ̀ pé àwọn kọ́ ló paá, ẹni tó pa ọmọ mi, náà máa ...
Kí ni àwọn ẹ̀sun tuntun tí ìjọba ìpínlẹ̀ Kaduna tún gbé dìde tako Ibrahim El-zakzaky?
'Lábẹ́ òfin àjọ ECOWAS, kó ṣééṣe kí Benin Republic jọ́wọ́ Sunday Igboho fún Nàìjíríà'
A ó bẹ̀rẹ̀ ìwádìí ẹsun ti US fi kan Abba Kyari, Ọ̀gá àgbà ọlọ́pàá ti pàṣẹ
Oúnjẹ tí àwọn Onífá tí wọn ń gbé wá sílé wa ló mù mí fi ẹsìn Krìstẹnì sílẹ dí Ogbójú Babaláwo àti Ẹ̀lẹ́bọ – Oluwo Olakunle
Igi Ọ̀pẹ abàmì tó dá ní orí 42 l'Ekiti rèé o! 'Bí mo ṣe ríi l'orí mi ń dìde fììì fììì'
Tope AjogbaJesu jáde láyé!
Ni ọpọ igba o lee jẹ ẹni akọkọ ti yoo gbe iroyin nla kan jade amọ ti ọpọ eeyan yoo maa bu pe nibo lo ti rii ti wọn o ni gbaa gbọ, nigba miran awọn iroyin yii maa n pada jẹ ootọ ti omii yoo si ni itumọ ọtọ.
Kemi Omololu-Olunloyo jẹ ọmọ Naijiria to tun kawe nipa imọ iṣegun oyinbo, ẹka pipoogun amọ iṣẹ iroyin lo n ṣe titi di oni.
Ninu ifọrọwanilẹnuwo rẹ pẹlu BBC Yoruba, o fesi pe ọpọ igba ti oun ti ko sọwọ ofin nitori ohun ti wọn pe ni iroyin ofege tabi ibanilorukọ jẹ, kii ṣe pe oun kan ṣee amọ awọn to maa n baa wa iroyin ni ko ṣe gbogbo iṣẹ ọfintoto wọn daadaa ki wọn to jabọ fun oun.
Mo ti fi iṣẹ́ akọ̀ròyìn sílẹ̀, iṣẹ́ ajíhìnrere Jesu ni ọpọ́n sún kàn- Kemi Olunloyo
Omololu Olunloyo Kọmíṣọnnà lẹẹmẹfà tó gbé ọpá àṣẹ fún aláàfin Oyo àti Ṣọun Ogbomọṣọ
Bakan naa, Kemi sọrọ o kunlẹ nipa igbe aye rẹ ati bi mọlẹbi rẹ ṣe kọọ silẹ ti oun naa ko si fẹ ni ohunkohun ṣe pẹlu wọn.
O tun mẹnu ba idi ti kii fii ṣẹnu ku sọrọ nipa bi awọn ọkunrin kan ṣe baa lopọ ti yoo maa sọọ lori ayelujara.
Ọrọ ija laarin oun ati gbajugbaja sọrọsọrọ ori ayelujara mii, Esther Aboderin ti ọpọ mọ si ESABOD ko gbẹyin.
Hushpuppi gbà pé òun jẹ̀bi ẹ̀sùn kíkó owó pamọ̀ lọ́nà àìtọ́, ọmọ Nàìjíríà míì tó ń báa ṣiṣẹ́ rèé
Oríṣun àwòrán, Hushpuppi/Instagram
Hushpuppi sọ wi pe ọga ọlọpaa kan ni Naijiria ran oun lọwọ lati fi panpẹ ọba mu olubaṣiṣẹpọ to fẹ tu aṣiri rẹ.
Ileeṣẹ olotu idajọ lorilẹede Amerika, DOJ ni awọn ti fi panpẹ ọba mu awọn ọṃ Naijiria mẹta to lọwọ ninu bi Raymond Hushpuppi Abbas ṣe ji iye owo to le ni biliọnu kan naira lasiko ti wọn n lu jibiti lori ẹrọ ayelujara.
FBI ni awọn fi panpẹ ọba mu awọn mẹta na ni Ọjọ Kejilelogun, Osu Keje lasiko igbẹjọ to ni Hushpuppi lo ọna ẹburu lati gba owo lọwọ oniṣowo kan.
"Orukọ wọn ni Yusuf Adekinka Anifowoshe, a.k.a. ""AJ,"" 26, tọ n gbe ni Brooklyn, New York; Rukayat Motunraya Fashola, a.k.a. ""Morayo,"" 28, to n gbe ni Valley Stream, New York ati Bolatito Tawakalitu Agbabiaka, a.k.a. ""Bolamide,"" 34, to n gbe ni Linden, New Jersey."
Awọn mẹtẹẹta naa ni wọn yoo yọju si ileẹjọ ni ilu Los Angeles ni Ogunjọ, Osu kẹjọ, ọdun 2021. Ẹwọn ogun ọdun lo n duro de wọn ti wọn ba jẹbi ẹsun ti wọn fi kan wọn.
Oniṣowo ti wo.n lu ni jibiti naa aṃ ti wọn ko darukọ rẹ ni lo n gbiyanju ati kọ ileewe fun awọn ọmọde ni Qatar.
Igi Ọ̀pẹ abàmì tó dá ní orí 42 l'Ekiti rèé o, 'bí mo ṣe ríi l'orí mi ń dìde fììì'
Ninu atẹjade naa ti FBI gbe jade ni Hushpuppi ti jẹwọ pe lootọ ni oun jẹbi gbogbo ẹsun ti wọn fi kan an.
Bakan naa ni Hushpuppi sọ wi pe ọga ọlọpaa ni Naijiria ran oun lọwọ lati fi panpẹ ọba mu olubaṣiṣẹpọ to fẹ tu aṣiri rẹ.
Ninu owo ti Hushpuppi ji naa ni o ti ra aago ọwọ to to $230,000  eleyii ti Richard Mile RM11-03 se, to si fi si oju opo ikansiraẹni Instagram.
Bakan naa ni wọn fẹsun kan Hushpuppi pe o lo owo naa lati ra iwe igbelu ni orilẹede St. Christopher and Nevis island kontri, to si tun fi ṣe igbeyawo ofege, to si sanwo abẹtẹlẹ fun awon oṣiṣẹ ijọba ni St.Kitts.
Oríṣun àwòrán, Screenshot/Hushpuppi/
Ilumọọka ori atẹjisẹ Instagram, Ramon Abass ti gbogbo eniyan mọ si Hushpuppi ti sọ fun ile ẹjọ pe oun gba pe oun jẹbi ẹsun  meji ti wọn fi kan.
Ẹsun naa to da lori igbimọ pọ lati kowo ilu pamọ lọna aitọ gẹgẹ bi ìwé kan tí BBC foju kan eyi ti agbẹjọro rẹ pẹlu sì sọ pé ìwé naa kii ṣe ayederu.
"Olujẹjọ naa ti yoo foju bale ẹjọ bayii lati bẹbẹ pe òun jẹbi ẹsun meji ti wọn fi kan oun ninu ipejọ orilede Amerika ati Ramon Olorunwa Abass ti wọn pe ni Case No. 2:20-CR-00322-ODW.
Ṣe ni Hushpuppi darukọ ọga ọlọpaa Abba Kyari nibi igbẹjọ pe oun fun un atawọn mii nileeṣẹ ọlọpaa ni owo abẹtẹlẹ. Amọ Abba Kyari ti fesi lori ayelujara rẹ pe A kò bèrè fún owó kankan lọ́wọ́ Hushpuppi - Abba Kyari dá èsì padà fún ileẹjọ́ US
Wọn fẹsun kan pe oun pamọpọ lati kowo ilu pamọ lọna aitọ eyi to si lodi si ofin kejidinlogun ti U.S.C § 1956(h). "" Bi iwe ile ẹjọ naa ṣe sọ."
Oríṣun àwòrán, USAO
Oríṣun àwòrán, USAO
Gẹgẹ bi iwe ẹsun ile ẹjọ to n ja rainrain yii ṣe sọ, Hushpuppi ṣe adehun pẹlu ile iṣẹ ti idajọ ilẹ Amẹrika ti Central District ti California (USAO).
Ati pe adehun yii ko kọja agbegbe USAO bákan naa ni ko ni nnkan ṣe pẹlu ijọba apapọ, ipinlẹ ati awọn agbejọro ilẹ okere, agbofinro tabi awọn alaṣẹ.
Nigba ti BBC kan si agbẹjọro Hushpuppi Loius Shapiro lati fi idi ọrọ mulẹ pe onibara rẹ gba pe oun jẹbi ẹsun, o si sọ pé òun kìí sọrọ nipa igbẹjọ ti oun ba n ṣe lọwọ.
Ṣugbọn nipa boya awọn ni Iwe to jẹyo lori ayelujara jẹ ootọ, O ni bẹẹ ni ootọ ni awọn iwe naa.
Awọn adehun miiran ti Hushpuppi tun ṣe gẹgẹ bi o ṣe han ninu iwe ọhun ni:
Oríṣun àwòrán, USAO
Oríṣun àwòrán, USAO
Kini ijiya to wa fun iru ẹsẹ Hushpuppi?
O ṣeeṣe ki o koju ẹwọn ogun ọdun ti wọ́n ba ṣe igbẹjọ tan gẹgẹ bi nnkan to wa ninu iwe ile ẹjọ naa.
" Olujẹjọ ni oye pe ijiya ẹsẹ si ofin ikejidinlogun orilde ilẹ Amẹrika Code Section 1956(h) ni ẹwọn ogun ọdun.
 Ọdun mẹta ni wọn yoo fi ma moju to, ti yoo si san owo itanran ẹgbẹrun lọ́nà aadọ́ta dọla tabi ilopo meji ere tabi adanu lori ẹsẹ ti o ṣe, bákan naa ni yoo tun san ọgọrun dọla gẹgẹ bi owo abẹwo"""
Iwe ile ẹjọ fi kun pe o ṣe pataki lati ni oye pe, ile ẹjọ yoo ni ki wọn san ẹkunrẹrẹ owo fun awọn ti o lu ni jibiti nitori pe o ti gba pe oun jẹbi ẹsun.
Bakan naa ni o gba pe nitori ifọwọsolwọpọ USAO pẹlu adehun yii, ile ẹjọ le ni ki o sanwo fun awọnti ko si lara awọn ti ko lu ni jibiti nitori pe o ti gba pe oun jẹbi ẹsun.
"Ni koko olujẹjọ gba pe yoo ṣe adapada fun gbogbo ẹni to ba ti fi ara ko ninu iwa ọdara ti olujẹjọ hu gẹgẹ bi iwe naa ṣe sọ.
Oríṣun àwòrán, USAO
Oríṣun àwòrán, USAO
Oríṣun àwòrán, USAO
Oríṣun àwòrán, usao
Oríṣun àwòrán, AFP
Awọn eleto abo Orilẹede United Arab Emirates lo kọkọ mu Hushpuppi to n gba ni Dubai ninu oṣu kini ọdun 2020 lẹyin ti wọn fẹsun kan pe oun gbiyanju lati ji ọpọ milọnu dọla nipa lilu Email ati ọna Yahoo-Yahoo ati awọn awọn ọna jibiti miiran.
Ile iṣẹ awọn agbẹjọro, ilé ifowopamọ  ati ẹgbẹ agbabọọlu Premiere League kan ni o tun pinu lati lu ni jibiti nigba ti wọn mu.
Ninu oṣu keje ọdun 2020, orilede UAE pada da Hushpuppi pada si Chicago ni orilede Amerika labẹ ẹka akanse FBI ti wọ́n si kọkọ gbe lọ si ile ẹjọ.
Lasiko to to wa ni atimọle, ile ẹjọ Ariwa Illinois ni orile-ede USA ti pasẹ pe ki wọn gbe Hushpuppi lọ si Los Angeles ni bi  igbẹjọ yoo
Kí ìgbẹjọ tó bẹrẹ Ramon Abass ti pe oun jẹbi  ẹsun mẹrin ti wọn fi kan oun, lati ori kiko owo owo pamọ lọna aitọ awọn oniruuru ẹsun mii.
Ki o to di asiko yii, awọn onimọ ti sọ fun BBC tẹlẹ  pe ti wọ́n ba ri pe Hushpuppi jẹbi ẹsun, o kere tan yoo lọ ẹwọn ogun ọdun.
Ìjoba fìyà jẹ el-Zakzaky lọ́nà àìtọ́, ṣùgbọ́n a fa gbogbo rẹ̀ lé Ọlọrun lọ́wọ́ - Islamic Movemnent of Nigeria
Oríṣun àwòrán, other
Ẹgbẹ awọn Musulimi, Islamic Movemnent of Nigeria ti sọ pe lootọ ni ijọba Aarẹ Muhammadu Buhari fiya jẹ aṣaaju awọn, Sheikh Ibrahim El-zakzaky,  ṣugbọn awọn fa gbogbo rẹ le Ọlọrun lọwọ.Agbenusọ ẹgbẹ naa, Ibrahim Musa lo sọ bẹẹ fun BBC Yoruba ninu ifọrọwerọ kan.O ni inu awọn dun pe ile ẹjọ ti tu El-zakzaky silẹ ninu ọgba ẹwọn to wa bo tilẹ jẹ pe o ti lo nnkan bii ọdun mẹfa ni ahamọ ọhun, toun ti iyawo rẹ.O ṣalaye pe ẹgbẹ awọn gẹgẹ bi Shia ko tii ṣe ipade lati lori irufẹ igbesẹ ti awọn yoo gbe nitori bi awọn yoo ṣe tọju rẹ lo gogo lọkan awọn lọwọ yii.Ibrahim ni o ṣeeṣe ki awọn pe ijọba apapọ lẹjọ lati san owo gba mabinu lori iya to fi jẹ adari awọn, ṣugbọn awọn ṣi fẹ ṣetọju bayii na.
Oríṣun àwòrán, AFP
Lẹyin ọ rẹyin, Ile ẹjọ giga kan nipinlẹ Kaduna, ti da Olori ìjọ ẹsin Isilaamu Shia, Islamic Movement of Nigeria, Ibrahim El-zakzaky ati iyawo rẹ, Zeenat silẹ pe ki wọn maa lọ ni alaafia.
El-zakzaky ati iyawo rẹ ti n jẹjọ lori ẹsun to ni i ṣe pẹlu idaluru ati kikorajọpọ lọna ti o tapa si ofin.
Amọ, ile ẹjọ ti yi gbogbo awọn ẹsun naa ti ijọba ipinlẹ Kaduna fi kan wọn danu bayii.
Ọdun 2015 ni ijọba mu El-zakzaky lẹyin ti rogbodiyan bẹ silẹ laarin awọn ọmọ ijọ rẹ ati awọn ọmọ ogun Naijiria nilu Zaria.
Ọpọ igba lawọn ọmọlẹyin El-zakzaky ti ṣe iwọde eleyii ti wọn fi n beere fun itusilẹ olori wọn ati iyawọ rẹ.
Ọpọ awọn ifẹhonuhan yii lo mu ẹmi lọ nigba ti ọpọ eeyan si farapa yana yana.
Wọnyii ni awọn iṣẹlẹ buruku to ṣẹlẹ lasiko iwọde ẹgbẹ musulumi Shi'ite ni Naijiria.
Shiite: Ẹ̀mí àti ara wa kọ ohun tí ìjọba ń ṣe sìwa láti 2015
Ọpọ ẹmi sun lọdun 2015 lẹyin ikọlu laarin ẹgbẹ Shi'ite ati ile iṣẹ ologun
Rogbodiyan bẹ silẹ nigba tawọn musulumi Shi'ite to n ṣe iwọde loju popo niluu Zaria nipinlẹ Kaduna kọlu awọn ọmogun to n kọwọ rin pẹlu ọga ọmogun oriilẹ, Tukur Buratai.
Ileeṣẹ ologun ni awọn musulumi Shi'itẹ di ọna mọ awọn ọga ologun to n kọja.
Ẹgbẹ Shi'ite fẹsun kan ileeṣẹ ologun oriilẹ Naijiria pe o yinbọn pa ọmọ ẹgbẹ awọn to le ni ọgọrun.
Ṣugbọn ileeṣẹ ologun ni awọn ẹgbẹ Shi'ite lo kọlu awọn iṣọmọgbe Buratai ṣugbọn wọn ni ko si ohun to jọ bẹẹ.
Ìbọn ọlọ́pàá ló pa èèyàn, ẹgbẹ́ wa kìí lo ìbọn - Shiite fárígá
Ẹ ṣọ́ra fún ìròyìn ẹlẹ́jẹ̀ lórí ètò ààbò - Ọlọ́pàá
Ọlọ́pàá ló ń fa rúkèrúdò lásìkò ìwọ́de wa-ẹgbẹ́ Shi'ite
Kílò fa èdè àìyedè láàrin ìjọba àti àwọn ọmọ lẹ́yìn El-Zakzaky?
Akọroyin, ọlọpaa atawọn mọkanla mii ṣagbako iku lasiko iwọde awọn ẹgbẹ Shi'ite l'Abuja lọdun 2019
Iwọde awọn ẹgbẹ musulumi Shi'ite bẹyin yọ lẹyin ti eeyan mẹtala dero ọru nibi nigba tawọn agbofinro kọlu awọn ẹgbẹ naa niluu Abuja.
Akọroyin kan, ọlọpaa kan ati eeyan mọkanla lo ba iṣẹlẹ naa lagbegbe Wuse niluu Abuja.
Ileeṣẹ ọlọpaa naa sọ pe awọn fi ọwọ ofin mu aadọta eeyan lori iṣẹlẹ ọhun.
Awọn ọmọ ẹgbẹ Shi'ite ṣe iwọde naa fun itusilẹ olori wọn, El-zakzaky ati iyawo rẹ to wa latimọle.
Oríṣun àwòrán, Other
Ọmọ ẹgbẹ Shi'ite marun un fara gbọta nnibi iwọde wọn l'Abuja lọdun 2020
Awọn ọmọ ẹgbẹ musulumi Shi'ite marunn un fara gbọta nibi iwọde ti wọn ṣe niluu Abuja.
Ikọlu naa waye ni ikorita Berger niluu Abuja laarin awọn ẹgbẹ Shi'ite ati awọn agbofinro.
Atimọle ijọba ipinlẹ Kaduna ni wọn ju,El-zakzaky ati iyawo rẹ si niluu Kaduna.
Hushpuppi: Wọ́n ti ń wá Ọgá Ọlọ́pàá Abba Kyari l'Ámẹ́ríkà láti wá jẹ́jọ́ọ kí ló wà láàrin rẹ̀ àti Hushpuppi
Oríṣun àwòrán, Daily Nigerian
Ilé ẹjọ́ Amẹrika pàṣẹ kí FBI fi ṣìkún òfin mú ọ̀gá ọlọ́pàá, Abba Kyari lórí ọ̀rọ Hushpuppi
Hushpuppi: Ẹ lọ mú Abba Kyari wá láti sọ tẹnu rẹ̀ - Ilé ẹjọ́ Amẹrika
Ile ẹjọ kan nilẹ Amẹrika ti paṣẹ pe ki wọn fi ṣikun ofin mu igbakeji kọmiṣọna ọlọpaa kan ni Naijiria, Abba Kyari.
Gẹgẹ bii iwe aṣẹ ile ẹjọ naa to tẹ iwe iroyin abẹle People's Gazzett lọwọ ṣe sọ, Ortis Wright lati ile ẹjọ naa to wa ni California lo ni ki ajọ ọtẹlẹmuyẹ FBI o ṣawari Abba Kyari lati wa sọ tẹnu rẹ lori ohun to mọ nipa bi Hushpuppi ṣe n lu awọn eeyan ni jibiti.
Ṣaaju ni Hushpuppi ti kọkọ sọ fun ile ẹjọ naa pe Abba Kyari lo ba oun fi ṣikun ofin mu alatako oun ninu iṣẹ jibiti, Chibuzor Vincent, lẹyin ti Chibuzor halẹ mọ Hushpuppi pe oun yoo tu aṣiri bo ṣe lu oniṣwo kan to jẹ ọmọ ilẹ Quatar ni jibiti.
Igi Ọ̀pẹ abàmì tó dá ní orí 42 l'Ekiti rèé o, 'bí mo ṣe ríi l'orí mi ń dìde fììì'
Iwe ile ẹjọ naa sọ pe Hushpuppi pẹlu awọn marun un miran gbimọpọ lati lu oniṣowo kan ni gbajuẹ, lẹyin ti wọn parọ fun oniṣowo naa pe awọn n ṣiṣẹ pẹlu banki ti yoo ya oniṣowo ọhun lowo lati fi kọ ile ẹkọ lorilẹ-ede Quatar.
Lara awọn ti wọn gbimọ pọ lati lu oniṣowo naa ni jibiti gẹgẹ bii iwe ile ẹjọ ọhun ṣe ṣalaye ni Abdulrahman Juma lati Kenya, Chibuzo Vincent lati Naijiria, to fi mọ Yusuf Anifowoshe; Rukayat Fashola; ati Bolatito Agbabiaka.
Ṣugbọn wahala bẹ silẹ laarin awọn eeyan naa lẹyin ti Vincent leri pe oun yoo tu aṣiri gbajuẹ naa, eyii to mu ki Hushpuppi maa lepa rẹ.
Kemi Olunloyo on Sunday Igboho: Mi ò gbè lẹ́yìn Yoruba Nation àmọ́ mo wà lẹ́yìn Sunday Igb
Iwe ile ẹjọ naa ni Kyari jẹ ọkan lara awọn igbakeji kọmiṣọna ọlọpaa to gbajumọ gidini Naijiria, oun lo fi ṣikun ofin mu Vincent lẹyin ti Hushpupi bẹẹ lọwẹ."""
Ẹwẹ, ninu atẹjade kan to fi lede loju opo Facebook rẹ, Kyari sọ pe oun ko mọ ohunkohun nipa jibiti kankan ati eosun ti wọn fi kan oun.
O ni lootọ ni Hushpuppi ke si awọn ọlọpaa pe Vincent halẹ pe oun yoo ṣekupa awọn mọlẹbi oun ni Naijiria ṣugbọn iwadii awọn fi han pe ko si ohun to jọ bẹẹ.
Kyari tun sọ pe oun ko gba owo Kankan lọwọ Hushpuppi ati pe yatọ si ọrọ Vincent, ohunkohun ko pa awọn mejeji pọ ayafi igba ti oun juwe aranṣọ oun si, ti aransọ naa si ba ran aṣọ, eyii to fi owo iṣẹ rẹ ranṣẹ si aranṣọ naa.
Bi ẹ ko ba gbagbe, Hushpuppi ti tọwọ bọwe pe lootọ ni oun lu ọpọ eeyan ni jibiti lori ayelujara ati pe oun gba pe oun jẹbi awọn ẹsun gbajuẹ ti wọn fi kan oun.
Eyii to n tumọ si pe o ṣeeṣe ki Hushpupi fi aṣọ penpe roko ọba nilẹ Amẹrika fun nnkan bii ogun ọdun.
Kọmisana ọlọpaa Naijiria, Abba Kyari ti sọ pe ir ni ẹsun ti wọn fi kan ileeṣẹ ọlọpaa pe wọn gba owo lọwọ Raymond 'Husspuppi' Igbalode to n jẹjọ lọwọ ni United States.
Bakan naa, wọn fẹsun kan pe Hushpuppi fun Abba Kyari ni owo abẹtẹlẹ.
Ẹka to n ri si idajọ nilẹ Amẹrika sọ pe awọn ti fi panpẹ ofin mu ọmọ orilẹede Naijiria mẹta bayii ni Amẹrika to n ran Hushpuppi Abbas lọwọ to fi ji miliọnu owo Dollar $1.1m ni ọna idigunjale wiwọke owo jade.
"Ninu atẹjade ti wọn fi sita lati ẹka ile ẹjọ naa ni ọjọ kejidinlọgbn oṣu keje, 2021 sọ pe Hushpuppi jẹwọ to si gba pe lootọ ni oun jẹbi ẹsun jiji owo gọbọi atawọn ẹsun mii to lu mọ eto akanṣe katakara ""Business Email Compromise Schemes""."
Mo gbà pé mo jẹ̀bi gbogbo ẹ̀sùn wíwọ́ké àti kíkó owó pamọ́ lọ́nà àìtọ́ - Hushpuppi
Oríire ńla ni ìdájọ́ El-Zakzaky jẹ́ lẹ́yìn ọdún mẹ́fà ní ọgbà ẹ̀wọ̀n - IMN
Ṣé lóòtọ́ọ́ ni ẹgbẹ́ illuminati lè sọ èèyàn di olówó? Ohun méjìlá tí a mọ̀ rèé
Atẹjade ẹka idajọ ilẹ Amẹrika ọhun (DoJ) tun ṣafihan rẹ pe yatọ fun Abba Kyari, hushpuppi tun san owo abẹtẹlẹ fun igbakeji kọmisana ọlọpaa Naijiria lati lee fi panpẹ ofin mu akẹgbẹ rẹ ninu jiji owo, Kelly Chibuzo Vincent to jẹ ẹni ogoji ọdun.
Eyi waye gẹgẹ bi atẹjade naa ṣe sọọ, lẹyin ti Vincent gbiyanju lati tu aṣiri iṣ ti wọn ṣe to si s fun afurasi naa ohun ti wọn ṣe sii.
"Ninu iwe naa, Kyari jẹ ọga onipo giga Kọmisana ileeṣẹ Ọlọpaa Naijiria ti wọn fẹsun kan pe o ṣe eto bi wọn yoo ṣe fofin mu Vincent ki wọn si juu si ẹwọn labẹ aṣẹ Abbas ti wọn yoo si fi awọn fọ́tò rẹ ranṣẹ si Abbas lẹyin ti wọn ba gbaa mu.
Amọ Abba Kyari ti fi ọrọ sita pe bẹẹ kọ lori oun ko si gba owo kankan lọwọ Hushpuppi.
Ọmọ Ìjọ Deeper Life Pọ́ńbélé ni ìyà mi àti bàbá mi, mo sì dàgbà síbẹ̀ àmọ́ bíbọ Èṣù ọ̀dàrà lọ́nà tó tọ́ -
ẹsun ti wọn fi kan Abba Kyari pe o da lori ẹri ti Hushpuppi gbe wa siwaju ile ẹjọ Amẹrika gẹgẹ bi ọkan lara nkan to fẹ fihan.
BBC gbiyanju lati kan gbọ latẹnu Abba Kyari gangan lori ọrọ yii ṣugbọn pabo lo ja si.
Ẹwẹ, o fi atẹjade sita loju opo facebook rẹ ninu eyi ti akọṣẹmọṣẹ ọga ọlọpaa naa kọọ sita pe lootọ o Hushpuppi kan si oun amọṣa ko tilẹ si labẹ ofin iṣẹ rara tori pe Vincent bẹrẹ si ni fi iku dẹru balẹ.
Ẹyin ara ati ọrẹ, Abbas ti a pada wa mọ si Hushpuppi pe ọfiisi wa ni nkan bii ọdun meji sẹyin lati sọ pe eeyan kan ni Naijiria to fẹ gba mi oun o si fi nọmba ipe ẹni naa ranṣẹ o tun bẹbẹ pe ki wọn gbe igbesẹ ki ẹni naa to lọ ṣekọlu si mọlẹbi ohun."
"A tọpinpin a si fi ofin mu afurasi naa amọ lẹyin iwadii ni gbogbo wa rii pe ko tilẹ si ẹni to n dẹru bolẹ lati gba ẹmi ẹnikẹni to si ni ọrẹ atijọ lawọn amọ ija owo wa laarin awọn. La ba pada tu afurasi naa silẹ pẹlu beeli""."
Ko sẹni to gba owo kobo lọwọ Abbas Hushpuppi. Afojusun wa ni lati gba ẹmi awọn eeyan la. Ipe idẹrubani nikan la maa n pe. Abba Kyari sọrọ.
Kí ni Ọ̀gágunfẹ̀yìntì Buratai ń ṣe ní Benin Republic, ìlú tí Sunday Igboho ti ń jẹ́jọ́?
'N10 la ṣì ń ta Ọṣẹ Aboke látayédáyé! Òòṣà ni àrùn ìgbóná, gbogbo yín lẹ sì níi lára, èèwọ̀ rẹ̀ rèé o'
Sunday Igboho: Agbẹjórò ní kò sí ohun tó jọọ́ pé orílẹ́èdè Benin ń gbèrò láti dá Sunday Igboho padà sílé
Oríṣun àwòrán, Others
Ile ẹjọ kan niluu Cotonou lorilẹede Benin paṣẹ pe ki wọn mu Oloye Sunday Adeyemo(Igboho) kuro ni ahamọ ọlọpaa.
Amọ, ile ẹjọ sọ pe ki Igboho si wa ni atimọle ti kii ṣe ti awọn ọlọpaa.
Ẹwẹ, ọkan lara awọn agbẹjọro Igboho ṣalaye fawọn akọroyin idi ti Igboho yoo fi wa ni atimọle fun igba diẹ.
Bí ìjọba bá kọ̀ tí kò ṣèdájọ́, tí Ọlọ́pàá kọ̀ pé àwọn kọ́ ló paá, ẹni tó pa ọmọ mi, náà máa ...
Olusegun Falola to jẹ ọkan lara awọn agbẹjọro Igboho ni Benin Republic sọ pe ajijagbara fun idasilẹ Yoruba Nation wa ni atiimọle lati daabo bo o ni.
Agbẹjọro Falola to jẹ Ọmọwe ninu ofin fikun ọrọ rẹ pe adehun ajọ ECOWAS gan an eyi ti Naijiria ati Benin naa buwọlu daabo bo Igboho.
Falola ni ijọba Naijiria gan an ko fẹsun ọdaran kan Ọgbẹni Adeyemo titi di akoko yii.
''Ofin orilẹede Benin ko faye gba ki eeyan wa ni atimọle ọlọpaa ju ọsẹ kan lọ.
Tope AjogbaJesu jáde láyé!
Igi Ọ̀pẹ abàmì tó dá ní orí 42 l'Ekiti rèé o, 'bí mo ṣe ríi l'orí mi ń dìde fììì'
Awọn alaṣẹ ijọba Benin Republic gbagbọ pe fifi Igboho silẹ lasiko ti awuyewuye si n lọ lọwọ lori ọrọ rẹ ni Naijiria ati Benin lewu fun abo rẹ.
Ijọba Benin rii bi ẹni pe Igboho nilo abo labẹ ofin lẹyin titi di igba ti awuyewuye to tẹ le bi wọn ṣe mu un niluu Cotonou yoo fi lọọlẹ.
Gẹgẹ bi mo ṣe sọ tẹlẹ, Igboho ko ṣẹ si ofin kankan lorilẹede Benin.
Koda ko tii lo pe ọjọ kan ni Cotonou ti wọn fi mu un ni papakọ ofurufu ni ọna rẹ si orilẹede Germany.
Igba to tii lo ni Benin Republic kere debi wi pe ko le raye lati gbero ati da wahala silẹ ni Benin.
Awọn agbofinro mu un nitori ọrọ oṣelu lati orilẹede Naijiria ni kii ṣe pe o ṣẹ si ofin nibi.
Igboho si wa lahamọ lati jẹ ki atẹkun fẹ si ọrọ naa ati lati jẹki alaafia jọba laarin Naijiria ati Benin.
Ẹnikẹni to ba sọ pe ki wọn fun Igboho lominira bayii fẹ gba ẹmi rẹ ni, nitori wọn le ṣeku pa a,'' Falola lo sọ bẹẹ
Lori akoko ti igbẹjọ yoo tun waye nile ẹjọ, agbẹjọro Falola sọ pe awọn adajọ lo le sọ igba ti ẹjọ naa yoo tun gberasọ.
O fikun ọrọ rẹ pe ko ṣeeṣe ki Benin jọwọ Igboho fun Naijiria lori ẹsun pe o n pe fun iyapa ẹya Yoruba lara Naijiria.
Myths about Mestrual period: Ṣé lóòtọ́ọ́ ni wíwọ páàdì lásìkò nǹkan oṣù lè já àbálé obìnrin?
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Oriṣiiriṣii nkan lawọn eeyan maa n sọ nipa nnkan oṣu obinrin, awọn eeyan kan gbagbọ pe oniruuru eewọ lo rọ mọ nnkan oṣu naa.
Oriṣiiriṣii eewọ nipa nnkan oṣu obinrin lawọn eeyan maa n sọ, ọkan lara rẹ ni pe ti ọkunrin ba ni ibalopọ pẹlu obinrin to n se nnkan oṣu lọwọ, iru  ọkunrin bẹẹ yoo ko arun lara ibalopọ.
Bakan naa ni wọn tun gbagbọ pe ti obinrin ba n lo paadi lasiko nkan oṣu, o le poora si inu oju ara rẹ.
Awọn nkan mii ti wọn tun maa n sọ ni pe irora nnkan oṣu maa n dinku, ti obinrin ba ti lọ sile ọkọ.
Awọn mii tun sọ pe o ko le karun HIV-AIDS lasiko nkan oṣu rẹ.
Bangladesh Brothel: Ọ̀pọ̀ àwọn àṣẹ́wó tó wà níbẹ̀ ni wọ́n bí sílé aṣẹ́wó náà
Ohun miran ni pe ti o ba n ṣe nnkan oṣu, ti o ba jẹ nkan to ni ṣuga daadaa, nkan oṣu rẹ yoo pọ.
Amọ, awọn onimọ iṣegun eleto ilera ti ja ọpọ ahesọ ọrọ ti ẹnikẹni ko le fidi rẹ mulẹ nipa nnkan oṣu obinrin.
Wọn ni ọpọ nkan ti wọn ti n sọ nipa nkan oṣu kaakiri agbaaye fun ọpọ ọdun lo pa ni lẹrin.
Wọn ni awọn kan ṣe ajeji ṣugbọn gbogbo rẹ lo lagbara lati ṣakoba fawọn to n ṣe nkan oṣu, ti wọn ba gba wọn gbọ.
Awọn kan tiẹ ni paadi nkan oṣu le jabale obinrin, eyi ni lilo paadi lasiko nkan osu fi jẹ eewọ lawọn orilẹede agbaye kan.
Awọn dokita onimọ nipa agọ ara obinrin ni otitọ ni pe awọ abale to bo oju ara ọlọmọge le ja tabi ki oju ara fẹ si.
Wọn ni ohun kohun lo le ṣokunfa eyi ni bii ere idaraya ati kẹkẹ gigun amọ awọ oju ara obinrin to ja ko le sọ bo ya obinrin ko tii mọ ọkunrin tabi bẹẹ kọ.
Lori pe ibalopọ lasiko nkan oṣu le pa ọkunrin, ko si ẹri ninu sayẹnsi pe ṣiṣe ibalopọ lasiko nkan oṣu lewu tabi ṣekupa eeyan.
Oba Gbolahan Timson shomolu: Obasanjo ti jẹ́wọ́ pé 'Mistake' ni Buhari ṣùgbọ́n...
Wọn maa n lọ ọrọ yii mọ awijare pe idọti wa lara nkan oṣu, ati pe, oriṣiiriṣii lo wa nibẹ, amọ ko ri bẹẹ.
Ko si ẹri to fidi rẹ mulẹ ninu iṣegun oyinbo pe eyan gbọdọ dẹkun ibalopọ lasiko nkan oṣu.
Lori wi pe irora nkan oṣu maa n dopin nigba ti obinrin ba ṣe igbeyawo, ko si ohun to jọ bẹẹ.
Awọn obinrin kan ti sọ pe irora nkan oṣu wọn dinku lẹyin ti wọn bimọ ṣugbọn ko ri bẹẹ fun gbogbo eeyan.
Awọn onimọ sayẹnsi nipa ara obinrin sọ pe ara nkan oṣu ni irora rẹ wa.
Maa ṣe ere idaraya lasiko nkan oṣu tori o le ba ile ọmọ jẹ, ko si ẹri to sọ pe ṣisẹ ere idaraya lewu lasaiko nkan oṣu tabi o le ba ile ọmọ jẹ.
Tunde Bakare journey in life: Bàbá bàbá mi ni Lèmọ́mù àkọ́kọ́ ní Sodeke Abeokuta ṣùgbọ́n..
Koda, iwadii fihan pe ere idaraya maa n ṣe adinku irora nkan oṣu.
Bo ya o ṣe tabi o ko ṣee, eyi ti o ba fẹ ni, amọ ko si ohun to ni ki o maa ṣe ere idaraya lasiko nkan oṣu ninu eto ilera.
AjogbaJesu Twins: Ọgbẹ́ inú, Ulcer ló pa Tope, ọ̀kan lárá àwọn ìbejì AjogbaJesu - Amágbálẹ́gbẹ́ rẹ̀
Oríṣun àwòrán, Ajogbajesu instagram
Tọpẹ,  ọkan lara awọn ibeji Ajogbajesu ti jade laye. Akọrin ẹmi naa jade laye lọjọ Ẹti nilu Ibadan
Gẹgẹbi ọkan lara awọn amugbalẹgbẹ rẹ ṣe sọ fun BBC News Yoruba,  ọgbẹ inu, iyẹn Ulcer lo ṣokunfa iku rẹ.
Gẹgẹ bi alaye ti amugbalẹgbẹ rẹ naa ṣe fun BBC News Yoruba, o ti to ọjọ melokan bayii ti akọrin naa ti n ba aisan ọgbẹnu inu Ulcer faa.
Bí ìjọba bá kọ̀ tí kò ṣèdájọ́, tí Ọlọ́pàá kọ̀ pé àwọn kọ́ ló paá, ẹni tó pa ọmọ mi, náà máa ...
O ni nigba ti awọn amugbalẹgbẹ rẹ kan de ile rẹ ni owurọ ọjọ Ẹti, ọgbọn ọjọ oṣu keje ọdun 2021 ni wọn baa lori ibusun to wa ti gbogbo ara rẹ ti le. Eyi lo mu ki ẹnikeji rẹ, iyẹn Kehinde o paṣẹ ki wọn tete maa gbe lọ si ileewosan.
Nigba ti wọn fi de ileewosan Ọyọmesi nilu Ibadan ni wọn rii pe ko si ẹjẹ lara wọn mọ. Nitori ọgbẹ inu ti wọn ni, o ti wọ aga ara wọn gan, nibẹ ni wọn dakẹ si ni owurọ yii
Aisan ọgbẹ inu yii lawọn dokita ni o ti wọ agọ ara akọrin ẹmi naa eleyi ti ko si jẹ ko si ẹjẹ pupọ lara rẹ mọ.
Ọmọ mẹta ati iyawo ni akọrin naa fi silẹ saye lọ.
Oríṣun àwòrán, other
Ọkan lara awọn ibeji AjogbaJesu, ti orukọ rẹ n jẹ Tọpẹ ti jade laye.
Tọpẹ AjogbaJesu gẹgẹ bi ọpọ ṣe mọọ jẹ ọkan lara awọn akọrin meji ninu ẹgbẹ orin AjogbaJesu Twins.
Orin Kristẹni ni wọn yan laayo lasiko ti irawọn wọn jade pẹlu ọwọ 'tungba'ti wọn fi nkọrin ẹmi tiwọn.
Ọkan lara awọn to sun mọ olorin naa sọ pe owurọ ọjọ Ẹti lo jade laye.
Igi Ọ̀pẹ abàmì tó dá ní orí 42 l'Ekiti rèé o, 'bí mo ṣe ríi l'orí mi ń dìde fììì'
Blessing Okagbare at Tokyo 2020 Olympics: Àjọ eré ìdárayá lágbáyé lé Blessing Okagbare kúrò ní Tokyo 2020 Olympics
Oríṣun àwòrán, Reuters
Ajọ to nboju wo ayẹwo ogun lilo laarin awọn elereidaraya ti paṣẹ lọ rọọkun nile naa fun eekan elere ije ọlọgọrun mita(100 meters) ati igba mita ( 200 meters) ọmọ Naijiria ni, Blessing Okagbare nibi idije Tokyo 2020 Olympics to n lọ lọwọ bayii lorilẹede Japan.
Ọpọ ọmọ Naijiria ti inu wọn n dun lọjọ Ẹti lori iroyin pe elere ije ọmọ Naijiria meji lo moribọ wọ ipele to kangun si aṣekagba ere ije onimita ọgọrun ni idunnu naa ko pẹ fun pẹlu iroyin pe ayẹwo fihan pe Okagbare to jẹ ọkan ninu awọn meji naa lo ogun amuṣẹya HCG eleyi to jẹ ara awọn ogun ti ajọ naa fi ofin de pe kawọn elere idaraya jina sii.
Bí ìjọba bá kọ̀ tí kò ṣèdájọ́, tí Ọlọ́pàá kọ̀ pé àwọn kọ́ ló paá, ẹni tó pa ọmọ mi, náà máa ...
Bi ẹ ko ba ni gbagbe lọjọ diẹ sẹyin lawọn ajọ yii kan naa yọ awọn elere idaraya ogun bi ẹni yọ jiga lori ẹsun pe wọn eto ayẹwo ogun oloro ti wọn ṣe fun wọn ko kun oju iwọn to yẹ fun elere idaraya to fẹ kopa ni idije agbaye bii Olympics. Mẹwaa ninu awọn elere idaraya naa lo jẹ ọmọ orilẹede Naijiria.
Blessing Okagbare jẹ ọkan gboogi ireti orilẹede Naijiria lati ri ami ẹyẹ gba ni idije Tokyo 2020 Olympics.
Ni idije Olympics ti ọdun 2008 ni Beijing lorilẹede China, Okagbare gba ami ẹyẹ Fadaka lẹyin to ṣe ipo keji ni idije ilẹ fifo ti a mọ si Long jump. Lẹyin eyi lo tun gba ami ẹyẹ miran ni idije ilẹ fifo ti a mọ si Long jump yii kan naa ati ere ije igba mita (200 meters) ni idije ere idaraya agbaye, World Championships lọdun 2013.
Igi Ọ̀pẹ abàmì tó dá ní orí 42 l'Ekiti rèé o, 'bí mo ṣe ríi l'orí mi ń dìde fììì'
AjogbaJesu Twins: Wọ́n ti kéde ètò ìsìnkú Tope AjogbaJesu àti ọjọ́ tí wọn yóò sin ín
Oríṣun àwòrán, Ajogbajesutwins/instagram
Awọn ẹbi Tọpẹ AjogbaJesu ti kede bi eto isinku rẹ yoo ṣe lọ o.
Ni ọjọ Ẹti ọgbọn ọjọ oṣu keje ọdun 2021 ni iroyin iku ọkan lara awọn gbajumọ akọrin ẹmi lorilẹede Naijiria Tọpẹ to jẹ Taiyelolu ibeji AjogbaJesu jade laye.
Ọpọlọpọ awọn ọmọ Naijiria  titi de oke okun si ni iku wọn ti da sinu ibanujẹ ọkan.
Awọn ẹbi Tọpẹ AjogbaJesu ti kede bi eto isinku rẹ yoo ṣe lọ o.
Ninu ọrọ to ṣe ni alaye fun BBC News Yoruba, Ọgbẹni Oyedepo Adetoyeṣe to jẹ alamojuto ọrọ iroyin ori ayelujara fun awọn Ibeji AjogbaJesu, ni awọn ẹbi akọrin ẹmi naa ti ṣalaye pe ọjọ kẹwaa oṣu kẹjọ ọdun 2021 ni wọn yoo sin olorin naa.
"O fi kun un pe ọjọ kẹsan oṣu kẹjọ naa ni wọn yoo ṣe isin aṣalẹ ẹyẹ ikẹyin ""Artiste night ""nibi ti awọn akẹrin ẹmi atawọn oṣere yoo ti ṣe ẹyẹ ikẹyin wọn fun un."
Oríṣun àwòrán, other
Nigba ti awọn mejeeji wa ni ọdun mejila ni wọn ni awọn ti bẹrẹ iṣẹ orin kikọ, gẹgẹ bi awọn mejeeji ṣe sọ ninu awọn ifọrọwanilẹnuwo ti wọn ti ṣe pẹlawọn ileeṣẹ igbohunsafẹfẹ kan sẹyin.
"Ni ọdun 2004 ni awo orin to gbe wọn saye, ti wọn pe akọle rẹ ni ""Winner"" jade sori atẹ."
Lara awọn olorin ti wọn ni awọn Ibeji AjogbaJesu ṣalaye pe o ko ipa ribiribi ninu aye ati iṣẹ orin wọn ni awọn agba akọrin bii Funmi Aragbaiye, Mega 99, Sẹnwẹlẹ Jesu ati Esther Igbẹkẹle.
Nipasẹ Iya awọn ni wọn ṣe ri orukọ AjogbaJesu ti wọn n jẹ nitori bi Mama ṣe kundun ijo jijo paapaa to ba ti niiṣe pẹlu ti Ọlọrun ati iṣẹ isin rẹ. Ninu eyi lawọn ọmọ ti mu orukọ inagijẹ orin wọn.
Bí ìjọba bá kọ̀ tí kò ṣèdájọ́, tí Ọlọ́pàá kọ̀ pé àwọn kọ́ ló paá, ẹni tó pa ọmọ mi, náà máa ...
Rachel Oniga is dead: Jide Kosoko, Hilda Dokubo, Yomi Fabiyi àtàwọn míì ṣèdárò Rachel Oniga tó lọ
Oríṣun àwòrán, Others
Ọpọ awọn osere ati ololufẹ ogbontarigi oṣere ni Rachel Oniga to jade laye lana ni wọn ti n kira wọn ku ara feraku.
Rachel Oniga to dagbere faye lẹni ọdun mẹrinlelọgọta.Mi kò mọ̀ pé àsìkò yìí ni máa dágbéré fún Rachel Oniga- Jide Kosoko
Jide Kosoko, agba ọjẹ osere naa ti sọrọ sita pe iku Oniga ṣe oun fuu.
O ni oun ko mọ pe ọrẹ bii ọmọ iya yii n dagbere lasiko yii fun oun ni.
Oríṣun àwòrán, @Jide Kosoko
Jide Kosoko ni nitootọ ni iku Rachel Oniga dun oun ṣugbọn oloogbe gbe igbeaye to wuni lori pupọ.
O dagbere fun oloogbe to ni o kọja akégbẹ ẹni lẹnu iṣẹ lasan pẹlu ileri pe gbogbo oṣere ni yoo maa ṣranti iṣẹ rere ati ohun maleegbagbe ti akinkanju obinrin yii, Rachel Oniga se silẹ lagbo tiata ko to lọ.
Bethel Baptist high school Kaduna: Mi ò gbàgbọ́ pé ìjọba Naijiria ń ṣe ojúṣe rẹ̀ lórí ètò
Oríṣun àwòrán, racheloniga
Wo ohun mẹ́wàá tó yẹ kí o mọ̀ nípa Rachel Oniga tó d'ágbére f'áyé
Ìtàn ìgbéayé gbajúgbajà òṣèré, Rachel Oniga tó jáde láyé rèé
Gbajugbaja oṣere tiata, Rachel Oniga ti jade laye lẹni ọdun mẹrinlelọgọta.
Okunade Sijuwade: Ìfẹ́ tí Sarun tó súnmọ́ Ooni jù láyé ní sí í ló sọ ọ́ di abọ́bakú- Adeye
Aarẹ ẹgbẹ awọn oṣere ni Naijiria, Actor's Guild of Nigeria, Emeka Rollas lo fidi iroyin naa mulẹ pe pe lootọ ni oṣerebinrin naa ti jẹ Ọlọrun nipe.
Rolla ni ọmọ oloogbe ọhun sọ fun oun pe oṣerebirin naa dagbere faye ni nnkan bii aago mẹwaa alẹ ọgbọn ọjọ, oṣu Keje, ọdun 2021 yii.
Ṣugbọn o fi kun pe oun ko tii le ṣalaye ohun to ṣokunfa iku oloogbe naa.
Olagunsoye Oyinlola: Kí Olorun dáríjì wá lórí ọ̀rọ̀ yíi, a ti kùnà ìlérí wa fún ìran Yorùb
Peter Fatomilola kìí ṣe agbódegbà Yahoo, Ó ń fẹ́ kí ìjọba, Òbí àti ilé ìjọsìn ṣe ohun tó y
Gbajugbaja oṣere tiata, Bolaji Amusan fi hann wa bo se láyà to lori ètò  ṣé o láyà.
Pupọ ninu awọn oṣere ẹgbẹ  rẹ lo ti bẹrẹ si n ṣedaro iku rẹ.
Lara awọn oṣere naa ni Jide Kosoko to sọ pe oun ṣi ranti gbogbo igba ti awọn mejeji  jọ maa n kopa ninu ere bi ana.
O ni Rachel Oniga kii ṣe akẹgbẹ oun nikan, ṣugbọn o tun jẹ bii ibatan si oun.
Igi Ọ̀pẹ abàmì tó dá ní orí 42 l'Ekiti rèé o, 'bí mo ṣe ríi l'orí mi ń dìde fììì'
Ni ti Hilda Dokubo, o ni bii iya ni Rachel Oniga jẹ si oun, eyii to mu ki iku rẹ jẹ ọgbẹ ọkan fun oun.
Bakan naa ni Yomi Fabiyi n ṣedaro oloogbe naa nigab to sọ pe awọn memeji ṣi fọrọ jomitooro ọrọ ni ọjọp mẹfa sẹyin.
Yatọ si awọn oṣere tiata, pupọ awọn ololufẹ Rachel Oniga lo ti bẹrẹ si n ṣedaro iku rẹ kaakiri agbaye.
Oríṣun àwòrán, Instagram
Iroyin to n tẹ wa lọwọ ni gbajugbaja oṣere tiata Yoruba, Igbo ati ede Gẹẹsi, Rachael Oniga ti jẹ Ọlọrun nipe.
Eni ọdun  mẹrinlelọgọta ni Oniga ko to jade laye.
Bí ìjọba bá kọ̀ tí kò ṣèdájọ́, tí Ọlọ́pàá kọ̀ pé àwọn kọ́ ló paá, ẹni tó pa ọmọ mi, náà máa ...
Aarẹ ẹgbẹ awọn oṣere ni Naijiria, Actor's Guild of Nigeria, Emeka Rollas ni lootọ ni oṣerebinrin naa ti jade laye.
Rollas sọ fun BBC pe akọwe oun pe ọmọ Racheal Oniga to fi idi rẹ mulẹ wi pe alẹ Ọgbọnjọ, Oṣu Keje, ọdun 2021 ni iya oun jade laye.
Titi di asiko yii, ko i tii si aridaju ohun to ṣokunfa iku rẹ.
Micheal Usifo Ataga: Ìyá, ìyàwó sọ̀rọ̀ ìwúrí nípa olóògbé níbí ìsìnkú
Oríṣun àwòrán, Others
Iya oloogbe adari ileeṣẹ Super TV, Michael Usifo Ataga ti sọ iwuri nipa ọmọ rẹ gẹgẹ bi alaanu to ni ifẹ oun ati awọn eniyan to sun mọ rẹ.
Iya ologbe naa sọ ọrọ yii nibi isinku ti ẹbi ati ara pesi lati ṣe ẹyẹ ikẹyin fun ni Ebony Vaults, ni Ikoyi, nipinlẹ Eko
Bonkẹlẹ ni wọn ṣe ẹyẹ ikẹyin naa fun ọjọ meji, to si jẹ awọn ẹbi ati ara nikan ni wọn pe si ẹyẹ ikẹyin.
Ọjọbo ni wọn ṣe aṣalẹ orin fun oloogbe naa, nibi ti awọn ẹbi ati ara ti sọ ọrọ iwuri nipa ọmọ rẹ.
Iya rẹ, Slyvia Ataga ni ọmọ oun ku iku ti ko tọsi  nitori ko t si ọmọ oun iru nkan ti wọn ṣe fun.
''Ọkan mi gbọgbẹ nipa iku ọmọ mi nitori eniyan ire ni to ni aanu, ti ko si si ẹni ti kii ṣe aanu fun.''
Oríṣun àwòrán, Others
Bakan naa iyawo rẹ, Brenda Ataga ninu ọrọ rẹ ni iroyin iku ọkọ oun ba oun ni inu jẹ gidigidi nitori kii ṣe iru iroyin ti oun ro si niyẹn.
'' Gbogbo ero lo wa si mi lọkan, amọ kii ṣe ti iku rara, ati pe nibo lo le wa, abi ki lo ṣẹlẹ, amọ iroyin iku kọ ni mo fẹ.''
Oríṣun àwòrán, Others
''Ati pese gbogbo ohun ti yoo ṣe moriya fun ọ lọjọ ayajọ ọjọ ibi rẹ, ki o kan wọle, ki a si ṣe ẹyẹ fun ọ, lo di nkan ti a ko le ri ọ mọ.''
Ọjọ Kẹrinlelogun, Oṣu kẹfa ọdun 2021 ni ileeṣẹ ọlọpaa Eko ṣafihan oju Chidinma nigba to jẹwọ pe oun lo n gun Ataga ẹni aadọta ọdun naa lọbẹ lọrun pa lẹyin gbọnmi sii omi o to.
Oríṣun àwòrán, Others
Ki ileeṣẹ ọlọpaa to gbe iroyin naa jade ni awọn ọrẹ Ataga fi lede wi pe wọn n wa Ataga to n gbe Banana Island lati Ọjọ Kẹtala, Osu Kẹfa, ọdun 2021.
Amọ lẹyin naa ni iroyin kan gbe e pe Chidinma ni oun ko jẹbi ẹsun ipaniyan ti wọn fi kan oun, nitori oun kọ ni oun pa, amọ a ko le fi idi iroyin naa mulẹ.
Bethel Baptist high school Kaduna: Nítòótọ́ lá ń gbé oúnjẹ lọ fún àwọn ajínigbé kí ebi má bàá pa àwọn akẹ́kọ̀ọ́ wa tí wọ́n jígbé
A máa ń gbàdúrà fún àwọn ajinigbé tí wọ́n bá fẹ́ lọ jí àwọn míì gbé - Akẹ́kọ̀ọ́ Bethel Baptist School Kaduna
Mi ò gbàgbọ́ pé ìjọba Naijiria ń ṣe ojúṣe rẹ̀ lórí ètò
Aarẹ apapọ ijọ onitẹbọmi ni Naijiria, Nigerian Baptist Convention, oluṣọagutan Israel Akanji ti sọ pe ijọba apapọ ti kuna ninu ojuṣe rẹ lati daabo bo awọn ọmọ Naijiria.
Lasiko to n ba BBC Yoruba sọrọ, Akanji ni ojuṣe akọkọ fun ijọba ni lati daabo bo awọn araalu.
Akanji lo fi ọrọ naa lede lẹyin ti awọn ajinigbe tu awọn akẹkọọ ijọ onitẹbọmi ti wọn ji gbe ṣaaju ni Kaduna silẹ.
Ojiṣẹ Ọlọrun naa ṣalaye siwaju si pe awọn ajinigbe naa ko fọwọ kan awọn akẹkọọ naa lọna aitọ, paapaa awọn to jẹ obinrin lara wọn.
Bẹẹ lo tun sọ pe awọn ajinigbe ọhun gba wọn laaye lati maa gbadura gẹgẹ bi ọmọlẹyin Kristi.
O ni wọn gba wọn laye lati maa ṣe isin, bii orin kikọ ati iwaasu lasiko ti wọn wa ni ahamọ.
Aarẹ apapọ ijọ onitẹbọmi naa sọ siwaju si pe awọn ajinigbe naa a maa ke si awọn ọmọ ti wọn ji gbe lati gbadura fun wọn lasiko ti wọn ba fẹ lọ ji awọn eeyan mii gbe.
O pari ọrọ rẹ pe bo ti tilẹ jẹ pe wọn ti ri awọn akẹkọọ naa pada, o ni awọn ṣi n wa awọn akẹkọọ miran to ṣi wa ni ahamọ.
Ẹ wo fidio yo wa loke yii fun ẹkunrẹrẹ.
Saraki arested: Agbẹnusọ EFCC ní àwọn ló fi ìwé pe Saraki
Oríṣun àwòrán, @bukolasaraki
Ajọ to n gbogun ti iwa jẹgudujẹra ni Naijiria, EFCC ti sọ pe Aarẹ ile igbimọ aṣofin Naijiria tẹlẹ, Bukola Saraki ti wa ni ahamọ awọn.
Agbẹnusọ ajọ naa, Wilson Uwujaren sọ fun BBC pe awọn lo fi iwe pe Saraki, ṣugbọn ko ṣalaye eredi ti wọn ṣe fi iwe pe Saraki ni ẹkunrẹrẹ.
Ṣaaju ni awọn ileeṣẹ iroyin abẹle kan ti kọkọ jabọ pe Saraki wa ni ahamọ EFCC lori ẹsun to rọ mọ ole jija ati lilu owo ilu ni ponpo.
Saraki ti fi asiko kan jẹ gomina ipinlẹ Kwara ri, iyẹn laarin ọdun 2003 si 2011.
Oun naa tun ni Aarẹ ile igbimọ aṣofin Naijiria laarin ọdun 2015 si 2019.
Lasiko to wa nile aṣofin agba ni Saraki ti kọkọ n koju oniruru ẹsun to jọ mọ ṣiṣe owo ilu baṣubaṣu ati ẹsun pe ko kede iye dukia to ni.
Bethel Baptist high school Kaduna: Mi ò gbàgbọ́ pé ìjọba Naijiria ń ṣe ojúṣe rẹ̀ lórí ètò
Ṣugbọn ile ẹjọ to ga julọ ni Naijiiria ni ko jẹbi ọkankan lara awọn eṣun ti wọn ka si lẹsẹ lọdun 2018.
Ni bayii ti EFCC tun ti fi iwe pe Saraki, o ṣeeṣe ki wọn tun bẹrẹ iwadii akọtun lori awọn ẹsun to jọ mọ eyii ti wọn ti kọkọ fi kan an ṣaaju.
Iroyin ni EFCC fẹsun kan Saraki pe o kowo ilu sapo labẹ asia awọn ileeṣẹ kan ti wọn ko tii fi orukẹ wọn lede.
Bí ìjọba bá kọ̀ tí kò ṣèdájọ́, tí Ọlọ́pàá kọ̀ pé àwọn kọ́ ló paá, ẹni tó pa ọmọ mi, náà máa ...
Michael Salako and bike man death: Àwọn ọ̀tẹlẹ̀múyẹ́ mú arákùnrin ẹní ogójì ọdún tó fí ìbínú lu Abudu ọlọ́kadà pa ní Abeokuta
Oríṣun àwòrán, Nigeria Police
Ileeṣẹ ọlọpaa ni ipinlẹ Ogun ti ṣe afihan arakunrin kan to fi ibinu lu ọlọkada kan pa nitori pe  o kọ lati gbe jade.
Micheal Salako la gbọ pe ọwọ awọn ọtẹlẹmuyẹ ọlọpaa ti tẹ lagbegbe Lafenwa ni Abeokuta tii ṣe olu ilu ipinlẹ Ogun.
Gẹgẹ bi alukoro ọlọpaa ipinlẹ Ogun, DSP Abimbola Oyeyemi ti ṣe sọ afurasi yi ti mọ ọlokada naa tipẹ nitori adugbo kan naa ni wọn jijọ n gbe.
Abimbola sọ pe lẹyin tawọn gba ọrọ lẹnu rẹ, Micheal ni oun lọ beere lọwọ Abudu tii ṣe ọlọkada naa pe ki lo  de to kọ lati gbe oun jade lana.
Nibi tawọn mejeeji ti n fa ọrọ naa ni ija ti bẹ silẹ ti Abudu si ṣubu lulẹ to si gba ibẹ di ero alakeji.
Bethel Baptist high school Kaduna: Mi ò gbàgbọ́ pé ìjọba Naijiria ń ṣe ojúṣe rẹ̀ lórí ètò
Alukoro ọlọpaa tẹsiwaju pe wọn ti gbe oku ọlọkada naa lọ si aaye igbe oku pamọ si ni mọṣuari lati le ṣayewọ lori ohun to ṣeku pa.
Ileeṣẹ ọlọpaa ṣeleri lati ṣayẹwo ni kikun lori ohun to ṣokunfa iku Abudu ọlọkada naa.
Gbajugbaja oṣere tiata, Bolaji Amusan fi hann wa bo se láyà to lori ètò  ṣé o láyà.
Ikọ BBC Yoruba ba agbẹjọro Sunday Igboho sọrọ lori idi to fi wa ni ahamọ
Attahiru Jega, APC, PDP: Ọ̀rọ̀ di gbas gbos, APC fèsì lórí ọ̀rọ̀ tí Jega sọ pé kí aráàlú má ṣé dìbo fún wọn
Ọrọ ti di gbas gbos laarin ẹgbẹ oṣelu mejeeji to lorukọ ni Naijiria,All Progressives Congress,APC,Peoples Democratic Party PDP ati alaga tẹlẹ ri ajọ eleto idibo Attahiru Jega.
Fakinfa yi ko si sẹyin ọrọ ti Ọjọgbọn Jega sọ ninu ifọrọwanilẹnuwo kan pẹlu BBC pe ki awọn ọmọ Naijiria ma se dibo fawọn ẹgbẹ yi.
Latari eyi, ẹgbẹ oṣelu PDP naa ti fesi pada ti wọn si ni ki Jega ma se fi awọn we ijọba APC ti ko seso rere fawọn ọmọ Naijiria.
Oríṣun àwòrán, Others
Ṣaaju ni ẹgbẹ oṣelu APC naa ti ni ki Jega ma ṣe da awọn papọ pẹlu PDP ninu ọrọ rẹ rara ti rara nitori PDP lo ba Naijiria jẹ tawọn ṣi n gbiyanjulati ṣe atunṣe.
Kola Ologbondiyan to jẹ akọwe ipolongo ẹgbẹ PDP sọ pe Jega ṣe afihan aimọkan pẹlu bi ko ṣe ri iyatọ to wa laarin ijọba awọn ati ti APC.
O tẹsiwaju pe lasiko ijọba PDP idagbasoke ba ọrọ aje Naijiria ni afiwe ti APC to sọ ọpọ sinu iya ohun iṣẹ.
Ologbondiyan ṣapejuwe dollar to ti gbowo lori  to fi mọ iye owo epo bẹntiroo to ti ga si labẹ ijọba APC.
O ni bi Jega ba foju sunukun wo, yoo ri pe awọn kii ṣe ẹgbẹ kanna pẹlu APC to n fi awọn we.
Ẹgbẹ́kẹgbẹ́ ní PDP lóòótọ́ ṣùgbọ́n má ṣé dà wá papọ̀ mọ wọn- APC
Ẹgbẹ oṣelu All Progressives Congress APC to wa lori oye ni Naijiria ti fesi sọrọ Attahiru Jega to sọ pe ki araalu ma ṣe dibo fun ẹgbẹ naa.
Jega to fi igba kan jẹ alaga ajọ eleto idibo Naijiria, INEC, ko fi mọ lori APC nikan,
O ni ẹgbẹ Peoples Democratic Party ati APC ko ni akọsilẹ daadaa kankan lati nkan bi ogun ọdun ṣẹyin ti wọn ti n ṣe ijọba ni Naijiria.
APC àti PDP ló ba Nàìjíríà jẹ́, ẹ má dìbò fún wọ́n mọ́- Attahiru Jega
Ọrọ rẹ yi lo mu ki ẹgbẹ oṣelu APC tutọ soke foju gba ti wọn si sọ pe ko ma ṣe da awọn pọ mọ ẹgbẹ PDP ati pe ọrọ ti ko fẹsẹ mulẹ lo n sọ nipa awọn.
Akọwe agba ẹgbẹ igbimọ amulelọwọ APC, Sen. John James Akpanudoedehe lo fi ọrọ yi sita ninu atẹjade.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Senatọ naa ni  ki Ọjọgbọn Jega mọ pe biba ẹgbẹ awọn lorukọ jẹ ko le mu agbega ba a ninu oṣelu.
''A ri nkan ti Jega kọ nibi to ti da ẹgbẹ wa pọ mọ PDP.
Lootọ ni pe PDP kuna lati ṣamuṣẹ ileri wọ́n fun araalu amọ ẹgbẹ wa lo n ṣe atunṣe gbogbo panti ti wọn da silẹ lẹyin ọdun mẹrindinlogun lori aleefa''
James tẹsiwaju pe ''a ko ni maa ba Jega gba ọrọ bi ẹni n gba igba ọti nitori naa a gba a ni imọran lati lọ kọju mọ iwadii ẹkọ ko si mu aridaju jade nipa iṣesi itẹsiwaju ti ẹgbẹ APC n gbiyanju lori''
Ninu ọrọ Jega to sọ fun BBC ninu ifọrọwanilẹnuwo kan, o ni  apẹrẹ ni gbogbo aburu tawọn ẹgbẹ APC ati PDP ṣe jẹ faraalu ki wọn ma dibo fun wọn mọ.
Kola Ologbodiyan: Jẹgudu jẹra ni ijọba APC
Jega ni''APC ati PDP ti 'se ijọba, a ti foju rii, wọn ko ni aniyan lati ṣe atunṣe''
''Ẹ wo nkan ti wọn sọ nipa awọn to kowo ilu jẹ,wọn lawọn yoo fiya jẹ wọn nigba ti wọn wa ni PDP, ṣugbọn nigba ti wọn pada si APC, wọn dakẹ pẹm lori ọrọ wọn ni''.
Kemi Olunloyo on Sunday Igboho: Mi ò gbè lẹ́yìn Yoruba Nation àmọ́ mo wà lẹ́yìn Sunday Igb
Ọjọgbọn Jega wa sọ pe idi ree ti oun fi darapọ mọ ẹgbẹ PRP lati le mu atunṣe ba Naijiria.
Titi di ba ṣe n ko iroyin yi jọ, ẹgbẹ oṣelu PDP ko ti fesi si ọrọ Jega.
Igi Ọ̀pẹ abàmì tó dá ní orí 42 l'Ekiti rèé o, 'bí mo ṣe ríi l'orí mi ń dìde fììì'
US Covid-19 Moderna Vaccine:Amẹ́ríkà fí abẹ́rẹ́ àjẹsára Covid-19 mílíọ̀nù mẹ́rin ṣọwọ́ sí Nàìjíríà
Oríṣun àwòrán, United States Mission Nigeria
Awọn oṣiṣẹ ileeṣẹ Amẹrika ni Naijiria n ṣe afihan abẹrẹ ajẹsara ti wọn fun Naijiria
Ijọba orileede Amẹrika ti ṣe iranwọ abẹrẹ ajẹsara Covid-19 miliọnu mẹrin ṣọwọ si orileede Naijiria.
Eyi jẹ ọna kan gbogi lati fi koju ajakalẹ aarun naa gẹgẹ bi awọn alaṣẹ Naijiria ti ṣe sọ.
Yatọ si abẹrẹ ajẹsara Moderna to kan Naijiria yi, awọn orileede Afrika mii yoo gba miliọnu marundinlọgbọn abẹrẹ yi lati ọdọ ijọba aarẹ Joe Biden.
Iranlọwọ abẹrẹ yi to jẹ ẹlẹẹkeji iru rẹ wa lara eto Covax ti wọn fi n ṣe iranwọ abẹrẹ ajẹsara fawọn orileede ti o ku diẹ kaato fun.
Awọn alaṣẹ ileeṣẹ ilera Naijiria lo gba abẹrẹ ajẹsara yi nilu Abuja tii ṣe olu ilu Naijiria.
Loṣu kẹta ọdun yi ni Naijiria tiu ṣaaju gba abẹrẹ ajsara to fẹ ẹ to miliọnu mẹrin AstraZeneca nipasẹ eto Covax yi kan naa.
Lọwọlọwọ bayi, ida kan ninu ida ọgọrun awọn eeyan Naijiria lo ṣẹṣẹ ri abẹrẹ ajẹsara gba ninu awọn eeyan igba miliọnu orileede ọhun.
Niṣe ni awọn alaṣẹ n bẹru pe ọwọja aarun Covid-19 ni Naijiria le bẹ silẹ nitori bi awọn to n ko aarun naa ṣe n pọ si lẹnu ọjọ mẹta yi.
Igi Ọ̀pẹ abàmì tó dá ní orí 42 l'Ekiti rèé o, 'bí mo ṣe ríi l'orí mi ń dìde fììì'
Tunde Bakare journey in life: Bàbá bàbá mi ni Lèmọ́mù àkọ́kọ́ ní Sodeke Abeokuta ṣùgbọ́n..
Ó wu Olorun lo fi fàmí sínú ìgbàgbọ́- Tunde Bakare ọmọ Lemomu Sani Anibijuwọn nile Kewu.
Gbajugbaja agbẹjọrọ to di ojiṣẹ Olorun ni, Tunde Bakare gba BBC Yoruba lalejo.
O sọrọ nipa irinajo aye rẹ lati igba kekere rẹ ko to di bi o ṣe di yii.
Oríṣun àwòrán, @Bakare
Bawo ni irinajo Tunde Bakare se bẹrẹ ni Islam di Onigbagbọ?
Tunde Bakre slaye fun BBC Yoruba pe oun bẹrẹ ile kewu lati ẹni ọdun mẹrin ki oun to ṣe wolimọ lọdun 1967.
O sọ irinajo rẹ lati ibẹrẹ ninu Islam gẹgẹ bi ọmọ ọmọ Lemọmu akọkọ ni Sodeke ni Abeokuta nipinlẹ Ogun.
O salaye nipa bi oun ṣe bẹrẹ iṣẹ fọto yiya ti oun si lọ ya ni ṣọọsi kan ti oun fi ba Jesu pade.
Lẹyin ibapade Jesu yii ni wọn le oun kuro nile ni 1974 ti oun si n sun nile epo ki oun to ri Sọọsi kan maa fori pamọ si.
Oríṣun àwòrán, others
Irinajo Bakare, Obasanjo àti Gani Fawehinmi:
Tunde Bakare sọ nipa bi oun ṣe jiṣẹ jiya lẹyin ti oun gba Jesu ti oun n ṣe iṣẹ agbafọ kaakiri Adugbo ki Oba Oke to gbọ adura ré.
O  ni lẹyin eyi ni oun di osisẹ banki ti oun fi lọ ka iwe si i di Amofin pẹlu iranlọwọ awọn eeyan kan.
Omọ Sanni  Bakre Anibijuwon nile Kewu ni oun tun fọ abọ nile itura lalẹ ti o n ṣiṣẹ ni ọdọ ajijangbara Gani Fawehinmi ogbontarigi Amofin lọsan.
Bakare ni nitori pe Olusegun Obasanjọ gba Sunday lọwọ wọn to gbe Satide le wọn lọwọ lo jẹ ki araba oun lọ tunra mu.
Tunde Bakare fa aaya fun BBC Yoruba, o sọ bi oun ṣe pada lu aluyọ ninu iṣẹ agbẹjọrọ ki Oluwa to pe e si iṣẹ rẹ ni kikun.
O mẹnuba ipenija ṣiṣẹ iṣẹ Oluwa ni kikun laifi nakn mii kun un.
O ni: Iyawo mi ni 'lawyer'ni oun fé kii ṣe 'Pastor'lẹyin ti Oluwa pe mi, iya mi bu sẹkun ni.
Bakare dupẹ ibi ti Olouwa sin in de bayii pẹlu igbagbọ lori ọjọ iwaju rẹ,
Ẹ̀yin ọdọ, ẹ fi ara yin jin fun Oluwa, ẹ tẹpa mọṣẹ, ẹ ma ṣe ọlẹ. ọjọ iwjau yin a dara nitori ibẹrẹ kọ ni oniṣẹ.
PDP youth leader jailed: Bí Kato ṣe d'èrò ẹ̀wọ̀n torí ó bú Buhari, Boss Mustapha
Oríṣun àwòrán, OTHERS
Ile ẹjọ́ Majisireeti kan ni Yola, Ìpínlẹ̀ Adamawa tí dajọ pé wọn rán olórí àwọn ọdọ lẹgbẹ òṣèlú Peoples Democratic Party ni ijoba ibile Hong, tí orúkọ rẹ  ń jẹ Ikamu Kanto lọ sí ẹ̀wọ̀n  ọdún kan gbáko.
O ri ẹwọn he látàrí pé ó sọ̀rọ̀ àbùkù sì Ààrẹ Naijiria, Ogagun Muhammadu Buhari ati akọ̀wé ijoba àpapọ̀, Boss Mustapha.
"Àwọn iwe iroyin sọ pé wọn fi olórí ọdọ náà sì ẹ̀wọ̀n lórí esun kan tí àwọn alatileyin akọ̀wé àgbà ijoba àpapọ̀ fi kan an lábẹ́ aburada ẹgbẹ́ to ń jẹ ""Adamawa Concerned Citizens"" èyí tí Husseini Gambo dárí."
Ní ọ̀sẹ̀ to koja, wọn  pé Kato kò wá kawọ ponyin ro ẹjọ́ nípasẹ̀ ọ́fíìsì àjọ Otelemuye DSS nípasẹ̀ ọ́fíìsì Agbejoro àgbà.
Kato sọ pé nítorí ìbínú bí ikọ Boko Haram ṣe kọlu ìlú Dabna níbi tí èèyàn tó lè ní ogún ti padanu ẹ̀mí wọn lo mu ki òun bọ si oju òpó Facebook láti fun pe sì akowe àgbà àti Ààrẹ Buhari.
O ni ki wọn le tun tẹsiwaju lori pipese eto aabo to peye ni.
Bí ìjọba bá kọ̀ tí kò ṣèdájọ́, tí Ọlọ́pàá kọ̀ pé àwọn kọ́ ló paá, ẹni tó pa ọmọ mi, náà máa ...
O tun ni lórí kikuna láti dá abo bo ẹ̀mí àwọn olùgbé ìlú náà tó jẹ́ ijoba ìbílẹ̀ tìrẹ to sì tún jẹ́ ibi tí akowe àgbà náà tí wá
Lẹyin tí adajọ Majisireeti náà, Dimas Elishama gbọ́ ẹjọ́ náà, ó ní Kato jẹbi ẹ̀sùn tí wọn fi kan an ó sì rán án lọ sí ẹ̀wọ̀n ọdun kan pelu faani egberun meedogbon náírà fún pé ó lo àwọn ọ̀rọ̀ àbùkù àti alufansa.
Ilé ẹjọ́  ni àwọn tí gbó ẹ̀bẹ̀ rẹ pé kí àwọn fi ojú àánú wo ọrọ náà, wọn tún wo ìhùwàsí rẹ lásìkò ẹjọ́ náà ni wọn  ba fi kún un pé kò ní lọ lai jìyà sugbọn yóò jìyà láti jẹ àpẹrẹ fún àwọn tó kú.
Tunde Bakare journey in life: Bàbá bàbá mi ni Lèmọ́mù àkọ́kọ́ ní Sodeke Abeokuta ṣùgbọ́n..
Emir Taraba 30 day Ultimatum: Àwọn olórí Fulani bèèrè àsìkò díẹ̀ síi lórí gbèǹdéke láti lé àwọn ọ̀daràn kúrò nínú igbó
Oríṣun àwòrán, Others
Awọn olori fulani darandaran ni ipinlẹ Taraba ti rawọ ẹbẹ si Emir ilu Muri to fi gbedeke lelẹ pe ki awọn ọdaran Fulani kuro ninu igbo bibẹ kọ oun yoo foju wọn ri mọbo.
Emir Abbas Tafida sọ lọjọ ọdun ileya pe awọn ọdaran yi ni ọgbọn ọjọ lati kuro ninu igbo lai se bẹ awọn ṣetan lati pa ẹnikẹni to ba sapamọ ninu wọn.
Awọn olori fulani lati ijọba ibilẹ mẹrinla ninu mẹrindinlogun to wa ni ipinlẹ naa lo ṣepade pẹlu Emir yi ni aafin rẹ ni Jalingo lọjọ Iṣẹgun.
Nibi ipade naa wọn beere fun oṣu marun un dipo ọgbọn ọjọ to fi lelẹ kawọn ọdaran Fulani wọnyi kuro ninu igbo.
Gẹgẹ bi iwe iroyin Naijiria Punch ṣe jabọ, olori awọn darandaran Fulani ni ipinlẹ naa Alhaji Sahabi Mahmud lo lewaju awọn to lọ rawọ ẹbẹ si Emir naa.
Tunde Bakare journey in life: Bàbá bàbá mi ni Lèmọ́mù àkọ́kọ́ ní Sodeke Abeokuta ṣùgbọ́n..
Nibi ipade naa la gbọ pe oludamọran si Gomina Darius Ishaku,ọgagun fẹyinti Angyu Agbu wa ati awọn aṣoju ikọ alaabo miran ni ipinlẹ ọhun.
Ninu atẹjade ti awọn olori Fulani fi sita, wọn ni ''awọn to ba yi iwa pada a o kọ orukọ wọn silẹ,awan to ba si kọ, a o fa wọn le agbofinro lọwọ''
''A ti pinu lati ma se faaye gba awọn ọdaran koda bi wọn ba jẹ ọmọ bibi inu wa.A ti bura lati tu aṣiri wọn ka si fi awọn to n ṣe agbatẹru wọn laibikita ipo wọn lawujọ''
Emir Tafida lasiko ipade naa sọ pe lati le fi koju awọn ọdaran ni aṣẹ toun pa.
O ni''Gẹgẹ bi olori to duro lori ododo, mi o ni faaye gba aiṣeede ati didaabo bo awọn ọdaran.''
Esabod, Sunday Igboho: Kò burú bí Igboho ṣe wà lẹ́wọ̀n báyìí,ọ̀rọ̀ rẹ̀ dàbí i ti aláboyún
Bi a ko ba gbagbe,ni ogunjọ oṣu Keje tii ṣe ọjọ ọdun Ileya awọn musulumi ni Emir yi fibinu sa pe o to gẹ pẹlu bi awọn ọdaran Fulani ṣe n da awọn eeyan rẹ laamu.
O ni oun fun wọn ni gbedeke ọgbọn ọjọ lati fi inu igbo silẹ bi bẹẹ kọ awan yoo  pa ẹnikẹni tawọn ba ba ninu igbo ninu wọn.
Emir yi to sọrọ lede Hausa ni awọn faaye gba awọn Fulani darandaran lati wa si ipinlẹ awọn ṣugbọn niṣe ni wọn ji awọn eeyan gbe ti wọn si n fipa ba awọn obinrin lo pọ.
Lẹnu lọọlọ yi, awọn araalu kaakiri Naijiria lo ti n kesi ijọba la ti wa nkan ṣe si awọn ọdaran Fulani to n da wahala silẹ nipa ijingbe,ipaniyan ati awọn iwa ọdaran mi.
Exam malpractice: Ọwọ́ ọlọ́pàá tẹ arákùnrin tó múra bí obìnrin láti bá ọ̀rẹ́birin rẹ̀ jókòó kọ ìdánwò èdè Gẹ̀ẹ́sì
Oríṣun àwòrán, Pulse Senegal
Ọrọ ifẹ, bi adanwo ni.
Arakunrin akẹkọọ fasiti kan ni orileede Senegal ti wọ gau lori pe o mura bi obinrin lati fi ba ọrẹbinrin rẹ joko idanwo ede Gẹẹsi.
Kaakiri oju opo ayelujara ni Senegal lawọn eeyan ti n ṣe alabapin aworan rẹ nibi to ti wọ aṣọ pupa to fi mọ ibori pupa.
Khadim Mboup to jẹ akẹkọọ ọmọ ọdun mejilelogun lawọn agbofinro mu lopin ọsẹ to kọja yi.
Alaye to ṣe nipa iṣẹlẹ yi ni pe ''ifẹ ti mo ni si ọrẹbinrin mi lo mu mi hu iwa yi''
O tẹsiwaju pe ọrẹbinrin rẹ n koju ipenija kikọ idanwọ ede Gẹẹsi naa.
Tunde Bakare journey in life: Bàbá bàbá mi ni Lèmọ́mù àkọ́kọ́ ní Sodeke Abeokuta ṣùgbọ́n..
Ni Senegal, ede Faranse ni wọn n sọ ti ede Gẹẹsi si jẹ ede  ti ko rọrun fun ọpọ eeyan la ti s tabi kọ.
Asiri Khadim tu lọjọ kẹta to ti n kọ idanwọ nigba tawọn adari idanwo fura si pe imura rẹ yatọ.
Lasiko ti wọn n kọ idanwo ede Gẹẹsi lọjọ Abamẹta ni wọn kesi awọn agbofinro ti wọn si gbe kuro ninu aaye idanwo naa.
Lati ibẹ, awọn agbofinro tọ ọrẹbinrin rẹ lọ ti wn si ri nibi ibugbe awn akẹkọọ to fara pamọ si.
Ọ̀pẹlọpẹ́ Ajá tí Ifa ní kí a fi ṣètùtù ní Ekiti ní 1942 ni kò jẹ́ kí ìjàmbá náà pọ̀ jù- Ol
Nigba ti yoo fi di ọjọ Aje wọn gbe lọ si iwaju adajọ lori ẹsun magomagọ idanwo ati lilo orukọ olorukọ bi ti eeyan.
Oun nikan kọ ni o wa nile ẹjọ, ọrẹbinrin rẹ ti wọn jijọ lẹdi apo pọ naa wa nile ẹjọ lọjọ Aje.
Agbẹjọro ijọba sọ pe lỌjọbọ ni wọn yoo bẹrẹ igbẹjọ awọn mejeeji.
Igi Ọ̀pẹ abàmì tó dá ní orí 42 l'Ekiti rèé o, 'bí mo ṣe ríi l'orí mi ń dìde fììì'
UEA lift travel ban: Wo nkan tó yẹ kí o mọ̀ báyìí tí ìrìnàjò bàálù bẹ̀rẹ̀ padà láàrin Nàìjíríà sí Dubai
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Orileede UAE ti gbẹsẹ kuro lori ofin to de lilọ bibọ baalu lati Naijiria ati orileede mẹwa mii.
Ajọ to n ri si iṣakoso iṣẹlẹ pajawiri ni Naijiria,NCEMA, lo kede ọrọ yi.
Ikede yi n waye lẹyin oṣu meji gbako ti  wọn ko fi faaye gba  baalu Naijiria kankan lati wọ ilẹ naa tori Covid-19
Pẹlu ikede yi, lati ọjọ Karun oṣu Kẹjọ arinrinajo to ba ti ni iwe moyege ayẹwo Covid-19  le kọja ni papakọ ofurufu UAE.
Loṣu kẹfa ọdun yi ni ikede to fofin de irinajo laarin Naijiria ti UAE kọkọ desi eti igbọ araalu.
Ọ̀pẹlọpẹ́ Ajá tí Ifa ní kí a fi ṣètùtù ní Ekiti ní 1942 ni kò jẹ́ kí ìjàmbá náà pọ̀ jù- Ol
Amọ bayi,NCEMA ti sọ loju opo wọn ni Twitter pe awọn arinrinajo to ba ti gba iwe ẹri moyege ayẹwo Covid-19 laarin ọjọ mẹta yoo le gba papakọ ofurufu UAE kọja.
''Wọn tun gbọdọ ṣafihan ẹri ibi ti irinajo wọn yoo kangun si plu pe awọn papakọ UAE yoo fi aaye sọtọ fawọn arinrinajo to n gba papakọ ofurufu wọn kọja''
Lara awọn orileede mii ti  ayipada ofin yi de ba ni India, Pakistan, Sri Lanka, Uganda, Vietnam ati  South Africa.
Awọn to ku ni Afghanistan, Indonesia, Bangladesh ati Nepal
Osun Osogbo: Ọdọọdún ni Àtáója ń gbàlejò gbogbo arugbá lásìkò ọdún Ọ̀ṣun Òṣogbo
Igba akọkọ kọ ni yi ti UAE ko ni gba ki awọn baalu wọn wa si Naijiria lati gbe arinrinajo tabi ki ti Naijiria wọ papakọ ofurufu wọn.
Lọjọ Kẹrin oṣu keji 2021 ni Emirates Airline gbegi dina ki awọn baalu wọn maa kero lati papakọ ofurufu Eko ati Abuja lọ si Dubai.
Aṣẹ yi ko sẹyin bi igbimọ to n mojuto ọrọ Covid-19 ni Naijiria ṣe kọ lati tẹle ilana ti wọn gbe kalẹ fun ayẹwo arinrinajo.
Gẹg bi Emirates ti ṣe sọ, wọn ni awọn yoo''ṣafihan ilana tuntun loju opo arinrinajo laipẹ''
Tunde Bakare journey in life: Bàbá bàbá mi ni Lèmọ́mù àkọ́kọ́ ní Sodeke Abeokuta ṣùgbọ́n..
Ni bayi, awọn arinrinajo Naijiria lọ si Dubai :
Ilé ẹjọ́ fún Sunday Igboho ní ànfààní láti rìn ní òmìnira láàrin ìlú
Ṣàǹgbá fọ́! Ìrètí Nàìjíríà fún góòlú, Adekuroye pòfo nínú ìjànkadì ní Tokyo 2020
Wo àwọn oúnjẹ́ tí yóò mú kí omi ọmú pọ̀ si fún ìyálọ́mọ́
Kí ló mú kí géńdé múra bí obìnrin láti bá ọ̀rẹ́bìrin rẹ̀ kọ ìdánwò?
Ẹ fún wa ní oṣù márùn ún láti fí lé àwọn ajínigbé Fulani kúrò nínú igbó- Olórí Fulani
Tokyo 2020: Odunayo Adekuroye: Ṣàǹgbá fọ́! Ìrètí Nàìjíríà fún góòlú, Adekuroye pòfo nínú ìjànkadì ní Tokyo 2020
Oríṣun àwòrán, @Daniel Igali facebook
Gbajugbaja ajijakandi, Odunayo Adekuroye ti ọpọ eeyan ti ni ireti pe oun ni yoo gba goolu fun Naijiria ninu idije Olympiki Tokyo 2020 fidi rẹmi lairo tẹlẹ.
Anastasia Nichita ọmọ orilẹ-ede Moldova lo fi iya jẹ Adekuroye niluu Tokyo.
Adekuroye lo kuku n kọkọ  n ṣiwaju ninu ijankadi ọhun, koda ami ayo mẹjọ si meji ni Adekuroye fi n ṣagba Nichita.
Ṣadeedee kan ni nkan yi biri, ti Odunayo ṣubu loju ija.
Iṣubu yii gan an lo mu ki Nichita bori ninu ija ipele ẹlẹni mẹrindilogun ọhun.
Esabod, Sunday Igboho: Kò burú bí Igboho ṣe wà lẹ́wọ̀n báyìí,ọ̀rọ̀ rẹ̀ dàbí i ti aláboyún
"Amọ, ireti diẹ sí wa fun Adekuroye lati gba ami ẹyẹ baba tawọn oloyinbo n pe ni ""bronze."""
Ṣugbọn to wà nibẹ ni pe Nichita to fẹyin Odunayo gbalẹ gbọdọ wọ Ipele aṣekagba ni Tokyo.
Tunde Bakare journey in life: Bàbá bàbá mi ni Lèmọ́mù àkọ́kọ́ ní Sodeke Abeokuta ṣùgbọ́n..
Ẹwẹ, Blessing Oborududu gbarada ninu ijankadi ti ẹ.
Koda, ami ẹyẹ fadaka ni Oborududu gba nigba ti ọmọ ilẹ Amẹrika, Tamyra Marianna Mensah fẹyin rẹ gbalẹ pẹlu ami ayo mẹrin sí ẹyọkan ninu ijankadi 68kg.
Ọ̀pẹlọpẹ́ Ajá tí Ifa ní kí a fi ṣètùtù ní Ekiti ní 1942 ni kò jẹ́ kí ìjàmbá náà pọ̀ jù- Ol
WhatsApp new update: Tóò bá ń dédé sọ fótò tàbí fídíò nù lórí fóònù, Watssap ló gbé ètò tuntun jáde ó!
Oríṣun àwòrán, WhatsApp
Aapu Watssap ṣẹ̀ṣẹ̀ ja àwọn aato tuntun kan tí yóò gbà àwọn tó ń loo láàyè láti rí fọto wọn  tàbí fídíò tó máa sábà pòórá lẹ́yìn tí wọn  ba ti rii.
Ṣe ẹ ṣàkíyèsí pé tẹẹ bá ti sì fọto náà fún ìgbà àkọ́kọ́, tí ẹ wo ó leekan tó sì parẹ lai fi pamọ sórí fóònù.
Watssap tí ni anfani ààtò tuntun tí àwọn gbé jáde yìí ni lati fún àwọn tó ń loo ni anfani àti leè ni aaye ikọkọ ara wọn lórí fóònù.
Ẹwẹ, àwọn ajafẹtọ ọmọdé àti ohun tó yẹ  kí wọn máa wò ní aapu tó ń pá fọto àti fídíò rẹ náà dára pupọ torí yóò lè seranwo láti fi aridaju ifipa bá ọmọdé lọ pọ pamọ.
Nítorí èyí, ẹgbẹ́ àwọn tó ń dá abo bo ẹtọ àwọn ọmọdé  tí kò sì ọ̀rọ̀ pẹ̀lú ileese to jẹ ìyá Whatssap, ìyẹn Facebook lórí ọrọ yìí.
Àwọn ọ̀rọ̀ ikọkọ náà túmọ̀ sí wí pé Ọlọpaa kò ní leè rí atejise náà, ẹni tó kọ ọ àti ẹni tó gbà á ní esi nìkan ni yóò rii sugbọn aapu èyí tó ń pá ọrọ rẹ kíákíá leè túmọ̀  sí pé àwọn fóònù tí Ọlọpaa bá gba lọwọ ẹni tí wọn ba mú kó ni ni aridaju ẹri ti wọn n wa.
Èyí sì tún wá leè fi àwọn ọmọdé sì ewu tó pọ̀ nípa fífún àwọn tó bá ṣe wọn níbi lanfani  àti má leè fi òfin gba wọn mu tí wọn yóò sì pá ẹri rẹ.
Nigbati akitiyan láti fòpin sí ifipa bá ọmọdé lọ pọ  bá tún wà forí san pọn torí èyí, Allison fi ọ̀rọ̀ lọ  ọga eka ààbò ileese naa.
Oríṣun àwòrán, Reuters
Watssap ni tiwọn ń sọ pé afiwe ohun tí àwọn ṣe kan je ohun too lè lọ fúnra rẹ ni - bíi too bá ń rà aṣọ too ni kí èèyàn kan yẹ ọ wò boo ṣe rí, tàbí kọọ fi nomba password rẹ ranse sì èèyàn kan.
Kii ṣe gbogbo nkan ti a ba pín lọ pọn dandan kí gbogbo èèyàn gbà, ileese Watssap lọ sọ bẹẹ.
Lórí ọpọlọpọ fóònù, yíya fọto lasan túmọ̀ sí pé yóò gbà ààyè lórí Kamẹra fóònù rẹ  títí láé.
Ní wón be gbé ààtò tuntun yẹn jáde fún gbogbo ènìyàn tí yóò sì bẹ̀rẹ̀ lọṣe yìí.
"Ẹni tó ń lọ fóònù yóò lè mọ pe ọ̀rọ̀ atejise, wiwo ó leekan ni báyìí toripe atunwo rẹ  yóò fara pamọ  tí ""icon"" ńlá kan tí yóò kó ""1"" soju ni yóò sì jáde dípò rẹ koo lè mọ."
"Yóò kan dabii pé ọ̀rọ̀ atejise rẹ  dédé pòórá bo se maa n rí lórí Snapchat, sugbọn ó sì ṣeéṣe kí òní nkan yà fọto ""screenshot"" rẹ tàbí gba fídíò ọ̀rọ̀ naa silẹ nígbà tó bá sí í fún ìgbà àkọ́kọ́ tàbí kó Kamera ojú èwe kan pẹ̀lú Kamera mìíràn."
Esabod, Sunday Igboho: Kò burú bí Igboho ṣe wà lẹ́wọ̀n báyìí,ọ̀rọ̀ rẹ̀ dàbí i ti aláboyún
Fọto náà kò ní pamọ sì ibi ìpamọ́ phone gallery.
Óò ní lè fi fọto náà ranse, fi pamọ, pín in tàbí máa kí rẹ  gẹgẹ bii ara ọ̀tọ̀.
Ọjọ́ yóò lọ lórí rẹ (expire) tí ó kó bá sii laarin ọ̀sẹ̀ méjì.
Ẹwẹ, ileese náà tí sọ pé àwọn ń ṣe eto lati rii pe awọn tó kàn ileese kò parẹ.
COVID19Nigeria: Èèyàn mẹ́rin kú, 747 míràn tún lùgbàdì aàrùn náà ní Nàìjíria
Oríṣun àwòrán, NCDC
Aarun Coronavirus tun ti mu ẹmi eeyan mẹrin miran lọ ni Naijiria.
Gẹgẹ bi ọrọ ti ajọ NCDC fi lede loju opo wn ni Facebook lalẹ Ọjọru, eeyan 747 tuntun miran lo tun fara kasa arun ọhun bayii.
Esi yii ti sọ apapọ awon to ti ko arun naa ni Naijiria lapapọ di 176,011, awọn 165,208 ti ri iwosan nigba ti awọn 2,167 si ti dero ọrun.
Ẹda tuntun aarun naa kan ti wọn pe orukọ r ni DeltaVariant ni ijọba ti kilọ pe ki araalu ṣọra fun.
Bi iye awọn eeyan to ṣẹṣẹ ko arun naa kaakiri Naijiria ṣe lọ ree:
Lagos-488
Akwa Ibom-121
Oyo-29
Rivers-25
Ogun-15
FCT -13
Kaduna-13
Kwara-11
Ekiti-10
Osun-10
Edo-6
Abia-3
Anambra-2
Plateau-1
Ipinlẹ mẹrin ni wọn ko ti ri eeyan kankan to ko aarun naa-Sokoto,Nasarawa,Kano ati Ondo.
Oríṣun àwòrán, NCDC
Igboho Aides Verdict: Afẹnifẹre gbóṣùbà fáwọn Adájọ́ Nàìjíríà lórí ìdájọ́ méjì tó kan Sunday Igboho
Oríṣun àwòrán, other
Ẹgbẹ idagbasoke ọmọ Yoruba ni Naijiria Afenifere ti gboṣuba kaare fun awọn adajọ meji to gbe idajọ kalẹ lori awọn amugbalẹgb Sunday Igboho.
Lọjọru yi ni awọn amugbalẹgbẹ naa gba itusilẹ nile ẹjọ giga Abuja eyi ti adajọ Obiora Egwaatu gbe kalẹ.
Bakan naa ni adajọ Akintola ni ilu Ibadan paṣẹ ki ajọ ọtẹlmuyẹ Naijiria DSS ma ṣe dunkoko mọ Sunday Igboho tabi ki ijọba gbẹsẹ le akoto owo rẹ.
Awọn idajọ mejeeji yi paapa fun awọn alatilẹyin Igboho ati awọn to n ja fun ominira ilẹ Yoruba dabi aṣeyọri nla.
Ninu atẹjade kan ti agbodegba ẹgbẹ naa Comrade Jare Ajayi fi sita, o ni idajọ ti adajọ Oladiran Akintola ati Obiora Egwaatu gbe kalẹ tunbọ ṣafihan ireti wa ninu ẹka idajọ Naijiria''
Jare Ajayi ni idajọ wọn yi waye lasiko tawọn araalu n ro pe ijọba apapọ n gbero lati mu Sunday Igboho to n koju igbẹjọ lọwọ ni Cotonou.
Afẹnifẹre gboriyin fun adajọ Egwaatu to sọ pe dandan ni ki ajọ DSS ko gbogbo awọn amugbalẹgbẹ Igboho wa si ile ẹjọ.
O ni adajọ yi mu ọkan akin pẹlu bo ṣe paṣẹ ki wọn gba beeli wọn ni ibamu plu ofin orileede Naijiria.
Esabod, Sunday Igboho: Kò burú bí Igboho ṣe wà lẹ́wọ̀n báyìí,ọ̀rọ̀ rẹ̀ dàbí i ti aláboyún
Yatọ si ti adajọ to gba beeli awọn amugbalẹgbẹ Igboho,Afẹnifẹre sọ pe idajo mejeeji tawọn ri yi fẹsẹ igbagbọ awọn rinlẹ pe ile ẹjọ nikan laraalu ti le gba idajọ to peye ti wọn ba tẹ oju ẹtọ wọn mọlẹ.
Bí ìjọba bá kọ̀ tí kò ṣèdájọ́, tí Ọlọ́pàá kọ̀ pé àwọn kọ́ ló paá, ẹni tó pa ọmọ mi, náà máa ...
Oshogbo Heavy Rainfall: Ọ̀pọ̀ ẹ̀mí àti dúkìá àìmoye mílíọ̀nú naira ṣòfò nínú ìjàmbá omíyale
Oshogbo Heavy Rainfall: Ọ̀pọ̀ ẹ̀mí àti dúkìá àìmoye mílíọ̀nú naira ṣòfò nínú  ìjàmbá omíya
Okere tan, oku eeyan mẹta lawọn aradugbo ti ri lẹyin ijamba omiyale agbara ya ṣoobu to waye ni Ipinlẹ Osun lỌjọru.
Oríṣun àwòrán, Jibola Oyekunle
Wakati mẹrin gbako ni ojo yi fi rọ tawọn adugbo kọọkan ni Osogbo ati Erin Osun si farakasa ojo arọrọda yi.
Ọpọ dukia lo ba iṣẹlẹ naa lọ eyi taa gbọ pe o bẹrẹ si ni rọ lati oru ọjọ Iṣẹgun ti ko si da titi di owurọ kutu Ọjọru.
'Bí ojú ọ̀nà agbàrá òjò tí ijọba ṣe n'IIorin ṣe ń pa àwọn ọmọ iléèwé wa rèé! Ẹ sàánú wa'
Ni adugbo Oke Ijetu ati Oke Oniti, wọn ri oku eeyan meji ti awọn ile kọọkan naa si faragba omiyale yi.
Ṣoobu itaja ni Rasco, Obate, Atimowa, Testing Ground, Awosuru, Oke Ayepe ati ni  Ita Olokan naa ko moribọ ninu ijamba yi.
Ara aradugbo Oke Ayepe kan to ba iwe iroyin Naijiria Punch sọrọ ṣalaye pe o ṣoju oun nigba ti wọn gbe oku arabinrin kan sọkalẹ lori igi to ha si.
Oríṣun àwòrán, Facebook/honlekan.badmus.1
O ni awọn musulumi to fẹ ki irun ayila lo ri oku naa loju agbara odo Okooko nibi to ha si aarin igi ọpẹ meji.
Oríṣun àwòrán, Facebook/honlekan.badmus.1
Adugbo Alie nijọba ibilẹ Olorunda ni Gomina Adegboyega Oyetola ti duro ba awọn aradugbo kẹdun lori iṣẹlẹ omiyale.
Oríṣun àwòrán, Jibola Oyekunle
Lasiko to n kaakiri lati ri bi ojo ṣe ba nkan jẹ. o ni o ṣe pataki ki awọn araalu maa tẹle ilana itọju ayika ẹni paapa eyi to ni ṣe pẹlu oju agbara.
''Pẹlu nkan taa ri, o fi han pe oju agbara to di latari bi awọn eeyan ṣe n da panti soju agbara lo da wahala silẹ.Ni ọpọ ibi, niṣe lawọn eeyan gbegi dina oju agbara''
Oba Gbolahan Timson shomolu: Obasanjo ti jẹ́wọ́ pé 'Mistake' ni Buhari ṣùgbọ́n...
Oba Gbolahan Timson Shomolu: Obasanjo ti jẹ́wọ́ pé 'Mistake' ni Buhari ṣùgbọ́n...
Tinubu náà a ti mọ̀ pé òun ṣe àṣìṣe ni Buhari ṣùgbọ́n ẹnu ẹ kò gbàá mọ́- Oba Shomolu Bariga,
Oba Gbolahan Timson to jẹ Jagunmolu ti ilu Shomolu Bariga ni ipinlẹ Eko gbalejo BBC Yoruba.
Kabiesi sọrọ nipa oṣelu Naijiria.
O mẹnuba aṣiṣe ti awọn bii Tinubu Ahmed to jẹ eekan ninu iṣelu iran yoruba ṣe se asise lati gbaruku ti Aarẹ Buhari lati de ipo adari Naijiria laisko yii.
Lori Ẹgbe Okunkun?
Oba Gbolahan sọrọ lori iṣẹlẹ ẹgbẹ okunkun to n peleke lojoojumọ ni ẹgbẹ okunkun n peleke sii laisko kan ni agbegbe oun.
O sọ bi 'Pyrate'ṣe bẹrẹ pẹlu Wole Soyinka ni Fasiti Ibadan gẹgẹ bii ọna lati fi kọ iya ti awọn Olukọ fi n jẹ akẹkọọ ati awọn ololufẹ wọn ni.
O ni nigba to ya, Oun ati awọn Baalẹ oun ati awọn eeyan Shomolu Bariga lo jọ tọwọ bọ iwe adehun pe ki wọn pa ọmọkọmọ ti wọn ba ba ibọn lọwọ rẹ.
O ni lẹyin pipa pẹlu agbara ofin yii ni nkan n rọju diẹ pada.
Oríṣun àwòrán, @Oba
PDP Crises: Secondus, Wike, BoT: A kò gbọdọ̀ tún ṣe àṣìṣe tí a fi kùnà ní 2015- PDP
Oríṣun àwòrán, Facebook/Peoples Democratic Party
Lẹyin ipade wakati mẹrin ti wọn ṣe nilu Abuja, igbimọ majeobajẹ ẹgbẹ  oṣelu Peoples Democratic Party PDP ko ribi yanju aawọ to jẹ bi ipenija fun ẹgbẹ naa.
Ẹnu igbimọ yi ko ko lori boya ki alaga ẹgbẹ naa Uche Secondus ṣi wa lori oye tabi ko fi ipo silẹ gẹgẹ bi awọn ọmọ ẹgbẹ kọọkan ti ṣe n beere.
Ohun ti igbimọ naa sọ ni pe awọn yoo ṣe agbekalẹ igbimọ tuntun eleyi ti yoo joko lori ọna ati yanju gbogbo ọrọ to n fa gbọnmi si omi o to.
Wàhálà àti ìkùnsínú láàrin ọmọ ẹgbẹ́ PDP, kí ni ọ̀nà àbáyọ?
Ṣẹnẹtọ Walid Jibrin lo dari ipade naa eyi ti ko fẹnu ko boya ki wọn daba ijiya fawọn ọmọ ẹgbẹ to lọwọ ninu rukerudo to n damu ẹgbẹ ọhun.
Bi nkan ti ṣe ri bayi, ojutu ọrọ ko le ni iyanju ayafi ti ipade yi ba joko jiroro tan.
Esabod, Sunday Igboho: Kò burú bí Igboho ṣe wà lẹ́wọ̀n báyìí,ọ̀rọ̀ rẹ̀ dàbí i ti aláboyún
Sẹnẹtọ Bukola Saraki ati Sẹnẹtọ David Mark to ba awọn akọroyin sọrọ kọ lati sọ oju abẹ niko ṣugbọn wọn ni ipade tawọn ṣe so eso rere.
Nigba tawọn akọroyin beere lọwọ Bukola Saraki boya wọn yoo jẹ ki igbimọ amuṣẹya ẹgbẹ naa pari saa wọn, o ni awọn yoo ṣe ipade laarin ọjọ meji si mẹta la ti le mọ ibi ti ọrọ n lọ.
Oríṣun àwòrán, Facebook/bukola.saraki
Fakinfa laarin alaga ẹgbẹ PDP Uche Secondus ati Gomina Nyesom Wike wa lara nkan tawọn eeyan kan tọka si pe o n da wahala silẹ ninu ẹgbẹ.
Olawale Dada: Igbá bárà kọ́ ló kàn, àwa náà n ṣoríire láyé pẹ̀lú ìpèníjà 'Cerebral Palsy'
Kí ni ọ̀nà àbáyọ sí aáwọ̀ tó fẹ́ dojú ẹgbẹ́ òṣèlú PDP bolẹ̀?
Bo tilẹ jẹ wi pe awọn mejeeji ko jade lati sọ pe ede aiyede wa, pupọ lo gbagbọ pe Gomina Wike ko dunnu si iṣakoso Secondus to si n pete pero lati yọ kuro lori oye.
Oṣu mẹta si mẹrin lo ku ti saa Secondus yoo fi pari ki awọn ọmọ ẹgbẹ to yan alaga mi.
Oríṣun àwòrán, Facebook/riversgovernmenthouse
Iṣẹlẹ ikọwefiposilẹ awọn ọmọ igbimọ amuṣẹya meje ninu ẹgbẹ naa tubọ mu ki awọn eeyan sọ pe o ṣeese ki wọn yẹ aga nidi Secondus nibi ipade awọn majeobajẹ ẹgbẹ.
Amọ bi nkan ti ṣe ri yi, o ṣeeṣe ki wọn ri ọna naa yanju ti igbimọ majeobaje ba tun ṣe ipade lori ọrọ itẹsiwaju ẹgbẹ
Oba Gbolahan Timson shomolu: Obasanjo ti jẹ́wọ́ pé 'Mistake' ni Buhari ṣùgbọ́n...
Ki ṣe akọkọ ree ti wahala yoo de ba ẹgbẹ oṣelu PDP.
Lọpọ igba ti ọdun idibo ba ti n sunmọ, orisirisi wahala lo maa n bẹ silẹ eyi to maa n ṣokunfa ki wọn yọ alaga ẹgbẹ naa.
Ninu ọrọ rẹ sawọn ọmọ ẹgbẹ,alaga igbimọ majeobajẹ ẹgbẹ Senatọ Walid Jibrin kesi awọn agbaagba ẹgbẹ lati woye nipa wahala to yọ awọn alaga ẹgbẹ to ṣaaju.
Oríṣun àwòrán, Facebook/Facebook/riversgovernmenthouse
O ni bayi tawọn ọmọ Naijiria n foju wo PDP gẹgẹ bi ẹgbẹ ti yoo gba awọn ọmọ Naijiria silẹ, ko tọ ki wọn tun wa sa ara wọn sinu wahala ija ti ko nidi.
''Ki a baa le ṣe ẹkunrẹrẹ  aseyọri a ni lati jawọ nibi gbogbo ija ti ko nidi laarin ara wa ki a ba ma ṣe ṣakoba fun adisọkan ẹgbẹ wa''
Yoruba Culture: ọjọ́ méje ni wọ́n fí n rẹ ẹ̀kú Danafojura kó tó jáde
Ninu awọn alaga ẹgbẹ ana  ti ko pari saa wọn labẹ ẹgbẹ PDP ni a ti ri
-Chief Audu Ogbeh
-Okwesilieze Nwodo
-Bamanga Tukur
-Ahmed Muazu ati
-Ali Modu Sheriff
Wo àwòrán ìgbéyàwó ọkùnrin tó gbé obìnrin mẹ́rin níyàwó lọ́jọ́ kan ṣoṣo
A ti mú afurasí darandaran méjì tó ń da màálù tó kan ọmọ oṣù mẹ́ta pa- Ọlọ́pàá
Òjò àrọ̀rọ̀dá gbẹ̀mí èèyàn mẹ́ta ní Oshogbo,ọ̀pọ̀ dúkìá ṣòfò
Níbo ló kù tí Messi yóò lọ báyìí?
Kò sí olóṣèlú kankan tó ń pàṣẹ fún wa pé kí á máa ti aráálú mọ́lé- DSS
Àwọn ìlúmọ̀ọ́ká Mẹ́wàá to kú nínú oṣù keje odun 2021
Ẹran Akíka(Pangolin) àti ìwo Erin d'ẹ́rù b'olẹ̀, ìjọba f'òfin gba bílíọ́nù 22 ẹran ara wọn
Sunday Igboho Update: Igboho ti sọ ohun tó fẹ́ kí a ṣe tí ọ̀rọ̀ bá bẹ́yìn yọ- Saheed Yusuf Ajikobi 1
Gbogbo ọ̀na ni Ọga mi Igboho ti fi sọ asọtẹlẹ iṣẹlẹ yii ṣaaju ko to ṣ\lẹ- Alhaji ajikobi 1
Okan lara awọn amugbalẹgbẹ Oloye Sunday Adeyemo ti ọpọ mọ si Sunday Igboho ba BBC sọrọ lori ibi ti ija ominira Yoruba Nation yii de duro nile Igboho.
Alhaji  Saheed Yusuf Ajikobi 1 ṣọ awọn ọrọ ti Sunday Igboho ba wọn sọ lori ominira Yoruba Nation lati tẹsiwaju laini fi ṣe ohunkohun n to ba ṣẹlẹ.
Alhaji Saheed ni Sunday Igboho jẹ oloju aanu ti ko si ẹni to sunkun de ile rẹ ti ko ba ẹrin jade.
O sọ bi Igboho se n saanu awọn eeyan lorisirisi ti Igboho ko fẹ ki iya jẹ ẹnikẹni ni sakani rẹ.
Ajikobi 1 tun sọ pe ija ominira Yoruba Nation n tẹsiwaju lai naani gbogbo idojuko ti wọn n ri bayii nile Igboho ati kaakiri.
Sunday Igboho ti sọ àsọtẹ́lẹ̀ ìṣẹ̀lẹ̀ yìí fún àwa mẹ́rin nínú amúgbálẹ́gbẹ̀ rẹ̀- Alhaji Yusuf
Bakan naa lo gba pe ija ominira Yoruba Nation jẹ ajọja fun ọpọ eeyan ti ko bẹru nkan ti yoo ṣẹlẹ.
O ni igbesẹ gbogbo awọn to wa nile Igboho lasiko yii ni lati bọwọ fun ofin pẹlu idupẹ lori idajọ Adajọ to waye lọsẹ yii lori ọrọ Oloye Igboho.
Oríṣun àwòrán, @Igboho
Oshogbo Heavy Rainfall: Ọ̀pọ̀ ẹ̀mí àti dúkìá àìmoye mílíọ̀nú naira ṣòfò nínú ìjàmbá omíya
Ọpọ dukia lo ba iṣẹlẹ naa lọ eyi taa gbọ pe o bẹrẹ si ni rọ lati oru ọjọ Iṣẹgun ti ko si da titi di owurọ kutu Ọjọru.Òjò àrọ̀rọ̀dá gbẹ̀mí èèyàn mẹ́ta ní Oshogbo,ọ̀pọ̀ dúkìá ṣòfò
BangladeshThunder bolts: Àrá sán pa èèyàn 17 níbi ayẹyẹ ìgbéyàwó
Oríṣun àwòrán, Elvis
Oriṣiiriṣii lo n ṣẹlẹ ni duniyan. O kere tan, eeyan mẹtadinlogun lo ba Ọlọrun ni alejo lẹyin ti aramọka san pa wọn.
Nibi ayẹyẹ igbeyawo lawọn eeyan naa wa lorilẹede Bangladesh ti iṣẹlẹ ọhun fi ṣẹlẹ.
Eeyan mẹrinla to fi mọ ọkọ iyawo gan an gan an lo farapa nibi iṣẹlẹ naa.
Amọ ori ko iyawo yọ nitori ko tii wa nibẹ nigba ti iṣẹlẹ ọhun waye.
Iroyin sọ pe awọn eeyan naa n bọọlẹ lati inu ọkọ oju omi niluu Shibganj lọ si ile iyawo nigba ti ara bẹrẹ si ni san.
Taye Osinowo Olaosebikafi Iyabo Ojo, Mide Martins, Jaye Kuti, Afeez Owo àtàwọn míì dárà ap
Awọn eeyan ilu naa ṣalaye pe oriṣiiriṣii ẹdun ara lo ba awọn eeyan naa.
Ọdọọdun ni ara maa n san pa awọn eeyan apa Guusu ilẹ Asia.
Oba Gbolahan Timson shomolu: Obasanjo ti jẹ́wọ́ pé 'Mistake' ni Buhari ṣùgbọ́n...
Koda, orilẹede Bangladesh kede iṣẹlẹ aramọka gẹgẹ bi ijamba fun orilẹede naa lẹyin ti ara san pa igba eeyan loṣu marun un ọdun naa.
Bakan naa, ara tun san pa eeyan mejilelọgọrin lọjọ kan ṣoṣo lasiko naa.
Awọn onimọ nipa oju ọjọ sọ pe bi awọn eeyan ṣe n gegi ninu igbo wa lara ohun to jẹ ki ara maa san pa awọn eeyan.
Wọn ni awọn igi to ga ninu igbo lo n maa n gba ara sara ki wọn to ge wọn lulẹ.
Olawale Dada: Igbá bárà kọ́ ló kàn, àwa náà n ṣoríire láyé pẹ̀lú ìpèníjà 'Cerebral Palsy'
Seyi Makinde: Gómìnà ìpínlẹ̀ Oyo ní òun jẹ dòdò báwọn nkan ṣe ń pè òun ní ''audio governor''
Oríṣun àwòrán, @seyiamakinde
Gomina ipinlẹ Oyo, Seyi Makinde sọ pe ipakọ o gbọ suti, ori ẹlẹgan an lo daru lọrọ awọn to n pe oun ni ''audio governor.''
Makinde sọrọ yii nigba to n ṣe ifilọlẹ awọn kọmiṣọnna meje to yan sipo pada lọjọ Ẹti niluu Ibadan.
Gomina ipinlẹ Oyo ṣalaye ninu atẹjade kan ti akọwe iroyin rẹ, Taiwo Adisa fi sita pe awọn alako ijọba oun ko ni ṣai ri ariwisi kan tabi omiran nipa iṣejọba oun.
Amọ, Makinde sọ pe ijọba oun ko ni kaarẹ nipa pipese ohun amaye dẹrun fawọn eeyan ipinlẹ Oyo.
''Mo ranti ni bii ọdun kan sẹyin pe awọn kan maa n sọ pe ''audio'' ni gbogbo iṣẹ ti a sọ pe a n ṣe nipinlẹ Oyo.
Ṣugbọn to jẹ pe ''audio'' lawọn iṣẹ iṣẹ ti a nṣe ni tootọọ, o tumọ si pe awọn eeyan n ri ẹri ohun ti a n ṣe.
Oba Gbolahan Timson shomolu: Obasanjo ti jẹ́wọ́ pé 'Mistake' ni Buhari ṣùgbọ́n...
Nigba ti a ba ṣetan ni wọn yoo mọ pe ọpọn ti tun siwaju ninu eto iṣejọba nipinlẹ Oyo.
Laipẹ yii ti mo n ba gomina kan sọrọ lo sọ fun mi pe, ''audio governor'' ni wọn n kọkọ pe mi.
Ṣugbọn ni bayii wọn ti n ri ohun ti a n ṣe, wọn n wa beere bo ya a maa le tẹsiwaju lati maa ṣe ohun ti n ṣe bayii.
Taye Osinowo Olaosebikafi Iyabo Ojo, Mide Martins, Jaye Kuti, Afeez Owo àtàwọn míì dárà ap
A o ti jẹ owo oṣu awọn oṣiṣẹ ati owo ifẹhinti fun ọdun meji, awawi naa ni wọn yoo maa wa titi ti wọn ko fi ni ri nkan kan sọ mọ,'' Makinde lo ṣalaye bẹẹ.
Makinde rọ awọn kọmiṣọnna to ṣẹṣẹ yan sipo lati tubọ ṣiṣẹ takun takun ki awọn eeyan ipinlẹ Oyo le ri ere ijọba oun jẹ.
Olawale Dada: Igbá bárà kọ́ ló kàn, àwa náà n ṣoríire láyé pẹ̀lú ìpèníjà 'Cerebral Palsy'
Gomina ni asiko ti ko si adari gidi ni ipinlẹ Oyo ti lọ.
O ni gbogbo kọmiṣọnna lo ni ipa pataki lati ko ninu titu ọkọ ipinlẹ Oyo lọna tawọn araalu yoo fi gbadun ijọba.
Yoruba Culture: ọjọ́ méje ni wọ́n fí n rẹ ẹ̀kú Danafojura kó tó jáde
McDonald's Burger ad: Obìnrin kan gbé McDonald's lọ ilé-ẹjọ́ torí ìpolówó Buger nínú àwẹ̀
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Obinrin ọmọ ilẹ Russia kan, Ksenia Ovchinnikova, ti gbe ile ounjẹ McDonald's lọ si ile ẹjọ lẹyin to sọ pe ipolowo cheeseburgers wọn ja oun laawẹ.
Ovchinnikova ṣalaye pe bi oun ti ri ipolowo burger yii ni oun pinnu lati ja awẹ oun lọdun 2019.
O ni asiko lẹnti yii gan an ni oun n gbiyanju lati jina si burger ati awọn ounjẹ mii lasiko awẹ ki oun to ri ipolowo burger yii to jẹ oju ni gbese.
Awọn ọmọ lẹyin Kristi ni Omsk to n tẹle kalẹnda Julian maa n yago fun ẹran jijẹ, ẹyin ati awọn nkan jijẹ mii ti wọn fi adiẹ ṣe lasiko lẹnti.
Ovchinnikova ni oun ko tii jẹ ẹran fun oṣu ki oun to ri ipolowo burger ti ile ounjẹ McDonald's gbe sita eleyii to mu ki oun ja awẹ ti oun n gba lọwọ ninu oṣu kẹrin ọdun 2019.
Taye Osinowo Olaosebikafi Iyabo Ojo, Mide Martins, Jaye Kuti, Afeez Owo àtàwọn míì dárà ap
Ọmọbinrin Russia fẹsun kan McDonald's pe wọn tapa si ofin idaabo bo onibara ati ohun to tabuku ẹsin oun.
Ovchinnikova dẹbi ru McDonald's pe wọn ṣe ipolowo ọja ẹran lasiko tawọn ọmọlẹyin Kristi yago fun ẹran.
Nitori naa, o n beere fun owo dọla mẹrinla $14 gẹgẹ bi owo gba ma binu fun inira ti igbesẹ fa fun oun.
Olawale Dada: Igbá bárà kọ́ ló kàn, àwa náà n ṣoríire láyé pẹ̀lú ìpèníjà 'Cerebral Palsy'
Lẹyin to ti gba awẹ fun ọdun mẹrindinlogun sẹyin, Ovchinnikova ko le mu mọ ra lati maa jẹ burger lẹyin to ri ipolowo McDonald's tan.
''Mo ti n gbaawẹ fun bi oṣu kan ki n to ri ipolowo ọja burger yii.
Ara mi ko gbaa mọ, mo ni lati lọ si ile ounjẹ ti ko jina si mi lati ra cheeseburger ni kiakia.
Mo si ti sọ fun ile ẹjọ lati ṣe iwadii rẹ lori ọrọ yii,'' Ovchinnikova ṣalaye.
Yoruba Culture: ọjọ́ méje ni wọ́n fí n rẹ ẹ̀kú Danafojura kó tó jáde
Hijrah: Gómínà ìpínlẹ̀ Kano àti Oyo fi ọjọ́ ajé àti Iṣẹgun sílẹ̀ fún ìṣìnmi ọdún Hijrah
Ipinlẹ Kano ati Oyo naa ti mú ọjọ ọtọọtọ fun awọn ara lati simi sile fun ayẹyẹ ọdun Hijrah.
Gomina ipinlẹ Kano Abdullahi Umar Ganduje ya ọjọ aje, ọjọ kẹsan osu kẹjọ gẹgẹ bi ọjọ isinmi lẹnu iṣẹ ni ipinlẹ naa.
Ganduje rọ awọn ara ilu lati gba adura fun orilede Naijiria lati gbaa lọwọ iṣoro eto abo to mẹhẹ.
Taye Osinowo Olaosebikafi Iyabo Ojo, Mide Martins, Jaye Kuti, Afeez Owo àtàwọn míì dárà ap
Gẹgẹ bi  atẹjade ti kọmisọna ọrọ to n lọ ni ipinlẹ naa fọwọsi Malam Muhammed Garba ṣalaye pe isinmi naa ni lati ṣe ayajọ ọdun tuntu  ninu Islam  1443 AH.
Ganduje ki awọn  musulumi ku orire ọdun tuntun ti o si pe fun idupẹ ati idakẹrọrọ.
Bakan naa lo rọ awọn eniyan ipinlẹ naa lati ran ijọba lọwọ ki wọn si gbiyanju lati ran ara wọn lọwọ fun igbeaye rere.
Ẹwẹ, Gomina ipinlẹ Oyo ti ni ki awọn ara ilu simi si ile wọn lọjọ Isegun ni ọjọ kẹwaa, osu kẹjọ lati ṣe ayẹyẹ ọdun Islam tuntun
Akọwe ijọba Olubamiwo Adeosun lo fi atéjade naa sita lọjọ Eti
Gẹgẹ bi o ṣe sọ Makinde rọ awọn Musulumi lati lo asiko naa fun adura, isọkan, alafia ati idagbasoke  orilede Naijiria.
Nigeria insecurity: David Jemibewon faraya lórí báwọn jàǹdùkú ṣe ń borí ọmọogun Nàíjíríà
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ilé asòfin ní kí Buhari wá sọ tẹnu ẹ
Akọsilẹ sọ pe ijọba Aarẹ Muhamamadu Buhari ti na owo to le ni tiriliọnu marun naira lori eto abo lati igba to ti gori aleefa lọjọ kọkandinlọgbọn oṣu karun un ọdun 2015.
Amọ akọsilẹ ọhun ṣalaye pe, bo tilẹ jẹ pe ijọba Buhari ti na owo tabua yii lori eto, ẹgbẹrun mọkanla eeyan ati okoo le ni irinwo (11,420) lawọn ọmọ Naijiria ti Boko Haram atawọn darandaran ti ṣekupa laarin ọdun mẹfa ti Buhari di aarẹ.
Ajọ to n ṣe iwadii lori ọrọ abo ni Naijiria, Nigeria Security Tracker, ajọ to n ri si ọrọ ilẹ okeere ati ajọ Amnesty International lo gbe akọsilẹ jade.
Laipẹ yii ni ile aṣofin agba niluu Abuja tun ṣẹṣẹ buwọlu afikun owona fun eto abo, N714.5bn ti Buhari gbe lọ siwaju ile.
Owo to le ni tiriliọnu mẹta naira, N3.11tn lo ti ba owo oṣu ati awọn nkan mii lọ lati ọdun 2016 di asiko yii.
Oba Gbolahan Timson shomolu: Obasanjo ti jẹ́wọ́ pé 'Mistake' ni Buhari ṣùgbọ́n...
N830.11bn ni owo ti ijọba ti na fun awọn akanṣe iṣẹ ni ẹka eto aabo ni akoko yii bakan naa.
Owo to le ni tiriliọnu kan naira ni ijọba Buhari tun na lati ra baalu ijagun atawọn nkan ijagun miran.
Amọ, pẹlu gbogbo owo gọbọi ti ijọba APC ti na lori eto abo yii, kaka ki ewe agbọn dẹ, niṣe lo n le koko si lọrọ naa.
Ajagun fẹyinti to jẹ gomina tẹlẹ ri lapa iwọ oorun guusu Naijiria, Agagunfẹyinti David Jemibewon lo ti wa bu ẹnu atẹ lu bawọn Boko Haram atawọn janduku ṣe n pa ọmọ Naijiria, ti ileeṣẹ ologun si n ni ijakulẹ pẹlu wọn.
O kere tan ogun ọmọgun ofurufu Naijiria lo padanu ẹmi wọn laarin oṣu mẹta, ti baalu awọn ọmọgun si ti ja lulẹ nigba mẹta.
Sunday Igboho Update: Igboho ti sọ ohun tó fẹ́ kí a ṣe tí ọ̀rs bá bẹ́yìn yọ- Saheed Yusuf
''Ọrọ eto abo ni Naijiria ti buru debi pe awọn eeyan n bẹru lati rinrin ajo.
Eyi si ti ṣe akoba fun ọpọlọpọ nkan bi awọn to fẹ ṣe iṣẹ oko lati gbin nkan ọgbin ati bẹẹ bẹẹ lọ.
Eyi si ti da omi tutu si awọn ọmogun gan an lọkan pẹlu bi awọn janduku yii ṣe n pa awọn akẹgbẹ wọn.
"Nkan o fara rọ ni Naijiria lori eto abo, ijọba gbọdọ wa nkan ṣe si ọrọ yii ni kiakia."""
Domestic Violence: Joy tún gún òǹlàjà, tó jẹ́ ẹ̀gbọ́n ẹni tí wọn jọ ń jà, ní ọ̀bẹ lọ́wọ́ òsì
Oríṣun àwòrán, Ogun State Police
Ija ko si ni sọọsi, Sadura , ki n se amin ni.
Amọ ọrọ kor i bẹẹ nile ijọsin kan nibi tawọn obinrin meji ti gbe pẹrẹgi ka ina nitori ọkunrin.
Ileesẹ ọlọpaa ipinlẹ Ogun ti mu arabinrin kan to da omi gbigbona soju iyawo ile kan, to fẹsun kan an pe o n yan ọkọ rẹ lale.
Obinrin naa, Joy Sunday, ẹni ọdun mẹtadinlogoji la gbọ pe ko bu ọwọ ile ijọsin ti wọn ti lọ se aisun wọ arabinrin Justinah Ameh, ko to da omi gbona si loju.
Atẹjade lati ọdọ alukoro ileesẹ ọlọpaa Abimbola Oyeyemi salaye pe, ẹgbọn Justinah lo fi ọrọ naa to awọn leti lagọ ọlọpaa to wa ni Agbado.
Gẹgẹ bo ti wi, o ni ile ijọsin Spring of Life Global Ministry to wa ni Giwa ni Agbado, ni isẹlẹ yi ti waye.
O ni  nigba ti oun n gbiyanju lati di arabinrin naa lọwọ mu, n se lo gun oun lọbẹ lọwọ osi.
Nigba tawọn ọlọpaa n fọrọ wa afurasi naa, Joy Sunday lẹnu wo, o ni ọjọ ti pẹ ti Justinah ti maa n fẹsun kan oun pe oun n yan ọkọ rẹ lale.
Female Car AC Repairer: Abimbola Adedigba ní àfojúsùn òun ni láti ní abúlé mẹkáníkì láìpẹ́
O ni oun ti igbiyanju lati yọ ero yii kuro lọkan rẹ, amọ ko sinmi lati maa fẹsun kan oun.
O sọ pe lọjọ taa n wi yii, Jistinah lo bẹrẹ si ni pariwo le oun lori nile ijọsin, to si n rọjo epe loun lori.
Joy ni ibinu yii lo mu ki oun lọ gbe omi gbona ka ina nile, ti oun si pada wa lati da lu lori ni ile ijọsin.
Nigba ti awọn ọlọpaa beere lọwọ rẹ pe se lootọ lo n yan ọkọ Justinah lale, o ni ko si oun ti oun ko le fi bura pe ko si oun to jọ bẹẹ laarin awọn.
Lọwọlọwọ bayi, Justinah n gba itọju nile iwosan.
Kọmisana ọlọpaa Edward Ajogun ti ni kawọn ọlọpaa bẹrẹ iwadii ni kiakia, lati le fi gbe ọrọ naa sile ẹjọ.
Oríṣun àwòrán, NigerianArmyHQ
Awọn janduku agbebọn tun ti ji ẹbi kan to n rinrin ajo lopopona Ewu-Ayetoro Ekiti ni ijọba ibilẹ Ido/Osi nipinlẹ Ekiti.
Awọn janduku naa ṣekupa olori ẹbi naa, wọn si gbe iyawo ati ọmọbinrin rẹ lọ.
Iroyin sọ pe ẹbi naa n rinrin ajo bọ lati ibugbe wọn niluu Eko wa si ipinlẹ Ekiti fun ayẹyẹ isinku kan ti yoo waye niluu Ewu Ekiti, ki wọn to ko sọwọ awọn ajinigbe.
Ẹnikan ti o mọ nipa iṣẹlẹ ọhun sọ pe eeyan mẹrin lo wa ninu ọkọ Lexus tawọn ẹbi yii fi rinrin ajo naa.
Ẹnikan mori bọ ninu wọn, awọn agbebọn pa baba, wọn si gbe iyawo ati ọmọbinrin kan lọ.
Oba Gbolahan Timson shomolu: Obasanjo ti jẹ́wọ́ pé 'Mistake' ni Buhari ṣùgbọ́n...
Awọn eeyan awujọ ti iṣẹlẹ naa ti ṣẹlẹ ti wa n gbiyanju lati doola awọn meji ti wọn gbe lọ, lọwọ awọn ajinigbe.
Lalẹ ọjọ naa lawọn ajinigbe yii kan si ẹbi wọn ti wọn si beere aadọta miliọnu owo itusilẹ lọwọ wọn.
Alukoro ile iṣẹ ọlọpaa ipinlẹ Ekiti, Sunday Abutu to fidi iṣẹlẹ naa mulẹ sọ pe, loju ẹsẹ ni ọkunrin ti wọn yinbọn fun naa gbẹmi mi.
Abutu ṣalaye pe awọn ọlọpaa atawọn oṣiṣẹ eleto abo mii bii Amotekun, Nigeria Security and Civil Defence Corps, to fi mọ awọn filante atawọn ọlọdẹ lo ti wọ igbo lọ lati doola awọn ti wọn jigbe lọ.
Alukoro ile iṣẹ ọlọpaa ni ipaniyan ati ijinigbe jẹ ohun ti gbogbo ọmọ Naijiria gbọdọ fọwọ sowọ pọ pẹlu awọn oṣiṣẹ eleto abo lati wa ojutuu si.
''Ọta orilẹede Naijiria lawọn ọdaran ajinigbe pawo ati apaniyan yii jẹ.
Ọ̀pẹlọpẹ́ Ajá tí Ifa ní kí a fi ṣètùtù ní Ekiti ní 1942 ni kò jẹ́ kí ìjàmbá náà pọ̀ jù- Ol
Ile iṣẹ ọlọpaa ko gbọ tabi mọ bo ya awọn ajinigbe ọhun ti kan si ẹbi lati beere fun owo itusilẹ awọn ti wọn jigbe lọ.
Amọ, ile iṣẹ ọlọpaa ti mu afurasi kan to n ṣiṣẹ pọ pẹlu awọn ajinigbe lagbegbe Ido Osi nipinlẹ Ekiti.
Ẹwẹ, lọjọ kẹwaa oṣu kẹrin ọdun 2021 yii naa ni awọn agbebọn kọlu Elewu ti Ewu Ekiti, Oba Adetutu Ajayi loju opopona yii kan naa.
Mide Martins: Ohun tó bá wu oníkálukú kó sọ, mò ń gbìyànjú lórí ọ̀pọ̀ bùkátà ìwájú mi
Oríṣun àwòrán, Mydemartins
Gbajugbaja oṣere tiata Yoruba, Mide Martins ti fesi si ọrọ ti akẹgbẹ rẹ ninu isẹ tiata, to tun jẹ ọrẹ mama rẹ, Ashabi Olorisha sọ pe ko tun iboji mama rẹ, Funmi Martins tabi tọju aburo rẹ, Damilare.
Ọrọ Damilare aburo rẹ lo kọkọ lu ori ayelujara pa tẹlẹ eyi ti ọpọ eeyan da ẹnu bo Mide pe ko tọju rẹ, lẹyin ti mama wọn ti ku tan.
Awọn ẹbi ṣepade pọ lati yanju ọrọ naa ni itubi inubi nigba naa.
Ṣugbọn laipẹ yii oṣere tiata kan, Ashabi Olorisha to fi ilẹ Amẹrika se ibujoko sọrọ pe Mide ko ṣe ohun kan si oju orori mama rẹ, ẹni to ti ku fun ogun ọdun bayii.
Bakan naa ni wọn ni Ashabi tun sọ pe Mide fi gbogbo ẹbi silẹ lai bikita, to si n palẹmọ lati se ariya alarinrin fun iranti ogun ọdun ti mama rẹ jade laye.
Taye Osinowo Olaosebikafi Iyabo Ojo, Mide Martins, Jaye Kuti, Afeez Owo àtàwọn míì dárà ap
Ṣugbọn Mide fesi ninu ifọrọwerọ to ṣe pẹlu iwe iroyin City People pe, oun mọ ohun ti oun n ṣe, ati pe oun ko le maa sọ ohun ti oun n ṣe fawọn eeyan lori ayelujara.
''Mi o le pa ara mi, mo mọ ohun ti mo ti gbe ṣe fun Damilare ti wọn sọ pe mi o bikita nipa rẹ yii.
Ohun to ba wu onikaluku ni ki wọn maa sọ, mo n gbiyanju agbara mi.
Eeyan ni emi naa, kii ṣe wi pe mo ni gbogbo nkan tan, ṣugbọn mo n gbiyanju pẹlu diẹ ti mo ni.
Mo si ni baba laye, ko si ẹni to beere pe bawo lo ṣe n jẹun, mo tun ni aburo mii to jẹ ọkunrin yatọ si Damilare.
Emi naa si ni awọn ọmọ temi naa. Bukaata pọ fun mi lọtun losi, amọ awọn eeyan kan ṣa wa lati bu ẹnu atẹ lu mi.
Esabod, Sunday Igboho: Kò burú bí Igboho ṣe wà lẹ́wọ̀n báyìí,ọ̀rọ̀ rẹ̀ dàbí i ti aláboyún
Nibo ni mo ti fẹ rowo lati pe Alhaji Wasiu Ayinde, KWAM 1 lati wa ṣere fun iranti ogun ọdun iku mama mi pẹlu bukaata to wa nilẹ fun mi yii?
"Ọdọọdun ni mo maa n ṣe iranti mama ṣugbọn n ki i pariwo nipa rẹ."""
Bakan naa ni Mide Martins salaye siwaju si pe oun maa n ṣe eto adura lọdọọdun fun iya oun, oun ṣi tun maa n ṣe iranwọ fawọn alaini lati ṣe iranti mama oun, ṣugbọn oun ko ki n gbe si ori ayelujara.
O ni ki onikaluku fi oun silẹ, ki wọn si jẹ ki Ọlọrun da oun lẹjọ bo ba jẹ ọmọ buruku ni oun tabi ọmọ daadaa.
Gbajumọ osere tiata naa ni oun ko ni lọ ya owo lati ṣe iranti ogun ọdun iku mama oun, bo ba ṣe wu oun ni oun maa ṣe e.
"Mide Martins tẹsiwaju pe ""Mo ti fa gbogbo eeyan to n sọ pe mi o tọju Damilare le Ọlọrun lọwọ, ko baa jẹ Ashabi Olorisha tabi aburo mama mi."
Ọlọrun nikan lo le dajọ fun gbogbo wa, iwọfa lẹnu, ohun to ba wu ẹlẹnu lo le fi ẹnu rẹ sọ.
Ẹ fi mi silẹ, ẹ jẹ ki Ọlọrun ati mama mi ṣe idajọ mi.
Igi Ọ̀pẹ abàmì tó dá ní orí 42 l'Ekiti rèé o, 'bí mo ṣe ríi l'orí mi ń dìde fììì'
Mi kii ṣe ẹnikan to maa n fi ọrọ ẹbi si ori ayelujara fawọn eeyan lati ri.
Bo ya iyẹn lo jẹ ki wọn maa sọ pe mi o ṣe eleyii, mi o ṣe tọhun.
Ṣugbọn iru ẹda ti Eleduwa da mi niyẹn, ko da mi lati maa saba fi ọrọ awọn ọmọ ti mo bi gan an sori ayelujara.
Mo fẹ ri Ashabi Olorisha fun ra mi lati beere idi ti o fi n sọ oriṣiiriṣii nipa mi gan an.
Bakan naa lo ṣe video pe mo n fẹ Sir Shina Peters, nigba ti mama mi mọ, lo jẹ ki mama mi ku.
Mo fẹ bi i leere nibi ti o ti n ri awọn iroyin to n sọ yii gan an.
O wu mi lati beere lọwọ rẹ idi to fi fẹ ba mi lorukọ jẹ, ti o fi n sọ oriṣiriṣii nipa mi,'' Mide lo ṣalaye bẹẹ.
Sunday Igboho Update: Igboho ti sọ ohun tó fẹ́ kí a ṣe tí ọ̀rs bá bẹ́yìn yọ- Saheed Yusuf
Hushpuppi Vs Abba Kyari: Falana ní ẹnú yà òun bí ìjọba ṣe fẹ́ lò ìlànà tó tọ́ fún ẹ̀sùn Kyari, tó sì ń rúfin lórí ọ̀rọ̀ Igboho àti Kanu
Gbajugbaja agbejọro agba ni Naijiria, Femi Falana ti sọrọ l'ori ẹsun ti FBI fi kan Abba Kyari.
Agba agbejọro, to tun jẹ ajafẹtọ ọmọniyan, Femi Falana, ti sọ pe ko si bi igbakeji Ọga ọlọpaa, Abba Kyari, ṣe le bọ mọ ileesẹ ọtẹlẹmuyẹ ilẹ America, FBI lọwọ.
Ileesẹ ọtẹlẹmuyẹ Federal Bureau of Investigation, FBI, kede ni oṣu to kọja pe Kyari gba owo riba lọwọ gbajúmọ ti wọn fi ẹsun lilu jibiti kan, Ramoni Igbalode Hushpuppi.
Nibi ipade ijiroro ori ayelujara Twitter kan ti ẹnikan pataki lara awọn oluwọde ENDSARS, Rinu Oduala, ṣe agbatẹru rẹ ni Falana ti sọ ọrọ naa.
Gẹgẹ bo ṣe sọ, o ni boya Abba Kyari fẹ tabi kọ̀, ilẹ America yoo mu u lati koju igbẹjọ.
Female Car AC Repairer: Abimbola Adedigba ní àfojúsùn òun ni láti ní abúlé mẹkáníkì láìpẹ́
"O ni ""iyalẹnu lo jẹ pe ijọba Naijiria to n lo iwa janduku lati koju àwọn to fẹ ẹ yapa kuro ni Naijiria, sọ pe oun yoo tẹle ilana to yẹ 'due process' lori ẹsun ti FBI fi kan Kyari."
Ileesẹ FBI sọ pe Hushpuppi fun Kyari ni ọpọlọpọ owo, lati fi ẹnikan ti wọn jọ n lu jibiti, Vincent Chibuzor si ẹ̀wọ̀n nitori jibiti owo to le ni miliọnu kan Dọla ti wọn lu.
Oríṣun àwòrán, CrimeFighters
Saaju la ti mu iroyin wa fun yin pe, ile asoju-sofin nilẹ wa ti kede pe o seese ki oun gba awọn ami ẹyẹ ti wọn ti fun ọga ọlọpaa Abba Kyari, to ba jẹbi awọn ẹsun ti ileesẹ ọlọpaa ilẹ Amẹrika, FBI fi kan-an.
Bẹẹ ba gbagbe, ajọ to n mojuto isẹ ọlọpaa lorilẹede yii lo ti pasẹ saaju pe ki Abba Kyari lọ rọọkun nile na, gẹgẹ bi ọga agba ọlọpaa nilẹ yii, Usman Baba ti beere fun.
Bẹẹ ba gbagbe ile asofin apapọ ilẹ wa lo ti kọkọ fi ami ẹyẹ da Abba Kyari lọla lọjọ Kọkanla osu Kẹfa ọdun 2020 nitori isẹ akin to n se lẹnu isẹ ọlọpaa ni Naijiria.
Laipẹ yii si ni ileesẹ ọlọpaa FBI kepe pe Abass Ramoni ti ọpọ eeyan mọ si Hushpuppi, ti wọn lo lu jibiti owo nla lori ayelujara, ka orukọ Kyari gẹgẹ bii ara awọn eeyan to pin owo jibiti naa fun.
Nigba to n sọrọ lori ami ẹyẹ ti ile asojusofin fun Kyari, alaga igbimọ ile to wa feto iroyin ati ọrọ araalu, Benjamin Kalu salaye igbesẹ ile asojusofin lori isẹlẹ yii fun iwe iroyin Punch.
Taye Osinowo Olaosebikafi Iyabo Ojo, Mide Martins, Jaye Kuti, Afeez Owo àtàwọn míì dárà ap
Kalu ni Abba Kyari ko tii ni ẹsẹ kankan lọrun lasiko yii titi ti wọn yoo fi lo jẹbi awọn ẹsun ti wọn fi kan.
"Ohun ti ofin ilẹ wa sọ ko ni amulumala ninu. Amin ẹyẹ ti ile asofin fun kii se amin ẹyẹ kansoso to ni ree, a ko si gbọdọ tii maa gba ami ẹyẹ naa kuro lọwọ rẹ.
Afurasi lasan si ni Kyari lori awọn ẹsun ti wọn fi kan-an lasiko yii, ti ko si tii ni ẹsẹ kankan lọrun ayafi igba ti wọn ba kede pe o jẹbi awọn ẹsun naa."
Ileesẹ ọlọpaa Amẹrika FBI lo ti sọ fun ile ẹjọ kan nilu Califonia pe Hushpuppi ati Kyari wa lara awọn afurasi mẹfa ti wọn fi ẹsun lilu jibiti kan lori ayelujara.
Apapọ owo ti wọn lo wa ninu jibiti ọhun ni Miliọnu kan ati ẹgbẹrun lọna ọgọrun dọla.
Sunday Igboho: Agbẹjọ́rò kéde ọjọ́ tó ṣeéṣe káwọn afurasí tí DSS kó, kúrò lọ́gbà ẹ̀wọ̀n
Ọpọ eeyan lo ti n foju sọna lati ri awọn eeyan mejila ti awọn agbofinro DSS ko nile Oloye Sunday Igboho ni ọjọ Kinni osu Keje ọdun 2021.
Ọjọru ọsẹ to kọja ni ile ẹjọ giga nilu Abuja si ti gbe asẹ kalẹ pe ki wọn lọ gba oniduro awọn eeyan naa ni ọgba ẹwọn ti wọn wa.
Amọ titi di akoko yii, awọn afurasi ọhun si wa ni ọgba ẹwọn, koda ibẹ ni wọn ti lo opin ssẹ yii, ti ọpọ eeyan si n beere pe ki lo tun n da wọn duro?
Amọ nigba to n salaye idi ti awọn afurasi mejeejila ko se tii kuro ni ọgba ẹwọn naa, agbẹjọro wọn, Pelumi Olajengbesi ni omi lo pọ ju ọka lọ nipa beeli wọn.
Olajengbesi ni awọn gbedeke to rọ mọ igbesẹ gbigba beeli awọn afurasi naa ni awọn ko tii se amusẹ rẹ, bo tilẹ jẹ pe awọn n saayan lọpọlọpọ lori rẹ.
Sunday Igboho Update: Igboho ti sọ ohun tó fẹ́ kí a ṣe tí ọ̀rs bá bẹ́yìn yọ- Saheed Yusuf
Amọ o fi ọwọ idaniloju sọya pe ti yoo ba fi di ọjọ Aje ọla, o seese ki awọn eeyan naa kuro ni ọgba ẹwọn, gba ile wọn lọ.
"A ti lero pe pẹlu idajọ ti adajọ gbe kalẹ, oniduro mẹrin pere la nilo lati fa kalẹ fun awsn eeyan naa amọ nigba ta beere alaye daadaa, a gbọ pe oniduro meji la gbọdọ fi silẹ fun ikọọkan wọn.
A ti wa n sa ipa wa lati ri oniduro mẹrinlelogun fun awọn eeyan mejeejila naa, a ko si fẹ pada lọ sile ẹjọ mọ, lati maa bẹbẹ pe ko din iye awọn oniduro naa ku.
Ọpọlọpọ eeyan ti n fi ifẹ han lati se atilẹyin fun wa lori ohun tawọn eeyan naa n ja fun, ta si n sisẹ pe titi ọjọ Aje, didun ni ọsan yoo so lori ọrọ naa."
Bẹẹ ba gbagbe, adajọ Eguatu to n gbọ ẹjọ naa lo ti gba oniduro awọn eeyan mejeejila pẹlu miliọnu marun naira fun ẹnikọọkan.
Osun Money Ritual: Wò ó bí Babaláwo ṣe gé apá, ẹsẹ̀, orí àti ọ̀kan oníbàárà rẹ̀ fi ṣe òògùn owó
Oríṣun àwòrán, Osun State Police
Yoruba ni ẹni to ba n wa iwakuwa, yoo ri irikuri.
Bẹẹ ni ọrọ ri fun ọkunrin kan, ti wọn pe orukọ rẹ ni Ayoade Moses Fasesan to n gbe nilu Ikirun, to tọ Babalawo kan lọ lati se oogun owo nitori sanmọni to lọ tiirin fun.
Babalawo naa, Faseun Afolabi, ẹni ogoji ọdun, lo wa sọ fun Ayo pe oun ko se oogun owo fun ẹnikẹni ri amọ ti Ayo sọ pe dandan, o gbọdọ se fun oun ni.
Idi ree ti Faseun se tọ agba awo miran, tii se ọrẹ rẹ lọ lati ran lọwọ se oogun owo fun Ayo, amọ oun to ro lọhun, kọ lo ba.
Babalawo keji naa, Fadare Afolabi, ẹni ọdun mejidinlogoji, lo wa gba Faseun nimọran pe ko jẹ ki awọn lo Ayo, lati fi se oogun owo fun ara awọn.
Lọjọ ti Ayo de lati se oogun owo yii, Fadare ati ọkunrin kan ti wọn pe ni Taiwo ti wa nikalẹ, ti wọn si fun Ayo lọrun pa.
Khadijat Oluboyo: Ilé ẹjọ́ sọ ọ̀rẹ́kùnrin rẹ̀ sí gbaga
Faseun, lasiko to n ka boro boro fun awọn ọlọpaa nipinlẹ Osun ni oun gan ni oun fa Ayo ni ẹsẹ mejeeji, ti Taye fi fun ni ọrun pa.
Awọn afurasi naa, tileesẹ ọlọpaa ipinlẹ Osun foju wọn han faraye tun salaye pe awọn ge ẹya ara Ayo, ti wọn si ta lati gba owo, nigba ti wọn lo awsn miran fun oogun owo.
"Faseun ni ""Ọwọ Ayo mejeeji ati ọkan rẹ ni wsn fun mi. Mo ta ọwọ kan ni ẹgbẹrun lọna ogun naira nigba ti mo fi ọwọ keji ati ọkan rẹ tọrọ."""
"Nigba toun naa n jẹwọ ẹsẹ rẹ, babalawo keji, Fadare ni ori oloogbe naa ati ẹsẹ rẹ mejeeji ni oun fi peelo oogun owo fun ara oun."""
Kọmisana ọlọpaa nipinlẹ Osun, Olawale Olokode lasiko to n bawọn akọroyin sọrọ, tun kede orukọ awọn afurasi yoku ti wọn tun ko lori isẹlẹ naa.
Lara wọn ni Adeleke Kabiru, ẹni ọdun mẹtadinlogoji, Oloyede Moruff, ẹni ọdun mọkandinlogoji, Oseni Mukaila ẹni ọdun mẹrinlelogun ati Badmus Sairu, ẹni ọdun mẹtadinlogoji.
"Olokode ni ""ọjọ Kẹrinlelogun osu Karun ọdun 2021 ni iya Ayo ke gbajare tọ awọn ọlọpa lọ pe oun ko ri ọmọ oun mọ."
LASU Ritual: Àwọn akẹẹgbẹ́ akẹ́kọ̀ọ́ LASU tí wọn fi ṣowó sọ̀rọ̀ lórí ìgbé ayé olóògbé
Iya Ayo ni studio lo dagbere pe oun n lọ amọ ti ko pada wale mọ, idi si ree ti awọn ọlọpaa ọtẹlẹmuyẹ fi bẹrẹ iwadii lori isẹlẹ naa.
Lasiko iwadii ọhun ni ọwọ tẹ babalawo akọkọ, Faseun Afolabi, ẹni to kọkọ sẹ pe oun ko mọ ibi ti Ayo wa amọ lẹyino rẹyin, o pada ka boroboro.
"Idi si ree ti ọwọ fi tẹ awọn afurasi yoku bi o tilẹ jẹ pe Taiwo, to fun Ayo lọrun pa ti na papa bora."""
Kọmisana ọlọpaa ni afurasi akọkọ yii lo mu awọn ọtẹlẹmuyẹ lọ sibi ti wọn sin oku Ayo si ladugbo Fidibomi nilu Ikirun, ti wọn si hu oku naa jade fun ayẹwo.
O ni wọn ti gbe oku oloogbe naa lọ si ibudo igbokusi tile iwosan ẹkọsẹ isegun Uniosun, ti iya Ayo si fi asọ ara oloogbe naa da mọ pe ọmọ oun ni.
Baba Khadijat Oluboyo jẹ́rìí ọmọ rẹ̀
Hushpuppi and Daddy Freeze: Ifedayo Olarinde ní Hushpuppi fi ìfẹ́ hàn lásìkò táwọn ìjọ Ọlọ́run gbógun tì òun
Oríṣun àwòrán, Hushpuppi
Yoruba ni arise ni arika, arika si ni baba iregun, ohun ti a ba se lonii, yoo di ọrọ itan to ba di ọla.
Eyi lo mu ki gbajumọ onwoye awujọ ka, Ifedayo Olarinde, ti ọpọ mọ si Daddy Freze se n salaye idi ti ko fi le gbagbe Ramoni Abass, ti ọpọ eeyan mọ si Hushpuppi.
Hushpuppi ni ọlọpaa ilẹ Amẹrika, FBI fi ẹsun kan pe o lu jibiti ori ayelujara ti owo rẹ to miliọnu kan ati ẹgb€run lọna ọgọrun Dọla.
Bakan naa ni Hushpuppi ti n ka awọn eeyan ti wọn dijọ lọwọ ninu ẹsun lilu jibiti naa, ninu eyi ta ti ri ọga ọlọpaa kan nilu Eko, Abba Kyari.
Bakan naa ni iroyin kan tun ni o seese ki Hushpuppi tun darukọ awọn eeyan miran to na ninu owo jibiti naa, paapaa awọn eeyan to ti ba ni ajọsepọ ri lorilẹede Naijiria.
Daddy Freeze s'alaye n to faa ti oun fi n tako idamẹwa
Nigba to wa n fesi lori ọrọ yii, Daddy Freeze, to ti ba Hushpuppi tọwọ bọwọ jẹun lori tabili kan naa salaye pe igba tawsn aye kọ oun silẹ, ni Hushpuppie tẹwọgba oun.
Ninu fidio kan to fi soju opo ayelujara, Daddy Freeze ni awọn ijọ Ọlọrun lo fi oniruuru aisan kan oun lasiko ti Hushpuppi tẹwọgba oun, ti ko si kọ ẹyin si oun.
"Nigba ti mo n fọnrere nipa iwa aidaa ti awọn ijọ Ọlọrun n hu lori gbigba idamẹwa, ni wọn kọju ija si mi, ti mo si dubulẹ aisan lọdun 2017.
Gbogbo ọna ni wọn fi kọlu mi ninu ara, wọn gba awọn ipolowo ọja ti mo n ba wọn se, ti orisun owo to n wọle fun mi si bẹrẹ si poora.
Amọ bi o tilẹ jẹ pe Hushpuppi yii ni wọn fẹsun kan pe o jẹ ogbologbo gbajuẹ, arakunrin yii lo kaanu mi, to si fi ifẹ ati atilẹyin han si mi lasiko isoro ọhun.
To ba wa jẹ pe awọn ijọ Ọlọrun duro ti mi lasiko isoro mi ni, se maa tẹle Hushpuppi lasiko to fi mọto ransẹ pe ki wọn lọ gbe mi wa sibi ti oun wa.
Bi mo ba foju gan ni Hushpuppi bayii, maa sọ fun pe ohun to n se ko dara amọ n ko le wọgile pe o fi ifẹ han si mi lasiko ti awọn ijọ Ọlọrun korira mi.
Bakan ni Daddy Freeze salaye pe lootọ̀ ni oun ko faramọ iwa lilu jibiti tabi gbajuẹ amọ nigba ti oun n ba eeyan kan pin yara sun lasiko ti oun lọ si ilu Dubai, ni Hushpuppi yari pe ki wọn gbe oun wa.
N ko mọ pe Hushpuppi n lọwọ ninu iwa jibiti amọ bi awọn eeyan se n sọrọ emi pẹlu rẹ, wọn ko se idajọ fun awọn ijọ Ọlọrun to fẹ pa mi."
Ta wa ni maa pe ni esu laarin awọn mejeeji, Hushpuppi ni tabi ijọ Ọlọrun? Ẹ fi ara yin si ipo mi lati se idajọ.
Mo si n kede fun gbogbo aye pe Hushpuppi ko fun mi lowo kankan, boya dọla mẹwa ni tabi marun. Ohun to kan se ni pe o fi ifẹ han si mi.
Tunde Bakare journey in life: Bàbá bàbá mi ni Lèmọ́mù àkọ́kọ́ ní Sodeke Abeokuta ṣùgbọ́n..
IPOB Sit-at-home: Ìjọba ní ẹnikẹ́ni tó bá dá wàhálá sílẹ̀ lórúkọ IPOB yóò fojú winá òfin
Oríṣun àwòrán, Getty Images
O ṣeeṣe ki rogbodiyan bẹ silẹ lapa ila oorun guusu Naijiria nibi ti ẹya Igbo pọ si lẹyin edeaiyede to waye lori ofin joko sile ẹ, ti ẹgbẹ ajijagbara fun idasilẹ Biafra, IPOB ṣe fawọn ẹya Igbo.
Lọsẹ to lọ ni IPOB ti kọkọ leri pe ẹnikẹni ko ni lọ sibi kan nilẹ Igbo lati oni ọjọ Aje, ọjọ kẹsan an oṣu kẹjọ ọdun 2021, ayafi ti ijọba apapọ ba fi olori wọn, Nnamdi Kanu silẹ.
IPOB sọ ninu atẹjade kan ti agbẹnusọ ẹgbẹ naa, Emma Powerful fi sita pe, ofin konle o gbele yoo gberasọ lọjọ Aje lati ago mẹfa owurọ si mẹfa irọle lojoojumọ, titi ti Kanu yoo fi kuro lahamọ ajọ DSS.
Ẹgbẹ IPOB ni ọna to tapa si ofin ni ijọba Naijiria fi gbe Kanu lati orilẹede Kenya wa si Naijiria.
''Gbogbo ọja, ile ẹkọ, ibudokọ, papakọ ofurufu ati nibi gbogbo kaakiri ilẹ Igbo lo gbọdọ wa ni titi pa lati aarọ di irọlẹ.
Female Car AC Repairer: Abimbola Adedigba ní àfojúsùn òun ni láti ní abúlé mẹkáníkì láìpẹ́
A mọ ipa ti igbesẹ yii le ni lori ọrọ aje ṣugbọn a n ṣe eyi lati jẹ ki gbogbo agbaye mọ pe a wa lẹyin olori wa, Kanu gbọingbọin.
Gbogbo awọn ajeji to ni Biafra naa gbọdọ tẹle ofin yii niwọn igba ti wọn si nilẹ Igbo.
Ẹnikẹni ko gbọdọ jade ki ikọlu pẹlu awọn agbonfinro maa ba ṣẹlẹ, a ko fẹ ki awọn oṣiṣẹ eleto abo Naijiria dunkoko mọ ẹnikẹni,'' ẹgbẹ IPOB ṣalaye.
Ṣugbọn ninu ọrọ tiẹ, aburo Kanu gan an, Kanunta Kanu kede wi pe oun ti paṣẹ pe ki wọn si so ofin jokoo silẹ ẹ rọ na fun igba diẹ.
Ninu atẹjade ti Kanunta naa fi sita, o ṣalaye pe awọn so ifẹhonuhan konle o gbele ọhun rọ nitori awọn akẹkọọ ile ẹkọ girama to n ṣe idanwo NECO lọwọ.
Oba Gbolahan Timson shomolu: Obasanjo ti jẹ́wọ́ pé 'Mistake' ni Buhari ṣùgbọ́n...
O ni awọn yoo maa kede ọjọ mii ti a o ṣe ifẹhonuhan naa laipẹ fun gbogbo eeyan.
Ẹwẹ, gomina ipinlẹ Anambra tẹlẹ ri, Chukwuemeka Ezeife ti bu ẹnu atẹ lu erongba IPOB lati fofin konle o gbele de awọn eeyan nilẹ Igbo.
Ezeife ni igbesẹ yii ko ni bimọ 're fun ilẹ Igbo lọna kanakn, bẹẹ ni ko si iranwọ kankan to le ti inu rẹ jade.
Ijọba ipinlẹ Enugu naa ti kilọ fawọn ọmọ ẹgbẹ IPOB pe ẹnikẹni to ba da rogbodiyan silẹ rugi oyin.
Ijọba rọ awọn araalu lati lọ si ibi iṣẹ oojọ wọn lai bẹru nitori eto abo to peye yoo wa fun gbogbo eeyan.
Ibadan Accident: Tírélà agbépo ṣekúpa ọmọ ìyá méjì àtàwọn mẹ́ta míì
Bi a ṣe n lọ, ti a nbọ, Ọba oke ko ni jẹ ki a ṣi rin o.
Ọmọ iya meji ti wọn n lọ fun idanwo aṣejade ile ẹkọ girama, NECO ni a gbọ pe o wa lara eeyan marun un ti tirela agbepo bẹntiro run mọ inu koto nla lagbegbe Celica niluu Ibadan lọjọ Aje.
Awọn ti iṣẹlẹ naa ṣoju wọn sọ fun BBC Yoruba pe ijanu tirela ọhun lo ja, eleyii to jẹ ki o gba taxi ti ero marun un wa ninu rẹ sinu koto ti o si tẹ wọn pa mọ'bẹ.
Ni bii ago meje aarọ ọjọ Aje ni ijamba ọkọ naa ṣẹlẹ lopopona mọrọsẹ Ibadan si Ile Ife.
Ọga ajọ ẹṣọ oju popo, FRSC, Uche Chukwurah fidi rẹ mulẹ pe ọkunrin mẹta ati obinrin meji lawọn eeyan to ku ninu ọkọ taxi ọhun.
Sunday Igboho: Femi Falani ní ẹjọ́ Igboho ní Cotonou ń kọ́ àwọn amòfin Nàíjíríà ní ẹ̀kọ́
Ni kete ti iṣẹlẹ naa waye ni awọn ẹṣọ oju popo atawọn panapana ti de sibẹ lati doola ẹmi awọn eeyan.
Bakan naa ni awọn panapana n gbiyanju lati yọ awọn ọkọ mejeeji kuro ninu koto.
Ṣugbọn wọn ko tete ri awọn ọkọ naa yọ lasiko bo ya nitori bi koto naa ṣe jin to lo fa eleyii.
Bi eeyan ba jẹ ori ahun, ti o ba de agbegbe Celica ti iṣẹlẹ ọhun ṣẹlẹ lọjọ Aje yoo bomi loju pẹli bi ọkọ agbepo yii ti pa taxi elero marun un pẹlẹbẹ.
Ẹwẹ, awọn eeyan agbegbe Celica ra ọwọ si ijọba lati pari iṣẹ lori ọna ti o n ṣiṣẹ lori rẹ lagbegbe naa ni kiakia lati le dena iru iṣẹlẹ bayii.
Wọn ni ijamba ọkọ to n ṣẹlẹ lagbegbe naa ti di lemọ lẹmọ nitori ọna ti ko dara nibẹ.
Ọ̀pọ̀ ẹ̀mí bọ́ nígbà tí ìjánu tírélà já, ó wó lu ọkọ̀ akérò taxi kan mọ́ inú kòtò n'Ibadan
Saaju la ti mu iroyin wa fun yin pe awọn eeyan agbegbe Celica niluu Ibadan ti ke gbajare si ijọba lati pari iṣẹ atunse oju popo to n lọ lọwọ loju ọna marosẹ Ibadan si Ile Ife.
Awọn ara adugbo naa sọrọ yii fun BBC Yoruba lẹyin ti tirela agbepo kan wo lu ọkọ taxi akero kan mọlẹ ninu koto laarọ ọjọ Aje, ọjọ kẹsan an oṣu kẹjọ.
Ohun tawọn ti iṣẹlẹ ọhun ṣoju sọ nipe ijanu ọkọ agbepo naa ni ko mu un mọ, to fi ya kuro loju popo, o gba ọkọ taxi akero naa, to si wọ lọ sinu koto nla kan to wa lẹba oju ọna naa pẹlu rẹ.
Ẹnikan ti ọrọ naa ṣoju rẹ, Sunday ṣalaye pe ọkọ taxi naa fẹ gbe ero loju popo ni, nigba ti tirela agbepo ti ijanu rẹ ko mu un mọ naa fi gbe ha ẹnu, ti o si lọ run mọ inu koto.
O ṣalaye pe ọkọ meji ni tirela naa gba, ṣugbọn ori ko ọkọ keji yọ.
Sunday ni ero mẹfa lo wa ninu ọkọ taxi ti tirela wo lu mọlẹ ninu koto lagbegbe Celica, to si pa mọto naa mọlẹ pẹlẹbẹ bii ile isana.
Ni kete ti iṣẹlẹ naa waye ni awọn ẹṣọ oju popo atawọn panapana ti de sibẹ lati doola ẹmi awọn eeyan.
Bakan naa ni awọn panapana n gbiyanju lati yọ awọn ọkọ mejeeji kuro ninu koto.
Ẹlomiran ti iṣẹlẹ ọhun ṣoju rẹ sọ pe ọpọ ẹmi lo ti ṣofo lagbegbe naa nitori ọna ti ko dara ti ijọba ti n ṣe lati ọjọ yii lai pari rẹ, igba akọkọ si kọ ree, ti ijamba yoo maa waye alagbegbe naa.
O sọ pe ijamba ọkọ mii ṣẹlẹ lagbegbe yii kan naa ninu eyi ti ero ọkọ bọọsi mejidinlogun ti padanu ẹmi wọn.
Ẹwẹ awọn oṣiṣẹ ẹṣọ oju popo, FRSC ati awọn panapana to wa nibi isẹlẹ naa kọ lati ba BBC Yoruba sọrọ lori isẹlẹ ọhun.
Female Car AC Repairer: Abimbola Adedigba ní àfojúsùn òun ni láti ní abúlé mẹkáníkì láìpẹ́
Awọn agba bọ, wọn ni ko si ohun ti skunrin se, ti obinrin ko le se ju bẹẹ lọ.
Bi ọrọ se ri ree pẹlu obinrin kan, Abimbola Adedigba to n sisẹ titun ẹrọ ọlọyẹ inu mọto, Air Conditioner (AC) se.
Adedigba, ti iya se koriya fun lati kọ isẹ naa, lo ti kọ ọpọ ọmọ isẹ jade ti gbogbo wọn si jẹ ọkunrin.
Nigba to n ba BBC Yoruba sọrọ, Adedigba ni o ti to ọdun mẹrindinlogun ti oun ti bẹrẹ isẹ naa, ti ọpọ awọn ọkunrin si maa n wa oun wa lati se atunse AC mọto wọn.
O fikun pe ọpọ ọkunrin lo ni nitori pe oun jẹ obinrin, oun maa jẹ olotitọ, ti oun ko si ja wọn kulẹ ri.
Bakan naa lo fikun pe abilekọ to wa lọọdẹ ọkọ ni ou, ti ọkọ oun si fara mọ isẹ ti oun n se, eyi to maa n jẹ ki oun wa laarin awọn ọkunrin lọpọ igba, toun si tun ni awọn ọkunrin bii onibara.
O wa kede pe afojusun oun ni lati se rere nidi isẹ naa, ki oun si ni abule mẹkaniki toun ni ọjọ iwaju.
Kwara Kidnap: Ọlọ́pàá ní agbègbè Oke Onigbin àti Omu Aran ni ìṣẹ̀lẹ̀ náà ti wáyé
Oríṣun àwòrán, Nigeria News
Awọn eeyan mẹtala miran tun ti ko si ọwọ awọn ajinigbe nipinlẹ Kwara.
Ninu wọn ni eeyan mẹfa kan to n dari lati ibi inawo igbeyawo ni ipinlẹ Ekiti wa.
Alukoro ileesẹ ọlọpaa ipinlẹ Kwara Ajayi Okasanmi lo fidi ọrọ yii mulẹ ninu atẹjade kan to fi sita.
O sọ pe laarin aala Kwara ati Ekiti ni awọn ajinigbe naa ti da awọn eeyan meje to n dari bọ lati ibi inawo igbeyawo ni Ekiti.
''Ibi ti wọn ti ko si ọwọ ajinigbe wa laarin Oke Onigbin ati Omu Aran ni nkan bi ago marun un abọ irọlẹ ọjọ Abamẹta.''
Isẹlẹ ijinigbe keji waye laarin Ekan Meje ni ijọba ibilẹ Oke-Ero ni ipinlẹ Kwara ati Ekiti.
Female Car AC Repairer: Abimbola Adedigba ní àfojúsùn òun ni láti ní abúlé mẹkáníkì láìpẹ́
Ninu awọn to ko si gbaga awọn alaburu yi ni Pasitọ kan iyawo rẹ ati awọn eeyan mẹrin.
Okasanmi to fidi isẹlẹ yii mulẹ ni awọn ti doola eeyan mẹjọ lapapọ.
Mẹrin ninu isẹlẹ ti Omu Aran, mẹrin mii ninu ti Oke Onigbin.
Amọ sa o ni awọn ko ti ribi doola Pasitọ ati iyawo rẹ to fi mọ eeyan mẹta to ku ninu awọn to n dari bọ lati ibi ayẹyẹ igbeyawo ni Ekiti.
''Agbarijọpọ awọn ikọ ẹsọ alaabo ati awọn fijilante lo le awọn ajinigbe naa wọnu igbo, taa si ri eeyan mẹrin doola.
A si n gbiyanju lati doola awọn mẹta to ku ninu awọn to lọ si ibi igbeyawo''
Okasanmi pari ọrọ rẹ pe, iwadii n tẹsiwaju ati pe awọn ti ri awọn afurasi kan mu lori isẹlẹ ọhun.
Esabod, Sunday Igboho: Kò burú bí Igboho ṣe wà lẹ́wọ̀n báyìí,ọ̀rọ̀ rẹ̀ dàbí i ti aláboyún
Jumoke‘s Death Trial: Ìyá olóògbé ní kíjọba gbé òkú ọmọ òun fún sílẹ̀ láti sín lẹ́yìn ọjọ́ pípẹ̀
Mọlẹbi Jumoke Oyeleke, ẹni ọdun mẹẹdọgbọn to jade laye lasiko iwọde Yoruba Nation lagbegbe Ojota nilu Eko ti gbe ileesẹ ọlọpaa lọ sile ẹjọ lori iku ọmọbinrin naa.
Bẹẹ ba gbagbe, ariyanjiyan ti n waye saaju lori iku to pa Jumoke ni ọjọ Satide, ọjọ kẹta osu Keje ọdun 2021.
Saaju ni ileesẹ ọlọpaa ti ni oun ko mọ nipa ọta ibọn ti wọn lo pa Jumoke, ti wọn si ni oku rẹ ti gan, kawọn eeyan kan to gbe wa si agbegbe Ojota, ti iwọde naa ti n waye.
Amọ ayẹwo awọn onisegun fi han pe ọta ibọn lo ba Jumoke to fi jẹ ipe Ọlọrun lọjọ naa.
Idi ree ti mọlẹbi oloogbe naa fi pe ẹjọ lati mọ ẹni to pa ọmọ wọn gan, ijiya to tọ si labẹ ofin ati ẹtọ to tọ si mọlẹbi to padanu ọmọ wọn naa.
'Ẹ má jẹ́ kí òkú ọmọ mi ráre o ìjọba! Ẹ gbée fún mi kí n lọ sin ín - Ìyá ọmọ ti wọ́n pa ní ìwọ́de Yoruba Nation
Igbẹjọ ọhun si lo waye ni Kootu kinni, ile ẹjọ Majisireti ilu Eko to wa ladugbo Ogba.
Nigba to n salaye bi iku ọmọ rẹ se waye fun BBC Yoruba lẹyin igbẹjọ naa, iya oloogbe naa, Ifeoluwa Oyeleke ni oun ko gbọ rara pe wọn fẹ se iwọde kankan ni ọjọ ti ìṣẹ̀lẹ̀ yii waye.
O ni oun ni awọn nnkan ti oun fẹ́ se nilẹ ni ọjọ́ ti iṣẹlẹ yii sẹ.
"Mo lọ si ibi isẹ, Jumoke, tii se ẹni ọdun mẹẹdọgbọn naa si maa n lọ si ibi isẹ ti wọn ti n ta Ice Cream ni oju dọsini amọ ni aago meje abọ awọn eniyan n pe mi pe nibo ni mo wa, ki n tete maa bọ.
Nigba ti mo dele, mo ri gbogbo eniyan ti wọn joko si palọ bọọda mi, wọn sa sọ fun mi pe ibọn pa Jumoke.
Lẹyin naa ni wọn ni ki n jẹ ki a lọ si agọ ọlọpaa Area H ni Ogudu, boya wọn yoo gbe oku rẹ fun wa, amọ bi ojo se n rọ to awọn ọlọpaa ko gba ki a wọle."
Female Car AC Repairer: Abimbola Adedigba ní àfojúsùn òun ni láti ní abúlé mẹkáníkì láìpẹ́
Ifeoluwa tẹsiwaju pe, nigba ti awọn ọlọpaa gba lẹyin o rẹyin pe ki awọn wọle, ọga ọlọpaa ibẹ ni lóòtọ́ọ́ oun gburo ibọn sugbon ko ye oun ibi ti ibọn ti wa.
O ni ọga ọlọpaa naa wa fi ọwọ sọya pe awon yoo se iwadii lati mọ ibi ti iro ibọn ti n dun, to si gba adirẹsi awọn pe ki awọn ma lọ.
Ile ẹjọ ti wa sun igbẹjọ naa siwaju di ọjọ Kẹfa osu Kẹsan ọdun to n bọ fun itẹsiwaju igbẹjọ ọhun.
Iya Jumoke fikun pe lọjọ naa, awọn ọlọpaa tun pada wa wo awọn sugbon lati igba naa, awọn ko gbọ ohunkohun mọ asiko yii.
Wayi o, iya Jumoke ti ke si ijọba atawọn osisẹ ọlọpaa lati fi oku ọmọ rẹ silẹ fun ko le tete lọ sin bo se yẹ.
Obinrin naa to n fi omije sọrọ lori iku ọmọ rẹ ni, ọpọ ti isẹlẹ naa soju rẹ ni ko mọ pe ẹjọ naa ti n bẹrẹ, to si fọwọ gbaya pe oun yoo tubọ ko ẹlẹ́ri wa sile ẹjọ gẹgẹ bi adajọ ti salaye.
Ninu alaye agbẹjọro to n gbọ ẹjọ naa, Amofin Taiwo Olawanle ni ile ẹjọ ti fi ọrọ wa eeyan mẹta lẹnu wo, pẹlu ọga Jumoke ati ọkunrin to wa nibẹ nigba ti isẹlẹ naa waye.
"Ile ẹjọ ni awọn ẹlẹri to sọrọ lonii gbọdọ fi ọwọ si iwe pe lootọ ni ọrọ naa se oju wọn koro.
Lootọ ni ọpọ eeyan n bẹru lati jade wa sile ẹjọ wa jẹri, paapaa nitori bi awọn ọlọpaa se ko eeyan mọkandinlaadọta, ti wọn si ni ọkan lara wọn lo pa Jumoke, ti onitoun ko si ni ibọn lọwọ lati fi pa eeyan.
Tunde Bakare journey in life: Bàbá bàbá mi ni Lèmọ́mù àkọ́kọ́ ní Sodeke Abeokuta ṣùgbọ́n..
Eyi gan lo mu ki ọpọ eeyan maa sa lati wa jẹri nile ẹjọ, ki ọwọ̀ ọlọpaa ma baa ba wọn.
Nigba toun naa n ba BBC Yoruba sọrọ,a buro Mama Jumoke to tẹ le ẹgbọn rẹ wa sile ẹjọ ni idajọ ododo ni nnkan soso ti awọn n beere fun lori iku to pa Jumoke laipe ọjọ.
Bkan lo ni awọn n fẹ ki ijọba tọju iya Jumoke, ki wn si fun ni ẹtọ to ba tọ si.
Sunday Igboho and 12 Suspects: DSS ń gbé ìgbésẹ̀ tuntun láti dojú béèlì àwọn ọmọlẹ́yìn Igboho méjìlà bolẹ̀
Ileeṣẹ agbofinro DSS ti kọwe si onidajọ Obiora Egwuatu ti ile ẹjọ giga apapọ nilu Abuja pe ko wọgile beeli to fun awọn ọmọlẹyin Sunday Igboho ti  ile ẹjs naa gba beeli wọn laipẹ yii.
Ninu iwe ipẹjọ tuntun naa ti wọn kọ, eyi ti akori rẹ jẹ FHC/ABJ/CS/647/2021 eyi ti agbẹjọro fun Sunday Igboho, Idowu Awo pe, DSS n fẹ ki Onidajọ Egwuatu wọgile aṣẹ beeli to pa lori Amudat Babatunde, Abideen Shittu, Jamiu Oyetunji ati Bamidele Sunday.
Ileeṣẹ agbofinro DSS n fẹ ki ile ẹjọ wọgile beeli naa ki o si fun awọn laṣẹ ati fi wọn sinu ahams pada titi ti wọn o fi gbe wọn wa sile ẹjọ pada lasiko isinmi ile ẹjọ.
Sunday Igboho Update: Igboho ti sọ ohun tó fẹ́ kí a ṣe tí ọ̀rs bá bẹ́yìn yọ- Saheed Yusuf
Amọṣa, agbẹjọro fun awọn eeyan mejila ti wọn ko nile oloye Sunday Igboho naa, Amofin Pẹlumi Jẹngbesi ti ṣalaye fun iwe iroyin The PUNCH pe awada kẹrikẹri ni igbesẹ ti ileeṣẹ agbofinro DSS ngbe yii.
Ni Ọjọru ọsẹ to kọja ni Onidajọ Obiora Egwuatu gba beeli awọn mejila naa lẹyin ti wọn lo ọsẹ marun un ni ahamọ awọn agbofinro DSS naa lẹyin ti wọn mu wọn lasiko ti awọn oṣiṣẹ DSS kan kọlu ile Igboho nilu Ibadan ni nnkan bii agogo kan oru ni Ọjọ kini oṣu keje ọdun 2021.
Sunday Igboho and 12 Suspects: Yomi Aliyu ní àwọn ti parí ìlànà tó yẹ́ ọ̀rọ̀ kù sọ́wọ́ àdájọ́ àti ilé ẹjọ́
Oríṣun àwòrán, others
Ni Ọjọ kẹrin oṣu kẹjọ ọdun 2021 ni ileẹjọ giga kan nilu Abuja gba beeli awọn eeyan mejila ti awọn oṣiṣẹ ileeṣẹ agbofinro DSS ko nile oloye Sunday Igboho nilu Ibadan.
Onidajọ Obiora Egwuatu paṣẹ pe ki wọn gba beeli awọn eeyan naa, bi o tilẹ jẹ wi pe ileeṣẹ DSS gbiyanju titi lati yi igbesẹ naa pada.
Amọṣa lẹyin ọjọ marun un ti aṣẹ yii ti waye, awọn eeyan mejila yii ko tii kuro ni ahamọ awọn agbofinro DSS.
Eyi kii ṣe nitori pe awọn oṣiṣẹ naa ko fẹ fi wọn silẹ o, bikoṣe pe awọn agbofinro wọn ko tii mu awọn gbedeke ti ile ẹjọ la kalẹ fun gbigba beeli wọn ṣẹ.
Sunday Igboho Update: Igboho ti sọ ohun tó fẹ́ kí a ṣe tí ọ̀rs bá bẹ́yìn yọ- Saheed Yusuf
Ninu ọrọ to ba BBC News Yoruba sọ lọsan ọjọ Aje, ọjọ Kẹsan osu Kẹjọ ọdun 2021, agba amofin Yọmi Aliyu SAN ṣalaye pe, awọn eeyan mejila naa ti wa nile ẹjọ nibi ti awọn amofin ti n ṣe eto gbogbo lati rii pe awọn ilana antẹẹle ti ile ẹjọ gbe kalẹ fun beeli wọn, wa si imuṣẹ.
Bakan naa nigba ti BBC News Yoruba beere pe ṣe awọn eeyan mejila yii yoo wale lọjọ Aje, o ni eyi ku si ọwọ adajọ ati ile ẹjọ.
O fi kun un pe, wọn ti ṣeto gbogbo to yẹ lọdọ awọn agbofinro DSS, wọn si ti wa nile ẹjọ lati lee yanju ohun gbogbo to ba yẹ.
Custom Service: Báwo ní ẹ̀mí mẹ́fà ṣe bọ́ lásìkò táwọn aṣọ́bodè ń lé onífàyàwọ̀ láàrín ìlu?
Oríṣun àwòrán, NNN
Eeyan mẹfa lo padanu ẹmi wọn nigba ti ọkọ awọn osisẹ asọbode Naijiria kọlu awọn eeyan to wa lẹgbẹ titi nilu Jibia, ipinlẹ Katsina.
Lowurọ ọjọ Aje ni isẹlẹ yii waye, ninu eyi ti eeyan oogun mii ti farapa.
Jibia jẹ ilu kan to wa lẹgbẹ ibode Naijiria pẹlu orilẹede Niger, ti pupọ awọn eeyan ibẹ si maa n se karakata laarin ilẹ mejeeji.
Ijamba ọkọ naa lawọn ti isẹlẹ ọhun soju wọn sọ pe o waye nigba tawọn osisẹ asọbode n le awọn afurasi onifayawọ kan, to wa ninu ọkọ J5 Peugeot.
Dẹrẹba ko ribi dari ọkọ mọ, lo mu ko rọlu awọn eeyan to wa lẹgbẹ titi'' ni alaye ti olugbe agbegbe naa, AlMustapha Danye se."
O ni ''lẹsẹkẹsẹ ni eeyan mẹfa ku, ti wọn si gbe awọn to farapa lọ si ileewosan ni Jibia. Mo gbọ pe awọn mii ku ninu wọn sugbọn mi o le fidi ọrọ yi mulẹ nitori mi o ba wọn de ibẹ''
Asẹ́yìn, àwọn ẹbí olóògbé ṣì ń fomijé dárò àwọn tóṣìṣẹ́ 'Custom' yìnbọn pa nílùú Iseyin
Onisowo kan Kabir Jibia ti isẹlẹ naa soju rẹ ni nkan bi ago mẹjọ aarọ lo waye.
"Ọlọkọ to ni J5 Peugeot yẹn wa lara awọn to maa n ra agbado lati ilu Dandume lati wa taa ni ibi. Wọn maa n saba fun awọn asọbode ni owo toun ti pe kii se isẹ fayawọ ni wọn se.''
O ni sugbọn onimọto yii kọ lati duro nibi ti wọn ti da duro ni Batsari, bi eeyan ba ti n pada bọ wa si Jibia.
Wọn fi ọkọ le lati ibẹ wọ inu ilu. Nigba ti wọn sare tẹle ni ọkọ wọn ya lọ ba awọn eeyan to wa lẹgbẹ titi."""
Arakunrin Jibia fikun pe awakọ J5 naa mọ oju ọna ilu daada ati pe o ti sa mọ awọn asọbode naa lọwọ.
Ọgbẹni Danye ni tiẹ sọ pe awọn asọbode naa fẹsẹ fẹẹ ni kete ti ijamba ọkọ yi waye.
''Nibẹrẹ nise lawọn eeyan n gbiyanju lati doola awọn ti o ha si ẹnu ọkọ sugbọn nigba ti wọn ri ti awọn asọbode sa lọ, ni wọn ba fi ibinu dana sun ọkọ wọn''
Sunday Igboho: Femi Falani ní ẹjọ́ Igboho ní Cotonou ń kọ́ àwọn amòfin Nàíjíríà ní ẹ̀kọ́
Alukoro ileesẹ asọbode to wa ni Katsina, Danba Isa sọ pe ko si ootọ ninu ọrọ tawọn eeyan sọ pe awọn n fi ọkọ le eeyan ni.
"O ni ""ohun taa mọ ni pe ijamba ọkọ lo waye, ko si si ẹni ti iru rẹ ko le sẹlẹ si. Ijamba naa waye lowurọ oni lẹyin tawọn osisẹ wa jẹun tan, ti wọn si n pada si ẹnu isẹ wọn."
Nigba ti wọn n lọ ni ijanu ọkọ kọsẹ, to si fa ijamba ọkọ naa''
Arakunrin Isa wa kesi awọn araalu lati sinmi gbigbe iroyin ẹlẹjẹ kiri.
Oríṣun àwòrán, other
Ile ẹjọ Majisireti kan ni Yaba, nipinlẹ Eko ti ju Chidinma Ojukwu, ti wọn fi ẹsun kan pe o pa oludasilẹ ileesẹ amohunmaworan Super TV, Usifo Ataga, si ẹ̀wọ̀n fun ọgbọn ọjọ.
Ọjọ Aje ni ileesẹ ọlọpaa ipinlẹ Eko gbe Chidinma to jẹ akẹkọọ Fasiti UNILAG, ati afurasi meji miran, lọ si ile ẹjọ naa.
Onidajọ Adeola Adedayo pàṣẹ pe ki wọn o fi si ẹ̀wọ̀n naa, titi ti ileesẹ eto idajọ yoo fi sọ nkan to ku lori ẹsun ipaniyan ti wọn fi kan an.
Ọjọ kẹẹdogun, oṣu Kẹfa, ọdun 2021, ni wọn gun Ọgbẹni Ataga pa sinu ile kan nipinlẹ Eko, ki ọwọ to o tẹ Chidinma to jẹ ọrẹbinrin rẹ.
Saaju ni ẹni ọdun mọkanlelogun ọhun jẹwọ pe ẹẹmeji ni oun gun Ataga ni ọrùn lasiko to fẹ ẹ fi ipa ba oun ni ibalopọ.
Sugbọn o tun pada sọ pe oun ko mọ nipa iku rẹ. O ni oun lọ ọ ra oúnjẹ lasiko naa, ati pe bi oun ko ṣe fi ọrọ iku rẹ to ileesẹ ọlọpaa leti, ati bi oun tun ṣe gba owo ninu apo àsùnwọ̀n rẹ ni banki, ni ẹbi ti oun jẹ
Hijra Celebration: Akeugbagold ní Ànọ́bì kò ṣe àjọ̀dún Hijrah nígbà àyé rẹ̀ àmọ́ kò sí ẹ̀sẹ̀ níbẹ̀
Ninu awọn ajọdun to wa ninu ẹsin Islammu, meji pere lo pọn dandan, ti o si se pataki fun gbogbo olugbagbọ ododo.
Awọn ajọdun yii, gẹgẹ bi awọn onimọ ẹsin se sọ, ni Eid Adha,ọdun ileya ati Eid Fitr,ọdun itunu awẹ.
Amọ nibayi ti awọn ọmọlẹyin Islammu kan ni Naijiria ti n beere fun ọjọ isinmi fun ayajọ ibẹrẹ ọdun musulumi taa mọ si First Muharram, pupọ lo ti n beere pe se lootọ ni ọjọ yii yẹ fun ajọdun.
Ni ipinlẹ Oyo ati Osun, to fi mọ awọn ipinlẹ mii lapa ariwa Naijria, ijọba kede isinmi lẹnu isẹ fun ajọ́dun ibẹrẹ ọdun musulumi tii se First Muharram.
Ni onka oju ọrun, Muharram ni musulumi maa n pe osu akọkọ ni afiwe January ti awọn to n lo onka Gregorian Calendar.
What causes coronavirus: Akeugbagold sọ àṣírí ohun ti àrùn coronavirus ń dá lárá f
Hijrah ti wọn so mọ ibẹrẹ ọdun yii ni isẹlẹ to waye nigba ti Anọbi Muhammad sa asala kuro ni Makkah to jẹ ilu rẹ lọ si Madinah.
Awọn to ni Anọbi ko se ajọdun Hijrah ni Point sugbọn...Akeugbagold
BBC Yoruba ba eekan onimọ ẹsin kan to fi ilu Ibadan se ibujoko, Sheik Taofeek Akeugbagold sọrọ lati yannana boya o tọ lati se ajọdun ọjọ Hijra abi ko tọna.
Ninu idahun rẹ, Sheikh Akeugbagold ni awọn to sọ pe ko ba ilana Islamu mu ati awọn to ni o baa mu, awọn mejeeji lo ri wi.
O ni lootọ ni pe Anọbi ko se Hijrah ati pe o ti lọ tan, ki awọn kan to se agbekalẹ ọdun naa.
''Umar, ọkan ninu awọn Sahabah lo sọ pe o yẹ ki awọn musulumi naa ni ọna ti wọn yoo maa fi se onka ọdun tiwọn.
''Saaju asiko yii tawọn musulumi yoo ba ranti ọdun, wọn a maa lo isẹlẹ to ba waye lati fi ranti ọdun naa bii apẹrẹ, ọdun ti omiyale sẹlẹ tabi ọdun ti iyan mu ni ilu.''
O ni nitori eyi, ''Lẹyin ọpọ ijiroro, Umar ni ki osu Muharram, ti Hijra to waye lasiko Anọbi bọ si,  maa jẹ ibẹrẹ ọdun onka ti musulumi.''
Sunday Igboho: Ladoja ní bí ìjọba kò bá fi ẹ̀lẹ̀ ṣe, ọ̀pọ̀ ajìjàgbara míì yóò dìde
Akeugbagold tun se lalaye pe, ẹkọ to wa nibi isipopada yii ni pe, o kọ awọn musulumi lẹkọ pe ti aye baa se n yi, ko saburu ki wọn lọ si ibomiran.
Akewugbagold tun fi kun ọrọ rẹ pe ni Saudi Arabia, awọn gan ko ya ọjọ sọtọ lọjọ isinmi fun ọjọ akọkọ Muharram sugbọn wọn a maa si ilẹkun Kaaba lọjọ yii lati se idanimọ ibẹrẹ ọdun tuntun mii.
O ni bi ijọba ti se fun awọn musulumi ni ọjọ yii gẹgẹ bi ọjọ isinmi lawọn ipinlẹ kọọkan dara nitori awọ́n eeyan Naijiria ko ribi jẹ anfaani ti awọn musulumi Saudi n jẹ lọdọ ijọba wọn.
''Ọwọ isinmi ti wọn fun wa yii da nitori yoo maa jẹ iranti fun wa. Se ẹ ri awọn Larubawa, wọn mọ pataki awọn onka osu yii.Wọn kii fii se ere.O ti mọ wọn lara''
''Ko si ẹsẹ ti wọn ba fun wa ni họlide Hijrah sugbọn Anọbi ko se laye rẹ. Apọnle ni fun awa musulumi. Ko si ninu Quran ati Hadith lootọ.''
Female Car AC Repairer: Abimbola Adedigba ní àfojúsùn òun ni láti ní abúlé mẹkáníkì láìpẹ́
Lakotan, Akeugbagold ni awọn musulumi dupẹ lọwọ awọn Gomina to ti ya ọjọ́ yii sọtọ, ati pe awọn n rọ́ awọn to ku lati se bẹẹ pẹlu.
"Sheikh Akewugbagold tun sọ pe ''A fẹ ki wọn fi se apọnle Islammu fun wa. Yoo dun mọ wa ninu pupọ ti wọn ba se bẹẹ."""
Sunday Igboho: Femi Falani ní ẹjọ́ Igboho ní Cotonou ń kọ́ àwọn amòfin Nàíjíríà ní ẹ̀kọ́
Yoruba ni ẹnu ti ẹnu rẹ ba to ọrọ, lo maa n sọ ọ.
Agba amofin kan lorilẹede Naijiria, to tun jẹ ajafẹtọẹni, Femi Falana ti salaye fun BBC Yoruba lori idi ti ijọba Naijiria fi n ba Sunday Igboho se ẹjọ.
Sunday Adeyemo, ti ọpọ eeyan mọ si Igboho ni ijọba Benin mu ni papakọ ofurufu kan nilu Cotonou pẹlu iyawo rẹ lasiko ti wsn n rinrin asjo lọ silẹ Germany.
Falana ni bo se yẹ ki orilẹede tẹle ofin ni ijọba Cotonou se nitori lọjọ keji ti wsn mu tọkọ-taya naa, ni wọn gbe wọn lọ sile ẹjọ.
O ni ijọba Naijiria lo fẹ di Igboho lapanyaka sinu baalu lati papakọ ofurufu lati maa gbe bọ ni Naijiria, gẹgẹ bo ti se fun Kanu lorilẹede Kenya, amọ ijọba Benin ni ko gba fun wọn.
Agba amofin naa wa salaye pe aibọwọ fun ofin ti pọ ju ni Naijiria amọ ti orilẹede Benin n bọwọ fun ofin, eyi to si mu ki Igboho wa ni ahamọ.
Bakan naa lo woye pe pe ijọba apapọ n gbe igbesẹ to tọ lori ẹsun kikopa ninu iwa lilu jibiti ti ijọba ilẹ Amẹrika fi kan ọga ọlọpaa Abba Kyari amọ ti ko se bẹẹ lori ọrọ Igboho ati Kanu.
Femi Falana tun yan pe ẹkọ nla ni bi ẹjọ Sunday Igboho se n lọ ni Cotonou n kọ awọn agbẹjọro lorilẹede Naijiria nitori bi wọn se n tẹle ofin.
Zambia Pastor: Èèyàn márùn-ún di èrò ẹ̀wọ̀n lẹ́yìn tí wọ́n sin wòlíì láàyè lásìkò ètò àdúrà
Oríṣun àwòrán, Zambia Daily Star/Facebook
Ara meeriri, mo ri ori ologbo lori atẹ ni ọrọ isẹlẹ kan to waye nigba ti wolii kan ni ki awọn ọmọ ijọ rẹ sin laaye, ki oun si pada jinde, amọ to gba ibẹ ku fin-fin.
Idile ẹlẹni marun kan lo pe wolii wa sinu ile wọn lati wa se isẹgun fun wọn to wa ni abule Mazonde, lorilẹ-ede Zambia, lati le awọn ẹ̀mí buburu jade.
A gbọ pe ni ṣe ni Wolii Shamiso Kanyama sọ fun awọn ọmọ ẹyin rẹ pe ki wọn o sin oun laaye, ki oun ba le ke pe awọn agbara ìwẹ̀nùmọ́ ti yoo wo ẹbí naa ṣàn kuro lọwọ agbara ati airi to n pa wọn ni ipakupa.
Lẹyin naa lo darapọ mọ àwọn ọmọ ẹ̀yìn rẹ lati gbẹ ibojì to fẹ ki wọn o sin oun si.
Ṣe ẹni ba rán ni nisẹ laa bẹru, a kii bẹru ẹni ti a o jẹ ẹ fun, n se ni àwọn eniyan naa ṣe bi Ọga wọn ṣe sọ, lẹyin to gbadura, to si bẹ sinu iboji fúnra rẹ, wọn ko iyẹpẹ le e lori bi oku.
Sunday Igboho: Femi Falani ní ẹjọ́ Igboho ní Cotonou ń kọ́ àwọn amòfin Nàíjíríà ní ẹ̀kọ́
Sugbọn ọrọ gba ibomiran yọ nigba ti awọn ọkunrin naa pada gbẹ iboji naa lati wo o boya wolii ti jinde bo ṣe sọ, oku rẹ ni wọn ba.
Wọn ti wa fi ẹsun ipaniyan kan eeyan marun-un ninu ẹbí naa lẹyin ti wolii naa, ti wọn pe si ile wọn fun eto adura, jade laye.
Awọn iwe iroyin abẹle nibẹ sọ pe, awọn afurasi marun-un naa farahan niwaju ile ẹjọ giga kan ni Harare, fun ẹsun pe wọn lọwọ si iku wolii Shamiso Kanyama, lasiko to n sisẹ iṣegun fun wọn.
Ẹnikan to rojọ tako àwọn eniyan naa nile ẹjọ, Father Zvidzai sọ pe, lootọ ni wolii naa ṣe bẹẹ, sugbọn oun gbiyanju lati da awọn eniyan naa duro nigba ti wọn bu iyẹpẹ diẹ le e lori, àmọ́ wọn ko gbọ.
Oríṣun àwòrán, Zambia Daily Star/Facebook
"Mo kilọ fun awọn ọkunrin naa pe o lewu láti sin eeyan laaye, sugbọn wọn ko gbọ.
Koda, Wolii Kanyama pariwo mọ mi pe mo n di àwọn angẹli oun lọwọ, to si ni ki wọn o tẹsiwaju lati ma a rọ iyẹpẹ sinu iboji naa."
PDP Crisis: Ologbondiyan ní ìjà inú ẹgbẹ́ náà kò sẹ̀yìn ìbò 2023, kìí ṣe nǹkan bàbàrà
Kola Ologbondiyan: PDP ni yóò mú ọmọ Nàíjíríà kúrò lóko ìyà tí wọn wà ní 2023
Iṣẹlẹ  to n waye lọwọ ninu ẹgbẹ People's Democratic Party  (PDP) jẹ nnkan ti o ma n waye ni gbogbo ẹgbẹ paapaa julọ ti o ba ti sunmọ asiko ti idibo miran n bọ.
Eyi ni alaye Kola Ọlọgbọdiyan, to jẹ akọwe ipolongo ẹgbẹ oṣelu PDP nilu Abuja lasiko ifọrọwerọ pẹlu BBC News Yoruba.
Kọla Ologbondiyan ni, gbogbo ọmọ ẹgbẹ naa ni o maa n fẹ ki ipo ẹni ti yoo jẹ alaga ẹgbẹ fun saa miiran bọ sọdọ rẹ, nitori naa gbọmisi-omi-oto to n lọ lọwọ yii yoo bẹ silẹ.
Bakan naa lo fikun pe àwọn to ti jẹ mínísítà tabi gomina tẹlẹ ti parapọ bayii, lati ri daju pe wọn mu alaafia wọ inu ẹgbẹ ati lati ṣe nnkan ti iwe ofin ẹgbẹ sọ laarin osu mẹrin to ku fun ipade gbogboogbo.
O wa pe fun ifẹnuko awọn ọmọ ẹgbẹ lojuna lati mu ki awọn ọmọ Nàìjíría le bọ nínu oko iya ti wọn wa.
Oladuni Giwa-Osagie: Òrùka mẹ́fà ní ọkọ́ mi fi bèèrè láti fẹ́ mi lẹ́ni ọdún 47
O ni ẹgbẹ ko gbọdọ fi han pe aarin awọn ko gun, ki wọn le mọ pe awọn setan lati dije, sùgbọn ọpọ lo n reti lati ṣe nnkan ti yoo han si gbogbo eniyan.
Saaju ọdun 2015, iwa jagidijagan ni ẹgbẹ oṣelu All Progressive Congress (APC) n hu nitori pe wọn fẹ gba ijọba sugbọn gẹgẹ bi ẹgbẹ to ti sinlu ri, ẹgbẹ oṣẹlu PDP mọ ilu tò nitori pe nigba ti wọn wa nipo aye, ko nira fun ara ilu bi asiko yii
Ologbondiyan ni gbogbo nnkan ti ẹgbẹ oselu APC sọ pe awọn yoo se lasiko ti wọn n pologo ibo, lati bi ọdun mẹfa si asiko yii, ko si eyi ti wọn mu ṣẹ.
"Akọwe Ipolongo ẹgbẹ oṣelu PDP ni ""ti a ba ni ki a gbe ẹgbẹ oṣelu APC si ori iwọn, òdo pọnbele ni wọn gba nitori ko si larija aseyọri kankan paapaa julọ lori ọrọ eto aabo."
Ologbọndiyan naa oju ọmọ Naijiria ti la ju pe ki eniyan maa se nnkan to pinu lati ṣe i ko ba ṣe awọn ọmọ Naijiria yoo yọ danu.
Sunday Igboho: Femi Falani ní ẹjọ́ Igboho ní Cotonou ń kọ́ àwọn amòfin Nàíjíríà ní ẹ̀kọ́
O rọ awọn ọdọ ati obinrin lasiko yii lati wa dije nitori pe ẹgbẹ PDP ti fi aaye silẹ lati mu ki nnkan ki o rọrun fun wọn.
O ní ni asiko yii, owo ìkanlẹkun nikan ni PDP n gba bayii lojuna lati mu ki awọn eniyan le darapọ mọ ẹgbẹ, ki wọn si le kopa ninu eto oselu.
Oríṣun àwòrán, PDP Facebook
Ibi ti ọrọ alaga ẹgbẹ oselu Peoples Democratic Party,Uche Secondus yoo ja si ko ti foju han pẹlu bi ipade awọn Gomina ẹgbẹ naa ko se fẹnu ko lori ọrọ rẹ.
Nibi ipade to waye ni Abuja lọjọ Aje lo yẹ ki wọn ti sọ boya Secondus yoo si wa lori ipo tabi ki wọn yọ saaju ipade gbogbogbo ẹgbẹ losu Kọkanla ọdun.
Amọ a gbọ pe ipade igbimọ amusẹya ẹgbẹ naa ko panupọ sọna kan lori ọrọ yii.
Ninu awọn ọmọ igbimọ naa, awọn mẹfa kan ni ko kọwe fipo silẹ tawọn iyoku ko si faramọ, amọ eyi ko tan sibẹ.
Awọn ọmọ ẹgbẹ to wa nile asojusofin naa ko fimọ sọkan lori iyọninipo Secondus.
Sunday Igboho: Femi Falani ní ẹjọ́ Igboho ní Cotonou ń kọ́ àwọn amòfin Nàíjíríà ní ẹ̀kọ́
Bi a ko ba gbagbe lỌ́jọbọ to kọja yii ni igbimọ majẹkobaje ẹgbẹ da si ọrọ awọn ọmọ igbimọ alasẹ ẹgbẹ meje to kọwe fiposilẹ.
Ninu awọn to lewaju ki Secondus fipo silẹ ni Gomina Nyesom Wike ti ipinlẹ Rivers, to ni Secondus n pete pero lati tun dije dupo alaga lasiko ipade apero ẹgbẹ to n bọ lọna ni.
Lẹyin ti wọn se eleyi tan, wọn ba awọn akọroyin sọrọ, ti wọn si ni awọn yoo jiroro laarin ọrọ mẹta lori bi wọn yoo se yanju aawọ to n koju ẹgbẹ naa.
Abalọ ababọ ijiroro yi ni eleyi taa tun gbọ pe wọn ko ti fẹnu ko lori boya Secondus yoo si wa lori oye tabi ko ko ẹru rẹ kuro gẹgẹ bi alaga ẹgbẹ.
Ni ọjọ Aje yii kanna, awọn Gomina kan ti wọn wa lẹyin Secondus ti Aminu Waziri Tambuwal Gomina ipinlẹ Sokoto lewaju wọn, si duro gbọin lẹyin Secondus pe ko pari saa rẹ gẹgẹ bi alaga ẹgbẹ.
Olawale Dada: Igbá bárà kọ́ ló kàn, àwa náà n ṣoríire láyé pẹ̀lú ìpèníjà 'Cerebral Palsy'
Tambuwal, lasiko to n ba awọn akọroyn sọrọ ni awọn yoo si tẹsiwaju pẹlu ipade naa, tawọn yoo si yanju ọrọ ni tunbi n nubi.
Nibi ti gbogbo eleyi ti n waye naa ni awọn ọmọ ẹgbẹ yii kan ti se iwọde pe dandan ni ki Secondus fipo silẹ gẹgẹ bi alaga.
Niwaju olu ileesẹ ẹgbẹ naa tii se Wadata Plaza, ni iwọde ifẹhonuhan yii ti waye.
Labẹ asia ikọ ti wọn pe orukọ rẹ ni Save PDP group mii, wọn ti ko ara wọn jọ pe ki Secondus fipo silẹ nitori pe ko kaju osunwọn.
Saaju ka to sọ nkan ti Secondus naa sọ, o tọ ka fi lelẹ pe Gomina Seriake Dickson tipinlẹ Bayelsa wa lara awọn to duro bi ike lẹyin Secondus.
Bẹẹ naa ni awọn Gomina kan ninu ẹgbẹ ni dandan, ki Secondus pari saa rẹ gẹgẹ bi alaga ati pe ipade gbogbo gboo ẹgbẹ nikan lo lagbara lati yọ ni ipo.
Ipade gbogboogbo yii lawọn to fẹ yọ Secondus lawọn ko le duro de nitori Secondus yoo fidi ẹsẹ rẹ mulẹ nipo alaga.
Ninu atẹjade tiẹ, Secondus sọ pe oun ko se nkankan to yẹ ki wọn fi yọ kuro nipo alaga.
O fi ọrọ yi sita ninu atẹjade to pe akori rẹ ni ''Idi ti mi o le fi fipo silẹ''
Ike Abonyi to jẹ agbẹnusọ rẹ lo fi sita lọjọ Aje ni Abuja.
Ni soki nkan ti Secondus sọ ninu atẹjade naa ni pe, ki awọn eeyan perete to n pe fun ifiposilẹ rẹ jade sita lati wa sọ fun araye idi ti wọn fi fẹ ki oun si ipo silẹ.
Ipade awọn Gomina si n tẹsiwaju loni tii se ọjọ Isẹgun.
T. B Joshua: Chris Okotie ní wòlíì èké, onídán àti onítànjẹ tó ń fi ara rẹ̀ wé Jesu ní Joshua
Pasitọ agba fun ijọ Household of God, Chris Okotie ti sapejuwe wolii TB Joshua gẹgẹ bi opurọ, wolii eke ati onidan to n fi bibeeli lu awọn eeyan ni gbajuẹ.
Oloogbe TB Joshua, ẹni to fẹsun yii kan ni oludasilẹ ijọ Synagogue Church of All Nations (SCOAN), to jade laye lọjọ Kẹfa osu Kẹfa ọdun 2021.
Ninu fọnran fidio kan to fi sita loju opo Youtube lọjọ Aiku, ni Chris Okotie ti sọ ọrọ yi nigba to n se atupalẹ iru onigbagbọ ti TB Joshua jẹ nigba aye rẹ.
Bẹẹ naa lo fẹsun kan Joshua pe wolii eke to n fi ara rẹ we Jesu ni.
Ki ni ododo nipa TB Joshua? Ta nii se? Njẹ ẹlẹsin Kristẹni ni tabi ọmọ lẹyin ẹsin shamanism? Njẹ ọmọlẹyin Jesu Kristi Oluwa wa ni? Tabi gbarọgudu alarinka?
TB Joshua: Ṣe ni ọ̀pọ̀ èèyàn ń wa ẹkún mu torí ikú òjijì tó pa wòlíì
Se wolii tootọ ni abi awọn eeyan si ọrọ rẹ gbọ?Tabi ka si ni sekusẹyẹ to sa sabẹ ẹsin nii se?
Diẹ ree ninu awọn ibeere ti Pasitọ Chris Okotie fi sita ninu fidio naa.
O tẹsiwaju pe ''Joshua ko pe ara rẹ ni Aposteli tabi Olukọni. Ko tiẹ pe ara rẹ ni Pasitọ nitori to ba pe ara rẹ lorukọ mi to yatọ si wolii, ko kunju osunwọn awọn orukọ wọn yi''
O ni idi ree ti ko fi le yi orukọ pada.
Okotie sọ pe ''O gbọdọ duro ti ipo to gbe fun ara rẹ yii ni. Onpidan to pe ara rẹ ni wolii nii se ati pe wolii eke ni.
Ninu fọnran yii bakan naa Okotie sọ pe Joshua n polongo igbagbọ to gbe ọla ati ipo bi Ọlọrun fun ara rẹ.
Bẹẹ ni o tun sọ pe Wolii Joshua a maa tan awọn eeyan jẹ nipa sise isẹ aanu, ki o ba le dabi pe iwa ati ise rẹ wa ni ibamu pẹlu ohun ti bibeeli sọ.
Ohun to fa ki Okotie maa sọ iru ọrọ bayi nipa Joshua paapa lẹyin iku rẹ ko ye wa si.
'Nínú ìran, Olúwa sọ fún mi pé èmi ni màá tẹ̀síwájú nínú iṣẹ́ ìráńṣẹ́ Wòlìí TB Joshua, kàyéfì ti ń ṣẹlẹ̀ nínú ìjọ mi báyìí'
Amọ lati igba ti wolii Joshua ti papoda ni Okotie ati awọn pasitọ mii ti n bẹnu atẹ lu.
Wolii TB Joshua nigba aye rẹ jẹ oniwaasu, ti ko fi taratara ba awọn akẹgbẹ rẹ mii ni Naijiria se.
Lọpọ igba lawọn nkan mii to maa n sọ ninu iwaasu rẹ maa n da awuyewuye silẹ.
Titi di igba ta fi n se akojọ iroyin yii, a ko gbọ esi kankan lati ile ijọsin TB Joshua tabi mọlẹbi rẹ lai tako ohun ti Okotie n sọ.
Saaju ki o to di ẹni to n polongo ẹsin, olorin takasufe ni Chris Okotie jẹ.
O tun fi igba kan sọ pe oun gbọ ipe lati di aarẹ orileede Naijiria.
Igbiyanju rẹ lati dije dupo aarẹ ja si pabo ninu idibo eyi to kopa lẹẹmẹta ọtọọtọ ni ọdun 2003,2007 ati 2011 labẹ asia ẹgbẹ oselu Fresh Party.
TB Joshua Burial: Wolii Synagogue SOAN jẹ́ Akàndá ẹ̀dá- Oba Enitan Ogunwusi, Ooni Ile Ife
Tope Ajogbajesu: Mọ̀lẹ́bí kan ní orin ikú ọdún yìí fò mí ru ní Tope kọ láàrin ọ̀sẹ̀ tó kú
Yoruba ni iku kii jẹ ki a dagbere fun ẹnikeji ẹni, ko to maa mu ni lọ.
Bẹẹ ni ọrọ ri pẹlu iku gbajumọ akọrin ẹmi nni, Tope Ajogbajesu, ẹni ti yoo wọ kaa ilẹ sun lonii.
BBC Yoruba se abẹwo si ile oloogbe naa, nibi ta ti ba aya rẹ, ibeji rẹ ati awọn mọlẹbi rẹ miran sọrọ lori ipa ti iku rẹ yoo ni lara wọn.
Aya oloogbe naa ni aisan ọgbẹ inu, taa mọ si Ulcer lo mu Tope ni oru Ọjọbọ, to si ku ni ọjọ Ẹti, bẹẹ lo yẹ ko gba ami ẹyẹ kan ni ọjọ Sunday.
O ni aisan ọgbẹ inu naa ti n yọ ọkọ oun lẹnu, ọjọ ti pẹ amọ oun dupẹ pe inu ifẹ Kristi ni ọkọ oun ku si, ti ko si jẹ ki Jesu bọ lọwọ oun.
Nigba toun naa n sọrọ, ikeji Tope Ajogbajesu ni oro ati ọgbẹ ọkan nla ni iku ẹnikeji oun fun oun nitori inu ifẹ nla ni awọn dijọ n gbe.
Mọlẹbi kan wa salaye pe isin kan ti Tope lọ ni ọsẹ to ku lo ti n kọrin pe iku ọdun yii fo oun ru laimọ pe ọsẹ naa ni yoo ku.
Marburg virus: Wo ohun tó yẹ ko mọ̀ nípa àrùn aṣekúpani tuntun lágbàáyé
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Bi ajakalẹ arun coronavirus ti n ba ilẹ Afirika finra lọwọ, arun mi ti wọn n pe ni Marburg tun wọle de.
Awọn oṣiṣẹ eleto ilera lorilẹede Guinea ti fidi rẹ mulẹ pe arun Margurg ti gba orilẹede naa wọ apa iwọ oorun Afirika.
Wọn ni ẹbi kan naa ni arun Marburg ati Ebola to ti ṣọṣẹ sẹyin l'Afirika jẹ amọ arun Margurg tete maa n tan kalẹ bi ina inu ọyẹ.
Ajọ eleto ilera lagbaaye, WHO ni kokoro arun yii ko ṣe wo loju rara nitori bi o ti maa n ṣọṣẹ.
Arun Marburg ni a gbọ pe o maa n ran awọn eeyan lati ara ẹyẹ adan to n jẹ eso.
Sunday Igboho: Femi Falani ní ẹjọ́ Igboho ní Cotonou ń kọ́ àwọn amòfin Nàíjíríà ní ẹ̀kọ́
Arun Marburg maa n ran lati eeyan kan si ẹlomiran nipa omi ara bii oogun, itọ tabi ikun.
Arun yii maa n fa ailera to lagbara, iba, koda o maa n jẹ ki ẹjẹ jade lara ẹlomiran.
Ayẹwo ẹjọ ti wọn ṣe fun ẹnikan to ku nile iwosan lorilẹede Guinea fihan pe arun Marburg lo ṣekupa ẹni naa.
Dokita ajọ WHO kan, Matshidiso Moeti ṣalaye pe arun Marburg lagbara lati tan kalẹ kaakiri debi to jina.
Iwadii n lọ lọwọ lati mọ awọn eeyan ti ẹni ti arun Marburg yii ni ibaṣepọ pẹlu ki o to dagbere faye.
Ijọba orilẹede Guinea ti ṣe itaniji awọn ilana ati dẹkun Ebola nibẹ lati le koju arun Marburg.
Igi Ọ̀pẹ abàmì tó dá ní orí 42 l'Ekiti rèé o, 'bí mo ṣe ríi l'orí mi ń dìde fììì'
Mínísítà féré ìdárayá, Sunday Dare sọ̀rọ̀ lórí àwọn ìṣẹ̀lẹ̀ ìdójútini tó wáyé ni Tokyo 2020 Olympics
Oríṣun àwòrán, olympics.com
Minisita fere idaraya ati idagbasoke awọn ọdọ lorilẹede Naijiria, Sunday Dare ti tọrọ aforijin lọwọ awọn ọmọ Naijiria.
O ni oun bebe fun idojuti to de ba orukọ orilẹede Naijiria ninu eyi ti awọn elere idaraya kan to n ṣoju Naijiria nibi ti wọn ti n fọwọ fọ aṣọ imuṣẹrẹ idaraya, iyẹn Jẹsi wọn.
Sunday Dare ti ọpọ ọmọ Naijiria ti bu ẹnu atẹ lu fun ohun iwọsi to waye ni ibi idije Tokyo 2020 Olympics to ṣẹṣẹ pari.
Ami ẹyẹ meji ni Naijiria gba nibi idije naa, bi o til.ẹ jẹ pe ohun ni eyi to dara julọ fun Naijiria laarin ọdun mẹtala, sibẹ ọpọ onwoye ere idaraya ni Naijiria ni o yẹ ki orilẹede Naijiria ṣe daradara ju eyi lọ.
Oniruuru kudiẹkudiẹ ati aikun oju iwọn awọn alakoso ere idaraya ni Naijiria lo waye.
Akọkọ ni bi ajọ ere idaraya lagbaya ṣe yọ ọwọ kilanko awọn elere idaraya mẹwaa lati Naijiria lawo idije naa lẹyin ti awọn alakoso ere idaraya ni
Naijiria kuna lati ṣe awọn ohun kan to yẹ ki wọn ṣe lori awọn oludije naa.
Sunday Dare ni oun tiraka pẹlu igbesẹ gbogbo to yẹ nigba ti iroyin iṣẹlẹ naa de ọdọ oun ṣugbọn aṣọ ko ba ọmọyẹ mọ nigba naa.
Tope Ajogbajesu: Mọ̀lẹ́bí kan ní orin ikú ọdún yìí fò mí ru ní Tope kọ láàrin ọ̀sẹ̀ tó kú
Minisita fere idaraya ṣalaye ninu atẹjade rẹ kan pe awọn eeyan kan wa ti wọn pete ati gbin wahala ati idarudapọ.
Sugbọn awọn oludije to ṣoju fun Naijiria ko lẹtọ si itiju ti oju wọn ri nitori pe gbogbo igbaradi to yẹ ni wọn ṣe lati yege ninu idije Tokyo 2020 Olympics naa.
Oríṣun àwòrán, olympics.com
O ni Naijiria yoo gbe ajọ kan kalẹ ti yoo maa ṣe ayẹwo gbogbo to ba yẹ fun awọn oludije ati elere idaraya gbogbo ni Naijiria.
O ni eyi yoo je ki wọn lee maa la ilana gbogbo ti ajọ ayẹwo agbaye WADA kọja.
Bakan naa ni Minisita Sunday Dare tun kọminu lori iṣẹẹ aito awọn aṣọ ere idaraya fawọn oludije.
Eleyii to ṣokunfa bi ọkan lara awọn oludije naa ṣe ni lati maa fọwọ fọ aṣọ wọn.
Sunday Igboho: Femi Falani ní ẹjọ́ Igboho ní Cotonou ń kọ́ àwọn amòfin Nàíjíríà ní ẹ̀kọ́
O ni gbogbo awọn ajọ ere idaraya gbogbo to n kopa ni idije Olympics naa ni wọn ti fun ni ohun gbogbo to yẹ fun ipese awọn ohun eelo fawọn oludije wọn ninu eyi ti aṣọ ere idaraya wọn gbogbo wa.
O fi kun un pe wọn ti paṣẹ fun ajọ ere idaraya oludije ti ọrọ naa kan lati pese alaye to yẹ lori ọrs aṣọ ereidaraya naa.
New York Governor resign: Gómìnà New York kọ̀wé fipò sílẹ̀ látàrí pé wọn ní ó hùwà kò tó sí àwọn obìnrin kan
Lori awuyewuye to ti n ja ranyinranyin lori ayelujara lori oro gomina Andrew Cuomo ni iroyin mii ti jade.
Opo awon obinrin kan ni won koko jade sita pe Gomina Andrew Cuomo to n tuko ipinle New York ni orile-ede America n fowo pa awon lara lona aito.
Gomina Andrew Cuomo ni won fi esun kan pe o n hùwà lọ́nà tí kò tọ̀nà sì àwọn obinrin naa.
Gomina yii wa soro sita pe oun moomo kuro nipo lasiko yii ki ise ilu le tesiwaju ni ipinle New York ni.
Loni ojo Isegun ni Gomina Andrew ni ikowefiposile naa yoo bere lojo merinla si oni.
Agbara isakoso ipinle New York yoo bo sowo Ogagun Kathy Hochul.
Ogbeni Cuomo to je eni odun metalelogota ni enu ti n kun pe ko kowe fipo sile lati ose to koja.
Koda, Aare Joe Biden gan an gba a ni moran pe ko se bée.
Okan ninu awon obinrin mokanla to ni Gomina huwa ko to si awon jade sita lojo Aje fun igba akoko.
Tope Ajogbajesu: Mọ̀lẹ́bí kan ní orin ikú ọdún yìí fò mí ru ní Tope kọ láàrin ọ̀sẹ̀ tó kú
Brittany Commisso to je akowe amugbalegbe gomina Andrew Cuomo lo soro lori amohunmaworan to n beere fun idajo ododo lori esun naa.
Sugbon gomina Andrew ni iro ni won n pa mo oun ki o to kowe fipo sile
Rochas Okorocha : Wo ìdí tí ìlú Iselu kò ṣe fi Rochas Okorocha joyè mọ́
Oríṣun àwòrán, Rochas okorocha
Oye to yẹ ko bọ si ọwọ Senetọ Rochas Okorocha, ni ilu kan nipinlẹ Ogun, ti bọ mọ lọwọ.
Ọjọ kinni, oṣu Keje, ọdun 2021,ni ilu Iselu nipinlẹ Ogun kọ lẹta si Okorocha, to tun ti jẹ gomina ipinlẹ Imo ri pe, àwọn fẹ ẹ fi jẹ oye.
Sugbọn ni ṣe ni ọba ilu naa, Oba Ebenezer Akintunde Akinyemi, Eselu ti Òṣèlú, tún kọ lẹta miran si Senetọ Okorocha lọjọ pe awọn ko fi jẹ òye mọ, ati pe ayẹyẹ iwuye ko ni i waye mọ.
Ifinijoye naa ni i ba sọ Okorocha di Ọtunba Asọludẹrọ ti ilu Iselu, nijọba ibilẹ Yewa, nipinlẹ Ogun.
Ọba Akinyemi sọ pe igbesẹ oun waye nitori ki alaafia ati isọkan le wa.
Oríṣun àwòrán, Eselu ti ilu iselu
Botilẹjẹ pe ko sọ nkan pato to mu ko yi eero rẹ padà, Ọba Akinyemi sọ ninu lẹta tuntun naa pe kii ṣe pe awọn korira Okorocha.
Ọjọ kọkandinlogun, oṣu Kẹjọ, ọdun 2021, lo yẹ ki iwuye naa o waye.
Titi di akoko ti a gbe iroyin yii jáde, Senetọ Okorocha ko ti i sọ ohunkóhun lori igbesẹ Eselu.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Idi ti wọn ko fi fi Senetọ Rochas Okorocha joye mọ ko han siwa, sugbọn ninu ọrọ to ba BBC sọ, Araba ilu Osogbo, Oloye Ifayemi Elebuibon sọ pe igbesẹ naa ko jẹ tuntun.
O ni wọn le má fi eniyan joye mọ, wọn si tun le rọ eniyan loye, nitori iroyin ìwà buburu.
O sọ pe o ṣe e ṣe ki wọn o ti gbọ́ iroyin ti ko dara nipa Okorocha lo mu wọn ṣe bẹ ẹ.
Nigeria diplomat manhandled in Indonesia: Orílẹ̀èdè Nàìjíríà ti sọ àwọn ìgbésẹ̀ tó fẹ́ gbé lórí aṣojú ìjọba Nàìjíríà tí wọ́n kọlù ní Jakarta
Oríṣun àwòrán, Ministry of foreign affairs Nigeria
Ijọba Naijiria ti ranṣẹ pe aṣoju rẹ ni Indonesia wale fun ijiroro lori bi awọn oṣiṣẹ wọlewọde orilẹede naa kan ṣe fun oṣiṣẹ ileeṣẹ aṣoju ijọba Naijiria lọrun mọ inu ọkọ
Minista fọrọ ilẹ Okeere ni Naijiria , Geoffery Onyeama ni awọn yoo gbe ajọṣepọ pẹlu Indonesia yẹwo lori ọrọ naa nitoripe ohun to ku diẹ kaa to ni.
Ninu ifọrọwerọ to ṣe pẹlu awọn akọroyin lọjọ Iṣẹgun nilu Abuja, Minisita fọrọ ilẹ okeere Geoffery Onyeama ṣalaye pe ijsba orilẹede Naijiria ko ni fi aye gba orilẹede yoowu lagbaye lati hu iwa kotọ fun ọmọ Naijiria yoowu.
O ni alaye ti aṣoju ijọba orilẹede Indonesia ṣe fun ijsba Naijiria tubọ mu ki ero ijọba Naijiria mulẹ sii pe ko yẹ ki irufẹ ihuwasi bẹẹ waye si ọmọ Naijiria yala oṣiṣẹ ileeṣẹ aṣoju ijọba tabi mọ Naijiria kankan.
Oríṣun àwòrán, Ministry of foreign affairs nigeria
Fidio kan to gbaye kan ṣe afihan bi awọn oṣiṣẹ ileeṣẹ wọlewọde ilẹ Indonesia ṣe hu iwa aitọ si oṣiṣẹ ileeṣẹ aṣoju ijsba Naijiria kan nibẹ.
Minisita fọrọ ilẹ okeere naa ni, bi o tilẹ jẹ pe ijọba orilẹede Indonesia ti tọrọ aforiji lori iwa kotọ naa, orilẹede Naijiria n fẹ ki wọn gbe igbesẹ ibawi to yẹ lori awọn oṣiṣẹ ileeṣẹ wọlewọde naa.
Iroyin sọ pe oṣiṣẹ ileeṣẹ aṣoju ijọba Naijirian naa n lọ ra ọja nile itaja nla kan ni ilu Jakarta, tii ṣe olu ilu orilẹede naa.
Oladuni Giwa-Osagie: Òrùka mẹ́fà ní ọkọ́ mi fi bèèrè láti fẹ́ mi lẹ́ni ọdún 47
Aropin ni ti eniyan amọ ilẹ aanu Oluwa kii su.
Bi ọrọ arabinrin Oladuni Giwa-Osagie se ri ree, ẹni to pe ẹni ọdun mẹtadinlaadọta ko to ni ade ori, to si bi akọbi rẹ nigba to ku diẹ ko pe ẹni aadọta ọdun.
Nigba to n ba BBC Yoruba sọrọ lori awọn ipo itiju, ẹgan, ibanujẹ ọkan ati ijakulẹ to ba a lasiko to fi n wa ọkọ, Oladunni ni ẹkun ni oun maa fi n se ounjẹ lojoojumọ.
O salaye pe wọn maa n fi ọkọ bu oun nibi isẹ, ti wọn si maa n lero pe oun ti se iranu ati isekuse ni oun ko se bimọ.
Bakan naa lo salaye pe sna ti wọn fi maa n ba oun sọrọ laarin ẹbi gan ko bu ọwọ fun oun gẹgẹ bii ti awọn to ni ọkọ, eyi to maa n pa oun lẹkun.
Oladuni ni oun ti lọ si ọpọ ile aladura, ti oju ohun si ti ri orisirisi, koda, wọn gba oun nimọran lati ls fẹ ẹni to ti ni iyawo nile amọ oun ko fẹ da ile onile ru.
O ni akoko kan tiẹ wa ti oun gbiyanju lati ra atọ ọkunrin ki oun le da amọ bi amọ oun pada tun ero oun pa ni.
Nigba to n salaye ayọ ọkan to ni nigba to ni ọkọ, Oladuni ni oruka mẹfa ni ọkọ oun fi beere lati fẹ oun, ti oun si n paarọ wọn lojoojumọ.
Nigba toun naa n sọrọ, ọkọ rẹ, Oladapo Giwa-Osagie salaye pe iru obinrin ti oun ti n wa lati ọjọ pipẹ ni Oladuni, inu oun ko si bajẹ ri lati ọjọ ti oun ti fẹ.
Awọn mejeeji wa gba awọn to n wa ọkọ ati aya nimọran lati duro ti Ọlọrun, ki wsn ma si ba ara wọn jẹ tabi lọ da ile onile ru tori pe wọn fẹ bimọ.
Àwọn ìtàn mánigbàgbé tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí:
Yoruba Nation: Akintoye àti èèyàn 1m fẹ́ kí àjọ UN tú ìwé òfin Nàìjíríà ká
Oríṣun àwòrán, Ilana Omo Oodua
Aarẹ ẹgbẹ Ilana Ọmọ Oodua, Ọjọgbọn Banji Akitoye yoo ṣaaju miliọnu kan eeyan, ti yoo ṣoju awọn ẹya to n beere fun iyapa lati ara Naijria, NINAS.
Ẹgbẹ naa n lọ si apejọ apapọ ajọ iṣọkan agbaye, UN loṣu kẹsan ọdun 2021 lati beere agbekalẹ ibo tawọn eeyan yoo fi sọ ero bo ya wọn fẹ yapa kuro lara Naijiria tabi wọn fẹ tẹsiwaju.
Ẹgbẹ Ilana Ọmọ Oodua lo fidi ọrọ yii mulẹ ninu atẹjade ti akọwe ẹgbẹ naa, Maxwell Adeleye fi sita lọjọ Iṣẹgun.
Ẹgbẹ NINAS yoo tun sọ fun apejọ UN lati tu iwe ofin Naijiria ọdun 1999 ka.
Awọn olori oniruuru ẹgbẹ awọn ẹya to n beere fun iyapa lati ara Naijiria ti wọn wa lati apa Guusu ati arin gbungbun Naijiria, ti kọkọ fẹnuko ninu ipade lọjọ kẹrindinlogun oṣu kejila ọdun 2020.
Ninu ipade yii naa wọn tun ti fẹnu ko pe ajọ UN gbọdọ fagile iwe ofin Naijiria ọdun 1999.
Sunday Igboho: Femi Falani ní ẹjọ́ Igboho ní Cotonou ń kọ́ àwọn amòfin Nàíjíríà ní ẹ̀kọ́
Apejọ ajọ iṣọkan agbaye UN yoo waye lati ọjọ kẹrinla si ọjọ kọkanlelogun oṣu kẹsan an ọdun 2021 yii.
Atẹjade naa sọ pe ẹgbẹ NINAS yoo maa kepe gbogbo awọn ẹya to wa lati apa Guusu ati aringbungbun Naijiria lati gbaruku ti ipe fun idasilẹ orilẹede ẹya wọn lara Naijiria.
Ẹgbẹ NINAS yoo tun beere nibi apejọ ajọ UN, lati fi ọmọogun apẹtu sija ranṣẹ si Naijiria lati daabo bo awọn eeyan apa Guusu Naijiria lọwọ awọn Fulani daran daran ati Boko Haram pẹlu ISIS to n pa wọn lojoojumọ.
Ọjọgbọn Akintoye, Ọjọgbọn Yusuf Turaki, akọwe agba NINAS, agbẹjọro Tony Nnadi, ati kọmiṣọnna akọkọ fun eto ẹkọ to tun jẹ alaga gbogbogbo ẹgbẹ Ilana Ọmọ Oodua, Ọjọgbọn Wale Adeniran lo buwọlu atẹjade naa.
Oladuni Giwa-Osagie: Òrùka mẹ́fà ní ọkọ́ mi fi bèèrè láti fẹ́ mi lẹ́ni ọdún 47
Lori iroyin kan to sọrọ nipa ẹgbẹ kan to n pe fun ki wọn fofin de ẹgbẹ Ilana Ọmọ Oodua ki wọn le maa lanfaani lati pe fun ohun kohun niwaju apẹjọ ajọ UN, atẹjade naa sọ pe lorukọ ẹgbẹ NINAS yoo fi fẹhonuhan nibi apjọ naa kii ṣe lorukọ ẹgbẹ Ilana Omo Oodua.
Gbogbo awọn ẹya to wa lati apa Guusu ati aringbungbun Naijiria to n gbe nilẹ Amẹrika ni ẹgbẹ NINAS ti kepe lati darapọ mọ wọn loṣu kẹsan ti wọn ba n ṣe ifẹhonuhan naa niluu New York.
Lizzy Anjorin: N kò fẹ́ Aláàfin o, àmọ́ ó ní ń kò gbọdọ̀ wá sí ààfin láìmú ọkọ wá
Oríṣun àwòrán, Instagram/Lizzy Anjorin
Alhaja Lizzy Anjọnrin Lawal ti ọpọ maa n pe mi ibu owo Mama Florida, tun ti ja gudugbẹ ọrọ lulẹ lori irin ajo aye rẹ, ki o to ṣe igbeyawo.
Ninu fọnran kan to gbe sori ayelujara, Lizzy ni ''gbogbo obinrin ni aṣẹwo, amọ, awọn ọkunrin ṣẹwo ju awọn obinrin lọ.''
Ṣugbọn Lizzy fikun ọrọ rẹ pe, awọn onitiata papa julọ awọn obinrin ninu wọn, lo ṣe ọmọluabi ju.
Lizzy ṣalaye pe ''nigba naa lọun, Mr Lawal maa n fun mi lowo, o dẹ maa n dun mọ mi gan an.
Mr Lawal lo kọkọ gba ile fun mi niluu Eko nitori mi o nile nigba naa.
Esabod, Sunday Igboho: Kò burú bí Igboho ṣe wà lẹ́wọ̀n báyìí,ọ̀rọ̀ rẹ̀ dàbí i ti aláboyún
Nigba to to asiko fun mi lati yan, gomina ati ọba alaye wa lara awọn to kọ ẹnu ifẹ si mi, ṣugbọn kii ṣe Alaafin o.
Ẹ tiẹ gbọ na, ẹyin ti ẹ ni mo n fẹ Alaafin, bawo ni mo ti maa ‘handle’ baba?
Alaafin gan an lo sọ fun mi pe ti n ko ba ti mu ọkọ wa, n ko gbọdọ de aafin mọ.
Mo jẹ obinrin to jẹ pe awọn ọkunrin maa n nifẹ mi gan an.
Mo fẹ ra ''sperm'' lati bimọ nipa ilana ''surrogate'' tori ko si ohun to buru nibẹ.
Ṣugbọn ayẹwo fihan pe ọjọ igbeyawo mi gan an ni mo loyun.
Mi o kii n fẹ ki eeyan ṣe awọn nkan ti mi o le ṣe fun eeyan fun mi.
Bi a ti ni kọmiṣọnna, minisita atawọn ipo mii, ni emi naa ni ipo mi lawujọ ti ẹnikẹni ko mọ.
Iru awọn ọrẹ ti mo n ba a rin kii ṣe awọn ọrẹ ti ẹ le maa ri kaakiri.
Ti a ba ti ja tan, kiakia naa ni a maa ti ba ara wa ṣere pada, e wo ni ki a ku si idi ija?
Oladuni Giwa-Osagie: Òrùka mẹ́fà ní ọkọ́ mi fi bèèrè láti fẹ́ mi lẹ́ni ọdún 47
Iwọ lẹnu ohun to ba wu ẹlẹnu lo le fi ẹnu rẹ sọ nipa mi.
Ti temi ni pe ti ko ba ti si wahala nile mi atawọn ti a n jọ n gbe, ti arin emi ati Ọlọrun mi si dara, o ti tẹ mi lọrun.
Ninu ọrọ ọkọ rẹ, Alhaji Lateef Lawal Adegboyega sọ pe Lizzy ko ni aṣiri kankan niwaju oun.
O ni nigba ti oun pade Lizzy fun igba akọkọ, oun ko le kọ ẹnu si i tori oju n ti oun.
''Lẹyin ti a pade ara wa ti a si fi ara wa silẹ, mi o fẹ iyawo kankan titi di igba ti a fi pade ara wa.
Ṣugbọn mo ni awọn ti a jọ maa n gbe si ara wa lẹnu lasan an ni.
Igba ti a maa fi fẹ ara wa pada, ko si iyawo kankan lọdọ mi nigba naa.
Ọpọ lo n sọ pe iyawo mi ti fi ile ọmọ rẹ ṣe oogun owo ṣaaju igbeyawo wa.
Ọrẹ mi kan gan an beere lọwọ mi lọjọ keji igbeyawo wa pe se iyawo mi si le bimọ.
Iyawo mi lo jẹ, ko baa lowo ju Alakija lọ, ko tun ni ju mi lọ, o gbọdọ gbọ ọrọ si mi lẹnu.
Taye Osinowo Olaosebikafi Iyabo Ojo, Mide Martins, Jaye Kuti, Afeez Owo àtàwọn míì dárà ap
Namibia Himba Women: Èéfín iná àti amọ̀ ni àwọn obìnrin yìí fi n ṣe ara lóge
Ara ọtọ ni awọn eniyan ẹ̀yà Himba lorilẹ-ede Namibia, nitori àṣà ati ìṣe wọn to yatọ si ti gbogbo aye.
Ẹya yii jẹ gbajugbaja ni Namibia, ti wọn si ma n pe wọn ni 'red people', eyi to tumọ si awọn eniyan pupa.
Awọn eeyan ẹ̀yà yii to ẹgbẹrun lọna aadọta, bẹ́ẹ̀ si ni awọn kan gbagbọ pe awọn obinrin wọn lo rẹwà julọ ni Africa.
Bo tilẹ jẹ pe awọn obinrin naa kii wẹ, ti wọn kii si fi omi ṣan ọwọ wọn, sibẹ wọn ko burẹwa.
Nise ni àwọn obinrin naa ma n fi èéfín ina wẹ lati le tun ara ṣe. Bii ti báwo?
Lojoojumọ, awọn obinrin naa ma n ko eedu to ni ina lara sinu ikoko, wọn o si da oriṣiriṣi ewe ati egbo igi sinu rẹ.
Oladuni Giwa-Osagie: Òrùka mẹ́fà ní ọkọ́ mi fi bèèrè láti fẹ́ mi lẹ́ni ọdún 47
Ti eefin ba ti n rú, wọn yoo tẹ ara wọn ba sori ikoko naa. Eefin to ba n jade yoo mu ki wọn o laagun, ti o n fọ ara wọn.
Lati wẹ gbogbo ara, wọn o fi aṣọ nla bo ara wọn, ki eefin ba a le duro si ara rẹ fun oogun.
Yatọ si eyi, ẹẹmeji ni wọn ma n fi ori ati amọ pupa pa ara wọn nitori oorun ati kokoro.
Awọn eniyan Himba gbagbọ pe àwọ̀ pupa jẹ àpẹẹrẹ ilẹ ati ẹ̀jẹ̀.
Aṣọ penpe ti wọn fi awọ ewurẹ ṣe ni awọn obinrin yii ma n wọ, ti wọn si ma n fi amọ pupa kun irun ori wọn.
Idi ti awọn eniyan naa kii se fi omi wẹ nipe, oju ọjọ lágbára pupọ lagbegbe wọn.
Inu aginju ni wọn n gbe, eyi to mu ko nira lati ri omi lo.
Ko tan sibẹ o. Àwọn obinrin yii tun ma n fi ibalopọ ọ̀fẹ́ ṣe alejo, ti ọpọ wọn si maa n fi ara silẹ lai wọ asọ to bo ọmu wọn.
Lojoojumọ si ni awọn eniyan ẹ̀yà yii n sisẹ karakara lati daabo bo àṣà wọn.
Goriola Hassan: Ilé Aṣòfin Ogun ní kí Hassan wá dàhùn ẹ̀sùn tí ẹgbẹ́ ọmọbíbí ìlú rẹ̀ fi kàn-án lórí ọba tó jẹ
Oríṣun àwòrán, Content
Gbajumọ osere tiata tẹlẹ to ti wa di ọba bayii, Goriola Hassan lo ti n ni ede aiyede pẹlu ile asofin ipinlẹ Ogun nitori oye ọba to jẹ.
Ile asofin ipinlẹ Ogun si ti wa pasẹ pe oun yoo ni ki awọn ọlọpaa gbe Goriola si ahamọ ni, to ba tun fi pe ara rẹ ni ọba ilu Imobi, to wa nijọba ibilẹ Ila-Oorun Ijebu nipinlẹ naa.
Ọjọ Isẹgun, ọjọ Kọkanla osu Kẹjọ ọdun 2021 ni ile asofin naa fi ikede yii sita, to si tun pasẹ pe ki Goriola yọju siwaju igbimọ ile to wa fun ọrọ oye jijẹ.
Gẹgẹ bi iwe iroyin Daily Post ti salaye, ile wa ni ti ọba naa ba fi faake kọri lati yọju siwaju igbimọ ile naa titi di ọjọ Kẹtadinlogun osu Kẹjọ ọdun 2021, gboro yoo gbe.
Alaga igbimọ ile to wa fun ọrọ oye jijẹ naa, Asofin Bolanle Ajayi ni ile ti fi iwe kan ransẹ saaju lati pe Goriola Hassan pe ko yọju siwaju wọn amọ to kọ lai yọju.
Oladuni Giwa-Osagie: Òrùka mẹ́fà ní ọkọ́ mi fi bèèrè láti fẹ́ mi lẹ́ni ọdún 47
O wa fun osere tiata tẹlẹ naa ni anfaani lati pada yọju siwaju igbimọ naa lọjọ isẹgun ọsẹ to n bọ, tii se ọjọ Kẹtadinlogun osu Kẹjọ, bibẹẹkọ, wọn yoo gbe janto.
Ajayi ni isọri awọn eeyan kan ti wọn pe ara wọn ni ẹgbẹ ọmọ bibi ilu Imobi lo kọwe ẹsun wa sile asofin nipa ọba naa, ti ile si fẹ fun ni anfaani lati wa sọ tẹnu rẹ.
O ni iwe ẹsun naa lo da lori bi Goriola Hassan se n pe ara rẹ ni ọba ilu Imobi-Ijebu.
Ile asofin ipinlẹ Ogun ti wa kesi Goriola lati jawọ ninu pipe ara rẹ ni ọba ilu Imobi-Ijebu.
Bakan naa ni wọn pasẹ fun Goriola lati yọju siwaju ile pẹlu awọn baalẹ mẹrindinlogoji to wa ni agbegbe rẹ.
Igbesẹ naa ni wọn sọ pe yoo fun awọn asofin ọhun ni anfaani lati wa ojutu titi laelae                                                                    si aawọ ọba jijẹ to n ba agbegbe naa finra.
Ajayi wa kede pe ti Goriola Hassan ba fi kọ lai yọju, ile yoo pasẹ fun ileesẹ ọlọpaa lati lọ gbe gbogbo awọn ti wọn ni ko ysju naa, paapaa Hassan.
Taye Osinowo Olaosebikafi Iyabo Ojo, Mide Martins, Jaye Kuti, Afeez Owo àtàwọn míì dárà ap
Yoruba Nation: Abdulsalam Abubakar sọ ìdí tí kò fi ṣeéṣe láti pín Nàíjíríà sí wẹ́wẹ́
Asaaju ijọba ologun tẹlẹ, Ajagunfẹyinti Abubakar Abdulsalam ti sisọ loju rẹ pe ofo ọjọ keji ọja ni aayan awọn eeyan to fẹ ya kuro lara Naijiria.
Abubakar sisọ loju ọrọ yii nibi eto ifọrọjomitoro ọrọ kan ti wọn fi sọri Ibrahim Babangida ati ogun to fi silẹ, eyi waye ni Ọjọbọ.
Abubakar lasiko to n sọ ero tiẹ lori bawọn eeyan kan se n beere fun idasilẹ orilẹede Yoruba ati Biafra kuro lara Naijiria, wa salaye idi ti erongba naa ko fi le jọ laelae.
O ni egungun ti wọnu ẹran, ẹran naa si ti wọnu egungun, ti ọpọ Yoruba si ti ba Hausa se igbeyawo, bẹẹ naa ni Fulani ti ba ẹya Igbo da ana laimọ iye igba, eyi ti yoo mu ko nira lati yapa.
"Tẹ ba ti tiẹ fọ Naijiria si yẹlẹyẹlẹ bayii, ki lẹ fẹ se nitori ko si abule tabi ilu tẹ de, tẹ ni ba ẹya Hausa, Igbo, Itsekiri tabi Yoruba nibẹ.
Peter Fatomilola: Robbery burú ju Yahoo lọ, iṣẹ́ ọpọlọ lọmọ Yahoo fi ń gba owó ìran baba
Tẹ ba wa da duro, nibo lẹ fẹ fi ti igbeyawo laarin ẹya kan ekeji si, nitori naa yoo nira lati fọ orilẹede Naijiria si wẹwẹ.
Amọ gbogbo wa lo yẹ ka pawọpọ lati wa ojutu si iwa aidaa tawọn kan n hu, yoo si dara kawọn eeyan maa tete tu asiri awọn onisẹ ibi, ti ko jẹ ki eto aabo wa duro re."
Adari Naijiria tẹlẹ naa wa rọ awọn araalu lati gba alaafia laaye, ki wsn si fara mọ oniruuru ẹya ati ede to wa nilẹ yii, ki wọn si tun maa wa irẹpọ laarin ara wọn.
Oríṣun àwòrán, Nigeria  police Ogun state
Owo te Mohammed, afurasi darandaran kan to gbe ibon AK47 nipinle Ogun
Ileese olopaa nipinle Ogyun ti so okunrin kan to pe oruko ara re ni Mohammed si gbaga olopaa.
Won mu u lojo Isegun, ojo kewaa, osu kejo, odun 2021 ni ipinle Ogun ni guusu iwo oorun Naijiria.
Ileese olopaa ni won gba ifitonileti nipase DPO to wa ni ekun Imeko pe awon Fulani meji kan n tin kiri agbegbe CAC Igbo Oba ni Iwoye Ketu pelu ibon AK 47 lowo won.
Ni kete ti ifitonileti yii de ódó DPO naa lo ti da awọn ọlọpaa mii sita pẹlu awọn ọdẹ aṣogbo ati awọn fijilante.
Oladuni Giwa-Osagie: Òrùka mẹ́fà ní ọkọ́ mi fi bèèrè láti fẹ́ mi lẹ́ni ọdún 47
Lẹyin ọpọlọpọ wakati ti wọn ti n ṣo igbo Oba ni ọwọ tẹ awọn Fulani afurasi meji naa.
Bi wọn si ti kọkọ mu Muhammed pẹlu ibọn AK 47 to gbe dani nibi to farapamọ si naa ni wọn ti fọwọ ofin mu u.
Ileeṣẹ ọlọpaa ipinlẹ Ogun ni o jẹ afurasi lara awọn ajinigbe to n ṣọṣẹ ni agbegbe Ketu.
Ninu atẹjade ti DSP Abimbola Oyeyemi to jẹ agbẹnusọ fun ileeṣẹ ọlọpaa ipinlẹ Ogun fọwọ si ni o ti ni pe Komiṣọnna ọlọpaa nipinlẹ Ogun ti paṣẹ lori ọrọ naa.
Tope Ajogbajesu: Mọ̀lẹ́bí kan ní orin ikú ọdún yìí fò mí ru ní Tope kọ láàrin ọ̀sẹ̀ tó kú
Abimbola ni Komiṣọnna Edward Awolowo Ajogun ti ni ki awọn otẹlẹmuyẹ agbofimro bẹrẹ iwadii ni kia.
O tun ni ki wọn tubọ wa igbo Oba naa lọ ki wọn le mu awọn to ku to jẹ oniṣẹ ibi nibẹ.
Admin staff raped college student: Iléeṣẹ ọlọpàá mú Olawale Jamiu, ti iléèkó College of Health lorí pé o fipá bá akẹkọọ lò pọ
Oríṣun àwòrán, Nigeria Police, ogun state
Okan lara awan osise ọgba ileẹkọ College of Health Technology lo ti ko si gbaga awọn ọlọpaa ipinlẹ Ogun latari ẹsun ifipabanilopọ.
Olawale Jamiu ẹni odun mọkandinlogoji naa ni wọn ni o fipa ba akẹkọọ ti awọn agbofinro fi orukọ bo lasiri naa lo pọ.
Ileesẹ ọlọpaa ti Ilese Ijebu ni awọn mu ọkunrin naa lẹyin ti awọn alasẹ ile ẹkọọ naa mu ẹjọ wa.
Wọn ni akẹkọọ naa fẹ wa gba faili eto ẹkọ rẹ ni nigba ti Jamiu Olawale fipa ba a lo pọ.
Awọn alasẹ ileẹkọ naa ni kete ti isẹlẹ yii sẹ ni akẹkọọ naa fi to awẹn alasẹ leti.
Oga agba ileesẹ Olopaa ekun yii ni Ilese Ijebu, Amuda Ajibola si pase pe ki wọn lọ mu ẹni ti a fẹsun kan naa.
Saaju ni wọn ni ọkunrin naa kọkọ parọ pe oun ko se bẹẹ sugbọn nigba ti o ri atẹransẹ to fi n bẹ ọmọbinrin to fipa ba lo pọ naa ni ọwọ rẹ jabọ.
Ni bayii, wọn ti mu ọmọbinrin naa lọ sile iwosan ni Ijebu Ode fun itaju to peye.
Sunday Igboho: Femi Falani ní ẹjọ́ Igboho ní Cotonou ń kọ́ àwọn amòfin Nàíjíríà ní ẹ̀kọ́
Kọmisọnna ọlọpaa nipinlẹ Ogun, Edward Awolowo Ajogun ti pask pe ki wọn fa iwadii ẹjọ naa le ẹka ọtẹlẹmuyẹ lọwọ.
Atejade ti Abimbola Oyeyemi tojẹ agbẹnusẹ fun ileesẹ ọlọpaa ipinlẹ Ogun fi sita ni o ti ni ni kete ti iwadii ba ti pari ni wọn yoo foju ba ile kjọ bi o ti yẹ.
Pakistan Blasphemy: Ìjà ẹlẹ́ṣìnmẹ̀sìn bẹ́ sílẹ̀ nítorí ọmọ ọdún mẹ́jọ tó tọ̀ sí ilé kéwú
Oríṣun àwòrán, other
Ọmọ ọdun mẹjọ kan ti wa ninu ewu idajọ iku lori ẹsun pe o tọ si ile ikawe ile ijọsin kan.
Lọwọlọwọ bayi ọmọdekunrin ẹlẹsin Hindu yi wa ni abẹ aabo ọlọpaa ni Pakistan.
Lẹyin ti wọn fẹsun kan an pe o mọọmọ tọ sara ninu ile ikawe ile ijọsin.
Ọmọde yi ni ẹni tọjọ ori rẹ kere julọ ti wọn fẹsun kan pe o tabuku ẹsin ni ilẹ naa to se pe ijiya iku lo so mọ ẹsẹ yi.
Wọn fi ẹsun kan pe o mọọmọ tọ si ori itẹ ninu ile ikawe Madrassa ti wọn ko awọn  tira si losu to kọja.
Awọn mọlẹbi ọmọdekunrin yi ti sa asala fun emi won.
Nigba ti ọpọ awọn ẹlẹsin Hindu ni Punjab naa si sa asala fun ẹmi wọn.
Eyi waye lẹyin ti awọn musulumi kan ya bo ile ijọsin awọn Hindu lẹyin ti ile ẹjọ gba oniduro ọmọdekunrin naa ti wọn si ni ko maa lọ sile.
Ọrọ yi le debi pe wọn ti ni kawọn ọmọọgun lọ si adugbo isẹlẹ yi lati le daabo awọn eeyan.
Tope Ajogbajesu: Mọ̀lẹ́bí kan ní orin ikú ọdún yìí fò mí ru ní Tope kọ láàrin ọ̀sẹ̀ tó kú
Lọjọ Abamẹta, eeyan ogun ni awọn agbofinro mu lori ẹsun pe wọn dana sun ile ijọsin Hindu.
Ọkan alara awọn mọlẹbi ọmọ yi to foripamọ ba awọn akọroyin sọrọ.
O ni ''ọmọ yi ko tiẹ mọ nipa ẹsun itabuku ẹsin ati pe ko tiẹ yee  bayi ohun ti o jẹ ẹsẹ rẹ ati idi ti wọn fi fi si ahamọ fọsẹ kan''.
Sunday Igboho: Femi Falani ní ẹjọ́ Igboho ní Cotonou ń kọ́ àwọn amòfin Nàíjíríà ní ẹ̀kọ́
"O salaye pe "" A ti fi sọọbu wa ati isẹ wa silẹ salọ.Gbogbo wa lẹru n ba wa pe wọn le wa gbẹsan nipa ikọlu si wa.A o fẹ pada si agbegbe yi.''"
O ni awọn ko lero pe wọn yoo gbe igbesẹ kan to jọju lati le mu awọn to wa nidi ikọlu yi tabi daabo bo awọn ẹya ti ko lẹnu  lọrọ lagbegbe ọhun.
Oladuni Giwa-Osagie: Òrùka mẹ́fà ní ọkọ́ mi fi bèèrè láti fẹ́ mi lẹ́ni ọdún 47
Nise ni ọrọ yi  se awọn amọfin ni kayeefi lori bi wọn se fi iru ẹsun yi kan ọmọde.
Ramesh Kumar, agbẹjọro to si tun jẹ olori ẹka alasẹ Hindu ni ''ikọlu tawọn eeyan se si ile ijọsin Hindu ati ẹsun itabuku ẹsin Islam ti wọn fi kan ọmọde yi ya mi lẹnu.
O ni o le ni ọgọ́run idile Hindu to ti sipo pada nitori ibẹru lori isẹlẹ yi.
O wa parọ́wa si ijọba lati pese aabo to peye.
Ikọlu sawọn ile ijọsin Hindu lẹnu ọjọ mẹta yi pọ si nitori awọn alakatakiti ẹsin ati awọn to gba nkan mii mọ ẹsin.
Twitter ban in Naijiria: Ìjọba Nàìjíríà ṣàlàyé ibi tí ìjíròrò pẹ̀lú Twitter dé dúró àti ìgbà tó ṣeéṣe kí Twitter padà sẹ́nu iṣẹ́ ní Nàìjíríà
Oríṣun àwòrán, other
Minisita feto iroyin lorilẹede Naijiria, Lai Mohammed ti ṣalaye asiko to ṣeeṣe ki ijọba apapọ o gbẹsẹ kuro lori ofin to fi de oju opo ikansiraẹni Twitter.
Bi ọrọ ti Minisita naa sọ lẹyin ipade igbimọ iṣejọba orilẹede Naijiria to waye nilu Abuja lọjọru ba ṣee tẹle, o ṣeeṣe ki ijọba gbẹsẹ kuro lori ofin naa laipẹ.
Ọgbẹni Lai Mohammed ṣalaye fun awọn akọroyin pe ijiroro pẹlu ileeṣẹ ikansiraẹni naa ti de ibi to lapẹrẹ, bẹẹni ojuutu si  ọrọ naa ti n sun mọ etile.
Bakan naa lo tun tẹnumọ gbedeke ti ijsba Naijiria la kalẹ fun eegun Twitter lati tun lee ṣẹyọ ni Naijiria ninu eyi to ti mẹnuba pe ki ileeṣẹ Twitter fi orukọ silẹ gẹgẹ biileeṣẹ okoowoni Naijiria ki o si ni awọn oṣiṣẹ lorilẹede Naijiria, ki o si maa san owo ori fun awọn alaṣẹ.
Amọṣa Ọgbẹni Mohammed ko ṣai tun sọ pe itẹsiwaju to loorin ti n waye laarin ijsba orilẹede Naijiria ati Twitter lọna ati yanju edeaiyede naa.
Ni ibẹrẹ oṣu kẹfa ọdun 2021 ni ijọba orilẹede Naijiria fofin de Twitter ni Naijiria lẹyin ti ikanni ikansiraẹni naa yọ atẹjade kan ti aarẹ Buhari fi soju opo naa lori pe o tako ọkan lara awọn ilana rẹ.
Oladuni Giwa-Osagie: Òrùka mẹ́fà ní ọkọ́ mi fi bèèrè láti fẹ́ mi lẹ́ni ọdún 47
Ninu atẹjade naa, Aarẹ Buhari ni awọn ajijagbara Biafra lẹkun ila oorun gusu orilẹede Naijiria yoo ri ọwọ oun laipẹ pẹlu ede ti wọn yoo gbọ eleyi ti awọn kan tums si iwa ipa lati ọdọ aarẹ Naijiria naa.
Amọṣa o, ijsba Naijiria ti jade sita lati sọ pe igbesẹ awọn ko ni ohunkohun lati ṣe pẹlu yiyọ ti wọn yọ atẹjade aarẹ danu bikoṣe lati daabo bo alaafia orilẹede Naijiria.
Èròjà tuntun tí Instagram gbé jáde láti dẹ́kun ìdẹ́yẹsí- wo bí o ṣe lè lòó
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ojuopo ikansiraẹni Instagram ti kede awọn eroja ati irinṣẹ tuntun fun didẹkun ọrọ alufansa lori ikanni naa ati didaabo bo awọn to n loo lọwọ awọn adunkukulajamọni.
"Awọn ohun elo ""makan"" naa yoo wa fun lilo kaakiri agbaye lati maa funrarẹ gbe awọn ọrọ ati atẹjade latọdọ awọn ti kii ṣe ololufẹ eeyan bẹẹ pamọ."
Instagram ṣalaye pe eroja tuntun naa yoo wa lati maa dena awọn to ba fẹ maa sọ ọrọ kotọ sawọn eekan lawujọ.
Awọn alaṣẹ ileeṣẹ Instagram n tọka si iṣẹlẹ idẹyẹsi to waye lẹyin ifẹsẹwọnsẹ aṣekagba idije Euro 2020 laarin ikọ agbabọọlu England ati Italy gẹgẹ bii ara ohun to sun wọn si igbesẹ tuntun yii.
Lẹyin ti England ja kulẹ ni ifẹsẹwọnsẹ nipasẹ pẹnariti, oju awọn agbabọọlu England to jẹ alawọ dudu ri to lọwọ awọn to dẹyẹsi wọn, paapaajulọ lori awọn ikanni ayelujara gbogbo.
Bi idẹyẹsi lori ayelujara wọnyii ṣe pọ lo faa ti olotu ijọba ilẹ Gẹẹsi o ke si ileeṣẹ Instagram atawọn oju opo ikansiraẹni miran pe ki wọn tubọ jawe sobi wọn lori didena idẹyẹsi loju opo wọn.
Instagram wa n woye pe ero oawọn ni pe awọn eroja tuntun ti wọn ṣẹṣẹ gbe kalẹ yii yoo lee daabo bo awọn eeyan lọwọ awọn ọrọ idẹyẹsi, ẹlẹyamẹya tabi idẹyẹsi yoowu.
Oríṣun àwòrán, Instagram
Instagram ni dipo eyi ti awọn tọrọ ba kan yoo fi baa pa awọn atẹjade tabi ọrọ bẹẹ rẹ funra wọn to si jẹ pe pupọ igba ni wọn maa n pa ọrọ awọn ololufẹ wọn miran rẹ pẹlu nipasẹ bẹẹ, eroja tuntun yii ni yoo maa pa awọn to n dẹyẹsi ẹni bẹẹ lẹnu mọ.
"Oju opo ikansiraẹni naa tun kede rẹ pe awọn yoo gbe eroja ""Hidden words system"" ti awọn ti kọkọ kede ṣaaju sita fun gbogbo eeyan lagbaye."
Eroja yii ti wọgile awọn ọrọ ati atẹjade to le ni ẹgbẹrun meji eleyi ti wọn fi doju idẹyẹsi kọ awọn agbabọọlu ilẹ Gẹẹsi lẹyin aṣekagba idije Euro 2020 to kọja.
Ilẹ Gẹẹsi lawọn eeyan to n dẹyẹsi ẹni nipa ti ẹya ti pọjulọ la gbaye.
Ida mọkandinlọgọrun awọn eeyan to ni awọn oju opo ti irufẹ ọrọ idẹyẹsi bẹẹ ti jade ni wọn ti wọgile.
Hushpuppi: Ẹgbẹ́ ọmọ bíbí Òkè Ọya bẹ̀bẹ̀ àtìlẹyìn fún Abba Kyari
Oríṣun àwòrán, Daily Nigerian
Agbẹjọro mọkanlelọgbọn lati oke Ọya ti yọnda lati ṣoju ọga ọlọpaa, DCP Abba Kyari lai gbowo lori ẹsun jibiti ti ile iṣẹ ọlọpaa ọtẹlẹmuyẹ ilẹ Amẹrika fi kan an pẹlu Ramon Abass(Hushpuppi).
Ile iṣẹ ọlọpaa orilẹede Naijiria ti ni ki igbakeji kọmiṣọnna ọlọpaa Kyari lọ rọkun nile na bi ajọ FBI ṣe n ṣe iwadii lori ẹsun ti wọn fi kan an.
Sunusi Bappah Salisu to jẹ agbẹnusọ fawọn agbẹjọro naa ṣalaye pe awọn amofin mọkanlelọgbọn yii wa lati ipinlẹ mọkandinlogun to wa lapa ariwa.
Salisu ni igbeṣẹ yii waye lẹyin ti ẹgbẹ Coalition of Northern Groups kepe awọn eeyan oke Ọya lati gbaruku ti Kyari.
''A pinnu lati gbija Kyari lọfẹẹ lati ri pe wọn ko fi ẹtọ Kyari dun un.
Blind Oniru: Muinat  Abdulfatai ní òun ro ara òun pin àmọ́ irú títà fún òun ní ìrètí ọ̀tun
Gbogbo ẹsun tawọn ọlọpaa FBI fi kan Kyari ni a o wo fini fini, ohun to mu ki ile ẹjọ sọ pe o gbimọ pọ pẹlu Hushpuppi lati lu awọn eeyan ni jibiti lori ayelujara.
A o beere awọn ibeere to nii ṣe pẹlu ẹtọ Kyari to le di titẹ mọlẹ tori ẹsẹ ikẹfa ati ikeje iwe ofin ilẹ Afirika sọ pe gbogbo eeyan lo lẹtọọ si ominira.
Iwe ofin naa tun sọ ninu awọn yii pe gbogbo eeyan lo lẹtọọ si abo ati pe wọn tun lẹtọọ lati sọ ti ẹnu wọn.
Bakan naa ni ajọ iṣọkan agbaye, UN sọ pe ẹnikẹni ti wọn ba fi ẹsun kan lo jẹ afurasi.
O digba ti ile ẹjọ ba fi idi rẹ mulẹ pe lootọọ lo jẹbi ẹsun ti wọn kan an lẹyin ti wọn ti fun oun naa laaye lati sọ ti ẹnu rẹ ni wọn le pe ni ọdaran.
Blind Oniru: Muinat Abdulfatai ní òun ro ara òun pin àmọ́ irú títà fún òun ní ìrètí ọ̀tun
Agbara wa ninu ipenija ara, ohun to ba si wu nii se, bii idan lo n ri.
Muinat Abdulfatai ni ipenija oju lati kekere, ti ko si riran rara amọ okoowo iru to nira fun abarapa lati se gan lo dawọle.
Nigba to n ba BBC Yoruba sọrọ lori ohun to gbe de idi okoowo naa, Muinat salaye pe isoro ti oun koju nile ọkọ lo sun oun de ilw baba oun, ti oun si fi dawọle okoowo iru.
O ni ile ẹkọ ni oun wa ti wahala oju naa fi bẹrẹ, ti ọkọ oun fi fẹ oun amọ ko tọju oun rara, ti ẹrọ ata ti oun fi n se isẹ aje si bajẹ.
Idi ree to fi ni oun fi gbe majele jẹ lati tọrọ iku nigba ti ireti pin amọ Ọlọrun ko fun oun, ti ile iwosan si gba oun silẹ.
O ni idi isẹ iru tita ni oun pada si, ti oun si n fi bọ ara oun atawọn ọmọ pẹlu.
Nigba to n salaye awọn ipenija to wa nidi iru sise, Muinat ni oun ko le se agbe jẹun nitori oun naa fẹ gbe nnkan rere se nile aye, idi ree ti oun fi dawọle okoowo kan.
O ni oun ni eeyan kan to maa n ba oun sa okuta kuro laarin awọn iyere amọ oun gan maa n sa funra oun nipa mimu iyere ni ẹyọ kọọka.
Obinrin to ni ipenija naa ni atẹlẹwọ ẹni ni kii tan ni jẹ, oun ko si fẹ fi iya jẹ ara oun, ni oun ko fi tọrọ bara.
Bola Tinubu: APC Eko ní Tinubu ló sọ Bode George di èèyàn lágbo òsèlú àmọ́ ògo rẹ̀ ti ń lọ sílẹ̀
Sáájú ìdìbò ọdún 2023 ní Nàíjírà àti ìpinu Asíwáju Bola Ahmed Tinubu láti di ààrẹ, oníruurú ọ̀rọ̀ ló n tàn ka lórílẹ̀-èdè Naàìjíríà.
Lára rẹ̀ ni ọ̀rọ̀ ti ìgbákejì alága ẹgbẹ́ òṣèlú People's Democratic Party (PDP) tẹ́lẹ̀ rí, Olabode George sọ pé, Ahmed Tinubu ko yẹ lẹni ti ó yẹ kí ó jẹ ààrẹ lọ́dún 2023.
Bode George fi kun pé, gbogbo ẹni to bá sì rò pé Tinubu ló tọ́ sí láti di ààrẹ, irú ẹni bẹ́ẹ̀ nílò àyẹ̀wò nílé ìwòsàn.
Bákan náà ló sọ pé láàrín ọdún mẹ́jọ tí Tinubu fi jẹ gómínà ìpínlẹ̀ Eko gbogbo àlùmọ́nì ìpínlẹ náà lo ṣe básubàsu.
Èyí lo wá mú kí àwọn ẹlẹgbẹjẹgbẹ nilẹ oruba ati èèkàn kan nínú ẹgbẹ́ òṣèlú All Progressive Congress (APC) fi n sọ òkò ọ̀rọ̀ padà sí Olabode George.
Nínú ọ̀rọ̀ tirẹ̀, alága ẹgbẹ́ Yorùbá Welfare Group (YWG) Alhaji Abdulkareem Adegoke Alawuje ṣàlàyé pé, ìjà ìlàra ni Bode George ń jà àti pé ìjà ìlàra kìí tán bọ̀rọ̀.
Blind Oniru: Muinat  Abdulfatai ní òun ro ara òun pin àmọ́ irú títà fún òun ní ìrètí ọ̀tun
Adegoke ni, gbogbo àwọn ìpìlẹ̀ tí ó wà ní ìpínlẹ̀ Eko lónìí, Tinubu ló ṣe àgbékalẹ wọn, nítori náà, Bode George ko rì nǹkan sọ lórí pe Tinubu ṣe àlùmọ́nì ìpínlẹ̀ Eko básubàsù.
Fún ọ̀pọ̀lọpọ̀ ọdún ni Tinubu ko fi gba owó láti ọdọ̀ ìjọba àpapọ̀ síbẹ̀ , ètò ọ̀rọ̀ ajé Eko sì n ru gọbọi síí ni
Bola Ahmed Tinubu ni olórí tí gbogbo ọmọ ilẹ̀ káàrọ̀-òò-jííre nílò ni àsìkò yìí, kíló de ti Yorùbá náà ló tún fa ọmọ Yorùbá sẹ́yìn.
Adegoke fi kún pé tí Bode George bá fẹ́ kúrò ní Nàìjíríà, kò ṣe nǹkankan fún ẹnikẹni nítorí kìí ṣe ọmọ Nàìjíríà tẹ́lẹ̀, ẹrú ló rà wọ́n wá, orúkọ ẹru tó ra àwọn baba ńla bàbá rẹ̀ lo ń jẹ George.
Ó ni kìí ṣe òní ni Bode George ti máa n sọ ọ̀rọ̀ yìí, kò sì ni turu kankan lára ẹnikẹni nítorí pé, agbegbe Ìjọrá ni wọn kó awọn iran rẹ to jẹ ẹru si lásìkò owò ẹrú, ó sì wà lára àwọn ti kò mọ orísun wọn mọ́.
Bode George s'ọrọ lori abadofin tuntun ipinlẹ Eko
"Adegoke ní gẹ́gẹ́ bi ọmọ Nàìjíríà àti ọmọ Yorùbá, kò sí nǹkan tí ó le ṣẹ̀lẹ̀ ní Nàìjíríà, tí mo fi le ròó pé mọ̀ fẹ́ fi orílẹ̀-èdè mí sílẹ̀
Gẹ́gẹ́ bi ẹni tó mọ pé wọ́n ra àwọn bàbá àwọn wá ni, kò ni niwọ́n lára láti padà sí ọ̀dọ́ àwọn tó rà wọ́n tàbi ibi ti wọ́n ti rà wọ́n kiri."""
"Àwá sì le júwe ibi ti wọ́n ti rà wọ́n pẹ̀lú agádagodo lẹnu wọ́n Láti ìgbà tí Bode George tí n ṣe òṣèlú kò sí ẹni tó ri ipa ire kan ti o se nilẹ Yorùba, ní Eko tabi ni orílẹ̀-edè Nàìjíríà."""
 Ṣebí Bode George naa ti jẹ Gómìnà rí, kí lo ṣe lásìkò rẹ̀, kò sí ipa kankan ti wọ́n ni.
Nínú ọ̀rọ̀ tirẹ̀, akọ̀wé ipòlongo fún ẹgbẹ́ òṣèlú APC ní ìpínlẹ̀ Eko, Joe Igbokwe ṣàlàyé pé ìlàra ni kò jẹ́ kí Olabode George gbádun nítori pé o kàn ń ṣe inúnibini sí àṣeyọri Bola Ahmed Tinubu ni Nàìjíríà ni.
Igbokwe to tẹpẹlẹ mọ pé, àṣeyọri Tinubu kò dúró ni ìpínlẹ̀ Eko nìkàn, bákan náà lo ni àwọn tó ti sọ di ènìyàn ńla láwùjọ, èyí ti òun gan jẹ́ ọ̀kan lára àwọn ti Tinubu sọ di èyàn.
Bode George dá sí aawọ̀ Buhari, Obasanjo
Igbokwe ni o ti dandan tí ènìyàn bá jẹ ìlúmọ̀ọ̀ká, ọ̀pọ̀ ni yóò ma sọ̀rọ̀ rẹ̀, 'tí ènìyàn kan ba n lọ sókè, tí ẹlòmíràn si ń lọ sílẹ̀, ẹni tó n lọ sílẹ̀ yẹn yóò maa ba ẹni tó wà lóke jẹ́ ni.
Bẹ́ẹ̀ ni ọ̀rọ̀ Bode George ṣe rí, Bode George ti tán, ó sì ń wá ẹni kúnra nítorí ètò òṣèlú rẹ̀ ti tán.
Saaju la ti mu iroyin wa fun yin pe, agba  ọjẹ kan ninu ẹgbẹ oselu PDP, Oloye Olabode George ti sọrọ soke lori erongba asaaju ẹgbẹ oselu APC, Asiwaju Bola Tinubu lati du ipo aarẹ.
George fi ero rẹ lori erongba Tinubu lati du ipo aarẹ han lasiko to n kopa lori eto ori tẹlifisan kan nileesẹ Arise TV lọjọru.
Lero ti asaaju ẹgbẹ PDP naa, ara gbogbo awọn eeyan to n sugba Tinubu lati di aarẹ lọdun 2023 ni ara wọn ko ya, wọn si nilo ayẹwo ọpọlọ.
Ọmọ igbimọ majẹobajẹ fẹgbẹ oselu PDP naa ni oun yoo kede pe oun kii se ọmọ Naijiria mọ, ti Tinubu ba fi di aarẹ Naijiria lọdun 2023.
Bẹẹ ba gbagbe, asaaju ẹgbẹ oselu APC kan, Adeseye Ogunlewe lo ti kọkọ kede pe Tinubu ni oludije to dantọ julọ lati dari Naijiria lọdun 2023.
Fayose gọ̀, ó fẹnu họra, Ọlọ́run á gbẹ̀san lára rẹ̀, àdàbí...- Bode George
Nigba to n fesi si ọrọ naa siwaju, George ni se ni oun bẹrẹ si ronu nigba ti oun gbọ ọrọ Ogunlewe naa nitori ọkunrin naa ti kọkọ sọrọ saaju lati tabuku Tinubu, to si wa ni akọsilẹ.
"Ki lo de tawọn eeyan kii le duro lori ọrọ ti wọn ba sọ gan? Ki lo de ti wọn n jo bi eleegun kiri laarin ọja?
Ta ba se agbeyẹwo ọdun mẹjọ ti Tinubu lo bii gomina nipinlẹ Eko, bawo la ti se idajọ rẹ si?
Mo setan lati ba Ogunlewe se ariyanjiyan nipa Tinubu nibi kibi, koda, ko baa jẹ ni itẹ oku ni aago mẹta oru, ọrọkọrọ lo n sọ lẹnu.
Koda, maa se ohun gbogbo to ba yẹ lati kede pe n ko kii se ọmọ orilẹede yi mọ ti Tinubu ba fi di aarẹ."
Bode George, ẹni to ni ọmọ ipinlẹ Eko ni oun, oun si mọ awọn nnkan ti Tinubu se, wa fi ọwọ sọya pe ko yẹ bii aarẹ rara, ti awọn gomina miran to dari ipnilẹ Eko si kaato julọ.
Toll Gates Fees: Owó bodè táwọn ọkọ̀ yóò san wà láàrin ₦200 sí ₦500 fún ìrìnàjò kan
Oríṣun àwòrán, FGN
Igbimọ alasẹ Naijiria ti buwọlu gbigba owo bode loju popo (Tollgate) pada lawọn opopona nla alabala meji, kaakari orilẹ-ede yii.
Awọn ọkọ aṣoju ilu, ọmọ ogun, kẹkẹ ẹlẹsẹ mẹta, ati ọkada nikan ni eto naa yọ silẹ.
Minisita fun iṣẹ òde ati ile gbigbe, Babatunde Fashola lo kede igbesẹ tuntun yii ni Ọjọru, lasiko to ba awọn akọroyin sọrọ lopin ipade ọlọsẹẹsẹ igbimọ alasẹ ti Igbakeji Aarẹ, Yemi Osinbajo dari.
Igbesẹ ti ijọba gbe yii waye lẹyin bi ogun ọdun ti isejọba Olusegun Obasanjo wo gbogbo awọn ibudo ti wọn ti n gbigba owo tollgate ni Naijiria ni ọdun 2003.
Ọgbẹni Fashola sọ pe, awọn opopona ti wọn o ti ma a gba owo yii jẹ ìdá mẹrinnla ati diẹ ninu opopona ẹgbẹrun marundinlogoji to jẹ ti ijọba apapọ, to si tun jẹ abala meji.
Blind Oniru: Muinat  Abdulfatai ní òun ro ara òun pin àmọ́ irú títà fún òun ní ìrètí ọ̀tun
Owo ti awọn ọkọ yoo ma a san yoo wa laarin igba Naira si ẹẹdẹgbẹta Naira, ni irinajo kan.
O ni ni bayii ti igbimọ alasẹ ti fọwọ́ si dida sisan owó toll gate pada ni awọn opopona kan, ileesẹ ìjọba ti oun n dari ti ṣe tan lati bẹrẹ awọn nkan ti yoo sọ bi eto naa yoo ṣe tete bẹrẹ.
Sugbọn sa, Fashola sọ pe kii ṣe 'ọ̀la' (kíákíá) ni eto naa yoo bẹrẹ.
Fashola sọ pe eto naa ko ni i bẹrẹ titi gbogbo àwọn opopona ti ọrọ kàn yoo fi wa ni ipo to dara fun ọkọ̀.
"Bakan naa lo sọ pe wọn yoo dunadura pẹlu awọn ileesẹ ìjọba to yẹ lori ọna ti wọn o gbe e gba."""
O ni kii ṣe atunse àwọn oju popo nikan ni wọn o ma a fi owo to ba n wọle ṣe, o ni ijọba yoo tun ma a fi la àwọn ọna miran.
Ati pe ilana imọ ẹ̀rọ igbalode ni wọn o fi ma a gba owo ni tollgate, ki akoyawọ le wa.
Taye Osinowo Olaosebikafi Iyabo Ojo, Mide Martins, Jaye Kuti, Afeez Owo àtàwọn míì dárà ap
Sunday Igboho: Ẹgbẹ́ ọmọ bíbí Igboho ké sáwọn Alfa, Pásítọ̀, oníṣẹ̀ṣe láti ké pe Ọlọ́run pẹ̀lú gba ààwẹ̀ àti àdúrà
Oríṣun àwòrán, sunday_Igboho/Instagram
Yoruba ni ẹni ti a ko ba le mu, Ọlọrun ọba ni a fi le lọwọ, ati pe ẹni mi ko sẹni, eeyan mi ko seniyan amọ ko ni jọ alaaro lasan.
Idi ree ti awọn eeyan ilu ajijagbara fun ilẹ Yoruba nni, Oloye Sunday Igboho fi bẹrẹ igbesẹ lati duro ti eeyan wọn ko le bọ lọwọ ipenija ati idojukọ to n ba finra lorilẹede Benin.
Awọn ọmọbibi ilu Igboho naa, ti wọn korajọpọ sabẹ aburada ẹgbẹ Ifelodun ọmọ Igboho, eyi ti Alhaji Imran Oloyoyo ko sodi, lo fidi isẹlẹ naa mulẹ.
Awọn eeyan ilu Igboho, to wa nijọba ibilẹ Oorelope nipinlẹ Oyo ti wa gunle eto aawẹ ati adura lati mu Sunday Igboho bọ ninu ọfin ofin to jin si nile ẹjọ.
Awọn eeyan ile Igboho lo n gunle ija inu ẹmi yii lati fi tako igbesẹ ijọba apapọ to fẹ di ajafẹtọ ẹni naa lapanyaka wọnu baalu wa sile lati ilu Cotonou.
Sunday Igboho Update: Igboho ti sọ ohun tó fẹ́ kí a ṣe tí ọ̀rs bá bẹ́yìn yọ- Saheed Yusuf
Nigba to n salaye igbesẹ ẹmi ti wọn fẹ gbe, Oloyoyo ni irọ to jinna sootọ ni wọn pa mọ Sunday Igboho pe o fẹ doju ijọba Buhari bolẹ ni.
O ni wọn kan fẹ sọ aja Igboho ni orukọ buruku ni ki wọn le so mọ igi lati pa nitori ohun to se ko kọja igbesẹ to gbe lati ja fun ominira Yoruba nitori iwa aidaa ti wọn n hu si wọn.
"Ni aye ti oju ti la yii, o n kọ mi lominu pe araalu ti ko ni olugbeja tabi ohun aabo kankan, ni wọn n naka aleebu si pe wọn fẹ doju ijọba bolẹ.
Bẹẹ ni lati igba tijọba ti kede pe oun n wa Sunday Igboho, ile ẹjọ kankan ko tii kede pe o jẹbi, nitori naa, alailẹsẹ lọrun si ni Igboho."
Alhaji Oloyoyo ni idi ree ti agbarijọpọ awọn ọmọ ẹgbẹ Ifelodun Igboho fi ke sawọn asaaju ẹsin Kristiẹni ati Musulumi to fi mọ awọn ẹlẹsin ibilẹ.
Blind Oniru: Muinat  Abdulfatai ní òun ro ara òun pin àmọ́ irú títà fún òun ní ìrètí ọ̀tun
O ni koko ohun ti wọn se ni lati gbe ohun soke, ke pe Ọlọrun ninu ẹbẹ aawẹ ati adura, ki ọmọ wọn le bọ lọwọ kinihun aye to gbe hanu.
Oloyoyo naa ni ireti si wa pe Ọlọrun ti da si ọrọ naa, to si ti pe adura wọn lori Sunday Igboho.
Tokyo 2020: Wo tábìlì ìṣirò Olympic tó kọjá àtàwọn orílẹ̀èdè tó ti gba àmì ẹ̀yẹ láti ọdún 2000
Oríṣun àwòrán, Olympics.Com
Ere idaraya Olympic to waye nilu Tokyo lorilẹede Japan bẹrẹ ni ọjọ Ẹti, ọjọ Kẹtalelogun osu Keje ọdun 2021, to si pari ni ọjọ Aiku, ọjọ Kẹjọ osu kẹjọ ọdun 2021.
Ọpọ orilẹede lo gba oniruuru ami ẹyẹ Wura Fadaka ati Baba ninu idije naa.
Koda, orilẹede wa Naijiria gan gba ami ẹyẹ fadaka meji ati Baba kan ninu idije Olympic kan, ta si gbe ipo kẹrinlelaadọta.
Awọn akojọpọ ree nipa awọn koko ohun to waye ninu idije naa, to fi mọ awọn orilẹede to gba ami ẹyẹ ati awọn oludije wọn.
Bi ikọ kan ti se daadaa si
Bi ikọ kan ti se daadaa si
Bi ikọ kan ti se daadaa si
Doctors‘ Strike: Àwọn dókítà tó ń woṣẹ́ níran ní UCH sọ̀rọ̀ lórí ẹ̀dùn ọkàn wọn
Ọpọ awọn dokita nile iwosan UCH to ba ikọ iroyin BBC Yoruba sọrọ lasiko abẹwo wa sibẹ, ti salaye pe ewu n bẹ loko longẹ, lori bi ọpọ awọn dokita se n ya lọ soke okun.
Bakan naa ni wọn fi ẹsun kan ijọba apapọ pe ọwo awọn dokita to sẹsẹ pari ẹkọsẹ to n ran awọn lọwọ, nijọba tun kọ lai san owo osu wọn.
Wọn fikun pe awọn ipinlẹ bii mọkandinlogun lo tun jẹ awọn dokita wọn lowo osu mẹrin si marun nigba ti ijọba si n san ẹgbẹrun marun pere gẹgẹ bii owo adojutofo fun ewu.
Awọn dokita naa wa fi ika hanu pe ijsba ati ileesẹ to n se akoso owo osu awọn osisẹ ijọba apapọ, IPPIS, ko fi orukọ awọn dokita kan soju opo ayelujara wọn, ti wsn ko si san owo osu awsn dokita naa.
O wa gba ijọba apapọ atawọn ipnilẹ nimọran lati mu idẹrun awọn dokita nibaada, bibẹẹkọ, ewu n bẹ loko longẹ lori ilera araalu.
Buhari: Ìjọba mi ti ń lo ẹ̀rọ ìgbàlódé láti pèsè èrè ìjọba alágbádá àti fún àgbéga Nàíjíríà
Oríṣun àwòrán, Muhammadu Buhari/Facebook
Bi ogun ẹni ba da ni loju, a fi gbari ni, ma si fi oko mi se aala, ọjọ kan ni eeyan maa n kọ ọ.
Eyi lo mu ki aarẹ Muhammadu maa leri leka, to si n tọ ilẹ la pe ijọba yoo gbajumọ eto aabo to mẹhẹ lorilẹede Naijiria.
Aarẹ Buhari fọwọ idaniloju yii sọya nibi ayẹyẹ ikẹkọjade ile ẹkọ ologun to wa nilu Abuja, eyi to waye lọjọ Ẹti.
Buhari, ẹni ti minisita eto aabo, Bashir Magashi soju fun wa salaye awọn igbesẹ ti ijọba rẹ n gbe lati se agbekalẹ ileesẹ alaabo tuntun, ko si se atunse awọn eyi to ti wa nilẹ tẹlẹ.
"Bi o tilẹ jẹ pe orilẹede wa n koju ipenija awọn agbebọn ati ikọ afẹjẹwẹ, ajinigbe, ija agbẹ ati darandaran pẹlu awọn agbesunmọmi.
Olawale Dada: Igbá bárà kọ́ ló kàn, àwa náà n ṣoríire láyé pẹ̀lú ìpèníjà 'Cerebral Palsy'
Sibẹ, ọna agbara ni ijọba mi fi n kọju oro si wọn ko le pese aabo to peye fun ẹmi ati dukia awọn ọmọ Naijiria.
A ti mu ki alaafia jọba ni agbegbe Niger-Delta, ta si ti gba ọpọ ilẹ lọwọ awọn adunkookomọni to wa lẹkun ila oorun ariwa Naijiria.
A si ti n tẹsiwaju lati ri daju pe eto aabo to dara fidi mulẹ fun alaafia ati idagbasoke Naijiria, lai naani awọn ipenija yii, igbẹkẹle wa ninu ilẹ yii ko mi rara."
Aarẹ Buhari tun fi ọwọ idaniloju sọya pe ijọba oun n gunle awọn amulo imọ ẹrọ igbalode lati mu ki omitooto ere ijọba awa ara wa de ẹẹkẹ awọn ọmọ Naijiria ati fun idagbasoke orilẹede yii.
Ileesẹ ọlọpaa ọtẹlẹmuyẹ nilu Abuja ti fi sọrọ sọrọ ori ayelujara YouTube kan, Israel Balogun, sì ahamọ nitori ẹsun pe o ba Apostle Johnson Suleman lórúkọ jẹ, to si tun n dọdẹ rẹ lori ayelujara.
Iroyin sọ pe fun bi i wakati mẹrin ni awọn ọlọpaa ọtẹlẹmuyẹ fi fi ọrọ wa Ọgbẹni Balogun lẹ́nu wo lori awọn ẹsun naa.
Lẹyin naa ni awọn yoo gba beeli rẹ, pẹlu awọn ilana to lagbara, ko to o di pe wọn tun fi si atimọle.
Ni ọjọ diẹ sẹyin ni Balogun fi fidio kan si ori ayelujara YouTube rẹ, nibi to ti bu ẹnu ẹtẹ lu fidio kan to safihan Apostle Suleman to sọ pe awọn áńgẹ́lì yoo fi owo si apo àsùnwọ̀n awọn ọmọ ijọ rẹ.
O sọ eyi lasiko ijọsin kan to waye ni ile ijọsin rẹ ni ilu Atlanta lorilẹ-ede America, ati ilu Auchi nipinlẹ Edo, lorilẹ-ede Naijiria.
Doctors‘ Strike: Àwọn dókítà tó ń woṣẹ́ níran ní UCH sọ̀rọ̀ lórí ẹ̀dùn ọkàn wọn
Ti àwọn ọmọ ijọ kan naa si bẹrẹ si ni fi atejisẹ han ninu isin naa pe awọn ti ri owo ninu apo asunwon banki wọn, lati ọdọ áńgẹ́lì.
Ọgbẹni Balogun sọ pe ayederu isẹ iyanu ni Apostle Suleman ṣe.
Ọrọ to sọ yii fa ariyanjiyan lori ayelujara. Bi awọn kan ṣe gboriyin fun Balogun fun bo ṣe bu ẹnu ẹtẹ lu Suleman, ni awọn kan n sọ pe Balogun fẹ ẹ fi ọrọ naa wa okiki ni.
Agbejọro fun Israel Balogun, Amofin Inibehe Effiong sọ fun BBC pe awọn ọlọpaa fi onibaara òun si atimọle, bo tilẹ jẹ jẹ pe funra rẹ lo lọ jẹ ipe ti wọn pe e.
O ni wọn kọ lati fi pasitọ naa silẹ, ti wọn si ni ko lọ ọ mu oniduro to jẹ oṣiṣẹ ijọba, to si tun gbọdọ setan lati fi iwe igbega to gba kẹhin lẹ́nu isẹ tabi lẹta idanimọ lati ibi to ti n sisẹ silẹ.
O ni lootọ ni sunkẹrẹ-fakẹrẹ ọkọ ko jẹ ki oniduro naa de agọ ọlọpaa, sugbọn gbogbo igbiyanju lati mu ki ẹlomiran to setan lati fi iwe ilé rẹ nilu Abuja silẹ, titi ti oniduro yoo fi de lonii, lo ja si òfo.
Blind Oniru: Muinat  Abdulfatai ní òun ro ara òun pin àmọ́ irú títà fún òun ní ìrètí ọ̀tun
O ṣalaye pe saaju ni agbejọro Wolii Suleman kọ lẹta si onibaara oun pe ko tọrọ aforijin fun ọrọ to sọ, ti oun oun si fi esi ránṣẹ pe ko ni idi kankan lati tọrọ aforijin.
"A jẹ ko ye wọn pe ko si ohunkóhun ti onibaara mi yoo tọrọ aforijin fún, bẹẹni a si setan lati yanju rẹ nile ẹjọ.
Sugbọn bi ọrọ ṣe ri bayii, o daju pe Suleman n lo ọlọpaa lati fi iya jẹ onibaara mi, eyi ti ile ẹjọ kò le fi aaye rẹ gba a. """
O ni awọn ẹsun ti wọn fi kan onibaara òun, Páṣítọ̀ Balogun ko boju mu rara.
Ninu iroyin ti awọn ileesẹ iwe iroyin kan gbe jáde, wọn ni Apostle Suleman sọ pe oun ko mọ nipa iwe ẹsun naa.
Bakan naa ninu fidio kan ti Apostle naa fi sita, o ni oun ti sakiyesi pe awọn eeyan ma n bu oun lori YouTube lati fi wa ero si oju opo rẹ, ati lati pawo.
O ni oun si ti pinnu lati gba owo fun eebu ti wọn n bu oun.
"Apostle naa sọ pe ""lasiko yii, bibu àwọn pasitọ ni awọn sọrọ sọrọ ori ayelujara fi n pa owo. Mo si jẹ ọkan lara awọn ti wọn ma n bu."""
"Mi o binu si wọn, nitori pe ẹgbẹrun eebu ko le di nkankan. Sugbọn nkan to n dun mi ni pe wọn yoo fi eebu bibu pawo ni ipari oṣu lọwọ YouTube.
 Nitori naa, a ni lati jọ dunadura pe wa a sanwo fun mi ti o ba bu mi."
"Ma a fi ọwọ si pe ko bu mi, to o ba sa ti fun mi ni owo, nitori pe ẹgbẹgbẹrun eebu ko le ja iranṣẹ Ọlọ́run tootọ bọ́.
Tope Ajogbajesu: Mọ̀lẹ́bí kan ní orin ikú ọdún yìí fò mí ru ní Tope kọ láàrin ọ̀sẹ̀ tó kú
Kola Ologbondiyan: PDP ni yóò mú ọmọ Nàíjíríà kúrò lóko ìyà tí wọn wà ní 2023
Akọwe ipolongo fun ẹgbẹ oselu PDP, Kola Ologbondiyan ni gbogbo nnkan ti ẹgbẹ oselu APC sọ pe awọn yoo se lasiko ti wọn n pologo ibo, lati bi ọdun mẹfa si asiko yii, ko si eyi ti wọn mu ṣẹ.
Ologbondiyan  ni ti a ba ni ki a gbe ẹgbẹ oṣelu APC si ori iwọn, òdo pọnbele ni wọn gba nitori ko si larija aseyọri kankan paapaa julọ lori ọrọ eto aabo."
O fikun pe oju ọmọ Naijiria ti la ju pe ki eniyan maa se nnkan to pinu lati ṣe i ko ba ṣe awọn ọmọ Naijiria yoo yọ danu.
O wa rọ awọn ọdọ ati obinrin lasiko yii lati wa dije nitori pe ẹgbẹ PDP ti fi aaye silẹ lati mu ki nnkan ki o rọrun fun wọn
Akọwe ipolongo fun ẹgbẹ oselu PDP,ní lasiko yii, owo ìkanlẹkun nikan ni PDP n gba bayii lojuna lati mu ki awọn eniyan le darapọ mọ ẹgbẹ, ki wọn si le kopa ninu eto oselu.
Covid-19 Delta variant Update: Ẹ̀dà Delta Variant COVID-19 ń gbèrú síi ní Nàìjíríà, ìjọba àpapọ̀ ra abẹ́rẹ́ àjẹsára 176,000
Oríṣun àwòrán, other
Bi ọwọ kẹta ajakalẹ arun  COVID-19 tun ti ṣe n gbilẹ sii lorilẹede Naijiria, ajọ to n gbogun ti ajakalẹ arun lorilẹede Naijiria, NCDC ti sọ pe ẹda kokoro arun naa ti wọn n pe ni Delta variant ti n gbilẹ sii lorilẹede Naijiria bayii ati pe lojumọ eeyan ẹẹdẹgbẹrin lo n ko arun naa.
Ni bayii, aadọjọ ẹgbẹrun  abẹrẹ ajẹsara Johnson and Johnson ni Naijiria n reti lọjọbọ.
Ko din ni ẹgbẹrin o din mẹwaa eeyan to tun ti ko aarun naa laarin wakati mẹrinlelogun sẹyin bi o tilẹ jẹ pe bi awọn eeyan ṣe n ṣe ayẹwo si ko mu ori ya to.
Lorilẹede Naijiria, o le ni miliọnu meji eeyan ti o ti ṣe ayẹwo kokoro arun naa, ninu eyi ti nnkan bii ọgọsan ẹgbẹrun eeyan ti ko arun naa to si ran ẹgbẹrun meji ati igba o din marun un eeyan lọ sọrun.
Bakan naa lawọn ibudo ayẹwo arun naa kaakiri orilẹede Naijiria wa ni ṣiṣi pẹlu bi awọn dokita ilewosan ẹkọṣẹ iṣegun kaakiri orilẹede Naijiria ṣe n gun le iyanṣẹlodi lọwọlọwọ bayii lori.
Doctors‘ Strike: Àwọn dókítà tó ń woṣẹ́ níran ní UCH sọ̀rọ̀ lórí ẹ̀dùn ọkàn wọn
Amọṣa, ijsba apapọ kede pe awọn ti ra abẹrẹ ajẹsara Johnson and Johnson to to ẹgbẹrun lọna ọgbọn gẹgẹ bi ara igbesẹ lati jawe sobi gbigba abẹrẹ ajẹsara arun ọhun.
Bakan naa ni ijsba orilẹede Naijiria tun fi kun un pe oun ṣi n tiraka lati rii pe ọwọ keji abẹrẹ ajẹsara naa tẹ awọn lọwọ lati lee ri pe ọpọ eeyan lo tun n gba abẹrẹ ajẹsara naa bẹrẹ lati sjọ Iṣẹgun ọsẹ to n bọ.
Ni bi a ṣe n sọrọ yii, nnkan bii miliọnu mẹrin eeyan lo ti gba abẹrẹ ajọsara COVID-19 pẹlu AstraZenecca ninu igba miliọnu eeyan to wa lorilẹede Naijiria.
OPIC Agbara loot police arrest: Lásìkò ti àwọn mẹta yìí ń jí ọja kó ní Ado Odo Ọta lọwọ tẹ wọn- Iléesẹ ọlọpàá Ogun
Oríṣun àwòrán, The Nigeria Police, Ogun state command
Jelili Waheed, Otun Taye ati Olu Adeniran ni ọwọ àwọn agbofinro tẹ lasiko ti wọn n ko nkan nile ìkó ọja pamọ si ni Ado Odo Ọta.
Awọn agbofinro ileesẹ ọlọpaa ni ipinlẹ Ogun ti fi oju awọn ọkunrin mẹta kan hande pe ole ni wọn.
Wọn ni ọwọ tẹ awọn ọkunrin mẹta naa nigba ti wọn n ji ọja ko nile iko ọja pamọ si to jẹ tile isẹ Sky Industry Limited eyi to wa ni OPIC ni agbegbe Abara nijọba ibilẹ Ado Odo Ọta nipinlẹ Ogun.
Ileese ọlọpaa fi atẹjade sita pe Waheed Jelili to jẹ ẹni ọdun mẹtalelọgbọn, ati Otun Taye to jẹ ẹni ọdun mẹrinlelogoji pẹlu Olu Adeniran to jẹ ẹni ọdun mẹrindinlaadọta ni ọwọ tẹ.
Agbenusọ fun ileesẹ ọlọpaa ipinlẹ Ogun, Abimbola Oyeyemi lo buwọlu atẹjade naa pe lẹyin ti DPO ẹkun Agbara ri ifitonileti gab pe awọn kan n sọsẹ nibẹ lo da awọn agbofinro sita.
Oladuni Giwa-Osagie: Òrùka mẹ́fà ní ọkọ́ mi fi bèèrè láti fẹ́ mi lẹ́ni ọdún 47
O ni Saleh Dahiru to jẹ ọga ọlọpaa nibẹ ni pe nkan bii ago mẹrin irọlẹ ni ọwọ tẹ awọn mẹtẹẹta yii nibẹ.
Lara awọn nkan ti wọn ri gba pada lọwọ awọn mẹtẹẹta ni ọkọ akẹru ti nọmba rẹ jẹ: AKD 747 XZ.
Blind Oniru: Muinat  Abdulfatai ní òun ro ara òun pin àmọ́ irú títà fún òun ní ìrètí ọ̀tun
Okọ yii ni wọn ti fi ko awọn ẹrọ amunwa jẹnẹratọ 300KVA, 25KVA kan ati Forklift kan to jẹ ti ileesẹ Sky
Abimbọla ni kọmisọnna ọlọpaa fun ipinlẹ Ogun, Edward Awolowo Ajogun ti pasẹ pe ki wọn lọ wadii iwa awọn ti ọwọ tẹ naa ki wọn si foju ba ile ẹjọ ni kete ti iwadii ba ti pari.
Tope Ajogbajesu: Mọ̀lẹ́bí kan ní orin ikú ọdún yìí fò mí ru ní Tope kọ láàrin ọ̀sẹ̀ tó kú
Hadiza, ìyàwó Ààrẹ Shagari jáde láyé lẹ́ni ọdún 80
Hadiza Shagari to jẹ iyawo aarẹ orilẹede Naijiria nigbakan ri, Shehu Usman Aliyu Shagari ti jade laye.
Iroyin n sọ pe arun covid-19 lo ṣekupa Iyawo aarẹ alagbada lorilẹede Naijiria nigbakan ri naa lọjọbọ, ọjọ kejila oṣu kẹjs ọdun 2021 nilu Abuja.
Atẹjade kan eyi ti ajagunfẹyinti Muhammad Bala Shagari lo fi iroyin iku rẹ mulẹ.
Nnkan bii agogo mẹta oru ni arabinrin Hadiza jade laye nileewosan Gwagwalada Isolation Center nilu Abuja.
Petrol Price: Sylva ní ẹ̀fẹ̀ ní àbá àwọn gómìnà tó dábàá èlé owó epo àmọ́ ìjọba yóò jíròrò pẹ̀lú ẹgbẹ́ òṣìṣẹ́
Oríṣun àwòrán, IPMAN
Ijọba apapọ Naijiria tun ti tẹnumọ pe oun ko ni pinnu lori iye ti lita epo tẹtirolu yoo jẹ afi to ba fẹnu ọrọ jona lori rẹ pẹlu ẹgbẹ osisẹ nilẹ wa.
Saaju ni ẹgbẹ awọn gomina ti kọkọ dabaa pe ki lita epo kan wa laarin ọrinlelọọdunrun naira (N380) si irinwo ati mẹjọ naira (N405) amọ tijọba ko tii buwọlu.
O wa yan pe owo lita epo yoo si wa bo se wa, titi tawsn ẹgbẹ osisẹ yoo fi pari ijiroro wọn pẹlu ijọba lori iye to yẹ ki owo lita epo kan jẹ.
Atẹjade kan ti Minisita abẹle fun ọrọ epo rọbi, Timipre Sylva fisita ti wa salaye pe lita epo petrolu kan ko le kọja naira mejilelọgọjọ (N162) si naira marunlelọgọjọ (N165) lẹyin ipade naa.
"O se dandan ka fi da awọn ọmọ Naijiria loju pe ijọba apapọ ko kanju lati fi owo kun owo lita epo pẹtirolu, ko le ba iye ti wọn n ta epo lọja agbaye bayii.
Blind Oniru: Muinat  Abdulfatai ní òun ro ara òun pin àmọ́ irú títà fún òun ní ìrètí ọ̀tun
Bi owo epo se wa lati osu Kẹfa ọdun yii naa ni yoo wa titi ta fi pari ifikunlukun wa pẹlu ẹgbẹ osisẹ.
Ọ si pọn dandan ka se alaye yii nitori iroyin kan to n lọ kiri nipa ipinnu ẹgbẹ awọn gomina to dabaa afikun owo lita epo pẹtirolu kan.
Mo wa n rọ awọn alagbata epo lati mase sọ owo ọja wọn di ọwọn tabi ti ileepo wọn pa, ki ọwọn gogo epo le wa fun araalu."
Oríṣun àwòrán, other
Àwọn 'Task Force' ìpínlẹ Eko ti ilé ìta oògùn ogún ní Shomolu, Bariga àti Oworonshoki
Kọmisọnna fun eto ilera nipinlẹ Eko, Ọjọgbọn Akin Abayomi ti fi atẹjade sita lori awọn ile itaja oogun ti wọn ti pa.
O ni idi pataki ti wọn fi gbe awọn ile itaja oogun naa ti pa ni nitori pe wọn ko tẹle ofin to ni i se pẹlu tita oogun ni ipinlẹ Eko.
Abayomi ni awọn miran tun n fi nkan mii kun oogun tita ni eyi ti wọn ko dẹ ni agbara lati maa se ni eyi to tako ofin.
Oladuni Giwa-Osagie: Òrùka mẹ́fà ní ọkọ́ mi fi bèèrè láti fẹ́ mi lẹ́ni ọdún 47
Ojọgbọn Abayomi ni titi awọn ile itaja oogun yii tọna labẹ ofin Section C34 to lodi si ayederu oogun ati awọn igbesẹ aitana lori ohun jijẹ ti Naijiria tọdun 1999.
O tun ni awọn ile itaja oogun ti ọrọ kan mii sẹlẹ nitori pe wọn ko ni aaye a n ko oogun pamọ si lọna to yẹ nigba ti awọn miran ko ni iwe ominira lati maa ta oogun bẹẹ ni awọn mii ni awọn oogun to ti bajẹ ti ọjọ ti lọ lori wọn lori igba.
Blind Oniru: Muinat  Abdulfatai ní òun ro ara òun pin àmọ́ irú títà fún òun ní ìrètí ọ̀tun
Bakan naa ni Abayomi ni awọn mii ni oogun ti ko yẹ ki wan ni lori igba lasiko ayẹwo ijọba sile itaja wọn ni ipinlẹ Eko.
O salaye lori awọn to ni asẹ lati ta ẹyọ ẹyọ ati awan to ni asẹ lati ta oogun ni pali ni pali.
Bakan naa lo ni ijọba ipinlẹ Eko yoo tẹsiwaju lati maa ko ayederu oogun kuro nilẹ ati lati maa se ayẹwo to yẹ fun awọn ile itaja oogun ki ọkan ara ilu le tubọ balẹ sii lori eto ilera wọn.
Tope Ajogbajesu: Mọ̀lẹ́bí kan ní orin ikú ọdún yìí fò mí ru ní Tope kọ láàrin ọ̀sẹ̀ tó kú
Nollywood Tonto Dikeh: Ọpọ Obìnrin ní inú wọn kún fún ìbànújẹ lásìkò yìí nítorí wọn kò yó ìfẹ lónà tó yẹ- Tonto Dikeh
Oríṣun àwòrán, Tontolet/instagram
Tonto Dikeh to jẹ ojuoge ninu awọn oserebinrin Nollywood ni Naijiria ti sọrọsoke lori ọrọ ifẹ.
O ni ọpọ obinrin ni inu wọn ko dun ti ọkan wan kun fun ibanujẹ lataari ifẹ to ti sọnu.
Tonto ni eyi ko sẹyin nitori pe awọn obinrin ko kọkọ ni ifẹ ara wọn saaju ki wọn to fi ọkan wọn fun ọkunrin kankan.
Tonto Dikeh gba imọran loju opo Instagram ẹ pe ki awọn Obi ati Alagbatọ fi ifẹ han si awọn ọmọbinrin wọn.
O ni ọpọ ni wọn jk onirobinujẹ ọkan latari pe wan ko ri ifẹ lati ọdọ obi wọn, bakan naa ni wọn ko nifẹ ara wọn.
Blind Oniru: Muinat  Abdulfatai ní òun ro ara òun pin àmọ́ irú títà fún òun ní ìrètí ọ̀tun
Tonto Dikeh ni oun n fojusona lati bi ọmọbinrin ti oun maa kọ nipa ifẹ ara ẹni saaju ifẹ ẹnikẹni.
O sọ iriri rẹ pe oun la ina kọja ki ọmọbinrin oun ma baa la irufẹ ina kan naa kọja.
Tunde Bakare journey in life: Bàbá bàbá mi ni Lèmọ́mù àkọ́kọ́ ní Sodeke Abeokuta ṣùgbọ́n..
Sunday Igboho: DSS fẹ́ gbọ̀nà ẹ̀bùrú yọ lórí béèlì àwọn méjìlá tí wọ́n mú nílé Sunday Igboho, àgbẹjọ́rò wọn ní ere ọmọdé ni wọ́n ńṣe
Oríṣun àwòrán, others
Agbẹjọro fun awọn eeyan mejila ti awọn agbofinro DSS  mu nile oloye Sunday Igboho ti kọminu lori iwe ẹjọ ti ileeṣẹ agbofinro DSS tun kọ sile ẹjs lati tako beeli ti wọn fun wọn.
Ni ilu Ibadan ni awọn agbofinro DSS ti ko awọn eeyan naa lasiko ti wọn kọlu ile oloye Sunday Igboho loru ọjọ keji oṣu keje ọdun 2021. Eeyan meji lo ku lasiko ikọlu naa.
Ni ọjọ kẹrin oṣu kẹjọ ọdun 2021 ni ile ẹjọ giga apapọ kan nilu Abuja gba beeli wọn.
Awọn eeyan naa ṣi wa lahamọ awọn agbofinro DSS lẹyin ti awọn agbẹjọro wọn ko tii ri ọrọ gbendeke beeli wọn yanju.
Yiyanju beeli naa n lọ lọwọ lawọn DSS ba tun gbe iwe ipẹjọ tako beeli naa dide eyi ti ọkan lara awọn agbẹjọro wọn, Pẹlumi Ọlajẹngbesi ṣapejuwe gẹgẹ bi ohun to ṣajeji to si tumọ si aṣilo ilana igbẹjọ.
O ni ohun to ṣe ajeji si ofin ilẹẹwa ni igbesẹ naa.
Sunday Igboho: Femi Falani ní ẹjọ́ Igboho ní Cotonou ń kọ́ àwọn amòfin Nàíjíríà ní ẹ̀kọ́
Ninu ọrọ to ba ileeṣẹ iroyin Premium Times sọ ni Ọjọru, amofin Ọlajẹngbesi ni titi di bi a ṣe n sọrọ yii ko ti si ẹsun kankan ti wọn ka si awọn eeyan naa lẹsẹ, sibẹ wọn n fẹ ki ile ẹjọ o yi ọrọ rẹ pada lori beeli to fun wọn lori ero wọn pe awọn n bọ wa pẹjọ.
Ohun ti DSS pe ẹjọ tako ni beeli awọn mẹrin ninu awọn mejila naa ti orukọ wọn n jẹ Amudat Babatunde, Abuideen Shittu, Jamiu Oyetunji ati Bamidele Sunday.
Onidajọ Obiora Egwuatu, ninu idajọ rẹ gba beeli awọn eeyan mejila naa to si wọgile ipe ti amofin DSS pe tako beeli awọn mẹrin naa.
Sunday Igboho: YCE rọ àwọn ọ̀dọ́ láti ṣọ́ra, ki wọ́n má baà di ẹran àmúso lọ́dọ̀ ìjọba bíí Igboho
Oríṣun àwòrán, sunday_igboho1
Ẹgbẹ awọn agbaagba nilẹ Yoruba, Yoruba Council of Elders(YCE) ni awọn n ṣiṣẹ labẹlẹ lati ri pe Oloye Sunday Adeyemo (Igboho) gba ominira lọgba ẹwọn to wa ni Cotonou lorilẹede Benin.
Akọwe agba ẹgbẹ YCE, Ọmọwe Kunle Olajide ṣalaye pe ọdọ Naijiria ko ni ireti mọ ninu orilẹede wọn nitori ko si ohun iwuri kankan fun wọn.
''Awọn ọdọ ko le fi ara da ọpọ nkan ti awọn agbalagba le gba mọ ra tori wọn maa n ro pe ijọba n fi akoko wọn ṣofo.
Ẹgbẹ YCE ko lodi si ohun tawọn ọdọ Yoruba n ṣe ṣugbọn a kan n kilọ fun wọn pe ki wọn rọra ṣe ni.
A ko fẹ ki ijọba sọ wọn di ẹran amoso tori ijọba lagbara to pọ, ohun to n ṣẹlẹ gan an niyii pẹlu ọrọ Igboho.
Kola Ologbondiyan: PDP ni yóò mú ọmọ Nàíjíríà kúrò lóko ìyà tí wọn wà ní 2023
Gbogbo agbara ti a ni, la n lo lati ri pe Igboho kuro ni atimọle to wa lorilẹede Benin Republic,'' Ọmọwe Olaide ṣalaye.
Ninu atẹjade mii ti akọwe ẹgbẹ YCE, ẹka ipinlẹ Ekiti, alagba Niyi Ajibulu fi sita, ẹgbẹ naa bu ẹnu atẹ lu eto abo to mẹhẹ kaakiri orilẹede Naijiria bayii.
Pa Ajibulu sọ ninu atẹjade naa pe ọrọ eto to mẹhẹ buru debi pe ẹru n ba awọn araalu lati rinrin ajo lati ibi kan lọ si ibomiran mọ.
''Eleyii buru pupọ, ko si gbọdọ tẹsiwaju, awọn Fulani darandaran, atawọn janduku ajinigbe lo yẹ ki ijọba wa nkan ṣe si ọrọ wọn ni kiakia.
Ẹgbẹ YCE gbagbọ pe orilẹede Naijiria wa fun gbogbo eeyan lai fi ti ẹya tabi ẹsin ṣe.
Ko si ẹni ti ko mọ awa Yoruba gẹgẹ bi ẹya to ni akinkanju, amọ iwa ẹlẹyamẹya ati siṣe egbe lẹyin ẹnikan ko dara.
Wikipedia: Ẹ̀nìkan sọ fún mi pé iṣẹ́ ìdọ̀tí ni màá ṣe ni mo ṣe ń ta ìwé
Ko si idi kan ti o le mu ki ẹnikẹni fiya jẹ tabi ṣe inunibini si ọmọ Yoruba kankan.
Iyẹn lo jẹ ki ẹgbẹ YCE ke pe gbogbo ọmọ Yoruba lati fọwọ sowọ pọ, ki wọn si fẹnu ko pẹlu gbogbo nkan to n ṣẹlẹ lasiko yii lorilẹede Naijiria.
Ẹgbẹ YCE tun fi asiko yii kepe ijọba apapọ pe ko faye gba ijọba awarawa ni tootọọ ati agbekalẹ iwe ofin tuntun yatọ si ti ọdun 1999,'' Pa Ajibulu lo sọ bẹẹ.
Chief Imam death: Ọlọ́pàá ní kò sí àpá lára òkú Ìmáàmù tó lè fihàn pé ajínigbé ló pa á
Oríṣun àwòrán, Facebook/M.O. Bakare
Ile iṣẹ ọlọpaa ipinlẹ Ogun ti sọ pe ko si ẹri to daju to fidi rẹ mulẹ pe awọn janduku tabi tabi awọn ajinigbe lo ṣekupa Imaamu awujọ Atiba ni Ijebu Ode, Sheikh Mushafau Bakare.
Inu mọto Imaamu naa si ni wọn ti ri oku rẹ ni ọsan Ọjọbọ.
Ni Ọjọru lawọn ẹbi Sheikh Bakare sọ fawọn ọlọpaa pe Imaamu naa ko pada wale lati igba to ti jade lọ.
Awọn ẹbi rẹ si ro pe o ṣeeṣe ko ti bọ sọwọ awọn ajinigbe pawo, ki wọn si ti ṣeku pa a.
Amọ ni owurọ Ọjọbọ ni wọn ri oku Imaamu naa ninu ọkọ Toyota Highlander to ṣẹṣẹ ra lagbegbe Ikangba ni ijọba ibilẹ Odogbolu nipinlẹ Ogun.
Awọn ọlọpaa to n ṣiṣẹ ni agọ ọlọpaa ẹkun Obalende ni Ijebu-Ode, lo ri oku Sheikh Bakare ninu ọkọ rẹ.
Wikipedia: Ẹ̀nìkan sọ fún mi pé iṣẹ́ ìdọ̀tí ni màá ṣe ni mo ṣe ń ta ìwé
Ṣugbọn agbẹnusọ ile iṣẹ ọlọpaa ipinlẹ Ogun, DSP Abimbola Oyeyemi, ṣalaye pe awọn ajinigbe kọ le gbe Imaamu yii.
Bakan naa ni DSP Oyeyemi sọ pe awọn agbebọn kọ lo pa Imaamu Atiba gẹgẹ bi ọpọ ṣe gbagbọ.
Agbẹnusọ ile iṣẹ ọlọpaa ni ko si apa kankan lara rẹ eyi to le fidi rẹ mulẹ bo ya awọn agbebọn tabi ajinigbe lo ṣeku pa a.
''Imaamu yii kuro ni ile lati lọ si ode ṣugbọn ko pada wale, eyi lo jẹ kawọn ẹbi rẹ fi ọrọ to awọn ọlọpaa leti.
Awọn ọlọpaa agbegbe Ijebu-Ode lo ri oku rẹ ninu ọkọ lẹgbẹ ọna nibi to duro si.
Ohun ti a gbọ ni pe Sheikh Bakara ni arun ẹjẹ ruru, o ṣeeṣe ko jẹ pe igba ti arun yii n yọ ọ lẹnu, ti ko si ri oluranlọwọ lo gbẹmi mi nitori ko si apa kankan lara oku rẹ,'' DSP Oyeyemi lo sọ bẹẹ.
Ẹwẹ, wọn ti sin oku Imaamu naa l'Ọjọbọ ni awujọ rẹ ni ilana ẹsin musulumi.
Osun Osogbo festival: Ọdún Osun gbìnàyá, t'onílé t'àlejò péjú fún ẹ̀bl àdúrà
Oni ọjọ kẹtala oṣu kẹjọ ọdun ni aṣekagba ọdun Osun Osogbo ti ọdun 2021 yii to waye ni ilu Osogbo, nipinlẹ Osun.
Gbajugbaja ni ojubọ oriṣa Ọṣun nilẹ Yoruba, ati kaakiri agbaye fun awọn to jẹ olufọkansin fun oriṣa naa.
Ilu Oṣogbo nipinlẹ Ọṣun ni igbo Ọṣun-Oṣogbo naa wa, ni agbegbe Eti Oso Ọṣun.
Niṣe lawọn oloriṣa Osun ro dẹdẹ kan dudu, aṣọ funfun balau ni ọpọ wọn wọ pẹlu ẹgba lọrun.
Bawọn obinrin ṣe ro iro aṣọ funfun lawọn ọkunrin naa ro aṣọ funfun, koda fila funfun ni wọn de pẹlu ilẹkẹ funfun lọrun.
Wamu wamu lawọn ọlọpaa duro lati ri pe abo wa fun awọn oloriṣa Osun to n sẹ ọdun.
Ọgọọrọ eeyan ti wọn wa lati ilẹ okeere atawọn to wa lorilẹede Naijiria lo peju pesẹ sibi ayẹyẹ ọdun Osun yii.
Awọn onimọ nipa ẹsin abalaye ni Naijiria sọ pe o ti le ni nkan bi ẹẹdẹgbẹrin ọdun ti awọn alaalẹ to tẹ ilu Osogbo do, ti bẹrẹ sii ṣe ọdun Osun Osogbo.
Ọdẹ nla kan, Olutimẹhin, lo jẹ adari awọn eeyan kan to n wa ọna abayọ si iyan to mu nibi ti wọn tẹdo si tẹlẹ.
Erongba wọn ni lati kọ ile ti wọn o maa gbe si eti odo Osun, ṣugbọn bi wọn ṣe bẹrẹ si ni ge awọn igi to wa nibẹ, itan sọ pe oriṣa odo naa, Osun, pariwo jade si wọn, o si le wọn kuro nibẹ.
Lẹyin naa lo sọ fun ẹni to dari awọn eeyan naa, Olutimehin, pe ko ko awọn eeyan rẹ lọ si ibi pataki kan (to di ilu Osogbo).
Osun ṣeleri lati daabo bo wọn, ti yoo si fun wọn ni ọrọ pupọ. Kikii pe ki wọn ma a fun un ni ẹbọ lọdọọdun.
Awọn eeyan naa gba lati maa ṣe bẹẹ. Ẹbọ ti wọn ma n fun un, lodi ọdun Osun Osogbo to n waye lọdọọdun bayii.
Lati igba naa si ni ibẹ ti di igbo mimọ nibi ti awọn olujọsin ti n korajọ lati sin jọsin fun.
Ohun si ni igbo oriṣa to tobi julọ titi di ode oni ni ilẹ Yoruba.
Lati mu ẹjẹ ti awọn to tẹ ilu Oṣogbo do, ṣe fun oriṣa Ọsun ṣẹ, wọn bẹrẹ si ni ṣe ọdun irubọ fun un ni ọdọọdun.
Ọsẹ meji gbako ni ayẹyẹ ọdun Osun-Osogbo fi ma n waye.
Bi eto ọdun Ọṣun-Oṣogbo ṣe ma n lọ
Ademuyiwa Wikipedia: Wọ́n fi ìgò lé mi, mo sì ń bá ìwọ̀sí pàdé lórí ìwé títà lójú pópó
Yoruba ni ẹni ti ko ba se bii alaaru ni Oyingbo, ko le se bii Adegboro lọja ọba, bẹẹ si ni ẹni ti yoo la, oju rẹ yoo ri to.
Awọn owe yii si la le sọ pe o jẹ mọ igbe aye ọkunrin kan, Adekola Ademuyiwa, to n ta iwe lọna ara ọtọ, nipa lilo awada, ẹfẹ ati ọpọlọ lati mu ki aje bu igba jẹ.
Idi si ree ti awọn onibara rẹ fi n pe ni Wikipedia.
Ademuyiwa, lasiko to n ba BBC Yoruba sọrọ lori ohun to sun de idi isẹ naa ni ẹnikan lo sọ fun oun pe isẹ idọti ni oun yoo se jẹun lati fi la.
O fikun pe inu oun maa n dun lati kiri lọ soju popo lọ ta iwe, eyi to rọrun fun oun lati se tori ko si ibi ti oun kii rin ẹsẹ de.
Ademuyiwa, ẹni to gbe oriyin fun iyawo rẹ to ti di oloogbe fun atilẹyin rẹ lati maa ta iwe naa, tun salaye pe oun maa n pa to ẹgbẹrun mẹwa si mẹẹdogun naira lojumọ ti ọja ba ya daadaa.
Nigba to n sọ awọn iriri rẹ nidi okoowo naa, Ademuyiwa ni obinrin kan ti oun fẹ fi se aya lẹyin iku iyawo oun, tabuku oun lori iwe tita naa.
Àwọn ìtàn mánigbàgbé tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí:
Bakan naa lo ni ẹnikan ti fi igo le oun ri lasiko ti oun npolowo iwe tita fun, o lẹ igo mọ oun amọ Ọlọrun ni ko jk ki igo naa ba oun.
Adekola Ademuyiwa wa rọ awọn ọdọ lati jara mọ isẹ, lai se ọlẹ nitori oun ti rin lati Iyana Ipade de Ikotun ri nitori iwe tita ati lati ri ti aje se.
Food Poison: Àwọn oúnjẹ́ mẹ́fà tó lè di májèlé ní àgọ́ ara ta bá jẹ wọ́n papọ̀
Oríṣun àwòrán, Pinterest
Agọ ara ọmọniyan yatọ sira wọn, ohun ti ẹda kan le jẹ ti yoo ba lara mu, si le sakoba fun agọ ara awọn eeyan miran.
Bi o tilẹ jẹ pe gbogbo ounjẹ lo ni anfaani to n se fun agọ ara amọ bi ire se wa ninu ibi, naa ni ibi wa ninu ire, ti isoro si le de ba ẹda lati ipasẹ awsn ounjk naa pẹlu.
Idi ree to fi dara ki ẹda kọọkan mọ irufẹ ounjẹ to ba lara mu ati eyi to le jẹ majele fun agọ ara ẹnikọọkan.
Bakan naa lo yẹ ki gbogbo eeyan mọ awọn ounjẹ kan to le se akoba fun agọ ara wa, to si le jasi iku ojiji, ta ba jẹ awọn ounjẹ naa papọ.
Onimọ nipa ounjẹ jijẹ, Habiba Haruna ba BBC sọrọ lori isọri ounjẹ mẹfa to le di majele ninu agọ ara fun ẹda kọọkan.
Afẹ Babalọla: Iyan ni mo fẹran julọ ninu ounjẹ
Ẹja ati Miliki jẹ ounjẹ to ni eroja asaraloore ta mọ si Protein to pọ pupọ, amọ ta ba pa ounjẹ mejeeji pọ, ta si jẹ wọn lasiko kan naa, ewu n bẹ loko longẹ.
Isoro le de ba ara wa ta ba jẹ ẹja ati miliki papọ nitori ara wa le kọ ọ.
Abala ẹya ara kan ko fẹran lati gba ounjẹ to ni eroja kan naa papọ lasiko kan naa, ta ba si se bẹẹ, o le da wahala silẹ.
Oniruuru ọna si ni ẹda kọọkan fi le se afihan pe aapapọ eroja ounjẹ mejeeji naa ko ba oun lara mu tabi pe o ti di majele ni agọ ara oun.
Ẹlomiran le maa bi nigba ti ẹlomiran le maa yagbẹ nitori pe o jẹ eroja mejeeji naa papọ, bi o tilẹ jẹ pe awsn mejeeji lo ni anfaani nla to n se fun ara.
Isọri eroja ounjẹ meji miran to tun le fa akoba fun agọ ara ta ba jẹ wọn papọ ni ọgẹdẹ ati miliki.
Amọ fun awsn eeyan miran, ajẹpọ miliki ati ọgẹdẹ le mu ki oorun kun wsn, ki wsn si sun daradara.
Ọgẹdẹ ni eroja kan ti wọn n pe ni Potassiun, ẹni ti eroja yii ko ba si to bo se yẹ ni agọ ara rẹ, le mu miliki mọ pọ ọgẹdẹ lai ni isoro.
Amọ fun ẹni ti o ba ni eroja Potassium to yẹ ninu ara, to ba fi jẹ ọgẹdẹ mọ miliki, isoro nla le ba agọ ara rk.
Lara irufẹ awọn isoro ti yoo maa ri ni ki ọrun maa yun, ko si maa họ, tabi ki irorẹ pupọmaa yọ loju rẹ, to si tun le ni aisan ẹjẹ riru.
Ti a ba fi miliki sinu eroja Lemon, kiakia ni yoo poora, tawọn eroja ara rẹ yoo si di akurẹtẹ
Idi si ree to fi jẹ pe ti ẹnikan ba po miliki papọ mọ Lemon, o le di majele ninu ara, bakan naa lo tun le jẹ ki aya maa ta eeyan.
Ẹpa dara fun agọ ara, to si wulo ni gbogbo ọna, bakan naa lo ni eroja asaraloore Protein ati Carbonhydrate.
Ẹpa tun jẹ eroja kan ti awọn eeyan to sanra maa n lo lati tiirin tabi mu adinku ba ọra ara.
Bakan naa ni eroja Olive oil dara lati setọju ara, to si tun n wo ọpọ aisan amọ ta ba da pọ mọ ẹpa, ta si jẹ, o le fa wahala fun agọ ara ti ko fẹran eroja Olive oil.
Bakan naa, ta ba lo oogun oyinbo pẹlu awọn ohun mimu aladun to ni gaasi ati eroja Lemon, o le se akoba fun agọ ara.
Onimọ nipa ounjẹ ni ta ba lo awọn ọti ẹlẹrindodo to ni gaasi ati eroja Lemon pẹlu oogun, ewu n bẹ loko longẹ.
O wa gba awọn eeyan nimọran pe ki wọn mase fi ohun mimu aladun lo oogun kankan, paapaa awọn ohun mimu to ni eroja gaasi ati Lemon.
Ti eeyan ba ko ẹran ati ẹyin tutu papọ, ewu nla ni fun agọ ara.
O le fa majele ba ara, to si tun le mu ki ẹlomin maa bi tabi yagbẹ nitori pe ko ba wsn lara mu.
Ẹran tutu le mu akoba ba ra ti a ko ba se daadaa.
Bakan naa ni onimọ nipa ounjẹ ss pe ẹyin tutu ko ni iwulo kankan fun agọ ara ayafi ta ba se tabi din, ka to jẹ.
Ẹyin tutu ko ni igbẹkẹle, ti a ko gbọdọ gbara le rara nitori ewu ni.
O wa gba awọn eeyan nimọran lati maa jẹ awọn ounjẹ ti yoo se ara wọn loore, ti yoo si se anfaani fun ara wọn lai ni akoba ninu.
Afẹ Babalọla: Iyan ni mo fẹran julọ ninu ounjẹ
Ogun state landgrabbers:Àwọn ajagungbalẹ̀ gba ilẹ̀ tó yẹ fún kíkọ́ iléèwé girama ní ìpínlẹ̀ Ogun
Oríṣun àwòrán, other
Ni ilu Isiun nijọba ibilẹ Ọbafẹmi Owode ni ipinlẹ Ogun, awọn ajagungbalẹ ti gba ilẹ ti wọn fẹ fi kọ ileewe girama nibẹ.
Gẹgẹ bi kabiyesi Olu ti ilu Isiun, Ọba Lawrence Adeyinka ṣe sọ ninu iwe ẹhonu to kọ si gomina ipinlẹ naa, Dapọ Abiọdun, ileewe girama Isiun High School ni wọn fẹ fi ilẹ  naa kọ ki awọn ajagungbalẹ to lọ gba ilẹ naa.
Ọba Lawrence ni iṣẹlẹ naa ti n dena igbesẹ ati gbe ileewe naa, eyi ti gomina ipinlẹ naa nigbakan ri, Ọlabisi Ọnabanjọ da silẹ lọdun 1980 dide pada.
Ọba Olu ti ilu Isiun tun ṣalaye pe titi ti wọn ti ileewe naa pa ti mu ki awọn akẹkọọ lati ilu naa  maa rin irin ọpọlọpọ kilomita lọ si awọn ileewe lawọn ileto to yi wọn ka ti awọn miran si wulẹ gbegi le iwe kika.
O nipatako afinimọna ti wọn ri siwaju ileewe naa lawọn kọlọransi naa ti wu danu ti wọn si ti n kọ ile sori ilẹ naa.
Wikipedia: Ẹ̀nìkan sọ fún mi pé iṣẹ́ ìdọ̀tí ni màá ṣe ni mo ṣe ń ta ìwé
Àjọ elétò ìdìbò INEC ní àwọn kan gbé òfégè ojú òpó ìforúkọsílẹ̀ olùdìbò síta yàtọ̀ sí ojúlówó ti INEC kéde
Oríṣun àwòrán, Inec
Ajọ eleto idibo ni Naijiria ti pariwo sita lori ayederu oju opo iforukọsilẹ ori ayelujara kan to wa nita.
Atẹjade kan ti alaga igbimọ iforukọsilẹ ati ilanilọyẹ awọn oludibo lajọ INEC, Festus Okoye fi sita ajọ INEC ni adirẹsi oju opo naa ni  https://register.inec-pvc.online/  pẹlu abuda ti wọn pe ni https://bit.ly/INEC-PvcReg2021.
Atẹjade naa fa awọn ọmọ Naijiria gbogbo leti lati maṣe ko sọwọ awọn kọlọransi to foju pamọ sẹyin ayederu oju opo naa.
Bakan naa ni INEC ni awọn ko fun ajọ tabi ẹnikẹni ni aṣẹ lati ṣe iforukọsilẹ lori ayelujara lorukọ oun.
Ajọ naa wa fi kun un pe oju opo iforukọsilẹ ori ayelujara to jẹ ojulowo ti ajọ naa ni https://cvr.inecnigeria.org,
Oríṣun àwòrán, Inec
Amọṣa alaga ajọ naa ti kọkọ ṣaaju kede agbekalẹ oju opo ayelujara kan silẹ fun awọnoludibo to ṣẹṣẹ fẹ forukọ silẹ lati lee ṣe bẹẹ lai si wọlukọlu lawọn ileeṣẹ ajọ INEC kaakiri orilẹede Naijiria paapaa lasiko ajakalẹ arun COVID-19 to gbode yii.
Ninu ọrọ kan ti alaga apapọ ajọ INEC, Ọjọgbọn Mahmood Yakubu ṣalaye pe ara awọn igbesẹ ọgbọn atinuda ti ajọ naa gbe kalẹ niyi lati mu ki eto iforukọ silẹ awọn oludibo o mu irọrun dani, ki o si  tun lee wa larọwọto awọn oludibo, ti yoo si mu eto naa jẹ awo rẹrin fawọn oludibo to fẹ dibo lorilẹede Naijiria.
Wikipedia: Ẹ̀nìkan sọ fún mi pé iṣẹ́ ìdọ̀tí ni màá ṣe ni mo ṣe ń ta ìwé
Yats si awọn to ṣẹṣẹ fẹ dibo fun igba akọkọ to fẹ tipasẹ bẹẹ fi orukọ silẹ, awọn to ti forukọ silẹ tẹlẹ ṣugbọn ti wọn fẹ ṣe ayipada ibudo ibi ti wọn ti forukọ silẹ ati ti wọn ti lẹtọ ati le dibo naa yoo le lo anfani oju opo ayelujara yii lati ṣe eyi.
Ondo state indigenes killed in Jos: Báyìí ní awakọ̀ Maruwa ṣé dóòlà ẹ̀mí mí lọ́wọ́ àwọn tó dá arìnrìnajò 22 lọnà ní Jos
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Arinrinajo kan ti ori ko yọ ti ṣalaye fun awọn oniroyin bi o ṣe moribọ ninu iṣẹlẹ ipaniyan awọn arinrinajo ni Jos.
Ni ọjọ Abamẹta  lawon  janduku kan  kọlu awọn musulumi to n dari bọ lati Bauchi lọ si iha Guusu Naijiria Eniyan bi mẹtalelogun ni wọn pa ninu wọn eniyan naa to n bọ lati ibi eto ayẹyẹ odun  tuntun Hijirah
Grandma Maruwa: Ó yẹ kí obìnrin sisẹ́ láì wojú ọkọ kó tó jẹun
"Muhammad Ibrahim jẹ okan ninu awon to moribọ ninu isẹlẹ ibi naa ni ipinlẹ Plateau to si sọ fun BBC pe bi kii ba ṣe ọpẹlọpẹ oni kẹkẹ Maruwa kan boya oun  naa ko ba ti di ara awọn oku bayii. ""Nigba ti isẹlẹ naa ṣe, mo kọkọ ro pe sunkẹrẹ fakẹrẹ ọkọ lasan ni, sugbọn ko pẹ ni mo bẹrẹ si ni ri ti wọn n ju okuta mọ mọto wa, mi o mọ bi mo ṣe gba oju ferese moto jade."""" Igba ti mo ba ara mi nilẹ ni oni kẹkẹ maruwa naa n pe mi pe ki n sare wọn inu kẹkẹ oun, bẹẹ ni mo ko sinu ẹ nnkan to ko mi yọ niyẹ. "" Ki o to di igba naa, oju ara mi ni mo fi ri bi wọn se n fi okuta fọ awọn eniyan lori"""
Oríṣun àwòrán, others
Aworan yii wa lati ibi rogbodiyan to waye ni Iwo-Road nilu Ibadan ni oṣu Kẹfa, ọdun 2021
Muhammed ni bi o tilẹ jẹ pe ori ko  oun yọ pẹlu ifarapa diẹ sibẹ ọjọ satide jẹ malegbagbe ni aye oun. Ni bayii, ijọba ti fi ofin konileogbele ni ijọba ibilẹ mẹta Jos North, Jos South ati Bass, ọpọ lo wa ninu ile wọn nito iṣẹlẹ naa.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ileeṣẹ ọlọpaa ti mu afurasi ogún lara awọn to pa awọn arinrinajo mejilelogun nilu Jos, nipinlẹ Ogun.
Ọjọ Satide ni wọn  pa awọn eniyan naa to jẹ arinrinajo lati ipinlẹ Ondo, lasiko ti wọn n pada sile lẹyin eto ẹsin Islam ni Bauchi.
Abule Rukuba ni ikọlu naa ti waye nigba ti awọn janduku ọhun yabo awọn ọkọ awọn arinrinajo naa.
Awọn to le ni ọgbọn lo tun fi ara pa laarin wọn.
Niṣe ni awọn onikupani ẹda naa yabo awọn ọkọ to gbe wọn, ti wọn si bẹrẹ si ni i ṣa wọn ni ada, lẹ okuta ati igi mọ wọn.
Ileeṣẹ ọlọpaa si ti di ẹbi iṣẹlẹ naa ru awọn ọdọ lati abule Iregwe, nibi ti ọpọ eeyan ti jẹ ẹlẹsin Kristiẹni.
Ninu atẹjade to fi sita, agbẹnusọ ileeṣẹ ọlọpaa Naijiria, Frank Mba sọ pe Ọga Agba ileeṣẹ ọlọpaa, Usman Alkali ti paṣẹ pe ki wọn o ko awọn ọlọpaa kogberegbe lọ si ipinlẹ Plateau lati mojuto eto aabo nibẹ.
Yatọ si awọn afurasi ti ọwọ tẹ, ileeṣẹ ọlọpaa sọ pe oun doola eeyan mẹtalelọgbọn miran .
Gomina Simon Bako Lalong ti ipinlẹ Plateau
Ninu iroyin miran lati gbọ pe ijọba ipinlẹ Plateau ti kede aṣẹ konile-o-gbele ni ilu Jos ati agbegbe rẹ nitori iṣẹlẹ iṣekupani naa.
Wakati mẹrinlelogun ni aṣẹ naa yoo fi ma a mulẹ.
Ijọba ipinlẹ naa sọ pe eeyan mẹtalelogun lo ku. Awọn alaṣẹ sọ pe ikede naa ṣe koko lati le dena ki eto abo dẹnu kọle.
Iṣẹlẹ ipani yii lo ti i buru ju ni Jos lati ọdun diẹ sẹyin ti ija ẹlẹyamẹya ati ti ẹsin dinku nibẹ.
Oríṣun àwòrán, others
Gomina ipinlẹ Ondo, Rotimi Akeredolu ti kesi awọn eniyan rẹ lati ni suuru, nitori ikọlu to waye si awọn kan ti igbagbọ wa pe ọmọ ipinlẹ naa ni wọn, nili Jos ni ipinlẹ Plateau.
Ọjọ Abamẹta ni iroyin jade pe awọn eeyan kan kọlu awọn eniyan naa lasiko ti wọn n rinrinajo pada lati ipinlẹ Bauchi si Gusu Naijiria.
Iṣẹlẹ yii lo waye lẹyin ọjọ diẹ ti ija kan ti kọkọ waye laarin awọn agbẹ to jẹ ẹlẹsin Kristiẹni ati awọn darandaran to jẹ Musulumi ni agbegbe naa.
Iroyin sọ pe ko din ni ọgbọn eeyan ti awọn jaguda yii pa lara awọn arinrinajo naa, ti ọpọlọpọ wọn si tun fi ara pa.
Ninu atẹjade ti Akọwe Ikede rẹ, Richard Olatunde fi sita ni alẹ ọjọ Abamẹta, Gomina Akeredolu sọ pe iroyin ti Gomina ipinlẹ Plateau fi to oun leti fihan pe arinfẹsẹsi ni awọn arinrinajo naa rin, nitori wọn ko mọ nkankan nipa ija to ti kọkọ waye.
Awọn iwadii to ti waye lori ipaniyan yii fihan pe awọn ọkọ awọn arinrinajo naa gba agbegbe ti rogbodiyan ti waye sẹyin, ti awọn to kọlu wọn si ro pe alatako ni wọn jẹ, nitori bi wọn ṣe kọ.
Gomina Akeredolu ni oun gba awọn eniyan ipinlẹ Ondo ni iyanju lati má fa wahala nitori iṣẹlẹ naa, to si bẹ wọn pe ki wọn o ma sọ ọrọ naa di nkan ti ko jẹ.
Mo ti ba arakunrin mi, gomina ipinlẹ Plateau sọrọ, o si ti fun mi ni idaniloju pe igbesẹ ti n waye lori iṣẹlẹ naa.Iwadii mi ati iroyin ti mo gbọ fihan pe lootọ ni wọn pa awọn eniyan kan, ti awọn to fi ara pa si ti n gba itọju nileewosan.
O daju pe arinfẹsẹsi ni iṣẹlẹ naa, gẹgẹ bi akẹẹgbẹ mi ṣe sọ fun mi. Mo si fẹ ẹ fi da awọn eniyan wa to n gbe ni ipinlẹ Plateau loju pe ko si ẹni to fẹ ẹ doju kọ wọn ninu ija ẹsin tabi ti ẹlẹyamẹya.
Bakan naa lo tun ba ẹbi awọn eniyan to padanu ẹmi wọn kẹdun.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ileeṣẹ ọlọpaa nipinlẹ Plateau ti sọ pe eeyan mejilelogun ti kagbako iku tawọn ọpọ si farapa ninu ikọlu kan to waye ni Jos.
Gẹgẹ bi wọn ṣe wi,musulumi lawọn arinrinajo to ku yii ti wọn si n dari bọ lati ibi ajọdun ọdun Hijrah kan ti wọn lọ ṣe ni Bauchi
Bi awọn arinrinajo yi ṣe n gba inu Jos kọja ni awọn kan da wọn lọna ti wọn si pawọn ni ipakupa.
O ṣeese ki iye eeyan to ku ninu iṣẹlẹ yi ju iye ti ọlọpaa pe lọ ti a ba wo nkan ti awọn ti ọrọ naa ṣoju wọn sọ.
Akọroyin kan to kan si ile iwosan lagbegbe iṣẹlẹ yi sọ fun BBC pe oun ka oku ọgbọn ti ọpọ si n gba itọju nibẹ
Gẹg bo ti ṣe wi, ọgbẹ ada lo wa lara pupọ awọn to farakasa iṣẹlẹ yi.
Ko tii si aridaju idi ti wọn fi doju ija kọ awọn arinrinajo musulumi wọn yi.
Wikipedia: Ẹ̀nìkan sọ fún mi pé iṣẹ́ ìdọ̀tí ni màá ṣe ni mo ṣe ń ta ìwé
Iṣẹlẹ yi waye lẹyin ikọlu kan laipẹ yi laarin awọn Fulani darandaran ati awọn agbẹ ẹya Iregwe ti pupọ wọn jẹ Kristẹni.
Gomina Simon Lalong ti bẹnu atẹ lu ikọlu yi to si ni ijọba ko ni faramọ iwa aibọwọ fun ofin kankan nipinlẹ naa.
Ija ẹlẹyamẹya ti waye kẹyin ni nkan bi ọdun 2001 ni Plateau ko to di pe o wa lọlẹ lẹnu lọọlọ yi.
Iṣekupaniyan eleyi lo buru julọ lẹnu igba ti ipenija aabo bẹrẹ si ni peleke si jakejado Naijiria.
Pa Olabode Olajide: Dẹ́rẹ́bà Awolowo ti jáde láyé l'ẹni ọdún 89
'Nígbà tí mò ń wà Awolowo, Gowon, Babangida, mo fi ara mi sípo ọ̀wọ̀ tóri ...'
Iroyin to n tẹwa lọwọ sọ pe awakọ to wa Chief Obafemi Awolowo nigba aye rẹ ti jade laye lẹni ọdun mọkandinlaadọrun.
Pa Olabode Olajide la gbọ pe o ki duniya pe o di gbere lẹyin aisan ranpẹ.
Mọlẹbi baba kan to fidi ọrọ yi mulẹ fun BBC sọ pe iku agbaọjẹ dirẹba yi waye lẹyin ọjọ mẹta ti iyawo rẹ papoda.
''Daddy wa ati Mummy wa ti ku.Pa Olajide Olabode ku ni nkan bi ago marun un aarọ.Mummy wa naa ku ṣaaju wọn ni ijẹta.Baba ku ni ana.''
Olabode Oladapo to jẹ ọmọ Pa Olabode ṣalaye pe wọn ku si Ado lẹyin ti wọn ṣaaju gbe wọn lọ si ile iwosan ni Ife.
''Wọn gbe wọn lọ si Ife ṣugbọn a gbe wọn pada wa si Ado. Nibẹ ni wọn ku si.''
Baba Olabode Olajide ni awakọ to wa ọpọlọpọ awọn aṣaaju orilẹede Naijiria.
Oríṣun àwòrán, Naija Gist
Ni gbogbo akoko to fi wa wọn, ko si eyi ti ko ranti ninu wọn to fi mọ igba ti awọn adari orilẹede mii lagbaye naa ba wa ṣe ibẹwo si awọn ti Naijiria.
Bo tilẹ jẹ pe baba Olajide ni awọn obi ko ri owo tọ ọ kọja ile iwe alakọbẹrẹ, o tiraka lati sọ ara rẹ di akọṣẹmọṣẹ ninu iṣẹ awakọ lai mọ wi pe eyi yoo sọ oun di mọlumọka to di lonii.
Laipẹ yi ni awọn eeyan tun ranti Pa Olabode nigbati igbakeji aarẹ Yemi Osinbajo ṣabẹwo si baba ati iyawo rẹ.
Yoruba Nation: Ààrẹ ẹgbẹ VOR sọ pé kí ọmọ Yorùbá di ààrẹ Naijiria kọ́ ni ọ̀nà àbáyọ
Aarẹ ẹgbẹ Awọn Agba Yoruba , ti wọn n pe ni Voice of Reasoning Alagba Olufemi Adegoke, ti sọ pe ko si nkan tuntun ti ọmọ Yoruba yoo sẹ to ba de ipo aarẹ Naijiria.
O ni ṣebi ọmọ Yoruba ni aarẹ nigba kan, Olusegun Obasanjo, ti ko si ri nkan pataki kankan ṣe lati mu ki igbeaye rọrun fun awọn ọmọ Yoruba.
O sọ pe  bakan naa ni Goodluck Jonathan to wa lati Gusu-Gusu Naijiria, ti oun naa ko ri nkan ṣe fun awọn eniyan rẹ.
Alagba Adegoke sọ pe ọpọlọpọ ọmọ Yoruba lo dibo fun Aarẹ Buhari nitori Yemi Osinbajo, ṣugbọn ẹnu Osinbajo paapaa ko tọrọ ninu iṣejọba.
“Nkan ti a nilo ni pe ka joko, ṣe atunsẹ ofin ọdun 1999, ka si dibo, ẹnikẹni to ba wọle naa ni.”
Lori ọrs ti oloye ẹgbẹ oṣelu Peoples’ Democratic Party, PDP, Oloye Bode George sọ nipa erongba Bola Tinubu lati dije fun ipo aarẹ lọdun 2023, Alagba Adegoke sọ pe otọ ọrọ ni  George sọ pe ki wọn o lọ ọ yẹ ọpọlọ Bola Tinubu wo.
“Idi ni pe gbogbo nkan to n sẹlẹ si awọn ọmọ Yoruba lati ọjọ yii, ko si eyi ti Tinubu sọrọ le lori. Ẹnikẹni to ba ni ki Tinubu ṣe aarẹ, o yẹ ki wọn o yẹ ori ẹni naa wo.
Bakan naa lo sọrọ lori akitiyan Sunday Igboho. O ni lootọ akinkanju ni Igboho, ṣugbọn kii ṣe ilana kumọ ni wọn fi n ṣe ijijagbara.
Ni ti ẹgbẹ wọn, VOR, awọn ko faramọ iyapa kuro ni Naijiria, ṣugbọn nkan ti awọn n polongo ni pe ki wọn o pin awọn nkan to wa ni Naijiria dọgba-dọgba fun gbogbo ẹya.
PIB bill meaning: Àwọn nkan tó yẹ láti mọ̀ nípa òfin eporọ̀bì tí Ààrẹ Buhari buwọ́lù
Oríṣun àwòrán, NNPC
Ofin tuntun lori eporọbi ti Aarẹ Buhari buwọlu ni ọjọ Aje, PIB 2020 jẹ ofin ti ireti wa pe yoo mu awọn atunto kan waye ni ẹka eporọbi ni Naijiria ati afẹfẹ gaasi.
Ọdun 2008 ni wọn kọkọ gbe kalẹ niwaju ile aṣofin apapọ, ki Aarẹ Muhammadu Buhari to o buwọlu lọjọ Aje, ọjọ kẹrindinlogun, oṣu Kẹjọ.
Ọpọlọpọ ofin to wa fun eporọbi ni Naijiria lo ti wa lati ọdun 1969, eyi to tumọ si pe wọn ko fi bẹẹ ba asiko yii mu mọ.
Oríṣun àwòrán, Nnpc
Ofin naa yoo  ṣe idasilẹ amojuto to koju osunwọn , ṣiṣe iṣẹ ni ọna to tọ, nipa ṣiṣe alakalẹ ojuṣe awọn oṣiṣẹ eporọbi ati ileeṣẹ, ti yoo si mu ki awn to n wa eporọbi tẹle ilana to yẹ.
Bakan naa ni yoo tun sọ ajọ NNPC di eyi ti yoo ma a pawo wọle lọna yanturu.
Ọkan pataki lara afojusun aba ofin naa ni lati ṣe igbelarugẹ wiwa ati tita eporọbi ni Naijiria fun anfaani awọn ọmọ Naijiria, ati lati mu idagbasoke to poju owo ba ẹka eporọbi.
Bakan naa ni yoo tun ri i daju pe aabo to peye wa ninu wiwa epo, gbigbe e lati ibi kan si ibomiran, akoyawọ ninu amojuto eporọbi ni Naijiria.
Yoo tun mu ki ifigagbaga wa lori iye ti awọn alagbata n ta epo bẹtiro ati gaasi, to fi jẹ pe onibaara le lọ si ibi to wu u.
Sugbọn ijọba ni yoo ma a mojuto idokoowo naa.
Ofin tuntun yii ti bori ofin mẹwaa to wa nilẹ tẹlẹ fun ọrọ eporọbi ni Naijiria
Aarẹ Muhammadu Buhari ti buwọlu ofin ti yoo mu atunto ba ẹka epo rọbi ti wọn n pe ni Petroleum Industry Bill, PIB tọdun 2021.
Oludamọran si aarẹ Buhari feto iroyin, Femi Adesina lo kede bẹẹ fawọn akọroyin nigba to ni ayẹyẹ bibuwọlu ofin tuntun naa yoo maa waye lọjọru.
Adesina ni ofin atunto ẹka epo rọbi tuntun yii lo wa lati se agbekalẹ ilana ọtun  fun ẹka epo rọbi ati idagbasoke awọn agbegbe ti epo rọbi ti n wa.
Ọjọ Kẹẹdogun osu keje ọdun 2021 ni ile asofin agba buwọlu ofin naa nigba ti ile asoju-sofin fontẹ lu lọjọ keji.
Wayi o, agbarijọpọ ẹgbẹ awọn eeyan agbegbe Niger Delta, PANDEF ti kede pe igbesẹ ti Buhari gbe, pẹlu bo se buwọlu ofin PIB naa, ko dara to.
"Agbẹnusọ apapọ fun ẹgbẹ PANDEF, Ken Robinson lo kede bẹẹ pẹlu afikun pe ""ọjọ ibanujẹ ati ọjọ buruku ni ọjọ oni jẹ lagbegbe Niger Delta ati Naijiria lapapọ."
Robinso, lasiko to n ba iwe iroyin Punch sọrọ ni bi o tilẹ jẹ pe awọn eeyan agbegbe Niger Delta tako igbesẹ naa, sibẹ aarẹ Buhari tẹsiwaju lati buwọlu ofin naa.
Yoruba Nation: Ààrẹ ẹgbẹ VOR sọ pé kí ọmọ Yorùbá di ààrẹ Naijiria kọ́ ni ọ̀nà àbáyọ
PANDEF lo ti kigbe saaju pe ida mẹwa owo tijọba ba n ri lati ara epo rọbi to n wa lagbegbe naa, ni ko maa fun awọn agbegbe ti epo naa ti wa.
Bakan naa lo yari lori ida mẹta ti ofin naa dabaa fun ijọba lati fun awọn agbegbe to n pese epo rọbi ninu owo to ba wọle lati ara epo naa.
"Eyi fihan pe ijọba Buhari ko naani ohun tawọn eeyan agbegbe Niger Delta n la kọja, awọn eeyan yii si lo n foju wina ayika wọn to ti bajẹ nitori epo ti wọn n wa nibẹ.
O se ni lanu pe lai naani bawọn araalu se pariwo to lori ida mẹta owo tasọrẹ ti ofin  naa gbe kalẹ fawọn agbegbe ti epo rọbi ti n wa ati ida ọgbọn fun ileesẹ NNPC.
Ọna tawọn eeyan n gba sisẹ aje lo ti bajẹ, ta si n jiya nitori iwakusa epo rọbi lagbegbe wa, sibẹ ijọba ko naani wa, to si tun n gbe awọn ofin ti ko dara le wa lori.
Adebimpe Oyebade: Láti yunifásítì títí dé àgbo tíátà láwọn ọkùnrin tí n fẹ́ bámi ní ìbálòpọ̀
Oríṣun àwòrán, Instagram/mobimpe
Gbajugbaja oṣere tiata Yoruba Adebimpe Oyebade ti tu kẹkẹ ọrọ lori ohun ti oju rẹ n ri lagbo oṣere tiata.
Ninu ifọrọwerọ pẹlu ileeṣe iroyin Naijriia This Day, adumaradan oṣere awẹlẹwa yi sọ pe nigba ti oun ti darapọ mọ Nollywood lawọn ọkunrin ti n gbiyanju lati ni ibalopọ pẹlu rẹ.
Adebimpe ṣalaye pe iru nkan bayi gbode kan ati pe ni ti toun lati igba toun ti wa ni ile ẹkọ fasiti ni oun ti n koju ipenija yi.
''Mi o le sọ pe mi o koju rẹ. Idi ta si fi n sa nipa iru iwa yi lagbo oṣere ni pe ojutaye la wa.''
''Nigba ti mo jẹ akẹkọọ fasiti, alamojuto mi ninu idanwo aṣekagba(project supervisor )fi ibalopọ lọ mi''
O ni nitori iriri oun, iru nkan bayi lagbo tiata ko jẹ  iyalẹnu rara.
''Awọn obinrin  ni mo da lẹbi bi awọn ọkunrin ṣe n fi ibalopọ lọ wọn. Idi si ni pe awa gan-an la maa n faaye gba wọn lati fi ibalopọ lọ wa.''
O tẹsiwaju pe bo ba ṣe pe awọn obinrin kii gba iru nkan bẹẹ ni, awọn to ti wa sọ di iṣẹ ko ni maa ṣe bẹ fun wọn.
''Oju mi ri to pẹlu awọn onilọkulọ nigba ti mo de Nollywood. O ṣu mi debi pe mo n beere pe ṣe mi o ti ṣi ọna ya si bayi. Ati oṣere ati oludari gbogbo wọn ni wọn n gbiyanju lati bami lajọṣepọ''
Nigba ti wọn wa beere lọwọ rẹ pe bawo lo ṣe bori awọn wọn yi, Adebimpe ni oun jẹ ki o yé awọn ọkunrin naa pe ko di dandan ki oun kopa ninu ere wọn.
Oba Ogboni Abalaye n fẹ́ kí wọ́n o má a fi ẹ̀sìn àbáláyé búra fún àwọn olóṣèlé Naijiria
O ni ọpọ eeyan lo maa n ṣe ohun ti ko bojumu nitori ki wọn baa le jẹ ilumọọka ṣugbọn ko ri bẹẹ lọdọ toun.
''Ki eeyan to le de ibi giga, o gba a suuru ati ki eeyan tẹra mọ iṣẹ. Mo mọ eeyan pupọ ṣugbọn kii ṣe gbogbo eeyan naa lo ri bẹ''
2022 Budget: Ìjọba Nàìjíríà fẹ́ yá N4.89 tirilọ̀nù láti san gbèsè ètò ìṣúná
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Lẹyin obitibiti gbese ti orilẹ-ede Naijiria ti jẹ, ijọba apapọ tun ti n gbero lati ya owo to to N4.89 tiriliọnu owo naira fún eto iṣuna ọdun 2022.Minisita eto inawo, Zainab Ahmed lo ṣi aṣọ loju eegun ọrọ yii l'Abuja.Minisita Ahmed ni owo ti ko wọle daadaa to fun Naijiria lo maa jẹ ki ijọba ya owo yii lati le loo fun eto iṣuna N13.98 tiriliọnu ti ijọba n gbero fun ọdun to n bọ.
Minisita ṣalaye ọrọ yii bakan naa fun igbimọ ile aṣoju-ṣofin to n ri si eto inawo.Hajia Ahmed ni bi owo Naira ṣe ja lulẹ sí dọla ati pọun naa ṣe akoba fun owo to n wọle fún orilẹ-ede Naijiria.Minisita ni  ijọba gbé ìgbésẹ lati ya owo san gbese N5.62 tiriliọnu ninu eto iṣuna ọdun 2022.Bakan naa ni minisita tun ṣalaye pe ijọba ti din iṣẹ akanṣe ku fun ọdun 2022 .
Oba Ogboni Abalaye n fẹ́ kí wọ́n o má a fi ẹ̀sìn àbáláyé búra fún àwọn olóṣèlé Naijiria
Minisita ṣalaye pe owo to to N259.315bn ni ijọba fi ṣe adinku iṣẹ akanṣe fun ọdun 2022.Hajia Ahmed ni eyi waye nitori bi ọrọ aje Naijiria ti n ṣe ojojo ati bi ajakalẹ arun covid-19 ti ṣakoba fun ọrọ ajé.Ni bayii, N1.76trn ni ijọba yoo na lori iṣẹ akanṣe lọdun 2021 eyi to kere si N2.02trn ti ijọba na lọdun 2021."
"N410.15 ni a fi ṣe gbedeke pasipaarọ owo naira sí dọla nigba ti a fi $57 dọla ṣe gbedeke owo agbaa epo rọbi fun eto iṣuna,"" minisita ṣalaye.Mínísítà fikun ọrọ rẹ pe awon ẹka ọrọ ajé mii yatọ sí epo rọbi dagba pẹlu owo to to N169.69trn."
Sunday Igboho Aides: Lẹyìn tí gbogbo ètò tó àwọn amúgbálẹ̀gbẹ́ kò rí adájọ́ tí yóò buwọ́lù béèlì wọn
Oríṣun àwòrán, Punch
Bi iya n la ba gbeni sanlẹ,Yoruba ni kekere a maa gun ori ẹni.
Bẹẹ lọrọ ri pẹlu bawọn amugbalẹgbẹ Sunday Igboho ti adajọ ni ki wọn lọ ṣeto beeli wọn ko ṣe ri adajọ lẹyin ti gbogbo eto beeli wọn pe tan.
Idi ni pe adajọ to yẹ ko buwọlu iwe itusilẹ wọn ti ṣe irinajo pajawiri lọ si ilẹ okere.
Gẹgẹ bi iwe iroyin Naijriia Punch ṣe jabọ, agbẹjọro awọn ti o wa ni ahamọ DSS wọn yi,Pelumi Olajengbesi, sọ pe gbogbo nkan ti adajọ Obiora Egwuatu ni ka wọn ṣeto lawọn ti ṣe.
O ni  ṣugbọn o jẹ iyalẹnu pe adajọ ile ẹjọ giga yi nilu Abuja ko si lorileede Naijiria.
Olajengbesi ni oun lọ si ọfisi ti wọn ti n ṣeto beeli awọn eeyan lọjọ Iṣẹgun ṣugbọn o ni  wọn sọ fun  oun pe adajọ ti rinrinajo kuro ni Naijiria
Sunday Igboho Update: Igboho ti sọ ohun tó fẹ́ kí a ṣe tí ọ̀rs bá bẹ́yìn yọ- Saheed Yusuf
''Gbogbo eto beeli la ti se ti igbakeji akọwe ile ẹj si ti buwlu.Sugbọn  awọn to wa ni ọfisi beeli ni adajọ to yẹ ko buwọlu iwe yi ti lọ fun idanilẹkọ kan ko si ni pada de titi di ọsẹ to n bọ''
Agbẹjọro yi sọ pe ọgbọn ki wọn baa le fi awọn amugbalẹgbẹ Igboho si ahamọ fọsẹ kan si lẹyin ti wọn ti ti wọn mọlẹ fun aadọta ọjọ ni wọn n da.
Ni ọjọ Kẹrin oṣu Kẹjọ ọdun 2021  ni adajọ Egwuatu  ti gba pe ki wọn tu awọn amugbalẹgbẹ yi silẹ lẹyin ti wọn ba ṣeto beeli wọn tan.
Sunday Igboho aides: Ó ṣeéṣe kí adájọ́ míràn buwọ́lu ìwé béèlì àwọn méjìlá tí DSS mú nílé Igboho lónìí
Oríṣun àwòrán, others
Adajọ tuntun ni ile ẹjọ giga apapọ to wa nilu Abuja ni ireti wa pe yoo buwọlu iwe aṣẹ beeli awọn eeyan mejila ti awọn agbofinro DSS ba ni ile aṣiwaju ipe fun idasilẹ orilẹede Yoruba, Yoruba Nation, Oloye Sunday Adeyẹmọ ti ọpọ mọ si Sunday Igboho.
Gẹgẹ bi ohun ti awọn iroyin abẹle gbogbo n sọ, awọn eeyan mejila naa ti mu gbogbo gbendeke ti adajọ Egwuatu to gbọ ẹjọ wọn la kalẹ fun beeli wọn ṣẹ.
Iroyin sọ pe, ọkan lara awọn agbẹjọro fun awọn eeyan mejila naa, Amofin Pẹlumi Ọlajẹmgbesi kan si ẹka to n mojuto ọrs beeli ni ile ẹjs naa ni ọjọ Iṣẹgun lati yan adajọ miran ti yoo buwọlu iwe beeli awọn eeyan naa.
O ti to nnkan bii aadọta ọjs ti awọn eeyan mejila naa ninu eyi ti obinrin kan wa ti lo ni ahamọ awọn DSS bayii.
Ninu ọrọ to ba BBC News Yoruba sọ lẹyin ọsẹ diẹ ti wọn mu awọn eeyan mejila naa si ahamọ, agbẹjọro fun Oloye Sunday Igboho, Amofin agba Yọmi Aliyu, San ṣalaye pe awọn agbofinro DSS ko fun awọn eeyan naa lanfani ati tọju ara wọn koda eyi to n jẹ obinrin ninu wọn gan ko lanfani si awọtẹlẹ tuntun yatọ si eyi to baa kuro nile lọjọ ti awọn oṣiṣẹ DSS kọlu ile Igboho ni ọjọ kini oṣu keje ọdun 2021.
Yollywood movies: Gbajúmọ̀ òṣèré, Rose Odika ní aráàú, àjọ 'Censors board'
Ọlajẹmgbesi sọ ṣaaju pe ẹka to n mojuto ọrọ beeli nile ẹjọ naa ti kọkọ ṣalaye fun oun lọjọ Iṣẹgun pe Onidajọ Obiora Egwuatu to yẹ ko buwọlu iwe aṣẹ beeli wọn ti rinrinajo lọ si oke okun lati moju to ohun kan ni kiakia.
O ṣalaye fun iwe iroyin The Punch pe Onidajọ Egwuatu lo yẹ ko buwọlu iwe naa ki o to di pe o lọ soke okun.
Oba Ogboni Abalaye n fẹ́ kí wọ́n o má a fi ẹ̀sìn àbáláyé búra fún àwọn olóṣèlé Naijiria
Lara gbendeke ti Ile ẹjọ beere fun beeli awọn eeyan naa ni oniduro mejimeji, ti apapọ rẹ fi jẹ mẹrinlelogun eleyi to mu idiwọ diẹ ba ijafafa ati gba beeli wọn lẹyin ti adajọ ni aye beeli yọ fun wọn nibi igbẹjọ to waye lọjọ kẹrin oṣu kẹjọ ọdun 2021.
Yollywood movies: Gbajúmọ̀ òṣèré, Rose Odika ní aráàú, àjọ 'Censors board' pẹ̀lú ọ̀nà àti ta ọjà ló mú kí fíìmù oníhòhò ó pọ̀ lórí igbá
Iṣẹ ere itage, sinima agbelewo ṣisẹ kii ṣe iṣẹ alagbe mọ gẹgẹ bi awọn eeyan ṣe maa n fi oju woo ni igba kan sẹyin. O ti di iṣẹ to n jawo, to n mu ọpọlọpọ biliọnu dọla owo ilẹ Amẹrika wọle pẹlu.
Amọṣa ohun kan ti o n kọ ọpọ lominu ni pe pẹlu bi iṣẹ yii ti ṣe gbẹrẹgẹjigẹ to bayii, awọn ohun kan to n waye nibẹ n ṣe akoba fun awujọ, ninu eyi ti bi ṣiṣi ara silẹ awọn oṣere, papajuls awọn to jẹ obinrin ninu wọn ṣe wa di tọrọ fọnkale.
Gbajumọ Oṣere Rose Odika to ba BBC News Yoruba sọrọ ninu ifọrọwerọ yii ṣalaye pe lootọ ohun to ku diẹ kaato ni eyi ṣugbọn ọna ti jẹ naa ni nitori gbogbo awọn to n gbe sinima jade lo n gbero ati ta ata jere ọja. O fi kun un pe lọpọlọpọ igba ti awọn oṣere ba gbe fiimu to fọnrere aṣa wa jade, gbogbo awọn to n kọminu lori ṣiṣi ara silẹ wọn naa ni kii raa, bẹlni owo yoo wọgbo ti yoo si di gbese si ọrun oṣere bẹẹ.
Bakan naa lo ṣalaye pe ijọba gbe ajọ ayẹwo kan kalẹ gẹgẹ bi ọlọpaa to n ṣọ iṣẹ ti awọn oṣere n gbe jade, ti a pe ni Nigeria Censors Board. O ni ko si sinima kan to n jade lorilẹede Naijiria ti ajọ yii ko mọ si, nitorina naa to ba jẹ pe lootọ ni wọn n ṣe iṣẹ wọn ni, ko yẹ ki iru awọn ohun ti a n sọrọ rẹ yii tun maa jẹyọ.
Goriola Hassan: Bí o ko ba yọju níwájú ilé, a ó fi ọlọ́pàá gbé ọ́, Alaga Igbimọ pàsẹ fún Goriola Hassan lórí ipò rẹ̀ bi ọba Imobi
Oríṣun àwòrán, other
Ile igbimọ asofin ipinlẹ Ogun tun ti ke si ọgbẹni Goriola Hassan lati farahan niwaju igbimọ tẹẹkoto lori ọrọ ijọba ibilẹ ati ifinijoye lori wahala to wa nilẹ nipa ipo ọba ilu Imobi-Ijebu.
Ipo Goriola gẹgẹ bi ọba Imobi ti n da gbọmisi-omi-o- to silẹ
"O yẹ ki o faraha niwaju ile igbimọ asofin ipinlẹ Ogun ni ọjọ keji osu kesan-an ni aago mọkanla owurọ.
Igbimọ tẹẹkoto ti Bolanle Ajayi n se alaga rẹ tun kọwe ipe ranṣẹ si Hassan lasiko ipade wọn fun igba keji lori ẹsun ti awọn ẹgbẹ ọmọ ibilẹ Imobi  kan mu lọ sile asofin nitori ipo ọba to wa ni ilu Imobi.
Ijoko keji yii ni awon lọbalọba to wa fun ipade naa to fi mọ Onitasin ti  Itasin, Oba Adenola Adegbesan, ati awọn Baalẹ ti ọrọ kan  lati agbegbe
Ajayi ati awọn ọmọ ile to ku ti paa lasẹ lati sinmi pipẹ ararẹ ni Olu ri Imobi nitori ijoba ipinlẹ Ogun ti kọwe ransẹ si lati ipase ile isẹ ijọba to n ri si ọrọ ijoba ibilẹ ati ifinijoye.
Oba Ogboni Abalaye n fẹ́ kí wọ́n o má a fi ẹ̀sìn àbáláyé búra fún àwọn olóṣèlé Naijiria
Alaga Igbimọ naa fi kun pe ti Hassan ba kọ lati gbọnran si ipe ile igbimọ asofin, bi o se kò lati wa fun meji akọkọ, eyi yoo mu ki awọn pe ọlọpaa lati mu.
Saaju ni abẹnugan ile Olakunle Oluomo sọ pe Goriola kan si oun ni ọsẹ lori ọrọ naa ri oun si sọ fun pe kosi sise ko si aiṣe ki o kọkọ yoju si ipe awon igbimọ tẹẹkoto, nitori ile ti ro wọn lagbara lati se iwadii ọrọ naa, lẹyin ti awọn ara ilu ti kọ iwe ẹsun si ile igbimọ asofin
Gómìnà Aminu Masariì ti ipínlẹ̀ Katsina ní àsìkò tó kí aráàlú ó lọ ra ìbọn láti dáàbò bo ara wọn lọ́wọ́ àwọn agbébọn
Oríṣun àwòrán, other
Ọrọ abo lorilẹede Naijiria ti di eyi to so ọlọgbọn ati omugọ kọ bayii; oniruru ọna abayọ si lo n jade lati koju rẹ.
Nibayii, gomina ipinlẹ Katsina lẹkun iwọ oorun ariwa orilẹede Naijiria, Aminu Masari ti ke sawọn araalu lati lọ wa ibọn atawọn ohun ija miran lọnakọna lati gbeja ara wọn lọwọ awọn janduku agbebọn to n jinigbe pawo bayii.
Ipinlẹ Katsina wa lara awọn ipinlẹ ti iwa ipa yii pọ ju si bayii bẹẹni apa awọn oṣiṣẹ agbofinro ko fẹrẹ kaa mọ.
Gomina Aminu Masari di ẹbi ru awọn araalu fun bi awọn agbebọn ṣe n ṣọṣẹ kaakiri.
O ni bi awọn araalu ṣe maa n jọwọ ara wọn silẹ bi ọlẹ ati ojo n tubọ mu ki awọn agbebọn naa o laya sii lati ṣe iṣẹ buruku wọn.
Lasiko abẹwo rẹ si ilu Jibia, ọkan lara awọn ileto to n fara kaasa ikọlu awọn janduku agbebọn wọnyii ni gomina Aminu Masaari sọ ọrọ yii.
Bi ẹ ko ba ni gbagbe, minisita fọrọ abo lorilẹede Naijiria lo kọkọ gbe aba yii kalẹ loṣu keji ọdun 2021  eleyi to mu ki ọpọlọpọ eeyan o bu ẹnu atẹ luu nigba naa.
Kola Ologbondiyan: PDP ni yóò mú ọmọ Nàíjíríà kúrò lóko ìyà tí wọn wà ní 2023
Ọpọlọpọ lo n foju wo ọrọ wọnyii gẹgẹ bi ọna kan ti ijọba fi n ta araalu lolobo nipa ijakulẹ wọn lori ọrọ abo ati ṣiṣi ojuṣe idaabo bo ara ilu pada sori araalu funra wọn.
Bakan naa lawọn lamẹtọ kan naa tun n jẹ ko di mimọ pe atunbọtan irufẹ ipe bayii to ba bọ sii yoo buru pupọ fun ọrọ abo ilu gan an.
Amotekun: Ikọ̀ Amotekun ní àwọn kọ́ ló pa ọmọ ọdún 15 tí wọ́n yìnbọn pa ní Ibadan, ọ̀tọ̀ ní ibi tí àwọn ti ṣiṣẹ́ lóru Ọjọ́bọ
Adari ikọ Amotekun nipinlẹ Oyo, Ajagunhfeyinti Olayinka Olayanju ti ṣe alaye wi pe ikọ ẹsọ alaabo naa ko mọ ohunkohun nipa iku ọmọ ọdun meedogun ti ọta ibọn da ẹmi rẹ legbodo loru mọju Ojoru ni agbegbe Mokola nilu Ibadan.
Ninu ọrọ to ba awọn akọroyin sọ lowurọ Ojoru ni olu ileese ikọ naa to n bẹ ni agbegbe Dandaru nilu Ibadan, Olayanju ṣalaye fun awon akọroyin pe ọtọ ni ibi ti ikọ naa ti ṣiṣẹ loru mọju ọjọ naa.
O tẹsiwaju pe ikọ Amotekun gba ipe pajawiri ni oru Ojoru ni agbegbe Sango nilu Ibadan, ibẹ si ni wọn yara lọ lati doola ẹmi awọn eeyan ti awọn ole ati ọdaran n da laamu.
O fi kun ọrọ rẹ pe nnkan iyanu gbaa ni bi iroyin ṣe gbode kan lowurọ Ojoru wi pe ikọ Amotekun ṣekupa ọdọkunrin kan ni agbegbe Mokola.
Ọkan lara awọn aṣoju agbegbe Sango ti ikọ Amotekun se abewo si loru moju, Arakunrin Olusola Olaleye naa ṣalaye fun akọroyin BBC pe looto ni awọn ke pe ikọ Amotekun ni nnkan bii aago kan aabọ oru nitori awọn igara ọlọṣa to n yọ awọn lẹnu lagbegbe naa lati bi oṣu melo kan sẹyin.
O ni gbogbo irin ti Amotekun rin loru mọju ko gba ọna Mokola ti wọn ti pa ọmọkunrin ẹni ọdun meedogun.
L'owuro Ojoru ni ọgọrọ awọn ọdọ lati agbegbe Mokola gbe oku ọmọkunrin naa lọ si olu ileese Amotekun ati ofisi gomina ipinle Oyo pẹlu ẹsun pe ikọ Amotekun lo ṣekupa ọmọ naa ṣugbọn ikọ naa jiyan ọrọ.
Yollywood movies: Gbajúmọ̀ òṣèré, Rose Odika ní aráàú, àjọ 'Censors board'
Iroyin yajoyajo lati ilu Ibadan n fidi rẹ mulẹ pe igboro ti daru lagbegbe Mọkọla nilu Ibadan lẹyin ti oṣiṣẹ Amọtẹkun kan yinbọn fun ọmọ ọdun marundinlogun kan nibẹ.
Awọn ọdọ kan bẹrẹ si nii wọde lọ si Sẹkitariati ijọba ipinlẹ Ọyọ lori bi awọn oṣiṣẹ Amọtẹkun ni ipinlẹ Ọyọ ṣe yinbọn fun awọn ọdọ kan.
Awọn oluwọde naa n ṣalaye pe ọdọmọdekunrin ọms ọdun marundinlogun ti wọn yinbọn naa ti jade laye ati pe o yẹ ko ba wọn joko ṣe idanwo aṣekagba girama WAEC lọwọlọwọ bayii.
Awọn ti iṣẹlẹ naa tun ṣoju wọn ṣalaye pe Ọjọru ni iṣẹlẹ naa waye.
Gẹgẹ bi ohun ti wọn sọ siwaju, akẹkọọ na n fẹ lọ ounjẹ ti yoo jẹ lagbegbe Sabo nilu Ibadan ni wọn fi ṣiimu gẹgẹ bi adigunjale ti wọn si yin in nibọn.
Awọn oluwọde naa ti gbe oku ọmọ naa kuro ni Mọkọla lọ si Sẹkitariati agodi .
Ghana Reverend Father Kiss: Àlùfáà Obeng Larbi tọrọ àforíjì lọ́wọ́ àwọn akẹ́kọ̀ọ́ tó fi ẹnu kò lẹ́nu
Oríṣun àwòrán, Other
Alufaa ijọ Anglican , Baltharzzar Obeng Larbi to fi ẹnu ko awọn akẹkọọbinrin lẹnu laipẹ yii ti tọrọ aforiji lọwọ awọn akẹkọọ naa.
Bakan naa lo tun tọrọ aforiji lọwọ awọn ẹbi wọn, ati ijọ Ọlọrun to fi mọ gbogbo araalu.
Ọsẹ to kọja ni fidio kan gba ori ayelujara, eyi to ṣafihan Alufaa Larbi, bo ṣe n fi ẹku ko awọn akẹkọọbinrin mẹta lẹnuwo, lasiko ti wọn n ṣe ayẹyẹ kan nile ẹkọ wọn, St. Monica College of Education, lorilẹ-ede Ghana.
Alufaa Larbi sọ pe oun n gbiyanju lati ki wọn fun bi wọn ṣe tayọ lẹnu ẹkọ wọn, paapaa bi wọn ṣe n lọ fun iṣẹ ode.
O ni akẹkọọ ipele kẹta ni awọn ọmọbinrin naa, ti wọn si n lọ fun iṣẹ ode ti wọn n pe ni 'teaching practice' ni ede Gẹẹsi.
Yoruba Nation: Mo faramọ́ àtúntò 'Restructuring' tí kò lọ́wọ́ ìṣèlú nínú- Oba Ahmed Adeku
Alufaa naa sọ pe ki gbogbo eniyan dari jin oun, ki wọn o si gbadura fun un lasiko idanwo yii.
Mo tọrọ aforijin fun awọn nkan ti mo ṣe ninu fidio naa. O daju pe mo ti fi ọwọ yẹpẹrẹ mu awọn nkankan . Mo gba pe iwa mi ko bojumu nibi to ti ṣẹlẹ, bi ko tiẹ si Covid-19 nita."""
Oba Ogboni Abalaye n fẹ́ kí wọ́n o má a fi ẹ̀sìn àbáláyé búra fún àwọn olóṣèlé Naijiria
Lẹyin ti fidio naa jade sita ni awọn alaṣẹ ijọ Anglican gbe igbimọ kalẹ lati wadii ọrọ naa, ti wọn si jẹjẹ pe awọn yoo ba Alufaa Larbi wi pẹlu ofin ati ilana ijọ wọn.
Lẹyin wakati mẹrinlelogun ni wọn paṣẹ fun alufaa naa lati fi isẹ silẹ fun igba diẹ, gẹgẹ bi alufaa ile ẹkọ naa, titi iwadii yoo fi pari.
Ti wọn si tun sọ pe eto igbani ni imọran ti n waye fun awọn akẹkọọbinrin naa, lati le dena ibanujẹ ọkan to le fẹẹ jade nipa iṣẹlẹ naa.
Ọlatunji, akẹ́kọ̀ọ́gboyè 'graduate' tó ń ta àkàrà 'Ó ta lẹ́nu' nílùú Osogbo
Ara meeriri, mo ri ori ologbo lori atẹ ni isẹlẹ to waye nile ẹkọ olukọni agba ti St Monica nilu Kumasi, lorilẹede Ghana.
Ayẹyẹ ikẹkọọjade lo n waye nile ẹkọ naa to jẹ ti ijọ Anglican, ti Fada Balthazar Obeng Larbi si jẹ Alufa ile ẹkọ naa.
Amọ Fidio kan to gba ori ayelujara kan lẹyin ayẹyẹ ikẹkọjade naa, lo se afihan Fada yii, to n fi ẹnu ko awọn akẹkọbinrin mẹta lẹnu lara awọn akẹkọọjade naa.
Koda, ọpọ awọn alejo lo wa ninu gbọngan ti ayẹyẹ naa ti n waye lo n patẹwọ fun  lasiko ti Fada naa gbe ẹnu si ẹnu awọn akẹkọọ ọhun.
Isẹlẹ yii si lo waye lasiko ti abala kẹta ọwọja arun arun Coronavirus n peleke si lorilẹede Ghana.
Fidio naa, ti ko to isẹju kan, lo n se afihan Fada Obeng Larbi yii, nibi to ti n fi ẹnu ko ikọọkan awọn akẹkọbinrin naa lẹnu.
Yollywood movies: Gbajúmọ̀ òṣèré, Rose Odika ní aráàú, àjọ 'Censors board'
"Akẹkọbinrin kẹta to lo ibomu lo kọkọ tiiri ara lati fi ẹnu ko Fada lẹnu amọ ti alufa naa ni ko yọ ibomu rẹ lati gba ""kiss"" oun."
Fidio yii lo ba ibinu ọpọ eeyan pade lori ayelujara, ti wọn si n pe Fada naa ni ẹni to le ba ọmọde lopọ tabi ko arun ba wọn lasiko arun Covid-19 yii.
Yoruba Nation: Ààrẹ ẹgbẹ VOR sọ pé kí ọmọ Yorùbá di ààrẹ Naijiria kọ́ ni ọ̀nà àbáyọ
Nigba to di ọjọ Isẹgun ni ijọ naa kede pe ki Fada Balthazar Obeng Larbi lọ rọọkun nile na lẹyin ipade ti awọn alasẹ ijọ ati ile iwe naa se lati tanna wadi ihuwasi rẹ to n fa ariwo naa.
Koda, loju ẹsẹ ni wn ti gba ipo alufa ileẹkọ naa lọwọ Fada yii, ti wọn si tun ni ko ni sisẹ bii amofin mọ fun ẹka eto ẹkọ lorilẹede Ghana fun ẹkun Ashante.
Bakan naa ni ijọ wa kede fawọn araalu pe wọn ti n se idanilẹkọ fun akẹkọbinrin mẹtẹẹta ti ọrọ yii kan.
Ilé wó lu Bisi, ọmọ ẹ̀yìn rẹ̀ kú, wọ́n gé ẹsẹ̀ rẹ̀ tó ń jẹrà, inú ìrora ló wà ṣùgbọ́n
"A ti ni ki Fada Balthazar Obeng Larbi lọ rọọkun nile na gẹgẹ bii Alufa ileẹkọ olukọni naa, ta si tun ko lọ sinmi lori awọn isẹ miran to n se titi ta fi pari iwadi wa lori awọn ẹsun ti wọn fi kan.
Bakan naa ni igbimọ to n tanna wadi ẹsun alufa naa yoo gbe aba kalẹ lori igbesẹ to kan lori isẹlẹ yii lẹyin iwadi wọn."
Ilé wó lu Bisi, ọmọ ẹ̀yìn rẹ̀ kú, wọ́n gé ẹsẹ̀ rẹ̀ tó ń jẹrà, inú ìrora ló wà ṣùgbọ́n Dókítà tún ń sọ pé...
Awọn agba bọ wọn ni bi a ba n wa ohun ti a o jẹ, ki a maa pade ohun ti yoo jẹ wa.
Ọrọ Abilekọ Bisi Ajayi jẹ eyi ti yoo gbomi loju ọpọlọpọ.
Bisi, jẹ oniṣowo kekeke to si jẹ wi pe inu ere to n ri lori owo rẹ yii lo fi n gbọ bukata ẹbi rẹ; iyẹn ohun, ọkọ ati ọmọ mẹrin ti wọn bi.
Amọṣa, lati nnkan bi oṣu meji bayii ni Bisi ti wa nile iwosan nibi ti ko le rin, koda ko lee yi ara pada funrarẹ lori ibusun to wa.
Nigba to n ṣalaye bi irinajo aye rẹ ṣe jẹ, Abilekọ Bisi Ajayi ni oun jade gẹgẹ bi iṣe rẹ lati wa ohun ti oun atawọn ọmọ oun yoo jẹ ni ọjọ kẹfa oṣu kẹfa ọdun 2021 ni ile kan fi wo lu oun ati ọmọ ti oun pọn si ẹyin, loju ẹsẹ ni ọmọ to pọn jade laye ti wọn si gbe oun tikalara digbadigba lọ si  ato egungun lọna ti ibilẹ fun itọju.
Amọṣa, o ni lẹyin asiko diẹ ni ẹsẹ naa bẹrẹ si nii run ti wọn si ni lati gee nileewosan.
Nigba ti o ṣi n ba iyipada ọtun to de ba aye rẹ yii finra ni wọn ba tun sọ fun un pe nnkan ti ṣe egungun ẹyin rẹ ati pe o nilo iṣẹ abẹ fun atunto rẹ.
Ibadan LG boss attack: Ẹgbẹ́ ALGON fún iléeṣẹ́ Immigration ní gbèǹdéke ọjọ́ kan láti fi ilé iṣé ìjọba ìbílẹ̀ Oyo sílẹ̀
Oríṣun àwòrán, other
Ẹgbẹ ijọba ibilẹ, ALGON, ẹka ti ipinlẹ Oyo ti fun ajọ to n ri si wiwọle ati jijade awọn eeyan si orileede Naijiria, Nigeria Immigration Service (NIS) ni gbedeke wakati mẹrindilogun lati kaasa wọn kuro ni gbogbo ile iṣẹ ijọba ibilẹ mẹtalelọgbọn to wa nipinlẹ Oyo.
Alaga ẹgbẹ ALGON l'Oyo, Họnọrebu Sikiru Sanda lo sọrọ yii fawọn akọroyin ni ijọba ibilẹ Ariwa Ibadan.
Họnọrebu Sanda ni igbesẹ yii ko ṣẹyin ikọlu tawọn oṣiṣẹ NIS ṣe sí alaga ijọba ibilẹ Ariwa Ibadan, Họnọrebu Sahib Yusuf.
Alaga ẹgbẹ ALGON l'Oyo ti wa kepe ọga agba ajọ NIS ni Naijiria pe lati ṣe iwadii iṣẹlẹ ọhun.
O ni awọn alaṣẹ ajọ NIS gbọdọ ri pe wọn fi awọn oṣiṣẹ wọn to fi iya jẹ alaga ijọba ibilẹ Ariwa Ibadan foju wina ofin.
Họnọrebu Sanda fikun ọrọ rẹ pe ajọ NIS gbọdọ tọrọ aforijin lọwọ alaga ijọba ibilẹ Ariwa Ibadan, bi bẹẹ kọọ, ọrọ naa yoo dé ilé ẹjọ.
Nigba ti o b'awọn akọroyin sọrọ, Họnọrebu Yusuf ni oun ko ṣe ohun kan to le mu ki awọn oṣiṣẹ NIS dunkooko mọ oun.
Alaga ijọba ibilẹ Ariwa Ibadan ni oun lọ yanju awọn ọrọ ọfiisi kan nile iṣẹ ajọ NIS ni ki wọn to ṣe ikọlu sí òun.
O ni ọrọ naa ko ba di nkan nla ṣugbọn oun ko fẹ da omi alaafia ipinlẹ Oyo ru ni.
Ohun ti Yorùbá ń pè ní Èṣù yàtọ̀ sí Sátánì nítorí Èṣù ní iṣẹ́ rere lọ́wọ́
Gbẹgẹdẹ gbina lagbegbe Agodi nilu Ibadan nirọlẹ Ọjọru, ọjọ kejidinlogun osu kẹjọ ọdun 2021 nigba ti iroyin kan pe oṣiṣẹ ileeṣẹ wọlewọde orilẹede Naijiria kan ti di igbaju olooyi lu alaga kansu kan nilu Ibadan.
Nigba to n ba BBC sọrọ lori iṣẹlẹ naa, Alaga ijọba ibilẹ Ibadan North, Shuaib Oladayo sọ pe kii ṣe iya diẹ ni awọn oṣiṣẹ ajọ immigration fi jẹ oun ni ọfiisi wọn.
Ọgbẹni sọ pe ẹnikan lara awọn kanselọ to wa ni ijọba ibilẹ naa lo gbọ ni ọfiisi awọn ajọ immigration pe awọn kan n fi ayederu lẹta ijọba ibilẹ naa ṣe aṣemaṣe ni ọdọ wọn.
"O ṣalaye pe ẹsun naa ni oun fẹ ẹ lọ yanju, lati jẹ ko ye wọn pe kii sẹ ọdọ oun ni lẹta naa ti n wa, ki ""oun to o kabuku""."
O ni awọn ti yanju ọrọ naa tan ni ọfiisi Ọga ajọ immigration, to si jẹ pe nibi ti oun ti n duro ni ita de kanselọ ti ọrọ kan ni awọn oṣiṣẹ ajọ naa kan ti wa a ba oun pe ki oun kuro nibẹ.
"Mo kọkọ ro pe ọga wọn kan lo n bọ ni, kia ni mo si bọ si ẹgbẹ kan. Amọ, iyalẹnu lo jẹ pe wọn bẹrẹ si ni i fi i abuku kan mi.
Ọga wọn kan pe mi lati tun ba wa yanju rẹ, ọfiisi rẹ loke si la wa ti mo fi sọkalẹ wa a wo awọn eniyan mi nitori ibẹru pe ija le ti bẹrẹ."""
Ilé wó lu Bisi, ọmọ ẹ̀yìn rẹ̀ kú, wọ́n gé ẹsẹ̀ rẹ̀ tó ń jẹrà, inú ìrora ló wà ṣùgbọ́n
O ni aarin ija ni oun bọ si , to si jẹ pe bi oun ṣe n gbiyanju lati beere nkan to ṣẹlẹ ni awọn oṣiṣẹ immigration yabo oun.
Ọnarebu Oladayo sọ pe gbogbo ọwọ ati ẹsẹ oun lo bo fẹlẹ-fẹlẹ lasiko ti awọn oṣisẹ immigration lu oun ni alubami.
O ni ṣugbọn, oun ko fi ṣe ibinu lẹyin ti DPO ọlọpaa agbegbe Testing Ground ni Iwo-Road da si ọrọ naa.
Oríṣun àwòrán, Shuaib Oladayo
Aworan yii ni Họnọrebu Shuaib Ọladayọ fi ranṣẹ lati ṣafihan ifarapa to ni lasiko ija naa
O ṣalaye pe lootọ ni awọn oṣiṣẹ ijọba ibilẹ naa fi ibinu sọ pe awọn ko ni i jẹ ki awọn oṣiṣẹ immigration gbe awọn ọkọ wọn to wa ninu ọgba ijọba ibilẹ naa jade nigba ti awọn oṣiṣẹ pari iṣẹ ọjọ naa,  ṣugbọn oun ba awọn eniyan oun wi, lẹyin ti DPO ọlọpaa tun pe oun.
"Koda, taya ọkọ ẹnikan lara wọn ti awọn eeyan mi ti jò, mo pe fọganaisa lati fẹ ẹ.
Ibi ti mo ti n ba fọga sọrọ, ẹyin ni mo kọ si awọn to ku. Bẹẹni ẹnikan lara awọn oṣiṣẹ immigration sare si mi. Bi ede aiyede ṣe bẹrẹ niyii, pe ṣe wọn tun fẹ ẹ wa na mi ninu ọfiisi mi ni."
O tẹsiwaju lati sọ pe bẹẹ ni awọn oṣiṣẹ immigration naa bẹrẹ si ni i yinbọn ati afẹfẹ taju-taju ni ẹnu ọna ijọba ibilẹ.
Ninu fidio to fi ranṣẹ si BBC, iro ibọn n dun lakọlakọ, ti awọn eeyan si n sa asala fun ẹmi wọn.
Yollywood movies: Gbajúmọ̀ òṣèré, Rose Odika ní aráàú, àjọ 'Censors board'
Nigba ti BBC kàn si agbẹnusọ ajọ immigration nipinlẹ Oyo, sọ pe oun ko le sọ ohunkohun lori iṣẹlẹ naa.
O ni idi ni pe oun ko ti i gba aṣẹ lati sọrọ, ati pe oun wa ni ileewosan ti oun ti n gba itọju nitori ọgbẹ ti oun gba lasiko wahala naa.
Gbẹgẹdẹ gbina lagbegbe Agodi nilu Ibadan nirọlẹ Ọjọru, ọjọ kejidinlogun osu kẹjọ ọdun 2021 nigba ti iroyin kan pe oṣiṣẹ ileeṣẹ wọlewọde orilẹede Naijiria kan ti di igbaju olooyi lu alaga kansu kan nilu Ibadan.
Awọn oju mi too kan ti ọrọ naa ṣoju wọn ṣalaye pe agbegbe ile ijọba Government house to wa ni Agodi ni iṣẹlẹ naa ti ṣẹlẹ lasiko ti alaga ijọba ibilẹ ariwa Ibadan, Họnọrebu Shuaib Ọladayọ pẹlu obinrin kan lọ gba iwe irinna silẹ okeere nileeṣẹ iwọle wọde Naijiria to wa nibẹ.
O tẹsiwaju pe pipe ti oṣiṣẹ Ileeṣẹ wọlewọde naa pe alaga kansu naa pe ibi to gbe ọkọ rẹ si ko bojumu to ati pe yoo ṣe idiwọ fun lilọbibọ ọkọ nibẹ lo mu ki ki Họnọrebu Shuaib o gbara ta.
Iroyin sọ pe alaga naa ke sawọn janduku kan lati lu awọn oṣiṣẹ wọlewọde naa eleyi to mu ki awọn pẹlu o lọ dira wa pẹlu awọn akẹgbẹ ti ọrọ fi di boolọ o ya fun mi.
Lasiko ti a fi ko iroyin yii jọ, a ṣi n tiraka lati kan si Họnọrebu Shuaibu ati ileeṣẹ wọlewọde Naijiria, Nigeria Immigration Service, ẹka ti ipinlẹ Ọyọ.
Aheregbe festival: ọdún Ahérégbé àti Amólè bẹ̀rẹ̀ lónìí l'Akure, Déjì ní kí wọ́n tí gbogbo ọjà pa
Ọdọọdun ni ọdun Ahérégbé àti Amólè maa n waye nilu Akure ti tọdun yi ko si yatọ si tatẹyinwa.
Niṣe lawọn araalu bọwọ fun aṣẹ ti Deji pa pe ki wọn ma ṣe ṣi ṣọọbu itaja.
Die ree ninu awọn aworan binkan ti ṣe lọ nibi ọdun yi ni Akure.
Paroparo lawọn ile itaja ni Ọja Oba ti tẹlẹ da ti ko si si karakatra kankan to n waye nibẹ.
Ki gbogbo nkan baa le lọ leto leto, awọn eeyan kan a maa kaakiri lati ri pe awọn eeyan tẹlẹ aṣẹ yi.
Ẹnikẹni ti wọn ba ri to ṣi ṣọọbu, wn a maa ko ọja rẹ ti ko si ni si nkankan ti yoo tẹyin rẹ bọ.
Oríṣun àwòrán, BBC Sport
Lara awọn eto to maa n waye nibi ọdun naa ni pe awọn ijoye yoo ṣe abẹwo si Deji ilu Akure.
Deji ti ilu Akure, Ọba Aladetoyinbo Ogunlade Aladelusi ti ni ki wọn ti gbogbo awọn ile itaja ati ṣọọbu to wa nilu naa nitori ọdun Aheregbe ati Amole ti yoo waye.
Awọn ọdun naa yoo waye lọjọ kọkandinlogun, oṣu Kẹjọ, ọdun 2021, ati ọjọ kẹrin, oṣu Kẹsan an, ọdun 2021 yii kan naa .
Ninu atẹjade ti agbẹnusọ ori ade naa, Adeyeye Michael fi ṣọwọ si awọn akọroyin, o ni igbesẹ naa ṣe pataki ki wọn le raye ṣe ọdun naa to maa n waye lọdọọdun.
Lasiko ọdun ọhun ni awọn agbagba ilu Akure maa n gbadura fun alaafia ilu naa, to fi mọ ilu Oba Ile, eyii ti ko fi bẹẹ jina si Akure.
Ko ni si kata-kara ninu awọn ilu memeji lasiko ti ọdun Aheregbe ati ọdun Amole yoo maa waye.
Ẹnikẹni to ba taja ni ayajọ ọdun naa le padanu ọja rẹ nitori awọn to n kaakiri ilu lati ri daji pe ọdun naa bo ṣe yẹ ko lọ le ko ọja irufẹ ẹnio bẹẹ.
Ilé wó lu Bisi, ọmọ ẹ̀yìn rẹ̀ kú, wọ́n gé ẹsẹ̀ rẹ̀ tó ń jẹrà, inú ìrora ló wà ṣùgbọ́n
To n tumọ si pe awọn to n kaakiri naa laṣẹ labẹ aṣa ilu Akure lati ko tabi gbẹsẹ ọja irufẹ oniṣowo bẹẹ.
Bakan ni ilu yoo ko iṣọwọ awọn miran si aarin igboro pẹlu paṣan lọwọ ti wọn a si maa ko paṣan bo ẹnikẹni to ba tapa si ilana to rọ mọ ọdun ọhun, bii ṣiṣi ṣọọbu.
Ṣaaju ni oloye Aṣamọ ti ilu Akure ti kọkọ sọ fun awọn akọroyin pe ọdun naa ṣe pataki niluu Akure ki alafia le jọba ninu ilu naa.
O fi kun pe ko pọju ti wọn ba ya ọjọ meji pere sọtọ laari n ọdun kan lati ṣe ọdun fun alaafia awọn araalu.
Àwọn èèkàn ẹgbẹ́ ní ilẹ̀ Yorùbá ní bí nǹkan ṣe rí pẹ̀lú àbò ní Nàìjíríà, bí aráàlú bá ní ìbọn fún àbò ara wọn kò burú o
Oríṣun àwòrán, Amotekun
Awọn ẹgbẹ ọmọ Yoruba kan ti sọrọ lẹyin ti gomina ipinlẹ Katsina, Bello Masari gba awọn ọmọ ipinlẹ rẹ nimọran pe ki wọn lọ ra ibọn lati daabo bo ara wọn.
Lara awọn ẹgbẹ naa ni ẹgbẹ Afenifere ati ẹgbẹ awọn agbagba ilẹ Yoruba, Yoruba Council of Elders, YCE.
Ninu ọrọ ti wọn ba BBC Yoruba sọ, wọn ni o ṣeni laanu pe odidi gomina ipinlẹ lo n sọ fun awọn eeyan rẹ pe ki wọn lọ ra ibọn lati daabo bo ara wọn.
Wọn ni eyii n tumọ si pe gomina ọhun ti kuna ninu ojusẹ rẹ gẹgẹ bii ijọba, ati pe ijọba naa ti dojuru.
Nigba to n ba BBC Yoruba sọrọ, akọwe agba ẹgbẹ YCE, Dokita Kunle Olajide sọ pe bo tilẹ jẹ pe awọn eeyan ilẹ Yoruba bọwọ fun ofin gidi ṣugbọn asiko ti to fun wọn lati lọ ra ibọn fun abo ara wọn.
"O ni ""Asiko ti to fun awọn eeyan lati maa ra ibọn lati daabo bo ara nibi ti ọrọ de duro yii, ṣugbọn wọn gbọdọ gba aṣẹ lọwọ ileeṣẹ ọlọpaa."""
Ilé wó lu Bisi, ọmọ ẹ̀yìn rẹ̀ kú, wọ́n gé ẹsẹ̀ rẹ̀ tó ń jẹrà, inú ìrora ló wà ṣùgbọ́n
"Olajide sọ pe ""Ọmọ wa to ba fẹ ra ibọn, ko lọ gba iwe aṣẹ lọwọ ijọba lati fi daabo ara rẹ, ko si ohun to buru nibẹ, ṣugbọn awa ko ni tẹ ofin loju mọlẹ."""
Nigba ti ọkan lara awọn aṣaaju ẹgbẹ Afenifere, Bashorun Sehinde Arogbofa n da si ọrọ naa, oun naa sọ pe ko si ohun to buru nibẹ ti ijọba ba fi aye gba awọn araalu lati maa lo ibọn fun abo ara wọn.
"O ni ""O yẹ ki ijọba faye gba awọn eeyan ilu, paapaa awọn to kawe, ti ọpọlọ wọn pe lati maa lo ibọn."""
"Arogbofa sọ pe ""Ṣe o tọ ki awọn ọdaran wọnyii ti wọn mọ ibọn n lo ka eeyan mọle ki eeyan ma le dabo bo ara rẹ ni?"""
Ṣugbọn ti awọn ọdaran naa ba mọ pe ẹni ti wọn fẹ lọ ba yii ni ibọn lọwọ, ati pe o mọ bi wọn ṣe n lo ibọn naa, wọn oo ronu wọn daadaa ki wọn to kọlu irufẹ ẹni bẹẹ.
Bo tilẹ jẹ pe baba Arogbofa ni ojuṣe ijọba ni lati daabo bo ẹmi ati dukia araalu, ṣugbọn ijọba ti kuna ninu ojuṣe rẹ, idi ree ti awọn araalu fi ni lati bẹrẹ si n dabo bo arawọn.
O pari ọrọ rẹ pe ijọba apapọ ni lati ri awọn ọmọ Naijiria gẹgẹ bii ọkan ṣoṣo, ko si tun jawọ ninu iwa ẹlẹyamẹya, bi bẹẹ kọ, o ṣeeṣe ki nnkan buru ju bo ṣe wa yii lọ.
Ṣaaju ni gomina ipinlẹ Katsina, Bello Masari ti kọkọ ke si awọn eeyan ipinlẹ rẹ pe wọn ni anfani lati lọ ra ibọn lọna ati daabo bo ara wọn.
Ninu atẹjade kan ti agbẹnusọ rẹ, Abdu Labaran Malumfashi fi lede, o ni ọrọ eto abo kii ṣe ojuṣe ijọba nikan, awọn araalu naa ni lati ji giri sii.
O sọ ọrọ naa lasiko to n ba ẹbi awọn eeyan kan to jade laye lẹyin ti ọmọ awọn oni fayawọ gba wọn kẹdun.
Ẹwẹ, ọpọ awọn onimọ nipa eto abo lo ti bẹrẹ si n fi erongba wọn lede lori ọrọ gomina ọhun.
Lai Mohammed: Ṣé mo jọ ẹni tó gba Benin Republic sá kúrò ní Nàìjríà ni, Lai Mohammed fèsí sí ìróyín pé Ó yọ́ kẹ́lẹ́ kúrò ní Nàìjíríà
Oríṣun àwòrán, other
"Minisita fun ọrọ iroyin ati aṣa lorilẹede Naijiria, Ọgbẹni Lai Mohammed ti sọ pe irọ ko si idi kan fun oun lati daṣọ bori kuro lorilẹede Naijiria bi ẹni ""to gba orilẹede Benin Republic sa kuro lorilẹede"""
Ni Ọjọru ni iroyin kan jade sita pe Minisita fọrọ iroyin ati aṣa, Lai Mohammed ti kuro lorilẹede Naijiria ati pe o yọ kẹlẹkẹlẹ lọ si orilẹede Amẹrika ni lati lee lọ ṣe ipade pọ pẹlawọn alaṣẹ ileeṣẹ oju opo ikansiraẹni Twitter.
Amọṣa ninu ifọrọwerọ kan to ṣe pẹlu ileeṣẹ akoryinjọ NAN, Lai Mohammed ni iroyin ofege lasan ni iroyin naa nitoripe gbogbo ọna to yẹ ki eeyan rin lati rinrinajo kuro ni Naijiria ni oun rin ki oun to wọ baluu.
Bakan naa lo fi kun un pe oun ko tori Twitter wa si Amẹrika bikoṣe lati ṣe ipade pẹlawọn ileeṣẹ iroyin agbaye gbogbo nipa ọkan-o-jọkan ilakaka ijọba Aarẹ Muhammadu Buhari lati koju igbesumọmi ati awọn agbebọn pẹlu ajinigbepawo ni Naijiria.
O ni iroyin ti iwe iroyin naa gbe jẹ apẹrẹ kan gboogi nipa ewu ayederu iroyin ati ijamba ti o lee mu ba orilẹede bi igbesẹ to yẹ ko ba waye lori gulegule awọn oju opo ayelujara.
Nigba ti wọn sọ pe mo yọ kẹlẹkẹlẹ kuro ni Naijiria, ṣe wọn fẹ sọ pe papakọofurufu ti ẹnikẹni ko si ni mo ti wọ ọkọ ofurufu ni abi boya mo rinrinajo lọ si Benin republic lati gba ibẹ kuro ni Naijiria?
Ilé wó lu Bisi, ọmọ ẹ̀yìn rẹ̀ kú, wọ́n gé ẹsẹ̀ rẹ̀ tó ń jẹrà, inú ìrora ló wà ṣùgbọ́n
Lai Mohammed ni papakọ ofurufu agbaye ti gbogbo eeyan n lo ni oun pẹlu lo, ti oun si ṣe gbogbo eto irinna to yẹ nitori naa ko si idi fun ẹnikẹni lati sọ pe oun daṣọ bori kuro ni Naijiria.
Ijọba orilẹede Naijiria ati ileeṣẹ Twitter ṣi n jiroro lori ọna ati pada sẹnu iṣẹ rẹ lẹyin ti ijọba fi ofin dee lẹyin to yọ atẹjade kan ti ileeṣẹ aarẹ fi sita.
Bi o tilẹ jẹ pe ijọba apapọ ni igbesẹ naa ko ni ohunkohun lati ṣe pẹlu yiyọ atẹjade aarẹ danu bikoṣe nitori iṣọkan orilẹede Naijiria, ọpọlọpọ awọn onwoye lo ti bu ẹnu atẹ lu igbesẹ ti ijọba Naijiria gbe lori ọrọ naa.
EndSARS: Àwọn ìyàwó àwọn ọlọ́pàá tó kú lásìkò ìwọ́de EndSARS ní sọ̀wédowo tí ọ̀gá àgbà ọlọ́pàá fún wọn kò gbówó jáde ní báǹkì
Oríṣun àwòrán, livetimesng.com
Awọn iyawo awọn ọlọpaa to kagbako iku ni ipinlẹ Ọyọ lasiko iwọde EndSARS ti pariwo sita lori airi owo sọwedowo ti ijọba fun wọn gba  gẹgẹ bi owo gba ma binu lori iku awọn baale wọn.
Loṣu kẹwaa ọdun 2021 ni awọn ọlọpaa yi padanu ẹmi wọn ti ijọba si fun mọlẹbi  kọọkan ni sọwedowo ẹẹdẹgbẹta ẹgbẹrun naira (N500,000).
Gẹgẹ bi wọn ti ṣe sọ fun BBC, gbogbo igba tawọn ba ti de banki lati gba owo naa, niṣe ni iwe naa maa n ta paupau lori ẹrọ ile ifowopamọ.
Ninu ọrọ ti wọn sọ nibi ipade kan ti wọn pe nilu Ibadan, wọn ni iwe sọwedowo ti n fori ko  jankariwọ ninu ile nitori ko fẹ ẹ wulo fawọn.
Wọn tsiwaju pe lati igba ti ọga ọlọpaa ti fun awọn ni iwe wọn yi lati oṣu kini ọdun 2021, ijakulẹ lawọn n ba pade ni banki ni gbogbo igba.
Wọn wa ke si aarẹ Muhammadu Buhari pe ko boju wo awọn ko bawọn dide si ọrọ naa nitori iya to n jẹ awọn lati igba ti awọn ọkọ wọn ti jade laye lẹnu iṣẹ wọn ko lẹgbẹ rara.
Awọn ọlọpaa marun un lawọn janduku pa nipinlẹ Ọyọ lasiko iwọde EndSARS ti ọpọlọpọ miran si fara ṣeṣe.
Awọn ọlọpaa to ku nigba iwọde naa ni ipinlẹ Ọyọ ni Adegoke Ajibọla, Rotimi Ọladele, Peter Abegunde, James Akanmu ati Alidu Yusuf Wada.
Ilé wó lu Bisi, ọmọ ẹ̀yìn rẹ̀ kú, wọ́n gé ẹsẹ̀ rẹ̀ tó ń jẹrà, inú ìrora ló wà ṣùgbọ́n
Secondus visits Obasanjo: Nítorí wàhálà tó ń wáyé lẹ́gbẹ́ òṣèlú rẹ̀, Uche Secondus, alága PDP mórílè ilé ààrẹ tẹ́lẹ̀, Olusegun Obasanjo
Oríṣun àwòrán, dailytrust
Alaga ẹgbẹ oṣelu PDP, Ọmọọba Uche Secondus ti gunlẹ si ilu Abẹokuta nile aarẹ orilẹede Naijiria nigbakanri, Oloye Oluṣẹgun Ọbasanjọ.
Ni nnkan bii agogo mejila ni Secondus gunlẹ, ti ọpọ si n woye pe abẹwo alaga apapọ PDP naa ko yẹ lori wahala to n lu agogo jo laarin ẹgbẹ oṣelu naa bayii.
Lọwọ yii, Secondus n ja fitafita lati di ipo rẹ mu gẹgẹ bi alaga ẹgbẹ oṣelu naa lẹyin ti awọn eekan kan laarin ẹgbẹ oṣelu naa n sọ fun un pe ile to lọ, ko fi ipo silẹ.
Gbogbo akitiyan awọn agbaagba ẹgbẹ oṣelu naa lati bomi pa ina wahala naa ni ko tii ba ọwọ rere jade.
Ohun ti o han si gbogbo eniyan ni pe Oloye Ọbasanjọ ti fa kaadi ọmọ ẹgbẹ rẹ ya to si ti juwọ si ẹgbẹ oṣelu PDP, amọṣa gẹgẹ bi ẹni to fi ọdun mẹjọ jẹ aarẹ alagbada labẹ aburada ẹgbẹ oṣelu naa, ọpọ onwoye lo n woo pe ko ni ṣai ni ipa to loorin laarin awọn eekan ọmọ ẹgbẹ oṣelu naa.
Kola Ologbondiyan: PDP ni yóò mú ọmọ Nàíjíríà kúrò lóko ìyà tí wọn wà ní 2023
Lagos bans street hawking: Ìjọba ìpìnlẹ̀ Eko fòfin de ọjà títà àti títọọrọ báárà lójú pópó
Oríṣun àwòrán, Polley Nina
Ijọba ipinlẹ Eko ti ṣagbakalẹ igbimọ kan ti yoo fopin si ki kiri ọja laarin oju popo atawọn to n tọrọ baara nipinlẹ naa.
Ijọba Eko sọ pe awọn gbe igbesẹ yii nitori awọn adigunajle to maa n fara pamọ sabẹ irufẹ ọja tita tabi agbe lati lo ọna ẹburu ja awọn araalu lole.
Ikede igbimọ tuntun naa lo waye nibi ipade awọn akọroyin kan ti kọmiṣona fun ọrọ awọn ọdọ ati idagbasoke awujọ, Olusegu Dawodu, ṣe onigbọnwọ rẹ, eyii to waye ni Alausa.
Dawodu ni wọn gbe igbimọ naa kalẹ lati kapa iwa ọdaran nipinlẹ Eko, eyii ti awọn kọlọrọsi kan n wu labẹ asia pe awọn taja tabi tọrọ baara.
O ni igbimimọ naa yoo bẹrẹ iṣẹ laipẹ lati fopin iwa idigunjale bẹẹ.
Gẹgẹ bii ohun to sọ, awọn n fopin si ki kiri ọja laarin oju popo nitori iroyin ti awọn gbọ pe pupọ lara awọn onibara atawọn ọlọja bẹẹ lo ni oniruru ohun ija oloro lara wọn.
"O ni ""Ijọba yoo ṣe ọpọ itaniji lawọn ileeṣẹ iroyin ki awọn eeyan le mọ igbesẹ ti ijọba n gbe lori ọrọ naa."""
Ilé wó lu Bisi, ọmọ ẹ̀yìn rẹ̀ kú, wọ́n gé ẹsẹ̀ rẹ̀ tó ń jẹrà, inú ìrora ló wà ṣùgbọ́n
Dawodu gba awọn olugbe ipinlẹ Eko nimọran lati maa ko awọn owo tabi dukia wọn lọ sile awọn ọmọ alaini iya tabi opo nibi ti wọn yoo ti lo owo naa bo ṣe yẹ ti ba  fẹ fi ṣe saraa.
"Ninu ọrọ rẹ, ""Titọrọ baara laarin adugbo kii ṣe ohun to yẹ ki a gba laaye lawujọ wa, bẹẹ naa ni tita ọjsa loju popo."""
Kọmiṣọna ọhun fi kun pe igbesẹ awọn ko lodi si ofin ipinlẹ Eko ti wọn gbe kalẹ lọdun 2015.
O ṣalaye pe igbese yii wa ni ibamu pẹlu ori 157, ati abala kinni ofin ipinlẹ Eko.
"Lasiko to n sọrọ nibi ipade ọhun, kọmiṣona ọlọpaa ipinlẹ Eko, Hakeem Odumosu sọ pe ""Opin ti de ba ọja tita loju popo nipinlẹ Eko."""
Odumosu ni ileeṣẹ ọlọpaa yoo fọwọsowọpọ pẹlu ijọba lati ri daju pe asiko awọn kọlọrọsi a lọ kolohun kigbe di ohun itan ni ipinlẹ Eko.
Mercy Aigbe: Mo bó ní kókósẹ̀, orúnkún àti apá lẹ́nú iṣẹ́, ìrora náà pọ̀
Oríṣun àwòrán, Instagram/Mercy Aigbe
Agba adura ni pe ohun ta jẹ la n wa, ka ma pade ohun ti yoo jẹ wa.
Adura yii lo gba pupọ fun agba osere tiata lobinrin kan, Mercy Aigbe lasiko to ni ijamba ẹnu isẹ nigba to n ya sinima kan laipẹ yii.
Mercy, ẹni to salaye bi ijamba naa se waye ninu fidio kan to gbe soju opo Instagram rẹ, ni ọpọ egbo ni oun gbe lasiko ti ijamba naa waye.
O ni oun bo lẹsẹ pupọ lasiko ijamba naa, ti oun si tun fi apa bo pẹlu eyi to waye nigba ti n ya sinima naa.
Yoruba ni ti ẹsin ba da ni, a tun gun ni. Eyi si lo mu ki Mercy kede pe oun dupẹ pe ijamba naa ko ju bayi lọ, o si to fun iru sinima ti oun fẹ gbe jade lati ipasẹ rẹ.
"Ijamba ẹnu isẹ ni, mo ni aimọye egbo lasiko ti mo n ya sinima kan, mo bo ni kokosẹ pupọ, koda, n ko ti le rin daadaa.
Ilé wó lu Bisi, ọmọ ẹ̀yìn rẹ̀ kú, wọ́n gé ẹsẹ̀ rẹ̀ tó ń jẹrà, inú ìrora ló wà ṣùgbọ́n
Amọ o to bẹẹ, o ju bẹẹ lọ ti n ba ro bi sinima naa ti kanka to. Isẹ ta yan laayo, la n se. A ko si ni owo meji, a gbọdọ se ni."
Ìgbẹ́jọ́ akẹ́kọ̀ọ́ tí àwọn olùkọ lú ní Ekiti tí bẹ̀rẹ̀, agbẹjọ́rò ní àfi kí ìjọba sàn 15mílíọ̀nù owó gbà má bínú
Oríṣun àwòrán, Google
Agbẹjọro to n soju ọmọ ọdun mẹjọ Gift Agenoisa ti wọn lu lẹgba nile ẹkọ Mary Immaculate Secondary School , Ado- Ekiti ti sọ pe awọn ko ni yẹ titi ti Gift yoo fi gba idajọ to yẹ.
Owo gbaa ma binu miliọnu mẹẹdogun ni awọn obi Gift n beere fun lọdọ ijọba ipinlẹ Ekiti ti wọn si fẹ ki wọn faaye gba ọmọ naa lati pada sile ẹkọ.
Ninu ifọrọwerọ kan pẹlu BBC agbẹjọro  Gift  Timmy Omotoso,sọ pe yatọ si pe awọn olukọ lu ọmọde naa, wọn tun sọ fun pe ko ma pada wa si ile ẹkọ naa mọ.
O ni nitori pe awọn ko fẹ ki ẹtọ rẹ di titẹmọlẹ lẹyin ti ile ẹkọ ko jẹ ko pada si kilasi lo mu ki awọn gba ile ẹjọ lọ.
O ṣalaye pe awọn gbiyanju pupọ lati kan si ijọba ipinlẹ Ekiti, iyawo Gomina, ati ileeṣẹ eto ẹkọ lati yanju ọrọ yi ṣaaju ṣugbọn pabo lo ja si.
Agbẹjọro Omotosho ni igbẹjọ ti bẹrẹ awọn si ni ireti pe ire lawọn yoo mu dari bọ lati ile ẹjọ.
''Adajọ ti bẹrẹ si ni gbẹjọ wa ṣugbọn wọn ti sunjọ igbẹjọ si ọjọ kejilelogun oṣu kẹsan ti wọn  ni ka tun pada si ile ẹjọ.''
Ohun ti Yorùbá ń pè ní Èṣù yàtọ̀ sí Sátánì nítorí Èṣù ní iṣẹ́ rere lọ́wọ́
Gẹgẹ bi agbẹjọro Omotosho to tun jẹ ajafẹtọmọniyan ti ṣe sọ,lọjọ ti Gift yoo pe ọdun mẹjọ ni awọn olukọ da sẹria fun pe o ṣe irun ti ko bofin mu wa sile ẹkọ.
O ni wọn lu ni ẹgba ogun titi de bi pe gbogbo ara rẹ bo ti Gift si pada wa daku.
''Wọn ko ẹgba yẹn bo lori ara debi pe o ni ifarapa lẹyin, ni ọwọ ati aya.Nigba ti ifarapa yẹn wa pọ fun, niṣe lo daku''
Oríṣun àwòrán, Ekiti State Government
Omotosho ni nigba tawọn ile ẹkọ ri wi pe Gift ti daku ni wọn to ṣẹṣẹ pe obi rẹ lori ago pe ki wọn wa si ile ẹkọ.
O ni abalọ ababọ ni pe wọn gbe Gift pada lọ si ile lati lọ tọju rẹ ṣugbọn o jẹ iyalẹnu pe nigba ti ara rẹ ya to fẹ pada si ile ẹkọ, awọn alaṣẹ ileewe ko gbaa laaye.
Agbẹjọro ni awọn gbiyanju lati kan si ileeṣẹ eto ẹkọ, iyawo Gomina ipinlẹ Ekiti ati ileeṣẹ to n mopjuto ọrọ obinrin ati ọmọde.
Ilé wó lu Bisi, ọmọ ẹ̀yìn rẹ̀ kú, wọ́n gé ẹsẹ̀ rẹ̀ tó ń jẹrà, inú ìrora ló wà ṣùgbọ́n
Gẹgẹ bo yti ṣe ṣalaye ileeṣẹ to n mojuto ọrọ obinrin ati ọmọde nikan lo kan si awọn pada lori ọrọ yi.
''Ọmọ ọdun mẹjọ ti ko mọ nkankan ni akẹkọọ ti awọn olukọ yi lu laludaku.Se ọmọ yi lomu owo lọwọ ara rẹ lọ si ile gẹrigẹri pe ki wọn ge irun fun ni?ṣebi ti ọmọ ba ṣe ṣe ko yẹ ki wọn pe awọn obi rẹ lati fẹjọ sun ni?''
Yoruba traditon: Ohun tí Yorùbá ń pè ní Èṣù yàtọ̀ sí Sàtánì nítorí Èṣù ní iṣẹ́ rere lọ́wọ́ -Ejùgbọ̀nà ìlú Rẹ́mọ
Ọpọlọpọ igba ni adapọ ati edeaiyede maa n waye lori Esu. Ta ni, bawo lo ṣe jẹ ninu itan iṣẹdalẹ Yoruba ati pe ṣe lootọ ni pe idi iṣẹ buruku la ti maa n ri?
Edeaiyede yii lo mu ki ọpọ maa daa pe ni Satani, sugbọn awọn baba mọnimọni ṣalaye pe iyatọ pọnbele lo wa laarin Esu ti iṣẹṣe Yoruba ati Satani ti ọps awọn iwe ẹsin miran n fihan.
Ninu igbagbọ Yoruba, aṣeburuku ṣe rere ni Esu jẹ, bẹẹni ko si irumslẹ kankan nilẹ Yoruba ti kii fi ti Eṣu laalu ogiri oko ṣe.
BBC News Yoruba tọ awọn agba lọ lagbegbe Ijẹbu lati mu ẹkunrẹrẹ ims ati alaye lori Eṣu, ojuṣe rẹ laarin awọn igba irumọlẹ, ati ohun to faa ti ọps maa fi n pariwo iṣẹ Eṣu ni bi iṣẹlẹ buburu kan ba ti ọdọ wọn jade.
Aheregbe and Amole festival in Akure: Ojú aráàlú rí màbo pẹ̀lú báwọn jàǹdùkú ṣe sọ àjọ̀dún Amole di 'ọdún olè jíjà' nílùú Akure
Oríṣun àwòrán, other
Ibinu ati ẹhonu lo tẹle ayẹyẹ ọdun Amọle, iyẹn ọdun iṣẹṣe ilu Akurẹ to waye lọjọbọ, ọjọ kọkandinlogun oṣu kẹjọ ọdun 2021.
Gẹgẹbi iroyin to tẹ BBC News Yoruba lọwọ kaakiri awọn agbegbe ilu Akurẹ lasiko ọdun naa ṣe sọ, ọpọ iwa ole, ijinigbe ati idaluru lo waye lasiko ọdun naa ti awọn janduku kan si n fọwọ lalẹ pe awọn lẹtọ lati ṣe bẹ labẹ iboju ọdun naa.
Fun apẹrẹ, lasiko ajọdun naa, nṣe lawọn janduku kan kọlu awọn eeyan lagbegbe Bọlajoko Junction ni Oke Aro ni opopona Idanre. Awọn janduku naa di ọna mọ ọkọ bọọsi kan to ko ounjẹ atawọn ohun elo ile miran ti wọn si ji gbogbo ohun to wa ninu rẹ lọ.
"Bakan naa lawọn oju mi too kan tun ṣalaye ohun ti oju ri awọn janduku kan ti wọn ni awọn n fi idi 'ofin maa ta ọja"" ti aafin Ọba Deji ti ilu Akurẹ pa pe ko gbọdọ si ṣiṣi ọja lọjọ ọdun Aheregbe ati Amọle naa mulẹ ni ṣe fi tipa gbe ọmọ okunrin aṣoju ileeṣẹ itaja kan ti wọn si tun jo taya ọkọ rẹ."
Okunrin naa gẹgẹ bi ileeṣẹ iroyin abẹle kan nilu Akurẹ ṣe sọ, arakunrin naa n gbe ọmọ rẹ lọ sileewe  lasiko ti awọn janduku naa da lọna ti wọn si ko gbogbo ọja ileeṣẹ rẹ to ko sinu ọkọ.
Oba Ogboni Abalaye n fẹ́ kí wọ́n o má a fi ẹ̀sìn àbáláyé búra fún àwọn olóṣèlé Naijiria
Gbogbo bi arakunrin naa ṣe n pariwo pe oun ko ta ọja, ọmọ oun loun n gbe lọ sileewe ko tu irun kan lara awọn eeyan naa, koda wọn tun gbe ọmọ rẹ naa pẹlu. Awọn aladugbo lagbegbe naa lo fariga tẹle awọn janduku ọhun lati gba ọmọ rẹ pada.
Ni Ọjọru ni atẹjade kan jade lati afin Ọba Deji ti ilu Akurẹ pe ayẹyẹ ọdun aheregbe ati amọle yoo waye, nitorina ki wọn ọja ati ṣọọbu ko wa ni titi pa. Amọṣa atẹjade naa ko sọ pe ki ẹnikẹni o maa jade tabi rin loju popo.
Ondo state citizen killed in Jos: àwọn Fúlàní ìpínlẹ̀ Ondo tí wọ́n pa mọ̀lẹ́bí wọn ní Jos pariwo síta
Usman Tefiu, ẹgbọn ọkan lara awọn Fulani to fi ipinlẹ Ondo ṣe ibugbe ti awọn agbebọn Origwe, ni ariwa Jos, nipinlẹ Plateau pa lọjọ Satide, Maman Lawal, ti rọ ijọba lati yara lati mu awọn to ṣe ijamba ọun lati dena awọn ara ilu lati gbẹsan funra wọn.
Tefiu to ti padanu ẹsẹ rẹ mejeeji to si n fi ọpa rin lo sọ pe ohun ati baba ohun ti ko riran ni o nira fun lati gba iku Maman to padanu ẹmi rẹ lakoko to n pada sipinlẹ Ondo lati ipinlẹ Bauchi.
Darandaran miran, Abdulai Shu'aibu eni ti'o padanu ọmọ re sọpe ohun gbogbo ko sebẹ sẹnu're mọ lẹyin ti wọn sọ iroyin ibanujẹ nipa iku ọmọ re fun, ti o si kesi ijoba lati fi panpẹ ofin mu awọn ti o sekupa ọmọ rẹ.
Nibi ipade alaafia ti won se nilu Ibaram-Akoko, to wa ni ijọba ibilẹ Iwọ oorun-Ariwa Akoko, igbakeji gomina, Lucky Aiyedatiwa to ṣoju Akeredolu ti sọ pe ijọba ipinlẹ Ondo ati Plateau n sisẹ takun-takun pẹlu awon ẹsọ alaabo lati fi panpẹ mu awọn to sọsẹ naa.
POS operator murder: Ọlọ́pàá mú afurasí tó pa oniṣowo ẹrọ igbowo POS kan, wọ́n ni àbọ̀dé ìgbẹ́jọ́ Sunday Igboho lọwọ́ tẹ̀ẹ́
Oríṣun àwòrán, other
Ileeṣẹ ọlọpaa ni ipinlẹ Ogun ti kede pe ọwọ awọn ti tẹ afurasi kan ti orukọ rẹ n jẹ Kẹhinde Jẹlili fun pipa oniṣowo ẹrọ igbowo POS kan ti orukọ rẹ n jẹ Abiọdun Ọdẹbunmi ati awakọ Uber kan ti o n jẹ Idowu Ademiluyi.
Alukoro ileeṣẹ ọlọpaa ni ipinlẹ Ogun, DSP Abimbọla Oyeyẹmi ṣalaye pe  lẹyin oṣu mẹta ti wọn ti n wa Jẹlili, ti ọpọ mọ si Oluọmọ lọwọ awọn ọtẹlẹmuyẹ tẹẹ.
DSP Oyeyẹmi tun fi kun un pe ilu Cotonou lorilẹede Benin Republic ni afurasi naa ti nbọ lẹyin to lọ peju sibi igbẹjọ ọkan lara awọn aṣiwaju idasilẹ orilẹede Yoruba, Sunday Igboho nibẹ.
O ni ọwọ ba afurasi naa pẹlu awọn afurasi apanijaye mẹta miran ti wọn pe orukọ wọn ni Abiọdun Akinọla, Johnson Fakẹyẹ ati Jamiu Akinọla. Wọn dana sun awọn dukia oloogbe Ọdẹbunmi naa lẹyin ti wọn ji miliọnu mẹrin lọwọ rẹ.
Bakan naa ni ọlọpaa tun gba ọkọ ayọkẹlẹ Toyota Camry, Toyota Corolla ati Toyota Rave 4 tawọn afurasi naa gba lẹyin ti wọn pa awọn to ni ọkọ naa.
Ondo state citizen killed in Jos: àwọn Fúlàní ìpínlẹ̀ Ondo tí wọ́n pa mọ̀lẹ́bí wọn ní
Amọṣa, ilana ọmọ Oodua to jẹ agbarijọpọ ẹgbẹ to n ja fun idasilẹ orilẹede Yoruba ṣalaye pe awọn ọlọpaa kan fẹ sọ oloye Sunday Adeyẹms loruks buruku ni nipa siso iṣẹ afurasi ti wọn mu mọ igbẹjọ rẹ.
Agbẹnusọ fun ẹgbẹ ilana ọmọ Oodua ti Ọjọgbọn Banji Akintoye n dari rẹ, Maxwell Adelẹyẹ ṣalaye pe ko si afurasi naa tabi afurasi yoowu ṣe lee ls sibi igbẹjọ Oloye Sunday Igboho ni Cotonou nitoripe awsn adajọ atawọn mọlẹbi rẹ kọọkan ni wọn gba laaye lati wọ ile ẹjọ.
O niẹgbẹ Ilana Ọmọ Oodua kii ṣe ẹgbẹ awọn ọdaran bẹẹni kii faye gba ohun ija oloro lawọn iwọde rẹ.
O ni iṣẹlẹ iku ọdọbinrin Jumọkẹ ti wọn ba oku rẹ lasiko iwọde Yoruba nation nilu Eko ati bi ọlọpaa ṣe yi ohun pada lọpọ igba lori ọrọ naa fihan pe ileeṣẹ ọlọpaa nilo ati mojuto ara rẹ ati pẹlu pe wọn n gbiyanju ati ta ẹrẹ si aṣọ ala ijijagbara Yoruba Nation.
Ohun ti Yorùbá ń pè ní Èṣù yàtọ̀ sí Sátánì nítorí Èṣù ní iṣẹ́ rere lọ́wọ́
Ife Modakeke clash: Wàhálà bẹ́ sílẹ̀ láàrín Ife àti Modakẹ̀kẹ̀ lẹ́yìn tàwọn kan pa ọmọ Modakeke márùn ún lọ́jọ́ Ẹtì
Oríṣun àwòrán, other
Iroyin lati ipinlẹ Ọṣun n sọ pe nnkan ko rọgbọ bayii laarin agbegbe ile Ifẹ ati Mọdakẹkẹ ni ipinlẹ naa lẹyin ti wọn ri oku awọn eeyan kan ti wọn pa lọna oko wọn.
Gẹgẹ bi awọn iroyin lati agbegbe naa ṣe sọ iṣẹlẹ buruku naa ṣẹlẹ ni nnkan bii agogo meje owurọ ọjọ Ẹti lagbegbe Toro ni Mọdakẹkẹ nigba ti awọn eeyan naa n lọ si oko wọn.
Alukoro ileeṣẹ ọlọpaa ni ipinlẹ Ọṣun, SP Yẹmisi Ọpalọla fi idi iroyin naa mulẹ fun BBC News Yoruba to si ni kọmiṣọna ọlọpaa nibẹ, Ọgbẹni Ọlawale Olokode ti paṣẹ kawọn ikọ ọlọpaa kogberegbe o lọ si agbegbe naa lati pẹltu si aawọ naa.
Iroyin sọ pe bi awọn ara ilu Mọdakẹkẹ ṣe gbọ iroyin naa ni awọn pẹlu ti mu ija lati koju ẹnikẹni to ba wa nidi ajalu naa.
Afghanistan Crisis: Ikọ̀ Taliban ti ń jó, wọ́n tún lọ ibùdó ìgbafẹ́ láti ṣeré yàtọ̀ sí ti tẹ́lẹ̀
Idi ni pe ọpọ fidio lo ti jade sita bayii to n se afihan awọn Taliban ni ibudo igbafẹ, ti wọn jo, ti wọn si n sere lorisirisi.
Ọpọ eeyan to wo awọn fidio yii lo n ya lẹnu pe se awọn ikọ Taliban to gba ijọba ni bi ogun ọdun lorilẹede Afghanistan ree abi awọn miran.
Awọn ikọ Taliban yii si ni awọn eeyan mọ bii agbebọn, ti wọn kii si rẹrin tabi jo, tabi fi aaye silẹ fun ere idaraya sise.
Koda, wọn ni ibẹru to bẹẹ gẹ debi pe awọn obinrin maa n gbọn niwaju wọn ni, ti ibọn kii si ja lara wọn.
Fidio mẹrin to wa lu sori ayelujara ni Ọjọbọ lo se afihan awọn ọmọde ati obinrin ti wọn pejọ nibudo igbafẹ kan lati wo awọn ikọ agbebọn naa.
Bakan naa ni fidio yii tun se afihan awọn ikọ Taliban ti wọn n fo soke-silẹ lori ohun eelo isere kan ti wọn pe ni Bouncing Castle.
Awọn ọmọde si ni wọn mọ, to maa n fi ohun isere naa dara ya.
Sunday Igboho Update: Igboho ti sọ ohun tó fẹ́ kí a ṣe tí ọ̀rs bá bẹ́yìn yọ- Saheed Yusuf
Amọ ninu fidio yii ni a ti ri awọn ọmọ ẹgbẹ Taliban naa, ti wọn si lawani ti wọn we sori kalẹ, lọna ati mu ki ere sise naa rọrun fun wọn.
Awọn ikọ Taliban naa sa n rẹrin, rẹrin titi ninu fidio naa ni, lai fajuro.
Oba Gbolahan Timson shomolu: Obasanjo ti jẹ́wọ́ pé 'Mistake' ni Buhari ṣùgbọ́n...
Fidio kẹta lo se afihan ikọ Taliban, ti wọn tun n wa kẹkẹ ere idaraya fun irin, ti wọn n pe ni Tred Mill, ti wọn si n rin lori rẹ.
Amọ wn ko si lawani wọn lori ninu fidio kẹta naa, boya nitori pe wọn ko bẹru pe o le tu tu lasiko ti wọn n rin naa.
Lẹyin ere idaraya yii ni awọn ikọ Taliban naa gba ile nla kan lọ, tii se ile ijọba ilẹ Afghanistan.
Ẹwa Agọnyin jẹ aayo ounjẹ Badagry
Gani Adams: Kò dín ní ₦3 bílíọ̀nù tí àwọn ọmọ ilẹ̀ Yoruba ti san fún àwọn ajínigbé láàrín ọdún méjì sẹ́yìn
Oríṣun àwòrán, aareganiadams
Aarẹ Ona Kakanfo ilẹ Yoruba, Iba Gani Adams ti sọ pe ko din ni biliọnu mẹta naira ti awọn eeyan apa Iwọ-oorun Naijiria ti san fun awọn ajinigbe laarin ọdun meji sẹyin.
O fi kun pe nnkan bii igba eeyan ni awọn ajinigbe ọhun ti ṣekupa laarin ọdun meji yii kan naa.
Aarẹ Ona Kakanfo lo sọ ọrọ naa nibi ipade eto abo ilẹ Yoruba kan to waye niluu Abeokuta.
O ni ko si iroyin nipa ijinigbe to maa n waye nilẹ Yoruba ti wọn ki n bu oun gbọ.
Gani Adams juwe ipade naa gẹgẹ bii eyii ti yoo fun gbogbo awọn ti orọ naa kan lanfaani lati jọ ṣiṣẹ papọ.
"O ni ""Gẹgẹ bii Aarẹ Ona Kakanfo, o ni awọn iroyin kan ti mo maa n gbọ to jẹ pe awọn ileeṣẹ eto abo mii gan kii gbọ si."""
Ohun ti Yorùbá ń pè ní Èṣù yàtọ̀ sí Sátánì nítorí Èṣù ní iṣẹ́ rere lọ́wọ́
Ni gbogbo igba ti nnkan ba ti ṣẹlẹ nibikibi, wọn maa n pe aago mi ti wọn a si bere lọwọ mi igbeṣe ti mo fẹ gbe lati yanju rẹ.
Ṣugbọn o ṣeni laanu pe mi o ni agbara lati ṣe bii awọn Aarẹ Ona Kakanfo aye atijọ, ṣugbọn mo ṣe iwọn ti mo le ṣe gẹgẹ bii Aarẹ.
Gani Adams ni ohun ibanujẹ nla ni pe awọn ọdaran Fulani n ṣe bo ṣe wu wọn nilẹ Yoruba, ati pe ti awọn ijọba ilẹ Yoruba ko ba ji giri si ojuṣe wọn, o ṣeeṣe ki igbẹyin ilẹ Yoruba da bi ti oke ọya.
Lẹyin naa lo ke si ijọba apapọ lati fi oju ṣunukun wo ọrọ ijọba ẹlẹkunjẹkun ti awọn ti  pariwo lati ọjọ pipẹ gẹgẹ bii ọna abayọ si eto abo to dojuru.
"O ni ""Ti ẹba ṣe iṣiro iye owo itusilẹ ti awọn eeyan agbegbe Oke-Ogun, Ibarapa, Ekiti, Akoko ati Yewa ti san fun awọn ajinigbe, yoo ti le ni biliọnu mẹta naira."""
Ti ẹ ba si ṣe iṣiro awọn ti wọn ti pa danu, wọn ti maa le ni irinwo, nitori naa o yẹ ki ijọba gbe ọrọ ijọba ẹlẹkunjẹkun yẹwo.
Ilé wó lu Bisi, ọmọ ẹ̀yìn rẹ̀ kú, wọ́n gé ẹsẹ̀ rẹ̀ tó ń jẹrà, inú ìrora ló wà ṣùgbọ́n
Yollywood Round up: Àpótí òní páálí láwọn àlejò yóò fí wọlé síbi àpéjẹ̀ ọjọ́ọ́bí Bobrisky
Oríṣun àwòrán, Instagram/bobrisky222
Gbajugbaja obinrin to n mura bi ọkunrin, Idris Okuneye ti ọpọ eeyan mọ si Bobrisky ti kede ipalẹmọ fun ayẹyẹ ọjọ ibi rẹ.
Bobrisky, ninu video tuntun to gbe soju opo Instagram rẹ salaye pe agba akọrin Fuji nni, King Wasiu Aynde Marshal, ti awọn eeyan tun mọ si Kwam 1, ni yoo kọrin nibi ayẹyẹ ọjọ ibi naa.
Bobrisky, ẹni ti yoo pe ọgbọn ọdun ni ọgbọnjọ osu Kẹjọ ọdun 2021 la ri ninu fidio naa, to n gbe apoti onipaali kan fun Ọba orin Wasiu Ayinde.
"Ninu Fidio naa ni Bobrisky ti ni ""@kingwasiuayindemarshal yoo wa nikalẹ lati kọrin fun awọn alejo mi lasiko ayẹyẹ ọjọ ibi ọgbọn ọdun mi.''"
''O maa lagbara gan ni, ẹ jẹ ki eto kika ọjọ ayẹyẹ bẹrẹ lati oni lọ, ka le mọ iye ọjọ to ku.''
Oniruuru ipalẹmọ si ni Bibrisky ti se nipa ayẹyẹ ọjọ ibi naa, laipẹ yioi la ri to gbe paali kan to kun fun iwe ipe sibi ayẹyẹ naa sori ayelujara.
Oríṣun àwòrán, Instagram/bobrisky222
Lara awọn eroja to wa ninu apoti iwe ipe sibi apejẹ ti yoo fi ransẹ si ikọọkan alejo to ba pe ni igo ọti waini kan, ororo itura oloorun didun, ife ọti waini to ni awọ goolu ati suti Sokoleti pẹlu ododo Rose funfun.
Awọn eroja yii si ni wọn fi asọ fẹlifẹti alawọ buluu we, ti Bobrisky si ni ẹnikẹni to ba ri apoti naa gba, ni o jẹ alejo pataki oun.
Yoruba Nation: Mo faramọ́ àtúntò 'Restructuring' tí kò lọ́wọ́ ìṣèlú nínú- Oba Ahmed Adeku
O ti to ọjọ mẹta ti awọn ololufẹ gbajugbaja osere tiata nii  Grace Oyin-Adejobi ti ọpọ mọ si Iya Oshogbo.
Niṣe lo jẹ ohun idunnu bi oṣere tiata Toyin Adegbola Toyin Tomato ṣe gbe mama soju iran awọn eeyan pada ni Instagram.
Toyin Tomato fi fọnran fidio ibi tawọn eeyan ti n kọ orin yẹ Iya Oshogbo si fun ti ayẹyẹ ọjọ ibi wọn.
Mama Grace Oyin Adejobi to ti sinmi nidi ere tiata lati nkan bi ọdun meloo kan sẹyin pe ẹni ọdun mejilelaadọrin loke eepẹ.
Ọrọ ti Sola Sobowale,Laburu fi n kilọ fun Debo Macaroni ati Mummy wa ree loju opo Instagram.
Ẹ ma foya kii ṣe ifọti tootọ bi kii ṣe pe awọn mẹtẹta jijọ kopa ninu fọnran fidio awada kẹrikẹri kan to jade laarin ọsẹ.
Oríṣun àwòrán, Instagram@mrmacaroni
Awọn ipa kogberegbe ni Sola Sobowale maa saba ko  lagbo oṣere tiata amọ bi aaye ba yọ silẹ o maa n bawọn kopa ninu awọn ere awada lẹẹkọọkan.
@mrmacaroni naa kuku fi esi awada da Sobowale lohun bayi  pe
Ondo Blocks price hike: Búlọ́kù N200 to di N400 ní ìpínlẹ̀ Ondo fẹ́ mú kí ìjọba àtàwọn olówò búlọ́kù tutọ́ sójú ara wọn
Oríṣun àwòrán, Sunshine Truth
Ijọba ipinlẹ Ondo ti paa laṣẹ fawọn awakọ tipa atawọn to n ṣe bulọọku ikọle lati owo yẹpẹ ati bulọọku si iye to wa tẹlẹ.
Ohun ti a gbọ ni pe wọn ti owo bulọọku lati N200 ati N300 lọ si N300 ati N400 lori bulọọku ''6'' ati ''9.''
Bakan naa ni iroyin sọ pe awọn awakọ tipa naa ṣe afikun owo yẹpẹ pẹlu idaji iye ti wọn n ta tẹlẹ.
Oludamọran pataki fun Gomina ipinlẹ Ondo lori iṣẹ ode ati ọgbọn inu, Ọgbẹni Doyin Odebowale lo kede aṣẹ ijọba ipinlẹ Ondo ọhun.
Odebowale ni ijọba fun awọn awakọ ati atawọn onibulọọku di ọjọ Aje to n bọ lati ṣe atunṣe.
O ni ijiya to tọ ni ijọba yoo fi jẹ ẹnikẹni to ba kọ eti ikun ti aṣẹ ijọba.
Oladamọran gomina ipinlẹ Ondo ṣalaye pe ile iṣẹ bulọọku ti ko ba tẹle aṣẹ ijọba yoo di titi pa.
Kaduna bandits: Àwọn ajínigbé yìnbọn pa ara wọn, lẹ́yìn èdè-ài-yedè lórí owó pínpín
Oríṣun àwòrán, Other
Ẹfun abi eedi? Ẹgbẹ awọn janduku ajinigbe pawo meji kọju ija si ara wọn ni ijọba ibilẹ Giwa nipinlẹ Kaduna.
Koda eleeru sun igi, mẹsan an ninu awọn janduku ọhun lo dero Ọlọrun lẹyin ti da ibọn bo ara wọn tan.
Kọmiṣọnaa eto abo abẹle nipinlẹ Kaduna, Samuel Aruwan, lo fidi iṣẹlẹ naa mulẹ fawọn akọroyin.
Kọmiṣọnna ṣalaye pe ko si ẹni to mọ pato ohun to ṣe okunfa ija laarin awọn janduku ọhun.
''Ṣugbọn awọn kan sọ pe ede-aiyede lori bi wọn ti pin owo itusilẹ ti wọn ti ri gba lo fa ija laarin ẹgbẹ mejeeji.
Wọn awọn kan ninu wọn ni ẹgbẹ kan ti yan ẹgbẹ awọn jẹ wi pe owo ti o kan wọn kere,'' Aruwan lo sọ bẹẹ.
Kọmiṣọnaa eto abo abẹle ipinlẹ Kaduna ni awọn eeyan lo sọ nipa iṣẹlẹ naa fun ijọba.
Bakan naa lo sọ pe awọn oṣiṣẹ eleto abo naa jẹri pe lootọọ ni iṣẹlẹ ọhun waye.
''Iwadii lori eto abo fihan pe olori awọn janduku ajinigbe kan ti wọn n pe ni Godon Mota yabo abule Garke l'Ọjọru ọsẹ yii.
Nibẹ a gbọ pe awọn ọmọlẹyin rẹ ti kọlu ẹgbẹ janduku ajinigbe miran eleyii ki mẹsan ninu wọn dero ọrun.
Adele gomina ipinlẹ Kaduna, Ọmọwe Hadiza Balarabe, gan an ti fi idunnu rẹ han si iṣẹlẹ ọhun.
O si rọ awọn oṣiṣẹ eleto abo lati maa kaarẹ ninu akitiyan wọn lati fi ọwọ ofin mu awọn janduku ti wọn n da ilu laamu.
Iwadii ṣi n lọ lọwọ lori ọna ati wa ojutu si eto abo to mẹhẹ nipinlẹ Kaduna,'' Aruwan ṣalaye.
Lionel Messi: Ṣé lóòtọ́ọ́ ni Lionel Messi lè gba ife ẹ̀yẹ Champions League fún PSG lẹ́ni ọdún 34?
Oríṣun àwòrán, Facebook/PSG
Ọpọ ololufẹ ere bọọlu lo ti sọrọ nipa igbesẹ Lionel Messi lati darapọ mọ ẹgbẹ agbabọọlu PSG lati Barcelona.
Awọn kan ni asiko ti to fun ẹgbẹ agbabọọlu PSG lati gba ife ẹyẹ UEFA Champions League eleyii ti wọn ko tii gba ri ninu itan wọn.
Agbaọjẹ agbabọọlu orilẹede Brazil to ti fẹyin ti naa sọ pe oun n gbọ oorun Champiọns League ni PSG bayii lẹyin ti Messi darapọ mọ wọn tan.
Ronadinho to ti figba kan ri gbabọọlu fun PSG ati Barcelona sọ pe ohun iwuri lo jẹ foun pe oun ti gba bọọlu fun ikọ agbabọọlu mejeeji.
O ni ife ẹyẹ UEFA Champions League ko jina mọ si PSG pẹlu Messi atawọn agbabọọlu mii bi Sergio Ramos ti wọn ṣẹṣẹ ra.
Messi mi ilẹ titi nigba to darapọ mọ PSG tan.
Niṣe lero pejọ biba si papa isẹre Parc des Princes nibi ti ẹgbẹ agbabọọlu PSG ti fi Messi han fun gbogbo aye.
Ọlatunji, akẹ́kọ̀ọ́gboyè 'graduate' tó ń ta àkàrà 'Ó ta lẹ́nu' nílùú Osogbo
Nọmba 30 lo wa lara jẹsi ti Messi yoo maa wọ ni ẹgbẹ agbabọọlu naa.
Ẹwẹ, gbajugbaja oniroyin to tun jẹ ololufẹ ẹgbẹ agbabọọlu Arsenal, Piers Morgan ni PSG ko le padanu lori owo oṣu gọbọi ti Messi yoo maa gba.
Morgan ni PSG yoo ri owo wọn pada laarin oṣu diẹ lati ara jẹsi rẹ ti wọn ba ta.
Oniroyin Morgan ni witi witi lawọn ololufẹ ere bọọlu n ra aṣọ Messi, eleyii ti yoo si tẹsiwaju bẹẹ.
Ọlatunji, akẹ́kọ̀ọ́gboyè 'graduate' tó ń ta àkàrà 'Ó ta lẹ́nu' nílùú Osogbo
Iṣẹ akara dindin ati tita jẹ ara awọn iṣẹ ti ọjọ ori rẹ pọ julọ ni ilẹ Yoruba, a si lee ka kun ara awọn iṣẹ ti ọpọ maa n foju iṣẹmbaye wo nilẹ Yoruba.
Ni ilu Oṣogbo, ni ipinlẹ Ọṣun lẹkun iwọoorun gusu orilẹede Naijiria arakunrin kan ti orukọ rẹ n jẹ James Ọlatunji dojukọ owo akara dindin ti ọpọ n fi oju iṣẹ obinrin wo lọpọ igba yii to si ti di ilumọọka lori rẹ.
Akẹkọọ jade to gboye lori imọ nipa akoso okoowo, Business administration ni Arakunrin Ọlatunji, o ni lẹyin ikẹkọjade oun, ti oun si wo pe kaka ki oun o maa tọrọ jẹ nitori aisi iṣẹ to wa lode loun fi gbe igba akara dindin ati tita leyi ti oun ko si kabamọ rẹ.
Ife Modakeke crisis: Ìpànìyàn tó wáye ni abúle Toro kìí ṣe ìjà láàrín Ife ati Modakeke - Ooni Ile Ife
Oríṣun àwòrán, Ooniadimulaife/instagram
Ààfin Ọọniriṣa ti Ile Ife Ọba Adewusi Enitan Ogunwusi, ọjaja keji, ni ibanujẹ ọkan lo jẹ lati gbọ nipa bi awọn agbẹ marun se padanu ẹmi wọn ni abule Toro ni Ile-Ife.
Yatọ si pe kabiyesi bẹnu atẹ lu  iṣẹlẹ aburu naa, kabiyesi ti tete fi ọrọ naa to awọn agbofinro ati awọn ẹsọ alabo miiran leti  ti wọn si gbe igbesẹ ni kiakia.
Ninu atẹjade ti adari iroyin ni aafin Ọọni Moses Olafare fọwọsi lo ti ṣalaye naa.
O ni pe, bi o tilẹ jẹ pe awọn kọlọrọsi eniyan kan n gboiyanju lati so iṣẹlẹ naa mọ wahala to wa laarin Ife ati Modakeke latẹyin wa sugbọn ọrọ ko ri bẹẹ.
Olafare ni aafin fi n da ara ilu loju pe iṣẹlẹ naa ko niṣe pẹlu Ife ati Modakeke bi ko se iṣẹ awọn ọdaran pọnbele ti ọwọ ofin kò si ni pẹ tẹwọn.
Ninu atẹjade naa Olafare ṣalaye pe gbogbo eniyan lo mọ pe olrilede Najiria n koju ọrọ ewto abo to mẹhẹ bi awọn agbegbe miiran lagbaye, sugbọn igbagbọ ni pe gbogbo rẹ yoo di afiẹyin ti eegun n fisọ laipẹ pẹlu ifọwọsọpọ ara ilu.
Ọlatunji, akẹ́kọ̀ọ́gboyè 'graduate' tó ń ta àkàrà 'Ó ta lẹ́nu' nílùú Osogbo
O ní ọpọ lo n gbiyanju lati sọ ọrọ naa mọ ẹlẹyamẹya lati gbe oju awọn agbofinro kuro lara awọn ọdaran to ṣiṣẹ ibi naa.
agbẹnusọ kabiesi lasiko to n gboriyin fun ijọba ati awọn eleto abo to fi mọ ọlọpaa, awọn ọtẹlẹmuyẹ, awọn soja ati awọn ọlọdẹ ti wọn tete dikde si ọrọ naa láti mu alafia jọba lawọn ilu gbogbo.
Ooni rọ gbogbo awọn ara ilu lati maa ba iṣẹ oojọ wọn lọ ni irọwọrọsẹ, nitori awọn oniṣẹ ibi naa kii ṣe asoju ipinlẹ ilu kankan
Oríṣun àwòrán, other
Gómìnà Osun, kọmíṣọ́nnà ọlọ́pàá sọ̀rọ̀ sókè lórí wàhàlà tó bẹ́ sílẹ̀ láàrín Ife àti Modakeke lọ́jọ́ Ẹtì
Ijọba ipinlẹ Ọṣun ti ke sawọn eeyan agbegbe Ifẹ ati Mọdakẹkẹ lati maṣe fi aye gba awọn kọlọrọsi janduku laarin wọn lati da wahala silẹ nibẹ.
Oba Gbolahan Timson shomolu: Obasanjo ti jẹ́wọ́ pé 'Mistake' ni Buhari ṣùgbọ́n...
Ipe naa n waye pẹlu bi ikayasoke oun ipaya ṣe gbode kan ni ilu Ifẹ ati Mọdakẹkẹ lọjọ Ẹti lẹyin ti awọn oniṣẹ ibi kan ṣeku pa eeyan marun un ti ọpọ funra si pe wọn jẹ agbẹ nilu Mọdakẹkẹ.
Ijọba ipinlẹ Ọṣun ninu atẹjade kan ti kọmiṣọna feto iroyin, Arabinrin Funkẹ Egbemode fi sita lo ti sọrọ.
O ṣalaye pe ipade kan ti waye laarin awọn alaṣẹ ijọba nipinlẹ naa atawọn alaṣẹ ileeṣẹ aalabo gbogbo nibẹ nibi ti wọn ti gbe ọrọ wahala to suyọ ni ifẹ ati Mọdakẹkẹ.
O fi kun un pe gomina ipinlẹ Ọṣun, Gboyega Oyetọla funrarẹ ti pe Ọọni ti ilu ile Ifẹ, Ọba Ẹnita Adeyẹye Ogunwusi, Ọjaja keji ati Ogunṣua ti ilu Mọdakẹkẹ, Ọba Moses Oyediran Ọladẹjọ ti awọn mejeeji si ti fi daa loju pe omi alaafia laarin ilu mejeeji yii yoo pada toro.
Yoruba Culture: ọjọ́ méje ni wọ́n fí n rẹ ẹ̀kú Danafojura kó tó jáde
Bakan naa ni ileeṣẹ ọlọpaa ni ipinlẹ Ọsun pẹlu ti ṣalaye pe igbesẹ ipana aawọ ti nlọ lọwọ lati ọjọ Ẹti ti iṣẹlẹ naa ti ṣẹlẹ.
Ninu atẹjade kan ti alukoro ileeṣẹ ọlọpaa ni ipinlẹ Ọṣun , SP Yẹmisi Ọpalọla fi sita lo ti sọrọ.
Kọmiṣọnna ọlọpaa ni ipinlẹ Ọṣun, Ọlawale Olokode ni awọn iroyin kan ti lu si ileeṣẹ ọlọpaa lọwọ ti yoo ṣe okunfa mimu awọn oniṣẹ ibi naa ni kiakia.
Okunade Sijuwade: Ìfẹ́ tí Sarun tó súnmọ́ Ooni jù láyé ní sí í ló sọ ọ́ di abọ́bakú- Adeye
Obi Cubana: Gbajúmọ̀ oníṣòwò ilé ijó, Obi Cubana ṣàlàyé ìgbésí ayé rẹ̀ àti bó ṣe di ẹni tí aráyé ń wárí fún
Oríṣun àwòrán, obi cubana
Gbajumọ olowo ile ijo ni, Obinna Iyiegbu ti ọpọ eeyan mọ si Obi Cubana ti ṣalaye gulegule ijọba lorilẹede Naijiria ṣe le oun lati inu kola-koṣagbe bs sinu ọrọ.
Laipẹ yii ni gbajumọ olowo ile ijo, Obi Cubana ṣe isinku iya rẹ Innyom Ezinne Uche Iyiegbu ni ilu  Oba ni ipinlẹ Anambra eyi to di ilu mọọka kaakiri agbaye, amọṣa o ṣalaye fun BBC pe ki iṣu oun to di iyan, oju rẹ ri mabo lọwọ odo.
Obi Cubana ni lootọ loni gbogbo agbaye lo mọ awọn ile ijo oun ti ko si fẹẹ si gbajumọ kan lorilẹede Naijiria, paapaajulọ nilu Eko ati Portharcourt ti ko na ibẹ ri ṣugbọn bii ile ounjẹ loun fi bẹrẹ ni ilu Abuja.
O ni gbọnmọgbọnmọ ijọba to n fi ojojumọ da oun laamu ti wọn n sọ pe ibi ti oun gbe ile ounjẹ oun naa si ni Abuja ko bojumu ni oun fi kuku fi ilu Abuja silẹ gba ilu Portharcourt ti oun si gba Portharcourt de Owerri.
Ninu ifọrọwerọ rẹ pẹlu BBC, Obi Cubana ṣalaye siwaju sii pe gbogbo bi awọn eeyan ṣe pariwo pe wọn ba owo ninu jẹ to lasiko isinku iya oun, oun ko le sọ ni pato iye owo ti wọn naa nibẹ nitori pe gbogbo bi wọn ṣe n na owo naa ni awọn n fi ṣe iranwọ fun awọn eeyan to ku diẹ kaato fun nibẹ lẹsẹkẹsẹ.
Ọlatunji, akẹ́kọ̀ọ́gboyè 'graduate' tó ń ta àkàrà 'Ó ta lẹ́nu' nílùú Osogbo
Bakan naa lo tun ṣalaye pe gbogbo maluu ti wọn pa fun isinku naa ko lounka to bẹẹ gẹl to jẹ pe oun ko lee ka wọn,  bẹẹni awọn ko lee pa gbogbo maluu naa tan.
Gbajumọ onile ijo naa ni pupọ awọn maluu to ku ti wọn ko pa loun pin fun gbogbo awọn ọbalaye to wa si ibi isinku naa, oun si tun pin fun awọn mọlẹbi oun ni idile baba ati iya ti o si tun ku si agbala oun nile.
Maluu ṣi n wọle fun mi o. Mo lọ si ipinlẹ Ẹbọnyi laipẹ yii, wọn tun fun mi ni maluu mẹtala nibẹ.
Nigba to n dahun ibeere lori idi to fi jẹ pe awọn oruks bii Opium, Pablo, Montana ati bẹẹbẹẹ lọ lo n sọ awọn ile iṣẹ rẹ gbogbo, Obi Cubana ni ile ijo ni awsn ileeṣẹ oun, nibi ti awọn eeyan ti lee maa sinmi lẹyin iṣẹ wọn nitori naa oun ko le maa sọ wọn ni  ile ijo St Augustine lai kii ṣe ile ijọsin nitori naa loun fi n sọ wọn ni awọn orukọ bẹẹ.
Yollywood movies: Gbajúmọ̀ òṣèré, Rose Odika ní aráàú, àjọ 'Censors board'
Gbajumọ oniṣowo ile ijo naa wa pari ọrọ rẹ pẹlu pe ko si iṣẹ ti ọms oun kan ba fẹ ṣe ti oun ko ni tii lẹyin koda ko jẹ iru iṣẹ ṣiṣe akoso ile ijo bii toun ni smọ bẹẹ ba fẹ tẹle.
Ọmọ mi ọdun mẹrin ni oun fẹ maa ya aworan mo si ṣetan ati tii lẹyin. Awọn ọmọ Davido ati Wizkid n kọrin. Akaimoye awọn aworan lo jẹ pe ẹgbẹlẹgbẹ miliọnu ni wọn n ta wọn. Melo ninu wa lo lee fọwọ sọya pe oun ni millionu kan dọla ri, ṣugbọn awọn ayaworan a maa pa owo yii pẹlu aworan wọn.
Emere celebration: Wo ohun tó ṣẹlẹ̀ níbi àjọ̀dún ẹgbẹ́ Emèrè Onítẹ̀síwájú l'Osogbo
Oríṣun àwòrán, Alaroye
Awọn ẹgbẹ Emere Onitẹsiwaju ti wọn ṣe ajọdun ọdun keji idasilẹ ẹgbẹ wọn nílùú Osogbo.
Ko Si ibo miran ti ajọdun ọhun ti waye ju ile Araba ilu Osogbo, Oloye Ifayemi Elebuibon lọ.
Aṣọ leesi funfun balau ni gbogbo awọn ọmọ ẹgbẹ wọ nibi ayẹyẹ naa.
Lati gbogbo ijọba ibilẹ to wa nipinlẹ Osun lawọn ọmọ ẹgbẹ Emere Onitẹsiwaju ti pejọ sibi ajọdun ọhun.
Nigba to n sọrọ nibi ajọdun naa, Aarẹ ẹgbẹ Emere Onitẹsiwaju lagbaaye, Iya-osa Oyelola Egbeyemi Elebuibon gboṣuba fun Eledua to jẹ kí ajọdun ṣeeṣe.
Bakan naa ni Iya-oosa tun dupẹ lọwọ gbogbo awọn oniṣẹṣe to fi mọ awọn adari wọn.
Egbeyemi Elebuibon ni igbelarugẹ aṣa ati ẹsin abalaye lo mu ki awọn pejọ sibi ajọdun naa.
O ni awọn alalẹ ilẹ Yoruba ti fi ìpìlẹ iṣẹ rere le'lẹ fún iran Yoruba
Iya-oosa ṣalaye pe o wa ku sọwọ awọn ọmọ Yoruba lati ri pe aṣa ati ẹsin abalaye ko di ohun igbagbe.
"Ni bayii, awọn eeyan ilẹ Yuroopu, Amerika ati Latin ti bẹrẹ si ni kọ aṣa ati ẹsin Yoruba.
Koda wọn tún n ṣe akitiyan lati fi le awọn ọmọ wọn lọwọ lai tiju nipa rẹ.
O wa ku si awa oni nkan gan an lọwọ láti máa jẹ kí àwon ọmọ ilẹ òkèèrè maa mọ awọn ọmọ wa ni aṣa ati ẹsin Yoruba, Iya-oosa lo ṣalaye bẹẹ."
Araba ilu Osogbo, Oloye Ifayemi Elebuibon at'awọn eekan ninu awọn oniṣẹṣe naa wa nibi ajọdun naa.
Alákóso ìjọba ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́ nígbàkanrí, Adetunji Olurin jáde láyé
Oríṣun àwòrán, NAtionalinsight
Alakoso ijọba ologun ni ipinlẹ Ọyọ nigbakan ri, Ọgagun Adetunji Idowu Olurin ti jade laye.
Olurin to tun figbakan ri ṣe alakoso alagbada ni ipinlẹ Ekiti nigba kan ri jade laye lẹni ọdun mejidinlọgọrun.
Ileewosan ẹkọṣẹ iṣegun fasiti ilu Eko (LUTH)
Ọms ilu Ilaro ni Ọgagun Olurin, o si kẹkọ ologun ni ile ẹkọṣẹ ogun ti ilẹ Naijiria, NDA ni Kaduna laarin ọdun 1967 si 1970, ileewe ẹkọṣẹ ologun School of Infantry, Quetta Pakistan lọdun 1973, ileẹkọ awọn lọgalọga lẹnuṣẹ ologun ni Naijiria, Army command and Staff college, ni ilu Jaji laarin ọdun 1977 si ọdun 1978.
Kaduna Kidnap: Àwọn ajínigbé tú àwọn ọmọ akẹ́kọ̀ọ́ Bethel mẹ́ẹ̀dọ́gun míràn sílẹ̀
Oríṣun àwòrán, The Nation
Mẹẹdogun ninu awọn ọmọ ọgọrin to ku ninu awọn ti ajinigbe ji gbe ni ile ẹkọ Baptist Bethel ni ipinlẹ kaduna ti tun gba itusilẹ.
Ni ọjọ karun osu, keje, ọdun 2021 ni awọn ajinigbe wọ ile ẹkọ naa ni agbegbe Damishi ni ijọba ibilẹ Chikun ti wọn si gbe akẹkọọ igba ati mọkanlelogun.
Ní ọjọ karunlelogun ni wọn tu awọn mejidinlọgbọn  silẹ lẹyin ti awọn obi san aadọta miliọn Naira.
Lẹyin eyi ni wọn tun ni ki wọn san ọgọrin miliọnu naijra miiran lati tu awọn ọgọrin toku silẹ ni ahamọ wọn.
Iroyin sọ pe wọn tun san owo itusilẹ miiran lati gba awọn mẹẹdogun yi, sugbọn ko si ẹni to le fi idi rẹ mulẹ iye ti wọn tun san.
Yoruba Nation: Mo faramọ́ àtúntò 'Restructuring' tí kò lọ́wọ́ ìṣèlú nínú- Oba Ahmed Adeku
Lasiko to n fi idi ọrọ naa mulẹ lowurọ ọjọ Aje alaga ẹgbẹ ọmọ lẹyin kristi (CAN) ẹni ọwọ  Joseph Hayab sọ pe mẹẹdogun  ni wọn tu silẹ loru Satide.
Oríṣun àwòrán, The Nation
Bode George: Èèkàn ẹgbẹ́ òṣèlú PDP sọ ìdí tí ẹgbẹ́ náà fi kùnà láti wọlé ìbò gómìnà l'Eko
Oríṣun àwòrán, @TheTrentOnline
Eekan ẹgbẹ oṣelu PDP nipinlẹ Eko, Oloye Bode George ti ṣalaye ohun to faa ti ẹgbẹ naa ko ṣe tii wọle ibo gomina lati ọdun 1999 di akoko yii.
Oloye George ṣalaye minu ifọrọwerọ to ṣe pẹlu iwe iroyin Punch pe awarada kẹrikẹri ni ọrọ eto idibo nipinlẹ Eko.
Bode George ni ọwọ lasan lawọn eeyan fi n ko iwe idibo kaakiri ibudo idibo l'Eko, eleyii to ni ko dara rara.
''A ti n sọ tipẹ pe ki a maa lo ẹrọ kọmputa fun eto idibo wa, ọpọ ko fẹ gbọ.
Eeyan kan ti ji owo ipinlẹ Eko debi wi pe o ti lowo ju orilẹede Naijiria gan an lọ, ba wo ni PDP ṣe fẹ bori ninu eto idibo bayẹn?
Ẹ wo eto idibo ijọba ibilẹ to lọ nipinlẹ Eko, o buru debi pe awọn araalu ko tilẹ jade dibo nitori wọn ti sọ ireti nu.
O rọrun fun wọn lati ra ibo pẹlu ọpọ eeyan ti ebi n pa niluu ti inu wọn ko dun.
Oba Gbolahan Timson shomolu: Obasanjo ti jẹ́wọ́ pé 'Mistake' ni Buhari ṣùgbọ́n...
Mi o mọ ibi ti orilẹede yii n lọ gan an, a ni lati ba awọn to n ṣe ijọba sọ otitọ ọrọ.
Kilode gan an ti a ko fi le maa lo ẹrọ kọmputa dibo ati gbe esi idibo jade ki awọn tawọn araalu dibo yan le maa de ipo?
Yoruba Culture: ọjọ́ méje ni wọ́n fí n rẹ ẹ̀kú Danafojura kó tó jáde
A o ti bẹrẹ ohun kankan bayii o, a ṣi n ṣe ere lọwọ pẹlu bi eto idibo wa ṣe ri lọwọ yii,'' Oloye George ṣalaye.
Igbakeji alaga gbogbo ẹgbẹ oṣelu PDP tẹlẹ rọ Aarẹ Muhammadu Buhari pe ki o faye gba atunto Naijiria bi eto idibo 2023 ti n kan ilẹkun.
Olawale Dada: Igbá bárà kọ́ ló kàn, àwa náà n ṣoríire láyé pẹ̀lú ìpèníjà 'Cerebral Palsy'
O ni eyi nikan lo le mu ki alaafia jọba lorilẹede Naijiria, ''irọ lasan an ni gbogbo awọn to n fo kiri bi ẹyẹ pe awọn lo maa jẹ aarẹ lọdun 2023.
Pẹlu eto idibo to wa nilẹ yii, eeru ni a ba nibẹ, eto idibo ti a n lo yii ko lootọọ, ẹ jẹ ka gbiyanju omiran wo,'' Oloye George lo sọ bẹẹ.
Taye Osinowo Olaosebikafi Iyabo Ojo, Mide Martins, Jaye Kuti, Afeez Owo àtàwọn míì dárà ap
Modakeke killings: Ilé iṣé ọlọ́pàá rọ àwọn akọ̀ròyìn láti lépa àlááfíà lórí ìṣẹ̀lẹ̀ ìṣekúpani nílùú Modakeke
Oríṣun àwòrán, other
Ile iṣẹ ọlọpaa ipinlẹ Osun ti rọ awọn akọroyin lati sọ otitọ lori iṣẹlẹ iṣekupani eeyan marun un to waye lọjọ Ẹti to lọ niluu Modakeke.
Alukoro ile iṣẹ ọlọpaa ipinlẹ Osun, Yemisi Opalola lo sọrọ yii fawọn akọroyin lalẹ ọjọ Abamẹta.
Opalola ni alaafia ni ipinlẹ Osun nilo lọwọ yii kii ṣe rogbodiyan.
''A gbọdọ huwa gẹgẹ bi ọmọluabi lẹnu iṣẹ wa lai ṣegbe lẹyin ẹnikan.
Bakan naa a ni lati fi ifẹ han si ilẹ wa papaa julọ ti a ba n jabọ iroyin to niiṣe pẹlu ẹlẹyamẹya tabi ọrọ oṣelu to le di wahala.
Ẹ jẹ ki a ranti pe ọmọ Oduduwa ni gbogbo wa, ẹ ma jẹ ka da epo si ina to n jo.
Oba Gbolahan Timson shomolu: Obasanjo ti jẹ́wọ́ pé 'Mistake' ni Buhari ṣùgbọ́n...
Mo fẹ fi da yin loju pe ko si ohun to jọ ija Ife ati Modakeke ninu ọrọ to wa nilẹ yii.
Nitori naa, ẹ jẹ ki a gba alaafia laaye lẹnu iṣẹ wa ki a maa da omi alaafia ru nipinlẹ Osun.
Yoruba Nation: Mo faramọ́ àtúntò 'Restructuring' tí kò lọ́wọ́ ìṣèlú nínú- Oba Ahmed Adeku
Ẹwẹ, ijọba ipinlẹ Ọṣun ti kọkọ ke sawọn eeyan agbegbe Ifẹ ati Mọdakẹkẹ lati maṣe fi aye gba awọn kọlọrọsi janduku laarin wọn lati da wahala silẹ nibẹ.
Gomina ipinlẹ Ọṣun, Gboyega Oyetọla funrarẹ ti pe Ọọni ti ilu ile Ifẹ, Ọba Ẹnita Adeyẹye Ogunwusi, Ọjaja keji ati Ogunṣua ti ilu Mọdakẹkẹ, Ọba Moses Oyediran Ọladẹjọ ti awọn mejeeji si ti fi daa loju pe omi alaafia laarin ilu mejeeji yii yoo pada toro.
Ọlatunji, akẹ́kọ̀ọ́gboyè 'graduate' tó ń ta àkàrà 'Ó ta lẹ́nu' nílùú Osogbo
Bakan naa ni ileeṣẹ ọlọpaa ni ipinlẹ Ọsun pẹlu ti ṣalaye pe igbesẹ ipana aawọ ti nlọ lọwọ lati ọjọ Ẹti ti iṣẹlẹ naa ti ṣẹlẹ.
Kọmiṣọnna ọlọpaa ni ipinlẹ Ọṣun, Ọlawale Olokode ni awọn iroyin kan ti tu si ileeṣẹ ọlọpaa lọwọ ti yoo ṣe okunfa mimu awọn oniṣẹ ibi naa ni kiakia.
Animal census: Ìjọba pàṣẹ pé kí wọ́n ka gbogbo ẹranko igbó àti ẹja inú omi
Eto ikaniyan ni a maa n gbọ, e wo tu ni ti ẹranko kika?
Bi ọrọ yii ti n ṣe ọpọ eeyan ni kayeefi niyii lẹyin ti ijọba orilẹede Kenya paṣẹ pe ki wọn ka gbogbo ẹranko igbo ati ẹja inu omi to wa lorilẹede naa
Igbesẹ yii waye lati le dẹkun bi awọn eeyan kan ṣe n pa awọn ẹran naa ni ipakupa.
Orilẹede Kenya to wa lapa ila oorun ilẹ Afirika ni ọpọlọpọ ẹya ẹranko ti ko wọpọ lagbaaye.
Kiniun ati agunfọn wa lara awọn ẹranko ti awọn eeyan n pa ni ipakupa lorilẹede Kenya.
Orilẹede Kenya nikan ni agbanrere funfun meji to ku lagbaaye wa bayii.
Ọpọ ẹja nla ''whales'' ati ''dolphins'' to fi mọ oriṣiiriṣii ijapa inu omi lo wa lawọn odo lorilẹede Kenya.
Yoruba Nation: Mo faramọ́ àtúntò 'Restructuring' tí kò lọ́wọ́ ìṣèlú nínú- Oba Ahmed Adeku
Akọroyin BBC, Ferdinand Omondi ṣalaye pe Kenya ti n gbiyanju lati ka awọn ẹranko kan tẹlẹ.
Ṣugbọn igba akọkọ ree ti Kenya yoo ka gbogbo ẹranko inu igbo ati ẹja inu omi.
Igbesẹ yii waye lati daabo bo awọn ẹranko yii ki awọn arinrin ajo afẹ le maa lanfaani lati ri wọn.
Ọlatunji, akẹ́kọ̀ọ́gboyè 'graduate' tó ń ta àkàrà 'Ó ta lẹ́nu' nílùú Osogbo
Minisita ile iṣẹ ijọba to n ri si irin-ajo afẹ lorilẹede Kenya, Najib Bala ṣalaye pe ''mimọ iye ẹranko ti a ni ni ijọba fi le ṣeto iṣuna fun itọju wọn.''
Ṣugbọn eto naa ko rọrun nitori ẹgbẹẹgbẹrun ẹranko igbo to wa kaakiri orilẹede Kenya.
Ilé wó lu Bisi, ọmọ ẹ̀yìn rẹ̀ kú, wọ́n gé ẹsẹ̀ rẹ̀ tó ń jẹrà, inú ìrora ló wà ṣùgbọ́n
Ọkan lara ọna ti wọn fẹ lo ka awọn ẹranko yii ni fifi baalu ka wọn lati oke.
Akọroyin BBC, Omondi ni o ṣoro lati mọ iye erin to wa ninu igbo ẹranko ni Kenya.
Kola Ologbondiyan: PDP ni yóò mú ọmọ Nàíjíríà kúrò lóko ìyà tí wọn wà ní 2023
O ṣalaye pe oju ẹsẹ awọn awọn erin ninu igbo ni wọn fi n ka wọn bayii.
Kika awọn ẹja inu omi naa ṣe pataki lati mọ awọn ibi ti awọn ẹranko inu omi ti nilo idaabobo julọ.
Working religious women: Ẹ̀lẹ́hàá kìí ṣe ọ̀lẹ- Aminat Adegoke
Alleged missing N106bn: SERAP gbé Buhari lọ sílé ẹjọ́ lórí owó tí wọ́n ló d'àwátì láwọn ilé iṣẹ́ ìjọba
Oríṣun àwòrán, Facebook/Bashir Ahmad
Ajọ SERAP to n ri itọpinpin awọn akanṣe iṣẹ ni Naijiria ti gbe Aarẹ Muhammadu Buhari lọ si ile ẹjọ lori biliọnu mẹrindinlaadọfa(N106bn) to di awati lawọn ileeṣẹ ijọba mọkandinblaadọjọ(149).
Ajọ SERAP pe Buhari lẹjọ lori ikuna rẹ lati ṣe iwadii ẹsun owo to di awati ọhun lawọn ile iṣẹ ijọba.
Igbesẹ yii tẹle ikede ọfiisi ayẹwe owo wo agba ni Naijiria lọdun 2018 pe N105,662,350,077 ti di awati tabi ki wọn ti ṣe e kumọ kumọ lawọn ileeṣẹ ijọba 149.
SERAP tun pe agbẹjọro agba ati minisita eto idajọ ni Naijiria, Abubakar Malami, SAN ati minisita eto inawo, Zainab Ahmed naa lẹjọ lori ẹsun kan naa.
Ninu ẹjọ ti SERAP pe pẹlu nọmba yii, FHC/ABJ/CS/903/2021, lọsẹ to lọ ni ile ẹjọ giga ijọba apapọ l'Abuja, ajọ naa fẹ ki ijọba paṣẹ fun Buhari lati ṣe iwadii owo to sọnu yii.
Ajọ SERAP fẹ ki ileẹjọ ri pe awọn to ba jẹbi ẹsun yii foju wina ofin ki wọn si da owo ijọba pada.
Yoruba Nation: Mo faramọ́ àtúntò 'Restructuring' tí kò lọ́wọ́ ìṣèlú nínú- Oba Ahmed Adeku
Ajọ naa ṣalaye ti ijọba ba ri owo yii gba pada, yoo dẹkun yiya owo kaakiri ti ijọba apapọ n ṣe bayii.
SERAP sọ pe gbese orilẹede jẹ yoo tun dinku ti ijọba ba le ri owo to di awati yii gba pada.
Ajọ SERAP ni owo ti wọn lo sọnu yii ti ṣe akoba fawọn ẹka ijọba, ko si le jẹ ki wọn ṣe ojuṣe wọn gẹgẹ gi ileeṣẹ ijọba.
SERAP tun sọ fun ileẹjọ pe ko paṣẹ fun aarẹ Buhari lati maa gbe eto iṣinu gbogbo ileeṣẹ ijọba jade lọdọọdun.
Ajọ naa ni eleyii yoo fawọn araalu lanfaani lati mọ bi ẹka ijọba kọọkan ṣe n nawo.
Ile ẹjọ ko tii kede ọjọ ti igbẹjọ yoo bẹrẹ.
Oba Ogboni Abalaye n fẹ́ kí wọ́n o má a fi ẹ̀sìn àbáláyé búra fún àwọn olóṣèlé Naijiria
Yoruba Nation: Mo faramọ́ àtúntò 'Restructuring' tí kò lọ́wọ́ ìṣèlú nínú- Oba Ahmed Adekunle Makama ti Kuta
Ẹ jẹ́ kí Gómìnà kọ̀ọ̀kan bẹ̀rẹ̀ 'Restructuring' ni ìpínlẹ̀ rẹ̀ pẹ̀lú ríró ìjọba ìbílẹ̀ lágbárá- Olowu ilẹ̀ Kuta
A mọ́ awọn Fulani Abalaye a dẹ tun mọ ti awọn to n gbe ibọn pe wọn yatọ sira wọn- Oba Kuta
Oba Ahmed Adekunle Makama ti Olowu Kuta sọrọ ilẹ kun lori oriṣi awọn Fulani to wa ni Naijiria bayii ati nkan to yẹ ki ijọba se fun koowa.
Bakan naa lo ni o yẹ ki ijọba pada si riro awọn ijọba ibilẹ lagbara ni ki alafia le jọba.
Oríṣun àwòrán, @Oba Kuta
Oba Kuta tun gba imọran pe ki atunto bẹrẹ lati ipinlẹ Gomina kọọkan.
O ni ile la ti n ko ẹṣo rode ni ọrọ Naijiria ba de bayii pẹlu ijiya to tọ si ẹnit o ba huwa aitọ.
Adigun Olowe: Ọmọ ọdún márùn-ún, Adigun Olowe jẹ oyè nílùú Eko
Oríṣun àwòrán, Adigun olowe/instagram
Ọdọmọde agbede-gbẹyọ Yoruba, Adebayo Olamilekan Israel,  ti ọpọ mọ si Adigun Olowe ti jẹ oye 'Ọdọ Agba Aṣa Ga' ti ilu Solu Alade, Ibeju-Lekki nipinlẹ Eko.
Ọmọ naa to gbajumọ fun bo ṣe ma n pa owe Yoruba loriṣiriṣi, to si tun ma n tumọ wọn.
Ọmọ ọdun marun-un ni ọmọ naa.
Ninu ọrọ to kọ si oju opo Instagram rẹ, lati kede ifinijoye naa, Adigun Olowe sọ pe ọjọ kẹrinla, oṣu Kẹjọ, ọdun 2021, ni Oba Muyideen Isgola Balogun, Onisolu ti Solu Alade, Ibeju-Lekki, fi oun jẹ oye naa.
O ni pẹlu ifinijoye yii, oun ni ẹni ti ọjọ ori rẹ kere ju ninu awọn to jẹ oye ibilẹ ni Naijiria.
Adigun Olowe sọ pe oun ko le sọ bi inu oun ṣe dun to o si ifinijoye naa.
"Ninu ifọrọwanilẹnuwo kan ti BBC Yoruba ṣe fun Adigun Olowe, baba rẹ, Adebayo Oladimeji Ishola ni lati kekere ti awọn ti bi ọmọ naa lo ti maa n ṣe awọn nkan to jẹ iyalẹnu, eyi to si mu ki iya iya rẹ fun un ni alajẹ ""Ara""."
Wo Adigun ọmọ ọdún mẹ́rin tí òwe Yorùbá àti ìtúmọ̀ gbó lẹ́nu rẹ̀ ju tìrẹ̀ lọ
O ni ọjọ kan lo kọkọ bẹrẹ rẹ tawọn ṣaadede ri i to tun ọrọ ti oun sọ lede Yoruba ati gẹẹ́si sọ papọ lẹẹkan ṣoṣo titi to fi dori pe o lee sọ owe ọgbọ̀n ati itumọ rẹ lede gẹẹ́si.
Hakainde Hichilema: Aarẹ tuntun tó ṣe ìbúra ní Zambia ṣelérí oúnjẹ mẹ́ta lójúmọ́ fún ará ìlú
Oríṣun àwòrán, EPA
Aarẹ tuntun tó ṣe ìbúra ní Zambia ṣelérí oúnjẹ mẹ́ta lójúmọ́ fún ará ìlú.
Aarẹ Hakainde Hichilema sọrọ yii lasiko ibura wọle sipo aarẹ nibẹ.
O ni ko si ọmọ Zambia ti a tun sun lebi mọ.
Ero kun papa iṣere ni Lusaka pupọ laisko ibura na.
Nítorí kí aafa lè máa rí iṣẹ́ ṣe ní wọ́n kò ṣe kó Alumaajiri nílẹ̀ tó fi di ohun tó dà yìí
Bakan naa lo seleri lati ma fi aaye gba ijekuje ati awọn oni jégudu jẹra ninu ijọba lasiko ré.
Ijoba rẹ ti gori aleefa bayii leyin to ti dije fun ọpọlọpọ igba.
Unijos students victims: Àwọn Fulani yabo 'hostel' wa, ọpẹ́lọpẹ́ àwọn Sọ́jà tí gómìnà ìpí
Eekan gboogi lara awọn oloṣelu alatako ni Orilẹede Zambia, Hakainde Hichilema ti di aarẹ orilẹede naa bayii,
Wọn si ti ṣe eto ibura fun niwaju ọpọlọpọ ero ni papa iṣire nla kan ni Lusaka tii ṣe olu ilu orilẹede naa.
Ibo to gbe Hichilema wọlẹ sipo aarẹ lẹyin ọpọlọpọ ọdun gẹgẹbi asiwaju ẹgbẹ alatako ti fun ọpọlọpọ awọn oloṣelu alatako kaakiri ilẹ Afiriki ni ireti pe bo pẹ bo ya, ọsan yoo so didun fun awọn naa pẹlu.
Wo bí Ààrẹ tuntun ní Zambia ṣe di  kóríyá fún gbogbo ẹgbẹ́ alátakò ní Áfíríkà
Lasiko to fi ṣe oṣelu alatako ninu eyi to ti gbe apoti ibo ni igba marun un ọtọtọ to si mi ki o to wa di aarẹ.
Oríṣun àwòrán, AFP
Ọgbẹni Hichilema fi oju wina wahala, ati idojukọ, koda akaimọye igba ni wọn luu bii bara, ti wọn fẹ afẹfẹ tajutaju tia-gaasi sii loju, ti wọn tilẹ tun tii mọle lọdun 2017 pe o kuna lati yago lọna fun awọn ọkọ to kọwọrin pẹlu aarẹ to fipo silẹ bayii, Edgar Lungu.
Oríṣun àwòrán, AFP
Wọ́n búra fún Aarẹ tuntun ní Zambia, inú ará ìlú dùn fún ìlérí tó ṣe fún wọn
Ààrẹ tuntun ní Zambia di kóríyá fún gbogbo olóṣèlú alátakò ní Áfíríkà
Nibayii ti Eleduwa gbe ise rẹ de bayii, arakunrin ti wọn ti fi igbakan ri kede gẹgẹ ọta ilu ti di ẹni wọn bura fun gẹgẹ bi aarẹ ikeje fun Orilẹede Zambia lẹyin to fagba han Ọgbẹni Lungu ninu idibo to waye ni ojọ kejila oṣu kẹjọ.
Iwuri nla gbaa lo jẹ gẹgẹ bi olori ẹgbẹ alatako lorilẹede Tanzania, Tundu Lissu ṣe sọ.
Babatunde Gbadamosi: Mo ta gbogbo dúkìá mi lásìkò kan kí ń tó padà di eèyàn lónìí
Ori ko Lissu yọ lọwọ awọn agbenipa lọdun 2017 lẹyin ti awọn ti ọpọlọpọ gba pe wọn jẹ agbefọba  yin in ni ibọn nigba mẹrindilogun.
Lissu ni awọn ọmọ orilẹede Zambia ti jẹ ko di mimọ pe ohun to ṣe é ṣe ni lainaani ohun ti  ẹgbẹ to ba n ṣe ijọba le mu awọn alatako ba la kọja.
Ọgbẹni Lissu padanu idibo aarẹ to kọja ni Tanzani eyi ti aarẹ John Magufuli to pada wa di oloogbe bori.
Oríṣun àwòrán, AFP
Amọṣa, Lissu ni wọn ṣe eru ibo naa ni ki o to sa fi orilẹede naa sile nigba tawọn agbofinro n gbero lati mu si ahamọ.
Kii ṣe Tanzania nikan ni afẹfẹ ireti yii fẹ de, o fẹ de Zimbabwe nibi tawọn ọmọ ẹgbẹ oṣelu alatako ti n dunnu.
Ondo Jos clash: Èmi nìkan ló padà dé nínú àwa márùn ún tí a jọ lọ ìpàdé àdúrà ní Jos- Bell
"Ninu ọrọ ikini ku oriire to kọ si oju opo ayelujara, ""Zimbabwe lo kan"" ni olori ẹgbẹ alatako nibẹ, Leson Chamisa kọ."
Ni Kenya ẹwẹ, iṣẹlẹ naa ti mu awọn ọmọlẹyìn olori ẹgbẹ alatako nibẹ, Raila Odinga lọkan le pe ilẹ lee rọ fun awọn lati gbin ọka si nibi eto idibo ti wọn n gbaradi fun nibẹ.
"Ọgbẹni Osinga ni esi idibo aarẹ lorilẹede Zambia naa ti ""fihan gbogbo Afrika pe ko si ohun ti ko ṣeeṣe"
Babatunde Gbadamosi: Mo ta gbogbo dúkìá mi lásìkò kan kí ń tó padà di eèyàn lónìí
Ojú Iya Jadesola Akande ri tó lọwọ awọn ọlọpaa kogberegbe ni LASU ni 1989- Babatunde Gbadamosi
Oju ẹni ma la a ri to .... ni ọrọ awọn agba Yoruba.
Oludije dupo gomina nigba kan ri ni ipinlẹ Eko to tun jẹ gbajugbaja onisowo to n kọ ile gbigbe ta fun awọn eeyan ba BBC Yoruba sọrọ lori ọna atila awọn ọdọ.
Babatunde Gbadamosi ti ọpọ mọ si Onisowo ile ọlọpọ eero ni ipinlẹ Eko mẹnuba bi irinajo rẹ se bẹrẹ nile ẹkọ giga fasiti LASU to jẹ Lagos State University.
Oríṣun àwòrán, others
O sọ nipa ohun ti oju awọn akẹkọọ ri lọwọ awọn ọlọpaa kogberegbe  'Mopol' nigba naa.
Gbadamosi sorọ nipa iya Jadesola Akande to jẹ adari ileẹkọ LASU ni 1989 naa jẹ ṣege iya ainidii lọwo awọn agbofinro ọhun.
Bandits killings: Àwọn jàndùkú agbébọn gbẹ̀mí èèyàn 24 ní Kaduna àti Katsina lópin ọ̀sẹ̀
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Awọn janduku agbebọn afẹmi-ṣofo tun ṣọṣẹ lọjọ Aiku, ọjọ kejilelogun oṣu kẹjọ nipinlẹ Kaduna ati Katsina.
Lọjọ Abamẹta lawọn kọlọnbiti ẹda ọhun kọkọ yabo awujọ Duba ni ijọba ibilẹ Batsari nipinlẹ Katsina nibi ti wọn ti ṣekupa eeyan mejila.
Eeyan mejila mii tun dero ọrun labule Mado, ni ijọba ibilẹ Zangon Kataf nipinlẹ Kaduna lẹyin ti ija bẹ silẹ laarin awọn darandaran atawọn eeyan abule naa to fẹ gbẹsan.
Batsari nibi ti wọn ti pa eeyan mejila ni ipinlẹ Katsina jẹ ibode awọn janduku afẹmi-ṣofo ti n ṣọṣẹ lẹkun iwọ oorun ariwa Naijiria.
Awujọ Batsari tun pa aala pẹlu igbo Rugu to wa lara ijọba ibilẹ mẹwaa tawọn janduku yii maa n ṣe ikọlu si.
Alukoro ile iṣẹ ọlọpaa ipinlẹ Kaduna, Isa Gambo fidi rẹ mulẹ pe awọn janduku agbebọn to le lọdunrun yabo ijọba ibilẹ Zangon Kataf pẹlu oriṣiiriṣii ibọn ati ohun ija oloro ni bii ago mẹsan ku iṣẹju mẹẹdogun lalẹ ọjọ Abamẹta.
Yoruba Nation: Mo faramọ́ àtúntò 'Restructuring' tí kò lọ́wọ́ ìṣèlú nínú- Oba Ahmed Adeku
Gambo ṣalaye pe awọn janduku ọhun da ibọn dolẹ kete ti wọn de abule Duba, lẹyin naa ni wọn bẹrẹ si ni jale ninu awọn ṣọọbu, ti wọn si tun ji awọn ẹran ọsin eeyan ilu naa.
Alukoro ile iṣẹ ọlọpaa ni eeyan mẹfa lo farapa yatọ si eeyan mejila to gbẹmi mi nibi iṣẹlẹ ọhun.
Oba Ogboni Abalaye n fẹ́ kí wọ́n o má a fi ẹ̀sìn àbáláyé búra fún àwọn olóṣèlé Naijiria
O fidi rẹ mulẹ pe awọn ọmogun atawọn ọlọpaa ṣi n tẹsiwaju lori ati le awọn janduku ọhun kuro ni Kaduna.
Gambo ni awọn eeyan mẹfa to ṣeeṣe nibi iṣẹlẹ ọhun ti n gba itọju nile iwosan.
Ọlatunji, akẹ́kọ̀ọ́gboyè 'graduate' tó ń ta àkàrà 'Ó ta lẹ́nu' nílùú Osogbo
Yahaya Bello vs Tinubu: Joe Igbokwe ní ọmọdé kò lè ṣèjọba Nàìjíríà, Tinubu ló ní ìrírí jùlọ
Oríṣun àwòrán, others
Alukoro ẹgbẹ osẹlu APC nipinlẹ Eko tẹlẹ, Joe Igbokwe naa ti fesi si ọrọ ti gomina ipinlẹ Kogi, Yahaya Bello to sọ pe ki Bola Tinubu fawọn ọmọde ninu ẹgbẹ laaye lati dupo aarẹ lọdun 2023.
Igbokwe sọ fun BBC Yoruba pe Ọlọrun nikan lo le ni ki Tinubu maa jẹ aarẹ Naijiria lọdun 2023.
Igbokwe to jẹ ọkan lara awọn oludamọran si Gomina Babajide Sanwo-Olu ṣalaye pe ayafi ti Tinubu fun ra rẹ ba yi ọkan rẹ pada wi pe oun ko dije mọ nikan loku.
''Iriri ṣagba ọgbọn, ati pe ẹru ajanaku lọrọ orilẹede Naijiria, kii ṣe ẹru ọmọde.
Joe Igbokwe ni: Orilẹede Naijiria tobi ju ohun ti ọmọde le ṣe adari rẹ lọ nitori ita to ba tọ si imu ni a maa fi n re imu.
Ko si ẹni tun ti ni iriri ti Tinubu ni lagbo oṣelu ni Naijiria.
Bello kan n sọ ọrọ tiẹ ni nitori ara rẹ, ṣugbọn Aṣiwaju ti rin jina lori irinajo rẹ lati jẹ aarẹ Naijiria.
Babatunde Gbadamosi: Mo ta gbogbo dúkìá mi lásìkò kan kí ń tó padà di eèyàn lónìí
O yẹ ki Naijiria tilẹ sanwo fun Tinubu ni lati wa jẹ aarẹ orilẹede yii.
Nitori ohun ti Tinubu yoo ṣe to ba di aarẹ Naijiria pọju.
Anfani nla lo maa jẹ ki fawọn eeyan Naijiria ti Tinubu ba le jẹ aarẹ orilẹede Naijiria,'' Igbokwe lo sọ bẹẹ.
Oríṣun àwòrán, Facebook/Jandor
Tinubu lẹ́tọ̀ọ́ láti dupò ààrẹ lẹ́gbẹ́ APC gẹ́gẹ́ bí àwọn ọmọdé náà ti lẹ́tọ̀ọ́ - Jandor
Jandor ní àti ọmọdé àti àgbà ló lẹ́tọ̀ọ́ láti díje fún ipò ààrẹ lọ́dún 2023
Eekan ẹgbẹ oṣelu APC to tun ṣagbatẹru ipolongo Lagos4Lagos ṣaaju ibo gomina ipinlẹ Eko ọdun 2023, Ọmọwe Abdul-Azeez Olajide Adediran.
Oun ni ọpọ mọ si Jandor ti fesi si ọrọ ti gomina ipinlẹ Kogi, Yahaya Bello sọ pe ki Aṣiwaju fawọn ọmọlẹyin lanfani lati dupo aarẹ lọdun 2023.
Nigba to n ba BBC Yoruba sọrọ, Ọmọwe Adediran ni ko si ẹni ti ko lẹtọọ lati dupo aarẹ lọdun 2023, ki ba ṣe ọmọde tabi agba.
Badagry: Ojú ọ̀nà àrèmabọ̀ fáwọn ẹrú tó ń lọ sókè òkun
Jandor sọ pe ko si ọrọ ninu ohun ti gomina Bello sọ nitori pe iwe ofin orilẹede Naijiria fun gbogbo eeyan lanfani lati dije fun ipo aarẹ to ba wu wọn.
Jandor yii lo ti n polongo pe Eko fun Eko lo maa bade ninu ibo gomina ipinlẹ naa lọdun 2023.
Jandor ni o da oun loju pe oun ni oun maa jẹ gomina ipinlẹ Eko lasiko idibo to n bọ.
Yoruba Nation: Mo faramọ́ àtúntò 'Restructuring' tí kò lọ́wọ́ ìṣèlú nínú- Oba Ahmed Adeku
Tinubu, fi ipò Ààrẹ sílẹ̀ fún àwa ọmọ rẹ kí o lè lọ sinmi- Yahaya Bello
Gomina ipinlẹ Kogi, Yahaya Bello ti sọrọ lori idi ti eekan ẹgbẹ oṣelu APC, Bola Tinubu ko ṣe gbọgọ gbe apoti ibo Aarẹ lọdun 2023.
Bello sọ pe o ti di dandan ki awọn aṣaaju ẹgbẹ APC ṣatilẹyin fun ọdọ to ba nifẹ lati gbe apoti idibo Aarẹ, ati pe adehun to wa laarin Tinubu ati Aarẹ Buhari ko lẹsẹ nilẹ.
Bo tilẹ jẹ pe Tinubu ko ti sọ ni gbangba pe oun fẹ dije du ipo Aarẹ, ṣugbọn patako ajuwe ipolongo rẹ ti wa kaakiri laarin ilu, paapaa nipinlẹ Eko.
Bello sọ fun awọn akọroyin pe oun bọwọ fun Tinubu gẹgẹ bii agba ọjẹ ninu oṣelu, amọ asiko ti to fun lati lọ sinmi.
"Bello ni ""Tinubu jẹ ọkan gboogi lara awọn aṣaaju wa, mo si gboriyin fun fún awọn iṣẹ to ti ṣe sẹyin ati akitiyan rẹ lati gbe ẹgbẹ wa de oke agba."""
Ṣugbọn tọwọ-tọwọ ni mo fi n sọ fun Tinubu gẹgẹ bii ọmọ pe ko lọ sinmi, ko fi ipo aṣaaju silẹ fun awọn ọmọ rẹ.
Niṣe lo yẹ ki Tinubu kọ awọn ọmọ to wa lẹyin rẹ bi wọn ṣe n ṣe eto ilu, ko si maa woye bi a o ṣe tun ilu ṣe loju aye rẹ.
Wikipedia: Ẹ̀nìkan sọ fún mi pé iṣẹ́ ìdọ̀tí ni màá ṣe ni mo ṣe ń ta ìwé
Bello ni Tinubu lẹtọ labẹ ofin lati dije du ipo Aarẹ, oun si rọ awọn araalu lati fun ni ọwọ to tọ si.
Nigba to n fesi si ibeere pe boya o ṣeeṣe ki Tinubu fi ẹgbẹ oṣelu APC silẹ ti ẹgbẹ naa ba kọ lati fun ni anfani lati dije, Bello ni o ṣoro ki eeyan kọ ile, ko tun fi ọwọ ara rẹ wo ile naa.
"O ni ""Mi o lero pe Tinubu le ṣe bẹẹ, ko ṣeeṣe ki eeyan kọ ile ko tun fi ọwọ ara rẹ wo ile ọhun, Tinubu ti kọja irufẹ iwa bẹẹ."""
Ni ti erongba rẹ lati du ipo Aarẹ, gomina ipinlkẹ Kogi naa sọ pe oun yoo fun gbogbo awọn to n fẹ ki oun du ipo Aarẹ ni esi ti akoko ba to.
Yoruba Nation: Ààrẹ ẹgbẹ VOR sọ pé kí ọmọ Yorùbá di ààrẹ Naijiria kọ́ ni ọ̀nà àbáyọ
Ẹwẹ, ẹgbẹ awọn ọmọ Yoruba kan, Yoruba Welfare Group, YWG, ni Tinubu ni awọn n fẹ ko di Aarẹ Naijiria lẹyin Mohammadu Buhari.
Aarẹ ẹgbẹ naa, Abdulhakeem Alawuje sọ fun awọn akọroyin pe aṣiwaju ni Tinubu, o si ti ni iriri yẹ lati tukọ Naijiria, nitori naa Bola Tinubu ipo Aarẹ kan.
Oba Ogboni Abalaye n fẹ́ kí wọ́n o má a fi ẹ̀sìn àbáláyé búra fún àwọn olóṣèlé Naijiria
Ifa religion: Àwọn Oníṣẹ̀ṣe ń fẹ́ kí Buhari fún wọn láàyè láti yanjú ìṣoro Naijiria lásìkò yìí
Oríṣun àwòrán, Ifashola Adedeji Durokifa
Ẹgbẹ awọn oniṣẹṣe nipinlẹ ogun ti ke si Aarẹ Muhammadu Buhari lati fun awọn laye lati yanju iṣoro to n koju ẹka eto abo Naijiria.
Oluwo Ifa ti ilu Egba, Oloye Ifagbeminiyi Baoku lo sọ ọrọ naa lasiko ayajọ ọjọ Iṣẹṣe ti ọdun 2021 to waye niluu Abeokuta.
Ayajọ ọjọ Iṣẹṣe naa jẹ ọjọ kan ti wọn maa n ya sọtọ nilẹ Yoruba fun awọn ẹlẹsin ibilẹ lati sin awọn oriṣa wọn.
Oluwo Ifa ti Egba naa sọ pe idi ti Naijiria ṣe n koju oniruru iṣoro ni ẹka eto abo ni pe awọn eeyan ti kọ awọn oriṣa adayeba silẹ, wọn ko si tẹle awọn alakalalẹ Ifa.
Baoku sọ pe ti Naijiria ba fẹ lati yanju awọn iṣoro to n koju rẹ, o ni lati lọ bi ifa leere.
"O ni ""Ijọba ti sun awa ẹlẹsin ibilẹ ti si ẹgbẹ kan, wọn ko si mọ pe awa gan ni ọna abayọ si awọn isọro to n koju Naijiria lọwọ yii."
Babatunde Gbadamosi: Mo ta gbogbo dúkìá mi lásìkò kan kí ń tó padà di eèyàn lónìí
Awọn ilana kan wa to rọ mọ ẹsin ibilẹ, ti a ba ṣe awọn nnkan to yẹ ki a ṣe gẹgẹ bi ilana ọhun ṣe gbe kalẹ ni, a ko ni maa koju awọn iṣoro to n dojukọ ilẹ wa lonii.
Oluwo Ifa ọhun wa ke si gomina dapo Abiodun ti ipinlẹ Ogun lati kede ayajọ ọjọ ọdun Iṣẹṣe naa, to jẹ ogunjọ, oṣu Kẹjọ ninu ọdun gẹgẹ bii ọjọ isinmi lẹnu iṣẹ ki awọn  to n ṣe ọdun naa le ri aye lati ṣe etutu to yẹ.
Badagry: Ojú ọ̀nà àrèmabọ̀ fáwọn ẹrú tó ń lọ sókè òkun
O fi kun pe kii ṣe ifakokoṣofo ni ti awọn eeyan ba n ṣe ọdun Ifa.
Ẹwẹ, alaga ẹgbẹ Iṣẹṣe Parapọ ni Egba, Ifaniaki Amosun sọ pe ọdun Iṣẹṣe naa ni ọna kan gboogi lati mu irẹpọ wa laarin gbogbo awọn oniṣẹṣe.
Yoruba Nation: Mo faramọ́ àtúntò 'Restructuring' tí kò lọ́wọ́ ìṣèlú nínú- Oba Ahmed Adeku
"Ifaniaki ṣalaye pe ""Gbogbo ẹlẹsin lo maa n kopa ninu eto idibo ni Najiria, ṣugbọn lẹyin ti awọn oloṣelu ba ti wọle ibo tan ni wọn maa n ṣe idẹyẹsi awọn ẹlẹsin ibilẹ."""
Ọdọdun ni awọn gomina maa kede ayajọ ọjọ isinmi fun awọn ẹlẹsin Kristẹni atawọn Musulumi, ki lo de ti wọn fi maa n yọ awa ẹlẹsin abalaye sẹyin?
O ye ki wọn ya ọjọ silẹ fun awa ẹlẹsin ibilẹ naa lati maa ṣe awọn isin wa, a n fẹ ki gomina wa ati minista fun ọrọ aṣa bojuwo ọrọ naa.
Lara awọn to peju sibi ọdun Iṣẹṣe naa ni Baba Iṣẹṣe ti Egba, Ọjọgbọn Ayinde Salami; Ojubono ti Egba, Oloye Onifade Ogundelde atawọn lọbalọba.
Victoria Aguiyi-Ironsi ti fi ayé sílẹ̀
Oríṣun àwòrán, IMSG
Iyawo adari ijọba ologun Naijiria nigba kan ri, Victoria Aguiyi-Ironsi ti jade laye lẹni ọdun mẹtadinlọgọrun un.
Iroyin ni arabibirin ọhun fi aye silẹ ni aarọ ọjọ Aje, ọjọ kẹtalelogun, oṣu Kẹjọ, ọdun 2021.
Ọjọ kọkanlelogun, oṣu Kọkanla, ọdun 2021 ti a wa yii lo yẹ ki ologbe naa pe ẹni ọdun mejidinlọgọrun un loke eepẹ ki ọlọjọ to de.
Ọkọ oloogbe ọhun, Aguiyi-Ironsi ni adari ijọba ologun Naijiria fun oṣu mẹfa ki wọn to gab ijọba lọwọ rẹ lọdun 1966.
Asiko iditẹgbajọba naa ni wọn ṣekupa Aguiyi-Ironsi atawọn ologun mii ti wọn jọjọ n ṣejọba lọdun naa lọhun.
Lẹyin iku ọkọ rẹ, arabinrin Victoria Aguiyi-Ironsi kọ lati ṣe igbeyawo pẹlu ọkunrin miran.
Ọmọ mẹjọ lo wa laarin awọn lọkọ-laya naa ki iku aitọjọ to pin awọn mejeji niya.
Funke Akindele Bello: 'Jenifa' ní ìjákulẹ̀ ìgbéyàwó òun àkọ́kọ́ fẹ́rẹ́ gbẹ̀mí òun ṣùgbọ́n òun kò gbà fún un
Oríṣun àwòrán, @Jenifa
Orí ayélujára ni mo ti gbọ́ pé ìgbéyàwó mi àkọ́kọ́ ti foríṣánpọ́n - Funmi Akindele Bello
Gbajumọ oṣere  Funkẹ Akindele ti ọpọlọpọ eeyan mọ si Jẹnifa ti ṣalaye ohun to kooyọ lọwọ wahala ipenija to la kọja nigba ti igbeyawo rẹ akọkọ foriṣanpọn.
Ninu ifọrọwerọ kan Funkẹ Akindele Bello gba awọn ọlọmọge niyanju lati tẹlẹ jẹjẹ lori ọrọ igbeyawo. O ni bi wọn ba fi girigiri wọ inu igbeyawo, girigiri naa ni wọn yoo fi jade.
O ni ori ayelujara ni igbeyawo oun akọkọ ti forijale agbọn ati peori ayelujara gan loun ti mọ pe igbeyawo oun ti tuka.
Mo n ya sinima kan lọwọ ni eeyan kan pe mi sọ fun mi. Mo sunkun titi bi ẹni maa ku
Yoruba Nation: Mo faramọ́ àtúntò 'Restructuring' tí kò lọ́wọ́ ìṣèlú nínú- Oba Ahmed Adeku
Bakan naa lo fi kun un pe ọpọ awọn iṣẹ olowo iyebiye loun padanu pẹlu igbeyawo naa.
Amọṣa o Jẹnifa ṣalaye pe oun ko jẹ ko da oun wolẹ.
O dupẹ lọwọ iya rẹ to se atọna imulọkanle fun oun lati gbaju mọ iṣẹ oun ki oun si tẹsiwaju.
Babatunde Gbadamosi: Mo ta gbogbo dúkìá mi lásìkò kan kí ń tó padà di eèyàn lónìí
Self defence Gómìnà Katsina ṣàlàyé ìdí tó fi ní káwọn èèyàn máa di ìhámọ́ra ogun
Oríṣun àwòrán, other
Gomina ipinlẹ Katsina,  Aminu Bello Masari ti ṣalaye idi to fi ni ki araalu maa di ihamọra ogun lati daabo bo ara wọn lọwọ awọn janduku afẹmi ṣofo.
Masari ni awọn eeyan ko kan le maa kawọ gbera ki awọn janduku maa pa wọn ni ipakupa.
Gomina Katsina ṣalaye pe awọn ẹṣọ eleto abo ko to lati pese abo to peye fawọn araalu.
Masari ni bi ijọba ṣe n gbiyanju agbara rẹ to lati pese abo fun araalu, ojoojumọ lẹmi awọn alaiṣẹ n ṣofo lọwọ awọn ajinigbe.
Awọn ti wọn ko ba pa, niṣe ni awọn ajinigbe pawo n gbe wọn lọ.
Babatunde Gbadamosi: Mo ta gbogbo dúkìá mi lásìkò kan kí ń tó padà di eèyàn lónìí
''Ijọba gbiyanju lati jiroro pẹlu awọn janduku afẹmi ṣofo yii, ṣugbọn pabo ni gbogbo rẹ ja si.
Ohun to jẹ ko ri bẹẹ ni pe awọn janduku yii ko ni olori kankan ti wọn le gbọran si lẹnu.
Oriṣiiriṣii ẹgbẹ janduku afẹmiṣofo lo wa ninu igbo ti wọn n ṣọṣẹ kaakiri.
Nítorí kí aafa lè máa rí iṣẹ́ ṣe ní wọ́n kò ṣe kó Alumaajiri nílẹ̀ tó fi di ohun tó dà yìí
Awọn ẹṣọ alaabo naa ko to nkan, sọja meloo lo wa nipinlẹ Katsina gan an?
Wọn o pọ nitori ọrọ eto abo to mẹhẹ gbogbo Naijiria lo kan.
Eyi gan an lo ṣakoba fun wa ni Katsina tori awọn eeyan ko kan le maa ka ọwọ gbera ki awọn janduku ṣi maa pa wọn.
Yoruba Nation: Mo faramọ́ àtúntò 'Restructuring' tí kò lọ́wọ́ ìṣèlú nínú- Oba Ahmed Adeku
Nibo ni wọn fẹ sa lọ, ti wọn ba sa kuro labule wọn?
O ṣe pataki fawọn araalu lati dide bayii, ki wọn si sa apa wọn lati gbaruku ti ijọba lori eto abo to mẹhẹ.
Oba Ogboni Abalaye n fẹ́ kí wọ́n o má a fi ẹ̀sìn àbáláyé búra fún àwọn olóṣèlé Naijiria
Nkan ti yatọ si ti ọdun to lọ ṣugbọn alaafia ko tii jọba tan nipinlẹ Eko.
Inu mi ko le dun gẹgẹ bi adari ipinlẹ Katsina ti awọn janduku ba tẹsiwaju si ni fẹmi awọn eeyan ṣofo tabi ki wọn maa ji wọn gbe pawo,'' Masari ṣalaye.
Yoruba Nation: Ààrẹ ẹgbẹ VOR sọ pé kí ọmọ Yorùbá di ààrẹ Naijiria kọ́ ni ọ̀nà àbáyọ
PDP crisis: Yánpọnyánrin PDP ń fẹjú síi, Uche Secondus ní òun kò bẹ̀rù àṣẹ ilé ẹjọ́, kí ẹgbẹ́ má bàjẹ́ ni tòun
Oríṣun àwòrán, @Secondus
Yanponyanrin laarin ẹgbẹ oṣelu PDP ti n waye baye fun osẹ diẹ eleyii ti awọn alagbara kan ninu ẹgbẹ naa n pe fun  Uche Secondus, alaga apapọ ẹgbẹ oṣelu naa.
Lẹyin ti ile ẹjọ giga kan nipinlẹ Rivers ti ni ko yẹba naa ko si ye e pe ara rẹ ni alaga apapọ ẹgbẹ Oṣelu PDP lorilẹede Naijiria.
Ọmọọba Uche Secondus ti ṣalaye pe ko si ohun kan to babara ninu rẹ ju wi pe ki oun pẹlu lọ si ile ẹjọ lati lọ da ile ẹjọ loun ipe rẹ.
Onidajọ Okogbule Gbasam ti ileẹjọ giga ipinlẹ Rivers to wa ni Degema ni Portharcourt paṣẹ ni ọjọ Aje petiti di igba ti wọn yoo fi yanju ẹjọ naa o, Secondus ko gbọdọ oe ara rẹ tabi ṣe ojuṣe alaga apapọ ẹgbẹ oṣelu PDP.
Ninu ọrọ ti amugbalẹgbẹ fun Ọmọọba Secondus sọ, alaga ẹgbẹ oṣelu PDP naa ni ẹruko ba oun boti wulẹ ko mọ lori ipẹjọ naa oun si setan lati yọju si ile ẹjọ lori rẹ.
Nítorí kí aafa lè máa rí iṣẹ́ ṣe ní wọ́n kò ṣe kó Alumaajiri nílẹ̀ tó fi di ohun tó dà yìí
Bi ẹnikẹni ba gbe Secondus ati ẹgbẹ oṣelu PDP lọ sile ẹjọ, o di dandan, yoo farahan ni  lati wi tẹnu rẹ. Awọn ọmọ Naijiria lo ni ẹgbẹ oṣelu yiio si tobi ju ẹnikẹni tabi ẹgbẹ kankan lọ titi kan awọn afipa du ipo.
Yanponyanrin laarin ẹgbẹ oṣelu PDP ti n waye baye fun osẹ diẹ eleyii ti awọn kan ninu ẹgbẹ naa ti gomina Nyesom Wike tipinlẹ Rivers ko sodi lati tun igbimọ isakoso ẹgbẹ naa ka.
Oríṣun àwòrán, PDP
Iléẹjọ́ ní kí alága gbogboogbò PDP, Uche Secondus lọ rọọ́kùn nílé
Rogbodiyan to n ṣẹlẹ ninu ẹgbẹ oṣelu PDP ti fori sọ ibi kan kan lójọ Aje, lẹyin ti ileẹjọ giga ipinlẹ Rivers ni ki ni alaga gbogbo ẹgbẹ naa, Uche Secondus lọ rọkun nile na.
Eeyan mẹrin, Ibeabuchi Ernest Alex, Dennis Nna Amadi, Emmanuel Stephen ati Umezirike Onucha lo ni ki ileẹjọ da Secondus duro gẹgẹ bi alaga ẹgbẹ ọhun.
Adajọ ileẹjọ giga ẹkun Degema, O. Gbasam sọ ninu idajọ rẹ pe aṣẹ gun ẹbẹ awọn mẹrin yii.
Nkan ko fara rọ ninu ẹgbẹ PDP lori awuyewuye ati yọ Secondus nipo ṣaaju ipade gbogbogbo ẹgbẹ naa to n bọ lọna.
Ẹwẹ, Secondus ti sọrọ lẹyin aṣẹ ile ẹjọ to ni ko gbọdọ pe ara rẹ ni alaga PDP mọ.
Kola Ologbondiyan: PDP ni yóò mú ọmọ Nàíjíríà kúrò lóko ìyà tí wọn wà ní 2023
Oludamọran Secondus lori ọrọ iroyin, Ike Abonyi sọ pe Secondus ṣetan lati sọ ti ẹnu rẹ ni ileẹjọ.
O ni ẹgbẹ oṣelu PDP kii ṣe dukia ẹnikan, awọn ọmọ Naijiria lo ni i.
Oba Ogboni Abalaye n fẹ́ kí wọ́n o má a fi ẹ̀sìn àbáláyé búra fún àwọn olóṣèlé Naijiria
New York governor: Kathy Hochul gómìnà obìnrin ìpínlẹ̀ New York àkọ́kọ́
Oríṣun àwòrán, Fcaebook/Kathy Hochul
Ipinlẹ New York lorilẹede Amẹrika ti ni gomina obinrin fun igba akọkọ ninu itan ipinlẹ naa.
Wọn bura fun Kathy Hochul loru ọjọ Aje si ọjọ Iṣẹgun lẹyin ti Andrew Cuomo kọwe fipo silẹ lọri ẹsun ifipa dẹnu ifẹ kọ awọn obinrin.
Adajọ agba ipinlẹ naa, Janet DiFiore lo dari eto ibura Hochul gẹgẹ bi gomina ipinlẹ New York tuntun.
Lẹyin ti wọn bura fun Hochul tan lo sọ loju opo Twitter ati Facebook rẹ pe iyi nla lo jẹ foun lati di gomina kẹtadinlọgọta ipinlẹ New York.
Agbẹjọro agba ni New York, Letitia James ti mi Hochul ku oriire pẹlu bi o ti di gomina obinrin akọkọ ipinlẹ naa.
James ni ọjọ nla lọjọ Iṣẹgun ti wọn bura fun Hochul jẹ ninu itan New York.
O gbadura fun Hochul pe yoo ruu, yoo si sọọ re bi o ṣe bẹrẹ si ni tukọ ipinlẹ New York.
Cuomo ti sọ tẹlẹ pe o tẹ oun lọrun lati kọwe fipo silẹ ju kawọn aṣofin dibo yọ oun nipo lọ.
Ọjọ Aje ọjọ kẹtalelogun oṣu kẹjọ ni Cuomo kuro ni ọfiisi gomina ipinlẹ New York patapata.
Sunday Igboho aides: Adájọ́ kọ̀ láti dáwọn ọmọlẹ́yìn Igboho mẹ́rin padà s'látìmọ́lé DSS
Oríṣun àwòrán, Sunday Igboho
Ile ẹjọ giga ijọba apapọ niluu Abuja ti fagile ẹgbẹ ajọ ọtẹlẹmuyẹ DSS to ni ki wọn dawọn ọmọlẹyin Sunday Igboho to ṣẹṣẹ gbomina pada si atimọle.Adájọ́ pàṣẹ ìtúsílẹ̀ mẹ́rin lára 12 ọmọlẹ́yìn Igboho tó wà ní àhámọ́ DSS l'Abuja
Ni ọjọ Iṣẹgun ni adajọ Obiora Egwuatu yi ẹbẹ DSS yii danu lẹyin ti agbẹjọro DSS, Ọgbẹni Idowu Awo, yọwọ kuro ninu ẹjọ naa.
O ya gbogbo eeyan to wa nile ẹjọ pe bi wọn ṣe fẹ ka ẹjọ ni agbọjọro ajọ DSS kede pe oun ko ni le tẹsiwaju pẹlu ẹjọ naa mọ.
Ọgbẹni Awo sọ fun ile ẹjọ pe oun ti pẹjọ kotẹmilọrun lori beeli ti ile ẹjọ giga fawọn mẹrin ọmọlẹyin Igboho.
Awo ni o san foun lati tẹsiwaju igbẹjọ ọhun nile ẹjọ kotẹmilọrun.
Ondo Jos clash: Èmi nìkan ló padà dé nínú àwa márùn ún tí a jọ lọ ìpàdé àdúrà ní Jos- Bell
Ṣugbọn adajọ yi ẹbẹ agbẹjọro DSS danu lẹyin ti agbẹjọro awọn ọmọlẹyin Igboho, Sunday Adebayo sọ tako ibeere DSS lati dawọn pada si atimọle.
Oru ọjọ kinni oṣu keje ni wọn DSS ko awọn eeyan mejila naa nigba ti wọn ṣe ikọlu si ile Igboho lagbegbe Soka n'Ibadan.
Unijos students victims: Àwọn Fulani yabo 'hostel' wa, ọpẹ́lọpẹ́ àwọn Sọ́jà tí gómìnà ìpí
Ẹwẹ, ni ibẹrẹ oṣu kẹjọ ni ile ẹjọ giga kan niluu Ibadan paṣẹ pe agbẹjọro agba ati minisita eto idajọ ni Naijiria, Abubakar Malami, ko gbọdọ mu Igboho fun ra rẹ lẹyin ti wọn ṣe ikọlu si ile rẹ.
Ile ẹjọ tun paṣẹ pe ajọ DSS ati Malami ko gbọdọ gbẹsẹ le apo ikowosi Igboho.
Koda ile ẹjọ naa tun kilọ fun Malami ati DSS pe wọn ko gbọdọ dunkoko mọ Igboho, wọn o si gbọdọ ṣe ohun buburu kan fun un.
Adájọ́ pàṣẹ ìtúsílẹ̀ mẹ́rin lára 12 ọmọlẹ́yìn Igboho tó wà ní àhámọ́ DSS l'Abuja
Adajọ Obiora Egwuatu ti ile ẹjọ giga ijọba apapọ l'Abuja ti buwọlu iwe aṣẹ itusilẹ mẹrin lara awọn ọmọlẹyin Sunday Igboho mejila ti wọn ko nigba ti wọn ṣe ikọle si ile rẹ niluu Ibadan
Nítorí kí aafa lè máa rí iṣẹ́ ṣe ní wọ́n kò ṣe kó Alumaajiri nílẹ̀ tó fi di ohun tó dà yìí
Eyi waye lẹyin tawọn eeyan naa ti lo ọjọ mẹtalelaadọta ni ahamo ajọ ọtẹlẹmuyẹ DSS niluu Abuja.
Iroyin kan sọ pe niṣe ni adajọ kọ eti ikun si gbogbo awijare agbẹjọro DSS, Idowu Awo, o si buwọlu lu iwe aṣẹ naa.
Awọn mẹrin naa ni Amudat Babatunde, Abideen Shittu, Jamiu Oyetunji, ati Bamidele Sunday.
Agbẹjọro fawọn eeyan naa, Pelumi Olajengbesi lo fidi ọrọ yii mulẹ fawọn akọroyin.
Yoruba Nation: Ààrẹ ẹgbẹ VOR sọ pé kí ọmọ Yorùbá di ààrẹ Naijiria kọ́ ni ọ̀nà àbáyọ
Olajengbesi ṣalaye pe adajọ ko le buwọlu iwe aṣẹ lati tu awọn mẹjọ yoku silẹ tori mẹta ninu awọn oniduro ti lọ ki awọn ohun ti ileẹjọ n beere fun beeli wọn to pe.
Awọn mẹjọ ọhun ni Abdullateef Onaolapo, Tajudeen Irinloye, Dikeola Ademola, Ayobami Donald, Uthman Adelabu, Olakunle Oluwapelumi, Raji Kazeem, ati Taiwo Tajudeen.
Amọ, agbẹjọro Olajengbesi ni awọn oniduro mii yoo rọpo awọn to ti lọ, adajọ yoo si paṣẹ itusilẹ ti wọn naa.
Babatunde Gbadamosi: Mo ta gbogbo dúkìá mi lásìkò kan kí ń tó padà di eèyàn lónìí
Olajengbesi ko ṣai rọ ile ẹjọ pe ko paṣẹ itusilẹ awọn eeyan naa.
Agbẹjọro DSS ni awọn mẹrin ti ile ẹjọ tu silẹ yii gan an lo mọ nipa ẹsun kiko nkan ogun pamọ sile ti wọn fi kan Igboho.
Oba Ogboni Abalaye n fẹ́ kí wọ́n o má a fi ẹ̀sìn àbáláyé búra fún àwọn olóṣèlé Naijiria
Lati ọsẹ to lọ lawọn oniduro ti wa nilẹ, ṣugbọn adajọ ni ko si nile.
Oru ọjọ kinni oṣu keje ni wọn DSS ko awọn eeyan mejila naa nigba ti wọn ṣe ikọlu si ile Igboho lagbegbe Soka n'Ibadan.
Eegunjobi Omotanbaje Ajobiewe- Èébú ní wọ́n kọ́kọ́ ń bù mí nígbà tí mo bẹ̀rẹ̀ ẹ̀ṣà pípé ní
Obasanjo Postrates to kings: Wo ìgbà mẹ́ta tí Olusegun Obasanjo ti fi ìdọ̀bálẹ̀ nàá fẹ́lẹ́fẹ́lẹ́ níwájú àwọn oríadé
Oríṣun àwòrán, others
Wo ìgbà mẹ́ta tí Olusegun Obasanjo ti fi ìdọ̀bálẹ̀ nàá fẹ́lẹ́fẹ́lẹ́ níwájú àwọn oríadé
Aarẹ orilẹede Naijiria nigba kan ri, Oloye Oluṣẹgun Ọbasanjọ kii ṣe Ajeji si ti ka bu óla fun aṣa ati iṣẹṣe paapaa fun awọn obalaye.
Ni ọjọ Aiku, ọjọ kejilelogun, osu kẹjọ, ọdun 2021 ni ariwo tun sọ lori ayelujara lẹyin ti aworan Oloye Ọbasanjọ nibi ti o ti fi orokun mejeeji kunlẹ fun ọba tuntun Olu ti ilu Warri, Ogiame Atuwatse kẹta.
Ohun to jọ ọpọlọpọ loju ni pe Oloye Ọbasanjọ, ẹni ọdun mẹrinlelọgọrin n wolẹ ki Olu ti ilu Warri ti ọjọ ori rẹ din diẹ ni Ogoji.
Fun awọn ti ko mọ nipa aṣa ati iṣe ilẹ Yoruba, eyi lee jẹ babara.
Oríṣun àwòrán, @Obasanjo
Bẹẹ si ni Oloye Ọbasanjọ ti ṣalaye pe kii ṣe Obalaye nikan ni oun wolẹ fun bi ko ṣe gbogbo awọn agbagba iṣaaju ti wọn ti joko sori itẹ naa sẹyin.
Yoruba Nation: Mo faramọ́ àtúntò 'Restructuring' tí kò lọ́wọ́ ìṣèlú nínú- Oba Ahmed Adeku
"Ninu atẹjade kan ti amugbalẹgbẹ fun Oloye Obasanjo lori ọrọ iroyin fi sita, ""aṣa ati iṣẹṣe ni. Alayeluwa Ogiame Atuwatse kẹta kọ lo wa lori oye mọ iṣẹṣe lo joko sibẹ bayii."
"Gẹgẹ bii baba ni ilẹ Afirika, Oloye Ọbasanjọ ko ni ṣalai juba ati fi ọwọ to ba yẹ fun awọn itẹ ọbalaye gbogbo."""
Eegunjobi Omotanbaje Ajobiewe- Èébú ní wọ́n kọ́kọ́ ń bù mí nígbà tí mo bẹ̀rẹ̀ ẹ̀ṣà pípé ní
Ṣe igba akọkọ niyi ti Oloye Oluṣẹgun Ọbasanjọ yoo wolẹ fun Ọbalaye kan?
"Gẹgẹ bi atẹjade ti amugbalẹgbẹ aarẹ tẹlẹ Oloye Oluṣẹgun Ọbasanjọ fi sita ṣe sọ, O ni: ""igba akọkọ kọ niyi ti aarẹ Obasanjo yoo maa wolẹ ki oriade."""
O ni Obasabjọ bọwọ fun asa Yoruba pupọ ni.
Yollywood movies: Gbajúmọ̀ òṣèré, Rose Odika ní aráàú, àjọ 'Censors board'
To ba ri bẹẹ, ẹ jẹ ka wo igba mẹta ọtọọtọ ti Oloye Ọbasanjọ ti bu ọwọ nla bayi fun awọn orilade:
1.Arole Oodua Ọọni Adeyẹye Ogunwusi, Ọjaja II ti ile Ifẹ.
Loṣu keji ọdun 2016 lẹyin osu kẹta ti Ọba Adeyẹye Ẹnitan Ogunwusi gun ori itẹ gẹgẹ bi Ọọni ti ilu ile Ife, Oloye Oluṣẹgun Ọbasanjọ bẹẹ wo.
Oríṣun àwòrán, @Obasanjo
Ninu aafin rẹ ni ile Oodua nilu ile Ifẹ ni Oloye Olusegun Obasanjo ti lọ ki i.
Gbogbo aya ni Oloye Oluṣẹ Ọbasanjọ da de ilẹ ti o si dọbalẹ kii lọjọ naa.
Yoruba Nation: Ààrẹ ẹgbẹ VOR sọ pé kí ọmọ Yorùbá di ààrẹ Naijiria kọ́ ni ọ̀nà àbáyọ
2.Agura ti Gbagura, Abẹokuta.
Losu kẹjọ ọdun 2019, Oloye Oluṣẹgun Ọbasanjọ kan si Ọba Saburee Babajide Bakre to jẹ Agura ti Gbagura nilu Abẹokuta.
Oríṣun àwòrán, @Obasanjo
Tọwọtọwọ bi isẹ rẹ naa lo tun naa fẹlẹfẹlẹ niwaju kabiyesi Agura.
Oba Ogboni Abalaye n fẹ́ kí wọ́n o má a fi ẹ̀sìn àbáláyé búra fún àwọn olóṣèlé Naijiria
3.Olu ti ilu Warri
Olu ti Ilu Warri, Ogiame Atuwatse kẹta ni ọba tuntun to ṣẹṣẹ jẹ lọjọ kọkanlelogun oṣu kẹjọ ọdun 2021.
Oríṣun àwòrán, @others
Nigba ti Oloye Õbasanjọ lọ kii ni afin rẹ lọ Aiku, erokun mejeeji lo fi kunlẹ kii.
Oloye Ọbasanjọ ko tẹti ninu ọla ati ọwọ ti o maa n fun awọn ọbalaye gẹgẹ bi ọmọ Yoruba tootọ.
Ninu aṣa Yoruba, gbogbo ọkunrin lo gbọdọ maa dọbalẹ fun oriade lainaani ọjọ ori tabi ọla tabi ọrọ ti irufẹ oriade bẹẹ ni.
Wikipedia: Ẹ̀nìkan sọ fún mi pé iṣẹ́ ìdọ̀tí ni màá ṣe ni mo ṣe ń ta ìwé
Osun APC crisis: Gomina Oyetola ti pè fún alàáfíà láàrin àwọn ọmọ ẹgbẹ́ APC tí Gboyega Famodun gbé lọ sílé ẹjọ́
Oríṣun àwòrán, Others
Gomina Oyetola to n tuko ipinlẹ Osun ti parọwa si ẹka awọn ọmọ ẹgbẹ APC nibẹ.
Gomina Oyetola ni pe ki alaga to n pe ẹjọ naa jawọ nibẹ bayii.
Lọjọ Isegun lo ni ki koowa jẹ ki alaafia jọba ninu ẹgbẹ APC nipinlẹ Osun ninu atéjade kan to fi sita.
Badagry: Ojú ọ̀nà àrèmabọ̀ fáwọn ẹrú tó ń lọ sókè òkun
Saaju ni alaga ẹgbẹ naa Omooba Famodun Gboyega ti pe ẹjọ lodi si awọn oloye ẹgbẹ kan ti wọn yabo ile ẹgbẹ pẹlu awọn ọmọ eriwo kan lọsẹ neji sẹyin.
Ismail Omipidan to jẹ akọwe eto iroyin gomina Oyetola lo buwọlu atẹjade naa.
Yoruba Nation: Mo faramọ́ àtúntò 'Restructuring' tí kò lọ́wọ́ ìṣèlú nínú- Oba Ahmed Adeku
Iroyin ni gomina ko si nile nigba ti iṣẹlẹ naa
Oyetola ni ki wọn wagbo dẹkun fun igbẹjọ naa leyin to bu ẹnu atẹ lu ikọlu awọn janduku nile iya egbẹ.
Oríṣun àwòrán, @APC
Akọ̀wé APC, èèyàn mẹ́fà míràn fojú ba ilé ẹjọ́ fún fífọ́ òkúta mọ́ ọmọ ẹgbẹ́ lórí l' Ọ̀ṣun
Akọ̀wé APC, èèyàn mẹ́fà míràn fojú ba ilé ẹjọ́ fún fífọ́ òkúta mọ́ ọmọ ẹgbẹ́ lórí l' Ọ̀ṣun
Akọwe igbimọ isakoso ẹgbẹ oṣelu APC nipinlẹ Ọsun, Rasaq Salinṣile ti dero ile ẹjọ pẹl'awọn eeyan mẹfa miran ti wọn jẹ ọmọlẹyin gomina ipinlẹ naa nigba kan ri to tun minisita f'ọrọ abẹle bayii, Ọgbẹni Rauf Arẹgbẹsola.
Eegunjobi Omotanbaje Ajobiewe- Èébú ní wọ́n kọ́kọ́ ń bù mí nígbà tí mo bẹ̀rẹ̀ ẹ̀ṣà pípé ní
Ẹsun wọn ni pe  wọn lọ da ile ẹgbẹ ru ti wọn si ti ipa bẹẹ lu arakunrin kan, Ajetunmobi Muideen ti wọn si tun fọ aga mọọ lori ti wọn si tun  okuta mọ ẹlomiran toruko rẹ n jẹ Babatunde Hamzat lori.
Rasaq Salinsile, Adelowo Adebiyi ni o n lewaju igun kan lẹgbẹ oselu APC nipinlẹ Osun ti wọn n pe ni The Osun Progressives, TOP.
Oun ati awọn meji kan ti ti jẹ kọmisonna ri labẹ ijọba gomina Arẹgbẹṣọla, Kazeem Salami ati Biyi Odunlade, Gbenga Akano oẹlu Alaba Popoola ati AzeezAdekunle ni awọn ti ileeṣẹ ọlọpaa ko lọ sile ẹjọ.
Ile ẹjọ Majisreeti kan nilu Osogbo ni wọn ko wọn lọ lati jẹjọ ẹsun ti wọn fi kan wọn naa.
Yanponyanrin ti n bẹ sulẹ lati bi ọdun mẹta sẹyin laarin ẹgbẹ oṣelu APC ni ipinlẹ Osun nitori aawọ laarin Gomina Gboyega Oyetọla ati Rauf Arẹgbẹṣọla to fi ipo naa silẹ.
Nítorí kí aafa lè máa rí iṣẹ́ ṣe ní wọ́n kò ṣe kó Alumaajiri nílẹ̀ tó fi di ohun tó dà yìí
Awọn onwoye kan ṣalaye pe bi gomina Oyetola ṣe n yi pupọ awọn eto ti ijọba Arẹgbẹṣọla gbe kalẹ danu kun ara ohun to n fa gbun-gbun-gnun laarin awọn mejeeji.
Amọsa awọn afurasi mẹtẹta baa ni awọn ko jẹbi ẹsun ti wọn fi kan wọn ati pe finifini lọwọ awọn mọ.
Oba Ogboni Abalaye n fẹ́ kí wọ́n o má a fi ẹ̀sìn àbáláyé búra fún àwọn olóṣèlé Naijiria
Ileẹjọ gba beeli wọn pẹlu milionu marun un naira, oniduro kan to gbọdọ jẹ oṣiṣẹ ijọba ni ipinlẹ naa ki o to sun igbẹjọ si ọjọ kẹrinlelogun osu kẹsan.
Wahala to fa ipẹjọ yii bẹ silẹ nibi ijoko igbimọ igbẹjọ kotẹmilọrun ti wọn gbe kalẹ lẹyin idibo wọọdu to waye lọjọ kẹrinla ọdun 2021.
Nibẹ ni awọn to n gbe lẹyin Ọgbẹni Rauf Arẹgbẹṣọla atawọn to gbẹ lẹyin Gomina Gboyega Oyetọla ti gbe ina woju ara wọn.
Nítorí kí Aafa lè máa rí iṣẹ́ ṣe ní wọ́n kò ṣe kó Alumaajiri nílẹ̀ tó fi di ohun tó dà yìí- Olagunsoye Oyinlola
Wo ọ̀nà àbáyọ mẹ́rin láti fi borí ogun Boko Haram ní Nàìjíríà- Olagunsoye Oyinlola
Oloye Olagunsoye Oyinlola ba BBC soro ni kikun lori ohu to ṣokunfa ogun Boko Haram ni ariwa Naijiria.
O sọ ohun ti oju rẹ ri ni Maiduguri lasiko to fi wa lẹnu iṣẹ ologun nibẹ.
Oríṣun àwòrán, others
Niger kidnap: Mẹ́fà nínú àwọn akẹ́kọ̀ọ́ ilé ẹ̀kọ́ Islamiyya Tegina ti kú sí àkàtà àwọn ajínigbé
Oríṣun àwòrán, Other
Mẹfa ninu mẹrindinlogoje akẹkọọ ile ẹkọ Salihu Tanko Islamiyya tawọn janduku ajinigbe pawo jigbe niluu Tegina nipinlẹ Niger ti ku si akata awọn ajinigbe.
Ọga ile ẹkọ naa, Abubakar Alhassan, ṣalaye pe lana ọjọ Iṣẹgun lawọn janduku ọhun sọrọ iku awọn akẹkọọ naa foun lori foonu.
Awọn ajinigbe ni aisan ajeji kan lo ṣekupa awọn ọmọ naa ninu igbo ti wọn wa.
Awọn janduku ajinigbe yii si duro lori ẹsẹ wọn pe igba miliọnu naira lowo itusilẹ tawọn n beere fun lawọn si maa gba, bo tilẹ jẹ pe mẹfa ti ku ninu awọn akẹkọọ naa bayii.
Abubakar Adam, ọkan lara awọn obi to ni ọmọ mẹfa lakata awọn ajinigbe naa fidi ọrọ ọhun mulẹ.
Iroyin kan tiẹ sọ pe awọn obi pakiti mọri wa aadọta miliọnu san fawọn janduku ọhun, ṣugbọn wọn ni igba miliọnu gbọdọ pe.
Nítorí kí aafa lè máa rí iṣẹ́ ṣe ní wọ́n kò ṣe kó Alumaajiri nílẹ̀ tó fi di ohun tó dà yìí
Awọn eeyan awujọ Alawa ni ijọba ibilẹ Shiroro nipinlẹ Niger State ti sọ tẹlẹ pe awọn ri awọn akẹkọọ ọhun nibi ti wọn ti n gbe wọn lọ lori ọkada.
Amọ, ko si ẹni to tii gburo wọn di akoko yii.
Babatunde Gbadamosi: Mo ta gbogbo dúkìá mi lásìkò kan kí ń tó padà di eèyàn lónìí
Ẹwẹ, kọmiṣọnaa ọlọpaa tuntun nipinlẹ Niger, Bala Kuryas ti sọ pe ile iṣẹ ọlọpaa yoo wa awọn ọmọ ri laipẹ.
Iṣẹlẹ ijinigbe ti ṣẹlẹ lera lera ni ipinlẹ Niger, awọn akẹkọọ lo si pọju ninu awọn ti wọn jigbe.
NDA Kaduna attack: Ìkọlù NDA sàfihàn pé ààrẹ Buhari ń gbìyànjú láti sọ Nàìjíríà di Afganistan ni- SOKAPU
Oríṣun àwòrán, SOKAPU
Agbarijọpọ awọn ọmọ bibi apa guusu ipinlẹ Kaduna,SOKAPU ti bẹnu atẹ lu iṣẹlẹ ikọlu awọn agbebọn si ibudọ ikọnilẹkọ awọn ọmọ ogun Naijria NDA.
Ninu atẹjade ti wọn fi sita, ẹgbẹ naa ni ikọlu yi fi han pe aarẹ n gbiyanju lati sọ orileede Naijiria di bi Afghanistan ti se ri ni.
Agbẹnusọ ẹgbẹ naa  Luka Binniyat sọ fun ileesẹ iwe iroyin Naijiria The  Punch pe ọna aibikita tawọn ọdaran yi fi doju ija kọ ibudo awọn ọmọ ogun ti eeyan kankan ko si farapa ninu wọn n tọka si eewu nla gidi  to n koju oselu awarawa ni Naijiria.
Ẹgbẹ naa sọ pe ti wọn koba ṣe nkankan si ikọlu yi, o ṣeeṣe ki ''ijọba Buhari maa palẹmọ ohun ti yoo ṣẹlẹ mi to n bọ ni''
O ni ''Ipaniyan awọn ọmọ ogun meji yi ati ijinigbe ọgagun kan ko ya awa ọmọ ẹgbẹ SOKAPU lẹnu rara.Idi ni pe iru ikọlu bẹ ti waye lẹẹmeelo kan  ni bareke awọn ọmọogun to wa ni ile ẹkọ Command and Staff College, Jaji to wa laarin Zaria ati Kaduna.Ninu ikọlu yi wọn ji maalu ati nkan ini miran lọ''
Binniyat  wa kilọ pe ti wọn ko ba gbe igbesẹ ni kiakia ki wọn si mu awọn ọdaran yi,o ṣeeṣe ki iru nkan to waye ni Afghanistan ṣẹlẹ ni Naijiria.
"Ọrọ ẹnu aarẹ latẹyinwa ati iṣeṣi rẹ fi han pe ko bikita lati gbe agbara fawọn alakatakiti''
''Boya iṣẹlẹ aburu yi yoo ta gbogbo eeyan ji yatọ si aarẹ Buhari ati awọn agbodegba rẹ nitori ero wọn si ọmọ Naijiria ko sunwọn rara''
O wa kesi gbogbo ọmọ Naijiria alti bẹnu atẹ lu iṣẹlẹ yi ki wọn si pe Gomina Kaduna Nasir El Rufai ati aarẹ Buhari si akiyesi lati gbaju mọ ojuṣe wọn ki Naijiria to tẹri sinu ọọfin ti awọn ko lero rara.
Bi a ko ba gbagbe lowurọ kutu ọjọ Iṣẹgun lawọn agbebọn yawọ NDA ti wọn si pa ọmọ ogun meji ki wọn to ji ọgagun kan gbe salọ.
Titi di ba ṣe n ṣakojọ iroyin yi, a ko ti mọ pato ibi ti wọn gbe lọ ṣungbọn ijọba gba ẹnu ileeṣẹ ologun sọrọ pe awọn yoo sawari awọn ọdaran yi.
Oríṣun àwòrán, Nigeria Defence Academy
Lowurọ ọjọ Iṣẹgun, ọjọ kẹrinlelogun lawọn janduku ajinigbe afẹmi ṣofo kọlu ọkan lara ile ẹkọ ologun NDA to wa niluu nipinlẹ Kaduna.
Ọmogun meji ni yinbọn pa nibẹ, koda wọn tun ji ọmogun to ti gboye Major lọ.
Lẹyin iṣẹlẹ naa ni iroyin kan sọ pe awọn ijinigbe ọhun n beere igba miliọnu naira owo itusilẹ fun ọmogun ti wọn jigbe lọ.
Iroyin mii to lu ori ayelujara pa bayii tiẹ tun sọ pe awọn janduku yii ti ṣekupa ọmogun ti wọn jigbe lọ.
Ohun koko marun un to yẹ ki o mọ nipa ile ẹkọ ologun NDA tawọn ajinigbe ṣe ikọlu si ni Kaduna ree.
koda Royal Military Forces Training College (RMFTC) ni wọn n pe orukọ ile ẹkọ naa nigba naa.
Lẹyin ominira Naijiria ni wọn yi orukọ rẹ pada si Nigerian Military Training College ki o to di Nigeria Defence Academy, NDA ti wọn n pe lonii.
Unijos students victims: Àwọn Fulani yabo 'hostel' wa, ọpẹ́lọpẹ́ àwọn Sọ́jà tí gómìnà ìpí
2.  Ile ẹkọ ologun NDA yii lo dara julọ lapa iwọ oorun Afirika
Ile ẹkọ ologun NDA yii fasiti ologun akọkọ iruẹ lapa iwo oorun Afirika.
Awọn orilẹede to wa lapa iwọ oorun Afirika ko ko iyan ilẹ ẹkọ NDA yii kere.
Babatunde Gbadamosi: Mo ta gbogbo dúkìá mi lásìkò kan kí ń tó padà di eèyàn lónìí
3.  Awọn akẹkọọ maa n gboye akọkọ ni fasiti jade nibẹ
Ile ẹkọ ologun nikan lawọn akẹkọọ ti maa n gboye akọkọ fasiti jade ti wọn ba ṣetan ẹkọ wọn.
Ọdun marun lawọn akẹkọọ maa n lo ni ile ẹkọ yii, mẹrin fun igbẹkọ, nigba ti ọkan yoku wa fun ẹkọṣẹ ologun.
Orí ayélujára ni mo ti gbọ́ pé ìgbéyàwó mi àkọ́kọ́ ti foríṣọ́npọ́n - Funke Akindele Bello
Ọlọ́run nìkan ló lè ní kí Tinubu má jẹ ààrẹ lọdún 2023, ìmọ̀ràn lọ̀rọ̀ Yahaya Bello- Joe Igbokwe
Wo ìgbà mẹ́ta tí Olusegun Obasanjo ti fi ìdọ̀bálẹ̀ nàá fẹ́lẹ́fẹ́lẹ́ níwájú àwọn oríadé
Secondus, alága PDP ní òun kò bẹ̀rù àṣẹ ilé ẹjọ́, kí ẹgbẹ́  má bàjẹ́ ni tòun
Akọ̀wé APC, èèyàn mẹ́fà míràn fojú ba ilé ẹjọ́ fún fífọ́ òkúta mọ́ ọmọ ẹgbẹ́ lórí l' Ọ̀ṣun
4.  Awọn ọbinrin ọmogun naa kẹkọọ gboye ni fasiti NDA yii
Ṣaaju ọdun 2011, awọn ọkunrin nikan lo maa kẹkọọ jade nile ẹkọ NDA yii ni Kaduna.
Lọdun 2011 ni lawọn ọmogun obinrin bẹrẹ si ni kẹkọọ jade ni ile ẹkọ ologun naa.
Nítorí kí aafa lè máa rí iṣẹ́ ṣe ní wọ́n kò ṣe kó Alumaajiri nílẹ̀ tó fi di ohun tó dà yìí
5.  Awọn akẹkọọ n gboye keji ati ẹkẹta fasiti ni NDA yii
Ọpọ eeyan ni ko mọ pe awọn ọmogun n gboye keji ati ẹkẹta fasiti ni fasiti ologun to wa ni Kaduna yii.
Koda awọn akẹkọọ ti wọn kii ṣe ologun naa lanfaani lati kẹkọọ gboye ni ile ẹkọ NDA yii to fi de ipele Ọmọwe lẹnu ẹkọ.
Wo ọ̀nà márùn ún tí o lè gbà dáàbò bò ara rẹ lọ́wọ́ ìjàmbá láì gbé ìbọn!
Ìdí rèé ti mo fi ní kí aráàlú máa di ìhámọ́ra ogun nítorí àwọn janduku- Gómìnà Katsina
Obìnrin di gómìnà ìpínlẹ̀ New York fún ìgba àkọ́kọ́ l'Amẹrika
Ìjà ṣẹ̀ṣẹ̀ bẹ̀rẹ̀ ni o, àwọn dókítà NARD tó ń yanṣẹ́lódì fárígá pẹ̀lú ìjọba
Wọ́n búra fún Aarẹ tuntun ní Zambia, inú ará ìlú dùn fún ìlérí tó ṣe fún wọn
Èèyàn márùn ún kú, ọ̀pọ̀ míì farapa lásìkò rògbòdìyàn àwọn ọmọ onílẹ̀ l'EKo
School Kidnap in Nigeria: Wo iye ìgbà tí wọ́n ti jí akẹ́kọ̀ọ́ gbé ní Nàìjíiríà
Oríṣun àwòrán, Others
01 September&comma; 2021
Awọn agbebọn to wa lori ọkada ati ọkọ akẹru Pick-up ti ji o kere tan&comma; aadọrin akẹkọọ ile ẹkọ Government Day Secondary School&comma; Kayan-Maradun nipinlẹ́ Zamfara gbe lọ.
Akẹkọọbinrin marun lo bọ kuro lọwọ awọn ajinigbe lọjọ keji osu Kẹsan-an&comma; ti wọn si ti da wọn pada sọdọ awọn obi wọn bi o tilẹ jẹ pe ọlọpaa ni wọ̀n gba wọn la ni.
Ni ojo ketala&comma; osu kesan an ni won tu awon akekoo to ku sile
24 August&comma; 2021
Àwọn agbébọn kọlu ilé-ẹ̀kọ́ ẹ̀kọ́ṣẹ àwọn ọmoogun ni ìhà aríwá-ìwọ̀òòrun ìlú Kaduna&comma; wọ́n  pa àwọn ọmọogun méjì ti wọ́n sì jí òmíràn gbé
17 August&comma; 2021
Wọ́n  jí àkẹ́kọ̀ọ́ mẹ́jọ àti olùkọ́ kan gbé ní ilé kẹ́wú kan ní abúlé Sakkai tó wà ní ìjọba ìbílẹ̀ Faskari&comma;  ìpínlẹ̀ Katsina.
Àwọn aláṣe abúlé ọ̀hún sọ pé nǹkan bíi ago mẹ́sàn án alẹ́ ni àwọn agbébọn kọlu ilé kéwú náà.
16 August&comma; 2021
Àwọn agbébọn kọlu ilé ìwé gíga ẹ̀kọ́ ètò ọ̀gbìn kan ní ìjọba ìbílẹ̀ Bakura tí wọ́n sì jí akẹ́kọ̀ àti òṣìṣẹ́ mọ́kàndínlógún lọ.
Wọ́n jí akẹ́kọ̀ọ́ mẹ́ẹ̀ẹ́dógún&comma; òṣìṣẹ́ kan&comma; ìyàwó rẹ̀ àti ọmọ rẹ̀ méjì. Wọ́n pa olùṣọ́ mẹ́rin àti ọlapàá kan.
Olórí ilé ẹ̀kọ́ náà&comma; Habibu Mainasara sọ pé àwọn ajínigbé náà bèrè àádọ́jọ (150) mílíọ́nù náírà gẹ́gẹ́ bíi owó ìtúsílẹ̀.
Ni ọjọ kẹ́tadinlọgbọn oṣu kẹjọ&comma; awọn Ọlọpaa sọ pe mejidinlogun ninu awọn ti wọn jigbe lo ti gba itusilẹ “lai san nkankan”. Bakan naa ko ye ẹnikẹni ohun to ṣẹlẹ si awọn to ku nigbekun.
5 July&comma; 2021
Wọ́n jí akẹ́kọ̀ọ́ mọ́kànlélọ́gọ́fà (121) gbé láti ilé ẹ̀kọ́ girama Bethel Baptist Secondary School&comma; ní Kaduna.
Lọ́jọ́ kẹẹ̀ẹ́dọ́gbọ̀n oṣù keje&comma; ọ̀kan lára àwọn olùdásílẹ̀ ilé ẹ̀kọ́ náà&comma; Reverend John  Hayab sọ fún BBC pé wọ́n ti dá akẹ́kọ̀ọ́ méjìdínlọ́gbọ̀n lẹ́yìn ìdúnadúrà láàrin àwọn ajínigbé àti àwọn òbí àwọn tón jí gbé. Kò sọ ní pàtó nípa bọ́yá wọ́n san owó ìtúsílẹ̀&comma; ṣùgbọ́n ó sọ pé “ó ṣeéṣe.”
Ni ọjọ kejidinlọgbọn oṣu kẹjọ&comma; ọmọ ile ẹkọ mejilelọgbọn ni wọn tu silẹ kuro ni'gbekun. Obi ọkan lara wọn sọ fun BBC pe lẹyin ti wọn san owo itusilẹ ni wọn to da wọn silẹ.
17 June&comma; 2021
Àwọn agbébọn ti jí àwọn akẹ́kọ̀ọ́ àti àwọn olùkọ́ kan gbé láti ilé ẹ̀kọ̀ọ́ girama ìjọba àpapọ̀ tó wà ní Yauri. A kò mọ iye èèyàn tí wọ́n jí gbé&comma; ṣùgbọ́n àwọn alakóso sọ ọgbọ̀n akẹ́kọ̀ọ́ ló móríbọ́.
30 May&comma; 2021
Àwọn agbébọn ti jí àwọn ọmọ ilée kéwú mẹ́rìndílógóje (136) gbé ní ìlú Tegina. Ọmọkùnrin àti ọmọbìnrin ló ń lọ sí ilée kéwú náà tí wan jẹ́ ọmọ ọdún mẹ́fàá (6) sí méjìdínlógún (18) .
Lọ́jọ́ kọ̀ọ́kànlélọ́gbọ̀n oṣù kaàrùn ún&comma; àwọn aláṣẹ ìpínlẹ̀ náà sọ pé wọ́n tú àwọn ọmọ mọ́kànlá sílẹ̀ nítorí pé wan kéré púpọ̀ láti lè rìn.
Ni ọjọ kẹrindinlọgbọn&comma; oṣu kẹjọ&comma; ni wọn fi o le ni ọgọrun un akẹkọo silẹ lẹyin ti Obi san $150&comma;000 owọ dọla fún awọn ajinigbe
24 April&comma; 2021
Wọ́n jí àwọn akẹ́kọ̀ọ́ fásitì ètò ọ̀gbìn ti ìjọba àpapọ̀ tó wà ní Makurdi gbé lọ́jọ́ kẹrìnlélógún oṣù kẹrin. Wọ́n sì dá wọn sílẹ̀ lọ́jọ́ kọ̀ọ́kàndínlọ́gbọ̀n oṣù kẹrin.
20 April&comma; 2021
Wọ́n jí ogún akẹ́kọ̀ọ́ gbé àti àwọn òṣìṣẹ́ mẹ́ta gbé ní fásitì Greenfield tó wà ní agbègbè Chikun ní ìpínlẹ̀ Kaduna. Agbẹnusọ ọlọ́pàá sọ pé wọ́n pa òṣìṣẹ́ kan
Wọ́n rí òkú akẹ́kọ̀ọ́ mẹ́ta lọ́jọ́ kẹtàlélógún  oṣù kẹrin&comma; wọ́n tún rí òkúu méjì nínú wọn lọ́jọ́ kẹrìnlélógún oṣù kẹrin&comma; èyí tó sọ iye akẹ́kọ̀ọ́ tó kú di mẹ́fà. Méjìdínlógún ṣì wà ní àhámọ́.
Wọ́n dá èèyàn mẹ́ẹ̀ẹ́dógún sílẹ̀ lọ́jọ́ kọọ̀kàndínlógún oṣù káàrù ún.
15 March&comma; 2021
Lẹ́yìn ọjọ́ mẹ́rin&comma; lọ́jọ́ kẹẹ̀ẹ́dọ́gún oṣù kẹta&comma; ìjínigbé kejì ṣẹlẹ̀ ní ilé  ẹ̀kọ̀ọ́ alákọ́bẹ̀rẹ̀ kan ní abúle Rema tó wà ní agbègbè Birnin Gwarí ní ìpínlẹ̀ kaduna.
Wọ́n kọ́kọ́ rò pé wọ́n jí àwọn ọmọ gbé ni&comma; ṣùgbọ́n àwọn alákósọ padà sọ pé kọ̀ sí akẹ́kọ̀ọ́ tí wọ́n jí gbé lẹ́yìn tí wọ́n ka àwọ̀n akẹ́kọ̀a tan. Ṣùgbọ́n wọ́n jí àwọn akẹ́kọ̀a mẹ́ta gbé&comma; wọn kì sì tíì tú wan silẹ̀.
11 March&comma; 2021
Wọ́n jí àwọn akẹ́kọ̀ọ́ mọ́kàndínlógójì (39) gbé ní ilé ẹ̀kọ́ gíga iṣẹ́ oko lọ́nà ìgbà ló dé ní ìpínlẹ̀ Kaduna tó wà ní iwọ́-oòrùn àríwá Nàìjíríà.
Àwọn agbésùmọ̀mí ya wọ ilé ẹ̀kọ́ náà tí wọ́n sì gbé àwọn akẹ́kọ̀ọ́ tí ọ̀pọ̀ wọn jẹ́ obìnrin lọ. Wọ́n ti tú àwọn akẹ́kọ̀ọ́ náà sílẹ̀&comma; díẹ̀díẹ̀.
Wọ́n dá máàrùn ún sílẹ̀ lọ́jọ́ kaàrún oṣù kẹrin&comma; márùn ún lọ́jọ́ kẹjọ oṣù kẹrin&comma; wọ́n sì dá mọ́kàndínlọ́gbọ̀n náà sílẹ̀ lọ́jọ́ kaàrùn ún oṣù kaàrùn ún.
26 February&comma; 2021
Wọ́n jí akẹ́kọ̀ọ́bìnrin mọ́kàndínlọ́gọ́rinlénígba (279) láti ilé ẹ̀kọ̀ọ́ girama ti obìrin ìlú Jangebe ní ìpínlẹ̀ Zamfara. Lẹ́yìn tí wọ́n lo ọjọ́ mẹ́rin ní àhámọ́&comma; wọ́n dá gbogbo mọ́kàndínlọ́gọ́rinlénígba náà sílẹ̀ lajọ́ kejì oṣù kẹta.
17 February&comma; 2021
Wọ́n jí akẹ́kọ̀ọ́&comma; òṣìṣẹ́ àti àwọn ẹbí wọn méjìlélógójì láti ilé ìwé girama Kagara ní ìpínlẹ̀ Niger. Lẹ́yìn ọjọ́ mọ́kànlá &comma; wọ́n tú àwọn akẹ́kọ̀ọ́ náà sílẹ̀ lọ́jọ́ kẹtàdínlọ́gbọ̀n oṣù kejì.
Kò sí àmọ̀dájú pé wọ́n san owó ìtúsílẹ̀ láti tú wọn sílẹ̀.
11 December&comma; 2020
Ní nǹkan bíi ago mẹ́sàn án ààbọ̀ alẹ́ wọ́n gbúrò ìbọn nínú ilé ẹ̀kọ̀a girama Kankara&comma; ní ìpínlẹ̀ Katsina. Àwọn tí ọ̀rọ̀ náà ṣojú wọn sọ pé àwọn agbébọn ya wọ inú yàrá àwọn akẹ́kọ̀ọ́ méje tí wan sì kó àwọn akẹ́kọ̀ọ́kùnrin mẹ́rìnlélógójìlélọ́ọ̀ọ́dúnrún (344) lọ.
Wọ́n fi àwọn ọmọ náà sí àhàmọ́ fún ọjọ́ mẹ́fà títí di ìgbà tí wan dá wọn sílẹ̀ lọ́jọ́ kẹtàdínlógún oṣù kejìlá ọdún 2020.
Opọ̀ igba ni wọ́n ti ji akekọ́ọ́ gbe ni orilé-ede Naijiria.
Wo ìgbésẹ̀ tí ìjọba ìpínlẹ̀ Plateau gbé lẹ́yìn ìkọlù tó wáyé lọjọ Isegun
Ìjọba ìpínlẹ̀ Plateau ti tún ṣe òfin kóníléógbélé oní láyípo ni ìjọba ìbílẹ̀ Àríwá Jos, ìpínlẹ̀ Plateau.
Adari ìbánisọ̀rọ̀ àti ọ̀rọ̀ tó n lọ fún gómìnà ipínlẹ̀ Plateau, Simon Lalong, Makut Macham lo kéde nínú àtẹ̀jáde kan tó fi síta l'Ọjọ́rú.
Òfin kóníléógbélé náà wáyé nítórí ìkólu tó ṣẹlẹ̀ ní Yelwa Zangam, abúlé kan ni ẹkùn Zangam ni ìpínlẹ̀ Plateau.
Gẹ́gẹ́ bí Gómínà ṣe sọ òfin kóníléógbélé náà yóò bẹ̀rẹ̀ láti aago mẹ́rin ìrọ̀lẹ́ òni ọjọ́ karùndinlọ́gbọ̀n, oṣù kẹjọ, ọdún yìí títí di ìgbà tí ẹnikẹ́ni ko tíì mọ̀.
Igbésẹ̀ oníwàrànṣesà yìí pọndandan nítorí wàhálà tó n dúkoko mọ ìwàláàyè àwọn ara ìlú ni ìjọba ìbílẹ̀, ó sì pọndandan kí a mójútó kí nǹkan to bàjẹ́ jìnà."""
 Èyí yóò ràn àwọn agbófinro lọ́wọ́ pẹ̀lú láti ṣe iṣẹ́ wọn bi ó ti tọ́ àti bi ó ti yẹ, àti láti ṣe àwárí àwọn tó ṣe iṣẹ́ aburú náà.
Gómínà tí wá rọ àwọn  ará ìlú pàápàá jùlọ àwọn ará àríwà ni Jos láti fọwọ́sowọ́pọ̀ pẹ̀lú ìjọba nípa tílèlé òfin kóníléógbélé náà ti yóò bẹ̀rl ni aago mẹ́rin ìrọ̀lé òní.
Nítorí kí aafa lè máa rí iṣẹ́ ṣe ní wọ́n kò ṣe kó Alumaajiri nílẹ̀ tó fi di ohun tó dà yìí
"Ìjọba ti pọn ni dandan fun awọn agbófinro pe kí wọ́n fi ọwọ́ òfin mú ẹnikẹni tí ó ba ki etí ọ̀gbọ̀in si àṣẹ náà."""
Gómìnà Lalong tun fi kun pé, òfin kónílé o gbélé alaago mẹ́fà alẹ́ sí ti ìdájí náà wà ni ìhà Gúúsù Jos náà títí di àsìkò ti wan kò mtí mọ̀.
Ẹ̀wẹ̀, àwọn tó n ṣe iṣẹ́ bi nọ́ọ̀sì, dókítà, oníròyìn, àwọn panápaná àti awọn eletò ààbò nikan ni ofin fi aaye gbà láti jáde.
Sùgbọ́n kí àwọn ènìyàn wọ̀nyí rii dájú pé, wọ́n mú ìwé ìdánimọ̀ wọn dání.
 Lẹ́ẹ̀kan si gómìnà bá àwọn to pàdánù ẹbi wọn láti fi ọ̀kan bálaẹ̀ kí wọ́n sì gba ìjọba láàyè láti  mójú tó ọ̀rọ̀ náà kí àwọn oníṣẹ́ ibi náà má baa fi ìyà jẹwọ́n gbé.
Oríṣun àwòrán, Lalong
Iroyin yajoyayo to n tẹ wa lọwọ lati ipinlẹ Plateau sọ pe awọn janduku agbebọn tun ti fi ẹmi eeyanto le lọgbọn ṣofo lagbegbe Yelwan Zangam ni ijọba ibilẹ ariwa ilu Jos.
Unijos students victims: Àwọn Fulani yabo 'hostel' wa, ọpẹ́lọpẹ́ àwọn Sọ́jà tí gómìnà ìpí
Ti ẹ ko ba gbagbe, bi ọsẹ meji sẹyin lawọn agbebọn ṣekupa arinrinajo mẹẹdọgbọn to n lọ si Ondo niluu Jos.
Amọ iroyin sọ pe bi ago mẹsan an ku iṣẹju mẹẹdogun ni alẹ ọjọ Iṣẹgun lawọn janduku yii yabo awujọ Yelwa Zangam nibi ti wọn ṣọṣẹ di oru mọju Ọjọru.
Ọba awọn ẹya Anaguta to wa lagbegbe tawọn agbebọn kọlu yii, Ujah Johnson Jauro fidi iṣẹlẹ ọhun mulẹ fawọn akọroyin.
Kọunsilọ wọọdu Ahwol lawujọ naa, Yusuf Ali ṣalaye pe awọn janduku naa dana sun awọn kan laaye.
Aṣofin ni afara to so awujọ naa pọ mọ awọn agbegbe mii lawọn janduku ọhun kọkọ bajẹ ko le nira fawọn ẹṣọ eleto abo lati wa doola awọn eeyan.
Ondo Jos clash: Èmi nìkan ló padà dé nínú àwa márùn ún tí a jọ lọ ìpàdé àdúrà ní Jos- Bell
Kọunsilọ naa ni bawọn janduku yii ti de awujọ naa ni wọn dabọn bolẹ, bakan naa lo sọ pe wọn tun dana sun ọpọ ile.
O ni ọpọ oku awọn eeyan ni wọn ti ko lọ si ile igboku si nigba ti ọpọ eeyan si fara pa yanayana.
Ile iṣẹ ọlọpaa ipinlẹ Plateau ko tii sọrọ lori iṣẹlẹ ọhun.
Mass burial Ghana: Tètè wá gbé òkú eèyàn rẹ bí bẹ́ẹ̀ kọ́ a ó sìn wọ́n papọ̀ mọ́ tí 200 lópin ọ̀sẹ̀- Iléeṣẹ́ Ọlọ́pàá
Oríṣun àwòrán, @Jubilee House
E wo lo ṣẹlẹ ti  ileeṣẹ ọlọpaa fi fẹ sinku oku 200 lẹẹkan ṣoṣo?
Kere o! ẹyin ti ẹ ba ni oku lọdọ wa, ẹ wa ko wọn bi bẹẹ ko, a o sin wọn papọ.
Ikede yi lo n jade lati ọdọ ileesẹ ọlọpaa lorileede Ghana eyi ti wọn ni awọn yoo sinku igba oku ti awọn ko mọ mọlẹbi wọ́n.
Ninu atẹjade kan ti wọn fi sita lọjọ Aje ni wọn ti n  kesi araalu bẹẹ.
Wọn ni ki onikaluku wa yọju lati ṣe idanimọ oku ti o ba jẹ ti wọn.
A n fi asiko yi rọ araalu pe ki wọn ma gbagbe  isinku awọn oku igba yi ta ti n tẹnumọ lati oṣu Keje lọna ti mu adinku b iye oku to wa ni ile ikokupamọsi ile iwosan wa''
Wọn tẹsiwaju pe igbakeji ree tawọn fẹ se isinku alapapọ fun awọn oku ti mọlẹbi wọn ko yọju.
Nítorí kí aafa lè máa rí iṣẹ́ ṣe ní wọ́n kò ṣe kó Alumaajiri nílẹ̀ tó fi di ohun tó dà yìí
"Wọn tun ni: ""Yoo dunmọ wa ti awọn araalu ba le kan si ẹka ikokupamọ wa bẹrẹ lati ọjọ Kẹtalelogun oṣu yi lati le tọka si oku ti o ba jẹ tiwọn ki wọn si gbe wọn lọ ki a ma ba ko wọn papọ mọ awọn oku mii lọ sin.''"
Babatunde Gbadamosi: Mo ta gbogbo dúkìá mi lásìkò kan kí ń tó padà di eèyàn lónìí
DSP  Yaw Nketia to buwọlu atẹjade yi ni awọn nilo ki araalu pawọpọ pẹlu awọn lori ọrọ yi.
Ileeṣẹ ọlọpaa lorileede Ghana ni awọn yoo fẹ ki awọn eeyan wa ṣaaju isinku tawọn fẹ se lopin ọsẹ yi lati mu adinku ba iye oku tawọn ko si ile ikokupamọ.
Unijos students victims: 'Àwọn Fulani yabo 'hostel' wa, ọpẹ́lọpẹ́ àwọn Sọ́jà tí gómìnà Lalong rán wá pèsè aàbò fún wa kó tó pẹ́ jù'
A dupe pe ori ko wa yọ, a ko mọ ibi ti ọpọ akẹkọọ ṣi wa- Aarẹ UNIJOS
Awọn akẹkọọ ipinlẹ Oyo ba BBC sọrọ lori ohun  to ṣẹlẹ si wọn ni Jos.
Kolawole Adedokun to jẹ aarẹ wọn sọrọ ilẹ kun.
Ogunlowo Samuel sọ bi awọn Fulani ṣe wa kọlu wọn ni nu ile egbe wọn .
O sọ bi wọn ṣe jajabọ pẹlu iranlọwọ awọn sohja ti gomina Lalong ran wa sibẹ.
Adesokan Afeez naa sọ diẹ lara ohun to ju awọn akanda ẹda ri to nipinlẹ Plateau.
Gbogob awọn akẹkọọ naa fi ayo han pe awọn apda sile pẹlu iranlọwọ moto akero ti gomina Seyi Makinde fi ranṣẹ si wọn.
Wọn tun sọ pe ọpọ ninu awọn akẹkọọ ni wọn ko tii ri titi di asiko yii to jẹ ọmọ Yoruba nilẹ Hausa.
Ondo Jos clash: Èmi nìkan ló padà dé nínú àwa márùn ún tí a jọ lọ ìpàdé àdúrà ní Jos- Bell
Awọn ti ori ko yọ ninu ikọlu to waye si awọn Fulani ipinlẹ Ondo ti wọn lọ si Plateau ba BBC Yoruba sọrọ ilẹ kun.
Usman Ahmad ti isẹlẹ naa kọkọ ba a lojiji bi o ṣe ṣoju rẹ ni aya oun ṣi n ja ninu paya di isinyi.
Lana Abdullahi to farapa pupọ naa sọ idaamu ti wón koju nigba ti wọn n sa asala fun ẹmi ara wọn.
Abubakar Bello mẹnuba ipa ti awọn soja ko funara ilu lati doola ẹmi iye awọn to ṣeku.
Harunna Mohammed atawọn to ku naa ni iru eyi ko dara nilu to lolori.
Alaga ẹgbẹ Fulani Miyetti Allah, Muhammad Kabir gba wọn nimọran lati maa beere fun eto aabo ki wọn to lọ sibi eto adura kankan léyin iṣẹlẹ yii.
NDA Attack: Ìkọlú sí NDA ti fihàn pé Buhari ń gbìyànjú l\ati sọ Nàìjíríà di Afghanistan ni- SOKAPU
Oríṣun àwòrán, @NDA
Agbarijọpọ awọn ọmọ bibi apa guusu ipinlẹ Kaduna,SOKAPU ti bẹnu atẹ lu iṣẹlẹ ikọlu awọn agbebọn si ibudọ ikọnilẹkọ awọn ọmọ ogun Naijria NDA.
Ninu atẹjade ti wọn fi sita, ẹgbẹ naa ni ikọlu yi fi han pe aarẹ n gbiyanju lati sọ orileede Naijiria di bi Afghanistan ti se ri ni.
Agbẹnusọ ẹgbẹ naa. Luka Binniyat sọ fun ileesẹ iwe iroyin Naijiria abẹlẹ kan , The Punch.
O ni pe ọna aibikita ti awọn ọdaran yi fi doju ija kọ ibudo awọn ọmọ ogun ti eeyan kankan ko si farapa ninu wọn n tọka si eewu nla gidi  to n koju oselu awarawa ni Naijiria.
Ẹgbẹ naa sọ pe ti wọn koba ṣe nkankan si ikọlu yi, o ṣeeṣe ki ''ijọba Buhari maa palẹmọ ohun ti yoo ṣẹlẹ mi to n bọ ni''
O ni ''Ipaniyan awọn ọmọ ogun meji yi ati ijinigbe ọgagun kan ko ya awa ọmọ ẹgbẹ SOKAPU lẹnu rara.
Unijos students victims: Àwọn Fulani yabo 'hostel' wa, ọpẹ́lọpẹ́ àwọn Sọ́jà tí gómìnà ìpí
Idi ni pe iru ikọlu bẹ ti waye lẹẹmeelo kan ni bareke awọn ọmọogun to wa ni ile ẹkọ Command and Staff College, Jaji to wa laarin Zaria ati Kaduna.
Ninu ikọlu yi wọn ji maalu ati nkan ini miran lọ''
Ondo Jos clash: Èmi nìkan ló padà dé nínú àwa márùn ún tí a jọ lọ ìpàdé àdúrà ní Jos- Bell
Binniyat  wa kilọ pe ti wọn ko ba gbe igbesẹ ni kiakia ki wọn si mu awọn ọdaran yi,o ṣeeṣe ki iru nkan to waye ni Afghanistan ṣẹlẹ ni Naijiria.
"Ọrọ ẹnu aarẹ latẹyinwa ati iṣeṣi rẹ fi han pe ko bikita lati gbe agbara fawọn alakatakiti''
Nítorí kí aafa lè máa rí iṣẹ́ ṣe ní wọ́n kò ṣe kó Alumaajiri nílẹ̀ tó fi di ohun tó dà yìí
''Boya iṣẹlẹ aburu yi yoo ta gbogbo eeyan ji yatọ si aarẹ Buhari ati awọn agbodegba rẹ nitori ero wọn si ọmọ Naijiria ko sunwọn rara''
O wa kesi gbogbo ọmọ Naijiria alti bẹnu atẹ lu iṣẹlẹ yi.
O ni  ki wọn si pe Gomina Kaduna Nasir El Rufai ati aarẹ Buhari si akiyesi lati gbaju mọ ojuṣe wọn ki Naijiria to tẹri sinu ọọfin ti awọn ko lero rara.
Bi a ko ba gbagbe lowurọ kutu ọjọ Iṣẹgun lawọn agbebọn yawọ NDA ti wọn si pa ọmọ ogun meji ki wọn to ji ọgagun kan gbe salọ.
Senato francis Fadahunsi: Ká ni wọ́n fún Buhari ladún mẹ́wàá sẹ́ypin ní, bóyá kò bá rí i ṣ
Titi di ba ṣe n ṣakojọ iroyin yi, a ko ti mọ pato ibi ti wọn gbe lọ ṣungbọn ijọba gba ẹnu ileeṣẹ ologun sọrọ pe awọn yoo sawari awọn ọdaran yi.
Oríṣun àwòrán, MBuhari
Ìkọlù sí NDA yìí ní yóò múṣẹ́ yá lórí fífi òpin sí ìwà ọ̀daràn ní Nàìjírà-Ààrẹ Buhari
Ààrẹ Muhammadu Buhari sọ pe ìkọlu tó wáyé ni ilé ẹ̀kọ́ ẹ̀kọ́sẹ́ NDA láti ọwọ awọn agbébọn ni yóò mu ki iṣẹ́ yá lórí fifi òpin sí ìwà ọ̀daran ni Nàìjíríà.
Rape survivor: Ìyá mi ni ń kò gbọdọ̀ sọ̀rs kí ilé má bà á dàrú- Oluwatobi Raji
Ààrẹ Buhari, lásìkò tó n sọ̀rọ̀ lóri ìṣẹ̀lẹ̀ tó wáye lọ́jọ́ Isegun ni Afaka ipinlẹ Kaduna nibi ti wọn pa awọn ọmọogun meji, ti wọn si pa ọkan.
Gẹ̀gẹ́ bi àtẹjáde tí olubádámọ̀ràn fún ààrẹ̀ lórí ọ̀rọ̀ tó n lọ Fẹmi Adesina fọ́wọ́ sí ló ti fi ìdí rẹ́ múlẹ̀ pé ìkọlù tó wáyé ni NDA  ni yoo palẹ ìwa ọ̀daran mọ́ ni Nàìjíríà.
 Ìkọlu tó wáyé ni ọgbà NDA yóò túbọ̀ kún àwọn ọmọogun lágbára ni kaka ti yóò fi da omítuntun si wọn lọ́kan gẹ́gẹ́ bi nǹka ti wọ́n ń fẹ́."" Gẹ́gk bi ààrẹ ṣe sọ."
"Ó tọ́ka sí pé ìkọlù náà tó yọri si pipadanu ẹmi àwọn ènìyàn wáyé ni àsìkò tí àwọn ọmọogun ti mu àwọn ọ̀daran wá sínú ìbẹ̀rù bojo, à[rẹ ni ìṣẹ̀lẹ̀ yìí ni yóò mu kí ìjọba tu ìwà ọ̀daràn ti gbòngbòti gbòngbò.
Nítorí kí aafa lè máa rí iṣẹ́ ṣe ní wọ́n kò ṣe kó Alumaajiri nílẹ̀ tó fi di ohun tó dà yìí
Ààrẹ kẹ́dùn pẹ̀lú àwọn ẹbí tí wọ́n pàdánù ènìyàn wọn , ti o sì gbàdúra kí ọlọrun tù wọ́n nínú.
Ààrẹ Buhari búra fún àwọn  ẹbi àwọn olóògbé pé wọ́n ko ni kú lásán àti pe oun ṣetán láti yanjú gbogbo ìṣòrò yìí.
Bákan náà ni ààrẹ dúpẹ́ lọ́wọ́ àwọn ọmọ Nàìjíríà àti àwọn ọmọogun Nàìjíríà, ti ó sì rọ àwọn tó n fi òṣèlú ṣe gbogbo nǹkan lori ọ̀rs ètò abo láti sọra ."
Ẹ̀wẹ̀, oga àgbà ilé iṣk ọmọogun Lucky Irabor ti fi ẹdun ọkàn rẹ̀ hàn lóri ìṣẹ̀lẹ̀ tó wáyé ni ọgbà NDA .
"Ó sàpejúwe ìṣẹ̀lẹ̀ náà gẹ́gẹ́ bi ""ìwà orí dídàrú"" o ní èyí kìí ṣe ìwà àwọn jànduku ti gbogbo ènìyàn mọ̀."
Ọ̀gá àgbà náà sọ èyí lásìkò tó n bá àwọn ońíròyìn ni Yola ni olúùlú Adamawa lọ́jọ́ Isegun.
Irabor ni: Ìṣẹ̀lẹ̀ tó wáyé ni Kaduna jẹ ti ìwà àwọn jànduku, sùgbọ́n ó jọ mọ bi ẹni pé, àwọn ọdàran wa jale nínu ilé ni.
Ondo Jos clash: Èmi nìkan ló padà dé nínú àwa márùn ún tí a jọ lọ ìpàdé àdúrà ní Jos- Bell
Bi wọ́n ṣe wọ inú ibl kìí ṣe ọ̀nà ti àwọn jàndùkú tí gbogbo ènìyàn mọ̀ ṣe máa n ṣe ni èyí, sùgbọ́n gbogbo nǹka ti a n wò ni èyín ti a si n ṣe ìwádìí.
Nínú àtẹ̀jadé ti adarí ètò ọ̀rọ̀ tó n lọ ọmọogun Benjamin Sawyer fọwọ́sí lo ti ṣàlàyé pé ọ̀pọ̀ àwọn ọmọogun n lepa àwọn ọdaran náà lójú méjèèjì.
Sale of children: Àgbá nọ́ọ̀sì dèrò ẹ̀wọ̀n lẹ́yìn tó ta ọmọ ọdún mẹ́fà ní N200,000
Oríṣun àwòrán, others
Yoruba bọ, wọn ọjọ gbogbo ni ti ole, ọjọ kan bayii ni ti olohun.
Agba nọọsi kan ti ri ẹwọn he lẹyin ti aṣiri owo kata kara ọmọde to n ṣe tu, ti o si n ka boro boro.
Ile ẹjọ giga niluu Uyo nipinlẹ Akwa Ibom dajọ ẹwọn ọdun mẹwaa fun Gertrude Akpan lẹyin to jẹbi ẹsun kata kara ọmọde.
Adajọ Okon Okon dajọ ju Akpan si ẹwọn ọdun mẹwaa lai fun un lanfaani fun lati san owo itanran,
Akpan ni ile ẹjọ fi idi rẹ mulẹ pe o ra ọmọdekunrin ọdun mẹfa niluu Uyo ti o si ta ọmọ naa fun ẹnikan ti orukọ rẹ n jẹ Kate Ogbonna niluu Owerri.
Ondo Jos clash: Èmi nìkan ló padà dé nínú àwa márùn ún tí a jọ lọ ìpàdé àdúrà ní Jos- Bell
Akpan, ẹni ọdun mẹtadinlaadọta jẹ ọmọbibi ilu Ikot Eyo ni ijọba ibilẹ Nsit Ibom ni ipinlẹ Akwa Ibom.
Akpan, iya ọmọ mẹta, jẹwọ pe oun ti ti n ṣe owo kata kara ọmọde lati ọdun 2008.
Unijos students victims: Àwọn Fulani yabo 'hostel' wa, ọpẹ́lọpẹ́ àwọn Sọ́jà tí gómìnà ìpí
Bakan naa lo sọ pe oun ti ṣiṣẹ ri gẹgẹ bi nọọsi ni ile iwosan Immanuel Hospital niluu Eket nibi ti oun ti ṣiṣẹ gẹgẹ bi olori awọn nọọsi lọdun 2015.
Lẹyin wi pe o jẹwọ, o tan ran awọn ọlọpaa lọwọ lati ri ọmọdekunrin to ta gba lọwọ ẹni to ta ọmọ naa fun niluu Owerri.
Adajọ ni o ṣeni laanu pe Akpan ti oun fun ra rẹ naa jẹ abaimọ le maa fi ọmó ọlọmọ ṣe owo kata kara.
Adajọ Okon nin iwa buruku gbaa ni agba nọọsi naa hu nitori ko jẹ ki awọn ọmọde to n fi ṣowo jẹ anafaani ifẹ ati didagba labẹ obi wọn.
Nítorí kí aafa lè máa rí iṣẹ́ ṣe ní wọ́n kò ṣe kó Alumaajiri nílẹ̀ tó fi di ohun tó dà yìí
Climate change famine: Àwọn èèyàn bẹ̀rẹ̀ sí ni máa jẹ tata nítorí ìyàn tó mú
Oríṣun àwòrán, WFP/TSIORY ANDRIANTSOARANA
Nnkan ko fara rọ mọ lorilẹede Madagascar lẹyin ti iyipada oju ọjọ ti jẹ ki iyan mu nilẹ naa bayii.
Ajọ iṣọkan agbaye, UN ṣalaye pe ẹgbẹẹgbẹru eeyan ni Madagascar ni ebi n pa bayii tori ọwọngogo ounjẹ nibẹ.
Ọwọngogo ounjẹ yii ko ṣẹyin ojo ti ko rọ fun ọdun mẹrin gbako eleyii to ṣakoba nkan ọgbin ni Madasgasacar.
Ọda ojo, eleyii to buru julọ ni ogoji ọdun ni Madadascar ti ṣakoba nla fun ere oko atawọn eeyan eeyan to wa lapa guusu orilẹede naa debi pe tata ni ọpọ eeyan n jẹ bayi.
Alakoso eto ounjẹ fun ajọ UN, Shelley Thakral, ṣalaye pe ki ṣe ija lo fa iyan to mu ni Madagascar bi ko ṣe ayipada oju ọjọ.
Nítorí kí aafa lè máa rí iṣẹ́ ṣe ní wọ́n kò ṣe kó Alumaajiri nílẹ̀ tó fi di ohun tó dà yìí
Ajọ UN sọ pe o kere tan eeyan bii ẹgbẹrun lọna ọgbọn ni ebi n ba finra bayii nibẹ.
Ajọ naa ni awọn eeyan yii yoo si tun pọ si pẹlu bi nnkan ṣe ri.
Rape survivor: Ìyá mi ni ń kò gbọdọ̀ sọ̀rs kí ilé má bà á dàrú- Oluwatobi Raji
Thakral ṣalaye pe eleyii ko ṣẹlẹ ri, ayipada oju ọjọ ki ṣe ẹbi awọn eeyan yii to n jiya lọwọ.
Awọn ara abule Fandiova ni ẹkun Amboasary lawọn eeyan ri ti wọn n jẹ ti wọn n wa tata kaakiri lati jẹ.
Iya ọlọmọ mẹrin kan, Tamaria ni oun tawọn ọmọ oun ti n jẹ tata bayii fun oṣu mẹjọ.
Tamaria ni ko si nkan mii tawọn le jẹ mọ nitori ojo ko rọ lati ri nkan oko jẹ.
Senato francis Fadahunsi: Ká ni wọ́n fún Buhari ladún mẹ́wàá sẹ́ypin ní, bóyá kò bá rí i ṣ
Obinrin mii to bimọ mẹta, Bole ni ewe loku ti oun ati awọn eeyan oun n jẹ bayii.
O ni ọkọ oun ṣẹṣẹ ku laipẹ yii ni nitori ai ri ounjẹ jẹ naa ni
Ondo Jos clash: Èmi nìkan ló padà dé nínú àwa márùn ún tí a jọ lọ ìpàdé àdúrà ní Jos- Bell
Ondo bullion van attack: Adigunjalè kọlu ''bullion van'' tó gbówó l'Ondo fún ìgbà kẹ́rin lóṣù méjì, èèyàn méjì tún kú
Oríṣun àwòrán, Other
Eeeyan meji lo tun gbẹmi mi lẹyin tawọn adigunjale tun kọlu ọkọ to n gbe owo lọ niluu Ofosu lọna mọrosẹ Ore si Shagamu ni ijọba ibilẹ Idanre nipinlẹ Ondo.
Ohun ti a gbọ ni pe ọkọ igbowo naa n lọ si Ore ni kawọn adigunle naa to da ibọn bo ọkọ naa.
Ẹnikan sọ pe ọlọpaa meji ati eeyan kan mii lawọn adigun jale ọhun yinbọn pa.
Awọn miran tun sọ pe eeyan marun un lo ku ninu iṣẹlẹ naa, awọn ọlọpaa atawọn oṣiṣẹ banki to tẹ le ọkọ naa.
A tun gbọ pe obiti biti owo ti ẹnikan ko mọ iye rẹ ni awọn adigunjale ọhun gbe lọ.
Ondo Jos clash: Èmi nìkan ló padà dé nínú àwa márùn ún tí a jọ lọ ìpàdé àdúrà ní Jos- Bell
Ẹnikan sọ pe awọn adigunjale ọhun ti lọ sa pa mọ fawọn to n gbe ọkọ igbowo naa lọ eyi to jẹ ti gbajugbaja banki kan.
Ilu Benin Benin nipinlẹ Edo ni wọn ti n gbe ọkọ owo naa bọ ki wọn to ko sọwọ awọn adigunle niluu Ofosu.
Senato francis Fadahunsi: Ká ni wọ́n fún Buhari ladún mẹ́wàá sẹ́ypin ní, bóyá kò bá rí i ṣ
Agbẹnusọ ile iṣẹ ọlọpaa, Funmilayo Odunlami to fidi iṣẹlẹ ọhun mulẹ sọ pe eeyan meji lo ku ninu iṣẹlẹ naa.
Odunlami sọ pe ọlọpaa kan ati awakọ igbowo naa lo ba iṣẹlẹ ọhun lọ.
Rape survivor: Ìyá mi ni ń kò gbọdọ̀ sọ̀rs kí ilé má bà á dàrú- Oluwatobi Raji
Alukoro ọlọpaa ni ilu Araromi Obu ni ọkọ igbowo naa n lọ ki wọn to dawọn lọna.
O ṣalaye pe iwadii ti bẹrẹ lori iṣẹlẹ naa, ati pe awọn ọlọpaa ti le awọn adigunjale ọhun lọ.
Eyi ṣẹlẹ lẹyin ọsẹ meji tawọn janduku agbebọn kọlu ọkọ igbowo kan ni Emure Ile ni ijọba ibilẹ Owo.
O ti di igba mẹrin ti iṣẹlẹ ikọlu ọkọ igbowo ti ṣẹlẹ bayii nipinlẹ Ondo laarin oṣu meji.
Rape survivor: Ìyá mi ni ń kò gbọdọ̀ sọ̀rọ̀ kí ilé má bà á dàrú- Oluwatobi Raji
Ariwo 'Idi mi gba ina jẹ' ni Woli ni ki n maa pa ko to kọlu mi- Tobi Raji
Oluwatobi Raji ni BBC wa kan ti o sọrọ nipa iriri rẹ gẹ gẹ bi ẹni to ti la ifipabanilopọ kọja.
O ni ọkunrin mẹwaa lo ti fipa ba oun lo pọ ri ṣugbọn oun n sọ nipa rẹ ki ọpọ ọdọ ma ba a ko si iru gbaga bẹẹ ni.
Tobi sọ bi ọrọ yi ṣe bẹrẹ pẹlu aburo iya rẹ lọmọ ọdun mẹjọ.
O sọ bi iya oun ṣe ni ki oun dakẹ ki ile ma baa daru.
O ni ni iya oun ba ni ki oun pa a móra.
Tobi gba Obi ati alagbatọ se gbọdọ tọju awọn ọmọ wọn.
Tobi Raji sọ awọn nkan mii to ṣẹlẹ si ati idi ti oun ṣe n fọnrere lodi si ifipabanilopọ ati ipa to yẹ ki Ijoba ko lori iṣẹlẹ bẹẹ.
Senato Francis Fadahunsi: Ká ni wọ́n fún Buhari lọ́dún mẹ́wàá sẹ́yin ní, bóyá kò bá rí i ṣe
Buhari kó ní agbárà mọ́, òun kọ́ ló ń ṣe ìjọba- Senato Francis Fadahunsi
Opo awọn ọmọ Naijiria lo ti n sọrọ ibi ti eto aabo Naijiria de duro labẹ iṣẹjọba aarẹ Buhari yii.
Senato Francis Adenigba Fadahunsi n ṣoju awọn ekun ipinlẹ Osun labẹ asia ẹgbẹ oṣelu PDP nile igbimọ aṣofin agba ni Abuja.
Oríṣun àwòrán, @fadahunsi
O ni pe agba ti de fun Buhari ni awọn to yii ka ṣe n baa ṣe ijọba rẹ.
O tun ṣalaye pe adura lo ku lasiko yii pẹlu awọn igbese akin.
Fadahunsio ni ọ̀rs Afghanista ti kọ awọn oloselu lọgbọn pe ko seni ti ko le gba ijọba.
O ni 'Rebel' le gba ijọba ti agbofinro ba dawọ silẹ bi o ṣe n ṣẹlẹ laisko yii ni Naijiria.
Fadahunsi salaye ọna abayọ lori ọrọ awọn ṣọja ati ipa to yẹ ki onikaluku ara ilu ati akọroyin ko fun idagbasoke Naijiria lai yọ oloselu kọọkan silẹ.
Ṣé lóòtọ́ ni pé ilé ẹjọ́ sọ pé kí Lizzy Anjorin san 9.5m fún ẹni tó pé lẹ́jọ́ nítorí ọ̀rọ̀ ọkọ rẹ̀?
Oríṣun àwòrán, lizzy anjorin/ dorcas adeyinka
Gbajugbaja agbohunsafẹfẹ lori ayelujara Facebook, Dorcas Adeyinka ti jawe olubori ninu ẹjọ kan ti gbajugbaja osẹrebinrin, Lizzy Anjorin pe e ni orilẹ-ede United Kingdom.
Oṣu kẹfa, ọdun 2021 ni Lizzy gbe Dorcas Adeyinka ati eeyan mẹta miran lọ si ile ẹjọ lorilẹ-ede UK, fun ẹsun ibanilorukọ jẹ.
Lizzy sọ pe wọn ba orukọ oun jẹ ni ọpọ igba lori ayelujara.
Ninu ikede to fi sita lori ayelujara Facebook rẹ, pẹlu abajade iwe ile ẹjọ, Adeyinka sọ pe Onidajọ Spearman QC paṣẹ pe ki Lizzy san ẹgbẹrun mẹtadinlogun Pọun fun Dorcas laarin ọjọ mẹrinla pere.
Bakan naa ni ile ẹjọ da ẹjọ naa nu, to si kọ lati paṣẹ fun Dorcas pe ko ma sọrọ nipa Lizzy Anjorin ati ọkọ rẹ, Ọgbẹni Lawal.
Unijos students victims: Àwọn Fulani yabo 'hostel' wa, ọpẹ́lọpẹ́ àwọn Sọ́jà tí gómìnà ìpí
Lati ọdun 2019 ti Lizzy Anjorin ti ṣe igbeyawo pẹlu ọkọ rẹ, Ọgbẹni Lawal, ni oriṣiriṣi awuyewuye ti n waye lori igbeyawo naa.
Ọpọ igba ni iroyin jade pe ọkọ ọlọkọ ni Lizzy gbà.
Ko si pẹ lẹyin igbeyawo naa ni obinrin kan, Fola Tinubu, jade si ori ayelujara pe oun ni obinrin ti Lizzy gba ọkọ rẹ.
O sọ ninu awọn fidio kan to fi si ori ayelujara pe ọmọ mẹrin ni Lawal fi silẹ fun oun nikan lati ma a tọju, to fi ko lọ si ile Lizzy, ti wọn si ṣe igbeyawo.
Botilẹ jẹ pe Lizzy sọrọ nigba naa pe o ti to ọdun mẹẹdogun ti oun ti mọ Lawal, o jẹ alaanu oun, ti oun ko si gba a lọwọ obinrin kankan.
Senato francis Fadahunsi: Ká ni wọ́n fún Buhari ladún mẹ́wàá sẹ́ypin ní, bóyá kò bá rí i ṣ
Dorcas Adeyinka to ma n sọrọ nipa awọn nkan to n lọ laarin ilu, lori ayelujara Facebook, to si tun ma n pe ara rẹ ni ajafẹtọ ọmọniyan, da si ọrọ naa, to si ṣe ileri lati gbeja Fola.
Lati asiko naa si lo ti ma n gbe oriṣiriṣi iroyin ati 'asiri' nipa Lizzy ati Lawal jade.
Lẹyin asiko diẹ, Lizzy ko le gba awọn ọrọ naa mọra mọ, o si pe Dorcas ni ẹjọ si ile ẹjọ kan ni United Kingdom, nibi ti Dorcas n gbe.
Ondo Jos clash: Èmi nìkan ló padà dé nínú àwa márùn ún tí a jọ lọ ìpàdé àdúrà ní Jos- Bell
Lizzy Anjorin fi fidio kan sita lori ayelujara Instagram rẹ ni Ọjọru pe irọ ni jijawe olubori ti wọn sọ pe awọn jawe olubori. Botilẹ jẹ pe ko darukọ ẹni to n ba a wi
O ni nkan ti ile ẹjọ sọ ni pe ki oun pe wọn lẹjọ ni Naijiria, niwọn igba to jẹ pe Naijiria ni oun n gbe.
Babatunde Gbadamosi: Mo ta gbogbo dúkìá mi lásìkò kan kí ń tó padà di eèyàn lónìí
Wọn win lori irọ... Wọn ni ki a pe wọn lẹjọ lati Naijiria, niwọn igba to jẹ pe Naijiria ni a n gbe. Oun gan-an lo pe wa ju.
Lizzy ṣalaye pe igbẹjọ gan-an ko ti i bẹrẹ lori ẹsun ti oun fi kan ẹni naa. O ni ile ẹjọ lati fi ofin de wọn lori ọrọ oun ni awọn ṣi lọ.
Bakan naa lo sọ pe oun yoo ṣi sọrọ lori idajọ ile ẹjọ naa.
Ninu ọrọ to pada sọ lori fidio to ṣe ni owurọ oni pe oun ko ni i sinmi ogun lori ọrọ naa. O ni idi ni pe awọn nkan to jẹ idunnu fun oun lo fẹ ẹ bajẹ.
O ni kii ṣe pe ile ẹjọ da ẹjọ nu. O ni ile ẹjọ sọ pe kii ṣe agbegbe oun ni ẹjọ naa ti waye.
Rape survivor: Ìyá mi ni ń kò gbọdọ̀ sọ̀rs kí ilé má bà á dàrú- Oluwatobi Raji
NDA Kaduna attack: Ẹ̀yin akọ̀ròyìn, ẹ má sọ ọ̀rọ̀ wa láì dá a mọ́ - Iléèṣẹ́ ológun
Oríṣun àwòrán, BASHIR AHMAD/FACEBOOK
Ẹka to n mojuto eto iroyin nileeṣẹ ologun Naijiria, ti bẹ awọn akọroyin pe ki wọn o ma  sọ ọrọ ileeṣẹ ologun lọna ti ko dara.
Eyi waye lẹyin ọjọ kẹta ti awọn agbebọn ti ẹnikẹni ko mọ, kọlu ile ẹkọ awọn ologun, Nigerian Defence Academy (NDA), nilu Kaduna, ti wọn si pa
Lati igba ti iṣẹlẹ naa ti waye ni awọn ọmọ Naijiria ti n beere oriṣiriṣi ibeere lọwọ ileeṣẹ ologun.
Ti oriṣiriṣi iroyin si n jade nipa iṣẹlẹ naa.
Oludari ẹka iroyin nileeṣẹ ologun, Ọgagun Benjamin Olufemi Sawyerr fi ọrọ ẹbẹ naa sita ni ori redio Voice of Nigeria, ati Federal Radio Corporation of Nigeria, FRCN, lọjọru, ọjọ kẹẹdọgbọn, oṣu Kẹjọ.
Oríṣun àwòrán, DIRECTORATE OF DEFENCE INFORMATION
Ọgagun Sawyerr sọ pe ki awọn ileeṣẹ iroyin fọwọsowọpọ pẹlu ileeṣẹ ologun, ki wọn o si ma a gbe iroyin to ba dara jade nipa ileeṣẹ ologun, fun idagbasoke ati alaafia orilẹ-ede Naijiria.
Ondo Jos clash: Èmi nìkan ló padà dé nínú àwa márùn ún tí a jọ lọ ìpàdé àdúrà ní Jos- Bell
Ṣugbọn ṣa, Agbẹnusọ fun Aarẹ Muhammadu Buhari, Garba Shehu, sọ pe igbiyanju lati fi iṣejọba Aarẹ Buhari ṣe ẹlẹya, ni nkan to ṣẹlẹ ni ileeṣẹ ologun.
Rape survivor: Ìyá mi ni ń kò gbọdọ̀ sọ̀rs kí ilé má bà á dàrú- Oluwatobi Raji
Garba Shehu sọ pe iṣẹlẹ naa bani lọkan jẹ.
Ọjọ kẹrinlelogun, oṣu Kẹjọ, ni ile ẹkọ ologun naa fi atẹjade sita pe awọn agbebọn kọlu ile ẹkọ naa, to wa ni Afaka, Kaduna.
Oríṣun àwòrán, DIRECTORATE OF DEFENCE INFORMATION
Awọn agbebọn naa wọ ibugbe awọn ọmọ ogun, ti wọn si pa eeyan meji. Wọn tun ji ẹnikan gbe lọ.
Ọjọ keji iṣẹlẹ naa si ni iroyin jade pe oju orun ni awọn ọmọ ogun to n mojuto ẹrọ ayaworan CCTV to wa ninu ọgba naa wa nigba ti ikọlu ọhun waye.
Ṣugbọn, ileeṣẹ ologun sọ pe irọ ni iroyin naa.
Unijos students victims: Àwọn Fulani yabo 'hostel' wa, ọpẹ́lọpẹ́ àwọn Sọ́jà tí gómìnà ìpí
Afganistan Evacuation: Reach, orúkọ ọkọ̀ òfurufú tíwọ́n bi ọmọ Afganistan ọjọ́si si náà ni wọ́n sọ ọmọbìnrin ọ̀hún
Oríṣun àwòrán, US Air mobility command
Wọ́n bí ọmọ kan lójú òfurufú lásìkò tí wọ́n ń  dóòlà àwọn ènìyàn  kúrò ní Afganistan ni wan ti sọ ni ní orúkọ ọkọ̀ ofurufú
Ọmọbinrin ti wọ́n bí sínú ọkọ̀ òfurufú ilẹ̀ Amẹríkà Ramstein Air base ni Germany ni wọ́n pe orúkọ rẹ̀ ni Reach èyí tó jẹ́ orúkọ ọkọ̀ òfurufú náà.
Ọ̀gá  àgbà ọmogun ilẹ̀ Amẹrika ni Europe, Tod Wolters lo sọ bẹ́ẹ̀ lásìkò tó ń bá àwọn oníròyìn  ni Pentagon l'Ọ́jọ́rú.
Ọkọ̀ òfurufú Boeing C-17 ti àwọn ọmọogun ilẹ̀ Amẹrika ti wọ́n mán pè ni Reach nípa lílò àwọn àtopọ̀ nọ́mbà ni wọ́n sọ orúkọ ọmọtun ti wọ́n dóòlà àwọn òbí rl ni Afganistan.
Sáájú ní ẹ̀ka  ọmọogun ojú òfurufú ti sọ lójú òpó twitter ni òpin ọ̀sẹ̀ tó kọjá pé obìnrrin kan bi ọmọ sínú  ọkọ̀ ofúrufu  láti Qatar si Germany   ti o sì kú díẹ̀ ki ọ̀rọ̀ yíwọ́.
O ní awakọ̀ òfurufu náà ni láti wá sí ilẹ̀ díẹ̀ láti jẹ́ kí atégun wà fún ẹni to n rọbí èyi si lo fun obìnrin  náà lánfàni láti bi ọmọ rẹ̀ láyọ̀,  ọmọ àti ìyá sì wà lálàfíà.
Àwọn sójà ló ran obinrin náà lọ́wọ́ ti wọ́n gbẹ̀bi fún nilé ìkẹ́rù sí nínú ọkọ̀ òfurufú ni kété ti wọ́n balẹ̀
Wolter ni àwọn ọmọogun sí n bá àwọn òbí  ọmọ náà sọ̀rọ̀ láti àsìkò náà títí di àsìkò yìí.
 Bí mó ṣe jẹ́ ajagun ojú òfurufú, yóò wùmí kí ọmọ ti wọ́n pè ni Reach yìí dàgbà kí ó dí ọmọ orílẹ̀-èdè ilẹ̀ Amẹrika, ki òun pẹ̀lú máá wa ọkọ̀ òfurufú fún àwọn ọmọogun ojú ofurufú Gẹ́gẹ́ bi Wolter ṣe sọ.
Kabul Airport Attack: Nǹkan ti a mọ̀ nípa ìkọlù tó wáyé ni Kabul
Lọ́sàn òní ni ìbúgbàmù kan dún ni kabul ti ṣe olúùlú Afganista.
Ẹ̀bá ẹnú ìbodè Abbey ti wọ́n ti má n  kó àwọn ènìyàn ti wan ń dóòlà lọ sí ill òkèrè ni pápákọ̀ òfurufú Afganistan lẹ́bàá ilé ìtura Baron .
Agbẹnusọ Pentagọn ti fi idi rẹ̀ múlẹ̀ pé àwọn orílẹ̀-èdè ilẹ̀ Amẹrika àti àwọn ọmọ Afganistabn lo ti jẹ ọlọrun nípè nígbà ti àwọn kan fi ara pa.
Àwòràn fi hàn pé ọ̀pọ̀ àwọn ènìyàn ló wà nílẹ̀ níbi ìṣẹ̀lẹ̀ náà.
Àwọn òṣìṣẹ́ ilẹ̀ Amẹrika náà fi kun pé ìró ìbọn náà ń dún lákọlákọ
Ìbúgbàmù náà wáyé ni kété tí ilẹ̀ Amerika àti ilẹ̀ Gẹ̀ẹ́sì sọ fún àwọn ọmọ orílẹ̀-èdè wọ́n láti jìnà sí pápákọ̀ òfurufú, tí wọ́n sì ti sọ fún wọ́n pé ó ṣeeṣe kí àwọn agbésùmọ̀mí ṣọṣẹ́.
Wọ́n ti jábọ̀ fún ààrẹ orilẹ̀-èdè Amẹrika, Joe Biden lórí nǹkan ti ó n ṣẹlẹ̀, bákan náà ni òun pẹ̀lú ń ṣàlàmí nǹkan ti ó n ṣẹlẹ̀ níbẹ̀
Ààrẹ ilẹ̀ Gẹ̀ẹ́sì, Boris Johnson àti Joe Biden ti ilẹ̀ Amẹrika ní yóò jọ jòkó ṣèpàdé láìpẹ́.
Ó kéré tán ènìyàn ọgọ́ta lo ti jẹ́ Ọlọ́run nípè ti àwọn ogóje sì ti ni ìpalára  níbi ìṣẹ̀lẹ̀ tó  wáyé ni pápákọ̀ òfurufú  gẹ́gẹ́ bí ọ̀gá ètò ilera kan ní Kabul ṣe sọ fún BBC
Pẹntagọn fi ìdí rẹ̀ múlẹ̀ pé, àwọn ọmọ ilẹ̀ Amẹrika to ku níbẹ̀ jẹ òṣìṣẹ́ ìrànwọ́, sùghbọ́ kò tíì sọ iy wọn.
dédé aago mẹ́fà ìrẹ̀lẹ́ ni ìbí gbàmù àkọ́kọ́  niẹ̀bọ́ ilé ìtùra Baron nítòsí pápákọ̀ òfururú.
Tí ìró ìbọ́n sì tèlé, nígbà náà ni ìbúgbàmù kèjì wáyé ní ẹ̀bá ìloro papakọ náà.
Ìròyìn sọ pé, nítòsí, kòtò tí wọ́n ń da ìdọ̀tí sí ni adó olóró kejì ti dún nígbà ti àwọn ènìyàn ń yẹ̀wé wọn wò, nítìrí náà inú kòtò náà ni wọ́n rọ sí
Ọ̀kan nínú òṣìṣẹ́ U.S sọ pé ọkàn nínú àwọn ènìyàn náà ti so àdó olóró mọ́ ara sáájú.
Orílẹ̀-èdè Amerika ati Gẹ́ẹ̀sì tí rà àwọn ọmọ ogun wọn láti lọ sọ agbegbe Abbey Gate.
Gẹ́gẹ́ bi ẹnìkàn ṣe sọ àwọn agbésùmọ̀mí náà ń yìnbọn sí àárín àwọn ènìyàn, sùgbọ́n ìròyìn mííràn tún sọ pé àwọn ọmọoogun Tgaliba naa yìnbọn sínú afẹ́fẹ́.
Ìye ènìyàn tó kú tí n peléke sí ni láti ìgbà tí ìṣẹ̀lẹ̀ náà ti ṣẹlẹ̀.
Iye ènìyàn tí ó kú láàrín àwọn ọmọ US àti Afgbanistan to fi mọ àwọn Taliban, ko ti ni iye.
Channels TV: Ilé iṣẹ́ amóhùnmáwòrán Channels ti sọ̀rọ̀ lórí ìròyìn tó ní DSS ti gbé òṣìṣẹ́ wọn
Oríṣun àwòrán, Channels TV
Iroyin to lu ayelujara pe ni irọlẹ Ọjọbọ ni pe ajọ ọtẹlẹmuyẹ DSS ti gbe awọn oṣiṣẹ ile iṣẹ amohunmaworan Channels TV to n tukọ eto Sunrise Daily.
Iroyin naa sọ pe igbesẹ yii ko ṣẹyin ifọrọwerọ pẹlu gomina ipinlẹ Benue, Samuel Ortom eleyii to bẹnu atẹ lu ijọba Aarẹ Muhammadu Buhari papaa julọ lori eto abo to mẹhẹ.
Ile iṣẹ amohunmaworan Channels TV ti sọ pe iroyin ofege lasan ni.
Wọn ni ko si oṣiṣẹ Channels ti ajọ DSS gbe ṣugbọn ajọ to n ṣakoso igbohun safẹfẹ lori radio ati ẹrọ amohunmaworan, NBC ranṣẹ pe awọn to n tukọ eto Sunrise Daily lati ṣe ipade pọ.
Ṣugbọn awọn oṣiṣẹ naa si pada si ẹnu iṣẹ wọn lẹyin ipade pẹlu ajọ NBC niluu Abuja.
Ondo Jos clash: Èmi nìkan ló padà dé nínú àwa márùn ún tí a jọ lọ ìpàdé àdúrà ní Jos- Bell
Ẹwẹ, ajọ DSS naa ṣalaye ni Ọjọbọ pe ko si ohun to jọ pe ajọ naa mu awọn oṣiṣẹ Channels TV meji.
Ninu atẹjade ti agbẹnusọ DSS, Peter Afunaya fi sita, o ṣalaye ajọ naa ti gbọ iroyin to n tan kalẹ lori ayelujara pe awọn ti mu oṣiṣẹ Channels Tv meji.
Rape survivor: Ìyá mi ni ń kò gbọdọ̀ sọ̀rs kí ilé má bà á dàrú- Oluwatobi Raji
''Irọ funfun balau ni eleyii, o ṣi le ṣi awọn eeyan lọna.
Ẹyin ti ẹ n gbe iroyin ayederu kaakiri, ẹ jawọ lapọn ti ko yọ,'' Afunanya lo sọ bẹẹ.
Senato francis Fadahunsi: Ká ni wọ́n fún Buhari ladún mẹ́wàá sẹ́ypin ní, bóyá kò bá rí i ṣ
Bathel Baptist Hisgh School: Àwọn akẹ́kọ̀ọ́ 32 lára àwọn tó le ní ọgọ́rùn tí wọ́n jí gbé ti gba òmìnira
Oríṣun àwòrán, dailytrust
Mejilelọgbọn lara awọn akẹkọọ ile ẹkọ girama Bethel Baptist High School ti awọn agbebọn gbe salọ nile nipinlẹ Kaduna, ti gba ominira.Wo iye ìgbà tí wọ́n ti jí akẹ́kọ̀ọ́ gbé ní Nàìjíiríà
Ibẹrẹ oṣu Keje, ọdun 2021, ni wọn ji awọn akẹkọọ naa, to le ni ọgọrun,  gbe nile ẹkọ wọn.
Ẹnikan lara awọn olori agbegbe naa sọ fun BBC pe wọn tu awọn ọmọ naa silẹ lẹyin ti wọn san owo fun awọn ajinigbe naa.
Diẹ lara wọn si ti gba ominira ni ọsẹ diẹ sẹyin, ṣugbọn igbagbọ wa pe akẹkọọ to to ọgbọn ṣi wa ni ahamọ.
Ikede tuntun yii waye lẹyin wakati diẹ ti awọn akẹkọọ to le ni ọgọrun, ile Keu ati ile ẹkọ giga imọ eto ọgbin, gba ominira lọwọ ajinigbe.
Awọn amoye gbagbọ pe owo ti awọn eeyan n san fun awọn ajinigbe lo tubọ mu ki ijinigbe o pọ si.
Thyroid foundation: eéwo ni mo kọ́ka pè é àṣé gẹ̀gẹ̀ ọrùn tó lé ẹbí, ará àti ọ̀rẹ́ ni mo n
Awọn akẹkọọ ile ẹkọ Islamiya to wa niluu Tegina ni ipinlẹ Niger ti gba ominira bayii.
Akẹkọọ mẹrinlogoje lawọn janduku ajinigbe pawo ọhun gbe lọ nile ẹkọ naa.
Mẹẹdogun ninu wọn moribọ lakata awọn ajinigbe loṣu kẹfa, niga ti mẹfa ku sinu igbo.
Owo itusilẹ to le ni miliọnu mọkanlelọgọta naira lawọn janduku ajinigbe pawo ọhun gba ki wọn to fi awọn akẹkọọ naa silẹ.
Awọn obi atawọn alaṣẹ ile ẹkọ naa lo jọ wa owo yii.
Test your Yoruba language skill: Wá ká jọ sọ Yorùbá...
Koda awọn alaṣẹ ile ẹkọ naa ni lati ta lara ilẹ ile ẹkọ ọhun nigba tawọn obi ta dukia wọn lati wa owo san fawọn janduku ajinigbe yii.
Awọn oṣiṣẹ ile ẹkọ naa tun fikun pe awọn ajinigbe tun gba alupupu yatọ si owo ti wọn gba.
Senato francis Fadahunsi: Ká ni wọ́n fún Buhari ladún mẹ́wàá sẹ́ypin ní, bóyá kò bá rí i ṣ
Oru ni wọn fi bọọsi ko awọn ọmọ naa gba ọna inu to wa lẹgbẹ ile ẹkọ wọn lọ.
Ọga ile ẹkọ naa, Abubakar Alhassan sọ fun BBC pe awọn akẹkọọ to bọ lọwọ awọn ajinigbe yii nilo itọju.
Ondo Jos clash: Èmi nìkan ló padà dé nínú àwa márùn ún tí a jọ lọ ìpàdé àdúrà ní Jos- Bell
Alhassan ni o ti rẹ awọn akẹkọọ naa, eyi gan an lo jọ ki wọn gbe wọn lọ si iloe iwosan fun ayẹwo ki wọn to lanfaani lati lọ si ile wọn.
Awọn obi ko le duro mọ lati ri awọn ọmọ wọn pada lẹyin ti wọn ti wa ninu igbo fun oṣu mẹta pẹlu awọn janduku ajinigbe.
O ti le lẹgbẹrun kan akẹkọọ ti wọn jigbe lawọn ile ẹkọ lati oṣu kejila ọdun 2020 si asiko yii.
Ọpọ ninu wọn lo si ti gbominira lẹyin tawọn ajinigbe gba owo itusilẹ.
Nítorí kí aafa lè máa rí iṣẹ́ ṣe ní wọ́n kò ṣe kó Alumaajiri nílẹ̀ tó fi di ohun tó dà yìí
Nigeria's debt: Ìjọba Buhari fi N2.02tn san èlé orí gbèsè láàrin oṣù mẹ́fà
Oríṣun àwòrán, Facebook/Bashir Ahmad
Pekele pekele, arugbo jẹ gbese ta ni o san an.
Ọrọ gbese ti Naijiria jẹ to doju rẹ bayii o. Oludamọran ọga agba ọfiisi eto iṣuna, Alfred Okon lo ja gudugbẹ ọrọ lulẹ nigba to sọ pe owo to le ni tiriliọnu meji naira ni Naijiria fi san ele ori gbese to jẹ
Okon ṣalaye pe ijọba Naijiria san obiti biti owo yii lati oṣu kinni si ikẹfa ọdun 2021.
Ohun to n wa kọ ọpọ onimọ iṣiro owo ninu ni pe owo ohun le ni ida aadọrun ninu ọgọrun owo to wọle fun si apo jọba laarin oṣu mẹfa yii.
O ṣalaye pe N2.23tn ni gbogbo owo to wọlẹ si apo ijọba laarin oṣu kinni ọdun 2021 si oṣu kẹfa eleyii ti ijọba lo 2.02 ninu rẹ lati san ele gbese.
Test your Yoruba language skill: Wá ká jọ sọ Yorùbá...
Ọgbẹni Okon ṣalaye siwaju sii pe N1.3tn ni ijọba gbe jade fun akanṣe iṣẹ lati ibẹrẹ ọdun to fi di oṣu kẹjọ yii.
Ninu ọrọ tiẹ, ọga agba lọfiisi eto iṣuna, Ben Akabueze sọ pe ijọba yoo tete ṣiṣẹ lori eto iṣuna ọdun 2022.
Ondo Jos clash: Èmi nìkan ló padà dé nínú àwa márùn ún tí a jọ lọ ìpàdé àdúrà ní Jos- Bell
Ọgbẹni Akabueze ṣalaye pe gbogbo awọn ẹka ijọba ti ọrọ eto iṣuna kan ti bẹrẹ iṣẹ lori rẹ.
O ni ko ni pẹ rara ti ijọba apapọ yoo fi gbe aba iṣuna lọ siwaju ile aṣofin niluu lati buwọlu u.
Akabueze ni eto iṣuna 2022 wa ni ibamu pẹlu eto ti ijọba apapọ n ṣe kaakiri orilẹede Naijiria.
Rachel Oniga burial: Wo bi ètò ìsìnkú gbajúgbajà òṣèré, Rachael Oniga ṣe lọ
Wọn ti sin oku agba oṣere, Rachael Oniga loni ọjọ Ẹti.
Awọn ọrẹ, ẹbi ati akẹẹgbẹ rẹ lo peju-pesẹ si adugbo Magodo, nipinlẹ Eko, nibi ti eto isinku naa ti waye.
Ọjọ Aje ni ayẹyẹ isin idagbere ti bẹrẹ fun oṣerebinrin naa, pẹlu eto idanilẹkọọ.
Bakan naa, ni Ọjọbọ, ọjọ kẹrindinlọgbọn, oṣu Kẹjọ, ni eto isin orin kikọ waye ni ile ijọsin Aguda, Catholic Church of Resurrection, Magodo, Phase 2.
Ọjọ Ẹti ni wọn tẹ ni itẹ ẹyẹ ni ile ijọsin naa, nibi ti eto isinku ti waye.
Gẹgẹ bi ikede ti ẹbi oloogbe fi sita, awọn ọmọ ati ẹbi nikan ni wọn gba laaye nibi eto isinku naa.
Diẹ niyi lara awọn aworan nibi eto isinku naa:
Nigeria debt profile: Níbi tí ìjọba àpapọ̀ ń bọ́rọ́ lọ àfàìmọ̀ káwọn tí Nàìjíríà jẹ ní gbèsè ó má fi ṣọfà, Atiku Abubakar ṣèkìlọ̀
Oríṣun àwòrán, other
Igbakeji aarẹ orilẹede Naijiria tẹlẹ, Alhaji Abubakar Atiku ti ke si ijọba apapọ pe ẹsọ-ẹsọ ni ko ṣe lori amojuto iṣuna orilẹ-ede Naijiria lọna ati le e di ọjọ ọla awọn iran ti n bọ mu daadaa.Ìjọba Buhari fi N2.02tn san èlé orí gbèsè nínú N2.23tn tó wọlé sápò ìjọba lóṣù mẹ́fà
"Ninu atẹjade kan to fi sita lọjọ Ẹti, eyi to pe akọle rẹ ni ""A ko gbọdọ jẹ ki gbese mu Naijria nitori awọn iran to n bọ"" ni Alhaji Atiku Abubakar ti sọ eyi."
O ni loṣu kẹfa, ọdun 2020 loun ti n pariwo soke lori bi gbese ṣe n fi ojoojumọ pọ si lọrun orilẹede Naijiria leyi to le e de ikorita koyeni mọ laipẹ.
Atiku ni nigba to tilẹ ti wa di eyi ti orilẹede Naijiria n fi ida aadọrun owo to n pawọle san gbese bayii, o fihan pe nnkan ko rọgbọ mọ ni o.
O ni ikilọ ti oun ṣe nigba naa ko lọwọ oṣelu tabi ohunkohun ninu bikoṣe gẹgẹ bi ọms orilẹede rere lati ta awọn alaṣẹ iṣuna Naijiria leti pe Naijiria ko gbọdọ wọ ọgbun gbese.
Senato francis Fadahunsi: Ká ni wọ́n fún Buhari ladún mẹ́wàá sẹ́ypin ní, bóyá kò bá rí i ṣ
Lọwọ ti a n ba lọ yii, orilẹede Naijiria ti n gbe ẹnu le pepele ti owo apawọle rẹ gan ko ni ka gbese sisan ọhun gan mọ. Eyi to tumọ si pe awọn taa jẹ ni gbese gan lee fẹ fiwa ṣọfa tọrọ ba kan karangida.
Babatunde Gbadamosi: Mo ta gbogbo dúkìá mi lásìkò kan kí ń tó padà di eèyàn lónìí
O ni bi a ko ba gbagbe, ni Ọjọbọ, ọjọ kẹrindinlọgbọn, oṣu kẹjọ, ọdun 2021 ni ileeṣẹ to n mojuto aba iṣuna orilẹede Naijiria gbe atẹjade kan sita pe triliọnu meji o le igba ati ọgbọn biliọnu naira (N2.23 Trilion) ni Naijiria pa wọle laarin oṣu mẹfa akọkọ ọdun 2021, ati pe triliọnu meji o le igba miliọnu naira (N2.02 Trillion) ninu rẹ ni wọn fi san gbese.
Nítorí kí aafa lè máa rí iṣẹ́ ṣe ní wọ́n kò ṣe kó Alumaajiri nílẹ̀ tó fi di ohun tó dà yìí
Sunday Igboho: Ọ̀jọ̀gbọ́n Wole Soyinka ní kí Benin Republic ó fi Sunday Igboho sílẹ̀ kó máa bá ìrìnàjò rẹ̀ lọ
Oríṣun àwòrán, other
Ogbontagi onkọwe, Ọjọgbọn Wọle Soyinka ti ke si awọn alaṣẹ ijọba orilẹede Benini Republic pe ki wọn tu eekan aṣiwaju ipe fun idasilẹ orilẹede Yoruba, Oloye Sunday Adeyẹmọ ti ọpọ mọ si Sunday Igboho silẹ.
Ọjọgbọn Soyinka ṣalaye nibi ifọrọwerọ kan to ṣe pẹlu awọn akọroyin ni ọjọ Ẹti.
Soyinka ni ẹṣẹ kan ti ijọba Naijiria lee ri ka si Sunday Igboho lẹsẹ ni pe o n ja fun awọn eeyan rẹ lati dojukọ wahala awọn darandaran fulani kan to ti sọ ara wọn di ariigbọdọ wi ikun imu baale lori awọn eeyan rẹ ni ipinlẹ Ọyọ.
Ọjọgbọn Soyinka ni oun ko gbagbọ pe Igboho ṣẹ ẹṣẹ kankan ju wi pe o sọrọsoke lori iwa aitọ tawọn kan n hu si awọn eeyan rẹ. Ọjọgbọn naa ṣalaye pe ni toun o, ọna alaafia ni Igboho gba pe ipe rẹ ti ẹnikẹni ko si lee tọka si pe o jẹ iwa ọdaran rara.
Rape survivor: Ìyá mi ni ń kò gbọdọ̀ sọ̀rs kí ilé má bà á dàrú- Oluwatobi Raji
"Oluwole ọmọ Soyinka ni: ""Nigba ti ijọba atawọn ileeṣẹ alaabo kọlu ile Igboho lọganjọ oru, ti wọn pa eeyan rẹ meji ti wọn si tun n pariwo laisi iwe aṣẹ ayẹwo lori ile rẹ pe awọn ba ohun ija oloro nibẹ...ta ni yoo gba itan ijapa ati ọbọ bẹẹ gbọ?"""
Senato francis Fadahunsi: Ká ni wọ́n fún Buhari ladún mẹ́wàá sẹ́ypin ní, bóyá kò bá rí i ṣ
Bakan naa lo tun bi awọn alaṣẹ ijọba orilẹede Benin Republic leere idi ti wọn fi n fi Igboho si atimọle dipo ki wọn fi silẹ ko maa ba irinajo rẹ lọ.
Nítorí kí aafa lè máa rí iṣẹ́ ṣe ní wọ́n kò ṣe kó Alumaajiri nílẹ̀ tó fi di ohun tó dà yìí
Baba Iyetade ni ko si ohun to tako iwe ofin orilẹede Naijiria ninu ki eeyan pe fun idasilẹ orilẹede niwọn igba to jẹ pe ọna alaafia lo gba n ṣe e labẹ ofin.
Test your Yoruba language skill: Wá ká jọ sọ Yorùbá...
Ghana Cathederal project: Ìmáàmù àgbà orílẹ̀èdè Ghana gbé owó kalẹ̀ fún kíkọ́ Ṣọ́ọ̀ṣì
Oríṣun àwòrán, AFP
Imaamu agba lorilẹede Ghana, Sheikh Osmanu Nuhu Sharubutu ti gbe owo to le ni ẹgbẹrun mẹjọ dọla kalẹ lati ṣe atilẹyin fun kikọ ijọ nla kristẹni kan lorilẹede naa.
Sheikh Sharubutu kede ẹdawo naa lasiko ti awọn igbimọ majẹobajẹ ti wọn gbe kalẹ fun kikọ ṣọọṣi nla naa bẹẹ wo ni ọfiisi rẹ.
O ni igbesẹ naa ko yẹ lẹyin lilọ igi ifẹ laarin awọn ẹlẹsin gbogbo nibẹ ni alẹye
Bi o tilẹ jẹ pe Orilẹede Ghana wa lara awọn orilẹede ti alaafia ti n jọba laarin awọn ẹlẹsin gbogbo lagbaye sibẹ ẹgbẹrun mẹjọ dọla ti Imaamu agba naa da fun kikọ ṣọọṣi naa jẹ eyi to ya ọpọlọpọ lẹnu.
Oba Ogboni Abalaye n fẹ́ kí wọ́n o má a fi ẹ̀sìn àbáláyé búra fún àwọn olóṣèlé Naijiria
Ṣọọṣi apapọ naa ti n fa ọpọlọpọ awuyewuye lorilẹede naa lẹyin ti ijọba orilẹede ọhun gbe aba gbigbe igbimọ ikowojọ naa dide lati ṣe koriya fawọn ọmọ orilẹede Ghana  lati lee dawo fun kikọ ṣọọṣi naa si ilu Accra tii ṣe olu ilu orilẹede naa.
Thyroid foundation: eéwo ni mo kọ́ka pè é àṣé gẹ̀gẹ̀ ọrùn tó lé ẹbí, ará àti ọ̀rẹ́ ni mo n
Ile ijọsin ọhun yoo na wọn ni owo to le ni ọgọrun miliọnu dọla.
Bakan naa ni wọn fi idi rẹ mulẹ pe kiko owo rẹ jọ ko ni lọwọ ijọba ninu.
Ọpọ lo ti kọminu lori kikọ ṣọọṣi naa eleyi ti wọn ni ko tọ lasiko ti ọrọ aje dagun lorilẹede naa.
Ohun ti Yorùbá ń pè ní Èṣù yàtọ̀ sí Sátánì nítorí Èṣù ní iṣẹ́ rere lọ́wọ́
Myrtle Corbin: Obìnrin tó ló àìdàpé ara rẹ̀, sọ ara rẹ̀ di olówó
Oríṣun àwòrán, Wikipedia
Yoruba ni ẹni ti yoo ga, ẹsẹ rẹ yoo tiirin, bẹẹ si ni tibi tire la dale aye, tibi tire la se ẹda eeyan, bi ire se wa ninu ibi, naa ni ibi wa ninu ire.
Bi ọrọ igbe aye arabinrin kan se ri ree, ẹni ti o ni aidape ara amọ ti ọba oke se e ni ogo pẹlu aidape ara naa.
Eyi si lo fidi rẹ mulẹ pe agbara wa ninu aidape ara, ta ba si lero pe Oluwa n se ibi, ase rere lo n se.
Arabinrin naa, Josephine Myrtle Corbin, lo ni ẹsẹ mẹrin, ile ọmọ meji, oju ara meji amọ ti ọba oke tun fun ni agbara lati bi ọmọ mẹjọ nile aye.
Gẹgẹ ba se ka loju opo Wikipedia, asise atọrunwa waye lasiko ti wọn loyun arabinrin naa, eyi to fa aidape ara fun.
Thyroid foundation: eéwo ni mo kọ́ka pè é àṣé gẹ̀gẹ̀ ọrùn tó lé ẹbí, ará àti ọ̀rẹ́ ni mo n
Bi igbe aye rẹ si se lọ ree eyi to yẹ ka fi se arikọgbọn.
Igba iloyun ati ibẹrẹ aye Myrtle Corbin:
Orukọ baba Myrtle Cobin ni William H. Corbin, tii se ẹni ọdun mẹẹdọgbọn nigba to fun aya rẹ, Nancy Corbin, ẹni ọdun mẹrinlelọgbọn loyun.
Agbegbe Lincoln County, nilu Tennessee lorilẹede Amẹrika ni awọn obi Myrtle Corbin n gbe lakoko ti wọn loyun rẹ.
Lọjọ ti ọmọ tuntun naa de ile aye ni ọjọ Karun, osu Kejila ọdun 1868, ni wọn ri pe ibeji lo fẹ wa saye amọ ti ikeji rẹ ko lagbara lati di odidi eeyan, to si jẹ aabọ ẹda to so mọ ekeji rẹ lara.
Ẹsẹ mejeeji to yẹ ko jẹ ti ekeji rẹ ti ko pe odidi ẹda, ni Myrtle Corbin papọ, ti ẹsẹ rẹ fi di mẹrin, to fi mọ ile ọmọ ati oju ara ekeji rẹ lo dapọ mọ tiẹ, to fi di meji-meji fun.
Nigba ti wọn bi Myrtle Corbin pẹlu abuku ara yii, ẹnu ya awọn dokita, ti wọn si ri pe o dabu sinu iya rẹ ni, amọ wọn yi ipo to wa pada, to fi rọrun lati bii, bibẹẹ kọ ọrun ni aala fun tiya-tọmọ.
Nigba ti wọn bi ọmọ yii, ko tii si isẹ abẹ rara lasiko naa lati gba ẹbi alaboyun tabi fi ya ibeji to lẹpọ.
Idi ree ti isẹda Myrtle Corbin fi se ara ọtọ lasiko ti wọn bi, ti ko si si ireti fun lati gbe ile aye.
Amọ riro ni ti eniyan, sise ni ti Ọlọrun, ọmọ naa n dagba, eegun rẹ si n le bii ti ọmọ to dape, bẹẹ lo n dagba ni ẹmi ati ni ọpọlọ.
Oríṣun àwòrán, Science Interest
Bawo lo se rọrun fun Myrtle Corbin lati gbe ile aye?
Awọn dokita si ri pe lati ibi ibadi ni ẹsẹ ikeji Myrtle Corbin ti so pọ mọ tiẹ, to si ni ara meji lati ibadi wa si isalẹ, eyi to mu ko tun ni oju ara ati ile ọmọ meji pẹlu.
Amọ o rọrun fun obinrin naa lati se akoso ẹsẹ ekeji rẹ naa, nitori ko gun to awọn ẹsẹ tiẹ mejeejiy, eyi to mu ko ma subu lasiko to ba n fi n rin.
Idi ni pe awọn ẹsẹ mejeeji ekeji rẹ naa lo wa ni aarin, ti wọn ko si ni agbara ra tabi ni imi ninu, ti ko si se fi rin rara.
Bakan naa, ọmọ ika ẹsẹ mẹta pere lo wa lara ẹsẹ ekeji rẹ naa.
Awọn ara ti Myrtle Corbin fi abuku ara rẹ da, to sọ di olowo:
Arẹwa pọnbele ni Myrtle Corbin, ti ọba oke si fi ẹwa jinki rẹ lai naani abuku ara yii.
Koda, obinrin giga ni, iwọn giga rẹ si jẹ ẹsẹ bata marun, o mọ lawọ, o ni ọpọlọpọ irun lori, to si tun ni oju buluu.
Nigba to di ẹni ọdun mẹtala, okiki obinrin naa ti kan yika agbaye nipa ọna to n gba mura, eyi to ya ni lẹnu pupọ.
Baba obinrin yii lo kọkọ ronu nipa ọna ti yoo fi wulo, to si bẹrẹ si patẹ rẹ ni awọn gbọngan sinima, ti ọpọ eeyan si n ya wa fi owo ribiribi wo akanda ẹda obinrin ẹlẹsẹ mẹrin naa.
Se ni Myrtle Corbin si n lo abuku ara rẹ lati fi pa owo nipa imura rẹ. Yoo si wọ awọn ọmọ ika ẹsẹ rẹ ti ko dape naa ni asọ ti oyinbo n pe ni socks.
Bakan naa ni yoo wọ bata fun awọn ẹsẹ ekeji rẹ to wa ni aarin ẹsẹ tiẹ, bi o tilẹ jẹ pe kii fi awọn ẹsẹ naa rin.
Nigba to ya, awọn eeyan to jẹ gbajumọ ninu isẹ amuludun bii P.T Barnum, Ringling bros ati Coney Island n ba Myrtle dowo pọ, ti wọn si n gbe isẹ afihan ara rẹ to n se larugẹ.
Okiki Myrtle Corbin si tan debi pe o n pa owo to to ọtalenirinwo o din mẹwa dọla ($450) ni ọsẹ kan, eyi to jẹ owo nla nigba naa.
Rape survivor: Ìyá mi ni ń kò gbọdọ̀ sọ̀rs kí ilé má bà á dàrú- Oluwatobi Raji
Nigba to pe ẹni ọdun mọkandinlogun, Myrtle Corbin se igbeyawo pẹlu James Clinton Bicknell, ẹni to pọn ni dandan fun aya rẹ lati mase patẹ aidape ara rẹ fun aye mọ.
Awọn mejeeji bẹrẹ isẹ oko dida ti ọkọ rẹ n se tẹlẹ, eyi to fihan pe ifẹ tootọ ni James ni si Myrtle, kii si se tori owo ti obinrin naa ni, lo se fẹ.
Amọ lẹyin igbeyawo wọn ni ọkọ rẹ ri pe oju ara meji ni Myrtle ni, ti oju ara keji si jẹ ti ibeji rẹ, eyi to mu ki obinrin naa jẹ obinrin kan soso lagbaye ti yoo ni oju ara meji.
Bakan naa, nigba to loyun ni asiri tu sọwọ awọn dokita pe ile ọmọ meji naa tun ni obinrin aramọnda yii ni, to si fi ile ọmọ apa osi loyun.
Lẹyin o rẹyin, ọmọ mẹjọ ni Myrtle Cobin bi sile aye amọ mẹta pere lo gbẹyin rẹ.
Nigba to di ọdun 1928, ti Myrtle Corbin pe ẹni ọgọta ọdun ni aisan ara kan kọlu u, eyi to ba awọ rẹ jẹ, ti ko si gbọ wiwo.
Lasiko yii, ko tii si iwosan fun arun ara naa ti wọn n pe ni Erysipelas, a streptococcal skin infection, amọ lode toni, horo oogun diẹ ti to lati wo aisan naa.
Nigba to di ọjọ Kẹfa, osu Karun ọdun 1928, Josephine Myrtle Corbin-Bicknell jade laye nilu Cleburne nipinlẹ Texas, eyi to fi opin si igbe aye obinrin kan soso to ni ẹsẹ mẹrin.
Se ni awọn mọlẹbi rẹ si n sọ oku ati posi rẹ lọwọ-lẹsẹ, ki awọn adigunjale maa baa ji gbe salọ.
Koda, awọn onisẹ iwadii, afi nnkan isẹmbaye pamọ atawọn onisegun oyinbo gan gbe owo kalẹ lati gba oku rẹ amọ awọn mọlẹbi rẹ taku, ti wọn si tubọ n sọ oku rẹ.
Oríṣun àwòrán, Screen Shot
Ẹkọ akọkọ ti itan aye Myrtle Corbin kọ wa ni pe ka ma jẹ ki aidape tabi abuku ara di wa lọwọ lati mase gbe ohun rere se nile aye.
Ẹkọ keji ni pe igbe aye Myrtle Corbin kọ wa lati mase jẹ ki ipo ta n la kọja se akoso aye wa nitori igba ko tọ lọ bii orere, aye ko tọ lọ bi ọpa ibọn.
Myrtle Corbin jẹ alabuku ara amọ eyi ko ni ko ma de ibi giga nile aye , o ni ẹkunrẹrẹ ayọ ati ohun amuyangan, eyi to yẹ ki awa naa fi se awokọse rere.
Lakotan, igbe aye Myrtle Corbin kọ wa lati ni ifarada, ipamọra ati ifiraẹnijin ni ipokupo ti a ba wa nitori ohun gbogbo lo n sisẹ pọ fun rere.
Grazing Researves: NINAS fọnmú pé ìfẹ̀hónú hàn tó kò ṣẹlẹ̀ rí ń bọ̀ lórí gbígba ilẹ̀ fún ìdaranjẹ̀ lẹ́kùn gúúsù
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Yoruba ni awifunni ko to da ni, agba ijakadi ni, bẹẹ si ni ogun awitẹlẹ kii pa arọ.
Idi ree ti ẹgbẹ to n polongo fun idasilẹ orilẹede Yoruba atawọn ẹlẹgbẹjẹgbẹ ajijagbara miran lẹkun guusu Naijiria fi n ke tantan lori ofin idaranjẹ tuntun ti ijọba fẹ gbe jade.
Awọn ẹgbẹ ajijagbara ni guusu Naijiria naa, ti wọn wa labẹ aburada Nigeria Indigenous Nationalities Alliance for Self Determination (NINAS) ti wa fi atẹjade kan sita lori ofin idaranjẹ naa.
Lara awọn ẹlẹgbẹjẹgbẹ to si wa labẹ aburada ẹgbẹ NINAS naa ni ẹgbẹ Ilana Omo Oodua atawọn ẹgbẹ miran lati ẹkun ila oorun ati aarin gbungbun guusu Naijiria to fi mọ Middle Belt.
Ninu atẹjade naa si ni NINAS ti n leri leka pe gomina to ba fi ilẹ awọn silẹ lẹkun guunsu Naijiria fun eto idaranjẹ ti ijọba apapọ n gbero fawọn Fulani yoo ri ibinu araalu.
Joke Silva: Olu, ó tó gẹ́ pẹ̀lú obìnrin yìí níkan tó ń ba ẹ ṣeré ìfẹ́ nínú sinimá
Ẹgbẹ NINAS ni iwọde ati ifẹhonu han araalu ti ko tii waye ri, ni iru gomina to ba gbe ilẹ rẹ kalẹ yoo foju wina rẹ, lawọn ipinlẹ to wa lẹkun guusu Naijiria.
NINAS, ti alagba Banji Akitoye jẹ alaga fun, ti Tony Nnadi si jẹ akọwe apapọ rẹ, lo ti wa n fi ewe ọmọ mọ awọn gomina ipinlẹ to wa labẹ aburada ẹgbẹ naa leti pe ki wọn tete gbọran.
Bakan naa ni wọn n dunkoko pe gomina to ba fi ẹsẹ bata ilẹ kan silẹ fun ijọba apapọ lati gbe kalẹ fun Fulani, yoo fi ika hanu nigbẹyin ni.
"A wa n rọ awọn gomina wa lati bọwọ fun ero araalu lori igbesẹ yiya ibudo kan sọtọ fun eto idaranjẹ Fulani eyi ti ijọba apapọ se.
A ko dunkoko mọ yin, amọ a n rọ yin ni pe gomina to ba gbe ilẹ wa silẹ feto idaranjẹ Fulani gbọdọ setan lati foju wina ibinu araalu to lagbara.
Thyroid foundation: eéwo ni mo kọ́ka pè é àṣé gẹ̀gẹ̀ ọrùn tó lé ẹbí, ará àti ọ̀rẹ́ ni mo n
Niwọn igba to jẹ pe ọpọ awọn Fulani darndaran yii ni wọn lo wa lati awọn orilẹede to mule ti Naijiria, gomina to ba wa gbe ilẹ ajogunba wa fawọn ajeji ni iwọde yoo da ipinlẹ rẹ wo de ipilẹ."
Bẹẹ ba gbagbe, ijọba apapọ lo ti fi ontẹ lu ofin kan to n fa awuyewuye eyi to se agbeyẹwo agbekalẹ ibudo idaranjẹ ọrinlelọọdunrun o din meji lawọn ipinlẹ mẹẹdọgbọn yika Naijiria.
Ọjọ Kọkandinlogun osu Kẹjọ ọọdun 2021 si ni ofin naa di bibuwọlu lati ọdọ aarẹ Muhammadu Buhari.
Victor Uwaifo: Èèkàn amúlúdùn méjì, Sir Victor Uwaifo àti Victor Olaotan jáde láyé
Oríṣun àwòrán, other
Agba akọrin, Sir Victor Uwaifo ti jade laye lẹni ọgọrin ọdun lọjọ Satide, ọjọ kejidinlọgbọn oṣu kẹjọ ọdun 2021.
Ọjọgbọn ninu iṣẹ orin naa jẹ gbajumọ kaakiri agbaye pẹlu gẹgẹ bi ogbontagi onigita ara ati fere fifọn.
Omilẹgbẹ ami ẹyẹ ni Sir Victor Uwaifo gba nigba aye rẹ nilẹ yii ati loke okun.
Awọn orin rẹ bii 'Mami water', 'Joromi', ati 'Guitarboy', kun ara awọn awo orin rẹ to gbajumọ julọ kari aye.
Bakan naa ni Sir Vitor Uwaifo jẹ akọrin akọkọ ti yoo gba ami ẹyẹ Member of the Order of Niger, MON ti ijọba apapọ orilẹede Naijiria.
Ni bayii oniruuru awọn eekan lagbaye ni wọn ti n daro rẹ.
Aarẹ Buhari ninu ọrọ idaro rẹ ni gbogbo orilẹede Naijiria ni yoo ṣafẹri Sir Victor Uwaifo gẹgẹ bi ẹni to fi ipa manigbagbe lele ni gbogbo ọna ẹda titi kan ẹka ẹkọ ati iṣakoso.
Nítorí kí aafa lè máa rí iṣẹ́ ṣe ní wọ́n kò ṣe kó Alumaajiri nílẹ̀ tó fi di ohun tó dà yìí
Ẹwẹ, Eekan elere itage, Victor Ọlaotan naa jade laye lẹni ọdun mọkandinlaadọrin.
Ọlaotan gbajumọ pupọ fun ipa to ko ninu ere ọlọsọọsẹ ni Tinsel.
Ọdun marun un ni ijamba ọkọ kan to ni, fi daa wolẹ ko to jade laye.
Ibudo yiya sinima agbelewo kan lo n lọ lọdun 2016, nigba to fi kagbako ijamba ọkọ naa.
"Iyawo rẹ, arabinrin Julia Ọlaotan to kede iku rẹ, wa dupẹ pupọ fun igbe aye rẹ, to si ni ko rọrun ki eeyan wa loju kan naa fun ọdun marun un. ""asiko to fun un lati lọ sinmi bayii"""
"Ninu ọrọ idaro to kọ nipa Victor Olaotan, gbajumọ elere tiata ni, Richard Mofe-Damijọ (RMD) ni bi o ti wu oun to, pe ki awọn olufẹ wa mase jade laye, paapaajulọ awọn elere itage, ""sibẹ iranti wọn ko ni parẹ kuro lọkan wa."""
Yoruba Nation: Mo faramọ́ àtúntò 'Restructuring' tí kò lọ́wọ́ ìṣèlú nínú- Oba Ahmed Adeku
Baba Ijesha case: Amofin Ogala ṣàlàyé bó ṣe di agbẹjọ́rò fún Baba Ijesha
Oríṣun àwòrán, other
Agba amofin to n duro fun gbajumọ oṣere tiata, Ọlanrewaju James Omiyinka, ti ọpọ mọ si Baba Ijesha, Amofin agba Babatunde Ogala SAN, ti sọ idi to fi n gbẹjọ ro fun Baba Ijesha.
Ninu ifọrọwerọ kan pẹlu iwe iroyin The Punch, Amofin Babatunde Ogala ṣalaye pe ko si ohun kan to jẹ koriya fun oun lati duro fun Baba Ijesha ju wi pe wọn fi ẹjọ rẹ lọ oun oun si tẹwọgba.
Amọfin agba naa ṣalaye siwaju sii pe niwaju ofin ko si ipo, bakan naa lọrọ si jẹ niwaju oun pẹlu.
O ni ofin nikan loun mọ, nigba ti wọn gbe ẹjọ naa tọ oun wa, oun woo daradara ti oun si rii pe awọn ọna kan wa ti a fi lee ti ipasẹ ẹjọ naa mu ilanilọyẹ jade lori ofin.
yyyy
Ni oṣu kẹrin ọdun 2021 ni iroyin jade pe Baba Ijẹsha lọwọ ninu aṣemaṣe kan pẹlu ọmọdebinrin kan.
Lẹyin asiko diẹ ni ahamọ ọlọpaa ni wọn gbe lọ si ileẹjọ to si n jẹjọ bayii niwaju Onidajọ Oluwatoyin Taiwo nile ẹjọ giga kan ni ilu Eko.
Wọn si ti sun igbẹjọ rẹ si ọjọ kẹtadinlọgbọn oṣu kẹsan ọdun 2021.
Nigeria Insecurity: Àwọn ọdọ́ Arewa ké sáwọn aṣáájú láti pe ìpàdé àjọ tó ńi ìrònú lórí Nàíjíríà
Oríṣun àwòrán, other
Ipe kan ti lọ sọdọ awọn adari orilẹede Naijiria pe ki wọn dide giri lati daabo bo orilẹede Naijiria, ki o ma baa dawo.
Ẹgbẹ awọn ọdọ kan lapa oke ọya NYLF ṣalaye pe ki awọn aṣiwaju wọnyii wa ọna lati pe ipade ironu laarin ara wọn, ki wọn lee wa ojutu si isoro to nkoju orilẹede Naijiria.
Bakan naa lẹgbẹ NYLF ke si Aarẹ tẹlẹ, Oluṣẹgun Ọbasanjọ, olori ijọba ologun tẹlẹ, Ibrahim Babangida ni wọn ni ko ṣaaju ijiroro naa.
Ẹgbẹ awọn ọdọ apa oke ọya naa tun rọ awọn eekan bii Theophilous Danjuma, Abdulsalami Abubakar, Oloye Earnest Sonẹkan atawọn miran, lati ko ipa to jọju ninu irufẹ apero bẹẹ. lọna ati koju ipenija to n koju orilẹede Naijiria.
Alaga apapọ ẹgbẹ naa, Elliot Afiyo ṣalaye nilu Abẹokuta, lẹyin ifikuluku pẹlu oloye Ọbasanjọ pe kii ṣe iroyin tuntun mọ pe ijinigbe ati ọrọ aje to dagun, n da Naijiria laamu.
Senato francis Fadahunsi: Ká ni wọ́n fún Buhari ladún mẹ́wàá sẹ́ypin ní, bóyá kò bá rí i ṣ
Bakan naa lo ni ijẹkujẹ, ipe fun ipinya wa lara awọn ipenija to n koju Naijiria lọwọ, eyi lo si mu ko di ọranyan fawọn olori wọnyii lati dide wa ọna abayọ si awọn ipenija naa.
Ẹgbẹ naa ni ododo ọrọ to koro ni pe, ẹgbẹ oṣelu APC to n ṣe ijọba ko ni ipinnu ati eroja oṣelu to yẹ lati koju ọpọ ipenija to n ba Naijiria finra, bakan naa lo fi kun un pe ẹgbẹ oṣelu PDP pẹlu ni iṣoro dukuu laarin ara wọn, leyi to fẹ ki oloye Ọbasanjọ ba wọn da si.
Ẹgbẹ naa ni awọn wa lara awọn ẹgbẹ to fọnrere ibo fun aarẹ Muhammadu Buhari ki o to ja jo awọn loju pe, aṣiyan patapata ni awọn yan, ti awọn si gbọdọ gbe igbesẹ atunṣe gbogbo to ba yẹ.
Nítorí kí aafa lè máa rí iṣẹ́ ṣe ní wọ́n kò ṣe kó Alumaajiri nílẹ̀ tó fi di ohun tó dà yìí
Nigerian Doctors Crisis: Àwọn dókítà tó kúrò ní Nàíjíríà lọ sílẹ̀ UK, US àti Saudi sọ ìrírí ayọ̀ tí wọn ń ní
Oríṣun àwòrán, Screen Shot
Iya kii se omi ọbẹ, Oluwa mase jẹ ka jẹ iya nile aje.
Adura yii ni awọn dokita to kuro ni orilẹede Naijiria, kọja lọ soke okun n fi se orin kọ, lasiko ti wọn tẹwọgba owo osu wọn akọkọ nilẹ okeere.
Kaakiri awọn orilẹede bii Saudi Arabia, United Kindom ati Amẹrika si ni awọn dokita lati orilẹede Naijiria fọn si nitori iya to n jẹ wọn lorilẹede Naijiria.
Awọn dokita naa, lasiko ti wọn n ba iwe iroyin Punch sọrọ salaye pe aini ohun eelo lati fi sisẹ ati owo osu tasọrẹ tawọn n gba lo mu kawọn pinnu lati gba ajo lọ sisẹ.
Bẹẹ ba si gbagbe, lọwọlọwọ bayii, awọn dokita ni Naijiria si wa lẹnu iyansẹlodi ti wọn n se tori ẹsun ailakasi ijọba si itọju wọn ati aidahun awọn ohun ti wọn n beere fun.
Lara awọn dokita naa ni bi o tilẹ jẹ pe awọn n siyemeji ki oun to wa sisẹ lorilẹede Saudi Arabia amọ awọn ro pe o san fun awọn lati wa ju ki ebi pa awọn si Naijiria lọ.
Doctors‘ Strike: Àwọn dókítà tó ń woṣẹ́ níran ní UCH sọ̀rọ̀ lórí ẹ̀dùn ọkàn wọn
"Nigba ti mo kọkọ tẹwọ gba owo osu mi ni Saudi, mo bu sẹkun ni. Ẹgbẹrun lana ọgọfa din meje nairia (N113,250) ni owo osu mi ni Naijiria, ibẹ ni maa ti bọ aya, ọmọ atawọn obi mi.
Aye le koko mọ mi, ti mo si maa n tọju ẹgbẹlẹgbẹ alaisan ki osu to pari, ti isẹ si fẹẹ yi mi lọrun lasiko naa.
Amọ Saudi Arabia ni ẹgbẹrun mẹta dọla si ẹgbẹrun mẹjọ ni oun yoo san fun mi, idi ree ti mo fi gba lati kuro nile.
Alaisan mẹrin si mẹjọ pere ni mo n tọju ni ọjọ kan soso, ti wọn si tun n fun mi ni isinmi ọjọ mẹrindinlogoji laarin ọdun kan.
Iya nla ni ijọba Naijiria fi n jẹ awọn dokita, o si yẹ ki wọn yipada, bibẹẹ kọ aimọye dokita ni yoo kuro ni Naijiria lọ soke okun, ijafara si lewu pẹlu."
Iwadi kan ti wa fidi rẹ mulẹ pe ida kan ati aabọ awọn dokita to gba idanilẹkọ ni Naijiria lo gba ilẹ UK lọ laarin osu Keje si Ikejila ọdun 2020.
Amọ ni bayii, iye wọn ti fo fẹrẹ soke si ida mẹta aabọ laarin osu Kẹrin si Ikarun ọdun 2021.
Badagry: Ojú ọ̀nà àrèmabọ̀ fáwọn ẹrú tó ń lọ sókè òkun
Afghanistan Crisis: Ikọ̀ Taliban ba òpó iná ọba jẹ́, kò sí omi mímu, ó tún ń gé ọwọ́ afurasí olè
Kangun kangun kangun, o ti wa n kangun sibi kan fun awọn eeyan orilẹede Afghanistan bayii lẹyin ti ikọ Taliban gba akoso orilẹede naa.
Nibayii, awọn araalu kan ni Herat ti sọrọ soke lori igbe aye inira ti wọn n gbe lorilẹede Afghanistan lati igba ti ikọ Taliban ti gba ijọba.
Ilu Herat yii si ni ilu to tobi sikẹta lorilẹede Afghanistan, to si jẹ ẹnu bode si orilẹede Iran.
Awọn eeyan naa, ti wọn fi fọnran ohun wọn ransẹ si BBC ni, igbe aye koba-kole naa ti n mu inira nla ba awọn pupọ.
Ọkan lara awọn eeyan naa ni, se ni oun maa n di oju oun nireti pe oorun ni oun n sun lọwọ, alakala si ni oun n la lọwọ, laipẹ si ni oun yoo si laju sile aye pada.
Oba Ogboni Abalaye n fẹ́ kí wọ́n o má a fi ẹ̀sìn àbáláyé búra fún àwọn olóṣèlé Naijiria
O ni ojoojumọ ni oun n gbọ orisirisi iroyin nipa ọsẹ ti ikọ Taliban n se, ti wọn si n fi iwa ipa bawọn araalu lo.
O salaye pe ni ẹba ile oun, oun gbọ pe ika Taliban ti ge ọwọ eeyan meji lori ẹsun pe wọn ji nnkan.
Bakan naa lo ni wọn ko gba ki awọn obinrin lọ sẹnu isẹ, bi obinrin yoo ba si jade kuro nile, ọkunrin kan gbọdọ tẹ le lẹyin.
"Obinrin kankan ko si tun gbọdọ si oju rẹ silẹ, ki ẹnikẹni ri nitori o gbọdọ wọ ibori ni.
Awọn ọkunrin gan ko gbọdọ wọ asọ Jeans ati T-Shirt amọ asọ ibilẹ orilẹede Afghanistan ni ki wọn maa wọ."
Ọkunrin miran to tun ba BBC sọrọ ni awọn ikọ Taliban yii tun ti n lọ lati ojule de ojule fun awọn eeyan lai naa ikede idarijin fun gbogbo eeyan ti wọn se.
O ni eleyi gan ti n ko irẹwẹsi ba awọn lorilẹede Afghanistan, to fi mọ oun gan alara, ti wọn si ni awọn akẹkọbinrin gbọdọ maa lo Hijab wa sileẹkọ ni.
"Saa kan pere lo ku ki n pari eto ẹks mi ni fasiti, n ko si fẹ ki wọn fi oun ontẹ orukọ tuntun orilẹede Afghanistan, eyiun Islamic Emirate of Afghanistan lu paali iwe ẹri mi.
Gbogbo ere ta ti jẹ lati ogun ọdun sẹyin lo ti wa sopin."
Ninu fọnran ohun miran, obinrin mii salaye pe nigba ti ikọ Taliban ba bẹrẹ ikọlu rẹ, ko ni si ina ọba lati lo.
O ni wọn ti ba opo ina ọba jẹ, ti ko ni si ina, bakan naa ni ko ni si omi mimnu fun awọn.
O fikun pe bi o tilẹ jẹ pe ounjẹ ati oogun to to wa nilu Herat, amọ lawọn agbegbe igberiko, ọpọ isoro lo n ba wọn finra.
"O nira fun awọn eeyan lati wa si ilu nlanla, ti wọn ko si ni oogun ati ounjẹ to to, amọ wọn ti si awọn ọna to lọ sawọn igberiko yii pada ni ọsẹ to kọja.
Ẹru ti wa n ba awọn eeyan ilu Afghanistan nipa ọjọ iwaju wọn ati ọrọ aje wọn, ti wọn si ti n ta awọn ohun eelo alona wọn bii tẹlifisan ati ẹrọ amomitutu.
Awọn owo ti wọn ba tu jọ yii ni wọn fi n rinrin ajo lọ si orilẹede Iran, Yuroope atawọn ilu ọlaju miran lagbaye."
O salaye siwaju pe iporuru ọkan nipa pe nnkan le buru si ju bayii lọ ti n ba awọn araalu, ti ọpọ wọn si n ronu bi wọn yoo se jade kuro lorilẹede naa.
People in Afghanistan’s third-largest city, Herat, explain how life has changed in recent weeks
Nigeria Insecurity: Rashidi Ladoja àtàwọn àgbà Yorùbá míì sọ òkò ọ̀rọ̀ sáwọn gómìnà Òkè Ọya tó wá bẹ̀bẹ̀
Oríṣun àwòrán, Nigerian Tribune
Agba kii wa lọja, ki ori ọmọ tuntun wọ, bẹẹ si ni agba ti ko ba kẹhun sọrọ, o di dandan ko kẹ itan sare.
Eyi lo mu ki awọn agbaagba lẹkun ariwa Naijiria to n kọminu lori ikunsinu iran Yoruba si ijọba aarẹ Buhari se bẹrẹ idirẹbẹ.
Igbesẹ naa, ni wọn lo wa lati tu ẹya Yoruba ninu, ti wọn si n tọ awọn agbaagba ilẹ Yoruba lọ lati rọ wọn pe ki wọn gba alaafia laaye.
Awọn eeyan naa, ni iwadii kan sọ pe wọn jẹ gbajumọ ninu ijọba Buhari, ti wọn si ti n lọ labẹlẹ lati wa ẹyọnu ẹya Yoruba.
Gẹgẹ bi iwe iroyin Tribune se sọ, lara awọn eekan lẹkun ariwa to n lọ kaakiri naa ni Gomina ipinlẹ Yobe, Mai Bala Buni, Abubakar Badaru ti Jigawa ati Atiku Bagudu tipinlẹ Kebbi.
Sunday Igboho: Ladoja ní bí ìjọba kò bá fi ẹ̀lẹ̀ ṣe, ọ̀pọ̀ ajìjàgbara míì yóò dìde
Iroyin naa ni laarin ọsẹ mẹta, awọn eekan ariwa naa ti lọ sile awọn agbaagba ilẹ Yoruba kan bii alagba Reuben Fasoranti ati Oloye Olu Falae.
Awọn yoku ni Oloye Rashidi Ladoja, Ayo Opadokun, Dokita Kunle Olajide ati Aarẹ Musulumi ilẹ Yoruba, Edo ati Delta, Alhaji Daud Akinola.
Lẹyin  ọpọ ipade ti wọn se nilu Ibadan Akure ati Abeokuta, awọn alejo lati ẹkun ariwa naa pẹlu awọn to gba wsn lalejo ni ko sọ ohunkohun fawọn akọroyin lori igbesẹ wọn ọhun.
Iroyin naa ni kii se pe awọn eeyan naa wa lati fa oju awọn agbaagba Yoruba mọra nitori ibo 2023, gẹgẹ bii iroyin to n lọ nigboro.
Gẹgẹ bi iwe iroyin naa se sọ, Ladoja lasiko ipade naa bu ẹnu atẹ lu ipo ti orilẹede yii wa labẹ isejọba Buhari ati iyansipo awọn eeyan ti ko tọ.
Bakan naa ni wọn ni Ladoja tun sọ fun awọn alejo naa pe se ni Buhari ati isejọba rẹ n se ẹya Yoruba bii eru ti wọn ko loju ogun.
Nítorí kí aafa lè máa rí iṣẹ́ ṣe ní wọ́n kò ṣe kó Alumaajiri nílẹ̀ tó fi di ohun tó dà yìí
Fun apẹrẹ, Ladoja ni ijọba apapọ si awọn ẹnu bode to wa ni ẹkun ariwa Naijiria, to si ti ẹnu bode to wa ni guusu, eyi to wa lati sẹ eegun ẹyin ọrọ aje wọn.
O fikun pe awọn asọbode n kọlu awọn ọja nlanla gbogbo nilẹ Yoruba lati beere ibi ti wọn ti ri ọja ko wọle amọ ti awọn olokoowo lati ariwa, bii Dangote ati Bua n gba ẹnu bode naa kọja.
Ko tan sibẹ, Ladoja tun sọ pe o ti han gbangba pe ẹkun ariwa ti setan lati pin kuro lara Naijiria pẹlu bi ijọba Buhari se n ya owo to fi n pese ohun eelo amayedẹrun si ẹkun ariwa nikan ati ilẹ Niger pẹlu.
Bakan naa lo ni se bi ohun ti Sunday Igboho sọ naa ni Emir ilu Mubi sọ, ẹni to fun awọn Fulani darandaran ni gbdeke ọjọ lati fi ilu rẹ silẹ amọ to jẹ pe Igboho nikan ni wọn n fi iya jẹ.
Ohun ti Ladoja sọ naa ni awọn agbaagba Yoruba yoku naa sọ fawsn alejo lati Oke Ọya naa, ti wọn si panupọ sọ pe ọrọ ibo 2023 kọ lo kan bayii.
Senato francis Fadahunsi: Ká ni wọ́n fún Buhari ladún mẹ́wàá sẹ́ypin ní, bóyá kò bá rí i ṣ
Banditry in Nigeria: Àwọn olùjọ́sìn náà ń gbaradì fún ìsìn ọjọ́ ìsinmi ní àwọn ajínigbé ya bò wọ́n
Oríṣun àwòrán, other
Awọn gende agbebọn kan ti kọlu ijọ Living Faith, tii se ara ijọ David Oyedepo eyi to wa nilu Osara loju ọna Lokoja si Okene nipinlẹ Kogi.
Awọn agbebọn naa lo ya wọ ọgba ile ijọsin ọhun lasiko tawọn akọrin atawọn ojisẹ Ọlọrun miran n gbaradi fun isin ọjọ isinmi lopin ọsẹ to kọja.
Ka to sẹju pẹ, o kere tan, wọn ti ji mẹta gbe lọ lara awọn ọmọ ijọ naa.
Iroyin naa ni se ni awọn ajinigbe ọhun n yinbọn laibikita lati le awọn eeyan to fẹ koju wọn sẹyin, ti wọn si raye gbe awọn eeyan ti wọn ji gbe lọ.
Gẹgẹ bi iwe iroyin Daily Post ti wi, Alaga ijọba ibilẹ Adavi nibi ti isẹlẹ naa ti waye, Joseph Omuya Salami lo fidi isẹlẹ naa mulẹ fawọn akọroyin lọjọ Aje lati ẹnu akọwe feto iroyin rẹ, Habeeb Jamiu.
Koda, Salami ni oun ati ọga ọlọpa to wa lẹkun naa ni awọn dijọ se abẹwo sile ijọsin naa, nibi ti wọn ti ji awọn eeyan lọ.
O wa fi ọwọ idaniloju sọya pe aayan ti n lọ pẹlu awọn agbofinro lagbegbe naa lati ri daju pe wọn doola awọn eeyan naa lọwọ awọn ajinigbe ọhun.
Oríṣun àwòrán, other
Gulegule awọn agbebọn ni ipinlẹ Zamfara, lapa iwọ orun ariwa orilẹede Naijiria ti sọ awọn iṣẹ ọrọ aje kan di eewọ bayii.
Awọn ọrọ aje bii nina ọja ọlọsọọsẹ, ọkada gigun lati alẹ wọ idaji pẹlu fifi ọkọ kiko awọn ẹran ọsin jade kuro ni ipinlẹ naa lo ti di eewọ bayii,
Bẹẹ ni ẹnikẹni to ba fẹ ko ẹran ọsin wọ ipinlẹ naa gbọdọ gba aṣẹ lẹyin iwadii finni-finni lati mọ otitọ iru ẹranko ti wọn fẹ ko wọle.
Eyi ni diẹ lara awọn igbesẹ ti ijọba ipinlẹ Zamfara n gbe lati dena gbọnmọgbọnmọ iwa ijinigbe, ipaniyan ati jiji ohun ọsin ni ipinlẹ naa.
Awọn ọja ọlọsọọsẹ saba maa n waye lawọn agbegbe igberiko nipinlẹ naa nibiti awọn eeyan kaakiri ileto ti maa n peju si gbangba lọsọọsẹ lati ṣeto karakata bii ohun jijẹ, ohun ọsin, awọn ohun elo oko ati aṣọ.
Nítorí kí aafa lè máa rí iṣẹ́ ṣe ní wọ́n kò ṣe kó Alumaajiri nílẹ̀ tó fi di ohun tó dà yìí
Bakan naa ni awọn alaṣẹ ipinlẹ naa tun ti gbe gbogbo ileepo nipinlẹ naa tipa ayafi awọn ileepo to wa ni ilu Gusau to jẹ olu ilu ipinlẹ naa,  atawọn olu ilu ijọba ipinlẹ mẹrinla to wa nibẹ
Bakan naa ni wọn paṣẹ fun awọn ileepo ti wọn yoo wa ni ṣiṣi naa pe wọn ko gbọdọ ta epo ti owo rẹ ju ẹgbẹrun mẹwa naira fun ẹnikẹni.
Kọmiṣọna ọlọpaa ni ipinlẹ Zamfara, Eyuba Elkanah ṣalaye fun awọn akọroyin lolu ilu ipinlẹ naa pe aṣẹ ti jade fawọn agbofinro nipinlẹ naa lati ṣiṣẹ lori awọn ofin tuntun ti ijọba gbe kalẹ wọnyii.
Orilẹede Naijiria n ba ipenija ipaniyan, ijinigbe pawo lọwọ awọn agbebọn atawọn ipinija ọrọ abo miran finra lọwọ bayii eleyii to mu ki ijọba, awọn ilu gbogbo atawọn idile kọọkan ni ipinlẹ naa o gbe awọn igbesẹ to nira diẹ lati koju iṣoro naa.
Oba Ogboni Abalaye n fẹ́ kí wọ́n o má a fi ẹ̀sìn àbáláyé búra fún àwọn olóṣèlé Naijiria
Boko Haram: Amẹ́ríkà ní ààrin òun àti Nàíjíríà dán mọ́ran ju Afghanistan lọ, kò sì le bàjẹ́
Orílẹ̀-èdè Amẹrika ni àwọn tí ṣetán láti ran orílẹ̀-èdè Nàìjíríà lọ́wọ́ nípa fífi ojú àwọn onigbọwọ Boko Haram, tó ń fi ojoójúmọ́ ba nǹkan jẹ́ lórí lédè yii han fun araye.
Wọ́n sọ èyí di mímọ̀ ni ọjọ́ Ajé nígbàtí aṣojú Amẹrika ni Nàìjíríà, Mary Leonard ń ṣe ìpàdé pẹ̀lú àwọn òníròyìn ni ilu Abuja.
"Nígbà tí ìbéèrè jẹyọ lori nǹkan tí Amẹrika yóò ṣe láti fi ran Nàìjíríà lọ́wọ́ láti mọ àwọn tó ń ṣe onígbọ̀wọ́ fún Boko Haram ni Nàìjíríà, Leonard ni "" Èyí gan ni àjọṣepọ̀ tí a fẹ́ bá Nàìjíríà ṣe."
 Mo ti sọ̀rọ̀ lórí kókó yìí fún ìgbà mẹ́ta ọ̀tọ̀ọ̀tọ̀ láàrin oṣù méjì sí àsìkò yii
Mi ò ní lé máa sọ kókó nǹkan tí à ó ṣe.
Ó ní kí àwọn ènìyàn mu ọ́kàn kúrò nínú pé bóyá ìbáṣepọ̀ tó wà láàrin Nàìjíríà àti ilẹ̀ Amẹrika yóò bàjẹ́ bó ṣe ṣẹlẹ̀ ní Afghanistan àti pé ìbáṣepọ̀ tó wà láàárín Nàìjíríà àti US dán mọ́rán ju ti Afghanistan lọ.
Nítorí kí aafa lè máa rí iṣẹ́ ṣe ní wọ́n kò ṣe kó Alumaajiri nílẹ̀ tó fi di ohun tó dà yìí
"Mò ń gbọ́ tí àwọn kan ń ṣàpẹẹrẹ ìṣẹ̀lẹ̀ tó wáyé ní Afghanistan, èyí kò jọ ara wọn rárá.
Bí ẹ bá tẹtí sí nǹkan tí ààrẹ Joe Biden sọ nípa bí àwọn ọmọogun Amẹrika ṣe lọ sí Afghanistan lákọ̀kọ́ jẹ́ nǹkan tó lágbára, ọmọ ilẹ̀ Amẹ́ríkà ẹgbẹ̀rún mẹ́ta ló kú."
Nínú ọ̀rọ̀ tirẹ̀ bákan náà, olórí ọmọogun ojú òfuurufú ni Yúróòpù, Jeffrey Harrigian sọ fún àwọn oníròyìn pé, ríra ọkọ̀ ogun òfurufú ni ó túbọ̀ so àjọṣepọ̀ ilẹ̀ Amẹ́ríkà ati Nàìjíríà pọ̀ sí, èyí yóò sì mú wọn dìde ìrànwọ́ nípa ètò ààbò.
Ó ní Tucano A-29 super lọ fún àwọn àti ìjọba ni Nàìjíríà ni ajọsepọ si.
Ìròyìn sọ pé, orílẹ̀-èdè yii ń kojú ètò àbò tó burú jùlọ báyìí nítorí wàhálà àwọn agbésùmí, ìwà jàndùkú, ìpànìyàn tó ń lọ káàkiri Nàìjíríà.
Bi ó tilẹ jẹ́ pé ọ̀pọ̀ àwọn agbésùmọ̀mí lo n kó nǹkan ìjà ogun tí silẹ, pàápàá jùlọ ni ìhà àríwá ìlà-oòrùn nítorí àwọn ọmọogun ń pa wọ́n, síbẹ̀ ètò ààbò ń burú sii ni.
Oríṣun àwòrán, The sun nigeria
Awọn olugbe ilu Yelwa Zangam ni ijọba ibilẹ Jos North ni ipinlẹ Plateau ṣi n gbọn riri lori ikọlu awọn agbebọn nibẹ lọjọ  marun un sẹyin eleyi to ran marundinlogoji ninu awọn olugbe ilu naa lọ sọrun ọsan gangan ti wọn si tun dana sun ọpọlọpọ ile nibẹ.
Ọkan mi gbọgbẹ lori ajalu nla to ba emi atawọn eeyan mi yii. A ko reti irufẹ iṣẹlẹ bayii ni ariwo ti olori ilu naa, Ajida Isa n pa lori aro.
Iyawo rẹ Susan, to jẹ ẹni ọdun mẹrindinlọgọta, atawọn mọlẹbi rẹ mẹfa ni wọn pa lasiko ikọlu awọn agbebọn naa.
Ikọlu naa to waye ni aṣalẹ ọjọ Iṣẹgun ti sọ olori ilu naa sinu hilahilo tori bi agbebọn se pa ọmọ rẹ ọkunrin, Ishaya to jẹ ọmọ ọdun mẹrindinlogun.
Bakan naa ni iyawo ọmọ rẹ Monica, to jẹ ẹni ọdun mejidinlogoji, ọmọ-ọmọ rẹ obinrin, Salvation Ishaya to jẹ ọmọ ọdun mẹtala ati ọmọ-ọmọ rẹ ọkunrin, Timura Ishaya to jẹ ọmọ ọdun mẹrin ba ikọlu naa lọ.
Oba Ogboni Abalaye n fẹ́ kí wọ́n o má a fi ẹ̀sìn àbáláyé búra fún àwọn olóṣèlé Naijiria
Ko tan sibẹ o, Barnabas Hosea ọmọ-ọmọ rẹ ọkunrin to jẹ ọmọ ọdun mẹtadindinlogun ati ọmọ-ọmọ rẹ ọkunrin miran, Ephraim Hosea to jẹ ọmọ ọdun mẹsan wa lara awọn ti agbebọn to wọ ileto wọn yinbọn pa.
Ajida Isa atawọn mọllẹbi rẹ ti jẹun tan, pe ki wọn wọle sun ni wọn bẹrẹ si ni gbọ iro ibọn lakọlakọ ni ita gbangba eleyi to mu ki gbogbo awọn olugbe ileto naa bẹrẹ si ni sa kijokijo lati du ẹmi ara wọn.
Awọn kan lara wọn ti ko mọ ohun to n lo sare wa sile Ajida Isa gẹgẹ bii baalẹ wọn lati wa fara pamọ sibẹ.
Amọṣa, ko pẹ pupọ ti awọn agbebọn naa yi afin naa pẹlu ka, ti wọn si yinbọn pa gbogbo awọn to wa nibẹ ki wọn to sọ ina si ile naa.
Igbakeji baalẹ ileto Yelwa Zangam Haruna Adamu ṣalaye fun akọroyin iwe iroyin The Punch pe, yatọ si awọn ti wọn yinbọn pa, awọn agbebọn naa tun da ina sun ọpọlọpọ awọn olugbe ilu naa.
Awọn mẹtadinlogun ni wọn dana sun, iye awọn ti wọn si yinbọn pa to ogun ni iye. Awọn miran ṣi wa ni ile iwosan.
Awọn ara ilu naa n na ika sawọn alamuleti wọn to jẹ Hausa/Fulani pe awọn lo wa nidi ikọlu naa nitori pe wọn n fẹ ki awọn fun wọn ni ilẹ wọn.
Nítorí kí aafa lè máa rí iṣẹ́ ṣe ní wọ́n kò ṣe kó Alumaajiri nílẹ̀ tó fi di ohun tó dà yìí
Gẹgẹ bi ohun ti igbakeji Baalẹ naa sọ, ilẹ ileto naa kan ti awọn Hausa/Fulani alamuleti wọn naa n lo fun isinku wọn ṣugbọn ti wọn fẹ gba patapata eyi ti awọn faake kọri pe ko lee bọ si lo fa ija naa.
O ni nigba ti awọn Hausa-Fulani naa kọkọ de ni wọn ni ki wọn tẹdo si ilẹ naa ti wsn si n lo ibẹ fun isinku wọn. Lẹyin ọpọlọpọ ọdun ti ẹni to ni ilẹ ni ki oun kuku ta a fun wọn ni wọn kọ pe awọn ko lee raa nitori pe ko si ẹni to ni ilẹ.
Adamu ni gbogbo foonu ibanisọrọ wọn ni wọn ko lọ pẹlu.
Nigba to n fesi, olori awọn ẹya Hausa ni ilu Yelwa Zangam, Alhaji Umaru ni awọn ko mọ ohunkohun nipa ikọlu naa ati pe wọn ti ko ọrọ aawọ lori ilẹ isinku naa lọ sọdọ ijọba ibilẹ agbegbe naa fun iyanju to yẹ.
Yoruba Nation: Mo faramọ́ àtúntò 'Restructuring' tí kò lọ́wọ́ ìṣèlú nínú- Oba Ahmed Adeku
Oba Ogboni: Bí ìwọ́de Yoruba Nation bá tún wáyé, màá bá wọn kópa níbẹ̀
Oba Ogboni: Bí ìwọ́de Yoruba Nation bá tún wáyé, màá bá wọn kópa níbẹ̀
Ọba Ogboni Abalaye, Tajudeen Bakare ti salaye awọn ohun to sẹlẹ ni ahamọ ọlọpaa lasiko ti wọn mu pe o se iwọde Yoruba Nation.
Ọba Ogboni lasiko to n ba BBC Yoruba sọrọ kede pe kii se pe oun yi awọn ọrọ ti oun sọ lasiko iwọde pada lẹyin ti awọn ọlọpaa mu oun tan gẹgẹ bi awọn kan se n sọ kiri.
O fikun pe ohun to sẹlẹ laarin ọjọ kẹta si ikẹrin osu Keje ọdun yii tawọn ọlọpaa mu oun pe oun se iwọde, to ba sẹlẹ si ẹlomiran, yoo ti ku.
"Kii se pe mo yi ohun ti mo sọ nibi iwọde pada nigba ti mo de agọ ọlọpaa, amọ ohun ti oju mi ri laarin ọjọ kan sira wọn ni agọ ọlọpaa, ni mo fi tun ọrọ miran sọ.
Mọja mọsa laa mọ akikanju loju ogun, ko ni dara ki ẹni to sọ pe oun n ja fun ilu, gba lati ku, idi ree ti mo fi sọ nnkan miran, mo si duro lori ohun ti mo gbagbọ.
Oba Ogboni Abalaye n fẹ́ kí wọ́n o má a fi ẹ̀sìn àbáláyé búra fún àwọn olóṣèlé Naijiria
To ba jẹ pe ẹlomiran ni isẹlẹ naa sẹlẹ si, laarin ọjọ Kẹta osu keje ti ọlọpaa fi mi si ahamọ si ọjọ Kẹrin osu kẹjọ ti wọn fi mi silẹ, onitọun yoo ti ku tabi yi ohun to sọ pada."
Nigba to n fesi lori iwoye awọn araalu pe ojo ni ati pe o yẹ ko poora mọ awọn ọlọpaa lọwọ ni, to ba jẹ pe lootọ lo jẹ Ọba Ogboni, Bakare ni ootọ ni ohun ti wọn sọ.
Amọ o ni eeyan mẹfa lo wa ninu mọto pẹlu oun lasiko ti ọlọpaa mu awọn, ti awọn eeyan naa kii si se ọmọ ẹgbẹ awo Ogboni.
O ni ti oun ba wa poora, ti awọn yoku si wa ni ahamọ ọlọpaa, ki ni yoo jẹ ipin wọn, idi si ree ti ohun ko fi poora lọna ati daabo bo awọn eeyan ti wsn mu pẹlu oun.
Ọba Ogboni ni oun ko mọ ohunkohun nipa ẹsun ipaniyan tawọn ọlọpaa pada fi kan oun nitori wọn ko ba ibọn lara oun lọjọ naa.
"Kii se ibi iwọde Yoruba Nation ni wọn ti mu wa, bẹẹ ni n ko pa eeyan kankan abi bawo ni ẹni ti ko ni ibọn se le pa eeyan?
Amọ ohun to yẹ ko ye araalu ni pe awọn ọlọpaa ko fi iya jẹ mi ni ahamọ sugbọn awọn nnkan wa to ju pe ki wọn fi iya jẹ eeyan lọ, eyi to sẹlẹ si mi ni ahamọ.
Sugbọn gbogbo eleyi ko yi ipinnu mi lati ja fun ilẹ Yoruba pada nitori bi iwọde miran ba tun waye, a jọ maa se ni.
Yoruba Nation: Mo faramọ́ àtúntò 'Restructuring' tí kò lọ́wọ́ ìṣèlú nínú- Oba Ahmed Adeku
Ọmọ Yoruba ni mi, mo si ti se ileri niwaju awọn alalẹ pe maa ti iran Yoruba lẹyin, nitori naa, ko si ihalẹ tabi idunkooko kankan to le mu mi yi ipinnu mi pada."
Bakan naa ni Ọba Ogboni Abalaye kede pe ahamọ ti oun wa awọn alalẹ lo fi oun pamọ nitori ibi to le fẹ sẹlẹ si ohun, ka ni oun ko si ni ahamọ ni.
"Sunday Igboho to wa ni ahamọ ni Cotonou, awsn alalẹ lo fi pamọ sibẹ, ko le wa laye, ki ọpọ ewu si le re kọja lori rẹ lo se wa nibi to wa.
Awọn alalẹ lo fi emi naa pamọ lasiko ti mo wa ni ahamọ ọlọpaa, tori naa ni n ko se ni dakẹ fun ijagudu fun ominira ilẹ Yoruba.
2023 Presidency: Àlàyé Ameachi rèé lórí bóyá lóòtọ́ ni àjọsọ wà láàrin Tinubu àti Buhari nìpa ìbò 2023
Oríṣun àwòrán, The Presidency
Mínísíta tó ń rí sí ètò ìrìnà àti iṣẹ́ òde ni Nàìjíríà tí fèsì sí ọ̀rọ̀ tó gbòde pé ààrẹ Muhammadu Buhari àti Asíwájú Bola Ahmed Tinubu ní àdéhùn tí wọ́n ṣe fún ipò ààrẹ ọdún 2023.
Ọ̀rọ̀ náà ló tí ń tàn ká láti ọdún 2015, kí ìdìbò ààrẹ to wáyé.
Àwọn kan sọ pé ẹgbẹ́ All Progressives Congress (APC) yọ Tinubu gẹ́gẹ́ bí oludije fun ìgbàkejì ààrẹ fún Buhari nítorí awuyewuye pé musulumi ati musumi kò lè di ààrẹ.
Wọn ni èyí sì lo mú kí Buhari fi ọkàn Tinubu balẹ̀ pe oun ni yoo gba ijọba lọdun 2023.
Èyí ló mú kí àwọn gómìnà ìhà Gúúsù àti àwọn olóyè ẹgbẹ́ òṣèlú People Democratic Party (PDP) bẹ̀rẹ̀ sí ní fi ẹ̀sùn kan APC pé wọ́n yí Nàìjíríà sí orílẹ̀-èdè Musulumi.
Yoruba Nation: Mo faramọ́ àtúntò 'Restructuring' tí kò lọ́wọ́ ìṣèlú nínú- Oba Ahmed Adeku
Àwọn alẹ́nulọ́rọ̀ péjọ láti rọ Tinubu, tí wọ́n sì ni kí o mú ẹni tí yóò jẹ ìgbàkejì fún Buhari wa.
Lẹ́yìn èyí, ni wọ́n yan kọmísọ́nà ètò ìdájọ́ nípìnlẹ̀ Eko nígbà kan rí, Yemi Osinbajo si ipo igbakeji aarẹ, tí wọ́n sì já Gómìnà ìpínlẹ̀ Ekiti, Kayode Fayemi sílẹ̀.
Ṣùgbọ́n ṣáájú ìdìbò ọdún 2019, ìròyìn sọ pé ààrẹ túbọ̀ fi dá Jagaban lójú pé òun ni yóò gba ipò lọ́dún 2023.
Lẹ́yìn ọ̀sẹ̀ díẹ̀, wọn ni Tinubu ransẹ́ pé Gómìnà ìpínlẹ̀ Osun tẹ́lẹ̀rí, Bisi Akande láti wá sìn òun lọ sí ilé iṣẹ́ ààrẹ fún àbẹ̀wò.
Làsìkò yìí gẹ́gẹ́ bí ìròyìn ṣe sọy, ní Tinubu tún ní kí ààrẹ Buhari tún ìlérí rẹ̀ ṣe, tí ààrẹ sì tún fọwọ́ sọ̀yà pé kódà bójú bá yẹjú, ohùn kò ní yẹ̀.
Ìgbàgbọ́ ni pé ìpàdé èyí wáyé nínú oṣù kíní ọdún 2018.
Nítorí kí aafa lè máa rí iṣẹ́ ṣe ní wọ́n kò ṣe kó Alumaajiri nílẹ̀ tó fi di ohun tó dà yìí
Nigba to n sọrọ lori isẹlẹ yii pẹlu iwe iroyin Daily Trust, Rotimi Amaechi ṣàlàyé pé òun kò ní ànfàní láti mọ kókó tó wà nínú àdéhùn wọn.
Gómìnà ìpínlẹ̀ Rivers nígbà kan rí ọhun ni, kò si ìdánilójú pé Buhari àti Tinubu ṣe irú ìpàdé ìdákọ́nkọ́ tó jọ bẹ́ẹ̀.
Ó fi kun pé òun gẹ́gẹ́ bí adarí gbogboogbò fún ìpolongo ẹgbẹ́ APC, kò sí àsìkò kankan tí òun péjú síbi irú ìpàdé bẹ́ẹ̀.
Ṣùgbọ́n tí ó bá wá jẹ́ pé ìpàdé ìdákọ́nkọ́ wáyé láàárín ààrẹ Buhari àti Asiwaju Ahmed Tinubu, òun kò mọ̀."""
" Tí ó bá jẹ́ pé ìpàdé ìtagbangba tí ẹgbẹ́ APC pè, tí mi ò sì sí níbẹ̀ ajẹ́ wípé nǹkan mìíràn wà níbẹ̀ nìyẹn.
Amaechi fi kún pé òun kò gbọ́ ìgbà kankan tí wọ́n sọ pé kí wọ́n gbé ìjọba fún Tinubu lọ́dún 2023.
Oríṣun àwòrán, Mudasiru Obasa
Ọmọ ilé igbimọ̀ asòfin ni ìpínlẹ̀ Eko ni a síwájú ẹgbẹ́ òṣèlú All Progressives Congress (APC) Bola Ahmed Tinubu mú ọ̀rọ̀ Nàìjíríà ni òkúnkúndùn
Agbenusọ ilé ìgbìmọ̀ asòfin Eko ìpínlẹ̀ Eko Mudashiru Obasa lo sọ èyí lẹ́yìn tí òhun àti àwọn ọmọ ilé ìgbìmọ̀ tó kù rin ìrìnàjò lọ sí ilẹ̀ òkèèrè láti lọ sàbẹ̀wò sí Asiwaju Ahmed Tinubu
Ó ní kokoko ni ara Asiwaju le, ti ko si si amin pe o n se ojojo kankan
Díẹ̀ lára àwọn tó sàbẹ̀wò sí Bola Ahmed Tinubu ni alága ìgbìmọ̀ tẹ̀ẹ́kótó lórí ìgbòkègbodò ọkọ̀ Temitope Adewale, alága ìgbìmọ̀ tẹ̀ẹ́kótó lórí ètò ìlú àti àyíká Nureni Akindanya àti alága tẹ̀ẹ́kótó lórí ètò ọ̀rọ̀ ajé ilẹ̀ òkèrè Sylvester Ogunkelu.
Thyroid foundation: eéwo ni mo kọ́ka pè é àṣé gẹ̀gẹ̀ ọrùn tó lé ẹbí, ará àti ọ̀rẹ́ ni mo n
Obasa ni bí Tinubu ṣe máa ń dẹ́rìn pa àwọn ènìyàn náà lọ sì ń ṣe àti pé ìfọ̀rọ̀wérọ̀ láàrin àwọn tó jọ kọ́wọ̀ọ́rin wáyé lórí àwọn nǹkan tó ṣe pàtàkì fún ìdàgbàsókè Nàìjíríà.
Ó ní abẹ̀wo náà ṣe pàtàkì nítorí ipò Tinubu gẹ́gẹ́ bí aṣáájú lórílẹ̀ - èdè yìí, ó jẹ́ atọ̀nà fún ọ̀pọ̀ àti aláànú ọ̀pọ̀ àwọn ọmọ Nàìjíríà.
Agbẹnusọ ilé sọ pé : Ọ̀rọ̀ Nàìjíríà jẹ a síwájú gidi gan. Kokoko ni ara rẹ̀ lè a sì ni ìfọ̀rọ̀wérọ̀ tó pọ̀ gidi gan pàápàá jùlọ lórí ìdàgbàsókè orílẹ̀-èdè Nàìjíríà."
"Inu rẹ̀ dùn gidi, ó ṣe àwàdà bí ó ṣe máa ń ṣe bákan náà sì ni ó ní ìgbàgbọ́ nípa ìlọsíwájú Nàìjíríà """
Babatunde Gbadamosi: Mo ta gbogbo dúkìá mi lásìkò kan kí ń tó padà di eèyàn lónìí
Sunday Igboho: Adájọ́ ní ìjọba kò gbọdọ̀ gbẹ́sẹ̀ lé àpò owó tàbí mú Sunday Igboho
Oríṣun àwòrán, Instagram sunday_igboho1
Ajijagbara ilẹ Yoruba, Sunday Adeyemo ti ọpọ èèyàn mọ sí Sunday Igboho, tún ti fẹyin ijoba gbalẹ nile ẹjọ.
Agbẹjọro agba ati mínísítà eto idajo ni Naijiria, Abubakar Malami ati ijoba Ààrẹ Muhammadu Buhari fẹ kí ilé ẹjọ fagile aṣẹ to pa pe ijoba ko gbodo mu Igboho, wọn ko sì gbọdọ dunkooko mọ.
Amọ adajọ Ladiran Akintola tile ẹjọ gíga ipinlẹ Oyo naa tun pàṣẹ pé ijọba ko gbọdọ gbẹsẹ le akaunti ọwọ Sunday Igboho.
Gbogbo nkan yii ni ijọba fẹ kí ilé ẹjọ yi danu ṣugbọn adajọ yi ẹbẹ Malami ati ijọba apapọ danu.
Adajọ ni ohun ti wọn n bèèrè fun lodi sí ẹtọ ọmọnìyàn.
Oba Ogboni: Bí ìwọ́de Yoruba Nation bá tún wáyé, màá bá wọn kópa níbẹ̀
Nigba to n fidi isẹlẹ naa mulẹ, agbẹjọro fun Sunday Igboho, Yomi Aliyu ni igba keji ree ti ijọba apapọ ati Malami yoo fi ẹyin janlẹ nile ẹjọ lori ọrọ Sunday Igboho.
O ni ile ẹjọ ti wa kede pe ọjọ Isẹgun, ọjọ Keje osu Kẹsan ọdun 2021 ni igbẹjọ naa yoo maa tẹsiwaju.
Grace Oyin Adejobi: Bí mo bá tún ayé wá, ọkọ mi ni màá padà fẹ́
Gbajumọ ni mama Grace Owoola Oyin-Adejobi ti ọpọ eeyan mọ si Iya Osogbo nitori o wa lara awọn obinrin to bẹrẹ ere tiata nibẹrẹ pẹpẹ.
Iya Osogbo, ẹni to sẹsẹ se ọjọ ibi ọdun kejilelaadọrun laipẹ yii ba BBC Yoruba sọrọ lori awọn iriri rẹ nile aye, ajọsepọ pẹlu ọkọ rẹ ati ere tiata.
O fikun pe iyawo marun ni oun fẹ fun ọkọ oun lati mu ki agbo ere tiata rẹ se aseye, ti oun ko si kabamọ nipa igbesẹ naa.
Grace Oyin Adejobi, ti ọkọ rẹ, Oyin Adejobi naa jẹ gbajumọ osere tiata tun fikun pe ile ẹkọ alakọbẹrẹ ni oun ati ọkọ oun ti pade, ti aanu rẹ si maa n se oun tori ipo akanda ẹda to wa.
Nigba to n salaye idi ti ko fi tẹsiwaju lẹnu ẹkọ rẹ lati kawe de ibi to lapẹrẹ, Iya Osogbo nigba ti oun wa niwe kẹrin ni oun fi owo ile ẹkọ ra asọ ọdun Ileya.
O ni idi ree ti wọn ko fi jẹ ki oun kawe siwaju mọ.
NDA Invasion: Fr Mbaka ní bí Buhari kò bá yíwà padà, díẹ̀ ní ìṣẹ̀lẹ̀ Afghanistan yóò jẹ́
Oríṣun àwòrán, State House Abuja
Alufa ijọ Adoration Ministry Enugu Nigeria, AMEN, Ẹniọwọ Ejike Mbaka ti ọpọlọpọ mọ si Fada Mbaka sọrọ lori ikọlu to waye si ileẹkọṣẹ agba fawọn ọmọogun ni Naijiria, NDA.
Ojisẹ Ọlọrun naa wa sapejuwe ikọlu ọhun bii ibẹrẹ pẹpẹ awọn ohun ajalu to n bọ lọna fun orilẹede Naijiria.
O ni bi aarẹ Buhari ko ba tete yi ọna rẹ pada tabi ki Ọlọrun tubọ dasi ọrọ Naijiria, nkan yoo yan lorilẹede Naijiria, koda kekere ni ikọlu naa.
Fada Mbaka to sọrọ yii lasiko isin ni ileejọsin naa, tun ṣekilọ pe bi awọn adari ko ba tete gbe igbesẹ to yẹ fun atunṣe, bintin ni ohun to ṣẹlẹ lorilẹede Afghanistan yoo jẹ lẹgbẹ eti ti yoo ṣẹlẹ si NAijiria lọjọ iwaju.
Iranṣẹ Ọlọrun naa tun pe fun itusilẹ awọn eekan aṣiwaju ẹgbẹ ajijagbara fun idasilẹ orilẹede Biafra, IPOB, Nnamdi Kanu kuro ninu ahamọ.
Grace Oyin Adejobi: Bí mo bá tún ayé wá, ọkọ mi ni màá padà fẹ́
O fi kun un pe o han gbangba pe iṣoro to n koju Naijiria kọja ọrọ Nnamdi Kanu, ati pe awọn to kọlu ile ẹkọṣẹ agba fawọn ologun naa kii saa n ṣe Kanu.
"Gẹgẹ bi mo ṣe sọ fun yin loṣu meji sẹyin, pe ohun ti ẹ n ri bayii ibẹrẹ wahala to n bọ ni, ojulowo wahala ṣi n bọ lọna.
Ifaara lasan leyi ti wọn n kọlu ileẹkọṣẹ agba fawọn ọmọogun ni Naijiria, NDA yii, apa keji n bọ"
Ban on Open Grazing deadline: Miyetti Allah ní eré lásán làwọn gómìnà gúúsù ń ṣe lórí òfin máse da ẹran nígboro
Oríṣun àwòrán, other
Ọjọ kini oṣu kẹsan ọdun 2021 ni gbendeke ti awọn gomina guusu Naijiria gbe kalẹ lati fopin si dida ẹran jẹ ni gbangba, ti n ṣe kẹrẹkẹrẹ sunmọ etile bayii.
Amọṣa, awọn fulani darandaran lorilẹede Naijiria ti ṣalaye pe ala ti ko lee ṣẹ ni ọrọ naa, awọn gomina naa kan n pa ila sẹnu ni.
Awọn darandaran Fulani labẹ aṣia ẹgbẹ Miyetti Allah ni awọn ko ni lee tẹle ofin naa nitori ọrọ ti kọja lori rẹ.
Ninu ifọrọwerọ kan pẹlu iwe iroyin Leadership, akọwe apapọ ẹgbẹ Miyetti Allah Kauta Kore, Saleh Hassan ni awọn darandaran Fulani ko ni tẹle ofin naa.
O fi kun un pe igbesẹ titọpasẹ awọn ojuna idaran jẹko ti ijọba apapọ ṣẹṣẹ gbe kalẹ, ni awọn fara mọ.
Grace Oyin Adejobi: Bí mo bá tún ayé wá, ọkọ mi ni màá padà fẹ́
Alhassan ni pẹlu aṣẹ irina bo se wu ni ti iwe ofin Naijiria gbe kalẹ, ko si ẹnikẹni to le le awọn lati mase daran jẹ nigboro, awọn ko lee tẹle aṣẹ awọn gomina naa.
Bakan naa lo fi kun un pe, ọgbọn ati da ipo aarẹ pada si ẹkun guusu Naijiria lawọn gomina naa n da ati pe ko lee bọ si.
"Agbara ti wọn n wa ko ni tẹ wọn lọwọ. A ti fi ẹjọ wọn sun Allah lati da ede aiyede silẹ laarin wọn. Nibo ni Sunday Igboho wa bayii? Nibo ni Nnamdi Kanu wa? Gbogbo wọn ti wa ni ẹwọn.
O ni gbogbo awọn to n foro ẹmi awọn darandaran bii Sunday Igboho, Nnamdi Kanu lo ti dero ẹwọn nitori Ọlọrun awọn ko sun.
Bakan naa lo fi kun un pe, gomina ipinlẹ Benue, Ortom pẹlu yoo foju wina idajọ to ba yẹ lẹyin to ba kuro ni ipo.
Ẹgbẹ Miyetti Allah ni bi ajọ EFCC ko ba gbe Ortom lẹyin to ba fi ipo silẹ, awọn funra awọn lawọn yoo ko ikọ fijilante awọn sita lati lọ mu u, ki wọn si faa le ọlọpaa lọwọ.
Sunday Igboho Aides: Olajengbesi àti Ilana Omo Oodua sọ ìdí tí DSS ṣe wowọ́ mọ́ èèyàn mẹ́rin
Oríṣun àwòrán, Omoyele Sowore Facebook
Ni ọjọ Aje ni okiki kan pe mẹjọ ninu awọn eeyan mejila tawọn oṣiṣẹ agbofinro DSS mu ni ile Sunday Igboho ni ọjọ kini oṣu keje ọdun 2021, ti gba idande.
Amọ ọpọ ibeere lo jade lori idi ti awọn DSS ko fi tu awọn mẹrin yoku silẹ lẹyin ti ile ẹjọ ti paṣẹ pe ki wọn gba oniduro wọn.
Ninu ifọrọwerọ rẹ pẹlu BBC News Yoruba, agbẹjọro fun awọn mejila naa, Amofin Pẹlumi Ọlajẹmgbesi ṣalaye pe idi ti awọn mẹrin yoku naa fi wa ni ahamọ.
Sugbọn o ni iṣẹ nlọ lati tu awọn mẹrinla yoku silẹ.
O fikun pe ohun ti ileeṣẹ DSS ko fẹ ko jade sita faraye gbọ, ti wọn fi n wonkoko mọ awọn eeyan naa ni ohun to pe ni iwa ibajẹ ati titẹ oju ofin mọlẹ ti wọn hu nile Sunday Igboho loru ọjọ ti wọn kọlu u.
O ni awọn fẹ kọkọ gba awọn mẹrin to ku naa silẹ na, ki awọn to yanju awọn ariwisi ti DSS n gbe sike lori awọn oniduro wọn.
O ni gbogbo ọgbọn ti awọn DSS n da ni pe  wọn ko fẹ ki awọn to wa lahamọ jade, ki wọn ma baa le sọ nnkan ti oju wọn ri ni ọjọ ti DSS wa si ile Oloye Sunday Igboho."
"Gẹgẹ bi ohun ti a gbọ ti a si gbagbọ, wọn ni awọn DSS atawọn ṣọja to wa, wọ gbogbo awọn yara, gbogbo gbọngan ati gbogbo ibi ti wọn ba wọ ni wọn kan n yinbọn si."""
O ni wọn ko tilẹ fẹ mọ boya eeyan wa nibẹ tabi ko si nibẹ ti wọn sa n ṣina ibọn bolẹ.
Ọkan ninu awọn ẹsọ Igboho ti DSS pa ko riran:
Oloogbe adogan (ọkan lara awọn meji ti wọn pa nile Sunday Igboho) ibi to sa pamọ si ninu ile iwẹ ni ibọn ti ba. Ẹni keji to jẹ alfaa tori pe ko riran daadaa, ni ko mọ ibi ti yoo gba, ibi ti o ti n kaakiri ni ibọn ti baa
O ni lara awọn mejila naa, eyi ti awọn oṣiṣẹ DSS fi ọmọ odo lu ninu wọn wa, ti Eleduwa kan da ẹmi wọn si.
Nítorí kí aafa lè máa rí iṣẹ́ ṣe ní wọ́n kò ṣe kó Alumaajiri nílẹ̀ tó fi di ohun tó dà yìí
Lori ọrọ ti DSS sọ pe lori awọn ohun ti wọn ba ni ile oloye Sunday Igboho loru ọjọ naa, Amofin Ọlajemgbesi ṣalaye pe ileeṣẹ agbofinro DSS nikan lo mọ ibi ti wọn ti ri ibọn.
Bakan naa lo kede ẹru DSS ni ibọn ti wọn n sọ pe awọn ri nile Igboho ati pe, awọn gan lo mọ ibi ti wọn ti ri wọn.
O fi kun un pe, bi wọn ba ni awọn ri oogun ati iwe irinna soke okun, ẹtọ oloye Sunday Adeyẹmọ ni lati ni awọn nnkan bayii.
O salaye pe niwọn igba ti wọn ko lee mu pasitọ nitori Bibeli, ti wọn ko si lee mu alfa nitori pe wọn ba Kurani ninu ile rẹ, gẹgẹ bi ọmọ Yoruba atata Sunday Igboho mu awọn nnkan iṣọra ati iṣẹṣe lọkunkundun.
Oba Ogboni Abalaye n fẹ́ kí wọ́n o má a fi ẹ̀sìn àbáláyé búra fún àwọn olóṣèlé Naijiria
Ninu ọrọ tiwọn, ẹgbẹ agbarijọpọ awọn to n ja fun idasilẹ orilẹede Yoruba, ẹgbẹ Ilana ọmọ Oodua ṣalaye pe awọn mọ pe awọn alagbara kan lo n mu ki awọn oṣiṣẹ DSS maa hu iwa itapa-sofin bo ṣe wu wọn.
Alagba Akinọla, to jẹ akọwe agba ẹgbẹ Ilana Ọmọ Oodua ni lẹyin ti ile ẹjọ ti sọ pe ki wọn gba oniduro awọn eeyan mejila naa, sọ fun BBC News Yoruba pe ohun ti iwa DSS n tọka si ni pe, wọn ko bọwọ fun ofin Naijiria, bẹẹ si ni ko si ẹni kan tabi ileeṣẹ kan to ga ju ofin lọ.
O ni DSS gbọdọ jẹjọ fun awọn eeyan meji ti wọn pa nile Sunday Igboho nigba ti wọn foru boju kọlu ile eekan to n ja fun idasilẹ orilẹede Yoruba.
Kidnapping in Zamfara: Àwọn jàndùkú tún ti jí èèyàn méjì gbé ní Zamfara
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Awọn agbebọn kan ti kọlu agbegbe Nahuche, ni ijọba ibilẹ Bungudu to wa ni ipinlẹ Zamfara.
Ẹnikan ti iṣẹlẹ naa ṣoju rẹ, Malan Abubakar, sọ pe lara awọn to ba iṣẹlẹ naa lọ ni ọlọpaa kan ati adari ikọ awọn fijilante.
Abubakar sọ fun awọn akọroyin pe awọn janduku ọhun tun ji eeyan meji gbe lọ lasiko ikọlu naa.
O ni awọn janduku naa kọkọ ya bo abule kan ni Nahuche ti wọn n pe ni Gidan Jan Bula, wọn si fi alupupu pa olori awọn fijilante naa lẹyin to kọju ija si wọn.
"O ṣalaye pe ""Wọn gbe iyawo mi lọ lasiko ikọlu naa."""
Abubakar sọ siwaju si pe awọn janduku naa lọ si agọ ọlọpaa Nahuchi nibi ti wọn ti doju ibọn kọ awọn ọlọpaa, ti ẹmi eeyan kan lara awọn ọlọpaa naa si sọnu.
Kayeefi: Àdììtú tó rọ̀ mọ́ ìdí tí ìlú Okeluse ṣe fi ọmọ ọdún 16, tó wà ní JSS 2 jọba
Gẹgẹ bii ohun to sọ, lẹyin na ni awọn janduku naa lọ sile ọkunrin kan, Alhaji Makwashe Nhuche to jẹ oniṣowo, ti wọn si ji okunrin ati obinrin kan gbe nibẹ.
O ni nnkan bii aago mẹta owurọ  si aago mẹrin idaji ni awọn janduku naa ṣọṣẹ naa.
Kii ṣe igba akọkọ ree ti awọn janduku yoo ji awọn eeyan gbe tabi kọlu agọ ọlọpaa nipinlẹ Zamfara, ijọba ipinlẹ ọhun si sọ pe adiyẹ oun n laagun, ṣugbọn iyẹ ara rẹ ni ko jẹ ki awọn ọmọ Naijiria mọ.
Ki lo ti ṣẹlẹ ṣaaju?
Oríṣun àwòrán, Muhammed Maradun
Ero gomina ipinlẹ Zamfara, Bello Matawalle ati ile iṣẹ ọlọpaa ṣọtọtọ lori ati dóòlà akẹ́kọ̀ọ́ mẹtalelaadọrin ti ile ẹkọ gírámà ilu Kaya ni ijọba ibilẹ Maradun ipinlẹ naa.
Lẹyin ọjọ marun ùn ti awọn akẹkọọ ile ẹkọ eto ọgbin ati ìmọ nípa ẹranko tó wà nílùú Bakura gb'ominira lọwọ awọn ajinigbe, ni iṣẹlẹ yii tun ṣẹlẹ.
Iroyin sọ pé nínú yara ikawe lawọn akẹ́kọ̀ọ́ ọhún wá, ti awọn janduku ajinigbe yìí fi dé, ti wọn sì gbe wọn lọ.
Olugbe ilu Kaya, Mallam Abu Kaya ṣàlàyé pe o ṣeéṣe kí àwon akẹ́kọ̀ọ́ ti wọn gbé lọ to ọgọrun.
Àmọ́, ile iṣẹ ọlọpaa ipinlẹ Zamfara ní mẹtalelaadọrin awọn akẹkọọ ti wọn jigbe lọ.
Abu fikun ọrọ rẹ pé, alupupu lawọn ajinigbe naa gbe wá sí ile ẹkọ ọhun.
Femi Branch: Gbogbo dúkìá mi àti ti ìyá mi ni mo tà láti tọ́jú ẹsẹ̀ mi fún ọdún méjì
"Abu ṣàlàyé pe ""awọn janduku ajinigbe yìí di gbogbo ọnà tó lọ sí ile ẹkọ naa, wọn sì bẹrẹ si ni yinbọn lati d'ẹru ba awọn eeyan."
Nibi ti awọn kan ti n yinbọn, lawọn mii ninu wọn ti wọ ile ẹkọ naa lọ lati gbe awọn akẹẹkọ ọhun.
Ẹwẹ, Gomina Matawalle ti wa rọ àwọn eeyan ipinlẹ Zamfara lati lo gbogbo ohun ìjà ti wọn ba ni, lati doola ara won lọwọ awọn janduku ajinigbe.
"Lati oni lọ, mo fẹ ki ẹ maa tu yaya jade doju ija kọ awọn janduku ajinigbe.
Ẹ ko gbọdọ sun ti ẹ ba ti gbọ pe awọn janduku ajinigbe n bọ wa si abule yin.
Ẹ mura silẹ dè wọn pẹlu ohun ija ti ẹ ba ni lọwọ.
A ko gbọdọ ṣojo mọ pẹlu ọrọ awọn janduku ajinigbe yìí, kì wọn le mọ pe a le bawọn ja, Matawalle lo sọ bẹẹ."
Nítorí kí aafa lè máa rí iṣẹ́ ṣe ní wọ́n kò ṣe kó Alumaajiri nílẹ̀ tó fi di ohun tó dà yìí
Amọ, ile iṣẹ ọlọpaa ipinlẹ Zamfara ti bẹbẹ adura, ki igbiyanju awọn ọm'ogun ati agbofinro lati doola awọn akẹẹkọ ti wọn jigbe le yọri sí rere.
Alukoro ile iṣẹ ọlọpaa ipinlẹ Zamfara, Mohammed Shehu rọ àwọn obi ninu atẹjade to fi sita pe, ki wọn maa gbàdúrà, ki wọn sì ṣe suuru bi awọn ọlọpaa ṣe n gbiyanju lati doola awon ọmọ wọn.
Bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé gómìnà ìpínlẹ̀ Imo fi ọkàn àwọn ará ìlú balẹ̀ pé kí olúkúlùkù lọ sí ibi iṣẹ́ òòjọ́ wọn, síbẹ̀ wọ́n ni ó sàn kí àwọn pàdánù iṣẹ́ òòjọ́ àwọn ju kí àwọn sọ ẹ̀mí nù lọ.
Gbogbo àwọn awakọ̀ nipinlẹ naa pẹ̀lú lo gbe ilé wọn jòkó, tí wọ́n sì sọ gbogbo àwọn arìnrìn-àjò sì kolobo.
Ṣáájú ni àwọn ọmọ IPOB ti sọ fún àwọn ọmọ Igbo pé kí olúkúlùkù jòkó sílè láti fi ẹ̀honu hàn lórí bí wọ́n ṣe tí aṣáájú wọn nínú ìjìjàgbara Nnamdi Kanu mọ́lé fún ẹ̀sùn ṣíṣe lòdì sí oríléedè rẹ̀, tí ó sì ń bá ìjọba àpapọ̀ jẹ́jọ́ n'ilu Abuja.
Bakan naa ni wọ́n ṣe kóníléógbéle náà ni ọjọ́ Kẹ̀sán oṣù kẹjọ, tí ọ̀pọ̀lọpọ̀ ènìyàn sì bàa lọ, ọ̀pọ̀ dúkìá ló ṣòfò pẹ̀lú.
Ní Ìpínlẹ̀ Ebonyi, gómìnà David Umahi tilẹ̀ sọ pé òṣìṣẹ́ tó bá kọ̀ láti wá síbi iṣẹ́ yóò pàdánù iṣẹ́, síbẹ̀ wọ́n gbà láti pàdánù iṣẹ́ tí ó fi mọ́ àwọn òṣìṣẹ́ ilé epo gómìnà fúnra rẹ̀.
Làsìkò tí wọ́n ni àwọn IPOB ń fi dandan mú àwọn ènìyàn láti tẹ̀lé òfin kóníléógbéle ni agbègbè Umuonyewere Umuowa ni ìjọba ìbílẹ̀ Ngor Opala, ìpínlẹ̀ Imo, ni àwọn àti sọ́jà kọjú ìbọn sí ara wọ́n ti àwọn mẹ́ta sì bá ìṣẹ̀lẹ̀ náà rin.
Àwọn tí ọ̀rọ̀ náà sójú wọ́n ṣàlàyé pé àwọn tó ń lọ láti ojúlé dé ojúlé yìí ń jà àwọn ènìyàn lólè.
Ó ní àwọn sójà kojú àwọn jàndùkú náà nílé epo kan nibí ti wọ́n ti ń jà ilé epo náà lólè owó àti fóònù.
Ọkọ̀ méjì tó fi mọ́ Rav4, ìbọn ìbílẹ̀, àwọn oògùn olóró nọ́mbà ọkọ̀ méjì ni wọ́n rí gbà lọ́wọ́ wọn.
Grace Oyin Adejobi: Bí mo bá tún ayé wá, ọkọ mi ni màá padà fẹ́
Ni ìpínlẹ̀ Imo yìí bákan pàápàá jù lọ ní Àwo Omamma, ìjọba Ìbílẹ̀ Oru East náà, ni wọ́n ti dáná sun ọkọ̀ tó ń kó ìwé ìròyìn lọ agbègbè naa.
"Gẹ́gẹ́ bi nǹkan tí awakọ̀ náà, Lateef Akanbi sọ, ""wọ́n dá mi dúró, ṣùgbọ́n bí mo ṣe rí pé jàndùkú ni wọ́n, pé wọn kii se ọlọ́pàá, mo bẹ́ wọ igbó ni,"
mo ti lọ sá pamọ́.
Láti jìnà ni mo ti gbọ́ tí wọ́n sọ pé ‘mú ẹgbẹ̀rún lọ́nà ọgọrun wá’, ó kó sí owó kankan lọ́wọ́ mi, mi ò jáde kúrò nínú mọ́tò, nnkan ti mo kan rí ní pe wọ́n ti dáná sí mọ́tò.
Agbenusọ fún ilé iṣẹ́ ọlọ́pàá ìpínlẹ̀ Imo, Michael  Abattam ni ìwádìí tí bẹ̀rẹ̀, nítorí pé ọ̀daràn ni àwọn tó kú, ìwádìí wá ń lọ lọ́wọ́.
Ẹ̀wẹ̀ ni Nsukka ni ìpínlẹ̀ Enugu, àwọn egungun lo ń yíde láti pọ́n ni dandan fún àwọn ènìyàn láti jòkó sile.
Bí ó tílẹ jẹ́ pé wọ́n ti dáwọ́ òfin kóníléógbélé ọjọọjọ́ Ajé dúró, síbẹ̀ ọ̀pọ̀ ni ẹ̀rù ń bá láti jáde lọ wá oúnjẹ òòjọ́ wọn.
Gbogbo òpópónà lọ dá páropàro.
Oba Ogboni: Bí ìwọ́de Yoruba Nation bá tún wáyé, màá bá wọn kópa níbẹ̀
Sunday Igboho: Yorùbá yóò gba òmìnira láìpẹ́, ó dá mi lójú
Oríṣun àwòrán, sunday_igboho1
Ajijagbara fun ilẹ Yoruba, Sunday Igboho ti sọ pe o da oun loju pe ipe fun orilẹede Oduduwa, Yoruba Nation yoo wa si imuṣẹ laipẹ.
Sunday Igboho to sọrọ lati ẹwọn ni orilẹede Benin Republic ni agbẹnusọ rẹ, Olayomi Koiki, fi isẹ rẹ jẹ fawọn ololufẹ rẹ.
Ninu ọrọ rẹ, Koiki ni Sunday Igboho ni ki oun dupẹ fun awọn adari ni ilẹ Yoruba ati kaakiri orilẹede Naijiria to ṣe atilẹyin fun oun, paapaa ni asiko ti oun wa ni panpẹ ni orilẹede Benin Republic.
Lara awọn ọba ti Igboho ni ki wọn dupẹ lọwọ rẹ ni Ooni of Ife, Oba Enitan Ogunwusi; Osile ti Oke Ona ilẹ Egba, Oba Adedapo Adewale Tejuoso; Olugbon of Orile Igbo, Oba Francis Alao.
Bakan naa ni Igboho ni ki wọn dupẹ lọwọ gbajugbaja ọjọgbọn ati onkọwe Wole Soyinka, Aarẹ orilẹede Benin Republic, Patrice Talon ati Minisita fun eto idajọ lorilẹede Benin Republic.
Grace Oyin Adejobi: Bí mo bá tún ayé wá, ọkọ mi ni màá padà fẹ́
Sunday Igboho ni afojusun oun ni pe bi orilẹede Benin Republic ti oun ti wa ni atimọle ṣe n gbadun ina ọba loore-koore, naa ni ilẹ Yoruba yoo ma gbadun rẹ lẹyin ti ominira ba de.
''Baba wa fi ikini ranṣẹ si gbogbo ọmọ Yoruba kaakiri agbaye.
Bakan naa lo fi ikini ranṣẹ si Ooni ti Ile Ife, Adeyeye Ogunwusi, fun aduroti ati atilẹyin wọn fun oun, nitori iyawo oun jiṣẹ wọn fun oun ni gbogbo igba.
O ni ki n ki Ọba Olugbọn pẹlu Ọba Tejuosho naa to ti wa ni orilẹede Benin Republic lọwọ bayii, amọ ti awọn ko i tii ri ara wọn.
Sunday Igboho ni ki n dupẹ lọwọ Ọjọgbọn Agba ati Onkọwe Wole Soyinka, aarẹ ilẹ Benin Republic ati minisita fun eto idajọ fun bi wọn ṣe pese aabo to peye fun iyawo Sunday Igboho lai jẹ ki ibi kankan sun mọ iyawo naa.''
Rashidi Ladoja: Ẹ jẹ́ kí Bùhárí gbá'pòtí ìbò, bóyá yóò borí
Bakan naa lo ni ki a wo bi Benin ṣe n jẹ igbadun ina ọba ni gbogbo igba eleyii to ṣọwọn ni Naijiria. Amọ Yoruba Nation yoo gbadun ina ọba bi eyi lẹyin ti wọn ba ṣe aṣẹyọri pẹlu gbigba eto wọn si ominira lọwọ ijọba Naijiria.''
Ikọ ọtẹlẹmuyẹ lorilẹede Naijiria lo fi panpẹ ọba mu Igboho ati iyawo rẹ ni Cotonou, Benin Republic ni ọjọ kọkandinlogun, Oṣu Keje, lẹyin to sakuro ni Naijiria lati bọ lọwọ ajọ ọtẹlẹmuyẹ ti wọn n wa naa.
Ajọ DSS lo yabọ ile Igboho ni ilu Ibadan, ti ẹmi sọfo ti wọn si mu lara awọn alatilẹyin rẹ, amọ ti wọn ko ri Igboho mu ni ilẹ rẹ.
Lẹyin naa ni Agbẹnusọ Ajọ DSS fi atẹjade sita wi pe ijọba orilẹede Naijiria n wa Sunday Igboho ki o si jọwọ ara rẹ lai si rogbodiyan nitori ọwọ yoo tẹ bi o fẹ bi o kọ.
Laipẹ naa ni ọwọ tẹ Sunday Igboho ati iyawo rẹ ni orilẹede Benin Republic lasiko ti oun ati iyawo rẹ n gbiyanju lati salọ si orilẹede Germany.
Amọ, iyawo Igboho gba itusilẹ kuro ni panpẹ ọlọpaa nigba ti Igboho ṣi wa ni atimọle ni orilẹede Benin Republic.
Oba Ogboni: Bí ìwọ́de Yoruba Nation bá tún wáyé, màá bá wọn kópa níbẹ̀
LASTMA: Àwọn awakọ̀ fí ẹ̀sùn kan awọn Taskforce, LASTMA pé wọ́n n gba owó gọbọi lọwọ wọn
Oríṣun àwòrán, LASTMA
Ileeṣẹ to n risi ọrọ oju popo nipinlẹ Eko, LASTMA ti ni awọn ko ni nkankan ṣe pẹlu ẹsun gbigba owo lọna aitọ lọwọ awọn awakọ nipinlẹ Eko.
Adari eto irina ni ileeṣẹ LASTMA, Bolaji Oreagba lo sọ bẹẹ lẹyin ti awọn awakọ da iṣẹ silẹ ni Ọjọ Aje kaakiri ipinlẹ Eko.
Oreagba lasiko to n ba BBC Yoruba sọrọ ni, ọrọ ko ri bẹẹ nitori awọn ko gba owo lọna aitọ lọwọ awọn awakọ, iṣẹ awọn ni awọn n ṣe.
O ni LASTMA ko ni nnkan ṣe pẹlu wọn, awọn Ajọ Taskforce nipinlẹ Eko to n gba owo ode lọwọ awọn awakọ, ni wọn koju ija si.
''Lootọ ni awọn awakọ da iṣẹ silẹ nipinlẹ Eko nitori ẹsun pe awọn taskforce n gba owo gọbọi lọwọ wọn ni ojoojumọ, amọ kii ṣe awọn LASTMA ni wọn fi ẹsun kan.''
Oríṣun àwòrán, OTHERS
''A ti kilọ fun awọn awakọ ati Taskforce ki wọn ma da omi alaafia ipinlẹ Eko ru, nitori naa ni a ṣe dasi ọrọ wọn kii ṣe pe awa ni wọn fi ẹsun kan.''
Ohun ti awọn awakọ ati arinrinajo sọ nipa idaṣẹsilẹ awọn awakọ nipinlẹ Eko
Awọn arinrinajo ni agbegbe Ikorodu nipinlẹ Eko fi ẹṣẹ rin ọpọlọpọ mile ni Ọjọ Aje lẹyin ti awọn awakọ daṣẹ silẹ, ti wọn si wa ọkọ wọn gunlẹ ni ipinlẹ Eko.
Ẹsun ti awakọ fi kan awọn Taskforce to n gba owo ode nipinlẹ Eko ati LASTMA ni pe owo ti wọn n gba ni ọwọ wọn ti poju ni ojoojumọ, lai tilẹ ro ipalara ti awọn eniyan n la kọja.
Iroyin ni awọn eniyan rin ọna jinjin bii Jibowu, Maryland, Ikeja nitori ko si ọkọ ti awọn eniyan yoo wọ, nitori awọn awakọ naa wa ọkọ gunlẹ, ti wọn ko si jẹ ki awọn awakọ akẹgbẹ wọn kankan ṣiṣẹ.
Wọn fi ẹsun kan LASTMA pe awọn ofin oju popo ti ohun pin awọn awakọ lẹmi ni wọn ma n pa laṣẹ fun wọn ni oju popo.
Kola Tubosun: Ọ̀pọ̀ ọmọ òyìnbó ló ń kọ́ èdè Yorùbá, ẹ̀yin ọ̀dọ́ ẹ gbé èdè abínibí lárugẹ
Afenifere: Ilana Omo Oodua ati Babatunde Gbadamosi fara mọ pé láìsí ìwé òfin tuntun, Yorùbá ń lọ
Oludije fun ipo gomina tẹlẹ f'ẹgbẹ oṣelu PDP nipinlẹ Eko, Ọgbẹni Babatunde Gbadamosi ti fẹnu kò pẹlu ẹgbẹ Afenifere lati pe fún ìwe ofin tuntun fún orilẹ-ede Naijiria ṣaaju idibo ọdun 2023.
Gbadamosi sọ fún BBC Yoruba pe, ayé sì wà fun ijọba to wa lóde lati ṣe ayipada iwe ofin Naijiria ṣaaju igba ti eto idibo gbogbogbo yóò fi waye lọdun 2023.
"Ijọba ologun lo ṣe agbekalẹ iwe ofin ti a n lo lọwọ yii, Wọn kan kọọ sibẹ pe awa ọmọ Naijiria lo gbe ofin yii kalẹ lati maa dari wa.
Ṣugbọn kii ṣe awa araalu lo ṣe agbekalẹ ofin naa. Aarẹ Naijiria ni ààrẹ to lagbara julo Lagbaye nitori bi iwe ofin ilẹ wa ṣe rí náà ni.
Ẹ jẹ ki a pada si iwe ofin Naijiria odun 1963. Ko sí Iyanjẹ níbẹ, ẹkun kọọkan lo n ṣe amojuto ẹkun rẹ pẹlu awọn nkan alumoni ti wọn ni.
Kola Tubosun: Ọ̀pọ̀ ọmọ òyìnbó ló ń kọ́ èdè Yorùbá, ẹ̀yin ọ̀dọ́ ẹ gbé èdè abínibí lárugẹ
Ṣugbọn bayii, gbogbo owo ori ti a ba san nipinlẹ Eko fún àpẹrẹ, Abuja ni wọn n ko o lọ.
Nitori naa, mo faramọ ki ijọba gbe iwe ofin tuntun jade ṣaaju eto idibo 2023, Gbadamosi ṣalaye."
Ẹwẹ, agbẹnusọ ẹgbẹ Ilana Omo Oodua, Maxwell Adeleye náà tún fìdí rẹ múlẹ fún BBC Yoruba pe ko ní sí ibo lọdun 2023, Lai sí iwe ofin tuntun àti atunto orilẹ-ede Naijiria.
Ọgbẹni Adeleye ni eto idibo lati beere lọwọ awọn ọmọ Naijiria Iori bo ya won sì fẹ tẹsiwaju gẹgẹ bí orilẹ-ede kan gbọdọ wáyé ṣáájú ibo ọdún 2023.
"Ijebu ati Oyo ba n ba ara wọn já, a o yanju rẹ ni itubi inubi tori èdè kan ni a n jọ n sọ.
Ṣugbọn iru rẹ ko le ṣeeṣe lọwọ yii nitori ede wa ko ye ara wa.
Oorun to wa loke si to aṣọ sa, aye sì wà láti ṣe agbekalẹ ofin tuntun ṣaaju eto idibo ọdun 2023.
Ìjọba kò le na idaji owo to ti na lori àtúnṣe iwe ofin Naijiria to n ṣe lọwọ lori agbekalẹ iwe ofin tuntun.
UK ti yapa kúrò lára ajọ EU, Yoruba naa lè yapa kúrò lára Naijiria.
Bi Naijiria ṣe wa yii ko le ṣiṣẹ, ko pe wa, Adeleye ṣalaye."
Saaju la ti mu iroyin wa fun yin pe, ẹgbẹ Afenifere tun ti ke sawọn ọmọ Naijiria lati maa daabo bo ara wọn lọwọ awọn agbebọn nitori wsn ti kede ogun nilẹ yii.
Bakan naa lo ni eto atunto orilẹede yii gbọdọ wa, lati yanju awọn isoro to n ba Naijiria finra ki eto idibo to n bọ to le waye.
Awọn ọrọ yii lo jẹyọ ninu abajade ti ẹgbẹ naa fisita lẹyin ipade wọn to waye nilu Ijebu Ode lọjọ Isẹgun nile Oloye Ayo Adebanjo, tii se adele alaga wọn.
Atẹjade naa ti akọwe apapọ fun ẹgbẹ Afenifere, Jare Ajayi fisita tun ni ke sawọn agbofinro lati dẹkun bi ọpọ eeyan ti iwa wọn ko tọ se n wọ ilẹ yii wa.
O ni eyi ni yoo wawọ awọn isẹ ibi to n gogo ni orilẹede yii bolẹ.
"Ẹgbẹ Afenifere ri pe awọn iwa idunkooko mọ ni to fi mọ ijinigbe ti n di tọrọ fọn kale, to si n kọ ni lominu, ti awsn eeyan wa ni Yewa, Oke Ogun atawọn agbegbe miran si n lọ fi tipa se atipo ni orilẹede Benin.
O yẹ ki ijọba atawọn agbofinro tete gbe igbesẹ lati fopin si eyi, ko si fi aabo ẹmi ati dukia to daju mulẹ.'
Ẹgbẹ naa tun wa kesi ijọba lati ri pe aabo to daju wa fun awọn eeyan to n gbe ni awọn ẹnu bode to wa ni Kogi, Oyo, Ogun, Kwara, Osun, Ekiti ati Ondo.
Bakan naa ni wọn ni iwaasu ti Afenifere yoo ma se kiri bayii ni pe ko si iwe ofin tun, ko si ibo lọdun 2023, nitori fifi akoko sofo ni ba ba se ibo pẹlu ofin ọdun 1999.
Ẹgbẹ naa tun wa kede pe gba gba gba ni oun wa lẹyin awọn gomina lẹkun guusu Naijiria ti wọn fi ofin de asa dida ẹran jẹko nigboro eyi to n gbera sọ lonii.
Bẹẹ ni wsn tun se sadankata si awsn gomina ilẹ Yoruba fun bi wọn se se agbekalẹ ikọ alabo Amotekun.
Nítorí kí aafa lè máa rí iṣẹ́ ṣe ní wọ́n kò ṣe kó Alumaajiri nílẹ̀ tó fi di ohun tó dà yìí
Kola Tubosun: Ọ̀pọ̀ ọmọ òyìnbó ló ń kọ́ èdè Yorùbá, ẹ̀yin ọ̀dọ́ ẹ gbé èdè abínibí lárugẹ
Onimọ nipa ede Yoruba kan, to tun n kọ awọn akẹkọọ fasiti ni ede Yoruba lorilẹ-ede AMẹrika, Kola Tubosun ti ke si awọn ọdọ lati gbe ede abinibi larugẹ.
Tubosun, ẹni to ti tumọ ọpọ ewi lede oyinbo si ti Yoruba lo kede bẹẹ lasiko to n ba BBC Yoruba sọrọ lori bi ede abinibi wa se n wọọkun.
Bakan naa lo ni o yẹ ki gbogbo ọmọ Yoruba gbe ede wọn larugẹ niwọn igba ti awsn ọmọ oyinbo n laagun lati gbọ ede abinibi tiwa.
O fikun un pe ta ba sọra, afaimọ ko ma jẹ pe awọn ọmọ oyinbo ti oun n kọ nisẹ, ni yoo pada wa maa kọ awọn ọmọ wa ni amulo ede Yoruba pada.
Onkọwe ati atumọ ede naa tun rọ awọn ọmọ Naijiria lati mase maa fi oju abuku wo aarẹ wa, to ba gba lati fi ede abinibi wa sọrọ ni ipade awọn orilẹede lagbaye.
Kola Tubosun wa gba ijọba nimọran lati gba awọn olukọ laaye lati maa fi ede abinibi kọ awọn akẹkọọ, ki eto ẹkọ kikọ le ye wọn daadaa.
Bakan naa lo kede pe ki wọn fun awọn akẹkọọ jade nile ẹkọ girama laaye lati maa fi ede abinibi kọ awọn idanwo asejade bii WAEC ati JAMB.
Covid-19 Vaccination: Bí àwọn aráàlú kan ṣe fara mọ́ ṣíse àbẹ́rẹ́ àjẹsára ní ọ̀rànyàn ní àwọn míì ta kò ó
Oríṣun àwòrán, State House
Ọkanojọkan ariwisi ti n waye lori igbẹsẹ ti ijọba fẹ gbe lati kan abẹrẹ Covid-19 nipa fun gbogbo eeyan ilu.
Laipẹ yii ni awọn ijọba ipinlẹ kan kede rẹ pe ẹni ti ko ba tii gba abẹrẹ naa ko ni lanfani lati ba awọn eeyan pejọ pọ ni awọn ile ijọsin bi i Mọṣalaṣi tabi Ṣọọṣi.
BBC Yoruba jade lọ si igboro lati gbọ ti ẹnu ara ilu lori igbesẹ naa, bẹẹ ni wọn ba akọroyin wa sọ ọpọlọpọ ọrọ ti ilẹ si kun.
Arakunrin kan ti o ba wa sọrọ fi idi rẹ mulẹ wi pe, oun ko ti i gba abẹrẹ naa, bẹẹ si ni oun ko ni aniyan lati gbaa nitori ijọba orilẹede Naijiria n fi iya jẹ ara ilu.
O tẹsiwaju wi pe, ọrọ abẹrẹ kọ lo ku lọrọ orilẹede Naijira biko ṣe igbesẹ ti yoo mu ki ara tu gbogbo eeyan ilu.
Oba Ogboni: Bí ìwọ́de Yoruba Nation bá tún wáyé, màá bá wọn kópa níbẹ̀
Ọkunrin mii to ba wa sọrọ ṣe alaye wi pe, ko si ohun to buru ninu igbesẹ naa nitori irọrun igi ni irọrun ẹyẹ.
O ni gbogbo eeyan lo yẹ ki o gba abẹrẹ naa ,ti ijọba ba le fi idi ẹ mulẹ wi pe ko ni ṣe ijamba si agọ ara ẹnikẹni.
A tun ba awọn obinrin naa sọrọ lasiko ti a wa nigboro.
Ọkan ninu wọn ni ko ṣeeṣe ki ijọba ni ki awọn eeyan ma lọ si ile ijọsin nitori aigba abẹrẹ COVID-19.
O ni Iroyin ti awọn n gbọ ni pe awọn eeyan to gba abẹrẹ naa n ṣaisan, bo tilẹ jẹ pe ko si ayẹwo to fi idi ọrọ yii mulẹ.
Oríṣun àwòrán, Reuters
Obinrin ẹlẹẹkeji to ba wa sọrọ fi kun alaye naa wi pe ko tọ ki a maa gba abẹrẹ COVID-19 nitori pe ibinu Ọlọrun ni ajakalẹ aarun naa. O ni dipo ki a maa gba abẹrẹ naa, ohun ti o tọ ni ki a ra ọwọ ẹbẹ si Ọlọrun pe ki o dari ẹṣẹ jin orilẹede Naijiria.
Arabinrin naa tẹsiwaju pe ohun kan ṣoṣo to le mu ki oun gba abẹrẹ naa ni ti Pasitọ awọn ni ṣooṣi ba kọkọ gbaa.
O ṣeeṣe ki ijọba apapọ atawọn oṣiṣẹ lẹka eto ilera lorilẹede Naijiria bii NMA, JOHESU ati bẹẹ bẹẹ lọ o forigbari laipẹ lori kikan abẹrẹ ajẹsara COVID-19 nipa.
Ijọba apapọ yan an lọjọ Iṣẹgun pe o ṣeeṣe ki oun bẹrẹ si ni ba ẹnikẹni to ba kuna ati gba abẹrẹ ajẹsara naa wi lẹyin ti ijọba ba ti pese rẹ si arọwọto awọn gbogbo eeyan.
Oludari agba fun ajọ eto ilera alabọde lorilẹede Naijiria, NPHD, Faisal Shuaibu lo yan ọrọ naa, nibi ipade kan to ṣe pẹlu awọn akọroyin nilu Abuja.
Bakan naa ni ile ẹjọ giga apapọ kan nilu PortHarcourt nipinlẹ Rivers, ti ka gomina ipinlẹ Edo, Godwin Obaseki lọwọ ko pe ko gbọdọ sọ gbigba abẹrẹ ajẹsara di ọranyan ni ipinlẹ naa.
Awọn ẹgbẹ dokita, NMA pẹlu ẹgbẹ apapọ awọn oṣiṣẹ lẹka eto ilera, JOHESU ti faake kọri lori ọrọ yii.
Kola Tubosun: Ọ̀pọ̀ ọmọ òyìnbó ló ń kọ́ èdè Yorùbá, ẹ̀yin ọ̀dọ́ ẹ gbé èdè abínibí lárugẹ
Bi ẹgbẹ awọn dokita ni Naijiria, NMA ṣe n sọ pe araalu ni ẹtọ lati kọ gbigba abẹrẹ ajẹsara naa, gẹgẹ bi ẹtọ ṣe wa fun wọn lati kọ gbigba itọju ilera.
Bakan naa ni ijọba ipinlẹ Ondo naa paṣẹ lọjọ Aje pe, bo pẹ bo ya, awọn yoo fofin de gbogbo awọn ti ko ni ẹri gbigba abẹrẹ ajẹsara naa pe wọn ko gbọdọ wa si mọṣalaṣi, ṣọọṣi ati awọn ibudo ita gbangba miran.
Ni tirẹ Oludari agba fun ajọ eto ilera alabọde lorilẹede Naijiria, NPHD, Faisal Shuaibu ni awọn ti ko gba abẹrẹ naa n ṣe akoba fun awọn eeyan miran lawujọ ni.
O ni ko si igba ti ijọba ko ni tọ ipasẹ ipinlẹ Edo ati Ondo lori ọrọ naa lati lo ilana ofin lori wọn.
Amọṣa ẹgbẹ apapọ awọn oṣiṣẹ lẹka eto ilera, JOHESU ni igbesẹ ti ijọba n gbero naa ko mu ọgbọn dani rara.
Agbẹnusọ fun ẹgbẹ JOHESU, Olumide Akintayọ ni o di igba ti abẹrẹ ajẹsara naa ba pọ to fun araalu ki irufẹ igbesẹ naa to lee mu ọgbọn dani bi o ti wulẹ o mọ.
Grace Oyin Adejobi: Bí mo bá tún ayé wá, ọkọ mi ni màá padà fẹ́
Buhari: Femi Falana ní àṣírí ti tú pé $2.1bn owó ohun ìjagun làwọn ọ̀gá ológun pín mọ́ ara wọn lọ́wọ́
Oríṣun àwòrán, Nigeria Army
Gbajugbaju amofin agba Femi Falana ti kọ iwe si aarẹ Muhammadu Buhari lati siju aanu to awọn ọmọ ologun aadọrin ti wọn dajọ iku fun lasiko ijọba Goodluck Jonathan.
Bakan naa ni Falana tun n bẹ aarẹ pe bo se n dari jin awọn ọmọ ikọ afẹjẹwẹ Boko Haram to ronu piwada, naa ni ko dari jin awọn ologun naa.
Falana ni laarin ọdun 2013 si 2014 ti ilẹ wa n jagun Boko Haram, awọn ohun ija ti ko ba igba mu ni wọn ko le awọn sọja lọwọ lati lọ koju awọn ikọ mujẹmujẹ to dihamọra gidi.
O fikun pe awọn sọja naa lo beere fun awọn ohun ija to poju owo lati daabo bo ilẹ yii lọwọ ileesẹ ologun amọ se ni wsn sọ tiwọn di ẹbi, ti wsn si fi iya nla jẹ wọn.
Dipo ki wọn dahun ibeere awọn sọja naa, se nileesẹ ologun fi ẹsun kan wọn pe agbẹyinbẹbọjẹ ni wọn nidi ogun ti Naijiria n gbe ti Boko Haram, ti wọn si ni ki wọn foju wina ofin."
Femi Branch: Gbogbo dúkìá mi àti ti ìyá mi ni mo tà láti tọ́jú ẹsẹ̀ mi fún ọdún méjì
Mo gbẹnu sọ fun mejidinlọgọta ninu wọn, nigba ti awọn lọya mii duro fun awọn mejila to ku nile ẹjọ ologun nilu Abuja laarin osu kẹjọ si ikejila ọdun 2014.
"Amọ sibẹ ileesẹ ologun dajọ iku fun awọn aadọrin sọja naa fun iwa iditẹ mọ orilẹede wọn."""
Amofin agba naa tun ran aarẹ leti nipa iwadi to se nigba to gori aleefa ti fidi rẹ mulẹ pe owo to le ni biliọnu meji ati miliọnu lọna ọgọrun Dọla, to yẹ ki ileesẹ ologun Naijiria fi ra ohun eelo ijagun lawọn ọga ologun da gba ibomiran lọ.
O ni abọ iwadii yii lo wa safihan pe awọn aadọrin sọja naa ko ni ẹbi nipa ibeere wọn fun ipese ohun ijagun to poju owo lati doju kọ ikọ Boko Haram.
Falana wa rawọ ẹbẹ si Buhari pe ko fi awọn aadọrin sọja naa silẹ ki wọn maa lọ ni alaafia lai ni ẹsun kankan lọrun.
Oríṣun àwòrán, other
Nipinlẹ Ọyọ ẹnikẹni ti idi ba yun, to wa lọ ṣegbọnṣẹ si ita gbangba, ẹgbẹrun marun 5000 owo itanran ni yoo san.
Ile aṣofin ipinlẹ Ọyọ lo buwọlu aba ofin tuntun naa to wa lori didena ṣiṣe gaa si gbangba ode.
Olori ile aṣofin ipinlẹ Ọyọ, Họnọrebu Adebọ Ogundoyin ṣe apejuwe iwa ṣiṣe gaa si ita gbangba, gẹgẹ bi eyi ti ko ba igba mu mọ ti wọn gbọdọ fi opin si lawujọ, yatọ si pe o n ti igi bọ oju eto ilera lawujọ.
Họnọrebu Ogundoyin woye pe o le ni ọgọrin aba ofin ti awọn ti buwọlu lati igba ti awọn ti wọle ni nnkan bi ọdun meji o le diẹ sẹyin ṣugbọn aba ofin yii, gẹgẹ bi o ṣe sọ ṣe pataki pupọ gẹgẹ bi igba ọtun ni ipinlẹ Ọyọ.
"Awọn eeyan wa gbọdọ dẹkun jiju imi kaakiri. Iwa yii a maa tan ajakalẹ arun kiri, idi si niyi ti ofin tuntun yii fi jade lati dẹkun iwa ibajẹ naa.
Aba ofin yii sọọ di ẹṣẹ fun ẹnikẹni lati ṣe gaa sita, ijiya to si wa fun un ni owo itanran ẹgbẹrun marun un naira tabi ijiya iṣẹ ilu fun ọsẹ kan gbako."
Kola Tubosun: Ọ̀pọ̀ ọmọ òyìnbó ló ń kọ́ èdè Yorùbá, ẹ̀yin ọ̀dọ́ ẹ gbé èdè abínibí lárugẹ
Pẹlu agbekalẹ ofin yii bayii, o ti di ọranyan fun awọn ileeṣẹ ati onile gbogbo lati maa kọ ile igbọnsẹ si ile tabi ibi iṣẹ wọn.
Ẹnikẹni to ba kuna eyi bayii yoo fara gba owo itanran ẹgbẹrun lọna aadọta tabi ẹwọn oṣu mẹta bẹẹni ileeṣẹ to ba kuna ati kọ ile igbọnsẹọ yoo fara gba owo itanran ẹgbẹrun lọna igba naira.
Bakan naa lo fi kun un pe ẹnikẹni to ba ṣeto ayẹyẹ ita gbangba lai ṣe ipese fun ile igbọnsẹ alagbeka, iru ẹni bẹẹ tabi ileeṣẹ bẹl yoo fara gba owo itanran ẹgbẹrun lọna ọgọrun naira.
Anti- Opening Grazing law: Ìpínlẹ̀ Eko, Oyo, Ekiti, Osun, Ogun ati Ondo fi òfin de ìwà fífi màálù jẹ oko
Oríṣun àwòrán, Others
Iroyin ayọ lo jẹ pe o di ẹsẹ bayii fun ẹnikẹni lati mase da ẹran jẹ oko mọ yika ilẹ Yoruba lapapọ.
Idi ni pe gbogbo awọn ipinlẹ to wa ni Kaarọ Oojire ni wọn ti buwọlu abadofin ma fi ẹran jẹko mọ fun awọn darandaran lati gbogun ti iwa ipaniyan, ijinigbe ati ifipabanilopọ.
Koda, awọn gomina ẹkun iwọ oorun guusu Naijiria yii tun fi ijiya to jopin ti awọn ofin naa lẹyin.
Ipinlẹ Eko si lo gbẹyin ninu awọn ipinlẹ to wa nilẹ Kaarọ oojiire ti wọn ti fi ọwọ si aba ofin naa.
Bẹẹ ba si gbagbe, awọn gomina ẹkun guusu Naijiria lo fi ohun sọkan lati gbe ofin naa kalẹ, to si ti bẹrẹ si fidi mulẹ lati ọjọ Kinni osu Kẹsan ọdun 2021.
Ẹ wo igba ti awọn ipinlẹ nilẹ Kaarọ oojire fi ọwọ si abadofin naa:Iroyin ayọ lo jẹ pe o di ẹsẹ bayii fun ẹnikẹni lati mase da ẹran jẹ oko mọ yika ilẹ Yoruba lapapọ.
Igangan Mayhem: Obìnrin Fulani kan ní òun pàdánù ọkọ, ọmọ mẹ́ta àti gbogbo dúkìá torí ìjà
Gomina ipinlẹ Ondo, Oluwarotimi Akeredolu ni Ọjọ Iṣẹgun, Ọjọ Kọkanlelọgbọn, ọdun 2021 buwọlu ofin to de dida ẹran kaakiri nipinlẹ naa.
Eyi waye lẹyin ọsẹ diẹ ti Ile Igbimọ Aṣofin nipinle naa uwọlu abadofin naa ki wọn to fi ranṣẹ si gomina lati sọ di ofun.
Kọmisọnna nipinlẹ Ondo, Donald Ojogo ni gomina Akeredolu buwolu ni ọfisi rẹ.
Ijọba ipinlẹ Ekiti ti ni gbedeke Ọjọ Kini, Osu Kẹsan an, ọdun 2021 lati gbegile dida ẹran kaakiri ipinlẹ naa ko le e ni ipa lara wọn nitori ofin naa ti fi ẹṣẹ mulẹ nibẹ tẹlẹ.
Ijọba ipinlẹ Ekiti ni labẹ iṣejọba Ayodele Fayoṣẹ nigba to di ipo gomina mu ni ipinlẹ naa ni wọn ti fofin de dida ẹran kaakiri igboro.
Wọn ni ofin naa si fi ẹṣẹ mulẹ ni ipinlẹ naa nitori naa ko si mimi kankan.
Ijọba ipinlẹ Oyo ti ni awọn ti ṣetan lati bẹrẹ si ni fi ẹnikẹni to ba rufin dida ẹran laarin ilu jofin lẹyin ti wọn fi lede pe ọdun 2019 ni wọn ti buwọlu ofin naa ni ipinlẹ naa.
Ijọba ni bio tilẹ jẹpe ko to di asiko yii, ko si ṣiṣẹ ofintoto bọya awọn eniyan n tẹle ofin yii, ohun gbogbo ti yi pada bayii.
Ijọba ni awọn ti gbe Ajọ amuṣẹya Taskforce dide lati ri pe awọn darandaran tẹlẹ ofin naa.
Gomina ipinlẹ Ogun, Dapo Abiodun naa ti buwọlu aba mase da ẹran ko lẹyin osu kan ti Ile Igbimọ Aṣofin ni ipinlẹ naa buwọlu u.
O si ti di eewọ lati da ẹran jẹ oko nipinlẹ Ogun bayii
Gomina ipinlẹ Eko Babajide Sanwoolu ti buwọlu ofin to de fifi ran jẹ laarin igboro ni ipinlẹ Eko.
Ohun ti eyi tunmọ si ni pe ẹnikẹni ti o ba da ẹran jẹ laarin ilu ni itako ofin yoo foju wina ofin.
Gomina buwọlu ofin yi ni ọjọ Aje lẹyin tawọn ọmọ ile aṣofin ipinlẹ naa fi ontẹ jan lẹyin ijiroro ni nkan bi ọsẹ kan sẹyin.
Ni ipinlẹ Osun, lọ fun gomina Adegboyega Oyetola naa ti buwọlu aba mase da ẹran jko, to si ti di ofin bayii.
Abadofin naa ni ile igbimọ aṣofin ọhun buwọlu ni Ọjọ Kejila, Osu Kẹjọ, ọdun 2021.
Lọwọ bayii ẹsẹ ni fun awọn darandaran lati da ẹmaalu yika tibu tooro ipinlẹ Osun.
Oríṣun àwòrán, Bayelsa State Ministry of Agriculture
Sunday Igboho: Alhaji Fatai ti kò ríràn ní ìbọn bà níbí tó ti ń wá ọ̀nà kiri láti sá pamọ́
Oríṣun àwòrán, Olayomi Koiki
Yoruba ni asegbe kankan ko si, asepamọ lo wa.
Idi ree ti asiri se tu nipa eeyan meji to jade laye lasiko ti awọn osisẹ ọtẹlẹmuyẹ DSS se ikọlu sile asaaju ajijagbara fun ilẹ Yoruba, Oloye Sunday Adeyemo, ta tun mọ si Igboho.
Agbẹjọro fun awọn eeyan ti DSS ko nile Sunday Igboho, Amofin Pelumi Olajengbesi lo ti wa sisọ loju rẹ nipa iru iku gbigbona to pa awọn mejeeji naa lọjọ Kinni osu Keje ọdun 2021 ti isẹlẹ naa waye.
Nigba to n ba BBC Yoruba sọrọ, Olajengbesi ni ọkan ninu awọn eeyan naa, ti orukọ rẹ n jẹ Alhaji Fatai ni ko riran bo se yẹ.
Bẹẹ ba si gbagbe, agbẹnusọ fun Sunday Igboho, Olayomi Koiki naa ti sọ saaju lọjọ ti isẹlẹ naa waye pe ori irun kiki ni Alhaji Fatai wa, nigba ti awọn DSS de.
Olajengbesi wa tẹ siwaju pe ni kete ti awọn osisẹ agbofinro naa de, ni ọkunrin yii n tarara kiri lai mọ ibi ti yoo ya si, tori ipenija airiran rẹ.
Ibi ti ọkunrin yii ti n wa ọna ti yoo gba sa pamọ ni ibọn ti awọn osisẹ DSS n yin laibikita ti baa, to si jade laye.
Nigba to tun n salaye bi ẹnikeji, ti ọpọ eeyan mọ si Adogan se ku lati ọwọ osisẹ DSS bakan naa nile Sunday Igboho, Amofin agba naa salaye pe ibi ti ọkunrin naa sa pamọ si ni ibọn ti lọ baa.
Olajengbesi ni ni kete ti awọn osisẹ DSS gunlẹ si ile Igboho ni wọn n yinbọn kiri laibikita, ti wọn ko si fẹ mọ boya ibọn ba ẹnikẹni.
Inu ile iwẹ kan ni Adogan sa pamọ si ki biọn ma baa ba amọ inu baluwẹ ọhun naa ni ibọn ti baa.
Olajengbesi wa ni ọpọ asiri lo wa nilẹ, ti ko tii tu sita nipa iwa ika ti awọn DSS hu nile Sunday Igboho eyi ti ko tii han fun araye.
O si woye pe ọna bi asiri naa ko se ni tu lo mu ki awọn osisẹ DSS yii fi aake kọri lati ko awọn eeyan mẹrin silẹ ninu awọn mejila ti wọn ko nile Igboho.
Saaju ni awọn eeyan ti isẹlẹ ikọlu DSS naa se oju wọn nile Sunday Igboho ti kede pe awọn osisẹ Dss wọ oku awọn eeyan mejeeji naa lọ silu Abuja, ti ẹjẹ ara wọn si n kan silẹ.
Lati ọjọ naa, ko si ẹni to fi oju kan oku wọn titidi oni.
Kola Tubosun: Ọ̀pọ̀ ọmọ òyìnbó ló ń kọ́ èdè Yorùbá, ẹ̀yin ọ̀dọ́ ẹ gbé èdè abínibí lárugẹ
Mike Bamiloye: Inú bí mi sí fíìmù ayé tí Ogunde, Baba Sala àti Ade-Love máa ń ṣe ni mo fi bẹ̀rẹ̀ sinimá ẹ̀mí
Oríṣun àwòrán, Mikebamiloye/Instagram
Gbajúgbajà òṣèré sinimá nilana ẹsin Kristẹni, tii tun se olùdásílẹ̀ ẹgbẹ osere Mount Zion Ministry, Mike Bamiloye, tí ṣàlàyé lórí bí òun ṣe bẹ̀rẹ̀ ṣíṣe sinimá àti àwọn ìpèníjà tí òun ti kojú nígbà náà.
Bamiloye, tii se ẹni ọdún mọ́kànlelọ́gọ́ta náà ló bọ́ sójú òpó instagram rẹ̀ láti ṣàlàyé bí ó ṣe bẹ̀rẹ̀ ìrìnàjò ìdásílẹ̀ ileesẹ iransẹ Mount Zion Ministry.
Ó ní ọmọ ọdún márùn-úndinlọ́gbọ́n ni òun, nígbà tí òun wo fíìmù India kan tí ó ń fi títóbi oṣó àti ajẹ́ hàn nínú sinimá náà, àti pé èyí ló bí òun nínú láti gbaná jẹ fún Ọlọ́run.
"Àkòrí fíìmù náà ni WHEN THE POWER CHANGE Hands"", mo wo sinima naa nígbà tí mo wà ní ọmọ ọdún márùn-úndinlọ́gbọ́n lọdún 1985, mò si ń gbóná fún Ọlọ́run pẹ̀lú ìran àgbàyanu láti sìn."
A ṣẹ̀ṣẹ̀ dá Mount Zion Ministry silẹ ni, a ṣẹ̀ṣẹ̀ ń ṣe ètò ìpàdé àdúrà ni.
Ẹ̀yin olórin ẹ̀mí tó ń bóra, lo èékáná gígùn, oò yàtọ̀ sí aṣẹ́wó hòtẹ́ẹ̀lì tí wọ́n ń gbé bíi súùtì Pepper Menti - Bola Are
Mo ní amóhùnmáwòràn aláwọ̀ dúdú àti funfun nígbà náà, tí mo gbé si ori àpótí nínú yàrá kan tí mo ń gbé.
Ní alẹ́ ọjọ́ kan, mo wo sinimá India kan tí ó sì ká mì lára láti ìbẹ̀rẹ̀ de òpin.
Láti ìbẹ̀rẹ̀ eré náà dé òpin ni mo fi ọkàn sí ṣùgbọ́n nígbà tí mo wòó tán, mo bú sẹ́kún, mo sá lọ sí àárín ọ̀dẹdẹ̀ ilé mi mo wa n kígbe lóhùn rara.
Jésù! lo mi! Jésù! Mo fẹ́ ṣe sinimá fún ọ! Na ọwọ rẹ lé mi kì ó lò mi! Ràn mí lọ́wọ́ láti ṣe sinimá fún ọ!
Bamiloye ni kò ye òun bí òun yóò ṣe wo sinimá tí kìí se tí ẹ̀mí, tí ìsọjí yóò sì bẹ́ sílẹ̀ nínú ayé oun.
Ó ní òun ti o wu òun jùlọ ni láti ṣe sinimá fún Ọlọ́run, ti èyí sì ń gbòòrò sì lojojumọ́
Inú ń bí mi sí gbogbo àwọn sinimá ayé tí wọ́n ń ṣe nígbà yẹn, kò tíì sí Nollywood nígbà náà
Ṣùgbọ́n àwọn sinimá Hubert Ogunde bí Aiye, Jayesinmi, Aropin-Nteniyan, Ayanmo.
"Àti fíìmù Moses Olaiya (Baba Sala) bi: Mosebolatan, Orun Mooru, Diamond, àti àwọn fíìmù tí  Ade Afolayan (ADE Love) ṣe bi  Taxi Driver."""
Femi Branch: Gbogbo dúkìá mi àti ti ìyá mi ni mo tà láti tọ́jú ẹsẹ̀ mi fún ọdún méjì
Gbajúgbajà òṣèré tó ṣe sinimá Abejoye tun ṣàlàyé pé, ní àsìkò náà kò sí Nollywood ṣùgbọ́n iná Jésù ń jó gidi nínú òun.
O ni inu a máa bí òun sì àwọn sinimá tí wọn máa fi ń hàn ní ilé ìjọsìn lásìkò ìsọjí, tí ènìyàn kò ní gbọ́ nnkan ti àwọn oyinbo ń sọ, tí ẹni tó ṣe òngbifọ̀ náà yóò máa sọ ń kan tó bá bọ́ síi lẹ́nu
Ó ní èyí gan ni àwọn nǹkan tí ó má ń bí òun nínú, ti oun se fẹ́ sinimá tí Naijiria fún àwọn Kristẹni.
"Mo lọ sí ọgbà ilé ẹ̀kọ́ Fáṣítì Ife ni gbọ̀ngàn Odùduwà nígbà naa, lati lọ wo sinimá Hubert Ogunde tí àkọlé rẹ ń jẹ́ AIYE.
Lẹ́yìn tí sinimá náà tan ní bí aago mọ́kànlá alẹ́, mo jáde ní gbọ̀ngàn náà báyìí, ọkàn mi kún fún èrò láti ṣe nǹkan fún Jésù ni, inú mi bajẹ́ gidi."
Amọ lẹyin akoko naa ni Mike Bamiloye gbe ọpọ sinima ẹmi jade, ninu rẹ si ni sinima olokiki ‘Agbara Nla’, to se afihan bi agbara Jesu se ju agbara awọn mi okunkun lọ.
Sunday Igboho: Timi Orokoya ní orin Iléyá tí òun kọ lọ́dún 28 sẹ́yìn, ló padà wá ṣẹ báyìí
Femi Branch: Gbogbo dúkìá mi àti ti ìyá mi ni mo tà láti tọ́jú ẹsẹ̀ mi fún ọdún méjì
Gbajumọ osere tiata ni Femi Branch, to si ti kopa ninu ere tiata to le ni ọgọrun.
Koda, onkọtan, adari ere ati osere tiata ni pẹlu, to si ti bẹrẹ isẹ ni ni ọgbọn ọdun o le diẹ sẹyin.
Nigab to n ba BBC Yoruba sọrọ, Femi Branch ni isẹ agbẹjọro ni baba oun fẹ ki oun lọ ka nile ẹkọ fasiti amọ dipo bẹẹ oun yan isẹ ere tiata laayo ni.
O fikun pe idi eyi ni baba oun se kẹyin si oun nitori ko nifẹ si bi oun se yan isẹ tiata laayo, ti awọn ko si ba ara awọn sọrọ fun ọdun meji ju bẹẹ lọ.
Nigba to n salaye awọn ipenija to n koju awọn elere tiata, Femi Branch ni o dabi ẹni pe inu awọn eeyan maa n dun ti nnkan ba bajẹ fun awọn osere tiata, bẹẹ ni ololufẹ awọn ni araalu jẹ.
O salaye pe awọn osere tiata kii se ẹbọra, bi awọn araalu si se n ni ipenija ara ati ọrọ aje naa ni awọn onitiata naa n ni, paapaa lori ọrọ igbeyawo.
O tun fikun pe akoko kan tiẹ wa ti oun ni ijamba ni oko ere tiata lọdun 2011 ni alẹ.
O ni ibi ti oun ti n fo lati ori ile ni oun balẹ, ti ẹsẹ oun mejeeji si kan, ti egungun mẹsan si fọ lẹsẹkẹsẹ.
O ni odidi ọdun meji ni oun fi tọju ẹsẹ naa, ti oun si ta gbogbo dukia oun ati ti iya oun lati tsju ẹsẹ naa.
O salaye pe oun ko kan pariwo fun araye lati tọrọ owotabi bẹbẹ fun iranwọ owo lagbo tiata nitori awọn ko fi bẹẹ nifẹ ara awọn lagbo tiata.
O wa fidi rẹ mulẹ pe lootọ ni iwa ibanilopọ maa n waye ninu isẹ tiata, o si yẹ ki ẹgbẹ naa maa ja fun wọn.
Muhammadu Buhari: Ààrẹ Buhari ní ọ̀pọ̀ iṣẹ́ àkànṣe tí òun ṣe yóò lérè lọ́jọ́ iwájú
Oríṣun àwòrán, other
Aarẹ Muhammadu Buhari ti sọ pe o di igba ti oun ba ti lọ tan ki awọn ọmọ Naijiria to lee mọ iyi oun.
Nigba to n sọrọ nilu Abuja lọjọru nigba to n ṣe ifilọlẹ igbimọ adari tuntun fun ajọ idokoowo owoolu, NSIA, aarẹ Buhari ni awọn iṣẹ akanṣe ti iṣejọba oun rawọle jẹ awọn ti yoo mu anfani ọlọjọ gbọọrọ wa fun orilẹede Naijiria.
Aarẹ wa rọ awọn ọmọ igbimọ ajọ naa lati wa ọna ti orilẹede Naijiria le fi ri anfani ipawo wọle lati ẹka miran yatọ si ẹka epo rọbi nitori afojusun awọn onims nipa epo rọbi ni pe owo epo rọbi lọja agbaye yoo ja walẹ si ogoji dọla lori agba epo rọbi kan nigba ti a o ba fi wọ ọdun 2030.
Nigba to n sọrọ ni tirẹ, minisita feto iṣuna Zainab Ahmed ni owo ti wọn fi bẹrẹ iṣẹ okoowo ni ajọ naa nigba ti aarẹ wọle ni ọdun 2015 jẹ biliọnu kan dọla.
O ni owo naa ti mu ere biliọnu mẹta abọ dọla wọle fun un bayii.
Femi Branch: Gbogbo dúkìá mi àti ti ìyá mi ni mo tà láti tọ́jú ẹsẹ̀ mi fún ọdún méjì
Lekan Salami Stadium: Ìjọba Oyo fèsì padà lórí aríwísí pé omi wọ pápá tí Makinde fi N5.3bn tún ṣe
Omi lórí pápá ìṣeré Adamasingba kìí ṣe tuntun, ó lè ṣẹlẹ níbi kíbi- Ìjọba OyoSeyi Makinde ṣí pàpá ìṣeré tó fi N5.3bn tún ṣe àmọ́ òjo bàá jẹ́ lọ́jọ́ ayẹyẹ ìṣíde
Ijọba ipinlẹ ti fesi lori iroyin to gba ori ayelujara nipa bi omi ṣe dagun si ori papa iṣere Adamasingba ti Gomina Seyi Makinde ipinlẹ Oyo
ṣi ni Ọjọ́rú.
Nigba ti o n ba BBC Yoruba sọrọ, akọwe iroyin fún Gomina Makinde, Taiwo Adisa sọ pe omi to dagun lori papa iṣere naa kii ṣe ohun ti oju ko riri.
"Ọgbẹni Adisa ni ""iru nkan bayii naa n ṣẹlẹ ní òkè òkun to fi mọ ninu idije Premier League gan an."
Ọpọ ìgbà ni a máa n ri bi yinyin ṣe maa n jabọ, ti o si máa n ṣakoba fun papa iṣere ti wọn ti n gbabọọlu.
Oríṣun àwòrán, OYSG
Igba miiran gan an, wọn máa wọgile ere bọọlu ti yinyin ba ti pọju lori papa.
Bakan naa lo fikun pe iṣẹ atunse papa ere idaraya naa ṣi n lọ lọwọ, ti isẹ ko si tii pari patapata nibẹ.
"Agbaṣẹse to n se atunse papa isere idaraya naa ṣẹṣẹ gbin koriko sori papa ere bọọlu ọhún, ni nkan bi oṣu meji sẹyin.
Gomina Makinde si lo pinnu lati ṣi papa iṣere naa ki ẹgbẹ agbabọọlu Shooting Stars le lanfaani lati máa lo o fún igbaradi idije Super 8 wọn ni.
Ijebu Ode ni Shooting Stars ti n lọ gbabọọlu lati ọjọ yii wa, eleyii ti ko si bojumu to."
O wa fikun pe o buru jai ki odidi ilu Ibadan, to jẹ olu ìlú ijọba iwọ oorun guusu Naijiria tẹlẹ má ni papa iṣere ti ẹgbẹ agbabọọlu ipinlẹ Oyo le maa lo.
Idi niyii, ti ijọba fi tètè ṣi papa iṣere naa nigba ti agbaṣẹṣe ko ti pari iṣẹ lori papa iṣere naa.
Seyi Makinde: Ẹ̀yin tẹ́ fẹ́ fi ọ̀rọ̀ ẹ̀sin ba Oyo jẹ́, ẹ ṣọ́ra ṣe
Fún àwọn tí wọn n sọ pé ijọba na biliọnu marun o le diẹ naira (N5bn) lori papa iṣere lasan, Taiwo Adisa ni kii ṣe ori papa Adamasingba nikan ni owo wà fún o.
"Ipele mẹta ni iṣẹ lori papa iṣere Adamasingba yìí pin sí, agbaṣẹṣe ṣẹṣẹ n pari iṣẹ lọ lori ipele kinni ni iṣẹ papa iṣere naa ni.
Agbaṣẹṣe sọ fún ijọba pe o kere tan, o máa to oṣu mẹta ki ori papa iṣere Adamasingba tó ṣee lo daadaa.
Lara N5bn yìí naa ni agbaṣẹṣe yoo ti kọ oríṣìíríṣìí gbọngan ere idaraya pẹlu awọn ohun elo igbalode.
Bakan naa, agbaṣẹṣe yóò tún kọ ile itura sí papa iṣere yìí láti lè maa ri owo ṣe àtúnṣe papa iṣere yìí, Adisa lo sọ bẹẹ."
Amọ agbaṣẹṣe to n ṣiṣẹ atunse papa isere idaraya naa kọ láti bá BBC Yoruba sọrọ nigba ti a kàn sí lati gbọ tẹnu rẹ lori isẹlẹ to waye lana ọhun .
Nnkan ayọ ati itura ni wẹliwẹli ojo maa n jẹ lọpọlọpọ igba ti o ba rọ si ori ilẹ fun gbogbo ẹda alaye.
Ṣugbọn awuyewuye ni ojo to rọ l'Ọjọru nibi ayẹyẹ atunṣe papa iṣẹre Lekan Salami, to n bẹ ni Adamasingba mu lọwọ.
Saaju ni gomina Seyi Makinde ti kede pe biliọnu marun ati miliọnu lọna ọọdunrun naira (N5.3bn) ni oun naa lati se atunse papa isere idaraya naa.
Ọwọ eeyan si lo n foju soju sode lati pe wo papa isere awodamiẹnu naa, ti wọn lo ba tawọn ilẹ okeere mu, nigba to ba di sisi.
Lara awọn eto ti wọn si la kalẹ fun ayẹyẹ sisi papa isere idaraya naa ni ifẹsẹwọnsẹ ere bọọlu laarin ẹgbẹ agbabọọlu 3SC ati NK Tabor Sezana lati orilẹede Slovenia.
Ayẹyẹ iside naa bẹrẹ ni pẹrẹu ni nnkan bi i aago marun un irọlẹ, ohun gbogbo lo si n lọ leto-leto, ko to di wi pe ojo bẹrẹ ni papa iṣere naa.
Lati ibẹ si ni ọpọplọpọ awọn eeyan ti o lọ wo iran ifẹsẹwọnsẹ ere bọọlu naa, ti bọ si ori itakun ayelujara lati fi aidun inu wọn han lori awọn kudiẹ-kudiẹ ti wẹliwẹli ojo naa tu sita lasiko ti ifẹsẹwọnsẹ n lọ lọwọ.
"Lori opo ikansiraẹni Facebook, ẹnikan ti orukọ rẹ n jẹ Morufu Smith kọọ sibẹ pe, ""Mo kọ iwe lati gbe oriyin fun Ṣeyi Makinde lori atunṣe papa iṣere Lekan Salami saaju ọjọ ayẹyẹ naa."
Mo si fi kun ọrọ mi pe laipẹ laijina a o mọ boya ojulowo ni awọn nnkan ti wọn tun se nibẹ.
O si ṣẹlẹ bẹẹ lasiko ti ifẹwọnsẹ n lọ lọwọ nitori ọpọlọpọ omi lo rogun si ori papa ti wọn ti n gba bọọlu, nitori ko si ibomii ti agbara ojo le ṣan si.
Femi Branch: Gbogbo dúkìá mi àti ti ìyá mi ni mo tà láti tọ́jú ẹsẹ̀ mi fún ọdún méjì
"Sé sàgbèlójúyòyò ni ‘renovations’ tí Sèyí se ni?""."
"Ẹlomii to tun fi ọrọ lede, Adebisi Adeniyi ni ""ọta ẹni ki i pa odu ọya"", ti ariwo si sọ lórí omi tó kún pápá ìṣeré Lekan Salami,"
O fi kun ọrọ rẹ pe awọn ọta ilọsiwaju lo n binu Ṣeyi Makinde nitori ojo to rọ nibi ayẹyẹ naa.
"Ninu ọrọ ti ẹ, Godwin Onoghokere ni ""Gomina Makinde(Ọyọ) na N5.3BN lati ṣe atunṣe papa iṣere ṣugbọn ojo tuna aṣiri iṣẹ to ni ọwọ oṣelu ninu""."
Awọn ọkanọjọkan fọnran lo ti lu ori ayelujara pa, ninu eyii ti awọn eeyan ti n ṣe afihan ibi ti omi ti n jo labẹ orule papa iṣere naa.
Ọpọ araalu ti wa n beere pe ta lo jẹbi aṣiṣẹ naa laarin ijọba ipinlẹ Ọyọ ati kọngila ti wọn gbe isẹ naa fun?
YCE: Níbo lẹ ti rí Yorùbá lókè ọya tó ń gun ẹṣin kiri àdùgbò pẹ̀lú èrò lẹ́yìn?
Oríṣun àwòrán, OYSG
Ẹgbẹ agbaagba nilẹ Yoruba, YCE ti kilọ fawọn Fulani to wa nilẹ Yoruba pe kí wọn ye bu ẹnu àtẹ lu aṣa ati iṣe Yoruba lagbegbe ti wọn ba n gbe.
Ẹgbẹ YCE ni awọn ko ni k'awọn Fulani ma ni aṣoju nilẹ Yoruba, amọ wọn ko gbọdọ tabuku aṣa awọn to gba wọn ni alejo.
Aarẹ ẹgbẹ YCE tẹlẹ rí, Dansaaki Samuel Agbede lo fidi ọrọ yii múlẹ.
"Agbede ni ẹgbẹ YCE wà fún idaabobo ati igbelarugẹ aṣa ati iṣe Yoruba ti o niṣe pẹlu ""ọmọluabi."""
Agbede ni lati ilẹ ni ẹgbẹ YCE kii ti ṣegbe lẹyin ẹnikan lori ọrọ oṣelu tabi ẹsin ṣugbọn kò fi ọrọ ilẹ Yoruba ṣere rara.
Nipa ti o n fesi si atẹjade kan ti ẹgbẹ kan ti orukọ rẹ n jẹ Igbimọ Apapọ Yoruba Lagbaaye fi sita, Agbede ni oni imọtara ẹni nìkan àti ọdalẹ lawọn ẹgbẹ naa.
Femi Branch: Gbogbo dúkìá mi àti ti ìyá mi ni mo tà láti tọ́jú ẹsẹ̀ mi fún ọdún méjì
Ẹgbẹ YCE fidi rẹ múlẹ pe ẹgbẹ kẹgbẹ tabi ẹya kẹya to ba wa nibi kibi ni Naijiria, lẹtọọ lati ni adari.
Ṣugbọn ohun ti wọn ko gbọdọ ṣe ni ki wọn maa tabuku aṣa ati iṣe awọn to gba wọn ni alejo.
"Nibo ni ẹ ti ri ibi ti awọn Yoruba ni Oke Ọya ti n gun ẹṣin káàkiri adugbo pẹlu ero lẹyin wọn? Ṣe iru eyi le ṣẹlẹ laelae ni Oke Ọya?
Wọn ni lati tẹ ilẹ jẹjẹ, nitori bi Yoruba ṣe gb'awọn ni alejo ko tumọ si pe ọdẹ ni iran Yoruba.
A ko sọ pé Yoruba ko le ba awọn ẹya mii gbe mọ, a ti gba ọpọ ẹya mii lalejo tipẹ."
Ṣugbọn awọn iṣẹlẹ ijinigbe pawo, ipaniyan at'awọn iwa ọdaran to ti pọ bayii ni a koro oju sí.
"A ko le maa ka ọwọ gbera ki a maa wo bi awọn Fulani ṣe n ṣọṣẹ nilẹ Yoruba,"" Agbede ṣalaye."
Oba Ogboni: Bí ìwọ́de Yoruba Nation bá tún wáyé, màá bá wọn kópa níbẹ̀
Kayeefi: Àdììtú tó rọ̀ mọ́ ìdí tí ìlú Okeluse ṣe fi ọmọ ọdún 16, tó wà ní SSS 2 jọba
Yoruba ni ori ti yoo de ade, ko ni se alai dade, ọrun ti yoo si wọ ilẹkẹ, ko ni salai wọ ọ, bakan naa ni ibadi ti yoo lo mọsaji, asọ ọba to jinna koro-koro, ko kuku ni se alai wọ.
Ni abala eto Kayeefi wa fun ti ọsu yii, bi ọrọ se ri ree pẹlu ọmọdekunrin kan to gbe ori aye waye, to tii kekere di baba ilu, ọkọ oso, ọkọ ajẹ, to si n se akoso odidi ilu fun lati ọmọ ọdun mẹrindinlogun.
Ọba Oloyede Adekoya Adeyeoba Akinrhare keji, tii se Arujalẹ Ojima tilu Okelusẹ, to wa ni kilaasi ikẹkọ agba keji tile ẹkọ girama, JSS 2, si la gbọ pe oun ni ọba ti ọjọ ori rẹ kere julọ nilẹ Yoruba lọdun 2019 to gori itẹ.
BBC Yoruba lọ ba Kabiyesi naa ni alejo nilu rẹ lati mọ bi isu se ku ati bi ọbẹ se bẹ, ti ọmọde se n jọba lori awọn agbaagba to wa nilu Okelusẹ lẹba ilu Akure.
Iwadii wa si fi han lati ẹnu awọn agbaagba ilu naa pe wọn kii du ọba nilu naa, ọmọkunrin to ba dagba julọ ni oye si kan.
Ifa to ba si mu ni ọba naa yoo fi jẹ orukọ gẹgẹ bi akọbi ọkunrin, idile kansoso si lo n jẹ ọba nilu Okelusẹ.
Nigba ti BBC Yoruba beere pe ti Kabiyesi to wa lori itẹ ko ba bi ọmọkunrin bii arole nkọ, Awọn agbaagba ni awọn alalẹ yoo yi oyun inu Olori pada si ọkunrin, ko to bi ni.
Ẹ maa ba wa kalọ lati mọ kayeefi to n waye nilu Okeluse paapaa nidi eto fifi ọba jẹ.
Bobrisky: Kí ló le mú kí Bobrisky fẹ́rẹ̀ bú sí ẹkún níbi ayẹyẹ ọjọ́ ìbí rẹ̀?
Oríṣun àwòrán, Bobrisky222/Instagram
Yoruba ni inu ẹni kii dun, ka pa mọra, gbogbo ẹni ti ọjọ ibi ba si ba laye, dandan ni ko se ọpẹ.
Boya eyi lo mu ki gbajumọ ọkunrin to n mura bi obinrin, Olanrewaju Idris Okuneye, ti ọpọ eeyan mọ si Bobrisky, se sajọdun ọjọ ibi ọgbọn ọdun to dele aye lọna ara ọtọ, to si dun, to larinrin.
Ọjọ Isẹgun, ọjọ kọkanlelọgbọn, oṣu Kẹjọ, ọdun 2021 si ni Bobrisky ṣe ayẹyẹ ọjọ ibi naa nilu Eko, ti aye gbọ, ti ọrun si mọ pẹlu.
Fun igba akọkọ lẹyin to ṣe ayẹyẹ ọjọ ibi ọgbọn ọdun rẹ naa, Bobrisky ti wa bọ sita lati salaye iye owo to na sori ayẹyẹ naa ati awọn eeyan jankan jankan lorilẹede Naijiria to gba lalejo.
Ọlọjọ ibi naa, to ti kọkọ lọ sisẹ abẹ idi loke okun lati le se idi balabala ko to di ọjọ ayẹyẹ naa kede pe oniruuru gbajumọ, olorin, elere ori itage, ati awọn miran lo wa nibẹ.
Oríṣun àwòrán, Bobrisky222/Instagram
Amọ ọkan lara awọn agba akọrin Fuji nni, Alhaji Wasiu Ayinde Marshall, ti ọpọ eeyan mọ si Kwam 1 si lo kan ilu si ọlọjọ ibi ati awọn eeyan nibadi nibi ayẹy naa.
Nigba to n kede iye owo to na lati fi se ọjọ ibi naa, miliọnu lọna ẹẹdẹgbẹta naira (N500m) ni ilumọọka ọkùnrin to n pe ara rẹ ni obìnrin ọhun sọ pe oun na sori ayẹyẹ naa.
Saaju lo ti kọkọ kede pe miliọnu méje Naira ni oun fi ya fọto imurasilẹ (photo shoot) fun ọjọ ibi naa.
Ọmọ ọlọjọ ibi sọ pe diẹ lo ku ki oun busẹkun ni alẹ ọjọ ayẹyẹ naa, nigba ti oun ri ero to wa lati yẹ oun si.
O ni ọkùnrin ati obinrin pataki lawujo, àwọn Ọga ileesẹ, ati awọn ilumọọka oloselu lo peju sibẹ.
Oríṣun àwòrán, Bobrisky222/Instagram
Bẹẹ ba si gbagbe, saaju la ti kọkọ mu iroyin wa fun yin pe apoti onipaali ti eroja lotisirisi kun inu rẹ, ti owo rẹ to miliọnu kan naira ni Bobrisky fi se iwe apejẹ lati fi pe awọn alejo wa sibi ayẹyẹ ọjẹ ibi rẹ naa.
Bakan naa ni awọn asọ ti ọlọjọ ibi naa wọn jẹ oju nigbese, to si daju pe owo nla ribiribi lo ra awọn asọ igbalode naa ni ti ibilẹ ati ti oloyinbo.
Koda, se ni asọ Kaba alawọ wura to wọ ni ọjọ ibi rẹ naa n kọna yanranyanran, ti awọn okuta onidan si to si ara asọ naa jingbinni.
Bakan naa ni akara oyinbo ti Bobrisky ge fun ayẹyẹ ọjọ ibi naa ga pupọ, to si to orisi mẹta, ti wọn jẹ olowo iyebiye.
Niwọn igba to si jẹ pe owo la fi n peena owo, owo nla ni Bobrisky pa lati ipasẹ ayẹyẹ ọjọ ibi rẹ naa, gẹgẹ bo se gbe fidio kan jade loju opo ayelujara rẹ́.
Oríṣun àwòrán, Bobrisky222/Instagram
Babatunde Usman: Òṣèré tíátà Okele ṣé fídíò síta,ẹ gbọ́ nkán tó sọ fún àwọn olólùfẹ́ rẹ̀
Oríṣun àwòrán, Instagram/okele_2bali
Osere tiata Yoruba nii, Babatunde Usman ti gbogbo eeyan mọ si Okele ti fi ọrọ idupẹ ranṣẹ sawọn ololufẹ rẹ lori aarẹ to de mọlẹ laipẹ.
Ninu fọnran fidio kan to fi si oju opo rẹ ni Instagram lo ti fi ikini yi ranṣẹ.
O ni ohun dupẹ pupọ paapa lọdọ awọn to pe tabi ti wọn fi ọrọ ikini ranṣẹ lasiko toun wa lori aarẹ.
Lọjọ Aiku to kọja yi  lo ṣe fidio naa sita ti o si jọ pe ko si nkankna to ṣe ninu fidio naa.
''Fun awuyewuye orisirisi  to n lọ lori ayelujara pe ki ẹ gbadura fun Okele.Okele ree, ko si nkankan to ṣe mi''
Babatunde ṣe ọrọ naa lowelowe to si ni ''mo dupẹ pe awọn to gbe koto ko gbẹ jin, ẹni to ko si naa Ọlrun ko ni ko da lapa''
O ni oun ni lati ṣe fọnran fidio naa sita lati dupẹ lọdọ awọn eeyan ati lati fi han ko si nkankan to ṣe oun.
Ọmọ bibi ipinlẹ Kwara ni adẹrinposonu ẹni ọdun mejilelogoji yi to si ti n ba ere tiata bọ to nkan bi ogun dun sẹyin.
Oríṣun àwòrán, okele_2/Instagram
Gbajugbaja adẹrinposonu nni, Babatunde Usman ti ọpọ eeyan mọ si Okele, lo ti di ero ile iwosan bayii nitori aidape ara.
Osere tiata miran, to jẹ ọrẹ timọtimọ si Okele, eyiun Saliu Gbolagade ti awọn eeyan tun n pe ni Ogboluke lo kede bẹẹ ninu fidio kan to fi soju opo Instagram rẹ.
Ogboluke, ẹni to n fi fidi naa fi ọrọ ransẹ si awọn eeyan kan lagbo tiata salaye pe kii se pe Okele mọọmọ fara pamọ lati mase yọju sibi ere sinima kan ti wọn pe si ni.
Amọ Ogboluke ni ko si ẹni ti kii rẹ, aidape ara lo gbe Okele sanlẹ, to si ti wa nile iwosan nibi to ti n gba itọju.
Osere tiata naa ni ti kii ba se pe oun wa sile iwosan naa lati fidi ootọ ọrọ mulẹ, oun naa ko ba ti mọ pe oun to n se Okele gbopọn pupọ.
Oríṣun àwòrán, ogboluke/Instagram
"Ogboluke wa yan pe ""Kii se pe mo se fidio yii lati bẹbẹ owo fun itọju Okele, amọ mo fẹ fidi rẹ mulẹ fun awọn eeyan to ni Okele n fi aisan parọ ni ko ma ba wa ya ere."
Ko yẹ ki eeyan sọ pe o fi aisan parọ, ni set ti emi naa ti n bọ, wọn lo fi aisan parọ ni, pe ko wa.
Emi dẹ mọ ẹni ti mo n pe, mo dẹ n sọ fun wọn pe o ni nnkan kan to sẹlẹ, amọ ka sa dupẹ lọwọ Ọlọrun ni.
"N ko fẹ sọ pe ipo ti Okele wa critical amọ ka sa dupẹ lọwọ Ọlọrun sa."""
Ogboluke wa gbadura fun Okele pe Ọlọrun ko ni jẹ kawọn sunkun lori rẹ, to si ni ọwọ aye ko ni tẹ nitori ẹni to n pa araye lẹrin ni, ko si ni sunkun lasẹ Ọlọrun Ọba.
Ninu fidio naa la ti ri Okele to sun sori ibusun, ti wọn n fa omi ati oogun si lara pẹlu rọba kan ti wọn so mọ apa ati imu rẹ.
Bakan naa ni rọba kan wa ni ọwọ isalẹ to lọ sinu ọra nla kan, ti itọ rẹ da rogun si, ti Okele si n se amin si awọn adura ti Ogboluke n se.
Sugbọn Ogboluke ko sọ pato iru aisan to n ba Okele wọya ija, to fi da wolẹ sile iwosan to ti n gba itọju.
Covid-19 Vaccines: Aráàlú sọ̀rọ̀ lórí èrò ìjọba láti sọ gbígba abẹ́rẹ́ àjẹsára di ọ́rànyàn
Ijọba Naijiria ati awọn gomina ipinlẹ kan ti kede pe awọn yoo gbe igbesẹ lati sọ eto gbigba abẹrẹ ajẹsara Covid-19 di ọranyan.
Bakan naa ni wọ̀n kede pe ẹnikẹni ti ko ba gba abẹrẹ naa yoo koju awọn ijiya kan, to si tun seese ki iru ẹni bẹẹ ma le lọ jọsin ni sọọsi tabi mọsalasi.
BBC Yoruba bọ sigboro lati mọ ero araalu nipa igbesẹ yii, ohun ti wọn sọ ree.
Sunday Igboho Aides: Amòfin Olajengbesi lérí láti gbé DSS lọ ilé ẹjọ́ lórí bo ṣe tàpá sí àṣẹ adajọ
Oríṣun àwòrán, Omoyele Sowore
Idunnu tí subu lu ayọ fún awọn olólùfẹ́ Sunday Igboho nigba ti DSS tun tu meji silẹ ninu àmúgbálẹ́gbẹ̀ẹ́ rẹ mẹrin to si ku ni ahamọ.
Orúkọ àwọn eeyan meji mii ti DSS tu silẹ lọjọ Ẹti ni Tajudeen Rinloye ati Uthman Adelabu.
Àmọ́ DSS ko tu obìnrin kan ṣoṣo to wa laarin wọn ati ọkunrin miran silẹ.
Orúkọ awọn mejeeji to ku ni ahamọ ni Amudat Babatunde ti ọpọ eeyan tun n pe ni Lady K ati Jamiu Oyetunji.
Nigba to n fidi iṣẹlẹ yii mulẹ, agbẹjọ́rò fun awọn eeyan mejila ti DSS ko nile Sunday Igboho, amofin Pelumi Olajengbesi kede pe oun yoo pada gbé Ileesẹ agbofinro DSS rele ẹjọ.
Olajengbesi, ninu atẹjade kan to fisita wa fi ẹsun aibọwọ fún àṣẹ ilé ẹjọ́ kan àjọ DSS, to si ni eyi to ba wu, lo n tẹle ninu àṣẹ tile ẹjọ pa fun.
Oríṣun àwòrán, Omoyele Sowore/Facebook
Olajengbesi ni DSS ko salaye idi kankan tó ṣe yari lati máṣe tu gbogbo awọn eeyan mejeejila naa silẹ ni ahamọ lasiko kannaa.
O fikùn pé gbogbo ilana ti DSS fi lélẹ̀ ni ikọ̀ agbẹ́jọ́rò naa ti tẹle lati gba idande awọn eeyan naa àmọ́ síbẹ̀ wọn kò fi eeyan meji yoku silẹ.
Bakan naa lo fikun pe DSS ko ni àṣẹ lati maa tu ẹnikẹni to ba wu silẹ tabi maa tẹle ọwọ àṣẹ ile ẹjọ to ba fẹ.
"Awawi àjọ DSS tẹ́lẹ̀ ni pe awọn agbẹjọ́rò ko pari awọn ilana to yẹ ki wọn tẹle lati tu àwọn eeyan mẹrin yoku silẹ.
Àmọ́ gbogbo ilana yii la ti parí titi ọjọ Ẹti, ọjọ́ kẹta oṣù Kẹ̀sán yii, àmọ́ ìyàlẹ́nu lo jẹ fun wa pe eeyan meji ninu mẹrin tun ni DSS fi silẹ.
Àmọ́ tí DSS ko ba tu àwọn eeyan meji to ku si ahamọ wọn silẹ títí di ọjọ Aje, ọjọ kẹfà oṣù kẹsàn-án, a pada gbe oludari agba fun àjọ DSS, Yusuf Magaji Bichi lọ sile ẹjọ lórí ẹsun titapa si àṣẹ ilé ẹjọ́."
Amofin Olajengbesi wa woye pe ko ni dara ki awọn dakẹ, ki DSS maa huwa taniyomumi nidi isẹ rẹ, ko si tun maa tapa si ofin ilẹ̀ wa.
Kayeefi: Àdììtú tó rọ̀ mọ́ ìdí tí ìlú Okeluse ṣe fi ọmọ ọdún 16, tó wà ní JSS 2 jọba
Graphology: Àǹfààní márùn-ún tó wá nínú ìmọ̀ nípa ‘Handwriting’ rẹ
Niwọn igba ti oju ti jẹ Ferese ara, bẹẹ naa ni ọwọ wa jẹ ferese si ọpọlọ.
Idi ree to fi rọrun lati mọ iru eeyan ti ẹda kan jẹ, iwa to le hu ati awọn aisan to n se iru ẹni bẹẹ lati ipasẹ ohun to ba kọ silẹ ta n pe ni Handwriting.
Gẹgẹ bi Dokita Oladipupo Macjob se salaye fun BBC Yoruba, imọ nipa awọn akọsilẹ yii ni a n pe ni Graphology.
Bakan naa ni Dokita Macjob ni imọ nipa awọn akọsilẹ yii ni anfaani orisi marun fun ẹda atawọn isẹ aayan laayo gbogbo.
Dokita Macjob wa rọ awọn onisẹ iwadii lati maa se amulo imọ nipa akọsilẹ ẹda naa, tii se Graphology lati fi mu agbega ba igbe aye ọmọniyan.
Erectile Dyfunction: Ǹ jẹ́ o mọ̀ pé ìgbà 21 ní oṣù kan ló yẹ kí ọkùnrin máa damira lásìkò ìbálòpọ̀?
Ọpọ ọkunrin lo saba maa n dakẹ ti nnkan ọmọkunrin wọn ba ti dẹnukọlẹ, ti ko si gberi mọ.
Wọn yoo wa fi ọrọ naa se iso inu ẹku, arunmọra, mọ sinu, awo mọ sikun.
Iwadii si ti fihan pe awọn ọkunrin ti ọjọ ori wọn wa laarin ọdun mejidinlogun si marundinlogoji lo ko ida mẹẹdogun ninu ida ọgọrun awọn eeyan ti nnkan ọkunrin wọn ko le daadaa.
Bẹẹ ni awọn ọkunrin ti ọjọ ori wọn ti le ni ogoji ọdun ko ida ogoji ninu ọgọrun awọn ọkunrin ti nnkan ọkunrin wọn ko sisẹ, ti oloyinbo n pe ni Erectile dysfunction (ED).
Eyi ko si sẹyin ẹlẹya to seese ki wọn fi se ni awujọ tabi asa idẹyẹsi to maa n saba wọpọ si iru ẹni bẹẹ.
Menopause: Ẹja nìkan ni ẹranko tí nǹkan oṣù rẹ̀ ń dáwọ́ dúró, yàtọ̀ sí èèyàn
Bakan naa ni wọn tun le maa yaju si iru ọkunrin bẹẹ, tabi ki iyawo rẹ maa ri fin, ti wọn ba fi tu asiri yii sita ninu ile tabi pẹlu ẹnikẹni
Nitori idi eyi, awọn ọkunrin ti nnkan wọn ko sisẹ mọ maa n da gbe agbelebu wọn lori ọrọ yii ni to si le fa ironu ati irẹwẹsi ọkan si wọn lara.
Bi eyi ba si waye, ọpọ aisan miran tun le gba ibẹ wọle si wọn lara, ti wọn si maa n bẹru lati sun mọ aya wọn ninu ile.
Bi ọkunrin ko si le se ojuse rẹ si iyawo rẹ bo se yẹ ninu ile, o maa n mu ki opo to gbe ile naa ro maa yẹ diẹdiẹ, ti ija yoo si maa waye lemọlemọ laisi idi kan pato.
Dokita Rasheed Adedapo Abassi, jẹ akẹkọjade nibudo ẹkọsẹ isegun fasiti Yale nilẹ Amẹrika, to si ni iriri ọdun mọkandinlogun lẹnu isẹ nipa ilera awọn ọkunrin.
O wa salaye nipa ohun to n sokunfa ki nnkan ọkunrin ma sisẹ mọ, iwosan rẹ ati awọn ọna ta fi le dena isẹlẹ yii.
Kemi Dairo: Iṣẹ́ abẹ nínú ọpọlọ àti ẹ̀rọ ni mo fi ń gbọ́ ọ̀rọ̀ báyìí
Erectile dysfunction (ED) eyiun ti nnkan ọkunrin ko ba sisẹ mọ ni asiko ti oko rẹ ko ba le fun odidi isẹju mẹẹdogun gbako.
Iwadii ti fihan pe ọkunrin to ba dape lara, ni nnkan ọkunrin rẹ gbọdọ le gbanko ni owurọ to ba ji.
Amọ dokita Abass ni to ba jẹ pe fun akoko ranpẹ ni oko ọkunrin kan fi n le, tabi ko le gbe nnkan ọkunrin to le naa wọ inu oju ara obinrin ti yoo fi rọ pẹsẹ, a jẹ pe onitọun ti ni aisan ti wọn n pe ni Erectile dysfunction (ED) ni.
Ọpọlọpọ nnkan lo n faa ti iru isẹlẹ yii fi maa n waye amọ marun pere ninu awọn ohun to n sokunfa ki nnkan ọkunrin ma sisẹ mọ ree:
Eroja omoonu Testosterone yii lo maa n mu ki ọkunrin dape lara nigba ti eroja omoonu ti wọn n pe ni Estrogene to wa lara obinrin lo maa n mu ki obinrin le loyun lati bimọ.
Yatọ si bo se n waye lara awọn ọkunrin, eroja omoonu Estrogene to n da loju ara obinrin lo maa n dinku ti obinrin ba ti pe ẹni aadọta ọdun.
Amọ ni ti awọn ọkunrin, eroja omoonu Testosterone ko le dinku laelae amọ awọn ipenija kan maa n ba finra.
Irẹwẹsi ọkan jẹ ohun kan gboogi to maa n se okunfa ki nnkan ọkunrin ma le bo se yẹ. Irẹwẹsi ọkan le waye ti isẹ ba bọ lọwọ ọkunrin, ti owo ba safẹrẹ lọwọ rẹ tabi ti ipenija ba wa ninu igbeyawo rẹ tabi lati ibikibi.
Awọn ohun to n mu irẹwẹsi ọkan wa yii yatọ si eyi ti sise ere idaraya n mu wa nitori ere idaraya maa n mu ki ọkan pọn ẹjẹ lọ si awọn isan to yẹ ni.
Amọ irẹwẹsi ọkan maa n pọn ẹjẹ yika gbogbo ara ni laibikita.
Aimaa se ere idaraya deedee (Ibalopọ):
O yẹ ka maa tẹnu mọ eleyi daadaa lati dena ki nnkan ọkunrin ma gberi. Ọkunrin gbọdọ kọ asa sise ere idaraya fun ọgbọ isẹju lojoojumọ.
"N jẹ o mọ ere idaraya ti mo maa n daba rẹ fun awọn alaisan ti mo n tọju? Ibalopọ oorekoore ni.
Mo si ni awọn abọ iwadii kan to fidi eyi mulẹ, ti mo le tọka si bii ẹri to daju. Dokita Abass lo sọ bẹẹ."
Dokita Abass wa daba fun awọn ọkunrin pe ki wọn maa da oje ara wọn ta n ms si Sperm ni igba mọkanlelogun losoosu.
O ni ibalopọ gbogbo igba maa n se iranwọ lati mu dena arun jẹjẹrẹ ile itọ ọkunrin, eyi to le se akoba lọjọ iwaju.
Eleyi le jẹ iyalẹnu fun ọpọ eeyan amọ gẹgẹ bi Dokita Abass se wi, ni ọdun diẹ sẹyin ka to wọnu ọdun 2000, ọpọ eeyan lo ni anfaani si omi ẹrọ to mọ, eyi ti wọn ti fi oogun apakokoro si.
Amọ o salaye pe aisi omi ẹrọ to mọ fun araalu lati mu, eyi to ni eroja asaloore ke ke ke ti wsn n pe ni macronutrients, n mu ki ọpọ nnkan ọkunrin ma gberi mọ.
O wa sisọ loju rẹ pe, wọn ti pọn ni dandan fun ijọba lati setọju omi ẹrọ to n pese fawọn araalu lati pọn mu pẹlu awọn eroja to n pa kokoro bii fluoride, calcium, selenite.
O ni gbogbo awọn eroja inu omi yii lo ni ojuse tiwọn lati se, ki awọn ọkunrin le ni oje to dara lara.
Yoruba Nation Agitation: Àwọn aláìní nǹkan ṣe lo n pè fún ìyapa Nàìjíríà- Gómìnà Oyetola
Oríṣun àwòrán, Oyetola
Gómìnà ìpińlẹ̀ Osun Gboyega Oyetola ti bẹnu àtẹ́ lu àwọn  tó ń pè fún Yorùbá Nation àti Biafra Republic
O ní àwọn tó n ṣe àtilẹyin fún ìpè yìí jẹ́ aláìní ǹnkan ṣe pẹ̀lú.
Lásìkò tó n péjú síbi ètò kan tí ìlé iṣẹ́ ìròyìn NAN gbékalẹ̀ ló tí sọ pé, isọkan orílẹ̀-èdè Nàìjíríà ló ṣe kókó jùlọ.
Ó ní òun ní ìgbàgbọ́ nínú àtúnṣe ètò ọ̀rọ̀ àjé àti ètò òṣèlú ìpínlẹ̀ kọ̀ọ̀kan ju kí olúkúlùkù lọ lọ́tọ̀ọ̀tọ̀ lọ.
 Ní bí èmi ṣe ròó, mí o faramọ́ kí àwọn ènìyàn lọ lọtọọtọ.Tí a ba tilẹ̀ ń sọ̀rọ̀ àtúntò, sùgbọ́n gbogbo àwọn tí wọ́n ń ronú sí pínpín Nàìjírià, wọn kò mọ̀ nǹkan ti wọ́n ń ṣe.
Ìbáṣepọ̀ wá ti jìnà, kárìnkápọ̀ yíyẹ ló ń yẹni ni ó yẹ kí a fi ọ̀rọ̀ náà jẹ́, àti pé tí ifọwọsowọ́pọ̀ bá wà, yóò ran wọ́n láwọ́ láti rí ẹ̀tọ́ wọn gbà.
Gómìnà ní ó sàn kí ìpińlẹ̀ pè fún kí àgbàra ìjọba àpapọ̀ dínkù ju pé kí wọ́n máá pè fún ìyàpa lọ.
" Kí ará ìlú gbárukù ti ìpínlẹ̀, kí ìpinlẹ̀ náà sì máá rí owó tó tó owó gbà láti ṣe àwọn iṣẹ́ ìlú wọ́n lọ́nà tí ó tọ́ àti tí ó yẹ.
Nedu Wazobia : Àyẹ̀wò DNA tí a ṣé fi hàn pé èmi kọ ní ìyàwó mí bí akọbi wà fún
Oríṣun àwòrán, NEDU&UZOR/IG
Lẹyin Gbas gbos  to waye laarin akọrin takasufe Tuface Idibia ati iyawo rẹ lori aṣemaṣe ninu igbeyawo wọn, adẹrinposonu nii, Nedu Wazobia naa ti n fa surutu pẹlu iyawo rẹ tẹlẹ.
Ìyàwó Nedu lo kọkọ bọ sori ayelujara instagram rẹ lati ṣalaye nnkan ti oju rẹ ri ninu igbeyawo rẹ pẹlu Ani Chinedu Emmanuel ti gbogbo eniyan mọ si  Nedu
Ohun taa gbọ ni pe iyawo rẹ tẹlẹ Uzoamaka Ohiri  niṣe ni Nedu  maa n lu oun ni ilukulu ti o si fi foto awọn apa to wa ni ara rẹ han.
Nedu ti orukọ rẹ n jẹ Ani Chinedu Emmanuel ati iyawo rẹ tẹlẹ Uzoamaka Ohiri lawọn eeyan tun mu ọrọ wọn bẹnu bayi lori ayelujara ni Naijiria.
Ninu awọn ẹsun to fi kan Nedu, Uzoamaka sọ pe lẹyin ọsẹ diẹ ti oun  ṣiṣẹ abẹ bimọ fun Nedu, ''Alhaji Musa'' lu oun lalubami lójú iya rẹ to gbe ọmọ tuntun ti oun bi lọwọ
Koda o fi awọn aworan ṣọwọ loju opo Instagram lati ṣafihan oju apa ibi ti o sọ pe Nedu ti lu oun.
Gbogbo ẹsun ti o fi kan wọnyi, Nedu sọ pe ko si ootọ ninu rẹ.
Oríṣun àwòrán, Instagram/nedu_wazobiafm
Ninu esi rẹ, o ni bi eeyan kankan ba tiẹ fẹ sọ ọrọ nipa ifiyajẹni ninu igbeyawo awọn, oun loun yẹ ko fẹsun kan an iyawo rẹ tẹlẹ.
O ni awọn ọlọpaa tiẹ ti ṣe iwadii ọrọ naa nigba tawọn fẹ mu opin ba ajọṣepọ wọn.
''Lori ẹsun pe mo fiya jẹ ninu igbeyawo wa, awọn ọlọpaa ti wadii ọrọ yi lẹẹmeeji , akọkọ ni agọ ọlọpaa Ajah ati igbakeji ti ile ẹjọ ṣe iwadii ọrọ yi ki wọn to tu igbeyawo wa ka''
Oríṣun àwòrán, Instagram/nedu_wazobiafm
Ni igba mejeeji, wọn ni mi o jẹbi ẹsun wọn yi mo si ni iwe ẹri lati fi gbe ọrọ mi lẹyin.
Ko tan sibẹ, Nedu sọ pe oun gbe awọn ọmọ mẹta tawọn bi lọ fun ayẹwo DNA ti esi si fi han pe akọbi ọmọ awọn kii ṣe ọmọ oun.
Oríṣun àwòrán, Instagram/nedu_wazobiafm
''Ọpọlọpọ ipenija lo koju igbeyawo wa. Lara rẹ ni agbere ti iyawo mii n ṣe eyi to mu ki n lọ ṣe ayẹwo fun wọn ti esi si fi han pe akọbi wa kii ṣe ọmọ mi botilẹ jẹ wi pe a jijọ n gbe pọ bi lọkọlaya.''
JOHESU fún ìjọba Nàìjíríà ní gbèdéke ọjọ́ 15 ṣáájú ìyanṣẹ́lódì, kà nípa nkán tí wọ́n n béèrè fún
Oríṣun àwòrán, others
Agbarijọpọ ẹgbẹ oṣiṣẹ ẹka eto ilera ni Naijiria JOHESU ti fi gbendeke ọlọjọmẹẹdogun lelẹ fun ijọba Naijiria lori sisan awọn gbese owo ajẹmọnu wọn.
Wọn ni bi ijọba ba kọ ti ko san owo yii, awọn yoo gun le iyanṣẹlodi ọlọjọgbọọrọ.
Aarẹ ẹgbẹ naa Biobelemonye Josiah, lo fidi ọrọ yi mulẹ ninu iwe kan to kọ si Minisita feto igbanisiṣẹ Naijiria Chris Ngige ati awọn alẹnulọrọ mii nilu Abuja lọjọ Abamẹta.
Gẹgẹ bi iwe iroyin Naijiria kan This Nigeria ṣe jabọ, Josiah ni gbendeke ọlọjọmẹẹdogun yi di dandan nitori aikọbiara si awọn ẹdun ọkan wọn lati ọdọ ijọba apapọ.
O ka awọn  orisirisi ọrọ to niṣe pẹlu ajẹmọnu oṣiṣẹ ti ijọba kuna lati sọ to fi mọ ajẹmọnu lati ọdun 2014, owo oṣu oṣiṣẹ ti ijọba di mọwọ ni 2018 ati awọn owo aabo fawọn oṣiṣẹ nitori  Covid-19.
Aarẹ JOHESU ni  ijọba ko tiẹ fesi si iwe tawọn kọ lẹyin ti wọn buwọlu adehun lati oṣu Kẹsan ọdun 2017.
''Gbogbo ẹyin oṣiṣẹ wa, a fẹ ki ẹ wa ni ṣẹpẹ de aṣẹ lati gunle iyanṣẹlodi bi awọn ijọba ko ba fesi si awọn ẹhonu wa.''
O sọ pe bẹrẹ lati oru ọjọ Kẹtadinlogun oṣu Kẹsan awọn oṣiṣẹ to wa labẹ aṣia JOHESU yoo bẹrẹ iyanṣẹlodi ni gbogbo awọn ile iwosan ijọba ibilẹ ati ipinlẹ jakejado Naijiria.
Titi di igba ta fi n ṣe akojọpọ iroyin yi, ijọba apapọ Naijiria ko ti fesi si ọrọ yi.
Lọwọlọwọ bayi, awọn dokita to wa lẹnu ikọṣẹ lawọn ileewosan jakejado Naijiria ta mọ si Resident Doctors wa lẹnu iyanṣẹlodi.
Nigeria Customs: ọgá ilééṣẹ́ aṣọ́bodè Buhari kò mọ̀ iṣẹ́ to -Sẹ́nẹ́tọ̀ Francis Fadahunsi
Oríṣun àwòrán, Facebook/customsng
Igbakeji alaga igbimọ ile aṣofin agba to n mojuto iṣẹ ajọ aṣọbode Naijiria Sẹnẹtọ Francis Fadahunsi ti ni ki ijọba wa ọna ti wọn yoo fi pawo wọlẹ lọdun 2022.
O ni eyi ṣe pataki  nitori ile ko ni faramọ yiya owo lati fi ṣeto isuna.
Bẹẹ lo tun pe fun iwadii kiakia lori  ina ati ilo gbogbo iṣẹ ti ileeṣẹ aṣọbode ṣe lati 2015 titi di asiko yi.
Ninu ifọrọwerọ kan to ṣe pẹlu ileeṣẹ iwe iroyin Naijriia Punch lo ti ṣalaye ọrọ yi.
Ṣaaju ki o to darapọ mọ oṣelu, Fadahunsi ti fi igba kan jẹ igbakeji ọga agba ilẹesẹ aṣọbode Naijiria.
O ni o ṣeni laanu bi awọn ileeṣẹ to yẹ ko maa pawo wọle fun Naijiria bi ileeṣẹ aṣọbode ti ṣe kuna nidi iṣẹ wọn lati wa owo ti Naijiria yoo fi ṣeto iṣuna.
O ni yato si eleyi, ileeṣe aṣọbode ko tun ja fafa to lati koju awọn onifayawo ti eleyi si mu ki Naijiria maa padanu obitibiti owo.
Senato francis Fadahunsi: Ká ni wọ́n fún Buhari ladún mẹ́wàá sẹ́ypin ní, bóyá kò bá rí i ṣ
Nitori naa Fadahunsi wa pe fun ikọwefiposilẹ ọga agba Customs,ọgagun fẹyinti Hameed Ali pẹlu bi ko ṣe ribi dẹkun ki ijọba maa yawo fi seto isuna.
O ni''ile aṣofin agba ko fara mọ ki Naijiria maa ya owo, ijọba apapọ ni lati wa wọrọkọ fi ṣada ''
''Gbogbo awọn olori ileeṣẹ ijọba to n pawo wọle ni lati sun ṣokoto wọn soke lati ṣiṣẹ tọ afojusun bi bẹẹ kọ wọn yoo gba iṣẹ lọwọ wọn''
Oríṣun àwòrán, Facebook/customsng
O ni ni kete tawọn ba wọle pada nile aṣofin awọn yoo daba ki ile ṣe iwadi iye kọntena ti o n wọ awọn ibudo ikẹrupamọ si.
''A o wa awọn ọga ileeṣẹ aṣọbode to ja fafa to si ti fẹyinti nidi iṣẹ ati awọn oniṣiro owo ti yoo sọ deede iye owo ti wọn n san wọle sakoto ijọba.''
Lọjọru to kọja yi ni ọga agba ileeṣẹ aṣbode sọ fun igbimọ ile to n mojuto ọrọ inawo pe awọn ko ribi pa owo wọle nitori iwa fayawọ ati awọn nkan miran.
Oríṣun àwòrán, Facebook/customsng
Fadahunsi sọ pe Hameed ko ni awijare kankan nitori ile aṣofin ti fun ni gbogbo nkan to nilo lati fi koju awọn ipenija yi.
O wa sọ pe aarẹ Buhari kuna pẹlu bo ti ṣe yan ọmọ ologun sipo ọga Customs yoo tunbọ maa kọdi erongba Naijiria lati sinmi gbese jijẹ.
O ni aṣiṣe nla gbaa ni bi aarẹ Buhari ti ṣe yan alaimọṣẹ ajagunfẹyinti sipo ọga agba ileeṣẹ aṣọbode.
Yoruba Oduduwa Nation: Ṣíṣe déédé àti ààbò tó péye láwọn Yorùbá Nation n já fún-Ooni
Oríṣun àwòrán, Yera Moses Olafare
Ooni Ile Ife Ọba Adeyeye Ogunwusi ti tun sọrọ lori igbiyanju awọn to n beere fun idasilẹ orileede Yoruba.
Ninu ifọrọwanilẹnuwo ti Ooni ṣe pẹlu ileeṣẹ iwe iroyin Naijiria, o ni awọn to n ja ija wọnyi n beere fun iṣe deede ati aabo to peye ni.
Oba Ogunwusi sọ pe ohun to daa ju ni ki Naijiria ṣe ọkan ṣugbọn ti awọn eeyan ko ba ri apẹrẹ eyi, o di dandan kawọn eeyan maa fapajanu.
Ọjaja Keji  sọ pe ohun ko le da awọn to n pe fun idasilẹOduduwa Nation lẹbi  nitori nkan ko ri bayi ni nkan bi ogun ọdun sẹyin.
''Nigba tawọn Yoruba wa nipo njẹ awọn eeyan fẹhonu han bayi? O gbọdọ ni idi to fi ri bayi gbogbo wa la si mọ pe wahala aisi aabo ati idigunjale lo fa''
Ori Ade naa sọ pe koda ni apa ariwa Naijiria awọn eeyan n fapajanu ati pe ohun to ṣe pataki ni ki wọn yanju awọn to n da wahala silẹ ati awọn ti o n beere nkan to lẹtọ.
''O gbọdọ ni idi ti wọn fi n sọpe awn fẹ lọ lọtọ. Imọran mi ni ki  ba wọ́n jiroro. Ẹ jẹ ka jiroro lori ibaṣepọ ati isọkan Naijiria ki nkan baa le to deede''
Ninu ifọrọwanilẹnuwo naa bakan naa, Ooni sọrọ nipa iṣẹlẹ to waye nibi ti Sunday Adeyemo Igboho ti tabuku rẹ.
Ooni sọ pe gẹgẹ bi baba ati ọmọ to ṣe daada ati eyi to ku diẹ kaato, gbogbo wọn loun jẹ baba fun.
Obateru Akinruntan: Wíwá ohun tá jẹ títí láé ló gbé wa kúrò nílé Ife
Yoruba Nation: Kò sí ìdí tí à ó fi bínú sí Akeredolu lórí ọ̀rọ̀ Yorùbá Nation
O ni awọn ko ni tori ohun to ṣẹlẹ kawọn wa pa Sunday Igboho ti lai ya si rara.
Oba Adeyeye ni awọn ti ṣe agbekalẹ igbimọ lori ọrọ Igboho ki gbogbo nkan baa le lọ deede ni Naijiria ati ki wọn ba le mojuto ọrọ rẹ.
''Awọn akọṣẹmọṣẹ la ni ko mojuto ọrọ yi.A si n ṣiṣẹ pọ pẹlu awọn alaṣẹ lati ti pe ohun gbogbo lọ leto leto''
Life at 40: Ìbálòpọ̀ àti nkán márùn-ùn míì tí o lè ṣé kí ará rẹ̀ fí jí pépé tó bá pé ogójì ọdún
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ibi agba ba de duro, bo pẹ boya ọmọde yoo pada de ba wọn nibẹ.
Eyi lo difa fun bi pupọ awọn to jẹ ọdọ ṣe n gun oke agba ni meni meji ti agba si n kan onikaluku.
Bi eeyan ba ti wa gun oke agba to di ẹni ogoji ọdun, ọ̀pọ̀ nǹkan to maa n ṣe ni yoo bẹrẹ si ni gba ọna mi yọ.
Yala nipa ounjẹ jijẹ ni tabi ibaṣepọ koda to fi mọ aṣọ wiwọ, diẹ ree ninu awọn nkan ti eeyan le ṣe lẹyin to pe ogoji ọdun ki ara rẹ le ji pepe
Omi mimu ni anfaani to n ṣe fun ara ṣugbọn o ṣeni laanu pe agbara  awọn ẹya ara to n lo omi yi a maa dinku bi eeyan ba ti re si ogoji ọdun.
Nitori eyi, pupọ eeyan to ba ti n dagba ni ko ni maa gbẹ oungbẹ omi mimu ti eleyi si le ṣe akoba fun ara wọn.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Wahala le de ba kidirin ẹni ti ko ba mu omi daada tabi ki oyi fẹ maa kọ.
Tori naa ri pe o mu omi daada ati loore koore bo ba ti gun oke agba de ogoji ọdun
Mimu ọti waini pupa (Red Wine)
Gẹgẹ bi iwadii kan tawn onimọ ṣe lori mimu ọti waini pupa, wọn ni o wa lara awọn ohun ta le fi koju didarugbo lojiji.
Awọn eronja to wa ninu ọtiwaini yi bi anti oxidants a maa mu ki ara eeyan ṣe jọlọ daada.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Iwaddi ọhun sọ pe tori pe waini pupa da bii ti ka mu lamupara kọ
Ikeemu kan tabi meji ọti waini pupa yi lojumọ loore to pọ fun alaafia ara bi eeyan ba ti n gun oke agba lọ.
Ninu awọn aisan to le fi waini koju ni aisan itọ ṣuga.Bẹẹ lo si le ko ni yọ lọwọ aarun jẹjẹrẹ to fi mọ aisan kan ti orukọ rẹ n jẹ Alzheimer
Ọpọ eeyan lo maa n ro pe bi eeyan ba ti n dagba lọ, erepa inu iyara laarin lọkọ laya gbọdọ maa diku.
Ọrọ ko ri bẹ rara.
Iwaadi ti fi han pe ibalopọ laarin tọkọtaya a maa mu ki ara wọn ji pepe, ki irun wọn maa dan daada ki wọn si ma tete darugbo loju.
Ninu iwadii awọn tọkọtaya ẹgbẹrun lọna ọgbọn, awọn onimọ ri pe awọn to n ni ibalopo o kere tan lẹẹmẹtaa lọsẹ ko tete gbora bi awọn akẹgbẹ wọn ti ko ṣe bẹ.
Onimọ nipa itọju awọ ara,Keira Barr,ni idamira lasiko ibalopọ a maa tu kẹmika kan jade ti a mọ si Oxytocin.
Oxytocin yi a maa jẹ ki ara eeyan balẹ daada ti ko si ni jẹ ki ara eeyan hunjọ pupọ.
Ara eeyan ni aimasundeede maa n fi abọ si.
Bi eeyan ba si ti n sunmọ ogoji ọdun, ko yẹ ko maa jẹ gbese orun lai san pada.
Iwadii kan fi han pe awọn  ti o sunmọ ogoji ọdun ti kii ri oorun sun deede a maa yara darugbo ju awọn akẹgbẹ wọn to n sun daada lalẹ.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Lara awọn nkan ti aisun deede maa n ṣe lakoba ni pe awọ ẹni ti ko sun daada ko ni dan mọran lẹyin to ba jade si inu orun.
O kere tan rii pe o sun oorun wakati mẹjọ nitori eleyi ni ọpọ oore to n ṣe fun ara rẹ to ba ti pe ogoji ọdun tabi ju bẹ lọ.
Ṣọ iru ounjẹ ti o n jẹ
Ounjẹ lọrẹ awọ lootọ ṣugbọn bi eeyan ba ti gun oke agba, o di dandan lati maa sọ iru nkan ti yoo maa jẹ.
Bi o ba nifẹ si ki awọ rẹ jọlọ biigba ti o ṣi wa lọdọ, rii pe o mu ayipada ba nkan to maa n jẹ tẹlẹ.
Ounjẹ to dara fun ara bi eso, ẹfọ,ounjẹ ti ko lọra lara pupọ maa n jẹ ki eekanna,irun ati awọ eeyan maa dan mọranmọran.
Yago fawọn ounjẹ alagolo,ṣuga pupọ ati ounjẹ to kun fun ọra ti ko ṣeni laanfani.
O tọ ki o mu adinku ba iyọ jijẹ nitori eleyi a maa jẹ ki ifunpa rẹ ga ju ti tẹlẹ lọ.
Fifa oju ro ni gbogbo igba, akoba lo maa n ṣe fun ara.
Ẹrin arinju naa ko da ṣugbọ, ju tatẹyinwa lọ, rii wi pe o n fi ẹrin da inu ara rẹ dun loore koore.
Oríṣun àwòrán, Instagram/Neduwazobia
Ẹrin rinrin maa n jẹ ki eeyan pa ironu rẹ,bẹẹ si ni a maa jẹ ki eeyan dabi pe o lo ajidewe.
Awọn onimọ sọ pe ẹrin rinrin da bi idaraya fun ọkan, a si maa jẹ ki ẹjẹ gba ibi to ba yẹ ninu ara ti eleyi ko si ni jẹ ki eeyan tete darugbo.
Guinea coup: Mọ̀ si nípa ọ̀gágun Mahamady Doumbouya tó dìtẹ̀ gbàjọba lọ́wọ́ Ààrẹ Alpha Condé*
Oríṣun àwòrán, EPA
Ọjọ karun un, oṣu Kẹsan an, ọdun 2021 ni awọn ọmọ ogun gbajọba lọwọ Aarẹ Alpha Condé ti orilẹ-ede Guinea lẹyin ti wọn ti kọkọ ṣina ibọn bolẹ nile rẹ.
Lẹyin naa ni ọgagun Mahamady Doumbouya kede lori ẹrọ amohunmaworan ilẹ naa kan pe awọn Ologun ti gbajọba lọwọ alagb ada.
O si sọ pe awọn ọmọ ogun yoo gbe ijọba fun ẹlomiran wọọrọwọ ti akoko ba to.
Agbegbe Forecariah, to wa ni iwọ oorun Guinea ni ọgagun naa n gbe ki iṣẹlẹ iditẹgbajọba naa to waye.
O kawe gboye nile ẹkọ War College"" ni France, o si ni iriri iṣẹ ogun jija fun ọdun marundunlogun lẹyin to ti lọ foju wina ogun ni Afganistan, Cote d'Ivoire, Djibouti ati Central African Republic."
Yoruba Nation: Kò sí ìdí tí à ó fi bínú sí Akeredolu lórí ọ̀rọ̀ Yorùbá Nation
"Doumbouya ṣiṣẹ ni France pẹlu ileeṣẹ ọmọ ogun rẹ titi di ọdun 2018 ki Aarẹ Condé to fiwe pe wale lati wa dari ikọ ""Special Forces"" ilẹ ọhun ti wọn n pe ni GFS."
Aarin ọdun 2018 yii kan naa ni awọn ileeṣẹ iroyin kan ni Guinea ti bẹrẹ si n kọ awọn iroyin kan nipa ọgagun ọhun lori awọn iwa aṣemaṣe kan ti wọn fi kan an.
Kayeefi: Àdììtú tó rọ̀ mọ́ ìdí tí ìlú Okeluse ṣe fi ọmọ ọdún 16, tó wà ní JSS 2 jọba
Ninu oṣu Karun un ọdun 2021 yii, Doumbouya wa lara awọn eeyan marundinlọgbọn ti ajọ EU fi ẹsun titẹ ẹtọ ọmọniyan loju kan ni Guinea, koda iroyin kan tilẹ sọ pe wọn ti mọle ni saa kan lori ọrọ kan naa.
Ninu oṣu Kẹjọ ọdun 2021 yii kan naa, iroyin ni wọn wọgile iwe ẹbẹ Doumbouya lati gba iwe irinna gẹgẹ bii ọmọ orilẹ-ede France nitori awọn iwa to n wu ti ko ba ti orilẹ-ede naa mu.
Covid-19 Vaccines: Aráàlú sọ̀rọ̀ lórí èrò ìjọba láti sọ gbígba abẹ́rẹ́ àjẹsára di ọ́rànyàn
Bẹẹ naa ni awọn kan n sọ pe ọwọ ọgagun naa ko mọ nitori awọn dukia to jẹ tirẹ, eyii to kọja iye owo to n gba loṣu lọ.
Apa ila oorun ẹkun Kan ni Ọgagun Mamady Doumbouya ti wa lorilẹede Guinea.
Doumbouya lọ sí ilé ìwé awọn ọm'ogun War College niluu Paris lorilẹ ede France.
Iriri ọdun mẹẹdogun ni Doumbouya ti ni lẹnu iṣẹ ologun.
Ọgagun Doumbouya ṣe iṣẹ apẹtu sija lorilẹ ede Afghanistan, Ivory Coast, Djibouti, CAR.
O tun ti ṣiṣẹ ri ni Israel, Cyprus, UK ati orileede Guinea ri.
Ọgagun Doumbouya tuntun ṣiṣẹ pẹlu ile iṣẹ ologun France lọdun 2018 nigba ti Ààrẹ Conde ni ko wa da  ẹgbẹ ológun GFS silẹ ní Guinea.
Oríṣìíríṣìí iroyin lo ti n jade nipa Ọgagun Doumbouya lorilẹ ede Guinea.
Iroyin kan jade lọdun 2021 pe Doumbouya ko ri iwe ọmọ onilu orilẹ-ede France gba nitori ihuwasi rẹ lodi sí ìlànà ileeṣẹ ologun France.
Bakan naa tun ile iṣẹ Friaguinee tun sọ pe bi o ti ni ọrọ rẹ kò hàn sí ọpọ èèyàn.
Friaguinee béèrè pé nibo ni Ọgagun Doumbouya ti ri owo ti o fi kọ oríṣìíríṣìí ile nigba ti owo oṣu rẹ kò ju $500 lọ.
Doumbouya wa lara awọn ọgagun mẹẹdogun ti wọn kede fún ijiya EU lori ẹsun titẹ ẹtọọ ọmọniyan mọlẹ.
Ẹwẹ, ajọ iṣọkan ilẹ Afrika, AU, to fi mọ ajọ EU at ECOWAS ti bu ẹnu atẹ lu iditẹgbajọba naa, wọn si ti sọ fun Doumbouya atawọn  ẹmẹwa rẹ ki wọn da ijọba naa pada fun awọn alagbada lai fọta pe
Guinea : Ìdí tí ìdìtẹ̀ gbàjọba Ààrẹ Alpha Conde ṣe wáyé ní Guniea
Oríṣun àwòrán, Guinea Tv
Awọn ologun ni orilẹ-ede Guinea ti gba ijọba nilẹ naa.
Iditẹgbajọba ti wo ijọba Ààrẹ Alpha Conde lulẹ.
Ọpọ ọmọ orilẹ-ede Guinea ni inu wọn kò dùn sí ijọba Aarẹ Conde lẹyin to wọlé fun saa kẹta ní bii ọdún kan din diẹ sẹyin.
Rogbodiyan bẹ sílẹ lẹyin ti Conde wọle tan, ẹgbẹ alatako naa kọju ìjà sí ijọba Conde.
Ile iṣẹ ologun gbe Conde, ẹni ọdun mẹtalelọgọrin sí  àhámọ́ lẹyin ti awọn eeyan gburo ibọn lẹgbẹ ile iṣẹ aarẹ ni Conakry.
Ọgagun GFS, Mahamady Doumbouya lo Kede lori ẹrọ amohunmaworan le awọn ologun ti gba ijọba.
Ọgagun Doumbouya ṣèlérí pé àwọn ologun yóò ṣètò lati gbe ijọba fún alágbádá.
O ni omi tuntun ti ri, ẹja tuntun Si ti wọọ lori ìṣèjọba orilẹ-ede Guinea bayii.
Ajọ AU, UN ati ECOWAS naa ti bu ẹnu atẹ lu igbesẹ awọn ologun ni Guinea.
Awọn yii fẹ ri pe awọn ologun gbe ijọba padà fún alágbádá ni kiakia.
Àwọn òjíṣẹ́ Ọlọrun tako ọ̀rọ̀ ọ̀gá àjọ NDLEA tó ní òògùn olóró ló n tú ìgbéyàwó ká
Oríṣun àwòrán, AFP
Awọn ojiṣẹ Ọlọrun kan ti sọ pe kii ṣe oogun oloro nikan lo maa n da idile ru.
Wọn ni iwa buburu ati ailẹkọọ ile lo maa n fa lọpọ igba.
Awọn ojiṣẹ Ọlọrun  naa lo sọ ọrọ ọhun nigba ti wọn n ba BBC Yoruba sọrọ lori ọrọ kan ti alaga ajọ to n gbogun ti egbogi oloro ni Naijiria, NDLEA, Mohamed Buba Marwa ati aya rẹ sọ pe o yẹ ki awọn afẹsọna maa ṣe ayẹwo egboogi oloro ṣaaju igbeyawo.
Agba ẹlẹsin Musulumi kan, Alfah Lukman Muktar Isalẹkoto,  sọ pe ìpìnlẹ̀ igbeyawo ti ko dara ati ailẹkọọ ile lo n da ọpọ idile ru laye ode oni.
"O ni ""Ọmọ miran ko mu igbo tabi egboogi oloro kankan, ṣugbọn agidi inu rẹ ko le jẹ ko rile ọkọ gbe tabi ki iyawo pẹ lọọdẹ rẹ."""
Tọkọtaya lu ọmọ ni gbanjo fun 400k
Wo bí ìbálòpọ̀ tó gbóná giri-giri ṣe le ran tọkọtaya lọ́wọ́ láti kojú ìpèníjà
Wo nkan márùn-ún tí o kò mọ̀ nípa ìbálòpọ̀ láàrin tọkọ-taya
Ilorin Cripple Couple: Ọṣẹ ìfabọ́ ni tọkọ-taya tó ní ìpèníjà ẹsẹ̀ ń tà láti bọ́ ọmọ mẹ́ta
Imaamu agba ọhun ṣalaye pe o yẹ ki awọn afẹsọna ni ẹkọ to dantọ ki wọn to wọ inu igbeyawo lọ.
O sọ siwaju si pe ẹlomiran bẹrẹ si n mu egboogi oloro nitori aṣifẹ ọkọ tabi aya.
Alfa naa ni o yẹ ki awọn afẹsọna ṣe iwadii ni kikun lori ẹnikẹni ti wọn ba fẹ gbe sile ki wọn to ṣe igbeyawo naa, kii kan n ṣe ki wọn gbe ara wọn  sile tan, ki wọn to ṣẹṣẹ maa kọ ẹkọ.
O pari ọrọ rẹ pe ẹbun akọkọ ti eeyan yoo fun awọn ọmọ rẹ ni irufẹ ẹni to ba fẹsile, eyii ti yoo di baba tabi iya irufẹ awọn ọmọ bẹẹ nitori ayaba lasan ni imukumu fun awọn miran jẹ ninu igbeyawo.
Ẹwẹ, pasitọ Isaac Ajifowowe naa da si ọrọ ọhun, ti oun  naa si sọ pe kii ṣe gbogbo awọn ti igbeyawo wọn tuka lo n lo ogun oloro, ṣugbọn iwa lo ju.
Wo àwọn ọ̀nà tí o lè gbà láti di ọjọ́ ogbó pẹ̀lú olólùfẹ́ rẹ
Pasitọ naa sọ pe idile ẹni ti ko ba mọ Ọlọrun ko le ṣe lai daru.
"O ni ""Ẹlomiran n lo oogun oloro lati pa ironu rẹ lẹyin ti ile rẹ ko toro mọ."""
Ṣiṣe ayẹwo oogun oloro kọ ni yoo mu ki idile layọ bikoṣe ki tọkọ-taya mọ Ọlọrun.
"Pasitọ naa pari ọrọ rẹ pe ""Eṣu lo n gbe inu idile ti wọn ko ba mọ Ọlọrun, ko ni nnkan ṣe pẹ oogun oloro lilo."
Alaga ajọ to n gbogun ti egboogi oloro lilo ni Naijiria, Mohamed Buba Marwa ati aya rẹ ti sọ pe ṣiṣe ayẹwo egboogi oloro lara awọn ti wọn ba fẹ ṣe igbeyawo ṣe pataki fun alaafia idile.
Marwa lo sọ ọrọ naa nibi eto ti ajọ kan ti kii ṣe ti ijọba, Coal to Diamond Support Network, ṣe onigbọwọ rẹ niluu Abuja.
Iyawo Marwa, toun naa wa nibi eto naa sọ pe igbesẹ ọhun ṣe koko lode oni nitori akaimoye idile ni oogun oloro ti tu ka liapẹ si akoko ti wọn gbe ara wọn sile gẹgẹ bii lọkọ laya.
Marwa, ti Shehu Dankolo, to jẹ ọkan gboogi lara awọn oṣiṣẹ NDLEA ṣoju fun sọ pe yatọ si igbeyawo, oniruru iṣoro ni egboogi oloro maa n fa ninu igbe aye awọn to n lo.
"O ni ""Irufẹ igbe aye ti awọn eeyan n gbe maa n sọ bii ọjọ ọla agbegbe tabi orilẹ-ede wọn yoo ṣe ri."""
Yatọ si pe oogun oloro maa n tu igbeyawo ka, o le fa oniruru aisan si eeyan lara, o tun maa n fa iwa ipa lawujọ, to fi mọ iku aitọjọ.
Nigba to n sọrọ, iyawo Marwa, Hajia Munirat Marwa sọ pe awọn ọdọ gbọdọ mu ṣiṣe ayẹwo oogun oloro fun ẹnikẹni ti wọn ba fẹ gbe sile ni ọkan pataki lara awọn imurasilẹ eto igbeyawo naa.
O ṣalaye pe iyatọ wa laarin ayẹyẹ ọjọ igbeyawo ati gbigbe papọ gẹgẹ bii lọkọ-laya lẹyin ayẹyẹ igbeyawo ọhun.
Munirat Marwa pari ọrọ rẹ pe awọn afẹsọna gbọdọ ṣe ayẹwo ẹnikẹni ti wọn ba fẹ gbe sile lọna ati wọgile awọn iṣoro igbeyawo kan bii lilu nilu bara, ija ojoojumọ ati bẹẹ bẹẹ lọ..
Sunday Igboho: Mo ti gbà fún Ọlọ́run níbí, Ọlọrun mọ̀ sí bí mo ṣe wà lẹ́wọ̀n
Oríṣun àwòrán, Sunday_igboho/Instagram
Gbajugbaja ajafẹtọẹni fun ilẹ Yoruba nni, Sunday Igboho, ti fi ọwọ gbaya pe bi oun se wa lọgba ẹwọn ni Cotonou ko nitumọ si oun nitori o ti wa ni akọsilẹ pe oun yoo se ni.
Sunday Igboho fi ọwọ idaniloju yii sọya ninu fọnran ohun rẹ kan to gba ori ayelujara kan nilu Cotonou eyi to tẹ BBC Yoruba lọwọ.
Igboho ni gbogbo ọrọ oogun ti oun ni, fiimu lasan ni amọ irin ti oun yoo rin nile aye, titi ti oun yoo fi jade laye, o ti wa lara oun ati Ọlọrun to da oun.
"Ti mo ba joko nigba miran, ti mo ba ranti ọrọ Alfa Muideen Bello, ara mi yoo balẹ ni. Lọjọ ti baba n ba mi sile, ti awọn sẹnatọ, gomina atawọn eeyan nla nla miran joko.
Alfa Muideen wa beere pe agbara ti Igboho n lo nibo lo wa, amọ gbogbo wọn n woju ara wọn, o wa ni ara mi ni Ọlọrun fi si.
O ni mo le dọbalẹ fun ọmọ ti wọn sẹsẹ bi amọ ibi ti Ọlọrun fi nnkan naa pamọ si mi lara, wọn ko le ri."
Sunday Igboho: 'Ǹkan tÍ Sunday Igboho Ṣe ní Ibarapa tún ti ṣelẹ̀ ní ìpínlẹ̀ Ogun'
Bakan naa ni Sunday Igboho sọ siwaju si pe oun ti gba fun Ọlọrun nibi ti oun wa yii, ti oun ko si bẹru ohunkohun mọ.
"Lẹyin Ọlọrun to ni mi, n ko bẹru ohun yowu mọ, gbogbo ohun to ba yẹ ki wọn da lara, ki wọn da.
Bi wọn ba gbe mi de iwaju adajọ yẹn, maa sọ fun pe n ko bẹru rẹ amọ mo bẹru Ọlọrun to ni mi ni, gbogbo ara ti wọn ba fẹ fi mi da, ki wọn fi mi da.
Bi wọn ba fẹ gbe mi lọ si Naijiria, ki wọn maa gbe mi lọ sibẹ, Naijria ti wọn n gbe mi lọ, ayafi ti ko ba si Ọlọrun nibẹ lo ku.
Ti Ọlọrun ba ti n bẹ ni Naijiria, ki wọn gbe mi lọ sibẹ, ko si nnkan ti wọn yoo se, sebi Kanu wa nibẹ, ija ti mo n ja ni Kanu n ja.
Gbogbo iyẹn a fi n dẹru ba ara wa ni, ti wọn ba fẹ mi lọ si Naijiria, hùn hun hún ayafi ti ko ba si Ọlọrun ni Naijiria lo ku.
Bi lọrun ba ti wa ni Naijiria, ki wọn maa gbe mi niso nibẹ, ko si ohun ti yoo sẹlẹ́."
Yoruba Nation: Kò sí ìdí tí à ó fi bínú sí Akeredolu lórí ọ̀rọ̀ Yorùbá Nation
Ajafẹtọ ẹni naa ni oun fi Ọlọrun bura, ọkunrin miliọnu kan ni oun, oun kii si bẹru ohunkohun amọ ibi to ka oun mọ ni.
O ni oun kii se eeyan lasan alailagbara amọ ọkunrin ni oun ti ko ba si ọkunrin nile mọ, to si se fi isẹ ogun ran.
Bakan naa lo ni oun ti yari mọ wọn lọwọ ni ọgba ẹwọn Cotonou ri pe ki wọn paarọ yara ti oun wa amọ nigba ti wọn faake kọri ni oun yari fun wọn.
Igboho ni oun kii se ọmọ kekere rara nitori ọdun yii ni oun maa pe ẹni aadọta ọdun, oun kan le ni ara kekere ni.
"Ni ọjọ ti mo change rẹ mọ wọn lọwọ nibi pe ninu ki wọn pa mi loni tabi ki wọn paarọ cell ti mo wa, wn yoo se ọkan.
Ninu kẹ yin gbogbo ibọn yin sibi tabi kẹ mu mi kuro nibi tẹ de mi mọ yii, ẹ gbọdọ se ọkan loni, wọn change rẹ tori gbogbo ohun ti mọ sọ, wọn mọ pe n ko fi bawọn sere."
Sunday Igboho ni oun n se bii dindinrin, mugun, ọdẹ fun eeyan amọ ti oun ba pada change rẹ, agbara wọn ko le ka oun mọ.
O ti wa ninu akọsilẹ pe maa se ẹwọn ni:
Sunday Igboho: Ọjọ́ méje ní áńkọ̀bù fi wà lọ́wọ́ mi táwọn agbẹjọ́rò mi kò sì rí nǹkan ṣe si
Oríṣun àwòrán, Igboho
Ilumọọka ajijagbara ọmọ Yoruba nni, Sunday Igboho ti n fi apa janu pe agbẹjọro oun, Amofin Salami ko yọju si oun fun bi osu meji, to si pe ara rẹ ni agbẹjọro oun.
Sunday Igboho lo n fi apa janu bẹẹ ninu fọnran ohun rẹ to lu ori ayelujara pa nilu Cotonou lorilẹede Benin, nibi to ti wa ni ahamọ.
Igboho, ẹni to kede bẹẹ lasiko ti amofin Salami yọju si lọgba ẹwọn lẹyin ọpọlọpọ ọjọ tun ni n se ni agbẹjọro naa tun n fi oun ba ẹlomiran sọrọ fun bii isẹju mẹẹdogun nigba ti oun yọju si.
Ajafẹtọni naa, to n fi ẹjọ amofin yii sun eeyan kan ninu fọnran oun naa ni idi ree ti oun fi sọ fun pe oun fẹ lọ jẹun, to si ni oun le maa lọ lasiko to n ba ẹni naa sọrọ fun ọpọ isẹju.
Awọn agbẹjọro mi kọ ni Ọlọrun, to ba wu wọn, ki wọn jawọ:
Wayi o, Sunday Igboho ti wa n i apa janu pe awọn agbẹjọro oun ko ni agbara lati gba oun silẹ lọwọ adajọ.
Gani Adams agbara
O ni bi gbogbo wọn se pọ to, oju wọn bayii ni adajọ se ni ki wọn maa gbe oun bọ lọgba ẹwọn lai jẹ pe wọn ri nnkan se si.
Igboho fikun pe awọn agbẹjọro naa kii se Ọlọrun nitori wọn ko ni agbara lati sọ fun adajọ pe ko ma gbe oun lọ si ọgba ẹwọn.
"Bi gbogbo awn lọya naa se pọ to, bii mẹwa, soju wọn ni adajọ se n gbe mi bọ ni ọgba ẹwọn, se Lọya nu?
Oju wọn ni wọn fi so ankọbu mọ mi lọwọ fun ọjọ meje, wọn ko ri tu afi igba ti amofin Falola to de, se awọn Lọya nuu?
Kee si se owo kekere ni wọn gba. Eyi to gba miliọnu marun, miliọnu mẹrin, bi wọn se gba owo lọ̀ niyẹn amọ wọn ko le tu ankọbu lọwọ mi.
Lai jẹ pe mo jale tabi se nnkan kan, emi ko bẹru Lọya tabi ẹnikankan. Gbogbo ara ti wọn ba fẹ fi mi da, mo ti wa pẹlu wọn."
Sunday Igboho: Femi Falani ní ẹjọ́ Igboho ní Cotonou ń kọ́ àwọn amòfin Nàíjíríà ní ẹ̀kọ́
O ni se ko yẹ ki agbẹjọro naa maa yọju si oun loore koore gẹgẹ bi oun se jẹ onibara rẹ ti wọn fi si ahamọ ọgba ẹwọn.
"O wa de ọdọ mi nibi yii, o n fi mi ro ẹjọ, to ba jẹ eeyan nla nibi yii, ko le jẹ eeyan nla to mi, ẹnu ilu yii nikan ni wọn ti mọ oun.
Agbara wọn kọ lo gbe mi debi, agbara Benin si kọ lo mu mi silẹ, o wu Ọlọrun bẹẹ ni. Ọlọrun lo mu mi silẹ funra rẹ, oun lo gbe mi wa sibi, oun naa ni yoo yọ mi nibi."
Igboho ni oun ni awọn agbaagba amofin ni Naijiria, ti oun maa n dari wọn, ti wọn si maa n wa ba oun ninu ile oun, ti oun si maa n ran wọn nisẹ.
"Ẹ wo iye amofin to n lọ se ẹjọ mi ni Ibadan, agba agbẹjọro mejilelogoji lo n lọ duro fun mi, ti n ko si tii fun wọn ni sile kan bayii ti n dan.
Mo dẹ n bori awọn ẹjọ naa ni, ni isẹju isẹju ni mo n bori ijọba apapọ nile ẹjọ nigba to jẹ pe Ọlọrun lo n sisẹ rẹ.
Gbogbo ẹyin baba mi naa ko si dakẹ adura, ti Ọlọrun naa si n gbọ adura yẹn. Mo tun na Malami pa ni ẹjọ kotẹmilọrun to pe.
Nigba to ya lo n sẹ pe oun kọ loun ran sọja tabi wa sile DSS lọ sile mi, ti oun kii si se Fulani tabi Hausa.
Adajọ wa koro oju si pe ki lo de ti wọn lọ sile mi loru, armoured tank ni wọn fi fọ ogiri wọle, ki lo de, n ko paayan, n ko jale, n ko si se nnkan kan."
Yoruba Nation: Kò sí ìdí tí à ó fi bínú sí Akeredolu lórí ọ̀rọ̀ Yorùbá Nation
Sunday Igboho ni oun ti oun sọ fun wọn ni pe iya ti wọn si n jẹ Yoruba ti to, awọn ko se mọ, bẹẹ Fulani si n pa Yoruba ni ipakupa lawọn ilu bii Saki, Igboho.
O ni oun wọ inu igbo lọ lati le wọn funra oun ni, ti ijọba ko si ni ẹri lati sọpe ibi ti oun ti pa Fulani ree nitori gbogbo iwọde ti oun n se, oun ko gbe ibọn lọwọ nibẹ.
"Ohun ti mo n sọ fun yin ni pe awa la ni epo, awa la ni gbogbo nnkan, ki lo de to se jẹ pe awa lẹ n fiya rẹ jẹ, awa lẹ n pa.
Gbogbo Naijiria ti daru, a le rin ni alẹ amọ a ko le rin ni alẹ mọ nisinyii, ẹ ko gbọdọ ni ẹ n bọ lati Eko wa si Ibadan mọ lalẹ, Fulani maa pa gbogbo ẹni to wa ninu mọto ni.
Wọn yoo wa ji awọn eeyan gbe lọ sinu igbo, wọn yoo ni ki wọn lọ mu miliọnu lọna ọgọrun naira wa, iru igbesi aye wo la n gbe lọ ni Naijiria yẹn."
Sunday Igboho ni oun ti oun n ba ijọba fa niyẹn, ko si ti pọ ju debi pe wọn yoo wa maa ni ki wọn lọ pa oun nigba ti kii se pe awọn lo ni mi oun lọdọ wọn.
Sunday Igboho ni oun ko bẹru ẹnikẹni nitori talaka ayeraye ni baba oun, to si ni oogun bii Sanpọnna amọ o ku naa ni.
"Ki n to wale aye, gbogbo irinajo mi ni Ọlọrun ti kọ si ori mi, ki iya mi to bi mi, pe bi maa se rinrin aajo aye mi ree.
Lọjọ ti wọn bi mi, ti wọn n ko mi jade, ti wọn ba sọ fun iya ati baba mi pe ọmọ tẹ bi yi o, yoo lowo, yoo si ni okiki, aye yoo si mọ.
Baba mi yoo sọ pe ọna wo lo fẹ gbe gba pẹlu ile ahoro ti wọn n gbe, ẹ wa wo lonii yii, se awọn wa ni Ọlọrun ni."
Sunday Igboho wa ni ki araye wa wo oun lonii, ki wọn wo oun ti oun da, eyi to fi han pe ọwọ Ọlrn ni ohun gbogbo wa, to fi mọ iku ati aye oun.
Ilú òyìnbò ní mo lọ lásìkò Covid ló gún mi ni kẹ̀ṣẹ́ láti bẹ̀rẹ̀
Oluwawemimo Tade, obìnrin àgbẹ̀ tó làmìlaaka jùlọ ní ìpínlẹ̀ Ondo ni kò si àwáwí fún ẹnikẹ́ni láti má ṣe iṣẹ́ àgbẹ̀, nítorí lẹ́yìn tí òun fi iṣẹ́ ìjọba sílẹ̀ ní oùn bẹ̀rẹ̀ sí ní ṣiṣẹ́ oko.
Ìya àfin Tade ní iṣẹ́ nọ́ọ̀sì ní oun kọ́kọ́ jíṣe ní kùtùkùtù ayé òun bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé, àgbẹ̀ ni ìyá àti bàbá òun láti ọjọ́ tí òun ti dáyé.
Tade ni láti ìgbà tí òun ti fi iṣẹ́ sílẹ̀ ni òun ti bẹ̀rẹ̀ sí ní ṣe isẹ́ okò, sùgbọ́n àyípadà dé ní lọ́dún 2020 lásìkò tí òun lọ bá ọmọ òun tọ́jú ọmọ ní ilú oyìnbó.
Ilú òyinbo yìí ni Coronavirus de ba mi tí mí o le wálé, sùgbọ́n nítorí ìfẹ́ tí mó ni si iṣẹ́ agbẹ̀ ni mó ba ni mo ba lo ra àwọn nkan ọ̀gbìn, mó gbìn sí ẹyinkule wọn.
Láti asiko yìí ni fọ́ran àwọn èso mi pàápàá jùlọ ti iṣu ṣe tànká gbogbo àgbáyé.
Ó rọ gbogbo ènìyàn pé kí wan máa ṣe ṣe àwáwi lórí ìdá tí wọn kò fi le dáko, nítorí ànfàní tó wà níbẹ̀ pọ̀.
Olajide Sowore: Òpó kan ní òkú ọkọ òun lòun fẹ́ lọ sin kí òun tó kó ṣọ́wọ́ ajínigbé
Oríṣun àwòrán, Sowore
Obinrin kan, Emmanuella Anyanwu, ti sọ pé àwọn agbegbọn to pa Olajide Sowore lopin ọsẹ to kọjá bere milliọnu mẹwàá naira owo itusilẹ lọwọ oun ki oun to moribọ nibi ti wọn ko wọn si.
Anyanwu ṣàlàyé pé òun ni rìnrìn àjò láti ìlú Eko sí ipinlẹ Imo lati lọ sin òkú ọkọ òun ni ki iṣẹlẹ naa to waye, òun sì fi N500,000 bẹ awọn ajinigbe naa ṣugbọn wọn kọ jalẹ.
Obìnrin opo naa ṣàlàyé ni agọ awọn ọlọpaa pe ọkọ awọn dẹnukọlẹ nítòsí ìlú Benin lọjọ náà lọhun, awọn sí sun inú ọkọ náà mọju.
"O ni ""Ni nnkan bíi aago mẹfa abọ idaji, awọn okunrin kan jade láti inú igbó, wọn sì bẹrẹ sí n yìnbọn sí wa, eyiti o mu ki a jọwọ ara silẹ fún wọn."""
Wọn ko gbogbo ẹrù wa, wọn sì kó wa lọ sínú igbó kiji kan ti irinajo rẹ tó nnkan bíi wakati meji.
Anyanwu sọ pe lẹyìn náà ni wọn bere onírúurú ibere lọwọ oun ki wọn tó sọ pé ajinigbe ni awọn, ti wọn sí ni àwọn yóò gba mílíọ̀nù mẹwàá naira owo itusilẹ lọwọ òun.
O ni ko pẹ diẹ sí asiko naa ti ojo bẹrẹ sí n rọ, ti wọn tun mu okunrin mii wa sinu ibudo náà ki oun to wa ọna lati sa asala.
Nigba to n sọrọ nípa irufẹ èèyàn tí awon ajinigbe naa jẹ, o ni oun gbagbọ pe Fulani ni wọn.
"Gẹgẹ bíi ohun tó sọ, o ni ""Mo gbagbọ pe Fulani ni wọn, nítorí lọjọ naa, wọn tú awọn màlúù wọn sílẹ kí wọn tó wà ji wa gbe."""
Nigba ti awọn akọroyin bere lọwọ rẹ bóyá awọn to ji í gbé lo pa àbúrò Omoyele Sowore, o ni awọn ajinigbe naa yinbọn lu ọpọ ọkọ loju popo lásìkò ti iṣẹlẹ naa wáyé.
Anyawu pari ọrọ rẹ pé nígbà tí òun sa kúrò ní àhámọ́ awọn ajinigbe náà, opo ẹrọ ibaraẹnisọrọ kan ni oun tọ fún nnkan bíi wákàtí meji ki oun to pade okunrin kan to mu òun lọ sí àgọ ọlọ́pàá.
Miyetti Allah ń fẹ́ kí ìjọba àpapọ̀ dẹ́kun àwọn gómìnà tó ń ṣòfin lòdì sí ẹran dídà láàrín ìlú
Ẹgbẹ awon darandaran ni Naijiria, Miyetti Allah, ti ke si ijọba apapọ lati bẹgi dina igbesẹ awọn gomina lati ṣe ofin to lodi si fifi maalu jẹko laarin igboro.
Akọwe ẹgbẹ naa, Saleh Alhassan, lo kede bẹẹ nibi ipade awọn akọroyin kan niluu Abuja.
O ni ofin naa yoo da omi alaafia to ti wa laarin Miyetti Allah atawọn eeyan igberiko  lati ọpọ ọdun sẹyin ru.
Oba Ogboni: Bí ìwọ́de Yoruba Nation bá tún wáyé, màá bá wọn kópa níbẹ̀
"Alhassan sọ pe ""A fẹ ki ile igbimọ aṣofin agba ati Aarẹ Naijiria gbẹsẹle igbesẹ awọn gomina kan lati fofin de awọn darandaran lẹnu iṣẹ oojọ wọn pẹlu ofin buruku ti wọn fẹ fi de fifi maluu jẹko laarin ilu."""
O yẹ ki ijọba apapọ da ileeṣẹ ti yoo maa ri si ọrọ ẹran ọsin ati ẹja sinsin gẹgẹ bo ṣe wa lawọn orilẹ-ede mii nilẹ Afrika, o si yẹ ki Naijiria le wa awọn ọna lati dojukọ awọn iṣroro ti ayipada oju ọjọ n mu ba awọn darandaran.
Alhassan sọ pe ofin tuntun ti awọn gomina naa dawọle yoo sọ awọn darandaran atawọn ogunlọgọ awọn to n fi ẹran ọsin jẹun sinu iṣẹ ti ko ṣe fẹnusọ.
Oríṣun àwòrán, Miyettti
Adari awọn Miyetti Allah naa tun ke si Aarẹ Muhammadu Buhari lati ṣe atungbeyẹwo awọn ibi ti wọn ti ya sọtọ tẹlẹ fun itọju ẹran ọsin  ni Naijiria, ko si kọ ibi ti wọn ti yoo ti maa tọju awọn ẹran ọsin ni ẹkun idibo kọọkan ni Naijiria.
Lẹyin naa lo ke si ile igbimọ aṣofin agba lati gba awọn darandaran naa silẹ nipa fifi ọwọ si ofin idasilẹ awọn ibudo ẹran  ni Naijiria.
Adari Miyetti Allah ọhun tun tọka si iwe ofin kan ti ajọ AU ati ECOWAS buwọlu to rọ mọ ẹran dida laarin awọn orilẹ-ede nilẹ Afrika.
O ni ti ijọba Naijiria ba ṣe agbekalẹ irufẹ ofin bẹ labẹle, ko ni si pe awọn atọhunrinwa adaran Fulani wa n pa eeyan bi ẹni pa ẹran ni Naijiria.
Miyetti Allah lo n sọ ọrọ yii lede lẹyin oṣu mẹrin ti awọn gomina ni iha guusu Najiria fofin de fifi ẹran jẹko laarin igboro.
Awọn gomina ọhun pade niluu Delta, nipinlẹ Asaba, nibi ti wọn ti ke si Aarẹ Buhari lati ba awọn ọmọ Naijiria sọrọ lori ọrọ naa.
Lẹyin oṣu meji si asiko naa ni wọn fẹnuko lati ṣe ofin lodi si dida ẹran laarin igboro lawọn ipinlẹ wọn lọna ati fopin si ipakupa ti awọn ọdanran Fulani n pa awọn eeyan wọn.
Sunday Igboho: Ìgbẹ́jọ́ yóò wáyé ní Ibadan lórí ẹjọ́ tí Sunday Igboho pe DSS àti Malami
Oríṣun àwòrán, Sunday_igboho/Instagram
Igbẹjọ yoo tẹsiwaju loni lori ẹjọ ti ajafẹtọmọniyan,Sunday Adeyemo,Igboho, pe ijọba apapọ Naijiria lori idaabo bo ẹtọmọniyan rẹ.
Lọwọlọwọ bayi Sunday Igboho wa ni ahamọ ni orileede Benin nibi ti awọn alaṣẹ ilẹ naa ti n ba ṣẹjọ.
Nipa ẹjọ to n waye loni ni Naijiria, adajọ ti  ṣaaju ni ki awọn agbe fun ijọba ati Minisita feto idajọ ma ṣe dunkoko mọ Sunday Igboho.
Ninu ohun ti adajọ sọ, o ni wọn ko gbọdọ fọwọ kan akoto owo Igboho bẹẹ si ni o lanfaani lati yan fanda nilu lai si idiwọ lọdọ ijọba tabi awọn agbodegba rẹ.
Ẹmeeji ọtọọtọ ni ile ẹjọ ti da Igboho lare lori ẹbẹ ti agbẹjọro agba Naijiria fi tako idajọ ti adajọ gbe kalẹ.
Adajọ Ladiran Akintola lo n dari ẹjọ naa ni ile ẹjọ giga to wa nilu Ibadan.
Gastroenteritis Outbreak: Kí ló dé tí ìgbẹ́ gbùùrù àti inú ríru fi ń dá ọlọ́kadà àti 'mai-bola' láàmú ní Ogun?
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ijọba ipinlẹ Ogun ti kede  ajakalẹ kokoro aifojuri kan to n daamu awọn ọlọkada ati awọn to n ṣalẹ ni ipinlẹ naa.
Niṣe ni aisan yi to maa n farahan nipa igbẹ gbuuru ati inu rirun gbode lagbegbe Magboro, Ofada ni ijọba ibilẹ Obafemi Owode.
Ileeṣẹ ilera fidi ọrọ yi mulẹ ninu atẹjade kan ti Kọmisana feto ilera Tomi Coker fi sita .
Wọn sọ pe awọn to ko aisan yi a maa saba ya igbe gbuuru, inu a maa run wọn, koda ẹlomii a maa bi pẹlu.
Tomi Coker ṣalaye pe ẹni tawọn fura si pe o ko aisan yi wọle ṣẹṣẹ dari pada si ipinlẹ naa.
Kọmiṣana yi ṣalaye pe ile igbọnsẹ lawọn to n ko aisan yi ti n saba lugbadi rẹ ati pe awọn ọlọkada ati awọn to n ṣa ilẹ lo pọ ninu awọn to lugbadi rẹ.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ile igbọnsẹ ti wọn lawọn fura si pe itankalẹ aisan yi ti bẹrẹ ti wa ni titi pa gẹgẹ bi Kọmisana ṣe ṣalaye.
Lọwọlọwọ o ni awọn to lugbadi aisan naa n gba itọju nile iwosan lati le dẹkun itankalẹ aisan yi.
O ni awọn ko ti le ṣe ayẹwo omi ara itọ tabi igbẹ awọn to ko aarun naa nitori awọn ko ni eeyan kankan to n koju aisan yi lọwọ bayi.
Ẹwẹ Kọmisana naa sọ pe awọn ile iwosan gbarọgudu kan ti da kun itankalẹ aisan yi nipa bi wọn ṣe n ṣe itọju awọn eeyan.
O ni ijọba ti ṣe idasilẹ awọn aaye itọju si ile iwosan to wa ni  Magboro-Akeran tawọn si ti pese ohun eelo itọju sibẹ.
Awọn onimọ sọ pe iru aarun yi a maa tan ka nipa omi tabi ounjẹ to ba ni kokoro aifoujri gastroentritis ninu.
O lewu fawọn agbalagba to ba ni ipenija lara ati awọn ọmọ ikoko.
Cut off Marks: Kíni nkán tí àjọ JAMB n ṣé f'awon akẹ́kọ̀ọ́ àríwá Nàìjíríà tí El Rufai kò dùn inú sì?
Oríṣun àwòrán, Facebook/nasirelrufai/
Gomina Nasir El-Rufai ti ipinlẹ Kaduna ti bẹnu atẹ lu bi awọn alaṣẹ ẹka eto ẹkọ ṣe n bu maaku fawọn akẹkọọ lati apa ariwa Naijiria.
O ni iyapa laarin maaki awọn akẹkọọ ariwa ati awọn akẹgbẹ wọn da bi fifa ori apa kan si fi ọkan silẹ.
Ninu ifọrọwanilnuwo kan pẹlu ileeṣẹ amohunmaworan Naijiria Channels TV lo ti fi ọrọ yi lede.
El Rufai ni fifun wọn ni odiwọn maaki kekere lati fi gbawọn sile ẹkọ giga, paapa ninu idanwo igbaniwọle si fasiti, JAMB ko dara to.
Koda o ni iru iṣesi bayi ti mu ki awọn akẹkọọ ẹkun Ariwa ya ọlẹ nidi ẹkọ wọn.
El Rufai to ti fi igba kan jẹ Minisita fun olu ilu Naijiiria, Abuja, ṣalaye pe didin maaki awọn akẹkọọ lati Ariwa Naijiria ko ṣe anfaani kankan bi kii ṣe pe o n koba agbegbe naa.
Oríṣun àwòrán, Facebook/nasirelrufai/
O wa rọ ajọ JAMB paapa lati fopin si iṣesi yi lati ṣe iwuri fawọn akẹkọọ naa lati ''gbaju mọ iṣẹ ki wọn si le figa gbagba pẹlu akẹgbẹ wọn''
''Tipẹtipẹ ni apa ariwa ti n tọ awọn apa yoku lẹyin nidi eto ẹkọ.
"Lati igba ti Naijiria ti gba ominira bo ti ṣe ri nuu.Ko ṣe anfaani kankan fun wa bi kii ṣe pe o mu ki awọn akẹkọọ wa ya ọlẹ''
O ni o yẹ ki wọn gba awọn akẹkọọ niyanju lati mura si ẹkọ ni ati pe awọn yoo bẹrẹ igbaradi fawọn ọmọ Kaduna lati pegede ninu idanwo ti wọn ba kọ.
Lẹnu lọọlọ yi awọn ileẹkọ ti wa ni titi pa ni ipinlẹ Kaduna nitori wahala ijinigbe to n waye ni gbogbo igba.
Gomina El Rufai ni ko ni pẹ tawọn yoo fi ṣi ileẹkọ pada fawọn akẹkọọ lati pada si kilasi wọn.
Sunday Igboho: Agbẹ́jọ́rò Sunday Igboho ní Benin Republic ṣàlàyé pé ìfẹ́ Yoruba lòun fi n gbẹjọ́ rẹ̀ rò
Oríṣun àwòrán, others
Agbẹjọro fun Sunday Igboho, lorilẹ-ede Benin, Amofin Ibrahim Salami, tun ti fesi si awọn ẹsun ti onibaara rẹ fi kan an pe ko mojuto ọrọ oun daadaa.
Ninu ọrọ kan to tun sọ fun BBC Yoruba, Amofin Salami sọ pe ẹni to wa ninu ọgba ẹwọn ko mọ igbiyanju ẹnikọọkan lori rẹ""."
O ni ati oun, ati awọn agbẹjọro yooku n ṣiṣẹ karakara.
O fikun pe kii ṣe nitori owo ni oun ṣe n ṣiṣẹ fun Igboho. O ni iṣẹ ti oun ṣe fun wọn ju owo lọ.
Iyawo Igboho gbe owo wa fun mi, ṣugbọn mo kọ ọ...Iṣẹ ti mo n ṣe kii ṣe nitori owo, nitori Yoruba, Oduduwa ni mo ṣe n ṣe e.
Ọgbẹni Salami fikun ọrọ rẹ pe, nigba ti ọrọ naa ba yanju, ni ki wọn o to o fun oun ni nkan ti wọn ba fẹ ẹ fun oun.
Ṣaaju lo ti kọkọ sọ sọrọ lori fọran ohùn kan to jade si ori ayelujara laipẹ yii.
Ninu fọnran naa to tẹ BBC  Yoruba lọwọ ni Sunday Igboho ti fi ẹsun kan agbẹjọro naa pe ko yọju si oun lati bi oṣu meji ti oun ti wa ni ẹwọn.
Ninu fọnran naa lo ti jọ pe Igboho n fi ẹjọ agbẹjọro naa sun ẹnikan, pe nigba ti agbẹjọro naa papa yọju si oun, niṣe lo tun n fi oun ba ẹlomiran sọrọ fun bi iṣẹju mẹẹdogun.
Eyi si lo bi Igboho ninu to fi fi ọrọ abuku ranṣẹ si awọn agbẹjọro to n ṣoju rẹ lorilẹ-ede Benin pe, wọn kii ṣe agbẹjọro daadaa.
Igboho sọ pe ṣe bi loju gbogbo wọn, ni adajọ fi paṣẹ pe ki wọn o gbe oun lọ si ọgba ẹwọn, ti wọn ko si ri ohunkohun ṣe nipa rẹ.
Bakan naa lo ni kii ṣe owo kekere ni oun san fun ẹni kọọkan wọn, amọ to ja si ofo.
Yoruba Nation: Kò sí ìdí tí à ó fi bínú sí Akeredolu lórí ọ̀rọ̀ Yorùbá Nation
Ṣugbọn nigba to n ba BBC sọrọ lori awọn ẹsun naa, Amofin Salami sọ pe ti ede aiyede ba tiẹ waye laarin oun ati onibaara oun, Sunday Igboho, kii ṣe inu iwe iroyin ni oun yoo ti sọ.
O ṣalaye pe awọn to gbe ohun naa jade ṣẹ si ofin orilẹ-ede Benin, fun bi wọn ṣe pin fọnran naa lai gba aṣẹ lọwọ Igboho tabi oun paapaa.
Ẹni to tete ma n binu ni Sunday Igboho, to si le fi ibinu sọrọ, amọ n ko ni titori bẹẹ sọ ọrọ temi naa fun awọn oniroyin.
O ni Igboho ko ba ẹnikẹni ṣe ifọrọwerọ, ti oun ko si le sọ bi fọnran ohun naa ṣe jade sita sori ayelujara.
O ni oun ko ni esi fun gbogbo nkan ti wọn ni Igboho fikan oun gẹgẹ bi ẹsun. O sọ pe oun n ba iṣẹ oun lọ, bẹẹ naa si ni gbogbo awọn agbẹjọro to n gbeja Igboho wa lẹnu iṣẹ wọn.
Bakan naa lo sọ pe lootọ lo yẹ ki Igboho binu si bi wọn ṣe fi si ẹwọn ni Benin, lai jẹ pe o ṣẹ si ofin wọn.
O yẹ ki gbogbo wa mọ pe ibinu to tọ ni ibinu Sunday Igboho.
Lóòtọ́ orin mi àti Lagbaja jọra ṣùgbọ́n ìyàtọ̀ díẹ̀ wà níbẹ - Labule
Ọpọ ọmọ Naijiria, paapaa awọn to jẹ ololufẹ orin Highlife ati Afrobeats ni wọn ti n saaro orin Lagbaja nitori pe o to ọjọ melokan ti eekan akọrin naa ti gbe ara rẹ kuro lagbo orin kikọ.
Amọṣa lasiko ti Lagbaja n kọrin ni ọdọmọkunrin kekere kan nigba naa ti n wo awokọṣe rẹ to si n tọ ipasẹ irinajo rẹ.
Arakunrin naa ti ọpọ mọ si Labule ti mu ipasẹ ọna orin Lagbaja bayii ti o si jẹ pe bi o ba ti n kọrin ọpọ ti ko ba tete mọ yoo maa bere pe ṣe Lagbaja niyi abi oun kọ.
Akọṣẹmọṣẹ imọ ẹrọ Civil Engineering ni Labule ni fasiti ilu Eko ki o to tun gba ilẹ Gẹẹsi lọ lati gba imọ kun imọ ninu rẹ; ṣugbọn ifẹ orin ko fi silẹ lo fi pada wa gbe igba orin ni Naijiria.
Buhari visit to Imo: IPoB IPOB kéde òfin kóńlé-ó-gbélé, wọ́n láwọn ò fẹ́ àbẹ̀wò Ààrẹ Buhari sí ìpínlẹ̀ Imo
Oríṣun àwòrán, other
Ẹgbẹ ajijagbara IPOB to n pe fun idasilẹ orilẹede Biafra ti tako igbesẹ Aarẹ Muhammadu Buhari lati ṣe abẹwo sí ipinlẹ Imo lọsẹ yii. Wọn ni awọn ko fẹ ri aarẹ ni regberegbe ẹkun ila oorun gusu orilẹede Naijiria lọwọ yii.
Adari eto fún ẹgbẹ IPOB, Chika Edoziem lo kede ọrọ yii.
Ọgbẹni Chika wa pàṣẹ ofin kóńlé-ó-gbélé lati tako àbẹwò Buhari sí ipinlẹ Imo ni l'Ojobo.
"A o fẹ Buhari nipinlẹ Imo nilẹ Biafra ni ọjọ kẹsan an oṣù kẹsan an yii.
Bakan naa ni ẹgbẹ naa tun fọnrere rẹ pe  ki gbogbo awọn ọbalaye atawọn ọtọkulu ilu o jina sibi abẹwo naa paapaa eto yowu ti gomina ipinlẹ Imo, Hope Uzodinma ba gbe kalẹ nitori Aarẹ Buhari.
Gomina ipinlẹ Imo, Uzodimma ti kede èròngbà Buhari tẹlẹ lati ṣe abẹwo sí ipinlẹ naa.
Uzodimma to kede abẹwo Aarẹ Buhari si ipinlẹ naa ṣalaye pe ọkan o jọkan akanṣe iṣẹ ni aarẹ yoo ṣi lasiko abẹwo rẹ naa.
Sunday Igboho vs DSS, AGF Malami: Agbẹjọ́rò fún Abubakar Malami ní kò sí àrídájú pé Sunday Igboho ló ni ilé tí DSS kọlù tàbí pé ẹ̀jẹ̀ èèyàn ló wà nílẹ̀ níbẹ̀ lẹ́yìn ìkọlù náà- Malami
Minisita fun eto idajọ ati amofin agba lorilẹede Naijiria, Abubakar Malami SAN ti sọ pe ko si aridaju to fi idi rẹ mulẹ pe Oloye Sunday Adeyẹmọ ti ọpọ mọ si Sunday Igboho lo ni ile tawọn DSS kọlu ati pe ko si idaniloju pe ẹjẹ eeyan lawọn ẹjẹ to wa nilẹ nibẹ lẹyin ikọlu ọhun.
Ni ọjọ Iṣẹgun nibi itẹsiwaju igbẹjọ ti aṣiwaju awọn to n pe fun idasilẹ orilẹede Yoruba, Oloye Sunday Adeyẹmọ ti ọpọ n pe ni Sunday Igboho pe ileeṣẹ alaabo DSS ati minisita fun eto idajọ lorilẹede Naijiria Abubakar Malami lori bi wọn ṣe kọlu ile rẹ ti wọn si gbẹ ẹmi ati ọpọlọpọ dukia jẹ.
Agbẹjọro fun Sunday Igboho, Amofin agba Yọmi Alliyu, SAN ko fidio meji wa sile ẹjọ naa to si rọ ile ẹjọ lati wo wọn gẹgẹ bi ara awọn ẹri niwaju rẹ.
Bi o tilẹ jẹ pe agbẹjọro fun Malami tako eyi to si ni pe adajọ nikan lo yẹ ko wo fidio naa ni kọrọ ọfiisi rẹ ṣugbọn ti adajọ to n gbọ ẹjọ naa, Onidajọ Ladiran Akintọla ni ko le ri bẹl, gbangba laṣa n ta ni oun yoo fi ṣe.
Fidio bi ile Igboho ṣe ri lẹyin ikọlu ti wọn kọlu ati bi Minisita fun eto abo lorilẹede Naijiria, Bashir Magashi ṣe ke sawọn eeyan lati di ihamọra ki wọn si gba ara wọn silẹ lọwọ awọn agbebọn ni agbẹjọro fun Igboho gbe kalẹ siwaju ile ẹjọ naa.
Lóòtọ́ orin mi àti Lagbaja jọra ṣùgbọ́n ìyàtọ̀ díẹ̀ wà níbẹ - Labule
Nigba to si fesi lori rẹ, Amofin Abubakar to n ṣoju Amofin Agba Naijiria Abubakar Malami ni ko si ohunkohun to le fi idi rẹ mulẹ pe ile Sunday Igboho ni wọn kọlu ati pe ẹjẹ eniyan lo wa nilẹ nile naa.
Ni ọjọ kini oṣu keje lawọn agbofinro DSS kọlu ile Sunday Igboho nilu Ibadan, eeyan meji lo ku nibẹ, dukia ẹgbẹlẹgbẹ naira lo si ṣofo nibẹ.
Nigba ti agbẹjọro fun DSS, Amofin T.A. Nurudeen pẹlu fi fidio meji silẹ niwaju ile ẹjọ, Ọkan lara awọn fidio naa ṣe afihan bi Sunday Igboho ṣe n sọ fun awọn eeyan pe ki awọn to n polongo ibo fun ọdun 2023 o lọ gbagbe rẹ to si tun ṣekilọ fawọn agbofinro pe ti wọn ba lepa oun wọn ko ni dele pada.
Saki Earth tremor: Ilẹ̀ mímì nílu Saki ti sọ àwọn olugbé ibẹ̀ sínú hílàhílo, ọ̀pọ̀ olùgbé ń sá fìlú sílẹ̀
Inu ikayasoke ati ipaya lawọn eeyan ilu Saki ni ipinlẹ Ọyọ n gbe bayii lẹyin iṣẹlẹ ilẹ mimi to n waye nibẹ lati nnkan bi ọsẹ meji bayii.
Iṣẹlẹ naa to ti wa di lemọlemọ ti mu ki awọn olugbe ilu naa kan tilẹ di ẹru wọn gba ibomiran lọ.
Ni bi a ṣe n ko iroyin yii jọ, awọn alaṣẹ ajọ to n mojuto ọrọ oju ilẹ ati iwọn rẹ lorilẹede Naijiria, NGSA, Nigerian Geological Survey Agency ti fi awon akosomose ranse si ilu Saki lati le lọ ṣe kokari iṣẹlẹ naa.
Nigba ti ikọ BBC News Yoruba de ilu Ṣaki lati mọ bo ṣe nlọ nibẹ awon olugbe ilu naa ṣalaye pe ọpọ igba ni ilẹ naa yoo ṣa dede maa dun ti yoo si tun maa kun.
Awọn agbegbe bii Mọdina, Balako, Muslim Hospital, Isalẹ Adinni, Ero ọmọ, Ilupeju lọna Ọgbọrọ, irisad, Markaz ati bẹlbẹẹ lọ ni iṣẹlẹ ilẹ mimi naa ti saba n waye.
Taliban take-over: Ẹgbẹ́ alátakò ní Taliban kìí ṣe ìjọba Afghanistan
Oríṣun àwòrán, Reuters
Ẹgbẹ alako lorilẹ ede Afghanistan ti ke pe gbogbo pe lati ma rí awọn Taliban gẹgẹ bi ijọba ilẹ naa.
Ijọba ilẹ Amerika ti bu ẹnu atẹ lu ijoba ti awọn Taliban fi lọlẹ eleyii ti ko sí obinrin kankan ninu wọn.
Awọn ọmogun to n kọju sí awọn Taliban lẹkun Panjshir naa sọ pe ijọba Taliban lodi sofin.
Amẹrika kọminu lori iru awọn eeyan to wa ninu ijọba Taliban.
Orilẹ-ede Amerika ṣalaye pe awọn eeyan bii Mullah Mohammad Hassan Akhund ati Sirajuddin Haqqani wa lara awon afurasi ti Amerika ati ajọ FBI n ṣe iwadii lori wọn.
Oríṣun àwòrán, Screenshot/bbc
Ẹgbẹ alatako NRF sọ pe ikede ijọba Taliban ṣiṣe ọta pẹlu awọn eeyan Afghanistan.
Ẹgbẹ Taliban ní awọn ti ṣẹgun NRF lẹkun Panjshir, amọ NRF ni ìjà si n lọ lọwọ.
Oríṣun àwòrán, Screenshot/bbc
Ninu atẹjade kan ti orilẹ-ede ti Amerika fi sita, o ni oun n kọminu iru awọn eeyan ti ẹgbẹ Taliban kò sí ijọba rẹ.
Ajọ EU naa tako ijọba ti Taliban kéde, o ni ko mu ileri rẹ ṣẹ lori awon to sọ pé yóò wà ni ijọba rẹ.
Ní bíi ọsẹ mẹta sẹyin ni Taliban gba ijọba orilẹ-ede Afghanistan.
Amọ, oríṣìíríṣìí ipenija lo n doju kọ ijoba wọn lori ọrọ ajé ati lórí bí ọpọ ko ti faramọ bi wọn ṣe gbajọba.
Banditry: Ọlọ́pàá mẹ́jọ wọ gàu lórí ẹ̀sùn ìbọn kíkó fáwọn jàndùkú.
Oríṣun àwòrán, others
Iroyin tó tẹ wá lọwọ ti sọ pe awọn afurasi ọlọpaa mẹjọ ti wọ gàu lori ẹsun pe wọn n ko ibọn fawọn janduku ni ipinlẹ Zamfara.
Iroyin sọ pe awọn ọlọpaa náà tún máa n gbe oogun oloro fawọn ọdaran yii.
Bakan naa ni iroyin ọhún tun ni awon afurasi ọlọpaa yìí tún máa n gbe epo bentiroolu ati disu lọ fawọn janduku ninu igbo.
Ipinlẹ Zamfara wa lara awọn ipinlẹ tawọn janduku ajinigbe ati afẹmiṣofo ti n ṣọṣẹ julọ ni Naijiria.
Lóòtọ́ orin mi àti Lagbaja jọra ṣùgbọ́n ìyàtọ̀ díẹ̀ wà níbẹ - Labule
Awọn ọmogun ti bẹ sinu igbó nibi ti wọn ti dojú ìjà kọ awọn janduku yii.
Ẹwẹ, Aarẹ Muhammadu Buhari ti sọ fawọn olori ileeṣẹ ologun lati wa ojutu sí ètò àbò tó mẹhẹ ni Naijiria.
Sunday Igboho: Agbẹjọ́rò DSS wọ ọkọ̀ One Chance"" làwọn adigunjalè bá jí fáìlì ẹjọ 'Igboho' gbé lọ́wọ́ rẹ̀?"
Oríṣun àwòrán, others
Agbẹjọro fun ajọ ọtẹlẹmuyẹ Naijiria DSS to n ṣẹjọ pẹlu ajafẹtọmniyan Sunday Igboho ti sọ fun adajọ pe iwe faili ẹjọ awọn amugbalẹgbẹ Igboho ti di awati.
Agbẹjọro Idowu  Awo sọ pe awọn adigunjale lo gba faili naa lọwọ akẹgbẹ oun to wọ mọtọ akero awọn oni One Chance.
O sọ fun adajọ Obiora Egwuatu to n gbẹjọ naa pe awọn nkan ini rẹ mii to fi mọ iwe ipẹjọ ni awọn olubi wn yi ji gbe lọ.
Ọkan lara awọn agbẹjọro fun awọn mejila ti awọn agbofinro DSS ko nile Oloye igboho naa, Amofin Pẹlumi Ọlajẹmgbesi to fi idi iroyin yii mulẹ fun BBC News Yoruba pe ohun ti agbẹjọro fun DSS sọ niwaju ile ẹjọ naa jẹ kayefi nla gba ti o si doju tini gan ni.
O ni bi awọn ole ba lee digun ja awọn oṣiṣẹ DSS ni ilu Abuja tii ṣe olu ilu Naijiria, ireti kekere lo wa fun mẹkunu ni eyi tumọ si.
ohun ti awọn oṣiṣẹ DSS sọ pe awọn adigunjale kọ luwọn ti wọn si ja wọn lole debi pe iwe ẹjọ si sọnu lasiko ti wọn n bọ nile ẹjọ jẹ idojuti gbaa.
Lóòtọ́ orin mi àti Lagbaja jọra ṣùgbọ́n ìyàtọ̀ díẹ̀ wà níbẹ - Labule
Ẹjọ ti wọn n ṣe lori ọrọ to wa nilẹ yi ni eleyi to ni ṣe pẹlu fifi ẹtọ awọn amugbalẹgbẹ Igboho ti DSS fẹ tẹju rẹ mọlẹ rinlẹ fun wọn.
Lẹyin alaye to ṣe fun adajọ, o wa beere fun isunsiwaju ẹjọ naa.
Ninu awọn amugbalẹgbẹ Igboho tio DSS mu, mẹwaa ni wn ti tu sil lẹyin ti ile ẹjọ gba beeli wọn.
Ṣaaju ni ile ẹjọ wọgile ẹbẹ ti DSS bẹ pe ki wọn da awọn mẹrin ninu awọn amugbalẹgbẹ wọnyi pada si ahamọ.
Sunday Igboho aides: Àjọ DSS fi ẹ̀sùn ìgbésùnmọ̀mí kan olùrànlọ́wọ́ Sunday Igboho méjì tó kù sí àhámọ́
Ajọ ọtẹlẹmuyẹ, DSS, ti fi awọn ẹsun to ni i ṣe pẹlu igbesunmọmi kan oluranlọwọ Sunday Igboho meji to ku si ahamọ wọn.
Lasiko igbẹjọ to waye ni ile ẹjọ giga ijọba apapọ nilu Abuja ni ajọ naa ti ka awọn ẹsun ọhun lẹyin oṣu meji ti wọn ti mu awọn eniyan naa ati awọn mẹwaa miran.
Ninu iwe ipẹjọ ti wọn pe ni FHC/ABJ/CR/305/2021 ni agbẹjọro ajọ DSS, S.M Bello ti fi ẹsun igbesunmọmi marun-un kan Noah Oyetunji ati Amudat Babatunde, to jẹ obinrin.
Ajọ naa fi ẹsun kan Oyetunji pe awsn ba awọn nkan ija oloro fun igbesunmọmi lọwọ rẹ.
Ni ti obinrin naa, Amudat Babatunde, wọn fi ẹsun kan an pe o polongo igbesunmọmi lori ayelujara Facebook rẹ.
Ìyàwó Igboho gbé owó wá fún mi, mo kọ̀ọ́ nítorí pé kìí ṣe torí owó ni mo fi n gbẹjọ́ rẹ̀ rò
"Ṣé lóòtọ́ ni agbẹjọ́rò DSS wọ ọkọ̀  ""One Chance"" tàwọn adigunjalè sì jí fáìlì ẹjọ 'Igboho' lọ́wọ́ rẹ̀?"
Buhari, dẹ́kun àwọn gómìnà tó ń ṣe òfin tako fífi ẹran jẹko- Miyetti Allah
Orí ló kó mi yọ lọ́wọ́ àwọn ajínigbé tó pa àbúrò Sowore - Opó
Amọ nigba to fesi si awọn ẹsun naa, agbẹjọro awọn afurasi ọhun, Pelumi Olajengbesi sọ pe awsn ẹsun naa ko lẹsẹ nilẹ, to si tun jẹ nkan itiju.
Ọjọ diẹ sẹyin ni ajọ ọtẹlẹmuyẹ DSS tu mẹwaa lara awọn afurasi mejila naa silẹ, lẹyin ọgọta ọjọ ti wọn ti wa ni ahamọ rẹ.
Eyi waye lẹyin ọpọ ọjọ ti ile ẹjọ ti paṣẹ pe ki wọn o gba beeli awọn eniyan naa.
Ọjọ kinni, oṣu Keje, ọdun 2021 ni wọn ko awọn eniyan ọhun lasiko ti wọn kọlu ile Sunday Igboho to wa ni agbegbe Soka, nilu Ibadan.
Eeyan meji ni iroyin sọ pe wọn yinbọn pa nibẹ.
Sunday Igboho trial: Olùdarí ìgbìmọ̀ ìgbẹ́jọ́ Igboho kéde ìgbésẹ̀ lórí àwọn agbẹjọ́rò tó ń gbọ́ ẹjọ́ rẹ̀ ní Cotonou
Oríṣun àwòrán, Instagram/Sunday Igboho
Oludari igbimọ igbẹjọ fun Sunday Igboho, Olasupo Ojo ti kede pe Igboho ko paarọ awọn amofin to n ṣoju rẹ ninu igbẹjọ to n lọ ni orilẹ-ede Benin Republic.Igboho sọrọ ninu fónrán kan pẹlu ibinu pe niiṣe lawọn agbẹjọro mẹwàá to n ṣoju rẹ kan n gba obitibiti owo, sibẹ òun sì wà ní atimọle ni Cotonou.Igboho ni awọn amofin mẹwàá yii kò tíì rí nkan ṣe sí bi oun ti wa ni atimọle fún bí aadọta ọjọ bayii.
Ajijagbara ilẹ Yoruba sọ ninu fónrán náà pé awọn naa ti Ọgbẹni Ibrahim Salami jẹ olori wọn fi oun silẹ ni ẹwọn lai bikita.Igboho fi aidunnu rẹ hàn s'awọn agbẹjọro naa lori bi wọn ṣe n ṣe si oun lẹyin ti ẹni kọọkan wọn ti gba miliọnu márún ùn marun un tan.Igboho ni oun o tiẹ bẹrù ki wọn gbe oun pada si Naijiria nibi ti igbẹjọ oun dé dúró bayii.Ṣugbọn adari igbimọ Igboho ti sọ pe awọn agbẹjọro naa ni yóò máa tẹsiwaju pẹlu igbẹjọ náà ni Cotonou.
Lóòtọ́ orin mi àti Lagbaja jọra ṣùgbọ́n ìyàtọ̀ díẹ̀ wà níbẹ - Labule
"A mọ awọn agbẹjọro to n ṣiṣẹ, bakan naa ni a mọ awọn ti ko ṣiṣẹ. A ti gbe igbesẹ ṣugbọn a ko da ẹnikẹni duro ninu wọn. Gbogbo wọn lo ni anfani kan tabi omiran ti wọn lori igbẹjọ yii. Ẹ maa gbagbe pe ilẹ okeere ni
igbẹjọ ti n waye. Idi niyii ti a fi n tẹsiwaju pẹlu gbogbo wọn, a lè dari wọn lori ohun ti a ba fẹ. Igboho le ma mọ iṣẹ tawọn amofin naa n ṣe, oun kan mọ nipa awọn ti o n foju ri ni. Gbogbo wọn kò lè máa yoju síi lẹwon,"
Ọgbẹni Ojo lo ṣalaye bẹẹ.
Ẹwẹ, ọkan lara awọn agbẹjọro Igboho ni Naijiria, Pelumi Olajengbesi ni inu igbimọ igbẹjọ ko dun si aawọ laarin aṣiwaju awọn to pe fun idasilẹ orilẹede Yoruba naa atawọn amofin rẹ ni orilẹede Benin Republic.Olajengbesi ni Igboho mọ ilọsiwaju to wa lori igbẹjo rẹ niluu Abuja ati Ibadan ṣugbọn inu rẹ ko dun sí bi ọ sí ti wa lẹwon ni Cotonou.
Alleged rape: Ọwọ́ tẹ bàbá ẹni ọdún 64 tó fi ìpá bá ọmọ ọdún méjì lòpọ̀ ní ìpínlẹ̀ Ogun
Oríṣun àwòrán, ogun state police
Ọwọ ti tẹ ọkunrin ẹni ọdun mẹrinlelọgọta kan, Ayotunde Taiwo ti wọn fi ẹsun kan pe o ba ọmọ ọdun meji ni ibalopọ.
Ọwọ ileeṣẹ ọlọpaa, ẹka ti ipinlẹ Ogun tẹ Taiwo, ni agbegbe Agbado, lẹyin ti iya ọmọdebinrin naa lọ ọ fi ẹjọ sun nileeṣẹ ọlọpaa lọjọ keje, oṣu Kẹsan-an, ọdun 2021.
Agbẹnusọ ileeṣẹ ọlọpaa ipinlẹ naa, Abimbola Oyeyemi, sọ ninu atẹjade kan pe, iya ọmọ naa sọ fun awọn ọlọpaa pe oun deedee ṣakiyesi pe ọmọ oun ko le rin daadaa mọ, to si jẹ pe bi oun ṣe n yẹ ara rẹ wo ni oun ri ti ẹjẹ n ṣan jade ni abẹ rẹ.
Nigba to si bi ọmọ naa leere nipa nkan to ṣẹlẹ, ọmọ na ọwọ si ile to kọju si ile wọn.
Nigba ti iya ọmọ naa sare de ile ọhun, o ba afurasi naa to n fọ ṣokoto awọtẹlẹ rẹ to ni ẹjẹ lara, eyi to fihan pe o ṣẹṣẹ ni ibalopọ pẹlu ọmọ ọdun meji naa tan ni.
Lọwọlọwọ, wọn ti gbe ọmọdebinrin naa lọ si ileewosan fun itọju.
Bakan naa ni ksmisanna ọlọpaa fun ipinlẹ Ogun, Edward Awolowo Ajogun ti paṣẹ pe ki wọn o gbe afurasi naa lọ si ẹka ileeṣẹ ọlọpaa to n pese atilẹyin fun mọlẹbi, eyi to wa ni Ọta, fun iwadii ati fifi oju rẹ ba ile ẹjọ.
Bisi Alawiye: Akọrin ẹ̀mí Bisi Alawiye ní àánú Ọlọ́run ló sọ òun di akọrin
Bisi Alawiye Aluko ni oun ni itan ki oun to tan, o ni ẹni ti ko ba ni itan ki o tan tan ko ni pẹ to maa fi tan.
O ni ju gbogbo rẹ lọ, aye ọpẹ yọ lori irinajo orin ẹmi ti oun n kọ.
''Awa olorin ẹmi lawọn eeyan n kan bayii, wọn o ka bibeli mọ, nitori naa a gbọdọ keyesi ara
Awa akọrin naa gbọdọ kopa ti wa lori ọrọ orilẹede Naijiria.
A gbọdọ fọwọ sowọ pọ pẹlu ijọba Naijiria
Ọga akọrin ni mama mi ni ṣọọṣi Kerubu ati Serafu ni Ile Ife, ibẹ ni orin ti maa n wu emi naa lati kọ.
Mo maa tẹ le mama mi lọ si ile ijọsin nigba naa,'' Bisi Alawiye lo ṣalaye bẹẹ.
Workers ex-President Obasanjo Kidnap: Ọlọ́pàá ti dóòlà òṣìṣẹ́ ààrẹ tẹlẹ, Olusegun Obasanjo sílẹ lẹ́yìn ọjọ́ méjì tí wọ́n jí wọn gbé
Oríṣun àwòrán, other
Awọn oṣiṣẹ aarẹ tẹlẹ Olusegun Obasanjo mẹta to ko si ọwọ awọn  ajinigbe ti gba itusilẹ leyin nkan bi wakati mejidinlaadọta.
Ni irọlẹ Ọjọru  ni a gbọ pe wọn ji wọn gbe ni ìjọba ibilẹ Obafemi owode ki wọn to tu wọn silẹ ni irọlẹ ọjọ Ẹti.
Alukoro ọlọpaa Abimbọla Oyeyemi to fidi ọrọ yi mulẹ sọ pe akitiyan awọn agbofinro lo mu ki awọn ajinigbe naa tu awọn oṣiṣẹ yi silẹ.
O ni lati igba ti won ti ji wọn l'awọn ọlọpaa ọtẹlẹmuyẹ ti wọ inu igbo tọ awọn ajinigbe ọhun lọ.
Lati ana l'awọn ìkọ ọtẹlẹmuyẹ wa ti n dun koko mọ awọn ajinigbe taa sì ti n tọ pínpín wọn
O tẹsiwaju pe àwọn to ipasẹ wọn dé igbó to wa lẹyìn ilé ẹkọ girama Day Waterman College.
Ibẹ ni wọn wa lati ana
Alukoro ọlọpaa naa ko sọ nkankan nipa boya wọn mu awọn ajinigbe naa tabi pe wọn doju ija kọ wọn. Bakan naa a ko ri aridaju boya wọn san owo itusilẹ fawọn ajinigbe.
Oríṣun àwòrán, other
Awọn janduku agbebọn ti ji oṣiṣẹ aarẹ Naijiria tẹlẹ ri, Olusegun Obasanjo lọ ni abule kan lẹgbẹ Abeokuta nipinlẹ Ogun ni Ọjọru.
Iroyin sọ pe awọn agbebọn ọhun gẹgun de awọn oṣiṣẹ naa labule Kobape ni ijọba ibilẹ Obafemi-Owode nipinlẹ Ogun.
Iroyin naa sọ pe alakoso ọrọ owo, ayẹwe owo wo ati adari ileeṣẹ ni awọn oṣiṣẹ mẹta Obasanjo ti wọn ji gbe lọ.
Bi ago mẹrin irọlẹ ni wọn ji awọn eeyan naa lẹyin tawọn agbebọn ọhun yinbọn si ọkọ Hilux tawọn oṣiṣẹ naa wa.
Alukoro ileeṣẹ ọlọpaa ipinlẹ Ogun, DSP Abimbola Oyeyemi, lo fidi iṣẹlẹ ọhun mulẹ.
Oko Obasanjo ko jina si agbegbe Kobape ti wọn ti ji awọn eeyan naa gbe lọ.
Anti-grazing bill: Miyetti Allah kéde iye mílíọ̀nù tí wọ́n fẹ́ máa ta màálù kan tí ìpínlẹ̀ Eko bá fòfin de ìdẹranjẹko
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ẹgbẹ darandaran Miyetti Allah ti sọ iye ti wọn yoo maa ta maalu kan ti ijọba ipinlẹ Eko ba fi le fofin de idẹranjẹko ni gbangba.
Akọwe ẹkun iwọ oorun guusu fun ẹgbẹ Miyetti Allah,  Mai-Kudu Usman lo fidi ọrọ yii mulẹ.
Lọjọ Aje ọjọ keje oṣu kẹsan an ni ile igbimọ aṣofin ipinlẹ Eko fi abadofin ma fẹranjẹko ni gbangba si igbimọ to n ri si eto ọgbin.
Usman parọwa si ipinlẹ Eko lati ran awọn darandaran lọwọ nitori dida ọgba ẹranko silẹ yoo la owo lọ.
O ni ọsin ẹran maalu loju kan naa le mu ki maalu kan to miliọnu meji naira.
Bakan naa ni Usman tun rọ ijọba lati ṣe iranwọ owo fawọn ọlọsin ẹran maalu loju kan naa.
''A ti ṣe adehun pẹlu awọn eeyan ipinlẹ kan lati ma sin maalu loju kan naa.
A jọ gba wi pe a maa forukọ silẹ gbogbo awa darandaran.
Awa Fulani maa n lọ lati ibikan si ibomiran ni, a mọ lootọọ ni awọn ọdaran Fulani wa ti wọn n da wahala silẹ.
A fẹ ki ijọba fun wa ni anfaani lati ba awọn eyan wa sọrọ.
A ti sọrọ pẹlu awọn ti ọrọ kan nipinlẹ Ondo, Ekiti ati Oyo lori ọrọ yii,'' Usman lo sọ bẹẹ.
Bakan naa, alaga awọn alapata nipinlẹ Eko, Alhaji Alabi Bamidele Kazeem, beere iranlọwọ ijọba fawọn daran daran.
O ni owo nla ni yoo maa na wọn lati maa sin ẹran maalu loju kan naa.
Lagos cemetery: Ìjì tó hú igi ńlá ní ìtẹ́ òkú l'Eko ba ibojì òkú 50 jẹ́, àwọn ẹbí sáré dìgbà dìgbà
Oríṣun àwòrán, Punch
Iji lile ti wo igi nla to wa ni ilẹ isinku agbegbe Abari, ni ijọba ibilẹ lla orun ipinlẹ Eko.
Iṣẹlẹ yii da omi alaafia agbegbe naa ru, eyi to mu ki awọn mọlẹbi sa kijo-kijo lọ si ibi ti iṣẹlẹ naa ti waye.
Awọn ti ọrọ naa ṣoju wọn ni o kere tan, aadọta iboji oku ni igi nla to wo lulẹ lasiko iji lile naa bajẹ.
Igi to wo lule naa ni awọn aṣọgba ni o ti le ni ẹgbẹrun ọdun ti igi naa ti wa ninu itẹ naa ki o to wolulẹ.
Iroyin lẹnu awọn ti iṣẹlẹ naa ṣoju wọn sọ pe aago mẹsan alẹ lẹyin ti awọn oṣiṣẹ ibẹ ti dari lọ si ile ni iṣẹlẹ naa waye, to si ba awọn iboji miran jẹ patapata, nigba ti awọn miran ko fi bẹẹ faragba igi to wo lulẹ naa.
Lara awọn oṣiṣẹ ibẹ sọ pe igba keji  re e ti igi nla yoo wo lulẹ ni agbegbe naa, ti wọn si ge igi naa si wẹwẹ.
''O ṣeni laanu pe wọn ko le e tun awọn iboji naa ṣe lasiko yii, nitori wọn kọkọ gbọdọ gbe igi naa kuro ni bi to wo lulẹ si''
''Bakan naa ni alaga ijọba ibilẹ naa ti kesi awọn ti yoo ge igi naa, ki awọn mọlẹbi le tun iboji oku wọn ṣe''
Ni kia ti iṣẹlẹ naa waye ni awọn mọlẹbi ti wọn sin eniyan wọn si bẹ ti n salọ si iboji naa lati wo ipa to ni lara ẹni wọn to sun si ibẹ.
Alaga ijọba ibilẹ naa tun fi atẹjade ranṣẹ si awọn mọlẹbi ti wọn sin oku si ibẹ lati wa wo boya igi to wo lulẹ naa ni ipa abi ko ni ipa lori awọn eniyan wọn to sun si ibẹ.
Ondo kidnap: Àwọn jàndùkú agbébọn jí èrò ọkọ̀ 18 tó ń lọ sí ìlú Eko láti Ondo lọ
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Awọn ajinigbe tun ti ṣọṣẹ nipinlẹ Ondo lẹyin ti wọn ji awọn arinrinajo to n lọ si ilu Eko gbe lọ.
Iroyin ni gbogbo awọn to wa ninu ọkọ elero mejilelogun ni wọn jigbe lọ.
Awọn arinrinajo naa ni wọn jigbe ni agbegbe Idoani-Ifira Akoko ni ẹkun ariwa ijọba ipinlẹ Ondo.
Iroyin ni ọkọ naa ni wọn da duro ni agbegbe Idoani-Ifira, nibi ti awọn agbebọn naa ti farapamọ si.
Awọn ti iroyin naa ṣoju wọn sọ pe awọn agbebọn naa bẹrẹ si ni yin ibọn soke lati dẹru ba awọn ara agbegbe naa ati awọn arinrinajo.
Awọn eniyan ni wọn kọkọ gba ohun ini awọn arinrinajo naa, ki wọn to ko wọn wọ inu igbo lọ.
Ninu ọrọ tirẹ, alukoro ileeṣẹ ọlọpaa ni agbegbe Isua Akoko, CSP Hakeem Sadiq ni awọn ọlọpaa kogberegbe pẹlu ajọṣepọ awọn ẹka miran ti wọ igbo lọ lati doola ẹmi awọn eniyan naa.
Nibayii, ọkan lara awọn mọlẹbi awọn ti wọn jigbe sọ pe awọn agbebọn naa tii bere owo ẹmi to to miliọnu mẹwa Naira lọwọ awọn mọlebi, ki wọn to le gba itusilẹ.
DR Congo Meningitis: Àrùn yínrùnyínrùn bẹ́ sílẹ́ ní DR Congo, àjọ WHO ní ìgbàgbọ́ àwọn èèyàn pé 'àwọn àjẹ́' ló wà nídí rẹ̀ ń dènà ìtọ́jú
Oríṣun àwòrán, Who
Iroyin kan n sọ pe ajakalẹ arun  yinrunyinrun ti bẹ silẹ lagbegbe ila oorun ariwa orilẹede DR Congo, bẹẹni awọn eeyan ileto ti arun naa ti n ṣọṣẹ n sọ pe awọn ajẹ atawọn ẹgbẹ ẹlẹyẹ lo n da arun naa silẹ.
Gẹgẹ bi ohun ti ajọ ilera lagbaye, WHO sọ fun BBC, ọpọlọpọ iṣoro lawọn ajọ ilera atawọn akọṣẹmọṣẹ lati wa ọwọ ajakalẹ arun naa bolẹ pẹlu igbagbọ awọn eeyan agbegbe naa pe awọn ajẹ ati ẹlẹyẹ ni wọn wa nidi bi arun yinrunyinrun naa ṣe n pọ si nibẹ.
Ni bayii, eeyan ọgọfa ni ajakalẹ arun naa ti ran lọ sọrun, bẹẹni nkan bi ọgọrun miran si tun ti wa nileewosan kaakiri fun itọju.
Iha ti awọn eeyan agbegbe naa kọ si arun naa kun ara ohun to fa iku ọwọọwọ nipasẹ ajakalẹ arun naa.
Gẹgẹ bi ajọ WHO ṣe sọ, dipo ki ọpọ awọn ti arun naa ba o tọju rẹ bi o ti tọ, nṣe ni awọn eeyan naa n sa lati ibudo kan si ekeji pẹlu ireti pe arun naa ko ni tẹle wọn.
Buhari Visits Imo: Nínú àṣẹ tí ìjọba àti Ipob, èwo ní yóò ṣẹ lásìkò àbẹ̀wò Ààrẹ Buhari sí Imo?
Bi ko ba si idiwọ kankan, aarẹ Buhari yoo tẹsiwaju pẹlu abẹwo rẹ si ipinlẹ Imo nibi ti ikọ Ipob ti ni kawọn araalu ma ṣe jade sita.
Ofin gbele rẹ ti ikọ to n pe fun idasilẹ orileede Biafra yi gbe sita jẹ eleyi ti wọn ko ṣẹṣẹ maa pe iru rẹ lagbegbe naa.
Gẹgẹ bi Ipob ti ṣe sọ, awọn ko wa Buhari lagbegbe awọn ati pe araalu ko gbọdọ jade lati wa ṣe ayẹsi aarẹ.
Amọ ṣa ileeṣẹ ọlọpaa ti ni ki awọn to ba fẹ fa wahala kankan ma ṣe jade sita nitori awọn duro ṣẹpẹ lati koju wọn.
Lowurọ ọjọbọ nigba ti akọroyin BBC jade lati wo nkan to n ṣẹlẹ ni ilu Owerri to jẹ olu ilu Imo, niṣe ni gbogbo titi da paro paro.
Ko si lilọ bibọ awọn ọkọ, bẹẹ naa si ni o jabọ pe titi pa lawọn ileẹkọ wa ni agbegbe naa.
Lawọn agbegbe kan, awọn ọlọpaa ati ọmọ ogun mi duro wamuwamu ni igbaradi lati gba aarẹ lalejo.
Ẹgbẹ ọmọ ilẹ Igbo Ohanaeze Ndi Igbo sọ pe abẹwo yi fi han pe Baba gbogbo Naijiria ni aarẹ Buhari jẹ.
Ninu atẹjade kan ti alukoro ẹgbẹ naa Oloye Alex Ogbonnia fi sita, o ni ''pẹlu abẹwo yi, aarẹ ti fi han pe baba gbogbo orileede nii ṣe''
O tẹsiwaju pe awọn ni igbagbọ pe abẹwo yi jẹ eyi to lamilaka ti yoo si mu iyipada ba itan igbesi aye ilẹ Igbo ni Naijiria.
Oríṣun àwòrán, Facebook/HopeUzodimma01
Ninu ọrọ ti wọn, ijọba ipinlẹ Imo sọ pe abẹwo yi yoo mu idagbasoke ba igbayegbadun ati eto ọrọ aje ipinlẹ naa.
Kọmisana feto iroyin,Declan Emeluba sọ pe aarẹ yoo ṣe ifilọlẹ awọn akanṣe iṣẹ mẹrin  kan ni ipinlẹ naa lasiko abẹwo rẹ.
Ipinlẹ Imo jẹ ibi ti olu ileeṣẹ ikọ ESN sodo si.
Lawọn ipinlẹ to wa ni ilẹ Igbo bi Anambra, Enugu ati Imo, awọn alatilẹyin Nnamdi Kanu to n beere idasilẹ orileede Biafra a maa tẹle aṣẹ konileogbele ti Ipob ba fi lelẹ.
5G network: Báyìí tí ìjọba Nàìjíríà ti buwọ́lù ìfilọ́lẹ̀ 5G, kí làwọn ǹkan tó yẹ kó o mọ̀ nípa rẹ̀?
Oríṣun àwòrán, Dr-Isa-Ali-Pantami-/Getty Images
Ijọba orileede Naijiria lẹyin atotonu pupọ ti pada buwọ́lu lilo ẹrọ alatagba itakun agbaye 5G.
Minisita feto ibaraẹnisọrọ, Ọjọgbọn Isa Pantami fi ikede yi sita lọjọru pe igbimọ alaṣẹ Naijiria ti faṣẹ si  lilo ẹrọ alatagba yi.
Ikede yi ni lẹsẹkẹsẹ ni 5G ti bẹrẹ si ni di lilo labala ti yoo waye laarin asiko yi si ọdun 2025.
Bayi to ti wa di lilo, yoo ṣe ọpọ ọmọ Naijiria lanfaani lati mọ si nipa ẹrọ alatagba yi, paapa pẹlu bi awọn orisirisi iroyin eyi to jẹ ootọ ati ayederu ti ṣe n kaakiri lori 5G.
Nkan pataki to yẹ ni mimọ nipa 5G ree taa se atupalẹ rẹ:
Njẹ ajọṣepọ wa laarin 5G ati Covid-19 ?
Nigba ti ijọba Naijiria kọkọ mẹnu ba lilo 5G, o bọ si asiko igba ti ajakalẹ aarun Covid-19 bẹrẹ si ni gbode ni dun 2020.
Lasiko naa, awọn ọmọ Naijiria kan n bẹru pe 5G yi ni ipa to n ko lori itankalẹ Covid-19.
Kínni ààrùn coronavirus nííṣe pẹ̀lú ìmọ̀ ẹ̀rọ 5G?
Lati le ṣalaye aarin yi, ijọba Naijiria sọ pe awọn kan si ajọ meji pataki-ajọ ilera lagbaye,WHO, ati ajọ to n risi ọrọ ẹrọ ibaraẹnisọrọ lagbaye,ITO.
Awọn mejeeji yi fidi ọrọ mulẹ pe ko si ibaṣepọ laarin awọn mejeeji ati pe 5G ko ni nkankan ṣe pẹlu itankalẹ aarun Covid-19.
Diẹdiẹ ni wọn fẹ bẹrẹ lilo 5G.
Ẹrọ alatagba yi ko le kaakiri gbogbo Naijria lẹẹkan naa.
Idi ni pe awọn nkan eelo rẹ yoo maa de agbegbe kọọkan lẹsẹlẹsẹ ni.
Awọn ilu nla bi Eko, Abuja ati awọn miran lo ṣeeṣe ki wọn kọkọ bẹrẹ si ni jẹ anfaani lilo 5G yii.
Naijiria nikan kọ lo wa ni ipele ṣiṣe amulo 5G bayi
Ninu alaye ti Minisita Pantami ṣe fawọn akọroyin, o ni orileede Amẹrika, United Kingdom ,Switzerland,Germany ati awọn orileede Europe mii ti n ṣe amulo 5G.
Ni Afirika, South Africa ati Lesotho naa ti n lo.
Oríṣun àwòrán, PA
5G yoo mu ayipada ba bi a ti ṣe n lo awọn ẹrọ alagbeka wa
Lawọn to wa ni ipo ti Naijiria wa pẹlu 5G la ti ri awọn orileede bi Kenya, Uganda, Morocco ati Egypt.
Ninu awọn anfaani ti 5G yoo mu wa fawọn to n lo ni pe data taa n lo yoo maa ṣiṣẹ ni kiakia ju ti 4G ti ọpọ n lo bayi.
Fun apẹẹrẹ, bi eeyan ba fẹ wo fidio lori ẹrọ ayelujara tabi to ba fẹ 'download' rẹ, asiko ti yoo fi le ṣe eleyi lori 5G yoo ya ju ti 4G lọ.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Fawọn to ba tun wa lẹka aabo bi awọn ọmọ ogun Naijiria, 5G yoo fun wọn lanfaani lati tete ṣe awọn iṣẹ to nilo ẹrọ alatagba ni kiakia.
Ẹka ifowopamọ,ẹkọ ati ọrọ aje miran naa yoo ri data 5G lo nipa mimu iṣẹ wọn ya, ti awọn onibaara ko si ni gba akoko to pẹ lati se karakata eyi keyi ti wọn ba fẹ ṣe.
Yoruba Self Determination: Àgbáríjọpọ̀ ẹgbẹ́ Yorùbá gbẹ́ná wojú Gumi lórí àbẹ̀wò rẹ̀ sí ìlú Sunday Igboho
Agbarijọpọ awọn ẹgbẹ itẹsiwaju ọmọ Yoruba ti bẹnu atẹ lu abẹwo ti Sheikh Gumi ṣe si ilu Igboho ni ipinlẹ Oyo.
Lopin ọsẹ to kọja ni Sheikh Gumi ati awọn ikọ kan lati Ariwa Naijiria lọ si ilu Igboho ti wọn si fi fọnran fidio kan sita nipa abẹwo wọn.
Ilu Igboho ni ilu abinibi gbajugbaja ajafẹtọmọniyan ilẹ Yoruba ni, Sunday Adeyemo ti gbogbo eeyan mọ si Sunday Igboho.
Ninu fọnran fidio naa Gumi ati Ọjọgbọn Yusuf sọ pe awọn wa ni Igboho nibi ti awọn ti ri tawọn eeyan n gbe igbe alaafia.
Awọn mejeeji ni awọn ko ri idi ti awọn kan bi Sunday Igboho yoo maa pe fun iyapa Naijiria dipo ki awọn eeyan Naijiria gbe pọ  pẹlu alaafia.
Ọrọ ti wọn sọ yi lo mu ki agbarijọpọ ẹgbẹ awọn ọmọ Yoruba sọ pe ero aburu ni Gumi ni lọkan pẹlu abẹwo rẹ to ṣe si ilu Igboho.
Dokita Steven Abioye to gbẹnusọ fawọn ẹgbẹ yi ni awọn iwa fifa ori apa kan da apa kan si yi ko ni ṣiṣẹ nilẹ Yoruba lọtẹ yi.
O ni ''Abẹwo Gumi yi si ilu Igboho lọwọ aburu ninu. Iṣesi awọn Fulani to kun fun ète lo n ṣe. Erongba wọn pẹlu abẹwo yi kii ṣe eyi to mọ''
Abioye tẹsiwaju pe ''bayi ti wọn ri pe saa ijọba Buhari ti fẹ tan,wọn  n wa ọna tawọn eeyan yoo fi foju daada wo wọn ki aarẹ Fulani mi ba le bọ sipo''
O ni iru etekete bayi ko le e mu awọn ọmọ Yoruba mọ bi tatẹyinwa.
''Ki lo de to fi ṣe pe ilu Igboho ni Gumi lọ ṣe abẹwo si dipo ilu miran?Nitori pe Sunday Igboho gbe orukọ ilu naa ga ni.Gbogbo ọgbọn ti wọn n da la ti mọ pata''
Odunlade Adekola yarí, ó ní kí àwọn òṣèrébìnrin tí òun bá sùn yọjú síta
Oríṣun àwòrán, Instagram/odunlade adekola
Gbajugbaja oṣere tiata lọkunrin, Odunlade Adekola ti fesi si iroyin kan to n lọ lori ayelujara, paapaa Instagram pe o ma n ba awọn obinrin ni ibalopọ, ko to o fi wọn sinu ere.
Ninu fidio kan to fi sita ni ọsan Ọjọbọ lo ti fesi si iroyin naa.
Ọjọ diẹ sẹyin ni akọroyin ori ayelujara Instagram kan, Gistlovers blog gbe iroyin sita pe Odunlade Adekola ma n ba awọn oṣerebinrin to wa labẹ rẹ ni ibalopọ ko to o fun wọn ni iṣẹ ṣe.
Iroyin naa sọ pe ilana fẹyin lelẹ ki n ba ọ sun, ko o ṣe ninu ere mi ni Adekola n lo.
Ko tan sibẹ o, iroyin ọhun tọka si awọn gbajumọ oṣerebinrin mẹta,  Taiwo Aromokun, Eniola Ajao ati Bukola Adeeyo, gẹgẹ bi awọn ti Adekola ṣe iru nkan bẹẹ fun.
Lóòtọ́ orin mi àti Lagbaja jọra ṣùgbọ́n ìyàtọ̀ díẹ̀ wà níbẹ - Labule
Bakan naa lo tẹsiwaju pe koda, ibalopọ na kii yọ awọn smọbinrin to jẹ akẹkọọ ere ori itage lọdọ Odunlade silẹ.
O fikun niṣe ni ikọọkan awọn ọmọbinrin ti Odun ba ti yan laayo bẹẹ ma n ri iyawo ile rẹ fin, ti wọn si ma n fi abuku kan.
Koda, o ni lọwọlọwọ, ọkan lara awọn akẹkọọbinrin rẹ  to n jẹ Nike, lo wa loju ọpọn Odun bayii.
Oríṣun àwòrán, Instagram/gistlovers_blog
Ẹsun ti Gistlover fi kan Odunlade Adekola
Amọ lẹyin ọjọ kẹta ti iroyin naa ti n ja kiri ori ayelujara, Odunlade Adekola ti fesi.
Eyi lo ṣe ninu fidio oniṣẹju mẹsan-an kan to fi si ori ayelujara Instagram rẹ ni ọsan Ọjọbọ pe oun nilo lati fesi si iroyin naa, nitori ọjọ iwaju.
Odunlade sọ pe kii ṣe eeyan bi t'oun ni yoo ma a ṣe iru nkan bẹẹ.
Kii ṣe eeyan bi temi Odunlade Adekola, ọmọ Seriki Balogun, ni ma a ṣẹṣẹ ni ki ọmọ kan gbe idi  wa ko to o di pe mo fun ni iṣẹ ṣe ninu fiimu mi.
O ni Ọlọrun lo n sọ eeyan di irawọ oṣere, kii ṣe eniyan.
"Gbogbo ẹyin ọmọbinrin ti ẹ ti gba ọdọ mi kọja gẹgẹ bi oṣere, ẹ bọ sita lati sọ boya lootọ ni mo n ba yion ni ibalopọ ki n to fi yin sinu fiimu mi.
Ọlọrun ko ni i bo eyikeyi ninu yin to ba bo aṣiri mi."""
Ọgbẹni Adekola to sọrọ pẹlu ibinu sọ pe lati bi ọdun mẹẹdọgbọn ni oun ti n ba iṣẹ oṣere bọ, ti oun ko si ni i gba ki akọroyin kankan ba orukọ oun jẹ tabi ba iṣẹ oun jẹ.
O ni oun kesi iru awọn oniroyin bẹẹ lati mu ẹri jade pe lootọ ni oun n fẹ Nike Hamzat lọwọlọwọ, to fi mọ awọn ọmọbinrin yooku ti wọn sọ pe oun ti ba ni ibalopọ ri.
O ṣalaye pe o ti to eeyan mẹẹdọgbọn to ti ara oun dide, ti wọn si ti di irawọ oṣere.
Ọrọ naa lo n sọ lọwọ ti iyawo rẹ naa fi dasi ọrọ naa pe irs ni pe Nike wa sinu ile wọn lati ba oun ja nitori pe o n fẹ ọkọ oun.
Odunlade sọ pe awọn akọroyin to gbe iru iroyin bẹẹ jade n gbiyanju lati ṣi awọn ololufẹ oun lọna, nitori okiki ara wọn.
To si tun fi epe ranṣẹ si awọn to n gbe iru iroyin naa sita.
September 11 attacks: Kí ló ṣẹlẹ̀ ní pàtó lọ́jọ́ kọkànlá, oṣù kẹsàn án, ọdún 2001 l’Amẹrika?
Oríṣun àwòrán, @Joe
Aarẹ Joe Biden ti ni ki awọn eniyan ilẹ America ni suuru
O ni ki wọn gba alaafia ati irẹpọ laaye nitori pe eyi lo le mu ki itẹsiwaju ba agbaye.
Ninu fọran fidio ti aarẹ Joe biden to n tukọ ilẹ America gbe sita lo ti sọ eyi lati sami ọjọ malegbagbe naa ni orilẹ-ede America.
O tun gboriyin fun awọn oṣiṣe iṣẹlẹ pajawiri to kopa akinkanju lasiko naa.
Lọjọ Iṣẹgun, ọkọ kọkanla, ọsu Kẹsan an, ọdun 2001, awọn ẹṣin-o-kọku agbesunmọmi ja awọn ọkọ baalu akero ilẹ Amẹrika kan gba, wọn si sọ ori awọn ọkọ naa mọ ile alaja pupọ kan niluu New York, nibi ti ẹgbẹgbẹrun ẹmi ti sọnu.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ile alaja World Trade Centre ti wọn ju ado oloro lu nilu New York
Wo ìṣẹ̀lẹ̀ mánigbàgbé tó wáyé l'Amẹrika ní 9/11/2001
Ikọlu naa jẹ eyii to gbomi loju eeyan julọ l'Amẹrika ati kaakiri agbaye.
Awọn agbesumọmi naa ja ọkọ baalu mẹrin gba ni iha ila oorun Amẹrika lasiko kan naa, wọn si dori awọn baalu ọhun kọ awọn ile nla ni New York ati Washington DC.
"Baalu meji dori kọ ile meji ti wọn n pe ni ""Twin Towers"" to jẹ ti ibi iṣowo lagbaye ni New York."
Eyii to mu ki ina nla sọ lara awọn ile ọhun, ti ọpọlọpọ eeyan si ha sinu rẹ.
Laarin wakati meji, ile naa to jẹ alaja aadọfa (110) da wo.
Baalu kẹta fori sọ iha iwọ oorun Pentagon, to jẹ olu ileeṣẹ ọmọ ogun ilẹ Amẹrika ni Washington.
Nigba ti ọkọ ofurufu kẹrin ja lule ni papa kan niluu Pennsylvania lẹyin ti awọn ero inu rẹ doju ija kọ awọn agbesumọmi naa, eyi ti igbagbọ wa pe o n lọ fori sọ ile ijọba ti wọn n pe ni Capitol ni Washignton DC.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Awọn olugbe ilu New York re e to n sa asala fun ẹmi wọn kuro nibi alapa ile naa
Apapọ awọn to ku nibi ikọlu na jẹ ẹgbẹrun mẹta din ni mẹtalelogun.
Ẹni to kere ju to ba iṣẹlẹ ọhun lọ ni  Christine Lee Hanson, to jẹ ọmọ ọdun meji pere, to ku pẹlu awọn obi rẹ, Peter ati Sue.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Awoku ile alaja pupọ ọhun re e lẹyin ikọlu naa
Nigba ti ẹni to dagba julọ jẹ ẹni ọdun mejilelọgọrin, Robert Norton, toun ti aya rẹ, Jacqueline, ti wọn jọjọ n lọ sibi ayẹyẹ igbeyawo.
Nigba ti baalu akọkọ kọlu ile kinni, nnkan bii ẹgbẹrun mẹtadinlogun eeyan ati irinwo lo wa ninu rẹ, 17,400, ṣugbọn mejidinlogun sa asala.
Awọn eeyan lati orilẹ-ede mẹtadinlọgọrin kaakiri agbaye lo si wa ninu ile naa.
Awọn wo lo ṣe ikọlu ọhun?Awọn ọmọ ikọ alakakiti ẹsin Musulumi kan ti wọn n pe ni al-Qaeda lo pinlẹ ikọlu naa lati orilẹ-ede Afganistan.
Ṣaaju ni al-Qaeda ati adari rẹ, Osama Bin Laden ti kọkọ di ẹbi rogbodiyan to n waye nilẹ awọn Arabu ru ijọba Amẹrika.
Lara awọn alakatakiti ẹsin ọhun jẹ awakọ ofurufu to kẹkọọ gboye nilẹ Amẹrika.
Awọn eeyan mọkandinlogun pere lo ṣe ikọlu naa, lara wọn si ni a ti ri ọmọ orilẹ-ede United Arab Emirates, Saudi Arabia, Egypt ati Lebanon.
Bawo ni Amẹrika ṣe fesi? Laarin oṣu kan ti ikọlu naa waye, Aarẹ George Bush fi awọn ọmọ ogun ṣọwọ si Afganistan lati pa ikọ Taliban run, ki wọn si ṣawari Osama Bin Laden.Ṣugbọn ọdun mẹwaa lẹyin ikọlu naa ni awọn ọmọ ogun Amẹrika to ṣawari Bin Laden ni Pakistan, ti wọn si fopin si aye rẹ, iyẹn lọdun 2011.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Akojọpọ aworan awọn eniyan to ku sinu iṣẹlẹ 9/11 lọdun 2001 re e ni '9/11 Museum' nilu New York
Ẹwẹ, ọdun 2003 ni wọn mu ẹni gan to pinlẹ ikọlu naa, iyẹn  Khalid Sheikh Mohammad, o ṣi wa ni atimọle ni  Guantanamo Bay lati ọdun naa titi di akoko yii fun igbẹjọ.
Ọdun 2021 yii ni awọn ọmọ ogun Amẹrika fi Afganistan silẹ lẹyin ogun ọdun ti wọn ti tẹkọ leti lọ sibẹ, eyii to n mu ibẹru wa sọkan ọpọ eeyan pe yoo yọri si ipadabọ Abija ikọ al-Qaeda.
Atubọtan iṣẹlẹ 9/11
Eto abo ni awọn papakọ ofuru tunbọ lagbara si.
L'Amẹrika, wọn ṣagbekalẹ ileeṣẹ to n ri si eto abo papakọ ofurufu ati ninu ọkọ ofurufu, iyẹn Transportation Security Administration.
Aarin ọdun kan pere ni wọn tun Pentagon kọ, awọn oṣiṣẹ si pada sinu ọọfisi wọn ninu oṣu Kẹjọ ọdun 2002.
"Ni bayii, wọn ti kọ ile mii si ibi ti Twin Tower wa tẹlẹ, orukọ tuntun ti wọn fun ni One World Trade Center, tabi ""Freedom Tower."""
Open Grazing Ban: Gómìnà Akeredolu ní darandaran tó bá da ẹran nígboro yóò fojú winá òfin
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Gomina ipnlẹ Ondo, Oluwarotimi Akeredolu ti kllọ fun ẹgbẹ awọn darandaran, Myetti Allah pe wọn ko gbọdọ tafa si ofin to de dida ẹran ni ipinlẹ Ondo.
Gomina Akeredolu ninu atẹjade to fi lede ni ẹnikẹni to ba tapa si ofin ki wọn ye e da ẹran kaakiri igboro yoo fi oju wina ofin.
O ni ofin naa yoo mulẹ ju bi wọn ṣe lero lọ, ti ẹnikẹni ba rufin naa.
''Ko ni si aye fun awọn ọdaran lati lo ọnakọna to wu wọn lati ṣiṣẹ ibi ni ipinlẹ Ondo.''
''Ijọba ipinlẹ Ondo ri fidio kan ti ẹgbẹ awọn darandaran Myetti Allah fi lede, gba ọwọ akọwe ẹgbẹ naa, Saleh Hassan.
''Ninu fidio naa ni wọn ti fi lede pe awọn darandaran n hu iwa ọdaran nitori iya ati iṣẹ to n ba awọn eniyan wọn finra.''
''Wọn sọ ninu fidio naa pe awọn gaju ofin ipinlẹ kankan lọ, to fi mọ ti ijọba apapọ''
Amọ ijọba ipinlẹ Ondo ninu esi wọn sọ wi pe ko si ẹya kan tabi ede kan to gaju ofin lo, nitori naa ẹnikẹni to ba rufin, yoo jẹ iya rẹ.
''A ko ni fi aye gba ki awọn onilẹ di ẹru ni ilẹ baba wọn nitori awọn ọdaran darandaran ti ko ni ifẹ si gbigbe pẹlu awọn eniyan ni alaafia.''
''Awọn ara ipinlẹ Ondo fẹran alejo, amọ wọn ko ni fi aye gba ki awọn darandaran gbakoso ilẹ wọn, ki wọn si ma a fi iya jẹ awọn agbẹ.''
Ọjọ Kini, Oṣu Kẹsan ni gomina ipnlẹ Ondo, Oluwarotimi Akeredolu buwọlu ofin to dena dida ẹran kaakiri ipinlẹ Ondo.
Abuja kidnap: ''N15m làwọn Fulani ajínigbé kọ́kọ́ bèèrè kí wọ́n tó gba N2.5m ọ́wọ́ wa l'Abuja''
Inu igbo kiji kiji ni a ti gbe miliọnu meji ati abọ naira lọ fawọn Fulani ajinigbe to gbe ọkọ ati ọmọ anti gbe lọ ni ijọba ibilẹ Bwari niluu Abuja.
Kehinde Ibiteye lo fidi ọrọ yii mulẹ fun BBC Yoruba nigba to n sọ ohun ti oju rẹ ri ki wọn to tu awọn ẹbi rẹ silẹ.
Ibiteye ṣalaye pe ọganjo oru ni lawọn ajinigbe pawo ọhun de ti wọn si gbe ọkọ ati ọmọ ẹgbẹ rẹ lọ.
O ni anfaani ti oun ni ni pe oun le sọ ede Hausa tawọn janduku ajinigbe ọhun n sọ.
''Miliọnu mẹẹdọgun ni wọn kọkọ sọ pe awọn maa gba, ṣugbọn mo bẹ wọn lorukọ Ọlọrun ti wọn n sin ti wọn fi gba miliọnu meji ati abọ naira.
Ṣugbọn ibi ẹru ni inu igbo lọdọ awọn ajinigbe naa, ko si ọkunrin to maa de ibẹ ti ẹru ko ni ba a.
Awọn ọlọpaa mọ nipa iṣẹlẹ yii, ṣugbọn wọn ko kọbi ara si ọrọ naa,'' Ibiteye ṣalaye.
Yoruba nation rally: Ìwọ́de Yorùbá Nation tẹ̀sìwàjú nílùú Sunday Igboho lọ́jọ́ Sátidé
Iwọde Yoruba Nation yoo gberasọ pada lọjọ Abamẹta, ọjọ kọkanla oṣu kẹsan ọdun 2021 yii ni ilu Igboho tii ṣe ilu abinibi Oloye Sunday Adeyemo ti ọpọ mọ si Sunday Igboho.
Olayomi Koiki to jẹ amugbalẹgbẹ ajijagbara ilẹ Yoruba naa lo fọrọ yii lede loju opo Facebook rẹ.
Ohun ti a gbọ ni pe iwọde yii yoo waye lati ṣe atilẹyin fun Igboho to wa ni atimọle lorilẹede Benin Republic.
Iwọde Yoruba Nation ti waye ni ipinlẹ Ogun, Ondo, Osun, Eko ati ipinlẹ Oyo bakan naa.
Iwọde yii lawọn to n ṣe iwọde fi n beere fun idasilẹ orilẹede Yoruba kuro lara Naijiria.
Awọn eekan lagbo oṣelu kan nilẹ Yoruba ko faramọ ipe fun idasilẹ orilẹede Yoruba
Igboho wa ni atimọle lọwọ lọwọ niluu Cotonou lorilẹede Benin Republic.
Oriṣiiriṣii ẹsun ni wọn fi kan Igboho to fi mọ ẹsun wiwọ orilẹede Benin Republic lọna aitọ.
Koiki ṣalaye pe laago mẹwaa ni iwọde naa yoo waye ati pe gbogbo ọmọ Yoruba agbaye ni agbatẹru eto naa.
Igboho is from Aladikun compound in Modeke, Igboho, Oyo state.
Ondo Bans Unions’/Associations’ Activities : Ìjọba Ondo bẹ́gilé ẹgbẹ́ ọlọ́jà, ó ní wọ́n ń ni aráàlú lára pẹ̀lú ọ̀wọ́ngógó owó orí ọjà
Ijọba ipinlẹ Ondo ti fofinde gbogbo awọn ẹgbẹ ọlọja ni ipinlẹ Ondo pẹlu aṣẹ pe wọn ko gbọdọ paṣẹ lori iye tawọn ọlọja yoo maa ta ọja wọn mọ.
Ijọba ipinlẹ Ondo ni oun gbe igbesẹ naa lati daabo bo awọn to n ra aja ni ipinlẹ naa pẹlu bi ọwọngogo owo ori ọja ṣe n waye tawọn ontaja si n bu owo gọbọi le ọja wọn.
Iwa gbigbe owo gegele le ori awọn sja naa ko yọ awọn to n ta ire oko silẹ pẹlu.
Atẹjade kan ti kọmiṣọna fun eto iroyin, Donald Ojogo fi sita ni bi awọn ọlọja ṣe n fi ara ni araalu nipa obitibiti owo ti wọn n gbe lori ọja n kọ ijsba to wa lode ni ipinlẹ ọhun lominu.
SCOAN: Lati igba ti TB Joshua ti lọ ni ijọ naa ko ti tẹsiwaju mọ nitori ọrọ ta ni yoo ṣe adari rẹ to n jẹyọ- Ìjọ SCOAN
Oríṣun àwòrán, other
Ijọ SCOAN, iyẹn Synagogue ti oludasilẹ rẹ, Wolii TB Joshua jade laye loṣu diẹ sẹyin ti ṣalaye pe nnkan o fi gbẹ rọgbọ lori ọrọ tani yoo ṣe olori ni ijọ naa lẹyin ti ilumọọka wolii naa ti jade laye.
Ninu atẹjade kan ti wọn fi sita ninu eyi ti wọn ti sọrọ lori idajọ ile ẹjọ to ni ki wọn yan iyawo oloogbe naa gẹgẹ bi ọkan lara awọn ọmọ igbimọ majẹobajẹ ijọ naa leyi ti waye.
Ọpọ lo n beere pe ki lo n ṣẹlẹ bayii ni ile ijọsin Synagogue lẹyin iku oludasilẹ ijọ naa, Oloogbe TB Joshua.
Nibayii, ile ẹjọ giga apapọ nilu Eko ti buwọlu iyansipo iyawo TB Joshua gẹgẹ bi ọkan lara awọn ọmọ igbimọ majẹobajẹ ijọ naa ileejọsin naa.
Onidajọ Tijjani Ringim pa aṣẹ yii lasiko to fi n gbe idajọ kalẹ lori ipẹjọ kan ti awọn ọmọ ijọ naa kan pe lorukọ awọn ọmọ ijọ.
Wọn rọ ile ẹjọ pe koyan iyawo oloogbe TB Joshua gẹgẹ bi ọmọ igbimọ oluṣakoso ijọ naa ni ibamu pẹlu ilana ofin ijọ Synagogue to tọka si iye awọn ọmọ igbimọ ọhun.
Wọn ni ọmọ igbimọ naa ni oludasilẹ ijọ naa nigba aye rẹ.
Ati pe awọn meji to ku gẹgẹ bi ọmọ igbimọ ijọ naa ko laṣẹ labẹ ofin lati gbe igbesẹ kankan nipa ijọ ọhun nitori pe eeyan mẹta lo gbọdọ wa ninu igbimọ.
Nitori pe ko si atako kankan latọdọ awọn ti wọn pe lẹjọ, ni ile ẹjọ ba paṣẹ pe ki orukọ iyawo TB Joshua o wọ igbimọ oluṣakoso  ijọ naa leyi ti yoo mu ojuutu ba ọrọ aṣiwaju nile ijọsin naa.
Atẹjade ti ijọ naa fi sita lori idajọ ile ẹjọ ṣalaye pe lati igba ti TB Joshua ti lọ ni ijọ naa ko ti tẹsiwaju mọ nitori ọrọ ta ni yoo ṣe adari rẹ to n jẹyọ.
Sex in the station: Jennifer lóun àti DPO ní ìbálòpọ̀ nínú ọ́fíìsì rẹ̀ àmọ́ òun kò jí ìbọn rẹ̀ gbé
Oríṣun àwòrán, AFP
Wahala kan ti n rugbo bọ ni agọ ọlọpaa to wa ni Denton laarin awọn ololufẹ meji.
Ọga ọlọpaa Adegoke Akinlade jẹ ọkan ninu awọn ti  ọrọ  yi ta ba  ti ọrẹbinrin rẹ arabinrin Jennifer Madueke si ni ẹnikeji.
Gẹgẹ bi a ṣe gbọ ninu iwe iroyin Naijria Punch, Adegoke ti sọ Madueke si ahamọ lori ẹsun pe o ji ibọn rẹ gbe nigba to sun sinu ọfisi rẹ mọjumọ.
Yatọ si ibọn to ni Jennifer ji, o tun sọ pe owo ẹgbẹrun lọna aadọta Naira ti oun ko si nu ọfisi, Jennifer ti ji owo yi gbe bakan naa.
Gẹgẹ bi iroyin to tẹ wa lọwọ, Jennifer to ti lo ọjọ mẹta lahamọ ni agọ ọlọpaa Denton ṣaaju ki wọn to gbe lọ si Panti sọ pe oun ko mọ nkankan nipa ibọn to di awati ninu ọfisi Adegoke.
Fakinfa naa tun gba ọna mi yọ pẹlu bi Jennifer ṣe ni ọga ọlọpaa ati oun jijọ ni ibalopọ ninu ọfisi rẹ moju ọjọ Ẹti ti o ni ibọn rẹ sọnu yi.
Alaye ti ọga ọlọpaa ṣe fun ileeṣẹ iwe iroyin Punch ni pe ni nkan bi ọdun meje sẹyin ni oun ati Jennifer ti fẹ ara wọn kẹyin ki iṣẹ to gbe oun kuro nilu Eko.
O ni ṣadede lawọn tun pade pada ni nkan bi oṣu kan ati abọ ṣẹyin tawọn si tun gba nọmba ara wọn.
O ni Jennifer bẹrẹ si ni wa si ọfisi oun amọ nigba ti iwa rẹ koba ti oun mu mọ, oun ni ko ma wa mọ.
Oríṣun àwòrán, @PoliceNG
A ko ribi Jennifer sọrọ lati fidi ọrọ yi mulẹ amọ lọjọ ti iṣẹlẹ ibọn to sọnu waye, Adegoke ni Jennifer wa ba oun ni ile igbafẹ kan nibi ti oun ati ọrẹbinrin oun miran jijọ n ṣe faaji.
Nigba ti ilẹ ṣu ti o ni oun ati ọrẹbinrin mi lawọn  fẹ maa lọ si ile wọn lawọn ko ri ọkọ ti yoo gbe awọn nitori naa ni mo fi ni ki wọn lọ sun ninu ọfisi mi.
Adegoke tẹsiwaju pe oun fi awọn mejeeji silẹ lati lọ ṣe iṣẹ lalẹ ṣugbọn oun pada wa ti oun si fun Jennifer ni owo ọkọ ẹgbẹrun mẹrin.
O ni nigba ti Jennifer lọ tan loun to mọ pe o ji ibọn ati owo gbe ninu ọfisi rẹ.
''Mo pe nọmba rẹ titi ṣugbọn ko gbe. Emi ati arabinrin keji ti wọn jijọ sun ninu ọfisi mi lọ si ọdọ awọn aladura ati alufaa ti wọn si sọ fun wa pe Jennifer lo ji ibọn ati owo mi.Koda mo fun awọn eeyan lowo ki wọn fi bami tọ pinpin ibi to wa.''
O fi kun pe nigba ti ọwọ yoo fi tẹ Jennifer, o jẹwo pe oun mu owo ninu baagi ti mo gbe pamọ ṣugbọn ẹgbẹrun meje loun mu kii ṣe ẹgbẹrun lọna aadọta Naira.
A gbọ pe ọrọ yi ti de etiigbọ Kọmisana ọlọpaa ṣugbọn ileeṣẹ ọlọpaa ko ti gbe igbesẹ kankan lati fi ni ki ọga ọlọpaa yi lọ rọọkun nile gẹgẹ bi Punch ṣe sọ.
Lọwọlọwọ bayii, agọ ọlọpaa to wa ni Panti ni wọn fi Jennifer si titi di igba ti wọn yoo fi mọ ibi ti ibọn to sọnu yi wa.
Yoruba Nation rally: ''Ìwọ́de Yorùbá Nation kò ní wáyé mọ́ nílùú Igboho torí a kò fẹ́ wàhálà''
Oríṣun àwòrán, sunday_igboho1
"Iwọde lati pe fun idasilẹ orilẹede Yoruba to ye ko waye nilu Igboho tii ṣe ilu Oloye Sunday Adeyẹmọ ti gbogbo eeyan mọ si ""Sunday Igboho"" l'ọjọ Abamẹta ti fi ori sanpọn."
Ohun ti o ṣokunfa idiwọ fun iwọde naa ni alaga ijọba ibilẹ Orelope, Honọrebu Akeem Adepọju fi idi rẹ mulẹ lasiko to n ba akọrọyin wa sọrọ.
"Adepọju ni, ""awọn eeyan to kede iwọde naa ko fi ọrọ to awọn agbofinro ati awọn eeyan to n ṣe akoso ilu Igboho leti, bẹẹ sini ko si ami idaniloju wi pe awọn olubi ẹda ko ni ja iwọde naa gba lati ṣe aburu""."
Alaga ijọba ibilẹ naa fi kun ọrọ rẹ pe gbogbo ọmọ orilẹede Naijiria lo lẹtọ lati ṣe iwọde ati ifẹhonuhan, ṣugbọn o yẹ ki awọn agbofinro ati awọn alakoso ilu mọ si gbogbo nnkan ti wọn ba fẹ ṣe fun amọjuto to peye.
Lara awọn ọdọ ilu Igboho to n gbero lati darapọ mọ iwọde naa ṣe alaye fun akọroyin wa pe ninu ipade pajawiri kan ti awọn ṣe lalẹ ọjọ Ẹti ni wọn ti fi ohun ṣọkan wi pe iwọde naa ko ni waye.
Irẹdi pataki ti wọn fi gbe igbesẹ naa sini lati dena wahala to ṣeeṣe ko ṣu yọ ninu iru iwọde bẹẹ.
"L'Ọjọbọ ni agbẹnusọ fun Sunday Igboho, Ọlayọmi Koiko kede rẹ lori itakun ikansiraẹni Facebook wi pe iwọde alagbara kan yoo waye nilu Igboho nitori pe ""iṣẹ Oloye Sunday Igboho gbudọ tẹsiwaju"", ṣugbọn ẹni to jọ agbẹnusọ fun Ilana Oodua(ẹgbẹ kan gboogi to n le iwaju ipe fun idasilẹ orilẹede Naijiria), Maxxwell Adeleye ṣe alaye pe gbogbo nnkan ti yoo mu itẹsiwaju de ba idasilẹ orilẹede Yoruba ni awọn fi ọwọ si, botilẹ jẹ wi pe awọn ko gbọ ohunkohun nipa iwọde to fẹ waye nilu Igboho l'ọjọ Abamẹta."
Adelẹye fi kun ọrọ rẹ pe Ọlayọmi Koiki lo kede iwọde naa, kii ṣe Ilana Oodua. O ni ṣugbọn eleyii ko tumọ si wi pe awọn tako igbesẹ naa.
Koiki ko tii fi ikede mii lede boya iwọde naa yoo waye tabi bẹẹ kọ, ni asiko ti a ṣe akojọpọ iroyin yii.
Gumi visits Igboho: Àwọn èèyàn ìlú Igboho ní Sheikh Gumi wọ ìlú náà bí olè lóru
Awọn ọmọbibi ilu Igboho nipinlẹ Oyo ti ke gbajare pe awọn ko mọ ohun kan nipa abẹwo Sheikh Gumi, koda wọn ni awọn ko gbabọde fun un.
Lemaamu, olori ọdọ, alaga ilu, olori awọn musulumi, Ifa Igboho atawọn eeyan ilu naa mii lo korajọ pọ ti wọn si fidi ọrọ yii mulẹ ninu fọnran kan ti wọn fi sita lori Facebook.
Wọn ni bi ole loru ni Gumi ṣe wọ ilu Igboho lai kan si ọba ilu naa tabi olori kankan.
Gbogbo wọn ni pa ẹnu pọ sọ pe ọba tabi adari ilu Igboho kankan ko gba owo lọwọ Gumi nigba to ṣabẹwo si ilu Igboho.
Wọn ni ti Gumi ba jẹ musulumi ododo, niṣe lo yẹ kọ lọ ba ọba ilu ki o si lọ kirun ni mọṣalaaṣi.
Ṣugbọn wọn ni Gumi ko ṣe bẹẹ, o wọ ilu Igboho bi ole loru ni.
Wọn wa rọ Gumi wi pe ko gbọdọ pada si ilu Igboho mọ bi bẹẹ kọ, yoo kan idin ninu iyọ.
''Ti Gumi ba n lọ ibi kibi, ko ṣọra ṣe, tori ilu Igboho kii ṣe ilu ti eeyan kan le maa wọ bi o ṣe wu u.
Irinajo Sunday Igboho si Benin Republic yẹ Ọlọrun to ṣe ẹda gbogbo wa.
A si gbagbọ pe ori naa lo maa ko o yọ ninu ọfin to wa ni Cotonou.
Eeyan pataki ni OLoye Sunday Igboho nilẹ Yoruba, tori naa gbogbo wa ni a wa lẹyin rẹ.
Ọmọ Akin ni Igboho, ọmọ Akin kii ṣojo, bi gbogbo awọn ọmọ ilu Igboho ṣe ri niyẹn,'' awọn ọmọbibi ilu Igboho lo sọ bẹẹ.
Àbẹ̀wò Sheikh Gumi sí ìlú Sunday Igboho ń bí mi nínú, Gani Adams bínú tán
Aareonakakanfo ilẹ Yoruba, Iba Gani Adams atawọn ọmọ ẹgbẹ igbimọ ẹṣọ eleto abo nilẹ Yoruba ti bẹnu atẹ lu abẹwo alarina awọn janduku agbẹbọn, Sheikh Ahmad Gumi si ilu Igboho tii ṣe ilu Oloye Sunday Adeyemo.
Ilu Igboho ni olu ileeṣẹ ijọba ibilẹ Oorelope ni ipinlẹ Oyo nibi to jẹ orirun Igboho fun ra rẹ.
Lọjọ Iṣẹgun ọsẹ yii ni fọnran kan lu ayelujara pa ninu eyi ti awọn eeyan ti ri Gumi ati ọga ajọ NHIS tẹlẹ ri, Ọjọgbọn Usman Yusuf.
Iba Gani Adams ṣapejuwe abẹwo Gumi silu Igboho gẹgẹ bi ohun to binu ninu.
Gani sọrọ yii ninu atẹjade kan ti ẹgbẹ igbimọ to n ri si eto abo nilẹ Yoruba fi sita ninu eyi ti wọn kilọ fawọn janduku agbebọn pe ki wọn jina rere si ilẹ Yoruba.
Wọn ni ọna lati pẹgan ati lati gbegi dina akitiyan awọn ajijagbara ilẹ Yoruba ni abẹwo Gumi si ilu Igboho jẹ.
Igbimọ to n ri si ọeọ eto abo nilẹ Yoruba tun sọ pe bi Gumi ṣe n sọrọ ninu fọnran  naa fihan pe oun lo wa lẹyin iṣẹlẹ ikọlu DSS si ile Igboho to wa lagbegbe Soka niluu Ibadan.
''Ọmọ Naijiria ni Gumi, o si lẹtọọ lati ṣe abẹwo si ibi kibi to wu u ni Naijiria.
Ṣugbọn kii ṣe bi ko lọ si ilu abinibi Sunday Igboho lati maa tako akitiyan rẹ lori idasilẹ orilẹede Yoruba.
Iwa to bini ninu eyi, o si le da rogbodiyan silẹ.
O dabi ẹni pe awọn janduku agbebọn ti n gbero lati kọlu ilẹ Yoruba ṣugbọn a ko ni gba fun wọn.
A fi asiko yii rọ awọn agbofinro ati gbogbo awọn ẹṣọ eleto abo lati wa lojufo bayii ju ti atẹyinwa lọ nilẹ Yoruba.
Male infertility: N kò lè ṣe gẹ́gẹ́ bí ọkùnrin, ṣùgbọ́n n kò mọ̀ títí tí mo fi ṣe ìgbéyàwó
Oriṣiiriṣii arun ni o wa ni duniyan, ki Eleduwa maa fi aisan ṣe wa tọmọ tọmọ ki o fawọn to wa ni idubulẹ aisan ni alaafia to peye.
Ọkunrin kan, ẹni ọdun marunlelọgbọn lo pariwo sita pe oun ko le ṣe gẹgẹ bi ọkunrin bo tilẹ jẹ pe o ni iyawo nile.
Ọkunrin ko tilẹ mọ pe oun ni iṣoro yii to fi ṣe igbeyawo nitori nkan ọkunrin rẹ maa n gberi ṣugbọn kii damira ni iṣoro to wa nibẹ.
Igba ti o mọ pe oun ni iṣoro yii asiko to ni ibalopọ pẹlu iyawo rẹ.
Nigba naa ni iyawo rẹ pe akiyesi rẹ pe ko damira lasiko tawọn jọ ni ibalopọ eleyii to ya ọkunrin naa lẹnu.
Lẹyin ọpọ ayẹwo ti o ṣe ni o to mọ pe arun tọ ṣuga to ti wọ ọ lara lo ṣokunfa aisan ti wọn n pe ni ''retrogade ejaculation'' eyi ti o ba a finra.
Ọkunrin yii pada sọ fun iyawo rẹ pe o le lọ fẹ ọkunrin mii tawọn ko ba le bimọ ti oun ba fi pe ọdun marunlelọgbọn.
Ọkunrin yii n beere fun iranwọ awọn ẹlẹyinju aanu lati le ṣe itọju ara rẹ.
EndSARS Investigative panel: Ìwádìí ti tú àṣírí pé ọta ìbọn àwọn ológun Nàìjíríà ló ṣọṣẹ́ níbi ìwọ́de EndSARS l'Eko
Ni oṣu kẹwaa ọdun 2021 ni yoo pe ọdun kan gbako ti iṣẹlẹ manigbagbe to waye ni Lekki Tollgate nilu Eko lasiko iwọde EndSARS lọdun 2020 ṣẹlẹ, amọṣa ko jọ bi ẹni pe afẹfẹ iṣẹlẹ naa tii jẹ rodo lọ mu omi tan patapata o.
Ni ọjọ Ẹti ni abọ iwadii lọna ati ṣi aṣọ loju awọn eeyan to wọ aṣọ ologun kọlu awọn oluwọde lọjọ buruku eṣu gbomimu naa jade.
Ileeṣẹ aṣeadi nipa imọ ijinlẹ Forensic ti ijọba gbe iwadi naa fun ti kede pe ọta ibọn ologun lawọn ọta ibọn ti wọn yin lu awọn oluwọde lọjọ naa.
Aṣoju ileeṣẹ naa ti orukọ rẹ n jẹ Joseph Funshọ ṣalaye niwaju igbimọ oluwadi tijọba ipinlẹ Eko gbe kalẹ lati ṣe iwadii awọn aṣemaṣe awọn ọlọpaa ni ipinlẹ Eko.
Gẹgẹ bi Ọgbẹni Funshọ ṣe sọ, ọdọ ileeṣẹ ọmọogun Naijiria ni wọn ti ri iforukọsilẹ lori awọn ọta ibọn ti wọn lo lọjọ naa ati pe ileeṣẹ ọmọogun Naijiria lo ni wọn.
Se ẹ rii, lai deena pẹnu, iyatọ wa laarin awọn ọta ibọn ti ileeṣẹ ologun Naijiria gbe kalẹ niwaju igbimọ yii atawọn aloku ọta ibọn ti o wa niwaju igbimọ yii
O ni awọn aloku ọta ibọn ti awọn ologun wa fihan niwaju igbimọ naa pe o jẹ tiwọn kii ṣe ikan naa pẹlu ohun ti awọn ba pade nibudo akọsilẹ awọn ologun.
O fi kun peawọn aloku ọta ti awọn ologun wa fihan niwaju igbims oluwadi ọhun kii ṣe eyi ti awọn to n ṣe ọta ṣe fun agba ibọn oni 7.62 X 39mm ti wọn lo nibi iwọde naa.
''N15m làwọn Fulani ajínigbé kọ́kọ́ bèèrè kí wọ́n tó gba N2.5m ọ́wọ́ wa l'Abuja''
Bi ẹ ko ba ni gbagbe, ni oṣu kọkanla ọdun 2020 ni olori ikọ ọmọogun ọwọ kọkanlelọganrin 81 Military Intelligence Brigade, Ọgagun Ahmed Taiwo farahan niwaju igbimọ to n wadi iṣẹlẹ manigbagbe to waye ni Lekki Tollgate nilu Eko atawọn aṣemaṣe awọn ọlọpaa ni ipinlẹ Eko to si ni ofifo ọta ti ko ni ẹtu kankan ninu lawọn yin ni agbegbe LekkiTollgate ni ogunjọ oṣu kẹwaa ọdun 2020.
Bakan naa ni Ọgagun Taiwo tun sọ nibẹ pe ofurufu lawọn ọmọogun to lọ sibẹ lsjọ naa  yinbọn si, wọn ko yinbọn lu ẹnikẹni ninu awọn oluwọde #EndSARS lọjọ naa.
ọ wa ṣalaye niwaju awọn ọmọ igbimọ naa lọjọ ọhun pe awọn ofifo ọta ibọn ti oun n sọ yii ko lee ṣe ijamba tabi akoba kankan fun ẹran ara eeyan ati pe to ba jẹ pe ọta ibọn tootọ ni wọn yin ni, ẹyọ kan ṣoṣo ọta ibọn naa lee pa eeyan mẹta lọwọ kan naa.
Ṣaaju eyi ni aileeṣẹ ọmọ ogun Naijiria ti kọkọ sẹ kanlẹ pe iroyin ofege ni iroyin to ni awọn lawọn yinbọn lu awọn oluwọde nibẹ, ki o to tun di pe o ṣẹri pada to si yi ohun pada pe lootọ awọn wa nibẹ ṣugbọn ofifo ọta ibọn lawọn yin.
Bandits in Northwest Nigeria: Ìrẹsì, Spaghetti àti sìgá làwọn agbébọn tún ń béèrè fún ìtúsílẹ̀ àwọn tí wọ́n bá jí gbé báyìí
Oríṣun àwòrán, other
Igbesẹ awọn ijọba ipinlẹ kan lapa iwọ oorun ariwa orilẹede Naijiria ti n ni ipa lara awọn agbebọn to n ṣọṣẹ lagbegbe naa bayii, gẹgẹ bi iroyin ṣe n sọ ọ.
Ko din ni awọn gomina mẹrin bayii ti wọn ti ti awọn ọja pa ni ipinlẹ wọn lati wa ọwọ awọn agbebọn naa bọlẹ ni agbegbe wọn.
Ko pẹ pupọ lẹyin igbesẹ titi awọn ọja ẹsẹkuku ni ipinlẹ Sokoto lawọn agbebọn ba bẹrẹ si ni beere fun ounjẹ gẹgẹ bi nnkan itusilẹ awọn eeyan ti wọn ba ji gbe.
Olugbe ilu kan ni Sabo Birni to ṣalaye fun awọn akọroyin sọ pe awọn agbebọn naa tu ọkan lara awọn ọmọ alabagbve oun ti wọn ji gbe silẹ lẹyin ti wọn fun wọn ni ounjẹ.
Wọn ji ọmọbinrin arakunrin kan gbe ni ileto wa, nigba ti a ko si ri owo ti wọn beere fun ko jọ, wọn ni pe ki a lọ muiwọn abọ irẹsi mẹwaa wa ki wọn to lee tu ọmọbinrin naa silẹ, wọn si mu adehun naa ṣẹ
Eeyan kan pẹlu tun ṣalaye fun akọroyin iwe iroyin Daily Trust ni ilu Sokoto lori bi awọn agbebọn ṣe beere fun ounjẹ ati ohun mimu ki wọn to le tu dẹrẹba wọn ti wọn ji gbe silẹ.
''N15m làwọn Fulani ajínigbé kọ́kọ́ bèèrè kí wọ́n tó gba N2.5m ọ́wọ́ wa l'Abuja''
O ni milisnu marundinlogun ni wọn kskọ beere fun ki wọn to gba ki awọn san ẹgbẹrun lọna ẹgbẹta naira N600,000 lọwọ ọga arakunrin naa. Wọn wa ni ki ọga rẹ atawọn mọlẹbi rẹ o fi owo naa ra ọpọlọpọ apo irẹsi, apoti ohun mimu, apo ohun jijẹ Spaghetti, ati siga ki wọn si ko ṣenji owo to ba ku dani wa fun awọn.
O ni ọga arakunrin dẹrẹba naa atawọn mọlẹbi rẹ ṣi n wa owo naa bayii.
Ènìyàn méjì pàdánù ẹ̀mí wọn níbi tí ògiri amọ̀ ti dà wó nílú Ibadan
Eeyan meji ọtọọtọ ni iroyin ti fi idiẹ mulẹ bayii wi pe wọn padanu ẹmi wọn nibi ti wọn ti n gbẹ iyẹpẹ amọ fun akanṣe iṣẹ ni agbegbe Apata nilu Ibadan.
Iṣẹlẹ laabi naa waye lalẹ Ọjọbọ ni ile nla ikẹrusi kan ti wọn n kọ lọwọ ni tosi ile ẹkọ 'Command Secondary school' to n bẹ ni ijọba ibilẹ Ido nipinlẹ Ọyọ.
Alaye ti ẹni ti iṣẹlẹ naa ṣe oju rẹ ṣe fun akọroyin wa ni pe ojo to rọ lasiko naa lo mu ki ogiri amọ naa ya lulẹ ti o si bo awọn eeyan meji mọle.
O tẹsiwaju wi pe ẹni ti o ni ibudo ti wọn ti n ṣiṣẹ naa, Adebayo Idogbe ti o ṣẹṣẹ de pada lati orilẹede China ati ẹlomii ti o jẹ oṣiṣẹ nileeṣẹ naa lo padanu ẹmi wọn nibi iṣẹlẹ naa.
Amọ to ya lulẹ lo bo awọn mejeeji mọle, ọkan ninu wọn si gbe ẹmi mi loju ẹsẹ ki o to di pe ẹnikeji jẹ Ọlọrun nipe l'ọwurọ ọjọ Ẹti lẹyin ti wọn gbee digbadigba lọ ile iwosan.
Lasiko ti a ṣe abẹwo si ibi iṣẹlẹ naa, a ko ri oṣiṣẹ oṣiṣẹ kankan nibẹ. Alaye ti awọn ara adugbo ṣe ni pe ijamba naa lo mu ki gbogbo awọn oṣiṣẹ kuro ni agbegbe naa.
Adari ileeṣẹ panapana ipinlẹ Ọyọ, Adeleke Ismail ti o fi idi iṣẹlẹ naa mulẹ ṣe alaye wi pe awọn oṣiṣẹ oun ati ikọ Amọtẹkun sarẹ lọ si ibi iṣẹlẹ pajawiri naa lati doola ẹmi awọn eeyan naa, ṣugbọn igbiyanju wọn ja si pabo.
O parọwa si awọn eeyan to ba fẹ dawọ le iru akanṣe iṣẹ bẹẹ lati gba awọn eeyan to mọ iṣẹ naa daju ki iru iṣẹlẹ bẹẹ ma baa waye mọ.
N kò lè ṣe gẹ́gẹ́ bí ọkùnrin, ṣùgbọ́n n kò mọ̀ títí tí mo fi ṣe ìgbéyàwó
Bakan naa ni iṣẹ iwadii tun fi idi ẹ mulẹ pe ile ikẹrusi nla ti wọn n kọ lọwọ nibi iṣẹlẹ naa lo wa lori ilẹ ti o jinkoto, bẹẹ sini oke nla to jẹ kiki amọ yii ka. Lojiji ni oke amọ naa yẹ lulẹ ti o si bo awọn eeyan to wa labẹ ile naa
mọlẹ.
Sex in the station: Kọmíṣọ́nà ọlọ́pàá Eko yọ ọ̀gá DPO tó sọ ìbọn ọlọ́pàá nu lẹ́yìn tó gbé obìnrin sùn sí ọ́fíìsì rẹ̀ nípò
Oríṣun àwòrán, AFP
Ọga ọlọpaa ẹkun Denton Divisional police station lagbegbe Ebutte Metta ni ipinlẹ Eko, CSP Adegoke Atilade ti n koju atubọtan ibọn ilewọ amuṣeiṣẹ rẹ to sọnu lẹyin ohun ti iroyin pe ni orun ibalopọ pẹlu ọrẹbinrin rẹ kan.
Atẹjade kan ti alukoro ileeṣẹ ọlọpaa ni ipinlẹ Eko fi sita ṣalaye pe kọmiṣọna ọlọpaa ni ipinlẹ Eko, Hakeem Odumoṣu ti paṣẹ ki wọn gbe e kuro ni ipo DPO ẹkun naa.
Igbesẹ naa n waye lẹyin ti okiki iroyin gbode kan pe ọga ọlọpaa Atilade gbe obinrin ẹni ọdun mọkandinlọgbọn kan ti orukọ rẹ n jẹ Jennifer Madueke ni agbesun ni ọfiisi rẹ lẹyin eyi ti ko ri ibọn ilewọ iṣẹ rẹ mọ.
Ni ọjọ kẹtadinlọgbọn oṣu kẹjọ ọdun 2021 ni iṣẹlẹ naa ṣẹlẹ.
Alukoro ileeṣẹ ọlọpaa nipinlẹ Eko ni DPO miran yoo gunlẹ si olu ileeṣẹ ọlọpaa ẹkun naa laipẹ.
Amọṣa, atẹjade naa ko sọ ibi ti wọn n gbe ọga ọlọpaa naa lọ bayii.
N kò lè ṣe gẹ́gẹ́ bí ọkùnrin, ṣùgbọ́n n kò mọ̀ títí tí mo fi ṣe ìgbéyàwó
Atilade ni iroyin gbe jade pe o gbe arabinrin Jennifer si ahamọ ni ileeṣẹ awọn ọlọpaa ọtẹlẹmuyẹ ni SCID ni Yaba lẹyin to ti kọkọ fi si ahamọ fun ọjọ mẹta ni agọ ọlọpaa Denton, Ebutte Meta nilu Eko.
Iroyin sọ pe ọga ọlọpaa Atilade ati arabinrin Madueke ti fi igba kan ri jẹ ọrẹ korikosun ki iṣẹ to gbe to Atilade kuro nilu Eko ni nnkan bii ọdun meje sẹyin. Awọn mejeeji tẹsiwaju pẹlu ere ifẹ wọn lẹyin ti wọn gbe ọga ọlọpaa naa pada silu Eko laipẹ yii.
Ibadan flood: Omi gbé arákùnrin ẹni ọdún 28 kan lọ ní Ibadan, Gómìnà Makinde bá mọ̀lẹ́bí kẹ́dùn
Oríṣun àwòrán, Insideoyo.com
Gomina ipinlẹ Oyo, Seyi Makinde, ti kan sí mọlẹbi arakunrin kan to padanu ẹmi rẹ ninu ìṣẹlẹ omiya'le agbara ya sọọbu kan ni Ibadan.
Adugbo Onilu Moniya ni arakunrin ẹni ọdun mejidinlọgbọn naa Abiodun Adeleke ti ba omi lọ.
Gẹgẹ bí iroyin to tẹwa lọwọ ninu ọjọ to ya ile ya sọọbu ní o ti padanu ẹmi rẹ lasiko to n ran awọn ọlọkada lọwọ lati sọdá odo Asanmajana.
A gbọ pé omi gbè lọ nibi to ti n ran awọn eeyan lọwọ ni.
Gomina Makinde lasiko àbẹwò si awọn ẹgbẹ onile ladugbo Onilu ba mọlẹbi ati araadugbo kẹdun iṣẹlẹ buruku yi
Ọgá agba ileesẹ to n mojuto àtúnṣe ojú ọnà Kamil Akinlabi to soju Gomina fi idaniloju hàn s'àwon araadugbo pe ìjọba yoo wa nkan ṣe sí iru iṣẹlẹ yi.
 Iṣẹlẹ iku ọmọ yín yi fọwọ kan wa l'ẹmi.A gba ladura ki eledua rẹ mọlẹbi rẹ l'ẹkun lori ikú rẹ
''N15m làwọn Fulani ajínigbé kọ́kọ́ bèèrè kí wọ́n tó gba N2.5m ọ́wọ́ wa l'Abuja''
Alaga ẹgbẹ awọn oníle ladugbo náà arakunrin Bukola Akintola dupẹ lọwọ Gomina nipa kika oroy iṣẹlẹ naa kun.
O ni púpọ awọn alaṣẹ lo ti n wa lori ọrọ omiyale yi ti kò sí seso kankan.
O wa rọ Gomina Makinde lati mu adehun rẹ ṣe sí awon araadugbo laipẹ.
Stucked Bones: Bí egungun bá há sí ọ̀nà ọ̀fun rẹ, wo ọ̀nà méje tí o lè gba yọ ọ
Oríṣun àwòrán, other
Nnkan ti a fẹ ṣe idanilẹkọ fun ara wa le lori yii, ko fẹẹ si ẹni ti ko ti ṣẹlẹ si ri. Bi ko ba ti ṣẹlẹ, o ṣeeṣe ki o waye nitori o nii ṣe pẹlu ounjẹ jijẹ, ko si si ẹni ti yoo sọ pe oun kii jẹun.
Lọpọ igba ti eeyan ba n jẹun ni egungun maa n ha si ọfun; ti iru nkan bayii ba wa ṣẹlẹ, inira nla lo maa n ko ba ẹni to ba sẹlẹ si, to si maa n gba oorun loju eeyan.
Koda, o le di egbo nla, ti eeyan yoo si nawo si yatọ si pe o see se ki onitọun ma le mu isẹ oojọ kankan se lasiko ti inira naa ba fi waye.
Amọ ko to di pe eeyan morile ile iwosan lati wa ọna abayọ si isẹlẹ inira yii, eeyan naa le tiraka ninu ile rẹ lati bọ lọwọ inira ti egungun naa n mu wa, to si le yọ funra rẹ lai si ewu.
Ohun meje ti a si le se ree, bi egungun ba ha si eeyan ni ọna ọfun ree:
Jijẹ ọgẹdẹ:
Oríṣun àwòrán, other
Ọgẹdẹ jẹ eso kan to rọ daadaa to si le ran wa lọwọ lati ti egungun to ba ha si ọfun wa lọ silẹ. Bi egungun naa ba kọ ti ko fẹ kuro, ṣaa ti wa ọgẹdẹ bo jẹ.
Nitori pe ọgẹdẹ rọ, yoo jẹ ki egungun naa lẹ mọ ọgẹdẹ naa, ti yoo si kuro ni ọna ọfun.
Burẹdi ati omi:
Oríṣun àwòrán, other
Ọna miran ree lati fí yọ eegun kuro l'ọna ọfun, ko si nira lati ṣe.
Ri burẹdi sinu omi, ki o si jẹ ninu rẹ. Gbe burẹdi tutu yii mi lẹẹkan naa, ki o ba le ti egungun naa kuro nibi to ti n se idiwọ.
Ọgbọn yii a tun maa jẹ ki egungun naa ba burẹdi lọ sinu ikun lati ọna ọfun lai mu inira wa.
Wu ikọ pẹlu agbara:
Oríṣun àwòrán, other
Eyi naa jẹ ọna kan gboogi ti o le fi yọ eegun lọna ọfun rẹ. Bi eegun naa ba ṣe tobi si, ni yoo tọka bi a o ti ṣe wukọ si.
Ti eegun ọhun ko ba tobi ju, o le wukọ diẹ, ti yoo si jade si enu rẹ. Iwọ ṣaa ti wukọ nigbakuugba ti o ba gburo pe nkankan ba ha si ona ọfun rẹ.
Lilo ororo Olive Oil:
Oríṣun àwòrán, other
Ororo yií maa n ṣiṣẹ daada lati yọ egungun to ba ha si ọfun, lilo rẹ kò sì le rara.
Iwọ ṣaa ti bu ororo yii diẹ sinu ikeemu, ko si di si ọna ọfun.
Mimu omi ko le ṣiṣẹ daada bi ororo yii nitori pe omi fẹlẹ ju ororo lọ.
Yiyọ ti ororo Olive maa n yọ, yoo tun jẹ ki egungun yii kuro lọna ọfun rẹ nirọrun ati ni kiakia.
Fun aimọye ọdun ni awọn dokita ti maa n lo ohun mimu ẹlẹrindodo lati yọ egungun to ba ha si ọna ọfun kuro.
Idi ni pe ni kete ti o ba mu awọn ohun mimu ẹlẹrindodo yii tan, to de inu ikun rẹ, ni eroga afẹfẹ gaasi yoo wa nikun rẹ, to si maa mi awọn gaasi yii jade.
Afẹfẹ gaasi to n mi jade yii ni yoo seranwọ lati ti egungun naa jade nibi to ha si ni ọfun rẹ.
Oríṣun àwòrán, The maids
Eroja omi Vinegar ni eroja kan ti wọn n pe ni asidi (Acid) ninu, ta ba si mu lasiko ti egungun ba ha wa lọfun, eyi yoo seranwọ lati fọ egungun naa si wẹwẹ, ti yoo si tun rọ lati tete gbe mi.
A le mu sibi omi Vinegar meji, ka da pọ̀ mọ̀ ife omi kan, ka si gbe mu.
Bakan naa, a tun le mu sibi Vinegar kan lẹsẹkẹsẹ ti egungun ba ha si wa ni ọna ọfun lai po Vinegar naa pọ mọ omi kankan.
Eroja omi Vinegar yii ko fi bẹẹ koro, paapaa ta ba po papọ mọ oyin.
Oríṣun àwòrán, Klye Levesque
Ti egungun ba ha si wa lọna ọfun, a tun le mu burẹdi, ka fi bọta (Butter) yi daadaa, eyi ti yoo gba egungun naa mu lọna ọfun, ti yoo si wọ wa sinu ikun wa.
Ẹ jẹ burẹdi naa, kẹ si ri pe ẹ fi itọ po daadaa ni ẹnu, ko to di pe ẹ gbe mi lẹẹkan naa.
Amọ ẹ ri pe ẹ gbe omi si ẹgbẹ yii, ti ẹ mu le ounjẹ yii lori, eyi ti yoo tete san egungun naa ati burẹdi pẹlu bọta wa silẹ.
Bi a ba wa se awọn ohun mẹjọ yii, ti egungun naa ko yọ, yoo dara ka gba ile iwosan lọ lati lọ ri dokita onisegun oyinbo, ko to di pe ọrọ naa yiwọ.
SCOAN leadership tussle: Ìyàwó Wòlíì TB Joshua di olórí ìjọ Synagogue
Oríṣun àwòrán, Tb joshua
Ijọ Synagogue, SCOAN ti yan iyawo oloogbe Wolii TB Joshua, Evelyn Joshua gẹgẹ bii adari tuntun ijọ naa bayii.
Ijọ naa ṣalaye ninu atẹjade kan loju opo Facebook rẹ pe gbogbo eto ijọ naa yoo wa labẹ itọni Ọlọrun ati idari arabinrin Evelyn Joshua bayii.
Gẹgẹ bi atẹjade naa ṣe sọ, akoko ti a yan lo to, wọn si rọ gbogbo awọn ọmọ ijọ naa lati maa fi adura tii lẹyin fun ogo Ọlọrun lati maa tii lẹyin.
Ṣaaju asiko yii ni oniruru iroyin ti n kaakiri nipa edeaiyede lori tani yoo ṣe olori ijọ naa lẹyin ti oludasilẹ ijọ ọhun, TB Joshua jade laye loṣu karun ọdun 2021.
Edeaiyede naa lo faa ti wọn fi le awọn ọmọlẹyin Wolii TB Joshua kan kuro ni gbagede ijọ naa laipẹ yii.
Thyroid foundation: eéwo ni mo kọ́ka pè é àṣé gẹ̀gẹ̀ ọrùn tó lé ẹbí, ará àti ọ̀rẹ́ ni mo n
Ileesẹ iransẹ TB Joshua kede pe oludasilẹ ijọ naa ati agba wolii lorilẹede Naijiria, Temitope Balogun Joshua ti dagbere faye loju opo Facebook rẹ, lọjọ Satide, ọjọ karun osu Kẹfa ọdun 2021.
Oríṣun àwòrán, AFP
Wolii Joshua, to dele aye ni ọjọ Kejila osu Kẹfa ọdun 1963, lo lo ọdun mejidinlọgọta loke eepẹ, ki ọlọjọ to de.
Ọ̀gá Bello: Àìgbọ́n ló ń da àwọn òsèré tíátà tó ń jà lórí ayélujára láàmú
Ikede naa fidi rẹ mulẹ pe Ọlọrun kii se ohunkohun lai fi iran rẹ han awọn wolii rẹ saaju, to si tọkasi iwe mimọ Amosi, ori kẹta ẹsẹ keje.
Adene Oluwabukola Deborah: Bàbá mi kò kọ́kọ́ fọwọ́ sí iṣẹ́ ìlù lílù ṣùgbọ́n....
Gẹgẹ bi ikede ijọ naa ti wi, Wolii Joshua sọrọ lọjọ Satide lasiko ipade to se pẹlu awọn alabasisẹpọ rẹ fun ileesẹ mohunmaworan ijọ rẹ, Emmanuel TV, to si dabi ẹnipe o n sọ asọtẹlẹ nipa iku rẹ.
Bussiness tips: Okòòwò márùn ún tí o lè bẹ̀rẹ̀ nínú ilé rẹ̀
Oríṣun àwòrán, other
Iṣẹ agbẹ da le gbingbin awọn ohun ọgbin ati sinsin awọn ohun ọsin fun igbayegbadun ọmọ eniyan. Ọpọ lo si maa fẹ ṣe ọgbin ṣugbọn to jẹ wi pe aisi aye to to lati ṣe iṣẹ ọgbin n di wọn lọwọ.
Eniyan nilo ounjẹ lati lee dagba ki o si wa laye ati lati ni okun ati agbara lara ṣe iṣẹ oojọ rẹ gbogbo.
Ẹ jẹ ki a wo diẹ lara awọn iṣẹ okoowo ti o lee ṣe ni gbagede ile rẹ.
Oríṣun àwòrán, other
Eyi le jẹ ata pupa tabi ata dudu tabi ata bẹẹbẹ.
Ata rọrun lati gbin, ko si fẹrẹ si oriṣi ilẹ kan ti ko tii le gberu. Ko si si ọja kan ti a kii tii ri awọn to n ta ata. Gbogbo eeyan lo n lo ata nitori awọn agba a maa da aṣamọ kan pe, 'ẹmi ti ko jẹ ata, ẹmi yẹpẹrẹ ni.'
Ọ̀gá Bello: Àìgbọ́n ló ń da àwọn òsèré tíátà tó ń jà lórí ayélujára láàmú
Oríṣun àwòrán, other
ehoro jẹ ẹran kan ti awọn eeyan maa n fẹran lati jẹ. Wọn kii pa ariwo, bẹẹ ni wọn kii da wahala tabi ẹgbin silẹ layika bi awọn ẹran ọsin miran bii aja.
Bi eniyan ba ti lee kan ago fun un, o lee bẹrẹ pẹlu ẹbi kan tabi meji ki o si fi wọn silẹ lati maa gun. Owo Ehoro to ba pe oṣu mẹrin a maa to ẹgbẹrun marun un Naira nigba miran.
Oríṣun àwòrán, other
Ọpọ eeyan lo maa n fẹran olu jijẹ, a lee fi se ọbẹ, tabi ohun ajẹgbadun bii Pizza. Inu awọn igi to wo to si ti n jẹra atawọn ohun ira miran ni a ti lee ri olu.
Lati gbin in, o le raa ni ọja, wu u ni oko tabi lọdọ awọn to ba n ṣe ọgbin rẹ. Inu ike to ni awọn ohun to ti doku ni ki o koo si. Wa lu iho si ara ike naa lati fi aye silẹ fun atẹgun lati maa wọle.
Yoruba Nation: Kò sí ìdí tí à ó fi bínú sí Akeredolu lórí ọ̀rọ̀ Yorùbá Nation
ohun ọgbin kan to tun rọrun lati gbin ni Tomato jẹ. Ẹ le ko eso rẹ sinu ike tabi agolo kan ti ẹ ti bu ilẹ si ninu.
Ohun ti eeyan nilo naa ni ilẹ, oorun ati omi. Ọja Tomato kii kuta lọpọ igba nitori awọn ti yoo raa wa lọpọ yanturu.
Oríṣun àwòrán, Tomatoes
Thyroid foundation: eéwo ni mo kọ́ka pè é àṣé gẹ̀gẹ̀ ọrùn tó lé ẹbí, ará àti ọ̀rẹ́ ni mo n
Ọpọlọpọ awọn eeyan lo fẹran awọn ewebẹ tutu. O maa n mu adidun ba ounjẹ. A le gbin ewebẹ si ayika ati gbagede ile wa. O si le pa ọpọlọpọ owo lati ara gbingbin ewebẹ. Awọn ewebẹ bii ila, ẹfọ loriṣiriṣi ati bẹẹbẹẹlọ a maa gberu daadaa ni ayika gbagede ile.
Oríṣun àwòrán, other
Bi o ba dẹ jẹ pe wọn ti fi sanmọnti kọnkere ilẹ ile rẹ, o lee lo garawa tabi aloku taya ọkọ. da ilẹ sinu wọn ki o si gbin eso nnkan to fẹ gbin.
Iwọ naa lee maa fi eyi pa owo si apo rẹ.
Adene Oluwabukola Deborah: Bàbá mi kò kọ́kọ́ fọwọ́ sí iṣẹ́ ìlù lílù ṣùgbọ́n....
Police shooting: Ọlọ́pàá Eko ní àwọn ti mú aríbọnyọ̀ ọlọ́pàá tó yìnbọn pa arábìnrin kan ní Ijeshatedo ní Sátidé
Oríṣun àwòrán, other
Ileeṣẹ ọlọpaa ni ipinlẹ Eko ni awọn ti fi panpaẹ ofin gbe aribọnyọ ọlọpaa to yinbọn gbẹmi arabinrin ẹni ọdun mejidinlogun kan lagbegbe ijẹṣatedo ni ipinlẹ Eko lọj Abamẹta.
Wahala waye lagbegbe naa lọsan ọjọ Abamẹta nigba ti awọn ibọn ọlọpaa kan lati ikọ ọtẹlẹmuyẹ SCID Panti ba arabinrin Monsurat Ojuade.
Atẹjade kan lati ọdọ Adekunle Ajiṣebutu to jẹ alukoro ileeṣẹ ọlọpaa ni ipinlẹ Eko ni aṣita ibọn ni iṣẹlẹ naa ati pe awọn ọlọpaa naa lọ si agbegbe naa lati lọ mu afurasi adigunjale kan ni ati pe wọn gbiyanju ati doola ẹmi rẹ ṣugbọn o ti ku ki wọn to de ileewosan.
O fi kun un pe kọmiṣọna ọlọpaa ni ipinlẹ Eko, Hakeem Odumoṣu ti paṣẹ pe ki wọn gbe ọlọpaa naa lọ sileẹjọ  ni kete ti wọn ba ti gba iṣẹ lọwọ rẹ lati lee jẹ ifaleti fun awọn ọlọpaa ẹgbẹ rẹ.
Bread high price: Àlékún bá iye owó búrẹ́dì l'Oṣun, Kwara lẹ́tyìn ìyanṣẹ́lódì ẹgbẹ́ oníbúrẹ́dì
Owo burẹdi ti lekun ni awọn ipinlẹ kan ni ilẹ Yoruba bi  Osun ati Kwara.
Eyi ko si ṣẹyin igbesẹ tawọn apapọ  ẹgbẹ  oniburedi gbe nipa iyanṣẹlodi ọlọjọ meji ti wọn gun le.
Ababọ iyanṣẹlodi yi ni bi wọn ti ṣe kede afikun iye owo burẹdi lawọn ipinlẹ mejeeji yi.
Gẹgẹ  bi alaga ẹgbẹ oniburẹdi ni ipinlẹ Osun Alhaji Onaopepo Bakare ati akọwe ẹgbẹ Adeeyo M.A ti ṣalaye, igbesẹ alekun yi waye kawọn baa ṣi le maa ṣ'owo burẹdi tita f'araalu ni.
Wọn ni  iyẹfun tawọn fi n ṣe burẹdi ti gbowo lori di ẹgbẹrun lọna mejilelogun Naira.
Femi Falana: Mẹ̀kúnnù gbọ́dọ̀ ṣetán láti gba ẹ̀tọ́ wọn, ìjọba ti kùnà lórí ẹ̀tọ́ ọmọnìyàn
Yatọ si iyẹfun wọn ni awọn nkan miran tawọn n lo lati fi peelo burẹdi ti lewo.
Lọjọ Ẹti ni wọn bẹrẹ iyanṣẹlodi ni Osun ti wọn si fopin sii ni ọjọ Aiku.
Ni bayi, wọn kede pe burẹdi ti wọn n ta ni ọgọrin Naira ti di ọgọfa Naira nigba ti eleyi ti wọn n ta ni ọgọfa Naira ti di aadọjọ Naira.
Buredi ti wọn n ta ni igba Naira ti wa di ojilenigba le mẹwaa Naira.
Alekun to ba iye owo burẹdi ti a ri ni Osun yi jẹyọ ni Ilorin ni ipinlẹ Kwara.
Burẹdi ti wọn n ta ni aadọta Naira ti di ọgọta Naira.
Oni ọgọrun Naira ti di Ọgọfa Naira.
Awọn mii ni burẹdi oni igba Naira to di ojilenigba le mẹwaa Naira bayi.
''Slice bread'' ti wọn n ta ni irinwo Naira ti di ẹẹdẹgbẹta  Naira nigba ti eleyi ti wọn n ta ni ẹẹdẹgbẹta Naira si ti di ẹgbẹta Naira.
Ati onibara ati awọn alarobọ burẹdi ti wọn pe sori eto ileeṣẹ redio kan ni Ilorin lo n ke irora lori alekun owo burẹdi yi ti wọn si rọ ijọba lati mu idẹkun ba ara ilu.
Eèmọ̀ wọ̀lú, ẹni tó ń ta ọtí àti ògógóró gún Oníbárà rẹ̀ pa ní Osun!
Oríṣun àwòrán, others
Arakunrin kan to n ta ogogoro ni agbegbe Ifon Orolu nipinlẹ Osun ti ko si gbaga ọlọpaa lẹyin to gun ọkan lara awọn onibara rẹ pa lasiko ti wọn n ja.
Afurasi to n ta ogogoro naa, Mumimi Olanipekun ni o gun Wale onibara rẹ pa, to si gbe ara rẹ lọ si agọ ọlọpaa lẹyin iṣẹlẹ naa.
Iroyin gbe e pe ija bẹ silẹ laaarin Olanipekun ati Wale to wa mu ogogoro ni ṣọọbu Olanipekun.
Lasiko ija naa ni Olanipekun fi afọku igo gun Wale ni ọrun ati ikun rẹ, ko to di pe Wale gbe ẹmi mi loju ọna ti wọn ti n gbe lọ si ileewosan.
''Ọjọ isinmi ni iṣẹlẹ naa waye, Mumini Onanipekun wọ iya ija pẹlu Wale to jẹ onibara rẹ igba gbogbo. Lasiko ija naa ni Olanipekun gun Wale pẹlu afoku igo ni ikun ati ọrun rẹ.''
Femi Falana: Mẹ̀kúnnù gbọ́dọ̀ ṣetán láti gba ẹ̀tọ́ wọn, ìjọba ti kùnà lórí ẹ̀tọ́ ọmọnìyàn
''Wale ko ku lẹsẹkẹsẹ, amọ asiko ti wọn n gbe digbadigba lọ si ileewosan lo gbẹmi mi.''
Awọn ti iṣẹlẹ naa ṣoju wọn ni wọn ko le e sọ pato ohun to fa ija laarin awọn mejeeji, amọ jinijini bo awọn ara agbegbe naa lẹyin iṣẹlẹ ọhun.
Suicide Prevention: ìwọ́de yìí wáyé láti gbógun ti pípa ara ẹni
Agbẹnusọ ileeṣẹ ọlọpaa nipinlẹ Osun, Yemisi Opalola fi idi iṣẹlẹ naa mulẹ, to si fikun pe iwadii nlọ ni pẹrẹwu lori iṣẹlẹ naa.
Twitter ban: Ó ti pé ọgọ́rùn ún ọjọ́ tí ìjọba ti f'òfin de Twitter
Oríṣun àwòrán, AFP
O ti pe ọgọrun ọjọ bayii ti ijọba orilẹede Naijiria to fi ofin de oju opo ikansira ẹni Twitter.
Amọ awọn ọmọ Naijiria si ti n sọ aidunnu wọn lori bi igbesẹ ijọba orilẹede yii.
Ọjọ kẹrin oṣu kẹfa ọdun 2021 yii ni ijọba Aarẹ Muhammadu Buhari kede ifofinde lilo Twitter ni Naijiria.
Lati igba naa ni ijọ ti n gbero lati ri pe awọn ileeṣẹ oju opo ayelujara fi orukọ silẹ lorilẹede Naijiria ki wọn to lanfaani lati maa ṣiṣẹ.
Koda, ọpọ awọn ileeṣẹ iroyin ni lati yọ oju opo Twitter wọn kuro ki wọn maa ba ri ibinu ijọba.
Wọnyii ni nkan mẹfa tawọn eeyan ti padanu lẹyin ti ijọba f'ofin de Twitter
1. Ifọrọjomintoro ọrọ
Lara nkan tawọn eeyan padanu nipa Twitter ni ifọrọjomitoro ọrọ ayelujara.
Nigba kugba ti iṣẹlẹ kan ba ti ṣẹlẹ lawọn maa n bẹrẹ si fọrọ jomitoro ọrọ lori rẹ.
Awọn kan le gba ọrọ kan bi ẹni n gba igba ọti fun ọpọlọpọ wakati titi ti yoo fi rẹ wọn.
2. Ipolowo ọja ara ẹni
Ọpọ ọmọ Naijiria lo maa n ṣe ipolowo ọja tabi iṣẹ ti wọn n ṣe loju opo Twitter.
Ọpọ eeyan lo n ṣe kata kara loju opo Twitter lai tiẹ ri ẹni ti wọn n ba duna dura.
Iru awọn eeyan bayii ti padanu iru anfaani yii ti wọn n ri jẹ lori opo Twitter.
3. Mimọ nipa ọrọ to n lọ kaakiri agbaye
Ọkan lara nkan tawọn eeyan tun padanu nipa aini anfani lati lo Twitter fun bi ọgọrun ọjọ bayii ni mimọ ohun to n lọ lọwọ lagbaaye.
Nibi kibi ni iṣẹlẹ kan tabi omiran ti le maa ṣẹlẹ lagbaaye, lori Twitter lawọn eeyan ti maa n kọkọ gbọ nipa rẹ.
Ileeṣẹ aladani atawọn ileeṣẹ ijọba gan an maa n lo Twitter lati kede igbesẹ wọn fun araye.
4. Fifi ara ẹni ṣe yẹyẹ
Ohun miran tawọn eeyan tun padanu lati igba ti wọn ko ti ri Twitter lo mọ ni fifi awọn eeyan ṣe yẹyẹ.
Ka ni pe ijọba ko tii fofin de oju opo Twitter ni Naijiria lasiko ti Tega ati Boma fi kuro nile Ẹlẹgbọn Agba, BBNaija ni, yẹyẹ ko pọju lori Twitter.
Wọn a maa fi ẹlọmiran ṣe yẹyẹ debi pe o maa ni lati sa kuro lori ẹrọ Twitter.
5.  Ofofo
Nkan mii tawọn eeyan tun padanu nipa airi Twitter lo ni ofofo ṣiṣe.
Gbogbo awọn iṣẹlẹ to n ṣẹlẹ bi ọrọ gbajugbaja oṣere Odunlade Adekola to binu sọrọ pe oun kii beere fun ibalopọ ki oun to lo obin ninu ere.
Ori Twitter ni ọrọ naa ko ba lagbara julọ ka ni pe ijọba ko ti fofin de Twitter ni.
6. Ibadọrẹ pọ
Ohun miran tawọn eeyan ti padanu nipa airi Twitter lo ni ibadọrẹ pọ awọn eeyan.
Ọpọ eeyan lo ni oriṣiiriṣii ọrẹ loju opo Twitter.
Koda, pupọ ninu awọn ọrẹ yii lawọn eeyan kii lanfaani lati ri soju bayii.
Idi niyii ti ọpọ fi n ke si ijọba lati gbẹsẹ kuro lori Twitter kawọn eeyan le ni anfani lati maa lo Twitter bi ti tatẹyin wa.
Ilẹ̀ ń j'ẹ̀nìyàn, ìyá ìyàwó gómìnà ìpínlẹ̀ Oyo tẹ́lẹ̀ Florence Ajimobi jáde láyé
Oríṣun àwòrán, Oyo Insight
Victoria Amudoaghan to jẹ iya iyawo gomina ipinlẹ Oyo nigba kan ri, Florence Ajimobi ti dagbere faye.
Gẹgẹ bi iroyin ti o tẹ BBC Yoruba, opin ọsẹ to lọ ni mama jade laye.
Ọjọ kẹẹdọgbọn oṣu kẹfa ọdun 2020 ni Gomina ipinlẹ Oyo, Abiola Ajimobi jẹ Ọlọrun nipe ni tiẹ.
Ọmọbibi ipinlẹ Delta ni mama aya gomina ipinlẹ Oyo tẹlẹ ti o si tun jẹ ọmọ ijọ Aguda nigba aye rẹ.
A o maa mu ẹkunrẹrẹ iroyin wa lori iṣẹlẹ naa laipẹ.
Boko Haram: Wo àwọn ọmọ Nàìjíríà mẹ́fà tí UAE ń wá lórí ẹ̀sùn ṣíṣe àtìlẹ́yìn owó fún Boko Haram
Oríṣun àwòrán, AFP
Ijọba orilẹede UAE ti kede pe oun n wa ọmọ Naijiria mẹfa to n ṣatilẹyin fun ẹgbẹ agbesunmọmi Boko Haram.
Awọn mẹfa yii lo wa lara eeyan mejinlogoji ti UAE kede pe awọn n wa lori ẹsun pe wọn n ṣagbatẹru fun igbesunmọmi.
Abdurrahaman Ado Musa, Salihu Yusuf Adamu, Bashir Ali Yusuf, Muhammed Ibrahim Isa, Ibrahim Ali Alhassan ati Surajo Abubakar Muhammad ni awọn ọmọ Naijiria mẹfa ọhun.
Iroyin sọ pe ni nkan bi ọdun kan sẹyin ni orilẹede UAE kede pe awọn ọmọ Naijiria naa n ṣe atilẹyin fun Boko Haram.
Awọn ọmọ orilẹede mii ti ilẹ UAE n wa ni Ahmed Mohammed Abdulla Mohammed Alshaiba Alnuaimi (UAE), Mohamed Saqer Yousif Saqer Al Zaabi (UAE), Hamad Mohammed Rahmah Humaid Alshamsi (UAE), Saeed Naser Saeed Naser Alteneiji (UAE) pẹlu Hassan Hussain Tabaja (Lebanon).
Awọn miran tun ni Adham Hussain Tabaja (Lebanon), Mohammed Ahmed Musaed Saeed (Yemen), Hayder Habeeb Ali (Iraq), Basim Yousuf Hussein Alshaghanbi (Iraq) ati Sharif Ahmed Sharif Ba Alawi (Yemen).
Ileeṣẹ iroyin kan lati UAE ṣalaye pe ijọba gbe orukọ awọn eeyan yii jade gẹgẹ bi ọkan lara ọna lati bi dẹkun awọn eeyan to n ṣagbatẹru igbesunmọmi.
Ẹwẹ, ile ẹjọ giga Abu Dhabi dajọ ẹwọn gbere fun ọmọ Naijiria meji, Surajo Abubakar Muhammad ati Saliuh Yusuf Adamu.
Bakan naa tun ni ile ẹjọ ni ki wọn fi orilẹede naa silẹ.
Ile ẹjọ dajọ ẹwọn ọdun mẹwaa fun Ibrahim Ali Alhassan, AbdurRahman Ado Musa, Bashir Ali Yusuf ati Muhammad Ibrahim Isa, to si tun sọ pe ki wọn fi orilẹede UAE silẹ.
Ile ẹjọ tun ni wọn jẹbi ẹsun dida ọgba ẹwọn Boko Haram silẹ.
Awọn eeyan yii ni wọn ni wọn fi owo to to $800,000 ṣe atilẹyin fun Boko Haram laarin ọdun 2015 si 2016.
Poor roads in Ekiti state: Femi: Ká yọ tòṣèlú kúrò, Fayemi, àwọn òpópónà Ekiti ti di ẹgẹrẹmìtì, Babafemi Ojudu làá mọ́ Gómìnà Fayemi
Oríṣun àwòrán, other
Ọrọ oṣelu nipinlẹ Ekiti tun ba ibomiran yọ pẹlu bi o ṣe fẹ jọ pe, awọn eekan ẹgbẹ oṣelu naa meji ti n ta si ara wọn bayii.
Kayọde Fayẹmi ni gomina ipinlẹ Ekiti, ọmọ ẹgbẹ oṣelu APC ni. Ọkan lara awọn to jẹ aṣiwaju lagbo oṣelu ni Babafẹmi Ojudu jẹ, ọmọ ẹgbẹ oṣelu APC naa ni.
Ireti ọpọlọpọ onwoye ni pe o yẹ ki ọrọ awọn mejeeji ye ara wọn, amọṣa eyi ko fẹ da bi ẹni pe o n ri bẹẹ lọwọ.
Atẹjade kan ti Ọgbẹni Fẹmi Ojudu fi sita lọjọ Iṣẹgun lo ti n wọ Gomina Kayọde Fayẹmi atijọba rẹ pe wọn ko karamasiki ipo awobọkanjẹ tawọn opopona to wa ni ipinlẹ naa wa.
Suicide Prevention: ìwọ́de yìí wáyé láti gbógun ti pípa ara ẹni
Ninu atẹjade naa, Ọgbẹni Ojudu ni oun ko lee dakẹ bi o tilẹ jẹ pe awọn kan lee maa ṣi ọrọ oun tumọ loun fi n pariwo lati pe akiyesi gomina Kayọde Fayẹmi ati ijọba rẹ si ipo arigbarimu ti awọn opopona wa ni ipinlẹ naa.
Femi Falana: Mẹ̀kúnnù gbọ́dọ̀ ṣetán láti gba ẹ̀tọ́ wọn, ìjọba ti kùnà lórí ẹ̀tọ́ ọmọnìyàn
"Femi ni: ""Ipo ti awọn opopona ni ipinlẹ Ekiti wa n ba eeyan lọkan jẹ. Mo wa nibẹ lopin ọsẹ to kọja n ko si fẹrẹ lee gba ohun ti oju mi n ri gbọ. Gbogbo opopona igboro ati awọn ti marosẹ to wọle tabi jade ni ipinlẹ naa ni wọn ti di ẹgẹrẹmiti."
Adene Oluwabukola Deborah: Bàbá mi kò kọ́kọ́ fọwọ́ sí iṣẹ́ ìlù lílù ṣùgbọ́n....
Ojudu fi kun un pe asiko to ki Gomina Fayẹmi o kede aṣẹ nnkan o fara rọ lẹka ipese ohun amayedẹrun ni ipinlẹ naa lati lee tubọ mojuto ẹka naa nitori pe iṣoro ati idojukọ tawọn olugbe ipinlẹ Ekiti maa n dojukọ bi ojo ba tun wa rọ lawọn ọna naa kii ṣe kekere.
Yoruba Nation: Kò sí ìdí tí à ó fi bínú sí Akeredolu lórí ọ̀rọ̀ Yorùbá Nation
Sunday Igboho trials in Benin Republic: Sunday Igboho ké sáwọn olólùfẹ́ rẹ̀ láti dáríji agbẹjọ́rò rẹ̀ ní Benin republic
Oríṣun àwòrán, other
Aṣiwaju ipe fun idasilẹ orilẹede Yoruba, Oloye Sunday Igboho ti  ke sawọn ọmọ Yoruba to wa lẹyin ijijagbara to n lepa pe ki wọn foriji ọkan lara awọn agbẹjọro to n gbọ ẹjọ rẹ ro lorilẹede Benin Republic, Amofin Ibrahim Salami.
Bi ẹ ko ba gbagbe, lọjọ diẹ sẹyin ni oloye Sunday Igboho ti fi ibinu rẹ han ninu fọnran ohun kan to lu ori ayelujara ja pe oun ko mọ iṣẹ tawọn lọya naa n ṣe ti oun fi di ẹni to n pẹ lẹwọn lorilẹede Benin Republic fun nnkan bii aadọta ọdun.
Ọkan lara awọn agbodegba fun Oloye Igboho, Aarẹ, Almaroof Bọbagunwa Yẹkini ninu fidio kan to fi sori ayelujara ti wa ṣalaye pe oun ati Oloye Sunday Igboho ti pada sọrọ lẹyin edeaiyede naa, o si ti rọ gbogbo awọn ololufẹ ijijagbara fun idasilẹ orilẹede Yoruba pe ki wọn darijin agbẹjọro Salami.
O ni ki gbogbo awọn ajijagbara atawọn to pariwo rẹ kaakiri o darijin. A nilo rẹ, oun naa si nilo wa, a jijọ nilo ara wa ni.
"Aarẹ Bọbagunwa Yẹkini to ṣapejuwe Igboho gẹgẹbi ""oriṣa ni Naijiria, akinkanju jagunkagun"" ti kii fi iwọsi lọ ẹnikẹni ṣalaye pe Igboho ko korira Amofin Salami atawọn ikọ agbẹjọwro ti wọn jumọ n ṣiṣẹ lori ẹjọ rẹ lorilẹede Benin, nitori naa ki wọn tete gbe awsn igbesẹ gbogbo fun ẹjọ naa lati tubọ mu esi to tọ jade."
Yoruba Nation One million man march: Àwọn tó ń ṣagbátẹrù Yorùbá Nation ní IPOB kò ṣiṣẹ pọ̀ pẹ̀lú àwọn
Oríṣun àwòrán, @Akintoye
Awọn to n ṣagbatẹru idasilẹ Yoruba nation ti ṣalaye fun ijọba Naijiria pe ẹgbẹ ajijagbara IPOB kọ lo ṣe agbekalẹ ifẹhonuhan tawọn n ṣe ni olu ileeṣẹ ajọ iṣọkan agbaye, UN lorilẹede Amẹrika.
Eyi ni esi wọn si atẹjade ijọba apapọ to kilọ pe wọn o gbọdọ ni ajọṣepọ pẹlu ẹgbẹ ajijagbara fun orilẹede Biafra, IPOB.
Lati ọjọ kẹrinla oṣu kẹsan an ọdun 2021 yii lawọn ajijagbara fun Yoruba Nation atawọn ẹya mii naa ni Naijiria ti n ṣe iwọde ni olu ileeṣẹ ajọ UN niluu New York lorilẹede Amẹrika.
Iwọde yii wa jẹ asiko kan naa pẹlu apejọ ajọ UN nibi ti Aarẹ Muhammadu Buhari atawọn olori orilẹede agbaye mii yoo ti sọrọ apilẹkọ.
Yoruba Nation: Kò sí ìdí tí à ó fi bínú sí Akeredolu lórí ọ̀rọ̀ Yorùbá Nation
Alaga ẹgbẹ NINAS to jẹ akojọpọ awọn ẹgbẹ ajijagbara ni Naijiria, Ọjọgbọn Banji Akintoye ni awọn n ṣe iwọde niwaju olu ileeṣẹ ajọ UN lati le jẹki gbogbo aye mọ bi awọn darandaran ṣe n fi ẹmi awọn eeyan ṣofo lapa Guusu ati arin gbungbun orilẹede Naijiria
Yorùbá Nation, yàgò fún IPOB níbi ìwọ́de tó ń lọ lọ́wọ́ ní New York bí bẹ́ẹ̀kọ́....- Ìjọba Buhari
Bí ewúrẹ́ Yorùbá Nation bá bá àgùntàn IPOB rìn ojú kàn náà là ó fí wò yín- Ìjọba Nàìjíríà
Ijoba Naijiria ni idi ti awọn se n lọgun bẹẹ ni pe labẹ ofin awọn ka IPOB gẹgẹ bi ẹgbẹ agbesunmọmi to n da omi alafiaa ru.
Suicide Prevention: ìwọ́de yìí wáyé láti gbógun ti pípa ara ẹni
Ninu atẹjade kan lati ọwọ oludamọran agba si aarẹ, Garba Shehu, o ni IPOB ni to awọn ọmọ ogun ẹgbẹrun lọna aadọta ọmọ ogun ti rẹ.
O fi kun un pe ko si ẹni ti yoo ka awọn to n beere fun idasilẹ Yoruba Nation kun lopin igba ti wọn ba n ba n ṣe iwọde to mu iwa janduku lọwọ.
Ọrọ́ ileesẹ aarẹ yi ko sẹyin bi awọn ọmọ ikọ IPOB se darapọ mọ awọn ti Yoruba Nation nibi iwọde ranpẹ ti wọn se niwaju ẹgbẹ isọkan agbaye ni New York.
Nibi iwọde yi ni wọn ti fi ẹhonu han lori awọn aiṣedeede to n waye ni Naijiria ati ipe wọn fun idasilẹ orileede Yoruba Nation.
Abiodun Duro Ladiipo, Moremi: Ǹ kò pé '40' ti Bàbá fi papòdà ṣùgbọ́n mo kọ̀ láti 'remarry'
Aarẹ Buhari la gbọ pe yoo kopa laipẹ yi nibi apero ajọ isọkan agbaye.
Agbẹnusọ aarẹ Garba Shehu tutọ soke foju gba ninu atẹjade rẹ to si ni ''iyalẹnu lo jẹ bawọn se ri ti awọn Yoruba Nation ko ṣe bikita lati darapọ mọ ikọ IPOB
Femi Falana: Mẹ̀kúnnù gbọ́dọ̀ ṣetán láti gba ẹ̀tọ́ wọn, ìjọba ti kùnà lórí ẹ̀tọ́ ọmọnìyàn
O ni ''ṣe IPOB to n da omi alaafia ru lagbegbe rẹ , to n ko awọn araalu ni panpẹ ti wọn si n tẹ ẹtọmọniyan mọlẹ ni ẹ fẹ ki wọn ka yin mọ?''
"Lai si iyemeji, awọn ọmọ  Naijiria ati gbogb aye yoo da yin lẹjọ  nipa iru awọnti ẹ n kọwọrin pẹlu''.
''Ko si ẹni ti yoo ka ẹgbẹ yin kun lopin igba ti ẹ baa n ba IPOB se pọ.Ti awọn alajọṣepọ wọn(IPOB) ba n tẹ ẹtọmọniyan mọlẹ, eyi yoo mu ki ajọ UN gaan foju sunukun wo ifarajin yin si mimu agbega ba afojusun UN''
Oríṣun àwòrán, Ilana omo oodua
Ìwọ́de Yoruba Nation lólú iléeṣẹ́ àjọ UN wáyé, bó ṣe lọ nìyí
Awọn to wa sibẹ wa pẹlu oniruuru patako alakọle lati fi ẹhonu wọn han.
Iwọde onimiliọnu kan eeyan tawọn ẹgbẹ to n pe fun idasilẹ orilẹ-ede Yoruba lawọn yoo ṣe niwaju olu ileeṣẹ ajọ United Nations waye loni bi wọn ṣe ṣeleri.
Amọṣa ohun ti oju BBC News Yoruba to nibẹ ni pe ero ko pọ bi wọn ṣe lero, bẹni awọn to wa wa pẹlu oniruuru patako alakọle lati fi ẹhonu wọn han.
Ọjọgbọn Banji Akintoye to jẹ aṣiwaju ẹgbẹ to n ja fun idaduro ilẹ Yoruba kede ṣaaju pe iwọde oni miliọnu eeyan yoo waye ni adojukọ olu ileeṣẹ ajọ iṣọkan agbaye, United Nation to wa nilu New York ni Amẹrika laarin ọjọ kẹrinla si ikẹrinlelogun oṣu kẹsan ọdun 2021.
Oríṣun àwòrán, Ilana oodua
Gẹgẹ bi o ṣe sọ iwọde naa wa lati pe akiyesi awọn awujọ agbaye si ipenija to n waye fun awọn ẹya ni Naijiria pẹlu igbenipa to n ṣẹlẹ kaakiri latọwọ awọn darandaran Fulani.
Bakan naa lo ni wọn yoo tun lo iwọde naa lati pe fun akiyesi agbaye lori ikslu awọn akọroyin ati wahala ọrọ abo ti ko gboriduro ni Naijiria.
Adene Oluwabukola Deborah: Bàbá mi kò kọ́kọ́ fọwọ́ sí iṣẹ́ ìlù lílù ṣùgbọ́n....
Àwọn ọmọdé Young boys ti yẹ̀yẹ́ Ronaldo àti ikọ̀ Manchester United pẹ̀lú 2-1
Oríṣun àwòrán, Reuters
Ẹfọn ti ja baluu Manchester United ninu ifẹswọnsẹ wọn pẹlu Young Boys lati orilẹede Switzerland.
Loju ewe iwe, ọpọlọpọ lo ti fi oju wo pe Manchester United toun ti ilumọọka atamatase, Christiano Ronaldo ti wọn ṣẹṣẹ ra, ni yoo bori.
Lootọ Ronaldo lo kọkọ ṣide goolu fun Manchester united nigba ti ifẹsẹwọnsẹ naa wọ iṣẹju kẹtala.
Amọṣa, nnkan gbẹyin yọ fun Manchester United nigba ti oludari ifẹsẹwọnsẹ naa le agbabọọlu Manchester United, Wan-Bissaka.
Moumi Ngamelu lo sọ ayọ naa di ọmi fun wọn nigba ti ere wọ iṣẹju kẹrindinlaadọrin ki Siebatcheu to fọba lee fun Young boys.
Ifẹsẹwọnsẹ Championsleague akọkọ ti Ronaldo yoo maa gba fun Manchester United niyi lẹyin to pada darapọ mọ wọn.
Masquerade vs muslims: Atọ́kùn egúngún, ọmọ rẹ̀ àti èèyàn méjì dèrò àtìmọ́lè lórí ẹ̀sùn ìpànìyàn ní mọ́ṣálááṣí
Oríṣun àwòrán, NAIJ.com
Wahala ati rogbodiyan lasiko ọdun egungun wọpọ kaakiri ipinlẹ Ọyọ.
Ile ẹjọ giga ilu Osogbo ti ju atọkun eegun, Oloye Kayode Esuleke, ọmọkunrin rẹ ati eeyan meji si atimọle lori ẹsun ni mọṣalaaṣi.
Adajọ Ayo Oyebiyi paṣẹ pe ki wọn gbe wọn lọ si ọgba ẹwọn to wa niluu Ilesha lọjọ Iṣẹgun.
Oloye Esuleke, Kola Adeosun, Akeem Idowu, ati Ifasola Esuleke lo n jẹjọ lori ẹsun ipaniyan onikoko mẹtala to da lori ibankanjẹ, dida alaafia ilu ru ati jagidijagan.
Amọ gbogbo wọn lo sọ pe awọn ko jẹbi ẹsun ti wọn fi kan awọn.
Adajọ sun igbẹjọ naa si ọjọ kọkanlelogun oṣun kẹsan ọdun 2021 yii.
Adene Oluwabukola Deborah: Bàbá mi kò kọ́kọ́ fọwọ́ sí iṣẹ́ ìlù lílù ṣùgbọ́n....
Ọjọ jọ kẹtadinlọgbọn, oṣu kẹsan an yii ni awọn eleegun atawọn musulumi ni mọṣalaasi Kamorudeen Society to wa ni Oluode Aranyin, Osogbo kọlu ara wọn.
Femi Falana: Mẹ̀kúnnù gbọ́dọ̀ ṣetán láti gba ẹ̀tọ́ wọn, ìjọba ti kùnà lórí ẹ̀tọ́ ọmọnìyàn
Nibẹ ni a gbọ pe ibọn ti ba Moshood Salawudeen ti o si gba ibẹ dero ọrun nigba ti ọpọ eeyan farapa nibi ikọlu naa.
Iroyin sọ pe wọn tun ba mọṣalaaṣi ọhun jẹ nigba tawọn eleegun naa n kọja lọ.
Yoruba Nation: Kò sí ìdí tí à ó fi bínú sí Akeredolu lórí ọ̀rọ̀ Yorùbá Nation
Ọkùnrin tó lẹ ''Super Glue'' mọ́ ǹkan ọkùnrin rẹ̀ láti rọ́pò ''condom'' ti dèrò ọ̀run
Kayeefi ni ọrọ yii jẹ fun ọpọlọpọ eeyan to ti gbọ nipa rẹ o.
Ọkunrin kan lo dero ọrun lẹyin to lẹ ''super glue'' oko rẹ nigba to gbagbe rọba idaabobo ṣaaju ibalopọ pẹlu ọrẹbinrin rẹ ti jẹ Ọlọrun nipe.
Salman Mirza, ẹni ọdun mẹẹdọgbọn ni iroyin sọ pe o lẹ ''super glue'' mọ nkan ọmọkunrin rẹ lati le dena oyun nigba ti o fẹ ni ablopọ pẹlu ọrẹbinrin rẹ nile itura kan niluu Gujarat lorilẹede India.
Oun ati ololufẹ rẹ ni a gbọ pe wọn lo oogun oloro ki wọn ba le lagbara fun ibalopọ gbankọgbi ti wọn fẹ ṣe nile itura.
Ileeṣẹ ọlọpaa ni Mirza ni wọn ba ni ita ile itura naa ni ọjọ keji.
Oloye Peter Fatomilola: Ọjọ̀gbọ́n olùkọ́ni ni Jesu àti Orunmila jẹ́, àwòkọ́ṣe sí rere si n
Ọga ọlọpaa niluu Ahmedabad ṣalaye pe awọn mejeeji tun fin awọn oogun oloro mii si imu ki wọn to bẹrẹ ibalopọ wọn.
Ọpọ eeyan ni adugbo ni wọn jẹri pe awọn mejeeji maa n ṣaaba lo oogun oloro papọ.
Ijesha tennager police death: O yẹ kí wọ́n máa yẹ ọpọlọ ọlapàá wò kí wọ́n tó gbà wọn síṣẹ
Nigba ti wọn ri Mirza nibi to wa ni ita ni wọn gbe e digba digba lọ si ile ile iwosan.
Amọ, ọwọ ti bọ sori, ile iwosan yii naa ni o ti dagbere faye.
Adene Oluwabukola Deborah: Bàbá mi kò kọ́kọ́ fọwọ́ sí iṣẹ́ ìlù lílù ṣùgbọ́n....
Awọn ẹbi Mirza pe fun iwadii lori ohun to pa ọmọ wọn.
Ile iṣẹ ọlọpaa sọ pe iwadii ti bẹrẹ lati mọ ohun to pa ọmọkunrin yii gan an, o ni esi maa to jade laipẹ.
Femi Falana: Mẹ̀kúnnù gbọ́dọ̀ ṣetán láti gba ẹ̀tọ́ wọn, ìjọba ti kùnà lórí ẹ̀tọ́ ọmọnìyàn
Kaduna kidnap: Àwọn jàndùkú jí Emir Bungudu gbé, wọ́n pa ọlọ́pàá lọ́nà mọ́rosẹ̀ Abuja sí Kaduna
Oríṣun àwòrán, Facebook/Abdulrahman Hussaini
Eto abo to mẹhẹ ni Naijria papaa julọ lẹkun ariwa ti wa n buruu si bayii.
Lọjọ Iṣẹgun ni iroyin kan jade pe awọn janduku ajinigbe pawo gbe Emir Bungudu, Alhaji Hassan Attahiru lọ lopona ilu Abuja si Kaduna.
Alukoro ileeṣẹ ọlọpaa ipinlẹ Kaduna, Mohammed Jalige lo fid iṣẹlẹ ọhun mulẹ ninu atẹjade to fi sita lalẹ ọjọ Iṣẹgun.
Jalige ṣalaye ninu atẹjade naa pe ọlọpaa kan dero ọrun lasiko ikọlu naa to ṣẹlẹ lagbegbe ilu Dutse lopona Abuja si Kaduna.
Alukoro ileeṣẹ ọlọpaa ni ọpọ eeyan ni wọn jigbe lọ pẹlu Emir Bungudu nigba ti awọn meji mi farapa yana yana.
O ni awọn ti wọn farapa naa ti n gba itọju bayii nile iwosan.
Oloye Peter Fatomilola: Ọjọ̀gbọ́n olùkọ́ni ni Jesu àti Orunmila jẹ́, àwòkọ́ṣe sí rere si n
Jalige fikun ọrọ rẹ pe ṣadeedee lawọn ajinigbe ọhun da awọn ero ọkọ naa lọna ti wọn si bẹrẹ si ni yinbọn ni mẹsan an mẹwaa.
Agbẹnusọ ileeṣẹ ọlọpaa ni awọn ẹṣọ eleto abo gbera pa lọ sibẹ lati doola awọn eeyan, ṣugbọn ọlọpaa kan ba iṣẹlẹ naa lọ.
Yoruba Nation: Kò sí ìdí tí à ó fi bínú sí Akeredolu lórí ọ̀rọ̀ Yorùbá Nation
O ni ọkọ mẹrin ni ileeṣẹ ọlọpaa ri nibi ti iṣẹlẹ ọhun ti waye nigba ti o sọ pe oun ko le sọ pato iye eeyan ti wọn jigbe lọ.
''Emir Bungudu wa lara awọn ti wọn jigbe lọ si ibi ti ẹnikan ko mọ bayii.
Adene Oluwabukola Deborah: Bàbá mi kò kọ́kọ́ fọwọ́ sí iṣẹ́ ìlù lílù ṣùgbọ́n....
Ṣugbọn iṣẹ n lọ lọwọ lati doola gbogbo awọn ti wọn jigbe lọ lai ni ifarapa.
Iru iṣẹlẹ ijinigbe yii ko saaba wọ pọ mọ lopopona Abuja si Kaduna lẹnu ọjọ mẹta yii ki eleyii to ṣẹlẹ,'' Jalige lo sọ bẹẹ.
Femi Falana: Mẹ̀kúnnù gbọ́dọ̀ ṣetán láti gba ẹ̀tọ́ wọn, ìjọba ti kùnà lórí ẹ̀tọ́ ọmọnìyàn
Ẹwẹ, ọga agba ọlọpaa ipinlẹ Kaduna, CP Mudassiru Abdullahi ti rọ awọn eeyan pe ki wọn maa ṣe bẹru lati maa rinrin ajo lopopona Abuja si Kaduna.
CP Abdullahi ni awọn ọlọpaa ko ni kaarẹ lati maa pese abo to peye fawọn eeyan loju ọna ọhun.
Covid-19 cure: ìjọba àpapọ̀ ké pe àwọn oníṣègùn ìbílẹ̀ láti wá oògùn Coronavirus
Oríṣun àwòrán, Instagram/Bashir Ahmad
Ijọba apapọ ti kepe awọn oniṣegun ibilẹ lati ṣe awari oogun ajakalẹ arun coronavirus to n ṣọṣẹ lorilẹede Naijiria.
Minisita abẹle fun eto ilera ni Naijiria, Dokita Olorunnimbe Mamora lo sọrọ yii nibi ayẹyẹ ayajọ oogun ibilẹ to waye niluu Abuja.
Minisita ni ọrọ ajakalẹ arun coronavirus ti de ibi ti awọn oniṣegun ibilẹ ni lati da si ọrọ ati wa oogun si arun naa lọna ti ibilẹ.
Dokita Mamora ṣalaye pe ijọba ti sọ fun ajọ NIPRD to n ri si pipoogun ati NAFDAC lati wa oogun covid-19 lati Naijiria.
Ọrọ yii jade lẹyin ti adari ajọ alaanu Bill & Melinda Gates Foundation (BMGF), Dokita Mark Suzman, ṣe bu ẹnu atẹ lu aidọgba to wa ninu pinpin abẹrẹ ajẹsara laarin awọn orilẹede to lowo atawọn ti ko rọwọ họri.
Oloye Peter Fatomilola: Ọjọ̀gbọ́n olùkọ́ni ni Jesu àti Orunmila jẹ́, àwòkọ́ṣe sí rere si n
Dokita Suzman ni iru nkan bayii ko boju mu, ati pe o le ṣakoba fun ọrọ aje fun igba pipẹ.
O ṣalaye pe bi ida ọgọrin ninu abẹrẹ ninu abẹrẹ ajẹsara covid-19 ti wọn n pin lagbaaye bayii lo n lọ si awọn orilẹede to lowo nigba ti ida kan ṣoṣo n lọ sawọn orilẹede ti ko rọwọ họri.
Femi Falana: Mẹ̀kúnnù gbọ́dọ̀ ṣetán láti gba ẹ̀tọ́ wọn, ìjọba ti kùnà lórí ẹ̀tọ́ ọmọnìyàn
Dokita Suzman pe fun imugbooro pinpin abẹrẹ ajẹsara papaa julọ nilẹ Afirika nibi ti wọn ti n ri abẹrẹ perete gba.
Suzman ni ajọ alaanu BMGF atawọn ijọba orilẹ-ede agbaye kan lo da COVAX bi ọdun kan sẹyin lati fi le pin abẹrẹ covid-19 kaakiri gbogbo orilẹede agbaye.
Amọ, o ni ọrọ ko ri bẹ mọ lẹyin tawọn orilẹ-ede to lowo n ko abẹrẹ naa pamọ ti wọn ko si jẹ ko kari.
Dokita Suzman sọ pe o yẹ ki ajọ iṣọkan agbaye jiroro ninu ipade wọn lori bi wọn ṣe maa gbe owo kalẹ lati fi ṣe iranwọ fun pinpin abẹrẹ covid-19 kari aye.
Coronavirus after one year in Nigeria: Níbo ni ọ̀rọ̀ Covid 19 dé dúró ní Nàìjíríà?
Smuggled vehicles: Àjọ aṣóbodè kìlọ̀ fáwọn iléeṣẹ́ ìjọba láti dẹ́kun ríra ọkọ̀ tòkunbọ̀ fàyàwọ́
Oríṣun àwòrán, NCS
Ajọ aṣọbode, Nigeria Customs Service (NCS) ti kilọ fawọn ọmọ ile igbimọ aṣoju-ṣofin pe ọpọ awọn ọkọ ''escort'' ti wọn lo ni ileeṣẹ ijọba lo jẹ ọkọ fayawọ.
Igbakeji ọga agba ajọ aṣọbode ni Naijiria, Aliyu Saidu lo ṣalaye ọrọ yii.
''O ṣeni laanu pe awọn eeyan pataki lo n lo ọkọ Hilux tawín oni fayawọ gbe wọ Naijiria.
Ti ẹ ba wo ori ẹrọ kọmputa wa, ko si akọsilẹ ọkọ Hilux dabi alara ninu akọsilẹ wa.
Ṣugbọn ọkọ Hilux yii pọ yanturu ni igboro eyi to tumọ si pe awọn eeyan ko maa ra awọn ọkọ naa nipasẹ ajọ aṣọbode mọ.
Oloye Peter Fatomilola: Ọjọ̀gbọ́n olùkọ́ni ni Jesu àti Orunmila jẹ́, àwòkọ́ṣe sí rere si n
Ọpọ owo to yẹ ki awọn eeyan maa san fun ijọba lori awọn ọkọ yii ni wọn ko san.
Eleyii tumọ si pe wọn ja ijọba lole ni.
Ijesha tennager police death: O yẹ kí wọ́n máa yẹ ọpọlọ ọlapàá wò kí wọ́n tó gbà wọn síṣẹ
Mo fẹ sọ fawọn ọmọ Naijiria pe Aarẹ Muhammadu Buhari nikan lo lagbara lati maa sanwo ori ọkọ lati oke okun wọ Naijiria,'' Saidu ṣalaye.
Igbakeji ọga agba ajọ aṣọbode ni Naijiria ile aṣofin lati gbe ofin kalẹ ti yoo mu ni dandan fawọn eeyan lati maa gba iwe ọkọ ti wọn fẹ ra ki wọn to raa.
Adene Oluwabukola Deborah: Bàbá mi kò kọ́kọ́ fọwọ́ sí iṣẹ́ ìlù lílù ṣùgbọ́n....
Warplane caught fire in Yobe:: Báàlù ológun tó já, to ṣekú pa àwọn ará ìlú Buhari ṣẹlẹ̀ nítòòtọ́- Nigerian Air Force
Oríṣun àwòrán, @Others
Ni irọlẹ ana, ọjọru, ọjọ kẹẹdogun, oṣu kẹsan an, ọdun 2021 yii ni baalu iajgun kan ja ni agbegbe Buhari ni ipinlẹ Yobe.
Oriṣiriṣi ariwisi ni awọn eniyan Naijiria ti n sọ nipasẹ iṣẹlẹ naa yatọ si pe ileeṣẹ ologun kọkọ sẹ pe ko ṣẹlẹ ki wọn to wa sọ pe o tun ṣẹlẹ laarọ oni.
Eyi lo mu ki a ṣe akojọpọ iye igba ti baalu ologun ti ja ni Naijiria laipẹ yii.
Lọjọ kẹrindinlogun, oṣu kinni, ọdun 2017 ni ọkan waye pẹlu ikọ ologun ofurufu ni Naijiria ni Maidugurito jẹ olu ilu ipinlẹ Maiduguri ni ariwa Naijiria nibi ti eeyan mejilelaadọta ti gbẹmi mi.
Lara awọn to ku ni awọn oṣiṣẹ eleto ilera, oṣiṣẹ iranẹnilọwọ ati awọn ajọ apese iranlọwọ ni ariw.
Iṣẹlẹ yii bi Ige ati Adubi lọdọ awọn ọmọ Naijiria eyi ti ikọ ologun ofurufu pada sọ pe aṣiṣẹ ni o fa a.
Ijesha tennager police death: O yẹ kí wọ́n máa yẹ ọpọlọ ọlapàá wò kí wọ́n tó gbà wọn síṣẹ
Lọdun 2019 ni awọn eeyan mọkandinlogun mii tun jalaisi ni abule Gajigana ni ipinlẹ borno.
Eyi waye leyin ti awọn ologun ofurufu Naijiria ni awọn n kọlu awọn Boko Haram alakatakiti.
Femi Falana: Mẹ̀kúnnù gbọ́dọ̀ ṣetán láti gba ẹ̀tọ́ wọn, ìjọba ti kùnà lórí ẹ̀tọ́ ọmọnìyàn
Laipe yii ni ilu Port harcourt ni ipinlẹ rivers ni guusu Naijiria ni baalu to n ju ado oloro tun kolu bootu onigi to n ko ohun jije ati ero ni osu kẹjọ odun.
Ileeṣẹ aabo Naijiria fi atẹjade sita pe wọn ko mọ nipa bootu naa tabi nipa awọn ero ati ohun jijẹ ti wọn n ko ati pe awọn to n ji epo rọbi wa ni awọn sọ ọ si.
Oríṣun àwòrán, @Nig Airforce
A kò mọ̀ọ́mọ̀, bàálù ìjagun tó pa àwọn eèyàn Yobe náà ṣèèṣì jábọ́ ni- Iléeṣẹ́ Ológun Nàìjíríà
Ileeṣẹ ọmọ ogun ofurufu ti fi ikede sita pe nitootọ ni baalu ijagun kan ja ni ilu Buhari ni ipinlẹ Yobe.
Saaju ni awọn ti iṣẹlẹ naa ṣoju wọn ti kọkọ sọ pe eeyan mẹ́wàá lo ba iṣẹlẹ naa rin.
Ni kete ti iṣẹlẹ yioi ṣẹlẹ ni ana ni ileeṣẹ ologun Naijiria ti sọ pe irọ ni.
Wọn ni ko si ohun to jọ beẹ.
Sugbon bayii, ileeṣẹ ologun ofurufu ni Naijiria ti kede pe lootọ lo ṣẹlẹ.
Wọn ti fi atejade sita pe asise ni iṣẹlẹ naa to fa ijamba to mu ẹnmi awọn eniyan kan lọ.
Ogagun Edward Gabkwet to jẹ adari agba ni NAF lo buwọlu atẹjade naa.
Abiodun Duro Ladiipo, Moremi: Ǹ kò pé '40' ti Bàbá fi papòdà ṣùgbọ́n mo kọ̀ láti 'remarry'
Bawo ni ìṣẹ̀lẹ̀ náà ṣe ṣẹlẹ̀?
Ogagun Edward ni pe won fi baalu ijagun naa lọ si agbegbe Kamadougou Yobe ni lati fi koju awon onise ibi Boko Haram ati ISWAP ko to ja.
O ni Operation Unity to jẹ iṣẹ akanṣe nibẹ gba ifitonileti pe awọn oniṣẹ ibi kan ti fẹ ṣọṣẹ ni agbegbe naa ni.
Oríṣun àwòrán, Twitter
Báàlù ìjagun kan já lulẹ̀ ní ìlú Buhari, ẹ̀mi àwọn aráàlú bọ́
Báàlù ìjagun kan ti gbiná nílùú Buhari, ẹ̀mi àwọn aráàlú bọ́
Iroyin to n tẹ wa lọwọ ni yajoyajo lati ipinlẹ Yobe ni pe baalu ijagun kan ti ẹnikẹni kò mọ ti gbina ni abule kan to n jẹ Buhari ijọba ibilẹ Yunusari l'owurọ Ọjọbọ tó si ti pa ọpọlọpọ araalu.
Awon olugbe ilu naa sọ fún BBC awọn ti kọkọ rí baalu ijagun mẹta to n fo l'oke.
Nigba to ya, ọkan ninu wọn dede gbina lapa ibomii ninu ilu naa to sì pa eeyan oun kan ati ìdílé rẹ, araalu kan sọ fún BBC.
O ṣẹlẹ pé ni nkan bíi ago mẹjọ abọ owurọ ti ọkan lára àwọn baalu na lulẹ nibi kan ninu ilu to si gbina, gbogbo ile to wà lápá ibẹ lo jona to bajẹ."
"O jẹ ọkọ baalu ijagun nla ti awon ologun ṣugbọn a o mọ pato ibi to ti wa,"" o sọ fún wa."
"Osojumikoro to wa níbẹ ni awọn o le sọ iye èèyàn to ti ba iṣẹlẹ naa lọ bayii, ""torí pé ninu ile wa nikan, a ti padanu eeyan meji bayii,"" araalu yii sọ fún BBC."
CBN: Banki àpapọ̀ Nàìjíría ti pasẹ titi ojú òpó Aboki FX pa
Banki apapọ Naijiria ti ni oun yoo ti Aboki FX to maa n sọ bi awọn  to n ṣe pasiparọ owo ilẹ okere (Bereau de change) ati àwọn ara ilú yoo se ma ra owo ilẹ okere, dọla ati oọun.
Ori atagba Aboki FX yii ni banki ọhun sọ bayii pe ko ba ofin mu ati pe iṣẹ ọdaran ni wọn n se nibẹ.
Gomina banki apapọ naa, Godwin Emefiele to sọ ọrọ yii lasiko to n ba awọn oniroyin sọrọ lẹyin ipade igbimọ ofin owo u=ile okere to waye ni ilu Abuja lonii.
Bakan naa lo fi kun un pe awọn yoo fi ẹni to ni atagba naa, Olusegun Oniwinde jofin .
"O ni  ""mo ti sọ fun awọn akọsẹmọsẹ wa lati koju mọoju opo iroyin rẹ , ki o si mọ daju pe a o mu oun pẹlu  nitori pe a ko le gba ki iru nkan bayii ma tẹsiwaju"""
"Gẹgẹ bi Emefiele ṣe sọ awọn ko si ẹni to da ""burudi ṣenji"" kankan mọ yatọ si awọn tó n ṣe katakara ati awọn to n ta ọja si oke okun."
Lasiko ti a nkọ iroyin yii lọwọ, Burudi ṣenji ni ayipada dọla kan jẹ ẹdẹgbẹta ati aadọrin naira loju opo Aboki FX.
Oju opo naa ṣalaye pe awọn burudi ṣenji n ra dọla ni ẹẹdẹgbẹta naira le ọgọta ti wọn si n taa fun ara ilu ni ẹẹdẹgbẹta naira le aadọrin.
Yoruba Nation: Femi Gbajabiamila ní àwọn èèyàn kan ló si òun gbọ́ lórí ọ̀rọ̀ tóun sọ nípa Yorùbá Nation
Oríṣun àwòrán, Femi Gbabiamila
Adari ile igbimọ aṣoju-ṣofin niluu Abuja, Femi Gbajabiamila ti ṣalaye pe oun ko sọ pe awọn to n pe fun idasilẹ Yoruba Nation ko yatọ si ẹgbẹ agbesunmọmi Boko Haram.
Ni Ọjọru ni iroyin gbee Gbajabiamila sọ pe ẹgbẹ IPOB to n pe fun idasilẹ orilẹede Biafra ati Yoruba Nation ko yatọ si Boko Haram.
Amọ, oludamọran adari ile igbimọ aṣoju-ṣofin lori ọrọ iroyin, Lanre Lasisi sọ ninu atẹjade to fi sita pe ọrọ ko ri bẹẹ.
Ọgbẹni Lasisi ṣalaye pe Gbajabiamila ko darukọ ẹgbẹ ajijagbara kankan ninu ọrọ rẹ.
''Oun ti adari ile igbọmi aṣoju-ṣofin sọ pe awọn ọdaran kan n lo iwọde tawọn kan fi n pe fun iyapa kuro lara Naijiria lati da rogbodiyan silẹ.
Femi Falana: Mẹ̀kúnnù gbọ́dọ̀ ṣetán láti gba ẹ̀tọ́ wọn, ìjọba ti kùnà lórí ẹ̀tọ́ ọmọnìyàn
Ọpọ awọn ọdaran to n pe ara wọn ni ajijagbara lapa Guusu Naijiria papaa julọ nilẹ Igbo ati Yoruba ti n da ilu ru.
Bakan naa ni wọn gba ẹmi awọn alaiṣẹ ti wọn si tun ṣe akoba fun ọrọ aje orilẹede Naijiria.
Oloye Peter Fatomilola: Ọjọ̀gbọ́n olùkọ́ni ni Jesu àti Orunmila jẹ́, àwòkọ́ṣe sí rere si n
Wọn o ṣetan lati jiroro pẹlu ijọba lori ohun to n dun wọ, nitori naa, wọn o yatọ si Boko Haram ati ẹgbẹ agbesunmọmi ISWAP.
Ko si ohun to jọọ pe Gbajabiamila darukọ ẹgbẹ kankan ninu ọrọ rẹ.
Ijesha tennager police death: O yẹ kí wọ́n máa yẹ ọpọlọ ọlapàá wò kí wọ́n tó gbà wọn síṣẹ
Ohun to sọ naa ni pe awọn ọdaran kan n fi ijijagbara boju lati ṣe iṣẹ ibi.
Gbajabiamila ko tabuku ijijagbara, bẹẹ ni ko si sọ pe awọn to n jija gbara ko yatọ si Boko Haram,'' Lasisi lo sọ bẹẹ.
Suicide Prevention: ìwọ́de yìí wáyé láti gbógun ti pípa ara ẹni
Prison Break in Nigeria: Ka nípa iye ìgbà tí ikọlu wáyé láwọn ọgbà ẹwọn Nàìjíríà
Oríṣun àwòrán, @others
Ikọlu sawọn ọgba ẹwọn Naijiria ko jẹ tuntun.
Bi iṣẹlẹ yi ṣe n waye ni lemọlemọ jẹ ohun to n kọ awọn ọpọ lominu.
Lootọ ijọba a maa sọ pe awọn ko ni foju ẹlẹ wo awọn to ba ṣe ikọlu si ọgba ẹwọn sugbọn ko jọ pe awọn araabi ka ihalẹ yi kun.
Ikọlu kan waye laipẹ yi ni ọgba ẹwọn to wa ni Kabba nipinlẹ Kogi nibi ti awọn okere tan ẹlẹwọn ojilerugba sa mọ awọn alaṣẹ lọwọ.
Ikọlu yi la gbọ pe awọn agbebọn ṣe si ọgba ẹwọn naa.
Yatọ si ikọlu yi, ẹ jẹ ka wo awọn miran to ti waye ṣaaju ni Naijiria.
Jẹ́ ká lọ sílu mi: Kò sí ìtàn Ibadan láìsí Efunsetan, Òkè méje, Bower's Tower àtàwọn ǹkan
Ikọlu si ọgba ẹwọn Bauchi
Ikọlu yi waye lọjọ Keje oṣu Kẹsan ọdun 2010 nigba tawọn agbebọn aadọta kọlu ọgba ẹwọn to wa ni Bauchi.
Wọn fura si pe awọn ọmọ ikọ agbesunmọmi Boko Haram lo ṣe ikọlu yi.
Awọn ẹlẹwọn 721 lo ribi salọ, wọn pa marun un ninu wọn ti mẹfa si farapa.
Femi Falana: Mẹ̀kúnnù gbọ́dọ̀ ṣetán láti gba ẹ̀tọ́ wọn, ìjọba ti kùnà lórí ẹ̀tọ́ ọmọnìyàn
Ikọlu ọgba ẹwọn Ogun
Ni ọjọ Kẹrin oṣu kini ọdun 2013 iroyin gbode pe awọn kan ṣe ikọlu si ọgba ẹwọn Sagamu Minimun Prisons.
A ko ri aridaju awọn to wa nidi isẹlẹ yi amọ awọn ẹlẹwọn ogun ribi salọ ti ọpọ oṣiṣẹ ẹlẹwọn si farapa.
Suicide Prevention: ìwọ́de yìí wáyé láti gbógun ti pípa ara ẹni
Ikọlu si ọgba ẹwọn Ondo.
Awọn afurasi adigunjale ni wọn fura si pe o wa nidi ikọlu yi.
Lọgbọnjọ, oṣu Kẹfa, ọdun 2013 si lo waye.
Ninu ikọlu ọgba ẹwọn Olokuta Medium Security Prison to wa ni Akure, awọn aadọta agbebọn lo ṣe iṣe aburu yi.
Oloye Peter Fatomilola: Ọjọ̀gbọ́n olùkọ́ni ni Jesu àti Orunmila jẹ́, àwòkọ́ṣe sí rere si n
O kere tan awọn ẹlẹwọn 175 lo ribi salọ.Eeyan meji ku ti ẹnikan si fara pa.
Ọgba ẹwọn Eko naa faragba ikọlu.
Lọjọ Kẹwaa, oṣu kẹwaa,  2014 ni Eko faragba ikọlu si ọgba ẹwọn to wa Kirikiri.
Awọn ẹlẹwọn ogun lo ba ikọlu yi lọ ti awọn farapa si to ọgọrin.
O ṣeni laanu pe awọn mejila ribi salọ ninu wọn.
Ijesha tennager police death: O yẹ kí wọ́n máa yẹ ọpọlọ ọlapàá wò kí wọ́n tó gbà wọn síṣẹ
Ikọlu ọgba ẹwọn Kogi
Ninu oṣu kọkanla, ni ikọlu waye si ọgba ẹwọn ijọba apapọ to wa ni Kotonkarfe ni ipinlẹ Kogi.
Afurasi ọmọ ikọ Boko Haram ni wọn lo ṣe iṣẹ yi.
Awọn ẹlẹwọn mẹrinlelogoje  lo sa mọ awọn agbofinro lọwọ nigba ti wọn si ri ọkan pa ninu wọn.
Ikọlu ọgba ẹwọn Ekiti
Ni ọgbọn ọjọ, oṣu Kọkanla ni ikọlu waye ni ọgba ẹwọn ijọba apapọ to wa ni Ado Ekiti.
Oṣiṣẹ ọgba ẹwọn kan ba iṣẹlẹ yi lọ.
Ni meni meji wọn ka ẹlẹwọn ọọdunrun le mọkanlelogoji to sa lọ.
Abiodun Duro Ladiipo, Moremi: Ǹ kò pé '40' ti Bàbá fi papòdà ṣùgbọ́n mo kọ̀ láti 'remarry'
Ikọlu  ọgba ẹwọn Minna
Ọjọ Kẹfa, oṣu Kejila ni awọn adigunjale kọlu ọgba ẹwọn yi to wa ni Minna olu ilu ipinlẹ Niger.
Wọn pa agbofinro kan,awọn ẹlẹwọn ọtalenigba le mẹwaa si ribi sa lọ
Ikọlu ọgba ẹwọn Kuje
Ni olu ilu Naijiria Abuja ni ikọlu yi ti waye ni ọgba ẹwọn to wa ni Kuje lọjọ Kẹrinlelogun, oṣu Kẹjọ, 2016.
Awọn ogbologbo ẹlẹwọn meji Solomon Amodu ati Maxwell Ajukwu ribi fo igana salọ.
Saaju ni ọjọ kọkandinlọgbọn, osu Kẹjọ, ọdun 2016 yi kanna ni awọn kan gbiyanju lati kọlu ọgba ẹwọn Kuje.
Lóòtọ́ orin mi àti Lagbaja jọra ṣùgbọ́n ìyàtọ̀ díẹ̀ wà níbẹ - Labule
Edo
Lọjọ Kọkandilogun, oṣu Kẹwaa, ọdun 2020 awọn kan to sa sabẹ pe awọn n se iwọde ENDSARS
Kogun ja ọgba ẹwọn to wa ni Benin.
Bẹẹ naa ni wọn yabo ọgba ẹwọn to wa ni Oko.
Lapapọ, ẹlẹwọn ẹgbẹrun meji din mẹsan lo salọ lawọn ọgba ẹwọn wọn yi
N kò lè ṣe gẹ́gẹ́ bí ọkùnrin, ṣùgbọ́n n kò mọ̀ títí tí mo fi ṣe ìgbéyàwó
Ikọlu ọgba ẹwọn Owerri
Lọjọ karun un, osu Kẹrin, ọdun  2021, awọn kan ti wọn fura si pe wọn jẹ ọmọ ikọ alaabo ilẹ Igbo, Eastern Security Network(ESN) se ikọlu si ọgba ẹwọn to wa ni Owerri.
Ado oloro ni wọn lo lasiko ikọlu yi.
O le ẹgbẹrun kan aabọ ẹlẹwọn to ribi sa ninu ikọlu yi.
Kola Tubosun: Ọ̀pọ̀ ọmọ òyìnbó ló ń kọ́ èdè Yorùbá, ẹ̀yin ọ̀dọ́ ẹ gbé èdè abínibí lárugẹ
Fani Kayode defects to APC: Sheikh Gumi ní Judasi ìran Yorùbá ni Fani-Kayode
Oríṣun àwòrán, Instagram/Real FFK
Ọpọ eeyan papaa julọ lagbo oṣelu lo n ti  n bẹnu ẹtẹ lu eekan oṣelu, Oloye Femi Fani-Kayode lori bi o ti fi ẹgbẹ oṣelu PDP lọ darapọ mọ APC ni Ọjọbọ.
Koda awọn onimọ nipa ẹsin gan an ko gbẹyin ninu awọn to koro oju si igbesẹ Fani-Kayode.
Ọkan lara awọn eeyan bẹẹ ni onimọ nipa ẹsin musulumi, Sheikh Ahmad Abubakar Gumi.
Gumi ni Judasi iran Oduduwa ni Fani-Kayode pẹlu igbesẹ rẹ to mu fi ẹgbẹ oṣelu PDP silẹ lọ APC.
Aarẹ Muhammadu Buhari fun ra rẹ lo tẹwọ gba Fani-kayode nile iṣẹ ijọba niluu Abuja ni Ọjọbọ.
Femi Falana: Mẹ̀kúnnù gbọ́dọ̀ ṣetán láti gba ẹ̀tọ́ wọn, ìjọba ti kùnà lórí ẹ̀tọ́ ọmọnìyàn
Sheikh Gumi ṣalaye pe Fani-Kayode ko ọrọ to sọ lọdun 2018 jẹ lẹyin to sọ nigba naa pe o san ki oun ku ju ki oun darapọ mọ ẹgbẹ APC tabi tẹ fun Buhari lọ.
Suicide Prevention: ìwọ́de yìí wáyé láti gbógun ti pípa ara ẹni
Gumi ni oun ko ka ọrọ Fani-Kayode kun mọ tipẹ tori oun mọ pe ọdalẹ eeyan ni.
Gumi fọrọ yii lede loju opo Facebook rẹ lẹyin ti Fani-Kayode darapọ mọ APC tan l'Abuja.
Ẹ̀mí Ọlọ́run ló darí mi láti darapọ̀ mọ́ ẹgbẹ́ òṣèlú APC - Femi Fani-Kayode
Minisita eto irina ofurufu tẹlẹ lorilẹede Naijiria, Femi Fani-Kayode ti pada darapọ mọ ẹgbẹ oṣelu to n jọba lọwọlọwọ, All Progressives Congress.
Oloye Peter Fatomilola: Ọjọ̀gbọ́n olùkọ́ni ni Jesu àti Orunmila jẹ́, àwòkọ́ṣe sí rere si n
Alaga igbimọ majẹobajẹ ẹgbẹ APC ati gomina ipinlẹ Yobe, Mail Mala Buni lo faa le aarẹ Buhari lọwọ l'Ọjọ Isegun, ọjọ kẹrindinlogun oṣu kẹsa nile aarẹ l'Abuja.
Ikede naa n jade lẹyin oṣu bii melo kan to sabẹwo ati ipade pẹlu awọn gomina ẹgbẹ oṣelu APC kan.
Oríṣun àwòrán, Tolu Ogunlesi
Lonii nile ijọba ni Avuja, eeyan kan wa darapọ mọ ẹgb oṣelu APC. Aarẹ to jẹ ololufẹ gbogbogbo si ti tẹwọ gbaa tọwọ-tẹsẹ. Nitoripe, bi Buhari ṣe ri lẹ ri yẹn. Eyi ni oluranlọwọ aarẹ, Tolu Ogunlesi fi sita.
"Ẹwẹ, oloye ẹgbẹ oṣelu Peoples Democratic Party tẹlẹ yii sọ pe ""ẹmi Ọlọrun"" lo dari oun lati ṣepinnu lilọ darapọ mọ ẹgbẹ to wa lori alefa."
Minisita tẹlẹ yii ni oun yoo ṣeranwọ lati kọ orilẹede Naijiria.
Ṣaalu nigba kan sẹyin ni FFK gẹgẹ bi inagijẹ́ rẹ bu ẹnu atẹ lu iroyin to fo kiri pe o ti darapọ mọ APC lẹyin ti aworan to ya pẹlu awọn gomina APC bọ sori ayelujara.
Abiodun Duro Ladiipo, Moremi: Ǹ kò pé '40' ti Bàbá fi papòdà ṣùgbọ́n mo kọ̀ láti 'remarry'
Ki Ọgbẹni Fani-Kayode to lọ darapọ mọ ẹgbẹ oṣelu APC, o jẹ gbajumọ alatako si ijọba ati ẹgbẹ oṣelu APC.
Ẹ wo lara awọn oko ọrọ to ti sọ nipa ẹgbẹ oṣelu naa tẹ́lẹ́:
Lakọkọ o ni irọ nla gbaa ni pe wọn ni oun darapọ mọ ẹgbẹ oṣelu APC to si ni o san ki oun ku ju ki oun darapọ mọ awọn oloorun lọ.
Oríṣun àwòrán, Screenshot
Femi Fani Kayode tun pe APC ni mujẹ-mujẹ, ẹni ègún, olubaṣe Boko Haram, Fulani Daradaran, apaayan lọwọọwọ, a pa iran rẹ, onija ẹsin, ololufẹ maalu, ole, atu ilu ka ati bẹẹ bẹẹ lọ ninu aduru ọrọ to sọ.
Oríṣun àwòrán, Screenshot
Ọpọlọpọ ọmọ Naijiria lo n fi ero ọkan wọn han lori ayelujara nipa bi FFK ṣe darapọ mọ ẹgbẹ oṣelu APC.
Bi o ṣe n ya awọn kan lẹnu pe ki lo sun un de 'bẹ gan lati darapọ mọ ẹgbẹ ti ẹkẹ eebu rẹ kii ṣi lara wọn, lawọn mii n beere pe talo kan ti yoo tun kuro ni ẹgbẹ alatako, PDP.
Oríṣun àwòrán, Screenshot
Oríṣun àwòrán, Screenshot
Ọkùnrin tó lẹ ''Super Glue'' mọ́ ǹkan ọkùnrin rẹ̀ láti rọ́pò ''condom'' ti dèrò ọ̀run
Wo iye ìgbà tí bàálù ìjagun ti já tó sì ṣekú pa àwọn ènìyàn ní Nàìjíríà
''APC yóò fún Goodluck Jonathan ní ànfàní láti dupò ààrẹ lọ́dún 2023 tó bá darapọ̀ mọ́ wa''
''Ìjọba, ẹ má da àwa tó ń ṣagbátẹrù Yorùbá Nation pọ̀ mọ́ IPOB''
Mi ò sọ pé àwọn tó ń pè fún Yorùbá Nation kò yàtọ̀ sí Boko Haram o- Gbajabiamila ṣàlàyé
Oríṣun àwòrán, Screenshot
Oríṣun àwòrán, Screenshot
Oríṣun àwòrán, Screenshot
Sunday Igboho trial: Ìjọba àpapọ̀ yarí pé kò sí N20bn kankan fún Igboho, ó yá nílé ẹjọ́
Oríṣun àwòrán, OTHERS
Ọrọ ti di isọrọ n gbesi laarin ijọba apapọ ati ẹgbẹ ajafẹtọ ọmọ Yoruba, Ilana Ọmọ Oodua to ti n ja fun idalare ajafẹtọ Yoruba, Sunday Igboho fun igba diẹ bayii.
Ni ti Ilana Ọmọ Oodua, wọn ti fi ọrọ sita lati ṣapejuwe idajọ ti ile ẹjọ da fun nipa ikọlu ti ajọ DSS ṣe si ile Sunday Igboho n'Ibadan ati gbogbo nkan to bajẹ to fi mọ ẹmi awọn eeyan to ba iṣẹlẹ naa rin pe ẹjọ naa ṣafihan pe imọlẹ ti tan si ọrọ to wa nilẹ o si ti fi otitọ han.
Ẹjọ to jẹ jade ni ile ẹjọ giga ipinlẹ Oyo eyi ti adajọ Ladiran Akintola dari ni pe ki ijọba san biliọnu lọna ogun naira owo gba mabinu fun ọṣẹ ti ajọ DSS ṣe si ile Igboho ni ọjọ kini oṣu keje ọdun 2021.
Amọ lọjọ yii kan naa ni ijọba apapọ ti fi atẹjade tiwọn da esi pada pe ko tan sibi idajọ ti ile ẹjọ giga ilu Ibadan da rara o, ile ẹjọ kotẹmilọrun lo kan.
Agbẹjọro agba fun ijọba, Abubakar Malami lo kede ipinu ijọba apapọ lati pe ẹjọ kotẹmilọrun nigba to n ba awọn oniroyin sọrọ ni Abuja.
Malami ni akitiyan ti n lọ lọwọ fun igbesẹ pipe ẹjọ kotẹmilọrun naa.
Ni ti Ẹgbẹ Ilana Omo Oodua eyi ti Ọjọgbọn Banji Akintoye n dari, wọn dupẹ fun ọna ti ile ẹjọ gba da ẹjọ naa wọn si ni ṣe ni ki ijọba bọwọ fun ofin ki wọn si san N20bn naa lai fi akoko ṣofo rara.
Ni idahun si gbogbo ẹri ti agbẹjọro Sunday Igboho, Yomi Aliyu mu wa, Malami ni ko si aridaju kankan niwaju ile ẹjọ pe ẹjẹ ti wọn ri ninu fidio ti wọn wo jọ ẹjẹ ọmọ eniyan atipe ile ti wọn fihan ninu fidio ọhun gan ko si aridaju pe ti Igboho ni.
O wa fọhun pe ki ile ẹjọ wọ ẹri ati gbogbo ipẹjọ wọn danu.
Agbẹjọro ajọ DSS, Ọgbẹni T.A Nurudeen ni aridaju gbudọ wa latọdọ dokita onimọ nipa ẹjẹ lati ṣafihan pe lootọ ẹjẹ eeyan ni wọn ri ninu fidio naa.
Bakan naa, Nurudeen naa ṣafihan fidio kan fun ile ẹjọ nibi ti wọn fẹsun kan Sunday Igboho pe o n dẹru bolẹ lati da Oduduwa Republic silẹ to si n rọ awọn Yoruba lati di ara lamure pẹlu oogun ati ibọn.
Ẹwẹ, lasiko to n ka idajọ rẹ, adajọ Ladiran Akintola ni ilana ti ajọ DSS lo lati lọ si ile Sunday Igboho lasiko ti iṣẹlẹ naa ṣẹ ko ki n ṣe ti ẹni to mọ iṣẹ.
Iléẹjọ́ ti ní kí ìjọba Nàìjíríà san ogún bílíọ̀nù fún Sunday Igboho gẹ́gẹ́ bí owó gbà má bínú!
Pẹlu ariwo ayọ ni awọn ololufẹ Oloye Sunday Igboho fi idunnu han ni isinyii ni ile ẹjọ ni Ibadan.
Adajo ile ẹjọ giga ni ilu Ibadan nibi ti Sunday Igboho ti pe ẹjọ yii tako ajọ DSS ati ijọba apapọ lo ti waye.
Ogun bilionu naira ni Adajo Ladiran Akintola ti ni ki ijoba san fun Sunday Igboho gege bii owo gba ma binu
Oríṣun àwòrán, Others
Lónìí ni ìdájọ́ yóò wáyé lórí N5.5b tí Sunday Igboho bèèré lẹ́yìn ìkọlù DSS sílé rẹ̀
"Idajọ lori ẹjọ oni N500bilionu fun ile re ati awon ohun ini re ti won baje ati 500 milionu fun awon nkan ara re ti Oloye Sunday Adẹyẹmọ ti gbogbo eeyan mọ si ""Sunday Igboho""."
O pe ẹjọ naa tako ijọba apapọ nipasẹ ileeṣẹ ọtẹlẹmuyẹ DSS yoo waye lonii nile ẹjọ giga to n bẹ nilu Ibadan, olu ilu ipinlẹ Ọyọ.
Agbẹjọro fun Sunday Igboho, Yọmi Aliyu lo ti n le iwaju igbẹjọ naa lẹyin ikọlu ti ajọ DSS ṣe si ile ajafẹtọmọniyan naa to n bẹ ni agbegbe Soka ilu Ibadan.
Ọjọ kinni, oṣu kẹje, ọdun 2021 yii ni iṣẹlẹ ọhun waye nibi ti ọpọlọpọ dukia ati ẹmi eeyan meji ti ṣofo.
Ọkanojọkan iwadii lo ti waye saaju asiko yii lati igba ti igbẹjọ naa bẹrẹ, ṣugbọn lonii ni igbẹjọ naa yoo yọri.
Gbogbo bo ba se n lọ nibẹ lonii ni BBC Yoruba yoo maa muwa si oju opo yin.
Guinea coup: ECOWAS f'òfin de àwọn ológun tó dìtẹ̀ gbàjọba ní Guinea
Oríṣun àwòrán, Yemi Osinbajo
Awọn adari ajọ ECOWAS ti fofin de awọn ologun to ditẹ gbajọba ni orilẹede Guinea ati ẹbi wọn lati maa le rinrin ajo kuro lorilẹede naa lọ si ibikan.
Ọpọ lo ti n reti ikede igbesẹ yii lẹyin ti awọn ologun doju ijọba alagbada bolẹ tan nibẹ.
Ajọ ECOWAS ti wa fun ijọba ologun ni oṣu mẹfa lati da ijọba pada fun alagbada.
Awọn ologun doju ijọba Aarẹ Alpha Condé bolẹ lori ẹsun iwa ibajẹ lẹyin to wọle idibo aarẹ fun saa kẹta.
Jẹ́ ká lọ sílu mi: Kò sí ìtàn Ibadan láìsí Efunsetan, Òkè méje, Bower's Tower àtàwọn ǹkan
Ajọ ECOWAS tun fofin de Guinea ninu igbimọ alaṣẹ ajọ naa titi digba tawọn ologun yoo fi da ijọba pada fawọn alagbada.
Ijesha tennager police death: O yẹ kí wọ́n máa yẹ ọpọlọ ọlapàá wò kí wọ́n tó gbà wọn síṣẹ
Ilu Accra ti ṣe olu ilu Ghana lawọn olori orilẹede ajọ ECOWAS ti ṣe ti ṣe ijiroro nibi ti wọn ti gbe awọn igbesẹ yii.
Femi Falana: Mẹ̀kúnnù gbọ́dọ̀ ṣetán láti gba ẹ̀tọ́ wọn, ìjọba ti kùnà lórí ẹ̀tọ́ ọmọnìyàn
FG vs resident doctors: Ilé ẹjọ́ kòtẹ́milọ́rùn ni yóò parí ọ̀rọ̀ yìí -Ẹgbẹ́ àwọn Dókítà Naijiria
Oríṣun àwòrán, NARD
Ẹgbẹ awọn dokita ti fesi si aṣẹ ti ile ẹjọ pa lọsan ọjọ Ẹti pe ki wọn pada sí ẹnu iṣẹ wọn ki wọ́n si pada lọ se ipade pẹlu ijọba lórí ẹ̀hónú wọn.
Wọn ni awọn ti ṣetan lati gbe ẹjọ naa lọ si ile ẹjọ ko tẹmi lọrun, ẹgbẹ awọn dokita ni awọn ti jẹ ki agbẹjọro ẹgbẹ naa mọ pe awọn yoo pe idajọ ile ẹjọ nija lati lọ si ile ẹjọ kotémilọrun ati pe ọmọ ẹgbẹ kankan ko ni pada si ẹnu isẹ.
Ikede yii waye ninu atẹjade kan ti aarẹ awọn ọmọ ẹgbẹ dokita Dokita Uyilawa Okhuaihesuyi ati akọwe ẹgbẹ naa Dokita Jerry Isogun jùmọ̀ fọwọ si lonii.
O ni awọn ti bẹrẹ igbesẹ gbigbe ẹjọ naa lọ si ile ẹjọ kotẹmilọrun.
Ayo Ewebiyi Mama Oriki: Ọwọ́ Òbí, Ìjọba àti àwọn Ọba ni ìdágbàsókè Yorùbá wà lásìkò yìí
"'' Gẹgẹ bi a se mọ, paapa julọ awọn to wa ni ile ẹjọ lonii nibi ti ile ẹjọ to n gbọ ẹjọ osisẹ ti pasẹ lori ẹjọ ti ijọba apapọ ati ẹgbẹ awọn dokita pe, idajọ naa ko tẹ wa lọrun """
 Lẹyin ti a fi ikuluku pẹlu agbẹjọro wa, ati ni ki o pe ẹjọ kotẹmilọrun  ki o si pe fun ki idajọ naa duro titi wọn yoo fi pe ẹjọ.
Saaju ni oni yii ni ile ẹjọ ti ni ki awọn dokita ile iwosan ijọba pada si ẹnu iṣẹ ninu idajọ ti Adajọ Bashar Alkali ṣe pe ki wọn pada si ẹnu isẹ
Ile- ẹjọ to n gbọ awuye-wuye Lori iyanselodi  laarin  ijọba apapọ  (Nigeria Industrial court) ati ẹgbẹ awọn dokita lorile ede Naijiria ti paa laṣẹ pe ki wọn  pada sẹnu ise wọn ni kiakia.
Abiodun Duro Ladiipo, Moremi: Ǹ kò pé '40' ti Bàbá fi papòdà ṣùgbọ́n mo kọ̀ láti 'remarry'
Ki wọn si bere ise wọn leye o-sọka
Bakan naa, ni ile -ejo tun paa lase pe ki egbe awon dokita ati ijoba lo fori-kori Lati yanju aawọ to wa laarin wọn ni itubi-inubi.
Bakan naa,ni ile -ẹjọ tun ni ki awọn agbejọrọ ijọba ati ẹgbẹ awọn dọkita lo forikori, ki wọn si mu ojo ti wọn yoo pada wa sile ẹjọ
Adajo Basha.A.Alkali  lo dajo bẹẹ pe ki awon dokita pada senu ise won ni kiakia
Femi Aborisade to be agbẹjọro fun ẹgbẹ awọn dokita to gun le iyanselodi ti ni awọn yoo forikori pẹlu awọn onibara wọn, iyen ẹgẹe awọn dokita boya wọn yoo tesiwaju nibi ẹjọ to wa nile ẹjọ kotẹmilọrun, tabi ki wọn fopin si iyanselodi ohun
Oríṣun àwòrán, Chris Ngige
Oni ni ile ẹjọ to n ri si ọrọ awọn oṣiṣẹ ati ileeṣẹ, NIC niluu Abuja yoo ṣe idajọ lori awuyewuye owo oṣu ati owo ajẹmọnu awọn dokita ati ijọba apapọ.
Oloye Peter Fatomilola: Ọjọ̀gbọ́n olùkọ́ni ni Jesu àti Orunmila jẹ́, àwòkọ́ṣe sí rere si n
Adajọ Bashar A. Alkali sun igbẹjọ naa si ọjọ Ẹti oni lasiko igbẹjọ to waye ni Ọjọru.
Awọn dokita ti n yanṣẹlodi lati ọsẹ meloo kan bayii lati fẹhonu han lori owo ti wọn ni ijọba n jẹ awọn.
Agbẹjọro ẹgbẹ awọn dokita, Femi Falana (SAN) ti kọkọ sọ pe ile ẹjọ naa ko lagbara to lati gbọ ẹjọ naa.
Ṣugbọn aggbẹjọro ijọba apapọ, Tochukwu Maduka, ni ko si ọrọ ninu ohun ti Falana n sọ.
Jẹ́ ká lọ sílu mi: Kò sí ìtàn Ibadan láìsí Efunsetan, Òkè méje, Bower's Tower àtàwọn ǹkan
Falana tun rọ ile ẹjọ pa ko paṣẹ wi pe ki ijọba ati ẹgbẹ awọn dokita pada lọ jiroro lori ati yanju ọrọ owo to da wahala silẹ.
Awon Dokita ti wa nile ẹjọ bayii niluu Abuja fun idajọ lori ọrọ naa.
Awon agbẹjọro to n ṣoju fun ẹgbẹ awon dokita ile iwosan ati aṣoju ẹgbẹ awọn dokita ile iwosan orile ede Naijiria si ti n fori kori.
Bestiality: Ọkùnrin kan dèrò àtìmọ́lé ọlọ́pàá lórí ẹ̀sùn ìbálòpọ̀ pẹ̀lú ewúrẹ́
Oríṣun àwòrán, Ewurẹ
Aye ti wa di oju keji bayii o. Ọkunrin kan, ẹni ọdun marundinlọgbọn, Nasiru Muhammad ti dero atimọle ọlọpaa lori ẹsun pe o ni ibalopọ pẹlu ewurẹ.
Agbẹnusọ ileeṣẹ ọlọpaa ipinlẹ Jigawa, ASP Lawan Shiisu ṣalaye pe ni ijọba ibilẹ Gwaram ni iṣẹlẹ ọhun ti ṣẹlẹ.
ASP Shiisu ṣalaye pe nigba tawọn ọlọpaa n kaakiri ilu Gwaram ni ọwọ tẹ Muhammad lagbegbe Kunnadi.
''Ni ọjọ kẹsan an oṣu kẹsan an ọdun 2021 lawọn ọlọpaa ri ọmọkunrin ọdun mẹẹdọgbọn yii nibi ti o ti n ba ewurẹ sun.
Nibẹ naa ni awọn ọlọpaa ti fi ọwọ ofin mu un.
Femi Falana: Mẹ̀kúnnù gbọ́dọ̀ ṣetán láti gba ẹ̀tọ́ wọn, ìjọba ti kùnà lórí ẹ̀tọ́ ọmọnìyàn
Muhammad wa ni atimọle ọlọpaa bayii nigba ti iwadii si n lọ lọwọ lori ọrọ naa.
Ọkunrin naa yoo foju ba ile ẹjọ lẹyin ti iwadii ba ti pari lori iṣẹlẹ ọhun,'' agbẹnusọ ileeṣẹ ọlọpaa ipinlẹ Jigawa lo sọ bẹẹ.
Suicide Prevention: ìwọ́de yìí wáyé láti gbógun ti pípa ara ẹni
ASUU Strike 2021: Ìyanṣẹ́lódì míràn kò ní pẹ́ bẹ̀rẹ̀ àyàfi tí Ijọba àpapọ̀ bá....- ASUU
Oríṣun àwòrán, @Others
Ẹgbẹ awọ̣n olukọ Fasiti ni Naijiria, ASUU ti kilọ wi pe o ṣeeṣe ki awọn bẹrẹ iyanṣelodi miran laipẹ.
Eyi ko ṣẹyin aimu adehun ti ijọba apapọ ṣe pẹlu awọn ẹgbẹ olukọ ṣẹ lati nkan bi osu mẹwaa sẹyin.
Oṣu kejila, ọdun 2020 ni ẹgbẹ oṣiṣẹ ASUU wọgile iyanṣẹlodi ti wọn gunle lẹyin ti ijoḅa apapọ ṣeleri lati ṣe agbeyẹwo gbogbo ibeere wọn ḷowọ ijọba.
Adari ẹka ẹgbẹ ASUU ni Benin, Ọjọgbọn Fred Esumeh lo sọ ọrọ yii lasiko to n ba awọn oniroyin sorọ wi pe o ṣeese ki iyanṣẹlodi miran bẹrẹ ni awọn ileewe fasiti kaakiri ni Naijiria nitori aibikita ijọba apapọ.
Esumeh ti ko sọ igba ti iyanṣẹlodi naa ma gberasọ sọ wi pe  awọn n duro de abajade ipade pẹlu awọn adaari gbogboogbo ninu ẹgbẹ ASUU lati mọ igbesẹ ti awọn yoo gbe.
Abiodun Duro Ladiipo, Moremi: Ǹ kò pé '40' ti Bàbá fi papòdà ṣùgbọ́n mo kọ̀ láti 'remarry'
Ọdun 2020 ni Osu Kẹta ni awọn olukọ fasiti gunle iyansẹlodi nitori igbesẹ ijọba apapọ lori asunwon owo awọn oṣiṣẹ, to fi mọ awọn abuku to wa kaakiri awọn fasiti ni Naijiria.
Amọ, ẹgbẹ ASUU ni titi di asiko yii ijọba ko tii gbe igbese kankan lati parọ asuwọn owo IPPIS ṛe pẹlu asuwọn ibi ikọwopamọsi fun awọn Fasiti, ti wọn pe oruko rẹ ni ''University Transparency and Accountability Solution ''.
Wọn ni ijọba apapọ mọọmọ se ifaṣẹyin nipa mimu ileri wọn ṣe nipa asunwọn owo University Transparency and Accountability Solution naa.
Bakan naa ni ijọba kọ lati san awọn ọmọ ajẹmọnu fun ẹka eto ẹkọ ni fasiti naa.
Jẹ́ ká lọ sílu mi: Kò sí ìtàn Ibadan láìsí Efunsetan, Òkè méje, Bower's Tower àtàwọn ǹkan
Kikọ lati fi iye owo to to ogoji bilionu naira silẹ lati fi tun awọn fasiti gbogbolowo ṣe.
Ẹwẹ, ẹgbẹ ASUU nipinlẹ Plateau ti fẹsun kan ijọba ipinlẹ naa labẹ aṣẹ ijọba gomina Simon Lalong  jẹ awọn olukọ ni gbese ̣ni osu mẹrin odun 2020.
Suicide Prevention: ìwọ́de yìí wáyé láti gbógun ti pípa ara ẹni
Bakan naa ni ijọba kuna lati gbe igbesẹ lori kikọ awọn ile igbe, iyẹn staff quarters fun awọn olukọ ni awọn ileewe fasiti, ni ipinlẹ naa.
Nursing and Midwifery Council of Nigeria: Nàìjiíríà pẹ́lù ibi ti àwọn nọ́ọ̀sí wọn ti kúnjú òṣùwọ̀n jùlọ ní àgbáyé
Oríṣun àwòrán, others
Akọwe agba ajọ Nursing and Midwifery Council of Nigeria, Dr Faruk Abubakar ti ni o kere tan ẹgbẹrun meje awọn nọọsi ni wọn n kuro lorilẹede Naijiria lọ si ibomiran ni ọdọọdun.
Abubakar ni eyi fihan gbangba pe awọn nọọsi lorilẹede Naijiria pẹlu awọn to lamilaaka, ti wọn si mọ iṣẹ wọn ni iṣẹ kaakiri agbaye.
Ni ipinlẹ Delta ni Abubakar ti sọ ọrọ yii lasiko to n gba awọn nọọsi ti wọn ṣẹṣẹ ṣe idanwo abajade tan ni iyanju nipinlẹ naa.
Abubakar ni o pọn dandan ki awọn nọọsi tẹ ipa mọ iṣẹ wọn, ki idagbasoke tunbọ ma a ba wọn lẹnu iṣẹ lai ni ifasẹyin.
Sabaa Akintola: Pẹ̀lú ẹsẹ̀ kan, mo le gun kẹ̀kẹ́, lúwẹ̀ẹ́ tàbí rán aṣọ pẹ̀lú ẹ̀kọ́ dókítà
Eyi ko ṣẹyin bi awọn onimọ ni ẹka eto ilera kaakiri Naijiria ṣe n fi orilẹede naa silẹ lọ si ibomiran nitori aiṣedede ijọba apapọ si wọn, ti wọn ko san owo oṣu wọn deede ati aipese awọn ohun elo ti wọn nilo lati ṣe iṣẹ wọn bi iṣẹ.
Jẹ́ ká lọ sílu mi: Kò sí ìtàn Ibadan láìsí Efunsetan, Òkè méje, Bower's Tower àtàwọn ǹkan
Amọ, kọmiṣọnna fun eto ilera nipinlẹ Delta, Dokita Ononye bu ẹnu atẹ lu bi awọn nọọsi ṣe n kuro ni Naijiria ni ọgọọrọ lọ si awọn orilẹede miran
Ononye ni ti ijọba ko ba bojuto ọrọ yii ni kiakia, nkan yoo tunbọ bajẹ si ni ẹka eto ilera ni Naijiria.
Abiodun Duro Ladiipo, Moremi: Ǹ kò pé '40' ti Bàbá fi papòdà ṣùgbọ́n mo kọ̀ láti 'remarry'
''O ṣeeni laanu wi pe awọn nọọsi ati dokita ti wọn gba ẹkọ ni Naijiria ni owo perete wa n kuro lorilẹede naa lọ si ibomiran lati lo lo imọ wọn fun awọn ibi ti wọn lọ tẹdo si.''
Oloye Peter Fatomilola: Ọjọ̀gbọ́n olùkọ́ni ni Jesu àti Orunmila jẹ́, àwòkọ́ṣe sí rere si n
''Eleyii jẹ ibanujẹ ọkan fun awọn adari ni ẹka eto ilera lorilẹede Naijiria nitori eto ilera ti mẹhẹ sibẹ tẹlẹ.''
Ijesha tennager police death: O yẹ kí wọ́n máa yẹ ọpọlọ ọlapàá wò kí wọ́n tó gbà wọn síṣẹ
Kọmisọnna fun eto ilera nipinlẹ Delta wa rọ awọn nọọsi naa lati tẹpa mọ iṣẹ wọn, ki ijọba naa si gbiyanju lati mu igbega ba eto ilera ni Naijiria.
Femi Falana: Mẹ̀kúnnù gbọ́dọ̀ ṣetán láti gba ẹ̀tọ́ wọn, ìjọba ti kùnà lórí ẹ̀tọ́ ọmọnìyàn
Climate Change: Wo ìpalára tí ojú ọjọ́ gbígbóná ń ní lára èèyàn
Ni ọdun 1980 si 2009, igba mẹrinla laarin ọdun ni oju ọjọ gbigbona to 50C ma n waye,amọ o ti da igba mẹrindinlọgbọn
Iwadii ti fihan pe oju ọjọ to n gbona lagbaye ti n goke si kaakiri orilẹede lagbaye.
Oju ọjọ to kọja 50C(122F) ti peleke si ni ida meji ju ti igba aye atijọ ni nkan bi ọdun 1980.
Bakan naa ni oju ọjọ gbigbona yii ti wa n ṣẹlẹ kaakiri awọn orilẹede lagbaye ju ti tẹlẹ lọ.
Ni ọdun 1980 si 2009, igba mẹrinla laarin ọdun ni oju ọjọ gbigbona to 50C ma n waye.
Amọ ni bayii, igba mẹrindinlọgbọn ninu ọdun kan ni oju ọjọ gbigbona jainjain ti ru soke si lati ọdun 2010 si ọdun 2019.
Bakan naa ni o ma n to ọsẹ meji nigba miran ti oju ọjọ gbigbona fi ma n wa ni 45C tabi ju bẹẹ lọ laarin ọdun.
Onimọ nipa ọrọ oju ọjọ ni fasiti Oxford ni ilu London, Dr Friederikw Otto ni oju ọjọ gbigbona yii ko ṣẹyin awọn ohun elo ti wọn fi n ṣe epo bẹntirol ti wọn n lo ninu ọkọ lo fa eyi.
Otto ni gbogbo agbaye lo wa ninu ewu oju ọjọ gbgbona to kọja keremi, paapaa lawọn orilẹede to wa ni gbungun agbaye at agbegbe Gulf pẹlu.
Ninu ọdun yii, orilẹ-ede Italy ni oju ọjọ gbigbona to to 48.8C, nigba ti Canada ni oju ojo to to 49.6C, to si ṣeeṣe ki awọn orilẹede miran ni ju bẹẹ lọ.
Awọn onimọ gba awọn to n ṣe epo bẹntirol nimọran lati mura ni kiakia lati fi opin si nitori ọrọ naa kan gbogbo agbaye.
Ipa wo ni oju ojo gbigbona yoo ni lara eniyan?
•Iwadii ileeṣẹ BBC fihan wipe oju ojo gbigbona le e fa ijamba fun agọ ara eniyan ati ọpọlọpọ ailera.
•ṣeeṣe ki awọn eniyan ni aisan ooru lati inu wa nitori oju ọjọ to gbona riri.
•Bakan naa ni oju ọjọ gbigbona n fa ki iyan mu ati awọn ina nla nla ni awọn agbegbe ti ko tii ṣẹlẹ ri.
•Awọn agbẹ naa yoo ni ipalara nitori ko ni si bi nkan ọgbin yoo ṣe dagba soke tabi gberu si nitori ilẹ gbigbẹ ati asalẹ.
ECOWAS f'òfin de àwọn ológun tó dìtẹ̀ gbàjọba ní Guinea
Ìyanṣẹ́lódì míràn kò ní pẹ́ bẹ̀rẹ̀ àyàfi tí Ijọba àpapọ̀ bá....- ASUU
Iléẹjọ́ ti ní kí ìjọba Nàìjíríà san ogún bílíọ̀nù fún Sunday Igboho gẹ́gẹ́ bí owó gbà má bínú!
Ẹ máa gbàá nìṣò, àwa Gómìnà ìhà Gúúsù f'ọwọ́ sí kí ìpínlẹ̀ má gba VAT
Wo iye ìgbà tí bàálù ìjagun ti já tó sì ṣekú pa àwọn ènìyàn ní Nàìjíríà
Femi Fani-Kayode Defection: Ọjọ́ to burú jùlọ nínú ìrìnàjò òṣèlú mi ni ọjọ́ ti FFK darapọ̀ mọ́ ẹgbẹ́ APC- Ojudu
Ọpọlọpọ ọmọ Naijiria ti n fọnmu lẹyin ti minisita eto irina tẹlẹri, Femi Fani Kayode kede ni ọjọ diẹ sẹyin pe oun n darapọ mọ ẹgbẹ oselu All Progressive Party (APC), ti olukuluku si n  bẹnu atẹ lu igbesẹ rẹ yii.
Oniruuru orukọ ni awọn eniyan ti fun pẹlu, eyi ko si ṣẹyin iru awọn nnkan to ti sọ nipa aarẹ Muhammadu Buhari ati ẹgbẹ oṣelu APC tẹlẹ.
Lẹyin bi ọjọ mẹta ti Femi Fani-Kayode ti kede Igbese yii, ti o si ya fọto pẹlu aarẹ Muhammadu Buhari ni Aso Rock, sibẹ awọn ọmọ Naijiria ko tii sinmi lori ọrọ rẹ.
Ninu ọpọ ariwisi awọn eniyan ninu awọn iwe iroyin lonii ni awọn miiran ti ṣalaye pe, Femi Fani kayode ti pada sinu eebi rẹ ati pe, o ti darapọ mọ awọn mẹjẹmẹjẹ to tikalara rẹ ti n pario awọn iwa aitọ ti wọn n wu gẹgẹ bi ẹgbẹ ati adari.
Ayo Ewebiyi Mama Oriki: Ọwọ́ Òbí, Ìjọba àti àwọn Ọba ni ìdágbàsókè Yorùbá wà lásìkò yìí
"Wọn ni o wu Kayode ki awọn eniyan maa pe ni awọn orukọ to ti n pe ẹgbẹ oselu naa tẹlẹ , bii ""apaniyan, ""ọmọ iparun"" ""alailojuti, iranṣẹ Boko Haram, alaini ibọwọ fun ẹsin ọmọlakeji ati bẹẹ bẹẹ lọ."
Wọn tun fi kun un pe Fani Kayode ni alailojuti ti ko si iru rẹ miran ni aye yii. ni kete ti foto rẹ jade si ori ayelujara nibi to ti duro pọ pẹlu aarẹ Muhammadu Buhari.
Abiodun Duro Ladiipo, Moremi: Ǹ kò pé '40' ti Bàbá fi papòdà ṣùgbọ́n mo kọ̀ láti 'remarry'
Fani Kayode to o ti lo ọpọ aye ati asiko rẹ lati tako aarẹ Muhammadu Buhari to si ti pe ẹgbẹ naa ni oniruuru orukọ buruku.
Díẹ̀ lára awọn nnkan ti Fani kayode ti sọ sẹyin ree  nipa APC ati ijọba Buhari ;
Oríṣun àwòrán, Fani Kayode
Awọn eniyan wa fesi pe Fani Kayode yoo maa wa ni aarin gbogbo nkan titi lai ni, nitori ko gbona ko tutu ni igba gbogbo.
Ati wi pe, Femi Fani kayode ti fi han pe gbogbo igba ni oun maa n pada sinu eebi rẹ, ati pe ko jẹ tuntun pe  o tun le ji ni ọla lati pada sinu ẹgbẹ oṣẹlu People's Democratic party (PDP)
Mi o nifẹ si lati jẹ ebi rẹ tabi ọrẹ rẹ- Reno Omokiri
Nínu ọrọ to n lọ yii bakan naa, ni Reno Omokiri to jẹ ọkan ninu awọn to ṣiṣẹ labẹ aarẹ Goodluck Jonathan tẹlẹri ti sọ pe, oun ko nifẹ si jijẹ ẹbi tabi ọrẹ Femi Fani Kayode lai.
Loju opo Facebook ti Omokiri kọ ọrọ naa si lo ti fesi si ibere ti wọ́n bi Fani Kayode lasiko to peju sibi Ifọrọwanilẹnuwo ni ile iṣẹ amohunmaworan Channels TV nibi to ti sọ pe ijọba Buhari n lepa Sunday Igboho ati  pe ẹbi ati ọrẹ oun ni Sunday Igboho.
Oloye Peter Fatomilola: Ọjọ̀gbọ́n olùkọ́ni ni Jesu àti Orunmila jẹ́, àwòkọ́ṣe sí rere si n
Eyi lo wa fa ti Reno Omokiri fi fun lesi pe, O pe igboho ni ẹbi ré , ''o pe Nnamdi Kanu ni ọrẹ ati ẹbi rẹ ati pe o jẹ ọkan ninu awọn ẹni to ni igboya julọ ni Naijiria, sibẹ o huwa esu yi sii wọn?''
''Eyi ń jẹ ki n maa fura si ọ, bawo ni awọn eniyan meji to sunmọ ọ yii pada kangun sinu pampẹ aarẹ Buhari, ti iwọ si lọ darapọ mọ ẹgbẹ APC''
''Ni bayii, mo kọ lati jẹ ọrẹ rẹ tabi ẹbi rẹ.''
Abiodun Duro Ladiipo, Moremi: Ǹ kò pé '40' ti Bàbá fi papòdà ṣùgbọ́n mo kọ̀ láti 'remarry'
Obafemi Ojudu ninu ọrọ tirẹ pẹlu ni ọjọ to buru julọ fun oun ni ọjọ ti Femi Fani Kayode darapọ mọ ẹgbẹ oṣelu APC.
Obafemi Ojudu to jẹ olubadamọran pataki fun aarẹ Muhammadu Buhari lori ọrẹ osẹlu ni inu oun ko dun rara pe Fani kayode darapọ mọ ẹgbẹ.
O kọ eyi soju opo Facebook rẹ  pe ''oni ni inu mi bajẹ julọ lati igba ti mọ ti bẹrẹ irinajo oṣelu.''
Lẹyin eyi ni Ojudu fi gbogbo awọn nnkan ti Fani Kayode ti kọ nipa ẹgbẹ APC sita loju opo rẹ, paapaa julọ ibi ti o ti sọ pe lai, oun ko le darapọ mọ ẹgbẹ oṣelu APC.
Jẹ́ ká lọ sílu mi: Kò sí ìtàn Ibadan láìsí Efunsetan, Òkè méje, Bower's Tower àtàwọn ǹkan
OPIC: Ilé aṣòfin ìpínlẹ̀ Ogun ti pasẹ ki adarí OPIC tẹ́lẹ̀rí dá #40 miliọ̀nù pada
Oríṣun àwòrán, Ogun
Ilé ìgbìmọ̀ asòfin ìpínlẹ̀ Ogun ti pàsẹ fun adarí ilé iṣẹ to n ri si okoòwò ati nǹkan ìní (OPIC) ọ̀gbẹni Babajide Odusolu láti da ogójì mílíọ̀nu ti ko le ṣàlàyé owó fun ọdún 2019 laarin oṣù mẹ́fà.
Èyí ni àfẹnukò ilé lásìkò ìjòkó ilé, abẹnugan ile Olakunle Oluomo ni Abeokuta lọjọ Eti lẹ̀yín ti wọ́n gba abá ìgbìmọ̀ tẹẹkoto lori iwe owo ijọba ati ìwa jẹgudujẹra ti Musefiu Lamidi n dari.
Lamidi lásìkò to n jábọ, sọ pe ìgbìmọ̀ naa ti yẹ iwe owo wọ lati ọdun 2015 titi di ọdun 2019.
Lamidi sọ bákan náà pé ki wọn gba aba naa wọlé ti Oludaisi  Elemide si kin lẹyin ti gbogbo ile naa si gbàá abajade igbimọ ọhun  wọlé pẹ̀lú ohùn wọn.
Akomolede: Akuko Gagara ni ìwé tó ṣàfìhàn ohun tó ń ṣẹlẹ̀ ní Nàìjíríà lásìkò yìí- Fatimo B
Bákan náà ni wọn pe àjọ tó ń ri si ìwà jẹgúdújẹrá (EFCC) láti ṣe ìwádìí ọkùnrin naa ati lati wo apo owo ijọba lati mọ ibi ti biliọnu meji abọ naira wọlẹ si lasiko idari rẹ nile iṣẹ.
Ayo Ewebiyi Mama Oriki: Ọwọ́ Òbí, Ìjọba àti àwọn Ọba ni ìdágbàsókè Yorùbá wà lásìkò yìí
Igbimọ naa tun daba pe ki wọn da gbogbo eto owo ti wọn ti se pada to fi mọ tita Heeka ilẹ mejọ ti wọn ta ni Iseri fun ile isẹ Rainerhill International  ni mílíọnù tó le diẹ ni aadọ́jọ.
Jẹ́ ká lọ sílu mi: Kò sí ìtàn Ibadan láìsí Efunsetan, Òkè méje, Bower's Tower àtàwọn ǹkan
Igbimọ naa ni gbogbo nkan ti awọn n se wa fun anfani ara ilu nitori naa gbogbo iwe ti wọn ti gbe fun ile isẹ Rainerhill nitori  ilẹ ti wọn ra ni o ti di ofo nigba ti ipinlẹ Ogun lo si ni ilẹ naa.
Abiodun Duro Ladiipo, Moremi: Ǹ kò pé '40' ti Bàbá fi papòdà ṣùgbọ́n mo kọ̀ láti 'remarry'
Bakan naa igbimọ naa tun ni ki ijọba fi ofin de gbogbo  banki mẹrindinlogun ti ile iṣẹ naa n kowo si.
Oloye Peter Fatomilola: Ọjọ̀gbọ́n olùkọ́ni ni Jesu àti Orunmila jẹ́, àwòkọ́ṣe sí rere si n
Covid- 19 Vaccine: Ẹ wo àwọn adarí ìjọ ní Naijiria tó tako abẹ́rẹ́ àjẹ́sára Covid-19 àti àwọn tó faramọ
Oríṣun àwòrán, OTHERS
Ọpọlọpọ awọn adari ijọ lorilẹede Naijiria ni ero wọn ṣe ọtọọtọ lori gbigba abẹrẹ ajẹsara Covid-19 ni Naijiria lati tako ajakalẹ arun ọhun.
Bi awọn adari ile ijọsin kan ṣe n sọ wi pe o dara lati gba Covid-19 fun idaabobo ara ẹni lọwọ arun naa ati fun ipolongo ihinrere Jesu Krisiti lati orilẹede kan si omiran lai si idiwọ nitori arun Covid 19,
Ni awọn adari ijọ miran ni ko si ohun to le e mu wọn gba abẹrẹ ajẹsara naa nitori wọn kọ ọ, ti wọn ko si ni igbagbọ ninu rẹ.
Lara awọn adari ijọ to tako gbigba abẹrẹ ajẹsara  naa ni Adari Ijọ Living Faith Church International (Winners Chapel), Bishop David Oyedepo; Adari Ijọ Omega Fire Ministries International, Apostle Johnson Suleman; Adari Ijọ  Household of God Church International Ministries, Pastor Chris Okotie; Adari Ijọ Christ Embassy, Pastor Chris Oyakhilome.
Oloye Peter Fatomilola: Ọjọ̀gbọ́n olùkọ́ni ni Jesu àti Orunmila jẹ́, àwòkọ́ṣe sí rere si n
Amọ, awọn adari ijọ kan ti wọn faramọ gbigba abẹrẹ ajẹsara Covid 19 ọhun ni Adari Ijọ Kingsway International Christian Centre, Pasitọ Matthew Ashimolowo; Adari Ijọ  Redeemed Evangelical Mission, Dr Mike Okonkwo; Adari Ijọ Trinity House, Ituah Ighodalo; Adari Ijọ Daystar Christian Centre, Pasitọ Sam Adeyemi ati Adari Ijọ Redeemed Christian Church of God, Pasitọ Enoch Adeboye to ni ohun yoo gba abẹrẹ ajẹsara naa lati polongo ihinrere Jesu Kristi.
Ayo Ewebiyi Mama Oriki: Ọwọ́ Òbí, Ìjọba àti àwọn Ọba ni ìdágbàsókè Yorùbá wà lásìkò yìí
Bishop David Oyedepo lasiko ayẹyẹ ogoji ọdun ti wọn ti bẹrẹ ihinrere ni ile ijọsin rẹ ni Ota, nipinlẹ Ogun ti ni ohun kii ṣe ẹranko ti yoo gba abẹrẹ ajẹsara Covid-19, nitori naa ohun ko nii gba abẹrẹ ajẹsara naa.
Bakan naa lo sọ fun awọn ijọ rẹ lati maṣe gba abẹrẹ ajẹsara naa nitori eroja iku ni wọn n pe ni abẹrẹ ajẹsara naa.
Bakan naa ni Apostle Johnson Suleman ni abẹrẹ ajẹsara naa ko fi ẹṣẹ mulẹ to, nitori naa ohun ko ni gba ẹnikẹni ni imọran lati gba abẹrẹ, ajẹsara naa.
Ninu ọrọ tirẹ, Chris Okotie ni abẹrẹ ajẹsara naa yoo mu ki awọn eniyan ma a wa ẹjẹ lati mu lẹyin ti wọn ba ti gba abẹrẹ ajẹsara naa tan nitori irinṣẹ esu ni abẹrẹ ajẹsara naa.
Ni Osu Kẹta ọdun 2021 yii ni Chris Oyakhilome bu ẹnu atẹ lu awọn iranṣẹ Ọlọrun miran ni Naijiria ti wọn n gba awọn ara ijọ wọn ni imọran lati gba abẹrẹ ajẹsara naa nitori ohun ti ko dara fun eniyan lati gba ni.
Abiodun Duro Ladiipo, Moremi: Ǹ kò pé '40' ti Bàbá fi papòdà ṣùgbọ́n mo kọ̀ láti 'remarry'
Bi o tilẹ jẹpẹ awọn adari ijọ kan ko faramọ, Ituah Ighodalo ninu ọrọ tirẹ ni ai ni imọ ni yoo mu ki eniyan ma a gbagbọ pe awọn ni igbagbọ lati bori arun kan nigba ti abẹrẹ ajẹsara wa nilẹ lati ṣe iranwọ fun idojuti arun naa.
'Ìyà Muinat kú nígbà tó ń mu ọmú lọ́wọ́ ni èmí ìyà-ìyá rẹ̀ ń tọ́jú rẹ̀ kí ògiri kíláàsì tó wó pa á'
Ninu ọrọ tirẹ, pasito Adeboye ni idi ti oun yoo fi gba abẹrẹ ajẹsara naa ni ti orilẹede kan ba kan an ni kanpa fun oun lati gba a,ki oun to le wọ orilẹede naa lati kede ihinrere Jesu Kristi.
Bakan naa lo gba awọn ọmọ ijọ rẹ lati gba abẹrẹ ajẹsara naa ti eru ajakalẹ arun Covid-19 ba n ba wọn, nitori o dara lati gba abẹrẹ ajẹsara naa ju ki eniyan ma a gbe ninu ibẹru-bojo lọ
Amọ awọn adari ijọ kan bi Adari Ijọ, Mountain of Fire and Miracles Ministries, Dr. Daniel Olukoya; Adari Ijọ Deeper Christian Life Ministry, Pasitọ William Kumuyi, Adari Ijọ The Sword of The Spirit Ministries International ati Adari Ijọ Pentecostal Fellowship of Nigeria, Bishop Wale Oke ati bẹẹ bẹẹ lọ.
Adari ati alákoso, ìjọ Redeemed Christian Church Of God Pásítọ̀ Enouch  Adejare Adeboye, ti ṣàlàyé pé òun ṣetán láti gba abẹ́rẹ́ àjẹsára Covid-19 nítorí ìtànkálẹ̀ ìhìnrere Jesu.
Oríṣun àwòrán, Adeboye
Ó ṣàlàyé ọ̀rọ̀ yìí lásìkò ìṣọ́-òrun olósooṣù ìjọ náà to wáye ni gbọ́gan ìpàgọ́ ìjọ náà ni mároṣẹ̀, Lagos/Ibadan.
Ẹni ọdún mọ́kàndínlọ́gọ́rin náà  sọ pé àánú Ọlọ́run lo pa gbogbo ọmọ Nàìjíríà mọ́ lati ìgbà yìí wá, àti pé àwọn ti àsìkò wọn ti tó láti kú ni àwọn to kú.
Lásìkò tó ń ba ẹgbẹ̀lẹ́gbẹ̀ àwọn ọmọ ìjọ náà sọ̀rọ̀, deboye ni, Ko si àsìkò kankan ti mo ti sọ fun yín pé kí ẹ ma gba àbẹ́rẹ́ àjẹsara Covid-19. 'Ẹ ò gbọ́ rí lẹ́nu mi'.
Kàkà tí ẹ ó fi máa gbé nínú ìbẹ̀rù bójójo, ẹ lọ gba abẹ́rẹ́ àjẹsára, ti ẹ ba ro pé gbigba abẹ́rẹ́ náà ni yóò fi yin ni ọkàn balẹ̀, ẹ lọ gba ki ẹ le ni ifọkanbalẹ.
Jẹ́ ká lọ sílu mi: Kò sí ìtàn Ibadan láìsí Efunsetan, Òkè méje, Bower's Tower àtàwọn ǹkan
"Baba Adeboye ṣàlàyé pé àwọn orílẹ̀-èdè kan wà ni àgbàyé ti wọ́n ni mí ò le wá sí orílẹ̀-èdẹ̀ àwọn ti mi o bá gba abẹ́rẹ́ Covid-19, Ko si nǹkan yti mi o lè ṣe fún Jesu."""
" Ẹ má jẹ́ ki ń gba rárá pé, ẹnu mi ni ẹ ti gbọ pé kí ẹ ma gba abẹ́rẹ́ ajẹsara.
Adeboye ṣàlàyé pé nǹkan ti o pani lẹ́rin  ni igbésẹ̀ àwọn gómínà kan tí wọ́n ni dandan ni abẹ́rẹ́ àjẹsara Covid-19 ki ènìyàn tó lọ sí ilé ìjọsìn.
Akomolede: Akuko Gagara ni ìwé tó ṣàfìhàn ohun tó ń ṣẹlẹ̀ ní Nàìjíríà lásìkò yìí- Fatimo B
Adeboye tọ́ka si pé irú àwọn adárí bẹ́ẹ̀ kùnà lati rii pé, àwọn abẹ́rẹ́ tó wa nilẹ̀ ko le tó fún àwọn ènìyàn tó wà nílẹ̀.
Nítori, ẹ̀yà Delta vatiant ni ọ̀pọ̀ àwọn orílẹ̀-èdè ti sọ abẹ́rẹ́ àjẹsára Covid-19 di nnkan to pọndandan láti wọ orílẹ̀-èdè mííràn.
Ó ti le ni ẹgbẹ̀rún lọ́nà igba ènìyàn tó ti ni ààrun
Ayo Ewebiyi Mama Oriki: Ọwọ́ Òbí, Ìjọba àti àwọn Ọba ni ìdágbàsókè Yorùbá wà lásìkò yìí
Mama Oriki sọ ọna abayọ ti ko ni jẹ ki ede, aṣa ati iṣẹṣe Yoruba ko parun
BBC Yoruba kan si Ayo Ewebiyi Mama Oriki lati kọ ẹkọ lara bi akewi naa ṣe bẹrẹ aye rẹ ki o le jẹ koriya fun awọn ọdọ asiko yii.
Mama Oriki sọ bi agbega ede ati aṣa Yoruba ṣe jẹ oun logun pupọ lati kekere aye rẹ.
Ayo Ewebiyi sọ bo ti ṣe gbe ede ati aṣa Yoruba kaakiri agbaye.
O mẹnuba bi awọn oyinbo ṣe n fẹ wa kọ ede ati aṣa iran Yoruba to dun lede to tun dara laṣa.
Iró ni pé ẹni tó bá ń kéwì tàbí ṣe ǹkan ìbílẹ̀ kìí sin Olodumare- Ayo Ewebiyi Mama Oriki
Mama Oriki mẹnuba ipa pataki ti awọn agba akewi bii Olanrewaju Adeoju, Ajobiewe ati awọn mii ti ko ki igbega le ba ede Yoruba.
Bakan naa lo sọ pataki ayelujara ti o fi n safihan iṣe ati ede Yoruba kaakiri agbaye.
Mike Bamiloye pá àrokò ìkìlọ ránṣẹ sí àwọn ọkùnrin Nàìjíríà lórí àgbèrè ṣíṣe
Oríṣun àwòrán, Mount Zion
Ẹyin ọkunrin Naijiiria, ẹ jawọ nibi piparọ obinrin bi ẹni parọ aṣọ.
Gbajugbaja oṣere ẹlẹsin Kristẹni ajihinrere Mike Bamiloye lo n  parọwa  bayi sawọn ọkunrin lati sinmi piparọ obinrin bi ẹni parọ '' handkerchief''
Ninu ọrọ to fi si oju opo rẹ ni Instagram lo ti gbawọn ni amọran yi.
Bamiloye ti ọpọ mọ fun ere ori itage ''Agbara nla'' ni lati ibẹrẹpẹpẹ lo ti yẹ ki awọn ọkunrin mojuto ibaṣepọ wọn pẹlu awọn obinrin.
O ṣakawe lati inu iwe bibeeli bi Samson ti ṣe ṣaṣiṣe nipasẹ iyawo to yan ati awọn obinrin miran to ni ajọṣepọ pẹlu.
O kesi awọn ọdọ iwoyi pe ki wọn ma ṣe fi obinrin ta tẹtẹ nitori ọrọ yi kii ṣe ọrọ awada rara.
O ni bi wọn ba ri piparọ obinrin gẹgẹ bi nkan igbadun adanu ni ytoo gbẹyin rẹ fun wọn.
''Ẹ bi Solomon,ẹ bi Samson,  ẹ bi Judah ati Tamar, ko si ọkunrin to moribọ ninu ere gele pẹlu obinrin''
Oríṣun àwòrán, Instagram/mikebamiloye
O gba awọn ọdọkunrin ni amọran pe ti wọn ba fẹ ṣe amuṣẹ ileri Ọlọrun ninu aye wọn, ki wọn ya tete ri pe wọn fẹ iyawo to dara.
Akẹ́kọ̀ọ́ ọmọ ọdún méjì kàn àgbákò ikú lọwọ ajá olùdásílẹ̀ ilé-ẹ̀kọ́
Oríṣun àwòrán, Bullmastif/Facebook
Aja buburu
Ọjọ ayọ ni ọjọ ti awọn obi ba mu ọmọ wọn sile ẹkọ lati forukọsilẹ fun ọmọ wọn.
Amọ ọjọ ayọ yi di ibanujẹ fawọn obi kan ti aja mẹwaa yabo ọmọ ọdun meji wọn ti wọn si ya yanayana.
Ni ile ẹkọ aladani kan to wa ni Amokpo Umuanunwa ni ipinlẹ Anambra ni iṣẹlẹ buruku yi ti waye.
Gẹgẹ bi ileeṣẹ iwe iroyin Naijiria kan The Nation ṣe jabọ, awọn obi ọmọ taa n wi yi mu ọmọ lọ lati w ile iwe ni ki o to kan agbako iku gbona.
A gbọ pe oludasilẹ ile ẹkọ naa Chinedu Oka n ṣin aja ninu ọgba ileewe naa toun ti ikilọ tawọn ilu ti kilọ pe ko ma sin aja nibẹ.
Araadugbo kan ti ọrọ naa ṣoju rẹ ni nigba tawọn obi ọmọ yi n buwọlu iwe iforukọsilẹ ni ọmọ naa tasẹ agẹrẹ l sibi tawọn aja wa.
Pistachio Green Puppy: Àwọn ẹgbẹ́ rẹ̀ jẹ́ aláwọ̀ funfun, tí òun sì jẹ́ aláwọ̀ ewé
Ǹjẹ́ o leè fẹ́ ẹni tó bá ń jẹ ẹran Ajá?
O ni ''Aja mẹwaa lo wa nibẹ ti wọn si bẹrẹ si ni bu ọmọ naa jẹ.Ko si eeyan kankan ni tosi lati doola rẹ''
Ki a to wo ka to fọ, awọn araalu ti fi ibinu wọ inu ọgba ileẹkọ naa ti wọn si yinbọn pa gbogbo aja to wa nibẹ.
Nigba to n fidi iṣẹlẹ yi mulẹ, olori abule ilu Nteje, Igwe Rowland Odegbo sọ pe eewọ ni aja sisin ni ilu awọn ati pe awọn yoo fi ijiya to tọ jẹ arakunrin to ni ileewe naa.
O ni ''arakunrin naa  mọ pe a klo faye gba aja sinsin ṣugbọn o keti ikun to si ko aja sinu ọgba rẹ.''
''Lọdọ wa, bi igba pe o ṣeku pa eeyan ni nkan to ṣe yi awọn to si yẹ yoo fi ijiya to t jẹ nitori a ko faaye gba iwa aburu''
O fi kun pe awọn lọwọ si bi awọn ọdọ ile ti ṣe dana sun awọn aja naa lẹyin ti wn pa wọn.
Ikenga Tochukwu to jẹ alukoro ọlọpaa ni ipinlẹ Anambra ti fidi ọrọ yi mulẹ to si ni alaafia ti pada si ilu.
Nkechi Blessing: Ọ̀pọ̀ ọ̀gá òṣèré ló ń bèèrè ìbálòpọ̀, kí obìrin tó gba eré tíátà lọ́wọ́ wọn
Oríṣun àwòrán, nkechiblessingsunday/Instagram
Yoruba ni bi ọrọ ba se n pẹ nilẹ, gbigbọn ni yoo maa gbọn si.
Bẹẹ ni ọrọ ri nipa isẹlẹ to waye si Baba Ijesha, ẹni ti wọn fi ẹsun sise asemase pẹlu ọmọkan kan, to si n jẹjọ lọwọ.
Lọtẹ yii, ọkan lara awọn osere tiata lobinrin, ti ọrọ naa ka lara pupọ, Nkechi Blessing Sunday tun ti sọrọ lẹẹkan si nipa isẹlẹ naa.
Nkechi, lasiko to n kopa lori ifọrọwanilẹnuwo kan lori Instagram pẹlu Jude Jideonwo salaye idi ti ọrọ naa se ka lara.
'Ìgbésí ayé tí kò pariwo ló dára'
Ninu alaye rẹ, Osere tiata lobinrin naa ni ọmọ ọdun mẹtadinlogun ni oun wa nigba ti ọkunrin kan fẹ fi tipa ba oun lopọ.
O salaye siwaju pe oun finu wenu nigba naa ni, amọ Ọlọrun nikan ni ko jẹ ki oun jẹ iwọ.
Mo sọ fun ẹgbọn mi obinrin kan pe n ko ti mọ ọkunrin ati pe ko si akọ kankan to tii si mo ni asọ wo ri amọ o ni irọ ni mo n pa."
Nigba naa, ọti bia ni iya mi maa n ta, ti mo si maa n jo gan.
Lọjọ kan ni anti mi yii wa ni ka jọ lọ sile ọrẹkunrin rẹ, ti mo si tẹle amọ n ko mọ pe o tan mi lọ sibẹ ni lati fidi ootọ mulẹ boya lootọ ni n ko mọ ọkunrin.
"Ko pẹ ta de ibẹ ni wọn fun mi ni ọti ẹlẹrindodo, ti mo si mu, ti anti mi si ni oun fẹ sare de ibi kan, to si ku emi ati ọrẹkunrin rẹ ninu ile."""
Nkechi tẹsiwaju pe bi anti oun se jade ni ọkunrin naa n gbe sunmọ oun, to si wa joko si ẹgbẹ oun pẹki-pẹki.
O ni ni kete ni skan oun lọ sibi ọrọ ajọsọ oun ati anti naa nipa pe oun ko mọ skunrin, ti ara si bẹrẹ si fu oun nitori oun ti ni oye nipa ibalopọ nigba naa.
O fikun pe ẹrun bẹrẹ si ni ba oun, ti oun si dide pe oun n lọ amọ ti ọkunrin naa dide lati di oun lọwọ mu, to si ni oun ko le lọ amọ ti oun yari mọ lọwọ.
Nkechi ni igba yii ni oun wa beere lọwọ ọkunrin naa pe se o fẹ fi tipa ba oun ni ajọsepọ ni? Eyi si lo ni o ya lẹnu pupọ, ti oun si ri ọna sa jade nibẹ.
O yẹ ki wọn se idajọ iku fun awọn afipabanilopọ ni, ko si yẹ ki wọn maa gbe wọn lọ sile ẹjọ, ni kete ti ọkunrin kan ba ti fipa ba obinrin kan lopọ, ni ki wọn lu pa.
yyyy
Ninu ifọrọwerọ naa ni Nkechi tun ti si agbada lori ọrọ kan to ni se pẹlu ipa ti ẹgbẹ osere TAMPAN ko lasiko ti isẹlẹ Baba Ijesha waye.
Nkechi ni lootọ ni oun bu ẹnu atẹ lu awọn asaaju ẹgbẹ osere naa, ti Alagba Bolaji Amusan, ti ọpọ eeyan mọ si Mr Latin ko sodi nitori pe wọn ko tete sọrọ lori isẹlẹ naa.
Amọ o ni nigba to ya ni Latin se fidio kan pe awọn ko le le Baba Ijesha kuro ninu ẹgbẹ TAMPAN nitori kii se ọmọ ẹgbẹ awọn, ti awọn si fara mọ ohun to sọ.
"Amọ tẹ ba fẹ mọ idi ti ọpọ wọn se dakẹ jẹ nigba ti ọrọ Baba Ijesha sẹlẹ, idi ni pe iru kan naa ni wọn.
Ko fẹ ẹ si ọga elere kankan ninu ẹgbẹ TAMPAN to le sare jade sọrọ lori ẹsun ifipabanilopọ nitori ọpọ wọn ni wọn maa n kọkọ beere lati tu obinrin ni asọ wo, saaju ki wọn to fun ni ipa kan lati ko ninu ere.
Femi Branch: Gbogbo dúkìá mi àti ti ìyá mi ni mo tà láti tọ́jú ẹsẹ̀ mi fún ọdún méjì
Bi wọn ba si fi sare sọrọ pẹrẹ, gbogbo awọn eeyan ti wọn ti fi ere gba asọ lara wọn ni yoo jade lati wa fi ẹsun kan awọn naa.
Lana kan abi omiran, gbogbo wọn ni wọn jẹbi ẹsun iwa ti Baba Ijesha hu, ti ẹnu wọn ko si le to ọrọ.
Wọn yoo fi ọwọ gbaya pe ti osere binrin kan ko ba sun pẹlu awọn, awọn ko ni gbe ipo kan fun ninu ere ti wsn ba fẹ se.
Nkechi Blessing wa ni isẹlẹ to ti waye saaju si oun lo mu ki oun gba ọrọ ẹsun Baba Ijesha naa kanri.
Afghanistan: Taliban kò jẹ́ káwọn obìnrin wọlé lẹ́yìn tí ilé ẹ̀kọ́ di ṣíṣí padà ní Afghanistan
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Awọn akẹkọọ ti wọle pada sile ẹkọ lẹyin ti ẹgbẹ Taliban gba ijọba lorilẹede naa.
Amọ, ijọba Taliban ko fun awọn akẹkọọbinrin lati wọle pẹlu awọn akẹgbẹ wọn ọkunrin.
Awọn akẹkọọ to jẹ ọkunrim atawọn olukọ ọkunrin nikan ni Taliban fun lanfani lati pada si yara ikawe wọn bayii.
Awọn akẹkọọbinrin to ba BBC sọrọ ṣalaye pe ibanujẹ ọkan lo jẹ fawọn pe ijọba Taliban ko jẹ kawọn wọle pada sile ẹkọ.
Wọn ni okunkun birimu ni gbogbo nkan ṣe ri loju awọn bayii, ti ọpọ wọn si n beere pe ki ni yoo sẹlẹ si ọjọ ọla awọn.
Jẹ́ ká lọ sílu mi: Kò sí ìtàn Ibadan láìsí Efunsetan, Òkè méje, Bower's Tower àtàwọn ǹkan
Ẹgbẹ Taliban to gbajọba loṣu to lọ ti sọ pe awọn n ṣiṣẹ lati gbe igbesẹ lori ọrọ naa.
Ọpọ lo n bẹru lẹyin ti Taliban pada sori aleefa pẹlu bi wọn ṣe fi ẹtọ awọn obinrin dun wọn lasiko ijọba wọn ni bi ọdun mẹẹdọgbọn sẹyin.
Ohun ti Taliban sọ lẹyin ti wọn gba ijọba ni pe awọn obinrin yoo lanfani lati lọ ile ẹkọ, wọn yoo si maa ṣiṣẹ.
Ṣugbọn ohun ti ofin ẹsin Islam ba sọ nipa rẹ ni ijọba Taliban yoo tẹle.
Ni bayii, ijọba Taliban ti sọ pe kawọn obinrin to n ṣiṣẹ si fidi mọle na, titi ti eto abo to muna doko yoo fi wa.
Koda, awọn ẹṣọ Taliban ti fiya jẹ awọn obinrin to n fẹhonuhan lori bi ko ṣe si obinrin kankan ninu ijọba Taliban.
Lọjọ Ẹti, o dabi ẹni pe ẹgbẹ Taliban ti wọgile ileeṣẹ ijọba to n ri si ọrọ awọn obinrin, lẹyin ti wọn rọpo rẹ pẹlu ẹka to n ri si ọrọ ẹsin Islam.
Suicide Prevention: ìwọ́de yìí wáyé láti gbógun ti pípa ara ẹni
Ghost Reappearance: Agbóòkújó kan ṣàlàyé ohun tí ojú rẹ̀ rí nígbà tí òkú yọ si
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ṣe bi airin jinna lai ri abuke ọkẹrẹ, ti eeyan ba de inu ibu, yoo ri ẹja to yarọ.
Ọkunrin agbookujo kan ti orukọ rẹ n jẹ Baffour Awuah ti ṣalaye ohun ti oju rẹ ri nidi isẹ gbigbe oku to yan laayo.
Gbajugbaja agbooku lorilẹede Ghana ni Awuah jẹ, o si ti n ṣiṣẹ yii fun ọdun diẹ, ki oju rẹ to ri eemọ to ri yii.
Awuah maa n wẹ fun oku, o si maa n wọ aṣọ fun wọn ṣaaju igba tawọn ẹbi wọn yoo lanfaani lati wa wo awọn oku naa fun igba ikẹyin.
Lọjọ kan ni ọkunrin yii n lọ si itẹ oku lati ṣe iṣẹ rẹ gẹgẹ bo ṣe maa n ṣe e.
Kayeefi: Facebook ni Wolii Arole Jesu fi tàn an wọ agbo, orí rẹ̀ ni wọ́n fi s'owó
Ọkọ ero ni Awuah wọ, ẹyin lo si joko si, ṣugbọn awọn ero mii naa joko si ẹyin pẹlu rẹ.
Ni kete ti o wọ ọkọ ọhun tan, ni obinrin kan to joko si ẹgbẹ rẹ pẹlu si ni ba a sọrọ.
Obinrin naa wa n beere lọwọ rẹ nipa ohun ibi ti o n lọ gan an ati ohun ti o n lọ ṣe nibẹ.
Agbooku yii ṣalaye fun obinrin naa pe oun n lọ wẹ fun oku obinrin kan ni, lẹyin naa ni oun tun maa wọ aṣọ fun oku ọhun.
Nigba naa ni obinrin sọ fun Awuah pe ki o wọ aṣọ fun oku naa daadaa lọna to boju mu.
Nigba ti awọn mejeeji de ibudokọ ti wọn ti sọ kalẹ, obinrin yii gba ọna tiẹ lọ, Awuah naa si mori le ọna itẹ oku to n lọ.
Iyalẹnu lo jẹ fun Awuah nigba to de ibi oloku to n lọ, ti o si fẹ wẹ fun oku ti wọn pe wa wẹ, amọ kayeefi lo jẹ fun pe oku to ba nilẹ jẹ ti obinrin ti wọn dijọ sọrọ ninu ọkọ.
Kayeefi: Àdììtú tó rọ̀ mọ́ ìdí tí ìlú Okeluse ṣe fi ọmọ ọdún 16, tó wà ní JSS 2 jọba
Bakan naa ni ko si iyatọ laarin oju obinrin ti o ba a sọrọ ninu ọkọ ati oku to fẹ wa wọ aṣọ fun.
Ti ọmọde ba de ibi ẹru, ẹru yoo ba a, ipaya ati ibẹru mu Awuah nigba to ri pe ero to ti n ba a sọrọ ninu ọkọ ni oku ti oun fẹ wọ aṣọ fun.
Idi si ree to se ni ki awọn ẹbi oku naa fun oun ni aworan oku naa to ya nigba to wa nile aye, ti jẹbẹtẹ si gbe ọmọ le Awuah lọwọ nigba to ri pe obinrin ti awọn dijọ wọ ọkọ papọ naa ni oku rẹ wa nilẹ.
Amọ, Awuah ṣe awọn eto kan lori oku naa, koda o da ọti Schnapps si oku naa lara ki o to wọ aṣọ fun un.
Awuah ni oriṣiriṣi iriri ni oun ti ri lẹnu iṣẹ agbooku, ṣugbọn ko le fi iṣẹ naa silẹ nitori awọn iriri yii.
Omidan jáde láyé lẹ́yìn tí ìlú lù ú, jáa sí ìhòhò lórí ẹ̀ṣẹ̀ tí kò ṣẹ̀
Fani-Kayode Visits Sunday Igboho: Mínísítà tẹ́lẹ̀ ní òun kò ní fi Igboho sílẹ̀
Oríṣun àwòrán, Real_ffk/Instagram
Yoruba ni ara la mọ, a ko mọ inu, bẹẹ si ni inu jinna, o ju ọrun lọ.
Sunday Igboho lo jẹ gbajumọ ajijagbara fun iran Yoruba, ti ọpọ eeyan n wari fun nilẹ Kaarọ Oojiire.
Tọmọde tagba si lo n wọ tẹle lẹyin nitori iwa akin to hu lati gbeja ẹya rẹ lọwọ awọn afurasi darandaran to n da ẹmi wọn legbodo laibikita.
Amọ lasiko kan ni iroyin tan kalẹ pe awọn eeyan kan loru mọju ọjọ ọjọ Isẹgun, ọjọ kẹrindinlọgbọn osu Kinni ọdun 2020.
Bi o tilẹ jẹ pe ile atijọ ti Sunday igboho n gbe ni ile naa, ti ko si si ninu rẹ lasiko ti isẹlẹ naa waye, sibẹ ọpọ dukia to wa ninu ile naa lo bajẹ.
FFK: Buhari ló ń fún àwọn Fulani láàyè láti máa pa ènìyàn'
Idi ree ti ọpọ eeyan se n wọ wa ki Igboho nile pe Ọlọrun yoo fi ofo ra ẹmi, lara wọn la si ti ri akọrin Fuji nni, Saheed Osupa, Asofin Sina Peller, tii se ọmọ ile asoju-sofin nilu Abuja.
Bakan naa ni Oloye Femi Fani-Kayode, FFK tii se minisita tẹlẹ fun eto irinna naa wa se ẹ pẹlẹ si Sunday Igboho nile rẹ nigba ti isẹlẹ ile jijo naa waye.
Nigba ti Fani-Kayode ati Sunday Igboho joko papọ lori aga kan naa lasiko abẹwo ọhun, ni FFK ti kan saara si Igboho fun isẹ ijijagbara to n se.
Bakan naa lo fi ọwọ sọya pe ko si ọrọ anboju wẹyin mọ lori awọn igbesẹ ijijagbara ti Igboho n gbe, paapaa lori bi wsn se jo ile rẹ naa.
FFK tun wa fi ọwọ sọya fun akọni ọmọ Yoruba naa pe gba gba gba ni oun wa lẹyin rẹ, mi mi kankan ko si le mi rara.
Yatọ si eyi, lẹyin abẹwo naa tun ni FFK tun sọrọ lawọn oju opo ibanidọrẹ rẹ lori ayelujara rẹ nigba naa, lati ki Sunday Igboho laya lori iwa aksni to n hu.
Ọrọ kan ti FFK kọ lo tun ni Oloye Sunday Igboho Oosha lo n soju ọpọ ọkan, ara ati ẹmi Oduduwa lonii."
Orukọ rẹ lo fara pẹ igboya, okun, ikoraẹninijanu ati agbara, bẹẹ ni kii bẹru tabi tẹriba labẹ ẹnikẹni.
"O jẹ koriya, itọni, amuyangan ati ayọ fun ọpọ miliọnu eeyan, bẹ ba si fi pa pẹrẹ, yoo da rogbodiyan ati wahala nla silẹ."""
Oríṣun àwòrán, Real_ffk/Instagram
Nigba to n fesi lori ohun ti FFK sọ, Sunday Igboho ni oun fi Ọlọrun bura, iru FFK lawọn nilo nitori pe asiwaju rere ni.
Ẹ sọ ọrọ kan pe a ko ni boju wẹyin mọ, iru ohun ti emi fẹ mọ gbọ lati ẹnu awọn baba wa niyẹn.
Sunday Igboho ni awọn tawọn n ba fa, wọn ro pe awọn n se fiimu ni, lo ba bu sẹkun, ti FFK si n bẹ pe ko dakẹ ẹkun nitori ko si nnkan kan.
"FFK ni "" Ko si nkankan, ko si nkankan rara, Alọrun to wa pẹlu rẹ, ti ko fi ẹ silẹ, ko dẹ si ẹni to maa fi ẹ silẹ, awa naa ko ni fi ẹ silẹ."""
Sunday Igboho wa tẹ siwaju pe awọn kan n se ipade pe awọn kan fẹ oun, ti FFK si n fi ọwọ idaniloju sọya pe ko le seese fun wọn.
"Sunday Igboho tẹsiwaju pe ""Yoruba gbọdọ lọ ni nitori pe iya n jẹ wa gan ni."""
Amọ awọn ọrọ ti FFK sọ nile Igboho yii lo ti bọ si apo ibinu awọn ọmọ Naijiria, ti wọ̀n si ri agba oloselu naa bii ọdalẹ.
Wọn ni ko yẹ ko jẹ iru eeyan bayii ni yoo da Sunday Igboho nipa lilọ dara pọ ijọba aarẹ Buhari.
Bẹẹ ba gbagbe, laipẹ yii ni Femi Fani-Kayode naa kede pe oun ti dara pọ mọ ẹgbẹ oselu APC, tii se ẹgbẹ oselu aarẹ Buhari, to ti sọrọ aidaa si tẹlẹ.
Oríṣun àwòrán, Real_ffk/Instagram
Sabaa Akintola: Pẹ̀lú ẹsẹ̀ kan, mo le gun kẹ̀kẹ́, lúwẹ̀ẹ́ tàbí rán aṣọ pẹ̀lú ẹ̀kọ́ dókítà
Yoruba ni ẹni ti yoo ga, ẹsẹ rẹ yoo tiirin, bẹẹ ni ọrọ ri fun akẹkọbinrin kan, Sabaa Akintola, to n kẹkọọ nipa imọ isegun nile iwosan UCH nilu Ibadan.
Sabaa, ti wọn ti ge ẹsẹ rẹ osi nigba to wa ni ọmọ ọdun mẹrin ni ọmuti kan lo kọlu oun niwaju sọọbu iya oun, eyi to run egungun ẹsẹ oun.
Nigba to n ba BBC Yoruba sọrọ, akẹkọọbinrin naa ni ọpọ ipenija ati idẹyẹsi ni oun ri ni kekere nitori bi wọn se ge ẹsẹ oun amọ eyi ko di oun lọwọ lati kawe de ibi giga.
Sabaa, to n kẹkọọ nipa itọju eyin ni oun n lo ayederu ẹsẹ lati rin, ti ko si si ohun ti ohun ko le se gẹgk bi awọn abarapa yoku.
O fikun pe oun le ran asọ, oun le wa kẹkẹ, ti oun si tun n luwẹ pẹlu, yatọ si pe oun jẹ akẹkọ imọ isegun oyinbo.
Obinrin naa wa gba awọn eeyan to ni ipenija ara nimọran lati mase ri gbedeke kan nipa ohun ti wọn le se nitori pe wọn ni ipenija ara.
NINAS UN Protest: Yoruba Nation béèrè kókó nǹkan mẹ́fà lọ́wọ́ Buhari ṣáájú ìwọ́de níwájú àjọ UN
Awọn to n beere fun idasilẹ orileede Yoruba ti fi ọrọ ranṣẹ si aarẹ Muhammadu Buhari lori nkan tawọn fẹ ko yẹwo ṣaaju iwọde wọn  ni ajọ isọkan agbaye United Nations, UN.
Wọn tun ni awọn yoo ṣe iwọde itagbangba niwaju ajọ UN lọjọ kẹrinlelogun oṣu Kẹsan, ti ipade ajọ naa yoo waye.
Ọjọ yii kan naa ni aarẹ Buhari yoo sọrọ niwaju igbimọ apapọ ajọ UN.
Lọjọ Aiku ni aarẹ Buhari gbera kuro ni Abuja lọ si New York lati kopa ninu ipade apapọ ẹlẹẹkẹrinlelaadọrin ajọ naa.
Agbẹnusọ fawọn ajijagbara naa, to wa ninu ẹgbẹ Ilana Omo Oodua, Maxwell Adeleye ninu atẹjade to fi sita ka awọn nkan mẹfa, ti wọn lawọn n fẹ.
Femi Falana: Mẹ̀kúnnù gbọ́dọ̀ ṣetán láti gba ẹ̀tọ́ wọn, ìjọba ti kùnà lórí ẹ̀tọ́ ọmọnìyàn
Atẹjade naa tun sọ pe alaga agbarijọpọ awọn ẹgbẹ to n beere fun idasilẹ Yoruba Nation, Ọjọgbọn Banji Akitoye ni ''kaka ki ijọba Buhari tẹti gbọ ohun t'araalu fẹ, niṣe lo n doju ija kọ awọn to fẹ dẹkun ikọlu lati ọwọ awọn darandaran Miyetti Allah''
''Ipe wa si ijọba ni ki wọn wo atẹjade ti NINAS gbe jade lọjọ Kẹrindinlogun oṣu Kejila ọdun 2020. Ipe yii ṣe pataki ki awọn ẹya to wa labẹ NINAS  le dunadura nnkan ti wọn fẹ lai si idiwọ''
Yoruba Nation: Kò sí ìdí tí à ó fi bínú sí Akeredolu lórí ọ̀rọ̀ Yorùbá Nation
O fi kun pe ohun tawọn fẹ ni ki ijọba ''ṣeto idibo ti araalu yoo ti sọ ohun ti wọn fẹ, referendum, ki awọn to wa lati iwọ guusu ati aarin gbungbun Naijiria yoo le gbe igbesẹ iṣejọba ara wọn.
A n beere fun ki wọn wọgile iwe ofin Naijiria ọdun 1999 ni kiakia''
''A o tun bẹrẹ iwọde wa lọjọ Kẹrinlelogun oṣu Kẹsan niwaju ileeṣẹ ajọ UN lati le sọ fun aarẹ Buhari pe, awọn Miyetti Allah rẹ ni ọta awọn eeyan aarin gbungbun Naijiria ati iwọ oorun guusu Naijiria.
Awọn gangan ni agbesunmọmi''
Insecurity in Nigeria: Ọba alayé rawọ́ ẹ̀bẹ̀ sí ìjọba láti dẹ́kun ìkọlù afurasí Fulani, kó tó di làásìgbò ńlá
Oríṣun àwòrán, Screen Shot
Agbalagba ti ko ba kẹhun sọrọ, afaimọ ko ma kẹ itan sare nitori aile sọrọ ni ibẹrẹ nnkan buruku.
Ọba alaye kan, Domini Yahaya ti ke gbajare fun gbogbo agbaye pe ikọlu awọn afurasi Fulani ti gba ẹmi aadọta eeyan, ti wọn si ba ọpọ dukia jẹ pẹlu.
Ọba alaye naa naa to wa lagbegbe Zango-Kataf ni guusu Kaduna salaye pe o tun le ni ile bii ọtalerugba o din mẹfa ti wọn ti jo kanlẹ.
Lara awọn eeyan ti wọn ni awọn afurasi Fulani naa n kọlu ni alaboyun ati awọn ọmọ wẹwẹ, ti wsn si tun ba sọọsi meje jẹ kanlẹ pẹlu.
Ọba alaye naa, lasiko to n bawọn akọroyin sọrọ nilu Kaduna lọjọ Aje wa n kaya soke nipa bi ipaniyan ọlọgọọrọ yii se n waye lai si ẹni to mu wọn.
Igangan Mayhem: Obìnrin Fulani kan ní òun pàdánù ọkọ, ọmọ mẹ́ta àti gbogbo dúkìá torí ìjà
O ni wọn ti gba akoso abule oun, ti ikọlu ojoojumọ naa si ti de gongo, eyi to le ru ibinu araalu soke kọja sisọ.
O fikun pe nitori ikọlu naa, ọpọ awọn ara abule naa ti wọn jẹ agbẹ, lo ti sa kuro lori ilẹ wọn lai le da oko mọ, to si le ni ẹgbẹrun mẹẹdogun araalu ti ko nile lori mọ.
Ọba Yahaya wa rawọ ẹbẹ sawọn agbofinro lati tete wa ọna dẹkun ikọlu ojoojumọ ọhun, eyi to le sokunfa rogbodiyan nla.
Oríṣun àwòrán, Goodluck Jonathan
Lẹyin ahesọ ọrọ ti gbalẹ kan pe aarẹ Naijiria tẹlẹ ri, Goodluck Jonathan n gbero lati dije ninu ibo aarẹ ọdun 2023, ikilọ ti jade fun aarẹ ana orilẹede Naijiria bayii o.
Ọga agba ẹgbẹ awọn onilọsiwaju, Progressive Governors' Forum (PGF), Ọmọwe Salihu Lukman ti kilọ fun Jonathan pe ko maa yẹyẹ ara rẹ nipa didije ninu ibo aarẹ ọdun 2023.
Ọmọwe Lukman ni afaimọ ki Jonathan ma ba orukọ rere to ti ni tẹlẹ jẹ to ba le dupo aarẹ ninu eto idibo ọdun 2023.
Lati igba ti eto idibo gomina ipinlẹ Bayelsa ti waye lọdun 2019 nibi ti Jonathan ti ran oludije gomina APC, David Lyon lọwọ lati jawe olubori ni ọpọ ti n sọ pe o n sẹ ajọsẹpọ pẹlu ẹgbẹ oṣelu APC loke.
Awọn kan tiẹ tun sọ pe adehun ti Jonathan ṣe APC ni pe wọn yoo fun oun ni anfani lati dije fun ipo aarẹ labẹ asia ẹgbẹ naa.
Sabaa Akintola: Pẹ̀lú ẹsẹ̀ kan, mo le gun kẹ̀kẹ́, lúwẹ̀ẹ́ tàbí rán aṣọ pẹ̀lú ẹ̀kọ́ dókítà
Ọmọwe Lukman beere pe bawo lo maa ṣe ri ti Jonathan ba darapọ mọ APC ṣugbọn ti wọn ko fun ni iyọnda lati dupo aarẹ lọdun 2023.
''Ọrọ ibo aarẹ ọdun 2023 kọ lo yẹ kawọn eeyan maa sọ nipa Jonathan.
Ọrọ bi Jonathan ṣe gba pe oun fidi rẹmi ninu ọdun 2015 ti Aarẹ Muhammadu Buhari fi wọle lo yẹ ki a maa sọ nipa Jonathan.
Nitori naa, ko yẹ ki ẹgbẹ oṣelu kankan ti Jonathan lati lọ dupo aarẹ, bi bẹẹ kọọ, wọn maa ba orukọ rẹ jẹ.
Ẹwẹ, iroyin sọ pe gomina ipinlẹ Ebonyi, Dave Umahi ati Ben Ayade ti Cross River to ṣẹṣẹ fi PDP silẹ lọ APC n gbero lati dije fun ipo aarẹ lọdun 2023.
Covid-19: Ìjọba Osun ní abẹ́rẹ́ covid-19 ti di dandan fáwọn òṣìṣẹ́ ìjọba àtàwọn elétò ìlera
Oríṣun àwòrán, Osun State Government
Gomina ipinlẹ Osun, Adegboyegba Oyetola ti paa laṣẹ fun gbogbo awọn alabaṣiṣẹ pọ rẹ, awọn oṣiṣẹ ijọba, awọn eleto ilera atawọn nipinlẹ naa lati gba abẹrẹ ajẹsara covid-19.
Gomina Oyetola ṣalaye pe igbesẹ yii jẹ ọkan lati dẹkun ajakalẹ arun coronaviris nipinlẹ naa.
Gomina sọrọ yii ninu atẹjade kan ti olori awọn oṣiṣẹ nipinlẹ Osun fi sita.
Oyetola sọ ninu atẹjade naa pe ijọba ipinlẹ Osun ṣetan lati ge ọwọja covid-19 kuru nipinlẹ Osun.
O ni idi niyii ti ijọba fi pese abẹrẹ coronavirus lawọn ileeṣẹ eto ilera kaakiri ipinlẹ Osun fawọn oṣiṣẹ lati le gbaa.
Sabaa Akintola: Pẹ̀lú ẹsẹ̀ kan, mo le gun kẹ̀kẹ́, lúwẹ̀ẹ́ tàbí rán aṣọ pẹ̀lú ẹ̀kọ́ dókítà
Gomina Oyetola ni gbigba abẹrẹ yii lo le daabo bo awọn oṣiṣẹ atawọn araalu lọwọ arun covid-19 to n ṣọṣẹ ni Naijiria.
Ijọba ipinlẹ Osun sọ ninu atẹjade ọhun gbogbo awọn ti ọrọ kan ko gbọdọ kọ eti ikun si aṣẹ gomina yii.
Bakan naa ni gomina rọ awọn oṣiṣẹ lati maa tẹle ilana ati dẹkun covid-19 bii ibomu wiwọ ati titakete siraẹni.
Gomina tun rọ wọn pe ki wọn yago fun apejọ ọpọ eeyan, ki wọn si maa fọ ọwọ wọn deedee pẹlu ọsẹ ati omi.
Oyetola rọ gbogbo awọn olori ileeṣẹ ijọba, ile ẹkọ giga, ati ijọba ibilẹ lati ri pe awọn oṣiṣẹ to wa labẹ wọn pa aṣẹ ijọba yii mọ.
Yoruba Nation: Kò sí ìdí tí à ó fi bínú sí Akeredolu lórí ọ̀rọ̀ Yorùbá Nation
Husband Searcher: Obìnrin náà ní òun yóò san owó orí ọkọ òun, ti òrùka ìgbeyàwó
Oríṣun àwòrán, Screen Shot
Ara meeriri kan ree o, a ri ori ologbo lori atẹ, Yoruba sa ni airin jinna ni airi abuke ọkẹrẹ, bi eeyan ba rin jinna, yoo ri ibi ti wọn ti n fi odo ibulẹ jẹun.
Bo se ri ree pẹlu obinrin wundia kan to wọ asọ igbeyawo maa kiri oju popo pe oun n wa ọkọ ti yoo fẹ oun sile, eyi to fun ọpọ eeyan niran wo.
Isẹlẹ yii si lo waye lagbegbe Buza nilu Dares Salam lorilẹede Tanzania, nigba ti obinrin naa gbe akọle kan lọwọ lati salaye pe oun n wa ọkọ ti yoo fẹ oun nitori ọjọ ti n lọ lori oun.
Fidio kan to gba awọn oju opo ayelujara kan lo se afihan obinrin naa pẹlu akọle to n salaye iru ọkọ to fẹ fẹ.
Gẹgẹ bi akọle naa ti wi, obinrin naa ni oun n wa ọkọ ti ọjọ ori rẹ wa laarin ogun ọdun si aadọrin ọdun, ti oun si setan lati san owo ori iru ọkunrin naa.
Hospital Wedding: Oṣù kan péré ni Tash fi ṣe ìgbéyàwó pẹ̀lú Simon kó tó kú
Bakan naa lo fi kun pe oun ti ra oruka igbeyawo pamọ eyi ti oun ati ọkunrin to ba gba lati fẹ oun yoo lo lati se igbeyawo.
Obinrin naa to wọ asọ igbeyawo tun sisọ loju rẹ pe ẹgbẹrun lọna mejilelogoje sile owo ilẹ Tanzania.
O fikun pe ẹlẹsin Kristiẹni ni oun amọ oun setan lati di ẹlẹsin musulumi to ba jẹ ọkunrin to fẹ fẹ oun jẹ ẹlẹsin Islam.
O ni irufẹ ọkunrin naa gbọdọ ni ibẹru Ọlọrun lọkan, ko si tun ni itẹriba pẹlu, to si tun gbọdọ ni ifẹ oun pupọ.
Obinrin ọhun wa fi ọwọ gbaya pe owo ko ni jẹ isoro awọn nitori Ọba Oke fi owo da oun lọla pupọ.
Yatọ si eyi, obinrin naa ni oun yoo maa lọ kaakiri awọn agbegbe to wa lorilẹede naa, lati kede pe oun n wa ade ori.
"Toríi ""Coro"", ẹ wo bí ètò ìsìn ìgbéyàwó orí ayélujára Zoom ṣe lọ"
Olojo Festival 2021: Aisha Yesufu ní káwọn aráàlú yé gbé ohun tó yẹ kí wọn ṣe, kọ́ Ọlọ́run lọ́rùn
Oríṣun àwòrán, Ooni of Ife
Lọjọ Aje ni iroyin jade pe Ọọni ile Ife, Ọba Adeyẹye Ogunwusi Ọjaja keji ti wọ ipebi fun ọjọ meje, gẹgẹ bi ara eto ayẹyẹ ọdun Ọlọjọ to maa n waye ni ọdọọdun.
Ooni, ninu ọrọ to fi ransẹ si araalu, ko to wọ ipebi lọ fun ọjọ meje salaye pe, ara ohun ti oun yoo ṣe lasiko naa ni lati gbadura ki Eledumare fọwọkan awọn oloṣelu ati adari gbogbo ninu.
Amọsa, ọrọ naa ti n fa oniruru ariyanjiyan laarin awọn ọmọ Naijiria. Lara awọn to ti sọrọ lori rẹ ni eekan ajafẹtọ araalu ni Naijiria, arabinrin Aisha Yesufu; ẹni to ni awada nla lọrọ naa jẹ fun oun nigba ti oun gbọ.
O ni kawọn ómọ Naijiria yee reti ki Olorun wa ba wọn ṣe ohun ti awọn funra wọn le ṣe.
Loju Aisha Yesufu, Olorun ti ṣe eyi to ju ninu ọrọ nipa fifun wa ni anfani ati agbara lati dibo yan awọn aṣiwaju rere, sibẹ ọpọlọpọ ni kii lo agbara naa.
Pẹlu bi eto idibo apapọ ti ọdun 2023 se n bọ lọna bayii, o ni ki awọn ọmọ Naijiria lo anfani ati agbara naa lo ja julọ.
Oríṣun àwòrán, Ooni of Ife Facebook
Gẹgẹ bi ara igbesẹ fun ayẹyẹ ọdun Ọlọjọ ti Ọdun yii, Ọọni ile Ifẹ, Ọba Adeyẹye Enitan Ogunwusi, Ọjaja keji ti wọ ipebi lọ lọjọ Aiku, nibi ti yoo wa fun ọjọ meje.
Itumọ ọdun ọlọjọ ni ọjọ ti ọjọ kọkọ bẹrẹ si ni jẹ ọjọ. Iyẹn ni pe ọjọ ti ojumọ kọkọ mọ lorilẹ aye.
Ninu iṣẹṣe ilu Ile Ifẹ, ọdun ọlọjọ ni wọn ya sọtọ lati ṣe ayajọ ọjọ ti Olodumare kọkọ da ile aye.
Ninu ọrọ rẹ ki o to wọ inu ipebi lọ Ọọni Ogunwusi ni ko si ohun meji ti oun nilo lati ṣe ninu ipebi ọlọjọ meje naa ju gbigba adura fun idagbasoke orilẹede Naijiria.
Olori ọba alade naa ni bi awọn ọmọ Naijiria ba woye daadaa, ọpẹ lo yẹ Naijiria paapaa pẹlu ajakalẹ arun COVID-19 to gbode lagbaye ṣugbọn ti ọṣẹ rẹ ṣu n mọ niwọnba ni Naijiria.
O ni sibẹ awọn adari ko gbọdọ sinmi lati rii pe ignayegbadun awọn araalu jẹ wọn logun. Ọọni Ogunwusi fi kun un pe idi gan niyi ti oun yoo fi lo ọjọ kẹfa ninu ipebi lati gbadura fawọn aṣiwaju ni Naijiria.
Olojo festival: Fídíò bí èrò ṣe darapọ̀ mọ́ Ọọ̀ni láti ṣọdún Ọlọ́jọ́ nílé Ifẹ̀ nìyí
Wiwọ ipebi ṣaaju ọdun ọlọjọ ṣe pataki pupọ, idi si niyi ti mi o le fi ṣere rara nitori ajogunba lọwọ awọn baba nka mi lati ẹgbẹkẹgbẹ ọdun sẹyin ni.
Bakan naa lo fi kun pe oun yoo lo asiko naa lati gbadura si Eledumare ko fọwọ tọ awọn oloṣelu lọkan ki wọn lee dẹkun fifi aye araalu ta keke, ki wọn si lee maa tẹti si awon ohun gbogbo to n dun araalu lọkan.
Sabaa Akintola: Pẹ̀lú ẹsẹ̀ kan, mo le gun kẹ̀kẹ́, lúwẹ̀ẹ́ tàbí rán aṣọ pẹ̀lú ẹ̀kọ́ dókítà
Seyi Makinde Defection: PDP ní ọ̀rọ̀ Fani-Kayode kò ṣé tẹ̀lé, asọ̀rọ̀ àná di bámíì ni
Oríṣun àwòrán, Seyi Makinde/ Facebook
Ẹgbẹ oselu PDP nipinlẹ Oyo ti ke s'awọn ọmọ Naijiria, lati fi ẹyinkule ọwọ da gbogbo ọrọ ti Fẹmi Fani-Kayọde ba sọ nu nitori atimaasebo rẹ ti fihan pe, ko duro soju kan ri, bẹẹ ni asọrọ ana di bamii ẹda ni.
Bẹẹ ba gbagbe, Minisita ana feto irina ofurufu, Femi Fani-Kayọde lo ni oun lo ṣokunfa bi awọn gomina kan ṣe dara pọ mọ ẹgbẹ oselu APC ati pe laipẹ Gomina Makinde tipinlẹ Ọyọ naa pẹlu yoo fo fẹrẹ lọ si APC.
Fani-Kayode sisọ loju ọrọ yii lasiko to n salaye idi to se kuro ninu ẹgbẹ PDP, rekọja lọ si APC laipẹ yii.
Amọ nigba to n ba BBC Yoruba sọrọ lori ohun ti Fani-Kayode sọ yii, ẹgbẹ PDP ni lọwọ yii, awọn to n ko ba igbaye-gbadun araalu ni wọn n korajọ si ẹgbẹ oṣelu APC, nitorina ajegbodo to n wẹni kunra lọrọ Fani-Kayọde.
Akọwe ipolongo f'ẹgbẹ oṣelu PDP nipinlẹ Ọyọ, Onimọ ẹrọ Hakeem Ọlatunji woye pe niwọn igba ti Aṣiwaju Bọla Ahmed Tinubu ko ti lee kuro lẹgbẹ oṣelu APC, ko si ohun ti yoo yẹju Makinde pẹlu kuro lẹgbẹ oṣelu PDP.
Seyi Makinde: Ẹ̀yin tẹ́ fẹ́ fi ọ̀rọ̀ ẹ̀sin ba Oyo jẹ́, ẹ ṣọ́ra ṣe
A ko fẹ Seyi Makinde ninu APC Oyo, yoo ba ọja jẹ fun wa ni - Abass Aleshinloye
Bakan naa ninu ọrọ tirẹ,  ẹgbẹ oṣelu APC ni ipinlẹ Ọyọ ni bi ẹlẹṣẹ to n lọ ṣọọsi tabi mọṣalaṣi fun irapada ọkan rẹ lọrọ Gomina Makinde yoo ri bo ba fẹ wa si ẹgbẹ oṣelu APC.
Ọkan lara awọn eekan ẹgbẹ oṣelu APC ni ipinlẹ ọyọ, Ọgbẹni Ayọdeji Alẹshinlọyẹ ṣalaye fun BBC News Yoruba pe iru wọn, a kii fa akoso ṣọọṣi tabi mọṣalaṣi ke wọn lọwọ.
O fi kun un pe gomina ipinlẹ Oyo, Seyi Makinde yoo kan wa ba ọja jẹ fun ẹgbẹ oṣelu APC ni ipinlẹ Ọyọ ni.
Ẹgbẹ oṣelu APC ni bi gomina Makinde ba ti le fi ọwọ sibi tọwọ gbe to si ṣetan lati tẹle ilana ofin ẹgbẹ oṣelu APC mu.
Bo ba wa, a jẹ pe o ti di atunbi ni, ṣugbọn a ko ro pe yoo lee wa darapọ mọ ẹgbẹ oṣelu APC.
Ọgbẹni Ayọdeji Alẹshinlọyẹ to jẹ alaga ajọ awọn alaga kansu, ALGON tẹlẹ ni ipinlẹ Ọyọ ni ko saye fun un lati dije fun ipo gomina lẹgbẹ oselu APC bi o ba jẹ pe nitori atidije lo tori fẹ wa si ẹgbẹ naa.
Sabaa Akintola: Pẹ̀lú ẹsẹ̀ kan, mo le gun kẹ̀kẹ́, lúwẹ̀ẹ́ tàbí rán aṣọ pẹ̀lú ẹ̀kọ́ dókítà
Insecurity In Nigeria: Ẹ yàgò fún ádùrá ṣiṣe nínú igbó kí ẹ má kò sí ọwọ àwọn ajínigbe-Iléeṣẹ́ ọlọ́pàá
Oríṣun àwòrán, Oasis of God Tv
Ileeṣẹ ọlọpaa nipinlẹ Ogun ti kilọ fawọn olujọsin lati yago fun ṣiṣe adura ninu igbo, ki wọn ma ba ko si ọwọ awọn ajinigbe.
Ninu atẹjade kan ti wọn fi sita gba latọwọ alukoro ọlọpaa ipinlẹ Ogun, Abimbola Oyeyemi, ileesẹ ọlọpaa ni ilu ti le kọja ki eeyan maa fi ara rẹ sinu ewu adura ṣiṣe ninu igbo.
Oyeyemi sọ pe bo tilẹ jẹ wi pe awọn araalu lẹtọ lati jọsin, amọ wọn ko gbọdọ maa ṣe adura lawọn agbegbe to ba da paro paro.
O ni iwe mimọ ni bi a baa n ṣe adura, ki a ma sun asunpara bakan naa.
Lọpọ awọn igbo to wa ni ipinlẹ Ogun, ṣiṣe eto isin adura paapa fawọn ẹlẹsin Kristẹni jẹ nkan to wọpọ.
Ipenija aabo lẹnu ọjọ mẹta yii si ṣe okunfa bi awọn ajinigbe ti ṣe n sa si abẹ igbo kijikiji lati ji awọn eeyan gbe, nibi ti wọn ba ti n ṣe ijọsin tabi iṣẹ wọn.
Tunde Bakare: Àjọjẹ kò dún bẹ́nìkan kò ní ló fa ìjà S Igboho,bẹ́ẹ̀ ìjọbati gbẹ́rù kọjá orí
Ni ipinlẹ Ogun paapa lawọn ilu to ba sun mọ igbo tabi ibode pẹlu orileede mii bi Benin, iṣẹlẹ ijinigbe ko jẹ tuntun.
Oyeyemi ṣalaye pe, iṣẹ ipese aabo yii, ti gbogbo ara ilu nii ṣe, tori naa, kawọn araalu daabo bo ara wọn ati dukia wọn.
Amọ ṣa, o ni ti o ba wa di dandan ki wọn ṣe ijọsin adura wọn yii, ki wọn kan si agọ ọlọpaa to wa ni itosi wọn fun aabo tabi imọran to peye.
Anti-Open Grazing law: Gómìnà ìpínlẹ̀ Eko tí buwọ́lu òfín máfi ẹran jẹko láàrín ìgboro l'Eko
Oríṣun àwòrán, @jimidisu
Gomina ipinlẹ Eko Babajide Sanwoolu ti buwọlu ofin to de fifi ran jẹ laarin igboro ni ipinlẹ Eko.
Ohun ti eyi tunmọ si ni pe ẹnikẹni ti o ba da ẹran jẹ laarin ilu ni itako ofin yoo foju wina ofin.
Gomina buwọlu ofin yi ni ọjọ Aje lẹyin tawọn ọmọ ile aṣofin ipinlẹ naa fi ontẹ jan lẹyin ijiroro ni nkan bi ọsẹ kan sẹyin.
Awuyewuye ofin to de fifi ẹran jẹko ati eleyi to ni ṣe pẹlu owo ori VAT jẹ eleyi tawọn aṣofin ipinl Eko jiroro le lori laipẹ yi.
Bi a ko ba gbagbe Olori ile naa, Mudashiru Obasa dari akọwe ile, Lekan Onafeko lati fi ẹda iwe ofin VAT naa sọwọ si Gomina Babajide Sanwo-Olu fun ontẹ.
Ile igbimọ aṣofin ọhun tun buwọlu ofin to tako fifi ẹran jẹko laarin ilu nipinlẹ Eko.
Ondo Fulani Herdsmen: Àgbe mẹ́ta ní àwọn Fulani darandaran tún pa Ọ̀wọ̀, Ondo
Awọn ofin mejeji naa gba ontẹ lasiko ti awọn aṣofin ile ofọwọ si nibi ijoko wọn lẹyin ti wọn ti ka fun igba kẹta.
Ni kete ti wọn buwọlu ofin naa tan, Olori ile ọhun kan sara si awọn ọmọ ile fun akitiyan wọn lati ri pe ipinlẹ Eko ko rẹyin laarin awọn akẹgbẹ rẹ.
Ipìnlẹ Eko naa ti darapọ mọ awọn ipinlẹ mii bi Ondo to ti buwọlu ofin to tako fifi ẹran jẹ laarin ilu ni Naijiria.
Africa Eye: Ọmọ ìgboro méje tó ń jò tà di aláṣeyọrí
Yoruba ni ẹni ti ko ba le se bi alaaru ni Oyingbo, ko le se bi Adegboro ni ọja ọba, ẹni ti yoo si ga, ẹsẹ rẹ yoo tiirin.
Owe yii lo ba awọn gende meje kan mu, ti wọn dagba soju popo lai ri isẹ oojọ kankan se, wọn ko nile lori bẹẹ naa si ni wọn ko ri ẹni fẹyin ti.
Awọn gende yii ko ri ọwọ mu lọ sẹnu, ti wọn si n gbe igbe aye wọn bi alaini ẹnikan, koda oju wọn n ri mabo loju popo ti wọn dagba si.
Àwọn iwadii ọtẹlẹmuyẹ Africa Eye tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí:
Idi ree ti ẹka iwadi ọtẹlẹmuyẹ BBC nilẹ Afirika se n tẹle wọn lẹyin lati finmu finlẹ mọ ibi ti ọrọ aye awọn gende meje naa yoo pada yọri si.
Amọ lẹyin ọdun meji, ori awọn ọmọ naa pada wa sọre, oju popo naa si ni wọn ti rinna pade oloore wọn.
Ijo jijo loju popo ti wọn yan laaye gbe wọn de ibi giga, ti wọn si kuro ni ojo popo.
Igangan Mayhem: Obìnrin Fulani kan ní òun pàdánù ọkọ, ọmọ mẹ́ta àti gbogbo dúkìá torí ìjà
Yoruba ni ọrọ kanlẹ, kan baale, koda yoo kan jẹjẹ ni mo joko mi nitori ibẹrẹ ogun laa mọ, ko si ẹni to le sọ opin rẹ.
Obinrin Fulani kan ree, Aishatu Saado to n fi omije salaye ipo ibanujẹ ayeraye to wa bayii nitori aawọ ati rogbodiyan to waye laarin ẹya Yoruba ati awọn Fulani.
Nigba to n ba BBC Yoruba sọrọ, Aishatu ni lẹyin ti Sunday Igboho wa si Igangan, to si le Seriki Fulani kuro, ni awọn araalu sọ fun ọkọ oun pe ko bura lati maa gbe nilu naa lai gba abọde fun awọn lọdọ Fulani ẹgbẹ rẹ.
O ni ọkọ oun bura lootọ amọ ko pẹ lẹyin igba naa ni awọn Fulani wa kọlu Igangan, ti wọn si pa ọpọ eeyan, ti wsn tun ba ọkẹ aimọye dukia jẹ.
Obinrin Fulani naa idi ree ti awọn eeyan kan fi wa kọlu awọn, ti wsn si pa ọkọ oun ati ọmọ rẹ mẹta pẹlu ọmọ-ọmọ rẹ kan.
Koda, o fikun pe wọn jo gbogbo dukia awọn, ti oun si wa ni kolobo bayii nitori ko si ilegbe mọ tabi dukia kankan, bẹk ni oun ko ni asọ lara mọ.
Obinrin naa, to n gbe nile ọmọ ẹgbọn ọkọ rẹ to ti di oloogbe naa ni isẹ Alfa ni ọkọ oun n se ati agbẹ, awọn kii si se darandaran rara.
Sunday Igboho: Ẹgbẹ́ ìlànà ọmọ Oodua ní kí Yorùbá túbọ̀ kún fún àdúrà kí ayọ̀ náà le dé
Oríṣun àwòrán, Sunday_igboho1/Instagram
Ẹgbẹ to ko gbogbo awọn to n pe fun idasilẹ Orilẹede Yoruba sodi, Ilana Ọmọ Oodua ti ke sawọn ajijagbara fun ilẹ Yoruba naa, lati maa foju sọna fun iroyin ayọ kan laipẹ nipa Oloye Sunday Adeyẹmọ, ti ọpọ mọ si Sunday Igboho to wa lahamọ lorilẹede Benin republic.
Maxwell Adelẹyẹ, to jẹ alukoro ẹgbẹ Ilana Ọmọ Oodua, ṣalaye ninu ifọrọwerọ kan pẹlu iwe iroyin The Punch lọjọ Aje pe, iroyin naa ko ni pẹ de nitori awọn ẹgbẹ ati lọgbalọgba to n ṣugba a rẹ ko sinmi.
Bakannaa lo ke s'awọn ọmọ Yoruba lati tubọ kun fun adura, ki iroyin ayọ naa le dohun ni kiakia.
Ni ọjọ kinni oṣu keje ọdun 2021 lawọn oṣiṣẹ DSS kọlu ile Sunday Igboho , wọn mu eeyan mejila, won si tun pa eeyan meji miran nibẹ ṣugbọn ori ko Sunday Igboho ni titẹ yọ lọjọ naa.
Awọn ọlọpaa ni papakọ ofurufu Cadjèhoun Airport nilu Cotonou mu Sunday Igboho nigba to n gbiyanju ati rinrinajo lọ sorilẹede Germany pẹlu iyawo rẹ.
Yoruba Nation: Kò sí ìdí tí à ó fi bínú sí Akeredolu lórí ọ̀rọ̀ Yorùbá Nation
Wọn ti fi iyawo rẹ silẹ, ṣugbọn Igboho funrararẹ ṣi wa ni lọgba ẹwọn lorilẹede Republic of Benin.
Laipẹ yii ni Sunday Igboho ke sawọn ololufẹ rẹ lati maṣe lo orukọ oun fun iwọde kankan lọwọ yii.
Lasiko to fi wa lọgba ẹwọn to n reti idajọ ni Benin Republic, Onidajọ Ladiran Akintọla tileẹjọ giga kan nipinlẹ Ọyọ ti paṣẹ pe ki DSS o san ogun biliọn naira fun Sunday Igboho lori ikọlu ile rẹ atawọn dukia olowo iyebiye ti wọn bajẹ nibẹ.
Igangan Mayhem: Obìnrin Fulani kan ní òun pàdánù ọkọ, ọmọ mẹ́ta àti gbogbo dúkìá torí ìjà
Sudan Failed Coup: Ọkọ̀ ìjagun kún ojú pópó láwọn òpópónà ìlu Khartoum
Oríṣun àwòrán, AFP
Ijọba ilẹ Sudan ti kede pe oun ti doju ete iditẹ gbajọba bolẹ lati ọdọ awọn ọmọ ogun kan lorilẹede naa.
Iroyin naa ni ọpọ rogbodiyan ologun lo ti n waye ni olu ilu orilẹede naa, Khartoum ati ilu Ombudman, ti wọn si ti gbe afara odo Nile to wa nilẹ naa tipa
Lootọ ni ete lati ditẹ gba ijọba n waye amọ a ti doju rẹ bolẹ, o si yẹ ki awsn araalu gan tako pẹlu Ileesẹ iroyin kan lorilẹede Sudan lo sọ bẹẹ ni aarọ ọjọ Isẹgun.
Bakan naa nileesẹ iroyin AFP kede pe awọn aditẹgbajọba naa tun gbiyanju lati gba akoso ileesẹ iroyin to jẹ ti ijọba apapọ orilẹede naa.
O ni ijọba orilẹede Sudan ni oun ti n saayan lati lati gbakoso ohun gbogbo lorilẹede naa ati isẹlẹ to waye ọhun.
Fidio kan to gba awọn oju opo ikansiraẹni lori itakun agbaye lo safihan ọkọ ijagun Armoured tank lawọn oju popo.
Igangan Mayhem: Obìnrin Fulani kan ní òun pàdánù ọkọ, ọmọ mẹ́ta àti gbogbo dúkìá torí ìjà
Ileesẹ iroyin AFP si ni lilọ bibọ ọkọ ati ero ti n waye diẹdiẹ lawọn opopona to wa nilu Khartoum.
Gẹgẹ bi iwe iroyin Reuters se wi, agbẹnusọ fun ileesẹ ologun lorilẹede Sudan, Mohammed Al Faki Suleiman kede pe ifọrọwanilẹnuwo fawọn afurasi aditẹgbajọba ti ọwọ tẹ yoo bẹrẹ laipẹ.
Ni ọdun meji sẹyin, ni wọn doju ijọba aarẹ Omar Al-Bashir bolẹ, tii se olori orilẹede Sudan to ti pẹ nipo naa julọ.
Lẹyin naa ni wọn fẹnu ko lori ilana bi wọn yoo se pin ipo laarin ara wọn eyi to fidi agbekalẹ isejsba naa mulẹ, ninu eyi ti awọn ologun, oloselu atawọn ikọ to n fi apa janu wa.
Oluwo: Ọba Yorùbá tó bá ń bọ òrìṣà, kò sí ìsinmi fun
Oríṣun àwòrán, emperortelu1/Instagram
Oluwo tilu Iwo, Ọba Abdulrashed Adewale Akanbi, Telu kinni ti kede pe ẹkun ariwa ni ipo agbara yoo ma duro si ayafi ti iran Yoruba ba yi iwa wọn pada.
Oluwo ni awọn ọba ẹkun ariwa Naijiria lo maa n sin Ọlọrun kan soso, tawọn ọba ilẹ Yoruba si maa n sin orisa.
O wa gba wọn nimọran pe ti ilẹ Yoruba ba fẹ maa wa nipo giga, asiko ti to, ki wọn tun ero wọn pa, ki wọn si pa orisa sinsin ti.
Oluwo gbe imọran yii kalẹ nibi isọji itusilẹ kan to waye nilu naa nibi ti ọba naa ti sọrọ fun awọn olujọsin.
Ọba Akanbi ni gbogbo awọn to n bọ orisa ni yoo maa jo ajorẹyin nigba ti awọn to n sin Ọlọrun Ọba yoo maa lọ siwaju ati siwaju.
Coronavirus: Oluwo ní kò sí ẹ̀bùn òkè òkun tó lée mú òun gbàlejò láàfin
O mẹnuba iwe Saamu ori kẹrindinlogun ẹsẹ ikẹrin (psalm 16:4) to si gba awọn ojisẹ Ọlọrun niyanju lati saayan bi iwa ibọrisa yoo se di ọrọ itan.
"Ta ni Sango, Ogun, Ọya, Ogun, Osun atawọn orisa alagbara miran tawọn eeyan nbọ?
Mo fẹ lu gbogbo ẹyin ọba nilẹ Yoruba, awọn pasitọ, wolii ati ẹni ọwọ lọgọ ẹnu, isẹ nla lẹ n se.
Ohun Ọlọrun si ti wa silẹ Yoruba pe ọba ti ko ba kọ orisa silẹ, ko ni nisinmi, gbogbo isoro tẹ si n koju lonii, isẹ ọba awọn ọba alaye ni.
Awọn ọba yii lo n gba abọde orisa sinu aafin wọn, eyi to yẹ ko jẹ ti Oluwa, ki wa ni yoo gbẹyin rẹ, se wọn ko wa ni maa ja bi?
Ki lẹ ro pe yoo jẹ ipa rẹ lori awọn araalu nigba ti ibi asẹ ba ti daru? Ẹyin gan ti wọ wahala nitori naa, ẹ ma ja mi niytan amọ ẹ gba imọran mi."
Oluwo wa gba awọn olujọsin naa nimọran lati lọ sọ fawọn ọba wọn pe ko gbọdọ si ibọrisa ninu aafin nitori wọn ko le maa sin Ọlọrun ati orisa papọ, ki wọn si ni ki ibukun maa pọ si, rara o.
"Orisa bibọ ni isoro ilẹ Yoruba, ki agbara si to le wa silẹ Kaarọ Oojire, a gbọdọ dẹkun orisa bibọ.
Agbara wa lẹkun ariwa nitori wọn korira orisa bibọ, ẹ ko si le ri orisa kankan ni sakani wọn.
Orisa bibọ jẹ ajeji nilẹ Yoruba, ko si ni dara fun awọn orisa naa, aye wọn ti bajẹ nitori naa, ẹ ye lọ si ojubọ wọn mọ."
Igangan Mayhem: Obìnrin Fulani kan ní òun pàdánù ọkọ, ọmọ mẹ́ta àti gbogbo dúkìá torí ìjà
Yoruba Nation Rally shooting: Ẹrí rè é pé lóòótọ́ ní ọta ìbọn pá Jumoke Adeleke lásìkò ìwọ́de Yoruba Nation
Oríṣun àwòrán, others
Imọlẹ ti bẹrẹ si ni  tan si ọrọ iyinbọnpaniyan arabinrin Jumoke Oyeleke ti ọta ibọn ṣekupa lasiko iwọde Yoruba Nation lọjọ Kẹta oṣu Keje ọdun yi.
Ko si sẹyin bi ileeṣẹ ọlọpaa ni Eko ṣe gba pe lootọ ni ọta ibọn ba Jumoke to ṣi mu ẹmi rẹ lọ.
Ọlọpaa to wa nidi iwadii iṣẹlẹ yi, IPO,  Onyeisi Nwaolai lo jẹri si ọrọ yi ninu atẹjade to gbe sita nipa ohun to wa nidi iku Jumoke.
Ninu iwe ijẹri  yi ti ileeṣẹ iroyin Naijiria Punch sọ pe o tẹ awọn lọwọ,awọn ọlọpaa lawọn ko le sọ pato ẹni to yinbọn naa ṣugbọn ọta ibọn ba Jumoke lootọ.
O sọ ninu iwe naa pe ''eeyan mẹjọ lo mu ẹri wa fun wa to fi mọ iya oloogbe Jumoke ati  ẹni to ni ṣọọbu ti ọta ibọn ti ba,Tosin Oyemade''
Igangan Mayhem: Obìnrin Fulani kan ní òun pàdánù ọkọ, ọmọ mẹ́ta àti gbogbo dúkìá torí ìjà
''Iwadii ṣi n tẹsiwaju lori ọrọ naa amọ ati ribi fidi ọrọ mulẹ bayi pe ọta ibọn ti a ko mọ ẹni to yin lo ba Jumoke''
Ninu ọrọ rẹ bakan naa, Onyeisi sọ pe awọn ri nkan ija oloro gba lọwọ awọn oluwọde kan ati pe awọn ti n ṣe ayẹwo finifini lori wọn.
Bi a ko ba gbagbe lọjọ Kẹta oṣu Keje ni awọn oluwọde Yoruba Nation Rally pe jọ si ọgba Gani Fawehinmi to wa ni Ojota.
Nigba tawọn ọlọpaa bẹrẹ si ni le awọn oluwọde yi ni ọta ibọn ba Jumoke ni ṣọọbu rẹ to wa ni Ojota lẹba ibi ti iwọde yi ti waye.
Awọn ọlọpaa kọkọ sọ ni ọjọ naa lọhun pe oku tawọn eeyan gbe ju sibẹ ni oku Jumoke wi pe kii ṣe ọta ibọn lo ba a.
Ṣugbọn awọn mọlẹbi Jumoke ati awọn araadugbo sọ pe nigba tawọn ọlọpaa le oluwọde wọ adugbo naa ni  ọta ibọn pa Jumoke.
Ko pẹ si igba naa lawọn ọga ọlọpaa pada lọ ki mọlẹbi Jumoke si ile ti wọn si gbe oku rẹ lọ si aaye igbokupamọ si ki wọn to pada wa sinku rẹ.
Iwadii ṣi n tẹsiwaju lati mọ boya ọta ibọn lati ọdọ ọlọpaa lo ṣeku pa Jumoke lootọ.
Sabaa Akintola: Pẹ̀lú ẹsẹ̀ kan, mo le gun kẹ̀kẹ́, lúwẹ̀ẹ́ tàbí rán aṣọ pẹ̀lú ẹ̀kọ́ dókítà
Daramola Abiodun tó jé agbenusọ ‘Immigration’ ní òrò kò rí béè rárá ní ilé isẹ ìwé ìrìnnà ní Ekiti
Iroyin to koko jade sita ni pe awon osise ile ise to n risi wiwole ati jijade awon eniyan ni Naijiria ti a mo si : 'Immigration service'  ti lu okunrin kan se lese.
Ogbeni Emmanuel Omoboriowo ni aworan re lori ibusun nile iwosan ikoni nise isegun ni Fasiti Afe Babalola ni ipinle Ekiti gba ori ayelujara kan tele.
O ni awon osise to n ri si iwole ati ijade awon eniayn Naijiria ni o fesun kan pe won kolu oun lasiko ti oun wa gba iwe iriina ololufe oun ninu ogba won ni ipinle Ekiti.
Iroyin naa ni awon osise ileese naa fiya je Emmanuel Omoboriowo to je eni odun mejidinlogbon to lo sibe lo gba iwe irinna ololufe re.
O ni won na oun bi eni n lu bara ni leyin ti won ni ki oun ma wo inu ileese naa ki oun si gbe moto oun sita.
O tun so pe nina naa kan eegun kokose oun ati orun oun pelu egungun owo otun oun.
Sugbon agbenuso ileese to n risi iwole ati ijade awon eeyan ni Naijiria, Ogbeni Daramola Abiodun so pe oro ko ri bee rara.
O ni pe Ogbeni Emmanue wa oko re wo inu ogba ileese naa ni ona to fi fee se awon ero mii lese ni eyi to tapa si ofin ileese naa ni.
Ni eyi ti o si n ba won lo agidi nibe ki oro to ba ibomii yo.
Ogbeni Abiodun ni ko si osise kankan to kolu ogbeni Omoboriowo rara bikose pe won pase pe ko gbe oko re sita kuro nibe ni ko ma baa se akoba fun awon ero miran to wa ninu ogba ileese naa ni.
Joke Silva: Olu, ó tó gẹ́ pẹ̀lú obìnrin yìí níkan tó ń ba ẹ ṣeré ìfẹ́ nínú sinimá
Ogbeni Abiodun Daramola ni pe oro naa ti de iwaju awon agbofinro ni ipinle Ekiti bayii.
Sugbon koko ti opo n so lori ayelujara ni pe atunse ye ko ba bi awon osise ileese to n mojuto iwe irinna lilo bibo ni Naijiriia se n se kaakiri agbaye si awon omo Naijiria.
Thyroid foundation: eéwo ni mo kọ́ka pè é àṣé gẹ̀gẹ̀ ọrùn tó lé ẹbí, ará àti ọ̀rẹ́ ni mo n
Iyabo Oko: Foluke Daramola ní màmá náà nílò láti na iṣan rẹ̀, wọ̀n sì nílò owó si
Oríṣun àwòrán, Screen shot
Iroyin ayọ to n jade sigboro bayii ni pe gbajumọ osere tiata nni, Iyabo Oko to n saisan ti ri iwosan gba.
Bẹẹ ba gbagbe, laipẹ yii ni osere tiata kan, Foluke Daramola kede loju opo Instagram rẹ pe ojojo n se Iyabo Oko, ti ara rẹ ko si le.
Ninu fidio naa si ni Foluke ati ọmọ Iyabo Oko ti n bẹbẹ fun iranwọ owo fun osere tiata naa, ki ara rẹ le ya pada.
Amọ ninu fidio miran to gbe soju opo Instagram rẹ lọjọ Isegun, ni Foluke Daramola ti sisọ loju rẹ pe Ọlọrun ti gbọ adura awọn lori Iyabo Oko.
Fidio naa lo kede pe ile iwosan ti ni ki Iyabo Oko maa lọ sile ams o nilo dokita ti yoo maa ba na isan ati egungun rẹ.
"Foluke Daramola ni ""Dokita ti ni ka maa gbe mama lọ sile amọ wọn nilo lati maa se Physio, ki isan ati egungun wọn le na."
A nilo eeyan to le maa ba wa se ni owo ti ko wọn ju, ti yoo ma ba wa tọju wọn.
"Ẹnikẹni to ba ni oju aanu, ti owo rẹ ko wọn ju, ẹ wa ba wa se."""
Lẹyin naa la ri ti Iyabo Oko n sọrọ, to si n fi osere tiata kan, Aderupoko, toun naa wa nile iwosan pẹlu Foluke se yẹyẹ pe o fẹran obinrin pupọ.
Iyabo Oko tun wa dupẹ pupọ lọwọ awọn to se iranwọ owo fun lati se itọju rẹ.
"Ẹ jọwọ, a si nilo iranwọ owo, ẹ ba wa tun fi owo ransẹ fun itọju mama Iyabo Oko, ọra wa ko ni su yin, tiyin naa ko ni su Ọlọrun.
Gbogbo owo tẹ da fun ajọ Para lori Iyabo Oko la gbe silẹ fun wọn lati fi se itọju wọn."
Labẹlẹ naa si la n gbọ ti mama naa n se adura kikankan fun awọn eeyan to n da owo fun pe wsn ko ni fi oju sunkun ọmọ.
Foluke ni ilu Ibadan ni Iyabo Oko wa, ẹnikẹni to ba si ni ohunkohun to fẹ se fun mama naa, le lọ se abẹwo si.
Igangan Mayhem: Obìnrin Fulani kan ní òun pàdánù ọkọ, ọmọ mẹ́ta àti gbogbo dúkìá torí ìjà
Hijab Female Footballer: Zulfah ní àlá òun ní láti jẹ́ agbábọ́ọ̀lù obìnrin tó dáńtọ́
Yoruba ni ọmọ ti yoo ba jẹ Aṣamu, kekere ni yoo ti maa jẹ ẹnu ṣamu-ṣamu.
Ọmọ ọdun mẹtadinlogun ni ọdọbinrin Zulfah Abdulazzes to si n lo iboju tawọn ẹlẹsin musulumi tawọn mọ si Hijab.
Amọ eyi mu ki Zulfah da yatọ lori papa gẹgẹ niwọn igba to jẹ pe isẹ bọọlu gbigba fawọn obinrin lo yan laayo.
Lasiko to n ba BBC Yoruba sọrọ, ọmọdebinrin naa ni ọmọ ọdun kan ati aabọ ni oun ti n gbe lọdọ iya oun agba, ki onitọun to jade laye lọdun 2017.
Akẹkọọbinrin agbabọọlu naa ni igbe aye le diẹ fun oun amọ afojusun oun ni pe lọjọ iwaju, ki oun di obinrin agbabọọlu to pegede julọ bii Azzezat Oshoala.
Amọ ti ko ba si lori papa lati gba bọọlu, obi, orogbo ati suti ni Zulfah maa n ta labẹ afara Ojota, ko le ri ọwọ mu lọ si ẹnu.
O wa salaye ọpọ ipenija to n koju lati awọn akẹẹgbẹ rẹ gẹgẹ bi agbabọọlu obinrin to n lo Hijab.
Iyabo Oko: Ọmọ òṣèré tíátà náà ní àìsí ọkọ̀ ayọ́kẹ́lẹ́ ṣe àkóbá fún ìtọ́jú màmá òun
Ni ọjọ Isẹgun la mu iroyin wa fun yin nipa ipo ti ara osere tiata nni, Iyabo Oko de duro.
Gẹgẹ ba se mu wa fun yin, wọn ti fi mama naa silẹ nile iwosan kan to wa nilu Ibadan, to si ti n lọ gba itọju ninu ile rẹ.
Amọ o nilo dokita onimọ nipa tito egungun ati isan, ta mọ si Physiologist, eyi ti yoo mu ki eegun ara rẹ tubọ le si.
Nigba to n salaye ohun to mu ki aisan mama rẹ tubọ peleke si lẹyin ọdun marun to ti bọ lọwọ arun rọpa-rọsẹ lẹyin to gba itọju nilẹ India ati UK.
Ọkan lara ọmọ mama naa, salaye pe aimaa lọ fun ayẹwo ati itọju loore koore nile iwosan lo se akoba, ti aisan naa tun fi yọju.
Hijab Female Footballer: Zulfah ní àlá òun ní láti jẹ́ agbábọ́ọ̀lù obìnrin tó dáńtọ́
Ohun to sẹlẹ yii lo fihan pe aisan yii ko ba ti yọju rara to ba jẹ pe mama mi ni ọkọ ti yoo maa gbe kiri.
"Ibi ti mama mi n gbe jinna pupọ si ile iwosan, o si maa n ro loju lati lọ nitori ko rọrun rara."""
Bakan naa lo fikun pe ọkada ni oun fi gbe Iyabo Oko de ikorita ile rẹ nigba to kọkọ ni aisan naa nitori ko si mọto to le gbe.
O salaye pe ikorita naa ni oun ti wa gba ọkọ to gbe lọ sile iwosan, ti wọn si sọ fun pe mama rẹ ti ni arun rọlapa-rọlẹsẹ, ta mọ si stroke lọdun diẹ sẹyin.
Ọmọ Iyabo Oko wa n bẹ awọn ẹlẹyinju aanu ọmọ Naijiria pe ki wọn dakun da owo jọ lati ra mọto fun mama oun, ko le maa fi rin, ki aisan naa ma baa tun yọju mọ.
"O ti to ọdun marun sẹyin ti aisan stroke akọkọ yọju amọ mama mi ko fẹ ki ẹnikẹni mọ nipa aisan naa.
Awọn ẹgbọn mi gbe lọ silẹ China fun itọju nla, ti ara wọn si ya amọ o se ni laanu pe lẹyin eyi, aisan naa tun ti sọ ọ wo fun igba meji ọtọọtọ mii.
O ni a ko gbọdọ sọ fun ẹnikẹni amọ ni ọsẹ kan sẹyin ni aisan naa tun de, eyi to se akoba fun awọn ọmọ ika ẹsẹ rẹ."
Ọmọ Iyabo Oko fikun pe mama oun ti n gbadun bayii, o ti n sọrọ, to si n da awọn eeyan mọ.
"Dokita tun ti wa fi da wa loju pe ta ba ri dokita to n na isan, to mọ isẹ rẹ nisẹ, idaniloju wa pe mama mi yoo le maa lo awọn ọmọ ika ẹsẹ rẹ."""
O wa mẹnuba pe awọn gbajumọ osere tiata bi Foluke Daramola, Iyabo Ojo, Mercy Aigbe ati Biodun Okeowo ni wọn ti se iranwọ owo fun mama oun.
Ayo Ewebiyi Mama Oriki: Ọwọ́ Òbí, Ìjọba àti àwọn Ọba ni ìdágbàsókè Yorùbá wà lásìkò yìí
Buhari Successor - Joe Igbokwe fèsì padà fáwọn àgbààgbà Ariwa tó ní ọ̀dọ́ àwọn ní ààrẹ ti ń bọ̀ ní 2023
Oríṣun àwòrán, State House
Eekan kan ninu ẹgbẹ oselu APC, Joe Igbokwe ti tutọ soke, fi oju gba a lori ikede kan ti awọn agbaagba  lẹkun ariwa naijiria fisita lori ẹni ti yoo rọpo aarẹ Muhammadu Buhari.
Ẹgbẹ awọn agbaagba ni Ariwa ilẹ yii lo kede ni Ọjọru pe ko si ohun to buru ninu ki aarẹ ti yoo rọpo Buhari tun wa lati ẹkun ariwa orilẹede yii.
Baba Ahmed, tii se agbẹnusọ fun ẹgbẹ awọn agbaagba naa fikun pe ẹkun ariwa Naijiria ko tii setan lati gbe ipo agbara silẹ lọdun 2023.
O wa gba awọn eeyan ti igbesẹ naa ko ba tẹ lọrun niyanju lati fi Naijiria fun awọn.
Amọ nigba to n fesi lori ọrọ yii, Igbokwe ni ọrun yoo ya bọ silẹ, ti ohun buruku yoo si maa ja lu ohun buruku, ti eeyan miran lati apa ariwa Naijiria ba tun rọpo aarẹ Buhari.
Igbokwe, ẹni to fi ọrọ naa lede loju opo ayelujara rẹ ni oun gbọ ohun ti Baba Ahmed sọ o amọ ọrun yoo bọ silẹ o.
Ọpọ ọmọ Naijiria si lo ti dara pọ lati maa tako ohun ti ẹgbẹ awọn agbagba Arewa sọ naa, tawọn gomina ẹkun guusu Naijiria naa si ti fun lesi pada pe awada akọ lasan lo n se.
Ondo School Without Chairs: Iléèwé kan rèé tí kò ní àga, tábìlì, olùkọ́, èlò ìkẹ́kọ̀ọ́
Oríṣun àwòrán, UCH
O kere tan, awọn dokita onisegun oyinbo bii ọtalelọọdunrun o din meje (253) ni wọn ti fi orukọ silẹ laarin ọgọrun ọjọ lati sisẹ pẹlu ijọba ilẹ United Kingdom.
Gẹgẹ bi oju opo itakun agbaye fun ajọ to n se akoso isẹ isegun nilẹ UK, to maa n fawọn dokita niwe asẹ lati sisẹ ti kede rẹ.
Laarin ọjọ Kẹwa osu Kẹfa si ogunjọ osu Kẹsan ọdun 2021, dokita ọmọ Naijiria bii ọtalelọọdunrun o din meje lo ti gba iwe asẹ lati sisẹ nilẹ naa.
Bakan naa, gẹgẹ bi iwe Punch ti salaye, laarin osu keje ọdun 2020 si osu Kẹsan ọdun 2021, awọn dokita to to ọtalelẹgbẹrin ati meji (862) lo ti gba iwe asẹ lati sisẹ ni UK lai naani arun Coronavirus to gbilẹ nibẹ nigba naa.
Lọwọ lọwọ bayii, dokita bii ẹgbẹrun mẹjọ ati ọrinlelẹẹdẹgbẹrin o din mẹta (8,737) ti wọn gba idanilẹkọ nipa isẹ dokita lorilẹede Naijiria, lo ti n sisẹ nilẹ UK.
Doctors‘ Strike: Àwọn dókítà tó ń woṣẹ́ níran ní UCH sọ̀rọ̀ lórí ẹ̀dùn ọkàn wọn
Nigba to n ba iwe iroyin naa sọrọ, igbakeji aarẹ ẹgbẹ awọn dokita to n gba imọ kun imọ ni Naijiria, Julian Ojebo ni o seese ki alekun ba bi awọn dokita se n lọ soke okun laarin ọsẹ melo kan si.
Ojebo ni ti ijọba ko ba san owo osu ati ajẹmọnu to yẹ fawọn onisegun oyinbo naa, o seese ki iye awọn ti yoo gba orilẹede Saudi Arabia lọ gan ju ti UK lọ.
O fikun pe o se ni laanu pe ijọba kuna lati wa ojutu si ohun tawọn dokita naa n beere fun lati ọjọ Kinni osu Kẹjọ ọdun 2021 ti wọn ti bẹrẹ iyansẹlodi.
Hijab Female Footballer: Zulfah ní àlá òun ní láti jẹ́ agbábọ́ọ̀lù obìnrin tó dáńtọ́
Akinyele Army Shooting: Àwọn olùgbé Akinyele figbe ta lórí ọ̀pọ̀ ọta ìbọn ológun tó ń wọnú ilé wọn
Lati ọjọ mẹta ni awọn ara agbegbe Omilabu ni ijọba ibilẹ Akinyele ni ilu Ibadan ti n kojú  yinyin ibọn loore-koore lati ọwọ awọn ọmọ ogun to wa ni Odogbo.
Adugbo Omilabu to paala pẹlu ibudo awọn ọmọ ogun ni Odogbo, Ojoo ni ilu Ibadan, ni ọta ibọn yinyin awọn ologun naa maa n rekọja si ati awọn adugbo to tun sun mọ.
Awọn aladugbo naa, to fi ẹdun ọkan wọn han lori ayelujara lo mu ki BBC Yoruba se abẹwo sibẹ lati wadi ohun gbogbo daju.
Lasiko abẹwo BBC si adugbo Omilabu naa, a gbọ pe isẹlẹ naa ko sẹsẹ maa waye, o si ti le ni ọpọ ọdun sẹyin ti wọn ti maa n gbalejo ọta ibọn awọ̀n ologun naa ninu yara wọn.
Alagba kan ni adugbo ọhun to ba ikọ BBC Yoruba sọrọ wi pe ọrọ naa ti wa ní ile ẹjọ nitori ko si iyipada lati ọdọ awọn ọmọ ologun, lẹyin ti awọn lọ parọwa fun wọn.
Awọn baba onile naa, ti wọn ko ogunlọgọ ọta ibọn to gba orule wọ yara wọn jade salaye pe, inu ewu ni awọn n sun, inu ewu si ni awọ̀n n ji si, igbakuugba si ni ọta ibọn le sere de ọdọ awọn.
Ibọn ti a wi ti ba ọpọlọpọ eniyan, o ti ba orule jẹ pupọ. Ti ẹ ba ni suuru diẹ, ẹ gbọ iro ibọn naa
"Nigba ti a se iwọde lo ba wọn, wọn fi da wa loju pe yoo dinku amọ ko si iyipada.
Ati ke si ijọba lati wa gba wa lọwọ ojo ọta ibọn naa, ko si wa nnkan se si ṣugbọn ko si iyipada kankan, ko da gan lọwọlọwọ bayii, wọn si n yin ibọn sita"""
Ọpọlọpọ awọn ara adugbo ni wọn maa n sa wọle ti ibọn ba ti n dun leralera, o si ti se ijamba fun ọpọlọpọ eeyan.
Akẹkọọ kan ni ibọn ba nile iwe kan to wa ladugbo yii, nibi to ti n sere ni ita, ti a pariwo sita, ko pẹ tun ni ibọn ba alaboyun, ile wosan awọn arabi naa ni a ru wọn lọ. 
"Ni pari, Alagba naa ni awon ko si ni ori ilẹ awọn ologun, ti ẹri si wa ti awon ti mu lọ si ile ẹjọ."""
Ki akọroyin BBC Yoruba si to pari ifọrọwanilẹnuwo to n se, lojiji lo n gbọ iro ọta ibọn nitootọ, to n dun lakọlakọ, ni akọroyin wa ba juba ehoro, to si sa asala si bibikan lati doola ẹmi rẹ.
Hijab Female Footballer: Zulfah ní àlá òun ní láti jẹ́ agbábọ́ọ̀lù obìnrin tó dáńtọ́
Ọmọ ẹgbẹ́ márùn ún lọ́dún mẹ́rin, Kí ló ń fa ikú ọ̀wọọ̀wọ́ lẹ́yìn Davido?
Oríṣun àwòrán, Instagram/Davido
Lagbo amuludun lọwọ yii, eeyan lee sọ pe nnkan ko fi bẹẹ fara rọ fun gbajumọ olorin David Adeleke ti ọpọlọpọ mọ si Davido.
Eyi ko seyin ariwo pe iku to n mu awọn eeyan lọ lagbo rẹ lati nnkan bi ọdun diẹ sẹyin.
Ọpọ awọn ololufẹ rẹ ni wọn ti n kọminu lori ipa ti iku awọn ọmọ ẹgbẹ rẹ wọnyi lee ni lara rẹ; ti awọn kan si n ba a gbadura ki Eduwa ba a dawọ ibi duro.
Awọn ọrẹ ti gbajumọ olorin naa to ti padanu laarin ọdun mẹrin pọ diẹ.
Oun pẹlu si ti fi ara rẹ si abẹ iṣọra lẹyin ti pasitọ kan sọ asọtẹlẹ bi osu kẹfa, ọdun 2021 pe ọrẹ rẹ kan yoo fi majele sinu ounjẹ fun un jẹ.
"Davido naa si ti fesi nigba naa loju opo ayelujara pe "" Ọlọrun yoo tu aṣiri awọn ẹni buburu to yi mi ka atawọn to jinna si mi. Amin."""
Hijab Female Footballer: Zulfah ní àlá òun ní láti jẹ́ agbábọ́ọ̀lù obìnrin tó dáńtọ́
Eyi ni ọmọ ẹgbẹ orin Davido to ti jade laye laarin ọdun mẹrin:
1.Fortunate Ateumunname.
Fortune ni ọpọlọpọ eeyan n pe apeja oruko ree.
Oun si ni ayaworan agba fun ileeṣẹ agborinjade Davido Music World (DMW).
Oṣu kẹsan an, Ọdun 2021 lo ku.
Oun si ni ọmọ ẹgbẹ Davido karun un ti yoo jade laye laarin ọdun mẹrin lọna to n fa ọpọ awuyewuye bayii.
2.Uthman, ti awọn eeyan mọ si Obama DMW:
Uthman ku ni osu kẹfa ọdun 2021. Iroyin sọ pe ariwo irora eemi lo pa ki o to jade laye.
Ayo Ewebiyi Mama Oriki: Ọwọ́ Òbí, Ìjọba àti àwọn Ọba ni ìdágbàsókè Yorùbá wà lásìkò yìí
3. Tagbo Umeike:
Inu ọkọ rẹ lo ku si niwaju ileewosan nla Lagos Island General Hospital.
Ọjọ ayẹyẹ ọjọ ibi tẹ lo jade laye lọdun 2017.
4. Olu Abiodun:
Orukọ inagijẹ ti wọn tun maa n pe e ni DJ Olu nigba aye rẹ.
DJ Olu naa jẹ ọkan lara awọn ọmọ ẹyin Davido to ku laarin ọdun mẹrin sẹyin bayii.
5. Tijani Ọlamilekan:
Inagijẹ rẹ njẹ Teejay.
Oun si ni ẹṣọ to n ṣọ gbajumọ olorin naa nigba aye rẹ.
Ọdun mọkanla lo fi ṣọ Davido ki o to jade laye ni oṣu kejila, ọdun 2020.
Anti Open Grazing Law: Àwọn èèyàn gúúsù ń fi ọ̀rọ̀ ránṣẹ́ padà sí El-Rufai lórí àtakò òfin
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Alaga awọn gomina apá guusu Naijiria, Rotimi Akeredolu ti koro oju sí gomina ipinlẹ Kaduna, Nasir El-Rufai lori bi o ṣe tako fifi ofin de idẹranjẹko lẹkun guusu.
Akeredolu ni ọgbọn ati ko  awọn janduku ajínigbé wọ apá guusu ni El-Rufai ń da.
El-Rufai ti kọkọ tabuku bi awọn ipinlẹ apá guusu ṣe ṣ'agbekalẹ ofin tó dé idẹranjẹko ni gbangba.
Àmọ́, Akeredolu sọ ninu atẹjade kan ti kọmiṣọnna eto iroyin nipinlẹ Ondo fi sita pe iru ẹni to ba sọrọ ti El-Rufai sọ ko yẹ nipo olori.
Gomina ipinlẹ Ondo sọ pe El-Rufai ń wa ọna lati ko awọn janduku ajinigbe  pawo afẹmi ṣofo lọ si ibo miran lẹyìn awọn ologun ti n fina mọ wọn bayii lapa Ariwa Naijiria.
Akeredolu fikun ọrọ rẹ pé irú ọrọ ti El-Rufai sọ yìí lè dá rogbodiyan silẹ laarin ilu.
Ondo School Without Chairs: Iléèwé kan rèé tí kò ní àga, tábìlì, olùkọ́, èlò ìkẹ́kọ̀ọ́
Gomina ipinlẹ Ondo ni fifi ẹran jẹko káàkiri ilu ti di eewọ bayii lapa guusu Naijiria, kò sì sí ohun tí ẹnikẹni le ṣe sí ọrọ naa.
Akeredolu ni awọn ti ko dun mọ kí wọn lọ fọwọ wọnu nitori aṣẹ ti gùn ofin tó dé idẹranjẹko ni gbangba lapa guusu Naijiria.
Oríṣun àwòrán, Facebook/NigerianArmy
Ọgagun agba ọwọ keje ileeṣẹ ọmọogun Naijiria, Ọgagun Abdulwahab Eyitayọ ni ẹgbẹrun mẹjọ lawọn ọmọogun agbesunmọmi Boko Haram to ti jọwọ ara wọn fun awọn ologun bayii.
O ni awọn agbebọn naa jọwọ ara wọn sílẹ lati inu ibuba wọn ni igno Sambisa atawọn ibuba miran.
Ọgagun Eyitayọ to tun jẹ ọgagun agba igun kini, Sector 1 Operaton Hadin Kai ṣalaye eyi lasiko to n gnalejo alukoro ileeṣẹ omogun oriilẹ ni Naijiria, ogagun Onyema Nwachukwu atawọn akọroyin lalejo nilu Maiduguri.
Hijab Female Footballer: Zulfah ní àlá òun ní láti jẹ́ agbábọ́ọ̀lù obìnrin tó dáńtọ́
Ogagun naa ni ohun ayọ ni bi awọn agbebọn naa ṣe n jọwọ ara wọn silẹ ati pe  bi awọn ologun ṣe n kona mọ wọn lo n ti wọn sita.
Ọgagun Eyitayọ fi kun pe lọpọ yanturu lawọn agbebõn Boko Haram n jọwọ ara wọn sílẹ lati igba tawọn ọmọ ogun ṣina ibọn fun wọn.
Ogagun naa ni pupọ awọn agbebọn naa lo jẹ pe igbaye gbadun awọn ẹbi wọn lo ṣokunfa bi wọn ṣe darapọ mọ awọn agbebọn naa.
O wa sekilọ pe eyikeyi awọn agbebọn naa ti ko baa jọwọ ara rẹ silẹ ki gbendeke ọjọ ti wọn fi silẹ fun wọn, yoo jẹ iyan rẹ niṣu ti ko si ni yọ awọn agbodegba ati baba isalẹ wọn pẹlu silẹ.
Oríṣun àwòrán, Facebook/NigerianArmy
Ọgagun Eyitayọ to tun jẹ ọgagun agba igun kini, Sector 1 Operaton Hadin Kai ṣalaye eyi lasiko to n gnalejo alukoro ileeṣẹ omogun oriilẹ ni Naijiria, ogagun Onyema Nwachukwu atawọn akọroyin lalejo nilu Maiduguri.
Goodluck Jonathan: Ààrẹ tẹ́lẹ̀, Goodluck Jonathan ti sọ̀rọ̀ sókè, Ó ní wàhálà Nàìjíríà fẹ̀rẹ̀ gbẹ̀mí ìyá òun lásìkò ìwọ́de 2012
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Aarẹ Naijiria nigbakan ri, Goodluck Jonathan ti ṣalaye pe kii ṣe ọgbẹ diẹ ni aworan posi oun tawon eeyan kan n gbe kiri lasiko iwọde lori epo bentiro to waye lọdun 2012 da sara iya oun.
"Aare Jonathan ṣalaye eyi ninu iwe rẹ tuntun to ṣẹṣẹ gbe jade to pe ni ""My Transition Hours.""."
"O ni ""Iwode naa n tẹsiwaju. Ninu gbogbo ẹ, eeyan kan ti aanu rẹ ṣemi julọ ni iya mi to wa pẹlu mi ni ile aarẹ nigba naa."
"Goodluck ni pe :   ""Ojojumọ lo n rii lori mohunmaworan bi awọn oluwọde ṣe n gbe fọto posi mi kiri ti wọn si n kọ akọle 'sun re o' sii lara."""
Aarẹ Jonathan ni ọpọlọpọ eeyan bii Alufaa agba inọ Winners Chapel, Bisọbu Oyedepo, alufa agba ijọ Anglican, Nichola Okoh atawọn mẹjọ miran lo n wa ba oun pe ki oun yi owo ori epo naa pada.
Hijab Female Footballer: Zulfah ní àlá òun ní láti jẹ́ agbábọ́ọ̀lù obìnrin tó dáńtọ́
O fi kun un pe ohun to kọ oun lominu ju nipe awọn alatako nilu Eko ti ja iwọde naa gba debi pe wọn tun ko ẹgbẹ oṣiṣẹ ti ìjọba oun ti ṣalaye bi ọrọ ẹkunwo epo se hẹ mọ abẹ lati b'awọn darapọ mọ iwọde naa.
AMCON 4.6Billion Debt: Gómìnà ìpínlẹ̀ Kwara tẹ́lẹ̀ sọ́rọ́ nípa nkán ìní rẹ̀ tí Amcon gbẹ́sẹ̀lé
Gomina ipinlẹ Kwara tẹl ri Abdulfatai Ahmed ti fesi lori fnran fidio to ṣafihan bi ajọ to n mojuto nkan ini Naijiria AMCON ṣe gbẹsẹ le dukia rẹ.
Lọjọru ni fidio kan gba oju opo ayelujara nibi ti agbẹjọro kan to ni oun n ba AMCON ṣiṣẹ ti sọ pe awọn wa lati fofin gba dukia Gomina tẹlẹ Ahmed.
Ninu fidio naa o sọ pe ileẹjọ fawọn laṣ lati gba ile naa to wa ni GRA nilu Ilorin nitori gbese ti ileeṣẹ Fati Ahmed jẹ ijọba.
Agbẹnusọ Gomina tẹlẹ Ahmed, Abdulwahab Oba sọ ninu atẹjade kan pe ijiroro n lọ lọwọ pẹlu Amcon lori gbese yi.
Nitori naa o ni  ko bojumu bi Amcon ti ṣe digun lọ gba dukia naa ti wọn si kede rẹ faye gbọ.
Ninu alaye to fi sita, Ahmed ni aigboraẹniye waye latari owo kan toun ya lọdọ awọn banki meji kan ti wọn wa da papọ mọ awọn owo mii tawọn ẹlomiran ya.
O ni o yẹ ki AMCON  ta ipin idokowo tawọn ile ifowopamọ yi gba kalẹ ni  bi oun ko ba ri owo san pada.
O ni lọwọ lọwọ awọn n jiroro pẹlu AMCON lati yanju ọrọ yi.
O ni o ṣeni laanu pe agbẹjọro to sọrọ ninu fidio yi mọ ibi tọrọ de duro ṣugbọn o ṣe aṣeju nipa pipariwo ọrọ naa sita.
Ondo School Without Chairs: Iléèwé kan rèé tí kò ní àga, tábìlì, olùkọ́ àti ohun èèlò ìkẹ́kọ̀ọ́
Ẹyin lo n di akukọ, awọn ọmọde oni ni yoo dagba to ba di ọla nitori awọn ni asaaju lọjọ ọla.
Amọ o seni laanu pe ọpọ awọn ogo wẹẹrẹ yii lo n la ipọnju nla kọja nidi ilakaka wọn lati kawe, di eeyan pataki, ki wọn si jẹ asaaju rere lọjọ ọla.
Apẹẹrẹ ni ti ile ẹkọ alakọbẹrẹ LA to wa nilu Bolowo, ni ijọba ibilẹ Ese-Odo, nipinlẹ Ondo nibi ti awọn akẹkọọ ti n sun tabi joko sori ilẹ lasan lati kọ ẹkọ.
Koda nibi ti nnkan buru de, ko aga, tabili, olukọ to to atawọn eroja ikẹkọọ to yẹ, koda, awọn pako ti wọn fi kọ ileẹkọ naa lo ti ja.
Nigba ti BBC Yoruba se abẹwo sile ẹkọ naa, a ri ba awọn olukọ, akẹkọọ, ọga ileẹkọ ati oriade to wa nilu naa sọrọ, ti gbogbo wọn si n fi tẹdun-tẹdun sọ iya nla to n jẹ ile ẹkọ naa ati awọn akẹkọọ rẹ.
Bakan naa la kan si ileesẹ to wa fun eto ẹkọ nileesẹ ijọba ibilẹ Ondo lati mọ boya wọn mọ ipo ẹyin ti ile ẹkọ alakọbẹrẹ naa wa, ati ewu nla to n rọ lori awọn akẹkọọ ibẹ.
Oludari kan to ba wa sọrọ ni ijọba ti n gbe igbesẹ lati ri si atunse ile ẹkọ naa, laipẹ si ni isẹ atunse naa yoo bẹrk.
Cooking Gas Danger: Wo ohun mẹ́wàá tó ṣe láti dènà ewu lílo iná afẹ́fẹ́ gáásì
Oríṣun àwòrán, Shutterstock
Fífi afẹfẹ gaasi dana ko fi akoko ṣofo rara, o ya ju dida ina igi tabi sitoofu lọ, kii si jẹ kí ikoko idana dudu.
Bi fifi afẹfẹ gaasi dana ṣe ni anfani to pọ yii naa lo ni ewu ninu.
Ọpọ eeyan ni afẹfẹ gaasi idana ti ṣe leṣe, ti ara wọn bo yanna yanna, nigba ti awọn miran dero ọrun.
Nitori idi eyi, ọpọ eeyan ni ẹru maa n ba lati lo afẹfẹ idana naa, paapaa awọn eeyan to ba ni ọmọde ninu ile.
Amọ ọna abayọ ti wa lati dena ewu to wa ninu lilo afẹfẹ gaasi lati dana ninu ile, awọn ọna mẹwaa yii si le wulo fun ọ.
Lilo foonu ni yara idana le jẹ kí ounjẹ jona lori ina.
O sí tun léwu fún gaasi fun rẹ nitori ile le sẹ yọ mọ ọ lara ti foonu naa ba gbina.
Ri daju wí pé ẹrọ iyẹfun eroja panapana rẹ wà ninu ile idana rẹ nitori ijamba ina to le ṣẹlẹ nigba kugba.
Eyi ni yoo tete dena ijamba ina ko to pẹ ju tabi ran mọ inu ile, eyi to le mu ofo ẹmi ati dukia wa.
Ewu wa ninu ki gaasi ku ju bo ti yẹ lọ nitori o le bẹrẹ sí ní jo.
Ti o ba si ti n jo, ijamba ina le ṣẹlẹ nigba kugba.
Ọpọ eeyan lo máa n mi silinda gaasi wọn wo lati mọ boya gaasi ṣi ku níbẹ.
Mimi silinda gaasi le jẹ ko bù gbamu eleyii to mu ewu lọwọ, to si le tun mu ẹmi lọ pẹlu.
Bakan naa ta ba lọ ra gaasi, ẹ ma gbe silinda yin si ẹyin ọkọ amọ ẹ gbe sinu ọkọ, ko maa baa maa yi kiri, eyi to le mu ewu lọwọ.
Nigba kugba ti o ba n lo gaasi, ri pe o wọ aṣọ ti o bo gbogbo ara rẹ tan.
Eyi jẹ ọna lati bọ lọwọ ewu ina aibaamọ gaasi naa le gbina, ti onitọun yoo si tete bọ asọ danu to ba gba mọ eeyan lara.
Ma se duro pẹ nile idana:
Awọn kẹmika to lagbara kan máa jade lati ara gaasi idana ti ko yẹ ko máa wọ inu ara eeyan.
Nitori naa, maṣe duro pẹ ju ni yara idana.
Kẹ́míkà gaasi le fa ẹfọri, ooyi kikọ ati èébì fún ọ.
Ma ṣe yin gaasi rẹ soke patapata:
Ni ọpọ igba láwọn eeyan máa n yin gaasi idana soke patapata.
Eleyii ni ewu ninu, ko yẹ ki ina gaasi jó kọja idi ikoko idana.
Ma ṣe dagunla sí gaasi to n jò:
"Ti o bá ṣe akiyesi pe ""cylinder"" gaasi n jo, yara ṣi ilẹkùn ati ferese ile idana silẹ ni kiakia."
Ti oorun gaasi naa ba n pọ si, kuro nilu ile ki o sí kepè awọn tó mọ nipa gaasi fún iranwọ.
Awọn nnkan eelo idana atawon nkan mii ko gbọdọ wa lori gaasi ni yara idana.
Ma se di ọpọ ẹru sori awọn silinda naa nitori o lewu.
Ma lo gaasi idana rẹ ti erunrun ounjẹ ba ti da sori rẹ:
Ki o to bẹrẹ sí ní maa lo gaasi idana rẹ, ríi pe kò sì idọti ounjẹ kankan lori gaasi.
Bi bẹẹ kọ, iru nkan yii ni yóò máa jo, ti yóò sì bẹrẹ sí ní maa run.
Biola Fowosere: Lẹ́yìn ọ̀pọ̀ ìgbà tí wọn ń já ṣọ́ọ̀bù rẹ̀, ọwọ́ pálábá afurasí olè kan ségi
Ọjọ gbogbo ni ti ole amọ ọjọ kan soso pere ni ti olohun.
Biola Fowosere, osere tiata ti ọpọ ènìyàn tun mọ̀ sí Ewatomilola Asake, ti safihan oju afurasi ole kan to wọ inu sọọbu rẹ lati gbe owo ati foonu.
Laipẹ yii ni Fowosere da omi loju lori oju opo ikansiraeni Instagram rẹ lati sọ ẹdun ọkan rẹ nipa awọn to n ja lole lati igba de igba.
Gẹgẹ bi Biola ti wi ninu fidio naa to fi omije se, o ni ti oun ba ti ko ọja sinu sọọbu naa, to kun de ẹnu, ni awọn kan yoo wa ja sọọbu naa, ti wọn yoo si ko ọja inu rẹ lọ.
O fikun pe eyi ti sọ oun di onigbese, ti wọn ko si fẹ ki oun ba ẹgbẹ pe.
Amọ ọwọ palaba ọkan ninu awọn to n gbe okunkun sisẹ ibi naa ti ṣegi, ti ọwọ si ba a nibi ti o ti n ji apo owo osere tiata naa ati foonu rẹ ninu sọọbu itaja rẹ.
O salaye pe ko pe isẹju meji ti oun lọ sile igbọsẹ lati sẹyọ, ni wọn ti gbe apo oun ti ọpọ owo ati foonu wa ninu rẹ.
Osere tiata naa wa rọ awọn eniyan ti wọn sa wa sibẹ lati wa lu ole naa pa, pe ki wọn jẹ ko fi oju wina ofin ni, ki wọn si mase se idajọ lọwọ ara wọn.
Bakan naa lo fikun pe ole naa ko wa ra nkankan ninu ṣọọbu rẹ, n ṣe lo wa ji awọn ẹru to wa ninu ṣọọbu oun.
''Ẹ jọwọ ẹ ma lu u pa o, ẹ fi silẹ nitori ole lo wa ja ni ṣọọbu mi.''
''Baagi owo mi lo gbe, to si ko gbogbo foonu mi laarin iṣẹju meji ti mo sare lọ gbọnṣẹ lẹyinkule.''
Laipẹ yii lo ke gbajare si gbogbo ọmọ Naijiria lati gba oun lọwọ awọn ole to n ja ṣọọbu oun ni gbogbo igba.
Fowosere salaye nigba naa pe, igba kẹta ni yii ti wọn n ja ṣọọbu oun laarin ọdun kan.
 Ní ọdún tó kọjá, wọ́n ji aṣọ tó tó Mílíọ̀nù kan àbọ̀ náírà sùgbọ́n títí dí òní mí o rí nǹkan kan
Amọ o fikun nigba naa pe awọn kan ko gbagbọ wi pe otitọ ni wọn ja oun lole, ko to di pe o fi fidio yii sita.
Gbajugbaja oṣere naa dupẹ lọwọ awọn eniyan to ran an lọwọ to si duro tii, bi o tilẹ jẹpe awọn ọlọpaa kọ lati ṣe ohunkohun si ọrọ ole ojoojumọ naa.
Ondo School Without Chairs: Iléèwé kan rèé tí kò ní àga, tábìlì, olùkọ́, èlò ìkẹ́kọ̀ọ́
Sunday Igboho: Amòfin Aliyu ń bi Malami pé ẹ̀sún wo ló tún wà nílẹ̀ tó fẹ́ fi kan ẹlẹ́jọ́ òun
Oríṣun àwòrán, Sunday_igboho1/Instagram
Amofin Yomi Aliyu, tii se asaaju ikọ agbẹjọro fun Oloye Sunday Igboho ti fun ijọba apapọ lesi lori bo se kede pe oun yoo fi ẹsun tuntun kan.
Bẹẹ ba gbagbe, ileẹjọ giga kan nilu Ibadan lo ti gbe idajọ kalẹ pe ki ajọ DSS ati ijọba apapọ san ogun biliọnu naira fun bi wọn se kọlu ile Sunday Igboho, ti wsn si tun ba dukia jẹ nibẹ.
Amọ agbẹjọro agba ati Minisita feto idajọ, Abubakar Malami lo kede ni Ọjọbọ pe ijọba yoo tun wọ Sunday Igboho ls sile ẹjọ fun ẹsun tuntun.
Nigba to n fesi si ọrọ yii, Yomi Aliyu wa n kọminu loju opo Facebook rẹ lori idi ti ijọba tun se fẹ fi ẹsun tuntun kan Sunday Igboho.
"O daju pe Malami ti faramọ bayii pe oun yoo tẹle asẹ ileẹjọ giga ni Ibadan titi ti yoo fi pe ẹjọ miran.
Oríṣun àwòrán, Yomi Aliyu SAN/Facebook
Eyi tumọ si pe agbofinro tabi ijọba ko ni yaju, halẹ tabi pa Sunday Igboho titi ti ijọpa apapọ yoo fi pinnu lori ohun ti yoo se ati igbesẹ to tun kan.
Amọ ohun to n ya wa lẹnu ni pe irufẹ ẹsun tuntun wo tun ni Malami n tọka si yii!
A wa n ki pe layọ ni yoo gunlẹ pada wa lati New York nibi to ti fesi naa si ọrọ naa."
Bi ina ko ba tan lasọ, ẹj ko le tan lori eekanna.
Afaimọ ki ijọba apapọ ma tun fi ẹsun mii kan ajijagbara ilẹ Yoruba, Oloye Sunday Adeyemo, ti ọpọ mọ si Sunday Igboho.
Lọsẹ to lọ ni ile ẹjọ paṣẹ pe ki ijọba apapọ san ogun biliọnu owo gba ma binu fún Igboho lori ikọlu ti ajọ DSS ṣe sí ile rẹ, nibi ti eeyan meji ti ku ti ọpọ dukia si ṣofo.
Àmọ́, agbẹjọro agba, to tun jẹ minisita eto ìdájọ, Abubakar Malami ti sọ pé ijoba lẹtọọ lati pe ẹjọ kotẹmilọrun lori ìdájọ náà.
Bakan naa ni Malami sọ pe ijọba apapọ tun fi ẹsun tuntun kan Igboho.
Adájọ Ladiran Akintola paṣẹ pe kí agbẹjọro agba Malami ati ajọ DSS san owo gba ma binu naa lẹyin ikọlu lọjọ kinni oṣu keje.
Ondo School Without Chairs: Iléèwé kan rèé tí kò ní àga, tábìlì, olùkọ́, èlò ìkẹ́kọ̀ọ́
Àmọ́, Malami ni kò sì ohun ti ijọba apapọ n ṣe ti o lodi sí ofin.
"Ijọba ni ẹtọ lati sọ fun ile ẹjọ miran lati yi idajọ ile ẹjọ giga ilu Ibadan danu.
O sí tun le wu ijoba ko tun wa awọn ẹsun mii sí Igboho lẹsẹ.
Nitori naa, a n ṣe ayẹwo ẹjọ náà lọwọ láti mọ iru igbesẹ ti a fẹ gbe bayii, Malami lo sọ bẹẹ."
Igangan Mayhem: Obìnrin Fulani kan ní òun pàdánù ọkọ, ọmọ mẹ́ta àti gbogbo dúkìá torí ìjà
Ti ẹ ko ba gbagbe, Yomi Aliyu tó jẹ agbẹjọro Igboho lo pe Malami ati ajọ DSS lẹjọ lati san ẹẹdẹgbẹta biliọnu naira fún Igboho gẹgẹ bi owo gba ma binu lẹyin ikólu DSS sí ile rẹ lagbegbe Soka niluu Ibadan.
Sabaa Akintola: Pẹ̀lú ẹsẹ̀ kan, mo le gun kẹ̀kẹ́, lúwẹ̀ẹ́ tàbí rán aṣọ pẹ̀lú ẹ̀kọ́ dókítà
Igboho sí wa ni atimọle lorilede Benin nibi ti wọn ti mu ùn lọnà Irinajo rẹ si orilẹ ede Germany.
Aliyu ni ile ati awọn ọkọ bọginni bọginni olowo iyebiye ni wọn bajẹ nile Igboho nibi ti wọn tun ti pa eeyan meji.
Open Grazing: Làásìgbò bẹ́ sílẹ̀ lẹ́bàá Ogbomoso torí màálù tó pa bàbá ìkókó ní ìkómọ ku ọ̀la
Iyalẹnu lo jẹ nigbati ọkunrin ẹni ọgbọn ọdun kan, Benjamin Oyelade, se alabapade iku ojiji nitori bi maa lu se ya soju popo lasiko to n gun ọkada kọja ni agbegbe Atapa Ogbomoso ni ijoba Surulere ni ipinlẹ Oyo.
Bamidele, tii se ẹni ọgbọn ọdun to n sisẹ Kafinta, lo se alabapade iku ojiji nigba to ku ọjọ kan pere ko se ikomọjade ọmọ tuntun ti iyawo rẹ sẹsẹ bi.
Ọkunrin yii ni wọn lo gun ọkada lati lọ ra epo bẹtiroolu, ko to se alabapade iku ojiji naa.
Isẹlẹ naa lo fa ki awọn ọdọ ilu Atapa fariga, ti wọn si sọ ina si abule tawọn Fulani tẹdo si lati gba ẹsan iku Oyelade, ti awọn agbofinro si ti dasi ọrọ naa.
Nigba ti BBC Yoruba gunlẹ si agbegbe naa lati tanna wadi ohun to sẹlẹ, baba ologbe, Babalola Solomon, to ba ikọ BBC News sọrọ ni ohun iyalẹnu lo jẹ fun oun tori ko pe ọgbọn isẹju ti ọmọ oun kuro ni ọdọ oun, ti isẹlẹ naa fi waye.
O tẹsiwaju pe ọmọ oun fẹ lọ epo pẹtiro si ẹrọ amunawa fun isọmọlorukọ ọmọ rẹ kẹrin lo pade iku ojiji lati ọwọ awọn maalu naa.
Nigba ti BBC kan si aya oloogbe, se lo n wa ẹkun mu pẹlu ara tutu, ti ko si le sọ ọrọ kankan nitori isẹlẹ naa ba lojiji.
Ondo School Without Chairs: Iléèwé kan rèé tí kò ní àga, tábìlì, olùkọ́, èlò ìkẹ́kọ̀ọ́
Nigba to n ba BBC Yoruba sọrọ,adari awọn Fulani darandaran, Muhammad Umaru ni ko si nkan to jọ bẹẹ rara, ti awọn Fulani ko si mọ nipa isẹlẹ naa.
Umaru ni lootọ ni awọn ọdọ ilu se ikọlu si ibudo awọn, to si rawọ ẹbẹ si wọn lati gba alaafia laaye ninu ilu naa.
Alaga ijọba ibilẹ Surulere, Adegbite Isaiah wa gbe osuba fun awọn agbofinro ati ikọ Amotekun lori bi wọn se fi pẹlẹ-putu yanju laasigbo naa.
Adegbite tun parọwa fun awọn araalu lati fi ifẹ ati alaafia ba ara wọn gbe papọ, ki wọn si ta kete si rogbodiyan.
Hijab Female Footballer: Zulfah ní àlá òun ní láti jẹ́ agbábọ́ọ̀lù obìnrin tó dáńtọ́
Awo Stage Play: Wo eré, ijó àti orin tó ń kọ́ wa lẹ́kọ̀ọ́ nípa ayé Awolowo àti aya rẹ̀
Arise ni arika, arika si ni baba iregun, ohun ta ba se lonii, itan ni yoo da to ba di ọla, o yẹ ka gbe ile aye se rere.
Oloye Obafemi Awolowo jẹ odu, ti kii se aimọ fun awọn oloko ni agbo awọn ọmọwe ati oselu to ti kọja lọ lorilẹede Naijiria.
Awolowo yii si wa laarin awọn akọni ọmọ Naijiria to gbe ina wo oju awọn oyinbo amunisin lati gba ominiria fun Naijiria.
Bakan naa lo ti tukọ ẹkun iwọ oorun guusu Naijiria, to si se gudugudu meje ati ya ya ya mẹfa fun iran Yoruba lasiko rẹ.
Amọ o se ni laanu pe awọn ọdọ iwoyii ti ọjọ ori wọn ko ju ogun si ọgbọn ọdun lọ ko mọ nipa awọn ribiribi ti Awolowo gbe ile aye se tabi iru eeyan to jẹ.
Ọna lati mase jẹ ki isẹ awọn akọni Naijiria bii Awolowo parun lo mu ki wọn se agbekalẹ ere onise yii ti yoo kọ awọn ọdọ iwoyi ni ẹkọ nipa igbe aye Awolowo ati aya rẹ, Hannah Dideolu Awolowo, HID.
BBC Yoruba ba wọn peju si ibudo ti ere onise ati orin pẹlu ijo naa ti waye, eyi ti igbakeji aarẹ, Yemi Osinbajo ati aya rẹ Dolapo, tii se ọmọ-ọmọ Awolowo peju si.
Awọn alejo pataki miran to tun wa nibẹ ni gomina ipinlẹ Eko, Babajide Sanwo-Olu àti ọmọ-ọmọ Awolowo miran, Olusegun, adari ile asoju-soju, Femi Gbajabiamila to fi mọ awọn eekanlu miran.
Eto miran ti won tun gbekale lati fi sami iranti aya Awolowo naa ni ti ifilole iwe nipa Awolowo ti ogbontarigi onkowe kan ko fun iranti akoni naa.
Ogbeni Lagada Abayomi to je gbajugbaja onkowe ati sorosoro to ko iwe naa ba BBC Yoruba soro lori pataki ki awon omo iwoyi mo sii nipa ipa ti akoni eda naa ko ninu itan iselu Naijiria.
Bee bi omo ko ba ba itan, o di dandan ko ba aroba to je baba itan.
Lightning kills family: Àrá sań pa èèyan mẹ́rin nínú ìdílé kan ṣoṣ
Oríṣun àwòrán, jplenio
Ara ti san pa eeyan mẹrin lati inu idile kan naa lagbegbe Muleba, Lake Victoria lorilẹ-ede Tanzania.
Agbẹnusọ fun agbegbe Muleba ti iṣẹlẹ naa ti waye, Thoba Nguvilla sọ nibi ipade awọn akọroyin kan pe ara ọhun san pa awọn mọlẹbi naa lalaẹ Ọjọbọ.
O ni tọkọ-taya atawọn ọmọ wọn ni ara naa san pa.
Nguvilla sọ siwaju si pe iṣẹ agbẹ ati apẹja ni awọn mọlebi naa yan laayo, ki iṣẹlẹ ibi ọhun to waye.
Ẹwẹ, alaga abule ti wọn n gbe, Robert Musiibah ṣalaye pe ina sọ lara orule ile wọn, ti ile naa si jona lasiko iṣẹlẹ ọhun.
Romeo and Juliet padà di ìwé Akinola àti Arike ní èdè Yorùbá
Kii ṣe igba akọkọ ree ti ara yoo san pa awọn eeyan nilẹ Afrika.
Nilẹ Yoruba, igbagbọ ọpọ eeyan ni pe irufẹ iṣẹlẹ bẹẹ kii ṣe oju lasan, paapaa ti wọn ba ti kọkọ fi ẹsun ole jija kan ikankan ninu awọn mọlẹbi naa.
Ṣugbọn awọn mii tun gbagbọ ohun gbogbo kọ lo lọwọ aye ninu nitori awọn nnkan miran maa n ṣadede waye.
Awo Stage Play: Wo eré, ijó àti orin tó ń kọ́ wa lẹ́kọ̀ọ́ nípa ayé Awolowo àti aya rẹ̀
UN 76th session: Buhari ń bèèrè fún àforíjìn gbèsè Áfíríkà lọ́dọ̀ àjọ àgbáyé
Oríṣun àwòrán, Femi Adesina
Aarẹ orilẹede Naijiria, Muhammadu Buhari ba ijoko ajọ iṣọkan agbaye, UNP sọrọ lọjọ Ẹti niluu New York, lorilẹede Amẹrika.
Bo tilẹ jẹ pe akojọpọ ẹgbẹ ajijagbara to n beere fun iyapa kuro lara Naijiria, NINAS ṣe ifẹhonuhan niwaju olu ileeṣẹ UNO, ti ipade awọn olori orilẹede lagbaaye ti n waye, sibẹ aarẹ Buhari si pada sọrọ nibi ipade naa.
Oluranlọwọ aarẹ lori ọrọ iroyin, Femi Adesina lo ṣalaye ohun ti Buhari sọ nibi ipade naa ninu atẹjade kan to fi sita.
Wọnyii ni koko marun un ninu ọrọ ti Aarẹ Buhari sọ nibi ipade ajọ iṣọkan agbaye niluu New York.
Romeo and Juliet padà di ìwé Akinola àti Arike ní èdè Yorùbá
Aarẹ Buhari bu ẹnu atẹ lu owo nkan ija oloro lọna aitọ to ti wọpọ bayii nilẹ Afirika ati kaakiri agbaye.
Buhari sọ fun  ijoko awọn olori orilẹede lagbaye eleyii to jẹ ẹlẹẹkẹrindinlọgọrin iru rẹ pe ọrọ naa n fẹ amojuto.
Aarẹ Naijiria ni tita ohun ija oloro yii lodi si ẹtọ ọmọniyan, ati pe ipa buruku ni eleyii n ni lawọn orilẹede Afirika.
Buhari sọ pe bi awọn eeyan kan ti n ṣe fayawọ nkan ija oloro lati orilẹede kan si omiran ko le bimọ 're fun orilẹede kankan.
Aarẹ Buhari tun tọrọ aforijin gbese ti Naijiria atawọn orilẹede mii ti ko rọwọ họri jẹ papaa julọ bi ajakalẹ arun covid-19 ti ṣakoba fun ọrọ-aje awọn orilẹede naa.
Aarẹ Naijria ni ele ori gbese tawọn orilẹede ti ko tii goke agba n san tẹlẹ ṣaaju ajakalẹ arun coronavirus pọ ju.
O ni eyi ti ṣakoba fun ijọba lati le mojuto ọrọ ilera atawọn akanṣe iṣẹ idagbasoke mii fawọnb araalu.
Buhari ni iranwọ nla ni yoo jẹ fawọn orilẹede bayii ti awọn ajọ ayanilowo lagbaaye ba le fori gbese ti wọn jẹ jin wọn.
Aarẹ Buhari ko ṣai sọrọ lori pinpin abẹrẹ ajẹsara labẹ eto COVAX ti ajọ eleto ilera lagbaaye ṣe agbatẹru rẹ.
Buhari wa dupẹ lọwọ awọn to gbe eto yii kalẹ nitori Naijiria ti jẹ anfani lara eto naa.
Aarẹ Naijiria tun dupẹ lọwọ awọn orilẹede bi Amẹrika, Turkey, India, China, ajọ EU atawọn ajọ mii fun iranlọwọ ti wọn ṣe fun Naijiria lori dẹkun ajakalẹ arun coronavirus.
Amọ, aarẹ ni ọkan lara ọna lati le Covid-19 lọ pata pata ni pinpin abẹrẹ arun naa dọgba dọgba kaakiri orilẹede agbaaye.
Aarẹ orilẹede Naijiria bu ẹnu atẹ lu iṣẹlẹ iditẹ gbajọba to waye lawọn orilẹede kan lapa iwọ oorun ilẹ Afirika bi Guinea ati Mali.
Buhari ni ifasẹyin ni eleyii jẹ pẹlu bi ijọba awarawa ṣe n fẹsẹ mulẹ lẹkun naa ati kaakiri ilẹ Afirika bayii.
O sọ nipa iranwọ ti Naijiria n ṣe pẹlu ajọ ECOWAS, AU ati UN lati wa ojutuu  si ọrọ naa.
Buhari ni Naijria ti ran ikọ pẹtu sija lọ sawọn orilẹede ti iṣẹlẹ yii iditẹgbajọba yii ti waye lati pe fun imupada ijọba alagbada.
Aarẹ Buhari idokowo to mọyan lori lai si ẹtan yoo ran ilẹ Afirika lọwọ.
Buhari ni ti awọn orilẹede Afirika ba le jẹ anfani okowo pẹlu awọn orilẹede to ti goke agba, wọn ko ni nilo iranwọ owo lati ọdọ wọn mọ.
Aarẹ ni anfaani si iru okowo bayii gan an nilẹ Afirika nilo ju owo iranwọ lati ọdọ awọn orilẹede to ti goke agba lọ.
Bobrisky: Òntàjà góòlù wọ́ Bobrisky nìlẹ̀ pé ó ra góòlù àwìn tó wọ̀ lọ́jọ́ ìbí rẹ̀ láì san owó pé
Oríṣun àwòrán, Bobrisky
Ọrọ iwe mimọ lo sọ pe iwọ ti o fẹ yọ igi loju ẹlọmiran, o kọkọ gbọdọ yọ iti igi to wa loju tiẹ na.
Bẹẹ gẹgẹ lo ri fun ilumọọka ọkunrin to n wọ aṣọ obinrin, Bobrisky, nigba ti ontaja goolu kan wa wọ nilẹ loju opo Instagram, lori ẹsun pe o gba awin goolu to wọ lọjọ ayẹyẹ ọjọ ibi rẹ.
Ohun to mu ọrọ yii wa ni bi Bobrisky ṣe tabuku gbajumọ osere tiata kan, Tonto Dikeh, tii se ọrẹ timọtimọ rẹ tẹlẹ, loju opo Instagram pe o jẹ oun ni gbese miliọnu marun naira.
Ontaja naa ni bi Bobrisky ṣe tabuku Dikeh lo bi oun ninu lati tu aṣiri tiẹ naa lori ayelujara.
Ontaja goolu naa ni alagabagebe ati oniyẹyẹ eeyan lasan ni Bobrisky.
Oríṣun àwòrán, Houseofamearypearl
Koda o ni ika eeyan ni Bobrisky pẹlu nitori o ra goolu lọwọ oun lai bikita lati sanwo rẹ fun ọjọ pipẹ.
Ọlọja goolu naa ni ọrọ ko dun lẹnu Bobrisky lati maa fi Tonto Dikeh ṣe yẹyẹ pe o jẹ gbese nigba ti o jẹ pe oun gan an fun ra rẹ, onigbese ni.
Amọ, ontaja naa tọrọ aforijin lọwọ agbẹjọro rẹ pe oun fi ọrọ naa lede lori ayelujara lẹyin ti ọrọ naa ti de ile ẹjọ.
''O gba awin goolu lọwọ mi, o kọ lati fun mi lowo lẹyin oṣu meloo bayii.
O tun laya lati wọ goolu mi nibi ayẹyẹ ọjọ ibi rẹ, o fi ya fọto, o wa tun laya lati maa fi ẹnikan ṣe yẹyẹ.
Bobrisky, oniyẹyẹ ale Amuda ni ọ, alagabagebe si ni ọ pẹlu.
A ṣe iwọ naa le sọ pe ẹnikan n jẹ ọ lowo, abọwaaba ni ọrọ rẹ, onigbese jati jati.
Iwọ tiẹ gbagbe pe ẹni ti o ba n gbe ile gilaasi ko gbọdọ maa sọ oko ni.
Agbẹjọro mi, mo tọrọ aforijin tori ọrọ naa ti de ile ẹjọ bayii, mo si n reti idajọ lori ọrọ naa, o ti fẹ pe ọdun kan bayii.
Ohun ti onisowo goolu lori Instagram naa, houseofamearypearl kọ yoo, lo ti wa fọn kaakiri lori ayelujara.
Ọrọ Bobrisky kan dabi ikoko to n sọ pe idi kẹtu dudu ni jare,'' ontaja naa lo faraya bayii lori Instagram.
Saaju ni Bobrisky ti lo goolu ta n sọrọ rẹ yii, fi tadi rekereke niwaju olorin ni ọjọ ayẹyẹ ọjọ ibi rẹ.
Oríṣun àwòrán, Houseofamearypearl
Romeo and Juliet padà di ìwé Akinola àti Arike ní èdè Yorùbá
Ko fẹ si akẹkọọ imọ nipa ẹkọ Litiresọ, ti ko ni ka iwe itan ololufẹ meji kan ti wọn pe ni Romeo and Juliet eyi ti akọni onkọwe nni, William Shakespeare kọ.
Amọ nitori awọn ogbontagi gẹẹsi atijọ to fi kọ iwe naa, o loju akẹkọọ tabi onkawe ti itan naa ye bo se yẹ amọ anfaani ọtun tun ti de lati gbadun itan ifẹ naa.
Idi ni pe iwe naa ti yipada di iwe ìtan ifẹ Akinola ati Arike ni ede abinibi tiwa, Yoruba.
Bí o bá ń fẹnukonu ju iye ìṣẹ́jú ààyá yìí lọ, wo adúrú kòkòrò tí wàá tí ibi ẹnu kò
Ká ní wọ́n fún Awolowo láyèè láti tukọ̀ Nàíjíríà ni, nǹkan kò ní rí báyìí
"Ọmọ ẹgbẹ́ PDP Oyo tí inú bá ń bí, ẹ kó ""mo kó - mo rò"" yín wá ká yanjú ẹ̀ - Makinde"
Wo ìdí tí àwọn tọkọ-taya kan ṣe ń ṣe ìgbéyàwó nínú pósí
"'Eniola Badmus wọ pátá lọ sí ààfin Oba Elegushi, ""ọ̀ín"" kí ló burú níbẹ̀?'"
Yatọ si eyi, ọpọ asa, ẹwa ede ati ise Yoruba tun ni wọn ti bọ iwe yii, ti yoo tubọ mu ko dun, ko si ni arinrin leti ẹni to ba ka a.
BBC Yoruba wa nibi ikojade itan ifẹ Akinola ati Arike yii, ti wọn se ni ere onise.
Bakan naa, a tun ba awọn eeyan to se agbatẹru iwe kika ati ere onise naa sọrọ lori ohun to pilẹ igbesẹ yii.
Fun igbadun isinmi opin ọsẹ yin, ẹ wa daraya pẹlu ere onise yii, Akinola ati Arike.
Wo ewu tó wà nínú fífi ọ̀sẹ̀ fọ ojú ara fún ọkùnrin àti obìnrin
Ọkùnrin tó fẹ́ bá mi d'ọ̀rẹ́ lórí Facebook fẹsẹ̀ fẹ́ ẹ nígbà tó rí mi lójúkojú  -  Folashade Adeyemo
Lagos Police: Ọwọ́ sìnkún ọlọ́pàá tẹ ọkùnrin tó so onígbèsè rẹ̀ mọ́lẹ̀ pẹ̀lú igi
Oríṣun àwòrán, Lagos State Police Command
Ọba Oke jọọ ma se jẹ ka sẹ ẹni ti ko ni gbọ ẹbẹ tabi tẹni ti ika.
Ileesẹ Ọlọpaa ipinlẹ Eko ti doola ẹmi ọkunrin kan, Reuben Alozie, to jẹ gbese miliọnu marun din ni irinwo naira (N4.6m) lọwọ ẹni to jẹ lowo, Oluchi Okoye.
Okoye, ti ọpọ eeyan tun mọ si PACA lo jẹ oludari ileesẹ kan.
Alozie to jẹ Okoye ni gbese ni wọn so mọlẹ bii ẹran amọ ti ori ko yọ nigba ti awọn ọlọpaa gba silẹ, ti wọn si mu Okoye, ẹni to jẹ ni gbese naa.
Gẹgẹ bi atẹjade kan ti agbẹnusọ fun ileesẹ ọlọpaa nipinlẹ Eko, Adekunle Ajisebutu fisita, se ni Okoye so onigbese rẹ mọ igi kan bii ewurẹ.
Oríṣun àwòrán, Lagos State Police Command
Gẹgẹ bi atẹjade naa ti wi, ojule kọkandinlọgbọn, opopona Abeokuta ladugbo Ebute Metta nilu Eko, ni isẹlẹ naa ti waye.
Ileesẹ ọlọpaa fikun pe odidi ọjọ kan gbako ni Okoye fi so Alozie mọlẹ bii ẹran, laarin Ọjọru, ọjọ Kejilelogun si Ọjọbọ, ọjọ Kẹtalelogun osu Kẹsan ọdun 2021.
Iroyin naa ni ọpẹlọpẹ ileesẹ ọlọpaa to lọ sinu ile naa lati lọ doola ẹmi Alozie, bi bẹẹ kọ, ẹmi rẹ le bọ sinu isẹlẹ yii.
Nigba to n salaye ohun to ri lọbẹ, to fi waru sọwọ, afurasi naa, Oluchi Okoye ni oun se idajọ lọwọ ara oun nitori gbogbo iyanju oun lati gba owo ti Alozie jẹ oun lo kuna.
Ileesẹ ọlọpaa ni iyawo Alozie ti wọn so mọlẹ, Angela Reuben lo mu ẹsun wa agọ ọlọpaa pe Okoye ti mu ọkọ oun lẹru, ti ko si jẹ ko ni ominira kankan rara.
Romeo and Juliet padà di ìwé Akinola àti Arike ní èdè Yorùbá
Kọmisana ọlọpaa nipinlẹ Eko, Hakeem Odumosu ti wa pasẹ pe ki wọn gbe afurasi naa lọ si ẹka iwadii ileesẹ ọlọpaa fun ẹkunrẹrẹ iwadii ati igbẹjọ.
Odumosu tun wa fi ewe ọmọ mọ awọn araalu leti lati maa tọ ipasẹ ofin dipo sise idajọ lọwọ ara wọn
Private Parts Cleaning: Ṣé ó yẹ kí obìnrin àti ọkùnrin máa fi ọ̀sẹ̀ fọ ojú ara?
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ọ̀pọ̀ èèyàn ló máa ń fẹ́ wà ní mímọ toni toni láì sí òórùn kankan tó ń jáde lójú ara àti gbogbo ara rẹ.
Àmọ́ kìí se gbogbo ènìyàn ló mọ pe kò yẹ kí àwọn máa fi ọ̀sẹ̀ fọ ojú ara nítorí ọ̀pọ̀lọpọ̀ ewu tó wà nínú rẹ.
Lára àwọn àgbègbè ojú ara tó léwu láti máa fi ọ̀sẹ̀ fọ ni ihò tó wà láàárín awẹ ojú ara obìnrin méjèèjì (Vagina Opening).
'Mo ti gba kádàrá lórí bí Ọlọrun ṣe dá mi'
Bákan náà ni ewu ń bẹ nínú fífi ọ̀sẹ̀ fọ ojú ibi tí nǹkan ọkùnrin tí la ẹnu ni òkè téńté.
Kò tán síbè o, kò tún yẹ rárá láti máa fi ọ̀sẹ̀ fọ ihò ìdí wa nibi ti a ti ń ya ìgbé nitori ihò tó wà níbè.
Gẹ́gẹ́ bá ṣe mọ̀ pé láti ìgbà èwe ni wọ́n ti kọ wa lati máa wà ní imototo.
Tantra: Ìlànà yìí ló ń kọ́ wa láti fi èémí àti ìṣẹ́po ara gbádùn ìbálòpọ̀
Ìdí sì rèé ta ṣe máa ń naani àwọn ẹ̀yà àti ojú ara wa, kí wọ́n le wà ní mímọ toni toni.
Ó sì yẹ ká le dá ara wa lẹkọọ  nípa ba ṣe ń fọ àwọn ibi kọlọfin wa tí kò hàn síta.
Gẹ́gẹ́ bí onímọ̀ kan tí wí,  omi nìkan ló yẹ ká máa fi fọ ojú ara wa nítorí àwọn ìdí wọn yìí:
Ihò ojú ara obìnrin àti ihò orí nnkan ọkùnrin pẹ̀lú ihò ta fi ń yà ìgbẹ ni kò ní òróró tó le mú kó máa dán tàbí yọ.
Ìdí rèé tí kò fi dára ká máa fi ọ̀sẹ̀ fọ àwọn abala mẹtẹẹta yìí nínú agọ ara wa.
Àwọn abala tó ń dán nítorí òróró ara to wà níbẹ̀ sì lo ń gba abọde àrùn fún agọ ara wa.
Ìdí sì rèé tó fi yẹ ká máa lo ọ̀sẹ̀ láti fọ àwọn àgbègbè náà dáadáa.
Àwọn abala tá ń sọ yìí kò nílò ààbò kankan nítorí a ti lo ọ̀sẹ̀ to ń pa kòkòrò láti fọ àwọn kòkòrò kékeré tí a kò le fi ojú rí náà dànù.
Níwọ̀n ìgbà tí ojú ara kò ti ní òróró tó le mu kó máa dán bọrọbọrọ, bí a bá fi ọ̀sẹ̀ fọ ó, ojú ara náà yóò gbẹ furu-furu ni.
Bí ojú ara bá sì gbẹ furu furu, eleyi lewu pupọ, tó sì lè ṣe okùnfà àwọn àkóbá kan fún ojú ara yìí, bóyá tí ọkùnrin ní tàbí obìnrin.
Gẹ́gẹ́ bí àwọn onímọ̀ tí ṣàlàyé, omi lásán láì ní oogun kankan lo dára láti máa fi fọ ojú ara.
Omi yìí le jẹ tútù, gbígbóná tàbí kó lọ wọ wọ.
Àmọ́ to bá fẹ́ kí àwọn ojú ara yìí túbọ̀ mọ toni toni, o lè lú iyọ̀ díẹ̀ mọ omi láti fi fọ ojú ara naa.
Lákòótán, ó yẹ ká tẹ mọ ara wa leti pé ojú ara obìnrin máa ń fọ ara rẹ fúnra rẹ, omi nìkan ló sì nílò, kii ṣe ọ̀sẹ̀.
Tóò bá fún ọkùnrinn lóúnjẹ́ tóo tẹ́ kiní yẹn sílẹ̀ fún un dáadáa... - Yinka TNT
Northern Governors Meeting: Akeredolu ní ìpàdé àwọn gómìnà àríwà kò ní kí ààrẹ má wá láti Gúúsù ní 2023
Oríṣun àwòrán, Rotimi Akeredolu
Alaga awọn gomina ni ẹkun Guusu Naijiria, Oluwarotimi Akeredolu ti fesi si abọ ipade awọn gomina lẹkun ariwa Naijiria eyi ti wọn se lọjọ Aje.
Awọn gomina lati Ariwa Naijiria lo panupọ sọ pe awọn ko faramọ ọrọ tawọn gomina Guusu sọ pe aarẹ gbọdọ wa lati ẹkun awọn lọdun 2023.
Nigba to n fesi lori ikede naa, Akeredolu ni awọn gomina ariwa ni ẹtọ labẹ ofin lati sọ ohun ero wọn lori ibo aarẹ ọdun 2023.
Gomina ipinlẹ Ondo ni iwọfa lẹnu, ko si ẹni to le sọ pe ki awọn gomina ariwa ma sọrọ, amọ eyi ko ni ohun kan ṣe pẹlu igbesẹ awọn gomina apa Guusu.
Laipẹ yii lawọn gomina apa Guusu sọ nibi ipade wọn to waye niluu Enugu pe, aarẹ Naijiria gbọdọ wa lati apa Guusu lọdun 2023.
Bakan naa ni wọn tun jiroro lori ọrọ gbigba owo ori VAT eyi ti wọn fẹnu ko le lori pe, awọn ijọba ipinlẹ lo yẹ ko maa gbaa.
"Ìran mi ò ja ẹ̀ṣẹ́ rí, ẹ̀gbin yìí ló ta lé mi tí mo fi di ""Scorpion"" Ọ̀gá ọ̀gá nínú ìjà"
Ẹ̀yin gómìnà Ariwa, ẹ dá a padà! Ààrẹ Naijiria gbọ́dọ̀ wá láti Gúsù ní 2023 - Afenifere
Bakan naa ni ẹgbẹ Afenifere ti fesi si ọrọ ti awọn gomina lati Ariwa Naijiria sọ pe ko si ninu ofin Naijiria pe ki wọn o maa pin ipo aarẹ kaakiri awọn ẹkun to wa ni Naijiria.
Akọwe ikede fun ẹgbẹ naa, Jare Ajayi sọ fun iwe iroyin Punch pe iyalẹnu lo jẹ pe awọn gomina naa sọ ọrọ yii, bo tilẹ jẹ pe awọn kan lara wọn ti kọkọ sọ pe ẹkun Guusu lo yẹ ki aarẹ ti wa lọdun 2023.
Ọgbẹni Ajayi sọ pe iha ti awọn gomina naa kọ si ọrọ naa fihan pe ọrọ ori ahọn ni iṣọkan ti wọn n polongo wa, ko si ninu ọkan wọn.
Oríṣun àwòrán, the Punch
"O ni lootọ ni ko si ninu iwe ofin Naijiria pe ki wọn o maa yan aarẹ ni ẹkun kọọkan, ""amọ o n waye nitori ki iṣọkan le wa""."
"Lootọ ni ẹgbẹ Afenifere gba pe ko si ibi ti aarẹ ko ti le wa, amọ akoyawọ ati  ilana dọgba-dọgba tọka si pe ẹkun Gusu ni aarẹ Naijiria gbọdọ ti wa lọdun 2023.
Nipa ṣiṣe bẹẹ nikan ni alaafia fi le wa ni orilẹ-ede yii."""
Ọjọ Aje ni awọn gomina to wa lawọn ipinlẹ mọkandinlogun to wa lẹkun ariwa Naijiria yari pe ipo aarẹ ko ni wa si ẹkun guusu lọdun 2023.
Oríṣun àwòrán, Simon Lalong
Ipinnu wọn yii lo tako adehun ti awọn gomina lẹkun guusu Naijiria se lasiko ipade wọn to waye laipẹ yii pe ẹkun guusu Naijiria ni ipo aarẹ gbọdọ wa lọdun 2023.
Eyi si lo wa lara ohun ti awọn gomina ẹkun ariwa Naijiria fi ohun sọkan le lori nibi ipade ti wọn se pẹlu awọn ọba alaye lọjọ Aje eyi to waye nile ijọba nilu Kaduna.
Alaga ẹgbẹ awọn gomina naa, tii tun se gomina ipinlẹ Plateau, Simon Lalong si lo ka atẹjade ti wọn fisita lopin ipade wọn ọhun lorukọ awọn akẹẹgbẹ rẹ.
Gẹgẹ bi awọn gomina naa ti wi, pinpin ipo aarẹ, gẹgẹ bi awọn gomina ẹkun guuusu se n beere fun, tako ofin ilẹ wa tọdun 1999 ti wọn se atunse rẹ.
Ọ̀wọ́ ọ̀tún Ọlọ́run Olódùmarè ni Ogboni máa wà bí ó bá re ibi àgbà ń rè
Wọn ni aarẹ ti wọn ba dibo yan gbọdọ ba ilana ti ofin ilẹ wa la kalẹ mu, lara rẹ si ni ko ni ibo to pọ julọ.
Bakan naa ni wn lo gbọdọ ni ida mẹẹdọgbọn ninu ọgọrun gbogbo ibo, ko si tun ni ida meji ninu mẹta ibo yika ipinlẹ mẹrindinlogoji to wa lorilẹede wa.
Gomina Lalong tọkasi pe bi o tilẹ jẹ pe awọn gomina kan lati ẹkun ariwa Naijiria ti fontẹ lu ibeere awọn gomina guusu pe ki ipo aarẹ bọ si ẹkun guusu lọdun 2023.
Amọ o ni apapọ awọn gomina lẹkun ariwa koro oju si ipe yii patapata.
Lori ọrọ owo ori ọja VAT to n fa awuyewuye laarin awọn ipinlẹ kan ati ijọba, awọn gomina ariwa fẹnuko pe niwọn igba ti ẹjọ naa ti wa nile ẹjọ, awọn ko ni sọrọ nipa rẹ.
Amọ Lalong salaye pe ko yẹ ki awọn gomina naa si owo ori ọja mu si owo ọja tita.
O ni bi ipinlẹ kọọkan ba gbe ofin owo ofin ọja kalẹ nipinlẹ rẹ, ọrọ naa yoo di gbigba owo ori ọja lọna pupọ eyi ti yoo mu ki ọja gbe owo lori, ti okoowo lati ipinlẹ kan si ekeji yoo si dẹnu kọlẹ.
Sabaa Akintola: Pẹ̀lú ẹsẹ̀ kan, mo le gun kẹ̀kẹ́, lúwẹ̀ẹ́ tàbí rán aṣọ pẹ̀lú ẹ̀kọ́ dókítà
Nipa aifararọ eto aabo lẹkun ariwa ilẹ yii, awọn gomina lẹkun naa gbosuba sileesẹ ologun lori aayan lati gbogun ti awọn agbebọn ati idaluru lẹkun naa.
Amọ awọn gomina yii wa fi oju laifi wo bi awọn osisẹ eleto idajọ kan se n lẹdi apo pọ pẹlu awọn onisẹ ibi naa, ti wọn i n tu awọn ọdaran ti wọn ba mu silẹ.
Soldier beats Corp Member: Àgùnbánirọ̀ Fidelia ti sọ́jà tó da omi ìdọ̀tí lé e lórí ní ìṣẹ̀lẹ̀ ń mú ojú ti òun
Oríṣun àwòrán, Ifeyinwa Fidelia
Yoruba bọ, wọn ni ẹni to ba ta ọfa soke, to yi odo bori, bi ọba aye ko ri i, ti ti ọrun n wo o.
Aje iwa ibajẹ ti ọmọogun obinrin kan, Chika Viola Anele, hu si agunbanirọ obinrin kan ni ilu Calabar, Ezeiruaku Ifenyinwa Fidelia, ti ṣi mọ ọ lori bayii lẹyin ti ileeṣẹ ọmogun ni awọn yoo fi iya totọ jẹ ẹ
Anele ni fidio kan to gbori ayelujara pa ṣafihan bi o ṣe n da omi idọti sori Fidelia titi ti gbogbo aṣọ rẹ fi tutu tan.
Ọ̀wọ́ ọ̀tún Ọlọ́run Olódùmarè ni Ogboni máa wà bí ó bá re ibi àgbà ń rè
Ẹwẹ, Fidelia ti sọrọ lori iṣẹlẹ naa fun igba akọkọ lati igba ti sọja naa ti fi iya jẹ ẹ.
Nigba ti o ba awọn akọroyin sọrọ lẹyin to pada si ilu Eko, Fidelia ni niṣe loju maa n ti oun nigba kugba ti oun ba ti ranti iṣẹlẹ naa.
Fidelia ni ''ọpọ eeyan lo ti n pe mi lori ago kaakiri orilẹede Naijiria ti wọn n sọ fun mi awọn ri fọto iṣẹlẹ naa.
Iṣẹlẹ ọhun ti jẹ ki n di ilumọọka bayii pẹlu bi fidio iṣẹlẹ naa ti lu ori ayelujara pa.''
Nigba ti wọn beere lọwọ rẹ iru ṣeria to fẹ ki wọn da fun ọmogun naa, o ni iru idajọ to yẹ ni wọn da fun un.
Fidelia sọ pe ko si iru ijiya ti wọn fun ọmogun naa ti ko tẹ oun lọrun.
O tun fikun ọrọ rẹ pe awọn ọmogun ko dunkoko mọ oun pe oun ko gbọdọ sọ nipa iṣẹlẹ naa fawọn akọroyin.
Bakan naa ni o fidi rẹ mulẹ pe gbogbo awọn akẹgbẹ ọmogun naa lo bu ẹnu atẹ lu iwa ti Anele hu.
Ileeṣẹ ologun ti kede pe esi idajọ Anele yoo jade faye gbọ laipẹ lori iwa to hu si Fidelia niluu Calabar.
Agbẹjọ́rò méjì yọ ẹ̀sẹ́ síra wọn níwájú adájọ ó ku ẹni tí yóò yanjú ọ̀rọ̀
"Ọmọ ẹgbẹ́ PDP Oyo tí inú bá ń bí, ẹ kó ""mo kó - mo rò"" yín wá ká yanjú ẹ̀ - Makinde"
Ó bà ni kò bàjẹ́, ẹ wo ọ̀rọ̀ tí Anthony Joshua sọ lẹ́yin tí Usyk fẹ̀ṣẹ̀ gbadé orí rẹ̀ láìròtẹ́lẹ̀
'Mo ti gba kádàrá lórí bí Ọlọrun ṣe dá mi'
INEC preparations for 2023 general poll: Ó ṣeéṣe kí àwọn òkú lẹ́tọ́ láti dìbò lọ́dún 2023, ìdí rèé gẹ́gẹ́ bí àjọ INEC ṣe sọ
Oríṣun àwòrán, other
O ṣeeṣe ki o ri orukọ awọn eeyan ti o mọ ti wọn ti ku ninu iwe orukọ awọn oludibo Naijiria o.
Maṣe pariwo kinla rara!
Alaga ajọ eleto idibo ni Naijiria, INEC, Ọjọgbọn Mahmood Yakubu ti ṣalaye ohun to lee ba eyi wa o.
Ọjọgbọn Mamood Yakubu ṣalaye pe ohun to ṣokunfa eyi ko ju wi pe ajọ INEC ko lanfani ati ṣe akọsilẹ to pe nipa awọn to ti ku lorilẹede Naijiria. Eyi, gẹgẹ bi ọrọ rẹ, lo n pagidina bi ajọ naa ṣe lee yọ orukọ wọn kuro ninu iwe.
Nigba to n gba Nasir Kwara to jẹ alaga ajọ ikaniyan lorilẹede Naijiria, NPC lale lolu ileeṣẹ ajọ INEC ni Ọjọgbọn Yakubu sọ ọrọ yii.alaga ajọ INEC naa ni awọn n gbiyanju loorekoore latiu maa yọ orukọ awọn ti ko lẹtọ lati dibo ni Naijiria nipasẹ imọ ẹrọ ṣugbọn imọ ẹrọ ko lee ran ajọ naa lọwọ lati mọ awọn to ti jade laye ninu iwe idibo.
O wa rọ ajọ ikaniyan ni Naijiria lati maa ṣeranwọ fun ajọ INEC paapaajulọ nipa orukọ awọn oṣiṣẹ ijọba to ti ku gẹgẹ bi wọn ba ṣe koo jọ pọ latinu awọn iwe akọsilẹ awọn ileeṣẹ ijọba ati ajọ ijsba gbogbo lati awọn ileewosan kaakiri Naijiria.
Premier league: Manchester city ti fojú Chelsea gbolẹ̀ pẹ̀lú góòlù kan sódo
Oríṣun àwòrán, Reuters
Ṣango Ikọ agbabọọlu Chelsea to n paraba to n fa igi iroko ya ni idije Premier league ilẹ Gẹẹsi lati igba ti saa bọọlu 2021/2022 ti bẹrẹ ko igi nla Manchester city lọna loni.
Goolu kan dondo ni Manchester city fi ṣe agba Chelsea lojude rẹ ni Stanford Bridge.
Atamatase Ikọ Manchester City, Gabriel Jesuit lo gba goolu naa wọle nigba ti ifẹsẹwọnsẹ naa wọ iṣẹju kẹtalelaadọta.
Igba akọkọ niyi ti Gabriel Jesuit yoo gba bọọlu sawọn Chelsea. O si ṣalaye ninu ọrs rẹ lẹyin ifẹsẹwọnsẹ rẹ pe ariire lo jẹ nitori oun ko mọ pe oun lee raye yi gba goolu naa wọle.
O fi kun pe lootọ wọn na awọn ni ipele aṣekagba Champions league ṣugbọn awọn ko mura ẹsan wa biko ṣe lati gba bọọlu to dangajia.
Lati igba ti Tuchel ti gba iṣakoso gẹgẹ bi akọnimọọgba ni Chelsea, igba kẹrin ti Chelsea yoo maa koju  Manchester city niyi, igba mẹtẹẹta iṣaaju si ni Chelsea ti fi oju wọn gbolẹ titi kan aṣekagba idije Champions League loṣu karun ọdun 2021.
Man United vs Aston Villa: ìyà tún gbé Manchester United hánu ní Old Trafford, góòlù kan sódo ni Aston Villa nà wọ́n mọ́lé
Oríṣun àwòrán, Getty Images
O dabi ẹni pe lọwọ yii, ẹgbẹ agbabọọlu Manchester United ti ṣe awure iya bayii pẹlu bi wọn ṣe n fidirẹmi  lawọn ifẹsẹwọnsẹ ti wọn n gba lẹnu lọwọlọwọ yii.
Ni ifẹsẹwọnsẹ wọn ti wọn gba pẹlu Aston villa ni idije Premier league lọjọ Satide, Manchester united tun fidirẹmi lojude wọn ni Old Trafford, goolu kan sodo ni Aston villa fi na wọn.
Agbabọọlu Aston Villa, Kortney Hause lo fi ori gbe goolu wọle fun Aston villa nigba ti ifẹsẹwọnsẹ naa wọ iṣẹju kejidinlaadọrun.
Amọṣa oreọfẹ to yọ fun Manchester united lati daa pada tun bọ mọ wọn lọwọ nigba ti Bruno Fernades tun gba pẹnariti ti wọn fun wọn soke fiofio nigba ni ifẹsẹwọnsẹ naa wọ iṣẹju to pari rẹ.
Nigba ti ifẹsẹwọnsẹ naa bẹrẹ, Manchester United lo kọkọ n ta biọbiọ.
Ko pẹ pupọ ti ifẹsẹwọnsẹ naa bẹrẹ ti wọn padanu Luke Shaw to jẹ eekan adele wọn lẹyin to ṣeṣe.
Bakan naa ni adele ẹyin wọn miran, Harry Maguire naa tun ṣeṣe ti wọn si gbe e jade ni ipele keji ifẹsẹwọnsẹ naa.
Igba keji niyi ti Aston Villa yoo ma bori Manchester united laarin ifẹsẹwọnsẹ mẹrindinlaadọta ti wọn ti gba ni Premier League.
Bobrisky: Mompha àti Bobrisky ti sọ̀rọ̀ sókè lórí àhesọ ọ̀rọ̀ pé wọ́n ń fẹ́ ara wọn
Oríṣun àwòrán, Facebook/Bobrisky
Ilumọọka ọkunrin to wọ aṣọ obinrin, Idris Okuneye, ti ọpọ mọ si Bobrisky, ti sọ pe ko si ohun tọ ahesọ ọrọ to n tan kalẹ lori Instagram pe ọrẹkunrin rẹ ni Ismaila Mustapha, ti iangijẹ rẹ njẹ Mompha.
Koda, Mompha fun ra rẹ naa ti sọ pe ko si ọrọ ifẹ laarin awọn mejeeji eleyii to tako ohun ti oluranlọwọ Bobrisky tẹlẹ ri, Kyme Oye ṣe sọ pe wọn ti fẹ ra ri.
Oye lo sọ pe Mompha ati Bobrisky ti fẹ ra ri nigba ti o n dahun ibeere ẹnikan lori itakun ikansira ẹni Instagram.
Ninu esi rẹ, Mompha faraya, o si sọ pe oun ṣetan lati gbe Oye lọ sile ẹjọ lori ẹsun ibanilorukọjẹ ti ko ba tọrọ aforijin ni kiakia.
Mompha tun sọ fun Oye pe o gbọdọ yọ ohun to kọ lori ọrọ naa kuro loju opo Instagram rẹ.
Mompha ni ki Oye gbaradi fun oun nitori oun ṣetan lati gbe ọrọ naa lọ si ile ẹjọ.
Ninu ifọrọwerọ kan pẹlu Daddy Freeze lori Instagram lọjọ Abamẹta, Mompha sọ pe ko si ẹri to le fidi rẹ mulẹ pe oun ati Bobrisky ti fẹ ra ri.
Mompha fikun ọrọ rẹ pe igba meji pere ni oun ri Bobrisky ri laye oun.
Bakan naa ni Mompha sọ pe oun ti kilọ fun Bobrisky tẹlẹ pe ko ye fi fọto oun soju opo Instagram rẹ mọ.
Agbẹjọ́rò méjì yọ ẹ̀sẹ́ síra wọn níwájú adájọ ó ku ẹni tí yóò yanjú ọ̀rọ̀
"'Eniola Badmus wọ pátá lọ sí ààfin Oba Elegushi, ""ọ̀ín"" kí ló burú níbẹ̀?'"
'Mo ti gba kádàrá lórí bí Ọlọrun ṣe dá mi'
O ni awọn obinrin wa nilẹ ti oun ba fẹ ṣe ṣina, Mompha ni ki lo maa sun oun debi pe oun maa ni ajọṣepọ pẹlu ọkunrin ẹgbẹ oun.
Bobrisky naa kuku sọ tẹnu rẹ ninu ifọrọwerọ naa pẹlu Daddy Freeze.
Bobrisky ṣalaye pe ko si ohun to jọ ọrọ ifẹ oun ati Mompha, o ni ko ṣẹlẹ rara.
''Ọrẹ lasan ni emi ati Mompha, ko si ohun to jọ ọrọ ifẹ laarin awa mejeeji.
Igba to kẹyin niyii ti mo maa sọrọ yii pe Mompha kii ṣe ololufẹ mi.
Koda, iyawo Mompha gan an le jẹrio sii pe ọrẹ lasan an ni emi ati Mompha, ko si nkankan laarin wa,'' Bobrisky ṣalaye.
Bobrisky ni awọn eeyan mọmọ ran Oye lati sọ ohun to sọ lati da wahala silẹ ni.
O ni ko ye oun ohun ti o mu kawọn eeyan maa gbe ahesọ ọrọ kiri pe oun ati Mompha n fẹ ara wọn.
Bobrisky ni awọn to wa nidi ọrọ yii fẹ da ile Mompha ru ni, ile ti wọn naa si maa daru ni.
Bobrisky ni Oye mọọmọ sọ pe oun n fẹ Mompha, kii ṣe pe o n dahun si ibeere ẹnikan lori ọrọ naa.
Two Lawyers fighting: Ki ló mú kí agbẹjọ́rò méjì fí ẹsẹ yọ eyin ará wọ́n níwájú adájọ ní Gombe
Oríṣun àwòrán, Politics Nigeria
Sinima agbelewo kọ leleyii. O soju mi koro ni.
Ki ni nkan to ṣẹlẹ ti agbẹjọro méjì fí yọ ẹsẹ si arawọn niwaju adajọ majisreeti to si di ohun tàwọn eeyan n ṣe kayeefi si loju opo ayelujara ni Naijiria?
Gẹgẹ bi awọn ileesẹ iroyin Naijiria kan ṣe sọ, John Yuwa Esq ati Mukna'an Kingsley Guruyen ni o wa nidi iṣẹlẹ yii.
O soju mi koro kan Daniel Agabi sọ fawọn akọroyin pe Ọgbẹni Guruyen lo kọkọ doju ija kọ akẹgbẹ rẹ.
"A ko ribi fìdí ọrọ yi múlẹ ṣugbọn o ni  ""Mo mọ bi ọrọ yi ṣe waye nitori agbẹjọro ti ẹjẹ bo aṣọ rẹ,Yuwa, akẹgbẹ mi nii ṣe."""
"O tẹsiwaju pe lasiko to n sọ atotonu rẹ niwaju adajọ ni agbẹjọro keji saadede fún un ni ẹsẹ ti ẹjẹ dẹ bẹrẹ sí ní da l'ẹnu rẹ""."
Oríṣun àwòrán, Politicws Nigeria
Ọ̀wọ́ ọ̀tún Ọlọ́run Olódùmarè ni Ogboni máa wà bí ó bá re ibi àgbà ń rè
O ni ẹni tí wọn dojú ìjà kọ ko da esi pada ṣugbọn o ke si awọn agbofinro ti wọn si wa gbe akẹgbẹ rẹ janto.
Yato si pe a ri awọn aworan agbẹjọro tí ẹjẹ wa lara aṣọ rẹ, BBC ko ribi fidi ọrọ naa múlẹ ju pé o waye lọjọbo ni ile ẹjọ majisreeti to wa ni Gombe  bi ileesẹ iwe iroyin Naijiria, Politics Nigeria ti ṣe sọ.
Kaakiri oju opo ayelujara ni aworan awọn agbẹjọro yii wa ti awọn eeyan si n ṣe èèmọ lórí ohun tó lè dá aduru wahala yi silẹ laarin awọn tó yẹ kí wọn gbofin ro.
Ẹjọ ti a gbọ pe o gbe awọn agbẹjọro mejeeji wa siwaju adajọ ni ṣe pẹlu ẹsẹ ọdaràn ti wọn pe nomba faili naa ni CMCIII/GM/42/2017.
Èyí taa tun ri ka ni pe arakunrin Yuwa ni o n soju ẹni tí wọn fẹsun kan ti akẹgbẹ rẹ Guruyen sí sojú ẹni to gbẹjọ wa.
Awọn tó jẹ akẹgbẹ awọn agbẹjọro mejeeji yi labẹ asia ẹgbẹ awọn agbẹjọro NBA ko tii fesi sí iṣẹlẹ naa.
Amọ iwe iroyin Politics Nigeria sọ pé arakunrin Yuwa ti kọ iwe ẹdun ọkan si ẹgbẹ agbẹjọro to wa ni Gombe pe ki wọn gbe igbese lori iṣẹlẹ ọhun.
"Ọmọ ẹgbẹ́ PDP Oyo tí inú bá ń bí, ẹ kó ""mo kó - mo rò"" yín wá ká yanjú ẹ̀ - Makinde"
Wo ewu tó wà nínú fífi ọ̀sẹ̀ fọ ojú ara fún ọkùnrin àti obìnrin
Àgùnbánirọ̀ Fidelia ti sọ irú ìdájọ́ tó ń fẹ́ fún sọ́jà tó da omi ìdọ̀tí lé e lórí
Wo ìdí tí àwọn tọkọ-taya kan ṣe ń ṣe ìgbéyàwó nínú pósí
Romeo and Juliet padà di ìwé Akinola àti Arike ní èdè Yorùbá
Bola Tinubu: Mo dúpẹ́ pé mo padà délé láyọ̀
Oríṣun àwòrán, Bola Tinubu
Asaaju ẹgbẹ oselu APC, Asiwaju Bola Tinubu ti n dupẹ lọwọ Ọlọrun pe o da oun pada si orilẹede Naijiria ni alaafia.
Tinubu, ẹni to ti kuro lorilẹede yii lati osu mẹta sẹyin lati lọ se isẹ abẹ nilu London lo n dupẹ bẹẹ nile ijọba ni Marina nibi apejẹ ikinni kaabọ ti ijọba ipinlẹ Eko se fun.
"Tinubu ni ""Ori mi wu amọ inu mi dun pe mo pada sile. Ọlọrun lo n fun ni ni iye, oun naa si lo le gba a."
Ọlọrun nikan lo le gba ẹmi mi tabi fun mi ni iye, ara mi si ti le koko pada, mo si dupẹ pe mo pada sile pẹlu alaafia pipe.
Tinubu wa dupẹ lọwọ awọn eeyan to seto ikinni kaabọ naa fun to si gbadura fun wọn pe Ọlọrun yoo dahun gbogbo ohun to n wu wọn lọkan.
Olota Of Ota: N kò fara mọ́ ìyapa Nàíjíríà, ìṣèjọba ẹlẹ́kùnjẹkùn ní ọ̀nà àbáyọ
Oríṣun àwòrán, other
Bola Tinubu ko tii kuro lorilẹede Gẹẹsi nibi to wa to ti n fun ara ni isinmi.
Ọrọ yii ni agbẹnusọ rẹ, Tunde Rahman fi dahun ibeere ti BBC News Yoruba taare sii lori aworan ati fidio to n ja rainrain lori ayelujara pe eekan ẹgbẹ oṣelu APC naa ti wa sile tabi gbera lọ si orilẹede miran fun iwosan.
Ọgbẹni Tunde Rahman ni laipẹ laijina ni Aṣiwaju Bọla Ahmed Tinubu yoo de si Naijiria ṣugbọn lọwọ yii Jagaban ko tii pada si Naijiria.
Aworan fidio ti wọn n gbe kiri yẹn kii ṣe tii isinyi o. Ti igba pipẹ sẹyin ni ti a n lọ si orilẹede Saudi Arabia ni oṣeeṣe ko jẹ.
O fi kun un pe ariwo ti awọn eeyan n pa nipa ilera Aṣiwaju Bọla Tinubu ko n ṣe ara rẹ nitori pe ohun kan ṣoṣo to ṣee naa ni ipenija orokun rẹ; orokun yii lo si lọ ṣe iṣẹ abẹ le lori lẹyin eyi ko si nnkankan to ṣee.
Akoko iwosan iṣẹ abẹ naa lo n la kọja, to si ti gbadun bayii.
Fun bii nnkan bi ọsẹ mẹrin si marun sẹyin ko lo igi gan lati fi rin mọ.
Oríṣun àwòrán, other
Sẹnetọ ana, Shehu Sani wa lara awọn eekan to gbe iroyin naa si ori ikanni ayelujara wọn pe agba oṣelu naa ti pada to si kii ku oriire araya.
O ti le ni nnkan bii oṣu meji bayii ti Aṣiwaju Bọla Ahmed Tinubu ti fi orilẹede Naijiria silẹ fun itọju ara rẹ loke okun.
Lati igba yii wa si ni ọpọlọpọ awọn oloṣelu ninu eyi ti ko yọ aarẹ orilẹede Naijiria, Mohammadu Buhari gan silẹ atawọn gomina kaakiri orilẹede Naijiria pẹlu to rinrinajo lọ oke oku si lọ n bẹẹ wo.
'Mo ti gba kádàrá lórí bí Ọlọrun ṣe dá mi'
Dog bit Undergraduate's scrotum in Ondo: Ọlọ́paàá Ondo ní akẹ́kọ̀ọ́ fásitì AAUA tí 'Charlie', ajá gé jẹ ní kórópọ̀n ti kúrò nílé ìwòsàn
Oríṣun àwòrán, Sunshinetruthng.com
Ileeṣẹ ọẹọpaa ni ipinlẹ Ondo ti ṣalaye bi ọrọ ṣe jẹ pẹlu aja to di eyi le agbegbe nnkan smọkunrin akẹkọọ kan ni fasiti Adekunle Ajasin, AAUA, to wa nilu Akungba.
Gẹgẹ bi ohun ti alukoro ileeṣẹ ọlọpaa ni ipinlẹ naa, Funmi Ọdunlami sọ, loots ni aja naa ge arakunrin naa jẹ ṣugbọn eyin rẹ kan ha koropọn akẹkọọ naa ni, wọn si ti gbe e lọ si ileewosan o si ti gba itọju.
Aja naa ti wọn ni wọn pe orukọ rẹ ni Charlie ni okiki rẹ kan pe o ti ge apa kan nnkan ọmọkunrin akẹkọ naa jẹ.
Ọ̀wọ́ ọ̀tún Ọlọ́run Olódùmarè ni Ogboni máa wà bí ó bá re ibi àgbà ń rè
Gẹgẹ bi iroyin ṣe sọ, akẹkọọ ti ọrọ naa kan fẹ lọ kiọrẹ rẹ kan ni ileegbe awọn akẹkọọ kan ti wọn n pe ni Vanilla Villa ni lasiko ti aja naa fi kọlu.
Alukoro ileewe fasiti naa, Oluwafẹmi Adegbeyeni to fidi iroyin naa mulẹ fawọn akọroyin ni lọgan ti iṣẹlẹ naa ṣẹ ni wọn gbe lọ sileewosan fun itọju
Alukoro ọlọpaa ni apa oke itan akẹkọọ naa ni aja yii bu jẹ, ṣugbọn ipa rẹ lo kan koropọn akẹkọọ naa.
Ileeṣẹ ọlọpaa ipinlẹ Ondo ni ẹya Pit-bull ni aja naa, Charlie si ni ẹni to nii sọọ.
'Mo ti gba kádàrá lórí bí Ọlọrun ṣe dá mi'
O fi kun un pe ọdun meji ati oṣu mẹta ni aja naa, akẹkọọ oniwe kẹrin ẹkọ imọ nipa ẹranko, Animal Science kan ti orukọ rẹ n jẹ Abass Ọlagunju lo ni aja naa.
O ni Sadiq Ọpẹyẹmi ni orukọ akẹkọọ ti aja naa doju ija kọ ati pe Sadiq n sare lọ pade Abass to ni aja naa ni aja naa fi buu so to si gee jẹ.
Alukoro Ọlọpaa ni ipinlẹ Ondo naa ni eyin aja naa ha koropọn akẹkọọ naa.
Arsenal vs Tottenham: Arsenal jẹ́wọ́ òǹnilẹ̀ North London han Tottenham pẹ̀lú àmì ayò 3-1
Oríṣun àwòrán, Premierleague.com
Ẹgbẹ agbabọọlu Arsenal gbo ewuro soju alamuleti wọn ni iha ariwa ilu London, iyẹn ẹgbẹ agbabọọlu Tottenham Hotspur pẹlu ami ayo mẹta si ẹyọ kan.
Ifẹsẹwọnsẹ naa to waye ni papa iṣire Emirates to jẹ ibuba Arsenal jẹ ọkan lara awọn ifẹsẹwọn to maa n fa  ariyanjiyan ati awuyewuye julọ ninu idije Premier league ilẹ Gẹẹsi.
Nigba ti ifẹsẹwọnsẹ naa wọ iṣẹju kejila ni Smith Rowe, agbabọọlu Arsenal gba goolu akọkọ wole. Eyi lo si mu ko di agbabọọlu to kere julọ ni ikọ Arsenal ti yoo gba bọọlu sawọn ni ifẹsọwọnsẹ laarin Arsenal ati Tottenham. Ẹni ọdun mọkanlelogun o le ọgọta ọjọ ni Emile Smith Rowe.
Nigba to di iṣẹju kẹtadinlọgbọn ni balogun ikọ Arsenal naa, Piere-Emerick Aubameyang  gba goolu keji fun Arsenal.
Oríṣun àwòrán, Premierleague.com
Bukayọ Saka lo fi ọba lee fun Arsenal nigba ti ifẹsẹwọnsẹ naa wọ iṣẹju kẹrinlelọgbọn ki wọn to lọ fun isinmi abala akọkọ.
Amọṣa nigba ti abala keji wọle de, awọn agbabọọlu Tottenham hotspurs gbọnra jigi ṣugbọn gbogbo itabiọbiọ wọn, goolu kan ṣoṣo ni wọn ri da pada nibẹ.
Son Heun-min lo gbaa pada nigba ti ifẹsẹwọnsẹ naa wọ iṣẹju kọkandinlọgọrin.
KSA mourns wife's death: Sunny Ade ti kéde ọjọ́ ìsìnkú ìyàwó rẹ̀, Risikat Adegeye, Ó ní ańgẹ́lì òun ló kú
Oríṣun àwòrán, other
Agbaọjẹ akọrin Juju nii King Sunny Ade ti sọrọ nipa iku iyaworẹ, ọmọọba Adejọkẹ Adegẹye ti wọn yoo sinku rẹ lọjọ Kọkandinlọgbọn oṣu Kẹsan .
KSA ṣapejuwe  iku Risikat Adegeye gẹgẹ bi eleyi to fọwọ kan mọlẹbi lẹmi ṣugbọn o ni oun dupẹ fun iru igbe aye ti Risikat gbe.
''Mo dupẹ fun Ọlọrun lori gbogbo nkan to ṣẹlẹ nitori gbogbo nkan lo yee ju awa ẹda lọ.Iku Risikat jẹ eyi to dun emi ati mọlẹbi mi''
King Sunny Ade ni Risikat kọja iyawo nikan fun oun.
O ni ''Angẹli mi ni mo si maa n pe ni baby mi.Iyawo ti gbogbo ọkunrin daada ati ọmọ daada gbọdọ ni Risikat jẹ''
Atẹjade lati ọdọ awọn mọlẹbi ni wọn yoo tẹ Risikat safẹfẹ ree lẹyin igba naa ni wọn yoo sin oku rẹ nilu Eko.
Sunny Ade wa fi ọrọ idupẹ ranṣẹ si awọn ọrẹ ati ololufẹ to ti n fi ọrọ ikini ranṣẹ lati igba ti Risikatu ti jade laye.
'Mo ti gba kádàrá lórí bí Ọlọrun ṣe dá mi'
Risikatu fi igba kan jẹ aṣofin nile aṣofin ipinlẹ Eko.
Ọmọ ọkunrin mẹfa lo bi fun King Sunny Ade ti a si tun gbọ pe o jade laye ni ọjọ kan si ọjọ ayẹyẹ ọjọ ibi Sunny Ade.
Saga, Nini Queen jáde nilé ẹlẹ́gbọ́n àgbà BBNaija, Pere àti Angel jáde sínú àdànwò BBNaija tuntun
Oríṣun àwòrán, BBNaija
Adura Saga gba nile ẹlẹgbọn agba bayii o pẹlu bi oun ati Ninu, korikosun rẹ ninu idije naa ṣe jade kuro nile ẹlẹgbọn agba BBNaija lọjọ Aiku.
Ṣaaju lọsẹ diẹ sẹyin ni Saga ti kọkọ sọ pe bi wọn ba lee le Nini kuro ṣiwaju oun, oun funra oun yoo pe fun iyọkuro ni o lati lee lọ ba korikosun oun nita ile ẹlẹgbọn agba.
Saga ko nilo igbesẹ yi mọ bayii nitori oun ati Nini ni wọn jọ le kuro nile ẹlẹgbọn agba lọjọ Aiku.
Amọṣa, awọn mejeeji nikan kọ ni wọn yọ. Ẹlẹgbọn agba tun le Queen naa pẹlu.
ṣaaju ninu eto naa ni Ebuka ti pe Pere niwaju gbogbo awọn olugbe naa to si ni oun ti yọ ọ kuro ni ile naa.
Oríṣun àwòrán, BBnaija
Bakan naa lo tun pe Angel pẹlu jade, ṣugbọn o ni oun ko yọ awọn mejeeji yii, ara idan ere eto naa ni gẹgẹ bi Ebuka to jẹ atọkun eto naa ṣe sọ. O ni aṣiri ni yoo jẹ laarin awọn oluworan eto naa ati Ẹlẹgbọn agba funrarẹ.
Ko tii han si ẹnikẹni ohun ti ẹlẹgbọn agba n pete rẹ ṣugbọn gbogbo awọn eeyan to n woo naa lo n fọwọleran wo ohun ti yoo ba ti ẹyin rẹ yọ.
Yoruba Nation: Afenifere àti Ilana Omo Oduduwa fèsì sọ́rọ̀ Alaafin tó ni kò s'ọ́nà nínú pínpín Nàìjíríà
Oríṣun àwòrán, Alaafin Oba Adeyemi III
Ẹgbẹ Afenifere ilẹ Yoruba ti sọ pe ọrọ ti Alaafin sọ pe atunto lo le mu ilọsiwaju ati iṣọkan ba orilẹede Naijiria kii ṣe iyapa wa ni ibamu pẹlu ero ẹgbẹ naa.
Nigba to n ba BBC Yoruba sọrọ, eekan ẹgbẹ Afenifere, Bashorun Seinde Arogbofa ṣalaye pe ohun to dara julọ fun Naijiria bayii ni pe ''ki a maa pinya.
Ai maa tẹle eto ijọba ẹlẹkun-jẹkun lo mi ki awọn eeyan bii Sunday Igboho ati IPOB maa beere fun iyapa kuro lara Naijiria.
"Ìran mi ò ja ẹ̀ṣẹ́ rí, ẹ̀gbin yìí ló ta lé mi tí mo fi di ""Scorpion"" Ọ̀gá ọ̀gá nínú ìjà"
Niṣe lo yẹ ki awọn ipinlẹ ati ẹkun kọọkan ma dari ọrọ aje wọn fun ra wọn ki wọn si maa fi si ida diẹ ranṣẹ si ijọba apapọ bi igba aye ijọba Obafemi Awolowo.
O si ti n bẹrẹ diẹdiẹ pẹlu bi awọn ipinlẹ lẹkun Guusu ti fofin de idẹran jẹko ni gbangba ati gbigba owo ori VAT fun ra wọn.''
Amọ, ero ẹgbẹ Ilana Omo Oduduwa yatọ lori ọrọ naa.
Alukoro ẹgbẹ Ilana Omo Oduduwa, Ọgbẹni Maxwell Adeleye sọ fun BBC Yoruba pe ọgbọn ni Alaafin fi sọrọ nitori abẹ ijọba lawọn ọba alaye wa nilẹ Yoruba.
''Abẹ alaga ijọba ibilẹ ni Alaafin wa, ohun ti ofin ti Fulani gbe le wa lọwọ sọ niyẹn.
Baba Alaafin ti awa mọ o, ẹyin otitọ lo wa, ọmọ ọdọ naa fi ọgbọn ṣee ni.
Alaafin to sọ pe oun wa lẹyin Igboho tẹlẹ ko le sọ nisinyii pe oun ko ṣe ti Igboho mọ.
Nitori idasilẹ orilẹede Yoruba ni Igboho n beere fun, nitori naa, ti baba ba sọ pe oun fẹ Yoruba Nation mọ, a jẹ wi pe baba ko ṣe ti Igboho mọ niyẹn.
Baba ni Alaafin jẹ fun wa, a ko si le maa gbo wọn lẹnu, ṣugbọn a mọ pe ọdọ wa ni ọkan wọn wa,'' Ọgbẹni Adeleye lo sọ bẹẹ.
Kò sí ọ̀nà nínú kí Nàìjíríà pín, àtúntò ló lè mú àlááfíà àti ìṣọ̀kan wá - Alaafin
Alaafin Oyo, Ọba Lamidi Adeyemi kẹta ti rọ awọn ọmọ Naijiria atunto orilẹede yii lo le mu iṣọkan ati ilọsiwaju wa kii ṣe pinpin Naijiria.
Alaafin rọ awọn eeyan lati kọ eti ikun si awọn to n pe fun iyapa kuro lara orilẹede Naijiria.
Oba Adeyemi sọrọ yii nibi ayẹyẹ ifilọlẹ yara ikẹkọọ marunlelọgbọn ile ẹkọ Royal Gold Model ati fifi ipilẹ mọṣalaaṣi kan lelẹ niluu Ibadan.
Iṣẹ́ abẹ tí Bola Tinubu ṣe ló fa àbẹ̀wò ọ̀pọ̀ èèyàn sọ́dọ̀ rẹ̀ - Fayemi
Sotitobire pe ẹjọ́ kòtẹ́milọ́rùn lórí ẹ̀wọ̀n gbére
Kíláàsì wó lé ọmọ ilé ẹkọ́ mẹ́ta lórí, ọ̀kan ti kú, ẹ wo ohun tó ṣe méjì tó kù
Ọ̀wọ́ ọ̀tún Ọlọ́run Olódùmarè ni Ogboni máa wà bí ó bá re ibi àgbà ń rè
Alaafin ni ọpọ nkan to ṣẹlẹ sẹyin lo ṣe okunfa iwa ẹlẹyamẹya ati idẹyẹsi laarin awọn ọmọ Naijiria.
Amọ, o rọ awọn ọmọ Naijiria lati wa ọna ti wọn le fi yanju awọn ohun to ti ṣẹlẹ sẹyin ni itubi inubi ki orilẹede Naijiria le tẹsiwaju.
''Mi o lero pe pinpin Naijiria ni ojutuu si iṣoro to n koju Naijiria.
Oríṣun àwòrán, Alaafin Oba Adeyemi III
Ṣugbọn a le ṣe atunto orilẹede yii lọna ti alaafia yoo fi jọba ti a o si maa gbe pọ ni alaafia.
A nilo lati wa ni iṣọkan ni Naijiria ki orilẹede yii maa baa pin yẹlẹ yẹlẹ,'' Alaafin lo sọ bẹẹ.
Oba Adeyemi ko ṣai lu adari ile ẹkọ naa, Alhaji Taofeek Akewugbagold, lọgọ ẹnu lori bi o ti n pe fun iṣọkan laarin awọn ọmọ Naijiria.
Ninu ọrọ tiẹ, Akewugbagold naa rọ awọn musulumi lati ma dẹyẹ si awọn ẹlẹsin miran.
Alhaji Akewugbagold ni ''ko yẹ ki awọn ẹlẹsin kan maa doju ibọn kọ awọn ẹlẹsin miran.
Onikaluku lo lẹtọọ lati ṣe ẹsin ti wọn ba fẹ tori ojiṣẹ Ọlọrun ni Jesu ati Anọbi Muhammad.''
Almufty Ilorin, Sheikh Sulaimon Onikijipa to sọrọ apilẹkọ nibi ayẹyẹ naa kepe awọn musulumi lati maa tẹle awọn ẹkọ iwe mimọ Quran, ki wọn si ye wa iṣẹ iyanu nibi ti ko si.
"'Eniola Badmus wọ pátá lọ sí ààfin Oba Elegushi, ""ọ̀ín"" kí ló burú níbẹ̀?'"
Agbẹjọ́rò méjì yọ ẹ̀sẹ́ síra wọn níwájú adájọ ó ku ẹni tí yóò yanjú ọ̀rọ̀
'Mo ti gba kádàrá lórí bí Ọlọrun ṣe dá mi'
CAN honours Plateau Imam: CAN fún Imam Abdullahi Abubakar , Leah Sharibu tó wà láhàmọ́ l'ami ẹyẹ
Oríṣun àwòrán, Channels TV
Ẹgbẹ ọmọlẹyin Kristi Naijiria ti fi ami ẹyẹ da Imaamu ẹlẹsin Islam kan, Abdullahi Abubakar to jẹ kawọn ẹlẹsin Kristẹni sa pamọ sinu mọṣalasi rẹ nigba ti ogun de nipinlẹ Plateau.
Awọn ọmọlẹyin Kristi to le ni igba ni Imam yii gba silẹ ni ijba ibilẹ Barkin Ladi.
Ẹgbẹ CAN ṣe idanilọla pẹlu ami ẹyẹ yii lọjọ Abamẹta nilu Abuja nibi ayẹyẹ ọdun marundinlaadọta ti ẹgbẹ CAN pe.
Imaamu Abubakar gba awọn Kristẹni to le ni igba la lọjọ kẹrinlelogun oṣu Kẹfa, ọdun 2019 nigba ti awọn afurasi ya wọ awọn ilu ni ijọba ibilẹ Barkin Ladi.
Ninu oṣu keje ọdun 2019, ijọba ilẹ Amẹrika da Imaamu ẹni ọdun mẹtalelọgọrin yii lọla pẹlu awọn adari sin mẹrin mii lati orilẹede Sudan, Iraq, Brazil ati Cyprus gẹgẹ bi ajijagbara fun alafia ẹsin kaakiri orilẹede wọn.
Ọ̀wọ́ ọ̀tún Ọlọ́run Olódùmarè ni Ogboni máa wà bí ó bá re ibi àgbà ń rè
Igbakeji aarẹ naa to wa nibẹ, Yemi Oṣinbajo rọ awn Kristẹni atawọn olori lati jẹ ololufẹ ṣiṣe ẹsin ni alafia ati titẹle alakalẹ ofin.
Lara awọn to gba ami ẹyẹ nibẹ naa ni igbakeji aarẹ, Yemi Oṣinbajo, o jiṣẹ aarẹ Muhammadu Buhari gẹgẹ bo ṣe ba ẹgbẹ CAN yọ.
Bi a ba n wa irẹpọ ati alafia lorilẹede Naijiria, awọn gbẹ ẹsin Kristẹni atawọn adari ẹsin ni Naijiria gbudọ maa waasu ibadọgba ni gbogbo igba ki wọn si ma kaarẹ ninu jija fun ẹsin alafia, idajọ ododo ati titẹle ofin.
"Oṣinbajo ni ""a gbudọ maa jẹ ki otitọ jade pe Kristi ko wa lati ṣagbekalẹ ẹsin tabi ba ẹnikẹni jẹ bi ko ṣe fifi ododo rẹ han fun gbogbo eniyan eyi to le mu eeyan jogun iye ainipẹkun""."
Igbakeji aarẹ tun gboriyin fun iṣẹ takuntakun ti awọn adari CAN n ṣe lati mu ilọsiwaju ba ẹsin to sin CAN ti di ohun elo pataki fun alafia ati irẹpọ niluu paapaa labẹ idari rẹ.
Koda o mnu ba ifọwọsowọpọ to wa laarin wọn atawọn atawn adari ti sin Islam atawọn ẹsin mii fun ipẹtu saawọ.
Taliban's law against Shaving beards: Wo dẹndẹ ìyà tó ń bẹ fún ọ báyìí o tóo bá fa irungbọ̀n ní Afghanista torí Sharia
Oríṣun àwòrán, Getty Images
O ti di ewọ bayii lati maa fa irugbọn lorilẹede Afghanistan, ijọba Taliban lo sọ bẹẹ.
Ijọba Taliban ti kilọ fawọn gẹrigẹri lẹkun Helmand pe wọn ko gbọdọ fa irugbọn fun ẹnikan kan mọ.
Taliban sọ pe eyi ṣe ilodi si ilana ofin Islam, ati pe ijiya to tọ ti wa fun ẹnikẹni to ba tapa si ikede ijọba yii.
Awọn ọlọpaa Taliban ti wa nilẹ lati maa da ṣeria fun ẹnikẹni to ba tapa si ofin ti ijọba gbe kalẹ yii.
Awọn gẹri-gẹri kan to wa ni olu ilu Afghanistan, Kabul naa ti sọ pe awọn ti gba aṣẹ yii lati ọdọ ijọba.
Igbesẹ yii tọka si pipa si ọna ti awọn Taliban fi ṣe ijọba wọn tẹlẹ lorilẹede naa bo tilẹ jẹ pe wọn ṣeleri lati ma mu aye le fawọn eeyan.
Ijọba Taliban ti bẹrẹ si ni fi ọwọ lile mawọn alatako lẹyin ti wọn gba ijọba loṣu to lọ.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Lọjọ Abamẹta ni wọn pa awọn afurasi ajinigbe mẹrin ti wọn si so oku wọn rọ lopopona Herat.
Awọn ọlọpaa ijọba Taliban ti lẹ ikilọ si awọn ile gẹri-gẹri ni ẹkun Helmand pe wọn gbọdọ maa tẹle ofin Sharia lori irun gigẹ ati irugbọn fifa.
Wọn sọ ninu ikilọ pe ko si aye fun awawi kankan lati ọdọ awọn gẹri-gẹri lori ọrọ yii.
Baba kan niluu Kabul sọ pe niṣe lawọn ọlọpaa Taliban n ṣọ awọn lọwọ lẹsẹ lati ti pe awọn tẹle ofin ti wọn ṣe agbekalẹ rẹ ni tipa tipa.
Lasiko ijọba Taliban laarin ọfdun 1996 si 2001, ijọba ko faye gba kawọn eeyan maa ṣe irun to ba wu wọn.
Ẹnikẹni ko gbọdọ ge irugbọn rẹ tabi rẹẹ silẹ rara lasiko ijọba Taliban nigba naa.
Bí o bá ń fẹnukonu ju iye ìṣẹ́jú ààyá yìí lọ, wo adúrú kòkòrò tí wàá tí ibi ẹnu kò
Wo ìdí tí CAN fi fún Imaamu kan l'ami ẹyẹ níbi ayẹyẹ ńlá ọdún 45 ti CAN pé
Ọ̀wọ́ ọ̀tún Ọlọ́run Olódùmarè ni Ogboni máa wà bí ó bá re ibi àgbà ń rè
Boko Haram ṣe ìkọlù sí Sokoto àti Yobe, wọ́n ba gbogbo ẹ̀rọ ìbánisọ̀rọ̀ jẹ́
Oríṣun àwòrán, AFP
Awọn ara ilu Sabon Birni ni ipinlẹ Sokoto ti ke gbajare sita pe awọn agbebọn ti gbakoso ilu wọn eleyii to mu ki ọpọlọpọ eniyan sa kuro lọ si Niger.
Awọn aṣofin mejeeji to n ṣoju ẹkun ijọba ibilẹ Sabon Birni sọ pe ijọba ibilẹ ọhun ti wa ni abẹ iṣakoso ikọ Boko Haram bayii nitori wọn ti ba gbogbo ojuko ibugbe awọn ologun jẹ nibẹ.
Eyi ko ṣẹyin iroyin pe awọn agbebọn ti pa awọn ọmọ ogun mẹtadinlogun ati araalu meji ni opin ọsẹ.
Lọwọlọwọ, a wa loju ibọn awọn agbebọn ni Sabon Birni. Eyi ni iroyin ti BBC gbọ lẹnu eeyan ọkan lara awọn ti awọn agbebọn ko ni papa mọra ti wọn kan si.
Kọmiṣọna fun  eto aabo nipinlẹ Sokoto tẹlẹri, Garba Moyi ni lootọ ni iṣẹlẹ naa waye, amọ wọn n duro de ikọ ologun lati fi iroyin naa lede.
''Lootọ ni a ti gbọ iroyin nipa ikọlu si ipinlẹ Sokoto ati awọn agbegbe ti awọn agbebọn ti ba awọn ẹrọ ayelujara jẹ nibẹ, ti ko si si bi awọn eniyan ṣe le ba ara wọn sọrọ''.
''Ilu marun un ti Kangara ati Katsira wa lara wọn ni wọn ṣekọlu si, ti wọn si pa eniyan mẹrin, ti awọn mẹfa si n gba itọju lọwọ ni ileewosan.
Bakan naa ni wọn ni awọn agbebọn naa dana sun awọn meji to farapamọ si ile ounjẹ lasiko ikọlu ọhun, ti wọn si jade laye.
Nibayii ko si eto aabo kankan mọ ni awọn agbegbe ti wọn ṣekọlu si yii nitori wọn ti pa awọn ẹṣọ alaabo to wa nibẹ, ti awọn araalu naa si ti fi ẹsẹ fẹ lọ si ẹyin odi lorilẹede Niger.
Ọ̀wọ́ ọ̀tún Ọlọ́run Olódùmarè ni Ogboni máa wà bí ó bá re ibi àgbà ń rè
Awọn araalu sakuro ni Yobe lẹyin ikọlu Boko Haram
Ko tan si ipinlẹ Sokoto nikan, awọn agbebọn yii tun ṣekọlu si agbegbe Babangida ni ipinlẹ Yobe.
Iṣẹlẹ yii ti mu ki ọpọlọpọ awọn araalu sa asala fun ẹmi wọn kuro nibe lai ti pe oṣu kan ṣẹyin ti awọn agbebọn yii ṣekọlu si ibẹ.
Awọn ti iṣẹlẹ naa ṣoju wọn ni awọn agbebọn yii ma n wa ni ọgọọrọ lati wa ṣekọlu si agbegbe naa, eleyii to fi mọ ilu Ọga Agba ọlọpaa, Usman Baba Alkali, ti awọn agbebọn naa si gbe asia wọn sibẹ.
Bakan naa ni awọn agbebọn ti ba awọn ẹrọ ayelujara jẹ nibẹ, ti ko si si bi awọn eniyan ṣe le ba ara wọn sọrọ lori ẹrọ ilewọ tabi ayelujara.
'Mo ti gba kádàrá lórí bí Ọlọrun ṣe dá mi'
Bobrisky: Láyé ìgbà tí mo ṣì jẹ́ ọmọkùnrin, ẹnu máa ń gbẹ, kò sẹni to maa ń fẹ́ wojú mi
Oríṣun àwòrán, WithChude
Gbajugbaja ọkunrin to maa n mura bi obinrin, Idris Okuneye ti ọpọ mọ si Bobrisky ti ni bi oun ṣe jẹ obinrin lọwọlọwọ yii, oun n gbadun rẹ gidi gan to si ti lana pupọ fun un.
Bobrisky n sọ eyi lori eto gbajugbaja afọrọwanilẹnuwo, Chude lori eto #WithChude nibi to ti n sọ pe awọn obinrin n sọ anfani nla nu pẹlu bi wọn ko ṣe ki n lo nkan ti Ọlọrun fun wọn daadaa.
O jẹ igba akọkọ ti Bobrisky yoo farahan lori ẹrọ amohunmaworan lọdun 2021 to tun jẹ ọdun kan naa to ṣe ayẹyẹ nla fun ọjọ ibi ọgbọn ọdun rẹ.
"Nigba to bii pe ""Ọkunrin ni wọn bi ẹ, ki lo de too fẹ parada di obinrin"", Bobrisky ni:"
Tori jijẹ obinrin bayii ti ṣi ọpọlọpọ ọna fun mi. Awọn obinrin o tilẹ mọ bi wọn ṣe lagbara to, ọpọ wọn ko mọ bi wọ́n ṣe le lo ẹbun ti wọn ni gẹgẹ bii obinrin.
"O ni nigba ti oun ṣi jẹ́ ọkunrin, ko sowo, ko tilẹ sẹni to maa n da si oun, to fẹ ba oun ṣe tori ai si owo. ""Mo kan n ""hustle ni""."
Ǹjẹ́ Bobrisky àti Mompha ń gbée síi fúnra wọn lóòtọ́? Ohun táa mọ̀ nìyí
Ẹ wo àtúpalẹ̀ bí Bobrisky ṣe ná ₦500m péré láti ṣe ọjọ́ ìbí
Bobrisky@30: Àpótí òní páálí láwọn àlejò yóò fí wọlé síbi àpéjẹ̀ Bobrisky
Bobrisky fi àwòrán tuntun léde lẹ́yìn tó parí iṣẹ́ abẹ ìdí tó ṣe
Bí o bá ń fẹnukonu ju iye ìṣẹ́jú ààyá yìí lọ, wo adúrú kòkòrò tí wàá tí ibi ẹnu kò
Baba Ijesha yóò farahàn nílé ẹjọ́ lónìí, àwọn ohun tí wọ́n fẹ́ ṣe níbẹ̀ nìyí
Ọ̀wọ́ ọ̀tún Ọlọ́run Olódùmarè ni Ogboni máa wà bí ó bá re ibi àgbà ń rè
Bobrisky ni igba naa loun pinu pe oun ko fẹ iru nkan bayii, oun fẹ jẹ ọga ara oun.
"Ni ti awọn kan koda lara awọn to n tẹlee lori ayelujara ni o n ja awọn kulẹ pẹlu bo ṣe n ṣe, Bobrisky ni ""haa, ki wọn ma roo bẹẹ́ o, ki wọn ma wo mi, ẹyin naa ẹ gbe tiyin jade""."
"Idris ni oun sunmọ iya to bi oun daadaa ko to di oloogbe. ""Eeyan kan ṣoṣo to nifẹ mi niyẹn to gbaruku ti mi nigba ti gbogbo eeyan kọ mi silẹ""."
O ni bo tilẹ jẹ pe baba oun gan kọkọ woo pe, ohun to yẹ koun maa 'ṣe kọ leleyii, oun tawọn jọ sọ kọ yii o pada gbaruku ti oun.
Owo ni gbogbo nkan o. Too ba n sọ pe owo kọ ni gbogbo nkan, o n parọ tan ara rẹ jẹ ni. Ṣe ti Buhari o ba jẹ aarẹ, o lee mọọ ni gbajumọ?. O ni too ba fẹ orukọ rere, pẹlu owo ni.
Bobrisky ni ori ayelujara ni gbogbo nkan wa bayii oun ko si fẹ sọrọ nipa rẹ.
O ni oun ṣaa fẹ jẹ ọga ara oun ti oun si fẹ lo nkan toun ni fi ri nkan ti oun fẹ gba lai ro ohun ti ẹnikni n sọ tori ohun to ba wu ẹlẹnu lo le fi ẹnu rẹ sọ.
Wo èrò Afenifere àti Ilana Omo Oduduwa lórí ọ̀rọ̀ Alaafin pé kò s'ọ́nà nínú pínpín Nàìjíríà
Fá irungbọ̀n rẹ, kòó forí kó ìyà lọ́wọ́ ìjọba Afghnistan - Taliban
Wo ìdí tí CAN fi fún Imaamu kan l'ami ẹyẹ níbi ayẹyẹ ńlá ọdún 45 ti CAN pé
Tinubu ṣe iṣẹ́ abẹ lá ṣe n bẹ̀ẹ́wò nílùú London, kìí ṣe nítorí ìbò 2023 - Fayemi
Oríṣun àwòrán, daily post
Gomina ipinlẹ Ekiti, Kayode Fayemi ti sọrọ lori ipo ti ilera Asiwaju ẹgbẹ oṣelu All Progressives Congress, APC, Bola Tinubu wa.
Oṣu diẹ sẹyin ni Tinubu rinrinajo lọ si ilu London, ti iroyin si gba ori ayelujara lasiko naa pe ara rẹ ko ya.
Bakan naa ni awọn iroyin kan tilẹ sọ pe o ti ku.
Ṣugbọn awọn iroyin yii ni oniruuru awọn oloṣelu, paapaa lati inu ẹgbẹ oṣelu APC, to fi mọ awọn gomina, ati ọmọ ile aṣofin lo lọ n ki Tinubu nibi to wa.
Awọn abẹwo naa to n waye lera-lera si n fa awuyewuye laarin awọn ọmọ Naijiria pe, o ni lati jẹ pe nkan n ṣe oloṣelu naa.
Àlááfíà ni Bola Tinubu wà - Sanwo - Olu
'Bola Tinubu ńbọ̀ ní Nàìjíríà láìpẹ́, àmọ́ kò tíì dé'
Tinubu ò kú o, àlááfíà ló wà, àmọ́...
Tinubu là ń dúró dè láti sọ ìpinnu wa fétò ìṣèlú 2023 - Akeredolu
Tinubu ló lè ṣeé lọ́dún 2023, Pa Fasoranti àti Oba Osemawe Ondo sọ̀rọ̀ sókè
Wo èrò Afenifere àti Ilana Omo Oduduwa lórí ọ̀rọ̀ Alaafin pé kò s'ọ́nà nínú pínpín Nàìjíríà
Bẹẹ ni awọn kan n sọ pe awọn abẹwo naa nii ṣe pẹlu eto idibo ọdun 2023.
Bi awọn oloṣelu ṣe wa lọ n ki Tinubu, ko si eyikeyi ninu wọn to sọ ohunkohun nipa nkan ti abẹwo wọn da le lori.
Koda, gomina ipinlẹ Eko, Babajide Sanwo-Olu paapaa sọ nigba to lọ pe ko si nkan to ṣe ilera Tinubu.
Ọ̀wọ́ ọ̀tún Ọlọ́run Olódùmarè ni Ogboni máa wà bí ó bá re ibi àgbà ń rè
Amọ ninu ọrọ ti gomina ipinlẹ Ekiti, to tun jẹ alaga ẹgbẹ awọn gomina ni Naijiria, Kayode Fayemi sọ pe wọn ṣe iṣẹ abẹ fun Tinubu nilu London lo fa abẹwo oriṣiriṣi naa.
O sọ eyi lasiko ifọrọwanilẹnuwo pẹlu ileeṣẹ agbohunsafẹfẹ Arise TV lọjọ Aiku.
Gomina Fayemi sọ pe oun ati gomina ipinlẹ Ondo, Rotimi Akeredolu ṣabẹwo si Tinubu ni London, lati ṣatilẹyin fun 'ni iru akoko yii'.
Awọn abẹwo wa jẹ ọna lati ṣatilẹyin fun ẹni to jẹ agba, awokọṣe ati ẹni pataki ninu ẹgbẹ wa, lasiko to nilo wa.
O ṣalaye pe awọn abẹwo naa ko ni ohunkohun lati ṣe pẹlu eto idibo ọdun 2023.
Fayemi si ni ẹni akọkọ to sọrọ ni gbangba nipa ilera ara Bola Tinubu.
Ko din ni ọgbọn oloṣelu to ti bẹ Tinubu wo nilu London to wa lọwọlọwọ.
Nnkan bii ọgbọn awọn oloṣelu lo ti lọ ṣabẹwo si eekan ẹgbẹ oṣelu APC, Bola Ahmed Tinubu niluu London laarin ọsu meji sẹyin.
Oṣu Kẹta ọdun yii ni oloṣelu naa ṣe ayẹyẹ ọjọ ibi ọdun mọ́kàndínláàdọ́rin loke eepẹ, tawọn kan si ti n sọ pe o n mura lati dije du ipo Aarẹ Naijiria lọdun 2023.
Amọ Tinubu funra rẹ ko tii mẹnuba tabi kede pe oun fẹ dije fun ipo aarẹ Naijiria rara.
Lara awọn ọrọ ti ọpọ ọmọ Naijiria n sọ lẹnu ọjọ mẹta yii ni pe, agba ọjẹ oloṣelu naa n ṣaarẹ, ṣugbọn agbẹnsuọ rẹ, Tunde Rahman ṣalaye ninu atẹjade kan pe, lootọ ni Tinubu ti tẹkọ leti lọ siluu London, ṣugbọn ko ṣaisan kankan.
Ọ̀wọ́ ọ̀tún Ọlọ́run Olódùmarè ni Ogboni máa wà bí ó bá re ibi àgbà ń rè
Lara akitiyan ati jẹ ki awọn araalu mẹnu kuro lori ahesọ ọrọ pe Tinubu n ṣaarẹ ni gomina ipinlẹ Eko, Babajide Sanwo-Olu se sọ lọjọ Kẹrin oṣu Kẹjọ pe oun ṣabẹwo si Tinubu ni London, alaafia si lo wa.
Yatọ si Sanwo-Olu, gomina ipinlẹ Ondo, Rotimi Akeredolu ati ojugba rẹ nipinlẹ Ekiti, Kayode Fayemi, to fi mọ gomina ipinlẹ Kano, Umar Ganduje naa ti ṣabẹwo si Tinubu niluu London.
Oríṣun àwòrán, IBileradio TiwantiwaTv
Lara awọn to tẹle Ganduje lọ si London ni iyawo rẹ, Hafsat Ganduje, ọmọ wọn, Umar Ganduje, awọn aṣofin mẹta ati mọlẹbi Ganduje mẹrin mii.
Awọn oloṣelu mii to tun ṣabẹwo si Tinubu ni London ni agbẹnusọ ile igbimọ aṣoju-ṣofin l'Abuja, Femi Gbajabiamila, gomina ipinlẹ ogun tẹlẹ, Ibikunle Amosun, gomina Bornu tẹlẹ, Kahsim Shettima ati aṣoju ẹkun idibo Magumeri nile aṣofin agba, Usman Zanna.
Bakan naa ni Aarẹ Muhammadu Buhari naa ti ṣabẹwo si Tinubu ni London.
Ko tan sibẹ, awọn mii to tun lọ ki Tinubu ni London ni:
'Mo ti gba kádàrá lórí bí Ọlọrun ṣe dá mi'
Pẹlu gbogbo bi awọn eeyan ṣe lọ n ki Tinubu niluu London yii, agbẹnusọ rẹ ṣi sọ sibẹ pe, alaafia lo wa ati pe ko ṣaisan kankan.
Wayi o, ibeere ti ọpọ ọmọ Naijiria n beere ni pe, to ba jẹ pe lootọ ni Tinubu ko dubulẹ aisan, eetiri ti awọn eeyan jankan lawujọ, paapaa awọn oloṣelu ṣe lọ n ki ni London?
Ogun missing police man: Ìyàwó ọlọ́pàá Ogun tó d'àwátì bímọ, ẹbí rẹ̀ fẹ́ gbé iléeṣẹ́ ọlọ́pàá lọ sílé ẹjọ́
Oríṣun àwòrán, Other
Lẹyin oṣu mẹsan ti ọlọpaa kan, Emmanuel Gene to n ṣiṣẹ lapa Ijebu Igbo nipinlẹ Ogun ti di awati, ẹbi rẹ ti ni awọn ṣetan lati gbe ileeṣẹ ọlọpaa lọ si ile ẹjọ.
Agbẹjọro ẹbi Gene, Kehinde Bamiwola Esq fi iwe ipẹjọ ranṣẹ si alaga ajọ PSC to n ri si ọrọ awọn ọlọpaa ati ọga agba ọlọpaa to fi mọ ọga ọlọpaa ipinlẹ Ogun.
Awọn ẹbi ọlọpaa naa n beere pe ki ileeṣẹ ọlọpaa wa ọmọkunrin naa ri bo ya o wa laaye ni tabi o ti ku.
"Ìran mi ò ja ẹ̀ṣẹ́ rí, ẹ̀gbin yìí ló ta lé mi tí mo fi di ""Scorpion"" Ọ̀gá ọ̀gá nínú ìjà"
Bi ẹ ko ba gbagbe, ọpọ eeyan lo ro pe awọn janduku ji Gene gbe lọ nibi tawọn ọlọpaa ti ṣiṣẹ kan ni Aba Tuntun loṣu kejila ọdun 2020.
O ti to bi ọdun kan bayii ti iṣẹlẹ naa ti ṣẹlẹ eleyii ti ẹbi rẹ ko gbọ ohun kan.
Koda, ohun ti a gbọ ni pe iyawo ọlọpaa naa ti bimọ bayii.
Awọn ẹbi Gene ti kepe ọga ọlọpaa ipinlẹ Ogun, alakoso iṣẹ ọlọpaa lagbegbe Ijebu Ode ati DPO ọfiisi ti Gene ti n ṣiṣẹ lati wa nkan ṣe si ọrọ to wa nlẹ yii.
Agbẹjọro Bamiwola Esq iyalẹnu lo jẹ pe DPO Ijebu Igbo,  S.P Kazeem Solatan sọ pe awọn gbalẹ-gbalẹ lo ji Gene gbe lọ ni ilu Aba Tuntun.
Ṣugbọn Bamiwola ni ohun to jẹ kayeefi ni pe ileeṣẹ ọlọpaa ri bata, baagi ati ibọn Gene.
''Bawo ni wọn ṣe maa ji i gbe ṣugbọn ileeṣẹ ọlọpaa ri awọn nkan rẹ yii ti wọn ko si ri oun gan an fun ra rẹ?
O jẹ iyalẹnu pe DPO ko le sọ pato ohun to ṣẹlẹ si Gene gan an.
Yàjó yàjó: Àwọn ajínígbé soro l'Eko, wọ́n jí Ọ̀gágun ojú òfurufú Sikiru Smith gbé
Ṣé o tí gbọ́ nípa eNaira, owó àìrí tuntun tí CBN ṣe ìfilọ́lẹ̀ rẹ̀? Nkan tí ó ní láti mọ̀ rèé
Iṣẹ́ abẹ tí Bola Tinubu ṣe ló fa àbẹ̀wò ọ̀pọ̀ èèyàn sọ́dọ̀ rẹ̀ - Fayemi
O ti fẹ pe ọdun kan bayii ti ileeṣẹ ọlọpaa ko si ri Gene doola to ba jẹ pe lootọọ ni wọn jigbe e.
A n duro de esi ileeṣẹ ọlọpaa lori oun to ṣẹlẹ si ọlọpaa Gene to di awati gan an,'' Bamiwola lo sọ bẹẹ.
Ẹwẹ, alukoro ileeṣẹ ọlọpaa ipinlẹ Ogun, DSP Abimbola Oyeyemi ṣalaye fun BBC Yoruba pe iṣẹ lawọn ọlọpaa naa lọ sẹ ni Aba Tuntun.
DSP Oyeyemi ni ko si ẹni to ran awọn ọlọpaa lọ sibi ti wọn ti n ja ija ilẹ, awọn kan ti wọn ni wọn gbe ohun ija oloro wọ agbegbe Ije Igbo lawọn ọlọpaa lọ fun.
''DPO gan an fun ra rẹ lo ṣaaju awọn ọlọpaaa lọ si ibi iṣẹ yii, wọn si fọwọ ṣinkun ofin mu gbogbo awọn to gbe oun ija oloro naa wọ ilu.
Nigba ti wọn n bọ lawọn kan lọ fawọn lọna, wọn si ji ọlọpaa mẹrin lọ pẹlu Gene, koda DPO gan an farapa nibi iṣẹlẹ ọhun.
Ileeṣẹ ọlọpaa ri mẹta ninu mẹrin awọn ọlọpaa ti wọn jigbe yii doola ṣugbọn.
Ṣugbọn ohun to ṣẹlẹ ni pe Gene to di awati yii ti sa kuro nibi tawọn mẹta yoku ti wọn ri doala naa duro si.
Ni bayii, ileeṣẹ ọlọpaa ti mu marun un lara awọn to ṣiṣẹ ibi yii.
Ko si ọrọ ninu ohun ti ẹbi Gene n sọ pe ileeṣẹ ọlọpaa ko ja ọrọ naa kunra rara,'' DSP Oyeyemi ṣalaye
Soldier beats Corp Member: Àgùnbánirọ̀ ní omi àti yẹ̀pẹ̀ ni sọ́jà pò pọ̀, tó dà lè òun lórí
Oríṣun àwòrán, Screen Shot
Agunbanirọ, Ezeiruaku Ifenyinwa Fidelia, ti sọja obinrin kan, ọgagun Chika Viola Anele da omi idọti le lori, ti ṣalaye ohun to ṣẹlẹ gan an laarin awọn mejeeji.
Agunbanirọ Fidelia ṣalaye pe, ọrọ naa bẹrẹ nigba ti awọn lọ si barake awọn ologun fun idije kan niluu Calabar.
''Mo jẹ ọkan lara awọn to n pin ounjẹ nibi eto naa lọjọ naa.
Mo fọwọ kan sọja kan ti a jọ maa n sọrọ lati ki i, ṣugbọn sọja obinrin yii Lt. Anele sọ fun mi pe o lodi sofin fun mi lati fọwọ kan ọmogun.
Mo ni lati pada si ibi ti mo duro si tẹlẹ lẹsẹ kẹsẹ.
Lẹyin naa ni ọga sọja mii na ọwọ si mi nigba to fẹ ki mi, ṣugbọn mo ni lati sọ fun un pe wọn ni a ko gbọdọ ba awọn ọmogun ba ọwọ.
Oríṣun àwòrán, Screen Shot
Amọ, Lt. Anele da mi lohun pe mo le bọ ọwọ pẹlu awọn sọja ṣugbọn n ko le fọwọ kan wọn ni.
Bayii ni a bẹrẹ si ni pin nkan ipanu ''Small chop'' nibẹ, eleyii ti sọja obinrin yii, Lt. Anele n ṣe agbatẹru rẹ.
O ṣẹlẹ pe ''small chop'' sọja kan danu nigba ta fẹ gbe le lọwọ, o si sọ fun mi pe ki n lọ gbe omiran wa foun.
Mo sọ fun un pe o ti tan, ṣugbọn o kọ jalẹ pe ki n lọ ba oun gbe omiran wa.
Bayii ni sọja Anele bẹrẹ si ni fi ọrọ gba mi lori pe oun ti ṣalaye fun mi tẹlẹ pe, nkan ipanu ti tan ayafi ti mo ba fẹ fun sọja ọhun ni eyi ti awa agunbanirọ maa jẹ lo ku.
Mo ṣa mu ninu ''small chop'' ti awọn agunbanirọ lọ fun sọja naa, ti o si jẹ ẹ.
Lẹyin idije yii ni Lt. Anele pe emi ati awọn akẹẹgbẹ mi yoku, o da mi yọ sita laarin wọn, ti o si bẹrẹ si ni sọ ọrọ bakungbe si mi pe n ko ni ọpọlọ rara.
"Ìran mi ò ja ẹ̀ṣẹ́ rí, ẹ̀gbin yìí ló ta lé mi tí mo fi di ""Scorpion"" Ọ̀gá ọ̀gá nínú ìjà"
O ni bawo ni mo ṣe tun wa ba oun lẹyin ti oun ti ṣalaye fun mi pe ''small chop'' ti tan.
Lẹyin naa lo pe ipade pẹlu awa agunbanirọ ti o si bẹrẹ si ni ko ilaali fun mi nibẹ.
Lt. Anele ni ki n ma yi ara mọlẹ pẹlu aṣọ NYSC lara mi, mo ni mi o le ṣee.
O tun sọ fun mi pe ki n maa joko idẹra kaakiri, mo tun kọ lati ṣee.
Mo bẹrẹ si ni joko idẹra ṣugbọn nigba ti o ri pe ko eyi ko ni ipa buruku lara mi, o ni ki n kunlẹ ki n si gbe okuta lọwọ.
O ni oun ko ni fi mi silẹ ti oun ko ba ri omi loju mi, ṣugbọn mo ju okuta naa silẹ nigba ti o rẹ mi.
Mo ni lati sọ fun pe n ko le ṣe ohun kankan mọ tori mi o jale, bẹẹ ni n ko si paayan.
Nigba yii gan an lo da omi ati yẹpẹ pọ ti o si bẹrẹ si ni daa le mi lori.
Bayii ni Lt. Anele n da omi idọti le mi lori ti o si n fi ike ibomi gba mi lori ṣugbọn n ko sọ ohun kan tori n ko fẹ ko mọ pe ohun ti o n ṣe fun mi n dun mi.
Hijab Female Footballer: Zulfah ní àlá òun ní láti jẹ́ agbábọ́ọ̀lù obìnrin tó dáńtọ́
O ni eyi yoo jẹ ẹkọ fun mi nitori ọjọ mii ṣugbọn n ko sọ ohun kan,'' agunbanirọ Fidelia ṣalaye
Ẹwẹ, ile iṣẹ ologun Naijiria ti ni igbẹjọ soja naa ti bẹrẹ ni kiakia wipe awọn yoo fi idiotitọ mulẹ fun awọn araalu lori iṣẹlẹ naa to fi mọ esi iwadii.
Garba Shehu: Inú aráàlú kò dùn sí ìwọ́dé Yoruba Nation àti IPOB tó wáyé l‘Amẹ́ríkà
Oluranlọwọ pataki fun Aarẹ Muhammadu Buhari feto iroyin, Garba Shehu, ti bu ẹnu atẹ lu iwọde ti awọn ọmọ Naijiria kan ṣe ni orilẹede Amẹrika.
Garba ni iwọde tí ikọ Yoruba Nation ati IPOB to n ja fun ominira ẹya Igbo ṣe lati tako Aarẹ Buhari lasiko to ba awọn adari lagbaye sọrọ ni ipade Ajọ Iṣọkan Agbaye to waye ni New York ko tọna.
Garba Shehu, ninu atẹjade to fi lede ni awọn to ṣe ifẹhọnuhan naa dunkoko mọ awọn oṣiṣẹ ijọba Naijiria lasiko ti wọn fẹ wọ gbagede ipade Iṣọkan Agbaye, UN naa.
Ààrẹ Buhari àti ìjọba rẹ̀ màá ń làágùn, ìyẹ́ àdiyẹ wọn ni kò jẹ́ kí ẹ mọ̀
O ni idunkokomọni nitori ẹya ni ikọ Yoruba Nation ati IPOB ṣe ni New York, eleyii to ni ko ba ofin mu.
Oluranlọwọ pataki fun Aarẹ Buhari naa ni, bi o tilẹ jẹ pe wọn ni aṣẹ labẹ ofin lati ṣe ifẹhọnuhan, amọ kii ṣe iwa to bu iyi kun ẹnikẹni lawujọ lati ma a dẹyẹ si eniyan nitori ẹya wọn.
Ẹni tó bá ni kí n fi iṣẹ́ kòkò mímọ sílẹ̀, mi ò lè fẹ́ẹ láéláé - Adekemi Àgùnbánirọ̀
Shehu ni asiko ti aarẹ Buhari n sọrọ lori awọn ipọnju ti orilẹede Naijiria n la kọja, ti o si n rọ awọn adari lagbaye lati dasi iṣoro wọn, ni awọn kan n ṣe ifẹhọnuhan tako aarẹ Buhari ni iwaju Ileeṣẹ Ajọ Iṣọkan agbaye naa.
'' Awọn to ṣe ifẹhọnuhan yii ti fihan pe awọn n ṣiṣẹ lodi si orilẹede Naijiria , ti wọn si n da rudurudu silẹ laarin ilu.''
''Bakan naa ni  awọn eeyan yii n pa awọn ẹṣọ alaabo, ti wọn si n di awọn araalu lọwọ lati ṣe iṣẹ oojọ wọn nitori wọn fẹ gbe ijọba ara wọn kalẹ ni ọna aitọ''
Gẹgẹbi ọrọ oṣiṣẹ ijọba Buhari naa, o ni aarẹ Buhari n ṣiṣẹ takuntakun lati ri pe ko si ẹni to tẹ ẹtọ ara ilu mọlẹ, ti o si mu ọrọ oju ọjọ to n ṣe segesege lọkunkundun lọna ati mu ki ipese ounjẹ ati idẹra de ba awọn ọmọ Naijiria.
O fikun pe aṣeyọri aarẹ Buhari ko ni abawọn kankan, to fi mọ ṣiṣe iranwọ fun awọn ọmọ Naijiria kọọkan lati di ipo agba mu ni awujọ lagbaye.
"Ìran mi ò ja ẹ̀ṣẹ́ rí, ẹ̀gbin yìí ló ta lé mi tí mo fi di ""Scorpion"" Ọ̀gá ọ̀gá nínú ìjà"
''Eleyii fihan pe alaafia ati ifimọṣọkan lawujọ jẹ aarẹ Buhari logun, nitori naa kii ni ifẹ si ohun rudurudu''
''Bakan naa ni aarẹ Buhari n gbiyanju lati ri pe laipẹ awọn eniyan to jẹ ọmọ orilẹede Naijiria to n gbe ni oke okun ni anfaani lati dibo fun ẹni ti ọkan wọn yan lasiko ti idibo ba n waye lorilẹede Naijiria.''
Malami: Ẹgbẹ́ ọ̀dọ́ Oduduwa ní Mínísítà fétò ìdájọ́ ń tẹ̀lé òfin lábẹ́ ìjọba alágbádá
Oríṣun àwòrán, Blueprint
Ẹgbẹ awọn ọdọ ọmọ Oduduwa lagbaye ti fi oye Omoluabi da Agbẹ́jọ̀ro agba ati Minisita feto idajọ, Abubakar Malami lọla lori bo se sisẹ sin ilẹ baba rẹ pẹlu ootọ.
Amugbalẹgbẹ feto iroyin fun minisita naa, Umar Jubrilu Gwandu lo kede bẹẹ ninu atẹjade kan to fisita.
Akinyele Olasunbo, tii se agbẹnusọ fun ẹgbẹ ọdọ Oduduwa lagbaye, wa se apejuwe Malami bii ọmọ Naijiria ti ko mọ ti ara rẹ nikan amọ n ri daju pe isejọba awa ara awa to ba ofin mu fẹsẹmulẹ pẹlu idajọ ododo lai segbe.
O fikun pe ipa ti minisita feto idajọ naa ko lati gbogun ti iwa ijẹkujẹ lo ti n so eso rere, to si tun ti mu agbega ba igbe aye ati ayanmọ ọmọ Naijiria.
Olasunmbọ wa kan saara si Malami lori bo se n saaju awọn ọlọpọlọ pipe ọmọ Naijiria ni ẹka eto idajọ, eyi to ni o mu ki o tayọ ni gbogbo ọna, to si jẹ awokọse rere.
Ẹni tó bá ni kí n fi iṣẹ́ kòkò mímọ sílẹ̀, mi ò lè fẹ́ẹ láéláé - Adekemi Àgùnbánirọ̀
Nigba to n fesi, Abubakar Malami, ẹni ti amugbalẹgbẹ aarẹ Buhari nidi igbogun ti iwa ọdaran nidi owona, Amofin Abiodun Aikomo soju fun wa fi ẹmi imoore han si ẹgbẹ ọdọ Oduduwa naa.
O wa mẹnuba ojuse pataki ẹgbẹ ajafẹtọẹni nidi aseyọri awọn eto idagbasoke eyi ti yoo ri daju pe agbega bawọn agbegbe igberiko wa.
Priapism: Àìsàn ǹkan ọmọkùnrin tó ń lè gìdìgbà láì rọlẹ̀ níí ṣe pẹ̀lú ẹ̀jẹ̀
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Iwadii fihan pe eni to ba ni aisan yii ko gbọdọ mu oti tabi fa siga ko ma baa peleke sii.
Arun ẹjẹ ti awọn oloyinbo n pe ni ''Sickle Cell'' abi ''Leukemia'' jẹ ọkan lara awọn aisan to wọpọ ninu igbeyawo nitori iru ẹjẹ ti awọn mejeeji ni.
Arun ẹjẹ le waye nigba ti awọn ololufẹ to fẹ ara wọn ba ni iru ẹjẹ bii AS ati AS tabi SS ati AS.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Arun to lagbara ni arun ẹjẹ, eleyii to ma n fa ipọnju fun awọn eniyan, awọn ẹbi to fi mọ awujọ paapaa.
Iwadii si fihan pe o kere tan, idaji awọn ọmọ ti wọn n bi lorilẹede Naijiria ni ọdọọdun lo ni arun inu ẹjẹ.
Arun ẹjẹ yii tun ma n ṣe akoba fun nkan ọmọkunrin to le mu ki o ma lee ṣe deede pẹlu ololufẹ rẹ.
Wo ohun tó ṣe kí àtọ̀ rẹ fi ní agbára láti di ọmọ
Àwọn ọ̀nà tí obìnrin fi le gbádùn ìbálòpọ̀
Ṣé ǹkan ọmọkùnrín rẹ ò ní padà kéré báyìí? Wo tuntun tí onímọ̀ Sáyẹ̀nsì gbéjáde
Mo fi nǹkan ọkùnrin mi sínú àgádádogo fún ọ̀sẹ̀ méjì fún ìbálòpọ̀, wàhálà bá de
Ààrẹ Buhari àti ìjọba rẹ̀ màá ń làágùn, ìyẹ́ àdiyẹ wọn ni kò jẹ́ kí ẹ mọ̀
Ẹni tó bá ni kí n fi iṣẹ́ kòkò mímọ sílẹ̀, mi ò lè fẹ́ẹ láéláé - Adekemi Àgùnbánirọ̀
Ni ọkunrin, arun ẹjẹ yii le mu ki apa wọn ma na si oke, ki ẹjẹ di si apa tabi ki o ma jade.
Ti nkan ọmọkunrin wọn ba na tan, o le ma tete rọle fun ọpọlọpọ wakati, eleyii ti awọn oloyinbo n pe ni ''Priapism'' Pseudomonas aeruginosa.
Ko si bi nkan ọkunrin ṣe le dede tobi si lai ṣe wi pe ẹjẹ n wọ kiri ni agọ ara eniyan bi o ṣe to ati bi o ti yẹ.
Igba kigba ti ara ọkunrin ba le, ni ẹjẹ to wa ni ibi nkan ọmọkunrin rẹ yoo le.
Ti ẹjẹ yii ko ba ṣan bi o ṣe to, ti o lọ di si inu isan kan, eyi le fa ki nkan ọmọkunrin gun sii, ko wu, ki o si le dain-dain.
Ti ara okunrin ba ti walẹ tan ti ẹjẹ yii a ṣan lọ si ibi to yẹ ki nkan ọmọkunrin yoo walẹ.
Amọ ti ọkunrin ba ni arun ẹjẹ, o ṣeeṣe ko ni aisan Priapism yii ti nkan ọmọkunrin rẹ ko ni lọ silẹ bọọrọ.
Eleyii n ṣẹlẹ si ọmọde ati agba to ba ni iṣoro yii, o ṣeeṣe ki wọn maa daku bakan naa.
Iwadii fihan pe aisan yi wọpọ laarin awọn eniyan lati bii ọdun mejila lọ si oke.
Amọ o lee ṣe ẹni ti ko ni arun ẹjẹ naa.
Oríṣun àwòrán, OTHERS
Za a iya sa allura a zuke jinin da ya daskare a gaban namji wanda hakan yana sa a samu sauƙi
Gẹgẹ bi dokita Ibrahim ṣe ṣọ, ko i tii si iwosan to peye fun arun yii lọwọ lọwọ bayii, nitori ọpọlọpọ awọn to ni arun ẹjẹ naa ni kii jade sita fun iranlọwọ.
Amọ, iranwọ wa fun awọn to ni aisan yii fun awọn to ba ṣẹlẹ si ni pajawiri.
''Wọn le fun un ni abẹrẹ ti yoo mu ki ẹjẹ to di naa duro si oju kan lai wọ lọ si ibomiran, ki o si jade ni oju ara.''
''Bakan naa ni wọn lee ṣe iṣẹ abẹ fun un lati mu ki ẹjẹ naa san si ita''.
''Amọ iṣoro to rọmọ iṣẹ abẹ yii ni pe o le fa ki nkan ọmọkunrin ku patapata lai ṣiṣẹ mọ.''
Dokita Ibrahim ni itọju to peye to wa lọwọlọwọ yoo mu ki ọyan ọkunrin ohun bẹrẹ si tobi lasiko to ba n gba itọju, ti yoo si maa yọ omi ọyan bi obinrin.
''Ko si si ẹni to fẹ iru eto ilera bẹẹ laarin awọn ọkunrin, nitori naa ni eto iwosan yii ko ṣe wọpọ laarin awọn ọkunrin.''
''Amọ iroyin rere ni pe iṣẹ nlọ lọwọ lati wa ọna abayọ to peye si ipenija yii laarin awọn ọkunrin.''
"Ìran mi ò ja ẹ̀ṣẹ́ rí, ẹ̀gbin yìí ló ta lé mi tí mo fi di ""Scorpion"" Ọ̀gá ọ̀gá nínú ìjà"
Kini a le ṣe lati bojuto arun ẹjẹ tabi ki nkan ọmọkunrin ma lọ silẹ lasiko?
Awọn ohun ti ẹni to ba ni aisan yii le ṣe lati dẹkun inira ti o ma n mu ba eniyan ni:
•Mimu omi loore-koore
•Lilọ ṣe igbọnṣẹ loore-koore
•Ṣiṣe ere idaraya yoo gbogunti ẹjẹ didi fun arun ẹjẹ
•Lilo oogun ti yoo mu ki inira naa dikun
•Ko gbọdọ lo omi tutu ju abi yinyin.
•Bakan naa ni ko tẹ ẹ jẹjẹ lasiko ibalopọ abi ko ri wi pe atọ ọmọkunrin, semen jade lasiko.
•Eni to ba ni aisan yii ko gbọdọ mu oti tabi fa siga ko ma ba a peleke si.
Discover Nigeria: Buhari ṣe ìfilọ́lẹ̀ ìwé tó sọ nípa ẹ̀wa Nàìjíríà ṣáájú ayẹyẹ òmìnira
Oríṣun àwòrán, Femi Adesina
Yoruba bọ, wọn ni alara nii gb'ara ga, bi adiẹ ba fẹ wọle, a bẹrẹ.
Bi ayẹyẹ ọdun mọkanlelọgọta ti orilẹede Naijiria gba ominira ṣe ku ọjọ kan, Aarẹ Muhammadu Buhari yoo ṣe ifilọlẹ iwe kan to sọ nipa ẹwa, awọn ibi irinajo afẹ ati ohun manigbagbe ninu itan Naijiria.
Oludamọran fun aarẹ lori ọrọ iroyin, Femi Adesina to fi ọrọ yii lede ṣalaye pe akọwe iwe naa ni ''DISCOVER NIGERIA'' eleyi to tumọ si ṣe awari Naijiria.
Adesina ni ayafọto aarẹ Buhari, Bayo Omoboriowo, lo kọ iwe naa eyi to sọ nipa irinajo Naijiria lati igba ominira titi di akoko yii.
Iwe naa to ni ewe to din mẹjọ ni irinwo(392) lawọn eeyan ti sọ pe yoo wa lara awọn to lamilaaka julọ ninu lagbaaye.
Iwe yii sọ nipa awọn ọba alaye, oriṣiiriṣii ẹya, ilẹ oko Naijiria ati okun ti Eledua fi jinki Naijiria.
Omoboriowo ṣalaye pe iwe naa wa lara awọn eto lati fi ṣe ayẹyẹ ọgọta ọdun ominira orilẹede Naijiria.
Yàtọ̀ sí ọkọ Dora Akunyili, wo àwọn ibòmìí tí wọ́n tún ti pààyàn ní Anambra lọ́jọ́ kan nàá
Kí ló mú kí agbẹjọ́rò àgbà yọ ọwọ́ nínú ìgbẹ́jọ́ Dibu Ojerinde ọgá JAMB tẹ́lẹ̀?
Àwọn Oba Yorùbá kan rèé tí wọ́n rọ̀ lóyè, tí Oba míràn jẹ lójú ayé wọn
Awọn ọdọ to le lọgọta ni wọn ṣiṣẹ pọ pẹlu Omoboriowo lori ati kọ iwe naa.
Ayẹyẹ ifilọlẹ iwe ọhun nile iṣẹ ijọba l'Abuja yoo tun ṣe afihan oriṣiiriṣii iṣẹ ọna lati ẹkun idibo mẹfa to wa ni Naijiria.
Koda oriṣiiriṣii ounjẹ awọn ẹya to wa ni Naijiria naa ko ni gbẹyin nibi ayẹyẹ ọhun.
Olori orilẹede Naijiria tẹlẹ. ajagun fẹhinti, Abdulsalami Abubakar, lo kọ ọrọ iṣaaju fun iwe naa.
Minisita eto iroyin ati ọrọ aṣa, Lai Mohammed lo kọ ọrọ ifihan fun iwe ọhun.
Koda, olori ologun Naijiria to tun jẹ aarẹ ologun orilẹede Naijiria tẹlẹ ri, Ibrahim Babangida naa ti ka iwe ọhun ti o si gboṣuba rabandẹ fawọn onkọwe Omoboriowo atawọn to ṣiṣẹ pọ pẹlu rẹ.
NIMC: NCC ní ẹni tí kò bá ní káàdì NIN títí di ìparí oṣù kẹwàá kò ní gba ''passport'' àti ìwé-àṣẹ ìwakọ̀ mọ́
Oríṣun àwòrán, NATIONAL IDENTITY MANAGEMENT COMMISSION
Ajọ NCC to n ri ileeṣẹ eto ibaraẹnisọrọ lorilẹede Naijiria ti sọ pe ẹnikẹni to ba kuna lati gba kaadi idanimọ NIN ko ni lanfaani lati iwe irinna ati iwe-aṣẹ iwakọ mọ.
Adari ẹka to n ri si ọrọ to kan araalu fun ajọ NCC, Ọmọwe Ikechukwu Adinde ṣalaye pe ọjọ kọkanlelọgbọn oṣu kẹwaa si ni awọn eeyan ni lati gba kaadi NIN wọn.
Ọmọwe Adinde ni ijọba apapọ si wa lori ẹsẹ rẹ pe ọjọ yii lawọn araalu ni da lati so nọmba kaadi idanimọ wọn pọ mọ opo ẹrọ ibanisọrọ wọn.
Ọmọwe Adinde ni ''laipẹ lai jina, awọn ti wọn ko tii ni kaadi idanimọ NIN ko ni lanfaani lati lo ọpọ nkan mọ ni Naijiria.
Lara awọn nkan ti wọn ko ni lanfani lati maa lo mọ ni iwe irinna ati iwe-aṣẹ iwakọ wọn.''
Ti ẹ ko ba gbagbe, lọjọ kẹẹdogun oṣu kejila, ọdun 2020 ni ijọba apapọ paṣẹ fawọn ileeṣẹ ibaraẹnisọrọ lati ju oju opo gbogbo awọn eeyan ti ko tii so opo wọn pọ mọ nọmba kaadi idanimọ wọn.
Lati igba naa ni ijọba ti n sun gbedeke ọjọ tawọn eeyan ni lati so nọmba kaadi NIN wọn pọ mọ oju opo ẹrọ ibanisọrọ wọn.
Nigba ti o n sọ nipa iwulo kaadi idanimọ fawọn araalu, Ọmọwe Adinde ni kaadi NIN yoo jẹ ki eto abo gberu sii ni Naijiria.
Bakan naa lo sọ pe kaadi idanimọ NIN jẹ ọkan lara ọna ti ijọba apapọ fẹ lo lati ri pe awọn araalu ri ipa ijọba lara wọn.
Efosa Idehen to jẹ ọkan lara awọn eekan lajọ NCC naa ṣalaye pe o maa ṣoro fawọn agbofinro lati mu awọn ọdaran ti ko ba ni kaadi idanimọ.
Ọga agba ajọ to n ṣakoso kaadi  idanimọ, NIMC nipinlẹ Eko, Funmi Opesanwo, sọ pe siso nọmba kaadi NIN mọ oju opo ẹrọ ibanisọrọ yoo daabo bo araalu lọwọ gbajuẹ.
Femi Adesina: Ilé ẹjọ́ ju ẹni tó n gbé àwọ̀ Femi Adesina wọ̀ sí ẹ̀wọ̀n ọdún 28, ó tùn pàdánù dúkìá
Oríṣun àwòrán, femi adesina/nigerian tribune
Ọ̀gà fi aṣọ ti ẹ silẹ, o n da aṣọ alaṣọ bora.
Ọrọ yii gan-an lo ti sọ Alfa kan, Jamiu Isiaka, deero ẹwọn bayii nipinlẹ Kwara, nitori pe o n gbe awọ ẹlomiran wọ.
Ọjọ Ọjọbọ ni Onidajọ Mahmud Abdulgafar, ti ile ẹjọ giga ijọba ipinlẹ Kwara dajọ ẹwọn ọdun mejidinlọgbọn fun Isiaka nitori pe o n fi ara rẹ pe Femi Adesina, agbẹnusọ Aarẹ Muhammadu Buhari.
Ajọ EFCC lo gbe Alfa naa lọ sile ẹjọ ni ọjọ kẹrinla, oṣu Kẹfa,ọdun 2019, fun ẹsun mẹrin to nii ṣe pẹlu pipe ara rẹ ni ẹlomii, jibiti, ati gbigba owo pẹlu irọ.
Wọn fi ẹsun kan Jamiu pe o n fi ara rẹ han gẹgẹ bi Ọgbẹni Femi Adesina, o tun pe ara rẹ ni Ọga Agba ajọ NNPC tẹlẹ, Maikanti Baru, lati lu ọmọ orilẹ-ede South Korea kan, Keun Sig Kim ni jibiti ọgbọn miliọnu Naira.
'Ìyà Muinat kú nígbà tó ń mu ọmú lọ́wọ́ ni èmí ìyà-ìyá rẹ̀ ń tọ́jú rẹ̀ kí ògiri kíláàsì tó wó pa á'
Jamiu sọ fun Sig Kim pe oun yoo baa gba iwe aṣẹ lati le maa ra epo rọbi ni Naijiria.
Amọ nigba ti wọn n fi ọrọ wa Jamiu lẹnu wo, o ni oun lo owo naa lati fi ṣe etutu fun ọkunrin naa ni.
Gẹgẹ bo ṣe sọ, o ni oun fi owo naa ra ẹyẹ igún, awọ eerin, agbari kiniun ati ẹdọ inaki fun etutu naa.
EFCC sọ pe ẹsun naa tako ofin iwa jibiti ti ọdun 2006.
Alfa Jamiu sọ pe oun ko jẹbi nigba ti wọn kọkọ gbe e lọ sile ẹjọ, amọ ko ri nkankan fi tako awọn ẹsun naa lasiko ti igbẹjọ n waye.
Nàìjíríà kàn wà ni, ẹ ò páàsì, ẹ ò féèlì, ẹ ò kúrò ní kíláàsì kan náà - Àwọn ọ̀dọ́
Onidajọ Abdulgafar sọ pe gbogbo ẹri ti EFCC ko wa sile ẹjọ fihan pe lootọ ni Jamiu jẹbi ẹsun mẹrin ti wọn fi kan an.
Eyi si lo mu ko dajọ ẹwọn ọdun meje fun ikọọkan awọn ẹsun naa.
Amọ, yoo ṣe ẹwọn naa papọ ni.
Bakan naa ni onidajọ naa tun sọ pe ki ijọba gbẹsẹ le awọn dukia kan ti wọn gba lọwọ Alfa Jamiu, eleyi to fi èrè jibiti naa ra.
Lara awọn dukia naa ni ile oni yaara mẹrin kan, ọkọ ayọkẹlẹ Toyota Corolla kan, Plasma TV kan, firisa, ẹrọ amunawa, ẹrọ to n fọ aṣọ ati ẹrọ amuletutu.
Buhari lifts Twitter ban: Buhari fún ọmọ Naijiria lẹ́bùn ayẹyẹ òmìnira, ó gbẹ́sẹ̀ kúró lórí Twitter pẹ̀lú ìkìlọ̀
Oríṣun àwòrán, Bashir Ahmad
Bi awọn ọmọ Naijiria ṣe n ṣe ayẹyẹ ayajọ ominira ọdunkọkanlelọgọta ti orilẹede Naijiria gba ominira, Aarẹ Muhammadu Buhari ti gbẹsẹ kuro lori ofin to fi de Twitter.
Ni oṣu kẹfa ọdun 2021 yii ni ijọba kede pe oun ti fofin de lilo oju opo igbọrọkaye Twitter lori ohun ti ijọba pe ni aṣilo rẹ.
Buhari ni lootọọ ni Twitter wulo lati maa fi pin iroyin ni waranṣesa, ṣugbọn ọpọ ọmọ Naijiria lo n lo lati huwa ọdaran.
Nàìjíríà kàn wà ni, ẹ ò páàsì, ẹ ò féèlì, ẹ ò kúrò ní kíláàsì kan náà - Àwọn ọ̀dọ́
Aarẹ Buhari ni ọpọ eeyan lo n Twitter lati gbe ayederu iroyin kiri nigba ti awọn mii n loo lati da ija ẹlẹyamẹya  ati ija ẹsin silẹ.
''Ẹgbẹlẹgbẹ miliọnu ọmọ Naijiria ni Twitter ti fun lanfani lati ba oriṣiiriṣii eeyan pade, ṣe owo ati anfani si iroyin yajo yajo.
Amọ, awọn iṣẹlẹ to ṣẹlẹ ni Naijiria ti fihan pe awọn nkan n lo Twitter lati huwa ibajẹ lawujọ.
Eyi gan an lo jẹ ki ijọba gbẹsẹ le Twitter ni ọjọ karun un oṣu karun un ọdun 2021 ki ijọba le wa ojutuu si iṣoro to n koju Naijiria nipasẹ Twitter.
Mo ṣe agbekalẹ igbimọ to ba Twitter sọrọ lati jiroro lori ọna abayọ eleyii ti wọn jọ fẹnu ko lori rẹ.
Buhari on Sunday Igboho: Buhari lè sọ nípa àwọn tó ń ti Igboho lẹ́yìn, àmọ kò sọ nípa àwọn alátìlẹyìn Boko Haram
Oríṣun àwòrán, Facebook/Bashir Ahmad
Ilana Omo Oduduwa ti fesi si ọrọ ti Aarẹ Muhammadu Buhari sọ ninu ọrọ apilẹkọ rẹ to ka lati ṣe ayajọ ominira orilẹede Naijiria to pe ọdun mọkalelọgọta bayii.
Aarẹ Buhari sọ ninu ọrọ apilẹkọ rẹ pe awọn eekan lawujọ lo wa nidi ọrọ ajijagbara ilẹ Yoruba, Sunday Igboho ati olori ẹgbẹ IPOB to n pe fun idasilẹ orilẹede Biafra, Nnamdi Kanu ti wọn fi n ṣe bo ṣe wu wọn.
Aarẹ ni ọkan lara awọn ọmọ ile aṣofin agba l'Abuja gan an wa lara awọn to n ṣe agbatẹru fun Igboho ati Kanu.
'Ìyà Muinat kú nígbà tó ń mu ọmú lọ́wọ́ ni èmí ìyà-ìyá rẹ̀ ń tọ́jú rẹ̀ kí ògiri kíláàsì tó wó pa á'
O ni bi ọwọ ṣe tẹ Igboho ati Kanu ti tu aṣiri awọn to n ṣe atilẹyin fun awọn mejeeji.
Buhari ni ijọba oun yoo fi ọwọ ofin mu gbogbo awọn to n ṣagbatẹru awọn to n beere iyapa kuro lara Naijiria tabi sọ ọrọ alufansa kiri.
Amọ, nigba to n ba BBC Yoruba sọrọ, agbẹnusọ fun ẹgbẹ Ilana Omo Oduduwa, Maxwell Adeleye ni ohun ti wọn kọ fun Aarẹ Buhari lo ka jade.
Ọgbẹni Adeleye ni Igboho ko ṣẹ si ofin lọna kọna, ileẹjọ gan an si ti sọ bẹẹ.
''Bibeere fun idasilẹ Yoruba ti Ilana Omo Oduduwa n ṣagbatẹru rẹ ko lodi si ofin.
Ofin Naijiria ati ofin ajọ iṣọkan agbaye gba ohun ti a n ṣe laaye.
Nàìjíríà kàn wà ni, ẹ ò páàsì, ẹ ò féèlì, ẹ ò kúrò ní kíláàsì kan náà - Àwọn ọ̀dọ́
Niwọn igba ti a ko ba da rogbodiyan silẹ, ti a si payan, ohun ti a n ṣe ko lodi si ofin.
Ti Buhari ba sọ pe oun mọ awọn to n ṣe atilẹyin fun Igboho, ko lọ gbe wọn.
Kilode ti ijọba ko tii gbe awa ti n ṣe ifẹhonuhan Yoruba Nation lati ọjọ yii?
A ti la ijọba Buhari mọlẹ nile ẹjọ niluu Ibadan ati Abuja lori ọrọ Sunday Igboho, abi ki lo tun ku?
Nigba ti Buhari sọ pe aṣofin kan wa lara awọn to n ti Igboho lẹyin, kilode ti ko sọ awọn to n ṣagbatẹru awọn janduku agbebọn ati Boko Haram?
Ati pe o yẹ ki Buhari darukọ ọmọ ile igbimọ aṣofin agba niluu Abuja to sọ pe o n ṣagbatẹru fun Igboho.
Gbogbo eyi ti Buhari n sọ yii ko sọrọ nibẹ, awa si wa lori ẹsẹ wa lori ipe fun idasilẹ orilẹede Yoruba,'' Ọgbẹni Adeleye lo sọ bẹẹ.
Ààrẹ Buhari àti ìjọba rẹ̀ màá ń làágùn, ìyẹ́ àdiyẹ wọn ni kò jẹ́ kí ẹ mọ̀
Aishat Adesina: Iléẹ̀kọ́ fásitì OAU dí títì pa lórí akẹ́kọ̀ọ́ tó gbẹ́mì mì ní iléwòsàn fásitì
Oríṣun àwòrán, Others
Awọn alaṣẹ fasiti Obafemi Awolowo, OAU ti paṣẹ fun awọn akẹkọọ lati maa lọ si ile wọn ti wọn si ti ọgba fasiti naa.
Eyi ko ṣẹyin ifẹhọnu han to ṣẹyọ lẹyin ti ọkan lara awọn akẹkọọ, Aishat Adesina gbẹmi mi nitori aisan to ṣe arabinrin naa.
Awọn akẹkọọ faraya nitori pe wọn da ẹbi iku akẹkọọbinrin naa ru ileewosan fasiti OAU nitori aibikita wọn ni eto ilera akẹkọọ naa nigba to lọ si ileewosan ọhun fun iwosan.
'Ìyà Muinat kú nígbà tó ń mu ọmú lọ́wọ́ ni èmí ìyà-ìyá rẹ̀ ń tọ́jú rẹ̀ kí ògiri kíláàsì tó wó pa á'
Awọn akẹkọọ to fariga naa ni awọn oṣiṣẹ eto ilera naa ko naani ẹmi akẹkọọ, ti wọn si sọ wi pe kii ṣe igba akọkọ niyii ti iru iṣẹlẹ naa ma waye.
Amọ, awọn alaṣẹ fasiti naa ni awọn ti sa gbogbo ipa awọn lati ba awọn akẹkọọ to n fẹhonuhan naa sọrọ, amọ pabo lo jasi.
Wọn fẹsun kan awọn akẹkọọ naa pe wọn n da rudurudu silẹ loju popo pẹlu bi wọn 'se ti opopona Ibadan si Ifẹ to fi mọ opopona Ede is Ifẹ pẹlu, eleyii to da inira silẹ fun awọn arinrinajo.
Bakan naa ni awọn adari ileewe naa fikun un pe ifẹhonuhan yii yoo ni ipalara lori eto ilera wọn ati awọn araalu to n rin irinajo.
Wọn rọ awọn akẹkọọ lati fi ileewe naa silẹ ni asiko yii, ki wọn si gba alaafia laaye.
Awọn alaṣẹ ileewe naa fi da awọn akẹkọọ loju wi pe iwadii yoo bẹrẹ lori iku akẹkọọbinrirn naa lai yọ ẹnikẹni silẹ.
Ẹgbẹ akẹ́kọ̀ọ́ OAU wọ́dé tórí pé wọ́n ní iléèwòsàn kò bìkítà nípa ẹ̀mí akẹ́kọ̀ọ́ tó gbẹ́mìí mì
Ẹgbẹ awọn akẹkọọ ni fasiti Obafemi Awolowo nilu Ile Ife, OAU ti fẹdun ọkan wọn han lori iku to pa ọkan lara wọn Aishat Adesina, tii se ẹni ọdun mẹrinlelogun.
Aishat Adesina yii lo jẹ akẹkọọ ọlọdun kẹrin ni ẹka imọ nipa ede ilẹ okeere, ti yoo si kẹkọọ jade ni ọdun yii amọ nitori aisan ti ko to nnkan, to mu ẹmi rẹ lọ lairotẹlẹ.
Atẹjade kan ti ẹgbẹ awọn akẹkọọ ni fasiti OAU, eyi ti alukoro ẹgbẹ naa, Ogunperi Taofeek Olalekan (Tao) fọwọ si, lo sisọ loju isẹlẹ naa.
Atẹjade naa ni Aishat lo wa lara ọpọ akẹkọọ to ti padanu ẹmi wọn nitori ailakasi awọn osisẹ eleto ilera nibudo ilera to wa ninu ọgba ile ẹkọ fasiti naa.
"O ba wa ninu jẹ pe ọkan lara ọmọ ẹgbẹ wa ni wọn tun n gbe oku rẹ lọ ba awọn ẹbi rẹ, nigba ti wọn n foju sọna si akoko ti yoo kẹkọ jade.
Nàìjíríà kàn wà ni, ẹ ò páàsì, ẹ ò féèlì, ẹ ò kúrò ní kíláàsì kan náà - Àwọn ọ̀dọ́
A ba n ransẹ ibanikẹdun sawọn mọlẹbi oloogbe yii amọ a ko le foju fo awọ̀n isẹlẹ to waye, eyi to mu ẹmi alaisi naa lọ, paapaa ipa ti ibudo iwosan fasiti naa ko."
Ẹgbẹ akẹkọọ naa ni iku Aishat kọ ni yoo jẹ akọkọ ti yoo waye nitori ailakasi awọn osisẹ ibudo ilera naa, ti iku akẹkọọ lati ọwọ wọn si ti n di lemọ-lemọ.
Ẹgbẹ akẹkọọ lọgba fasiti OAU wa n ke si awọn alasẹ ileẹkọ naa lati sewadi iku to pa Aishat, ki wọn si jẹ osisẹ ti aje naa ba si mọ lori niya to jopin.
"Awọn osisẹ yii lo kọ lati fun Aishat ni itọju kiakia to nilo amọ ti wọn wa ni ki wọn maa gbe lọ sile iwosan Seventh-Day nigba ti ẹmi ti fẹ bọ lẹnu rẹ tan.
Lai si iwadii to yẹ ni kiakia, awọn alasẹ ọgba fasiti OAU kan n fi ẹmi awọn akẹkọọ wọn sinu ewu ni, a ko si ni gba kẹ maa fi ẹmi wa ta kati, ka si maa ku bi adiẹ.
Ààrẹ Buhari àti ìjọba rẹ̀ màá ń làágùn, ìyẹ́ àdiyẹ wọn ni kò jẹ́ kí ẹ mọ̀
Wayi o, igbimọ alasẹ ile ẹkọ fasiti OAU ti kẹdun iku akẹkọọ naa, Aishat Adesina to jade laye nitori awọn arun aile foju ri kan to n ba finra.
Atẹjade ti alukoro ile ẹkọ fasiti naa, Abiodun Olanrewaju fisita salaye pe lootọ ni Aishat yọju sibudo ilera to wa lọgba ile ẹkọ naa, ti wọn si fun ni oogun pe ko tun pada wa.
Atẹjade naa ni Aishat pada wa sile iwosan naa lọjọbọ ana, ti wọn si ni ko tete maa lọ sile iwosan Seventh Day fun itọju to peye nibi to papa ku si.
Awọn alasẹ ile ẹkọ fasiti OAU wa ba awọn obi, ọrẹ ati akẹkọọ ẹgbẹ rẹ kẹdun lori iku aitọjọ to mu ẹmi alaisi naa lọ.
Bakan naa ni wọn rawọ ẹbẹ lati bu omi suuru mu lori isẹlẹ yii, ki wọn si mase fa wahala lati pagidina idanwo ilaji simẹsita to n lọ lọwọ.
Sanusi Lamido faraya lórí àwọn tó ń pè fún pínpín ipò ààrẹ sí kùn kan
Emir tẹlẹ fun ilu Kano, Sanusi Lamido Sanusi naa ti tako asa pinpin ipo aarẹ laarin ẹkun guusu ati ariwa Naijiria.
Sanusi, ẹni to fi atako rẹ yii han lasiko to n kopa lori eto ori mohunmaworan Arise TV ni lọpọ igba `ni oun ti maa n tako ijiroro to nii se pẹlu ẹkun ti aarẹ yoo ti wa.
Aarẹ tẹlẹ fun banki apapọ ilẹ wa naa ni orilẹede Naijiria nilo aarẹ ti yoo pegede ni, lai naani ẹkun to ti wa.
Lọpọ igba ni mo ti maa n tako ero yii, ti mo si maa n sọ pe ibi ti aarẹ ba ti jade wa ko se nnkan kan."
A ti ri awọn gomina lẹkun guusu ti wọn n ni ọdọ awọn lo yẹ ki aarẹ ti wa lọdun 2023, nigba ti awọn gomina ẹkun ariwa ni ọdọ awọn ni aarẹ yoo ti wa.
Nàìjíríà kàn wà ni, ẹ ò páàsì, ẹ ò féèlì, ẹ ò kúrò ní kíláàsì kan náà - Àwọn ọ̀dọ́
N jẹ ẹ m pe ẹnikẹni ko darukọ ohun ti wọn n fẹ?
Ohun ti gbogbo eleyi wa fun ni lati gbe ipo aarẹ fun ẹkun kan, ti eegun nla yoo si jade nibẹ.
Idi niyi to fi jẹ pe lẹyin gbogbo igbesẹ yii, wọn yoo pada fa oludije meji ti ko wulo kankan kalẹ fun Naijiria.
"Amọ awọn to ba wu lati jẹ aarẹ ni ki wọn yọju sita, boya lẹkun ariwa ni tabi ni guusu Naijiria."""
Sanusi Lamido Sanusi ni awọn isẹlẹ to se koko lo wa niwaju Naijiria bayii, eyiun igbesẹ kikede esi ibo lati ori ayelujara ti yoo jẹ ki esi ibo pegede amọ ti awọn eeyan kan n ta ko o.
O ni eyi tumọ si pe wọn n kede fun ilẹ Naijiria pe awọn fẹ se magomago ibo ni, ki wa lo de ti a ko panupọ maa sọrọ lori eleyi?
"Akude kansoso ta ni gẹgẹ bii orilẹede ni pe a kii ronu rara. A gbọ fa fa to ba di ọrọ pe ka wa owo lati ipasẹ isẹ oojọ.
Amọ a kii lo ọpọlọ wa, irufẹ awọn eeyan yii si lo n mu wa sere ni Naijiria.
Oduduwa republic: Mo kọ̀ láti kópa nínú ìwọ́de Yoruba Nations rally ni Eko- Iba Gani Adams
Ẹyin ẹ sa fun emi ni aarẹ ti yoo kajuẹ lati ibikibi ni orilẹede yii, ki awa si dibo fun, kii sa se pe yoo gbe ipo aarẹ lọ si abule rẹ."
Bakan naa ni Sanusi wa bu ẹnu atẹ awọn ẹlẹgbẹjẹgbẹ ajafẹtọ ẹni ati ile asofin apapọ ilẹwa, to ni wọn ko mọ isẹ wọn nisẹ rara.
Ridwan Scorpion Oyekola: October 30 ni màá tún ìjà jà láti gba belt mi padà àmọ́ kò sí onígbọ̀wọ́
Ridwan Scorpion Oyekola tun ti ba BBC Yoruba sọrọ lori ohun to jẹ ẹdun kan rẹ lọwọ lọwọ bayii, eyi to si le se akoba fun ẹsẹ kikan to yan laayo.
Oyekola ni lẹyin osu mẹfa ti oun gba ami ẹyẹ bẹliti agbaye, lo yẹ ki oun tun ija miran ja lati tun bẹliti naa gba.
O ni osu kẹfa ọdun 2021 lo yẹ ki ija keji naa ti waye, amọ ko si onigbọwọ fun oun eyi ti ko tii jẹ ki ija naa waye.
Akansẹ agbaye naa ni ajọ to n se kokari idije naa ti n yọ oun lẹnu, ti wọn si ti fi ọjọ ija naa si ọgbọnjọ osu Kẹwa taa wa yii.
Amọ o ni titi di akoko yii, onigbọwọ kankan ko tii si fun oun lati ja ija naa, to si n ke si aarẹ mMuhammadu Buhari atawọn ọlọrọ lorilẹede yii, lati wa se iranwọ fun lori ika oun.
Oyekola ni lai si onigbọwọ, wọn le gba bẹliti agbaye naa lọwọ oun, eyi to le se akoba fun ẹsẹ kikan to yan laayo, ti yoo si da omi tutu si lọkan.
Police officer sacked: Kí ló mú kí iléeṣẹ́ Ọlọ́pàá já ìwé máà lọ sílé fún Ọlọ́pàá tó wà ní 'Coma' fún oṣù mẹ́sàán?
Oríṣun àwòrán, JOAN JEPTOO
Arakunrin ọlọpaa kan to dubulẹ oorun ọlọjọ pipẹ eleyi ti oloyinbo n pe ni Coma ti taji pada lati ri pe wọn ti kọwe gba iṣẹ lọwọ rẹ.
Kọnstebuuli Reuben Kimati Lel ni ẹni taa n wi yi, iṣẹlẹ naa si waye lorileede Kenya.
Ẹsun tawọn ọga rẹ nibi iṣẹ fi kaan ni pe o sa lẹnu iṣẹ lai sọ fun ẹnikankan.
Reuben gẹgẹ bi ibatan rẹ kan ṣe sọ fun BBC farapa ninu ijamba ọkọ ni gbogbo igba ti wọn fi n wa to si n gba itọju ni ile iwosan nla kan ni Kenya.
Ko si ẹni to mọ pe o wa ni ile iwosan nitori wọn o ri iwe idanimọ lara rẹ nigba ti wọn gbe digba de ile iwosan.
'Ìyà Muinat kú nígbà tó ń mu ọmú lọ́wọ́ ni èmí ìyà-ìyá rẹ̀ ń tọ́jú rẹ̀ kí ògiri kíláàsì tó wó pa á'
Lọsẹ to kọja lawọn mọlẹbi rẹ sọ pe o ṣẹṣẹ taji loju oorun ati pe awọn naa ti  n wa kaakiri fọjọ pipẹ kawọn to wa mọ ibi to wa.
''A ro pe o ti ku ni nitori nọmba rẹ ko lọ lori  foonu rẹ mọ.Nibẹrẹ ọdun yi, a lọ gba oku kan ni mọṣuari ti a ro wi pe oku rẹ ni''
''Nigba ti a pada ṣe ayẹwo la wa ri pe kii ṣe Reuben''
Lọjọ Kọkanlelogun oṣu Kejila ọdun 2020 ni wọn gbe Reuben lọ si ile iwosan nla Kenyatta  to wa ni olu ilu Nairobi.
O farapa ninu ijamba ọkọ kan ni wọn fi gbe lọ si ibẹ.
Ko si ami idanimọ kankan lara rẹ ti ko si taji lati le ṣalaye ibi to ti n bọ tabi ẹni to jẹ.
Ni gbogbo igba yi, awọn ọga rẹ nibi iṣẹ ọlọpaa ti kọwe gba iṣẹ lọwọ rẹ ti wọn si fẹsun kan pe o sa lẹnu iṣẹ.
Koda wọn fi iwe sita pe  ki wọn mu nibi kibi ti wọn ba ti ri.Nigba ti wọn wa titi ti wọn o ri lo mu ki ileeṣẹ ọlọpaa yọwọ ninu ẹsun yi.
Reuben ti taji pada ṣugbọn yatọ si pe o sọ orukọ rẹ ati pe ọlọpaa loun jẹ, ko ranti nkan to ṣẹlẹ.
Aṣírí tú! A ti mọ àwọn tó ń ṣagbátẹrù Sunday Igboho àti Nnamdi Kanu nínú ìjọba - Buhari
Ilé ẹjọ́ ju Àfáà tó ń gbé àwọ̀ Femi Adesina wọ̀ sí ẹ̀wọ̀n ọdún 28, ó tún pàdánù dúkìá
Iléẹ̀kọ́ fásitì OAU dí títì pa lórí akẹ́kọ̀ọ́ tó gbẹ́mìí mì ní iléwòsàn fásitì
Wòólì Alfred kú lọ́dún 1964, ó tún padà wà sí ìlú Agelu f'ọ́jọ́ mẹ́rìnlá!
Awọn ọlọpaa lagbegbe ile iwosan yi lo pada tọ awọn mọlẹbi rẹ lọ ti wọn fi mọ pe Reuben ṣi wa laye.
Ibatan rẹ Joan Jeptoo ni awọn ti sọ ireti nu pe o ṣi wa laye ki wọn to pe awọn lati wa wo nile iwosan.
"Mo ri ni ile iwosan Kenyatta ṣugbọn ko da mi mọ bẹẹ ko si ranti ẹnikankan ninu mọlẹbi rẹ''
Ile iwosan ti ni ko pada sile rẹ ni Koibatek lagbegbe Baringo nibi ti iyawo rẹ ati awọn mọlẹbi ti n tọju rẹ.
Iroyin ayọ ni pe awọn ileeṣẹ ọlọpaa ti n gbiyanju lati da pada sẹnu iṣẹ.
Ibatan rẹ to ba ileeṣẹ iwe Iroyin Daily Mail sọ ni Reuben to ti le ni aadọta ọdun n foju sọna de igba ti yoo fẹyinti lẹnu iṣẹ.
'Ìyà Muinat kú nígbà tó ń mu ọmú lọ́wọ́ ni èmí ìyà-ìyá rẹ̀ ń tọ́jú rẹ̀ kí ògiri kíláàsì tó wó pa á'
Sunday Dare to Obasanjo: Sọ nkán tóo ṣé láti pèsè iṣẹ́ f'áwọn ọ̀dọ́ kó tó máa bẹnu àtẹ lu Buhari
Minisita feto ọdọ lorileede Naijiria, Sunday Dare ti sọrọ tako aarẹ tẹlẹ Olusegun Obasanjo lori ọrọ to sọ pe ewu nla lọrọ aipese iṣẹ fawọn ọdọ Naijiria.
Ninu ifọrọwanilẹnuwo kan pẹlu ileeṣẹ iwe iroyin Naijiria Punch lo ti lede ọrọ yi.
Dare ni Oloye Obasanjo ko yẹ lẹni tii naka alebu si ijọba to wa lode yii lori ipese iṣẹ fawọn ọdọ.
O sọ pe ka ni ijọba Obasanjo to ṣaaju ba ti koju ipenija yi ni, ko ba ma ri bi o ti ṣe ri loni.
''Kini aarẹ Obasanjo ṣe lọdun mẹjọ to wa lori oye lati fi koju aisiṣẹ fawọn ọdọ? Bo ba ṣe pe o gbe igbesẹ lasiko ijọba rẹ ni awa naa ko ba ri nkan tẹle'.
Sunday Dare ni ipenija airiṣẹ awọn ọdọ ko bẹrẹ ni ọdun mẹfa sẹyin labẹ iṣakoso ijọba Buhari.
O ni o ṣe pataki ki eeyan wo ipenija yi pẹlu ibi ti eto ọrọ aje lagbaye n lọ.
'Ìyà Muinat kú nígbà tó ń mu ọmú lọ́wọ́ ni èmí ìyà-ìyá rẹ̀ ń tọ́jú rẹ̀ kí ògiri kíláàsì tó wó pa á'
''Ki ajakalẹ Covid-19 to de ba gbogbo aye, ẹ ri bi awọn orileede Yuroopu ati Amẹrika naa ṣe n tiraka. Ipenija to ba gbogbo aye yii ko yọ Naijiria lẹsẹ silẹ''.
O ni akọsilẹ wa wi pe awọn eeyan n padanu iṣẹ wọn ti iṣẹ ohun iya si n peleke kaakiri.
Dare ṣalaye awọn orisirisi ọna ti ileeṣẹ rẹ ati ijọba lapapọ ṣe n ṣagbekalẹ eto lati koju airiṣẹ ọdọ ni Naijiria.
Igba akọkọ kọ niyi ti aarẹ Obasanjo yoo ma sọrọ lori airiṣẹ laarin ọpọ ọdọ Naijiria.
Bẹẹ si ni kii ṣe lasiko ijọba to wa lori oye yi nikan lo ti mẹnu ba ipenija yi.
2023 Presidency: Kokoko lara mí le, Mo kàn ń gbà ìtọ́jú ni- Tinubu ṣàlàyé ìdí tó sì fi wà ní London
Oríṣun àwòrán, Tinubu
Aṣíwájú ẹgbẹ́ òṣèlú All Progressives Congress, Bola Ahmed Tinubu sọ̀rọ̀ sókè lẹ́yìn bi ọjọ́ mẹ́ta tí oníruuru fótò bí àwọn olóṣelú ṣe ń se àbẹ̀wò sí ní ilú London lati lọ kíi, tó fi mọ ààrẹ Nàìjíríà, Muhammadu Buhari.
Sùgbọ́n Asíwajú Ahmed sọ pé, kokoko ni ara òun lé, òun kan n gba itọjú lásán nilú London ni.
Tinubu fi ọ̀rọ̀ yìí dá àwọn ọmọ ilé ìgbìmọ̀ asojú sòfin láti ìhà Arèwá tó ṣe àbẹ̀wò si ni ilú London lọ́jọ́ Eti lójú.
Gómínà ìpińlẹ̀ Eko nígbà kan rí, ti ó ti wà ni ilú London láti bi oṣù mẹ́ta sẹ́yìn, lẹ́yìn tí  o  lọ ṣe iṣẹ́ abẹ̀ orókún rẹ̀, ẹ̀wẹ̀, ó sàpèjúwe ìtójú náà bi èyí tí ó nira púpọ̀.
Tinubu sọ pé, Ọlọ́rún àti àwọn ènìyàn bi ti yín yii lo jẹ ki ara mi le  kokoko, mo kan gba ìtójú ni, sùgbọ́n ó nira gidi"""
Lati ìgbà tí Tinubu tí lọ sí ilú London ni ọ̀pọ̀ ènìyàn tí ń bẹ̀ẹ́ wò níbẹ̀, láti orí ààrẹ Muhammadu Buhari, Abẹnugan ilé ìgbìmọ̀ asòfin, Femi Gbajabiamila, Gómìnà Abdullahi Ganduje ti ìpińlẹ̀ Kano, Dapo Abiodun, ti ìpínlẹ̀ Ogun.
Àwọn mííràn tún ni,  Babajide Sanwo-Olu ti ìpińlẹ̀ Eko Rotimi Akeredolu (Ondo), àti  Kayode Fayemi (Ekiti).
Pípẹ́ ti Tinubu pé ni ìlú London yìí tí mú kí ọ̀pọ̀ máá bu ẹnu àtẹ́ lùú pé orílẹ̀-èdè Nàìjíríà ló yẹ kí ó dúró sí láti gba ìtójú.
Tó fi mọ́ Reno Omokri tó sọ pé, ti Tinubu bá di ààrẹ lọ́dún 2023, òun náà yóò máá lọ ilú òyìnbó bọ̀ láti lọ máá gbá òitọ́jú bi ti ààrẹ Buhari tó m fi owó ara ilú ló tójú ara rẹ̀ lókè òkun.
Bí mo ṣe ná $88,521 lórí, igún, ìfun eerin, agbárí kìnnìhún láti gbé ẹbọ
Ọkunrin kan ti wọn mu fun ẹsun lilo orukọ ẹlomiran àti iluni ni jibiti ti ṣalaye bi o ṣe na ẹgbẹrun lọ́mejidinlaadọrun ati ẹẹdẹgbẹta dọla to gba lọwọ ẹni to lu ni jibiti.
Ọdaran naa, to n jẹ Jamiu Isiaka ni wọn ti ran lọ si ẹwọn ọdun mejidinlọgbọn  fun lilo orukọ olubadamọran pataki lori ọrọ to nm lọ ati iroyin fun aarẹ Muhammadu Buhari, Femi Adesina.
Wọn ni o jẹbi ẹsun lilu ọmọ South Korea kan keun Sig Kim ni jibiti owo dọla 88,521 tó jẹ ọgbọ̀n mílíọnu Naira.
Ọ̀ṣọ́ Aṣọ Òkè ti kọjá lílo ìlẹ̀kẹ̀ níkan
Isiaka lasiko to n bẹbẹ pe oun ko jẹbi ẹsun gẹ́gẹ́ bi iroyin NANS  se sọ lo ṣalaye fun ile ẹjó giga ipinlẹ Kwara to fi ikalẹ si ilu Ilorin pe oun fi owo naa gbe ẹbọ ni.
Diẹ ninu owo naa, ni oun fi ra igun, awọn eerin, ifun eerin, agbari kinnihun ati ẹdọ gorilla ti oun sapọp lati gbe ẹbọ.
Ẹka ajọ EFCC ti kọkọ gbe ọdaran naa lọ di ile ẹjọ ni ọjọ kẹrinla, ninu osu kẹfa ọdun 2019 lori ẹsẹ mẹrin eyi ti o si ni oun ko jẹbi ẹsun.
Lasiko idajọ rẹ adajọ Mahmud Abdulgafar ṣalaye pe ẹri to daju ti wa niwaju ile ẹjọ, olujẹjọ naa si jẹbi ẹsun ti wọn fi kan
Lẹyin eyi ni adajọ ni o jẹbi ẹsun ti o si ni ki o lọ ẹwọn ọdun meje fun ẹsun kọọkan kí o si maa ṣe bi o ṣe n pari ọkan.
Ile ẹjọ tun ni ki wan gba gbogbo nkan ni rẹ fun ijọba apapọ nitori pé gbogbo nmǹmkan ti o kojọ lọna aitọ.
Àwọn nnkan ti wọn gba lọwọ rẹ ni ile ilẹ kan ni Oke-Foma, Ilorin, ọkọ Toyota Corolla, Amohunmaworan ẹrọ amuna wa, ati amuletutu.
Bakan naa ni ile ẹjọ ni ki o ṣe atunsẹ lọdọ ẹni ti o lu ni jibiti.
Il ẹjọ ni o n pe ara rẹ ni olubadamọran pataki fun aarẹ Muhammadu Buhari, Femi Adesina ati adari ile isẹ NNPC Maikanti Baru  fun Keun Sig Kim ọmọ South Korea lati lu ni jibiti ọgbọn miliọnu Naira.
Awọn ọlọpaa ati ajọ EFCC mu ẹri jade lori bi o se gba owo gọbọi lọwọ Keun nitori o pe ara rẹ ni ọga agba kan ninu ijọba ati pe oun n ran lọwọ lati gba awọn iwe ni NNPC.
Yomi Fabiyi tutọ́ sókè fojú gbàá lórí ọ̀rọ̀ onimọ̀ àyẹ̀wò Forensic tí Adájọ́ pé wá jẹ́rìí nìgbẹ́jọ́ Baba Ijesha
Oríṣun àwòrán, Instagram/yomi fabiyi
Yomi Fabiyi tun ti n sọko ọrọ pẹlu awọn eeyan lori igbẹjọ James Omiyinka Olanrewaju ti gbogbo eeyan mọ si Baba Ijesha.
Eyi ti a tun ri gbọ bayi ni i ṣe pẹlu ọrọ to kọ si oju opo rẹ ni Instagram to ti ni  oun ko mọ idi tawọn eeyan fi n bu oun lori ijẹri onimọ ayẹwo.
Onimọ ayẹwo yi ni awọn oloyinbo n pe ni ''Forensic expert Witness.''
Ṣaaju ni ileẹjọ sọ pe ki ẹni yi  wa sọrọ lori ifọrọwanilẹnuwo to ṣe fun ọmọdebinrin ti wọn ni Baba Ijesha ṣe aṣemaṣe pẹlu.
Ninu ọrọ to sọ loju opo Instagram, Fabiyi ni ki awọn eeyan sinmi eebu ati epe ti wọn n ṣẹ fun oun ki wọn si jẹ ki ileẹjọ ṣe iṣẹ wọn bo ṣe yẹ.
O ni: ''Ko si nkankan ti onimọ yi sọ ti a ko tii gbọ tẹlẹ.
Ẹ jọwọ, ẹ jẹ ki ile ẹjọ ṣe iṣẹ wọn''
'Ìyà Muinat kú nígbà tó ń mu ọmú lọ́wọ́ ni èmí ìyà-ìyá rẹ̀ ń tọ́jú rẹ̀ kí ògiri kíláàsì tó wó pa á'
Fabiyi ni: ''Wọn pe arabinrin yi wa lati wa sọrọ gẹgẹ bi olujẹri ni.
Ẹ gbọ nkan to sọ nile ẹjọ. Ko sọ pe oun ṣe ayẹwo ọwọ, iwadii dokita tabi nkan mii''
Oríṣun àwòrán, Instagram@yomifabiyi
Fabiyi ṣalaye pe nkan ti arabinrin naa kan ṣe ni pe ''o ba ẹni ti ọrọ kan ni ifọrọwerọ nikan ni.''
O rọ awọn to n bẹnu atẹ lu u pe ki wọn wa imọ si nipa eto igbẹjọ nitori ile ẹjọ ko tiẹ ti sọ pe ki wọn beere ọrọ lẹnu onimọ ayẹwo yi.
O ni ki awọn eeyan ṣe suuru lati gbọ idajọ ileẹjọ ki wọn to bẹrẹ si ni gbe lẹyin ẹnikankan.
Traditional Birth Control: Wò àwọn nkán ìbílẹ̀ tí àwọn obìnrin òde òní fi n fètòsọ́mọbíbí
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ki a to lọ jina ninu apilẹkọ yi, a fẹ fi ikilọ kekere yi sita.
Ko si aridaju pe ilana ifetosọmọbibi kankan wa ti kii ja ni kulẹ.
Yala ti oloyinbo ni tabi ti ibilẹ, eeyan le lo ilana ifetosọmọbibi ki o si pada wa  loyun to n sa fun
Ko si ohun ti ko le ṣẹlẹ.
Igbagbo Yoruba ati ifetosọmọbibi
Bayi taa ti sọ eyiun ni tan, ka bọ si akori ọrọ wa gan an.
Ẹni tó bá ni kí n fi iṣẹ́ kòkò mímọ sílẹ̀, mi ò lè fẹ́ẹ láéláé - Adekemi Àgùnbánirọ̀
Aṣa awọn Yoruba kun fun orisi ilana ati eto eleyi ti wọn fi n gbọ ipenija eyikeyi to ba de ba wọn lagọ ara.
Lara awọn ipenija yi leleyi to ni ṣe pẹlu ilera awọn obinrin paapa fawọn to ba fẹ fi eto si ọmọ bibi.
Akomolede: Akuko Gagara ni ìwé tó ṣàfìhàn ohun tó ń ṣẹlẹ̀ ní Nàìjíríà lásìkò yìí- Fatimo B
Ki awọn obinrin to bẹrẹ si ni lo kọndọọmu,abẹrẹ tabi awọn oogun lati fi feto si ọmọ bibi, awọn iya wa paapa ti wọn ni imọ nipa ewe ati egbo, wọn a maa lo nkan ibilẹ ti wọn naa.
Lara nkan ti wọn maa n lo ni oruka,ẹgba ọwọ, asejẹ  ati ilẹkẹ idi lati fi ṣeto ifetosọmọbibi.
Oríṣun àwòrán, nanbyet
Awọn alagbo ọmọ kan to fi ilu Osogbo ṣe ibujoko ṣalaye fun ileeṣẹ iwe Iroyin Punch pe  awọn nkan wọn yi ṣi wa.
Koda wọn ni  awọn obinrin ode iṣẹnyi  a maa wa sọdọ awọn lati wa ra a.
'Ìyà Muinat kú nígbà tó ń mu ọmú lọ́wọ́ ni èmí ìyà-ìyá rẹ̀ ń tọ́jú rẹ̀ kí ògiri kíláàsì tó wó pa á'
Arakunrin Shina Elebuibon to n ta ewe ati egbo ni Osogbo ṣalaye  pe ẹgba ọwọ,oruka ati ilẹkẹ idi wa lara awọn nkan tawọn n peelo.
''Lootọ lawọn mii a maa fi awọn ilẹkẹ idi yi ṣe oge ṣugbọn fawọn to ba beere wọn le lo lati feto sọmọ bibi.''
Shina Elebuibon ṣalaye pe awọn maa n ṣalaye orisi ilana ifetosọmọbibi fawọn obinrin to ba wa sọdọ awọn.
O ni bi apẹrẹ, pipeelo ilẹkẹ idi ko gba asiko pupọ lati ṣe bẹẹ naa ni ti ẹgba ọwọ.
Oloye Peter Fatomilola: Ọjọ̀gbọ́n olùkọ́ni ni Jesu àti Orunmila jẹ́, àwòkọ́ṣe sí rere si n
Elebuibon ni:  ''Mo ma ni ki wọn ra awọn ilẹkẹ tabi ẹgba yi wa.Bi a ba ti peelo to yẹ si tan, ẹni naa gbọdọ wọ to ba fẹ ni ibalopọ ki o baa maa fi loyun''
Ọgbẹni Shina tun sọ pe awọn a tun maa lo koro kan ti wọn n pe orukọ rẹ ni iwerejeje tabi oju ologbo.
Oríṣun àwòrán, @nanbyet
Shina Elebuibon  ni:  ''Bi a ba ti lọ koro yi tan,ma o fi awọn nkan eelo miran si ti obinrin naa yoo si gbe mi.
Iye koro to ba gbe mi ni yoo tọka iye ọdun ti ko fi ni loyun''
Ṣé ìwọ mọ̀ pé Olodumare lè lo Aje láti gbé ẹ lọ síbi ire?- Abiodun Fatomilola
Arabinrin Afolabi ti oun naa ṣalaye nipa awọn nkan ibilẹ yi sọ pe tẹlẹ lawọn alakọwe ko fi taratara gba ti wọn ṣugbọn nisin yi, awọn naa ti n lo ti ibilẹ yi.
Abiodun Duro Ladiipo, Moremi: Ǹ kò pé '40' ti Bàbá fi papòdà ṣùgbọ́n mo kọ̀ láti 'remarry'
''Lọwọlọwọ awọn alakọwe,oṣiṣẹ ijọba Kristẹni ati musulumi lo maa n wa si ọdọ wa.Ohun to jẹ ki wọn maa wa ni pe pupọ lo jẹri si pe awọn nkan wọn yi n ṣiṣẹ daada.''
Ninu alaye tawọn elewe ọmọ yi ṣe wọn ni awọn le fọwọ rẹ sọya pe awọn nkan wọn yi a maa jẹ bi idan.
Adeyemi Olubunmi Crown: Láti ìgbà ti mo ti fún ọkọ mi ni ẹ̀bùn mọ́tò ni ìfẹ́ wa ti yàtọ̀
Botilẹ jẹ wi pe awa ko ri aridaju pe bẹẹ lọrọ ri, iru nkan bayi ko jẹ tuntun lawujọ awọn Yoruba.
Owo ṣipini ti ko gun ni lapa lawọn elewe ọmọ a maa gba lọwọ awọn alabara wọn gẹgẹ bi wọn ṣe ṣalaye.
Ayo Ewebiyi Mama Oriki: Ọwọ́ Òbí, Ìjọba àti àwọn Ọba ni ìdágbàsókè Yorùbá wà lásìkò yìí
Kaakiri awọn ile iwosan ọfẹ ni idanilẹkọ ati eto ifetosọmọbibi fawọn araalu.
Ninu awọn eto yi leleyi tawọn obinrin a maa fi sinu apa, oju ara tabi eleyi ti wọn a maa lo bi tabilẹti loore koore.
Eyikeyi to ba ṣiṣẹ fun yin, ẹ ma gbagbe pe Eledua lo n fi ọmọ ta ni lọrẹ nigba kigba to ba wu.
Oríṣun àwòrán, Facebook/YohaibFashionStudio
Igbiyanju lda n gba, eleyi ti yoo ba di ọmọ iriri ti fi han lorisirisi pe ifetosọmọbibi ko ni le daa duro.
Ati sayẹnsi ati imọ awọn baba wa, ko si eleyi to le sọ pato bi iru nkan bayi ṣe n waye.
Ojú Bolanle rèé, afurasí adigunjalè tí òun àti àwon akẹgbẹ́ rẹ n kò ìbẹrù bá ará àdúgbò
Ọjọ ayajọ ominira Naijiria ni ọjọ Kinni, oṣu Kẹwaa jẹ fun ọpọ eeyan.
Ṣugbọn ọjọ yi ni  afurasi adigunjale kan ati awọn akẹgbẹ rẹ yan laayo la ti lọ fi ko ibẹrubojo ba awọn ẹlẹran ara bi ti wọn.
Bi Oluwa ti ṣe fẹ, ọwọ palaba awọn afurasi yi segi nigba ti awọn ọlọpaa ipinlẹ Ogun ribi mu wọn ki wọn to ribi digunjale ni Ilese Ijebu.
Gẹgẹ bi atẹjade ti alukoro ọlọpaa ipinle Ogun, Abimbola Oyeyemi fi sọwọ si BBC, o ni nkan bi ago mejila abọ oru lawọn adigunjale yabo Silva Estate Odomalasa.
Ọ̀ṣọ́ Aṣọ Òkè ti kọjá lílo ìlẹ̀kẹ̀ níkan
Lẹyin tawọn kan kepe ọlọpaa  o ni awọn agbofinro agọ ọlọpaa Ilese Ijebu tara l sibẹ ti wọn si ribi koju awọn afurasi wn yi.
Awọn afurasi adigunjale naa sa wọ igbo nigba ti wn gburo ọlọpaa ṣugbọn ọwọ tẹ kan ninu wọn ti orukọ rẹ n jẹ Bolanle.
Ọpẹlọpẹ awọn araadugbo ti wọn jijọ le wọn, afurasi yi ko ba ri bi sa bi awọn iyoku rẹ.
Wọn ri ibọn agbelẹrọ kan lọwọ rẹ ati ọta ibọn.
Abiodun Duro Ladiipo, Moremi: Ǹ kò pé '40' ti Bàbá fi papòdà ṣùgbọ́n mo kọ̀ láti 'remarry'
Alukoro ọlọpaa Oyeyemi sọ pe wọn ti n tọ pinpin awọn to ku lọ ni ibamu pẹlu aṣẹ adele Kọmisọnna DCP Abiodun Alamutu.
Bẹẹ lo ni wọn ti gbe Bolanle ti ọwọ tẹ lọ si ẹka ọtẹlẹmuyẹ fun iwadii kikun.
Oloye Peter Fatomilola: Ọjọ̀gbọ́n olùkọ́ni ni Jesu àti Orunmila jẹ́, àwòkọ́ṣe sí rere si n
Female Private Part Odour: Ohun méta rèé tó ń fa kí abẹ́ obinrin má a rùn...
Oríṣun àwòrán, others
Orisirisi nkan lo le fa a ki oju ara obinrin ma a run yatọ si oorun ti o ba wa lati ọrun.
Lati ara ounjẹ jijẹ, ilera ara ati awọn nkan miran ma a n fa ki oorun oju ara yipada.
Ọpọlọpọ igba ni awọn eniyan ma n gbiyanju lati wa atunṣe si iṣoro yii nipa lilo awọn ohun oloorun tabi ọṣẹ, amọ eleyii lewu ni ọpọlọpọ igba.
Ọ̀ṣọ́ Aṣọ Òkè ti kọjá lílo ìlẹ̀kẹ̀ níkan
Gẹgẹ bi obinrin, ti o ba ri i pe oju ara rẹ n run kọja bi o ṣe yẹ, abi omi abẹ yi pada si awọ ti ko ba ti tẹlẹ mu, o ṣeeṣe ko o ti ni kokoro oju ara tabi aisan miran.
Àwọn ọkùnrin tó wà nínú ayé wa gbúdọ̀ bọ̀wọ̀ fún wa - Adarí FIN
Awọn ohun to le fa ki oju abẹ ma a run re e;
Nigba ti ''Condom'' ti o n lo ko ba ara rẹ mu:
Nigba miran awọn eroja ti wọn fi se rọba idabobo ''condom'' le ma ba ara rẹ mu
Divorcee: Ó sàn kí wọ́n yàgò fúnra wọn ju ki wọ́n ṣe ara wọn léṣe- Fisayo
Kọndọọmu mi lasiko ibalopọ le ma ba ẹni to n lo o ni ara mu, eleyii to le e jẹ ki oju ara ma a run, tabi ki o ma a yun ẹni naa. Tiraka lati lo ẹya condom miran bọya yoo ba ọ lara mu.
'Bí aya bá kọ ọkọ rẹ̀ silẹ̀, kó wà láì lọ́kọ̀'
Nipasẹ Kokoro aifojuri Bacteria Vaginosis (BV):
Ọkan gboogi lara awọn kokoro aifojuri re e to ma n fa ki oju abẹ ma a run. Aisan yii ma n bọ si ara obinrin lasiko ibalopo eleyii to le fa awọn arun miran si ara ti a ko ba tete bojuto.
O le fa ki oyun bajẹ lara obinrin to ba ni aisan kokoro aifojuri yii lara.
Working religious women: Ẹ̀lẹ́hàá kìí ṣe ọ̀lẹ- Aminat Adegoke
Awọn ounjẹ ti ko ṣe ara loore:
Opọ obinrin lo fẹran lati maa jẹ ipapanu ti ko ṣe ara wọn loore.
Nigba ti awọn eroja ara bii pH levels ara obinrn ko ba pe, o ṣeese ki oju ara rẹ ma a run.
Akomolede: Akuko Gagara ni ìwé tó ṣàfìhàn ohun tó ń ṣẹlẹ̀ ní Nàìjíríà lásìkò yìí- Fatimo B
Nitori naa, ẹ jẹ ounjẹ to jẹ ọrẹ aawọ to si n mu ara ji pepe.
Jijẹ eso ati ewebẹ se pataki pupọ fun obinrin ati wara naa ki gbogbo eroja ara wọn le maa ṣiṣẹ bi o ti yẹ.
IPOB Sit at Home: Ẹ̀yin ọmọ Yoruba ẹ darapọ̀ mọ́ wa látí tako ìjọba Naijiria lórí àtìmọ́lé Nnamdi Kanu
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ẹgbẹ ajijagbara to n pe fun Biafra Nation, IPOB ti kesi awọn ọmọ Yoruba ati gbungun Naijiria lati darapọ mọ ifẹhọnuhan awọn lati tako ijọba Naijiria lori atimọle Nnamdi Kanu.
Ẹgbẹ IPOB ni awọn n ṣe ifẹhọnuhan nipa jijoko si ile lọna ati gbe wa si ileẹjọ ni Ọjọ Kọkanlelogun, Osu Kẹwaa, ọdun 2021.
IPOB ni aṣẹ ti awọn pa fun awọn eniyan lati joko sile fun oṣu kan ni lati ṣe atilẹyin fun Nnamdi Kanu to wa ni apanpẹ ajọ DSS.
Ninu atẹjade ti agbẹnusọ ẹgbẹ IPOB, Emma Powerful fi lede lo ti kesi gbogbo awọn oniṣowo to jẹ ẹya Igbo ni ile ni oko lati ti ileeṣẹ wọn fun oṣu kan lọna ati ṣe atilẹyin fun Kanu.
Ebun Oloyede Olaiya Igwe sọ ohun tí ojú rẹ̀ rí lásìkò àìsàn kídìnrín tó yọ ọ́ lẹ́nu
''Awa ẹgbẹ IPOB n kesi awọn ekeji wa to n ja fun ominira ilẹ Yoruba ati awn to wa ni gbungun Naijiria lati darapọ mọ wa fun osu kan lai lọ si ibi iṣẹ gẹgẹ bi atilẹyin fun olori wa, Nnamdi Kanui.''
Ayo Ewebiyi Mama Oriki: Ọwọ́ Òbí, Ìjọba àti àwọn Ọba ni ìdágbàsókè Yorùbá wà lásìkò yìí
''Gbogbo ẹyin ololufẹ Biafra ni ile ni oko to fi mọ awọn ẹlẹsin Kristeni to wa iha Ariwa orilẹede Naijiria, amọ ti ijọba Naijiria n fi iya jẹ, ẹ darapọ mọ wa ki a jọ satilẹyin fun Nnamdi Kanu.''
''Iya ati iṣẹ ti awọn Fulani ọdaran darandaran fi n jẹ awọn eniyan ti to gẹ, to fi mọ ipaniyan ati ifiyajẹni ni ọna aitọ.''
Oríṣun àwòrán, Getty Images
''Asiko ti to lati jẹ ki ijọba ati awọn Fulani darandaran yii mọ wi pe a kii ṣe atẹmẹrẹ, ki wọn ye e fi iya jẹ wa mọ.''
''A parọwa si gbogbo awọn eniyan lati koju ijọba apapọ nipa jijoko si ile wọn titi ti Ajọ DSS yoo fi mu Nnamdi Kanu wa si ileẹjọ fun igbẹjọ rẹ ninu oṣu yii.''
Abiodun Duro Ladiipo, Moremi: Ǹ kò pé '40' ti Bàbá fi papòdà ṣùgbọ́n mo kọ̀ láti 'remarry'
''Mazi Nnamdi Kanu jẹ ajijagbara to n ja fun ẹtọ awọn eniyan paapaa ni orilẹede Naijiria , ti ko si fi igba kan hu iwa ibajẹ si ẹnikẹni.''
''O ṣeni laanu pe Ajọ DSS ti i mole lai gbe lọ si ileẹjọ lọna ati fi iya jẹ ni atimọle to wa naa.''
Osu Keje, ọdun 2021 ni ijọba Naijiria ati DSS fi panpẹ ọba mu Nnamdi Kanu lati oke okun wa si Naijiria, ti wọn si ti tii mole lati igba naa.
Àwọn ọkùnrin tó wà nínú ayé wa gbúdọ̀ bọ̀wọ̀ fún wa - Adarí FIN
Ni Osu Keje, ni adajọ ni ileẹjọ giga ti ilu Abuja, Binta Nyako paṣẹ fun ijọba apapọ lati mu Kanu wa si ileẹjọ ninu Osu Kẹwaa yii, ki igbẹjọ rẹ le tẹsiwaju.
Ọ̀ṣọ́ Aṣọ Òkè ti kọjá lílo ìlẹ̀kẹ̀ níkan
Reno Omokri: Gbogbo ẹ̀yín tí ẹ bá ní dola ninú ''acount'' yín sí Naijiria, inú ewu le wà
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ileeṣẹ Banki apapọ lorilẹede Naijiria, CBN ti ni irọ patapata ti ko si otitọ kankan nibẹ ni iroyin gbe ijọba fẹ gbe ẹṣẹ le apo asunwọn ọwọ awọn eniyan to wa ni iye owo ilẹ okeere.
Ninu atẹjade ti wọn fi lede ni wọn ti ni awọn ẹni ibi lo n pa irọ fun awọn eniyan.
CBN ni awọn ko ni lailai gbe iru igbesẹ bẹẹ nitori awọn ọmọ to wa ni apo iṣuna yii kii ṣe ti wọn, nitori naa awọn ko le e gbe ẹṣẹ le.
Ebun Oloyede Olaiya Igwe sọ ohun tí ojú rẹ̀ rí lásìkò àìsàn kídìnrín tó yọ ọ́ lẹ́nu
''Awọn ẹni ibi to fẹ da wahala silẹ lawujọ, ki awọn eniyan bẹrẹ si ni bẹru ni wọn n fi iru iroyin bayii lede.''
''Ẹyin araalu ko si ohun to jọ igbesẹ bẹẹ, wọn kan fẹ ba igbagbọ ti awọn eniyan ni ninu banki apapọ jẹ ni.''
Bakan naa ni wọn fikun un pe iroyin ti wọn ko ba ti ri ni oju opo wọn ko wa lati ọdọ wọn,nitori naa ki awọn eniyan ma gbe ọkan ara wọn soke nitori awọn oniroyin ẹlẹjẹ.
Africa Eye wádii àwọn tó wà nídìí ìgbésùmọ̀mí ni Mozambique
CBN ni gbogbo awọn to wa ni idi iroyin ofege yii ni yoo foju wina ofin.
Oríṣun àwòrán, AFP
Saaju ni Reno Omokri ti sọrọ:
Gbogbo ẹ̀yín tí ẹ bá ní dola ninú ''acount'' yín sí Naijiria, inú ewu le wà
Agbẹnusọ tẹlẹri fun aarẹ Goodluck Jonathan, Reno Omokri ti kilọ fun awọn ọmọ Naijiria ti wọn ba ni owo ilẹ okeere si inu apo isuna ''Account'' wọn lati ṣọra ṣe nitori ijọba Naijiria ṣetan lati gbẹṣẹle owo wọn.
Adepoju Abdulsalamm ẹni ọdun 18 tó n fi kẹ̀kẹ́ dára fi kiri ẹja tó fi n tà wàràwàrà
Ninu fidio to fi lede ni Reno Omokri ti kilọ fun awọn ọmọ Naijiria bẹẹ pe ki wọn ko owo wọn kuro ni apo isuna ''Domiciliary account''
Omokri ni idi ni pe gbese ti orilẹede Niajiria ti jẹ si ilẹ okeere ti kọja keremi, eleyii to ti mu ijọba jẹ iye owo to to triliọnu mẹrindinlogoji.
Gbogbo ẹ̀yín tí ẹ bá ní dola ninú ''account'' yín sí Naijiria, inú ewu le wà - Reno Omokri
O ni eleyii tun mọ si pe orilẹede Naijiria ko ni owo lati san awọn gbese ti wọn jẹ awọn orilẹede ni agbaye.
Àwọn ọkùnrin tó wà nínú ayé wa gbúdọ̀ bọ̀wọ̀ fún wa - Adarí FIN
''Aarẹ Buhari fun ara rẹ sọ ni ipade Ajọ Iṣọkan Agbaye, UN pe ki awọn ti wọn jẹ ni gbese fi silẹ fun awọn nitori iya ati iṣẹ ti ohun ba wọn finra.''
''Amọ wọn tun n bere fun iranlọwọ lati ya owo miran, eleyii ti ko mu ọpọlọ dani fun ẹnikẹni, ti yoo si fa Naijiria si oko ẹru.''
Omokri ni eleyii tun mọ si pe ijọba yoo bẹrẹ si ni gbeṣẹ le owo awọn eniyan to wa ni banki, paapaa awọn owo ilẹ okeere ti awọn eniyan ko fi  ọwọ kan.
O wa parọwa si awọn eniyan lati lọ ko owo wọn kuro ni domiciliary account, nitori owo to wa ni apọ iṣuna yii jẹ biliọnu mẹrindinlogun naira.
Ọ̀ṣọ́ Aṣọ Òkè ti kọjá lílo ìlẹ̀kẹ̀ níkan
2021 World Teachers Day: ọdún tó n bọ̀ lowó oṣù tuntun fáwọn olùkọ́ Nàìjíríà yóò di gbígbà...
Oni ni ayajọ awọn olukọni lagbaye.
Ajọ UNICEF ati ILO to fi mọ Educational Internation lo maa n ṣagbatẹru eto ayajọ yi.
Lorileede Naijiria bi tawọn ilẹ miran ti iṣẹ olukọ ti gbajumọ, pupọ lo n fi ọjọ yi ṣagbeyẹwo iṣẹ olukọ,ipenija ati afojusun ọjọ iwaju.
Akori ayajọ ti ọdun yi ni ''Teachers at the Heart of Education Recovery'' eyi to tumọ si ipa tawọn olukọ n ko ninu ijipada eto ẹkọ.
Akori yi ṣe pataki paapa ti a ba wo bi ajakalẹ Covid-19 ti ṣe mu iyipada ba eto ẹkọ ti ọpọ akẹkọọ ko si ribi kẹkọ ni kilaasi bi tatẹyinwa.
Lawọn orileede ti ọwọja aarun yi ti peleke, titi di asiko yi, awọn akẹkọọ ko ribi pada si kilasi ti eyi si mu ifaṣẹyin ba ẹkọ wọn.
Teachers retirement age and years of service: Ìrírí àwọn àgbà olùkọ́ ṣì wúlò fún àwa ọ̀dọ́
Ni Naijiria awọn olukọ ati akẹkọọ ti pada si kilasi ti eto gbogbo ṣi n lọ ṣugbọn awọn ipenija to ba eto ẹkọ mii ṣi wa.
Diẹ ninu wọn ni ipenija aabo paapa ọrọ ijinigbe awọn olukọ ati akẹkọọ lawọn ile ẹkọ lati alakọbẹrẹ to fi de fasiti.
Amọ ọkan ninu ipenija ti ọpọ n mẹnu ba ni eleyi to ni ṣe pẹlu owo oṣu awọn olukọ ti ko to lati fi gbọ bukata.
Laipẹ yi ni ijọba Naijiria kede pe awọn yoo ṣe afikun owo oṣu olukọ lọna ati mu ki awọn ọlọpọlọ pipe wa si idi iṣẹ olukọni.
Alakuko/Elega Schools: Aráàlú ní olùkọ̀ọ́ àti akẹ́kọ̀ọ́ ti sá ní kíláàsì tí kò dára
Yatọ si afikun owo oṣu yi, aarẹ Buhari kede awọn moriya bi eto ile igbe,owo ajẹmọnu ati igbaradi loore koore fawọn olukọ.
Minisita feto ẹkọ Naijiria Chukwuemeka Nwajuba sọ laipẹ yi pe ọdun to n bọ 2022 lawọn olukọ yoo bẹrẹ si ni gbadun afikun owo oṣu yi.
Adepoju Abdulsalamm ẹni ọdun 18 tó n fi kẹ̀kẹ́ dára fi kiri ẹja tó fi n tà wàràwàrà
O fi ọrọ naa lede nibi apero idanilẹkọ kan to waye ni Abuja lara eto ayajọ olukọ ni Naijiria.
Minisista ọhun sọ pe awọn ṣe gbogbo eto lati ri pe awọn olukọ gba owo oṣu to tọ si wọn loṣu kini ọdun 2022.
Ọ̀ṣọ́ Aṣọ Òkè ti kọjá lílo ìlẹ̀kẹ̀ níkan
''Aarẹ ti buwọlu afikun owo yi, a si n gbiyanju lati ri pe o gberasọ ni ọdun 2022''
O fi kun pe ''Aarẹ ti lewaju nipa ṣiṣe agbekalẹ ilana ti yoo mu iyipada ba iṣẹ olukọni ni Naijiria.''
Àwọn ọkùnrin tó wà nínú ayé wa gbúdọ̀ bọ̀wọ̀ fún wa - Adarí FIN
Ati pe ''ohun to ku ni ki awọn alẹnulọrọ bi awọn Gomina,ile aṣofin ati awọn mii darapọ mọ eto yi ko ba le kẹsẹjari''
VAT Dispute in Supreme Court: Àwọn ìpínlẹ̀ Gúúsù-Gúúsù darapọ̀ mọ́ ìgbẹ́jọ́ nílé ẹjọ́ gíga jùlọ
Oríṣun àwòrán, Facebook/Ifeanyi Okowa
Awọn Gomina ipinlẹ to wa ni Guusu-Guusu Naijiria ti pinu lati darapọ mọ awọn akẹgbẹ wọn to n ba ijọba apapọ ṣẹjọ VAT.
Igbẹjọ lori ọrọ owo ori ọja VAT yi ti sun de ile ẹjọ giga lẹyin ti ijọba apapọ ni idajọ ti ile ẹjọ kọtẹmilọrun gbe kalẹ ko dun mọ awọn ninu.
Inu atẹjade onigun mẹfa kan ti wọn fi sita lọjọ Aje ni awọn Gomina wọn yi ti ni awọn ṣetan lati tako ajọ FIRS lori gbigba owo ori.
Gomina ipinlẹ Delta, Ifeanyi Okowa, to dari ipade wọn to waye ni Port Harcourt lo fi ọrọ yi to awọn akọroyin leti.
Yatọ si Okowa Gomina Nyesom Wike Rivers,,Godwin Obaseki,Edo,Emmanule Udom,Akwa Ibom  ati Sẹnẹtọ Duoye Diri,Bayelsa peju sibi ipade naa.
Africa Eye wádii àwọn tó wà nídìí ìgbésùmọ̀mí ni Mozambique
Awọn Gomina yi tun sọ awọn ọrọ mi to ni ṣe pẹ pẹlu idagbasoke agbegbe wọn to fi mọ idasilẹ ikọ alaabo ti wọn naa.
Adepoju Abdulsalamm ẹni ọdun 18 tó n fi kẹ̀kẹ́ dára fi kiri ẹja tó fi n tà wàràwàrà
Igbesẹ awọn Gomina Guusu-Guusu Naijiria yi wa ni ibamu pẹlu ipinu awọn Gomina ẹkun iwọ oorun Guusu,South West.
Ebun Oloyede Olaiya Igwe sọ ohun tí ojú rẹ̀ rí lásìkò àìsàn kídìnrín tó yọ ọ́ lẹ́nu
Ṣaaju lawọn naa ti lawọn faramọ ki awọn ijọba ipinlẹ maa gba owo ori VAT yi.
Nibi ipade wọn to waye lọjọ Kẹrindinlogun oṣu Kẹsan ni Asaba ni wọn ti sọ ipinu yi ati awọn nkan miran to jẹ wọn logun.
Oríṣun àwòrán, Facebook/Ifeanyi Okowa
Ipinlẹ bi Eko ati  Rivers lo lewaju awọn to fẹ gba owo yi nitori wọn ti ṣe agbekalẹ ofin ti yoo fawọn oṣiṣẹ wọn lagbara lati gba owo yi dipo FIRS to n gba tẹlẹ.
Bayi ti awọn ipinlẹ Guusu-Guusu tun darapọ mọ wọn,iye wọn ti n pọ si.
Ọ̀ṣọ́ Aṣọ Òkè ti kọjá lílo ìlẹ̀kẹ̀ níkan
Amọ ṣa awọn ipinlẹ bi Kano ati Katsina ti fariga pe awọn yoo kọdi gbigba owo VAT yi lati ọdọ awọn ijọba ipinlẹ.
Nibi tawọn wọn yi ti fi erongba wọn han, awọn ipinlẹ miran bi Kwara ko ti sọ boya awọn yoo faramọ igbesẹ yi.
Òhun táa mọ̀ rèé nípa ìròyìn pé EFCC mú ìyàwó Gómìnà Ganduje ìpínlẹ̀ Kano
Oríṣun àwòrán, Facebook/Abubakar Aminu Ibrahim
Hajiya Hafsat Ganduje to jẹ aya gomina ipinlẹ Kano, Abdulahi Ganduje to pada sile.
Iroyin naa fidi e mule pe o ti kuro ni ọgba ajọ EFCC to n mojuto iwa ajẹbanu ni Naijiria .
Saaju ni okan lara awọn amugbalẹgbé gomina Kano lori ifitonileti lori ayelujara fi lede pe Hajiya Hafsat ti n lọ si agọ EFCC ni Abuja.
Iroyin to gba igboro kan ni pe EFCC ti gbe aya gomina naa lalẹ ọjọ Aje.
Sugbọn ọkan lara awọn to sunmọ Gomina Ganduje ti ko fẹ ki a darukọ oun sọ fun BBC ni pe ọrọ ko ri bẹẹ.
Adepoju Abdulsalamm ẹni ọdun 18 tó n fi kẹ̀kẹ́ dára fi kiri ẹja tó fi n tà wàràwàrà
Titi di asiko yii ko sẹni to le sọ nipato ohun ti aya gomina ba bọ lati EFCC s\ugbọn ohun to daju ni pe o lọ sibẹ.
Samuel Oluwafemi sọ bí Covid 19 ṣe bí ìdíje oníjó àti eré fún àwọn Odi àti Adití sí rere
Iroyin ni pe EFCC ti ranṣẹ pe aya gomina naa lọsẹ meloo kan sẹyin ko wa ṣalaye awọn nakn kọọkan ti ko si lọ.
Oríṣun àwòrán, KNSG
Ṣé lóòótọ́ ní pé EFCC mú ìyàwó Gómìnà Ganduje ìpínlẹ̀ Kano?
Ajọ to n gbogun ti iwa ajẹbanu ni Naijiria  EFCC  ti mu iyawo Gomina ipinlẹ Kano,Hajia Hafsat Ganduje lori ẹsun iwa ajẹbanu ti ọmọ rẹ fi kan an.
Ọ̀ṣọ́ Aṣọ Òkè ti kọjá lílo ìlẹ̀kẹ̀ níkan
Oṣiṣ ijọba ipinlẹ Kano kan ti o ni ka ma darukọ oun lo fidi ọrọ yi mulẹ fun BBC.
O ni awọn oṣiṣẹ EFCC wa si Kano ti wọn si mu ''Gogo'' lọ si Abuja lati lọ dahun si awọn ibeere kan.
Amọ o ṣalaye fun BBC pe ifọrọwanilẹnuwo naa ti pari ti wọn si ti da pada sile,.
Ifọrọwanilẹnuwo lati ọdọ EFCC yi n waye lẹyin ti iwe iroyin Naijiria ti ṣaaju gbe pe Hajia Hafsat kọ lati dahun si iwe ipe ti EFCC fi ranṣẹ si.
Gẹgẹ bi awọn akọroyin ṣe sọ, ọmọ Hafsat,Abdulazeez Ganduje lo fi ẹsun kan iya rẹ lọdọ EFCC  pe ọwọ iya rẹ ko mọ.
Oríṣun àwòrán, Facebook/Abubakar Aminu Ibrahim
Ẹwẹ lowurọ ọjọ Iṣẹgun,loludamọran agba kan lori ọrọ ayelujara  fun Gomina Ganduje Abubakar Aminu Ibrahim ṣe afihan aworan Gomina ati iyawo rẹ.
Àwọn ọkùnrin tó wà nínú ayé wa gbúdọ̀ bọ̀wọ̀ fún wa - Adarí FIN
Ninu aworan yi to wa loju opo rẹ ni Facebook, o kọkọ kọ sibẹ pe awọn mejeeji n dari lati Abuja lẹyin irinajo.
Nigba ti yoo fi pẹ diẹ si igba naa lo tun kọ sibẹ pe Gomina ati iyawo rẹ lọ fun ipade kan ni Abuja.
Oríṣun àwòrán, Facebook/Abubakar Aminu Ibrahim
Lai Mohammed on banditry: Kìí ṣe pé ìjọba ń fi ọwọ́ jẹ́jẹ́ mú àwọn jàndùkú
Oríṣun àwòrán, @thebridgenewsng
Ijọba àpapọ̀ ti ni bi oko ọrọ ṣe ń wá níbi lọhun pé ìjọba ń tẹ ẹ jẹjẹ ninu bi wọn ṣe  ń koju awọn janduku ko boju mu rara o si le ṣi eeyan lọ́nà.
Minisita fún ìròyìn àti àṣà, Lai Mohammed lo fi eyi lede ni ọjọ Isegun nigba to n sọ̀rọ̀ lori eto owuro lori amohunmaworan NTA pé iwa ọ̀daràn ni janduku tí kò si ní nkankan ṣe pẹlu ẹsin.
Lai Mohammed ni ọna ti ijọba àpapọ̀ n  gba gbogun ti awọn janduku apani nipasẹ lilo awọn ológun kii se lati fi iyato tó wà laarin awọn janduku atawọn agbesunmomi hàn rara.
Mo lero pe orúkọ lasan la fi n  ṣe ìyàtọ̀, ọ̀daràn ni ọ̀daràn n jẹ, iru ọwọ kan la si n gbe fi koju wọn.
Lai Mohammed ni eleyi gaan lo mu ki ọrọ táwọn eeyan ń sọ sì ijọba ká wọn lára pe wọn ń dẹ ọwọ bo ba ti kan awọn agbebon yàtọ̀ sí àwọn agbesunmomi.
Irọ patapata gbaa ni eleyi, Iroyin ofege sì ni pẹlu ti awọn alaidaa eeyan kan n gbe kiri.
Lai ni ko tilẹ̀ mú ọgbọn wa ki àwọn ológun maa fi ọwọ ti ko le mu awọn agbebon to jẹ pe wọn ń pa Ọlọpaa àti sọja.
Adepoju Abdulsalamm ẹni ọdun 18 tó n fi kẹ̀kẹ́ dára fi kiri ẹja tó fi n tà wàràwàrà
Ó fi kun un pé àti ori ilẹ̀ àti inú afẹ́fẹ́ ko ni faaye ìyàtọ̀ silẹ nínú bí àwọn ológun ṣe ń koju àwọn agbebon àtàwọn janduku. Lai Mohammed ni pẹlu igbesẹ ti awọn ń gbe lọwọlọwọ, awọn ń borí.
O ni awọn gomina naa ti kọ ẹ̀kọ́ latara ohun to  n sẹlẹ latẹyin wa ti wọn si ti gba pe awọn o ni bá awọn  agbesunmomi duna dura dípò bẹẹ kí wọn gbá tẹle wọn lai da wọn si.
Bákan naa lo ni bibẹgi dina lilo itakun ayélujára àti títa epo ninu kẹẹgi láwọn ìlú tó wà lágbègbè ibodè Naijiria ń so èso rere gidi gan.
"Kódà ó ní to fi mọ òfin ""ẹ má wa kẹkẹ"" láwọn ọjà kan àti fifagile awọn ibùdókọ kan náà ń so èso rere."
Àwọn ọkùnrin tó wà nínú ayé wa gbúdọ̀ bọ̀wọ̀ fún wa - Adarí FIN
Nkechi Blessing sọ̀rọ̀ nípa ikú ìyá rẹ̀, ó tún tú àṣírí kàbìtì nípa ìhùwàsí ara rẹ̀ táyé kò mọ̀
Oríṣun àwòrán, Nkechi Blessing
Gbajugbaja Òṣeré fíìmù Yorùbá yii Nkechi Blessing jẹ oṣere kan ti ẹnu kò ṣi lára rẹ.
Laipẹ yii ni ṣáájú iku iya rẹ àmọ́ pẹlu gbogbo eyi náà Nkechi kọ lati gba ọjẹgẹ, ṣe lo sì ń mókè ninu isẹ rẹ to sì ti di ólórúkọ ńlá laarin awọn akẹgbẹ rẹ bo tilẹ̀ jẹ́ pé ọmọ ẹ̀yà Igbo ni.
Iroyin tilẹ̀ sọ pe ko fi iya rẹ ṣeré rara kódà títí di ìgbà ikú rẹ inú ilé Nkechi lo n gbe.
Adepoju Abdulsalamm ẹni ọdun 18 tó n fi kẹ̀kẹ́ dára fi kiri ẹja tó fi n tà wàràwàrà
Ó fi hànde pé irẹpọ to wa laarin oun ati iya rẹ to bẹẹ to sọ ní gbangba pe iya òun ni igi lẹyin ọgba oun.
Nkechi sọ nigba kan ri pe bi òun bá padanu ìyá òun nìkan ni ohun tó lè mú òun sọkún lai tilẹ̀ mọ pe ọlọ́jọ́ ti ń kan ilẹkun.
Afi tí iku sì de ni ọjọ kẹtalelogun oṣù Kẹ̀sán ọdun 2021 tí màmá Gloria Obasi Sunday ti wọn n pe ni Mummy Nkechi dagbere faye.
"Ẹni ọdun méjìlélógún ni mi mo dẹ sì ń gbé pẹlu ìyá mi. Torí tìrẹ gan ni mí ó ṣe tíì kò lọ bá ọkọ mi, mo sunmọ ìyá mi gidi gan mi ò sì lè fi silẹ. Kí n tó fún ẹ ní mílíọ̀nù kan, máa tí fún ìyá mi ni mílíọ̀nù marun-un.
Africa Eye wádii àwọn tó wà nídìí ìgbésùmọ̀mí ni Mozambique
Nkechi sọ lẹyin iku iya rẹ pé kani àwọn dókítà béèrè owó láti doola ẹ̀mí rẹ, òun a bẹ gbogbo ayé láti ran òun lọwọ."
"Nkechi ni inu rirun lásán ni ìyá òun ni ó ṣe òun. ""Nkan to gbẹ̀yìn ti mo gbọ́ nìyẹn o""."
Nkechi sọ pupọ nípa ìyá rẹ àti bó ṣe fi igboya tọ ọ dàgbà.
Àwọn ọkùnrin tó wà nínú ayé wa gbúdọ̀ bọ̀wọ̀ fún wa - Adarí FIN
"Nkechi ni òun ó lè fi gbigbajumo bọ ẹbi oun. ""Ẹ gba gbigbajumo yín kẹẹ fi ẹbi mi silẹ."
"Mi ò lè jẹ akuṣẹ Òṣeré láyé. Mo fẹ́ kí n lè tọ́ka si ọkọ kan pé owó isẹ mi ni mo fi raa""."
Ọ̀ṣọ́ Aṣọ Òkè ti kọjá lílo ìlẹ̀kẹ̀ níkan
Nkechi ni awọn osere akẹgbẹ awọn elédè gẹ̀ẹ́sì ń pá owó gidi gan àti pé oogun wọn ni wọn ń lọ tẹẹ  bá rí wọn tí wọ́n ń ra gbogbo nkan.
Nkechi jẹ ko di mimọ pe àwọn eeyan ńlá ńlá lo ko owo sínú fíìmù gẹgẹ bii onigbọwọ.
Ebun Oloyede Olaiya Igwe sọ ohun tí ojú rẹ̀ rí lásìkò àìsàn kídìnrín tó yọ ọ́ lẹ́nu
Ó fi wọn we fiimu Yoruba to ni eeyan kan lè dédé yà wọle kò dẹ máa kopa ninu ere.
"Mo leè sọ awọn eeyan fún yín nínú fíìmù Gẹ̀ẹ́sì tí wọn kò gbé ère ara wọn jáde ri ti wọn si n kore owó gidi gan. Oludokoowo láwọn to n ṣe fíìmù Gẹ̀ẹ́sì torinaa ni wọn ṣe ń kore owó gidi gan.
Nínú iforowanilenuwo kan tó ṣe ló ti sọ̀rọ̀ nípa ìdí tó fi dá sí ọrọ Baba Ijesa èyí tó mú ki wọn dáa dúró laarin awọn osere TAMPAN.
Ó ní òun ó lè sọ pé wọn fipa bá òun lopọ rí àmọ́ ó sún mọ́ ọn.
Pé ẹ lè mi kúrò lagbo TAMPAN gaan tún jẹ́ ọna lati ran mi lọwọ""."
'Ìyà Muinat kú nígbà tó ń mu ọmú lọ́wọ́ ni èmí ìyà-ìyá rẹ̀ ń tọ́jú rẹ̀ kí ògiri kíláàsì tó wó pa á'
"Wọn ní kilode to máa ń jà lórí ayélujára, ó ní ""ẹ o le bu mi ki n dakẹ. ""Ẹ jẹ ki n yà yín lẹ́nu, èmi àti ọkọ mi ò kí n ṣe ọrẹ ara wa lori Instagram."
Ó lè di ọjọ kan ka ni ìjà lórí Whatssap taa tí ń sọ̀rọ̀ lojoojumo kí n dẹ lọ yọ ọ kuro lára àwọn ọrẹ mi lórí Instagram.
Nàìjíríà kàn wà ni, ẹ ò páàsì, ẹ ò féèlì, ẹ ò kúrò ní kíláàsì kan náà - Àwọn ọ̀dọ́
tí àwọn oniroyin ayelujara yóò ti lọ gbé e èyí sì lè tún bá ọ̀pọ̀lọpọ̀ irẹpọ jẹ.
"Nkechi fi kún un pé inú òun dùn pẹlu bí òun ṣe ń ṣe nkan òun fún àpẹrẹ ""mo ṣe ìgbéyàwó kò sì sí ẹni tó mọ sii. Inú mi dùn gidi gan pelu igbe ayé mi mo sì ń ṣe fàájì""."
Ẹni tó bá ni kí n fi iṣẹ́ kòkò mímọ sílẹ̀, mi ò lè fẹ́ẹ láéláé - Adekemi Àgùnbánirọ̀
Sunday Igboho Health Condition: Ààrẹ Talon, a fẹ́ kí ẹ pàṣẹ ìtúsílẹ Igboho kí o ba à lè rí ìtọjú gbà- Koiki
Oríṣun àwòrán, Others
Asiwaju Igbimọ Yoruba lagbaye, Yoruba World Congress,Ọjọgbọn Banji Akintoye ti ni kawọn alatilẹyin idasilẹ Yoruba Nation fọkan balẹ lori idande Sunday Igboho.
Sunday Adeyemo Igboho to jẹ ọkan gbogi ninu awọn to n ja fun ẹtọ Yoruba wa ni ahamọ awọn agbofinro ni orileede Benin.
O ti to ọjọ mẹta to wa nibẹ ti awọn to sunmọ si n paya lori ipo ti alaafia rẹ wa.
Ninu fọnran fidio kan ni alagba Naji Akintoye ti n ba awọn eeyan sọrọ loju opo Instagram pe awọn tawọn jẹ Baba fun Igboho ko da Igboho da bukata ara rẹ ni Benin.
''Awa taa jẹ Baba rẹ, a ko kuro nibi. Laipẹ yi ni ọrọ yoo niyanju''.
Àwọn Òṣèré fíìmù Yorùbá tẹ́ ò ro tó tí jápaa lọ ìlú Òyìnbó rèé
Obìnrin tó bá ń gbé bùkátà kò ní ọkọ kódà kó wà nílé ọkọ - Kemi Afolabi
Facebook ń ṣàkóbá fún ọpọlọ ọmọdé ó sì ń káàrẹ̀ bá ìjọba àwaarawa, àṣírí tú! - Òṣìṣẹ́ iléeṣẹ́ Facebook
Samuel Oluwafemi sọ bí Covid 19 ṣe bí ìdíje oníjó àti eré fún àwọn Odi àti Adití sí rere
Ọjọgbọn Banji Akintoye sọ pe idaduro to n waye ko ṣẹyin bi awọn adajọ orileede Benin ṣe maa n gba isinmi lọdọọdun eyi to fa ti wọn ko fi tete yanju ọrọ Sunday Igboho.
O tẹsiwaju pe lọjọ Iṣẹgun to kọja ni wọn gbe Sunday Igboho lọ si ile ẹjọ lẹyin tawọn adajọ wọle pada sẹnu iṣẹ.
Agbaọjẹ ajafẹtọmọniyan yi dupẹ lọwọ awọn alatilẹyin Igboho to si ni ''asiko ti to ki awa Yoruba kuro ni orileede Naijiria ki a si ni orileede tiwa.''
Oríṣun àwòrán, others
BBC ko ribi fidi ọrọ mulẹ nipa ipo alaafia Sunday Igboho ju nkan ti agbẹnusọ rẹ Olayomi Koiki fi sita ninu atẹjade kan.
Akori atẹjade naa to wa loju opo Instagram rẹ lede Gẹẹsi ati Faranse ni pe Oloye Sunday Igboho nilo itọju kiakia.
Koiki sọ pe awọn fẹ ki aarẹ orileede Benin Patrice Talon lo ipo rẹ lati seto itọju Sunday Igboho nitori ailera rẹ.
Koiki ko sọ ibi to ti fẹ ko gba itọju tabi iru ailera to n ba Sunday Igboho ṣugbọn o ni ko ni da a to ki nkan ṣẹlẹ si Igboho lakata ijọba Benin to wa.
''Aarẹ Talon, ẹ jọwọ ẹ bawa fẹnu si ọrọ ki wọn baa le tu Igboho silẹ nitori ilera rẹ nilo itọju kiakia''
Africa Eye wádii àwọn tó wà nídìí ìgbésùmọ̀mí ni Mozambique
''A mọ pe ẹ lagbara lati ṣe nitori a ko fẹ ki nkankan ṣẹlẹ si lasiko to wa labẹ ahamọ lorileede yin''
Lati ogunjọ oṣu Keje ni Oloye Sunday Adeyemo Igboho ti wa ni ahamọ lorileede Benin.
Ebun Oloyede Olaiya Igwe sọ ohun tí ojú rẹ̀ rí lásìkò àìsàn kídìnrín tó yọ ọ́ lẹ́nu
Suspected Kidnappers: Ọwọ ọlọ́pàá tẹ afurasí ajínigbé tó máa n dibọn bí dírẹ́bà láti jí àwọn arìnrìnàjò gbé
Oríṣun àwòrán, Nigeria Police
Ileeṣẹ ọlọpaa lorileede Naijiria sọ pe ọwọ awọn ti tẹ awọn afurasi ajinigbe ogun to n da omi alaafia ilu ru lagbegbe iwọ oorun ariwa Naijiria.
Alukoro ọlọpaa Sunday Mba to fi ọrọ yi sita ninu atẹjade kan sọ pe awọn ti ọwọ tẹ jẹ ọmọ ikọ ajinigbe meji ọtọọtọ to n ji awọn eeyan gbe loju ọna marosẹ.
Mba sọ pe ibọn atamatase mọkanla ati ado oloro aṣekupani mọkanla lawọn ri gba lọwọ awọn afurasi yi.
Gẹgẹ bi atẹjade to fi sita ti ṣe sọ, ogunagbongbo inu awọn afurasi yi a maa dibọn bi awakọ lati le fi ji awọn eeyan to ba wọ ọkọ rẹ gbe.
Wọn ni bo ba ti gbe awọn ero tan, yoo ta awọn akẹgbẹ rẹ lolobo ti wọn yoo si da awọn eeyan naa lọna.
Bi wọn ṣe n gba owo lọwọ awọn ti wọn ji gbe, bẹẹ naa ni wọn a tun maa pa awọn mi ninu awọn to ba ko si wọn lọwọ.
Oríṣun àwòrán, Nigeria Police
Yatọ si awọn ajinigbe wọn yi, alukoro ọlọpaa sọ pe awọn tu mu ikọ awn to n ji ọkọ gbe ti wọn a si tun maa ṣe fayawọ ọkọ.
Ọkọ mẹẹdogun ni wọn ri gba pada lọwọ wọn ti a si gbọ pe wọn a maa gbe ọkọ ti wọn ba jigbe lọ si orileede Niger lati lọ ta a nibẹ.
Samuel Oluwafemi sọ bí Covid 19 ṣe bí ìdíje oníjó àti eré fún àwọn Odi àti Adití sí rere
Etche local Council fracas: Kà nípa ohun tó ṣẹlẹ̀ táwọn jàǹdùkú fi fa aṣọ ya mọ́ káńsẹ́lọ̀ obìnrin lára
Oríṣun àwòrán, Cynthia Nwala
Ọrọ ti di gbọnmi si omi o to laarin obinrin aṣofin kan nile aṣofin ijọba ibilẹ Etche ni Rivers ati alaga kansuu ijọba ibilẹ naa.
Ko si syin bi arabinrin Cynthia Nwala ṣe fẹsun kan alaga kansuu na pe o ni ki awọn janduku fa aṣọ rẹ ya ti wọn si ba ọkọ rẹ jẹ.
Babanbari ọrọ yi ni bi aworan kansẹlọ ti wọn fa aṣọ rẹ ya yi,arabinrin Cynthia Nwala ṣe gba oju opo ayelujara kan.
Ninu aworan naa niṣe ni aṣọ rẹ ya ti ara rẹ si  han sita.Bẹẹ naa ni a ri aworan ọkọ kan ti wọn fọ gilasi rẹ.
Arabinrin Cynthia Nwala to jẹ olori ọmọ ile  aṣofin ni Etche sọ pe alaga kansuu Chinedu Onyeche lo ran adari eto aabo rẹ CSO lati da sẹria fun oun.
Ṣé ìwọ mọ̀ pé Olodumare lè lo Aje láti gbé ẹ lọ síbi ire?- Abiodun Fatomilola
Ninu alaye rẹ to ṣe fawọn akọroyin, o ni nitori ti oun fẹ gbe ọpa aṣẹ ile kuro ni wọn fi fa aṣọ oun ya ti wọn si ba ọkọ oun jẹ.
O ni atunṣe n lọ lọwọ ni ile aṣofin nitori naa loun fi gbe ọpa aṣẹ ki nkan ma baa ṣe ọpa naa.
Samuel Oluwafemi sọ bí Covid 19 ṣe bí ìdíje oníjó àti eré fún àwọn Odi àti Adití sí rere
Iṣẹlẹ yi ti mu iriwisi ọtọọtọ wa ṣugbọn alaga kansuu ti wọn fẹsun kan pe o ni ki awọn janduku lu Cynthia,Chinedu Onyeche sọ pe irọ ni Cynthia pa mọ oun.
Agbẹnusọ alaga yi Oluo Anyimachukwu to fi ọrọ lede loju opo Facebook rẹ ni alaga ko ran eeyan kankan lati ya aṣọ Cynthia tabi ki wọn ba ọkọ rẹ jẹ.
O ni adari eto aabo CSO alaga kii ṣe ọmọ ile igbimọ aṣofin tori naa ko le da si ọrọ to n lọ laarin awọn aṣofin.
Adepoju Abdulsalamm ẹni ọdun 18 tó n fi kẹ̀kẹ́ dára fi kiri ẹja tó fi n tà wàràwàrà
Atẹjade to fi sita ni yatọ si ohun to sọ fawọn akọroyin''Cynthia lo  ko awọn ọlọpaa ati janduku ogun wa lati wa fi ipa gbe ọpa aṣẹ kuro nile''
O ni igbe gbajare ti awọn aṣofin ke lo mu ki CSO wa lati wa daabo bo awọn ọmọ ile aṣofin lọwọ Cynthia ati awọn janduku to ko lọwọ.
Adeyemi Olubunmi Crown: Láti ìgbà ti mo ti fún ọkọ mi ni ẹ̀bùn mọ́tò ni ìfẹ́ wa ti yàtọ̀
Lori ọrọ yi, awọn ikọ ajafẹtọmniyan obinrin ni ilu Port Harcourt ti ṣe iwọde lọ si ọfisi Gomina ipinlẹ naa.
Wọn ni awọn fẹ ki Gomina wa wọrọkọ fi ṣada lori bawọn eeyan ṣe n ṣe ikọlu sawọn obinrin lọna ti ko bofin mu.
Ẹni tó bá ni kí n fi iṣẹ́ kòkò mímọ sílẹ̀, mi ò lè fẹ́ẹ láéláé - Adekemi Àgùnbánirọ̀
N6.25trn deficit: Àwọn onímọ̀ ètò ọrọ̀ ajé ní kí ilé aṣòfin takò owóyàá tí ìjọba fẹ fí ṣètò ìṣúná ọdún 2022
Oríṣun àwòrán, @BashirAhmad
Ẹgbẹ awọn to n pese oun elo,Manufacturers Association of Nigeria, ati awọn onimọ eto ọrọ aje ti n sọ ero ọkan wọn nipa gbese ti ijọba fẹ gba lati le ṣeto isuna ọdun 2022.
Lara awọn to tako igbesẹ yi to ba ileeṣẹ iroyin Naijiria Punch sọrọ la ti ri gbajugbaja onimọ eto ọrọ aje,Pat Utomi.
Ninu ifọrọwanilẹnuwo ti wọn ṣe pẹlu awọn akọroyin Naijiria, wọn ni ki ile aṣofin Naijiria tete kesi aarẹ Buhari ko tọwọ ọmọ bọ aṣọ lori ẹyawo to n gbero lati fi ṣeto iṣuna.
Wọn ni bi ko ba ṣe bẹ, o ṣeeṣe ki o sọ ọjọ iwaju Naijria sinu ewu nla.
Lọjọru ni ijọba Naijiria sọ erongba rẹ lati ya owo ti yoo fi ṣeto isuna N16.45tn lọdun 2022.
Gẹgẹ bi ijọba ti ṣe sọ, apapọ owo ti wọn ya ko ti ju ida mejilelogun ninu ida ọgọrun owo  ọja ati nkan ti wọn ba pese ni Naijiria lọdun naa.
Minisita feto isuna Zainab Ahmed ni o di dandan kawọn maa ya owo lati fi pese ohun amayedẹrun nitori owo to n wọle fun ijọba ko to.
O ni ''bi a ba gbẹkẹle owo to n wọle nikan,bo tilẹjẹ wi pe owo to n wọle n lekun,owo ina ijọba n lekun si ni to fi mọ owo oṣu oṣiṣẹ''.
Adeyemi Olubunmi Crown: Láti ìgbà ti mo ti fún ọkọ mi ni ẹ̀bùn mọ́tò ni ìfẹ́ wa ti yàtọ̀
''Owo gbese ti Naijiria n ya jẹ ohun to n kan awọn eeyan lominu. ṣugbọn bi a ba ṣafiwe iye ti Naijria n ya, ko ti kọja agbara''
Amọ kii ṣe bayi lawọn onimọ bi Pat Utomi tiṣe ri ọrọ yi si.
Ebun Oloyede Olaiya Igwe sọ ohun tí ojú rẹ̀ rí lásìkò àìsàn kídìnrín tó yọ ọ́ lẹ́nu
Utomi to fi igba kan dije ipo aarẹ Naijiria sọ pe ọwọngogo nkan le ma jẹ ki iyatọ kankan wa ti owo isuna ba lekun si.
O ṣalaye pe nkan ti o yẹ ki ijọba ṣe ni ki wọn diowo ina ku ki wọn si wo awọn ọna miran lati fi pa owo wọle si yatọ si eleyi to wa nilẹ.
Ọ̀ṣọ́ Aṣọ Òkè ti kọjá lílo ìlẹ̀kẹ̀ níkan
Ninu alaye ti rẹ, ọjọgbọn Fasiti Olabisi Onabanjo nipa eto ọrọ aje,Sheriffdeen Tella ni ''O yẹ ki ile aṣofin foju sunukun wo alaye ti ijọba gbe kalẹ''
O ni gbese yi ti pọju to si tunmọ si pe ''wọn yoo tẹsiwaju lati maa ya owo si ni.Nkan to ṣe pataki ni ki a mọ bi isuna ti owa nile ba ti ṣe n ṣe si.A le maa le ribi ṣeto isuna yi bo ṣe yẹ''
Samuel Oluwafemi sọ bí Covid 19 ṣe bí ìdíje oníjó àti eré fún àwọn Odi àti Adití sí rere
Ẹwẹ,onimọ mii, Bongo Adi  sọ pe iye owo ti ijọba n pa wọle labẹle ṣi kere ati pe ko si iyipada kankan to lamilaka nipa owo ori ti wọn n ri gba.
Lakotan ẹgbẹ awọn to n pese nkan ilo,MAN sọ pe owo isuna N6.25trn  ti ijọba n gbero yi n kan awọn lominu.
Adepoju Abdulsalamm ẹni ọdun 18 tó n fi kẹ̀kẹ́ dára fi kiri ẹja tó fi n tà wàràwàrà
Ọga agba ẹgbẹ yi Segun Ajayi Kadri ni ''gbese owo taa ya ti wọ wa lọrun,ki a tun fi owo gbese ṣeto owo isuna yo tun da kun wahala to wa nilẹ ni''
O ni gbese kii ṣe nkan to buru ṣugbọn ki wn lo owo naa si ipese ohun amayedẹrun ati igbega eto ọrọ aje ni eyi to ṣoro lati ṣe.
Africa Eye wádii àwọn tó wà nídìí ìgbésùmọ̀mí ni Mozambique
Segun ni ọrọ ku si ọdọ ile aṣofin lati boya wn yoo buwọlu owo ti ijọba fẹ ya yi abi wọn yoo tako.
O rọ awọn aṣofin lati daabo bo ọjọ iwaju orileede Naijiria nitori ojuṣe wọn nilati ṣe agbeyẹwo nkan ti wọn fẹ fi ẹyawo yi ṣe.
Weird places and animals: Ẹ wo Ajá tó ń gbọ́ òórùn àìsàn ibà, ẹja tí a ko gbọdọ̀ pa àti ọọọ̀nì tó ń gbọ́ àdúrà ní Ìbàdàn
Airijinna lai ri abuke ọkẹrẹ ni Yoruba a maa sọ.
Bi eeyan ba de igbo to to igbo, yoo ri ẹranko to n tiro.
Nkan aramọnda orisi ni oju ti ri lẹnu igba ti awa naa ti n gbe ile aiye.
Laipẹ yi ni a ri iroyin to ja ranyin kaakiri pe igi kan to wo pa awọn eeyan ti o wu nidi ti tun sọji dide pada.
Awọn nkan wọn yi jẹ ohun to ṣe ni leemọ ti ọpọ ko si ribi ṣe alaye ohun to le fa iru iṣẹlẹ naa.
BBC ṣe akojọpọ awọn nkan awamaridi paapa to ni ṣe pẹlu ẹranko to wa layika wa.
Die ree ninu wọn:
Ilu Aawẹ nipinlẹ Oyo ni Guusu Naijiria ni adagun odo Sogidi wa nibi ti  awọn eeyan ko ti gbọdọ pa ẹja to wa ninu rẹ.
Awọn ẹja yi  ti wa ninu odo naa lati dun 1750.
Sogidi Lake: Kòṣẹja-kòṣèèyàn lá bá nínú adágún odò náà -Ojedele
Ẹja wọnyi yi kii ṣe ẹja lasan, ko ṣẹja ko ṣe eeyan ni wọn.
Orisi ẹja ati eewọ lo rọ mọ awọn ẹja to wa ninu odo yi ti awọn to n ṣamojuto odo naa si sọ fun BBC ohun toju awọn to ja ẹja ri .
Adeyemi Olubunmi Crown: Láti ìgbà ti mo ti fún ọkọ mi ni ẹ̀bùn mọ́tò ni ìfẹ́ wa ti yàtọ̀
Alaye ti a gbọ lati ẹnu Oloye Raufu Yesufu to jẹ mọgaji ile Delesolu ti wọn ti n sin ọọni yi ni Ibadan ni pe igbẹ ọọni yi ti di oogun ara lile fawọn eeyan kan.
O ṣe ẹyin naa ni kayeefi abi?
Ọdún 1940 ni wọ́n ti ń sin ọ̀ọ̀nì ilé Delesolu ní Ìbàdàn
Bẹẹ lo ṣe ri fun ọpọ eeyan to ba ṣalabapade ọọni yi ti babanla awọn to n sin bẹrẹ si ni tọju rẹ lati ọdun 1940 ninu ile.
Loju awọn ọmọ inu ile Delesolu, aṣa ni kii ṣe ẹsin rara toripe wọn gba pe ko si awo kan lawo ẹwa lori ọọni naa.
Adepoju Abdulsalamm ẹni ọdun 18 tó n fi kẹ̀kẹ́ dára fi kiri ẹja tó fi n tà wàràwàrà
Bi a ba ni ki a fi ti imọ ọde oni wo, ko yẹ ki ijapa Ogbomoso to ti wa pada jade laye pẹ to bo ti ṣe p to laye ki o to pada  ku.
Ogbologbo ijapa l'aafin Sọun
Baba Kabiyesi oni to jẹ Jagunjagun lo pade rẹ leti igbo to si mu  wale latoju ogun.
Alagba ni orukọ rẹ, o ni awọn oṣiṣẹ lati aafin Kabiyesi to n tọju oun nikan.
Ebun Oloyede Olaiya Igwe sọ ohun tí ojú rẹ̀ rí lásìkò àìsàn kídìnrín tó yọ ọ́ lẹ́nu
Oṣiṣẹ meji tabi ju bẹẹ́ lọ lo n tọju oun nikan nigba to wa laye.Koda,lati kekere ni awọn kan ti n tọju rẹ ti wọn si dagba sẹnu ẹ.
Gbogbo ounjẹ ti eniyan n jẹ loun naa n jẹ to fi mọ eso bii Ọpẹ Oyinbo, Ibẹpẹ,Ọgẹdẹ. bakan naa, o n jẹ Amala, Irẹsi, Dodo ati Ẹwa ati bẹẹ bẹẹ lọ.
Africa Eye wádii àwọn tó wà nídìí ìgbésùmọ̀mí ni Mozambique
Kayeefi eleyi jẹyọ latara iwadii kan ti awọn onimọ sayẹnsi ṣe to fi han pe awọn aja le gboorun aisan iba lara eeyan.
Ojọgbọn Steve Lindsay ti fasiti Durham ni ilẹ̀ United Kingdom, lo ṣe agabtẹru iwadii naa nibi ti wọn ti lo ìbọ̀sẹ̀ àwọn ọmọde mẹta lati orilẹ-ede Gambia.
O fidi ẹ mulẹ pe bi ẹfọn to n fa àìsaǹ ibà ṣe maa n gboorun naa ni o ti han pe àwọn ajá naa n gboorun.
Ọjọgbọn Steve fidi ẹ mulẹ pe kẹmikaa kan maa n jade lára ẹni to ba ni aisan ibà ni eyi ti awọn ajá naa le gbọ oorun rẹ lara eniyan.
Ìbọ̀sẹ̀ àwọn ọdọmọde naa ni wọn lò fun iwadii yii ni eyi ti àwọn aja naa gba meje ninu mẹwaa dàadáa.
Samuel Oluwafemi sọ bí Covid 19 ṣe bí ìdíje oníjó àti eré fún àwọn Odi àti Adití sí rere
Ti awọn ẹranko la sọ tan yi, ẹ jẹ ki a wo awọn aaye aramọnda ti awọn eeyan agbegbe ibi ti wọn wa maa n foju abami wo wọn.
Ilu ikọgọsi Ekiti lo gbajugbaja, to si tun jẹ ibudo igbafẹ nitori omi odo kan to nmu omi gbigbona ati tutu jade.
Wo itan omi gbigbona ati tutu ni Ikọgosi Ekiti
Gẹgẹbi ẹnikan to sọrọ nipa odo naa ti wi, tiyale-tiyawo (Awọ ati Awẹle) ni wọn di omi Ikọgọsi.
O ni awọn eeyan maa nwa lati origun mẹrẹẹrin agbaye ni ojoojumọ lati bu omi Ikọgọsi fun iwosan.
Squash: Dele Oladejo ní iṣẹ́ ńlá ni eré ìdárayá Squash, olówó àti akọni ẹ̀dá ló ń gbá a
Yatọ si Colorado ni orileede Amẹrika, ilu Ado Awaye ni ipinlẹ Oyo ni adagun omi ori apata tun wa lagbaye.
Ko kun ri ko lọ ilẹ si toun ti bi ojo ba ṣe le rọ to,Ado awaye jẹ ibudo ti ọpọ eeyan maa n ṣe eemọ ti wọn ba de ibẹ.
Colorado ni Amẹrika àti odò Awaye ní Naijiria nikeji àdágún órí àpáta ní gbogbo àgbáyé!
Ogbeni Ayo Adams to jẹ alakoso irinajo afẹ́ nibẹ ṣalaye fun BBC Yoruba ni kikun lori odo adagun naa.
O ni awọn kan ti wọn ko sinu odo naa ko pada jade bẹẹ nigba ti wọn sọ okuta sinu odo adagun ọhun, ìlú jinjin si Oyo ni wọn ti lọ ri awọn nkan naa.
Ẹni tó bá ni kí n fi iṣẹ́ kòkò mímọ sílẹ̀, mi ò lè fẹ́ẹ láéláé - Adekemi Àgùnbánirọ̀
Chiwetalu Agu arrested by Army: Kí ni òṣèré yìí ṣe tí àwọn ológun gbé e jàǹtò? Ẹṣẹ tí wọn kà síi lọrùn rèé
Oríṣun àwòrán, Nigerian Army
Gbajugbaja oṣerekunrin, Chiwetalu Agu ti gbominira lẹyin ti awọn sọja mu u lọjọ Ọjọbọ, ọjọ keje, oṣu Kẹwaa.
"Akẹẹgbẹ rẹ, Destiny Etiko lo fi iroyin naa sita loju opo Instagram rẹ pe ""Wọn ti tu Uncle Chiwetalu Agu silẹ...Ọlọrun o ṣeun."""
Oṣerebinrin miran, Chizzy Alichi naa fidirẹmulẹ pe wọn ti tu u silẹ, to si wa ni alaafia.
Ṣugbọn, ileeṣẹ ologun ko ti i fi ikede sita boya wọn ti tu u silẹ.
Ileeṣẹ ologun orilẹede Naijiria ti sọ pe lootọ ni awọn fi ọwọ ofin mu gbajugbaja oṣere Chiwetalu Agu.
Ṣé ìwọ mọ̀ pé Olodumare lè lo Aje láti gbé ẹ lọ síbi ire?- Abiodun Fatomilola
Gẹgẹ bi atẹjade ti awọn ologun fi sita lati olu ileeṣẹ wọn, wọn muu toripe wọn ni o n ko awọn ọmọ kgbẹ to n ja fun idasilẹ orilẹede Biafra (IPOB) jẹ to si n ṣe atilẹyin fun wọn.
Wọn fi kun un pe awọn gba oṣere naa mu nigba to wọ aṣọ ti wọn ran pẹlu awọ asia ẹgbẹ Biafra, wọn si gbee lati fi ọrọ waa lẹnu wo.
Ẹni tó bá ni kí n fi iṣẹ́ kòkò mímọ sílẹ̀, mi ò lè fẹ́ẹ láéláé - Adekemi Àgùnbánirọ̀
Bo tilẹ jẹ pe wọn ni o n kọjalẹ ko fẹ fi wọn fi ọwọ ipa mu oun, ṣe ni wọn gbee janto lọ si atimọle wọ amọ wọn ni awọn ko fiya kankan jẹẹ.
Bakan na ninu atẹjade awọn ologun, wọn ni awọn bọwọ fun ẹtọ awọn araalu gẹgẹ bo Se wa ninu ofin ilẹ Naijiria bẹẹ naa si ni awọn koro oju si ki ẹnikẹni tẹ ẹtọ eeyan loju mọlẹ tabi ko ẹgbẹ jọ lati ru ofin.
Eleyi waye gẹgẹ bi fidio kan ṣe jade nibi ti awọn ọkunrin kan to wọ aṣọ ologun da gbajugbaja oṣere naa, Chiwetalu Agu duro ni Onitsha, ipinlẹ Anambra.
Nigba naa ni iroyin bẹrẹ si ni tan ka pe awọn ologun ti gbe oṣere naa.
Oríṣun àwòrán, Nigerian Army
Ninu fidio naa, awọn ologun kan da bọọsi kan ti wọn kọ Chukwuetalu films si lara wọn si wọ oṣere naa bọlẹ titi ti ero fi tu jade afigba ti iro ibọn le wọn sa lọ.
Loṣu to kọja ni ọrọ Agu gba ori ayelujara kan tori pe o wọ aṣọ kan ti wọn fi asia Biafra ran.
Oríṣun àwòrán, Nigerian Army
Chiwetalu Agu to jẹ gbajugbaja ni ọpọlọpọ mọ si Ichie Ogwu, eekan si ni lagbo oṣere Nollywood to tun jẹ adẹrinpoṣonu.
Oṣere naa jẹ ọmọ ilu Enugu ni iha Guusu-Ila Oorun to si ti bẹrẹ ere sinima tipẹ tipẹ ki Nollywood tilẹ to bẹrẹ.
Samuel Oluwafemi sọ bí Covid 19 ṣe bí ìdíje oníjó àti eré fún àwọn Odi àti Adití sí rere
O ti kopa ninu ọpọlọpọ fiimu bii Taboo, Wedding Party apa keji.
Agu gbajumọ gidi gan fun awada ṣiṣe pẹlu awan oriṣiriṣi ọrọ ẹna to maa n ti ẹnu rẹ jade eyi to mu ki gbogbo ẹya fẹran lati maa wo ere rẹ gan to fi mọ ẹya Yoruba.
Adepoju Abdulsalamm ẹni ọdun 18 tó n fi kẹ̀kẹ́ dára fi kiri ẹja tó fi n tà wàràwàrà
Ọpọlọpọ yoo tun ranti rẹ daadaa fun ipa oloye tabi baale ile to buru tabi to maa n ṣe ika ninu sinima.
Ebun Oloyede Olaiya Igwe sọ ohun tí ojú rẹ̀ rí lásìkò àìsàn kídìnrín tó yọ ọ́ lẹ́nu
Zamfara Kidnap: Koríko láwọn tí orí kó yọ lọ́wọ́ ajínigbe jẹ fún ọjọ́ tí wọ́n fí wà ní àhámọ́
Oríṣun àwòrán, Zamfara State Police
Ileeṣẹ ọlọpaa nipinlẹ Zamfara ti doola ẹmi awọn eeyan mẹtadinlaadọwa lati ọwọ awọn ajinigbe.
Ọjọ mejilelaadọta ni wọn lo ni akasọ awọn alaburu yi ki ori to ko wọn yọ.
Alukoro ọlọpaa Mohammed Shehu to kede itusilẹ wọn sọ pe awọn ti ko awọn eeyan wọnyi le awọn alaṣẹ ipinlẹ lọwọ.
Ko sọ pato boya wọn san owo idoola amọ o ni nigba tawọn agbofinro n para inu igbo Tsibiri lawọn ri awọn eeyan wọn yi.
Ninu aworan ti o gba ori ayelujara kan, niṣe ni awọn ti wọn doola yi dabi ẹni ti ebi n pa ti ko si ni alaafia to.
Ọkan ninu awọn to moribọ yi to ba ileeṣẹ iwe iroyin Naijiria Punch sọrọ ni oju awọn ri to lasiko tawọn fi wa ni ahamọ.
Arabinrin naa ti orukọ rẹ n jẹ Iklima Murtala sọ pe awọn janduku to ji awọn gbe ko fun awọn lounjẹ jẹ.
Adeyemi Olubunmi Crown: Láti ìgbà ti mo ti fún ọkọ mi ni ẹ̀bùn mọ́tò ni ìfẹ́ wa ti yàtọ̀
''Nigba ti wọn gbe wa de ibi ti wọn ko wa si, lẹyin ọjọ diẹ ti wọn fi fun wa lounjẹ niṣe ni wọn kọ lati fun wa lounjẹ lẹyin igba naa''
'A ko ri nkankan ṣe ju pe ki a wa koriko to ba ṣe jẹ lagbegbe naa ki a si maa jẹ ki ẹmi ma ba bọ mọwa lọwọ''
Ṣé ìwọ mọ̀ pé Olodumare lè lo Aje láti gbé ẹ lọ síbi ire?- Abiodun Fatomilola
O ṣalaye pe eeyan mẹtadinlogun lebi lu pa ninu awọn ti wọn ji gbe.Koda o ni eeyan meji mii ku nigba ti wọn gbe awọn pada de Gusau.
Africa Eye wádii àwọn tó wà nídìí ìgbésùmọ̀mí ni Mozambique
Laipẹ yi ni awọn alaṣẹ ni ipinlẹ Zamfara ati Kaduna ti oju opo ikansiraẹni lori foonu lọna ati koju ipenija awọn ajinigbe ati janduku.
Ebun Oloyede Olaiya Igwe sọ ohun tí ojú rẹ̀ rí lásìkò àìsàn kídìnrín tó yọ ọ́ lẹ́nu
Ijọba ni ababọ igbesẹ yi ni awọn eeyan ti awọn ribi doola yi to fi mọ awọn ajinigbe mii ti ọwọ awọn ti tẹ.
Senato Francis Fadahunsi sọ ohun tó ń ṣẹlẹ̀ lórí kíkó ẹ̀rù wọlé láti ẹnubodè Nàìjíríà báyìí
Lai jẹ́ pe wọ́n yọ ologun to n dari ileeṣẹ aṣọbode ki wọn si fi ẹni to kọṣẹmọṣẹ sii, nkan ko le rọgbọ- Senato Fadahunsi Francis.
Senatọ Francis Adenigba Fadahunsi to n ṣoju ẹkun Ilesa nile igbimọ asofin agba ni Abuja ba BBC Yoruba sọrọ lori ipo ti ile iṣẹ aṣobode Naijiria wa lasiko yii.
O mẹnuba ohun ti o le ṣo gẹgẹ bi ẹni to ti ṣe iṣẹ aṣọbode fun ọpọlọpọ ọdun pẹlu iriri, o sọ nipa ọna abayọ si iṣoro ibẹ gẹgẹ bii alaga igbimọ to n ri si ọrọ ẹnubode Naijiria nile igbimọ Asofin.
Fadahunsi ni ọwọ iyawo awọn aṣọbode ko mọ nipa kiko ẹru wọle lati ilẹ okeere.
Koda, o ni kii ṣe bi wọn ṣe kọ wọn ni won n ṣiṣẹ mọ.
Wo ohun tó yẹ kí ará ìlú ṣe tí 'Custom' bá ṣèṣì pa wọ́n- Senatọ Fadahunsi
Nigba ti BBC kan si ileeṣẹ aṣọbode Naijiria lati fesi si awọn ẹsun yii, wọn ni wọn maa ṣe iwadii ki wọn si kan si BBC pada.
Sugbon titi di asiko yii, ileeṣẹ aṣọbode Naijiria ko tii kan si BBC pada.
Catholic Seminary Attack: Ọkadà ní agbébọn gùn wọ iléẹ̀kọ́ Àgùdà láti jí èèyàn gbé
Oríṣun àwòrán, ICIRNigeria
O kere tan awọn agbebọn ti ji awọn akẹkọọ mẹta gbe lọ ni ileẹkọ imọ ijọ ''Catholic'' ni ipinlẹ Kaduna.
Ileeṣẹ ọlọpaa to fi idi iṣẹlẹ naa mulẹ ni awọn agbebọn naa wa ni ọgọọrọ wọn si ileẹkọ ''Catholic Seminary'' ti wọn si ji awọn akẹkọọ gbe, ti awọn miran si farapa.
Ọlọpaa naa ni awọn agbebọn naa lo ọkada lati fi wọ ileẹkọ ''Saint Albert Seminary'' ni agbegbe Kagoma, ti wọn si ṣina bolẹ, ti wọn si salọ.
Ileeṣẹ ọlọpaa naa ni awọn ti wọn farapa naa ti wa ni ileewosan, ti wọn si ti bẹrẹ si ni wa awọn agbebọn naa.
Lara awọn akẹkọọ ti iṣẹlẹ naa ṣoju wọn ni awọn ko le e sọ ni pato iye akẹkọọ ti awọn agbebon jigbe lọ.
Awọn ti iṣẹlẹ naa ṣoju wọn ni ibọn alagbara ni awọn agbebọn da bolẹ lasiko ti awọn akẹkọọ naa ṣẹṣẹ pari adura irọlẹ tan ni ṣọọṣi to wa ni ileẹkọ naa.
Latifat Tijani: Ìjọba Naijiria ń ṣèlérí láti mọ́ rírì mi àmọ́ láti 2016, pàbó ló ń já sí
Wẹrẹ ti awọn akẹkọọ bẹrẹ si ni gbọ iro ibọn bayii ni wọn fi ẹsẹ fẹ, ti olukaluku si bẹrẹ si ni sa asala fun ẹmi wọn.
''Awọn ti ori ko yọ nikan ni wọn jajabọ lọwọ awọn ajinigbe naa, ti wọn si ko awọn akẹkọọ ti a ko tii le sọ iye wọn. ''
Wọn kesi ijọba lati wa wọrọkọ fi ṣe ada lori ijinigbe ojoojumọ ni awọn ileẹkọ to wa ni ariwa orilẹede Naijiria, ki wọn le doola ẹmi awọn eniyan.
O kere tan akẹkọọ to le ni ẹgbẹrun ni awọn ajinigbe ti jigbe lọ ni ileẹkọ girama ati fasiti, bẹrẹ lati Oṣu Kejila, ọdun to kọja.
Ọpọlọpọ awọn agbebọn yii ni wọn n bere fun owo ẹmi awọn ti wọn ba jigbe, ki wọn to doola ẹmi wọn.
Ileeṣẹ ọmọogun orilẹede Naijiria ni awọn ti ran ikọ ọmọogun ni ẹgbẹgbẹrun wọn lọ si awọn agbegbe yii.
Africa Eye wádii àwọn tó wà nídìí ìgbésùmọ̀mí ni Mozambique
Bakan naa ni wọn pa awọn ẹrọ ayelujara ati ẹrọ ibanisọrọ ni awọn agbegbe wonyii, ki ọwọ le tete tẹ awọn ajinigbe to n da ẹmi awọn eniyan legbodo ni ojoojumọ.
Amo gbogbo igbiyanju yii pabo lo jasi, nitori awọn agbebọn yii ṣi n ṣọṣẹ ni gbogbo igba, ti wọn si n fi ẹmi awọn akẹkọọ ati olukọ ṣofo, to fi mọ awọn araalu.
Oríṣun àwòrán, others
Wọn ti gba awọn obinrin ni imọran pe ki wọn o má fún awọn ọkunrin ni ibalopọ, ti wọn ba fi kọ lati gba abẹrẹ ajẹsara Covid-19.
Eyi ko sẹyin bi ọpọ eeyan ko fẹ ẹ gba abẹrẹ naa kaakiri agbaye.
Ni orilẹ-ede South Africa, imọran ti wọn gba awọn obinrin naa di dandan paapaa bi awọn ọkunrin ni Eastern Cape ṣe kọ ẹyin si abẹrẹ naa.
Gẹgẹ bi iroyin ti Daily Maverick gbe jade l'oṣu Kẹsàn-án, oludari ajọ to n mojuto eto ilera ni agbegbe naa, Nomakhosazana Meth lo fi ikede naa sita.
O ni imọran naa wulo, paapaa fun awọn obinrin ti ko ti i ṣe igbeyawo.
Akomolede ati Asa: Ọ̀rọ̀ Asopò ni á ń gbéyẹ̀wò pẹ̀lú Arabìnrin Tope Atoyebi láti Ilorin
"Eyi yoo si daabo bo ""ẹyin mejeeji""."
Obìnrin lo pọ ju ninu awọn to ti gba abẹrẹ.
Eeyan to le ni miliọnu kan lo si ti gba abẹrẹ ajẹsara Covid-19 ni agbegbe Eastern Cape, bo tilẹ jẹ pe miliọnu mẹrin aabọ ni afojusun awọn alasẹ, ti yoo ba fi di oṣu Kẹrin, ọdun to n bọ.
Ooni Ogunwusi: Ẹ sinmi àdíjàlẹ̀ ìròyìn, Adeleke kò ní òun yóò ra bàálù fún mi
Oríṣun àwòrán, Ooni Of Ife
Ooni tilu Ile Ife, Ọba Adeyeye Enitan Ogunwusi ti pariwo fun araye pe irọ to jinna sootọ ni ahesọ ọrọ kan to n ja rain pe Sẹnetọ Ademola Adeleke seleri lati ra baalu fun oun.
Atẹjade kan ti akọwe feto iroyin si Ooni, Moses Olafare fisita lo sisọ loju ọrọ yii fawọn akọroyin.
Atẹjade naa salaye pe ofuutu fẹẹtẹ, aasa ti ko ni kaun lasan ni iroyin naa to jade sita lasiko ti oludije fun ipo gomina laẹ ẹgbẹ oselu PDP nipinlẹ Osun, Ademola Adeleke wa se aago laafin si Ooni.
Iroyin eke naa ni lasiko yii ni Adeleke seleri pe oun yoo ra baalu fun Ooni Ogunwusi lati maa fi se ẹsẹ rin.
Amọ atẹjade naa ti wa sẹ lori ọrọ ọhun, to si salaye pe aafin Ooni kọ lo fi atẹjade sita nipa ọrọ naa, gẹgẹ bi awọn ileesẹ iroyin kan ti polongo rẹ.
Oríṣun àwòrán, Ooni Of Ife
"Se ni awọn akọroyin kan to fẹ ta ẹrẹ si asọ aala oloselu naa, to si tun fẹ wọ Ooni nilẹ, se magomago iroyin naa, ti wọn si kọ ohun ti ko ri bẹẹ.
Yoo si dara ti ẹni ti ọrọ yii ba ru loju wa wo fidio abẹwo Adeleke si aafin Ooni fun aridaju ọrọ to sọ ati esi ti Ooni fọ pada fun."
Atẹjade naa ni pato ohun ti Ooni sọ fun agba oselu naa ni pe ki wọn ri daju pe eto idibo gomina to n bọ ko lọwọ laasigbo ninu, eyi ti oloselu naa fara mọ.
Gẹgẹ bi Olafare ti salaye, Adeleke seleri lati se atunse oju ọna Ile Ife ati akọpari papakọ ofurufu to wa nilu Ido-Osun sugbọn awọn akọroyin alaparutu kẹyin sawọn iroyin gidi yii.
Gẹgẹ ba se mọ pe awọn idile Adeleke ni ọpọ Baalu ni ikawọ wọn, eyi lo mu ki Ademola Adeleke se awada pe Baba, baalu aladani tẹ maa gun gan wa nilẹ.
Ojú mi ti rí lọ́pọ̀ lọpọ̀, àmọ́ mo dúpẹ́ pé mo ti pé ọdún márùn ún lórí oyé- Ooni
"Abẹwo Adeleke kọ ni igba akọkọ tabi ikẹyin ti awọn oloselu yoo wa se abẹwo si Ooni ninu aafin rẹ nibayii ti idibo gomina mii n kanlẹkun, tawọn naa si tun n bọ laipẹ, to fi mọ gomina to wa nipo."""
Atẹjade naa wa n fi ewe ọmọ mọ awọn adijaalẹ akọroyin leti pe ki wọn sọra fun iroyin eke, to si tun n rọ awọn araalu lati mase gba iroyin eke naa gbọ nitori ọrun apoaadi lo ti wa.
Yoruba VOR: A kò fẹ́ ìwé òfin ọdún 1999 mọ́, òhun ló fi àwọn èèyàn wa sínú ìṣẹ́
Oríṣun àwòrán, Ilana Omo Oodua Worldwide TV
Ẹgbẹ awọn ọmọ Yoruba kan, Voice of Reason Advocacy for Social Development Foundation, VOR, ti bẹrẹ itaniji lawọn igberiko lọna ati mu ki awọn ọmọ Yoruba ṣatilẹyin fun bi ijọba apapọ yoo ṣe pa iwe ofin ọdun 1999 ti, ti yoo si pe fun idibo lati mọ ero araalu lori ọjọ ọla Naijiria.
Lara awọn eeyan jankan to wa ninu ẹgbẹ naa ni awọn ọmọwe, awọn agbagba, onimọ eto ilera, onimọ nipa eto iṣiro, awọn akọroyin, awọn onimọ ẹrọ ati bẹẹ bẹẹ lọ.
Ẹgbẹ naa ni afojusun awọn ni lati jẹ ki araalu mọ ewu to wa ninu ofin ọdun 1999 naa, ati pe iwe ofin ọhun lo fa bi idagbasoke ṣe ku diẹ kaato nilẹ kaarọ oojire.
Lara awọn ọna lati jẹ ki awọn eeyan mọ afojusun wọn, ẹgbẹ naa ti bẹrẹ ipolongo lawọn ori redio kan niluu Ibadan.
Ninu atẹjade ti aṣoju ẹgbẹ ọhun, Dokita Seyi Roberts fi lede, o ni ẹgbẹ naa ti fi ara wọn jin lati ri daju pe awọn eeyan ilu mọ bo ṣe n lọ ninu igbiyanju awọn lati gba ẹtọ ilẹ Yoruba pada.
"O ni ""A oo bẹrẹ pẹlu fifa iwe ofin magomago ti ọdun 1999 ti awọn ologun gbe le wa lọwọ ya, eyii to fi awọn eeyan wa sinu oṣi, iya ati iyanjẹ."""
Sen Francis Fadahunsi sọ ohun tó ń ṣẹlẹ̀ lórí kíkó ẹ̀rù wọlé láti ẹnubodè Nàìjíríà báyìí
Yatọ si awọn ipolongo ori redio ti wọn n ṣe, VOR tun sọ pe awọn ti ri awọn patako ajuwe si awọn agbegbe kan to ṣe pataki niluu Ibadan, eyii ti wọn fi n ke si awọn araau lati ṣagbatẹru bi wọn yoo ṣe fa iwe ofin naa ya.
Ọkan lara awọn patako ajuwe naa ni wọn ri mọ opopona Eko si Ibadan lagbegbe Guru Maraji.
Bẹẹ naa ni wọn ri awọn mii si ọna Iwo Road niwaju ile ẹkọ giga Premier University niluu Ibadan yii kan naa.
Ẹwẹ, VOR kọ ni ẹgbẹ akọkọ ti yoo sọ pe ayederu ni iwe ofin ọdun 1999, ti wọn si sọ pe ki ijọba fa iwe ofin naa ya ko si pe ipade apero laarin awọn ẹya ni Naijiria tabi ki olukuluku maa lọ nilọ tirẹ.
Bí Oduduwa Republic bá bẹ̀rẹ̀, a ò ní ṣe aburú fún àwọn tó takò wá, ìlànà ààtẹ̀lé rèé - Banji Akintoye
Tunde Bakare: Bí ọ̀pọ̀ ẹ̀yà ṣe ń lọgun láti kúrò ní Nàíjíríà fihàn pé a nílò àtúntò
Oríṣun àwòrán, Presidency
Adari ijọ ati pasitọ agba ijọ, Citadel Global Church, Pasitọ Tunde Bakare ti kesi Aarẹ Buhari lati fagile iwe ofin ọdun 1999 nitori ohun lo n ṣokunfa ifaṣẹyin fun Naijiria.
Bakare sọ eyi lasiko isin ni ile ijọsin rẹ to pe akori iwaasun ọhun ni ''Bi o ṣe n lọ lorilẹede Naijiria'', ''The state of the Nation''.
Isin naa waye ni gbagede ile ijọsin rẹ to wa ni olu ile ijọsin naa ni ipinlẹ Eko.
Pasitọ Bakare ni awọn idojuko to n ba orilẹede Naijiria finra ko ṣẹyin eto oṣelu to mẹhẹ lati ibẹrẹ wa, eleyii ti awọn ijọba ologun doju rẹ bolẹ nigba ti wọn gbakoso iṣejọba Naijiria.
Bakare ni ija ẹlẹyamẹya, ẹlẹsin mẹsin to fi mọ awọn ẹkun to n lọgun pe wọn fẹ kuro lorilẹede Naijiria, eleyii ti ko yọ ẹkun kankan silẹ, fihan pe Naijiria nilo atunto.
Tunde Bakare: Àjọjẹ kò dún bẹ́nìkan kò ní ló fa ìjà S Igboho,bẹ́ẹ̀ ìjọbati gbẹ́rù kọjá orí
Gẹgẹ bi ọrọ rẹ, ohun to ṣe pataki kọ ni ibi ti aarẹ orilẹede yoo ti wa, to ba jẹ pe orilẹede Naijiria duro ire.
''O dami loju pe iwe ofin ọdun 1999 ko so eso rere kankan fun Naijiria, iku lo mu wa fun orilẹede yii.''
Bakan naa lo kesi aarẹ Buhari lati ṣe ojuṣe rẹ ki o si ye e gbe iṣẹ fun Ile Igbimọ Aṣofin ti Naijiria.
''Aarẹ Buhari, ya iwe ofin ọdun 1999 ko si ṣe atuntọ ati  atunṣe orilẹede Naijiria pada.''
''Aibikita ni ki awọn kan ma a lọgun idibo gbogboogbo ọdun 2023 lai kọkọ wa wọrọkọ fi ṣe ada lori ọrọ atunto orilẹede Naijiria.
Olota Of Ota: N kò fara mọ́ ìyapa Nàíjíríà, ìṣèjọba ẹlẹ́kùnjẹkùn ní ọ̀nà àbáyọ
Pasito Tunde Bakare wa kilọ fun aarẹ Buhari pe ti ko ba tun orilẹede Naijiria to, akọsilẹ yoo wa wi pe o kuna gẹgẹ bi aarẹ nigba to wa ni ipo.
Bakare to jẹ amofin ati agbẹjoro naa ti fi igba kan dije dupo igbakeji aarẹ pẹlu aarẹ Buhari ni idibo si ipo aarẹ ni ọdun 2011.
Oríṣun àwòrán, The Presidency
Aarẹ tẹlẹ fun orilẹede Naijiria, Oloye Olusegun Obasanjo ti rọ awọn ọmọ Naijiria lati mase sọ ireti nu nipa orilẹede yii.
Obasanjo ni ẹpọn agbo kan n mi lasan ni, ko ni ja nitori awọn isoro to n ba Naijiria finra ko kuku ni gbe mi.
Oloye Obasanjo fi ọwọ idaniloju yii sọya lasiko to n sọrọ nibi eto kan to waye pẹlu ilẹ Amẹrika nile iyawe-kawe rẹ nilu Abeokuta.
Nigba to n sọrọ apilẹkọ nibi eto naa, Obasanjo ni mimi kankan ko mi igbagbọ ti oun ni nipa orilẹede yii pe ọjọ ọla yoo dara, ti ilẹ yii yoo si duro re.
Obasanjo, ẹni ti igbakeji alakoso ile iyawe-kawe rẹ, Kayode Aderinwale soju fun fikun pe isoro yowu ti kii ba maa koju Naijiria lọwọ kii se isoro ikọlu bikose isoro ipadasẹyin.
Igbagbọ mi ninu Naijiria ko yinjẹ, ireti mi nipa ọjọ ọla si le koko, bi o tilẹ jẹ pe ọpọ lo n kọminu nipa baa se doola ọjọ ọla wa.
Aremu: Eré ìtàn nípa ìbí, àti jéèyàn pẹ̀lú ìpèníjà Olusegun Aremu Obasanjo
"Mo ri ireti ninu ipinnu ọkan, itiraka ati iwa aikaibọnu awọn ọmọ Naijiria, mo si ri ireti ninu atako wọn nigba ti wọn ba sun wọn kan ogiri.
Mo ri ireti ninu ilakaka, ifọkansin ati igboya lasiko ti iyapa ba n koju wọn, mo si tun ri ireti nipa ọpọ ipinnu ọkan awọn ọdọ Naijiria lati se rere.
Mo tun ri ireti ninu bawọn ọdọ ati agbaagba ọmọ Naijiria se n fi gbogbo agbara wọn tako iwa ibi to n gbinlẹ lorilẹede yii.
Lakotan, mo tun ri ireti ninu ihuwasi ati igbesẹ awọn ọmọ Naijiria lati beere fun isejọba alagbada pẹlu ọgbọn atinuda wọn nipa orilẹede yii."
Olusegun Obasanjo ni ireti tun wa fun oun pe ọjọ ọla Naijiria yoo dara, ta ba wo iyapa ati ojulowo asa wa laarin iran ọmọniyan.
Olusegun Obasanjo: Ọmú ìyá mi ti mo fi ń mùkọ ni kekere ló jẹ ki ń lókun
Fuel Crisis and Strike: Ẹgbẹ́ àwọn awakọ̀ àtẹgbẹ́ òǹtàjà epo aládani wọ́gilé ìyanṣẹlódì tó yẹ kó bẹ̀rẹ̀ lónìí
Oríṣun àwòrán, PA Media
Ẹgbẹ awọn awakọ epo pẹtirolu PTD awọn alagbata epo aladani atawọn alagbata epo to da duro ti kede pe awọn ti wọgile iyanṣelodi wọn to yẹ ko bẹrẹ lonii kaakiri ilẹ Yoruba.
Igbesẹ yii ni abọ ipade ti wọn ṣe pẹlu awọn adari ajọ NNPC niluu Ibadan lọjọ Aiku.
Wọn tun sọ pe awọn yoo ṣe ipade mii lọla ọjọ kejila, oṣu Kẹwaa niluu Abuja lati mọ igbesẹ ti awọn yoo gbe.
Ninu atẹjade kan ti akọwe apapọ ẹgbẹ naa, Afolabi Akporeha fi lede, o ni wọn wọgile iyanṣelodi ọhun nitori igbagbọ awọn pe ijọba apapọ yoo mu ileri rẹ ṣẹ lẹyin ti awọn ṣepade niluu Ibadan, ati lẹyin ipade ti yoo waye niluu Abuja lọjọ Isegun.
Olota Of Ota: N kò fara mọ́ ìyapa Nàíjíríà, ìṣèjọba ẹlẹ́kùnjẹkùn ní ọ̀nà àbáyọ
Akporeha sọ pe, kii ṣe pe awọn fẹ mọọmọ fiya jẹ awọn araalu pẹlu iyanṣẹlodi ọhun, ṣugbọn awọn n fẹ ki eto abo to peye wa fun awọn oṣiṣẹ ti wọn ba n gbe epo lati ilu kan si omiran loju popo ni.
O ni bo tilẹ jẹ pe igbesẹ awọn yoo ni ipa to lagbara lara awọn ọmọ Naijiria, awọn ko ni la oju awọn silẹ ki ẹka eto epo rọbi dibajẹ.
O wa pari atẹjade ọhun pe awọn ko ni fa ṣẹyin ninu gigunle iyanṣẹlodi naa lakọtun, ti ijọba ko ba ṣe awọn ohun ti wọn n beere fun.
ki lo ti ṣẹlẹ sẹyin?
Ọwọn gogo epo petrirolu n bọ nilẹ Yoruba nibayii ti ẹgbẹ awakọ epo pẹtirolu PTD awọn alagbata epo aladani atawọn alagbata epo to da duro gbe asẹ tuntun sita.
Asẹ naa ni pe ki awọn ọmọ ẹgbẹ wọn dẹkun gbigbe epo eroja epo rọbi lati oni ọjọ ni ẹkun guusu Naijiria.
Igbesẹ naa lo waye lẹyin gbedeke ọjọ mẹta ti awọn ẹgbẹ yii fun ileesẹ to n se akoso eroja epo rọbi PPMC, eyi to wa sopin lọjọ karun osu kẹwa ọdun 2021.
Ajọ PPMC ni wọn fẹsun kan pe o n mu ko nira fun awọn alagbata epo lati ri awọn eroja epo rọbi ra lori atẹ.
Tẹlẹ tẹlẹ, awọn ontaja yii lo ni akọsilẹ katakara epo, ti onikaluku wọn si mọ akọsilẹ igba to yẹ ki ikọọkan wọn gbe epo amọ ti wọn ti sọ di ipinnu lati Abuja bayii.
Sen Francis Fadahunsi sọ ohun tó ń ṣẹlẹ̀ lórí kíkó ẹ̀rù wọlé láti ẹnubodè Nàìjíríà báyìí
Bakan naa ni wọn tun ni ileesẹ to wa fun eto eroja epo rọbi DPR tun se alekun owo isọdọtun iwe asẹ okoowo wọn atawọn owona miran amọ DPR ti yi ohun pada lori igbesẹ yii.
Gẹgẹ bi alaye ti osisẹ alarina fun ajọ IPMAN lẹkun iwọ oorun Naijiria ti wi, ileesẹ PPMC ko tii pahunda lori ipinnu rẹ lati sọ epo dọwọn fun awọn.
O ni idi ree ti awọn ẹgbẹ yii se pinnu lati gunle iyansẹlodi ti wọn kede rẹ bẹrẹ lati oru oni lọ.
"Igbesẹ ijọba yii ti n wọnu ere kekere ta n jẹ tẹlẹ, miliọnu meje ati ẹgbẹrun lọna ẹẹdẹgbẹrin naira (N4.7m) la n gbe ọkọ lita epo ẹgbẹrun lọna mẹtalelọgbọn.
Amọ nibayii, Abuja ni ajọ PPMC ti n se akoso awọn ti yoo ri epo ra, ti wọn si tun se alekun iye ontaja epo ti yoo maa ra epo naa ati owo igbepo.
Peter Fatomilola ní àìsí ẹ̀kọ́ ń mú káwọn òṣèré tíátà ó máá ṣe oun tí kò tọ́.
Gbese ti pa ọpọ alagbata epo nitori aitete ri owoya banki da pada, ti ọpọ si n tun epo naa ra lati ọdọ awọn alagbata mii ni owo to wọn.
Ohun ta si mọ ni pa iyansẹlodi nikan ni ede ti ijọba gbọ, a ko si ni yẹsẹ kuro lori ipinnu lati yan isẹ lodi."
Adunni Ade: Kò dára kí ọkùnrin máa fi ‘Microphone’ sí ara obìnrin lásìkò eré tíátà
Oríṣun àwòrán, iamadunniade/Instagram
Gbajugbaja oṣere tiata Yoruba, Adunni Ade ti ko aroye bẹnu lori bi amoju ẹrọ agbohunsafẹfẹ kan, se fi ibalopọ lọ oun lasiko ti wọn n ṣe ere sinima kan.
Ẹni ọdun mọkandinlogoji yii ṣalaye ọrọ naa ninu fidio kan to gbe soju opo Instagram rẹ.
Adunni ni ẹni naa, ti ko darukọ rẹ, ta omi oge si oun lara lọna aitọ lasiko to fẹ fi ẹrọamohunbugbẹmu (microphone) si oun lara.
Adunni  Ade fi kun ọrọ  pe, iṣẹlẹ yii lo mu ki oun maṣe faaye gba ẹnikẹni ninu awọn ọkunrin amoju ẹrọ lati fọwọ kan oun mọ.
"O ni ""Mi o ki n faaye gba awọn ọkunrin amoju ẹrọ agbohunsafẹfẹ fọwọ kan mi nitori ọkan ninu wọn lo nawọ ere ifẹ si mi lọna aitọ''"
Ṣé ìwọ mọ̀ pé Olodumare lè lo Aje láti gbé ẹ lọ síbi ire?- Abiodun Fatomilola
Se lo ti ọwọ bọ inu asọ kaba ti mo wọ̀, to si na ọwọ rẹ de ibi ibadi mi lori awijare pe oun fẹ́ fi mic si mi lara.
Eyi mu ki n fẹrẹ daku, ti mo si gan sibẹ, koda, o gba mi ni akoko diẹ ki n to sọrọ sita, mo si n pariwo pe ki lo de se tun fi ọwọ kan mi lẹyin ti mo ti kilọ fun saaju tẹlẹ pe ko mase fi ọwọ kan mi mọ.
"Se ni ara mi n gbọn, ti mo si n pariwo pe iru ẹni bẹẹle fi tipa ba eeyan lopọ nitori pe o fi ọwọ kan mi ni ibi ti ko ba mi lara mu."""
Arẹwa oṣere tiata yii tun ṣalaye pe oun gbiyanju lati fi ọrọ naa to awọn alaṣẹ ẹgbẹ awọn leti ṣugbọn oun yi ipinnu naa pada nigba tawọn eeyan ki ẹbẹ mọlẹ.
"N ṣe ni ẹni taa n wi yii ko agidi bori pe oun ko ṣe nkankan to buru. O fi ọwọ rẹ bọ mi lẹyin nitori pe o ni oun fẹ fi mic si mi lara''
''Ohun ti ko bojumu leyi jẹ fun mi.
Iṣẹlẹ ibalopọ tabi awọn aṣemaṣe miran jẹ eleyi tawọn oṣerebinrin tiata a maa koju nidi iṣẹ wọn."
Adunni Ade ni ọkunrin amojuẹrọ yii ko bẹbẹ tabi tọrọ aforijin lọwọ oun titi di akoko yii ti oun si fi ọrọ naa to agbẹjọro oun leti.
O ni oun ko tii fẹ gbe ọkunrin naa lọ sile ẹjọ bayii amọ to ba tun hu iru iwa yii tabi ta ko ohun lori isẹlẹ yii, oun se tan lati ba fa a gidi.
Adunni ni koda lawọn agbo oṣere tiata to gbajugbaja bi Hollywood, ọpọ awọn obinrin lo ti ke gbajare pe awọn ọkunrin a maa fi ilọkulọ lọ awọn nidi ere tiata.
O salaye pe nilẹ okeere, ko si ọkunrin onimọ ẹrọ ti wọn n gba laaye lati lọ fi ẹrọ amohunbugbẹmu si ara obinrin osere tiata lara lasiko igbaradi fun ere sise.
O wa gba awọn osere tiata atawọn onimọ ẹrọ wọn to n wo ilẹ Amẹrika fun awokọse nimọran pe ki wọn se awokọse ohun to dara lara wọn.
Bakan naa lo tun gba awọ̀n eeyan nimọ̀ran lati maa sọrọ soke nigba ti ohunkohun ko ba tẹ wọn lọrun, wọn ko si gbọdọ dakẹ lasiko ti ẹnikẹni ba se ohunkohun ti ko dara.
Adeyemi Olubunmi Crown: Láti ìgbà ti mo ti fún ọkọ mi ni ẹ̀bùn mọ́tò ni ìfẹ́ wa ti yàtọ̀
Pandora Papers: Oyetola ní òun kọ́ ló bá Tinubu ra ile Diezani tó wà ní London
Oríṣun àwòrán, Nigerian Government
Orin ọwọ mi ma re funfun nẹnẹ ni Gomina  ipinlẹ Osun, Gboyega Oyetola n kọ lori iroyin to gbode pe o wa lara awọn ti wọn fẹsun kan ninu iwe Pandora Papers to jade.
Ninu iwe yii lawọn akọroyin oniwadii ijinlẹ ti tu aṣiri ọna alumọkọrọyi tawọn olori ijọba ati awọn mii fi n ko owo ati ọrọ ilu pamọ lọna aitọ.
Eyi to kan Oyetola ni pe wọn lo ileeṣẹ rẹ kan lati fi ra ile ti ijọba Naijiria fẹ gbẹsẹ le lara dukia Minisita fepo rọbi Naijiria tẹlẹ Diezani Madueke.
Ile ta n wi yii ni agba ọjẹ oṣelu ẹgbẹ APC, Bola Ahmed Tinubu ti n gba alejo awọn eeyan, to fi mọ aarẹ Buhari nilu London.
Ninu atẹjade kan to fi sita lati ọwọ agbẹnusọ rẹ, Ismail Omipidan, Oyetola ni oun ko ṣe aburu kankan tabi ra dukia lorukọ ileeṣẹ kan, ti wọn n pe orukọ rẹ ni Aranda Overseas Corporation.
Oríṣun àwòrán, NAtional Assembly
''A ti ri awọn iroyin to jade lẹnu ọjọ mẹta yii lori iwe Pandora to jade eyi to mu ki a fẹ sọ oju abẹ niko''
O ṣe lalaye pe, lọdun 2011 ti oun lọ darapọ mọ oṣelu loun ti fi ipo oludari ileeṣẹ naa silẹ to fi mọ ipin idokowo ti oun ni ninu rẹ.
Omipidan ni ''Oyetola ko ni nkankan ṣe pẹlu ile ti wọn ni o ra yii tabi arakunrin Aluko to ni debi pe yoo tiẹ ni ajọṣepọ kankan pẹlu rẹ''
''Lati 2011 titi di wakati yii ti Oyetola ti n ba ijọba ṣiṣẹ gẹgẹ bi olori oṣiṣẹ ijọba ni o ti lajọṣepọ pẹlu ileeṣẹ Global Investment Offshore, ko si le ra ile taa n wi yi tabi ko ni ki eeyan ba oun ra gẹgẹ bi ẹsun ti wọn fi kan an''
Omipidan tẹsiwaju pe Ọlọrun to gbe awọn de ibi tawọn de yii, ko ni da awọn da bukata awọn.
Ile ti ọrọ da lori yii ni iwe Pandora tọka si pe agba ọjẹ oloṣelu ẹgbẹ APC nni, Bola Ahmed Tinubu ra lọwọ Aluko, tii se alabaṣe minisita feto ọrọ epo rọbi tẹlẹ, Diezani Madueke.
Oríṣun àwòrán, Ismail Omipidan Facebook
Olota Of Ota: N kò fara mọ́ ìyapa Nàíjíríà, ìṣèjọba ẹlẹ́kùnjẹkùn ní ọ̀nà àbáyọ
Olota tilu Ota, Ọba Adeyemi Obalanlege ti ke si ijọba apapọ lati fori jin Oloye Sunday Igboho to wa ni ahamọ ni Cotonou.
Oriade naa ni ko si iru ẹsẹ yowu ti Igboho ko baa sẹ, ọmọ awọn ni awọn ko si le ta nu, amọ oun n rawọ ẹbẹ sijọba lati fi ori jin.
Ọba Olota rawọ ẹbẹ bẹẹ lasiko ifọrọwerọ rẹ pẹlu BBC Yoruba lori awọn ohun to n lọ nilẹ Yoruba ati Naijiria lapapọ.
Oriade naa ni ohun ko ni sọ boya ohun ti Igboho se dara tabi ko dara amọ ki ijọba fori jin lo se koko.
Nigba to n sọrọ lori iwa ipa tawọn afurasi Fulani kan n lo, Olota ni nibayii ti ofin ma da ẹran jẹko laarin ilu ti wa, ojuse awọn agbofinro ni lati ri pe ofin naa mulẹ.
O fikun pe alejo kọọkan nilẹ Yoruba lo gbọdọ tẹle ofin wa, eyikeyi ninu wọn ti ko ba si le bọwọ fun ofin ta ba fi lelẹ lọdọ wa, ni ko pada silu rẹ.
Lori ero awọn eeyan kan to n pe fun atunto Naijiria, oriade naa ni oun fara mọ isejọba ẹlẹkunjẹkun ta ti se ri, eyi to gbe wa pupọ.
O ni ilana isejọba naa lo mu kawọn ara ilu tubọ sun mọ ijọba lẹsẹkuku amọ ba se tẹwọgba ilana isejọba tilẹ Amẹrika yii lo ko wahala de, tawọn ijọba si jinna pupọ si araalu.
Ọba Obalanlege wa kede pe oun ko fara mọ iyapa Naijiria rara nitori agbara wa ninu ajọsepọ wa, sugbọn isejọba ẹlẹkunjẹkun labẹ ẹya kọọkan nikan ni ọna abayọ si isoro Naijiria.
Sunday Igboho: Gani Adams ní ìjìjàgbara Yoruba Nation kò le di àpatì, àwọn kò ní dákẹ́
Oríṣun àwòrán, NewsDay Nigeria
Aarẹ Ona kakanfo ilẹ Yoruba, Iba Gani Adams ti ki Oloye Sunday Igboho ku oriire ayẹyẹ ọdun kọkandinlaadọta rẹ loke eepẹ.
Ọjọ kẹwaa, oṣu Kẹwaa, ọdun 1972 ni wọn bi Sunday Igboho, to si jẹ ọmọ ilu Igboho, ni ijọba ibilẹ Oorelope, nipinlẹ Oyo.
Adams wa rọ awọn gomina mẹfẹfa to wa nilẹ Yoruba lati duro le ijọba apapọ lọrun ko le fi Igboho lọrun silẹ ninu ọgba ẹwọn to wa lorilẹ-ede Benin.
Aarẹ Gani Adams lo fi ọrọ naa lede ninu atẹjada kan loju opo Instagram rẹ, eyii ti agbẹnusọ rẹ, Kehinde Aderemi buwọlu.
Iba tun ke si ijọba ilẹ Benin lati tu Igboho silẹ ninu ọgba ẹwọn naa to wa lai fọta pe.
Atunto Naijiria la n fẹ - Aarẹ Onakakanfo, Gani Adams
O ni bayii ajigbara naa ti pe ẹni ọdun mọkandinlaadọta, eyii tumọ si pe kii ṣe ọmọde mọ, ọna kan ṣoṣo ti awọn eeyan si le gba mọ riri iṣẹ Ọlọrun ninu aye rẹ ni ko maa ja fun ẹtọ araalu bo ṣe n ṣe tẹlẹ.
Gẹgẹ bii ohun to sọ, nibi ti ọrọ Naijiria de duro bayii, ijijagbara Yoruba Nation ko le di apati, awọn to si n pe fun idasilẹ orilẹ-ede tuntun naa ko ni dakẹ titi di igba ti wọn yoo jajabọ lọwọ ijọba aninilara.
"Aarẹ sọ pe ""Boya Sunday Igboho wa laarin wa ni o tabi o wa ni Benin Republic, igbagbọ temi ni pe ojuṣe gbogbo wa ni lati ba ṣe ajọyọ ayẹyẹ ọjọ ibi rẹ."""
Sunday Igboho fulani ultimatum: Àwọn ará Kebbi àti Zamfara ló n jínígbé ní Oke Ogun- Serik
Ijijagbara fun ominira Yoruba ko le ku lailai, ko sì sí bi ijọba apapọ ṣe le dukoko mọ wa to a ko ni boju wẹyin ninu ojusẹ wa titi ti a fi maa gba ominira ilẹ Yoruba.
Nitori naa, mo wa fi akoko yii rọ gbogbo awọn gomina mẹfa to wa nilẹ Yoruba lati gbogun ti ijọba apapọ ko tu Sunday Igboho silẹ, ohun kan ṣoṣo ti wọn le ṣe ree pẹlu ipo wọn lati fi han pe ojulowo ọmọ kaarọ oojire niwọn jẹ.
Gani Adams ni oun naa ti fi awọn akoko kan ṣe ọjọ ibi oun ninu ahamọ ri, Eledumare nikan ni oun si gbojule lakoko naa ti oun si gbagbọ pe ni igbẹyingbẹyin, ododo ni yoo bori eke.
O pari ọrọ rẹ pe bo tilẹ jẹ Igboho n koju irufẹ nnkan ti oun ti fi awọn akoko kan koju ri, yoo gba itusilẹ laipẹ bi oun naa ṣe gab itusilẹ.
Olota Of Ota: N kò fara mọ́ ìyapa Nàíjíríà, ìṣèjọba ẹlẹ́kùnjẹkùn ní ọ̀nà àbáyọ
Whale Vomit: Akúṣẹ́ apẹja bọ́ sínú agbami ọrọ̀ lẹ́yìn tó rí èébì ẹja Wéèlì tówó rẹ̀ tó $1.2 milíọ̀nù he létíkun
Ti a ba n gba adura si Eleduwa pe ‘mu mi ṣe kongẹ oore lẹnu iṣẹ mi’, a fi ka yara ṣe amin adura naa ni kia.
Idi ni pe adura yii ti gba fun arakunrin apẹja kan to ko oore ẹgbẹlẹgbẹ dọla owo ilẹ Amẹrika lẹnu iṣẹ ẹja pipa.
Apẹja ni arakunrin Narong Phetcharaj lorilẹede Thailand, ki ori to gbe e ko ire nigba to ri eebi ẹja abubutan Weeli, ti iye rẹ to miliọnu kan ati ẹgbẹrun lọna igba dọla owo ilẹ Amẹrika he, leti okun Niyom,
Iroyin sọ pe, ṣaaju, oju to n pọn igún apẹja yii kii ṣe kekere nitori iṣoro nla ni ọrọ jijẹ mimu fun oun atawọn ẹbi rẹ.
Lẹyin to ri eebi ẹja Weeli naa he tan lo ba fi lọ awọn akọṣẹmọṣẹ ni ileewe fasiti Prince of Songla University.
Olota Of Ota: N kò fara mọ́ ìyapa Nàíjíríà, ìṣèjọba ẹlẹ́kùnjẹkùn ní ọ̀nà àbáyọ
Awọn ni wọn ṣe iwadi ti wọn si ri aridaju pe ambergris, iyẹn eebi latẹnu ẹja Weeli ni eroja naa, to si jẹ wi pe ohun ni wọn fi n ṣe ororo itura oloorun didun pafuumu olowo iyebiye.
"Kini ọhun to le bi okuta, eyi ti ọpọ n da pe ni ""goolu to n lefo loju omi"" ni wọn ni iye rẹ to ẹgbẹrun marundinlogoji ni iwọn kilo kan."
Iwọn ọgbọn kilo eebi ẹja abubuutan Weeli naa ni apẹja yii ri leti okun, ti ireti si wa pe yoo lanfani ati taa lowo ti yoo to ẹgbẹlẹgbẹ miliọnu dọla owo ilẹ Amẹrika.
"Ẹya ẹja Weeli ti wọn n pe ni ""Sperm Whales"" lo maa n pọ eebi yii; bi eebi yii ṣe tobi to si tun wuwo to, ori omi lo maa n lefoo si, tabi ki ọwọ iji omi o gba a wa si etikun."
Bi eebi yii ba ti wa gbẹ tan ni yoo wa di ohun oloorun didun eleyi ti awọn onimọ sọ pe awọn akọṣẹmọṣẹ n wa kiri.
Adepoju Abdulsalamm ẹni ọdun 18 tó n fi kẹ̀kẹ́ dára fi kiri ẹja tó fi n tà wàràwàrà
Saaju ni ọdun yii, awọn apẹja kan naa ṣe kongẹ eebi ẹja abubutan Weeli yii ni erekuṣu Aden nitosi agbami Yemen. Nigba ti wọn la gogongo ẹja naa, ni wọn ri kini nla naa to le kokoko, to hun jọ si ọna ọfun rẹ.
Si iyalẹnu wọn, miliọnu kan o le ọgọrun ẹgbẹrun dọla ni wọn taa ti wọn si pin owo naa laarin ara wọn ti wọn si tun pin lara rẹ fun awọn to ku diẹ kaato fun ni ileto wọn.
Gẹgẹ bi iwadi ijinlẹ latọdọ awọn akọṣẹmọṣẹ ṣe sọ, inu ifun iwọn ida kan si marun un awọn ẹya ẹja Weeli ti wọn n pe ni Sperm Whales yii ni o ti maa n jade.
"Ọkan lara awọn apẹja naa ṣalaye fun BBC pe, ""A pinnu lati fi iwọ mu ẹja Weeli naa, a gbe e wa si eti okun nibi ti a ti gee lati mọ nnkan to wa ninu rẹ. Ki n ma tan yin, eebi ẹja yii lo wa ninu rẹ."""
"O fi kun un pe, ""oorun rẹ ko dara rara, ṣugbọn owo gọbọi lo ba de."""
Ebun Oloyede Olaiya Igwe sọ ohun tí ojú rẹ̀ rí lásìkò àìsàn kídìnrín tó yọ ọ́ lẹ́nu
President Buhari on Lagos/ Ibadan expressway: Ààrẹ Buhari ni ọdún 2023 ni iṣẹ́ yóò parí lórí òpópónà Eko si Ibadan
Oríṣun àwòrán, Tolani Alli
Aarẹ Mohammadu Buhari ti orilẹede Naijiria ti ṣalaye igba ti atunṣe opopona marosẹ Eko si Ibadan to nlọ lọwọ yoo pari.
O ti to ọdun diẹ bayii ti iṣẹ atunṣe ti bẹrẹ lori opopona marosẹ ọlọgọfa kilomita naa ṣugbọn ti ko tii pari.
Aarẹ Buhari ṣalaye nibi ipade apero ayẹwo ibi ti iṣẹ de duro fawọn minisita nilu Abuja pe eto iṣuna idagbasoke ohun amayedẹrun ti aarẹ gbe kalẹ ni wọn yoo fi yanju rẹ.
O ni lasiko iṣejọba oun ni wọn yoo pari rẹ lọdun 2023.
Bakan naa lo sọ pe iṣejọba oun yoo tun pari afara keji lori odo Ọya ti wọn n pe ni Second Niger bridge pẹlu ki iṣejọba oun to kuro lọdun 2023 pẹlu.
Olota Of Ota: N kò fara mọ́ ìyapa Nàíjíríà, ìṣèjọba ẹlẹ́kùnjẹkùn ní ọ̀nà àbáyọ
Opopona maroṣẹ naa ati ipo to wa jẹ eyi to ks ọpọlọpọ ọmọ Naijiria lominu ki wọn to bẹrẹ atunṣe rẹ eyi to ti n fẹrẹ kọja ida aadọta bayii.
Opopona ọhun lọpọ gba pe o jẹ opopona ti awọn ọkọ n rin ju lorilẹede Naijiria.
Kwara Brutal Flogging: Ilé àṣòfin kéde òfin tí yóò dènà ìfìyàjẹni lọ́nà àìtọ́
Oríṣun àwòrán, Screen Shot
Ile Igbimọ Aṣofin ni ipinlẹ Kwara ti rọ ijọba lati bẹrẹ igbesẹ lori ofin to de ifiyajẹni lọna aitọ nipinlẹ naa.
Eyi ko ṣẹyin iṣẹlẹ to waye ni ileẹkọ Madrasah Arabic School nibi ti adari ileẹkọ naa ti paṣẹ pe ki wọn na awọn akẹkọọ ni nitori wọn lọ si ile ijo lo ṣe ariya.
Fidio to ja ranyin lori ẹrọ ayelujara safihan bi awọn akẹkọọ ọkunrin marun un ṣe n na awọn akẹkọọ obinrin pẹlu aṣẹ adari ileẹkọ.
Ọmọ Ile Aṣofin ipinlẹ Kwara, Adetiba Olanrewaju (Oke- Ero) ni ihuwasi adari olukọ ileẹkọ naa ko ba ofin mu , to si bu ẹnu atẹ lu iṣẹlẹ naa to waye ni agbegbe Ganmo, ni ijọba ibilẹ Ifẹlodun, ni ipinlẹ naa.
Ile igbimọ aṣofin naa rọ ijọba lati kesi awọn ti ọrọ naa kan ki wọn fi ijiya to tọ jẹ ẹnikẹni tabi ileeṣẹ to ba n ṣe iru tabi hu iru iwa bẹẹ ni ipinlẹ Kwara.
Adejoke Ewaede: Ìfẹ́ àṣà Yorùbá ló mú kí ń pinnu láti máa wọ aṣọ àdìrẹ̀ nìkan
Bakan naa ni wọn rọ ijọba lati bẹrẹ ilanilọyẹ nipa lilo ẹrọ ayeluyara ati awọn ọna ibanisọrọ miran lati fi to awọn araalu leti, ni gbogbo ede ti wọn gbọ, lori ofin to de iwa ipa ni ipinlẹ naa.
Ile Aṣofin naa gboriyin fun gomina Abdulrahman Abdulrazaq lori igbeṣẹ to gbe ni kiakia nipa iṣẹlẹ to waye ni ileẹkọ naa.
Gomina Abdulrazaq gbe igbimọ ẹlẹni-mẹwaa dide lati ṣewadii iṣẹlẹ naa ati ohun ti o ṣokunfa rẹ.
Nibayii, wọn ti ni ki adari ileẹkọ Madrasah Arabic School naa lọ rọkun ni ile fun igba diẹ titi iwadii yoo fi pari lori iṣẹlẹ naa.
Oríṣun àwòrán, Screen Shot
Ilé iṣẹ́ ọlọ́pàá ni ìpínlẹ̀ Kwara ni ìwádìí ìṣẹ̀lẹ̀ tó wáyé nílé Kewu kan tí bẹ̀rẹ̀ ni pẹrẹwu bí àwọn se ń fi ọ̀rọ̀ wá adarí ilé Kewu Misbaudeen Al Islamiy lẹ́nu wò fún bí ó ṣe pa á láṣẹ kí wọ́n lu àwọn akẹ́kọ̀ọ́ márùn-ún pé wọ́n lọ ilé ijó.
Ajayi Okasanmi tó jẹ́ agbẹnuso ọlọ́pàá ìpínlẹ̀ Kwara lo fìdí ọ̀rọ̀ náà múlẹ̀ lọ́jọ́ Ajé.
"Bí mo ṣe ń sọ̀rọ̀ lọ́wọ́lọ́wó yìí, wọn ń ṣe Ìfọ̀rọ̀wanilenuwo fún adarí ilé Kewu náà, bákan náà ni ìwádìí ọlọ́pàá ti bẹ̀rẹ̀ lórí ọ̀rọ̀ náà.
Ó Kún pé adarí ilé Kewu náà tí gba ìwé gbélé ẹ títí òpin ìwádìí ọlọ́pàá. Ẹ̀wẹ̀, ilé iṣẹ́ ọlọ́pàá ni àwọn kò fi adarí ilé ẹ̀kọ́ náà sí àtìmọ́lé.
Làsìkò tó ń fèsì lórí ìṣẹ̀lẹ̀ náà, Kọmísọ́nà ètò ẹ̀kọ́ ni ìpínlẹ̀ Kwara Sa'adatu Modibbo Kawu sọ pé ilé iṣẹ́ òun ti ṣe àgbékalẹ̀ ìgbìmọ̀ tí yóò ṣe ìwádìí ìṣẹ̀lẹ̀ náà
Latifat Tijani: Ìjọba Naijiria ń ṣèlérí láti mọ́ rírì mi àmọ́ láti 2016, pàbó ló ń já sí
Kawu sọ pé olórí ilé Kewu náà tó sọ pé òun ló pa á láṣẹ pé dá sẹ̀ríà fún àwọn ọmọ náà tí wà nílé náà títí gbogbo ìwádìí yóò fi parí.
Ìjọba ti ko àwọn ọmọ náà lọ sí ilé ìwòsàn bákan náà fún àyẹ̀wò àti ìtọ́jú tó péye. Èyí ni láti rí i dájú pé kò sí ẹni tí o farapa tàbí tí ọ̀rọ̀ náà yóò máa dàmú ọpọlọ rẹ"" gẹ́gẹ́ bí Kawu ṣe sọ"
Àwọn onímọ̀ Islamu mìíràn tó bá BBC sọ̀rọ̀ ti fi èrò kan náà hàn ní orí ọ̀rọ̀ náà
Sheik Sayyid Musa Aloba láti ìlú Ilorin nípìnlẹ̀ Kwara ṣàlàyé pé kò bá ojú mú kí olùkọ́ tàbí ẹnikẹni lu akẹ́kọ̀ọ́ bẹ́ẹ̀
"Gbajúgbajà ónímọ̀ fi kún pé ""gbogbo ilé ẹ̀kọ́ yala tí ẹṣin tàbí tí ìgbàlódé náà ni máa ń bá ọmọ wí tí wọ́n bá ṣẹ̀"
Ṣùgbọ́n kìí ṣe bí ti kí gbogbo ènìyàn pé lè enikan lórí kí wọn wá máa lù ú
Ṣùgbọ́n tí ẹ̀sẹ̀ tí akẹ́kọ̀ọ́ náà ṣe bá pọ̀jù ó yẹ kí wọn fi tó àwọn aláṣẹ tó bá yẹ létí kí wọ́n sì tọ ọna tó yẹ.
Dókítà Jabir Sani Maihula is tó jẹ́ olórí ẹ̀ka ẹ̀kọ́ èdè Arabu àti ẹ̀sìn Islamu ni Fáṣítì ìpínlẹ̀ Sokoto ṣàlàyé pé ẹ̀sẹ̀ tó níṣe pẹ̀lú ọtí mímú kii se fún àwọn tó kii se alaṣẹ láti dá.
Olota Of Ota: N kò fara mọ́ ìyapa Nàíjíríà, ìṣèjọba ẹlẹ́kùnjẹkùn ní ọ̀nà àbáyọ
Ó ní èyí ni ìlànà tó yẹ kí wọ́n gbé gbà adájọ́ kóòtù Sẹ̀ríà nìkan sì ló lè da
Onímọ̀ yìí fi kún pé bótilẹ̀ jẹ́ pé kò sí ibi tó wà nínú kurani pé iye ẹgba báyìí lọ tó sì ẹni náà.
Àwọn ilé ẹ̀kọ́ tó kù náà ni Nàìjíríà máa ń bá ọmọ tó bá ṣẹ̀ wí nípa lílo ẹgba  sugbọn ń iwọntún-wọnsì ni, kò gbọdọ̀ kọjá àfaradà
Àwọn onímò méjèèjì fẹnu kò pé àṣà àwọn ilé ẹ̀kọ́ ni Nàìjíríà ni lati na a ọmọ tó bá ṣe, ṣùgbọ́n kò sí ilé ẹ̀kọ́ tàbí òbí tó ní eto láti lu ọmọ ni ìlùkulù
Nínú fọ́nrán kan tí ó lu orí ayélujára pa lópin ọ̀sẹ̀ ni a ti rí àwọn gende mẹ́rin tí wọ́n de fìlà funfun tí wọ́n sì wọ aṣọ aró, ọmọbìnrin kan kúnlẹ̀ sí àárín wọn tí wọ́n sì ń lù ú lẹ́gbẹ̀ nípa titẹ̀lé àṣẹ adarí ilé Kewu náà.
Àwọn aláṣẹ ilé Kewu náà ni lílu àwọn ọmọ náà ni làti yí ayé wọn padà, ó ní àwọn rí àwọn ọmọ náà nínú fọ́nrán tí wọn ń mu ọtí ni ilé ijó àwọn òbí wọn náà ló sì mú ẹjọ́ wá sí ilé Kewu.
Fọ́nrán míì náà tún jẹyọ tí akekoo kan kúnlẹ̀ tí àwọn tó kù sì ń da ọtí lè lórí
Wọn tún ń di mọ ọmọbìnrin kan lára wọn. Ìdí tí a fi lu wọn nìyẹn nítorí abẹ́ àkóso wa ní wọ́n wà, èyí ni nǹkan tí àwọn aláṣẹ ilé Kewu náà sọ.
Adeyemi Olubunmi Crown: Láti ìgbà ti mo ti fún ọkọ mi ni ẹ̀bùn mọ́tò ni ìfẹ́ wa ti yàtọ̀
Boko Haram: Obìnrin mẹ́fà, ọmọ mẹ́sàn-án rin kílómítà àádọ́rún fún ọjọ́ mẹ́fà láti Yobe sí Bornu
Oríṣun àwòrán, Borno State Government
Àwọn obìnrin mẹ́fà àti ọmọ mẹ́san jàjàbọ́ lọ́wọ́ Boko Haram lẹ́yìn tí wọ́n rìn nínú igbó fún ọjọ́ mẹ́fà.
Kọmísọ́nà fọ́rọ̀ obìnrin nípìńlẹ̀ Borno, Zuwaira Gambo lo sisọ loju ọrọ yii lasiko to n safihan àwọn obinrin náà fun gomina ìpínlẹ̀ Borno, Babagana Zulum lọ́jọ́ Aje.
Gambo ni kìí ṣe ọdọ awọn nikan ni àwon Boko Haram ti kó àwọn ènìyàn mẹ́ẹ̀dógún yìí nítorí pé àwọn mìíràn ni abúlé ìpínlẹ̀ Adamawa àti Yobe ni wọn ti wá.
Wọ́n jí àwọn eeyan mẹ́ta àti ọmọ wọn gbé ní abúlé Takulashi nínú oṣù Kẹ̀wá ọdún tó kọjá nígbà tí àwọn tó kù wá láti abúlé Cofure nípìnlẹ̀ Adamawa.
Iwa ìjínigbé ti wọn si wáyé nínú oṣù Kàrún ọdún yìí gẹ́gẹ́ bí Kọmísọ́nà tó ń rí sí ọ̀rọ̀ obìnrin ṣe sọ.
Latifat Tijani: Ìjọba Naijiria ń ṣèlérí láti mọ́ rírì mi àmọ́ láti 2016, pàbó ló ń já sí
Àwọn obìnrin náà, tó fi mọ́ ọ̀kan tó wà nínú oyún oṣù mẹ́jọ láti abúlé Cofure fi ẹsẹ̀ rìn fún ọjọ́ mẹ́fà nínú igbó Buni Yadi ni ìpínlẹ̀ Yobe, lọ sí ìlú Damboa ni ìpínlẹ̀ Borno.
Gẹgẹ bi Gambo ti salaye, ìrìnàjò tó tó kìlómítà àádọ̀rún ni awọn obinrin naa gunle, to si nira pupọ.
"Inú mi dùn púpọ̀ láti gba àwọn ọmọ mi yìí lẹ́yìn tí wọ́n ti jẹ́ ìyá lọ́wọ́ àwọn agbésùmọ̀mi.
Gbogbo nǹkan tó wà ní ìkápá mi ni maa ṣe láti rán wọ́n lọ́wọ́. Èyí ni ọ̀rọ̀ tí Gómìnà Zulum sọ lásìkò to ń gbà alejo awọ́n obinrin naa."
Community Police: Onímọ̀ ààbò ní ọ́lọ́pàá tó wà nílẹ̀ ló nílò ìtọ́jú kìí ṣe ìdásílẹ̀ ikọ̀ ọlọ́pàá agbègbè
Oríṣun àwòrán, NPF
Àìní àtilẹ̀yìn ìjọba àti ará ìlú ni ìṣòro tí àwọn ọlọ́pàá Nàìjíríà ń kojú tí wọ́n kò fi lè ka àpá ètò ààbò tó mẹ́hẹ ni Nàìjíríà.
Ónímọ̀ nípa ètò abo ni Nàìjíríà, ọ̀gbẹ́ni Dotun Ojon lọ fìdí ọ̀rọ̀ yìí múlẹ̀ lásìkò tó ń bá BBC Yorùbá sọ̀rọ̀lọjọ Isẹgun.
Ojon, lásìkò to ń dá sí ìbéèrè nípa bílíọ̀nù mẹ́ta náírà lè diẹ̀ tí ìjọba àpapọ̀ gbé kalẹ fún ìdásílẹ̀ ọlọ́pàá àgbègbè, lo sisọ loju ọrọ naa.
Ọ̀gbẹ́ni Ojon ni kàkà tí ìjọba yóò tún fi lo owó naa láti ṣe àgbékalẹ̀ ileesẹ alaabo tuntun, yoo kuku san kó fi owó náà rọ okun sápá àwọn ọlọ́pàá.
Bakan naa lo ni owo ọhun yoo tun wulo fun amojuto àwọn ikọ̀ elétò ààbò tó ti wà nílẹ̀ pàápàá jù lọ, ikọ̀ Amotekun àti Ọlọ́pàá Nàìjíríà.
Latifat Tijani: Ìjọba Naijiria ń ṣèlérí láti mọ́ rírì mi àmọ́ láti 2016, pàbó ló ń já sí
Buhari, fi N3.3bn ra ibọn fun ọlọpaa, dipo agbekalẹ ọlọpaa agbegbe - Ojon
Ó ní wọ́n ti gba àwọn kọstabu si iṣẹ́ ọlọ́pàá pẹ̀lú ìrètí pé wọ́n yóò mọ agbegbe wọ́n daadaa nígbà náà, ṣùgbọ́n láti ìgbà yẹn náà kò fi bẹ́ẹ̀ sì ìyàtọ̀.
Ojon ni bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé wọ́n ṣe èyí lásìkò náà nítorí pé àwọn ìjọba ìpínlẹ̀ fẹ́ ṣe ìdásilẹ̀ Amotekun ni.
Sùgbọ́n o ni àsìkò yìí tí wọ́n ti rí pé àwọn ènìyàn tí ń ní ìfẹ́ sí bí àwọn Àmọ̀tẹ́kùn ṣe ń ṣe, bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé àwọn àṣìṣe mìíràn náà wá ní ìhà wọ́n.
Olórí ẹgbẹ́ YPP nípìnlẹ̀ Ondo náà tún fi kún pé, kò ní dára kí ijọ́ba fi owó tùùlù-tuulu yí ṣe òfò pẹ̀lú ìdásilẹ̀ ọlọ́pàá àgbègbè.
O ni yoo dara kí wọ́n fi ra ohun èlò àti ibọn fún àwọn ọlọ́pàá, bákan náà ló pé kí ìjọba ṣe ìdánilẹ́kọ̀ọ́ fún àwọn ọlọ́pàá láti mọ bí a ti ń bá ará ìlú ṣe.
Ojon ni eyi se pataki nítorí ọ̀pọ̀ ará ìlú ni kò ní ìgbàgbọ́ nínú ọlọ́pàá Nàìjíríà.
Peter Fatomilola ní àìsí ẹ̀kọ́ ń mú káwọn òṣèré tíátà ó máá ṣe oun tí kò tọ́.
Buhari, wa bi ebi, ìṣẹ àti ìyàn yóò ṣe dínkù láàrin àwọn ará ìlú ná, dipo Ọlọpaa agbegbe:
Nínú èrò tìrẹ ọ̀gbẹ́ni Dele Farotimi ni ìjọba àpapọ̀ kan fi ẹ̀tẹ̀ sílẹ̀, máa pa làpálàpá ni, nítorí pé kí ṣe àsìkò ló yẹ kí orílẹ̀èdè bí Nàìjíríà ṣẹ̀ṣẹ̀ máa sọ̀rọ̀ nípa ètò ọ̀rọ̀ ọlọ́pàá agbègbè.
Ó ní kìí ṣe òní ni ìjọba yóò maa buwọ́lu owó kan fún iṣẹ́ ìlú, tó sì jẹ́ pé àwọn kan ni yóò pín owó náà.
Ọ̀gbẹ́ni Dele Farotimi ni nǹkan tí ó ṣe pàtàkì jùlọ lọ́wọ́lọ́wó ni bí ebi, ìṣẹ àti ìyàn yóò ṣe dínkù láàrin àwọn ará ìlú ná, èyí lásán lo ni yóò mú àdínkù bá ìwà ọ̀daràn láwùjọ.
Kì í ṣe òní ni ìjọba tí ń ṣe irú ètò yìí ṣùgbọ́n kii sí àbájáde gidi kankan
Farotimi wá ṣàlàyé pé, tí ìjọba bá ti mójú tó èyí tán, ó ṣe pàtàkì láti jẹ́ kí ìdájọ́ òdodo wá láàrín ìlú, kí wọn sì máa tẹ́lẹ̀ òfin.
O ní láìsí èyí kò sì irú owó tí ìjọba lè gbé sílẹ̀ fún ọ̀rọ̀ àbò tí ó lè ní ìtumọ̀, tí ara ìlú kò bá nírètí pé ọ̀la yóò dára ju òní wọn lọ.
Ebun Oloyede Olaiya Igwe sọ ohun tí ojú rẹ̀ rí lásìkò àìsàn kídìnrín tó yọ ọ́ lẹ́nu
Àṣìṣe márùn ún tí àwọn lọ́kọláyà ńṣe nípa owó àti níní ìmọ̀ nípa ara wọn
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Jijiroro lori iṣuna ati eto inawo jẹ ohun kan to n fa ọpọlọọ wahala fun awọn eeyan paapaajulọ awọn lọkọlaya.
Bi a ba wo ọrọ gbogbo, iṣoro eto inawo ati iha ti koowa n kọ si ọrọ owo lee fa oniruuru nnkan fun ọpọlọpọ eyan eleyi to mu ki sisọrọ nipa rẹ o fẹ nira pupọ.
O ṣe pataki ki a sọrọ nipa ọna ti a le gba ṣe amojuto owo tabi iṣuna wa pẹlu awọn ọkọ tabi iyawo wa ki o ma baa fa wahala ni ọjọ iwaju. Amọṣa, bi o ko ba tii ni anfani lati ṣeto ijiroro yii bayii, o dara ki o tete wa aye fun.
Ninu iṣẹ iwadii ijinlẹ kan to waye laipẹ yii, lori awọn ohun to n fa wahala laarin awọn lọkọlaya, ohun marun un lo jẹyọ lori ohun ti awọn lọkọlaya n koju nipa ọrọ owo ati ọna ti wọn le gba yanju rẹ.
1.Aisi asiko fun ijiroro lori inawo ninu igbeyawo tabi ifẹ:
Ọpọlọpọ nnkan to ṣe pataki fun igbesi aye wa, gẹgẹ bi riri dokita tabi akọṣẹmọṣẹ nipa itọju eyin; bẹẹ gẹgẹ ni o yẹ ki a maa ṣe lori ọrs owo.
Sisọrọ nipa owo ati inawo lee nira pupọ, ṣugbọn o ṣe pataki fun igbeyawo lati kogoja.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ṣe eto asiko to dara julọ fun iwọ ati ololufẹ rẹ lati jiroro nipa inawo yin. Maṣe duro de igba ti ẹnikan ninu ẹyin mejeeji ba na owo to gọbọi lati ra ohun kan tabi nigba ti iṣoro iṣuna ba waye.
Ohun to ṣe pataki ni pe ki ẹ joko sọrs lori inawo yin, o lee da lori bi ẹ ṣe n nawo si, ohun ti ẹ n san owo fun, bi iṣuna ṣe n ri tabi fifi owo pamọ fun ohun kan to ṣe pataki. Ohun to ṣaa ṣe pataki ni pe ki ẹ fi asiko silẹ lati jiroro lori owo.
Oríṣun àwòrán, Thinkstock
Ọna ti o ba gba na owo rẹ lawọn asiko kan sẹyin lee ni ipa lori ọna ti o o gba na owo rẹ lasiko yii, eyi si ni idi ti lọkọlaya lati mọ ipo ti eto inawo ọkọ tabi iyawo wọn wa.
Bi o ba lee mọ nipa ilana inawo atẹyinwa ololufẹ rẹ, yoo ran ọ lọwọ pupọ lori bi ẹ ṣe n na owo yin lọwọlọwọ.
Bi ololufẹ rẹ ba wa lati idile ti o lowo, ti owo kii ṣe iṣoro fun, o ṣeṣe ki ọna ti o gba n fowopamọ o ma dun mọ ọ ninu pupọ.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ni kete ti o ba ti mọ itan nipa iṣuna ololufẹ rẹ, nibẹ loo ti le mọ nipa ilana ti wọn fi n na owo ti yoo si ran ọ lọwọ lati maṣe bọ sọwọ aṣiṣe owo.
Lasiko ti ẹ ba n ṣeto afojusun inawo yin, iwọ ati ololufẹ rẹ gbọdọ joko jiroro  lati mọ awọn ohun gan ti ẹ fẹ gan ni pato.
Ọpọ awọn lọkọlaya lo maa n gba pe ololufẹ wọn fara mọ ohun ti wọn fẹ nipa iṣuna lai sọrọ rẹ rẹ. Lẹyin o rẹyin ni wọn yoo wa rii pe irọ ni wọn n pa.
Latifat Tijani: Ìjọba Naijiria ń ṣèlérí láti mọ́ rírì mi àmọ́ láti 2016, pàbó ló ń já sí
Gẹgẹ bi lọkọlaya, ẹyin mejeeji nilo lati jiroro lori awọn idojukọ yin nipa inawo, dukia ti ẹ ni ati iye owo oṣu ti ẹni kọọkan yin n gba.
Lẹyin eyi, ṣe ilakalẹ inawo yin bii owo ori, sisan owo san an diẹdiẹ lori ọkọ rira. Nitori pe dandan ni sisan awọn owo wọnyii, o rọrun lati tete bẹrẹ si ni ṣeto iṣun alori wọn.
Oríṣun àwòrán, Alamy
Lọpọ igba ni edeaiyede yoo maa waye lori iṣuna yin bi ọkan ninu awọn lọkọlaya ba n yọ ninu aṣuwọn ajumọni wọn lati nawo fun ohunkohun.
Nitori eyi, o ṣe pataki ki ẹyin mejeeji ṣe eto lori bi ẹ o ṣe maa na owo lsna ti ko ni ṣokunkun si ẹni keji.
Olota Of Ota: N kò fara mọ́ ìyapa Nàíjíríà, ìṣèjọba ẹlẹ́kùnjẹkùn ní ọ̀nà àbáyọ
Fifi ara pamọ fun ololufẹ rẹ lori ọrọ owo, kaadi igbowo ATM rẹ ati awọn ohun tuntun ti o n gbero lati ra lewu pupọ. Ohun to ṣe pataki naa ni ki ẹyin mejeeji jẹ olootọ si ara yin.
Bi o ba ti n di pe ẹyin mejeeji ko lee ṣalaye ohun ti ẹ n ra fun ara yin nitori ero pe ẹnikeji rẹ ko ni fọwọsi ohun ti o fẹ ra naa, a dara ki ẹ jumọ joko jiroro pọ lori rẹ
Princess Mako: Ẹ wo ọmọbabinrin ilẹ̀ Japan to sọ ipò iyebíye ti owó rẹ̀ tó $1.3m nù nítorí olólùfẹ́
Oríṣun àwòrán, Getty Images
111Ọmọbabinrin ilẹ Japan, Mako ti ṣetan lati ṣe igbeyawo pẹlu ololufẹ rẹ to jẹ araalu ni Oṣu Kẹwaa, ọdun 2021.
Ọmọbabinrin Mako lo gbe igbesẹ yii lẹyin ọpọlọpọ ọdun ti wọn ti wa lori ọrọ naa laaarin ẹbi rẹ
Ki o to le fẹ araalu naa yoo fi ipo rẹ silẹ, ti igbeyawo yoo si waye ni Ọjọ Kẹrindinlọgbọn, Oṣu Kẹwaa yii.
Ọdun 2018 ni ọmọbabinrin Mako ati ololufẹ rẹ ti fẹ ṣe igbeyawo, amọ awọn ẹbi Arakunrin Komuro wa ninu gbese,ni wọn ko ṣe le ṣe igbeyawo naa ni ọdun meji sẹyin.
Awọn ololufẹ mejeeji ni yoo pada si orilẹede Amerika lati lo ma a gbe nibi ti ọkọ ti n ṣiṣẹ agbẹjọrọ.
Ọpọlọpọ iroyin nipa ọmọbabinrin naa ti baba rẹ jẹ ọba Fumihito ati ẹbi afẹsọna rẹ, Komulo fa aisan irẹwẹsi ọkan fun ọmọbabinrin naa.
Sunday Igboho‘s Birthday: Àwọn olólùfẹ́ Igboho rawọ́ ẹ̀bẹ̀ sí ìjọba Benin láti túu sílẹ̀,
Bakan naa ni auntie rẹ, Masako naa ni ipenija aisan irọnu ọkan lẹyin ti ọpọ eniyan fi oju si lara pe ki o bi arẹmọ ọkunrin.
Ọdun 2012 ni ọmọbabinrin ati ololufẹ rẹ pada lasiko ti wọn jẹ akẹkọọ ni ileẹkọ fasti imọ ẹsin Kristẹni ni Tokyo.
Awọn mejeeji ṣe mọmi n-mọ ọ ni ọdun 2017, ti wọn si fẹ ṣe igbeyawo ni ọdun 2018, ki iwadii to fihan pe iya Komuro jẹ ọkọ afẹsọna rẹ tẹlẹri ni gbese.
Olota Of Ota: N kò fara mọ́ ìyapa Nàíjíríà, ìṣèjọba ẹlẹ́kùnjẹkùn ní ọ̀nà àbáyọ
Leyin naa ni ile ọba fi iroyin lede pe awọn lo lọwọ si ifasẹyin igbeyawo wọn nitori wọn gbọdọ san gbese ti iya rẹ jẹ ki o to le fẹ ọmọ wọn.
Iroyin ni Ọmọbabinrin Mako yoo padanu iye owo to to 150 million yen ($1.3m; £0.97m) to yẹ ko gba to ba n fẹ ọkọ gẹgẹ bi idile ọba.
Bakan naa ni ko ni le e ṣe ayẹyẹ igbeyawo naa gẹgẹ bi ọmọọba laafin amọ bii ti awọn araalu.
Eyi jẹ ki ọmọbabinrin naa jẹ ẹni akọkọ ti yoo kuro ni idile ọba bẹẹ lai si ayẹyẹ igbeyawo to rọmọ
Labẹ ofin orilẹede Japan, ọmọbabinrin yoo sọ ipo rẹ nu to ba fẹ araalu ti ko wa lati idile ọba, amọ ofin yii ko de ọmọbakunrin ilẹ Japan rara.
Masquerade Robbers: Ọwọ́ ọlọ́pàá tẹ afurasí egúngún méjì tó fi àdá gba owó
Ọwọ ijọba ipinlẹ Ondo ti tẹ egungun mejilori ẹsun pe wọn ji owo to to ẹgbẹrun lọna ọtalelọọdunrun naira o le mẹwa (₦370,000).
Bakan naa ni wọn fi ẹsun kan awọn egungun naa pe wọn fi ada da ọgbẹ si ara ẹni to ni owo naa, Adinoyi Muhammed.
Orukọ awọn ara ọrun naa ni Sheriff Ojo ati Muhammad Lukman, ti awọn mejeeji si ti n naju lagọ ọlọpaa bayii, ti wọn yoo si tun fi oju ba ile ẹjọ laipẹ.
Gẹgẹ bi agbẹnusọ fun ileesẹ ọlọpaa nipinlẹ Ondo, Funmi Odunlami ti salaye ninu atẹjade kan to fisita, agbegbe Melenge nilu Ipele nipinlẹ Ondo ni awọn egungun mejeeji yii ti sisẹ ibi naa.
"Odunlami ni ""Awọn afurasi ole yii ni wọn n dibọn bii egungun, wọn fi ada sa Adinoyi Muhammed lati gba owo lọwọ rẹ."
Adejoke Ewaede: Ìfẹ́ àṣà Yorùbá ló mú kí ń pinnu láti máa wọ aṣọ àdìrẹ̀ nìkan
Bakan naa ni wọn tun gba ẹrọ foonu rẹ ti owo rẹ to ẹgbẹrun mejilelọgbọn naira ati asọ kan towo rẹ to ẹgbẹrun meji ati aabọ naira.
"Wọn tun da ọgbẹ si ara baba ọmọkunrin ti wọn ja lole naa, Saliu Ajayi lara, tawọn ọlọpaa si ti gba ada meji, oogun abẹnu gọngọ ati ẹku eegun lọwọ wọn."""
Ileesẹ ọlọpaa ti wa n leri leka pe laipẹ ni awọn afurasi mejeeji naa yoo fi oju ba ile ẹjọ.
Oríṣun àwòrán, Ogun State Police
Ọwọ ileesẹ ọlọpaa nipinlẹ Ogun ti tẹ ọkunrin kan, Abidemi Oluwaseun, ẹni ọdun marundinlogoji, lori ẹsun pe o kọlu ile ẹkọ kan.
Lasiko ikọlu naa, wọn fi ẹsun kan Abidemi pe o ko awọn afurasi janduku lọ ba olukọ kan nibẹ, ẹni to fẹsun kan pe o lu ọmọ oun obinrin, ọmọ ọdun mẹẹdogun.
Atẹjade kan ti osisẹ alarina fun ileesẹ ọlọpaa nipinlẹ Ogun, Abimbola Oyeyemi fisita lo sisọ loju ọrọ yii.
Bakan naa ni atẹjade ọhun fikun pe ọwọ tẹ awọn eeyan meji mii, Fayesele Olabanji, ẹni ọdun mẹẹdọgbọn ati Alebiosu Quawiyu, ẹni ọdun mẹrinlelogun, lori isẹlẹ yii.
Ọga ile ẹkọ naa, Baptist Girls College to wa ladugbo Idi Aba nilu Abeokuta, lo pe awọn ọlọpaa nipe pajawiri pe awọn ọkunrin mẹta ti kọlu ile ẹkọ naa pẹlu ọkọ kan ti ko ni nọmba.
Ridwan Oyekola: October 30 ni màá tún ìjà jà láti gba belt mi padà àmọ́ kò sí onígbọ̀wọ́
Awọn ọkunrin naa lo ni wọn ko ada tuntun lọwọ, ti wọn si n dunkoko pe awọn yoo sa olukọ kan ni ada nile iwe naa.
Ni kete ti ipe pajawiri naa de, ni ọga ọlọpaa to wa ni agọ ọlọpaa Kemta, Opebiyi Sunday, lewaju awọn osisẹ rẹ lati ko awọn eeyan naa ninu ọgba ile ẹkọ ọhun.
Asiko yii si ni wọn gba ada ati ọkọ ti wọn gbe wa se ikọlu naa.
Sunday Igboho‘s Birthday: Àwọn olólùfẹ́ Igboho rawọ́ ẹ̀bẹ̀ sí ìjọba Benin láti túu sílẹ̀,
Nigba ti wọn n fi ọrọ wa Abidemi lẹnu wo lori ohun to ri lọbẹ, to fi wa iru sọwọ, o salaye pe ọmọ oun atawọn akẹẹgbẹ rẹ ni wọn n fi olukọ wọn se yẹyẹ ni kilaasi lasiko to n kọ wọn lẹkọọ lọwọ.
Idi ree ti olukọ naa fi sa awọn to lewaju iwa aidaa, to si fi ẹgba na wọn gẹgẹ bii ijiya ẹsẹ wọn, amọ se ni ọmọbinrin naa lọ rojọ fun baba rẹ nile pe olukọ na oun.
Eyi si lo mu ki baba naa, Abidemi ko awọn afurasi janduku meji lọwọ lati kọlu ile ẹkọ naa pẹlu ada lọwọ lati gbẹsan lara olukọ to lu akẹkọọ naa.
Wayi o, Kọmisọna ọlọpaa nipinlẹ Ogun, Lanre Bankole ti pasẹ pe ki wọn se iwadii isẹlẹ naa, ki wọn si ko awọn afurasi naa sile ẹjọ laipẹ.
Bakan naa lo sekilọ pe ileesẹ ọlọpaa ko ni fara mọ iru iwa ọdaluru bayii lawọn ile ẹkọ ijọba tabi ti aladani nitori iwa sise idajọ lọwọ ara ẹni lo jẹ.
Latifat Tijani: Ìjọba Naijiria ń ṣèlérí láti mọ́ rírì mi àmọ́ láti 2016, pàbó ló ń já sí
Femi Fani-Kayode: Àlàyé rèé lórí bí wọn ṣe lò mí láti bá Sunday Igboho sọ̀rọ̀ èyí tó dènà ogun abẹ́lé
Oríṣun àwòrán, real_ffk/Instagram
Ilumọọka oloselu to sẹsẹ lọ lati inu ẹgbẹ oselu PDP bọ si APC, Oloye Femi Fani-Kayode ti sọrọ lori ọna ti ijọba apapọ fi doola ogun abẹle ti ko ba waye ni Naijiria lati ipasẹ ẹlẹya mẹya.
Bakan naa ni Fani-Kayode tun sọrọ nipa awọn ajọsepọ rẹ pẹlu gbajumọ ajijagbara fun ilẹ Yoruba, Oloye Sunday Igboho, to fi mọ awọn ohun ti wọn dijọ gbe inu yara sọ.
Oloye Femi Fani-Kayode sisọ loju awọn ọrọ yii lasiko to n kopa lori eto tẹlifisan AIT kan, Talking Violence, ti wọn gbe sori afẹfẹ lalẹ ọjọ Isẹgun.
Fani-Kayode kede pe ogun abẹle ko ba waye ni Naijiria amọ wọn tete doola rẹ ni ko fi seese, ti Ọlọrun si lo oun ati gomina ipinlẹ Kogi, Yahaya Bello lati pa ina isẹlẹ naa.
O ni Igboho ti di ilumọọka laarin awọn ọmọ Yoruba lori ayelujara lasiko to fun awọn Fulani to wa nilẹ Yoruba ni gbedeke pe ki wọn palẹ ẹru wọn mọ nilẹ, to si se amusẹ ọrọ rẹ.
Nigba to n sisọ loju ohun to pa ohun ati Sunday Igboho pọ ati idi to fi sun mọ Igboho, Fani Kayode ni isẹlẹ kan lo waye, ti wọn pe oun si lati lọ ba igboho sọrọ.
FFK: Buhari ló ń fún àwọn Fulani láàyè láti máa pa ènìyàn'
Fani-Kayode ni lalẹ ọjọ kan ni oun gba ipe kan ni oru lati ọdọ gomina ipinlẹ Kogi, Yahaya Bello, ẹni ti awọn ti dijọ n ni ajọsepọ lasiko igba naa.
O ni oun lọ jẹ ipe rẹ, asiko yii si ni awọn ontaja to n ko ounjẹ wa lati ẹkun ariwa wa si ẹkun guusu Naijiria fi aake kọri lati ko ounjẹ wa silẹ Yoruba.,
O ni asiko ti laasigbo bẹ silẹ ni agbegbe Shasha nilu Ibadan ni ọrọ naa waye eyi to mu ẹmi awọn ọmọ Yoruba ati Hausa kan lọ.
Fani Kayode fikun pe gbogbo aayan ni wọn ti sa saaju lati jẹ ki awọn o0ntaja ounjẹ naa maa ko ounjẹ pada wa si ẹkun guusu amọ ti wọn faake kọri, idi si ree ti Bello fi ke si oun.
Fani-Kayode salaye pe aarẹ Muhammadu Buhari ti kesi gomina Yahaya Bello pe ko wa ọna lati pari aawọ naa laarin ọjọ mẹta, ki kiko ounjẹ wọle si pada si ẹkun guusu Naijiria.
"Idi ti Yahaya Bello se fẹ ki n wa lara ikọ ti yoo duna dura naa ni pe awọn eeyan ẹkun ariwa ti n dunkooko pe awọn yoo bẹrẹ si ni pa awọn eeyan ẹkun guusu.
Igbesẹ naa si lo ti foju han pe yoo bẹrẹ laipẹ ti a ko ba tete wa nnkan se si, ohun ti wọn si n fẹ ni pe ki n ba Sunday Igboho sọrọ.
Wọn fẹ ki Igboho fi ọwọ sọya pe tawọn eeyan ẹkun ariwa ba bẹrk si ko ounjẹ wa si ilẹ Yoruba pada, aabo yoo wa fun ẹmi ati dukia wọn.
Ni asiko yii, awọn eeyan lati ariwa Naijiria ti n ko aasa wọn lọpọ yanturu kuro ni ẹkun guusu Naijiria, ti wọn si pada sile."
Sunday Igboho fulani ultimatum: Àwọn ará Kebbi àti Zamfara ló n jínígbé ní Oke Ogun- Serik
Fani-Kayode wọn mọ pe oun sun mọ Sunday Igboho bii isan ọrun ni wọn se ke si oun lati lọ ba sọrọ pe iwa igbẹsan kankan ko ni waye.
O ni awọn eeyan ariwa naa salaye pe lootọ ni ẹmi awọn eeyan awọn kan ti ba isẹlẹ naa lọ lasiko ti rogbodiyan kan waye ladugbo Lekki, nibi ti wọn ti sun sọọbu awọn Hausa.
Bakan naa si lo ni wọn sọ pe awọn tun padanu awọn eeyan Ariwa lasiko lasiko laasigbo to waye ni adugbo Shasha nilu Ibadan.
"Yahaya Bello wa sọ nkankan to fọwọ ba mi lọkan, o ni ijọba apapọ to ja fitafita lati ri daju pe isẹlẹ ipaniyan naa ko waye, to si n daabo bo ẹmi awọn eeyan guusu Naijiria lapa oke ọya.
A wa pada sinu yara, nibẹ si ni mo ti pe Sunday Igboho, mo si sọ fun pe mo wa lọdọ gomina Kogi, to si n gbọ gbogbo ohun ta fẹ sọ.
Fani-Kayode ni oun salaye fun Igboho nipa ohun ti oun fẹ ko se, eyi ni pe ko fi ọwọ gbaya pe ijamba kankan ko ni se awọn eeyan Ariwa to n ko ounjẹ wa silẹ Yoruba.
Igboho da mi lohun pe to ba jẹ pe nnkan ti mo fẹ niyẹn, o wa fọwọ gbaya pe funra oun gan ni oun yoo lewaju wọn ls sibi ti wọn yoo ti ja ounjẹ wọn silẹ, ti mimi kankan ko si ni mi wọn."
Bakan naa ni Igboho ba gomina Yahaya Bello sọrọ funra rẹ ati awọn eeyan jankan jankan mẹrin miran ti wọn wa nibẹ.
"Ni kete ti Igboho si fi ọwọ idaniloju yii sọya ni idunkooko to n waye lati apa oke ọyape awọn yoo maa pa awọn ara guusu lọ silẹ patapata."""
O fikun pe ni kete tawọn eeyan yii gbọ ohun Sunday Igboho ni skunrin to wa nidi igbesẹ lati maa kọlu awọn eeyan guusu Naijiria jade sita pe awọn ko ni gbe igbesẹ naa mọ.
Ko tan sibẹ, Fani-Kayode ni awọn tun ba awọn gomina kan nilẹ Yoruba sọrọ lati jẹ ki wọn mọ awọn igbesẹ ti awọn gbe naa, ti gbogbo wọn si fi ọwọ si.
O wa fi ọwọ gbaya pe, ti oun ko ba sun mọ Igboho, bawo ni yoo ti seese lati ba sọrọ, ti alaafia yoo si jọba, eyi to dena ogun abẹle ti ko ba waye ni Naijiria.
Ridwan Oyekola: October 30 ni màá tún ìjà jà láti gba belt mi padà àmọ́ kò sí onígbọ̀wọ́
Odunlade Adekola: Ẹgbẹ́ Mùsùlùmí korò ojú sí sinimá kan tí Odun gbé jáde tí wọn ló ń fi Islam tayín
Ẹgbẹ́ ajàfẹ́tọ mùsùlùmí kan tó ń jẹ́ Ta'awunu Human Right of Nigeria (THURIST) ti ké gbàjarè pé, òṣèrè tíátà, Odunlade Adekola n fi ọ̀rọ̀ ẹsin Musulumi tayín.
Nínú àtẹ̀jáde kan ti adarí ẹgbẹ́ náà, Amofin Sulaymon Tadese fi síta lójú òpó Facebook ẹgbẹ́ náà, ló tí sọ pé Odunlade Adekola gbé fọ́nrán sinimá kan síta, níbi tó tí n fí àwọn obìnrin ẹlẹ́hà kan ṣe yẹyẹ láàrín àwùjọ.
"Gẹ́gẹ́ bí ó ṣe kọ "" Wọ́n ti pe àkíyèsí wa sí simina àgbéléwò kan tí mo ni ìgbàgbọ́ pé gbájúgbàjà òṣèré Odunlade Adekola lo gbe síta, èyí tí èròngbà fi yé ni pé, ó n gbìyànjú láti fi àwọn obìnrin músùlùmí ẹlẹha ṣe yẹ̀yẹ́."""
"THURIST ni nínú fọ́nrán náà tó pe àkọlé rẹ̀ ni ""Iku ni"", ni wọ́n ti ṣe àfihàn obìnrin ẹlẹ́hà kan tó wọkọ̀ èrò, tí ó sì n ń sọ fún onímótò pé, ìyànà ọ̀run ni òun ti fẹ́ sọ̀kalẹ̀."
O ni irú èyí n fí obìnrin ẹlẹ́hà náà ṣe yẹ̀yẹ́ ni, nítori pé kò sí ìbì kankan  tó n jẹ́ ìyànà ọ̀run níbikibi ni Nàìjíríà.
Ebun Oloyede Olaiya Igwe sọ ohun tí ojú rẹ̀ rí lásìkò àìsàn kídìnrín tó yọ ọ́ lẹ́nu
"Kò tán síbẹ̀, olùkọ ìtàn náà tún ṣe àfihàn òbìnrin ẹlẹ́hà náà gẹ́gẹ́ bi wèrè, tí ó sì ń gbìyànjú láti sọ àwọn òbìnrìn tó lo ẹ̀há bi ẹni ti ko tọ́ láwùjọ.
Àìní ìfàradà ẹ̀sìn nínú sinima náà dé orí góngó nígbà tí olùkọtàn ọ̀hún ṣàfihàn obìnrin tó lo ẹhá náà, níbi to ti gbé àdá sókè, tó sì fẹ́ ṣá ẹnikẹ́ni tó bá wa ni àyíká rẹ̀ pa."
THURIST ni nítorí ìdí èyí, ni àwọn ṣe n ké pé ẹgbẹ́ TAMPAN àti ọ̀gbẹ́ni Odunlade Adekola láti gbé àwọn ìgbéṣẹ̀ yìí lẹ́yọ-osọkà.
"Láti fi òpin sí ṣíṣe fíìmù IKU NI"", ki wọ́n si yọ́ kúrò lórí gbogbo ìkànni ìwòràn tó fi mọ́ Youtube láàárin ọjọ́ méje."""
Oríṣun àwòrán, THURIST Facebook
Bakan naa ni Thurist n fẹ kí ẹgbẹ́ fi ọgbẹ́ni Odunlade Adekola si abẹ ìbáwí ní ìlàna ofin ẹgbẹ́ TAMPAN.
Ẹgbẹ́ THURIST tún ké pe àjọ tó n mójú tó sinima tí wọn n gbé jáde láti dènà irú àwọn sinimá bẹ́ẹ̀ láti mase jáde si àwùjọ.
Bákan náà ni wọ́n ni pe kí ẹni to gbe sinima náà jáde kọ iwé ìtọ̀rọ aforíjì sí àwọn àjọ musulumi, kí wọn sì gbe jáde lójú òpó ti gbogbo ènìyàn yóò ti ri, pèlú ìdániloju pe àwọn ti yọ fọ́nran náà kúrò láàrín ọjọ́ méje.
"Bí o bá wá kọ̀ tí kò ṣe èyí, égbẹ́ náà ni àwọn ṣetán láti tẹ́síwájú láti pe TAMPAN lẹjọ́ lórí ọ̀rọ̀ náà.
Oríṣun àwòrán, THURIST Facebook
Gbogbo igbiyanju BBC Yoruba lati kan si Odunlade Adekola, ka le gbọ tẹnu rẹ lori isẹlẹ yii lo ja si pabo.
Wumi Toriola: Mo gbé ọ̀pọ̀ ìgbésẹ̀ láti lóyún lẹ́yìn ìgbeyàwó àmọ́ pàbó ló jásí kí Ọlọ́run tó síjú àànú wò mí
Oríṣun àwòrán, Wumitoriola/Instagram
Igbagbọ ọpọ ọmọ Yoruba ni pe Ọlọrun lo n se ọmọ, kii se eeyan, agbara iloyun ati ọmọ bibi si wa lọwọ Eledumare ọba to le se ohun gbogbo.
Igbagbọ awọn eeyan yii si lo wa si imusẹ ninu aye gbajugbaja osere tiata lobinrin kan, Wumi Toriola.
Bi o tilẹ jẹ pe Wumi se igbeyawo alarinrin, to si pẹ diẹ ko to fi inu soyun, ọpọ eeyan lo n lero pe o kan wu bẹẹ ni lai mọ pe isoro nla ni oserebinrin naa la kọja.
Toriola, ẹni to bọ soju opo Instagram rẹ lati kede ayẹyẹ ọdun keji ti ọmọ rẹ de ile aye, wa lo anfaani ọjọ ibi naa lati kede fun araye nipa ọpọ isoro to la kọja, ko to di ọlọmọ nile aye.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí:
Ninu alaye rẹ, Wumi ni lẹyin ayẹyẹ igbeyawo oun, oun ati ọkọ oun pinnu lati sinmi diẹ naa, kawọn to bẹrẹ owo ọmọ bibi.
Amọ nigba ti akoko isismi wọn buse ni wọn ba ko mọ isẹ ọmọ bibi sugbọn gbogbo aisun tọkọtaya naa tọsan toru lo ja si pabo, ti oyun ko si duro rara.
Oríṣun àwòrán, Wumitoriola/Instagram
Laarin osu mẹfa akọkọ ta pinnu lati loyun ni a ko fi gbọ ko amọ n ko tiẹ mọ lọran kankan nigba naa."
"Amọ nigba to di ọjọ kan, ni eeyan kan sọ fun mi pe se mo lero pe o rọrun lati finu soyun ni, sebi igbeyawo ni mo se yẹ, ki lo de ti n ko se tii loyun, to ba jẹ pe lootọ lo rọrun lati se bẹẹ."""
Wumi ni igba yii gan ni oun to mọ ọrọ naa ni nnkan patak, ti oun si gba ile iwosan to wa fun oyun nini ati ọmọ bibi lọlati lọ se ayẹwo pẹlu ọkọ oun.
Amọ o ni dokita fidi rẹ mulẹ pe saka ni ara oun ati ọkọ oun da, ti ko si si nkankan to n se idiwọ fun awọn mejeeji lati finu se oyun.
"Amọ sibẹ n ko lyun lẹyin ayẹwo yii, ti mo si tun lọ sibi ti wọn yoo ti se iranwọ lati fi ẹrọ kan gbe atọ ọkọ mi sile ọmọ mi, ti oloyinbo n pe ni Intrauterine Insemination.
Ẹmeji ni wọn se nnkan yii fun mi, ti gbogbo rẹ si kuna, n ko gbọ pa, bẹẹ ni n ko gbọ ko.
Amọ nigba to ya Ọlọrun lo sisẹ iyanu rẹ, ti mo si loyun, eyi ti mo fi bi ọmọkunrin to pe ọdun meji yii."
Oríṣun àwòrán, Wumitorioa/instagram
Wumi Toriola wa gba awọn ololufẹ rẹ to n woju Ọlọrun ninu igbeyawo wọn nimọran pe kii se awọn nikan lo n la iru isoro naa kọja.
Aimọye miliọnu obinrin lo n ba isoro airọmọbi yii finra, amọ mase ri ara rẹ bi ẹni ti ko le finu soyun laelae nitori isẹ iyanu rẹ sun mọ itosi.
O tun wa rọ iru awọn eeyan yii wipe ki wọn mase fi oogun wọn sere, ki wọn si maa lọ sile iwosan loore koore, bẹẹ ni ki wọn maa gbadura si Ọlọrun nitori Ọlọrun to ya Wumi Toriola lẹnu, yoo ya awọn naa lẹnu.
Kongsberg Bow and Arrow Attack: èèyàn márún ún gbẹ́mì mì nínú ìkọlu ófà àti ọrún
Oríṣun àwòrán, Hakon Mosvold/NTB/via Reuters
Police have cordoned off large parts of the town
O kere tan ẹmi obinrin mẹrin ati ọkunrin kan ti ba iṣẹlẹ ikọlu ọrun ati ọfa lọ ni orilẹede Norway.
Ileeṣẹ ọlọpaa ni awọn gbọ nipa iṣẹlẹ naa ni nkan bi ọwọ irọlẹ ni agbegbe Kongsberg, ni orilẹede naa.
Gẹgẹ bi ọrọ awọn ọlọpaa arakunrin naa wa lati iha North Germany, ti ọjọ ori rẹ ko si ju ẹni ọdun metadinlogoji lọ.
Awọn ti iṣẹlẹ naa ṣoju wọn ni inu ọja ti awọn eniyan ti n ra nkan ni iṣẹlẹ naa ti waye, ti ọlọpaa si pẹlu awọn meji to farapa ninu iṣẹlẹ naa.
Ẹnikan to wa nibẹ lasiko iṣẹlẹ naa ni oun ri ti rogbodiyan bẹ silẹ, ti obinrin kan sapamọ, ti ọkunrin kan si duro si ẹgbẹ kan pẹlu ọrun si ejika rẹ, to si gbe ọfa si ọwọ rẹ.
Lẹyin naa ni wọn ri awọn eniyan ti wọn bẹrẹ si ni sa asala fun ẹmi wọn, to fi mọ arabinrin kan to gbe ọmọ kekere dani, to si n sa asala fun ẹmi rẹ.
Wọn fikun pe arakunrin afurasi naa lo awọn ohun elo ija miran yatọ si ọfa ati ọrun, amọ awọn ọlọpaa ko sọ ju bẹẹ lọ.
Ileeṣẹ ọlọpaa ni awọn ti kọkọ mu ọkunrin naa fun ifọrọwanilẹnuwo lẹyin to darapọ mọ ẹsin Islam.
Akokoro eyín lè ṣe ìpalára fún àtọ̀ ọkùnrin, ó sì lè yọrí sí ṣàkóbá fún ọkàn èèyàn
Bakan naa ni wọn fikun pe awọn ti wọn ku ninu ikọlu naa jẹ eni aadọta si aadọrin ọdun.
Ọpọlọpọ eniyan lo ti bu ẹnu atẹ lu ikọlu naa to fi mọ Olotu Ijọba orilẹede naa ti yoo fi ipo silẹ laipẹ, ti olori eto idajọ miran yoo si tun gba ipọ bakan naa.
Agbẹjọro afurasi apaniyan naa ni o wa ni panpẹ ọlọpaa, ti wọn si ti bẹrẹ ifọrọwanilẹnuwo lori iṣẹlẹ naa, lati le fi idi rẹ mulẹ boya iṣe igbesunmọmi ni.
Ileeṣẹ ọlọpaa ni afurasi naa lọ si agbegbe to pọ, ti wọn si ti ya awọn agbegbe naa sọtọ pẹlu aṣẹ ki awọn eniyan joko si ile titi iwadii yoo fi pari.
Igba ti iṣẹlẹ igbesunmọmi iru rẹ ti ṣẹlẹ ri ni ọdun 2011, lẹyin ti ọkunrin alakatakiti kan pa eniyan mẹtadinlọgọrin, ti ọpọlọpọ si jẹ ọmọde nibi ti wọn ti n ṣe ayẹyẹ ni agbegbe Uloya, lorilẹede naa.
Ridwan Oyekola: October 30 ni màá tún ìjà jà láti gba belt mi padà àmọ́ kò sí onígbọ̀wọ́
Mompha: Iléẹjọ́ ní kí EFCC gbẹ́sẹ̀ lé aago àti awò ojú márùn-ún rẹ̀ pẹ̀lú fóònù iphone 8 kan
Oríṣun àwòrán, mompha/Instagram
Ileẹjọ giga kan nipinlẹ Eko ti pasẹ pe ki ajọ EFCC gbẹsẹle awọn dukia ẹsọ ara olowo iyebiye to jẹ ti Ismaila Mustapha, ti ọpọ eeyan mọ si Mompha.
Awọn ẹsọ ara naa ni awo oju marun olowo nla, aago olowo iyebiye marun ati foonu ibaraẹnisọrọ iphone 8.
Awọn dukia olowo iyebiye tii ni ajọ EFCC gba lọwọ Mompha losu Kẹwa ọdun 2019 nigba ti wọn mu ni papakọ ofurufu Nnamdi Azikwe to wa nilu Abuja.
Adajọ Lewis Allagoa lo pasẹ bẹẹ lẹyin to gbọ ẹbẹ agbẹjọro fun EFCC, Chinenye Ugwoke, to si ni asẹ naa yoo mulẹ titi ti EFCC yoo fi pari iwadii wọn lori Mompha ati ileesẹ rẹ, Ismalob Global Investment Ltd.
Mompha, ẹni tii se gbajumọ lori ayelujara lo ti n foju wina ẹsun onikoko mẹrinla to nii se pẹlu gbigbe owo tuulu lọ soke okun lọdun 2019, eyi to to biliọnu mẹtalelọgbọn o din diẹ (N32.9 bn).
2021 Twin Festival: Aráàlú ní Ifá ló sọ pé ìbejì yóò pọ̀ ní Igboora, kìí ṣe jíjẹ Ìlasa
Awọn eroja olowo tuulu mọkọọkanla naa ni iwọnyii:
Awo oju marun ti wọn mọ idamọ wọn si Tomford - TF586; Cartier - B17C76B; Montblanc - MB0045S ati Louis Vuitton- Z1186E.
Awọn aago ọwọ marun naa ni orukọ wọn n jẹ Rolex Oyster Perpetual; Audemars Piguet; Audemars Piguet- J46220; XY Hublot - 1321920 ati XY Hublot- 924206.
Nọmba idamọ ẹrọ ibaraẹnisọrọ iPhone 8 naa ni C8PVF1LKJC6C.
Agbẹjọro ajọ EFCC bẹ ileẹjọ pe ko pasẹ ki awọn gbẹsẹle awọn eroja yii lọna ati da olujẹjọ lọwọ kọ ko maa baa tọwọ bọ awọn eroja ọhun, eyi ti awọn fura si pe o fi owo to ri lọna eru ko jọ.
Oríṣun àwòrán, Capenter
Ọmọ ilé ìgbìmọ̀ aṣojú ṣòfin kan l'Abuja láti ìpínlẹ̀ Osun ti ni àwọn olókoòwò kéékèkè tó fi mọ́n àwọn káfíntà àti àwọn dẹ́rẹ́bà ọkọ ìgboro lo gbọdọ̀ máa san owó orí lórí òwò wọn.
Fakeye Olufemi, ọmọ ẹgbẹ́ òṣèlú All Progressives Congress to n sojú Boluwaduro/Ifedayo/ Ila ni ìpínlẹ̀ Osun ló sọ èyí níwájú ilé aṣòfin apapọ.
Òfin isúná ọdun 2020 yọ gbogbo àwọn ilé iṣẹ́ kéékèkè ti owó ti wọ́n pa ko ju mílíọ̀nù mẹ́ẹ̀dọ́gbọ́n lọ lọ́dun sílẹ̀ nínú sísan owó orí.
Olufemi, lásíkò to n dásí ètò isúna ọdún 2022 lásìkò ìjọkó ilé, ló tí ni èyí yóò túbọ mu ki owọ iṣúná rú gọ́gọ́ si fún ìjọba àpapọ̀.
Bákan náà lo fi kú pé, òun ni ifẹ̀ láti sọ fún àwọn ìgbìmọ̀ aláṣẹ ijọba pé tí wọ́n bá n pinu láti yáwó fún iṣẹ́ òde kan , ki wọ́n yá owó náà nínú oṣù kíní tàbí ikèjì sí ikẹta, kìí ṣe ki wọ́n má yáwó ní osù kẹrin ọdún nítorí kò lé rọrùn láti tún máá gbé ètò ìṣúná pàdá wá sí iwájú ilé fún atúntò.
Adejoke Ewaede: Ìfẹ́ àṣà Yorùbá ló mú kí ń pinnu láti máa wọ aṣọ àdìrẹ̀ nìkan
" Mo gbọ́ pé, wọ́n ti buwọlu owó sáà méjì, bẹ́ẹ̀ sáà tó kẹ́yìn nínú ọdún ni a wa. Èyí ba gbogbo gbogbo wàhálà ti a ti n ṣe láti ẹ̀yin wá láti ri dáju pé, ètò iṣún ti ààrẹ gbé wá si iwájú ilé kọja.
 Mó n ri bi owó ti ìjọba n pa wọle ṣe n dínkù lójoojúmọ́, sùgbọ́n mo mọ̀ pé gbogbo ènìyàn ló n sa owó orí nígbà náà, yálà o jẹ́ káfíntà, abí awakọ èrò, ohun yó[wù kí o ma ṣe gẹ́gk bi iṣẹ́ òòjọ́."
" O ṣe pàtàkì kí ètò owó orí wá ní Nàìjíríà láti fi aayè gba gbogbo ènìyàn láti san owó orí, Jáde lọ kí o lọ bèrè lọ́wa àwọn ènìyàn níta idá ọgọ́rin sí àádọ́rùn tó n ṣe iṣẹ́ ara wọn wọn kìí san owó orí.
Ẹ̀wẹ̀, ti a bá n gbọ́ pé FIRS ń fẹ ètò owó orí gbígbà sí, kíló dé tí wan ko wá ọ̀nà láti mú kí àwọn ènìyàn yìí máa san owó, yálà ò ń ṣiṣẹ́ káfíntà, awakọ̀, tàbi oun ta ìrẹ̀si ninú ọjà.
Àwọn ènìyàn yìí n rí bẹ̀nbẹ owọ, sùgbọ́n wọn kìí san kabọ̀.
Afenifere Vs Buhari: Ìsọwọ́ gba àkóso àwọn agbésùmọ̀mí ń pè fún ìgbésẹ̀ kíákíá
Oríṣun àwòrán, Nigeria Army
Ẹgbẹ to n ja fun itẹsiwaju awọn ọmọ ilẹ Yoruba, Afenifere ti kesi aarẹ orileede Naijiria lati wa wọrọkọ fi ṣada lori ipenija aabo to n ba ilẹ naa.
Ninu atẹjade kan ti akọwe ipolongo ẹgbẹ naa, Comrade Jaye Ajayi fi sita, o ni ijọba ni lati tete gbe igbesẹ to munadoko ki Naijiria ma baa tuka.
Ni paapa, Jaye sọ pe ọwọ tawọn agbesunmọmi ṣe n pẹka si lawọn ilu apa ariwa Naijiria ati bi awọn agbebọn ṣe n ṣoro ni ilẹ Igbo jẹ ohun to yẹ fun atunṣe kiakia.
Gẹgẹ bi o ti ṣe ṣalaye, o ni iwadii kan fi han pe awọn agbebọn yabo olu ileeṣẹ agọ ọlọpaa to wa ni
Umulokpa, ni ijọba ibilẹ Uzo-Uwani ni Enugu lọjọ Ẹti ti wọn si jin ọlọpaa kan gbe.
O ni eyi nikan kọ, wọn tun gbe awọn eeyan meje mii to wa ni ibudo ti wọn ti n kọ nipa ẹsin,St Albert the Great Institute of Philosophy, ni Kaduna lọjọ Aje.
O sọ pe awọn iṣẹlẹ yi jẹ itọka si ọwọja bi awọn agbebọn ṣe n ṣe ikọlu si awọn agọ ọlọpaa ati ibudo awọn ọmọ ologun ni Naijiria.
''Lọsẹ to kọja la gbọ pe awọn aṣẹku ọmọ ikọ Boko Haram n da ibuba silẹ lawọn abule kọọkan ni ilu Kuje ni Abuja to jẹ olu ilu Naijria''
''Koda alaga ijọba ibilẹ Shiroro ni ipinlẹ Niger  Họnọrebu Suleimn Chukuba naa sọ pe awọn agbesunmọmi ti gba ibudo to fẹ ẹ to ẹẹdẹgbẹta ni agbegbe naa''
Adejoke Ewaede: Ìfẹ́ àṣà Yorùbá ló mú kí ń pinnu láti máa wọ aṣọ àdìrẹ̀ nìkan
Yatọ si awọn akawe yi ti Afenifere sọ pe o to ki wọn wa nkan ṣe si, ẹgbẹ naa tẹsiwaju pe lawọn apa kan ilẹ kaarọ o jiire bi  opopona Ibadan si Ijebu, apa kan Ondo,Ekiti,Ogun ati Osun,iwa ijinigbe ati adigunjale n waye
leralera.
''Iru nkan bayi tun ṣẹlẹ ni ipinlẹ Edo to fi mọ awọn ibomiran naa''
Ninu amọran wọn, afẹnifẹre ni ijọba aarẹ Muhammadu Buhari mọ́ gbogbo ipenija to n koju Naijiria bẹẹ si ni wọn mọ ọna abayọ.
Wọn ni idi ni pe Aarẹ fun ara rẹ nigba to n polongo ibo lọdun 2011 labẹ asia CPC  ti sọ pe idasilẹ ọlọpaa abẹle jẹ ọna kan gbogi lati fi dẹkun ipenija aabo to n koju Naijira.
Oríṣun àwòrán, Nigeria millitary
Lootọ ni aarẹ ko wọle ni ọdun 2011 ṣugbọn lati igba to ti wa lori oye,o ṣa ti yẹ ko wa nkan ṣe si ọrọ yi nipa lilo aba to da nigba to n polongo ibo.
Afẹnifẹre sọ pe asiko ka maa fẹsẹ wọle ko si mọ bi kii ṣe pe ki aarẹ wa wọrọkọ fi ṣada.
Ninu amọran ti wọn gba aarẹ ni pe ki:
PDP Chairmanship race: Iyorchia Ayu di alága tuntun fún ẹgbẹ́ òṣèlú PDP
Oríṣun àwòrán, other
Aarẹ ile asofin agba nigba kan ri, Sẹnetọ Iyorchia Ayu ni wọn yan bayii gẹgẹ bi alaga tuntun fun apapọ ẹgbẹ oṣelu PDP bayii.
Fun asiko diẹ ni ariyanjiyan ti n waye lori ta gan ni yoo dari ẹgbẹ oṣelu PDP wọ inu saa idibo loriṣiriṣi to n bọ lọna ti yoo si ṣide fun eto idibo apapọ ọdun 2023.
Orukọ Sẹnetọ Ayu jade lẹyin ipade ọlọpọ wakati laarin awọn ọmọ igbimọ ẹgbẹ oṣelu naa lẹkun ariwa orilẹede Naijiria, eleyi to waye nile ijọba ipinlẹ Bauchi to wa nilu Abuja.
Igbimọ iṣakoso apapọ ẹgbẹ oṣelu PDP ti pin ipo alaga ẹgbẹ oṣelu naa fun iha ariwa.
Anambra election and police security: Ọ̀lọ́pàá 34,587 níjọba àpapọ̀ ń rán lọ Anambra láti kojú agbébọn tó bá gbémú lásìkò ìbò gómìnà
Oríṣun àwòrán, Nigeria police
Oṣu kọkanla ọdun 2021 ni eto idibo sipo gomina nipinlẹ Anambra yoo waye, bẹẹni kukukẹkẹ awọn ikọlu agbebọn ko yee waye nibẹ eleyi to n mu ki ọpọlọpọ maa bere pe ṣe ibo yoo lee waye nipinlẹ Anambra?
Nibayii, ọga agba ọlọpaa lorilẹede Naijiria, Usman Alkali Baba ti ko ọlọpaa ẹgbẹrun mẹrinlelọgbọn o le ọrinlelẹẹdẹgbẹta ati meje (34,587)  lọ si ipinlẹ Anambra bayii.
Lasiko ipade agbeyẹwo ibi tọrọ abo de duro eleyi tawọn lọgalọga lẹnu iṣẹ ọlọpaa maa n ṣe loorekoore, eyi to waye lolu ileeṣẹ ọlọpaa nilu Abuja lọjọbọ ni Ọga ọlọpaa Alkali Baba ti paṣẹ ki wọn ko awọn ọlọpaa naa gba Anambra lọ.
O ni igbesẹ naa ṣe pataki lẹyin ti wọn ṣe ọfintoto awọn wahala to lee fẹ bomipana alaafia lasiko idibo sipo gomina to n bọ lọna nipinlẹ Anambra.
Bakan naa lo tun paṣẹ ki wọn ko baluu ọlọpaa mẹta dani bi wọn ba nlọ ki wọn si ko awọn irinṣẹ ọlọpaa oju omi, ọlọpaa to n fẹranko ṣiṣẹ atawọn ẹka miran pẹlu dani lọ koju awọn agbebọn tabi janduku to ba fẹ gbemu lasiko idibo naa.
Olota Of Ota: N kò fara mọ́ ìyapa Nàíjíríà, ìṣèjọba ẹlẹ́kùnjẹkùn ní ọ̀nà àbáyọ
Awọn ọlọpaa kogberegbe MOPOL, awọn ti ikọ to n koju ado oloro awsn to n koju agbesunmọmi ati awsn ikọ miran nileeṣẹ ọlọpaa n ko lọ sipinlẹ Anambra.
Atẹjade kan ti alukoro ileeṣẹ ọlọpaa lorilẹede Naijiria, Frank Mba fi sita fi kun un pe gbogbo awọn ọga agba ẹlẹkunjẹkun, ati kọmiṣọna ọlọpaa nipinlẹ gbogbo lorilẹede Naijiria ni wọn ti ke si pe ki wọn tete lo tubọ so okun abo ko le daindain lawọn ẹka ti wọn fiwọn jẹ le lori.
Son Kills Father Over Chicken Head: Orí adìyẹ fà wàhálà láàrin Godwin àti bàbá rẹ̀ nípínlẹ̀ Ondo, ló bá ṣá bàbá rẹ̀ làdá pa
Oríṣun àwòrán, Pbs
Ọjọ buruku eṣu gbomi mu lọjọ naa ti arakunrin kan ṣa baba rẹ lada pa nitori o fun lori adiẹ jẹ ninu adiẹ to pa lati fi ṣe aburo rẹ lalejo.
Godwin Matthew ẹni ọdun mẹrindinlogun la gbọ pe o ṣa baba rẹ lada pa nilu Akure.
Alukoro ọlọpaa Funmi Odunlami ninu atẹjade to fi sita sọ pe iyawo oloogbe naa lo  fi iṣẹlẹ ipaniyan naa to awọn agbofinro leti ni agọ ọlọpaa to wa ni Ala.
''Ni ọjọ kẹsan oṣu Kẹsan ni arabinrin Christianah Audu Matthew  mu ọrọ ipaniyan wa si agọ ọlọpaa pe ọmọ rẹ Godwin Matthew tẹle baba rẹ lọ si oko ṣugbọn awọn pada wa mọ pe o ṣa baba rẹ lada pa''
''Lẹyin iwadii afurasi naa sọ pe baba oun ni ki oun pa adiẹ fi ṣe aburo rẹ Emmanuel Audu lalejo.Nitori pe baba rẹ fun ni ori adiẹ ikan jẹ lo mu ki o ṣa baba rẹ lada pa''
Ileeṣẹ ọlọpaa tun ṣalaye fun awọn akọroyin ninu atẹjade naa pe awọn ti mu arakunrin ẹni ọdun mẹrinlelọgọta kan Ajayi Awe to fipa ba ọmọdebinrin ọmọ ọdun mẹfa kan lo pọ.
Gẹgẹ bi o ti se sọ, ni nkan bi ago mẹ́jọ alẹ ni arabinrin Obademi Fatimah kan wa fẹjọ sun lagọ ọlọpaa pe eeyan kan fipa ba ọmọde kan lo pọ.
Adeyemi Olubunmi Crown: Láti ìgbà ti mo ti fún ọkọ mi ni ẹ̀bùn mọ́tò ni ìfẹ́ wa ti yàtọ̀
Ninu alaye yi, o ni ọmọ oun ti wọn forukọ bo lasiri ti wọn jijọ n gbe ni ile kan naa ni arakunrin Ajayi Awe fipa ba lopọ ninu ile rẹ.
Awọn ọlọpaa ni wọn ti mu afurasi naa lọ si ahamọ ti ọmọdebinrin to farakasa iṣẹlẹ naa si ti n gba itọju nile iwosan.
Bakan naa ni alukoro ọlọpaa ni afurasi ọhun ti jẹwọ ẹsun ti wọn fi kan.
O ni ko ni pẹ tawọn yoo fi gbe lọ si ile ẹjọ lẹyin iwadii ọlọpaa.
Ó kéré tán, ó yẹ kí èèyàn máa pààrọ̀ ìfọyín rẹ̀ lẹ́ẹ̀kan láàrín oṣù mẹ́ta - Dókítà eyín
Dokita kan to n ṣe itọju eyin, Modupe Oyetade ti sọ pe ti eeyan ko ba tọju eyin rẹ daadaa, o le yọri si aisan ọkan.
Ninu ifọrọwerọ pẹlu BBC Yoruba, Oyetade ṣalaye pe aisan kan ti wọn n pe ni akokoro le pa eeyan lara.
Gẹgẹ bii ohun to sọ, awọn kokoro to n gbe ninu ẹnu eeyan ti ko si kuro nibẹ le ṣakoba fun ọkan eeyan.
Dokiya naa ṣalaye siwaju si pe awọn kooro eyin ọhun tun le ṣakoba fun alaboyun.
O ni “Ti awọn kokoro ba wa ninu eyin, ti wọn ko si kuro nibẹ, ti wọn korajọ sinu erigi, o le fa aisan ọkan fun eeyan.”
“To ba jẹ obinrin to loyun ni, awọn kokoro naa a lọ si ibi ti ile ọmọ rẹ wa, wọn a jẹ ki o bi ọmọ ti ko tii to bi.”
Oyetade sọ siwaju si pe “Ẹlẹkẹta, awọn kokoro naa le lọ si ibi nnkan ọmọkunrin ti wọn ti n pese aatọ, wọn a dẹ lọ fa adinku ba ipa irufẹ ọkunrin bẹẹ lati le fun obinrin loyun lasiko ibalopọ.”
Lẹyi naa lo gba awọn eeyan nimọran lati dẹkun lilo awọn nnkan to le pa ẹyin wọn lara lati fọ ẹnu bii omi batiri ati bẹẹ lọ.
Niti awọn to maa n lọ ṣe èjí atọwọda nitori ẹwa, awọn to fẹran lati maa lo igi itayin fun wakati pipẹ atawọn to fẹran lati maa bo eyin wọn ko le funfun daadaa lai kọkọ kan si dokita wọn, Oyetade sọ pe ewu nla ni wọn n fun ilera ara wọn.
Ẹkunrẹrẹ ohun ti dokita eyin naa sọ wa ninu fidio yii.
Nigerian army: Agbésùmọ̀mí 13,000 ló jọ̀wọ́ ara wọn fún ìjọba láàrín ọ̀sẹ̀ méjí
Oríṣun àwòrán, HQ Nigerian Army
Ileeṣẹ ọmọ ogun Naijiria ti sọ pe ko din ni ẹgbẹrun mẹtala ọmọ ẹgbẹ agbesumọmi to ti jọwọ ara wọn fun ijọba apapọ laarin ọsẹ meji sẹyin.
Aṣoju alukoro ileeṣẹ ọmọ ogun, Bernard Onyeuko lo fi ọrọ naa lede nibi to ti sọ pe awọn mọlẹbi awọn agbesunmọmi naa wa lara awọn eeyan ọhun, to fi mọ awọn iyawo atawọ ọmọ wọn.
O ni awọn ṣekupa mọkandinlọgbọn lara awọn agbesumọmi naa, nigba ti wọn fi ṣikun ofin mu mẹtala ninu wọn.
Onyeuko ni Akitiyan awọn ọmọ ogun ori ilẹ ati oju ofurufu ni iha Ariwa ila-oorun Naijiria ti  so eso rere, adinkun si ti ba bi awọn agbesunmọ ni ṣe n kọlu awọn Naijiria."""
Laarin asiko ti a n sọrọ rẹ yii, pupọ ninu awọn agbesumọmi naa ni a ti ran lọ si ọrun aremabọ, ti a si ti fi ṣikun ofin mu ọpọ, to fi mo awọn to n ṣe agbodega fun wọn.
Akokoro eyín lè ṣe ìpalára fún àtọ̀ ọkùnrin, ó sì lè yọrí sí ṣàkóbá fún ọkàn èèyàn
Ileeṣẹ ọmọ ogun sọ siwaju si pe eredi ree ti ọpọ ninu awọn eeyan ọhun ṣe n jọwọ ara wọn fun ijọba apapọ.
"O ni ""Eyi lo fa ti wọn fi  jọwọ ara wọn fun ijọba ti wọn si n ko awọn ohun ija wọn silẹ tawọn ti ẹbi wọn lẹyin ti wọn ri pe ija naa kii ṣe eyii ti wọn le bori."
Lẹyin naa lo ke si awọn ọmọ Naijiria lati ṣatilẹyin fun ileeṣẹ ọmọ ogun ki ọrọ igbesumọmi le di ohun igbagbe ni Naijiria.
University of Ibadan new VC: Ohun tó yẹ kí o mọ̀ nípa Ọ̀jọ̀gbọ́n Oyebode Adebowale, gíwá tuntun ní fásitì Ibadan
Oríṣun àwòrán, other
Igbimọ iṣakoso fasiti ilu Ibadan ti yan Ọjọgbọn Kayọde Oyebọde Adebọwale gẹgẹ bi Giwa tuntun fun ile ẹkọ giga naa.
Igbimọ naa labẹ idari Oloye John Odigie-Oyegun buwọlu orukọ Ọjọgbọn Adẹbọwale gẹgẹ bi giwa kejila fun fasiti naa to ti pe aadọrin ọdun lẹyin ti ipo naa ṣofo ni ọjọ kini oṣu kejila ọdun 2020.
Oloye Odigie-Oyegun ṣalaye ninu atẹjade kan to fọwọsi pe eeyan mẹrindinlogun lo dide fun ipo naa  ki wọn to yan Ọjọgbọn Adẹbọwale.
Chiwetalu Agu: Mí o kàbàámọ̀ pé mo wọ́ aṣọ''Rising Sun'' tí wọ́n torí rẹ̀ mú mí
Oríṣun àwòrán, Google
Ilumọọka oṣere tiata Nollywood ti awọn ọmọ ogun ati DSS Naijiria mu laipẹ yi, Chiwetalu Agu ti ṣalaye ohun ti oju rẹ ri ni ahamọ.
Lasiko to n ba awọn akọroyin sọrọ, o ni n ṣe ni wọn fi oun si iyara to dọti, ti ko si si aṣọ lori ibusun ti wọn fun oun.
Koda o ni ibusun ti wọn gbe fun oun ti ya jatijati pẹlu.
O ni nkan bi wakati mẹsan si mẹwaa ni wọn fi n beere ọrọ lọwọ oun ṣugbọn wọn ko fi ọwọ kan oun.
Lọjọ Iṣẹgun to kọja yi ni wọn tu Chiwetalu silẹ kuro lahamọ ajọ ọtẹlẹmuyẹ DSS lẹyin tawọn ọmọ Naijiria fẹnu si ọrọ rẹ.
Akokoro eyín lè ṣe ìpalára fún àtọ̀ ọkùnrin, ó sì lè yọrí sí ṣàkóbá fún ọkàn èèyàn
Ṣaaju ni o ti kọkọ wa ni ahamọ lọdọ awọn ọmọ ogun ti wọn ni o wọ aṣọ to ṣafihan ikọ IPOB ti ijọba fofin de.
Ninu ifọrọwerọ yii bakan naa, Chiwetalu sọ pe oun pinu lati fara da nkan ti oju ba ri lai ba awọn agbofinbro naa ṣe agidi.
''Mo lọ sibẹ ki wọn baa le gbọ nkan ti mo fẹ wi ni. Mi o ba ija lọ. Ijọba yii n ṣe bi ologun pupọ. Ki lo de ti wọn yoo mura kankan mọ eeyan ti kii ṣe ologun''
"''Aarẹ Buhari ni lati pa iwa bi ologun to n hu ti. Bi ọrọ ba de ilẹ, o yẹ ki o ṣe bi baba ni nitori ti ọrọ ba tẹsiwaju bayi, ipe fun iyapa yoo le ju bo se wa yii lọ."""
Nigba ti wọn beere lọwọ rẹ boya wọn dun koko mọ debi pe ẹru n ba lasiko ti o wa ni ahamọ, Chiwetalu sọ pe wọnk o ṣe bẹẹ.
''Wọn ko ba ọrọ de ibẹ yẹn boya nitori pe emi naa hu iwa ọmọluabi. Ko buru pupọ ṣugbọn kii ṣe ibi ti mo fẹ pada lọ.''
Chiwetalu tun sọ pe oun ko ribi ba mọlẹbi oun sọrọ lasiko ti oun wa ni ahamọ, ti eleyi si fọwọ kan oun lẹmi.
Adejoke Ewaede: Ìfẹ́ àṣà Yorùbá ló mú kí ń pinnu láti máa wọ aṣọ àdìrẹ̀ nìkan
Agba Oṣere wa kede pe oun ko ko abamọ wiwọ aṣọ ti wọn tori rẹ mu u.
O ni aṣọ naa ṣafihan oorun to n ran ni ati pe imọ nipa Geography sọ pe iha ila oorun ni oorun ti maa n yọ jade, ti a si maa wọ ni apa iwọ oorun.
''Ko jẹ iyalẹnu. Lila bi oorun a maa waye titi laelale ni. Bi eeyan ba ti sinmi lati maa la, o ku ni yẹn''
''Wiwa ti a wa si ile aye, a wa lati dagba si, lati ja fun ẹtọ wa lai bikita ohun ti ẹlomiran n ro lọkan''
Kwara Abduction: Taiwo àti Kehinde pẹlú awakọ̀, ọlọ́pàá àti ọmọ ọ̀dọ̀ oríàdé bọ́ sọ́wọ́ ajínigbé
Oríṣun àwòrán, NPF
Gende agbebọn ti ji eeyan marun to jẹ ẹbi ati osisẹ ọba alaye kan, Olobbo tilu Obbo-Aiyegunlẹ to wa nipinlẹ Kwara.
Lara awọn eeyan marun ti wọn ji gbe naa la ti ri ibeji kabiyesi, Taiwo ati Kehinde ti wọn jẹ ọmọ ọdun mẹfa pẹlu osisẹ alaabo ọba alaye naa to n jẹ Lawrence Abiodun.
Bakan naa ni wọn tun gbe awakọ Kabiyesi lọ to n jẹ Kunle ati ọmọ ọdọ oriade naa, ti wọn pe orukọ rẹ ni Bukunmi Akanbi.
Nigba to n fidi isẹlẹ yii mulẹ, agbẹnusọ fun ileesẹ ọlọpaa nipinlẹ Kwara,Okasami Ajayi sọ fun iwe iroyin Daily Post pe awọn eeyan naa lo n rinrin ajo bọ lati ilu Osi pada lọ si Obbo-Aiyegunle.
Owalobo funra rẹ, Oba Samuel Adelodun, gan gan si lo funra rẹ lo fi isẹlẹ naa, to waye ni deede aago mẹfa abọ irọlẹ ọjọbọ to awọn ọlọpaa leti.
Akokoro eyín lè ṣe ìpalára fún àtọ̀ ọkùnrin, ó sì lè yọrí sí ṣàkóbá fún ọkàn èèyàn
Okasanmi ni ọkọ Toyota Sienna oriade naa, ti wọn kọ Owalobo tilu Obbo-Aiyegunle si lara, to n gbe awọn eeyan naa pada bọ sile, ni wọn ri lẹba ọna nibi ti isẹlẹ naa ti waye.
"Ni kete ti iroyin naa tẹ wa lọwọ ni Kọmisana ọlọpa nipinlẹ Kwara, Amienbo Tuesday Assayomo, fọn awọn osisẹ ọlọpaa to n dena ijinigbe atawọn ọdẹ ibilẹ lọ si agbegbe naa.
Awọn eeyan yii lo pasẹ fun lati se awari awọn ajinigbe naa, ki wọn si doola ẹmi awọn eeyan ti wọn ji gbe pẹlu."
Kọmisana ọlọpaa naa tun wa rọ awọn araalu to ba kofiri awọn ajinigbe naa tabi mọ ohunkohun nipa wọn lati tete fi to ọlọpaa leti.
O si tun rọ awọn araalu lati maa da nikan rin ni awọn oju popo to da ni asalẹ.
Adejoke Ewaede: Ìfẹ́ àṣà Yorùbá ló mú kí ń pinnu láti máa wọ aṣọ àdìrẹ̀ nìkan
2021 Twin Festival: Aráàlú ní Ifá ló sọ pé ìbejì yóò pọ̀ ní Igboora, kìí ṣe jíjẹ Ìlasa
Ajọdun ọdun ibeji to waye ni ọdun 2021 dun, to si larinrin pupọ nitori awọn eeyan jankan-jankan to peju sibẹ, to fi mọ Alaafin tilu Oyo, Oba Lamidi Olayiwola Adeyemi Kẹta.
Ninu ifọrọwerọ ti BBC Yoruba se fawọn ibeji ati araalu ni wọn ti salaye idi ti awọn ibeji se pọ silu Igboora ati ohun to fa sise ajọdun naa lọdọọdun.
Lara awọn ibeji to ba BBC Yoruba sọrọ lo koro oju si bi awọn obi kan se maa n gbe awọn ibeji jo kiri lati se agbe jẹun.
Awọn ibeji naa ni eyi ko dara to rara nitori awọn ibeji kii se olosi tabi alagbe ọmọ, ti wọn si n ke si ijọba lati se ofin ti yoo pa asa naa rẹ.
Bakan naa ni awọn araalu sọ pe ero awọn eeyan kan to ni bi wọn se maa n jẹ ọbẹ Ilasa to wọpọ julọ nilu Igboora, lo mu ki wọn maa bi Ibeji ko tọna rara.
Awọn kan ni Ifa lo ti kọkọ kede saaju pe ilu naa yoo gbajumọ fun bibi Ibeji lorilẹ aye, eyi to n wa si imusẹ bayii.
Awọn miran ni eeyan le jẹ ọbẹ Ilasa lai ma bi ibeji amọ ti eeyan ba mu omi ilu Igboora sori ounjẹ naa, eroja mejeeji yii ni yoo parapọ lati mu ibeji wa.
Ẹkunrẹrẹ fidio bi ọdun ibeji se lọ nilu Igboora lọdun 20121 ree, ẹ wo o.
Masten Wanjala: Mo máa ń díbọ́n bíi olùkọ́ni agbábọ́ọ́lù láti tan àwọn ọmọdé tí mò ń pa
Oríṣun àwòrán, Directorate of Criminal Investigation, Kenya
Ọkunrin kan, Masten Wanjala, ẹni ogun ọdun, ti jẹwọ pe oun ti pa ọmọdekunrin marun laarin ọdun mẹwa.
Bakan naa lo tun jẹwọ pe se ni oun maa n fun awọn ọmọ naa ni oogun mu, ki oun to pa wọn, ti oun yoo si tun mu ẹjẹ wọn lẹyin ti oun ba pa wọn tan.
Wanjala lo jẹwọ bẹẹ fun ileesẹ ọlọpaa ilẹ Kenya, to si ni ọmọ ọdun mẹrindinlogun ni oun wa, nigba ti oun pa ọmọdekunrin akọkọ.
O ni se ni oun maa n dibọn bii akọnimọọgba fawọn agbaabọọlu ke ke ke, ti oun yoo si tan awọn ọmọde naa lọ sibi to dakẹ lati pa wọn.
Nigba miran, Wanjala ni oun maa n ji awọn ọmọ naa gbe lati gba owo lọwọ awọn obi wọn.
Báyìí ni mo ṣe san nínú oore Ọlọ́run tó fi Kábíyèsì Ooni ti Ile Ife ta èmi Silekunola lọ́rẹ - Olorì Wòlíì Naomi
2021 Twin Festival: Aráàlú ní Ifá ló sọ pé ìbejì yóò pọ̀ ní Igboora, kìí ṣe jíjẹ Ìlasa
Ilu Nairobi si lo ti ni oun ti maa n pa awọn ọmọde naa ati lẹkun ila oorun ati iwọ oorun orilẹede Kenya.
Niwọn igba to jẹ pe asegbe kankan ko si, asepamọ lo wa, ọwọ awọn agbofinro papa tẹ afurasi apaayan yii, ti wọn si fi si ahamọ, ko le foju ba ile ẹjọ.
Amọ nigba to ya ni iroyin gbalẹ kan pe Wanjala ti sa kuro ni ahamọ, ti ẹnikẹni ko si mọ ibi to wa.
Awọn ọlọpaa mẹta to wa lẹnu isẹ lasiko ti afurasi naa di awati lọjọru to kọja si ni ijọba ti sọ si ahamọ lori ẹnu pe awọn lo se onigbọwọ bo se salọ.
Ileesẹ ọlọpaa ni awọn fura pe Wanjala ri aaye sa kuro ni ahamọ lasiko ti awọn n pe orukọ awọn afurasi to wa nibẹ ni.
Idi si ree ti awọn alasẹ se kede pe wọn n wa ọdọmọkunrin mujẹ mujẹ naa, ki awọn eeyan si fi iroyin nipa rẹ to awọn leti.
Ninu oniruuru ọrọ ti awọn araalu n kọ sori ayelujara, ni wọn ti n tutọ soke, fi oju gba pe ejo lọwọ ninu.
Adejoke Ewaede: Ìfẹ́ àṣà Yorùbá ló mú kí ń pinnu láti máa wọ aṣọ àdìrẹ̀ nìkan
Ni kete ti Wanjala ti sa kuro ni ahamọ ọlọpaa ni ọkan awọn araalu ko ti balẹ mọ, ti wọn si n tọ ipasẹ rẹ kiri.
Wọn tọpasẹ rẹ de ile kan ni abule Bungoma, ti wọn si lu pa nibẹ.
Ẹnikan ti isẹlẹ naa soju rẹ sọ fun iwe iroyin kan nilẹ Kenya pe afurasi ọhun lo pada sile lọdọ awọn obi rẹ, ti wọn ni awọn ti kọ lọmọ tẹlẹ.
Ileesẹ ọlọpaa Kenya ni bi o tilẹ jẹ pe o lọ fi ara soko sinu ile kan amọ awọn araalu ka mọ ibẹ, ti wọn si yin ni ọrun pa sibẹ.
Gẹgẹ bi iwe iroyin Reuters ti wi, wọn ti n se iwadii lọwọ lati ri daju pe Wandala ni eeyan ti wọn lu pa, bi o tilẹ jẹ pe wọn ni awọn obi rẹ ti da oku naa mọ bii ọmọ wọn.
Akokoro eyín lè ṣe ìpalára fún àtọ̀ ọkùnrin, ó sì lè yọrí sí ṣàkóbá fún ọkàn èèyàn
Amọ sa, ọkan lara iya awọn ọmọde mẹwa ti afurasi naa pa sọ fun BBC pe oun wu oun lati ba Wanjala sọrọ, ki wọn to lu pa.
O ni ohun ti oun ko ba bi ni pe ki lo de to se hu iru iwa ika bii eyi.
"Ko ba wu mi ki n ri ko kawọ pọnyin ro ẹjọ ninu igi niwaju adajọ lati sọ ohun to ri lọbẹ, to fi wa iru sọwọ.
Grace Adhjambo salaye pe o yẹ ko le sọ idi to fi pa awọn ọmọ wa, to si fi wa sinu irora ayeraye."
Ọkan lara awọn ọmọ kekere ti Wanjala pa yii ni oku Brian Omondi to ti n jẹra, to si wa lara oku awọn oku mẹrin ti ọlọpaa ri ni ẹba ilu Nairobi losu Keje ọdun 2021.
Ayẹwo awọn onimọ isegun oyinbo fi han pe wọn fun awọn ọmọ naa lọrun pa ni, ti wọn si tun lu wọn ni nnkan lori.
Ridwan Oyekola: October 30 ni màá tún ìjà jà láti gba belt mi padà àmọ́ kò sí onígbọ̀wọ́
Ileesẹ to n se iwadii iwa ọdaran lorilẹede Kenya wa n fi ika hanu pe afurasi naa ko iku nifa lai koju idajọ.
Koda, awọn araalu ti n pe pe ki ọga ọlọpaa lorilẹede Kenya kọwe fipo silẹ nitori bi afurasi naa se kuro ni ahamọ ọlọpaa.
Bakan naa ni awọn eeayn n fi awọn ọlọpaa se ẹlẹya lori ayelujara, ti iku Wanjala si tun ran awọn araalu leti ẹhonu wọn sawọn agbofinro lorilẹede naa.
Sunday Igboho: Ẹ̀yin oríadé ẹ dìde, wàhálà ń bọ̀ nílẹ̀ Yorùbá, ọ̀dọ́ 10m fẹ́ jà fún Igboho
Yoruba ni bi wọn ba le ewure titi, to fi sun kan ogiri, yoo pada bu olowo rẹ jẹ ni.
Owe yii ni awọn alatilẹyin ajijagbara fun iran Yoruba kan, Oloye Sunday Adeyemo, ti ọpọ eeyan mọ si Igboho n pa fun ijọba apapọ.
Bẹẹ ba gbagbe, Sunday Igboho lo ti wa ni ahamọ ọgba ẹwọn nilu Cotonou fun bii osu mẹta bayii, ti ẹjọ rẹ ko si fori sọ ibi kankan.
Bakan naa ni ijọba Naijiria kede lọjọ Ẹti pe oun ti mọ awọn eeyan to n se atilẹyin fun Sunday Igboho lati maa jijagbara.
Lara awọn eeyan to si darukọ pe o n ti Igboho lẹyin ni ọmọ ile asofin agba kan ati eeyan kan ti wọn lo n se onigbọwọ fun ikọ Boko Haram.
Irú omi àti oúnjẹ tí wọ́n ń fún Sunday Igboho, a ó mọ̀ọ́, à ń fura sí ohun tó ń lọ lọ́wọ́ látìmọ́lé Cotonou
Nibayii, asaaju awọ̀n eeyan to jẹ alatẹle Sunday Igboho ti wa kede pe awọn ọdọ to le ni miliọnu mẹwa ti setan lati ja fun asaaju wọn naa.
Alhaji Yusuff Saheed Ajikobi, to n se akoso Sunday Igboho lo sisọ loju ọrọ yii fun BBC Yoruba lasiko ifọrọwerọ kan.
Ajikobi ni awọn ọdọ naa ti setan lati woju ijọba, ki wọn si bẹrẹ si fa wahala lẹsẹ lati pe fun idande Sunday Igboho.
O ni Igboho ko sẹ amọ ti ijọba ba ni o sẹ awọn, se ni ki wọn tete fi ori jin, ki wahala to fọn ina soju.
"Awọn ọdọ yii ni inu n bi tori bi wọn se ti Sunday Igboho mọle lainidi amọ awa la n di wọn lọwọ mu pe ki wọn ni suuru na, ki wọn mase da wahala silẹ.
Sunday Igboho Update: Igboho ti sọ ohun tó fẹ́ kí a ṣe tí ọ̀rs bá bẹ́yìn yọ- Saheed Yusuf
Awọn ọdọ to jẹ atẹle Sunday Igboho yii ri gbogbo ohun to n lọ nilẹ Igbo lapa ila oorun guusu Naijiria, ti wọn si ti setan lati da irufẹ wahala yii silẹ lẹkun iwọ oorun guusu Naijiria pẹlu.
Ba si se n mu wọn lọwọ silẹ yii lati mase fa wahala ni wọn ti n ri wa bii ọdalẹ, nitori wọn gba pe iku ya ju ẹsin lọ.
Ijọba ti mu ki aye nira pupọ fun awọn ọdọ, ti wọn ko si fi bẹẹ ni ireti kankan mọ ninu ilẹ Naijiria.
Koda, awọn eeyan wa ko bẹru awọn osisẹ agbofinro mọ ni akoko ta wa yii, ti ohun gbogbo si ti dẹnu kọlẹ.
Gbogbo awọn isẹlẹ yii ati bi wọn se fi Sunday Igboho si ahamọ laini ẹsẹ kankan lọrun pato lo n sun awọn ọdọ naa kan ogiri lati ja."
Alhaji Ajikobi wa n ke si awọn oriade nilẹ Yoruba ati awọn oloselu lati tete dide si ọrọ yii ko to pẹ ju.
O ni yoo dara ki wọn rọ ijọba lati tete tu Sunday Igbogbo silẹ ni ahamọ ko to pẹ ju, ko le lọ gba iwosan to yẹ.
Olota Of Ota: N kò fara mọ́ ìyapa Nàíjíríà, ìṣèjọba ẹlẹ́kùnjẹkùn ní ọ̀nà àbáyọ
Katsina Kidnap: Ọmọ lẹ̀dí àpò pọ̀ mọ́ ará abúlé méjì láti jí bàbá rẹ̀ gbé gba owó
Oríṣun àwòrán, Nigerian Police Force
Hamza Isah, tii se ẹni ọdun mẹẹdọgbọn to wa lati abule Rinjin Gora nipinlẹ Katsina ti jẹwọ pe oun lo lẹdi apo pọ mọ awọn ajinigbe lati gbe baba rẹ ninu ile wọn.
Hamza ni ẹgbẹrun lọna igba naira ni awọn agbebọn naa seleri lati fun oun lori isẹ naa.
Ọdọkunrin naa, ti oun ati baba rẹ, Alhaji Isah Maigora tii se ẹni ọgọta ọdun maa n saba woju ara wọn, lo n sọ tẹnu rẹ ni agọ ọlọpaa bayii.
Hamza ni oun ati eeyan meji miran, ni abule awọn, ti gbogbo wọn dijọ wa ni ahamọ ọlọpaa, ni awọn dijọ pete pero lati gbe baba oun, ẹni to si wa nibi ti wọn fi pamọ si, ti ẹnikẹni ko tii mọ bayii.
Osisẹ alarena fun ileesẹ ọlọpaa nipinlẹ Katsina, Isah Gambo, lo fi oju awọn afurasi ajinigbe naa han fawọn akọroyin ni olu ileesẹ ọlọpaa ipinlẹ naa lọjọ Ẹti.
Ogogo wá sí iléèwé wa, mo kéwì fún un ló sọ mi di èèyàn ńlá lórí ayélujára - Akinwumi Akewi
"Mo maa n ba baba mi ja ni ọpọ igba ni. Mo wa lọ si ọdọ Auwal Magaji pe ko ran mi lọwọ pẹlu ajilẹ.
Amọ o ni kii se nipa ajilẹ nikan ni oun uoo fi ran mi lọwọ, amọ oun yoo fun mi ni owo to pọ, ti mo ba gba lati se iranwọ fun wọn lati ji baba mi gbe.
Loju ẹsẹ naa lo ti fun mi ni ẹgbẹrun lọna ogun naira, to si seleri pe oun yoo fun mi ni ẹgbẹrun lọna igba naira, ti wọn ba ji baba mi gbe, ti wọn si ri owo gba lọwọ rẹ.
Mo ni yoo nira pupọ lati ri baba mi gbe nitori aabo to daju wa ni ayika wa amọ wọn ni ki n ma yọ ara mi lẹnu nipa iyẹn.
Wọn wa fun mi ni orisi oogun abẹnu gọngọ mẹfa pe ki n ri mọlẹ ni agbala wa, mo si se bẹẹ;
Lẹyin ọjọ kẹta ni wọn wa sinu ile wa, ti wọn si ji baba mi gbe lọ, amọ mo pinnu lati tu asiri ọrọ yii.
Idi ni pe lẹyin ọjọ kẹta ti wọn ji baba mi gbe, mo lọ ba Auwalu Magaji pe mo fẹ da owo to fun mi pada, amọ o ni ẹmi mi wa ninu ewu ti mo ba sọ fun ẹnikẹni.
Amọ nigba ti awọn ọlọpaa gbe mi wa si ahamọ wọn, ti iya nla si jẹ mi ni mo ba tu asọ loju eegun, ti mo si tu asiri naa sita."
Àwọn abirùn ọmọ tí òbí wọn tì mọ́lé ni mo lọ ń kó jáde láti máa kọ́ lẹ́kọ̀ọ́ iléèwè - Sekinat Ahmed
Amọ agbẹnusọ fun ileesẹ ọlọpaa sọ fawọn akọroyin pe ẹgbọn Hamza, ti orukọ rẹ n jẹ Buhari Isah, lo n fura nipa awọn ọrọ to n jade lẹnu aburo rẹ lẹyin ti wọn ji baba wọn gbe tan.
O ni se ni aburo oun n leri leka pe oun yoo ni owo to pọ laipẹ laijinna.
Idi ree ti Buhari fi ke sawọn ọlọpaa pe ki wọn wa da si ọrọ naa, lasiko ifọrọwanilẹnuwo naa si ni asiri tu.
Amọ awọn afurasi meji yoku ti wọn fi ẹsun ijinigbe naa lan ti sẹ pe awọn ko mọ ohunkohun nipa isẹlẹ yii, ti ileesẹ ọlọpaa si ni iwadii si n lọ lọwọ nipa isẹlẹ naa.
Man puts Himself Up for Sale: Hisbah kéde ìdí tó fí mú ọkùnrin tó lù ará rẹ ní gbanjo ₦20m
Oríṣun àwòrán, SANI IDRIS/ FACEBOOK
Njẹ ẹ ranti arakunrin ọmọ ọdun mẹrindinlọgbọn to ni oun fẹ lu ara oun ni gbanjo ogun miliọnu naira?
Ikọ ọlọpaa ẹsin Hisbah ni Kano ti mu .
Wọn ni ni idi tawọn fi mu ni pe ẹsin Isilaamu tapa si ki eeyan ni oun fẹ ta ara oun.
Laipẹ yi ni iroyin gba oju opo ayelujara nigba ti Aliyu Na Idris le ara rẹ sori igba, to si ni ẹni ba ni ogun miliọnu naira lanfaani lati ra oun.
Olori ikọ Hisbah Haruna Inb Sina fidi ọrọ mulẹ pe, awọn ti mu arakunrin naa ati pe ọdọ awọn lo sun mọjumọ.
''Bẹẹ ni lalẹ ana la mu, o si sun lọdọ wa mọjumọ ṣugbọn mi o ti ba sọrọ''
Ọga Hisbah naa sọ fun BBC pe lowurọ Ọjọru ni oun yoo lọ ba arakunrin naa ti awọn yoo si jọ fọrọ jomi toro ọrọ.
Timi Osukoya: Ọ̀pọ̀ olórin ẹ̀mí ló ń kọrin torí owó tàbí afẹ ayé
"Ninu ẹsin Isilammu, eewọ ni ki eeyan gbe ara rẹ kalẹ fun tita labẹ eyikeyi idi to le wu. Mo maa ṣe alaye si nipa ọrọ yii ta ba ri arakunrin naa''
Aliyu to n ṣiṣẹ aransọ ko to gbe ara rẹ sita fun tita sọ fun awọn akọroyin pe iya ohun iṣẹ lo fa sababi toun fi fẹ ta ara oun.
Aliyu kọ si ori patako pe ki awọn eeyan wa ra oun ni miliọnu lọna ogun Naira.
O ṣalape pe ''Awọn mọlẹbi mi mọ si nkan to n ṣẹlẹ to si jẹ pe nitori aisowo ni.Mo kọkọ gbiyanju ni Kaduna ṣugbọn mi o ri eeyan ra mi ki n to wa lọ si Kano''
Awọn kan ti gbe owo lori mi ṣugbọn iye ti wọn da le mi lori ko ti to ogun miliọnu ti mo fẹ''"
"Afojusun mi ni pe bi mo ba fi ri eeyan ra mi, mo maa fun ijọba ni miliọnu marun un gẹgẹ bi owo ori ninu rẹ''
O tẹsiwaju pe ''maa fun awọn obi mi ni miliọnu mẹwaa,miliọnu meji fun ẹni to ba mi polowo,maa si fi miliọnu mẹta to ku si ọdọ ẹni to ba ra mi lati maa fi ṣe itọju mi''
Onwoye kan lawujọ Nura Isah to n gbe ni Kano sọ fun BBC pe o se pataki ki Hisbah mu Aliyu lootọ.
Amọ ọpọ eeyan lo ri gẹgẹ bi ere ohun ẹfẹ to si yẹ ki Hisbah ma ṣe da si ọrọ naa.
Hisbah  ko ba kan pe joko ki wọn si gba nimọran ni dipo bi wọn ṣe mu''"
''Awọn ara Kano kuku ka ọrọ rẹ kun. Amọ bayi ti wọn mu, nkan to n wa pe ki awọn eeyan foju si ọrọ rẹ lo ti wa ri bayii''
Oríṣun àwòrán, SANI IDRIS/ FACEBOOK
Yoruba ni airin jinna ni airi abuke ọkẹrẹ, ti eeyan ba rin jinna, yoo ri ibi ti wọn ti n fi odo ibulẹ jẹun.
Bẹẹ ni ọrọ ri pẹlu ọkunrin kan, Aliyu Na Idris, ẹni ọdun mẹrindinlọgbọn lati ipinlẹ Kaduna, to n polowo ara rẹ fun tita fun ẹnikẹni to ba fẹ lati ra a nilu Kano.
"Idris to ni isẹ aransẹ ni oun n se lo ti n rin gbere gbere kiri awọn opopona nilu Kano pẹlu akọle kan lọwọ rẹ to ni ""Ọkunrin yii wa fun tita pẹlu ogun miliọnu naira."""
Iroyin naa ni o ti to ọjọ marun bayii ti Aliyu ri n polowo ara rẹ kiri oju popo, to n wa onibara ti yoo ra a bii ẹru.
Nigba to n bawọn akọroyin to se alabapade rẹ sọrọ, Aliyu ni isoro ile aye, airijẹ, airimu lo mu ki oun pinnu lati ta ara oun, bi apap ko ba sa se san, a n ka lori ni.
Pistachio Green Puppy: Àwọn ẹgbẹ́ rẹ̀ jẹ́ aláwọ̀ funfun, tí òun sì jẹ́ aláwọ̀ ewé
O ni awọn mọlẹbi oun gan ti mọ pe oun ti n polowo ara oun fun tita, koda, oun ti polowo ara oun ni Kaduna.
Amọ o ni nigba ti oun ko ri onibara gidi ti yoo ra oun, ni oun wa si Kano pẹlu ireti pe oun yoo ri onibara gidi ti yoo san owo ti oun n beere.
Lootọ ni ọpọ eeyan fẹ san miliọnu mẹwa, marun ati ẹgbẹrun lọna ọọdunrun naira lati ra mi amọ awọn owo yii kere si iye ti mo fẹ ta ara mi.
Aliyu ni isẹ aransọ ti oun n se lo kuna tori ọda owo, ti oun si padanu ọpọlọpọ awọn onibara oun, eyi to mu ki aye le lati gbe, ti owo si ta oun lọwọ.
O ni oun ko ni owo lọwọ lati se ile aye, ka to wa sọ pe oun yoo dokowo, idi si ree ti oun se n lu gbanjo le ara oun lori fun tita.
"Nigba ti wọn bi pe ki lo fẹ fi ogun miliọnu naira se to ba ta ara rẹ, Aliyu ni ""Maa fun awọn obi mi ni miliọnu mẹwa ninu owo naa."
Maa tun san miliọnu marun bii owo ori fun ipinlẹ ti wọn ba ti ra mi, maa fun ẹni to seranwọ lati polowo mi fun tita ni miliọnu meji naira.
"Miliọnu mẹta naira to ku ni ẹni to ta mi yoo ba mi fi pamọ fun itọju ara mi lojoojumọ."""
Ogogo wá sí iléèwé wa, mo kéwì fún un ló sọ mi di èèyàn ńlá lórí ayélujára - Akinwumi Akewi
O wa salaye pe oun mọ pe oun ko ni ni ominira mọ lẹyin ti wọn ba ra oun amọ eyi ko da omi tutu si oun lọkan rara.
Aliyu ni oun ti pinnu lati maa se ifẹ ọkan ẹni to ra oun nitori ibi to ba wu ẹfuufu lẹlẹ nii dari igbẹ si, ibi to ba wu olowo ẹni, nii ran ni lọ.
Bakan naa lo leri leka pe bi onibara kankan ko ba yọju lati ra oun nilu Kano, oun yoo tun morile ipinlẹ miran lati polowo ara oun fun tita.
Femi Adesina: Afenifere àti Ohaneze Ndigbo fún Adesina lésì bó ṣe fi Buhari wé Awolowo, Azikwe
Oríṣun àwòrán, Femi Adesina
Awọn oniruuru ẹlẹgbẹjẹgbẹ ni Naijiria lo ti n fun oludamọran si Aarẹ Buhari, Femi Adesina lesi, lori bo se ni araalu nifẹ Buhari ju Awolowo ati Azikwe lọ.
Lara awọn ẹgbẹ to fun Adesina ni esi ọrọ rẹ pada ni Afenifere ati Ohanaeze Ndigbo.
Ọjọ Ẹti ni Femi Adesina kede fun araye pe awọn araalu nifẹ aarẹ Muhammadu Buhari pupọ, ti ero tuulu si maa n jade lati yẹ si nigba kuugba to ba se abẹwo si agbegbe kan.
Bakan naa lo ni ifẹ tawọn ọmọ Naijiria ni si Buhari yii wọ to bẹẹ gẹ, ti ko si asaaju kankan tẹlẹ ni Naijiria tabi ninu ẹya kọọkan ti wọn nifẹ rẹ bii Buhari to wa lori aleefa yii.
Ninu awọn ti Adesina ni wọn ko ni okiki  ati ẹran ifẹ lara to aarẹ Buhari ni Obafemi Awolowo, Nnamdi Azikwe, Sheu Shagari, Aminu Kano to fi mọ MKO Abiola.
2021 Twin Festival: Aráàlú ní Ifá ló sọ pé ìbejì yóò pọ̀ ní Igboora, kìí ṣe jíjẹ Ìlasa
Nigba to n fesi si ohun ti Femi Adesina sọ naa, ẹgbẹ Afenifere ni Adesina sọrọ yii lati mu ki awọn araalu tubọ se odiwọn isesi ati ijọba Buhari ni.
O ni ọmọ ọsan to n ko ponpo ba iya rẹ ni Adesina, ọrọ rẹ yii si lo le se okunfa sisọ oko ọrọ si aarẹ lati ọdọ awọn araalu.
Wọn wa sọ fun Adesina pe ero tuulu to n ri lasiko ti aarẹ n kọja naa ko jade lati ki kaabọ amọ wọn fẹ ko ri awọn ni ati iya nla to n jẹ wọn labẹ isejọba Buhari.
Wọn wa se apejuwe Femi Adesina pe iwa agabagebe lo n hu pẹlu bo se fi aarẹ Buhari we Awolowo, Azikwe atawọn asaaju miran nilẹ Naijiria.
Akokoro eyín lè ṣe ìpalára fún àtọ̀ ọkùnrin, ó sì lè yọrí sí ṣàkóbá fún ọkàn èèyàn
Ẹgbẹ itẹsiwaju ọmọbibi ilẹ Igbo lorileede Naijiria,Ohanaeze Ndigbo,ti bẹnu atẹ lu agbẹnusọ aarẹ Buhari, Femi Adesina, pẹlu bo ti ṣe ṣafiwe Buahri pẹlu awọn to ja fun ominira Naijiria.
Ohanaeze sọ pe afiwe yi da bi ẹni fi oorun we iku ati pe o dabi ki a fi Idi Amin ti Uganda we Winston Churchill ilẹ Gẹẹsi.
Akọwe ipolongo Ohanaeze, Mazi Okechukwu Isiguzoro to fi atẹjade yi sọwọ ni awọn wọnyi ko ṣe fi we pẹlu Buhari lọna kọna.
O ni o ṣeeṣe pe Adesina n san ọna ti iṣẹ ko fi ni bọ mọ lọwọ rẹ ni nitori pe Femi Fani Kayode ko ti darapọ mọ APC.
Atẹjade naa sọ pe ''Tọwọtọwọ la fi n ranti ipa ti Azikiwe, Awolowo ati awọn baba nla wa mi ko lati ri pe Naijiria di amuyangan nilẹ Afrika''
O fi kun pe ''Wọn ṣapa wọn laiṣe oju ṣaaju,lilo ipo ni ilokulo tabi yiyawo laini idi eyi taa mọ ijọba Buhari si lati ọdun 2015 to de ori oye''
Adejoke Ewaede: Ìfẹ́ àṣà Yorùbá ló mú kí ń pinnu láti máa wọ aṣọ àdìrẹ̀ nìkan
Ohanaeze ni Adesina ko kuna wi pe Buhari ju awọn wọn yi lọ nitori ọrọ aje Naijiria dẹnu kọlẹ lẹmeeji  labẹ akoso rẹ.
Ati pe ijọba Buhari lo sọ Naijiria di olu ilu awọn ti oṣi ohun iṣẹ ta julọ lagbaye.
Ẹgbẹ naa wa ni yatọ si Buhari, awọn olori ilẹ yi ṣaaju bi Awolowo ati Azikwe n sanna bi eto ẹkọ ọfẹ ati awọn ilana mi to mu ayedẹrun yoo ṣe rinlẹ lasiko wọn.
Wọn ni lai fabada, ki Adesina maṣe fi Buhari we awọn asaaju yii nitori apejuwe wọn yoo dabi ẹni fi iku we oorun ni.
Oluwo of Iwo: Mí ò kánjú láti fẹ́ ìyàwó míìràn ìgbà tó bá yá náà ló yá
Oríṣun àwòrán, emperortelu1
Yoruba bọ wọn ni apọnle ko si fun ọba ti ko l'olori laafin ṣugbọn ọrọ yi ko ṣebi ẹni de eti Oluwo ilu Iwo Ọba Abdulrasheed Akanbi Telu1.
Idi ni pe Oluwo ti sọ ninu ifọrọwero kan pe oun ko kanju lati fẹ iyawo miran tori naa ki awọn eeyan lọ ṣe mẹdọ.
Oriade yi ti ọpọ mọ fun imura ati ọrọ ṣisọ ni aawọ waye laarin oun ati olori rẹ Chanel Chin ti awọn mejeeji si ti pinya to ọjọ mẹta.
Ninu ifọrọwanilẹnuwo yi, Oluwo sọ nipa aṣa fifẹ iyawo to ju ẹyọkan lọ ati idi ti oun ko fi fẹ ju iyawo kan lọ.
O ni bi eeyan ba wo inu bibeeli eeyan yoo ri pe Isaac ati Jacob, iyawo pupọ ni wọn fẹ, koda ninu aṣa Yoruba, iru nkan bayi ko jẹ tuntun.
''Awọn baba wa a maa niyawo pupọ amọ emi gẹgẹ bi iranṣẹ araalu, mo nifẹ si iyawo kan.''
O ni fifẹ iyawo kan ni yoo jẹ ki oun le ṣe iṣẹ ilu ti oun yan laayo amọ ti agbara ati aaye ba wa o ṣeeṣe ki oun fẹ ju ẹyọkan lọ.
''Bi eeyan ba ṣe iṣẹ pupọ ni ita yoo ni lati sinmi. Bẹẹ lo si tun ni iṣẹ to pọ lati ṣe ninu ile. O ni lati ṣojuṣe rẹ nile lọdọ awọn iyawo rẹ ti wọn ba pọ''.
''Ṣugbọn to ba jẹ ẹyọkan ni, a ṣi le maa faradaa fun ara wa nitori ifẹ. A o jọ ṣiṣẹ ilu papọ ni''.
Nigba ti wọn beere lọdọ Oluwo boya awọn araalu n damu rẹ pupọ lori fifẹ iyawo mi o ni wọn ko daamu oun.
Oríṣun àwòrán, emperortelu1
Oba Rasheed ni oun mọ pe awọn araalu ko ni fẹ ki oun fẹ iyawo mi ti yoo fẹ fun oun ni majele jẹ.
''Fifẹ iyawo, kii ṣe nkan taa ṣe fun eeyan. Lati ọkan lo ti maa n wa.''
''Mo mọ pe awọn eeyan mi ko ni fẹ ki n fẹ iyawo mii ti yoo tori pe ko ri owo gba ti yoo si f fun mi ni majele jẹ''
Nipa ibaṣepọ rẹ pẹlu olori Chanel to kuro laafin, Oluwo ni awọn kan lo ran wa si aafin lati wa tabuku oun.
Oríṣun àwòrán, emperortelu1
O ni oun ko mọ ni Canada tẹlẹ bi kii ṣe igba to de Naijiria ati pe bo ti ṣe de aafin lo ti bẹrẹ si ni ka gbogbo ọrọ ati iṣe oun sori foonu.
''Ki lo de ti obinrin yoo fi maa rikọọdi eeyan fun odidi ọdun mẹrin? Nigba ti mo ka a mọ, o ni afi ki n san owo bomilaṣiri fun oun''.
Oluwo tẹsiwaju pe Olori Chanel ni oun yoo tu aṣiri ohun tawọn se tile fi jona bi ko ba san owo fun oun.
''Mo sọ fun un pe ko tu aṣiri to ba fẹ tu. Ayafi ti kii ba ṣe pe Olorun lo fi mi sori aleefa yi, ko si ẹni to le yọ mi. Olodumare pada da mi lare lori ọrọ yi''.
Tinubu ló ní kí n dákẹ́ bí bẹ́ẹ̀ kọ́, mo mọ èsì tó yẹ kí ń fún Lai Muhammed- Gómìnà Kwara
Asiwaju Bola Ahmed Tinubu gbami nimọran pe ki n ṣe suuru lori ọrọ ti o n daamu ọkan mi nipa Lai Muhammed ṣugbọn mi o le gbagbe abuku to fi kan  mi.
Esi ree lati ẹnu Gomina ipinlẹ Kwara Abdulrahaman Abdulrazaq lori aawọ to n fa gbọnmi si omi o to laarin ohun ati Minisita Lai Mohammed.
Igba akọkọ ree ti Gomina yoo sọrọ nipa aawọ yi. Koda igba akọkọ rẹ ree ti yoo tilẹ ba akọroyin sọrọ lati igba to ti de ori alefa ni nkan bi ọdun meji.
Ninu ifọrọwerọ yi, Gomina ni ko si ootọ ninu ọrọ ti Minisista ati awọn kan n sọ pe ohun ko leeyan ninu ẹgbẹ.
Bẹẹ lo ni lati igba toun ti kọ lati ko owo ẹgbẹ fun awọn kan ninu ẹgbẹ ni wọn ti gbogun ti oun.
O ṣe akawe orisirisi ọna ti Minisita Lai Mohammed fi n gba owo lasiko ipolongo ibo lorukọ oun ti ko si fi owo naa jiṣẹ.
''Bẹẹ ni lati igba ti mo kọ lati gbowo kalẹ fun awọn aṣaaju APC Kwara ni wọn ti kẹyin si mi ninu ẹgbẹ.Wọn o kopa ninu ipolongo mi''
''Ile ni wọn joko si ti wọn n wo DSTV titi taa fi pari idibo aarẹ ti wọn si yọju ni idibo Gomina ku ọjọ meloo kan''
Lara ohun ti oju rẹ ri to sọ ninu ifọrọwerọ yi ni bi wọn ko ti ṣe jẹ ki oun wọ inu ọkọ aarẹ gẹgẹ bi oludije ipo Gomina lasiko ti aarẹ wa ṣe ipolongo ni Kwara.
''Ọpẹlọpẹ ọkan lara awọn ẹsọ aarẹ to pada kesi mi lati wa joko sinu ọkọ aarẹ, ẹyin ọkọ akero bọọsi Coaster ni wọn ko ba fimi si''
Abdulrrahaman Abdulrazaq to jẹ Gomina nigba ti iji gbe awọn eekan ẹgbẹ PDP bi Bukola Saraki lọ labẹ asia ''O to gẹ'' sọ pe awọn ko mọ ipa ti Lai Mohammed n ko ni Kwara.
O tẹsiwajupe ko si Minisita kankan ninu awọn mejeeji to wa lati  Kwara ti wọn maa n wa sile debi ti awọn yoo ri ipa wọn lara ilu.
Bọla Tinubu: Ìpínlẹ̀ Ọ̀ṣun kò ní owó mi lọ́wọ́
''Abuja lawọn mejeeji wa.Wọn kii wa si Kwara.Eko ni Lai maa n lọ.Ibẹ ni ile rẹ wa.Bẹẹ lọrọ ri pẹlu Gbemi Sraki naa. Bi igba pe a ko ni Minisita ni''
O ti to ọjọ mẹta ti aawọ ti wa nilẹ laarin Gomina ati awọn eekan inu ẹgbẹ APC ti pupọ ninu wn si ni ko jẹ ki awọn lẹnu lọrọ ninu ẹgbẹ lati igba to ti de ori oye.
Laipẹ yi ni wọn ṣe idibo abẹlẹ ninu ẹgbẹ oṣelu APC ni Kwara ti awọn igun meji ọtọọtọ si ṣeto idibo wọn.
Ko to di asiko yi, Minisita Lai Mohammed naa ti bẹnu atẹ lu Gomina Abdulrahaman Abdulrazaq ninu fọnran fidio kan nibi to ti ni Gomina ko fi owo kankan kalẹ lasiko ipolongo idibo.
Lai Mohammed sọ fun awọn ọmọ ẹgbẹ to peju sibi ifilọlẹ olu ile ẹgbẹ APC ni Ilorin pe ''amunibini ni Gomina ati pe ojo lo da ẹiyele pọ mọ adiẹ''
Fashola on Rising Debt: Idi ti ijọba Naijiria fi n jẹ gbese
Endsars anniversary: Falz ní kò sí ohun tí yóò yẹ ìwọ́de tí yóò wáyé ní Lekki Toll Gate ní Oct 20
Ni bayii ti awọn ọmọ Naijiria kan ti n mura lati ṣe iwọde ni iranti ifẹhonuhan EndSARS to waye lọdun 2020, ọpọ eeyan lo ti bẹrẹ si n sọ erongba wọn lori iwọde ọhun.Lara awọn eeyan naa ni gbajugbaja olorin takasufe, Folarin Falana, ti ọpọ awọn ololufẹ rẹ mọ si Falz.Ṣaaju ni ileeṣẹ ọlọpaa ipinlẹ Eko ti kọkọ fi atẹjade kan sita lati ọwọ alukoro rẹ, Adekunle Ajisebutu pe awọn ko ni gba ki ẹnikẹni ṣe iwọde kankan ni iranti iwọde EndSARS.
Oríṣun àwòrán, The africa report.com
"Falz ti wa sọ pe ariwo ẹnu lasan ni ileeṣẹ ọlọpa n pa nitori ko si ohun ti yoo yẹ iwọde naa.O ni ""Awọn were, kọmiṣọna ọlọpaa ni ki a ma jade sita nitori wọn mọ pe ogunjọ oṣu Kẹwaa ti n sumọle.""""Wọn ni ki a má jade lọjọ naa, ṣe ori wọn ti daru ni?""""Ko si ohun ti wọn ba ṣe tabi irufẹ ẹni ti wọn le jẹ, wọn ko le ni ki a ma ṣe iwọde lọjọ naa."""
Iwoyi ọdun to kọja ni awọn ọdọ tu sita ni Naijiria, ti wọn si n ṣe iwọde tako  bi awọn agbofinro SARS ṣe n fi iya jẹ awọn araalu lọna aitọ.Iwọde naa lọ daadaa kaakiri apa Iwọ Oorun Naijiria, paapaa niluu Eko ki nnkan to yiwọ ni iloro Lekki Toll Gate.
Wahala bẹ silẹ lẹyin ti awọn ọmọ ogun fi ibọn tu awọn oluwọde naa ka logunjọ, oṣu Kẹwaa, ọdun 2020.
Oríṣun àwòrán, Reuters
Nibẹ ni awọn eeyan kan ti padanu ẹmi wọn ti ọpọ eeyan si farapa lẹyin ti awọn ṣọja dana ibọn ya awọn oluwọde ọhun.Bo tilẹ jẹ pe iwadii ti bẹrẹ, ijọba ipinlẹ Eko si ti san owo gba mabinu fun awọn eeyna kan ti iṣẹlẹ naa kan gbungbun.
Ko tii si ẹnikankan to tii foju wina ofin lori iṣẹlẹ lọhun, eyii to n bi ọpọ ọdọ ninu.
Wayi o,ọpọ iwe pelebe lo ti n lọ kaakiri ori ayelujara Naijiria lori bi iwọde naa yoo ṣe waye.Ni ti ọrọ SARS to jẹ eku ẹda to da gbogbo rogbodiyan naa silẹ, ileeṣẹ ọlọpaa sọ pe awọn ko gbero lati da ẹka ọhun pada gẹgẹ bii awọn kan ṣe n ṣe n sọ laarin ilu.
Bashiru Olokada: Ọwọ́ ọlọ́pàá tẹ afurasí ọdọmọkùnrin mẹ́ta tó se'kú pa Bashiru ọlọ́kadà ní Ogere
Oríṣun àwòrán, Ogun State Police Command
Ileeṣẹ ọlọpaa nipinlẹ Ogun ti ṣafihan awọn ọdọmkunrin mẹta kan ti wọn ṣa ọlọkada kan pa ki wọn to ji ọkada rẹ gba lọwọ rẹ.
Ọkan ninu wọn Samson Odunayo to jẹ ọmọ ọdun mejidinlogun sọ pe nitori owo data ẹẹdẹgbẹta Naira toun yoo ra si foonu lo mu ki oun ba wọn pa ọlọkada naa.
Lọjọ Ẹti to kọja yi ni Kọmisana ọlọpaa Ogun Lanre Bankole ṣe afihan wọn.
ṣé ẹ lè gbàgbá pé Ajá gidi kọ́ leléyìí tẹ́ẹ bá kòó lọ́nà? Àwọn agbárí tó ṣeé bá BBC sọ̀rọ̀
Awọn afurasi meji to ku ti wọn mu pẹlu Samson ni Sodiq Awokoya ati Jimoh Rilwan lagbegbe Ogere.
Gẹgẹ bi Odunayo ti ṣe sọ fun awọn akọroyin, o ni gbajuẹ ori ayelujara taa mọ si yahoo yahoo loun n ṣe.
O fi kun pe igba akọkọ toun yoo pa eeyan re ati pe oun nilo owo data ni kiakia lo mu ki oun bawọn pa Bashir Umaru to ni ọkada.
Ìdí tí Ooni Ogunwusi fi gbé ọmọ rẹ̀ obìnrin tó ṣe ọjọ́ ìbí 28 sáyé àti bó ṣe tọ́ ọ dàgbà
Ìgbìmọ̀ tí ìjọba ìpínlẹ̀ Eko gbé kalẹ̀ lórí #ENDSARS ti parí ìṣẹ́, àbọ̀ rèé
Adepoju Abdulsalamm ẹni ọdun 18 tó n fi kẹ̀kẹ́ dára fi kiri ẹja tó fi n tà wàràwàrà
''Sodiq lo fa mi wọ inu iṣẹ ọdaran.Igba ẹlẹẹkeji wa si re ki ọwọ to tẹ wa.''
''Iṣẹ alakọkọ taa ṣe, a o pa eeyan kankan. Ẹgbẹrun mẹta abọ Naira la gba lọwọ ẹni naa''
Ninu iroyin to tẹwa lọwọ nipa iṣẹlẹ naa, ọwọ tẹ awọn afurasi wọnyi nigba ti wọn fẹ lọ ta ọkada ti wọn ji gbe fun ẹnikan.
Ẹni naa gẹgẹ baa ṣe gbọ bẹrẹ si ni fura si awọn ọdọkunrin yi nigba ti wn ko le ṣalaye ibi ti wọn ti ri ọkada ti wọn fẹ ta.
Kia o ti ta awọn ọlọpaa lolobo ti wn si gbe wọn lọ si agọ ọlọpaa.
Ni agọ ọlọpaa lawọn mọlẹbi Bashir Umar to ni ọkada ti wọn fẹ ta ti ri ọkada Bashir nigba ti wọn lọ fẹjọ sun pe awọn ko ri Bashir mọ.
Nibẹ si ni awọn agbofinro ti tẹ awọn afurasi yi ninu ki wọn to mu wọn lọ sibi ti wọn pa Bashir si.
Awọn ọlọpaa baa ti wọn ge oku Bashir yannayanna ti wọn si fi ori rẹ kọ igi.
Kọmisana ọlọpaa ti ni ki wọn gbe awọn afurasi yi lọ si ẹka ọtẹlẹmuye ṣaaju ki wọn to ko wọn lọ si iwaju adajọ.
Robotic Dog Akungba varsity students: Àwọn agbárí ọmọ ilé ẹ̀kọ́ tó ṣeé bá BBC sọ̀rọ̀ lórí bó ṣe di ajá
To ba fi le ri eeyan tabi to gbọ ohun, awọn to ṣee ti ko iṣẹ sii lori pe ko bẹrẹ si ni gbo eeyan tabi nkan naa.
Aja agbelẹrọ yii jẹ akanṣe iṣẹ a'sekagba ikawe awọn ọmọ ile ẹkọ fasiti Adekunle Ajasin mẹta kan ti ṣaadede ti gbajugbaja bayii lẹyin ti aworan iṣẹ ọwọ wọn jade sori ayelujara ti awọn eeyan si bẹrẹ si ni pin in kaakiri.
Oríṣun àwòrán, Adeyi Stephen
Ọmọ ile ẹkọ fasiti Akugba ni ipinlẹ Ondo ni awọn mẹtẹta - Aiyegbeni John Osoke, Charles Olalekan, ati Adeyi Stephen, wọn jọ korajọ lati jọ ṣeto, po eelo rẹ wọn si jọ 'se aja idaabobo naa jade.
"Lara ohun pataki ti wọ́n se fun iwulo Aja yii nipe wọn ṣe ẹrọ ilewọ oludairi ti oloyinbo n pe ni ""Remote:"" lati lee dari rẹ ko maa gbo tabi ṣe ohun to ba wu olowo rẹ."
Wo ohun tí ọlọ́pàá sọ nípa 'Charlie', ajá tó gé kórópọ̀n akẹ́kọ̀ọ́ fásitì AAUA jẹ l'Ondo
Ìkúnlẹ̀ Abiyamọ ò! Ajá mẹwàá yà ọmọ ọdún méjì jẹ ní Anambra
Ǹjẹ́ o leè fẹ́ ẹni tó bá ń jẹ ẹran ajá?
Ìdí tí Ooni Ogunwusi fi gbé ọmọ rẹ̀ obìnrin tó ṣe ọjọ́ ìbí 28 sáyé àti bó ṣe tọ́ ọ dàgbà
Oríṣun àwòrán, Adeyi Stephen
Olukọ wọn ni fasiti ni oun ri awọn akẹkọọ mẹtẹta gẹgẹ bi akinkanju to gbọ ẹkọ daadaa ni oun ṣe fi oye awọn nkankan han wọn lati le da nkan ṣe funra wọn ti wọn si fakọyọ.
Ninu ifọrọwanilẹnuwo pẹlu BBC Yoruba, awọn ọmọ ile ẹkọ fasiti naa sọ ohun to sun wọn kẹrẹkẹrẹ de bẹ.
Gẹgẹ bi wọ́n ṣe sọ ọ, iṣẹ akanṣe Aja yii le mu ojutuu de ba iṣoro ati ipenija aabo lai fibẹẹ jẹ ki eniyan da sii pupọ ju bii kika fidio, gbigbọ ariwo tabi pipariwo. Bakan naa, wọn ṣalaye fun BBC awọn ipenija ti wọn koju lasiko ti wọn n ṣe iṣẹ akanṣe aṣekagba fasiti yii.
₦500 tí màá fi ra 'Data' láti fí ṣé Yahoo-yahoo ló mú mí yín ọlọ́kadà lọrùn pa
Mí ò ṣe sinimá 'Iku ni' láti tàbùkù ẹ̀sìn Islam - Olufunmi Bakare
Ẹ wò irú èèyàn tí Fashola ní kí àwọn ọmọ Nàìjíríà dìbò wọ́n fún ni 2023
Ẹ gbọ́ ohun tí Falz sọ lórí ìwọ́de tí yóò wáyé ní ìrántí ìfẹ̀hónúhàn EndSARS ní Lekki Toll Gate
'Olóyè Sunday Igboho fi ọ̀rọ̀ kánmọ́ kánmọ́ ráńṣẹ́ láti Cotonou nípà owó ìtọ́jú ìlera rẹ̀'
Maolud Nabiyy: Kí ló dé tàwọn Mùsùlùmí kàn kìí b'áwọn kópa nínú ọjọ́ ìbí Anobi Muhammad?
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Aarẹ orileede Naijiria Muhammadu Buhari ti fi ikini ranṣẹ si awọn musulumi orileede naa lori ajọdun ọjọ ibi Anọbi Muhammad (SAW).
Kaakiri agbaye lawọn musulumi n kopa ninu ajọdun ti wọn fi n ṣe iranti ọjọ ti wọn bi Anọbi yi.
Ninu atẹjade to fi sita, o ni oun fi akoko yi gba awọn musulumi niyanju lati ''wa afirijin ki wọn si samulo ẹkọ ati igbe aye Anobi (SAW)
Ṣaaju ni ijọba Naijiria ti kede ọjọ Kọkandilogun oṣu Kẹwa gẹgẹ bi ọjọ isinmi lẹnu iṣẹ.
Ọjọ yi ṣe deede ọjọ Kejila oṣu Rabi'al-awwal ti awọn musulumi Sunni kan a maa fi ṣe ayajọ yi.
Ni tawọn Shia,ọjọ Kẹtadinlogun oṣu yi kanna ni wn ya sọtọ.
Oríṣun àwòrán, MUHAMMADU BUHARI FILE
Ibi ti ayajọ yi ti ṣẹwa
Wọn ya ọjọ yi sọtọ lati maa fi ṣe iranti ọjọ ibi Anọbi Muhammad(SAW)
Ko si akọsilẹ pato ọjọ ti wọn bi Anọbi gangan ti eyi si mu ki awọn musulumi maa mu ọjọ ọtọọtọ.
Lede larubawa  Maolud tunmọ si ọjọ ti wọn bi eeyan to si j pe nilu Makkah ni orileede to n jẹ Saudi Arabia ni wọn ti bi Anọbi ni ọdun 570AD
Leyi tii jẹ ododo Anọbi ko ṣe ayajọ ọjọ ibi rẹ nigba to wa laye koda awọn to sunmọ ni Sahabee ko ṣe ajọdun yi.
Ni asiko awọn Abbasids lẹyin iku rẹ lawọn kan kọkọ bẹrẹ ajọdun yi ti awọn miran si ni lasiko awọn Fatimid ni wọn sọ di ajọdun ti olori ilu gaan fọwọ si.
Awọn orileede wo lo n  kopa ninu ajọdun yi?
Ko fẹẹ si orileede musulumi tabi orileede tawọn musulumi pọ si  ti wọn o ti maa ṣe ajọdun yi.
Ethiopia, India, UK, Turkey, Nigeria, Sri Lanka, France, Germany, Italy, Iraq, Iran, Maldives, Morocco, Jordan, Libya, Russia ati Canada wa lara wọn.
Amọ ṣa ni orileede Qatar ati Saudi wọn kii ṣe ajọdun yi bẹẹ si ni wọn o ya ọjọ sọtọ fun toripe wọn ka kun eewọ.
Oríṣun àwòrán, AFP
Awọn musulumi gbe Anọbi si ipo ọla ati ẹyẹ ṣugbọn kii ṣe gbogbo wọn lo gba pe o yẹ ki wọn fi ayajọ Maolud yẹ si.
Idi ti wọn fi sọ bẹ nipe ko si ninu akọsilẹ ofin Islam bẹẹ si ni Anọbi ko pa awọn musulumi laṣẹ lati ṣe .
Fun awọn to maa n ṣe ayajọ yi, wọn a maa ṣe ile wọn lọjọ ti wọn wọn a si maa pinnkan jijẹ ati mimu lasiko yi.
Pupọ maa n pin ounjẹ lati fi ṣe itọrẹ tawọn mii a si maa ka orin ewi nipa Anọbi si eti igbọ awọn ọmọ wọn
Awọn ti kii ṣe ayajọ yi gba pe o da ki eeyan maa gba awẹ lọjọ Aje nitori Anọbi naa a maa ṣebẹ ni iranti ọjọ ti wọn bi saye.
Ọrọ yi jẹ eleyi to n ja rainrain laarin awọn musulumi paapa awọn to gbagbọ pe ko yẹ ki wọn ṣe afikun nkan ti Anọbi ko ṣe ninu ẹsin.
Fawọn to n ṣe wn ni nitori ifẹ ati apọnle tawọn ni si Anọbi lawọn fi n ṣe ayajọ yi.
Ninu alaye wọn, wọn ni wọn a maa ṣe ayẹsi ni tiko to Anọbitori naa o y ki awọn ṣe iranti ati apọnle pẹlu ayajọ yi
Gẹgẹ bi awọn Kristẹni kọọkan ti kii bawọn ṣe ajọdun Keresi nitori Jesu ko pawọn laṣẹ rẹ, awọn musulumi kan paapa awọn to n ṣe isọjipada Sunnah Anọbi, Ahlul Sunnah ni afikun bayi tako ilana ẹsin Islaamu.
ENDSARS Lekki Shooting: Ọdún kàn lẹyìn ikọlu tó wáyé ní Lekki, kò ṣì sí àrídájú òhun tó ṣẹlẹ̀
Oríṣun àwòrán, other
Ogunjọ oṣu Kẹwaa ọdun 2020 jẹ ọjọ manigbagbe ninu itan orileede Naijiria.
Ọjọ yi ni ikọlu waye laarin awọn ọmọ ogun Naijiria ati awọn oluwọde ENDSARS ni agbegbe Lekki Toll Gate ni ilu Eko.
Iwọde tawọn oluwọde yi n ṣe ti n lọ lojoojumọ bẹrẹ lati ọjọ Keje oṣu Kẹwaa ti wọn ti ni o to gẹ pẹlu ijiya tawọn ọlọpaa SARS fi n jẹ araalu paapa awọn ọdọ.
Wo ìyà tó jẹ Adedotun Clement níbi ìwọ́de EndSARS ní Lekki Toll Gate àtohun táwọn tó sọ̀rọ̀ ń bèrè fún
Ninu apilẹkọ yi, BBC Yoruba boju wẹyin lati wo iṣẹlẹ to waye lọjọ yi eyi to pada kangun si ikọlu ati iyinbọn si awọn oluwọde.
Ni ṣiṣẹ n tẹle awọn ohun ta ri ko jọ ree nipa iṣẹlẹ iyinbọnpaniyan to waye ni Lekki Toll Gate.
Iṣẹlẹ kan to lamilaka waye ni ọjọ Kọkandinlogun oṣu Kẹwaa.
Kii ṣe ni Eko lo ti waye ṣugbọn awọn ti Eko naa mọ riri rẹ lara ohun naa si ni ṣe pẹlu ọrọ ENDSARS.
Oríṣun àwòrán, Timothy Ojon
Ijọba ipinlẹ Edo kede konileogbele oniwakati mẹrinlelogun nitori ikọlu tawọn janduku ṣe si ọgba Ẹwọn Benin ati Oko.
Ninu ikọlu yi, ni ṣe ni awọn janduku to sa sabẹ iwọde ENDSARS N dunkoko mọ ara ilu ti wọn si n jale kaakiri ilu.
Ka nípa nkán tí Iyabo Ojo àti àwọn èèkàn amúlúdùn sọ lórí 'sex tape' Tiwa Savage
Fídíò ìbálòpọ̀ tó lu jáde nípa olórin Tiwa Savage, èsì ọlọ́rọ̀ gangan rèé
ṣé ẹ lè gbàgbá pé Ajá gidi kọ́ leléyìí tẹ́ẹ bá kòó lọ́nà? Àwọn agbárí tó ṣeé bá BBC sọ̀rọ̀
Oríṣun àwòrán, Godwin Obaseki Facebook
Pẹlu bi nkan ti ṣe ri yi, ọpọ lo ti n ro pe o ṣeeṣe ki iru rẹ naa waye ni Eko.Ọrọ pada ri bẹẹ.
Logunjọ,awọn Janduku sọ ina si agọ ọlọpaa ni Iganmu
Bawọn oluwọde ti ṣe ji lowurọ ọjọ Iṣẹgun tii ṣe ogunjọ oṣu Kẹwaa lati tẹsiwaju pẹlu ifẹhonuhan wọn, pupọ ni ko lero pe ewu nla n bẹ lọjọ naa.
Awọn to gbe igba orin ti bẹrẹ si ni lu ilu tawọn to n ba awọn oluwọde sọrọ naa si ti bẹrẹ ọrọ iwuri pe ki wọn maa ṣe jẹ ki ihalẹ ijọba mu wọn lọkan.
Lagbegbe Orile ti ko jina pupọ si Lekki Toll Gate wahala naa de oju ẹ nigba tawọn janduku kan ṣe ikọlu si agọ ọlọpaa nibẹ ti wọn si sọ ina si.
Oríṣun àwòrán, Google
Kaakiri loju opo ayelujara lawọneeyan ti ri fọnran fidio yi.
Awọn ọlọpaa fi atjade sita pe awọn yoo koju awọn to ba fẹ da omi alaafia ilu ru.
Gbangba ti pada wa dẹkun ti kedere si ṣetan lati bẹẹ wo.
Irú omi àti oúnjẹ tí wọ́n ń fún Sunday Igboho, a ó mọ̀ọ́, à ń fura sí ohun tó ń lọ lọ́wọ́ látìmọ́lé Cotonou
Logunjọ oṣu Kẹwaa lẹyin to ni oun wo bi awọn janduku ṣe n da igboro ru lori iwọde ENDSARS, Gomina Babajide Sanwoolu kede konile o gbele.
Ikede yi yi de oju opo rẹ ni Twitter ni nkan bi ago mejila ọsan ku diẹ.
Oríṣun àwòrán, SCREEN GRAB TWITTER /SANWOOLU
Ọrọ naa ti wa de oju rẹ bayi ti ọpọ ara ilu Eko to n ṣiṣẹ lagbegbe Lagos Island si bẹrẹ si ni palẹmọ ki gbendeke yi to pe.
Ẹwẹ, bi ijọba Eko ti ṣe kede konileogbele ni ipinlẹ naa ni Gomina Kayode Fayemi ti Ekiti naa s pe konileogbele yoo bẹr ni ago mẹwaa alẹ.
Oríṣun àwòrán, Ekiti State Government
Lati ago mọkanla kọja ti ijọba fi ikede yi sita, awọn oluwọde to wa ni Lekki ni ko si giri pe ile lapoti awọn yoo joko de idi awn ti ijba ba ran wa.
Ninu awọn fnran fidio ati ohun ti oniroyin wa jabọ, niṣe ni wn tsiwaju pẹlu orin kikọ ti wn si s pe ki gbogbo awọn to ba fẹ duro ri pe wọn o fa wahala kankan.
Ago mẹrin lu awọn oluwọde ko kuro ni Lekki bẹẹ si ni awọn agbofinro ko ti de.Ohun to waye lyin igba naa ree:
Ibi ibọn yinyin yi ni ariyanjiyan ti waye.
Awọn ọmọogun sọ pe awọn ko yin ọta ibọn gidi ṣugbọn awọn oluwọde ni ọrọ ko ri bẹ.
Ninu iwadii kan ti BBC ṣe lyin iṣẹlẹ yi, awon oṣojumi koro ti ko f fojuhan ni awọn eeyan ba iṣẹlẹ naa lọ.
Lọjọ Keji iṣlẹ yi, Gomina Sanwoolu tọrọ aforijin lọwọ awọn araalu to si s pe eeyan kan ku ti awọn meji mii sifarapa.
Oríṣun àwòrán, Babajide sanwo-olu/twitter
Lẹyin igba yi, wn ṣe agbekalẹ igbimọ iwadii ti yoo t pinpin ohun to ṣẹlẹ ati iye awn eeyan to ku ninu ikọlu yi.
Igbimọ pari iṣẹ  ti wọn si kede owo gba ma binu to le ni miliọnu irinwo Naira fawọn to mẹjọ wa siwaju rẹ
Igbimọ naa pari iwadii rẹ bawọn ọdọ Naijiria kan ṣe n gbaradi ayajọ iranti ọdun kan iwọde ENDSARS .
O ti pe ọdun kan bayi to si jẹ pe pupọ idahun si  ibeere ohun to ṣẹlẹ ni ko ti ni idahun.
UI robbers attack: Ọmọ ilé ẹ̀kọ́ UI méjì fórí kó ọta ìbọn lọ́jọ́ kan ṣoṣo, wọ́n tún pàdánù ẹ̀mí wọn
Oríṣun àwòrán, UI
Fasiti UI
Awọn akẹkọọ fasiti ilẹ Ibadan, UI pe fun adura lẹyin ti wọn padanu eeyan meji laarin ọjọ kan
Awọn akẹkọọ ati oṣiṣẹ fasiti ilẹ Ibadan ti n karibọnu lati ṣọfọ meji ninu awọn akẹkọọ naa to padanu ẹmi wọn laarin wakati mẹrinlelogun.
Ọkan ninu awọn oloogbe naa, Adegoke Adedayọ ti o wa ni opin ẹkọ ni ẹka ti a ti n kọ nipa itan ni wọn yinbọn pa lowurọ ọjọ Aiku lasiko ti idigunjale kan n waye lopopona UI si Bodija.
Wo àwọn Fasiti Nàìjíríà tó gbégbá orókè lágbàyé
Òṣìṣẹ́ Fásitì Ìbàdàn méje dèrò àtìmọ́lé lórí àyídáyidà ìdánwò
Fásitì UI f''orin tàkasúfèé wá ojúùtú si ìṣòro ẹ̀kọ́ ìṣirò
ṣé ẹ lè gbàgbá pé Ajá gidi kọ́ leléyìí tẹ́ẹ bá kòó lọ́nà? Àwọn agbárí tó ṣeé bá BBC sọ̀rọ̀
Bakan naa ni akẹkọọ kan to wa ni ipele ikeji ni ẹka ti a ti n kọ nipa imọ sayẹnsi ohun ọgbin ati ẹranko, Ayọmide Adeyẹmọ padanu ẹmi rẹ sọwọ ijamba ọkọ lasiko ti o fẹ ọda ni ẹnu ọna abawọle ile ẹkọ giga naa.
Adari ikansiraẹni ni fasiti ilẹ Ibadan, Tunji Ọladẹjọ ti o fi idi iṣẹlẹ naa mulẹ fi kun ọrọ rẹ pe ileeṣẹ ọlọpaa ti bẹrẹ iṣẹ iwadii idigunjale to waye.
Aarẹ ẹgbẹ awọn akẹkọọ ni fasiti naa, Yinka Adewọle gbogbo igbiyanju lati doola ẹmi awọn akẹkọọ naa lo jasi pabo.
O ni igbimọ to n ṣe akoso awọn akẹkọọ ti n gbero lati ṣe agbekale eto adura ati ilanilọyẹ fun awọn akẹkọọ ki aabo to peye le wa lori wọn.
Ìdí tí Ooni Ogunwusi fi gbé ọmọ rẹ̀ obìnrin tó ṣe ọjọ́ ìbí 28 sáyé àti bó ṣe tọ́ ọ dàgbà
₦500 tí màá fi ra 'Data' láti fí ṣé Yahoo-yahoo ló mú mí yín ọlọ́kadà lọrùn pa
Ìgbìmọ̀ tí ìjọba ìpínlẹ̀ Eko gbé kalẹ̀ lórí #ENDSARS ti parí ìṣẹ́, àbọ̀ rèé
Nkán mẹ́rin tó yẹ kóo mọ̀ nípa àjọ̀dún Maolud Nabiyy tàwọn Mùsùlùmí ń ṣé
Hike in cooking gas price: Àlàyé rèé lórí ohun tó ń fa ẹ̀kúnwó gegele lórí owó orí afẹ́fẹ́ ìdáná gáàsì
Oríṣun àwòrán, other
Lọwọlọwọ yii, gbogbo ọmọ Naijiria paapaa julọ awọn to n lo afẹfẹ idana gaasi ni wọn n pariwo bayii pe owo gegele ti afẹfẹ idana naa gbe lori bayii ti fẹ gbẹmi awọn. Amọṣa o awọn alaṣẹ ipese afẹfẹ idana gaasi lorilẹede Naijiria ti ṣalaye sita ohun to ṣokunfa owo gegere to gun ori afẹfẹ idana naa bayii.
Farouk Ahmed to jẹ alaṣẹ agba ileeṣẹ to n ṣe ṣakoso awọn ileeṣẹ ati lajọlajọ lẹka epo rọbi lorilẹede Naijiria, NPRA ti ṣalaye pe aisi idokoowo to kuna lẹka ipese afẹfẹ gaasi lorilẹede Naijiria, LPG lati ọpọlọpọ ọdun sẹyin lo n faa.
Ahmed ṣalaye siwaju sii pe ajọ naa yoo mu iṣẹ ṣe lori rẹ lati rii daju pe nnkan pada si bo ṣe yẹ. O ni ko yẹ ki Naijiria o maa ni ipenija ẹkunwo owo afẹfẹ idana gaasi nitori bi Eleduwa ṣe fi jinkin orilẹede naa lọpọ yanturu ti kii ba ṣe ailakasi awọn ijọba iṣaaju lori mimu idokoowo to jọju wọ ẹka naa lawọn ọdun to ti lọ.
Ni bi a ṣe n sọrọ yii, owo agolo silinda oniwọn 12.5kg ti wọn n ra ni ẹgbẹrun mẹrin naira (N4000) loṣu kini ọdun 2021 gbera lọ si ẹgbẹrun mẹfa ati igba Naira (N6,200) loṣu keje ọdun 2021, ki o to tun gbera di ẹgbẹrun meje ati ẹẹdẹgbẹrin Naira (N7,800) loṣu kẹsan ọdun 2021 kan naa. Eyi tumọ si ẹkunwo onida mẹtala ninu ọgọrun (13%) lori iye owo ori afẹfẹ idana gaasi.
Ọpọlọpọ awọn oniṣowo ohun elo idana yii atawọn to n raa lo ni wọn ti n kerora lori rẹ bayii.
ṣé ẹ lè gbàgbá pé Ajá gidi kọ́ leléyìí tẹ́ẹ bá kòó lọ́nà? Àwọn agbárí tó ṣeé bá BBC sọ̀rọ̀
Governor Sanwo-Olu and Taye Oniyakuya: Sanwo-Olu ti gba àwòrán apanilẹ́rín tí Boda Taiye Oniyakuya yà nípa rẹ̀
Oríṣun àwòrán, other
Aṣe ori to maa gbeni ko alawoore ko di dandan ko tobi tuulutuulu. Aworan to gbe Bọda Taiye Oniyakuya ko gomina ipinlẹ Eko, Babajide Sanwo-Olu kii ṣe eyi to fi gbogbo ara gbadun.
Amọṣa, Gomina Babajide Sanwo-Olu ti tẹwọ gba aworan apanilẹrin nipa rẹ ti Taiwo Osinọwọ, ọdọmọdekunrin oniṣẹ ọna aworan yiyan kan ti ọpọ mọ si Bọda Taiye Oniyakuya ya.
Ọdọmọde ayaworan naa bọ si gbangba ode lẹyin to fi aworan aworẹrin nipa Gomina Sanwo-Olu lori ayelujara.
"O sọọ lori ayelujara pe oun ya aworan Gomina Sanwo-Olu. ""Mo dupẹ lọwọ Ọlọrun fun aṣeyọri iṣẹ yii. Mo si mọ pe gomina yoo fẹran rẹ. Emi ṣi ni ayaworan to gbayi julọ ni UAR."""
Aworan naa kan gomina Sanwo-Olu lara, loun naa baa daa lohun pe:
Se emi naa lo ya bayii? Mo lero pe waa nifẹ lati gbe e lemi lọwọ abi? O daa, wa gbe e fun mi ni ọfiisi mi. Hmmmm...
Gomina Sanwo-Olu pe ayaworan naa si ori pepele ibi to ti n sọrọ lati kii to si fi daa loju pe ko si eera kan ti yoo rin in.
Taye Osinowo Olaosebikafi Iyabo Ojo, Mide Martins, Jaye Kuti, Afeez Owo àtàwọn míì dárà ap
Ṣaaju ni Bọda Taye Oniyakuya ti sọ fun gomina ipinlẹ Eko pe awọn eeyan kan ti gba oun ni amọran pe ki oun maṣe yọju sii nitori pe gomina naa lee fi panpẹ ofin mu nitori aworan iyakuya to ya nipa rẹ.
O ni awọn kan tilẹ sọ fun oun pe ọgba ẹwọn kirikiri ko jina si ile gomina ti oun ti fẹ lọ yọju sii.
Amọṣa gominaSanwo-Olu ni oun ṣetan lati sanwo fun aworan naa gẹgẹ bi ẹmi imọriri iṣẹ ọna ọhun.
Sex Tape: Small Doctor, Salawa Abeni, Toke Makinwa wà lára àwọn Gbajúmọ̀ tí fídíò ìbálòpọ̀ wọn ti bọ́ sí orí ayélujára ...
Oríṣun àwòrán, Instagram
Ọpọlọpọ eniyan lo ti jade lati fi atilẹyin wọn han fun gbajugbaja olorin takasufe, Tiwa Savage ti fidio ibalopọ rẹ jade si ori ẹrọ ayelujara.
Oṣẹ to kọja ni Tiwa Savage fun ara rẹ fi lede pe ẹnikan n dunkoko mọ oun nitori o ni fidio ibalopọ oun lọwọ, to si n bere owo.
'Mi ò yàtọ sí Krìstẹni tàbí Mùsùlùmí tóun náà da ẹsìn rẹ pọ mọ jíjẹ Dokita, Babaláwo Dókítà l'èmi'
Iṣẹlẹ yii ti mu ki ọpọlọpọ ọmọ Naijiria ma a fi ero wọn han lori awọn gbajumọ lawujọ ti iroyin fidio ibalopọ wọn ti jade si ori ẹrọ ayelujara.
Oríṣun àwòrán, Others
Lara awọn gbajugbaja ilumọọka miran ti aworan ihoho wọn ti bọ si ori ẹrọ ayelujara ni;Small Doctor, Salawa Abeni, Toke Makinwa ati awọn miran.
Oríṣun àwòrán, Instagram/@officialsalawaabeni
Osu Kẹrin, ọdun to kọja ni akọrin Waka lorilẹede Naijiria, Salawu Abeni fi lede pe ẹni kan n dun koko mọ oun lati fi aworan ihoho oun lede ti oun ko ba fun ni owo.
Loju opo Instagram rẹ lo ti fi atẹjade ti eni naa fi ranṣẹ si si oju ọpọ ayelujara fun ara rẹ.
Ninu atẹjade naa lo ti fi lede pe oun ko ni jẹ ki ẹnikẹni dunkoko mọ oun.
Lẹyin naa ni ileeṣẹ ọlọpaa fi panpẹ ọba mu ẹni to n dunkoko mọ Salawu abẹni, ẹni ọdun mọkandinlogun.
Ogogo wá sí iléèwé wa, mo kéwì fún un ló sọ mi di èèyàn ńlá lórí ayélujára - Akinwumi Akewi
Oríṣun àwòrán, Instagram/@smalldoctor
Ọdun 2017 ni fidio jade nibi ti gbajugbaja olorin takasufẹ ti n fi ọwọ kan ara rẹ ninu fidio ti wọn fi si ori Snapchat.
Amọ lẹyin naa ni iroyin jade pe awọn gbajuẹ ayelujara ni wọn gba ọna ẹburu lati wọ ori foonu rẹ, ti wọn si fi fidio naa lede.
Oríṣun àwòrán, Instagram/Toke Makinwa
Osu Kẹrin, ọdun 2020 ni gbajugbaja oniroyin, Toke Makinwa fi lede pe awọn kan ni ti oun ko ba san owo wọn yoo fi aworan ihọhọ rẹ si gbagba.
Lẹyin naa lo fi aworan ihoho ara rẹ si sita fun ara rẹ, to si ni pe ayederu ni eleyii ti o wa ni ọwọ ẹni to n dunkoko mọ wọn.
Oríṣun àwòrán, Instagram/Tiwa Savage
Ninu  ọrọ tawọn eeyan n mu bẹnu loju opo ayelujara ni Naijiria, oke tente leleyi to ni ṣe pẹlu fidio ibalopo Tiwa Savage to lu sita wa.
Ọkẹ aimọye awọneeyan lo n wa fidio naa bi ẹni  n wa owo ti awọn si n sọ iriwisi ọtọọtọ nipa rẹ.
Laipẹ yi ni akọrin takasufẹ naa pariwo sita pe eeyan kan fẹ fi fọnran yi gba owo lọwọ oun to si niboun ko ba san owo oun yoo lu sita.
Irú omi àti oúnjẹ tí wọ́n ń fún Sunday Igboho, a ó mọ̀ọ́, à ń fura sí ohun tó ń lọ lọ́wọ́ látìmọ́lé Cotonou
Fidio naa ti wa lu sita bayi ti awọn gbajumọ ori ayelujara ati awọn mii si ti n sọ ero wn nipa rẹ.
Die ree ninu awọn to da si ọrọ yi ati nkan ti wn ni lati sọ.
Gbajugbaja oṣere tiata Yoruba Iyabo Ojo wa lara awọn to ni ki Tiwa Savage ma ṣe foya lori fidio naa to lu sita.
Loju opo rẹ ni Instagram@iyaboojofespris, niṣe lo fi fidio orin Tiwa Savage kan sibẹ to si ni ko si ẹni ti kii gbẹsẹ, ki Tiwa Savage maa bori lọ.
Ọrọ yi to ko ko pọ ṣugbọn labẹ rẹ awọn eeyan mii naa tun da si ti ọp n fi atilẹyin wn han si Tiwa Savage pe ko ma ṣe foya.
Oríṣun àwòrán, Tiwa Savage
Fun apẹrẹ, @am_tolufatokiladega n beere pe kini Tiwa Savage ṣe to buru?O ni igboya rẹ lati koju ẹni to fẹ fi fidio naa gba owo lọwọ rẹ jẹ iwuri.
O ni bi Tiwa Savage ko ba kọ lati san owo fun ẹni naa ni, ki ba ma gbadun owo mẹnumọ to fẹ gba lori nkan to ṣe.
Asiko to yẹ ki ẹyin ololufẹ Tiwa fi ifẹ han ree-Daddy Freeze
Ilumọọka sọrọsọrọ Daddy Freeze ti dari ọrọ sọdọ awọn to pe ara wọn lololufẹ Tiwa Savage
Oríṣun àwòrán, Daddy Freeze
Nkan to ṣe,gbogbo eeyan lo n ṣe.Iyatọ to wa ni pe o kan gbe kamẹra lọ sibẹ ni.
O ṣalaye pe  'fọnran ibalopọ' rẹ yi yoo tabuku awọn obinrin ni ko si ni da ko ribẹ
O fi kun pe asiko rẹ kawọn obinrin gbaruku ti kan lara wọn ki wn si sinmi lati maa fi ṣe yẹyẹ.
"Ẹni tẹ n wo fi ṣe awokọṣe ree,aayo yin tabi ki lorukọ tẹ n pe.Asiko lo de yi lati gbaruku ti,''
''Ko nilo owo yintabi nkan mii,ifẹ lo nilo ki  fi han an."
Oṣere Nollywood nii,Susan Peters naa da si ọrọ yi
Oríṣun àwòrán, Instagram/Susan Peters
Loju opo r ni Instagram, niṣe lo beere pe ki lo de ti eeyan yoo fiya fidio obinrin ti ko ni fi oju ara rẹ si.
"Ki lo de ti wa tiẹ fi lọ ya fnran fidio gan alara?
O fi kun pe ''Ohun kohun to ba ṣe,wa gbẹsan rẹ...gboingboin la wa lẹyin rẹ''
Oríṣun àwòrán, Instagram/Susan Peters
Ọrọ ti Mercy Aigbe naa sọ ko fi taratara yatọ si eleyi ti Iyabo Ojo sọ.
Oríṣun àwòrán, Instagram/Mercy Aigbe
Ninu fnran fidio kan ti oun ṣe oṣerebinrin Gorgina Onuoha sọ pe ''ọkunrin to ba nifẹ r ko ni ya fidio ibalopọ yin''
O gba awọn obinrin lamọran pe ki wọn ma ṣe fi gbogbo ọkan tan ọkunrin toun ti bi ifẹ ba ṣe n pa wn bi ọti to.
Ma fi ọkan tan eeyan tan, koda to fi mọ ọkọ rẹ.''"
Kini Tiwa Savage s nipa fidio yi?
Ninu ọrọ to fi sita loju opo ayelujara, o ni awọn to wa nidi ki wọn ba orukọ oun jẹ pẹlu fidio naa n binu oun tori pe oun fi ọr naa ṣe awada loju agbo.
O ni pẹlu boun ti ṣe logun sita lori fidio naa, oun ti ribi ka wn lọwọ ko.
Laiko to n kọrin loju agbo, Tiwa sọ pe ko ni si ni ti yoo ri fọnran fidio yi amọ o jọ pe awọn to n halẹ mọ ti pada fi sita faraye.
Shatta Wale: Iléesẹ́ ọlọ́pàá Ghana mú akọrin tàkasúfèé, Shatta Wale wọ́n ní ayédèrú ìròyìn ló ń gbé kiri pé ẹnì kan yinbọn mọ́ òun
Oríṣun àwòrán, Twitter/ shattawalegh
Ileesẹ ọlọpaa orilẹ-ede Ghana ti mu akọrin takasufe, Shatta Wale, lori ìbọn to ni awọn kan yin mọ oun.
Eyi waye lẹyin wakati mẹrinlelogun ti iroyin jade pe eeyan kan yinbọn mọ.
Bakan naa ni awọn ọlọpaa mu afurasi meji, nitori pe wọn pín ayederu iroyin kaakiri pe eeyan kan yinbọn mọ Shatta Wale.
Ileesẹ ọlọpaa sọ pe iwadii awọn fihan pe ẹnikẹni ko yinbọn mọ Wale.
Awọn meji ti wọn mu ni Kojo Owusu Koranteng (Nana Dope) ati Eric Venator (Gangee), fun pe wọn fi ayederu iroyin naa da ìpayà ati ẹ̀rù silẹ niluu.
Alẹ́ ọjọ Aje ni iroyin jade pe ẹnikan yinbọn mọ Shatta Wale.
Wo ìyà tó jẹ Adedotun Clement níbi ìwọ́de EndSARS ní Lekki Toll Gate àtohun táwọn tó sọ̀rọ̀ ń bèrè fún
Koda, diẹ lara awọn ọmọ ikọ rẹ fi idi iroyin naa mulẹ loju opo ayelujara wọn.
Lẹyin wakati diẹ si ni Wale fúnra rẹ sọ pe irọ ni iroyin naa.
Nnamdi Kanu:Ṣé ẹ̀ṣẹ̀ ni láti bú ààrẹ̀ Nàìjíríà báyìí? Wo ohun tí òfin sọ nípa rẹ̀
Ijọba orilẹede Naijiria sọ ninu ẹsun keji ti wọn fi kan adari ẹgbẹ to n ja fun Biafra, Nnamdi Kanu pe o fi ọrọ to sọ lori ileeṣẹ rẹdio rẹ (Biafra Radio) lati London sọ ọrọ eebu si aarẹ Nigeria, Muhammadu Buhari.
Wọn ni o pe aarẹ ni oriṣiriṣi orukọ ti ko daa. Bẹẹ si ni ijọba ni eyi tumọ si pe o ti ti ru ofin abala 375 labẹ ofin to ni ṣe pẹlu awọn ọdaran, ẹka Code Act, Cap C 77, ati ofin orilẹede Naijiria ti ọdun 2004.
Nnamdi kanu to fara han nile ẹjọ giga agba ti ilu abuja ni Ọjọbọ ọsẹ sọ fun adajọ pe oun ko jẹbi awọn ẹsun ti ijọba fi kan oun yii.
Oríṣun àwòrán, CRIMINAL CODE ACT
CRIMINAL CODE ACT
Iwe ofin ori 33 ẹsẹ 373, 374, 375 ati 376 ti orilẹede Naijiria to ni ṣe pẹlu ọrọ awọn ọdaran sọrọ nipa sisọ ọrọ alufansa si eeyan.
Ọrọ alufansa tabi ṣiṣe nkan alufansa jẹ ki nkan to lee tabuku ba iwa ire eeyan wa latọdọ ẹlomiran.
Eyi si lee ṣi ẹni bẹẹ silẹ fun ikorira, fifini ṣe ẹsin tabi riri idẹyẹsi tabi ko tilẹ ba ẹni naa jẹ eyi to lee mu wọn ri ewu tabi jẹ ki awn eeyan maa korira tabi ba iṣesi ẹni naa jẹ lawujọ.
Labẹ bo ṣe wa ninu abala iwe ofin naa, ẹnikẹni to ba ṣe agbejade ọrọ tabi iwa alufansa to si jẹ irọ jẹbi ẹsun ibanijẹ ati pe o yẹ ko fi wọn ọdun meji jura.
Gbẹgẹdẹ fẹ́ gbiná láàrín Oluwo àtàwọn ìgbìmọ̀ Ìmáàmù àti Àlfáà ilẹ̀ Yorùbá, wọ́n ní Oluwo ń kọjá àyè rẹ̀
Bí Ooni ti Ile-Ife, Pásítọ̀ Sam Adeyemi, Woli Agba, Falz, Mr Macaroni, Tiwa Savage ṣe ṣe àyájọ́ Endsars!
Ìjọba ní kí wọ́n bẹ̀rẹ̀ sí ni ṣe àyẹ̀wò ọpọlọ f'áwọn Ọlọ́pàá àti agbófinró
Àwọn abirùn ọmọ tí òbí wọn tì mọ́lé ni mo lọ ń kó jáde láti máa kọ́ lẹ́kọ̀ọ́ iléèwè - Sekinat Ahmed
Ajijagbara fun awọn to n pe fun Biafra, Nnamdi Kanu ti sṣaaju ọ ni waju adajọ pe oun ko jẹbi gbogbo ẹsun tuntun ti ijọba Naijiria fi kan an.
Ohun to ṣẹlẹ ni pe adajọ agba fun ijọba ṣe atunṣe awọn ẹsun ti wọn fi kan an ti wọn si gbe lọ siwaju ile ẹjọ - ẹsun idunkoko mọni ati ẹni to n da ilu ru.
Nibayii, ile ẹjọ tun ti sun igbẹjọ rẹ siwaju di ọjọ Kẹwa oṣu Kọkanla ọdun 2021, bakan naa wọn ti ni ko pada si ahamọ ajọ DSS.
"Adajọ ile ẹjọ kọ iwe ti awọn agbẹjọro Nnamdi Kanu gbe wa gẹgẹ bi wọn ṣe woye rẹ pe ""ko ri ẹsẹ fi mulẹ rara labẹ ofin ko si ni iyi rara""."
'Fídíò ẹ̀rí táa wò ṣàfihàn ibi tí Baba Ijesha ti ń rán ọmọ Princess létí bí òun ṣe fi ọwọ́ kàn án ní ọmọ ọdún méje'
Àwọn agbébọn ṣèkọlù àdó olóró sí ojú irin Kaduna sí Abuja, orí ló kó wa yọ! - Shehu Sani
Ìjọba ní kí wọ́n bẹ̀rẹ̀ sí ni ṣe àyẹ̀wò ọpọlọ f'áwọn Ọlọ́pàá àti agbófinró
'Mi ò yàtọ sí Krìstẹni tàbí Mùsùlùmí tóun náà da ẹsìn rẹ pọ mọ jíjẹ Dokita, Babaláwo Dókítà l'èmi'
"Awọn ẹsun meje ti ijọba fi kan Nnamdi Kanu ko nitumọ rara labẹ ofin eyi ni Ejiofor sọ.
Idi ti a fi sọ eyi pe kii ṣe ẹsun rara ni pe eeyan ko lee sin niluu London ko si di ẹṣẹ ni Naijiria torinaa gbogbo ẹsun wọn ko lẹsẹ nilẹ labẹ ofin."
Awọn ẹsun ti wọn tun ṣe ọhun ni:
Gbogbo ọna to lọ si ile ẹjọ giga ti ilu Abuja ni wọn ti di gbagba pẹlu bi awọn agbofinro ṣe wa nibẹ lati mojuto ọrọ abo nibi igbẹjọ ajijagbara fun Biafra, Nnamdi Kanu.
Ọpọlọpọ agbẹjọro lawọn ọlọpaa o jẹ ki wọ́n wọ inu ọgba ile ẹjọ naa.
Amọ iroyin ni ṣe ni wọn yọlẹ gbe Nnamdi Kanu wọle si ile ẹjọ ti awn eeyan dii ni waju ati lẹyin.
Ijọba Naijiria ṣe atunṣe awọn ẹsun ti wọn fi kan an wọn si tun ko awn tuntun mii jade amọ ti wọn o tii fihan ni gbangba.
Ajijagbara yii la gbọ pe ijọba orileede Naijiria fi ẹsun igbesunmmi ati iditẹgbajọba kan an.
Bi wọn ba fi le da lẹbi ẹsun yii, ẹwọn gbere ni ijiya ti yoo jẹ ipin rẹ.
'Mi ò yàtọ sí Krìstẹni tàbí Mùsùlùmí tóun náà da ẹsìn rẹ pọ mọ jíjẹ Dokita, Babaláwo Dókítà l'èmi'
O ti ṣe diẹ ti Nanamdi Kanu ti wa lahamọ lọdọ awọn ikọ ọtẹlmuyẹ DSS Naijiria gẹgẹ bi awọn agbẹjọro rẹẹ ti ṣe sọ.
Lọsẹ to kọja ni ijọba Naijiria mu iyipada ba awọn ẹsun ti wọn fi kan an ti wọn si tun sọ pe o lọwọ ninu ṣiṣe akoso ileeṣẹ to lodi ofin.
Bẹẹ naa ni wọn sọ pe o lọwọ ninu titẹ awọn iwe ti ọrọ inu rẹ n bani lorukọ jẹ.
Awọn agbẹjọro rẹ ti ni ki ijọba ri wi pe wọn gbe Nnamdi Kanu wa si ileẹjọ lỌjọbi tii ṣe oni.
Boya yoo yọju tabi ko ni yọju, ipade di ileẹjọ.
Wo ìyà tó jẹ Adedotun Clement níbi ìwọ́de EndSARS ní Lekki Toll Gate àtohun táwọn tó sọ̀rọ̀ ń bèrè fún
Niṣe ni ọkan awọn eeyan ko balẹ nigba ti awọn alaṣẹ ko gbe wa sile ẹjọ loṣu Keje lati wa jẹjọ.
Lẹnu ọjọ mẹta yi, ikọlu ati iwa janduku orisirisi lo n waye ni ilẹ Igbo lati igba ti  ijọba ti mu Kanu pada.
Koda,ni ọjọ Iṣẹgun to kọja yi awọn agbebọn kan pa ori ade meji nibi ipade awọn lọba lọba.
Oṣu Kẹwa ọdun 2015 ni wọn kọkọ mu Kanu ṣugbọn o sa ni Naijiria lọdun 2017 nigba ti awọn ọmọ ogun Naijiria yabo ile rẹ.
Idibo to n bọ lọna ni Anambra jẹ ọkan lara awọn nkan tawọn araalu n jaya si.
Pẹlu ikọlu ati iwa janduku eyi to ṣokunfa iku ọpọ awọn araalu ati agbofinro, ko si ẹni to le sọ boya idibo yi yoo waye lalaafia.
Ibo Jews: Mọ̀ nípa àwọn ọmọ Naijiria tó fẹ́ kí Ísírẹ́lì tẹ́wọ́ gbà wọ́n gẹ́gẹ́ bí ẹ̀yà Júù
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Fun ọpọlọpọ ọdun, ni awọn ọmọ Naijiria kan to ko ara wọn jọ ti n pe ara wọn ni ẹ̀yà Júù, sugbọn bi orilẹ-ede Ísírẹ́lì ko ṣe tẹwọ gba wọn jẹ ibanujẹ.
Lara awọn eeyan yii n ko ara jọ ni ọkan lara awọn agbegbe to wa nilu Abuja, Jikwoyi, nibi ti wọn ti n jọsin.
Ni ile ijọsin wọn ti wọn pe ni Gihon Hebrew Synagogue, to tumọ si Sínágọ́gù àwọn Hébérù, ni wọn gbe tabili kan si inu agọ ti wọn fi imọ̀ ọ̀pẹ ṣe, lati fi ṣe ajọyọ Sukkot, to n ṣàpẹẹrẹ iye ọdun ti awọn Júù lo ninu aginjù lasiko ti wọn n lọ si ilẹ ileri.
Olori wọn, Shlomo Ben Yaakov sọ fun akọroyin BBC to bẹ ile ijọsin naa wo lasiko ajọyọ ọhun pe bi awọn ṣe n ṣe lọwọ lọwọ naa ni wọn n ṣe ni Ísírẹ́lì.
O sọ eyi lasiko ti awọn eeyan naa n ṣe àjọpín akara ati waini.
Ẹya Igbo ni Ọgbẹni Yaakov ti wa. Orúkọ abisọ rẹ si ni Nnaemezuo Maduako.
Ọpọlọpọ àwọn eeyan ẹ̀yà Igbo lo gbagbọ pe Júù ni orírun wọn, ati pe awọn jẹ ọkan lara ẹ̀yà Ísírẹ́lì mẹwa to sọnù ni wọn, botilẹjẹ pe kii ṣe gbogbo wọn lo n ṣe ẹsin awọn Júù bí ti Ọgbẹni Yaakov.
Ó ṣe ni láàánú pé ìjọba kò kọ́ ẹ̀kọ́ kankan lára ìwọ́de ENDSARS - Bukola Saraki
Wo àwọn gbajúmọ̀ míràn yàtọ̀ sí Tiwa Savage tí fídíò ìbálòpọ̀ wọn ti bọ́ sí orí ayélujára ...
EndSARS: Atúpalẹ́ rèé lórí ìkọlù  tó wáyé ní Lekki Toll Gate lọ́jọ́ 20 Oct, 2020
Wo ohun tí Baba Ijesha sọ fún BBC níbi ìgbẹ́jọ́ rẹ̀ tó wáyé lónìí
Wo ìyà tó jẹ Adedotun Clement níbi ìwọ́de EndSARS ní Lekki Toll Gate àtohun táwọn tó sọ̀rọ̀ ń bèrè fún
Awọn ẹ̀yà yii ni igbagbọ wa pe wọn di awati lẹyin ti wọn ko Ísírẹ́lì lọ si igbekun ni bi ọdun 8th Century.
Àṣà dida abẹ fun ọmọkùnrin, ṣíṣe ọ̀fọ̀ oku fun ọjọ meje, ajọyọ òṣùpá tuntun, ati ṣíṣe igbeyawo ni abẹ àtíbàbà, to wọpọ nilẹ Igbo, jẹ ara nkan to mu wọn gbagbọ pe ẹ̀yà Júù ni wọn.
Sugbọn Chidi Ugwu, ọmọ ẹya Igbo to tun jẹ onimọ nipa àwọn nkan abalaye ni University of Nigeria, nilu Enugu, sọ pe lẹyin ogun Biafra  to waye ni 1967 si 1970 ni ọrọ jíjẹ ẹ̀yà Júù bẹrẹ laarin awọn Igbo.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
O ni nitori bi awọn eeyan ẹ̀yà Igbo ṣe n ja fun ominira lati kuro ni Naijiria, to si jọ iru awọn ipenija ti awọn ọmọ Ísírẹ́lì ní, lo mu wọn ma a pe ara wọn ni ẹ̀yà Júù, lati ṣe iwuri.
O ni nkan itiju ni lati ma a pe ẹ̀yà Igbo ni ẹ̀yà to sọnù lati ibi kan.
Iléesẹ́ ọlọ́pàá Ghana mú akọrin tàkasúfèé, Shatta Wale nítorí ayédèrú ìròyìn pé ẹnì kan yinbọn mọ́ ọn
Free Sunday Igboho lariwo tó gbóde bí àwọn alátìlẹ́yìn rẹ̀ ṣe darapọ̀ mọ́ ìwọ́de ENDSARS ní Ibadan
Bakan naa lo sọ fun BBC pe ayẹwo DNA to waye ni ọpọ ọdun sẹyin lati mọ boya lootọ ni, ko fihan pe wọn tan pẹlu Júù.
Rabbi Eliezer Simcha Weisz, alaga igbimọ to n mojuto àwọn Rabbi (Olukọni) - ajọ to n buwọlu àwọn to ba pe ara wọn ni ẹ̀yà Juu, naa sọ pe ko daju.
Wọn sọ pe ẹ̀yà Gad ni awọn, ọkàn lara awọn ọmọ Jakọbu - sugbọn wọn o ni ẹ̀rí pe ọmọ Júù ni baba nla wọn.
O tun sọ fun BBC pe kaakiri aye ni awọn eeyan ti n lo awọn àṣà ti wọn n tọ́ka si pe o jẹ ti Júù.
O ni ayaafi ti awọn ọmọ Naijiria to jẹ Juu ba yipada si ẹsin Juu ki awọn to le tẹ́wọ́ gba wọn.
Àmọ́, Ọgbẹni Yaakov sọ pe abuku ni ayipada si ẹsin naa jẹ fun awọn.
Oluwo vs League of Imaams and Alfas: Àwọn ìgbìmọ̀ Ìmáàmù àti Àlfáà ilẹ̀ Yorùbá fẹjọ́ Oluwo sun Gómìnà Oyetola, ṣùgbọ́n Oluwo ní kò sẹ́ni lè fọwọ́ rọ́ òun sẹ́yìn
Oríṣun àwòrán, Emperor Abdulrasheed Adewale Akanbi Telu 1/faceboo
Igbimọ awọn alalufa ati Imaamu nilẹ Yoruba, Edo ati Delta ti ke si gomina ipinlẹ Ọsun pe ko ke si kabiyesi Oluwo ti ilu Iwo, Ọba Abdulrasheed Akanbi pe ko tọwọ ọmọ rẹ bọṣọ lori ero gba rẹ lati yan Mufti agba fun ilẹ Yoruba.
Imaamu agba ipinlẹ Ekiti, Alaaji Jamiu Kewulere to ko igbimọ naa sodi lọ sọdọ gomina Oyetọla fẹsun kan Ọba Akanbi pe o n gbero lati fi Sheik Daud Mọlaasa  joye Mufti qgba fun ilẹ Yoruba.
Àwọn abirùn ọmọ tí òbí wọn tì mọ́lé ni mo lọ ń kó jáde láti máa kọ́ lẹ́kọ̀ọ́ iléèwè - Sekinat Ahmed
Igbimọ awọn alalufa ati Imaamu nilẹ Yoruba, Edo ati Delta ṣalaye ninu lẹta ti agbẹjọro wọn kọ ranṣẹ si gomina ipinlẹ Ọṣun, ileeṣẹ alaabo DSS, kọmiṣọna ọlọpaa nipinlẹ naa, Wale Olokode woye pe awọn Imaamu atawọn alaafaa nikan lo lẹtọ lati lati fi eeyan si ipo naa.
Wọn ni ikọja aye, orun ori kẹkẹ ni igbesẹ ti Oluwo Akanbi fẹ gbe yii nitori ko si bi jijẹ oye Mufti Agba ṣe kan an.
Nitori idi eyi ni a fi n pe akiyesi yin lori igbesẹ ti Oluwo fẹ gbe yii ki o to da wahala ẹsin silẹ laarin awọn ilu ekeyi to lew domi alaafia ru.
Nigba ti BBC News Yoruba kan si Oluwo ti ilu Iwo lati gbọ ti igun rẹ lori ọrọ yii, O ni  oun ko ni ọrọ kan lati sọ lori rẹ ṣugbọn ko si ẹni kan to lee fi ọwọ rọ oun ṣẹyin nilẹ Yoruba.
Ni ilu Naijiria yii, ko si ẹni to lee fọwọ rọ Oluwo sẹyin. Mo ti di Ọba ti ẹnikẹni ko le fa sẹyin. Ọlọrun lo gbe wa kalẹ.
Amọṣa, gomina Oyetọla ti ni oun yoo boju wo ọrọ naa
2023 Nigeria: Atiku sọ pé òun leè ṣé àtúnṣe Nàìjíríà, báwo ló tí ṣe fẹ́ gbée gbà?
Oríṣun àwòrán, Facebook/Atiku.org
Igbakeji aarẹ tẹlẹri ni Naijiria, Atiku Abubakar ti sọ pe orileede naa nilo olori ti yoo ṣe atunto ọrọ aje ti yoo si mu ki oun gbogbo wa ni ṣẹpẹ.
Ẹni to si ni o kaju osunwọn iṣẹ yi ni oun.
O fi ọrọ yi lede nibi ayẹyẹ ọjọ ibi ati ifiwelọlẹ alaga ileeṣẹ iroyin DAAR Communications,Raymond Dokpesi.
Atiku fi kun pe Naijiria nilo adari ti yoo mu isọkan wa ti yoo ṣe atunto ti yoo si daabo bo araalu.
Nigba ti awọn akọroyin beere lọwọ rẹ pe ṣe o lero pe oun le ṣe o fesi pada pe''Mo ti sọ bẹ tẹlẹ, Mo maa ṣe''
Odu ni Atiku Abukar jẹlagbo oṣelu Naijiria kii ṣe aimọ faraalu.
Bi o ba dije du ipo ninu idibo to n bọ ni 2023,eyi yoo jẹ igba ẹlẹkẹẹfa ti yoo kopa ninu idibo.
Ṣaaju lo ti du ipo aarẹ lọdun  1993, 2007, 2011, 2015 ati 2019.
SARS Panel Report: Sanwoolu ṣèlérí pé gbogbo nkán tó bá wa nínú àbájáde ìwádìí ìgbìmọ̀ Endsars ní aráàlú yóò mọ
Oríṣun àwòrán, Facebook/Babajide Sanwo-olu
Bi gbogbo araalu ṣe n foju sọna de abajade iwadii igbimọ ENDSARS ti ijọba gbe kalẹ Gomina Babajide Sanwoolu ti sọ pe awọn ko ni d'aṣọ bo esi iwadii naa.
O ni boya o gbe ijọba tabi ko gbe awọn, gẹlẹ bi igbimọ ba ti ṣe daba ni awọn yoo gbe si eti igbọ araalu.
Sanwo-olu sọ pe abajade yi yoo jẹ ki ijọba le fagbara kun igbiyanju mimu irẹpọ wa ati ki iru rẹ ma ṣe waye mọ.
Àwọn abirùn ọmọ tí òbí wọn tì mọ́lé ni mo lọ ń kó jáde láti máa kọ́ lẹ́kọ̀ọ́ iléèwè - Sekinat Ahmed
Lọjọbọ ni Gomina fi ọrọ yi lede lẹyin ti awọn ọdọ ṣe iwọde iranti ọdun kan ti ikọlu waye laarin awọn oluwọde ati ọmọ ogun Naijria ni Lekki Toll Gate.
Gomina sọ pe ohun tawọn tori rẹ ṣe agbekalẹ igbimọ yi ni lati tan imọlẹ si ẹsun iwakiwa tawọn ọlọpaa SARS n hu si araalu.
Nàìjíríà nìlò olórí tí yóò mú ìsọkan bá ìlú, èmi lẹni náà - Atiku Abubakar
Ṣé ẹ̀ṣẹ̀ ni láti bú ààrẹ̀ Nàìjíríà báyìí? Wo ohun tí òfin sọ nípa rẹ̀
Wo ìyà tó jẹ Adedotun Clement níbi ìwọ́de EndSARS ní Lekki Toll Gate àtohun táwọn tó sọ̀rọ̀ ń bèrè fún
''Igbimọ pari iṣẹ wọn ni ọjọ mẹta sẹyin (Ọjọ Aje) ti wọn si ni ka fun awọn lasiko lati ṣe akojọpọ abajade iwadii wọn''.
A ko mọ nkan to wa ninu abajade wọn ṣugbọn ijọba wa ko ni da'sọ bo o. Awa kii ṣe iru ijọba bẹẹ''.
Gomina tun sọrọ nipa awọn ọdọ kan ti agbofinromu lọjọ iwọde iranti ọdun kan ENDSARS.
O ni oun ti paṣẹ ki wọn tu gbogbo ẹni ti wọn mu lasiko iwọde ti wọn ṣe pẹlu ọkọ silẹ ayafi ẹnikan ti wọn ba nkan ija oloro lọwọ rẹ.
Lasiko iwọde yii, awọn agbofinro dun koko mọ awọn oluwọde kan ati akọroyin ti eleyi ṣi ṣebi ẹni ta epo si aṣọ aala iranti ti wọn gbero pe ajọdun yi yoo jẹ.
Ọkan lara awọn ọdọ to ba wọn kopa gẹgẹ bi ọmọ igbimọ yii fi to BBC leti pe lootọ lawọn ti pari iwadii ati pe abajade ko ni jade si eti igbọ araalu.
Ẹwẹ igbimọ naa ti kọkọ kede owo gba ma binu irinwo miliọnu Naira le mẹwaa fawọn kan to yọju lati sọ bi ọlọpaa SARS ṣe hu iwa aida sawọn.
Igbimọ ipinlẹ Eko yatọ si awọn ti ipinlẹ miran nitori pe o ko iwadii ọrọ SARS ati ikọlu to waye ni Lekki Toll Gate logunjọ oṣu Kẹwa ọdun 2020 papọ.
Sunday Igboho linked with Boko Haram Sponsor: Malami sọ̀rọ̀ sókè pé Sunday Igboho ń gbowó ìgbésùnmọ̀mí lọ́wọ́ agbódegbà Boko Haram
Oríṣun àwòrán, Sunday Adeyemo/instagram
Ijọba apapọ ti gbe e sita pe awọn ti kẹẹfin ajọṣepọ laarin eekan ajafun idasilẹ orilẹede Yoruba, Oloye Sunday Adeyẹmọ ti ọpọ mọ si Sunday Igboho ati ọkan lara awọn agbodegba fun awọn agbebọn Boko Haram.
Amofin agba fun orilẹede Naijiria, Abubakar Malami (SAN) salaye lasiko to n ka abajade igbimọ tẹẹkoto ti aarẹ gbe kalẹ lati tu iṣu de isalẹ ikoko ọrọ Sunday Igboho ati aṣiwaju ẹgbẹ IpoB, Nnamdi Kanu.
O ni ijọba apapọ ti ri aridaju ajọṣepọ laarin Surajo Muhammad ti wọn ran lọ sẹwọn gbere laipẹ yii lorilẹede United Arab Emirates lori ẹsun ṣiṣe atilẹyin fun igbesumọmi ati Sunday Igboho.
Ẹwẹ, ẹgbẹ Ilana ọmọ Oodua ti fi esi ranṣẹ si ijọba pe Àwàdà kẹrí-kẹrì ni ẹ̀sùn ìgbésùnmọ̀mí tí Malami fi kan Sunday Igboho - Ilana omo Oodua.
Irú omi àti oúnjẹ tí wọ́n ń fún Sunday Igboho, a ó mọ̀ọ́, à ń fura sí ohun tó ń lọ lọ́wọ́ látìmọ́lé Cotonou
Bakan naa lo fi kun un pe laarin ọdun 2013 si 2020, Igboho gba owo to to miliọnu mẹtadinlaadoje naira, (N127m)  latọdọ awọn agbodegba kan ninu eyi ti aṣofin apapọ orilẹede Naijiria kan wa.
"Malami ṣalaye pe, ""Iwadii naa fihan pe Sunday Igboho jẹ ọkan lara awọn alaṣẹ ileeṣẹ Adesun International Concept Limited ti wọn da silẹ lọjọ kẹtalelogun oṣu kẹrin ọdun 2010. O ni Oladele Oyetunji ati Aderọpo Adeyẹmọ gẹgẹbi adari pẹlu. Aṣuwọn owo banki mẹtalelogoji ni Sunday Igboho nii ṣe pẹlu lawọn banki mẹsan ọtọọtọ."""
"O fi kun un pe ọkan gboogi lara awọn agbodegba awọn ajafun ipinya Naijiria naa lawọn rii pe o jẹ aṣofin apapọ kan. ""Miliọnu mẹtadinlaadoje o le ẹgbẹrun marundin laadọjọ Naira (N127, 145,000 ni Sunday Igboho gba laarin ọjọ kejilelogun oṣu kẹwaa ọdun 2013 ati ọjọ kejidinlọgbọn oṣu kẹsan ọdun 2020 lati ipasẹ aṣuwọn ifowopamọsi ileeṣẹ Adesun International Concept ltd""."
Ogogo wá sí iléèwé wa, mo kéwì fún un ló sọ mi di èèyàn ńlá lórí ayélujára - Akinwumi Akewi
O ni ọrinlelugba o din meje miliọnu naira ati ẹgbẹrun lọna aadọwa o le mẹjọ, o le ẹgbẹrun igba o le mẹtamiliọnu (N273, 198, 200) ni owo to wọ aṣuwọn ifowopamọsi Sunday Igboho laarin ọjọ karundinlogun oṣu kẹta ọdun 2013 si ọjọ kọkanla oṣu kẹta ọdun 2021. Iwadi si fihan pe ileeṣẹ Adesun International Concept ltd (to jẹ ileeṣẹ Igboho gẹgẹ bi ijọba ṣe sọ) fi miliọnu mejila ati ẹgbẹrun lọna ọtalelẹẹdẹgbẹrin o din mẹwaa naira ranṣẹ si ileeṣẹ AbbalBako & Sons.
Amofin agba orilẹede Naijiria, Abubakar Malami tun fi kun pe ileeṣẹ Abbal Bako ati Abdullahi Usman to jẹ agbodegba rẹ wa lara awọn afurasi lori iwadii ẹsun gbigbe owo kalẹ fun igbesunmọmi.
O ni Abdullahi Usman yii n ba Surajo Ababubakar Muhammad ti wọn ran lọ ẹwọn gbere lorilẹede UAE fun ṣiṣe agbodegba igbesumọmi ni ajọṣepọ owo ati pe iwadii ijọba ti fihan pe ajọṣepọ n wa laarin awọn to n ja fun idasilẹ orilẹede ẹya wọn, iwa igbodedegba fawọn agbesunmọmi ati dida omi alaafia ru lorilẹede Naijiria.
O wa fi kun un pe ijọba apapọ yoo gbe igbesẹ gbogbo to ba yẹ labẹ ofin lati rii daju pe amojuto to tọna waye ki wọn si fi gbogbo awọn taje rẹ ba ṣi mọ lori jofin.
Sunday Igboho news: Èmi ò rán alátẹnujẹ olóṣèlú tàbí ajagunfẹ̀yìntì kankan láti lọ bẹ Buhari Sunday Igboho pariwo síta
Oríṣun àwòrán, Sunday adeyemo/instagram
Eekan ọmọ Yoruba to n pe fun idasilẹ orilẹede Yoruba, Sunday Adeyẹmọ ti ọpọ eeyan mọ si Sunday Igboho  ti pariwo sita pe oun ko ran ẹnikẹni niṣẹ lati maa lọ bẹ Aarẹ orilẹede Naijiria, Muhammadu Buhari tabi ijọba apapọ lorukọ oun.
Sunday Igboho ṣalaye pe awọn agbẹjọro oun nikan loun fi ọrọ si lẹnu lorukọ oun nibikibi tabi nigbakugba.
Ọrọ yii jẹyọ ninu atẹjade kan eyi ti ileeṣẹ amofin Yọmi Alliyu SAN to jẹ agbẹjọro fun oloye Sunday Igboho fi sita.
Ogogo wá sí iléèwé wa, mo kéwì fún un ló sọ mi di èèyàn ńlá lórí ayélujára - Akinwumi Akewi
Atẹjade naa fi kun un pe Sunday Igboho ko ran oloṣelu kankan to n yapa lati ẹgbẹ oṣlu kan lọ si omiran , tabi ajagunfẹyinti kankan niṣẹ lati lọ maa gbẹnu sọrọ fun oun.
A rii gbọ pe awọn oloṣelu kan ti n ko girigiri bo onibara wa, Oloye Sunday Adeyẹmọ ti inagijẹ rẹ n jẹ  Igboho Ooṣa ati iyawo rẹ, Arabinrin Rọpo Adeyẹmọ lorilẹede yii ati nilu Cotonou lati fun wọn laṣẹ lati ls si ileeṣẹ aarẹ orilẹede Naijiria gẹgẹ bi ọna lati wa atilẹyin fun ifẹ tuntun ti wọn ri ati iyapa wọn lọ si ẹgbẹ oṣelu APC lsna ati le lọ woju rere awọn to wa nipo
Atẹjade naa tun ṣalaye rẹ ni kikun pe Sunday Igboho  ko si fun ẹgbẹ oṣelu kankan bẹẹni ko si ni ifẹ tabi ikorira fun ẹgbẹ oṣelu kankan pẹlu nitori gbogbo awọn ololufẹ rẹ ko ms lẹgbẹ oṣelu tabi ilu kan.
Irú omi àti oúnjẹ tí wọ́n ń fún Sunday Igboho, a ó mọ̀ọ́, à ń fura sí ohun tó ń lọ lọ́wọ́ látìmọ́lé Cotonou
Ṣugbọn gbogbo awọn gomina ipinlẹ mẹfẹẹfa to wa lẹkun iwọ orun gusu Naijiria lo bọwọ fun gẹgẹ bi aṣoju tootọ fun iran Yoruba
O ni o ṣeni laanu pe oloṣelu kan ti orukọ rẹ ti di atẹmẹrẹ ti ko si ni ariwisi rere laarin iran Yoruba, pẹlu oṣiṣẹ abo kan to ti fẹyinti  lee maa ko girigiri bo Igboho ati iyawo rẹ lati fun awọn laṣẹ ki wọn le lo awọn ọdọ ilẹ Yoruba ati ileeṣẹ aarẹ lai wo bi wọn ṣe fi eekan ọmọ Yoruba naa sẹwọn lọna aitọ lorilẹede Benin Republic.
Oníṣòwò ni mí, n ò kìí ṣe agbésùnmọ̀mí, Sunday Igboho ti dá Abubakar Malami àti ìjọba àpapọ̀ Nàìjíríà lési ẹ̀sùn ìgbésùnmọ̀mí tí wọ́n fi kàn án
Oríṣun àwòrán, Sunday Igboho/ instagram
Oloye Sunday Adeyẹmọ ti ọpọ mọ si Sunday Igboho ti da ijọba apapọ orilẹede Naijiria loun lori ẹsun didaṣẹpọ pẹlawọn agbodegba igbesumọmi Bokoharam ti wọn fi kan an.
Ninu atẹjade kan ti agbẹjọro fun oloye Sunday Igboho, Amofin agba Yọmi Alliyu SAN fi sita, wọn ni atamọ-atamọ ni minisita feto idajọ mallam Abubakar Malami SAN n wa lati ṣe lọna ati lee so Sunday Igboho pọ mọ awọn agbodegba igbesunmọmi lorilẹede Naijiria.
Ogogo wá sí iléèwé wa, mo kéwì fún un ló sọ mi di èèyàn ńlá lórí ayélujára - Akinwumi Akewi
Wọn fi kun pe miliọnu mejila o le naira (N12.7 million) ti ijsba apapọ n gbiyanmju ati so mọ eto igbesumọmi ko lẹsẹ nlẹ rara. O ni ninu atẹjade ti wọn ka faraye, ko si gbajumọ oniṣowo bii Sunday Igboho ti kii da owo pọ pẹlawọn ti n ṣe paṣiparọ owo ilẹ okeere ati pe owo ti wọn n sọ yii Igboho lo fi ranṣẹ si ileeṣẹ Abbal Bako ti o jẹ ti Abdullahi Umar gẹgẹ bi wọn ṣe sọ. O ni to ba jẹ pe awọn eeyan wọnyi lo n ṣe agbodegba fun Sunday Igboho, kii ṣe igboho lo yẹ ko maa fi owo ranṣẹ si wọn, awọn gan ti wọn n fi ẹsun kan pe wọn n ṣe agbodegba fun iwa igbesumọmi lo yẹ ki wọn maa fi owo ranṣẹ sii.
Wo ìyà tó jẹ Adedotun Clement níbi ìwọ́de EndSARS ní Lekki Toll Gate àtohun táwọn tó sọ̀rọ̀ ń bèrè fún
Oniṣowo ọkọ ni oloye Sunday Adeyẹmọ labẹ ileeṣẹ Adesun International Concept lt. Ṣe o wa tums si pe gbogbo awọn to ba n ra ọkọ lọwọ rẹ tabi awọn to n ta ọkọ fun ni agbesunmọmi?
Oloye Sunday Adeyẹmọ ti inagijẹ rẹ n jẹ Igboho Ooṣa ko bẹrẹ ipe fun idasilẹ orilẹede Yoruba ṣaaju ọdun to kọja. Nitorina bi eeyan ba ri  owo ti apapọ rẹ jẹ ọrinlelugba o din meje miliọnu naira (N273m) laarin oṣu kẹwaa ọdun 2013 si oṣu kẹsan ọdun 2020, o fihan pe Igboho kii ṣe akurẹtẹ oju o rọlari ẹda ni. biliọnu meji naira ni owo ori ile rẹ ti awọn ẹṣọ DSS kọlu ni ọjọ kini oṣu keje.
'Mi ò yàtọ sí Krìstẹni tàbí Mùsùlùmí tóun náà da ẹsìn rẹ pọ mọ jíjẹ Dokita, Babaláwo Dókítà l'èmi'
Wọn wa ke si ijsba apapọ pe ko darukọ aṣofin to fi owo ranṣẹ si oloye Sunday Igboho fun iwa igbesunmọmi bi wọn ko ba ni wọ gbese ẹsun ibanilorukọjẹ.
Amofin Alliyu tun jẹ ko di mims pe titi di bi a ṣe n sọrọ yii, ijsba apapọ ko tiiroju ọjọ fi pe Sunday Igboho lẹjọ iwa ọdaran kanakan, yala igbesunmọmi.
EndSars 2021: Ọ́ọ́físà tó lu awakọ̀ Uber níbi ìwọ́de EndSARS gba ìwé máa lọ ilé ná
Oríṣun àwòrán, LNSC
Awọn alaṣẹ ajọ agbofinro adugbo nipinlẹ Eko, Lagos State Neighbourhood Safety Agency ti da oṣiṣẹ wọn meji to huwa aitọ si ọkunrin awakọ kan nibi iwọde iranti EndSARS to waye ni Lekki Toll Gate ni Ogunj oṣu Kẹwa.
Adari agba ajọ naa, Ọmọba Ọmọwe Ifalade Oyekan lo ṣipaya eyi ni olu ileeṣẹ ajọ naa to wa ni agbegbe Safety Arena, Bolade Oshodi.
Wọn jẹ ko di mimọ pe iwa ti awọn ọọfisa naa hu tabuku ihuwasi eeyan to yẹ ko jẹ ọmọ ẹgbẹ ajọ yii.
Ni kete ti fidio bi wọn ṣe fiya jẹ Clement gba gbogbo ori ayelujara kan lawọn eeyan bẹrẹ si ni ja fun un pe idajọ ododo gbudọ waye tori ko ni ẹṣẹ kankan.
Akọroyin BBC to wa nibi iwọde iranti EndSARS fihan ninu fidio bi awọn ọọfisa ṣe n gbe ọkunrin naa digba digba lati muu ni dandan wọ inu ọkọ wọn amọ ti oun naa n kọjalẹ pe oun ko ni wọ ibẹ rara tori oun kii ṣe ọdaran.
Wo ìyà tó jẹ Adedotun Clement níbi ìwọ́de EndSARS ní Lekki Toll Gate àtohun táwọn tó sọ̀rọ̀ ń bèrè fún
EndSARS: Atúpalẹ́ rèé lórí ìkọlù  tó wáyé ní Lekki Toll Gate lọ́jọ́ 20 Oct, 2020
Free Sunday Igboho lariwo tó gbóde bí àwọn alátìlẹ́yìn rẹ̀ ṣe darapọ̀ mọ́ ìwọ́de ENDSARS ní Ibadan
Wọ́n ní ìpànìyàn wáyé ní Lekki, àmọ́ a kò rí ẹ̀jẹ̀ tàbí òkú èèyàn kankan títí d'òní- Lai Mohammed
''Sójà yìnbọn fún mi ní ìwọdé EndSars lọ́dun tó kọ̀ja, àmọ́ máà tún darapọ̀ mọ́ ìwóde láti ṣèrántí àwọn tó kú''
Nigba ti gbogbo iwọde ọhun tun pari, awọn ọmọ Naijiria bọ sori ayelujara lati tun maa pe fun ki idajọ ododo waye fun Clement. Koda agbẹjọro kan ti baa ṣe ipade to si ni oun yoo ja fun ẹtọ rẹ.
Oyekan ṣalaye pe atawọn ọọfisa mejeji ati ọga alamojuto wọn lo ti foju wina ofin niwaju igbimọ afiyajni fun ẹsun pe wọn ṣe araalu baṣubaṣu.
Iwa ti wọn hu yii lee da omi alafia ilu ru to si lodi si ofin inu iwe ofin ajọ agbofinro adugbo ti ipinlẹ Eko paapaa ni ẹka ikeji, ikẹta, ikẹrin, ikarun ati ikẹfa eyi to sọ nipa  bi ihuwasi ọọfisa si araalu ṣe yẹ ko ri.
Àwàdà kẹrí-kẹrì ni ẹ̀sùn ìgbésùnmọ̀mí tí Malami fi kan Sunday Igboho - Ilana omo Oodua
Sunday Igboho ní òun tí gbúró olóṣèlú kan tó fẹ́ fi orúkọ rẹ̀ gbokùn lọ́dọ̀ ààrẹ, òkò ọ̀rọ̀ tó fi ránṣẹ́ síi nìyí
Sunday Igboho fún Abubakar Malami àti ìjọba àpapọ̀ Nàìjíríà lési ẹ̀sùn ìgbésùnmọ̀mí tí wọ́n fi kàn án
Ogogo wá sí iléèwé wa, mo kéwì fún un ló sọ mi di èèyàn ńlá lórí ayélujára - Akinwumi Akewi
Oyekan ni bo tilẹ jẹ pe iwadii n tẹsiwaju lati mọ awọn ijiya mii to tọ si wọn gẹgẹ bi arufin, awọn ti baba yọ wọn lẹnu iṣẹ naa fun igba diẹ.
Nigba to n fi igbaradi ajọ naa han lati moju to abo araalu ati dukia, Oyekan ba awọn oṣiṣẹ wọn sọrọ pe ki wọn jẹ akọṣẹmọṣẹ nigba ti wọn ba n ṣe iṣẹ wọ.
O tun wa tọrọ aforijin lọwọ arakunrin ti wọn ṣe ni jamba pe ko fi ọwọ wọ inu. O ni ijọba Eko ni erongba gidi fun irẹpọ wọn pẹlu awọn araalu tori awọn ni alabaṣiṣẹpọ awọn agbofinro ati pe iru iṣẹlẹ aidaa yii ko ni waye mọ.
Báwo ni orísun omi ilẹ̀ Adúlawọ̀ lọ́jọ́ ọ̀la ṣe péye tó ní ìlú àti orílẹ̀èdè rẹ?
Rosemary Ndlovu: Nítorí owó, ọlọ́pàá obìnrin kan pa mọ̀lẹ́bí rẹ̀ márùn-ún àti ọ̀rẹ́kùnrin rẹ̀
Oríṣun àwòrán, AFP
Titi ti igbẹjọ rẹ fi pari, ni Rosemary Ndlovu sọ pe awọn ẹlẹri n parọ mọ oun ni
Ile ẹjọ ti sọ pe obinrin kan to jẹ ọlọpaa tẹlẹ, Nomia Rosemary Ndlovu jẹbi ẹsun pipa mọlẹbi rẹ marun-un ati ọrẹkunrin rẹ.
Laarin ọdun 2012 si 2018 lo pa awọn mẹfẹẹfa pẹlu iranlọwọ agbanipa.
Idi to si fi pa wọn ni pe ko le gba owó ti ileeṣẹ adojutofo ẹmi yoo san fun ẹbi ẹni to ba ku.
Nomia Ndlovu ti fi igba kan jẹ ọlọpaa orilẹ-ede South Africa.
Ọwọ pada tẹ ẹni ọdun mẹrindinlaadọta ọhun lẹyin to tun gbe agbanipa miran lati ba a pa aburo rẹ obinrin, lọ si ileeṣẹ ọlọpaa.
Ogogo wá sí iléèwé wa, mo kéwì fún un ló sọ mi di èèyàn ńlá lórí ayélujára - Akinwumi Akewi
Bakan naa ni ile ẹjọ sọ pe Ndlovu tun jẹbi igbiyanju lati pa iya rẹ, Maria Mushwana, to si tun ṣe mago-mago owo lati ileeṣẹ adojutofo, lẹyin to ti ko 1.4m Rand ($95,000) owo orilẹ-ede South Africa sapo.
Lasiko igbẹjọ rẹ to waye fun oṣu mẹta, agbẹjọro ijọba ṣalaye pe niṣe ni Arabinrin Ndlovu ṣeto adojutofo fun awọn ẹbi rẹ ko to pa wọn.
Ibatan rẹ, Madala Homu, lo kọkọ pa ninu oṣu Kẹta, ọdun 2012.
Lẹyin naa lo pa aburo rẹ, ko to pa ọrẹkunrin rẹ, ati ọmọ aburo rẹ mẹta.
Oṣu Kinni, ọdun 2018, lo pa ẹni to pa kẹhin, Brilliant Mashego.
O ma n gba agbanipa ni fun awọn to ba fẹ pa, ṣugbọn lọdun 2013, fun'ra rẹ lo fun aburo rẹ Audrey Somisa Ndlovu, ni majele jẹ ko to fun un lọrun pa.
"Ṣé ẹ ti gbọ́ nípa bí ""Flubot Malware"" ṣe lè kọlu fóònù yín lójijì? - NCC"
Àwọn agbébọn ya wọ ọgbà ẹ̀wọ̀n ní Oyo, wọ́n tú àwọn ẹlẹ́wọ̀n sílẹ̀
Ọ́ọ́físà tó lu Clement awakọ̀ Uber níbi EndSARS gba ìwé máa lọ ilé ná
Àwàdà kẹrí-kẹrì ni ẹ̀sùn ìgbésùnmọ̀mí tí Malami fi kan Sunday Igboho - Ilana omo Oodua
'Mi ò yàtọ sí Krìstẹni tàbí Mùsùlùmí tóun náà da ẹsìn rẹ pọ mọ jíjẹ Dokita, Babaláwo Dókítà l'èmi'
Opin de ba ipaniyan rẹ lẹyin to gbe iṣẹ fun ẹnikan lati tun ba a pa aburo rẹ miran ati ọmọ rẹ marun-un, ni oṣu Kẹta, ọdun 2018.
Ṣugbọn ọkunrin to gbe iṣẹ naa fun un sọ fun awọn ọlọpaa. Eyi si lo mu ki wọn o dẹ pakute fun, ti wọn fi ni akọsilẹ ohun rẹ bo ṣe n gbeero lati pa awọn ibatan rẹ naa.
"Ninu fọnran ohùn naa ni wọn ti gbọ ti Ndlove n sọ bo ṣe fẹ ki wọn o dana sun awọn mẹfẹẹfa laaye ninu ile wọn, to si tun sọ pe ""oun nilo owo ti oun yoo gba lori wọn""."
O ti kọkọ sọ nile ẹjọ pe oun ko jẹbi, to si ni irọ ni awọn aadọta ẹlẹri ijọba n pa mọ ọ.
Ṣugbọn agbẹjọro ijọba, Riana Williams, ṣafihan awọn ẹri to fi ibaṣepọ rẹ han pẹlu ọpọlọpọ awọn to pa ṣaaju iku wọn, ati anfaani to jẹ lẹyin rẹ.
Ẹri fihan pe Ndlovu lo ṣaba ma n ri wọn kẹhin ki wọn o to ku, tabi ko jẹ ẹni akọkọ to ṣakiyesi pe wọn di awati.
Orukọ ara rẹ lo fi silẹ ninu iwe adojutofo gẹgẹ bi ẹni ti yoo jogun, ko le ba ri owo lori owo adojutofo ẹni to ku, ati owo isinku.
Oṣu to n bọ ni wọn o ṣe idajọ rẹ nile ẹjọ.
"NCC Alerts to Telcoms: Ṣé ẹ ti gbọ́ nípa bí ""Flubot Malware"" ṣe lè kọlu fóònù yín lójijì?"
Oríṣun àwòrán, AFP
Ọsẹ to kọja ni ajọ to n mojuto awọn ileeṣẹ ibaraẹnisọrọ ni Naijiria, NCC, ke si awọn araalu lati ṣọra fun kokoro ijamba Flubot Malware to le ṣe foonu wọn.
1. Ẹrọ ibanisọrọ Android ni Flubot ma n doju kọ
Kokoro Flubot ma n fi ara rẹ han bi awọn Ápp banki, lati le gba akọsilẹ nipa awọn App miran to wa lori foonu rẹ. Afojusun rẹ si ni lati gba akọsilẹ nipa rẹ, kaadi ATM rẹ, ati 'password' to fi n lo App banki lori foonu.
2. Atẹjiṣẹ SMS ni wọn fi n pin Flubot
Flubot ma n wọ ori foonu nipasẹ atẹjiṣẹ, o si le ṣe amí awọn atẹjiṣẹ to ba wọle, o le pe awọn nọmba ori foonu rẹ, o le ka tabi kọ atẹjiṣl, o si tun le ko awọn nọmba ti o ni sori foonu rẹ lọ si ile agbara rẹ.
3. O le gba ori foonu rẹ ṣe ijamba fun ẹlomiran
To ba ti wọ ori foonu rẹ nipasẹ atẹjiṣẹ, yoo fi iru atẹjiṣẹ bẹẹ ranṣẹ si awọn nọmba to wa lori foonu rẹ pe ki awọn naa download ayederu app naa.
4. Awọn kokoro miran le gba ibẹ wọle
Ti Flubot ba wọ ori foonu kan, o le yọri si pipanu owo. Bakan naa ni 'malware' yii yoo ṣi ọna silẹ fun awọn to wa ni idi bo ṣe wọle lati tun fi awọn iru malware mii ranṣẹ sori foonu naa.
"Flubot yìí máa n farahàn lórí fóònù ""Android"" rẹ gẹ́gẹ́ bi àwọn abánifẹ̀rù ránṣẹ́ DHL, FEDEX, Correos tàbi èròjà Chrome tí ó ń lò lórí fóònù rẹ̀, èyí ni yóò si fi gba ẹ̀lòmííràn láàyè sórí fóònù rẹ láti mọ bi ǹkan ṣe ń lọ."
Nínú àtẹjáde tí olùdarí ọ̀rọ̀ tó kan ará ìlú ní NCC Dr Ikechukwu Adinde fọ́wọ́ si ló ti ṣàlàyé pé ní ọ̀pọ̀ ìgbà, irú àwọn kòkòrò yìí wà láti ba àwọn ǹkan jẹ́ lórí fóònù, tàbí láti ni ànfàní si lílo fóònù náà.
Ogogo wá sí iléèwé wa, mo kéwì fún un ló sọ mi di èèyàn ńlá lórí ayélujára - Akinwumi Akewi
NCC ní gẹ́gẹ́ bi nǹkan ti àwọn gba láti ọ̀dọ̀ àjọ tó n ri si ìṣẹ̀lẹ̀ pàjáwìrì ẹ̀rọ ayára bí àsá ni Nàìjíríà (ngCERT) ló ṣàlàyé pé, Android ni Flubot n koju, ti yóò si wá bi ẹni pe o ni láti gba áàpù ààbò sórí ẹ̀rọ ìpè rẹ.
ngCERT fi kun un pé, nígbà mííràn kòkòrò yìí a wá bíi áàpù bánkì rẹ̀ láti tàn ọ lọ sórí ojú òpó òfégè, tí wọn yóò sì jí àwọn dátà rẹ lójúnà láti pada jí owó tó wà nínú àpò ìkówópamọ rẹ̀ ni Bánki.
Flubot yìí bákan náà tún máà n tàn ká nípa àtẹ̀jíṣẹ (sms) tí o si le rí àwọn nǹkan mííràn tó bá ń wọlé sí orí fóònù rẹ̀, ká àtẹ̀jísẹ́ rẹ bákan náà ni o le fi àwọn nọ́mbà orí fóònù rẹ ránṣẹ́ si olú ilé wọ́n.
Malware tuntun yìí a maa sọ èròjà ààbò orí fóònù rẹ di aláìlágbára ti o si le fa kí ènìyàn pàdánù owó, bákan náà ló ni ilékùn mííràn tí yóò gba ọ̀nà ẹ̀yìn ṣí láti mú àwọn ẹni ibi yìí fi orúkọ tàbi nǹkan ìní rẹ hùwà ọdaràn tàbí kí o tún kó àwọn kòkòrò míírà sórí fóònù rẹ.
Kíni àwọn nǹkan tí o le ṣe láti dènà Flubot lórí fóònù rẹ̀?
1. Má tẹ ojú ìlà (link) kankan ti wọ́n ba fi àtẹjíṣẹ́ ránṣẹ́ sí ọ, bákan náà si ni kí o má gba áàpù tábi gba aapu ìdáàbòbo kankan sí orí fóònù rẹ.
2. Lo àwọn áàpù tó ń dènà kòkòrò tàbi tí yóò ta ọ lólobó ti nǹkan ti ko dara bá wà lórí fóònù rẹ (Antivirus).
3.  Ṣe àyẹ̀wò kí o tó tẹ ojú ìlà tàbí gba áàpù kan si orí fóònù rẹ.
4. Gbé àgádágodo tó lágbára sí ẹnú ọ̀nà àwọn áàpù tí ò ń lò, kí ó sì tún fí áàpù oní ọ̀nà méjì (2FA) tí o bá fẹ́ lo fóònù.
5. Máa dáàbò bo iṣẹ́ rẹ lójoojúmọ ati àwọn dáta rẹ kí o ma baa sọnú.
6. Ti àwọn nǹkan wọ̀nyìí bá bá ọ wí, ó ṣe pàtàkì kí o dá fóònù rẹ padà sí bi o ṣe ràá lóní wàrànsesà, èyí yóò yọ gbogbo kòkòrò tí kò tọ́ to bá ti wà lórí fóònù rẹ kúrò.
7.  Má ṣe àdápàdà àwọn àápù tí ò ń lọ tẹ́lẹ̀, yálà tun wọn gbà sí ori fóònù rẹ, o le ké si ngCERT lójú òpó incident@cert.gov.ng fún ìrànwọ́.
"8. Bákan náà o nílò láti ṣe àyípadà sí 'Password"" rẹ pàápàá jùlọ lórí gbogbo àwọn áàpù tí òun lò àti gbogbo àtẹ̀jíṣẹ́ Banki rẹ."
9. Bí o bá wá rò pé ẹni ti ko tọ ti ni àṣẹ si fóònù rẹ, tètè kan sí Banki ré lati ṣe àtúnṣe.
Nollywood: Kìí ṣe nǹkan ìtìjú pé èmi ni mò ń gbọ́ bùkátà ẹbí mi - Nkechi Blessing
Oríṣun àwòrán, Nkechi
Gbájúgbajà  òṣèré  Nollywood Yoruba Nkechi Blessing Falegan pe kò sí ǹǹkan ìtìjú fún òun láti jẹ́ ẹni to n gbọ́ bùkátà àwọn ẹbi òhun.
Ojú òpó Insagram rẹ ló ti fi ìdí ọ̀rọ̀ yìo múlẹ̀ lásìkò tó n ṣe ìránti oṣù kan ti ìyá rẹ re ibi àgbà n re.
Gbajúgbajà òṣèré náà pàdánù ìyá rẹ lẹ́yín ọjọ́ díẹ̀ sí ayẹyẹ ọjọ́ ìbí rẹ̀, tí ó sì ṣe ẹ̀yẹ ìkẹyìn fún ìyá rẹ ni ọ̀eẹ̀ tó kọjá.
Oríṣun àwòrán, Nkechi Blessing
Lẹ́yìn ayẹyẹ ọkú náà ni òṣèré ọhún lọ sí ilẹ Gẹ̀ẹ́sì láti lọ bá ọkọ rẹ David Adelegan tí kò sí nibi ayẹyẹ ìsìnku ìyá Nkechi Blessing.
Ó ṣàlàyé pé, ìyá òun àti ẹbi tí òin nílò láti gba bùkàta wọn ó fàá tí òun fi n ṣe iṣẹ àṣefẹ́ẹ̀kú, kìí ṣi ṣe ohun ìtìjú rárá.
Ní báyìí òṣeré náà ni òun ṣeetan láti padà sí ẹnu isẹ́ àti láti tẹ̀síwájú lẹ́nu iṣẹ́.
Nkechi Blessing dúpẹ́ lọ́wọ́ gbogbo àwọn ènìyàn tó dúró tìí lásìkò ìsìnkú ìyá rẹ̀.
Nítorí owó, ọlọ́pàá obìnrin kan pa mọ̀lẹ́bí rẹ̀ márùn-ún àti ọ̀rẹ́kùnrin rẹ̀
"Ṣé ẹ ti gbọ́ nípa bí ""Flubot Malware"" ṣe lè kọlu fóònù yín lójijì? - NCC"
Ọ́ọ́físà tó lu Clement awakọ̀ Uber níbi EndSARS gba ìwé máa lọ ilé ná
Ogogo wá sí iléèwé wa, mo kéwì fún un ló sọ mi di èèyàn ńlá lórí ayélujára - Akinwumi Akewi
Sit at home Ipob: Ẹgbẹ́ IPOB kéde kónílé-ó-gbélé ọ̀sẹ̀ kan lásìkò tí ìdìbò gómìnà Anambara yóò wáyé
Ẹgbẹ to n ja fun idasilẹ orilẹ-ede Biafra, IPOB ti kede iwọde ọlọsẹ kan gbako jakejado ilẹ Igbo, bẹrẹ lati ọjọ karun-un si ọjọ kẹwaa, oṣu Kọkanla.
Ipob sọ pe iwọde ati ofin konile-o-gbele naa jẹ ọna lati mu ki ijọba apapọ tu Nnamdi Kanu silẹ.
Ṣugbọn ṣa, ikede naa waye lasiko ti idibo gomina ipinlẹ Anambra ku diẹ. Ọjọ kẹfa, oṣu Kọkanla ni idibo naa yoo waye.
Akọwe ipolongo fun IPOB, Emma Powerful, to fi ikede naa sita ni ọjọ Satide sọ pe:
Lẹyin ti wọn ti sun igbẹjọ olori wa, Mazi Nnamdi Kanu, si ọjọ kẹwaa, oṣu Kọkanla, awa ọmọ ẹgbẹ IPOB n kesi awọn ọmọ ilẹ Biafra, awọn ọrẹ Biafra, ati awọn to fẹran ominira, pe IPOB yoo da gbogbo nkan duro ni ilẹ Biafra, bẹrẹ lati ọjọ karun-un si ọjọ kẹwaa, oṣu Kọkanla.
O ni ọjọ Aiku nikan ni anfaani wa fun awọn eeyan lati jade, ki wọn o le lọ sin Ọlọrun.
Powerful sọ pe awọn yoo gbe igbesẹ naa, ti ijọba Naijiria ba fi kuna lati tu Kanu silẹ lai gba ẹjẹ kankan titi ọjọ kẹrin, oṣu Kọkanla.
O ni lootọ ni awọn mọ inira ti ofin konile-o-gbele naa ni lara awọn araalu, ṣugbọn o jẹ dandan nitori ki ki nkan le dara fun gbogbo ọmọ Biafra.
Ọgbẹni Powerful tẹsiwaju pe awọn ko ni i gba ki wọn o ma a ṣe igbẹjọ Kanu ni bonkẹlẹ, tabi labẹ ofin Sharia.
O sọ eyi nitori bi awọn oṣisẹ alaabo ko ṣe jẹ ki ẹnikẹni wọle sinu gbọngan igbẹjọ rẹ lọjọ kọkanlelogun, oṣu Kẹwaa.
IPOB ni awọn yoo jẹ ki ijọba Naijiria mọ pe aadọrin miliọnu eeyan to jẹ ọmọ Biafra, ni Nnamdi Kanu n ṣoju.
Ooni on Sunday Igboho: Ọpọlọ ló yẹ kí Sunday Igboho fi jìjà ìlú, kìí ṣe ariwo lásán -
Ooni tilu Ile-Ife, Oba Adeyeye Enitan Ogunwusi, Ojaja Keji ti salaye pe ọpọlọ lo yẹ ki Sunday Igboho fi ja ija ilu, kii se nipa ariwo.
Ooni salaye bẹẹ lasiko to n ba BBC Yoruba sọrọ ninu akanse eto ifọrọwanilẹnuwo kan to fi sami ọjọ ibi rẹ.
Ọba Ogunwusi ni oun ti ba aarẹ Buhari sọrọ pupọ nipa Sunday Igboho tẹlẹ, ti wọn si ni ki oun lọ sọ fun pe ko dakẹ ijijagbara to n se amọ ko gbọ.
O ni eebu lo n bu oun, ti ọpọ awọn ọmọ Yoruba to n gba nimọran si ti pọ ju lai mọ pe maa jo lọ, mo n wo ẹyin rẹ ni wọn n se fun.
Ooni ni sibẹ ọmọ ẹni kii se idi bẹbẹrẹ, ka fi ilẹkẹ si idi ọmọ ẹlomiran, sibẹ ọmọ oun si ni Sunday Igboho ati pe ẹya rẹ lo n ja fun.
Oriade naa ni ko seese ki eeyan kan soso maa ba ijọba ja nigba ti onitọun ko ni ohun ijagun ninu ile.
O ni ọpọ awọn eeyan to n ti Igboho lẹyin lo wa loke okun, ti ipo ti orilẹede Naijiria si wa n ka wọn lara nitori ọpọ wọn lo fẹ wa sile pada.
Ọba alaye naa wa ni suuru ni awọn yoo fi yanju gbogbo rẹ, ti Ọlọrun Olodumare yoo si gba fun wa ni Naijiria.
Coup attempt in Sudan: Ìròyìn n sọ pé ìdìtẹ̀ gbàjọba n wáyé lọ́wọ́ ní Sudan
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Awọn ọmọ ogun orilẹ-ede Sudan ti mu ọpọlọpọ awọn ọmọ igbimọ ijọba awaarawa si atimọle.
Bakan naa ni wọn ti ti ilẹkun mọ olootu ijọba, Abdalla Hamdok, mọ ile rẹ.
Awọn iroyin yii lo n jade lati orilẹ-ede Sudan, to wa ni Africa.
Ileesẹ ologun ko tii sọrọ lori isẹlẹ yii amọ awọn ẹgbẹ to fara mọ ijọba alagbada ti n pe fun iwọde oju popo.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Awọn ologun atawọn olori ẹgbẹ to n ja fun ijọba awarawa ti n tako ara wọn lati bi ọdun meji ti wọn ti doju ijọba Omar al-Bashir bolẹ.
Lẹyin igbakoso ijọba naa ni wọn se agbekalẹ awọn ọmọ igbimọ ti yoo da ijọba pada fun awọn alagbada.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ko si ẹni to le sọ awọn to wa nidi bi wọn ṣe fi ọwọ ofin mu awọn eeyan naa ni idaji.
Amọ, atẹjade kan ti ileeṣẹ ijọba to n ri si ọrọ iroyin fi sita sọ pe awọn ikọ ologun kan lo wa nidi ọrọ naa.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
A n ṣi n ṣe akojọpọ iroyin yii lọwọ. Ẹ ma a kàn si oju opo yii loore-koore fun bi nkan ṣe n lọ ni orilẹ-ede Sudan.
US Fake Marriage Pastor: Ẹ̀wọ̀n ọdún márùn-ún ni ìkọ̀ọ̀kan ẹ̀sùn jìbìtì àti irọ́ pípa tí wọn fi kan Pásítọ̀ gbérù
Oríṣun àwòrán, facebook
Olusọagutan kan ni Maryland lorilẹede Amẹrika, tii se ẹni aadọta ọdun, Joshua Olatokunbo Shonubi ni wọn ti fi ẹsun kan pe o se ọpọ ayederu igbeyawo laarin awọn mẹkunnu nilẹ Amẹrika atawọn ajeji lọna ati gba iwe igbelu.
Wọn fi ẹsun kan Pasitọ naa pe o se magomago loju ọna ati gba iwe igbelu ni Amẹrika, to si n se ayederu igbeyawo, ayederu iwe igbelu ati genje iwe adehun gbigba ile.
Joshua Olatokunbo Shonubi, to tun n jẹ Olatokunbo Joshua Shonubi, ni awọn agbẹjọro ijọba nilu naa wọ lọ sile ẹjọ pe o n lu jibiti nipa igbeyawo ati iwe asẹ iwọlu taa mọ si Visa, to si tun ko awọn genje iwe ẹri awọn ileesẹ ijọba silẹ.
Atẹjade tawọn agbefọba naa fisita ni Shonubi gbe nilu Bowie, to si tun jẹ Pasitọ ijọ New Life City to wa lẹba Hyattsville ni Maryland yii kan naa amọ maili mejila ni ilu mejeeji fi jinna sira wọn.
Tunde Bakare journey in life: Bàbá bàbá mi ni Lèmọ́mù àkọ́kọ́ ní Sodeke Abeokuta ṣùgbọ́n..
Atẹjade naa ni lati ọdun 2014 titi di ọdun 2021  ni Pasitọ Shonubi fi se magomago yii, to si gba ẹgbẹlẹgbẹ dọla lati ọwọ awọn ajeji ni orilẹede miran pe oun yoo bawọn seto igbeyawo pẹlu awọn ọmọ ilẹ Amẹrika.
Bakan naa ni wọn tun fi ẹsun kan Shonubi pe gẹgẹ bii Pasitọ, o n gba awọn eeyan ti ko ni agbara lati tọju ara wọn sọdọ rẹ, to si n kọ wọn lati maa se igbeyawo pẹlu awọn ọmọ ilẹ Amẹrika, eyi to ni yoo tete jẹ ki wọn ni iwe igbelu.
Nigba mii, Shonubi yii ni wọn lo maa n seto igbeyawo yii funra ara rẹ nile ijọsin rẹ tabi ko ran tọkọ taya naa lọ si Virginia fun ayẹyẹ igbeyawo nla.
Awọn agbefọba naa ni ni kete tawọn eeyan naa ba ti se igbeyawo tan, ti wọn si san owo nla fun Shonubi, oun ni yoo ba wọn seto iwe ti wọn yoo fi sọwọ si ileesẹ to n ri si ọrọ iwe igbelu, ti yoo si fi adirẹsi rẹ sibẹ, ọwọ rẹ si ni iwe tabi iroyin nipa igbesẹ naa yoo maa de si.
Shonubi yii tun ni wọn ni yoo fi awọn ayederu iwe sọwọ si ileesẹ naa pẹ́lu iwe sọọsi rẹ, ti yoo si sọ nipa bo se mọ tọkọ taya naa si, to si maa n tọ wọn sọna ninu ẹmi ati bi igbeyawo wọn se da lori ifẹ pipe.
Wọn ni o to iru ayederu iwe ẹri bayii bii mejidinlogoji ti Shonubi ti se fawọn ofege lọkọ laya, ti yoo si tun pese ẹbu iwe to fihan pe awọn tọkọ tiyawo naa dijọ n gbe papọ ni.
Ikọ agbẹjọro agbefọba naa ni Shonubi ni ọwọ ti tẹ bayii, to si ti yọju siwaju adajọ ni Baltimore lọjọ, to si seese ko fi ẹwọn ọdun marun marun jura lori awọn koko ẹsun lilu jibiti ati irọ pipa ti wọn fi kan.
Oyo Jail Break: Ọ̀gá àgbà ọgbà ẹ̀wọ̀n fèsì lórí ìròyìn pé Wakili Iskilu wà lára àwọn ẹlẹ́wọ̀n tó sálọ lọgbà ẹ̀wọ̀n Abolongo l'Oyo
Oríṣun àwòrán, BBC/others
Ọpọ lo ti n sọ pe afurasi olori awọn Fulani ajinigbe, Iskilu Wakili wa ni ọgba ẹwọn Abolongo niluu Oyo nibi tawọn afurasi agbebọn ṣe ikọlu si ti wọn si tu awọn ẹlẹwọn silẹ.
Ajọ to n ṣe akoso ọgba ẹwọn ni Naijiria, NCS ẹka ti ipinlẹ Ọyọ ṣe alaye wi pe awọn ẹlẹwọn ẹgbẹrin ati metadinlogoji, 837 to n reti igbẹjọ ni ọgba ẹwọn Abolongo to n bẹ nilu Ọyọ lo salọ.
Awọn ẹlẹwọn ọhun raye salọ lẹyin tawọn afurasi agbebọn yawọ ọgba ẹwọn naa ni alẹ ọjọ Ẹti.
Ohun ti awọn eeyan n sọ ni pe Iskilu to wa lọgba ẹwọn naa lo ṣe okunfa bi awọn agbebọn sẹ kọlu ọgba ẹwọn naa.
Awọn eeyan naa ni Iskilu wa lara awọn ẹlẹwọn to salọ.
Ṣugbọn ninu ọrọ rẹ, ọga agba ọgba ẹwọn ni Naijiria, Tukur Ahmed ti fidi rẹ mulẹ pe Iskilu ko si lọgba ẹwọn Abolongo debi pe yoo raye salọ lati ibẹ.
Ọdun to kọja ni awọn ọmọ ẹgbẹ Oodua Peoples Congress (OPC) le Wakili kuro nilu Ayete nipinlẹ Oyo, ti wọn si fi le ọlọpaa lọwọ.
Awọn ara ilu naa fi ẹsun kan an pe oun ni balogun awọn Fulani to n ni araalu lara nibẹ.
Bakan ni o ṣalaye pe afurasi agbenipa, Sunday Shodipe ti ọwọ tẹ ni agbegbe Akinyele lọdun 2020, naa ko si ni ọgba ẹwọn Abolongo gẹgẹ bi awọn eeyan kan ṣe n sọ kaakiri.
Oríṣun àwòrán, Oyo State Government
Ọgbẹni Ahmed fidi ọrọ yii mulẹ nigba to n sọrọ lori ẹrọ Radio Nigeria lori iṣẹlẹ naa.
Ọga agba ọgba ẹwọn ni Naijiria ṣalaye pe ọgba ẹwọn to wa niluu Ibadan ni Iskilu ati Shodipe wa kii ṣe Abolongo niluu Oyo.
Ọpọ ninu awọn ẹlẹwọn to wa ni ọgba ẹwọn Abolongo lo ti pada fun ra wọn nigba tawọn agbofinro mu awọn mii.
Alukoro ileeṣẹ ọgba ẹwọn ti ẹka ilu Oyo naa, Olanrewaju Anjọrin, sọ fun BBC Yoruba pe Iskilu ati Shodipe ko si ni ọgba ẹwọn l'Oyo.
Amọ o fidi rẹ mulẹ pe Ọgbẹni Olaniyan Amos ti ajọ EFCC fẹsun jibiti lilu kan wa ni ọgba ẹwọn Abolongo niluu Oyo ni tirẹ.
Anjorin ṣalaye pe ọkunrin naa ko salọ sibi kan nigba tawọn agbebọn kọlu ọgba ẹwọn l'Oyo.
O ni Ọgbẹni Amos si wa ni ọgba ẹwọn naa titi di akoko yii.
Ẹwẹ, minisita ọrọ abẹle, Ogbeni Rauf Aregbesola, ti sọ pe gbogbo awọn ẹlẹwọn to salọ ni ileeṣẹ ọgba ẹwọn yoo mu pada.
Oríṣun àwòrán, Federal Ministry of Interior
Minisita fun ọrọ abẹle, Rauf Aregbesola ti se abẹwo si ọgba ẹwọn naa
Ogbeni Aregbesola sọrọ yii nigba to ṣabẹwo si ọgba ẹwọn Abolongo nibi ti iṣẹlẹ ọhun ti waye.
''Ikọlu si awọn ọgba ẹwọn wa ni Naijiria ti n pọju, o si n kọ wa lominu.
Amọ, o to gẹẹ bayii, a gbọdọ wa nkan ṣe si ọrọ naa, ṣugbọn mo fi n da awọn ọmọ Naijiria loju pe awọn to wa nidi ikọlu yii atawọn ẹlẹwọn to salọ lọwọ ofin yoo ba.
Mo gboṣuba fawọn ẹṣọ eleto abo wa fun iṣẹ ribi ribi ti wọn ṣe lati doju ija kọ awọn afurasi agbebọn to ṣe ikọlu si ọgba ẹwọn Abolongo.
A ti mu awọn kan ninu awọn ẹlẹwọn to salọ, o dami loju pe a o mu awọn to ku naa,'' Ogbeni Aregbesola lo sọ bẹẹ.
Rumuekpe Port Harcout explosion: Èèyàn 25 jóná níbi ọ̀pá epo tó fọ́
Oríṣun àwòrán, Other
Ko din ni eeyan mẹẹdogun to jona kú nibi ibugbamu to waye ni ibudo ifọpo kan ti ijsba ko fọwọ si nipinlẹ Rivers.
Awọn ileeṣẹ iroyin abẹle sọ pe awọn ọmọde wa lara awọn to ku.
Bakan naa n i awọn ti iṣẹlẹ naa ṣoju wọn sọ pe ina bẹrẹ si ni jo lẹyin ri ọpa epo kan bu gbamu ni ibudo ifọpo ayederu naa to wa ni ilu Rumuekpe, nijọba ibilẹ Emohua, nipinlẹ Rivers.
Ibugbamu akọkọ yii lo tun ran awọn ọpa epo miran to wa ni agbegbe ọhun, ti gbogbo si gbina.
Ọpọlọpọ ile lo jona, ti awọn eeyan si farapa.
Nkan to wọpọ ni agbegbe Niger Delta ni ki awọn ọdọ ma a wa epo bẹtiro ni awọn ibudo ti ko ba ofin mu, nipa fifọ ọpa eporọbi.
Awọn alaṣẹ sọ pe o to ẹgbẹrun lọna ẹigba àgbá epo ni Naijiria n padanu lojoojumọ, nitori bi awọn kan ṣe n fọ ọpa epo.
Hunger in Afghanistan: Ọkọ àti ìyàwó ta ọmọ wọn ní N200,000 nítoró ìṣẹ́
Yoruba bọ, wọn ni ti ebi ba kuro ninu iṣẹ, iṣẹ buṣe.
Ṣugbọn ọrọ ebi nikan kọ ni iṣoro to n koju awọn ọmọ orilẹede Afghanistan, papaa julọ lati igba ti ẹgbẹ Taliban ti gba ijọba nibẹ.
Rukerudo, rogbodiyan ati oriṣiiriṣii ajalu lo ti n ṣẹlẹ kaakiri Afghanistan lati igba ti Taliban ti gba ijọba.
Gbogbo iranwọ ti Aghanistan n ri gba tẹlẹ lati ọdọ awọn orilẹede agbaaye to rọwọ họri ni ko si mọ bayii lati igba ti Taliban ti gori aleefa.
Laipẹ yii ni ajọ iṣọkan agbaye, UNO ke gbajare pe ẹgbẹlẹgbẹ miliọnu eeyan ni Afghanistan ni ebi yoo pa ku ti orilẹede naa ko ba ri iranwọ lati ilẹ okeere.
Akọroyin BBC, Yogita Limaye to wa n Afghanistan jabọ pe ni ilu Herat ọpọlọpọ ẹbi ni atijẹ atimu nira fun.
Oriṣiiriṣii nkan lawọn obi n ṣe lati ri pe awọn ọmọ wọn ri ounjẹ jẹ.
Nibẹ ni a ti ri ọkọ ati iyawo kan ti wọn ta ọmọbinrin wọn ni ẹgbẹrun un lọna igba naira tii ṣe ẹẹdẹgbẹta owo dola, $500.
Iya ọmọdebinrin naa ṣalaye pe oun ati ọkọ oun pinnu lati ta ọmọ awọn ki awọn le ri owo ra ounjẹ fawọn ọmọ to ku.
Iya ọmọ naa ṣalaye pe ''ebi lo n pa wa ku lọ lo jẹ ki a ta ọmọdebinrin wa ki a ba le ri ounjẹ jẹ ni pẹlu awọn ọmọ wa to ku.
Ko wu mi ki n ta ọmọ mi amọ ohun to de lo ni ki a ri ohun.''
Iṣẹ ako idọti ni baba ọmọdebinrin yii n ṣe ṣugbọn owo perete ni o n ri nibẹ.
Baba ọmọ naa sọ pe ''ebi n pa wa, ko si iyẹfun, ko si ororo, a o ni ohun kankan.
Ọmọdebinrin mi ko mọ ohun to le ṣẹlẹ si i lọjọ iwaju bayii, mi o tiẹ mọ bo ya inu rẹ dun si bi a ṣe ta a.
Ṣugbọn ohun ti a gbọdọ ṣe ni nitori iṣoro airijẹ ati airi mu to n doju kọ wa.''
Kete ti ọmọ ba ti bẹrẹ si ni rin ni awọn obi wọn maa n ta wọn ni Afghanistan.
Cultism: Ọmọ ẹgbẹ́ òkùnkùn dèrò àtìmọ́lé torí ó fẹ́ da ìdánwò ilé ẹ̀kọ́ rú l'Ogun
Oríṣun àwòrán, ABIMBOLA OYEYEMI,
Ọwọ ileeṣẹ ọlọpaa ipinlẹ Ogun ti tẹ afurasi ọmọ ẹgbẹ okunkun kan lasiko to n gbiyanju lati da ile ẹkọ ru nigba ti wọn n ṣe idanwo.
Iṣẹlẹ naa wa ye nile ẹkọ imọ ẹrọ ipinlẹ Ogun to wa ni Igbesa, to wa ni Ado Odo, ni ijọba ibilẹ Ota.
Ọwọ tẹ afurasi ọhun lẹyin ti awọn ọlọpaa gbọ pe awọn ọmọ ẹgbẹ okunkun ọhun n mura lati kọlu ile ẹkọ naa.
Iroyin ni ede aiyede ti kọkọ waye laarin awọn akẹkọọ kan atawọn alaṣẹ ile ẹkọ naa, eyii to mu ki awọn alaṣẹ ọhun sun idanwo naa to yẹ ko waye ṣaaju siwaju.
Gẹgẹ bii atẹjade ti agbẹnusọ ileeṣẹ ọlọpaa ipinlẹ Ogun, Abimbola Oyeyemi fi lede, awọn ọmọ ẹgbẹ okunkun naa gbimọ pọ lati da idanwo naa ru lẹyin ti wọn ko mura lati ṣe idanwo naa ṣaaju.
Oyeyemi sọ pe ni kete ti awọn ọlọpaa gbọ nipa erongba awọn ọmọ ẹgbẹ okunkun ọhun ni wọn gbera lọ sibẹ pẹlu ajọṣepọ ileeṣẹ NSCDC, to fi mọ ikọ eto abo ile ẹkọ gbogboniṣẹ naa.
Lasiko ti wọn n yẹ awọn akẹkọọ naa wo ki wọn to wa yara idanwo ni akara awọn ọmọ ẹgbẹ okunkun naa tu sepo.
Oyo Jailbreak: Wo ọṣẹ́ tí àwọn ẹlẹ́wọ̀n Abolongo ṣe fáwọn ará Oyo àti bí wọn ṣe rí wọn mú
"O ni ""Bi ayẹwo ọhun ṣe n lọ lọwọ, a ka apo dudu kan mọ afurasi yi ati omiran ti wọn  pe ni Aloma lọwọ, ṣugbọn Aloma fẹsẹ, ti ọwọ si tẹ Ojo Akinola."""
Nigba ti a yẹ inu apo dudu naa wo, a ba ibọn ilewọ atọwọrọ kan ti ọta kan si wa ninu rẹ ninu apo ọhun.
"Alukoro ọlọpaa na tẹsiwaju pe ""Nigba ti a fi ọrọ wa afurasi naa lẹnu wo, o jẹwọ pe ọmọ ẹgbẹ okunkun 'AYE' ni oun, ati pe awọn ẹgbẹ oun wa lati da idanwo naa ru ni."""
Ẹwẹ, kọmiṣọna ọlọpaa ipinlẹ Ogun, Lanre Bankole ti paṣẹ ki wọn gbe ẹjọ naa si ọọfisi ẹka CID fun iwadii ni kikun ati ki wọn le tete ṣawari awọn ọmọ ẹgbẹ naa to na papa bora.
Ki lo ti ṣẹlẹ sẹyin?
Oríṣun àwòrán, Facebook/Dapo Abiodun
Ileeṣẹ ọlọpaa ipinlẹ Ogun sọ pe iwadii n lọ lọwọ lori iṣẹlẹ akẹkọọ to ran awọn janduku lọ lu olukọ mejii ni ile ẹkọ Community High School niluu Ijoun, ijọba Ariwa Yewa nipinlẹ Ogun.
Agbẹnusọ ileeṣẹ ọlọpaa ipinlẹ Ogun, DSP Abimbola Oyeyemi to ba BBC Yoruba sọrọ ṣalaye pe awọn akẹkọọ naa n pariwo ni kilaasi wọn nigba ti ọkan lara awọn olukọ ti wọn lu n kọ awọn akẹkọọ mii lọwọ ni kilaasi keji.
Iroyin kan tiẹ sọ pe awọn janduku yii lu awọn olukọ naa debi wi pe wọn di ero ile iwosan.
''Ariwo tawọn akẹkọo yii n pa lo jẹ ki olukọ yii lọ bawọn wi ni kilaasi wọn.
Lẹyin naa ni akẹkọo yii lọ ran awọn janduku lọ si ile ẹkọ naa ti wọn si lu awọn olukọ yii ati omiran ni alubami.
Kilaasi SS1 ni akẹkọọ yii wa, ileeṣẹ ọlọpaa si ti mọ akẹkọọ naa ṣugbọn iwadii n lọ lọwọ lati fi ọwọ ofin mu akẹkọọ naa.
Ti a ba ti gba akẹkọọ naa mu, o di dandan ki o foju ba ile ẹjọ.
Ẹnikẹni tabi akẹkọọ ki akẹkọọ to ba da ile ẹkọ ru yoo foju ba ile ẹjọ, ileeṣẹ ọlọpaa ko ni gba iru wọn laaye,'' DSP Oyeyemi ṣalaye.
DSP Oyeyemi lo ṣai ṣalaye pe obi to ko awọn janduku lọ sile ẹkọ lati lu olukọ to ba ọmọ rẹ wi ni ile ẹkọ Unity High School, Kajola ni Ibooro ti n foju wina ofin bayii.
Agbẹnusọ ileeṣẹ ọlọpaa ṣalaye pe awọn mẹta ni awọn ti fi ọwọ ofin mu bayii lori iṣẹlẹ naa ti wọn si n jẹjọ lọwọ.
DSP Oyeyemi tun sọ pe awọn janduku mii tawọn naa ko ada ati oriṣiiriṣii nkan ija oloro lọ lu olukọ nile ẹkọ Baptist College ni Idi -Aba naa ti n jẹjọ bayii.
Awọn eeyan kan tiẹ sọ pe oriṣiiriṣii nkan ija oloro lawọn janduku ọhun lo lati fi lu awọn olukọ naa.
2023 Presidential Election: CAN bẹ olóṣèlú láti máṣe káyà aráàlú sókè lásìkò ìpolongo ìbò
Oríṣun àwòrán, Rev Supo Ayokunle
Awọn adari ẹgbẹ ọmọlẹyin Kristi ni Naijiria CAN, ti kilọ fawọn oloṣelu Naijiria lati maṣe da wahala silẹ nipa gbigbe oludije aarẹ ati igbakeji rẹ to jẹ ẹlẹsin kanna kalẹ fun idibo aarẹ 2023.
Ẹgbẹ CAN ni awn ko ni fara mọ pe ki oldije fun ipo aarẹ ati igbakeji rẹ jẹ Musulumi ati Musulumi tabi Kristeni ati Kristẹni.
Aarẹ ẹgbẹ naa Rev.Samson Ayokunle lo fidi ọrọ yi mulẹ lasiko ipade awọn olori ẹgbẹ naa pẹlu igbakeji aarẹ ile aṣofin agba, Sẹnẹtọ Obarisi Ovie Omo-Agege  ni ọfisi rẹ lỌjọbọ.
O ni ''nitori idibo 2023 to n bọ lọna a fẹ rọ ẹyin oloṣelu lati maṣe ka araalu laya soke nipa ipolongo ati ọrọ ti yoo ma jade lẹnu yin.
Ilu kan gogo lọwọ ta wa bayi paapa nitori ipenija aabo to wa nilẹ''
Ogogo wá sí iléèwé wa, mo kéwì fún un ló sọ mi di èèyàn ńlá lórí ayélujára - Akinwumi Akewi
''Bẹẹ naa la fẹ ki ẹ ri pe lori ipo aarẹ, ẹ ri wi pe deede wa nibẹ. A ko fẹ tikẹẹti Musulumi pẹlu Musulumi tabi Kristẹni ati Kristẹni''
O tẹsiwaju nipa fifi ẹdun ọkan rẹ lori bi eto ọrọ je sẹ dẹnu kọlẹ ati ipa ti eleyi ni lori iṣakoso ilẹ yi to fi mọ inira to n ba araalu lori rẹ.
O rọ ijọba lati wa ọna ti wọn yoo fi mu idẹrun ba araalu.
O ni ''Ọwọngogo nkan to gbode yi n kan ile ijọsin lominu ti pupọ awọn eeyan wa ko si niṣẹ lọwọ.
Bo ti lẹ jẹ wi pe a mọ riri ile aṣofin nipa kikesi awọn ẹka alaṣẹ lati mu iyipada wa, a fẹ ki wọn tubọ pese ọna ti awọn oniṣowo yoo fi ẹ ri iṣẹ ṣe daada.
Lara rẹ ni ki wọn foju fo awọn owo ori kan fawọn to ba n pese ọja labẹle''
Igbakeji aarẹ ile aṣofin agba Sẹnẹtọ Obarisi Ovie Omo-Agege wa dupẹ lọwọ wọn fabẹwo yii, to si ni iru ifikunlukun bẹẹ yoo mu ki ibaṣepọ to gun rege wa laarin CAN ati ile aṣofin Naijiria.
"Ọrọ ẹni ti yoo di ipo aarẹ mu ni Naijiria jẹ eleyi ti ọpọ maa n foju si, paapa nibi ti awọn ti maa n wo ọrọ ẹya ati ẹsin ki wọn to dibo fun ẹnikẹni.
Ooni: A kìlọ̀ fún Sunday Igboho pé kó dákẹ́ àmọ́ kò gbọ́, èébú ló ń bú wa
Yatọ si CAN to mẹnu ba ọrọ yii, ni bayi ti ọjọ idibo ti n sunmọ, o ṣeeṣe ki awọn ẹgbẹ mi naa maa dide lori afojusun wọn nipa ẹni ti yoo dipo aarẹ ati igbakeji mu ni Naijiria.
Lọpọ igba awọn ẹgbẹ oloṣelu a maa fẹnukọ laarin ara wọn nipa yiyan musulumi ati Kristeni lati dije dupo aarẹ ati igbakeji labẹ asia wọn.
Iwe ofin Naijiria ko fi ti ẹya tabi ẹsin ṣe nipa ẹni to le du ipo yii tabi ti ẹgbẹ kankan le fa kalẹ.
Oríṣun àwòrán, Facebook/Bukola Saraki
Aarẹ ile igbimọ aṣofin agba niluu Abuja tẹlẹ rẹ, Bukola Saraki ti ṣi aṣọ loju eegun lori bo ya o le fi ẹgbẹ oṣelu PDP silẹ lọ APC.
Saraki fi ọrọ yii lede ninu ifọrọwerọ rẹ lori ileeṣẹ amohunmaworan Arise News lọjọ Iṣẹgun.
Saraki ni ko lo boju mu ti oun ba fi PDP silẹ lọ si APC nitori oun kii ṣe oni imọ tara ẹnikan ẹda.
''Lori ibeere wi pe ṣe mi o lo lọ si ẹgbẹ oṣelu APC ti PDP ko ba yan mi gẹgẹ bi oludije aarẹ fun ibo ọdun 2023, ko si ohun to jọ bẹẹ rara.
Mo gbiyanju lati dupo aarẹ lọdun 2015 ninu ẹgbẹ PDP ṣugbọn n ko ni anfani lati ṣe bẹẹ.
Lẹyin naa ni mo jẹ oluṣakoso ipolongo ibo fun Atiku Abubakar to jẹ oludije ipo rẹ fun ẹgbẹ PDP nigba naa.
Mo ṣiṣẹ takun takun fun Atiku ṣaaju ibo ọdun 2015.
Mo ni awọn ọmọ ati ọmọ ọmọ, ohun to jẹ mi logun bayii ni pe ki a fi orilẹede to dara silẹ fawọn ọmọ wa.
Mo fẹ Naijiria ti iṣẹ yoo ti pọ lọpọ yanturu fawọn ọdọ wa ti Eledua jogun ọpọlọ pipe fun un.
Lootọọ ni mo sọ pe awọn ọmọ ẹgbẹ PDP kan maa ya lọ si ẹgbẹ miran amọ iyẹn ko tumọ si pe mo maa ya lọ,'' Saraki lo sọ bẹẹ.
Saraki ko sọ ni pato bo ya yoo dije fun ipo aarẹ lọdun 2023.
O ni bi nkan yoo ti ṣenu ire fun PDP ninu eto idibo to n bọ lo jẹ oun logun bayii gẹgẹ bi ọmọ ẹgbẹ PDP.
Saraki ṣalaye pe idi niyii ti oun fi wa lara awọn to n ri si ati pari aawọ to wa laarin awọn ọmọ ẹgbẹ kan.
Gomina ipinlẹ Kwara nigba kan sọ pe lẹyin ti ẹgbẹ ba fẹsẹ mulẹ daadaa ṣaaju eto idibo ọdun 2023 lawọn ọmọ ẹgbẹ to le maa sọ nipa bo ya wọn fẹ dije fun ipo kan tabi omiran.
O ni oun yoo kede ipinnu oun faye gbọ lori bo ya oun yoo dije fun ipo aarẹ lọdun 2023 amọ ko tii to asiko bayii.
Diezani Alison-Madueke: Ìjọba lu kọ́mú, góòlù àti ilé mínísítà epo rọ̀bì tẹ́lẹ̀ Diezani ní gbàǹjo
Oríṣun àwòrán, EFCC
Ijọba apapọ ti bẹrẹ si lu awọn dukia minisita eporọbi tẹlẹ ni Naijiria, Diezani Alison-Madueke ni gbanjo.
Minisita epo rọbi tẹlẹ ọhun ti n jẹjọ lori ẹsun ṣiṣe owo ilu kumọ kumọ lasiko ijọba Aarẹ Goodluck Jonathan.
Lara awọn dukia Diezani ti ijọba fẹ ta ni ile awo dami ẹnu to wa ni Banana Island lagbegbe Ikoyi niluu Eko.
Awọn dukia Diezani ti ijọba tun fẹ ta ni goolu olowo iyebiye, aṣọ igbeyawo fun obinrin marunlelọgọfa, kootu mọkanla, kọmu mọkanla, iborun mẹtalelaadọrin.
Awọn nkan mii ni faanu meji, aṣọ bẹẹdi mẹfa ati bata olowo iyebiye mẹrinlelọgọta.
Bakan naa ni ijọba apapọ ti bẹrẹ idiyele dukia olori ileeṣẹ ọmogun ofurufu tẹlẹ ri, Air Chief Marshal Alex Badeh naa.
Ijọba ti kọkọ gbẹsẹ le ile ọgagun Badeh to wa ni Wuse 2 ati Maitama lori ẹsun iwa ajẹbanu lẹnu iṣẹ ọba.
Ni ọsẹ to lọ ni ijọba apapọ bẹrẹ ayẹwo fawọn onimọ nipa dukia tita to le ni ẹgbẹta lati ṣakoso tita awọn dukia tawọn oṣiṣẹ ọba ra lọna eeru.
Oríṣun àwòrán, Efcc
Awọn dukia naa to ti di ti ijọba lo wa ni agbegbe mẹẹdọgbọn kaakiri orilẹede Naijiria.
Dukia bii ọkọ, ile, ẹrọ ibaraẹnisọrọ, ẹrọ kọmputa ati awọn nkan mii to jẹ 1,620 ni ijọba apapọ fẹ lu ni gbanjo.
Ipinlẹ Eko ni awọn dukia yii pọ si julọ pẹlu ile mọkanlelọgbọn ati ọkọ 589.
Alaga igbimọ to n ri si tita dukia ti ijọba ti gbẹsẹ le, Mohammed Etsu ṣalaye pe igbimọ naa yoo ri pe abo to muna doko wa lori awọn dukia naa.
Diezani ti wa lorilẹede UK lati ọdun 2015 ti ijọba aarẹ Jonathan pari, lati igba naa si ni ko tii pada si Naijiria.
Ẹwẹ, alaga ajọ EFCC to n gbogun ti iwa ajẹbanu, Abdulrasheed Bawa, sọ loṣu Karun-un pe biliọnu mẹrinla Naira ni iye ti goolu Diezani to.
South West Governors: Akeredolu ní Tinubu kájúẹ̀ láti ṣe àkóso Nàìjíría
Oríṣun àwòrán, Seyi Makinde
Alaga ẹgbẹ awọn Gomina fun ilẹ Yoruba, Rotimi Akeredolu ti sọ pe Asiwaju Bola Tinubu to jẹ agba ọjẹ  fẹgbẹ APC koju osunwọn lati dari Naijiria.
Lasiko ti awọn Gomina naa sabẹwo si ile Tinubu to wa ni Bourdillon lo ti sọrọ naa.
Bakan naa lo fi kun pe Tinubu n gbiyanju gẹgẹ bi olori fun ẹkun iwọ oorun guusu Naijiria.
Lẹnu ọjọ mẹta yii ni awọn oloselu kan jakejado Naijiria ti n kan si Bola Tinubu ti ọpọ n woye pe o fẹ dije dupo aarẹ Naijiria lọdun 2023.
Amọ titi di ba se n sọrọ yii, Tinubu ko ti fi erongba rẹ han sita lori boya yoo du ipo aarẹ abi bẹẹ kọ.
Awọn Gomina Ekiti, Ogun, Oyo, Eko si lo peju sile Tinubu lasiko abẹwo yii.
Amọ Gomina ipinlẹ Ekiti Kayode Fayemi ko si laarin wọn.
Oríṣun àwòrán, Seyi Makinde
Iroyin kan ni Fayemi  wa ni Eko lasiko abẹwo yii sugbọn a ko le sọ pato idi ti ko se ba awọn gomina naa lọ sile Tinubu.
Akeredolu, lasiko to n ba awọn akọroyin sọrọ ni awọn kan si Tinubu to sẹsẹ dari irinajo pada sile lati London ni.
Ọpọ awa eeyan ẹkun guusu Naijiria la ri asaaju ẹgbẹ APC naa bi ara wa, ta si ni igbagbọ ninu ilana to fi n ṣe asaaju, eyi to fihan pe o n sa ipa rẹ lati dari wa."
Tinubu kii se asaaju fun ilẹ Kaarọ Oojire nikan amọ o tun jẹ asaaju fun ẹgbẹ to n dari Naijiria, APC.
"Sugbọn awa eeyan ẹkun iwọ oorun guusu ri gẹgẹ bi asaaju wa."""
Bi a ko ba gbagbe awọn Gomina yii, to fi mọ awọn oloselu miran ni Naijiria se abẹwo si Tinubu nigba to wa ni London lẹyin isẹ abẹ lori orunkun rẹ to se nilu ọba.
Akeredolu ko sẹṣẹ maa sọ pe gbọingbọin lawọn Gomina wa lẹyin Tinubu to loun ri gẹgẹ bi ''Kapọ'' ẹgbẹ awọn.
Timi Osukoya: Ọ̀pọ̀ olórin ẹ̀mí ló ń kọrin torí owó tàbí afẹ ayé
Flogging on Altar: Pásítọ̀ na àwọn ọmọ ìjọ láti mọ̀ bí wọn ṣe gbóná fún Ọ́lọ́run
Oríṣun àwòrán, Screen shot
Yoruba ni airin jinna ni airi abuke ọkẹrẹ, bii eeyan ba rin jinaa, yoo ri ibi ti wọn ti n fi odo ibulẹ jẹun.
Bẹẹ ni ọrọ ri ninu ijọ kan ti ẹnikẹni ko mọ orukọ rẹ, nibi ti olori ijọ naa ti da awọn ọmọ ijọ rẹ kan dubulẹ si ori pẹpẹ, to si n ko bẹliti ya wọn.
Fidio naa to gba ori ayelujara kan lo se afihan pasitọ naa ati pasitọ kekere mii ninu ijọ ọhun, ti wọn n na awọn tọkunrin tobinrin to jẹ ọmọ ijọ wọn, to sun silẹ lori pẹpẹ ni idi.
Gẹgẹ bi ọrọ ti olori ijọ naa se sọ ninu fidio naa, o ni oun n fi bẹliti na wọn lati mọ bi wọn se gbona si, ti wọn si setan fun isẹ iransẹ to wa niwaju wọn.
Awọn ọmọ ijọ naa lo wọ asọ kootu oyinbo dudu ati buluu, ti wọn si doju bolẹ sori pẹpẹ nibi ti wọn sun si.
Ooni: A kìlọ̀ fún Sunday Igboho pé kó dákẹ́ àmọ́ kò gbọ́, èébú ló ń bú wa
Asiko ti awọn pasitọ yii n to ẹgba si ibadi awọn ọmọ ijọ to wa lori pẹpẹ naa, ni awọn ẹgbẹ akọrin ijọ naa n kọ awọn orin pẹlu ohun ilẹ lati se koriya fawọn ọmọ ijọ to n jẹgba naa.
Iyalẹnu lo wa jẹ pe bi awọn pasitọ mejeeji yii se n na awọn ọmọ ijọ naa to, wọn ko pariwo, janpata tabi mira jigi, eyi ti yoo se afihan pe iya ti wọn n jẹ ko ba wọn lara mu.
Awọn araalu faraya lori ayelujara tori bi Pasitọ se n ko bẹliti bo ọmọ ijọ lori pẹpẹ:
Wayi o, awọn araalu ti n fi apa janu lori fidio to jade sita naa, ninu eyi ti pasitọ ti n na awọn ọmọ ijọ lori pẹpẹ.
Ọpọ eeyan to n tara poro lori isẹlẹ naa lo n pariwo pe Ọlọrun ma kuku ku aibinu o.
Ogogo wá sí iléèwé wa, mo kéwì fún un ló sọ mi di èèyàn ńlá lórí ayélujára - Akinwumi Akewi
Koda awọn miran n beere pe ki ni ka ti se iwa ika tawọn Pasitọ naa n hu sawọn ọmọ ijọ rẹ yii si lasiko yii ta n pariwo tako iwa ika awọn ọlọpaa si araalu.
Awọn miran ni ati Pasitọ to n na eeyan, ati awọn ọmọ ijọ ti wọn n na ni wọn ko ni oye to, ko si yẹ ka huwa ika si ara wa nitori pe a fẹ sin Ọlọrun.
Gunmen Attack Church: Ọjọ́ Àìkú ní agbébọn ya wọ ṣọ́ọ́ṣì lásìkò ìsìn, ọ̀pọ̀ olùjọ́sìn di àwátì
Oríṣun àwòrán, Reuters
Se ni ibanujẹ tun dori awọn agba kodo ni ipinl Kaduna lọjọ Aiku, nigba tawọn agbebọn tun ya wọ ile ijọsin onitẹbọmi Baptist kan to wa ni ilu Kakau Daji.
Awọn onisẹ ibi yii lo gbẹmi olujọsin meji nigba ti wọn ji ọgọọrọ eeyan lọ.
Aarẹ fun ipade ajọ nla ijọ onitẹbọmi, Ẹni ọwọ Ishaya Jangado to fidi isẹlẹ yii mulẹ tun tọkasi pe oun ko tii le sọ iye eeyan tawọn ajijigbe ọhun ko lọ.
Gẹgẹ bo ti salaye, aarọ ọjọ Aiku ni isẹlẹ naa waye amọ ijọba ipinlẹ Kaduna ati ileesẹ ọlọpaa ko ti fesi lori rẹ.
Lero ti ẹni ọwọ Joseph Hayab ti ẹgbẹ agbarijọpọ awọn ọmọlẹyin Kristi CAN, isẹlẹ naa lo tun n fidi eto aabo to dori kodo ni Naijiria mulẹ.
O ni se ni wọn n pa awọn araalu bii adiẹ, to si jẹ pe atẹjade lati bawọn kẹdun nikan ni wọn jẹ ijọba, ọjọ si ti pẹ tawọn ikọ afẹjẹwẹ yii ti n soro fun awọn olujọsin.
Oríṣun àwòrán, NPF
Ileeṣẹ ọlọpaa ipinlẹ Ogun ti fi ọwọ ofin mu afurasi ọmọ onilẹ mẹta ti wọn yabo abule Jegede lagbegbe Igbesa ni ijọba ibilẹ Ado Odo pẹlu oriṣiiriṣii ohun ija oloro ti wọn fi ṣe awọn eeyan lọṣẹ.
Ọjọ Aje ọjọ kẹẹdọgbọn oṣu kẹwaa ni wọn mu Adewale Muyibi, Kamoru Ayodele ati Taofeek Ogundele.
Awọn agbofinro morile abule naa lẹyin ti awọn eeyan kan tawọn lolobo pe, awọn ọmọ onilẹ ọhun ti da ibọn bolẹ nibẹ.
Ọga agọ ọlọpaa lagbegbe Agbara, Saleh Dahiru, lo ṣaaju awọn ọlọpaa lọ si abule naa, nibi tawọn ọmọ onilẹ naa ti yinbọn fun eeyan mẹfa.
Awọn ọlọpaa lo doola eeyan mẹfa naa, Sunday Okorie, Shoneye Akeem, Lakan Oloyede, Jimoh Musibau Akande Oyedeji ati Hamzat Idiris ti wọn si tun gbe wọn lọ si ile iwosan.
Oyo PDP Crisis: Olopoeyan ní Makinde yá PDP láti dìbò ni, àwọn kò ní gbà kó ba ẹgbẹ jẹ
Lẹyin ọ rẹyin, mẹta lawọn ọlọpaa ri mu ninu awọn ọmọ onilẹ naa nigba tawọn to ku fẹsẹ fẹ.
Oriṣiriṣi ọta ibọn lawọn ọlọpaa ri gba lọwọ awọn ọdaran naa labule Jegede.
Ẹwẹ, kọmiṣọnaa ọlọpaa ipinlẹ Ogun, CP Lanre Bankole ti paṣẹ pe ki wọn ko awọn afurasi ọmọ onilẹ naa lọ si ẹka ileeṣẹ ọlọpaa to n ri si iwadii.
Bakan naa ni ọga ọlọpaa Ogun paṣẹ pe ki awọn ọlọpaa ṣe awari awọn to salọ ninu awọn ọdaran ọhun.
CP Bankole wa kilọ fawọn gbalẹ gbalẹ lati ki ọwọ ọmọ wọn bọ aṣọ nipinlẹ Ogun, bi bẹẹ kọọ, ilẹ yoo ga ju wọn lọ.
O ni oun ko le laju silẹ ki awọn kọlọnbiti ẹda kan maa da ilu ru nipinlẹ Ogun.
Timi Osukoya: Ọ̀pọ̀ olórin ẹ̀mí ló ń kọrin torí owó tàbí afẹ ayé
Sudan Coup: Mọ̀ si nípa ọ̀gágun Abdel Fattah al-Burhan tó darí ìdìtẹ̀gbàjọba ní Sudan
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ọgagun agba lorilẹede Sudan, Abdel Fattah al-Burhan ti ni awọn ologun gbajọba ki ogun abẹle ma ṣe waye ni Sudan.
Ọgagun al-Burhan to dari ifipa gbajọba naa ni oun yọ Olotu Ijọba, Abdalla Hamdok kuro ni ọọfisi rẹ lọ si ile fun anfaani ara rẹ ni, amọ o ti pada si ile bayii.
Awọn to fi ipa gbajọba naa gba agbegbe Khartoum, ti wọn si tun igbimọ ti awọn ologun gbe kalẹ lati pin agbara pẹlu wọn, ki ijọba tiwantiwa le pada si orilẹede naa.
Amọ ni bayii, ko ye ẹnikẹni bi ijọba tiwantiwa yoo ṣe gboro lorilẹede Sudan, lẹyin ifipagbajọba yii.
Ọgagun al-Burhan lo ti n ṣe adari igbimọ alakoso ologun ''Sovereign council'' ati adari ikọ ọmọogun ibẹ, ko to di pe o wa gba ijọba patapata ni Ọjọ Aje.
Timi Osukoya: Ọ̀pọ̀ olórin ẹ̀mí ló ń kọrin torí owó tàbí afẹ ayé
Ọgagun naa da igbimọ ijọba tiwantiwa ru, o fi panpẹ ọba mu Olotu Ijọba, Abdalla Hamdok ati awọn eekan ni ijọba ti awọn ologun ti gba lati pin ijọba pẹlu.
Al-Burhan kii ṣe ẹni ti awọn eniyan mọ ki iditẹ gbajọba to yọ Aarẹ Omar Hassan al-Bassar kuro ni ipo to waye ni ọdun 2019.
Nigba naa lọun, oun ni ẹni kẹta to dagba ju ni ikọ ologun lẹyin Ọga agba awọn ologun.
Lẹyin iditẹ gbajọba naa ni minisita fun eto aabo fi ipo silẹ to si darukọ al-Burhan gẹgẹ bi ẹni ti yoo di igbimọ ologun ti yoo gbe ijọba ologun kalẹ fun ijọba tiwantiwa mu.
Oríṣun àwòrán, AFP
Oṣu Kẹjọ, ọdun 2019 ni wọn fi si ipo adari ikọ ''Sovereign council'' lorilẹede Sudan.
Bakan naa lo jẹ adari fun ikọ ologun Sudan to ja ninu ogun orilẹede Yemen ni ọdun 2015.
Lẹyin ti wọn gbajọba lọwọ Bahir ni Burhan ṣiṣẹ pọ pẹlu ijọba ilẹ United Arab Emirate, Saudi Arabia ati Egypt.
Ni Oṣu Kẹta, ọdun yii lo gbalejo Aarẹ orilẹede Egypt, Abdel Fattah ai-Sisi ni Khartoum, lọna ati ṣiṣẹ pẹlu Sudan fun ibaṣepọ pẹlu Israel.
Ni Oṣu Kẹwaa, ọdun 2020 ni Burhan ati Abdalla Hamdok to yọ ni ipo ni Ọjọ Aje ṣe ipade pọ pẹlu Olotu Ijọba orilẹede Israel, Benjamin Netanyahu ati Aarẹ orilẹede Amerika tẹlẹri, Donald Trump ti wọn jọ jiroro lori ọna ati jọ ṣiṣẹ papọ.
Bakan naa ni minisita fun ọrọ ilẹ okeere ni ilẹ Amerika, Mike Pompeo dupẹ lọwọ rẹ nigba naa fun igbiyanju lati dọrẹ papọ pẹlu orilẹede Israel.
Ko tan sibẹ, Burhan jẹjẹ fun ileẹjọ to n gbẹjọ iwa ọdaran lagbaye, ICC pe oun yoo jọwọ al-Bashir fun wọn lati foju wina ofin, lori ẹsun ifiyajẹni ati iwa ọdaran ni agbagbe Darfur.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Amọ, eto idajọ fun awọn eniyan agbegbe Darfur lo fa gbọnmi si omi o to laaarin awọn araalu ati ikọ ọmọogun.
Oyo PDP Crisis: Olopoeyan ní Makinde yá PDP láti dìbò ni, àwọn kò ní gbà kó ba ẹgbẹ jẹ
Oniruuru laasigbo lo ti n ba ẹgbẹ oselu PDP nipinlẹ Oyo finra lati bi ọjọ melo kan, ti onigbo si ti da igbo si meji, ti ọrọ ti di konko jabele, kaluku lo n se tiẹ.
Idi ni pe awọn eeyan kan ti ta kete ninu ẹgbẹ naa, ti wọn si kọ ẹyin si gomina Seyi Makinde tii se ọmọ ẹgbẹ wọm ti ogiri ẹgbẹ PDP ni Oyo si ti lanu, ti ọpọ alaamu ti ri aaye wọ ibẹ.
Awọn igun ti ko ba gomina Makinde se papọ yii lo pe ara wọn ni igun PDP ti inu n bi, koda, wọn da se ipade abẹnu tiwọn lọtọ ni, ti wọn si mu ki igbimọ alasẹ PDP ni Oyo pin si igun meji.
Ọkan lara awọn to n dari igun PDP ti inu n bi naa ni Alhaji AbdulRasheed Adebisi, ti ọpọ eeyan mọ si Ọlọ́pọ̀èèyàn, ẹni to ba BBC News Yoruba nipa idi ti igun wọn se n fi apajanu.
Olopoeyan ni Seyi Makinde wa ya pepele ẹgbẹ PDP lo ni, awọn ko si jẹ ko ba jẹ mọ awọn to ni ẹgbẹ lọwọ.
O fikun pe ọkọ aloku ni gomina n ra lati fa ohu ẹta horo eeyan mọra, to si n polongo rẹ lori ayelujara.
O ni igbesẹ naa fi han pe iṣẹ ati osi pọ ninu PDP ni eyi se n waye, to si ni gomina naa ni anfaani lati ko gbogbo eeyan mọra ninu ẹgbẹ atawọn alatako gan pẹlu.
Amọ nigba to n sọrọ nipa awọn eeyan to da PDP Oyo si meji naa, Akọwe alukoro fun ẹgbẹ naa, Akeem Adetunji ni o yẹ ki awọn eeyan naa se suru ni.
O ni gbogbo ohun ti ko to, ni yoo pada sẹkun, o si yẹ ki n gba Makinde laaye ko maa pin ere ijọba alagbada fiẹ diẹ titi yoo fi kan wọn.
Oyo Jailbreak: Aregbesola ní òun kò kọ̀ ìrànwọ́ CCTV tí Makinde fẹ́ rì sí ọgbà ẹ̀wọ̀n Abolongo
Oríṣun àwòrán, Rauf Aregbesola
Minisita fun ọrọ abẹle Ọgbẹni Rauf Aregbesola ti salaye pe oun ko kọ iranwọ ti gomina ipinlẹ Oyo, Seyi Makinde fẹ se si ọgba ẹwọn Abolongo nilu Oyo.
Aregbesola ni wọn si oun gbọ lori ọrọ naa ni eyi ti wọn ni oun sọ nigba ti oun n kopa lori eto redio kan nilu Ibadan lati ori foonu.
Atẹjade kan ti akọwe feto iroyin rẹ, Sola Fasure fisita lo sisọ loju ọrọ yii pẹlu afikun pe awọn ọbayejẹ ẹda kan lo n gbe iroyin ẹlẹjẹ naa kiri nitori ifẹkufẹ ara wọn.
"Saaju ni mo ti kọkọ rọ awọn ijọba ipinlẹ lati kọ awọn ile fun awọn afurasi tile ẹjọ ko tii se idajọ wọn nitori ida aadọrin awọn eeyan to wa lọgba ẹwọn lo n reti idajọ lọwọ.
Bakan naa ni mo sọ pe ijọba apapọ yoo mọ riri iranwọ tawọn ijọba ipinlẹ ba se lati sugba aayan to n lọ lọwọ nidi minu agbega bawọn ohun eelo amayedẹrun lawọn ọgba ẹwọn wa.
Kiki Osinbajo: T;o bá yá owó lọ́wọ́ ẹnikẹ́ni, máa gbìyànjú láti da padà
Amọ o se ni laanu pe awọn ọbayejẹ kan yi ohun ti mo sọ po lati gbe mi kọlu awọn araalu."
Aregbesola wa rọ awọn ijọba ipinlẹ atawọn eeyan ti ọrọ ilẹyii gberu lati ri daju pe agbega ba ilana eto idajọ nilẹ yii atawọn ohun elo to wa lawọn ọgba ẹwọn.
Oríṣun àwòrán, Seyi Makinde/Facebook
Minisita fun ọrọ abẹle lorilẹede Naijiria, Ogbeni Rauf Aregbesola ti ni Gomina ipinlẹ Oyo, Seyi Makinde ko ni aṣẹ lati fi ẹrọ camera CCTV si ọgba ẹwọn Abolongo ni ipinlẹ Oyo.
Eyi ko ṣẹyin ọrọ ti Gomina Makinde sọ lasiko to ṣe abẹwo si ọgba ẹwọn Abolongo, ti awọn agbebọn ṣekọlu si nipinlẹ naa lọjọ Ẹti.
O kere tan ẹẹdẹgbẹta awọn to wa ni ẹwọn ni wọn sakuro lọgba ẹwọn naa lasiko ti iṣẹlẹ ọhun waye.
Makinde lasiko to ṣabẹwo si ọgba ẹwọn naa ni ijọba oun yoo gbe igbesẹ lati ri pe eto aabo ko mẹhẹ ni awọn ọgba ẹwọn nipinlẹ Oyo.
O ni ijọba yoo pese awọn ohun eelo igbalode fun eto aabo bii CCTV, ki wọn le ma a tọpasẹ iṣẹlẹ to n waye nibẹ.
Oyo PDP Crisis: Olopoeyan ní Makinde yá PDP láti dìbò ni, àwọn kò ní gbà kó ba ẹgbẹ jẹ
Amọ, lasiko to n fesi, olubadamọran lori ọrọ iroyin fun Aregbesola, Sola Fasure ni bi o tilẹ ṣe pe inu ire ni gomina Makinde fi sọ ọrọ naa, amọ ko laṣẹ tabi agbara lati ṣe iru nkan to jọ bẹẹ si awọn ọgba ẹwọn.
''Ohun ti Makinde le ṣe ni ki o gba awọn ni imọran nitori ileeṣẹ ijọba to n risi ọrọ abẹle, eleyii ti Aregbesola jẹ minisita rẹ, lo le e pa iru aṣẹ bẹẹ.''
''Bakan naa ni a ti n ṣiṣẹ lati mu idagbasoke ba awọn ọgba ẹwọn kaakiri orilẹede Naijiria, bẹrẹ lati ilu Abuja ati Kano.''
''O ṣe ni laanu pe iṣẹlẹ Abolongo waye ko to di pe atunṣe awọn ọgba ẹwọn de ipinlẹ Ọyọ.''
''Amọ iranwọ ti ijọba ipinlẹ le ṣe to wa ni ikawọ wọn ni lati ri pe awọn to wa ni ọgba ẹwọn ti wọn n duro de idajọ ri idajọ gba ni kiakia.''
''Sunkẹrẹ fakẹrẹ awọn adajọ lori awọn ẹjọ to wa ni ileẹjọ lo fa bi awọn ọgba ẹwọn yii ṣe kun fọfọ, ti ọpọlọpọ wọn si n reti idajọ.
O ni eyi lo fa afunpọ ni awọn ọgba ẹwọn yii, ti awọn agbebọn fi raye ṣekọlu si bẹ.''
''Ijọba apapọ ti bẹrẹ si ni kọ awọn ọgba ẹwọn to lee gba ẹgbẹrun mẹta eniyan lẹẹkan naa ni awọn ẹkun mẹfẹẹfa to wa lorilẹede Naijiria, ti eleyii to wa ni Abuja ati Kano pẹlu ileẹjọ wọn si ti wa ni ṣẹpẹ.''
Seyi Makinde: Ẹ̀yin tẹ́ fẹ́ fi ọ̀rọ̀ ẹ̀sin ba Oyo jẹ́, ẹ ṣọ́ra ṣe
''Ijọba ipinlẹ gbọdọ ran ijọba apapọ lọwọ lati ri pe awọn adajọ wọnyii n da ẹjọ lasiko lai si pe ki wọn ma a sun siwaju ni gbogbo igba, nitori agbara ti wọn ni ni ikawọ niyẹn kii ṣe ki wọn fi CCTV si ọgba ẹwọn.''
Amọ olubadamọran fun Aregbesola naa fikun un pe aba to dara ni gomina Makinde muwa, ti minista naa yoo si gbeyẹwo ni finifini.
Sunday Igboho's Priest: Ìyá Babaláwo Igboho ní agbófinró gbé Arifanlajogun láì mọ ibi tó wà láti oṣù mẹ́ta
Oríṣun àwòrán, Dada Arifanlajogun
O ti to oṣu mẹta bayii ti awọn eeyan kan ti wọn funra si bii ọtẹlẹmuyẹ DSS wọ ile Dada Fasoto Arifanlajogun, ti o jẹ oniṣegun ati Babaláwo Sunday Igboho n'ipinlẹ Ekiti, ti ẹnikẹni ko si mọ ibi to wa.
Iya Dada, Olomitutu Fasoto, ti o jẹ yeye Ọṣun lo sisọ loju ọrọ yii fun akọroyin BBC Yoruba nilu Ikere Ekiti
.Yeye Olomitutu ni ẹni ọdun mejidinlọgbọn ni ọmọ oun ti awọn agbofinro naa wa gbe lọ lai fi ẹsun kankan kan-an.
O salaye pe gbogbo igbiyanju awọn lati se awari Abọrẹ naa lo ja si pabo, ti gbogbo ileesẹ agbofinro ti awọn lọ si n sẹ pe awọn ko mọ nipa irin ọmọ oun.
"O wi pe ""ohun gbogbo lo tọka si pe ajọ DSS lo gbe ọmọ mi lọ nitori awọn ajọ ẹṣọ alaabo yoku ni ko si ọmọ oun ni ọdọ awọn, ti awọn ko si mọ ohunkohun nipa rẹ."
Ooni: A kìlọ̀ fún Sunday Igboho pé kó dákẹ́ àmọ́ kò gbọ́, èébú ló ń bú wa
Olomitutu ni ọmọ oun lo jẹ oniwatutu, to si n ṣe iṣẹ iṣegun rẹ pẹlu ibẹru Ọlọrun amọ o jẹ ohun iyalẹnu pe wọn le wa gbe tori pe o jẹ babalawo fun Sunday Igboho.
O ni oun ti bọ èṣù, ti oun si tun gbe gbogbo igbesẹ to yẹ ki oun gbe gẹgẹ bi ẹlẹsin abalaye amọ to ja si pabo.
O wa ke sawọn ọmọ Naijiria lati gba ọmọ oun silẹ ko le pada sọdọ aya ati ọmọ rẹ, ọmọ ọdun marun.
Nigba ti oun naa n ṣàlàyé bi iṣẹlẹ naa se waye, Aderonke Apalara to jẹ ana Dada sọ pe awọn ẹṣọ alaabo ti wọn ko wọ aṣọ ara ni wọn wa mu Arifanlajogun.
Apalara ni awọn ẹsọ alaabo naa ti gbogbo wọn jẹ mẹwa lo di ihamọra ogun, ti wọn si wọle wọn pẹlu ọkọ hilux funfun meji.
O fikun pe nnkan bii agogo marun ọjọ kẹrindinlogun oṣu keje ọdun 2021 ni wọn ti wa gbe Arifanlajogun naa.
"Aderonke ni ""nigba ti awọn ẹṣọ naa ri pe awa ẹbi ko jẹ ki wọn gbe Arifanlajogun lọ, ni wọn lo ọgbọn alumọkọrọyi pe agọ ọlọpa ni Okesha ni wọn n gbe lọ, ki a si wa pade rẹ nibẹ."
"Amọ nigba ti a de Okesha, ni a to mọ pe irọ funfun balawu ni wọn pa pe ọlọpa lawọn ati pe gbogbo igbiyanju mọlẹbi lati mọ ibi to wa lati oṣu mẹta sẹyin lo ja si asan."""
Ki ni ileesẹ ọlọpaa ati DSS ni Ekiti sọ nipa isẹlẹ naa:
Nigba ti ikọ iroyin BBC Yoruba kan si Alukoro ọlọpa n'ipinlẹ Ekiti, Sunday Abutu, o ni ileesẹ ọlọpaa ko mọ ohunkohun nipa isẹlẹ naa.
O wa rọ awọn mọlẹbi Arifanlajogun lati lọ fi ẹjọ sun lọna to tọ ni agọ ọlọpa to ba sunmọ wọn ju lọ.
Bakan naa, nigba ti a kan si ileesẹ agbofinro DSS to wa nipinlẹ Ekiti, wọn sọ fun BBC Yoruba pe awọn ko le sọ ohunkohun nipa isẹlẹ naa, amọ ka kan si olu ileesẹ awọn to wa nilu Abuja.
Bi ọrọ naa ba si se lọ, a maa mu wa fun yin.
Oyo PDP Crisis: Olopoeyan ní Makinde yá PDP láti dìbò ni, àwọn kò ní gbà kó ba ẹgbẹ jẹ
Babe on Whatsapp Case: Sikiru Jamiu dèrò iléẹjọ́ torí ó pe ìyàwó oníyàwó ní ‘Babe’ ní Whatsapp
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Yoruba ni iwọ oju kokoro, nibo lo ba olowo rẹ de?, to si dahun pe oun yoo sin de pẹrẹ-pẹrẹ ilẹ.
Bo se ri gan ree pẹlu ọkunrin kan, to ri oju tan, to wa n wa airoju kiri lati ipasẹ sina sise.
Ọkunrin ọhun ti wọn pe orukọ rẹ ni Sikiru Jamiu lo ti wọ gau lori bo se kan si iyawo ile kan, to si n pe ni orukọ to jẹ mọ ti ololufẹ.
"Jamiu tii se olugbe ilu Ijebu Ode, ni ileesẹ ọlọpaa nipinlẹ Ogun ti wa fẹsun kan pe o n pe iyawo ile naa, Opeyemi Adegbesan ni ""babe"" eyi to kọ soju opo ikansiraẹni Whatsapp obinrin naa."
Nibayii ọkunrin naa ti n kawọ pọnyin rojọ niwaju adajọ lori idi to fi san iru asọ yii se oro pẹlu iyawo oniyawo.
Oyo PDP Crisis: Olopoeyan ní Makinde yá PDP láti dìbò ni, àwọn kò ní gbà kó ba ẹgbẹ jẹ
Gẹgẹ bi iwe ipẹjọ tileesẹ ọlọpaa pe, eyi ti officialsamolatunji1 fi si oju opo Instagram rẹ, iwe naa ni wọn kọ ni kootu majisireti ti Ijebu Ode, ti wọn kọ ni ogunjọ osu Kẹwa ọdun 2021 ti sọ.
Jamiu sẹ ẹsẹ naa ni aago mẹjọ kọja isẹju meji ni ọjọ Kọkandinlogun osu Kẹsan Ẹsun naa si ni wọn lo seese ko da omi alaafia to wa ninu igbeyawo obinrin naa ati ọkọ rẹ, Akintunde Adegbesan ru.
O si seese ki Jamiu fi asọ penpe roko ọba fun odidi osu kan gẹgẹ bi iwe ofin to n dena iwa ọdaran nipinlẹ Ogun ti laa kalẹ.
Oríṣun àwòrán, officialsamolatunji1/Instagram
"Iwe ipẹjọ naa sọ bayii pe ""iwọ Sikiru Oluwaseun Jamiu ni opopona Fidipote nilu Ijebu Ode hu iwa to le da igbeyawo ru laarin Akintunde Adegbesan ati aya rẹ, Opeyemi Adegbesan."
Ohun to kọ soju opo Whatsapp obinrin naa, tii se 'Good Morning  Babe' pẹlu nọmba ipe 08059491562 ati 08138868837 si lo ni ijiya labẹ ofin.
Isẹlẹ yii lo ti n gbona lori ayelujara, ti oniruuru eeyan si n sọ ero wọn nipa isẹlẹ naa.
2023 Election: Mimiko padà sí PDP lẹ́yìn ìpàdé ìdákọ́ńkọ́ pẹ̀lú Seyi Makinde, Nyeson Wike l'Ondo
Oríṣun àwòrán, daily post
Gomina ipinlẹ Ondo nigba kan, Olusegun Mimiko ti darapọ mọ ẹgbẹ oṣelu Peoples Democratic Party, PDP.
Lasiko ti awọn gomina kan lati inu ẹgbẹ PDD, ṣe abẹwo si ile oloṣelu naa to wa ni ilu Ondo, nipinlẹ Ondo, ni Ọjọbọ, ni eyi waye.
Awọn gomina naa ni Aminu Tambuwal lati Sokoto, Okezie Ikpeazu lati Abia, Nyesom Wike lati Rivers, ati Seyi Makinde lati Oyo.
Koko abẹwo awọn gomina naa si ni lati bẹ Mimiko pe ko darapọ mọ ẹgbẹ wọn.
Ṣaaju asiko yii, ọmọ ẹgbẹ oṣelu Zenith Labour Party, ZLP, ni Mimiko jẹ.
Yatọ si pe Segun Mimiko darapọ mọ PDP bayii, awọn alẹnu-lọrọ ninu ẹgbẹ ZLP lati ijọba ibilẹ mejidinlogun to wa nipinll Ondo lo tun darapọ mọ PDP pẹlu rẹ.
Kiki Osinbajo: T;o bá yá owó lọ́wọ́ ẹnikẹ́ni, máa gbìyànjú láti da padà
"Awọn olori ẹgbẹ ZLP naa sọ pe awọn gbà lati darapọ mọ PDP ""nitori pe igbesẹ naa yoo gba Naijiria kuro lọwọ ijọba APC, ti yoo si tun fi ẹsẹ rẹ si oju ọna alaafia ati ilọsiwaju""."
Igba kẹta re e ti Olusegun Mimiko yoo fi ẹgbẹ oṣelu kan silẹ lati darapọ mọ PDP.
Ọmọ ẹgbẹ oṣelu Alliance for Democracy, AD ni lọdun 1999, to si ṣe kọmisanna eto ilera ipinlẹ Ondo labẹ ijọba Adefarati.
O darapọ mọ ẹgbẹ PDP lẹyin naa, to si ṣe minisita labẹ ijọba Olusegun Obasanjo.
O tun fi PDP silẹ lati darapọ mọ Labour Part, nibi to ti dupo gomina to si wọle, ṣugbọn ko to o pari saa rẹ lo tun ti pada si PDP.
Lẹyin naa lo tun lọ si ZLP nibi to ti dupo sẹnetọ ni 2019, ṣugbọn o ni ijakulẹ.
Oríṣun àwòrán, Sam Olusegun
Gomina ipinlẹ Ondo tẹlẹri, Olusegun Mimiko ti gbalejo gomina mẹrin latinu ẹgbẹ oselu PDP ni ile rẹ ni ipinlẹ Ondo.
Eyi ko ṣẹyin iroyin pe Mimiko ti ṣetan lati darapọ mọ ẹgbẹ oṣelu PDP lorilẹede Naijiria.
Awọn Gomina to wa ṣepade pẹlu rẹ ni gomina ipinlẹ Oyo, Seyi Makinde, gomina ipinlẹ Rivers, Nyeson Wike, Gomina ipinlẹ Sokoto, Aminu Tambuwal ati gomina ipinlẹ Abia, Okezie Ikpeazu.
Wẹrẹ ti awọn gomina naa de si ile rẹ ni ilu Ondo, ni wọn wọ iyẹwu lọ lati lọ ṣe ipade.
Saa keji ijọba Mimiko nigba to wa ni ipo gomina, lo fi ẹgbẹ oselu Labour Party silẹ lati lọ darapọ mọ ẹgbẹ oṣelu PDP.
Oyo PDP Crisis: Olopoeyan ní Makinde yá PDP láti dìbò ni, àwọn kò ní gbà kó ba ẹgbẹ jẹ
Amọ o pada si ẹgbẹ oṣelu Zenith Labour Party- ZLP ki idibo sipo gbogboogbo to waye, nibi to ti dije dupo sẹnatọ ni ẹkun Guusu Ondo, ti Sẹnatọ Ayo Akinyelure ti ẹgbẹ oṣelu PDP si fi ẹyin rẹ janlẹ.
Bakan naa lo ṣe atilẹyin fun igbakeji gomina nipinlẹ Ondo tẹlẹ, Agboola Ajayi lasiko to dije gomina lẹgbẹ oselu ZLP nipinlẹ Ondo to si fi idi rẹmi.
Iroyin ni lati igba ti wọn ti kede pe o ṣeeṣe ko pada si ẹgbẹ oṣelu PDP ni awọn kan ninu ẹgbẹ naa ti n fi apa janu.
Laipẹ yii ni Aarẹ ile Igbimọ Aṣofin tẹlẹri, to jẹ eekan ninu ẹgbẹ oṣelu PDP, Bukola Saraki fi lede pe gomina tẹlẹri kan yoo darapọ mọ PDP laipẹ, ti awọn kan si sọ wi pe o ṣeeṣe ko jẹ Mimiko.
Ooni: A kìlọ̀ fún Sunday Igboho pé kó dákẹ́ àmọ́ kò gbọ́, èébú ló ń bú wa
Oyo jail break: Ọ̀pọ̀ olùgbé Abolongo fara pa torí ìkọlù ẹlẹ́wọ̀n, wọ́n ń sá kúrò nílé
Yoruba bọ, wọn ni ki oju ma ri ibi, gbogbo ara ni oogun rẹ.
Eyi lo difa fawọn olugbe agbegbe ọgba ẹwọn Abolongo niluu Oyo kan ti wọn ti fi adugbo naa silẹ bayii lẹyin ti ado oloro mii tun bu gbamu nibẹ lọjọ Iṣẹgun.
Ọjọ Ẹti ọsẹ to lọ lawọn agbebọn yabo ọgba ẹwọn naa nibi tawọn ẹlẹwọn kan ti salọ lẹyin ikọlu to waye pẹlu oriṣiiriṣii ohun ija oloro.
Bo tilẹ jẹ pe ileeṣẹ ọlọpaa ṣalaye fawọn olugbe adugbo pe awọn lo ṣee ti ado oloro tawọn agbebọn fi silẹ ninu ọgba ẹwọn bu gbamu ko o le ṣe akoba fawọn eeyan, awọn ara adugbo naa ni inu ibẹru-bojo lawọn wa.
BBC Yoruba ṣe abẹwo si agbegbe Abolongo lati mọ bi awọn olugbe agbegbe naa ṣe wa lẹyin ibugbami ado oloro ẹlẹẹkeji nibẹ.
Oyo PDP Crisis: Olopoeyan ní Makinde yá PDP láti dìbò ni, àwọn kò ní gbà kó ba ẹgbẹ jẹ
Arakunrin Oladokun Quadri, to jẹ alaga awọn olugbe agbegbe Abolongo ati arabinrin Ola adua ti oun naa n gbe adugbo yii ṣalaye fun BBC Yoruba pe ọpọ eeyan lo ti fi adugbo naa silẹ lẹyin ti ado oloro tun bu gbamu fun igba keji.
Ọgbẹni Quadri ni ibẹru-bojo ni ọpọ fi fi ile wọn silẹ lẹyin ti ado oloro mii tun bu gbamu lọjọ Iṣẹgun tori iyalẹnu lo jẹ fun wọn.
Quadri ni ''ọpọlọpọ ayalegbe ni ko pada sile lẹyin ado oloro ẹlẹẹkeji to bu gbamu lọgba ẹwọn Abolongo.
A rawọ ẹbẹ si ijọba lati gba wa tori ẹmi wa ṣe koko.
Iwadi ti a ṣe fihan pe ado oloro ti awon agbebọn ri mọlẹ nigba ti wọn kọlu ọgba ẹwọn Abolongo lọjọ Ẹti to lọ lawọn ọlọpaa yin ki o maa ba ṣe akoba fawọn eeyan.
"Ṣugbọn ẹru si wa lara wa nitori bi ibugbamu alakọkọ ti ṣẹlẹ tẹlẹ."""
Olugbe adugbo Abolongo mii, arabinrin Iya Adua ni ọkan awọn ko balẹ, tori awọn eeyan kan ba iṣẹlẹ ibugbamu akọkọ lọ.
Iya Adua ni ''mo pade ọga Amotekun ti ibọn ba ni alẹ ọjọ naa ti o si sọ fun wa pe awọn agbebọn le oun wọ inu igbo.
Eyi gan an lo jẹ ki ọpọ eeyan salọ lẹyin ibugbamu ẹlẹẹkeji ti ti ọjọ Iṣẹgun tori ọkan wa ko balẹ.
Timi Osukoya: Ọ̀pọ̀ olórin ẹ̀mí ló ń kọrin torí owó tàbí afẹ ayé
Eeyan meji ni awa ọdẹ ibilẹ padanu lasiko ta n sa ẹlẹwọn kiri igboro Oyo:
Ọkan lara awọn ọlọdẹ ilu Oyo to ba BBC Yoruba sọrọ ṣalaye pe o ṣe pataki ki ijọba ro awọn ẹṣọ eleto abo lagbara nitori iru ikọlu bayii.
O ni ọpọ awọn ẹlẹwọn ni awọn ọlọdẹ ibilẹ n ṣà kaakiri nilu Oyo, ti wọn si pa meji lara awọ, ti wọn si ba isẹlẹ naa lọ.
"A bẹ ijọba torí ogun naa le amọ a dupẹ pe a ja ajaṣẹgun bi o tilẹ jẹ pe meji ninu awa ọdẹ ibilẹ ba isẹlẹ naa lọ.
Awa ko mọ ohun to fa ikọlu naa amọ o jẹ eyi to taba ara ile ati ara oko, a si ti mu ọpọ awọn ẹlẹwọn yii pada si ọgba ẹwọn Abolongo.
Ogboju ọdẹ naa sọ pe oogun ko le ko ilu Oyo, amọ awa naa yoo fi aayan kun aayan wa lati daabo bo ilu wa sugbọn ijọba ni lati fun awa ẹṣọ eleto abo ni irinṣẹ ijagun lati koju iwa ọdaran."
Customs vs Smugglers: Aṣọ́bodè dèrò ọ̀rùn lábúlé Fagbohun lẹ́yìn ìkọlù pẹ̀lú àwọn afurasí onífàyàwọ́ l'Ogun
Oríṣun àwòrán, NCS
Oba oke ko ni jẹ ki a lọ si ajo alọ de o, agba adura ni.
Amọ ọrọ ko ri bẹ fun ẹṣọ aṣọbode kan to jẹ Ọlọrun nipe lẹyin ikọlu pẹlu awọn afurasi onifayawọ labule Fagbohun ni ijọba ibilẹ Yewa nipinlẹ Ogun.
Koda ohun ti a gbọ ni pe aṣọbode miran tun di awati lẹyin iṣẹlẹ ọhun.
Ọjọ Iṣẹgun ọjọ kẹrindinlọgbọn oṣu kẹwaa ọdun 2021 yii ni iṣẹlẹ naa ṣẹlẹ ni abule Fagbohun nibi tawọn aṣọbode ti lọ ṣiṣẹ.
Iroyin ti a gbọ fidi rẹ mulẹ pe kete ti awọn afurasi onifayawọ yii foju gan ni ọkọ awọn ẹṣọ aṣọbode ni wọn da bajinantu bolẹ, ti ẹṣọ aṣọbode si di awati lẹsẹ kẹsẹ.
Ọjọru ni wọn ri oku ọkan lara awọn ẹṣọ meji to dawati ninu odo kan lẹba ilu Ajegun Iyaloosa eleyii ti ko si si ibọn rẹ lọwọ rẹ mọ.
Senato francis Fadahunsi: Ká ni wọ́n fún Buhari ladún mẹ́wàá sẹ́ypin ní, bóyá kò bá rí i ṣ
Agbẹnusọ ẹṣọ aṣọbode, Theophilus Duniya to fidi iṣẹlẹ ọhun mulẹ ṣalaye pe ọwọ ti ba awọn afurasi kan lori iṣẹlẹ naa.
Duniya sọ pe jẹjẹ lawọn ẹṣọ aṣọbode n ṣiṣẹ wọn kawọn onifayawọ yii to da rogbodiyan silẹ nibi ti ẹnikan ti dero ọrun ti ẹlomiran si di awati.
Agbẹnusọ ẹṣọ aṣọbode rọ awọn eeyan pe ki wọn ye doju ija kọ awọn ẹṣọ aṣọbode mọ.
''Iṣẹ ojọ wa ni a n ṣe, orilẹede Naijiria lo ran wa niṣẹ kii ṣe awa ni a ran ara wa.
Ofin ti ijọba apapọ gbe kalẹ ni awa n ṣe imuṣẹ rẹ, a ko ba ẹnikan ja.
Ẹ jọwọ ti ẹ ko ba ni iranwọ ti ẹ le ṣe fawọn eṣọ aṣobode, ẹ maa doju ija kọ wọn.
Awa naa ni ẹbi, bakan naa ni a ni ara ti yoo beere wa, lati ilu kan ni Naijiria ni awa naa ti sẹ wa.
Nitori naa, awọn naa lẹtọọ lati gbaye gbadun lorilẹede Naijiria lai si ẹnikan ti yoo ge ẹmi wa kuru,''agbẹnusọ ẹṣọ aṣọbode ṣalaye.
Ẹwẹ, iroyin fidi rẹ mulẹ pe awọn eeyan abule Fagbohun fi ilu naa silẹ lẹyin ti iṣẹlẹ yii waye tan nibẹ.
Oyo PDP Crisis: Olopoeyan ní Makinde yá PDP láti dìbò ni, àwọn kò ní gbà kó ba ẹgbẹ jẹ
Amarachi Nwachukwu: Ibi padà di ire fún olómi ‘Pure Water’ tó dákú, ó bá àánú ńlá pàdé
Oríṣun àwòrán, Facebook/Obiora Okonkwo
Yoruba ni ori lo n gbe ọla ko ni? Ki Oba oke tete gbe ti wa ko wa.
Bẹẹ lọrọ ri fun arabinrin akuṣẹẹ kan, Amarachi Nwachukwu, ti o n kiri omi inu ọra ti ọpọ mọ si ''pure water'' niluu Okpoko nipinlẹ Anambra.
Ni ọjọ ti Eleduwa yoo sọ ọrọ Amarachi di ayọ lo ṣubu yakata nibi to ti n kiri ''pure water'' toun ti omi lori ati ọmọ lẹyin rẹ.
Aṣe otitọ ni pe atori ọkan ṣekan ni Eleduwa, lasiko ti obinrin yii ṣubu gan an ni oludige ipo gomina ẹgbẹ oṣelu Zenith Labour Party, ZLP nipinlẹ Anambra, Dokita Obiora Okonkwo, n ṣe ipolongo ni Okpoko.
Ninu ẹrẹfọ ni Amarachi ṣubu si, nibẹ naa ni Dokita Okonkwo ti pinnu lati foju ara rẹ ri ẹni to ṣubu pẹlu omi lori rẹ.
Kiki Osinbajo: T;o bá yá owó lọ́wọ́ ẹnikẹ́ni, máa gbìyànjú láti da padà
Amarachi ṣalaye fun oludije fun ipo goimna ẹgbẹ ZLP pe ebi lo jẹ ki oun ṣubu tori oun ko ti jẹun fun ọjọ meji.
''Gaari ni mo mu sun ni bi ọjọ meji sẹyin, o ti rẹ mi, n ko si ni okun lara mọ.
N ko ni ọkọ, igba naira ti ẹnikan bun mi ni mo fi ra ''pure water'' ti mo n kiri ki n le maa ri nkan jẹ,'' Amarachi ṣalaye.
Amọ ayọ ni gbogbo rẹ ja si fun Amarachi lẹyin ti Dokita OKonkwo ra ọunjẹ fun un ti o si tun ṣe iranwọ ẹgbẹrun lọna igba naira fun.
Fada ijọ St. Charles Lwanga ni Dokita Okonwo fun ni N200,000 naa pe ko fun obinrin yii lati fi bẹrẹ owo to ba wuu u.
Oloṣelu Okonkwo kọ lati fun Amarachi gan-an gan-an lowo naa lati le daabo bo o lọwọ awọn janduku to le fẹ gba owo ọhun lọwọ rẹ.
Oríṣun àwòrán, Facebook/Obiora Okonkwo
Amọ o sọ fun pe ki o lọ gba owo rẹ nile ijọsin lọwọ fada.
Ṣe ẹ mọ pe agba tan laa gba ọlẹ, bi a ba daṣọ fun un, a paa laro.
Oludije ipo gomina fẹgbẹ ZLP tun ṣeleri lati gbe Amarachi lọ si ile iwosan fun ayẹwo ilera rẹ.
Ilé ẹjọ́ da ẹjọ́ tí Uche Secondus pè láti dá ìpàdé gbogbogbò ẹgbẹ́ PDP dúró nú
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ile ẹjọ kotẹmilọrun kan niluu Port Harcour ti dajọ pe ipade gbogbogbo ẹgbẹ oṣelu PDP gbọdọ tẹsiwaju lọjọ Satide gẹgẹ bi wọn ṣe gbero rẹ tẹlẹ.
Adajọ G.O. Kolawole to dari igbimọ ile ẹjọ naa da ẹjọ ti alaga ẹgbẹ oṣelu PDP tẹlẹ, Uche Secondu, pe lati wọgi le ipade naa nu.
Ṣugbọn ile ẹjọ ọhun sọ pe ẹjọ keji ti Secondus pe lori bi wọn ṣe yọ ọ kuro nipo alaga ẹgbẹ naa yoo tẹsiwaju.
Pẹlu idajọ yii, awọn aṣoju ẹgbẹ PDP to ti korajọ si gbagede Eagles Square yoo tẹsiwaju ninu ipade ti wọn fẹ ṣe.
Ipade naa yoo waye lọjọ Satide, ọgbọn ọjọ, ati ọjọ Aiku, ọjọ kọkanlelọgbọn, oṣu Kẹwaa, ọdun 2021 yii.
Kiki Osinbajo: T;o bá yá owó lọ́wọ́ ẹnikẹ́ni, máa gbìyànjú láti da padà
Ko din ni ẹgbẹrun mẹta abọ awọn aṣoju ẹgbẹ oṣelu PDP ti yoo peju sibi ipade ọhun, nibi ti wọn yoo ti yan awọn adari tuntun fun ẹgbẹ naa.
Ọdun 2017 ni Secondus gori alefa gẹgẹ bii alaga ẹgbẹ oṣelu PDP lẹyin to ti kọkọ wa lori oye naa gẹgẹ bii alaga fidihẹ laarin ọdun 2015 si 2016.
Ki lo ti ṣẹlẹ sẹyin?
Oríṣun àwòrán, Screenshot
Ile ẹjọ kotẹmilọrun kan niluu Port Harcourt ti  sunidajọ rẹ siwaju lori igbẹjọ ti alaga gbogbo ẹgbẹ oṣelu PDP tẹlẹ, Uche Secondus pe tako bi ẹgbẹ naa ṣe ni ko lọ rọkun nile.
Uche Secondus tun n rọ ile ẹjọ naa lati wọgile ipade gbogbogbo ti ẹgbẹ naa mura lati ṣe lọgbọn ọjọ ati ọjọ kọkanlelgbọn oṣu yii tẹsiwaju.
Ṣaaju ni PDP ti kọkọ mu ọgbọn ọjọ ati ọjọ kọkanlelọgbọn oṣu yii fun ipade ti wọn yoo ti yan awọn alaṣẹ tuntun fun ẹgbẹ oṣelu naa lẹyin rogbodiyan to waye ninu ẹgbẹ ọhun ṣaaju, nibi ti wọn ti fi ọwọ osi juwe ile fun igun ẹgbẹ naa ti Secondus n dari.
Ṣugbọn igbesẹ naa ko dun mọ Secondus ninu, eyii to mu ko pe ẹjọ lori bi wọn yọ nipo alaga, ati pe ki ile ẹjọ da ipade naa ti yoo waye duro.
Ṣugbọn ile ẹjọ ti wa sọ pe ẹjọ to pe ko lẹsẹ nilẹ.
Ni bayii, ipade ẹgbẹ oṣelu naa yoo waye lọjọ ti wọn ti da ṣaaju.
Ọdun 2017 ni Secondus gori alefa gẹgẹ bii alaga ẹgbẹ oṣelu PDP lẹyin to ti kọkọ wa lori oye naa gẹgẹ bii alaga fidihẹ lati ọdun 2015 si 2016.
Oyo PDP Crisis: Olopoeyan ní Makinde yá PDP láti dìbò ni, àwọn kò ní gbà kó ba ẹgbẹ jẹ
Facebook yí orúkọ padà sí Meta
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ileeṣẹ opo ikansiraẹni lori ayelujara, Facebook ti kede orukọ tuntun ti ileeṣẹ naa yoo maa jẹ bayii.
Orukọ tuntun naa ni Meta.
Atunṣe  yii lo n waye lasiko ti ileeṣẹ naa n koju oniruru atako lati ọdọ awọn aṣofin orilẹ-ede Amẹrika.
Ninu ipade ita gbangba kan lori ayelujara, oludasilẹ ileeṣẹ ọhun, Mark Zuckerberg sọ pe ileeṣẹ naa yoo tubọ tẹpẹlẹ mọ ohun ti wọn ṣe tẹlẹ atawọn anfani ti awọn eeyan n jẹ lara ileeṣẹ naa kaakiri agbaye.
"Zuckerberg ni ""Lọwọ yii, o fẹe da bi pe ohun kan ṣoṣo ni awọn eeyan mọ ileeṣẹ wa fun, eyii ti ko ṣafihan awọn oniruru nnkan mii ti an ṣe lọwọ yii, tabi ti a oo ṣe lọjọ iwaju."""
Faceboo ni atunto ti awọn n ṣe lọwọ yoo ko gbogbo aapu awọn papọ labẹ orukọ kan ṣoṣo, eyii ti yoo mu ayipada nla ba ileeṣẹ naa.
Ileeṣẹ ọhun tun ṣafihan ami tuntun ti awọn eeyan yoo maa fi da ileeṣẹ naa mọ ni olu ileeṣẹ naa to wa ni Menlo Park, ni California, eyii ti yoo rọpo ami ti awọn eeyan mọ si tẹlẹ to ni awọ buluu.
Oyo PDP Crisis: Olopoeyan ní Makinde yá PDP láti dìbò ni, àwọn kò ní gbà kó ba ẹgbẹ jẹ
Zuckerberg sọ pe orukọ tuntun naa tumọ si pe ẹnikẹni to ba fẹ maa lo eyikeyi ninu awọn ohun ti ileeṣẹ naa n ṣe yoo ni lati kọkọ lo oju opo Facebook.
Nnkan bii ọsẹ melo kan sẹyin ni Mark Zuckerberg kọkọ kede pe awọn yoo yi orukọ ileeṣẹ naa pada.
Inu oṣu Keji, ọdun 2004 ni Mark Zuckerberg, Eduardo Saverin, Andrew McCollum, Dustin Moskovitz, ati Chris Hughes da Facebook silẹ nigba ti wọn jọjọ n gbe yara kan gẹgẹ bii akọkọọ ni fasiti Harvard, ni Massachusetss, nilẹ Amẹrika.
Timi Osukoya: Ọ̀pọ̀ olórin ẹ̀mí ló ń kọrin torí owó tàbí afẹ ayé
Kiki Osinbajo: Tó bá yá owó lọ́wọ́ ẹnikẹ́ni, máa gbìyànjú láti da padà
Kiki Osinbajo, tii se ọmọ igbakeji aarẹ Yemi Osinbajo ti salaye fun BBC Yoruba nipa awọn ọna ti eeyan fi le lo ori ayelujara lati mu ki okoowo gbooro si.
Bakan naa lo sọrọ lori awọn ipenija tawọn ọdọ Naijiria n koju ninu isẹ ati okoowo wọn, to si fi awọn iriri to ti la kọja bii olokoowo se apẹrẹ.
Ko tan sibẹ, Kiki tun sọrọ nipa ọna to gba bẹrẹ okoowo ati ipenija to n koju awọn obinrin aye ode oni.
Soyinka: Nàíjíríà sì ń dojúrú lọ, a sì ń wòran
Oríṣun àwòrán, Wole Soyinka
Agba Onkọwe nni, Ọjọgbọn Wole Soyinka ti tẹnu bọ ọrọ lori ohun toju rẹ ri lori ọrọ iwe kaadi moyege Covid-19 lasiko to n dari irinajo bọ.
Irinajo rẹ yii lati orileede France pada si Naijiria ja si pabo diẹ tan, nigba tawọn oṣiṣẹ ileesẹ ofurufu to fẹ wọ yari pe ko ni wọ baalu lai si iwe aṣẹ lati rinrin ajo lọ si Naijiria.
Nibi apero kan to waye nilu Eko lori akori Covid, Tekinọlọji ati riran eeyan lọ si ẹyin odi, lo ti jiroro pẹlu awọn akọroyin.
O ni lootọ ni wọn ko ran oun lọ si ẹyin odi amọ inira to ba oun lasiko wakati mejidinlaadọta ti oun fi n sa soke sa silẹ, fẹẹ jọ bẹẹ.
Gbogbo awọn arinrinajo to ba n pada wa si Naijiria ni wọn gbọdọ fi iroyin nipa rẹ soju opo kan ti ijọba Naijiria ṣe idasilẹ rẹ.
Kiki Osinbajo: T;o bá yá owó lọ́wọ́ ẹnikẹ́ni, máa gbìyànjú láti da padà
Lara ohun ti ẹni naa yoo kọ sibẹ ni pasipọọti ati nọmba tikẹti rẹ.
Lẹyin to ba fi awọn ilana yii ṣọwọ, ni wọn yoo fun ni ami moyege nipa ohun taa n pe ni ''barcode'' eleyi to fi han pe o lanfaani lati tẹsiwaju pẹlu irinajo rẹ.
Onkọwe naa sọ nipa iriri rẹ, to si ni iṣẹlẹ airotẹlẹ ko le ṣe ko ma waye tori naa, idiwọ yi kii ṣe nkan ti eeyan le ri nkan ṣe si.
Amọ o ni ''bi wọn ba tako ọmọ onilu lati wọ ilu abinibi rẹ latari aṣiṣe awọn ẹlomiran, wahala wa ni yẹn''
Soyinka ni gbogbo abẹrẹ Covid-19 to yẹ koun gba loun gba ni gbedeke iye wakati ti ijọba la kalẹ 'sugbọn o jọ pe o ni abẹrẹ kan ti wọn pe ni PCR ti oun ko mọ nipa rẹ ''
O ni wahala aisi orukọ oun ninu oju opo ijọba yi mu fakinfa wa fọpọ wakati ti awọn oṣiṣẹ ileeṣẹ ọkọ ofurufu naa si n lọ ti wọn n bọ lati le yanju ọrọ yi.
Ninu alaye rẹ, o ni o le debi pe oun beere boya baalu miran wa to n lọ si orileede mi ni Afrika ti wọn ko nilo lati ṣe iru ayẹwo yi.
Wọn fesi pada pe ọkan wa to n lọ si Lome ṣugbọn ki Soyinka to darapọ mọ baalu naa ni wọn b sọ fun pe wọn fun ni iyọnda nitori ipo rẹ lati tẹsiwaju.
Ooni: A kìlọ̀ fún Sunday Igboho pé kó dákẹ́ àmọ́ kò gbọ́, èébú ló ń bú wa
Lori iyọnda yi, Soyinka sọ pe ''ko yẹ ki wọn maa wo ipo eeyan lati le jẹ ki o wọ ilẹ baba rẹ tori naa ki awọn eleto tọrọ kan wa nkan ṣe si idiwọ yi.'
''Ilana yi ti wọn tori rẹ dami duro ṣe eeyan ni kayeefi nitori awọn ibeere ti wọn n beere loju opo naa ko ni nkan ṣe pẹlu Covid-19.Bo ṣe ileesẹ ilera ni tabi eleyi to n ṣeto aabo labẹle, wọn ni lati yanju ọrọ yi''
O ni o to ki wọn sinmi lati maa foju tabi hu iwa si awọn ọmọ Naijiri lajo bi igba pe ọdaran ni wọn.
Sunday Igboho: Ọwọ́ ọlọ́pàá Cotonou tẹ akọ̀royìn tó fi fọ́nran ohùn Sunday Igboho síta
Iroyin to n tẹ wa lọwọ ni yajoyajo fihan pe ọwọ ileesẹ ọlọpaa ni orilẹede olominira Benin ti tẹ akọroyin kan, to n pin fọnran ohun oloye Sunday Igboho kaakiri.
Orukọ akọroyin naa ni Adekunle Aremu, tii se agbohunsafẹfẹ ori redio kan nilu Cotonou.
A gbọ pe ọjọbọ ni awọn ọlọpaa mu Adekunle yọju sile ẹjọ kan nilu naa.
Iroyin naa ni akọroyin naa lo pe Sunday Igboho lori foonu rẹ, to si bẹrẹ si ka ohun rẹ silẹ lasiko to n ba sọrọ lai sọ fun pe oun yoo se bẹẹ.
Idi ree ti Sunday Igboho se fariga lori isẹlẹ naa, eyi to tu ọpọ asiri nla nla jade, to si pe akọroyin naa lẹjọ lori iwa to hu naa.
Sunday Igboho Update: Igboho ti sọ ohun tó fẹ́ kí a ṣe tí ọ̀rs bá bẹ́yìn yọ- Saheed Yusuf
Nigba to n ba BBC Yoruba sọrọ lori isẹlẹ yii, agbẹjọro Sunday Igboho ni Cotonou, Ibrahim Salami, ti ohun rẹ wa ninu fọnran naa tun salaye pe oun ni oun n soju Igboho nile ẹjọ lori ọrọ naa.
Salami ni Sunday Igboho gan lo fi ọwọ si iwe ipẹjọ naa lati ẹjọ sun ijọba orilẹede Benin pe oun ko fara mọ igbesẹ ti akọroyin naa gbe.
"Ninu ofin orilẹede Benin, o lodi si ofin lati ka ohun eeyan kan silẹ lai kọkọ sọ fun onitọun tabi gba asẹ lọwọ rẹ lati se bẹẹ́.
Bakan naa, bi akọroyin ọhun se pin fọnran ohun Igboho naa sita tun tako ofin, eyi to mu ki ẹsẹ ti akọroyin naa sẹ di meji."
Lati ọjọ Aje ni awọn ọlọpa nilu Cotonou ti mu akọroyin naa si atimọle, ti wọn si gbe yọju sile ẹjọ lọjọbọ.
Ooni: A kìlọ̀ fún Sunday Igboho pé kó dákẹ́ àmọ́ kò gbọ́, èébú ló ń bú wa
Adekunle Aremu sọ niwaju adajọ pe pe foonu oun lo maa n gba ohun ẹni ti oun ba n ba sọrọ silẹ boya oun fẹ bẹẹ tabi tako.
Amọ ile ẹjọ ni irọ nla ni awijare rẹ naa nitori foonu kii se bẹẹ.
Nigba ti wọn bi pe ki lo de to se pin fọnran ohun naa kaakiri fawọn araalu lai naani awọn ọrọ asiri to wa ninu rẹ.
Adekunle salaye pe ohun fẹ tun nnkan se ni oun fi se bẹẹ amọ adajọ naa ni pe o lu ofin, to si ni ki wọn lọ fi pamọ si ọgba ẹwọn.
Lọwọ lọwọ bayii, akọroyin naa ti n naju lọwọ lọgba ẹwọn ti Sunday Igboho wa nilu Cotonou, ti igbẹjọ rẹ si n tẹsiwaju.
Ọjọ Kejila osu Kọkanla ọdun 2021 ni igbẹjọ afurasi naa yoo tun waye lati mọ iru ijiya sẹ ti adajọ yoo fun akọroyin naa.
Bẹẹ ba gbagbe, a ti mu iroyin wa fun yin saaju nipa fọnran ohun Sunday
Oyo Jailbreak: Wo ọṣẹ́ tí àwọn ẹlẹ́wọ̀n Abolongo ṣe fáwọn ará Oyo àti bí wọn ṣe rí wọn mú
Yoruba bọ, wọn ni ki oju ma ri ibi, gbogbo ara ni oogun rẹ.
Eyi lo difa fawọn olugbe agbegbe ọgba ẹwọn Abolongo niluu Oyo kan ti wọn ti fi adugbo naa silẹ bayii lẹyin ti ado oloro mii tun bu gbamu nibẹ lọjọ Iṣẹgun.
Ọjọ Ẹti ọsẹ to lọ lawọn agbebọn yabo ọgba ẹwọn naa nibi tawọn ẹlẹwọn kan ti salọ lẹyin ikọlu to waye pẹlu oriṣiiriṣii ohun ija oloro.
Bo tilẹ jẹ pe ileeṣẹ ọlọpaa ṣalaye fawọn olugbe adugbo pe awọn lo ṣee ti ado oloro tawọn agbebọn fi silẹ ninu ọgba ẹwọn bu gbamu ko o le ṣe akoba fawọn eeyan, awọn ara adugbo naa ni inu ibẹru-bojo lawọn wa.
BBC Yoruba ṣe abẹwo si agbegbe Abolongo lati mọ bi awọn olugbe agbegbe naa ṣe wa lẹyin ibugbami ado oloro ẹlẹẹkeji nibẹ.
Alaga awọn olugbe agbegbe Abolongo ati arabinrin Ola adua ti oun naa n gbe adugbo yii ṣalaye fun BBC Yoruba pe ọpọ eeyan lo ti fi adugbo naa silẹ lẹyin ti ado oloro tun bu gbamu fun igba keji.
Ọkan lara awọn ọlọdẹ ilu Oyo to ba BBC Yoruba sọrọ ṣalaye pe o ṣe pataki ki ijọba ro awọn ẹṣọ eleto abo lagbara nitori iru ikọlu bayii.
O ni ọpọ awọn ẹlẹwọn ni awọn ọlọdẹ ibilẹ n ṣà kaakiri nilu Oyo, ti wọn si pa meji lara awọ, ti wọn si ba isẹlẹ naa lọ.
Alaafin: Olorì Damilola ní òun ṣetán láti padà sí ààfin Oyo, ọ̀rẹ́ ló ní kí òun máa ba Aláàfin jẹ́
Oríṣun àwòrán, officialqueendamifanpage/Instagram
Yoruba ni bi obinrin ko ba dan ile ọkọ meji wo, ko ni mọ eyi to san.
Bẹẹ ni ọrọ Olori Damilola da bayii, ẹni tii se aya Alaafin Oyo, Ọba Lamidi Olayiwola Adeyemi kẹta to ko kuro ninu aafin ni bii osu mẹfa sẹyin.
Damilola, tii se olori kekere lo n fi ẹsun kan Alaafin nigba naa pe oriade naa ko tọju oun ati ọmọ kansoso to bi fun.
Amọ iyalẹnu lo jẹ bayii pe Olori naa ti n ge ika jẹ, to si n kabamọ pe oun kuro ninu aafin Oyo.
Ninu ikede kan ti ayaba naa se soju opo Instagram rẹ lọjọ Aiku, lo ti ni oun wa tọrọ aforijin lọwọ gbogbo ẹbi Adeyemi, tii se Alaafin Oyo.
Alaafin: Olori Aanu Adeyemi ṣàlàyé ìdí tó ṣe gẹ́ Oba Lamidi Adeyemi ti ìlú Oyo
O ni awọn ohun ti oun sọ nipa Ọba naa kẹyin ni oun ti ko jẹ, ti oun si fẹ ki gbogbo ẹbi dari jin oun.
"Mo fẹ ko ye gbogbo eeyan pe kii se pe wọn kan nipa fun mi lati kọ nnkan ti mo n kọ yii, koda, ọkan ati ara mi lo ji pepe.
Mo si fẹ sọ pe gbogbo ohun ti mo ti sọ laidara nipa Alaafin, paapaa pe ọba alaye naa ko tọju mi ati idi ti mo fi kuro ninu aafin Oyo, lo jẹ irọ patapata.
Awọn ọrẹ mi lo ti mi pe ki n se bẹẹ, ko si wa lati ọkan mi."
Olori Damilola tun fikun pe oju oun ti la bayii, ti oun si ti mọ ọtun yatọ si osi, mo si kabamọ pe mo fẹ fi ori ade wọlẹ nita gbangba,
O fikun pe oun ti lọ sile Alaafin to wa nilu Eko ati Abuja lati lọ tuuba fun oriade naa, ti omije ti omije si ni oun fi n kọ ọrọ yii.
"Mo n bẹ gbogbo abiyamọ aye, ẹ ba mi bẹ ọkọ mi, Alaafin Oyo pe ko dari jin mi, mo ti se tan, o ti ja mi loju.
Oríṣun àwòrán, officialqueen_dami/Instagram
Gbogbo ẹyin ti mo si gba owo lọwọ yin, maa da owo yin pada ni kete ti mo ba tipada si ọdọ ọkọ mi ni aafin Oyo.
Oloye nikan ni ọrọ yii ye pe ko si ibi to dabi ile."
Bawo ni Olori Damilola se kuro ni aafin Oyo:
Ninu iroyin yii, Nigba to kuro ni aafin Oyo, olori naa ni ọrẹ oun kan ti oun ni ko maa ran oun lọwọ ninu asọ adirẹ ti oun n ta, to si n gbe ninu aafin pẹlu oun, ni Alaafin tun fẹ, to si ti loyun fun.
Amọ igba ti oun yari ni Ọba naa ni ki oun ko ẹru oun jade kuro ninu aafin, ti oun si gba Eko lọ.
Lasiko to wa ni Eko yii, ni Olori Damilola fi igbe ta pe oun ko ri owo ti oun yoo fi gba ile tabi tọju ara oun, ti awọn ẹlẹyinju aanu si bẹrẹ si da owo jọ fun.
Oríṣun àwòrán, Gistlovers
Bakan naa nio aburo baba to bi Olori Damilola ke sita nigba naa pe irọ ni gbogbo oun ti Olori naa sọ nitori Ọba Adeyemi n tọju rẹ.
Baba naa, to ni oun ni oun ku fun Damilola bii baba tun fikun pe Alaafin n tọju awọn aburo Damilola pẹlu, to si n sanwo ile ẹkọ wọn to fi mọ iya to bi Damilola gan alara.
Amọ se ni (ninu iroyin yii) Olori Damilola fesi pada fun baba naa nigba naa, to si ni onijẹkujẹ ni, ati pe o ti gba owo lọwọ Ọba Adeyemi lo se ni ki oun pada si aafin rẹ.
Oríṣun àwòrán, Damilola/instagram
Banditry in Nigeria: Lai Muhammed ní torí pé agbébọn ń gbowó ilẹ̀ ní Ariwa, kò túmọ̀ pé wọn ti gba àkóso
Oríṣun àwòrán, Nigeria Army
Minisita ọrọ iroyin ati aṣa ni Naijiria, Lai Mohammed ti sọ pe awọn janduku agbebọn to n gba owo lọwọ araalu lapa Ariwa, ko tumọ si pe wọn ti gba ijọba.
"Mohammed sọrọ yii nigba to fesi si iroyin kan ti iwe iroyin Economist Magazine kọ niluu London pe ''Afaimọ kawọn agbesunmọmi, awọn to n pe fun iyapa atawọn agbebọn ma doju Naijiria bolẹ."""
Minisita ni o ṣe ilodi bi iwe iroyin Economist ṣe sọ pe awọn agbesunmọmi ti ṣe agbekalẹ ijọba wọn lapa ila oorun ariwa Naijiria.
"N jẹ ẹ mọ pe apa ariwa Naijiria nikan kọ ni gbigba owo ilẹ ti n ṣẹlẹ?
Wọn wa lapa guusu Naijiria naa, koda ọmọ ita tabi agbero tawọn oloyinbo n pe ni ''area boys'' ni ọpọ mọ wọn si.
Kiki Osinbajo: T;o bá yá owó lọ́wọ́ ẹnikẹ́ni, máa gbìyànjú láti da padà
Iyẹn ko dẹ tumọ si pe awọn agbebọn tabi agbesunmọmi n ṣọṣẹ nibẹ.
Mi o kan fẹ darukọ ni, awọn agbero ni ibudo wọn lawọn ilu nla ni Naijiria nibi ti wọn ti n gbowo ilẹ.
Eleyii ko tumọ si pe wọn ti gba ijọba tabi wọn da ijọba ti wọn ni lawọn ilu ti wọn wa,'' Mohamed ṣalaye.
Minisita eto iroyin ati ọrọ aṣa rọ awọn ileeṣẹ iroyin Naijiria pe ki wọn ye maa gbe iroyin ti tawọn ileeṣẹ iroyin ilẹ okeere gbe jade lai ṣe ayẹwo rẹ.
O sọ siwaju pe ẹka iwe iroyin Ecomist Magazine tii ṣe The Economist Intelligence Unit sọ pe Atiku Abubakar ẹgbẹ oṣelu PDP ni yoo wọle ibo aarẹ lọdun 2015.
Amọ ko ri bẹẹ nitrori Aarẹ Muhammadu Buhari lo wọle ẹlẹẹkeji pẹlu ibo to le ni miliọnu mẹta.
Ọgbẹni Mohamed ni eleyii fihan pe iwe iroyin Economist Magazine le ṣe aṣiṣe.
Ogogo wá sí iléèwé wa, mo kéwì fún un ló sọ mi di èèyàn ńlá lórí ayélujára - Akinwumi Akewi
Minisita ni ko boju mu bi awọn ileeṣẹ iroyin Naijiria ṣe n bẹ mọ iroyin to jade ninu iwe iroyin ilẹ okeere lai ṣe ayẹwo fini fini ohun ti iroyin naa da le lori.
Mohamed ni kii ṣe asiko tawọn Boko Haram n jọwọ ara wọn pe awọn ko ja mọ lo yẹ ki iwe iroyin Economist maa sọ pe awọn agbesunmọmi ti ni ijọba ti ara wọn lapa ariwa Naijiria.
Oluwo: Àwọn adarí ẹ̀sìn Musulumi ṣe ayẹyẹ fún 'Grand Mufti, Oluwo kò yọjú
Oríṣun àwòrán, Others
Awọn adari ẹsin Musulumi kan ṣabẹwọ si ilu Iwo, nipinlẹ Osun lati ṣe moriya fun Sheik Daood Imran Molaasan ti wọn yan gẹgẹ bi ''New Grand Mufti'' ilẹ Yoruba.
Oluwo ti ilu Iwo, Oba AbdulRasheed Akanbi lo yan Sheik naa ni oye ẹsin Musulumi.
Eleyii ti fa ariyanjiyan, ti o si ti di ọrọ ileẹjọ pẹlu idajọ pe Oluwo ko ni aṣẹ lati yan aṣoju ẹsin Musulumi, ati wi pe ko da ọwọ duro lori iyansipo naa.
Ajọ League of Imams and Alfas lo gba ileẹjọ lọ lati pata si igbese Oluwo lati yan ẹnikẹni si ipo Musulumi.
Amọ lẹyin wakati diẹ ti idajọ akọkọ naa waye, ni ileẹjọ giga tilu Osogbo tun pasẹ pe oun gbẹsẹ le asẹ akọkọ to waye saaju lati tako iyansipo Grand Mufti naa, to si ni ki wọn tẹsiwaju lati fi oye naa jẹ.
Oríṣun àwòrán, Oluwo of Iwo
Iwe asẹ ile ẹjọ naa ti Oluwo fi sọwọ sile isẹ BBC Yoruba fihan pe ọjọbọ, ọjọ kejidinlọgbọn osu kẹwa ọdun 2021 ni ileẹjọ pasẹ naa.
Amọ, n ṣe ni awọn eniyan pejọ si ibi ayẹyẹ naa ni opin ọṣẹ lati yọ pẹlu oloye naa, amọ Oluwo ko yọju sibẹ.
Nibi ayẹyẹ naa ti ẹgbẹ awọn Musulumi ni ilu Iwo ati Jamaát Taáwunil Muslimeen ṣe agbatẹru fun, ni Molaasan ti salaye pe Oluwo ti fi oun jẹ oye naa ki ọrọ ileẹjọ to de ilẹ.
Oyo Jailbreak: Wo ọṣẹ́ tí àwọn ẹlẹ́wọ̀n Abolongo ṣe fáwọn ará Oyo àti bí wọn ṣe rí wọn mú
Malaasan to jẹ aarẹ ẹgbẹ Musulumi, Jama'atu Ta'awunul Mumineen ni oun yoo wa ọna lati ṣepade pẹlẹ-putu pẹlu awọn to n fi apa janu lati ri pe alaafia ati ifimọṣọkan waye laarin awọn musulumi.
O ni awọn yoo jiroro lori ohun ti ẹsin Musulumi jẹ, ti awọn yoo si pe awọn adari ẹsin Musulumi Sunni ati Sufi lati ṣiṣẹ pọ lori ilọsiwaju ẹsin wọn.
Awọn to pejọ si ibi ayẹyẹ naa ni Waziri ilẹ Yoruba, Sheik Yaqoob Muhammad AbdulBaqi, awọn adari ẹsin Musulumi lati ipinlẹ Oyo, Ogun, Kwara ati ilu Eko.
Bakan naa ni awọn adari ẹsin naa ṣabẹwọ si Oluwo ni afin ọba, nibi to ti gbadura fun wọn to si ti gba wọn niyanju lati ṣiṣẹ pọ ninu irẹpọ.
Oríṣun àwòrán, Sheikh Dawood Imran Molaasan
Saaju la ti mu iroyin wa fun yin pe, awuyewuye ko ti tan lori bi Oluwo ti ilẹ Iwo, Oba AbdulRasheed Akanbi ṣe yan Sheik Dawood Imran Molaasan gẹgẹ bi Grand Mufti ilẹ Yoruba.
Ni Ọjọbọ, ọjọ kejidinlọgbọn oṣu kẹwaa ọdun 2021 yii ni ile ẹjọ giga kan niluu Osogbo paṣẹ pe Sheikh Molaasan ko gbọdọ pe tabi ri ara rẹ gẹgẹ bi Grand Mufti ilẹ Yoruba mọ titi ti ẹjọ ti wọn pe e yoo fi yanju.
Ẹgbẹ awọn lmam atawọn aafa lo gbe ọrọ naa lọ si ile ẹjọ lati da Oluwo duro lori ati yan Sheik Molaasan loye.
BBC Yoruba kan si Oluwo lori ọrọ yii, ṣugbọn kabiyesi ko fesi amọ Oluwo ni ki a ba Sheikh ti oun fi joye gan an sọrọ.
Sheikh Molaasan sọ fun wa pe oun kii ṣe ọmọ ẹgbẹ awọn Imam ati aafa to pe ẹjọ yii, nitori naa, wọn ko le lo ofin kankan le oun lori.
Kiki Osinbajo: T;o bá yá owó lọ́wọ́ ẹnikẹ́ni, máa gbìyànjú láti da padà
O ṣalaye pe awọn agbẹjọro oun naa ti wa lori ọrọ yii, wọn yoo si pade nile ẹjọ pẹlu awọn to pe oun lẹjọ.
Lori ọrọ ti ẹgbẹ Imam atawọn aafa to sọ pe ko tọ si ọba alaye lati yan ẹnikẹni si ipo Mufti, Sheikh ni ọba laṣẹ lati yan Mufti gẹgẹ bi o ti laṣẹ lati yan Imam.
''Ẹgbẹ awọn baba wa kan ninu ẹsin Islam ni awọn to pe wa lẹjọ lori oye Mufti ti Oluwo fi mi jẹ.
A kii ṣe ẹgbẹ kan naa, a kan jọ jẹ ẹleṣin Islam ni ati pe ti ile ẹjọ ba da ẹjọ ti ko ba tẹ wa lọrun, a ni anfani lati pe ẹjọ kotẹmilọrun.
Emi o bawọn ṣe ẹgbẹ wọn, ẹgbẹ Ta'awun musulumi ni ẹgbẹ tiwa eleyii ti a si forukọ silẹ pẹlu ajọ C.A.C.
Gbogbo mọṣalaaṣi wa ni ko si labẹ awọn Imam yii, bakan naa ofin ko fawọn Imam lagbara lati yan ẹnikẹni sipo.
Ati pe awọn Imam to pe mi lẹjọ yii ko fi orukọ silẹ pẹlu ajọ ijọba C.A.C.
Oluwo ti fi emi jẹ oye yii tipẹ, awẹjẹ-wẹmu lasan an ni a fẹ ṣe lọjọ Abamẹta ki ẹgbẹ Imam yii to pe mi lẹjọ,'' Sheikh Molaasan
Akeugbagold rọ Oluwo lati fi ọrọ oye ẹsin Islam silẹ fawọn Alfa àti Imaamu:
Ẹwẹ, Sheikh Akeugbagold Taofeeq ti rọ Oluwo lati maa dasi ọrọ oye jijẹ ninu ẹsin Islam.
Akeugbagold sọ fun BBC Yoruba pe niṣe lo yẹ ki Oluwo fi awọn aafa silẹ lati maa yan eeyan sipo fun ra wọn.
''Awọn ọba ni wọn maa n yan Imam si ipo nilẹ Yoruba, amọ o le ma ba ẹsin Islam mu.
Amọ, awọn aafa lo yẹ ki wọn maa fawọn eeyan jẹ oye ninu ẹsin Islam, mo si mọ pe awọn aafa ilu Iwo mọ bẹ.
Ṣugbọn emi maa gba baba wa Oluwo ni imọran lati fi ọrọ ẹsin silẹ fawọn aafa.
Ki wọn ma ba wọn fa tabi ba wọn du ohun kohun.
Lẹyin Imam tawọn ọba maa n yan sipo, wọn kii dasi awọn oye yoku ninu ẹsin Islam,'' Akeugbagold lo sọ bẹẹ.
Oluwo ilu Iwo ba BBC Yoruba sọrọ lori awuyewuye pẹlu awọn Ọba
Ninu atẹjade kan ti Oluwo fisita lọjọ Ẹti, tii se ọjọ keji ti idajọ naa waye, o ni oun n tẹsiwaju lọla ọjọ Satide lati se ayẹyẹ iwuye Grand Mufti Yoruba jẹ.
Ọba alaye naa ni lẹyin ifikunlukun to yẹ, awọn eeyan ti ọrọ naa kan ti pahunpọ fọwọsi yiyan Sheik Dawood Imran gẹgẹ bii Grand Mufti tilu Iwo.
Justice Mary Odili: Àwọn agbófinró ya bo ilé Onídájọ́ Mary Odili, àwọn ohun tuntun tó súyọ rèé
Oríṣun àwòrán, Other
Onídájọ́ Mary Odili, adajọ ileẹjọ to ga julọ ni Naijiria ti awọn agbofinro ya bo ile rẹ lọjọ Ẹti
Awọn agbofinro ya bo ile Onidajọ Mary Odili nilu Abuja lalẹ ọjọ Ẹti, eyi si ti n fa ọpọlọpọ ariwisi ati awuyewuye pẹlu bi o ṣe jẹ wi pe onidajs agba ni Mary odili ni ile ẹjọ to ga juls lorilẹede Naijiria.
Amọṣa, ajọ EFCC to jẹ ajs to n gbogun ti iwa ijẹkujẹ ati gbogbo iwa aitọ miran to nii ṣe pẹlu iṣuna ati ọrọ aje lorilẹede Naijiria ni awsn ko mọ nipa rẹ o.
Bakan naa ni ileeṣẹ agbofinro DSS naa ti sọ pe laye o, awọn naa ko mọ nnkankan nipa rẹ.
Agbọn n sẹ ikandu nsẹ, oju oloko si ree gbagungbagun.
Ni alẹ ọjọ Ẹti kan naa ni Gomina ipinlẹ Rivers, Nyesom Wike atawọn eekan to jẹ ọrẹ ẹbi Odili ti ṣabẹwo si ile naa lati ms bo ṣe n lọ nibẹ.
Koko ọrọ ni pe, lati awọn akoko diẹ sẹyin bayii, onidajọ Mary Odili ati ọkọ rẹ Peter Odili to figba kan ri jẹ gomina ipinlẹ Rivers ti n ni iforigbari pẹlu awọn alaṣẹ kan lorilẹede Naijiria, ko si si ẹni lee sọ ni pato ẹni gan ninu awọn mejeeji ti awọn agbofinro tori kọlu ile wọn.
Oríṣun àwòrán, other
Gomina Wike atawọn ọrẹ ẹbi Odili nile wọn lalẹ ọjọ Ẹti
Awọn iroyin abẹle kan n gbe kiri pe awọn agbofinro ni kikẹẹfin tawọn kẹẹfin pe iwa aitọ"" kan n lọ nile naa lawọn fi sare kọlu ibẹ lati lee koju rẹ."
ṣaaju asiko yii ni awọn iroyin kan ti jẹyọ lori ayelujara ninu eyi ti eeyan kan ti orukọ rẹ n jẹ Aliyu Ibrahim ti gbe jade ninu iwe ẹlẹri ofin kan pe awọn ọlọpaa n gbero lati gba iwe aṣẹ lati ls ṣayẹwo awọn ile kan nilu Abuja ti wọn fura si pe awọn iṣẹ to gba ifura ti n waye.
Oríṣun àwòrán, other
Gomina Wike nile ẹbi Odili lalẹ ọjọ Ẹti
Lọjọ Ẹti ni adajọ Majisireeti agba kan ni ile ẹjọ majisireeti kan ni Wuse zone 6 nilu Abuja ti orukọ rẹ n jẹ Emmanuel Iyanna fun awsn agbofinro ni iwe aṣẹ naa, gẹgẹ bi BBC ṣe sewadi rẹ, sga slọpaa kan ti orukọ rẹ n jẹCSP  Ajodo Lawrence lo si gba iwe aṣẹ naa.
Oríṣun àwòrán, other
Gomina Wike atawọn ọrẹ ẹbi Odili nile wọn lalẹ ọjọ Ẹti
Se lootọ ni adajọ Majisireeti agba Emmanuel Iyanna mọọmọ gbe aṣẹ kalẹ fun ikọlu agbofinro sile onidajọ Odili?
Nibayii adajọ Majisireeti agba Emmanuel Iyanna ti n sọ pe ileeṣẹ eto idajọ labẹ amofin agba orilẹede Naijiria, Abubakar Malami fi ọgbọn alumọkọrọyi tan oun ni lati gbe iwe aṣẹ ẹ lọ tu ile rẹ jade.
Awọn iwe iroyin abẹle kan lorilẹede Naijiria si ti gbee pe ni kete ti adajọ Majisireeti agba Emmanuel Iyanna ri oju ọrọ lo paṣẹ ki wọn wọgile iwe aṣẹ to kọkọ pa naa.
Gẹgẹ bi BBC ṣe rii ka, iwe aṣẹ naa wa fun ojule kẹsan, opopona Imo, Maitama Abuja, ṣugbọn adirẹsi ile Onidajọ Mary Odili tawọn agbofinro naa lọ kọlu jẹ ojule Kẹsan.
Oríṣun àwòrán, other
Oríṣun àwòrán, other
Oríṣun àwòrán, odili
Oríṣun àwòrán, other
Oríṣun àwòrán, other
Awọn ọlọpaa ko tii sọ ohun tawọn oṣiṣẹ wọn n ṣe ni ẹnu ọna Onidajọ Mary Odili, bẹẹni ko daju boya Peter Odili wa nile lasiko ti iṣẹlẹ naa ṣẹlẹ.
Ohun ti a mọ ni pe ọga ọlọpaa CSP Ajodo Lawrence to gba iwe aṣẹ ile ẹjọ yii jẹ ọkan lara awọn ọmọ ikọ oluwadi labẹ igbimọ to n gba owo ori dukia labẹ ileeṣẹ eto idajọ lorilẹede Naijiria.
Ooni: A kìlọ̀ fún Sunday Igboho pé kó dákẹ́ àmọ́ kò gbọ́, èébú ló ń bú wa
Agbẹjọro fun Odili ba awọn akọroyin sọrọ lẹnu ọna ile Onidajọ Odili.
"O ṣe apejuwe iwe aṣẹ ile ẹjọ naa gẹgẹ bii ""aṣiṣe ti ko yẹ ko waye"""
Ohun ti BBC ri daju ni pe, ni nnkan bii agogo marun un irọlẹ lawọn agbofinro naa ya bo ile onidajọ Mary Odili, ṣugbọn awọn ikọ agbofinro to n ṣọ ile naa ko jẹ ki wọn ri aye wọle.
Igba akọkọ kọ niyi tawọn agbofinro yoo maa ya wọle awọn onidajọ lorilẹede Naijiria.
Ogogo wá sí iléèwé wa, mo kéwì fún un ló sọ mi di èèyàn ńlá lórí ayélujára - Akinwumi Akewi
Bola Tinubu and Yemi Osinbajo: Ìjíròrò tó wáyé láàrín Bola Tinubu àti Igbákejì ààrẹ Yemi Osinbajo, ohun tó ṣẹlẹ̀ níbẹ̀ nìyí
Oríṣun àwòrán, Tolani alli
Ni ọjọ Ẹti ni igbakeji aarẹ Yẹmi Oṣinbajo lọ ki aṣiwaju ẹgbẹ oṣelu APC, Bsla Ahmed Tinubu ni ile rẹ to wa nilu Abuja.
Ohun ti ọpọ ti n sọ ṣaaju asiko yii ni pe ọrọ gbigbe igba ibo aarẹ ọdun 2023 ti n da họwuhọwu silẹ laarin awọn mejeeji yii.
Amọṣa awọn amugbalẹgbẹ aṣaaju ẹgbẹ oṣelu APC naa ṣalaye pe ojo ti n pa igun Aṣiwaju Bọla Tinubu ati igbakeji aarẹ Yẹmi Ọṣinbajo bọ lọjọ to ti pẹ lati aye alalumọlẹ.
Amugbalẹgbẹ fun Bọla Tinubu lori ọrọ iroyin, Tunde Rahman ṣalaye fun BBC News Yoruba pe ajọṣepọ awọn mejeeji yii ti n bọ lọjọ pipẹ.
O fi kun pe ipade laarin awọn mejeeji yii kii ṣe ohun to jẹ babara bikoṣe ipade ikini ẹku ọjọ mẹta ti igbakeji aarẹ lọ ki Ahmed Bọla tinubu lẹyin to ti irinajo itọju ara rẹ de.
'Mi ò yàtọ sí Krìstẹni tàbí Mùsùlùmí tóun náà da ẹsìn rẹ pọ mọ jíjẹ Dokita, Babaláwo Dókítà l'èmi'
O fi kun un pe ko soun to jọ ọrọ idibo 2023 ninu ijiroro wọn.
Gbogbo aye lo ms pe ipade laarin awọn mejeeji nikan leyi, ko si ẹni to lee mọ hulẹhulẹ rẹ, ṣugbọn ohun ti a mọ ni pe ko si ọrọ idibo 2023 ninu ọrọ wọn, ajọṣepọ wọn ti bẹrẹlati ọjọ pipẹ nitori naa ko yẹ ko si babara ninu ipde wọn. Ikini laarin eeyan meji to ti mọ ara wọn lati ọjọ pipẹ wa  ni.
PDP convention: Ìpàdé ìdìbò 'convention' ẹgbẹ́ òṣèlú PDP ń gbìnàyá l'Abuja
Lẹyin ti igbesẹ alaga ẹgbẹ oṣelu PDP tẹlẹ, Uche Secondus lati pagidina igbade idibo itagbangba ẹgbẹ oṣelu PDP bọ si pabo, awọn aṣoju ẹgbẹ oṣelu naa yoo kọrajọ silu Abuja lọjọ Satide ọgbọnọjọ ati ọjọ kọkanlelọgbọn oṣu kẹwaa ọdun 2021 lati yan awọn adari ẹgbẹ oṣelu naa.
Ṣaaju lọpọ ti n woye pe ṣe ipade idibo ẹgbẹ naa yoo lee waye lẹyin ti Uche Secondus gbe ẹgbẹoṣelu naa lọ siwaju ile ẹjọ kotẹmilọrun nibi ti ile ẹjọ kotẹmilọrun nilu PortHarcourt ti paṣẹ pe ko sohun to gbọdọ di ipade idibo naa lọwọ.
Ipo mọkanlelogun ni wọn yoo wa awọn eeyan tuntun ti yoo maa tukọ ẹgbẹ naa si, eeyan bii mẹtadinlọgbọn ni yo si maa du ipo naa.
Amọṣa ohun ti Gomina ipinlẹ Adamawa, Ahmadu Fintiri to jẹ alaga igbimọ to n ṣe aayan ipade idibo gbogboogbo naa sọ ni pe ipo mẹta pere ninu awsn ipo  naa  ni wsn yoo dibo le lori lẹyin ti ẹnu ti ko lori awọn ti wọn yoo gbe si ipo yoku.
Itakangbọn fun ipo igbakeji alaga apapọ ẹgbẹ oṣelu PDP fun ẹkun gusu Naijiria yoo wa laarin gomina ipinlẹ Ọṣun tẹlẹ, Ọlagunsoye Oyinlọla ati igbakeji gomina ipinlẹ Ọyọ tẹlẹ, Taofeek Arapaja.
O fidi rẹ mulẹ pẹlu pe igbimọ ayẹwo awọn oludije ti wọgile orukọ awọn oludije kan bii Wale Ọladipọ to gbero ati dije fun ipo igbakeji alaga, Eddie Ọlafẹsọ ati Akintan Oludaisi to gbero ati dije fun ipo akọwe ipolongo. Iwọgile wọn waye lori ẹsun pe wọn gbe ẹgbẹ oṣelu naa lọ sile ẹjọ lawọn asiko kan sẹyin.
Bakan naa ni wọn tun wọgile erongba Amofin Muo-Aroh SAN lati dije fun ipo akọwe apapọ ẹgbẹ oṣelu naa nitori pe kii ṣe ipinlẹ Imo ti wọn pin ipo naa si lo ti wa.
PDP Convention: Àrà ọ̀tọ̀ ní ìdìbò 'convention' tọ̀tẹ̀ yí, òru mọ́jú la ti yanjú ọ̀rọ̀ lórí ọ̀pọ̀lọ́pọ̀ ipò -Seyi Makinde
Ipo mọkanlelogun ni wọn yoo wa awọn eeyan tuntun ti yoo maa tukọ ẹgbẹ naa si, eeyan bii mẹtadinlọgbọn ni yo si maa du ipo naa.
Gomina Makinde ni mejidinlogun ninu awọn ipo naa ni wọn ti yanju eeyan ti yoo diimu ni tubiinubi.
APC Oyo Primaries: Àwọn aṣaájú ké gbàjaré pé ìbò abẹ́nú APC Oyo tó kọjá mẹ́hẹ
Ipade idibo abẹnu ẹgbẹ oselu APC nipinlẹ Oyo waye ni ọjọ Satide, tawọn ọmọ igbimọ alasẹ ẹgbẹ tuntun si fi oju han.
Amọ sibẹ, ọrọ si ku lori abọ ipade idibo abẹnu naa nitori awọn igun kan ninu ẹgbẹ oselu APC nipinlẹ Oyo ti n fi apa janu, ti wọn si kọ esi idibo ọhun.
Alaga ẹgbẹ oṣelu naa to n fi ipo silẹ, Oloye Akin Ọkẹ ṣalaye pe itọsẹ lo lọyọ, o ye ki wọn ṣe ohun gbogbo bo ṣe tọ.
Oloye Ọkẹ ni aifẹ tẹle ilana tawọn babanla ẹgbẹ naa fi lelẹ ni ipilẹ ẹgbẹ oṣelu naa, lo n fa gbogbo dukuu laarin ẹgbẹ naa.
O ni ohun to ku diẹ kaato ni lati rii pe awọn eeyan kan lẹgbẹ oṣelu APC gbimọ pọ lati mu ayederu orukọ wọ inu iwe orukọ awọn aṣoju idibo to yẹ ko farahan nibi ipade idibo yan adari, congress, to waye ni ipinlẹ Ọyọ.
O ni gbogbo awọn to wa gẹgẹ bi ọmọ igbimọ kokari eto idibo naa ni wọn fọwọsi pe ki wọn ṣe ohun gbogbo bo ṣe tọ.
Seyi Makinde: Kò sí ìjà láàrin èmi àti Fayose, àjọṣepọ̀ wa gún régé
O fi kun pe ibẹru awọn eekan ẹgbẹ naa gbogbo ṣaaju eto idibo naa ni pe, awọn eeyan kan ti tọwọ bọ iwe orukọ awọn aṣojudibo l'Eko ati l'Abuja.
O ni bo tilẹ jẹ pe awọn awọn aṣiwaju ẹgbẹ oṣelu naa ko gba eyi gbọ nigba naa, eleyi to mu ki wọn beere fun iwe orukọ ti wọn yoo lo fun idibo naa lọjọ Ẹti.
Amọṣa, iyalẹnu lo jẹ lati rii pe ọpọ asawọ lo ti wọ inu iwe orukọ naa, gẹgẹ bi Oloye Akin Ọkẹ ṣe sọ fun BBC News Yoruba.
Ẹwẹ, minisita fun ere idaraya, Sunday Dare ti oun pẹlu ti fi ẹhonu han lori igbesẹ naa ni awọn eeyan perete kan ni wọn fẹ fi tipatipa ja ẹgbẹ oṣelu naa gba mọ awọn ọmọ ẹgbẹ oṣelu naa lọwọ ni ipinlẹ Ọyọ.
Ninu atẹjade kan to n lọ kaakiri awọn iwe iroyin abẹle ni Naijiria, Sunday Dare ṣalaye pe awọn to wa nidi eto naa n wa ọna lati tu ẹgbẹ naa ka ni.
Igbesẹ awọn iwọnba perete lati ja ẹgbẹ oṣelu yii gba ko ni jọ. Ọpọ awọn ọmọ ẹgbẹ oṣelu naa lo duro lori idagbasoke rẹ.
Oyo PDP Crisis: Olopoeyan ní Makinde yá PDP láti dìbò ni, àwọn kò ní gbà kó ba ẹgbẹ jẹ
Lara awọn agbaagba ẹgbẹ oṣelu naa to n tako eto naa bayii ni  alaga ajọ feto ibaraẹnisọrọ (NCC), Ọjọgbọn Adeolu Akande ati oludije fun ipo gomina lẹgbẹ oṣelu APC nigba kan ri, Oloye Olasunkanmi Tegbe.
Awọn yoku ni oludije gomina to kọja nipinlẹ Ọyọ, Oloye Adebayo Adelabu; Olagunju Ojo; Fatai Ibikunle ati Ọmọọba Ayodeji Abass-Aleshinloye.
Awọn yoku ni Oloye Sarafadeen Alli, to figbakan ri jẹ akọwe ijọba ipinlẹ Oyo atawọn eekan ẹgbẹ APC miran.
Amọṣa, nigba ti BBC News Yoruba kan si awọn ọmọ igbimọ tuntun ti wọn ṣẹṣẹ yan naa, Ọgbẹni Mojeed Ọlaọya, ti wọn ṣẹṣẹ yan gẹgẹ bii alaga fun ẹkun idibo gusu ipinlẹ Ọyọ ṣalaye pe ko si kalọkabọ kankan lori ọrọ yii.
O ni ohun ti awọn n fẹ ni pe ki igbimọ apapọ ẹgbẹ naa da si aawọ naa lọ, igbesẹ wọn si lawọn n reti lọwọ.
Amọṣa, alaga to n fipo silẹ lẹgbẹ oṣelu naa, Oloye Akin Ọkẹ rọ gbogbo awọn ọmọ ẹgbẹ oṣelu APC nipinlẹ Ọyọ lati ṣe suuru, ki wọn fi wa ojuutu si ọrọ ọhun.
"Bakan naa lo ke si Ọgbẹni Ọmọdewu ti wọn ṣẹṣẹ kede gẹgẹ bi alaga ẹgbẹ oṣelu naa, lati ṣe pẹlẹ ko si duro naa ""nitori nigba ti alaafia ba wa leyan lee sọ pe oun n ṣe alaga."""
Ipade idibo abẹnu ẹgbẹ oselu APC nipinlẹ Oyo waye ni ọjọ Satide, tawọn ọmọ igbimọ alasẹ ẹgbẹ tuntun si fi oju han.
Amọ sibẹ, ọrọ si ku lori abọ ipade idibo abẹnu naa nitori awọn igun kan ninu ẹgbẹ oselu APC nipinlẹ Oyo ti n fi apa janu, ti wọn si kọ esi idibo ọhun.
Ipade idibo naa, ti Gambo Lawan se alaga fun lo waye ni papa Liberty nilu Ibadan, ti iroyin si ni awọn janduku kan tilẹkun mọ alaga naa lati aago meje aarọ, ti ko si le peju sibi ti ipade ọhun ti waye.
Awọn janduku naa si lo sọ fun Gambo pe ko ni ri ọna lọ ayafi to ba kede pe oun ti wọgile idibo abẹnu naa, ti ko si ni waye mọ.
Koda, ni ibẹrẹ eto naa ni awọn igun kan ninu ẹgbẹ APC nipinlẹ Oyo ti ni ki wọn wọgile idibo abẹnu naa nitori oniruuru orukọ awọn oludibo to jẹ ayederu lo ti jade sita.
PDP Convention: Àrà ọ̀tọ̀ ní ìdìbò 'convention' tọ̀tẹ̀ yí, òru mọ́jú la ti yanjú
Igba keji si ree ti wọn yoo sun eto idibo naa siwaju, ti wahala si tun fẹ bẹ silẹ ni igba kẹta.
Awọn igun to n fi apa janu naa, ti wọn tilẹkun mọ Gambo lati jẹ ko ri ọna de ibi ipade naa ni ko mọ pe akọwe igbimọ to n se kokari ibo ọhun, atawọn ọmọ igbimọ naa kan, ti de ibudo ti idibo naa yoo ti waye.
Nigba to n fi idi isẹlẹ yii mulẹ lori eto ori redio kan nilu Ibadan, Gambo ni o ya oun lẹnu pe awọn eekan kan ninu ẹgbẹ oselu naa le ran awọn janduku lati wa fa ọwọ aago ibo naa sẹyin.
A gbọ pe gbogbo aayan gomina tẹlẹ nipinlẹ Oyo, Adebayo Alao Akala lati yọ Gambo ninu ahamọ tipa ti wọn fi si naa lo ja si pabo.
Ọpẹlọpẹ awọn ọlọpaa, Civil Defence ati DSS lo jẹ ki Gambo gba idande ni aago meje alẹ lẹyin ti idibo ti pari tan.
Amọ lẹyin abọ idibo to waye lasiko ipade apapọ ẹgbẹ APC naa, Isaac Omodewu, tii se Kọmisana tẹlẹ labẹ ijọba Ajimobi ni wọn kede pe o jawe olubori bii alaga ẹgbẹ oselu APC nipinlẹ Oyo.
Ninu ọrọ akọsọ rẹ, Omodewu rọ awọn ọmọ ẹgbẹ oselu naa lati gba alafia laaye, ki wọn fi ọwọ wọnu, ki wọn si pa imọ pọ lati mu ki ẹgbẹ naa de ibi giga.
O wa dupẹ lọwọ awọn asaaju ẹgbẹ oselu APC nipinlẹ Oyo fun atilẹyin wọn, to si fi ọwọ gbaya pe oun yoo pari ija laarin awọn ọmọ ẹgbẹ to n fi apa janu.
Awọn igun ti Unity Forum, Ajimobi Legacy, Zenity Labour Party ati Oloye Adeniyi Akintola si lo ti ki alaga tuntun fun ẹgbẹ naa ku oriire.
Atẹjade kan ti Sẹnatọ Ayoade Adeseun, Oloye Sarafa Alli, Amofin Ayo Ojeniyi ati Asofin Tolu Sadipe dijọ fi ọwọ si wa kan saara si awọn ọmọ ẹgbẹ naa fun bi wọn se se ojuse wọn nilana isejọba awa ara wa.
Bakan naa ni wọn yonbo wọn fun bi wsn ko se gba ki alaga ipade idibo abẹnu naa dari idibo mọkaruru, eyi to mu mẹrin ninu awọn ọmọ igbimọ alako ipade naa kọwe fipo silẹ.
Wayi o, awọn igun ẹgbẹ oselu APC ti inu n bi ti n fi apa janu lori esi idibo abẹnu naa nibi ti Isaac Omodewu ti jawe olubori bii alaga ẹgbẹ.
Timi Osukoya: Ọ̀pọ̀ olórin ẹ̀mí ló ń kọrin torí owó tàbí afẹ ayé
Iyabo Ojo: Tiwa Savage fun ní N500,000, àwọn míì fi màálù méjì, ọtí wáìnì ránṣẹ
Oríṣun àwòrán, iyaboojofespris/Instagram
Yoruba ni bu fun mi, ki n bu fun ọ, ni ọpọlọ n ke lalẹ odo, ka rin, ka pọ, yiyẹ si lo maa n yẹ ni.
Bo se ri fun gbajumọ osere tiata, Iyabo Ojo ree nibayii to n gbaradi fun ayẹyẹ iranti ọdun kan ti mama rẹ, Victori Olubunmi Fetuga dagbere faye.
Nigba to n fi iwe ipe sibi apejẹ naa ransẹ sawọn ọrẹ ati ololufẹ rẹ, paali to da bi apoti ni Iyabo Ojo fi se iwe ipe ransẹ sawọn eeyan yii.
Enoho Peggy Ovire (Ego Oyibo) si lo se afihan awọn eroja to wa ninu apoti naa fun araye ri loju opo Instagram rẹ.
Lara awọn ohun to kun inu apoti paali naa ni asọ ẹbi olomi buluu ati goolu pẹlu gele asọ oke buluu, ọti waini ti wọn tẹ aworan oloogbe naa si lara ati orukọ rẹ.
Bakan naa ni ni ẹrọ to n lo oorun lati sọ saaji batiri foonu wa ninu apoti iwe ipe naa pẹlu iwe ipe gan funra rẹ, ko si si ẹni to gba paali naa, ti ori rẹ ko ni wu.
Ko tan sibẹ o, Bakan naa ni gbaju gbaja akọrin takansufe nni, Tiwa Avage fi ẹgbẹrun lọna ẹẹdẹgbẹta naira ransẹ si Iyabo Ojo gẹgẹ bi ẹbun fun igbaradi ayẹyẹ naa.
Iyabo Ojo funra rẹ si lo sisọ loju ọrọ yii loju opo Instagram rẹ nigba to n ki akọrin naa pe o seun, o ku anawọsi.
Tun wẹ, ni Iyabo tun kede pe ọkunrin kan to pe ni aburo rẹ, Ade Smith ati ileesẹ kan to n ta ẹsọ goolu fi maalu kọọkan ransẹ si lati lo fun ayẹyẹ naa.
Oríṣun àwòrán, iyaboojofespris/Instagram
Bakan naa ni ileesẹ kan to n se bata fi ọpọ ọti waini ransẹ ransẹ si ọmọlooku ọhun, to si n ki gbogbo wọn pe wọn seun.
Ọpọ ololufẹ Iyabo Ojo to fesi si awọn ikede naa lo salaye pe eeyan to lawọ ni Iyabo Ojo funra rẹ, o si ti ran ọpọ eeyan lọwọ sẹyin.
Wọn wa n sọ fun pe oun naa ti da omi siwaju, o di dandan ko tẹ ilẹ tutu nitori ẹni to ba saanu, yoo maa ri aanu gba.
Oríṣun àwòrán, iyaboojofespris/Instagram
Kidnapping In Oyo: Ìjọba tú àṣírí ọ̀nà tuntun tí ajínigbé ń gbà jí akẹ́kọ̀ọ́ gbé
Oríṣun àwòrán, OYSG
Yoruba ni igi gogoro ma gun mi loju, ati okeere ni a ti n lọ ọ.
Idi ree ti ijọba ipinlẹ Oyo se n figbe ta fawọn obi ati araalu lori ọna ẹburu ati ọgbọn alumọkọrọyi tawọn ajinigbe n gba bayii lati sisẹ ibi wọn.
Ninu atẹjade kan ti ijọba Oyo fisita lati ipasẹ akọwe agba fun ileesẹ eto ẹkọ, Arabinrin Atere, ni ijọba ti n rọ awọn akẹkọ, olukọ ati obi lati mase wọ mọto ọfẹ lati ọdọ ẹni ti wọn ko mọ.
Ijọba ni o n bọ, o n bọ awọn laa dẹ de amọ lojumọ toni, oju ni wọn n mu to, o si yẹ kawọn araalu gbọ ikilọ yii, ki wọn ma baa ji wọn gbe.
Ijọba ni awọn ajinigbe ti n dibọn bii akẹkọọ nipa wiwọ asọ ile ẹkọ, ki wọn le dara pọ mọ awọn akẹkọọ lati ji wọn gbe.
Oríṣun àwòrán, Oyo State Government
Atẹjade naa salaye pe ilu Ibadan ni awọn ajinigbe ti n dibọn bayii julọ lati ji awọn akẹkọọ gbe lọ, ti wọn si n rọ awọn obi lati luaago ikilọ yii fun awọn ọmọ wọn.
"Atẹjade naa ni ""Wọn ti dari mi lati sọ fun yin pe o se dandan ki gbogbo araalu maa fi oju sọri, ki wsn si mase maa wọ ọkọ ọfẹ."
Idi ni pe iwadii ọtẹlẹmuyẹ ti sisọ loju rẹ pe se ni awọn agbofinro n wọ asọ ile ẹkọ lati maa ji awọn akẹkọọ gbe.
Tawọn ọmọ naa ba si ti wọ inu mọto awọn ajinigbe yii, ni wọn yoo gbe wọn lọ sibi ti ẹnikẹni ko mọ.
"A wa n rọ awọn eeyan ti ọrọ yii gberu lati kilọ fawọn ọmọ wọn pe ki wọn ko ara wọn nijanu, ki wsn si mase wọ ọkọ ọfẹ."""
PDP Convention: Àrà ọ̀tọ̀ ní ìdìbò 'convention' tọ̀tẹ̀ yí, òru mọ́jú la ti yanjú
Bobrisky: Ayé lèmi fẹ́ jẹ kí n tó sọ̀rọ̀ ọ̀run, má ṣe wàhálà wàásù fún mi nípa ọ̀run
Oríṣun àwòrán, Bobrisky/facebook
Okunẹyẹ Idris Ọlanrewaju ti ọpọ eeyan mọ si Bobrisky, ti ke si gbogbo awọn to n waasu ijọba ọrun fun un pe ki wọn lọ simẹdọ nitoripe oun ti gboju kuro ni ohunkohun to nii ṣe pẹlu ọrun.
Ẹyin naa kọ haa!
Bobrisky ṣalaye lori awọn ikanni rẹ loju opo ayelujara pe, ki gbogbo awọn to n waasu fun oun pe ki oun yi igbe aye oun pada o lọ wa ọrọ mii sọ nitori pe lọwọ ti oun wa bayii, 'aye laa jẹ ka to ṣọrun' loun gbe dani o.
O ni ki wọn jẹ ki oun jẹ igbadun aye yii na ki wọn to maa sọrọ ọrun.
Oríṣun àwòrán, Facebook/Bobrisky
Maa wulẹ damu ara rẹ lati waasu fun arabinrin yii, Emi ti yọ ọwọ mi kuro ninu ohun gbogbo to niiṣe pẹlu irinajo ọrun.
Eyi ni ohun ti Bobrisky kọ soju opo ayelujara Facebook rẹ pe aye loun kọkọ fẹ jẹ na o ki oun to maa sọrọ ọrun.
Ikede yii si lo jẹ iyalẹnu fun ọpọ awọ̀n ololufẹ Bobrisky, ti wọn si n tọr aforijin fun, ti ọpọ wọn si n tubọ waasu fun nipa ọrun rere.
Gómìnà díbọ́n bíi aláìsàn lọ ṣèwádí aṣemáṣe àwọn òṣìṣẹ́ iléèwòsàn, ọ̀rọ̀ kọ sísọ
Oríṣun àwòrán, Meru FM 88.3 Official/Facebook
Gomina ipinlẹ kan to fi aṣiri ipo rẹ pamọ ls si ile iwosan kan ṣugbọn ohun to ba pade nibẹ kọja sisọ. Muthomi Njuki
Gomina ipinlẹ Tharaka Nitu, Arakunrin Muthomi Njuki ṣe abẹwo si ileewosan kan. Ko fẹ ki wọn mọ pe oun lẹni to wa bẹ wọn wo lo mu ki Muthomi wọ aṣọ agbojo kan pẹlu ibomu ati fila eleyi ti yoo mu ko ṣoro fun ẹnikẹni lati daa mọ.
Gbogbo awọn to wa nile iwosan naa ni ko da gomina agbegbe naa to wa bẹ wọn wo mọ, ṣe awọn agba bọ wọn ni irinisi ni isọnilọjọ.
Eredi igbesẹ gomina Muthomi Njuki ni lati tu aṣiri ihuwasi awọn dokita ati nọọsi ileewosan si iṣẹ ti wọn n gba owo oṣu fun.
Iroyin sọ pe, oniruuru ẹhonu ati iwe ifisun lawọn araalu ti kọ sii lori ohun ti oju wọn n ri nigba ti wọn ba lọ si ile iwosan.
Ọpọ awọn araalu ni agbegbe naa niwọn n fi apa janu pe nigbakugba ti awọn ba ti lọ si ileewosan naa lo maa n gba awọn dokita ati nọọsi ibẹ lọpọ akoko ki wọn to da awọn lohun.
Kiki Osinbajo: T;o bá yá owó lọ́wọ́ ẹnikẹ́ni, máa gbìyànjú láti da padà
Bakan naa ni wọn tun n kerora pe wọn tun lee ma da awọn lohun, ki wọn ni ki awọn lọ pada lọjọ miran.
Ibi aye awọn to wa fun iwosan ni gomina Muthomi joko si fun ọpọlọpọ akoko, nibi to ti n wo iṣesi awọn dokita ati nọọsi ileewosan naa.
Nigba to pẹ, lo dide to si yọ gbogbo ohun to wọ fi bo aṣiri idanimọ rẹ kuro.
O da wọn lẹkọ lori ihuwasi iṣẹ ẹni, to si gba wọn nimọran pe ki wọn rii daju pe wọn n ṣe iṣẹ ti wọn n gbowo oṣu fun pẹlu ibẹru Ọlọrun.
Oríṣun àwòrán, Meru FM 88.3 Official/Facebook
Yinka Odumakin kò parẹ́ :Lẹyìn oṣù kẹfà tó dágbére fáyé ìyàwó rẹ bí ìbejì
Oríṣun àwòrán, @DrJoeOdumakin
Iroyin ayọ leleyi fawọn ara ọrẹ ati alabaṣe mọlẹbi agbẹnusọ ẹgbẹ Afenifere to jade laye,Yinka Odumakin.
Iyawo rẹ, Joe Odumakin la gbọ pe o ti bi ibeji lantilanti ni Amẹrika.
Joe, ẹni ọdun marunlelaadọta la gbọ pe o bi awọn ọmọ yi lẹyin oṣu mẹfa ti ọkọ rẹ jadelaye.
Loju opo rẹ ni Facebook to fi ikede yi si, o ṣalaye pe alaafia ni iya awọn ikoko yi ati awọn ikẹ mejeeji naa wa.
Joe sọ pe iṣẹ iyanu ni bibi awọn ọmọ yi jẹ nitori Yinka Odumakin ti n gbẹ oungbẹ pe ki awọn bi ọmọ mi ti wọn yoo sọ ni orukọ rẹ.
Ni ọdun mejidinlogun sẹyin lawọn tọkọtaya yi bi ọmọ kẹyin ti dide awọn ibeji ọkunrin ati obinrin yi si jẹ ayọ abaratintin fun mọlẹbi wọn.
Atẹjade to fi sita ṣalaye pe ''Iroyin ayọ ni pe Joe finu ṣoyun amọ ko ribi feti gbọ iro idunnu yi nitori pe iku yọ ọwọ rẹ lawo''
''Ṣugbọn o ti sọ aṣọtẹlẹ nipa iru orukọ awọn ọmọ yi ati bi a o ti ṣe wo wọn dagba''
Ni ọjọ Kẹta oṣu Kẹrin ni Yinka Odumakin dagbere faye.
Tinubu: Ọ̀rọ̀ òṣèlú kọ́ ló gbé mi lọ sọ́dọ̀ Buhari, àbẹ̀wó lásán ni
Oríṣun àwòrán, State House
Aṣaaju ẹgbẹ oṣelu APC, Bola Ahmed Tinubu ti ṣe abẹwo si Aarẹ Muhammadu Buhari nile ijọba to wa l'Abuja.
Lẹyin ipade naa ni Tinubu sọ fun awọn akọroyin pe kii ṣe ọrọ oṣelu lo gbe oun lọ sọdọ Buhari.
Ni bayii ti eto idibo ọdun 2023 ti n sunmọle, ọpọ eeyan lo lero pe ọrọ oṣelu ni Tinubu lọ ba Buhari sọ.
Amọ nigba to n ba awọn akọroyin sọrọ lẹyin abẹwo naa, Tinubu sọ pe oun kan lọ ki Aarẹ kaabọ pada si Naijiria ni, iyẹn lẹyin to tajo de lati Saudi Arabia, nibi to ti lọ ṣe Umra.
Agba oloṣelu naa ni oun lọ dupẹ lọwọ Buhari fun bo ṣe ṣabẹwo si oun niluu London lasiko ti oun lọ gba itọju nibẹ.
"O ni ""Abẹwo mi wa lati fi ẹmi imoore han si Aarẹ fun abẹwo to ṣe si mi lẹyin iṣẹ abẹ ti mo ṣe niluu London, eyii to mu inu mi dun gidi."""
Nitori naa idi ti mo ṣe lọ ki niyẹn, ati lati kii kaabọ lati Saudi.
PDP Convention: Àrà ọ̀tọ̀ ní ìdìbò 'convention' tọ̀tẹ̀ yí, òru mọ́jú la ti yanjú
"Tinubu tẹsiwaju pe ""Kii ṣe nipa ọrọ oṣelu rara, mo kan lọ ki kaabọ ati lati dupẹ lọwọ rẹ fun ifẹ to fi han si mi ni, ko ju bẹẹ lọ."""
Ti ẹ ko ba gbagbe, Aarẹ Buhari wa lara awọn ọgọọrọ oloṣelu to lọ sabẹwo si Tinubu lasiko to lọ gba itọju niluu London.
Ṣaaju naa ni ọpọ eeyan ti kọkọ ṣakiyesi pe awọn ko kofiri Tinubu laarin ilu fun saa kan, eyii to mu ki awọn kan maa sọ pe o ti jade laye ni.
Amọ agbenusọ rẹ yara tete ke sita ninu atẹjade kan pe irọ ni iroyin naa, koko lara ọta agba oloselu naa le.
Ooni: A kìlọ̀ fún Sunday Igboho pé kó dákẹ́ àmọ́ kò gbọ́, èébú ló ń bú wa
Lizzy Anjorin: Florida ọmọ mi gbà mi tórí kò mú ìdá kan nínú àbùdá mi, ti bàbá rẹ̀ ló mú
Oríṣun àwòrán, lizzyanjorin_original/Instagram
Gbajumọ oṣere tiata Yoruba, Lizzy Anjorin ti fi esi ayẹwo baba ọmọ rẹ to ṣe sita loju opo Instagram rẹ.
Lasiko to n kede esi ayẹwo ọhun, esi naa fi han pe ọkọ rẹ, ọgbẹni Lawal ni baba ọmọ naa.
Ninu atẹjade ọhun lo ti kede ọjọ ibi ọmọ naa bii ọjọ Kinni, ọsu Kọkanla, to si tun sọ pe ọmọ naa mu DNA baba rẹ, kaka ko mu ti oun.
Lẹyin naa lo ṣe fidio kan nibi to ti sọrọ lori ayẹwo naa ati esi to ba jade, o tun fi fidio ṣe ipolowo ọja to n ta.
Ninu fidio naa ni Lizzy ti n salaye pe alaidaa ati alabosi ni ọpọ eeyan, ti wọn si ri ti oun ru oyun ọmọ oun, Florida fun osu mẹsan.
O ni oun ru kan egungun lasiko ti oun wa ninu oyun amọ oun ko mu ida kan ninu abuda ara ọun amọ o ko ida mọkandinlọgọrun ninu abuda baba rẹ.
Oríṣun àwòrán, lizzyanjorin_original/Instagram
Ṣaaju ni tọkọ-taya ọhun ti kọkọ ṣe suna ọmọ naa ni ilu mẹwaa nilẹ Amẹrika laarin oṣu Kẹfa ọdun yii.
Iyẹn lẹyin ti wọn ti kọkọ bi ọmọ naa loṣu Karun un.
Inu oṣu Keje ọdun 2020 ni tọkọ-taya naa ṣe igbeyawo nibi ti awọn mọlẹbi atawọn ọrẹ awọn mejeji peju si.
Ọpọ awọn ololufẹ Lizzy Anjorin lo ti bẹrẹ si n kii ku oriire lori ibi ọmọ naa.
Ẹwẹ, awọn eeyan kan lara awọn to n tẹle oṣere naa lori ayelujara sọ pe, ko bojumu to, bo ṣe fi esi ayẹwo naa sori ayelujara nitori ọjọ ọla ọmọ ọhun, nigba ti awọn miran fara mọ.
Seyi Makinde: Àtúntò Nàíjíríà nìkan lọ̀nà àbáyọ, kìí ṣe ìpè fún ìyapa
Seyi Makinde: Kò sí ìjà láàrin èmi àti Fayose, àjọṣepọ̀ wa gún régé
Gomina ipinlẹ Oyo, Onimọ ẹrọ Seyi Makinde ti woye pe ko yẹ ki awọn eeyan to n ja fun iyapa Naijiria ati agbekalẹ orilẹede Yoruba Nation maa tapa si ofin ilẹ wa.
Gomina Makinde woye ọrọ yii lasiko to kopa lori akanse ifọrọwanilẹnuwo kan pẹlu BBC Yoruba.
Makinde ni ọpọ awọn eeyan to n pe fun Yoruba Nation, eyi ti Oloye Sunday Igboho ko sodi, ni wọn ko ri ogun ri.
"A ko le tapa si ofin Naijiria nitori pe a fẹ fi ẹhonu han, awọn ofin wa ta gbọdọ tẹle lori awọn igbesẹ wa.
Ọpọ awọn eeyan yii, to n pe fun iyapa Naijiria ni ogun ko se oju wọn ri, o si yẹ ko ye wọn pe wọn kan le mọ ibẹrẹ ogun, wọn le ma mọ igbẹyin rẹ.
Oyo PDP Crisis: Olopoeyan ní Makinde yá PDP láti dìbò ni, àwọn kò ní gbà kó ba ẹgbẹ jẹ
Awọn baba nla wa to se idasilẹ Naijiria mọ ohun ti wọn fi sun, ori bibẹ si kọ ni oogun fun ori fifọ."
Gomina Makinde ni ọpọ awọn ajijagbara yii lo ti tan awọn eeyan jẹ to pọ nipa idi ti wọn se n pe fun iyapa Naijiria, ti ọpọ eeyan ko si mọ otitọ to wa nidi igbesẹ wọn.
O wa fi ọwọ gbaya pe ilana atunto ni a nilo lorilẹede Naijiria, nibi ti gbogbo wa yoo ti joko sọrọ nipa ọjọ ọla ati atunse ilẹ yii.
Anfaani wa fun gbogbo wa pe ka dijọ joko sọrọ papọ, ka le mọ ibi ti wahala wa ti bẹrẹ ati ọna abayọ.
Nigba to n sọrọ lori awọn igbesẹ to n gbe ti aabo to peye yoo fi wa nipinlẹ Oyo, Makinde ni oun ti fi owo to lookọ si ẹka eto aabo, to si n so eso rere.
Bakan naa lo ni ni saa isejọba oun ni oun se agbekalẹ ikọ alaabo Amotekun eyi to n sisẹ takuntakun lati pese eto aabo to mọyan lori yika ipinlẹ Oyo.
PDP Convention: Àrà ọ̀tọ̀ ní ìdìbò 'convention' tọ̀tẹ̀ yí, òru mọ́jú la ti yanjú
"O yẹ ka maa dupẹ fun ipo ti eto aabo wa nipinlẹ Oyo ni, ta ba fi we bi eto aabo se mẹhẹ lawọn agbegbe kan lorilẹede Naijiria.
Lootọ ni ipo ti ko dara ti eto aabo wa ni Naijiria n kọ ọpọ eeyan lominu amọ mo ti na owo nla lati pese eto aabo to peye yika ipinlẹ Oyo.
Mo ra ọpọ ọkọ isẹ fawọn ileesẹ agbofinro lorisi lorisi lati maa fi paraaro kaakiri ipinlẹ yii, ti ifọwọsowọpọ si wa laarin awọn ileesẹ agbofinro naa."
Gomina Seyi Makinde tun wa sọrọ nipa aayan to ti se lori eto ẹkọ, atunse oju popo yika ipinlẹ Oyo ati ipese eto ilera to yanranti fawọn eeyan ipinlẹ naa.
Seyi Makinde: Ẹ̀yin tẹ́ fẹ́ fi ọ̀rọ̀ ẹ̀sin ba Oyo jẹ́, ẹ ṣọ́ra ṣe
Seyi Makinde: Ìfẹ́ Ọlọ́run ni mo fẹ́ kò ṣẹ lórí ayé mi lórí ìbò 2023
Gomina ipinlẹ Oyo, Onimọ ẹrọ Seyi Makinde salaye pe oun setan lati pari aawọ pẹlu awọn igun PDP to n fi apa janu nipinlẹ Oyo.
Gomina Makinde kede ọrọ yii lasiko to kopa lori akanse ifọrọwanilẹnuwo kan pẹlu BBC Yoruba.
Makinde ni oun setan lati wọna abayọ sawọn ibi to ba ku si, ki aawọ le pari laarin awọn ọmọ ẹgbẹ PDP to n binu.
Lori ibasepọ rẹ pẹlu gomina tẹlẹ nipinlẹ Ekiti, Ayodele Fayose, Makinde ni ko si aawọ kankan laarin oun ati agba oselu naa.
Gomina Oyo ni awọn ọmọ ẹgbẹ kan lo maa n da aarin awọn asaaju ẹgbẹ ru nitori ohun ti wọn yoo ri jẹ nibẹ.
Nigba to n sọrọ lori boya yoo du ipo gomina fun saa keji tabi du ipo aarẹ lọdun 2023, gomina Makinde ni ifẹ Ọlọrun ni oun ko fẹ ko sẹ lori aye oun.
O ni oun sẹsẹ ba isẹ tawọn eeyan ipnlẹ Oyo gbe fun oun de idaji ni, o si di ọdun 2023 ki oun to mọ igbesẹ ti Ọlọrun fẹ ki oun gbe.
Ikoyi Collapsed Building: Bí ilé alájà mọ̀kànlélógún ṣe dà wó lulẹ̀ ní Ikoyi, l‘Eko rèé
Eeyan kan ti ku ti eeyan kan mii si farapa ninu iṣẹlẹ ile alaja mọkanlelogun kan to wo lulẹ nilu Eko.
Adugbo Gerard ni Ikoyi ni iṣẹlẹ naa ti waye.
Awọn eeyan tọrọ naa ṣoju wọn lasiko ti ile naa wo sọ fun akọroyin BBC pe, iye eeyan to wa labẹ ile naa nigba to wo fẹrẹ to ọgọrun tabi ju bẹẹ lọ.
Bi isẹlẹ naa se waye ree nilu fidio yii.
Ikoyi Collapsed Building: Òṣìṣẹ́ pajawiri ti bẹ̀rẹ̀ sí ní tú ilé tó wó lulẹ̀ láti dóòlà àwọn tó wà níbẹ
Ikoyi Collapsed Building: Bí ilé alájà mọ̀kànlélógún ṣe dà wó lulẹ̀ ní Ikoyi, l‘Eko rèé
Ileeṣẹ ọlọpaa Naijiria ti sọ pe awọn ti ri oku eeyan mẹrin gbe jade labẹ ile to wo ni Ikoyi nilu Eko.
Kọmisana ọlọpaa Hakeem Odumosu lo sọ bẹ fawọn akọroyin lasiko to ṣe abẹwo si ibi ti ile ọhun ti wo lọjọ Aje.
O ni wn si tun ribi doola ẹmi eeyan mẹta kan ninu iṣẹlẹ naa.
Amọ akọroyin BBC kan to wa nibẹ sọ pe ọkan lara awọn oṣiṣẹ alagbelebu pupa Red Cross sọ pe  oku eeyan marun un lawọn toi gbe jade.
Lọwọlọwọ bayi awọn alaṣẹ ti gbegi di ibi ti ile yi ti wo tawọn ọmọ ogun ilẹ Naijiria kan si ti duro wamu nibẹ.
Titi di asiko taa n ko iroyin yi jọ, ko si ẹni to le sọ pato nkan to mu ki ile naa wo.
Igbakeji Gomina ipinlẹ Eko Femi Hamzat to fi mọ awọn alaga ijọba ibilẹ kọọkan lerekusu Eko ti yọju sibi iṣẹlẹ yi.
Eeyan kan ti ku ti eeyan kan mii si farapa ninu iṣẹlẹ ile alaja mọkanlelogun kan to wo lulẹ nilu Eko.
Adugbo Gerard ni Ikoyi ni iṣẹlẹ naa ti waye.
Awọn eeyan tọrọ naa ṣoju wọn lasiko ti ile naa wo sọ fun akọroyin BBC pe, iye eeyan to wa labẹ ile naa nigba to wo fẹrẹ to ọgọrun tabi ju bẹẹ lọ.
Titi di asiko ti a fi n ko iroyin yii jọ, awọn oṣiṣẹ adoola ẹmi ko ti de ibi lati wa gbe awọn eeyan kuro labẹ ile naa.
Oṣiṣẹ kan to wa nibẹ sọ pe nkan bi ago kan ọsan ni ile naa wo ṣugbọn awọn ko ti ribi gbe ju eeyan meji jade.
''Wọn ti kọ ile naa lọ si oke. Awa fẹ ṣe iṣẹ soakaway ati digester ni ile naa ṣadede wo.
''Eeyan meji ni wọn ri yọ.Ọkan ku ninu wọn ẹnikeji wọn ti gbe lọ si ile iwosan''
Ni ọsan ọjọ Aje ti ṣe ọjọ Kini oṣu Kọkanla ni awọn eeyan bẹrẹ si ni fi fọnran fidio ati aworan ile to wo lulẹ naa sori ayelujara.
Ninu awọn fọnran fidio ta a ri, n ṣe ni eruku n sọ laala ti a si tun ri ti awọn eeyan n sa kuro nibi ile to wo yii.
Ko ti daju iye eeyan to padanu ẹmi wọn ninu iṣẹlẹ yi ati boya wọn n kọ ile naa lọwọ ni tabi o si jẹ ilegbe tawọn eeyan wa ninu rẹ.
Obi Cubana: EFCC gbé bàbá olówó lórí ẹ̀sùn pé ó ń gbé owó púpọ̀ rìn, tí kò sì sanwó orí
Oríṣun àwòrán, obi_cubana/Instagram
Ilumọọka olowo kan ati olokoowo, Obinna Iyiegbu, ti ọpọ eeyan mọ si Obi Cubana lo ti kawọ pọnyin ro ẹjọ niwaju awọn osisẹ ajọ EFCC lọjọ Aje.
Ẹsun ti wọn fi kan ni pe o n gbe owo tuulu kiri, bakan naa ni wọn ni o tun n sa fun owo ori ni sisan.
Ọmọ bibi ipinlẹ Anambra naa to tun jẹ alakoso ile ijo kan lo gunlẹ si ileesẹ Ajọ EFCC ni Jabi, nilu Abuja ni deede aago mejila ọsan Ọjọ Aje.
O si wa nibẹ nibi to ti n dahun ibeere tawọn osisẹ EFCC n takoto rẹ si titi di alẹ Ọjọ Aje.
Bi o tilẹ jẹ pe awọn ẹsun ti wọn fi kan baba olowo yalumọ naa ko fi bẹẹ rinlẹ, amọ ẹnikan sọ fawọn akọroyin pe gbigbe owo tuulu kiri ati aisan owo ori lawọn ẹsun ti wọn tii fi kan.
Sunday Igboho Aide: Omiyale ni DSS rọ̀jọ̀ ibọn sí Igboho, wọ́n wá pa ni àmọ́ ó bọ́
Bi o tilẹ jẹ pe ajọ EFCC ko tii jade sita wa salaye bi ọrọ naa se jẹ amọ iwadii ni lootọ ni Cubana wa ni akata EFCC.
Bẹẹ ba gbagbe, Obi Cubana yii ni ẹnu kun laipẹ yii lasiko to se isinku mama rẹ nilu Oba, nipinlẹ Anambra, to si na owo yawalu, ti aye gbọ, ti ọrun gan si mọ pẹlu.
O pa maalu to le ni igba, gẹgẹ bi iroyin ti sọ, ti ọpọ eeyan si n sọrọ nipa bi owo nla se wọlẹ sibi eto isinku naa nibi ti awọn eekanlu yika Naijiria ati loke okun peju si.
Sunday Igboho Aide: Omiyale ni DSS rọ̀jọ̀ ibọn sí Igboho, wọ́n wá pa á ni, àmọ́ ó bọ́ lọ́wọ́ wọn
Yoruba ni ẹni to yẹ ki iku pa amọ to ba si ni fila, o yẹ ko maa dupẹ ni.
Idi ree ti ọkan lara awọn alatẹle Sunday Igboho, Ọmọọba Onaolapo Ademola Omiyale fi n dupẹ lọwọ Ọlọrun pe ẹmi rẹ ko bọ lọjọ tawọn osisẹ DSS ya bo ile Sunday Igboho.
Bẹẹ ba gbagbe, ọjọ Kinni, osu Keje ọdun 2021 ni awọn DSS kọlu ile Igboho to wa ni adugbo Soka nilu Ibadan ni deede aago kan abọ oru, ti wọn si ko awọn eeyan, ba ọpọ dukia jẹ.
Nigba to n ba BBC Yoruba sọrọ lori ohun ti oju rẹ ri lọjọ naa ati ni ahamọ DSS, Omiyale ni bawọn agbofinro naa se de, ni oun ti ransẹ si iya oun pe ko fi asọ funfun sin oun.
O fikun pe oun ti n ke keu to jẹ mọ ti oku pẹlu ireti pe opin yoo de ba ẹmi oun ni alẹ ọjọ naa.
Omiyale ni awọn DSS foju kan Sunday Igboho lọjọ naa, ti wsn si da ọpọ ọta ibọn bo o amọ akọni ọmọ Yoruba nii se.
O ni awọn DSS mọọmọ wa pa Igboho lọjọ naa ni, o si yẹ ko ku amọ o papa bọ mọ wọn lọwọ.
Nigba to n salaye ohun ti oju rẹ ri ni ahamọ DSS ki wọn to gba oniduro wọn, Omiyale ni irẹsi ti ko jinna, lai si iyọ tabi ata ni awọn n jẹ.
O tun ni ọbẹ dudu to da bii ọili mọto ni wọn fi n se ọbẹ ti awọn n jẹ, bẹẹ ni otutu ikọlu DSS naa ko si ti kuro ni ara oun rara.
Kwara: Àwọn adarí iléẹ̀kọ́ wọ gàù fún gbígba owò lọ́wọ́ àwọn akẹ́kọ̀ọ́ lọ́nà àìtọ́
Oríṣun àwòrán, NUT
Ijọba ipinlẹ Kwara ti fi imu awọn adari ileẹkọ girama kan fọnrin lori ẹsun pe wọn n gba owo ti ijọba ko fi ọwọ si lọwọ awọn akẹkọọ.
Iroyin ni igbeṣẹ ijọba yii ko ṣẹyin bi awọn obi kan ṣe lọ fi ẹjọ sun ni ẹka ileeṣẹ ijọba to n risi ọrọ eto ẹkọ, Ministry of Education and Human Capital Development, ni ilu Ilorin.
Wọn fi ẹsun kan awọn adari ileẹkọ naa pe wọn n gba awọn owo to yatọ si owo PTA ti ijọba fi ọwọ si ki wọn ma a gba lọwọ awọn akẹkọọ.
Ijọba ni awọn pe awọn adari ileẹkọ naa ki wọn le wa wi tẹnu wọn lori ẹsun ti wọn fi kan wọn, ko le jẹ ẹkọ fun awọn to ku lati yee gba owo ti ko yẹ lọwọ awọn akẹkọọ.
Kọmiṣọnna fun eto Eko nipinlẹ naa, Hajia Saádatu Modibbo Kawu ni awọn ṣe ipade pajawiri pẹlu awọn adari ileẹkọ naa, paapaa awọn ti wọn tọka si pe wọn n gba owo aitọ lọwọ awọn akẹkọọ.
Olugbon Twins: Ọba Alao àti Olorì rẹ̀ bí ìbejì lẹ́yìn tí nǹkan oṣù ti dúró lẹ́ni ọdún 53
''Awọn obi kan ti wa fi ẹjọ awọn adari ileẹkọ sun pe wọn n gba owo ju owo PTA ti ijọba fọwọ si ati awọn nkan mi ti ijọba ko lọwọ si.''
Ninu ọrọ rẹ, Kawu ni ijọba ko ni dakẹ lroi iṣẹlẹ ibanilorukọ jẹ ni awọn ileẹkọ ijọba.
O fikun pe ijọba n ṣiṣẹ takun takun lati ri pe aye rọrun fun awọn obi ati awọn akẹkọọ nipa owo sisan ni awọn ileẹkọ ijọba nipinlẹ naa.
Kọmiṣọna naa ni awọn adari ileẹkọ naa fẹ doju ijọba gomina Abdulrahman Abdulrazaq bole ni ọna eto ẹkọ.
Awọn ileẹkọ ti wọn fẹsun kan naa ni UBE Ita Ayisa, UBE Olulande, United Secondary School, Taiwo Isale, United UBE, Taiwo Isale ati Oke-Aluko Junior and Senior Secondary School, in ilu Ilorin.
Awọn to ku ni UBE Ganmo, Senior Secondary School, Ganmo and Senior Secondary School, Amoyo, in ijọba ibilẹ Ifelodun ni ipinlẹ Kwara.
Sunday Igboho Aide: Omiyale ni DSS rọ̀jọ̀ ibọn sí Igboho, wọ́n wá pa ni àmọ́ ó bọ́
Yomi Fabiyi: Kò bójú mu bí ẹgbẹ́ TAMPAN ṣe dá mí dúró torí sinimá Oko Iyabo, màá pe ẹjọ́
Oríṣun àwòrán, realyomifabiyi/mrlatin1510/Instagram
Gbajumọ oserekùnrin, Yomi Fabiyi, ti ke si ẹgbẹ awọn oṣere, TAMPAN, lati pa orúkọ oun rẹ kuro ninu akọsilẹ awọn osere ti wọn fun niwe lọ rọọkun nile na tabi kuro ninu ẹgbẹ naa.
Fabiyi sọ pe oun kii ṣe ọmọ ẹgbẹ naa, nitori naa ni àṣẹ ti wọn pa ko ṣe le fidi mulẹ.
O ni oun ka lẹta kan ti wọn fi pe oun si ipade alaafia ninu oṣu Keje, sugbọn àṣírí pada tu si oun lọwọ pe nkan mii ni wọn fẹ sọ.
Oṣu Keje ni ẹgbẹ TAMPAN fi ikede sita pe awọn da Yomi Fabiyi duro, ti wọn si ni ko lọ rọọkun nile na kuro ninu ẹgbẹ ọhun.
Igbesẹ yii waye nitori sinima Oko Iyabo ti Yomi Fabiyi gbé jade, eyi ti ọpọlọpọ tọka si pe o dá lori ẹjọ ẹsun ifipabanilopọ ti oserekunrin, Baba Ijesha n jẹ lọwọ.
Yomi Fabiyi ló ni ki òun àti ìyàwó rẹ̀ yàgò fún ra wọn
Wọn ni o tako ofin ati ilana iṣẹ tiata lati lo orúkọ, akọsilẹ tabi iṣẹlẹ nipa ẹnikẹni, ninu sinima lai jẹ pe ẹni naa fi àṣẹ si i.
Yatọ si igbesẹ ẹgbẹ TAMPAN, ile ẹjọ tun pasẹ pe wọn ko gbọdọ safihan sinima naa ni ibikibi lasiko yii.
Ọgbẹni Fabiyi sọ pe ti ẹni ti kii ṣe akọṣẹmọṣẹ oṣere gan-an ba wo sinima Oko Iyabo, yoo ri pe oun ko si lara ẹni ti wọn fi ẹ̀tọ́ rẹ dùn.
O ni koda, gbogbo awọn ti wọn sọ pe oun fi sinima naa bá wi ni oun bọ̀wọ̀ fun pẹlu bi oun ko ṣe lo gbogbo orúkọ ti wọn n jẹ, aworan tabi ohùn wọn.
"O ni ""pẹlu nkan to ṣẹlẹ yii, ko buru ti mo ba sọ pe TAMPAN lo mu ki ijọba gbogun ti sinima mi, emi gan-an-gan, ati orisun ọrọ aje mi."""
Idi ni pe ọjọ kẹfa, oṣu Kẹfa, ni iṣẹ pari lori Oko Iyabo, saaju ki awọn oṣiṣẹ ile ẹjọ to o pari iyansẹlodi wọn.
O ni ti akoko ba to, oun yoo fi ilana ofin gbèjà ara oun nitori pe oun ko bẹru eniyan kankan, a fi Ọlọ́run.
Oríṣun àwòrán, realyomifabiyi/Instagram
Lori ofin ti ile ẹjọ fi de sinima naa, Oko Iyabo, Ọgbẹni Fabiyi sọ pe oun yoo tẹle ofin naa bo se yẹ.
"O sọ pe sinima oun kii ṣe nipa ẹjọ ifipabanilopọ ti Baba Ijesha n jẹ rara. "" Nitori naa, gbigbogun ti sinima Oko Iyabo ko bojumu""."
Ani Chukwuemeka: Mo ṣe fídíò láti tọrọ owó tórí àìsàn ìtọ̀ ṣúgà tó fa egbo tí kò jinná ní ìdí mi
Oríṣun àwòrán, Screen Shot
Oṣere tiata kan, Ani Chukwuemeka ti ri ẹ̀bùn miliọnu mẹfa Naira gba lati fi ṣe itọju ara rẹ.
O ti to asiko diẹ ti oserekunrin naa ti wa ni idubulẹ aisan, ko to o di pe Woli Jeremiah Fufeyin, fun ni owo naa ni ọjọ Aiku to kọja.
Fido kan ti wolii naa gbe soju opo Facebook rẹ lo se afihan igbesẹ naa, to si tun fun aya Ani ati ẹni to sin wa wa ni ẹgbẹrun lọna ẹẹdẹgbẹta naira ẹnikọkan.
Chukwuemeka, nigba to n fi idunnu rẹ han lori ẹ̀bùn owo naa sọ pe iyalẹnu lo jẹ fun oun.
O ṣalaye pe lọdun 2020 ni eto ilera oun dẹnu kọlẹ, ti wọn si ṣe iṣẹ abẹ lori egbò kan to wa ni ìdí oun nilu Owerri.
Sunday Igboho Aide: Omiyale ni DSS rọ̀jọ̀ ibọn sí Igboho, wọ́n wá pa ni àmọ́ ó bọ́
Sugbọn, nkan túbọ̀ n buru si ni, nitori pe aisan itọ ṣuga to n ṣe e, se akoba pupọ fun iwosan egbo naa.
Eyi si lo mu ko ṣe fidio kan to fi si ori ayelujara lati tọrọ owo lọwọ awọn eniyan.
Ninu fidio naa, Chukwuemeka sọ pe oju oun ti fẹ ẹ fọ́ nitori kokoro 'cataract' to ti wọ inu oju kan.
Bakan naa lo ni awọn aisan to n ṣe oun ti mu ki oun ni aisan rọpa-rọsẹ, stroke.
O wa dupẹ lọwọ wolii naa fun oju aanu to si wo ati ọwọ ọrẹ to na si ọhun.
Fidio naa ni Woli Fufeyin ri, to si pe oṣere naa si ile ijọsin rẹ lati fun lowo fun itọju ara rẹ.
Igba akọkọ kọ niyi ti Woli naa fun oṣere to n ṣàìsàn ni owo.
Oríṣun àwòrán, AFP
COP26: Àwọn olórí orílẹ̀èdè àgbáyé ṣèlérí dídẹ́kun gẹdú gígé nígbó lọ́dún 2030
Awọn olori orilẹede agbaye to le ni ọgọrun ni wọn ṣetan bayii lati dẹkun gige igi nigbo lọna kotọ.
Nigba ti a ba fi ri ọdun 2030, gẹgẹ bi ara awọn afẹnuko akọkọ to waye nibi ipade apero lori idaabobo oju ọjọ COP26 to n lọ lọwọ, ofin yii yoo ti wa si imusẹ.
Lara awọn orilẹede to wa ninu afẹnuko yii ni Brazil pẹlu ọpọlọpọ gbogbo saare igbo didi to ni.
Bakan naa ni aarẹ orilẹede Naijiria, Muhammadu Buhari pẹlu ti fi ẹnu si ọrọ naa.
Ninu ọrọ tirẹ naa to sọ nibẹ, Aarẹ Buhari ni laipẹ ti oun ba de ipo gẹgẹ bi alaga agbarijọpọ orilẹede Afirika lori idaabobo igbo didi, ilẹ Africa yoo tubọ tun tẹmpẹlẹ mọ igbesẹ lati da awọn ilẹ to ti di aṣalẹ ni Afirika pada si ipo ọlọra.
Lara awọn ẹjẹ ti awọn olori orilẹede to peju nibi ipade COP26 naa jẹ ni akojọ biliọnu mẹrinla pọun ilẹ Gẹẹsi latọwọ awọn ijọba ati aladani fun igbesẹ tuntun ọhun.
Sunday Igboho Aide: Omiyale ni DSS rọ̀jọ̀ ibọn sí Igboho, wọ́n wá pa ni àmọ́ ó bọ́
Ọpọ awọn akọṣẹmọṣẹ lo ti kan sara si igbesẹ naa, amọṣa ohun to n kọ wọn lominu ni bi irufẹ ifẹnuko bẹẹ to waye lọdun 2014 ṣe kuna lati mu adinku ba wahala igi gẹdu gige ninu igbo lọna kotọ.
"Olotu ijọba orilẹede Gẹẹsi, Boris Johnson to n gbalejo ipade naa nilu Glasgow ṣe apejuwe afẹnuko ọhun gẹgẹ bi ""adehun to lamilaaka lati daabo bo awọn igbo lorilẹ aye."
Ipade naa yoo waye fun ọsẹ meji gbako, ọpọ si rii gẹgẹ bi ohun to ṣe pataki fun mimu iṣoro aṣemaṣe oju ọjọ ati ayika wa si iyanju.
Awọn orilẹede to ti fifẹ han fun afẹnuko naa ni:
Uniabuja Abduction: : Àrá àdúgbò ní aago kan òru ní agbébọn ya wọ fásitì Abuja lọ́jọ́ Ìṣẹ́gun, wọ́n jí olùka àti akẹ́kọ̀ọ́ lọ
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Awọn agbebọn ti kọlu ilegbe awọn oṣiṣẹ fasiti ìlú Abuja, ti wọn si gbe eeyan mẹfa lọ, ni owurọ kutu ọjọ Iṣẹgun, ọjọ kejì, oṣu Kọkanla.
Awọn ara adugbo sọ pe ni nkan bi aago kan oru ni awọn agbebọn naa wọ inu ọgbà naa, ti wọn si ṣíṣẹ fun bi wakati kan.
Olukọ kan sọ fun BBC pe olukọ mẹta ati ọmọ wọn meji, to fi mọ oṣiṣẹ fasiti naa kan, ni wọn ji gbe lọ.
Kọmisana ọlọpaa nilu Abuja, Babaji Sunday fi idi iṣẹlẹ naa mulẹ ninu atẹjade to fi sita.
O ni awọn ọdaran naa kọlu ibi ti awọn oṣiṣẹ UNIABUJA n gbe ni agbegbe Giri, ni ijọba ibilẹ Gwagwalada nilu Abuja, ti wọn si ji eeyan mẹfa gbe lọ.
Sunday Igboho Aide: Omiyale ni DSS rọ̀jọ̀ ibọn sí Igboho, wọ́n wá pa ni àmọ́ ó bọ́
Ọgbẹni Sunday sọ pe awọn agbebọn naa salọ ni kete ti wọn gburo àwọn oṣiṣẹ eleto aabo to jẹ apapọ àwọn ọmọ ologun ati ọlọpaa to lọ sibẹ lati daabo bo àwọn araalu.
Bakan naa lo sọ pe awọn oṣiṣẹ alaabo ti n sisẹ pẹlu ara ilu, lati le doola awọn eeyan ti wọn ko lọ.
Ẹ̀wẹ̀, agbenusọ fasiti naa, Habib Yakoob sọ pe awọn ko ti le fidi orúkọ awọn ti wọn ji gbe mulẹ.
Attack on Akintoye house: Ẹgbẹ́ ọmọ Yorùbá ní kí Buhari yé dúnkokò mọ́ Igboho, Akintoye àti Kanu
Agbarijọpọ ẹgbẹ ọmọ Yoruba to n pe fun iyapa iran Yoruba lara Naijiria, ti kilọ fun Aarẹ Muhammadu Buhari pe ko jawọ lọrọ Sunday Igboho, Nnamdi Kanu ati Ọjọgbọn Banji Akintoye, ti wọn n pe fun iyapa lara orilẹ-ede Naijiria.
Ẹgbẹ Yoruba ni didunkoko mọ awọn mẹtẹẹta ko ni fopin si ipe fun iyapa lara orilẹ-ede Naijiria.
Ẹgbẹ naa fi idi ọrọ yii mulẹ ninu atẹjade ti akọwe ẹgbẹ ọhun, Ọmọwe Steve Abioye fi sita.
Ẹgbẹ agbarijọpọ ọmọ Yoruba to n pe fun iyapa naa wa fi aidunnu rẹ han si ikọlu tawọn agbebọn ṣe si ile Ọjọgbọn Akintoye niluu Ado-Ekiti.
"Ẹgbẹ naa ni ""ẹni iyi ni Ọjọgbọn Akintoye jẹ, o si ti kopa ribiribi ninu idasoke awujọ, ilẹ Yoruba ati orilẹ-ede Naijiria lapapọ ki o bẹrẹ si ni fun iyapa iran Yoruba lara Naijiria."
Akintoye bẹrẹ si ni pe fun iyapa lara Naijiria lẹyin ti awọn eeyan apa ariwa Naijiria ko faramọ atunto iṣejọba Naijiria.
Mesach Oyediran: Ọba ni Dafidi tó ń lu dùùrù, tó sì kọ sáàmù, ta ni èmi tí kò ní le yin
Fun idi eyi, a n kepe ijọba apapọ lati ṣe iwadii ikọlu si kọ ile Ọjọgbọn Akintoye niluu Ado-Ekiti ati pe ki ijọba fi awọn ọdaran to ṣiṣẹ ibi jofin.
Eyi ni yoo jẹ k'awọn ọmọ Naijiria le mọ pe ijọba ko lo wa nidi ọrọ naa.
Ohun kan to le mu opin ba ipe fun iyapa lara Naijiria ni ki Buhari ṣeto lati da Naijiria pada si iwe ofin ilẹ wa ọdun 1966  to fun ẹkun kọọkan lagbara lati da wa.
Ọna miran ni pe ijọba Buhari ni lati ṣe agbeyẹwo abọ apero ọmọ Naijiria to waye lasiko ijọba Aarẹ ana, Goodluck Jonathan.
Ijọba Buhari gbọdọ mọ pe igbesẹ lati pa Igboho, Kanu ati Ọjọgbọn Akintoye kọ ni ọna lati dẹkun ipe fun iyapa lara orilẹ-ede Naijiria.
"Koda, awọn eeyan mii yoo tun dide yatọ sí Igboho, Kanu ati Akintoye  ayafi ti ijọba ba gba lati ṣe atunto Naijiria loku."""
Ileesẹ ọlọpa ipinlẹ Ekiti lo ti mu ike ọta ibọn AK47 ti wọn ri nile adari ẹgbẹ Ilana ọmọ Oodua, Ọjọgbọn Banji Akintoye, lẹyin ti awọn agbebọn ti a ko mọ ẹyẹ to ṣu wọn, ṣabẹwo si ile rẹ ni Satide to kọja.
Ọlọdẹ to n ṣọ ile naa, Mudasiru Olanrewaju, sọ fun BBC News Yoruba nilu Ado Ekiti pe awọn ọlọpa lo mu ọta naa lakoko ti wọn ṣe abẹwo si ile naa lẹyin awuyewuye to waye lori iṣẹlẹ ọun.
Olanrewaju ṣalaye pe awọn agbebọn ti oun ko ri ṣabẹwo si ile alagba Banji Akintoye, ẹni to ti le ni ọgọrin ọdun, to wa lagbegbe Similoluwa nilu Ado Ekiti, ni aago mẹfa kọja iṣẹju diẹ laarọ ọjọ Satide.
O ni awọn janduju naa lo da ibọn bo orule ati ogiri yara oun to wa lẹgbẹ fẹnsi ile naa, nibiti wọn gba wọ inu ọgba.
O ni oun ko ri ẹnikẹni nigba ti ohun jade amọ oun ri ike ọta ibọn nilẹ ati tabili kan ti o bajẹ  lẹyin wakati diẹ tohun fẹẹ lo wẹ
Sunday Igboho Herbalist: Agbófinró mẹ́fà ló wọ́lé wá gbé ọmọ mi láì mọ́ ibi tó wà
O wipe lọgan lohun fi iṣẹlẹ naa to olori alaabo adugbo naa, Omotayo Olatunji, leti to si pe awọn ọlọpa.
Olanrewaju fikun pe awọn ọlọpa wa lọjọ naa ti wọn si tun pada wa lọjọru, ti wọn fi gba ike ọta ibọn naa lọ.
Ọga awọn ẹṣọ agbegbe ọhun, Olatunji, nigba to n ba BBC Yoruba sọrọ wipe igba akọkọ niyi ti irufẹ iṣẹlẹ naa yoo ṣẹ ni agbeegbe naa.
O fikun pe awọn agbaagba lagbegbe naa ti forikori lori bi eto aabo yoo ṣe nipọn sii lagbeegbe naa.
Alakoso fun ẹgbẹ Ilana ọmọ Oodua nipinlẹ Ekiti, Alufa Praise Ayodele wa bu ẹnu atẹ lu iṣẹlẹ ikọlu naa, o si rọ ileesẹ ọlọpa lati tu iṣu ọrọ naa de isalẹ ikoko.
Alukoro fun ileesẹ ọlọpa nipinlẹ Ekiti, Sunday Abutu, ni iṣẹlẹ ọhun ni awọn akọroyin ti pariwo rẹ ju bo ṣe yẹ lọ tori pe kii ṣe ikọlu bi wọn ṣe wi.
Abutu ṣee lalaye pe ileesẹ ọlọpa ti mu ike ọta ibọn ti wọn ri nibẹ fun ayẹwo to peye lati le ṣiṣọ loju eegun ọrọ naa.
Bo tilẹ jẹ pe oju ọta ṣi wa lara ile alagba Akintoye ti a ko si tii mọ awọn to ṣe iṣẹ naa, alaafia lo ti pada jọba lagbegbe ọun.
Oríṣun àwòrán, Banji Akintoye
Ẹgbẹ Ilana Omo Oodua to n pe fun iyapa orile-ede Yoruba lara Naijiria ti kede pe awọn agbebọn kan  kọlu ile adari ẹgbẹ naa, Ọjọgbọn Banji Akintoye to wa niluu Ado-Ekiti.
Alukoro ẹgbẹ naa, Maxwell Adeleye ṣalaye ninu atẹjade to fi sita pe ọjọ Abamẹta, Ọgbọnjọ oṣu Kẹwaa ọdun 2021 ni iṣẹlẹ ọhun waye.
Adeleye sọ pe awọn agbebọn naa gun ori aga to wa ni iwaju ile Akintoye ti wọn sì bẹrẹ sí ní yinbọn mọ geeti ile naa.
Amọ, Ọjọgbọn Akintoye ko sì nile lasiko ikọlu naa ko sí si ẹni tó farapa nibi iṣẹlẹ ọhun.
Alukoro ẹgbẹ Ilana Omo Oodua ni ọta ibọn ti o ṣeeṣe ki o jẹ AK-47 wa nilẹ ninu ile Ọjọgbọn Akintoye.
Oríṣun àwòrán, ẹgbẹ Ilana Omo Oodua
O ni ileeṣẹ ọlọpaa ipinlẹ Ekiti ti bẹrẹ iwadii lori iṣẹlẹ naa.
Bí Oduduwa Republic bá bẹ̀rẹ̀, a ò ní ṣe aburú fún àwọn tó takò wá, ìlànà ààtẹ̀lé rèé - Banji Akintoye
Ọmọbibi ilu Ado-Ekiti ni Akintoye n ṣe.
Ọjọgbọn Akintoye ṣoju ipinlẹ Ondo atijọ gẹgẹ bí sẹnẹtọ laarin ọdun 1979 sí 1983 nigba ijọba Ààrẹ Shehu Shagari.
Akintoye lo n ṣe agbatẹru ipe fún iyapa iran Yoruba kuro lara Naijiria.
Salawa Abeni: Mi ò mọ̀ pé mo lè di ọgọ́ta ọdún láyé pẹlú àìlera mi
Oríṣun àwòrán, officialsalawaabeni/Instagram
Ẹni ọdun ba laye, o yẹ ko ṣọpẹ fún Eleduwa fun idasi ati abo rẹ.
Eyi gan an ló jẹ ki gbajugbaja Olorin Waka, Queen Salawa Abeni dupẹ lọwọ Ọba Oke to da a sì di ẹni ọgọta ọdun loke eepẹ.
Ọjọ kẹrinlelogun oṣu kẹwaa ọdun 2021 yii ni awọn Salawa dawọọ ọjọ ibi ọgọta ọdun fun ùn ni ile itura Oriental niluu Eko  eleyii ti ko mọ nipa rẹ titi di ọjọ naa.
Salawa Abeni, lasiko to n ba iwe iroyin City People sọrọ, o ni sọ pe o ku diẹ ki oun daku lẹyin ti oun ri ero biba ninu gbọngan tawọn ọmọ rẹ ti ṣeto kalẹ ni ile itura naa nibi ti alejo to to ẹẹdẹgbẹrin ti joko.
"Ti ko ba jẹ pe awọn kan dì mi mu lapa ọtun ati osi ni, ko si ọgbọn rẹ, n ko ba daku.
Olugbon Twins: Ọba Alao àti Olorì rẹ̀ bí ìbejì lẹ́yìn tí nǹkan oṣù ti dúró lẹ́ni ọdún 53
Mí o le gbagbọ ohun ti mo ri, mi o lero pe awọn ọmọ mi le ṣe iru nkan bayii ti n ko sí ni mọ.
Ọrọ naa dabi iditẹ gbajoba awọn ologun ni, ọpọ to sun mọ mi lo mọ nipa rẹ ṣugbọn wọn ko sọ fun mi.
Àmọ́, inu mi dun, ayọ mi kun, mi o tiẹ le ṣalaye bi inu ṣe dun to lọjọ naa.
Ṣugbọn mo dupẹ lọwọ Ọlọrun ati gbogbo eeyan to gbimọ pọ pẹlú awọn ọmọ mi lati ṣe ayẹyẹ yii fún mi.
Mí o mọ pe awọn eeyan si tun ni ifẹ mi bayii.
Iyalẹnu nla lo jẹ fun mi nigba ti ọmọbinrin mi n ṣalaye awọn to fi owo ranṣẹ sí oun fun ayẹyẹ ọjọ ibi ọgọta ọdun mi.
O sọ fun mi pe lori foonu mi loun ti ri nọmba ọpọ ọrẹ mi ti oun sí bẹrẹ sí ni mura fun ayẹyẹ naa, Salawa lo sọ bẹẹ."
"Queen Salawa ni ""lasiko awẹ Ramadan loṣu karun ùn gan an ni ọjọ ibi mi ti mo pe ọgọta ọdun laye."
Amọ, mi o le ṣe ayẹyẹ naa tori awẹ to wà nita.
Kiki Osinbajo: T;o bá yá owó lọ́wọ́ ẹnikẹ́ni, máa gbìyànjú láti da padà
Ṣugbọn lati aago mejila oru ọjọ ti mo pe ọgọta ọdun yìí ni mo yi nilẹ titi di aago mẹrin aarọ ti mo n dupẹ lọwọ Ọlọrun.
"Mí o mọ pe mo lè di ọgọta ọdun laye pẹlu gbogbo nkan ti mo ti la kọja laye."""
Lori bo ya o si maa tẹsiwaju ninu orin kikọ lẹyin to pe ọgọta ọdun laye, Salawa ni oun si maa kọ ọrin lọ ni o.
O ni niwọn igba to jẹ pe awọn agbaagba ninu iṣẹ orin kikọ bi Ebenezer Obey, King Sunny Ade ati Alhaji Kollington Ayinla ko tii fẹyin ti ninu orin kikọ.
"Mo mọ ibi ti ori n gbe mi lọ, mo sí mọ pe Eledumare maa mu mi de ibẹ.
Ẹnikẹni to ba maa dé ibi gíga laye, waa ni ipenija iṣubu ṣugbọn wa a tun dide pada.
Ooni: A kìlọ̀ fún Sunday Igboho pé kó dákẹ́ àmọ́ kò gbọ́, èébú ló ń bú wa
Bi ọrọ mi ṣe rí niyẹn, eyi dẹ ni mo gbagbọ pẹlu ọrọ aye mi, Queen Salawa lo ṣalaye bẹẹ."
Olugbon Twins: Ọba Alao àti Olorì rẹ̀ bí ìbejì lẹ́yìn tí nǹkan oṣù ti dúró lẹ́ni ọdún 53
Aramonda ni isẹ Oluwa, awamaridi si ni pẹlu nitori oun lo le se ohunkohun ti ẹda kan ko le se.
Ọna ara yii naa ni Ọba oke fi ta Olugbon tile Igbon, Ọba Francis Alao ati Olori rẹ, Ayaba Olusola Adedoyin Alao lọrẹ ibeji lanti lanti.
Olori, tii se ẹni ọdun mẹtalelaadọta lo ni oun ti ni arun jẹjẹrẹ tẹlẹ amọ ti Ọlọrun wo oun san, ti oun ko si lero pe o seese ki oun tun loyun pada lẹyin ti nnkan osu ti duro.
Olori naa, ti oun ati Olugbon ti se igbeyawo lati ọdun mejidinlogun amọ ti ikọọkan wọn ti ni ọmọ tẹlẹ ni igbeyawo ti wọn ti se saaju, lo ti n woju Ọlọrun fun ọmọ.
Lasiko ti wsn n ba BBC Yoruba sọrọ, Olugbọn ati Olori rẹ ni kii se ọna atọwọda ni awọn ibeji naa gba wa sile aye nitori o ya awọn naa lẹnu pe Olori loyun pẹlu ọjọ ori rẹ ati ipo ti ilera rẹ wa.
Wọn wa salaye bi irinajo naa se lọ, titi ti wọn fi bi awọn ọmọ naa ati oore ọfẹ Ọlọrun lori aye wọn.
"Ire Poly Student: Akẹ́kọ̀ọ́ Poly kú l'Osun ""lẹ́yìn tó ti ilé ọ̀rẹ́kùnrin rẹ̀ dé"
Oríṣun àwòrán, Osunpoly
Iroyin to tẹ wa lọwọ lati ipinlẹ Osun sọ pe akẹkọọbinrin kan nile ẹkọ gíga gbogbonṣe to wa ni ilu Iree ti dero ọrun, lẹyin to ṣe abẹwo sí ile ọrẹkunrin rẹ.
Akẹkọọ naa ti wọn pe orukọ ni Wumi, ni a gbọ pe o bẹrẹ si ni pọ ẹjẹ ati itọ lẹnu lẹyin to pada de lati ile ọrẹkunrin rẹ.
Iroyin sọ pe wọn gbe akẹkọọ naa digba digba lọ si ile iwosan to wa nitosi amọ ile iwosan ko gba a nigba ti wọn ri bi o ṣe n ṣe.
Wumi ni a gbọ wí pe o jẹ Ọlọrun nipe ni irọlẹ ọjọ Abamẹta to kọja, ki wọn to gbe e dé ile iwosan mii.
Agbẹnusọ ile ẹkọ giga gbogbonṣe ilu Iree, Tope Abiola to fidi iṣẹlẹ ọhun múlẹ ṣalaye pe ọrẹkunrin akẹkọọ naa kii ṣe ọmọ ile ẹkọ ọhun.
Olugbon Twins: Ọba Alao àti Olorì rẹ̀ bí ìbejì lẹ́yìn tí nǹkan oṣù ti dúró lẹ́ni ọdún 53
Ọgbẹni Abiola ṣalaye pe ko sí ẹni to mọ ohun to ṣe okunfa iku ọmọbinrin naa titi di akoko yii.
O ni ileeṣẹ ọlọpaa si n ṣe iwadii lori iṣẹlẹ naa.
Ọgbẹni Abiola ni ipele akọkọ (ND 1) ni akẹkọọ naa wa nibi to ti n kẹkọọ nipa iṣẹ akọroyin.
Ṣugbọn akẹkọọ kan to ba awọn akọroyin sọrọ fidi rẹ múlẹ pe ọmọ ile ẹkọ naa ni ọrẹkunrin rẹ n ṣe.
Akẹkọọ ọhun fikun ọrọ rẹ pé awọn ọlọpaa ti mu ọrẹkunkunrin Wumi lẹyin iku rẹ.
O ni wọn ti gbe oku Wumi lọ sí mọṣuari niluu Ikirun bayii.
Ẹwẹ, agbẹnusọ ileeṣẹ ọlọpaa ipinlẹ Osun, Yemisi Opalola ni iwadii ti bẹrẹ lori iṣẹlẹ naa.
Sunday Igboho Aide: Omiyale ni DSS rọ̀jọ̀ ibọn sí Igboho, wọ́n wá pa ni àmọ́ ó bọ́
Bank Fraud: Ọ̀gá báńkì rí ẹ̀wọ̀n ọdún 18 he lórí jìbìtì N219m owó oníbàárà
Oríṣun àwòrán, Getty Images
A se ẹni ti a gboju oku le, ko jọ ẹni agba, abi ki ni ka ti pe ẹni ti a fẹtin ti, to fi ẹgun sọwọ, ẹni ta ni ko fẹ ni loju, to fi ata sẹnu.
Ọga banki tẹlẹ kan ree, Olìver Anidiobi, to ti di ero ẹwọn lori pe o lu awọn onibaara ni jibiti okolerugba o din ẹyọ kan miliọnu naira, N219m.
Anidiobi, ti ajọ EFCC gbe lọ sile ẹjọ ni adajọ C.O. Ajah, dajọ ẹwọn ọdun mejidinlogun fun niluu Enugu lori ẹsun ole jija ati yiyi iwe owo.
Ajọ EFCC to jẹ olupẹjọ gbe Anidiobi lọ ile ẹjọ lọjọ keje oṣu karun ùn ọdun 2019 lori ẹsun pe o lo ipo rẹ, lati ri pe banki olokoowo kekeke OHHA kan san N219m ni orukọ rẹ.
Wọn ní Anidiobi gbe owo naa sí asunwọn ikowosi ọlọjọ pipẹ (fixed deposit account) ṣugbọn o lu jibiti owo naa lati lo o fun ra rẹ.
Olugbon Twins: Ọba Alao àti Olorì rẹ̀ bí ìbejì lẹ́yìn tí nǹkan oṣù ti dúró lẹ́ni ọdún 53
Ile ẹjọ fidi rẹ múlẹ pe, ọga banki naa kọ ile marun un, o sí tun ra ọpọ ilẹ si ọna mọrosẹ ilu Enugu si Port Harcourt.
Bakan naa ni wọn ní ọga banki tẹlẹ ọhun tun n kọ ile mii lọwọ niluu Enugu.
"Ile ẹjọ tun fidi rẹ múlẹ pe o tun fi N65m ṣe owo s'ogun dogoji ti wọn pe ni ""Let's Partner with You"" ti ọkunrin kan ti wọn pe ni Patrick Nwokike jẹ alakoso rẹ."
Adájọ Ajah sọ pe Anidiobi kó tako ajọ EFCC lori gbogbo ẹsun ti o fi kan an.
"Adájọ ni ""o túmọ si pe otitọ ni gbogbo ẹsun ti wọn fi kan Anidiobi tori ko ri ariwisi kankan si ẹsun ti wọn fi kan an."
"Awọn ẹri ti EFCC mu wa sile ẹjọ fidi múlẹ to lati dajọ."""
Bayii ni ile ẹjọ ṣe dajọ ẹwọn ọdun mejidinlogun fun Anidiobi.
Adajọ tun pàṣẹ pe ki wọn lọ tá gbogbo dukia ti Anidiobi fi owo naa ra, ki wọn sì da owo ti wọn ba ri níbẹ pada fun banki olokowo kekeke OHHA.
'Mi ò yàtọ sí Krìstẹni tàbí Mùsùlùmí tóun náà da ẹsìn rẹ pọ mọ jíjẹ Dokita, Babaláwo Dókítà l'èmi'
Poly Ibadan Stray Bullet: Àwọn aláṣẹ ilé ẹ̀kọ́ Poly ṣàlàyé bí ìbọn ṣe bá akẹ́kọ̀ọ́
Oríṣun àwòrán, Screen Shot
Rogbodiyan bẹ silẹ nile ẹkọ giga gbogboniṣe Poly Ibadan l'ọjọ Iṣẹgun lẹyin ti aṣita ibọn ba akẹkọọ kan ninu ọgba ile ẹkọ naa.
Akẹkọọ naa ti wọn pe orukọ rẹ ni Babatunde Taibat to n bẹ ni ipele akọkọ, ND1, ni ẹka ti wọn ti wọn ti n kọ nipa ṣiṣe amulo ẹrọ igbalode fun imọ sayẹnsi, ni a gbọ pe aṣita ibọn ba lasiko ti awọn ẹṣọ abo n lepa awọn ọdaran kan ninu ọgba ile ẹkọ naa.
Digbadigba ni wọn gbe akẹkọbinrin naa lọ si ile iwosan ẹkọṣẹ imọ iṣegun Oyinbo, UCH nilu Ibadan, nibi ti o ti n gba itọju bayii.
Ọkan lara awọn akẹgbẹ akẹkọọ naa ti o ba akọrin wa sọrọ, Adekọla Adewale ṣalaye wi pe ni nnkan bi aago mẹrin abọ irọlẹ ni iṣẹlẹ naa waye.
O ni awọn akẹkọọ naa wa ninu gbọngan nla kan ti wọn ti gba idanilẹkọ laarin aago mẹta ọsan si mẹrin abọ irọlẹ.
Oríṣun àwòrán, Screen Shot
Bo tilẹ jẹ pe awọn alakoso ile ẹkọ giga naa ko ti i fi idi ọrọ mulẹ lori ẹni to yin ibọn naa, alaye ti wọn ṣe fun awọn oniroyin ni pe iṣẹ iwadii n lọ lọwọ lori iṣẹlẹ naa.
Ninu atẹjade kan ti wọn fi lede, igbimọ to n ṣe akoso ile ẹkọ giga naa ṣalaye pe ẹmi akẹkọbinrin naa ko ba iṣẹlẹ ọhun lọ, bẹẹ si ni o ti n gba itọju bayii.
Bakan naa ni alamojuto feto igbaniwọle nilẹ ẹkọ giga naa, Arabinrin Modupẹ Fawale pa arọwa si awọn akẹkọọ lati mase foya nitori iṣẹ iwadii ti bẹrẹ ni pẹrẹu lori ohun ti o ṣokunfa ibọn ti wọn yin ninu ọgba ile ẹkọ naa.
Ninu ọrọ tiẹ, alukoro ile ẹkọ giga naa, Arakunrin Adewole Ṣoladoye fi idi ọrọ mulẹ pe lootọ ni aṣita ibọn ba akẹkọọ kan, ti wọn si ti gbe lọ si ile iwosan UCH  fun itọju bayii.
Olugbon Twins: Ọba Alao àti Olorì rẹ̀ bí ìbejì lẹ́yìn tí nǹkan oṣù ti dúró lẹ́ni ọdún 53
O fi kun ọrọ rẹ pe, Giwa agba ile ẹkọ naa, Ọjọgbọn Kareem Adekunle lo gbe owo silẹ fun itọju akẹkọbinrin naa, ṣugbọn o ja niyan pe awọn ọkan lara awọn ẹṣọ aabo to n bẹ ninu ọgba ile ẹkọ naa lo yinbọn.
Adekunle salaye pe iṣẹ iwadii naa ṣi n lọ lọwọ lati ṣe awari ẹni to yin ibọn naa.
Gomina babajide Sanwo-Olu ti ṣe abẹwo si ibudo ile ọlọpọ aja to wo lagbegbe Ikoyi ni ilu Eko
Nigeria Security: Ọwọ́ Amotekun tẹ ọ̀dọ́kùnrin 18 tó rìn gbéregbère wọ Akure láti òkè ọya Nàìjíríà
Oríṣun àwòrán, Amotekun
Awọn eeyan mejidinlogun lati apa ariwa orilẹede Naijiria  lawọn oṣiṣẹ agbofinro Amọtẹkun ni ipinlẹ Ondo ti mu bayii.
Wọn ni wọn wọ ipinlẹ naa lai mọ ẹnikẹni tabi ni iṣẹ kan pato ti wọn fẹ wa ṣe nibẹ.
Ajọ agbofinro Amọtẹkun ni ipinlẹ Ondo ṣalaye pe ewu nla ni wọn jẹ fun eto abo ipinlẹ naa.
Agbegbe opopona marosẹ Ileṣa si Akurẹ ni wọn ti kọkọ kẹẹfin wọn ti wọn si fi ara wọn pamọ sẹyin awọn apo ẹwa ni inu ọkọ akẹru kan leyi ti awọn oṣiṣẹ Amọtẹkun si ts ipasẹ wọn de agbegbe Arakalẹ ni ilu Akurẹ.
Oríṣun àwòrán, dailypost
Ninu ọrọ to ba BBC News Yoruba sọ, Oludari agba fajọ agbofinro Amọtẹkun ni ipinlẹ Ondo, Oloye Adetunji Adelẹyẹ ṣalaye pe nigba ti wọn fi ọrọ wa wọn lẹnuwo, awọn ọdọ naa ṣalaye pe eeyan kan lo fi awọn si ọkọ wa si ilu Akurẹ.
Wọn ni ẹni naa sọ fun awọn pe bi wọn ba ti de Akurẹ, wọn yoo ri ẹni ti wọn fẹ lọ ba, ti yoo si sọ nnkan ti wọn fẹ lọ ṣe fun awọn, eyi lo mu ki awọn tubọ fura si irinajo wọn.
Oloye Adeleẹyẹ fi kun pe Amọtẹkun ti fa wọn le awọn adari ẹgbẹ Miyetti Allah lọwọ wọn si ti da wọn pada si apa oke Ọya orilẹede Naijiria ti wọn ti wa.
Ikoyi Collapsed Building: Mọ̀ sì nípa Femi Osibona tó ni ilé alájà 21 tó wó ní Ikoyi
Oríṣun àwòrán, Femi Osibona
Oriṣiiriṣii iroyin lo ti lu ori ayelujara pa lori Ọgbẹni Femi Osibona, akọleta to ni ile alaja mọkanlelogun to da wo ni Ikoyi niluu Eko lọsan an ọjọ Aje.
Ọjọ Kinni osu Kọkanla ọdun 2021 ni isẹlẹ ile to da wo naa waye lopopona Gerrard, Ikoyi-Lagos Island nilu Eko
Ẹni to kọ ile yii naa si n se ipade lọwọ pẹlu awọn eeyan kan ni, nigba ti ile naa da wo lulẹ, ti ọpọ eeyan si ha si abẹ rẹ, to fi mọ awn alejo ati awọn lebira to n kọ ile naa.
Femi Osibona gan an fun ra rẹ si wa labẹ awoku ilé to wo naa, ti ẹnikan ko sí mọ boya o si wa laaye tabi o tí jẹ Ọlọrun nipe.
Awọn mii tiẹ sọ pe awọn ọlọpaa ti gbe ọkunrin naa lẹyin ijamba ile to n kọ to wó lu awọn eeyan mọlẹ naa.
Ikoyi Collapsed Building: Bí ilé alájà mọ̀kànlélógún ṣe dà wó lulẹ̀ ní Ikoyi, l‘Eko rèé
Femi Osibona jẹ ẹni aadọta ọdun to wa lati ilu Ikenne to si kawe gboye fasiti loke okun.
Ọgbẹni Femi Osibona ni ọga agba ileeṣẹ akọleta Fourscore Homes Limited to n kọ ile alaja mọkanlelogun to wó ni opopona Gerrard ni Ikoyi niluu Eko.
Osibona jẹ ọmọ ẹgbẹ awọn akọleta, NHBRC(National Home Builders Registration Council) ni orilẹ-ede South Africa.
Bakan naa lo jẹ ọmọ ẹgbẹ Zurich Building Guarantee nilẹ Yuroopu.
Ilu Eko ni Osibona ti lọ sí ilé ẹkọ akọbẹrẹ.
Bakan naa ni o lọ sí ilé ẹkọ girama Mayflower Secondary School niluu Ikenne nipinlẹ Ogun, ki o to lọ sí oke okun lati tẹsiwaju ẹkọ rẹ.
Osibona kawe gboye ninu ẹkọ iṣowo ati eto inawo ni fasiti Croydon ni UK.
Ọdun 1997 ni Osibona bẹrẹ owo akọleta ati ilẹ rira ni Hackney niluu London.
Lẹyin naa ni ileeṣẹ ọhun ni ẹka lorilẹede South Africa ati Naijiria, ti wọn si bẹrẹ sí ní kọ ile nla nla kaakiri agbaye.
Lọdun 2009 ti Ajagunfẹyinti Brig-Gen Buba Marwa jẹ aṣoju ijọba Naijiria ni South Africa, ileeṣẹ Osibona, Fourscore Homes kọ ile awodamiẹnu mẹfa ti wọn n pe ni Fourscore Mansions ni Waterkloof ni Pretoria.
Osibona ni akọleta ọmọ ilẹ Afirika akọkọ to kọ ile alaja meje lorilẹ ede UK.
Ile naa ni wọn pe ni Fourscore Mansion to wa ni 113, Albion Drive London Fields, E8, 4LZ, East London.
Oríṣun àwòrán, Facebook
Ọrọ ti Femi Osibona sọ nipa ileeṣẹ rẹ ree:
"Ileeṣẹ wa ti fihan araye ni UK, Amẹrika, South Africa ati Naijiria pe agba ọjẹ ni wa ninu ile kikọ.
Ileeṣẹ Fourscore ni agbara lati fakọyọ nibikibi ti a ba ti n kọle.
Ki n to bẹrẹ owo akọleta, oju mi ri to.
Mo ta bata loṣu kẹsan an ọdun 1991 lẹyin ti mo kawe gboye HND tan ni UK.
Bakan naa ni mo ta aṣọ kootu, ki n to fi owo yii silẹ lọdun 1998.
Ọdun 1997 gan an ni mo bẹrẹ owo akọleta ati ilẹ rira.
Mo ti kọ ile to le ni aadọta niluu London ati Manchester.
Lati ibẹ ni mo ti lọ si South Africa nibi ti mo tun ti kọ àwọn ilegbe kan.
Lẹyin ti mo ti kọ ọpọlọpọ ile niluu oyinbo, ni mo pinnu lati wa ṣe bakan naa nilẹ ni Naijiria.
Ileeṣẹ Fourscore mi lo kọ ile 360 Tower ni Ikoyi ati awọn ile miran niluu Eko.
Oríṣun àwòrán, Screen shot
Ọrọ ti Pasitọ Matthew Ashimolowo sọ nipa Femi Osibona ree:
Alufaa ati oludasilẹ ijọ Ki ijọ Kingsway International Christian Centre(KICC) niluu London naa sọrọ lori ibaṣepọ to ni pẹlu Femi Osibona.
Ninu fidio kan to n ja rain lori ayelujara ni Ashimolowo ti sọ pe lọdun 2001 ni oun kọkọ mọ Femi Osibona.
Osibona lo fun mi ni aṣọ kootu ti mo wọ lọ síbi eto ti ijọba Redeem pe mi sí l'Abuja, lẹyin ti wọn ti ṣe aṣiṣe ni papakọ ofurufu, ti wọn si gbe ẹru mi lọ sí Jamaica."
Osibona ti n gbọ iwaasu mi tipẹ tẹlẹ bo tilẹ jẹ pe ijọ Celestia lo n lọ.
O tí gbọ iwaasu mi lori igbala ọkan, itusilẹ ati okoowo.
Lẹyin ti Osibọna gbọ iwaasu mi, o lu aluyọ, o sí kọ ile nla marundinlaadoje ni Centurion lẹgbẹ Johannesburg ni South Africa.
Lẹyin naa lo pe mi, o si sọ pe oun fẹ wa sí ọdọ mi ni Ghana nibi ti mo ti n waasu.
Nigba to de, ni mo bi mi leere pe nibo ni ki oun tun ti lọ kọ ile bayii ṣugbọn mo sọ fún un pe ki o lọ beere lọwọ awọn oludamọran rẹ lori ọrọ owo.
Amọ, o ni imọran mi dara ju ti wọn lọ.
Léyìn naa ni mo gb'ọwọ le e lori, ti mo si gbàdúrà fun ùn. Mo ni ko lọ si Naijiria.
Femi Fourscore ni wọn maa n pe e:
Gbara ti Femi de sí ìlú Èkó ni o ra ilẹ ni Ikoyi, ti o si kọ ile ogoji eleyii to ta ọkọọkan ni miliọnu kan dọla.
Nibayii, Ashimolowo ni Femi tun ti fidio kan ranṣẹ sí oun nibi ti o ti n kọ ile awodamiẹnu ni Ikoyi.
Aṣọ ati tai lasan ni ọkunrin yii n ta l'Abuja tẹlẹ o.
"Ṣugbọn lonii, o tí ni oríṣìíríṣìí dukia ile,"" Ashimolowo lo sọ bẹẹ."
Oríṣun àwòrán, Screen shot
Ibasepọ Femi Osibona pẹlu Dele Momodu ati Oluwo ti Iwo:
Yatọ si pe Femi Osibona sun mọ awọn eeyan Ọlọrun, to si jẹ ẹni ẹmi to maa n gbadura loore koore, bakan naa lo tun sun mọ awọn eeyan nla nla nilẹ Naijiria ati lẹyin odi.
Koda, fidio kan gan n ja lori ayelujara nibi ti awọn ojisẹ Ọlọrun kan atawọn olorin ẹmi ti lọ ba Femi Osibona gbadura nibi ile to n kọ lọwọ naa.
Bakan naa ni oniruuru fidio ati aworan wa lori ayelujara to n sọ nipa bi Osibona ati Oloye Dele Momodu pẹlu Oluwo ti sunmọra si.
Bakan naa ni Dele Momodu ti fi fidio kan soju opo Instagram rẹ eyi to n se afihan iyawo rẹ ati Femi Osibona plu awn oyinbo kan ti wọn wa lori ile to da wo naa ni ọsẹ kan sẹyin.
Oríṣun àwòrán, delemomoduovation/Instagram
Nigba ti BBC yoruba kan si Oluwo tilu Iwo lati mọ ipo to wa lori isẹlẹ naa nitori bo se sun mọ Femi Osibona si, Oluwo ni ọkan oun rẹwẹsi nipa isẹlẹ naa, to si ba oun ninu jẹ gidi.
Aworan kan to wa loju opo Facebook Oluwo, eyi to fi sibẹ ni ọjọ Kẹsan osu Kwa ọdun 2021, eyiun ọsẹ mẹta ki isẹlẹ ile didawo naa to waye, lo n safiihan Femi Osibona to n mu Oluwo rin yika ile to da wp naa.
Oríṣun àwòrán, Telu Initiatives - greater Iwo Empire Facebook
Sunday Igboho Herbalist: Agbófinró mẹ́fà ló wọ́lé wá gbé ọmọ mi láì mọ́ ibi tó wà
O ti to oṣu mẹta bayii ti awọn eeyan kan ti wọn funra si bii ọtẹlẹmuyẹ DSS wọ ile Dada Fasoto Arifanlajogun, ti o jẹ oniṣegun ati Babaláwo Sunday Igboho n'ipinlẹ Ekiti, ti ẹnikẹni ko si mọ ibi to wa.
Iya Dada, Olomitutu Fasoto, ti o jẹ yeye Ọṣun lo sisọ loju ọrọ yii fun akọroyin BBC Yoruba nilu Ikere Ekiti
Yeye Olomitutu ni ẹni ọdun mejidinlọgbọn ni ọmọ oun ti awọn agbofinro naa wa gbe lọ lai fi ẹsun kankan kan-an.
Olomitutu ni ọmọ oun lo jẹ oniwatutu, to si n ṣe iṣẹ iṣegun ibilẹ rẹ pẹlu ibẹru Ọlọrun amọ o jẹ ohun iyalẹnu pe wọn le wa gbe tori pe o n ba Sunday Igboho rin.
O ni oun ti bọ èṣù, ti oun si tun gbe gbogbo igbesẹ to yẹ ki oun gbe gẹgẹ bi ẹlẹsin abalaye amọ to ja si pabo.
O wa ke sawọn ọmọ Naijiria lati gba ọmọ oun silẹ ko le pada sọdọ aya ati ọmọ rẹ, ọmọ ọdun marun.
Nigba ti BBC Yoruba kan si agbẹnusọ fun ileesẹ Ọlọpaa nipinlẹ Ekiti, Abutu Sunday, o ni awọn ko gbọ nipa isẹlẹ naa, o si jẹ iyalẹnu pe lẹyin osu mẹta ni wọn sẹsẹ nileesẹ ọlọpaa sẹsẹ n gbọ.
Ethiopia War: Kí ló ń ṣẹlẹ ní Ethiopia tí ìrọkẹkẹ ogun fi gbalẹ níbẹ?
Oríṣun àwòrán, AFP
Ijọba orilẹede Ethiopia ti se agbekalẹ ofin ilu ko fara rọ yika tibu tooro orilẹede naa lọjọ Isẹgun nitori irọkẹkẹ ogun to gbalk kan ni ariwa orilẹede naa.
Ijọba ti wa n kede fun awọn eeyan to n gbe ni olu ilu orilẹede naa, Addiss Ababa pe ki wọn dihamọra pẹlu ohun ija lati fi daabo bo ara wọn.
Eyi ri bẹẹ nitori bi awọn ikọ ogun ọlọtẹ lapa ariwa ẹkun Tigray se n sun mọ ẹkun guusu orilẹede naa.
Arọwa yii lo waye lẹyin ọjọ diẹ ti ikọ ọlọtẹ Tigray People's Front (TPLF) se kede pe oun ti gba akoso  ilu nla meji to to irinwo kilomita si Addis Ababa.
Amọ ijọba ilẹ Amẹrika ti n rawọ ẹbẹ si ikọ ọlọtẹ naa pe ko mase gba akoso Addis Ababa nitori awọn eeyan to n gbe nibẹ le ni miliọnu marun
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Wahala lo n waye laarin ijọba Ethiopia atawọn ọmọ ogun Tigray lẹkun ariwa lo n gbena woju ara wọn, eyi to ti da orilẹede naa sinu rogbodiyan nla.
Ogun naa si ti bẹrẹ ni bi ọdun kan sẹyin lapa ẹkun ariwa Ethiopia.
Nibayi naa, ijọba ilẹ Amẹrika ti wa n ke si awọn ọmọ orilẹede rẹ lati fi orilẹede Ethiopia silẹ ni kiakia.
Sunday Igboho Herbalist: Agbófinró mẹ́fà ló wọ́lé wá gbé ọmọ mi láì mọ́ ibi tó wà
Anambra Election: IPOB ní òun kò ní kópa nínú ìbò gómìnà Anambra
Oríṣun àwòrán, AFP
Ẹgbẹ ajijagbara IPOB to n pe fun idasilẹ orilẹ-ede Biafra, ti fagile ofin konle o gbele ọlọsẹ kan to kede ṣaaju eto idibo gomina ipinlẹ Anambra ọjọ Abamẹta.
Akọwe iroyin ẹgbẹ naa, Emma Powerful lo kede igbesẹ yii ninu atẹjade kan to fi sita ni irọlẹ Ọjọbọ.
Oni ọjọ karun ùn oṣu kọkanla ọdun 2021 yii lo yẹ ki ofin konle o gbele naa bẹrẹ titi di ọjọ kẹwaa oṣu yii eleyii ti ko ba ṣakoba fun eto idibo gomina ipinlẹ Anambra ọjọ Abamẹta.
Bakan naa ni IPOB sọ pe oun ko ni kopa ninu eto idibo ọhun.
Emma ṣalaye ninu atẹjade naa pe, awọn wọgile ofin konle o gbele tawọn kede tẹlẹ lẹyin tawọn eekan ilu at'awọn lọba lọba nilẹ Igbo parọwa s'awọn pe káwọn jẹ kí ibo gomina Anambra waye ni alaafia.
Mesach Oyediran: Ọba ni Dafidi tó ń lu dùùrù, tó sì kọ sáàmù, ta ni èmi tí kò ní le yin
"Ki ẹnikẹni ma ṣe ro pe a gbe igbesẹ yii nitori bi awọn ẹṣọ eleto abo ṣe lu ipinlẹ Anambra ati ilẹ Igbo pa lo jẹ kí a gbé igbesẹ yii.
Awọn agbaagba to ba wa sọrọ ti fi da wa loju pe awọn yoo sa gbogbo agbara awọn lati ri pe ijọba apapọ tu olori IPOB, Nnamdi Kanu silẹ ni ahamọ ijọba.
Awọn eeyan lanfaani lati jade lọ dibo fun ẹnikẹni to ba wu wọn.
Ẹtọ awọn eeyan ni lati kopa ninu eto idibo, ati pe eyi tun túmọ sí pe ẹgbẹ IPOB ni igbagbọ ninu eto ijọba awaarawa, aburo Kanu lo sọ bẹẹ."
A ti gbọ pe ajọ ọtẹlẹmuyẹ DSS n gbero lati lo awọn janduku lati da rogbodiyan silẹ nibi eto idibo gomina ipinlẹ Anambra.
A si gbọ pe DSS ṣetan lati sọ pe ẹgbẹ IPOB lo ṣagbatèru ipaniyan ati rogbodiyan to ba waye ninu eto idibo naa.
#BBCNigeria2019: Nnamdi Kanu sọrọ lórí àwọn oludije PDP àti APC
Ẹgbẹ IPOB kii ṣe ẹgbẹ adaluru, a n rọ awọn eeyan ipinlẹ Anambra lati dibo ki wọn si duro ti ibo wọn.
Ko gbọdọ si ibo rira tabi eeru ninu eto idibo Anambra.
"A ki gbogbo ọmọ ẹgbẹ IPOB ati awọn eeyan orile-ede Biafra kaakiri agbaye fun atilẹyin wọn,"" Emma lo sọ bẹẹ ninu atẹjade to fi sita."
Ẹwẹ, ajọ eleto idibo INEC ti sọ tẹlẹ pe eto idibo gomina Anambra yoo tẹsiwaju lai fọta pe.
Hajiya Zainab Aminu Abubakar to jẹ oṣiṣẹ INEC sọ pe gbogbo eto lo ti to bayii fun eto ibo naa lati gberasọ.
Ọgọọrọ awọn ọmogun, ọlọpaa at'awọn ẹṣọ eleto aabo mii lo ti wa ni ipinlẹ Anambra lati ri pe eto idibo naa kẹsẹ jari lọjọ Abamẹta.
Ko si ẹni to mọ bi nkan yoo ṣe ri nipinlẹ Anambra  lọjọ Abamẹta lori bi eto abo ti mẹhẹ nibẹ.
Amọ, ohun kan to daju ni pe ajọ INEC ti ṣetan, bẹẹ ni awọn ẹṣọ eleto abo naa ti gbaradi lati pese abo to peye fawọn eeyan lasiko eto idibo gomina ipinlẹ Anambra.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Nibayi ti ipalẹmọ fun eto idibo gomina nipinlẹ Anambra ti doju ọgbagade, awọn onims kan ti n sekilọ fun aarẹ Muhammadu Buhari pe ko sa gbogbo ipa rẹ lati ri daju pe eto idibo naa yọri si rere.
Ọmọwe Abubakar Kari, tii se onimọ nipa ọrọ oselu lọgba fasiti Abuja lo gba aarẹ nimọran bẹẹ lasiko to n ba BBC sọrọ.
Kari ni itiju nla ni fun ijọba to ba fi kuna lati se aseyọri nidi eto idibo naa.
Eto idibo to se iyebiye ree, a si le sọ pe o jẹ idanwo fun ijọba Naijiria nipa bo se kaato to lati seto idibo kaakiri gbogbo Naijiria, kii se nipinlẹ Anambra nikan.
"Kari fikun pe ""Ofin ilẹ wa se agbekalẹ iyipada lati ọwọ ijọba kan si omiran lọdun mẹrin mẹrin."
Oríṣun àwòrán, NDH
"Amọ asiko yii la mọ boya ijọba lagbara lati fi tipa sọ fun ikọ kan pe ko se ohun ti oun n fẹ tabi boya isọri awọn eeyan kan lagbara lati se ohun to ba wu wọn."""
O tẹsiwaju pe ti awọn ikọ to n pe fun iyapa yii, IPOB ba yege lati dena eto idibo naa gẹgẹ bo ti seleri a jẹ pe ijọba Naijiria ti kuna niyẹn.
O ni lakoko yii ati ni ọjọ iwaju, awọn eeyan miran tabi igun kan naa le dide nibikibi lati da ijọba lọwọkọ, ko ma le se ohun to ba fẹ se.
Ẹwẹ, Ijọba ilẹ Amẹrika ni oun n reti pe wọn yoo seto idibo gomina nipinlẹ Anambra naa, ti alaafia yoo si jọba nibẹ lasiko idibo.
Bakan naa nijọba ipinlẹ Anambra gan ti fun awọn osisẹ rẹ nisinmi, to si ti kede pe ki wọn ti awọn opopona to wọ inu ipinlẹ naa pa, lọna ati ri daju pe eto idibo ọhun kẹsẹ jari.
Nibayi naa, ẹgbẹlẹgbẹ awọn ọmọ ogun ilẹ wa, to fi mọ awọn ọlọpaa atawọn ileesẹ agbofinro miran lo ti fi awọn osisẹ wọn ransẹ si Anambra lati ri daju pe eto idibo ọhun lọ nirọwọ irọsẹ.
Sunday Igboho Herbalist: Agbófinró mẹ́fà ló wọ́lé wá gbé ọmọ mi láì mọ́ ibi tó wà
Domestic Violence in Nigeria: Ọkùnrin tó fi sísọ́ọ̀sì gún aya rẹ̀ pa kó sí gbaga ọlọ́pàá l‘Ogun
Oríṣun àwòrán, Ogun Police Command
Ọwọ ileeṣẹ ọlọpaa ipinlẹ Ogun ti tẹ okunrin ẹni ọdun mẹrinlelogun kan, Mojiyagbe Olamilekan, lori ẹsun pe o gun iyawo rẹ pa.
Ninu atẹjade ti alukoro ileeṣẹ naa, Abimbola Oyeyemi fi lede, o ni agbegbe Oke ola, ni  Ode Remo ni afurasi naa ti fi sisọọsi gun aya rẹ pa.
Oyeyemi sọ ninu atẹjade naa pe ọwọ awọn tẹ afurasi ọhun lẹyin ti awọn eeyan adugbo to n gbe, ke gbajare si awọn ni nnkan bii ago mẹta ọsan.
"O  ni ""Ohun ti a gbọ ni pe ọkunrin ọhun ti aya rẹ mọ inu yara to si bẹrẹ si n lu ni ilu bara, ariwo rẹ ni awọn eeyan adugbọ gbọ ti wọn fi  kan si ileeṣẹ wa."""
Gbogbo igbiyanju awọn ara adugbo lati ri pe o ṣi ilẹkun yara to ti aya rẹ naa mọ lo ja si pabo.
Sunday Igboho Herbalist: Agbófinró mẹ́fà ló wọ́lé wá gbé ọmọ mi láì mọ́ ibi tó wà
Atẹjade ọhun tẹsiwaju pe, ọga ọlọpaa Ode Remo ko awọn oṣiṣẹ rẹ lọ sile ti iṣẹlẹ naa ti waye, wọn si fi agidi ja ilẹkun afurasi naa ṣugbọn ọrọ naa ti bọ sori, nitori inu agbara ẹjẹ ni wọn ba obinrin ọhun.
Oyeyemi ni lẹyin naa ni wọn gbe obinrin naa digba-digba lọ sile iwosan kan ni Isara Remo lati doola rẹ ṣugbọn o ti padanu ẹmi rẹ nigba ti wọn yoo fi de ile iwosan ọhun.
Lẹyin naa ni wọn fi ṣikun ofin mu afurasi naa ti wọn si fi si atimọle, nigba ti wọn gbe oku aya rẹ lọ sile igbokusi lati tọpinpin ohun to mu ẹmi rẹ lọ.
Ẹwẹ, kọmiṣọna ọlọpaa ipinlẹ Ogun, Lanre Bankole ti paṣẹ ki wọn gbe ẹjọ naa si ẹka ti wọn ti n ṣe iwadii ẹsun ipaniyan fun iwadii to peye.
Bankole tun ni afurasi ọhun gbọdọ foju bale ẹjọ ni kete ti iwadii naa ba ti pari.
Olugbon Twins: Ọba Alao àti Olorì rẹ̀ bí ìbejì lẹ́yìn tí nǹkan oṣù ti dúró lẹ́ni ọdún 53
U.I Graduation: Fásitì Ibadan sé ìlẹ̀kún mọ́ ọ̀pọ̀ akẹ́kọ̀ọ́jáde àti òbí wọn lásìkò ìkẹ́kọ̀ọ́jáde
Oríṣun àwòrán, Advance U.I
Ninu awọn ọjọ moriwu, ọjọ manigbagbe ati ọjọ ayẹyẹ ti ẹda kan maa n fi oju sọna fun ni ọjọ ti eeyan ba gba oye ikẹkọjade nile ẹks giga fasiti.
Saaju ikẹkọgboye, ni obi yoo ti na owo ati ara lati ri pe ọmọ rẹ se aseyege ninu imọ ẹkọ to yan laayo, ti akẹkọọ naa yoo si tiraka pẹlu ara ati ọpọlọ lati mase ja awọn obi rẹ kulẹ.
Bakan naa ni yoo fi oju sọna lọjọ ti yoo di ominira, ti yoo gba paali iwe ẹri moyege kuro ni fasiti, to si di akọsẹmọsẹ nidi ẹka imọ eto ẹkọ to ka fun ọdun mẹrin, marun tabi meje.
Bakan naa ni obi yoo maa ro ọjọ ti ọmọ oun yoo kẹkọjade, ti wọn yoo gẹ fila ati gele, fi ile pọn ọti, fi ọna ro ọka, ti yoo si ya fọto tikatika pẹlu ọmọ rẹ to n kẹkọ jade.
Ni ọdun 2020 ti arun Coronavirus lu agbaye ka, ọpọ fasiti ni ko seto ayẹyẹ ikẹkọjade fawọn akẹkọjade rẹ nitori bi ọwọja arun naa se n gbilẹ si, ninu eyi ti fasiti Ibadan wa lara wọn.
Sunday Igboho Herbalist: Agbófinró mẹ́fà ló wọ́lé wá gbé ọmọ mi láì mọ́ ibi tó wà
Amọ iyalẹnu lo tun jẹ lọdun 2021 yii nigba tile ẹkọ fasiti Ibadan tun fi ikede kan sita lọjọru, ọjọ Kẹta osu Kọkanla pe isọri awọn akẹkọ to ba gba oye imọ ijinlẹ onipo kinni nikan ni ko yọju fun ayẹyẹ ikẹkọjade lọgba ile ẹkọ naa.
Nibi ayẹyẹ ikọkọjade naa, ti yoo waye laarin ọjọ Kẹẹdogun si Ikẹtadinlogun osu kọkanla ọdun 2021 ni fasiti Ibadan ti ni oun ko fẹ kofiri awọn akẹkọ yoku ati obi wọn nibi ayẹyẹ ikẹkọjade naa.
Atẹjade kan ti alukoro fun fasiti Ibadan, Olatunji Oladejo fisita ni ile ẹkọ giga naa gbe igbesẹ ọhun lati dẹkun itankalẹ arun Coronavirus ni.
Atẹjade naa wa fikun pe gbogbo akẹkọ to n kẹkọjade nile ẹkọ giga naa lo gbọdọ san gbogbo owo to ba yẹ patapata, boya wọn wa se ayẹyẹ ikẹkọjade ni tabi bẹẹkọ.
O ni ile ẹkọ naa yoo duro de wọn lati gba owo yii ni kete ti wọn ba yọju lati wa gba iwe ẹri wọn.
Olugbon Twins: Ọba Alao àti Olorì rẹ̀ bí ìbejì lẹ́yìn tí nǹkan oṣù ti dúró lẹ́ni ọdún 53
Lakotan, atẹjade ọhun wa n rọ awọn akẹkọjade ati awọn obi wọn to n bọ fun ayẹyẹ ikẹkọjade lati tẹle awsn ilana to n dena arun Coronavirus.
Bakan naa ni wọn rọ awọn akẹkọjade yoku ti ko jẹ onipo kinni lati lọ soju opo ayelujara, maa kopa nibi ayẹyk ikẹkọjade naa.
Herbalist kills Baby for Ritual: Oníṣègùn pòórá mọ́ àwọn ọ̀dọ́ tó ń lù ú lọ́wọ́
Oríṣun àwòrán, UNUNUMA BIDEMI EDWARD ODOI
Ọjọ keji, oṣu Kẹwaa, ọdun 2021 yii ni awọn ọdọ kan lagbegbe Eduoha, ni ijọba ibilẹ Guusu Ahoada, ni Rivers ke gbajare pe ọwọ awọn tẹ oniṣegun kan, ti wọn fẹsun kan pe o sin ọmọ jojolo laaye.
Gẹgẹ bii ohun ti awọn oṣojumikoro sọ, ọkunrin ọmuti kan to lọ ṣẹyọ ninu igbo lo ka afurasi oniṣegun naa, nibi to ti n sin ọmọ jojolo naa ti iye ọjọ ori rẹ ko tii ju oṣu mẹta lọ.
Iroyin ni oniṣegun naa n ka ọfọ ati ayajọ le ọmọ ọhun lori bo ṣe n sin, ṣugbọn ọmuti naa wọ jade ninu igbo ọhun, o si ke ibosi le lori.
Nnkan bii aago kan ọganjọ oru ni iṣẹlẹ naa waye gẹgẹ bii ohun ti a gbọ.
Lasiko ti awọn ọdọ ilu bẹrẹ si n da ibeere bo afurasi naa, ni wọn wọ lọ sile rẹ lati wo awọn ohun to wa nibẹ amọ iroyin ko to afojuba.
Oríṣun àwòrán, Ununuma Bidemi Edward Odoi
Lara awọn ohun ti wọn ri ninu ile rẹ ni oniruru ọ̀bẹ, apakan ile ọhun ni awọn ṣẹkẹṣẹkẹ nla, to fi mọ awọn aga ti wọn kan mọlẹ.
Oṣojumokoro kan sọ fun BBC pe ọkunrin naa kii ṣe ajoji ladugbo naa, nitori ibẹ lo kọ ile si, ṣugbon ile naa ni ogiri to ga pupọ ti ẹnikẹni ko le ri ohun to ba n ṣẹlẹ ninu rẹ.
Awọn eeyan adugbo naa tun sọ pe afurasi ọhun ni ọmọ ati aya ti wọn dijọ n gbe papọ.
Iroyin ni bi wọn ṣe wọ inu ile naa, ni wọn bẹrẹ si n lu ni ilu bara nitori awọn ohun ti awọn eeyan ri nibẹ, ṣugbọn ṣadede lo poora laarin wọn bi wọn ṣe n na lọwọ.
Eredi ree ti awọn eeyan naa ṣe sọ ina sile ọhun.
Oríṣun àwòrán, UNUNUMA BIDEMI EDWARD ODOI
Oriṣiriṣi aworan awọn eeyan lo wa ninu ile ọkunrin naa, bii ọkunrin, obinrin atawọn ọmọde.
Lara awọn aworan naa ni wọn kan si ara ogiri, nigba ti wọn so awọn mii mọ agadagodo, ti wọn si ti mọ inu ẹwọn.
Awọn ọdọ to ya bo ile naa tun foju ganni oniruru oogun abẹnugọngọ, ki wọn to sọ ina si.
"Ọkan lara awọn oṣojumokoro naa ni ""Awọn eeyan kan ri aworan awọn mọlẹbi wọn kan nibẹ bo tilẹ jẹ pe awọn mọlẹbi wọn naa ti dagbere faye."""
Mo ri awọn eeyan ti mo mọ nibẹ, mo tilẹ pe ẹni naa, ti mo si lọ fun ni aworan ọhun, ṣugbọn ẹsẹ ti n dun ẹni naa fun awọn akoko kan.
Mo ri aworan ti wọn de ṣẹkẹṣẹkẹ mọ ti wọn tun fi sinu ẹwọn iru eyii ti wọn maa n tọju aja si.
Bo tilẹ jẹ pe ko sẹni to tii le sọ ni pato irufẹ eeyan ti afurasi naa, Mike Indiana jẹ, iroyin ni awọn babalawọ ati onịsegun wọpọ lagbegbe ti iṣẹlẹ naa ti waye.
Ẹnikan tilẹ sọ fun BBC pe ọpọ awọn olugbe agbegbe naa lo gba lati maa fi ọrọ to awọn oniṣegun ni agbegbe naa leti, kaka ki wọn gbe ẹjọ lọ si agọ ọlọpaa.
Ẹwẹ, ileẹṣẹ ọlọpaa ipinlẹ Rivers ni awọn ti gbọ nipa iṣẹlẹ naa, amọ wọn n reti alaye lẹkunrẹrẹ lati ọọfisi ẹka ti Ahoada.
Anambra 2021 Election: Bí o ṣe le mọ ìbùdó ìdìbò rẹ̀ ní Anambra
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ti o ba jẹ oludibo nipinlẹ Anambra, to si fẹ kopa ninu eto idibo to n bọ yii, wo akọsil yii lati sedamọ ibudo idibo rẹ.
Eyi ni ko ni jẹ ko sina lasiko to ba n lọ dibo tabi ko lọ sibi ti ko yẹ.
O maa nilo oju opo JavaScript lati le wo awọn nkan to wa ni oju ewe yi
Kọ nọmba koodu yi lati le fi mọ ibudo idibo rẹ
Bi apẹrẹ 04-01-01-010
Ijọba ipinlẹ
Wọọdu
Ibudo idibo
Ọrọ afikun
Anambra 2021 Election: Wo àkọsílẹ̀ nípa ìtan ayé àwọn oludìbò gómìnà Anambra
Fun ọpọ ẹyin ti ẹ ko mọ ohunkohun nipa awọn eeyan to n dije fun ipo gomina nipinlẹ Anambra.
Ẹ wa ka iroyin yii lati mọ nipa oludije mejila to n du aga gomina nipinlẹ́ Anambra mọ ara wọn lọwọ.
Ẹ wa mọ atimaasebọ wọn, ilu ti wọn ti wa, isẹ ti wn n se tẹlẹ, ọjọ ori wọn ati ẹgbẹ oselu ti wọn n dije labẹ rẹ.
Emezana Purity: Kí ló mú òjòwú ọ̀rẹ́kùnrin fì ìbínú yìnbọn lu ọ̀rẹ́bìnrin rẹ̀ lẹ́yìn tó lóun kò ṣe mọ́
Ọlọrun lo ni maa wa laye loni ni ọrọ to n jade lẹnu arabinrin Emezana Purity nigba to n ṣalaye bi ojowu ọrẹkunrin rẹ ti ṣe binu yinbọn lu.
Ọrẹkunrin rẹ ti wọn ko fẹ ara mọ James Eno, lo yinbọn lu Emezana nile rẹ to wa ni Warri ni ipinlẹ Delta.
Iroyin Purity gba oju opo ayelujara kan, ti ọpọ eeyan si n ran ọrọ ẹni ọdun mẹrinlelogun yi lẹnu.
Ileeṣẹ ọlọpaa nipinlẹ Delta ti wa fidi ọrọ yii mulẹ fun BBC, ti wọn si ni iwadii ti bẹrẹ ni pẹrẹwu.
Purity tẹnu bọrọ fun BBC nileewosan to ti n jẹ irora lati ipasẹ ibọn yinyin naa, to si ṣalaye bi Eno ṣe wa ba oun nile, to fa ibọn yọ lẹyin toun sọ pe oun ko ṣe mọ.
"Ọrọ kan wa laarin wa ti mo si pada ri ododo rẹ. Bi mo ṣe ni mi o ṣe mọ fun, pe ka yẹra diẹ fun ara wa. Mi o sọ fun pato pe mi o ṣe mọ''
Kò tíì tó oṣù kan tí èmí àti Favour bẹ̀rẹ̀ sí ni fẹ́ ara wa tí mo pa á ṣe ògùn owó
Purity sọ pe James fẹsun kan oun pe oun n fẹ alabaṣiṣẹ rẹ nibi toun ti n ṣowo. O sọ pe alabagbe kan ni oun ati ẹni naa.
Ko gba mi gbọ tori naa mo ba pinnu  pe ka maa lọ lọtọọtọ lati fi koore anbili''"
Bi Purity ti ṣọ fun pe Eno pe ko ṣe mọ, bẹẹ ni ọkunrin naa fa ibinu yọ, to si ni ki obinrin naa ko owo ti oun fi da ni okoowo pada.
''Bo ti ṣe n fibinu sọrọ ni Mama mi ba gba mi nimọran pe o le ṣe mi ijamba''
Nitori naa lawọn mọlẹbi mi ba fi ni ko fun awọn lasiko diẹ lati san owo naa pada. O ni ko buru.
Amọ ko ṣe suuru di igba naa
" Dokita ni iyalẹnu lo jẹ pe mo ye iṣẹlẹ ibọn yinyin naa''
Purity wa tẹsiwaju lati salaye bi ọrẹkunrin rẹ ṣe ṣadede yọ si lati gbẹmi rẹ.
O yọ ibọn jade to fẹ yin mọ mi. Bi mo ṣe na ọwọ mi soke ni yẹn''"
Oríṣun àwòrán, Emezana Purity/Facebook
O ni ọta ibọn naa gba ọwọ oun jade to si wọ inu aya rẹ lọ ko to pada jade lẹyin rẹ.
"Ori lo yọ mi pe ọta ibọn naa ko wọ inu ọkan mi lọ ṣugbọn o fọ egungun aya mi mẹta''
Purity fi kun pe, ọkan ninu egungun aya to fọ naa ya ẹdọ fooro rẹ tori naa wọn ni lati yara ṣe iṣẹ abẹ fun oun.
O ni lati igbati wọn ti ṣe iṣẹ abẹ yii tan, a ti mi daada ti di iṣoro fun oun.
Bi mo ba mi yoo dabi pe wọn fi nkan gun mi laya''"
Awọn Dokita sọ pe iyalẹnu lo jẹ pe Purity si wa laye lẹyin ibọn yinyin naa.
Ọjọ mẹrin gbako ni Purity fi n gba afẹfẹ oxygen nitori ko le da nikan mi fun ara rẹ .
Mesach Oyediran: Ọba ni Dafidi tó ń lu dùùrù, tó sì kọ sáàmù, ta ni èmi tí kò ní le yin
Inu fufu:
Nigba ti wọn ṣi n fẹ ara wọn, Purity ni oun ri apẹrẹ pe ọrẹkunrin oun a maa yara binu pupọ.
"Mo ti maa n gbọ pe iru nkan bayi n ṣẹlẹ koda mo ri loju opo ayelujara amọ mi o lero pe o le ṣẹlẹ simi''
O ni bi ọta naa ti ṣe ba oun, loun ba sare wọle toun si dibọn bi igba pe oun ti ku.
Ina ọba lọ nigba naa ti eyi si mu ki ariwo ẹrọ amunawa generator bo iro ibọn naa mọlẹ nigba ti Eno yinbọn mọ.
O ni nigba toun ko gburo rẹ mọ loun ba figbe ta tawọn alabagbe si sare gbe oun lọ si ile iwosan.
Purity ti lo to ọjọ mẹjọ bayi ni ile iwosan ti ireti si wa pe ara rẹ ko ni pẹ ya.
Ikoyi Collapsed Building: Dele Momodu bẹ̀bẹ̀ adura ki awọn to ha sabẹ ile to da wo jade l'ayọ
Oríṣun àwòrán, delemomoduovation/Instagram
Oniruuru iroyin lo ti n jade sori ayelujara nipa akikanju ọkunrin kan, Wale Bob-Oseni, to fi ilẹ Amẹrika se ibujoko pẹlu iyawo ati ọmọ.
Amọ irinajo to gbe wa silẹ Naijiria lo dabi nnkan, nibi to ti se agbako ile to da wo ni Ikoyi, to si ha si abẹ ilẹ titi di akoko yii.
Ọjọ kinni, osu Kọkànla, ọdún 2021 yìí ni Wale Bob-Oseni, n rinrinajo rẹ pada silẹ Amẹrika to ti wa.
Amọ ipe kan to gba lórí agọ rẹ lati ọdọ ọrẹ rẹ, Femi Osibona lo mu ko ya bara duro nibi ile to da wo naa.
Wale Bob-Oseni wa lára àwọn èèyàn tí ilé alájá mọkanlelogun da wo le lórí lagbegbe Ikoyi, nílùú Eko.
Oríṣun àwòrán, Dele Momodu
Ọkunrin naa ti ọjọ ori rẹ kò ju bíi àádọta ọdún lo wa pẹlu awọn èèyàn mii tile da wo lori ni Ikoyi, ti ọrẹ rẹ, Femi Osibona n kọ.
Isẹlẹ ile to da wo naa, ti Wale Bob-Oseni ha sinu rẹ jẹ eyiti o se ni laanu gidigidi nítorí oun ati ẹbi rẹ ko ronu irufẹ isẹlẹ yii rara.
Titi di akoko ti a n ko iroyin yii jọ, kò sí ẹni tó tíì le sọ ibi tabi irufẹ ipo ti ẹni tó n kọ ile ọhun wa ati ọrẹ rẹ yii.
Ilẹ Amẹrika ni Wale Bob-Oseni n lọ, ko to gba ipe lati yọju sí ilé náà, ti ko si pada sile rẹ mọ tàbí lọ sí Amerika to ti pinnu rẹ lati lọ bákan náà.
Nínú fídíò kan to jade lẹyin iṣẹlẹ náà, ni ọkunrin kan ti ọpọ gbagbọ pe òun ni awakọ Wale Bob-Oseni tí n pohunrere ẹkun.
Awakọ naa, ti oun naa wa nibi ile to da wo yii ni Amẹrika lo n lọ o, èmi ni mo sì n gbe lọ."""
Ọpọlọpọ awọn gbajumọ niluu Eko lo ti bẹrẹ sí n tara poro lori isẹlẹ yii tori bi awọn  eeyan se ha sabẹ ilẹ tabi ba iṣẹlẹ ọhun lọ.
Oríṣun àwòrán, delemomoduovation/Instagram
Ogbontarigi akọroyin, Dele Momodu wa lára àwọn èèyàn tí ọrọ ile to da wo náà kan gbọngbọn.
Ṣaaju ni Dele Momodu ti kọkọ ṣabẹwo sile naa ko to da wo, toun ti ẹni tó n kọ ilé náà, to fi mọ Olúwo ti ilu Iwo, Oba Abdulrasheed Adéwálé Akanbi.
"Lẹyin iṣẹlẹ naa ni Momodu sọ loju opo Instagram rẹ pé ""Ẹ ba mi máa gbàdúrà fún Femi Osibona, Wale Bob-Oseni, atawọn mii to ha sabẹ ile naa to da wo, ki wọn le jade layọ, ki Ọlọrun si tẹ awọn to ti jade laye sí afẹfẹ rere."""
Dele Momodu tun fi fídíò kan lede nibi ti awọn ọmọ Ile igbimọ aṣofin ipinlẹ Oyo ti sabẹwo si nílé rẹ to wà lorilẹ-ede Ghana.
Gẹgẹ bíi ohun tó sọ, awọn aṣofin ọhun fi akoko naa ṣadura fún àwọn tó fara gba níbi ilé to da wo náà.
Mesach Oyediran: Ọba ni Dafidi tó ń lu dùùrù, tó sì kọ sáàmù, ta ni èmi tí kò ní le yin
Ọpọ oriade nilẹ Yoruba ni maa n pe ara ni ọlọrun kekere, alasẹ igbakeji orisa, bẹẹ ni wsn kii fi oribalẹ fun ẹnikan.
Amọ ọba alaye kan ree to n fi ori ade tẹ duuru nile ijọsin lai boju wẹyin.
Nigba to n ba BBC Yoruba sọrọ lori idi to se n tẹsiwaju lati maa tẹ duuru nile Ijọsin, Ọba Mesach Oyediran tii se Olulalokun tilu Yakoyo ni oun n fi ọwọ oun yin Ọlọrun logo ni.
Ọba Oyediran ni ọdun mejidinlọgbọn niyi ti oun ti n lu duuru, baba oun tii se alufa si lo se iwuri isẹ naa fun oun.
Oriade naa ni ọpọ ọrẹ oun lo ti n fapa janu pe o yẹ ki oun ti dẹkun titẹ duuru ni sọọsi gẹgẹ bi ọba alaye amọ ti oun ko da wọn lohun.
O ni ọba naa ni Dafidi to fi n tẹ duuru, to si kọ saamu, ta wa ni oun ti ko ni le tẹsiwaju lati maa fi ọwọ oun yin Ọlọrun logo nitori pe oun jẹ ọba.
Babatunde Olatunji: Alùlùgbayì ọmọ Nàìjíríà tó fìlù kojú ìdẹ́yẹsí ní Amẹ́ríkà
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ọdun mẹta ṣaaju igbesẹ Rosa Parks lati fẹhonu han ninu bọọsi akero gẹgẹ bi ara ọna ẹhonu tako idẹyẹsi awọn alawọ dudu, alulugbayi ọmọ Naijiria nni, Babatunde Ọlatunji naa ti fẹhonu han tako idẹyẹsi ẹlẹyamẹya lẹkun guusu orilẹede Amẹrika. O jẹ ọkan lara awọn iran adulawọ akọkọ to ko ipa manigbagbe ninu titako idẹyẹsi ẹlẹyamẹya lorilẹede Amẹrika- to si tun tẹsiwaju lati maa ṣe bẹẹ ti doni.
Awọn aṣiwaju lawọn ọdun 1950 si 1969 fun mi ọpọlọpọ iwuri, Ajafẹtọ ọmọniyan Opal Tometi, to jẹ ọkan lara awọn oludasilẹ ẹgbẹ Black Lives Matter movement lo ṣalaye bẹẹ fun BBC.
Nigba ti Martin Luther King Jr ka ọrọ apilẹkọ manigbagbe rẹ to pe akori rẹ ni Mo ni ala rere (I have a dream) lasiko iwọde to waye ni ilu Washington lọdun mẹtadinlọgọta sẹyin, ẹgbẹrun lọna ọtalelẹgbẹrun o din mẹwa eeyan lo kopa ninu iwọde naa ninu eyi ti a ti ri James Baldwin, Harry Belafonte ati Sidney Poitier.
'CAC Agbala Itura ni mo ti bẹ̀rẹ̀ ìlú lílú kí ń tó máa bá Janet, àbúrò Michael Jackson lù Gangan àti Omele'
Scrabble: Yorúbà Scrabble ni àkọ́kọ́ ní èdè abínibí nílẹ̀ Afrika
Lara awọn eeyan pataki to wa nibẹ ni eeyan kan ti ọpọ  ko lee lero pe yoo wa nibẹ - ayan onilu ọmọ Naijiria ti orukọ rẹ n jẹ Babatunde Ọlatunji.
Ọdun 1927 ni a bii sinu mọlẹbi Yoruba kan ni ipinlẹ Eko. Ọlatunji si janfani ẹkọ ọfẹ lati lọ kawe nileewe Morehouse College ni Atlanta lọdun 1950.
"O di eekan onilu pẹlu awo orin mẹtadinlogun, awo orin rẹ akọkọ to gbe jade lọdun 1959 pẹlu akọle ""Drums of Passion"" ti ọpọ gboṣuba fun gẹgẹ bi eyi to pe akiyesi awọn alawọfunfun si orin rẹ."
Lootọ, Ọlatunji ti fi ogun rere lelẹ nipa ti iṣẹ orin ninu eyi ti a ti ri mimu ti wọn mu orukọ rẹ ranṣẹ fun ami ẹyẹ Grammy ati awọn orin to gbe kalẹ fun awọn sinima ni Broadway ati Hollywood, ṣugbọn iwọnba lawọn eeyan mọ nipa ilakaka rẹ gẹgẹ bii afọnrere ija fun ẹtọ ọmọniyan.
"O jẹ olufọkansin fun ẹtọ ọmọniyan lawujọ ni gbogbo ọjọ aye rẹ, ni ọrọ kan ti Robert Atkinson, to ba ọlatunji ṣiṣẹ pọ lori kikọ iwe itan igbesi aye rẹ ti wọn gbe jade ni ọdun meji lẹyin iku rẹ lọdun 2005 pẹlu akọle 'The beat of My Drum."""
Ẹni to yẹ lati maa ṣe iranti rẹfun ipa to ko lori ijafẹtọ aparo kan o ga jukan lọ lorilẹede Amẹrika ni, koda o ti bẹrẹ ṣaaju ki eyi ọwọja iwọde ijafẹtọ naa to gbẹrẹgẹjigẹ ni.
Ìkúnlẹ̀ Abiyamọ oo! Ìyá ju ọmọ rẹ̀ méjì sí Kànga
Èèyàn 94 kú lásìkò tí wọ́n ń gbọ́n epo bẹntiróòlù
Màá ṣèrànwọ́ láti dojú ìjà kọ afẹ̀jẹ̀wẹ̀ nílẹ̀ Niger tó pa èèyàn 69 - Buhari
Protein Marasmus: Wo èwu tó wà nínú kí ọmọdé má ní èròjà Protein lára
Gẹgẹ bi akẹkọ ileewe Morehouse, ọpọlọpọ ahesọ to da lori aini imọ to to nipa Afirika ni Ọlatunji dojukọ, ti o si ni lati tiraka da awọn akẹkọọ ẹgbẹ rẹ lẹkọ nipa orin, aṣa ati iṣe ilẹ Afirika.
Lasiko faaji lọgba fasiti rẹ lo ti kọkọ bẹrẹ si ni kọ ori ilẹ Afirika, pẹlu awọn are onilu kaakiri awọn ile ijọsin adulawọ atawọn alawọ funfun jakejado Atlanta.
Oríṣun àwòrán, Olatunji family
Babatunde Ọlatunji lọsi orilẹede Amẹrika lọdun 1950 lati kọ ẹkọ o si ṣe igbeyawo pẹlu Ammiebelle Bush lọdun 1957
Baba lo tan imọlẹ si iyi ati ẹyẹ jijẹ adulawọ laarin awọn adulawọ ọmọ ilẹ Amẹrika  nipa ṣiṣe agbatẹru ifọnrere aṣa ilẹ Afirika eyi to ṣe koriya ati amuṣẹya fun igbedide iji iwọde ẹtọ ọmọniyan, gẹgẹ bi Atkinson ṣe sọ.
"Lasiko to jẹ wi pe ijọba to wa lode gan fọwọ si idẹyẹsi ẹlẹyamẹya lorilẹede Amẹrika, Ọlatunji ko ṣai tete mọ pe idẹyẹsi ẹlẹyamẹya wa, ti o si bẹrẹ si ni ko awọn akẹkọọ jọ lati dide kọju ija si ofin idẹyẹsi ẹya ti wọn n pe ni ""Jim Crow lawọ"" nigba naa lẹkun gusu orilẹede naa."
Lọdun 1952, ọdun mẹta ṣaaju ki Rosa Parks to gbe igbesẹ to fa iwọde kikọ lati wọn bọọsi akero Montgomery, (Montgomery Bus Boycott) ni Alabama, Ọlatunji ṣe iwọde tirẹ ninu awọn bọọsi akero lẹkun gusu orilẹede naa.
Lasiko kan, oun atawọn akẹkọọ kan wọ wọ aṣọ ilẹ Afirika kan wọ bọọsi akero kan ninu eyi ti iwa idẹyẹsi ti maa n jẹyọ daadaa lasiko igba naa ni Atlanta. Wọn fi aye gba wọn lati joko si aye to wu wọn ninu ọkọ naa nitori pe wọn ko da wọn mọ gẹgẹ bii adulawọ ọmọ Amẹrika to jẹ pe nigba naa ẹyin ọkọ ni wọn maa n fi aye ijoko wọn si.
Ni ọjọ keji, wọn wọn ọkọ bọọsi kan naa pẹlu aṣọ oyinbo lọrun wọn, wọn si faake kọri pe awọn ko ni joko si aye ẹyin ninu bọọsi naa nigba ti awakọ naa paṣẹ pe ki wọn lọ ree joko si ọwọ ẹyin. Ọlatunji atawọn akẹgbẹ rẹ tẹsiwaju lati maa tako idẹyẹsi yii lọna yii lai naani ihalẹ pe wọn yoo ju wọn si ẹwọn.
"Ọlatunji ṣi ṣalaye lori iwọde yii pe, ""A bẹrẹ ifẹhonuhan naa ni bonkẹlẹ,"" O ni, ""a jẹ ọkan lara awọn to bẹrẹ ipe fun ominira ni ibẹrẹ ọdun 1950."
"Iyawo Ọlatunji, Iyaafin Ammiebelle Ọlatunji to jẹ ẹni aadọrun ọdun ṣalaye fun BBC pe Ọlatunji ni wọn maa n pe""lati wa bomi pa wahala lawọn ileto gbogbo"", bii asiko ti iwọde to gbona janjan n waye lọdun 1965 lawọn ileto tawọn alawọ dudu n gbe ni Watts ni Los Angeles."
O ri ara rẹ gẹgẹ bii ajafẹtọ ilẹ Adulawọ to n ṣetan ni gbogbo igba lati mu iṣọkan ba awọn ọmọ ilẹ Afrika atawọn ọmọ Amẹrika to jẹ adulawọ. Gẹgẹ bi Iyafin Ọlatunji ṣe sọ nipa ọkọ rẹ.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Babatunde Ọlatunji pẹlu Malcom X nibi ayẹyẹ kan lati sami ominira Naijiria kuro labẹ ijọba amunisin ilẹ Gẹẹsi ni Harlem lọjọ kini oṣu kẹwaa ọdun 1960
Ọlatunji di aarẹ ẹgbẹ awọn akẹkọọ nileewe giga Morehouse, eyi lo si mu ki o ṣe alabapade ọpọlọpọ awọn ajafẹtọ ọmọniyan nigba naa bii Martin Luther King Jr ati Malcolm X.
Afẹfẹ ijijagbara lọwọ ijọba amunisin to n fẹ kaakiri ilẹ Afirika laarin ọdun 1950 si 1969, ninu eyi ti oun pẹlu ti kopa, lo ṣe atọna fun ikopa Ọlatunji ninu iwọde ijafẹtọ ọmọniyan ni Amẹrika.
Ni ọdun 1958, o rinrinajo lọ si ilu Accra lati kopa nibi ipade apapọ awsn ọmọ ilẹ adulawọ, All African People's Conference, ti adari orilẹede Ghana lasiko igbominira rẹ, Kwame Nkuruma gbe kalẹ.
Ipade apapọ yii ko awọn aṣiwaju ija fun igbominira kaakiri ni Afirika atawọn aṣoju jọ lati orilẹede mejidinlọgbọn kaakiri ilẹ Afirika lati fi ọgbọn kun ọgbọn lori ọna ati tubọ tẹmpẹlẹ mọ atako ijọba amunisin awọn alawọnfunfun Yuroopu nigba naa.
Awọn eekan ajafẹtọ lorilẹede Amẹrika bii Claude Barnett, oludasilẹ ileeṣẹ itẹwe iroyin Associated Negro Press to wa ni Chicago ati Alphaeus Hunton, to jẹ akọwe igbimọ to n ṣe kokari ọrọ Afrika nigba naa.
Ọjọgbọn Louis Chude-Sokei, oludari ẹka ẹkọ imọ nipa ilẹ Afirika ati Amẹrika ni fasiti Boston, ṣalaye pe ifọrọwerọ ati ifimọ we imọ n waye laarin awọn ọmọ ilẹ Afirika atawọn ọmọ orilẹede Amẹrika to jẹ wi pe ominira awọn orilẹede bii Ghana ati Naijiria nigba naa lo n ṣe koriya fun wọn.
"O tun ṣalaye fun BBC pe, ""Pẹlu bo ṣe jẹ pe afojusun kan naa ni wọn ni nipa ijijagbara lọwọ iwa ẹlẹyamẹya, kii ṣe babara mọ lati ri awọn ọmọ ilẹ Afirika atawọn ọmọ orilẹede Amẹrika to jẹ adulawọ ti wọn n jọ n ṣe aṣepọ lori aṣa ati awọn ọrọ miran to jẹ mọ ominira ati ijijagbara"""
Lọdun 1957, Martin Luther King Jr, gba iwe ipe lati wa ba orilẹede Ghana ṣe ajọyọ ominira rẹ, nibẹ lo si ti pade. Ipade ye ni ipa manigbagbe lara King, ẹni to ri ọpọlọpọ iwuri mu jade fun igbesẹ jija fẹtọ ọmọniyan to gbe dani pẹlu eto ijijagba ominira orilẹede Ghana.
"Orilẹede Ghana ni ẹkọ lati kọ wa gẹgẹ bi ọrọ ti Luther King Jr sọ ninu iwaasu rẹ akọkọ lẹyin to pada de latorilẹede Ghana. ""Ẹkọ naa si ni pe...ko si amunisin to n fẹ fun ẹni to n sin in ni ominira bọrọbọrọ. Iṣẹ aṣelaagun lo gbọdọ ṣe."""
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Babatunde Ọlatunji sunmọ Martin Luther king to wa lapa alaafia ninu aworan yii ati Malcolm X to wa lapa ọtun- awọn mejeeji wa ninu fọto yii ni igba kan ṣoṣo ti wọn jijọ pade nigba aye wọn ldun 1964
"Ni ọdun 1962 nibi ipade apapọ awọn adari to jẹ alawọ dudu nilẹ Amẹrika, iyẹn American Negro Leadership Conference, Luther King Jr tunbọ yannana ibarẹpọ to wa laarin ijọba amunisin ni Afirika ati iwa idẹyẹsi ni Amẹrika, to si wi pe awọn mejeeji fẹ fi ara pẹra nitori gbogbo abalọ-ababọ rẹ naa ni ijẹgaba, fifi agidi munisinlu lọna oṣelu ati  tẹmbẹlu ọmọniyan."""
Amọ, akẹgbẹ Luther King, Malcolm X ni tirẹ fara mọ awọn igbesẹ idoju ija kọ awọn amunisin bi o ṣe n waye pẹlu awọn ọmọ ẹgbẹ Mau Mau lorilẹede Kenya, pẹlu igbagbọ pe lilo lara awọn igbesẹ wọn lee ran wọn lọwọ lati dẹkun awọn ẹgbẹ Ku Klux Klan ni Amẹrika.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Awọn ọmọ rẹ obinrin ni Ọlatunji lo ṣe awokọṣe fun ọpọ olorin Jazz, ko si fi iṣẹ ṣere
Bakan naa lo pade omilẹgbẹ awọn aṣiwaju ilẹ Afirika lati jiroro lori ijijagbara awọn smọ ilẹ Amẹrika to jẹ adulawọ, ki o si ri atilẹyin gba lọwọ aarẹ akọkọ lorilẹede Tanzania, Julius Nyerere. Lọdun 1964, Nyerere ran Malcolm X lọwọ lati rọ awọn aṣiwaju ilẹ Afirika lati buwọlu afẹnuko kan nibi ipade apapọ  ajọ iṣọkan awọn orilẹede Afirika, OAU to rọ ilẹ Amẹrika pe ko fopin si idẹyẹsi ati iwa ẹlẹyamẹya lorilẹede naa.
Malcolm  X tun ba awọn  awọn ọmọ ilẹ Afirika lorilẹede Amẹrika sọrọ, nibẹ loun ati Ọlatunji si ti pade to si rọọ pe ko wa lu ilu  nibi iwọde awọn ajijagbara nibẹ.
"Gẹgẹ bi ọrọ ti Atkinson sọ, ""O ni ajọṣepọ to dan mọran pẹlu Martin Luther King ati Malcolm X,"""
Baba jẹ alarinna laarin igun meji nigba naa: King jẹ ẹni to di opo alaafia mu, bẹẹni Malcolm kii fi gbogbo igba fara mọ iru ọna bẹẹ.
Ohun to nifẹ si to si mumu ni ookan aya rẹ
"Ọlatunji ṣe ọpọlọpọ ere fun ẹgbẹ NAACP ati ile ijọsin Souther Christian Leadership Conference to jẹ ti Luther King. Ni ọdun 1960, o farahan nini awo orin onijo Jazz fun ẹtọ ọmọniyan ti wọn pe akọle rẹ ni ""We Insist! Pẹlu akọwe ere oniṣe ni Oscar Brown Jr ati Max Roach."
Bi baba mi ṣe maa n fara si ere gbogbo to ba n ṣe nibi to ti maa n ṣe afihan ifẹ to ni si iṣe, ọrọ ẹkọ inu iṣẹ ọna rẹ atawọn ololufẹ rẹ a maa ya mi lẹnu pupọpupọ, Fọlaṣade, ọkan lara awọn ọmọ rẹ mẹrin lo sọ eyi fun BBC.
"O ni, ""Ẹmi itẹpamọṣẹ rẹ ga pupọ, eyi lo si fi kọ gbogbo awọn ọmọ rẹ atawọn to sun mọ ọ."""
"Ọmọbinrin rẹ kekere, Modupẹ naa fi kun un pe: ""Titi to fi jade laye ko fi ẹmi ifara jin fun iṣẹ naa silẹ"""
Ni ọdun 2003 ni baba wọn ku nigba to ku ọjọ kan ko pe ọmọ ọdun mẹrindinlọgọrin. Ogun orin kikọ ati jijafẹtọ smọniyanto fi silẹ ṣi n tẹsiwaju lati iran de iran, paapaajulọ laarin awọn ọmọ ilẹ Afirika to wa ni orilẹede Amẹrika bayii, ti wọn n fi igbe aye rẹ ṣe awokọṣe pẹlu bi o ṣe duro gẹgẹ bi alarena laarin ilẹ Afrika ati gbogbo agbaye yoku.
A ti tẹwọ gba iṣẹ naa lọwọ awọn iran to ti kọja lọ, awa naa si n tẹsiwaju pẹlu ire ije naa ti wọn bẹrẹ, ni ọrọ ti Omidan Tometi ti ẹgbẹ BLM sọ nipa rẹ.
"Ẹni to kọ iwe itan igbesi aye Ọlatunji fi kun un pe: ""Asiko to dara gan niyi fun awọn eeyan lati mọ nipa Baba."
Awọn iwọde fun idajọ odod wọnyi jẹ tuntun to si tun lagbara ju eyi ti baba kopa ninu rẹ lọgọta ọdun sẹyin.
Nothern Elders Forum: Ẹ wo ọ̀pọ̀ ohun tí ẹ̀kùn Àríwá ń fẹ́ àtúnṣe rẹ̀ nínú òfin ilẹ̀ wa
Oríṣun àwòrán, Hakeem Baba-Ahmed
Ẹgbẹ awọn agbaagba ni Ariwa Naijiria ti sọ pe ẹkùn naa yoo ṣiṣẹ pọ pẹlu awọn ẹ̀yà to ku ni Naijiria lati yan adari to koju òṣùwọ̀n.
Ẹgbẹ naa sọ eyi gẹgẹ bi erongba tuntun lori ìpinnu rẹ pe Ariwa ni Aarẹ yoo ti wa lọdun 2023.
Agbẹnusọ fun ẹgbẹ naa, Ọmọwe Hakeem Baba-Ahmad, lo sọ ọrọ naa ninu atẹjade to fi sita lẹyin ipade ti adari wọn, Ọjọgbọn Ango Abdullahi pè.
O sọ ninu atẹjade naa pe lara ohun ti wọn tun sọ nibi ipade naa ni pe, wọn fi ẹnu kò pe ki wọn wọgile awọn ajọ eleto idibo ni ipinlẹ ninu atunse ofin to n lọ lọwọ.
O ni awọn eniyan Ariwa fẹ ẹ sisẹ pọ pẹlu awọn ọmọ Naijiria to kù, lati yan adari to kun oju òṣùwọ̀n, ti yoo si da ẹ̀mí igbagbọ ati ireti nipa ọjọ ọ̀la pada si ọkàn araalu.
Mesach Oyediran: Ọba ni Dafidi tó ń lu dùùrù, tó sì kọ sáàmù, ta ni èmi tí kò ní le yin
Ẹgbẹ NEF sọ pe anfaani pupọ ni yoo jẹ fun awọn ọmọ Naijiria, ti awọn ẹgbẹ́ oṣelu miran ba wà, yatọ si PDP ati APC.
Bakan naa lo sọ pe asiko ti to fun ijọba, lati fi opin si awọn ajọ eleto idibo ni ipinlẹ, ki INEC si ma a ṣe ojúṣe wọn.
Wọn ni lootọ ni awọn naa korò oju si iṣẹ Boko Haram ni Ila Oorun Ariwa, sugbọn nkan to le mu ki awọn faramọ ki ijọba sapejuwe àwọn agbebọn naa ni agbesunmọmi, ni ti yoo ba mu ayipada rere ba eto aabo to mẹhẹ.
Ikoyi Collapsed Building: Àwọn ohun pàtàkì nípa Femi Osibona rèé
Oríṣun àwòrán, Screen Shot
Ni irọlẹ ọjọbọ, ọjọ Kẹrin osu Kskanla ọdun 2021 ni iroyin gba ilẹ kan pe ikọ to n se awari awọn eeyan to ha si abẹ ile to da wo ni Ikoyi nilu Eko ti ri oku ẹni to ni ile to wo naa.
Oluwa rẹ ni gbajugbaja akọleta, Femi Osibona.
Oun si ni alasẹ ati Oludari ileesẹ akọleta ati abani ra ilẹ Fourscore.
Lati ọjọ Aje, ọjọ Kinni osu Kọkanla ọdun 2021 ti ile alaja mọkanlelogun ti wọn n kọ lọwọ naa si adugbo Ikoyi, ti da wo lulẹ, ni ariwo ti sọ pe ẹni to ni ile naa wa nibẹ.
Odu ni Femi Osibona, kii se aimọ fun oloko ni awujọ awọn to n ta ilẹ ati ile ati awọn to n ra pẹl.
Ẹ wo ohun to yẹ kẹ mọ nipa oloogbe Femi Osibona
Mesach Oyediran: Ọba ni Dafidi tó ń lu dùùrù, tó sì kọ sáàmù, ta ni èmi tí kò ní le yin
Ọpọ eeyan lo ti n se idaro nipa akọni akọsẹmọsẹ akọleta naa to lọ, a si n gbadura pe ki Ọba Oke tẹ si afẹfẹ rere.
Lẹyin ọjọ kẹrin to ha sabẹ ile to wo ni Ikoyi, wọn ti ri oku Femi Osinbona yọ kuro ninu ile ọhun.
Oṣibọna ni baba olowo to n kọ ile  to wo naa ti ọpọ eeyan si ku ninu rẹ ni ọjọ Aje lopopona Gerard ni Ikoyi.
Akọroyin BBC jabọ pe awọn oṣoju mi koro ti ṣaaju sọ pe arakunrin Osibona wa ninu ile naa lasiko to wo ṣugbọn lati igba ti wọn ti n gbe oku jade wọn ko ti ri oku rẹ.
Amọ bayi awọn mọlẹbi rẹ ti sọ pe awọn ti ri oku rẹ ninu awọn ti wọn gbe jade lọjọbọ
Ẹwẹ, Kọmisana ọlọpaa Hakeem Odumosu tun fidi ọrọ yi mulẹ fun BBC pe lootọ ni wọn ti ri oku rẹ.
O ni  wọn ti gbe lọ sile iwosan awọn ologun to wa ni Ikoyi.
Babagana Umara Zulum: Nínú òṣìṣẹ́ ìlera 29 ta gbà sílé ìwòsàn náà, ẹyọ kan ṣoṣo ló wá láti tọ̀jú aláìsàn
Oríṣun àwòrán, The Governor of Borno State/Facebook
Iroyin ko to afojuba lọjọ ti gomina ipinlẹ Borno, Ọjọgbọn Babagana Umara Zulum, dibọn lai mura bii gomina lọ se abẹwo airotẹlẹ lọ sibudo ilera kan to jẹ tijọba lọjọbọ.
Gomina naa ko ko awọn ẹsọ tabi ọkọ afọnfere rẹ dani nigba to lọ sile iwosan naa.
Lasiko abẹwo rẹ naa, gomina ri awọn osisẹ ilera lorisirisi ti wọn n gba owo to to ẹgbẹrun mẹjọ si mẹwa naira lọwọ awọn alaisan fun itọju to yẹ ko jẹ ọfẹ.
Nigba to jẹ pe ọjọ ta ba ri ibi, ni ibi n wọlẹ, kia mọsa ni gomina Zulum ransẹ pe Kọmisana feto ilera, Arabinrin Juliana Bitrus, pe ko wa tẹle oun ninu ọkọ alaisan onijoko mẹwa ti wọn maa n lo ni papakọ ofurufu.
Deede aago kan abọ ọsan ọjọbọ ni gomina Zulum kuro nile ijọba lai fọn mọto fere yafunyafun eyi to ya ọpọ awọn amugbalẹgbẹ rẹ lẹnu.
Oríṣun àwòrán, The Governor of Borno State/Facebook
Koda, kọmisana feto ilera gan ko mọ idi to fi se bẹẹ, o sa n wo gomina ni.
Ni kete ti Zulum gunlẹ sile iwosan naa, lo lọ si ibudo ilera Gwange II ti wọn sẹsẹ kọ silu Maiduguri, tijọba si pese awọn ohun eelo ilera igbalode si.
Sugbọn se ni jẹbẹtẹ gbe ọmọ le gomina lọwọ nigba to ri awọn osisẹ peleto ilera to n gba owo riba to wa laarin ẹgbẹrun mẹjọ si mẹwa naira ki wọn to se ayẹwo tabi itọju alaisan to ni arun iba lasan
"Gomina ni ""Awọn osisẹ to wa nile iwosan yii, Gwange II  sọ pe ki awọn to le wo arun iba, awọn maa n gba to ẹgbẹrun mẹjọ si mẹwa naira lọwọ awọn alaisan."
Koda wọn ti sọ ibudo ilera ti ijsba kọ di ile iwosan aladani eyi to mu ki ọpọ araalu ti agbara wọn ko ka owo naa lati san, pa ile iwosan naa ti.
"Se ni awọn osisẹ ilera to wa nibẹ n gba owo naa, ti wsn si n da si apo ara wọn lai boju wẹyin."""
Gomina Zulum ti wa pasẹ fun ajọ to wa feto ilera alabọde nipinlẹ Borno lati tu isu de isalẹ koko nipa awọn osisẹ ile iwosan naa, ko si tete mọ awọn ọbayejẹ ẹda to wa nidi gbigba abẹtẹlẹ naa.
Oríṣun àwòrán, The Governor of Borno State/Facebook
Bakan naa lo ni gbogbo awọn osisẹ ti aje iwa ibajẹ naa ba si mọ lori ni ko fi iya to yẹ jẹ labẹ ofin.
Zulum ni ọkan rẹ wa bajẹ pe bi o tilẹ jẹ pe awọn akọsẹmọsẹ osisẹ ilera mọkandinlọgbọn nijọba n san owo osu fun nile iwosan naa, sibẹ, osisẹ ilera kan soso lo wa nibẹ, to n da awọn alaisan lohun.
Isẹlẹ yii lo tun mu gomina Zulum dibọn lọ sile iwosan ijọba miran, Gwange 1, amọ se lo ba ohun gbogbo to n lọ leto leto, bo se yẹ nibẹ, eyi to mu inu rẹ dun.
Se ni awọn osisẹ ilera to yẹ wa nikalẹ lati da alaidsan lohun lai gba owo riba kankan lọwọ wọn.
Mesach Oyediran: Ọba ni Dafidi tó ń lu dùùrù, tó sì kọ sáàmù, ta ni èmi tí kò ní le yin
Ikoyi collapsed building: Ta ló ń so Igbákejì ààrẹ, Yemi Osinbajo pọ̀ mọ́ ìṣẹ̀lẹ̀ ilé alájà púpọ̀ tó dà wó ní Eko?
Oríṣun àwòrán, Professor yemi osinbajo/ facebook/bbc
Lati igba ti iṣẹlẹ ile alaja pupọ kan to da wo lagbegbe Ikoyi nilu Eko ti waye lọjọ Aje, ọjọ kini oṣu Kọkanla ọdun 2021, oniruuru awuyewuye lo ti waye.
Bi awuyewuye ti ṣe waye lori ohun to fa iṣẹlẹ naa, ni awuyewuye waye lori iye awọn to ti ku, awọn ti wọn ti ri gbe jade laaye, ati bẹẹbẹẹ lọ.
Amọṣa lọwọ yii, awuyewuye to n waye ni lori ẹni gan to ni ile naa.
Bi o tilẹ jẹ pe iroyin lati ọdọ ijọba ti fidi rẹ mulẹ pe ọgbẹni Oṣibọna, ti oun pẹlu wa lara awọn ti wọn ti ku labẹ awoku ile naa lo ni ile alaja mọkanlelogun naa.
"Sugbọn awọn iroyin kan latọdọ awọn ileeṣẹ iroyin abẹle kan bii ""Sahara Reporters"" n mu orukọ miran jade. Orukọ ta ni?"
Ikoyi Collapsed Building: Bí ilé alájà mọ̀kànlélógún ṣe dà wó lulẹ̀ ní Ikoyi, l‘Eko rèé
"Ninu atẹjade kan to gbe jade ninu iwe iroyin rẹ ọjọ kẹrin oṣu Kọkanla ọdun 2021, Sahara Reporters ni ""wọn ti rii pe igbakeji aarẹ orilẹede Naijiria, Yẹmi Oṣinbajo ni ajọṣepọ pẹlu ile alaja mọkanlelogun to da wo nipinlẹ Eko"""
Iwe iroyin naa tun kọọ pe, awọn alami awọn sọ fun awọn pe Igbakeji Aarẹ Yẹmi Osinbajo lo ra ilẹ naa lọwọ oloye Michael Ade-Ojo, to jẹ oludasilẹ ileeṣẹ Elizade Motors, lẹyin to de ipo igbakeji aarẹ.
Oríṣun àwòrán, Professor yemi osinbajo/ facebook
Ileesẹ aarẹ Naijiria ti fi atẹjade sita lori rẹ pe ko si ohun to kan igbakeji aarẹ pẹlu dukia ilẹ ati ile to dawo naa.
Atẹjade kan ti agbẹnusọ fun igbakeji aarẹ, Ọjọgbọn Yẹmi Oṣinbajo, Laolu Akande fi sita sọ pe gbogbo dukia ti igbakeji aarẹ ni lo ti kede fun ijọba gẹgẹ bi ofin orilẹede Naijiria ti ṣe laa kalẹ.
"O ti wa setigbọ igbakeji aarẹ pe iroyin irọ kan ti ileeṣẹ iroyin Sahara Reporters gbe jade lọjọ kẹrin oṣu kọkanla ọdun 2021 n kaakiri nipa ile alaja pupọ to da wo laipẹ yii pe:
Atẹjade naa ni ko si nnkankan ti igbakeji aarẹ ba gomina ipinlẹ Eko tabi oṣiṣẹ ijọba ipinlẹ naa kankan sọrọ nipa yiyọ iwe ti wọn le fi ti ile naa pa ki o to dawo.
Ati pe ko si igba kankan to gbe igbesẹ lati di iṣẹ awọn ajọ to n mojuto ọrọ ile gbigbe nipinlẹ Eko lọwọ.
Igbakeji aarẹ ṣalaye ninu atẹjade naa pe, o fihan daadaa pe iṣẹ iroyin onisọnu lawọn ileeṣẹ agberoyin jade 'Sahara Reporters' ṣe, ti o si ti fi ṣọwọ si awọn agbẹjọro rẹ fun igbesẹ gbogbo to ba tọ.
Ki ni Oloye Micheal Ade-Ojo, alaga ileeṣẹ Elizade sọ?
Oríṣun àwòrán, ovation international
Amọṣa, Oloye Michael Ade-Ojo pẹlu ti sọrọ sita lori rẹ pe, irọ lasan niroyin naa ati pe oun ati Igbakeji aarẹ Oṣinbajo ko fi igba kankan ni idunadura lori ilẹ ti wọn kọ ile to da wo naa si.
O ṣalaye ninu atẹjade kan to funrarẹ buwọlu lati bomi pa ina awuyewuye ti iroyin iwe iroyin naa da silẹ pe, ilẹ to wa ni adojukọ ilẹ ti wọn kọ ile to da wo naa si ni toun, oun ko si ṣetan lati taa fun ẹnikẹni bi o ti wulẹ o mọ.
O ti wa seti igbọ mi pe atẹjade kan latọdọ Sahara Reporters n sọ pe emi ni mo ni ilẹ ti wọn kọ ile alaja pupọ to da wo ni Ikoyi nilu Eko."
Oríṣun àwòrán, Oloye Michael Ojo
"Iroyin naa tun sọ pe mo ta ilẹ naa fun igbakeji Aarẹ, Yẹmi Oṣinbajo, ni kete to wọle si ipo.
Irọ funfun balau ti awọn iroyin mejeeji yii. Mo wa n sọ ko ye tẹru tọmọ pe mi o fi igba kankan ni ilẹ yii."
Ko le ye gbogbo eeyan, Mo ni dukia kan si ẹgbẹ ile ti a n sọrọ rẹ yii, ti mi o si tii ta, ti mi o dẹ nii lọkan ati ta fun ẹnikẹni.
Awọn ọrẹ ati alabaṣiṣẹpọ Igbakeji Aarẹ naa ti da si ọrọ naa pẹlu
Oríṣun àwòrán, Professor yemi osinbajo/ facebook
Ẹwẹ, Ọgbẹni Richard Akinọla gbe atẹjade kan sita lorukọ awọn ọrẹ ati alabaṣiṣẹpọ Ọjọgbọn Yẹmi Osinbajo ninu eyi to ti yannana rẹ pe bii igba ti eeyan n parọ mọ aja lati lee sọ lorukọ buruku niroyin naa, eyi to pe ni kobakungbe.
"Awọn iroyin kan sọ pe Ọgbẹni Fẹmi Osibọna jẹ agbodegba fawọn eekan kan ni ijọba, awọn miran tilẹ so o pọ mọ igbakeji aarẹ, nigba ti awọn kan fi ọgbọọgbọn n darukọ gomina ipinlẹ Eko.
Fun anfani awọn ti wọn le fẹ gbọ ti iroyin aṣinilọna yii, awa gẹgẹ bii ọrẹ ati alabaṣiṣẹpọ igbakeji aarẹ n fẹ fọ orukọ rẹ mọ tonitoni pe ko mọ sii, bẹẹ ni ko nipin ajọni kankan ninu ileeṣẹ ẹni to kọ ile alaja naa tabi ọrọ aje rẹ."
Ju gbogbo rẹ lọ, lasiko ti a fi n ko iroyin yii jọ, ko din ni eeyan mẹrindinlogoji ti awọn oṣiṣẹ adoola ẹmi ati ọlọpaa ti kede pe wọn ti jade laye lẹyin ti wọn ri oku wọn gbe jade labẹ awoku ile alaja mọkanlelogun naa.
Ninu wọn ni Ọgbẹni Fẹmi Oṣibọna to ni ile naa wa.
Bẹẹni iṣe idoola ẹmi ṣi n tẹsiwaju, ti ijọba ipinlẹ Eko pẹlu si ti gbe igbimọ oluwadi dide lori rẹ.
Mesach Oyediran: Ọba ni Dafidi tó ń lu dùùrù, tó sì kọ sáàmù, ta ni èmi tí kò ní le yin
Baba Ijesha rape case: Ilé ẹjọ́ ti sún ìgbẹ́jọ́ sí ọjọ́ Kejìlá oṣù yìí
Igbẹjọ Baba Ijesha ti n tẹsiwaju nílé ẹjọ gíga to n gbọ ẹsun ifipabanilopo to wa ni Ikeja, niluu Eko.
Ikọ olupẹjọ mu ẹlẹri kan wà ṣiwaju adájọ lati sọ ohun ti oju rẹ tó nípa igbẹjọ náà lónìí.
Ẹlẹri ọhun to jẹ ọlọpaa, ASP Wahab Kazeem sọ pe oun loun ṣe ìwádìí ẹsun ti wọn fi kan Bàbá Ijesha.
Kazeem ni awọn gba ohun afurasi silẹ lórí ìwé ati lori fidio ti wọn fi ẹrọ ilewọ ya.
Ọ ni ìwádìí awọn fi hàn pé ọmọ kékeré ti ọjọ ori re ko ju mẹrinla lọ ní Baba ijesha fi ọwọ kan.
Ọ fi kun pe afurasi, ìyẹn Baba Ijesha jẹ́wọ́ fún àwọn pe lóòtọ ni oun fi ọwọ kan ọmọ naa lọnà tí kò tọ.
ASP Kazeem sọ níwájú ilé ẹjọ náà pé, ẹlòmíràn, ti wọn pe orúkọ rẹ ni Abigael so fún àwọn pe Baba Ijesha ba oun ṣe aṣemáṣe nigba ti oun wa ni ọmọ ọdún méjìlá, ṣugbọn Baba Ijesha ni irọ ni ẹsun náà.
O fi kun pe awọn ṣe ìwádìí ẹsun Abigael yíì lọ sí ilé tí afurasi naa n gbe tẹlẹ lagbagbe Ajah, nílùú Eko, ti ẹni tó ní ilé ọhun sí sọ pé lootọ ni Baba Ijesha n gbe ile naa tẹlẹ.
Ìkọ olupẹjọ ti fi ọrọ ti onile Baba Ijesha ni Ajah kọ, to fi mọ ọrọ arabinrin Abigeal ati ọrọ Baba Ijesha lelẹ gẹgẹ bíi ẹrí, ìyẹn exhibit nile ẹjọ náà.
Ṣugbọn agbẹjọro Baba Ijesha sọ pé kò yẹ ki ilé ẹjọ gba ọrọ naa wọlé nítorí onibara oun kọ ọrọ naa lẹyìn tí àwọn ọlọ́pàá tí kọkọ lu ni ilubara.
"Ewe, ile ìjọ ti gba ọrọ naa wọlé gẹgẹ bíi ""Exibit K."""
"Leyin náà ni ikọ olupẹjọ ṣàfihàn fọran kan níwájú adájọ, ninu fọran náà ni wọn ti n fi ọrọ wa afurasi lẹnu wò, nibi ti afurasi ti n sọ pé ""Mo fi ọwọ kàn ọmọ náà."""
Ṣugbọn olori agbẹjọro Baba Ijesha, Babatunde Ogele ni ẹrí náà ko l'ẹsẹ nilẹ nítorí agbẹjọro afurasi kò sí níbi tí wọn ti n fi ọrọ wa lẹnu wò, eyiti ko ba òfin mu.
Lẹyinorẹyin, adájọ Oluwatoyin Taiwo to n gbọ ẹjọ náà ti sun sí ọjọ Ẹtì, ọjọ kejìlá, oṣù yìí ki àwọn olupẹjọ le mu awọn ẹlẹri to kù wá, tii ṣe awọn ọlọpaa to kọkọ n ṣe iwadii ọrọ náà.
Ondo Amotekun: Kí ni ọ̀dọ́ àríwá 18 tó dirá ìjà ń wá l‘Ondo, tí wọn fi dojú ìjà kọ Àmọ̀tẹ́kùn?
Oríṣun àwòrán, Ondo Amotekun
Ọrọ ipenija aabo paapa ni ilẹ kaarọ o jiire lo mu ki awọn Gomina panupọ lati ṣe idasilẹ ikọ alaabo Amọtẹkun.
Igbesẹ naa ti wa n so eso rere bayi pẹlu bi Amotekun ipinlẹ Ondo ti ṣe n koju awọn to n wa lati ita  wa da omi alaafia ilu ru.
Ninu iṣẹ ti wọn ṣe taa ri  to gbọngbọn leleyi ti wọn ti mu awọn ọdọkunrin mejidinlogun kan  to dira ija wa lati ariwa Naijiria si ipinlẹ naa.
Ọga ikọ Amọtẹkun Oloye  Adeleye Olusanyero sọ fun BBC Yoruba pe loru Ọjọbọ lawọn ikọ Amọtẹkun ṣalabapade awọn ọdọ yi nigba ti wọn fẹ wọ Ondo.
O ni awọn gbiyanju lati da wọn duro ṣugbọn kaka ki wọn duro, niṣe ni wọn fi ọkọ wọn gun ori igi tawọn fi dina ti wọn si fere ge.
Oríṣun àwòrán, Ondo Amotekun
O ni koda wọn doju ija kọ awọn nipa yinyin ibọn lu awọn ṣugbọn awọn pada ribi mu wọn.
''Ni nkan bi kilomita mejilelogoji si Akure la ti pade wọn lỌjọbọ. A le wọn titi de ilẹ Oluji nibi ti ọwọ ti pada tẹ wọn''
Oríṣun àwòrán, Ondo Amotekun
Adeleye sọ pe nigba tawọn fọrọ wa dirẹba wọn lẹnu wo, o ni ẹni to ni koun gbe wọn wa ti ko awọn eeyan naa ati ẹru s'ọkọ ki oun to de idi ọkọ.
''Wọn kan ni ki n wa gbe wọn lọ si Ondo ni,mi o mọ wọn ri tabi nkan ti wọn gbe sọwọ'' ni alaye ti dirẹba naa ṣe fun ọga Amọtẹkun.
Amọ ọga Amọtẹkun ni awọn ko gba arakunrin naa gbọ rara.
Ninu awọn kan ti wọn ba lọwọ wọn ni ọta ibọn, ibọn atọwọda ati ọpọlọpọ ọbẹ.
Oríṣun àwòrán, Ondo Amotekun
Wọn ko ti sọ nkan ti wọn fẹ fi nkan ija yi ṣe tabi ibi ti wọn ti ran wọn wa.
Ọga Amtẹkun ṣalaye pe iwadii ṣi n lọ lọwọ ati pe bi awọn ba pari awn yoo ko wọn lọ si ileẹjọ.
''Ofin to da Amọtẹkun silẹ fun wa lagbara lati ṣe iwadii ti wa lori awọn taa ba ri pe wọn wu iwa ọdaran.''
''A fẹ ki araalu fọkanbalẹ pe digbi la wa lati koju awọn to ba fẹ da omi alaafi ilu ru.Iru rẹ ko ṣẹṣẹ maa waye. A o ni mikan lati koju wọn''
Ni nkan bi ọjọ meloo kan ni BBC jabọ pe Amọtẹkun mu awọn ọdọ mejidinlogun kan lati ariwa Naijiria ti wọn rin irin regberegbe.
Bi awọn wọn yi ko ṣe ri alaye ṣe lori nkan ti wọn wa ṣe, Amọtẹkun fawọn le Miyetti Allah lọwọ ti wọn si fi wọn le ọkọ pada si oke ọya.
Abubakar Shekau: Ìyá olórí Boko Haram banújẹ́ lórí bí ọmọ rẹ̀ ṣé ṣeọ̀pọ̀ èèyàn níbi
Oríṣun àwòrán, Screen shot
Yoruba bọ wọn ni ko sí bi a o ṣe peri aja, ti a ko ni pe ori ikoko ta fi se e.
Eyi lo difa fun Falmata Abubakar to jẹ iya olori ẹgbẹ agbesunmọmi Boko Haram, Abubakar Shekau  to figbe ta fun araye.
O ni ibanujẹ ọkan lo jẹ foun pe ọmọ ti oun bi lo n fa irora fun ẹgbẹlẹgbẹ awọn eeyan ti ko mọwọ ti mẹsẹ.
Eyi ni igba akọkọ ti iya Shekau yoo sọrọ lati igba ti iroyin kan gbe jade pe o ti ku.
Falmatu sọrọ yii ninu ifọrọwerọ kan lori ileeṣẹ amohunmaworan Trust TV nibi to ti sọ pe oun ko le sọ ni pato bo ya Shekau bimọ ko to faye silẹ lọ.
Oríṣun àwòrán, AFP
"Ohun kan ti o pa awa mejeeji pọ ni pe emi ni mo bi i lọmọ, o tan!
Mi o le sọ nipa iku rẹ gan an nitori ọdun mejidinlogun ni mo ri soju gbẹyin.
Ọrọ Shekau maa n fun mi ni ọgbẹ ọkàn, Ọlọrun nikan lo maa ṣe idajọ to tọ fún un pẹlu gbogbo nkan to ti ṣe.
Shekau kuku dagba labẹ mi gẹgẹ bí ọmọ ṣe maa n dagba labẹ obi.
Àmọ́, nigba to lọ si ilu Maiduguri, tíì ṣe olu ilu ipinlẹ Borno, lati lọ kẹkọọ nipa ẹsin islam lo ya iyakuya.
Níbẹ lo ti pade Muhammad Yusuf to jẹ oludasilẹ ẹgbẹ Boko Haram, Iya Shekau lo sọ bẹẹ."
Oríṣun àwòrán, VOA
Ẹgbẹ agbesunmọmi mii, ISWAP lo kede iku Shekau ninu fọnran kan to fi lede lọjọ karun ùn oṣu mẹfa ọdun 2021 yii.
Iroyin sọ pe Shekau fi ado oloro pa ara rẹ lẹyin tawọn ọmọ ẹgbẹ ISWAP lọ ka mọ Ibudo rẹ.
Ọdun 2009 ni Shekau di olori Boko Haram lẹyin ti Yusuf ku si atimọle awọn ọlopaa tan.
Bi awada bi ere ni Shekau bẹrẹ si ni dari ẹgbẹ naa lọjọ naa lọhu,n ki o to wa tan kalẹ dé ibi gbogbo ila oorun ariwa orilẹ ede Naijiria bayii.
Labẹ aṣẹ Shekau, Boko Haram ti ran ọpọ eeyan lọ sí ọrun ọsan gangan, wọn n ju ado oloro kaakiri ilu.
Wọn n ji awọn eeyan gbe, wọn si n tun ṣe ikọlu si ọgba ẹwọn níbi tí wọn ti n tu awọn ẹlẹwọn silẹ.
Lẹyin ti Shekau di ilúmọọka tan laarin ninu ẹgbẹ agbesunmọmi Boko Haram, awọn eeyan ilu rẹ maa n tiju lati b'awọn eeyan to wa lati awọn ilu mii nipinlẹ Bornu ṣe ajọṣepọ.
Wọn ni oju ọdaran l'awọn eeyan maa n fi wo awọn lawujọ.
Yusuf Harun to jẹ ọmọ ilu Shekau ṣalaye fún BBC pe ni gbogbo igba loju maa n gba oun ti nitori ọrọ Abubakar Shekau.
"Harun ni itiju nla lo jẹ pe ""ọmọ ilu Shekau ni mi tori iwa buruku ti Shekau n wu."
"Ọpọ ọmọ ilu wa ni kii le sọ pe ọmọ ilu Shekau ni awọn nitori oju tawọn eeyan maa fi n wo wọn lawujọ."""
Isa Sani to jẹ olugbe ipinlẹ Bornu ni ọpọ ọmọ ilu Shekau lo maa n sọ pe ilu miran ni awọn ti wọn wa tori itiju.
O ni Shekau ti fun ilu rẹ ni orukọ buruku eleyii ti o si le ma yipada láéláé.
Mesach Oyediran: Ọba ni Dafidi tó ń lu dùùrù, tó sì kọ sáàmù, ta ni èmi tí kò ní le yin
Anambra Governorship Election: Bí èsì ìbò ṣe ń jáde lọ́wọ́ ní Anambra
Bi ikọ kan ti se daadaa si
Abuja KerosineTanker Explosion:Àwọn ọmọdé àti ìsọ̀ jóná ráú-ráú nígbà tí táńkà kẹrosínìí jóná
Oríṣun àwòrán, Abubakar Usman/Facebook
Awọn eeyan ti ko si ẹnikẹni to le sọ iye wọn lo ti sọ ẹmi wọn nu ninu isẹlẹ ijamba ina kan to waye ni agbegbe Kubwa nilu Abuja.
Isẹlẹ ina ọhun to waye lalẹ ọjọ Ẹti ni awọn eeyan ti isẹlẹ naa soju wọn ni tanka epo Karosini to gbina lojiji lo sokunfa rẹ.
Ọwọja ina ọhun lo bẹrẹ si tan kalẹ bii ọwara ojo  si awọn ọja adugbo miran  to mule ti Kubwa, to si jo ọpọlọpọ sọọbu kanlẹ.
Koda, ọpọ eeyan ti ina ọhun gba mu lo jo kanlẹ, ti wọn si dagbere faye nigba ti awọn eeyan miran fara pa yanna-yanna.
Awọn eeyan ti isẹlẹ ijamba ina naa soju ina wọn sọ fun BBC pe awọn ọmọde kan gan jona kọja sisọ lasiko ti ina naa mu wọn.
Protein Marasmus: Wo èwu tó wà nínú kí ọmọdé má ní èròjà Protein lára
Oniruuru awọn eeyan lo n sọ iroyin to tako ara wọn nipa isẹlẹ ina ọhun, ti awọn kan si sọ pe ado oloro lo bu.
Amọ awọn ara adugbo ti isẹlẹ ijamba ina naa soju wọn salaye pe  tanka kan ti epo Karosini wa ninu rẹ lo gbina.
Nibayii, awọn ọlọpaa, awọn osisẹ panapana atawọn osisẹ adoola ẹmi nibi isẹlẹ pajawiri lo ti de sibi isẹlẹ naa.
Bakan naa ni awọn osisẹ ọlọpaa ti ya agbegbe ti ijamba naa ti waye sọtọ kawọn osisẹ pajawiri le raye sawari awọn eeyan to fori sọta isẹlẹ naa.
Afeez Akintunde: Ẹbí alága NURTW tí afurasí sọ́jà gbé nílùú Oyo sọ pé ó ní àìsàn ẹ̀jẹ̀ ríru
Oríṣun àwòrán, Akintunde Afeez
Iroyin miran tun ti jade nipa awọn oṣiṣẹ alaabo to ṣe e ṣe ko gbe Alaga ẹgbẹ awakọ ero, NURTW, tẹlẹ nilu Oyo, Alhaji Afeez Maruf Akintunde nile rẹ lọsẹ to kọja.
Ṣaaju ni ẹbi Akintunde kàn si BBC pe ni Ọjọru to kọja ni awọn kan to mura bi ọmọ ologun yabo ile rẹ to wa nilu Oyo, ti wọn si gbe e lọ sibi ti ẹbi rẹ ko mọ.
Ninu iroyin ti ileeṣẹ akoroyin jọ Naijiria, NAN, fi sita, ọmọ rẹ, Ọgbẹni Azeez Akbar sọ pe awọn ọmọ ikọ Operation Burst lo gbe baba oun.
Operation Burst ni ikọ alaabo ti ijọba ipinlẹ Oyo gbe kalẹ lati maa mojuto eto aabo. Awọn sọja ati awọn oṣiṣẹ alaabo mi si lo wa ninu ikọ̀ naa.
Ọgbẹni Akbar sọ pe ni owurọ kutu ni iṣẹlẹ naa waye. O ni koda, towẹẹli ti baba oun ro mọ idi ni wọn kọkọ fẹ fi maa gbe lọ, ki awọn ẹbi to bẹbẹ pe ki wọn o jẹ ko wọ aṣọ.
"Ileeṣẹ ajọ Operation Burst to wa nilu Oyo ni wọn kọkọ gbe baba oun lọ, ṣugbọn lẹyin iṣẹju diẹ, wọn fi nkan bo o loju, wọn si gbe lọ si ibi ti a ko mọ.
Nigba to tun di bi aago mọkanla alẹ ọjọ naa, wọn gbe pada wa sile lati mu foonu  rẹ. Lati igba naa si ni a ko ti mọ ibi to wa mọ."""
"O ni awọn ti de ọfiisi Operation Burst nilu Oyo, nibi ti wọn ti sọ fun awọn pe ""lati ilu Abuja ni awọn ti gba aṣẹ pe ki awọn ṣeto bi ọwọ yoo ṣe tẹ Alhaji Akintunde""."
Bakan naa lo sọ pe baba oun ni aisan ẹjẹ riru, to si ṣeeṣe ki ilera rẹ buru si ti ko ba fi ri oogun rẹ lo tabi jẹ awọn ounjẹ to yẹ.
Awọn afurasi osisẹ ologun kan ti gbe alaga ẹgbẹ awakọ ero NURTW tẹlẹri nilu Ọyọ, Alhaji Afeez Maroof  Akintunde lori ẹsun pe o n se onigbọwọ Sunday Igboho ati fifọ ọgba ẹwọn Abolongo.
L'owurọ Ọjọbọ, ọjọ Kejidinlogun osu Kọkanla ọdun 2021 ni awọn agbẹbọn to wọ aṣo ologun yawọ ile gbajugbaja oloṣelu naa.
Akintunde, to tun jẹ alaga tẹlẹri fun ẹgbẹ awakọ, NURTW nilu Ọyọ,  ti awọn eeyan mọ si 'Tula Ọyọ', ni awọn ologun gbe lọ lai darukọ ibi ti wọn ti wa tabi ṣe afihan iwe to fun wọn laṣẹ lati gbe igbesẹ naa.
Ọkan lara awọn ọmọ Akintunde to ba BBC Yoruba sọrọ, Alhaji Afeez Akbar ṣe alaye pe, ni nnkan bi i aago meje aabọ owurọ ni iṣẹlẹ naa waye ni ile wọn to n bẹ nilu Ọyọ.
O ni baba oun ro aṣọ mọ idi lasiko to n mura lati wọ ile iwẹ ni awọn afurasi aṣoju ileeṣẹ ologun to di ihamọra ogun naa ya wọle.
O ni kete ti wọn wọle ni wọn nawọ gan Alhaji Akintunde lai se ayẹwo ohunkohun ninu ile naa.
Timothy Adegoke: Màmá olóògbé ní ògó ilé àwọn ni wọ́n pa, ikú rẹ̀ kò gbọdọ̀ já sásán
Akbar fi kun ọrọ rẹ pe, lẹyin ọpọlọpọ ẹbẹ ti aya Akintunde bẹ, ni wọn to fun ọkọ rẹ lanfani lati wọ aṣọ, ti wọn si gbe lọ.
Idile Akintunde fi idi ọrọ mulẹ pe, gbogbo awọn afurasi ọmọ ologun to yawọ ile naa lo di ihamọra ogun, to fi mọ awakọ to gbe wọn wa.
O ni gbogbo aṣọ ti wọn wọ wa, ni ko si orukọ lara rẹ.
Awọn mọlẹbi Akintunde ni iwadiii ati ọfintoto tawọn se ṣe fi idi rẹ mulẹ pe ilu Abuja ni wọn gbe lọ, ti o si wa ni akata ẹka ileesẹ ologun kan lọwọlọwọ bayii.
Wọn ni  bo tilẹ jẹ pe ileeṣẹ ologun kọkọ jiyan ọrọ naa nigba ti ọkan lara awọn mọlẹbi Alhaji Akintunde pe wọn lori ẹrọ ibanisọrọ.
Akbar ni lara ẹsun ti wọn fi kan ni pe Alhaji Afeez Akintunde wa lara awọn to n ba Oloye Sunday Adeyẹmọ, ti ọpọ eeyan n pe ni 'Sunday Igboho ko owo jọ, lati pe fun idasile orilẹede Yoruba.
Bakan naa ni wọn tun fi ẹsun kan wi pe Akintunde mọ si bi awọn agbebọn kan ṣe ya wọ ọgba ẹwọn Abolongo nilu Ọyọ lọjọ kẹtalelogun oṣu kẹẹwa, ti wọn si tu awọn ẹlẹwọn silẹ.
Akbar ṣe alaye siwaju si i pe, baba oun ko mọ ohunkohun nipa awọn ẹsun ti wọn fi kan an.
"O ni lọwọ bayii, baba oun ko ni to ẹgbẹrun mẹwa naira ninu apo asunwọn rẹ. ""Nibo lo ti wa fẹ ri owo ṣe onigbọwọ fun Sunday Igboho?""."
O fi kun ọrọ rẹ wi pe ijọba lanfani lati ṣe iṣe iwadii ni gbogbo ọna, ki wọn si fi idi otitọ mulẹ.
Sunday Igboho: Ìjọba Buhari ló ní ẹ̀bi, ẹ yé dá ẹ̀bi rú àwọn tó ń bèrè fún 'Yoruba Nation'
Timothy Adegoke: Màmá olóògbé ní ògó ilé àwọn ni wọ́n pa, ikú rẹ̀ kò gbọdọ̀ já sásán
Akẹkọọ to n wa imọ kun imọ ni fasiti OAU ni Ile Ife ni Timothy Adegoke, idanwo si lo lọ se to fi duro sile itura Hilton to wa nilu naa.
Amọ lẹyin ọjọ diẹ lo di awati, ki wọn to wa ri oku rẹ lẹba ile itura naa, ti awọn ọlọpaa si ti ko awọn afurasi to jẹ osisẹ ile itura naa si ahamọ.
Koda, ẹni to ni ile itura naa, Ramon Adedoyin gan wa ni ahamọ ọlọpaa, ti iwadi si ti n lọ lọwọ.
Nigba ti BBC Yoruba de ilu Eruwa, tii se ilu abinibi oloogbe Adegoke, se ni awọn obi rẹ, ọmọ aya atawọn aburo rẹ n wa ẹkun mu.
Ninu ọrọ rẹ, aya oloogbe salaye bi ọkọ rẹ se rin, to fi se agbako iku ojiji, to si ni oun gbọ pe wọn ri aje lara ọkọ oun ni wọn se lo o.
Bakan naa ni awọn obi Timothy ni ogo idile awọn ni ọkunrin naa jẹ, iku rẹ ko si gbọdọ ja sasan, gbogbo ẹni to ba si lọwọ ninu dida ẹmi rẹ legbodo, ni ko gba idajọ to yẹ.
Nigba to n ba BBC Yoruba sọrọ lori isẹlẹ naa, agbẹnusọ fun ileesẹ ọlọpaa ipinlẹ Osun, Yemisi Opalola tako ọpọ ahesọ ọrọ to n lọ lori iku oloogbe naa lori ayelujara.
Opalola ni irọ to jinna sootọ ni pe wọn pa Timothy Adegoke lati fi se etutu ni nitori o ni ẹyin ara oloogbe naa kankan ko di awati lara rẹ.
Anambra election: Ìbẹ̀rù-bojo gbalẹ̀ bí ètò ìdìbò gómìnà Anambra yóò ṣe waye lónìí
Lati ọjọ Ẹti ọjọ karun un oṣu kọkanla ni ibẹru-bojo ti gbalẹ nipinlẹ Anambra ṣaaju eto idibo gomina ipinlẹ naa lonii ọjọ Abamẹta.
Gbogbo ọja, opopona ati ile ifowopamọ lo da paro paro nitori ẹru n ba awọn eeyan lati jade.
Koda, awọn eeyan kan sa kuro nipinlẹ Anambra lati sa asala fun ẹmi wọn nitori wọn ko mọ ohun to le ṣẹlẹ lasiko eto idibo.
Ọpọ eeyan ni wọn ri ni ibukọ nibi ti wọn ti n wọ ọkọ lọ si ipinlẹ Enugu, Delta. Edo, nigba ti awọn mii n lọ si ipinlẹ Abia.
Ọkan lara wọn to sa lọ si ilu Asaba nipinlẹ Delta ni oun ti fẹ lọ fori pamọ titi di igba ti eto idibo naa yoo fi tan.
Ẹlomiran tiẹ sọ pe ọkan oun ko balẹ lati duro si Awka ti ṣe olu ilu ipinlẹ Anambra lasiko idibo, o ni Enugu ni oun mori le.
Oríṣun àwòrán, INEC
Ẹnikan ti ko darukọ ara fawọn akọroyin ni ko si ẹni to fẹ ku lo jẹ kawọn eeyan maa kuro ni Anambra ṣaaju eto idibo gomina.
O ni ẹgbẹ IPOB lo jẹ ki onikaluku maa bẹru pẹlu ohun ti wọn n ṣe nilẹ Igbo.
Ohun to jẹ iyalẹnu fun ọpọ eeyan ni pe ẹgbẹ IPOB ti fagile ofin konle-o-gbele to kede ṣaaju eto idibo ọhun eyi to le maa mu awọn eeyan bẹru.
Bakan naa ni ileeṣẹ ọlọpaa kede pe awọn agbofinro ẹgbẹrun lọna mẹrinlelọgbọn ni yoo mojuto eto idibo naa ki abo to peye le wa.
Ẹgbẹ awọn agbaagba nilẹ Ibo, Ohanaeze Ndigbo naa parọwa si awọn eeyan ipinlẹ Anambra lati jade dibo lonii lai bẹru.
Amọ, awọn kan ni aijade awọn eeyan ipinlẹ naa nii ṣe pẹlu bi ijọba ṣe kede ọjọ meji gẹgẹ bi ọjọ isinmi lati gbaradi fun eto idibo gomina tuntun ipinlẹ Anambra.
Ọpọ eeyan lo ti ra ounjẹ sile ṣaaju eto idibo ki wọn le maa ri nkan ninu ile wọn ti wọn ko ba jade lasiko idibo.
Awọn eeyan tiẹ sọ pe ẹru n ba awọn pẹlu bi awọn ẹṣọ eleto abo ti pọ nipinlẹ Anambra tawọn ti ibọn ati oriṣiiriṣii ohun ija oloro lọwọ wọn.
Niger Republic killings: Buhari ṣèlérí ìrànwọ́ láti dojú ìjà kọ agbésùnmọ̀mí láwọn ilẹ̀ tó yí Nàijíríà ká
Oríṣun àwòrán, Facebook/Bashir Ahmad
Aarẹ Muhammadu Buhari ti bu ẹnu ẹtẹ lu iṣẹlẹ ipaniyan to ṣẹlẹ ni orilẹede Niger Republic.
Aarẹ Buhari sọrọ yii lọjọ Ẹti lori bi iṣẹlẹ igbesunmọmi ṣe n gbilẹ si to si n tan kalẹ kaakiri.
Eeyan bii mọkandinlaadọrin lawọn agbesunmọmi pa ni ifanna faṣu laarin ibode Niger ati Burkina Faso.
Ninu atẹjade ti oludamọran Aarẹ Buhari, Garba Shehu fi sita, aarẹ ṣeleri iranwọ fun orilẹede Niger atawọn orilẹede to yi Naijiria ka lati doju ija kọ awọn agbesunmọmi nibẹ.
Buhari ṣe apejuwe iṣẹlẹ ipaniyan naa gẹgẹ bi eyi to ba ni lọkan jẹ pupọ.
Protein Marasmus: Wo èwu tó wà nínú kí ọmọdé má ní èròjà Protein lára
''Ibanujẹ ni o jẹ bi awọn agbesunmọmi ṣe da awọn eeyan loro kaakiri apa iwọ oorun ilẹ Afirika.
A gbọdọ sa gbogbo agbara wa lati ri pe a ṣegun awọn agbesunmọmi lapa iwo oorun Afirika.
Ọrọ igbesunmọmi kii ṣe ohun ti a le maa fi oju iṣẹlẹ abẹle wo mọ.
Igbesunmọmi dabi ina inu ọyẹ to n ran kaakiri bayii lapa iwo oorun ilẹ Afirika.
Asiko ti wa to bayii lati wa egbo dẹkun fawọn agbesunmọmi to n ṣakoba fun ọrọ aje awọn orilẹede lapa iwọ oorun Afirika,'' Buhari lo ṣalaye bẹẹ ninu atẹjade ti ileeṣẹ aarẹ fi sita.
Sierra Leone Tanker explosion: Ìjàmbá iná sọ lásìkò tí táńkà epo àti ọkọ̀ akérò forí sọra
Oríṣun àwòrán, Reuters
O kere tan, eeyan mejilelaadorun lo ti farapa ninu iṣẹlẹ ijamba ina kan to wáyé nilu Freetown, lorile-ede Sierra Leone.
Ijamba ina náà lọ waye nigba ti ọkọ akẹru ati tanka epo bentiroolu fi ori sọ ara wọn.
Opopona Bai Bureh ladugbo Wellington nilu Freetown tii ṣe Olu ilu Sierra Leone ni iṣẹlẹ naa ti waye.
Ọpọlọpọ eeyan lo sare lọ bu epo bentiroolu nigba ti iṣẹlẹ naa waye, àmọ́ sadede ni iná sọ, ti ọpọ eeyan si ha síbẹ̀.
Iroyin naa ni ṣe ni wọn gbe awọn eeyan to farapa  sile ìwòsàn kaakiri ìlú Freetown.
Ààrẹ orílẹ̀èdè Sierra Leone, Julius Maada Bio wa ni Scotland nibi to ti n ba wọn peju sibi ipade apero nípa oju ọjọ lagbaye COP26, lasiko ti iṣẹlẹ naa waye.
Àmọ́ loju opo Twitter rẹ lo ti n daro àwọn eeyan to fori sọta iṣẹlẹ naa.
Protein Marasmus: Wo èwu tó wà nínú kí ọmọdé má ní èròjà Protein lára
Adanu ẹ̀mí to ba ni lẹru ni iṣẹlẹ naa, ijọba mi yoo sa ipa gbogbo lati ṣe iranwọ fáwọn eeyan to fori sọta ijamba ina náà.
Olootu ìjọba ilu Freetown, Yvonne Aki-Sawyer ni oku eeyan mẹrin lo si wa nibi ti iṣẹlẹ naa ti waye.
Awọn ọlọ́pàá ti n ṣe iranwọ fun àjọ to ń ṣe akoso ijamba lorilede Sierra Leone lati doola ẹ̀mí ninu ijamba ọhun.
Ikoyi house collapse: Sanwo-Olu ṣèlérí ìrànwọ́ owó fún ètò ìsìnkú àwọn tó kú
Oríṣun àwòrán, Babajide Sanwo-Olu
Gomina ipinlẹ Eko, Sanwo-Olu ti ṣeleri pe ijọba yoo ṣe iranwọ owo fun eto isinku awọn ti ile alaja mọkanlelogun wo pa lagbegbe Ikoyi niluu Eko lọjọ Aje ọjọ kinni oṣu kọkanla ọdun 2021 yii.
Sanwo-Olu sọrọ yii nigba to tun ṣe abẹwo si ibi ti ile naa ti dawo lọjọ Abamẹta niluu Eko.
Gomina ipinlẹ Eko fun awọn to ba fẹ ni iranwọ owo naa wa fun nitori awọn ẹbi mii le maa nifẹ si iru owo bẹẹ.
Wòólì Alfred kú lọ́dún 1964, ó tún padà wà sí ìlú Agelu f'ọ́jọ́ mẹ́rìnlá!
Bakan naa ni Sanwo-Olu ṣalaye pe ijọba ipinlẹ Eko tun ti ṣe iranwọ owo fawọn to moribọ nibi iṣẹlẹ naa.
O ni owo ti ijọba fun wọn yoo ran wọn lọwọ pẹlu jijẹ mimu lẹyin ti wọn ba gbadun tan.
Ẹwẹ, gomina ipinlẹ Eko ti sọ pe ijọba ti ri eeyan mẹfa mii ti wọn yọ laaye nibi ile naa.
Sanwo-Olu ni awọn eeyan mẹfa naa wa lara awọn tawọn ẹlẹyinju aanu kan tete yọ gbara ti iṣẹlẹ ọhun ṣẹlẹ.
Gomina ni orukọ awọn eeyan naa ni Glory Samsom, Ndajor Ahmed, Yunusa Abubaka, Ajiboye Habib, Jeremiah Samson, ati ọkunrin kan to n jẹ Emem.
O ni ile iwosan ileeṣẹ ọlọpaa Police Hospital ni Falomo ni wọn gbe awọn eeyan naa lọ fun itọju nibi ti awọn kan ti lọ sile lara wọn lẹyin ti wọn gbadun tan.
Gomina ni o ti di eeyan mẹẹdogun to moribọ bayii nibi iṣẹlẹ naa pẹlu mẹsan an tawọn oṣiṣẹ adoola ẹmi yọ laaye tẹlẹ.
Sanwo-Olu to ṣabẹwo si ibi ti ile ọhun ti dawo pẹlu Aṣiwaju Bola Tinubu sọ pe o ti di oku eeyan mejilelogoji ti wọn ti yọ labẹ ogiri alapa to wo bayii.
Gomina ipinlẹ Eko ni awọn ẹbi awọn eeyan to ku ti bẹrẹ si ni maa wo awọn eeyan wọn ninu oku to wa ni mọṣuari.
Sanwo-Olu ni ijọba n ṣe ayẹwo oku awọn ti wọn ko le damọ daadaa ki awọn ẹbi wọn le mọ oku to jẹ ti wọn.
Gomina ni iṣẹ si n lọ nibi ti iṣẹlẹ naa ti waye lati yọ awọn to ba si tun wa labẹ ogiri alapa.
Ikoyi house collapse: Bíríkìlà t'órí kó yọ ní òun rò pé òun máa kú ni lẹ́yìn tí ó wà lábẹ́ ògiri àlàpà fún ọjọ́ kan
Oríṣun àwòrán, LASEMA
Aja to re'le ẹkun to bọ, o yẹ ka ki aja ku ewu.
Bayii gan an ni ọrọ ṣe ri pẹlu awọn eeyan to moribọ nibi ile to da wo lagbegbe Ikoyi niluu Eko lọjọ kinni oṣu kọkanla.
Iroyin ko to amojuba ni ọrọ naa lẹyin tawọn ọhun ṣalaye ohun ti oju wọn ri labẹ ogiri alapa ti wọn ha si ki iranwọ to de lati fa wọn yọ.
Bí mo ṣe káa sára tí mo gbé òkú ọmọ sínú ọkọ̀ lọ ṣe iṣẹ́ apanilẹ́rìín láì fihàn - Woli Agba Ayo Ajewole
"'Wọ́n gba irun abẹ́ wa, irun abíyá wa, a lọ búra, ilé ""Nylon"" la tún ń gbé ni Mali fi ṣe iṣẹ́ aṣẹ́wó'"
Ta ló ni ilé alájá 21 tó wó pa àwọn èèyàn ní Ikoyi gan? Ìjọba Eko ti fèsì
Ọkan lara awọn eeyan mẹẹdogun ti ori ko yọ nibi iṣẹlẹ naa, Nurudeen Solagbade to ba awọn akọroyin sọrọ nile iwosan nibi to ti n gba itọju ṣalaye pe oun ko mọ pe oun ko ni ba iṣẹlẹ naa lọ.
Solagbade ẹni ọdun mẹtalelọgbọn wa lara awọn birikila to n rẹle nibi ile ọhun ki o to wo lulẹ.
Solagbade to jẹ ọmọbibi ilu Iwo ni awọn marunlelọgbọn ni awọn jọ lọ ṣiṣẹ nibi ile naa lati Ibafo nipinlẹ Ogun.
"''Ori aja kẹẹdogun ile naa ni mo ti ṣiṣẹ nibi ti mo ti n rẹle ki ile naa to dawo lojiji lọjọ naa""."
Ọjọ akọkọ ti maa lọ ṣiṣẹ nibẹ naa ni iṣẹlẹ yii ṣẹlẹ, koda n ko ba ti lọ sibi iṣẹ ọhun amọ ko si owo ti mo fi le gbọ bukata ẹbi mi lọwọ ni.
Emi ati ọmọ ilu mi, Waliu Lateef ati Ayo(ti wọn si n wa oku rẹ) ni wọn gbe iṣẹ rirẹ aja kẹẹdogun naa fun pe awọn yoo san ẹgbẹrun lọna ogoji naira fun wa.
O kudiẹ ki a pari iṣẹ lọjọ naa ni ile yii dawo, mo kọkọ ro pe ẹrọ ''lift'' ile naa lo wo lulẹ ni ki n to rii pe ogiri alapa ti bo mi mọlẹ.
Lẹyin ti mo lo wa labẹ ogiri alapa fun ọjọ kan lai si ounjẹ, omi ati afẹfẹ lati mi sinu daadaa pẹlu oku awọn eeyan to rọgba yi mi ka, mo ro pe opin ti de ba aye mi ni.
Afi ti mo ri iho kekere kan ti aff ti rọra n fẹ wle gbe imu mi si.
Wòólì Alfred kú lọ́dún 1964, ó tún padà wà sí ìlú Agelu f'ọ́jọ́ mẹ́rìnlá!
A o le sun o le sun loru ọjọ Aje iṣẹlẹ naa titi di owurọ ọjọ keji, a ni lati rakoro lọ si ibi iho kan ti atẹgun ti wọle diẹ diẹ lati le maa mi daadaa.
Laarẹ ọjọ keji ọjọ Iṣẹgun ni a gbọ ohun awọn eeyan ti a si bẹrẹ si ni ke fun iranwọ lati jade kuro labẹ ogiri to wo luwa mọlẹ.
Nigba to ya ni wọn da wa lohun pe ki a fara balẹ, Ọlọrun fun rẹ lo yọ wa, o ju ọgbọn ati oye wa lọ.
Mi o tiẹ lero wi pe mo le moribọ lati ri awọn ẹbi mi pada tori ọpọ ni a jọ ha si abẹ ile to da wo naa.
Mo si jẹ irora ni ẹyin ati ẹsẹ osi mi, ṣugbọn mo si n gba itọju to peye lọwọ nile iwosan,'' Solagbade lo sọ bẹẹ.
Ẹwẹ, Lateef to wa pẹlu Solagbade naa sọ pe oun ko mọ pe oun si tun le wa laye mọ.
Lateef ni ''mo ti gbadura lati beere fun aanu lọwọ Ọlọrun nitori mo ti ro pe opin ti de ba aye mi labẹ ile to wo lu wa mọlẹ.
Aanu Ọlọrun ko mi yọ tori mo ti gbadura ki n le ri ọrun wọ, ori idubulẹ ni mo wa fun ọpọ wakati ti o si rẹ mi sibẹ.
Ogiri ti wo lu ọpọ eeyan mọlẹ ti wọn si tiraka lati mi, kii ṣe iku to dara lati ku rara, koda n ko gbadura rẹ fun ọta mi.
Oku awọn eeyan pọ nibi ti mo wa eleyii to bami lẹru, n ko le ṣiṣẹ mọ nibi ile to ba ga pẹlu iriri mi nibi iṣẹlẹ yii.''
Lateef fi oju, aya ati ẹsẹ ọtun rẹ ṣeṣe, amọ o si n gba itọju lọwọ nile iwosan.
Gomina Babajide Sanwo-Olu fidi rẹ mulẹ pe eeyan mẹẹdogun ni Eledua ko yọ nibi iṣẹlẹ naa nigba ti wọn ti ri oku eeyan mejilelogoji yọ nibẹ.
Protein Marasmus: Wo èwu tó wà nínú kí ọmọdé má ní èròjà Protein lára
Afenifere sọ̀rọ̀ àbùkù sí agbẹnusọ Buhari lẹ́yìn tó tako àwọn tó ń bu ẹnu àtẹ́ lu ìjọba rẹ̀
Oríṣun àwòrán, Ournaijanews
Ẹgbẹ ọmọ Yoruba, Afenifere ti sọko si agbẹnusọ Aarẹ Muhammadu Buhari, Femi Adesina, lori bo ṣe tako awọn to n bu ẹnu atẹ lu ijọba to wa lode.
Akọwe agba ẹgbẹ Afenifere, Sola Ebiseni lo sọ ọrọ naa ninu atẹjade kan pe ijọba Buhari ti ja awọn ọmọ Naijiria kulẹ, o si tọ ki awọn araalu maa sọrọ abuku si.
Ṣaaju ni Adesina ti kọkọ sọ pe oun dẹkun lati maa lọ si ṣọọṣi kan niluu Abuja nitori pe alufaa ijọ maa maa n bu ẹnu atẹ lu iṣẹjọba Buhari.
Atẹjade ọhun ni lati igba aye awọn wolii ninu bibeli ni wọn ti maa sọrọ si ijọba ti asiko ba n ni awọn araalu lara.
"O ni ""Laye igba ti wa yi gan, awọn ojiṣẹ Ọlọrun bii Martin Luther king, Desmond Tutu, Biṣọọbu agba Okogie, Biṣọọbu Gbonigi, Matthew Kukah, Tunde Bakare atawọn mi ko dẹkun lati maa ba ijọba sọ ootọ ọrọ ti wọn ko ba ṣe daadaa."""
Afenifere sọ pe bo tilẹ jẹ pe awọn ojiṣe Ọlọrun kan n ba ijọba sọ ootọ ọrọ, awọn ojiṣẹ Ọlọrun mii wa ti wọn ko le ba ijọba ijọba sọ eyii tii ṣe ododo ọrọ nitori ohun ti wọn yoo jẹ.
Ẹgbẹ ọmọ Yoruba naa tẹsiwaju pe irufẹ awọn ojiṣẹ Ọlọrun bẹẹ lo n tan Aarẹ Muhammadu Buhari jẹ pe o le maa ṣe ohun to wu bii ko maa fi iya jẹ awọn ajijabara nigba ti awọn ọdaran n yan fanda laarin ilu.
Protein Marasmus: Wo èwu tó wà nínú kí ọmọdé má ní èròjà Protein lára
"O ni ""A ni awọn iranṣẹ Ọlọrun kan bii awọn irinwo wolii Ahabu ninu bibeli ti wọn n doju ija kọ Michaili, awọn lo n jẹ ki awọn adari tubọ maa ṣe aṣiṣe si."""
Irufẹ awọn olubadamọran bẹẹ pọ ninu ijọba yii ti wọn jẹ ki Aarẹ gbagbọ pe o lagbara lori ilẹ awọn ẹya kan, ati pe wọn le yan lati fọwọ mu ilẹ wọn tabi ẹmi wọn.
Awọn eeana yii kan naa ni wọn n tan Aarẹ jẹ pe awọn eeyan bii Sunday Igboho le pin Naijiria ati pe pipa Nnamdi Kanu nikan ni ọna abayọ si ọrọ awọn ajijagbara Biafra.
Oba Gbolahan Timson shomolu: Obasanjo ti jẹ́wọ́ pé 'Mistake' ni Buhari ṣùgbọ́n...
Onigbeti: Ọba ìlú Igbeti, Emmanuel Oyekan Oyebisi Afasegbejo I, ti wàjà
Oríṣun àwòrán, PAce setters News
Onigbeti ti ilu Igbeti, Ọba Emmanuel Oyekan Oyebisi, Afasegbejo I, ti jade laye.
Ori ade naa gori itẹ awọn baba nla rẹ lọdun 2004 ko to dagbare faye lẹni ọdun mẹtadinlọgọrin lọdun 2021.
Alaafin ti ilu Oyo, Ọba Lamidi Olayiwola Adeyemi III, ti ba ẹbi ati gbogbo awọn olugbe ilu Igbeti kẹdun iku ọba alaye naa.
"'Wọ́n gba irun abẹ́ wa, irun abíyá wa, a lọ búra, ilé ""Nylon"" la tún ń gbé ni Mali fi ṣe iṣẹ́ aṣẹ́wó'"
Ninu atẹjade kan lori Facebok ni Alaafin ti ba ẹbi atawọn eeyan nilu naa kẹdun.
"Atẹjade ọhun ni ""Alaafin Ọba Adeyemi III ba ẹbi, awọn ọmọ ọba atawọn eeyan ilu Igbeti kẹdun lori iku Ọba Emmanuel Oyebisi Afasegbejo I."""
A gbadura fun ẹbi ati araalu ti fi silẹ saye lọ ki Ọlọrun tu wọn ninu.
Wòólì Alfred kú lọ́dún 1964, ó tún padà wà sí ìlú Agelu f'ọ́jọ́ mẹ́rìnlá!
Ẹwẹ, kọmiṣọna fun ọrọ agbegbe ati ohun amuṣagbara ni ipinlẹ Oyo, Abiodun Oni naa tun ti ba ẹbi oloogbe ọhun kẹdun.
Oni sọ pe ki awọn eeyan ilu Igbeti ma ṣe ba ọkan jẹ nitori oloogbe naa gbe igbe aye rere ko to dagbare faye.
Awọn ẹbi oloogbe ti ni awọn yo kede bi eto isinkun rẹ yoo ṣe lọ laipẹ.
Protein Marasmus: Wo èwu tó wà nínú kí ọmọdé má ní èròjà Protein lára
Sale of baby born by mentally challenged wowan: Òṣìṣẹ́ ìjọba méjì tó ta ọmọ aláàrùn ọpọlọ l'Ondo fojú bálé ẹjọ́
"Awọn olupẹjọ ninu igbẹjọ awọn oṣiṣẹ ijọba meji, Adeyemi Sarumi ati Florence Orisamehin lori ẹsun jiji ọmọ arabirin Deborah Olorundare ti o ni ipenija ọpọlọ ni ipinlẹ Ondo ni wọn ti fi orukọ ẹlẹri mẹwa silẹ lati gbe ẹjọ wọn lẹsẹ.Awọn oṣiṣẹ agba meji naa nile iṣẹ to n mojuto ọrọ awọn obirin ati idagbasoke awujọ nipinlẹ Ondo ni wọn koju ẹsun ilẹdi apo pọ ati ijinigbe leyi ti wọn ni awọn ko jẹbi rẹ.Lẹyin ti wọn ko awọn ẹni afẹsunkan naa de iwaju onidajọ Adeyemi Fasanmi ti ile ẹjọ giga ipinlẹ Ondo to kalẹ si ilu Akure, adari awọn agbẹjọro awọn olupẹjọ, Bunmi Koyenikan, sọ pe ijọba ti ṣetan ẹjọ bi ko ṣe ti iwe ti awọn olujẹjọ beere fun.Koyenikan ni awọn mẹta ninu awọn ẹlẹri ti wọn fẹẹ pe ni wọn wa nile ẹjọ, ti awọn toku si ṣetan lati yọju lakoko ti ile ẹjọ ba ṣetan lati ri wọn.Agbẹjọro awọn afẹsunkan mejeeji, Steve Adebọwale ati Victor Olatoyegun, sọpe wọn ko le tẹsiwaju pẹlu ẹjọ naa nitori pe wọn nilo lati gba awọn iwe akọsilẹ kan latọwọ awọn olupẹjọ lati fi ṣegbe lẹyin ẹjọ wọn.Awọn iwe akọsilẹ naa lofimọ awọn nkan ti olupẹjọ fẹ lo lati fi ṣagbekalẹ ẹjọ wọn, akọsilẹ ẹri awọn olujẹri ti ajọ DSS ati awọn eṣọ alaabo miran fọrọ wa lẹnu wo, papajulọ eyi to tako awọn afẹsunkan .Wọn waa bẹbẹ beeli f'áwọn afẹsunkan naa.Ninu ìdájọ rẹ, onidajọ Fasanmi fun Sarumi and Orisamehin ni beeli miliọnu kan naira ati oniduro wọn ti o gbọdọ jẹ oṣiṣẹ ijọba ti owa ni akaṣọ kejila soke.O fun awọn olujẹjọ ni ọsẹ kan lati ṣe gbogbo eto beeli wọn, o si sun igbẹjọ si ọjọ kejidinlogun oṣu kini odun 2022  ki atotonu le bẹrẹ ni pẹrẹwu.Onidajọ Fasanmi kọ ẹbẹ agbẹjọro Adebowale lati maṣe jẹ ki awọn akọroyin bawọn pejọ fun ẹjọ naa lori ẹsun pe awọn kan lara wọn gbe iroyin kobakungbe nipa awọn afẹsunkan.Ninu ọrọ rẹ ""ẹjọ yi jẹ eyi ti o kan ara ilu. Ako le sọpẹ ki awọn akọroyin ma bawa pejọ. Ti wọn ba kọ iroyin ti ko tọ, ẹ pe wọn lẹjọ. Emi ko ni agbara lati paṣẹ lati majẹ ki awọn akọroyin maa wa sile ẹjọ. Bẹẹ ni ẹ ko tii tọka si iroyin kan ti wọn kọ ti o tabuku yin"""
Fun ẹsun igbimọpọ lati ta ọmọ arabirin kan, Deborah Olorundare to ni arun ọpọlọ, awọn oṣiṣẹ ijọba meji, Adeyemi Sarumi ati Florence Orisamehin ti farahan niwaju ile ẹjọ giga kan niluu Akure.
Awọn oṣiṣẹ ijọba mejeeji yi ni wọn n koju ẹsun ipadi apo pọ ati jiji ọmọ gbe niwaju onidajọ Adeyemi Fasanmi ti ile ẹjọ giga ipinlẹ Ondo.
Ọmọ Deborah ti wọn tọju si ile awọn ọmọ alailobi nipinlẹ Ondo ki iya rẹ fi le gbadun ni awọn afurasi naa ta fun obirin kan ni ọpọlọpọ naira.
Deborah, to sọ pe ọmọbirin ni oun bi, ni wọn gbe ọmọkunrin kan ti ko gbadun fun lẹyin ti ara rẹ ya tan leyi to mu ko figbe bọnu.
Ajọ ọtẹlẹmuyẹ DSS ni wọn ṣe ọfintoto ọrọ naa ti wọn si fi abọ iwadi wọn ṣọwọ si ijọba leyi to mu ki wọn fa Sarumi ati Orisamehin de waju adajọ.
Awọn to yọju sile ẹjọ laarọ yii ni awọn oṣiṣẹ ijọba meji ti wọn fẹsun kan, agbẹjọro wọn, ẹbi ati awọn agbẹjọro ijọba ti arabinrin Bunmi Koyenikan dari wọn.
Ẹwẹ, ohun ti a gbọ ni pe obinrin ti awọn afurasi yii ta ọmọ naa fun ti tẹkọ leti lọ si oke okun, ti ko si ṣeni to le sọ akoo ti yoo pada wa si Naijiria.
'Ẹ yé tan ara yín, èmi mo ni aṣọ 100 yard tó jábọ́ lát'ọ̀run táwọn ará Ondo ń ya mọ́ ara wọn lọ́wọ́'
Ki lo ti ṣẹlẹ ṣeyin?
Oríṣun àwòrán, succo /Pixabay
Ọwọ ofin  ijọba ipinlẹ Ondo ti tẹ awọn oṣiṣẹ rẹ obinrin meji kan ti wọn fẹsun kan pe wọn ji ọmọ obinrin to ni arun ọpọlọ, ti wọn si ta ọmọ naa ni miliọnu kan naira.
Awọn obinrin naa, Sarumi Adeyemi ati Orisamehin Florence Bosede jẹ ọga agba nileeṣẹ ijọba to n ri si ọrọ awọn obinrin.
Lẹyin ti ileeṣẹ naa ti kọkọ da seria fun wọn, won tun foju bale ẹjọ giga to wa niluu Akure lori ẹsun iditẹ ati ijọmọgbe.
Gẹgẹ bii ẹjọ ti agbẹjọro ijọba, Bunmi Koyenika, gbe lọ siwaju ile ẹjọ, iya ọmọ naa, Deborah Iretioluwa Olorundare jẹ alarun ọpọlọ lasiko to bi ọmọ ọhun, ko si nile lori, eyi to mu ki awọn ẹlẹyinju aanu gbe lọ sile iowosan MM Catholic Hospital niluu Ondo.
Lẹyin ti ileeṣẹ to n ri si ọrọ awọn obinri n gbọ nipa iṣẹlẹ iya ọlọmọ ọhun ni wọn gbe lọ sile iwosan awọn alarun ọpọlọ, Neuro Psychiatric Hospital, to wa ni Oda Road, l'Akure.
Ṣugbọn lẹyin ti obinrin naa lo oṣu diẹ nile iwosan ọhun lo bẹrẹ si n gbadun, o si bẹrẹ si n bere fun ọmọ rẹ.
Ṣaaju ni wọn ti kọkọ gba ọmọ naa lọwọ rẹ ti wọn si gbe ọmọ ọhun lọ sile awọn ọmọ alaini iya.
Bo tilẹ jẹ pe adehun wa laarin ile iwosan awọn alarun ọpọlọ yii atawọn afurasi lati maa gbe  ọmọ naa wa sile iwosan ki iya rẹ le maa ri nitori o le tete jẹ ko gbadun, iroyin ni awọn afurasi naa kọ lati mu ileri wọn ṣẹ.
Lẹyinorẹyin, ara obinrin naa da, o si kuro nile iwosan ti wọn ti n tọju rẹ.
Ẹwẹ, lẹyin to gbadun tan,  oun ati ile iwosan bẹrẹ si n bere ọmọ tuntun jojolo naa lemọ-lemọ ni ọrọ gbọna mii yọ.
Protein Marasmus: Wo èwu tó wà nínú kí ọmọdé má ní èròjà Protein lára
Iroyin ni awọn afurasi gbe ọmọ kan wa fun obinrin ọhun, ṣugbọn ọmọ okunrin abinrun ni wọn gbe wa fun, eyii to mu ko kọ jalẹ to si n lọgun pe ọmọ oun kii ṣe abinrun, ati pe obinrin ni oun bi.
Lẹyinorẹyin, ileeṣẹ ọtẹmuyẹ DSS da si ọrọ naa lẹyin to fi ọrọ wa iya ọmọ naa, ile iwosan ti ọrọ kan, to fi mọ awọn afurasi lẹnu wo, awọn afurasi ọhun si foju bale ẹjọ.
Ẹsun ti wọn n jẹjọ rẹ niwaju adajọ ile ẹjọ giga niluu Akure ni pe wọn ji ọmọ gbe, wọn si paarọ ọmọ naa pẹlu ọmọ abirun, eyii to waye lọjọ kẹrinla, oṣu Kẹsan an, ọdun 2020.
Iroyin ni iṣẹlẹ yii ti tu aṣiri awọn eeyan kan to maa n ji ọmọ awọn alarun ọpọlọ nileeṣẹ to n ri si ọrọ awọn obinrin nipinlẹ Ondo ge lati ta.
Wòólì Alfred kú lọ́dún 1964, ó tún padà wà sí ìlú Agelu f'ọ́jọ́ mẹ́rìnlá!
Iwadii DSS fi han pe, lootọ, obinrin ni ọmọ ti a n sọrọ rẹ yii, lootọ si ni awọn afurasi ji ọmọ naa ti wọn si lọ ta fun obinrin kan ti orukọ rẹ  n jẹ Toyin Olabiwonninu lẹyin to fun wọn ni miliọnu kan naira.
Ko tan sibẹ, iroyin ni obinrin ti wọn ta ọmọ naa fun, iyẹn Olabinwonnu ti fi Naijria silẹ lọ soke okun, ko si sẹni to le sọ igba ti yoo pada wale.
Wayi o, igbẹjọ ọrọ naa yoo bẹrẹ lọjọ kọkanla, oṣu ti a wa yii ni kootu adajọ A.A Fasanmi nile ẹjọ giga to wa niluu Akure.
Sunday Igboho Herbalist: Agbófinró mẹ́fà ló wọ́lé wá gbé ọmọ mi láì mọ́ ibi tó wà
Pastor Adeboye on 2023 Election: Wọ́n bi mi pé ta ni yóò di ààrẹ Nàìjíríà lọ́dún 2023
Oríṣun àwòrán, PAstor E.A Adeboye/Facebook
"Mo ni bawo lo ṣe da ọ loju pe Naijiria yoo wa lọdun 2023 Mo gbadura ko wa o tori naa, ẹ ma ṣi ọrọ mi gbọ ṣugbọn ṣe o da ọ loju?"""
Adari ijọ irapada eyi ti ọpọ mọ si Reedeem Church of God ni Naijiria, Pasitọ Enoch Adejare Adeboye ti ju ibeere nla kan kalẹ nipa ibo fun aarẹ Naijiria ti yoo waye lọdun 2023.
Lasiko ti Adeboye n ṣe iwaasu ọjọ isinmi idupẹ ti oṣu kọkanla eyi ti wọn maa n ṣe loṣooṣu ni olu ijọ naa to wa ni Ebute Meta, Eko ni ọrọ naa jade lori boya Naijiria yoo ṣi wa tabi ko ni si mọ lọdun 2023.
"O ni awọn eeyan wa bi oun pe ""baba, ta ni yoo di aarẹ orilẹede lọdun 2023, mo si bere pe aarẹ orilẹede wo, wọn ni ti Naijiria, mo da wọn lohun pe ṣe Naijiria gan yoo ṣi wa lọdun 2023""."
Pásítọ̀ Adeboye bú ẹnu àtẹ́ lú ìjọba tó fofin dé ìsìn ìrékọjá sí ọdún tuntun
RCCG: Pásítọ̀ Adeboye ṣáájú ìwọ́de àdúrà CAN lòdí sí ìpànìyàn ní Nàìjíríà
Adeboye, ìmọ̀ràn rẹ láti dènà panṣágà tako àwọn obìnrin - Ọmọ Nàíjíríà
Adejare Adeboye: Olúwa yóò dá gbogbo ohun ta sọnù ní 2020 padà ní ilọ́po méje fún wa
Pasitọ Adeboye ni ki ẹnikẹni ma ṣe yi ọrọ ohun mọ nkankan o amọ o tun tun un sọ pe ṣe o daa yin loju pe orilẹede Naijiria yoo ṣi wa lọdun 2023?
Adeboye ni awọn kan n wa iyi ati ipo ohun agbara oṣelu ni gbogbo ọna ti wọn si ṣetan lati pa ara wọn lori ibo ọdun 2023.
"O ni awọn bẹẹ ko mọ boya wọn yoo tilẹ di ọla tori ""ko sẹni to mọ nibi taa wa yii ati iwọ to n wo wa boya oo di ọla""."
Wọn o tilẹ mọ boya ọdun 2022 gan yoo wa. Bi 2023 ba tilẹ wa wa, wọn o mọ boya awọn gan yoo ṣi wa laye. Ko sẹni to lee sọ daju pe oun yoo wa laye lọla.
"Adeboye ni Ọlọrun nikan lo n ṣe ipinu ẹni ti yoo wa laye lọdun 2023. ""Ẹni kan n bi mi pe tani mo ro pe yoo di aarẹ""."
Ṣé lóòtọ́ ni Lateef Adedimeji àti Bimpe Oyebade fẹ́ ṣègbéyàwó lọ́tẹ̀ yìí lóòtọ́? Lateef bá BBC Yoruba sọ̀rọ̀
Erin wó! Orí Adé kan ti wàjà l'Oyo
Taaooma tọrọ aforíjìn pé ó bá ìgbákejì ààrẹ ṣèpàdé, èsì Mr Macaroni àtàwọn ọdọ́ rèé
Sanwo-Olu ṣèlérí ìrànwọ́ owó fún ètò ìsìnkú tó dára f'àwọn tí ilé alájà 21 wó pa ní Ikoyi
''Mo ti gbàdúrà fún àànú láti r'ọ́run wọ̀ lẹ́yìn tí mo wà lábẹ́ ilé tó wó ní Ikoyi fún ọjọ́ kan''
"'Wọ́n gba irun abẹ́ wa, irun abíyá wa, a lọ búra, ilé ""Nylon"" la tún ń gbé ni Mali fi ṣe iṣẹ́ aṣẹ́wó'"
Ṣaaju ibẹrẹ isin naa ni Pasitọ Adeboye ti gbadura fun gbogbo awọn onile ati ayalegbe pe Ọlọrun yoo jẹ ki ẹmi wọn gun lati jere iṣẹ wọn.
O kẹdun pẹlu gbogbo awọn to padanu mọlẹbi wọn ninbi ile alaja mọkanlelogun to dawo ni Ikoyi, ipinlẹ Eko o si gbadura fun wọn.
"Adeboye ni bi ko ba tii kan ọ, oo le mọ ohun ti awọn to padanu eeyan to sunmọ wọn n la kọja. ""Mo ti ni iriri temi nibẹrẹ ọdun yii, mọ si mọ bo ṣe ri"". A kò ní pe Ọlọ́run ní ẹjọ́ lórí ìkú ọmọ wa, Dare Adeboye - Ẹbí Adeboye"
Ikú Dare Adeboye kò ní ǹkankan ṣe pẹ̀lú Covid-19, a bẹ̀bẹ̀ láti dá wà lákòókò yìí - Ẹbi Adeboye
Ikú kò m'ọmọdé, kò màgbà, ẹ gbàdúrà fún ìdílé mi àti aya pẹ̀lú ọmọ olóògbé- Pásítọ̀ Adeboye
"Gẹgẹ bi Adeboye ṣe sọ, Ọlọrun nikan lo ni igbega lọwọ tori bo ṣe gbe eeyan kan ga lo lee rẹ ẹlomiran silẹ. ""Jẹ ki ireti rẹ wa lori bibọ Jesu Kristi lẹẹkeji."
"Bo ba wu u lati gbe ọ ga yoo gbe ọ ga amọ wa Ọlọrun na"". Eyi lo fi kadi ọrọ rẹ to si ni ki awọn eeyan gbadura pe ohunkohun ti ko ni mu wọn de ọrun ki Ọlọrun maṣe fun wọn rara."
Primate Ayodele: Pásítọ̀ ìjọ INRI sọ tẹ́lẹ̀ pé ọrọ̀ ajé Nàìjíríà yóò dẹnu kọlẹ̀ síi lọ́dún 2022
Oríṣun àwòrán, Facebook/Primate Babatunde Elijah Ayodele
Ọpọ ọmọ orilẹede Naijiria lo n pariwo ilu o fararọ lasiko yii bi gbogbo nkan ṣe wọn gogo lọja ti atijẹ si nira fun ọpọ eeyan.
Amọ alufa ijọ INRI Evangelical Spiritual Church, Primate  Elijah Babatunde Ayodele ti sọ pe a ṣẹṣẹ n me ẹyẹ bọ lapo ni.
Primate Ayodele ni nkan yoo le ju bayii lọ fawọn ọmọ orilẹede Naijiria lọdun to n bọ.
Pasitọ Ayodele to sọ tẹlẹ ni ibẹrẹ ọdun yii nipa ile to wo pa awọn eeyan ni Ikoyi niluu Eko sọ pe ọrọ aje Naijiria yoo tubọ dẹnu kọlẹ sii lọdun 2022.
''Oju awọn ọmọ Naijiria yoo ri to lọdun 2022 nitori iyan yoo mu sii.
Ọrọ aje Naijiria tẹsiwaju lati maa dẹnu kọlẹ, koda agbọjẹ oloṣelu kan yoo tun ku lọdun 2022.
Ẹni ti yoo jẹ aarẹ Naijiria gan an ninu idibo 2023 yoo jẹ iyalẹnu fun gbogbo eeyan.
Lori ọrọ aarẹ, mo ti sọ tẹlẹ pe tawọn eeyan apa guusu ko ba fimọ ṣọkan, ara oke Ọya ni yoo tun jẹ aarẹ Naijiria lọdun 2023.
Awọn ipinlẹ kan yoo doju bo ilẹ ni Naijiria, awọn minisita kan to wa ni ijọba Aarẹ Muhammadu Buhari yoo gba idaduro lẹnu iṣẹ.
Bakan naa, o san fun Aṣiwaju Bola Tinubu ko gbaju mọ ipinlẹ Eko ko si gbagbe nipa ipo aarẹ tori awọn oluṣelu tuntun kan ti yoo dide ni yoo gba ijọba Naijiria.
Agbẹjọro agba ati minisita eto idajọ ni Naijiria, Abubakar Malami yoo koju oriṣiiriṣii iṣoro.
Ẹ sọ fun gomina ipinlẹ Oyo, Seyi Makinde pe ko ye ba igbakeji rẹ ja mọ, bi bẹẹ kọọ, o maa ṣe ara rẹ.
Mi o tii ri ẹni to le la Gboyega Oyetola mọlẹ ninu ẹgbẹ oṣelu PDP fun saa keji ninu ibo gomina nipinlẹ Osun.
Kayode Fayemi gbọdọ ṣe atunṣe ninu ẹgbẹ oṣelu APC l'Ekiti, bi bẹẹ kọ, ko ni wọle fun ipo gomina fun saa keji.
Ikoyi house collapse: Ìjọba ìpínlẹ̀ Eko sọ̀rọ̀ lórí ẹni tó ni ilé alájá 21 tó dà wó ní Ikoyi
Oríṣun àwòrán, LASEMA
Oriṣiiriṣii iroyin lo ti lu ori ayelujara pa lori ẹni to ni ile alaja mọkanlelogun to da wo lagbegbe Ikoyi niluu Eko.
Lati igba ti iṣẹlẹ ọhun ti ṣẹlẹ ni oniruuru awuyewuye ti n lọ lori rẹ.
Bi awuyewuye ti ṣe n waye lori ohun to fa iṣẹlẹ naa, ni awuyewuye waye lori iye awọn to ti ku, awọn ti wọn ti ri gbe jade laaye, ati bẹẹbẹẹ lọ.
Bí mo ṣe káa sára tí mo gbé òkú ọmọ sínú ọkọ̀ lọ ṣe iṣẹ́ apanilẹ́rìín láì fihàn - Woli Agba Ayo Ajewole
Amọṣa lọwọ yii, awuyewuye to n waye ni lori ẹni gan to ni ile naa.
"Ninu iroyin rẹ ọjọ kẹrin oṣu Kọkanla ọdun 2021, Sahara Reporters ni ""wọn ti rii pe igbakeji aarẹ orilẹede Naijiria, Yẹmi Oṣinbajo ni ajọṣepọ pẹlu ile alaja mọkanlelogun to da wo nipinlẹ Eko""."
Iwe iroyin naa tun kọọ pe, awọn alami awọn sọ fun awọn pe Igbakeji Aarẹ Osinbajo lo ra ilẹ naa lọwọ oloye Michael Ade-Ojo, to jẹ oludasilẹ ileeṣẹ Elizade Motors, lẹyin to de ipo igbakeji aarẹ.
Amọ, ileesẹ aarẹ Naijiria ti fi atẹjade sita lori rẹ pe ko si ohun to kan igbakeji aarẹ pẹlu dukia ilẹ ati ile to dawo naa.
Atẹjade kan ti agbẹnusọ fun igbakeji aarẹ, Ọjọgbọn Yẹmi Oṣinbajo, Laolu Akande fi sita sọ pe gbogbo dukia ti igbakeji aarẹ ni lo ti kede fun ijọba gẹgẹ bi ofin orilẹede Naijiria ti ṣe laa kalẹ.
Atẹjade naa ni ko si nkankan ti igbakeji aarẹ ba gomina ipinlẹ Eko tabi oṣiṣẹ ijọba ipinlẹ naa kankan sọrọ nipa yiyọ iwe ti wọn le fi ti ile naa pa ki o to dawo.
"'Wọ́n gba irun abẹ́ wa, irun abíyá wa, a lọ búra, ilé ""Nylon"" la tún ń gbé ni Mali fi ṣe iṣẹ́ aṣẹ́wó'"
Ati pe ko si igba kankan to gbe igbesẹ lati di iṣẹ awọn ajọ to n mojuto ọrọ ile gbigbe nipinlẹ Eko lọwọ.
Bakan naa ni Oloye Ade-Ojo, alaga ileeṣẹ Elizade sọ pe irọ lasan n'iroyin naa ati pe oun ati Igbakeji aarẹ Oṣinbajo ko fi igba kankan ni idunadura lori ilẹ ti wọn kọ ile to da wo naa si.
"Oloye Ade-Ojo ni ""mo ti n tẹnu mọọ pe mi o fi igba kankan ni ilẹ yii."
Ko le ye gbogbo eeyan, mo ni dukia kan si ẹgbẹ ile ti a n sọrọ rẹ yii, ti mi o si tii ta, ti mi o dẹ nii lọkan ati ta fun ẹnikẹni.
Amọ, ijọba ipinlẹ Eko ti fidi rẹ mulẹ fun BBC Yoruba pe akọleta, Femi Osibona ti oun naa ba iṣẹlẹ naa lọ lo ni ile ọhun.
Kọmiṣọnna fun eto iroyin, Gbenga Omotosho sọ fun BBC Yoruba pe gbogbo eeyan lo mọ pe Osibona lo ni ile naa.
''Osibona ti oun naa di oloogbe nibi iṣẹlẹ yii naa lo ni ile to da wo ni Ikoyi.
Ṣugbọn o ṣeni laanu pe ẹni to ni ile lo jẹ awọn eeyan logun lẹyin ti eeyan mejilelogoji ba iṣẹlẹ naa lọ.
O dabi ẹni pe awọn eeyan wa ṣa fẹran ki wọn maa sọ ọrọ ikọkọ.
Wọn fẹran lati maa wa ọna lati ṣe ibajẹ ti iṣẹlẹ kan ti ṣẹlẹ lai kaanu awọn ti iṣẹlẹ ọhun ṣẹlẹ si.
Emi ko ro pe ko ro pe ede-ai-yede figba kan wa lori ẹni to ni ile naa.
Igbakeji aarẹ osinbajo gan an ti sọ pe oun yoo gbe ẹnikẹni to ba sọ pe oun loun nile naa lọ si ile ẹjọ.
Awọn eeyan ko ni aanu loju mọ gẹgẹ eniyan, a kan wa huwa bi ẹranko,''Ọgbẹni Omostosho lo ṣalaye bẹẹ.
Kọmiṣọnna Omotosho tun fidi rẹ mulẹ pe awọn oṣiṣẹ iṣẹlẹ pajawiri si n tẹsiwaju lati ṣawari awọn eeyan to ba tun le wa labẹ ogiri alapa ile to da wo naa.
Lagos bulding collapse: Mo gbàdúrà kí Ọlọrun tu gbogbo ẹbí Osibona nínú - Abiodun
Oríṣun àwòrán, Prince Dr. Dapo Abiodun - MFR
Gomina ipinlẹ Ogun, Dapo Abiodun ti ṣabẹwo si oloye Emmanuel Osibona, to jẹ baba to bi Femi Osibona to kọ ile alaja mọkanlelogun to da wo niluu Eko.
Abiodun lo kede ọrọ naa loju opo Facebook rẹ, to si fi aworan bo ṣe baba agba naa kẹdun iku ọmọ rẹ lede.
"O ni ""Lalẹ ana ni mo ṣabẹwo si Baba Ijọ Our Saviour's Anglican Church to wa ni Ikene, oloye Emmanuel Osibona, to jẹ baba oloogbe Olufemi Adegoke Osibona."""
Ọgbẹni Osibona ni alaṣẹ ileeṣẹ Fourscore Homes to jade laye lẹyin to ha sabẹ ile alaja mọkanlelogun to da wo naa.
"Abiodun tẹsiwaju pe ""Mo ba Baba kẹdun lori iṣẹlẹ ibi naa, mo si tun gbadura pe ki Ọlọrun tu oun atawọn mọlẹbi ninu lori iṣẹlẹ laburu naa."""
Oríṣun àwòrán, Prince Dr. Dapo Abiodun - MFR
Ti ẹ ko gbagbe, ọjọ kinni, oṣu Kọkanla, ọdun 2021 yii ni ile naa dawo, to si wo pa nnkan bii ogoji eeyan, bo tilẹ jẹ pe wọn ri awọn eeyan gbe jade labẹ ile ọhun laaye.
"'Wọ́n gba irun abẹ́ wa, irun abíyá wa, a lọ búra, ilé ""Nylon"" la tún ń gbé ni Mali fi ṣe iṣẹ́ aṣẹ́wó'"
Lara awọn to ba iṣẹlẹ naa lọ ni ọpọ oṣiṣẹ to n ṣiṣẹ ninu ile naa lasiko to da wo, to fi mọ Femi osibona to ni ile naa.
Lẹyin ti ile ọhun dawo, ọpọ eeyan lo  sọ pe igb akeji Aarẹ, Yemi Osibanjo lo ni ile ọhun lẹyin to ra ile rẹ lọwọ baba olowo, Micheal Ade Ojo ti ọpọ mọ si Elizade.
Ṣugbọn Osibanjo ati Elizade ti sọ pe awọn ko mọ nnkankan nile naa, ati pe awọn kọ ni wọn ni.
Ta ló ni ilé alájá 21 tó wó pa àwọn èèyàn ní Ikoyi gan? Ìjọba Eko ti fèsì
Wòólì Alfred kú lọ́dún 1964, ó tún padà wà sí ìlú Agelu f'ọ́jọ́ mẹ́rìnlá!
Ondo fees hike: Àwọn ọmọ ilé ẹ̀kọ́ tó ṣẹ̀ṣẹ̀ wọlé nìkan ni àfikún owó náà kàn - UNIMED
Oríṣun àwòrán, Rotimi Akeredolu Aketi
Awọn akẹkọọ kan ni fasiti ẹkọṣẹ iṣegun ijọba ipinlẹ Ondo, UNIMED, ti sọrọ lẹyin ti ijọba ipinlẹ naa ṣafikun iye owo ile ẹkọ naa ni nnkan bii ida ọgọrun un o le.
Lara awọn akẹkọọ ọhun to ba BBC Yoruba sọrọ sọ pe iroyin afikun owo ile ẹkọ naa da bi ẹni to gbọ iku baba rẹ lai ro tẹlẹ lo ri lara oun.
Awọn akẹkọọ naa to n kẹkọọ nipa iṣẹ dokita sọ pe ko rọrun lati ri owo ti awọn n san tẹlẹ, anbelete bayii ti wọn ṣẹṣẹ fi kun owo ile ẹkọ naa.
"O ni ""A fẹ ẹ ya were nigba ti a gbọ pe ijọba ti fikun owo ile ẹkọ wa... ẹru ba wa a ko si mọ nnkan ti a le ṣẹ nitori awọn alaṣẹ ile ẹkọ naa ko gba fun wa lati ṣe ẹgbẹ akẹkọọ ti yoo maa ja fun wa."""
Bo tilẹ jẹ pe wọn ko fẹ ki a fi orukọ wọ lede, awọn akẹkọọ ọhun ni nnkan ko rọrun fun wọn, ibanujẹ nla si ni afikun owo ile ẹkọ naa jẹ.
"Ọkan lara wọn sọ pe ""Inu mi ko dun rara nitori baba to n tọ mi nilẹ ẹkọ yii n ṣiṣẹ ko si ri owo oṣu gba."""
Ti mo ba ti pari ni kilaasi bayii, ni ṣe ni mo maa tun lọ sinu oko lati lọ kọ ẹgẹ, ẹ jọwọ ẹ bawa bẹ gomina Rotimi Akeredolu ko ba din wa owo naa ku.
"'Wọ́n gba irun abẹ́ wa, irun abíyá wa, a lọ búra, ilé ""Nylon"" la tún ń gbé ni Mali fi ṣe iṣẹ́ aṣẹ́wó'"
BBC Yoruba kan si awọn alaṣẹ fasiti naa lati mọ eredi afikun owo ọhun.
"Agbẹnusọ ile ẹkọ naa, Ọgbẹni Temitope Oluwatayo ṣalaye fun BBC pe lootọ ni UNIMED ṣafikun owo ile ẹkọ naa, amọ ki ṣe gbogbo awọn akẹkọọ ni ọrọ naa kan."""
Gẹgẹ bii ohun to sọ, awọn akẹkọọ to ṣẹṣẹ fẹ wọ ile ẹkọ ọhun nikan ni yoo san iye owo ti wọn kede rẹ.
"O ni ""Kii ṣe gbogbo awọn akẹkọo wa ni ọrọ afikun naa kan o, bikoṣe awọn to ṣẹṣẹ fẹ wọ fasiti naa bii akekọọ tuntun."""
Kii si ṣe pe a kan dede pinnu lati ṣafikun owo naa, ṣugbọn a wo bi ohun gbogbo ṣe ri ni akoko yii, a ko si fẹ ki ile ẹkọ rẹyin lawujọ, a ni lati bẹgbẹ pe.
Kii ṣe owo perete ni wọn fi n kọ ẹkọ nipa imọ iṣẹgun, a ko si fẹ ki awọn akẹkọọ wa jẹ purutu lawujọ ẹgbẹ wọn, idi ree ti a ṣe fi kun owo ọhun.
Ki lo ti ṣẹlẹ sẹyin?
Oríṣun àwòrán, Rotimi Akeredolu Aketi
Ijọba ipinlẹ Ondo ti ṣe afikun iye owo ile ẹkọ ẹkọṣẹ iṣegun to wa niluu Ondo, University of Medical Sciences, UNIMED.
Awọn alaṣẹ ile ẹkọ naa lo kede afikun owo tuntun naa loju opo lori itakun agbaye.
Pẹlu afikun tuntun yii, iye owo ti awọn ti kii ṣe ọmọ ipinlẹ Ondo yoo maa san ti ni afikun to le ni ida aadọta ju iye owo ti awọn akẹkọọ to jẹ ọmọ ipinlẹ Ondo yoo maa san.
Ikede naa tun fi han pe awọn akẹkọọ eto imọ iṣegun ti kii ṣe ọmọ ipinlẹ Ondo yoo maa san ₦2.245m lọdun nigba ti awọn ọmọ onilu yoo maa san owo ti iye rẹ ko din ni ₦1.320m lọdun.
Awọn akẹkọọ lati ipinlẹ Ondo to n kẹkọọ bii Biochemistry ati Physiology yoo maa san ₦350,000 lọdun nigba ti awọn akẹkọọ lati ipinlẹ miran yoo maa san ₦400,000.
Oríṣun àwòrán, Oladokun Bolu Samuel
Wayi o, awọn eeyan kan ti bẹrẹ si n bu ẹnu atẹ lu ijọba ipinlẹ Ondo fun afikun owo ile ẹkọ naa, paapaa lasiko ti eto ọrọ aje Naijiria dẹnukọle yii.
Lara awọn eeyan naa ni agbẹnusọ ẹgbẹ oṣelu PDP l'Ondo, Kennedy Peretei to sọ pe ijọba to wa lode l'Ondo ko kọbi si irufẹ iya to n jẹ awọn araalu.
Wòólì Alfred kú lọ́dún 1964, ó tún padà wà sí ìlú Agelu f'ọ́jọ́ mẹ́rìnlá!
Peretei lo sọ ọrọ naan ninu atẹjade kan to fi ṣọwọ si awọn akọroyin.
Lasiko to n gba awọn obi ti wọn ko le san owo naa nimọran lati mu awọn ọmọ wọn kuro nile ẹkọ ọhun, o ni Akeredolu kuna lati ri pe ko si iṣẹ ni ipilẹ Ondo, ati pe ọpọ obi awọn akẹkọọ naa lo jẹ oṣiṣẹ ijọba ti ko gba owo oṣu dede.
Bakan naa lo tun ṣapejuwe iye owo ti wọn n san lawọn ile ẹkọ ijọba to yi ipinlẹ Ondo ka, bii Ekiti ati Ogun.
O ni o yẹ ki ijọba Rotimi Akereolu gbe ọrọ naa yẹwọ ko to maa fi aye ni awọn eeyan lara.
Ẹwẹ, kii ṣe iga akọkọ ree ti ijọba ipinlẹ Ondo yoo ṣafikun owo ile ẹkọ.
Ṣaaju Akeredolu lo ti kọkọ ṣafikun owo ile ẹkọ fasiti Adekunle Ajasin, to wa niluu Akungba-Akoko, eyii to mu ki ọpọ awọn akẹkọọ ọhuntu si igboro fun ifẹhonuhan lọdun 2019.
US travel: Orílẹ̀èdè Amẹ́ríkà ti ṣí ibodè wọn padà lẹyìn oṣù ogún
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Bẹrẹ lati ọjọ Ajé, awọn arinrin-ajo to ba ti gba gbogbo abẹrẹ ajẹsara COVID-19 wọn pe yoo lanfaani lati wọ orileede Amẹrika.
Nkan bi ọdun kan ati oṣu mẹjọ sẹyin ni  wọn ti ibode ilẹ naa lasiko ti Aarẹ Donald Trump fi ni iṣakoso.
Igbesẹ yi kan awọn ti kìí ṣe ọmọ Amẹrika lati orileede ọgbọn.
Ninu wọn l'awọn to wa lati ilẹ Gẹẹsi ati awọn tó wà lati awọn orileede to wa ni Yuroopu.
Ọpọ ni ko raaye foju kan mọlẹbi wọn, ti ètò ọrọ aje irinajo afẹ si dẹnukọlẹ lasiko naa.
Yatọ si ilana pe awon to ba fẹ wọlé pada gbọdọ ti gba abẹrẹ ajẹsara, awọn ilana mi wa ti Amẹrika gbe kalẹ.
Àjọ to n gbogun ti àjàkálẹ̀ aarun ni Amẹrika, CDC ni ofin lori iru abẹrẹ ajẹsara ti wọn faramọ ki eeyan to le wọ ilẹ wọn.
Awọn abẹrẹ naa re e:
•Johnson & Johnson
•Pfizer-BioNTech
•Moderna
•AstraZeneca,
•Covaxin
•Covishield
•BIBP/Sinopharm
•Sinovac
Yatọ si pe wọn gba abẹrẹ pe, arinrin-ajo gbọdọ mu ẹri to fi hàn pé ayẹwo COVID-19 tọka sí pé wọn kò laarun náà.
Ọjọ mẹta sí igba ti wọn ba rìn irinajo ni wọn gbọdọ ti ṣe ayẹwo yi.
Iwe ẹri yi ko pọn dandan fun awọn ọmọde, ṣugbọn awọn ti ọjọ orí wọn kòbá kọja ọdun meji sí metadinlogun yoo ṣe ayẹwo laarin ọjọ mẹta sí marun un ti wọn ba wọ Amẹrika.
Yato si iwe ẹ̀rí yi, èèyàn lè tún mu ẹri to ṣafihan pe eeyan moribọ lọwọ COVID-19 laarin oṣu mẹta sẹyìn ṣaaju irin-ajo rẹ.
Ṣaaju asiko yi Amẹrika fòfin de awọn ọmọ orilẹede wọnyi lati ma ṣe wọ ilẹ wọn nitori COVID-19.
Orileede naa ni:
Ohun tó wà nílẹ̀ bayi ni pé kò sí idiwọ mọ, fun awọn eeyan lati awọn orilẹ-ede naa lati wọ Amerika pada.
Bi eeyan ba ṣa ti gba abẹrẹ ajẹsara COVID-19 rẹ pe,kò sí idiwọ lati wọ Amẹrika nisinyii.
Rwanda electric motorcycles: Rwanda lèwájú nínú lilo ọ̀kadà tó n lo iná ẹ̀lẹ́tíríkì
Oríṣun àwòrán, Ampersand
O ti to nkan bii ọdún méjìlá tí Didier Ndabahariye ti n fi ọkada rẹ ko ero kaakiri igboro Kigali, lorilẹ-ede Rwanda.
Ọkan lara àwọn ọlọkada tawon eeyan mọ sí moto nilu naa lo jẹ.
Laipẹ yi lo paarọ okada rẹ pẹlu orisi mii to jẹ ọkan lára àwọn akọkọ alupupu igbalode to n lo ina ẹlẹtiriki ni Africa.
Nigba ti mo kọkọ bẹrẹ, nkan nira diẹ nitori iru ọkada yii ko mọ mi lara ati pe ẹmẹẹwa lo maa n pana
Amọ lẹyin asiko diẹ, mo mọ bi o ṣe n ṣiṣẹ ati gigun rẹ. Mo si bẹrẹ sí ní ri owo fi pamọ sii.
Oríṣun àwòrán, Ampersand
Didier Ndabahariye wa lara ẹgbẹrun mẹẹdọgbọn ọlọkada to n ṣiṣẹ ni Kigali
O wa lara awon ọgọta ọlọkada to n gun ọkada to n lo ina ẹlẹtiriiki lati ileeṣẹ Ampersand ni Rwanda.
Mo nifẹ si awọn okada tuntun yi tori o máa n ṣiṣẹ pẹ daada lai sí wàhálà bi awọn eleyi to n lo ẹnjini. Wọn máa n rin daada loju popo, ti won kò sí kí n yọnu
Ileesẹ tuntun Ampersand lo wa nidi iyipada yi ti wọn sì ni ìgbàgbọ pé laarin ọdún marun-un si asiko yii, gbogbo ọlọkada ni Rwanda yóò ti darapọ mọ lilo iru okada yi.
Afojusun yi jẹ eleyi to lagbara lati ṣe nitori o to egberun marundinlọgbọn ọlọkada èrò to n ṣe iṣẹ ni Kigali, ti won  a sì máa rí irin to to wakati mẹwàá lojumọ.
Ọgá ileesẹ Ampersand, Josh Whale so iyatọ to wa laarin alupupu elépo ati eleyii to n lo ina ẹlẹtiriki.
O ni lootọ awọn elépo le rín to ọgọrun kilomita lojumọ, ṣugbọn èéfín tí wọn n tu sita kọja àfaradà.
Ṣugbọn, ko si nkan to jọ bẹẹ fun awọn to jẹ ẹlẹtiriki.
Bakan naa lo sọ pe gbigba ina si ara ọkada to n lo ẹlẹtiriki dinwo ju rira bẹtiro lọ.
Orilẹ-ede Rwanda ṣe agbekalẹ awọn nkan ìwúrí kọọkan ti yoo jẹ ki lilo ọkada ẹlẹtiriki gbooro sí.
Lara rẹ ni pe wọn mu adinku ba owo ina.
Oríṣun àwòrán, Ampersand
Ijọba orilẹ-ede rwanda n ṣe oriṣiriṣi eto lati ṣe igbelarugẹ ọkada onina
Ipese aaye ọfẹ fun ibi ti àwọn ọlọkada yóò ti maa gba ina sara okada wọn.
Bi ilu Eko, ni orilẹ-ede Naijiria ṣe ya ọna sọtọ fawọn ọkọ BRT, Rwanda náà se ọna tí àwọn ọlọkada ẹletiriki yóò máa rin loju popo.
Awọn ileesẹ irinna mii si ti n fifẹ han sí didarapo mọ igbesẹ yi.
Ileesẹ bi Volkwagen ni Rwanda ati Siemens ti n d'owo pọ láti ṣe awọn ọkọ ayọkẹlẹ to n lo ina.
Electoral Act Bill: Àwọn aṣòfin Naijiria buwọ́lu fífi èsì ìdìbò ránṣẹ lórí ayélujára
Apapọ ile asofin Naijiria ti buwọ́lù àṣẹ fun àjọ eleto idibo INEC lati le fi esi idibo ránṣẹ gba ori ayelujara.
Wọn fòntẹ̀ lù lẹyìn tí wọn gbà abajade igbimọ iwadii lori ọrọ yi lọjọ Ìṣẹgun.
Ohun tí eyi tumọ sí ni pe awon aṣòfin ti pari isẹ lori àtúnṣe ofin tó dé eto idibo ni Naijiria.
Ohun tó kù bayi ni pé kí wọn fi ranṣẹ sí aarẹ Muhammadu Buhari ko buwọ́lù.
Ariwo aráàlú to pọ loṣu Kẹwàá  lori pe ki wọn jẹ kí INEC máa fi esi idibo ránṣẹ lori ayelujara  leyin tawon eeyan ni wọn kò gbọdọ f'asẹ sí aba Electoral Act  lo mu  kawon aṣofin gbe igbesẹ yi.
Awijare awọn asofin lori ọrọ yi ni pe INEC ko le gbe esi idibo jade lori ayelujara ayafi ti wọn ba gba iyọnda lọdọ àjọ to n mojuto eto ibaraẹnisọrọ iyen NCC pe nẹtiwọki wa lati fi sebẹ.
Awọn aṣòfin tun fọwọ si pe awọn ẹgbẹ oṣelu gbọdọ ṣeto idibo abẹnu eleyi ti awọn ati INEC ṣetán láti fojú sí imusẹ rẹ.
Igbimọ ẹlẹni-meje kan ni ile asofin gbe kalẹ lati ṣe ìpàdé pelu ile Asoju sofin lati wo iyatọ to wa laarin ofin tó dé eto idibo Nàìjíríà,Electoral Act , tó wà nílẹ̀ ati eleyi ti wọn fẹ ṣàtúnṣe.
Nitori wàhálà jagidijagan ati jiji apoti ibo gbe tó máa n saba waye lasiko
idibo ni Naijiria, lo mu ki ile aṣofin agba gbe ìgbésẹ láti ṣàtúnṣe ofin tó dé eto idibo ni Nàìjíríà ni 2019.
Ile ṣàgbékalẹ̀ aba ofin kan ni 2019 eyi ti yóò ri pe INEC samulo fifi esi idibo ránṣẹ gba ayelujara.
Kiakia láwọn asofin ká ofin naa to sì yarade abala keji eto aba ofin.
Pẹlu atunṣe yii, ireti wa pé INEC yoo lo àtẹ orukọ oludibo gbogbo ti yoo wa lójú ayelujara.
Bakan naa ni wọn yoo fi èsi ranṣẹ nipa ojú òpó ayelujara yi kan náà
Charles Soludo ti jáwé olúborí gẹ́gẹ́ bí gómìnà ìpínlẹ̀ Anambra
Oríṣun àwòrán, FACEBOOK/CHARLES CHUKWUMA SOLUDO
Ni alẹ ọjọ Iṣẹgun ni ajọ INEC kede apapọ esi idibo gomina to waye nipinlẹ Anambra.
Ọjọ Satide ni idibo naa waye, ṣugbọn wọn ko pari rẹ nitori awọn idiwọ kan.
Eyi si lo mu ki idibo naa tẹsiwaju ni ijọba ibilẹ Ihiala lọjọ Iṣẹgun.
Gbogbo èsì ìbò gómìnà Anambra rèé
Wo àkọsílẹ̀ nípa ìtan ayé àwọn oludìbò gómìnà Anambra
IPOB fagilé òfin kónílé-ó-gbélé ọlọ́sẹ̀ kan ṣáájú ìbò gómìnà Anambra
Wo ìdí tí àjọ INEC fi yọ orúkọ gómìnà báńkì àpapọ̀ tẹ́lẹ̀, Chukwuma Soludo kúrò nínú àwọn olùdíje gómìnà Anambra
Lara awọn esi ibo ti wọn kede ni ọjọ Aiku lo fihan pe Charles Soludo to ti fi igba kan jẹ Gomina banki agba Naijiria, CBN, lo n lewaju.
Oun ni oludije fun ẹgbẹ All Progressives Grand Alliance, APGA.
Oludije ẹgbẹ oṣelu All Progressive Grand Alliance, Charles Chukwuma Soludo lo gba ọpọlọpọ ida ibo ti wọn n pe ni 2/3 gẹgẹ bi alakalẹ ajọ INEC eyi to mu ko bori ni ibamu pẹlu ofin Naijiria.
APC: 43,285
APGA: 112,229
PDP: 53,807
YPP: 21,261
Wo ohun díẹ̀ tó yẹ kóò mọ̀ nípa Charles Soludo
Isẹ oojọ: Onimọ nipa ọrọ
Ọjọ ori: Ọdun mọkalelọgọta
Charles Chukwuma Soludo ti jẹ gomina gomina banki apapọ ilẹ wa ri laarin ọdun 2004 si 2009.
Igba akọkọ ree ti yoo gbiyanju lati dije fun ipo gomina nipinlẹ Anambra. Ldun 2010, o fidi rẹmi lasiko to wa labẹ ẹgbẹ oselu PDP, ti Peter Obi si jawe olubori. O tun gbiyanju lati dije dupo gomina lọdun 2013 labẹ ẹgbẹ oselu APGA amọ igbimọ to n sayẹwo oludije ninu ẹgbẹ oselu naa ja kulẹ.
Ilu Isuofia nijọba ibilẹ Aguata lo ti wa.
'Ọba Yorùbá kìí ṣe aláṣẹ ìkejì Orìṣà mọ́ látòní lọ! Krìstẹ́nì, Mùsùlùmí àti Àbáláyé yóò máa ṣe ayẹyẹ pọ látòní'
Ọwọ́ ọlọ́pàá tẹ olórí pátápátá fún àwọn ajínigbé kan l'Ekiti
Wo ohun tí ọkọ àti ìyàwó, Lateef Adedimeji àti Bimpe fi síta fúnra wọn to fihàn pé ọjọ́ ti súnmọ́
Kí ló mú Princess Comedian máa wa ẹkún mu láàrọ̀ kùtù?
Bí mo ṣe káa sára tí mo gbé òkú ọmọ sínú ọkọ̀ lọ ṣe iṣẹ́ apanilẹ́rìín láì fihàn - Woli Agba Ayo Ajewole
Nomthi Odukoya: Pásítọ̀ Odukoya pàdánù ìyàwó rẹ̀ ẹlẹ́ẹ̀kejì lẹ́yìn ikú Bimbo Odukoya lọ́dún 2005
Oríṣun àwòrán, pastornomthi
Wọn ti kede eto isinku iyawo Pasitọ Agba ijọ Fountain of Life Church, Nomthi Odukoya.
Ninu ikede kan ti ọkọ rẹ, Taiwo Odukoya fi sori ayelujara Instagram rẹ ni eyi ti jẹyọ.
Ọjọ Aje, ọjọ kẹjọ, oṣu Kẹwaa, ọdun 2021, ni Simangele Rosemary Nomthansazo Odukoya jade laye.
Ẹni ọdun mẹtadinlaadọta ni.
Aisan jẹjẹrẹ si ni ẹbi rẹ sọ pe o pa a, lẹyin to ba a finran fun ọdun meji.
Bi eto naa yoo ṣe lọ niyii:
Aṣalẹ orin ati idaro yoo waye ni ọjọ Aje, ọjọ kọkandinlọgbọn, oṣu Kọkanla, ọdun 2021.
Eto isinku yoo waye ni ọgbọn ọjọ, oṣu Kọkanla bakan naa.
Ile ijọsin ọkọ oloogbe, Fountain of Life Church, to wa ni adugbo Ilupeju, nipinlẹ Eko, ni awọn eto naa yoo ti waye.
Ọmọ orilẹ-ede South Africa ni Nomthi.
O si fi ọmọ meji saye lọ.
Ijọ Fountain of Life Church ti kede iku iyawo Pasitọ Agba wọn, Pasitọ Nomthi Odukoya.
Ijọ naa kede ninu atẹjade kan ti wọn fi sita lori ayelujara wọn.
Gẹgẹ bi atẹjade naa, Pasitọ obinrin Nomthi Odukoya ku nitori aisan jẹjẹrẹ to ba a finra fun ọdun meji.
Aisan jẹjẹrẹ ba a finra fun ọdun meji, o duro lori ọrọ Ọlọrun, o si ja fitafita.
A fẹran rẹ pẹlu gbogbo ọkan wa, ṣugbọn taa ni wa lati kọju ija si ifẹ Ọlọrun.
Otitọ ibẹ ni pe gbogbo wa la o dagbare fun aye. Nitori naa, titi ti a o tun fi pade, o dabọ Pasitọ Nomthi.
Pasitọ Nomthi Odukoya ni iyawo keji Pasitọ Taiwo Odujkoya, to jẹ oludasilẹ ṣọọṣi Fountain of Life Church.
Nomthi fẹ Pasitọ Taiwo Odukoya ni oṣu Kinni, ọdun 2010, lẹyin ti iyawo rẹ akọkọ, Bimbo Odukoya kú ninu ijamba baalu kan ni ọjọ kẹwaa, oṣu Kejila, ọdun 2005.
Ọmọ orilẹ-ede South Africa ni Nomthi jẹ́.
Ọdun mọkanla ni igbeyawo wọn, wọn si bi ọmọ meji funra wọn.
Titi di igba to ku, ipo Igbakeji Pasitọ Agba lo wa ninu ijọ naa, nibi to ti n ran ọkọ rẹ lọwọ lati ṣe amojuto ṣọọṣi naa to ni to ẹgbẹrun mẹwaa ọmọ ijọ.
Aarẹ orilẹ-ede Naijiria, Muhmaamadu Buhari ti ranṣẹ ibanikẹdun si Pasitọ Taiwo Odukoya, lori iku iyawo rẹ Nomthi.
Ọjọ Iṣẹgun ni Nomthi jade laye, lẹyin to ba aisan jẹjẹrẹ finra fun ọdun meji.
Oluranlọwọ fun Aarẹ Buhari lori eto iroyin, Femi Adesina, sọ ninu ikede kan to fi si ori Facebook pe Buhari gbadura ki ọlọrun ti Pasitọ Taiwo Odukoya ninu.
Aarẹ ba pasitọ naa, ṣọọṣi rẹ ati gbogbo Kristiẹni lapapọ kẹdun lori iṣẹlẹ naa, to si ṣapejuwe rẹ gẹgẹ bi iṣẹlẹ to ba ni lọkan jẹ.
O rọ Pasitọ Odukoya lati gba iṣẹlẹ naa mọra, pẹlu igbagbọ pe ko si nkan to le ṣẹlẹ, lai jẹ pe Ọlọrun mọ si.
Bakan naa ni Igbakeji Aarẹ nigba kan, Atiku Abubakar sọ pe ibanujẹ nla ni ilu Pasitọ Nomthi Odukoya jẹ fun oun. O ni oun gbadura pe ki ẹni to ku sun re o.
Ogun kidnap: Ajínigbé ń bèèrè owó ìtúsílẹ̀ N10m, Codiene, igbó àtí oúnjẹ fún ìtúsílẹ̀ èèyàn mẹ́ta tí wọ́n gbé
Oríṣun àwòrán, Others
Awọn janduku agbebọn to ji eeyan mẹta gbe nipinlẹ Ogun ti beere fun miliọnu mẹwaa naira ati oogun oloro fun itusilẹ wọn.
Ohun ti a gbọ ni pe awọn janduku ajinigbe naa yinbọn fun ẹnikan to n ṣagidi pẹlu wọn ṣugbọn ẹni naa pada moribọ lọwọ wọn.
Awọn ajiigbe ọhun ni iroyin sọ pe wọn sa pamọ sinu igbo lagbegbe Obada-Oko niluu Abeokuta nibi ti wọn ji awọn ọmọ ijọ alaṣọ funfun kan gbe ni bii ọsẹ meloo sẹyin.
Agbẹnusọ ileeṣẹ ọlọpaa ipinlẹ Ogun, DSP Abimbola Oyeyemi, to fidi iṣẹlẹ ọhun sọ pe awọn agbofinro ti mu ọkan lara awọn afurasi ajinigbe naa.
Abimbola ni ogbontarigi ninu awọn ajinigbe ọhun ni ileeṣẹ ọlọpaa mu.
O ni ileeṣẹ ọlọpaa ti bẹrẹ iwadii lori iṣẹlẹ ọhun, bakan naa lo fi da araalu loju pe gbogbo wọn lọwọ ọlọpaa maa tẹ.
Nigba ti o n ṣalaye bi ori ṣe ko o yọ lọwọ awọn janduku ajinigbe ọhun, Razaq Lasisi, sọ pe nibi iṣẹ ojọọ oun loun ti n pada lọ ile laago mẹsan an alẹ.
Agbegbe kan ti wọn n pe ni Ogba Kehinde ti ko jina si ile mi ni wọn ti gbiyanju lati ji mi gbe.
Lasisi ni ''ọkan lara wọn yinbọ fun mi lẹẹmeji bi mo ti n tiraka lati salọ, omiran tun di mi mu ṣugbọn mo gba iyẹn ni ẹṣẹ eleyii to jẹ ko fi mi silẹ.
Niṣe ni ẹjẹ bo mi bi mo ti n sare lọ, ile aladugbo mi kan ni mo sare wọ.
Kete ti mo de ibẹ ni mo sọ fun wọn pe ki wọn gbe mi lọ si ile iwosan Aro ti wọn ti n ṣe itọju awọn alarun ọpọlọ.''
Koda, awọn janduku ajinigbe ọhun ti pe lati beere fun miliọnu mẹwaa naira gẹgẹ bi owo itusilẹ fawọn ti wọn jigbe lọ.
Bakan naa ni wọn tun beere fun oogun codeine, marijuana, omit ati ounjẹ gẹgẹ bi ohun ti wọn tun fẹ gba fun itusilẹ awọn ti wọn jigbe lọ.
''Ṣugbọn lẹyin ti bẹ wọn tan, wọn gba pe ki a mu miliọnu kan ati aabọ wa fun owo itusilẹ.
Amọ, wọn ni a o gbọdọ maa mu oogun codiene, igbo, ounjẹ ati omi,'' Lasisi lo ṣalaye bẹẹ.
Niger school fire: Akẹ́kọ̀ọ́ ọmọdé mẹ́ẹ̀dọ́gbọ̀n dèrò ọ̀run nínú ìjàmbá iná tó ṣẹlẹ̀ ní yàrá ìkàwé wọn
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Aworan eto isinku yii jẹ ti awọn eyyan kan ti wọn si ni orilẹ-ede Sieraa Leone lasiko ilẹ riri to waye ni ọdun 2017.
Eto isinku ti bẹrẹ fun awọn ọmọde mẹrindinlọgbọn to kú lasiko ti ina jo ile ẹkọ wọn nilu Maradi.
Ọjọ Aje ni ina sọ lara awọn yaara ikẹkọọ wọn ti wọn fi igi ati koriko kọ lorilẹ-ede Niger.
Nibi eto isinku naa, ni awọn minisita ati awọn ọga agba lẹnu iṣẹ ijọba naa peju si.
Ọpọlọpọ awọn ọmọde lo ṣi wa ni ileewosan nibi ti wọn ti n gba itọju nitori ina to jo wọn.
Aarọ kutu ọjọ Iṣẹgun ni awọn obi awọn ọmọ naa pejọ si ileewosan nla to wa ni Maradi, nibi ti wọn gbe oku awọn ọmọ wọn si ṣaaju isinku.
Bakan naa ni ijọba ti kede ọjọ mẹta gẹgẹ bi ọjọ ti wọn o fi ṣọfọ awọn ọmọ naa.
Ọjọ ori wọn wa laarin ọdun mẹta si mẹjọ - ti ọpọ ninu wọn si jona kọja debi pe ko wọn ko ṣe e damọ.
Kí ló mú Princess Comedian máa wa ẹkún mu láàrọ̀ kùtù?
'Ọba Yorùbá kìí ṣe aláṣẹ ìkejì Orìṣà mọ́ látòní lọ! Krìstẹ́nì, Mùsùlùmí àti Àbáláyé yóò máa ṣe ayẹyẹ pọ látòní'
Bí mo ṣe káa sára tí mo gbé òkú ọmọ sínú ọkọ̀ lọ ṣe iṣẹ́ apanilẹ́rìín láì fihàn - Woli Agba Ayo Ajewole
Ko ti si ẹni to mọ nkan to fa ijamba ina ọhun to waye nile ẹkọ alakọbẹrẹ naa.
Ṣugbọn iru ijamba bẹẹ ti waye ri ni ni awọn ile ẹkọ kan ni Niger, to fi mọ olu ilu orilẹ-ede naa, Niamey, to si pa ogunlọgọ ọmọde.
Ni bayii, ijọba ti fi ofin de kikọ awọn akẹkọọ ni awsn yara kilaasi ti wọn fi igi ati koriko ṣe. Ṣugbọn, ko ti i sọ eto miran to ṣe fun awọn kilaasi miran fun wọn.
Ọpọ igba ni ẹnu ti kun ijọba orilẹ-ede naa pe ko pese aabo to peye fun awọn akẹkọọ lẹyin awọn ijamba ina to ti waye sẹyin.
Orilẹ-ede Niger wa lata awọn orilẹ-ede ti eto ẹkọ wọn buru julọ ni agbaye.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
O kere tan akẹkọọ ọmọde mẹẹdogbọn lo ṣagbako iku lorilẹede Niger ninu ijamba ina to ṣẹlẹ ni yara ikawe wọn lapa guusu orilẹede naa.
Oṣiṣẹ ijọba kan ṣalaye pe awọn ọmọde ọhun ko ju ọdun marun si mẹfa lọ.
Ọpọ eeyan lo farapa yana yana nibi iṣẹlẹ ina ọhun to ṣẹlẹ lasiko tawọn ọmọde naa n gbẹkọọ lọwọ ni yara ikawe wọn ti wọn fi koriko kọ lẹkun Maradi ni Niger.
Ko sẹni to ti mọ ohun to ṣe okunfa iṣẹlẹ ọhun titi di asiko ti a kọ iroyin yii.
Lorilẹede Niger, wọn maa n fi igi ati koriko kọ awọn yara ikawe lẹyin ti ile oni bulọọku ko ba gba awọn akẹkọọ mọ.
Adari ijọba ẹkun Maradi, Chaibou Aboubacar, sọ fawọn akọroyin pe yara ikẹkọọ mẹta ni ina yo ninu iṣẹlẹ ọhun.
Ẹnikan ti iṣẹlẹ naa ṣoju rẹ ṣalaye pe oun rii bi wọn ṣe n ko oku awọn ọmọde sinu ọkọ ti wọn si n gbe awọn to farapa lọ si ile iwosan.
O ni ipo to lagbara lawọn ọmọde to farapa ninu iṣẹlẹ naa wa.
Ni bayii, ijọba ti paṣẹ pe ki da igbẹkọ duro ni ile ẹkọ naa.
Ijamba ina lawọn ile ẹkọ ko wọpọ rara ni orilẹede Niger.
Amọ ogun akẹkọọ lo gbẹmi mi ninu iṣẹlẹ ijamba ina to ṣẹlẹ ni ile ẹkọ kan niluu Niamey tii ṣe olu ilu orilẹede sẹyin ninu ọdun yii.
Yara ikẹkọọ ti wọn fi koriko kọ mejidinlọgbọn lo jona ninu iṣẹlẹ naa eleyii to jẹ ki awọn eeyan maa sọrọ.
Ikoyi house collapse: Ẹni kọ̀ọ̀kan tó fẹ́ rà nínú ilé alájà 21 tó wó l'Eko ti ṣàdéhùn láti san N206m sí N1.24bn kó tó wó
Oríṣun àwòrán, LASEMA
Awọn Yoruba maa n gbadura kan pe ki Edua ma jẹ ki ohun ti a ko ro ba ohun ti a n ro jẹ.
Bayii gan an lọrọ ṣe ri pẹlu awọn eeyan to fẹ ra ninu ile alaja mọkalelogun to da wo lagbegbe Ikoyi niluu Eko lọjọ kinni oṣu kọkanla.
Ninu ifọrọwerọ ti awọn eeyan kan lara wọn ṣe pẹlu iwe iroyin Punch, wọn fidi rẹ mulẹ pe awọn ti buwọlu iwe adehun lati san owo toto N206.5m($500,000 ) si N1.24bn($3m) ẹni kọọkan.
Awọn iwe adehun ti wọn fi han akọroyin Punch ṣe afihan rẹ rẹ pe wọn lanfanni lati san owo yoku laarin ọdun mẹrin lẹyin ti wọn ba ti sanwo akọkọ tan.
Wọn ni ileeṣẹ akọleta Fourscore Heights Limited sẹ agbekalẹ ati sanwo to ku lọna to rọrun fawọn.
Wọn eeyan le maa san owo toku loṣooṣu, lẹẹmẹrin lọdun, lẹẹmeji lọdun tabi lẹẹkan lọdun, eleyii to ba wu yin ni.
Bakan naa ni wọn ṣalaye pe aja ile ti o ba fẹ ra ba ṣe ga si ni owo rẹ yoo ṣe pọ to.
Ẹnikan lara awọn to fẹ ra ile nibẹ sọ pe oun san N266m fun ile oni yara mẹta ti oun fẹ ra ninu awọn ile to wa lati aja kẹjọ lọ silẹ.
Amọ, o sọ pe akọleta to ni ileeṣẹ Fourscore Heights Limited din oun lowo nitori ọrẹ ni awọn jọ jẹ.
O ni awọn jọ ṣe kekere ni lati ileewe Mayflower niluu Ikene nipinlẹ Ogun, bakan naa lo ni awọn jọ wa ni ilu London ni.
O ṣalaye pe oun gbọ pe awọn to fẹ ra ile lati aja kejila lọ soke lọ san owo to le ni N492m.
O fikun ọrọ rẹ pe awọn to fẹ ra ile lati aja kẹtadinlogun lọ soke san owo to le ni N1.24bn($3m).
Dọla ni wọn sọ pe ileeṣẹ Fourscore Heights Limited sọ fawọn pe ki awọn fi sanwo.
Ileeṣẹ naa o ti fesi si gbogbo ọrọ tawọn eeyan n sọ nipa wọn titi di akoko yii.
Eeyan mejilelogoji ni ijọba ipinlẹ Eko sọ pe wọn ku nibi iṣẹlẹ naa nigba ti ori ko eeyan mẹẹdogun yọ nibi iṣẹlẹ ọhun.
Woli Agba Ayo Ajewole: Mo bọ́ sínú ọkọ̀, mo kéé gidi gan mo sì nu ojú nù lọ ṣe eré lórí ìtàgé
Woli Agba: Ti wọn ba sọ fun mi pe iyawo mi ti bimọ mo fẹ lọ kede rẹ lori itage ere ti mo n ṣe lọwọ ki wọn ba mi yọ...
Dokita: Woli Agba a dẹ maa n gbadun yin gan o, koda mo gbiyanju gidi gan amọ  ma binu o ọmọ taa n reti ti pada
Woli Agba: O pada, lọ sibo, o pada bawo, ki lo lọ ṣe?
Dokita ni gẹgẹ bi iṣẹ mi, ki n tun lọ pa iyawo mi lẹrin lori bẹ́ẹ́dì ile iwosan lẹyin to sọ fun mi pe oun gbiyanju ṣugbọn mọ taa bi ti pada.
Gbajugbaja adẹrinpoṣonu ti ọpọ eniyan fẹran, Ayo Ajewole ti orukọ itage rẹ n jẹ Woli Agba kẹnu bọ ọrọ, omi kun rọrọ si ni loju bo ṣe n ṣalaye fun BBC Yoruba oun toju apanilẹrin n ri labẹ aṣọ amọ tẹrin tẹrin yii naa lo tun fi n sọọ.
Ninu akanṣe ifọrọwanilẹnuwo taa ṣe pẹlu rẹ, apanilẹrin yii ṣalaye bo ṣe ku fẹẹrẹ ko gun ori itage lọjọ kan to si gba ipe pe ko maa bọ nileewosan ti iyawo rẹ ti n rọbi lọwọ.
'Ẹ yé tan ara yín, èmi mo ni aṣọ 120 yard tó jábọ́ lát'ọ̀run táwọn ará Ondo ń ya mọ́ ara wọn lọ́wọ́'
Kí ló fàá tí Dele máa ń ṣe àìgbọ́ràn sí Wòlíì?
Mr Macaroni, Taaooma, Woli Agba, Adeyemi Elesho sọrọ lórí ìpè láti ṣèpàdé pẹ̀lú ìgbákéjì ààrẹ Yemi Osinbajo
Wo àwọn èèkàn, ìlúmọ̀ọ́ka olórin tó ṣàbẹ̀wò sí ijọ Celestial Church ti Genesis Global
Ayé òò! Ọmọ ilé ẹ̀kọ́ alákọ́bẹ́ẹ̀rẹ̀ mẹ́ẹ̀dọ́gbọ̀n jóná mọ́ yàrá ìkẹ́kọ̀ọ́ tí wọn fi igi àti koríko kọ́
Ọwọ́ ọlọ́pàá tẹ olórí pátápátá fún àwọn ajínigbé kan l'Ekiti
"Ajínigbé ń bèèrè N10m, ""Codiene"", igbó àtí oúnjẹ fún ìtúsílẹ̀ èèyàn mẹ́ta tí wọ́n gbé l'Ogun"
Ni ọjọ ti mo ni iṣẹ apanilẹ́rin lati ṣe gangan ti awọn eeyan ti n reti pe Woli Agba n bọ o ni mo gba ipe lati ileewosan.
Ero Woli Agba ni ko de ileewosan ki wọn sọ fun un pe o ti bimọ ko lee pada sọọ lori itage pe ki wọn ba oun yọ ni wọn ba ni Dokita fẹ rii ni ọfiisi.
Íroyin ibanujẹ ni Woli Agba ba pada lọ sinu ọkọ amọ alaye pọ ninu fidio yii bi woli Agba ṣe kaa sara to ṣi tun lọ ṣere lori itage lọjọ kan naa.
Ayo Ajewole wa sọ bi ọrọ rẹ ṣe pada di ayọ.
Wo ohun tí ọkọ àti ìyàwó, Lateef Adedimeji àti Bimpe fi síta fúnra wọn to fihàn pé ọjọ́ ti súnmọ́
Kí ló mú Princess Comedian máa wa ẹkún mu láàrọ̀ kùtù?
'Ọba Yorùbá kìí ṣe aláṣẹ ìkejì Orìṣà mọ́ látòní lọ! Krìstẹ́nì, Mùsùlùmí àti Àbáláyé yóò máa ṣe ayẹyẹ pọ látòní'
Wọ́n ti bẹ̀rẹ̀ ètò ìsìnkú àwọn akẹ́kọ̀ọ́ 26 tó jóná mọ́ yàrá ìkẹ́kọ̀ọ́ wọn
Ọwọ́ ọlọ́pàá tẹ olórí pátápátá fún àwọn ajínigbé kan l'Ekiti
Kidnapping in Ekiti: Àwọn ajínigbé kó sí gbaga ọlọ́pàá ní ìpínlẹ̀ Ekiti
Oríṣun àwòrán, ASP Sunday Abutu
Ẹka ileeṣẹ ọlọpaa to n ri iṣẹlẹ pajawiri, RSS, ni ipinlẹ Ekiti ti fi ṣikun ofin mu okunrin kan, Ogunyemi Bunmi, ti wọn fẹsun kan pe oun ini olori awọn ajinigbe ni ipnlẹ naa.
Nigba to n ṣi aṣọ loju eegun afurasi naa atawọn afurasi mii, alukoro ileeṣẹ ọhun, ASP Sunday Abutu sọ fun awọn akọroyin pe ilu Ikere Ekiti ni ọwọ ti tẹ afurasi ọhun, to jẹ ọmọ oloye kan niluu Ado-Ekiti.
Abutu sọ pe afurasi naa jẹwọ ni agọ ọlọpaa pe oun lo wa nidi ijinigbe oniṣowo epo bẹntiro kan, Alhaji Suleiman Akinbami niluu Ado-Ekiti, ati aya olori awọn wọnlẹ-wọnlẹ ni ipinlẹ Ekiti tẹlẹ, Osalusi Dapo, to fi mọ ẹnikan ti wọn pe orukọ rẹ ni Olowo Bolaji niluu Ipoti-Ekiti.
'Ẹ yé tan ara yín, èmi mo ni aṣọ 100 yard tó jábọ́ lát'ọ̀run táwọn ará Ondo ń ya mọ́ ara wọn lọ́wọ́'
Afurasi ọhun mu awọn agbofinro lọ si ibi ti oun atawọn ẹmẹwa rẹ n fi ori pamọ si, to tun jẹ ibi ti wọn maa n ko awọn ti wọn ba ji gbe pamọ si.
Agbẹnusọ ọlọpaa naa fi kun pe ikọ afurasi naa jẹwọ pe awọn lo ji oloye kan, Ajayi Abiodun gbe.
Oloye naa jade laye lasiko to n gbiyanju lati moribọ lọwọ awọn ajinigbe ọhun to si fo jade kuro ninu ọkọ nigba ti wọn  gbe lọ sinu igbo kan ni ipinlẹ naa.
Bí mo ṣe káa sára tí mo gbé òkú ọmọ sínú ọkọ̀ lọ ṣe iṣẹ́ apanilẹ́rìín láì fihàn - Woli Agba Ayo Ajewole
Abutu kede orukọ awọn ọmọ ikọ ajinigbe naa gẹgẹ bii Banji Akeem ti apẹle rẹ n jẹ Yellow; Jimoh  Dele, ti wọn n pe ni Dele Detim; Johnson, ti wọn n pe ni Yellow Okada ati Dayo Igwe to ti na papa bora.
Gẹgẹ bii ohun to sọ, ileeṣẹ ọlọpaa ti n ṣiṣẹ takun-takun lati mu awọn ọmọ ikọ naa to ti na papa bora ati lati fọ ipinlẹ naa mọ.
Lara awọn ohun ti wọn ri gba lọwọ awọn ajinigbe ọhun ni ibọn ibilẹ, ọta ibọn ati ọkọ ayọkẹlẹ Toyota Corolla kan.
Lẹyin naa lo gba awọn araalu nimọran lati maṣẹ dakẹ gbera ti wọn ba kofiri iwa ọdaran lagbege wọn.
"'Wọ́n gba irun abẹ́ wa, irun abíyá wa, a lọ búra, ilé ""Nylon"" la tún ń gbé ni Mali fi ṣe iṣẹ́ aṣẹ́wó'"
Princess Comedian: Kí ló mú Princess Comedian máa wa ẹkún mu láàrọ̀ kùtù?
Oríṣun àwòrán, princesscomedian
Ohun to le mu ki agbalagba dede sun ẹkun arokan jade kọjaa keeyan ni o n ṣe ere ni.
Gbajugbaja adẹrin poṣonu, Princess Damilola, ti ọpọ mọ si Princess Comedian lo dede bẹrẹ si n wa ẹkun mu nitori eto kan to n mura lati ṣe laipẹ yii.
Ninu fidio kan to fi lede loju opo Instagram rẹ lo ti n sun ẹkun pẹlu ipaya lori bii eto kan yoo ṣe lọ.
Gẹgẹ bii ohun ti Princess sọ, awọn ọrẹ rẹ to n wo bii alatilẹyin ja a kulẹ lasiko to n mura fun eto adẹrinposonu naa.
'Ẹ yé tan ara yín, èmi mo ni aṣọ 100 yard tó jábọ́ lát'ọ̀run táwọn ará Ondo ń ya mọ́ ara wọn lọ́wọ́'
"Princess ni ""Mi o le sun, idi rẹe ti mo ṣe n gbe fidio yii sita fun awọn eeyan kan."""
Ọjọ marun un si asiko yii ni eto apanilẹrin ti mo fẹ ṣe yoo waye ṣugbọn awọn ti mo lero pe yoo ba mi polongo eto naa ko ri temi ro.
Gbogbo awọn ti mo n reti ki wọn kede eto naa loju opo wọn ko ṣe ohunkohun nipa rẹ.
Lara awọn eeyan ti Princess darukọ ni adari eto Gbenga Adeyinka, Iledare Olajunwonlo, ti ọpọ eeyan mọ si Jaywon, Julius Agu, Alibaba, eti bẹẹ bẹẹ.
"Pẹlu ibanujẹ ọkan ni Princess fi darukọ awọn eeyan ọhun to si  sọ pe ""Awọn bii Tee A ati Gbenga Adeyinka to maa n ki mi laya pe ki n tẹsiwaju ninu iṣẹ apanilẹrin ko tilẹ sọrọ kankan lori eto naa loju opo wọn."""
Ọwọ́ ọlọ́pàá tẹ olórí pátápátá fún àwọn ajínigbé kan l'Ekiti
Ayé òò! Ọmọ ilé ẹ̀kọ́ alákọ́bẹ́ẹ̀rẹ̀ mẹ́ẹ̀dọ́gbọ̀n jóná mọ́ yàrá ìkẹ́kọ̀ọ́ tí wọn fi igi àti koríko kọ́
"Ajínigbé ń bèèrè N10m, ""Codiene"", igbó àtí oúnjẹ fún ìtúsílẹ̀ èèyàn mẹ́ta tí wọ́n gbé l'Ogun"
Bí mo ṣe káa sára tí mo gbé òkú ọmọ sínú ọkọ̀ lọ ṣe iṣẹ́ apanilẹ́rìín láì fihàn - Woli Agba Ayo Ajewole
O fi kun pe awọn eeyan gan ti yoo kopa ninu eto naa ko tilẹ fi ipolowo rẹ sita soju opo wọn.
Princess ni eto naa yoo waye, yala wọn sọrọ nipa rẹ ni o tabi wọn kọ.
Lẹyin naa lo bu ṣekun, to si sọ pe oun n saaro ọrẹ oun to di oloogbe laarin ọdun yii, iyẹn olorin takasufe, Sound Sultan.
Bi ẹ ko ba gbagbe, Princess yii lo pe Olanrewaju Omidina, Baba Ijesha lẹjọ lori ẹsun pe o fi ipa ba ọmọ oun lopọ.
Ẹjọ naa ṣi n lọ lọwọ nile ẹjọ to giga to wa ni Ikeja, niluu Eko.
"'Wọ́n gba irun abẹ́ wa, irun abíyá wa, a lọ búra, ilé ""Nylon"" la tún ń gbé ni Mali fi ṣe iṣẹ́ aṣẹ́wó'"
Operation Feed Yourself: Ìjọba Naijiria kéde ọ̀nà láti pèsè ọ̀pọ̀ oúnjẹ láàrín ìlú
Oríṣun àwòrán, Tolani Ali
Ijọba Naijiria ti kede eto ti yo mu ki ounjẹ pọ yanturu laarin ilu lọna ati gbogun ti iṣoro aito ounjẹ aṣaraloore.
Igbakeji Aarẹ, Ọjọgbọn Yemi Osinbajo lo kede eto naa nibi ipade kan to waye nile Aarẹ niluu Abuja.
Osinbajo sọ pe ijọba apapọ yoo ṣiṣẹ papọ pẹlu awọn ajọ kan lati ṣe agbekalẹ oko igbalode atawọn oko etile.
Lara awọn to wa nibi ipade naa ni igbakeji akọwe apapọ ajọ iṣọkan abaye, UN, Amina Mohammed; awọn gomina ipinlẹ; awọn aṣoju ajọ iranwọ bii UNICEF; Bill and Melinda Gates Foundation, ajọ Aliko Dangote Foundation, atawọn ajọ agbaye mii.
Oríṣun àwòrán, Tolani Ali
"Nibi ipade naa ni Osinbajo ti kede eto kan ti wọn pe ni ""Fun Ara Rẹ Lounjẹ,"" Operation Feed Yourself, eyii ti yoo ran ijọba lọwọ lati pese ọpọ ounjẹ fun awọn araalu."
"O ni ""Awọn ọna kan wa ti awọn ipinlẹ ati ijọba apapọ le gba laarin asiko yii si oṣu mejila"" ti yoo mu ki awọn araalu le jẹ ajẹyo ati ajẹṣẹku."
Bí mo ṣe káa sára tí mo gbé òkú ọmọ sínú ọkọ̀ lọ ṣe iṣẹ́ apanilẹ́rìín láì fihàn - Woli Agba Ayo Ajewole
Igbakeji Aarẹ sọ pe eto naa yoo wa ni oniruru ipele bii idasilẹ awọn oko nla-nla ati oko kekeke lawọn igberiko ati lẹba ile.
Gẹgẹ bii ohun to sọ, eto naa yoo mu ki awọn araalu bii ẹnikọkọọkan, to fi mọ awọn ile ẹkọ lati da oko ti wọn silẹ.
"Osinbajo sọ pe ""Yatọ si pe eto yii yoo ran onikaluku atawọn idile lọwọ lati jẹ ajẹyo ati ajẹṣẹku, yoo tun fun Naijiria lanfani lati maa ko ounjẹ lọ silẹ okeere."""
"'Wọ́n gba irun abẹ́ wa, irun abíyá wa, a lọ búra, ilé ""Nylon"" la tún ń gbé ni Mali fi ṣe iṣẹ́ aṣẹ́wó'"
Ondo Sky Cloth: Bóyá ó ní ogún kan tó pọ̀ tó fẹ́ ja ìdílé mi ní Ọlọ́run bá mi fi gbígbé aṣọ yẹn ṣe ìṣẹ́gun
Nkan bii ọjọ melo kan sẹyin ni ariwo gba gbogbo ilu kan nipinlẹ Ondo kan nigba ti awọn araalu bẹrẹ si ni fa aṣọ funfun nla kan mọ ara wọn lọwọ ti wọn n ya a kutukutu plu igbagbọ pe lati ọrun ni ọlọrun ti juu kalẹ wa si aye.
BBC Yoruba boju wo ọrọ yii a si ṣe iwadii finifini lati mọ ohun to ṣẹlẹ gangan.
Ẹ yéé gbé ìròyìn òfegè kiri nípa olóògbé Femi Osibona, ó ṣèlérí N25M fún ìjọ mi àmọ́... - Genesis
Bó ṣe òṣèlú náà ló gbà, a léè fi wọ ọ̀rọ̀ Sunday Igboho - Malami
Wọ́n tún ti yọ òkú èèyàn méjì síi níbi ilé tó wó l'Eko, ó di èèyàn 45 tó kú níbẹ̀ báyìí
Iwadii wa ni ipinlẹ Ondo lo fihan pe ibi ti aṣọfunfun pupọ oni yaadi pupọ ti awọn eeyan n du mọ ara wọn lọwọ yii ni ile arabinrin kan to maa n fi oriṣiriṣi aṣọ ṣe gbọngan ayẹyẹ ni ọṣọ.
Arabinrin Agnes Fadoju ṣalaye pe ni ọjọ ti oun fọ aṣọ naa, oun saa si ẹyin ile idana wọn ti gbogbo ara ile wọn si jade lọ ibi iṣẹ oojọ wọn.
'Ọba Yorùbá kìí ṣe aláṣẹ ìkejì Orìṣà mọ́ látòní lọ! Krìstẹ́nì, Mùsùlùmí àti Àbáláyé yóò máa ṣe ayẹyẹ pọ látòní'
Charles Soludo ti jáwé olúborí gẹ́gẹ́ bí gómìnà ìpínlẹ̀ Anambra
Ọwọ́ ọlọ́pàá tẹ olórí pátápátá fún àwọn ajínigbé kan l'Ekiti
Wo ohun tí ọkọ àti ìyàwó, Lateef Adedimeji àti Bimpe fi síta fúnra wọn to fihàn pé ọjọ́ ti súnmọ́
Mi ò lè sùn, mó ń ronú, mi ò lè ṣe ǹkan torí Lanre - Princess
Lọsan ni awọn eeyan bẹrẹ si ni pe mi lati bi mi pe ṣe mi o sa aṣọ iṣ mi sita tori aṣọ kan wa loju ofurufu to ti rin jina to n dru ba eeyan to n ṣe bii ejo.
Agnes ni oun da wọn lohun pe aṣọ ti oun sa jẹ aṣọ to pọ gidi gan ti atẹgun ko lee gbe lọ.
Afi to ibẹ to rii ti wọn n pin aṣọ naa mọ ara wọn lọwọ lootọ to si ri aridaju pe aṣọ oun ni.
Koda o ni ọpọ eeyan lo n taa mọ ori ti wọn n fi si ori ọja wọn pẹlu igbagbọ pe iyanu ni lati ọrun.
Ọkọ arabinrin naa, Akinolu  Fedogun fi kun un pe iyawo ohun lo sa aṣọ to fi n ṣe iṣẹ ṣiṣe gbọngan ayẹyẹ lọṣọ̀ọ́ sita ile idana wọn lọjọ Iṣẹgun ọsẹ ti iṣẹlẹ náà ṣẹ.
"Ṣe ọmọ táa bí ""fine"" ni ìyàwó mi ń bèrè, mo tún ń pa á lẹ́rìín kó má mọ̀ pé ọmọ ti kú - Woli Agba Ayo Ajewole"
"Ajínigbé ń bèèrè N10m, ""Codiene"", igbó àtí oúnjẹ fún ìtúsílẹ̀ èèyàn mẹ́ta tí wọ́n gbé l'Ogun"
"'Tí wọ́n bá bá ẹ sùn tí wọn ò ""release"" wọ́n á gba owó wọn, àwa la ń ra Kọ́ńdọ́ọ̀mù tí wọ́n fi ń bá wa sùn ní Mali'"
Oluwo God festival: Ọba Ogboni ìwásẹ̀ ní wọn ò ṣètùtù tó yẹ fún Oluwo kó tó jọba lójẹ́ kó máa ṣ'ìwà hù
Ọba Ogboni iwasẹ, Adeyinka Adisa Sangolade Arifanlajogun naa ti fesi si ọrọ ti Oluwo ilẹ Iwo, Oba Abdulrasheed Akanbi pe ko si ohun to n jẹ oriṣa mọ nilẹ Yoruba wi pe ọba lo jẹ gaba lori awọn oriṣa.
Ọba Igboni iwasẹ ni Oluwo ti yo tan, o wa n wa bẹkun bẹkun kiri lo jẹ ko maa sọ gbogbo ọrọ to n sọ kaakiri,
''Nigba mii, ti eeyan ba yo tan a maa wa bẹkun bẹkun kaakiri, nkan ti eeyan ko tọ si ti wọn gba gbe fun eeyan, o ṣeeṣe ki eeyan ṣii lo.
'Ẹ yé tan ara yín, èmi mo ni aṣọ 100 yard tó jábọ́ lát'ọ̀run táwọn ará Ondo ń ya mọ́ ara wọn lọ́wọ́'
Tori pe ti ẹ ba woo, iwa Oluwo yatọ si iwa gbogbo ọba ilẹ Yoruba.
Eledumare lo ṣe ẹda awọn oriṣa, awọn ọba naa si wa ninu awọn ti ori ṣa da.
Oluwo fẹ ba ilu Iwo jẹ, awọn alalẹ ko si ni gba fun un, awọn onilẹ atawọn igba iwasẹ ko le gba fun.
Awa o ka Oluwo mọ awọn ọba ilẹ Yoruba nitori ẹ ko mọ iru nkan to ti mu ki o to maa sọrọ lawujọ.
Awọn ooṣa ti Oluwo n tabuku wọn ṣi n wo Oluwo lọwọ ni, to ba to asiko wọn o kan si i tori ọjọ tio ọmọde ba mulẹ lo ma n mọ ki i mọ ọjọ ti yoo da a.
Ba wo ni Oluwo ṣe maa sọ pe ko si nkankan to n jẹ oriṣa nilẹ Yoruba?
Wọn ni oogun ti eeyan ko ba fi owo ṣe, ẹyin aaro lo n gbe, ẹni ti ko ni iru ẹni, ko le mọ iyi ẹni.
Wọn kan lọ mu Oluwo wa jọba ni wọn o ṣe gbogbo etutu to yẹ ki wọn ṣe fun un ki o to jẹ ọba,''Oba Ogboni Iwasẹ lo sọ bẹẹ.
Oba Ogboni tun sọ pe iru kan naa pẹlu Oluwo ni gbogbo awọn to n fi oju ọlaju wo awọn ohun ti Oluwo n ṣe.
O ni o ṣe pataki ki wọn maa fi Ifa ṣe iwadii ẹnikẹni to ba fẹ jẹ ọba nilẹ Yoruba.
'Gómìnà Osun ẹ kìlọ̀ fún Oluwo lórí ọ̀rọ̀ ẹnu rẹ̀ pé Ọba kìí ṣe ìkejì Orìṣà!' Àwọn ẹlẹ́sìn ìbílẹ̀ tutọ́ s'ókè
Oluwo ti ilẹ Iwo, Oba AbdulRasheed Akanbi ṣe ọdun Olodumare lọjọ Iṣẹgun ọjọ kẹsan an oṣu kọkanla ọdun 2021, aye gbọ ọrun mọ.
Amọ, ẹgbẹ awọn ẹlẹsin ibilẹ, Traditional Religion Worshippers Association (TRWASO), ti kepe gomina ipinlẹ Osun, Adegboyega Oyetola wi pe ko kilọ fun Oluwo lori ọrọ ẹnu rẹ ti wọn pe ni ọrọ alufansa.
Nibi ọdun Ọlọrun Ọba yii ni Oluwo ti sọ faraye pe oun kọ ni Ọba, Ọlọrun nikan ni Ọba, Ọlọrun nikan si ni gbogbo eeyan to wa nibi ayẹyẹ Ọdun Ọlọrun Ọba waa yin.
Oluwo ni ''ọba alade gbọdọ maa gboṣuba fun Eledua to jẹ Ọba awọn ọba.
O ṣeewọ ki ọba alade maa sin oriṣa kekeke, Ọlọrun ọba nikan lo yẹ ki gbogbo ọba maa wari fun.
Mi o le sikeji si oriṣa kankan nitori mi kii ṣe ẹru ooṣa.
Mo lagbara lori gbogbo oriṣa nitori emi ni mo n ṣoju Eledumare to n jẹ Kabiyesi.''
"Ṣaaju nigba ti Oluwo kọkọ kede pe oun yoo ṣe ayẹyẹ yii, akọle to pee ni ""Ọdun Olodumare"" amọ nigba to ya, Oluwo yii pada si ""Ọdun Ọlọrun Ọba"" fun idi to jẹ wipe Kabiyesi nikan lo mọ."
Amọ, ẹgbẹ awọn ẹlẹsin ibilẹ TRWASO ti fun Oluwo ni ọjọ mọkanlelogun lati tọrọ aforijin lọwọ awọn.
Ẹgbẹ awọn ẹlẹsin ibilẹ sọ nibi ipade ti wọn ṣe nile Araba ilu Osogbo, Oloye Ifayemi Elebuibon pe Oluwo gbọdọ dẹkun fifi ori awọn ẹlẹsin gba ara wọn.
Aarẹ ẹgbẹ TRWASO, Ọmọwe Oluseyi Atanda sọ pe ti Oluwo ko ba fẹ wọ ade awọn oriṣa mọ, o yẹ ko fi aafin naa silẹ.
Ọmọwe Atanda ni ti ijọba ipinlẹ Osun ati Oluwo ko ba dawọn lohun titi di ọgbọnjọ oṣu kọkanla, miliọnu kan awọn ẹlẹsin ibilẹ ni yoo ṣe ifẹhonuhan lọ si ilu Iwo pe ki ijọba rọ ọ loye.
O ni aimọye igba ni Oluwo ti ṣe oriṣiiriṣii nkan ti ko bojumu fun ọba alade lati maa ṣe.
Sleeping tips: Tí ó kó bá sùn ni àárín aago yìí... Ò ń ṣe àkóbá fún ìlera ọkàn rẹ
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Àwọn ónímọ̀ sọpé tí ènìyàn bá sùn láàrin aago Mẹ́wàá sì aago mọ́kànlá lọ dára fún ọkàn. Wọ́n fẹnukò lórí àbájáde yìí lẹ́yìn tí wọ́n lo ènìyàn ẹgbẹ̀rún lọ́nà méjìdinlaadọ́run tí wọ́n fi ara wọn sílẹ̀.
Àwọn ìgbìmọ̀ to wà lẹ́yìn ìwádìí Bionbank tí wọ́n ṣe ni UK yìí nìgbàgbọ́ pé bí ènìyàn bá sùn gẹ́gẹ́ bí aago àgọ́ ara ènìyàn máa ṣèrànwọ́ láti mọ ìbáṣepọ̀ tó wà láàárín bí ó ṣe lè mú àdínkù bá ààrùn ọkàn àti súròkí.
Wákàtí mẹ́rìnlélógún ni àsìkò tí ara wa ń kà pàápàá jù lọ ara tó bá pe. Kíni àwọn ónímọ̀ ṣàwárí fún àsìkò tó yẹ láti sùn.
Ọ̀nà àbáyọ mẹ́wàá rè é fún aláboyún tí kò bá rí oorun ṣùn
Ajàfẹ́tọ́ obìnrin tó wá sí Nàìjíríà torí àwọn akẹ́kọ̀ọ́bìnrin Chibok tí wọ́n jígbé Malala Yousafzai ṣe ìgbéyàwó
Oluwo ti yó tán, ó ń wá bẹ́kùn bẹ́kùn kiri, àwọn òrìṣà tó ń tàbùkù ṣì ń wò ó lọ́wọ́- Ọba Ogboni ìwásẹ̀
Ọmọ kan ṣoṣo tó bí fún mi ni wọ́n gún lọ́dún mẹ̀ta sẹ̀yìn kí wọ́n tó gún òun náà pa báyìí
Ẹ yéé gbé ìròyìn òfegè kiri nípa olóògbé Femi Osibona, ó ṣèlérí N25M fún ìjọ mi àmọ́... - Genesis
'Ẹ yé tan ara yín, èmi mo ni aṣọ 100 yard tó jábọ́ lát'ọ̀run táwọn ará Ondo ń ya mọ́ ara wọn lọ́wọ́'
Nínú àtẹ̀jáde kan tí wọ́n ṣe nínú ìwé jọ́nà European Heart, àwọn olùwádìí naa mú kí àwọn tó fara wọn sílẹ̀ fún lílò nibi ìwádìí náà lo ẹ̀rọ kan tí yóò máa ka àsìkò tí wọ́n sùn tàbí tí wọ́n jí.
Wọ́n sì ṣe àmójútó nǹkan tí yóò ṣẹlẹ̀ sí ọkàn wọn àti bí gbogbo ìlera ara wọn yóò ṣe wá fún ọdún mẹ́fà.
Àwọn ẹgbẹ̀rún mẹ́ta péré nínú àwọn tó jẹ́ àgbà nínú wọn ló ní ààrùn ọkàn Ọ̀pọ̀ àwọn tó ní ààrùn náà ni àwọn tó sùn lẹ́yìn aago mẹ́wàá sì mọ́kànlá tó yẹ kí wọ́n sún.
Àwọn tí wọn ń sún ọrùn àsìkò
Síbẹ̀ èyí sì farahàn pé ìṣòro náà sì wà nibẹ lẹ́yìn tí wọ́n ti ṣe àtúnṣe àsìkò oorun wọn.
Àwọn olùwádìí náà wọ́nà láti wá ojútùú sì àwọn nǹkan míràn tí ó lè ṣe okùnfà ààrùn ọkàn bí ọjọ́ orí, ìwọ̀n, ọ̀rá tó pọ̀ lára, ṣùgbọ́n wọ́n ni ìwádìí àwọn kò lè sọ ní pàtó èyí tó jẹ́ níbẹ̀.
"Ẹni to ṣe àgbékalẹ̀ ìwádìí náà, Dr David Plans láti Fáṣítì Exeter sọ pé"" ìdí tí a kò fi lè fi ẹnu kò lórí nǹkan pàtó tó ṣe okùnfà èyí nínú ìwádìí wá ní pé, àbájáde ìwádìí jẹ́ kí ó ye wa pé tí ènìyàn bá tètè sùn tàbí kí ó pẹ́ sùn, ó lè jẹ́ ìdíwọ́ fún aago ara, pẹ̀lú ààrùn to níṣẹ́ pẹ̀lú ọkàn."
"Àsìkò tí ó léwu jùlọ láti sùn ni lẹ́yìn aago méjìlá òru, ìdí ni pé ó kó ni jẹ́ kí ara ní anfaani lati ri imọ̀lẹ̀ àárọ̀ tí ó máa ń ṣe atunto aago ara lojoojumo.
Ẹ yéé gbé ìròyìn òfegè kiri nípa olóògbé Femi Osibona, ó ṣèlérí N25M fún ìjọ mi àmọ́... - Genesis
Wo ohun tí ọkọ àti ìyàwó, Lateef Adedimeji àti Bimpe fi síta fúnra wọn to fihàn pé ọjọ́ ti súnmọ́
Mi ò lè sùn, mó ń ronú, mi ò lè ṣe ǹkan torí Lanre - Princess
Mo gbàgbọ́ nínú Ọlọ́run Mẹ́talọ́kan ló jẹ́ kí n bá Oluwo ti Iwo pé níbi Ọdún Olodumare - Òṣèré Jumoke Odetola
'Wọ́n gba irun abẹ́ wa, irun abíyá wa, a lọ búra, ilé Nylon"" la tún ń gbé ni Mali fi ṣe iṣẹ́ aṣẹ́wó'"
Obinrin to ń sun
Regina Giblin to jẹ́ nọ́ọ̀sì àgbà lórí ìtọ́jú ìṣòro ọkàn nílé ìwòsàn British Heart Foundation, sọ pé:  ìwádìí tó gbòòrò yìí ń sọ ní pe, ènìyàn gbọ́dọ̀ máa sùn láàrin aago mẹ́wàá alẹ́ sí aago mọ́kànlá láti mú kí ọkàn wọ́n jí pépé fún ìgbà pípẹ́Ẹ̀wẹ̀, ó ṣe pàtàkì láti rántí pé ìwádìí náà kan lè sọ ìbáṣepọ̀ tó wà láàárín méjèèjì ṣùgbọ́n kí ó máa lé fi ìdí rẹ̀ múlẹ̀ ni pàtó.
Ìwádìí nílò lórí àsìkò tí ènìyàn ń sùn àti iye wákàtí tó gbọdọ̀ jẹ́. Sísun oorun tó tó ṣe pàtàkì fún àgọ́ ara wa, àti fún ọkàn láti jẹ́ kí ìlera kẹ́ṣẹ járí pàápàá julọ àwọn àgbà níláti sùn fún wákàtí méje láàrin òru gẹ́gẹ́ bí ó ṣe sọ.
 Ṣùgbọ́n oòrùn nìkan kọ́ ni ó lè fa wàhálà sí àgọ́ ara. Ó ṣe pàtàkì láti mójú tó bí ó ṣe ń gbé ìgbé ayé, àyẹ̀wò ẹ̀jẹ̀ nípa ìfúnpá rẹ àti ọ̀rá inú ara, mójú tó bí o ṣe sanra sí, máa ṣe ìdárayá lóòrèkóòrè, mú àdínkù bá iyọ̀ jíjẹ àti ọtí mímu. Jẹ oúnjẹ tí gbogbo èròjà rẹ pé fún àgọ́ ara tó ní àlàáfíà.
Malala Yousafzai kúrò lẹ́gbẹ́ àwọn omidan, o ṣe nikkah nílùú Birmingham
Oríṣun àwòrán, Getty Images
"Ajafẹtọ ọmọniyan, to tun gba ami ẹyẹ ""Noble Prize,""  Malala Yousafzai ti ṣe igbeyawo pẹlu ololufẹ rẹ niluu Birmingham."
Malala ati ololufẹ rẹ, Asser Malik ṣe nikkah wọn nibi ti wọn ti so awọn mejeji pọ ni ilana ẹsin Musulumi.
Ẹni ọdun mẹrinlelogun naa sọ pe ọjọ igbeyawo ọhun jẹ ọjọ manigbagbe ninu igbe aye oun.
Lọdun 2017 ni Malala wa si orilẹede Naijiria lati ba awọn adari sọrọ fun jija fun ẹtọ ọmọbinrin.
Malala, to jẹ ajafẹtọ awọn obinrin ni Pakistan ṣalọ ilẹ Geẹsi fun atipo lẹyin ti ikọ Taliban yinbọn lu ni ori lọdun 2012.
"Lasiko to n kede iroyin igbeyawo naa loju opo Twitter rẹ, o ni ""Emi ati Asser ti di lọkọ-laya nibi ayẹyẹ nikkah kekere kan pẹlu awọn mọlẹbi wa."""
Oríṣun àwòrán, MALIN FEZEHAI
Ọmọ ọdun  marudinlogun ni Malal wa nigba ti Taliban doju ija kọ ọ ni Pakistan nitori pe n sọrọ soke fun ẹtọ awọn obinrin.
'Ẹ yé tan ara yín, èmi mo ni aṣọ 100 yard tó jábọ́ lát'ọ̀run táwọn ará Ondo ń ya mọ́ ara wọn lọ́wọ́'
Lọdun naa lọhun ni Taliban kọlu ọkọ bọọsi ile ẹkọ rẹ ti wọn si ṣina ibọn bolẹ, oun atawọn ọrẹ rẹ meji lo farapa ninu ikọlu ọhun.
Lẹyin to gbadun tan ni oun atawọn ẹbi rẹ lọ ṣatipo niluu Birmingham, nibi to pe ni ile rẹ keji.
Oríṣun àwòrán, MALIN FEZEHAI
"Niga to maa fi di ọmọ ọdun mẹtadinlogun, o di ẹni to kere julọ lagbaye ti yoo gba ami ẹyẹ ""Noble Prize."""
Lati ibẹ lọ, Malala lọ si fasiti Oxford, o si di ọkan lara awọn ajafẹtọ ọmọniyan to lamilaaka julọ lagbaye.
Bí mo ṣe káa sára tí mo gbé òkú ọmọ sínú ọkọ̀ lọ ṣe iṣẹ́ apanilẹ́rìín láì fihàn - Woli Agba Ayo Ajewole
Woman kiiled three years after daughter: Bàbá ọmọ obìnrin tí wọ́n gún l'Akure sọ bí ọ̀rọ̀ náà ṣe rí lára rẹ̀
Oríṣun àwòrán, naijanews
Awọn mọlẹbi obinri ti wọn gun pa niluu Akure lẹyin ọdun mẹta ti wọn ti kọkọ gun ọmọ rẹ naa pa ti ṣalaye bi iku rẹ ṣe ri lara awọn wọn.
Lara awọn mọlẹbi oloogbe ọhun ti BBC ba sọrọ ni ọkọ to n fẹ tẹlẹ, iyẹn Oloye Ajila.
Ajila ṣalaye fun BBC pe iroyin iku obinrin naa ba oun lojiji, o si jẹ kayeefi fun oun pẹlu.
"Nigba to n ba BBC Yoruba sọrọ, o ni ""Mo kigbe AH! Ki ni obinrin yii ṣe ti wọn fi ṣe irufẹ ikọlu bayii si?"""
Okunrin naa ṣalaye fun BBC pe bo tilẹ jẹ pe o ti le ni ọdun mẹrin ti awọn mejeji ti pinya gẹgẹ bii lọkọ-laya, ọmọ kan ṣoṣo ti obinrin ọhun bi fun oun ni awọn kan ṣeku lọdun mẹta sẹyin.
Gẹgẹ bii ohun to sọ, ija wa laarin wọn gẹgẹ bii lọkọ-laya, awọ si ti pinyan, eredi ree ti awọn mejeji ko ṣe tii ri ara wọn soju lati ọpọ ọdun sẹyin.
"O ni ""O bi ọmọ kan ṣoṣo fun mi, ọmọ naa si ni awọn kan pa ni nnkan bii ọdun mẹta ṣeyin, koda ile mi ni wọn sin ọmọ naa si, amọ a ko tii foju kan ara wa titi ti iṣẹlẹ yii fi waye."""
'Ẹ yé tan ara yín, èmi mo ni aṣọ 100 yard tó jábọ́ lát'ọ̀run táwọn ará Ondo ń ya mọ́ ara wọn lọ́wọ́'
Ara ile obinrin naa miran ti BBC tun kan si lori iṣẹlẹ ọhun, Muyide Kayode sọ pe irufẹ ọna ti wọn fi pa ọmọ obinrin naa lọdun mẹta sẹyin ni wọn fi tun fi iya rẹ pa bayii.
Kayode ni eeyan daadaa ni obinrin naa jẹ ko to jade laye.
BBC Yoruba tun kan si Funmilayo Odunlami, to jẹ agbẹnusọ ileeṣẹ ọlọpaa ipinlẹ Ondo ti iṣẹlẹ naa ti waye.
Odunlami ni iwadii ti bẹrẹ, awọn yoo si fi atẹjade sita laipẹ.
"O ni ""A ti gbọ nipa iṣẹlẹ naa, ṣugbọn iwadii n lọ lọwọ."""
Ṣe ẹ mọ pe o loju ọrọ ti a le sọ sita nipa irufẹ iṣẹlẹ bayii ki ohun ti a ba sọ ma ba di iwadii wa lọwọ.
Ṣugbọn a ti gbọ, a si ti bẹrẹ iwadi lori iṣẹlẹ naa.
Ki lot ti ṣẹlẹ ṣeyin?
Oríṣun àwòrán, Daily Post
Wọn ti ṣekupa obinrin kan, Yemisi Ajayi, niluu Akure, lẹyin ọdun mẹta ti awọn eeyan kan gun ọmọ rẹ obinrin pa.
Wọn gun obinrin naa pa nile rẹ to wa ni Abusoro, lagbegbe Ijọka Road, niluu Akure.
Gẹgẹ bii ohun ti awọn oṣojumikoro sọ, igba marun un ni wọn gun obinrin naa ni ikun lori ibusun rẹ.
Bí mo ṣe káa sára tí mo gbé òkú ọmọ sínú ọkọ̀ lọ ṣe iṣẹ́ apanilẹ́rìín láì fihàn - Woli Agba Ayo Ajewole
"Ṣaaju lọdun 2018 ni awọn kan ti kọkọ gun ọmọ rẹ obinrin to jẹ ẹni ogun ọdun, Oluwaseun Ajila ""Fiona"" pa nile yii kan naa."
Titi di akoko yii, ko si ṣeni to le sọ awọn to wa nidii iṣẹlẹ iku ọmọ obinrin ọhun ki wọn to tun gun oun naa pa.
Ọkan lara awọn oṣojumikoro ọhun, ti ko fẹ ki a fi orukọ oun lede sọ pe ọkan lara awọn olugbe ile obinrin naa lo ke gbajare sita ki wọn to ri oku rẹ ninu agbara ẹjẹ.
"O ni ""Ọmọde naa ṣalaye fun awọn eeyan pe oun n wa iya oun lẹyin ti oun ji tan, ki le wọn jọ gbadura papọ, amọ ko ri iya rẹ ọhun."""
Wòólì Alfred kú lọ́dún 1964, ó tún padà wà sí ìlú Agelu f'ọ́jọ́ mẹ́rìnlá!
Ko pẹ si akoko yii to ri oku iya rẹ naa ninu iyara, ti awọn awọn to ṣiṣẹ ibi naa si ti da aṣọ bo oku rẹ nibi yo wa.
"Oṣojumikoro naa tẹsiwaju pe ""Nigba ti mo de ibẹ lonii, ni ṣe ni mo bu sẹkun ki n to ke si awọn eeyan to wa layika."""
Ẹlomiran to ba awọn akọroyin sọrọ ni iṣẹlẹ naa ba oun ninu jẹ gidi gan nitori ọdun mẹta sẹyin ni awọn kọlọrọsi kan ti kọkọ pa ọmọ rẹ obinrin ninu ile yii kan naa.
Nigba ti BBC Yoruba kan si alukoro ileeṣẹ ọlọpaa ipinlẹ Ondo, Funmilayo Odunlami, o fidi iṣẹlẹ naa mulẹ.
Odunlami fi kun un pe iwadii ti bẹrẹ lati mọ ohun to ṣokunfa ipaniyan naa.
Ikoyi house collapse: Wọ́n tún ti yọ òkú èèyàn méjì síi níbi ilé tó wó l'Eko, èèyàn mẹ́ẹ̀dógún ló mórí bọ́
Oríṣun àwòrán, LASEMA
Awọn oṣiṣẹ adoola ẹmi pajawiri tun ti yọ eeyan labẹ ogiti alapa ile da wo lagbegbe Ikoyi niluu Eko ni Ọjọru.
Eyi lo jẹ ko di eeyan marunlelogoji to ku nibi iṣẹlẹ naa bayii lẹyin ti wọn ti yọ mẹtalelogoji tẹlẹ.
Kọmiṣọnna eto iroyin nipinlẹ Eko, Ọgbẹni Gbenga Omotoso lo fọrọ yii lede lalẹ Ọjọru loju Facebook ijọba ipinlẹ Eko.
Bakan naa ni o ṣalaye pe irọ ni ahesọ ọrọ kan tawọn eeyan n gbe kiri pe ijọba ti paṣẹ pe ki wọn wo awọn ile meji ti ileeṣẹ Fourscore Limited kọkọ kọ sẹgbẹ eyii to wo lulẹ.
Omotosho ni ''igbimọ to n ṣe iwadii lori iṣẹlẹ ile to wo ni Ikoyi ṣi n ba iṣẹ wọn lọ.
Igbimọ yii lo maa ṣe ayẹwo lori awọn ile meji ti wọn kọkọ kọ sẹgbẹ eleyii to wa lati mọ bo ya ijọba maa da a wo lulẹ.
Wọn ko tii ṣe ayẹwo yii, nitori naa o lodi fun awọn eeyan lati maa sọ pe ijọba ti ni ki wọn wo awọn ile naa.
Awọn oṣiṣẹ adoola ẹmi ṣi n ba iṣẹ lọ nibi ile to wo, lilọ bibọ ọkọ lopona Gerrard ti iṣẹlẹ ọhun ti waye ti n lọ geere lẹyin ti a ṣi ọna ọhun pada.
Awọn ẹbi ti awọn eeyan wọn wa lara awọn to ku nibi iṣẹlẹ naa ṣi n lọ si ile iwosan IDH ni Yaba lati gbe oku eeyan wọn.
Ẹbi to to mejilelọgbọn lo ti lọ fun ayẹwo ara wọn ni ile iwosan naa lati le mọ oku to jọ ti wọn.
Ti ayẹwo ko ba le fidi rẹ mulẹ daadaa, ijọba maa jọwọ oku naa fun ẹbi to fẹ gbe e.
Ijọba ti gbe igbimọ kan kalẹ ti yoo maa ṣe amojuto bi wọn ṣe n gbe oku awọn eeyan fun ẹbi wọn.
Ọjọ kinni oṣu kọkanla yii ni ile alaja mọkanlelogun naa da wo lojiji ni opopona Gerrad ni Ikoyi nibi ti eeyan marunlelologoji ti ku ti eeyan mẹẹdogun ti mori bọ.
"Tí ó kó bá sùn ní aago yìí sí aago yii, àkóbá tí ò ń ṣe fún ìlera ọkàn rẹ nìyìí""Ọmọ kan ṣoṣo tó bí fún mi ni wọ́n gún lọ́dún mẹ̀ta sẹ̀yìn kí wọ́n tó gún òun náà pa báyìí"""
Oluwo ti yó tán, ó ń wá bẹ́kùn bẹ́kùn kiri, àwọn òrìṣà tó ń tàbùkù ṣì ń wò ó lọ́wọ́- Ọba Ogboni ìwásẹ̀
"'Òbí mi máa ń bá wa wí gidi ní kékeré, ohùn tí mo ṣe ní fásitì tó mú mi gba ""Distinction"" 10, àmi ẹ̀yẹ̀ 5, ilé ọ̀fẹ́, owó rèé'"
Ibadan Petrol tanker accident: Tánkà agbépo bẹntíróò ṣubú n'Ibadan, àwọn èèyàn ń gbọ́n epo láì bẹ̀rù iná
Oríṣun àwòrán, Other
Iroyin to n tẹ wa lọwọ lati ilu Ibadan tii ṣe olu ilu ipinlẹ Oyo sọ pe tanka agbepo bẹntiro kan ti ṣubu lagbegbe Olorunsogo ti epo inu rẹ si danu.
Ohun to jẹ iyalẹnu ni pe wọn niṣe lawọn eeyan n gbọn epo to danu lai nan ni bo ya ina le gba lojiji.
Awọn to wa ladugbo naa fi idi rẹ mulẹ pe idaji Ọjọbọ oni ni tanka ọhun to gbe epo jala lọna ẹgbẹrun mẹtalelọgbọn ṣubu ni Olorunsogo.
A gbọ wi pe awọn oṣiṣẹ adoola ẹmi ti wa nibẹ ti wọn ṣi n sa apa wọn lati ri pe ijamba ina ko ṣẹlẹ lati ibẹ.
Ṣugbọn bi wọn ṣe kilọ fawọn eeyan lori ewu ijamba ina to le ṣẹlẹ, niṣe ni wọn kọ eti ikun tu wọn si bẹrẹ si ni gbọn epo.
Awọn eeyan agbegbe Olorunsogo ti iṣẹlẹ naa ṣoju wọn ṣalaye pe ọkọ tanka agbepo naa takati ti o si ṣubu soju ọna mọrosẹ Eko si Ibadan.
Sunday Igboho: A ṣì lè jèbùrẹ́ lórí ọ̀rọ̀ Sunday Igboho àti Kanu tí wọ́n bá kàn sí wa - Malami
Oríṣun àwòrán, sunday_igboho1
Ijọba apapọ Naijiria ti sọ pe awọn ṣi le lo eto oṣelu lati yanju ọrọ oloye Sunday Igboho ati Nnamdi Kanu.
Agbẹjọro agba ni Naijiria, Abubakar Malami lo fi ọrọ naa lede.
Malami sọ pe ijọba apapọ ko le la oju rẹ oju rẹ silẹ ki awọn kan wa maa da ilu ru mọ ọ lori.
Gẹgẹ bii ohun to sọ, ti araalu ba hu iwa ọdaran, o ti di dandan ki ijọba da sẹria fun irufẹ araalu bẹẹ.
"O ni ""Iwa ọdaran ko ni orukọ meji bi koṣe iwa ọdaran, ṣugbọn ijọba ko le maa wo awọn ọdaran niran lai da sẹria fun wọn labẹ ofin."""
Mi o le sọ ni pato pe a maa yanju ọrọ to wa nilẹ pẹlu ọrọ oṣelu, pẹlẹkutu tabi pe a o jeburẹ lai ṣe pe awọn ti ọrọ kan kọkọ kan si wa.
Ti wọn ba kan si wa lori ọna abayọ, a oo gbe ohun ti wọn ba sọ yẹwo to ba ni gbongbo, to ba jẹ eyii to ni gbongbo lẹyin naa ni a le sọ boya ijiroro le waye.
Malami sọ pe ijọba ko kan le dede sọ pe ọna kan bayii  tabi ọna miran ni awọn yoo gbe ọrọ naa gba.
"'Òbí mi máa ń bá wa wí gidi ní kékeré, ohùn tí mo ṣe ní fásitì tó mú mi gba ""Distinction"" 10, àmi ẹ̀yẹ̀ 5, ilé ọ̀fẹ́, owó rèé'"
"O ni ""a o kan le dede gbe igbesẹ ijiroro tabi ọna abayọ lọna oṣelu bayii lai ṣe pe awọn ti ọrọ kan kọkọ kan si wa, ṣugbọn a oo mọ ohun ti a o ṣe ti akoko ba to."""
Ṣaaju ni Igboho ti kọkọ bọ mọ awọn oṣiṣẹ ileeṣẹ ọtẹlẹmuyẹ DSS lọwọ lasiko ti wọn kọlu ile rẹ loru ọganjọ ọjọ kinni, oṣu Keje, ọdun yii, niluu Ibadan.
Lẹyin naa lo tẹkọ leti lọ silẹ Benin Republic, lọna ati gba ibẹ lọ si Germany, ṣugbọn ileeṣẹ ọlọpaa agbaye, Interpol mu mọlẹ, to si gba ibẹ de ile ẹjọ Benin.
Ni ti Kanu, ijọba Naijiria fi tipa-tikuku ji gbe lati ilẹ Kenya wa si Naijiria lati jẹjọ lori ẹsun iditẹ ati igbiyanju lati da Naijiria ru.
'Ẹ yé tan ara yín, èmi mo ni aṣọ 100 yard tó jábọ́ lát'ọ̀run táwọn ará Ondo ń ya mọ́ ara wọn lọ́wọ́'
Ilé ìgbìmọ̀ aṣòfin fọwọ́ sí ìgbésẹ̀ Ààrẹ Buhari láti ya $16b àti €1bn
Oríṣun àwòrán, Ayo Akinfe
Ile igbimọ aṣofin Naijiria ti buwọlu ẹbẹ Aarẹ Muhammadu Buhari lati ya owo ti iye rẹ to $16,230,077,718, ati €1,020,000,000.
Owo miran ti ile aṣofin naa tun buwọlu ni miliọnu márùndínláàdóje dọla.
Gbese naa ni ajọ banki agbaye, ile ifowopamọ Exim ni China, awọn ile ifowopamọ kan, to fi mọ banki idagbasoke ilẹ Afrika, AfDB yoo ṣagbatẹru rẹ.
Wọn fọwọ si yiya owo yii lẹyin ti ile naa tẹwọgba esi iwadii igbimọ to n ri si iye gbese ti Naijiria jẹ, eyii ti alaga igbimọ naa, sẹnetọ Clifford Ordia gbe wa siwaju ile aṣofin ọhun.
Nigba to n jabọ iwadii wọn, Ordia sọ pe awọn iṣẹ akanṣẹ ti wọn ya owo rẹ lọdun 2018 si 2020 ti n lọ lọwọ.
Ọ ni awọn iṣẹ akanṣe ti wọn yoo fi owo naa ṣe yoo mu aye dẹrun fun awọn araalu, ati pe awọn owo ori ti wọn yoo gba lori awọn iṣẹ akanṣẹ naa yoo tun pa owo wọle sapo ijọba apapọ.
Inu oṣu Kẹsan an ọdu 2020 ni Aarẹ Muhammadu Buhari gbe igbesẹ lati ya awọn owo naa ni afikun awọn owo kan to ti kọkọ ya laarin ọdun 2018 si 2020.
"'Òbí mi máa ń bá wa wí gidi ní kékeré, ohùn tí mo ṣe ní fásitì tó mú mi gba ""Distinction"" 10, àmi ẹ̀yẹ̀ 5, ilé ọ̀fẹ́, owó rèé'"
Ṣaaju ni ile aṣofin ọhun ti kọkọ buwọlu owo ti iye rẹ to $8.3 miliọnu ati €490 miliọnu gẹgẹ bii owo ti wọn fẹ ya.
Nigba to n sọrọ lori eredi ti yiya owo naa ṣe ṣe pataki, Buhari sọ pe awọn owo naa yoo ran ijọba lọwọ lati mu ki eto ọrọ aje Naijiria gberu si, ati lati pese iṣẹ yanturu fun awọn araalu.
Ẹwẹ, awọn ọmọ Naijiria kan ti n bu ẹnu atẹ lu ijọba Buhari fun bo ṣe n ya owo lọwọ awọn ijọba ilẹ okeere, paapaa China lawọn ọdun diẹ sẹyin.
'Ẹ yé tan ara yín, èmi mo ni aṣọ 100 yard tó jábọ́ lát'ọ̀run táwọn ará Ondo ń ya mọ́ ara wọn lọ́wọ́'
Sunday Igboho: Agbẹjọ́rò Igboho ní ìjọba Benin kò tíì rí ẹ̀sùn ọ̀daràn kankan fi kàn án láti oṣù mẹ́ta tó ti wà lẹ́wọ̀n
Oríṣun àwòrán, Abubakar Malami, SAN
Agbẹjọro Yomi Aliu(SAN) to n ṣoju Sunday Adeyemo Igboho nibi ẹjọ ti ijọba apapọ pe e ti fesi si ọrọ ti agbẹjọro agba ati minisita eto idajọ ni Naijiria, Abubakar Malami sọ pe ijọba si le jeburẹ fi oṣelu yanju ọrọ naa.
Amọ Malami fidi rẹ mulẹ pe Igboho atawọn eeyan ti ọrọ kan ni lati kan si ijọba na lori ọrọ naa.
Ni ọjọ kẹwaa oṣu kọkanla ni Malami sọrọ yii nigba ti o n kopa ninu eto kan lori ẹrọ amohunmaworan Arise TV.
Oluwo dá èsì ńlá padà fún àwọn olórìṣà tó ní kò tọ́ síi kó ní Ọba Yorùbá kìí ṣe ìgbákejì Òrìṣà
Ṣugbọn ninu esi rẹ, Oloye Aliu ni Igboho dunnu si bi ijọba ti tun ero rẹ pa pe kii ṣe ipa lo le yanju ọrọ to wa nilẹ yii.
''Ijọba naa ti wa ri pe ọrọ awọn ẹya to beere fun iyapa lara orilẹede Naijiria kii ṣe ohun ti wọn le fi ipa mu.
Bi wọn ṣe n dunkoko mọ Igboho ti wọn gbe e ju si atimọle nilẹ okeere kọ ni ọna abayọ si ọrọ to wa nlẹ yii.
Ijọba gbọdọ bọwọ fun ofin eleyii ti ile-ẹjọ ti paṣẹ pe ki ijọba san ogun biliọnu naira fun Igboho lori ẹjọ to wa nilẹ yii.
Gbige ti wọn gbe ju si ẹwọn n fun un ni igboya sii lati teṣiwaju nipa bibeere fun iyapa orilẹede Yoruba lara Naijiria.
Lakọkọ naa ti ijọba ba n wa ọna abayọ si ọrọ Igboho, ki o kọkọ sọ fun orilẹede Benin ti o ka kun ipinlẹ kẹtadinlọgbọn Naijiria pe ko tu Igboho silẹ lati kọkọ lọ tọju ara rẹ na ni Germany.
Pásítọ̀ ran bàbá lọ́wọ́ láti fi ọmọ rẹ̀ ṣe oògùn owó, ọká bá fó!
Wọ́n ní mo máa ń lọ bá ìyá tó bí mi sùn ní gbogbo ọjọ́ Tuesday, àṣírí ti tú, àwọn náà ti ń fojú balé ẹjọ́ o! - Genesis
Ọmọ kan ṣoṣo tó bí fún mi ni wọ́n gún lọ́dún mẹ̀ta sẹ̀yìn kí wọ́n tó gún òun náà pa báyìí
Ijọba Benin ko tii ri ẹsun ọdaran kankan fi kan Igboho lati bi oṣu mẹta to ti wa lẹwọn lọna aitọ ni Cotonou,'' Aliu lo sọ bẹẹ.
Agbẹjọro Igboho ni onibara oun ti foun ni iyọnda lati buwọlu adehun pẹlu ijọba apapọ niwọn igba ti adehun naa ba ti tẹ ẹgbẹ Oodua rẹ lọrun.
Igboho ki gbogbo awọn ololufẹ rẹ papa julọ awọn ọmọ ẹgbẹ Ilana Yoruba/Oodua Nation nile ati nilẹ okeere.
Igboho n rọ gbogbo wọn lati tubọ tẹsiwaju lati maa bọwọ fun ofin ki wọn si maa fa wahala pẹlu ẹnikẹni.
Ọjọ kinni oṣu keje ọdun 2021 yii lawọn ajọ ọtẹlẹmuyẹ DSS yabo ile Igboho ni Ibadan nibi ti wọn ti ṣekupa eeyan meji ti wọn si ko eeyan mejila lọ si Abuja.
Ilu Cotonou lorilẹede Benin ni wọn ti mu Igboho nibi ti o ti n rinrin ajo lọ si Germany ti wọn si ju si atimọle.
Ondo curfew: Ìjọba kéde òfin kónlé-ó-gbélé ní Igbara-Oke lẹ́yìn tí rògbòdìyàn bẹ́ sílẹ̀ lórí ìbò kánsílọ̀
Oríṣun àwòrán, Rotimi Akeredolu Aketi
Gomina ipinlẹ Ondo, Rotimi Akeredolu ti kede ofin konle-o-gbele ọlọjọ kan niluu Igbara-Oke tii ṣe ibujoko ijọba ibilẹ Ifedore nipinlẹ naa.
Gomina Akeredolu kede ofin konle-o-gbele nibẹ lẹyin ti rogbodiyan bẹ silẹ lori esi ibo kansilọ to waye ni ijọba ibilẹ naa.
Akọwe iroyin fun gomina Ondo, Richard Olatunde, lo fi ọrọ naa lede niluu Akure.
Akeredolu ni aṣẹ naa ti mulẹ nin kiakia, bakan naa lo paṣẹ fawọn oṣiṣẹ eleto abo lati ri pe awọn araalu tẹ le ofin konle-o-gbele ọhun ki alaafia le jọba.
Gomina ipinlẹ Ondo tun rọ awọn ọba alade atawọn alẹnulọrọ to fi mọ gbogbo awọn tọrọ kan lati kilọ fawọn ọmọlẹyin wọn pe ki wọn ki ọwọ ọmọ wọn bọ aṣọ.
Gomina Akeredolu ni ijọba ko ni fi oju 're wo ẹnikẹni to ba tapa si ofin konle-o-gbele naa.
Ifẹhonuhan lo kọkọ bẹrẹ niluu Igbara Oke lẹyin eto idibo kansilọ to waye ki ọrọ naa to di nla.
Sinikiwe Kademaunga Wedding photos: Ọmọ orílẹ̀-èdè Zimbabwe tí kò ní ọwọ́ àti ẹsẹ̀ ṣe ìgbéyàwó
Oríṣun àwòrán, INSTAGRAM/SINIKIWE KADEMAUNGA
Gbajugbaja olugbani ni imọran kan lorilẹ-ede Zimbabwe, Sinikiwe Kademaunga, ti wọn bi lai ni ọwọ ati ẹsẹ, ti ṣe igbeyawo.
Yatọ si pe Sinikiwe ko ni ọwọ ati ẹsẹ, o tun jẹ aràrá.
O fi awsn aworan lati ibi ayẹyẹ igbeyawo rẹ sita lori ayelujara.
Eyi waye lẹyin oṣu diẹ to fi aworan ọkọ afẹsọna rẹ sita fun aye ri lori Instagram, ni ọjọ kinni, oṣu Kẹjọ.
Olugbani ni imọran ọhun ni ọpọ gbagbọ pe ọjọ kọkanlelọgbọn, oṣu Kẹwaa, ọdun 2021 lo ṣe igbeyawo, nitori o kọ deeti naa si abẹ awọn aworan to fi sita.
Awọn aworan naa re e ti Sinikiwe ati ọkọ rẹ ya.
Oríṣun àwòrán, INSTAGRAM/SINIKIWE KADEMAUNGA
Oríṣun àwòrán, INSTAGRAM/SINIKIWE KADEMAUNGA
Oríṣun àwòrán, INSTAGRAM/SINIKIWE KADEMAUNGA
Oríṣun àwòrán, INSTAGRAM/SINIKIWE KADEMAUNGA
Oríṣun àwòrán, INSTAGRAM/SINIKIWE KADEMAUNGA
Oríṣun àwòrán, INSTAGRAM/SINIKIWE KADEMAUNGA
Ṣaaju ni Sinikiwe ti kede ninu oṣu Keji, ọdun 2021 pe oun ati ololufẹ oun n reti akọbi ọmọ oun, nitori pe oun wa ninu oyun.
Pẹlu aworan to fihan pe o wa ninu oyun lo fi kede iroyin naa.
Oríṣun àwòrán, Sinikiwe Kademaunga
O kede ninu oṣu Keji pe oun ti loyun akọbi ọmọ oun
Orilẹ-ede Zimbabwe ni Sinikiwe ti wa. O jẹ oṣiṣẹ ajọ ẹlẹyinju aanu, o ma n kọ nkan sori ayelujara, o si tun jẹ olugbani ni imọran nipa igbe aye ẹda.
Wọn bi Sinikiwe pẹlu aarun kan, eyi to ṣe idiws fun-un lati dagba boṣe yẹ.
Ọwọ ati ẹsẹ rẹ ko dagba tan, bẹẹni ko ni ọmọ ika ọwọ tabi ti ẹsẹ kankan.
O tun wa a jẹ aràrá.
Ṣugbọn, ko jẹ ki abuku ara rẹ naa ṣe idiwọ fun igbe aye rẹ.
O sọ ninu ifọrọwanilẹnuwo kan pẹlu ileeṣẹ iroyin BTV pe o ṣoro fun ẹbi rẹ lati gba kadara lori iru ọmọ to jẹ nigba ti wọn bi.
O ni niṣe ni awọn ọmọde ma n fi oun ṣe yẹyẹ, lasiko to wa ni ọmọde, to ba n gbiyanju lati ba wọn ṣere.
Mi o ki n ri i pe jijẹ alaabọ ara ni nkan ṣe pẹlu òṣì
Sinikiwe Kademaunga sọ fun BBC ninu ifọrọwanilẹnuwo kan ni ọdun 2019 pe oun kii ri ara oun gẹgẹ bi ẹni to ni ipenija ara. Ayaafi ni awọn akoko kan tabi iṣẹlẹ to ba ran oun leti.
Mo jẹ obinrin to gbagbọ pe mo ni afojusun, ti kii si ri aleebu ara gẹgẹ bi ọna lati jẹ oloṣi.
Ọlọrun fun mi ni ọpọlọ, o fun mi ni ohun gbogbo ti mo nilo lati ṣe awọn nkan mere-mere ti mo fẹ ẹ ṣe.
Sinikiwe le ba eeyan ṣe 'make-up' oju, ati si oju ara rẹ botilẹ jẹ pe ko ni ọwọ.
Sinikiwe Kademaunga re e to n ṣe 'make-up' si oju ara rẹ
O ni gbigbarale awọn ẹlomiran ma n din iyi ati ẹyẹ kù ni.
O si ma n gba awọn ọdọ to jẹ alaabọ ara bi tiẹ ni imọran pe ko si ohun ti wọn ko le ṣe tabi jẹ ni aye.
Ethiopia: Orílẹ̀èdè tó ní oṣù mẹ́tàlá,, tó tún jẹ́ ibi tí Àpótí Ẹ̀rí Israel wà
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ọjọ kinni, oṣu Ṣẹrẹ (January) ni ọpọ awọn orilẹ-ede lagbaye ma n ṣe ajọyọ ọdun tuntun.
Ṣugbọn ni oril-ede Ethiopia, ọjọ kọkanla, oṣu Kẹsan ni wọn maa n  bẹrẹ ọdun tuntun ti wọn.
Orilẹ-ede yii jẹ ibi kan to yatọ si awọn orilẹ-ede agbaye to ku.
Kini idi to fi jẹ bẹ ati pe iru ayẹyẹ wo ni wọn maa n ṣe lajọyọ ọdun tuntun?
Mọ si nipa awọn nkan to mu Ethiopia yatọ si awọn orilẹ-ede yooku ni agbaye.
Kii ṣe eyi nikan o - Kalẹnda ti Ethiopia n lo paapaa yatọ si eyi ti gbogbo eeyan n lo. Lọwọlọwọ, ọdun 2014 ni orilẹede naa wa bayii.
Ọjọ Satide, ọjọ kinni, oṣu Kọkanla ni wọn bẹrẹ ọdun tuntun.
Idi ni pe wọn n ṣe onka ọdun ibi Jesu Kristi lọna to yatọ. Nigba ti ijọ Aguda ṣe atunsẹ si onka rẹ ni ọdun 500 AD, ijọ igbaani ni Ethiopia ko sẹ bẹẹ.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ni awọn orilẹ-ede kan, awọn ọmọde ma n kọ akọsori nipa iye ọjọ to wa ninu oṣu kọọkan.
Ṣugbọn ni Ethiopia, ko si nkan to n jẹ bẹẹ: Ọgbọn ọjọ lo wa ninu oṣu mejila, ti oṣu kẹtala to kẹhin ọdun si ma n ni ọjọ marun-un tabi mẹfa.
Orilẹ-ede Italy gbiyanju lati wọ Ethiopia, to n jẹ Abyssinia lasiko naa, ni  ọdun 1895.
Asiko yii ni awọn orilẹ-ede lati Yuroopu n pin ilẹ Africa mọ ara wọn lọwọ.
Arákùnrin Ethiopia yìí ń fi ọwọ rin
Ṣugbọn, idojuti ni Italy ba kuro ni Ethiopia.
Wọn gbiyanju lati fi ọgbọn wọle si Ethiopia, nitori pe wọn ti ṣẹgun Eritrea to wa ni ẹgbẹ rẹ. Wọn ba tii fun ọpọlọpọ ọdun.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ọdọọdun ni ajọyọ ma n waye lati ṣe iranti ogun ti wọn ti ṣẹgun Italy, Battle of Adwa. O pe ọdun 125 ninu oṣu Kẹta.
Ṣugbọn, Ethiopia ṣẹgun wọn loju ogun ti a mọ si Battle of Adwa.
Ẹgbẹẹgbẹrun ikọ ogun Italy lọna mẹrin ni awọn ọmọ ogun Ethiopia ṣẹgun wọn laarin wakati diẹ lọjọ kinni, oṣu Kẹta, ọdun 1896.
Asiko Ẹmpẹrọ Menelik II ni ogun naa waye.
Wo òkè ìṣẹ̀mbáyé Abanijorin yìí l'Ekiti tó máa ń bá ọ̀kọ̀ rìn lójú pópó tó tún ní ilé ìwòran orí ìtàgé nínú rẹ̀
Wọn fi ipa mu Italy lati fi ọwọ si iwe adehun pe oun ko ni dan iru rẹ wo mọ.
Ọkan lara awọn Ẹmpẹrọ to jẹ lẹyin Menelik, Haile Selassie, lo anfaani iṣẹgun ti wọn ni lori Italy lati beere fun idasilẹ ajọ iṣọkan ilẹ Africa, Organisation of African Unity (OAU), to ti di African Union bayii.
Ilu Addis Ababa to jẹ olu ilu Ethiopia si ni olu ileeṣẹ rẹ wa.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Awọ mẹta gboogi to wa lara asia orilẹ-ede Ethiopia n ṣapẹrẹ iṣọkan Africa - awọn awọ naa wọpọ lara asia awọn orilẹ-ede ilẹ Africa
3. Ethiopia ni Apoti Ẹri awọn ọmọ Isirẹli wa
Ni igbagbọ ọpọ ọmọ orilẹ-ede Ethiopia, Apoti Ẹri, ninu eyi ti ofin mẹwa ti Ọlọrun fun Mose wa, ko sọnu.
Ijọ Igbaani ni Ethiopia sọ pe Apoti Ẹri naa wa ni abẹ ìṣọ ati abo ni gbogbo igba, ninu ile ijọsin Our Lady Mary of Zion Church niluu Aksum, nibi ti ko ti si aaye fun ẹnikẹni lati ri i.
Jẹ́ ká lọ sílu mi: Kò sí ìtàn Ibadan láìsí Efunsetan, Òkè méje, Bower's Tower àtàwọn ǹkan
Itan sọ pe Apoti Ẹri naa bọ si ọwọ ile ijọsin ọhun nipasẹ Ayaba Sheba.
Igbagbọ awọn eniyan orilẹ-ede Ethiopia ni pe lati Aksum lo ti rinrinajo lọ si Jerusalẹmu lati ri Ọba Solomọni lati mọ nipa ọgbọn ti iroyin sọ pe Solomọni ni, ni nkan bi ọdun 950 BC.
Ninu ile ijọsin yii, Our Lady Mary of Zion Church niluu Aksum, ni Apoti Ẹri to ni ofin mẹwa ti Ọlọrun fun Mose wa
Itan naa to wa ninu iwe Kebra Nagast sọ nipa bi Makeda, Ayaba Sheba, ṣe bi ọmọkunrin kan, Menelik (to tumọ si ọmọ ẹni to gbọn),  fun Solomọni.
Ati bi ọmọ naa ṣe rinrinajo lọ si Jerusalẹmu lẹyin ọpọ ọdun, lati lọ mọ baba rẹ.
Akọsilẹ itan naa sọ pe Solomọni fẹẹ ki ọmọ naa duro, ko si jọba lẹyin iku rẹ, amọ o ni oun n pada lọ si ile lọdọ iya oun.
'Ẹ yé tan ara yín, èmi mo ni aṣọ 100 yard tó jábọ́ lát'ọ̀run táwọn ará Ondo ń ya mọ́ ara wọn lọ́wọ́'
Ọkan lara awọn ọmọ Isirẹli ti Solomọni yàn pe ko tẹle pada, lo ji Apoti Ẹri naa gba, to si fi ayederu rọpo rẹ.
Nigba ti aṣiri tu si Menelik lọwọ, o gbà lati gbe e pamọ, nitori igbagbọ pe eto Ọlọrun ni pe ki apoti naa duro ni Ethiopia.
Pẹlu agbara ati ẹmi si ni awọn Kristiẹni ijọ Igbaani ni Ethiopia fi n pa apoti naa mọ.
"Itan sọ pe lasiko ti Anọbi Muhammed n koju idẹyẹsi nilu Mecca, nigba to ṣẹṣẹ bẹrẹ si ni i waasu, o sọ fun diẹ lara awọn ọmọ ẹyin rẹ pe ki wọn o lọ si ilu kan to n jẹ Abyssinia, ""ẹ o ri ọba kan ti ko faaye gba ifiyajẹni""."
Awọn eniyan naa gba imọran rẹ, wọn si lọ si Aksum, nibi ti Ọba Armah, to jẹ Kristiẹni ti ki wọn kaabọ, ti wọn si fi aaye gba wọn lati ṣe ẹsin wọn.
Abule Negash ti wọn fun wọn nigba naa lo ti di Tigray bayii, nibi ti awọn arinrinajo naa kọ mọṣalaaṣi ti awọn kan sọ pe oun lo ti pẹ julọ ni Africa.
Oríṣun àwòrán, AFP
Abala kan re e ninu mọṣalaṣi to wa ni Negashi
Amọ, ni ọdun to kọja, ado oloro wo mọṣalaaṣi naa lasiko ogun to waye ni Tigray.
Awọn Musulumi ni ilu naa tiẹ gbagbọ pe ọmọ ẹyin Anabi mẹẹdogun ni wọn sin si ilu Negash.
Irinajo si Aksum si ni Hijra akọkọ ninu akọsilẹ itan Islam.
Lonii, ida mẹrinlelọgbọn awọn eeyan to wa ni orilẹ-ede Ethiopia lo jẹ Musulumi.
Amotekun Ondo: Ìwádìí ń tèsíwájú lórí afurasí ajínigbé tó n múra bíi wère ní gáréèjì Akure
Oríṣun àwòrán, Facebook/Amotekun
Ọwọ palaba arakunrin kan to n dibọn bii were lati maa fi ji awọn eeyan gbe ti ṣegi nipinlẹ Ondo.
Gẹgẹ bi iroyin taa ri ka lati ileeṣẹ iroyin Naijiria Legit.ng,n ilu Akure ni ikọ Amọtẹkun ti mu Labram Ibrahim.
A gbọ pe Gareeji ọkọ to wa ni Akure ni ẹni ọgbọn ọdun yi ti n rinrin gberegbere kaakiri ki ọwọ to tẹẹ.
Ninu ọrọ awọn to n taja ni gareeji naa, wọn sọ fun ileeṣẹ iroyin PM News pe ''ṣaaju ki wọn to mu Ibrahim, niṣe lo maa n rin kaakiri gareeji Akure si orita Itanla''
Wọn tẹsiwaju pe lọpọ igba ni ọkọ ayọkẹlẹ jiipu kan ma n wa lati gbe Ibrahim lọ.
''Ihuwasi rẹ yii lo mu ki awọn eeyan fura sii ti wọn si korajọ lati lu''
Ooni: A kìlọ̀ fún Sunday Igboho pé kó dákẹ́ àmọ́ kò gbọ́, èébú ló ń bú wa
Nigba ti ileeṣẹ BBC Yoruba kan si ọga agba ajọ Amọtẹkun ni Ondo Adeleye Olusanyero, ko sọ pato ibi ti arakunrin naa wa bayi.
Yatọ si pe ko sọrọ boya arakunrin naa wa ni ọdọ awọn tabi ko si,Adeleye ni awọn ṣi n tẹsiwaju pẹlu iwadii ati pe bawọn ba pari awọn yoo fi to akọroyin leti.
''Ni kete taa ba ti ni iroyin miran si nipa iṣẹlẹ yi ati iwadii wa, a o fi to yin leti''lọrọ to sọ kẹyin ki o to pari ifọrọwanilẹnuwo naa
Ondo accident: Ìjàmbá ọkọ̀ gba ẹ̀mí èèyàn mẹ́fà, àwọn márùn ún farapa ní òpópónà Okitipupa
Oríṣun àwòrán, AFP
O kere tan eeyan mẹfa ti jona ninu ijamba ọkọ kan to waye ni Olla loju ọna Okitipupa si Ọrẹ nipinlẹ Ondo.
Ọkọ nla akero Coaster kan ati ọkọ J5 kan to ko ogogoro  la gbọ pe o kọlu ara wọn ninu ijamba yi.
Awọn kan tọrọ naa ṣoju wọn ni o ṣeeṣe ki eeyan to ku to mẹwa.
Bakan naa la gbọ pe igba ti ọkan ninu awọn ọkọ yi fẹ sare gba iwaju ẹlẹẹkeji ni wọn kọlu ara wọn ti wọn si gbana.
Pupọ awọn arinrinajo to wa ninu ọkọ akero Coaster naa la gbọ pe wọn n pada si Akure lati Okitipupa nibi  ti wọn ti kopa ninu inawo ọkan lara awọn ọga ijọba ibilẹ Odigbo.
Ijọba ibilẹ Akure North la gbọ pe o ni ọkọ ọhun.
Kaakiri oju opo ayelujara lawọn eeyan ti n pin fọnran fidio ijamba ọkọ yi nibi ti awọn ọkọ naa ti n jona tawọn eeyan kan to farapa si n ke irora,
Sikiru Alonge to jẹ ọga agba ajọ ẹsọ oju popo fidi ọrọ yi mulẹ fun ileeṣẹ iroyin The Cable sọ pe awọn kole sọ iye eeyan to ku lọwọ bayi.
Amọ ṣa o ni awọn ti  doola eeyan marun un to farapa tawọn si tigbe wọn lọ si ile iwosan State Specialist Hospital ni Okitipupa ati Prima Hospital to wa ni Ore.
O ni awọn ajọ FRSC pẹlu ọlọpaa lo jijọ pa ina ọkọ naa.
Oke Abanijorin in Ekiti: Òjò kò rọ̀ sórí òkè yìí rí àmọ́ inú gbọ̀ngàn rẹ̀ tutù minimini
Ori Oke naa wa ni ilu Iyin-Ekiti ni ipinlẹ̀ Ekiti. Abanijorin ni wọn n pe e fun idi to da yatọ gidi gidi.
Ọba ilu Iyin-Ekiti, Ọba Adeniyi Ajakaye sọ fun BBC Yoruba pe bi eeyan ba n rin loju popo ninu ilu naa, a dabi ẹni pe oke naa n ba eeyan rin lọ ni.
"Koda titi di isinsiyii, ti ẹ ba wa ninu ọkọ ti ẹ n wa a lọ, a dabi ẹni pe ẹ jọ n lọ ni ti oke naa si n tẹle yin lọ nitori titobi rẹ.
Àjọ tó ń mójútó pínpín iná ọba fikún owó 'Metre' k'áráàlù lè sáré tete lọ gba 'Prepaid'
Ọ̀pọ̀ arìnrìnàjò jóná, àwọn mìí tún farapa nínú ìjàmbá ọkọ̀ ní Okitipupa
Oluwo dá èsì ńlá padà fún àwọn olórìṣà tó ní kò tọ́ síi kó ní Ọba Yorùbá kìí ṣe ìgbákejì Òrìṣà
Laye igba ti ọna ṣi jẹ tooro ti wọn o tii ṣe opopona nla ọlọda, bi eeyan ba n rin lọ, yoo dabi pe ẹ́yin ati oke yii jọ n lọ ni, idi niyii ti a fi n pee ni Oke Abanijorin."
Lori oke yii kan naa ni awọn nkan amọọmọ da ti awọn ara ilu naa pe ni nkan agba iyanu ti Eledumare da.
Fun apẹrẹ lori oke naa ni ẹni to n ṣafihan ohun gbogbo fun BBC Yoruba pe ojo kii rọ sibẹ ko si bi ojo naa ṣe rọ̀ to.
Gbọngan nla kan to ri bii gbọngan olobiri aye ti aye ode oni ti wọn n pe ni Amphi Theatre wa labẹ okuta nla kan lori oke yii to si ni ijoko okuta to lee gba eeyan irinwo eyi ti wọn ba nibẹ to ti wa ni tito kalẹ.
Koda wọn ni lati inu ilẹ ni omi tutu ti n mu ibẹ tutu bii pe wọn gbe ẹrọ amule-tutu sibẹ.
Yato fun eyi, wọn ba awọn nkankan to n fi apẹrẹ han bii pe awọn eeyan kan ti gbe lori oke yii ri bii, oju ọlọta, awọn koko ati abọ iṣẹmbaye.
Oluyin ti ilu Ekiti sọ fun BBC Yoruba pe iyanu nla ni Ọlọrun fi ta awọn lọrẹ ni ilu naa ti ọpọlọpọ eeyan kaakiri agbaye si le wa maa lo fun igbafẹ. Oke yii ga to iwọn bata ẹẹdẹgbẹrun to si gba akọroyin wa to irin wakati kan lati de oke rẹ pẹlu awọn ti wọn jọ lọ.
Unilorin beats lecturer to stupor: Ara lẹ́kíṣọ́rà Zakariyyah ti ń yá lẹ́yìn tí ọmọ 400L lù ú - Aláṣẹ Fásitì
Oríṣun àwòrán, OTHERS
Iroyin to tẹ wa lọwọ latiri fidio kan to tan ka lori ayelujara nipe ọmọ ile ẹkọ kan ni ẹka imọ ẹkọ Sayẹnsi Microbiology ni Fasiti Ilorin lu olukọ rẹ obinrin bii bara.
Iroyin ni ọmọ ile ẹkọ naa ti inagijẹ rẹ n jẹ Captain Walz jẹ gbajumọ ninu ile ẹkọ giga naa ti wọn si ni ko ṣe eto lilọ kọ iṣẹ labẹ ileeṣẹ eyi ti awọn ọmọ ile ẹkọ maa n ṣe ki wọn to pari (SIWES) ti wọn si ni o lọ ba olukọ naa fun iranwọ.
Olukọ naa ti orukọ rẹ jẹ Arabinrin Zakariyyah ni alabojuto akanṣe iṣẹ aṣekagba
"Eeyan kan ti iṣẹlẹ naa ṣoju rẹ koro ṣugbọn ti ko fẹ darukọ ara rẹ jẹ ko di mimọ pe Captain Walz ni oun maa ""n ri arabinrin naa (ati awọn mii, olugbaninimọran fun ipele ẹkọ to wa) loju ala rẹ ti wọn lepa rẹ."
"Lo ba gbe igbesẹ loju aye lati lọ si ọfiisi rẹ pẹlu ero lati lọ lu u pa titi doju iku""."
Ẹ̀wẹ̀, BBC Yorùbá ribi kan si baba to bi Captin Walz to jẹ ka mọ orukọ rẹ gangan,
Ọmọ mi ti kọ́kọ́ bọ́ra sí hòhò l'àdúgbò, orí ìso ló wà kí o tó sá lọ lu Lẹ́ksọrà ní ọjọ́ kejì -  Baba Captain Walz
Kìí ṣe oògùn ìbílẹ̀ ni mo fi ń rántí déètì ọjọ́ àti oṣù lórí, ohun tí mo ṣe nígbà èwe rèé - Alaafin Oyo
Blessing Olajide: Ẹ̀bí akẹ́kọ̀ọ́jáde fásitì Ilorin tí wọn pa ṣàlàyé ikú rẹ̀
Wọn ni ṣaaju asiko yii,  o ti maa n lọ si ile ọga to jẹ olugbaninimọran fun ipele ẹkọ to wa lati kan ilẹkun rẹ.
Iroyin ni o s fun olugbaninimran ọhun pe oun o ba ti pa a to ba jẹ pe oun ṣeeṣi ri ilẹkun ṣi ni gbogbo awọn ọjọ to n wa.
O sọ gbogbo eyi nigba tọwọ tẹẹ lọdọ awọn agbofinro ileewe to si ni oun n foju si awọn akẹgbẹ oun kọọkan naa lara.
Eeyan kan to mọ gbogbo ohun to ṣẹlẹ lo ṣalaye pe Captain Walz lọ si ọfiisi ọga obinrin naa lati bẹẹ toripe ko ṣe eto SIWES.
O wọ ọfiisi ọga naa o si n gba tabili gba gba gba, arabinrin naa sọrọ sii lo ba sunmọ ọ to si bẹrẹ si ni gba obinrin naa leti.
Ẹni to ṣoju rẹ ni obinrin naa gbiyanju lati sa ṣugbọn ṣe lo tun n le e titi to fi sa wọ inu ọfiisi kan am Captain Walz tun fọ ferese wọle to si n lu u bii bara.
Wo òkè ìṣẹ̀mbáyé Abanijorin yìí l'Ekiti tó máa ń bá ọ̀kọ̀ rìn lójú pópó tó tún ní ilé ìwòran orí ìtàgé nínú rẹ̀
O ni obinrin naa n kigbe fun iranwọ ṣugbọn awọn eeyan ko pọ ninu ileewe toripe wọn ṣẹṣẹ wọle saa ẹkọ ni.
Wọn ni o le obinrin naa titi to fi jẹ ko bọ sipo ko mọ ohun to n ṣe mọ.
Nigba ti BBC Yoruba kan si awọn alakoso ile ẹkọ giga naa, ohun ti wọn sọ nipe lootọ, gbogbo eyi ṣẹlẹ amọ ara arabinrin naa ti n ya bayii ati pe ibẹwọ Ọga agba ile ẹkọ naa, Ọjọgbọn Suleiman Age Abdulkareem pẹlu awọn Ọga mii si mọlẹbi wọn fihan pe lootọ, ara rẹ ti n ya.
Ọgbẹni Kunle Akogun to jẹ oludari ẹka eto gbogbo, to ba BBC Yoruba sọrọ sọ pe Ọga agba ile ẹkọ ti fi aridaju han pe idajọ ododo ni yoo ṣẹlẹ to si ni wọn yoo tọju ẹni to faragba, fasiti yoo si san owo rẹ.
Oluwo dá èsì ńlá padà fún àwọn olórìṣà tó ní kò tọ́ síi kó ní Ọba Yorùbá kìí ṣe ìgbákejì Òrìṣà
Fashola ṣàlàyé ọ̀nà tuntun tí ìjọba àpapọ̀ Nàìjíríà gbé kalẹ̀ tí o fi lè di onílé
Ijọba apapọ orilẹede Naijiria yoo bẹrẹ tita awọn ile alakọra labẹ eto ikọle ọlọpọyanturu ti ijọba apapọ orilẹede Naijiria, National Mass Housing Programme.
Gẹgẹ bi minisita fọrọ iṣẹ ode ati ileegbe, Babatunde Raji Fashọla ṣe sọ, awọn ile naa yoo bẹrẹ lati ori miliọnu meje ati ẹgbẹrun lọna igba Naira (N7.2 million).
Minisita Fashọla ṣalaye lasiko ti wọn n ṣi oju opo ayelujara fun eto ikọle naa nilu Abuja pe eyi yoo fun awọn ọmọ orilẹede Naijiria lanfani ati ra ile laisi iyanni ni pọsin tabi ṣegbe rara.
Bakan naa lo tun ṣalaye lori eto mohunmaworan abẹle kan pe iriri ti ko ṣee fi sẹnu rẹrin eyi tawọn ọmọ Naijiria ti doju kọ labẹ irufẹ eto yii tẹlẹ lo mu ki wọn gbe e lọ sori ayelujara.
Wo òkè ìṣẹ̀mbáyé Abanijorin yìí l'Ekiti tó máa ń bá ọ̀kọ̀ rìn lójú pópó tó tún ní ilé ìwòran orí ìtàgé nínú rẹ̀
O ni awọn ile yii wa kaakiri orilẹede Naijiria pẹlu afikun pe eyi ti owo ori rẹ pọ julọ ni miliọnu mẹrindinlogun ati ẹgbẹrun  lọna aadọwa Naira. (N16.19 million).
Bakan naa ni Minisita Fashọla ṣalaye pe awọn ile bii ẹgbẹrun marun un ni wọn ti n kọ ti wọn si ti fẹrẹ pari kaakiri Naijiria.
Annie, ìyàwó 2face tọrọ àforíjì, ṣùgbọ́n Pero, ìyá ọmọ 2face ní àfi kó san N500 fún ọ̀rọ̀ tó sọ nípa òun
Oríṣun àwòrán, Annieidibia/official2baba/perosaiyemi/instagram
Gbajumọ oṣere sinima ni to tun jẹ iyawo gbajumọ olorin takasufe, 2Face, Annie idibia ti rawọ ẹbẹ sawọn si ọkọ rẹ atawọn miran to ta ẹrẹ si lori ayelujara loṣu kẹsan ọdun yii.
Annie gbe atẹjade aforijin yii jade loju opo instagram rẹ lọjọ Satide, ọjọ kẹtala oṣu kọkanla ọdun 2021 lasiko to n ṣe ayẹyẹ ọjọ ibi rẹ. O ni alaafia nikan loun n fẹ gẹgẹ bi ẹbun ọjọ ibi oun.
Loṣu kẹsan ọdun yii ni Annie pariwo le ọkọ rẹ, 2face atawọn ẹbi rẹ lori loori ayelujara ti ọrọ ọhun si si eyi ti wọn n gba bi ẹni n gba igba ọti nigba naa.
Annie fi ẹsun kan 2face pe o lọ n sun si abẹ orule kan naa pẹlu Pero, to bi ọmọ fun gbajumọ akọrin takasufe naa. Bakan naa lo tun pariwo faye pe awọn ẹbi 2face ko fẹran oun lainaani gbogbo ilakaka oun lati ṣe ohun ti wọn fẹ.
Oríṣun àwòrán, Annieidibia/instagram
Nibayii Annie ti pa ẹnu ọrọ da o, o si ti tuba lọwọ ọkọ rẹ atawọn ẹbi ọkọ rẹ pe ki wọn foriji oun nitori iṣẹlẹ naa.
Ilana tuntun niyi fun mi, yoo si wu mi lati bẹrẹ lakọtun. Oniruuru nnkan lo ti ṣẹlẹ lọdun yii, ọpọ ire ati ọpọ ẹdun ọkan.
Wo òkè ìṣẹ̀mbáyé Abanijorin yìí l'Ekiti tó máa ń bá ọ̀kọ̀ rìn lójú pópó tó tún ní ilé ìwòran orí ìtàgé nínú rẹ̀
Amọṣa ni bayii, Pero Adeniyi to jẹ iya awọn ọmọ 2face kan ti wa fi iwe ipẹjọ ranṣẹ si Annie bayi pe afi ko san ẹgbẹrun lọna ẹẹdẹgbẹta naira fun ibanilorukọ jẹ.
"Ninu ẹjọ to pe naa lawọn agbẹjọro rẹ ti tọka si awọn ọrọ to sọ loju opo Instagram nibi to ti n darukọ pe ọkọ rẹ 2face pe o n ""digba di agbọn rẹ lọ sorilẹede Amẹrika lati lọ ri obinrin naa atawọn ọmọ rẹ"""
"Wọn ni ọrọ rẹ naa n ro onibara awọn, iyẹnPero Adeniyi ni aṣọ ""obinrin oniwakiwa"""
ISWAP attack army base in Borno: Iléeṣẹ́ ọmọogun Nàìjíríà ti dárúkọ ọ̀gágun táwọn agbébọn ISWAP pa ní Borno lọ́jọ́ Sátidé
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ọgagun ileeṣẹ ọmọogun Naijiria kan atawọn ṣọja mẹta miran ni awsn agbebọn ti pa lasiko ikọlu kan to waye ni ipinlẹ Borno.
Awọn agbebọn tawọn eeyan  furasi pe wọn jẹ ọmọ agbebọn Islamic West Africa Province (ISWAP ) kọlu awọn ọmọogun Naijiria ni ibudo ologun kan nibẹ.
Atẹjade kan eyi ti alukoro ileeṣẹ ọmọ ogun oriilẹ, Onyema Nwachukwu  fi sita ni irọlẹ sjọ Satide ṣalaye pe orukọ ọgagun agba naa ni Dzarma Zirkusu ati pe oun atawọn ọmọogun mẹta miran padanu ẹmi wọn ni ijọba ibilẹ Askira/Uba nibi ti ibudo ologun naa wa.
Ileeṣẹ ologun ṣalaye ninu atẹjade naa eyi to tẹ BBC News Yoruba lọwọ pe awọn ọmọogun Naijiria ti ṣẹ awọn agbebọn ISWAP naa lẹyin ṣugbọn ija ṣi n gbona girigiri nibẹ.
Lasiko ti wọn fi gbe atẹjade naa sita, baluu ogun A-Jet marun lawọn ẹka ọmọogun ofurufu fi ranṣẹ.
Oríṣun àwòrán, HQ Nigerian Army/facebook/screnshot
Bakan naa ni wọn tun ran ọkọ ogun A-29, ọkọ Dragon combat meji ti wọn fi ba ọkọ agbebọn mẹsan ati ọkọ ayẹta APC kan to jẹ tawọn agbebọn naa jẹ.
Bakan naa ni olori ileeṣẹ ọmọogun oriilẹ ni Naijiria, Ọgagun agba Faruk Yahaya ti wa ranṣẹ ibanikẹdun si ẹbi awọn ọmọogun to sun loju ija naa.
O si ke sawọn ọmọogun naa lati ma tẹti loju ija naa titi ti wọn yoo fi rẹyin awọn agbebọn ISWAP naa.
Wo òkè ìṣẹ̀mbáyé Abanijorin yìí l'Ekiti tó máa ń bá ọ̀kọ̀ rìn lójú pópó tó tún ní ilé ìwòran orí ìtàgé nínú rẹ̀
African World Cup qualifiers: Pẹnáritì gbé Super Eagles borí Liberia pẹ̀lú góòlù méjì sí òdo
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ikọ agbabọọlu Naijiria, Super Eagles tun ṣe kẹrẹkẹrẹ sun mọ ipele to kan ninu ifẹsẹwọnsẹ lati mọ awọn orilẹede wo ni yoo kopa ni idije ife ẹyẹ bọọlu agbaye lọdun to n bọ.
Nibi ifẹsẹwọnsẹ wọn pẹlu awọn ikọ Lone Stars ti Liberia ni ilu Tangers lorilẹede Morocco, ikọ Super Eagles bori pẹlu goolu meji.
Latifat Tijani: Ìjọba Naijiria ń ṣèlérí láti mọ́ rírì mi àmọ́ láti 2016, pàbó ló ń já sí
Victor Osimhen lo gba goolu akọkọ wọlu pẹlu pẹnariti nigba ti ifẹsẹwọnsẹ naa wọ iṣẹju karundinlogun ki Ahmed Musa to fọba lee pẹlu pẹnariti miran nigba ti ifẹsẹwọnsẹ naa wọ iṣẹju kẹrinlelaadọrun.
Pẹlu esi ifẹsẹwọnsẹ yii orilẹede Naijiria lo n leke ipin 'C' bayii pẹlu ami mejila ti Cape Verde, Central African Republic ati Liberia si n tẹle pẹlu ami mẹwaa, mẹrin ati mẹta ni ṣisẹ n tẹle.
Oríṣun àwòrán, Screenshot
Ilu Tangers lapa ariwa orilẹede Morroco ni ifẹsẹwọnsẹ naa ti waye lẹyin ti ajọ ere bọọlu afẹsẹgba lagbaye sọ pe papa iṣire to wa ni ilu Monrovia lorilẹede Liberia ko ku oju iwọn rẹ.
Rivers Pastor kills wife:Ṣé lóòótọ́ ní pé Pásítọ̀ yí Chris fún ìyàwó rẹ̀ lọ́rùn pa nítorí owó?
Oríṣun àwòrán, Elvis Opurum
Pasitọ Chris Amadi ti ijọ Shalom Mercy Ministry to wa niluu Aluu, ni ipinlẹ Rivers ti wa ni gbaga ọlọpaa bayii lori ẹsun pe o fun iyawo rẹ lọrun pa.
Iroyin ni Amadi ti kọkọ gbiyanju lati fẹsẹ fẹ lẹyin iṣẹlẹ naa ki ọwọ ofin to ba.
Awọn oṣojumikoro kan ninu ẹbi oloogbe naa sọ fun awọn akọroyin pe wahala bẹ silẹ lori ọrọ owo ti wọn n pa wọle lati ile ẹkọ ti wọn da silẹ lorukọ oloogbe naa, Solution International School.
Gẹgẹ bii ohun ti a gbọ, obinrin ọhun lo da ile ẹkọ naa silẹ ko to ṣe igbeyawo pẹlu afurasi lọdun 2012.
Wahala bẹrẹ lasiko ti Solution, iyẹn oloogbe, bere lọwọ ọkọ rẹ idi ti yoo fi le awọn akẹkọọ̣ kan kuro nile ẹkọ naa nitori pe wọn ko tii san owo ile ẹkọ lai kọkọ bere lọwọ oun.
Ẹgbọn oloogbe, Odinaka Opurum ṣalaye fun awọn akọroyin pe oloogbe naa koro oju si ọkọ rẹ lẹyin ti awọn obi kan bẹrẹ si ni pe lori ago lati fi ẹjọ ọkọ rẹ sun pe awọn korira iwa to n wu si awọn ọmọ wọn.
Oríṣun àwòrán, Elvis Opurum
Ile ẹkọ to da wahala silẹ
"O ni ""Ọkọ rẹ lọ sile ẹkọ naa lọjọ Kẹsan an, oṣu yii lati le awọn akẹkọọ kan kuro nibẹ nitori gbese ti wọn jẹ ṣugbọn awọn obi awọn ọmọ naa bẹrẹ si n pe iyawo lati bere eredi ti yoo fi le awọn ọmọ pada sile, o si ṣeleri lati ṣe iwadii lọwọ ọkọ rẹ."""
Nigba to dele to bere bi ọrọ ṣe jẹ lọwọ ọkọ ni ija bẹrẹ ti okunrin ọhun si bẹrẹ si n lu, asiko naa lo tẹ lọrun mọlẹ titi to fi daku.
Lẹyin to daku tan lo gbe digbadigba lọ sile iwosan kan to wa lẹba ile ti wọn n gbe, ibẹ ni wọn ti sọ fun obinrin naa ti dakẹ.
Oríṣun àwòrán, Elvis Opurum
Tọkọtaya ati awọn ọmọ wọn
Bo tilẹ jẹ pe wọn gba niyanju pe ko gbe lọ sile iwosan UPTH ṣugbọn kaka ko ṣe bẹẹ, ni ṣe lo gbe pada sile wọn, to si ko awọn aṣọ rẹ kan ni igbiyanju lati na papa bora.
Opurum sọ siwaju pe kii ṣe igba akọkọ ree ti okunrin yii yoo lu iyawo rẹ nilu bara, ṣugbọn obinrin naa n foriti nitori ifẹ to ni si ọkọ rẹ .
Bẹẹ ko fẹ kọ ọkọ rẹ silẹ lọna ati jẹ apere rere fun awọn ọdọ ijọ wọn.
Ọdun 2012 ni tọkọ-taya naa ṣe igbeyawo, wọn si bi ọmọ obinrin meji ati okunrin meji.
Obasanjo: Ẹ ò lè jíròrò l'órílẹ̀èdè yín bẹ́ ò bá paná ìjà ogún tẹ́ẹ ṣì ń jà
Oríṣun àwòrán, Others
Aṣoju patakii àjọ isọkan agbaye fun pipẹtu sááwọ̀ to tun jẹ Ààrẹ orileede Naijiria tẹ́lẹ̀ rí, Oloye Olusegun Obasanjo tí kilọ fún pé ìjíròrò ko leè pèsè alafia rara ni orileede Ethiopia niwọn ìgbà ti wọn ba si tẹsiwaju nínú ogun tí wọn n bá ara wọn ja to si n le sii.
Ọgbẹni Obasanjo to ṣẹ̀ṣẹ̀ padà de lati orileede náà laipẹ nibi to ti bá àwọn alasẹ ijọba orileede naa sọ̀rọ̀ àti ẹgbẹ́ to ń ṣojú awọn to n ja fún ominira awọn eeyan ilẹ̀ Tigray (TPLF) tí wọn ti jọ ń doju ogun kọ ara wọn to ti le ni ọdun kan bayii.
Oloye Obasanjo ni oun ni ireti nípa bibara ẹni jiroro o amọ pe igun mejeeji nilo lati sọ awọn nkan ijagun silẹ na ki wọn dawọ ija duro na ki wọn si wa ibi pẹlẹbẹ ti wọn ti leè mu ijiroro wọn na.
Titi di asiko yii, tirela ṣi gba àárín àwọn mejeeji koda ó duro pa síbẹ̀ ni tori ija wọn ko i ribi aa yanjú ẹ si.
Kìí ṣe oògùn ìbílẹ̀ ni mo fi ń rántí déètì ọjọ́ àti oṣù lórí, ohun tí mo ṣe nígbà èwe rèé - Alaafin Oyo
Bàbá ẹni ọgọ́ta ọdún dèrò ilé ẹjọ́ nítorí ó wọ inú oko Obasanjo láì gba àṣẹ
Wo àìsàn tí Ààrẹ Nààijíríà tẹ́lẹ̀, Olusegun Obasanjo ń bá fínra láti ọdún 35 sẹ́yìn
Buhari o, tètè ṣètò àtúntò Nàíjíríà ká le è dènà ogun abẹ́lé lẹ́ẹ̀kejì - Obasanjo figbe bọnu
Obasanjo, Gowon, Muhammed- wo àwọn olóri Nàìjíríà lọ́dọ̀ọ́
Aremu: Eré ìtàn nípa ìbí, àti jéèyàn pẹ̀lú ìpèníjà Olusegun Aremu Obasanjo
Àwọn ará Tigrayan ni láyé ko lee si ijiroro ayafi bi awọn aláṣẹ ijọba bá nawọ ìranwọ si Tigray níbi ti ọpọlọpọ ẹgbẹẹgbẹ̀rún eeyan ti ń koju ìyàn àti ìṣẹ́.
Ni ti ijọba Ethiopia, wọn ni awọn Tigray gbudọ moye nipa ipò ati àṣẹ tí àwọn ní ki wọn si ko ara wọn kuro awọn ni ẹkùn naa eyi tii ṣe Amhara àti Afar.
Koda ọrọ ija wọn ti wa buru jáì to bẹẹ ti awọn  ẹgbẹ́ bíi mẹsan kan ti  wa nilẹ to ti da imọ pọ pẹ̀lú ẹgbẹ́ TPLF tàwọn ará Tigrayan.
Pẹlu bo ṣe jẹ pe awọn ajija Tigray tí ń sunmọ olú ìlú orileede Ethiopia, ó ṣeéṣe ki wọn fẹ tẹra mọọ sii ki wọn tilẹ̀ to gba lati dawo ogún dúró pátápátá tàbí tilẹ̀ lọ ki ara bo ijiroro alafia kankan.
Gbogbo ayé wà ní ọdún 2021, àmọ́ 2014 ni Ethiopia ṣẹ̀ṣẹ̀ bẹ̀rẹ̀
Wo ìdí tí ìjọba Naijiria ṣe fẹ́ ẹ́ ta iléèṣẹ́ ọkọ̀ reluwé fún aládàáni
Ọmọ Fásitì Unilorin lu lẹ́kíṣọ́rà obìnrin lálùbami torí ó ríi lójú àlá
Wo òkè ìṣẹ̀mbáyé Abanijorin yìí l'Ekiti tó máa ń bá ọ̀kọ̀ rìn lójú pópó tó tún ní ilé ìwòran orí ìtàgé nínú rẹ̀
Sani Dangote : Àbúrò oníṣòwò Aliko Dangote tó jẹ́ igbákejì Dangote Group jáde láyé
Oríṣun àwòrán, Dangote Group
Awọn to  gbọ iroyin naa kọkọ ro pe Aliko Dangote ilumọọka oniṣowo lo jade laye.
Amọ kii ṣe Aliko, Sani Dangote aburo rẹ to tun jẹ igbakeji aarẹ ileeṣẹ Dangote lo ki duniya pe o di gbere.
Lọjọ Aiku yi ni Sani jade laye ti ileeṣẹ Dangote ko si sọ pato ohun to ṣokunfa iku rẹ.
Iroyin to n tẹwa lọwọ sọ pe orileede Amẹrika lo ku si lẹyin aisan ọlọjọ pipẹ.
Ileeṣẹ Dangote ṣapejuwe iku rẹ yi gẹgẹ bi eleyi to fọwọ kan ni lẹmi.
Ọmọ mi  ti kọ́kọ́ bọ́ra sí hòhò l'àdúgbò, àbúrò rẹ̀ ń mójú tóo ló sá lọ lu Lẹ́ksọrà ní ọjọ́ kejì -  Baba Captain Walz
Wọ́n gbé ẹyin ẹlẹ́yin IVF sínu obìnrin kan, àṣírí bá tú lọ́jọ́ ìkúnlẹ̀ pé ọmọ ọlọmọ ló bí
Ikú Ọ̀gágun Dzarma Zirkusu kan mi l'égungun gidi torí Nàìjíríà ló ń jà fún tí ISWAP fi pa á - Buhari
Ẹ ò lè jíròrò l'órílẹ̀èdè yín bẹ́ ò bá paná ìjà ogún tẹ́ẹ ṣì ń jà - Obasanjo
Oríṣun àwòrán, DANGOTE GROUP
Ta ni Sani Dangote ko to jade laye
Sani Dangote ko lokiki to ẹgbọn rẹ Aliko Dangote ṣugbọn oniṣowo to munadoko loun naa ṣe.
Ṣaaju iku rẹ, o ni ipin ninu awọn ẹka karakata to fi mọ ẹka ọgbin,ile ifowopamọ ati ipese ọja.
O jẹ ọga lawọn ileeṣẹ to fi mọ Nigerian Textile Mills Plc, Nutra Sweet Limited, Gum Arabic Limited ati Dangote Textile Mills Limited.
Bẹẹ naa la gbọ pe o jẹ ọkan lara igbimọ alaṣẹ Alsan Insurance Brokers, Dan-Hydro Company Limited, Dansa Food Processing Company Limited ati Dangote Farms Limited.
Àwọn ọmọ ọkùnrin mẹ́tà ló timi mọ́lé tí wọ́n n bá mi sùn lójoojúmọ́ ni Libya
Koda o tun di ipo igbakeji alaga ẹgbẹ African Gum Arabic Producers Association to si tun jẹ aarẹ ẹgbẹ Lagos Polo Club lẹẹmeji ọtọọtọ.
Sani jẹ elere idaraya Polo ko dantọ
Nitori bo ṣe jẹ oludari to munadoko, wọn fi ipo da lọla gẹgẹ bi oludari agba ileeṣẹ orileede Romania ni Naijiria.
Orisirisi ipo ati oye lo si dimu to fi mọ ti Chartered Institute of Shipping of Nigeria ti wọn tun fi jẹ aarẹ ẹgbẹ awọn to n pese  ajilẹ ni Naijiria,FERSAN.
Unilorin student beats lecturer: Àwọn nkán tí aláṣẹ ilé ẹ̀kọ́ lè ṣé rèé láti fí dẹkùn ìṣẹlẹ akẹ́kọ̀ọ́ tó n lú olùkọ
Isọwọ bi awọn akẹkọọ ti ṣe n da bantẹ iya fawọn olukọ wọn lẹnu ọjọ melo kan yii jẹ nkan to n kọ ọpọ lominu ni Naijiria.
Yala ni ileẹkọ girama ni tabi lawọn to wa ni fasiti niṣe ni iwa yi n peleke sii tawọn oluwoye si n ke gbajare pe ki awọn alẹnulọrọ wa nkan ṣe sii.
Laipẹ yi ni akẹkọọ fasiti Ilorin kan lọ ka olukọ rẹ mọ inu ọfisi to si lu laludaku.
Ṣaaju asiko yi a tun gbọ pe inu ibẹrubojo lawọn olukọ ileẹkọ girama kan wa ni ipinlẹ Ogun nitori  bawọn akẹkọọ kan ṣe sọọ di aṣa tuntun lati maa doju ija ka olukọ wọn.
Lootọ iru awọn iṣẹlẹ bayile ti waye nigba kan ri ṣugbọn igi gogoro ma gun mi loju, at'okere la ti n wo o ni Yoruba maa n wi, eyi lo mu ki BBC Yoruba tete maa wo o lati okere.
Ileeṣẹ iroyin BBC ba akọsẹmọṣẹ onimọ nipa ọrọ ọpọlọ kan lati fasiti ilu Eko sọrọ to si ṣalaye ohun to le fa iru iwa yi laarin awọn akẹkọọ.
Àwọn ọmọ ọkùnrin mẹ́tà ló timi mọ́lé tí wọ́n n bá mi sùn lójoojúmọ́ ni Libya
Ọjọgbọn Olurotimi Coker sọ pe awọn nkan to le ṣokunfa iru wa yi pọ.
O ni eleyi to lewaju ninu rẹ ni pe pupọ awọn akẹkọọ fasiti ati ile ẹkọ a lode oni ti n yara dagba ti pupọ a si maa dabi agbalagba ni oju ati ni ihuwasi.
Onimọ yi sọ pe bi eeyan ko ba dagba de aaye kan, kole ṣaadede sọ pe ohun yoo lu olukọ rẹ.
Wo òkè ìṣẹ̀mbáyé Abanijorin yìí l'Ekiti tó máa ń bá ọ̀kọ̀ rìn lójú pópó tó tún ní ilé ìwòran orí ìtàgé nínú rẹ̀
'''Bi ẹ ba ri awọn akẹkọọ to wa ni ile ẹkọ girama tabi fasiti lode oni, niṣe ni wọn da bi agbalagba loju. Ọpọ lo ti n gbe irin ti wọn si ti ni iṣu lapa bii ẹni to n ja ẹṣẹ.''
Ọjọgbọn Olurotimi ni nitori pe wọn ri gidigba loju wọn a maa foju wo awọn olukọ to ba kere si wọn ti wọn a si maa ro pe o yẹ ki ipa awọn ka iru ẹni bẹẹ.
''Ti a ba mu bi wọn ti ṣe ri gidigba yii ta wa fi lilo awọn oogun oloro pẹlu rẹ, eleyi a maa mu ki wọn gboya lati koju awọn alaṣẹ lai bikita rara''.
Ṣe awọn olukọ lẹ́bi ninu ọrọ yii?
Ọjọgbọn yi ni awọn olukọ ni lati kọ ẹkọ sii nipa bi wọn yoo ṣe maa ba awọn akẹkọ́ọ sọrọ.
O ni idi ni pe pupọ awọn akẹkọọ yi lo ti di agbalagba ti wọn si gbọdọ maa fi ọgbọn ati oye ba wọn sọrọ.
''Awọn olukọ tawọn akẹkọọ yi n doju ija kọ lawọn ti wọn ro pe wọn kii gba gbẹrẹ rara. Bi wọn ba ti foju wo olukọ pe o buru iru awọn eeyan bayi ni wọn maa n ba ja''.
O ni lati koju iru iṣẹlẹ yi, awọn alaṣẹ ile ẹkọ gbọdọ wa ọna lati daabo bo awọn olukọ.
Ọkan lara ọna abayọ ti Olurotimi sọ ni pe ki wọn fun awọn olukọ ni idanilẹkọ to peye lori biba awọn akẹkọọ lo.
Alaafin Oyo Oba Lamidi Adeyemi: Kìí ṣe oògùn ìbílẹ̀ ni mo fi ń rántí déètì ọjọ́ àti oṣù lórí
Oríṣun àwòrán, Alaafin Oba Lamidi III
Alaafin ilu Oyo, Oba Lamidi Adeyemi tí sapejuwe iyi to wa ninu bo ṣe ni imọ pé o da bíi idokoowo ni to sì ni ere pupọ ninu.
Oba Adeyemi tún jẹ́ ko di mimọ pe oogun tí àwọn èèyàn ro wípé òun n lo to fi jẹ pe ọgbọn orí àti ọpọlọ pọ to bẹẹ ni iye ọjọ orí to wa, bàbà ṣi máa ń rántí nkan perepere, o ni irọ gbaa ni, oun ko lo oògùn kankan.
Ori ade yìí mẹ́nu bá ọrọ náà níbi eto ayẹyẹ igbaniwọ ile ẹ̀kọ́ gíga ìkẹrindínlógún Fasiti Lead City ti wọn pe e si gẹgẹ bi alejo pataki to si n sọ̀rọ̀ nípa awọn to n ro wípé Alaafin máa ń lo oogun ìbílẹ̀ lati lee rántí awọn ọjọ, oṣù àti ọdun pàtàkì gẹgẹ bawọn eeyan ṣe woye rẹ pe kii gbagbe irú nkan báyìí.
Nigba to n bu ẹnu ẹtẹ lu ọrọ naa, Ọba Adeyemi ni òun maa  n rántí ọjọ tori idokoowo toun ṣe si igbesẹ níní imọ.
Mo mọọmọ ko owó àti akoko lorii mímú imọ mi gbòòrò sii ni tori pe mo fẹ́ di sọ̀rọ̀-sọ̀rọ̀ itagbangba nítorí ipò mi.
Bá wo ni òrékelẹ́wà Adedoja tó gbàmì ẹ̀yẹ ''Miss Oyo 2020'' ṣe jẹ́ sí Alaafin?
Alaafin bi ibeji l‘ẹẹmeji lọsẹ kansoso
Ẹ̀yin oríadé, tẹ bá fẹ́ mọ ìtàn Yorùbá, ẹ lọ kọ́ lọ́dọ̀ Alaafin - Oluwo
Ìdí tí mo fi ń dé fìlà Abetiaja nì gbogbo ìgbà nìyìí - Alaafin
Ọba Adeyemi rọ  awọn ọmọ Naijiria lati dokoowo ohun tí wọn ní sinu idagbasoke imọ ati ọgbọn ori wọn.
"Alaafin ni ""nigba ti mo wa ni Fasiti Usman Dan Fodio gẹgẹ bii Ọga Giwa Fáṣítì, mo dá nìkan san owó iléèwé awọn ọmọ ilẹ̀ ẹ̀kọ́ igba láti lọ ṣe imọ ẹ̀kọ́ to ba wu wọn."
"Too ba ko gbogbo ti apo rẹ síta, too ko lori idagbasoke ọpọlọ rẹ, okoowo to dára gidi nìyẹn""."
Alaafin ni ni gbogbo ibi tí òun bá ti ń sọ̀rọ̀ tòun ń rántí déètì ọjọ́, asiko àtàwọn iṣẹlẹ àtẹ̀yìnwá, awọn èèyàn máa ń rò pé mo lo oògùn ni torí ọpọlọ òun pé yekeyeke.
"Àmọ́ kii ṣe bẹẹ, titori pe mo nifẹ láti di Ọga nínú sọ̀rọ̀-sọ̀rọ̀ ìta gbangba ni.
Ohunkohun too ba fẹ láyé too bá sì fi ọkan rẹ sii too beere lọwọ Ọlọ́run pe ko ṣe é fún ọ, yoo ṣe é fun ọ ."
Ta ni Sani Dangote àbúrò àti igbákéjì ààrẹ Iléeṣẹ́ Dangote tó jáde láyé?
Ìdí rèé tàwọn akẹ́kọ̀ọ́ òde òní ń gbéná wojú Ọ̀gá, dá sẹ̀ríà fáwọn olùkọ́ wọn- Ónimọ̀ àyẹwò ọpọlọ
Wọ́n gbé ẹyin ẹlẹ́yin IVF sínu obìnrin kan, àṣírí bá tú lọ́jọ́ ìkúnlẹ̀ pé ọmọ ọlọmọ ló bí
Ikú Ọ̀gágun Dzarma Zirkusu kan mi l'égungun gidi torí Nàìjíríà ló ń jà fún tí ISWAP fi pa á - Buhari
Ẹ ò lè jíròrò l'órílẹ̀èdè yín bẹ́ ò bá paná ìjà ogún tẹ́ẹ ṣì ń jà - Obasanjo
Àwọn ọmọ ọkùnrin mẹ́tà ló timi mọ́lé tí wọ́n n bá mi sùn lójoojúmọ́ ni Libya
Bode George vs Tinubu: Igbokwe képe Bode George láti jèbùrẹ́, kó sì fa Tinubu mọ́ra
Oríṣun àwòrán, other
Alukoro ẹgbẹ oṣelu APC nipinlẹ Eko tẹlẹ, Joe Igbokwe ti rọ awọn alẹnulọrọ nipinlẹ Eko lati yanju gbọmi sii omi o to to wà laarin Asiwaju Bola Tinubu ati eekan ẹgbẹ oṣelu PDP, Oloye Bode George.
Igbokwe ni lati ọdun 1999 ti orile-ede Naijiria ti pada si ijọba awaarawa  ni ọrọ Tinubu ati Oloye George ko ti wọ rara.
"Loju bayii ni awọn eekan  ẹgbẹ oṣelu PDP nipinlẹ Eko lati ọdun 1999 ti darapọ mọ ẹgbẹ oṣelu AD, AC, ACN ati APC bakan naa.
Oloye Bode George nikan ni eekan ẹgbẹ oṣelu PDP ti ko darapọ mọ ọkàn kan ninu awọn ẹgbẹ yii.
Bode George ti gbiyanju, o si ti fihan pe ọkunrin mẹta nii ṣe.
Ati pe o ti fihan gbogbo eeyan pe ẹni to maa n duro lori ipinnu rẹ ni i ṣe.
Amọ, ko yẹ ki Oloye Bode George maa fi akoko rẹ ṣofo lori aawọ ati iyapa.
O yẹ ki Oloye Bode George gbe ọrọ yii yẹwo ki o si ṣe ohun to tọ.
Àwọn ọmọ ọkùnrin mẹ́tà ló timi mọ́lé tí wọ́n n bá mi sùn lójoojúmọ́ ni Libya
Titako Asiwaju ni gbogbo  igba ko le mu nkan kan wa.
Ti ọmọ ẹni ba dara, ẹ jẹ ka sọ, ti eeyan ba ju wa lọ bakan naa, ẹ jẹ ki a gba fun un.
Ọga mi, ika o dọgba, ẹ jẹ ki a gba fun ọga.
Gbogbo eeyan ni Asiwaju nilo to fi mọ Bode George lati tẹsiwaju ninu Irinajo oṣelu rẹ.
Idi gan an niyii ti mo fi n rọ awọn eekan ilu nipinlẹ Eko lati pẹju si ija to wa laarin Tinubu ati Bode George, Igbokwe lo sọ bẹẹ."
Yollywood: Gbajúmọ̀ òṣèré, Ijebu ní Ọgbọ́n lòun fi ń yẹra fún gbọ́yísọ̀yí lágbo àwọn òṣèré
Oríṣun àwòrán, Ijebuu/instagram
Gbajumọ apanilẹrin lagbo sinima ede Yoruba, Tayọ Amokade ti ọpọ eeyan mọ si Ijebu ti ṣalaye fun araye pe ati dide goke ko rọgbọ fun oun nitoripe awọn iṣẹ ti ọpọ ko fi oju rena ni oun ti ṣe ki itanṣan ọla to tan si oun.
Ijẹbu ṣalaye ninu ifọrọwanilẹwo kan pe iṣẹ ẹrọ amunawa, jẹnẹretọ titunṣe loun n ṣe ki oun to di ilumọọka oṣere.
Bakan naa lo ṣalaye nipa oniruuru ijakulẹ ti oun dojukọ ki aye to mọ oun.
Iṣẹ ẹrọ amunawa, jẹnẹretọ titunṣe ni mo kọkọ fi bẹrẹ. Mo jẹ eeyan ti kii fi iṣẹ jafara rara, gbogbo anfani ti mo ba si ri ni mo maa n mu lọkunkundun.
Oríṣun àwòrán, Ijebuu/instagram
Bakan naa lo tun sọrọ lori awọn awuyewuye to maa n waye lagbo awọn oṣere to si ni, oun n gbiyanju ni igba gbogbo lati yẹra fun ẹrẹ awuyewuye to n waye lẹka naa.
O ni bi o ti wulẹ wu ki oṣere sare to lati yẹera fun awọn gbọyisọyi lagbo amuludun, awọn iṣẹlẹ ori ayelujara ti jẹ ko ṣoro pupọ.
Itunu Babalola: Ọmọ Nàìjíríà tí wọ́n jù sẹ́wọ̀n láì ṣẹ̀ ní Cote D'Ivoire ti kú, ìjọba Nàìjíríà fàáké kọ́rí
Oríṣun àwòrán, David Hundeyin/facebook
"Agba adura l'awọn Yoruba maa n gba pe ""a ko ni ri alakoba."""
Ọmọ Naijiria kan, Itunu Babalola, to jẹ oniṣowo niluu Bondoukou lorilẹede Cote D'Ivoire ti wọn ju si ẹwọn lai ṣẹ ti jade laye bayii.
Akọroyin kan, David Hundeyin lo fidi iṣẹlẹ ọhun mulẹ loju opo Facebook rẹ.
Gẹgẹ bi o ti ṣalaye, Itunu ku lẹyin to ko arun kan ni ọgba ẹwọn to wà.
"Iroyin to n tẹ mi lọwọ lati orilẹede Cote D'Ivoire ti sọ pe Itunu Babalola ti ku sẹwon.
Gbogbo ileri ajọ NIDCOM to n ri si ọrọ awọn ọmọ Naijiria nilẹ okeere, Abike  Dabiri-Erewa to jẹ ọga ajọ naa, ati ileri ijọba ipinlẹ Oyo, ti jasi pabo.
Gbogbo eeyan lo jẹbi ọrọ iku Itunu, ọmọ Naijiria mi tun ti tẹri gbaṣọ, Hundeyin lo gbara ta bẹẹ."
Àwọn ọmọ ọkùnrin mẹ́tà ló timi mọ́lé tí wọ́n n bá mi sùn lójoojúmọ́ ni Libya
Ohun tí a gbọ tẹlẹ ni pe Itunu dero ẹwọn ni Cote D'Ivoire nitori o kọ lati gba ẹgbẹrun lọnà ọgọrun owo riba tawọn ọlọpaa ni ko gba fun iṣẹlẹ ọmọkunrin kan to ja a lole nigba to wa si Naijiria.
Iroyin sọ pe awọn ọlọpaa dunkoko mọ Itunu pe awon yoo da ṣeria fun un ti ko ba gba owo ti awọn fun un lati bo ẹjọ ọmọkunrin to ji ẹru rẹ ko mọlẹ.
Iroyin naa sọ pe ẹbi ọga ọlọpaa to wa lori ẹjọ naa ni ọmọkunrin to jale nile Itunu i ṣe.
Idi gan an niyii ti ọga ọlọpaa ọhun ṣe fun ni owo ko le gbagbe ọrọ naa, ṣugbọn o ni oun o gba owo.
Gẹgẹ bi iroyin naa ṣe sọ lọdun 2019, awọn ọlọpaa wa ẹsun si Itunu lẹsẹ pe o n ṣe fayawọ eeyan wa sí orilẹ-ede Cote D'Ivoire.
Bi Itunu ṣe dero atimọle niyii ti o si pada di ero ẹwọn lai mọwọ, lai mẹsẹ.
Bí mo ṣe káa sára tí mo gbé òkú ọmọ sínú ọkọ̀ lọ ṣe iṣẹ́ apanilẹ́rìín láì fihàn - Woli Agba Ayo Ajewole
Ọpọ ọmọ Naijiria lo kepe ijọba Naijiria lati yọ Itunu ninu ọfin to wa ni Cote D'Ivoire.
Ijọba Naijiria nipasẹ ajọ NIDCOM ti sọ pe iwadii fihan pe Itunu ko mọ ohun kan nipa ẹsun ti wọn fi kan an.
Wọn ní akoba ni wọn fi ọrọ naa ṣe fun Itunu.
Ẹwẹ, ijọba apapọ ti pàṣẹ pé kí wọn ṣe ayẹwo oku Itunu lati mọ ohun to ṣeku pa a gan an.
Ajọ NIDCOM lo kede ọrọ yii ni ọjọ kẹẹdogun oṣu kọkanla ọdun 2022 yii.
Dabiri-Erewa ni iku Itunu ṣeni laanu nitori pe ijọba ti sanwo fun agbẹjọro to yoo ṣakoso ẹjo kotẹmilọrun lori ọrọ rẹ ni Cote D'Ivoire.
Ẹwọn ogun ọdun ni wọn ran Itunu lori ohun ti ko mo ohun kan nipa rẹ.
Obi Cubana: Ilé ijó 'Hustle and Bustle' di tìtì pa lẹ́yìn ikú olùgbafẹ́ kan
Oríṣun àwòrán, Instagram/obi cubana
Ile ijo Hustle and Bustle to jẹ ti gbajugbaja oniṣowo un ni, Obinna Iyiegbu ti ọpọ mọ si Obi Cubana ti di titi pa.
Ohun ti a gbọ ni pe awọn alaṣẹ ile ijo naa kede pe ibi igbafẹ ọhun tipa di ọjọ mii ọjọ 're lẹyin ti ina gbe olùgbafẹ́ kan lọjọ Aiku ti o si gba ibẹ dero ọrun.
Ninu atẹjade kan ti ile ijo ọhún fi sita, wọn ṣalaye pe awọn ti ile ijo naa tipa tori onibaara wọn kan to ku lai ro tẹlẹ.
Wọn ni ọgbẹ ọkàn ni iṣẹlẹ naa jẹ eleyii ti awọn nilo asiko diẹ lati mu ọkan awọn le lori iṣẹlẹ naa.
Iwadii ti BBC ṣe fihan pe obinrin ni ẹni to ku naa ṣugbọn BBC ko mọ bi iṣẹlẹ ọhun ti waye.
Awọn alaṣẹ ile ijo gbadura pe kí Eledua tun awọn ẹbi oloogbe naa ninu.
Oríṣun àwòrán, Instagram
Awọn ẹṣọ ile ijo niluu Abuja sọ fun BBC pe ile ijo ọhún ti wa ni titi pa lootọọ.
Amọ, awọn ẹṣọ naa ko ṣalaye ni kikun ohun to ṣẹlẹ gan an.
Ile ijo Hustle and Bustle wa ni agbegbe Wuse 2 ni nọmba 80, Aminu Kanu Crescent.
Ile ijo Hustle and Bustle jẹ ọkan lara awọn okoowo Obi Cubana.
Ilorin River Dead body: Àwọn wò ló sọ òkú tí wọn dè lọ́wọ́ àti ẹnu sínú odò Asa ní Ilorin?
Oríṣun àwòrán, Kwara Fire Service
Ileeṣẹ ọlọpaa nipinlẹ Kwara sọ pe awọn ti bẹrẹ iwadii lori oku arakunrin kan ti wọn ri ninu odo Asa lọjọ Aje.
Oku yi ti wọn ko le sọ pato ẹni tii ṣe la gbọ pe wọn de lokun lọwọ ti wọn si fun aṣọ mọ lẹnu.
Alukoro ọlọpaa Kwara, Ajayi Okasanmi sọ pe nkan bi ago mẹta ọjọ Aje tawon gbo pe oku arakunrin naa lefo lori omi ni awọn sare lọ sibẹ.
Ilé ẹ̀kọ́ Fásítì Unilorin fọwọ́ òsì júwe ilé fún akẹ́kòó tó lù olùkọ lálùbami
Sunday Igboho: Ìjọba Buhari ló ní ẹ̀bi, ẹ yé dá ẹ̀bi rú àwọn tó ń bèrè fún 'Yoruba Nation'
O sọ fun BBC Yoruba pe  ni nigba tawọn yoo fi de eti odo naa, awọn ileeṣẹ panapana ti gbe oku naa jade.
''Lootọ ni wọn gbe oku yi jade taa si ri pe wọn de arakunrin naa lokun lọwọ ati lẹnu.''
Okasanmi tẹsiwaju pe pẹlu bawọn ti ṣe ri oku yi, o daju pe awọn kan lo ṣekupa arakunrin naa ki wọn to ju oku rẹ sinu odo.
''Kọmiṣana ọlọpaa ti pa wa laṣẹ lati bẹrẹ iwadii lori iṣẹlẹ yi ti a o si maa fi to yin leti bo ba ti ṣe  n lọ''
O ni awọn ko ni akọsilẹ pe awọn eeyan maa n ju oku sinu odo yi ati pe ohun ti iwadii yoo fidi rẹ mulẹ ni awọn to wa nidi iru iwa yi.
Ijaw Paternity test: Mọ́ síi nípa ìgbàgbọ́ àwọn Ilaje nípa ọmọ ọkọ àti ọmọ àlè
Boko Haram gbàjọba ní ìlú Shiroro áti Rafi ní ìpínlẹ̀ Niger l'ẹ́bá Ilorin
Oríṣun àwòrán, Reuters
Awọn ọmọ ogun Naijiria ko sinmi lati fẹyin Boko Haram janlẹ.
Awọn ọmọ ẹgbẹ agbesumọmi Boko Haram ti gba iṣakoso abule marun un ni ijọba ibilẹ Rafi ato Shiroro, nipinlẹ Niger.
Akọwe ijọba ipinlẹ ọhun, Alhaji Ahmed Matane lo fi ọrọ naa to awọn akọroyin leti niluu Mina lasiko to n ba ileeṣẹ News Agency of Naijiria sọrọ.
Matane sọ pe awọn agbesumọmi naa ti gbajọba niluu Hanawanka ati Madak ni Rafi, ati Kurebe, Gussauto fi mọ Farina Kuka ni Shiroro, eyii to mu ki awọn olugbe agbegbe naa ma fi ile wọn silẹ.
Gẹgẹ bii ohun to sọ, ni ṣe ni awọn agbesumọmi ọhun n yan fanda lawọn agbegbe ọhun pẹlu iniruru ohun ija oloro lọwọ wọn lai si idiwọ Kankan.
O ni ijọba ipinlẹ naa ti fi ọrọ ọhun to awọn agbofinro leti lati le wa nnkan ṣe si ọrọ naa.
Wo ìdí mẹ́fà tí ìjóba kò se tíì kápá Boko Haram
Ageku ejo Boko Haram si n soro bii agbọn
'A ti pa Boko Haram run patapata'
Miliọnu mẹta naira lowo ori Shekau
Ó dùn mí pé èmi ló bí Abubakar Shekau tó dá ayé lóró
Lẹyin ti awọn agbesumọmi ISWAP ṣekupa ọgagun Brig-Gen. Dzarma Zirkusu atawọn ọmọ abẹ rẹ, awọn ọmọ ogun ti pada si agbegbe ọhun, nibi ti wọn ti pa nnkan bii aadọta lara awọn agbesumọmi naa ni ijọba ibilẹ Askira Uba, ni ipinlẹ Bornu.
Matane sọ pe ibinu ni awọn ọmọ ogun fi pa awọn agbesumọmi ọhun, eyii ti ọgagun Brig-Gen. Onyema Nwachukwu dari rẹ.
Ṣaaju ni ọga agba ileeṣẹ ọmọ ogun Naijria, Lt-Gen. Farouk Yahaya ti kọkọ ṣabẹwo si mọlẹbi ọgagun ti awọn ọmọ ikọ ISWAP ṣekupa ọhun.
Ni iroyin miran, gomina ipinlẹ Bornu, Babagana Zulum, ti sun ayẹyẹ ṣiṣi awọn iṣẹ akanṣe kan, eyii to yẹ ko waye siwaju lati kẹdun awọn ọmọ ogun ti ẹmi wọn sọnu.
Lóòtọ́ ni wọ́n de òkú táa gbé jáde nínú odò Asa, Ilorin lọ́wọ́ àti ẹnu - Ilééṣé ọlọ́pàá
Kò sí Ilana Omo Oodua mọ́ ní UK, a fẹ́ ṣe àtúnṣe - Ilana Ọmọ Oodua
Iná ẹlẹ́tíríìkì gbé èèyàn kan ni ilé ijó Obi Cubana l'Abuja, ó fò ṣánlẹ̀ kú
Sheikh Gumi kọ́ ilé ẹ̀kọ́ fáwọn Fulani Darandaran nínú igbó Kaduna
Àwọn ọmọ ọkùnrin mẹ́tà ló timi mọ́lé tí wọ́n n bá mi sùn lójoojúmọ́ ni Libya
Agbẹnusọ Zulum, Isa Gusau sọ pe gomina naa yoo lọ bẹ mọlẹbi awọn ọmọ ogun ti ẹmi wọn sọnu wo kaka ko lọ ṣi awọn iṣẹ akanṣe naa.
Ẹwẹ, olori ẹlẹsin Musulumi, Sheikh Ahmad Gumi ti ni iwa janduku le di ohun itan ni Naijiria ti ijọba ba le pese ẹkọ to peye fun awọn janduku naa bi wọn ṣe n jọwọ ohun ija wọn.
Gumi sọ pe ni ṣe lo yẹ ki ijọba gbe owo gọbọi kalẹ fun idanilẹkọọ ati atunṣe aye awọn janduku naa kaka ko maa na obitibiti owo lori ileeṣẹ ọmọ ogun lati ra awọn ohun ija oloro.
Olori ẹlẹsin naa lo fi ọrọ ọhun lede ni gbagede Sheikh Uthman Bin Fodio Centre, to jẹ ile ẹkọ Musulumi to kọ fun awọn Fulani daran-daran ni abule Kohoto.
Oyingbo Market Protest: Folashade Tinubu ti ọjà Oyingbo pa torí N5m, àwọn ọlọ́jà ń ṣe iwọ́de
Oríṣun àwòrán, Folashade Tinubu-Ojo
Iyaloja Gbogboogbo nipinlẹ Eko, Arabinrin Folashade Tinubu-Ojo ti fesi si iwọde ti àwọn ọlọja kan ni Oyingbo ṣe.
Owurọ Ọjọ́rú ni awọn ọlọja naa ṣe iwọde, ti wọn si fi ẹ̀sùn kan Iyaloja naa pe o ti ọjà pa fun ọ̀sẹ̀ meji, to si tun n beere miliọnu marun Naira lọwọ wọn.
Ṣugbọn ninu ọrọ to sọ fun BBC Yoruba, Arabinrin Tinubu-Ojo sọ pe nitori obitibi ìdọ̀tí to wa ninu ọgbà ile itaja naa ni òun ṣe ti i pa.
Àwọn alamí ìjọba kan ti wà láàrín àwa ajìjàgbara Yoruba Nation tó ń bínú pé Sunday Igboho ti ga ju àwọn lọ - Akintoye
'Ó ṣeéṣe kí ẹ̀dà ìwé àbájáde ìwádìí ìgbìmọ̀ EndSARS tó lu sórí ayúlujára yàtọ̀ sí èyí t'íjọba yóò gbé jáde'
Àṣẹ̀yìnwá àṣẹ̀yìnbọ̀, Ijọba Eko sọrọ lórí àbọ̀ ìgbìmọ̀ igbẹjọ́ lórí #EndSARS
Ìdí nìyí tí mo fi kọ́ ilé ẹ́kọ́ fáwọn Daran-daran Fulani - Sheikh Gumi
APC kéde N22.5m owó fọ́ọ̀mù fáwọn tó fẹ́ díje fún ipò gómìnà l'Osun àti Ekiti
Ilééṣé ọlọ́pàá Osun tí mú Olùdarí ilé ìtura tí Akẹ́kòó fásìtì OAU ti dédé pòórá
Itunu Babalọla Death:Àgbáyé ẹ gbà mí, mọ fẹ́ ìdájọ́ òdodo lórí ikú ọmọ mí! ìyà yí tí pọ̀jù
O ni koda, gbogbo sọọbu to wa ni àwọn òkè 'complex' naa ni wọn pati, ti gbogbo wọn si n ta ọjà ni ìsàlẹ̀ ati oju ọna.
Oríṣun àwòrán, OTHERS
Ọpọ igba ni àwọn to ma n na ọjà Oyingbo ti fi ẹ̀sùn ransẹ si mi pe ọjà naa ti dọti ju.
Bẹẹ ni mo si baa nigba ti mo ṣe abẹwo síbẹ̀. Koda, agidi ni mo fi raaye gbe ọkọ wọlé nitori ìdọ̀tí to kun gbogbo ọjà naa.
Ọdún 1999 ni mo tí ń gbìyànjú láti gba SAN kí wọ́n tó fún mí ẹ̀ní ọdún 90 -Toriola Oyewo
Arabinrin Tinubu-Ojo ni alaga ìjọba ibilẹ agbegbe Oyingbo lo kọkọ ti ọjà naa.
O ni lati bi ọ̀sẹ̀ bii mẹta ni àwọn òṣìṣẹ́ akolẹ ko ìdọ̀tí ti n ko ìdọ̀tí ninu ọjà naa.
O sọ pe lati ìbẹ̀rẹ̀ pẹpẹ ni oun ti sọ fun àwọn ọlọja naa pe o di igba ti isẹ àtúnṣe ba pari, ki ọjà naa to di ṣíṣí pada.
Bakan naa lo sọ pe owo itanran fun pe ọjà dọti lai naani gbogbo ikilọ, ni miliọnu marun-un Naira ti wọn ni ki awon ọlọja naa san.
Àwọn ontaja kan ninu ọjà Oyingbo, ọkan lara awọn ọja nla nipinlẹ Eko ti n ṣe iwọde tako ẹni to jẹ Iyaloja gbogboogbo nipinlẹ Eko, Arabinrin Folashade Tinubu-Ojo.
Owurọ Ọjọ́rú, ọjọ́ kẹtàdínlógún, oṣù Kọkanla, ni iwọde naa waye ni Oyingbo.
"Orisirisi akọle ni àwọn ọlọja naa gbe dani, lara eyi ti a ti ri ""Gbogbo Eko, ẹ gba wa lọwọ ọmọ Tinubu, o ti ba Oyingbo jẹ."""
Oríṣun àwòrán, OTHERS
"Ìtàn tó rọ̀ mọ́ òwe ""Ẹni tí kò ṣe bíi aláàárù l‘Oyingbo..."
Ọnà ayédèrú ní wọn gbà gbé àbájáde ìwádìí Endsars tàwọn èèyàn n sọ̀rọ̀ nípa rẹ̀ jáde - Ọgágun Irabor
'Kò sí nkan tó burú nínú bí Akeredolu ṣe yan ọmọ rẹ̀ sí ipò! Ayé ń ṣe irú ẹ̀'
Iléeṣẹ́ Navy dákẹ́ lórí ibi tí Cute Abiola há sí àmọ́ àṣírí tí agbẹjọ́rò rẹ̀ tú fún BBC rèé
Ẹnikan to jẹ onisẹ ọwọ ni Oyingbo, àmọ́ ti ko fẹ ka darukọ rẹ sọ pe lootọ ni Iyaloja naa ti abala kan ninu ọjà Oyingbo pa.
O ni abala to jẹ àwọn sọọbu ti wọn kọ (shopping complex) ni ọrọ naa kan.
O sọ pe iroyin ti oun gbọ ni pe Iyaloja náà, Folashade Tinubu-Ojo pasẹ fun àwọn to n lo àwọn sọọbu ọhun, to fi mọ awọn to n taja lẹgbẹ titi, pe ki wọn o da miliọnu marun Naira jọ, ki wọn o si fi ransẹ si oun.
Oríṣun àwòrán, OTHERS
"Nitori pe àwọn ọlọja naa ko ko owo lọ, lo ṣe ti àwọn ile itaja wọn pa lati fun ọsẹ meji.
Ninu fidio iwọde ọhun to wa lori ayelujara, nise ni àwọn ọlọja, paapaa àwọn to n ta nkan ti ẹnu n jẹ, n da awon oúnjẹ bi gari, irẹsi, anamọ l, ẹ̀fọ́, ati bẹẹ bẹẹ lọ, si oju titi.
Wọn ni bi wọn ko ṣe jẹ ki àwọn si sọọbu ti ba àwọn ọjà naa jẹ.
Botilẹ jẹ pe a kò tii le sọ nkan to mu Iyaloja naa ṣe bẹẹ, àwọn iroyin kan ni nitori pe àwọn ọlọja naa kii tun ọjà ṣe, to si ma n kun fun ìdọ̀tí ati ẹ̀gbin lo fi ṣe bẹẹ gẹgẹ bi ìbáwí.
'Kò sí nkan tó burú nínú bí Akeredolu ṣe yan ọmọ rẹ̀ sí ipò! Ayé ń ṣe irú ẹ̀'
Iléeṣẹ́ Navy dákẹ́ lórí ibi tí Cute Abiola há sí àmọ́ àṣírí tí agbẹjọ́rò rẹ̀ tú fún BBC rèé
Ọnà ayédèrú ní wọn gbà gbé àbájáde ìwádìí Endsars tàwọn èèyàn n sọ̀rọ̀ nípa rẹ̀ jáde - Ọgágun Irabor
Àwọn ọmọ ọkùnrin mẹ́tà ló timi mọ́lé tí wọ́n n bá mi sùn lójoojúmọ́ ni Libya
Unilorin Student Beats Lecturer: Iléẹ̀kọ́ fásitì Ilorin tí jáwé máa lọ sílé rẹ fún akẹ́kòó tó dá sẹ̀ríà fún lẹ́kíṣọ́rà rẹ̀
Oríṣun àwòrán, Unilorin fm
Yunifasiti ilu Ilorin ti le akẹkọọ to lu olukọ rẹ lalubami, Salaudeen Aanuoluwa Waliu kuro nile ẹkọ wọn.
Eyi waye lẹyin to jẹjọ niwaju igbimọ ibawi fasiti naa lọjọ Aje tii ṣe ọjọ Kẹẹdogun oṣu yi.
Ọgbẹni Kunle Akogun to jẹ agbodegba ile ẹkọ naa lo fidi ọrọ yi mulẹ fun BBC.
O ni lẹyin atotonu ati ayẹwo ẹri to wa niwaju wọn igbimọ naa ri pe Waliu jẹbi ẹsun pe o ṣiwọ lu olukọ rẹ.
Amọ ṣa Akogun ni anfaani wa fun lati pe ẹjọ kotẹmilọrun laarin ọjọ mejidinlaadọta ti wọn gbe idajọ yi kalẹ.
O tẹsiwaju pe awọn ti fa ọrọ naa le ọlọpaa lọwọ lati tẹsiwaju iwadii ati ijẹjọ lori ẹsun ti wọn ba ri pe o tọ labẹ ofin.
Bi a ko ba gbagbe, iroyin gbode pe arakunrin akẹkọọ lẹka imọ sayẹnsi tawọn eeyan mọ si Captain Walz ṣadede lọ ba olukọ rẹ lọfisi to si lu lalubami.
Olukọ naa arabinrin Zakariyyah la gbọ pe o ti n gba itọju ti ara rẹ si ti n ya nile iwosan ti wọn gbe lọ
November 16 Public Holiday: Gómìnà Obiano fòntẹ̀ lù àyájọ́ Ọ̀jọ ìbí Zik, ó ní kí ìjọba àpapọ̀ náà ṣé bẹ́ẹ̀
Oríṣun àwòrán, AFP
Gomina ipinlẹ Anambra ti kede ọjọ Kẹrindinlogun oṣu Kọkanla gẹgẹ bi isinmi lẹnu iṣẹ lati fi ṣe ayẹsi Nnamdi Azikiwe.
Gomina  Willie Obiano sọ pe awọn ṣe bẹẹ ni iranti ọjọ ibi agbaọjẹ oloṣelu ati olori nigba kan ri ni Naijiria yi.
Nnamdi Benjamin Azikiwe ti ọpọ a maa pe ni  Zik"" lo jẹ aarẹ akọkọ ni Naijiria laarin ọdun 1963 si 1966."
Nilu Zungeru ni wọn ti bi Zik lọdun 1904 nibi to jẹ ipinlẹ Niger lode oni.
Ọdun  ẹlẹẹkẹẹta ree ti ipinlẹ Anambra  to jẹ ilu abinibi Zik yoo maa ṣe ayajọ yi ti wọn si yaa sọtọ gẹgẹ bi ọjọ isinmi.
Gomina Obiano ko fi mọ ni ipinlẹ rẹ nikan, o loun fẹ ki ijọba apapọ ya ọjọ yi sọtọ ko si di ọjọ isinmi kaakiri Naijiria.
O ni iru apọnle bayi naa ni wọn ṣe fun Kwame Nkruma lorileede Ghana ati Julius Nyerere ti Tanzania.
Oríṣun àwòrán, johan10
Amọ ṣa ijọba Naijiria ṣi ti ṣe ayẹsi Zik nipa fifi aworan rẹ sara ẹẹdẹgbẹta Naira owo Naijiria.
Lati oṣu Kẹrin ọdun 2001 ni ile ifowopamọ agba CBN ti ṣapọnle Zik pẹlu owo yi to jẹ owo to tẹle eleyi to ga julọ ni Naijiria
Azikiwe lo ṣe idasilẹ banki ifowopamọ tiwantiwa akọkọ,African Continental Bank, ṣugbọn banki yi ti kogba wọle
Fasiti Naijiria to wa ni Nsukka  taa mọ si UNN, Zik naa lo da silẹ.
Lara awọn babanla orileede yi to ṣapa lati ri pe Naijiria gba ominira lọwọ awọn oyinbo amunisin ni Zik wa.
Eyi lo mu ki ọpọ maa ṣapejuwe rẹ gẹgẹ bi ''Baba idasilẹ ijẹ orileede ni Naijiria''
Oríṣun àwòrán, UNN
Nnamdi Benjamin Azikiwe dagbere faye ni ilẹ iwosan eto ẹkọ ilera fasiti Enugu to wa ni Ituku.
O ku lọjọ Kọkanla oṣu kaarun ọdun 1996.
Ọkọ̀ Awólọ́wọ̀ yìí ti lọ yíká Nàíjíríà
Ogbomoso: Ẹbọ ọkùnrin àti obìnrin tí kò ní ìbálòpọ̀ rí ni wọ́n rú dènà ogun Fulani
Ondo kidnappers: Àwọn agbébọn pa èèyàn méjì l’Akure, wọ́n ṣá ẹlòmíràn ní àdá lórí
Oríṣun àwòrán, other
Awọn ajinigbe ti ṣa okunrin meji kan pa niluu Ala, lẹba ilu Akure, nipinlẹ Ondo.
Agbẹnusọ ileeṣẹ ọlọpaa ipinlẹ Ondo, Odunlami Ibukun ṣalaye fun BBC Yoruba pe awọn mẹrin ni awọn ajinigbe naa ṣakọlu si, ṣugbọn ẹnikan moribọ ninu wọn, ẹnikan wa ni ikawọ awọn naa nigba ti awọn meji ti jade laye.
"O ni ""Iṣẹlẹ naa ṣeni laanu gidi gan, lana ni a gbọ pe wọn ṣa okunrin kan  ni ada niwaju ori rẹ, a si gbe okunrin ọhun lọ sile iwosan."""
Lẹyin naa ni a gbọ pe mẹrin ni wọn, ati pe maalu ni wọn fẹ lọ ra ki ikọlu naa to waye.
Ko pẹ ti a gbe iwadii dide ti a ṣawari oku awọn okunrin meji ninu igbo ti iṣẹlẹ naa ti waye, ti wọn jẹ meji lara awọn mẹrin ti awọn ajinigbe naa kọlu.
Ẹgbẹ awọn alapata ti fi to wa leti pe awọn ajinigbe ọhun ti pe awọn lati fi to awọn leti pe ikawọ awọn ni ẹnikan to ku wa.
Odunlami sọ pe iwadii ti bẹrẹ, awọn yoo si gbiyanju lati doola ẹnikan to wa ahamọ awọn ajinigbe ọhun, ati lati fi ṣikun ofin mu awọn afurasi naa.
Ẹwẹ, Nasiru Jamiu, to jẹ okunrin to moribọ ninu awọn okunrin mẹrin ti iṣẹlẹ naa ṣẹ si ti ṣalaye fun awọn akọroyin niluu Akurẹ bi ọrọ naa ṣe jẹ.
"O ni ""Awọn ajinigbe ọhun pe awọn ọga mi lori ago lati wa ra maalu, a si tẹkọ leti lọ bawọn, ṣugbọn ni kete ti a de ibẹ ni wọn ṣina bolẹ ti wọn si ji ọga mi gbe lọ sinu igbo."""
Gẹgẹ bii ohun to sọ, lasiko ijinigbe ọhun ni wọn ṣa ni ada lori, ṣugbọn o da bii ọgbọn lati ṣe bii ẹni to ti ku titi ti awọn ajiigbe ọhun fi wọ inu igbo lọ.
"Jamiu ni ""Awa mẹta gbiyanju lati salọ ṣugbọn wọn ṣa mi ni ada, mo si ṣubu lulẹ, mo dibọn bii ẹni ti ẹmi ti bọ lara rẹ."""
Lẹyin ti mo ri pe ko si ẹnikẹni mọ lagbegbe naa ni mo dide, ti mo si bẹrẹ si n salọ ninu igbo.
Sunday Igboho: Ìjọba Buhari ló ní ẹ̀bi, ẹ yé dá ẹ̀bi rú àwọn tó ń bèrè fún 'Yoruba Nation'
Okunrin naa pari ọrọ rẹ pe oju oun koro ni wọn ji ọga oun gbe lọ sinu igbo ṣugbọn oun ko le sọ ni patọ ibi ti awọn okunrin to ku wa.
"O ni ""Mo ri nigba ti wọn n gbe ọga mi lọ, sugbọn ni ti awa to ku, mi o mọ ibi ti awọn okunrin meji naa wa, boya wọn ti ji awọn naa gbe ni o tabi wọn ti pa wọn, mi o le sọ."""
Ni iroyin kan naa, agbẹnusọ ọlọpaa l'Ondo ni awọn ko tii le fidi rẹ mulẹ boya awọn Fulani darandaran lo wa nidi iṣẹlẹ ijinigbe naa, tabi awọn ẹgbẹ mii.
Endsars panel report: Àṣẹ̀yìnwá àṣẹ̀yìnbọ̀, Ijọba Eko Sọrọ lórí ìjábọ̀ ìgbìmọ̀ igbẹjọ́ lórí #EndSARS
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ijọba ipinlẹ Eko nipasẹ Kọmísọ́nà fun ọrọ to ń lọ  ati Ilana eto, Ọgbẹni Gbenga Omotoso, ti fesi si iroyin igbimọ EndSARS to n lọ kaakiri.
Igbimọ Idajọ ti ipinlẹ Eko lori atunṣe fun awọn ti o farapa nípa iwa ipa àti ifiya jẹni ti SARS ati awon nnkan tó jọ mọ ti fi ijabọ abajade rẹ ranṣẹ si Gomina Babajide Sanwo-Olu ni ọjọ Aje.
Komisona ninu àtẹ̀jáde kan ni Ọjọbọ, ṣe akiyesi pe awọn ariyanjiyan to ń lọ nigboro lori ijabọ naa ko wúlò.
Ẹwẹ, Gbenga Omotoso ni ó ṣe pàtàkì  fún àwọn eniyan lati yago fun bíbu ẹnu atẹ lu isẹ ribiribi àti ero rere ti ijọba ni sì iṣeto igbimọ yii, àti àwọn ìpinnu wọn  lati ṣe iṣẹ rẹ lẹkunrẹrẹ -  Igbimọ náà se amujáde òtítọ́ nínú ìwádìí wọn.
'Ó ṣeéṣe kí ẹ̀dà ìwé àbájáde ìwádìí ìgbìmọ̀ EndSARS tó lu sórí ayúlujára yàtọ̀ sí èyí t'íjọba yóò gbé jáde'
Ilééṣé ọlọ́pàá Osun tí mú Olùdarí ilé ìtura tí Akẹ́kòó fásìtì OAU ti dédé pòórá
Ìdí nìyí tí mo fi kọ́ ilé ẹ́kọ́ fáwọn Daran-daran Fulani - Sheikh Gumi
Itunu Babalọla Death:Àgbáyé ẹ gbà mí, mọ fẹ́ ìdájọ́ òdodo lórí ikú ọmọ mí! ìyà yí tí pọ̀jù
"“Ni ibamu pẹlu òfin tribunal ọdún 2015, a ti ṣeto igbimọ kan lati gbe Iwe kan tí yoo salaye ìgbésẹ̀ jade lórí nnkan ti ijọbọ ń pinnu. Ni akoko ti o yẹ, ijọba yoo jẹ ki a mọ àwọn ero rẹ lori gbogbo awọn ọrọ ti igbimọ naa gbé kalẹ ninu iwe ti won yoo kọ, "" gẹ́gẹ́ bí àtẹ̀jáde náà ṣe sọ."
Ṣaaju ni iroyin ti kọkọ sọ pe 'Gómìnà Sanwo-Olu kò tíì ka ìwé àbájáde ìwádìí EndSARS' torinaa ko ni le fesi si ohun tawọn eniyan n gbe ka.
Gomina ipinlẹ Eko, Babajide Sanwo-Olu ko tii ka iwe abajade iwadi igbimọ iwadii EndSARS, iwa kotọ awọn ọlọpaa ati wahala to waye ni Lekki Toll gate.
Eyi loun ti ọgbẹni Gboyega Akoṣile, agbẹnusọ fun gomina ipinlẹ Eko sọ.
O sọrọ yii pẹlu awuyewuye lori ẹda iwe abajade iwadii naa kan to lu sita.
Gẹgẹ bi Akọṣile ṣe sọ, gbogbo abọ iwadii igbimọ  naa ni ijọba yoo fi sita laifi igbakan bọkan ninu.
"Gomina ko tii ri iwe iwadii naa, ko tilẹ tii yẹ ẹ wo. O ṣa ti gbe igbimọ ẹlẹni mẹrin kalẹ lati yẹẹ wo ki wọn si gbe iwe amuṣẹya kan jade.'
Ki lo wa ni inu ẹda iwe abajade iwadii naa to wa
Ẹda iwe iwadii naa ti igbimọ oluwadi ti ijọba ipinlẹ Eko gbe kalẹ yọju rẹ sita pe ileeṣẹ ọmọogun Naijiria mọọmọ kọju ibọn si awọn oluwọde to wa ni Lekki Toll gate ni ogunjọ oṣu kẹwaa ọdun 2020 ṣugbọn ti wọn  gbiyanju lati da ọwọ boo mọlẹ.
Iwe abajade naa darukọ eeyan mejidinlaadọta gẹgẹ bi awọn to faragba nibi iṣẹlẹ lekki Toll gate ninu eyi ti mọkanla ti ku, mẹrin si di eyi ti a n wa, gẹgẹ bi ẹda abajade naa ṣe sọ.
Ọdún 1999 ni mo tí ń gbìyànjú láti gba SAN kí wọ́n tó fún mí ẹ̀ní ọdún 90 -Toriola Oyewo
Bakan naa lo tun yọ oju rẹ sita pe lẹyin ti awọn ologun pari yinyinbọn nibẹ lawọn ọlọpaa naa bọ sibẹ lati palẹ gbogbo nnkan mọ lati palẹ awọn ọta ibọn ti wọn yin nibẹ mọ.
Awọn to ṣoju wọn n ṣalaye pe ọkọ akẹru nla ni wọn fi ko oku awọn eeyan ti wọn yinbọn pa nibẹ.
Ileeṣẹ ọmọogun ni awọn ko yin ibọn ni Lekki Toll gate lasiko iwọde naa rara.
Amọṣa, gomina Sanwo-Olu ti ṣeleri lati dari iwe naa iwadii naa si igbimọ ọrọ aje apapọ orilẹede.
Oríṣun àwòrán, U.S. Mission Nigeria/BBC
Ijọba ilẹ Amẹrika ti ke si ijọba ipinlẹ Eko ati ijọba apapọ orilẹede Naijiria pe ko tete ṣe ohun to ba yẹ lori abajade iwadii igbimọ oluwadi ti wọn gbe kalẹ lati wadii awọn ẹsun iwa kotọ ti wọn fi kan ẹka ileeṣẹ ọlọpaa SARS ati ohun to ṣẹlẹ ni Lekki Toll gate lọdun 2020.
Ninu atẹjade kan ti ileeṣẹ aṣoju ijọba orilẹede Amẹrika ni Naijiria fi sita, Orilẹede Amẹrika dunnu si ipari iṣẹ igbimọ oluwadii ati gbigbe abajade wọn kalẹ."""
O ni oun ti awọn n reti bayii ni ki ijọba ipinlẹ Eko gbe igbesẹ lori rẹ gẹgẹ bi ara ọna ati ṣe ohun to tọ nipa iwọde #EndSARS naa ati awọn iṣẹlẹ to waye ni Lekki Tollgate ni ogunjọ oṣu kẹwaa ọdun 2020.
Orilẹede Amẹrika ni awsn iṣẹlẹ naa yọ oju oniruuru ifisun jade eleyi to kọju si awọn eeyan kan lẹka ileeṣẹ alaabo.
O wa fi kun pe ijọba ipinlẹ Eko ati ijọba apapọ gbọdọ gbe igbesẹ to yẹ lori iwa familete ki ntutọ gbogbo tawọn oṣiṣẹ alaabo hu lati tan ẹdun ọkan awọn ti wọn rẹ jẹ tabi idile wọn.
Oríṣun àwòrán, lasg
Ni ọjọ Aje, ọjọ karundinlogun oṣu kọkanla ọdun 2021 ni igbimọ oluwadi ti ijọba ipinlẹ Eko gbe kalẹ lori ẹsun aṣemaṣe ti wọn fi kan awọn ọlọpaa SARS ati ohun to ṣẹlẹ ni Tollgate logunjọ oṣu kẹwaa ọdun 2020.
Gomina ipinlẹ Eko, Babajide Sanwo-Olu ti fi ọkan awọn eeyan balẹ pe ko si ọrọ oku oru kankan bo ti wulẹomọ lori ọrọ abajade iwadii igbimọ naa ati wi pe oun ti gbe igbimọ ẹlẹni mẹran kan kalẹ lati gbe iwe ilana ijọba, - White paper, jade lori rẹ lọna ati lee mu ki ijọba ipinlẹ Eko gbe igbesẹ gbogbo to ba yẹ lori rẹ ni kiakia.
Ni alẹ ọjọ Aje ni kete lẹyin ti igbimọ naa gbe abajade iwadi rẹ iwaju gomina ipinlẹ Eko ni iji awuyewuye lori abajade naa ti jade sigboro pe ẹda abajade naa kan ti lu sita eyi to sọ pe lootọ lawsn ologun yin ibọn ni Tollgate ti ọpọ si ku ti awọn miran si fara ṣeṣe.
Amọṣa gomina Sanwo-Olu ni gbogbo abajade iwadii naa ni wọn yoo fi sita fun gbogbo araalu lati ri lai fi igba kan bọkan ninu.
O fi kun un pe ni kete ti awọn igbimọ tẹẹkoto ẹlẹni mẹrin naa ba ti gbe iwe ilana ijọba, - White paper, jade lori rẹ laarin ọsẹ meji ni igbimọ iṣejọba ipinlẹ Eko ti wọn yoo si tun fi ṣọwọ si igbimọ ọrọ aje apapọ orilẹede Naijiria.
Sunday Igboho: Ìjọba Buhari ló ní ẹ̀bi, ẹ yé dá ẹ̀bi rú àwọn tó ń bèrè fún 'Yoruba Nation'
O fi da awọn eeyan ipinlẹ Eko ati olugbe ipinlẹ naa loju pe ilana ofin ati ifẹ araalu ni wọn yoo tẹle lori ọna naa dipo ohun ti awọn kan n sọ pe wọn lee ṣe loku oru.
Gomina Sanwo-Olu ni ko si igba kan ti oun tabi ijọba oun gbiyanju ati doju iṣẹ igbimọ iwadii naa ru.
Ninu ọrọ tirẹ to sọ, alaga igbimọ naa, Adajọfẹyinti Okuwobi ni owo to to irinwo o le mẹwaa miliọnu Naira ni wọn buwọlu fun sisan fun aadọrin eeyan gẹgẹ bi owo gba maa binu lori awọn iwa familete n tutọ awọn ọlọpaa.
O fi kun pe iwe ẹhonu ojilelugba o din marun (235) ni igbimọ naa tẹwọ gba, ninu eyi to jẹ pe mẹrinla pere lo da lori iṣẹlẹ to waye ni agbagbe Lekki Tollgate ni ipinlẹ Eko.
Human body parts: Ọmọbìnrin rí ara èèyàn nínú fìríìjì ọ̀rẹ́kùnrin rẹ̀
Oríṣun àwòrán, South african police
Oriṣiiriṣii lo n ṣẹlẹ ní duniyan ti a wa yii.
Ọmọbinrin kan lo ba ara eeyan ninu firiiji ọrẹkunrin rẹ niluu Soweto  lorilẹede South Africa.
Ọmọkùnrin náà, ẹni ọdun mẹtadinlọgbọn ti ko si gbaga ọlọpaa bayii niluu Soweto.
Awọn ọlọpaa mu ọkunrin naa lọjọ Abamẹta lẹyin ti wọn ri ara eeyan to di sinu baagi ninu firiiji ninu yara to gba.
Ileeṣẹ ọlọpaa ni ọmọbinrin to jẹ ọrẹbinrin ọkunrin naa ni ri awọn ara eeyan yii ninu firiiji nigba ti ọkunrin ọhun fi í silẹ lọ sí ọja.
Ọmọbinrin naa ri ara eeyan nigba to n wa ounjẹ ti o le jẹ.
Iroyin kan tiẹ sọ pe ọmọkunrin ọhun kun ara rẹ ni ọbẹ nigba ti wọn fẹ mu un.
Agbẹnusọ ileeṣẹ ọlọpaa, Brigadier Brenda Muridili ni ọmọkunrin yoo foju ba ile ẹjọ lori ẹsun ipaniyan laipẹ.
Wo òkè ìṣẹ̀mbáyé Abanijorin yìí l'Ekiti tó máa ń bá ọ̀kọ̀ rìn lójú pópó tó tún ní ilé ìwòran orí ìtàgé nínú rẹ̀
Muridili ṣalaye pe ko si ẹni to le sọ ara ẹni ti ọkunrin yii gbe sí inu firiiji.
Amọ, o ni iwadii ti nbẹrẹ lori ẹya ọhun lati ti le ẹni to jẹ gan an.
Ọrẹkunrin rẹ ni a gbọ pe ọkunrin yii pe wí pe ko wa  ṣe isinmi opin ba ọsẹ nile oun.
Nigba ti ọkunrin yii jade ni ọmọbinrin naa ri ara eeyan ninu firiiji eleyii to ba a l'ẹru gan an.
Sunday Igboho: Ìjọba Buhari ló ní ẹ̀bi, ẹ yé dá ẹ̀bi rú àwọn tó ń bèrè fún 'Yoruba Nation'
O pariwo lẹyin to ri ara eeyan tan, o sí sare kaba kaba lọ ba ara ile kan to n jẹ Sarah Marumole lati rẹ ẹ lẹkun.
Sarah ṣalaye fun ileeṣẹ iroyin SABC ni South Africa pe ṣadeedee ni omobinrin naa sare wọ ile awọn ti o si n gbọn.
O ni ọmọbinrin yii bẹrẹ si ni pọ bi o ti n gbọn.
"Ọlopaa ni ọkan lara awọn alabagbe to wa ba wa nibi ile ọkunrin yii.
Ẹlomiran naa tun darapọ mọ wa ti gbogbo wa si duro ti ọmọkunrin ọhun fi de lati ọja to lọ.
Bayii ni wọn ṣe mu ọmọkunrin yii to gbe ara eeyan pamọ́ sí inu firiiji o, Sarah ṣalaye."
Nigeria vs Cape Verde: Super Eagles rápálá wọ ìpele kómẹsẹ̀-ó-yọ Qatar 2022, ọ̀mì ni wọ́n ta pẹ̀lú Cape Verde l'Eko
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ikọ agbabọọlu Naijiria, Super Eagles tun rapala wọ ipele to kan ninu ifẹsẹwọnsẹ lati mọ awọn orilẹede wo ni yoo kopa ni idije ife ẹyẹ bọọlu agbaye lọdun to n bọ.
Nibi ifẹsẹwọnsẹ wọn pẹlu awọn ikọ Cape Verde ni papa iṣere Teslim Balogunto wa nilu Eko, ikọ Super Eagles ta ọmi.
Victor Osimhen lo gba goolu akọkọ wọle nigba ti ifẹsẹwọnsẹ naa ko tilẹ tii pe iṣẹju kan ki Júlio Tavares  to daa pada nigba ti ifẹsẹwọnsẹ naa wọ iṣẹju karun un.
Pẹlu esi ifẹsẹwọnsẹ yii orilẹede Naijiria ti kogoja lati kopa ninu ipele komẹsẹ-o-yọ ti yoo waye laarin awọn orilẹede to leke ipin kọọkan ipele to pari yii.
Oríṣun àwòrán, Screenshot
Oṣu kẹta ọdun 2022 ni ipele naa yoo bẹrẹ.
Kampala blasts: Àdó olóró agbésùnmọ̀mí ṣekúpa èèyàn mẹ́ta ní Kampala
Awọn agbesunmọmi ti kọlu ilu Kampala ti ṣe olu ilu Uganda nibi ti wọn ti ṣekúpa eeyan mẹta ti awọn to le l'ọgbọn si fi ara pa.
Ileeṣẹ ọlọpaa ni awọn agbesunmọmi mẹta naa yin ado oloro ti wọn so mọ ara wọn l'ẹgbẹẹ gbọngan ile aṣofin ni Kampala.
Ileeṣẹ ọlọpaa ni awọn to ku nibi iṣẹlẹ ọhun si maa pọ sii nitori ẹya ara awọn si wa nilẹ ti ado oloro ṣe baṣu baṣu.
Ijọba ti di ẹbi iṣẹlẹ naa ru ẹgbẹ kan to n jẹ Allied Democratic Forces (ADF) to wa orile-ede DR Congo.
Ikọlu naa waye laarin iṣẹju mẹta pere.
Oríṣun àwòrán, Reuters
Ẹwẹ, wọn tun ti ri ado oloro l'awọn ibikan niluu Kampala.
Agbẹnusọ ileeṣẹ ọlọpaa, Fred Enanga, ẹru si n ba awọn eeyan titi di akoko yii.
Enanga ni ileeṣẹ ọlọpaa gbagbọ pe awọn agbesunmọmi si wa ni ilu Kampala.
O ni ọwọ ileeṣẹ ọlọpaa ti ba agbesunmọmi kẹrin ti oun naa fẹ yin ado oloro.
Ọlọpaa meji lo wa ninu awọn tó bá iṣẹlẹ naa lọ nigba ti marun un ninu to fara pa wa ni ẹsẹ kan aye, ẹsẹ kan ọrun.
Nigeria Navy vs Cute Abiola: Ilééṣé ológun tí sòrò nípa òhun tó ṣokunfa atímọlè Cute Abiola
Oríṣun àwòrán, Facebook/thecuteabiola/Nigerian Navy
Ileeṣẹ ologun ori omi ti pada ṣalaye idi ti wọn fi sọ gbajugbaja oṣere apanilẹrin Cute Abiola si ahamọ.
Wọn ni Cute Abiola ko sọnu si ibi kankan ati pe iroyin ẹlẹjẹ gbaa leyi jẹ.
Ninu atẹjade kan ti wọn fi sita ni idahun si ariwo to gbode nipa ibi ti Abiola wa, wọn ni ahamọ awọn ni Abiola wa nitori awọn ẹsẹ kan to ṣẹ.
Wọ́n ti ń bèrè lọ́wọ́ abúrò ọkọ mi pé èlò ni wọ́n fẹ́ gbà, ẹ ṣàánú wa o! - Ìyàwó Timothy tó kú sí Hilton Hotel Osun figbe ta
Lẹ́yìn Titi Masha, Kwam 1 gbé ìyàwó tuntun, Emmanuella Ropo l'Abeokuta, bó ṣe lọ rèé
Àwọn alamí ìjọba kan ti wà láàrín àwa ajìjàgbara Yoruba Nation tó ń bínú pé Sunday Igboho ti ga ju àwọn lọ - Akintoye
'Ó ṣeéṣe kí ẹ̀dà ìwé àbájáde ìwádìí ìgbìmọ̀ EndSARS tó lu sórí ayúlujára yàtọ̀ sí èyí t'íjọba yóò gbé jáde'
Itunu Babalọla Death: Ìjọba Nàíjìríà fèsì sí ìbéèrè Baba Itunu Babalola lórí òkú ọmọ rẹ̀!
Àṣẹ̀yìnwá àṣẹ̀yìnbọ̀, Ijọba Eko sọrọ lórí àbọ̀ ìgbìmọ̀ igbẹjọ́ lórí #EndSARS
Ìdí nìyí tí mo fi kọ́ ilé ẹ́kọ́ fáwọn Daran-daran Fulani - Sheikh Gumi
APC kéde N22.5m owó fọ́ọ̀mù fáwọn tó fẹ́ díje fún ipò gómìnà l'Osun àti Ekiti
Ilééṣé ọlọ́pàá Osun tí mú Olùdarí ilé ìtura tí Akẹ́kòó fásìtì OAU ti dédé pòórá
Itunu Babalọla Death:Àgbáyé ẹ gbà mí, mọ fẹ́ ìdájọ́ òdodo lórí ikú ọmọ mí! ìyà yí tí pọ̀jù
Ọgagun Suleman Dahun to fọwọ si atẹjade yi lorukọ Ọga agba ileeṣẹ ologun yii sọ pe o tapa si ofin ileeṣẹ naa nipa lilo opo ayelujara ni .
Oríṣun àwòrán, Nigerian Navy
Irọ́ ńlá lẹ pa, mi ò kó ọ̀rọ̀ mi jẹ́ lórí ìṣẹ̀lẹ̀ Lekki Toll Gate - Lai Mohammed
Àwọn ọlọ́jà ní Oyingbo ṣe iwọ́de, wọ́n ní Folashade Tinubu ti ọjà pa torí  N5m
Ọnà ayédèrú ní wọn gbà gbé àbájáde ìwádìí Endsars tàwọn èèyàn n sọ̀rọ̀ nípa rẹ̀ jáde - Ọgágun Irabor
'Kò lòdì sí ofin láti yàn mọ̀lẹ́bí sí ipò, àmọ́ ṣé ọ̀mọ̀ Akeredolu kójú'òsùwọ̀n ìpò tí bàbá rẹ̀ yàn án sí?' - Onímọ̀ òṣèlú
APC kéde N22.5m owó fọ́ọ̀mù fáwọn tó fẹ́ díje fún ipò gómìnà l'Osun àti Ekiti
Bẹẹ lo ṣalaye pe o kọ lati tẹle awọn aṣẹ kan tawọn pa fun.
''Ileeṣẹ yi fi asiko yi sọ fun awọn oṣiṣẹ rẹ lati rii pe wọn tẹle aṣẹ ati ilana ologun to ni ṣe pẹlu lilo awọn oju opo ayelujara.''
''Ilana yi wa lati daabo bo awọn ọmọ ogun ati iṣẹ ta baa n ṣe lẹka ọmọ ogun orileede Naijiria''.
Oríṣun àwòrán, Facebook/thecuteabiola
Agbẹjọro apanilẹẹrin Cute Abiola ti iroyin gbode pe o di awati ti ṣalaye ibi ti arakunrin naa wa.
Ninu ifọrọwanilẹnuwo pẹlu ileeṣẹ BBC, Fatai Adebanjo sọ pe ahamọ ileeṣẹ ọmọ ogun ori omi ni Cute Abiola wa.
Amọ ṣa agbẹjọro naa ko sọ idi ti awọn ileeṣẹ yi ti Cute Abiola n ba ṣiṣẹ fi mu u kalẹ lai fi to awọn mọlẹbi rẹ leti.
Ọdún 1999 ni mo tí ń gbìyànjú láti gba SAN kí wọ́n tó fún mí ẹ̀ní ọdún 90 -Toriola Oyewo
Ninu alaye rẹ, agbẹjọro Fatai sọ pe Abiola ti orukọ abisọ rẹ n jẹ Abdulgafar Ahmed kuro nile to si wọ iṣẹ ni ileeṣẹ awọn ọmọ ogun omi to wa ni NNS Ojo l'Eko.
Ṣugbọn nigba ti yoo fi di ọjọ Iṣẹgun to yẹ ko pada sile, awọn ọrẹ ati mọlẹbi ko ri.
Airi Cute Abiola yi lo mu ki wọn ke gbajare ti ọrọ naa si di nkan to gbode kaakiri oju opo ayelujara.
Oríṣun àwòrán, Facebook/thecuteabiola
Agbẹjọro ọhun tẹsiwaju pe nigba toun de ọfisi rẹ loun rii pe o wa ni ahamọ ṣugbọn ko si ẹnikankan to ṣalaye idi to fiwa nibẹ.
Iroyin ti a n kẹfin ni BBC ni pe o ṣeeṣe ki ahamọ yi ni nkan ṣe pẹlu aworan kan ti Abiola fi sita laipẹ yi.
Ninu rẹ a ri pe o gbe ibọn AK47 lọwọ ninu ere fiimu kan to n ba wọn kopa ninu rẹ
Oríṣun àwòrán, thecuteabiola
Ọnà ayédèrú ní wọn gbà gbé àbájáde ìwádìí Endsars tàwọn èèyàn n sọ̀rọ̀ nípa rẹ̀ jáde - Ọgágun Irabor
Ìjọba ìpínlẹ̀ kàn kéde ọ̀jọ ìsinmi ní ìrántí Zik, wo òhun tí wọ́n yóò máa ṣe lọ́jọ́ ìbí rẹ̀
Sunday Igboho: Ìjọba Buhari ló ní ẹ̀bi, ẹ yé dá ẹ̀bi rú àwọn tó ń bèrè fún 'Yoruba Nation'
Ohun to ṣe yi labẹ ofin awọn ileeṣẹ ọmọ ogun ori omi tapa si ofin.
Oṣiṣẹ wọn ko gbọdo gbe ibọn dani laiṣe pe o wa nidi iṣẹ.
Gẹgẹ baa ṣe gbọ, lọdun to kọja wọn fi si atimọle nitori pe o ya aworan pẹlu aṣọ ologun lọjọ ayajọ ibi rẹ.
Titi di ba ṣe n ko iroyin yi jọ, BBC ko tii ribi ba ọga ẹka iroyin NNS WEY, Ọgagun Okiewalu N.A sọrọ.
Gbogbo ipe wa sori ago rẹ ko ti ri idahun lati le ṣalaye ẹsẹ ti Cute Abiola ṣ to fi di ero atimọle
Oríṣun àwòrán, Facebook/thecuteabiola
Gbajugbaja apanilẹrin, Abdulgafar Ahmad Oluwatoyin, ti awọn ololufẹ rẹ tun mọ si Cute Abiola ti di àwátì.
Oluwatoyin to tun jẹ ọmọ ogun ori omi, ni akẹgbẹ rẹ ninu iṣẹ awada ṣíṣe, Mr Macaroni, kede loju opo Twitter rẹ pe ẹbi ati ọrẹ rẹ n wa.
Oríṣun àwòrán, Mc ALways
Ikede naa sọ pe ọjọ Aje, ọjọ kẹẹdogun, oṣù Kọkanla, ni iyawo Cute Abiola ati awọn alajọṣiṣẹpọ rẹ ti gburo rẹ kẹhin.
Iroyin sọ pe ni nkan bi aago mẹfa owurọ ọjọ naa lo kuro nile, lati lọ si ibi isẹ rẹ nileeṣẹ ọmọ ogun ori omi. O de ibi isẹ ni nkan bi aago meje, o si pe iyawo rẹ lati jẹ ko mọ pe oun ti de ọfiisi.
Lati igba naa si ni oun ati awọn alajọṣiṣẹpọ ti gburo rẹ mọ.
Adeherself sọ̀rọ̀ sókè lẹ́yìn tí Cute Abiola ṣe ìgbéyàwó ìdánkọ́nkọ́ l'Ogbomoso
Òṣìṣẹ́ ológun Navy ni mí àmọ́ àwàdà ayélujára ló sọ mí di olókìkí - Cute Abiola
Arúmọjẹ lásán ni lọkọ-láya tí èmi àti Cute Abiola jọ́ ń ṣe tẹ́lẹ̀, ìyàwó rẹ̀ ti dé- Adeherself
Ma a pa ara mi si Cute Abiola lọrun bo ṣe já mi silẹ tori afẹsọna miran
Sunday Igboho: Ìjọba Buhari ló ní ẹ̀bi, ẹ yé dá ẹ̀bi rú àwọn tó ń bèrè fún 'Yoruba Nation'
Lẹyin to pe iyawo ati awọn alajọṣiṣẹpọ rẹ pe oun ti de ibi iṣẹ, ko ti i pada sile lọdọ ẹbi rẹ, bẹẹni ẹnikẹ́ni ko gburo rẹ titi di asiko yii.
Ṣugbọn sa, iroyin kan ti a ko tii fidirẹmulẹ sọ pe inu ahamọ ileeṣẹ ọmọ ogun ori omi lo wa lati igba to ti de ibi isẹ lọjọ Aje.
Bẹẹni ko si ẹni to mọ ẹ̀sùn ti wọn fi kan an, eyi to gbe de atimọle.
Iroyin naa tun sọ pe lati olu ileeṣẹ ologun naa ni àṣẹ ti wa pe ki wọn o fi Cute Abiola si ahamọ.
"Ni odun 2020, ileeṣẹ ologun ori omi ti fi si ahamọ ri, ""nitori pe o fi aṣọ ologun ya aworan ayẹyẹ ọjọ ibi rẹ, to si tun fi aworan naa sori ayelujara Instagram."
Ọmọ ilu Ilorin, nipinlẹ Kwara ni Abdulgafar Ahmad Oluwatoyin.
Ọdun 1996 ni wọn bi.
O si ti bẹ̀rẹ̀ isẹ apanilẹrin lati kekere. Sugbon o di ilumọọka lati ọdun 2015.
Oṣù Karun-un, ọdun 2021 lo ṣe igbeyawo.
Òṣìṣẹ́ ọmọ ogun ori omi Naijiria, Nigerian Navy ni.
Bakan naa lo tun jẹ apanilẹrin ati oṣere ori itage.
Ìjọba ìpínlẹ̀ kàn kéde ọ̀jọ ìsinmi ní ìrántí Zik, wo òhun tí wọ́n y'[o máa ṣe lọ́jọ́ ìbí rẹ̀
Àwọn ajínigbé pa èèyàn méjì l’Akure, ẹnìkan móríbọ́, ẹnìkan ṣì wà ní ìkáwọ́ wọn
Lóòtọ́ ni wọ́n de òkú táa gbé jáde nínú odò Asa, Ilorin lọ́wọ́ àti ẹnu - Ilééṣé ọlọ́pàá
'Ọ́lọ́run mo dúpẹ́ o pé wọn ò kà mí mọ́ ẹni tó ti wọlẹ̀ báyìí níbi afẹ́fẹ́ gáàsì tó búgbàmù'
Lekki EndSARS Report: Ọgá àgbà iléeṣẹ́ ológun Nàìjíría bẹnu atẹ́ lu bí wọn ṣé gbé èsì ìwádìí Endsars jáde
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ọga agba ileeṣẹ ọmọ ologun lorileede Naijiria,Ọgagun Lucky Irabor ti fesi lori ọrọ abajade igbimọ iwadii ENDSARS ti awọn kan ti lu sita.
O ni ilana ti wọn gba lati fi gbe esi yi jade ko boju mu ati pe ohun ko le ti sọrọ lori abajade yi nitori ijọba ko ti gbe jade sita.
Iwe abajade yi tawọn kan lu sita sori ayelujara sọ pe awọn ọmọ ogun Naijiria ṣeku pa awọn oluwọde lai nidi ni Lekki Toll Gate.
Sunday Igboho: Ìjọba Buhari ló ní ẹ̀bi, ẹ yé dá ẹ̀bi rú àwọn tó ń bèrè fún 'Yoruba Nation'
Lucky Irabor to n ba awọn akọroyin sọrọ lẹyin to ṣabẹwo si Gomina ipinlẹ Edo ni ilu Benin ni ''bi abajade yi jẹ ootọ bi ko jẹ, mi o le sọ''
''Mo mọ pe ilana to y ni pe ki wọn fi abajade yi sọwọ sawọn alaṣẹ ki wọsi gbe iwe mii jade lori rẹ ki a to wa le sọrọ nipa abajade yi''
O ni ''amọ ṣa mo fẹ fi to yin leti pe ileeṣẹ ọmọ ologun Naijiria jẹ ileeṣẹ akọṣẹmọṣẹ. A ko si ro pe o yẹ kawọn eeyan maa bẹnu atẹ lu ileeṣẹ ologun bayi''
Ẹwẹ ajọ ajafẹtọmniyan Amnesty International ti kesi ijọba Naijiria lati ri pe awọn to lọwọ ninu ipaniyan Lekki Toll Gate foju wina ofin.
Wọn fi ọrọ yi sita ninu atjadekan loju opo Facebook wọn ni idahun si abajade igbimọ iwadii lori ikọlu to waye ni Lekki logunjọ oṣu Kẹwa ọdun 2020.
Amnesty sọ pe awọn dunnu si abajade yi ti o ṣafihan ootọ nipa nkan to ṣẹlẹ ni Lekki ni itako ohun ti ijọba Naijiria sọ pe o ṣẹlẹ.
Titi di asiko taa n ṣe akojọpọ iroyin yi, ijọba apapọ Naijiria ko ti fesi si ọrọ yi.
EndSARS panel report: Rinu Oduala, adarí ìwọ́de EndSARS dúró lórí pé bí irọ́ àwọn ìjọba bá lọ lógún ọdún, òtítọ́ á lékè
Oríṣun àwòrán, other/savvyrinu/instagram
Iwe akọsilẹ abajade iwadii igbimọ lori aṣemaṣe awọn ọlọpaa ati iṣẹlẹ to waye ni Lekki Toll gate logunjọ oṣu kẹwaa ọdun 2020, to wa nigboro lori ayelujara, eleyi to n fa ọpọlọpọ awuyewuye bayii yats si eleyi to wa lọwọ ijọba ipinlẹ Eko.
Ọkan lara awọn ajafẹtọ to runpa runsẹ si iwọde naa lọdun 2020, Rinu Oduala lo sọ bẹẹ ninu ifọrọwerọ pẹlu BBC News Yoruba.
O ni lootọ ni ẹda kan jade sita lara abajade iwadii awọn igbimọ naa ṣugbọn ohun to wa ninu rẹ lee yatọ si ohun to wa ninu eyi ti wọn gbe kalẹ fun gomina ipinlẹ Eko.
Itunu Babalọla Death:Àgbáyé ẹ gbà mí, mọ fẹ́ ìdájọ́ òdodo lórí ikú ọmọ mí! ìyà yí tí pọ̀jù
O ṣalaye pe idi ni pe awọn oniruuru afikun ati ayọkuro lo lee ti waye laarin ẹda to lu sita ati eyi ti wọn fountẹ lu gbe le gomina lọwọ.
Arabinrin Rinu Oduala tun tẹsiwaju lati sọ pe ko ni ya awọn ajafẹtọ to lewaju iwọde EndSARS lọdun 2020 lẹnu bi abajade iwe ilana ijọba iyẹn 'White paper' lori abọ iwadii igbimọ naa ba yatọ si ohun to wa ninu ẹda iwe iwadii to lu sita.
"Ijọba ko ni so okun mọ ara rẹ lẹsẹ, Ekeji ni pe a ti gbọ nipa oriṣiriṣi igbimọ sẹyin bii igbimọ oputa atigbimọ oriṣiriṣi. Gbogbo awọn aba tawọn igbimọ yii n gbe jade, ṣe ijọba maa tẹle awọn aba naa? Pupọ ninu awọn ti orukọ wọn jade ninu ẹda to lu sita yii la ri pe inu ijọba ni wọn wa, ṣe ijọba yoo lee fi wọn jofin?'
O ni nitori pe ọpọ ọmọ Naijiria mọ irufẹ ijọba ti wọn ni pe lati ipilẹ ni wọn ti fẹ doju ọrọ ohun to ṣẹlẹ ru nipa pipariwo kiri agbaye pe ko si ikọlu kankan nibẹ ati pe ko si eeyan kankan to ku.
Rinu Oduala ni ohun to han si gbogbo eeyan kaakiri ni nitoripe gbogbo agbaye lo ri ohun to ṣẹlẹ ati bi awọn agbofinro ṣe huwa ipa si awọn araalu paapaa awọn ọdọ lorilẹede Naijiria lasiko naa.
Oríṣun àwòrán, lasg
Lori ọrọ aṣuwọn ifowopamọsi rẹ ti ijọba gbẹsẹ le nigba naa, arabinrin Rinu Oduala ṣalaye pe lẹyin oniruru ifigagbaga ofin laarin amofin agba Fẹmi Falana ati ijsba Naijiria, wọn ti gbe ẹsẹ kuro lori aṣunwọn ifowopamọsi naa.
O ni gbogbo ẹsun igbesunmọmi ati awọn ẹsun miran ti ijọba fi kan oun atawọn miran lasiko iwọde naa ni wọn ko lee fi idi rẹ mulẹ to si mu ki amofinagba Fẹmi Falana o fariga pe niwọn igba ti wọn ko ba ti le ṣe eyi ki wọn gbẹsẹ ati apa kuro lori awọn aṣuwọn naa lo tọ.
O ni wọn ti gbẹsẹ kuro lori ti toun, ṣugbọn wọn ṣi gbẹsẹ le awọn miran.
Bí mo ṣe káa sára tí mo gbé òkú ọmọ sínú ọkọ̀ lọ ṣe iṣẹ́ apanilẹ́rìín láì fihàn - Woli Agba Ayo Ajewole
Lori ọrọ awọn to n ja fun ipinya orilẹede Naiijiria ati idasilẹ orilẹ€de ẹya wọn, arabinrin Rinu ṣalaye pe bi idajọ ododo ko ba fidi mulẹ, ti awọn kan n ṣegbe ti wọn si n tẹ oju ofin mọlẹ, ko si bi awọn kan to ni ẹhonu ko ṣe ni pariwo sita pe ara n kan wọn ti wọn yoo si fẹ beere fun idaduro tiwọn.
O ni oun ti oun farams ni igbesẹ ti yoo fun awọn ọdọ ni ọjọ ọla to dara.
Davido: Davido ní Wema Bank ń pe òun fún ìpàdé nítorí ẹ̀dáwó N1milion tó pè sí àṣùwọ̀n wọn
Oríṣun àwòrán, davido/facebook
Gbajumọ akọrin takasufe, David Adeleke ti ọpọ mọ si Davido ti n da ori ayelujara ru lati Ọjọru to ti ke sawọn ọrẹ rẹ pe ki wọn da milọnu kọọkan naira fun oun ni ti ọjọ ibi oun to n bọ lọna.
Ere ati awada lọpọ eeyan pe ara ti 'ọmọ baba olowo' gbe sita yii, ṣugbọn ka to wi ka to fọ ni ojo owo ti bẹrẹ si ni rọ si aṣuwọn ifowopamọsi ti Davido fi sita fun awọn ọrẹ rẹ naa o.
Amọṣa ko pẹ pupọ ti ojo owo rọ ti okiki tun pe pe gbajums olorin naa ti sọrọ sita pe Banki Wema Bank to lo aṣuwọn ifowopamọsi wọn fun idawojọ naa n pe oun fun ipade.
Koda bi ikowojọ yii ṣe n gbona janjan naa ni ileefowopamọsi Wema Bank naa kanlu agbo rẹ tawọn pẹlu gbee sita pe, Na bank wey Davido dey use we go dey use now."" Eyi to tumọ si, banki ti Davido n lo lemi naa fẹ maa lo bayii."
Oríṣun àwòrán, davido/instagram
Gbajumọ olorin Takasufe Davido ti gbe ọna kan kalẹ lati da awọn ọrẹ rẹ tootọ mọ. O ni asiko to ti oun yoo mọ awọn gan to jẹ ọrẹ oun atawọn ti ọwọ epo laraye n bani la laarin wọn.
Ninu fidio kan to fi sita, ilumọọka akọrin takasufe naa ṣalaye pe ki ọkọọkan awọn ọrẹ oun o fun oun ni miliọnu kan naira gẹgẹ bi ara ọna lati mọ awọn to jẹ ọrẹ ootọ ninu wọn.
Davido ni oun fẹ ko awọn ọrẹ oun jọ sinu lati lee lọwọ ninu riran awọn eeyan lọwọ gẹgẹ bi oun pẹlu ti ṣe maa n ṣe lati ọjọ pipẹ wa.
Itunu Babalọla Death:Àgbáyé ẹ gbà mí, mọ fẹ́ ìdájọ́ òdodo lórí ikú ọmọ mí! ìyà yí tí pọ̀jù
Gbogbo ẹyin ọrẹ mi, miliọnu kan-kan naira!
Iroyin kaakiri awọn ileeṣẹ iroyin abẹle n sọ pe, bi a ṣe n sọrọ yii, iye owo to ti n wọ aṣuwọn akọrin naa ti kọja aadọrun miliọnu naira.
Lara awọn eekan to ti fifẹ han si OBO bayii ni Mr Eazi, Emoney, Raimi Lateef Abiola,Nengi ti Big Brother, dorathybachor,diamondplatnumz, focalistic lati south Africa, stanleyenow lati cameroun ati bẹẹlọ.
Awọn ikorodu bois naa fi ẹgbẹrun marun ranSẹ.
Oríṣun àwòrán, davido/facebook
Gbajumọ olorin naa ni miliọnu mẹwaa loun ti ri laarin isẹju meje.
O ni awọn to ba lee fun oun ni miliọnu kan naira lara awọn ọrẹ oun loun mọ ni ọrẹ tootọ
Davido ni ọgọrun miliọnu naira loun nilo ni ikowojọ naa.
Police vs Olokada: Kí ló fa rúgúdù láárín ọlọ́pàá àtàwọn ọlọ́kadà ní Obalende, l'Eko?
Gbẹgẹdẹ gbina lọsan Ọjọru nigba ti awọn ọlọpaa atawọn ọlọkada lagbegbe Ọbalende nilu Eko gbena woju ara wọn.
Gẹgẹbi ohun ti awọn o ṣoju mi kan sọ fun BBC News Yoruba, ni nnkan bii agogo mọkanla owurọ ọjọru lawọn ọlọpaa ikọ Taskforce nipinlẹ Eko ya wo agbegbe abẹbẹ afara to wa ni Ọbalaende tawọn ti ihamọra ogun eyi to ba ọpọ awọn eeyan to wa lagbegbe naa, yala ọlọja tabi awọn to n gba ibẹ lọ si ibikan lojiji ti kaluku si bẹrẹ si ni sa asala kaakiri lati yẹra fun iro ibọn ti wọn n gbọ lakọlakọ.
Lẹyin iṣẹju diẹ ni wọn ni o ṣẹṣẹ han si awọn eeyan pe awọn ọlọkada lawọn ọlọpaa naa wa ba.
Awọn kan lara awọn ọlọkada naa la gbọ pe wọn kọkọ doju ija kọ awọn ọlọpaa naa ki awọn ọlọpaa to le wọn wọ agbegbe ati sọkalẹ afara Ọbalende lọ si ọna Ikoyi ati Falọmọ.
Bi gbogbo eyi ṣe n lọ lawọn ọlọpaa naa n yinbọn kikankikan soke pẹlu tajutaju.
Nigba ti gbogbo girgiri naa yoo fi pari, ọpọlọpọ alupupu ọkada ni wọn ti ko ti akọroyin BBC News Yoruba si tun ri  ọkada kan ti wọn ti dana sun.
Nigba ti skan lara awọn agbero kan tọrs naa ṣoju rẹ ṣalaye ọrọ fun BBC News Yoruba, O ni arakunrin to ni ọkada naa lo funra rẹ dana sii nigba ti awọn ọlọpaa naa fẹ fi tipatikuuku gbe.
Arakunrin naa dana sii nitori pe o mọ pe bi wọn ba le gbe ọkada naa lọ, ko si bi oun ṣe fẹ rii gba mọ laelae lo fi kuku funrarẹ dana si
Akitiyan akọroyin BBC News Yoruba lati ba ẹni to lewaju ikọ naa sọrọ lo ja si pabo pẹlu bi awọn ọlọpaa naa ṣe pakuru mọọ ti wọn si ni awọn yoo luu ni alubami bi ko ba tete wabigba.
Badagry building collapse: Èèyàn mẹ́rin kú sábẹ́ ilé alájà kan tó dàwó ní Badagry
Oríṣun àwòrán, lagos fire and rescue service
Lẹyin ọsẹ meji ti ile alaja mọkanlelogun kan wo lagbegbe Ikoyi ni ipinlẹ Eko ti ẹmi ọpọlọpọ si baa lọ, ile miran tun ti da wo lagbegbe Badagry ni ipinlẹ kan naa.
Amọṣa o, ile alaja kan leyi, eeyan mẹrin ni wọn ti yọ labẹ rẹ.
Itunu Babalọla Death:Àgbáyé ẹ gbà mí, mọ fẹ́ ìdájọ́ òdodo lórí ikú ọmọ mí! ìyà yí tí pọ̀jù
Atẹjade kan ti oludari ileeṣẹ panapana ipinlẹ Eko, Margaret Adeṣẹyẹ  fi sita, ileeṣẹ naa gba ipe pe ile alaja kan naa da wo lagbegbe Sunny filled flour mills Estate ni Magbọn, Badagry.
Atẹjade naa ṣalaye pe awọn oṣiṣẹ ileeṣẹ panapana to wa ni Badagry ti doola ẹmi eeyan marun ni abẹ awoku ile naa ti wọn n kọ lọwọ. Bẹẹni akitiyan n lọ lọwọ lati yọ awọn to ṣi ha si abẹ ile naa.
Awọn oṣiṣẹ to n ṣiṣẹ ni ile naa ni iṣẹlẹ naa ba ti wọn si ti doola wọn pẹlu oniruuru ifarapa, pupọ wọn lo si ti n gbadun ni ileewosan.
A ṣi n mojuto iroyin yii lati mọ bo ṣe n lọ si.
Osun Hotel Murder: Ohun táa mọ̀ rèé nípa ikú akẹ́kọ̀ọ́ Fásitì OAU tó kú sí hòtẹ́ẹ̀lì Osun àti bí ọwọ́ ṣe tẹ olùdarí hòtẹ́ẹ̀lì
Oríṣun àwòrán, Facebook/Timothy Adegoke/Oduduwa University
Ileeṣẹ ọlọpaa ipinlẹ Osun ti kede pe awọn ti mu alaga ati oludasilẹ ile itura Hilton Hotel and Resort, Ile-Ife, Ramon Adegoke Atobatele Adedoyin.
Eyi ko si ṣẹyin iwadii ti wọn lawọn n ṣe lori iku akẹkọọ fasiti Obafemi Awolowo, OAU, Timothy Adegoke ti wọn ni o de si ile itura Hilton ko to ṣaadede poora.
Ninu atẹjade ti alukoro ọlọpaa Opalola Yemisi fi ṣọwọ si BBC, o ni ṣaaju ki awọn to mu Adedoyin, awọn ti mu eeyan mẹfa kan ti awọn fura si pe wọn mọ si iku akẹkọọ yii.
Ẹwẹ, BBC Yoruba ti kan si idile Timothy, a si ba iyawo, baba ati iya rẹ ni gbolohun nibi ti wọn ti ke gbajare pe: Wọ́n ti ń bèrè lọ́wọ́ abúrò ọkọ mi pé èlò ni wọ́n fẹ́ gbà, ẹ ṣàánú wa o! - Ìyàwó Timothy tó kú sí Hilton Hotel Osun figbe ta
Itunu Babalọla Death: Ìjọba Nàíjìríà fèsì sí ìbéèrè Baba Itunu Babalola lórí òkú ọmọ rẹ̀!
Itunu Babalọla Death:Àgbáyé ẹ gbà mí, mọ fẹ́ ìdájọ́ òdodo lórí ikú ọmọ mí! ìyà yí tí pọ̀jù
Timothy Adegoke la gbọ pe o de si ile itura Hilton lati Abuja lọjọ Kaarun oṣu Kọkanla ti o si fẹ sun sibẹ ki o baa le ribi kopa ninu idanwo ẹka ileẹkọ OAU ti yoo waye lọjọ keji.
Lọjọ Keje Oṣu Kọkanla ni wọn kede pe Adegoke ti di awati lẹyin ti iyawo ati awọn mọlẹbi rẹ ko gburo rẹ mọ.
Lẹyin tawọn mọlẹbi fẹjọ sun ni agọ ọlọpaa Edun Abon Police, wọn gbe ẹjọ naa lọ si ẹka to n ṣe iwadii iwa ọdaran iyẹn State Criminal Investigation Department lọjọ Kẹsan oṣu Kọkanla.
Oríṣun àwòrán, Facebook/Oduduwa University
Abalọ ababọ, ọlọpaa lawọn ri oku Adegoke ninu saare kan ti wọn sin in si ti wọn si ti gbe oku naa lọ fun ayẹwo lati mọ ohun to ṣeku pa.
Bakan naa wọn lawọn ti mu eeyan mẹfa kan tawọn fura si pe wọn lọwọ ninu iṣẹlẹ naa.
Ọlọpaa ni iwadii ṣi n tẹsiwaju ati pe awọn n fi ọrọ wa Ramon Adegoke Atobatele Adedoyin lẹnu lati mọ ohun to ṣẹlẹ gaan.
Ki lo le mu ki wọn ṣeku pa Adegoke ni ile itura to de si?
Ibeere yi lo gba ẹnu awọn eeyan to n fọkan ba ọrọ yi bọ lati igba to ti lu sita.
Onimọ iwe iṣiro ni Adegoke to si fi ilu Abuja ṣe ibujoko.Ẹekọọkan lo n de si ile itura Hilton nitori eto ẹkọ to n ṣe ni ẹka fasiti OAU to wa ni Moro.
Ninu nkan ti ẹgbọn rẹ kan sọ fun gbajugbaja akọroyin nilu Ibadan, Olayomi Hamzat ninu fọnran fidio, awọn oṣiṣẹ ile itura lo gbimọran pọ lati pa Adegoke.
Ọrọ yi ko ti ribi fidi mulẹ lati ọdọ awọn ọlọpaa.
Ni kete ti wọn ba gbe esi iwadii wọn jade, a o maa fi to yin leti
Kano Romance Scammer: Báyìí nì ọwọ́ ọlọ́pàá ṣé tẹ gbájúẹ̀ tó n fí ọ̀rọ̀ ifẹ́ gba fóònù lọ́wọ́ àwọn obìnrin
Oríṣun àwòrán, Nigeria Police
Ẹ tẹti bẹlẹjẹ lati gbadun iroyin yi.
Ọwọ ọlọpaa Kano ti ba arakunrin kan to n fi ọgbọn alumọkọrọyi ji foonu awọn eeyan.
Ko tan sibẹ, foonu awọn obinrin lo n ji gbe lẹyin to ba ti fi ẹtan ati jibiti kọrin ifẹ si wọn leti tan.
Gẹgẹ bi a ti ṣe gbọ, o kere tan obinrin mẹrin lo ti fi gbajuẹ gba foonu lọwọ wọn.
Lọjọ Kọkanla oṣu Kọkanla ni ọrọ yi deti igbọ awọn ọlọpaa lẹyin ti arabinrin kan ni ijọba ibilẹ Kano Municipal fẹjọ sun pe arakunrin kan t'orukọ rẹ n jẹ Muhammad ti ji foonu oun gbe.
O ni arakunrin naa parọ fun oun pe o nifẹ oun to si gba foonu tirẹ ati ti aburo rẹ pe oun yoo ra foonu tuntun mii fun wọn.
Itunu Babalọla Death:Àgbáyé ẹ gbà mí, mọ fẹ́ ìdájọ́ òdodo lórí ikú ọmọ mí! ìyà yí tí pọ̀jù
Bi foonu ti ṣe wa lọwọ rẹ lo ba sọ pe oun sọ kọkọrọ ọkọ nu.
Ibi ti wọn ti n wa kọkọrọ ọkọ to sọnu ni Muhammad ti poora bi iso.
Oríṣun àwòrán, Gallo Images
Ninu atẹjade ti ọlọpaa fi sita, wọn ni afurasi ẹni ọdun mejilelogun yi jẹwọ ẹṣẹ rẹ lẹyin ti ọwọ awọn tẹ.
O sọ fun wọn pe ogbologbo ninu ka fi ọrọ ẹtan ba obinrin sọrọ loun jẹ ati pe oun a si maa gba foonu lọwọ wọn.
Wọn lo tun sọ pe oun ti ribi gba foonu obinrin mẹrin.
Alukoro ọlọpaa Kano DSP Abdullahi Haruna Kiyawa sọ pe awọn fimu finlẹ daada ki ọwọ to tẹ afurasi naa.
O ṣalaye pe iwadii ṣi n tẹsiwaju tawọn ko si ni pẹ lati gbe lọ si ile ẹjọ.
Labẹ ofin Naijiria, bi wọn ba da lẹbi nile ẹjọ, o le ṣẹwọn ọdun meje.
"Alaafin of Oyo: Alaafin fún ọmọbìnrin rẹ̀ tó gbé ipó ""First Class"" jáde ní fásítì lẹ́bùn ọkọ̀ ayọ́kẹ́lẹ́"
Oríṣun àwòrán, other
Alaafin Oyo, Oba Lamidi Adeyemi ti fi ọkọ bọginni kan da ọmọbinrin rẹ, Zainab Adebunmi Adeyemi lọla lẹyin to gbe ipo kinni (First Class) jade ni fasiti Lead to wa niluu Ibadan.
Ninu ẹkọ imọ nipa ẹya ara eeyan ni Adebunmi ti kẹkọọ gboye fasiti akọkọ jade.
Alaafin fi ẹbùn ọkọ naa mọ riri iṣẹ takuntakun ti Adebunmi ṣe eleyii to fi pegede ninu ẹkọ rẹ.
Ọmọbabinrin Adebunmi bu si ẹkun ayọ ti o si fi ikunlẹ bẹ lati dupẹ lọwọ Ikubabayeye.
Iroyin sọ pe Eledumare fi ọpọlọ pipe jinki Adebunmi ninu ẹkọ to ti gboye jade ati ninu awọn ẹkọ miran.
Ọmọbabinrin Adebunmi dupẹ lọwọ Eledua fun ore ọfẹ to ni, bakan naa lo tun dupẹ lọwọ Alaafin ati Olori Ramat Adedayo Adeyemi fún ipa ribiribi ti wọn ko ninu igbe aye rẹ.
O ni bi wọn ṣe wo oun dagba pẹlu ọgbọn ati ìmọ  Ọlọrun wa lara awọn nkan to ran oun lọwọ lati tayọ lẹnu ẹkọ oun.
Itunu Babalọla Death:Àgbáyé ẹ gbà mí, mọ fẹ́ ìdájọ́ òdodo lórí ikú ọmọ mí! ìyà yí tí pọ̀jù
"Adebunmi ni ""awọn nkan ti wọn ti fi kọ mi lati ilẹ lo fun mi lagbara lati le kọju si iwe mi ju awọn ẹgbẹ mi lọ."
Ni aafin Oyo ni ayẹyẹ ẹbun ọkọ ti Alaafin fi ta Adebunmi ti waye.
Alaafin gan an ti lọ fun ayẹyẹ ikẹkọọ jade fasiti Lead tẹlẹ ni Ibadan ki o to wa fun ọmọbinrin rẹ ni ẹbun ọkọ.
Gernot Rohr: Ṣé lóòtọ́ ni ọ̀nà ti pin fún Gernot Rohr gẹ́gẹ́ bí akọ́nimọ̀ọ́gbá Super Eagles Nàìjíríà?
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Iroyin to n jade sori ayelujara bayii n sọ pe o ṣeeṣe ki ajọ ere bọọlu afẹsẹgba ni Naijiria, NFF ti yọ akọnimọọgba ikọ Super Eagles, Gernot Rohr kuro nipo.
Iroyin naa n sọ pe ajọ NFF ti gbe igbesẹ lori yiyọ ọ ni ipo lẹyin ti awọn esi ti ikọ Super Eagles tiraka rapala wọ ipele to kan lati kopa ni idije ife ẹyẹ agbaye Qatar 2022.
Amọṣa bi iroyin yii ṣe n jade lawọn iroyin miran tun n jade pe ko ri bẹẹ.
Koda awọn ileeṣẹ iroyin ere idaraya labẹle bii Sporting Sun ṣalaye pe agbẹnusọ fun ajọ NFF, Ademọla Olajire sọ fun ileeṣẹ iroyin naa pe ko si ohun to jọ ọ.
O fi kun un pe o di igba ti igbimọ to ga julọ lajọ NFF ba ṣe ipade ki wọn to lee gbe irufẹ igbesẹ bẹẹ lati gba iṣẹ lọwọ akọnimọọgba Gernot Rohr.
Amọṣa iroyin to n tẹ BBC News Yoruba lọwọ lasiko ti a fi n ko iroyin yii jọ n sọ pe ipade igbimọ naa  n lọ lọwọ. Sugbọn a ko lee sọ boya ọrọ nipa rirọ akọnimọọgba Super Eagles naa nipo ni wọn pe ipade yii le lori tabi boya o wa ninu awọn ọrọ ti wọn yoo jiroro le lori nibẹ.
Latifat Tijani: Ìjọba Naijiria ń ṣèlérí láti mọ́ rírì mi àmọ́ láti 2016, pàbó ló ń já sí
Kwam 1's new wife: Emmanuella Ropo di aya Kwam 1, bó ṣe lọ rèé
Oríṣun àwòrán, PM News Nigeria
Lẹyin ọdun mẹta ti gbajugbaja olorin Fuji, Wasiu Ayinde ti ọpọ mọ si Kwam 1 fẹ iyawo rẹ kekere, Titi Masha ni Ijebu-Ode, agogo igbeyawo tun ti dun laarin olorin naa ati ọmọ ẹlẹ kan, Emmanuella Ropo.
Lọjọru ọsẹ ni igbeyawo Kwam 1 waye niluu Abeokuta pẹlu apọnbeporẹ arẹwa obinrin, Aderopo Emmanuella ti gbogbo ilu mi titi.
Ropo jẹ ẹni to ti le ni Ogoji ọdun lọjọ ori nigba ti Wasiu Ayinde jẹ ẹni ọdun mẹrinlelọgọta to si ti ni ọmọ to le ni ogoji latọdọ ọpọlọpọ obinrin.
Wọ́n ti ń bèrè lọ́wọ́ abúrò ọkọ mi pé èlò ni wọ́n fẹ́ gbà, ẹ ṣàánú wa o! - Ìyàwó Timothy tó kú sí Hilton Hotel Osun figbe ta
Wọ́n lù mí bíi ẹní máa kú, wọ́n ya aṣọ mọ́ mi lọ́rùn nílé Princess kí n tó dé àgọ́ ọlọ́pàá - Baba Ijesha
Ìkúnlẹ̀ abiyamọ ò! Wo bí arábìnrin yìí ṣé bínú dá omi gbígbóná s'ará ọmọ ọ̀dọ̀ rẹ̀
Pásítọ̀ onísọjí tó fí ipá bá olóyún oṣù mẹ́jọ sùn ní Ondo, ohun tí a mọ̀ rèé
Amọṣa kii ṣe pe o fẹ gbogbo wọn sile.
Iyawo ti wọn mọ mọ Kwam 1 ju ni Yewande to n gbe ni Canada ti wọn si ni ọmọ marun papọ.
Taa ni arẹ̀wà obìnrin, Emmanuella Ropo tí ìròyìn n sọ pé òun ni ìyàwò K1 tuntun?
Kwam 1 dá àwọn tó ń wọ́ ọ tuurutu nílẹ̀ pé ó jẹ́ gbèsè dollar iṣẹ́ orin kan l'Amẹ́rika
Ṣé lóòtọ́ ni Alaafin Ọyọ ti fẹ́ olorì tuntun láti ẹ̀yà Igbo? Ẹ wo ǹkan tí a mọ̀ nípa rẹ̀
Itunu Babalọla Death: Ìjọba Nàíjìríà fèsì sí ìbéèrè Baba Itunu Babalola lórí òkú ọmọ rẹ̀!
Oríṣun àwòrán, Kwam1
Wasiu ko fi bo rara gẹgẹ bo ṣe maa n pe ara rẹ ni alaya pupọ eyi ti oloyinbo n pe ni Polygamist to si ni oun ko tii de ipo ti Fela Anikulapo gbajugbaja olorin to ti d'oloogbe to ni akọsilẹ iyawo mẹtadinlọgbọn.
"Oṣu to kọja ni iroyin brẹ si ni ta si awọn eeyan leti pe Kwam 1 tun ti fẹ ṣe iyawo pẹlu ẹlẹ tuntun yii. Koda o fi orin kan sori ayelujara ninu eyi to ti n pe e ni ""Ajike Okin ati Neulla Ajike Mi""."
Emmanuella naa fi ọrọ ifẹ rẹ sita nipa igbeyawo naa to n gbadura fun ẹmi gigun ninu ifẹ ati idunu fun oun ati Kwam 1.
Oríṣun àwòrán, EmMANUELLA Ropo/Instagram
Gbas-gbos ti ń wáyé ṣáájú ìdìbò sí ipò gómìnà Osun, kí ló ń ṣẹlẹ̀ láàrín Aregbesola, Oyetola?
Buhari ti sọ̀rọ̀ sókè lórí àbájáde ìwádìí EndSARS, ilẹ̀ Amẹ́ríkà sì ti fun lésì
Àwọn alamí ìjọba kan ti wà láàrín àwa ajìjàgbara Yoruba Nation tó ń bínú pé Sunday Igboho ti ga ju àwọn lọ - Akintoye
Ilééṣé ọlọ́pàá Osun tí mú Olùdarí ilé ìtura tí Akẹ́kòó fásìtì OAU ti dédé pòórá
Itunu Babalọla Death:Àgbáyé ẹ gbà mí, mọ fẹ́ ìdájọ́ òdodo lórí ikú ọmọ mí! ìyà yí tí pọ̀jù
EndSARS report: Buhari ti sọ̀rọ̀ sókè lórí àbájáde ìwádìí EndSARS, Ó ní ohun táwọn ìpínlẹ̀ bá mú bọ̀ lòun ń retí
Oríṣun àwòrán, Nigeria presidency
Aarẹ Buhari ni oun yoo duro de awọn esi to ba jade lawọn igbimọ oluwadii gbogbo ti awọn ijọba ipinlẹ kọọkan gbe kalẹ
Aarẹ Muhammadu Buhari ti sọrọ lori abajade iwadii EndSARS pẹlu idaniloju pe ijọba apapọ yoo faye silẹ lati tẹle awọn ilana gbogbo to yẹ.
O ni oun yoo duro de awọn esi to ba jade lawọn igbimọ oluwadii gbogbo ti awọn ijọba ipinlẹ kọọkan gbe kalẹ lati tanna wadii awọn iwa aṣemaṣe awọn ọlọpaa lorilẹede Naijiria.
Aarẹ Buhari sọ eleyi di mimọ nigba to n gba alejo akọwe fọrọ ilẹ okeere lorilẹede Amẹrika Antony Blinken nilu Abuja.
Itunu Babalọla Death: Ìjọba Nàíjìríà fèsì sí ìbéèrè Baba Itunu Babalola lórí òkú ọmọ rẹ̀!
Aarẹ ṣalaye pe ijọba apapọ ko lee fi aṣẹ tirẹ lelẹ lori awọn ọrọ naa nigba to jẹ pe awọn ipinlẹ ti gbe igbimọ kalẹ ti wọn si ti fun awọn igbimọ yii ni gbedeke ohun ti wọn yoo ṣe.
Ninu ọrọ tirẹ, akọwe ọrọ okeere nilẹ Amẹrika, Antony Blinken ni igbesẹ to loorin fun idagbasoke eto ijọba tiwantiwa; bẹẹ lo yannana rẹ pe ko si ibi ti iṣe ko si nitori pe orilẹede Amẹrika naa ni awọn iṣoro aṣemaṣe ọlọpaa.
O ni awọn n reti pe eto atunto to yanranti yoo waye lori rẹ.
Itunu Babalọla Death:Àgbáyé ẹ gbà mí, mọ fẹ́ ìdájọ́ òdodo lórí ikú ọmọ mí! ìyà yí tí pọ̀jù
EndSARS report: Àwọn ọmọ ẹgbẹ́ òṣèlú tó kéré jù lọ nílé asòfin sọ pé ìjọba àpapọ̀ ní ẹjọ́ láti jẹ lórí ìpànìyàn Lekki Tollgate
Oríṣun àwòrán, Channels TV
Agbarijọpọ awọn ọmọ ẹgbẹ́ oselu to kere julọ ni ile asoju-sofin Naijiria, sọ pe oun ti ṣe agbeyẹwo abajade iwadii ogbimọ ti ipinlẹ Eko gbe kalẹ lori ọrọ iwọde EndSARS.
Àwọn asofin naa sọ pe ijoba apapọ ni ẹkọ lati kọ.
Wọn sọ ninu atẹjade kan ti olori àwọn  ọmọ ẹgbẹ oselu to kere julọ nile asofin naa, Ndudi Elumelu fi ọwọ si, ti wọn si fi sita lọjọ Ọjọbọ, pe abajade iwadii naa fihan pe lóòótọ́ ni ipaniyan waye ni Lekki Tollgate ni ogunjọ, oṣù Kẹwàá, ọdun 2020, botilẹ jẹ pe awọn kan sọ pe irọ ni.
"Lẹyin ti a fi ara balẹ ṣe agbeyẹwo abajade iwadii ogbimọ ti ijọba ipinlẹ Eko gbé kalẹ lori ọrọ EndSARS, a ri pe igbiyanju ijọba apapọ lábẹ́ ẹgbẹ́ oselu All Progressives Congress, APC, lati bo bi wọn ṣe pa awọn ọdọ Naijiria ni Lekki Tollgate, jẹ ẹri pe ijọba ṣe atilẹyin fun diditẹ mọ awọn ọmọ Naijiria.
Wo bí ọkọ̀ tó gbé bẹntiróò ṣe gbiná n'Ibadan, ọkọ̀ méjì jóná ráùráú
Gbas-gbos ti ń wáyé ṣáájú ìdìbò sí ipò gómìnà Osun, kí ló ń ṣẹlẹ̀ láàrín Aregbesola, Oyetola?
Buhari ti sọ̀rọ̀ sókè lórí àbájáde ìwádìí EndSARS, ilẹ̀ Amẹ́ríkà sì ti fun lésì
Itunu Babalọla Death: Ìjọba Nàíjìríà fèsì sí ìbéèrè Baba Itunu Babalola lórí òkú ọmọ rẹ̀!
Bakan naa si ni ẹri to wa ninu abajade iwadii ọhun, to fihan pe awọn osisẹ alaabo to jẹ ti ìjọba, ko oku awọn ti wọn pa lọ, ti wọn si tun pa àwọn ẹri iṣẹlẹ naa rẹ, jẹ ẹrù wiwo lori ìjọba apapọ to ti kọkọ sọ pe ipaniyan naa ko waye."
"Yàtọ̀ si eyi, awọn asofin naa tun bu ẹnu ẹtẹ lu minisita eto iroyin ati àṣà, Lai Mohammed, fun bose sare sọ lori agbohunsafẹfẹ pe ipaniyan ko waye ni Lekki Tollgate, lai bikita fun awọn ẹlẹri iṣẹlẹ ibanujẹ naa.
Wọn ni o yẹ ki Lai Mohammed kọ̀wé fi ipo rẹ silẹ ni tabi ki Aarẹ Muhammadu Buhari daa duro, pẹlu ẹri tuntun to jade bayii.
Wọn tun rọ àwọn ìgbímọ to n ṣe iwadii ni awọn ipinle miran pe wọn ko gbọdọ bo iṣẹlẹ bẹẹ mọ́ra.
Ẹgbẹ ọmọ ẹgbẹ oṣelu to kere julọ nile aṣojusofin ni Naijiria sọ pe awọn ti ṣagbeyẹwo abajade iwadii lori endsars lEko tawọn ṣi ri pe ijọba apapọ ni ibeere lati dahun si.
Awọn aṣofin yi sọrọ naa ninu atẹjadekan ti olori ọmọ ẹgbẹ to kere julọ nile Ndudi Elumelu fi sita lỌjọbọ.
O ni esi yi fidi rẹ mulẹ pe lootọ ni iapniyan waye nibi ikọlu Lekki TollGate logunjọ oṣu Kẹwa ọdun 2020 yatọ si bi ijọba ṣe n jiyan pe ko sohun to jọ ọ.
''Awa ọmọ ẹgbẹ to kere julọ nile lẹyin agbeyẹwo fiudi rẹ mulẹ pe igbiyanju ijba APC lati fọwọ bo ipaniyan awọn ọdọ Naijiria lati ọwọ awọn ọmọ ogun fi han pe ijọba lọwọ si idunkoko mọ araalu to waye yi''
O tẹsiwaju pe ''Bi igbimọ yi ṣe fidi rẹ mulẹ pe lootọ ni ipaniyan waye ni Lekki Toll Gate ti awọn agbofinro si gbe oku salọ kuro nibi iṣẹlẹ yi ti wa di ẹbi ru ijba apapọ to ti ṣaaju jiyan pe ipaniyan ko waye''
Bakan naa ni ẹgbẹ awọn ọmọ ẹgbẹ to kere julọ yi tun bẹnu atẹ lu Minisita feto iroyin ati aṣa Lai Mohammed ''to sare sọ fawọn akọroyin ki igbimọ to gbe iwadii jade pe ko si ipaniyan to ṣẹlẹ ni Lekki toun ti pe ẹri to fi eleyi han pọ nilẹ''
Wọn ni o jẹ ohun iyalẹnu pe ijọba ti ẹ fẹ daṣọ bo nkan to ṣẹlẹ logunjọ oṣu Kẹwa ti wọn si ni dandan ki wọn ri pe idajọ ododo fidi mulẹ.
Wọn ba awọn mọlẹbi awọn to padanu ẹmi wọn ninu ikọlu yi kẹdun ti wọn si ni kawọn ọmọ Naijiria ma ṣe foya lasiko yi.
Itunu Babalọla Death:Àgbáyé ẹ gbà mí, mọ fẹ́ ìdájọ́ òdodo lórí ikú ọmọ mí! ìyà yí tí pọ̀jù
Ohun to wa nita bayi ni ẹda abajade igbimọ yi nitori ijọba kọ lofi sita, awọn kan lo tu abajde yi sita.
Ninu ilana to de gbigbe iru abajade yi kalẹ ni ki ihjọba kọkọ gba lọwọ igbimọ lẹyin igba naa ki wọn wa gbe iwe jade lori rẹ taa mọ si White Paper.
Eleyi ni ijọba ipinlẹ Eko ṣeleri lati ṣe nigba ti wọn gba abajade iwadii igbimọ lọwọ igbimọ naa lọsẹ yi.
Gomina Babajide Sanwo-Olu ipinlẹ Eko ti ni gbogbo araalu lawọn yoo jẹ ki o mọ nkan to wa ninu abajde igbimọ yi.
Osun Governorship Election: Ìró ìbọn dún lákọ-lákọ ní ìpàdé ìgún APC tó ń ṣàtìlẹyìn fún Rauf Aregbesola
Saaju idibo sipo gomina ni ipinlẹ Osun, awọn alatilẹyin fun minisita fun ọrọ abẹle lorilẹede Naijiria, Rauf Aregbesola ati awọn alatilẹyin fun gomina ipinlẹ Osun, Gboyega Oyetola ti koju oro si ara wọn.
Eyi ko ṣẹyin iṣẹlẹ to waye nibi ipade igun The Osun Progressives ti igun APC ni ipinlẹ Osun nibi ti awọn agbebọn ti ṣekọlu si ibẹ, ti wọn si n yinbọn lakọlakọ soke lasiko iṣẹlẹ naa.
Agbegbe Oranmiyan House, Gbongan Road ni ilu Osogbo ni iṣẹlẹ naa ti waye ni ọsan gangan.
Itunu Babalọla Death: Ìjọba Nàíjìríà fèsì sí ìbéèrè Baba Itunu Babalola lórí òkú ọmọ rẹ̀!
Lẹyin iṣẹlẹ naa ni awọn alatilẹyin fun Aregbeṣọla da ẹbi ru awọn alatilẹyin fun gomina ipinlẹ Osun, Gboyega Oyetola pe awọn lo wa ni idi ikọlu awọn agbebọn si ibi ipade awọn.
Awọn ti iṣẹlẹ naa soju wọn ni awọn ọlọja to wa ni agbegbe naa sare ti ile itaja wọn, ti olukaluku sa asala fun ẹmi wọn.
Oríṣun àwòrán, Others
Fidio to safihan iṣẹlẹ naa ni ọkọ dudu Sienna Sports Utility lo wa si ibi ipade naa ti awọn agbegbọn mẹta si bẹrẹ si ni yin ibọn lakọlakọ si gbogbo agbegbe naa, ti wọn si n rin wolu ibi ti wọn wa.
Awọn ọmọ ẹgbẹ naa sa asala fun ẹmi wọn amọ ọkan lara awọn ọmọ ẹgbẹ, Razaq ni wọn lo koju awọn agbebọn naa ti wọn fi sa wọ inu ọkọ wọn pada ti wọn si lọ.
Itunu Babalọla Death:Àgbáyé ẹ gbà mí, mọ fẹ́ ìdájọ́ òdodo lórí ikú ọmọ mí! ìyà yí tí pọ̀jù
Lẹyin iṣẹlẹ naa ni alaga ẹgbẹ The Osun Progressives, TOP, Lowo Adebiyi fẹsun kan gomina Adegboyega Oyetola ati awọn alatilẹyin rẹ ni igun Ileri Oluwa faction gẹgẹ bi awọn to wa ni idi iṣẹlẹ naa.
Amọ agbẹnusọ fun gomina Oyetola, Ismail Omipidan ni gomina Oyetola ko ni nkankan ṣe pẹlu iṣẹlẹ to waye naa.
Ibadan NTA Tanker explosion: Ọkọ̀ méjì jóná ráùráú níbi tí ọkọ̀ tó gbé bẹntiróò ti gbiná ní Ibadan
Ọkọ agbepo kan to kun dẹmu dẹmu ti yọ lori titi to si gbana ni olu ilu ipinlẹ Oyo lỌjọbọ,
Adugbo NTA lopopona Bus Stop ni ijamba ina yi ti ṣẹlẹ.
Ina to sọ latara ibugbamu epo inu ọkọ yi ṣokunfa bi ọkọ meji kan ti wọn wa lagbegbe naa ṣe jona raurau.
Ọga ileeṣẹ panpana nilu Ibadan Ismail Adeleke to fi ọrọ yi lede sọ pe ohun ati awọn oṣiṣẹ panapana ko fi ọrọ falẹ ti wọn si sare lọ sibẹ lati pa ina naa.
Gẹgẹ bi alaye to ṣe, o ni niṣe ni ina naa bẹrẹ lati inu ẹnjini ọkọ naa lasiko ti awakọ n wakọ lọ.
Ibẹrubojo to de ba pẹlu bo ti ṣe ri ina yi lo mu bẹ jade kuro ninu ọkọ.
Itunu Babalọla Death: Ìjọba Nàíjìríà fèsì sí ìbéèrè Baba Itunu Babalola lórí òkú ọmọ rẹ̀!
''Ọkọ naa yọ lori titi to si da epo inu rẹ silẹ.Bi epo ṣe n danu ni ina naa n tọ lẹyin.Ọkọ meji jona ninu iṣẹlẹ yi ṣugbọn ẹmi kankan ko bọ''
Kaakiri loju opo ayelujara lawọn eeyan n ṣe alabapin fọnran fidio ina yi lasiko to n jo.
Amọ ọga panapana tẹsiwaju pe nigba ti yoo fi di ago mọkanla awọn ti ribi pa ina naa tanyanyan.
Buhari ti sọ̀rọ̀ sókè lórí àbájáde ìwádìí EndSARS, ilẹ̀ Amẹ́ríkà sì ti fun lésì
Àwọn alamí ìjọba kan ti wà láàrín àwa ajìjàgbara Yoruba Nation tó ń bínú pé Sunday Igboho ti ga ju àwọn lọ - Akintoye
Itunu Babalọla Death:Àgbáyé ẹ gbà mí, mọ fẹ́ ìdájọ́ òdodo lórí ikú ọmọ mí! ìyà yí tí pọ̀jù
Child Violence: Ọgá ọmọ ọdọ tó fí ìbínú dá omi gbóná s'ará ọmọ ọdọ rẹ̀ kò sí pànpẹ ọlọ́pàá
Oríṣun àwòrán, FIDA Rivers State
Ileeṣẹ ọlọpaa nipinlẹ Rivers ti mu arabinrin kan lori ẹsun ifiyajẹ ọmọde kan to da omi gbigbona sii lara.
Arabirin Oluchi Chinedu Nkemjika la gbọ pe o da omi gbona sara ọmọ ọdọ rẹ ọmọ ọdun mẹsan lara.
Lọwọlọwọ bayii,ọmọdebinrin naa wa ni ile iwosan to ti n gba itọju lori apa ti omi gbona yi da si ẹyin ati ibadi rẹ.
'Mo fọ kọ́mú, pátá, ògiri ilé lórí 200,000 láìlèfọhùn lórílẹ̀èdè Oman'
Iroyin to tẹwa lọwọ tun sọ pe nitori ti ọmọọdọ yi lu ọmọ ọga rẹ ni o ṣe da omi gbona si ara rẹ.
Sam Chukwuejina to jẹ alabagbe arabinrin yi lo fi ọrọ yi to awọn ọlọpaa leti nigba to ri apa to wa lara ọmọ naa.
O ni odidi ọjọ mẹrin ni arabinrin yi ko fi ṣe nkankan nipa itọju ọmọde yi.
Chukwuejina to jẹ aarẹ ẹgbẹ araadugbo Paradise Avenue ni awọn lati gbogun ti obinrin naa ki o to jọwọ ọmọ naa ati ki awọn ọlọpaa to bẹrẹ iwadii.
Ileeṣẹ ọlọpaa ipinlẹ Rivers sọ pe ẹṣẹ nla leyi jẹ labẹ ofin to de ẹtọ awọn ọmọde.Eyi lo mu ki wọn gbe ẹjọ naa le ẹka iwadii iwa ọdaran lọwọ lati ṣewadii.
Kini ofin ẹtọ ọmọ sọ nipa iṣẹlẹ yi?
Oríṣun àwòrán, Adata Bio-Briggs, FIDA
A kan si arabinrin Adata Bio-Briggs to jẹ agbẹjọro labẹ ẹgbẹ agbẹjọro obinrin Naijiria FIDA.
Ninu alaye rẹ, o sọ pe awọm ko ṣẹṣẹ maa ri iru iṣẹlẹ bayi ti awọn ọgabinrin  ti maa n hu iwa ipa sawọn ọmọ ọdọ wọn.
O ni bi wọn ṣe n fi ebi pawọn ni wọn a maa lu wn koda ẹlomii a maa fi ata si oju ara awọn ọmọ ọdọ tabi ki wọn fi iron gbona jo wn lara tabi omi gbigbona.
Adata Bio-Briggs sọ pe ofin to n sọ awọn ọmọde lọwọ ijiya lo n mojuto iru iwa bayi.
Itunu Babalọla Death:Àgbáyé ẹ gbà mí, mọ fẹ́ ìdájọ́ òdodo lórí ikú ọmọ mí! ìyà yí tí pọ̀jù
O tẹsiwajupe labẹ ofin yi, ọmọde ti o jẹ ọmọ ọdun mẹsan tabi ti ko pe ọdun mejilelogun ko tọ lati ṣiṣẹ ọmọọdọ labẹ ẹni ti kii ṣe mọlẹbi rẹ.
Ifọmọṣowo ẹru lo sọ pe eleyi jẹ.
Labẹ ofin yi o ni ẹni ba fi iya jẹ ọmọde ti ọwọ ofin ba tẹ, yoo san owo itanran N500,000 tabi ko lọ si ẹwọn tabi ko si san owo ki si tun lọ sẹwọn pẹlu.
Lakotan o ni iṣoro tawọn ni pẹlu fifi ofin yi lelẹ ni pe ọpọ lo maa n fi ẹsẹ ile tọ ọrọ yi ti wọn o si nijẹ kode etigbọ awọn agbofinro.
Police Tok-tok pesin SP Nnamdi Omoni say even though di family of di 9 year old girl dey ask to withdraw di case, di matter now na State offence and dem go charge am go court even if both families settle.
Anthoy Bliken: Buhari gbàlejò akọ̀wé Amẹ́ríkà, ọ̀rọ̀ wọn lórí yíyọ Nàìjíríà kúro ninu akatakítí ẹ̀sìn
Oríṣun àwòrán, TOLANI ALLI
Ààrẹ Muhammadu Buhari ti ṣe àpèjúwe yíyọ Nàìjíríà kúrò lára àwọn orilede tí kò ní òmìnira ẹṣin tí orílẹ̀-èdè Amẹ́ríkà gẹ́gẹ́ bí nnkan tó dára fún ilosiwaju Naijiria.
O tun soro lori ijabọ àwọn ìgbìmọ̀ tó gbejọ ifiyajeni ọlọpaa Endsars to waye ni ìpínlẹ̀ eko èyí tí aje ibajẹ sì sí mọ àwọn ọmọ ológun àti ọlọ́pàá lórí fún ẹ̀sùn ipaniyan nipakupa.
Aare naa sọrọ nigba ti o gbalejo Akowe ilẹ AMẸRIKA, Anthony Blinken, ni ile ìjọba l'Abuja l'Ọjọbọ.
Lásìkò to ń dúpẹ́ lórí yiyọ Naijiria kuro ninu  awọn orilẹ-ede ti o lodi si ominira ẹsin,  Buhari ṣe akiyesi pe ominira ẹsin wa ni l'orilẹ-ede yìí ati pe “ko si ẹnikan ti a ṣe idẹyẹ si nítorí igbagbọ tàbí ẹṣin rẹ.
Oríṣun àwòrán, US Mission in Nigeria
Gege bi o se sọ, ẹkọ jẹ pataki ni orilẹ-ede tí Naijiria nitori nigbati a ba kọ awọn eniyan kan, awọn ipele kan wa ti wọn kii yoo ṣubu kọjá rẹ lai."""
Bakan naa ni aarẹ dupẹ lọwọ orilẹede Amẹrika fun gbigba orilẹ-ede Naijiria laaye lati ra awọn ohun elo ogun lati gbogun ti ìgbésùmọ̀mí ni orilẹ-ede yii, ati lati fi se nnkan ikẹkọ fun awọn ọmọ ogun Naijiria.
“O n ṣe iranlọwọ fun wa lati mu Àlãfíà jọba ní ìhà Ariwa-ila-oorun, ati pe a ti ni ilọsiwaju pupọ lati ọdun 2015.
“A n gbìyànjú pupọ lori aabo, ati pe awọn eniyan ti o kan mọ riri awọn akitiyan wa,” bí o ṣe sọ.
Oríṣun àwòrán, TOLANI ALLI
US secretary of state Anthony Bliken wit Nigeria Vice President Professor Yemi Osinbajo for di State House, Abuja
Washington  yọ Naijiria kuro ninu akojọ awọn orilẹ-ede ti o ni awọn ifiyesi ominira ẹṣin ní Ọjọ́rú,   ṣaaju ki Akowe ti ilẹ̀ Amẹrika Antony Blinken to wá sí orilẹ-ede gẹgẹ ètò irin-ajo tí ó pinu lati ṣe sì àwọn ilẹ̀ Afirika.
Blinken ṣe ìkéde yìí gẹ́gẹ́ bí wọn ṣe má ń ṣe lọdọọdún l'Ọjọro ti awọn orilẹ-ede ti o tún wa nibẹ tí jẹ́  Myanmar, China, Eritrea, Iran, North Korea, Pakistan, Russia, Saudi Arabia, Tajikistan ati Turkmenistan gẹgẹbi awọn orilẹ-ede ti o nílò amojuto pataki.
Bakan naa lo tún fi Algeria, Comoros, Cuba ati Nicaragua sinu atokọ yìí fun ailominira ẹsin, ati pe o yan awọn ẹgbẹ alakatakiti tí wọ́n sì tún pẹka kaakiri àwọn awọn ibòmíràn pẹlu, I èyí jẹ́ ọ̀kan pàtàkì tí a wò.
Oríṣun àwòrán, TOLANI ALLI
Osun Hotel Murder: Ìyàwó Timothy Adegoke bú sẹ́kún pé àwọn kan ti ń fi owó lọ abúrò ọkọ òhun lórí ẹjọ́ yìí
Oríṣun àwòrán, OTHERS
Ẹni to jẹ oludasile Hilton Hotel, Rahman Adedoyin to jẹ ilé ìtura ti ìròyìn sọ pé akẹ́kọ̀ọ́ Fáṣítì Obafemi Awolowo ti Ilé-Ifẹ̀, Timothy Adegoke kú si ti sọ̀rọ̀ pe oun ko mọ nkankan nipa iku rẹ rara.
Adedoyin to ti wa ni ahamo Ọlọpaa Ìpínlẹ̀ Osun bayii lori ẹ̀sùn ikú Adegoke to jẹ akẹ́kọ̀ọ́ imọ ipele Masters jẹ ko di mimọ pe oun ko padi àpò pọ mọ  awọn oṣiṣẹ oun tabi ẹnikẹ́ni lati pá akẹ́kọ̀ọ́ naa.
Gẹgẹ bo ṣe sọ, igba àkọ́kọ́ ti yoo gbọ́ nipa Adegoke ni igba ti awọn Ọlọpaa kede rẹ pe o di awati.
'Saaju ni iroyin ti sọ pe Adegoke lọ si ilu Ile-Ife lati lọ kọ idanwo kan ni Fasiti OAU ni nigba ti ikede rẹ jade pe o di awati lọjọ Keje oṣu Kọkanla nigba ti wọn gbọ pe wọn ko rii ninu kilaasi idanwo lọjọ Kẹfa ti iyawo rẹ  ati ẹbi ko si gburo rẹ lori foonu.
Wọn ri oku Adegoke lẹyin igba ti ọwọ Ọlọpaa tẹ awọn afurasi atawọn oṣiṣẹ ile itura naa. Igba to ya ni awọn Ọlọpaa kede pe wọn ti ri oku rẹ.
Iroyin taa tun gbọ ni pe Rahmon Adedoyin yii kan naa  ni oludari Fasiti Oduduwa.
"Nigba ti Adedoyin n sọrọ ẹwẹ, o sọ lede Yoruba wipe oun n ṣiṣẹ karakara fun owo ati ọrọ oun ni to si n rọ awọn eeyan pe ki wọn sọ oun ""lorukọ apaayan tabi afini ṣogun owo""."
Ninu ọ̀rọ̀ kika silẹ kan to tẹ awọn oniroyin lọwọ ti ọkan lara awọn amugbalẹgbẹ rẹ sọ pe lootọ ni ọrọ ni oludasilẹ ile itura ọhun n rawọ ẹbẹ si awọn araalu pe ki wọn duro de iwadii awọn Ọlọpaa.
O ni:
Emi Rahmon Adedoyin ko ki n ṣe apaniyan tabi afini ṣogun owo. Ọlọrun ti baba bukun mi na to ti fun mi lowo latigba ti mo wa lọmọ ọdun mẹ́rindinlọgbọn titi di isinsiyii ti mo ti pe ẹni ọdun marundinlaadọrin bayii.
"Adedoyin fi kun un pe oun ko paayan ri laye oun. ""Musulumi ododo ni mi. Adegoke gba yara nọmba 305 ni Hilton Hotel. Ile itura to fi orukọ rẹ sil ko kọkọ san owo ni orukọ rẹ sinu asunwọn owo ile itura""."
"Bakan naa lo ni ko si akọsilẹ pe o san owo si asunwo owo Banki WEMA. ""Mi o mọ bi wọ́n ṣe fun un ni yara lai san owo sinu asunwọn owo to jẹ ti ileeṣẹ gangan."
Bí ọmọbìnrin tí wọ́n parọ́ mọ́ pé ó gbé òògùn olóró tó sì wọ ẹ̀wọn ní Saudi ti dara pọ̀ mọ́ NDLEA
Freedom Park: Ẹ̀wọ̀n tí àwọn òyìnbò lọ fún ọdun 100 ní Naijiria rèé tí ọ̀pọ̀ ẹ̀mí lọ̀
"Igba ti awọn Ọlọpaa bẹrẹ si ni wa Timothy ni wọn ṣẹṣẹ sọ iru nkan bẹẹ fun mi.
Nigba ti awọn Ọlọpaa ṣewadii ti wọn ri oku Timothy nibi ti wọn ju oku rẹ si  ti awọn ọga Ọlọpaa yẹ gbogbo ara rẹ wo ti wọn rii pe ko si ẹya ara to sọnu lo wa ye wipe ko sẹni to ran wọn ki wọn yọ ẹya rẹ kankan."
O ni oun n rọ gbogbo eeyan pe ki wọn ni suuru ki wọn jẹ ki awọn ọlọpaa ṣe iṣẹ wọn.
O ṣalaye bo ṣe bẹrẹ kekeke ni Ile-Ife gẹgẹ bii olukọ to n kọ awọn ọmọ nile ko to wa lọ sile iwe giga awọn olukọni ati Fasiti.
Mi o figba kan kuro ni Ile-Ife ri ki Ọlọrun to bunkun fun mi to sọ mi di olowo. Ọrọ mi mọ. Mi o si na owo ẹjẹ.
Lẹyin ti ọwọ awọn agbofinro tẹ awọn afurasi to se iku pa arakurin Timothy Adegoke ni ile itura kan ni ilu Ile ife, awọn idile Adegoke ti kigbe sita pe awon afurasi ti n bere pe elo ni a fẹ gba.
Iroyin ti j ka mọ pe oludasile ile iwe giga fasiti Oduduwa University, Ọmọwe Ramon Adedoyin to si jẹ pe oun naa lo ni ile itura Hilton Hotel ti Timothy ku si.
Ilééṣé ọlọ́pàá Osun tí mú Olùdarí ilé ìtura tí Akẹ́kòó fásìtì OAU ti dédé pòórá
Ìkúnlẹ̀ abiyamọ ò! Wo bí arábìnrin yìí ṣé bínú dá omi gbígbóná s'ará ọmọ ọ̀dọ̀ rẹ̀
Pásítọ̀ onísọjí tó fí ipá bá olóyún oṣù mẹ́jọ sùn ní Ondo, ohun tí a mọ̀ rèé
Wọ́n lù mí bíi ẹní máa kú, wọ́n ya aṣọ mọ́ mi lọ́rùn nílé Princess kí n tó dé àgọ́ ọlọ́pàá - Baba Ijesha
Àwọn ọ̀dọ́ opó l'obìnrin sọ ìrírí wọn l'awùjọ
Iyawo oloogbe, Arabinrin Adegoke Bolatito Victoria, ninu ifọrọwerọ pẹlu ile iṣẹ́ BBC NEWS YORUBA lo fi ẹsun kan afurasi ti Ọlọpaa mu pe awọn kan lọ ba aburo ọkọ oun to maa n pe ni baba ọkọ ti wọn si n gbe igbese lati fun idile awọn ni owo ki wọn le yanju ọ̀rọ̀ naa lai pariwo sita. Amọ BBC Yoruba ko lee fidi eleyii mulẹ.
"Ninu itara o ni, ""wọn fi owo lọ baba ọkọ mi, ṣe owo le da ọkọ mi pada ni. Ẹyin ijoba ẹ ma wo wa niran, ẹyin ọmọ Naijiria ẹ dide iranlọwọ fun wa o!"""
Iyawo Timothy ni awọn o lẹlomiran mọ ni idile Adegoke tori Timothy ni gbogbo awọn gbe ọkan le.
Oun lo n bọ iya ati baba pẹlu awọn aburo rẹ. Ọmọ mẹta ni a bi fun ara wa, ṣe owo le da oro ti won da idile Adegoke duro? Lẹyin ti wọn pa ọkọ mi ni irinajo ti ko le wale mọ, ẹ gba mi ooo.
Lafikun, Arabinrin Adegoke Bolatito Victoria ni ọ̀rọ̀ naa kii ṣe titẹ oju ọmọ eniyan mọlẹ nikan ṣugbọn pẹlu fifi ọpọlọpọ ọmọ orilẹede si ewu to le mu ẹmi lọ gẹgẹ bi o ṣe mu ẹmi ọkọ rẹ, Arakunrin Timothy Adegoke lọ.
Pẹlu omije ati ibanuje ọkan ni awon obi Timothy Adegoke, Baba Moses ati Mama Bose Adegoke ni awọn n rawọ ẹbẹ si ijọba lati ma jẹ ki iku ọmọ wọn lọ lai si idajọ ododo.
Mama Bose Adegoke ninu ọ̀rọ̀ rẹ ni ọkanlawọn ọmọ ni ọmọ awon jẹ ki iṣẹlẹ yii to ṣẹlẹ, ti iku rẹ si da ọpọlọpọ irinajo ru nitori Timothy ni o n gbọ bukata awọn ati awọn aburo r to fi mọ iyawo ati ọmọ mẹta.
Oríṣun àwòrán, OTHERS
Àwọn alamí ìjọba kan ti wà láàrín àwa ajìjàgbara Yoruba Nation tó ń bínú pé Sunday Igboho ti ga ju àwọn lọ - Akintoye
Wọ́n yọ Nàìjíríà kúrò lára àwọn orílẹ̀èdè alákatakítí ẹ̀sì lágbàáyé, ọ̀pẹ́ Buhari sí Anthony Bliken rèé
Itunu Babalọla Death:Àgbáyé ẹ gbà mí, mọ fẹ́ ìdájọ́ òdodo lórí ikú ọmọ mí! ìyà yí tí pọ̀jù
Ààrẹ Buhari buwọ́lu N656 bílíọ́nù gbèsè owó ìrànlọ́wọ́ fún àwọn ìpínlẹ̀
Oríṣun àwòrán, NIGERIA PRESIDENCY
Ààrẹ Muhammadu Buhari ti buwọlu owo to le ni ẹgbẹ̀ta miliọnu Naira (656.112) gẹgẹ bi owo iranwọ fun àwọn ipinlẹ mẹrindinlogoji to wa ni Naijiria.
Níbi ipade ìbímọ to n sa mojuto ọrọ aje Naijiria ni Igbakeji Aare, Yemi Osinbajo, ti kede igbesẹ naa.
Agbẹnusọ fun Osinbajo, Laolu Akanbi, sọ ninu atẹjade kan pe owo to le ni biliọnu mejidinlogun Naira (18.225) ni ipinlẹ kọọkan yoo gba, ti wọn o si san gbese naa laarin ọgbọn ọdun pẹlu èlé ìdá mẹsan.
Ileesẹ aare sọ pe oun gbe igbesẹ naa lati ran awọn ìjọba ipinlẹ lọwọ ki wọn o le ri owo gbọ bukaata, paapaa fun gbese owo eto isuna ti wọn jẹ tẹlẹ.
Minisita eto inawo ati isuna, Ọmọwe Zainab Ahmed, sọ fun igbimọ naa pe banki apapọ Naijiria, CBN, ni yoo samojuto owo yiya naa.
Ẹẹmẹfa si ni awọn ipinlẹ yoo gba owo naa laarin oṣù mẹfa.
Buhari on Nnamdi Kanu: Buhari ní òun á gbé ìtúsílẹ̀ Nnamdi Kanu yẹ̀wò, ṣùgbọ́n yóò le díẹ̀
Oríṣun àwòrán, Nigeria presidency
Aarẹ Buhari ni nigba ti Nnamdi Kanu kọkọ sa mọ ofin lọwọ, a rii mu pada wale ni oun fi woo pe a dara ko koju ilana gbogbo to yẹ niwaju ile ẹjọ.
Aarẹ Buhari ti jẹ ko di mimọ pe o ṣeeṣe ki oun gbe ọrọ itusilẹ aṣiwaju ẹgbẹ ajijagbara ilẹ Igbo, IpoB, Nnamdi Kanu yẹwo.
Itusilẹ nnamdi Kanu, to wa ni ahamọ ijọba bayii lẹyin ti wọn fi ẹsun iditẹ gbajọba atawọn ẹsun nlanla miran kan, wa lara ẹbẹ ti awọn agbaagba ẹya Igbo to bẹ aarẹ wo nileeṣẹ aarẹ nilu Abuja gbe ka iwaju Aarẹ Muhammadu Buhari lasiko abẹwo wọn.
Amọṣa aarẹ ni ibeere wọn naa wuwo pupọ fun oun gẹgẹ bi aṣiwaju orilẹede Naijiria nitori atunbọtan rẹ le gidigidi nitori pe ohun ko tii figbakan ri da si ọrs awọn ẹka iṣedajọ lorilẹede Naijiria.
Ohun ti ẹ bere fun yii lagbara gan ni, ṣugbọn maa gbe e yẹwo.
Aarẹ Buhari ni nigba ti Nnamdi Kanu kọkọ sa mọ ofin lọwọ, a rii mu pada wale ni oun fi woo pe a dara ko koju ilana gbogbo to yẹ niwaju ile ẹjọ. Ki oun pẹlu lọ ro ẹjọ awijare rẹ niwaju ile ẹjọ.
Oríṣun àwòrán, Nigeria presidency
Ninu ọrọ tirẹ, alagba Mbazulike Amaechi ti ṣiwaju igbimọ awọn agbaagba ẹya Igbo naa ṣalaye pe yoo dara gidigidi lati lo ọna oṣelu dipo ọna ologun lati yanju ọrọ Ijọba apapọ ati Nnamdi Kanu.
Ninu ọrọ tirẹ, alagba Mbazulike Amaechi ti ṣiwaju igbimọ awọn agbaagba ẹya Igbo naa ṣalaye pe yoo dara gidigidi lati lo ọna oṣelu dipo ọna ologun lati yanju ọrọ Ijọba apapọ ati Nnamdi Kanu.
"O ni bi ijọba apapọ ba lee tu nnamdi Kanu silẹ 'ko ni sọ awọn nnkan to n sọ tẹlẹ mọ."""
Alagba Amaechi ni gẹgẹ bi agbalagba ti ọjọ ti lọ lori rẹ, ko wu oun lati fi ile aye silẹ laijẹ pe alaafia jọba lorilẹede abinibi oun.
Lara awsn miran to wa ni igbimọ naa ni gomina tẹlẹ ni ipinlẹ Anambra, Chukwuemeka Ezeife, Biṣọbu Sunday Onuoha ti ijọ eleto Methodist, Amofin Goddy Uwazurike, aarẹ ẹgbẹ ajafẹtọ Igbo nigbakanri, Aka Ikenga ati Tagbo Mbazulike Amaechi.
#EndSARS: Amẹrika ń fẹ́ ìdájọ́ òdodo lórí ìwàdìí ìṣẹ̀lẹ̀ ìwọ́de #EndSARS ní Lekki toll gate
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Orilẹede Amẹrika ti ni oun n reti esi ijọba apapọ ati ijọba ipinlẹ Eko lori abọ igbimọ to ṣe iwadii lori iwọde #EndSARS nibi tawọn eeyan ti sọ pe awọn ọlọpaa ati sọja pa awọn oluwọde ni Lekki toll gate niluu Eko ni ogunjọ oṣu kẹwaa ọdun 2020.
Igbimọ oluwadii ẹlẹni mẹjọ ti adajọ to ti fẹyinti, Doris Okuwobi, fi abọ iwadii rẹ ṣọwọ si ijọba nibi ti wọn ti fidi rẹ mulẹ pe awọn sọja ati ọlọpaa yinbọn pa awọn eeyan to n ṣe ifẹhonuhan wọọrọwọ ni Lekki toll gate.
Igbimọ naa sọ ninu abọ rẹ to fi sita pe o kere tan eeyan mẹsan an ni wọn ṣekupa nini iṣẹlẹ ọhun.
Àwọn ọ̀dọ́ opó l'obìnrin sọ ìrírí wọn l'awùjọ
Eeyan mejelaadọta ni igbimọ ọhun sọ pe wọn farapa ninu eyi ti mejilelogun fara gba ọta ibọn  nigba ti awọn sọja ati ọlọpaa ṣe ikọlu sawọn mẹẹdogun.
Victor Sunday Ibanga, Abuta Solomon, Jide, Olalekan Abideen Ashafa, Olamilekan Ajasa, Kolade Salami, Folorunsho Olabisi, Kenechukwu Ugoh, ati Nathaniel Solomon ni orukọ awọn ti wọn lo gbẹmi mi nibi iṣẹlẹ naa.
Igbimọ ọhun tun sọ pe Abiodun Adesanya, Ifeanyi Nicholas Eji, ati Tola ati Wisdom naa ṣagbako iku nibi iṣẹlẹ naa.
Amọ, akọwe ijọba orilẹede Amẹrika to n ri si ọrọ ile okeere, Anthony Blinken, sọ lasiko ipade rẹ pẹlu Aarẹ Muhammadu Buhari ilẹ Amẹrika n reti igbesẹ ijọba apapọ ati ti ipinlẹ Eko lori abajade igbimọ oluwadii to fi esi rẹ ṣọwọ si ijọba.
Blinken sọ fun Buhari pe ki ijọba gba ọrọ awọn ẹbi awọn eeyan to ku tabi farapa ninu iṣẹlẹ ọhun ro.
Lẹ́yìn Titi Masha, Kwam 1 gbé ìyàwó tuntun, Emmanuella Ropo l'Abeokuta, bó ṣe lọ rèé
Àwọn alamí ìjọba kan ti wà láàrín àwa ajìjàgbara Yoruba Nation tó ń bínú pé Sunday Igboho ti ga ju àwọn lọ - Akintoye
Itunu Babalọla Death: Ìjọba Nàíjìríà fèsì sí ìbéèrè Baba Itunu Babalola lórí òkú ọmọ rẹ̀!
Abọ iwadii naa tun fidi rẹ mulẹ pe eeyan mọkalelaadọta lo ku lapapọ lasiko iwọde EndSARS nipinlẹ Eko.
Igbimọ naa sọ pe ara oku awọn eeyan yi ni oku mọkandinlọgọrun ti wọn pin kaakiri ile iwosan niluu Eko.
Ṣugbọn agbẹjọro fun ijọba ipinlẹ Eko, Abiodun Owonikoko (SAN), ni kudiẹ kudiẹ wa ninu abọ igbimọ oluwadii to fi ṣọwọ si ijọba.
O ni kudiẹ kudiẹ bi ogoji lo wa ninu abọ igbimọ naa ati pe o lodi bi igbimọ ọhun ti jẹ ki abọ iwadii rẹ han sita si gbogbo eeyan.
Hirsutism: Wo ohun tí ojú obìnrin tó ní irun ní gbogbo ara ń rí torí ó dà bí ọkùnrin
Ara meeriri lo maa n jẹ ni ọpọ igba, tawọn obinrin maa n ni irun lara bii ti ọkunrin, tori awọn ọkunrin lo maa n saaba ni irun ni oju ati gbogbo ara.
Amọ arun kan wa ti wọn n pe orukọ rẹ ni  'Hirsutism' eyi to maa n mu ki eroja ara ọkunrin maa peleke lara obinrin.
Awọn eroja yii lo maa n mu irun ara ọkunrin jade lawọn agbegbe ti ọkunrin ti maa n ni irun lara bii aya, ẹsẹ ati ẹyin.
Iru arun yii gan an ni ọmọ ọdun mọkandinlogun, Nwaonicha-Emeghani Chidube, ọmọ orilẹede Naijiria ni.
"Chidbe ni ''ariyanjiyan kan waye laarin emi ati ọmọkunrin kan, lo ba pe mi ni ""Ọgbẹni""."
Àwọn ọ̀dọ́ opó l'obìnrin sọ ìrírí wọn l'awùjọ
O dun mi gan an, bi gbogbo eeyan ṣe n pe mi ni 'Ọgbẹni' niyẹn.
"Ṣugbọn mo padi ọrọ da fun un: mo ni bi o ba n pe mi ni ọkunrin, jẹ ka jọ ja bi ọkunrin nigba naa."""
Lara awọn ohun to n fa arun yii ni ohun tawọn onimọ iṣẹgun oyinbo n pe ni polycistic ovary Syndrom (PCOS), Cushing's syndrome,
Ati lawọn igba kọọkan, o le jẹ eewo jẹjẹrẹ ti a mọ si 'tumour.'
Nigba ti Chidube pe ọmọ ọdun mẹrindinlogun lo kọkọ bẹrẹ si nii ṣe akiyesi irun to n hu lawọn agọ ara rẹ kan.
O kọkọ ba ni lẹru gan, PCOS kii ṣe ohun ti o kan le ṣadeedee ni, ki o si foju foo.
"''Ọpọ igba ni mo maa n ro o pe ṣe mo maa le bimọ bayii?"""
Nigba wo ni maa dẹkun ati maa sanra tabi ga sii?
Koda nigba ti mo wa nileewe girama, mo maa n rii daju pe mo ge gbogbo irun mi lọsọọsẹ
Ọgbẹ abẹ a wa kun gbogbo ọrun mi, maami a wa maa sọ fun mi pe:
 Ma da ara rẹ laamu. Igba ti mo gbe aworan kan soju opo instagram ni mo to bẹrẹ si ni gba bi mo ṣe ri.
Ibẹrẹ ọdun yii niyẹn, ṣaaju, oju maa n ti mi lori rẹ ni.
Itunu Babalọla Death: Ìjọba Nàíjìríà fèsì sí ìbéèrè Baba Itunu Babalola lórí òkú ọmọ rẹ̀!
Ọpọlọpọ awọn ọmọbinrin ni wọn maa n kan si mi lati ọpọlọpọ awọn orilẹede lati sọ bi ti wọn ṣe ri.
Wọn a sọrọ nipa bi awọn ọkunrin ṣe n ja wọn silẹ nitori bi ara wọn ṣe ri, mo wa di ọlọrẹ pupọ.
Ọkan mi wa maa n balẹ ti mo ba ti wa n gbọ awọn ọrọ wọnyii, ti mo si tun n mọ awọn eeyan sii.
Emi nikan kọ ni o n ni idojukọ yii, awọn obinrin miran bẹẹ naa wa.
Awọn arẹwa obinrin to n la nnkan bayii kọja.
Emi nikan ni ọmọbinrin to ni irun lara laarin ọpọlọpọ eeyan.
Mo wa maa n ri ara mi gẹgẹ bi eeyan pataki nitori awọn eeyan n wo mi ni awoyanu.
Wọn a maa sọ pe ọmọbinrin yii ni irun lara.
O jẹ ohun to maa n mu mi wo ara mi gẹgẹ bi eniyan ọtọ, nibi kibi ti mo ba wa, awọn eeyan maa n mọ.
A gbọdọ gba ara wa gẹgẹ bi a ṣe ri gẹgẹ bi obinrin. Eeyan ọtọ ni wa.
Oniruuru ẹya, iwọn ati ipo ni a ba wa saye, eyi si lee jẹ ibukun fun wa,'' Chidube lo sọ bẹẹ.
Itunu Babalọla Death:Àgbáyé ẹ gbà mí, mọ fẹ́ ìdájọ́ òdodo lórí ikú ọmọ mí! ìyà yí tí pọ̀jù
Lateef and Mo’Bimpe: Adebimpe ní òun kò ní fi iṣẹ́ eré tíátà sílẹ̀ lẹ́yìn ìgbéyàwó òun pẹ̀lú Lateef Adedimeji
Oríṣun àwòrán, Instagram/adedimejilateef
Gbajugbaja oṣere ori itage, Adebimpe Oyebade naa ti sọrọ soke lori igbeyawo rẹ to n bọ lọna pẹlu akẹgbẹ rẹ, Lateef Adedimeji.
Lara awọn nkan ti Adebimpe sọ ni pe ko tii si ọrọ ọfẹ laarin awọn mejeeji nigba ti oun sọ pe Lateef kii ṣe ọrẹkunrin oun.
Ninu ifọrọwerọ to ṣe pẹlu iwe iroyin Punch, Adebimpe, sọ pe Lateef ko tii kọ ẹnu ifẹ si oun lasiko ti oun sọ ni gbangba pe kii ṣe ọrẹkunrun oun.
''Mi o ro pe o tọna lati maa sọ ọrọ aye mi lori ayelujara de bi ọrọ ọrẹkunrin mi.
Mi o nilko lati ṣe bẹẹ nitori n kii ṣe alafẹyẹyẹ obinrin to maa n gbe ọrọ aye ara rẹ kaakiri, gbogbo eeyan lo si mọ mi bẹẹ.
Iru eeyan ti mo jẹ niyẹn, mo sọ ninu ifọrọwerọ ti mo ṣe nigba naa pe ko si nkankan laarin emi ati Lateef.
Ti o dẹ ṣe ri nigba naa niyẹn, nitori Lateef kii ṣe ọrẹkunrin mi nigba naa,'' Adebimpe lo ṣalaye bẹẹ.
Oríṣun àwòrán, Instagram/adedimejilateef
Ìgbà akọkọ kọ niyii ti aworan igbeyawo ti jade nipa awọn mejeeji
Nigba to n sọ nipa ayẹyẹ igbeyawo wọn to n bọ lọna, Adebimpe ni kii ṣe igbeyawo idakọnkọ lawọn fẹ ṣe nitori awọn ti ọpọ ero to fi mọ awọn akọroyin pẹlu.
Bakan naa ni Mo'Bimpe sọ pe oun ko ṣetan lati fi iṣẹ oṣere silẹ nitori oun fẹ ṣe igbeyawo pẹlu akẹgbẹ oun.
O ni ikan ko di ekeji lọwọ, nitori naa igbeyawo ko le ṣe idiwọ fun iṣẹ tiata ti oun yan laayo.
Mo'Bimpe ni oun maa gbiyanju lati ri pe igbeyawo oun kẹsẹ jari, ati pe awọn yoo si jọ wa papọ fun igba pipẹ, bakan naa, oun ko ni dakẹ adura.
Davido ti kéde bí yóò ṣe ná ₦200m tó rí gbà fún ayẹyẹ ọjọ́ ìbí rẹ̀
Oríṣun àwòrán, davido
Olorin takasufe, David Adeleke, ti ọpọ awọn ololufẹ rẹ mọ si Davido ti kede pe oun yoo pin gbogbo owo to ri gba fun ayẹyẹ ọjọ ibi rẹ si ile awọn ọmọ alainiya kaakiri Naijiria.
Iye owo ti Davido ni oun yoo pin sawọn ile awọn ọmọ alainiya naa jẹ òjìlénígba lé mẹwaa miliọnu naira lapapọ.
Davido lo kede igbesẹ naa ninu atẹjade kan to fi sita loju opo Instagram rẹ lọjọ Abamẹta.
"Atẹjade naa ni ""Mo fẹ fi ẹmi imoore mi han si gbogbo awọn ọrẹ mi atawọn ololufẹ mi fun oun ti wọn ṣe lẹnu ọjọ mẹta yii."""
Bii ere, bi awada ni mo fi bere lọwọ awọn ololufẹ mi pe ki wọn da owo jọ fun ayẹyẹ ọjọ ibi mi ti yoo waye laipẹ, ṣugbọn iyalẹnu lo jẹ fun mi pe awọn eeyan fun mi ni igba miliọnu naira.
Lẹyin naa lo sọ pe oun yoo fi aadọta miliọnu naira kun igba miliọnu naira ti wọn da fun oun lati pin si awọn ile awọn ọmọ alainiya kaakiri Naijiria.
"O ni ""Inu mi maa n dun lati ṣoore fun awọn eeyan, idi ree ti inu mi ṣe dun lati kede pe gbogbo igba miliọnu naira ti mo ri gba ati aadọta miliọnu naira mii ti n o fi kun un yoo lọ sile awọn ọmọ alainiya."""
Àwọn ọ̀dọ́ opó l'obìnrin sọ ìrírí wọn l'awùjọ
Ọmọ baba olowo naa tun sọ pe oun ti gbe igbimọ kan dide ti yoo maa ri si bi wọn yoo ṣe pin owo ọhun.
Ti ẹ ko ba gbagbe, ọjọ kẹtadinlogun, oṣu Kọkanla ti a wa yii ni Davido ke si awọn ọrẹ rẹ lori ayelujara pe ki wọn da miliọnu kọọkan naira fun oun lati fi ṣe ayẹyẹ ọjọ ibi.
Ṣugbọn ka to wi, ka to fọ, awọn eeyan ti da owo to le ni ọgọrun un miliọnu naira jọ fun lati ṣe ayẹyẹ ọjọ ibi naa laarin wakati mẹrinlelogun.
Ọjọ kọkanlelogun, oṣu Kọkanla, ọdun 1992 ni wọn bi Davido.
Itunu Babalọla Death: Ìjọba Nàíjìríà fèsì sí ìbéèrè Baba Itunu Babalola lórí òkú ọmọ rẹ̀!
Okada ban: Iléeṣọẹ́ ọlapàá ìpínlẹ̀ Eko rún alùpùpù 482 jégé-jégé lẹ́yìn tí wọ́n gbẹ́sẹ̀le lọ́wọ́ àwọn ọlọ́kadà
Oríṣun àwòrán, ADEKUNLE AJISEBUTU
Ijọba ipinlẹ Eko ti run alupupu ti iye rẹ din diẹ ni ẹẹdẹgbẹta jege-jege lẹyin ti wọn gbẹsẹle awọn alupupu naa kaakiri ipinlẹ ọhun.
Awọn alupupu naa wa lara awọn ti wọn gba lọwọ awọn ọlọkada to tapa si ofin ijọba ipinlẹ naa pe oun ko fẹ ri awọn ọlọkada lawọn agbegbe kan.
Ninu atẹjade ti agbẹnusọ ileeṣẹ ọlọpaa ipinlẹ Eko, CSP Adekunle Ajisebutu fi lede lọjọ Abamẹta, o ni ileeṣẹ naa gba awọn alupupu ọhun kaakiri ipinlẹ naa.
Nigba to n sọrọ nibi ti wọn ti run awọn alupupu ọhun jege-jege ni ọọfisi ijọba to wa ni Alausa, kọmiṣọna ọlọpaa, Hakeem Odumosu sọ pe kii ṣe igba akọkọ ree ti awọn yoo run awọn alupupu ti wọn gbẹsẹle bẹẹ.
Odumosu ni wọn ti maa n run awọn ọkada jege-jege bẹẹ tẹlẹ, ṣugbọn awọn ni lati jẹ ki awọn araalu mọ ibi ti awọn alupupu ti awọn n gbẹsẹle n lọ lo jẹ ki wọn ṣe ni ojukaye.
Oríṣun àwòrán, ADEKUNLE AJISEBUTU
Kọmiọna naa ṣalaye pe ni ṣe ni awọn maa n run awọn alupupu naa tako ọrọ ti awọn eeyan kan n gbe kiri pe ni ṣe ni awọn maa n ta awọn alupupu ti wọn ba gbẹsẹle ni gbanjo.
Lẹyin naa lo kilọ fun awọn ọlọkada to n tapa si alakalẹ ijọba ipinlẹ Eko lori irinsi awọn ọlọkada lati so ewe agbejẹ mọwọ.
Àwọn ọ̀dọ́ opó l'obìnrin sọ ìrírí wọn l'awùjọ
O ni ki awọn to n ṣe ọkada lawọn ibi ti wọn ti fofin de lọ yi iwa wọn pada, bi bẹẹ kọ, wọn yoo foju wina ofin laipẹ.
Odumosu tun sọ siwaju si pe awọn yoo tẹsiwaju lati maa run awọn ọkada ti wọn ba gbẹsẹle jege-jege titi ti awọn to n tapa si ofin naa yoo fi yi iwa wọn pada.
Ti ẹ ko ba gbagbe, ọjọ kinni, oṣu Keji, ọdun 2020 ni ijọba ipinlẹ Eko gbẹsẹle ọkada lawọn agbegbe kan nitori eto abo ati oniruru ijamba to maa n waye awọn agbegbe ọhun.
Freedom Park: Ẹ̀wọ̀n tí àwọn òyìnbò lọ fún ọdun 100 ní Naijiria rèé tí ọ̀pọ̀ ẹ̀mí lọ̀
Jumoke Oyeleke: Wo ẹ̀bùn ńlá tí ìjọba fi ta ìyá tó pàdánù ọmọ rẹ̀ lásìkò ìwọ́de lọ́rẹ
Oríṣun àwòrán, Lagos State Government
Idunnu ti subu lu ayọ fun iya Jumoke Oyeleke, tii se ọmọbinrin to ku lasiko iwọde Yoruba Nation nilu Eko.
Gomina ipinlẹ Eko, Babajide Sanwo-Olu ti haaya ile oni yara meji ti wọn kọ si adugbo Ikorodu, eyi ti gbogbo ẹsọ inu ile wa ninu rẹ, fun obinrin naa, to si sanwo ile ọdun mẹta.
Bakan naa ni ijọba ipinlẹ Eko tun fi miliọnu kan naira ti ile naa nidi, to si ko wọn fun iya Jumoke Oyeleke.
Atẹjade kan ti akọwe iroyin si gomina ipinlẹ Eko, Gboyega Akosile fisita ni obinrin naa ati awọn ọmọ rẹ ni wọn n gbe ninu ile alapa kan to wa ni adugbo Ogudu nipinlẹ Eko tẹlẹ, ko to di pe ijọba dide iranwọ fun wọn.
Nigba to n ko kọkọrọ ile merẹnti naa le Arabinrin Ifeoluwa Oyeleke, tii se iya Jumoke lọwọ, amugbalẹgbẹ fun gomina ipinlẹ Eko, Titi Oshodi ni ijọba n feti leko lori ọrọ naa lati igba ti asita ibọn ti pa ọmọbinrin naa lasiko iwọde Yoruba Nation.
Oríṣun àwòrán, Lagos State Government
"Ilegbe tuntun ti wọn haaya fun awọn idile Jumoke to jalaisi lasiko iwọde Yoruba Nation ni a wa bayii, a ti de ile ti wọn n gbe tẹlẹ lati mọ ipo ọrọ aje arabinrin naa, ti aanu si se wa.
Nibayii, a wa ko kọkọrọ ile tuntun le obinrin naa ati ọmọ rẹ mẹta to ku lọwọ lati maa gbe ibẹ, gomina Sanwo-Olu si lo siju aanu yii wo wọn, bi o tilẹ jẹ pe ko seese mọ lati ji Jumoke pada saye.
Bakan naa ni gomina Sanwo-Olu tun ni ka fun wọn ni miliọnu kan naira, ko le mu adinku ba isoro ọrọ aje ti wọn n koju, ti wọn yoo si tun le bẹrẹ igbe aye ọtun."
Oshodi ni niwọn igba ti ẹnikẹni ko mọ tẹlẹ pe irufẹ isẹlẹ aburu yii le sẹlẹ, ni gomina Sanwo-Olu se tete seto fun idile naa tẹlẹ.
O ni gomina naa haya ilegbe fun wọn lati maa gbe nigba to n gbe igbesẹ akọtun fun wọn lọjọ iwaju, ki wọn le tẹsiwaju.
'Ẹ má jẹ́ kí òkú ọmọ mi ráre o ìjọba! Ẹ gbée fún mi kí n lọ sin ín - Ìyá ọmọ ti wọ́n pa ní ìwọ́de Yoruba Nation
Iya Jumoke ni yoo nira lati ri owo ile mii san lẹyin ọdun mẹta ti owo tijọba san ba jo tan:
Nigba to n fesi lori ọwọ ọrẹ ti ijọba Eko na si naa, Iya Jumoke tii se ọmọ ọdọ to n bawọn eeyan tun ile se, to si tun n tọju ayika ile dupẹ lọwọ ijọba Eko.
Iya ọlọmọ mẹta naa wa tun n fi omije rawọ ẹbẹ si gomina Babajide Sanwo-Olu lati se iranwọ fun ipese isẹ oojọ ti yoo pẹ titi, ko le rọrun fun oun lati tọju awọn ọmọ to ku.
"Ile ta n gbe tẹlẹ, a haya rẹ ni amọ wọn le wa kuro nigba ti wsn ta ile naa, ti n ko si ri owo gba ile miran.
Idi ree ta se n ls gbe ile ti wọn fi pako kọ fun odidi ọdun kan, ki Jumoke gan to ku, ọmọ ijọ wa kan si lo seranwọ fun wa lati maa gbe ibẹ.
Jumoke ni akọbi mi, mo wa n dupẹ lọwọ ijọba ipinlẹ Eko fun bi wọn se ranti emi ati awọn ọmọ mi. Wọn haya ile yii fun mi ni.
Amọ ko si bi mo se fẹ ri owo ile miran san lẹyin ọdun mẹta ti owo ile yii pa jo tan, mo fẹ ki wọn pese isẹ gidi fun mi, maa si maa se kata kara pẹlu miliọnu kan naira ti wọn fun mi yii"
Osun Hotel Murder: Iléeṣẹ́ ọlọ́pàá Osun kède ìgbésẹ̀ tó fẹ́ gbé láti fi ojú àṣebi hàn
Oríṣun àwòrán, OmoluabiTv
Ileeṣẹ ọlọpaa ipinlẹ Osun ti sọrọ lori ibi ti wọn ba iwadii wọn de lori iku to pa ọgbẹni Timothy Adegoke nile itura kan to wa niluu Ile Ife.
Agbẹnusọ ileeṣẹ naa, Yemisi Opalola sọ fun BBC Yoruba pe awọn ti bẹrẹ ayẹwo oku naa (Pathology), awọn yoo si fi abajade iwadii awọn sita laipẹ.
Opalola lo fidi ọrọ naa mulẹ ni idahun si ibeere ti awọn araalu n beere lori ibi ti wọn ba iṣẹ naa de.
Gẹgẹ bii ohun to sọ, ileeṣẹ ọlọpaa ti lọ wu oku ọkunrin naa nibi ti wọn sin si, awọn onimọ ijinlẹ si ti mu lara ẹya ara lọ sinu laabu fun iwadii to peye, eyi ti yoo tu iṣu de isalẹ ikoko irufẹ iku to pa.
"O ni ""Lẹyin to ku ti wọn si gbe oku rẹ sinu igbo kan ni Ile Ife, a gbera, a si gbe awọn to mọ nipa imọ ijinlẹ bi wọn ṣe maa n ṣe ayẹwo oku lati mọ irufẹ iku to pa oloogbe naa dani, to fi mọ awọn mọlẹbi rẹ."""
Àwọn ọ̀dọ́ opó l'obìnrin sọ ìrírí wọn l'awùjọ
A n duro de esi ayẹwo patọlọji naa lati mọ igbesẹ ti yoo kan fun wa lori ọrọ ọhun.
Alukoro ọlọpaa naa sọ siwaju si pe ko si ootọ ninu ọrọ ti awọn eeyan n gbe kiri pe awọn to da ẹmi arakunrin naa legbodo ge ẹya ara rẹ kankan lọ.
"O ni ""Awọn kan n sọ pe wọn ge apa tabi wọn ge ẹsẹ rẹ, ṣugbọn irọ ni o."""
Awọn ẹbi oloogbe wa nibẹ nigba ti a ṣe ayẹwo lẹyin ti a wu oku rẹ, gbogbo ohun to wa lara rẹ lo pe, ti awọn ẹbi rẹ si foju wọn ri, a ko mọ ibi ti awọn eeyan ti ri irufẹ awọn iroyin bẹẹ o.
Itunu Babalọla Death: Ìjọba Nàíjìríà fèsì sí ìbéèrè Baba Itunu Babalola lórí òkú ọmọ rẹ̀!
Opalola sọ pe kii ṣe ọrọ ti awọn araalu ba n sọ ni yoo tete jẹ ki ileeṣẹ ọlọpaa tete ri ojutu ohun to ṣokunfa iṣẹlẹ naa.
Lori awọn ti ọwọ ti tẹ lori iṣẹlẹ ọhun, Opalola ni eeyan meje lo wa ni ahamọ awọn bayii.
Awọn eeyan naa ni awọn oṣiṣẹ mẹfa lati ile itura ti igbagbọ wa pe iku rẹ ti waye, to fi mọ oludasilẹ ileeṣẹ naa, Ramon Adedoyin.
Ẹwẹ, ẹgbẹ awọn akẹkọọjade fasiti Oduduwa ti ẹni to ni ile itura ti Adegoke ti ku da silẹ, OOU, ti ke si ileeṣẹ ọlọpaa lati ṣe iwadii kikun lori iṣẹlẹ naa, ki wọn si fi oju gbogbo awọn to lọwọ ninu iku oloogbe naa lede.
"Ninu atẹjade kan ti wọn fi ṣọwọ si awọn akọroyin lọjọ Abamẹta ti wọn pe akọle rẹ ni ""Ile itura Hilton kii ṣe fasiti Oduduwa,"" ni wọn ti kede ọrọ naa."
Atẹjade ọhun ti Aarẹ ẹgbẹ naa, Olatunji Olayinka buwọlu sọ pe ile itura Hilton ni iṣẹlẹ naa ti waye, kii ṣe fasiti Oduduwa, nitori naa ki awọn araalu dẹkun ati maa so iṣẹlẹ ọhun pọ mọ fasiti Oduduwa.
Itunu Babalọla Death:Àgbáyé ẹ gbà mí, mọ fẹ́ ìdájọ́ òdodo lórí ikú ọmọ mí! ìyà yí tí pọ̀jù
ILana Omo Oodua: Ẹgbẹ́ IOO jáwé gbélé ẹ fún Otunba Olukoya, fòǹtẹ̀ lu Adeleye àti Akinwande
Oríṣun àwòrán, other
Ẹgbẹ Ilana Omo Oodua to n beere fun idasilẹ orilẹede iran Yoruba ti salaye nipa awọn ohun to fa awuyewuye to n waye ninu ẹgbẹ naa.
Ninu atẹ́jade kan ti ẹgbẹ naa fi sọwọ si BBC Yoruba, o ni oun ti ja ewe gbele ẹ fun Otunba Folasade Olukoya, tii se ọkan lara awọn asoju rẹ ninu ẹgbẹ ajijagbara fun iyapa Naijiria lapapọ, NINAS.
Bakan naa ni ẹgbẹ ọhun tun ṣalaye ninu atẹjade naa pe, Ọgbẹni Maxwell Adeleye ati Dokita Kayode Akinwande yoo si maa tẹsiwaju pẹlu ipo wọn lati ṣoju Ilana Omo Oodua ninu ẹgbẹ NINAS.
Ọjọgbọn Banji Akintoye to jẹ aarẹ Ilana Omo Oodua ni alaga ẹgbẹ NINAS ni Naijiria.
Ṣaaju ni Ọgbẹni Tony Nnadi, Esq to jẹ akọwe ẹgbẹ ajijagbara LNC (Lower Niger Congress) sọ pe Ọgbẹni Adeleye ko si lara awọn aṣoju ẹgbẹ Ilana Omo Oodua ni NINAS mọ.
Sunday Igboho: Ìjọba Buhari ló ní ẹ̀bi, ẹ yé dá ẹ̀bi rú àwọn tó ń bèrè fún 'Yoruba Nation'
Ṣugbọn ẹgbẹ naa daa pada pe ko si ohun to jọ bẹẹ, ati pe awada kẹri kẹri ni ọrọ naa.
Wọn Ọgbẹni Adeleye si ni agbẹnusọ Ọjọgbọn Akintoye ati fun ẹgbẹ Ilana Omo Oodua.
Amọ, ẹgbẹ IOU ṣalaye ninu atẹjade ti wọn sita pe Otunba Olukoya kii ṣe aṣoju awọn mọ ninu ẹgbẹ NINAS nitori o ti fi ẹgbẹ naa silẹ.
Wọn rọ awọn ẹgbẹ ajijagbara mii lati mọ bayii pe Otunba Olukoya kii ṣe aṣoju ẹgbẹ OOU mọ.
''A n fi akoko yii sọ fawọn eeyan pe Ọgbẹ Nnadi ko le maa la le wa lọwọ ninu ẹgbẹ IOU.
A rọ Ọgbẹni Nnadi lati gbaju mọ ohun ti o ka an, ki o ye sọrọ gẹgẹ bi alatako iran Yoruba.
Akojọpọ ẹgbẹ ajijagbara fun orilẹede tuntun ni ẹgbẹ NINAS jẹ, kii ṣe Nnadi lo ni ẹgbẹ naa.
Lakotan, a fi ọntẹ lu Ọgbẹni Adeleye ati Dokita Akinwande gẹgẹ bi aṣoju wa nitori wọn fihan pe ọmọ Yoruba atata ni wọn jẹ.
A o maa kede ẹni ti yoo rọpa Olukoya gẹgẹ bi ọkan lara aṣoju mẹta ti a ni ninu ẹgbẹ NINAS,'' ẹgbẹ IOU lo ṣalaye bẹẹ.
Ogun ọmọ ẹgbẹ IOU to fi mọ Ọjọgbọn Akintoye gan an lo buwọlu atẹjade naa.
Wo òkè ìṣẹ̀mbáyé Abanijorin yìí l'Ekiti tó máa ń bá ọ̀kọ̀ rìn lójú pópó tó tún ní ilé ìwòran orí ìtàgé nínú rẹ̀
Daddy Freeze: Ọmọ Oyedepo gbọdọ̀ ṣàlàyé ìdí tó fi ri bíbélì 15 mọ́lẹ̀ nínú ṣọ́ọ̀ṣì Winners l'Amerika
Oríṣun àwòrán, Daddy Freeze
Sọrọsọrọ ori redio ati ayelujara, Ifedayo Olarinde, ti ọpọ mọ si  Daddy Freeze, tun ti sọrọ tako ijọ Living Faith Church, Winners ti o jẹ ijọ Biṣọọbu David Oyedepo.
Amọ, kii ṣe Biṣọọbu Oyedepo ni Daddy Freeze n ba wi lọtẹ yii, ọmọkunrin rẹ, Pasitọ Isaac Oyedepo to jẹ pasitọ ijọ Winners to wa ni Maryland l'Amẹrika, lo n baa wi.
Daddy Freeze sọrọ yii lẹyin ti Pasitọ Isaac Oyedepo naa sọ ninu iwaasu rẹ kan to wa lori ayelujara pe, ijọ naa ri bibeli mọlẹ si òpó igun ile mẹẹdogun to gbe sọọsi wọn ni Amẹrika duro, gẹgẹ bi opo ti ijọ naa duro le lori bii ọrọ Ọlọrun.
Pasitọ Isaac sọ pe akori iwaasu rẹ fun oṣu yii lo da lori bi bibeli tii ṣe ọrọ Ọlọrun ṣe jẹ opomulero awọn kristẹni.
O sọ ninu iwaasu naa pe ibi gbogbo ti opo wa ninu gbọngan ṣọọṣi to wa ni Maryland ni awọn yọ kuro ti awọn si fi bibeli rọpo wọn.
Adejare Adeboye: Olúwa yóò dá gbogbo ohun ta sọnù ní 2020 padà ní ilọ́po méje fún wa
Amọ, Daddy Freeze tu itọ soke, o si fi oju gbaa lori ọrọ naa, o ni ko tọna rara.
Daddy Freeze ni ọrọ dabi ẹni ti ebi n pa ti o wa n fi gaari ra ara, dipo ki o mu un.
Daddy Freeze tun sọ pe ohun ti ọmọ Biṣọọbu Oyedepo sọ dabi ẹni ti ebi n pa ti o wa n fi elubọ pa ara rẹ.
Sọrọsọrọ naa ṣalaye pe, inu ọpọlọ oun, ni oun ri bibeli mọ kii ṣe inu ilẹ nitori o lodi si ọrọ Ọlọrun.
O ni kika ni bibeli wa fun, ko wa fun riri mọlẹ ninu ṣọọṣi.
''Idi gan an niyii ti mo fi kepe pasitọ Isaac lati wa ṣalaye oun to ri, ti wọn fi ri bibeli mọlẹ ninu ṣọọṣi.
Nitori ohun to sọ yii tako ohun ti emi mọ nipa ọrọ Ọlọrun,'' Daddy Freeze lo sọ bẹẹ.
Odu ni Daddy Freeze nipa titako awọn ojiṣẹ Ọlọrun, kii ṣe aimọ fun oloko.
Koda o ti figba kan tabuku oludasilẹ ijọ Winners gan an, Biṣọọbu Oyedepo fun ra ri.
Timothy Adegoke: Aya onílé ìtura sàlàyé ipò tí ọkọ rẹ̀ wà lórí ẹ̀sùn ìṣekúpani
Oríṣun àwòrán, Ramon Adedoyin/Facebook
Yoruba ni ọrọ okeere, bi ko ba din ọkan, yoo le ọkan ni.
Oniruuru iroyin si lo ti n jade sori ayelujara nipa iku akẹkọọ kan, Timothy Adegoke, to ku sile itura Hilton to wa nilu Ile Ife.
Koda, awọn ọlọpaa ti ko awọn afurasi kan si ahamọ lori isẹlẹ naa, to fi mọ ẹni to ni ile itura naa, Ọmọọba Rahmon Adedoyin.
Ọna lati tan imọlẹ sawọn ahesọ ọrọ naa lo mu ki iyawo Adedoyin kigbe sita lati sẹ ọpọ awọn iroyin ti ko fi ẹsẹ mulẹ, to n jade lori isẹlẹ naa.
Bakan naa lo sọrọ lori awọn ẹsun ti ko fifi eniyan se etutu ọla eyi ti wọn n fi kan ọkọ rẹ lori ayelujara, eyi to ni ko ri bẹẹ.
Nigba to n ba iwe iroyin Premium Times sọrọ, aya Adedoyin ni ọmọ Naijiria rere ni ọkọ oun, bẹẹ ni kii lọwọ ninu isẹ ibi rara.
'Ẹ yé tan ara yín, èmi mo ni aṣọ 100 yard tó jábọ́ lát'ọ̀run táwọn ará Ondo ń ya mọ́ ara wọn lọ́wọ́'
"Ọkọ mi ko mọ ohunkohun nipa isẹlẹ isekupani naa, lootọ ni ọkunrin naa ku sile wa, ti awọn ọlọpaa si ti bẹrẹ iwadii nipa rẹ.
Ọpọ eeyan lo n kigbe kiri pe ọkọ mi ti salọ, eyi ko ri bẹẹ rara, ọkọ mi ko sa lọ sibikibi, awọn ohun to n sẹlẹ yii wa lati dan igbagbọ wa wo lasan ni.
Ohun gbogbo to pamọ, kedere lo han si Ọlọrun ọba amọ mo kọkọ daro pẹlu awọn mọlẹbi oloogbe, mo si mọ pe ọpọ awọn to n tan ayederu iroyin naa ka ni iku alaisi ka lara.
Amọ ju gbogbo rẹ lọ, mo n ba awọn idile ti isẹlẹ naa sẹlẹ si kẹdun iku eeyan wọn to lọ, paapaa iyawo oloogbe."
Bẹẹ ba gbagbe, Timothy Adegoke lo jẹ akẹkọọ to n gboye-koye ni fasiti Obafemi Awolowo nilu Ile Ife, to si duro sile itura Hilton fun idanwo to fẹ se ni Ife.
Amọ se ni ọkunrin naa di awati, ti wọn si ri oku rẹ lẹyin o rẹyin nibi ti wọn sin si lẹba ile itura ọhun.
"'Wọ́n gba irun abẹ́ wa, irun abíyá wa, a lọ búra, ilé ""Nylon"" la tún ń gbé ni Mali fi ṣe iṣẹ́ aṣẹ́wó'"
Ọlọ́pàá dóòlà òṣìṣẹ́ iléèṣẹ́ 'Pure Water' méje tí ajínigbé gbé sálọ ní Kwara
Oríṣun àwòrán, AFP
Ìgbà àkọ́kọ́ kọ́ nìyí tí irú ìṣẹ̀lẹ̀ bẹ̀ yòó wáyé
Ileeṣẹ ọlọpaa nipinlẹ Kwara ti doola eeyan meje to jẹ oṣiṣẹ ileeṣẹ kan to n ṣe omi inu ọra 'Pure water' lọwọ ajinigbe.
Ọjọ Ẹti ni iroyin sọ pe awọn agbebọn kan yawọ ileeṣẹ Lafrcdeen Pure Water to wa ni abule Sosoki, ti wọn si ji oṣiṣẹ meje ati ẹni to ni ileeṣẹ naa gbe lọ…
Agbẹnusọ ọlọpaa nipinlẹ Kwara, Ajayi Okasanmi sọ ninu atẹjade kan pe oṣiṣẹ kan pere ni ori ko yọ ninu ikọlu naa.
Yatọ si awọn eeyan yii, awọn agbekan naa tun ju ọkunrin agbẹ kan, Olulaja Adegboja, ẹni ọdun mẹrindinlọgọta gbe, lasiko to n bọ lati oko rẹ ni Olla.
Okasanmi sọ pe gende ọkunrin mẹfa to ni nkan ija oloro lọwọ lo gbe ọkunrin na, ti wọn si gbe wọ inu igbo.
"O ni ""ni kete ti iroyin naa jade, ni kọmisanna ọlọpaa nipinlẹ naa, CP Tuesday Assayomo, ko awọn ọlọpaa kogberegbe sita, ti wọn si ri awọn eeyan naa gba pada pẹlu ajọṣepọ awọn ọlọdẹ ati fijilante."
Akitiyan wọn lo yọri si didoola meje lara awọn oṣiṣẹ ileeṣẹ Pure Water naa, ti wọn si n gbiyanju lati doola awọn to ku si ahamọ ajinigbe.
EndSARS Victims: Ìyá méjì nínú mẹ́ta ti kú nínú àwọn ọmọ tí ọlọ́pàá gbé torí ìwọ́de
Ni ọdun 2020 to kọja ni iwọde EndSARS waye jake jado orilẹede yii amọ atubọtan rẹ ko tii kasẹ nilẹ nitori awọn idile kan to wa nipo ibanujẹ lọwọ-lọwọ nitori rẹ.
BBC Yoruba se alabapade awọn idile mẹta kan ti wọn ni awọn ọlọpaa lo wa loru lati wa ko awọn ọmọ wọn nitori ẹsun pe wọn lọwọ ninu iwọde EndSARS.
Nigba ti wọn n sọ bi ọrọ naa se waye, awọn mọlẹbi yii ni aarin oru ni awọn agbofinro de pẹlu ibọn sile wọn lati wa ko awọn gende naa lati ọdun kan sẹyin, ti wọn ko si ri wọn mọ.
Koda, wọn ni meji ninu awọn iya awọn ọmọkunrin naa lo ti jade laye nitori isẹlẹ yii, ti awọn baba wọn si ti dubulẹ aisan lori ọrọ naa.
Awọn mọlẹbi naa ni gbogbo igbiyanju awọn lati gba idande awọn ọmọ naa lo ja si pabo, ti awọn ọmọ eyi to ti ni iyawo ninu wọn ko si le lọ sile ẹkọ mọ.
Amọ gbogbo iyanju BBC Yoruba lati ba ileesẹ ọlọpaa ipinlẹ Oyo sọrọ lori isẹlẹ naa lo ja si pabo.
Sunday Igboho: Oluwo ní káwọn Ọba, àgbààgbà Yoruba rọ Buhari kó tú Igboho sílẹ̀
Oluwo ti ilu Iwo, Ọba Abdulrosheed Adewale Akanbi ti rọ awọn lọbalọba,awọn agbaagba ati awọn eekan ni ilẹ Yoruba lati gbera lọ ba Aarẹ Buhari lori ọrọ Sunday Igboho.
Oba Akanbi fi ero re lede ninu atejade to ti pe fun itusilẹ ajijagbara fun ilẹ Yoruba Nation, Sunday Igboho naa.
O ni itusilẹ Sunday Igboho yoo mu ilọsiwaju ati iṣọkan ba Naijiria gẹgẹ bi orilẹede kan ti ko le e yapa.
Bakan naa lo kesi awọn lọbalọba kaakiri ilẹ Yoruba lati gbimọpọ lori ọna ati fi Sunday Igboho silẹ, to si ṣe apejuwe rẹ gẹgẹ bi ''Ọmọ wa''.
Oluwo ni iṣọkan Naijiria lo jẹ oun logun ati wi pe itusilẹ Sunday Igboho yoo dẹkun rudurudu ati ipe fun iyapa to tan ka ile, ka oko ni Naijiria.
Oluwo dá èsì ńlá padà fún àwọn olórìṣà tó ní kò tọ́ síi kó ní Ọba Yorùbá kìí ṣe ìgbákejì Òrìṣà
O tun kesi Aarẹ Buhari pe ko bun iyi fun awọn lọbalọba ni ilẹ Yoruba ati awọn eekan ti yoo gbera wa ba a, nitori eyi yoo safihan fun awọn ọmọ Yoruba ni ile ati lẹyin odi pe iṣọkan Naijiria jẹ wa logun.
Oba Akanbi fikun un pe ki ijọba apapọ ni Naijiria jiroro pẹlu ijọba ilẹ Benin Republic, lọna ati ri pe Igboho pada si Naijiria lai si ọrọ igbẹjọ mọ.
O ni eleyii yoo tun jẹ ki ọpọlọpọ ololufẹ iṣọkan Naijiria gberasọ ni ilẹ Yoruba.
''Ariyanjiyan ati aigbọraeniye to n waye lori ọrọ Sunday Igboho to wa ni igbekun yoo dopin, ti awọn oriade ni ilẹ Yoruba, to fi mọ awọn agbaagba, ba le gbera lọ si ọdọ Aarẹ Buhari.''
''Nitori ọmọ wa ni Sunday Igboho bi o tilẹ jẹpe o ti ṣe awọn aṣiṣe kan nigba to n lọgun fun idasilẹ Yoruba Nation.''
''Awọn aṣiṣe to ṣe yii ko jẹ ki imọ rẹ lori itusilẹ ilẹ Yoruba kuro lara orilẹede Naijiria wa si imuṣẹ.''
''Nitori naa, mo rọ awọn ti ọrọ kan, ki wọn fi imọ ṣọkan, ki wọn si gbera lọ si ọdọ Aarẹ Buhari lati beere fun itusilẹ Sunday Igboho ni igbekun to wa ni Benin Republic.''
Timothy Adegoke: Màmá olóògbé ní ògó ilé àwọn ni wọ́n pa, ikú rẹ̀ kò gbọdọ̀ já sásán
''Ti aarẹ Buhari ba gba ọrọ awọn agbaagba ilẹ Yoruba yii yẹwo, yoo mu ilọsiwaju ati iṣọkan ba orilẹede Naijiria gẹgẹ bi ẹyọ kan.''
''Ijọba apapọ nikan lo le e gba Sunday Igboho silẹ lọwọlọwọ bayii nitori a gbọdọ doola ẹmi ọmọ wa .''
''Titu Igboho silẹ lai si ọrọ ileẹjọ nibẹ mọ yoo bu iyi kun ijọba orilẹede Naijiria, eyi ti yoo jẹ ilọsiwaju ati igbelarugẹ''.
Ọba Akanbi wa kesi awọn ọmọ Naijiria lati fi ifẹ han si ara wọn gẹgẹ bi orilẹede kan ati ẹya kan ki ohun gbogbo le rọrun pẹlu itẹsiwaju fun orilẹede Naijiria.
Oríṣun àwòrán, Sunday_igboho/Instagram
Agbẹjọrọ Sunday Igboho, Pelumi Olajengbesi ti sọrọ nipa ifẹ to wa laarin ẹya Igbo pẹlu bi awọn eekan ni ilẹ Igbo ṣe parapọ lati lọ ba Aarẹ Buhari lori ọrọ Nnamdi Kanu to wa ni panpẹ Ajọ DSS.
Olajengbesi ti wa ke si gbogbo awọn eekan ni ilẹ Yoruba lati kọ ẹkọ lara ẹya Igbo lori ọrọ Sunday Igboho.
Ninu atẹjade kan ti Olajengbensi fi soju opo ayelujara rẹ, lo ti sapejuwe bi awọn eekan ni ilẹ Igbo ṣe parapọ lati lọ ba Aarẹ Buhari lati bẹbẹ lori ọrọ Nnamdi Kanu to wa ni panpẹ Ajọ DSS.
Ninu ọrọ rẹ, o sapejuwe bi eekan ni ilẹ Igbo to jẹ aṣofin ati minisita ni igba ijọba alagbada akọkọ, Oloye Mbazulike Amaechi ṣe gbera gẹgẹ bi asaaju pẹlu awọn eekan miran lati lọ ba aarẹ Buhari.
O fikun wi pe pẹlu bi Nnamdi Kanu ṣe ri ati awọn ẹsun ti wọn fi kan an, awọn adari ati eekan ni ilẹ ẹya Igbo pe Kanu ni ''Ọmọ Wa''.
Ooni: A kìlọ̀ fún Sunday Igboho pé kó dákẹ́ àmọ́ kò gbọ́, èébú ló ń bú wa
Amọ, Olajengbesi ni ọrọ ko ri bẹẹ fun awọn adari ni ilẹ Yoruba ati awọn eekan, bakan naa lori ọrọ Sunday Igboho.
''Awọn eekan ni ilẹ Igbo ko bẹru pe ki awọn eniyan fi wọn ṣe yẹyẹ lori ọrọ Nnamdi Kanu, wọn dide gẹgẹ bi ẹya ti ọrọ wọn ṣe ọkan ti wọn si ni ifẹ ara wọn.''
''Bi o tilẹ jẹ pe awa Yoruba ni asa ati iṣe to wuyi amọ ko si ifẹ laaarin ara wa nitori awọn agba ilẹ Yoruba ti safihan rẹ lori ọrọ Sunday Igboho, ti ko si si ifimọṣọkan lori ọrọ rẹ.''
''Ko si ọrọ gboogi lati ẹnu awọn adari naa, wọn wa da Sunday Igboho nu bi ọmọ orukan.''
''Awọn agbaagba ni ilẹ Yoruba kọ ẹyin si bi o ti lẹ jẹpe Igboho ko ṣe daadaa to, ifẹ awọn Yoruba lo n ja fun.''
Sunday Igboho: Ìjọba Buhari ló ní ẹ̀bi, ẹ yé dá ẹ̀bi rú àwọn tó ń bèrè fún 'Yoruba Nation'
Agbẹjọro naa wa kesi awọn agbaagba ni ilẹ Yoruba lati kẹkọ lara ẹya Igbo to ti fi ipo asaaju han lori iṣọkan ati ṣiṣe iṣẹ pọ gẹgẹ bi ẹya kan naa.
Bakan naa lo ni awọn eekan ni ilẹ Yoruba ni ọkunrin ati obinrin to fi mọ awọn adari ẹsin, gbọdọ parapọ lati ṣe ohun to tọ lori ọrọ Sunday.
O ni paapaa awọn ti aarẹ Buhari ma n gbọ ọrọ si lẹnu ni ilẹ Yoruba gbọdọ fihan lasiko yii pe ọmọluwabi ni wọn ati pe wọn fẹran ara ilu.
EndSARS Victims: Ìyá méjì nínú mẹ́ta ti kú nínú àwọn ọmọ tí ọlọ́pàá gbé àmọ́ torí ìwọ́de
Jumoke Oyeleke: Agbẹjọ́rò ẹbí olóògbé ní ₦1m kéré bíi owó gbà máa bínú fún ìyá lórí ikú ọmọ rẹ̀
Oríṣun àwòrán, Lagos State Government
Agbẹjọro fun ẹbi Jumoke Oyeleke to ku lasiko iwọde Yoruba Nation nilu Eko, Taiwo Oyeleke ti koro oju si bi ijọba ipinlẹ Eko ṣe fun mama rẹ, Ifeoluwa Oyeleke ni miliọnu kan naira, ti wọn si tun gba ile fun un.
Nigba ti o n ba BBC Yoruba sọrọ, agbẹjọro Taiwo Olawanle sọ pe ọgbọn alumọkọrọyi ni ijọba lo, to fi fun arabinrin naa lowo, ti o si tun sanwo ọdun mẹta sile merẹnti fun un.
Ọgbẹni Olawanle sọ pe ko tọna fun ijọba ipinlẹ Eko lati ṣe bẹẹ, niwọn igba to jẹ pe ẹjọ naa si wa nile ẹjọ.
''Fifi ọwọ ọla gba ni loju ni ohun ti ijọba ipinlẹ Eko ṣe fun mama Jumoke tumọ si.
Miliọnu kan naira ti wọn fun ati ile ti wọn gba fun un ko to ẹmi ọmọ rẹ to di oloogbe.
Ti a ba tun wo o lọna mii, awọn igbimọ oluwadii iwa ipa awọn ọlọpaa lori iṣẹlẹ EndSARS dajọ pe ki wọn fun awọn ẹbi eeyan to ku ni miliọnu marun un si mẹfa.
EndSARS Victims: Ìyá méjì nínú mẹ́ta ti kú nínú àwọn ọmọ tí ọlọ́pàá gbé àmọ́ torí ìwọ́de
Ẹyin wa n lọ fun obinrin yii ni miliọnu kan naira ati ile merẹnti, ti owo ile naa ba tan, ta lo maa san omiran?
Awa o gba eleyii wọle, ati pe ẹjọ si wa nile ẹjọ, a ko ti mọ ẹni to ba Jumoke bayii tori awa gbagbọ pe ọlọpaa lo pa a, amọ awọn ni ọlọpaa kọ.
A ko tii ri idi gbogbo ọrọ to wa nilẹ yii, wọn wa gbẹyin wa lọ fun iya oloogbe lowo.
O digba ti a ba mọ ẹni to pa Jumoke ki a to le mọ ohun ti a maa beere lọwọ ijọba ipinlẹ Eko gẹgẹ bi owo gba ma binu.
Ijọba ko tun fi ọrọ naa to awa agbẹjọro ẹbi Jumoke leti nigba ti wọn fẹ gbe igbesẹ yii.
"Ṣe miliọnu kan naira to lati ra ẹmi eeyan pada? Igba wo ni wọn maa to na miliọnu kan naira tan?"""
'Ẹ má jẹ́ kí òkú ọmọ mi ráre o ìjọba! Ẹ gbée fún mi kí n lọ sin ín - Ìyá ọmọ ti wọ́n pa ní ìwọ́de Yoruba Nation
Bakan naa ni Olawanle salaye pe adẹrinpoṣonu kan, Mr Macarona fun mama ọmọ yii ni ẹgbẹrun lọna ẹẹdẹgbẹrun naira.
O ni ti ẹnikan ba le ṣe iru nkan bayii fun mama ọmọ naa, meloo meloo wa ni ijọba ipinlẹ Eko?
Bakan naa lo fikun pe awọn ko ri miliọnu kan naira gẹgẹ bi owo gba ma binu to yẹ fun ẹni ti wọn yinbọn pa ọmọ rẹ.
Olawanle wa ni awọn tiẹ ni igbagbọ pe kii ṣe ijọba ipinlẹ Eko lo wa nidi igbesẹ yii.
Agbẹjọro naa tun fikun ọrọ rẹ pe, alaanu kan ti ṣeto ile gbigbe fun mama oloogbe yii, eyi to jẹ ki ile ti di meji bayii.
Amọ o ni o ku si ọwọ iya Jumoke lati yan ile ẹni to fẹ lọ gbe, boya ile ti ijọba ipinlẹ Eko rẹnti fun ni abi eyi ti alaanu kan gba fun.
Sugbọn Olawanle ni o di dandan ki owo ile ile kan sofo danu ninu ile mejeeji nitori obinrin naa atawọn ọmọ rẹ ko le gbe ile meji papọ.
Àwọn ọ̀dọ́ opó l'obìnrin sọ ìrírí wọn l'awùjọ
Lekki Massacre Panel Reports: - Adegboruwa ní wọn ti ṣá ọmọ ìgbìmọ̀ olùwádìí kan ní ìṣákúṣàá
Oríṣun àwòrán, Getty Images/BarristerNG
Agbẹjọro to wa lara awọn ọmọ igbimọ to tanna wadi ẹsun isekupani to waye ni Lekki lasiko iwọde EndSARS, Ebun Olu-Adegboruwa ti kigbe sita o.
Adegboruwa yii lo figbe ta pe ete ti n lọ labẹnu lati gba ẹmi oun nitori abọ igbimọ oluwadii naa to ni lootọ ni wọn seku pa awọn oluwọde ni Lekki Toll Gate ni ogunjọ osu kẹwa ọdun 2020.
"Atẹjade kan ti Adegboruwa fisita lọjọ Aje lati ke gbajare nipa iku to n rọ dẹdẹ lori rẹ naa, lo pe akori rẹ ni ""Ijọba ni kẹ mu ti ohunkohun ba sẹlẹ si mi."""
Bẹẹ ba gbagbe, igbimọ oluwadii nipa isekupani to waye lasiko iwọde EndSARS ni iloro Lekki naa, lo gbe abọ iwadi rẹ kalẹ laipẹ yii.
Ninu abs iwadi oloju ewe ọọdunrun ati mẹsan naa si lo ti tọkasi pe eeyan mẹsan lo dagbere faye ni iloro Lekki lasiko iwọde EndSARS nigba tawọn ologun ya bo ibi iwọde naa lagunjọ osu Kẹwa ọdun 2020.
Wo ìyà tó jẹ Adedotun Clement níbi ìwọ́de EndSARS ní Lekki Toll Gate àtohun táwọn tó sọ̀rọ̀ ń bèrè fún
Adegboruwa, ẹni to soju awọn ikọ ajafẹtọẹni ninu igbimọ oluwadii ọhun ni se ni awọn osisẹ ọba kan n doju ifiyajẹni kọ awọn ọmọ igbimọ naa.
"Lati igba ta ti gbe abọ iwadi igbimọ naa kalẹ, ọpọ idunkooko mọ ni ati ikọlu ni mo n ri lati ọdọ awọn asoju ijọba, paapaa lawọn oju ewe iwe iroyin.
N ko sẹ ẹsẹ kankan yatọ si pe mo dara pọ mọ awọn eeyan nla lorilẹede yii, ti wsn ko ni abawọn kankan, lati soju ẹgbẹ awọn agbẹjọro ati ajafẹtọẹni pẹlu awọn mẹkunnu fun isẹ ilu.
Gbajumọ agbẹjọro ijọba meji lo si ti ru ọkan araalu soke lati ta ko mi lori mohunmaworan pklu awọn ẹsun ti ko lẹsẹ nlẹ.
Amọ gbogbo igbesẹ yii ni n ko jẹ ko tu irun kankan lara mi tabi gba lati mu ki idunkooko ijsba pa mi lẹnu mọ.
Mo wa n rọ awọn ọmọ Naijiria, awọn akẹẹgbẹ mi lẹnu isẹ agbẹjọro, awọn ajafẹtọẹni atawọn ọmọ Naijiria pe ijọba ni kẹ mu, ti ohunkohun ba sẹlẹ si mi."
EndSARS Victims: Ìyá méjì nínú mẹ́ta ti kú nínú àwọn ọmọ tí ọlọ́pàá gbé àmọ́ torí ìwọ́de
Adegboruwa tun fikun pe ni alẹ ọjọ Aiku ni wọn kọlu ọkan lara awọn ọmọ igbimọ oluwadi nipa isekupani to waye ni Lekki naa, Arabinrin Kamsiyochukwu Ibe, ti wọn si sa ni isakusa.
O ni isẹlẹ naa fihan pe wọn mọọmọ fẹ gba ẹmi rẹ ni, ti awọn aworan ti agbẹjọro rẹ si safihan rẹ bii ẹri to daju nipa ikọlu naa, fi idi ero naa mulẹ.
Agba amofin naa ni oun jẹ ipe ijọba lati wa sisẹ sin ilu ni pẹlu otitọ inu pe wsn gbe igbimọ naa kalẹ lati sọ otitọ pọnbele, eyi ti awọn ti se.
O ni iyoku wa ku sọwọ ijọba atawọn ọmọ Naijiria lati se ohun to tọ pẹlu abọ igbimọ oluwadi naa.
Baba Suwe: Wo ohun mẹ́jọ tó ṣe kókó nípa olóògbé Babatunde Omidina
Oríṣun àwòrán, Adesola Omidina
Ní kété ti wọn kéde iku ogbontarigi adẹrinposonu nni, Babatunde Omidina, ti ọpọ eeyan mọ si Baba Suwe ni ọpọ eeyan ti n bèèrè pé awọn fẹ mọ sii nipa oloogbe naa.
Ọjọ Aje, ọjọ Kejilelogun osu Kọkanla ọdun 2021 ni Baba Suwe, tii se gbajumọ osere tiata ati adẹrinposonu, dagbere faye lasiko aisan ọlọjọ pipẹ.
Ọdun mẹtalelọgọta ni oloogbe agba osere naa lo loke eepẹ, ko to tẹri gbasọ.
Ọjọbọ, ọjọ Kẹẹdọgbọn osu Kọkanla ọdun 2021 ni Baba Suwe si wọ kaa ilẹ sun nilana ẹsin Islam nile rẹ to wa ni opopona Oluwatimiro, ibudokọ Ewu-Elepe, ni opopona Ijede nilu Ikorodu
Oríṣun àwòrán, the_appreciation_room
A bi Babatunde Omidina ni ọjọ kejilelogun, osu kẹjọ, ọdun 1958 ni Ijoba ibile Ikorordu nipinlẹ Eko ni guusu Naijiria.
Baba Suwe dagba ni agbegbe Lagos Island nipinle Eko.
O lọ sile ẹkọ alakọbẹrẹ Jamaitu Islamial ati Children Boarding School ni Osogbo ni ipinlẹ Osun.
Lẹyin naa lo lọ sile ẹkọ girama ti Adekanbi Commercial High School ni Mile 12 nipinle Eko.
Ileẹkọ Ifeoluwa Grammar School ni Osogbo nipinle Osun lo ti pada se idanwo asekagba oniwe mẹwaa rẹ
Babatunde Omidina bẹrẹ isẹ ere itage ni sise lọdun 1971 ko to di gbajugbaja pẹlu ere sinima agbelewo Omolasan.
Awon ere mii to gbe Baba Suwebatu jade sita ni Iru Esin ti Olaiya Igwe, Ebun Oloyede se ni 1997, Baba Jayejaye ti oun ati Funke ?Akindele jọ se papọ pẹlu Femi Adebayo
Lodun 2011 ni ajọ NDLEA to n gbogun ti asilo oogun oloro fẹsun kan Baba Suwe ni eyi ti ile ejọ giga ipinlẹ Eko pada danu pe ibanilorukọjẹ ni ẹsun naa.
Oloogbe Bamidele Aturu to jẹ ajafẹtọ ọmọniyan lo soju fun Baba Suwe ninu igbejọ naa.
Baba Suwe: Bi eto isinku Babatunde Omidina se lọ ree
Ki lo ti ṣẹlẹ sẹyin?
Oríṣun àwòrán, omo_omidina/Instagram
Iroyin to n tẹ wa lọwọ ni yajoyajo ni gbajugbaja oṣere tiata Yoruba, Babatunde Omidina, ti ọpọ awọn ololufẹ rẹ mọ si Baba Suwe ti jade laye.
Ọmọ oloogbe ọhun, Adesola Morenikeji Omidina lo kede iku agba oṣere naa loju opo Instagram rẹ.
"Morenikeji ni ""Eyii ni lati kede pe baba mi, ọgbẹni Babatunde Omidina ti jade laye... ki Ọlọrun ti ẹmi rẹ si afẹfẹ rere."""
Gẹgẹ bii ọpọ awọn ololufẹ rẹ sẹ mọ, Baba Suwe ti fi awọn akoko kan ṣaisan, eyii ti mu ki awọn eeyan kan maa gbe iroyin ofege nipa iku rẹ ṣaaju.
Lara awọn to ṣeranwọ owo fun oloogbe naa lasiko naa ni wolii Esther Ajayi.
Ọjọ kejilelogun, oṣu Kẹjọ, ọdun 1958, eyiun ọdun mẹtalelọgọta sẹyin, ni wọn bi baba Suwe ni Lagos Island, ni ipinlẹ Eko.
Lẹyin ti iroyin iku Baba Suwe lu jade lori ayelujara, ọpọ awọn ololufẹ rẹ lo ti bẹrẹ si n ṣedaro iku rẹ.
Lara awọn agba oṣere to ti ṣedaro iku Baba Suwe ni arabinrin Modupe Johnson, ti ọpọ eeyan mọ si Fali Werepe.
Yatọ si Fali Werepe, awọn oṣere mii bii Yomi Fabiyi naa ti n kẹdun iku Baba Suwe.
Adura wa ni pe ki Eledua tẹ ẹ si afẹfẹ rere.
Baba Suwe: Ọmọ olóògbé kan tàbùkù bí wọn ṣe ń pín fídíò òkú bàbá rẹ̀ kiri lórí ayélujára
Oríṣun àwòrán, Baba Suwe
Lẹyin wakati diẹ ti gbajugbaja osere tiata nni, Babatunde Omidina, ti ọpọ eeyan mọ si Baba Suwe jade laye, awuye wuye ti n su yọ lori oku rẹ.
Ni kete ti oloogbe naa mi kanlẹ, ni fidio orisi meji ti n ja rain-rain lori ayelujara eyi to se afihan oku apanilẹrin naa.
Ọjọ Aje ni agba osere tiata naa dagbere faye lasiko aisan ọlọ pipẹ to ti n ba finra.
Ninu fidio akọkọ, ni ọkunrin apọnbeporẹ kan to pe oloogbe naa ni baba oun, ti se afihan ara rẹ ati oku Baba Suwe ni kete to ku, ti oku rẹ si la ẹnu silẹ.
Obinrin naa to di ori oku Baba Suwe mu lo n fi omije sọrọ pe baba oun ti lọ.
"Ọkunrin naa ni ""Ko si ẹbi, ko si ara, a pe wọn lootọ amọ ko si ẹbi. Baba mi ti lọ, mo maa n nifẹ ọkunrin yii ni gbogbo igba, ẹyin ẹbi mo dupẹ o, ẹ seun o,  amọ n ko ni sọ ju bayii lọ."""
Fidio keji naa lo fi ara pẹ ti akọkọ, ninu fidio naa si ni wọn ti se afihan oku Baba Suwe lati ori de isalẹ.
Oloogbe naa lo sun sori ibusun, o la ẹnu silẹ, ti oju ibi ti wọn lẹ pilasita si wa ni apa mejeeji rẹ.
Baba Suwe lo wọ asọ ankara olomi buluu eyi to wọ titi to fi mi kanlẹ, to si sun silẹ laimira bi o tilẹ jẹ pe fidio naa ko ni ohun.
Ninu fido naa si lo ti foju han pe Baba Suwe ti ru pupọ ko to jade laye, to si yatọ si Baba Suwe to ni omi lara, eyi ti gbogbo aye mọ.
Ọpọ eeyan lo ti n sọ ero ọkan wọn lori awọn fidio mejeeji naa, eyi to n tabuku oloogbe, ti wn si n bu ẹnu atẹ lu ẹni to wa nidi bi fidio naa se de ori ayelujara.
Ope Aiyeọla: Nkan pa emi ati Baba Suwe pọ
Boya ariwisi awọ̀n araalu yii lo mu ki ẹlomiran, to jẹ ọmọ oloogbe naa, Adesola Omidina se kede loju opo ayelujara rẹ lati tako igbesẹ afihan oku baba rẹ lori ayelujara.
Ọmọ Omidina @ omo_omidina loju opo Instagram, lo fi atẹjade kan sita pe oun n fi gbogbo ẹnu tabuku awọn fidio mejeeji naa.
O ni awọ̀n fidio to n se afihan oku baba oun lawọn oju opo ayelujara ni ko tọna bi wọn se gbe jade rara.
Bakan naa lo sẹ lori ẹsun pe awọn ko ri oluranlọwọ kankan lati se itọju oloogbe naa lasiko to wa lori ibusun aisan.
O ni ẹgbẹ awọn osere tiata, TAMPAN, ijọba, awọn wolii, ẹbi ati ololufẹ baba oun ni wọn sugba awọn niwọnba bi agbara wọn ti mọ, ti wọn si se iwọn ti wọn le se.
Adesola Omidina wa lo anfaani ikede naa lati tọrọ aforijin lọwọ awọn ẹlẹgbẹjẹgbẹ, awọn eeyan ati ẹbi wọn.
Ọmọ Baba Suwe naa wa n rọ awọn araalu lati kọ ẹyin si awọn fidio ti ko tọna naa, eyi to ti lu ori ayelujara pa.
Oríṣun àwòrán, omo_omidina/Instagram
Nibayii na, ikede ti jade lori eto isinku Baba Suwe.
Atẹjade miran ti ọmọ oloogbe, Adesola Omidina fisita loju opo Instagram rẹ ni aarọ ọjọ Isẹgun kede pe Ọjọbọ ni wọn yoo gbe oku oloogbe naa wọ kaa ilẹ.
Atẹjade naa ni ile oloogbe to wa ladupo Elepe nilu Ikorodu ni wọn yoo ti sin Baba Suwe ni deede aago mẹwa owurọ.
Adesola Omidina ni awọn mọlẹbi oloogbe yoo kede ayẹyẹ isinku nigba to ba ya.
Ọjọ Aje, ọjọ Kejilelogun osu Kọkanla ọdun 2021 ni agba osere tiata naa, tii tun se adẹrinposonu ti ọpọ eeyan mọ si Baba Suwe ki aye pe o digbose.
Ọdun mẹtalelọgọta ni alawada naa lo loke eepẹ, ko to dagbere faye lasiko aisan ọlọjọ pipẹ to ba finra.
Oríṣun àwòrán, omo_omidina/Instagram
Sunday Igboho: DSS bẹ ilé ẹjọ́ láti gbà òun láàyè kó gbé Igboho wá sí Nàìjíríà kúrò ní Cotonou
Oríṣun àwòrán, Sunday_igboho1/Instagram
Ajọ ọtẹlẹmuyẹ Naijiria, DSS ti rọ ile ẹjọ giga to wa niluu Ibadan wi pe ko so aṣẹ to pa pe oun ko gbọdọ fọwọ kan Sunday Igboho rọ.
Ajọ DSS sọ fun ile ẹjọ pe ti Igboho ba pada si Naijiria, ni awọn yoo to ni lanfani lati pe ẹjọ kotẹmilọrun.
Agbẹjọro Igboho, Yomi Aliu, SAN to ba BBC Yoruba sọrọ ṣalaye pe, igba akọkọ ree ti DSS yoo tu asiri pe awọn lo ti Igboho mọle ni lorilẹede Benin Republic.
Lori ogun biliọnu naira owo gba ma binu ti ile ẹjọ paṣẹ tẹlẹ pe ki ajọ DSS san fun Igboho, lori bi wọn ṣe se ikọlu si ile rẹ niluu Ibadan, DSS ni owo naa pọ ju ohun ti awọn le san lọ.
Wọn ni sisan aduro owo yii fun Igboho le ṣakoba fun ọrọ aje orilẹede Naijiria niroti owo naa pọ lapọju.
Oríṣun àwòrán, Yomi Aliyu
Amọ, agbẹjọro Aliu sọ fun ile ẹjọ pe, o lodi sofin lati ju Igboho si atimọle lẹyin igba ti ile ẹjọ ti paṣẹ pe wọn o le mu un tabi ṣe ohun kan si i.
Bakan naa ni agbẹjoro Igboho sọ fun ile ẹjọ pe ẹgbẹlẹgbẹ tiriliọnu ni eto iṣuna orilẹede, nitori naa sisan ogun biliọnu naira fun Igboho ko le ṣakoba fun ọrọ aje Naijiria.
Lẹyin atotonu ajọ DSS ati agbẹjọro Igboho, adajọ paṣẹ pe ki banki apapọ Naijiria, CBN san ogun biliọnu naira to sọ tẹlẹ fun Igboho, o pẹ tan ninu oṣu kinni ọdun 2022 to n bọ.
Adajọ wa sun igbẹjọ siwaju si ọjọ kejila oṣu kinni ọdun 2022.
Ilé ẹjọ́ sún ìgbẹ́jọ́ ọmọlẹ́yìn Sunday Igboho méjì síwájú torí kò sí atúmọ̀ èdè Yorùbá sí Gẹ̀ẹ́sì
Ile ejọ giga ijọba apapọ niluu Abuja ti sun igbẹjọ ọmọlẹyin Sunday Igboho meji to yẹ ko waye lọjọ Aje, ọjọ kejilelogun oṣu kọkanla siwaju nitori ko si ẹni to le tumọ ede Yoruba fun wọn.
Jamiu Oyetunji ati Amudat Babatunde wa lara eeyan mejila ti ajọ DSS gbe lọ nigba ko ṣe ikọlu si ile Igboho lọjọ kinni oṣu keje.
Ẹsun onikoko marun un to da lori igbesunmọmi ni ajọ DSS ṣẹṣẹ fi kan awọn mejeeji.
Ninu ẹjọ ti ajọ DSS ṣẹṣẹ pe, ajọ naa sọ pe ibọn ati awọn nkan ija oloro fun igbesunmọmi wa lọwọ, Oyetunji.
Bakan naa ni DSS sọ pe Amudat to jẹ ẹnikeji lo oju opo Facebook rẹ fun ipolongo igbesunmọmi.
Laipẹ yii ni ile ẹjọ paṣẹ pe ki ajọ DSS fun awọn ọmọlẹyin Igboho mejila ti wọn ju si atimọle wọn niluu Abuja ni ominira.
Ti ẹ ko ba gbagbe, agbẹjọro DSS, I. Awo, sọ fun ile ẹjọ lọjọ kẹjọ oṣu kẹsan an pe oun wọ ọkọ awọn ole ti wọn n pe ni ''One Chance.''
Timothy Adegoke: Màmá olóògbé ní ògó ilé àwọn ni wọ́n pa, ikú rẹ̀ kò gbọdọ̀ já sásán
O sọ fun ile ẹjọ pe awọn ọdaran to wa ninu ọkọ naa ja faili ẹjọ awọn ọmọlẹyin gba lọ.
Nigba ti asiko to fun ẹjọ naa lọjọ Aje, agbẹjọro wọn, Pelumi Olajengbensi, sọ fun ile ẹjọ pe awọn onibara oun ko gbọ ede oyinbo.
Gbogbo igbiyanju lati ri ẹni to le ṣe ongbufọ fun wọn, pabo lo ja si.
Eyi lo jẹ ki adajọ, Obiora Egwuatu, sun igbẹjọ siwaju di ọjọ kẹrinlelogun oṣu kinni ọdun 2022.
Eeyan meji lo jẹ Ọlọrun ni pe lasiko ti ajọ DSS ṣe ikọlu si ile Igboho lagbegbe Soka ni Ibadan.
Lẹyin naa ni Igboho fun ra rẹ fi Naijiria silẹ ti o si mori le orilẹede Germany.
Ṣugbọn awọn agbofinro mu un pẹlẹ iyawo rẹ lọna ajo wọn niluu Cotonou nibi ti Igboho ti wa lẹwọn lati igba naa.
EndSARS Victims: Ìyá méjì nínú mẹ́ta ti kú nínú àwọn ọmọ tí ọlọ́pàá gbé àmọ́ torí ìwọ́de
Bola Tinubu: N kò rán ẹnikẹ́ni láti bẹ̀rẹ̀ ìpolongo fún ìbò ààrẹ ọdún 2023
Oríṣun àwòrán, Bola Tinubu
Asiwaju Bola Ahmed Tinubu ti fesi si iroyin to tan kalẹ lori ayelujara pe o ti ṣe agbekalẹ ohun ti yoo fi ṣe ipolongo fun ibo aarẹ ọdun 2023.
Oluranlọwọ lori ọrọ iroyin si Tinubu, Ọgbẹni Tunde Rahman lo sisọ loju ọrọ yii fun BBC Yoruba, to si ni iroyin ofege lasan ni.
Ọgbẹni Rahman ṣalaye pe o digba ti Tinubu ba to kede erongba rẹ lati dupo aarẹ, ki o to le sọ nipa ipolongo ibo.
''Ko si ohun to jọọ pe Tinubu ti ṣe agbekalẹ eto ipolongo fun ibo aarẹ ọdun 2023, Asiwaju ko tii kede pe oun yoo dije ninu ibo aarẹ to n bọ lọdun 2023.
Awọn oriṣiiriṣii ẹgbẹ awọn ololufẹ Tinubu lo wa nidi ọrọ iroyin ipolongo fun ibo aarẹ orilẹede Naijiria to wa lori ayelujara.
Asiwaju ko mọ ohun kan ni pa rẹ, bakan naa ni ko mọ ohunkohun nipa awọn eeyan to n ha raisi ati ẹwa ninu baagi kaakiri.
Timothy Adegoke: Màmá olóògbé ní ògó ilé àwọn ni wọ́n pa, ikú rẹ̀ kò gbọdọ̀ já sásán
Awọn afẹnifere ti wọn nifẹ Asiwaju lo n ṣe awọn nnkan yii fawọn eeyan, Asiwaju ko ran ẹnikan ni iṣẹ, ko si fun ẹnikan kan lowo lati maa pin raisi tabi ẹwa.
A o le da awọn eeyan yii lọwọ kọ nitori itọrẹ aanu ni wọn n ṣe fawọn ti ko rọwọ họri lawujọ.
Asiko kan tiẹ wa ti Asiwaju ni lati dupẹ lọwọ awọn eeyan yii fun iṣẹ itọrẹ aanu ti wọn n ṣe fawọn eeyan.
O ti pẹ ti awọn eeyan yii ti n ṣe awọn ohun ti wọn n ṣe ni orukọ Tinubu bo tilẹ jẹ p e ko mọ nipa rẹ,'' Ọgbẹni Rahman lo ṣalaye bẹẹ.
Oriṣiiriṣii nkan bii aṣọ ilewọ, fila, ounjẹ inu baagi lawọn eeyan kan n pin eleyii ti orukọ Tinubu fun ipo aarẹ ọdun 2023 wa lara rẹ.
Timothy Adegoke: Kọmíṣọ́nà ọlọ́pàá Osun ní ọmọbíbí Rahmon Adedoyin tó ni ilé ìtura tí Adegoke kú sí, ló jù òkú rẹ̀ sígbó
Oríṣun àwòrán, Timothy Adegoke/Rahmon Adedoyin/Facebook
Kọmiṣọnna ọlọpaa nipinlẹ Osun, Wale Olokode ti ni ọkan lara awọn afurasi ninu iku Timothy Adegoke, to jẹ akẹkọọ fasiti Obafemi Awolowo, ti jẹwọ bi iṣẹlẹ naa ṣe waye.
Afurasi naa, Roheem Adedoyin lo jẹ ọmọ ẹni to ni ile itura Hiltons Hotels and Resort, Ile-Ife, ni ọlọpaa ni oun lo ṣakoso bi wọn ṣe gbe oku naa kuro ninu ile itura lọ ju si inu igbo.
Ọga ọlọpaa nipinlẹ Osun ni Roheem ni alakoso ile itura naa ti Adegoke ti ku, to si wa nibẹ nigba ti iṣẹlẹ naa ṣẹlẹ, to si ṣeto bi wọn ṣe gbe oku rẹ kuro ni ile itura naa, ti wọn si lọ sin lai fi to ọlọpaa leti.
Lasiko to n sọrọ lori redio Rave FM, Osogbo ni Olokode ti ni, Roheem ti na papa bora, to si jẹ pe iwadii ọlọpaa lo jẹ ki wọn mọ ibi ti wọn gbe oku naa pamọ si.
''Ọkan lara awọn afurasi jẹwọ pe ọmọ Ramon Adedoyin ti orukọ rẹ n jẹ Roheem Adedoyin to jẹ ọmọ ẹni to ni ile itura naa, ti sa kuro ni ilẹ yii lati igba ti iṣẹlẹ naa ti ṣẹlẹ.
Timothy Adegoke: Màmá olóògbé ní ògó ilé àwọn ni wọ́n pa, ikú rẹ̀ kò gbọdọ̀ já sásán
''Afurasi naa jẹwọ pe Roheem lo ṣakoso bi wọn ṣe lọ sọ oku arakunrin naa si inu igbo, ti oun naa si tẹle wọn pẹlu oṣiṣẹ agba meji to tẹle wọn lọ si inu igbo.''
''Ko si ẹnikẹni ninu awọn oṣiṣẹ yii to fi ẹjọ sun ọlọpaa, awọn mọlẹbi ti wọn bẹrẹ si ni wa ọkunrin naa, ti awọn ọlọpaa kogberegbe ti wọn si bẹrẹ si ni ṣe iwadii bi arakunrin naa ṣe di awati ninu ile itura, ti wọn si lo ri oku rẹ ninu igbo.''
Olokode ni oun ko mọ nkankan nipa igbohunsafẹfẹ ti Adedoyin ṣe ni panpẹ ọlọpaa nibi to ti sọ wi pe oun ko jẹbi ẹsun ipaniyan ti wọn fi kan oun.
Amọ nibayii, awọn mọlẹbi ti kesi ileeṣẹ ọlọpaa lati salaye bi Adedoyin ṣe n jaye ọba ni ahamọ ọlọpaa nitori o jẹ ilumọọka ni awujọ.
Agbẹjọro mọlẹbi naa, Adekilekun ni awọn ti kesi ọlọpaa lati ri pe idajọ ododo jọba ni iwadii yii lai ṣe ojusaaju fun ẹnikẹni lori iṣẹlẹ yii.
O ni awọn ti bẹrẹ iwadii lori bi Adedoyin ṣe bẹrẹ si ni ṣe igbohunsafẹfẹ ninu ahamọ lasiko to wa ni ikawọ wọn.
''Ohun itiju lo jasi pẹlu bi ọpọlọpọ ọrọ ṣe n jade lati ẹnu awọn eniyan ti wọn fẹ gbeja ẹni to ni ile itura ti iṣẹlẹ naa ti ṣẹlẹ, Rahmon Adedoyin wi pe ko ṣẹ ẹsẹ kankan.''
''Ohun ti a fẹ ni ki onikaluku duro de idajọ ileẹjọ lori iṣẹlẹ yii lati sọ ẹni to jẹbi ẹsun yii tabi bẹẹkọ lai lo ọna ẹburu lati ma a ke gbajare si awọn eniyan lawujọ lati gbe ija wọn ja.''
Oríṣun àwòrán, Timothy Adegoke/Rahmon Adedoyin/Facebook
Iroyin ni awọn onimọ nipa ayẹwo oku naa de ọgba ile iwosan ẹkọni Osun State University Teaching Hospital (UNIOSUNTH), Osogbo, ni nkan bi aago meji ọsan ni Ọjọ Aje
Awọn onimọ nipa ayẹwo oku ti ṣayẹwo iru iku to pa akẹkọkunrin ni fasiti Ọbafemi Awolowo University, ti Ile Ife.
Iroyin ni awọn onimọ nipa ayẹwo oku naa de ọgba ile iwosan ẹkọsẹ isegun fasiti ipinlẹ Osun (UNIOSUNTH) to wa nilu Osogbo, ni nkan bi aago meji ọsan Ọjọ Aje.
Amọ awọn onisegun naa ko gba awọn mọlẹbi, ati awọn oniroyin laaye si agbegbe naa, amọ wọn n woye bi o ṣe nlọ lati ileẹjọ.
Ninu ọrọ rẹ, agbẹnusọ fun ileeṣẹ ọlọpaa nipinlẹ Osun, Yemisi Opalola sọ fun awọn oniroyin pe wọn ko tete ṣe ayẹwo oku naa nitori awọn mọlẹbi sọ wi pe awọn fẹ ki aṣoju awọn wa nibẹ lasiko ayẹwo naa.
Timothy Adegoke: Màmá olóògbé ní ògó ilé àwọn ni wọ́n pa, ikú rẹ̀ kò gbọdọ̀ já sásán
Bakan naa ni iroyin ni pe awọn mọlẹbi fa onimọ nipa ayẹwo oku ti yoo soju wọn silẹ, nigba ti awọn alayẹwo oku naa wa nibẹ ni ibi ayẹwo naa, ti gbogbo wọn si ri bi wọn ṣe ṣe ayẹwo naa.
Dokita Waheed Oluogun lati fasiti imọ ẹkọ iṣegun naa lo ṣe ayẹwo oku Timothy.
Amọ dokita naa ni awọn ọlọpaa ni oun yoo fi abajade ayẹwo naa ṣọwọ si ni nikan bi ọsẹ meji si mẹta si isinyii, ti esi ayẹwo naa ba jade.
Ninu ọrọ ẹbi Adegoke, eyi ti agbẹjọro Naheem Adekilekun kede sita, wọn ni o di igba ti ayẹwo oku naa ba jade ki awọn to sọ ọrọ kankan lori rẹ.
Adekilekun wa parọwa si awọn ileeṣẹ ọlọpaa pe ki wọn maṣe ṣe ojusaaju lori iṣẹlẹ naa, ki wọn si fi iya to tọ jẹ ẹni to ṣe iṣẹ laabi yii.
Timothy Adegoke ni wọn lo tẹ ọkọ leti wa si ipinlẹ Osun lati wa ṣe idanwo ni fasiti Obafemi Awolowo OAU , ki o to di awati ni Ọjọ Keje, Oṣu Kọkanla, ọdun 2021.
Lẹyin naa ni awọn ọlọpaa ri oku rẹ ninu igbo ni agbegbe to wa loju ọna Ede si Ife, lasiko ti wọn bẹrẹ si ni wa.
Ileeṣẹ ọlọpaa ni awọn afurasi mẹfa to jẹ oṣiṣẹ ile itura Hilton Hotels and Resort ati Ramon Adedoyin to ni ile itura naa. ni wọn ti mu lẹyin ti iwadii fihan pe lootọ ni Adegoke wa si ile itura naa lati gba yara, ki o to di awati.
EndSARS Victims: Ìyá méjì nínú mẹ́ta ti kú nínú àwọn ọmọ tí ọlọ́pàá gbé àmọ́ torí ìwọ́de
Baba Suwe: Ọmọ olóògbé ní wàhálà tí bàbá òun kojú lọ́wọ́ NDLEA kò tán lára rẹ́ tó fí kú
Ọmọ gbajugbaja apanilẹrin osere tiata to di oloogbe, Babatunde Omidina, ti ọpọ eeyan mọ si Baba Suwe, ti tu kẹkẹ ọrọ silẹ nipa iriri baba rẹ lọwọ ajọ to n gbogun ti oogun oloro ni Naijiria, NDLEA.
Omidina Adebowale Junior, lasiko to n ba BBC Yoruba sọrọ lori awọn nnkan ti ko le gbagbe nipa baba rẹ, salaye pe oun ati baba oun maa n ja pupọ, eyi yoo si jẹ ki oun saaro rẹ pupọ.
O ni arẹmaja ko si, ajamarẹ ni ko sunwọn amọ kii pe isẹju marun ti awọn yoo fi pari rẹ.
O fikun pe awọn mejeeji mọ ọwọ ara awọn, to si n gba oun nimọran lati tẹsiwaju ninu isẹ agbabọọlu ti oun n se.
Adebowale ni alawada ninu ile ni baba oun, bo si se n se ninu sinima naa lo n se loju aye, to si han gbangba pe lati ọrun lo ti mu ẹbun awada wa.
EndSARS Victims: Ìyá méjì nínú mẹ́ta ti kú nínú àwọn ọmọ tí ọlọ́pàá gbé àmọ́ torí ìwọ́de
Wahala ajọ NDLEA wa lara oun to tete pa Baba mi:
Adebowale Omidina, lasiko to n salaye ohun to se okunfa iku baba rẹ ni, wahala ti baba oun koju lọwọ NDLEA jẹ eleyi ti ọgbẹ rẹ ko tan lọkan baba Suwe titi to fi jade laye.
Adebowale sọ pe oun ko le sọ pàtó boya wahala NDLEA yii lo fa aarẹ sara Baba Suwe ṣugbọn nkan ko jọra mọ lati igba naa fún idile awọn.
Bẹẹ ba gbagbe, lọdun 2011 ni ajọ NDLEA fi ẹsun kan Baba Suwe pe o gbe oogun oloro amọ lẹyìn iwadii wọn, ko fi ẹri to daju mulẹ nile ẹjọ lori ẹsun pe lootọ ni Baba Suwe gbe oogun oloro.
Idi si ree ti ile ẹjọ fi da Baba Suwe silẹ, to si ni ki ajọ to n dena gbigbe oogun oloro naa fun ni miliọnu mẹẹdọgbọn naira owo gba ma binu amọ ko ri owo naa gba titi to fi ku.
Baba Suwe sọ pe iriri oun ni ahamọ ajọ NDLEA naa, ni ko jẹ ki oun le rin daada mọ lẹyin ti oun jade ni ahamọ wọn.
Ni kete to si kuro ni ahamọ, tileẹjọ da lare, ni Baba Suwe bẹrẹ aisan ọlọjọ pipẹ, koda, wọn gbe lọ soke okun fun itọju ni asiko kan amọ ko si fi bẹẹ gbadun, titi ti ọlọjọ fi de ba a.
Timothy Adegoke: Màmá olóògbé ní ògó ilé àwọn ni wọ́n pa, ikú rẹ̀ kò gbọdọ̀ já sásán
Adebowale Omidina, ni kete ti baba rẹ di oloogbe, lo ti fẹsun kan awọn mọlẹbi ninu fónrán fidio kan tó gbòde kan pe, wọn pa baba rẹ ti, lai setọju rẹ titi to fi ku.
Fidio mejeeji ti Adebowale ju sori ayelujara naa lo fa awuyewuye laarin ẹbi, koda, awọn ẹgbẹ osere tiata gan fara ya lori rẹ.
Amọ Adebowale, lasiko to n ba BBC Yoruba sọrọ, ti wa tọrọ aforijin lọwọ ẹbi atawọn alajọsisẹpọ baba rẹ, ti fidio naa tabuku wọn.
Adebowale salaye pe iku baba oun lo ba oun lojiji, itara naa si ni oun fi se fidio naa lai lero pe o le ru ọkan eeyan kankan soke.
"Mo tọrọ aforijin lọwọ awọn eeyan ti fidio ti mo se, nibi ti mo ti gbe oku baba mi sita ba tabuku wọn, ẹ ma binu, ọmọde lo n se mi.
Itara iku baba mi lo mu mi kede pe ko si ẹnikan, oju opo Whatsapp mi si ni mo gbe fidio naa si, amọ bo se wa gbalẹ kan kaakiri awọn oju opo ayelujara ni ko ye mi rara.
Adebowale ni igbakigba ti oun ba fi fidio ibi ti baba mi ti n ṣe ere tiata han, inu rẹ maa n dun, ti yoo si maa beere pe ṣe awọn yoo sí tun ṣe ere tiata pada mọ?
Igba mii wọn a bù s'ẹkun, igba mi wọn a sì maa rẹrin, sugbọn mo máa n fi wọn lọkan balẹ pe wọn yoo tun pada máa ṣe ere tiata"""
O ni nise ni baba Suwe a máa ronu pupọ nipa iyawo rẹ ati awọn ọmọ naa.
O ni koda laipẹ yii lọ sọ fún àwọn pe oun ko lero pe oun ni asiko púpọ lati lo pẹlu awọn mọ
Freedom Park: Ẹ̀wọ̀n tí àwọn òyìnbò lọ fún ọdun 100 ní Naijiria rèé tí ọ̀pọ̀ ẹ̀mí lọ̀
Ojisẹ Ọlọ́run fún osere tíátà ni ₦8m láti ṣiṣẹ abẹ
Oríṣun àwòrán, prophet Jeremiah Omoto Fufeyin ministries
Yoruba ni ori ẹni nii gbe alawo rere ko ni, bi ori ba si pẹ nilẹ, yoo di ire ni.
Bi ọrọ se jẹ ree pẹlu osere tiata kan, Clem Ohamese ẹni to ri aanu miliọnu mẹjọ naira gba lati ọwọ ojisẹ Ọlọrun kan.
Bẹẹ ba gbagbe, BBC Yoruba ti kọkọ mu iroyin wa fun yin saaju nipa Ohamese to kede pe oun fẹ sisẹ abẹ nitori pe oun ko le rin daadaa.
O ni ijamba ọkọ ti oun ni, lo ti se akoba fun awọn ọmọ ika ẹsẹ oun, tawọn dokita si ni oun nilo isẹ abẹ, ko to di pe oun yoo le rin daadaa.
Oríṣun àwòrán, prophet Jeremiah Omoto Fufeyin ministries
Ìdí sì rèé tí Clem Ohamese ṣe gbé fídíò kan síta pé òun fẹ́ ṣiṣẹ́ abẹ, kí àwọn èèyàn gbà àdúrà fún òun.
Fídíò yìí ni ọkàn lára àwọn gbajugbaja ojisẹ Ọlọ́run kan, Wolii Jeremiah Omotofufeyin ri, to ṣe na ọwọ aanu si osere tiata naa.
Wolii Omotofufeyin gbe ẹ̀bùn Milíọ̀nù mẹ́jọ náírà fún Clem Ohamese láti fi ṣiṣẹ abẹ ọhun.
Ẹ̀bùn owó náà, to jẹ kikida beba sì ni wòlíì Omotofufeyin gbé kalẹ lásìkò ìsìn tó wáyé nínú ìjọ rẹ lọ́jọ́ Aiku níbi tó ti fún osere tíátà náà ni owo beba.
Oríṣun àwòrán, prophet Jeremiah Omoto Fufeyin ministries
Clem Ohameze, òṣèré tíátà ní àìlera, ó ń bẹ̀bẹ̀ àdúrà lórí iṣẹ́ abẹ
Oríṣun àwòrán, Screen Shot
O kere o pọ, ki Eleduwa ma jẹ ki aisan ṣe wa, ko ma ṣe ẹni ti a mọ.
Gbajugbaja osẹre tiata Nollywood, Clem Ohameze lo n bẹbẹ adura lọwọ awọn ọmọ Naijiria bi o ti fẹ lọ fun iṣẹ abẹ ẹyin rẹ.
Ohameze ṣalaye ninu fidio kan ti o fi si ori ayelujara, lo ti sọ pe oun fi eegun ẹyin ṣeṣe ninu ijamba ọkọ to ṣẹlẹ si oun.
O sọ pe ijamba ọkọ naa ti oun fi ẹyin ṣeṣe lawọn dokita sọ fun oun pe o ti ṣakoba fun ẹsẹ oun.
Eyi ni ko le jẹ ki o le rin bayii, ṣugbọn pẹlu iṣẹ abẹ ti o fẹ ṣe, o yẹ ki ara rẹ le pada bọ sipo.
Itunu Babalọla Death:Àgbáyé ẹ gbà mí, mọ fẹ́ ìdájọ́ òdodo lórí ikú ọmọ mí! ìyà yí tí pọ̀jù
Amọ, o sọ ninu fidio to fi lede lori ayelujara pe iṣẹ abẹ ọhun n ba oun lẹru.
''Mo nilo iranlọwọ awọn ọmọ Naijiria nipa adura bi mo ṣe n lọ fun iṣẹ abẹ yii.
Ayẹwo ti wọn ṣe fun mi lẹyin ti ijamba ọkọ ṣẹlẹ si mi tan, lo fihan pe koko eegun kan ninu eegun ẹyin mi ti yẹ le omiran.
Eleyii lo mu ki ẹru pọ lori eegun ẹyin mi ti ko si le jẹ ki n rin.
Wọn tọju mi fun igba diẹ, mo gbadun diẹ, ṣugbọn laipẹ si akoko yii mo ṣe akiyesi pe mo n ni inira ti mo ba ti n rin.
Mo pada lọ si ile iwosan nibi ti mo ti ṣe ayẹwo MRI lori ẹyin mi.
Lẹyin ayẹwo yii ni awọn dokita sọ fun mi pe mo nilo iṣẹ abẹ lati ya koko eegun ẹyin mi meji to wa lori ara wọn ki n le maa rin daadaa.
Ṣugbọn ẹru ba mi nigba ti wọn sọ fun mi ọna ti wọn maa n gba ṣe iṣẹ abẹ naa.
Wọn ṣalaye fun mi pe wọn maa ni lati la ọrun mu lẹyin ki wọn lanfani lati ya koko egungun to sun lera wọn sọtọ.
Amọ, bi ọjọ ṣe n gori ọjọ, mo ri pe ara inira naa n pọ si fun mi lati rin.
Lẹyin naa ni mo pinnu lati ṣe iṣẹ abẹ ti wọn sọ yii ki n le maa rin pada.
Ọkan mi daru gan an, ailera mi yii si ti ṣakoba iṣẹ mi ni gbogbo ọna.
Loṣu to n bọ ni mo maa lọ fun iṣẹ abẹ yii, mo si mọ pe adura yii yoo gba lori mi, Ọlọrun yoo si ko mi yọ,'' Ohameze lo ṣalaye bẹẹ.
Timothy Adegoke: Màmá olóògbé ní ògó ilé àwọn ni wọ́n pa, ikú rẹ̀ kò gbọdọ̀ já sásán
Timothy Adegoke: Iléèṣẹ́ ọlọ́pàá ní àwọn kò ṣègbè lẹ́yìn Adedoyin tó ni ilé ìtura Hilton, ti akẹ́kọ̀ọ́ OAU kú sí
Oríṣun àwòrán, Rahman Adedoyin
Ileeṣẹ ọlọpaa ipinlẹ Osun ti ṣalaye pe Ọmọba Rahman Adedoyin, to jẹ ọkan lara awọn afurasi lori iṣekupani akẹkọọ fasiti OAU, Timothy Adegoke, ti ka fọnran ohun rẹ to lu oju ayelujara pa silẹ, ki awọn ọlọpaa to mu un.
Agbẹnusọ ileeṣẹ ọlọpaa, Yemisi Opalola lo fidi ọrọ yii mulẹ fawọn akọroyin.
Opalola ni fọnran ti ọkunrin naa sọrọ ninu rẹ pe, oun ko mọwọ mẹsẹ ninu ibi wn se pa Adegoke tabuku ileeṣẹ ọlọpaa tori ọpọ eeyan ro pe ni akata ọlọpaa lo ti sọrọ yii.
O ni iṣẹlẹ yii gan an ti jẹ ki ileeṣẹ ọlọpaa tubọ jara mọ iwadii ti wọn n ṣe lori awọn to ṣeku pa Adegoke.
Opalola ni ''afurasi Adedoyin sọ fun awa ọlọpaa pe oun sọrọ ninu fọnran nigba ti awọn ọlọpaa bẹrẹ si ni ko awọn oṣiṣẹ oun ni ile itura Hilton ni Ile Ife.
Timothy Adegoke: Màmá olóògbé ní ògó ilé àwọn ni wọ́n pa, ikú rẹ̀ kò gbọdọ̀ já sásán
O ni oun ti sọrọ sinu fọnran yii ki awọn ọlọpaa to mu oun, ati pe oun ṣalaye ninu fọnran yii lati le jẹ kawọn eeyan ti wọn n pe oun ni oloogun owo mọ pe oun ko lọwọ ninu iku Adegoke.
O ni awọn eeyan ti sọ oun ni orukọ ti oun kii jẹ lai fi oju ofin wo ọrọ naa.
Ọjọ kọkanla ati ikejila oṣu kọkanla ni ileeṣẹ ọlọpaa mu awọn oṣiṣẹ Adedoyin nigba ti oun gan an dero agọ ọlọpaa lọjọ kẹẹdogun.
O ni oun ko tiẹ mọ pe fọnran naa ti lu ori ayelujara pa ki awọn ọlọpaa to sọ fun oun.
Adedoyin tiẹ tun sọ fun awa ọlọpaa pe foonu oun gan an ko si lọwọ oun mọ.''
Agbẹnusọ ileeṣẹ ọlọpaa wa ni awọn ko ni da isẹ duro lori ati tu iṣu de isalẹ koko lori iṣẹlẹ ọhun.
Opalola tun ṣalaye pe ileeṣẹ ọlọpaa ko figba kankan sẹgbe lẹyin Adedoyin.
Eto idibo 2020 Oríṣun àwòrán, Facebook /Nana Akufo-Addo Àkọlé àwòrán, John Mahama ati Nana Akufo Addo n fi oju pa ara wọn rẹ Eto idibo Ghana: Ọdun yii jẹ ọdun ibo didi, a o si bẹrẹ pẹlu orilẹede Ghana nibi ti wọn yoo ti ṣe eto idibo aarẹ wọn l'ọdun yii.
Nítorí náà, gbogbo ìran Jesu láti ìgbà Abrahamu títí di ti Dafidi jẹ́ mẹrinla; láti ìgbà Dafidi títí di ìgbà tí wọn kó àwọn ọmọ Israẹli lẹ́rú lọ sí Babiloni jẹ́ ìran mẹrinla; láti ìgbà tí wọn kó wọn lẹ́rú lọ sí Babiloni títí di àkókò Kristi jẹ́ ìran mẹrinla.
” Òun ati gbogbo ilé rẹ̀ bá gba Jesu gbọ́.
Arsenal ti lu Man City wọ FA Cup final, Man United ti DJ Cuppy sa lọ fìdí rẹmi Ṣe ẹkọ nla kọ ni yii pe nigba miran o san ki eeyan kuku maa faradaa pẹlu eṣu to ti mọ tẹlẹ ju angẹli ti oo tii mọ iwa to maa hu to ba ya lọ.
 Ekun yii yoo maa kede ewu to wa titi osu meta sii lati rii pe awon opa omi ko gbe kaakiri.
Súre fún èmi náà, baba mi.
Nigba ti BBC kan si Agbẹnus fun gomina Akeredolu, o ni bẹẹ ni ọga oun ati ọga ajọ NDLE wa ni orilẹede Thailand lọwọlọwọ.
Kíni àwọn ìgbẹ́sẹ̀ láti dènà omíyale àgbàrá ya sọ́ọ́bù Ó ṣe pàtàkì láti mọ pé kò yẹ láti kọ́le si etí ibí ti omí odò ń gbà kọjá tabi kọle si ojú àgbàrá: O wá ṣeéṣe ki ẹlòmiran ti kọ́le si ètí omí, ọ̀nà abáyọ míràn tún ní pé, lásìkò ọ̀gbẹlẹ̀, o ṣe pàtàkì láti mọ ọgbà yii ilé náà ka, bákan náa ní kí a gbìyànjú láti gbin igi ti yóò dúro bi araba lati dí agbàrá lọ́wọ́, láti ma wọle.
" Ó ń tọ́ka si fọ́nran kan tó jáde lọ́dún to kọjá níbi ti Ganduje tí ń ko dọ́la sápò, nígbà ti ti ọkunrin kan tí wọ́n pe ni kọgila tó ń ko owó fun Gbanduje.
Eyi lo mu Abiola du ipo gomina ni ẹẹkan si fun saa keji, to si tun wọle pada bii gomina ipinlẹ Oyo, eyi ti ko sẹlẹ rí ninu itan oselu ipinlẹ naa.
Dokita Lloyd, to jẹ Ọjọgbọn nipa Itan ati ero ẹda ni Fasiti Indiana ṣalaye pe ti o ba ge ọpọlọpọ isan kuro ni ara idọ obinrin, ara ko ni i gbe daadaa fun ibalopọ, nitori pe awọn iṣan to ṣe pataki lo n ge""."
OLUWA sọ nípa ìdílé ọba Juda pé,“Bíi Gileadi ni o dára lójú mi,ati bí orí òkè Lẹbanoni.
igbaaya , ti o si gbẹmii mi lẹsẹkẹsẹ.
"Eniola tun rọ awọn ololufẹ, ẹbi ati ọrẹ to maa n sọ pe o ti tobi ju lati bu omi suru mu.
Àwọn ọmọ Yorùbá wo ni mínísítà ní ìjọba Buhari?
 Ni bayii a n tiraka lati pese awon ohun amayederun pelu owo kekere ti a n ri.
Nígbà tí wọ́nm sì bẹ̀rẹ̀ sí ọ̀rọ̀ mi í sọ ti èkínní ń bú mi tí èkejì ń bú mi tí wọ́n ń fi ọ̀rọ̀ mi dárayá tí wọ́n ń sọ ọ́ ní ìsọ ẹ̀gàn tí wọ́n sí ń pè mí ní orúkọ tí bàbá àti ìyá mí kò sọ mí, inú bí mi, mo fa àdá yọ mo bọ́ ssí ààrin wọn bí ìmọ̀nàmọ̀nà mo ṣá ọkùnrin yìí ó ṣubú lulẹ̀, ìyàwó mi sá lọ ṣùgbọ́n kò mọ̀ pé emi ni.
” Ó wá sọ fún mi pé, “Àwọn wọnyi ni wọ́n ti kọjá ninu ọpọlọpọ ìpọ́njú.
”Wọ́n dá a lóhùn pé, “Ṣe ohun tí ó bá tọ́ lójú rẹ.
Ìwọ náà yóo dàgbà, o óo di arúgbó, ní ọjọ́ àtisùn rẹ, ikú wọ́ọ́rọ́wọ́ ni o óo kú.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Election 2019 Updates: Atiku ní ìbò 18m ni mo ní, Buhari sì ní ìbò 16.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, SS3 ní mo wà báyìí, mo sì ti gba àmì ẹ̀yẹ̀ púpò nílé-lóko gẹ́gẹ́ bí onílù - Ayansike ''O da wa loju ninu ẹgbẹ oṣelu APC pe Arakunrin Oluwarotimi Akeredolu, SAN ati oludije fun igbakeji Gomina pẹlu rẹ, Lucky Ayedatiwa to gbangba sun lọyẹ ninu eto idibo to n bọ papaa julọ pẹlu awọn iṣẹ akansẹ ti ijọba Akeredolu ti ṣe laarin ọdun mẹrin akọkọ nipinlẹ Ondo,'' Ọgbẹni Kalejaye lo sọ bẹẹ.
 Gẹgẹ bi ile-isẹ  ọlọpaa  ti sọ, o yẹ ki asọfin Saraki yọju si ile-isẹ ọtẹlẹmuyẹ to wa ni Guzape, ni Abuja.
Wọ́n ta ẹ̀jẹ̀ aláìṣẹ̀ sílẹ̀,àní, ẹ̀jẹ̀ àwọn ọmọkunrin,ati ti àwọn ọmọbinrin wọn,tí wọ́n fi bọ àwọn oriṣa ilẹ̀ Kenaani;wọ́n sì fi ẹ̀jẹ̀ sọ ilẹ̀ náà di aláìmọ́.
Àwọn arakunrin rẹ̀ bá wá láti tù ú ninu.
Fẹlẹ́, tó jẹ alága ẹgbẹ́ ọlọ́kọ̀ èrò ní ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́, dagbere faye lẹ́ni ọdún méjìdínlọ́gọ́ta Awọn oloselu, asoju ẹgbẹ awakọ jakejado ẹkun iwọ orun-guusu, to fimọ awọn amuludun naa ko gbẹyin nile oloogbe.
 Kẹhinde sọ pe, ọrọ ti Ọbasanjọ sọ yii ko tumọ si pe ko mọ iha ẹni to wa, bi ko ṣe pe 'ọdẹ tabi omugọ eniyan nikan ni ko ni mọ ibi to n lọ lasiko ti aijafafa, iwa ibajẹ, ailafojusun, aibọwọ f'ofin ati ṣiṣe ègbè n ba orilẹede rẹ jẹ."
Ijọba ilẹ Gẹẹsi ti kede ẹni to jawe olubori ninu ibo Olootu ijọba ilẹ Gẹẹsi ti wọn di lọjọ Isẹgun.
Ẹ̀ ń fi ẹ̀ṣẹ̀ àwọn eniyan mi wá oúnjẹ fún ara yín, ẹ sì ń mú kí wọ́n máa dá ẹ̀ṣẹ̀ kún ẹ̀ṣẹ̀ 
"O ni, ""Awọn eniyan daradara wa kaakiri; ọ gbọdọ wa wọn kan."
Ìdàgbàsókè tí ó máa ń wà nínú àwùjọ kò sẹ ̀ yìn ìfọwọ ́ sowọ ́ pọ ̀ bí àti ránmú un gángan ò ti sẹ ̀ yìn èékánná .
Ẹfunsetan Aniwura, obìnrin tó ju ọkùnrin lọ Ọ̀rọ̀ǹpọ̀tọ̀niyùn, Aláàfin obìnrin àkọ́kọ́ rèé, tó ní nǹkan ọkùnrin Idajọ naa sọ ajọ EFCC di ajawe olubori gẹgẹ bi adajọ ṣe ni arabinrin Jonathan ko ni aridaju lati fi han pe ọna to tọ ni oun fi ri owo naa ati idi ti wọn ko fi ni gba owo naa lọwọ rẹ.
Bàbá mi, bí ẹ ti sọ̀rọ̀ jú, ẹ dẹ́rù bà mí lọ́pọ̀lọpọ̀, bí ikú bá jẹ́ aláàánu kò gbọdọ tíì ṣe bẹ́ẹ̀ mú yín lọ.
Ìkọlù Benue: Adaran pa àlùfáà méjì, ọmọ ìjọ 13 nílé ìjọsìn
Tinubu, ojú tì ẹ́, o ta Yorùbá fún ọ̀tá torí àdánìkànjẹ - Fani-Kayode Oríṣun àwòrán, Bola Tinubu Minisita tẹlẹ ni Naijiria Femi Fani Kayode, ti kọ lẹta ranṣẹ si asaaju ẹgbẹ oselu APC, Asiwaju Bola Ahmed Tinubu, lẹyin ti Aarẹ Muhammadu Buhari yan Alaga fidiẹ tuntun fun ẹgbẹ oṣelu APC.
Awọn kan tilẹ ti n tọwọ bọwe lori itakun chanage.
- Yinka TNT Lasiko ti a n sọrọ rẹ yii, awọn eebo amunisin lo n dari akoso ilẹ yii, ko si si ohun to n jẹ orilẹ-ede Naijiria, ti ileesẹ ọlọpaa si wa labẹ akoso wọn.
Ibi kii se agbegbe ti wọn yoo maa wa lẹẹkọọkan nitori o yẹ kawọn Amotekun ati Civil Defence wa nibi ni gbogbo igba amọ ko si nkankan nibẹ.
Àwọn adẹ́tẹ̀ mẹrin kan wà ní ẹnubodè Samaria, wọ́n sọ fún ara wọn pé, “Kí ló dé tí a óo fi dúró síbí títí tí a óo fi kú?
Nítòótọ́, ó ti gbé ìkáàánú wa lọ, ó sì ti ru ìbànújẹ́ wa;sibẹsibẹ a kà á sí ẹni tí a nà,tí a sì jẹ níyà láti ọ̀dọ̀ Ọlọrun.
Ó wá bi wọ́n pé, “Kí ni ẹ rò nípa èyí?
Ó tẹ̀síwájú pé 'ẹ jẹ́ ká ko àwọn ọmọ wa lédè Yoruba to dan mọ́ran'.
Se lootọ ni pe eniyan le ko Coronavirus lara ẹni to ti kú?
O foya pe ẹlomiran ko tilẹ ni gbe ija rẹ dori ayelujara, wọn lee pete ibi labẹlẹ eyi ko si dara lati padanu ẹnikẹni.
Mo ní, ‘Nígbà gbogbo ni wọ́n máa ń ṣìnà ní ọkàn wọn.
Ẹ la ọ̀nà, ẹ la òpópónà,kí ẹ ṣa òkúta kúrò níbẹ̀.
Wọ́n bá fi ìyókù pamọ́ títí di òwúrọ̀ gẹ́gẹ́ bí Mose ti sọ fún wọn; kò sì rùn, bẹ́ẹ̀ ni kò yọ ìdin.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'A fẹ́ kí àwọn sẹ́nétọ̀ gba ẹlòmíì láàyè' ''Nibi ti a ti ni awọn ileeṣẹ wọnyii, ki ni ipa ti wọn ni?
Ohun ti awọn aṣofin naa ni o faa ti wọn fi sa kuro ni ilu Akurẹ ko ṣẹyin bi wọn ṣe ni abo to peye ko si fun ẹmi awọn lati igba ti wọn ti yọ olori ile naa tẹtẹ nipo.
Aare so fun gominaa naa pe”olola julo e se daadaa.
AMAA 2018 Ami eye fun osere amugbalegbe to dara ju
O yari lati yi ọrọ rẹ pada toun ti pe ẹgbẹ to wa ni ijọba ni ki o da ọrọ na pada.
Ẹ ṣàánú mi, ẹ ṣàánú mi, ẹ̀yin ọ̀rẹ́ mi,nítorí ọwọ́ Ọlọrun ti bà mí!
O ni ẹbi awọn ko tilẹ mọ alukoro ileeṣẹ naa rara.
'Ìdùnnù wa kọ́ ni kí á má fún ọmọ Nàìjíríà ní 'Visa' Lẹ́yìn oṣù márùn ún, Buhari kọ̀ láti yọ ọ̀ga NHIS Ta ló gé orí ọkùnrin mẹ́ta ní Lekki?
Ẹwẹ, lori ijinigbe to n waye, ẹka ẹgbẹ awọn agbẹjọro nilu Ọwọ nipinlẹ Ondo ṣe iwọde lọjọ kejila, oṣu Kejila pe ki ijọba o kede nkan o fararọ lori ijinigbe.
Ilẹ̀ Juda yóo di ẹ̀rù fún àwọn ará Ijipti, ẹnikẹ́ni tí ó bá gbọ́ yóo bẹ̀rù nítorí ohun tí OLUWA àwọn ọmọ ogun ti pinnu láti ṣe sí Ijipti.
Ó ranṣẹ pada sí Solomoni, ó ní, “Mo gbọ́ iṣẹ́ tí o rán sí mi, n óo sì ṣe ohun tí o ní kí n ṣe fún ọ nípa igi kedari ati igi sipirẹsi.
Àṣìṣe ló ṣẹlẹ̀ níbi ètò ìsìnkú Abba Kyari- FCTA Yewande bí'mọ tuntun jòjòló, Mercy Aigbe pàdánù èèyàn rẹ̀, Toyin Abraham fèsì lórí aṣoju NCDC Ìtàn Manigbagbe: Àwọn àjakalẹ-àrun to ti wáyé rí ṣáájú Coronavirus Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí kan sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
Adwa je oju oja ti o bale si arin gungun ila oorun Ethiopia ni Tigray, ti awon ara ilu ko le se lati ma sabewo si lojumo kan.
kí ó lè dá wọn lẹ́kun ìṣe wọn,kí ó lè gba ìgbéraga lọ́wọ́ wọn;
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Baby abandoned on dunmpsite: Mo ti bímọ mẹ́rin tẹ́lẹ̀ fún bàbá méjì nínú òṣí- Dupe Ogbomos O wa rọ ijọba lati seranwọ lori atunse ọna naa.
Gbogbo ilé ọmọ aláìgbọràn nílẹ̀ Yorùbá, Ọlọ́pàá ń bọ̀ wá yẹ̀ yín wò Nínú òkuǹkùn birimù birimù ni mo wà báyìí ni ilé Ìjọba - Igbakeji Gomina Kogi àná Ǹjẹ́ o mọ̀ pé ètò ìdìbò kan wà tí erin àti òkúta Dáyámọ́ǹdì leè yí èsì rẹ̀ padà Eyi wáye lẹ́yin ti wọ́n so igbẹ́jó náà pọ̀ adájọ́ àgbà Abubakar Malami nínú ejọ náà.
Ẹ̀mí bá gbé mi sókè ní ojúran, ó gbé mi wá sí ilẹ̀ àwọn ará Kalidea, lọ́dọ̀ àwọn tí wọ́n wà ní ìgbèkùn.
"Wọ́n ti ní kí Jolaosho ""TBlak"" wá káwọ́ pọ̀nyìn r'ojọ́ ìdí tó fi ya ""Blue Film"" nínú igbó Osun Osogbo 'Níbo lo ti gbé ọmọ aràrá wa ni bàbá mi kò bá bi ìyá mi' - Aràrá adájọ́ Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí 6:10 Fídíò, Yoruba Language: Akomolede ati Asa Yoruba tọ̀sẹ̀ yí rèé lẹ́nu olùkọ́ wa, Duration 6,1030 Ògún 2020 6:18 Fídíò, Akomolede: Bolaji Faleke ni Olùkọ́ tó ń kọ́ wa ní àṣà oge ṣiṣe lórí BBC Yorùbá, Duration 6,181 Owewe 2020 Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí 2 sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn."
Oríṣun àwòrán, AFP Àkọlé àwòrán, Awon omo wonyi ti setan lati bere ikoni si ipo agba leyin odun yii Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Isẹ́ Tíátà tí mò ń se ti tó mi jẹun' Oríṣun àwòrán, EPA Àkọlé àwòrán, Awon omo ogun ile n so eranko yii pelu ohun gbogbo ti won ni Ni orilẹ-ede Kenya ni a ti ri awọn ọmọ ogun ilẹ yii ti wọn n ṣo diẹ lara awọn erinmi ni Kenya.
Àwọn Farisi jáde lọ sí ọ̀dọ̀ rẹ̀, wọ́n ń dán an wò nípa fífi ọ̀rọ̀ wá a lẹ́nu wò, wọ́n ní kí ó fi àmì láti ọ̀run hàn wọ́n.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsèjẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọ Gomina tẹlẹ naa lo fi ọpọ igo ọti lile Hennessy sinu apo imọtoto fun arun Coronavirus ti wọn n pin fawọn olugbe ilu Nairobi, to si ni ọti lile naa le dena arun Covid-19.
Ọjọ kẹrindinlọgbọn oṣu Kẹsan Wọn bi arabinrin Madikizela-Mandela nilu Bizana, Transkei (Eastern Cape).
Ọgbẹni Powell to jẹ onimọ nipa oṣelu sọ pe awọn ologun kii fẹ gbọ pe awọn fipa gbajọba.
Ẹ̀wẹ̀, Femi Fani-Kayode naa tun ti wá fèsì, tí òun pẹ́lú sì rán Odunakin si Tunde Bakare pé ìbéérè lásán ni òun ń bèrè o.
Ilumọọka elege ara ni agbabọọlu ọmọbibi orilẹede Argentina, Maradona jẹ, koda awọn eeyan kan gbagbọ pe oun ni agbabọọlu to dantọ julọ ninu iwe itan.
"Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ojude Ọba 2019: Àwọn èèkàn lórílẹ̀-èdè Nàìjíríà ti péjú fún ayẹyẹ ojúde Ọba 13 Ògún 2019 Àkọlé àwòrán, Ojude Oba tí ọdún yìí ti gbéra sọ pẹ̀lú oníruuru àwọn aṣọ alárànbara yorùba to ń wúni lóri, Awọn ẹgbẹ́ Tobalàṣẹ obinrin rèé nínú àṣọ okè aláwọ̀ ewé 'Kò sí ohun tó burú nínú bí Ajimobi ṣe dá Yewande tó pa ọkọ rẹ̀ sílẹ̀' Àwọn Fadá mẹ́rin gbà itusílẹ̀ lọwọ àwọn ajínigbé Samuel Okwaraji: Ó pé ọgbọ̀n ọdún tí lónìí ti akọni àgbábọ̀ọ̀lù papo dà Ẹ ṣe àwárí ọdànran tó bọ mọ́ọ yín lọ́wọ́ - Turkur Buratai Àkọlé àwòrán, Gbogbo àwọn ọmọ ẹgbẹ́ Gbobaniyi lókùnrin àti lóbìrin ló ti lọ ki ọba aláde lóri ìjòkò Àkọlé àwòrán, Lẹ́gbẹ́ lẹ́gbẹ́ ni gbogbo àwọn ti wọ́n péju síbi ayéyé Ojude Oba tí ọdún 2019 Àkọlé àwòrán, Tokùnrin tobinrin ló wọsọ ìgbà níbi àyẹyẹ ojude oba tọdún yìí, Ẹgbẹ́ Bọbakẹ́yẹ Ọkunrin ni àwọn yìí Àkọlé àwòrán, Tarúgbó tomidàn ló wà nibi àyẹyẹ yìí, gbogbo oju wọ́n lo gúrégé pèlú, àwọn ẹgbẹ́ bọ́bakẹ́yẹ obinrin rèé Àkọlé àwòrán, Gbogbo àwọn olóyè àti èèkàn ìlú ló péjú Àkọlé àwòrán, Kìí ṣe àwọn ẹgbẹ́ gbẹ́ jọdá nìkàn ló péju, àwọn ọdọ náà jáde wá láti yẹ́ àṣ]a ìbílẹ̀ sí Àkọlé àwòrán, Aláàfin Ọyọ, ikú bábá yèyé, Ọba Lamidi Adeyemi náà péjú síbi ayẹyẹ ojúde Oba ní'lú Ijebu Àkọlé àwòrán, Gómínà ìpínlẹ̀ Ogun, Dapo Abiodun àti Awùjalẹ̀ Ijẹ̀bú Ọba Sikiru Adetona Àkọlé àwòrán, Gómìnà tẹ́lẹ̀rí ní ìpínlẹ̀ Ogun, Ọtunba Gbẹnga Daniels Àkọlé àwòrán, Ẹgbẹ́ Bọ́baguntẹ ilẹ̀ Ijẹbu Àkọlé àwòrán, Gbogbo ojú tó ti ríra típẹ tún ni àànfàni láti ṣe ""Ẹ k;u àti"" Àkọlé àwòrán, Ẹgbẹ́ Obafunwaji Obinrin Adedoyin rèé nínú aṣọ ofi aláwọ̀ búlù Àkọlé àwòrán, Ẹgbẹ́ Tobalaṣẹ Ọkunrin náà ko gbẹ́yìn Àkọlé àwòrán, Gbogbo àwọn ọmọ ẹgbẹ́ Gbobaniyi lókùnrin àti lóbìrin ló ti lọ ki ọba aláde lóri ìjòkò Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!"
OLUWA tún wá, ó dúró níbẹ̀, ó pe Samuẹli bí ó ti pè é tẹ́lẹ̀, ó ní “Samuẹli!
 “Gbigbogun-ti iwa-ibaje ko le e waye lojo kan soso, bee si ni ki i se eto ti eniyan le e pari lọdun kan, asiko se pataki pupo lati koju iwa-ibaje.
Ni Naijiria titi pa ni gbogbo ile ẹkọ yoo wa titi di igba ti wọn yoo fi se agbeyẹwo ẹkunrẹrẹ.
Kò sí owó lọ́wọ́ wa mọ́ rárá.
Arap Moi: Ilé ẹjọ́ ní kí aààrẹ Kenya àná san owó ìtanràn $10m fún opó nítorí ilẹ̀
Elebu Road ti wa di Alao-Akala Way.
Ǹjẹ́ ẹ ti jẹun ní KFC láìpẹ́ yìí bí?
"Awọn iroyin ti ẹ lee nifẹẹ si: Buhari dasi ipaniyan Benue 'Gba Buhari ni'mọran ifẹyinti' ""Bẹẹ ba gbagbe, eto ifikunlukun taa nse lo mu ki wọn tu awọn olukọ fasiti ilu Maiduguri silẹ pẹlu awọn osisẹ ọlọpa obinrin, awọn akẹkọ to fi mọ awọn agunbanirọ pẹlu."
a lè sọ ̀ rò nípa àwọn ọ ̀ wọ ́ ọ ̀ rò mìíràn , tó yàtọ ̀ sí Àwọn ọ ̀ rọ ̀ orúkọ àti àwọn ọ ̀ rò ìse , sùgbón ẹ jẹ ́ kí á padá séyìn láti wo àwon ìjíròrò wa fún ìbáramu .
A tun ti pe ẹgbẹ awọn apoògun lati sọ fun wọn pe, a ti gbẹ́sẹ̀ lé awón oògùn naa.
Bí Jesu ti ń sọ̀rọ̀ ni àwọn eniyan bá dé.
wọn kò sì gbọdọ̀ gbàgbé majẹmu tí òun bá wọn dá.
Koda ninu àṣà ilu ti mo ti wa, àwọn eeyan kii rinrinajo ifẹ, lasiko ti wọn bi ni.
Agidi ni Arsenal fi gba ọmọ alayo meji si meji pẹlu ikọ agbabọọlu Southampton lopin ọsẹ to kọja ninu idije Premier League.
N óo wá ninu agbára OLUWA Ọlọrun,n óo máa kéde iṣẹ́ òdodo rẹ, àní, iṣẹ́ òdodo tìrẹ nìkan.
Awọn eeyan ka ọrọ rẹ wewo wọn si lọ dibo, ababọ ibo ni pe Bukola Saraki fidirẹmi ninu ibo.
Ẹ̀ṣọ́ NSCDC ṣèèṣì yìnbọ̀n pa ọlọ́pàá ọ̀tẹlẹ̀múyẹ́ DSS l'Osun O ni ọrọ abuku ni asoju Kwam 1, Kunle Rasheed sọ nipa iṣẹlẹ naa fun BBC News Yoruba nibi to ti sọ fun ẹgbẹ FIBAN lati sa ipa wọn lori iṣẹlẹ naa, koda wọn le e gbe awọn lọ si ileẹjọ.
Kò sí iṣẹ́ kan tí kò lérè,ṣugbọn ọ̀rọ̀ ẹnu lásán láìsí iṣẹ́, a máa sọ eniyan di aláìní.
Gẹgẹbi ọrọ awọn ọlọpaa, iyawo to d'oloogbe naa, Alizee ati ọmọ rẹ to jẹ ọmọ ọdun mẹrin ni wọn ba oku wọn ninu ile wọn to wa ni Banana Island, ni ilu Eko pẹlu amin lilu ni ara wọn.
Eyi tumọ si pe wọn yoo fi awọn owo naira tuntun rọpọ awọn to dọti gẹgẹ bi adari ẹka to ri si ẹnawo naira, arabinrin Priscilla Eleje ṣe sọ.
Jesu dá wọn lóhùn pé, “Ẹ má ṣe kùn láàrin ara yín mọ́.
Wọ́n sọ fún un pé, “Ṣé kì í ṣe pé ọ̀kan ninu àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ ni ọ́?
Oríṣun àwòrán, Osinbajo/instagram Àkọlé àwòrán, Ìbéèrè mẹ́rin ti Laolu Akande bèrè lọ́wọ́ Festus Adedayo Ẹ̀wẹ̀, oluranlọwọ pàtàki si igbákeji ààrẹ feto iroyin ni ki Adedayo sàlàyé ẹka ìjọ RCCG naa àti ọjọ ti àdúra náà wáye gẹ́gẹ́ bo ṣe fẹ̀sùn kan igbakeji aarẹ.
Wo òfín tuntun tí INEC ṣe fún ìdìbò 2019 Wo àwọn tó dipò ìlú mú tí wọ́n jẹ́jọ́ lórí dúkìa Guardiola gbóṣùbà fáwọn agbábọ́ọ̀lù Man City Òní lóyẹ k'ọ̀gá ọlapàá Ibrahim Idris fẹ̀yìntì Kini oun ti wọn tilẹ n dibo le lori gan?
Lara wọn ni, Fasiti ijọba apapọ ipinlẹ Eko, ni ọdun 1967 si 1970, ati University of Leeds, ni ilu ọba.
Nítorí náà, ẹ pa àwọn ìfẹ́kúfẹ̀ẹ́ ẹ̀yà ara yín ti ayé run: àwọn bíi àgbèrè, ìwà èérí, ìṣekúṣe, ìfẹ́kúfẹ̀ẹ́, ati ojúkòkòrò tíí ṣe ìbọ̀rìṣà.
" Yatọ si amugbalẹgbẹ aarẹ to ti lugbadi arun ọhun, gomina ipinlẹ Bauchi, Bala Mohammed naa ti fara kaasa arun ọhun.
''Buhari, Zamfara là fẹ kí o lọ, kìí ṣé Jordan'' Ọ̀rọ̀ǹpọ̀tọ̀niyùn, Aláàfin obìnrin àkọ́kọ rèé, tó ní nǹkan ọkùnrin Rélùwéè tẹ alágbe kan pa ní Eko Bakan naa, Aarẹ Buhari koro oju si bi awọn ẹlẹgbẹ okunkun ti n fẹmi awọn eeyan ṣofo nipinlẹ Rivers.
Kòsí àṣà tó faramọ́ fífi èmí ènìyàn ṣe ìrúbọ - Olúwó Ìpínlẹ̀ Ondo ti ní gómìnà tuntun Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Yoruba World Congress: Mi o fi gbogbo ẹnu sọ pé ẹ̀yà Yorùbá yóò tún èrò rẹ̀ pa ní October 1- Akintoye28 Owewe 2020 6:18 Fídíò, Akomolede: Bolaji Faleke ni Olùkọ́ tó ń kọ́ wa ní àṣà oge ṣiṣe lórí BBC Yorùbá, Duration 6,181 Owewe 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Ọkunrin kan wà ní Jerusalẹmu tí orúkọ rẹ̀ ń jẹ́ Simeoni.
Bí kò bá wá wù yín láti máa sin OLUWA, ẹ yan ẹni tí ó bá wù yín láti máa sìn lónìí.
Ipade naa bere laago mewaa owuro, ti o si kun fun awon eniyan jakan-jankan miiran ti won ti figbakan je gomina ri, ti o fi mo oga agba ile-ise olopaa.
Ẹ ranti àwọn nǹkan ti àtijọ́,nítorí pé èmi ni Ọlọrun, kò sí Ọlọrun mìíràn mọ́.
Onnoghen jẹ̀bi ẹ̀sùn tí wọ́n fi kàn án, ó pàdánù owó rẹ̀ Ilé ẹjọ́ kòtẹ́milọ́rùn da ẹjọ́ Onnoghen nù Mọ̀ nípa adelé adájọ́ àgbà tuntun, Ibrahim Tanko Muhammed Gẹgẹ bi akọsilẹ inu iwe naa, ifẹyinti Onnnoghen gẹgẹ bi adajọ Naijiria yoo bẹrẹ ni ọjọ kejidinlọgbọn oṣu karun un.
COM Àkọlé àwòrán, Ọmọ ilu Eko ni akọbi Kofi Annan, Ama, fẹ Akọ̀wé àpapọ̀ tẹ́lẹ̀ rí fún àjọ ìsọ̀kan agbayé (UN), Kofi Annan, to papoda ni ẹni ọgọrin ọdun kii ṣe eniyan lasan.
Ní kété tí adájọ́ gbé ìdájọ́ rẹ kalẹ tán, ní Arogundade ṣubú lulẹ nílé ẹjọ́, táwọn mọlẹbi rẹ náà sì bu sí ẹkún kíkorò.
Biṣọọbu Oyedepo sọrọ yii lasiko to fi n waasu ni ijọ rẹ.
Pẹlu esi yii, o jẹ ayo meje ti wọn gba wọle Dynamo ti eyi si je
Nigeria-China Loan: Afenifere korò ojú sí ìjọba Buhari, bó ṣe ń yáwó kiri
Bakan naa ni awọn ọlọpaa sọ pe ‘awọn ti n ṣayẹwo akọsilẹ ẹrọ ibanisọrọ
Mo sàlàyé rẹ̀ yékéyéké nínú àpilẹkọ mi lọ́jọ́ Jimọ.
35 Kíyèsíi, èmi kò dá yín lẹ́bi; ẹ máa lọ ní àwọn ọ̀nà yín ẹ má sì ṣe dẹ́ṣẹ̀ mọ́; ẹ ṣe àwọn iṣẹ́ tí mo pa láṣẹ fún yín pẹ̀lú àròjinlẹ̀.
Ni igbà ti ó yá, o ni ilé àti ọlà ju gbogbo àwọn yoku ni abúlé ṣùgbọ́n kò to, ó bẹ̀rẹ̀ si ra oko si titi dé oko àwọn ọmọ bàbá rẹ yoku.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Àlàyé rèé lórí bí wọ́n ṣe mú mi lẹ́rú ní 1837 - Ajayi Crowther Samuel Ajayi Crowther, òjíṣẹ́ Ọlọ́run tó gbé èdè Yoruba lárugẹ To bá fẹ́ jàǹfààní iná ọba tí kò ṣẹ́jú látọ̀dọ̀ ìjọba, ọ̀nà ẹ̀bùrú tó gbà rèé Èmi àti Bọla Tinubu fẹ́ lo ‘German Mercenaries’ láti gbé MKO Abiọla kúrò lẹ́wọ̀n - Dele Momodu Mo nífẹ̀ẹ́ Khafi torí kìí díbọ́n tàbí hùwà oníwà - Gedoni sọ̀rọ̀ ìdágbére Lara awọn imọ to n dahun si ọpọ ibeere awọn obinrin ni bi wọn se lee fọ oju ara wọn, titi de awọn ọna ti kokoro aifojuri lee gba sediwọ fun oyun nini ati ọmọ bibi.
Ihò náà jẹ́ ibi tí Dafidi ati àwọn eniyan rẹ̀ farapamọ́ sí.
Ile-ise omo ogun Naijiria ti setan lati ni ibasepo pelu ajo isokan agbaye lojuna ati mu igberu ba eto isomoniyan ni papaajulo ni ikorita ti awon isele lolokan-o-jokan bati waye.
Jọ̀wọ́, arabinrin mi, gbé ọ̀rọ̀ náà kúrò lọ́kàn, ọmọ baba kan náà ni ẹ̀yin mejeeji, nítorí náà, má sọ fún ẹnikẹ́ni.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Gov Ganduje Vs Sanusi: Ganduje kò lẹ́tọ̀ọ́ láti yan Emir mẹ́rin 15 Èbibi 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Òpin ọ̀sẹ̀ ni Gomina ìpínlẹ̀ Kano, Abdullahi Ganduje fi ìwé àsẹ fún àwọn Emir tuntun mẹ́rin láti bẹ̀rẹ̀ isẹ́.
Ni iha keji ẹwẹ, awọn arinrinajo lati South Africa naa nkoju iru kan naa lẹyin ti eya Covid-19 yii jẹyọ nibẹ pẹlu eyi si yatọ si iru eyi ti wọn ri ni UK.
ng tabi ayelujara ti ileesẹ ologun Naijiria gan-an-gan, tẹ bọtinni to ni 'recruitment', ki o si yan SSC tabi DSSC ni oju ewe to ba ṣi.
Owó tí Kiddwaya bá rí ní BB Naija, ìdá kan fún Erica, ìkejì fọ́mọ aláìníyàá - Baba Kiddwaya Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Donald Trump gbìyànjú nípa ètò àlááfíà ló jẹ́ kí n fàá kalẹ̀ fún àmì ẹ̀yẹ Nobel Peace Prize- Christian Tybring- Gjedde9 Owewe 2020 Fídíò, Akomolede ati Aṣa lori BBC: Mọ̀ si nípa oríṣìí ẹ̀ka ìsọ̀rí ọ̀rọ̀ àti ìwúlò wọn8 Owewe 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Ó ga ní igbọnwọ mẹ́wàá (mita 4½).
 O wa gbadura pe ki Ọlọrun kẹ Ajimọbi, ko gẹ ẹ, ko si san gbogbo laada to yẹ ko duro jẹ fun ninu saare."
Iye àwọn ọmọ Lefi tí wọ́n pada dé láti oko ẹrú nìwọ̀nyí:Àwọn ọmọ Jeṣua ati Kadimieli láti inú ìran Hodafaya jẹ́ mẹrinlelaadọrin
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Human trafficking: Ààrẹ Buhari, ẹ̀yin gómìnà ìpínlẹ̀ Yorùbá, ẹ rántí wa ní Oman, àwọn ọmọ De Gea y'ẹ́yin, Man United k'àbùkù lọ́wọ́ Chelsea, Cuppy já pa Man United vs Chelsea: De Gea y'ẹ́yin, Man United k'àbùkù lọ́wọ́ Chelsea, Cuppy já pa!
“Mo fi ara mi búra, ogun ni yóo pa àwọn tí ń gbé àwọn ìlú tí ó ti di ahoro.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Christmas & Border Closure: ìrẹsì dí góòlù fún Kérésì 2019 Pẹlu abajade ifẹsẹwọnsẹ yii, o fihan pe ifẹsẹwọnsẹ kan ṣoṣo ni Arsenal tii bori ninu mẹrindinlogun ti wọn gba sẹyin.
Bẹ́ẹ̀ ni ẹ ti kọ́ ọ̀rọ̀ ìyìn rere lọ́dọ̀ Epafirasi, àyànfẹ́, alábàáṣiṣẹ́pọ̀ wa.
Wọ́n bá bẹ̀rẹ̀ sí bi ara wọn pé, “Ta ni èyí, tí afẹ́fẹ́ ati òkun ń gbọ́ràn sí lẹ́nu!
a Hushpuppi, lori ẹsun pe o lu jibiti lori ayelujara, ni awọn ọmọ Naijiria kan ti n tọka si awọn gbajumọ ti aworan wọn ti jọ han lori ayelujara ri.
Pé kí wọ́n kó wọn lẹ́rù.
Shades of Zinedine Zidane with the roulette.
Bakan naa lo ni ile asofin yoo sisẹ lori ọna tawọn ẹkun kọọkan yoo fi maa se akoso awọn ohun alumọọni to wa ni ẹkun wọn, gẹgẹ bawọn ọmọ ilẹ yii ti n fẹ.
BBC Yorùbá: Temidayọ Ọlọfinsawo ní kò rọrùn láti darí òṣìṣẹ́ ọlọ́pọlọ pípé
Esau bá yipada ní ọjọ́ náà, ó gbọ̀nà Seiri.
Lati kekere ni awọn obi rẹ ti kọ ara wọn silẹ gẹgẹ bii lọkọ-laya, ṣugbọn Fashek ko kuro ni ilu Benin city pẹlu iya rẹ.
Banana Island Ghost – BB Sasore- Nigeria
Minisita fun oro Abele, Abdulrahaman Bello Dambazau lo so eleyii di mimo niluu Abuja.
Àjàgà wúwo ni baba mi gbé bọ̀ yín lọ́rùn, ṣugbọn tèmi yóo tún wúwo ju ti baba mi lọ.
Alaye wọn ni wi pe iyanṣẹlodi alainigbendeke yoo gbinaya bi ijọba ba kọ lati ṣe ohun ti o tọ lẹhin ọjọ marun un.
Àwọn ìjòyè ń fi í ṣe yẹ̀yẹ́, wọ́n ń sọ pé, “O gba àwọn ẹlòmíràn là; gba ara rẹ là bí ìwọ bá ni Mesaya, àyànfẹ́ Ọlọrun.
Ajọ Marie Stoppes ma n ta to miliọnu meji kọndọmu l'oṣooṣu ni orilẹ-ede naa.
Ọgbẹni Shehu ko sọ boya Leah Sharibu wa laye aki ko si ninu atẹjade tirẹ ṣugbọn o ni oun ti fi ọrọ naa to ọfiisi aarẹ leti wọn yoo si gbe igbesẹ.
Winnie Mandela di olóògbé lẹ́ni ọdún mọ́kànlélọ́gọ́rin
Offa Bank Robbery: Àwọn ọlọ́pàá fí ìyà jẹ wá láti sọ nkan ti wọn fẹ ká sọ ni Kò sí èèyàn kánkan tó kù nílé tó wó ní Ibadan- NEMA Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí kan sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
"Ọgbẹni Kabutey sọ pe ""awọn ọlọpaa to wa sibi iṣẹlẹ naa ko sọ ohunkohun, wọn kọ lọ si ibi ti ọkunrin to lewaju awọn agbebọn naa duro si, wọn ba sọrọ ọrẹ si ọrẹ, wọn gba nọmba ara wọn, wọn si yọnda rẹ ko ma a lọ""."
O tun so pe “Bi ẹ se n ka ὸfὸ to waye lori ọja yin, mo baa yin kẹdun lori isẹlẹ buruku yii.
”Wọ́n ní, “Rabi, níbo ni ò ń gbé?
Ni ti Wale Adetona, o ni to ba jẹ pe Obasanjo lo kọ atẹjade naa, ohun to wa lọkan rẹ lo sọ nipa Kashamu, ko si yẹ ki awọn binu si ọrọ naa.
Confederation of African Football to jẹ ajọ bọọlu alafẹsẹgba ti ilẹ adulawọ ni awọn eeyan ti n fẹsun oriṣiiriṣii kan.
"Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Mummy calm down: Oreoluwa di 'Ambassador' ilésṣẹ́ tó ń ṣòwò ilẹ̀ àti ilé 29 Agẹmo 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 23 Ògún 2020 Oríṣun àwòrán, @ore_mommycalmdown Ileeṣẹ kan ni ilu Abuja ti yan Oreofeoluwa Lawal-Babalola, ti ọpọ eeyan mọ si ""Mummy calm down"" gẹgẹ bi aṣoju rẹ."
" Ọpọlọpọ igba ni mo ma n wa ni agbedemeji ìwọ ati isẹ iranṣẹ.
Iṣẹ iṣiro owo ni Ninalowo kọ ni faisiti lorilẹ-ede Amẹrika ti o si fi ṣe iṣẹ fun ni ile ifowopamọsi ki o to tẹle ohun ti ọkan rẹ fẹ, iyẹn iṣẹ ere ori itage.
Ipaniyan yi waye lẹyin isẹlẹ ti ilu California, nibi ti agbebọn kan ti pa eeyan mẹta nibi ayẹyẹ afihan ounjẹ kan.
(Telegraph) EFCC kó akẹ́kọ̀ọ́ fásitì UNIOSUN Wo àwọn tí gómìnà ìpínlẹ̀ Oyo fi orúkọ wọn sílẹ̀ fún ipò kọmísánnà Ẹ wo ọmọ ọdún méje tó di Gómìnà l'Ekiti Ẹni orí yọ, ó dilé!
Nitirẹ, Pep Guardiola ṣalaye pe nnkan ko ṣẹnure fun awọn agbabọọlu rẹ nitootọ.
Ilakalẹ fun ayẹwo ẹni to ba ni arun yii ki o to lee gba iwe ṣaka lara da ni lati ṣe ayẹwo meji ọtọọtọ eyi ti yoo fihan pe ko ni arun naa mọ; mejeeji yii si ni Makinde ṣe bayii.
FF - BBC News Yorùbá BBC News, YorùbáFò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Issac Promise' Death: Àdánù ń lá ni ikú agbábóòlù mẹta jẹ fún wa - NFF 4 Ọ̀wàrà 2019 Oríṣun àwòrán, facebook Àkọlé àwòrán, Oloogbe Isaac Promise Ajọ ti o ri si ere boolu ni Naijiria ko dunnu rara si bi iku ojiji ti n pa awọn ọjẹ wẹwẹ agbaboolu lorilẹede yii.
    “mo sì dúpẹ́ lọ́wọ́ Ọlọ́run pé àsẹ̀yìnwá àsẹ̀yìnbọ̀ rẹ̀ mo dé ibi tí àbúrò mí wà lẹ́yìn oṣù kẹta tí mo ti kúrò ní ilé.
PDP Cross River South; Ifeanyi Uba, YPP, Anambra South; Haliru Dauda Jika, APC
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù AFCON 2019: Ṣìṣeṣìṣe Troost-Ekong ṣokùnfà ìyà àjẹsùn fún Nàìjíríà lọ́wọ́ Algeria 10 Agẹmo 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 15 Agẹmo 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Super Eagles gbiyanju, ṣugbọn omi pọ ju ọka lọ, ami ayo meji ni Algeria fi ṣe wọn leegun ẹyin lalẹ ọjọ Aiku minu ifẹsẹwọnsẹ to kangun si aṣekagba ninu idije AFCON.
Oríṣun àwòrán, Fatima Muhammad Awọn ọmọ naijiria ti wọn fẹran lati maa gbafẹ́ kiri nitori ooru to mu lẹkun ariwa Naijiria ati ilọwọwọ lẹkun guusu.
Awọn ara adugbo lọ ọ fi ọrọ to ileesẹ ọlọpaa l'eti, ti wọn si ti gbe iyawo Adekunle lọ si agọ wọn láti ran wọn lọwọ ninu iṣẹ iwadii.
 O ni ohun to se pataki ni ki awon to ni iberu Olorun wa nibi ipo oselu, ki won si mu ife awon eniyan sẹ.
Àwọn eniyan Israẹli ya alẹ́ ọjọ́ náà sọ́tọ̀ fún OLUWA, láti ìrandíran wọn.
Oríṣun àwòrán, @habsonfloww Eto aṣa Laarin ọsẹ yii ni ijọba Yuroopu wọgile gbogbo ohun to jẹ mọ ipade ita gbangba lati le dẹkun itankalẹ arun naa, koda, wọn gbẹsẹ le lilọ si ile ijọsin.
Ọ̀pọ̀ ọmọ Nàìjíríà sì ti bẹ̀rẹ̀ sí ni gba ọ̀rọ̀ náà bí ẹni gba igbá ọtí lórí ayélujára.
AMVCA7Award: Yewande Famakin lo gba àmì ẹ̀yẹ sinima èdè ibílẹ̀ MVCA7 Award: Ronke Odusanya, Oyebade Adebimpe, Funke Akindele, Yewande Famakin àti Toyin Abrham tani ami ẹyẹ yoo já mọ lọ́wọ́?
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù EU: Òfo ni ètò ìdìbò 2019 ní Naijiria 17 Òkùdu 2019 Oríṣun àwòrán, Google Àkọlé àwòrán, Ẹka to n se iwadii ni Ajọ Isọkan Yuroopu, EU EOM ni awọn ri asemase ninu eto idibo to kọja lorilẹede Naijiria.
Madagascar na Naijiria pẹlu ami ayo meji sodo Akọni ṣubú l'ójú ìjà, Madagascar fi 2-0 la Super Eagles mọ́lẹ̀ ni eyi to dun ọpọ ọmọ Naijiria.
Orílẹ̀-èdè Amẹrika kò ṣọ́ wọlé-wọ̀de mi àti ìdílé mi- Atiku fèsì O sọ ọrọ yii fawọn ọlọpaa lasiko igbaradi yiyan bi ologun ti wọn ṣe lati jẹ ki awọn araalu mọ pe ṣamu-ṣamu lawọn ti gbaradi de ọjọ idibo.
Nigeria Democracy: Buhari buwọ́lu àbádòfin 'June 12' gẹ́gẹ́ bí àyájọ́ ọjọ́ ìjọba àwarawa
4 Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold 5 Covid-19 pa Ọlọ́lá Akin Olugbade, ẹ wo dúkìá jaburata tó fisílẹ̀ 6 Ẹ wo ọba kan nílẹ̀ Yorùbá, tí kò ṣe ètùtù tàbí náwó ànájù, kó tó jọba 7 Ǹjẹ́ ó ṣeéṣe kí ìyáwò rẹ gbé ọmọ àlè wá sílé láì mọ̀?
oniruuru ile-ise kara-kata ori ero ayelujara; ipese ayika to rorun fun emi ati
Irú ìwà tí a ní kí ẹ máa hù nìyí, kí ẹ lè jogún ibukun tí Ọlọrun ṣèlérí fun yín.
Eyi jẹyọ ninu esi ayẹwo ti ajọ NCDC gbe jade, lati ipinlẹ mejila, ati ilu Abuja.
Eyi to mu ko ku Laycon ati Dorathy.
Lẹ́yìn náà, da òrùka wúrà meji mìíràn, kí o dè wọ́n mọ́ ìsàlẹ̀ àwọn èjìká efodu, níwájú ibi tí ó ti so pọ̀ mọ́ àmùrè rẹ̀.
Ṣugbọn Amnoni kọ̀, kò jẹ ẹ́, ó ní kí ó sọ fún gbogbo àwọn tí wọ́n wà ninu ilé kí wọ́n jáde, gbogbo wọn bá jáde.
Nigba ti BBC ṣabẹwo sile iwosan ọhun, a foju ganni awọn obinrin to ṣẹṣẹ bi ọmọ tuntun ati ẹbi wọn ti ẉon sun ni ita gbangba.
N óo fi Sedekaya, ọba Juda ati àwọn ìjòyè rẹ̀ lé àwọn ọ̀tá wọn lọ́wọ́ ati àwọn tí wọn ń wá ẹ̀mí wọn.
Ori ko Kayode Soyinka yọ ninu ibagbamu ado oloro naa amọ o farapa diẹ.
    Ẹ̀yin ọ̀rẹ́ mi, òjò òwúrọ̀ ni ń bí olówó nínú, olówó a gẹlẹtẹ, ìwọ̀fà a sì gẹlẹtẹ, irú ọ̀rọ̀ yìí kò le ṣàì fa ìbànújẹ́ wa,  inú sì bẹ̀rẹ̀ sí bí bàbá yìí bí ó bá ti rí ọmọ rẹ̀.
Awọn ologun ko fi bẹ ẹ ja lori ilẹ mọ, nitori pe awọn to n ku lara wọn ti pọju.
” Awon ti o setore owo naa ni, Alhaji Aliko Dangote ati enikeji re Alhaji Abdulsamad Rabiu.
Idẹyẹsi miran ni bi awọn araale ati ara adugbo ṣe n huwa si ẹni to ba ni ipenija yii nipa sisọ ọrọ ẹgan tabi huwa si wọn bi ẹni pe wọn kii ṣe eniyan ẹlẹran ara bii ti wọn.
OLUWA ti ṣe ìbúra tí ó dájú fún Dafidi,èyí tí kò ní yipada; ó ní,“Ọ̀kan ninu àwọn ọmọ rẹni n óo gbé ka orí ìtẹ́ rẹ.
Mo ti di ẹni ọgọrin ọdún, kò sì sí ohunkohun tí ó tún wù mí mọ́.
Aare Muhammadu Buhari ti ranse ikini ku oriire si Aare Vladimir Putin ti orile-ede Russia, latari bi o se tun jawe olubori ninu eto idibo ti o waye lorile-ede naa.
Ọba Ogunwusi, Ọjaja Keji, di Ọba kọkànlélaadọta Ilé Ifẹ̀, lẹhin ti Ọba Okùnadé Sijúwadé pa ipò dà ni ọjọ́ kejidinlọgbọn, oṣù keje odun Ẹgbàálemẹ͂dógún.
Àwọn ọkunrin náà sọ fún Rahabu pé, “A óo mú ìlérí tí o mú kí á fi ìbúra ṣe fún ọ ṣẹ.
Òun ni a kọ nípa rẹ̀ pé, ‘Wò ó!
 Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Dele Momodu : Lẹ́yìn Buhari àti Atiku, èrò ọjà làwọn olùdíje yóòkù ní ìdìbò 2019 Alẹ ọjọ Abamẹta to kọja ni wọn ji awọn ọmọ ilẹ okeere naa to jẹ oṣiṣẹ abanikọle gbe nile ọti kan."
Idi ti EFCC ṣe mu Sheu Sani S'ahamọ.
Abileko Lizzy Uwaezuoke to n sise pelu ajo to n mojuto igbejade fiimu agbelewo ni Naijiria naa ni akosile fiimu agbelewo lede Igbo lo kere julo ninu awon fiimu ti a n gbe jade ni Naijiria.
maa jẹ sese yoo fi sawadanu ni.
O wa rọ awọn obi tabi alagbatọ to ṣi n wa ọmọ wọn lati tẹ siwaju lọ sawọn ileewosan ti wọn ko wọn lọ fun ayẹwo eeyan wọn.
'Ilé làbọ̀ ìsinmi oko fọ́mọ Yorùbá lórí Brexit' Àwọn ọmọ Nàìjíríà tó ń dá bírà láàgbáyé Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Mo ti gba kádàrá lórí bí Ọlọrun ṣe dá mi' Shehu ni Aarẹ Muhammadu nikan lo le sọ asiko ti oun yoo yan awọn minisita ti yoo rọpọ awọn to fipo silẹ.
" BBC gbiyanju lati ba Ọgbẹni Siddiqi ati iyawo rẹ tuntun sọrọ lori iṣẹlẹ naa, ṣugbọn wọn ko si ni arọwọto.
F Odunjo morile ilu London lati lọ sile ẹkọ olukọni kan nibẹ Laarin ọdun 1924 si 1927 ni J.
1 52738 Orilẹede Zimbabwe 305 2.
Oríṣun àwòrán, Boko Haram Ọmọkunrin náà wa bẹ́ ìjọba pé ko bá àwọn ajínígbé sọ̀rọ̀ lórí ǹkan tí wọ́n ba fẹ́ gbà kí àwọn le lọ ilé àwọn ni àlááfíà.
Nigba ti akọroyin BBC bere lọwọ rẹ pe se yoo gba ni irọwọrọsẹ ti o ba fidirẹmi ninu idibo naa, Atiku sọ pe o da oun loju pe oun ko ni fidirẹmi.
Ìṣẹ̀lẹ̀ kan wáyé, ọmọdébìnrin ọmọ ọdún 15 ni olóògbé tí ó máa ń múra bí ẹ̀dá-inú ìtàn tí a mọ̀ sí cosplay.
16 Àti nígbànáà, kíyèsíi, wọ́n sọ wọ́n sì rò nínú ọkàn wọn—Àwa yíò wòó bóyá Ọlọ́run ti fún un ní agbára láti túmọ̀, bí ó bá sì rí bẹ́ẹ̀, yíò tún fún un ní agbára bákanáà lẹ́ẹ̀kan síi.
àwọn eniyan wọnyi, tí wọ́n ti rí ògo mi ati àwọn iṣẹ́ ìyanu tí mo ṣe ní Ijipti ati ninu aṣálẹ̀, ṣugbọn tí wọ́n ti dán mi wò nígbà mẹ́wàá, tí wọ́n sì ṣàìgbọràn sí mi, 
Gẹgẹ bii agbẹnusọ fun aafin ṣe sọ, ni owuro ọjọ aje ni Merghan wọ ile igbẹbi lọ pẹlu ọkọ rẹ, Harry ni ẹgbẹ rẹ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Abiola Ajimobi: Tinubu ní àwọn ìpínlẹ̀ ló yẹ kó máa gba owó orí ọjà 17 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Oríṣun àwòrán, @AsiwajuTinubu Laarin oniruuru wahala to n ranju mọ eto abo ni Naijiria, aṣiwaju ẹgbẹ oṣelu APC, Bọla Ahmed Tinubu ti pe fun agbekalẹ ọlọpaa agbegbe ati ipinlẹ.
Mika láti inú ìdílé Usieli, Ṣamiri láti inú ìdílé Mika.
Koda, o tun wọ inu ọkọ ti yoo gbe kaakiri wo .
  Nítorípé bí ènìà bá ṣe jáde kúrò nínú oko àgùntàn ni á ṣe kòóngẹ́e atọ́ka tí wọ́n ṣe síbẹ̀.
1 Iṣẹ́ títóbi ati yíyanilẹ́nu kan ti fẹ́ jáde wá sí àwọn ọmọ ènìyàn.
m ni ojú mi déédé fọ́ níbi tí mo ti ń darí ọkọ̀ ni Ọrẹgun Ikẹja -LASTMA Yesufa Oriṣii ikinni to wọpọ bii: Ẹ ku ewu ọmo tuntun; Ẹ ku ọwọ lomi; Ayọ naa a kari; Olorun a wo o; Olorun a da a si, E ku ajabọ, O maa ni ọ̀wọ́ rere lẹ́yìn ati bẹẹ bẹẹ lọ ni a gbọ.
Buhari lati maa jẹ ki awon eniyan ri i gege bi eni ti ko lee tẹle ọrọ rẹ.
Ojogbon Yemi Osinbajo soro yii nibi ifiga-gbaga to waye niluu Eko, to je Gusu orile ede Naijiria, ti egbe Simmons Cooper Advocacy Development SCAD se onigbonwo re.
naa ri i pe awon ibudo idibo ti won ya sọtọ fun awon abarapa lo jẹ pe ibẹ kun fọfọ
(Abubakar) Shekau ko ni ọna kankan lati ji wọn gbe toripe ọpọ igbesẹ ti jade lati bẹgi dina wọn lkun Ila Oorun-Ariwa torinaa o han daju pe awọn ajinigbe lo ji awọn ọmọ naa""."
Ni ohun ti ọpọlọpọ n sọ lori ọrọ naa nigba ti wọn gbọ.
'Òjíṣẹ́ ni Ifá jẹ́ fún àwa Yorùbá' Àwọn ọmọ ẹgbẹ́ oṣèlú gbéna wojú awọn agbófinro Wo Ángẹlì tó n sàn owo ìtọjú àwọn aláìsàn #Bum bum war:Yemi Alade tọrọ àforíjìn lọ́wọ́ Tiwa Savage Abule Kalinova ni orilẹ-ede Ukraine ni o ti wa fun ọpọlọpọ ọdun.
lẹ́yìn tí ó ti ṣẹgun Sihoni, ọba àwọn ará Amori tí ń gbé Heṣiboni; ati Ogu, ọba àwọn ará Baṣani, tí ń gbé Aṣitarotu ati Edirei.
Sisọ fun awọn ololufẹ mi Mo ti rinrinajo ifẹ lọpọlọpọ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìgbìmọ̀ iṣedajọ orílè-èdè Nàìjíríà NJC nikan lo le yọ adajọ-Amofin 3 Ìgbé 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ilé igbimọ aṣofin n beere pe ki wọn yọ adajọ agba ipinlẹ Kogi Awuyewuye to n waye nipinlẹ Kogi nipa yiyọ adajọ agba ipinlẹ naa ti mu ki awọn eeyan máa beere ibeere kan eleyi to niṣe pẹlu boya awọn ẹka ijọba miran lagbara lati yọ ọsiṣẹ ẹka iṣedajọ.
Lẹ́yìn tí OLUWA bá ti ṣe yín lóore, bí ẹ bá kọ̀ ọ́ sílẹ̀, tí ẹ sì bẹ̀rẹ̀ sí bọ àwọn oriṣa àjèjì, yóo yipada láti ṣe yín níbi, yóo sì pa yín run.
"Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ladọja: A ṣe awa naa lee ni BBC tiwa 19 Èrèlè 2018 Àkọlé àwòrán, Ifilọlẹ BBC Yoruba yoo waye lọjọ kọkandinlogun oṣu keji ọdun ""Lẹyin orẹyin, ala d'ohun."
Kọmiṣọna feto ilera nipinlẹ Eko, Ọjọgbọn Akin Abayọmi lo ṣalaye eyi ninu atẹjade kan lọjọru.
" #Otogelagos: 'Ọlọ́pàá kọ́ ló da ìpàdé àwọn alátakò Tinubu rú' Àfikún ìdìbò ààrẹ yóò wáyé lọ́jọ́ kẹsàn án oṣù kẹ̀ta Ohun márùn-ún tí Atiku ń bèrè lọ́wọ́ Buhari níbi ìpàdé rẹ̀ pẹlú Abdulsalam, Kukah APC pàṣẹ lọ rọ́ọ́kún nílé fún Amosun, Okorocha Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, #NigeriaDecides: BBC ti wa ni gbogbo ìpínlẹ̀ Naijiria láti firoyin gbogbo tóo yin létí Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Nkan ti awọn eeyan nsọ lori BBC Yoruba Dogara ni o si ya oun lẹnu pe ẹni ti wọn pe ni olori orilẹede kan lee sọ iru ọrọ yii jade, eyi to tako ẹjẹ to jẹ lati daabo bo ẹmi ọm orilẹede yii kọọkan lasiko ibura rẹ.
Papakọ ofurufu Akure ko jina si Ipinlẹ Ekiti Ojikutu ni ko si idi ti ko fi yẹ ki Ipinlẹ Ekiti ati Ondo jijọ maa ṣe akoso papakọ ofurufu to wa ni Akurẹ nitori wipe wọn sun mọ ara wọn.
Ajafẹtọmọniyan kan ti pe fun fifun awọn ẹṣọ alaabo ilu labẹle ni
wa tun salaye pe, oniroyin naa lo tun le je ki won mo ohun ti won le se ati ile
“N óo fi ògo mi hàn láàrin àwọn orílẹ̀-èdè, gbogbo wọn ni yóo sì rí irú ẹjọ́ tí mo dá wọn ati irú ìyà tí mo fi jẹ wọ́n.
Wọn ran ọgbẹni Mandela lọ si ẹwọn gbere.
Tí ẹ bá ń ṣe àwọn nǹkan wọnyi, ẹ kò ní kùnà.
O ni esi Mabuza lori ise ti awon eeyan n padanu pupo lojo bo ko dara to.
Ewe, gomina oun wa fi ipinnu re mule lati se amulo isuna owo naa bi o ti to ati bi o se ye.
Mo n fi oju sọna lati sisẹ pẹlu ikọ awọn minisita ati ẹnikọọkan to wa lẹka eto ẹkọ nilẹ Gẹẹsi.
Awọn onimọ nipa kata kara gan an jẹri pe owo ti ra New Kim ya agbado ha sawọn lẹnu.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù NIS: Ẹgbẹ́ dókítà làwọn kò mọ sí ìrìnàjò dókítà 58 tí NIS dènà mọ́ láti lọ sí London 22 Ọ̀pẹ̀̀ 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 11 Agẹmo 2020 Oríṣun àwòrán, Others Àkọlé àwòrán, Ẹgbẹ́ dókítà làwọn kò mọ sí ìrìnàjò dókítà 58 tí NIS dènà mọ́ láti lọ sí London Ẹgbẹ awọn dokita oniṣegun oyinbo ni Naijiria, NMA, lawọn ko mọ si irinajo awọn dokita mejidinlọgọta to n rinrin ajo.
Ìjọba ìpínlẹ̀ Ondo pàṣẹ fún àwọ̀n agbófinró láti mú àwọn fijilanté fulani l'Ondo
Ninu ọrọ mii, adura ni Funke Akindele gba to sọ asọtẹlẹ si oṣu ikẹfa pe ko bi ibukun ko si wẹ gbogbo ọgbẹ wa danu.
Oríṣun àwòrán, Toba Adedeji Àkọlé àwòrán, ìwọde náà n waye nípìnlẹ̀ Osun ati Ekiti bakan naa Ó fi kún ọ̀rọ̀ rẹ pé àwọn ìjọ tó kú yóò mú ọjọ́ tó bá wù wọn láti ṣe ìwọde tiwọn, ṣùgbọ́n ìròyìn kan òun lára pé Ọsun àti Èkìtì náà ń ṣe ìwọde tí wọn lọ́wọ́.
Fásitì ìpínlẹ̀ Ekiti dá òṣìṣẹ́ 355 padà sẹ́nu iṣẹ́ Ilé ìwòsàn l'Àbuja ti ya àwọn ìbejì tí wọ́n sọpọ̀ láyà lọ́fẹ̀ẹ́ Kò sí wàhálà lórí ìkọlù Iran, lákọ ni America wà- Trump Kò sí wàhálà lórí ìkọlù Iran, lákọ ni America wà- Trump Aarẹ ilẹ Amerika, Donald Trump ti fi awọn ọmọ America lọkan balẹ pe ko si wahala.
Mo fa ojú ro, mò ń káàkiri,mo dìde nàró láti bèèrè ìrànlọ́wọ́ láàrin àwùjọ.
Iṣẹ́ márùn ún tí àwọn adarí ẹgbẹ́ APC gbọ́dọ̀ ṣe kíákíá kí omi má tẹ̀yìn wọ ìgbín lẹ́nu Iré dé!
Oríṣun àwòrán, Kenechuckwu/twitter Àwọn míràn tún ni Pasitọ, Daystar Christian Centre, Sam Adeyemi, ajàfẹ́tọ ọmọniyan, Aisha Yesufu; agbábọ́ọ̀lù Nàìjíríà nígbà kan rí, Kanu Nwankwo; ọ̀mọ̀wé Joe Abah, Kiki Mordi, gbájugbajà òṣèré Nollywood Yul Edochie àti Uche Jombo.
ẹtọ won lori eto idibo .
Agbofin Ile Igbimọ Aṣofin naa wa ki gbogbo musulumi,
 o yẹ ki ijọba mọ pe kò yẹ ki wọ́n fi àye gba awọn tii ki ṣe ọmọ Naijiria láti wọle si orilẹ̀-èdè yìí."
Deede aago mẹjọ owurọ la gbọ̀ pe awọn janduku ọhun ya bo ile iwosan ijọba naa, wọn n yin ibọn soke laibikita, ti wọ́n si dẹru ba awọn alaisan to wa nibẹ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ifa Worshippers: Àwọn ẹlẹ́sìn ìbílẹ̀ ń fẹ́ kíjọba pín èrè òṣèlú alágbádá yíká gbogbo ẹ̀sìn A ko setan lati yan adari ẹgbẹ tuntun - Igbimọ Fidihẹ Wayi o, igbimọ fidihẹ fẹgbẹ oselu APC ti gbọnmu pe oun ko ni seto ipade apapọ awọn ọmọ ẹgbẹ naa lati yan awọn adari tuntun gẹgẹ bawọn kan se n beere fun.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Covid 19 update: Wo ǹkan mẹ́wàá tó yẹ kí o mọ̀ tí o bá fẹ́ lọ fún ìsinmi lẹ́yìn Covid 19 22 Bélú 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 23 Bélú 2020 Oríṣun àwòrán, others Ọpọlọpọ eniyan lo n kundun ati rinrinajo lọ si ilu miran tabi orilẹede miran lati lọ sinmi, lẹyin ọpọlọpọ oṣu ti wọn ti wa nile nitori arun Coronavirus.
Ẹ ṣọra fun ọti mimu nitori o ni caffeine ti o ni eroja to n jẹ diuretics to n mu ni tọ ni ọpọ igba.
Bẹẹ lo fi ikini ranṣẹ si awọn ọmọ Naijiria nile loko lẹyin odi pe wọn ku ajọdun ọdun Ileya.
Oríṣun àwòrán, AFP Àkọlé àwòrán, Ọkọ ofurufu An-26- bii iru eleyi lo jẹ onipele meji fun kiko awọn ọmọogun ati awọn araalu Ọpọlọpọ ọmọ Naijiria lo si ti n fi ero han lori ipinnu ijọba Ipinlẹ Ekiti yii lori Twitter: Àwọn ìròyìn mìíràn ti ẹ lè nífẹ̀ẹ́ sí: Sowore, AAC ti yọ Leonard Ezenwa tó kéde ìyọnípò Ṣòwòrẹ́ A ò tì ilé Saraki pa ní'lú Eko - EFCC Adeleke yóò borí nílé ẹjọ́ tó gajù lọ- Dele Adeleke Bí ọlọ́pàá bá mú ọ, kí ló yẹ kí o ṣe?
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Omí pọ̀ ju ọkà lọ fún Unai Emery, ìfìdírẹ̀mi mí ló bade fún lọ́wọ́ Frankfurt 29 Bélú 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Omí pọ̀ ju ọkà lọ fún Unai Emery, ìfìdírẹ̀mi mí ló bade fún lọ́wọ́ Frankfurt Ninu atẹjade ti Arsenal fi soju opo twitter wọn ni wọn ti kede ipinnu wọn bayii.
Ẹgbẹ́ ajàfẹ́tọmọnìyàn - BBC News Yorùbá BBC News, YorùbáFò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Say no to rape: Ìdájọ́ ikú ni a fẹ́ fún àwọn afipábánilòpọ̀ - Ẹgbẹ́ ajàfẹ́tọmọnìyàn 6 Òkùdu 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 7 Òkùdu 2020 Agbarijọpọ awọn ẹgbẹ ajafẹtọmọniyan bii mẹrinla ọtọọtọ ti koro oju si iwa ifipabanilopọ ati iṣekupani ti awọn obinrin n koju lawujọ.
láti ẹni ọgbọ̀n ọdún títí dé aadọta ọdún, àwọn tí wọ́n lè ṣiṣẹ́ ninu Àgọ́ Àjọ 
Jubril fipo rẹ silẹ lẹyin ti ẹgbẹ afọbajẹ ni Nazarawa fi jẹ Emir tuntun ni ipinlẹ naa.
Uganda Condom Case: Ilééṣẹ́ ìjọba àti aládáni wọ gàù nítórí Kọ́ńdọ̀mù tó fa HIV, gonorrhoea àti òyun
Ogunleye ni kíkó ìwọ́ ọmọ wẹ́wẹ́ pamọ́ jẹ̀ ǹkan tó le wáye ni ẹ̀ẹ̀kan lọ́ja ayé ènìyàn láti rí ìwòsàn fún àwọn ààrùn to lágbára púpọ̀, ó fi kún pé, ibi ti wan ti máa n ri irú èròjà yìí tẹ́ẹ̀ ni inú mùdùnmúdùn inú egungun ènìyàn.
Ọ̀pọ̀lọpọ̀ ènìyàn ni ó ka àjọ̀dún sí “ìgbógunti àṣà” tàbí “ìrẹ̀sílẹ̀ ìlú”.
Ninu idije naa ni Egypt ti na Zimbabwe pẹlu ami ayo kan si odo nipa kọju si mi koo gba a sile.
Nígbà tí àlá bá pọ̀ ọ̀rọ̀ náà yóo pọ̀.
Ipinnu lati yan igbimo naa waye leyin ti aare orile ede Naijiria Muhammadu Buhari  ti faake kori pe sise alekun odun awon igbimo amusese ti egbe won, ko ba ofin mu.
O gba awọn adari nimọran lati ṣe ohun to yẹ fun igbadun ati alaafia ara ilu nitori awọn alalẹ ati ara ọrun n wo wọn.
Diezani gan an ní Hushmummy tó ń bú àwọn Yahoo boys- Àwọn Ọmọ Naijiria lórí Twitter
Ẹnikẹ́ni tí ó bá súnmọ́ àwọn ohun mímọ́ yóo kú.
" Patoranking,Teni,Burna Boy: tá ní yóò gbà àmì ẹ̀yẹ̀ Headies?
Ẹ dúró lórí ohun tí mo kọ.
Atupa olojumẹrindinlogun: titan atupa olojumẹrindinlogun eyi ti itan sọ pe o ti le ni ẹgbẹta ọdun ni yoo tẹlee.
Agbawọlẹ ni ti eekan ni Anthony Joshua fi ija naa ṣe nitori gbogbo awọn onidajọ lewaju ija naa ni wọn gbe idajọ kalẹ pe AJ lọwọ rẹ moke juls nigba ti ija naa fi ti ẹnu bodo ni randi kejila.
Wọ́n sì dáhùn pé, “Ẹ jẹ́ kí á múra kí á sì kọ́ ọ.
Olootu ijọba ilẹ Gẹẹsi, Theresa May lo kọkọ lọ si ilu Abuja lati ri aarẹ Muhammadu Buhari l'ọjọru.
“Ẹ gbógun ti Babiloni yíká, gbogbo ẹ̀yin tafàtafà.
Ẹ sọ̀rọ̀ jáde, kí ẹ sì ro ẹjọ́ tiyín,jẹ́ kí wọ́n jọ gbìmọ̀ pọ̀.
Gẹ́gẹ́ bí àṣẹ àwọn olórí ati àwọn àgbààgbà, ẹnikẹ́ni tí kò bá farahàn títí ọjọ́ mẹta, yóo pàdánù àwọn ohun ìní rẹ̀, a óo sì yọ ọ́ kúrò láàrin àwọn tí wọ́n ti oko ẹrú dé.
Sugbọn ko sọ ninu ọrọ apilẹkọ rẹ pe o ti pe irinwo ọdun ti awọn ẹru akọkọ to jẹ adulawọ kalẹ si Virginia.
O gbọdọ wa ni ibamu pẹlu eto to wa nilẹ yi ni.
Oríṣun àwòrán, @adedimejilateef Ayẹyẹ ọhun dun, gbọngbọn kan si, eyi lo mu omije bọ loju awọn obi rẹ nigba ti wọn pari ajọyọ ọhun.
Nǹkan yan, àwọn aṣẹ́wó fẹ́ daṣẹ́ sílẹ̀ nítorí ẹ̀kúnwó epo ní Nàìjíríà Ọlọ́pàá kọlu àwọn ọmọ onílẹ̀, ní ìbọn àṣìyìn pa ènìyàn méjì Ìbúgbàmù gbogbo ìgbà nílù ú Èkó, kí ló ń ṣokùnfà rẹ̀?
Ọmọbọlanle Ajọkẹ, se o mọ pe mo naani rẹ.
Ẹwa Agọnyin yi ni wọn lo n f'ara lokun to si dara fun eroja asara loore.
Bi rere bi awada, ọrọ naa di ti agọ ọlọpaa, eyi mu ki Alfa Babatunde Sotitobire dero agọ ajọ ọtẹmuyẹ DSS.
Oríṣun àwòrán, @APCNigeria O ni ''ninu aba isunna ọdun 2018 ati ti 2019 ijọba daba lati na biliọnu mẹrinlelogun ati biliọnu meje naira lori awọn ọkọ wọn yii, amọ ile ko fọwọ si nina owo yi'' Yishau tẹsiwaju pe ''tohun ti bẹẹ, ijọba gbe ọkọ okoolelẹgbẹrin (820) wọle lati oke okun ni biliọnu meje naira, to si jẹ pe ọkọ okoolelẹẹdẹgbẹta (520) ninu awọn ọkọ yii ṣi wa ni ibudoko ọkọ oju omi.
Ta ló fipá bá Jennifer lò pọ̀?
Wọn ni, “ohun akọkọ to jọ mi loju ni ti ede Yoruba ti wọn fi n ṣe ijiroro Ile, bo tile ṣe pe ko fi gbogbo ara ya mi lẹnu nitori mo ti mọ tẹlẹ ki n to wa sibi pe iṣẹ kekere kọ ni Ile Aṣofin yii n ṣe lat ṣe igbelarugẹ ede ati aṣa Yoruba”.
Agbegbe Lekki ni ipinlẹ Eko ni iṣẹlẹ naa ti waye ni ile iwe aladani to jẹ eleyii ti awọn akẹkọọ n gbe ninu rẹ.
Diego Maradona ṣiṣẹ́ abẹ lórí ẹ̀jẹ̀ tó dì sí i lọ́pọlọ lẹ́yìn ọjọ́ ìbí ọgọ́ta ọdún Àlàyé rèé lóríi ìdí tí wọ́n fi ń pe aya ní ìyàwó Ẹ wo ẹyẹ ayékòótọ́ tó kó olówó rẹ̀ yọ lọ́wọ́ ikú gbígbóná Ọ̀rọ̀ ìjókòó ìgbìmọ̀ ìwádìí #EndSARS náà dé ìpínlẹ̀ Ogun Àwọn agbébọn kọlu iléèwé, wọn bọ́ olùkọ́ àti akẹ́kọ̀ọ́ sí ìhòhò Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Orlando Owoh: Èmí àti Oladipupo Owomoyela jọ lọ ẹ̀wọ̀n Alágbọn- Caroline Owoh, aya Orlando Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Ibadan Tailor: Ilé-ẹjọ́ dá ẹjọ́ lòdì sí ìwà ọ̀gá ọlọ́pàá sí télọ̀ rẹ̀18 Bélú 2020 Fídíò, Soyinka Cancer: Àṣe ara mi ni iso ti n run gbogbo bí mo ṣe n ṣèrànwọ́ lórí jẹjẹrẹ27 Bélú 2019 Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
 lẹ ́ yìn ọ ̀ pọ ̀ lọpọ ̀ ẹ ̀ kọ ́ tí mò tí rí kọ ́ nÍkọ ̀ lé ọ ̀ run , oorun rá mi lọ lọ ́ wọ ́ kan ni sáá .
Àwọn ni ọmọ Ṣemu, ní ìdílé ìdílé wọn, olukuluku ní agbègbè tirẹ̀.
Nigba ti Naomi wa ni ọmọ ọdun mẹta ni awọn obi rẹ gbe lọ si orileede Amerika pẹlu ẹgbọn rẹ obinrin,Mari.
Kini yẹn ko lee fi bẹẹ rọgbọ."
unity party of nigeria ( upn ) ló ti fìgbà kan jẹ ́ ẹgbẹ òṣèlú ilẹ ̀ nàìjíríà tẹ ́ lẹ ̀ tó lààmì laaka ní àpá ìwọ ̀ oòrùn ilẹ ̀ nàìjíríà lásìkò ìjọba àwa-arawa ẹlẹ ́ kejì ( second republic ) ní ọdún 1978-1983 .
Gomina mẹrin lo ti jẹ ni ipinlẹ Eko lati igba ti ijọba awarawa ti bẹrẹ.
Wọ́n dá Farao lóhùn pé, “Àwọn obinrin Heberu yàtọ̀ sí àwọn obinrin Ijipti.
Ó ni ẹ̀gbìnrìn ọ̀tẹ̀ wọn kò sẹ̀yìn àwọn ìgbésẹ̀ tó ń gbé láti mú àtúntò bá ẹgbẹ́ òṣèlú APC kó lè ni ipa rere.
Gege bi iroyin ohun pe, awon olugbe ipinle Ondo san igba Naira N200 fun duropu kookan ,ni ipinle Rivers awon olugbe n san igba Naira N200.
" To ba si ti sọ pe bẹẹni, wọn yoo sọ fun un pe ko yan orukọ to fẹ ki wọn o maa pe e.
Akọsilẹ n fihan pe, gbogbo ẹkunjẹkun lagbaye lo ti n ri ọwọja arun yii bayii, eyi ti o tilẹ tun ti peleke sii pẹlu ida ọgbọn ninu ọgọrun laarin ọdun 2016 si 2017.
Ìṣẹ̀lẹ̀ yìí súyọ lẹ́yìn tí gbogbo àwọn olórí ẹgbẹ́ òṣèlú APC kò le fẹnu kò lórí ẹni ti yóò dí àdelé alága ẹgbk òṣèlú APC lẹ́ypin ti ilé ẹjọ́ fún Adams Oshiomhole ni ìeé lọ rọ́kún nílé.
Ẹni tí ó bá jẹ ẹran-ara mi, tí ó sì mu ẹ̀jẹ̀ mi, olúwarẹ̀ ń gbé inú mi, èmi náà sì ń gbé inú rẹ̀.
”Awon omo ogun n se iwode lowo nibe bayii lati sawari awon omo ogun olote boko Haram, paapaa julo ni agbegbe Baga.
 Àwọn aamì sábà maa ń jẹyọ láàrín ọjọ ́ márùn ùn .
Ẹ má mú àpò owó lọ́wọ́, tabi àpò báárà.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ṣáájú ààwẹ̀ Ramadan, àwọn ọlọ́pàá Sharia ń mú aṣéwó àti ọ̀daràn nípínlẹ̀ Kano Àjọ SERAP ke gbàjarè lóri jíjan àbá owó ìfẹ̀yìti lóntẹ̀ ni Bayelsa Baale Apese d'àwátì, ó bọ́ sọ́wọ́ ajínigbé!
Ẹwẹ, oludamọran aarẹ lori ọrọ iroyin, Femi Adesina sọ oko ọrọ sawọn oniroyin ori ayelujara kan to ni wọn ti n kọroyin pe Aarẹ Buhari lọ gba itọju nilẹ Gẹẹsi ni.
Oríṣun àwòrán, AFP Àkọlé àwòrán, Oriṣiriṣi akoba ni kẹmika ibora maa n ṣe fun ara.
Nígbà tí ó bá yá, àwọn ìwo mẹ́wàá tí o rí yìí ati ẹranko náà, yóo kórìíra aṣẹ́wó náà, wọn óo tú u sí ìhòòhò, wọn óo bá fi í sílẹ̀ ní ahoro.
Wọn kò dá àwọn olùkọ́ míì dúro ní Kaduna 'Ekute jẹ ogun oloro lagọ ọlọpa' Saraki pe fun ajọṣepọ Ghana ati Naijiria Ni ipari, ọjọgbọn Oloyede ṣalaye nipa igbesẹ JAMB lati daabo bo awọn oṣiṣẹ wọn ki ẹnikẹni ma ro pe wọn le ṣe wọn lésẹ lasiko idanwo nitori pe ọmọ ijọba ni oṣiṣẹ JAMB.
Mo fi ara mi búra pé, n kò ní da yín lóhùn.
Oludije fun ipo gomina ni  Ipinle
orile ede India  lati tete bere ise won
Igba mẹrindinlogun ọtọtọ ni Maradona ṣoju Argentina ninu idije ife ẹyẹ agbaye.
Ẹ gbadura pé kí sísá yín má bọ́ sí ìgbà òtútù nini, tabi sí Ọjọ́ Ìsinmi.
    Nígbà tí a dé ìlú Itanjẹ-ènìyàn yìí, ayédèrú-ẹ̀dá pè mi sí [[ikọ̀kọ̀ lọ́jọ́ kan, ó wí fún mi pé ki ń máṣe gbẹ́kẹ̀lé ìyàwó mi, nítorí alaalẹ́ ni ìyàwó mi àti ọkùnrin kan ń pàdé ara wọn tí wọn sì ń fi ẹnu ko ara wọn lẹ́nu tí wọ́n ń lọ́ mọ ara wọn gídí gbágbá.
ti o bura fun awon oludamoran tuntun naa ni ipinle Sokoto.
 Àkọlé àwòrán, Liliya tí n ṣe ìrànwọ́ fún àwọn ọmọ to n koju iru isoro bẹẹ Liliya tí pé ọdún mẹ́jìdínlọ́gbọ̀n báyìí sùgban kò mọ̀ pé òun ni ipenija yìí titi ti o fí bàlágà."
Oríṣun àwòrán, Others Obasanjo ni aile se akoso oniruuru ẹya to wa nilẹ yii lo mu ki orilẹede yii pin yẹlẹyẹlẹ, eyi to jẹ isoro kan gboogi to n ba wa finra.
Nitori pe o di dandan lati ni ẹrọ yii sinu ọkọ wọn nitori awọn ni wọn saaba maa n sagbakọ ijamba ọkọ loju popo.
(710,000 ) Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Siga tita d‘eewọ lẹba ile ẹkọ ‘Mu ọti nilu Ilọrin, ko ri ẹwọn he’ Wo oríṣiríṣi ìgbádun ibálòpọ̀ láwọn orílẹ̀èdè mìíràn Àwọn olórí lágbàyé ń dárò Kofi Annan Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Sunday Adelaja: Tẹ́tẹ́ làwọn pásítọ̀ tó ń gba owó ‘ìserere’ ń ta Àwọn onimọ sọ pe, ọna kan ṣoṣo lati daabo bo àwọn ọmọde ni lati dẹkun siga mimu.
Ilé ọba tójó ẹwà ló bùsi
Olubadan: Aáwọ̀ ń parí láàrín ìgbìmọ̀ lọ́ba-lọ́ba nílẹ̀ Ibadan
Lásìkò tó n bá BBC news Yoruba sọ̀rọ̀ kọmísọ́nà ètò ìlera náà sàlàyé pé, ibi ètò ìsìnkú rẹ̀ ni àwọn ti n bọ̀ bi òun ṣe n bá BBC sọ̀rọ̀ lọ́wọ́.
Ó gbé wọn kalẹ̀ ninu tẹmpili: marun-un ní ìhà gúsù, marun-un yòókù ní ìhà àríwá.
Ọlọrun bá sọ fún ọkunrin tí ó wọ aṣọ funfun náà pé, “Bọ́ sí ààrin àwọn àgbá tí wọn ń yí, tí wọ́n wà lábẹ́ àwọn Kerubu.
je oludije ti egbe naa yoo lo ninu idibo gomina to n bo yii nipinle Oyo.
OLUWA ti ṣe ohun tí ó ṣèlérí láti ẹnu Elija, wolii rẹ̀.
Gideoni mú mẹ́wàá ninu àwọn iranṣẹ rẹ̀, ó sì ṣe bí OLUWA ti ní kí ó ṣe, ṣugbọn kò lè ṣe é lọ́sàn-án, nítorí ẹ̀rù àwọn ará ilé ati àwọn ará ìlú rẹ̀ ń bà á, nítorí náà lóru ni ó ṣe é.
Gbenga Adebayo ti o je Aare egbe ti o n fun ni niwe eri, ti a mo si Association of Licensed Telecommunications Operators lorile-ede Nigeria so nilu Eko pe, “lai fi akoko sofo, a le ri awon ohun pata ki fayo nile ise yii, niwon igba ti o ba ti n pese oja to dara”.
O jẹ ilu ti o ni ibi igbafẹ ẹgbẹ omi julọ ati ẹja odo.
" Ọbasanjọ ati Buhari rẹrin si ara wọn Ni nkan bi ọjọ diẹ sẹyin ni aarẹ orilẹede yii tẹlẹ ri, Oloye Olusẹgun Ọbasanjọ fi lẹta rẹ si aarẹ Buhari sori ẹrọ ayelujara lori alaye ati iwoye rẹ nipa isejọba ti aarẹ Buhari dari.
O ni: O ṣi n ṣe gbogbo wa ni kayeefi titi di isinyi, ko tiẹ ye wa mọ ni adugbo Warawa yii, nitori laipẹ ni ọmọ kan pa iya rẹ ni eyi to ṣi n ya wa lẹnu.
ede( Nigeria Labour Congress NLC), omowe Peter Ozo-Eson, naa ni igbimo ipinle
Ó dá wọn lóhùn pé, “Kí ni Mose pa láṣẹ fun yín?
Báyìí ni ojú àwọn mẹrẹẹrin ati ìyẹ́ wọn rí: Ìyẹ́ wọn ń kan ara wọn; bí wọ́n bá ń rìn, olukuluku wọn á máa lọ siwaju tààrà, láìyà sí ibikíbi, bí wọn tí ń lọ.
Orin kan tí gbogbo àwọn ọmọdé máa nkọ ní ìlú wa nígbàtí mo wà ní kékeré nìyẹn.
Ohun marun un ree ti awọn eeyan ko mọ nipa Mr Macaroni.
 Ohun ti @GbemiDennis sọ si ọrọ naa niyi."
Ìṣẹ̀lẹ̀ náà tó wáyé nílu Bikoro tún ṣẹlẹ̀ lẹ́yìn ọdún kàn tí Ebola pa ènìyàn mẹ́rin lórílẹ̀èdè náà.
Lọjọru ọsẹ, gẹgẹ bi ijade nile ati ipejọpọ ṣe ti n bẹrẹ pada lorilede Naijiria, bẹẹ naa ni itankalẹ arun Coronavirus bẹrẹ si ni fi sihin sọhun.
Ki a ti ibi ibeere yi bẹrẹ nitori orukọ ti arakunrin kan Mo'Sopaiqu Odedeyi pe Micheal Jackson niyi, nigba to n fesi si ariyanjinyan naa.
Bí a ko bani gbagbe, Aisha ti fìgbàkan rí sọọ ́lórí BBC Hausa pé, bí nǹkan ṣe ń lọ nígbà náà kò bá yí padà, òun kò ní polongo ìbò fún ọkọ òun mọ́.
Bakan naa ni wọn tẹsíwájú pé àwọn kò gbé lẹyìn Saraki tàbí ni ero lati kopa gẹgẹ bi ẹgbẹ oselu.
Bí o bá wi fún ẹnìkan pé máṣe bá mi lo Yorùbá “ìtúmọ̀ ọ̀rọ̀ rẹ ni” “maṣe púrọ́ fún mi”.
Ẹ máa ran ẹni tí ara ń ni lọ́wọ́.
'Màálù tó bá tàsẹ̀ àgẹ̀rẹ̀ níwájú ilé mi, ó dẹran àsun!
Ẹni tí ó fẹ́ràn fàájì yóo di talaka,ẹni tí ó fẹ́ràn ọtí waini ati òróró kò ní lówó lọ́wọ́.
O ni eyi lo mu ki awọn ọdọ to ku ya lọ si agọ ọlọpaa to wa ni ilu naa.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù South Africa Lions: Àwọn aláṣẹ rọ àwọn ará abúlé tí kìnìún wà láti má a fojú sọ́rí 7 Òkùdu 2019 Oríṣun àwòrán, Reuters Awọn kiniun mẹrinla ni wọn ti sa kuro ni ahamọ wọn ni ọgba ẹranko Kruger, to wa ni orilẹede South Africa.
" O ni lootọ ni oun faramọ awọn ẹgbẹ naa nitori iwa ko tọ ti ijọba de ijọba n fi oju wọn ri ṣugbọn oun ko lee tẹlẹ ọna miiran ju iṣọkan orilẹede Naijiria lọ.
Iṣẹlẹ pipa awọn erin lọna aitọ kii ṣe tuntun lawọn orileede kan ni Afrika.
Ẹ fi ṣe àmì sí ọwọ́ yín, ati ìgbàjú sí iwájú yín, nítorí pé pẹlu ipá ni OLUWA fi mú wa jáde ní ilẹ̀ Ijipti.
gbogbo àwọn alabojuto, àwọn olórí, àwọn ìgbìmọ̀, ati àwọn gomina kó ara wọn jọ, wọ́n sì fi ohùn ṣọ̀kan pé kí ọba ṣe òfin kan pé, ẹnikẹ́ni kò gbọdọ̀ bèèrè ohunkohun lọ́wọ́ oriṣa kankan tabi eniyan kankan fún ọgbọ̀n ọjọ́, bíkòṣe lọ́wọ́ òun ọba.
Lara awon iko agbaboolu ti aare Weah kopa fun nile okere lati ri ni: iko agbaboolu Monaco, Paris Saint-Germain, Marseille ati iko agbaboolu AC Milan.
Ko si bi eeyan ṣe lee darukọ orilẹ€de Naijiria ti a ko ni ranti oloye Oluṣẹgun okikiọla Arẹmu Ọbasanjọ.
Alukoro ọlọpaa nilu Kampala, Patrick Onyango sọ fun awọn akọroyin pe baba ati iya awọn ọmọ naa ko si nile nigba ti iṣẹlẹ yi ṣẹ.
Gigara ti owo osu wọn gara ko ṣẹyin awọn owo ajẹmọnu fun akanṣe iṣẹ bii ṣiṣe ẹsọ kaakiri fawon eeyan tabi ileeṣẹ.
Èyí sì maa n mú kí wọ́n fi ara mọ́ àwọn kan tí wọ́n gbàgbọ́ pé 'kìí ṣègbè.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Natalia Mufuta ìyá Yakub, Kamil àti Adam sọ̀rọ̀ lórí bí wọ́n ń sọ èdè mẹ́rin pàpọ Ìdí tí mo fi gbàdúrà ìyàwó bíi Chanel Chin fáwọn tó d'ẹ̀bi ìkọ̀sílẹ̀ rẹ̀ rù mí rèé - Oluwo Oluwo ni oun n fẹ olori ti yoo nifẹ awọn eeyan Iwo ni, ti o si ṣetan lati sin wọn gẹgẹ bi oun ti oun jẹ ọba ti n ṣe.
Nítorí náà inú mi dùn púpọ̀ láti mọ̀ ọ́ lónìí.
Ẹgbẹrun kan owo dọla($1,000) lo gbe le e lori.
Àwọn eniyan náà jáde, wọ́n sì lọ wá imọ̀ ọ̀pẹ ati ẹ̀ka igi wá, wọ́n sì pàgọ́ fún ara wọn, kaluku pàgọ́ sí orí ilé, ati sí àgbàlá ilé wọn ati sí àgbàlá ilé Ọlọrun pẹlu, wọ́n pàgọ́ sí ìta Ẹnubodè Omi ati sí ìta Ẹnubodè Efuraimu.
Ọ̀pọ̀lọpọ̀ onkowe miran lo ti sise lori iwe yii ni awọn Fasiti Naijiria gbogbo.
“A fẹ́ kí ọba mọ̀ pé, a lọ sí agbègbè Juda, a sì dé ilé tí wọ́n kọ́ fún Ọlọrun tí ó tóbi.
Atẹjade kan ti alukoro ileeṣẹ ọlọpaa l'Eko, Olumuyiwa Adejọbi fi sita, wa rọ araalu lati gboju kuro nidi ohun tawọn akọroyin kan n sọ pe o ṣokunfa iku rẹ.
Bouteflika pada sori itage oṣelu lọdun 1999 nigba to dupo aar plu atilẹyin awọn ologun.
Eyi waye lẹyin ọjọ diẹ ti awọn janduku kọlu ọgbà ẹ̀wọ̀n meji nipinlẹ Edo.
Gaiyu ará Dabe ati Timoti náà bá a lọ, ati Tukikọsi ati Tirofimọsi; àwọn jẹ́ ará Esia.
Ó ní, ‘Ohunkohun tí Ọlọrun bá ti sọ di mímọ́, ìwọ kò gbọdọ̀ pè é ní aláìmọ́ mọ́.
Mubarak wulo gan ninu pipilẹ ikọlu ojiji ti wọn ṣe si ikọ ogun Israel ninu ogun Arab ati Isreal ni ibẹrẹ ọdun 1973.
Ija naa bẹrẹ nigba ti gomina Obaseki to n dari awọn alatilẹyin rẹ lọ si aafin ọba koju awọn onijagidijagan to di oju ọna ati kọja wọn pẹlu ibọn, igo ati ọpọlọpọ ohun ija oloro.
6 3181 Orilẹede Djibouti 61 6.
Àkọlé àwòrán, Apá APC le má ká ohun tó le tẹ̀yìn rẹ̀ yọ tí Buhari bá kọ̀ láti tú Zakzaky sílẹ̀.
O sọrọ gẹgẹ bi iya ati abiyamọ pe oun ko le koju kuro lara iṣẹlẹ yii.
Mo ni awọn ọmọ nilẹ, mi o si ni i fẹ́ fi wọn sinu ewu."
adele adajo agba lorile-ede Naijiria Tanko Muhammad tuko re, so lojo Eti wipe,
Ṣe Trump lagbara lati gbeṣẹle oju opo ikansiraẹni?
ati Asaraya ọmọ Hilikaya, ọmọ Meṣulamu, ọmọ Sadoku, ọmọ Meraiotu, ọmọ Ahitubu, olórí àwọn òṣìṣẹ́ ní ilé Ọlọrun; 
Wo àwọn ìbéèrè tí Tinubu bi gómìnà Sanwo-Olu àtàwọn olùwọ́de tó faragbọta ní Lekki Tollgate Ó tó gẹ́ẹ́!
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ilesha Baruba: Ìjọba ìpińlẹ̀ Kwara bá ẹbi àwọn tó sòfò ẹ̀mí kẹ́dùn ni Baruteen 9 Sẹ́rẹ́ 2021 Oríṣun àwòrán, Getty Images Gómínà ìpińlẹ̀ Kwara AbdulRahman Abdulrazaq ti bá ẹbí àti ọ̀rẹ́ àwọn tó kú ni ọjọ́ Ẹtì nínú ìjà tó bẹ́ sílẹ̀ ni Ilésha Baruba láàrín ará ìlú àti ikọ̀ ọmọogun aṣọ́bode níbẹ̀.
Sugbọn ijọba ipinle Kaduna ti fesi sọrọ naa.
Kò tíì dákẹ́ ọ̀rọ̀ tí ń sọ, ni àwọn kan bá dé láti ilé olórí ilé ìpàdé tí Jesu ń bá lọ sílé, wọ́n ní, “Ọmọdebinrin rẹ ti kú, kí ni o tún ń yọ olùkọ́ni lẹ́nu sí?
Coulibaly, tii se ẹni ọdun mọkanlelọgọta ni ẹgbẹ to n se ijọba lọwọ ni orilẹ naa ti fa kalẹ bii oludije ninu ibo aarẹ to n bọ losu kẹwa ọdun yii.
Àjànàkú nipò adarí rere, ó kúrò lẹ́rù ọmọdé Ipò àgbà ló yẹ́ kí a ti bá olórí - Fani-Kayode Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 3 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 5 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
O óo ní ọrọ̀ ati ọlá tóbẹ́ẹ̀ tí kò ní sí ọba kan tí yóo dàbí rẹ ní gbogbo ọjọ́ ayé rẹ.
Ẹ kí Maria, ẹni tí ó ti ṣiṣẹ́ pupọ láàrin yín.
Oríṣun àwòrán, AfricanDrumFestival Àkọlé àwòrán, Ọkanojọkan awọn agbaṣaga ni wọn yoo kopa nibi ajọdun naa Ninu ọrọ tirẹ, Alaafin ti ilu Ọyọ, Ọba Lamidi Adeyemi ṣalaye pe 'aṣa jẹ ọna kan gboogi lati ṣe aato ilu.
"Wọn ni ""a ti gba f'Ọlọrun pe olori ati aṣiwaju wa ti dagbere faye, a si n fi akoko yii ṣeranti rẹ."
Ìrìnàjò wa náà sì nì èrè gidigidi.
Wọ́n sọ fún ara wọn pé, “Ẹ jẹ́ kí á ṣe bíríkì, kí á sì sun wọ́n jiná dáradára.
Èrò àwọn ọmọ Naijiria ṣọ̀tọ̀ọ̀tọ̀ lórí àwọn ti Sanwo Olu yàn sípò Wo ipò tí Buhari fún Faṣọla, Lai Mohammed, Saraki àti bẹ́ẹ̀ bẹ́ẹ̀ lọ Kíni àwọn ọ̀dọ́ Naijiria ń fẹ́ lọ́wọ́ àwọn mínísta tuntun?
Bẹ́ẹ̀ ni ìlànà tí OLUWA pa láṣẹ fún Mose láàrin ọkọ ati aya ati láàrin baba ati ọmọ rẹ̀ obinrin, tí ń gbé ninu ilé rẹ̀.
tuntun omo bibi ipinle Anambra ohun.
Ọ̀pọ̀lọpọ̀ òkú ẹyẹ igún ré bọ́ lọ́jà Eke-Ihe Àwa ò mọ ẹgbẹ́ kankan tó ń jẹ́ fijilanté fulani l'Ondo- Ìjọba ìpínẹ̀ Ondo Mo mọ̀ọ́mọ̀ dá €37,000 ti mo rí he padà ni -Ọmọ ogun Bashir Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ẹ lọ mú ẹ̀rí ibi tí a ti gba owó wá- NLC/TUC 15 Ọ̀wàrà 2018 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 28 Bélú 2018 Àkọlé àwòrán, 'Àwa ò gba owó lọ́wọ́ Fayose ooo' Àìtó eyín ká làá dọwọ́ bòó, àwọn olórí òṣìṣẹ̀ méjèjì tí wọn fi ẹsùn owó rìbá kan Nigeria Labour Congress (NLC) àti Trade Union Congress (TUC) ti fèsì.
Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí NÍ YÀJÓYÀJÓ Covid 19: Ìjọba ìpínlẹ̀ Ogun pàṣẹ kí wọ́n ṣí gbogbo ilé ìjọsìn, ilé ìgbafẹ́ padà lẹ́kúnrẹ́rẹ́ Lebanon Explosion: Ibùdó tí igba èèyàn ti kú lóṣù kẹjọ ní iná míràn ti jó10 Owewe 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 3 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 5 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Nítorí ní ọpọlọpọ ìgbà, a máa ṣubú lu iná; ní ọpọlọpọ ìgbà ẹ̀wẹ̀, a máa ṣubú sinu omi.
Ààrẹ̀ Buhari ní ọ̀dọ́ tó bá tún ba dúkìá ìlú jẹ́ yóò fojú winá òfin kíkọlu àbò ìlú Oríṣun àwòrán, Femi Adesina Saaju la ti sọ fun yin pe, Aarẹ Buhari ti ke si awọn ọdọ to n wọde kaakiri orilẹede Naijiria lati pada sile olukaluku wọn ki wọn si dẹkun iwa bẹẹ nitori ẹdun ọkan wọn ti wọn fẹ ki ijọba gbọ ti dun korokoro leti oun ati ijọba oun.
Ọjọgbọn Ngozi Okonjo-Iweala jẹ minisita ijọba meji lorilẹede Naijiria-2003 si 2006 labẹ aarẹ Oluṣẹgun Ọbasanjọ, 2011 si 2015 labẹ iṣejọba aarẹ Goddluck Jonathan.
Nisinsinyii n óo ní ìṣẹ́gunlórí àwọn ọ̀tá mi tí ó yí mi ká;n óo rúbọ ninu àgọ́ rẹ̀ pẹlu ìhó ayọ̀,n óo sì kọ orin aládùn sí OLUWA.
Oríṣun àwòrán, Said Ẹwẹ, iwadii ti ajọ LASEMA ṣe lori ile naa fi han pe alaja mẹta ni ti o si ni ojule mẹfa oni yara kan, palọ kan to si kun fọfọ pẹlu awọn to gba a lẹyin ti atunlekọ kan ti idile kan gba tun un kọ.
asiri , ki ijoba  lee di iru ọna bẹẹ, ki
Sani aigbọra ẹni ye laarin Yoruba ati Igbo lori oludije ti ṣoju guusu Naijiria ninu ibo aarẹ ọdun 2023 le fun awọn eeyan ariwa lanfaani lati tun jẹ aarẹ lọdun 2023.
Oríṣun àwòrán, Lere Olayinka Oríṣun àwòrán, Lere Olayinka Lere Olayinka fi kun ọrọ rẹ pe ti ina ko ba ti lawo, kii jo kọja odo eleyi to tumọ si pe awọn kan ni wọn n ru ina si bi ọrọ yii ṣe di fa kin fa.
Wọ́n kúrò ní aṣálẹ̀ Sini, wọ́n lọ pàgọ́ sí Dofika.
good people, great nation jade fun atunṣe orukọ Naijiria Labẹ iṣejọba aarẹ Naijiria ti o di oloogbe, Musa Yaradua ni wọn ti yan an gẹgẹ bii minisita fun eto iroyin ati ibanisọrọ lọdun 2008 si 2010.
Nígbà tí oòrùn ń lọ wọ̀, wọ́n kéde fún gbogbo àwọn ọmọ ogun pé, “Kí olukuluku pada sí agbègbè rẹ̀!
Ìjẹta, mọ́júmọ́ àná, ni ọjọ kọkàlélógún sí ìkejìlélógún oṣù kejìlá ọdún.
 Idaduro ipese ounje ati oogun yoo fa ajakale arun ati iyan tijoba ko be tete gbe igbese to ye lasiko yii”.
se ipade  abẹle pelu awon omo orile
Nítorí láàrin gbogbo àwọn orílẹ̀èdè tí wọ́n bá wí, kò sí ilẹ̀ aláwọ̀ funfun kankan níbẹ̀.
Solomon Sunday àti Cpl Aliyu Mukaila tó wọ́n so mọ agbegbe Iba.
Mo kọ̀ láti yí ọ̀rọ̀ mi padà lórí ètò ẹ̀kọ́ ọ̀fẹ́ - Gómìnà Dapo Abiọdun 'Operation Rewire' EFCC / FBI sèso owó tó lè ní mílíọ̀nù N153 Ẹ ṣèwádìí ikú Ọ̀jọ̀gbọ́n Gideon Okedayọ - ASUU Ọlagunju tẹsiwaju wi pe ifẹ ọkan awọn ara ilu lo gbe onibara oun de ipo ti ko si ni ohunkohun ṣe pẹlu ẹsun mago-mago ti ẹgbẹ oṣelu APC fi kan an.
Wọ́n bá lọ sọkún níwájú OLUWA títí di ìrọ̀lẹ́, wọ́n wádìí lọ́dọ̀ OLUWA, wọ́n ní, “Ṣé kí á tún gbógun ti àwọn ará Bẹnjamini tí í ṣe àwọn arakunrin wa?
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Female Genital Mutilation Day: Ọ̀mọ̀wé kan ní obìnrin tí kò bá dá abẹ́ yóò ṣe ìṣekúṣe O ṣalaye pe oun to yẹ ijọba ṣe ni lati maa lo ẹrọ igbalode lati tọpinpin awọn ọdaran, nitori simu kan to eniyan lati ṣe iṣẹ ibi.
Nítorí pé ẹ̀jẹ̀ eniyan tí ó pa wà ninu rẹ̀, orí àpáta ni ó da ẹ̀jẹ̀ wọn sí, kò dà á sórí ilẹ̀, tí yóo fi rí erùpẹ̀ bò ó.
Ngige so pe,“A o bere ijiroro wa pada lose to n bo.
Eyi jeyo lati odo akowe agba fun eto ẹkọ lorile ede Naijiria, Sonny Echono nigba ti o n side ipade igbimo to sakoso  eto ẹkọ, ni eyi ti o je ikẹ́tàlélọ́gọ́ta, iru re ti yoo waye niluu Abuja.
Orilẹ-ede Morocco jẹ orilẹ-ede ti awọn musulumi ẹlẹsin Islam pọ si pupọ.
Kí ó sọ pàṣán rẹ̀ sílẹ̀,kí ó má nà mí mọ́!
Oríṣun àwòrán, funkejennifaakindele Lara wọn ni African Movie Academy Award (AMAA) gẹgẹ bi oṣerebinrin to dantọ ju, AfroHollywood fun oṣerebinrin to n ṣatilẹyin ju; awọn ami ẹyẹ mii to gba gẹgẹ bi oṣerebinrin to tayọ ju ni Future Awards, Dynamix Awards, City People, City People fiimu to dara ju lọdun.
bí obinrin yìí bá lọ ní ọkọ mìíràn, 
ẹ̀rù bà á gidigidi, nítorí pé ìlú ńlá ni ìlú Gibeoni bí ọ̀kan ninu àwọn ìlú ọba aládé.
Jesu wá wí fún un pé, “Ọmọbinrin, igbagbọ rẹ ti mú ọ lára dá, máa lọ ní alaafia.
" Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Lagos King: Mátikú ọba tó lo lo ọdun mẹta lórí oyé latari rogbodiyan Eko Rita ni ọkọ oun ta kindinrin oun nitori pe agbara mọlẹbi rẹ ko ka owo ori ti o n beere fun.
O tun so pe, paapanbari be ni wipe, iko omo ogun Operation LAFIYA DOLE 
Ninu orukọ mẹrinla ọhun lati ri ọkunrin mẹtala, ati obinrin kan.
Ọba Aládélúsi Ògúnladé-Aládétóyìnbó gun Ori Oyè ilu Àkúrẹ́
Ṣugbọn bí kò bá ní agbára tó láti ra ilẹ̀ náà pada fúnra rẹ̀, ilẹ̀ náà yóo wà ní ọwọ́ ẹni tí ó rà á lọ́wọ́ rẹ̀ títí di ọdún jubili.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ọọni ogunwusi bẹrẹ abẹwo si orilẹede Brazil Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Ọọni ogunwusi bẹrẹ abẹwo si orilẹede Brazil 11 Òkùdu 2018 Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí 2 sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 2:23 Fídíò, Water Generator: Ó leè ṣiṣẹ fún wákàtí mẹfà, kó tó sinmi, Duration 2,2310 Òkùdu 2020 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
Sááju ni èdè àìyedè ti wáyé lórí ọ̀rọ̀ yìí, ti àwọn ọmọ ilé ìgbìmọ̀ aṣofin àgbà sì ti ni àwọn ti gbẹ́sẹ̀ lé ètò náà nítori mínísítà kọ̀ láti ṣe ni ìlànà tí àwọn ń fẹ́.
Nigba ti wọn n kalẹ alaye ẹhonu wọn ọhun nilẹ, wọn fẹsun kan pe wọn ja awọn lole ni nidi akojọpọ esi ibo aarẹ eyi to mu ki wọn fidi rẹmi ninu abajade esi ibo ọhun.
Ẹ̀dá afàyàfà ni Òjòlà-ìbínú àyà ni ó si fi máa ń fà lọ wẹ̀ ní àgbàlá lójoojúmọ́.
Nítori àwọn àtúgbẹ́yẹ̀wò, o níra láti ṣe àkójọpọ fún àwọn ọkọ́ naa Orisun: Johns Hopkins University atawọn ajọ eto ilera ilu Iye akọsilẹ to waye gbẹyin 7 Oṣù Ọ̀pẹ̀ 2020 14:22 WAT+3 Gbenga Adeboye: Ó tẹ́ bàbá mi lọ́rùn pé ká mu gàárì nílé ju kí ebi pa ará ìta lọ - Ọmọ Gbenga Adeboye Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Gbenga Adeboye: Ó tẹ́ bàbá mi lọ́rùn pé ká mu gàárì nílé ju kí ebi pa ará ìta lọ - Oluwadamilola Adeboye, tíì ṣe ọmọbìnrin gbajugbaja adẹrinposonu nnì, Gbenga Adeboye, tí sọ àwọn ìrírí tó sì rántí nípa bàbá rẹ̀ tó ti di olóògbé.
“Ìwọ ọmọ eniyan, sọ fún àwọn ọmọ Israẹli pé mo gbọ́ ohun tí wọn ń sọ pé, ‘Àìdára wa ati ẹ̀ṣẹ̀ wa wà lórí wa, a sì ń joró nítorí wọn; báwo ni a óo ṣe yè?
Nígbà tí mo wí báyìí tán, Baba-onírùgbọ̀n náà tún fún mi lésì, ó ní, ‘Rùngbọ̀n mi rí yẹ̀ùkẹ̀ o, kò rí yẹ̀ùkẹ̀ o, a óò dé ilé ọkùnrin náà lọ́la dandan.
Oṣu meji lẹyin rẹ lo ṣe ikọlu ni Mozambique.
O ni ohun to ba wu onikaluku lo le sọ nipa erongba rẹ lori iṣẹlẹ iku Kashamu ni eyi to fihan pe ohun to wu Aarẹ Obasanjo naa lo sọ sita ninu ero tirẹ.
Ko bimi ninu ṣugbọn mi o ro pe o yẹ ka wa ba ọmọluabi jẹ nitori oṣelu'' Nigba ti BBC kan si Sẹnẹtọ Dabiri loju opo Whatsapp rẹ lati fesi si ọrọ yi, o fi aworan iroyin naa ranṣẹ lai sọ nkan mii mọ.
Siasia gba ẹnu awọn aṣoju ati amofin rẹ sọrọ nibi ipade kan to ṣe pẹlu awọn oniroyin niluu Abuja.
Ọmọde si ni a n ran nisẹ.
Eyi lo si mu ko gba ami ẹyẹ nla mẹta, World Boxing Association, International Boxing Federation and World Boxing Organization.
Awọn firi nidi ọkẹ naa, ti wọn gbajugbaja fun isẹ alọnilọwọgba lagbegbe Lekki, ni wọn pe oruk wọn ni Adebayọ Ayọmide ati Isaac David.
N óo sọ ọ́ di orílẹ̀-èdè tí yóo tóbi, tí yóo sì lágbára jù wọ́n lọ.
Ọlọrun ní, “Ṣebí bí ẹ ti jẹ́ sí mi ni àwọn ará Etiopia náà jẹ́, ẹ̀yin ọmọ Israẹli?
Plea Bargain: Agbẹjọ́rò ní apanìyàn nìkan ní kò le è bẹ̀bẹ̀ láti dá ẹ̀mí tó pa padà
Oríṣun àwòrán, Getty Images Iku ọmọ rẹ mu ko jẹ anfaani àwọn nkankan, nitori pe awọn eeyan gbagbọ pe baba daadaa ni.
Oríṣun àwòrán, Others Okoye ní láti le ri dájú pé, ètò ìdìbò lọ ni irọwọ́rọsẹ̀, àjọ INEC ti kan sí ọlọpàá ojú omi, àwọn ọmọogun ojú omi àti àwọn ilé iṣẹ́ ààbò tó farapẹ láti ràn wọ́n lọ́wọ́.
OLUWA bá sọ fún un pé, “Ogbó ti dé sí ọ, ṣugbọn ilẹ̀ pupọ ni ó kù láti gbà.
Àwọn ẹrú tí oluwa wọn bá dé, tí ó bá wọn, tí wọn ń ṣọ́nà, ṣe oríire.
Gbogbo ohun ìríra tí àwọn orílẹ̀-èdè tí OLUWA lé jáde fún àwọn ọmọ Israẹli ń ṣe, ni àwọn náà ń ṣe.
Coronavirus tips: Ìlànà ojúlówó márùn ún tó kápá ìtànkálẹ̀ COVID-19
Fi ara rẹ sinu okunkun - A nilo lati wa ninu okunkun, ki ara si balẹ, ki omoonu kan, ti wọn n pe ni Release Melatonin, to n fa oorun sisun, lee sisẹ rẹ.
O ni oju opo kan sori ayelujara Facebook, nibi to ma n fi awọn fidio to fi n gbe afojusun rẹ lẹyin, si.
Ọwọ́ tẹ báàlẹ̀, Ṣinkó mẹ́tàdínlógún tó ń jí kùsà wà ní ìpínlẹ̀ Ọ̀ṣun Awọ awọn agbofinro ti tẹ awọn ọmọ orilẹede China mẹtadinlogun kan ti wọn n ji kusa wa ni ipinlẹ Ọṣun Ikọ alaabo ajumọṣe ti ijọba ipinlẹ Osun ṣẹṣẹ da silẹ lo he awọn eeyan naa lagbegbe Ileṣa ati Ifẹ ni ipinlẹ Ọṣun.
Bí ẹ bá ń hùwà ṣe-á-rí-mi, ẹ kò ní èrè lọ́dọ̀ Baba yín tí ń bẹ ní ọ̀run.
  iṣọkan "" iṣura ati idajọ "" agbara "" ( oxford university press , 2013 ) , fleurbaey ati blanchet beere lọwọ awọn ami ti o ṣe pataki julo ( gẹgẹbi awọn idagbasoke ti awọn eniyan ati awọn atọka ti a ṣe lori imọ iwadi ayọ ) ."
Ẹ má debi a ò pèyín o
Bi o tilẹ jẹ pe ọpọ eeyan lo gba Idiagbon nimọran pe ko ma pada wa si Naijiria mọ lati Mecca, ti ọba Saudi gan si fun laaye lati duro sibẹ, amọ Idiagbon ko gba.
Aṣaju ni Oladejo jẹ ninu kikọ iwe arosọ ati iwe ere to da yatọ pẹlu ọna ti o n gba lo ede ilẹ Afirika ninu itan rẹ.
Ẹni to bori: Kenya Burundi vs Egypt.
lojuna ati ri daju pe ebi ko pa awon omo kekeeke ile iwe alakobere yii bi won
Orile ede Naijiria ti tọwọbọ iwe adehun eto
ti àwọn ará Amori, ti àwọn ará Kenaani, ti àwọn ará Girigaṣi ati ti àwọn ará Jebusi.
"Awọn ìjòye Emir ń fojú sùnukùn wó ẹ̀sùn náà""."
Olódodo ń ṣègbé,kò sí ẹni tí ó fi ọkàn sí i.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Buns ni ọmọ mi jẹ tán ní ṣọ́ọ̀ṣì, ló bá di àwátì' Bi a se lee lo iwe akọsilẹ orukọ awọn abanilopọ lọna aitọ: Ko si aaye fun ẹnikẹni lati sadede fi orukọ eeyan kan sinu iwe akọsilẹ naa pe o huwa ibalopọ lọna aitọ Iru ẹni ti orukọ rẹ yoo ba wọ iwe akọsilẹ ọhun gbọdọ ti kọkọ foju ba ileẹjọ, koju igbẹjọ, ti adajọ yoo si ti kede pe o jẹ ẹsun ibanilopọ lọna to lodi sofin, ki wọn to kọ orukọ rẹ silẹ, ti yoo si a faraye ri A lee fi orukọ awọn eeyan to n ba ọmọde lopọ tabi ti wọn fẹsun kan, eyi ti adajọ ti gba pe o jẹbi ẹsun naa sinu iwe akọsilẹ ọhun.
" Mo si sọ fun Oyetunji pe ko di iyawo rẹ mu ko fi emi silẹ"" O fi kun un pe ọkọ oun ko ṣe ẹtọ gbogbo to yẹ lori ọmọ kan ṣoṣo ti wọn bi fun ara awọn."
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Agbẹjọ́rò àgbà lọ sẹ́wọ̀n nílùú Èkó A ò gba ìbálòpọ̀ akọ ṣákọ tàbí abo sábo Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Fídíò òògùn ikọ́ Codeine: Àpọ̀jù rẹ̀ ń ya ọ̀dọ́ ní wèrè Lori ọrọ eto aabo lorilẹede Naijiria, Ọba Rilwan kesi Ijọba Apapọ lati se agbeyẹwo gbogbo awọn eto aabo to wa fun ẹkun kọọkan lorilẹede Naijiria.
Onnoghen pe ẹjọ lati tako igbesẹ ijọba to fi ọwọ osi juwe ile fun titi wọn yoo fi gbọ idajọ lori iwa ibajẹ ti wọn fi kan an ati lati tako ile ẹjọ to n gbẹjọ iwa ibajẹ(CCT) lati ma se gbọ ẹjọ rẹ.
Ni ọjọ kẹwa oṣu karun ni awọn oṣiṣẹ ajọ EFCC gbe Naira Marley lẹyin ọpọlọpọ ifimufinlẹ lori bi o ṣe n lẹdi apo pọ pẹlawọn ti o n lu jibiti lori ayelujara.
Awọn ọdọ naa tẹnumọ wipe ninu adura ni awọn yoo ti sọrọ soke ki ayipada le deba orilẹede Naijiria.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Lassa Fever: Ìwádìí ní èèyàn 219 ni ibà Lassa pa lọ́dún tó lọ́, 29 lọ́dún yìí, tètè dènà rẹ̀ 28 Sẹ́rẹ́ 2020 Lori eto Laahanmi ti BBC Yoruba, a se atupalẹ ohun ti iba Lassa jẹ, ọsẹ to n se lawujọ wa ati awọn ọna ta fi lee dena rẹ.
Won ti pase fun adari omo-ogun orile ede Naijiria, ogagun Tukur Buratai lati duro si Ila oorun Ariwa orile ede yii titi ti eto aabo yoo se fẹsẹ mulẹ sii.
Bi ọwọ ba si ti kan an , o lee taare rẹ si oju rẹ, imu tabi ẹnu rẹ.
Nígbà tí ó ṣe tí mo rí jọ̀wọ̀lọ̀ tí mo sì ń kú lọ.
Ijẹri ọmọbinrin naa wa lara aabọ iwadi ti ajọ ajafẹtọ ọmọniyan, Human Rights and Trial International gbe kalẹ.
 Won ba n kan je lopolopo, se oro aje ni ka wi ni abi eto aabo abi awon ohun amayederun ti won o le dase.
Òun ló ni agbára ati ọgbọ́n,òun ló ni ẹni tí ń tan ni jẹ,òun náà ló ni ẹni tí à ń tàn.
Àwọn ẹ̀mí èṣù náà bá bẹ Jesu pé, “Bí o óo bá lé wa jáde, lé wa lọ sinu agbo ẹlẹ́dẹ̀ ọ̀hún nnì.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ileya: Saraki, awọn gómìnà rọ aráàlú láti máse sọ ìrètí nù 18 Ògún 2018 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 21 Ògún 2018 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ààrẹ Muhammadu sàlàyé pé ẹ̀sìn níkàn lọ̀nà àbáyọ láti jẹ kí ènìyàn hùwà tó tọ́ sí Ọlọ́run àti ọmọ ẹ̀dá.
Apapọ awọn to ti ri iwosan nipinlẹ kọọkan si ti pe 12,108.
Lagos Building collapse: Aisha Buhari ṣàbẹ̀wò ṣàwọn tí ilé wó lù níléèwòsàn
Igbakeji gomina oun tun so pe, idagbosoke ilana ohun ti safihan pe, ipinle ohun ni lati saseyori ni awon agbegbe eto ogbin, ohun alumoni-ile, ohun amusagbara, asa, igbafe, oro ile-gbigbe ati awon agbegbe miira ti o se koko.
Iya Adodo lo bi ọmọbinrin ati ọmọkunrin akọkọ fun Ọba Adeyemi, eyi ta lee pe ni Bẹẹrẹ ati Arẹmọ laafin Ọyọ.
Àwọn olórí alufaa ati àwọn amòfin ń wá ọ̀nà bí wọn yóo ti ṣe pa Jesu nítorí wọ́n bẹ̀rù àwọn eniyan.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìgbìmọ̀ iṣedajọ orílè-èdè Nàìjíríà NJC fẹ́ ṣèpàdé lórí Onnoghen 28 Sẹ́rẹ́ 2019 Oríṣun àwòrán, NJC Àkọlé àwòrán, Ìgbìmọ̀ iṣedajọ orílè-èdè Nàìjíríà NJC lagbara lati jiroro nipa yiyọ adajọ kankan lorileede Naijiria Igbimọ iṣedajọ orile-ede Naijiria n palẹmọ lati ṣe ipade pajawiri lori ọrọ adajọ agba Naijiria Walet Onnoghen ti ijọba apapọ fun ni iwe lọọrọkun nile.
Ogunbanjọ fi kún pé àwọn ọmọde àkanda ẹkọ ni ireti ['e kò si ibi ti àwọn kò le de.
Igbakeji ree ti kiniun yoo sa jade kuro ninu ile rẹ, ti yoo si sekupa eniyan lorilẹ̀ede Naijiria laarin osu mefa.
Sibẹ, wọ́n dán Ọ̀gá Ògo wò, wọ́n sì ṣọ̀tẹ̀ sí i;wọn kò tẹ̀lé ìlànà rẹ̀.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Afárá Third mainland gb’ẹ̀gbọn Ọ̀rẹ́kùnrin mi fún mi ní àárùn HIV, mo sì gbẹ̀san Nnamdi Kanu ti awọn alaṣẹ ati agbofinro lorilẹede Naijiria ti n wa lati ọdun to kọja kede lori redio laipẹ yii pẹ ọpẹlọpẹ orilẹede Israel ni oun ṣi fi wa.
Àkọlé àwòrán, Allen Onyema: Amẹrika fẹ̀sùn jìbìtì $20b kan olùdàsílẹ̀ ilé iṣẹ́ ọkọ̀ òfurufú Air Peace Ni ipari atẹjade naa, ẹka idajọ ilẹ Amẹrika sọ pe alaiṣẹ si ni Onyema ati Eghagha afi ti ijọba Amẹrika ba fidi rẹ mulẹ pe lootọ ni wọn jẹbi ẹsun ti wọn kan wọn.
Fashola ni kii ṣe ijọba apapọ lo ni ile ẹkọ alakọbẹrẹ tabi ile iwosan alabọde ijọba ibilẹ.
Bí mo bá ń fi èdè àjèjì gbadura, ẹ̀mí mi ni ó ń gbadura, ṣugbọn n kò lo òye ti inú ara mi nígbà náà.
"Koda, ibudo ikẹru si ọhun kii se ti ijsba, wọn kan gbe silẹ fun wa lati lo ni.
“Àwọn òfin tí o gbọdọ̀ fún àwọn ọmọ Israẹli nìwọ̀nyí: 
Adari ile-ejo to wa lorile ede Naijiria ,  Ibrahim Tanko  Muhammed ti  bura fun igbakeji aare orile ede Naijiria Ojogbon Yemi Osinbajo.
Iṣari bí ọmọkunrin mẹta: Kora, Nefegi ati Sikiri.
 lẹ ́ yìn èyí , àwọn bíi Ọlá balógun àti herbert ogunde bẹ ̀ rẹ ̀ sí níí ṣe fíìmù pẹ ̀ lú irínṣẹ ́ tuntun .
Ẹ gba Ọlọrun gbọ́, kí ẹ sì gba èmi náà gbọ́.
Ọkọ̀ ojú omi ''fẹri'' kọlu afárá, ọkọ̀ méjì já sódò Olùkọ́ tó kù nínú ìṣẹlẹ ilé to jo nínú ọgbà UI tí kọ̀wé fipo silẹ̀ tipẹ-Alukoro fásitì Kínni ife ẹ̀yẹ ti Tiger Woods gbà ní Augusta fi yàtọ́?
Ayọ̀ ẹ̀yin tí ẹ̀ ń fúnrúgbìn sí etí odò yóo pọ̀,ẹ̀yin tí ẹ ní mààlúù ati kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ tí ń jẹ káàkiri.
Ọdun 2008 ni iroyin kọkọ gbale-gboko nipa apọnbeporẹ olori naa, lasiko to bi ibẹta lanti-lanti ni ọọdẹ Alaafin.
Nígbà tí ó tú èdìdì kẹta, mo gbọ́ tí ẹ̀dá alààyè kẹta ní, “Wá!
Yóo gbẹ níbi tí wọ́n gbìn ín sí.
Nítorí pé kò pa mí ninu oyún,kí inú ìyá mi lè jẹ́ isà òkú fún mi.
Naijiria, Ibrahim Buba tun tesiwaju pe , ile akede Naijiria ,Voice of Nigeria
Magu,'estimated billing' àti àwọn ohun míràn tí ilé aṣòfin Nàìjíríà kò rí yanjú Ààrẹ Abdulaziz Bouteflika ti kowe fipo silẹ Ilé ìgbìmọ aṣofin ti dájọ tí wọn ó fọwọsi àbádofin ìsúna 2019 Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Àyà mi kọ́kọ́ máa ń já nígbà ti mo ṣẹ̀ṣẹ̀ bẹ̀rẹ̀ -Alaga iduro ọkùnrin Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ojojúmọ ní mọ ń kẹ́kọ̀ọ́ lára ọmọ mi to jẹ akanda Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Níbo lowó ìrànwọ́ ẹ̀kọ́ wa wà?
ori ire fun saa miran yii.
Forbes 2018 list: Àwọn ọmọ Nàìjíríà dẹ́bi àdínkù tó bá owó Dangote rú Ààrẹ Buhari
Sanusi wọ gau torí pé o kọrin bù Gómìnà Ganduje Ọlọ́pàá Sharia Kano mú èèyàn tó lé ní 80 tori oúnjẹ nínú ààwẹ̀ Ṣé ìnàkí tún gbé owó tó lé ní mílíọ̀nu mẹ̀fà Náírà mì ni?
Bí wọ́n bá dúró, wọn a ká ìyẹ́ wọn wálẹ̀, 
Iwa nabi tu igbeyawo ọgbọn ọdun ka Ọmọọba Gẹẹsi fẹ di ọkọ‘yawo Ọsinbajo se‘dana ọmọbinrin rẹ nile ijọba Ogbeni Adewale ṣalaye pe ori ayelujara ni awọn ti pade ti ina si wọ ki ẹbi, ara ati iyekan to ba wọn yọ ayọ igbeyawo wọn.
Nígbà tí ìyà mi parí ọ̀rọ̀ rẹ, èmi náà dáhùn, mo ní ‘Ìyá mi, irú ìfẹ́ wo ló tó yìí!
Lori ifẹsẹwọnsẹ aadọta ni wọn de ki ẹgbẹ agbabọọlu Manchester United to fẹyin wọn gbolẹ ti wọn si da wọn duro.
Sakaraya, ọmọ Meṣelemaya ni olùṣọ́ ẹnu ọ̀nà Àgọ́ Àjọ.
O gbiyanju lati gba tikẹẹti ẹgbẹ oṣelu Republican fun ile igbimọ asoju-sofin, lọdun 2014 ati 2016, sugbọn o fidi rẹmi nigba mejeeji.
Lara awon to tun wa nibi ipade yii ni a ti ri gomina
” Joṣua sì bọ́ bàtà ẹsẹ̀ rẹ̀.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ohun méje pàtàkì nípa Commonwealth Ilẹ̀ gbígbẹ́ ní Bọ́ùn: Ìpìnlẹ̀ mẹ́fà leè má nìí iná ọba Buhari, Trump yóò ṣèpàdé l'Ámẹ́ríkà Arakunrin yamu sọwipe adari ajọ ọlọọpa, Ibrahim Idris ti ran awọn ikọ ọlọọpa to n wa ọkọ ofurufu si agbeegbe naa lati se iwadi ofintoto nipa isẹlẹ naa Agbẹnusọ ile isẹ ipinlẹ Benue naa wa fikun wipe ajọ ọlọọpa yoo sa ipa wọn lati ri wipe ọwọ tẹ awọn asekupani naa, ti wọn yoo si foju wina ijọba.
Pẹlu àtìlẹ́yìn Ọlọrun a óo ṣe akin,nítorí òun ni yóo tẹ àwọn ọ̀tá wa mọ́lẹ̀.
Àwọn ọmọ Israẹli sá fún àwọn ará Filistia, wọ́n sì pa ọpọlọpọ àwọn ọmọ Israẹli ní orí òkè Giliboa.
Apẹẹrẹ iru rẹ to wa ninu Bibeli ni Abarahamu to san idamẹwaa lori gbogbo ohun to ko bọ lati oju ogun.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Àṣìṣe ọlọ́pàá àti Adájọ́ sọ mí di ẹni tí wọ́n dájọ́ ikú fún, ọpẹ́lọpẹ́ Fayoṣe tí ko buwọlu Bakan naa ni ijọba tun fi ountẹ lu Middle East Airline, British Airways, Delta, Qatar, Ethiopian Airlines, Emirates Airlines, Air Peace, Virgin Atlantic, Asky Airlines, Africa World Airways, Air Cote-d' Ivoire, Kenya Airways, EgyptAir, Turkish Airlines lati bẹrẹ iṣẹ pada ni Naijiria.
Èrò yín dàbí fùlùfúlù, gbogbo ìṣe yín dàbí pòpórò ọkà.
30 Agẹmo 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 17 Bélú 2020 Iṣoro pọ ninu igbeyawo mi ṣugbọn kò si ibi ti mo n lọ -Joke Silva Iriri kọja ẹgbẹ abẹwu, ohun ti agbalagba ri lori ijokoo, Yoruba ni oju ọmọde ko lee too laelae lori iduro.
Nigba toun naa n fesi lori ikede Buhari yii, ẹgbẹ agbarijọpọ awọn ẹlẹgbẹjẹgbẹ oselu lorilẹede Naijiria, CUPP, kesi awujọ agbaye lapapọ lati tete di ẹru ẹmi to ba bọ lasiko idibo ru aarẹ Buhari.
Mo fẹ́ kí ẹ mọ̀ dájúdájú pé ẹ kò ní tíì ya gbogbo ìlú Israẹli tán kí Ọmọ-Eniyan tó dé.
 lati dekun wahala to maa n be sile laarin ijoba ati awon osise ati lati mu iwa aparo kan ga ju okan lo, nipa owo ti awon osise orile ede naa maa n gba.
 Atunto ẹka ipese ina ọba Oríṣun àwòrán, @MsTyma_ Àkọlé àwòrán, Tinubu ni ki Buhari o ṣọra lori ọrọ owo ori sisan lori ọja, VAT Bọla Tinubu ni ijọba Buhari gbọdọ mojuto ọrọ ipese ina ọba nitori ko si idagbasoke ti o lee de ba orilẹede Naijiria laisi ipese ina ọba."
Ó yára láti mọ ète ati èrò ọkàn eniyan.
"m ni ojú mi déédé fọ́ níbi tí mo ti ń darí ọkọ̀ ni Ọrẹgun Ikẹja -LASTMA Yesufa Mo ti kó kúrò nílé Olu Jacobs rí lẹ́ẹ̀mejì- Joke Silva ""Mo fẹ́ pa ara mi torí ojú àbùkù tí wọn ń fi wò mí pé mo fi iṣẹ́ abẹ bímọ"" Èmi àti Saheed kìí ṣe ọmọdé, a ti jọ ṣe Sinimá papọ̀, èyí túmọ̀ sí pé ìjà ti parí - Fathia Balogun O fikun pe, ileesẹ naa fẹ fi ẹmi imoore rẹ han si Iya Rainbow fun ọpọ ipa takuntakun to ti ko nidi isẹ tiata, lo mu kawọn seto ayẹyẹ ọjọ ibi ọlọjọ meje naa, nibiti awọn gbajumọ olorin bii Pasuma, ati Dare Melody yoo ti kopa, ti awọn yoo si tun se abẹwo si awọn ibi to se koko nilu ọhun."
‘Láti ìgbà tí mo ti kó àwọn eniyan mi jáde láti ilẹ̀ Ijipti, n kò yan ìlú kan ninu gbogbo ilẹ̀ Israẹli pé kí àwọn ọmọ Israẹli kọ́ ilé ìsìn sibẹ, níbi tí wọn óo ti máa sìn mí, ṣugbọn, mo yan Dafidi láti jọba lórí Israẹli, eniyan mi.
Awọn awakọ ero kii ye ko akokun ero Lara awọn eto ti ijsba ipinlẹ Eko gbe kalẹ lori eto irinna ni pe awọn awakọ ero to ba ṣiṣẹ gbọdọ mu ibomu lọkunkundun ati pe ida ọgọta lero ti wọn gbọdọ maa gbe.
Ó sọ fún wọn pé, “Ẹ̀ ń sùn ni!
Nígbà tí àwọn oníṣẹ́ Hesekaya ọba jíṣẹ́ fún Aisaya, 
Nigba ti agbasẹse ti ijoba gba lati maa ri si imototo
ní ilẹ ̀ yorùbá ati níbi gbogbo ti ẹ ̀ dá ènìyàn ń gbé , ìbágbépọ ̀ ẹ ̀ dá ṣe pàtàkì púpọ ̀ .
Nígbà tí Dafidi rú ẹbọ tán, ó súre fún àwọn eniyan ní orúkọ OLUWA, 
Oloogbe naa ni Alaga ileeṣẹ Credit Switch Technology.
'Kìí ṣe gbogbo ohun tí dókìtà ni kí n má jẹ torí àìsàn jẹjẹrẹ ni mo tẹ̀lé' Ǹjẹ́ o nímọ̀ nípa agogo inú ara rẹ?
’ “Gbogbo eniyan yóo sì dáhùn pé, ‘Amin.
Bí mo ti yipada, mo rí ọ̀pá fìtílà wúrà meje.
Bakan naa, Olubadan ti Ibadan, Oba Saliu Adetunji ti juwe Ọlọwọ ti Ọwọ gẹgẹ bi ẹni rere, to fẹran ara ilu, Ọba Saliu si tun ba awọn ara Ọwọ kẹdun ọba wọn to waja.
Dagunro lo maa n se ere to jẹ mọ ti asa ibilẹ, to si maa n se ere oloogun pẹlu ọfọ, oun si ni osere tiata keje ti yoo silẹ bora ninu awọn osere tiata Yoruba lọdun yii.
Èmi àti Bọla Tinubu fẹ́ lo ‘German Mercenaries’ láti gbé MKO Abiọla kúrò lẹ́wọ̀n - Dele Momodu Ìjọba Germany mú afurasi ọmọ Boko Haram 'Àwọn akọni mẹ́rin gun ọ̀kadà láti Germany wá sí Nàìjíríà' Àwọn ọjọ́ ìsìnmi tó máa wà nínú ọdún 2020 ní Nàìjíríà Samson Ọmọtọṣọ mẹnuba oriṣi ẹka ere idaraya 'Skating' to wa lasiko yii ati awọn igbesẹ inu ṣiṣe wón.
Àwọn ọmọ ẹ̀yà Gadi wọnyi ni olórí ogun, àwọn kan jẹ́ olórí ọgọrun-un ọmọ ogun, àwọn kan sì jẹ́ olórí ẹgbẹrun, olukuluku gẹ́gẹ́ bí wọ́n ti jẹ́ akikanju sí.
Ṣé Òfin wá jẹ́ ẹ̀ṣẹ̀ ni?
Báyìí ni àwọn olùdíje ìpínlẹ̀ Eko ṣe fẹ́ kojú ìṣòro ìlera
Aaroni sì wí fún Mose pe, “Olúwa mi, jọ̀wọ́ má jẹ́ kí á jìyà ẹ̀ṣẹ̀ ìwà àìgbọ́n wa.
Ijamba ina to sele ni ogba awon olopaa Venezuela to wa ni ilu Valencia ni ipinle Carabobo ti pa awon eniyan méjídínláàdọ́rin , gege bi awon osise ijoba se so.
Ajọ to n mojuto eto ina ilẹtiriki lorlẹ-ede yi, Nigerian Electricity Regulatory Commission (NERC), ti fi ọwọ si afikun lori owo ina tuntun naa.
EFCC:A ti gbà ìwé àṣẹ láti fí Fayose sí àhámọ́ Bí ayẹyẹ ọjọ́ ìbí Ọọ̀ni ilé Ifẹ̀ ṣe lọ rè é Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 2016 ni Angel kọ́kọ́ gbé àwo orin rẹ̀ síta láti fi bèrè ìdí tí òun fi yàtọ̀ Nitorina, Dokita naa wa parọwa si awọn obinrin ki wọn se kiakia, ki wọn le bimọ ni ọdun mẹtalelogun si mẹrinlelogun, ki o si pari ọmọ bibi ki o to pe ọmọ ọdun marunlelọgbọn.
Segubu ni ó bí Jairi, tí ó jọba lórí ìlú ńláńlá mẹtalelogun ní ilẹ̀ Gileadi.
Mr Latin, Jide Kosọkọ àti Mama Rainbow sọ̀rọ̀ lórí ìjà Toyin ati Lizzy 'Àwọn ti Micra ló jẹ̀bi rògbòdìyàn awakọ̀ tó wáyé lánàá n'Ìbàdàn' 'Àwọn ti Micra ló jẹ̀bi rògbòdìyàn awakọ̀ tó wáyé lánàá n'Ìbàdàn' Wọn ti wa rọ awọn eniyan ilu lati yẹra fun rira ẹran maalu lasiko yii ni pataki, ẹran ti ara pa yii fun ilera ara wọn.
Mo fún ìwọ ati àwọn ọmọ rẹ lọkunrin ati lobinrin, gẹ́gẹ́ bí ìpín wọn títí lae.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ondo election 2020: Igbákejì gómìnà Ondo, Agboola Ajayi ní lóòtọ́ lòun fẹ́ f'ẹgbẹ́ PDP sílẹ̀ láti jẹ́'pè aráàlú ṣùgbọ́n.
Awọn igbese to ti waye lori isuna 2018 Losu keje ọdun 2017, Minister feto isuna so pe ijọba yoo fi eto isuna ranse losu kẹwa ọdun 2018 Losu kọkanla ọdun 2017, Aare Buhari se agbekale isuna ọdun 2018 ni iwaju igbimo apapọ ile asofin Losu kejila odun 207, ile asofin agba ni, o se se ki ipenija wa fun isuna odun 2018 pelu bi awọn olori ileese ijọba se ko lati wa salaye ọrọ lori isuna wọn Losu kinni odun 2018, akọwe agba fun ijọba apapọ ọgbẹni Boss Mustapha ni ijọba n se iyemeji lori amulo ilana to kuna nigbati wọn ba buwọlu isuna 2018 Losu keta odun 2018, Aarẹ Buhari ati awọn olori ile asofin se ipade lori isuna 2018 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Nígbà tí Dafidi parí ọ̀rọ̀ rẹ̀, Saulu dáhùn pé, “Ṣé ohùn rẹ ni mò ń gbọ́, Dafidi ọmọ mi?
“Nígbà tí wọ́n bá mu yín lọ sinu ilé ìpàdé ati siwaju àwọn ìjòyè ati àwọn aláṣẹ, ẹ má ṣe dààmú nípa bí ẹ óo ti ṣe wí àwíjàre tabi pé kí ni ẹ óo sọ.
Ninu iwaasu rẹ to se ninu ijọ rẹ to wa nilu Eko, lọjọ Kẹrinla, osu Keje, ọdun 2013, ti wọn si gbe sori ayelujara, ni TB Joshua ti n ke tantan nipa ajalu to n bọ.
O dìgbà tí mo bá dórí àgá kí ń tó sọ ìpinnu mi - Fatai Owoseni SSANU, NASU gbé fásitì Ibadan tì pa Ìpínlẹ̀ Ondo ti ní gómìnà tuntun Òyìnbó sísọ di èèwọ̀ ní ìpínlẹ̀ Ekiti A o maa muu wa fun igbadun yin, bi ohun gbogbo ba ṣe n ṣelẹ loju opo yii.
Èyí ni ìrìnàjò lọ sí òkè òkúta Robin Hood.
Ṣugbọn ó ní ẹrubinrin ará Ijipti kan tí orúkọ rẹ̀ ń jẹ́ Hagari.
Bayii, eka ikaniyan ti ajo Isokan Agbaye ni akosile ti n fihan pe asa yii ti n dinku lasiko olaju yii lawon orile ede kookan lagbaye sugbon awon orile ede miran yii n see.
Oríṣun àwòrán, AFP Àkọlé àwòrán, Mínísítà ètò àbò lórílẹ̀èdè Sudan, Awad Ibn Auf tó fipò sílẹ̀ lẹ́yìn tó dárí ìgbésẹ̀ tó yọ ààrẹ Omar Al-Bashir nipo.
fi lelẹOfin naa fun igbimọ naa
O ni aarẹ lẹ ṣe ijọba nibikibi, ati wipe ko ni lati fi to awọn aṣofin leti ti o ba fẹ lọ ṣẹ abẹwẹ ranpe nilu ọba.
Minisita fun iroyin ati asa Lai Mohammed, naa tun sọ pe iyipada oju-ọjọ ati iyangbẹ ilẹ lo n fa wahala to maa n sẹlẹ laarin awọn ọdaran ati agbẹ lorilẹ ede Naijiria.
Mubarak gbajumọ ọrọ abẹle ṣugbn nigba naa o bẹrẹ si ni so okun irẹpọ yi pẹlu awọn adari ilẹ Arab paapaa ju lọ ọmọ ọba Saudi, Fahd.
Iko omo ogun orile-ede Naijiria ti so pe, awpn omo ogun olote boko-haram méjílélọ́gbọ̀n  ti jowo ara won fun awon omo-ogun ohun nipinle Borno.
 Ó jẹ ́ ìgbàgbọ ́ pé àkọ ́ kọ ́ nínú ìbejì ni táíwò ( tàbí táyé ) tí ó gbèrò láti kọ ́ kọ ́ jáde wá sáyé láti finmú fínlẹ ̀ bóyá agbègbè ibi tí wọ ́ n fẹ ́ wọ ̀ dára tàbí kò dára láti wà sínú ẹ ̀ .
Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Risikat Azeez: Aya gómìnà tún fẹ́ gba sọ́ọ́bù, ra ọjà fún obìnrin olójú búlúù8 Owewe 2020 5:58 Fídíò, Akomolede ati asa Yoruba: Ẹ wá kọ́ nípa àpòtí ìṣura èdè wa lórí BBC Yorùbá, Duration 5,5820 Ògún 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 3 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 5 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Àjọ NBC fi ẹgba ìbáwí rẹ̀ na AIT, Arise TV àti Channels nítorí ìwọ́de ENDSARS 23 Ọ̀wàrà 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 26 Ọ̀wàrà 2020 Oríṣun àwòrán, Twitter/ait/channels/arise Ajọ to n mojuto eto igbohunsafẹfẹ lori redio ati tẹlifisan ni Naijiria, NBC, ti na ẹgba ibawi rẹ si ileeṣẹ agbohunsafẹfẹ mẹta, AIT, Arise TV, ati Channels.
Bo tilẹ jẹ pe ati dije ipo aarẹ Harris lọdun 2020 ko yọri si rere to si juwọọlẹ ṣaaju ọpọ awọn ti wọn jọ n du u, o ṣi mọ itumọ wiwa labẹ iru ayẹwo bẹẹ.
Minisita feto iroyin ati asa, Lai Muhammed lo fesi bayi nigba to n ba akọroyin BBC Igbo sọrọ lori ẹsun ti iyawo Nnamdi Kanu, Nchechi Okwu-Kanu fi kan ijọba apapọ, wipe awọn lo mọ ibi ti ọkọ ohun wa, lati bi osu die sẹyin.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Yorùbá tone mark: Fífi àmì ohùn sí orí ọ̀rọ̀ Yorùbá ṣe pàtàkì Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
"JP CFR LLD SAP ""Ọkọ mi, Alaafin Oyo lo ṣe agbatẹru ẹkọ mi nile iwe, to si n tọ mi sọna lati koju ipenija aye ati ile aye laifọtape."
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ìjọba fẹ́ kọ́lé 300,000, pẹ̀lú ìrànwọ́ fún àgbẹ̀ 4m láti mú àdínkù bá ìṣẹ́ - Osinbajo Wò ó bí Alaafin àti aya àkọ́fẹ́ rẹ̀, Olorì Abibat ṣe pàdé ní èwe Coronavirus ti fa ọ̀wọ́ngógó oúnjẹ ní ìpínlẹ̀ Eko, Kano, Rivers àti Abuja- NBS Àwọn èrò yarí lórí sísan owó àyẹwò covid-19 bí bàálù ilẹ̀ òkèèrè ti ba s'Abuja lẹyìn oṣù márùn ún Ẹ wo ààrẹ orílẹ̀-èdè tó ń ṣèdárò Ẹja akóredé tó d'olóògbé Àbá àpérò 2014 CONFAB lojútùú sí àtúnṣe ìwé òfin Nàìjíríà- Afenifere sáwọn sẹ́nẹ́tọ̀ Ìjọba ìpínlẹ̀ Ogun fún àwọn ọmọ ilé ìwé ní ìgbéga sí kílààsì tó kàn láì ṣe ìdánwó nítori Covid-19 Aarẹ wa pasẹ fawọn minisita pe ki wọn jade lọ maa gbe ijọba oun nija lọdọ araalu nipa sise afihan awọn aseyọri alailẹgbẹ ti oun ti se lori aleefa.
Bakan naa ni wọn yoo ma dibo yan gomina ipinlẹ mẹrindinlogoji ninu ipinlẹ aadọta lorilẹede Amerika.
Ṣugbọn kaka ki ewe agbọn dẹ lori ọrọ ibo ọjọ Kejila osu Kẹfa ọdun 1993, ko ko ko lo tun n le si, ti rogbodiyan si tun suyọ lasiko ti wọn n ṣami ayajọ ọdun kan ti idibo naa waye.
"Oríṣun àwòrán, Sunday Adeyemo ""N ko gba kọbọ lọwọ ẹnikẹni ki n to gbe igbesẹ yii, ifẹ iran Yoruba ti mo ni si lo mu mi se bẹẹ."
Wọn ti mu obinrin kan ni Saudi Arabia lẹyin to sare gun ori pepele lọ dimọ onkọrin ọkunrin kan, Majid al-Mohandis.
" O tẹ siwaju ninu ọrọ rẹ wipe, yiyi orukọ pada nikan ko to, sugbọn o yẹ ki ijọba gbe awọn igbesẹ ti o wa ni ibamu pẹlu yiyi orukọ pada.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Akọroyin ọmọ Philippines Maria Ressa nigba ti wọn n ṣe iwadii lori rẹ Courtney Radsch lati ajọ to n ja fun aabo awọn akọroyin ni ọrọ gbigbogun ti awọn akọroyin pẹlu ọrọ ẹnu ti wa wọpọ bayii, paapaa ni orilẹede Philippines ati Amerika.
Báyìí ni ẹ óo ṣe rú ẹbọ sísun olóòórùn dídùn sí OLUWA ní ojoojumọ fún ọjọ́ meje náà yàtọ̀ sí ẹbọ sísun ati ẹbọ ohun mímu ojoojumọ.
Caleb Ikechukwu ni lori ọrọ náà, iwadii ṣi n lọ lọwọ.
Ki wọn lo ororo ti yoo mu oju ara obinrin yọ, lasiko ibalopọ.
Noa bá ṣe gbogbo ohun tí OLUWA pa láṣẹ fún un.
Bákan náà ni Gómìnà tún ṣe afilọlẹ ètò ẹ̀kọ́ ọ̀fẹ́ fún àwọn ọmọ wọ́n bákan náà Báyìí ni 50 Kobo ṣe dá ìfẹ̀hónú Ali Must go"" sílẹ̀ tó mú ọ̀pọ̀ ẹ̀mí akẹ́kọ̀ọ́ lọ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Kété tí wọ́n bá ti báa yín sùn tàn torí pé ẹ tóbi, ẹ gbà pé ìfẹ́ yẹn ti parí - Auntie Remi Ọlọ́yàn ńlá Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!"
Adari Naijiria nigba kan naa wa rọ ijọba ipinlẹ Ọyọ lati ri wi pe wọn seto igbaye gbadun fun awọn olugbe ipinlẹ naa.
Òkun yìí ni ààlà ilẹ̀ náà ní apá ìwọ̀ oòrùn.
 Oun ati awọn olorin bii Majek Fashek ati Oritiz Wikili ni wọn jọ n kọrin lasiko kan naa.
Ti ẹ ko ba gbagbe, Ighalo gan an fun ra rẹ ṣalaye laipẹ yii bi o ti fi owo ounjẹ ọsan rẹ lọ wo ere bọọlu Man U.
"Ibeere to ṣe koko ju lasiko eto idibo yii ni pe: ṣe igbeaye rẹ dara ju boṣe wa ni dun mẹrin sẹyin, ṣe o lowo si ni tabi o toṣi si?
Koeman tuko Ajax Amsterdam gba ife-eye idije Eredivisie lorile-ede Netherland ti saa (2001-02, 2003-04), besini O tun tuko PSV Eindhoven gba irufe ife-eye naa lodun (2006-07).
Olaniyonu ,oluranlowo abenugan ile igbimo asofin agba Saraki ,lori iroyin ati
 níbẹ ̀ wọn yóò wọ inú àwọn àpò atẹ ́ gùn inú ẹ ̀ dọ ̀ fóró , wọn yóò sì ṣàn lọ sókè nínú ọ ̀ nà-ọ ̀ fun , níbití a ó ti wú wọn jáde bí ikọ ́ , tí a ó sì gbé wọn mì .
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù WAEC: Ìdá 82% àwọn tó jókòó ṣedánwò WASSCE 2019 ló yege 26 Agẹmo 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Miliọnu kan abọ awọn akẹkọọ to pegede ninu idanwo naa Ajọ onidanwo mẹwaa, WAEC ti gbe esi idanwo aṣekagba ileewe girama ti oṣu kẹfa, ọdun yii, West African Senior School Certificate Examination (WASSCE) jade.
Ati etí tí ń gbọ́ràn, ati ojú tí ń ríran,OLUWA ló dá ekinni-keji wọn.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Whatsapp: Àwọn gbéwiri s'àtakò sí Whatsapp, yára ‘Update’ rẹ̀ 14 Èbibi 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ile isẹ ẹ̀rọ ibaraẹnisọrọ Whatsapp ti ni ki awọn 1.
Wọ́n ni ìwà tí àwọn tí ó ṣáájú yin hù ní ìlú àwọn kò tẹ́ àwọn lọ́rùn, àwọn Àkàrà-oogun fi ojú àwọn rí nnǹkan.
Àṣà àti èdè Yorùbá dùn púpọ̀, o ní ìtumọ̀ kíkún Wo àwọn àwòràn tó làmìlaaka nílẹ̀ Adúláwọ̀ lọ́sẹ̀ yìí Kíkọ́ ẹ̀kọ́ gboyè nínú iṣẹ́ ìṣègùn ìbílẹ̀ yóò pèsè ìtọ́jú tó péye fọ́mọ Nàìjíríà- Ẹgbẹ́ àwọn dókítà Wọ́n mú ọjọ́ ìgbẹ́jọ́ agbésúnmọ́mí 9/11 tó ṣẹlẹ̀ l'Amẹrika Bakan naa lo ni ko si ewu kankan nitori ounjẹ ojo wọn ni awọn ti wọn mu naa wa wa si ipinlẹ Eko.
Ọna abayọ to wa fun ọ, to ba ni ikun to tobi ni pe ko se adinku suga ati ounjẹ afara lagbara to n jẹ, taa mọ si Carbonhydrate, jẹ ounjẹ niwọn tun wọnsi, ko si maa sinmi.
Oríṣun àwòrán, EFCC Àkọlé àwòrán, Ajọ tó ń gbogun ti iwà ìbàjẹ́, EFCC tí fi ọ̀pọ̀ ìgbà polongo kí àwọn ọmọ Naijiria ṣọ́ra fún ìwà 419.
Naijiria loju pe, ijọba oun yoo rii pe gbogbo awon agbofinro ati ọlọpaa orile
Oríṣun àwòrán, oau Àkọlé àwòrán, Ní ọjọ Aiku ni wọn ji Ọjọgbọn Adegbẹhingbe gbe.
 Ṣaaju ni ajọ to n ri si eto idibo, INEC, ti kọkọ sọ fun awọn ẹgbẹ oṣelu lati fi orukọ awọn oludije wọn ranṣẹ ko ti di ọjọ kejidinlogun, oṣu Kẹjọ, ọdun 2020 tabi ko gbagbe lati kopa ninu eto idibo ọhun."
O ti n mọ́ra bayìí (Day 8-15) Ni ipele kẹta, ó yẹ ki iyatọ ti maa ba ara nítori, ara ti mọoo pe oun gba ààwẹ báyìí.
Ará, kí ni kókó ohun tí à ń sọ?
Lara awọn to ti fi ohun wọn si iwọde naa ni ogbontagi agbabọọlu fun Arsenal, Mesut Ozil ati Marcus Rashford.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Adebola Ademilua: Àìrísẹ́ ṣè lẹ́yìn ìwé kíkà ló sọ mi dí ìyá onírú, mo dúpẹ́ tèmi Ẹlomiran ti ko fẹ ki a fi oruko oun lede sọ pe awọn oṣiṣẹ LUTH ko gbogbo ibusun to wa ninu ile iwosan to yẹ ki wọn sun kuro.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Awọn eku maa n ko arun iba orere ran gaari Ni ọjọ aiku ni iroyin tun kan wipe awọn mẹta miran tun ti di ero ọrun nipasẹ arun gbẹmi-gbẹmi yii.
Ìlú tí ó kún fún irọ́ ati ìkógun,tí àwọn adigunjalè kò fi ìgbà kan dáwọ́ dúró níbẹ̀!
Awọn olukọ kan n kọ awọn ọmọ ni ita kilaasi ti awọn miran si n kọ ọrọ si ilẹẹlẹ dipo oju patako.
O ṣalaye pe bi ọpọ ọkunrin ba nyan ale nitori ati ba obinrin bẹẹ lajọṣepọ ni kii ṣe nitori ifẹ ati pe ibalopọ laarin ọkunrin ati obinrin to ba fẹ sile a maa yatọ O ni ajẹku ẹba ni obinrin to n ba ọkọ oun sun n jẹ nitori oun gangana lo ti jẹ ogidi ẹran ara rẹ tan.
Buratai wa gba awon osise ile-ise ologun nimoran lati mo ohun ti won n se, lati je olufokan jin ati laikaare, ni iyanju ati gbaruku ti awon aseyori ti won n se lowo.
Ajọ to n gbogun ti iwa ibajẹ ni Naijiria, EFCC, lo gbe Nyame lọ sile ẹjọ lori awọn ẹsun naa.
Ọgọrọ eeyan lo peju pesẹ sibi eto isinku naa lati ṣe ẹyẹ ikẹyin fun un.
Fún ọjọ́ mẹta, kò ríran, kò jẹ, bẹ́ẹ̀ ni kò mu.
Mane dá iná yá Kepa lábẹ́ lẹ́ẹ̀mejì bí Liverpool ṣe lu Chelsea lálùmọ́lẹ́ bíi bẹ̀m̀bẹ́.
A kò tíì lè sọ ti ìfipabánilòpọ̀ àmọ́ òkúta ni wọ́n fi fọ́ orí Azeezat - Ọlọ́pàá Oyo Agbarijọpọ awọn ẹgbẹ ajafẹtọmọniyan bii mẹrinla ọtọọtọ ti koro oju si iwa ifipabanilopọ ati iṣekupani ti awọn obinrin n koju lawujọ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Coronavirus in Nigeria: Èèyàn 675 ló tún ti ní Covid-19 ní Naijiria 20 Agẹmo 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 11 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Eeyan ẹgbẹta ati marundinlọgọrin ni esi ayẹwo coronavirus ti ajọ NCDC fi sita ni ọjọ kẹwaa, oṣu Kejila dun 2020 fihan pe o tun ti ni aarun naa ni Naijiria.
Oga agba ajo NCDC, Onisegun oyinbo Chikwe Ihekweazu, lo so eyi di mimo l’ Abuja pe awon iko alayewo The Nigeria Field Epidemiology and Laboratory Training Programme (NFELTP) ni o sagbateru re ni Abuja.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù EndSARS: Olatunde Abolarinwa London Tailor ní òun á ṣe baba fún mi, kò tilẹ̀ dúró ṣe bàbá àwọn ọmọ tirẹ̀ tóríi ìwà Ọlọ́pàá Mopol Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ EndSARS: Olatunde Abolarinwa London Tailor ní òun á ṣe baba fún mi, kò tilẹ̀ dúró ṣe bàbá àwọn ọmọ tirẹ̀ tóríi ìwà Ọlọ́pàá Mopol 4 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 5 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Iṣẹlẹ Kayeefi wa ti oṣu yii jẹ kayeefi ṣugbọn ko si irọ kankan nibẹ.
Eleyi jẹ ọkan gboogi ninu igbesẹ ile aṣofin Naijiria kan ti wọn ko ti ribi ba de ibi to yanju ti ko si daju pe wọn yoo ri yanju ki saa ijọba wọn to pari.
Awon oko ofurufu fun ogun meji F15 ni won yan tele lati lo wa baalu naa ki won to gbo bo se ja pelu ariwo nla.
"Ladugbo nkan toju iya wn n ri ko kere, ọmọde mii a ri i a kan dede sa lọ pe ""ẹhn ẹ wa wo iruu oju yii, ti yoo họ""."
Ibi ipade yii si lo ni awọn ti tete gbe digba-digba lọ sile iwosan, sugbọn aisan lo se e wo, ko si ẹni to ri ti ọlọjọ se.
’ Lẹ́yìn èyí Ayédèrú-ẹ̀dá sọ̀rọ̀ o ní, ‘Mo mọ̀ dájú ṣá pé bí obìnrin náà bá tún dé ẹ ó ba a fi ìjà pa ẹẹ́ta.
Amọ, o fikun ọrọ rẹ pe atundi ibo ko ni waye nitori eto idibo naa si n tẹsiwaju lonii, koda o sọ pe igbimọ eto idibo abẹnu yoo kede ẹni to ba bori ninu idibo abẹnu naa l'Ọjọru.
egbogi oloro, Nigeria’s Drug Law Enforcement Agency, NDLEA, ti dana sun oko kan
Onimọ nipa ounjẹ jijẹ, Oluwatobi Oyedeji ninu ọ̀rọ̀ to ba BBC News Yoruba sọ, sọ pe ounjẹ ti a ko ti i ṣe to ba ni kokoro ninu tumọ si pe ounjẹ ti wọn ko fi kẹmika kankan gbin ni.
Nítorí pé mo ti fọ́ Moabu, bíi ohun èlò tí ẹnikẹ́ni kò bìkítà fún.
Nítorí náà, fi ọkà baali, òróró ati ọtí tí ìwọ oluwa mi ti ṣèlérí ranṣẹ sí èmi iranṣẹ rẹ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Revolution Now: Iléejọ́ ní àjọ DSS kò láṣẹ láti ti Sowore mọ́lé ju ọjọ́ 45 lọ 8 Ògún 2019 Oríṣun àwòrán, @YeleSowore Ileẹjọ giga ijọba apapọ to wa nilu Abuja ti pasẹ fun ajọ ọtẹlẹmuyẹ ilẹ wa pe ko gbọdọ fi asaaju ikọ to n se iwọde Revolution Now, Omoyele Sowore, si ahamọ kọja ọjọ marundinlaadọta lọ.
”Eliṣa dáhùn pé, “Bí OLUWA ti ń bẹ, tí ìwọ náà sì wà láàyè, n kò ní fi ọ́ sílẹ̀.
Àwọn tí ń fọ́nnu kò lè dúró níwájú rẹ;o kórìíra gbogbo àwọn aṣebi.
Wo àwọn Adelé-Ọba aládé méje tó jẹ́ obìnrin nílẹ̀ Yorùbá Akẹ́kọ̀ọ́ 333 ni a kò tíì le sọ nípa wọn nílé ẹ̀kọ́ Kankara Katsina- Ìjọba Nàìjíríà Ogun abẹ́lé tó ń ja Akeredolu l'Ondo, òní la ó mọ̀ bóyá yó borí rẹ̀ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Africa Eye: Wo ìtàn ìyá kan ìyá kan àtàwọn olè ajọ́mọgbé tó n ta ọmọ ní Kenya Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Ojo ti n pa igun kikọrin pọ awọn olorin ọmọ Naijiria ati South Africa bọ, ọjọ ti pẹ.
Wọ́n ń bi í pé, “Irú àṣẹ wo ni o fi ń ṣe nǹkan wọnyi?
Ó wí pé, “Jẹ́ kí èmi náà kú pẹlu àwọn ará Filistia.
    Nígbà tí a wòye pé ilẹ̀ ń ṣu lọ èmi àti ìyàwó mi díde, a múra ó di ibi tí à ń gbé, ọjọ́ kejì ni a sì kúrò ní ìlú yìí.
Àwọn arakunrin ní Listira ati Ikoniomu ròyìn Timoti yìí dáradára.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Senegal naa ja ninu idije Russia 2018 Àwọn ikọ̀ ẹgbẹ́ agbábọ́ọ̀lù kọọkan ń ṣe ju bí àwọn èrò ṣe rò lọ nigba ti àwọn miiran n já wálẹ̀ láìròtẹ́lẹ̀.
Òun ati àwọn olórí ogun ati àwọn tí wọ́n ń ṣọ́ ọba ati àwọn tí wọn ń ṣọ́ ààfin sin ọba láti ilé OLUWA lọ sí ààfin.
Nígbà náà ni OLUWA tún bá Jobu sọ̀rọ̀ láti inú ìjì líle, ó ní,
A ò fẹ àwáwí, owó wa ni ẹ san - àwọn òṣìṣẹ́ ilé aṣòfin Amosun lẹ́tọ̀ọ́ láti gbè lẹ́yìn oludíje tó bá wù ú - APC Ahamọ ẹka ọtẹlẹmuyẹ ileeṣẹ ọlọpaa Ipinlẹ Eko (SCID) ni olorin takasufe Small Doctor ti orukọ rẹ gangan n jẹ Michael Owusu Addo, sùn lati ọjọ Aje tí àwọn ọlọ́paa ti mu.
Nigba to n sọrọ nibi apero kan to da lori ọna lati ṣeto aabo to mọyan lori, Monguno ṣalaye pe lai fopin si Almajiri bayii, yoo pada wa ṣakoba fun orilẹede Naijiria lọjọ iwaju.
Wolii Hagai ati wolii Sakaraya, ọmọ Ido, bẹ̀rẹ̀ sí sọ àsọtẹ́lẹ̀ fún àwọn Juu tí wọ́n wà ni Juda ati Jerusalẹmu ní orúkọ Ọlọrun Israẹli, ẹni tí ó jẹ́ orí fún wọn.
Àwọn eniyan yóo máa pè yín ní alátùn-únṣe ibi tí odi ti wó,alátùn-únṣe òpópónà àdúgbò fún gbígbé.
Alaafin Oyo sọ eyi lasiko ti awọn gomina ni iwọ-oorun Naijiria, awọn minisita, awọn lọbalọba ni ilẹ Yoruba ṣe ipade pẹlu asoju Muhammadu Buhari.
ÌTÀN: Ò tó ọgbọ̀n ọdún sẹ́yìn báyìí ní ìletò kan tí ń jẹ́ Sọkúlú lẹ bàá ìlú kan tí ń jẹ́ Fẹ̀yìntì.
Ileesẹ agbokujo Kingdom Blue, Kings & Queens Funeral Services ati Black Phoenix sọ fun awọn akọroyin wipe, awọn oṣiṣẹ ile ijọsin naa tan awọn jẹ.
" O fi kun pe pupọ ninu awọn eeyan to wa ni ipo to ga ju ninu ijọba to n tukọ orilẹ-ede yii lọwọ lo wa lati apa oke ọya, ti awọn ẹya to ku ko si rọwọ mu.
Ọ̀dọ̀ OLUWA ni ìgbàlà àwọn olódodo ti ń wá;òun ni alátìlẹ́yìn wọn ní àkókò ìṣòro.
Ọkunrin yìí yọ sílẹ̀ ninu owó tí wọ́n rí lórí rẹ̀, ó bá mú ìyókù wá siwaju àwọn aposteli.
Ìjọba ìpínlẹ̀ Eko ti kéde orúkọ àwọn ọlọ́pàá tó fi ìyà jẹ àwọn olùwọ́de End Sars Àbádòfin ìṣúná 2021 ré kọjá ìpele ìkejì nílé aṣòfin àgbà Pásítọ̀ Enoch Adeboye darapọ̀ mọ̀ #ENDSARS, ó fún ìjọba Nàìjíríà ní ìmọ̀ràn ọ̀nà àbáyọ Wo àwọn ojúṣe àti èèwọ̀ fún ikọ̀ ọlọ́pàá SWAT tó gba iṣẹ́ lọ́wọ́ SARS Wo diẹ lara awọn to fi adun ati aṣeyọri si iwọde End SARS naa to n lọ lọwọ: 1.
Tunisia , eleyii lo si  fun Iko agbabọọlu
Ǹjẹ́ bí eniyan bá rí ọ̀tá rẹ̀, ó lè jẹ́ kí ó lọ ní alaafia?
Eeyan 90 ló ní Covid-19 ní Nàìjíríà lọ́jọ́ Iṣẹ́gun Awọn to ni aarun coronavirus ni Naijiria tun ti le si bayii, lẹyin ti ajọ NCDC kede esi aadọrun eeyan to tun ṣẹṣẹ ni, lọjọ Iṣẹgun.
Fi agbára orúkọ rẹ gbà mí, Ọlọrun,fi ipá rẹ dá mi láre.
Ile naa wa ni agbegbe Oluyọle ni ilu Ibadan, ṣugbọn a ko ri ẹnikẹni ti o le ba wa sọrọ nibẹ.
Gbogbo àwọn tí wọn ń ṣe iṣẹ́ iranṣẹ ninu tẹmpili ati àwọn ọmọ àwọn iranṣẹ Solomoni jẹ́ irinwo ó dín mẹjọ (392).
A ti wá mọ̀ nípa ǹkan ìgbàlódé à sì ń fẹ́ ohun tí yóò bá ìní wa pàdé gẹ́lẹ́ bó ti yẹ tó fi mọ̀ èyí tí à ń mú wọ inú yàrá."
Wo àwọn oúnjẹ márùn ún tó ń mú kí àtọ̀ ọkùnrin dára síi Wo ibi fún èsì ìdìbò yíyan aàrẹ tuntun ní orílẹ̀-èdè Ghana Ọlọ́pàá, sójà yabo Lekki Toll Plaza láti dènà ìfẹ̀hónúhàn míràn Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Akomolede ati Asa lori BBC: Olùkọ́ Kikelomo Ogunboye tan ìmalẹ̀ sí ìwà olè ọ̀gá ọlọ́pàá Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Tàkúté ti mú un ní gìgísẹ̀,ó ti kó sinu pańpẹ́.
Àbúrò mi yìí, kìí ṣe ọmọ ìyá mi, àbúrò bàbá mi obìnrin nni ó bí i, ó sì jẹ́ ọmọ líle.
Wọ́n jọ ń jẹun pẹlu ayọ̀ ati pẹlu ọkàn kan.
Laxman Narasimhan ni ọja rọba idaabobo ti lọọlẹ gan an lasiko yii koda to fi de orilẹede Uk.
Olukuluku mú ohun ìjà tí ó fẹ́ fi pa eniyan lọ́wọ́.
Ó bi Jesu ní ọpọlọpọ ìbéèrè ṣugbọn Jesu kò dá a lóhùn rárá.
Wọ́n bá fà á lọ́wọ́ lọ sí Damasku.
olubori, mo si fi n daa yin loju pe, maa gbiyanju lati sa ipa mi lati rii pe
INEC ni orúkọ ẹgbẹ́ òṣèlú Ezekwesili yóo hàn lórí ìwé ìdìbò #BBCNigeria2019 Fake News: BBC Kò ṣe ètò ìrànwọ́ ìwé kíkà lásìkò yìí Ilẹ Gẹẹsi fẹ kọ ẹwọn si Naijiria Àwọn agbébọn fọ́ ọgbà ẹ̀wọ̀n ni Minna Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Obìnrin ló ni ilé àti àdúgbò fún ìdí èyí wọ́n lè ṣe ìlú dáadáa' Nkan bi ọdun 1950s ni wọn kọ El Helicoide laye igba naa ti orilẹede Venezuela ni ala ire to si n pa ọpọlọpọ owo wọle latara epo rọbi.
3 Folurunsho Alakija to wa ni ipo mọkandilogun ni biliọnu $1.
Nítorí ìfẹ́ ayérayé tí ó ní sí Israẹli ni ó ṣe fi ọ́ jọba lórí wọn, kí o lè máa ṣe ìdájọ́ ẹ̀tọ́ ati ti òdodo.
Ibudo iko nnkan iṣẹnbaye lọjọ si ti ilẹ Gẹẹsi sọ pe, idaji goolu to wa lagbaye lo wa ni ijọba Musa nikan laye igba yẹn.
Iṣọla Oyenusi rèé, ẹnití ìfẹ́ obìnrin ṣun dé ìwà ìdigunjalè Ẹfunroye Tinubu - Ògbóǹtagí oníṣòwò, olówò ẹrú àti afọbajẹ Samuel Ajayi Crowther, òjíṣẹ́ Ọlọ́run tó gbé èdè Yoruba lárugẹ Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, AFCON 2019: Níbo ni ọ̀rọ̀ owó ajẹmọnu ikọ Super Eagles dé dúró?
O soro lori ipese eto eko to yaranti fun awon ogo weere to je ijoba oun logun lasiko yii pelu idunu lori aseyori eto pinpin ounje fawon akekoo ile iwe alakobere to ti n bi eso rere ni Naijiria bayii pelu ileri pe yoo to kari gbogbo ipinle.
'Ẹ má pè mí ní Kupe; DJ Copy l'orúkọ mi' Ìjọba ti ilé ijó Shina Peller, Quilox pa Kò tíì pẹ́ jù bí ìjọba bá leè sọ ẹni tó pa olóògbé Bola Ige - Ààrẹ Gani Adams A kò fòfin de owó naira tó ti pẹ́ ní Naijiria- CBN #parental guidance Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí kan sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
Apànìyàn kan takú sí ibi ìpànìyàn lẹ́yìn tí ó pa ènìyàn tán; òmíràn fi ìwé pẹlẹbẹ ìdánimọ̀ọ rẹ̀ gba iyàrá tí ó tọ́jú òkú ẹni tí ó pa sí.
ni o so di mimo pe eto ẹkọ ati ilera yoo wa lopo yanturu fun  awon  omo bibi ati olugbe Ipinle Oyo.
Ajúṣefínní, ọ̀rẹ́ orímóògùnjẹ́ ni ó bá Orímóògùnjẹ́ ra ilẹ̀ tí ó ń kọ́ ilé sí.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Iléesẹ́ ológun: Àwọn ọmọ-ogun ṣi wá gbọ́ lórí ìsípò-rọpò wọn ni 16 Agẹmo 2018 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 13 Ògún 2018 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Boko Haram: Awọn ọmọogun ò sọnu, enikan péré ló farapa Àláfíà ti gbàjọba ní pápákọ̀ òfurufú táwọn ọmọogun orílẹ̀ gbà lánàá, láti fẹhonu han lóri bí wọn se pín wọn sí ibùdó tuntun fún iṣẹ́ wọn.
Àjẹsára náà kò léwu láti lò , èyí sì kan àwọn tó ní àkóràn àrùn hiv pàápàá .
ni ìbéèrè tí spọ̀ ń bèèrè Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí EndSARS: Makinde kéde ìrànwọ́ fáwọn ẹbí ọlọ́pàá tó bá rògbòdìyàn EndSARS lọ láti inú N500m tí a yà sọ́tọ̀3 Bélú 2020 Fídíò, EndSARS, EndSWAT Protests: Òbí agbábọ́ọ̀lù Kazim Tiamiyu Kaka àtàwọn míì tí ọlọ́pàá pa sọ̀rọ̀, omijé bọ́ lójú3 Bélú 2020 EFCC: Ìwádìí lórí ẹ̀sùn ìwà jẹgúdújẹrá tí wọ́n fi kan Babatunde Fowler tó jẹ́ àdàrí iléeṣẹ́ FIRS tẹ́lẹ̀2 Bélú 2020 Fídíò, Soyinka Cancer: Àṣe ara mi ni iso ti n run gbogbo bí mo ṣe n ṣèrànwọ́ lórí jẹjẹrẹ27 Bélú 2019 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 3 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 5 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Olùfẹ́, mo gbadura pé kí ó dára fún ọ ní gbogbo ọ̀nà ati pé kí o ní ìlera, gẹ́gẹ́ bí o ti ní ìlera ninu ẹ̀mí.
Mo ti gbé àpótí ẹ̀rí sibẹ, inú rẹ̀ sì ni majẹmu tí OLUWA bá àwọn eniyan Israẹli dá wà.
Oríṣun àwòrán, @simonfmudu Eeyan mọkanla lo fi ara gbọgbẹ lorisirisi lasiko ikọlu naa, ti wọn si tun jo ọpọ ilegbe kanlẹ.
Naomi dáhùn, ó ní, “Ó dára, máa bá àwọn ọmọbinrin rẹ̀ lọ, ọmọ mi, kí wọ́n má baà yọ ọ́ lẹ́nu bí o bá lọ sinu oko ọkà ẹlòmíràn.
O kere tan eniyan mọ́kànlélógóje lo padanu emi won sinu isele omiyale agbara ya soobu ati ala ile lorile-ede Japan.
Ṣugbọn OLUWA gúnwà títí lae,ó ti fi ìdí ìtẹ́ ìdájọ́ rẹ̀ múlẹ̀.
Dafidi sá fún Saulu ní ọjọ́ náà.
Idi ni pe isẹlẹ ibugbamu miran tun ti waye nilu Eko lọjọ Isẹgun ninu ibudo itaja kan ti wọn ti n ta afẹfẹ gaasi ati eroja Kanbaadi.
Nígbà tí ọkùnrin náà kí mi èmi náà rọra dá a lóhùn ọ jàre, nítorí kí ni ńkọ́?
Mowe naa ni agọ Ọlọpa ti awọn obi Favour lọ nigba to di pe wọn n wa ọmọ wọn.
Ọba Saliu Adetunji n gba tabuku wọn, ki oriade naa si tete wa idahun si awọn ẹsun tawọn fi kan.
O seese ki ofin konile-o-gbele tẹsiwaju fun ọsẹ meji ni ipinlẹ Eko, Ogun ati Abuja Wọn le e gbegile ofin konile-o-gbele, eleyii ti yoo fayegba itankalẹ arun Coronavirus lati agbeegbe kan si omiran.
Nígbà tí Josẹfu jí láti ojú oorun, ó ṣe gẹ́gẹ́ bí angẹli Oluwa náà ti pàṣẹ fún un.
ÌLÀNÀ TÍ À Ń GBÀ ṢIṢẸ́ Fún iṣẹ́ to níkìmí nínú, bí iṣẹ́ ìwádìí tàbi kíkọ ìròyìn tó níṣe pẹ̀lú dátà, a máa ń ràn yín lọ́wọ́ láti ni òye bi a ṣe ń se iṣẹ́ wa nípà sísàfihàn bi aṣe ṣe àkójọ dátà àti ìtúpalẹ̀ ohunkohun to ba dabi ẹni pe ó ta kókó, àwọn àròsínú tàbi ìlànà míràn ti a gbà ṣiṣẹ́- bí àpẹẹrẹ, àwọn àpẹẹrẹ ìkẹ́kọ̀ọ́, ìwọ̀n àyẹwò, sisasoju, awọn àlà àìtọ́, báwo ni a ṣe gba dátà, ọ̀nà wo lo gbà báramu lágbàyé, pẹ̀lú ìgbà àti àkókò Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Ǹjẹ́ àwọn lọ́balọ́ba nípa tí wọ́n ń kọ nínú òṣèlú orílẹ̀ èdè Nàìjíríà?
" O salaye siwaju sii wipe asiko to fun Aarẹ Buhari lati gbe igbesẹ to tọ ni kiakia!
Bi eto isinkun naa ṣe lọ ree.
Ẹ kò sì gbọdọ̀ ri òpó mọ́lẹ̀ kí ẹ máa bọ ọ́, nítorí pé OLUWA Ọlọrun yín kórìíra wọn.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Cerebral Palsy: àrùn tó n gba omijé lójú ẹni láìnídìí Oṣu meji ṣaaju ọjọ igbeyawo, o lọ si ṣọọbu aṣaraloge kan, wọn si fun un ni ipara kan lati mu ki ara rẹ o pupa.
Kí wọ́n sì mú akọ mààlúù kékeré mìíràn wá, fún ẹbọ ìmúkúrò ẹ̀ṣẹ̀.
Ẹfunsetan Aniwura, obìnrin tó ju ọkùnrin lọ Ọ̀rọ̀ǹpọ̀tọ̀niyùn, Aláàfin obìnrin àkọ́kọ́ rèé, tó ní nǹkan ọkùnrin Taiwo Akinkunmi, ọmọ Ibadan tó ya àsìá Nàíjíríà Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Kayefi BBC Yorùba: Bàbá ọmọ, Mọ́ṣúárì, Ọlọ́pàá kẹ́jọ́ rò nípa òkú ọmọ tó pòórá Igbakeji aarẹ ni ọtọ ni Eto kikọ Gaa Fulani (Ruga Settlement) ọtọ ni Eto ayipada fun sinsin maalu (National Livestock Transformation Plan).
Oríṣun àwòrán, @bbnaija Àkọlé àwòrán, Eyi ga ju, eto ti ko ba ti gbe aṣa ga ko yẹ wa O ni: Mo ti ba awọn ajọ to n risi igbohun safẹfẹ lorilẹ-ede yi sọrọ, nitori pe ohun to n sẹlẹ lori BBNaija jẹ nkan ti o buru jai.
Àní ìwọ gan-an lọ dùn jù
Ó sọ fún un pé, “Má bẹ̀rù, nítorí pé ọwọ́ Saulu, baba mi, kò ní tẹ̀ ọ́.
Bẹ́ẹ̀ sì ni àwọn ìsọ̀ olóúnjẹ́ onikanòjọ̀kan náà máa nwà káàkiri fún àwọn èrò láti ra óújẹ jẹ.
'Àwọn agbábọ́ọ̀lù Super Eagles já wa kulẹ̀ ní ìdíje wọn pẹlúù Madagascar' Àwọn orílẹ̀èdè àjọ ECOWAS yóò máa ná owó kan nàá l'ọ́dún 2020 'A fẹ́ kúrò ní Larubawa nítorí à kò gba ẹ̀sìn' Ọkọ mi kò le f'ipá bá ẹnikẹ́ni lò pọ̀ láíláí - Modele Fatoyinbo Ninu iwadii BBC Africa Eye ni a ti rii pe ọpọ n fẹsun kan awọn oṣiṣẹ eleto aabo IRT pe wọn n fiya jẹ awọn eniyan lọna aitọ.
(Kiriati Seferi ni orúkọ tí wọ́n ń pe Debiri tẹ́lẹ̀.
Ṣugbọn nígbà tí àwọn ìwẹ̀fà tí ọba rán jíṣẹ́ fún un, ó kọ̀, kò wá siwaju ọba.
Gomina ipinlẹ Ọyọ naa fikun pe, awọn ipo to jẹ gboogi ni isejọba oun ni awọn ọba naa yoo ti kopa fun ilọsiwaju ipinlẹ naa.
O ni wọn n ṣe eyi nitori ibẹru pe wọn le bọ kuro ninu ẹwọn bi awọn ọmọ ogun ilẹ Turkey ṣe n ṣakọlu si agbegbe ọhun.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Fathia Balogun: Kò sí ẹni tó bá mi lò pọ̀, kó tó fún mi ní isẹ́ Ni opin ọsẹ to kọja ni Timi Dakolo ke ibosi sita pe lẹyin ọpọlọpọ ọsẹ ti awọn ti fi iwe ipẹjọ siwaju ileeṣẹ ọlọpaa, awọn ko tii gbọ pe wọn ti pe iranṣẹ Ọlọrun naa fun ifọrọwanilẹnuwo.
Nibi ti oun ti n gbiyanju lati gun ọkada ti wọn ti wọn gbe wa, ni awọn ara adugbo sare le e mu.
Iwọde naa ti mu ki ijọba apapọ tu ẹka naa ka, to si ṣagbekalẹ ẹka tuntun miran to pe ni SWAT, ṣugbọn awọn ọdọ naa ni ko tẹ wọn lọrun.
”Idabo bo ara-ilu ati ohun ini wonBakan naa, lara ohun ti won tun sagbeyewo re, ile-igbimo asofin yoo tun sewadi lori idojuko to n koju ile-ise Dana Air Limited , lati mo ohun to sokunfa ijamba oko ofurufu won gbogbo, ni ona lati dabo-bo emi ara-ilu ati ohun ini won.
- Amẹ́ríkà fọnmú O ni awọn ikọ SARS da Kazeem duro, ti wọn si fi ẹsun kan pe o jẹ ọmọ Yahoo, oni jibiti ori ayelujara, nitori imura rẹ, ṣugbọn o ṣalaye fun wọn pe iṣẹ bọọlu gbigba ni oun n ṣe.
Ńṣe la máa sáré bọ́ síta pẹ̀lú ẹ̀rọ ayàwòrán wa àti àwọn irinṣẹ́ rẹ̀.
Ọwọ́ mi ni mo fi ta ojú ọ̀run bí aṣọ,tí mo sì pàṣẹ fún oòrùn, òṣùpá ati àwọn ìràwọ̀.
jẹ ki o wa ni isọkan.
Hazard darapọ mọ Chelsea lọdun 2012, o si ti gba apapo ayo mẹwaa sagbọn fun Chelsea ninu idije Premier League ti saa yii.
Aba iṣuna ọdun 2021 ti Sanwo-Olu gbe kalẹ naa, lo pe akori rẹ ni ‘aba iṣuna to sọ ireti ji pada’.
Àwọn tí wọn ń pète ibi ti ṣìnà,ṣugbọn àwọn tí wọn ń gbèrò ire yóo rí ojurere ati òtítọ́.
Ohun ti wọn fun eṣu, eṣu gba a lọjọ naa, ti ọpọ dukia si bajẹ laarin ilu, o kere ẹmi eeyan to le ni ọgọrun ba iṣẹlẹ naa rin.
Ọgbẹni Arẹgbẹsọla keboosi imọran yi sita lasiko ayẹyẹ iranti ọlọdọọdun awọn akọni to ti sun loju ija atawọn to fara gbọgbẹ eyi to waye nilu Osogbo.
Bakan naa lo koro oju si ijọba ilẹ South Africa pe o mọọmọ n fi ọrọ titi ọwọ bọ iwe adehun igbọraẹniye laarin orilẹede mejeeji falẹ.
Àwọn ọmọ Lefi tí wọ́n bá wọn lọ ni: Ṣemaaya, Netanaya, ati Sebadaya; Asaheli, Ṣemiramotu, ati Jehonatani; Adonija, Tobija ati Tobadonija.
Ẹ wo baba wa Ogunwusi yii, lati kekere ni wọn ti sọ fun awọn naa pe wọn yoo jọba.
pe ara rẹ ni ọga ọlọpaa orilẹede Naijiria.
Àlọ rámirámi ni à ń rí ni ọ̀ràn Lúmọ̀ogun, a kì í rábọ̀ rẹ̀.
A óo bọ́ aṣọ kúrò lára wọn, kí ojú ó lè ti Ijipti.
Kò sí ẹni tó lè yọ mi nípò Sẹnetọ -Dino Melaye
Minisita eto isuna lo fi ikede yii sita lẹyin ipade igbimọ alaṣẹ ikejidinlogun ti ori ayelujara to waye l'Ọjọru ọsẹ.
Ọdún ìbejì sọkutu-wọ̀wọ̀ ní Igboọrà, àṣírí bí wọn ṣe ń bí ìbejì tú Àgbéyẹ̀wò àṣà: Ìdí tí Yorùbá kìí fí tufọ ikú òjìji fún èèyàn Ìpínlẹ̀ Ọ̀ṣun kò le è sanwó o ọmọ́gọ̀ lórí LAUTECH- Gómìnà Oyetola Awakọ̀ bàálù ológun òfurufú obìnrin àkọ́kọ́ ní Nàìjíríà rè e Bakan naa ni Norma Ka Mbele sọ wi pe, igbesi aye oun ti yi pada lati igba ti wọn ti fi ipa ba oun lopọ, nitori ko si obinrin ti wọn yoo fipa ba lopọ, ti aye rẹ yoo tun ri bakan naa mọ.
NCDC kéde èèyàn 601 tó ṣẹ̀ṣẹ̀ lùgbàdì Covid-19 ní Nàìjíríà Lara awọn to peju sibi ayẹyẹ naa ni awọn gbajugbaja oṣere tiata Yoruba bii Femi Adebayo, Tayo Odueke ti ọpọ mọ si Sikira Sindodo, ati bẹẹ bẹẹ lọ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, End SARS, End SWAT: Ó pé mi bí SARS kò ṣe sọ mí dolówọ́- Fulani Kwajafa Bakan naa nileeṣẹ ọmogun sọ fawọn araalu pe ki wọn fọkan balẹ, wọn ni awọn ṣetan lati daabo bo wọn.
Iye itajẹsilẹ ati ifiniṣẹṣo owo ni Naijiria n kọ ni lominu."
Baraki bá dá a lóhùn pé, “Bí o óo bá bá mi lọ ni n óo lọ, bí o kò bá ní bá mi lọ, n kò ní lọ.
Osinbajo, ẹni to fidi rẹ mulẹ pe oun ti ba ọpọ awọn oluwọde to fara gbọgbẹ, ti wọn wa nile iwosan sọrọ, tun wa kẹdun pẹlu awọn araalu ati ọlọpaa yika ilẹ wa, ti ikọlu naa kan.
O ni oun yoo fopin si idẹyẹsi.
Nínú ipa iṣẹ́ títúmọ̀ Ìwé ti Mọ́mọ́nì, Oliver, tí ó ntẹ̀síwájú gẹ́gẹ́bí akọ̀wé, ní kíkọ àwọn ohun tí Wòlíì npè, ní ìfẹ́-inú pé kí a bùn òun ní ẹ̀bùn ìtumọ̀.
Gbọ́ ohùn rẹ̀ tí ń dún bí ààrá,ati ariwo tí ń ti ẹnu rẹ̀ jáde.
"Ninu iwoye temi, isẹ si pọ fun awọn obinrin lati se ki wọn lee de ibi ẹkunrẹrẹ wọn.
2019 in Retrospect: Wo àwọn èèyàn jáńkán tí yóò rékọjá sí 2020 nínú ọgbà ẹ̀wọ̀n
Nilẹ Gẹẹsi o ti mu Minisita feto ilera Nadine Dorries.
Ṣugbọn a kò kọ́ ẹ̀yin bẹ́ẹ̀ nípa Kristi.
Ìjì líle fẹ́ jáde láti inú yàrá rẹ̀,òtútù sì mú wá láti inú afẹ́fẹ́ tí ń fẹ́.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Oluwo Divorce: Olúwòó ilú Iwo: Èèwọ!
Gaddafi ló l‘ẹ̀bi ìkọlù darandaran - Bùhárí Ọọ̀ni : Oluwo lorukọ oyè tí ọba Ìwó ń jẹ́ Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Nibẹ naa ni ọpọ awọn ololufẹ rẹ ti n fesi pe, awọn ṣetan lati tẹle lọ irinajo ọhun.
Brexit: Àpẹẹrẹ́ burúkú ni ìjọba gẹ̀ẹ́sì ń fi lílẹ̀ -Ọ̀jọ̀gbọ́n Wole Soyinka
Àkọlé àwòrán, Gomina ipinlẹ Kogi, Yahaya Bello naa kopa nibi eto isinku naa.
Àwọn onírẹ̀lẹ̀ yóo tún láyọ̀ láti ọ̀dọ̀ OLUWA.
Dokita Ratcliff ni beeyan nkankan, o lee fun ọpọlọ rẹ ni isimi.
Eyi mu ki wọn o faramọ iṣejọba orilẹ-ede Britain.
Ó bá sọ fún wọn pé, “Gbogbo ìjọba tí ó bá gbé ogun ti ara rẹ̀ yóo parun.
“Nígbà náà ni àwọn náà yóo bi í pé, ‘Oluwa, nígbà wo ni a rí ọ tí ebi ń pa ọ́, tabi tí òùngbẹ ń gbẹ ọ́, tabi tí o jẹ́ àlejò, tabi tí o wà ní ìhòòhò, tabi tí o ṣàìsàn, tabi tí o wà lẹ́wọ̀n, tí a kò bojútó ọ?
Owo tita ọmọ kekeke ti bẹrẹ sini jẹ òwò ti n mu ogunlọgo miliọnu wọle fawọn to n sowo naa.
Àwọn onímọ̀ ìjìnlẹ̀ ṣetán láti dán abẹ́rẹ́ covid-19 tí fásítì Oxford ṣe wò nílẹ̀ Afirika Kòkòrò coronavirus sì wà lára mi títí mo fi kúrò ní ibùdó ìtójú àwọn alárùn covid-19 l'Eko- Motosinoluwa Afolaranmi Mo wọ bàtà àti fìlà wọ pẹpẹ Cele láti ṣe wáàsí, kò sí ṣọ́ọ̀ṣì tí n kò le wọ̀ - Sheik Buhari ọmọ Musa Gómìnà Ondo Akeredolu ṣí ilẹ̀kùn ṣọ́ọ̀ṣì àti mọ́ṣáláṣí sílẹ̀ fún ìjọ́sìn Ìtàn ìgbésí ayé Oshodi, ọmọ Tápà léǹpe tó di akọni ní ìlú Eko Femi Adebayo di àgbà àáfà òníláwàní, Iyabo Ojo fi sìgá dárà, Allwell Ademola di ọmọdé padà, tí Wazo si bímọ tuntun Onisegun oyinbo naa tun rọ awọn obinrin lati ni imọtoto lasiko nnkan oṣu, ki wọn si yago fun titi ọwọ bọ oju ara wọn loore koore, ki arun ma baa wọ ibẹ.
L'Ogun, 'were' to sa ọmọ meji pati wa lahamọ A ko lee sọ boya 'were' lọkunrin to sa ọmọ meji"" Leon van Biljon dí èrò ọrun nípasẹ̀ Kìnìún rẹ̀ Ikú dóró!"
Ẹ óo jẹ ẹran, ẹ óo sì mu ẹ̀jẹ̀.
Báyìí ni ó ku bàbá mi sílẹ̀ gẹ́gẹ́ bi ènìyàn tí àwọn alábàáṣiré rẹ̀ ń lọ gẹ́gẹ́ bíẹyẹ.
Gbéra nílẹ̀, kí o ràn wá lọ́wọ́!
Ẹ kọ gbogbo ẹ̀ṣẹ̀ yín tí ẹ̀ ń dá sí mi sílẹ̀.
"Ilé ẹjọ́ tó ga jùlọ ní Nàìjíríà wọ́gilé ẹ̀wọ̀n Orji Uzor Kalu, pàṣẹ ìgbẹ́jọ́ tuntun Kọmíṣọ́nà Ọlọ́pàá kó gbogbo ọlọ́pàá ẹkùn Ondo lọ fún àyẹ̀wò COVID-19 ""Ọkọ kọ̀ mí, mo fẹ́ jẹ májèlé torí mo bímọ tó ní ojú ara takọtabo"" Coronavirus: Ǹjẹ́ àwọn dókítà tó ń tọ́jú eyín ń ṣisẹ́ lásìkò pàjáwìrì?"
'Oògùn olóró máa ń jẹ́ ki n bá ara mi jà, ti màá ṣerami léṣe' NDLEA gbéṣèlé tọ́ọ̀nù mẹ́rìn oogun Tramadol Opó ni mí, ṣùgbọ́n ọ̀pọ̀ ló ń rí opó bíi gbọkọgbọkọ Bakan naa ni awọn ti wọn ti bọ lọwọ ajaga oogun oloro wọnyii parọwa fawọn ti wọn ṣi n muu pe, o ṣeeṣe lati fii silẹ.
Ó tún jáde kúrò ní agbègbè ìlú Tire, ó la ìlú Sidoni kọjá lọ sí òkun Galili ní ọ̀nà ààrin Ìlú Mẹ́wàá.
Oríṣun àwòrán, Other Ọgbẹni Ọlọgbọdiyan ni ọpọ eeyan lo farapa nigba tawọn mii si dero ile iwosan ninu iṣẹlẹ ọhun lolu ilu ipinlẹ Kogi ti eto idibo naa ti waye.
ìgbéraga ti sọ irú ẹni bẹ́ẹ̀ di aṣiwèrè, kò sì mọ nǹkankan.
Oríṣun àwòrán, Twitter/Bdayo90 Gómìnà Seyi Makinde bá ẹbí Isiaq Jimoh tó kàgbákò ikú òjijì dárò Gomina Seyi Makinde to n tukọ ipinlẹ Oyo ti kẹdun iku ọmọdekunrin ti wọn yinbọn lu lasiko iwọde ENDSARS to waye nilu Ogbomoso.
Ẹni tí ó ja ìyá tabi baba rẹ̀ lólè,tí ó ní, “Kì í ṣe ẹ̀ṣẹ̀”,ẹlẹgbẹ́ apanirun ni.
Lẹ́yìn náà wọ́n kó àwọn òbúkọ fún ẹbọ ìmúkúrò ẹ̀ṣẹ̀ wá sọ́dọ̀ ọba ati ìjọ eniyan, wọ́n sì gbé ọwọ́ lé wọn lórí.
 eko iwoorun ati okowo ayeodeoni tesiwaju ni kikankikan ni guusu ju ni ariwa lo , ipa eyi n han ninu aye oloselu naijiria de oni .
Wúrà ni ó fi ṣe gbogbo àwọn ohun èlò tí yóo máa wà lórí tabili náà: àwọn àwo pẹrẹsẹ ati àwọn àwo kòtò fún turari, abọ́, ati ife tí wọn yóo máa fi ta nǹkan sílẹ̀ fún ètùtù.
Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Àwọn ọmọ Nàìjíríà yarí lórí èròngbà ilé aṣòfin pé kí àjọ FRSC má a lo nkan ìjagun7 Bélú 2020 6:18 Fídíò, Fire accident victim: AbdulQudus Bello ṣàlàyé bí òun ṣe dí aláàbọ̀ ara nítorí pọpọ́ọ̀fù àti ìbínú jàǹdùkù àdúgbò, Duration 6,187 Bélú 2020 NÍ YÀJÓYÀJÓ US Elections: Donald Trump ti n fi àmì hàn pé òun ṣetán láti kúrò ní White House Èyí tí a wò jùlọ 5:03 Fídíò, Omolola Arohunmolase Welder: Mo ti fí iṣẹ́ 'Welder' gbayì láwùjọ, tó mo fi tọ́ ọmọ yanjú, Duration 5,039 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 5:39 Fídíò, Akomolede ati Asa lori BBC: Olùkọ́ Kikelomo Ogunboye tan ìmọ́lẹ̀ sí ìwà olè ọ̀gá ọlọ́pàá Audu gẹ́gẹ́ bí àwòkọ́ṣe àsìkò yìí, Duration 5,398 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 4:11 Fídíò, Oba Adeyeye Ogunwusi: Ojú mi ti rí lọ́pọ̀ lọpọ̀, ọ̀pọ̀ èèyàn ni kò tilẹ̀ gbàgbọ́ pé mo lè jọba- Ooni, Duration 4,117 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 4:43 Fídíò, Promise Akinlade: ọmọ ọdún mọ́kànlá tó ń fi ìlù dárà bíi àgbàlagbà sọ̀rọ̀ nípa tálẹ́ǹtì rẹ̀, Duration 4,437 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 0:59 Gbọ́, Ìsẹ̀lẹ̀ jákèjádò orílẹ̀èdè àgbáyé láàárín ìṣẹ́jú kan, Duration 0,59wákàtí 5 sẹ́yìn 7:03 Fídíò, Olumuyiwa Bolade Adedeji Military Bruitality: Bí arákùnrin onípèníjà ara tí sọ́jà lù ṣe dé, Duration 7,035 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 4:45 Fídíò, Yoruba Films: Ẹ̀ẹ́ bẹ̀ mi kúrò láyé ni, mi ò lè kú - Fadeyi Oloro, Duration 4,4526 Èrèlè 2020 2:48 Fídíò, Esther Ajayi: Èmi náà ti borí ìṣòro rí ló ń mu mi ṣojú àánú, Duration 2,481 Ògún 2019 6:08 Fídíò, Adebola Ademilua: Àìrísẹ́ ṣè lẹ́yìn ìwé kíkà ló sọ mi dí ìyá onírú, mo dúpẹ́ tèmi, Duration 6,0827 Bélú 2020 5:55 Fídíò, Soyinka Cancer: Àṣe ara mi ni iso ti n run gbogbo bí mo ṣe n ṣèrànwọ́ lórí jẹjẹrẹ, Duration 5,5527 Bélú 2019 BBC News, Yorùbá Ìdí tí ẹ fi le è nígbàagbọ́ nínú ìròyìn BBC Ìlànà Lílò Nípa BBC Òfin Àṣírí Cookies Kàn sí.
OLUWA dá Satani lóhùn pé, “Ó dára, ohun gbogbo tí ó ní wà ní ìkáwọ́ rẹ.
Aisha Lawal ti kopa ninu ọpọlọpọ ere agbelewo Yoruba ati ede Gẹẹsi.
igbega ati ilosiwaju ba Ipinle Oyo lapaapo.
Àwọn ọmọ Juda náà ni: Ataaya, ọmọ Usaya, ọmọ Sakaraya, ọmọ Amaraya, ọmọ Ṣefataya, ọmọ Mahalaleli, ọ̀kan ninu àwọn ọmọ Pẹrẹsi.
Infantino sefilole Dikko, eni ti o tun dipo alaga katakara, onigbowo ajo NFF, lati darapo mo igbimo ohun saaju ipade apero ajo FIFA keta ti yoo tun waye.
Ọpọlọpọ gomina ni ẹkun iwọ oorun guusu lorilẹ-ede Naijria ni wọn ti fi igba kan lọ si aarin ilu lati lọ ba awọn eniyan ṣiṣẹ tabi ran wọn lọwọ, tabi ki wọn jẹun pẹlu wọn ni ita gbangba.
Bí bẹ́ẹ̀ kọ́, ẹ óo kú.
Sheikh Mohammed tun darapọ mọ ileeṣẹ ipolongo ilu Dubai lati fi ikede yii sita loju opo Twitter.
Saulu sọ fún Dafidi pé, “Merabu ọmọbinrin mi àgbà nìyí, n óo fún ọ kí o fi ṣe aya, ṣugbọn o óo jẹ́ ọmọ ogun mi, o óo sì máa ja ogun OLUWA.
Àwọn alufaa yóo rú ẹbọ sísun ati ti alaafia rẹ̀.
Mo kábámò pé mo fipá bá Ìyá ẹni ọgọrin ọdún sún ní Kano- Muhammad Zulfara'u Ọwọ́ ọlọ́pàá tún tẹ afurasí tó fipá bá odi àti adití lòpọ̀ nílùú Ibadan BBC Yoruba wa ṣe akojọpọ diẹ lara awọn eniyan to ti fara gba iru iṣẹlẹ yii laarin awọn ọmọ Yoruba, ẹ wo o: Awọn gbajumọ ti wọn kede iku wọn nigba ti wọn wa laaye: Ayinla Kollington Oríṣun àwòrán, Others Nigba kan ni ariwo gba ilẹ kan pe, Kebe n Kwara, Alhaji Ayinla Kollington ti dagbere faye, amọ aṣẹyinwa aṣẹyinbọ, irọ lo jasi, to si gbe awo orin tuntun jade lori rẹ.
Láti gbé ìrò (‘ìṣọ́nikiri’ tàbí ‘ìdásílẹ̀-lẹ́wọ̀n-kọ́jọ́-ìdásílẹ̀-tó-pé’) sínú làákàyè àwọn ènìyàn gbogbo.
Gege bi ile-ijosin kan gbogi lara
Bakan naa, aare macron menu ba, erongba ile France to n lo lowo lati sefilole ayeye ti o pe akori re ni:“oju asa ati ise ile Afrika loke okun”.
Níbẹ̀ ni Elija ti bèèrè lọ́wọ́ Eliṣa pé, “Kí ni o fẹ́ kí n ṣe fún ọ kí á tó gbé mi kúrò lọ́dọ̀ rẹ.
Orilẹ-ede Naijiria ati Algeria yoo tun maa figagbaga loni, awọn ọmọ orilẹ-ede Naijiria, paapaa julọ awọn ololufẹ ere bọọlu ni wọn ti n foju sọna lati mọ ewo ninu awọn agbabọọlu ikọ Super Eagles ti yoo mu iyatọ wa ninu ifẹsẹwọnsẹ naa.
Ninu oro re, Davido yanayana, ebun ti ko se yesile ti o wa nile Afrika.
Wọ́n pète àrékérekè sí àwọn eniyan rẹ;wọ́n sì gbìmọ̀ pọ̀ sí àwọn tí ó sá di ọ́.
láti inú ẹ̀yà Dani, ó rán Amieli, ọmọ Gemali; 
Síbẹ̀ àwọn ọmọdékùnrin àti ọmọdébìnrin wọ̀nyí dàbí àhọ́n àti ẹnu sí ara wọn a sì máá bá ara wọn sọ̀rọ̀ ni ihò tí ń bẹ láti ògiri.
Farao bá bọ́ òrùka èdìdì ọwọ́ rẹ̀, ó fi bọ Josẹfu lọ́wọ́, ó wọ̀ ọ́ ní aṣọ funfun olówó iyebíye, ó sì fi ẹ̀gbà wúrà sí i lọ́rùn.
Nígbà ti Solomoni parí adura ati ẹ̀bẹ̀ rẹ̀ sí OLUWA, ó dìde kúrò níwájú pẹpẹ níbi tí ó kúnlẹ̀ sí, tí ó sì gbé ọwọ́ sókè.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ìdìbò Èkìtì lọ ‘wọ́ọ́rọ́wọ́’ Àwòrán ìbò Èkìtì lọ́dún 2014 fún àwòkọ́gbọ́n Ẹgbẹ́ PDP tọrọ̀ àforíjì lọ́wọ́ Ọbasanjọ Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí 2 sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
Aare tun so pe, igbimo isakoso yii, yoo maa se akole gbogbo ise, erongba ajo NFF lapapo fun idagbasoke boolu afesegba ni Naijiria.
- Ilé ẹjọ́ ìpínlẹ̀ Ondo Wọn ti sún igbejo sì ọlá ọgbọ́n ọjọ́ oṣù kẹfà fún ìparí gbígbé jọ àwọn ẹlẹri wòlíì Alfa Babatunde.
Ó ṣeéṣe kí baba mi fi ọwọ́ pa mí lára, yóo wá dàbí ẹni pé mo wá fi ṣe ẹlẹ́yà.
Wọn fikun wi pe, ileeṣẹ naa tun kọ lati sọ kulẹkulẹ ohun gan an to ṣekupa Richard lẹnu iṣẹ ati bi o ṣe ku.
‘Ṣe awọn obi yoo fi iṣẹ silẹ ati gbogbo ohun ti wọn ba n ṣe lọna ati ri pe wọn bojutọ ọmọ?
Irọ̀ ni ìjọba ń pa, Ikọ Amọtẹkun ba ofin Naijiria mu- Ìgbìmọ̀ Yoruba Wo ohun tó yẹ kó mọ̀ nípa Gomina Imo ti ilé ẹjọ́ giga ye àga mọ́ nídí Ọ̀pọ̀ àwòrán tó ń ṣeni láàánú rèè nípa ogun abẹ́lé Nàíjíríà Èyí ni bí ogun abẹ́lé Biafra ṣe bẹ̀rẹ̀ ní Nàìjíríà Idile Akintola Akintola ṣe igbeyawo pẹlu Oloye Faderera Akintola, Eleduwa si fi ọmọ marun un jinki wọn.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù May 27: Nàìjíríà se Àyájọ́ ọjọ́ àwọn èwe 27 Èbibi 2018 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 27 Èbibi 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Àyájọ́ ọjọ́ àwọn èwe lónìí Ẹ̀rín ẹ̀ẹ̀kẹ́ àwọn èwe a máa mú 'nú ẹni dùn, ojú wọn bíi ti Ángẹ́lì a sì máa gbilẹ̀ nínú ọkàn ẹni.
Ṣugbọn àwọn olódodo yóo wọ ìyè ainipẹkun.
Nitori iṣẹlẹ yii ni Basirat ṣe gbe Niyi lọ sile ẹjọ pe ki wọn o tu igbeyawo wọn ka.
Farao bá lé Mose, ó ní, “Kúrò lọ́dọ̀ mi; kí o sì ṣọ́ra rẹ gidigidi, n kò gbọdọ̀ tún rí ọ níwájú mi mọ́; ní ọjọ́ tí mo bá tún fi ojú kàn ọ́, ọjọ́ náà ni o óo kú!
Saulu wí fún àwọn eniyan náà pé, “Ẹ jẹ́ kí á lọ kọlu àwọn ará Filistia ní òru kí á kó ẹrù wọn, kí á sì pa gbogbo wọn títí ilẹ̀ yóo fi mọ́ láì dá ẹnikẹ́ni sí.
Shiite: Suhaila El-Zakzaky ní ẹgbẹ́ àwọn kọ́ ló kéde àti dáwọ́ ìwọ́de dúró
OLUWA Bá Àwọn Eniyan Rẹ̀ Wí.
Ti iroyin iku Parakoyi Ibadan, Oloye Bode Akindele ta tun ṣẹṣẹ gbọ laipẹ yii, si tun da omi tutu si ọkan awọn eeyan.
Wọ́n jagun, OLUWA sì fi wọ́n lé Sisera, olórí ogun Jabini ọba Hasori lọ́wọ́, àwọn ará Filistia ati ọba Moabu náà sì ṣẹgun wọn.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Ó ṣe pàtàkì kí obìnrin gbádùn ìbálòpọ̀ nítorí.
Saulu bi í léèrè pé, “Ọmọ, ta ni baba rẹ?
Ninu ifọrọwanilẹnuwo kan pẹlu BBC, Kayode Soyinka to jẹ olootu iwe iroyin Newswatch ni London sọ pe oun ati Dele Giwa jijọ wa nile rẹ ni GRA lọjọ kọkandinlogun, oṣu Kẹwaa, ọdun 1986 ni.
Ẹwẹ, Aarẹ Muhammadu Buhari ni oun nikan ko ni oun maa maa lo agbara lori eto aabo nitori pe gomina naa ipinle kookan naa ni agbara lati daabo bo awọn eniyan ipinlẹ rẹ.
"bákan náà ni a ní a tún rí àwọn tí wọ ́ n ń pè ní "" dance and musical film "" ( oníjó ) ."
Reuters ni awọn ko le sọ igbesẹ ti Abba Kyari tabi ileeṣẹ ijọba apapọ n gbe bayii.
Alhaja Kudirat Abiola pé ọdún mẹ́tàlélógún lónìí to wọ káà ilẹ̀ sùn, ọ̀pọ̀ ló gbàgbọ́ pé ìkú rẹ̀ kìí ṣe àmúwá ọlọrun nítori àwọn agbanípa ló pa a, nígbà ti ìjọba fi ọkọ rẹ̀ sẹ́wọ̀n.
'Tàpá sófin ojú pópó kóo ṣọdún lẹ́wọ̀n' Buhari ní Nàìjíríà ti bẹ̀rẹ̀ ìgbẹ́sẹ̀ ìmúṣẹ àdéhùn Paris 2020 Ọ̀pọ̀ ló ṣì n ṣelédè lẹ́yìn Barrywonder!
Sùgbọ́n fún ìgbà keji Sẹnatọ Dino Melaye tun fidirẹmi.
Ọ ̀ pọ ̀ ìtàn ló rọ mọ ́ bí òrìṣà agẹ ́ mọ ṣe dé ilẹ ̀ Ìjẹ ̀ bú-Òde tí ó jẹ ́ olú ìlú ìjọba fún gbogbo ilẹ ̀ Ìjẹ ̀ bú .
AFCON 2019: Àwọn ọmọ Naijiria sọ̀rọ̀ lórí ìdíje Madagascar àná
ipinle Enugu , igbakeji adari omo egbe to kere julo, ogbeni Adesegun Adekoya lati
Ipo ate tuntun miran yoo tun jade lojo karundinlogun osu keta odun ti a wayi.
Gbogbo ìrìnàjò náà gba bíi wákàtí márùún.
Israel Adesanya ti fi ẹ̀ṣẹ́ yanjú Romero Àwọn tó fẹ́ kí ọba máa ta ilẹ̀ ilú ló fẹ́ yọ Oluwo lóyè- Ẹgbẹ̀ Baálẹ̀ Iwo.
Àwa mọ̀ dájú pé Òfin jẹ́ nǹkan ti Ẹ̀mí.
Diẹ lo ku ti idibo abẹle ẹgbẹ oṣelu People's Democratic Party nipinlẹ Kogi yoo waye.
"Inu mi ko dun rara si isesi wa, o nira lati kopa ninu iru ifẹsẹwọnfẹ yii, mo tiẹ n wa iru ọrọ ti maa fi se apejuwe rẹ.
Ọba bá sọ fún wolii náà pé, “Jẹ́ kí á lọ sí ilé mi kí o lọ jẹun, n óo sì fún ọ ní ẹ̀bùn fún ohun tí o ṣe fún mi.
Awọn onwoye sọ pe lasiko ajakalẹ Coronavirus yi, niṣe ni ọwọja awọn to n lu gbajuẹ oju ayelujara n pọ si.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: ‘Ojú larí, ọ̀rẹ́ kò dénú ni Tinubu ń se lọ́dọ̀ Buhari’ Èèyàn 2m gòkè Àràfá nípalẹ̀mọ́ fọ́dún Iléyá Ọjọ́rú là ó ti afárá 3rd Mailand pa Ninu ọrọ to ba BBC Yoruba sọ lati orilẹede Saudi Arabia, Aarẹ ẹgbẹ awakọ ero l'orilẹede Naijiria, Alhaji Najeem Yasin ni ''dokita to n tọju oloogbe Taofeek Oyerinde lo pe oun lati tufọ rẹ ati pe ohun ti ṣe eto bi oku oloogbe naa yoo ṣe de ilu Ibadan lati ilu Abuja ni.
Nkankan tó wùmí ní ìlú Èkó ni bí wọ́n ṣe kun gbogbo ọkọ̀ àti kẹ̀kẹ́ akérò ní ọ̀dà kannáà.
Ọ̀rọ̀ ọlọ́gbọ́n dàbí ẹ̀gún, bẹ́ẹ̀ ni àkójọ òwe tí olùṣọ́-aguntan kan bá sọ dàbí ìṣó tí a kàn tí ó dúró gbọningbọnin.
Lẹyin eyi o di aarẹ labẹ ijọba awa ara wa laarin ọjọ kọkandinlọgbọn oṣu kaarun ọdun 1999 si ọjọ kọkandinlọgbọn oṣu karun ọdun 2007.
Ogbontagi ọmọ Oodua to gbe ogo ilẹ Adulawọ ga ni, ko si yẹ ka ma mọ itan igbesi aye rẹ, ati ọgbọn ta lee ri kọ ninu rẹ.
Ṣugbọn iyawo rẹ̀ dá a lóhùn pé, “Bí ó bá ṣe pé OLUWA fẹ́ pa wá ni, kò ní gba ẹbọ sísun ati ẹbọ ohun jíjẹ tí a rú sí i lọ́wọ́ wa, bẹ́ẹ̀ ni kò ní fi nǹkan wọnyi hàn wá, tabi kí ó sọ wọ́n fún wa.
AH, ti wọn n kọ sẹyin ọdun yii tun mọ si lẹyin igba Hijrah.
Àkọlé àwòrán, Four Square Church tí ní kí olùkọ́ fásitì Eko, Pasitọ̀ Boniface, lọ fìdímọ́lé.
Awọn iroyin ti ẹ lee nifẹẹ si: Kano Pillars k'ẹdun iku Chinedu Udoji Idije Olympics: Wọn n ṣe'wadi Krushelnitsky Mossos d'Esquadra - olori ileeṣẹ ọlọpa l'ẹkun naa, ninu ọrọ kan to ba BBC sọ ṣaaju ni, awọn mẹrẹẹrin fẹ naju lọ ni Barcelona, sugbọn wọn ri wipe ita ti da paro, nitori eyi ni wọn ṣe wọ takisi kan lọ si ile ounjẹ igbalode kan ti wọn kii tilẹkun rẹ tọsan-toru.
Araba awo ilu Oṣogbo pari ọrọ rẹ pe, ifa lo ma n yan Ọba laye atijọ, ṣugbọn bayii oju ni wọn fi n yan ẹni to lọla tabi to lorukọ lawujọ lati di ọba.
Àkọlé àwòrán, Lẹyin ti wọn fún olukopa kọọkan láàyè láti sọ nípa ohun ti wọn o fi owó wọn ṣe ti wọn ba gbàá Àkọlé àwòrán, Mahassin Quadri lo gbá ẹbùn owó $5000 níbí ètò ìdíjè Tony Elumelu tọdún 2018 Àkọlé àwòrán, Kìí ṣe Mahassin nikan ló kopa nínú ìdíje náà, ọ̀pọ̀ àwọn ọdọ̀ míràn náá wá láti oníruuru orilẹ̀-èdè.
Ẹni ti ó ni iwé-igbelu lati ṣe iṣẹ́ ti ko ti di ará ilú kò ni ẹ̀tọ́ si ilé Ìjọba, ṣùgbọ́n wọn ni ẹ̀tọ́ si ilé-ìwòsàn ọ̀fẹ́.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Seyi Makinde: Iléẹjọ́ ní àwọn alága ìbílẹ̀ kó gbọdọ̀ gbé ìgbésẹ̀ kankan títí ìdájọ́ iléẹjọ́ Kòtẹ́milọ́rùn 30 Agẹmo 2019 Oríṣun àwòrán, Facebook/Seyi Makinde Ileẹjọ ti fun Gomina Ipinlẹ Oyo, Seyi Makinde laṣẹ lati yan awọn alaga tuntun si awọn ijọba ibilẹ mẹtalelọgbọn to wa nipinlẹ naa.
A n parọwa fun koowa lati fi ede Yoruba ati aṣa ọmọluwabi kọ ọmọ wa lati kekere.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: 'Alífábẹ́ẹ́tì Ohùn Oduduwa di ìtẹ́wọ́gbà ni Ajaṣẹ' Ṣẹ gbọ́ nípa Alájọ Ṣómólú, tó ta mọ́tò ra kẹ̀kẹ́?
Kó má a lọ bẹ̀ ẹ́ ní ìséde coronavirus fún ọ̀sẹ̀ méjì míràn - Ìjọba Nàìjíríà Owó tó kàn mí nínú N4 mílíọ̀nù ìbejì Akeugbagold tí a jí gbé, bàtà ni mo fi rà-Afunrasí Coronavirus ti di ara wa, kò le è kúrò mọ láéláé - WHO Coronavirus cases in Africa- Atọ́nà bí nkàn ṣe ń lọ ní Afirika Bakan naa, wọn fẹsun kan ileeṣẹ amohunmaworan Loveworld to jẹ ti pasitọ naa pe o sọ pe ogun Hydroxychloroquine lagbara lati ṣegun arun Covid-19 to n ba gbogbo aye finra.
Ẹsita bá dáhùn pé, “Bí inú kabiyesi bá dùn sí mi, mo fẹ́ kí kabiyesi ati Hamani wá sí ibi àsè tí n óo sè fun yín ní alẹ́ òní.
Ojú rẹ dàbí adágún omi ìlú Heṣiboni,tí ó wà ní ẹnubodè Batirabimu.
Ọmọ aráyé ń wo ìpàkọ́ ẹlòmíràn, wọn kò jẹ́ wo ìpàkọ́ ara wọn.
Ti awọn adehun yi ba ṣe aṣeyọri, awọn mejeeji ko nii le dije pẹlu ẹgbẹ agbabọọlu Libya ni ọjọ mọ ninu idije ti CHAN ti o n lọ lọwọ lorilẹede Morrocco.
Ibikibi to wu ki igi ifẹsẹwọnṣe naa wọ si, aṣekagba yii yatọ gedegbe si ọpọlọpọ to ti waye ṣeyin ni Champions League.
Ọ̀nà tó fi le è mọ gbájúẹ̀ babaláwo - Ẹlẹ́buìbọn Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Awọn alabagbe rẹ sọ pe awọn yoo ṣi awọn ẹbun kan laisun ọjọ Keresi tawọn yoo si ṣi eyi toku lowurọ ọjọ Keresi.
Ni ọsẹ yii, oniruuru àrà ni awọn gbajumọ oṣere tiata ọhun da loju opo Instagram koowa wọn, koda, ọpọ wọn lo pa ni lẹrin, ta si mu diẹ ninu rẹ wa fun yín.
Sugbon óò, asiko ti aarun náà lọ kò tíì pé, èyí kò sì lè jẹ ki a ní àwọn àkọsílẹ̀ tó dájú.
    Ẹ̀yin bàbá mi, ẹ bẹ̀rẹ̀ sií wádìí ọ̀ràn yìí, nítorí ẹ kò mọ irú àìsàn tí ó déedéé kọlu mi, ẹ kò mọ irú ohun tí ó dé bá mi, yálà òkè-ilẹ̀ ni, wárápá ní, ibà ni, làkúrègbé ni, ọlọ-inú ni, aràn-àyà ni, ẹ̀yyìn dídùn ni tàbí ìgbẹ́-ọ̀rìn ni – gbogbo ìwọ̀nyí kò yé yín, àfi ìgbà tí ó wu Olódùmarè tí o fi oníṣègùn tòótọ́ hàn yín ni mo tó di ẹni ti ń ṣiré kiri.
 lẹ ́ yìn èyí ni òǹkọ ̀ wé wá bẹ ̀ rẹ ̀ sí ní í ṣe àlàyé àwọn ẹbí tí ó pín èdè aáfíríkà sí .
Àwọn ìjọba ìbílẹ̀ yìí ni yóò sọ ẹni ti yóò jáwé olúbóri.
Awọn oniṣowo ọhun lawọn ti bẹrẹ sí ni gbe igbesẹ lati yan Babalọja tuntun ki Olubadan to Kede YK Abass gẹgẹ bí babalọja tuntun.
Bloomberg gbero lati dupo aarẹ gẹgẹ bi ọlọdanni ninu ibo aarẹ tọdun 2008 ati tọdun 2016.
Iroyin na n jà kiri lori awọn oju opo ikansira ẹni lori ayelujara pe, oun ra ọpọ ohun ija oloro pamọ saaju eto idibo gboogbo to kọ̀ja, lati da rugudu silẹ nipinlẹ Ogun.
@DoctorEmto, oun tiẹ sọ yanya pe banki Zenith ti n yọ naira mẹẹdogun bii owo ori ti oun ba fi owo ransẹ lati ori ẹrọ ibaraẹnisọrọ.
Timoti ọmọ mi, ọ̀rọ̀ àṣẹ yìí ni mo fi lé ọ lọ́wọ́, gẹ́gẹ́ bí àsọtẹ́lẹ̀ tí àwọn wolii sọ nípa rẹ̀ tí mo fi yàn ọ́, pé kí o ja ìjà rere pẹlu agbára àṣẹ yìí.
Nàíjíríà yóò gbóná janjan lẹ́yìn ìbò ààrẹ 2023 àyàfi.
OLUWA sọ fún Mose ati Aaroni pé, 
Ṣugbọn tí ẹ bá ń ṣe dáradára, tí ẹ jìyà tí ẹ faradà á, èyí jẹ́ ẹ̀yẹ lójú Ọlọrun.
Awọn gbajugbaja laarin awọn ọdọ Naijiria bii olorin, oṣere, adẹrinpoṣonu lo dide lati dari awọn ọdọ akẹgbẹ wọn.
O ṣalaye pataki iṣẹ yii fun BBC Yorùbá ati awọn ohun idunnu ati ipenija to rọ mọ ṣiṣe alaga iduro.
Bí Coronavirus ṣe ń tàn kálẹ̀ náà ní ìròyìn èké nípa rẹ̀ ń pọ̀ si Làá hàn mí dé, ètò tó ń ṣàlàyé ohun tó yẹ ká ṣe láti dènà àrùn Coronavirus Àǹkóò àrùn coronavirus dé orílẹ̀èdè Togo Awọn to ti padanu ẹmi wọn lọwọ aisan naa ni Italy bayi ti kọja okoolenigba ati mẹwa(230) tawọn alaṣẹ si n kede iku eeyan aadọta laarin wakati mẹrinlelogun.
 O menuba Pataki awon omo pe:  “Awon omo wa ni oja ola wa.
Akọroyin fun BBC ni ẹkun Gusu Afrika, Dan Jawad sọ pe ogunlọgọ awọn ọmọ orilẹede Libya wa lara awọn ti o ku ati awọn ti o yọ ninu ewu naa.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù EndSWAT: Wo àwọn Májẹ̀kóbàjẹ́ tó wà nídìí ìwọ́de #EndSARS / End SWAT 14 Ọ̀wàrà 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 16 Ọ̀wàrà 2020 Oríṣun àwòrán, others Iwọde End SARS to n lọ lọwọ kaakiri awọn ilu nla ni Naijiria ni ọpọ awọn onwoye ohun to n lọ ti sọ pe o jẹ ọkan Pataki lara awọn iwọde to ni eto julọ ni Naijiria.
Ta ni ó lè ṣe bí òun ti í ṣe fún mi!
Nígbà náà ni agbọ́tí sọ fún Farao pé, “Mo ranti ẹ̀ṣẹ̀ mi lónìí.
Afínjú ẹyẹ tí I f’àkísà ṣè ‘rọ̀rí
Ẹ má mú àpò tí wọ́n fi ń ṣagbe lọ́wọ́ lọ.
OLUWA bá wí fún Gideoni pé, “Àwọn ọọdunrun (300) tí wọ́n fi ahọ́n lá omi ni n óo lò láti gbà yín là, n óo sì fi àwọn ará Midiani lé ọ lọ́wọ́.
Abilekọ Blankson ni, gomina ipinlẹ Rivers, Nyesom Wike, ti ṣeleri lati pese iranlọwọ fun eto ẹkọ awọn ọmọ oun, ati lati fun oun ni iṣẹ nileeṣẹ ijọba.
Meṣulamu ni baálé ní ìdílé Ẹsira,Jehohanani ni baálé ní ìdílé Amaraya,
Bo tilẹ jẹ pe Ode ati Ishinigbo nikan ni ofin ọhun wa fun, Ojogo sọ pe ko ni si kalọ kabọ awọn eeyan ni ilu mejeji titi di igba ti ijọba yoo tun kede igbesẹ tuntun lori ọrọ ọhun.
Ẹ fi ara yín kọ́ ilé ẹ̀mí bí òkúta ààyè, níbi tí ẹ óo jẹ́ alufaa mímọ́, tí ẹ óo máa rú ẹbọ ẹ̀mí tí Ọlọrun yóo tẹ́wọ́ gbà nípasẹ̀ Jesu Kristi.
5 Adajọ sun igbẹjọ Eni, Shell siwaju Nàìjírìa pàdánù $6bn owó epo lórí ìwà àjẹbánu ‘Naijiria gbọdọ wadi Shell, Eni’ Iroyin ta gbọ ni pe awọn ọga kan ni ile iṣẹ Shell to n wa epo rọbi ni Naijiria fun awọn oṣiṣẹ ijọba kan ni abẹtẹlẹ lati le gba aye ipọnpo OPL 245 lọdun 2011.
O ni, ‘oun fi dawọn loju wipe gbogbo awọn ọmọ orilẹede Naijiria ti wọn wa ni panpẹ awọn ajinigbe lawọn yoo gba lagbatan pẹlu awọn ọmọbinrin ileewe Dapchi.
Chatta ni Ẹ́ jẹ́ ka maa wẹyin ara wa wo lati mọ ohun to n sẹlẹ nitori ti onitiata yoo ba fi ku, ere lasan ni wọn yoo ro pe o n se."
Owo ti wọn fi n ṣe iṣakoso Ileri:Lati ṣiṣẹ pọ pẹlu ile aṣofin lati mu adinku ba iye owo ti wọn fi n gbọ bukata iṣakoso.
Awọn ni amuludun fun eto gbogbo ti ẹgbẹ oṣelu APC nipinlẹ Eko ba gbe kalẹ lọwọlọwọ.
Ninu fọ́nran kan to fi ìgbà kan jà rànyin-ranyin lóri ayelujára nibi ti Kabiyesi Abdulrashed Akanbi ati Aafa náà ti n ni àriyanjiyan lori pé Kabiyesi n fẹ aya Aafa Iwo.
Covid-19 pa Ọlọ́lá Akin Olugbade, ẹ wo dúkìá jaburata tó fisílẹ̀ Ìjọba ìpińlẹ̀ Kwara dá owó tí àwọn obìrin 25 fi kọ́ ilé Ẹ̀kọ́ fún àwọn ọmọ wọ́n pada Ìjọba àpapọ̀ pàṣẹ kí ilé-ẹ̀kọ́ wọlé ní ọjọ́ 18, oṣù kíní ọdún.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, N100,000 Nairà mà ni Dino gbé dání lójú agbo, kò náwó yàlà-yòlò - Ayefele Muftau ni lati igba ti awọn ti maa n ṣe iwọde, ijọba ko figba kan s pe awọn gba eti ẹni kan ri tabi paayan.
 nitori pipe rẹ , iku atinuwa , ati ajinde , jésù ṣẹgun satani ati iku , o si ṣẹgun .
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Amotekun: Akeredolu ní àwọn iléeṣẹ́ aláàbò ni yóò ṣèdánilẹ́kọ̀ọ́ fáwọn ẹ̀sọ́ náà 15 Ẹrẹ̀nà 2020 Alaga awọn gomina lẹkun iwọ oorun guusu Naijiria, Rotimi Akeredolu ti kede pe ọsẹ tuntun taa bẹrẹ yii ni wọn yoo gba awọn ẹsọ alaabo fun ikọ Amotekun sisẹ.
Coronavirus: Àwọn ohun tí a kò tíì mọ̀ nípa àrùn Covid-19 Àrùn Coronavirus fa'lẹ̀ya láwọn ìletò aláwọ̀dúdú ní Amẹ́ríkà Kí lo mọ̀ nípa fẹntilétọ̀, ohun èlò aṣèrànwọ́ èémí Èyí ni ìdí tí coronavirus ṣe n pa àwọn kan, tí kò sì pa àwọn kan Ipele to lagbara Ti arun yi ba tẹsiwaju ko ni sẹyin pe awọn ọmọ ogun ara n sisẹ kọja bo se yẹ lati koju kokoro aifojuri yi .
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ṣé ìwọ láyà ti o mọ òwe Yorùbá dáadáa?
Oríṣun àwòrán, Facebook/Omipidan Ismail Lọpọ awọn ipinlẹ ni Naijiria, awọn eeyan ko kọbi ara si ilana ti ijọba gbe kalẹ lẹyin ti wọn dẹwọ isede.
Zainab Aliyu: Orílẹ̀èdè Saudi túu sílẹ̀ lẹ́yìn oṣù mẹ́rin tó ti wà ní àhámọ́
Èyí ni ilẹ̀ tí àwọn ọmọ Efuraimu gbà, gẹ́gẹ́ bí iye ìdílé wọn.
“Bí èdè-àìyedè kan bá bẹ́ sílẹ̀ láàrin àwọn ọmọ meji, tí wọ́n bá lọ sí ilé ẹjọ́, tí àwọn adájọ́ sì dá ẹjọ́ náà fún wọn, tí wọ́n dá ẹni tí ó jàre láre, tí wọ́n sì dá ẹni tí ó jẹ̀bi lẹ́bi, 
Obasanjo: Ètò ààbò tó mẹ́hẹ lè dá'jà ẹlẹ́yàmẹ̀yà sílẹ̀
àwọn gbẹ́nàgbẹ́nà, àwọn ọ̀mọ̀lé ati àwọn agbẹ́kùúta, kí wọ́n sì ra igi ati òkúta tí wọn yóo lò fún àtúnṣe ilé OLUWA.
Amọṣa Tẹjuoṣo ṣalaye pe awọn eeyan tun ti n poungbẹ fun orin Jazz bayii.
Ula bí: Ara, Hanieli ati Risia.
Wo àwọn òṣìṣẹ́ kólẹ̀-kódọ̀tí tó ń fi ẹ̀mí wọn wéwu kí Abuja leè mọ́ tónítóní Wo àwọn nkan tó yẹ́ kí o mọ̀ nípa 'Awawa Boys', ọ̀kan lára ẹgbẹ́ òkùnkùn tó n dá Eko rú Ṣé Akpabio ṣetán láti dárúkọ àwọn Aṣòfin tó gba iṣẹ́ àkànṣe lọ́wọ́ NDDC?
Àwọn ọmọ Aṣeri ní ìdílé-ìdílé nìwọ̀nyí: ìdílé Imina, ìdílé Iṣifi ati ìdílé Beria.
Awon esi rere ti a ti riAbileko Winifred Oyo-Ita  ni pe iru ipade ijiroro yii yoo so eso rere.
Eniyan ogun lo ku nibi isele ijamba omiyale to waye  ni asale ojo kan ni Nakuru, lorile-ede Kenya.
Ni erongba lati fa awon olokoowo ki won ko tun bo maa wo orile-ede Naijiria lati China, ile ifowopamo agba CBN ti ro awon olokoowo ti o n ko oja ile China wole lati maa samulo owo China- yuan dipo owo dola ti won n lo.
Igbakeji Aare Mahamudu Bawumia so nibi ipade elekun-jekun kan lori oro eka epo-robi ati iwakusa pe, isakoso ijoba orile-ede Ghana tele, ti fun awon ile-ise aladani ni anfaani lati sayewo ati maa waku funra won.
A máa gbé àwọn onírẹ̀lẹ̀ ga,a sì máa pa àwọn tí ń ṣọ̀fọ̀ mọ́.
"Tori naa ""ọmọ Yorùbá tó bá sọ̀rọ̀ ogun, ẹ gbé e!"
Ò ti pé ọdún 27 tí Shah Rukh Khan ti ń se fíìmù India Buhari ṣàlàyé ìdí tó fi yọ Onnoghen fún Afẹ́nifẹ́re Yoruba Àwọn elétò ààbò ń fìyà jẹ àwọn èèyàn púpọ̀ jù ni Nàìjíríà Buhari san lára owó àjẹmọ́nú Super Eagles!
Ẹ máa fara wé mi bí èmi náà tí ń fara wé Kristi.
Se ni ilu Gusau, nipinlẹ Zamfara kan gbinrin nipari osu Kẹjọ ọdun 2020 nigba ti eeyan mejidinlogun latinu ọpọ ẹbi tẹri gbasọ ninu ijamba ọkọ .
Ọrọ naa ṣe ọpọ ni kayefi lataari pe ajọ naa ko tawọn lolobo pe irufẹ iṣẹlẹ bayi yoo waye.
Bakan naa o fikun pe eniyan 799 ni o wa ni panpẹ ọlọpaa lori ẹsun ifipabamilopo, ti 631 ninu wọn si ti fi oju ba ile ẹjọ.
ti ko si nile iwe dinku lorile ede Naijiria.
Áà, jọ̀wọ́ wò mí sàn, kí o mú mi wà láàyè.
 Ọ ̀ kan lára awọn àìsàn kan tí a mọ ̀ sí àwọn àrùn tí a kò kàsí ní ilẹ ̀ -olóoruní í ṣe .
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ìbaàrún pe ọdún kan Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Joint Security: Ọdẹ ìbílẹ̀, OPC, Aṣọ́gbó, ọlọ́pàá, ológun yóò máa pèsè ààbò nílẹ̀ Yorùbá 28 Ògún 2019 Ileesẹ ọlọọpa ipinlẹ Ogun ti fi idunnu rẹ han si idasilẹ ẹka eto aabo alajumose ni ilẹ Yoruba lati dẹkun ijinigbe ati ipaniyan.
Èyí kìí ṣe àkọkọ ikọlu láàrin àwọn ará ìlú àti Gómìnà Mutua.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, World Diabetes Day: Ọdún kọkandinlogun ti mo ti wà lẹ́nu itọ ṣúgà nìyí O ni wọn gbe oun lori timutimu lati kọja odo mẹrin lati ile ki wọn to de ile iwosan ọhun.
Ni ọdun 2015 bakanaa, kiniun kan sa jade kuro ninu ile re ni igboro ilu Jos, sugbọn won pa-a, ko to se ẹnikeni lese.
Amòfin Ojo sàlàyé pé láti ọdún díẹ̀ sẹ́yìn ti òun ti ń bá àwọn tí wọ́n kojú ìwà ipá nínú ilé ṣiṣe òun ṣàkíyèsí pé ìtàn wọ́n máa n jọra.
Garba Shehu ni ijọba apapọ n gbe gbogbo igbesẹ to yẹ lati daabo bo ẹmi ati dukia awọn eniyan Naijiria.
Araba ilu Oṣogbo, Oloye Ifayẹmi Ẹlẹbuibọn lo ṣọ ọrọ yii lasiko ajọdun ọdun kẹwaa rẹ lori oye gẹgẹ bi araba awo ilu Oṣogbo.
Àkọlé àwòrán, 'Ẹni ti a fa kalẹ yi ko kundun ode owanbẹ.
Ile iṣẹ ologun sọ pe ajagun fẹyinti naa ko tii di riri lẹyin ti wa inu odo adagun kan ti wọn lero pe ibẹ ni wọn ju ọga ologun naa si, ṣugbọn ọkọ mẹta ni wọn ko jade lati inu odo naa.
Ohun ta le sọ ni pe ko si ẹni to le sọ ibi ti idibo aarẹ yoo fi si ṣaaju igba ti wọn yọ Trump.
" Akeugbagold ni nìbẹ̀rẹ̀ ìjíròrò òun pẹ̀lú àwọn ajinigbe, ṣe ni àwọn ajomogbe náà ń kanra jagbe mọ òun, àmọ́ ní báyìí wọn tí ń nawọ ìfẹ́ lórí fóònù si òun.
Ẹ̀rù ìyà ni Norway dì lé Super Falcons lórí ní 2019 Women's World Cup Ẹ̀mí 18 ṣòfò ní Òpópónà Akure sí Ọwọ Emir Muhammadu Sanusi II ti fèsì sí ẹ̀sùn Gómìnà Kano Africa Eye, ẹ̀ka ọ̀tẹlẹ̀múyẹ́ ile iṣẹ BBC lo ṣe iṣẹ takun takun yii lati tu aṣiri ohun to fara sin to n ba aye ọpọlọpọ jẹ ni Naijiria.
Iwe mimo fi mule pe, ko si idunnu ati ayo ninu ohun aye yii, bikose iwa pelu ajosepo  Olorun ati eniyan”.
k1 de ultimate tí ó tún jẹ ́ ọba orin fújì ṣe àwárí ìmọ ̀ àti ẹ ̀ bùn orin kíkọ rẹ ̀ nígbà tí ó wà ní ọmọ ọdún mẹ ́ jọ .
O Fagunwa kú, dúkìá rẹ̀ sì ń fọhùn síbẹ̀, ilé rẹ̀ rèé Samuel Ladoke Akintọla jẹ́ Agbẹjọ́rò àti Akọ̀ròyìn tí ọ̀rọ̀ dá lẹ́nu rẹ̀ Ayinla Ọmọwura, orin èébú àti oríyìn lo fi di ọ̀rẹ́ àwọ̀n obìnrin Taiwo Akinkunmi, ọmọ Ibadan tó ya àsìá Nàíjíríà Ni ọpọlọpọ igba, wọn a ti rin jina de ibi ti ko yẹ ki wọn to mọ pe kii ṣe ọwọ aye bi ko ṣe pe ni ilana ilera, Vitiligo maa n ṣẹlẹ.
Awon omo ile igbimo asoju tuntun ti iye wọn jẹ àádọ́sàn án ( 170) lo wa pẹlu Gbajabiamila,lọjọ Aiku lasiko ti o n fi
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Aworan bi jẹjẹrẹ inu ifun 'colon cancer' ṣe ma n ri Awọn apẹẹrẹ wo lo ma n fihan?
Akọle naa si lo ni Eyi ni ọna ilu Igbo Olodumare nibi ti igbin ti ga ju Ijapa lọ Wo ohun tí yóò ṣẹlẹ̀ ní ìpàdé àwọn èèkàn Yorùbá láti mú kẹ́ẹ dìbò fún Tinubu ní 2023 Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Kollington ṣàlàyé bí orin Fuji ṣe bẹ̀rẹ̀ gan an ní Nàiìjíríà Oríṣun àwòrán, @battravels Oke Langbodo: Bakan naa ni Oke Langbodo wa ninu Igbo Olodumare , ara igi kan si ni wsn so akọle to n juwe ọna sori oke naa si."
Iléeṣẹ́ Ọlọ́pàá ṣetán láti bẹ̀rẹ̀ ètò ìgbanisíṣẹ́ lákọ̀tun Wọ́n ti yìnbọn pa olórí ẹgbẹ́ jàndùkú ''One Million Boys'' ní Ibadan’ Ìwà Jẹgúdújẹrá ní Naijiria kò gba òjú bọ̀ọ̀rọ̀ - Aarẹ Buhari Wo àwọn nkan tí ó yẹ kí o mọ̀ nípa Bitcoin, kí o tó ó dáwọ́ le e Olorì àgbà mẹ́rin tó jẹ́ igi lẹ́yìn ọgbà fún Aláàfin Adeyemi Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ọmọ ọdún méjìlá yìí sọ bó ṣe di téélọ̀ táwọn àgbà ń bẹ́rí fún Bawo ni mo ṣe lee darapọ mọ ileesẹ ọlọpaa Naijiria?
Bukola Saraki fi 'Gbas Gbos' ọ̀rọ̀ ránṣẹ́ lórí 'ilẹ̀ bàbá rẹ̀' tí ìjọba Kwara gbà padà 'Ilé aṣòfin àgbà l'Abuja leè dà wó lulẹ̀ láì ṣe àtúnṣe rẹ̀ ní kíákíá o' Irú ẹ̀dá wo ni aṣòfin Bukola Saraki jẹ́?
Ìtàn miran lati ọwọ oṣere Netherlands, Sinterklas, to tun dale Saint Nicholas, to gbajumọ laarin awọn olowo ni New York, bi i Washington Irving ati Clement Clark Moore ni nkan bi ọdun 1800.
Aarẹ Trump ati aarẹ Ukraine, Volodymyr Zelensky jijọ sọrọ lori ẹrọ alagbeka lọjọ kẹẹdọgbọn oṣu Keje ọdun yi.
O ni: Sisoro lori koko pataki yii to soju abe niko lori ki awon eniyan maa soro ikorira lasiko yii se pataki ni Naijiria.
Lara awọn nnkan yii ni ọrọ iku ọwọọwọ to n waye ni ilu Kano.
ile-ise ikọ ogun oju –omi ,vice Admiral Ibok-Ete Ibas  ti ni ọwọ awon agbofinro ti ba awon afurasi to
Mo sì mọ̀ wí pé tí mo bá sọ ìtàn náà fún-un yín kò burú, bí a bá sì jọ gbádùn-un rẹ̀ kò léèwọ̀.
Sanwo-Olu fẹ́ fojú-rinjú pẹ̀lú ọmọ tó ní kí ìyá òun ‘Calm down’ Mamman Daura rí ìjà ọmọ Nàíjíríà torí ó pè fún wíwọ́gilé pínpín ipò ààrẹ lẹ́lẹ́kùn jẹkùn Ìkúnlẹ̀ abiyamọ, ìkókó mẹ́jọ kú nílé ìwòsàn lálẹ́ ọjọ́ kàn Dayo Amusa gbarata lórí bí agbófinró ṣe ń pa ọ̀dọ́ láì nídìí Ẹyìn tí Hydroxychloroquine, Zinc ati Zithromax da lára yá,ẹ bọ síta wà jẹrìí mí-Dr Stella Emmanuel Ki ni awọn nnkan to wa ninu Bibeli naa?
Lọwọ ipari ijọba Mugabe, awọn eeyan bẹnu atẹ lu wi pe o ti n lo si ilu okere pupọ ju fun itọju ara rẹ.
"Opral Benson, ẹni ti oge ṣíṣe sọ di gbajúmọ̀ àti Yeye Oge ìlú Eko Gomina Sanwo-Olu sún ọjọ́ ""ṣiṣẹ́ láti ilé"" síwájú fún àwọn òṣìṣẹ́ ìjọba Ki lo de ti awọn ọkunrin se maa n ni 'ọdun bia'?"
Ẹ rú ẹbọ òdodo,kí ẹ sì gbẹ́kẹ̀lé OLUWA.
  Abájọ tí ìyà arúgbó náà ṣe mọ ọ̀nà yìí dáadáa.
Ṣugbọn Baba wa nípa ti ẹ̀mí ń tọ́ wa fún ire wa, kí á lè bá a pín ninu ìwà mímọ́ rẹ̀.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Àwọn ọmọ Nàíjíríà ló ṣiṣẹ́ takò mí ní Ireland kí ń má baà wọlé ìbò Káńsélọ̀ - Yemi Adenuga Èmi àti Bọla Tinubu fẹ́ lo ‘German Mercenaries’ láti gbé MKO Abiọla kúrò lẹ́wọ̀n - Dele Momodu Irọ́ ńlá!
Ikéde yìí wáye lónìí ọjọ ìṣẹ́gun lẹ́yìn ti ilé ẹjo pàṣẹ pe àjọ INEC ní àṣẹ lati ṣe àtúndi ibo nibẹ̀.
Ṣugbọn Ọmọyẹ, to jẹ aletilapa ọmọ ko kuku yan iṣẹ aayan laayo kan ni pato, ọlẹ, alapa-masisẹ ni, to si n ti ile ọkunrin kan bọ si omiran lai jẹ pe wọn fẹ sile nisu-lọka.
 O ni:“Iṣẹ takuntakun la n jijọ ṣe bayii pẹlu awọn ẹṣọ alaabo yooku lati ri daju pe aabo to peye wa ni ipinlẹ yii”Bakan naa, Alaga Ẹgbẹ Awọn Oniroyin ni Orilẹ-ede Naijiria (Nigeria Union of Journalists (NUJ), ẹka ti Ipinlẹ Eko, Ọmọwe Quasim Akinreti ninu ọrọ tirẹ, sọ pe iṣẹ nla ni ojuṣe awọn oniroyin ninu eto idibo, bii ilanilọyẹ, ikọnilẹkọọ, ati mimọ ero ọkan ara ilu.
Lara ẹsun ti wọn fi kan gomina Fayemi ni wi pe o ṣiṣẹ tako oludije sipo gomina labẹ ẹgbẹ oṣẹlu APC, Pasito Ize Iyamu ninu idibo sipo gomina to lọ ni Edo.
Mo wà láàyè, ṣugbọn kì í ṣe èmi ni mo wà láàyè; Kristi ni ó ń gbé inú mi.
Nítorí pé, nípasẹ̀ rẹ̀ ni a ti dá ohun gbogbo, lọ́run ati láyé: ati ohun tí a rí, ati ohun tí a kò rí, ìbáà ṣe ìtẹ́ ọba, tabi ìjọba, tabi àwọn alágbára, tabi àwọn aláṣẹ.
0 1296806 Orilẹede Poland 32844 86.
Nigba to n fesi si ibeere, oludari ileeṣẹ naa gba pe wọn yọ ẹrọ ayaworan kuro eyi ti wọn n lo lati fi mọ awọn ọkọ to kọja laarọ ọjọ iṣẹlẹ ibọn yinyin naa.
Atẹjade kan ti ileesẹ ọlọpaa fisita loju opo Twitter rẹ salaye pe, eyi ko tumọ̀ si pe wọn fẹ́ ti tọkọtaya naa mọle ni, amọ o jẹ ara ohun eelo iwadi lati tan imọlẹ si ẹsunkẹsun tawọn eeyan ba gbe wa siwaju awọn.
Oúnjẹ rùn sí wọn,wọ́n sì súnmọ́ bèbè ikú.
Òun ló dífá fún wa lọ́jọ́ náà, táa fi tẹsẹ̀ mọ́nrìn kúrò nínú igbó náà, táa darí sí ìgbèríko táa fi ṣe ibùdó.
Awọn nnkan ti mo ri pe yoo waye ree, orilẹede Naijiria, ẹ gbadura.
Ned Nwoko: Regina Daniels kàn wù mí ni, mo nàwọ́ sí i ó sì di tèmi
Bákan náà ni àwọn Kerubu mejeeji yìí rí, bákan náà sì ni títóbi wọn.
Àwọn àṣà àti ìse tó yọ obìnrin sílẹ̀ nílẹ̀ Yorùbá 'Kò sí ohun tó burú nínú bí Ajimobi ṣe dá Yewande tó pa ọkọ rẹ̀ sílẹ̀' Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Wòlíì Kasali sọrọ nípa awuyewuye pé o lè ìyàwó rẹ̀ jáde nílé Amọṣa nigba ti a pe alukoro apapọ ileeṣẹ ọlọpaa lorilẹ-ede Naijiria lori ẹrọ ibanisọrọ, a ko rii ba sọrọ.
Jeremaya bá pada sọ́dọ̀ Gedalaya, ọmọ Ahikamu ní Misipa, ó sì ń gbé pẹlu rẹ̀ láàrin àwọn eniyan tí wọn kù ní ilẹ̀ náà.
ìwárìrì mú wọn níbẹ̀;ìrora sì bá wọn bí obinrin tí ń rọbí.
O ni awọn senetọ ti n na owo to pọju ni eyi ti ijọba yi le fi owo naa ṣe nkan miran fawọn ara ilu.
Pupọ eeyan lo ti n reti ki Pasito Adeboye to jẹ agba ninu ẹsin mẹnu ba ọrọ naa.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Akomolede ati asa Yoruba: Ẹ wá kọ́ nípa àpòtí ìṣura èdè wa lórí BBC Yorùbá Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Akomolede ati asa Yoruba: Ẹ wá kọ́ nípa àpòtí ìṣura èdè wa lórí BBC Yorùbá 18 Ògún 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 20 Ògún 2020 Ede Yoruba ti fẹ di ajeji laarin awọn ọdọ iwoyi, idi si ree ti BBC Yoruba fi se agbekalẹ eto yii lati maa kọ wa ni ede ati asa Yoruba.
Awọn aṣoju ẹgbẹ ni ipinlẹ Ondo lo dibo yan ẹni to wọle, nitori naa gẹgẹ bi ọmọ ẹgbẹ oṣelu APC tootọ, ko si idi fun oun lati sọ pe bẹẹni tabi bẹẹkọ lọwọ yii.
Kannywood: A ó fòfín dé eré ìfẹ ṣíṣe fún ọdun díẹ̀
“Níbi tí òkú ẹran bá wà, níbẹ̀ ni àwọn gúnnugún yóo péjọ sí.
O ni awọn onimọ ẹsin yoo wa ninu igbimọ yi.
Mo mọ wi pe Gomina Fayemi ko fi ọrọ yi sere rara'' Ogunleye ni nigba ti Covid-19 yoo ba fi kasẹ nilẹ, gomina yoo raaye lati se ifilọlẹ ikọ Amọtẹkun.
Sarfa ati Mawa kò rí ara wọn rí ṣaaju iṣẹ abẹ pataki yii ṣugbọn ireti wa lọkan awọn obi wọn pe iṣẹ abẹ lati ya wọn sọtọ naa yoo yọri si rere.
Èmi ni OLUWA tí mo sọ yín di mímọ́, 
Bí ìkùukùu tíí parẹ́ tí a kì í rí i mọ́,bẹ́ẹ̀ ni ẹ̀mí tí ó lọ sí ipò òkú rí,kò ní pada mọ́.
Àwọn ọmọ Noa mẹtẹẹta yìí ni baba ńlá gbogbo ayé.
Lara awọn ohun ti wọn fi n ranti Bello titi di akoko yii ni ni aktitiyan rẹ lati mu irẹpọ ba awọn eeyan oke ọya nilẹ Naijiria.
2bn fún Obanikoro 25 Òkùdu 2019 Oríṣun àwòrán, Others Àkọlé àwòrán, EFCC: Ẹlẹ́rìí ṣàlàyé bí wọ́n ti ṣé gbé N1.
Nígbà náà ni Joabu lọ sí ilé Absalomu, ó bi í pé, “Kí ló dé tí àwọn iranṣẹ rẹ fi ti iná bọ oko mi?
"A ni ki Tunde ma wọle afigba to fipa wọle to tun fi ọlọpa mu awọn ẹṣọ Aisha ti ko fẹ ko wọle""."
Àwọn ẹṣin pupa, ati ẹṣin rẹ́súrẹ́sú ati ẹṣin funfun dúró lẹ́yìn rẹ̀.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, The New Pandemic: Kíni àwọn onímọ̀ sáyẹ́ńsì ń sọ nípa rẹ̀?
Ẹ̀mí wá sọ fún mi pé kí n bá wọn lọ láì kọminú.
Ẹ jẹ́ kí ó hàn sí gbogbo àwọn ìjọ bẹ́ẹ̀.
Sẹnẹtọ Mamora sọrọ naa nibi ayajọ oogun ibilẹ tọdun 2019 niluu Abuja.
Àwọn ọmọ Ṣobali ni Aliani, Manahati ati Ebali; Ṣefi ati Onamu.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ilẹ̀ Amẹ́ríkà wà lẹ́yìn àwọn olùwọ́de, Buhari dẹ́kun ìpànìyàn - Joe Biden Mọ̀ nípa DJ Switch, akíkanjú obìrin sàfihàn fídíò ìpànìyàn Lekki bó ṣe ń wáyé Buhari, máṣe gbá ìpànìyàn Lekki sórí ààtàn, kò yẹ́ kí ológun yin ọ̀dọ́ níbọn - Bode George Ọ̀kan lára olùwọ́de tó fara gbọgbẹ́ ní Lekki jáde láyé - Sanwo-Olu Kò sí olùwọ́de tó kú ní Lekki - Sanwo-Olu N kò lọ́wọ́ nínú ìpànìyàn, kò dáa bí wọn ṣe lo ọta ìbọn ní Lekki - Tinubu Ọjọ́ Ìsẹ́gun di ọjọ́ ìbànújẹ́ fún ọ̀pọ̀ ìdílé ní Nàíjíríà torí òkú tó ṣùn Ọ̀dọ́ 30 ń gba ìtọ́jú lọ́wọ́ nílé ìwòsàn torí ọ̀gbẹ́ ìbọn ní Lekki - Sanwo-Olu ṣàlàyé O ni aarẹ Buhari gbọdọ fi iwa irẹlẹ, ẹni to lẹran eeyan lara ati ijolootọ lati dahun si awọn ibeere awọn eeyan yii, ki o si rii daju pe idajọ ododo waye nibi to yẹ.
Muhammadu Buhari yoo maa fi ilu Abuja silẹ lọ si United Kingdom lọjọBọ fun  irinajo
Gbogbo àwọn iranṣẹ ọba ni wọ́n ti lọ kí Dafidi ọba, pé, ‘Kí Ọlọrun rẹ mú kí Solomoni lókìkí jù ọ́ lọ, kí ìjọba rẹ̀ sì ju tìrẹ lọ.
)Ǹ bá lè ní àkọsílẹ̀ ẹ̀sùn tí àwọn ọ̀tá fi kàn mí!
'Kò ní sí ìdíwó mó nínú ìṣàmúló ètò ìṣúná ìpínlẹ́ Oyo' Ejò wo ló mi ₦118m láàrin UCH àti ìjọba Oyo?
Ẹwẹ, o ni oun yoo nilo ifọwọsowọpọ ile aṣofin lati fopin si pinpin iṣẹ akanṣe NDDC mọra wọn lọwọ nile igbimọ aṣofin ati ṣiṣe atunto ajọ naa.
Oríṣun àwòrán, @others Àkọlé àwòrán, Awọn eniyan ilẹ okeere wa ba Buhari yọ ayọ ayajọ iṣejọba alagbada O ni ijọba oun ti mojuto ọrọ atunṣe eto ẹkọ ati idagbasoke eto ọrọ aje Naijiria, yatọ si titun awọn opopona ṣe.
eniyan n jẹ owo fun ipese ina mona-mona.
Barrister ló sọ mí di èèyàn ńlá - Ayinla Kollington Ìtàn tó wà nídi òwe ‘Sebótimọ Ẹlẹ́wà Sàpọ́n’ Ìtàn tó rọ̀ mọ́ òwe ‘aṣọ kò bá Ọ́mọ́yẹ mọ́.
Omijé ni mo fi ń ṣe oúnjẹ jẹ tọ̀sán-tòru,nígbà tí wọn ń bi mí lemọ́lemọ́ pé,“Níbo ni Ọlọrun rẹ wà?
Àwọn olórí alufaa ati àwọn àgbà ti rọ àwọn eniyan láti bèèrè fún Baraba, kí wọ́n pa Jesu.
Nkan mẹ́ta ni ọjọ́ náà wà fún.
Ìbú ati òòró rẹ̀ yóo rí bákan náà, yóo sì ga ní igbọnwọ meji, àṣepọ̀ mọ́ ìwo rẹ̀ ni kí o ṣe é.
Bakan naa lo tun rọ awọn ileewe lati lo awọn ọna ikẹkọ ori ayelujara fi maa kọ awọn akẹkọọ wọn naa titi di igba ti wọn yoo fi kede ọjọ iwọle tuntun.
Kí àwọn ọmọ Israẹli má baà tún máa fi ẹran wọn rúbọ sí oriṣa bí wọ́n ti ń ṣe rí.
Láti ibẹ̀ ni wọ́n ti lọ sí ìhà àríwá, títí dé Jaseri.
Mo lóbìnrin tó bímọ fún mi, ṣùgbọ́n ọ̀rọ̀ ìyàwó kò tíì yọ fún mi báyìí-Pasuma Pasuma kìí ṣe ọkọ mi o!
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ayo Adebanjo: Màá túbọ̀ parí aáwọ̀ Obasanjo àti Gani Adams torí ilẹ̀ Yorùbá kò gbọdọ̀ bàjẹ́ 10 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Oríṣun àwòrán, Etim Baba Grace Okon/Facebook Eekan inu ẹgbẹ Afenifere, Alagba Ayo Adebanjo ti fi aidunnu rẹ han lori aawọ to wa laarin aarẹ ana, Oloye Olusegun Obasanjo ati Aarẹ Ọna Kakanfo fun ilẹ Yoruba, Oloye Gani Adams.
Mínísítà fun ètò ìròyìn, Oloye Láì Muhammed, lo fèsì naa pada pe ''aheso ọrọ ni Obasanjo n sọ ati pé ìjọba Buhari ko ráàyè a n diran moni lẹsẹ'' Ọrọ náà jẹyọ nínú atẹjade kàn ti o fí ṣòwò s'awọn akoroyin lọjọ Ẹtì nílu Èkó.
Oríṣun àwòrán, thecableng Kini o ti sele sẹyin?
Àwọn eniyan ti ń retí Sakaraya.
Ewe, labe akoso Tite, Brazil padanu ifesewonse meji pere, won jawe olubori ninu ifesewonse ogun, ti iko naa si gba ami dogba-dogba merin.
BBNaija 2020 ń bẹ̀rẹ̀ lónìí, wo gbogbo bí ètò Big Brother Naija yóò ṣe lọ àti ẹ̀bùn #85 mílíọ̀nù tó wà fún jíjẹ Ẹlẹẹkarun eto Big Brother Naija lo n bẹrẹ lonii, ọjọ kọkandinlogun, oṣu keje, ọdun 2020.
Amọ, awọn kan sọ pe asọtẹlẹ Ọgbẹni West si le wa si imuṣẹ nitori Trump ti gbọrọ idibo naa lọ si ileẹjọ.
ní ọjọ́ tí ọmọ-ọ̀dọ̀ náà kò retí, ati ní àkókò tí kò rò tẹ́lẹ̀ ni oluwa rẹ̀ yóo dé, yóo kun ún wẹ́lẹwẹ̀lẹ, yóo sì fún un ní ìpín pẹlu àwọn alaiṣootọ.
Ile bẹrẹ eto yii labẹ adari Sẹnẹtọ Bukola Saraki lọdun 2016.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ọjọ́ kannáà ni Lionel Messi àti Cristiano Ronaldo fi ìdíje ife ẹ̀yẹ àgbáyé sílẹ̀ Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 3 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 5 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Lọ́dọ̀ tèmi, Luis Carlos jẹ́ onílàákàyè ẹ̀dá kan, ó gbọ́njú nínú ìròyìn gbígbà àti ìkànsì-ara-ẹni nínú Venezuela ti wa yìí tí kò fara rọ.
Nígbà tí Mose kọ gbogbo ohun tí ó wà ninu ìwé òfin yìí tán patapata, 
Yin OLUWA, ìwọ ọkàn mi,OLUWA, Ọlọrun mi, ó tóbi pupọ,ọlá ati iyì ni ó wọ̀ bí ẹ̀wù.
"Nigba naa ni wọn ṣe agbekalẹ NADECO ti awọn ologun fi n ṣọ ibi gbogbo lorilẹ-ede Naijiria ṣugbọn Dele Momodu pa owe pe ""mo n ree mugi wa, mo n ree mugi wa, ọgbọọgbọn lagba fi n sa fun ejo"" ni awọn fi yọlẹ sa kuroni Naijiria O ni eyi sele nitori ijọba ologun to mu ohun gbogbo le koko lo mu oun atawọn ọdọ mii sa kuro nile gba ọna ẹnu ibode Sẹmẹ."
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù #Queen Dihya: Obinrin tó gbógun tàwọn agbésùnmọ̀mí ni Algeria Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ #Queen Dihya: Obinrin tó gbógun tàwọn agbésùnmọ̀mí ni Algeria 30 Ọ̀wàrà 2018 Asiko tijọba Roomu àti Byzatine n yipada ni akọni obinrin yii jade sita.
Láti mú kí àwọn ọmọ ìbílẹ̀ àti ọmọ àgbáyé ó fi ọkàn sí ìdájọ́ àti fún ìdásílẹ̀ẹ Alaa ní ọjọ́ 17 oṣù Ẹrẹ́nà.
Nígbà tí Kristi, ẹni tíí ṣe ẹ̀mí yín bá farahàn, ẹ̀yin náà yóo farahàn pẹlu rẹ̀ ninu ògo.
Kí Ọba Oníbú ọrẹ bá abiyamọ tọ́jú ọmọ; kí Ó fún wúndíá ní ọkọ àǹfààní; kí Ó fún ọmọkùnrin ní ìyàwó àlàáfíà; ọmọbìnrin tí kò fẹ́ẹ́ ní ọkọ àti ọmọkùnrin tí kò fẹ́ẹ́ní ìyàwó kí Olódùmarè fún wọn ní ìgbésí-ayé rere.
Ọmọ ẹgbẹ́ òkùnkùn ṣoro ní Ijebu Ode, ọ̀pọ̀ ẹ̀mí sọnù Ara mi rẹwà ló jẹ́ kí n máa ṣí ara sílẹ̀- Victoria Kolawole Ṣé lóòtọ́ ni tírélà ti gba ààrín Ronke Odusanya àti bàbá ọmọ rẹ̀, Jago?
Aijẹun to ati aijẹun lasiko a maa ṣe akoba fun ọpọlọ, bakan naa ni ounjẹ aranju jẹ le ṣakoba fún ọpọlọ, ki ato ṣẹṣẹ sọ nipa ounjẹ ajẹju naa ni eyi to nipa buruku tó n ko lara ọpọlọ wa.
ka àwọn ọkunrin wọn láti ẹni ọgbọ̀n ọdún títí dé aadọta, àwọn tí wọ́n lè ṣiṣẹ́ ninu Àgọ́ Àjọ.
Iṣẹ ọgbin ''Ohun ti ijọba Oṣun fẹ ṣe ni lati sọ iṣẹ agbẹ di iṣẹ to lowo lori eleyi ti yoo wu ọpọ lati maa ṣe,'' Gomina Oyetola woye bẹẹ.
A dupẹ fun Ọlọrun loriii awọn nnkan pupọ ti Ọlọrun loo fun oun naa ni awa naa n jẹ loni.
Arábinrin kan ní Magodo, ní Ipinlẹ̀ Eko fi ọmọ rẹ̀ ọmọ ọdún méjì sílẹ̀ nínú ọkọ̀ wọ inú ilé lọ ko fi sare mu nkan, ni ọkọ̀ náà bá tàkìtì kí ó to jáde sita.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Kidnapping in Nigeria: Ara sọ́ọ́bù oníṣòwò ni wọn ti rí nọ́ńbà ìpè rẹ̀, tí wọn sì tàn-án jáde lásìkò ìsìn 3 Bélú 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 26 Agẹmo 2020 Oríṣun àwòrán, Others Ọjọ gbogbo ni ti ole, amọ ọjọ kan soso ni ti olohun, bẹẹ lọrọ ri nigba tọwọ palaba awọn afurasi ajinigbe kan segi laipẹ yii.
Ẹni ti o jẹ igbakeji Minisita fun eto aabo ni ilẹ naa, Andrey Kartapolov yoo ṣaaju ikọ ti yoo ṣe iwadii ọrọ naa.
"Emi kii mu ọti lile tabi siga, adanilaraya ni mi, mo si mọ ọna ti mo n gba lati ba Ọlọrun mi sọrọ, ẹ mase se idajọ mi.
Minisita wa ki awon musulumi ku aseyori awe Ramadan to pari yii, o wa ro gbogbo omo orile ede Naijiria lati lo ayeye odun yii lati gbadura fun alaafia, isokan , aseyori ati iduso-sinsin orile ede yii.
Gbajugbaja osere tiata lobinrin, Iyabọ Ojo ti bọ soju opo Instagram rẹ lati gbarata lori ohun ti ọpọ osere tiata n la kọja, to fi mọ ohun gan alara funra rẹ.
Nínú ọ̀rọ̀ olori tẹ́lẹ̀ri, ó ni 'oore-ọ̀fẹ́ ń bẹ nínú ìdáriji, ẹwà sì ń bẹ nínú ìfọmọ̀niyan ṣe, mo kí Ọ̀ọ̀ni àti olori rẹ̀ tuntun' Láìpẹ́ yìí ni kabiesi kéde ayàba láàfin fún ìgbà àkọkọ lẹ́yìn tí ìgbéyàwó òun àti Wuraola dàrú lọ́dun tó kọjá.
 kò tí ì hàn bóyá kòkòrò náà lè fa àìsàn si ara ẹranko .
Nítorí ìfẹ́ rẹ tí kì í yẹ̀ dára ju ìyè lọ,n óo máa yìn ọ́.
Awọn olujẹjọ yoku ni olori oṣiṣẹ ni ọọfisi gomina, Oloye Oyebisi Ilaka, kọmisana fun iṣẹ ode ati igbokegbodo ọkọ, Raphael Afonja, to fi mọ igbimọ to n pawo wọle fun ijọba ipinlẹ Oyo.
Yorùbá dùn lédè, ẹ máa sọọ́ Amọ, o fikun wi pe orẹ oun to sun mọ ọga agba Ajo Inec fi oun lọkan balẹ wi pe ohun gbogbo yoo lo ni iroworose, amo baba obasanjo ni opo oro ko kun agbon ni oro naa ri, ati wi pe ki ajo inec o fi ododo leke ni idibo gbogboogbo naa.
Kehinde Ayoola: Ọ̀rọ̀ tí Kọ́míṣọ́nà fọ́rọ́ àyíká ní ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́ bá BBC News Yorùbá sọ gbẹ̀yìn kó tó jáde láyé nìyí Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Oro ti Ayoola ba wa sọ gbeyin Ìròyìn tó ń tẹ̀ wa lọ́wọ́lọ́wọ́ ní wí pé Kọmiṣọna fọrọ Ayika ati ohun alumọni ilẹ ni ipinlẹ Ọyọ, Kẹhinde Ayọọla ti jade laye.
Sugbọn pẹlu iranlọwọ pe emi ni mo n san owo ileewosan rẹ, o rọrun fun mi lati wo akọsilẹ awọn oun to ti gba itọju fun nileewosan.
Aṣẹyinwa aṣẹyinbọ, Joao Teixeira de Faria jọwọ ara rẹ fawọn agbofinro to si sọ ninu fọnran fidio kan pe ''mo jọwọ ara mi fun idajọ agbara to gajulọ ti mo si mu ileri ṣẹ lati fi ara mi fun awọn to n ṣe idajọ orilẹ aye.
ti alagba Tayo Alasoadura, naa si di Minisita
  Ènìà ní láti ṣọ́ra kí ọkọ̀ má lọ gbá olúwarẹ̀ .
Ọdún-un 2016 ni a ṣe ìgòo ọtí-líle náà, ìyẹn ní ìrántí ọdún kẹtàdínlọ́gbọ̀n tí ìṣẹ̀lẹ̀ láabi ọjọ́ 4 oṣù Òkúdù wáyé.
Iroyin sọ pe eniyan marun pẹlu iya arugbo kan ati awọn ọmọ-ọmọ rẹ ni wọn padanu ẹmi wọn ni Akungba-Akoko, nigba ti ọkọ akero kọlu wọn, ni ẹgbẹ ọnọ ọja Ibaka ni agbegbe Ile-ẹk giga fasiti ti Akungba Akoko.
Ẹwẹ, àwọn obinrin kan ti ṣe iwọde, nipinlẹ Katsina, lati beere fun ominira àwọn akẹkọọ ile ẹ̀kọ́ GSSS, Kankara.
Atiku tun gboriyin fawọn oṣiṣẹ ile iwosan kaakiri orilẹede Naijiria fun iṣẹ takuntakun ti wọn n ṣe lasiko ajakẹlẹ arun covid-19 yii.
kí ó tó yípo lọ sí ìsàlẹ̀, sí ẹsẹ̀ òkè tí ó dojú kọ àfonífojì ọmọ Hinomu, níbi tí àfonífojì Refaimu pin sí ní ìhà àríwá.
Lati oṣu kejila ọdun 2019 ti Arteta ti di akọnimọọgba Arsenal, awọn agbabọọlu rẹ ti kaadi pupa mẹfa.
Kí ẹ sọ fún baálé ilé náà pé, ‘Olùkọ́ni sọ pé níbo ni yàrá ibi tí òun óo ti jẹ àsè Ìrékọjá pẹlu àwọn ọmọ-ẹ̀yìn òun wà?
Pasuma ni ere tiata lo da awọn mejeeji pọ.
Ni ayé àtijọ́, kò si itẹdi à lò sọnù bi ti ayé òde òni.
Àwọn tí wọ́n bá yà sọ́dọ̀ rẹ̀ kò ní mọ̀ pé ikú wà ní ilé rẹ̀,ati pé inú isà òkú ni àwọn tí wọ́n bá wọ ilé rẹ̀ wọ̀.
''Ka to wi, ka to fọ, wọn yinbọn pawọn akẹgbẹ wa ti a jọ wa ninu ọkọ, nibi ti gbogbo wa ti mọ pe ewu n bẹ loko longẹ niyẹn,'' Senaya lo woye bẹẹ.
Mother Language Day: Ẹgbẹ́ Akọ́mọlédè l‘Eko ṣe káre sí BBC Yorùbá fún àgbéga àṣà
Ó bá sọ fún àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ pé, “Àwọn ohun tí ó tó kórè pọ̀, ninu oko, ṣugbọn àwọn òṣìṣẹ́ kò pọ̀.
Igba ti wọn ti Paul Sodje lọ san owo ẹmi aburo rẹ ti wọn jigbe ni wọn ko gburo rẹ mọ '' Nigba to n salaye bi iṣẹlẹ naa ṣe bẹrẹ ni bi ọsẹ meji sẹyin, Akinsemola ni lasiko ti wọn fẹ lọ sin mọlẹbi rẹ to ku ni ipinlẹ Delta, ni wahala naa bẹrẹ.
5 owó naira ni ọọfiisi àjọ INEC ni Zamfara Uganda ti bẹrẹ ìgbésè láti fi ikú ṣefàjẹ fún ẹní bá ṣe ìgbéyàwó akọ si akọ ati abo si abo Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí 2 sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 2:23 Fídíò, Water Generator: Ó leè ṣiṣẹ fún wákàtí mẹfà, kó tó sinmi, Duration 2,2310 Òkùdu 2020 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
Ẹ fura o, wọ́n ti ń fi orúkọ Adeboye àti Olukọya lu jìbìtì ní Facebook Kí la tún gbọ́ nípa ìdámẹ́wàá?
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, What causes coronavirus: Akeugbagold sọ àṣírí ohun ti àrùn coronavirus ń dá lárá f Nínú ọ̀rọ̀ rẹ̀ Jimi Disu to jẹ ìlúmọ̀ọ́ká oníròyìn sàlàyé pé ìjọba to ba mọ ǹkan tó ń ṣe kò ni fi irú ọ̀rọ̀ bàntàbanta bẹ́ẹ̀ si ọwọ́ àrá ilú, ó ní ọ̀rọ̀ tó níṣe pẹ̀lú ètò ọrọ̀ ajé àti iléra ará ilú kìí ṣe ǹkan àmú ṣeré.
Ninu ọrọ ẹgbẹ, APC ni Gomina Ibikunle Amosun ko ti kọja aaye rẹ pẹlu bo ṣe ni oun ko ni gbè lẹyin oludije ẹgbẹ APC, fun ipo Gomina nipinlẹ Ogun.
Wọn bii ni ọjọ kejidinlọgbọn, oṣu kọkanla ọdun 1955, ṣugbọn o jẹ ipe Eledumare lọdun 2020 lẹyin to ni arin Covid-19.
Ogbeni Okechukwuwa seleri lati fi egbe naa to egbe to n mojuto ipolongo idibo aare Buhari(Buhari Campaign Organisation), leti lai fi oro ohun fale rara.
Wọn ni ti wọn ba fi idi ẹ mulẹ pe lootọ ni arun naa n tankalẹ lati inu afẹfẹ, yoo mu atunṣe si ofin iyansọtọ dani ni inu ile ni ibi ti eniyan ba pọ si.
’ Ẹ̀gbọ́n ìyá bàbá miobìnrin ni ó ń ké tí ó fa irun mọ́ ara rẹ̀ lórí, tí ó ń gbé ara rẹ̀ ṣánlẹ̀, tí ó ń sọkún kíkorò kíkorò bẹ́ẹ̀.
Amọm ibeere kan tawọn eeyan n beere ni pe bo ya Pochettino le gba ife ẹyẹ UEFA Champions League ti PSG ti n gbiyanju lati gba fun wọn.
Wọ́n bá mú ọmọ ewúrẹ́ kan ninu agbo, wọ́n pa á, wọ́n sì ti ẹ̀wù Josẹfu bọ inú ẹ̀jẹ̀ rẹ̀.
Atẹ́gùn ọkọ̀ akẹ́rù náà lásán ló fẹ́ kẹ̀kẹ́ Marwa kúrò lójú títì tó fi forí sọ òpó kan, tí awakẹ̀kẹ́ àti àwọn èrò fi ara pa.
“Ẹ wà ní ìmúrasílẹ̀, kí ẹ di ara yín ní àmùrè, kí àtùpà yín wà ní títàn.
Èyí ni yóo jẹ́ ààlà ilẹ̀ náà ní apá ìlà oòrùn.
Ọkan lara awọn oṣiṣẹ ile itaja ọhun sọ fun BBC pe, ọja ti awọn jnanduku na ji ko, fẹẹ to ọgbọn miliọnu naira.
Àwọn tí wọn ń sin àwọn oriṣa lásánlàsàn kọ̀,wọn kò pa ìlérí wọn sí ọ mọ́.
Orlando Owoh jade laye lọjọ kẹrin, oṣu kọkanla lọdun 2008.
Nitori naa, mo n ro awon omo orile ede yii lati fowosowopo pelu wa ninu ija gbigbokun ti iwa ibaje.
Obitibiti ọlọpaa lo pejọpọ si Ile Igbimọ Aṣofin ipinlẹ Edo to wa ni ilu Benin.
Iṣẹ ọna ati yiya aworan to yan laayo ko ba a mọ lorilẹede Naijiria nikan, ṣe lo ti gbe e pade awọn ọlọla to si ti mu u rinrinajo kaakiri agbaye.
Awọn eeyan to wa l'Amerika ti juwe iru igbẹjọ ti ileẹjọ a ṣe fun Hushpuppi a Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Yetunde Bakare dárà lórí ètò Ṣé o láyà, ẹ ràn án lọ́wọ́ nínú ìbéèrè tó ṣì Nkan miran ti FBI tun sọ Lara jibiti ti Hushpuppi ati awọn isọmọgbe rẹ tun gbiyanju lati ṣe ni jiji ọgọrun un miliọnu Euro (to jẹ miliọnu mẹrinlelọgọfa Dọla), lati ara ẹgbẹ agbabọọlu kan ninu idije Premier League.
Ọmọ kan ni Chanel bí fún Oluwo, orukọ rẹ a si maa jẹ Oduduwa.
Ohun tí ọba ń bèèrè yìí le pupọ, kò sí ẹni tí ó lè ṣe é, àfi àwọn oriṣa, nítorí pé àwọn kì í ṣe ẹlẹ́ran ara.
 Dokita Ajayi, eni ti Dokita Francis Arogundari gbenu e
Ewe, loju oja awon olokoowo pasipaaro owo Naira je ọ́ọ̀dúnrún le méjílélọ́gọ́ta(N362), ti pasipaaro re nile ifowopamo agba CBN si je ọ́ọ̀dúnrún le marun(N305).
Ó bẹ̀rẹ̀ sí jóná bí ògùṣọ̀.
Premier League yóò bẹ̀rẹ̀ padà lóṣù kẹfà Ẹ̀rù n ba àwọn agbábọ́ọ̀lù Premier League láti padà sórí pápá nítorí coronavirus Arsenal rántí Invincibles,"" ó pé ọdún mẹ́rìndínlógún tí Arsenal gba ife Premier League Àwọn jẹsí tó gbajúmọ̀ nínú ìtàn ìdíje bọ́ọ́lù Lasiko ti ọja rira agbabọọlu ṣi silẹ ninu oṣu kinni ọdun 2020 ni Ighalo darapọ mọ Manchester United lati ikọ agbabọọlu China, Shanghai Shenhua."
Ijamba ọkọ naa waye ni opopona Al Maruf, Abule Egba ni ipinlẹ Eko.
Ikede naa n waye pẹlu bi ajọ naa ati orilẹede Naijiria ṣe n gbaradi fun eto idibo gomina ni ipinlẹ Edo ati Ondo.
Nítorí náà kò sí ìdí tí a óo fi tún yan alufaa mìíràn dípò rẹ̀.
Kyari ko iyan ipo igbakeji aarẹ, Oṣinbajo kere.
Ó ni bó tilẹ̀ jẹ́ pé òun ti gbọ́ ọ̀pọ̀lọ́pọ̀ ọ̀rọ̀ lórí ẹ̀sùn náà, kò sí òtítọ́ kankan níbẹ̀ Oludije naa ni òun yóò fi òpin sí bí àwọn ọkọ́ agbépo ṣe ń dá wàhálà sílẹ̀ lójú pópó Ìpínlẹ̀ Eko àtí wípé òun yóò fi iná oju popo sí gbógbó kọ́lọ́fín ìlu tí ǹkan búburú ti ń ṣẹlẹ̀ Oríṣun àwòrán, PIUS UTOMI EKPEI Ó ní àwọn iléeṣẹ́ ìjọba tí ọ̀rọ̀ kàn yóò ṣe agbéyẹ̀wò owó gọbọi tí àwọn ayálégbé ń san fún onílé ní Ìpìnlẹ̀ Eko Lórí ẹ̀sun pé àwọn ará ìlú kò mọ oun tó ń wà nínú ìṣúná owó Ipinlẹ Eko, Sanwo-Olu ní òun yóò gbíyànjú láti fi ojú ọ̀rọ̀ iṣúná owo ìpínlẹ̀ náá síta, tí ará ìlú yóò sì mọ̀ bí ìjọba ṣe ń ná owó wọn Oríṣun àwòrán, Sanwo Olu Campaign O gbìyànjú láti dáhùn ìbéère nípa agbára tí olórí ẹgbẹ́ òṣèlú APC, Oloye Bola Tinubu ní lórí ìṣèjọba Ìpinlẹ Eko.
Gẹgẹ bi ọkan lara awọn akẹẹgbẹ rẹ nileesẹ naa, Temie Gíga-Bosun ṣe sọ loju opo Twitter rẹ, ọlọpọlọ pipe ni Oke, to si jẹ onitiju eniyan.
 Fun idi eyi, awa aṣofin a rọ ẹyin aṣiwaju, ẹyin ara ilu ati ẹyin alatilẹyin ẹgbẹ oṣelu wa ati ẹlẹgbẹjẹgbẹ lati maa gbe igbesẹ ti yoo maa mu alaafia jọba ni ṣaaju idibo, lasiko idibo ati lẹyin idibo yii.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Olubadan: Ìpàdé àláàfíà wáyé láàrin Olubadan àti àwọn àgbà ìjòyè tí Ajimobi sọ di ọba.
Bakan naa lo gbadura fun aya gomina ipinlẹ Kwara to se alatọna oore naa, pe Ọba Oke yoo fun ni ẹmi gigun ati alaafia, ti wsn yoo si se aseye ti alakan n sepo lori oye.
 bí ó tilẹ ̀ jẹ ́ pé Àyìnlá Ọmọwúrà kú nígbà tí ó wà ní ọmọ ogójì ọdún ó lé díẹ ̀ ní ọdún 1980 .
Ọpọlọpọ ọmọ Naijiria to fi mọ awn oloṣelu lo n funpe si ijọba pe ki wn tete ba ijọba orilẹede uganda sọrọ ki Omah Lay atawọn to ku rẹ ma baa pẹ lẹwọn.
Day 16: Adebayo Adelabu ṣisẹ́ lówó, ó sì bá òsèlú nílé #BBCNigeria2019 Àtìpó 162 míì dé padà láti Libya Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Igba ọtun de fawọn afọju ninu eto idibo Adari ẹgbẹ to pọ ju lọ nile, Ọgbẹni Sanai Agunbiade fi eyi lede nigba to m ba awọn oniroyin ile igbimọ aṣofin ipinlẹ naa sọrọ lẹyin ipade pajawiri ti wọn ṣe lalẹ ọjọru.
Oríṣun àwòrán, osun state government Amọṣa lẹyin ti ọrọ ikọ naa ho ṣukuṣuku fun igba diẹ lo ba da wai, eleyi to ti nkọ ọpọ lominu pe ṣe kii ṣe pe ohun naa, gẹgẹ bi ọpọlọpọ eto ijọba miran ti fori ks igbo.
Bí Fayemi bá tasẹ̀ àgẹ̀rẹ̀, àwọn oníbáwí rẹ̀ wà l'Ekiti-Peter Fatomilọla Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Ọmọ ilu Ibadan, nipinlẹ Oyo ni Kuforiji O gba iwe ẹri ninu imọ isiro, ati iwe ẹri imọ ijinlẹ kejì ninu imọ amojuto okoowo,lati Fasiti ipinlẹ Delaware.
Nigba to n salaye bi isẹlẹ naa se waye, arabinrin Adeola, tii se ẹni ọdun marundinlaadọta ni ada ni awọn afurasi ọhun fi sa oun lasiko ti oun n du ẹmi ọmọ oun lọwọ ikọlu, ti oun si ba ara oun ninu agbara ẹjẹ.
Ó kó ọba Jehoiakini, ati ìyá rẹ̀, ati àwọn aya rẹ̀, àwọn ìwẹ̀fà rẹ̀ ati àwọn ìjòyè ilẹ̀ náà ní ìgbèkùn láti Jerusalẹmu lọ sí Babiloni.
Ẹni tó bá ń bínú kàn ń bínú lásán ni- Oyedepo 3) Tinuade Babalola Adejuiyegbe: Tinuade ni Oluboropa, ti ilu Iboropa Akoko- Akoko, ni ipinlẹ Ondo.
2 mílíọ́nù owó ìtanràn Ìjọba Nàìjíríà ti gbà láti san N30b owó àjẹmọ́nú fún ASUU Àjẹ́ àti Aṣẹ́wó ní ìyá Rainbow - Òjòpagogo Wo ìsọ̀rí àwọn tó jẹ́ kí ìwọ́de End SARS / end SWAT lárinrin àti ìtumọ̀ Alaga egbe ọmọlẹyin Kristi, CAN ni ipinlẹ Anambra Asoju biṣọọbu agba ijọ Anglican Asoju Biṣọọbu agba ijọ Aguda, Asoju ẹgbẹ ijọ emi mimọ PFN, Asoju alaga igbimọ awọn lobaloba ni Anambra, Agbejoro agba ni Anambra, Kọmiṣonna fun ọrọ ọdọ awon meji to jere julọ ni igbimọ iṣejọba ipinlẹ naa.
Dafidi fi àwọn ọmọ ogun ṣọ́ Siria ti Damasku, àwọn ará Siria di iranṣẹ Dafidi, wọ́n sì ń san ìṣákọ́lẹ̀ fún un.
NCDC kéde èèyàn 423 míràn tó ṣẹ̀ṣẹ̀ lùgbàdì Covid-19 ní Nàìjíríà, 263 gbàwòsàn Wo àwọn iléèwé gíga tó ti bẹ̀rẹ̀ sí ní ta fọ́ọ̀mù JAMB post UTME screening ní Naijiria Ẹ wo ohun tó yẹ kí ẹ mọ̀ nípa oògùn 'Sputnik V' Russia tó ń wo àrùn Coronavirus Ẹgbẹgbẹ̀rún ọmọ Nàìjíríà ní yóò má a kú lójoojúmọ́ tí wọn bá gbà wọ́n láàyè láti gbébọn dání- Amofin Bàbá naa tí orúkọ rẹ̀ ń jẹ́ Mati Audu ni ìròyìn sọ pé ó wá láti ìjọba ìbílẹ̀ Tsanyawa ni ipinlẹ Kano.
odun 2019 ti bẹrẹ bayii niluu Abuja.
"Aya gómìnà Kwara gba ilé fún Risikat olójú búlúù àti ọkọ rẹ̀ Ṣaaju ni Ifayemi Elebuibọn ti sin awọn Ọba alade ni gbẹrẹ ipakọ lori oro gbigbe gẹgẹ bii aṣa ti ko yẹ ko parun Ọ̀pọ̀lọpọ̀ Ọbalayé ní kò yàtọ̀ sí èèyàn lásán - Elebuibon ""Ọpọlọpọ awọn ọbalaye ni ilẹ Yoruba ni ko yatọ si eeyan lasan nitori wọn n tapa si iṣẹṣe ati iṣẹmbaye""."
Gẹgẹ bi wọn ṣe darukọ wọn, awọn oṣiṣẹ ajọ FRSC naa ni Bayegunmi ati Abioye.
Agbabọọlu Sierra Leone to tun je balogun ẹgbẹ rẹ ni wọn ni o ṣe magomago.
Jehoaṣi ọba, ọmọ Jehoahasi, ṣẹgun Benhadadi ní ìgbà mẹta, ó sì gba àwọn ìlú tí wọ́n ti gbà ní ìgbà ayé Jehoahasi, baba rẹ̀ pada.
Tanko Muhammad: Ààrẹ Buhari fikún sàá Muhammad Tanko nípò adelé adájọ́ àgbà
aṣeyọri wọn latilẹ wa, paapaa laarin ọdun mẹrin si asiko yii.
fulani darandaran ati awọn ikọlu miiran ti wọpọ bayii.
'Ètò ìdìbò sípò gómìnà Ondo, Edo yóò wọ́lẹ̀ nítorí rògbòdìyàn APC ' O seese ki eto idibo nipinlẹ Edo ati Ondo ki o ma lọ ni ọna ti awọn eniyan foju si nitori rogbodiyan to n waye nibẹ.
fasiti Ibadan lati gba iwe ẹri imọ ijinlẹ akọkọ, B.
“Anthony wa lara aagbaboolu odo ti o dara julo ti a ni fun akoko
Australia dipo kerin mu ninu ipo ate ajo FIBA ti o sese jade, Turkey wa ni ipo keje, bee si ni Argentina dipo karundinlogun mu lagbaye.
Bi o tilẹ jẹ pe wọn papa fi dokita naa silẹ lẹyin wakati kan amọ ẹpa ko boro mọ nitori oku alaboyun ati ọmọ inu rẹ lo ba nile iwosan naa.
Awọn ọmọ ikọ agbesunmọmi Boko Haram ti fi ohun sita pe awọn lawọn ji awọn akẹkọọ ni girama Kankara ni ipinlẹ Katsina.
    ‘A gba ọba náà ni ìyànjú pé kí o jẹ́ kí wọn bu apá fún òun ṣùgbọ́n gbangba ló wí fún wa pé òun ko níí jẹ́, a bá kúrò ní aafin.
Oríṣun àwòrán, Twitter/Omoyele Sowore Gbogbo ileeṣẹ nla nla lo kogba sile, awọn oṣiṣẹ banki atawọn oṣiṣẹ ijọba ko lọ di ibi iṣẹ.
Sanwo-Olu sọ pe awọn yoo fi eroja 'white blood cells' ọhun pamọ sinu amu nkan tutu, ti wọn yoo si lo lati fi tọju awọn miran to ba tun ni arun COVID-19 ọhun.
During Ramadan, Muslims are expected to fast from dawn to sunset, abstaining from food and water.
Gideoni pada sí ilé rẹ̀, ó sì ń gbé ibẹ̀.
Akọrọyin BBC ni awọn to n mojuto eto idibo naa kọ lati gba awọn ti ko ni ojulowo bébà idibo da ni nitori wọn ni ko tọna ni eyi to si fa ariwo nla.
Kọmisana feto ayika, Abiodun Abudu Balogun lo fidi ọrọ yii mulẹ, lasiko to n se abẹwọ sawọn agbegbe kan to farakasa isẹlẹ yii lọjọ Aiku ni ilu Abeokuta.
20 Kíyèsíi, èyí ni iṣẹ́ rẹ, láti pa àwọn òfin mi mọ́, bẹ́ẹ̀ni, pẹ̀lú gbogbo agbára rẹ, iyè àti okun.
Wéré ni mo bá bojú wẹ̀hìn.
Jesu lọ sí òdìkejì òkun ní ilẹ̀ àwọn ará Geraseni.
Mose jáde, ó lọ sọ ohun tí OLUWA sọ fún àwọn ọmọ Israẹli; ó sì mú àwọn aadọrin olórí náà wá sí ẹnu ọ̀nà Àgọ́ Àjọ.
Ǹjẹ́ a lè bí ilẹ̀ ní ọjọ́ kan,tabi kí á bí orílẹ̀-èdè kan ní ọjọ́ kan?
Ojoojumọ ni iroyin ijinigbe n jade lorilẹ-ede Naijria, botilẹjẹ pe ọga agba ileeṣẹ ọlọpaa sọ laipẹ yii pe o ti dinku lẹyin ti awọn ọlọpaa so okun aa bo le lawọn opopona nla.
O ni ohun to kan awọn ikọ ọlọpaa kogberegbe SARS ni gbigbogun ti iwa idigunjale ati ijinigbe pẹlu awọn iwa ipa gbogbo miiran sugbọn ẹsun ti awọn eeyan fi n kan wọn bayii fihan pe ibi ti wọn fi ẹlẹmọṣọ wọn ṣọ kọ lo n ṣọ bayii.
Lẹ́yìn náà, ó pada sí Jerusalẹmu.
 Ìtàn yí ni àwọn ẹlẹ ́ sìn ìbílẹ ̀ yorùbá gbàgbọ ́ tí wọ ́ n sì fi ṣe ọ ̀ pákútẹ ̀ lẹ ̀ ì ) àgbọ ́ wọn nípa ìṣẹ ̀ dá ayé .
Fake News: Wọ́n padà ká a nílẹ̀ ṣùgbọ́n àbàwọ́n rẹ̀ ṣì wà lára mi
ìlú-nlá Salt Lake, Utah, ilẹ̀ Amẹ́ríkà
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Wọ́n rí alààyè obìnrin tó ti kú tẹ́lẹ̀ nínú mọ́ṣúárì 2 Agẹmo 2018 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 3 Agẹmo 2018 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ko sẹni to le kede oku eeyan ti ọlọjọ kò ba tii dé Obinrin kan ti n gbadun diẹ̀-diẹ̀ nile ìwosan lẹ̀yin ti wọn ba laaye ninu firiiji ti wọn n ko oku pamọ si ni mọṣuari.
Fayoṣe àti Fayẹmi dì mọ́ra wọn l'Eko Ọga ọlọpaa agbegbe ti iṣẹlẹ naa ti ṣẹlẹ Bob Gualtieri sọ fun awọn oniroyin wipe ni ọjọ ti awọn obinrin naa pa baba wọn, wọn kọkọ fun ni ogogoro ati oogun orun mu.
Ṣeyi Law: Ọ̀rọ̀ ìlú yìí tó kéèyàn de aago méjì
Saulu ati àwọn ọmọ ogun Israẹli pa ibùdó tiwọn sí àfonífojì Ela, wọ́n sì múra ogun de àwọn ọmọ ogun Filistini.
Oṣu Keje, ọdun 2018 ni wọn yan Adeọsun sipo adari to dimu titi di asiko yii, nibi to ti n mojuto eto ikọni ati agbeyẹwo isọwọ sisẹ awọn ọmọ ogun Naijiria.
Agbẹjọ́rò Maina yọ ọwọ́ kúrò nínú ìgbẹ́jọ́, Ó lóun kò ṣé mọ̀ Ninu ọrọ ti aṣoju awọn oṣiṣẹ fẹyinti sọ fun ileeṣẹ iroyin Naijiria Punch, wọn ni awọn Gomina ti ko da ipin ti wọn ninu owo ifẹyinti oṣiṣẹ ko lẹtọ lati ya ninu rẹ.
‘Bi Gomina Ajimobi se yan adarí òsìsẹ́ tuntun ní Oyo kò dí wa lọ́wọ́’ 'Olódo ni mí nílé ìwé kí n tó ṣàwárí ẹ̀bùn mi' Kò sí ààbò, kò síṣẹ́; Àwọn dókítà LUTH bínú tán Lẹ́yìn igbe Atiku, Ààrẹ Ilé Ẹjọ́ kòtẹ́milọ́rùn yọra rẹ̀ nínú ìgbẹ́jọ́ èsì ìdìbò ààrẹ Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí kan sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
Lẹ́yìn tí OLUWA ti fi ìyapa sí ààrin Israẹli ati ìdílé Dafidi, Israẹli fi Jeroboamu ọmọ Nebati jọba.
Nígbà náà ní mo wí lọ́kàn ara mi pé,“Àwọn aláìní nìkan nìwọ̀nyí,wọn kò gbọ́n;nítorí wọn kò mọ ọ̀nà OLUWA,ati òfin Ọlọrun wọn.
Ó ní, ‘Mo mọ ohun tí n óo ṣe!
Babangida ni kosi ọmọ Naijiria kankan to yẹ ko sọ ẹmi rẹ nu lori pe oun bere fun ẹtọ rẹ lọwọ ijọba tiwantiwa.
Se, ori yeye lo n mogun taisẹ lo po, lati igba ti Joy
Alukoro fun ile iṣẹ ọlọpaa ipinlẹ Oṣun, Folasade Odoro naa sọ aridaju pe Ọjọgbọn Adegbehingbe ti mori bọ lọwọ awọn ajinigbe.
O’ju bọ̀rọ̀ la fi ń gba ọmọ lọ́wọ́ èkùrọ́ ńdan?
Nisinsinyii tí mo ti dàgbà, tí ewú sì ti gba orí mi,Ọlọrun, má kọ̀ mí sílẹ̀,títí tí n óo fi ròyìn iṣẹ́ ńlá rẹ,àní, iṣẹ́ agbára rẹ, fún gbogbo àwọn ìran tí ń bọ̀.
Losu kẹjọ ni Leah Cambridge to jẹ ọmọ Turkey doloogbe lataari iṣẹ abẹ idi ni eyi to dẹmi ọmọ ọdun mọkandinlọgbọn naa legbodo.
Omar al-Bashir to n tuko orile ede Sudan ti dide lati gbegba ibo fun saa keta isejoba pelu atileyin awon egbe oselu re lodun 2020.
 Iwe mimọ Kurani sọ fun wa pe
Arabinrin Baiwa, tun so pe awon igbimo egbe ti n gbe igbese lati wa ojutuu si awon ipenija to n dojuko eto iselu ati igbe aye-gbadun awon obinrin lorile ede Naijiria.
Nítorí n óo kó àwọn orílẹ̀-èdè jọ láti gbógun ti ìlú Jerusalẹmu.
Mo yáa tẹsẹ̀ mọ́nrìn ní tèmi, èmi adúláwọ̀ tòótọ́ 🙂
Lana tii ṣe ọjọ kọkanla oṣu Kaarun ni ọwọ tẹ wọn.
Nígbà tí ó tó àkókò àti jẹun òwúrọ̀, mo jẹun, bí mo sì ti jẹun tán tí mo jókòó lórí àga mi kan báyìí ni ìyàwó mi dé tí ó kúnlẹ̀ níwájú mi, ó dáhùn ó sì wí pé: Kábíyèsí aláṣẹ, èkejì òrìṣà, àtàrí àjànàkú tí kì í ṣe ẹrù ọmọdé, baba tí ó ju baba ẹlòmíràn lọ, olórí ìlú, baba ijòyè, ọ̀kánlàwọ́n ọkùnrin, ènìyàn pàtàkì láàrin àwọn ènìyàn pàtàkì, ẹni títóbi láàárin àwọn ẹni tí ó tóbi; ojúlówó ọmọlúwàbí, ọkùnrin jáde inú àwọn ènìyàn ń dùn, baálé mi tòótọ́, fọ́rífọ́rí ni mo ń fi yín ṣe.
Man City fìbínú gbẹ̀san lára Tottenham Messi ati Ronaldo: Lionel Messi ati Cristiano Ronaldo ni wọn ti n gba ami ẹyẹ yii mọ ara wọn lọwọ lati ọdun bii mẹwaa sẹyin.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Mọ̀ síi nípa Shina Rambo tó pàdé Jesu lọ́gbà ẹ̀wọn lẹ́yìn tó ti jalè Wàhálà míì dé!
Ipinlẹ Eko lo ṣi n lewaju ninu awọn ipinlẹ mẹrinlelọgbọn, ati ilu Abuja, ti aarun naa ti de ni Naijiria.
Ìpínlẹ̀ Oyo, Ogun, Ondo buwọ́lu àbádòfin Àmọ̀tẹ́kùn Ẹ wo àwọn ìlérí tí Buhari ṣe láti ọdún 2015 àmọ́ tí kò tíì mú ṣẹ Fọnran fidio kan, eleyi to ṣe afihan iṣẹlẹ yii ti gba oju opo Twitter kaakiri, ti awọn ọmọ Naijiria si ti n sọ pe bi aarẹ ko ti ṣe mojuto eto aabo ko jẹ ohun to dun mọ awọn.
Òun ni kí ẹ máa yìn, òun ni Ọlọrun yín, tí ó ṣe nǹkan ńláńlá tí ó bani lẹ́rù wọnyi fun yín, tí ẹ̀yin náà sì fi ojú ara yín rí i.
Bí Jesu ti ń rìn lọ lẹ́bàá òkun Galili, ó rí Simoni ati Anderu arakunrin rẹ̀ tí wọn ń da àwọ̀n sinu òkun, nítorí apẹja ni wọ́n.
Ó gbé agbada omi kalẹ̀ sí apá gúsù ìhà ìlà oòrùn igun ilé náà.
"Lọpọ igba eeyan yoo wa ninu ibẹrubojo ni.
eleto iidbo niluu Yola , ni ipinle Adamawa .
ẹkarun-un, bẹ́ẹ̀; ẹkẹfa, bẹ́ẹ̀, ekeje bẹ́ẹ̀, ẹkẹjọ, bẹ́ẹ̀, ẹkẹsan-an, bẹ́ẹ̀, ẹkẹwaa, bẹ́ẹ̀, ikọkanla bẹ́ẹ̀, ekejila náà, bẹ́ẹ̀.
Coronavirus tún ti ṣe ọṣẹ́ lórí iṣẹ́ líla ojú ọ̀nà relùwe láti Eko sí Ibadan - Ìjọba àpapọ̀ Àrùn Coronavirus fa'lẹ̀ya láwọn ìletò aláwọ̀dúdú ní Amẹ́ríkà Oluwo: Ọ̀pọ̀ òjò lo ti rọ láàrin èmi àti Olúwòó, olorì Chanel sọ̀rọ̀ ǹkan ti oju rẹ ri ni Iwo Àkọlé àwòrán, Mo ti bá ọba Olúwò lóri ọmọbinrin ọdún mẹ́tàlá rìí- Olorì chanel O tun ti n rugbo bọ o.
Oríṣun àwòrán, @AkinwunmiAmbode Àkọlé àwòrán, Ohun to fidi rẹ mulẹ ni pe ohun to n fa eyi ko yẹ lẹyin bi wọn ṣe ni awọn eeyan kan dide lati ba gomina Ambode dije fun aṣia ẹgbẹ oṣelu Ọrọ yii ti da ori ikanni ayelujara twitter ru bayii.
Òwe Yorùbá ti ó sọ wi pé “Ojú àlejò ni a ti njẹ igbèsè, ẹhin rẹ  la nsaán”.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Omoyele Sowore : Àwọn orílẹ̀èdè márùn-ún tí ìjìyà ti wà fún ẹni tó bá bú ààrẹ 25 Owewe 2019 Oríṣun àwòrán, Omoyele Sowore Àkọlé àwòrán, Ijọba apapọ Naijiria ni Sowore fi ifọrọwanilẹnuwo bu aarẹ Omoyele Sowore ti pari gbogbo eto beeli rẹ lọjọru ṣugbọn awọn alaṣẹ kọ lati tu silẹ.
Oríṣun àwòrán, others Lasiko to n ba BBC Yoruba sọrọ, Lai sọ pe eniyan to fi ara ṣiṣẹ fun Naijiria, to si nifẹ orilẹ-ede naa ni Kyari jẹ nigba aye rẹ, tako bi ọpọlọpọ ṣe maa n bu ẹnu atẹ lu u.
Gẹgẹ bi wọn ṣe yọ Sanusi nipọ lọdun yii naa ni wọn yọ baba to bi baba Sanusi ọhun naa nipo, ẹsun ti wọn fi kan baba bab a rẹ naa ni pe, o n tẹ oju ofin mọlẹ.
Minisita fun eto isuna orilẹede Naijiria, Abilekọ Zainab Ahmed lo sọ bẹẹ lẹyin ipade igbimọ alasẹ ti ijọba apapọ, Federal Executive Council ni ilu Abuja.
Àwọ̀ ara mi di dúdú, ó ń bó,egungun mi gbóná fún ooru.
Musa Diru to jẹ alaga ẹgbẹ awọn oṣiṣẹ ile iṣ irina ofurufu (NUATE) ni ipinlẹ Eko sọ fun BBC pe awọn oṣiṣẹ awọn ko ni lọ ibi iṣẹ lati ọjọru titi ijọba yoo fi da wọn lohun.
Ajọ SERAP tun rọ agbẹjọro agba ni Naijiria lati ri pe gbogbo orukọ to yẹ ko wa ninu iwe iforukọsilẹ naa lo wa nibẹ fun anfani araalu.
Awọn eeyan kan ti wa n gbe iborun kiri pe o yẹ kawọn ọkunrin maa ge irugbọn wọn lati dena arun Coronavirus, eyi ti ko ri bẹẹ rara.
Oríṣun àwòrán, SRJ O ni òun ń ṣe iṣẹ́ tí wọn kọ́kọ́ fun òun takuntakun, ní wón tún ṣe fún òun ní isẹ akọni mìíràn, tíì ṣe agbenuso fún ilé.
ati láti jẹ́ kí àwọn tí kò kọlà lè yin Ọlọrun nítorí àánú rẹ̀.
Wọ́n fi rán àwọn iranṣẹ tí wọn ń gun àwọn ẹṣin tí wọ́n lè sáré dáradára, àwọn ẹṣin tí wọn ń lò fún iṣẹ́ ọba, àwọn tí wọ́n ń bọ́ fún ìlò ọba.
Jerusalema Remix - Burna Boy ati Master KG.
Ọgbẹ́ni Ahmad Salkida sọ pe, oun gbìyànjú lati dúnàá dúrà pẹlu ikọ̀ ọun lori bi wọn yoo se da awọn ọmọ wọ̀yí silẹ̀, sugbọn ti gbogbo ìgbìyànjú oun já sí pàbó.
Fóònù náà tí owó rẹ̀ tó ẹgbẹ̀rún lọ́nà ààdájọ Naira.
Atunṣe ọjọ kẹtalelogun oṣu kọkanla: A ti ṣe atunṣe lori akọsil iroyin yii lati lee jẹki o di mim pe ESAT TV ko mọ nipa didọgbọn si fidio naa, tabi wọn mọọmọ gbe ayederu rẹ si ori afẹfẹ.
Iwe iroyin Daily Star Sunday lo gbe ìròyìn síta pe agbabọọlu náà tó ẹni ogún ọdún ya fidio ará rẹ níbi to tí n ṣe fàájì apejẹ nínú ilé rẹ.
Àwọn ìpín ọmọ ogun Dafidi tí wọ́n wá sọ́dọ̀ rẹ̀ ní Heburoni, láti gbé ìjọba Saulu lé Dafidi lọ́wọ́ gẹ́gẹ́ bí ọ̀rọ̀ OLUWA nìyí: 
 “O se pata ki lati je ki awon omo orile-ede South Sudan fi erongba okan won han, latari ati le se aseyori ninu eto alaafia naa.
Gomina Ganduje fikun ọrọ pe ipinlẹ Kano ti ya ibi kan sọtọ fawọn Fulani lati maa fi ẹran jẹko.
Pension: Ohun tí o ní láti ṣe kí owó ìfẹ̀yìntì rẹ̀ má wọgbọ́
Iroyin naa fi idi rẹ mulẹ pe ipinlẹ Eko ni awọn mẹta tuntun ti wọn ṣẹṣẹ ṣawari naa ti wa.
Àwọn ọmọ Lefi di alufaa láìsí ìbúra.
Èrè kí ni eniyan ń jẹ ninu gbogbo làálàá rẹ̀, tí ó ń ṣe nílé ayé?
Nítorí náà, Dafidi yin OLUWA níwájú gbogbo eniyan, ó ní: “Ìyìn ni fún ọ títí lae, OLUWA, Ọlọrun Israẹli, Baba ńlá wa, 
Mo kó gbogbo ọ̀rọ̀ ti mo sọ sí akòròyìn Daily Trust jẹ-Femi Fani-Kayode Eko já n'ípò kíní, Èèyàn 252 ló forí kó Covid -19 ní Nàìjíríà lọ́jọ́ Ajé Ìjọba àpapọ̀, ẹ gbà lọ́wọ́ ìrẹ́jẹ iléeṣẹ́ DSTV àti èlé owó rẹ̀ - ọmọ Nàìjíríà faraya 'Ó tẹ́mi lọ́rùn kí n pàdánù ẹsẹ̀ mi, ju kí ǹkan ṣe oyún inú mi' Gẹ́gẹ́ bi ó ṣe sọ, ó ni ìwádìí ti fi han pé àwọn aggbésùmọ̀mi Islamic State ti wà nínú igbó Lùsádà, ilú yìí ló já si ìgbó ọra eyi ti kò sì ju wákàti méji lọ si ìpínlẹ̀ Sokoto.
”Aare wa fi da igbimo awon
Àti pé ilé-aiyé yìí ò dúró lójú kan rárá.
Ọlọfinsawo ni lẹka eto oselu, BBC Yoruba ti seto ipade ita gbangba fawọn oludije gomina ni ipinlẹ marun nilẹ Kaarọ Oojire.
Kó àwọn ọmọ rẹ̀ wá pẹlu, kí o sì wọ̀ wọ́n ní ẹ̀wù.
Àwọn ọmọ Israẹli sì bẹ̀rẹ̀ ìrìn àjò wọn láti aṣálẹ̀ Sinai, wọ́n tò lẹ́sẹẹsẹ.
to wa nibẹ ko ni fi sinu apoti idibo, yoo fi si ibomiran.
Laipẹ yii ni ija naa bẹ silẹ laarin Toyin ati Liz.
Koda ọtọ ni ibi ti awọn mii n lọ ni Mowe ṣugbọn awọn ọlọkọ maa n saba lo ọla pe ipade adura yii wa ti wn si mọ pe ero pupọ ni yoo lọ ibẹ lati dede gbe owo le iye ti wọn n gbe ọkọ tẹlẹ ni iye to ba wu wọn.
Samuẹli wí pé, “OLUWA kò yan eléyìí.
Ile-ifowopamo orile-ede Nigeria ti se ikilo fawon omo orile-ede Nigeria lati sora nipa, kikowo lori oja ikoko owo takada ti a mo si Cyptocurrencies, eyi ti o lagbara ti ko si lowo ofin ninu lorile-ede NigeriaNinu atejade kan niluu Abuja lojo-Ru, adele oga-agba eka eto ibanisoro nile-ifowopamo naa, Isaac Okoroafor so pe, idokowo owo takada bi: Bitcoin, Ripples, Monero, Litecoin, Dogecoin, Onecoin, ati kata-kara owo yii ni ko niwe eri ninu bakan naa ni ile-ifowopamo agbaye ko si fowo si tita re.
Ṣugbọn Jesu dá wọn lóhùn pé, “Ìran burúkú ati ìran oníbọkúbọ ń wá àmì.
'Títẹ àwọn afipábánilopọ̀ lọ́dàá kọ́ ni ọ̀nà àbáyọ sí ìwà ìfipábánilopọ̀' Bawo ni iṣẹlẹ naa ṣe ṣẹlẹ si Elizabeth?
Loṣu to lọ ni Guardiola gbe owo to le ni miliọnu kan owo dọla kalẹ lorilẹede Spain lati gbogun ti itankalẹ aarun coronavirus.
eyi ti yoo  jẹ ki igbaye-gbadun ba gbogbo
Ẹgbẹ oṣelu APC lo ti kọkọ fi atẹjade sita ninu eyi to ti fẹsun kan gomina Makinde pe o n fi oju tẹmbẹlu ọfiisi aarẹ debi pe kii ni ibanisọrọ kankan pẹlu aarẹ.
Oríṣun àwòrán, others Àkọlé àwòrán, Ọ̀pọ̀ ọmọ ẹgbẹ́ wa ló n tẹpo níye tó kéré sí iye ti PPPRA fi síta- IPMAN Níbẹ̀rẹ̀ oṣù tuntun, jálá epo bẹtiróò fò fẹ̀rẹ̀ sí ₦143.
Oyè Mọ́gàjí àti Báálẹ̀ ti di owó rèé, ọjà rèé ní Ibadan - Lekan Balogun Ọkọ̀ ojú omi ''fẹri'' kọlu afárá, ọkọ̀ méjì já sódò Adájọ́ pàṣẹ kí wọ́n fi ọlọ́pàá tó lọ́wọ́ nínú ikú Kolade Johnson sí àhámọ́ “Kò sí àgbègbè Nàìjíríà kánkan tó wà lábẹ́ àkóso Boko haram” O gba awọn ọdọbinrin ni imọran pe ko si ohun ti wọn ko le ṣe ti wọn ba ti gbagbọ ninu ara wọn pẹlu atilẹyin Olorun.
- Ilé ẹjọ́ ìpínlẹ̀ Ondo Ògo ilẹ̀ Ibadan míì lọ, Pàràkòyí Olóyè Bode Akindele dágbére fáyé Wọ́n rí òkú ọmọ ọdún mẹ́fà tí wọ́n fipá bálopọ̀ nínú mọ́ṣálàáṣí ní Kaduna Ẹ dá àwọn ẹ̀ṣọ́ aláàbò igbákejì gómìnà ìpínlẹ̀ Ondo padà ní kíá - ọ̀gá àgbà iléeṣẹ́ ọlọ́pàá Awọn orilẹ-ede miran nilẹ Afrika to ti ṣilẹkun ile iwe rẹ.
Nígbà tí wọ́n rán an létí pé ìjọba àpapọ̀ mà ti gba àṣẹ ilé ẹjọ́ láti dá wọn lẹ́kun, ààrẹ NUPENG ní, à ń retí àṣẹ""."
Àwon àgbà a máa gba atẹ́gùn àláfíà sára.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Afárá 3rd Mainland: Ìjọba ṣí afárá lẹ́yìn àtúnṣe 25 Agẹmo 2018 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 26 Ògún 2018 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Iṣẹ́ àtúnṣe ti parí lórí afárá 3rd Mainland ní ìlú Eko Ijọba ipinlẹ Eko ti kede pe afárá 3rd Mainland si erekusu ile Eko ti wọn ti pa lalẹ Ọjọbọ ti di ṣiṣi bayii.
Iwadii naa to waye laarin obi ati alagbatọ ẹgbẹrun kan ni o ṣafihan pe ida mọkandinlaadọta obi ko faramọ lilo ẹrọ alagbeka ibanisọrọ nile iwe.
 Ó lọ ilé -ìwé alákọ ̀ ọ ́ bẹ ̀ rẹ ̀ ti ilé iṣé awórin-túnrin-rọ nípìnlẹ ́ delta , Ó tẹ ́ síwájú nípa lílọ ile-ìwé girama ti ilé -iṣẹ ́ ifọpo orilẹ-èdè nàìjíríà .
Ohun ni Aarẹ ọna kakanfo karundinlogun to jẹ.
Gege bi abajade ipade awon toro kan gbongbon nile ifowopamo agba, won se ifilole sise amulo owo China-yuan loju oja fun awon olokoowo, papaajulo lati tun maa samulo owo awon ile okere ti o kogun si eka Asia.
Awọn olorin a ni, 'aguntaṣọọlo, ọkunrin ogun' ati bẹẹbẹẹ lọ; ṣugbọn ki ni ami ohun ti ede Yoruba fi si ori ọrọ yii?
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Mike Tyson vs Roy Jones: Ìjà Mike Tyson pẹ̀lú Roy Jones Jr kò ní wáyé mọ́ lóṣù tó ń bọ̀- The Ring 10 Ògún 2020 Oríṣun àwòrán, Instagram/miketyson Ija laarin abẹṣẹ ku bi ojo to ti fẹyin ti, Mike Tyson ati Roy Jones ti di siso rọ bayii.
"Ọkùnrin kan pa ara rẹ̀ sínú ọgbà àjọ TRACE tó n mójútọ ìrìnnà ọkọ̀ nípìnlẹ̀ Ogun 'Orísúnmibáre ni àìsàn 'Polio' tó kọlù mí ní kékeré' John Blake wà ní ICU, ọlọ́pàá tó yìnbọn fún un bẹ̀rẹ̀ ìsinmi tipá tipá Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Bí ẹ ṣe mọ̀wé tó, ẹ wá dánrawò níbí pẹ̀lú ""Àpólà Ọ̀rọ̀ Orúkọ - Noun Phrase Koda, ọpọ awọn olugbe agbegbe yii ni wọn ti n fi ile wọn silẹ nitori iku ojiji to n pa wọn."
OLUWA dá mi lóhùn, ó ní: “Kọ ìran yìí sílẹ̀; kọ ọ́ sórí tabili kí ó hàn ketekete, kí ó lè rọrùn fún ẹni tí ń sáré lọ láti kà á.
O ni idi ni pe, Baalẹ ni Ataọja ilu Oṣogbo ati Akirun ti ilu Ikirun nigba iwaṣẹ ki alaafin to wa gbe ade le wọn lori ati pe ni gbogbo asiko naa, Ọba alade ni Oluwo.
"Iru ọmọ bẹẹ yoo lo ọjọ diẹ ko to lee ri baba rẹ""."
ti abala fifun awọn ẹṣọ lagbara lati maa fọwọ ṣinkun ofin mu awọn ọmọ
 àwọn ààmì farajọ ti ibà dengue .
Pierre-Emerick Aubameyang ni agbabọọlu kẹrin ni inu itan Arsenal ti yoo jẹ goolu meji ninu ifẹsẹwọnsẹ kan naa ni papa iṣire Wembley lẹyin Reg Lewis (aṣekagba FA Cup lọdun 1950), Charlie Nicholas (aṣekagba League Cup lọdu 1987) pẹlu Alexis Sanchez ni idije FA Cup lọdun 2015.
Wọ́n sin ín sinu ibojì òkúta tí ó gbẹ́ fúnrarẹ̀ ní ìlú Dafidi.
Mo ti tọ́jú ilé, mo sì ti pèsè ààyè sílẹ̀ fún àwọn ràkúnmí rẹ.
 O maa ngbami leti, to si tun fẹ pa mi.
Ọjọ kinni, oṣu Kẹrin ni isede naa kọkọ bẹ̀rẹ̀, ki gomina tun to o kede ọjọ mẹrinla miran.
Toyin Abraham gan an fun ra rẹ ko tii sọ ohun kan lori adehun igbeyawo naa, ṣugbọn olusakoso rẹ, Samuel Olatunji popularly ti ọpọ mọ si Bigsam lo fọrọ naa lede loju opo Instagram rẹ.
Ẹ má máa mójútó nǹkan ti ara yín nìkan, ṣugbọn ẹ máa mójútó nǹkan àwọn ẹlòmíràn náà.
Abẹwo ọmọ Naijiria si ilu yii yoo fun ẹni naa ni anfaani lati lo oṣu mẹfa lai gba iwe aṣẹ.
Àwọn ayaba ìbáà tó ọgọta,kí àwọn obinrin mìíràn sì tó ọgọrin,kí àwọn iranṣẹbinrin sì pọ̀, kí wọn má lóǹkà,
Ó kan sárá sí àwọn olùdìbò pàápàá àwọn ọ̀dọ́ pé wọn kò gbà kí wọ́n fi wọ́n ṣe jàndùkú sùgbọ́n tí wọ́n gba àláfíà láàyè lásìkò ìdìbò gómìnà tó kọjá.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Aisha Buhari: Afenifere, PDP, ajàfẹ́tọ̀ọ́ ẹni ni àgbà Buhari kò tolé 16 Ọ̀wàrà 2019 Oríṣun àwòrán, @aishambuhari Ọrọ ọhun bẹrẹ bii awẹwa nigba ti Fatima ọmọ Mamman Daura, gbe fidio kan sita, ninu eyi ti ohun iyawo aarẹ, Aisha Buhari ti n sọrọ lohun rara.
Ìgbà mìíràn ẹ̀wẹ̀, ìkùukùu náà yóo dúró lórí Àgọ́ Àjọ fún ọjọ́ bíi mélòó péré.
Ó fi yìnyín pa mààlúù wọn;ó sì sán ààrá pa agbo aguntan wọn.
 a lọ ́ mọdé ò mẹ ̀ là .
23 Ìgbé 2020 Fídíò, Nigeria movie industry: Àgbà òṣèré, Lere Paimo ní àìgbọràn ló ń da ọ̀pọ̀lọpọ̀ àwọn òṣèrè sinimá láàmú11 Ọ̀wàrà 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Tabi o mọ ìgbà tí wọ́n bímọ?
 Ìdí rèé tí àwọn ẹbí láṣòrè ṣe fi gbogbo ọ ̀ rọ ̀ tó kábíèsí létí nípa ìpinnu tí jìjì ṣe .
Covid 19 vacine updates: America kan sárá si Dókítà Ogbuagbu, ọmọ Nàìjíríà tó ṣàwárí abẹ́rẹ́ àjẹsára COVID-19 àkọ́kọ́
Ọkàn mi ń fà sí ìgbàlà rẹ, OLUWA;òfin rẹ sì ni inú dídùn mi.
" Yomi Fabiyi wa gbosuba fun ikọ alaanu ti Foluke Daramola da silẹ, to pe ni para, eyi to n ṣe itọju awọn alaini, pẹlu afikun pe, o seese ki abuku ta ba eeyan nidi ṣiṣe isẹ aanu amọ eyi ko yẹ ko da omi tutu si eeyan lọkan.
0 4 Orilẹede Vanuatu 0 0.
Ètò ìsìnkú Abba Kyari tako ìlànà ìjìnàsíraẹni lórí ààrùn covid-19- Àwọn ọmọ Nàìjíríà yarí Awuyewuye lórí nǹkan márùn ún tí ó níí ṣe pẹ̀lú Abba Kyari nígbà ayé rẹ̀ rèé Ọ maa n fi sọkan lati wa aaye to to lati boju to wọn pẹlu iwọn ounjẹ ti yoo yo wọn lasiko.
9ice fi èro rẹ han lori ọrọ yii.
Àjálù kì í dẹ̀yìn lẹ́yìn àwọn ẹlẹ́ṣẹ̀,ṣugbọn olódodo yóo máa rí ire.
OLUWA sì dáhùn pé, “Lọ sí Keila nítorí n óo fún ọ ní ìṣẹ́gun lórí àwọn ará Filistia.
Olajide ni oun ko ri iwe kankan gba pe ki oun lọ rọọkun nile lati ọdọ ẹgbẹ YCE, iroyin eke lasan si ni kede to ni wọn le oun kuro ninu igbimọ ẹgbẹ agbaagba Yoruba.
Ẹsan lo n ke lori Naijiria, eeyan tẹẹ pa ti pọ ju ni, ti ẹ fi ro pe Fulani nikan lo n pa eeyan""."
Nigba ti o n sọrọ nipa bi o ti ṣe ri owo, o ni oun ri iṣe to fi ri owo ni kete ti irin ajo ile iwe oun pari, oun si fi owo naa ra ile.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Giroud 100th cap: fi àràmọ̀ndà góòlù méjì ṣayẹyẹ ìfẹsẹ́wọnsẹ̀ ọgọ́rùn ún tó gbá fún France 8 Ọ̀wàrà 2020 Oríṣun àwòrán, Instagram/giroud918 Ọpọ olololufẹ ere boolu lo bu ẹnu ẹtẹ lu ẹlẹsẹ ayo, Olivier Giroud lẹyin to kuna lati gba goolu kankan sawọn fun ẹgbẹ agbabọọlu orilẹede Faranse ninu idije ife ẹyẹ agbaye lọdun 2018.
mo ile igbimo asoju-sofin lorile ede Naijiria , ti o tun je akowe igbimo to n
Nítorí náà, n óo bínú sí wọn; n óo fi ìrúnú pa wọ́n rẹ́, n óo sì gbẹ̀san ìwà wọn lára wọn.
Ọ̀kan ninu àwọn ẹrú Olórí Alufaa, tí ó jẹ́ ẹbí ẹni tí Peteru gé létí bi Peteru pé, “Ǹjẹ́ n kò rí ọ ninu ọgbà pẹlu rẹ̀?
Awuyewuye ati arinyanjiyan oriṣiriṣi lo si ti n waye lori awọn ti ẹgbẹ oṣelu APC, ṣẹṣẹ yan sipo adari ẹgbẹ.
Mimu ẹ̀jẹ̀ ejò máa ń fún ọkùnrin lágbára
Wọ́n bu oúnjẹ fún àwọn ọmọ wolii láti jẹ.
Ọṣun fi ara rẹ han gẹgẹ bii olu odo naa pẹlu ileri lati daabo bo wọn, ki o si mu awọn obinrin wọn maa bi sii bi wọn ba lee maa rubọ fun oun.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Àwọn wòòlí ń takora lórí ẹni tí yóò di ààrẹ láàrin Buhari àti Atiku 5 Sẹ́rẹ́ 2019 Àkọlé àwòrán, Guru Maharaj: Buhari ní yóò wolé nínú ìdìbò 2019 Olùdásílẹ̀ ìjọ One Love Family, Satguru Maharaj ní ààrẹ Muhammadu Buhari tó ń dije lábẹ àsía ẹgbẹ́ òṣèlú All Progressives Party (APC), ni yóò fidi alátako rẹ̀ Alhaji Atiku Abubakar, tó ń dije lábẹ́ égbẹ́ òṣèlú People's Democratic Party(PDP) janlẹ̀.
aye  sile fun obinrin naa lati
Pepsi náà dàbí èyí tí wọ́n ti ṣí sílẹ̀ látààná, kò tiẹ̀ ru rárá – ó kàn dà bí omi lásán.
Ogunlọgọ eniyan lo ti di alainile lori ni agbegbe Jibiya nipinle Katsina latari ìṣẹlẹ omíyalé ọjọ Aiku Oun ti oju wọn ri o kọja afẹnusọ.
Awọn olukopa to ba yege, yoo nilo lati fi ojulowo ẹdà awọn iwe ẹri wọn fun igbimọ to wa fun ẹkọ ọfẹ.
Ọba Aromọlaran wa bu ẹnu atẹ lu iwa awọn obi, awọn ile-iwe kan ati awọn oloye ilu kan ti wọn ki i kọbi ara si sisọ ati ẹkọ ede Yoruba.
Edo after election: Àwọn aṣòfín ní ìpínlẹ̀ Edo ti yọ Abẹnugan Ilé, Francis Okiye bí jìgá
”Jesu wá sọ fún àwọn eniyan pé, 
Ẹ dìde kí ẹ máa gbadura, kí ẹ má baà bọ́ sinu ìdánwò.
yiyan awon alakoso lorile ede yii sipo .
Ibi tí ó wó sí, náà ni ó sì kú sí.
Àrùn náà a má a wáyé ní ọ ̀ pọ ̀ lọpọ ̀ agbègbè káàkiri àgbáyé , a sì má a ran iye àwọn ènìyàn tó tó mílíọ ̀ nù kan .
Ọ̀pọ̀ ninu àwọn eniyan tẹ́ aṣọ wọn sọ́nà; àwọn mìíràn ya ẹ̀ka igi, wọ́n tẹ́ wọn sọ́nà.
"Bí ẹ ṣe mọ̀wé tó, ẹ wá dánrawò níbí pẹ̀lú ""Àpólà Ọ̀rọ̀ Orúkọ - Noun Phrase Èyí tí a wò jùlọ 5:03 Fídíò, Omolola Arohunmolase Welder: Mo ti fí iṣẹ́ 'Welder' gbayì láwùjọ, tó mo fi tọ́ ọmọ yanjú, Duration 5,039 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 5:39 Fídíò, Akomolede ati Asa lori BBC: Olùkọ́ Kikelomo Ogunboye tan ìmọ́lẹ̀ sí ìwà olè ọ̀gá ọlọ́pàá Audu gẹ́gẹ́ bí àwòkọ́ṣe àsìkò yìí, Duration 5,398 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 4:11 Fídíò, Oba Adeyeye Ogunwusi: Ojú mi ti rí lọ́pọ̀ lọpọ̀, ọ̀pọ̀ èèyàn ni kò tilẹ̀ gbàgbọ́ pé mo lè jọba- Ooni, Duration 4,117 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 4:43 Fídíò, Promise Akinlade: ọmọ ọdún mọ́kànlá tó ń fi ìlù dárà bíi àgbàlagbà sọ̀rọ̀ nípa tálẹ́ǹtì rẹ̀, Duration 4,437 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 0:59 Gbọ́, Ìsẹ̀lẹ̀ jákèjádò orílẹ̀èdè àgbáyé láàárín ìṣẹ́jú kan, Duration 0,59wákàtí 5 sẹ́yìn 7:03 Fídíò, Olumuyiwa Bolade Adedeji Military Bruitality: Bí arákùnrin onípèníjà ara tí sọ́jà lù ṣe dé, Duration 7,035 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 4:45 Fídíò, Yoruba Films: Ẹ̀ẹ́ bẹ̀ mi kúrò láyé ni, mi ò lè kú - Fadeyi Oloro, Duration 4,4526 Èrèlè 2020 2:48 Fídíò, Esther Ajayi: Èmi náà ti borí ìṣòro rí ló ń mu mi ṣojú àánú, Duration 2,481 Ògún 2019 6:08 Fídíò, Adebola Ademilua: Àìrísẹ́ ṣè lẹ́yìn ìwé kíkà ló sọ mi dí ìyá onírú, mo dúpẹ́ tèmi, Duration 6,0827 Bélú 2020 5:55 Fídíò, Soyinka Cancer: Àṣe ara mi ni iso ti n run gbogbo bí mo ṣe n ṣèrànwọ́ lórí jẹjẹrẹ, Duration 5,5527 Bélú 2019 BBC News, Yorùbá Ìdí tí ẹ fi le è nígbàagbọ́ nínú ìròyìn BBC Ìlànà Lílò Nípa BBC Òfin Àṣírí Cookies Kàn sí."
  Aye su mi, ọna mi daru, mo sọkun, ọkan mi poruru, mo ro pe ohun gbogbo ti tan fun mi.
Ẹ má gbàgbé láti tẹ̀lé mi lórí YouTube o, kí n lè mọ̀n dájú pé ẹ ń gbádùn mi.
Nígbà tí ó bá wa ní Asọsi, ó wọnú ọkọ̀ wa, a bá lọ sí Mitilene.
"Gbajugbaja ọdọ olorin Davido ni ""Mo duro pẹlu Allen Onyema."
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Rev Fr Ejike Mbaka: Ìfọ̀rọ̀wánilẹ́nuwò ní BBC bá dé ọ̀dọ̀ òjíṣẹ́ Ọlọ́run, ìyà ló fi pàdé wọn 10 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Oríṣun àwòrán, Facebook/Adoration Ministry Enugu Nigeria Gbajugbaja ojisẹ Ọlọrun kan ninu ijọ Aguda katoliki, Fada Ejike Mbaka atawọn ọmọ ijọ rẹ kan kọlu awọn akọroyin BBC meji ati awakọ wọn nilu Enugu.
Lati ibẹrẹ iṣẹ rẹ ninu ajọ EFCC si ni awuyewuye ti n waye nipa rẹ.
Oríṣun àwòrán, SERAP Wọ́n ni ó ṣe pàtàkì kí ó fi àwọn aláíní àti tálákà ṣe àkọ́ka nínú ìpnu rẹ̀ ni àsìkò yìí.
Ileewe alakọbẹrẹ Subuola Memorial Nursery and Primary School ati ileewe girama Loyola College ni ilu Ibadan ni o lọ ki o to lọ gba oye ijinlẹ HND ninu imọ iṣiro owo nile ẹkọ gbogbounṣe, the Polytechnic, Ibadan.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Elephants Death: Erin mẹ́fa d'olóògbé níbi tí wọ́n ti fẹ́ dóòlà ẹ̀mí ara wọn 2 Ọ̀pẹ̀̀ 2019 Oríṣun àwòrán, Khao Yai National Park Àkọlé àwòrán, Erin mẹ́fa d'olóògbé níbi tí wọ́n ti fẹ́ dóòlà ẹ̀mí ara wọn Erin mẹfa ṣagbako iku lorilẹ-ede Thailand nibi ti wọn ti n gbiyanju lati doola ẹmi ara wọn.
Èmi fúnra mi ni n óo fà wọ́n ya pẹ́rẹpẹ̀rẹ, n óo sì kúrò níbẹ̀.
"Mẹtẹẹta jade pọ lẹkan naa ni okiki mi ṣe burẹkẹ lọdun naa.
Ènìyàn 26,000 ni àìsàn jẹjẹrẹ ń pa lóòjọ́ O ni ijọba oun ṣe eleyi nipa agbekalẹ eto ilera fun mutu-muwa eyun-un ni, Osun Health Insurance Scheme (OHIS).
Wo àlàyé bí Inec yóò se náwó nínú ìbò 2019 Tinubu: Ọbasanjọ kò lè yan olùdíje fún wa Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí kan sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
Bẹ́ẹ̀ ni Kristi ń ṣe sí ìjọ.
Salawa lo sọ ọrọ yii ninu ifọrọwerọ kan pẹlu BBC.
ti won yan si tabi ile-ise re fi lu awon ara ilu ni jibiti bi o
Ìyá rẹ̀ sọ fún àwọn iranṣẹ pé, “Ẹ ṣe ohunkohun tí ó bá wí fun yín.
Yomi Akintola tun fi igba kan jẹ aṣoju ijọba orilẹ-ede Naijiria ni Hungary, bakan naa ni iyawo ọmọ rẹ kan, Dupe Akintola jẹ aṣoju ijọba Naijiria ni Jamaica.
Coronavirus: Ushbebe, adẹ́rínpòṣónú ní bí ìjọba ṣe fòfin de ìrìnàjò wọlé láti ilẹ̀ òkèrè mú òun pàdánù owó l
Oríṣun àwòrán, Nimc Oríṣun àwòrán, Nimc Bakan naa ni ko yọ ajọ eleto idibo, INEC silẹ.
O ni awọn a maa na ẹgbẹrun lọna ọgọrun un kan si ẹẹdẹgbeta ẹgbẹrun si miliọnu kan naira lori alaisan kọọkan ni eyi to ni i ṣe pẹlu bi Covid 19 ba ti ṣe ṣọṣẹ to lara alaisan bẹẹ.
Fi atọ́ka sí oríta níbi tí ọ̀nà ti yà wọ ìlú.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Afenifere: Ìgbà wo ni Bola Tinubu di ọmọ ẹgbẹ Afenifere?
 idi niyi ti a fi n pe agẹrẹ ni ìlù ogun .
Ẹnìkan tí ó dàbí ọmọ eniyan jókòó lórí ìkùukùu náà.
Ọkunrin naa sọ fun BBC pe wọn fi tipa tikuku gbe oun kuro nile oun lọ si ile iwosan nitori ibẹru pe awọn alawọ dudu lee ko arun naa ran awọn ọmọ ilẹ China.
Dino Melaye ni Sẹnẹtọ to n ṣoju Kabba/Bunu/Ijumu ni iwọ orun ipinlẹ Kogi ni ile aṣofin agba lọwọlọwọ.
Orilẹede Canada si ni orilẹede keji to tu okun ofin lọrun Kukuye lẹyin ti orilẹ-ede Uruguay ti se bẹẹ.
Nígbà tí àwọn alufaa tí wọ́n gbé Àpótí Majẹmu OLUWA jáde kúrò ninu odò Jọdani, bí wọ́n ti ń gbé ẹsẹ̀ lé ilẹ̀ gbígbẹ, ni omi odò náà pada sí ààyè rẹ̀.
Àwọn òṣèré, olórin Yorùbá gbàdúrà fún MC Oluomo
Ẹyẹ òwìwí yóo máa dún lójú fèrèsé, ẹyẹ ìwò yóo máa ké ní ibi ìpakà wọn tí yóo dahoro; igi kedari rẹ̀ yóo sì ṣòfò.
Ọsan naa ni eroja Vitamin C ni ara.
Eyi waye lẹyin ti awọn gomina ipinlẹ mẹrindinlogoji pa ẹnu pọ wi pe, awọn ko ni lee san ẹgbẹrun mejidinlogun gẹgẹbi owo osu osisẹ to kere julọ losoosu.
Ipinlẹ Eko, Aṣofin Moshood Ọshun sọ pe atunṣe si ofin yii ṣe pataki  nitori pe awọn aṣagbeyẹwo iṣuna owo yii ni
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Nigeria border closure: Ìdí tí Ààrẹ Buhari kò ṣe tíì ṣí ibodè tó tì pa rèé 24 Èrèlè 2020 Oríṣun àwòrán, @alabiopeyemiola Àkọlé àwòrán, Buhari parọwa si awọn orilẹ-ede ti ọrọ naa kan lati ni suuru Aarẹ Muhammadu Buhari ti sọ pe oun n duro de esi igbimọ to n ri si ọrọ ibode to di titi pa, eyi ni Tripartite Committee"" ko to gbe igbeṣẹ to kan lori ibode ọhun."
 1x Magazine BandollierOgagun agba ti iko  keje ti ekun naa  Abdulmalik Bulama Biu  wa ro iko omo ogun orile ede yii lati tubọ maa
Gẹgẹ bi igbakeji oludari ibudo naa ti sọ fun BBC, awọn inaki naa ni wọn kọ lati maa sin awọn eeyan to n tọju wọn jẹ, lati igba ti wọn ti ri wọn he, ti wọn yoo si duro bii eeyan lati ya fọto.
Ààrẹ fi nǹkan ọkùnrin rẹ̀ pa mí lójú, kó tó fipá bámi lòpọ̀ - Ọmọge Arẹwà Panumọ́, yé parọ́, ₦15m ni Sẹ́nétọ̀ kan ń gbà lówó oṣù - Itsey Sagay sí Lawan Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Obiaku fikun pe, igbimọ oludari ajọ to n gbogun ti iwa ipa ninu ile ti n jiroro lori bi asoju awọn naa, Oreoluwa, yoo se maa waasu fun awọn eeyan, lati maa fi ara balẹ, tii calm Down.
Èèyàn mẹ́tàdínláàdọ́fà ló móríbọ́ lọ́wọ́ Covid-19, 443 míì tún lùgbàdì rẹ̀ lọ́jọ́ Ẹtì Èèyàn 16 kú lẹ́yìn tí bàálù Air India já lulẹ̀ , tó sì kán sí méjì ní Kerala Ilé ẹjọ́ ti dájọ́ Naira Marley, wọ́n ní kó san owó ìtànràn, kó tún tọrọ àforíjì Ẹwẹ, baba ọmọ naa to doloogbe bere pe ki ileeṣẹ ọhun pese fidio ti ẹrọ ayaworan CCTV to n ka ohun ti awọn eeyan n ṣe ni ileeṣẹ naa ki ọrọ lede.
Lóòtọ́ ni ọkọ mi lù mí bí àṣọ òfì, àmọ́ gómìnà ti bá wa parí ẹ̀, ẹ máa gbàdúrà fún ìdílé mi- Dokita Ifeyinwa Mi ò kí n ṣe afẹfẹ-yẹ̀yẹ̀ lórí ayélujára nítorí pé mí ò ní dúkìá tí mó le fihàn- Ronke Oshodi-Oke Àwọn èèyàn tí bẹ̀rẹ̀ sì ní gba abẹ́rẹ́ àjẹsára fún ìdènà àrùn Coronavirus ni ilẹ̀ Gẹ̀ẹ́sì Ohun tó yẹ kí o mọ̀ nípa ìgbésẹ̀ tí Amẹ́ríkà fẹ́ gbé lórí Nàìjíríà nítorí ọ̀rọ̀ ẹ̀sìn Ologbodiyan ni igbesẹ t wọn gbe yii ti wọ inu iwe itan lọ paapaa bi PDP ṣe ni awọn araalu n ṣajọyọ lẹyin ti wọn gbọ pe ẹgbẹ to ti n ko idamu ba wọn tuka.
O ni ilu London ni ẹni akọkọ to ni arun ọhun ni Osun ti wa, ṣugbọn ara rẹ ti da ṣaka bayii lẹyin to lo ọjọ mejidinlogoji nibi to ti gba itọju.
Pásítọ̀ Adeboye kéde ààwẹ̀ ọjọ́ 63 fọ́mọ ìjọ rẹ̀, ariwo sọ lórí ayélujára Ìwádìí BBC rèé lórí ìjà APC tó fẹ́ gbẹ̀mí Sẹ́nátọ̀ l‘Osun Ìlú tuntun tó kún fún ohun àdáyébá láìsí ọkọ̀ tàbí òpópónà ń bọ̀ ní Saudi Arabia Kí ló ń pa ẹbí Orisabunmi lọkọ́ọ̀kàn, àkúfà ni àbí àmúwá Ọlọ́run?
Wọ́n sì dáhùn pé, “A óo dá gbogbo rẹ̀ pada, a kò sì ní gba nǹkankan lọ́wọ́ wọn mọ́.
Àwọn mìíràn gba ohun tí ó sọ gbọ́, ṣugbọn àwọn mìíràn kò gbàgbọ́.
Ẹ máa fi wọ́n ṣe ọ̀rọ̀ sọ nígbà tí ẹ bá jókòó ninu ilé yín, ati nígbà tí ẹ bá ń rìn lọ lójú ọ̀nà, ati nígbà tí ẹ bá dùbúlẹ̀, ati nígbà tí ẹ bá dìde.
Amasaya pe àwọn eniyan Juda ati Bẹnjamini jọ, ó pín wọn sábẹ́ àwọn ọ̀gágun ní ẹgbẹẹgbẹrun ati ọgọọgọrun-un gẹ́gẹ́ bí ilé baba wọn.
SWAT: Ìpínlẹ̀ Osun àti Nasarawa ni ẹ̀kọ́ ìgbáradì SWAT ti n wáyé
Ewe, ni idahun si ibere won lati lo
lori isẹlẹ naa” lati mu eto aabo ni ọkunkundun ni ekun
A ti wádìí àwọn nǹkan wọnyi,òtítọ́ ni wọ́n.
Nibayii, o ti di osisẹ eleto ilera mẹfa lo ti lugbadi aarun yii kaakiri awọn ipinlẹ ipinlẹ mẹfa-Ebonyi, Benue, Nasarawa, Kogi, Ondo ati Edo.
South Africa ló kọ́kọ́ pàsẹ kónílé-ó-gbélé to le jùlọ ni oṣù kẹta ọdún yìí.
Naijiria, awon emewa re ati awon oloselu akegbe re lalejo.
’ rèé Ẹ̀yin èèyàn Oyo, ẹ sọ tẹnu yín lórí àbá àjẹbánu tí Makinde dá - SERAP Bakan naa la gbọ pe ileeṣẹ ọlọpaa ti ran awọn ikọ kogberegbe ọga ọlọpaa tẹlẹ wọn.
Ijoba orile ede Naijria ti ni
Nítorí náà, n óo jẹ yín níyà, ẹ̀yin ọmọ Israẹli; nítorí irú ìyà tí n óo fi jẹ yín, ẹ múra sílẹ̀ de ìdájọ́ Ọlọrun yín, ẹ̀yin ọmọ Israẹli!
Gẹgẹ bi ohun ti a ri akọsilẹ rẹ, ọmọọba Adewale Oyekan fun Lateef Bello, tii se ọmọ ọdọ Alhaja Edun ni ẹgbẹrun lọna ọgọta Naira.
Isẹlẹ yi ni o tẹle ọpọlọpọ iwa ipa laaarin Fulani darandaran ati agbẹ lagbegbe guusu iwọ-oorun Naijiria.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Enìyàn mẹ́ta kú nínú ìjàmbá ọkọ̀ ní'lù Abuja 7 Owewe 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Kíló fa tí ọkunrin yìí fi gbẹ̀mi ènìyàn mẹ́ta tó si sálọ O kéré tán ènìyàn mẹ́ta ló ti jẹ́ Ọlọrun nípe tí àwọn mẹ́ta míràn sí ní oníruuru ìpalára nígbà ti àwa kọ Mercedes Benz funfun kan lọ sorí mọ́ 4matic àti kẹ̀kẹ́ Maruwa méjì míràn ní agbègbè Gwarimpa nílùú Abuja.
" Oluomo tun sisọ loju rẹ pe, ko si ẹnikẹni to kọ oun ni ọkọ wiwa, oun kan n sun ọkọ siwaju diẹ-diẹ ni ori tọọnu ni gareeji bii kọndọ, ni oun fi mọ ọkọ wa.
Dájúdájú n óo san ẹ̀san fún wọn,n óo sì bá wọn dá majẹmu ayérayé.
Ẹ gbọ́ arábìnrin Adéoyè síwajú síi: Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fọ́nrán ohùn, Àjọ onísirò Nàíjíríà: Àdínkù bá owó ọjà si ìdá mẹ́tàlá Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Èèyàn 587 ló lùgbàdì àrùn Coronavirus ní Naijiria ní Ọjọ́rú Báyìí ni orin ìsìn ìkẹyin olóògbé Ibiduni Ighodalo ṣe lọ Ohun tí a mọ̀ nìyí nípa ìdí tí Victor Giadom fi gbà'jọba ẹgbẹ́ òṣèlú APC Báyìí ni orin ìsìn ìkẹyin olóògbé Ibiduni Ighodalo ṣe lọ Ki ni hun to ṣẹlẹ gan?
” Ahabu, ọba Israẹli, bá paradà, ó sì lọ sójú ogun.
Justice Osei le dún bíi ẹranko 50
Ìwọ̀n òróró gbọdọ̀ péye gẹ́gẹ́ bí ìlànà; ìdámẹ́wàá ìwọ̀n bati mẹ́wàá ni òṣùnwọ̀n bati kan ninu òṣùnwọ̀n kori kọ̀ọ̀kan òṣùnwọ̀n kori gẹ́gẹ́ bíi ti homeri.
6 10494 Orilẹede Uruguay 280 8.
Aare wa ni ipinle Eko lojoRu lati
oludije fun ipo aare satileyin fun oludije fun ipo aare fun egbe PDP ati APC.
Iko agbaboolu Italy ti wa lai si akonimoogba Kankan ti o n tuko iko ohun lati osu melo kan seyin, eyi ti iko ohun ti gba ise lowo Gian Piero Ventura latari aise deede iko ona, ti iko ohun ko si tun pegede fun ife eye idije agbaye to n bo lona yiiAncelotti, ti o je akonimoogba iko agbaboolu Bayern Munich tele ri, se ipade po pelu awon osise ajo to n ri si boolu afesegba orile-ede Italy ni Rome lose ti o koja.
Mò ń kọ ìwé yìí sí Titu, ọmọ mi tòótọ́ ninu ẹ̀sìn igbagbọ kan náà.
 Egbe osise ile igbimo asofin (National Assembly under the auspice of Parliamentary Staff Association of Nigeria, PASAN ) kọ lati je ki awon adari ile igbimo asofin jokoo fun ipade won, nigba ti won n fehonu han lori ajemonu owo , igbega lenu ise ati ẹkọ to ye ki awon osise yii leto si , ni eyi ti o wa ninu iwe ofin , ti won fowo si.
Bí ọmọdé bá máa ránṣẹ́, a rán àgbàlagbà ní iṣẹ́, bí ọmọdé àti àgbàlagbà bá jẹun tán, àgbà ni ń fọ àwọ.
0 85 Orilẹede Grenada 0 0.
Idi ree to fi n lọgun tantan tan pe, ọmọ ẹgbẹ ọlọkọ ero kankan abi ẹnikẹni to ba gbero lati fa wahala lẹsẹ lasiko ayẹyẹ ibura oun sipo gomina, eyi ti yoo waye lọjọru, yoo jẹ iyan rẹ nisu.
Wòlíì náà ti fi ibùgbé rẹ̀ kalẹ̀ sí ilé Peter Whitmer Àgbà, níbẹ̀ ni ó ngbé títí tí iṣẹ́ ìtumọ̀ ìwé náà fi dé ìparí àti tí wọ́n fi gba àṣẹ láti tẹ ìwé tí ó nbọ̀ náà sí ìta.
“Èmi OLUWA ti fi ìwọ Sefanaya jẹ alufaa dípò Jehoiada tí ó jẹ́ alufaa tẹ́lẹ̀ rí, ati pé mo ní kí o máa ṣe alabojuto gbogbo àwọn wèrè tí wọn ń sọ àsọtẹ́lẹ̀ ní ilé èmi OLUWA, kí o sì máa kan ààbà mọ́ wọn ní ẹsẹ̀, kí o máa fi okùn sí wọn lọ́rùn.
Ninu eto idibo kan ti ileeṣẹ iroyin ere idaraya BBC Sport gbe kalẹ lori bi o ṣe yẹ ki wọn pari idije liigi, ida mọkandinlogoji ninu awọn to dibo naa fẹ ki wọn wọgile saa liigi yii, ida mejidinlọgbọn ninu ọgọrun fẹ ki wọn pari rẹ bi o ti wu ko pẹ to.
Nítorí náà, ọba Israẹli pèsè oúnjẹ fún wọn lọpọlọpọ.
Àwọn tí wọ́n fi èrò wọn pamọ́ fún OLUWA gbé;àwọn tí iṣẹ́ wọn jẹ́ iṣẹ́ òkùnkùn,tí ń wí pé, “Ta ló rí wa?
Ọmọ Ààrẹ lẹ́tọ̀ọ́ láti ṣe ìgbéyàwó yálà àwọn ará ìlú fẹ́ràn ìjọba bàbá rẹ̀ tàbí bẹ́ẹ̀ kọ́ - Aisha Buhari Ǹjẹ́ ọmọ Buhari lásẹ láti wọ Ọkọ̀ òfúrufú Nigeria Air force lọ sí òde?
Sagir Musa, se sọ, pe  lasiko ikọlu naa mẹ́tàdínlọ́gbọ̀n  awon iko olote Boko Haram ni won pa , ti wọn si gba awon ohun elo ija ogun wọnyi lọwọ
Balogun ni bi aago mọkanla aabọ alẹ ni ọkunrin ọun wa sile awọn to si yinbọn lẹẹmẹta, o ni oun gan an ni ọkunrin naa wa wa ṣugbọn o ṣe ijamba fọmọ oun nigba ti ko ri oun.
Eeyan to ti ni aarun coronavirus l'orilẹ-ede Naijiria ti pe ẹgbẹrun mẹjọ ati mejidinlaadọrin bayii.
Awọn alẹnulọrọ ns'ọrọ loridasilẹ ileesẹ ọlọpa agbegbe Ọsinbajo pe fun ọlọpa agbegbe Lẹyin ọpọ ijiroro lori ọrọ ọhun ni ile wa fi ẹnu ko wipe ki ijọba apapọ o pasẹ fun ileesẹ ọmọogun ofurufu lati lo anfani fifo loju ofurufu lati fi se awari ibuba awọn agbebọn to kun igbo nla kaakiri ki wọn si le wọn jade.
Ọmọba ilẹ̀ Gẹ̀ẹ́sì náà, Charles ti ní àrùn coronavirus Àyẹ̀wò ti fihàn pé Yemi Osinbajo kò ní coronavirus, ṣáká lara baba dá Coronavirus- Atọ́nà bí nkàn ṣe ń lọ ní Afirika Coronavirus: Wo ohun tí o ní láti ṣe láti dáàbò bo ara rẹ Ofin tuntun yi ni ijọba Australia sọ pe yoo bẹrẹ lati ago kan ọsan, ọjọ karundinlogun, oṣu kẹta, ọdun 2020 lẹyin ti iye awọn eeyan to ni aarun Coronavirus n peleke sii.
Omi díámọ́ṅdì la fi kọ orúkọ tọkọtaya sí ìgbèrí ibùsùn náà.
Nigba to si jẹ pe saa keje lo fẹ se bayii lori aleefa, o yẹ kẹ mọ awọn ohun meje nipa aarẹ Biya, ti orilẹ-ede Cameroon naa.
Àdó okoró búrẹ́kẹ' Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Gbajugbaja oṣere sinima ede oyinbo ati igbo ni Naijiria, Mike Ezuruonye lo bọ sori ayelujara lati ko bilala ọrọ fun Kunle Afọnlayan.
maa ṣọra ni gbogbo igba, ki a le maa ṣọ awọn iwa buruku, ti a le o fi tete
Bákan nàá ni Olorì Memunat Omowumi Adeyẹmi tó bí ìbejì ọmọbìnrin méjì nínú oṣù Kẹta bákan nàá.
Aarẹ ilẹ Ireland tẹlẹri, Mary Robinson to fi mọ agbẹjọrọ agba lorilẹede Gambia, Hassan Jallow ati Leonard McCarthy to jẹ igbakeji aarẹ Banki apapọ lagbaye, wa lara igbimọ to ṣe iwadii Adesina finifini.
Children's Day: Àwọn ọmọdé tó ń ṣe bẹbẹ láwùjọ Afíríkà Ààrẹ Muhammadu Buhari buwọ́lu owó ìṣúná ọdún 2019 Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Afeez Agoro: O ṣòro fún mi láti wọ Danfo jáde Muazu ṣalaye pe awọn ajinigbe naa sọ fun awọn pe awọn kan to wa ni ipo pataki n lọwọ si awọn ijinigbe to n waye ni Naijiria.
Igboho tun gbosuba fun gomina Seyi Makinde ati Iba tilu Kishi fun aayan wọ̀n lati fi ẹsẹ eto aabo mulẹ lagbagbe naa.
Sibẹsibẹ nígbà tí wọ́n bá wà ní ilẹ̀ àwọn ọ̀tá wọn, n kò ní ṣàì náání wọn; bẹ́ẹ̀ ni n kò ní kórìíra wọn débi pé kí n pa wọ́n run patapata, kí n sì yẹ majẹmu mi pẹlu wọn, nítorí èmi ni OLUWA Ọlọrun wọn.
Oríṣun àwòrán, Seyi makinde Coronavirus in Nigeria: Seyi Makinde, gómìnà ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́ ní ìpàdé ètò ọrọ̀ aje Nàìjíríà lòun ti kó àrùn COVID-19 Ni ọjọ aje ni gomina ipinlẹ Ọyọ, Ṣeyi Makinde kede rẹ faye gbọ pe oun naa ti dara pọ mọ iye awọn to ti ko arun Coronavirus lorilẹede Naijiria.
Farao bá yára pe Mose ati Aaroni, ó ní, “Mo ti ṣẹ̀ sí OLUWA Ọlọrun yín ati sí ẹ̀yin pàápàá.
Eid el Kabir: Ọjọ́ márùn-ún ló ṣe kókó nínú iṣẹ́ Hajj
nítorí ó ń sọ ninu ọkàn rẹ̀ pé, “Bí mo bá sá ti lè fi ọwọ́ kan etí aṣọ rẹ̀, ara mi yóo dá.
 ) ( take the right fork .
“Bí ẹnikẹ́ni bá ń tàn ọ́ níkọ̀kọ̀ pé kí o lọ bọ oriṣa-koriṣa kan, tí ìwọ tabi àwọn baba rẹ kò bọ rí, olúwarẹ̀ kì báà jẹ́ arakunrin rẹ, tíí ṣe ọmọ ìyá rẹ, tabi ọmọ rẹ, lọkunrin tabi lobinrin, tabi aya rẹ, tí ó dàbí ẹyin ojú rẹ, tabi ọ̀rẹ́ rẹ tí o fẹ́ràn ju ẹ̀mí ara rẹ lọ; 
'Eyi ni bi àgbàrá omíyalé sẹ ru ìyàwó mi lọ' ‘A ó ran àwọn tó lùgbàdì omíyalé ìpínlẹ̀ Kogi lọ́wọ́’ Ẹ̀kún omi gbé ọmọ oṣù mẹ́ta lọ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Olusegun Obasanjo: Ọmú ìyá mi ti mo fi ń mùkọ ni kekere ló jẹ ki ń lókun Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Dangote-BRT Accident: Lasema ní ìjánu ọkọ̀ Dangote tó já ló fa ìjàǹbá náà 27 Ògún 2019 Oríṣun àwòrán, Lasema Àkọlé àwòrán, Gẹ́gẹ́ bi olùdari LASEMA Osanyintolu Oke ṣe sọ pé kò sí ẹni ti kò farapa nínú ọkọ náà àfi ọmọbinrin kan ló pàdánu ẹmi rẹ̀.
Leyin eto idibo ni akowe ile
Àwọn tí wọn ń lépa wa yáraju idì tí ń fò lójú ọ̀run lọ.
Wolves bu Arsenal jẹ bí ajá Tẹrin tọyaya ni gbogbo awọn oloye to atawọn ara ilu ni Kano fi n ki Mike.
Ọpọ ko tilẹ beere ohun ti o mu ki Aisha Buhari ke gbajare si ọga ọlọpaa.
NAF LAUNCHES OPERATION THUNDER STRIKE 2 AGAINST BOKO HARAM INSURGENTS, RECORDS SUCCESSFUL STRIKES IN BORNO STATEhttps://t.
Rochas ni senetọ to n ṣoju iwọ oorun ipinlẹ Imo bayii nile igbimọ ijokoo kẹsan an.
Bi o si jẹ ti IPPIS naa ni, ko ṣa ti faye gba owo ajẹmọnu wa.
Wọ́n gbógun tì mí gidigidi, tóbẹ́ẹ̀ tí mo fẹ́rẹ̀ ṣubú,ṣugbọn OLUWA ràn mí lọ́wọ́.
Covid-19 second wave: ''Ìjọba kò tíì pàṣẹ ìlànà ìtakété-síra-ẹni padà nínú BRT la ò ṣe tíì ma tẹ̀le''
Oríṣun àwòrán, @A_Oshiomhole Amọṣa, aarẹ ile aṣofin agba ti fa lẹta naa le igbimọ tẹẹkoto lori ọrọ gbese abẹle ati toke okun fun amojuto to ba yẹ ki o si jiṣẹ pada fun ile naa ni ọsẹ meji.
 Nígbà tó ń sọ̀rọ̀ lórí owoya bilionu lọ́nà ẹgbẹ̀rin àti àbọ̀ náírà tí ìjọba Nàìjíríà ṣẹ̀ṣẹ̀ yá, Ajibola ni irọ tó jinna sooto ni èyí."
Baalu aare bale si papa ofurufu aare to wa niluu Abuja ni deede aago 16:40 GMT.
Orí Joabu ati ìdílé baba rẹ̀ ni ẹ̀bi ìjìyà ikú yìí yóo dà lé.
Ó súre fún ẹ̀yà Josẹfu pé:“Kí OLUWA rọ òjò ibukun sórí ilẹ̀ wọn,kí ó sì bu omi rin ín láti abẹ́ ilẹ̀ wá.
Wò ó, eniyan burúkú lóyún ibi, ó lóyún ìkà, ó sì bí èké.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Lockdown updates: Naira Marley gbóríyìn fún Jude Chukwuka pẹ̀lú #1 míliọnù Funtua jẹ ojulowo oniṣowo ni igba aye rẹ, ti o si ṣiṣẹ ijọba fun ọgbọn ọdun O ṣiṣẹ gẹgẹ bi adari ni ileeṣẹ ijọba ti National Institute of Policy and Strategic Studies (NIPSS), Kuru.
Ṣugbọn alukoro DSS ti sọ pe ayederu iroyin ni gbogbo ẹ.
ó sì rẹ ara rẹ̀ sílẹ̀ níwájú OLUWA, ó fa aṣọ rẹ̀ ya ó sì sun ẹkún nígbà tí ó gbọ́ ìlérí ìjìyà tí mo ṣe nípa Jerusalẹmu ati àwọn eniyan ibẹ̀, pé n óo sọ Jerusalẹmu di ahoro ati ibi tí àwọn eniyan yóo máa lo orúkọ rẹ̀ láti gégùn-ún.
World Breastfeeding Week: Fífún ọmọ lọ̀yan kìí wá lásán, ó nílò ìdánilẹ́kọ̀ọ́
Kò sí àmì kan tí a óo fún un àfi àmì Jona.
Àwọn aṣofin mẹrindinlogun naa ni wọn da duro ni oṣu kẹfa ọdun 2018 nigba iṣejọba gomina ana, Ayo Fayose.
Abubakar kọ ààdọ́jọ mílíọ̀nù náírà, owó àbẹ̀tẹ́lẹ̀ ti olóògùn fàyàwọ́ kan fi lọ̀ọ́, láti gbé òògùn ogoji ọkọ ajagbé tó kún fún Tramadol wọle.
Èyí ju ọ̀pọ̀ ọmọ Naijiria , àjọ NFF, LMC, ẹbi, ọ̀rẹ àti àwọn ọmọ ẹgbẹ àgbá bọọlu jákejádo Naijira sínú ọ̀fọ̀.
Eric Trump to je omo Aare Trump fi atejade sita pe: Ölopolo pipe ni Brad ni eyi ti a ko le sai menuba fun aseyori wa ni 2016.
Asiko kan naa ni ọwọ tun tẹ ọmọdekunrin kan ni ilu Benin ni Ipinlẹ̀ Edo, ti wọn fi ẹsun kan pe o lọ ji pata awọn obinrin ka lori okùn.
Se ni o ta kan de ibi ti ina naa ti n jo lẹyin to fagile eto ọrọ to gbero lati ba awọn ọmọ orilẹ-ede naa sọ lonii.
Josaya bá pàṣẹ fún Hilikaya olórí alufaa, ati àwọn alufaa yòókù ati àwọn tí wọn ń ṣọ́ ẹnu ọ̀nà ilé OLUWA, pé kí wọ́n kó gbogbo ohun èlò ìsìn oriṣa Baali, ati ti oriṣa Aṣera, ati ti àwọn ìràwọ̀ jáde.
Prophecy 2020: Primate Ayodele, Baba Adeboye àti Father Mbaka sọ àsọtẹ́lẹ̀ nípa 2020!
"Oríṣun àwòrán, MICHELE SPATARI/AFP/GETTY Àkọlé àwòrán, Ija ti awọn ọmọ South Afrika gbe koju awọn ọmọ Naijiria ti la ọpọ ẹmi ati dukia lọ ""A kò ní ra ọjà South Africa mọ́, a ó gbẹ̀san oró tí wọn ń dá wa - Ọmọ Nàíjíríà fárígá"" Igi gogoro ma gun mi loju, ati okeere la tii wo o, o wa to asiko bayi ki ijọba Naijiria wa wọrọkọ fi ṣada lori ọrọ ikọlu South Afrika sawọn ọmọ Naijiria to n di lemọlemọ bayii."
 o si tun kowe nipa kriketi .
Wọn ni ti obinrin ba tin-in-rin ju bi o ṣe yẹ lọ, o le bi ọmọ ti ko tobi, ti oṣu rẹ ko pe, tabi ki ọmọ naa o ma a ni gìrì ni ìkókó.
" Oríṣun àwòrán, @sanwoolu Bakan naa ni Akọwe ijọba ilẹ America nigba kan, Hilary Clinton ti kesi Aarẹ Muhammadu Buhari, ati ileesẹ ologun Naijiria lati fi opin si pipa awọn ọdọ to ṣe iwọde #ENDSARS.
“Nígbà tó bá tó àkókò, n óo rán àwọn ikọ̀ ninu ọkọ̀ ojú omi, wọn ó lọ dẹ́rù ba àwọn ará Etiopia tí wọn ń gbé láìfura.
Àkójọpọ̀ àwòrán láti àpéjẹ ìdúpẹ́ Aisha Buhari Ìjọba pàṣán ni ìjọba Buhari yóò jẹ́ fún Nàìjíríà ní sáà kejì- Ṣoworẹ Ọjọ́ Àbámẹ́ta la ó mọ ẹni tí yóò lékè láàrín bàbá ìsàlẹ̀ àti àwọn mẹ̀kúnnù nipinlẹ̀ Ọyọ.
O ni ohun ribiribi ti Oloye ṣe si ipinlẹ Kwara ati orilẹede Naijiria lapaapọ ju ki wọn maa gba ilẹ rẹ lọ.
 Èdè yorùbá náà jẹ èdè nìjẹ ̀ r-kóńgò tó ní olùbánisọ ̀ rọ ̀ ìbílẹ ̀ tó pọ ̀ jù .
Omi yóo máa ṣàn jáde láti orí gbogbo òkè gíga ati gbogbo òkè ńlá, ní ọjọ́ tí ọpọlọpọ yóo kú, nígbà tí ilé ìṣọ́ bá wó lulẹ̀.
 ìtumọ ̀ èyí ni wí pé bí ifá bá fẹ ́ ẹ ́ ṣe nǹkan lile ti ó rí bí idan , àṣẹ Èṣù ló ní láti lò .
naa ni orile ede Naijiria tun n fi asiko naa ki awon to farapa pe ,ki Ọlọrun
Ẹwẹ, ni Naijiria ajọ NCDC kede eeyan ọọdurun le mẹrinlelaadọta to ti fori ko ajakalẹ arun naa lọjọbọ.
Ati adun ati ipenija oṣelu ni Bouteflika yago fun lẹyin gbogbo ẹsun ti wọn fi kan an nigba to n dari ile iṣẹ to n ri si ọrọ ilẹ okere lo ba na papa bora kuro ni Algeria ldun 1983 ti ibi to wa si ru ni loju.
Idi ree ti BBC Yoruba fi gbe igbimọ kan kalẹ ninu eyi ta ti ri awọn musulumi ati Kristiẹni, ti wọn ti jiroro nipa awọn adun to wa ninu ọdun Ileya.
Bí a bá sì kú, Oluwa ni a kú fún.
Pẹ̀lú abẹ̀rẹ̀ àjẹsára yìí, ẹ̀fọn kankan kò lè mú àìsàn ibà wá Lasiko to n se ifilọlẹ iwe rẹ ti oun ati oloogbe Dokita Bala Usman kọ lori iwe ilana ofin Naijiria ti ọdun 1976, Osoba ni awọn to n pe fun atunto Naijiria n ja fun ikun ara wọn.
Nítorí náà báyìí ni kí o ṣe, ọmọ mi,kí o lè gba ara rẹ là:lọ bá a kíákíá, kí o sì bẹ̀ ẹ́.
Ọdun 1931 ni Duro dele aye, o ṣe bẹbẹ lagbo tiata, to si gbe ere itage de ilu oyinbo ko to papoda lọdun 1978 lẹni ọdun mẹtadinlaadọta.
Sudan removed from terrorist list: America yọ Sudan kúrò nínú ìwé orílẹ̀-èdè tó ń ṣagbátẹrù ẹgbẹ́ agbésùnmọ̀mí lágbàyé
Kọmísọ́nà ètò ẹ̀kọ́ arábìnrin Folasade Adefisayo ló sọ èyí di mímọ̀ nínú àtẹ̀jáde kan to fọ́wọ́si lọ́jọ́bọ̀.
Wọn wọ Roland wọ inu ija yi ti awọn ọmọ ẹgbẹ okunkun si doju ija kọọ leemeji ọtọọtọ.
Aminat Abiọdun, Iyalode ilẹ Ibadan jade laye Iroyin ti o tẹ BBC News Yoruba lọwọ ṣalaye pe ni owurọ ọjọ naa ni Iyalode Abiọdun ju awa silẹ.
Títí di bí a ti ń sọ̀rọ̀ yìí, ebi ń pa wá, òùngbẹ ń gbẹ wá, aṣọ sì di àkísà mọ́ wa lára.
Gomina Udom Emmanuel  so pe, “A ko wa sibi lati wa polongo egbe oselu, tabi se ikede ibo.
OLUWA ní lẹ́yìn náà kí n fọ́ ìgò amọ̀ náà ní ojú àwọn ọkunrin tí wọ́n wà pẹlu mi, 
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Akoroyin tawọn agbofin fi si ahamọ lorilẹede Naijiria gba itusilẹ 7 Ẹrẹ̀nà 2018 Oríṣun àwòrán, AFP Àkọlé àwòrán, Lọjọọru ọsẹ to kọja ni ileesẹ ọtẹlẹmuyẹ DSS ransẹ peTony Ezimakor ti wọn si mu u si ahamọ Awọn alasẹ orilẹede Naijiria ti tu oniroyin kan silẹ lẹyin ti wọn fi si ahamọ fun ọjọ meje.
COM Awon omo Naijiria kan saara si ẹgbẹ agbaboolu obinrin Naijiria, Super Falcons lẹyin ti ikọ France bori wọn ninu idije ife ẹyẹ agbaye awọn obinrin pẹlu ami ayo kan si odo.
Ìpè orí fóònù tó mú kí America fẹ́ yọ ààrẹ Trump rèé Oṣù Kínní ọdún 2020 ti pẹ́ jù, ẹ ṣe ìgbẹ́jọ́ mi kíákíaá - Donald Trump Soleimani ń gbìmọ̀ràn láti kọ lù wá l'Amerika la ṣe kọ́kọ́ yára mú u balẹ̀ - Trump Lori ẹsun pe o ṣe idiwọ fun ile aṣofin, ibo mẹtalelaadọta si mẹtadinlaadọta ni ẹgbẹ rẹ fi dibo gbe lẹyin rẹ.
Ó sì sọ fún Dafidi pé, “Baba mi fẹ́ pa ọ́, nítorí náà fi ara pamọ́ sí ibi kọ́lọ́fín kan lọ́la, kí o má ṣe wá sí gbangba.
oluko yoo maa tẹle , ki won si tun se eto ẹkọ ti yoo maa jẹ ki awon akẹkọọ mọ
 Madagascar fagba han Super Eagles pelu ami ayo meji sodo(2-0) lojo Aiku(Sunday) lati duro sori oke tente tabili ikoto keji, ti won si tun pegede sipele ti o kan ninu idije naa.
O fi eyi s pe awọn ọmọ aye ode ko mọ itan.
Fásitì yìí ti bẹ̀rẹ̀ sísan àjẹẹ́lẹ̀ gbèsè owó orí náà láti ọdún 2017 ṣùgbọ́n òbítíbitì gbèsè owó orí tàwọn ìṣàkóso tó ti lo ìgbà kọjá jẹ sílẹ, ló ń fa wàhálà yii."
Nígbà tí ó bá jáde láyé, tí ó bá sì re ibi àgbà rè, n óo fi ọ̀kan ninu àwọn ọmọ rẹ̀ jọba, n óo sì jẹ́ kí ìjọba rẹ̀ lágbára.
”Iyipada rereAsofin naa tun dabaa pe ki atunse ba ofin orile ede Naijiria lati le je ki awọn gomina maa dari agbofinro ti wọn ba gbe wa si ipinlẹ wọn.
 bí ó bá jẹ ́ ìwọ ̀ n àjẹsára náà méjì péré ni a fún ni , a gba ni nímọ ̀ ràn láti gba ìwọ ̀ n àjẹsára náà mìíràn lọ ́ jọ ́ iwájú .
O mẹnuba awọn iṣẹlẹ to ti ṣẹlẹ lati ọsẹ meji sẹyin pe nitootọ ni awọn ara ilu laṣẹ lati fi ẹhonu han si nkan ti ko ba tẹ wọn lọrun.
Ohun tí ó tọ́ ni n óo sì fi ẹnu mi sọ.
, ẹgbẹ́ òṣèré tíátà pàṣẹ fún Lizzy àti Toyin Kemi Afolabi tete fi ẹsun kan Gloria loju opo instagram rẹ pẹlu fidio Gloria to fi sita ati nọmba to ni o fi n pe oun.
Adari JAMB ni ajọ ọhun ti n ri ninu owo ti wọn na ni inakuna naa gba pada diẹ diẹ nigba ti igbesẹ ṣi n lọ lori ọna ati ri awọn owo mii gba bi o ti yẹ labé ofin Naijiria.
Amaka ati Jubi, ti wọn sọrọ lorukọ awọn ọmọ ẹgbẹ naa ni, awọn da ẹgbẹ Lush Beauties silẹ lati jade se iwuri fawọn eeyan to sanra ni, ki wọn lee mọ pe ara sisan kii se arun, amọ ki wọn jade sita tori ko si ohun ti wọn ko lee se pẹlu ara sisan.
Aare soro naa lasiko abewo alaga ati awon olusakoso(LADOL Integrated Logistics Enterprise) sile ise aare lojoBo(Thursday), niluu Abuja.
Àwọn ọkunrin náà bá kúrò níbẹ̀, wọ́n gba ọ̀nà Sodomu lọ, ṣugbọn Abrahamu tún dúró níwájú OLUWA níbẹ̀.
Nígbà tí ọ̀rọ̀ wá rí bí ó ti rí yìí, oluwa mi, jọ̀wọ́, jẹ́ kí èmi di ẹrú rẹ dípò ọmọdekunrin yìí, jẹ́ kí òun máa bá àwọn ẹ̀gbọ́n rẹ̀ pada lọ.
NYSC: àgùnbánirọ̀ márùn ún gb'òmìnira lọ́wọ́ ajínigbé
Ṣùgbọ́n àṣejù wọn nípa ètò ṣiṣe ti pọ̀ jù, ìlú ibẹ̀ ni mo ti mọ̀ pé kò sí nǹkan náà ní òde ayé yìí tí àṣejù rẹ̀ dára.
Liverpool da ata gúngún sójú Tottenham gba ife ẹ̀yẹ Champions League Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Sekinat Quadri ọmọ ọdun meje ajẹsẹ to fẹ dabi Anthony Joshua Eyi mu ki ariwo sọ gee laarin awọn oluworan bi ẹgbẹrun mọkandinlogun to wa ni papa ija naa.
Wo bí fóònu rẹ kó ṣe ní kó àrun Coronavirus bá ọ Coronavirus: Wo ohun tí o ní láti ṣe láti dáàbò bo ara rẹ Wo àwọn irọ́ tí wọ́n ń pa fún ọ nípa àrùn Coronavirus Báwo ni o ṣe le mọ̀ pé o ní àrùn Coronavirus?
Wọ́n bá bẹ̀rẹ̀ ìrìn àjò wọn.
Ní ẹ̀yìn odi ìlú Angola, pánda   tí kò wúlò ni ìwé ìdánimọ̀ pélébé, kò sí àmì ìdánimọ̀ kan tí ó wà bí kò ṣe ìwé ẹ̀rí ọmọ-ìlú-fún-ìrìnnà.
 “ Mo fe rọyin pe ti ile igbimo
Àwọn agbófinró ń wá ọlọ́pàá tó yìnbọn lu olólùfẹ̀ẹ́ méjì, lẹ́yìn tí wọ́n gbé akẹgbẹ́ẹ̀ rẹ̀
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Olùkọ́ OAU: Ẹ̀sùn àdínkù ọjọ́ orí àti ìbéèrè ìbálòpọ̀ lọ́nà àìtọ́ ni wọ́n fi kàn-án 19 Ìgbé 2018 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 19 Bélú 2018 Oríṣun àwòrán, ICPC Àkọlé àwòrán, Ohùn un ọ̀jọ̀gbọ́n Akindele tí o ń bèèrè fún ìbálòpọ̀ ìgbà márùn ún lọ́wọ́ akẹ́kọ́bìnrin kan bọ́ sójú agbami ayélujára Àjọ ti o n gbogun ti iwa ibajẹ lorilẹede Naijiria, ICPC ti gbé olukọni fasiti ti wọn fẹsun kan pe o ṣe iduna-dura ibalopọ ati maaki pẹlu akẹẹkọbinrin kan ni fasiti Ọbafẹmi Awolọwọ nilu Ile-Ifẹ, lọ siwaju ile ẹjọ giga kan nilu Oṣogbo, Nibayii, adajọ ti wa pasẹ pe ki Ọjọgbọn Richard Akindele lọ jọkòó si ọgba ẹ̀wọ̀n báyìí.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Mọrèmi: Ọọ̀ni ní láìsi Mọrèmi, kò leè sí ilẹ̀ Yorùbá Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Mọrèmi: Ọọ̀ni ní láìsi Mọrèmi, kò leè sí ilẹ̀ Yorùbá 3 Sẹ́rẹ́ 2019 Awọn eekan ilu lọ̀kunrin ati lobinrin lo peju si ibi ayẹyẹ ifilọlẹ ere ati orin itan igbe aye akọni obinrin ilẹ Yoruba nni, Mọremi Ajansoro.
2017 ti ajo IMF  sagbeyẹwo owo ti orile
 Ọ ̀ pọ ̀ lọpọ ̀ ìyábọ ̀ ìròyìn jẹ ́ kó di mímọ ̀ wípé irú ìṣẹ ̀ lẹ ̀ bíì tó ṣẹlẹ ̀ kẹ ́ yìn wáyé ní ìgbà ogun barbary kejì ní ọdún 1815 , b ́ ótilẹ ̀ jẹ ́ wípé irú ìṣẹ ̀ lẹ ̀ bẹ ́ ẹ ̀ ti wáyé bí ọdún 1821 sẹ ́ yìn .
Nígbà tí Joṣua rán wọn pada lọ sí ilé wọn, tí ó sì súre fún wọn, ó wí fún wọn pé, 
Awon olopaa ni won lọ pade re ni papa ofurufu lati tele lo sile re, ni eyi ti Bobi  Wine so pe oun ko nifee si iru iwa bẹẹ.
Isele ijamba ina ti o waye labule merin kan ti o kogun si eka
Sugbọn ọwọ palaba awọn eeyan naa segi nitori ati ọkunrin ati obinrin ni awọn agbofinro mu l'owurọ ọjọ Abamẹta.
Nǹkan yan, àwọn aṣẹ́wó fẹ́ daṣẹ́ sílẹ̀ nítorí ẹ̀kúnwó epo ní Nàìjíríà Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Èmi gan máa ń béèrè lọ́wọ́ ara mi pé ta ni Wole Soyinka gangan' Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Amdi ko sọ ni pato iye ọmọ Naijiria ti wọn ti ri mu ninu awọn mẹtadinlọgọrin ti wọn fẹsun kan naa.
Obinrin yìí bá tún dáhùn pé, “Kabiyesi, jọ̀wọ́, jẹ́ kí n sọ gbolohun kan yìí sí i.
”Ó ní, “Ẹgbaagbeje ni mò ń jẹ́, nítorí a kò níye.
Amọ ibeere to wa n gba ẹnu ọpọ eeyan ni pe, se awọn obinrin ti saayan to lorilẹede Naijiria, lati kopa ninu oselu?
Àkọlé àwòrán, Bí wọ́n ṣe kó mi mọ́ rògà ìròyìn òfégè kan tó leè kóbá olùdíje Ààrẹ ẹgbẹ́ alátako Nigbẹyin gbẹyin, gbogbo iroyin ofege ni wọn ti yọ kuro nita ti wọn si ti tun un kọ.
5 mílíọ̀nù lórí aṣíwájú ẹ̀sìn Shiite lóṣù?
Kíni ìdí tí wọn fẹ́ fòfin de lílo ọ̀rá nylon ní Naijiria?
Iṣẹ́ OLUWA tóbi,àwọn tí ó nífẹ̀ẹ́ sí i sì ń wá a kiri.
Bí wọ́n ti ń dè é mọ́lẹ̀ láti máa nà án, Paulu bi balogun ọ̀rún tí ó dúró pé, “Ẹ̀tọ́ wo ni ẹ níláti na ọmọ-ìbílẹ̀ Romu láì tíì dá a lẹ́jọ́?
Lati lee rii pe didun lọsan so fun oun ni igbẹjọ naa, Sẹnetọ Ademọla Adeleke ti kede amofin agba mẹfa pẹlu awọn agba ọjẹ agbẹjọro mẹtadinlogun miran gẹgẹ bii ikọ ti yoo gbe awijare ẹjọ rẹ kalẹ niwaju awọn adajọ agba orilẹede yii ti yoo gbọọ.
“Nítorí náà, kabiyesi, tí ó bá dára lójú rẹ, jẹ́ kí wọ́n lọ wo ìwé àkọsílẹ̀ ní Babiloni bí kìí bá ṣe nítòótọ́ ni Kirusi pàṣẹ pé kí wọ́n tún ilé Ọlọrun kọ́ ní Jerusalẹmu.
Obinrin ọmọ ilẹ Gẹẹsi kan, Faye Mooney lo ti se alabapade iku ojiji rẹ ni ilu Kaduna lasiko to lọ se ariya lati ilu Eko.
Àwọn obìnrin Ekiti fi tọ̀yàyà tọ̀yàyà kí Fayẹmi
Àwọn ọba Taṣiṣi ati àwọn ọba erékùṣù gbogboyóo máa san ìṣákọ́lẹ̀ fún un;àwọn ọba Ṣeba ati ti Seba yóo máa mú ẹ̀bùn wá.
Arábìnrin Olúwaseun Táyọ̀ Balógun, tó jẹ́ onísòwò àwọ̀tẹ́lẹ̀ obìnrin sàlàyé lórí orísirísi kọ́mú tó wà lọ́jà báyìí àti àsìkò tí a leè lò wọ́n.
Ní ọjọ́ kẹsan-an, oṣù kẹrin, ọdún kọkanla ìjọba rẹ̀, wọ́n wọ ìlú náà.
Orílẹ̀-èdè Chad pé ọgọ́ta ọdún, àwọn ara ìlú ń pariwo lábẹ́ Aàrẹ Deby tó gba 'Field Marshal' Wo ohun tó yẹ kí o mọ̀ nípa Yahaya Sharif-Aminu tó gba ìdájọ́ ikú ní Kano lórí ẹ̀sùn ọ̀rọ̀ òdì sí Ànọ́bì Ẹgbẹ́ òṣèlú ZLP gbàmí tọwọ́tẹsẹ̀ láti díbò gómínà ní Ondo- Agboola Ajayi Coronavirus: Ewu wo làwọn òṣìṣẹ́ elétò ìlèra ń kojú ní Nàìjíríà?
Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Fídíò, Baby abandoned on dunmpsite: Mo ti bímọ mẹ́rin tẹ́lẹ̀ fún bàbá méjì nínú òṣí- Dupe Ogbomọṣọ4 Owewe 2020 Fídíò, Akomolede: Bolaji Faleke ni Olùkọ́ tó ń kọ́ wa ní àṣà oge ṣiṣe lórí BBC Yorùbá1 Owewe 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Oríṣun àwòrán, @HQNigerianArmy Idi ni pe, Akọwe ile ẹjọ yoowu ni yoo buwọlu oju ìwé akọkọ, ti Alaga tabi Akọwe ijọba ibilẹ rẹ yoo si buwọlu oju iwe keji.
Ọkunrin tí ìyá rẹ̀ jẹ́ ọmọ Israẹli yìí bá sọ̀rọ̀ òdì sí orúkọ OLUWA, bí ó ti ń búra ni ó ń ṣépè.
Àkọlé àwòrán, Ǹjẹ́ lóòótọ́ èèyàn le rí oúnẹ́ ọgbọ̀n náírà rà ní Kano?
Ìlànà rẹ ni ogún mi títí lae,nítorí pé òun ni ayọ̀ mi.
"Ẹ ̀ bùn nobel ( "" Ẹ ̀ bùn nobel ní èdè gẹ ̀ ̀ ẹ ́ ̀ si àti nobelpriset ní ède sweden "" norwegian : "" nobelprisen "" ) ní àwọn èbùn odoódún káríayé tí àwọn ìgbìmọ ̀ ará scandinafia ń fún ni fún ìdámọ ̀ ìmúlọsíwájú àṣà àti ìmọ ̀ ìjìnlẹ ̀ ."
A kò ní ǹkan ṣe pẹ̀lú ẹgbẹ́ òsèlú -Adeboye Ìkìlọ̀ ẹ̀kun omi wáyé fún ìpínlẹ̀ méjìlá Àwọn olùdíje Ọṣun jẹ́wọ́ ara wọ́n Ọ̀rọ̀ LAUTECH gba àpérò f'áwọn Olúdíje Ọṣun Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ìkọ BBC Yorùbá ṣe àbápade ọkùnrin tó ní òún le darí òjò síbi tó wù òun Ọ̀gá àgbà àjọ náà, Mustapha Yunusa Maihaja sàlàyé fún BBC pé ènìyàn ogójì ló tí kú ni ìpínlẹ̀ náà.
Wọ́n ṣe ìpinnu láti kọ àwọn aya wọn sílẹ̀, wọ́n sì fi àgbò kọ̀ọ̀kan rú ẹbọ ìmúkúrò ẹ̀ṣẹ̀ wọn.
Ǹjẹ́ o lè ní àjọṣe pẹlu àwọn ìkà aláṣẹ,àwọn tí ń fi òfin gbé ìwà ìkà ró?
Àwọn tí wọ́n ba ní ibùba yára jáde, wọ́n gbógun ti Gibea, wọ́n sì fi idà pa gbogbo àwọn ará ìlú náà run.
Sanusi ni labẹ akoso Gomina Babajide Sanwo-Olu, ijọba lodi si iwa kankan ti yoo tapo si aṣọ ala ilu Eko, labẹ pe wọn fẹ polowo ọja ''Ko si ẹni ti yoo sa pamọ si abẹ ika kan pe oun n ṣe ipolowo ọja lati ṣe afihan ihoho eleyi ti o lodi si aṣa wa.
Aminat Abiọdun ni iyalode kẹtala ti o jẹ ni ilẹ Ibadan.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìjọba Ọ̀yọ́: Kò sí ilé kan tí wọn kò tíì bí ìbejì ní Igbó Ọrà Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Ìjọba Ọ̀yọ́: Kò sí ilé kan tí wọn kò tíì bí ìbejì ní Igbó Ọrà 15 Ọ̀wàrà 2018 Awọn ibeji to ba BBC Yoruba sọrọ ni ilu Igbo Ọra, lasiko ọdun ibeji to waye nibẹ ni, orisa ni ibeji, obi ti ko ba si gbe awọn jo kiri laye atijọ yoo se aisan.
Nítorí náà ni èmi ṣe fẹ́ràn òfin rẹju wúrà lọ; àní, ju ojúlówó wúrà.
Ẹ̀ ń bá paramọ́lẹ̀ pa ẹyin rẹ̀,ẹ sì ń ran òwú aláǹtakùn,ẹni tí ó bá jẹ ninu ẹyin yín yóo kú.
Eyi to jasi wi pe, bi awọn gomina tẹlẹri wọnyii se ngba owo ifẹyinti ni ipinlẹ ti wọn ti se ijọba ri ni wọn tun ngba owo osu lẹnu ipo ilu tabi ipo oselu ti wọn n dimu lọwọlọwọ.
Àṣírí ilé tí wọ́n ti ń fipá bá àwọn ọmọdékùnrin lò tú síta Gẹgẹ bii ohun ti wọn ni ọkan ninu obi naa sọ, ọgbọn miliọnu naira ni awọn ajinigbe naa n beere lori ọmọ kọọkan ti wọn ji gbe; ṣugbọn ọgọrun miliọnu naira lapapọ lawọn alaṣẹ ileewe naa ni agbara awọn ka.
igbimo tuntun ohun saaju idibo fun eni ti o tuko ile-igbimo naa.
Agbejọ́rò Dakolo:Mílíọ́nù mẹ́wàá náírà tí a béèrè kì í ṣe owó gbà má-bínú Koko to jọ awọn eeyan loju ni pe ọmọ iran Igbo lati ipinlẹ abia gba fun ọmọ Yoruba lati ipinlẹ Oṣun pe ki apejẹ ma wa lẹyin isin igbeyawo wọn lẹnu.
O ni Dalung n gbiyanju lati sọ fun ajọ IAAF pe a kii da owo pada lorilẹede Naijiria Kí ló ṣe ikú pa Adewura Latifat Bello lẹ́yìn ọ̀sẹ̀ méjì tí wọ́n ń wá a?
Dambazau ni won ti ri awon ona abayo kan fenuko le lori leyin ipade yii ti yoo je ona abayo sisoro eto aabo to n ba Naijiria finra.
Lẹ́tà Obasanjo: Àjálù ń bọ̀ bíi ti Rwanda, tí Buhari kò bá ṣàtúnṣe ètò ààbò Fulani nìkan kọ́ ló ń pa ènìyàn ní Naijiria -Tinubu Sanwo Olu yan kọ̀míṣọ́nnà 25 àtàwọn olùbádámọ́ràn Mahrez dá Super Eagles dùbúlẹ̀ lórí pápá oko tútù Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Olórí Ọ̀dọ́ l'Ondo ní oníkálùkù yóò bẹ̀rẹ̀ sí ní jà fúnra wọn Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
naa, Laimọye igba ni mo ti ba  egbe osise
O sọ pe awọn ọlọpaa wa si ibi ti iṣẹlẹ naa to waye lẹyin ti awọn ọmọ ogun kọlu wọn tan, ti wọn si fi gaasi tajutaju tu wọn ka.
"O ni, ""#Talk, o ṣe pataki fun wa lati maa sọrọ sita."
Wo diẹ lara bi iwọde naa ṣe waye lawọn ilu nla ni Naijiria ni ọjọ Aje: Ipinlẹ Ekiti: Nilu Ado Ekiti, tii se olu ilu ipinlẹ Ekiti, iroyin to wa lati ibẹ ni se lawọn oluwọde oluwọde naa ti gbogbo opopona pa lai si lilọ bibọ ọkọ ati ero Oríṣun àwòrán, @Ekitiupdate Awọn opopona to gbajumọ ti wọn tipa naa ni ọna Fajuyi Park, Okeyinmi, Ijigbo, Adebayo, Basiri ati Ajilosun.
O ní ṣé mo rántí nkan tí mo sọ?
Riri i layika mi maa n fun mi ni ọpọlọpọ okun.
Ifojusode, iwadii, alarina, iya gbọ, baba gbọ, àti mọmi-ki-n-mọ-ẹ wa lara igbesẹ inu igbeyawo Yoruba Oríṣun àwòrán, @ore Àkọlé àwòrán, Imura lọkọlaya maa n gbe aṣa Yoruba ga lọjọ ti ẹbi ọkọ ba ko awọn ẹru idana wa bii iṣu, eso, ẹja, epo, iyọ, owo orí, ireke, aadun, oyin, ṣuga ati bẹẹ bẹẹ lọ.
 iselu ni botswana unwaye labe eto orile-ede olominira oloselu asoju , nibi ti Ààrẹ ilẹ ̀ bòtswánà ti je olori orile-ede ati olori ijoba , ati labe sistemu egbe oloselu pupo .
akọsilẹ fihan pe eeyan mẹẹdogun lo ba iwọde naa lọ lọdun 2012.
Mo fẹ́ kí ẹ mọ̀ dájúdájú pé bí ẹnikẹ́ni bá pa ọ̀rọ̀ mi mọ́, kò ní kú laelae.
Ni ipinlẹ Eko bakan naa, awọn oniburẹdi ni ohun to fa ọwọngogo burẹdi ni iye ti wọn ra awọn eronja ti wọn nilo, owo ọkọ to wọn gogo ati bii ijọba apapọ ṣe fi owo kun owo ori ti awọn eniyan n san.
Iṣẹ iwadii wọn yii tun se afihan idi to fi ṣe pataki lati gbe iru aṣa bẹẹ ṣẹgbẹ kan.
Ki wọn si maa kọ wọn ni ẹkọ lati ori ayelujara.
Èmi ni mo fún ọ ní agbáratí o fi sọ àwọn ìlú olódi di òkítì àlàpà.
Omi yii ni yoo si mu, titi ti yoo fi gba ọrun alakeji lọ.
Kathleen Thomas wẹ la agbami Bristol ja
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Gbemisola Saraki: APC ló ni ìbò gomina ní Kwara ní Satide 4 Ẹrẹ̀nà 2019 Oríṣun àwòrán, Wikipedia Àkọlé àwòrán, Sẹ́nétò Gbemisola Saraki tí ó jẹ́ mọ̀lẹ́bí Bukola Saraki ti fi ìgbà kan sojú ẹkùn Asa/Ilorin ní ọdún 1999 àti 2003 si 2011.
Ẹ̀gà fa ojú ro, o sì wí fún àwọn ọmọ rẹ̀, kí wọ́n máa di ẹrù, ó ní, ‘ọwọ́ ẹni kì í tan ni í jẹ, ọkàn ẹni ni àlùfáà ẹni, ní ìwọ̀n bí ọkùnrin náà ti pinnu àti ṣe nǹkan rẹ̀ fún ara rẹ̀, kò ni ṣàì ṣe e.
Gomina Abdullahi Ganduje to ṣalakoso ibo naa ni Buhari ni 2,931,235 ìbò.
”Aare egbe osise tun ni asiko niyi ki awon ile-ise aladaani so fun awon omo orile ede Naijiria ohun ti won fenuko le lori nibi ipade naa.
Ẹ wo ohun tó yẹ kí ẹ mọ̀ nípa gbajúgbajà òṣèré tíátà Yoruba Tóyìn Afọlayan Díẹ̀ lára àwọn òṣèré Nollywood ti wọ́n ti ṣe ìgbéyàwó lẹ́ẹ̀kejì Bakan naa ni o le ṣabẹwo si awọn orilẹ-ede wọnyii lai nilo iwe aṣẹ Igbelu.
We Came In Sprint Carts – South Africa
Níbo ni ọlọrun Hamati ati ti Aripadi wà?
Ṣugbọn sibẹsibẹ ibinu gbígbóná OLUWA tí ó ti ru sókè sí Juda nítorí ìwà burúkú Manase kò rọlẹ̀.
Ní ọjọ́ kan náà ni àwọn ọmọ rẹ mejeeji, Hofini ati Finehasi, yóo kú.
Aṣọ-Òfì tàbi Aṣọ-Òkè jẹ́ aṣọ ilẹ̀ Yorùbá.
''Iyawo rẹ, Laila Abdurrasheed naa ni awọn ileeṣẹ to n ṣe imọtoto ti wọn pe ni Spotless ati Flawless lasiko ti wọn n ṣe iwadii'' Amọ, adajọ Abang to n gbọ ẹjọ naa ti sun igbẹjọ siwaju di Ọjọ Kẹrin, Ọṣu Kejila, ọdun 2020.
Jesu dá a lóhùn pé, “Ẹnu ara rẹ ni o fi sọ ọ́; ṣugbọn mo fẹ́ kí ẹ mọ̀ pé láti ìsinsìnyìí lọ, ẹ óo rí Ọmọ-Eniyan tí ó jókòó lórí ìtẹ́ pẹlu agbára Ọlọrun, tí ìkùukùu yóo sì máa gbé e bọ̀ wá.
Ko pẹ pupọ naa ti wọn ṣe ikọlu si Gomina ipinlẹ Borno Babagana Zulum lasiko to ṣabẹwo si Baga botilẹ jẹ pe awọn ọmọ ogun ni kii ṣe Boko Haram lo kọlu Gomina.
Seun ni bo ba jẹ ijọba apapọ gan lo wa si ile oun lati wa da wahala silẹ, tabi mu oun lai gba iwe aṣẹ, ohun maa ṣina ibọn bolẹ funwọn ni.
Máṣe jẹ́ kí ibà Lassa pa ọ́, wo ọ̀nà láti dènà rẹ̀ Amọṣa kọmiṣọna feto ilera nipinlẹ Eko ko ṣai fi awọn olugbe ipinlẹ naa lọkan balẹ pe ko si idi fun wọn lati foya nitoripe eto gbogbo ti to lati kapa iba naa to ba fẹ gbera sọ nibẹ.
 a yí padà sí orísirísi èdè pàtàkì ni orílè yúrópù ni arin ogórun - ọdún èjìdínlógún , bé sí ni òpòlopò omòwe ni orílè yúrópù ni won tókasí ipa rè ni òrí òrò ẹ ́ kọ ́ ni bé .
Nìyí Adebayo ni Gomina alágbáda àkọ́kọ́ ní ìpínlè Ekiti laarin ọdun 1999 sì ọdún 2003 ni abẹ ẹgbẹ oselu AD.
Mo si ti ṣetan lati pada ṣenu isẹ.
Ta ni ọmọ Naijiria tí wọ́n gún pa ní London?
Ilẹ ẹjọ fagilé ìbò ọmọ ẹgbẹ́ APC nípinlẹ̀ Ogun pè kí àtúndì ìbò wà Ronaldo, Messi ẹ yàgò lọnà fagbábọ́ọ̀lù Nàìjíríà tó n gbowò julọ!
Olópàá Nàíjíríà: A ti rí owó NNPC tí wọ́n kó sílé ìfowópamọ́
Àwọn Ọmọ-Ẹ̀yìn Jesu Ń Já Ọkà Ní Ọjọ́ Ìsinmi.
Jonatani bá bẹ̀rẹ̀ sí bá àwọn ará Filistia jà, wọ́n sì ń ṣubú níwájú rẹ̀, bí wọ́n ti ń ṣubú ni ọdọmọkunrin tí ń ru ihamọra rẹ̀ ń pa wọ́n.
'Bàbá Ọbasanjo ń jowú Ààrẹ Buhari ni' Ijọba orilẹ-ede Naijiria ti fun Aarẹ tẹlẹri, Olusegun Obasanjo lesi lẹyin to bu ẹnu atẹ lu isejọba Aarẹ Buhari.
Ẹnikẹ́ni kò wẹ egbò yín, wọn kò dì wọ́n,bẹ́ẹ̀ ni wọn kò fi òògùn sí wọn.
8 6767 Orilẹede Swaziland 122 10.
Ṣùgbọ́n, báwo ni o ṣe le dá ayédèrù ìròyìn mọ̀?
Mi ò ní wọ Uber mọ́ tí wọ́n bá leè fi owó lée nítorí àfikún owó orí tí Sanwo Olu ṣe Àwọn nkan tó yẹ kí o mọ̀ nípa ṣíṣe ìṣirò àsìkò tí o bá n yé ẹyin Wo bí o ṣe le fi ẹjọ́ sun àjọ FCCPC tí o bá ra ọjà tó ti 'expire' 'Àwa ọmọ Nàìjíríà tó farapa fẹ́ wálé láti Lebanon, ìjọba kó wa pamọ́' Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Victor Agunbiade ni ojú àlá ni Ọlọrun ti yan iṣẹ́ ọmọ ogun ojú omi fún òun ní America Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí 6:18 Fídíò, Natalia Mufutau ìyá Yakub, Kamil àti Adam sọ̀rọ̀ lórí bí wọ́n ń sọ èdè mẹ́rin pàpọ, Duration 6,1831 Ògún 2020 6:10 Fídíò, Yoruba Language: Akomolede ati Asa Yoruba tọ̀sẹ̀ yí rèé lẹ́nu olùkọ́ wa, Duration 6,1030 Ògún 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Ẹwẹ, oludasilẹ ileeṣẹ Yemkem bu ẹnu atẹ bi Aarẹ Muhammadu Buhari ti buwọlu lilo agbo ti orilẹ-ede Madagascar ṣe fun itọju aarun covid-19.
“Nígbà náà, ẹ dá mi lóhùn, ẹ ní, ẹ ti ṣẹ̀ sí OLUWA, nítorí náà, ẹ óo dìde, ẹ óo sì lọ jagun, gẹ́gẹ́ bí OLUWA Ọlọrun ti pa á láṣẹ fun yín.
Joṣua pàṣẹ fún àwọn eniyan náà pé, “Ẹ kò gbọdọ̀ pariwo, bẹ́ẹ̀ ni ẹnikẹ́ni kò gbọdọ̀ gbọ́ ohùn yín.
Ọ̀kan ninu àwọn angẹli alágbára bá gbé òkúta tí ó tóbi bí ọlọ ògì, ó jù ú sinu òkun, ó ní, “Bẹ́ẹ̀ ni a óo fi tagbára-tagbára sọ Babiloni ìlú ńlá náà mọ́lẹ̀ tí a kò ní rí i mọ́.
Oríṣun àwòrán, Tunji Oladejo Àkọlé àwòrán, Awọn yara kan jo ninu ile Othman Zubair ki awọn panapana to ribi pa wọn ''Ori ibusun ti o sun si, ina yẹn ko de ibẹ,amọ gbogbo ibi iyoku ninu ile naa lo jo.
Fayọse wa rọ awọn ara ipinlẹ Ekiti lati ma se sọ ireti nu, nitori wi pe otitọ yoo jọba nigba gbogbo.
Theresa May: A dúpé lọ́wọ́ Minisita fún isẹ́ tó se lásìkò rẹ̀
O ni ti wọn ba ṣe bẹ ẹ, wọn n le ire, ayọ ati ibukun jinna si ọmọ naa ni.
Bẹ́ẹ̀ ni ẹ tí ń ṣe láti kékeré yín,ẹ kì í gbọ́rọ̀ sí OLUWA lẹ́nu.
Igi ló ṣubú lulẹ̀ tí mo jókòó lé orí igi àfi ìgbà tí atẹ́gùn fẹ́ tí igi tí ó ṣubú lulẹ̀ dìde, ìdì rẹ̀ náà sì ni eléyìí tí ìwọ fi rí mi tí mo lé téńté lórí igi.
Nígbà tí mo jí ní ọjọ́ keji láti fún ọmọ ní oúnjẹ, mo rí i pé ó ti kú.
Hananaya wolii bá bọ́ àjàgà kúrò lọ́rùn Jeremaya, ó sì ṣẹ́ ẹ.
agbofinro  yoo gbe awon ti won mu lasiko
Ṣugbọn bí mo bá ṣẹgun rẹ̀, tí mo sì pa á, ẹ óo di ẹrú wa.
Gbogbo àwọn tí wọ́n wà ní àgọ́ tí a kà ní ìsọ̀rí-ìsọ̀rí jẹ́ ọgbọ̀n ọ̀kẹ́ ó lé ẹgbẹtadinlogun ati aadọjọ (603,550).
Sàsà ènìyàn ló ń fẹ́ ni lẹ́yìn bí a ó bá sí ní ilé, t'ẹrú t’ọmọ ló ń fẹ́ ni lójú ẹni.
Kí wọn má baà fà mí ya bíi kinniun,kí wọn máa wọ́ mi lọ láìsí ẹni tí ó lè gbà mí sílẹ̀.
ẹlẹri mẹsan ni awọn agbẹjọro ijọba pe nigba ti awọn agbẹjọro fun Wolii Sọtitobirẹ atawọn ọmọ ijọ rẹ naa si pe ẹlẹri marundinlogun ati ọpọlọpọ ẹri.
INEC: Ẹ tètè forúkọ àwọn aṣojú ẹgbẹ́ yín sílẹ̀ láàrin ọjọ́ kan, bí bẹ́ẹ̀ kọ́.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Tá láwọn ọba aládé àti olóṣèlú tí EFCC n wà lórí owó ìrànwọ́ N2bn ní Kwara?
Ile ẹjọ nikan lo le sọ iye tẹni ba tapa si ofin irina yoo san, akoto ijọba si ni owo yi yoo lọ'' Bẹẹ naa lo sọ pe ki awọn ara ilu ma ṣe jafara lati fẹjọ eyikeyi ọlọpaa to ba beere owo abẹtẹ sun ni kiakia.
Kí ng fi gé àkọsílẹ̀ yìí kúrú, ti àríwá nìkan ni mo mẹ́nu bà.
ipade naa ni,Simon Lalong , lati ipinle Plateau; Kashim Shettima, Borno; Aminu
Ohun tí ó ṣẹ́kù ninu ìyẹ̀fun náà di ti Aaroni ati àwọn ọmọ rẹ̀.
Nígbà tí àwọn ọmọ wọn bá rí i,inú wọn yóo dùn,ọkàn wọn yóo sì yin OLUWA.
O tenumo pe,  awon agbegbe ti laasigbo ti waye naa je agbegbe ti won n pese ire oko ti o poju ni ipinle naa.
Èmi kò ní sí ninu ayé mọ́, ṣugbọn àwọn wà ninu ayé.
”Àwọn tí wọ́n wà ní Bẹtẹli sì dáhùn pé, “Ibojì wolii tí ó wá láti Juda tí ó sì sọ àsọtẹ́lẹ̀ àwọn ohun tí ò ń ṣe sí pẹpẹ ìrúbọ yìí ni.
Ẹ kò gbọdọ̀ kórìíra àwọn ará Ijipti nítorí pé ẹ ti ṣe àtìpó ní ilẹ̀ wọn rí.
Idi ree to fi sa kuro ni orilẹ-ede naa, lọ dara pọ mọ igun ọmọ-ogun ọlọtẹ, ti wọn kan-an nipa fun lati doju ija kọ ìjọba ilẹ Burundi, ti ẹya Tutsi n lewaju rẹ.
•Awọn asofin agba yoo sewadi ilẹkun baalu Dana to fo yọ Bawo ni ilẹkun baalu Dana to fo yọ nilu Abuja?
Ganduje ń bèèrè bí Emir Sanusi ṣe se owó ìlú mọ́kumọ̀ku Ilé ìgbìmọ̀ aṣòfin ikẹ̀jọ kógbá sílé l'Abuja Àbẹ́wò ọlọ́jọ́ mẹ́ta Trump sí UK nínú àwòrán 'Ọmọ Naijiria 25,794 ló kú sí rògbòdìyàn láàrin ọdún mẹ́rin' Temitọpẹ ṣalaye nipa ṣiṣe ere idaraya ki oun le ni agbara bi ọkunrin lati fi le maa lu ilu fun ọpọlọpọ wakati.
O tun wa kesi awọn araalu to fẹ lati dara pọ mọ ifẹhonu han naa yika Naijiria, lati ko ara wọn jọ soju popo fun iwọde alaafia.
“Ṣé o ti wọ orísun òkun lọ rí,tabi o ti rìn nísàlẹ̀ ibú rí?
Wahala tun bere lasiko ti alaga egbe APC Adams Oshiomlole n ba awon eniyan
Nítorí pé, ẹni ìyàsọ́tọ̀ ni yín fún OLUWA Ọlọrun yín, OLUWA ti yàn yín láti jẹ́ eniyan tirẹ̀ láàrin gbogbo àwọn eniyan tí wọ́n wà lórí ilẹ̀ ayé.
Awọn akẹgbẹ Bawa-Garba to ja fun-un lori ọrọ naa lati igba ti wọn ti da a lẹjọ sapejuwe rẹ gẹgẹ bi dokita akọṣẹmọṣẹ.
Lowurọ ọjọbọ ọsẹ yii ni awọn janduku ti wọn dira pẹlu ohun ija ṣaadede yabo ibi ti awọn ọdọ ti n ṣe iwọde ni agbegbe Alausa ni Eko nibi to jẹ pe awọn ọdọ kan sun mọju niwaju ọfiisi gomina.
O salaye pe, “mo n lo asiko yii lati dupe pupo lowo ile-ise Third Observers Nigeria Limited bi won se fun awon ile-ise ti won n fun awon onibara won ni ere owo-ipin idokowo naa, eyi yoo ta awon ile-ise yoku ji lati dara po mo iru igbese yii”.
ọpọ igba ni o si maa n forigbari pẹlu awọn oniroyin.
Àwọn nǹkan tí wọ́n fi igi ati amọ̀ ṣe wà níbẹ̀ pẹlu.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Tone marks: Ṣé ẹ̀yin lè ṣe jú àwọn tó f'àmì sí Awọlumatẹẹ?
Wọ́n bá dá wọn lóhùn gẹ́gẹ́ bí Jesu ti wí fún wọn.
“Ṣe àgbàlá kan sinu àgọ́ náà.
Kí olukuluku yín ati Aaroni pẹlu mú àwo turari rẹ̀, kí ẹ sì fi turari sí i láti rúbọ sí OLUWA.
Oko oju irin to kuro ni ipinle Eko lo si Kano gbera ni aago mejila osan lojo Eti, osu kokanla ojo kesan an ninu odun ti a wayii,ti yoo si pada siluu Eko ni ojo kejila osu kokanla lọdun 2018.
Ọjọgbọn naa tun beere fun pe ki minisita fun eto aabo ko ọrọ ti o sọ danu, eyi ti o n gbe agbara wọ awọn darandaran lati tẹsiwaju iwa ipaniyan.
Adari ajọ naa, Mallam Ishaq Modibbo Kawu sọ wi pe ile-iṣẹ igbohunsafẹfẹ ti o ba lodi si awọn ofin to de igbohunsafẹfẹ, yoo f'oju wina ofin ilẹ Naijiria.
Sibẹ òtítọ́ ni mo sọ fun yín.
Ìsòro tó bá de ba ọmọ ènìyàn , ènìyàn náà ni yóò yanju rẹ̀ Ó yẹ ki gbogbo ènìyàn fọ́wọ́sowapọ̀, bákan náà ni ó yẹ kí àwọn olórí dìde gírí láti mú ìsopọ̀ àwọn ènìyàn wáyé.
Nígbà tí mo sì yí padà ǹjẹ́ kí n baà máa sálọ n kò rí ojú ibi tí mo bá wọ ilé náà mọ́, mo sáré síwá sáré sẹ́hìn n kò mọ èyí tí mo lè ṣe mo bá fi ara pamọ́ sí orígun kan nínú ilé náà wí pé kí kìnnìún náà máa bọ̀ kí ó kúkú pa mi jẹ.
Bí ó ti ń sọ ọ̀rọ̀ yìí, ìkùukùu bá ṣíji bò wọ́n.
K1 De Ultimate tun ki gbogbo awọn alatilẹyin Pasitọ Oladele ninu orin rẹ bakan naa.
Àwọn tó bá akọ̀ròyìn BBC Yorùbá, Olu Alebiosu, sọ̀rọ̀ ní, àwọn ọmọ ẹgbẹ́ ọlọ́kọ̀-èrò ọ̀hún ṣà dédé kọlù àwọn ẹgbẹ́ òṣìṣẹ́ tí wọ́n tò kalẹ̀, ní ìgbáradì fún ètò yan-bí-ológun níwájú gómìnà ìpínlẹ̀ Èkó, Akinwunmi Ambode, láti kásẹ̀ ayẹyẹ náà nílẹ̀.
 síbẹ ̀ síbẹ ̀ , àkókò yìi léjẹ ̀ ókéré ọsẹ ̀ kan sí ju ọdún kan .
Bakan naa, iko agbaboolu Leicester City gbo ewúro sojúu Chelsea pẹ̀lú àmì ayò kan sòdo.
Ajọ NCDC kẹdun pẹlu idile oloogbe naa.
O tumọ si 'pipe awọn ọba si ipade'.
alakansensọri, ọdẹ ati iko eleto aabo lorile ede yii fun atleyin won.
Saraki ni pe ajọ naa fẹ gbẹsẹ le ile oun to wa niluu Ilorin.
Bi ẹ ko ba gbagbe Buhari dije fun ipo aarẹ labẹ asia ẹgbẹ oṣelu ANPP ninu idibo gbogbogbo ọdun 2003 ṣugbọn o fidi rẹmi, nigba ti Olusegun Obasanjo ẹgbẹ oṣelu PDP wọle ibo naa.
Sugbọn Ọgbẹni Xi, to yẹ ko sọkalẹ lori oye ni ọdun 2023, o kọ lati s'afihan ẹni ti ole jẹ aarẹ lẹyin rẹ nigba ipade ẹgbẹ Kọmunisti ninu osu kẹwa.
Iṣẹlẹ keji yi waye ni ilu Yargamji ni ipinlẹ Katsina yi kan naa.
Mose wí fún àwọn eniyan náà pé, “Ẹ̀yin ọmọ Israẹli, ẹ fi ọkàn sí àwọn ìlànà ati òfin tí mò ń kọ yín yìí, kí ẹ máa tẹ̀lé wọn, kí ẹ lè wà láàyè, kí ẹ lè dé ilẹ̀ tí OLUWA Ọlọrun àwọn baba yín ń mu yín lọ, kí ẹ sì lè gbà á.
Ajafẹtọẹni Kunle Wiseman Ajayi lo sọ ọrọ naa fun BBC Yoruba, lẹyin ti minisita fun eto ibaraẹnisọrọ ati ọrọ aje ori itakun agbaye, Isah Pantani sọ pe, ijọba n gbe igbesẹ lati ri dena ki eeyan kan lo ju kaadi ipe mẹta lọ.
Ewu ìjà to ba ni awọ omi goolu lara ni Cindy fẹran lati maa wọ lasiko to ba n lọ gbagede ija.
Ọkanojọkan ifojusọna lawọn eeyan si ti ni lori ohun ti yoo tẹyin rẹ jade paapaajulọ pẹlu mọhurumọhuru awọn fulani darandaran kan lẹkun naa.
Itankalẹ coronavirus ti mu ki ọpọlọpọ ninu awọn sọọsi nlanla naa ko tun eero wọn pa.
Gẹgẹ bi awọn alasẹ ti se sọ, eto igbanisisẹ yi yoo gba eeyan ẹgbẹrun lọna irinwo sisẹ lẹka orisirisi bi isẹ ọgbin, ilera, eto ẹkọ, ile kikọ, isẹ ọna ati imọ ẹrọ tẹkinọlọji.
Gege bi ile-ise akoroyin kan tun se so,””Indonesia je orile-ede ti o ni iko-o olugbe tawon elesin musulumi posi julo lagbaye, eyi ti Widodo n gbero lati lo awon ojogbon ninu esin Musulumi lorile-ede naa lati mu igbe aye Alafia wa si Afghanistan.
Àárẹ̀ mú mi patapata, gbogbo ara sì wó mi;mò ń kérora nítorí ẹ̀dùn ọkàn mi.
Eyi je idagbasoke ninu ona ikoroyin ti ko ni segbe feni kan tabi fun ako tabi abo ju ara won lo.
Laipẹ yii ni wọn fẹsun kan Gomina Fayemi pe o fẹ rọ Ewi of Ado-Ekiti, Oba Rufus Adejugbe loye atawọn ọba alaye mẹwaa mii ti ọpọ mọ si awọn Ọba Pelupelu.
’’Mo ti gbiyanju lati gbogun ti iwa ibajẹ lorile ede Naijiria .
Ajọ LASEMA ni ọkọ tipper mẹta lo lọ run ọkọ akero igboro mọlẹ pẹlu awọn ẹrọ to wa ninu ọkọ naa.
Ayọ méjì ṣọkan ní wọn fi fakoyo ninu ifẹsẹwọnsẹ tó wáyé lọjo ìṣẹgun.
Koda ọpọ ti rii gẹgẹ bii baraku pẹlu isejọba, oṣelu ati igbe aye awọn ọmọ Naijiria lapapọ.
" Ọga ọlọpaa Kwajafa ṣalaye pe aṣẹ ti ijọba ologun igba naa labẹ olori ologun, Ọgagun Muhammadu Buhari gbe sita fun ọga ọlọpaa nigba naa, Etim Inyang pe ko lọ wa nnkan ṣe si iṣẹlẹ idigunjale to n fojojumọ pọ si lorilẹede Naijiria, bi bẹẹkọ iṣẹ oun atawọn lọgalọga nileeṣẹ ọlọpaa naa yoo lọ sii.
Ninu atẹjade kan to fi sita loju opo Instagram rẹ lowurọ ọjọ Aje ni alufaa Fatoyinbo ti ṣe ikede naa.
O jẹ ko di mimọ wi pe gẹgẹ́ bii gbogbo ọmọ ọba ni ile Ife ni oun naa ṣe jẹ ni Ifẹ nitori Ọọni obinrin akọkọ ni Ile Ifẹ jẹ iya nla idile oun.
Lẹ́yìn ọjọ́ díẹ̀ Paulu wí fún Banaba pé, “Jẹ́ kí á pada lọ bẹ àwọn onigbagbọ wò ní gbogbo ìlú tí a ti waasu ọ̀rọ̀ Oluwa, kí a rí bí wọ́n ti ń ṣe.
Ninu fidio yii ti BBC Yoruba se lati fi seto ilanilọyẹ fun araalu, lo n sọ awọn ohun to yẹ ka se akiyesi rẹ ninu itọ wa.
Ni ọjọ́ kẹta inú Moṣétán bẹ̀rẹ̀ si i wú titi ara fi ni.
O fikun pe, ọpọlọpọ isoro yii ni ko jẹ kawọn eeyan rí oun ninu sinima mọ nitori ohun gbogbo to dagun fun oun.
E Maha pe ki ile ẹjọ paṣẹ ki awọn ọlọpaa ye dun koko mọ Dino Melaye ki wọn si jẹ ki awọn mọlẹbi rẹ lanfaani ati ri.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Armed Robbery: Ọmọ Nàìjíríà mẹ́jọ gba ìdájọ́ ikú ní UAE 20 Ìgbé 2019 Oríṣun àwòrán, @TosinadedaMedia Àkọlé àwòrán, Awọn adigunjale Ijọba orilẹede United Arab Emirate ti dajọ iku gbere fun ọmọ Naijiria mẹjọ lori ẹsun idigunjale.
Buhari gbọ́dọ̀ bẹ̀rẹ̀ ìwádìí Ganduje láàrín ọjọ́ mẹ́rìnlá - SERAP Àwọn aṣòfin àpapọ̀ ń dí mi lọ́wọ́ iṣẹ́-Buhari Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Àjọ Ọlọ́pàa Naijiria: A ó fi òsìsẹ́ SARS tó se isẹ́ ibi náà jófin Ẹwẹ, ọga ọlọpaa ni Ipinlẹ Eko, Imohimi Edgal ti paṣẹ pe ki wọn ti gbogbo ile ọti to wa ni agbegbe ibudo ọlọpaa to wa ni Ikeja pa.
Ninu awọn olori to kuro laafin laipẹ yii ni olori Aanu wa.
Àwọn ọmọ ogun Arabia tí wọn ń jà káàkiri pa gbogbo àwọn ọmọ Jehoramu, ọba Juda, àfi Ahasaya, àbíkẹ́yìn rẹ̀.
Adajọ Oathman Musa ni ẹsun ti Busola pe mọ Fatoyinbo ko lẹsẹ n le, bakan naa ni wọn fi akoko ile ẹjọ sere.
Àfẹ́sọ́nà Davido, Chioma nàá ti ní ààrùn Coronavirus Fíímù ṣíṣe dáwọ́ dúró, Joke Muyiwa di 'grandma', Lizzy Anjorin sọ pé coronavirus ko gbọdọ̀ díwọ́ ọjà títà Coronavirus- Atọ́nà bí nkàn ṣe ń lọ ní Afirika Coronavirus: Wo ohun tí o ní láti ṣe láti dáàbò bo ara rẹ Lati igba ti ajakalẹ arun yii ti de orilẹede Naijiria, eniyan kan lo ti ku nitori arun naa, ti ile iwosan si ti fi awọn mẹta silẹ lẹyin ti wọn bori arun naa.
Ṣugbọn bí orílẹ̀-èdè kan bá ṣe àìgbọràn, n óo yọ ọ́ kúrò patapata, n óo sì pa á run.
Ṣugbọn ṣa, awọn oluwọde naa pada le awọn janduku naa lọ.
Bí Joṣua ti na ọwọ́ rẹ̀, wọ́n sáré wọ inú ìlú náà, wọ́n gbà á, wọ́n sì yára sọ iná sí i.
Ero buruku ma n fa ipaya lasiko idanwo, ri wi pe o mu ero ti ko dara kuro lọkan lasiko idanwo naa.
 A o se eto ibura fun aare ni ojo kejila, osu
Fún ọ̀pọ̀lọpọ̀ ọdún, onidajọ ọ̀daràn kò ṣe idájọ òdodo fún Aláwọ̀-dúdú, èyi kò ran nkan lọ́wọ́.
Èmi tí mo jẹ́rìí sí ọ̀rọ̀ iranṣẹ mi,tí mo sì mú ìmọ̀ àwọn ikọ̀ mi ṣẹ,èmi tí mo wí fún Jerusalẹmu pé,‘Àwọn eniyan yóo máa gbé inú rẹ,’tí mo sì wí fún àwọn ìlú Juda pé,‘A óo tún odi yín mọ,n óo sì tún yín kọ́.
Nítorí pé nígbà mìíràn ẹni tí ó ti ṣiṣẹ́ pẹlu ọgbọ́n, ìmọ̀ ati òye yóo fi gbogbo rẹ̀ sílẹ̀ fún ẹni tí kò ṣe làálàá fún wọn.
Kia tun ni awọn osere tiata naa tun ya bo oju opo Instagram wọn lati dupẹ lọwọ awọn alaanu to gba ọrọ ẹdun Ajirebi naa ro.
Mọjumọ ọjọ Aje yii ni ojo naa ṣakoba fun odi ti wọn mọ yika ọgba ẹwọn ọhun, tawọn ẹlẹwọn si fẹsẹ fẹ.
Ijó ni gbogbo ẹda alààyè jo titi ti ilẹ̀ fi ṣu ko.
Solskjaer fárígá lẹ́yìn tí Van Persie ló ń rẹ́rìn-ín Àgùtàn Arsenal kò tíì paṣọ èṣí dà lábẹ́ Mikel Arteta Lampard yájú sí Mourinho,ẹgba ayo méjì s'odo ló tò sídìí akọ́nimọ́ọ́gba rẹ́ tẹ́lẹ́ Wo àwọn ọ̀tá tó ń da orílẹ̀èdè Nàìjíríà láàmú Ọmọ Nàìjíríà ẹ ṣọ́ra fún ìrìn alẹ́ nítorí àwọn tó fẹ́ gbẹ̀san ikú Soleimani Oun ni agbabọọlu akọkọ ti yoo gba goolu mẹta wọle ninu ifẹsẹwọnsẹ kan ṣoṣo ni liigi mẹta ọtọọtọ lagbaye, iyẹn liigi ilẹ Gẹẹsi (Premier league), liigi orilẹede Spain (la liga) ati liigi ilẹ Aguda, orilẹede Italy (Serie A).
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ojú mi ti rí lọ́pọ̀ lọpọ̀, àmọ́ mo dúpẹ́ pé mo ti pé ọdún márùn ún lórí oyé- Ooni Ọgagun agba Sani Abacha: Ṣaaju iku rẹ lọdun 1998, ọgagun agba Sani Abacha ni olori ijọba ologun ni Naijiria.
 Inu mi dun pe, en nawo sibi ti o lapere, ninu epo robi.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Abẹ́rẹ́ àjẹsára àkọ́kọ́ tó n dènà ibà yóò dì mímú lò ní Malawi 23 Ìgbé 2019 Oríṣun àwòrán, D Poland/PATH Àkọlé àwòrán, Wọn ti saaju dan iṣẹ abẹrẹ yi wo lara awọn eeyan ti o si ṣiṣẹ daada Iṣẹ ibẹrẹ lori pipese abẹrẹ ajẹsara eleyi ti yoo daabo bo awọn ọmọde lọwọ airun iba ti bẹrẹ lorileede Malawi.
AfCFTA: Orilẹẹde 44 t'ọwọ bọ'we ilana okoowo tuntun fun Afrika
Àwọn ará Edomu, ati àwọn ọmọ Iṣimaeli,àwọn ará Moabu, ati àwọn ọmọ Hagiri,
Báwo ni ètò 'Nigeria Youth Investment Fund' yóò ṣe ṣiṣẹ́ Gẹ́gẹ́ bi mínísítà ṣe sọ, ètò Nigeria Youth Investment Fund"" kìí ṣe iṣẹ́ ti àwọn ènìyàn yóò ma gba owó oṣù, tàbi ìrọgùn sápá tàbi ètò adájútòfò kankan ti ìjọba ti ṣe tẹ́lẹ̀, O ṣalaye pe èyí yàtọ̀ gédégédé, yóò maa fún àwọn ọ̀dọ́ láànfàní láti le bẹ̀rl okoòwò wọ́n, láì ṣiṣẹ́ lábẹ́ ẹnikẹ́ni."
Akinyẹmi tun mu da BBC Yoruba loju pe, baba n gbalejo kan nile rẹ nilu Abẹokuta, lọwọlọwọ ni.
We  are indeed proud of you.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù 'Alagbalúgbú' jẹ́ ọ̀rọ̀ tí Yorùba fi ń ṣàpèjúwe agbára òkun Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ 'Alagbalúgbú' jẹ́ ọ̀rọ̀ tí Yorùba fi ń ṣàpèjúwe agbára òkun 28 Òkùdu 2018 BBC Yorùbá ní káwọn ènìyàn fàmì sí ọ̀rọ̀ 'alagbalúgbú' (re-re-re-mi-mi).
Ṣugbọn nígbà tí alufaa bá yẹ̀ ẹ́ wò, tí ó sì rí i pé àrùn náà ti wòdú lẹ́yìn tí a fọ aṣọ náà, kí ó gé ọ̀gangan ibẹ̀ kúrò lára ẹ̀wù, tabi aṣọ, tabi awọ náà.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ẹ̀mí kan náà ló n darí ìrìnàjò wa táa fi jọ kọ́lé papọ̀- Ìbejì Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Ẹ̀mí kan náà ló n darí ìrìnàjò wa táa fi jọ kọ́lé papọ̀- Ìbejì 22 Bélú 2019 Lati oṣu mẹwaa di ẹni ọdun marundinlọgọta lati jọ wa papọ gẹgẹ bii ẹni kan ninu ara meji- Ibeji Arabinrin Taiwo Olawoyin ati Arabinrin kehinde Adeniran ni awọn ibeji ti ko sẹni to le ri aarin wọn lẹyin ọdun marundinlọgọta ti wọn ti lo loke eepẹ.
Wọn foju rénà Southampton, oun lo dẹ ba akọsilẹ wọn jẹ bayii.
Egbé agbábọọlù Super Eagles gbàgbé ohun eèlò wọn - Ọlajiire Wike kò wó Mọṣáláṣi rárá o -Fayẹmi lórúkọ gbogbo Gómìnà Nítoríi fóònù ìbánisọ̀rọ̀, géńdé méjì kú sínú u kọ̀ǹga l'Ékìtì O ni awọn ti wọn farakasa iṣẹlẹ naa wọkọ nilu Offa ti wọn si n lọ si Katsina ṣugbọn nigba ti wọn de agbegbe kan ti wọn n pe ni Ajana laarin Abuja si Kaduna ni wọn ko si ọwọ awọn ajinigbe.
Ọ̀rọ̀ tí ń gbénú ilédì tí ń kùn yùnmùyùnmù
Awọn eeyan ko pọ pupọ lorilẹede Algeria, eeyan mẹtadinlogun si lo ni kilomita kan, eyi ti ko ri bẹẹ ni orilẹede Burundi, ti eeyan okoolenirinwo ati mẹta n lo kilomita kan.
DDisplay : Eyi ni sise afihan orukọ awọn to fi
Lukman Olayiwola Mustapha -Ò yege 9) Shuaib Yahman Abdullahi -Ò yege 10) Moshood Mustapha -Ò yege 11) Dele Mohammed Belgore (SAN) - ó yọwọ́ pé òun kò ṣe mọ́.
 ajẹ ́ bu àti olóde tẹ ̀ lé olú-Ìwà nínú ìrìnàjò wọn wá sí agbègbè Ìjẹ ̀ bú .
” Naomi bá dá a lóhùn, ó ní, “Ó dára, máa lọ, ọmọ mi.
Orilẹ-ede America nikan ni aṣoju ti ko faramọ iyansipo rẹ nibi ipade to waye l'Ọjọru.
org, idile ti ko ri ọwọ rọri lo ti wa, nitori oju owo pọn awọn obi rẹ pupọ.
Kí ló dé tí o fi tún ń sọ pé, ‘Fi Baba hàn wá?
Wọ̀nyii ni lara ohun ti awọn eniyan nsọ lori ẹrọ ayelujara Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Awọn obi ati ara ilu Chibok si nreti awọn ọmọ to ku Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, ‘Ara fu mí nígbàtí bàbá gbé Bíbélì ìdílé fúnmi’ Awuyewuye owó tí Àbáchà jí Kí la tún gbọ́ nípa ìdámẹ́wàá?
Latorii awọn Biṣọọbu ati gbogbo ijọ lo n gbe nkan lura ki wọn to lọ si Ṣọọṣi naa ti wọn si gbagbọ pe yoo mu ẹmi mimọ sọkalẹ si aarin wọn.
Ṣebí ó ṣe ẹ̀tọ́ ati òdodo,ṣebí ó sì dára fún un.
Wọ́n bu ẹnu àtẹ́ lu ìwà yìí gidigidi.
Olukopa obinrin ti o dara julo
awon to n dana ounje ta, bee si ni fun awon agbe ti o to ẹ̀gbẹ̀rún lona ọgọ́rùn ún lati
Ṣugbọn ohunkohun tí ó ti jẹ́ èrè fún mi ni mo kà sí àdánù.
Agbẹnusọ fun ileeṣẹ ọlọpaa Ipinlẹ Eko ni wọn n ṣe iwadii pe o ṣeeṣe ko jẹ pe o gbẹmi ara rẹ ni 'tori igo Sniper meji ti wọn ba ninu yara rẹ ninu ile igbafẹ naa.
Kò ṣe àlàyé bi Ì̀jọba ilú rẹ ti ngba owó iwà ibàjẹ́ pamọ́ lati fi tú ilú wọn ṣe.
United ninu ifesewonse idije Uefa Champions League ti o waye lojo
Laarin igboro lawọn ilu nla nla, awọn alatako oloogbe Nkurunziza ẹni ọdun mọkanlelaadọta ni afi la, ko gbudọ lọ fun saa kẹta tori pe o lodi si ofin.
Oríṣun àwòrán, Reuters Àkọlé àwòrán, The start of a key day in the House of Representatives Esi awọn ibo abẹle kan ṣafihan pe ero ṣe ọtọọtọ laarin awọn to fẹ Trump ati awọn alatako r.
Bi o tile jẹ wipe aago mejila ni wọn sọ wipe eto naa yoo gbinaya, titi di aago meji ọsani, nnkan ko tii fi bẹẹ ṣarajọ nitori awọn alejo pataki ti wọn n reti ko tii gunlẹ si papa ipolongo.
''Agbẹ ni mi bẹẹ si ni mo jẹ ajinigbe.
Seun Abolarinwa to jẹ eegun to wa nidi yiyi ohun ere Bollywood pada si ede Yoruba sọ bo ṣe n ṣe e fun BBC Yoruba to fi n jade ni ọna ti awọn eniyan fẹran.
Ẹ wo àbájáde ìwádìí wa Èèyàn 38,344 ló ti ní COVID-19 ní Nàìjíríà lẹ́yìn tí 543 kún un lọ́jọ̀rú Bàbá mi Aláàfin, ẹ ṣeun ẹ̀bùn owó tí ẹ fún èmí àti ọkọ mi- Lizzy Anjọrin Oṣu aawẹ ni Dhu al- Hijjah Yatọ si pe o gba aawẹ lọjọ Arafa, o ṣe pataki lati gbawẹ lati ibere lẹẹkan oṣu naa.
Ọlọrun wà láàrin rẹ̀,kò ní tú bẹ́ẹ̀ ni kò ní ṣí kúrò;Ọlọrun yóo ràn án lọ́wọ́ ní òwúrọ̀ kutukutu.
"Akọwe ijọba lori iroyin, Nick Mangwana sọ pe ""awọn obinrin mẹtẹta yii wa lara awọn ọdọ ẹgbẹ oṣelu MDC to tapa si ofin isede lorilẹede lati lọ kopa ninu ifẹhonuhan to lodi si ofin""."
26 Àti pé èmi Olúwa pàṣẹ fún un, ìránṣẹ́ mi Martin Harris, pé òun kì yíò sọ ohun kankan fún wọn mọ́ nípa àwọn ohun wọ̀nyí, àyàfi bí òun yíò sọ pé: mo ti rí wọn, a sì ti fi wọ́n hàn sí mí nípa agbára Ọlọ́run; ìwọ̀nyí ni àwọn ọ̀rọ̀ tí òun yíò sì sọ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù APC- àjòjì ọkùnrin kan gbàsàkóso iìkànì Twitter rẹ̀ 14 Ìgbé 2018 Oríṣun àwòrán, Twitter.
Ṣugbọn ọpọ awakọ lo kọ eti ọgbọin si ikilọ naa, eyii to ṣalekun sunkẹrẹ-fakere oju popo ipinlẹ ọhun.
 Ó sì ń pè fún àtúnṣe .
Òwe yi túmọ̀ si pé, bi a jẹ oúnjẹ inú ewé tán, à ju ewé nù.
Ọ̀pọ̀ àwọn ọ̀dọ́ onísòwò ló ti jẹ àǹfàní lára rẹ̀.
”Ìyá rẹ̀ dáhùn pé, “Bèèrè orí Johanu Onítẹ̀bọmi.
Emi nikan ni mo si ni iru rẹ ninu ẹbi wa.
Niṣe ni ina fo lati ara awọn ina igbalode ti wọn fi ma n dawọ idunnu nibi ayẹyẹ fo si i lori, ti irun rẹ si gbina.
Inú ń bí àwọn ọmọ orílẹ̀-èdè Angola látàrí iye owó ìwé ẹ̀rí ọmọ-ìlú-fún-ìrìnnà tuntun 30,500 kwanzas (ó tó 97 owó dollar) tí ìjọba ṣẹ̀ṣẹ̀ polongo ní ọjọ́ 21 oṣù Ṣẹẹrẹ.
Mo rán Mose ati Aaroni sí wọn ní ilẹ̀ Ijipti, mo fi àjàkálẹ̀ àrùn bá àwọn ará Ijipti jà, lẹ́yìn náà mo ko yín jáde.
Oríṣun àwòrán, @justeventsonlin Ọjọ kẹwaa, oṣu Kejila, ọdun 2020 ni iroyin gbode kan pe awọn janduku kan kọlu ile igbimọ aṣofin ipinlẹ Ogun, ti wọn si ji ọpa aṣẹ rẹ gbe lọ.
Jakọbu gbà bẹ́ẹ̀, ó ṣe ọ̀sẹ̀ igbeyawo Lea parí, lẹ́yìn náà Labani fa Rakẹli, ọmọ rẹ̀ fún un.
0 13 Orilẹede Mongolia 0 0.
Àwọn àjakalẹ-àrun to tí wáyé ri: Àjakalẹ-àrun Ẹyi àbí Ṣanponna, tí wọn pé ní Antonine Plague: Àjakalẹ-àrun olode yìí wáyé láàárín ọdún 165 CE ni àwọn ilẹ̀ tó wà lábẹ́ àkóso ìjọba Róòmù.
“Ẹnikẹ́ni tí obinrin bá bí, ọlọ́jọ́ kúkúrú ni,ó sì kún fún ìpọ́njú.
Ìlú tí ó wọ aṣọ funfun, ati aṣọ àlàárì ati aṣọ pupa.
Damilola Falodun ati Oyinlola Solanke ni ko rọrun lati ni ominira ni Oman lai jẹ pe obinrin ba ọga rẹ sun, ti awọn mejeeji si salaye itu ti awọn ọga wọn fi wọn pa lọhun.
Akanbi mi, má fọ̀ ọ́, mo wà pẹ̀lú ẹ; Ẹni tó ṣe ìgbéyàwó olórùka ló l'ọkọ - Lizzy Anjorin Gbogbo orin egúngún bìkiafù tí wọ́n kọ sí mi l'étí nípa Ajayi tí mi o gbọ̀ ló bu mí lọ́wọ́- Akeredolu Ǹjẹ o yẹ kí èèyàn máa sùn lẹ́nu iṣẹ́?
Kàkà bẹ́ẹ̀, bí ẹnìkan bá gbá yín létí ọ̀tún, ẹ kọ ti òsì sí i.
Fìlà rẹ gbọọrọ, bí ojú rẹ kò bá fọ́, fìlà rẹ tí ìwọ ń pè ní odé yìí dára ju fìlà orí awa lọ?
"Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Àwọn kan fẹ́ da Naijiria rú torí ààbò tó mẹ́hẹ - Osinbajo gbarata Abúlé tí wọn kìí ti sọ ọmọ ní orúkọ, ohùn arò ni wọ́n fi ń pè wọ́n Nàìjíríà ni ìkómọ àwọn ìbẹ́ta mi yóò ti wáyé lẹ́yìn tí mo bá gba páálí wọn l'Ámẹ́ríkà Barrister ló sọ mí di èèyàn ńlá - Ayinla Kollington Lara ohun ti awọn ọlọpaa kọ sinu iwe ipe ọhun ni pe "" ileesẹ naa fẹ tanna wadi ẹsun lilẹdi apo pọ lati huwa ọdaran, irọ pipa, etekete ati idunkooko mọ ẹmi ẹni, ninu eyi ti wọn ti darukọ yin."
Gómínà ìpínlẹ̀ Rivers Nyesom Wike, ní Gomina ìpínlẹ̀ Kano ń dógbọ́n láti lo ọ̀rọ̀ mọsálási tí kò ṣẹlẹ̀ láti maa dá rúkèrúdò òṣèlú sílẹ̀.
 akọ ibà maa ń fa àwọn ààmì èyí tí ó wà lára akọ ibà , ìgara , bíbì àti ẹ ̀ fọ ́ rí .
Kí Ọlọrun gbà á sílẹ̀ nisinsinyii bí ó bá fẹ́ ẹ!
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Dokita yii gbiyanju lati ran Mogadishu lọwọ O ni perete awọn ọkọ̀ igbe-alaisan ló sile iwosan bẹẹ awọn to wa kii yọju ti ẹ ba pé wọn ati pé wọn tun n da owo gọbọi ti wọn ba jaja wa.
Olubiyo tun rọ ijọba lati yẹ ọrọ naa wo daada, ki o to kọja afẹnusọ.
Aisha Buhari: Aya Ààrẹ Buhari ké sí àwọn aya gómìnà pé kí wọ́n lọ paná ìdàrúdàpọ̀ ágbègbè kóówá
O ti fi igba kan jẹ oluranlọwọ pataki fun Minisita olu ilu Naijiria , Oloye Jumoke Akinjide , o si ti bẹrẹ oṣelu lati igba naa pẹlu ẹkọ to kọ lara baba rẹ.
Magu fikun un wi pe ajọ EFCC ti setan lati ri i wi pe iwa ibajẹ ati aṣemaṣe dopin ni orilẹ-ede Niajiria, paapaa lọdun 2020 ti a wa yii.
Sugbọn nigba to pe ẹni aadọta ọdun, o pade ololufẹ mi i, Philippe Padieu - o jẹ ẹni to ni ọrẹbinrin to pọ, oun naa lo si fun un ni aarun HIV.
Wọn bi minisita tẹlẹ naa leere pe awọn inawo kan to ṣe nigba naa, eleyii to ni oun ko lee ranti mọ.
Kí o sì sọ ohun tí èmi OLUWA àwọn ọmọ ogun wí fún un, pé, ‘Wò ó!
Apá kejì dùn púpọ̀ pẹ̀lú, ṣùgbọ́n , ọ̀rẹ́ mi, jẹ́ kí á fi èyìínì di òwúrọ̀ ọ̀la.
Nigba to ya ni agba osere tiata kan, Yomi Fabiyi bẹrẹ si da awọn akẹẹgbẹ rẹ lẹkun lori ọrọ naa, ati bi wọn se n daro oloogbe lọna to mu ikunsinu lọwọ.
Kí ló dé tí a fi fi ìmọ́lẹ̀fún ẹni tí ọ̀nà dàrú mọ́ lójú;ẹni tí Ọlọrun ti tì sinu àhámọ́?
Oríṣun àwòrán, queenola2 Instagram Amọ ko si atẹjade kankan to wa lati aafin Oyo lori isẹlẹ naa, ti ko si si ẹni to lee fidi rẹ mulẹ, boya Olori Badrat si wa ninu aafin abi o ti ko kuro.
Matt Hancock salaye pe o kere tan ọgọta agbegbe ni wọn ti ri akọsilẹ itankalẹ arun Covid-19 tuntun yi.
Nígbà tí ó ní kí á tún lọ ra oúnjẹ díẹ̀ wá, 
Ko wa tan sori gomina ipinlẹ Abia nikan o, awọn gomina mii to ti lugbadi Coronavirus ree: Gomina ipinlẹ Bauchi, Bala Mohammed Oríṣun àwòrán, Twitter/Bala A.
 orin rí bí i díńgí tí a fi ń tún ìwà ènìyàn ṣe .
" Ọjọgbọn Ṣoyinka ṣalaye pe owo to yẹ ki ijọba fi koju ajakalẹ arun bi Coronavirus ni awọn kan ti ko sapo, ti wọn si ti fi ṣe awọn iṣe akanṣe ti ko ṣe ara ilku lanfani kankan.
Àwọn ni ìlú ati ìletò tí ó wà ninu ilẹ̀ tí ó kan ẹ̀yà Nafutali gẹ́gẹ́ bí iye ìdílé wọn.
Nígbà tó ń sọ̀rọ̀ nípa akẹẹgbẹ rẹ, Ògún Majek, tí ìròyìn gbalẹ pé ó ṣe alaisi laipẹ yii, Bàbá Wande ni irọ ni, Ogun Majek sì wá láàyè, tí àlàáfíà sí ti ń to lọwọ.
Ati pe ki Olorun mu inu oun dun sii ṣaaju ayẹyẹ ọjọ ibi oun lọdun to m bọ.
orilẹ-ede miiran jẹ, lati ṣe jẹjẹ nitori eyi yoo tun ṣe akoba fun
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù DFL: Ìdánilẹ́kọ̀ọ́ yìí tún ń kọ́ àwọn akẹ́kọ̀ọ́ girama ní iṣẹ́ Asoná, bàtà àti báágì ṣíṣe Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ DFL: Ìdánilẹ́kọ̀ọ́ yìí tún ń kọ́ àwọn akẹ́kọ̀ọ́ girama ní iṣẹ́ Asoná, bàtà àti báágì ṣíṣe 14 Ògún 2019 Atẹlẹwọ ẹni kii tan ni jẹ ni Yoruba n sọ, idi ree ti ajọ kan ti wọn n pe ni Design For Life (DFL) se gunle eto idanilẹkọ fawọn obinrin to wa nile ẹkọ girama, lati kọ awọn isẹ miran to n mu owo wale yatọ si isẹ aransọ.
Sugbon a mọ pe, ayan to mu kọngọ lọwọ, lo mọ ohun to n fi ilu sọ, amọ o ṣee ṣe ki awọn arojinlẹ ọrọ naa da lori iku Ibidunni Ighodalo to jade laye lọsẹ to kọja.
O ni igbesẹ yii jẹ ọna ati mọ riri awọn eniyan to ti ko ipa ribi ribi ninu idagbasoke ipinlẹ Oyo, ninu iṣẹ wọn ati si awọn araalu.
Elétùú Òdìbò ló sì máa ń fi Ọba Èkó jẹ, èyí ò ya ni lẹ́nu tìtórí orúkọ ìdílé (Gbádéṣeré) yìí fi hàn bẹ́ẹ̀.
Tramadol: Orísun ikú, àìní-rètí àti Boko Haram
Kò gbọdọ̀ sọ ara rẹ̀ di aláìmọ́, kí ó sì ba ara rẹ̀ jẹ́, nítorí olórí ló jẹ́ láàrin àwọn eniyan rẹ̀.
O fi da awon eniyan loju pe igbimo yii yoo se ise won bi ise lati lee mu ipinnu awon eniyan se.
Gbogbo àwọn ohun èlò pẹlu wúrà ati fadaka tí baba rẹ̀ ti yà sọ́tọ̀ fún OLUWA, ati àwọn tí òun pàápàá yà sọ́tọ̀, ni ó dá pada sinu ilé OLUWA.
Ohùn náà tún dún létí rẹ̀ lẹẹkeji pé, “Ohun tí Ọlọrun bá ti sọ di mímọ́, o kò gbọdọ̀ pè é ní ohun àìmọ́!
Gẹgẹ bi agbẹnusọ yii ṣe sọ, wọn ni awọn janduku to maa n bẹ ọpa epo lati ji epo wa lo da wahala yii silẹ.
òkúta onikisi ati àwọn òkúta tí wọ́n fi ń ṣe iṣẹ́ ọnà sára efodu tí àwọn alufaa ń wọ̀, ati ohun tí wọn ń dà bo àyà; 
bí Noa, ati Daniẹli ati Jobu bá tilẹ̀ wà níbẹ̀, bí èmi OLUWA Ọlọrun fi ara mi búra pé, wọn kò ní lè gba ọmọkunrin tabi ọmọbinrin wọn là.
Ẹlẹ́wọ̀n 44 kú sọ́gbà ẹ̀wọ̀n nítorí ooru tó mú púpọ̀ Wo àwọn iléèwé gíga tó ti bẹ̀rẹ̀ sí ní ta fọ́ọ̀mù JAMB post UTME screening ní Naijiria Ìdí rèé tí a ṣe fẹ́ sin Majek Fashek sílẹ̀ Amerika- Randy Fashek Ẹ wo ohun tó yẹ kí ẹ mọ̀ nípa oògùn 'Sputnik V' Russia tó ń wo àrùn Coronavirus Ti wọn ba ti mu awọn obi naa, wọn gbọdọ mu awọn Alfa, pasitọ, olukọ ati imaamu pẹlu awọn alabagbe ọmọ to ba ti wu iwa ibajẹ lawujọ tabi darapọ mọ ẹgbẹ okunkun.
Ní àríwá ìwọ-oòrùn Thailand, àlọ́ kan tí ó dá lórí Ta Sorn tí Tongsin Tanakanya sọ ṣe ìgbélárugẹ ìṣọ̀kan láàárín aládùúgbò ní ìlú iṣẹ́ àgbẹ̀.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Buhari buwọ́lu owó oṣù tuntun fáwọn ọlọ́pàá Kò sí ohun tó yípadà pẹ̀lú ìwọṣọ akẹ́kọ̀ọ́ ISI"" 'Èèwọ̀' gààrí fún àwọn èèyàn ipínlẹ̀ Ondo Hubert Ogunde rèé, baba àwọn òsèré tíátà Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Jide Kosọkọ: Isẹ́ tíátà yóò gòkè tíjọba bá gbówó kalẹ̀ láti seré Asoju fun ijọba apapọ to jẹ Minisita fun Eto Ẹkọ , Malam Adamu Adamu ni, awọn yoo tẹsiwaju pẹlu ifọrọjomitoro ọrọ lọjọ iwaju lati wa opin si iyansẹlodi naa."
Atamọtaṣe, Olivier Giroud lo gbayo alakọọkọ wọle fun Chelsea nigba ti ifẹsẹwọnsẹ naa di iṣẹju mẹẹdogun.
“Nibayii ti aare Muhammadu Buhari ti tọwọbọ 
Buhari, o kò ṣe bẹbẹ kankan láì jẹ́ pé o gba Leah Sharibu náà sílẹ̀ Wo àwọn nǹkan to tún nílò NIN fún yàtọ̀ fún ìforúkọsílẹ̀ síìmù Apapọ owo aba isuna naa ni biliọnu lọna ọrinlerugba o din mẹwa naira (N266bn), tijọba si n reti abọ ile asofin lori rẹ.
Gege bi oludari ile-ise LG Electronics nile Afrika, Taeick Son se so:“Ki a to yan Alex Iwobi gege bi asoju wa, a fikunluku lopolopo lati wo ipa re ti o n ko lori papa, ati ni papaajulo bi awon eniyan se nife re si jakejado.
Omi ọyan to kọkọ jade lara ọyan fun ọjọ mẹta akọkọ lẹyin ti iya ba bi mọ tan dara pupọ, nitori pe awọn eroja to wa ninu rẹ dara fun ilera ọmọ tuntun.
Lẹ́yìn náà, Ahitofeli wí fún Absalomu pé, “Jẹ́ kí n ṣa ẹgbaafa (12,000) ninu àwọn ọmọ ogun, kí n sì bẹ̀rẹ̀ sí lépa Dafidi lọ lálẹ́ òní.
Ti wọn ṣi ṣetan lati kọ awọn ohun iranwọ ti wọn fẹ fun awọn ti ojo arọrọda ṣọṣẹ si agbegbe wọn, to si ba awọn ohun ini wọn ka.
Oni yi gan an si ni o pe ọdun mẹtalelọgọrin loke eepẹ.
N óo ṣe ìdájọ́ àwọn ará Moabu; wọn yóo wá mọ̀ pé èmi ni OLUWA!
4) Awọn to n ṣẹṣo yoo pade wahala nla.
Jesu wí fún un pé, “Dìde, ká ẹní rẹ, kí o máa rìn.
Àtẹ́rígbà ati ìloro rẹ̀ rí bákan náà pẹlu àwọn ti ẹnu ọ̀nà àkọ́kọ́.
 ) ( the winners of the heats run in the chief race .
Ninu ọrọ ti alukoro ileeṣẹ ọlọpaa, DCP Frank Mba fi sita, Ọga agba Adamu pa aṣẹ fun gbogbo awọn igbakeji rẹ, awọn kọmisọna ọlọpaa, awọn adari igun ọlọpaa kọọkan awọn ọgagun to moju to awọn bareke ni ipele ijọba ipinlẹ titi de ijọba apapọ, awọn ọlọ́paa MOPOL atawọn ikọ alaabo to ku lati tu sita fun iṣẹ yii.
Bẹ́ẹ̀ ni n kò ní pa gbogbo ẹ̀dá alààyè run mọ́ bí mo ti ṣe yìí.
Nítorí Ẹ̀mí Mímọ́ jẹ́rìí sí ọ̀rọ̀ náà fún wa.
"Báyìí ni 50k ṣe dá ìfẹ̀hónú ""Ali Must go"" sílẹ̀ tó mú ọ̀pọ̀ ẹ̀mí akẹ́kọ̀ọ́ lọ Wo ojú àwọn òṣèré yìí láì lo ""Make-up"" orí ìtàgé bó ṣe rí gẹ́lẹ́ Wumi Toriọla ti sọ̀rọ̀ sóke láti fi idí rẹ̀ múlẹ̀ pé òun àti ọ̀rẹ́ òun níjà Báyìí ni 50k ṣe dá ìfẹ̀hónú ""Ali Must go"" sílẹ̀ tó mú ọ̀pọ̀ ẹ̀mí akẹ́kọ̀ọ́ lọ Ẹni tó jí ọ̀pá aṣẹ ń bọ̀ wá túbá fúnrarẹ̀, mo fi dáa yín lójú gẹ́gẹ́ bí ìyá - Erelu Kuti Mi ò ṣẹ̀ máa pín ǹkan lọ́wọ́ ara mi fún aráàlù, ilé mi gangan kọ́ ni wọ́n ti jí ""Palliative"" kó - Họ́nọ́rébù Agunbiade Oṣere ni Oluwaremilekun Faith Fatolu ṣugbọn ti awọn ololufẹ rẹ maa n pe ni Auntie Remi."
 Ti eto si tun ti wa nile lati tesiwaju lodun 2019 ti won ba tun yan
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Foreign Secretary: Gboingboin ni a wà lẹ́yìn Nàìjíríà lórí ìgbógun ti Boko Haram 3 Èbibi 2019 Àkọlé àwòrán, Akòwé Àgbà Ilè Gẹ̀ẹ́sì ti sàbẹ̀wò sí àwọn ikọ̀ ọmọogun Naijiria tó ń kojú ikọ̀ agbésùnmọ̀mí Boko Haram ní Àríwá Naijiria.
Ní ìgbà kan tí ọba Siria ń bá ọba Israẹli jagun, ó bá àwọn olórí ogun rẹ̀ gbèrò ibi tí wọn yóo ba sí de àwọn ọmọ ogun Israẹli.
Ẹ óo ké pè mí nígbà náà,ṣugbọn n kò ní dáhùn.
Ènìyàn dúdú ni, ó fi dúdú wu ni.
N óo fi ìtara ati ibinu gbẹ̀san ìpànìyàn lára rẹ.
" Lawal sọ pe, o le ni biliọnu mẹ́sàn-án Naira (9.
Iran sọ ado oloro si ibudo awọn ọmọ ogun America lorilẹ-ede Iraq ni agbegbe Al-Asad ati ni inu Irbil Oríṣun àwòrán, Empics Àkọlé àwòrán, Ibudo naa ni won ti n woye nkan to ti baje bayii Fonran fidio to safihan bi ọkọ ofurufu naa ṣe ja yii ni Mehdrad Torabi gbe soju opo twitter re: Saaju asiko yii ni Aarẹ Trump ti sọ pe kiko ibudo ọmọ ogun America kuro ni Iraq ko le ṣenuure fawọn eniyan orilẹ-ede naa.
Lẹ́yìn tí a ti mọ odi náà tán, tí mo ti ṣe àwọn ìlẹ̀kùn rẹ̀, tí mo sì ti yan àwọn olùṣọ́ ẹnu ọ̀nà, ati àwọn akọrin ati àwọn ọmọ Lefi, 
seleri, bee si ni won ti fi da ajo to n motuto ere boolu afesegba lagbaye FIFA,
Abducted Child: Bàbà Aisha ní iléèwé ló ti ń bọ̀ nígbà tó bọ́ sọ́wọ́ ajínigbé lóṣù Kẹta
mí o ba ti jk ki o maa lọ láàlafia, sùgbọ́n ikwọ lo fi ọwọ ara rẹ fa wahala, inu mi si du pé mo wọ̀n kún fún ọ, ti o ba pàde ènìyàn ti oo mọ ri ni ọjọ míràn, o maa fi ara balẹ̀ láti mọ irú ẹni ti wọ́n jẹ́"" ""Mo jà bí ẹní pé mo mú nkan ni"" Bobrisky fi kún pé bi oun yóò ba tilẹ̀ gba ẹ̀bẹ̀ rẹ̀ yóò sùn mọjú ní àgọ́ ọlọàá yóò ra fóònù túntun Iphone X Max bákan náà ni yóò tún móto oun ṣe."
Nígbà tí ẹ̀mí mi ń bọ́ lọ,mo gbadura sí ìwọ OLUWA,o sì gbọ́ adura mi ninu tẹmpili mímọ́ rẹ.
Kogi, ogbeni  Matthew Kolawole to n soju
Bí Jesu ti rí wọn, ó pè wọ́n.
"Nígbà míràn àwọn ọmọde a pade mi lóju pópó láti bèrè idi ti mo fi pári, súgbọ̀n mí kìí mọ bí maa ṣe ṣe àlàyé lóri rẹ̀ Ríràn àwọn míràn lọ́wọ́ Liliya sàlàyé pé ìwà dídẹ́yẹ sini àti níní ìfẹ́ ara ẹni máà ń jẹ ǹkan to nira fun àwọn ọmọ to ni ààrun yìí àti òbi wọ́n, nítori ìdí èyí ni mó ṣe ń ràn wọ́n lọ́wọ́ fún égbẹ́ ti mó dá sílẹ̀ "" Mó mọ pè ọ̀pọ̀ òbí àwọn ọmọ tí wan ní ààrun tìí ma n fòyà pé ọmọ àwọn kò ni rí ọkọ fẹ́ tàbi rí iọṣẹ́ gidi."
Yorúbà sọ wi pé “Igi kan ki da a ṣe igbó”, eyi túmọ̀ si wi pé ki i ṣe Olóri Ìjọba Òṣèlú àti àwọn Òṣèlú yoku nikan ni ó yẹ ki ó ṣe àtúnṣe ohun ti ó ti bàjẹ́ fún ọ̀pọ̀lọpọ̀ ọdún ṣùgbọ́n gbogbo ọwọ́ ló yẹ ki ó ṣe àtúnṣe lati gbógun ti iwà ibàjẹ́.
alaga egbe agbe oniresi ni ipinle Ebonyi naa tun so pe eto eyawo ti awon ri gba
Ó lè jẹ ohun jíjẹ ti Ọlọrun rẹ̀, kì báà ṣe ninu èyí tí ó mọ́ jùlọ tabi ninu àwọn ohun tí ó mọ́.
Èmi Paulu, ẹlẹ́wọ̀n nítorí ti Kristi Jesu, ati Timoti, arakunrin wa, ni à ń kọ ìwé yìí sí Filemoni, àyànfẹ́ wa ati alábàáṣiṣẹ́ wa, 
Ìtàn ayé Seyi Makinde, gómìnà tuntun ní Ọ̀yọ́ Buhari, kò sí iṣẹ́, owó àti Oúnjẹ́ - Ọmọ Nàíjíríà figbe ta Bakan naa ni Sodo tun se sadankata si Makinde pe, o fọwọ gbaya pe awọn osisẹ ijọba ipinlẹ Ọyọ seese ki wọn gba owo osu to ju ẹgbẹrun lọna ọgbọn naira lọ.
Yóo ṣe ohun tí mo fẹ́ fún mi.
Nígbà tí Jesu dé inú Tẹmpili, bí ó ti ń kọ́ àwọn eniyan lẹ́kọ̀ọ́, àwọn olórí alufaa ati àwọn àgbààgbà ìlú wá sọ́dọ̀ rẹ̀, wọ́n bi í pé, “Irú agbára wo ni o fi ń ṣe nǹkan wọnyi?
Òkú ènìyàn mọ́kànlá ni mo rí níbi tí ìṣẹ̀lẹ̀ nàá ti wáyé, tó fi mọ́ òkú obìnrin kan tó n tọ́mọ lọ́wọ́.
gbe jade : “Lorukọ ajọ to n mojuto  eto isẹ 
    Ohun tí ó mú kí a tilẹ̀ pinnu àti lọ ilé ọba náà kò ju ti ilẹ̀ ẹ́ gbóná tí ó bẹ̀rẹ̀ sí ;i jà ti ó sì jẹ́ pé o ń pa púpọ̀ nínú wọn.
Lẹyin naa lo sọ fawọn ero to n ba sọrọ pe, ki wọn yabo ile aṣofin nibi ti wọn ti n fi ontẹ lu Joe Biden gẹgẹ bi aarẹ tuntun, ti Amerika ṣẹṣẹ dibo yan.
Oríṣun àwòrán, Others Ọpọ eeyan si lo ri olori agba bii ẹni to ko ni mọra, iya rere ati onifarada ẹda, ti kii kanra mawọn ọdọ ati olori kekere.
Nítorí ibinu gbígbóná OLUWA,ẹnikẹ́ni kò ní gbé ibẹ̀ mọ́;yóo di ahoro patapata;ẹnu yóo ya gbogbo ẹni tí ó bá gba Babiloni kọjá,wọn yóo sì máa pòṣé nítorí ìyà tí a fi jẹ ẹ́.
O lè mú wọn wá fún OLUWA gẹ́gẹ́ bí ọrẹ àkọ́so oko, ṣugbọn wọn kò gbọdọ̀ fi wọ́n rúbọ lórí pẹpẹ bí ẹbọ olóòórùn dídùn.
Ẹ kọ́kọ́ wádìí wọn láti mọ ẹni tí ó wá láti ọ̀dọ̀ Ọlọrun, nítorí ọpọlọpọ àwọn èké wolii ti wọ inú ayé.
Olori ile aṣofin ipinlẹ Ọyọ, Aṣofin Michael Adeyemo jade laye lowurọ ọjọ ẹti ni ileewosan Jericho nilu Ibadan.
Ìdí tí mo fi ń ṣe ayẹyẹ ọjọ́ ìbí 35 lọ́dọọdún rèé- Allwell Ademola Wo ojú Akeem t'Ọlọ́pàá mú pé ó fipá bá ọ̀dọ́mọbìnrin kan sùn létí odò l'Oṣun Ìjà d'ópin, fún ìgbà àkọ́kọ́, bàálù gbéra láti Israel lọ sí UAE Wọ́n ti sún ìdájọ́ àwọn sójà tó pa ìyá àti ọmọ ní ọdun 2018 sí oṣù tó m bọ̀ Ààrẹ Buhari buwọ́lu gbígbé ìṣàkoso nọ́mbà ìdánimọ̀ (NIMC) lọ sí ẹ̀ka ìjọba tó ń rí sí ìbáraẹnisọ̀rọ̀ Ninu ọrọ ti Remmy Hazzan, olubadamọran fun gomina ipinlẹ Ogun lori ọrọ ibanisọrọ ṣalaye fun ileeṣẹ iroyin naa, pe wọn ko tii le wọle.
Ṣiugbọn lẹyin ti orilẹ-ede Cameroun ti gbẹyẹ mọ New Zealand lọwọ pẹlu ami ayo meji si ẹyọ kan, ọwọ orilẹ-ede Thailand, tii yoo maa waako pẹlu Chile bayii ni idajọ ku si, lati mọ boya Falcons yoo tẹsiwaju tabi tẹ ọkọ leti pada sorilẹede Naijiria.
tí wọn ń fi ibinu lu àwọn eniyan láì dáwọ́ dúró,tí wọn ń fi ibinu ṣe àkóso àwọn orílẹ̀-èdè,tí ó ń ṣe inúnibíni lemọ́lemọ́.
Awọn eniyan bi ẹgbẹrun lọna aadọsan to ti sunmọ awọn to ni aarun Ebola lo ti gba abẹrẹ ajẹsara naa.
Wọn sọ Gauri ọmọ ọdun mẹrindinlogun di ọmọ ogun laarin ọsẹ kan wọn si ran an lọ soju ogun.
"Oríṣun àwòrán, Screenchot/@adedimejilateef Mr Macaroni sọ pe ""Ẹ mura si."
Ni bi a ṣe n sọrọ yii, erongba yii ti n ni ipa lori oju opo rẹ to jẹ pe o le ni ẹgbẹrun mẹfa ati ẹgbẹta eeyan lo n tẹlee.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Èmi àti Yaradua jùmọ̀ ṣe ìdánwò WAEC lọ́dún 1961 ni-Buhari Kí ló fà á t'Adeọsun tún fi wà lórí òpó ayélujára ìjọba?
4m Orukọ mii ti Anthony n jẹ ni Olaseni.
Awọn aladugbo obinrin naa sọ fun BBC pe ọdun to kọja ni ọkọ obinrin naa ku, oun atawọn ọmọ rẹ mẹta lo si n gbe ninu ile naa.
N30,000 ni mo gbà fún orí, ọwọ́ àti ẹran ara wòlíì Bosede - Kayeefi Ẹ kọ́ nípa ohun tí Yorùbá ń pè ní Àrígiṣẹ́gi Wọ́n ta ère Ọ̀ṣun Osogbo sí Togo - Bàbá Ọṣun figbe ta Baṣọ̀run Gáà, tó yan ọba mẹ́rin, pa ọba mẹ́rin àmọ́ ọba karùn-ún ló pa á Ẹ ba wa kalọ lati mọ ọpọ anfaani ti ejo ni fun eeyan tẹẹ ba jẹ ẹ, ninu fidio yii.
Ẹ̀mí sọ pàtó pé nígbà tí ó bá yá, àwọn ẹlòmíràn yóo yapa kúrò ninu ẹ̀sìn igbagbọ, wọn yóo tẹ̀lé àwọn ẹ̀mí ẹ̀tàn ati ẹ̀kọ́ tí ó ti ọ̀dọ̀ àwọn ẹ̀mí èṣù wá.
Oríṣun àwòrán, BBC Sport Ó lé ní ìgbà ènìyàn lo ti ṣe ódìgbà ó ṣe sí dúníyàn lẹ́yìn ìbúgbàmù Beruit.
 Èyí sì bí ilẹ ̀ america nínú , ìdí nìyí tí wọ ́ n fi dá ' sí ogun àgbáyé ní ọdún 1917 .
láti iwájú ẹnu ọ̀nà ní àbáwọlé, títí kan ìloro ẹnu ọ̀nà tí ó wà ninu, jẹ́ aadọta igbọnwọ (mita 25).
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Mo fẹ́ kí àyẹyẹ ìgbeyàwó mi dùn ni mo se bú sẹ́kún - Ọkọ ìyàwó ẹlẹ́kún Ebi yóò ti lu Nàíjíríà pa, tó bá jẹ́ PDP kò se dáadáa - Jonathan Ìjìyà síse ayédèrú isẹ́ onísẹ́ kò kún tó - Jide Kosọkọ Samuel Ladoke Akintọla jẹ́ Agbẹjọ́rò àti Akọ̀ròyìn tí ọ̀rọ̀ dá lẹ́nu rẹ̀ Àràbarà pósí rèé, ibùgbé ìkẹyìn tó jẹ ojú ní gbèsè Hubert Ogunde rèé, baba àwọn òsèré tíátà Ebi sọ ìyá àgbà di awa kẹ̀kẹ́ Maruwa O fikun pe inu oun maa n dun lati ba ọkọ oun rin ni titi, tawọn yoo si fa ara awọn lọwọ, bi o tilẹ jẹ pe awọn eeyan yoo maa fi ọwọ tọ̀ ara awọn lasiko tawọn ba n kọja ni popo.
Awọn agunbanirọ padanu ẹmi wọn lasiko awọ̀n eto idibo kan to ti waye ni Naijiria, ati ninu awọn iṣẹlẹ mi i.
“Nítòótọ́ mo jẹ́ aláìmọ̀kan jùlọ ninu gbogbo eniyan,n kò ní òye tí ó yẹ kí eniyan ní.
Pẹ̀lú èsì ìbò náà, Tambuwal ti wọlé padà fún sáà keji, gẹ́gẹ́ bíi gómìnà ìpínlẹ̀ Sokoto.
Aare wa ro gbogbo omo orile ede Naijiria lati se atileyin fun ijoba to wa lori aleefa paapaa julo nipa erongba re lati mu idagbasoke ba eto oro aje orile ede yii.
"Toyin Abraham ni o ti jẹ ohun to wu oun lọkan lati di abiyamọ, o si dupẹ pupọ pe Ọlọrun wa fun un ni ""Ire"" tirẹ."
Awọn oṣiṣẹ eleto ilera meji f'ara kaasa aarun iba lassa naa laarin ọjọ kẹrindinlọgbọ osu keji ọdun 2018 si ọjọ kẹrin osu kẹrin ọdun 2018 nipinlẹ Ebonyi.
Yóo fi ìdajì rẹ̀ dáná, yóo fi se oúnjẹ, yóo fi se ẹran rẹ̀ pẹlu.
Ninu iroyin miran, gbaju-gbaja oṣere to tun jẹ olokoowo, Lizzy Anjorin sọ pe itankalẹ aarun coronavirus ko le da ọja tita oun duro.
Kò ka àwọn ìwà àìṣedéédé wọn sí wọn lọ́rùn.
Oludari ere ọhun to n gbe niluu Jos lo n rinrinajo lọ si ipinlẹ Plateau lati Kaduna lọjọbọ to kọja pẹlu aburo rẹ, ati awọn ọrẹ nigba ti awọn ajinigbe naa da wọn lọna.
Wọ́n dàbí kinniun tí ó ṣetán láti pa ẹran jẹ,àní bí ọmọ kinniun tí ó ba ní ibùba.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Títí d'òní, Bàbá mi dara pọ̀ mọ́ iṣẹ́ ológun kò sí padà wálé - Grandma Biafra A wa gbadura pe Ọba oke tẹ Alfred Olabode Akanni Thomas si afẹfẹ rere nibayii to ti pe ọdun mẹtadinlaadọrin to ti jade laye.
Oríṣun àwòrán, @kizento_ Koda, wọn tun tu awọn afurasi to wa ni ahamọ silẹ, ti wọn si tun jo lara agọ ọlọpaa kan.
Aare Buhari soro naa di mimo lasiko ipade re pelu asoju tuntun ile Denmark si Naijiria, ogbeni Jesper Kamp, aare Buhari fikun un oro re pe, orile-ede Naijiria setan lati fayegba orile-ede kookan lagbaye to ba fe ni ajosepo pelu re, paapaa julo ni eka eto agbe ati okoowo.
O yẹ kẹ ranti lẹta to kọ si aarẹ Muhammadu Buhari lati jẹ ko mọ bi ori se n ta araalu si nipa ọrọ aje to dagun ati eto aabo to mẹhẹ, eyi to lapa rere.
Ní etí gbogbo àwọn eniyan, Jesu sọ fún àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ pé, 
Wọ́n ń fi yé wọn pé kí eniyan tó wọ ìjọba Ọlọrun, ó níláti ní ọpọlọpọ ìṣòro.
Awọn agbalagba ati awọn ti wọn ti ni aisan lara tẹlẹ (bii itọ ṣuga, aisan inu ọkan ati ikọ efee) le ṣaisan gidi.
Nígbà tí a dé ibi tí wọ́n wà tí a wo apá kan àgbàlá náà báyìí, egungun agbárí ènìyàn tíó wà ní ibẹ̀ ju ẹgbẹ̀rún lọ.
" Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Àwòkọ́ṣe ìwà ìrẹ̀lẹ̀, òtítọ́ àti olùfẹ́ mẹ̀kúnnù ni Ayo Fasanmi - Ìjọba Osun Àwa àti fijilanté pẹ̀lú ọdẹ́ ìbílẹ̀ ló dojú kọ adigunjalè ní First Bank Okeho - Iléeṣẹ́ ọlọ́pàá Ọmọ mi kò tíì mọ̀ pé òun ti di ìlúmọ̀ọ́ká, ó ń wádìí bó ṣe ń rí ara rẹ̀ lórí ayélujára"" Ìtàn ọba Yorùbá tí wọn yẹgi fún torí ó jí ọmọ gbé ṣe ètùtù Ẹ káàbọ̀ sọ́jọ́ Arafat, tí Ọlọ́run yóò fi ààwẹ̀ Mùsùlùmí pa ẹ̀ṣẹ̀ wọn rẹ́ O tẹsiwaju pe, ọmọ ogun ọhun, ti wọn ko darukọ rẹ, ṣekupa oloogbe naa, niwaju olu ileeṣẹ wọn, nigba ti oloogbe n ba ẹnikan sọrọ lori ẹrọ ilewọ."
Ẹnikan to lọ si ibi iṣẹlẹ naa tiẹ sọ pe pata ti Grace wọ ti ya gbalagbala.
Ẹ̀yin náà mọ̀ pé gbogbo agbára mi ni mo ti fi sin baba yín, 
Bí àrùn ẹ̀tẹ̀ bá bo gbogbo ara eniyan láti orí dé àtẹ́lẹsẹ̀ níwọ̀n bí alufaa ti lérò pé ó lè mọ lára eniyan, 
Alufaa yóo wá bu díẹ̀ ninu ẹbọ ohun jíjẹ yìí, gẹ́gẹ́ bí ẹbọ ìrántí, yóo sì sun ún lórí pẹpẹ.
Adehun naa ni wọn ro wipe yoo ṣe iranwọ fun ọja tita laarin awọn eniyan to le ni biliọnu kan pẹlu ireti pe owo to le ni trilion meji dọla.
Aare Buhari wa seleri atileyin ijoba apapo lati ri daju pe iko ohun tesiwaju lati maa se aseyori ni gbogbo ona.
Ìwà ipá nínú ìdílé máa ń bí ìgè àti àdùbí ni tó lè já sí ikú
Oríṣun àwòrán, LASEMA Àkọlé àwòrán, Eniyan mẹrin ni o padanu ẹmi wọn Afikun yoo ba owo ẹnu ibode Ikoyi, Lekki Afikun owo'bode Lẹkki fa ibinu araalu Ileeṣẹ Laema wipe awọn ti palẹ mọ ibi ti ijamba ọkọ naa ti ṣẹlẹ.
Iroyin naa si jẹ eyi to ba ni lọkan jẹ pupọ.
Àwọn ọkunrin náà bá gbé ẹ̀bùn náà, wọ́n sì mú ìlọ́po meji owó tí wọ́n nílò, ati Bẹnjamini, wọ́n lọ siwaju Josẹfu ní Ijipti.
Agbára Dafidi bẹ̀rẹ̀ sí pọ̀ sí i, nítorí pé OLUWA Ọlọrun àwọn ọmọ ogun wà pẹlu rẹ̀.
Ipele akoko ni Oloogbe Grace Oshiagwu wa ni ile ẹkọ giga gbogboniṣe, Oke Ogun Polytechnic, Saki nipinlẹ Ọyọ.
Ó tọ́ bẹ́ẹ̀ nítorí pé igbagbọ yín ń tóbi sí i, ìfẹ́ ẹnìkọ̀ọ̀kan yín sí ara yín sì ń pọ̀ sí i.
Pasitọ Suleman naa loun yoo gbe awọn ọmọ Naijiria wale O jọ pe igbesẹ ti Allen Onyeama gbe yi ti ṣe koriya fawọn miran lati nawọ iranwọ sawọn to fẹ wale lati South Africa.
Oríṣun àwòrán, Other Ifura Kurunmi yìí ń di òótọ́ nígbà tí Ibadan tẹsiwaju láti máa gba isakọlẹ lọ lọ́wọ́ àwọn ìlú amọna tó wa lábẹ́ rẹ, tó si ń rọ Ìjàyè pé kó lọ san isakọlẹ tiẹ̀ sì Ọ̀yọ́, lai gba àwọn ìlú abẹ rẹ láàyè láti ṣe bẹ́ẹ̀.
Igbesẹ Oluwoo ti ilu Iwo, Ọba Adewale Akanbi, lo fa sababi ọrọ yi.
 O je ise akanse ti mo fi inu didun sise fun lati odun meta abo seyin gege bi gomina.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Èmi gan máa ń béèrè lọ́wọ́ ara mi pé ta ni Wole Soyinka gangan' Olunloyo sì lo gbe adé àti ọ̀pá àṣẹ fún Aláàfin ti Ọ̀yọ́, Ọba Lamidi Olayiwola Adeyemi Kẹta lórí nigba to jẹ Ọba.
Ọkunrin náà ṣe bí Josẹfu ti pàṣẹ fún un, ó sì mú àwọn ọkunrin náà wọ ilé Josẹfu lọ.
Eniyan óo wá fi ayọ̀ wá siwaju Ọlọrun,yóo sì ròyìn ìgbàlà Ọlọrun fún gbogbo aráyé
 Ọ ̀ gbẹ ̀ rì akọrin-ifá ni yóò máa fi oríṣìí ohùn kan náà gbe ara wọn .
"Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ikọ̀ aláàbò Nàìjìríà dojú kọ Shiite Ọlọ́pàá mú 115 ẹlẹ́sìn Shiite Ọlọ́pàá àti Shiites tún fìjà pẹ́ẹ́ta Muftau Zakariyau, tó jẹ́ Olùdarí ẹgbẹ́ Shiite ní ẹkùn Gúúsù ìwọ̀ oorùn Nàìjíríà, sọ fún BBC Yorùba pé, ''àwọn wá láti sọ fún Tinubu pé Buhari tó gbé wọlé sípò ti gbàbọ̀dè fún Nàìjíríà""."
Àwọn meje tí wọ́n rù hangangan náà ki àwọn meje tí wọ́n sanra rọ̀pọ̀tọ̀ rọ̀pọ̀tọ̀ mọ́lẹ̀, wọ́n sì gbé wọn mì, Farao bá tají.
”Akonimoogba agba iko Manchester United, Jose Mourinho  naa ti so tele ri pe, Ibrahimovic yoo kuro ninu iko naa ti iwe isise re naa ba wasi ipari ni saa yii.
 a má a ṣiṣẹ ́ lára iye àwọn ènìyàn tó fẹ ́ rẹ ̀ tó 95 % nínú àwọn tó gbàá , agbára rẹ ̀ a sì má a wà fún ìgbà tó tó , ó kéré jù , ọdún mẹ ́ ẹ ̀ dógún , tó bá sì ṣeé ṣe , jálẹ ̀ ìgbé-ayé ènìyàn .
Lẹyin eyi ni ileekọ fasiti Babcock fi atẹjade kan sita pe akẹkọ ileewe naa ni ọmọbinrin ti wọn n ba lopọ ninu fidio naa, to si jẹ akẹkọ ọlọdun kẹta ni ẹka ẹkọ nipa imọ isiro owo.
Wọ́n bá kó àwọn ẹran ọ̀sìn wọn tọ Josẹfu lọ, Josẹfu sì fún wọn ní oúnjẹ dípò àwọn ẹran ọ̀sìn wọn, agbo ẹran wọn, agbo mààlúù wọn ati kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ wọn.
Sunday Igboho rán agbénipa sí mi láti gb'ẹ́mi mi-Auxilliary Èèyàn 20 mííràn tún ti lùgbàdì ààrùn Coronavirus ní Naijiria Síńimá kòṣewòtán, Pásítọ̀ fo fẹ́ǹsì láti sá mọ́ agbófinró lọ́wọ́ ní Àkúrẹ́ 82% ọkùnrin ní kó mọ̀ pé òun ní àìsàn jẹjẹrẹ asẹtọ ní Naijiria Gẹgẹ bi ohun ti eeyan kan to ṣoju rẹ sọ ni kete ti ọrọ ja jo alagba Olowokande lọwọ tan lo bẹlugbẹ to si na papa bora lati lee sa mọ panpẹ awọn ọlọpaa lọwọ.
Ọkùnrin kan wà ní ìlú lápá-edé , olówó ní í ṣe .
Àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ bá lọ jí i; wọ́n ní, “Oluwa, gbà wá là, à ń ṣègbé lọ!
"Gbogbo ènìyàn ni yoo maa fi oju si ìjọba ìbílẹ̀ yìí lára nítori pé, ọ̀pọ̀ ló ní ìgbàgbọ́ pé, ""ọmọ wa ni ẹ jẹ kó ṣee"" ni wọ́n yoo fi ṣe."
Amasaya ọba, ọmọ Joaṣi gbé ọdún mẹẹdogun lẹ́yìn ikú Jehoaṣi ọba Israẹli.
Mo gbadura sí OLUWA, mo ní, ‘OLUWA Ọlọrun, má ṣe pa àwọn eniyan rẹ run.
Hilikaya alufaa, ati Ahikamu ati Akibori ati Ṣafani ati Asaya bá lọ wádìí lọ́wọ́ wolii obinrin kan tí ń jẹ́ Hulida, tí ń gbé apá keji Jerusalẹmu.
Ní ọjọ́ mejeeje yìí, ẹnikẹ́ni kò gbọdọ̀ ṣiṣẹ́ rárá, àfi oúnjẹ tí ẹ óo bá jẹ nìkan ni ẹ lè sè.
Nibi ipade ọhun ti yoo waye loju opo ibaraẹnisọrọ Zoom ni NDCD, pẹlu ajọṣepọ NYSC ati PTF yoo ti da awọn ọdọ naa lẹkọọ lori awọn ohun to yẹ ki wọn ṣe lati dabo bo ara wọn.
Ìjìyà ń bẹ fún àwọn ti adé ọ̀rọ̀ náà bá ṣí mọ́ lóri -Ọga àgbà FRSC Ta ni Seun Fakorede, ọmọ ọdún 27 tó fẹ́ di kọmiṣọna?
Ààlà ti apá ìhà gúsù ilẹ̀ náà bẹ̀rẹ̀ ní àtiwọ ìlú Kiriati Jearimu lọ títí dé Efuroni, títí dé odò Nefitoa, 
Wayi o, Lizzy wa salaye lẹyin o rẹyin pe oun kuku ki Toyin ku oriire ọmọ tuntun amọ oun ko polowo tabi gbe larugẹ gẹgẹ bi awọn osere yoku tii n se, ni ko jẹ ki ọpọ eeyan mọ pe oun ki Toyin ku ewu ọmọ.
m ni ojú mi déédé fọ́ níbi tí mo ti ń darí ọkọ̀ ni Ọrẹgun Ikẹja -LASTMA Yesufa Inú mi dùn pé ẹni tó gbà ìjọba lọ́wọ́ mi ń san gbèsè tí mo fi kalẹ - Aregbesola Dokita Aro ni, ni kete ti oun ti kofiri awọn ami aipe ara naa, ni oun ti fi to olori ikọ isegun to wa lati ipinlẹ Eko leti, tawọn si gbe lọ sile iwosan pẹlu ọkọ alaisan pajawiri, nibi ti wọn ti fidi rẹ mulẹ pe aisan iba ni Kẹmi ni, ti wọn si fun ni abẹrẹ fun ọjọ mẹta.
Ẹwẹ, Aarẹ Ọna Kakanfo ni koda bi ipo ààrẹ ba bọ si ọwọ̀ iran Yoruba, o ṣee ṣe ki o buru ju ti ẹlomii gan lọ.
"Ninu ọrọ rẹ, Ọga agba ẹgbẹ agbabọọlu Arsenal, Ivan Gazidis, ni, ""Ọkan lara awọn agbabọọlu ti mo fẹran julọ ni Santi jẹ."
Ọkan lara awsn arinrinajo naa to ba BBC News Yoruba sọrọ to pe ara rẹ ni Labakẹ ṣalaye pe pupọ ohun ti awọn alaṣẹ n fi oju awọn ri ni ko kun oju iwọn ati pe wọn ko ro tiwọn rara ninu eto wọn.
Òun kan náà ni a fi ń ṣépè fún eniyan tí a dá ní àwòrán Ọlọrun.
N óo sọ àwọn ìlú rẹ di aṣálẹ̀ìwọ pàápàá yóo sì di ahoro;o óo wá mọ̀ pé èmi ni OLUWA.
àwọn eniyan kan, tí wọ́n wá láti Ijipti, tẹ̀dó sórí gbogbo ilẹ̀ òun.
Ṣugbọn ẹ̀yin àyànfẹ́ mi, ẹ̀yin ẹ ranti ohun tí Oluwa wa Jesu Kristi ti ti ẹnu àwọn aposteli rẹ̀ sọ tẹ́lẹ̀.
Igba miran, wọn a ba awọn dukia ẹgbẹ bẹ jẹ.
N óo fún àwọn ẹlẹ́rìí mi meji láṣẹ láti kéde iṣẹ́ mi fún ọtalelẹgbẹfa (1260) ọjọ́.
Ọpọ lo fẹ ri bawọn mejeeji ti jọ sun pọ ninu ile Ozo to jẹ olori ile.
“Àwọn ará Pasia ati àwọn ará Ludi ati àwọn ará Puti wà láàrin àwọn ọmọ ogun rẹ bí akọni.
Kí n má gbẹ̀san ara mi, lára irú orílẹ̀-èdè yìí?
Wọ́n sọ ilẹ̀ rẹ̀ di ahoro.
Bakan naa ni oludari OPC ni agbegbe Ibarapa sọ pe inu ọkọ bọọsi mẹta ni wọn ti mu awọn afurasi naa to digun mọra.
"Bi igba ti a fẹ mọọmọ gba ẹmi ara wa ni taa ba n wọ asọ ọlọpa lati le awọn ọdaran.
Lẹ́yìn gbogbo ohun tí ó ṣẹlẹ̀ sí wa, nítorí ìwà burúkú wa ati ẹ̀ṣẹ̀ ńlá tí a dá, a rí i pé ìyà tí ìwọ Ọlọrun fi jẹ wá kéré sí ẹ̀ṣẹ̀ wa; o jẹ́ kí àwa tí a pọ̀ tó báyìí ṣẹ́kù sílẹ̀.
Oríṣun àwòrán, Facebook/Gabola-Church Ọrọ naa ṣe yin ni haa hun abi?
Sẹnetọ Rafiu salaye pe, igba ti aba ofin naa ba de iwaju awọn asofin, ni wọn yoo ṣe ayẹwo rẹ finifini, lẹyin eyi ni wọn yoo ṣe atunse si ofin to nii ṣe pẹlu owo oṣu oṣiṣẹ ni Naijiria.
yoo ran awon ọdọ lọwọ lati le koju ipenija  ati  awon anfaani ode –oni.
Omo egbe ECOWAS tun fe ki awon omo orile ede China wa fun  ere igbafẹ lorile ede Afirika.
Awọn asiwaju ikọ alaabo gbogbo lorilẹede Naijiria naa yoo maa darapọ mọ ọgagun ileesẹ ọmọogun ofurufu, Sadique Abubakar pẹlu alakoso eto aabo patapata lorilẹede Naijiria, Ajagunfẹyinti Babagana Monguno to ti digba-dagbọn rẹ lọ ẹkun naa saaju akoko yii.
“Ní àkókò náà, wọn yóo fà yín lé àwọn eniyan lọ́wọ́ pé kí wọ́n jẹ yín níyà, kí wọ́n sì pa yín.
Ile-ise olopaa lorile-ede Turkey tun ti mu awon afurasi meji miiran latari esun ti won fi kan won pe, won lowo si ikolu sile asoju orile-ede Amerika(United States embassy) eyi ti o waye lojo aje(Monday) ni olu-ilu orile-ede ohun ti n se Ankara.
Ni ọmọ ọdun mkanla lo ko lọ si ilẹ UK lati maa gbe nibẹ O ti di ọmọ ilu ọba to ni iwe igbe ilu labẹ ofin bayii bẹẹ lo si tun jẹ ọmọ Naijiria nipa ìbí.
Nǹkan tí mo fẹ́ kí ẹ ṣe fún wa nìyí, mo fẹ́ kí ẹ ṣe àpèjúwe ọ̀nà ffún wa dáadáa, nítorí bí Ọlọ́run kò bá kọ ìlérí, ilẹ̀ kò níi í mọ́ bá mi ní ilé yìí lọ́la.
Ó dìgbà o, ìyá mi, dandan ni pé kí a pínyà lònìí, nítorí ìwọ kò sí láàárin ará ayé mọ́, ìwọ wà láàárin àwọn ará ọ̀run, kí bàbá mi fún mi, ọ̀gbẹ́ni Akọ̀wédìran, ki ẹ má ṣe gbàgbé mi kí ẹ máa bá mi bẹ Ẹlẹ́dàá kí Ó ṣe ọ̀nà mi ní rere.
ṣe wọn yoo ni ki wọn maa lọ si ile bii ti awọn orilẹede kan nii?
Ibi tí a ti ń wá Ewédayépọ̀ kiri ni ẹni kan ti wáá yọ́ kẹ́lẹ́kẹ́lẹ́ sọ fún wa wí pé Ewédayépọ̀ kò sí nínú ìyàrá àti wí pé ó ti sá gun òkè àjà lọ.
mefa lati gbogun ti iko sunmọmi ni ekun Ariwa, paapaa julo ni ipinle Katsina.
Àwọn kan ninu àwọn amòfin dá a lóhùn pé, “Olùkọ́ni, o wí ire!
Ẹni tí ó bá wà lóko kò gbọdọ̀ pada sẹ́yìn láti lọ mú ẹ̀wù rẹ̀ tí ó bọ́ sílẹ̀.
Ọlọrun lọ bá a níbẹ̀, Balaamu sì sọ fún Ọlọrun pé, “Mo ti tẹ́ pẹpẹ meje, mo sì ti fi akọ mààlúù kọ̀ọ̀kan ati àgbò kọ̀ọ̀kan rúbọ lórí pẹpẹ kọ̀ọ̀kan.
Boya ni o tilẹ ti gbọ nipa owo anabọ ri?
Ninu ọrọ ibanikẹdun rẹ, aarẹ Buhari pẹlu tun gbadura itunu fun alagba Faṣọranti.
Ṣùgbọ́n bí mo ti dé ọ̀hún ni ẹni ti mo wá lọ ti gbọ́ pé mo dé, ó sì sá bá oko lọ, mo wá àbúrò mi títí n kò rí i, nígbà tí ó pẹ́ ṣa mo gbúròó rẹ̀ pé ó wà lóko, mo sì fi ènìyàn ṣe ènìyàn wọ́n mú mi lọ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Fasoranti: Dẹ́rẹ́bà tó wa ọmọ Fasoranti ṣàlàyé bí wọ́n ṣe pa Funke Olakunrin Ninu ọrọ rẹ, o ni ijọba n se aito lori bi wọn se n koju ipaniyan ati ijinigbe nitori awọn eleto aabo maa n sa gbogbo agbara wọn lati ri wi pe ki wọn má gba ẹmi awọn olowo lawujọ, sugbọn ẹmi awọn araalu ko jọ wọn loju.
0 1366 Orilẹ́ẹede Boswana 34 1.
Bakan naa ni wọn tun ṣalaye pe lootọ ara Ajimọbi ko ya, sibẹ o wa laaye ko ku.
Mo sì tún ń gbadura pé kí ó lè là yín lójú ẹ̀mí, kí ẹ lè mọ ìrètí tí ó ní tí ó fi pè yín, kí ẹ sì lè mọ ògo tí ó wà ninu ogún rẹ̀ tí yóo pín fun yín pẹlu àwọn onigbagbọ, 
Coronavirus in Nigeria: Seyi Makinde fojú hàn n'íta fún ìgbà àkọ́kọ́ lẹ́yìn tó ṣẹ́gun Coronavirus
Josẹfu bá ranṣẹ láti pe Jakọbu baba rẹ̀ wá ati gbogbo àwọn ẹbí rẹ̀.
Ẹni to bori: Algeria Guinea vs Congo DR.
Oríṣun àwòrán, twitter/Seyi makinde Bakan naa lo tun fi kun un pe awọn ileejọsin pẹlu lee pada si nii ṣi ilẹkun wọn silẹ fun ijọsin lati ọjọ Aje kan naa Sugbọn ida kan ninu mẹrin awọn eeyan to n wa si ileejọsin naa tẹlẹ ni aye gba lati maa jọsin fun asiko yii na ti wọn ko si gbọdọ maa tẹle ofin ati ilana igbimọ amuṣẹya naa.
Ọ̀rọ̀ nípa rẹ̀ yóo yé àwọn tí kò gbúròó rẹ̀ rí.
Ṣugbọn kí àkókò igbagbọ yìí tó tó, a wà ninu àtìmọ́lé lábẹ́ òfin, a sé wa mọ́ títí di àkókò igbagbọ yìí.
Idunnu ṣubu layọ nibi ikọmọjade ọmọ tuntun ti Ọlọrun ta idile Ọjọgbon Samuel Olu Otubusin lọrẹ lẹyin ogoji odun ti wọn ṣe igbeyawo.
Abramu di ẹni tí ó ní ọpọlọpọ aguntan, akọ mààlúù, akọ kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́, iranṣẹkunrin, iranṣẹbinrin, abo kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́, ati ràkúnmí.
Ohun tí o ṣe yìí kò dára, mo fi OLUWA ṣe ẹ̀rí pé, ó yẹ kí o kú, nítorí pé o kò dáàbò bo oluwa rẹ, ẹni àmì òróró OLUWA.
Ibe Kachikwu ti fèsì wí pé òun kò parọ́ ìwé ẹrí, bí kò ṣe wi pé àwọn akọ̀ròyìn ṣi òun gbọ́ ní.
Aarẹ Rwanda, Paul Kagame gba eku ida adari ajọ AU
Ajọ naa ni Adesina ko jẹbi kankan ninu gbogbo ẹsun iwa ajẹbanu ti wọn fi kan an.
Sihoni kò gbà kí àwọn ọmọ Israẹli gba orí ilẹ̀ rẹ̀ kọjá.
O fikun-un pe, idije ohun yoo se iranwo lati sawari awon odo ti o lebun ere boolu afesegba.
Ẹ̀we, ewu yiì ti di ọ̀rọ̀ ti wọ́n ń fà nitori pe asíídìì to wà nínú rẹ̀ ga púpọ̀.
Ìyá mi a máa sọ̀rọ̀ kan fún àwa ọmọ rẹ̀ nígbà tí a wà ní èwe ó sì sọ ọ fún wa títí a fi dàgbà, a máa wí báyìí pé ẹni tí ó bí ọmọ tí ọmọ náà kò gbọ́n ń ṣe òwò àṣedànù.
Ọ̀rọ̀ orin tí ó lágbára gbérí, ọgbọ́n ń tayọ àti ìrìnàjò ìṣíjú ojú ẹsẹ̀:
Ènìyàn Abódiakọ-akọ́diabo tí ó tó bí 250 láti agbègbè jákèjádò ìlú Pakistan.
’’John Momoh, alaga fun egbe akoroyin lorilẹ ede  Naijiria lo dari ijiroro naa.
Mo fẹ kọkọ ni owo temi na ki wọn ma baa ni mo fẹ wa kowo jẹ nigba ti mo ba kara bọ oṣelu.
Ẹnikan to wa lati China lo ra ẹyẹle New Kim to jẹ abo ti ko si ju ọdun meji lọ.
Oríṣun àwòrán, @NGRPresident Àkọlé àwòrán, Ọjọ mẹrin ni ife naa yoo lo lorilẹede Naijiria ni ilu Abuja ati Eko O ni ọjọ mẹrin ni ife naa yoo lo lorilẹede Naijiria ni ilu Abuja ati Eko.
Republic lojo Aiku lasiko to n ba adari ile –ifowopamo ti awon musulumi soro
Ó tún fi kún un pé, “Mo fẹ́ kí ẹ mọ̀ dájúdájú pé kò sí wolii kan tíí ní iyì ní ìlú baba rẹ̀.
Nígbà tí Mose rí ìran náà, ẹnu yà á.
Amọ wn ni ọkan ninu awọn oluranlọwọ fun Bola Tinubu ti lugbadi arun naa to si ti ya ara rẹ sọtọ.
Ṣùgbọ́n èmi pàápàá mọ̀ pé ó túbọ̀ ń fẹ́ràn mí sí i.
 Àgbàrá-òkè yìí ni wón wá fi ń pe àdúgbò yìí kí ó tú di wí pé , ó ń jé òkè-àgbàrá tàbí òkè-àgbàá .
Igba lara wọn lo ti pada sile, sugbọn Ọgbẹni Shehu sọ pe ijọba ń gbiyanju lati mọ iye akẹkọọ to ṣe e ṣe ko fọn kaakiri agbegbe naa, lẹyin ti wọn sa lasiko ikọlu to waye.
 Ìdí rèé tí mo fi yan ikọ̀ PMS rọ́pò NURTW nípìnlẹ̀ Oyo - Seyi Makinde ""Buhari, Olóṣèlú àtàwọn òjíṣẹ́ Ọlọ́run ló mú àjẹbánu gogò ní Nàíjíríà"" Ooni Adeyeye ti Ile Ife fẹ sèrànwọ́ owó iléèwè fún akẹ́kọ̀ọ́ 5 mílíọ̀nù ní Nàìjíríà Ọkùnrin kan rí ẹ̀wọn he lẹ́yìn tó lu obìnrin ní jìbitì ìfẹ́ tí iye rẹ̀ tó $15,000 lórí ayélujára Nibayii wọn ti gbe ọpa aṣẹ naa fun kọmisọna ọlọpaa ipinlẹ Eko, Hakeem Odumosu to ti paṣẹ fun igbakeji kọmisọna ni ẹka ọtẹlẹmuyẹ, Yetunde Longe, lati da abo bo ọpa aṣẹ naa ko si kan si awọn ọlọpaa ipinlẹ Ogun lorii didaa pada."
Àkọlé àwòrán, Ijọ Sotitobirẹ: Idí ilé òrìsà ni ọ̀rọ̀ náà yoò ti yànju- Ọọni Ife Ní ọjọ ru ni òkíkí kan pé wọ́n ri òkú ọmọ kan nibi ti wọ́n rì í mọ́lẹ̀ si niwáju pẹpẹ ilé ìjọsin Sọtitobirẹ, èyí si lo ṣe okùnfa ti àwọn ọdọ àti ara ilú fi lọ dána sun ilé Woli àti ijọ Sotitobirẹ nilu Akure.
Ọmọ aráyé a máa fkláti wa iṣu níbitíwọn kò gbìn iṣu sí, wọn a máa béèrè ọ̀gẹ̀dẹ̀ níbi tí wọn kò tọ́jú ọ̀gẹ̀dẹ̀ sí, àwọn tí kò bá lè fi kọ́bọ̀ tọrẹ wọn a máa fẹ́ kí ẹlòmíràn fisísì fún àwọn.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Obinrin jẹ amuludun' Gerard Lambe.
Afurasi naa, ti ko ní agbẹjọro to ṣoju rẹ nile ẹjọ sọ pe, awọn ọrẹ oun lo fi ọgbọ́n ẹ̀wẹ́ fa oun sinu iwa buruku naa, to si tun bẹbẹ pe ki ile ẹjọ siju aanu wo oun.
Akọ̀ròyìn Morocco, Hajar gbà ìdájọ́ ẹ̀wọ̀n lórí ẹ̀sùn àgbèrè àti pé o ṣẹ́yún Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
’’Ugba tun so pe orile ede Naijiria gbosuba fun  awọn  ololufe yii bi wọn  se lo si orile ede Russia lati  lo yẹ  awọn  Super Eagles  si lorile ede Russia.
Ìpínlẹ̀ Ọ̀ṣun kò le è sanwó o ọmọ́gọ̀ lórí LAUTECH- Gómìnà Oyetola Ìjọba àpapọ̀ kò leè ṣùn torí ìyanṣẹ́lódì òṣìṣẹ́ tó ń bọ̀ A ti gbé kọ́kọ́rọ́ sẹ́nu ibodè Nàìjíríà kí ọrọ̀ ajé wa leè gbé pẹ́lí- ìjọba àpapọ̀ Rape: Norma Ka Mbele ní ayé òun kò rí bákàn náà mọ́ lẹ́yìn ìfipábálòpọ̀ Sanwo-Olu: Etí mi kò di sí ìrora aráàlú, ẹ fara dàá pẹ̀lú mi Ni bayii, ọpọ awọn ẹlẹgbẹjẹgbẹ ati ọlọgbajọgba ni wọn ti jade lati wi tẹnu wọn lori ọrọ yii.
Gbóhùn mi nítorí ìfẹ́ rẹ tí kì í yẹ̀,OLÚWA, dá mi sí nítorí òtítọ́ rẹ.
Lana ọ̀jọ́bọ ni Olujẹri (Police witness), Hassan Attila ṣe àlàyé fún ilé ẹjọ́ bí ọwọ sikun àwọn ọlọ́pàá tí ṣe tẹ àwọn afurasí náà tí wọ́n sì gbé wọn lọ olú ilé ìṣe àjọ ọlọ́pàá ní ìlú Abuja nínú osun karùn-ún ọdún 2018.
Gomina ipnlẹ Ogun, to fi mọ awọn eekan lawujọ lo ṣedaro rẹ gẹgẹ bi gbajumọ to si tun jẹ eniyan pataki ni awujọ.
Gomina ipinle Ọyọ, Seyi Makinde ti fi orúkọ Seun Fakorede, ẹni ti o je ọmọ ọdun metadinlọgbọn ránsẹ́ si ile igbimọ asofin ipinlẹ naa, fún ipò kọmíṣónà.
OLUWA a máa ràn wọ́n lọ́wọ́, a sì máa gbà wọ́n;a máa gbà wọ́n sílẹ̀ lọ́wọ́ àwọn eniyan burúkú,a sì máa gbà wọ́n là,nítorí pé òun ni wọ́n sá di.
Awọn eniyan kii wa ẹni ti yoo sọ fun wọn wipe nnkan ti awọn n ṣe ko dara.
"Ọlọpaa to rojọ tako o nile ẹjọ, ASP Eze Nnabuaku, sọ fun ile ẹjọ pe, ""ijiya wa fún awọn ẹsun ti wọn fi kan Kingsley, ninu ofin ọ̀daràn, ti ipinlẹ Ebonyi."
Oríṣun àwòrán, Twitter/@ayemojubar Ifẹhonuhan lori afikun owo epo ọdun 2004 Iyansẹlodi ati ifẹhonu han tun bẹrẹ lọdun 2004 lẹyin ti ijọba Obasanjo tun ṣe afikun owo epo bẹntiro lati N40 si N45.
Nítorí náà, mo bẹ̀ ọ́, dáríjì mí, kí o sì bá mi pada, kí n lọ sin OLUWA níbẹ̀.
Abdel Moneim Abol Fotouh ati awon adari miiran ninu egbe oselu ni won fi owo sinkun ofin mu lojo-Bo , leyin ojo keji ti o pada de lati ilu London, nibi ti won ti foro wa lenu wo lori Aare Abdel Fattah al-Sisi.
Amọ bi o tilẹ jẹ pe Toyosi moribọ lọwọ isẹlẹ iku naa, awakọ to wa ọkọ to wa ninu rẹ ko ye isẹlẹ naa, to si gba ibẹ lọ si ọrun alakeji.
'Daura' di orúkọ tó ń bí awuyewuye lóríṣiríṣi ní ayélujára
Ó ṣẹ ẹranko, emi náà rọra jókòó mo ká gúlútú lórí igi.
Pa orúkọ wọn rẹ́ kúrò ninu ìwé ìyè;kí á má sì kọ orúkọ wọn mọ́ ti àwọn olódodo.
O tun fikun pe, ọpọ isẹ ribiribi ni oun n se gẹgẹ bii agba osere laarin awọn ọjẹ wẹwẹ onitiata nidi hihu iwa to tọ lawujọ ati didẹẹkun wiwọ asọ iwọkuwọ.
Maria Tú Òróró Dà Sára Jesu ní Bẹtani.
Iroyin so pe, awon agunbaniro mejilelogun lo ko ra won lo sibi odo naa lati lo wedo ki isele buruku ohun o to waye.
Alapinni rọ awọn eniyan ki wọn farabalẹ kọ iṣẹ ti wọn ba yan laayo ki wọn le di agba ọ̀jẹ̀ nibẹ koda ko ṣe iṣẹ tiata.
 Ọmọ ẹgbẹ tuntun ti wọn ṣẹsẹ yan saarin wọn ni Ọgbẹni Afọlabi Ayantayọ, ti o ti jẹ Akọwe-agba fun ijọba ibilẹ Agege fun igba mẹta ri.
N kò ní oúnjẹ nílébẹ́ẹ̀ ni kò sí aṣọ.
Awon omo egbe agbaboolu ‘Super Eagles’ ti Naijiria ti fireti han pe didun losan a so ninu idije oloresore ti won fe gba pelu Three Lions ti England ni London lojo AbametaOpo awon omo Naijiria ni won ni inu won ko dun to bi egbe agbaboolu Super Eagles sese ninu idije oloresore won pelu ‘Leopard’ ti DR Congo nilu Port Harcourt lose to koja ti won fi jot a omi (1-1).
Isà òkú ti ṣetán, yóo gbé wọn mì,ó ti yanu kalẹ̀.
Ọba sì tún béèrè, ó ní, Ńjẹ́ ìwọ ti ní obìnrin?
Ó fẹ́ràn àwọn àlejò, a sì máa fún wọn ní oúnjẹ ati aṣọ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Offa Descendant Union: A dupẹ́ lọ́wọ́ àwọn agbófinró tó dóòlà àwọn ọmọ Ọffa lọ́wọ́ ajínigbé 9 Owewe 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 11 Owewe 2019 Oríṣun àwòrán, @NigerianPolice Àkọlé àwòrán, Kí a tó sanwó ajínigbé ní àwọn agbófinró dóòlà ọmọ Ọffa mẹ́fà -ODU Ori ti ko awọn ọmọ bibi ilu Offa mẹfa ti awọn ajinigbe jigbe yọ ninu igbekun awọn alaburu.
Ọrọ yii wa lara awọn ohun ti Ọgbẹni Mba fi sita lori Twitter lori bi awọn eeyan ti le wuwa ti ọlọpaa ba fẹ mu wọn.
8 Covid-19: Ilé aṣojú-ṣòfin l'Abuja dábàá kí ìjọba sún ìwọlé àwọn akẹ́kọ̀ọ́ síwájú pẹ̀lú oṣù mẹ́ta 9 Mo ti ní ìyàwó àfẹ́sọ́nà, ayẹyẹ ìgbeyàwó mi ń bọ̀ láìpẹ́ - Lateef Adedimeji 10 Ọwọ́ tẹ ènìyàn méjì tó ń ta ayédèrú aṣọ iṣẹ́ ikọ̀ Àmọ̀tẹ́kùn BBC News, Yorùbá Ìdí tí ẹ fi le è nígbàagbọ́ nínú ìròyìn BBC Ìlànà Lílò Nípa BBC Òfin Àṣírí Cookies Kàn sí.
Mose bá pe Miṣaeli ati Elisafani, àwọn ọmọ Usieli, arakunrin Aaroni, ó ní, “Ẹ lọ gbé òkú àwọn arakunrin yín kúrò níwájú ibi mímọ́, kí ẹ sì gbé wọn jáde kúrò láàrin ibùdó.
Wọ́n ní oúnjẹ lọpọlọpọ, ara sì rọ̀ wọ́n, ṣugbọn wọn kò ran talaka ati aláìní lọ́wọ́.
Nigba ti o n ba ikọ BBC sọrọ, olori ajọ alaabo oju popo (FRSC), Ọladele Clement, ṣalaye pe ọkọ ajagbe naa ni o ti wa ni ahamọ ajọ naa.
Ẹsin wo ni Hushpuppi n ṣe?
Àbí owú rẹ yóo máa jó bí iná?
O damiloju pe, iyipada otun yoo tun ba bi mo se n gba boolu si labe akoso Pep.
Ọmọ Yorùbá tó bá ti rú òfin, ẹ gbé e jàntò - Oluwo Mo ṣe tán láti kú tọmọ taya bí wọn kò bá fi El-Zakzaky sílẹ̀ - ọmọ ẹgbẹ́ Shiite Ọlọ́pàá Kwara ti rí ọmọ orílẹ̀-èdè Turkey mẹ́rin gbà padà lọ́wọ́ ajínigbé!
 nígbà ayé rẹ ̀ ( láti 1640 síwájú si ) , ó ṣalábápàdé jansenism .
"Elebuibon fikun pe, ""Nkan to ma n fa akuba le jẹ nipasẹ nkan ti obi se, tabi awọn ọmọ."
O tun salaye pe  ijoba si n sa
Mo bá sọ fún wọn pé, “OLUWA ni ó bá mi sọ̀rọ̀, 
Oun ni oludasilẹ ati oludari ileeṣẹ Oriental Energy.
Kànga kan tí ó ní omi wà níbẹ̀, tí Jakọbu gbẹ́ nígbà ayé rẹ.
Fasiti OAU: À wádìí olùkọ́ tó fẹ́ bá akẹ́kọ̀ọ́ lò fún máákì
 Gomina se alaye pe oun gbe awon igbese akin eleeyi
"Boduong sọ fún akọ̀ròyìn kan wípé ""o sáà nílò ẹnìkan láti máa tọ́jú rẹ."
Oríṣun àwòrán, Remi Fatolu Àwọn ọ̀dọ́ ya bo ààfin Akire láti jí oríadé gbé Agbára wa kò ká àrùn Covid-19 mọ́ - Ìjọba ilẹ̀ Amẹrika Taa gan ló ni Lekki Toll gate láàrin aráàlú àti Asiwaju Tinubu?
Delta Accident: Orí yọ dírẹ́bà ọkọ̀ tó jóná ráúráú ní Delta
Ẹ jẹ ki wọn mọ wipe iru ẹ ko gbọdọ ṣẹlẹ mọ l'Ọṣun Mo ti ṣe gomina ri fun ọdun mẹjọ, bakan naa sini mo ti jẹ alaga igbimọ awọn gomina.
Nítorí pé, èmi ni OLUWA Ọlọrun yín, ẹ ya ara yín sí mímọ́, kí ẹ sì jẹ́ mímọ́, nítorí mímọ́ ni èmi Ọlọrun.
Awọn alarafa naa yoo lo akoko wọn loke Arafa yii lati gbadura fun itẹwọgba isẹ haji wọn ati kika ẹsẹ iwe mimọ Alukurani titi ti oorun yoo fi wọ.
OLUWA bá sọ fún Mose pé, 
Aarun coronavirus ko le tan lori ilẹ aye patapata.
Eyi jẹ idahun rẹ si iroyin to n ta kalẹ pe ẹgbẹ jawe lọ sinmi fun un.
Bẹẹ si ni awọn ọmọ Naijria ti n fi ero wọn han lori ọrọ naa lori ayelujara, nibi ti wọn ti n sọ fun gbogbo eniyan ki wọn tu jade lati fi ẹhonu han lori ọrọ naa.
2021 Nigerian Budget: Àbádòfin ìṣúná 2021 ré kọjá ìpele ìkejì nílé aṣòfin àgbà
BBC Yoruba jade sita lọ fi ọrọ wa awọn ọdọ lẹnu wo lori ohun ti wọn n reti lọdọ awọn minista tuntun yii.
Ti a ko ba gbagbe, awọn ile isẹ ologun Naijiria ti ran ikọ wọn lọ si agbeegbe naa lati da wọ isẹlẹ naa duro, sugbọn ikọlu si n waye lawọn igberiko kookan lagbeegbe naa.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Mo máa n forin mi kìlọ̀ ìwà ìbàjẹ́ láwùjọ ni -Hameen Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Mo máa n forin mi kìlọ̀ ìwà ìbàjẹ́ láwùjọ ni -Hameen 25 Òkùdu 2019 Inu mi maa n dùn ti mo ba n kọrin -Hameen Hassan Al-Hameen Williams ni ọdọmọde olorin ti BBC ba ni alejo lasiko yii.
Oríṣun àwòrán, Twitter/Charly Boy Àkọlé àwòrán, Ẹgbẹ Our Mumu Don Do Charly Boy loju opo Twitter rẹ sọ pe 'ti baba ko ba sọrọ, o tumọ si pe baba ni ni tootọọ.
Àwòrán àwọn afurasí tí a fi léde kìí ṣe òfegè, ṣùgbọn a dọ́gbọ́n síi - Iléeṣẹ́ ọlọ́pàá Ọ̀dọ́bìnrin, ẹ ṣọ́ra!
Bí bẹ́ẹ̀ kọ́, ó lè fà ọ́ lé onídàájọ́ lọ́wọ́.
Kini mo ti da laye ti maa ma fi eeyan ṣe yẹyẹ?
Kì í wá ṣe fún orílẹ̀-èdè wọn nìkan, ṣugbọn kí àwọn ọmọ Ọlọrun tí ó fọ́nká lè papọ̀ di ọ̀kan.
ibọwọ  fun aare Buhari juu lọ.
Gomina Yobe l'awọn o tii ri awọn ọmọ tan jigbe- Baba ọmọ 'Ileesẹ ọmọogun Naijiria ko mọ nipa awọn ọmọ ti wọn tu silẹ' L'asiko yi gan ọrọ naa kun fun iruju nibi ti awọn alaṣẹ ti kọkọ daba wipe awọn ti gba awọn ọmọ naa silẹ ki wọn o to wa tọrọ aforijin lẹyin ọrẹyin wipe ọrọ na ko ri bẹ.
Inú mi ìbá dùn láti fún ọ ní owó fadaka mẹ́wàá ati ìgbànú akikanju ninu ogun jíjà.
Dafidi bi í léèrè pé, “Ṣé o lè mú mi lọ sọ́dọ̀ àwọn ọmọ ogun náà?
Chelsea pòkọ ìyà fún Dynamo Kiev pẹ̀lú 5-0 Kí ló mú kí Aubameyang fi Black Panther dáwọ̀ọ́ ìdùnnú?
Èyì gan-an ló dífá fún òṣèrèbìnrin, to tún jẹ́ oníṣòwò, Lizzy Anjorin, tó sọ ìdí tí òun àti ọkọ rẹ̀ ṣe wà papọ̀ fún ọdún mẹ́rìnlá, kì wọ́n ó tó ó sẹ ìgbéyàwó.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Turkey n fi omi ara ọpọlọ ti wọn ti rẹ se ara rindin Ohun to wọpọ ni orilẹede Turkey ni lati fi igba aya ati ọmu akukọ fi se ounjẹ jijẹ.
Wo ohun mẹ́wàá tó yẹ kí o mọ̀ tí o bá fẹ́ lọ fún ìsinmi lẹ́yìn Covid 19 DSS ti fi ẹ̀sọ́ àbò abẹnugan ilé ìgbìmọ̀ asofin tó pa fẹ́ndọ̀ l'Abuja sátìmọ́lé Wọ́n ti rí òkú Alága ẹgbẹ́ APC ní Nasarawa tí àwọn agbébọn jí gbé lọ́jọ́ Satide Wo ọ̀nà tí ọrọ̀ ajé Naijiria tó dẹnu kọlẹ̀ gba kàn ọ Iléeṣẹ́ ọlọ́pàá ṣàfihàn ojú àwọn afurasí tó se ẹran ara ọlọ́pàá jẹ ní Ibadan Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Fídíò, Akọ́mọlédè àti Àṣà lórí BBC Yorùbá: Kọ́ síi nípa iṣẹ́ tí oúnjẹ ń ṣe lára níbí24 Bélú 2020 Fídíò, Akomolede Yoruba: Kí ni ìdí tí aṣọ fi máa ń pọ̀ lára Egúngún ju Orò lọ́?
Ki ẹnikẹ́ni tóó wọ inu igbó náà, iwin yìí a wí pé kí olúwarẹ̀ ṣe ìbúra bí òun bá ṣẹ ẹ̀ṣẹ̀ wọnnì rí tàbí òun ko ṣẹ̀ wọ́n rí, bí olúwaarẹ̀ kò bá le búra a fa kùmọ̀ rẹ̀ yọ, a fọ́ ọ ní kùmọ̀ ní àtàrí, a nà án ní igi lẹ́hìn ọrùn, a dá olúwaarẹ̀ ní ìbàdá, onítọ́hùn a di ẹni tí ń rìn yẹ́ńkúyẹ́ńkú kiri.
O wa fi da awọn eniyan loju wipe, Amẹrika ko ni faye gba ija ẹsin lorilẹede Naijiria, ti opin yoo si de ba isekupani awọn Fulani Darandaran ni Benue.
Bakan naa ni awon ebi awon ti o farapa nibi isele naa ti gbe awon ebi won to farapa lo sile iwosan fun itọju”.
Nítorí náà ni ọkàn mi ṣe ń yọ̀, tí inú mi dùn;ara sì rọ̀ mí.
Gbohùngbohùn gba orín náà nínú igbó kankan, bẹ́ẹ̀ ni fèèrè náà dún ju fèèrè ọba lọ, níwọ̀n ìgbà tí orin náà sì ti jẹ orin arò ńkọ́, kò le ṣàì kó wọ ẹbọra náà ni ibi kọ́lọ́fín agbárí lọ; Olóòótọ́ tẹ orí alábòsí ba.
Àkàrà-oògùn báà rora fi ìdí lé orí àpáta ẹ̀bá ọ̀dọ̀  mi, ó bẹ̀rẹ̀ sí sọ̀rọ̀ bi oódẹ, ó ní:-
O tun ṣalaye pe ọmọ Naijiria kan ti o dari lati ilẹ Faranse tawọn ri apẹrẹ pe o le ni aisan naa ti wa labẹ ayẹwo.
Aarẹ Zambia ni titi laelae lorilẹ ede naa yoo maa ṣe iranti Matfishi to lọ.
Murray ati Orlik tun se ikinlo pe, adinku yoo ba GDP lagbaye, bi irewesi yoo se ba ifiga-gbaga ati pasi-paro imo ijinle ero, bakan naa ni ijakule yoo de ba ipede nnkan lagbaye.
Iroyin ni Ajanah ku sile itọju awọn alarun Covid-19 to wa ni Gwagwalada, ni ilu Abuja.
Wọn gbudọ gba iwe aṣẹ agbẹkanga.
Ti a o ba gbagbe pe a-pa-rapo egbe awon osise ti ni ninu  ipade ti awon se pelu ijoba  lori ekunwo owo osu awon osise, leyin ti awon osise aladaani ti rawo ebe si won lati fenuko  lori  ogbon egberun, pe iye yii ni awon lagbara lati san.
Yinka Ajia: ìbẹ̀rù Ọlọrun ni mo fẹ́ fi tukọ̀ Kwara ti mo ba wọlé
Èyí dífá fún bí Oluwo ti Ilu Iwo, Ọba Abdulrosheed Adewale Akanbi, Telu 1 se ro dédé tí o sí kàn dudu nibi ayẹyẹ ti wọn ti n joye asiwaju awọn Igbo to wa ni ilu Iwo.
Ní ìlú Chibok ni awọn òbí awọn ọmọ òuń ti gbéra lati lọ sí ìlú Yola lọ yọjú sí àwọn ọmọ wọn.
Iroyin fi mule pe, West Bromwich Albion fopin si ise re latari aise dede iko naa, eyi ti o mu won wa ni isale tabili idje ile geesi English Premier League.
Ohun ìríra ni ẹbọ eniyan burúkú, pàápàá tí ó bá mú un wá pẹlu èrò ibi.
O ni ti eniyan ba lọ awọn popona, ile iwe ati awọn ile iwosan to wa ni iru awọn ipinlẹ to fẹ na owo yanturu si dida papakọ ofurufu silẹ wọnyii, wọn yoo ri wipe ọpọ awọn nkan miiran wa to nilo iro owo yii.
Àwọn ohun kàyéèfì tó le mú kí ọmọbìnrin ní oyún ìju Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Pásítọ̀ ló sọ fún mi pé Ọlọ́run pè mí láti di Olokun tó ń bọ omi' O ni ''Ara mi ko ti bọ sipo latari bi mo ṣe forigbalẹ.
Ki aare to bowolu iwe isuna
Bí yìnyín kò ṣe yẹ ní àkókò ooru,ati òjò ní àkókò ìkórè,bẹ́ẹ̀ ni iyì kò yẹ òmùgọ̀.
Atẹjade àwọn asofin agba PDP yìí wáye nitori àwọn ìròyìn kán tó ń nàka sí ààrẹ ilé ìgbìmọ̀ aṣofin àgbà, sẹnatọ Bukola Saraki pé o ń pinnu láti lọ́wọ́ si ọ̀nà ti ààrẹ tuntun ilé aṣofin ẹlẹkẹsan yóò fi dide.
Kọjú sí mi, kí o sì ṣàánú mi;fún èmi iranṣẹ rẹ ní agbára rẹ;kí o sì gba èmi ọmọ iranṣẹbinrin rẹ là.
“Nígbà tí ẹ bá ń gbadura, ẹ má ṣe bí àwọn aláṣehàn.
Ẹgbẹ Ndigbo lo fi iwe pe Sẹnetọ Ekweremadu si ibi eto nla kan ti awọn ọmọ ẹya igbo to n gbe ni ilu naa gbe kalẹ.
Gege bi ile-ise omo ogun orile
Ogungbinle: Àwọn onílé rò pé asẹ́wó ni mi
 nípà tíátà ṣíṣe yálà nípa eré ìtàgé tàbí ti àgbéléwò ni àtúnṣe ti ń bá ọ ̀ pọ ̀ lọpọ ̀ ayé tí ó wà ní ìkòríta ìríjú , tí wọn kó si mọ ohun tó yẹ lati ṣe .
Ó ní n kò gbọdọ̀ mu ọtí waini, tabi ọtí líle.
naa Jacob Zuma kuro lori aleefa.
Ṣugbọn ní alẹ́ ọjọ́ náà gan-an, Ọlọrun sọ fún Natani pé, 
"Ileeṣẹ iroyin abẹle kan pe Ayobami sọ fun akọroyin wọn pe lootọ l'oun ṣèlérí iṣẹ fún arákùnrin náà gẹgẹ bi ""ghost worker,"" ṣugbọn ko ṣẹyin bo ṣe ma n yọ oun lẹnu ni gbogbo igba fún iṣẹ, ti òun sì má n sọ fun pe òun yóò wà nkan ṣe si, ko le fún òun ní ìsinmi."
Ìgbeyàwó Fayose: Ìjó Shaku-shaku ni gómìnà fi dárayá
Tabi tí wọ́n bá sọ pé, ‘Ẹ wá wò ó ní ìyẹ̀wù,’ ẹ má ṣe gbàgbọ́.
Láti ọdún 2015, abódiakọ-akọ́diabo tí ó tó 500 ni a ti rán lọ sí ọ̀run alakákeji ní Pakistan , Jannat Ali sì tún sọ wípé Abódiakọ-akọ́diabo 60 ni a dá ẹ̀mí wọn ní ẹ̀gbodò ní ọdún tí ó kọjá.
Wọ́n ti sọ ara wọn di aláìmọ́ lọpọlọpọ, bí ìgbà tí wọ́n wà ní Gibea.
Ní ọdún kẹta tí Kirusi jọba ní Pasia, Daniẹli, (tí à ń pè ní Beteṣasari) rí ìran kan.
Dafidi ati gbogbo àwọn ọmọ Israẹli bẹ̀rẹ̀ sí jó níwájú OLUWA, wọ́n sì ń kọrin pẹlu gbogbo agbára wọn.
Ile iwe Ikeja Central Primary School ni olukọ wa lori oge ṣiṣe ti wa.
"Ati ri ọrẹ, ojulumọ gan nira lasiko yii ṣugbọn dokita dabaa wiwa eeyan mii too le ba ṣe ere idaraya yoo wulo tori ""eeyan ẹlẹran ni wa ti wiwo ẹrọ kọmputa ṣaa tabi Zoom ko to fun ni layọ""."
ibi idibo mẹ́tàléláàdọ́wàá (193) to wa ni
òkúta onikisi ati òkúta tí wọn yóo tò sí ara efodu ati sí ara aṣọ ìgbàyà.
Awọn koto wọnyii ni o maa n kun fun omi nigba ojo ti o si maa n fana atogbemulemu awọn ọkọ.
Kó sì tó dí pé àwọn ènìyàn dóòlà rẹ̀, ó ti kú.
ún milionu dola ni ijoba orile ede India fẹ  lo lati fi mu idagbasoke ba ohun elo ero
Ọmọ Jese ni Dafidi, ará Efurati ní Bẹtilẹhẹmu ti Juda; Ọmọkunrin mẹjọ ni Jese bí, ó sì ti di arúgbó nígbà tí Saulu jọba.
Wọ́n ti gbé ìbùsùn bàbá mi sí pálọ̀.
Ilẹ̀ etí òkun yóo di pápá oko fún àwọn darandaran, ati ibi tí àwọn ẹran ọ̀sìn yóo ti máa jẹko.
Ta ló da 'ewé' bo N4.
Àkọlé àwòrán, Ọ̀gá àgbà fún àjọ eleré bọ́ọ̀lù ni Ghana (GFA) Kwesi Nyantakyi gba ẹgbẹ̀rún lọ́nà márunléọgọ́ta dọ́là gẹ́gẹ́bíi rìbá.
Lọ́nà kejì, ò lè jẹ́ wí pé bóyá nítorí pé ẹsẹ̀ lásán tó fi rín nígbà náà tàbí nítorí pé aginjù tó fi orí là nígbà náà ló ṣe rò wí pè ibi tí òun ti rìn ti nàsẹ̀ díẹ̀ sí ọ̀dọ̀ àbúrò òun lo ṣe dúró ni ibi tí a ń pè ní Ijẹ̀bú-Jẹ̀ṣà lónìí.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ikọlu wáyé láàrin àwọn ọmọ ogun Nàìjìríà àti Shiite 16 Ìgbé 2018 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ikọlu wáyé láàrin àwọn ọmọ ogun Nàìjìríà àti Shiite Fọ́fọ́ ni gbogbo àwọn ìlooro kọ̀ọ̀kan kún fún òkúta àti agolo gáàsì ní ìlú Abuja lẹ́yìn ìkọlù tó wáyé láàrin àwọn ọmọ ogun Nàìjíríà àtàwọn afẹ̀hónú hàn tó n bèèrè fún ìtúsílẹ̀ adarí ẹgbẹ́ Shiite, Sheikh Ibrahim Zakzaky.
Nígbà tí Saulu ati àwọn ọmọ ogun rẹ̀ gbọ́, ẹ̀rù bà wọ́n gidigidi.
Ninu fidio kan lori ayelujara ni Randy ti ṣalaye ọrọ yii.
Ọlọrun sọ awọsanma náà ní ojú ọ̀run.
Oríṣun àwòrán, AFP Ó ṣe pàtàkì láti bèrè lọ́wọ́ àwọn agbẹ̀bí tàbí dókítà wọn ibi tí ó dára jù láti bímọ sí.
Section 107 Ijọba yoo lanfani ati fagile iwe aṣẹ bi ẹnikẹni ba n lo omi nilokulo.
pé OLUWA ni wọn kò gbọdọ̀ gbógun ti àwọn ọmọ Israẹli, nítorí pé arakunrin wọn ni wọ́n, ati pé kí olukuluku pada sí ilé rẹ̀, nítorí pé ìfẹ́ òun Ọlọrun ni ohun tí ó ń ṣẹlẹ̀ yìí.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Pásítọ̀ ló sọ fún mi pé Ọlọ́run pè mí láti di Olokun tó ń bọ omi' Ati ni gbogbo agbaye?
Ṣugbọn Dafidi ti gbé àpótí ẹ̀rí Ọlọrun wá láti Kiriati Jearimu sinu àgọ́ tí ó pa fún un ní Jerusalẹmu.
Nàìjíríà yóò dá ṣèríà fún Senegal lónìí- Balógun Flying Eagles Donald Trump ti pàdé Ọbabìnrin Elisabeth tilẹ̀ Gẹ̀ẹ̀sì Sìgá mímu ń di èèwọ̀ oògùn ìlera pípé lagbaye Iléeṣé MTN ti san bíliọnù N55 owó ìtanràn wọn tó kù -MTN Ṣugbọn awọn ọmọ Naijiria kan ni ko si oun to buru ninu ọrọ Kumuyi naa.
O Fagunwa, Adebayo Faleti, Akinwumi Iṣọla, Lawuyi Ogunniran àti Oladejo Okediji ṣiṣẹ silẹ ki wọn to lọ3 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Àwọn méjèèjì ti ń figagbága nínú ìbò Nàìjíríà ní ọjọ́ tí ó ti pẹ́.
Sùúrù ni mo fi dúró de OLUWA,ó dẹ etí sí mi, ó sì gbọ́ igbe mi.
Mo ṣebí lórí ọ̀pá fìtílà ni à ń gbé e kà.
Níbi tí ó ti ń rìn kiri ninu pápá ni ọkunrin kan bá rí i, ó bi í pé, “Kí ni ò ń wá?
Bí àwọn ènìyàn ìlú kan bá mú àjọyọ̀ àjọ̀dún ìlú mìíràn ní òkúnkúndùn ju bí ó ṣe yẹ, èyí fi hàn wípé orílẹ̀-èdè náà ń jẹ ìyà ìgbógunti àṣà.
Wọn ni eyi ṣẹlẹ lẹ́yìn ti wọn ti gbà wọ̀n ní ìmọ̀ràn láti máa tẹ̀síwájú nínú ìrìnàjò wọ́n lọ́jọ́ náà, sùgbọ́n ní kété ti wọ́n tẹ̀síwájú ni àgbàrà òjò gbá ọmọbìnrin náà lọ àmọ́ orí kó ọlọ́kadà yọ.
Aarun yii ti o tun jẹ ikeji
Titi di bi a ti ṣe n ko iroyin yi jọ.
Ta ni ǹ bá tilẹ̀ tún sìn, bí kò ṣe ọmọ oluwa mi.
Nígbà tí OLUWA bá fun yín ní ìsinmi kúrò ninu làálàá ati rògbòdìyàn ati iṣẹ́ àṣekára tí wọn ń fi tipá mu yín ṣe, 
#ENDSARS: Íjìyà tó tọ́ sí Charles Omotosho ni wọ́n dá fún un
Bakan naa ni ẹgbẹ Afẹnifẹre naa ni awọn faramọ ohun ti Obasanjo sọ nitori Aarẹ Buhari ti kuna lati jẹ ki isọkan o jọba lorilẹede Naijiria.
Ó ti wó ọ lulẹ̀ láìṣàánú rẹ;ó ti jẹ́ kí ọ̀tá yọ̀ ọ́,ó ti fún àwọn ọ̀tá rẹ ni agbára kún agbára.
Ìtàn Ọba Yorùbá tí wọ́n yẹgi fún torí ó jí ọmọ gbé ṣe ètùtù Boko Haram da ìbọn bo ọkọ̀ gómìnà Borno, ẹ̀ṣọ́ àláàbò rẹ̀ farapa Ẹ káàbọ̀ sọ́jọ́ Arafat, tí Ọlọ́run yóò fi ààwẹ̀ Mùsùlùmí pa ẹ̀ṣẹ̀ wọn rẹ́ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Justice for Richard: Òbí àkẹ́kọ̀ọ́ tó kú síléeṣẹ́ ọṣẹ ń bèèrè fún ìdájọ́ lórí ikú ọmọ wọn Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
“Gomina ipinle  Borno State , Babagana Zulum naa tun so pe : “Ipinle
Koda ijọba ipinlẹ Eko gan ti kede fawọn araalu lati mọ awọn oju ọna ti wọn yoo ti pa ati awọn eyi ti ijọba yoo si fun lilo, eyi tawọn araalu ni yoo tubọ dakun sunkẹrẹ fakẹrẹ ọkọ ni Eko lasiko abẹwo aarẹ naa ni.
Nítorí náà, OLUWA fúnrarẹ̀ yóo fun yín ní àmì kan.
Àjàlọ ́ run àti balufẹ ́ ni ó jẹ ́ adarí ọ ̀ wọ ́ kẹrìn .
Musa Mani Àkọlé àwòrán, 2019 Elections: Àwọn òṣèré Yorùbá tó wà nínú ìgbìmọ̀ ìpolongo APC Òṣìṣẹ́ ẹka arinrinajo ọkọ̀ òfúrufú Nàìjíríà fagilé ìyanṣẹ́lódì 8.
Kódà, a rí ibi tí ilẹ̀ ò tilẹ̀ mọ́n rárá lọ́jọ́ náà.
Ọ̀kan náà ni àwọn àlá mejeeji.
Ọlọrun pàápàá tún jẹ́rìí sí ọ̀rọ̀ náà nípa àwọn àmì ati iṣẹ́ ìyanu ati oríṣìíríṣìí iṣẹ́ tí ó ju agbára ẹ̀dá lọ, tí ó ṣe nípa Ẹ̀mí Mímọ́ tí ó pín gẹ́gẹ́ bí ìfẹ́ rẹ̀.
"Ọjà àìmọye mílíọ̀nù naira ni wọ́n kó nílé ìtajà mi torí ìgbẹ̀san ìkọlù South Africa ""Naijiria gbọdọ̀ kẹ̀yìn sí ìrẹ́pọ̀ pẹ̀lú South Africa"" Xenophobic Attack: 'Nàìjíríà ló máa forí kó kíkọlu iléeṣẹ́ South Africa jùlọ' Xenophobic Attack: Àwọn ọmọ Nàìjírìá bínú kọlu Shoprite l'Eko Àjọ Commomwealth gbọ̀dọ pé ìpáde pàjáwìrì lori ọ̀rọ̀ Brexit- Wole Soyinka Ayọade ni awọn kan lo gbe alupupu wa, ti wọn si lu awọn ọlọdẹ to n ṣọ ọọfisi naa ni bii aago mẹwa aabọ alẹ ana, lẹyin eyii ni wọn si dana sun ọọfisi ileesẹ MTN naa pẹlu kẹgi ẹpo bẹntiro ti wọn gbe dani."
 Ẹsẹ ̀ ifá ṣàlàyé bí gẹ ̀ lẹ ̀ dẹ ́ ṣe bẹ ̀ rẹ ̀ pẹ ̀ lú Òrìṣà yemọja tí ń ṣe ' ìyá gbogbo Òríṣà àti ohun abẹ ̀ mí .
Oríṣun àwòrán, Efcc Diẹ lara awọn ẹṣọ ara ọhun ni ẹgbà ọwọ (419); oruka ọwọ (315); yẹti (304); ẹgba ọrun (267); aago ọwọ (189); ẹgba ọrun ati yẹti alaṣepọ (174).
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ìdí tí Buhari fi gbọ́dọ̀ buwọ́lu àbádòfin ìdìbò 2018 Orí yọ Fayose nínú ìjàmbá ọkọ̀ Amosun lẹ́tọ̀ọ́ láti gbè lẹ́yìn oludíje tó bá wù ú - APC 'Ọ̀pọ̀ fẹ́ kí n kú nígbà tí mo ṣàìsàn' Èmi ni òpómúléró fún òtítọ̀ sísọ̀ - Oyedepo Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí 2 sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Àjọ Ìlera lágbàyé, WHO ti ní ènìyàn kan nínú aláboyún mẹ́ta ní àwọn eletò ìlera ma ń fìyà jẹ lásìkò ìbimọ ní Naijiria.
Bo tilẹ jẹ pe a ko tii ri idanilojuu ọjọ ori rẹ ṣugbọn awọn ohun ti a mọ ni pe o ṣeeṣe ko kere to ọmọ ogun ọdun.
wa ro ijoba apapo lati kọ aba ti ajo to n mojuto owo ina lagbaaye  IMF mu wa , pe ki ijoba apapo fi kun owo ori
Ninu ifọrọwerọ ni o ba BBC Yoruba ni o ni ijakulẹ ireti patapata ni isẹlẹ naa jẹ nitori awọn alasẹ ajọ naa ti fi wọn lọkan balẹ wi pe isẹ yoo bọ sii fun wọn nipasẹ ajọ naa.
Nítorí náà ọ̀rọ̀ OLUWA sí wọn yóo jẹ́ tòfin-tòfin,èyí òfin tọ̀hún ìlànà.
Àwọn agbókùú fẹ́ fàá lọ ilé ẹjọ́ 27 Èrèlè 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 1 Ẹrẹ̀nà 2019 Oríṣun àwòrán, Alph Lukau/Facebook Àkọlé àwòrán, Pasitọ Alph Lukau (ní aṣọ buluu) ni oun jí arakunrin yii dide Ẹgbẹ awọn agbokujo ni South Afrika ti ni awọn yoo gbe pasitọ to ni oun ji oku arakunrin kan dide lọ ile ẹjọ́.
Wọn óo máa gbé ilẹ̀ tí mo fún Jakọbu iranṣẹ mi, ilẹ̀ tí àwọn baba ńlá yín gbé.
Eniyan mẹta lára awọn méjìdínlogoji tí wón fi orúkọ wọn ṣọwọ sílè Ìgbìmò asofin ipinlẹ Eko ni wọn yọ kuro Sanwo Olu yan kọ̀míṣọ́nnà 25 àtàwọn olùbádámọ́ràn.
”“Nitori naa, ohun ti won tun ba so leyin, eyi ki i se otito.
Toyin Abraham bí ọmọkùnrin jòjòló El-Zakzaky fẹ́ jayé ọlọ́ba ní India, kò sígbà tí kò ní padà wálé - Ìjọba àpapọ̀ Aarẹ Buhari sọ ọrọ yii lasiko to ṣe abẹwo si ibudo awọn atipo eeyan ti eeyan bii ẹgbẹrun kan le aadọta, ti ogun agbebọn Boko haram le kuro nile wa, eyi to wa ni ipinlẹ Katsina.
Oríṣun àwòrán, @others Àkọlé àwòrán, Ẹ ma ba ẹnikẹni ja nitori ọrọ mi Nigba ti Pasitọ Biodun Fatoyinbo de sinu ijọ loni, o ki gbogbo awọn eniyan rẹ ku aduroti lasiko yii.
Ọpọlọpọ awọn to sọrọ to fi mọ Davido ni '' igbagbọ awọn ninu Desmond Eliot ti dopin, pẹlu ọrọ iranu to sọ jade lẹnu''.
Iru iya bẹẹ le gbe ọmọ ale wọle lai fura pe oun ti gbe ọmọ ọba fun ọsun.
Bí ogun bá tí ń bẹ̀rẹ̀ ni a óo ti pa ọba Israẹli run.
iṣọkan wa ni awọn ipinlẹ apa Iwọ Oorun Gusu orilede yi ni eyi ti a ti jiroro
Alameleki, Amadi, ati Miṣali, ní apá ìwọ̀ oòrùn, ilẹ̀ náà dé Kamẹli ati Ṣihori Libinati.
“Ìjì Àkísà” ní àwọn ohun tí ó mú soca yàtọ̀  bíi irúfẹ́ lavway ìpè-àti-ìfèsì, pẹ̀lú àyè tí ó fẹ́ fún àwọn ènìyàn láti fi àkísà.
Ẹwẹ, Pasito Fatoyinbo naa ti fesi si ọrọ naa loju opo Instagram pe ile ẹjọ ko ti ranṣẹ pe oun naa Gbajugba ayaworan lo fi ẹsun kan Biodun Fatoyinbo pe o fipa ba oun lo pọ ni ọpọlọpọ ọdun sẹyin ti Fatoyinbo si fariga pe ọrọ ko ribẹ.
"Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Ohùn gooro ló gbé mi dé ọ̀dọ̀ ààrẹ̀ Bush, Obama, Obasanjo, Goodluck, Buhari' Ó ní ""lóòtọọ́ a rí òkú kan ní inú adágunní Ipaja ṣùgbọ̀n a kò tíì le fi ẹnu ọ̀rọ̀ jóná báyìí nítorí òkú rẹ̀ ti ń jẹrà."
Àwọn ọmọ ogun ilẹ̀ Nàìjíríà dóòlà ẹ̀mí ẹni méjì ní Owena ní Ondo
" Oríṣun àwòrán, @NGRPresident Àkọlé àwòrán, Iṣoro ati idamu ti awọn ileeṣẹ la kọja lọdun 2016 si 2017 ti di ohun igbagbe"" O ni yoo dara pupọ bi ijọba ba n tẹsiwaju lati yẹ awọn ẹka miran yatọ si epo rọbi wo fun idagbasoke eto ọrọ aje."
Gẹgẹ bi a ṣe gbọ, ọmọdekunrin yii pariwo irora sita nigba tawọn oniṣẹẹbi naa n kọluu, ṣugbọn ki iya rẹ to lee ṣawari ibi ti igbe irora naa ti wa, wọn ti ṣaa lada ti o si ti wa ninu agbara ẹjẹ.
Oludari eto iroyin fun NYSC, Adenikẹ Adeyẹmi ni, ọga agba fun ajọ ọhun ti kilọ pe, ko si ayederu akẹkọjade Fasiti, nilẹ yii abi loke okun ti yoo kopa ninu eto agunbanirọ mọ.
 A si fẹ fi akoko yii sọ fun aya olori wa, iyẹn, Florence Ajimobi pedigbi ni a wa lẹyin lọjọ gbogbo.
Bẹẹ lo fi kun ọrọ rẹ pe ninu ewu to wa nibẹ nipe ''awọn ti wọn ba bẹ lati ṣiṣẹ lori oju-opo naa le parọ ohun to wa nibẹ nigba kuugba.
" Tunde Idiagbon, ọ̀gágun kògbagbẹ̀rẹ́ tó ní ẹ̀ẹ̀kan lóṣù ló yẹ kí ológun máa rẹ́rìín Ìjọba Nàìjíríà ti sún ọjọ́ tí ìrìnàjò bàálù sílẹ̀ òkèèrè yóò bẹ̀rẹ̀ padà síwájú Àwọn òṣèré Nollywood tí wọn ò sí lóri amóhùmáwòrán mọ́ Músò Músò!
Ẹgbẹ agbabọọlu Espanyol ni Pochettino ti kọkọ ṣiṣẹ gẹgẹ bi akọnimọọgba.
Àwọn olùpolongo ìdìbò Aketi àti Jegede ń forígbárí l'Ondo, bí wọ́n ṣe n yìnbọn ni wọn n sun táyà ₦750m ni Akeredolu ń gbà lóṣù fún ‘Security Vote’ àti ₦150m owó oṣù - Agboola Ajayi fèsì INEC kéde agbègbè ẹsẹ̀ odò 270 ti èrú ìbò ti le wáyé ní ìpínlẹ̀ Ondo Ọ̀pọ̀ aráàlú Owo wà nílé ìwòsàn, síbẹ̀ APC àti PDP kò gba ẹ̀bi Ẹ gbọ́ òhun tí àwọn olùdíjé sípò gómìnà nípínlẹ̀ Ondo sọ nípa Bàbá ìsàlẹ̀.
Àwọn olórí alufaa ati àwọn Farisi ti pàṣẹ pé ẹnikẹ́ni tí ó bá mọ ibi tí Jesu wà, kí ó wá sọ, kí wọ́n lè mú un.
Àwọn ọmọ Jakọbu yóo pada ní ìfọ̀kànbalẹ̀ ati ìrọ̀rùn,ẹnikẹ́ni kò sì ní dẹ́rù bà wọ́n mọ́.
“Ìwọ ọmọ eniyan, sọ fún Farao, ọba Ijipti, pẹlu ogunlọ́gọ̀ àwọn eniyan rẹ̀ pé,Ta ni ó lágbára tó ọ?
Eyi si ti fa ariyanjiyan laarin awọn ololufẹ wọn.
Ọlọ́pàá kò rí ǹkankan lábẹ́ pẹpẹ ilé ìjọsìn mi - Olùṣọ́àgùntàn Akure Ọmọ Naijiria tó lé ní 300 ti padà wálé láti South Africa Àwọn olólùfẹ̀ Toyin Abraham ati Liz Anjorin ti gbé ọ̀rọ̀ wọn rù sórí, ẹ wo òjò òkò ọ̀rọ̀ Ọmọdé 27 jóna ráuráu mọ́'le níléèwè Liberia Àwa kìí jà lásìkò tiwa, ta ló bí ẹ tí wàa máa jà?
Ireti wa pe, ipade alatilekun mori ni ipade ohun yoo je, ti won yoo si jabo ipade naa fun awon akoroyin leyin ipade ohun.
Wọ́n bá ń bi ara wọn léèrè pé, “Ta ló dán irú èyí wò?
Ìjọ kò ní tilẹ̀kùn ilé ìjọsìn nítorí àrùn Coronavirus - Ondo PFN Èyí ni ipa tí àdínkù owó epo bẹtiró yóò mú bá ọ̀rọ̀ ajé Nàìjíríà Ẹyin ilé ìjọsìn, ẹ tilẹ̀kùn ṣọ́ọ̀ṣì àti mọ́ṣáláṣí yín láti dènà àrùn Coronavirus - ìjọba Eko Ẹ wo ohun tí baba Adeboye sọ lórí ọ̀rọ̀ Coronavirus Kí ni ìtumọ̀ Pelúpelú, ìlànà àkàsọ̀ ọba tó fa wàhálà l'ọ́balọ́ba l'Ekiti Àwọn ọba Yorùbá kan rèé tí wọ́n rọ̀ lóyè, tí ọba míràn jẹ lójú ayé wọn Bakan naa lawọn eekan inu ẹgbẹ oṣelu ADP ati ZLP darapọ mọ PDP nibi ipadae itagbangba naa ti wọn pe ni ipade iṣọkan ni Ibadan.
Àwọn akọrin ewì-alohùn ráàpù, Lilo Kwanza àti Adérito Gonçalves, kọ orin kan, tí wọ́n sì ya àwòrán-an orin tí ó dá lóríi ìwọ́de ìfẹ̀hónúhàn yìí, “Ìwé ẹ̀rí ọmọ-ìlú-fún-ìrìnnà 30,000″ ni àkọlé orin náà, tí ó ń ṣe ẹ̀fẹ̀ lórí iye owó tabua tí ọmọ-ìlú yóò san fún ìwé ìrìnnà.
A padà san owó ìtanràn fáwọn ajínigbé kí wọ́n to fi àwọn mẹ́tẹ̀ẹ̀ta sílẹ̀- Ẹbí Japan ṣèrànwọ́ N149m fún Nàìjíríà lórí ètò ààbò!
O ni ìrọ̀lẹ́ ọjọ kan ti oun n lọ ile oun ni oun ri ipolowo iyikoto ọun ti oun si gbiyanju rẹ̀ wò, ko to wa di pe oun jẹ obitibiti owó.
Wọn óo kó o sinu gbọ̀ngàn ninu ilé ìpa-nǹkan-mọ́-sí.
Kọmiṣona ọlọpaa ni ipinlẹ Rivers, Mustapha Dandaura ni, afurasi ọhun ti fun awon agbofinro ni awọn iroyin kan, bẹẹni iwaadi awọn yoo ṣe koko lori idi ti afurasi naa ṣe n fi n gbẹmi awọn eniyan, ati lati mọ awọn alabaṣeṣẹpọ rẹ.
Ojo to ti gba bọọlu ri fun ẹgbẹ agbabọọlu Naijiria, Super Eagles n rinrin ajo pẹlu Iluyomade to n gba bọọlu fun ẹgbẹ agbabọọlu Abia Comets lati ilu Akurẹ ki wọn to ko sọwọ awọn ajinigbe lọna ilu Benin.
Gbogbo ìran yìí sì ru yín lójú,bí ọ̀rọ̀ inú ìwé tí a fi èdìdì dì.
 O ni, opolopo awon oloselu ni o ti fenu seleri, eleyi ti won ko muse, bee si ni elomiiran yoo fenu fun awon eniyan lounje lasiko ipolongo ti won ko si ni mu ileri won se.
Gẹgẹ bi iroyin to wa latọdọ ọlọpaa, obinrin naa fẹsun kan pe lasiko tawọn mejeeji pade ara wọn ni olu ilu orilẹede France, Paris lẹyin ti wọn ti jọ n sọrọ lori ayelujara ni ṣẹlẹ naa waye nile itura tawọn de si.
A ko gbe ọ wọle lati wa fidirẹmi ninu idibo, a ko lee gba eyii rara."
Ọpọ awọn eniyan pataki lati inu ijọ Methidist orilẹ-ede Nigeria (Methodist Church Nigeria) ni wọn pejọ sibi ajọdun orin naa, bii awọn biṣọọbu, awọn ojiṣẹ Ọlọrun ẹni-ọwọ, awọn ọga akọrin ati oniduuru.
Bí ó ti parí rírú ẹbọ sísun náà tán ni Samuẹli dé.
Àní títí di ìsinsìnyìí ẹ kò ì tíì lè jẹ ẹ́, 
Oríṣun àwòrán, Abiola ajimobi O mẹnu ba kikọ ile lai sọ fun ọkọ rẹ.
Bẹ́ẹ̀náàni ọ̀pọ̀ ènìà ló ka kẹ̀kẹ́ gígùn kún eré-ìdárayá òòjọ́.
Nígbà tí ó tó àkókò láti sìnkú Abineri, Dafidi ọba pàápàá tẹ̀lé òkú rẹ̀.
Oríṣun àwòrán, Federal Ministry of Humanitarian Affairs Ijọba apapọ tun ni ilana tawọn fẹ lo yii, ni yoo jẹ ko rọrun lati ri awọn akẹkọọ naa fun ni ounjẹ lasiko yii ti gbogbo ile ẹkọ wa ni titi pa nitori igbele arun Coronavirus.
Bí a ti yọ sí wọn ni Olóhùn-un-dùùrù ti bẹ̀rẹ̀ sí fún fèérè bíó sìti ń fun fèèrè ni a rí i tí gbogbgo wọn sùn lọ a sì kọjá wọn.
Ìkérora àwọn ọmọ Israẹli a máa mú kí àánú wọn ṣe OLUWA, nígbà tí àwọn ọ̀tá wọn bá ń fìyà jẹ wọ́n, tí wọ́n sì ń ni wọ́n lára.
Ṣé ẹ lè kí Liverpool kú oríire báyìí?
Buhari, yoo fi ilu Abuja sile lonii yii lati wa ni Dakar, lorile ede Senegal
Alamojuto agba Ile-iṣẹ naa wa fi da wọn loju pe bo ti lẹ ṣe pe idije ere idaraya naa n wa si opin ni ọjọ Aiku, Sunday yii sibẹ Ile-iṣẹ Rite Food yoo tẹ siwaju ninu akitiyan wọn lati maa ṣatilẹyin fun ere idaraya.
Gbọngan Ladi Kwali nilu Abuja ni o ti n waye.
Minisita tun tesiwaju pe ayeye ajodun asa ti o maa n waye niluu Abuja je ohun ti o wa lati gbe asa laruge, ni eyi ti gbogbo awon ipinle merindinlogoji  ati ilu Abuja to wa lorile ede Naijiria maa n kopa nibe.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Premier League Ipo kẹfa ni ikọ Chelsea wa bayii lori tabili idije Premier league ti Arsenal ati Manchester United si n siwaju wọn.
À ṣé olóòrùn ni ayálégbé mi tó ń fojóojúmọ́ ṣakọ lórí ayélujára- Onílé Lisa Li A ti ní mílíọ̀nù 11 Naira láti se ẹjọ́ pẹlú ilé-isẹ́ ọlopaa Naijiria!
Umar Usman ati Precious Owolabi ni wọn tẹri gbaṣọ ninu ikọlu ọlọpaa ati ẹgbẹ Shiite, nigba ti wọn n ṣe iwọde l'Abuja lọjọ Aje.
Àwọn oníṣòwò Temani ń wò rá rà rá,àwọn ọ̀wọ́ èrò Ṣeba sì dúró pẹlu ìrètí.
Ó wí pé kòsí nkan náà tí Ọlọ́run fẹ́ tí òun kò ní ṣe.
Nígbà tí wọ́n jáde, aré ni wọ́n sá kúrò ní ibojì náà, nítorí ńṣe ni wọ́n bẹ̀rẹ̀ sí gbọ̀n pẹ̀pẹ̀, tí wọn ń dààmú.
Ó pàṣẹ fún un pé kò gbọdọ̀ pa wọ́n.
Awọn kan gbagbọ pe wọn mọọmọ n fi iwe irinna dun awọn ọmọ Naijiria laini idi pataki kankan.
Bẹẹni kii ṣe owo oṣu kekere lo n ba iṣẹ yii wa l'awọn orilẹede miran lagbaye.
leyin oga agba olopa ile yii.
ENDSARS: Wo ìgbà mẹ́rin tí ìjọba ti tú ikọ̀ ọlọ́pàá SARS ká sẹ́yìn ṣùgbọ́n.
"Oladapo ni "" Ti awọn obi ba lọ sile ijọsin, nibo ni wọn fẹ fi awọn ọmọ wọn si, ṣe wọn yoo tilẹkun mọ wọn sile ni abi wọn yoo ko wọn da si titi?"
Adan salaye fun BBC pe: mo gbiyanju lati rọ awọn alaanu miran lati dide iranlọwọ paapaa awọn oniworobo ki n le rowo ra ọkọ bọọsi kekere keji.
Farisi wà láàrin àwọn eniyan tí ó wà pẹlu rẹ̀, tí ó gbọ́ ọ̀rọ̀ yìí.
Oríṣun àwòrán, AFP Àkọlé àwòrán, Gomina ipinlẹ Ekiti, Kayọde Fayẹmi ni gbogbo igbesẹ ni ijọba ipinlẹ naa n gbe lati rii pe ọṣẹ arun Coronavirus nipinlẹ naa mọ leeyan kan to wa lọwọlọwọ.
agbaboolu Chelsea lalejo ni papa isere Old Trafford.
6 Kíyèsíi, wọn ti wá ọ̀nà láti pa ọ́ run; Bẹ́ẹ̀ni, àní ẹni náà nínú ẹni tí ìwọ ní ìgbẹkẹ̀lé, ti wá ọ̀nà láti pa ọ́ run.
Estrosi ni diẹ lo ku ki wọn ge ori baba agba kan, to wa gbadura ja, ti wọn si yinbọn mọ afurasi kan, ki wọn to ti i mọle.
Afurasi ọhun ti wa tu asiri ara rẹ pe, igba akọkọ kọ ree ti iru isẹlẹ naa yoo waye lati ipasẹ oun nitori ọmọ tuntun yii kii se akọpa fun ajẹ oun.
Àwọn ọba mejeeji ni yóo pinnu láti hùwà àrékérekè, wọn ó sì máa purọ́ tan ara wọn jẹ níbi tí wọ́n ti jọ ń jẹun; ṣugbọn òfo ni ọgbọ́n àrékérekè wọn yóo já sí; nítorí pé òpin wọn yóo dé ní àkókò tí a ti pinnu.
(Àwọn Sadusi ni wọ́n ní kò sí ohun tí ń jẹ́ ajinde òkú.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ẹ wo ọ̀nà àbáyọ tí àwọn olùdíje gómìnà pèsè sí ìṣòro Eko Ọmọọbabinrin Adebisi Ogunsanya (YPP) Àkọlé àwòrán, àwọn olùdíje ìpínlẹ̀ Eko Adebisi Ogunsanyan ni ijọba oun yoo yẹ owo ti awọn eleto ilera n gba ni owo oṣu wo wọn yoo si fi kun un nitori ọpọlọpọ wọn ni ko gba owo ti ko peye.
Ó bá mú wọn wọ ilé, ó fún wọn ní oúnjẹ.
Wo aláànú tó n wa ọkọ̀ tí wọ́n fi n gbé aláìsàn lọ́fẹ̀ẹ́ Omíyalé gbẹ̀mí èèyàn méje, o tún ba dúkìá púpọ̀ jẹ́ Ìbọn ti kò lo ọ̀ta làwọn ọlọ́pàá a máa kọ́kọ́ yìn- IG Macron, aarẹ France ṣèlérí láti tún Notre-Dame kọ́ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ọ̀dọ́kùnrin tó kọ́kọ́ ṣe ẹ̀rọ tó ń tu ìyẹ́ lára adìyẹ Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
 tí ó rí tín-ín-rín léèdì náà se enu tín-ín-rín .
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Akomolede ati Aṣa lori BBC:Wo ìrúfẹ́ ìgbeyàwó méje tó wà nílẹ̀ Yorùbá àti ojúṣe Alárinà Ẹ o ranti pe ọjọ Karundinlọgbọn, oṣu Kẹfa, ọdun 2020, ni wọn tu igbimọ oludari ti Alaga ẹgbẹ APC nigba kan, Adams Oshiomole ko sodi ka, ti wọn si gbe igbimọ fidihẹ, ti gomina ipinlẹ Yobe, Mai Mala Buni, dari kalẹ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìsẹ̀lẹ̀ jákèjádò orílẹ̀èdè àgbáyé láàárín ìṣẹ́jú kan Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Ìsẹ̀lẹ̀ jákèjádò orílẹ̀èdè àgbáyé láàárín ìṣẹ́jú kan 12 Agẹmo 2018 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 17 Agẹmo 2018 Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí 3 sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 2:23 Fídíò, Water Generator: Ó leè ṣiṣẹ fún wákàtí mẹfà, kó tó sinmi, Duration 2,2310 Òkùdu 2020 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
Asilo ẹbun wa ninu nkan to n ṣe wa ni Naijiria ti a ko fi dagbasoke'' Ó tó gẹ́ẹ́!
5 Nítorínáà, bí ìwọ bá béèrè ní ọwọ́ mi, ìwọ yíò rí gbà; bí ìwọ bá kan ìlẹ̀kùn a ó ṣí i fún ọ.
Ìpele tàbí ìsọ ̀ rí márùn-ún ni a lè pín gírámà èdè sí .
Nibi ipari idanileko naa to waye nilu Abuja ti n se olu ilu orile-ede Nigeria,Alamojuto agba ati oludari ile –ise naa ni orile-ede Nigeria ,Omo –oba birin Gloria Akobundu so wi pe eto yi je ibamu pelu erongba ijoba to wa lori aleefa bayi lati ran awon obirin ati odo langba lowo lati le daduro laaye ara won.
O fi kun oro re pe, “awon ilu naa ni ipa pataki lati ko, lati le je ki awon ohun elo ti won pese naa le tojo, ati pe itoju awon ohun elo naa dowo won, tori naa ni a se ni igbimo alamoju to omi to mo-gaara ati eto ayika ni awon ilu kookan, ti won yoo maa moju to awon ohun elo ohun”.
Yóo kọ́ ààfin ńlá fún ara rẹ̀ ní ààrin òkun ati ní òkè mímọ́ ológo; sibẹ yóo ṣègbé, kò sì ní sí ẹni tí yóo ràn án lọ́wọ́.
Usaya tún kọ́ àwọn ilé ìṣọ́ ní Jerusalẹmu níbi Ẹnubodè tí ó wà ní igun odi, ati sí ibi Ẹnubodè àfonífojì, ati níbi Ìṣẹ́po Odi.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Bisi Alimi: Ìyà mi rò pé n kò leè ṣe ni àmọ́ n kò ní ìfẹ́ abo ni mo ṣe fẹ́ akọ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Àwọn to n bá ẹlẹkun sunkún ní Ghana Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Fi ìfẹ́ rẹ tí kì í yẹ̀ tẹ́ wa lọ́rùn ní òwúrọ̀,kí á lè máa yọ̀, kí inú wa sì máa dùnní gbogbo ọjọ́ ayé wa.
Kayọde Makinde, tii se baba ọmọ ti wọn bẹ lori naa, lasiko to n ba BBC Yoruba sọrọ pẹlu omije loju ni, oun ran ọmọ oun lati lọ gba owo wa lẹnu ẹrọ ATM, lo ba di awati.
Àgọ́ rẹ̀ kún fún àwọn tí kì í ṣe tirẹ̀,imí-ọjọ́ fọ́nká sí gbogbo ibùgbé rẹ̀.
Neko mú Jehoahasi lọ sí Ijipti, ibẹ̀ ni ó sì kú sí.
Jọ̀wọ́, ro ọ̀rọ̀ wa wò,nítorí pé eniyan rẹ ni gbogbo wa.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ojo arọrọda Eko ṣe idiwọ fún káràkátà Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Ojo arọrọda Eko ṣe idiwọ fún káràkátà 7 Owewe 2018 Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí 2 sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 2:23 Fídíò, Water Generator: Ó leè ṣiṣẹ fún wákàtí mẹfà, kó tó sinmi, Duration 2,2310 Òkùdu 2020 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
Gomina Fayemi lo pada tu Ojo silẹ pẹlu agba ra ipo rẹ.
Èémí OLUWA tó dàbí ìṣàn imí-ọjọ́ ni yóo ṣá iná sí i.
Ibọn pa agunbanirọ kan ni Eko: Oríṣun àwòrán, @Innex9 Aworan miran to tun n fọ ni lori ni ti oku agunbanirọ kan ti wọn n pin kiri pe wọn yinbọn pa nilu Eko.
Emir Sanusi sọ òkò ọ̀rọ̀ sáwọn mínísítà Seyi Makinde, yé é sọ̀rọ̀ mi láìdà - Gomina Ajimobi Ganduje Video - Ìwádìí ilé aṣòfin foríṣánpọ́n Ijoba ipinle naa lasiko ti wọn n sọrọ ni awọn gbe igbesẹ lati pin ọba ilu naa si mẹrin lati mu ibasepọ to gbooro ati eyi to dan mọran wa laaarin awọn ara ilu ati ọba wọn.
Oríṣun àwòrán, Kola Carew Facebook Àkọlé àwòrán, Ọkan lara awọn ere ti Tunrayọ Adeoye se, to fi di ilumọọka ni fiimu kan ti wọn pe ni Igbekun.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Tani yóò tẹ̀síwájú ní Champions league?
Àwọn ìṣẹ̀lẹ̀ mánigbàgbé tó wáyé nínú oṣù Kẹ́wàá ọdún 2020 Wo ìgbà márùn ún tí Buhari ti rìnrin àjò lọ sókè òkun fún ìtọ́jú ara rẹ̀ Mo ṣetán láti dojú ìjà kọ ẹnikẹ́ni tó bá fẹ́ bá ọ̀rọ̀ ajé Eko jẹ́- Sanwo Olu Sanwo-Olu buwọ́lu ìgbésẹ̀ ìjọba láti tún Eko ṣe lẹ́yìn rògbòdìyàn EndSARS Eeyan to le ni miliọnu mẹrindinlaadọta ni arun coronavirus ti ràn ni agbaye.
Nígbà tí wọ́n dé Kapanaumu, àwọn tí ń gba owó Tẹmpili lọ sí ọ̀dọ̀ Peteru, wọ́n bi í pé, “Ṣé olùkọ́ni yín kì í san owó Tẹmpili ni?
Ìran Isaaki ọmọ Abrahamu nìyí, Abrahamu ni baba Isaaki.
Kankara Abduction: Ohun ìbànújẹ́ ni bí wọ́n ṣe jí akẹ̀kọ̀ọ́ t'o le ni 300 gbé
Minisita feto ẹkọ ni Naijiria, Adamu Adamu ti kede lọjọ Ẹti pe ki gbogbo ile ẹkọ di sisi pada.
 dida ara wa ni ida 70-80 % ninu awọn eniyan ti o ni irufẹ ẹjẹ 2 ati 3 hcv pẹlu itọju ọsẹ mẹrinlelogun .
Aaroni sọ gbogbo ohun tí OLUWA sọ fún Mose fún wọn, ó sì ṣe àwọn iṣẹ́ ìyanu náà lójú gbogbo àwọn àgbààgbà náà.
Bí eniyan ṣe ń kú, ni ẹranko ṣe ń kú.
O fẹ́ ẹ̀rí pé igbagbọ ti kò ní iṣẹ́ ninu jẹ́ òkú?
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Christmas: Ẹni ti ọdun ba ti bá láyé yẹ kó dúpẹ́ Ninu ẹ̀sìn Kristiẹni, ọpọ maa n pọn ọn le gẹgẹ bi alaabo awọn ti ko ni iya ati baba, awakọ oju omi ati awọn ẹlẹwọn.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù APC: A kò ní ìjìyà kankan fún Amosun lórí ìgbésẹ̀ rẹ̀ 3 Ọ̀pẹ̀̀ 2018 Oríṣun àwòrán, @Govsia Ẹgbẹ oṣelu APC ti fesi lori ikede kan ti Gomina ipinlẹ Ogun, Ibikunle Amosun se laipẹ yii pe, oun yoo gbe lẹyin oludije fẹgbẹ oselu APM, Adekunle Akinlade lati di gomina ipinlẹ Ogun lọdun 2019.
Bí Ganduje bá pàdánù ìdìbò gómínà, kí ni yóò ṣe?
Oloyede ni Franklin gba iye maaki aadọtalelẹlọọdurundinmeji(348) ninu erinwo(400).
Ni Naijiria, awọn darandaran ati agbẹ a maa saaba kọlu ara wọn, ti eyi a si ma mu ọpọ ẹmi lọ.
Ó kó àwọn ọ̀gágun sinu àwọn ìlú olódi ní Juda.
24b) fun eto Ẹkọ ati okoolelọọdunrun o din marun naira (N315.
Ẹ wá OLUWA nígbà tí ẹ lè rí i,ẹ pè é nígbà tí ó wà nítòsí.
'Ojú inú mi ni mo fi ń rí àwọn irinṣẹ́ tí mo fi ń ṣe mọkálíìkì' 'Àwọn òyìnbó máa ń fẹ́ tọ́ oúnjẹ mi tí wọ́n rí lórí Instagram wò' Ilé ẹjọ́ pàṣẹ kí wọ́n fi àwọn afurasí tó pa àkẹ́kọ̀ọ́ LASU sí ẹ̀wọ̀n Obìnrin Kwara tí wọ́n tà sóko ẹrú ní Lebanon figbe ta, ọwọ́ tẹ èèbó kọ̀ráà tó ṣiṣẹ́ náà Èyí tí a wò jùlọ 5:03 Fídíò, Omolola Arohunmolase Welder: Mo ti fí iṣẹ́ 'Welder' gbayì láwùjọ, tó mo fi tọ́ ọmọ yanjú, Duration 5,039 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 5:39 Fídíò, Akomolede ati Asa lori BBC: Olùkọ́ Kikelomo Ogunboye tan ìmọ́lẹ̀ sí ìwà olè ọ̀gá ọlọ́pàá Audu gẹ́gẹ́ bí àwòkọ́ṣe àsìkò yìí, Duration 5,398 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 4:11 Fídíò, Oba Adeyeye Ogunwusi: Ojú mi ti rí lọ́pọ̀ lọpọ̀, ọ̀pọ̀ èèyàn ni kò tilẹ̀ gbàgbọ́ pé mo lè jọba- Ooni, Duration 4,117 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 4:43 Fídíò, Promise Akinlade: ọmọ ọdún mọ́kànlá tó ń fi ìlù dárà bíi àgbàlagbà sọ̀rọ̀ nípa tálẹ́ǹtì rẹ̀, Duration 4,437 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 0:59 Gbọ́, Ìsẹ̀lẹ̀ jákèjádò orílẹ̀èdè àgbáyé láàárín ìṣẹ́jú kan, Duration 0,59wákàtí 6 sẹ́yìn 4:45 Fídíò, Yoruba Films: Ẹ̀ẹ́ bẹ̀ mi kúrò láyé ni, mi ò lè kú - Fadeyi Oloro, Duration 4,4526 Èrèlè 2020 7:03 Fídíò, Olumuyiwa Bolade Adedeji Military Bruitality: Bí arákùnrin onípèníjà ara tí sọ́jà lù ṣe dé, Duration 7,035 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 2:48 Fídíò, Esther Ajayi: Èmi náà ti borí ìṣòro rí ló ń mu mi ṣojú àánú, Duration 2,481 Ògún 2019 6:08 Fídíò, Adebola Ademilua: Àìrísẹ́ ṣè lẹ́yìn ìwé kíkà ló sọ mi dí ìyá onírú, mo dúpẹ́ tèmi, Duration 6,0827 Bélú 2020 5:55 Fídíò, Soyinka Cancer: Àṣe ara mi ni iso ti n run gbogbo bí mo ṣe n ṣèrànwọ́ lórí jẹjẹrẹ, Duration 5,5527 Bélú 2019 BBC News, Yorùbá Ìdí tí ẹ fi le è nígbàagbọ́ nínú ìròyìn BBC Ìlànà Lílò Nípa BBC Òfin Àṣírí Cookies Kàn sí.
Covid-19 jẹ aisan ranpẹ to se pe laarin eeyan mẹjọ ninu mẹwa to ba mu,apẹrẹ ti wọn yoo ni ko ni ju ikọ ati ara gbigbona lọ.
Mo ti fa ẹni tí ọkàn mi ń fẹ́ lé àwọn ọ̀tá rẹ̀ lọ́wọ́.
 ohun tí èyí túmọ ̀ sí ni pé àwọn ìtàn méjì náà ni wọ ́ n gbajúmọ ̀ jù lọ .
Jonatani bí Meribibaali, Meribibaali sì bí Mika.
Turari yìí ni adura àwọn eniyan Ọlọrun, àwọn onigbagbọ.
Ìwọ akọ̀wé mi, ǹjẹ́ o kò rí i pé ó yẹ kí ènìyàn múra sí irú ìjà bẹ́l ńdan?
Gbogbo eniyan rọ Dafidi, pé kí ó jẹun ní ọ̀sán ọjọ́ náà ṣugbọn ó búra pé kí Ọlọrun pa òun bí òun bá fi ẹnu kan nǹkankan títí tí ilẹ̀ yóo fi ṣú.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù State Assembly: Adebo, Oluomo di adarí ilé aṣòfin ìpínlẹ̀ Oyo, Ogun 10 Òkùdu 2019 Oríṣun àwòrán, @Adebo_ogund, Olakunle Taiwo Oluomo Àkọlé àwòrán, Họnọrebu Adebo Edward Ogundoyin ati Họnọrebu Olakunle Taiwo Oluomo Awọn Ile igbimọ aṣofin ipinlẹ Oyo ati Ogun ti kede awọn to jawe olubori gẹgẹ bii adari ile.
" Bakanaa lo tun fi idi rẹ mulẹ pe ko din ni dokita mẹjọ to ti ku nipasẹ arun iba lassa bayii, eleyi to ni ko yẹ ko ri bẹẹ ka ni ohun eelo idaabobo to peye wa fun awọn dokita atawọn osisẹ eleto ilera yoku ni.
Lára ewu ti ó wà ninú ki èniyàn tori ẹni burúkú fọ́jú, ọ̀pọ̀ ti tàsé iyàwó tàbi ọkọ rere lai farabalẹ̀ wo iwà ẹni ti ọmọ wọn mú wálé tàbi tàsé ẹni rere.
Kan òrùlé sí orí ọkọ̀ náà, ṣugbọn fi ààyè sílẹ̀ láàrin orí rẹ̀ ati ẹ̀gbẹ́ rẹ̀ yíká, tí yóo jẹ́ ìwọ̀n igbọnwọ kan.
Bakan naa, awon ti o tun kopa ninu igbaradi ohun ni: Nicolas Otamendi, Gonzalo Higuain, Angel Di Maria, Javier Mascherano ati Marcos Rojo.
Iya to jẹ ẹfanjẹliisi yii o jẹ bẹmbẹ lọna yidi.
Najiria yoo waako pelu Croatia ninu ifesewonse akoko idije agbaye ohun, ni papa isere Kaliningrad lojo kerindinlogun osu kefa odun ti  a wa yii.
N óo ba yín lọ; bí ó bá wà níbẹ̀, n óo wá a kàn, bí ó bá tilẹ̀ wà láàrin ẹgbẹẹgbẹrun eniyan ilẹ̀ Juda.
Osinbajo ni ọjọ kẹtadinladọrin ree ta ti se ifilọlẹ eto naa, idi si ree ta fi gbọdọ se amusẹ rẹ ni kiakia, ki ori to ta araalu jinna."
Oòrùn, òṣùpá, ati àwọn ìràwọ̀ yóo jábọ́bí ewé tií rẹ̀ sílẹ̀ lára ìtàkùn àjàrà,àní, bí ewé tií wọ́ dànù lórí igi ọ̀pọ̀tọ́.
Wọn yóo bá mi kẹ́gbẹ́ ninu aṣọ funfun nítorí wọ́n yẹ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Abiola Ajimobi: Ẹbí Kolapo Isola ṣẹ́ pé òun kò gba ₦30m lọ́wọ́ Ajimobi fún ìsìnkú bàbá wọn 5 Agẹmo 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 11 Agẹmo 2020 Ẹbi ati ara Gomina Ipinlẹ Oyo tẹlẹri, Kolapo Ishola ti bu ẹnu atẹ lu ọrọ ti olori oṣiṣẹ fun Abiola Ajimobi nigba to wa nipo gomina, Gbade Ojo sọ nipa eto isinku rẹ.
Ni kete ti iṣẹlẹ naa ṣẹle ni wọn ti fi to Ọlọpa leti ti wọn si ti bẹrẹ iwadii lori ọrọ naa ati lati wa obinrin naa ri.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ẹkunwo lori ọja kun ara abajade afikun owo ori ọja to n wẹle sorilẹede Naijiria, gẹgẹbi awọn asofin se sọ Awọn asofin naa kọminu lori ohun ti wọn pe ni igbesẹ awọn ileesẹ ati lajọlajọ ijọba kan lorilẹede Naijiria lati maa gbe awọn igbesẹ ti yoo ko ifasẹyin ba idagbasoke eto ọrọ aje orileede naa.
"Iṣẹ́ Kudirat Abiọla ṣì ń fọhùn síbẹ̀, lẹ́yìn ọdún 23 tó papòdà Ọba Adesoji Aderemi, Ọọ̀ni Ifẹ̀ tó gba ipò ọba mọ́ tòṣèlú Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Mo ń ṣa ike jọ láti san owó ilé iwé ọmọ mẹ́ta' O ni ""ko sẹ́ni to n sọrọ wahala mọ tabi ṣiṣe atunto FIFA lati isalẹ, ọrọ bọọlu nikan lo ku ti a maa n sọ."
Ṣugbọn ofin wa faaye gba ki ọkunrin fẹ iyawo miran ti o si fawọn ofin de bi eeyan ṣe ma fẹ iyawo ọhun.
Olusola, ẹni to kọ ẹkọ nipa sinima ṣiṣe nilẹ Amẹrika fikun un pe, ọpọ ipenija ni oun n koju nidii isẹ naa, ti awọn osere yoku kii si fẹ pe oun lati wa ṣiṣẹ pẹlu wọn.
Bótiwù kó jẹ́, nkan ìyanu gidi ni òkuta yìí.
pada si orile ede Naijiria  ni ọjọ keji,osu
Bí àwọn tí kò fàmì hàn ṣe ń pín Oríṣun àwòrán, Getty Images A mọ̀ pé lẹ́yìn ọjọ́ márùn-ún ni ààrùn náà tó máa n fàmìhàn tó bá mú ènìyàn, ṣùgbọ́n ki wọn tó bẹ̀rẹ̀ síní fàmìhàn nkọ́, àwọn míràn kò tilẹ̀ ni fàmìhàn rárá.
Oríṣun àwòrán, Reuters Àkọlé àwòrán, Ẹgbẹ́ agbábọ́ọ̀lù Nàìjíríà ti já ní AFCON Musa ni awọn mọ pe awọn ọmọ Naijiria fẹran ere bọọlu gan an, o ni awọn ti ṣetan lati pa wọn lẹrin.
Gomina Ipinlẹ Eko, Akinwunmi Ambode lo kọkọ dide iranlọwọ fun awọn eniyan aadọta tọ ha si ibẹ, ti ọpọlọpọ si ti wa to ha si orilẹede Russia.
Lẹ́yìn rẹ̀ ni Gabai ati Salai.
Lọdun 2014, Seyi Makinde kara bọ didu ipo gomina labẹ asia ẹgbẹ
Obìnrin takuntakun, obinrin to ju ọkùnrin lọ, obinrin to si n fi ọba jẹ tabi rọ ọba loye ni arábìnrin Tinubu nigba aye rẹ, ẹni to yan kata-kara owo ẹrú laayo nigba aye rẹ.
Saulu ati àwọn ọmọ ogun rẹ̀ lọ láti wá Dafidi.
O mẹnuba awọn ipenija to koju ṣaaju idibo gẹgẹ bii obinrin to n dije dupo nipinlẹ Ọyọ ninu ẹgbẹ tuntun.
Ohun to jẹ iyalẹnu fun awọn araalu naa ni pe ko si ẹni to mọ ibi ti awọn kokoro oyin ọhun ti wa.
 ibi gama si papọ ̀ mọ ́ rògbòdìyàn tí àwọn ọmọkùnrin gbé dìde ní ọdún 1835 , ọmọ ọdún márùn-ún péré ni gama ní àsìkò yìí .
Èmi ni oúnjẹ tí ó wà láàyè tí ó ti ọ̀run sọ̀kalẹ̀.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Black women live matters: Ọdún 2015 ní àwọn ọlọ́pàá pa India Kager láìní ìdí- Gina Best Koda, iroyin sọ pe ile ti wọn ba wọ, ti baale ile ibẹ ba kọ lati fun wọn lowo, bibasun ni iyawo rẹ, tabi ki wọn o ṣe ọkunrin naa yanna-yanna.
Ta ló ń kọ yín ni ohun tí ẹ̀ ń sọ wọnyi?
Ẹ̀yin olólùfẹ́ mi àti ẹbí ni mo bẹ̀ 'Torí N2,500 owó irun, ọmọ Fásitì EKSU gún ọ̀rẹ́kùnrin rẹ̀ pa Athletico bu omi la ìgara Christiano Ronaldo, ní Madrid Ọlọ́pàá kò rí ǹkankan lábẹ́ pẹpẹ ilé ìjọsìn mi - Olùṣọ́àgùntàn Akure Ọkọ Toyin ṣalaya pe, laye atijọ nigba ti ohun wọ iṣẹ tiatia, ti ko si ẹrọ ayelujara, awọn eeyan ma n wo awọn ọsere loke ni, ṣugbón laye ode oni, awọn oṣere ko ni iyi mọ.
Wọn fikun un pe ọna abayọ n bọ laipẹ llati koju arun Coronavirus.
Lizzy Anjorin vs Toyin Abraham: Èrò àwọn olólùfẹ̀ Toyin Abraham ati Lizzy Anjorin lórí ìjà tó bẹ́ sílẹ̀ láàrín wọn
Bio tilẹ jẹpe obinrin ati awọn ọmọdebirnrin lo jẹ apa kan ti a ba da iye awọn eniyan to wa lagbaye si meji, ti wọn si ni awọn ohun ribiribi ti wọn le e gbeṣe naa.
Tí ara ba ti bẹ̀rẹ̀ si ni ń jo ọ̀rá dànù, èyí máà ń ṣe ìrànwọ fún ara láti dínku ti ẹni náà ba sanra, èyí a si maa mu adinku ba àisàn ìtọ̀ súgà.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Pẹlu Esi yii, o fihan pe ifẹsẹwọnsẹ meji pere ni Manchester united ṣi bori bayii ni mẹfa ti wọn gba bayii ni saa yii.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Baby abandoned on dunmpsite: Mo ti bímọ mẹ́rin tẹ́lẹ̀ fún bàbá méjì nínú òṣí- Dupe Ogbomos Kolawole fikun wi pe, asiko ti ijọba gbe igbesẹ naa ni ko rọrun fun awọn ọmọ Naijiria, nitori ọrọ aje to dẹnukọlẹ ati arun Coronavirus to n ba gbogbo agbaye finra.
Ìgbà ó pẹ́ ṣa a rí ẹnìkan tí ó wí pé: káàbọ̀, Ìrìnkèrindò, ẹ múra, àwọn ẹranko ń fẹ́ bá yín jagun.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù 2021 Prophecies: Ayodele ní ọwọ́ pálábá Abubakar Shekau yóò ségi lọ́dún tuntun 27 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 28 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Oríṣun àwòrán, Facebook/Primate Babatunde Elijah Ayodele Oludasilẹ ijọ INRI, Primate Elijah Ayodele ti gbe awọn asọtẹlẹ to le ni igba sita fun ọdun 2021.
Ìwọ́ ọ̀rẹ́ mi, báyìí ni bàbá mi ṣe tí ó fi fẹ́ ìyá mi, lákòókò tí wọ́n sì fi bími, ìyá mi, níwọ̀n ìgbá tí òun náà ti jẹ́ iwin, ó rọra yọ́ kẹ́lẹ́kẹ́lẹ́ lọ síìsálú ọ̀run óo já ọ̀kan nínú àwọn èèso igi ìyè ó fi í fún mi mo sì jẹ́ ẹ́ bẹ́ẹ̀ ni n kò lè kú títí ayé mọ.
"Títí di àsìkò yìí mí ò ti gbọ́ láti ọ̀dọ̀ àwọn ìgbìmọ̀ àyẹ̀wò pé èmì ni wọ́n yọ, tàbi ki wọ́n kọ lẹta nípa rẹ, wọ́n ni, wọ́n ni, ní mò ń gbọ́.
, yaya mefa lati maa pese idanilẹkọọ fun awon osise won loorekoore.
Ní ọdún kinni tí Beṣasari jọba ní Babiloni, Daniẹli lá àlá, o sì rí àwọn ìran kan nígbà tí ó sùn lórí ibùsùn rẹ̀.
Àwọn tí inú wọn ìbá dùn lọpọlọpọbí wọ́n bá rí ẹni gbé wọn sin.
Nítorí ọpọlọpọ ní ń jẹ́rìí èké sí i, ṣugbọn ẹ̀rí wọn kò bá ara wọn mu.
Ó ti pa ẹran rẹ̀,ó ti pọn ọtí waini rẹ̀,ó sì ti tẹ́ tabili rẹ̀ kalẹ̀.
Oríṣun àwòrán, facebook Wo ǹkan mẹ́rin tó yẹ kí o mọ̀ nípa ètò ìdìbò aàrẹ Ghana tó máa wáyé lọ́la Wọn kọkọ jọ pade lọdun 2012, lẹyin naa lọdun 2016 ati lọdun 2020 yii.
Mose, Eleasari ati àwọn olórí jáde lọ pàdé àwọn ọmọ ogun náà lẹ́yìn ibùdó.
gbogbo awọn sọrọ, a tun ni awon alaga egbe  ati  adari  egbe 
Àbí aṣọ wo ni ó tún ní tí yóo fi bora sùn?
Osun: Ọdun 2011 ni ofin ti wọn fidi mulẹ, deede owo ti wọn n gba lasiko ti wọn wa lori oye si ni owo ifẹhinti Gomina ati igbakeji rẹ.
O goke agba di ga lẹnu iṣẹ yii titi ti wọn fi yan an gẹgẹ bii adari igbimọ adari ajọ NNPC.
gégé bí ìtàn se so , Ààre kúrunmí ko ìréje ìdí nìyí tí òun àti aláàfin Òyó ìgbà náà oba Àláàfin Àdélú tí ó jé omo bíbí aláàfin Àtìbà tí ó gbésè fi gbéná wojú ara won látàrí wípé Ààre kúrunmí kò láti san ìsákólè odoodun fún Òyó .
    Ìgbà tí ọ̀rọ̀ òkè Ìrònú kanlẹ̀, mo ná owó fún Ìrìnkèrindò àti àwọn tí ó bá a wá sí ìlú wa kí ó ba à lè fún mi ni ipò ńlá.
Ṣugbọn ó dáhùn pé, “Èyí tí ó jù ni pé àwọn tí ó ń gbọ́ ọ̀rọ̀ Ọlọrun, tí wọ́n sì ń pa á mọ́ ṣe oríire.
Tí a fiṣọwọ́ ní 5:575:57 Ìwọ́de ńlá yóò bẹ́rẹ̀ lọ́jọ́ táwọn gómìnà bá yá ₦17trn nínú owó ìfẹ̀yìntì òṣìṣẹ́ - NLC Ẹgbẹ osisẹ ti yari lori igbesẹ awọn gomina ipinlẹ ni Naijiria lati ya lara owo ifẹyinti awọn osisẹ to wa nipamọ.
Ẹ kúkú ti mọ̀ pé làálàá tí ẹ̀ ń ṣe níbi iṣẹ́ Oluwa kò ní jẹ́ lásán.
Gbogbo wa ni a gbọ́, nígbà tí ọba pàṣẹ fún ìwọ ati Abiṣai ati Itai pé, nítorí ti òun ọba, kí ẹ má pa Absalomu lára.
’ rèé Afọnja, ẹni tó finú wénú ní Ilọrin, àmọ́ tó jẹ iwọ Ẹfunsetan Aniwura, obìnrin tó ju ọkùnrin lọ Ọ̀rọ̀ǹpọ̀tọ̀niyùn, Aláàfin obìnrin àkọ́kọ́ rèé, tó ní nǹkan ọkùnrin Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Dókítà ọ̀mùtí ní India se iṣẹ abẹ tó mú ẹmi olóyún àti ọmọ rẹ̀ 28 Bélú 2018 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ko pẹ lẹyin iṣẹ abẹ ti Dokita naa ṣe ti aboyun ohun ati ọmọ rẹ papoda.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, SS3 ní mo wà báyìí, mo sì ti gba àmì ẹ̀yẹ̀ púpò nílé-lóko gẹ́gẹ́ bí onílù - Ayansike Minisita fun eto irinna, Rotimi Amaechi, gẹgẹ bi iwe iroyin The Punch ṣe jabọ, sọ fún awọn akọroyin pe ijọba buwọlu owo naa fun idagbasoke oju ọna ọkọ reluwe ti yoo so bẹrẹ lati ipinlẹ Kano-Dutse-Katsina-Jibia, titi de Maradi lorilẹ-ede Niger Republic.
O pe ọdun mọkanlelọgbọn lonii ọjọ kejila oṣu kẹjọ ọdun 2020 ti gbajugbaja agbabọọlu orilẹede Naijiria Samuel Sochukwuma Okwaraji ṣubu loju ija.
A kò fipá mú ẹnikẹ́ni láti dá Ruga, aàgọ́ Fulani sílẹ̀ -Iléeṣẹ́ aàrẹ Biodun Fatoyinbo fi ipò sílẹ̀ lorí ẹ̀sùn ìfipábánilòpọ̀ Yan àwọn tí o fẹ̀ fún ẹgbẹ agbábọ́ọ́lù ààyò rẹ Seyi Awolowo, ọmọ-ọmọ Awolowo, kí ló ń wà lórí ètò BB Naija?
Wò mí, ọ̀rẹ́ mi, gbé ojú sókè, ojú ni ọ̀rọ̀ wà, Ọlọ́run tóbi Lọba, máa ṣọ́ra, máa ṣọ́ra, máa ṣọ́ra kí o tóó máa ṣátátá ọmọnìkejì rẹ, nítorí bàbá mi ni ó máa ń kéde fún gbogbo aráyé wi pé kí wọn kí ó má ṣe dá ẹ̀ṣẹ̀ mọ́, ìyàlẹ́nu ló sì jẹ́ l’ọ́jọ́ náà, nígbà tí òun pàápàá rí i wí p’w ìwà tí òun wí pé kí ènìyàn má ṣe hù wọn-ọnnì ni òun náà pàápàá ń hù, ẹ̀sẹ̀ tí òun wí pé kí àwọn aráyé má ṣe dá ni òun náà pàápàá ń dá, ìrìn tí òun wí pé kí ènìyàn má ṣe rìn ni òun pàápàá ń rìn, ọ̀rọ̀ tí òun wí pé kí àwọn ọmọ aráyé má ṣe sọ ni òun pàápàá ń sọ, ìtìjú pàdé ìtìjú, ní ọjọ́ tí bàbá mi rí ẹ̀ṣẹ̀ wọn-nnì nínú ìwé oníbodè, níbi tí onítọ̀hún tò wọ́n sí gbàgàgadagba.
Surieli ọmọ Abihaili ni yóo jẹ́ olórí wọn.
Ni ti ohun gan to fa ede ayede laarin gomina Rotimi Akeredolu ati igbakeji rẹ.
Oríṣun àwòrán, Getty Images EFCC bẹ̀rẹ̀ ìwádìí lórí ẹ̀sùn ìwà jẹgúdújẹrá tí wọ́n fi kan Fowler tó jẹ́ àdàrí iléeṣẹ́ Alpha Beta ''Àjọ NERC ti fún Disco láṣẹ láti padà sí owó tàríìfù tuntun iná mọ̀nàmọ́ná'' Báyií ni o ṣe lè wo èsì ìdánwò WAEC rẹ tí yóò jáde lónìí ọjọ́ Ajé Ẹ dẹ̀kun lílo Sniper àti Dichlorvos fún ìtọ́jú oúnjẹ- NAFDAC kìlọ̀ US Election 2020: Ṣé èsì ìdìbò Ààrẹ Amẹrika yóò jáde lálẹ́ ọjọ́ ìdìbò?
Bakan naa lo tun kọ ọrọ àpilẹ̀kọ to pọ nipa ilẹ Africa, fun awọn iwe iroyin.
O sọ pe lootọ ni yoo pa ọrọ aje lara, ṣugbọn awọn ko gbọdọ fi ọwọ yẹpẹrẹ mu ọrọ coronavirus.
maasai je eya awon eniyan ni apailaoorun afrika .
Mo ṣe ṣe oríire tó báyìí, tí ìyá Oluwa mi fi wá sọ́dọ̀ mi?
Wọn yi lawọn ariran ti o kùnà lórí ẹni tí yóò di ààrẹ Naijiria.
Ni bayii, a ti ri mẹẹdọgbọn pada ninu awọn to sa lọ o ṣi ku marundinlọgọrun sita ti a o tii mọ ibi ti wọn wa""."
Oríṣun àwòrán, Nimc Loju opo twitter yii ni ẹ ti lee ri fọọmu naa gba: https://twitter.
Ile-ise alabo lorile-ede Philippine ti fowo sinkun mu okunrin alejo kan ti won fesunkan pe o n sakojo awon omo-ogun olote islam lorile-ede naa.
"Ipinlẹ Edo ni gomina wa nigba to gbọ pe Abiola Ajimobi kú.
Kí ó tó lọ sí Gerari, Ọlọrun farahàn án, ó sì kìlọ̀ fún un pé kò gbọdọ̀ lọ sí Ijipti, kí ó máa gbé ilẹ̀ tí òun sọ fún un.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Owó tí mo ń rí lórí Garri ni mo fi ń ran ọkọ lọ́wọ́' Iroyin ni ṣe awọn ajinigbe ọhun di ihamọra bi ẹni n lọ oju ogun ki wọn kọlu ile Alhaji naa, ti wọn si gbe iyawo ati ọmọ rẹ lọ.
Rẹfirí Nestor Pitana to jẹ ọmọbibi orilẹede Argentina ti di ilumọọka lẹyin to fun France ''penalty'' ninu ifẹsẹwọnsẹ aṣekagba idije ife ẹyẹ agba ni Russia.
Bi ẹ ko ba gbagbe, laipẹ yii ni awọn ọdọ ilu Eko ya bo aafin kabiyesi Ọba ilu Eko, Akiolu ti wọn si fọ aafin rẹ gbe awọn ohun iṣẹmbaye titi kan ọpa aṣẹ Ọba naa lọ.
Oludari ẹka ọrọ to kan araalu labẹ ajọ NCC, ọmọwe Ikechukwu Adinde, l'Ọjọbọ ni awọn pa aṣẹ yii ki ajọ naa baa le ṣe ayẹwo iwe owo iye awọn to n ra afẹfẹ ibanisọrọ lọwọ wọn.
Lásìkò tó ń bá BBC Yorùba sọ̀rọ̀, Ọbasanjọ ni ki ọ̀rọ̀ òun tó dayọ, ojú ti rí, pàápàá jùlọ lásìkò ti òun wà lọ́gbà ẹ̀wọ̀n.
lati daabobo orile ede yii, ki a si tun pese alaafia lorile ede Naijiria.
Mo fi ṣíbí tọ́ díẹ̀ sẹ́nu, ni òógùn bá bò mí, ahọ́n mi ṣe bí ẹní fẹ́ bó.
Ìjọba Nàìjíríà ti parí ìwádìí lórí àgbo Covid-Organics ti Madagascar kó ránṣẹ́ sí i Oríṣun àwòrán, Rotimi Akeredolu Aketi Akeredolu lo jawe olubori ninu abẹle to waye ninu ẹgbẹ oṣelu APC lati yan oludije sipo gomina ninu idibo ti yoo waye loṣu kẹwaa ọdun 2020.
N kò ní wà pẹlu yín mọ́, àfi bí ẹ bá run àwọn ohun ìyàsọ́tọ̀ tí ó wà láàrin yín.
Àwọn ọmọ ogun náà fọ́n káàkiri, wọ́n ń jẹ, wọ́n ń mu, wọ́n sì ń jó, nítorí ọpọlọpọ ìkógun tí wọ́n rí kó ní ilẹ̀ àwọn ará Filistia ati Juda.
'Black Friday' àyájọ́ ẹ̀dínwó ọjà tó gbá ayé kan 'Ẹ má fi ọmọ kẹ́ ọmọ mọ́, ìbí kò ju ìbí lọ' Àwòrán díẹ̀ lára àwọn ǹkan ti ASUU ń jà fún nì yí Ọ̀ọ̀ni Ilẹ̀ ifẹ̀, John Mahama, sọ̀rọ̀ lórí ìṣọ̀kan ilẹ̀ Áfíríkà Albert ati Mileva jọ kọkọ n kọ iwe papọ ni ni eyi to fihan pe Mileva mọwe pupọ ti o si maa n ṣalaye nkan miran miran fun Albert.
Eliṣa dáhùn pé, “Má bẹ̀rù nítorí pé àwọn tí wọ́n wà pẹlu wa ju àwọn tí wọ́n wà pẹlu wọn lọ.
NANS: Ọ̀wọ́ngógó owó ilé ìwé ló jẹ́ kí àwọn akẹ́ẹ̀kọ́ máa fi fásitì sílẹ̀
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ethiopia Airlines Crash: Iyanrìn làwọn ẹbí olóògbé bàálù Ethiopia rí gbà dípò òkú èèyàn wọn 17 Ẹrẹ̀nà 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 30 Ẹrẹ̀nà 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ijamba baalu Ethiopia Ibanujẹ nla lawọn ẹbi eeyan mẹtadinlọgọjọ, ti ọmọ Naijiria Ọjọgbọn Pius Adesanmi jẹ ọkan lara wọn, to padunu ẹmi ninu ijamba baalu Ethiopia babọ lọjọ Aiku lẹyin ti wọn fun wọn iyanri lati ibi ti baalu naa ja si dipo oku ẹbi wọn to ku.
Mubarak beere lọwọ awọn oṣiṣẹ eleto ilera ilẹ Ghana boya wọn maa gbe igbesẹ lati ya Aarẹ Akufo-Addo to ṣẹṣẹ rin irinajo de lati ilẹ Yuroopu sọtọ ni iyara ahamọ tabi bẹẹ kọ.
Ìwọ Ọlọrun àwọn baba mi,ni mo fi ọpẹ́ ati ìyìn fún,nítorí o fún mi ní ọgbọ́n ati agbára,o sì ti fi ohun tí a bèèrè hàn mí,nítorí o ti fi ohun tí ọba ń bèèrè hàn wá.
Fun iru ara ọtọ iṣẹ ọpọlọ yii, gbogbo awọn ololufẹ rẹ loju opo instagram Samo Baba Comedian ko le ṣai ma kan sara si i bi wọn ṣe ni o n paronu rẹ laye awọn ti iṣ rẹ si da yatọ.
40 Tàbí ìwọ ha le sáré káàkiri síi gẹ́gẹ́bí afọ́jú adarí?
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ogundiya: Àṣìṣe Dókítà ló sọ mi di aláàbọ̀ ara lórí kẹ̀kẹ́ Omololu Olunloyo tún tiraka nínú ètò oselu lẹ́yìn èyí àmọ́ kò di ipo kankan mú mọ, tí o sì di àgbà ọjẹ fún àwọn ọmọdé oselu.
Alábòyun ṣe iṣẹ́ abẹ pẹ̀lú abẹfẹ́lẹ́, ó gbé ọmọ jádé nínú ara a rẹ̀ Kinni AIT ri sọ si ọrọ yii?
Oríṣun àwòrán, Kayode Ajulo Àkọlé àwòrán, Agbejoro Afegbua ni eni to ba sẹ, lo ma'n saa Leyin igbana, ni awon agbejọro re fi iwe sowo si ile ejo giga nilu Abuja wi pẹ awọn setan lati yo oruko ileesẹ mohunmaworan apapọ ti Naijiria, NTA ati channels kuro ninu ejo naa.
Ṣùgbọ́n olúkúlùkù ń ṣo tirẹ̀ ṣáá ni a kò sì mọ èyí tí à bá gbàgbọ́, èyí tí ó dá wa lójú ni wí pé àwa àti Ìbànújẹ́-ìsàlẹ̀ ni a jọ kúrò ní ìlú Òjòlá-ìbínú, àwa àti Ìbànújẹ̀-ìsàlẹ̀ kò sì jọ la àfoní-fojì àwọn olórí-burúkú obìnrin já.
Ambode ní kò sí gìrì, eré ọwọ́ lásán ni EFCC ń ṣe Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Bí wọ́n bá fá irun mi, agbára mi yóo fi mí sílẹ̀, yóo rẹ̀ mí n óo sì dàbí àwọn ọkunrin yòókù.
Ó fi ìkùukùu bora, òṣùmàrè sì yí orí rẹ̀ ká; ojú rẹ̀ dàbí oòrùn; ẹsẹ̀ rẹ̀ dàbí òpó iná.
Bi wọn ṣe fẹ ki a maa sọ Yoruba apapandodo yii, awọn ti wọn wa ni ilu yẹn ti wọn jẹ ede mii, bawo ni wọn ṣe fẹ maa ba ara wọn sọrọ.
Awọn iroyin ti ẹ le nifẹ̀ si: Charles Okah gba'dajọ ẹwọn gbere 'Naijiria ko laṣeyọri lori gbigbogun t'iwa ijẹkujẹ' Rufai Imam di adajọ agba ile ẹjọ Sharia ‘A ko mọ ibi ti Nnamdi Kanu wa’ Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Akomolede Yoruba: Kí ni ìdí tí aṣọ fi máa ń pọ̀ lára Egúngún ju Orò lọ́?
Gẹgẹ bi alaga egbe oselu APC,aarẹ nigbagbọ
Ṣugbọn nkan ti wọn se fun wa ko dara rara."
O yẹ ko tẹ ẹ jẹjẹ ni, a mọ pe gomina Seyi Makinde n ṣiṣẹ daadaa ṣugbọn ko fi apẹrẹ ọmọ ile iwe ti oun sọ fi kọgbọn, ko kawe mẹrin akọkọ rẹ ja na.
Àyè àti fi àmì sí ‘n’ àti ‘m’ ( ǹ ń, m̀ ḿ )
"Awọn eeyan kan ni ki wọn mu ọmọ mi kuro lọdọ mi, ti wọn ko si gbọdọ gba mi laaye lati lọ si ileewe jẹleosinmi rẹ nitori bi mo se ri tabi pe mo dabi ẹni to n fi aake pa eniyan.
Agbẹnusọ fun ile isẹ ọlọpa naa, Chike Otti sọ wipe ẹni ti wọn fẹsun kan yoo kawọ pọnyin rojọ ni ile ẹjọ to wa ni Yaba, ni ilu Eko.
Nítorí OLUWA tóbi, ó yẹ kí á máa yìn ín lọpọlọpọ;ó sì yẹ kí á bẹ̀rù rẹ̀ ju gbogbo oriṣa lọ.
fun ẹkun  Kabba/Bunu tun ti jawe olubori
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Revolution Now: Àwọn tó ń ṣèwọ́de ní ọta ìbọn ológun àti ọlọ́pàá kò dẹ́rù ba àwọn 14 Ògún 2019 Agbegbe Unity Fountain nilu Abuja ko rẹrin rara lọsan ọjọru nitori iwọde ti awọn ajafẹtọ ẹni se.
Àwọn eniyan ń rọ́ lọ sọ́dọ̀ Paulu.
Ọ̀tọ̀ọ̀tọ̀ ní èrò ṣe fún àwọn míran nítorí wọn gbàgbọ́ pé ọgbọ́n àrékérekè lásán ní àti pé kò sí ẹni to lè tú iṣẹ́ olúwa wò nípa rírọ òjò tàbí dídáa dúró.
Ọkàn mi mọ́, ṣugbọn n kò wí pé mo pé, Oluwa ni ẹni tí ó ń ṣe ìdájọ́ mi.
Fayose bu ẹnu atẹ lu igbesẹ naa loju opo Twitter lọjọ Aiku, o ni, igbẹsẹ ọhun lọwọ oṣelu ninu bẹẹni o si le fa aawọ papaa julọ lẹyin ti oun kọwe ranṣẹ si ajọ naa pe, oun n bọ lati wa jẹjọ lori ẹsun ti wọn fi kan oun.
Ó tẹ̀ sí ọ̀nà àwọn ọba Israẹli gẹ́gẹ́ bí ilé Ahabu nítorí ọmọ Ahabu, ni iyawo rẹ̀, ó ṣe ibi níwájú OLUWA.
Dánáfojúrà, àgbà eégún ti kò gbọdọ̀ fojú kan eégún míràn!
Olùkọ́ OAU: Ẹ̀sùn àdínkù ọjọ́ orí àti ìbéèrè ìbálòpọ̀ lọ́nà àìtọ́ ni wọ́n fi kàn-án
sefilole ile-ise ti yoo maa mojuto awon orisirisi isele nipase sise amulo ero
Gbogbo nǹkan yòókù tí Joaṣi ọba ṣe ni a kọ sinu Ìwé Ìtàn Àwọn Ọba Juda.
Gbogbo eniyan ni wọn n pe ni ọmọ Yahoo ti awọn ọlọpaa si n foju ole wo.
orile-ede Naijiira, papasibe won tun yanfanda enu kaakiri.
Alukoro fun Ajọ ọlọpa, Adekunle Ajisebutu sọ wipe Kọmisọnna ọlọpa ni ipinlẹ naa, Abiọdun Adekunle Odude lọ si ibi isẹlẹ yii, ti o si ri daju wipe alaafia pada sagbegbe naa.
Ta ni Sadiya Umar Farouq tí ìròyìn ń gbé pé òun ló fẹ́ dí ìyàwó tuntun Buhari?
’ Ó yẹ kí á ṣe àkíyèsí pé Àlàó ni oríkì Pópóọlá.
Àwọn adìẹ sùn lọ tantan, afẹ́fẹ́ tútù rọra ń fẹ́ ]awọn èkúté ń jẹ ẹ̀rún oúnjẹ láàrin àgbàlá, bí ènìyàn kò bá fetí sílẹ̀ tán kò lè gbúròó ẹnu wọn, ṣùgbọ́n òwìwì ń kígbe lẹ́ẹ̀kọọkan, mo sì gbóhùn èlúlu, bẹ́ẹ̀ ni àdán fẹ́rẹ̀ fi ìyẹ́ gbá mi lórí, nítorí òru ni àkókòo ìgbádùn fún ẹranko náà.
Coronavirus báwọn lálejò nílé ìjọba Canada, aya olóòtú ilẹ̀ náà ló náwọ́ gán Oríṣun àwòrán, Reuters Aya Olootu ijọba ilẹ Canada, Sophie Gregoire Trudeau ni ayẹwo kan ti fihan pe o ti gba alejo kokoro Coronavirus ni agọ ara rẹ.
Àwọn aṣojú láti Àgbáríjọ Olùgbèjà Ẹ̀tọ́ Ọmọnìyàn gbìyànjú láti jà fún un, àmọ́ a sọ fún wọn wípé fún “àǹfààní ìlú” ni a fi dá Wakabi padà sí ìlúu rẹ̀:
OLUWA ní, “Dájúdájú eniyan mi mà ni wọ́n,àwọn ọmọ tí kò ní hùwà àgàbàgebè.
“Ṣugbọn tí ó bá wí fun yín pé, òun kò ní jáde ninu ilé yín, nítorí pé ó fẹ́ràn ẹ̀yin ati gbogbo ìdílé yín, nítorí pé ó dára fún un nígbà tí ó wà lọ́dọ̀ yín, 
Gbogbo ẹran-ara kì í ṣe oríṣìí kan náà.
Secret Cults in Nigeria: Ìyá àti ọmọ tó wà nínú Márúwá bá ìjà ẹgbẹ́ òkùnkùn lọ
Ni ti Umar, o ṣẹṣẹ pada de lati mọsalasi to ti lọ kirun irọlẹ ni iṣẹlẹ naa waye.
Ipade naa, ti Ọọni tilu Ile Ifẹ, Ọba Adeyeye Ẹnitan Ogunwusi lewaju rẹ, wa fohun sọkan pe ki Oluwo lọ rọọkun nile na fun osu mẹfa.
Ni ọjọ buruku naa, adajọ ni, oun to bi Joel ninu ni wipe, Adeleke sọ fun ọmọkunrin naa wipe oun ko le san owo ọsẹ meji eyi ti ko tii ṣiṣẹ rẹ fun.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Fásitì Ghana lé olùkọ́ méjì tí àṣírí wọ́n tú lórí ẹ̀sùn ìbálòpọ̀ lọlé Àpọ̀jù òògùn ikọ́ olómi Codeine, ìbẹ̀rẹ̀ wèrè Ọ̀rọ̀ ń bọ́ lóríi fídíò Codeine 'Kìí ṣe àròsọ, mo ní fọ́nrán fídíò àwọn ẹlẹyẹ ìlú mi' Bí ìròyìn BBC nípa oògùn ikọ́ Codeine ṣe ń tún ayé tó ti bàjẹ́ ṣe Ìwádìí fídíò ayélujára tú àṣìrì ìpànìyàn Boko Haram Koda, awọn akẹkọjade kan lawọn ileẹks naa tun salaye ohun ti oju wọn ati ti awọn akẹẹgbẹ wọn kan ti ri lọwọ awọn olukọ to kundun ibalopọ naa.
Ìyà Tí OLUWA Fi Jẹ Jerusalẹmu.
Bí a ti gbọ́ ti Mose, bẹ́ẹ̀ ni a óo máa gbọ́ tìrẹ náà.
Ní báyìí ènìyàn tó dín díẹ̀ ní ẹgbẹ̀rùn lọ́nà ààdọ́rin ló ti lùgbàdì ààrun Covid-19 ní Nàìjíríà, nígbà ti ènìyàn ẹgbẹ̀rún mẹ́rìnleọgọ́ta ti gba iwòsàn Bákan náà ní ènìyin tó lé ni ẹgbẹ̀run kan ni ikú ti pa.
Oríṣun àwòrán, @followlastma O ni ileeṣẹ VIO nipinlẹ Eko ti ni awọn ohun elo igbalode, lati fi ṣe ayẹwo iwe ọkọ lati mọ ayederu yatọ si ojulowo.
awọn oludibo le gbe lati yọ asoju ni Ile Igbimo Asofin Ipinlẹ ati ti ijọba
nítorí ó ti bojúwo ipò ìrẹ̀lẹ̀ iranṣẹbinrin rẹ̀.
Ile igbimọ Asofin ni ipinlẹ Eko ti fi iwe pe gomina ipinlẹ Eko, Akinwunmi Ambode lati wa jẹjọ ẹsun iwa ibajẹ ti wọn fi kan an, ko lee ni anfaani lati wa sọ tẹnu rẹ.
Nígbà tí àwọn ìjọba kan mọ rírì ètò ìjọba àwa-arawa nípasẹ̀ ṣíṣe ìbò pẹ̀lú ọlọ́pọ̀-ẹgbẹ́ òṣèlú àti sọ nígbangba nípa àjọṣe, nínú ìṣe, ọ̀pọ̀ máa ń lo àṣẹ tí ò ṣe é yí padà  wọ́n sì ń lo agbára àṣẹ yìí lórí ẹ̀rọ-ayárabíàṣá bí ọjọ́ ṣe ń gun orí ọjọ́.
OLUWA, o tóbi pupọ, tìrẹ ni agbára, ògo, ìṣẹ́gun, ati ọlá ńlá; nítorí tìrẹ ni ohun gbogbo ní ọ̀run ati ní ayé.
O fẹsun kan an wi pe nitori o jẹ baba isalẹ fun awọn, o fẹ gaba lẹ wọn lori, ki o si sakoso gbogbo nkan to n wọlẹ si ipinlẹ naa fun ara rẹ nikan.
Rutu tún fi kún un fún Naomi pé, “Boasi tilẹ̀ tún wí fún mi pé, n kò gbọdọ̀ jìnnà sí àwọn iranṣẹ òun títí tí wọn yóo fi parí ìkórè ọkà Baali rẹ̀.
 Bode George ni Fayose ko bọwọ fun agba, ewu to si wa lori oun, kii se pe oun fi owo ra a, bẹẹ ni ko lọgbọn ori, Ọlọrun yoo si gba ẹsan lara Fayose, ayafi ti ko ba wa dọbalẹ ni ọọfisi mi lai mọye igba lati beere fun iranlọwọ."
Josẹfu pàṣẹ pé kí wọ́n di ọkà sinu àpò olukuluku wọn, kí ó kún, kí wọ́n dá owó olukuluku pada sinu àpò rẹ̀, kí wọ́n sì fún wọn ní oúnjẹ tí wọn yóo jẹ lójú ọ̀nà.
“Ẹ̀yin tí ẹ mọ òdodo, ẹ gbọ́ ohùn mi,ẹ̀yin tí ẹ fi tọkàntọkàn gba òfin mi,ẹ má bẹ̀rù ẹ̀gàn àwọn eniyan;ẹ má sì jẹ́ kí yẹ̀yẹ́ wọn já a yín láyà.
Eléyìí yà mí lẹ́nu nítorí n kì í dé ilé ọba tẹ́lẹ̀ bẹ́ẹ̀ ni kò sì sí ọ̀ràn tí mo dá, ṣùgbọ́n bàbá mi a ti má lọ sí ààfin lẹ́ẹ̀kọ̀ọ̀kan kí ó tó di pe títán dé bá a, nítorí òun àti ọba ìlú wa ti ń ṣe ọ̀rẹ́ tẹ́lẹ̀ kí ó tó di pé onítọ̀hún gun orí oyè.
Bakan naa ni ọpọlọpọ awọn ọga ologun ti wa ni iyasọtọ nitori aarun naa, lẹyin ti ọkan lara wọn, Charles Ray ni i.
A túbọ̀ fi ìdí Òfin múlẹ̀ ni.
Paulu wọ inú ilé ìpàdé lọ.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Iṣọla Oyenusi rèé, ẹnití ìfẹ́ obìnrin ṣun dé ìwà ìdigunjalè Taiwo Akinkunmi, ọmọ Ibadan tó ya àsìá Nàíjíríà Damasus, Omotola, Ezekwesili, Funmi Iyanda dá sí ẹ̀sùn ìfipábánilòpọ̀ Fatoyinbo Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Ile ifowopamọ agba Naijiria naa ni kikọ nnkan lede larubawa kii ṣe ami idanimọ ẹsin Islam.
Kí oore-ọ̀fẹ́, àánú ati alaafia láti ọ̀dọ̀ Ọlọrun Baba, ati Kristi Jesu, Oluwa wa, wà pẹlu rẹ.
Bakan naa si ni aarẹ Trump bu ẹnu atẹ lu awọn apaniyan, awọn adunkokomọni, awọn janduku ati adigunjale ti o nigbagbọ pe awọn lo wa lẹyin gbogbo ifẹhonu han to n waye lọwọ lọwọ nilẹ Amẹrika.
O tun ni o sì ti n gbọ́ran àti sọ̀rọ̀ báyìí lábẹ́ iṣẹ́ ìránṣẹ́ pásìtọ Favour Chimobi ti ìjọ Elijah Ministry ní Port Harcourt ti oun ati pasitọ David Favour jọ ń ṣiṣẹ́ pọ̀.
Oríṣun àwòrán, Instagram Egbegbe pẹlu ẹnikan to n jẹ Oyekan Ayomide ni wọn mu lọdun 2017 ti wọn farahan niwaju adajọ agba Oluremi Oguntoyinbo lori ẹsun mẹrindinlogoji to ni i ṣe pẹlu owo ko to di pe ọwọ tẹ awọn mii ti ẹsun pa wọn pọ.
mímọ́ ni ọ́ sí àwọn tí ọkàn wọn mọ́,ṣugbọn àwọn alárèékérekè ni o fi ọgbọ́n tayọ.
Ó tẹ̀ sí ìwà ẹ̀ṣẹ̀ baba rẹ̀, ó sì bọ àwọn ère tí baba rẹ̀ bọ.
Iléesẹ́ ológun Nàìjíríà bẹnu àtẹ́ lu ìwádìí Amnesty International
orile-ede Naijiria ati pe lati tun pese ona miiran ti yoo maa mu owo wo apo
World Smallest Baby: Dípò oṣù mẹ́sàn-án, wọ́n bí ọmọ yìí ní oṣù mẹ́rin àbọ̀
Àwọn èèyàn tí bẹ̀rẹ̀ sì ní gba abẹ́rẹ́ àjẹsára fún ìdènà àrùn Coronavirus ni ilẹ̀ Gẹ̀ẹ́sì Lóòtọ́ ni ọkọ mi lù mí bí àṣọ òfì, àmọ́ gómìnà ti bá wa parí ẹ̀, ẹ máa gbàdúrà fún ìdílé mi- Dokita Ifeyinwa Èyí ni ìtàn Ọkùnrin tó rí ẹ̀wọ̀n he nítorí àkùkọ aládúgbò rẹ̀ tó pa Diẹ lara wọn niyi: Oloye Sunday Micheal Afọlabi.
A si lee se apejuwe Henry Fajemirokun bii atapata dide, to de ibi giga, lati ipasẹ okoowo eyi to yẹ kawọn ọdọ fi se awokọse rere.
" O ni bi ijọba agbaye ba lee maa lọgun pe akoba ti ike n ṣe fun ayika pọ lọ jara, akoba ti epo rọbi n ṣe fun ayika ko ṣee maa fi ẹnu sọ Gẹgẹ bii aarẹ MOSOP naa ṣe sọ, akoba epo rọbi yii ni awọn eeyan agbegbe Ogoni n ba finra eleyi to nilo apewo ijọba atawọn ileeṣẹ gbogbo ti ọrọ kan.
”Aare lo fun irinajo olojo merin si orile ede Poland , nibi ti yoo ti maa se ipade agbaye lori oju-ojo ni Katowice.
Ajọ naa ni awọn ẹbi lo fun wọn laṣẹ lati kede iku Ibang lẹyin ti ayẹwọ fihan pe o ni arun Coronavirus.
00, nigba ti won n ta adiye inu yinyin ni egbefa N1,200 naira, amo dirika garri si duro lori odunrun N350 naira.
Àpèjúwe mi yìí kò ní kún tó tí mo bá fẹnu ba gbogbo nǹkan láìsọ ẹ ̀ yà èdè tí ìlú Ọ ̀ gbàgì ń sọ .
“o dun mi pupo, inu mi si baje nigba ti mo  tun gbo nipa isele buruku miiran to sele ni ipinle Bauchi, nibi ti iji lile ti ba opolopo dukia to wa ni  awon ilu ati agbegbe je , ti awon eniyan miiran si farapa yeleyele.
O ni ẹsin kii ṣẹ nnkan ti ''eeyan gbọdọ dimu lati ma fi tapa si ẹtọ ọmọniyan ti ofin agbaye la kalẹ'' O mu apẹrẹ iṣẹlẹ kan ti o nii ṣe pẹlu awọn obinrin kan ti wọn fẹ gbiyanju lati ni aṣepo laarin ara wọn ti ile ẹjọ Sharia si lodi si ẹyi pẹlu ijiya fun wọn.
Abrahamu jẹ́ ẹni ọdún mọkandinlọgọrun-un nígbà tí ó kọ ilà abẹ́.
Oníṣẹ́ ni ọkùnrín náà ìgbéga ẹ̀ sì tó ẹ̀kọ́ fún ìwọ àti èmi.
Bi o tilẹ jẹ pe baba yii sa ipa tiẹ fun orilẹede rẹ lasiko to wa ni opepe, ni ẹni ọdun mẹtalelogun,amọ bawo ni orilẹede rẹ se n mọriri rẹ nipa sise itọju rẹ lasiko ti agba de sii yii?
Nígbà tí wọ́n kéré ní iye,tí wọn kò tíì pọ̀ rárá, tí wọn sì jẹ́ àjèjì ní ilẹ̀ náà,
Jẹ́ kí n máa ranti ìfẹ́ rẹ tí kì í yẹ̀ láràárọ̀,nítorí ìwọ ni mo gbẹ́kẹ̀lé.
Ọpọ ololufẹ rẹ si lo mọ si Pa Ajirebi nitori orukọ to fun ara rẹ ree ninu ere tiata, ti awọn eeyan si mọ mọ.
Oríṣun àwòrán, Others Adebayo sọ pe ọga awọn paṣẹ lẹyin ti asiri ti tu ki awọn mu Kayode lọ si ileeṣẹ ọlọpaa fun ijiya to tọ si.
Sọ àsọtẹ́lẹ̀ orílẹ̀èdè tí yóò borí ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ t'òní Ẹ̀yin tẹ́ẹ tako àgbékalẹ̀ àgọ́ Fulani, ìkórira ló ń yọ yín lẹ́nu - Ìjọba àpapọ̀ Lai Muhammed yóò fojú ba'lé ẹjọ́ - ICPC Thomas John: Kí ló yẹ kóo mọ̀ nípa adelé alága NNPC tuntun?
Alhaji Umaru Musa Yar'adua gbe Turai niyawo lọdun 1975 wọn si ni ọmọ meje - obinrin marun ati ọkunrin meji.
'Buhari yoo s'ọrọ laipẹ' - Okorocha Ọmọ Prof.
Wo àwọn tí Pondei fara jọ pẹ̀lú ààrẹ̀ níwájú ijẹ́jọ́ Ọkùnrin kan pa ara rẹ̀ sínú ọgbà àjọ TRACE tó n mójútọ ìrìnnà ọkọ̀ nípìnlẹ̀ Ogun Wo àwọn nkan tó yẹ́ kí o mọ̀ nípa 'Awawa Boys', ọ̀kan lára ẹgbẹ́ òkùnkùn tó n dá Eko rú Wo àwọn òṣìṣẹ́ kólẹ̀-kódọ̀tí tó ń fi ẹ̀mí wọn wéwu kí Abuja leè mọ́ tónítóní Báwó ni òògùn dexamethasone ṣe ń ṣiṣẹ́ lára Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Olofa ina: ẹ parí òwe yìí pé ìgbà tí ara bá tu ìgbẹ́ láà ri eṣú.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ìpínlẹ̀ Kaduna dá àwọn olùkọ́ tuntun dúró Ẹmi marun sọnu ninu ija Kaduna Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Òpó keji rí bákan náà pẹlu èso Pomegiranate.
Ninu ìdílé Harimu: Elieseri, Iṣija, ati Malikija; Ṣemaaya, ati Ṣimeoni.
Inu omi ni abo ẹ̀fọ̀n yoo ye ẹyin rẹ si, eyi ti yoo dagba di ẹ̀fọn; abo ẹ̀fọn maa n wa ẹ̀jẹ̀ lati fi bọ́ awọn ẹyin wọn.
Ṣugbọn èyí tí kò bá mọ̀, tí ó bá tilẹ̀ ṣe ohun tí ó fi yẹ kí ó jìyà, ìyà díẹ̀ ni yóo jẹ.
Ọlọ́pàá fi páńpẹ́ ọba mú ọmọ ogun ilẹ̀ Naijiria Àkọlé àwòrán, Lagos Building Collapse: Ilé alájà méjì wó lu ọmọ mẹ́rin ni Bariga Ọpọlọpọ ile ni awọn ijọba ti ya sọtọ lati wo ni ipinlẹ Eko bayii.
Ènìyàn kán kú, méèje farapa nínú ìjàmbá afárá Otedola ní Eko Àwọn ìbejì mi kò le rìn dáadáa nítorí ọgbẹ́ tí wọ́n dá sí wọn lára ní ìgbèkùn - Akeugbagold Ọ̀gá àgbà ọlọ́pàá pàṣẹ pé kò gbọdọ̀ sí ìdádúró fún àwọn tí iṣẹ́ wọn ṣe kókó lásíkò ìséde Ààrẹ Buhari ti fi ọwọ́ òsì júwe ilé fún Ọ̀gá Àjọ ìdánwò NECO àti àwọn mẹ́rin míràn O ni ohun kan ṣoṣo to si le bori arun ọhun ni igbele ati pe, ko si bi arun naa ṣe le kasẹ nilẹ patapata, yoo si maa wa bii HIV ati ọfikin ni.
Jọ̀wọ́, OLUWA Ọlọrun Israẹli, fún mi ní èsì.
Alamojuto ere bọọlu meji rẹwọn he ni Burundi Ìkọlù abúlé Burundi gb'ẹ̀mí èèyàn 26 Burundi da eto idibo bi ọgbọn Iroyin sọ pe ọjọ ori awọn ọmọ to wa l'ẹwọn naa ko ti i to ọdun mejidinlogun.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù High Profile Corruption Cases in Nigeria: EFCC fọwọ́ òfin mú èèyàn 865 lọ́dún 2020 30 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 31 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Oríṣun àwòrán, Nigeria Prison service Adele alaga ajọ EFCC to n gbogun ti iwa ibajẹ ni Naijiria, Ọgbẹni Mohammed Abba ti kede pe ọta le lẹgbẹrin eeyan le marun un (865) ni ajọ naa fọwọ ṣinkun òfin mu lọdun 2020.
Nígbà tí abàmi ẹ̀dá náà ti kígbe ni gbogbo wa ti fún ṣòkòtò le; ṣùgbọ́n nígbà tí olúkúlùkù wa ti mú àdá tí a gbé ìbọn tán a rí i pé oògùn ọwọ́ wa kò ní í lè tó fún ìjà náà nígbà tí a si ń fẹ́ẹ́ lo àwọn oògùn pàtàkì tí a mú fún Ewédayépọ̀ pamọ́ a kò rí Ewédayépọ̀ mọ́, ó ti sálọ bámúbámú.
Ìjọba Nàìjíríà ti kéde pé kí ilé ìtura ṣí padà, kí ìlé ìwé máa palẹ̀mọ́ ìwọlé àwọn akẹ́kọ̀ọ́ Oríṣun àwòrán, @GarShehu Ijọba orilẹ-ede Naijiria ti fi ọjọ kun isede coronavirus jakejado Naijiria.
Ogbẹni Abayọmi Asaniyan to jẹ oludari ẹka ajọ FRSC ni ipinlẹ Kebbi ni ariwa Naijiria lo sọ eyi di mimọ fawọn oniroyin nipinlẹ Kebbi.
 O ni: “A n sise papo ni ki a le fenuko lori Jerusalem geg bii olu ilu”.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, AAUA; Ọ̀pọ̀ ìgbà ni SARS ma ń lu àwọn akẹ́kọ̀ọ́ fásitì wa Ṣaaju asiko yii ni awọn ọmọ orilẹede Naijiria ti n pe fun opin si iṣẹ awọn ọlọpaa SARS pẹlu ami ipolongo #EndSARS nitori awọn ẹsun ifiyajẹni ati titẹ ẹtọ ọmọniyan mọlẹ ti wọn fi n kan wọn.
Sean Tembo to n dari ẹgbẹ Patriots for Economic Progress (PEP),fi orisirisi ọrọ sita loju opo ayelujara eleyi to fi tọka si pe ọpọlọ aarẹ ko munadoko.
Ò ń pète ìparun;ẹnu rẹ dàbí abẹ tí ó mú, ìwọ alárèékérekè.
Ẹ̀yin ati àwọn arọmọdọmọ yín, ẹ gbọdọ̀ máa pa ìlànà yìí mọ́ gẹ́gẹ́ bí òfin títí lae.
Funke Akindele, oníròyìn, agbẹjọrò àti òṣèré; ohun tí ẹ kò lérò nípa rẹ̀ Ẹ wo àwọn ìlúmọ̀ọ́ká olórin, òsèré tó ti sẹ̀wọ̀n rí!
“Nígbà tí ọjọ́ ìwẹ̀nùmọ́ rẹ̀ bá pé, kì báà ṣe fún ọmọkunrin tabi fún ọmọbinrin, yóo mú ọ̀dọ́ aguntan ọlọ́dún kan wá sí ọ̀dọ̀ alufaa ní ẹnu ọ̀nà Àgọ́ Àjọ fún ẹbọ sísun, kí ó sì mú yálà ọmọ ẹyẹlé tabi àdàbà wá, fún ẹbọ ìmúkúrò ẹ̀ṣẹ̀.
Agunbiade ni owo ara mi ni mo lọ fi ra awọn nkan jijẹ ti mo fẹ pin, ọtọ ni awọn nkan iranwọ ti ijọba ipinlẹ Eko si ti lẹ orukọ mọ gbogbo nkan to jẹ iranwọ Covid-19""."
Shina Olukolu je ki o di mimo pe lara ipinnu ile -ise oloopa ni lati ri pe awon
Asán ninu asán, ọ̀jọ̀gbọ́n ní, asán ni gbogbo rẹ̀.
Agbebọn pa eeyan 17 l'Amẹrika Trump: O to gẹẹ lori ọrọ ilokulo ibọn lawujọ Akẹ̀kọ̀ọ́ méje pàdánù ẹ̀mí wọn ní China Nígbà tí wọn yóò fi gbé dé ilé ìwòsan, àwọn dókítà ní ọ ti je Olohun ni pé.
Fún ìdí èyí, bí Ọbásanjọ́ ṣe tàbùkù Buhari ní gbangba tó, ó níí ṣe pẹ̀lú agbára àti ipò ẹgbẹ́ tí àwọn méjèèjì wà gẹ́gẹ́ bí ọ̀gágun tí ó ti jagun fẹ̀yìntì.
Ẹ óo lé àwọn ará Kenaani jáde, bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé irin ni wọ́n fi ṣe kẹ̀kẹ́ ogun wọn, tí wọ́n sì jẹ́ alágbára.
OLUWA dáhùn, ó ní, “Bí mo bá rí aadọta olódodo ninu ìlú Sodomu, n óo dá gbogbo ìlú náà sí nítorí tiwọn.
Ethiopa kedun nipa awon to padanu ẹmi won ninu isele ifipagbajoba ohun.
Ewe, eyi ni yoo di igba keji ti Pliskova yoo pegede sipele keji asekagba idije WTA.
Ṣugbọn mo ní àwọn nǹkan díẹ̀ wí sí ọ.
"Ilé ẹjọ́ ju ọmọ ìjọ tó fi ìpá bá ọmọ pásítọ̀ rẹ̀ sùn ní ìpínlẹ̀ Ondo sí ẹ̀wọ̀n gbére Àwọn ẹgbẹ́ Tijjaniyya ti yọwọ́ kílàńkó Yahaya Sharif kúrò láwo ẹgbẹ́ wọn ní Kano ""Mi ò ní wọ Uber mọ́ tí wọ́n bá leè fi owó lée nítorí àfikún owó orí tí Sanwo Olu ṣe"" Ilé ayé mi ti d'ojú bolẹ̀ pẹ̀lú ikú àfẹ́sọ́nà mi- àfẹ́sọ́nà Immaculate Okochu Ogundipe gbé fásitì Unilag ló sí iléẹjọ́ nítórí wọn yọ́ ní ipò VC Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ibadan Death: Àwọn ará àdúgbò Akinyele ké sita lórí iṣékúpani tó ń wáyé ní ìlú Ibadan."
Tó bá di ìgbà náà, àwọn odò tí wọ́n kún fún omi ìyè yóo máa ṣàn jáde láti Jerusalẹmu.
Tí a fiṣọwọ́ ní 9:01 10 Ọ̀pẹ̀ 20209:01 10 Ọ̀pẹ̀ 2020 Ẹgbẹ́ òṣèlú alátakò takú láti gba èsì ìbò ààrẹ ní Ghana Awọn onwoye eto idibo labẹle ati lẹyin odi si lo ni ko si apade alude kankan ninu ibo naa, kedere lo han fun araye bo se lọ.
Àjọ tó ń mójútó àyíká l'Eko mú 123 ọlọ́kadà tó ń bọ̀ láti Jigawa Àlejò àpàndodo ni Fayoṣe, a kò fìwé pèé - Afuye Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Ó kú, wọ́n sì sin òkú rẹ̀, Pekahaya, ọmọ rẹ̀, sì jọba lẹ́yìn rẹ̀.
 Eleyii lo mu ki owo palaba awon afurasi odaran mokandinlogbon(29) ni ipinle Oyo segi ti owo sinkun oloopa ipinle Oyo si te won.
si oun ti mo lee se , o yẹ ki won ko o wa nitori pe a nilo rẹ bayii ni oju ona  Kaduna-Abuja ati  fun oju ona oko  irin Lagos- Ibadan , ti ko ni pẹ pari.
A ó ṣèwádíi òṣìṣẹ́ LASTMA tó ń ka owó àbẹ́tẹ́lẹ̀ nínú fídíò - LASTMA Báwó ni òògùn dexamethasone ṣe ń ṣiṣẹ́ lára Igbọnṣẹ ikẹyin ti Mujeeb ṣe niyi o ki awọn oniṣẹẹbi naa to kọlu ti wọn si paa ki wọn to bẹ lugbẹ.
Èèwọ̀ ni pé kí o ru ẹní rẹ!
Nibayii, eniyan marundinlaadọrin lo ti ni aarun naa ni Naijiria.
Ìgbìmọ̀ aláṣe ilé ìwé OAU sọ pé, nínú gbogbo ìwádìí, ó fi hàn pe ọ̀jọ̀gbọ̀n náà lo ipò àgbára láti dún-koko mọ́ akẹkọọ náà ni.
Lanre Kuti ni mo fẹ́ - Jaiye Kuti Àwọn àádọ́ta ọ̀dọ́ wọ gàù nítorí ilé ijó ní Ilorin Oríṣun àwòrán, Others Oríṣun àwòrán, Seyi Edun/instagram Ọ̀pọ̀ àwọn olólùfẹ́ Lizzy lágbo òṣèré ló ti ń kí i kú oríire.
Ẹnìkan wá bi í pé, “Alàgbà, ǹjẹ́ àwọn eniyan tí yóo là kò ní kéré báyìí?
Àwọn ọmọ Juda ní ìdílé-ìdílé nìwọ̀nyí: ìdílé Ṣela, ìdílé Peresi, ati ìdílé Sera.
Igbagbo wọn si ni wi pe iyanṣẹlodi naa yoo ṣe idiwọ fun iṣẹ awọn asofin eleyi ti yoo mu ki ọrọ naa ni iyanju.
Nkan tí kò gbà ju ìsẹ́jú kan lọ tẹ́lẹ̀, ó di oun tí a nfi ìsẹ́jú mẹ́rin ṣe.
Ohunkohun tí ó bá dá hù fún ara rẹ̀ ninu oko yín, ẹ kò gbọdọ̀ kórè rẹ̀.
O ni afojusun oun ni bi Zarka yoo ṣe gbagbe ohun to ti sẹlẹ latẹyinwa.
”Agbenuso fun ile-ise omo –oogun ofurufu tun tesiwaju pe” Nigba ti oko ija ogun   ofurufu ti ile –ise omo oogun ofurufu n lo kaakiri lati pese aabo ni awon agbegbe kan ,ni won gbo pe iko olote fe lo kolu Gashigar pelu awon ado oloro ati ibọn bi metala , ko to di pe iko omo oogun ofurufu orile ede yii bere si n maa rojo  ibọn lati inu oko ija ogun ofurufu naa pelu atileyin awon omo –oogun ori-ile si ikọ ọlọtẹ.
ede ti awon ile-ise pọ nibẹ sugbon ti ọrọ  won da bi igba ti omo ẹlẹran to n jẹ eegun
Oríṣun àwòrán, Abdul Momoh Àkọlé àwòrán, Ọ̀kẹ́ àìmọye sì ni owó àwon ọkọ̀ àti pátákó ìpolówó ọjà tíigi wó lù lásìkò tí ìjì náà fi jà.
Abike Dabiri-Erewa sọ pe iroyin ofege gbaa ni ọrọ yi.
Ikọ̀ ìwádìí BBC ṣí àwọn tó ń jí ìkókó gbé sí gbangba Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Lady Peller: Ọjọ́ ni ọjọ́ tí idán yíwọ́ fún ọkọ mi lẹ́yìn tó gé mi sí méjì, mo kú tán15 Bélú 2020 Yoruba World Assembly: Ìlú Ibadan ni wọ́n tí ṣe àgbẹ́kalẹ̀ ẹgbẹ́ ọmọ Yorúbá tuntun16 Bélú 2020 Fídíò, Nelly Ating Photographer: Omíjé kún rọ́rọ́ lójú mi níbùdó àwọn tí Boko Haram dá lóró15 Bélú 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Bákan náà ni Ìpínlẹ̀ Èkó to jẹ́ orírun ààrùn Coronavirus ni Nàìjíríà náà ń ṣe ìdánilẹ́kọ̀ọ́ orí redio àti telefísọ̀n, ṣùgbọ́n wọn ò sọ àsìkò tí ilé ẹ̀kọ́ yóò wọlé.
Lẹyin orilẹ-ede India, China ati Naijiria to ṣe ipo kẹta, awọn orilẹede ti wọn tun ti bi ọmọ to pọ no Pakistan (!
Buhari kéde ọ̀rọ̀ yìí lásìkò tó ń gbàlejò ààrẹ orílẹ̀-èdè South Africa, Cyril Ramaphosa.
Àwọn tí wọ́n gbọ́ nípa mi, ń pè mí ní ẹni ibukun,àwọn tí wọ́n rí mi ń kan sáárá sí mi.
tọwọbọ iwe adehun alaafia, o si ti di dandan ki a ri eto alaafia yii.
Gẹgẹ bi ajọ to n moju to n ajakalẹ aarun ni Naijiria (NCDC) se sọ loju opo twitter rẹ lọja Ẹti, ipinlẹ marundinlogun pẹlu olu ilu ilẹẹwa lawọn eeyan tuntun tun ti ṣẹyọ pẹlu arun naa lọjọ kọkanla oṣu kejila ọdun 2020.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Genotype: Kí làwọn àǹfàni àti ewu tí ẹ̀yà jínótáìpù rẹ le mú bá ìgbé ayé rẹ̀?
Orọ awọn ẹlẹsin Shiite ti di nkan miran lọwọ ni Naijiria lasiko yii.
Ọgbẹ́ni Sola Fasure tó jẹ́ agbẹnusọ lórí ìgbóhùn sáfẹ́fẹ́ fún gómìnà Arẹgbẹ́sọla ló sọ èyí dí mímọ lónì nílú Osogbo.
Mo wá ìgbàlà rẹ títí, àárẹ̀ mú ọkàn mi;ṣugbọn mo ní ìrètí ninu ọ̀rọ̀ rẹ.
Richard Osuolale Abimbola Akinjide wá sílè ayé, ó ṣe ayé rẹ, o jagun, ó sẹgun, to sì ṣe àṣeyọrí nínú gbogbo ohun tó dá wọ lé.
S Embassy Gbogbo igbiyanju BBC lati ba awọn agbofinro sọrọ lori iṣẹlẹ paapaa olobo ti wọn ni ẹnikan tawọn yii ja si pabo Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
 A ti se ipade lorisirisi pelu oga agba ile-ise iko omo ogun ati awon toro kan gbongbon ninu pipese aabo fun-lu.
O tun fi asiko ohun gba awon osise
Iku rẹ si da jinnijinni bo ọpọlọpọ eeyan.
Àwọn náà yóo jẹ ìgbẹ́ ara wọn tí wọn yóo sì mu ìtọ̀ ara wọn bí ẹ̀yin náà.
Nítorí ọ̀kan ni yóo ṣe: ninu kí ó kórìíra ọ̀kan, kí ó fẹ́ràn ekeji, tabi kí ó fara mọ́ ọ̀kan, kí ó má ka ekeji sí.
Gẹgẹ bii ifọrọwerọ Dokita Akinjide pẹlu BBC News Yoruba, o ni o yẹ ki ijọba mọ pe ọrọ orilẹede yii ti di ti 'eyi wumi ko wu ọ' O fi kun un pe atunto orilẹede Naijiria nikan ni ọna abays fun irufẹ edeaiyede ati awuyewuye bayii.
Komreedi Babatunde Adekomi fikun wi pe awọn osisẹ lorilẹede Naijiria lo gba owo osu to kerejulọ lagbaye, ti iya ati isẹ si n koju awọn eniyan.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Ohun to have iwadii yii jade ni Ireti gidi amọ ṣa, o ti ya ju lati mọ boya eyi nikan ti to lati dajọ pe o nṣiṣẹ lati da abo bo ara bẹẹ si ni awọn oogun ayẹwo mii ṣi wa lọna.
Ẹgbẹ TUC ni ọna abayọ meji pere ni awọn fun ijọba apapọ ki alaafia to lee jọba.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Gbajúgbajà òsèré tó tún mọ́ ọbẹ̀ sè Ijebu Gbajugbaja oṣere meji Ijebu ati Afeez Owo lo jọ di beba kan ti wọn kọ ''END SARS NOW'' si dani ninu iwọde #EndSARS naa ni.
nigba ti BBC pe olubadamọran pataki fun aarẹ lori ọrọ iroyin, Ọgbẹni Fẹmi Adesina, o ni oun yoo sọrọ lori rẹ bi o ba ya.
Eyi lo difa fun idile oloogbe agbaọjẹ Olorin Fuji, Sikiru Ayinde Barrister ati K1 De Ultimate, Wasiu Ayinde Marshal ti wọn ti pẹtu sí aawọ to wa laarin wọn.
Atẹjade kan, ti agbẹnusọ fun ajọ EFCC, Tony Orilade fisita lọjọ isẹgun lo sisọ loju ọrọ yii.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Bat: Kìí ṣe ènìyàn nìkàn ló ń ṣe òfin ìyàsọ́tọ̀ lásìkò àìsàn ẹranko kan rèé tó ń ṣe bẹ́ẹ̀ 27 Ọ̀wàrà 2020 Ǹjẹ ẹmọ̀ pé kìí ṣe ènìyàn nìkan lo ń ṣe ètò ìyaraẹni sọ́tọ̀ lásìkò tí wọ́n bá ń ṣe àìsàn?
jẹ́ ẹgbaa mejilelogun ó lé aadọta lé ní ẹgbẹjọ (45,650).
Wọn ni o si ṣe pàtàkì ki wọ́n fi ipò ààrẹ silẹ láti lọ sinmi nilé, nígbà ti elo miran dáhun pe nnkan ti o ṣe pataki si òun ni pé, owó ti àarẹ fẹ́ ya, ó se pataki ki wọ́n ka àwọn ǹkan ti wọ́n fẹ́ fi owó náà ṣe ki wọ́n to yaa.
Omo odun metadinladorin onisegun oyinbo naa fi egbe Brotherhood sile ni odun 2011 lati dije labe oselu ti o da duro ni odun 2012, ni eyi ti ko si ni nkankan se pelu egbe ohun latigba naa.
Nígbà tí àwọn ará Moabu gbọ́ pé àwọn ọba mẹtẹẹta ń bọ̀ láti gbógun tì wọ́n, wọ́n pe gbogbo àwọn tí wọ́n lè lọ sógun jọ, ati àgbà ati ọmọde, wọ́n sì fi wọ́n sí àwọn ààlà ilẹ̀ wọn.
3 5337 Erekusu Cape Verde 109 20.
Lasiko ti o fi n tẹwọgba abajade iṣẹ igbimọ to gbe kalẹ fun iyipada iṣejọba nipinlẹ Ekiti ni Ọmọwe Fayẹmi kede eyi.
Amuyẹ meji ni Bitcoin ni: owo ori ayelujara ni, awọn kan si tun n ri gẹgẹ bi ọna abayọ miran.
Nítorí náà, pàṣẹ pé kí wọ́n kó gbogbo àwọn ọmọ Israẹli jọ, kí wọ́n pàdé mi ní orí òkè Kamẹli.
Oun ti ẹ le fẹ mọ sii nipa awọn to n figagbaga ree Pernille Harder Oríṣun àwòrán, Reuters Àkọlé àwòrán, Pernille Harder Ọjọ́ orí: 26 Orílẹ̀èdè: Denmark Iye ìgbà tí ó ṣójú orílẹ̀èdè rẹ̀: 110 Ẹgbẹ́ agbábọ́ọ̀lù: VFL Wolfsburg Ipò: Ọwọ́ iwájú (Forward) Ada Hegerberg Oríṣun àwòrán, RONNY HARTMANN Àkọlé àwòrán, Ada Hegerberg Ọjọ́ orí: 23 Orílẹ̀èdè: Norway Iye ìgbà tí ó ṣójú orílẹ̀èdè rẹ̀: 66 Ẹgbẹ́ agbábọ́ọ̀lù: Olympique Lyonnais Ipò: Ọwọ́ iwájú (Forward) Lindsey Horan Oríṣun àwòrán, MARK RALSTON Àkọlé àwòrán, Lindsey Horan Ọjọ́ orí: 24 Orílẹ̀èdè: USA Iye ìgbà tí ó ṣójú orílẹ̀èdè rẹ̀: 62 Ẹgbẹ́ agbábọ́ọ̀lù: Portland Thorns Ipò: Ọwọ́ àárín (Midfielder) Sam Kerr Oríṣun àwòrán, DANIEL POCKETT Àkọlé àwòrán, Sam Kerr Ọjọ́ orí: 25 Orílẹ̀èdè: Australia Iye ìgbà tí ó ṣójú orílẹ̀èdè rẹ̀: 67 Ẹgbẹ́ agbábọ́ọ̀lù: Perth Glory and Chicago Red Stars Ipò: Ọwọ́ iwájú (Forward) Saki Kumagai Oríṣun àwòrán, FRANCK FIFE Àkọlé àwòrán, Saki Kumagai Ọjọ́ orí: 28 Orílẹ̀èdè: Japan Iye ìgbà tí ó ṣójú orílẹ̀èdè rẹ̀: 102 Ẹgbẹ́ agbábọ́ọ̀lù: Olympique Lyonnais Ipò: Agbá 'wájú ilé mọ́ ọwọ́ ààrín (Defender/defensive midfielder) Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù #Segun: Kí ló mú akẹ́kọ̀ọ́ mu òògùn apakòkòrò tóríi máàkì 167 nínú JAMB?
ti ro ijoba apapo ati awon omo orile-ede Naijiria ti alafia orile-ede yii mumu
Kí ni ìdí tí ilé ẹjọ́ tún ti sún ìgbẹ́jọ́ Alfa Babatunde Sotitobire síwájú Àwọn afunrasí lórí ikú Funke Olakunrin ti wà nílé ẹjọ́ ní Akure Ikú mú Steven tó lọ dẹ́nu ìfẹ́ kọ olólùfẹ́ rẹ̀ lábẹ́ omi lọ Wọ́n tún ti pa ọmọbìnrin míì lásìkò ìbálòpọ̀ tipá nílùú Ibadan Lero ti Akanmu, erokero ati iku ojiji ko jinna si arugbo to ba da nikan wa nile, ti aigbọ ọrọ Ọlọrun ni oore koore ko si le ṣe awọn ọmọde loore.
Afirika , eto aabo gbọdọ  mulẹ sinsin.
oselu alatako lojoRu(Wednesday), iroyin fi mule pe omobinrin kan padanu emi re
Seyi Awolowo dupẹ lọ́wọ́ lórí akanṣe eto BBC Yorùbá dupẹ lọwọ awọn ololufẹ rẹ fún gbogbo ibo ti wọn di fun un nile Ẹlẹgbọn agba eyi ti gbogbo eeyan mọ si Big Brother Nigeria.
Oloye Abdul Tawab Olaitan Ile-Aje Adeniyi lo kọpa ninu ere agbelewo ti wọn ṣe ni ọdun 1986, ti wọn si pe akọle rẹ ni ''Arelu''.
Lòrò bá di wòmí n wò ó fún gbogbo won.
Buhari lọ sí Plateau sùgbọ́n kò dé àwọn ìlú tó rí ìkọlù ''Awa ko faramọ dida agọ Fulani silẹ ni ipinlẹ Benue tori pe, a ko ni ilẹ lati ya sọtọ fun awọn to fẹ fi ẹran jẹ'' Ortom kasẹ ọrọ nilẹ pe ''ọta ilọsiwaju ati alaafia lawọn to n pe fun idasilẹ agọ Fulani'' Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
8 billion ( 2005 ) .
Nínú ọ̀rọ̀ rẹ̀, ó ni àlàálẹ̀ oríṣiríṣi ló ti wà fún àwọn ìpele ẹ̀kọ́ ní ìpińlẹ̀ Eko pàápàá jùlọ èyí to níṣe pẹ́lú sí pípéjú ọgbà ilé iwé.
Á dìgbò lù ú láìṣàánú rẹ̀,á sá lọ kúrò lọ́wọ́ agbára rẹ̀.
Ibi ti Abiọla sun si ree Àkọlé àwòrán, Awọn eeyan lo ayajọ isinmi June 12 lati yẹ́ MKO Abiọla si Àkọlé àwòrán, Bi onirese Abiọla ko tilẹ fin igba mọ, sibẹ eyi to ti fin ko lee parun Àkọlé àwòrán, Ẹni ti araye n fẹ ni MKO Abiọla, ko ni arun kankan lara Àkọlé àwòrán, Awọn akọroyin atawọn ajaftọ ẹ́ni ni ilu Ibadan naa fi aaye silẹ láti ranti MKO Abiọla Àkọlé àwòrán, Ọrọ bọ ni ayajọ June 12 nilu Ibadan BBC News, Yorùbá Ìdí tí ẹ fi le è nígbàagbọ́ nínú ìròyìn BBC Ìlànà Lílò Nípa BBC Òfin Àṣírí Cookies Kàn sí.
bi Oshoala se so, “Iko Barcelona je okan lara iko agbaboolu ti o dara
Bakan naa, iwadi ti fihan pe ere idaraya loorekoore dara lati gbọn irẹra danu.
Mose ati Aaroni, ati Nadabu, ati Abihu, ati aadọrin ninu àwọn àgbààgbà Israẹli bá gòkè lọ, 
Ẹnikẹ́ni tí ó bá bá aya baba rẹ̀ lòpọ̀, ó dójúti baba rẹ̀, pípa ni kí wọ́n pa àwọn mejeeji, ẹ̀jẹ̀ wọn yóo wà lórí ara wọn.
Mursi pe , o yi iwe ti o fi dibo aare ti o fi dije lodun 2012.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù EPL: Asise rẹpẹtẹ s'okunfa ifidirẹmi fun Arsenal 31 Sẹ́rẹ́ 2018 Oríṣun àwòrán, AFP/GETTY IMAGES Àkọlé àwòrán, Sam Clucas gba ami ayo meji wọle ninu idije ti asọle Arsenal Petr Cech ti se asise l'ojule Asise Petr Cech ti o jẹ asọle fun ẹgbẹ Arsenal nigba ti wọn wọ'ya ija pẹlu Swansea nibi ti wọn ti fidi rẹmi pẹlu ami ayo mẹta si ẹyọ kan lalẹ ọjọ isẹgun.
Eniyan ẹlẹ́ran-ara bí àwa ni Elija.
Bakan naa ni wọn fin oogun apakokoro si aarin ìlú.
" Ààrẹ Buhari ṣèpàdé pẹ̀lú Ọ̀gá Àgba iléèṣẹ́ ọlọ́pàá lórí #ENDSARS, ẹ wo àbájáde ìpàdé wọ́n Gomina Kano tí ní kí olùrànlọ́wọ́ rẹ̀ lọ rọ́kún nílé nítori o bu Ààrẹ Buhari lórí #EndSars #EndSARS: Pe nọ́mbà wọ̀nyìí láti fẹjọ́ ọlọ́pàá SARS sùn Sagamu: Ìkọlù wáyé bí ará ìlú ṣe gbéná wòjú ọlọ́pàá torí ikú agbábọ́ọ̀lù Rògbòdìyàn bẹ́ sílẹ̀ l'Ogbomọṣọ, àwọn ọ̀dọ́ kọlu ààfin Ṣọun Adájọ́ pàṣẹ kí wọ́n fi ọlọ́pàá tó lọ́wọ́ nínú ikú Kolade Johnson sí àhámọ́ O ni ohun to mu awọn lọ sibi ti wọn ti n fa wahala ni pe lọ ni pe awọn ọlọpaa n pariwo si aafin lati wa a ba awọn ọdọ naa sọrọ gẹgẹ bi ọmọ ilu, nitori wọn n gbiyanju lati dana sun agọ ọlọpaa ni.
Ọmọ mi ti ṣèlérí pé oun máa mú mi lọ sí òkè òkun k'àwọn SARS tó pá á - Iya Kazeem Tiamiyu Súnkẹ́rẹ fakẹrẹ ọkọ òpópónà marosẹ̀ Lagos-Ibadan tòní tún kọ sísọ Iléeṣẹ́ BBC fẹ́ ṣíi yín lójú nípa ohùn obìnrin tó ń jó lọlẹ̀ lórí ayélujára Ọ̀jọ́ eérú t'ọdún yìí bẹ̀rẹ̀ pẹ̀lú aṣọ ọ̀fọ̀ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Mi ò kí ń ṣèèyàn burúkú tàbí Babalawo bí ẹ ṣe mọ̀ mí nínú eré - Fadeyi Oloro Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Sagamu: Ògo ọjọ́ iwájú ìdílé wa ni Kazeem tí àwọn SARS ṣekúpa - Iya Kazeem Tiamiyu26 Èrèlè 2020 Social Media Week 2020: Iléeṣẹ́ BBC yóò máa ṣíi yín lójú nípa ohùn obìnrin tó ń jó lọlẹ lórí ayélujára26 Èrèlè 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
 Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Òwe: Kí ni ìtumọ̀ òwe ikú tó ń pa ojúgbà ẹni?"
Tí Ọwá bá fẹ́ bọ̀gún, ó ní ipa tí Ọba Ijẹ̀bú-Jẹ̀ṣà gbọ́dọ̀ kó níbẹ̀, ó sì ní iye ọjọ́ tí ó gbọ́dọ̀ lò ní Ilẹ̀ṣà.
MMM: EFCC ìpínlẹ̀ Enugu fi ìkìlọ síta lórí ètò sogúndogójì
Kí ó má ṣé ní sísẹ̀ntẹ̀lẹ̀
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Tantra: Ìlànà yìí ló ń kọ́ wa láti fi èémí àti ìṣẹ́po ara gbádùn ìbálòpọ̀ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Tantra: Ìlànà yìí ló ń kọ́ wa láti fi èémí àti ìṣẹ́po ara gbádùn ìbálòpọ̀ 15 Ẹrẹ̀nà 2020 Christiana, tii se oludanilẹkọ nipa ibalopọ lorilẹede Singapore, to jẹ ẹni ọgbọn ọdun, ni pẹlu ilana idanilẹkọ Tantra, a lee mu ara wa debi to ga julọ ninu ibalopọ.
 igi la fi ngbẹ agẹrẹ .
 Sanyeri, ẹni to tun sọrọ nipa ajọṣepọ rẹ pẹlu baba ati iya rẹ ni, Mo fẹran iya mi, awọn eeyan si iya oun ju iyawo ile oun lọ, oun ko si le ma darukọ rẹ ninu ere nitori o ṣe atilẹyin fun oun nidii isẹ tiata, kí oun to ní orukọ.
ki won mo pe eti to ba gbo alọ,o yẹ ki o  gbọ
Bakan naa ni Sowore ni lilọ kuro lẹgbẹ oṣelu kan lọ si omiran ko le e nipa buburu lori ati debi ipo gomina rẹ, nitori nkan ti awọn eniyan fẹ ni o ṣe.
O tun ni wọn gbọdọ pe ipade gbogbo ile ni pajawiri ṣaaju ọjọ kinni, oṣu keje, ọdun yii ni kia.
Biu tun sọ pe ile ise ologun ( NASA) ti se
Awọn mii ti n gọ si ori tabili ile idana tabi ki wọn maa lo ẹrọ ayarabiaṣa lori ibusun wọn eyi ti wọn ti n ṣe fun ọpọlọpọ oṣu bayii.
Bakan naa lo mẹnuba àwọn ọrẹ to ni to pọ ṣugbọn to jẹ pé ọ̀tọ̀ ni aaye ti oun fi oṣere-binrin Doris Simeon si.
Jakọbu tún bẹ̀rẹ̀ sí bá ìrìn àjò rẹ̀ lọ, ó pàgọ́ rẹ̀ sí òdìkejì ilé ìṣọ́ Ederi.
Wọ́n jíṣẹ́ fún un, wọ́n ní, “Hesekaya ní kí á sọ fún ọ pé: ‘Ọjọ́ ìṣòro ni ọjọ́ òní, ọjọ́ ìyà, ati ọjọ́ ẹ̀sín.
Lati igba naa ni Egbegb ti dero ẹwon latari pe ko sẹni to le san owo ọhun.
Aarẹ ana ni ọrọ eto aabo Naijiria ti kọja ohun ti oun le dakẹ le lori nitori ọwọ ti fẹ bọ sori bayii pẹlu aibikita ijọba apapọ.
Atẹjade ileeṣẹ ọhun fi han pe wn yoo ṣi maa ba ẹbi naa sọrọ lati ṣeranwọ lasiko ikẹdun yii.
Covid-Organics si ni wọn pe orúkọ rẹ.
Nígbà ti awọn kan ní èróngbà àwọn ni pé ó yẹ ki Super Eagles fakọyọ ju bí wọn ṣe se lọ nítori ọ̀pọ́ ànfani ni wọ́n sọnu, sibẹ̀ yiniyini kẹ́ni le ṣe omíràn ni ọ̀rọ̀ náà yoo jẹ ni àwọn kan ń sọ Wọn ni ó ṣe pàtàki kí wọ́n lọ túra mu láti jáwe olúbori nítori pe àwọn ni ìgbàgbọ́ pé wan yóó de ipile to kayin si aṣekagbá ninu idije náà.
A o ni gba ki awon eniyan kan,
Christian Eriksen gba bọọlu sinu awọn lẹyin isẹju mọkanla, ti Tottenham pẹlu ami ayo meji sodo f'opin si bi o se si ẹgbẹ agbabọọlu kankan to na ikọ Manchester United ni saa yi.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Mo ń ṣa ike jọ láti san owó ilé iwé ọmọ mẹ́ta' Akọwe agba naa ni ajọ naa maa ṣatilẹyin to yẹ fun ẹbi Maxim pẹlu owo ati pe awọn yoo ṣe iwadii naa bi o ti yẹ.
Kí ó mú àgbò kan tí kò ní àbààwọ́n wá sí ọ̀dọ̀ alufaa, ó gbọdọ̀ rí i pé àgbò yìí tó iye tí wọn ń ra ẹran fún ẹbọ ìmúkúrò ẹ̀bi, alufaa yóo ṣe ètùtù fún un fún àṣìṣe rẹ̀ tí ó ṣèèṣì ṣe, OLUWA yóo sì dáríjì í.
Akẹ́kọ̀ọ́ kan ní ìbéèrè lórí òfin ilé-ìwé lórí Weibo:
Ipinlẹ Eko ni mọkandinlaadọta ninu awọn eeyan ọhun ti wa.
Mo rí ère kan tí ń múni jowú ní ìhà àríwá ẹnu ọ̀nà pẹpẹ ìrúbọ.
won pinnu lati ran awon ti ko to lọwọ.
Peter àti Paul Okoye, Innocent Idibia (Tuface), Bankole Wellington (Banky W), Tiwa Savage, Michael Ajereh (Don Jazzy ) àti Yemi Alade.
” Tí kò bá le pè é dáradára, tí ó bá wí pé, “Siboleti,” wọn á kì í mọ́lẹ̀, wọn á sì pa á létí odò Jọdani náà.
Face mask: Owó ìtanràn N40,000 nítorípé mí ò wọ ìbòmú- Vincent Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ẹjo jegudujera wa lara awọn eyi ti opo ni Naijiria ma nf'ọkan tele Adajọ Majistireti kan ni ilu Ekiti ti dajọ pe ki arakunrin kan to kọ lati wọ ibomu lasiko Coronavirus yi san owo ijiya ẹgbẹrun lọna ogoji Naira.
tí ẹ bá mú ninu agbo ẹran yín láti fi rú ẹbọ sísun sí OLUWA tabi láti fi san ẹ̀jẹ́, tabi láti fi rú ẹbọ àtinúwá, tabi ẹbọ ní ọjọ́ àjọ yín, láti pèsè òórùn dídùn fún OLUWA; 
"Oshiomole tun tẹsiwaju pe, ""ti mo ba n sọrọ gẹgẹ bii ẹni to rinu rode nipa ọrọ ẹgbẹ osisẹ, o da mi loju pe awọn ẹgbẹ osisẹ ko kan lee wa lasan amọ wọn gbọdọ ni apọn lati lo gbogbo agbara wọn lai boju wẹyin."
O ni bi won se fi egbe naa sinu ipinnu won yoo je ki idagbasoke tubo ba awon to n wa ekusa lorile ede Naijiria.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù COZA: A ti wọ́gilé ìwọ́de lórí COZA tí a fẹ́ ṣe tẹ́lẹ́ nítorí.
Ìwé kan wà ní oókan-àyà ọkùnrin náà ohun ti wọ́n sì kọ sí ibẹ̀ ni èyí: ‘Ní ọjọ́ tí Ẹlẹ́dàá bá máa ṣe idájọ́ ẹ̀dá a óò dá ọ sílẹ̀ a ó sì fi ìyà jẹ baba ńlá tí ó bí ọ.
Ẹgbẹrun mejila naira ni mo ti na le oko yii lori, o san ki e pa mi ju ki ẹ baa jẹ lọ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Iléeṣẹ́ ààrẹ: Buhari kò bú ọdọ, àwọn ọ̀bàyéjẹ́ ń pa irọ́ 19 Ìgbé 2018 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Iléeṣẹ́ ààrẹ ní ojúṣe ìjọba ni láti pèsè àyè tó tọ̀nà sílẹ̀ fún olúkúlùkù láti mú àlá rere wọn ṣẹ.
Ibùgbé rẹ̀ yóo jẹ́ èyí tí ó lógo.
Seyi: Yatọ fun awọn nkan ti mo n ṣe tẹlẹ ki n to l fun eto naa bii arinrinoge, ere agbelewo, maa tun maa ṣe agbekalẹ eto fun awọn eeyan jankanjankan ati pẹlu awọn nkan ti mo n ṣe tẹlẹ.
Ó jọ bí ẹni pé ẹ kò lérò pé irú mi lè woṣẹ́ ni?
Nígbà tí Ọlọrun ọ̀gá ògo pín ilẹ̀ ìní fún àwọn orílẹ̀-èdè, ó ṣètò ibi tí orílẹ̀-èdè kọ̀ọ̀kan yóo máa gbé,gẹ́gẹ́ bí ìdílé kọ̀ọ̀kan láàrin àwọn ọmọ Israẹli.
Òpópónà kan yóo wà níbẹ̀,a óo máa pè é ní Ọ̀nà Ìwà Mímọ́;nǹkan aláìmọ́ kan kò ní gba ibẹ̀ kọjá,àwọn aláìgbọ́n kò sì ní dẹ́ṣẹ̀ níbẹ̀.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, SS3 ní mo wà báyìí, mo sì ti gba àmì ẹ̀yẹ̀ púpò nílé-lóko gẹ́gẹ́ bí onílù - Ayansike Sibẹ mi o ṣai ni ibaṣepọ pẹlu awọn eeyan ẹya miran, paapaa julọ, awọn eya Igbo nitori naa, kii ṣe ohun to bojumu fun emi ati Mike Ezuruonye lati wa sọ ọrọ naa di ti ẹlẹya-mẹya.
Nígbà tí alága àsè tọ́ omi tí ó di ọtí wò, láì mọ ibi tí ó ti wá, (bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé àwọn iranṣẹ tí ó bu omi náà mọ̀), alága àsè pe ọkọ iyawo.
Kò sí ẹni tí ó bá ń súré ìje tí ó lè gba èrè àfi bí ó bá pa òfin iré ìje mọ́.
Àwọn ará ìlú Ṣekemu bá rán àwọn kan ninu wọn, wọ́n lọ ba ní ibùba ní orí òkè de Abimeleki.
Iroyin ni wọn pa omo ogun mẹtala nigba ti wọn dena de wọn eyi to bi iku ogunlọgọ awọn ẹya mejeeji.
Àṣìta ìbọn ló pa obìnrin nílùú Eko lọ́jọ́ Satide- Ọlọ́pàá Ìjọba Buhari ń wùwà bíi ìjọba Abacha lórí ọ̀rọ̀ Ṣoworẹ- Ṣoyinka EFCC gbé agbẹjọ́rò àti àna Atiku lọ iléẹjọ́ lórí ẹ̀sùn gbígbé owó tùùlù rìn Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Yollywood: Sinimá Ajé Ọjà tún so Fathia àti Saheed Balogun pọ̀ nínú Sinimá Ọpọ lo ti n sọ pe ọrọ ifẹ wa laarin awọn mejeeji lẹyin ti wọn ri wọn pọ loriṣiiriṣii ibi ti wọn ti n ṣe inanwo.
Àdùnní : Àdùnní ni ìyàwó tí orímóògùnjẹ ́ kọ ́ kọ ́ fẹ ́ .
Joabu sọ iye àwọn eniyan tí ó kà fún ọba: Ogoji ọ̀kẹ́ (800,000) ni àwọn ọkunrin tí wọ́n tó ogun jà ní ilẹ̀ Israẹli, àwọn ti ilẹ̀ Juda sì jẹ́ ọ̀kẹ́ mẹẹdọgbọn (500,000).
Awọn eeyan kan kan saara fun un bi ero ti se pọ nibi ayẹyẹ ọhun ti wọn si ni ifasẹyin ni kikuro ninu ẹgbẹ Akpabio yoo jẹ fun PDP.
Kódà ó ti di dandan láti lo ibomu, tá si ti ń rán ibomu lọ́wọ́, bẹ́ẹ̀ la tún yàgò fún ara wa pẹ̀lú ṣíṣe isede.
Lati awọn orilẹede bii Amẹrika, Austria, Brazil, Cuba, Trinidad and Tobago, Jamaica, Spain Canada ati bẹẹbẹẹ lọ ni wọn ti n wa.
Ninu ọrọ to ba BBC News Yoruba sọ lori ẹrọ ibanisọrọ lẹyin ti ajọ to n gbogun ti ajakalẹ arun tun kede eeyan mẹsan miran pẹlu arun Korona ni ipinlẹ Ọṣun lọjọru, Gomina Oyetọla ṣalaye pe arun Korona ki ba ti burẹkẹ to bayii kani ijọba apapọ tete ti gbogbo ẹnuibode ni ki wọn si paṣẹ konileogbele fun gbogbo ọmọ orilẹede Naijiria.
Èrò àwọn ọmọ Naijiria: Awọn kan gba pe iran Igbo lo kan lati dari Naijiria nitori pe ọwọ wọn ni agbara yẹ ko wa bayii Bẹẹ ni awọn miran n kilọ fun ijọba yii lati ṣọra nipa ileri ṣiṣe fun iran kankan nitori alaafia Funke Akindele ti di ìyábejì #Bum bum war:Yemi Alade tọrọ àforíjìn lọ́wọ́ Tiwa Savage Ìyanṣẹ́lódì ni a máa fi ṣíde 2019 tí Buhari kò bá ṣe tiwa.
Wọ́n ń fipa múwa láti dí Musulumi Ní ọ̀pọ̀ ìgbà ni wọn máa ń sọ fún wa pé tí a ba ti gbà láti di Musulumi ní àwọn yóò dá wa padà sí ọ̀dọ̀ àwọn òbí wa.
Nítorí pé, nígbà tí wọ́n bá ń bọ̀, tilé-tilé ni wọ́n wá.
Ìdùnnú subú layọ̀ láàrìn àwọn òṣèré tíátà nínú ọṣẹ yìí.
“Sọ fún àwọn ọmọ Israẹli pé kí wọ́n gba ọrẹ jọ fún mi, ọwọ́ ẹnikẹ́ni tí ó bá ti ọkàn rẹ̀ wá láti ṣe ọrẹ àtinúwá ni kí wọ́n ti gba ọrẹ náà.
Ìjọba gbé ilé ijó oníhòhò tì pa lórí ẹ̀sùn títàpá sí ìlànà àti dẹ́kun coronavirus Ọkọ̀ àjàgbé agbépo kan tún dànù l'Eko Coronavirus: ''Ìjọba kò tíì pàṣẹ ìlànà ìtakété-síra-ẹni padà nínú BRT la ò ṣe máa tẹ̀le'' Wọ́n ti fi Omah Lay sínú ọgbà ẹ̀wọ̀n ní Uganda Ta gan ló jí àwọn akẹ́kọ̀ọ́ GSSS Kankara, àwọn jàǹdùkú tíjọba mọ̀ ni tàbí Boko Haram?
Òun ni yóo máa pèsè ẹbọ ìmúkúrò ẹ̀ṣẹ̀, ẹbọ ohun jíjẹ, ẹbọ sísun ati ẹbọ alaafia láti ṣe ètùtù fún àwọn ọmọ Israẹli.
Awọn agbabọọlu naa yoo tun kopa ninu ifẹsẹwọnsẹ ọlọrẹsọrẹ miran pẹlu orilẹede Serbia nilu London nilẹ Gẹẹsi, iyẹn ni ọjọ mẹrin lẹyin ifẹsẹwọnsẹ ọlọrẹsọrẹ pẹlu Poland naa.
Ọlọrun fi wọ́n sí ojú ọ̀run láti máa tan ìmọ́lẹ̀ sórí ilẹ̀ ayé, 
Ṣé lóòtọ́ ni Adajọ́ Àgbà Naijiria, Tanko Muhammad náà ti ní Covid-19?
“Ará Amoni ati Moabu kankan kò gbọdọ̀ bá ìjọ eniyan OLUWA péjọ, arọmọdọmọ wọn títí dé ìran kẹwaa kò gbọdọ̀ bá ìjọ eniyan OLUWA péjọ; 
Aare Muhammedu Buhari ti setan lati yan ise fun awon minisita tuntun Ghana ti mu àwọn afurasí ajínigbé ọmọ Naijiria mẹ́ta Háà, ó ṣe!
Wọn kò gbọdọ̀ bá ìwúkàrà lọ́wọ́ yín, ati ní gbogbo agbègbè yín, fún ọjọ́ meje.
Àti pé tí àwọn iléèṣẹ́ ìròyìn nla kò bá jábọ̀ ìrìyìn nàá, ó gbọdọ̀ wà ní ojú òpó mì í.
A ó rí i ní iwájú pé filísíà Olówólàgbà yìí ni orúkọ mìíràn fún ìyàwo Orímóògùnjẹ́ tí ó jí owó Orímóògùnjé gbé.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Supreme Court: Ilé ẹjọ́ gíga jùlọ sún ìgbẹ́jọ́ ìbò Kano, Imo àti Sokoto 13 Sẹ́rẹ́ 2020 Oríṣun àwòrán, OTHER Ile ẹjọ to ga ju lọ lorilẹede Naijiria ti sun igbẹjọ to yẹ ko waye lonii lori ibo ipinlẹ mẹfa lorilẹede yii siwaju.
1 270 Orilẹede Fiji 2 0.
Ngozi Okonjo-Iweala ló borí gẹ́gẹ́ bí obìnrin àkọ́kọ́ tó di olórí ajọ okoòwò l'ágbàáyé, WTO Ẹ má à gbìyànjú láti bo àṣírí ìpànìyàn tó wáyé ní Lekki, á ní ẹ̀rí tó dájú - Amnesty International Àkùkọ dojú ìjà kọ ọlọ́pàá, ikú ló já sí fún agbófinró Wo àwọn ìpínlẹ̀ tí ọlọ́pàá ti bẹ̀rẹ̀ àyẹ̀wò ojúlé sí ojúlé káàkiri Nàìjíríà torí ohun tí wọ́n jí kó Lasiko to n ṣe afihan awọn ọdaran naa l'Ọjọru ni olu ileeṣẹ ọlọpaa to n bẹ ni agbegbe Ẹlẹyẹle ilu Ibadan, kọmisana ajọ ọlọpaa nipinlẹ Ọyọ, Joe Nwachukwu Enwonwu ṣe alaye wi pe ọlọpaa mẹfa ni wọn da ẹmi wọn legbodo.
Ó yan àwọn alufaa ti ara rẹ̀ fún ibi ìrúbọ ati fún ilé ère ewúrẹ́ ati ti ọmọ aguntan tí ó gbé kalẹ̀.
Àwọn ará Amaleki ń gbé ìhà gúsù ilẹ̀ náà.
Ìbẹ̀rẹ̀ Ìrìnàjò Sí Òkè Ìrònú tí ń Bẹ nínú Igbó Elégbèje
Ṣugbọn ki ti ẹ ni iye owo yii tumọ si?
Àwọn tí ó gbọ́n lójú ara wọn gbé;tí wọ́n ka ara wọn kún ẹni tí ó ní ìmọ̀!
Ni owurọ ọjọ Iṣẹgun ni iroyin gbode kan pe awọn iwe ipolongo ibo kan to jẹ ti Ọgbẹni Agboọla Ajayi labẹ aṣia ẹgbẹ oṣelu ZLP ti wa kaakiri igboro ilu Akurẹ tii ṣe olu ilu ipinlẹ Ondo.
títí di bi mo ṣe ń sọ yìí , kò sí ìwé kankan nípa àwọn ẹ ̀ ka-èdè yorùbá lórí àtẹ .
Iroyin kan ti ileesẹ ọkọ ofurufu Dana gbe soju opo Twitter rẹ ni ilẹkun baalu wuwo, to si mulẹ debi pe ko lee da si, tabi jabọ funra rẹ lai jẹ pe ẹnikẹni fi ọwọ kan-an.
Ó kìlọ̀ fún wọn ó ní, “Ẹ ṣọ́ra gan-an, nítorí pé kì í ṣe eniyan ni ẹ̀ ń ṣiṣẹ́ fún, OLUWA ni.
Agbegbe Yakasai ni wọn ti bii ni ọdun 1963 ki o to tẹle Sheikh Abdulwahab lọ tẹdo si Mẹdina lẹyin igbeyawo wọn.
"Lẹyin naa ni yoo gba atẹranṣẹ ""ePIN"" lori ẹrọ alagbeka rẹ."
Peteru dá wọn lóhùn pé, “Ẹ ronupiwada, kí á ṣe ìrìbọmi fún ẹnìkọ̀ọ̀kan yín ní orúkọ Kristi.
Milton ni eyi ti tan de awọn agbegbe miran bii Denver, Malven, Turffontein, Tembisa ati awọn adugbo miran bayii.
Bisobu agba ,John Onayekan naa tun so pe  “Ẹni ti o ba wa sibi yii, ti o ri bi
Ajọ ere idaraya olympics lagbaye, IOC lo gbe ikede yii jade lẹyin ipade igbimọ iṣakoso rẹ to waye loni ọjọ Aje, ọgbọn ọjọ oṣu kẹta ọdun 2020.
Àwọn tí Wọ́n Pada láti Oko Ẹrú.
Loruko egbe oselu ANC, minisita tuntun fun oro omi ati imo-toto ayika, Gugile Nkwinti ti o je minisita fun oro ile, ki atunto to ba igbimo amusese naa lale ojo-Aje so pe, igbimo amusese egbe oselu yoo satileyin fun abadofin ohun.
Ẹ sì ń bèèrè pé, ‘Ọ̀nà wo ni à ń gbà jà ọ́ lólè?
O fidi ẹ mulẹ pe ti ile Toke Makinwa ba wa nibẹ ko si ohun ti ẹnikẹni le ṣe sii nitori ko sẹni to kọja ofin.
”Aare Buhari wa lo anfaani naa lati safihan gbogbo aseyori ti isakoso isejoba re ti gbese lati igba ti o ti sefilole isejoba re lọdun 2015, papaa julo ni awon eka eto aabo, gbigbogun ti iwa ibajẹ ati mumu igberu ba eto oro aje.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Nigeria Election: Kò sí ìwé ìrìnnà 'VISA' fáwọn ọmọ Naijiria tó hùwà àìtọ́ nígbà ìdìbò 24 Agẹmo 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, A ko ni fun oniṣẹ ibi ni iwe irinna Amerika Ilẹ Amerika ti fi ofin de fifun awọn oniṣẹ ibi lasiko idibo Naijiria ni iwe irinna.
Ohùn kan láti ọ̀run wá sọ pé, “Àyànfẹ́ ọmọ mi nìyí, inú mi dùn sí i gidigidi.
”OLUWA dá a lóhùn pé, “Mú ọ̀dọ́ mààlúù kan lọ́wọ́, kí o wí pé o wá rúbọ sí OLUWA ni.
Bi o sẹ le tọju oyun iju: Oríṣun àwòrán, Getty Images Itọju ti wọn yoo fun obinrin to ba ni oyun iju nii ṣe pẹlu ọjọ ori, to ba ṣi fẹ ẹ bimọ, bi iju naa ṣe tobi si, ati ibi to wa ninu ile ọmọ.
"Nnkan to jẹ wa logun nisin yii ni bi a se maa mu u, gbogbo wa la n gbiyanju lati wa ọna bi a se maa mu.
Òwe Yorùbá ti ó sọ wi pé “Awọ kò ká Ojú ìlù, Ọmọ Onilù ni òhún fẹ́ má a sun Awọ jẹ” bá ìròyìn ti ó jáde ni lọ́wọ́-lọ́wọ́, bi àwọn Òṣèlú ti bá owó ọrọ̀ ajé Nigeria jẹ nipa bi wọn ti ṣe pin owó ohun ijà fún Ológun lati ra ibò.
Aarẹ Buhari ni awọn aṣepati akanṣe iṣẹ ti o wa nilẹ ni wọn yoo tubọ mojuto ni inu saa eto iṣuna ọdun 2019 gẹgẹ bi ijọba apapọ ṣe ṣe ni saa iṣuna 2018 ti o n pari lọ.
Wọn ni ki ileeṣẹ African Independent Television ati Ray Power FM lọ rọọkun nile na.
NCDC ni eniyan mẹjọ miran lo lugbadi arun naa ni ipinlẹ Eko, meji ni ipinlẹ Enugu ati ẹyọkan ni ipinlẹ Edo.
 itan indonesia ti gba ipa latodo awon alagbara okere ti won wa sibe nitori awon ohun alumoni toni .
cyril lionel robert james ( 4 january 1901 - 19 may 1989 ) to tun gba oruko ikowe j.
Láti ibẹ̀ Jesu gbéra, ó lọ sí agbègbè ìlú Tire, ó sì wọ̀ sí ilé kan.
Oríṣun àwòrán, Reuters Ohun to yẹ ko mọ nipa arun Coronavirusti: Coronavirus maa n jẹ ki o soro fun eniyan lati mi daadaa, tabi mi kanlẹ Agbeegbe Wuhan ni orilẹede China ni wọn ti kọkọ gbọ nipa aisan naa.
Nítorí náà, OLUWA ní, “Àkókò ń bọ̀, tí wọn kò ní máa búra mọ́ pé, ‘Bí OLUWA, tí ó kó àwọn ọmọ Israẹli jáde kúrò ní ilẹ̀ Ijipti tí ń bẹ,’ 
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ìfipálówó: Bàbá ọmọ tí wọn gé lórí ní òun rán an láti l gbowó lẹ́nu ATM ni Nigba ti akọroyin BBC Yoruba kan si agbenusọ ileeṣẹ ọlọpaa ni Ipinlẹ Eko, Bala Elkana, o sọ wipe iwadi n lọ lọwọ lori bi awọn ọkunrin mẹta naa ṣe ku.
Olumilua wa ni taa ba tun wo ohun ti Khafi se, iru asa yii wọpọ lori eto BB Naija latẹyin wa, ko si tii se ohun to lodi sofin, tabi sẹ ẹsẹ to lowura debi pe wọn yoo ran ni ẹwọn tabi gbẹmi rẹ, eyi to nilo ki ijọba ipinlẹ rẹ tete da si.
ẹni tí ó ń yọ ẹ̀mí rẹ kúrò ninu ọ̀fìn,tí ó fi ìfẹ́ rẹ̀ tí kì í yẹ̀ ati àánú dé ọ ládé.
Igbẹjọ awọn afunrasi Boko Haram bẹrẹ loni Boko Haram pa èèyàn 25 ní Màìdúgùri Ìjọba Germany mú afurasi ọmọ Boko Haram 'A ti pa Boko Haram run patapata' Iroyin ti a ti ri gba tẹlẹ: Boko Haram ṣíná fún àwọn tó lọ ìsìnkú, èèyàn 23 pàdánù ẹ̀mí wọn.
Igbesẹ ti Alaafin gbe yii, o fẹ tun fi da ogun silẹ laarin awọn lọba-lọba Ekiti ni.
Ẹwẹ, o wa rọ awọn ọlọpaa naa lati ma ṣe fi ohun ija ogun tu awọn
O ni alagagebe ni ijọba apapọ pẹlu bi o ti tako eto Amọtẹkun nigba ti o faye gba ọlọpaa Shariah, Hisbah nipinlẹ to le ni mẹwaa lapa ariwa orilẹede Naijiria.
Èrò àwọn èèyàn ṣọ̀tọ̀tọ̀ lẹ̀yìn tí ìjọba kéde pe ó ṣeṣe ki òfin kónílé-ó-gbélé mìí wàyé Òfin lè má mọ ògùn ṣùgbọ́n èmí gbàgbọ́ pé ǹkan wà nídìí bí wọ́n ṣe pa ọmọ mi - Baba Favour Ṣe lilo Methtoletom lé koju aarun Corornavirus?
nigba ti oludije labe egbe oselu ,All Progressives Congress (APC) Muhammed
Ẹ pín ilẹ̀ náà fún àwọn ẹ̀yà mẹsan-an yòókù ati ìdajì ẹ̀yà Manase.
Wọ́n kó ọpọlọpọ oúnjẹ, àkàrà dídùn tí wọ́n fi èso ọ̀pọ̀tọ́ ṣe, ìdì èso resini, waini, ati òróró, pẹlu akọ mààlúù ati aguntan, nítorí pé ayọ̀ kún gbogbo orílẹ̀-èdè Israẹli.
Minisita fun ọrọ oṣiṣẹ ati iṣẹ ṣiṣẹ, Chris Ngige lo fọrọ naa lede ni Ọjọru lẹyin ipade igbimọ alaṣẹ ijọba apapọ ti Aarẹ Muhammadu Buhari dari rẹ ni Abuja.
Kí ló dé tí ẹ̀ ń ná owó yín lórí ohun tí kì í ṣe oúnjẹ?
Amuneke fipò sílẹ̀ gẹ́gẹ́ bí akọ́nimọ̀ọ́gbá Tanzania Òsìsẹ́ Custom tó déédé sọ ara rẹ̀ di Ọ̀gá Àgbà CG ní ìdàmú ọpọlọ - Attah Ẹ yé irọ́ pa, mí o fún Super Eagles ní ẹbùn owó kánkan -Sanwo Olu ''Amọ ti idiwọ ba wa ti ko ni jẹ ki igbẹjọ nibẹ rọrun,ilu ti ọdaran n gbe ni ibi to kan lati gbẹjọ naa.
Ṣe sí èmi iranṣẹ rẹ, gẹ́gẹ́ bí ìfẹ́ rẹ tí kì í yẹ̀,kí o sì kọ́ mi ní ìlànà rẹ.
24 Òkùdu 2020 Àwọn òmùwẹ̀ ń wá èèyàn kan tó pòórá lẹ́yìn ìjàmbá ọkọ̀ ojú omi to dójúdé l'Eko24 Òkùdu 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
 Ni owurọ ọjọ aje ni Ezenwa kede lori mohunmaworan pe wọn ti yọ Ṣoworẹ nipo gẹgẹ bii alaga ẹgbẹ oṣelu naa."
N óo fi gbogbo ara wí pé,“OLUWA, ta ni ó dàbí rẹ?
Diẹ lara awọn orin to kọ ni: Pon pon pon Kondo If I die Rap Rules ANTHEM Everyday Ni 94 Where Ya 94 SISI eko Ghetto Dreams Loni Ni Democracy Thank God Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
" Ilorin gbàlejò Wizkid, àwọn olólùfẹ́ rẹ̀ fẹ́ ẹ̀ gbée lójú agbo Bi àwọn kan ṣé n jẹ àsun ní àwọn míì n ṣeré lórí omí láti gbádùn Kérésì àná Ìjọba Buhari kò tíì fi akọ̀ròyìn kankan sátìmọ́lé láti ọdún 2015 - Garba Shehu Èyí ni ìdí tí Bàbá Kérésì fi máa n wọ aṣọ pupa àti funfun nígbà gbogbo Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Larisa: Má jẹ́ kí ọjọ́ orí rẹ dí ẹ lọ́wọ́ láti bẹ̀rẹ̀ ohunkóhun to wù ọ Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 3 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 5 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
ICC pari iwadi lori pipa Shiites, IPOB Ọlọ́pàá àti Shiites tún fìjà pẹ́ẹ́ta Ilé ẹjọ́ fún Elzakzaky àti ìyàwó ní ẹ̀tọ́ sí ètò ìwòsàn Agbébọn pa ènìyàn 14, ọmọọ̀gun Naijiria sígun ni Kaduna Garba Shehu ni akọsilẹ ile ẹjọ lo fihan pe iṣe IMN ti gba ọpọ ẹmi ati dukia ni eyi ti ko yẹ ko ri bẹẹ ni ilu to lọba ati ijoye, eyi to ṣokunfa igbẹjọ yii.
Ni Ìlú-Ọba, lẹhin ọdún mẹtalelogoji, èrò jade lati di ìbò bẹni-bẹ́ẹ̀kọ́ lori àjọṣepọ̀ pẹ̀lú ẹgbẹ́ Ìlú-Oyinbo méjidinlọ́gbọ̀n ni Ọjọ́bọ̀, oṣu Kẹfa, ọdún Egbàálémẹẹdógún.
“Ya àwọn ọmọ Lefi sọ́tọ̀ láàrin àwọn ọmọ Israẹli, kí o sì wẹ̀ wọ́n mọ́.
Òun sì mọ bí nkan ṣe rí.
3 Òkùdu 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ìjì ńlá ló ń ja alága ẹgbẹ́ òṣèlú APC, Adams Oshiomhole lọ́wọ́; ṣùgbọ́n kí ni ẹ̀ṣẹ̀ rẹ̀ gan Iji nla lo n ja lagbo ẹgbẹ oṣelu APC bayii.
Ronaldo Brazil làgbà gbogbo agbábọ́ọ̀lù, kì í ṣẹgbẹ́ ẹ Messi àti Ronaldo- Roberto Carlos
Fi igi akasia ṣe àwọn ọ̀pá, kí o sì fi wúrà bò wọ́n.
Mo sọ fun yín nígbà náà pé, ẹ ti dé agbègbè olókè àwọn ará Amori, tí OLUWA Ọlọrun wa fi fún wa, 
Ẹ̀ wo bí àwọn ẹ̀ṣọ́ ojú etí òkun ṣe ń ṣiṣẹ́ l'Eko O ṣójú mí kóró bí wọ́n ṣé fí àdó olóró pa Dele Giwa lọdún 1986- Soyinka Ṣòwòrẹ́, káàbọ̀ ságbo àwa tí wọ́n ti fẹ̀sùn kàn rí -Soyinka Ọgbọn ti itan igbe aye Lisabi Agbongbo Akala: O kọ wa pe agbajọ ọwọ la fi n sọya, ajeje ọwọ kan ko gbe ẹru dori Itan naa tun fi ye wa pe ko si ogun ti a ko lee sẹ ninu irẹpọ A tun ri ọgbọn kọ pe a gbọdọ nifẹ ilu wa gẹgẹ bi ara wa Gbogbo alagbara to n jẹ gaba lori aye wa la lee sẹgun wọn pẹlu irẹpọ ati isọkan.
Ẹni tí ó bá gba Ọmọ gbọ́ ní ìyè ainipẹkun.
Bakan naa ni Ọbasanjọ tun faramọ ọpọ koko ọrọ ti aya aarẹ n mẹnuba ninu awọn igbe gbajare to n ke pe, eto aabo Naijiria ko yanranti to , to si rọ Aisha Buhari pe ko pe ọkọ rẹ tẹ lori awọn ọrọ naa.
Alufaa yóo pada wá ní ọjọ́ keje láti yẹ ilé náà wò.
“Ti o ba gbe egungun lasiko ibo, a o mu ọ, bẹẹ si ni a o si ẹku eegun ti o wọ.
Òmùwẹ̀ kó s'ọ́wọ́ ẹja Sháàkì nínú odò, ikú ló padà já sí Wo ọ̀nà tí ọrọ̀ ajé Naijiria tó dẹnu kọlẹ̀ gba kàn ọ Ìpínlẹ̀ Eko ya ọ̀nà tuntun fún ọkọ̀ epo DSS ti fi ẹ̀sọ́ àbò abẹnugan ilé ìgbìmọ̀ asofin tó pa fẹ́ndọ̀ l'Abuja sátìmọ́lé O tẹsiwaju pe wọn gbẹsẹle awọn ọkọ naa lẹyin ti aẉon awakọ wọn tapa s'ofin irinna oju popo ti ipinlẹ Eko gbe kalẹ lọdun 2018.
Wọ́n fìdí rẹ̀ múlẹ̀ pé Saraki ṣe afárá olókè sí ìlú lásìkò tó wà nípò, èyí tó jẹ́ àǹfààní fún ìlú.
ISIS àti Boko Haram fẹ́ ṣoro lásìkò ìbò 2019 - Amẹrika Ageku ejo Boko Haram si n soro bii agbọn Àfojúsùn àtúntò FSARS ni láti mú àgbéga bá iṣẹ́ ọlọ́pàá- IG 'Ejò lọwọ nínú lórí ikọlù àwọn ọmọ ogun Nàìjíríà' Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Àwọn tí ń sáré ń pàdé ara wọn lọ́nà,bẹ́ẹ̀ ni àwọn ikọ̀ ń pàdé ara wọn,bí wọ́n ti ń sáré lọ sọ fún ọba Babiloni pé ogun ti gba ìlú rẹ̀ patapata.
Àkọlé àwòrán, Obinrin mẹrin ati ọkunrin kan ni wọn ti pa ni adugbo Akinyele Ọmọ mẹta ni oloogbe fi silẹ saye lọ, mẹji ninu wọn wa laarin ọmọ ọdun mẹrin si mẹfa.
Tabi, adùn wo ní ń bẹ ninu funfun ẹyin?
Pierre-Emerick Aubameyang ati Nicolas Pepper to ṣẹṣẹ rọpo mọ Arsenal lanfaani lati gba goolu sawọn fun Arsenal, ṣugbọn wọn ko lo anfaani ti wọn ni.
Ní ìgbà mìíràn ẹ̀wẹ̀wẹ̀, ìdíje Ìwọ́de Ojúnà máa ń ní orin àyànfẹ́ tí kò ní afigagbága rárá; kò sí rí bẹ́ẹ̀ nígbà mìíràn, ìfigagbága náà máa ń le dé ibi wípé ó máa ń ṣòro láti yan olúborí.
Ṣugbọn ó kọ́ rán ọkunrin kan ṣáájú wọn,Josẹfu, ẹni tí a tà lẹ́rú.
Paige Milianni afẹsọna Raheem Sterling lati England.
'Àwọ̀ ara Nisha wà ní ipò tó ba ni lẹ́rù gan'
Pásítọ̀ gún ìyàwó rẹ̀ lọ́bẹ nínú ṣọ́ọ̀ṣì, ló bá tì í bọ ara rẹ̀ náà níkùn Wo àwọn ọ̀tá tó ń da orílẹ̀èdè Nàìjíríà láàmú Kano: À ti fa àwọn oníbalòpọ̀ akọsákọ tí a mú le òbi wọ́n lọ́wọ́- Ọlọpàá Hisbah Bauchi State: Okú 596 ló ṣì ń gba owó oṣù Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Inu mi bàjẹ́ nígbà tí mo bí i, odidi oṣù mẹ́ta, mi ò lè gbàdúrà s'Ọ́lọ́run' Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Ní báyìí à ń dúró de ilé iṣẹ ijọba apapọ tó n ri sí ètò ẹ̀ka gíga ni Nàìjíríà lati kede ohun to kan.
UK fẹ́ so ìjókòó ilé rọ̀, kíni èyí túmọ̀ sí?
Jerusalẹmu yóo di ìlú mímọ́,àwọn àjèjì kò sì ní ṣẹgun mọ́.
Ikede yi to wa lati ọfiisi ọga agba ọlọpaa, Muhammad Adamu ṣalaye pe wọn ti ṣe agbekalẹ ikọ tuntun ti yoo rọpo SARS.
Bakan naa ni wọn fikun pe arun Coronavirus naa yoo fi miliọnu kan o le kun awọn ogo wẹẹre ti arun otutu aya yoo mu lọ ninu ọdun 2020 yii.
Mo ti rì sinu irà jíjìn,níbi tí kò ti sí ohun ìfẹsẹ̀tẹ̀;mo ti bọ́ sinu ibú,omi sì ti bò mí mọ́lẹ̀.
Lati kekere lo ti bẹrẹ ere apanilẹrin ninu ile ijọsin.
Mo gbẹ́kẹ̀lé OLUWA, àní, mo gbé ọkàn mi lé e,mo sì ní ìrètí ninu ọ̀rọ̀ rẹ̀.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Kolade Johnson; Iléeṣẹ́ ọlọ́pàá ní ọwọ́ ti tẹ àwọn afurasí ọlọ́pàá tó ṣekúpaá 1 Ìgbé 2019 Oríṣun àwòrán, Nigeria Police Ileeṣẹ ọlọpaa nipinlẹ Eko sọ pe ọwọ oun ti tẹ awọn ọlọpaa ti wọn fẹsun kan pe o pa ọdọmọkunrin kan nilu Eko.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Fadeyi Oloro: Ọfọ̀, àyájọ́ kò ràn án lọ́jọ́ tí 'ṣó o láyà' bá a lálejò Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Kò sì gbọdọ̀ jáde kúrò ninu ibi mímọ́ náà, tabi kí ó sọ ibi mímọ́ Ọlọrun rẹ̀ di aláìmọ́, nítorí pé, òróró ìyàsímímọ́ Ọlọrun rẹ̀ wà lórí rẹ̀.
80 ni wọ ́ n ti ń gbóhùn sáfẹ ́ fẹ ́ .
Ní ìbẹ̀rẹ̀ ìṣẹ̀dá ayé ni OLUWA ti dá mi, kí ó tó bẹ̀rẹ̀ àwọn iṣẹ́ àrà rẹ̀.
Nígbà tí ẹ bá ń lọ bá àwọn ọ̀tá yín jà lójú ogun láti gba ara yín lọ́wọ́ àwọn tí ń ni yín lára, ẹ óo fọn fèrè ìdágìrì.
Kristẹni ni oun, ọkọ oun jẹ musulumi, iya oun naa jẹ musulumi, baba oun jẹ Kristẹni, ti iya baba oun si jẹ musulumi, nigba ti baba baba oun si jẹ Kristẹni.
8 146885 Orilẹede Haiti 238 2.
Rwanda ti ṣọọsi 700 pa lori ẹsun aṣemaṣe
Kaka ko se bẹẹ, ofi ẹse ara rẹ rinlẹ lori oye ni nitori wipe ẹgbẹ pinnu lati fi orukọ rẹ ati igbagbọ iselu rẹ sinu iwe-ofin ẹgbẹ oselu naa- eleyi fun ni irufẹ agbega ẹni to da ẹgbẹ naa silẹ, Chairman Mao.
Ó bá rán wọn lọ sí Bẹtilẹhẹmu.
Wọn ni ṣe ni awọn to ni ile naa n ṣe atunṣe ti ko bofin mu ko to di pe ile naa wo lulẹ.
O ya, a n lọ silu Eko lọ se ariya, Naira Marley, o ya sunmọ ibi, jẹ ka ls se ariya fun Lekan ooooo.
Oríṣun àwòrán, others Auxiliary ni alaga ajọ, Park Management System (PMS) to n ṣe akoso awọn ibudọ kaakiri ipoinlẹ Oyo lati igba ti Gomina Seyi Makinde wọgile ẹgbẹ NURTW nipinlẹ Oyo.
“Mo ni igbagbo lori awon ile-ise ti won wa ni oja-idokowo, a le mu ayipada rere ba oro orile-ede yii, ki si maa gbokan le epo-robi tuntun nikan.
Àkọlé àwòrán, O jẹ́ ọkan lára ojúṣẹ́ Hisbah láti máa mú àwọn ọmọbinrin tó bá ń rìnrìn àrè kákìri ìlú, ó si ṣeéṣe kí wọn jẹ́ aṣẹ́wo Gẹ́gẹ́ bí àwọn ọlọpaa Hisbah ṣe sọ, oní nààbì ní àwọn ọmọbinrin yìí, tí wọn sì ń wa àwọn oníbara nínú iṣẹ́ wọn, sùgbọ́n ọ̀pọ̀ àwọn ọmọbinrin yìí ló sọ pe, ìdíkan tàbí òmíràn ló gbé àwọn jáde kúrò nílé ní àsìkò ti wọn mú àwọn.
Nigba to n fi idi isẹlẹ naa mulẹ lọjọ Satide, agbẹnusọ fun ileesẹ ọlọpa nipinlẹ Zamfara, Mohammed Shehu ni iyọ ti wọn fi se ounjẹ lo seese ko ni majele ninu.
    “Àwọn òbí rẹ̀ ló kúkú jẹ́ kí ó rí bẹ́ẹ̀, ìtàn ọkùnrin náà yóò sì fi hàn yín ohun tí ó jẹ́ kí ìṣẹ̀dá tirẹ̀ kúkú yàtọ̀ tó bẹ́ẹ̀.
Amọṣa, ẹka ileeṣẹ ọrọ abẹle, ọrọ abo, eto ẹkọ ati ilera ni o lewaju ninu ipin owo lẹkajẹka ninu eto iṣuna naa.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Adams Oshiomole: Idí tí mo fi faramọ́ ìpinu NEC- Oshiomole 16 Òkùdu 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 27 Òkùdu 2020 Oríṣun àwòrán, Other Alága ẹgbẹ́ òṣèlú All Progressives Congress tẹ́lẹ̀rí, Adams Oshiomhole sàlàyé lọ́sàn òní pé òun ti faramọ́ ìpinnu ìgbìmọ ẹgbẹ́ (NEC).
Ṣugbọn ife náà yóo kọjá lọ́dọ̀ yín,ẹ óo mu ún ní àmuyó,ẹ óo sì tú ara yín síhòòhò.
Egbe oselu naa pase ki Zuma fipo aare sile, ni eyi ti won so fun awon oniroyin pe, Aare Zuma yoo so si oro naa loni.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Otedola bridge fire: Ọkọ̀ akẹ́rù rí ìjánu rẹ̀ já ló kọlù ọkọ̀ agbépo tó fa ìjàmbá iná ní Otedola lópópónà Lagos-Ibadan- LASEMA 14 Ọ̀wàrà 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 17 Ọ̀wàrà 2020 Oríṣun àwòrán, @LASEMA Ajọ to n mojuto iṣẹlẹ pajawiri loju popo ni ipinlẹ Eko, LASEMA ti sọrọ lori ohun to ṣẹlẹ ninu ijmaba ina afara Ọtẹdọla.
Gẹgẹ bi o ṣe kọ ọ, nkan bii ago mẹta ọsan ni Adenikẹ kagbako ọta ibọn ọlọpaa lọjọ naa lọdun 1996.
darajulo – Jurgen Klopp (Liverpool)Akonimoogba Obinrin ti o
Mo tun ka awon leta ti egbe oselu  PDP ati APC ko lati fi ki aare ku ori-ire.
Ojú wa rí tó ní Egypt, bí wọ́n ṣe ń tẹ̀ wá lọ́mú, ni wọ́n ń gbá wa ní ìdí"" Ọlọ́wọ̀ tìlú Ọ̀wọ̀ tuntun gorí ìtẹ́, idà àlááfìà ló mú ní Ìpèbí Á máa ṣíjú àánú wo ẹlẹ́wọ̀n láti mú àdínkù bá ọgbà ẹ̀wọ̀n - Ìjọba Ọyọ Ìdí rèé tí ilẹ̀ Afirika fi gbọdọ̀ kópa nínú dídán abẹ́rẹ́ coronavirus wò Ẹ jẹ ka jọ foju se mẹrin bi ẹrọ naa se n sisẹ si."
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Aràrá bíi tèmi, kó má rò pé kò sì ǹkan tó lè ṣe láyé ju iṣẹ́ agbe lọ' Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Ṣugbọn ajọ naa ko sọ orukọ ẹgbẹ agbabọọlu to jẹ.
O salaye pe, lati bi odun die bayii, iranlowo owo latodo awon egbe alaanu ti kere pupo, ni eyi ti o pon dandan, ki ijoba salekun idokowo ni eka eto ilera fun awon ara-ilu.
Ọnidajọ Garba to ka idajọ naa sita sọ pe ṣiṣe bẹ 'ko mu ọgbọn dani''.
" Ó ní ''àwọn kò ní sinmi ìfẹ̀hónú hàn títí tí ọ̀gá àwọn yóò fi gba òmìnira.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Aarẹ Trump yọ Rex Tillerson kuro nipo 13 Ẹrẹ̀nà 2018 Oríṣun àwòrán, Reuters Àkọlé àwòrán, Ọgbẹni Tillerson lo ọdun kan pere lẹnu iṣẹ Aarẹ orilẹede Amerika, Donald Trump ti yọ minisita fun ọrọ ilẹ okeere lorilẹede Amẹrika, Rex Tillerson kuro loye bi ẹni nyọ jiga.
ni gba iwa aparo kan ga ju  okan lọ, ati
Bakan naa,ni yoo tun din wahala ti awon onisowo maa n koju lasiko ti won ba
Iṣẹ́ àwọn mìíràn ninu wọn ni láti máa tọ́jú ohun ọ̀ṣọ́ tẹmpili ati ohun èlò mímọ́, ati ìyẹ̀fun ọkà, waini, òróró, turari, ati òjíá.
Ṣugbọn ẹni tí ó bá kórìíra arakunrin rẹ̀ wà ninu òkùnkùn; kò mọ ibi tí ó ń lọ, nítorí òkùnkùn ti fọ́ ọ lójú.
O ni eyi jẹ apẹrẹ oniruru ikọlu ti awọn ọlọpaa n dojukọ lẹnu iṣẹ wọn Amọṣa ọga ọlọpaa patapata lorilẹ€de Naijiria ni ko si ẹnikẹni to ba tun ṣiwọ lu ọlọpaa to n ṣe iṣẹ rẹ mọ lorilẹede Naijiria ti ko ni jẹ iyan rẹ ni iṣu.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Parental Guidance: Ọdún méjì ni kí ẹ ti bẹ̀rẹ̀ kíkọ́ ọmọ nípa ìbálòpọ̀ 'Boxing Day' tun jẹ ọjọ ti awọn orilẹ-ede kan bii Hungary, Germany, Poland ati Netherlands maa n ṣe ajọyọ ọjọ to tẹle ọjọ ọdun Keresimesi.
Aare gbosuba fun Kelani latari ise akoni, ise ara oto lati dari itan ere ori amohunmaworan ni ona ti yoo gba yi aye oluworan pada si rere, besini mimu idagbasoke ba Asa ati ise lorile-ede yii.
Nítòótọ́ ó ṣubú, ṣugbọn ojú rẹ̀ wà ní ṣíṣí sílẹ̀.
, kí ni ìparí òwe náà?
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Kloe: Èmi kìí mu òògùn olóró, àmọ́ mo fẹ́ràn láti máa wà lẹ́bà omi Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Kloe: Èmi kìí mu òògùn olóró, àmọ́ mo fẹ́ràn láti máa wà lẹ́bà omi 19 Ẹrẹ̀nà 2019 Kloe Oluwabusayọ, tii se ara awọn to lọ si BB Naija salaye fun BBC Yoruba pe, ko si ọrọ ifẹ kankan laarin oun ati KB inu BB Naija.
Akojọpọ rẹ re e: Ènìyàn 245 míràn tún ti ní Covid-19 ní NàìjíríàÀjọ NCDC kéde èèyàn 184 míràn tó ni ààrùn Covid-19 lórílẹ̀-èdè Naijíríà Ajọ to n gbogun ti ajakalẹ aarun ni Naijiria, NCDC, ti kede pe esi ayẹwo Covid-19 ti fihan pe ojilerugba le maarun eeyan lo tun ti ni aarun naa l'orilẹ-ede Naijiria.
Nínú ọ̀rọ̀ rẹ Gíwá ilé ìwosan náà ọjọ̀gbọ́n Abdaullah Yussuf fí aṣeyọri náà sọri ìṣẹ́ takuntakun àti ìfarajì àwọn dókítà mẹ́rìndíláádọ́rin tó péjú ṣe iṣẹ abẹ náà.
”Kí ìwẹ̀fà má sì sọ pé,“Wò ó!
Bakan naa lo ni kaka ki Tinubu o ba aarẹ Buhari sọrọ lati wuwa rẹrẹ si awọn ọmọ Naijiria, ki iya ma ba jẹ wọn, niṣe ni Asiwaju n gbe lẹyin Buhari, ẹni to wa jakulẹ bayii.
egbe All Progressives Congress, APC, se niluu Maiduguri, ni ipinle  Borno , nibi ti ogiri papa isere naa ti ya
Gbolohun 'Transmission Transmission' rẹ ti o n tẹnumọ pa ọpọ eeyan lẹrin ti o si mu ki awọn kan ṣe kayefi iṣẹlẹ naa.
9m kalẹ̀ fún owó oṣù òṣìṣẹ́ ní Kwara Ayefele fi orin ẹ ṣeun sẹ́nu kí Ajimobi Lati ibẹrẹ ọsẹ yii, BBC yoo ma a se agbeyẹwo ọrọ ti awọn oludije to gbajugbaja ti sọ lori ohun ti awọn yoo se lori eto ẹkọ, eto ilera, eto ọrọ aje ati eto aabo.
ede yii kan an si nile aare lati ki aare ku ori-ire.
jado orilede Naijiria, ninu eyi ti Ipinle Oyo, Osun ati Ogun je Ipinle akoko ati
Lassa Fever: Ìwádìí ní èèyàn 219 ni ibà Lassa pa lọ́dún tó lọ́, 29 lọ́dún yìí, tètè dènà rẹ̀
Aké ọmọ agbabọọlu Bournemouth lo gba goolu naa wọle nigba ti ifẹswọnsẹ naa wọ aadọrun iṣẹju Son lo kọkọ gba kaadi alawọ pupa nigba ti ifẹsẹwọnsẹ naa wọ iṣẹju kẹtalelogoji ti Foyth si gba tirẹ ni iṣẹju kejidinlaadọta.
awon omo orile ede Niajiria nimoran lati ni suuru fun aare orile ede Najiria , Muhammadu
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Òbí tó n fa sìgá n fi ọmọ rẹ̀ sínú ìdè àìsàn l'ọ́jọ́ iwájú Àwòrán ọ̀pọ ohun tó bàjẹ́ ní iléesẹ́ rédíò Yinka Ayefẹlẹ Mo ti fọ́ bàbá mi, Ọ̀gá Bello létí rí - Fẹmi Adebayọ̀ Wo oríṣiríṣi ìgbádun ibálòpọ̀ láwọn orílẹ̀èdè mìíràn Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Sunday Adelaja: Tẹ́tẹ́ làwọn pásítọ̀ tó ń gba owó ‘ìserere’ ń ta Agbẹnusọ ọlọpaa ni Ipinlẹ Eko, Chike Oti ni, Akinola lọ sinu ṣọọbu ti iya rẹ naa ti n ta ọja niwaju ile wọn.
Oludije ti ibo rẹ ba kere ju lọ ni wọn yoo fọwọ osi juwe ile fun Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Tóò bá fún ọkùnrinn lóúnjẹ́ tóo tẹ́ kiní yẹn sílẹ̀ fún un dáadáa.
Ni aṣalẹ oni ni ireti wa pe Aarẹ Muhammadu Buhari yoo bun awọn ọmọ orilẹede Naijiria sori lori ohun to kan gẹgẹ bi igbesẹ lori aṣẹ konileogbele.
Ṣugbọn ẹgbẹ APC ko fun un lanfaani lati jẹ oludije ẹgbẹ ọhun ninu idibo ọdun 2020, lẹyin rogbodiyan to ṣẹlẹ pẹlu alaga gbogbo-gboo ẹgbẹ oṣelu naa tẹlẹ, Adam Oshiomole.
Gbogbo ọ̀nà OLUWA ni ó kún fún ìfẹ́ tí kì í yẹ̀ ati òtítọ́,fún àwọn tí ń pa majẹmu ati òfin rẹ̀ mọ́.
Ilu Abuja ni awọn to ni i pọ si, pẹlu eeyan mọkanlelọgọta, nigba ti eeyan ọgọta ni nipinlẹ Eko.
Penina, orogún Hana, a máa fín in níràn gidigidi, kí ó baà lè mú un bínú, nítorí pé OLUWA kò fún un ní ọmọ bí.
Inú bí OLUWA sí àwọn ọmọ Israẹli, ó bá fi wọ́n lé àwọn jàǹdùkú ọlọ́ṣà kan lọ́wọ́, wọ́n sì bẹ̀rẹ̀ sí jí wọn ní nǹkan kó.
“OLUWA yóo bukun ọ ní ààrin ìlú, yóo sì bukun oko rẹ.
Alakoso ajọ INEC nipinlẹ ọhun, Ọjọgbọn Kyari Mohammed kede pe, Bala la gomina Ipinlẹ Bauchi lọwọlọwọ Mohammed Abdulahi mọ́lẹ pẹlu ibo ẹgbẹrun mẹfa o le lọdunrun un.
Nítorí pé aláìgbọ́n ń sọ̀rọ̀ òmùgọ̀,ọkàn rẹ̀ sì ń pète ibi.
awon ero agbohunsilẹ alagbeeka ti yoo ma sofofo awon ile –ise redio to ba n gbe
Ọrọ naa yoo kan awọn ile ẹkọ pẹlu'' Okada Ban: ọjọ kini oṣù keji ni òfin tuńtun yóò bẹ̀rẹ̀ Maryam Sanda, ìyàwó tó pa ọkọ rẹ, ri ìdájọ ikú he Tí Coronavirus bá wọ Naijiria lóní, ṣé a lè kápá rẹ̀?
Sotitotbire: Ilé ẹjọ́ dá Alfa Babatunde padà sí áhàmọ́ọ́ bẹ́ẹ̀ni ó tún sún ìgbẹ́jọ́ si Ọjọ́-Bo̩
Ó ní, “Ẹ má ṣe fi ọwọ́ kan àwọn ẹni àmì òróró mi,ẹ má sì pa àwọn wolii mi lára!
Ọdún 1991 làkọ́kọ́ idije ife ẹyẹ agbaye fun awọn agbabọọlu obinrin.
Gẹgẹ bi oludari ati alakoso ile iṣẹ epo, Makinde ti darapọ mọ
eko lorile ede Naijiria ti se gudu gudu meje , yaya mefa laarin odun merin ti
’ Ṣugbọn nisinsinyii OLUWA ti kọ̀ wá sílẹ̀, ó sì ti fi wá lé àwọn ará Midiani lọ́wọ́.
Ìwọ ni o ṣá sọ fún mi pé, ‘Ire ni n óo ṣe fún ọ, n óo sì sọ àwọn ọmọ rẹ di pupọ bí iyanrìn etí òkun tí ẹnikẹ́ni kò ní lè kà tán.
Ni ọdun 2015, o gbe ajọ kan ti kii ṣe ti ijọba kalẹ, eyii to pe Soulace Africa"" pẹlu afojusun lati ṣadinku ipa ti ogun n ko ninu aye awọn eeyan, paapaa ni Naijiria."
Àwọn ẹ̀yà Gadi ń gbé òdìkejì ẹ̀yà Reubẹni ní ilẹ̀ Baṣani, títí dé Saleka: 
Akeredolu, ẹni to fi ọwọ idaniloju naa sọya lori eto itakurọsọ BBC Yoruba tun ni oun yoo tesiwaju lati pari awọn isẹ ti oun n ṣe lọwọ, tara ilu ba fi dibo yan oun pada.
Àwọn alágbàro yìí tún lù ú, wọ́n fi àbùkù kàn án, wọ́n bá tún dá òun náà pada ní ọwọ́ òfo.
Àwọn Fadá mẹ́rin gbà itusílẹ̀ lọwọ àwọn ajínigbé Wọn tún ti ji ọ̀pọ̀ èrò kó ni Birnin Gwari Ọwọ́ ọlọ́pàá tẹ afurasí ajínigbé 93, àti ìbọn 'AK47' márùndínlógójì Nibi ti kafinta kan ti n ba Firdausi kan pako ti yoo to aṣọ adirẹ to n gba lati ọwọ iya rẹ fun tita, lo ti taju kan, to si ri ọkunrin kan to n tọrọ bara.
Ìgbà tí ènìyàn bá sì kọjá igbó náà tán tí o fi ìlú àwọn ẹyẹ àti ti ẹranko sílẹ̀ ni olúwarẹ̀ yóò tó rí ọ̀nà náà tí ó bá apá ọ̀tún lọ.
 ohun méjì ní mo fẹ ́ ṣọ ̀ rọ ̀ rẹ ̀ nínú ogún-lọ ́ gọ ̀ àwọn àṣà àti ìṣe tí ó ń bẹ nílẹ ̀ yorùbá .
Ẹni tí ó bá ní Ẹ̀mí lè wádìí ohun gbogbo, ṣugbọn eniyan kan lásán kò lè wádìí òun alára.
Nítorí pé, ẹnikẹ́ni tí ó bá ní àbùkù kò gbọdọ̀ súnmọ́ ibi pẹpẹ láti rú ẹbọ, kì báà jẹ́ afọ́jú, tabi arọ, ẹni tí ijamba bá bà lójú jẹ́, tabi tí apá tabi ẹsẹ̀ rẹ̀ kan gùn ju ekeji lọ, 
Nígbà náà ni wọ́n ké pe OLUWA ninu ìpọ́njú wọn,ó sì yọ wọ́n kúrò ninu ìṣẹ́ wọn.
O ṣalye ajọṣepọ to wa laarin oun ati Faith ti wọn kọkọ jọ gbe ati Obalọla ati Funmi to ni iyara ti wọn ti na an laiyọ Jessicca naa silẹ.
Lara awọn ohun ti Yadudu beere fun lọwọ ijọba ipinlẹ Ọyọ ni lati wa ojutu si awọn ipenija to niṣe pẹlu ala ilẹ, eto aabo ati bẹẹbẹẹ lọ.
Lẹyin naa ni wa sanwo fun iforukọsilẹ nọmba ti o ba fẹ, bakan naa ni wa tun sanwo fun iwe aṣẹ ọkọ wiwa loju popo.
Àìdúródéédé kòkòrò àìlèfojúrí afàìsàn tí à ń pè ní bacteria lára ni ó ń fa bv .
Awọn alatako ẹlẹkun jẹkun ni wọn jọ n dije dupo bayii ni India ninu eto idibo naa.
láti Heṣiboni, títí dé Ramati Misipe ati Betonimu; ati láti Mahanaimu títí dé agbègbè Debiri; 
Obìnrin náà ti gbé ìlara wọ̀ bí ẹ̀wù; ó fi owú-jíjẹ sán yẹ̀rì, ó ró aṣọ wọ̀bìà sí ìbàdí, ó sì fi ìborùn ojùkòkòrò lékeè aṣọ.
Ọpọ igba ni mo ma n wo Adekola, lati kiyesi bo ṣe n ṣere, ki emi le gba ọna mii ti ko jọ tiẹ yọ.
Ogunlogo awon eniyan ni won peju-pese si apa ariwa orile-ede naa, lati sami ayeye iranti ogofa odun ti won jagun pelu awon omo orile-ede Italy, ni iyanji ati dekun itankale ile-Euro si ile Africa, eyi ti olori Menelik II dari re, ti o si se bee segun okan lara ibi agbara ile-Euro.
"Nitori naa mi o gba ọna ti mọ ma n gba nitori mo ti pẹ, awọn sọja naa si ṣẹsẹ kọlu Reinumuje to gba ọna ti mo maa n gba tẹlẹ, wọn ro wi pe emi ni mo wa ninu ọkọ naa.
“Gbogbo àwọn ọ̀tá wa ń wẹnu sí wa lára.
Ẹ̀rù ba gbogbo eniyan, wọ́n fi ògo fún Ọlọrun, wọ́n ní, “Wolii ńlá ti dìde ni ààrin wa.
Human Rights day: Aṣíwájú ajàfẹ́tọ̀ọ́ ní Àìbọ̀wọ̀ fẹ́tọ̀ọ́ ọmọnìyàn ló ń fa wàhálà ètò àbò
“Mo mọ̀ pé o lè ṣe ohun gbogbo,kò sì sí ohun tí ó lè da ìpinnu rẹ rú.
 eròngbà wa nínú aròko yìí ni láti tanná sí àmúlò èdè yorùbá ní orísirísi ònà .
Ilẹ̀ UAE ti n fún àwọn arìnrìnàjò ní ìwé ìrìnnà ọlọ́dún márùn ún Siasia bẹ̀bẹ̀ ìrànwọ́ N100m lọ́wọ́ ọmọ Nàìjíríà láti ṣejọ́ jìbìtì tí FIFA fi kàn án Ṣo mọ̀ pé J.
Jakọbu ati Ìdílé Rẹ̀ Lọ sí Ijipti.
Ninu ọrọ Agbẹnusọ Ile naa, o fi da awọn oṣiṣẹ loju pe ẹgbẹ oṣelu All Progressive Congress (APC) to n ṣe ijọba bayii ti ṣe gbogbo eto to yẹ ti yoo mu igbesi aye rọrun fun awọn oṣiṣẹ.
COZA: Mi ò fípá bá obìrin lò pọ̀ rí láyé mi - Pásítọ̀ Fatoyinbo Ọkọ mi kò le f'ipá bá ẹnikẹ́ni lò pọ̀ láíláí - Modele Fatoyinbo Biodun Fatoyinbo fi ipò sílẹ̀ lorí ẹ̀sùn ìfipábánilòpọ̀ O fẹ́ yọ́ wọ ààyè ibùsùn àwọn obìnrin lọwọ́ ọlọ́pàá bá tẹ̀ ẹ!
Sẹnetọ Dino Melaye Ni oṣu karun un, ọdun 2018, ileeṣẹ ọlọpaa gbe Dino Melaye to jẹ ọmọ ileegbimọ aṣofin agba nigba naa lọ sile ẹjọ lori ẹsun to niiṣe pẹlu idibo ni ẹkun aringbungbun ariwa ipinlẹ Kogi.
Nítorí ojú mi ti rí ìgbàlà rẹ,
Ní ìgbà kan, Jesu ń lé ẹ̀mí èṣù kan tí ó yadi jáde.
Ó pé ọdún mọ́kànlélọ́gbọ̀n tí Samuel Okwaraji ṣubú lójú ìjà Ninu fidio naa, a ri i bi awọn kan ṣe gbe e ti wọn gbe e sinu ọkọ ọlọpaa ti wọn si gbe e lọ nigba ti awọn toku taa ri ti wọn n ba a sọrọ n fihan pe inu wọn dun.
Da Rocha: Ìlú Iléṣà ni bàbá miliọníà àkọ́kọ́ ti wá, àmọ́ ó ṣe ẹrú ní Brazil
Pàtàkì ọdún Ojúde Ọba fún ìran Yorùbá Ìdí rèé tí Gboyega Oyetola fi ń yẹra láti tètè yan kọmíṣọ́nà Khafi wọ gàu lẹ́nu iṣẹ́ lórí ẹ̀sùn ìbálòpọ̀ ní BB Naija Àwọn aláṣẹ kéde ìséde lọ́gbà fásitì Ibadan Eeyan mẹtala lo wa laaye, eeyan mẹta ku, agbalagba kan ati majesin kan ni wọn n wa bayii."
- Aráàlú ń bèèrè Ẹ fura, làásìgbò le wáyé ní ìjọba ìbílẹ̀ mẹ́fà yìí lásìkò ìbò gómìnà Ondo - YIAGA Wo ìṣẹ̀lẹ̀ márùn-ún tí kò bá pín Nàíjíríà sí yẹ́lẹ-yẹ̀lẹ Kini awọn ọmọ ilẹ Amẹrika n sọ?
Ọba Akanbi ni oun ni alaṣẹ lori oriṣa, o ni oun kii ṣe ekeji oriṣa nitori Eledumare loun n ṣoju nisin yii.
D ninu imọ ẹkọ Reaction Kinetics ni Queen's University Canada.
Àìsàn ìtọ̀ súgà kò túmọ̀ sí pé èèyàn ti gba ọjọ́ ikú- Dókítà Wilson Mo bọ́ lọ́wọ́ igbó mímu ṣùgbọ́n ìnira ilé Aafa Ọlọrẹ ti pọ̀jù- ọ̀dọ́ kan Wo ìlú tí wọ́n tí ń ta ọmọ ọ̀dọ̀ kan fún #1.
Agbẹnusọ aarẹ ni iṣẹlẹ kekere yii lawọn eeyan wa rari mọ ti wọn sọ di babara ti wọn si n sọrọ si ijọba ati aarẹ Buhari.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Champions league: Athletico bomi paná ayọ̀ Juventus ní ìpadàbọ̀ Ronaldo sí ìlú Madrid 19 Owewe 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Idunnu kọkọ ṣubu layọ fun Christiano Ronaldo atawọn akẹgbẹ rẹ ni Juventus nigba ti wọn kọkọ gba goolu meji wọle sinu awọn Athletico Madrid nibi ifẹsẹwọnsẹ to waye laarin wọn lalẹ ọjọ iṣẹgun nibi idije Champions league.
Saaju ifọwọ si yii, Aarẹ Buhari ti kọkọ kede orukọ Ẹniọwọ Rufai Imam, gẹgẹbii adele adajọ agba ilẹjọ naa ni ọjọ kẹrindinlogun osu kẹta ọdun 2017 lẹyin ti ẹni to di ipo naa mu tẹlẹ ti fẹyinti.
Alábòyun ṣe iṣẹ́ abẹ pẹ̀lú abẹfẹ́lẹ́, ó gbé ọmọ jádé nínú ara a rẹ̀ SEC: Tinubu kò gbọdọ̀ ṣe olúdarí iléeṣẹ kankan fódùn márùn ún Akẹ́kọ̀ọ́ Poly Iree jáde láyé lẹ́yìn tó ṣubú ní gbọ̀ngàn iṣèdánwò Divock Origi to wọ le fun Roberto Firmino lo gba goolu keji sawọn fun ikọ LIverpool.
Gbogbo ile ẹkọ ti ikọ BBC Yoruba ṣe abẹwo si, lo ṣe amulo awọn ohun elo ti o le daabo bo akẹkọọ ati olukọ lọwọ kokoro Coronavirus, bẹrẹ lati orii omi ati ọṣẹ, iboju, to fi mọ ilana itakete si ara ẹni.
" Èlé orí owóyàá China rọjú la ṣe fẹ́ gbà á - Ìjọba àpapọ̀ Oríṣun àwòrán, Getty Images Bi ijọba apapọ ko ba gba owoya mọ, opin de ba isẹ idagbasoke ta n se nu u.
Ó mú gbogbo àwọn ọba wọn, ó pa wọ́n.
Lara awọn eeyan to ti fori sọta iwa ọdaran lati awọn afurasi ọhun ni arabinrin kan ọga rẹ ran nisẹ, ti wọn si fi oogun gba miliọnu kan ati ẹgbẹrun lọna ẹgbẹrin naira (N1.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Religion tolerance in Nigeria: Obìnrin Mùsùlùmí ní òun ṣe ilé àlùfà ní ọ̀ṣọ́ kérésì láti polongo ìrẹ́pọ̀ 18 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Oríṣun àwòrán, The Cable NG Ramatu Tijjani, ẹlẹsin Musulumi kan to n gbe ni ipinlẹ Kaduna, ti ṣe ile alufa kan, Mobel Wuye lọṣọ pẹlu 'igi Keresi'.
ni awon gomina wonyi, Mohammed Abubakar, ipinle  Bauchi, Nasir El-Rufai gomina ipinle Kaduna
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ìjọba AbdulRazaq ti wólé aláànúú wa ní Ilorin Ki lawọn alatilẹyin Saraki sọ?
”Wọ́n ní, “Meje, ati ẹja kéékèèké díẹ̀.
O ṣalaye pe iru ounjẹ bẹẹ to fi mọ ananmọ maa n ko ni jẹ ki ọra pọ lara eeyan eleyi to le mu tobi tabi yọkun.
Awọn iroyin ti ẹ lee nifẹẹ si: Ọmọ Naijiria di asofin agba ni Italy 'Fulani Ilorin l'ọkọ mi' Iroyin sọ wi pe awọn osisẹ ileesẹ ọtẹlẹmuyẹ apapọ orilẹede Naijiria, DSS ya bo ọfiisi ati ilee rẹ ti wọn si ko awọn nkan kan lọ nibẹ.
Bẹ́ẹ̀ ni àwọn mìíràn ń sọ pé, “A ti yá owó láti lè san owó ìṣákọ́lẹ̀ lórí ilẹ̀ oko ati ọgbà àjàrà wa.
Wọ́n wonkoko mọ́ ète burúkú wọn;wọ́n ń gbìmọ̀ àtidẹ okùn sílẹ̀ níkọ̀kọ̀,wọ́n ń rò lọ́kàn wọn pé, “Ta ni yóo rí wa?
“ ‘Jẹ́ kí ìrì sẹ̀ sí i lára, kí ó máa bá àwọn ẹranko jẹ koríko; 
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Wo àrà tí ọ̀rá omi tí òún jù nù ń dà Ki ni ẹsun ti wọn fi kan an?
Wọ́n kúrò ní Bẹtẹli, nígbà tí ó kù díẹ̀ kí wọ́n dé Efurati ni ọmọ mú Rakẹli, ara sì ni ín gidigidi.
Nítorí ohun tí ò ń ṣe ti tu àwọn onigbagbọ lára, arakunrin mi.
ati ni ojo keji osu keta.
OLUWA bá dá a lóhùn pé, “Kì í ṣe ọkunrin yìí ni yóo jẹ́ àrólé rẹ, ọmọ bíbí inú rẹ ni yóo jẹ́ àrólé rẹ.
O wa rawọ ẹbẹ sawọn araalu lati maa tubọ se atilẹyin fun ileesẹ naa, ko lee tubọ tẹsiwaju.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Buhari, Olóṣèlú àtàwọn òjíṣẹ́ Ọlọ́run ló mú àjẹbánu gogò ní Nàíjíríà"" Ooni Adeyeye ti Ile Ife fẹ sèrànwọ́ owó iléèwè fún akẹ́kọ̀ọ́ 5 mílíọ̀nù ní Nàìjíríà Ọkùnrin kan rí ẹ̀wọn he lẹ́yìn tó lu obìnrin ní jìbitì ìfẹ́ tí iye rẹ̀ tó $15,000 lórí ayélujára Àwọn jàndùkú ṣọṣẹ́ nílé aṣòfin ìpínlẹ̀ Ogun, wọ́n jí ọ̀pá àṣẹ gbé!"
Ayọ̀ ń bẹ fún ẹni tí a dárí ìrékọjá rẹ̀ jì,tí a bo ẹ̀ṣẹ̀ rẹ̀ mọ́lẹ̀.
Gbogbo àwọn ọmọ rẹ̀ ni wọ́n máa ń lu aro ati hapu, tí wọ́n sì ń tẹ dùùrù lábẹ́ àkóso baba wọn ninu ìsìn ninu ilé Ọlọrun.
 Awon okunrin meji ni o ku , ti awon eniyan mejo si fi ara pa”.
dibo niluu re Daura, nipinle Katsina lojo Eti(Friday) fun idibo aare ati
Eyi lo mu ki n tẹsẹ duro de, to si jẹ ki n pẹ ju asiko ti mo maa n jade kuro ninu ile lọ, owurọ ọjọ naa ni Dimka ṣọṣẹ.
Tẹ ibi yii ki o dahun bi o ṣe yẹ.
Idi ni yi ti a fi mu akori # LeaveOurDaughtersAlone (to tumọ si ẹ fi awọn ọmọ wa silẹ) lati pe fun fifopin si ajalu nla yii pẹlu ireti wi pe wọn yoo gba itusilẹ.
Lẹ́yìn náà wọ́n da òrùka wúrà meji, wọ́n sì dè wọ́n mọ́ etí kinni keji ìgbàyà náà, lọ́wọ́ inú ní ẹ̀gbẹ́ tí ó kan ara efodu.
Ṣugbọn Cesar Azpilicueta ṣe aṣiṣe, eyi to mu ki Arsenal o gba pẹnariti.
Ṣugbọn ta ni yoo gba goolu sawọn lalẹ oni laarin awọn mejeeji ni papa iṣere Wanda Metropolitano niluu Madrid?
Awọn ariwo kan wa to maa n mu aarẹ ba ọpọlọ, apa ibi kan ninu ọpọlọ ni yoo mu u.
 púpọ ̀ nínú àwọn tí ó ń sọ ọ ́ yìí ni ó wà ní pakísítáánì ( pakistan ) ní bàlúṣísítáànì ( baluchistan ) .
Igbesẹ kan naa lo ni lati gbe to ba wa ni orilẹ-ede Naijiria.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Babatunde Fashola: Àwọn alájẹbánu gba owó fún isẹ́ iná mọ̀nàmọ́ná 5 Èbibi 2019 Oríṣun àwòrán, WIKIPEDIA Àkọlé àwòrán, Minisita fun ọrọ isẹ ati ile gbigbe, Babatunde Fashola ti fi orukọ awọn ile isẹ to fẹsun ajẹbanu kan.
Ọbasanjọ tako ìnáwó Ààrẹ Buhari fún ìpèsè inà ọba
Àwọn ọmọ Ulamu jẹ́ jagunjagun, tafàtafà ni wọ́n, wọ́n sì lókìkí.
Okonjo, to ti fi igba kan jẹ minisita fun eto inawo ni Naijiria, ni obinrin akọkọ to de ipo naa lati ọdun mẹẹdọgbọn ti wọn ti da ajọ WTO silẹ.
Ojú ọ̀run ń kéde òdodo rẹ̀;gbogbo orílẹ̀-èdè sì ń wo ògo rẹ̀.
Victor Moses: Ọmọ pásítọ̀, ìjà ẹ̀sìn ni Kaduna fa ikú àwọn obí rẹ̀
agbaboolu ti o n kopa ninu idije EPL ni yoo maa gbaradi lati dije fun ife-eye
Níbi tí kò bá ti sí ìtọ́ni, orílẹ̀-èdè a máa ṣubú, ṣugbọn ẹni tí ó bá ní ọpọlọpọ olùdámọ̀ràn yóo máa gbé ní àìléwu.
O so pe “ilana se pataki ju abajade lo , nitori pe lati le je ki idagbasoke ba eto ijọba tiwa-n-tiwa lorile ede Naijiria, ki I se nipa sise atileyin fun oludije kan, yala  lati inu egbe mi tabi fun egbe alatako.
Ẹkunrẹrẹ lori iroyin yii wa ni: Afurasí Fulani ṣekú pa ọmọ olórí ẹgbẹ́ Afẹ́nifẹ́re, Fasoranti Àwa ọba alayé ń wọ́nà láti ṣẹ́ eegun ẹ̀yin ọ̀daràn Fulani - Ọọ̀ni Ẹ yàgò fún ìwà adìẹ dàmí lóògùn nù, màá fọ lẹ́yin lásìkò ìjà - Buhari Ǹjẹ́ ẹ mọ ohun tí igbákejì ààrẹ Yemi Osinbajo sọ nílé bàbá Fasoranti Ọlọ́pàá, a fún yín ní gbèdéke ọjọ́ 21 láti mú àwọn tó pa ọmọ Fasoranti - OPC Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Fasoranti: Dẹ́rẹ́bà tó wa ọmọ Fasoranti ṣàlàyé bí wọ́n ṣe pa Funke Olakunrin Awọn Iroyin ti ẹ le nifẹ si Ìtàn tó wà nídi òwe ‘Sebótimọ Ẹlẹ́wà Sàpọ́n’ Ìtàn tó rọ̀ mọ́ òwe ‘aṣọ kò bá Ọ́mọ́yẹ mọ́.
J’aimerai remercier tous les joueurs, coachs, équipes, et supporters, que j’ai rencontré et ont fait de cette carrière un moment très spécial.
Oríṣun àwòrán, osun state government Ọgbẹni Ṣẹyẹ Oyelẹyẹ ṣalaye pe ko sohun meji to n da ibẹrẹ iṣẹ iks naa duro lawọn ipinlẹ ju wahala ajakalẹ arun coronavirus to gba aye kan bayii.
 Èyí lèjẹ lára lílo ogùn lílé kòkòrò àti ìwọṣọ dáradára .
 Ijoba ekun yii san gbese naa fun ise akanse ipese omi, oju ona, oju oko reluwe, ilera, eto eko ati ise awon agbale.
" Àkànṣe owó oṣù lá wa olùkọ́ ń fẹ́ yàtọ̀ sí tàwọn òṣìṣẹ́ ìjọba míì - NUT A gbẹ́sẹ̀ lé ilé kan tó jẹ́ ti Bukola Saraki, torí àpò ìjọba ló ti mú owó sanwó ilẹ̀ - Ilé aṣòfin Irọ́ ni Cameron pa mọ́ mi lórí ọ̀rọ̀ àwọn akẹ́ẹ̀kọ́ Chibok- Jonathan figbe ta Lara awọn oludije to ku nile ni Seyi, Omashola, Mercy, Mike ati Frodd, ti anfaani si wa fun ikọọkan wọn lati moke, ti yoo si gba ẹbun owo miliọnu lọna ọgọta naira.
Ọlọpa ko lee sọ boya 'were' lọkunrin to sa ọmọ meji pa l'Ogun
Khalissa ni tirẹ ni, o yẹ ki Toyin gbe Lizzy Anjorin lọ ile ẹjo ni, nitori, ẹnu orofo Lizzy lo fẹ koba.
Hussein ni ṣe ariwo ti awọn eeyna n pa naa kọ ni yii lasiko yii.
Oríṣun àwòrán, Busola Dakolo/Facebook Àkọlé àwòrán, Ìwáàdí ẹ̀sùn ìfipábánilòpọ̀ kò tíì parí Ajọ PFN sọ pe iwadii naa ko pari nitori Pasitọ Fatoyinbo kọ lati yọju si igbimọ ẹlẹni marun-un to n ṣewadii ẹsun naa.
Ṣugbọn ní àkókò yìí, ẹ pa gbogbo àwọn nǹkan wọnyi tì: ibinu, inúfùfù, ìwà burúkú, ìsọkúsọ, ọ̀rọ̀ ìtìjú.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Femi Adesina: Bí àwọn ọmọ Nàìjíríà bá f'ara balẹ̀ wọ́n ó rí iṣẹ́ ribiribi tí Buhari ti ṣè 10 Èrèlè 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 7 Ògún 2020 Oríṣun àwòrán, @BashirAhmaad Olubadamọran pataki si aarẹ Buhari lori ọrọ ibanisọrọ ati ipolongo, Femi Adesina ti ni ki awọn ọmọ Naijiria farabalẹ lati le ri iṣẹ daada ti aarẹ Buhari ti gbe ṣe.
Oríṣun àwòrán, Emmanuel Anneh Ṣugbọn ko ṣeeṣe fun awọn dokita lati ṣe isẹ abẹ fun wọn ni igba naa nitori ara wọn ko le daadaa.
O ni ti kii ba ṣe nitori Obasanjo ni, ki ba ma ti si ilu Owu ninu maapu orilẹ-ede Naijira.
Nígbà tí ó di ọjọ́ kan, Hẹrọdiasi rí àkókò tí ó wọ̀ láti ṣe ìfẹ́ rẹ̀.
Ọọni ti Ile Ife, Adeyeye Ogunwusi nigba ti awọn obi ọmọ yọju si i laafin sọ pe ki wọn ma foya, o ṣe iléri pé òun yóò tu iṣu dé ìsàlẹ̀ ikoko lóri ọ̀rọ̀ náà ati pé ìpè yòó lọ si ọdọ àwọn àjọ DSS láti ma jẹ́ ki àwọn alagbara kankan o yọ woli náà kuro latimọle titi ti ọ̀rọ̀ yòó fi yanju.
Irọ́ ni pé wọ́n hú òkú Kolawole Gold lórí pẹpẹ ìjọ ọkọ mi- Bisola aya Sotitobire Ẹ wo èrò bìbà níbi ìwọ́de #EndSARS ní ìlú Ibadan Wo bí àwọn jàndùkú ṣe yabò àwọn olùwọ́de #ENDSARS ní Alausa l'Eko àti Abuja Ìjàmbá ọkọ̀ akérò àti tírélà pa èèyàn mẹ́rin lọ́nà mọ́rosẹ̀ Ore sí Benin Alaga ajọ to ri si eto ibaraẹnisọrọ ni Nigeria Communications Commission, NCC, Ọjọgbọn Adeolu Akande naa ko gbẹyin ninu awọn to n ki Oba Alaafin ku ọdun ọjọ ibi wọn.
Nigba to n sọrọ lori atilẹyin ti wọn n ṣe fun awọn oloogun ibilẹ lori iwosan arun Covid-19, Fayemi ni o se ni laanu pe oogun oloyinbo la gbajumọ, ko si si ohun to buru nibẹ ti itọju arun naa ba ti ọdọ oogun ibilẹ wa.
“Ọ̀gágun Ijipti pàṣẹ fún àwọn ọmọ ogun rẹ̀ pé,‘Ẹ tọ́jú asà ati apata,kí ẹ sì jáde sójú ogun!
Ṣugbọn bí iyọ̀ bá di òbu, báwo ni a ti ṣe lè mú kí ó tún dùn?
Eeyan 55,632 ni apapọ ni wọn ti fara ko aarun Coronavirus, ti awọn 43, 610 si ti ri iwosan gba lọwọ ajakalẹ arun ọhun.
'Logo Benz yóò lẹ́yìn fún àwọn ọ̀dọ́ tó bá ṣògùn owó' Olamide ati Lil Kesh dá wàhálà sílẹ pẹ̀lú 'Logo Benz' Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Ọba Adesoji Aderemi, Ọọ̀ni Ifẹ̀ tó gba ipò ọba mọ́ tòṣèlú MKO Abiola, iṣẹ́ aṣẹ́gità ló fi bẹ̀rẹ̀ okoòwò Iṣọla Oyenusi rèé, ẹnití ìfẹ́ obìnrin ṣun dé ìwà ìdigunjalè Taiwo Akinkunmi, ọmọ Ibadan tó ya àsìá Naijiria Lara awọn ohun ti awọn ajafẹtọ ẹni naa n beere fun ni ilana isejọba rere eyi ti yoo dẹ awọn ọmọ Naijiria lọrun, paapa nidi ipese ina ọba to duro re pklu owo ti ko gunpa, ki ijọba si tun se atunse awọn ibudo ifọpo wa eyi ti yoo mu opin de ba asa ka maa ko epo wọle.
Gbogbo Ọgbọ́n àlùmọ̀kúrọ́yin wọ́n Oníruurú àwọn ọgbọ́n tí wọ́n maa n lo lati fi dẹ́rùba àwọn ọmọ tó wà ni àhámọ ní pe wọn tí gbé ọpọ ninu àwọn obi wọn náà.
Ibi ọrọ de duro Awọn adola ẹmi ti sọ pe ogun eeyan lo ba iṣẹlẹ ọhun lọ ti awọn marundinlọgbọn si farapa.
Àwọn Juu ni yóo kọ́kọ́ fún, lẹ́yìn náà yóo fún àwọn Giriki.
Bí wọ́n bá ní kí á dúró kí àwọn tọ̀ wá wá, a óo dúró níbi tí a bá wà, a kò ní lọ sọ́dọ̀ wọn.
Mo dá ọjọ́ méje fún ọba.
Nítorí ìfẹ́ OLÚWA tí ó lágbára ni àwa kò fi ṣègbé, nítorí ti àánú rẹ kì í kùnà.
'Ekute jẹ ogun oloro lagọ ọlọpa' #BBCGOVDEBATE: Ọgbọ́n ìmọ̀ àti òye ní ń ò fi ṣe ìjọba- GNI Sọ àsọtẹ́lẹ̀ orílẹ̀èdè tí yóò borí ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ t'òní Presidential Election Tribunal: Láyé, a ò lè gba ẹ̀bẹ̀ PDP láti yẹ ojú òpó ayélujára INEC wò Ajọ to n risi igbelarugẹ ẹkun Iwọ-Oorun orilẹede Naijiria lo se agbatẹru ipade laaarin awọn gomina mẹfa lati gbogun ti eto aabo to mẹhẹ.
naijiria ni orile-ede ti awon eniyan posijulo ni afrika botilejepe iye gangan ko i je mimo .
Oga agba oloopa, Abubakar Adamu tun tesiwaju  ninu oro re pe ko si  osise eleto aabo tabi oloopa orile-ede kan to
“Ohun ti a jiroro nibi ipade naa ni eto idibo lati yan awon oludije ni osu kesan an ,odun yii.
Aare Muhammadu Buhari soro yii ni Paris lojo Aiku nigba to n pe fun ijiya to nipon fun awon to n ji owo ilu ko lo si oke okun.
Gẹ́gẹ́ bí ó ti wà ní àkọsílẹ̀ pé, “Mo ti yàn ọ́ láti di baba fún ọpọlọpọ orílẹ̀-èdè.
Nítorí náà, níwọ̀n ìgbà tí eniyan ti sàn ju aguntan lọ, ó tọ́ láti ṣe rere ní Ọjọ́ Ìsinmi.
Ọrẹ ẹbọ tirẹ̀ ni: àwo fadaka kan tí ìwọ̀n rẹ̀ jẹ́ aadoje (130) ṣekeli, abọ́ fadaka kan tí ìwọ̀n rẹ jẹ́ aadọrin ṣekeli, ìwọ̀n tí wọn ń lò ní ibi mímọ́ ni wọ́n fi wọ̀n ọ́n.
Bí a ti ń kọ wón là ń tawon lé'rú fún àwọn orílẹ̀ èdè míràn.
Ẹ ò lé fi tipa gbárùkù tí ẹni ti mí o nífẹ̀ẹ́ si ni dandan'' àwọn ǹkan ti dino sọ rèé lóri ẹ̀rọ ibanisọ̀rọ̀ Dandan ní kí a mú Dino sí àhámọ́ wa-Ọlọ́pàá Ilé iṣẹ́ ọlọ́pàá ti jáde pé àwọn ò ní kúrò nílé Sẹ́natọ Dino Melaye títí yóò fi fojú hàn fún àwọn láti mú.
Ṣugbọn mò ń sọ fun yín pé Solomoni pàápàá ninu ọlá rẹ̀ kò wọ aṣọ tí ó dára tó wọn.
Abileko Ajibola wa ro ogagun Omozoje lati ri i pe won tesiwaju ninu ise
Aago marun un irọlẹ ni ọkọ ofurufu aarẹ balẹ ni papakọ ofurufu Malam Umar Musa Yar'adua ni ipinlẹ Katsina.
Àgbà òṣèré tíátà míràn tún jáde láyé!
Oòrùn ṣókùnkùn, ó dàbí aṣọ dúdú.
Gbajugbaja olorin Fuji ati osere tiata, Wasiu Alabi Pasuma ti ọpọ eniyan mọ si Ọ̀gáńlá"" ti dupẹ lọwọ Ọlọrun fun oriire ọjọ ibi ọdun mọkanlelaadọta loke eepẹ."
sì máa fin a ilẹ ̀ lẹ ́ ẹ ́ mẹ ́ ta mẹ ́ ta .
Ki lo bi ero pe iwa buruku ni awọn ọmọ Naijiria n hu loke okun: Ni ẹnu ọjọ mẹta yii, oniruuru iroyin iwa kotọ nipa awọn ọmọ orilẹ-ede Naijiria to wa loke okun lo n fọn kalekako lori ayelujara.
 Ó wà lára àwọn olùdásílẹ ̀ académie de peinture et de sculpture ní ọdún 1648 .
Ninu ọrọ naa, JAMB wipe nitoripe awọn jẹ ojulowo ajọ t'o fẹran ilọsiwaju awọn akẹkọ ni awọn ṣe fi aaye s'ilẹ fun awọn ti ko ba tii f'orukọ s'ilẹ fun idanwo naa lati se eyi laarin ọsẹ meji.
Kì í ṣe ìtorí iṣẹ́ tí eniyan ṣe, kí ẹnikẹ́ni má baà máa gbéraga.
Dafidi bèèrè lọ́wọ́ rẹ̀ pé, “Ta ni oluwa rẹ, níbo ni o sì ti wá?
Ẹni tí ó bá lè gba èyí, kí ó gbà á.
Oríṣun àwòrán, @efcc Ṣugbọn wọn ko ri bi brẹ ìjẹ́jọ́ ti awọn mejeji yii bii ti Mompha ti wọn fi ẹsun ọtọ kan to si ni oun ko jẹbi ẹsun iye owo to to biliọnu mẹtalelọgbọn ti wọ́n fi kan an atipe o ni ile iṣẹ to n ṣe pasiparọ owo ilẹ okere kan lai gbaṣẹ lọwọ banki to ga ju lọ ni Naijiria.
Lara wọn sọ wi pe iya ati iṣẹ lorilẹede Naijiria kọja bo ṣe yẹ lasiko ofin konile o gbele lorilẹede Naijiria.
Àkọlé àwòrán, APC pin si meji ni Kwara, awon kan n dibo loni Hon Ishola Balogun-Filani to jẹ alaga ẹgbẹ APC ni Kwara ba BBC Yoruba sọrọ lori idibo naa pe ẹka ti wọn to n dibo loni ni ajọ INEC yoo gba wọle nitori pe aṣẹ wa lati òkè pé ki awòn ṣeto idibo naa loni ni.
O wa ki aburo baba rẹ ku oriire.
Aare fi aidunnu rẹ han nipa bi
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Àwọn gómìnà ilẹ̀ Yorùbá parapọ̀ láti gbógun ti ààbò tó mẹ́hẹ!
Aisaya Jíṣẹ́ OLUWA fún Ahasi Ọba.
Ọ̀nà ẹlẹ́bi kì í gún,ṣugbọn ìrìn aláìlẹ́bi a máa tọ́.
Nítorí àwọn ẹlẹ́ṣẹ̀ pàápàá fẹ́ràn àwọn tí ó bá fẹ́ràn wọn.
Wo àwọn ọmọdé mẹ́ta tó ń fi èdè Yorùbá dá bírà ní Finland!
Nígbà tí Saulu gbọ́ pé Dafidi wà ní Naioti ní Rama, 
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Operation Puff Adder: Ọwọ́ ọlọ́pàá tẹ afurasí ajínigbé 93, ọ̀pọ̀lọpọ̀ ìbọn 'AK47' àti aṣọ ṣọ́jà 16 Èbibi 2019 Oríṣun àwòrán, Nigeria Police Àkọlé àwòrán, Yatọ si awọn nkan ija oloro, awọn ọlọpaa tun ri awọn aṣọ ọmọ ogun tgba lọwọ awọn afurasi naa.
Bakan naa ni Alfa Jamiu tun dibọn pe oun ni oludari agba tẹlẹ fun ileeṣẹ ipọnpo rọbi orilẹede Naijiria, NNPC, lati ṣe gbajuẹ fun oyinbo Koraa naa.
Bí ẹnikẹ́ni bá jẹ ninu oúnjẹ yìí, olúwarẹ̀ yóo wà láàyè laelae.
Kii ṣe lati maa fi wọn we awọn ojugba wọn ti o lowo lọwọ, ti wọn ko si mọ ibi ti wọn ti ri owo ti wọn n na.
Má tún máa ṣe ìfẹ́kúfẹ̀ẹ́ ẹ̀dá mọ́, ṣugbọn máa ṣe ìfẹ́ Ọlọrun ninu gbogbo ìgbé-ayé rẹ tí ó kù.
ati àwọn arakunrin rẹ̀ wọnyi: Ṣemaaya, Asareli ati Milalai, Gilalai, Maai ati Netaneli, Juda, ati Hanani, pẹlu àwọn ohun èlò orin Dafidi eniyan Ọlọ́run.
Ìyẹn ni pé wọ́n wà fúnwa gẹ́gẹ́ bí àjẹára ni.
ise naa pelu gbogbo awon osise alaabo miran fun atileyin won to je ki won se
Hesekaya bá kọjú sí ògiri, ó gbadura sí OLUWA, 
Ẹ ṣọ́ra fún ìròyìn ẹlẹ́jẹ̀ lórí ètò ààbò - Ọlọ́pàá Iléeṣẹ́ ọmọ ogun dá Bashir tó ri owó he lọ́lá Omi ara Ọ̀pọ̀lọ́ jẹ́ ẹlẹ́rìndòdò tó ń mára jípépé, ẹ máa mú Bakan naa lo ṣalaye kikun lori ipa pataki ti awọn fijilante ko ni Kwara nipa wiwọ inu igbo lọ titi wọn fi ṣawari awọn oniṣẹ ibi naa.
Lọdun 2019 ta wa yii si lo dibo wọle gẹgẹ bii Kanselọ alawọ dudu akọkọ ti wọn yoo dibo yan lorilẹede Ireland.
Dokita Matshidiso Moeti to jẹ adari WHO nilẹ Adulawọ ni ilẹ Yuroopu, North america ati ilẹ Asia nibi ti awọn arugbo pọ si julọ.
Wo ìtàn ayé gbajúmọ̀ adigunjalè méje nílẹ̀ Yorùbá Adewumi ni, o se ni laanu pe, gbingbin egboogi oloro ati igbo n peleke si ni ipinlẹ Kogi ati ni Naijiria.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Nigeria 2019 budget: Ààrẹ Muhammadu Buhari buwọ́lu owó ìṣúná ọdún 2019 27 Èbibi 2019 Oríṣun àwòrán, Bashir Ahmad Àkọlé àwòrán, Ààrẹ orílẹ̀-èdè Nàìjíríà buwọ́lu owó ìṣúná 2019 Aarẹ Muhammadu Buhari ti buwọlu owo iṣuna ọdun 2019.
Igbeṣẹ yii waye lai ti pe wakiti mẹrinlelogun ti ẹgbẹ oṣelu naa le oluranlọwọ pataki fun aarẹ Buhari, Senator Babafemi Ojudu ati awọn mẹwaa miran kuro ninu ẹgbẹ APC.
O sàn ká wà láyé láì lówó lọ́wọ́ ju ká ya sinimá, ká kó Coronavirus lọ - Latin pariwo fáwọn òṣèré tíátà Ìdá 90% nínú àwọn olówó Naijiria lo n lọ ilé babaláwo- Mr Latin Àwọn òṣèré sinimá Yorùbá tó padà lọ sí fásiti lẹ́yìn tí wọ́n bẹ̀rẹ̀ eré.
Oríṣun àwòrán, @AAAjimobi PDP sọ siwaju si pe igbesẹ sise ayẹwo isejọba to kọja yoo fun ijsba tuntun to wa nipinlẹ Ọyọ ni anfaani lati mọ ọpọ igbesẹ ti ijọba Ajimọbi gbe lori aleefa.
Abenugan ana ,fun igbimo asofin lorile ede Naijiria Ken Nnamani, to tun je alaga igbimo egbe to n ri si awuye-wuye  lo so eleyii, nigba ti igbimo n jabo iroyin fun alaga egbe APC, Adams Oshiomhole niluu Abuja.
Ẹ kò gbọdọ̀ fi ìyá ẹran ati ọmọ rẹ̀ rúbọ ní ọjọ́ kan náà; kì báà jẹ́ mààlúù, tabi aguntan, tabi ewúrẹ́.
Babatunde Gbadamọsi (ADP) Àkọlé àwòrán, àwọn olùdíje ìpínlẹ̀ Eko Gbadamọsi tẹnu mọ eto ilera ọfẹ fun tolori tẹlẹmu ni ipinlẹ Eko.
30 Èbibi 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, OIC n ṣepade Wọn da ẹgbẹ Organisation of Islamic Cooperation ti ọpọ mọ si OIC silẹ lọdun 1969 pẹlu orilẹede mẹtadinlọgọta.
yin ni , ki e je adari rere fun awon to wa leyin yin ni gbogbo igba, ki won lee
Àjọ onísirò Nàíjíríà: Àdínkù bá owó ọjà si ìdá mẹ́tàlá
"Atẹjade naa ni ""Ọmọ ogun kan labẹ ẹka 202 Battalion ni ilu Bama lo ṣadede yin ibọn lu oloogbe ọhun, ni nnkan bi aago mẹwaa abọ aarọ, eyi to yọri si iku rẹ."
Òmùgọ̀ eniyan níí káwọ́ gbera,tíí fi ebi pa ara rẹ̀ dójú ikú.
"Wo àwọn ìbejì tó mú ẹ̀dọ̀ àti egungun àyà kan ṣoṣo wá látọ̀run Ṣé Nàìjíríà lẹ́mìí nkan tí Ghana ń ṣe fáwọn akẹ́kọ̀ọ́ ""Secondary"" tí yóò wọlé ní October yìí?"
Láìpẹ́ yìí, ẹ ronupiwada, ẹ sì ṣe ohun tí ó tọ́ lójú mi; ẹ kéde ìdásílẹ̀ fún àwọn arakunrin yín.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ìgbẹ́tì: Òkè Ìyámàpó ló gba wàá sílẹ̀ lọ́wọ́ ogun Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
 alátìlẹyìn ni odù jẹ fún Ọ ̀ rúnmìlà .
Kí ìyípo kan máa jẹ́ ọdún kan.
Bẹ ba si ranti, bi Olori Badra naa se maa n kọ ọrọ itunu soju opo ayelujara rẹ naa ree lasiko to la rogbodiyan kọja ni Aafin Oyo.
Ó wá sọ fún wọn pé, ‘Gbogbo ẹni tí ó bá ní ni a óo tún fún sí i.
Awọn obi Toyin, Yeyeluwa Odebunmi, Ọgbẹni Segun Odebunmi wa nikalẹ ninbi eto ọhun to waye nile awọn obi Toyin Abraham.
’ rèé Lasiko ti BBC se abẹwo si ọdọ mama naa, ti ọpọ eeyan mọ si Mama Arsenal nitori bo se nifẹ si ẹgbẹ agbabọslu Arsenal, ẹnu ko gba iroyin.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Anthony Joshua: Ajagba akẹ̀ṣẹ́ ọmọ Nàìjíríà lóun ṣetán láti f'ẹ̀ṣẹ́ dín dòdò ìyà fún AJ 3 Owewe 2020 Oríṣun àwòrán, Instagram Yoruba bọ, wọn ni o di oni karangida, adiẹ n jẹ ifun ara wọn.
N óo rán ejò sí ààrin yín:paramọ́lẹ̀ tí kò ní gbóògùn;wọn yóo sì bù yín jẹ.
Wọn fẹsun kan an pe, Magu a maa ṣe arifin si awọn to juu lọ lẹnu iṣẹ.
Mo wá a ṣugbọn n kò rí i.
Àmọ́ o, òyìnbó tó saiyé dẹ̀rọ̀ pẹ̀lú ẹ̀rọ-ìgbálẹ̀ níjọ́sí ti tún gbé tuntun dé o.
Coronavirus: Orílẹ̀èdè Cameroon ti ní alárùn àkọ́kọ́
" Ìyàwó wọ sòkòtò fún ayẹyẹ ìgbéyéwò rẹ̀, ní wáhálà bá bẹ́ sílẹ̀ Kílódé tí Ọọni Ife, Oba Ogunwusi kò fi gbọdọ̀ rí ọmọ rẹ̀ tuntun ti Olorì Naomi bí títí di bíi ẹ̀yìn oṣù mẹ́fà?
Si sẹ́ Àgbàdo lẹhin li lọ 
ìyàwó kú sínú kàngà nígbeyàwó kú ọ̀la Gómìnà Kwara kéde àgùnbánirọ̀ àtàwọn míì gẹ́gẹ́ bí kọmíṣọ́nnà tuntun Ǹjẹ́ o mọ àwọn ẹ̀yà ara rẹ ti'nú ara àti ìta lédè Yorùbá?
Oun ni ọmọ Eritrea akoko ti yoo soju orilẹẹde rẹ nibi idije Winter Olympics.
WỌ́N WÀ NÍBẸ̀: NÍNÚ ÀWỌN ỌGBÀ Ẹ̀WỌ̀N ÀTI IBOJÌ-ÒKÚ.
Neha Sharma: obìnrin tó ń múra bíi ọkùnrin láti leè ṣiṣẹ́ gẹrígẹrí
Nítorí náà, OLUWA Ọlọrun ní níwọ̀n ìgbà tí gbogbo yín ti di ìdàrọ́, n óo ko yín jọ sí ààrin Jerusalẹmu.
Ni tirẹ, Alhaji Atiku Abubakar ni ohun to dun mọ ni lodo ikun ju guguru oloyin lọ Ni pe AJ gba ipo rẹ pada.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Kemi Lala: mo ń gbìyànjú láti mú inú òbí mi dùn Lẹyin ija ajaku akata laarin awọn ologun atawọn ajinigbe ọun nibi ti ọkan ninu awọn ajinigbe naa ti farapa.
Àkọlé àwòrán, Bi ikọ Boko Haram se n se ikọlu rẹ losoosu Awọn ibudo ti Boko Haram n kọlu ko yatọ lati ọdun meji sẹyin.
Ṣugbọn Saulu dá wọn lóhùn pé, “A kò ní pa ẹnikẹ́ni lónìí, nítorí pé, òní ni ọjọ́ tí OLUWA gba Israẹli là.
Marijuana ni àwọn olóyìnbó ń pe egbò igi igbó yìí, àwọn ọmọ Nàìjíríà a sì máa pè é ní Igbo.
Àwọn tí kò mọ Ọlọrun wà láàrin yín!
Marseille padanu anfaani lorisirisi lati da ami-ayo naa pada, sugbon ifesewonse naa tun wa buru jai leyin ti agbaboolu aarin iko naa, Dimitri Payet farapa, ti o si jade niseju mọ́kànlélọ́gbọ̀n saa kinni ohun.
 Ọkan o jọkan awọn ọmọ orilẹede Naijiria nile ati loke okun ni wọn ti n sọrọ lori ọrọ yii."
"O ni, ""gbogbo nnkan lo wọn tẹlẹ, Owo ti wọn fi kun epo yoo kan jẹ ki nnkan tun wọn si i ni ti ara yoo si maa ni gbogbo ara ilu."
Ni ilu aarẹ, Daura nipinlẹ Katsina ni ariwa Naijria ni wọn yoo kọ ọgba ile ẹkọ naa si.
Lẹ́yìn ọ̀sẹ̀ kan, CAF ní kí Esperance dá ife ẹ̀yẹ CAF Champions League padà CAF kéde orúkọ àwọn olùdíje àmì ẹ̀yẹ agbábọ́ọ̀lù Áfíríkà Mohammed Salah gba àmì ẹ̀yẹ̀ CAF fún ìgbà kejì Super Falcons gòkè odò bọ́ sípele ìkẹrìndínlógún ní France Bakan naa ni wọn ni ko ṣe iwadii awọn ẹsun ti wọn n sọ nipa ajọ agbabọọlu ilẹ Adulawọ.
Atẹjade kan lati ọdọ ileeṣẹ ọlọpaa ni ipinlẹ Kogi sọ pe Acheju Abuh lorukọ obinrin ti o kagbako iku ojiji ninu ile rẹ ni Ochadamu,eyi to wa ni ijọba ibilẹ Ofu, nipinlẹ Kogi.
Ajihinrere Mike Bamiloye ati iyawo rẹ Gloria, ni ọmọ ọkunrin meji ati abigbẹyin obinrin kan, tawọn naa yan lọwọ ara wọn lati darapọ mọ iṣẹ iranṣẹ fiimu Kristẹni, ti baba ati iya wọn n ṣe.
Ní àkókò ìjọba Dafidi, ìyàn ńlá kan mú, fún odidi ọdún mẹta.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù LUTH: Nítorí àìsan owó oṣù, àwọn dókítà ARD da iṣẹ́ sílẹ̀ ní ilé ìwòsàn LUTH nílùú Èkó 29 Bélú 2018 Oríṣun àwòrán, LUTH Àkọlé àwòrán, Gẹ́gẹ́ bí ìròyìn tí ó ń tẹ̀wálọ́wọ́ ṣe sọ, àìsan owó oṣù ló ṣokùnfà iyanṣẹ́lódì náà.
6 Èbibi 2019 Profile: Duchess of Sussex25 Bélú 2020 Duke of Sussex: The party prince who carved his own path19 Sẹ́rẹ́ 2020 Royal Family tree and line of succession20 Agẹmo 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Angela Merkel ni olori orilẹede latilẹ okeere keji to bẹ Naijiria wo laarin ọsẹ yii.
Ẹ̀rù tí ó bà wọ́n pupọ kò jẹ́ kí ó mọ ohun tí ì bá wí.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ladoja Loju opo Twitter agbẹnusọ fun Gomina Sanwo Olu ni wọn ti fi tayọtayọ kede aṣeyọri Sanwo Olu pẹlu igbesẹ igbimọ yi Agbẹjọro fun ẹgbẹ AD ati LP, agbẹjọro Bola Aidi loun dupe lọwọ igbimọ naa fun idajọ ti wọn gbe kalẹ.
Naijiria (Association of Senior Civil Servants of Nigeria), Ogbeni Ibrahim
 Ras mo nifẹ rẹ, ibanujẹ nla ni yii.
A jẹ́ pé ẹ̀rọ kan ṣoṣo yìí ni ọ̀pọ̀lọpọ̀ ń gbé káàkiri.
Nigeria Police Recruitment 2020: Àwọn ohun tí ẹ nílò fún àyẹ̀wò ìgbanisíṣẹ́ ọlọ́pàá tí yóò bẹ̀rẹ̀ ní Mon, Aug 24 Èsì ìdánwò òhun tí a ṣé síwájú là n bá fínra báyìí ní Nàìjíríà- Yemi Shodimu Ileeṣẹ ọhun sọ pe nigba to ba ya awọn yoo fi ikede sita gba ojulowo opo wọn lori ayelujara.
Ẹ̀yin, tí ẹ kì í ṣe Juu, wá dàbí ẹ̀ka igi olifi tí ó lalẹ̀ hù ninu ìgbẹ́.
Jesu wí fún àwọn iranṣẹ pé, “Ẹ pọn omi kún inú àwọn ìkòkò wọnyi.
Ko tan sibẹ o, o tun jẹ ẹbun foonu, ọda, eroja fun inu ile, ounjẹ ọfẹ, aṣoju ileeṣẹ, ati ẹẹdẹgblta Dọla owo Bitcoin.
Wo ẹsẹ̀ ẹni tí ó ń mú ìyìn rere wá lórí àwọn òkè ńláńlá, ẹni tí ń kéde alaafia!
Ẹni to ba dan an wo, yoo de ile ẹjọ fun ẹsun ipaniyan tabi oniruuru ẹsun ti yoo si da lori ipele ẹṣẹ rẹ.
Bo tilẹ jẹ pe ileeṣẹ ọlọpaa kọkọ ṣe pe oun ko lọwọ ninu iku okunrin naa, ṣugbọn awuyewuye to tẹlẹ iṣẹlẹ ọhun ko kere rara.
Aṣa ikini nilẹ Yoruba ṣafihan ibọwọfagba to ṣe koko ninu aṣa Yoruba lainii fi ṣe ipo, tabi ipele igbega ti eniyan wa.
Noa mu àmupara ninu ọtí waini ọgbà rẹ̀, ó sì sùn sinu àgọ́ rẹ̀ ní ìhòòhò.
Ẹ yan eniyan mẹta mẹta wá láti inú ẹ̀yà kọ̀ọ̀kan, n óo sì rán wọn jáde lọ láti rin ilẹ̀ náà jákèjádò, kí wọ́n lè ṣe àkọsílẹ̀ ibi tí wọ́n bá fẹ́ gẹ́gẹ́ bí ìpín tiwọn, lẹ́yìn náà, kí wọ́n pada wá jíyìn fún mi.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fọ́nrán ohùn, Seun Kuti: Kii ṣe Macron ni aarẹ France akọkọ ti yoo kọkọ bẹ Fela wo Funmilayo Ransome Kuti wa lara awọn to ja fitafita lati ri i pe awọn obinrin lẹtọ lati kopa ninu idibo lorilẹ-ede yii.
Èmi kò forí ṣọta ìjàmbá ọkọ̀ òfúrufú kankan - Obasanjo Wo àwọn ìlérí tàwọn Gómìnà tuntun ṣe nínú ìbúra wọn Ta ni Babajide Sanwo Olu, gomina tuntun l‘Eko?
Àyọkà yìí tàbí apá rẹ̀ únfẹ́ àtúnṣe sí.
Àwọn ọ̀tá wa sì wí pé, “Wọn kò ní mọ ohun tí ń ṣẹlẹ̀, bẹ́ẹ̀ ni wọn kò ní rí wa títí tí a óo fi dé ọ̀dọ̀ wọn, tí a óo pa wọ́n, tí iṣẹ́ náà yóo sì dúró.
OLUWA ní, “Nítorí pé àwọn eniyan mi gọ̀,wọn kò mọ̀ mí.
Aarẹ Muhammadu Buhari ba awọn ọmọ orilẹede Naijiria sọrọ loni lori wahala to ti jẹyọ pẹlu iwọde #EndSARS to gbode lorilẹede Naijiria.
bí o bá ri wúrà mọ́ inú erùpẹ̀,tí o fi wúrà Ofiri sí ààrin àwọn òkúta ìsàlẹ̀ odò,
” Nígbà náà ni ó wá wí fún arọ náà pé “Dìde, gbé ibùsùn rẹ, máa lọ sí ilé rẹ.
Èèyàn 216 míràn ṣẹ̀ṣẹ̀ kó COVID-19 ní Nàìjíríà Àwọn ará ìlú Ikarẹ Akoko ń ṣọ̀fọ̀ Ọba Adegbite, Ọwá Ale Ikarẹ tó wàjà Bí ìjà bá wà láàrin èmi àti Olubadan, a ó yanjú ẹ ní pẹ̀lẹ́kùtù, ọ̀rọ̀ bàbálọ́jà kò lè dìjà Bàbá ẹni ọgọ́ta ọdún dèrò ilé ẹjọ́ nítorí ó wọ inú oko Obasanjo láì gba àṣẹ Bí ìjà bá wà láàrin èmi àti Olubadan, a ó yanjú ẹ ní pẹ̀lẹ́kùtù, ọ̀rọ̀ bàbálọ́jà kò lè dìjà Wo ọ̀nà tí o le è gbà láti má san àfikún owó iná ẹ̀lẹ́ńtíríìkì tuntun Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Fídíò, Baby abandoned on dunmpsite: Mo ti bímọ mẹ́rin tẹ́lẹ̀ fún bàbá méjì nínú òṣí- Dupe Ogbomọṣọ4 Owewe 2020 Fídíò, Akomolede: Bolaji Faleke ni Olùkọ́ tó ń kọ́ wa ní àṣà oge ṣiṣe lórí BBC Yorùbá1 Owewe 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
láti inú ẹ̀yà Bẹnjamini, ó rán Paliti, ọmọ Rafu; 
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù New Covid 19 update: Ẹ̀yà kòkòrò Covid-19 míràn jáde ní ọgọ́ta agbègbè nílẹ̀ Gẹẹsi, àjọ elétò ìlera fọkàn ará ìlú balẹ̀ 15 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Oríṣun àwòrán, @NCDC Ẹyà kòkòrò Covid-19 míràn yọjú ní ọgọta agbègbè nílẹ́ Gẹẹsi, àwọn eleto ìlera ni k'ara ilu má fòyà.
Agbegbe ẹya Igbo to wa ni Delta lawọn obi Kelvin ti wa, bo si ṣe n sere ni ede Yoruba naa lo n kopa ninu sinima oloyinbo.
lori eto ẹkunwo yii pe, awon ti owo osu won kere pupọ, lo yẹ
Ileeṣẹ ologun orilẹede Naijiria ti fẹsun kan gomina ipinlẹ Rivers, Nyesom Wike pe o gbiyanju lati fi owo ra awọn ọmọ ogun lasiko idibo to waye nipinlẹ Rivers.
Ṣugbọn nígbà tí mo rò bí nǹkan wọnyi ṣe lè yé mi,mo rí i pé iṣẹ́ tíí dáni lágara ni.
OLUWA, ìwọ ni ò ń ṣàánú fún ọmọ tí kò lẹ́nìkan.
Nítorí náà, èmi OLUWA Ọlọrun, ní, ẹ ti jẹ́ kí n ranti ẹ̀ṣẹ̀ yín, nítorí pé ẹ ti tú àṣírí ẹ̀ṣẹ̀ yín, ninu gbogbo ohun tí ẹ̀ ń ṣe ni ẹ̀ṣẹ̀ yín ti hàn; ogun yóo ko yín nítorí pé ẹ ti mú kí n ranti àwọn ẹ̀ṣẹ̀ yín.
Jakande pé 90 láì gba àmì ẹ̀yẹ kankan ní Nàíjíríà -Osoba Ipa tí ìyànsípò Olóòtú ìjọba Gẹ̀ẹ́sì tuntun yóò mú bá ‘Brexit’ Kò sí ìwé ìrìnnà 'VISA' fáwọn ọmọ Naijiria tó hùwà àìtọ́ nígbà ìdìbò Bakan naa, o sọ pe aikawe ọpọ ninu wọn lo ṣokunfa ki ọpọ wọn ti di agbebọn bayii.
Ajọ NCDC naa fi lede loju opo ikansiraẹni Twitter wọn ni Ọjọ Isinmi.
Yóo dínà mọ́ àwọn arìnrìnàjò nítorí níbẹ̀ ni a óo sin Gogu ati gbogbo àwọn eniyan rẹ̀ sí.
Àkọlé àwòrán, Oro ikolu saown ajoji ni South Africa Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Àwọn ọmọ Naijiria sọrọ lori àwọn agbalagba ti wọn n dije dupo aarẹ ni Naijiria lasiko yii.
Nígbà tí ó rí ọba, ó dọ̀bálẹ̀ gbalaja, ó ní, Kábíyèsí, ki Ọlọ́run bùn yín lẹ́mìí, kí Èdùmàrè jẹ́ kí ẹ pẹ́ ní orí ilẹ̀ ayé.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Pistachio Green Puppy: Àwọn ẹgbẹ́ rẹ̀ jẹ́ aláwọ̀ funfun, tí òun sì jẹ́ aláwọ̀ ewé Kini a le sọ nipa iku Fatai Rolling Doller?
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìdí ti àwọn kọmísọna ṣe to láti kí ìyáwó gómìnà tuntun káàbọ̀ 2 Owewe 2019 Oríṣun àwòrán, Shaharudeen Galaje Àkọlé àwòrán, Gbogb àwọn amúgbálẹgbẹ́ gomina Bauchi àti àwọn kọmisona ló dúro wámuwámu de aya tuntun gomina ṣeṣẹ fẹ́ Ọkan nínú àwọn tó dúro sí pápakọ ofurufu láti gba ìyáwo tuntun ọmọ Lẹbaniisi tí Gomina Bauchi ṣẹṣẹ fẹ́ sàlàyé pé kò sí ǹkan ti awọn ń se ju pé àwọn ń tèle àṣà àti ìṣe.
Mo bá gba ife náà lọ́wọ́ OLUWA, mo sì fún gbogbo orílẹ̀-èdè tí OLUWA rán mi sí mu: 
Ni ọdun 1983 si 1985, Ọgagun agba Muhammadu Buhari pẹlu igbakeji rẹ, Oloogbe Ọgagun agba Tunde Idiagbọn k'ara bọ yiyọ awọn awọn oloṣelu kan ti wọn si dojukọ gbogbo iwa ibajẹ ti gbongbo ti gbongbo.
Kìnìhún joko jẹ ẹran ara afurásí ọdẹ tí kò gbààyè kó tó ṣọdẹ
Ẹni mímọ́; tí kò ní ẹ̀tàn, tí kò ní àbùkù, tí kò bá àwọn ẹlẹ́ṣẹ̀ kẹ́gbẹ́, tí a gbé ga kọjá àwọn ọ̀run.
NLC: Àwọn olósèlú ń la títì láì sanwó osù torí owó tí wọn yóò rí lórí àkànse isẹ́
Oríṣun àwòrán, Instagram/toyin_abraham Laipẹ yii ni osere tiata naa bi ọmọkunrin kan to pe orukọ rẹ ni Ire, ti ọpọ eeyan si n ki ku oriire.
OLUWA fúnrarẹ̀ ti tú wọn ká,kò sì ní náání wọn mọ́.
Restructuring: Àgbékalẹ̀ orílẹ̀èdè Nàìjíríà lọ́wọ́ yìí kò lè fàyè ìdàgbàsókè sílẹ̀ fún ẹ̀yàkẹ́yà-Ọ̀jọ̀gbọ́n Banji Akintoye
Wọn yóo fi ọ̀kan rú ẹbọ ìmúkúrò ẹ̀ṣẹ̀, wọn yóo sì fi ekeji rú ẹbọ sísun.
Ejo ati aja naa ko gbẹyin ninu awọn ẹranko to n sekupa eniyan lọdọọdun.
"A ń fikunlukun pẹ̀lú FBI láti mú àwọn ""Yahoo Boys"" tó kù- EFCC Eyi lo wa n faa ti ọpọ fi n ṣebeere boya ohun rere kan tilẹ lee ti Nasarẹti yii jade?"
Ó ní ìwo mẹ́wàá ati orí meje.
Wọ́n gbadura pé, “Ìwọ Oluwa, Olùmọ̀ràn gbogbo eniyan, fi ẹni tí o bá yàn ninu àwọn mejeeji yìí hàn, 
Obinrin naa ke gbajare si ijọba Naijiria ati ijọba agbaye lati gbawọn lọwọ awọn ajinigbe ni kiakia.
Safar: Oṣu keji ọdun ree, o tumọ si ifayegba, nitori oṣu yii lawọn larubawa maa n ṣe ikọlu sawọn ilu to ba wa lagbegbe wọn laye atijọ.
Bẹẹ ni wọn ni awọn olujọsin gbọdọ tẹle ilana bi wiwọ ibomu,fifọ ọwọ ati ijinasiraẹni lasiko ti wọn ba n kirun.
Lọjọ kẹtadinlogun oṣu kẹta 2020 yii ni ile igbimọ aṣoju-ṣoju gbe igbimọ kan kalẹ lati ṣe iwadii afikun owo tariifu DSTV ni Naijiria.
Iroyin to kọkọ jẹ jade lowurọ ọjọ Ẹti ni pe idi ti awọn kan fi lọ buwọlu iwe pe awọn yọ gomina Fayemi ni pe o ṣiṣẹ tako oludije sipo gomina labẹ ẹgbẹ oṣẹlu APC, Pasito Ize Iyamu ninu idibo sipo gomina to lọ ni Edo.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Àwọn òṣìṣẹ́ pápákọ̀ òfúrufú MMA2 ṣẹ́welé ìyansẹ́lódì ‘Ọbasanjọ àti Atiku yóò jọ pàdánù nínú ìbò Ààrẹ’ Taa ni Jọkẹ Silva, òsèré tíátà tó ń se ọjọ́ ìbí ?
Nítorí nǹkan ti ara wọn ni gbogbo àwọn yòókù ń wá, wọn kò wá nǹkan ti Jesu Kristi.
Addo: Atunto n bọ ni ileesẹ ọlọpa Ghana laipẹ
Ọga Bello - BBC News Yorùbá BBC News, YorùbáFò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Yolllywood: Ọlọ́run ló kọọ pé àwọn ọmọ mi yóò ṣiṣẹ tíátà, èmi kọ lo kàn-án nípa fún wọn - Ọga Bello 17 Ìgbé 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 28 Ìgbé 2020 Oríṣun àwòrán, Oga Bello Àkọlé àwòrán, Ọlọ́run ló kọọ pé àwọn ọmọ mi yóò ṣiṣẹ tíátà, èmi kọ lo kàn-án nípa fún wọn - Ọga Bello Àgbà osere tíátà Adebayo Salami, tí ọ̀pọ̀ èèyàn mọ si ọga Bello, tí sọ ìhà tó kọ sí bí àwọn ọmọ bibi inú rẹ, se ń ba se ere tíátà.
 yorùbá pó ́ ńbélé ni ọ ̀ pọ ̀ àwọn òlùgbé Ògbómọ ̀ sọ ́ .
Eyi lo mu ki itan tọkọtaya Imudia paapaajulọ arabinrin Oluwakẹmi Uduehi to bi ọmọ marun lẹẹkan ṣoṣo.
 wọ ́ n rìn títí tí wọn fi dé igbó Àkúrẹ ́ , ibí ni wọ ́ n ti bá wọn pa erin .
Iléesẹ̀ Ọlọ́pàá: Ọlọ́pàá 22 farapa nínú ìkọlù Shiite
Kíni N11trn owó ìrànwọ́ epo tí ìjọba àpapọ̀ san fún àwọn agbépo lè rà?
Ìlé-ayé yìí kún fún nkan àdìtú àti ìyanu.
Àwọn alufaa ati àwọn ọmọ Lefi bá ya ara wọn sí mímọ́ láti gbé Àpótí Majẹmu OLUWA Ọlọrun Israẹli.
Ní orílẹ̀èdè Ghana, wọ́n ti se ìfilọ́ọ́lẹ̀ ìwádìí tí yóò máa se ọ̀fintótó àwọn ọmọ̀ ilé ìwé girama ní ààrin gùngbùn Ashanti tí àwọn olùkọ́ wọ́n ńfipá bá lò pọ̀.
Bó tilẹ̀ jẹ́ pé díẹ̀ ní àbádofín yìí fi yàtọ sí èyí ti àwọn ọmọ ilé ìgbìmọ asofin àgbà to kọja ṣe àgbékalẹ rẹ̀, sùgbọ́n Musa ni bí ayélujára ṣe ń ràn ìṣẹ̀jọba lọ́wọ́ ni àwọn ènìyàn ń lòó láti ṣe akóba fun ọmí aláafíà Naijíríà, nítori náà o ṣe pàtàkì láti mójú tóo.
Ninu gbogbo ohun tí ó ṣẹlẹ̀ yìí, Jobu kò dẹ́ṣẹ̀, kò sì dá Ọlọrun lẹ́bi.
Ayọ̀ ń bẹ fún ẹni tí ó bá gbẹ̀san lára rẹ,fún gbogbo ohun tí o ti ṣe sí wa!
soro ni ipinle Gombe,pe awon se ipinnu ohun lati satileyin fun oludije naa
Oríṣun àwòrán, Babajide Sanwoolu Àwọn iléeṣẹ́ àdáni tí Sanwoolu ti ṣe adarí Gomina tuntun ti ajọ INEC kede náà jẹ́ alága iléeṣẹ́ Baywatch Group Limited àti First Class Group Limited nígbà kan rí.
Ó mú mi rántí nkan tí ẹnìkan wí lóri Twitter níjọ́sí.
"Amọ Akeugbagold ni ""obinrin naa lo n na awọn ọmọ mi ni anajati lasiko ti wọn wa ni akata rẹ, irọ si lo n pa pe ko mọ ohunkohun nipa iṣẹlẹ naa."
Ó gbé ọwọ́ rẹ̀ sókè, ó súre fún wọn.
Iroyin Kayeefi BBC Yoruba toṣu kẹjọ, ọdun yii da lori lọkọlaya Saidi ati Bọsẹ ti wọn n fojoojumọ ja ninu ile ni Akurẹ nipinlẹ Ondo.
aare orile ede Ghana, Nana Addo Dankwa Akufo-Addo, ati oludari ijoba orile ede
 ( ojoibi march 1 , 1927 ) je akorin , osere ati ati alakitiyan awujo ara amerika .
Iru mudunmudun wo lo ba awọn owo ifẹhinti yii wa, eyi to yẹ ki a dijọ yẹ wo lawọn ipinlẹ kọọkan lorileede Naijiria, ti iru eto yii wa fawọn to ti fi ipo oselu silẹ Kwara: Lọdun 2018 ni ijọba ipinlẹ Kwara mu ayipada ba ofin to de sisan owo ifẹyinti fawọn to ti jẹ Gomina tabi igbakeji wọn ni ipinlẹ naa.
Ìdí rẹ̀ tí a fi fi Àpáta-ìgbẹ̀yìn ṣe Gómìnì ibẹ̀ ni pé òun jẹ́ ẹni líle, kò ní gba ìwọ̀sí fún àwọn Èdìdàrẹ́, nítorí wọn kò gba ojú bọ̀rọ̀.
Ọna si jin lori ọrọ ibo yii.
"Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: ""Ẹ̀yin obìnrin, ẹ lọ kọ́ iṣẹ́ káfíńtà torí ó lówó lórí ju iṣẹ́ aránṣọ lọ"" Àwọn obìnrin yarí, wọ́n kò fẹ́ àwọn ọkùnrin ní òde ijó wọn Pàtàkì ọdún Ojúde Ọba fún ìran Yorùbá Lórí ìmọ̀ràn Sunday Igboho, Ẹlẹbubọn ní yóò dára kí Yorùbá padà sí àmúlò èròjà ìbílẹ̀ fún ààbò O ní àwọn kọgila tó dáńtọ́ tí wọ́n sì mọ iṣẹ́ wọ́n bi iṣẹ́ tí akọsílẹ̀ sì ti fi hàn pé wọ́n kìí fi iṣẹ́ wọ́n ṣere ni àwọn yóò kọ́kọ́ gbé iṣẹ́ fún ní kété ti ìjọba bá ti bẹ̀rẹ̀ iṣẹ́ òde."
Oríṣun àwòrán, others Awọn ti ọrọ naa ṣẹlẹ loju wọn ṣalaye pe Blake n pẹtu si ija laarin obinrin meji k'awọn ọlọpaa to bẹrẹ sí ni yin taju taju.
Idi ni pe lọla ode yii ni idajọ yoo waye nile ẹjọ giga ilu Akure lori ẹsun ijọmọgbe ti wọn fi kan Alfa Babatunde ati ọmọ ijọ rẹ mẹfa miran.
Oluṣọ agutan naa ni àwọn kìí sọrọ̀ lóri ìrírí olúkulúkù nítori onikaluku lọ mọ apá ibi ti wọ́n ti n gbọ́ ìmísi.
bi awon ikọ oloogun ati agbofinro se pọ ni ibudo idibo ni eyi ti o n da ẹru ba
Chelsea dìgbájú ru Watford bí olè tó jí ike owó Ọlọ́pàá ń gbé Adeleke lọ ile ẹjọ́ lónìí Àwọn ọmọge wọ gàù l'Abuja nítorí asọ péńpé Ẹwẹ, akọnimọọgba ikọ Liverpool, Jurgen Klopp ti sọ pe ẹru ko ba odo ẹgbẹ agbabọọlu naa bo tilẹ je pe awọn ẹlẹsẹ ayo meji Mohamed Salah ati Roberto Firmino ko ni le kopa ninu ere bọọlu ọhun lẹyin ti wọn farapa.
Niluu Watford lorilẹede England, ni wọn ti bi Joshua lọjọ kẹẹdogun oṣu kẹwaa ọdun 1989, amọ bi iṣu lo maa jẹ orilẹede Naijiria lẹnu.
Bakan naa ni ọga ọlọpaa naa paṣẹ fun olu ilu ileeṣẹ ọlọpaa ni ilu Abuja lati tu ikọ SARS ti Abuja ka.
Ẹgbẹ awọn ọmọlẹyin Kristi ni orilẹede Naijiria, CAN lo kede to si ni asiko to fun awọn gbogbo igun ati ijọ lati pa ohun pọ sọrọ lori awọn ipaniyan yii.
nibi agọ idibo to wa ni Lateef Jakande ni ipinlẹ Eko.
Ijọba ilẹ naa ti gbe ilana kalẹ lori awọn ohun to yẹ ki awọn ile iwe ṣe lati dabo bo awọn akẹkọọ.
Kò sí ẹni tó lè sọ bóyá ìṣẹ̀lẹ̀ ìjàmbá ọkọ̀ òfurufú yìí níi ṣe pẹ̀lú ọ̀rọ̀ tó n ṣẹlẹ̀ láàrin America àti Iran.
Oríṣun àwòrán, Facebook/Adekunle Abdulkabir Akinlade Àkọlé àwòrán, Gomina Ibikunle Amosun n gbero lati pada si ile asofin gẹgẹ bi Seneto lọdun 2019 Ẹwẹ,Gomina ipinlẹ Oyo, Abiola Ajimọbi naa ti ni oun ati awn eekan ẹgbẹ yo pa'mọranpọ lati yan ẹni ti yoo soju ẹgbẹ ninu idije Gomina lọdun 2019.
Adari iko banki agbaye, Patrizio Paganolo seleri yii lasiko ti iko naa se ipade pelu igbakeji aare orile ede Naijiria ojogbon Yemi Osinbajo.
Adehun Theresa May pẹlu EU lori Brexit pin si meji, ipinnu ti ofin de nipa kikuro ninu EU tabi ipinnu ti ofin ko de.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Secret Cults in Nigeria: Ìyá àti ọmọ tó wà nínú Márúwá bá ìjà ẹgbẹ́ òkùnkùn lọ 9 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 10 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Ko din ni ogun eeyan to dagbere faye nigba ti ọpọ miran fi ara gbọgbẹ lorisirisi lasiko tawọn tawọn ẹgbẹ okunkun fija pẹẹta nilu Ijebu Ode.
 nípa iṣẹ ́ bọ ́ ọ ̀ lù rẹ ̀ , ó jáwé olúborí tí ́ ó sì gba ife-ẹ ̀ yẹ grand slam mẹ ́ ta , èyí tí ó sò di ìkan nínú àwọn tó dára jùlọ nínú tenis ní amẹ ́ ríkà .
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ẹ̀mí kan náà ló n darí ìrìnàjò wa táa fi jọ kọ́lé papọ̀- Ìbejì Ileeṣẹ iroyin naa ni pe Onyema ni ẹsun ti wọn fi kan oun tako iru eeyan t'oun jẹ ati pe oniṣowo to wa ilọsiwaju orilẹ-ede Naijiria ni oun.
Ìdí rèé tí mo fi gbàdúrà ìyàwó bí Chanel Chin fáwọn tó d'ẹ̀bi ìkọ̀sílẹ̀ rẹ̀ rù mí- Oluwo Oral Sex: Bóo bá ń gba ẹnu ní ìbálòpọ̀, wo àìsàn tóo lè kó lójú ara rẹ 'Nínúu kí a yọ oyún inú rẹ tórí iṣẹ́ abẹ tàbí kóo wà nínú ìrora' Oyenusi ló mú mi wọ ẹgbẹ́ adigunjalè kó tó di pé mo b'Ólúwa pàdé - Kayode Williams 'Gómìnà Akeredolu ló wà nídí ìgbésẹ̀ yíyọ igbákejì rẹ̀, ìdí wàhálà wa nìyí' Otunba Alao-Akala to ṣe ọjọ ibi aadọrin ọdun loke eepẹ laipẹ yii ni igbesẹ oun lati ma dije fun ipo gomina mọ yoo f'oun lanfaani lati ṣiṣẹ ipẹtu si aawọ ti gomina ipinlẹ Oyo tẹlẹ, oloogbe Abiola Ajimobi gbe le oun lọwọ daadaa.
Kò sí oúnjẹ, kò sì iná, ẹ wá fẹ tí àwọn èèyàn mọle, kò leè ṣeé ṣe, èmi kò sì mọ bí ijọba wá ṣe fẹ ṣe.
Ó sọ ọmọ náà ní Beraya nítorí ibi tí ó dé bá ìdílé wọn.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Balogun market fire: Olubadamọran gomina sọrọ lori ina náà Nigba ti BBC n fidi ọrọ naa mulẹ fun wọn lati fihan pe obinrin yii gbe ṣhiṣha wọle ni wọn fi nọmba ọga miran silẹ lati ba sọrọ ṣugbọn gbogbo igbiyanju wa ja si pabo lati ba ẹni naa sọrọ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Black women live matters: Ọdún 2015 ní àwọn ọlọ́pàá pa India Kager láìní ìdí- Gina Best Bákan náà ní òṣìṣẹ́ tó ń sùn lẹ́nu iṣẹ́ n kó ìnira bá àwọn òṣìṣẹ́ to kù ni, nítorí àwọn kan ló ń ṣe iṣẹ́ rẹ̀ lásìkò tó n sùn.
Bakan naa ni wọn wa rọ ijọba lati ba wọn se atunsẹ oju ọna naa ti o ti bajẹ patapata.
Aare wa dupe lowo awon egbe  BSG fun atileyin won lasiko to n dije fun ipo aare lodun 2015 titi di asiko to wa lori aleefa yii, o ni atileyin won ni se pelu  emi ifokansi  ati igbagbo ti won ni ninu orile ede yii.
A fẹ́ kí ìtara yín túbọ̀ pọ̀ sí i nípa ṣíṣe iṣẹ́ ìfẹ́ pẹlu.
Olori ile asofin ni ipinlẹ Oyo, Adebo Ogundoyin nigba to n sọrọ lori ofin naa ni, ikọ amọtẹkun yoo bẹrẹ iṣẹ lẹyin ọṣẹ diẹ si akoko yii, tawọn gomina ba sọ di ofin.
Ajọ naa gbe atẹjade naa jade ni Ọjọbọ ninu eyi to ti ṣalaye wipe ni ọdun 2018 nikan, ọmọde to le ni irinwo ni o ku sinu laasigbọ ọke ọya.
Ṣugbọn Jesu sọ pé, “Ẹ jẹ́ kí àwọn ọmọde wá sọ́dọ̀ mi; ẹ má dí wọn lọ́nà, nítorí ti irú wọn ni ìjọba ọ̀run.
Maa sọ fun Buhari ko jawọ ninu oṣelu Awọn kan to tun kopa ninu ibeere naa ni awọn yoo gba aarẹ Buhari ni iyanju tabi sọ fun pe ko fẹhinti ninu oṣelu, ko si pada si ilu rẹ, Daura nipinlẹ Katsina.
Ara Isaaki bẹ̀rẹ̀ sí gbọ̀n gidigidi, ó wí pé, “Ta ló ti kọ́ pa ẹran tí ó gbé e tọ̀ mí wá, tí mo jẹ gbogbo rẹ̀ tán kí o tó dé?
Ronaldo fi góòlù mẹ́ta bẹ̀rẹ̀ ọdún 2020 pẹ̀lú Cagliari
Yóo gba ilẹ̀ oko yín tí ó dára jùlọ ati ọgbà àjàrà ati ti olifi yín, yóo sì fi fún àwọn iranṣẹ rẹ̀.
” Oloogbe pasito Power Aginighan wa lati ipinle  Delta .
OLUWA yóo mú ìfẹ́ rẹ̀ ṣẹ lórí mi,OLUWA, ìfẹ́ rẹ tí kì í yẹ̀ wà títí lae.
Beckham, àgbábọ́ọ́lù tẹ́lẹ̀ rèé tó ń sọ èdè Yorùbá Champions League: Ajax f'imú Tottenham fọn fèrè Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, '500 level'' ni mo wà nígbà tí mo di adélé Ọba' Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Helen Paul sọ idi tó fi gba orúkọ ní kékere Ṣugbọn Glenn Murray dayo ọhun pada lẹyin to yẹ ile Arsenal pẹlu pẹnariti ti wọn fun ẹgbẹ agbabọọlu Brighton.
Gbogbo àwọn obinrin tí ọ̀rọ̀ náà jẹ lógún, tí wọ́n sì mọ irun ewúrẹ́ ran, ni wọ́n ran án wá.
Akosile ate ohun fihan pe, Seplat dipped je N13.
Absalomu bá pe àwọn iranṣẹ rẹ̀, ó sì wí fún wọn pé, “Oko Joabu wà lẹ́gbẹ̀ẹ́ tèmi, ó sì gbin ọkà baali sinu rẹ̀, ẹ lọ fi iná sí oko náà.
Ni ilu Eko, ọtalenirinwo o din mẹwa naira lowo tawọn arinrinajo n san fun ayẹwo Covid-19.
Oyewọ fikun pe ijọba fẹ gbe igbesẹ naa nifọwọkọwọ pẹlu awọn asaaju ẹsin, awsn ẹlẹgbẹjẹgbẹ lawujọ ati awọn ẹgbẹ alaanu gbogbo.
"N ko tiẹ mọ ohun ti eeyan lee sọ, amọ mo kan n jẹrora ninu ọkan mi ni, ti mo si n woye pe bawo ni wọn yoo se yẹgi fun obinrin akẹẹgbẹ mi?
Omíyalé àgbàrà ti ya ṣọ́ọ̀bù ní Niger Wọ́n gbé Akọ̀ròyìn ní Morocco lọ sílé ẹjọ́ lórí ẹ̀sùn àgbèrè àti oyún ṣíṣẹ́ Ṣé lóòtọ́ ni PDP fẹ́ kẹ̀yìn sí Gómìnà Seyi Makinde nípínlẹ̀ Oyo?
Ijinigbe bi eleyii ko ṣẹṣẹ maa waye lorilẹede Naijiria to fi mọ iha Guusu-Iwọ Oorun Naijiria eyi ti ipinlẹ Ọṣun wa.
Garba Shehu wa so pe, bi oloye Obasanjo se so ninu iwe ti
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ìwà ìkórííra n pọ̀si ní orílẹ̀èdè South Africa Àwọn tí ìsẹ̀lẹ̀ náà sojú wọn sọ pé Nwaogu rawọ́ ẹ̀bẹ̀ s'áwọn ọlọ́pàá sùgbọ́n wọ́n kọ etí ikún síi.
Tambuwal wọlé fún sáà kejì ní Sokoto Gómìnà Aminu tambuwal ti ipínlẹ̀ Sokoto ti lewaju ninu àtúndì ìbò gómìná tó wáyé lánàá ọjọ́ Satide.
Igba akọkọ kọ niyi ti iru igbẹjọ bẹ waye ni India, akọsilẹ ijọba nipa iwa ọdaran ni ọdun 2016 fihan pe ẹgbẹrun mẹwa le ni mejidinlaadọrin iru iwa ifipabanilopọ lo waye lati ọdọ ẹni ti obinrin mọ tp ṣe adehun lati fẹ ẹ sile bi iyawo.
Latari eyi lori ẹ̀rọ ayelujara, awọn eniyan tun fesi lori eyi to sẹ̀ jẹ jade latẹnu pasitọ Adeboye.
 Àwọn àjẹsára táífọ ́ ọ ̀ dù wà lórí Àkójọ Àwọn egbògi kòṣeémáàní ti Àjọ Ìlera Àgbáyé , àwọn òògùn tó ṣe pàtàkì jùlọ tí a nílò fún ètò ìlera ìbẹ ̀ rẹ ̀ pẹ ̀ pẹ ̀ yòówù iye owó rẹ ̀ lójú pálí jẹ ́ bíi 4.
Nígbà tí àwọn amòfin ninu àwọn Farisi rí i tí ó ń bá àwọn ẹlẹ́ṣẹ̀ ati àwọn agbowó-odè jẹun, wọ́n bi àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ léèrè pé, “Kí ló dé tí ó fi ń bá àwọn agbowó-odè ati àwọn ẹlẹ́ṣẹ̀ jẹun?
Àwọn mẹtẹẹta pinnu láti lọ mọ ikú wọ́n múra o di ìdí ìrókò.
Odekunle si lo jẹ ọkan lara awọn ikọ olubadamọran fun Aarẹ Buhari lori igbogun ti iwa jẹgudujẹra lawujọ, Presidential Advisory Committee Against Corruption, PACAC.
O fikun oro re pe, omi oyan se koko fun awon omo owo ti o sese bere igbe aye tuntun, ti o si le so boya omo yoo wa laye tabi ikeji.
iná ati yìnyín, ati ìrì dídì,ati ẹ̀fúùfù líle tí ń mú àṣẹ rẹ̀ ṣẹ.
Nítorí náà, jẹ́ kí á mú ọ̀kọ̀ rẹ̀ ati ìgò omi rẹ̀ kí á sì máa lọ.
Alukoro fun ile iṣẹ ologun ofurufu, Commodre Ibikunle Daramola to fidi ọrọ naa mulẹ Iroyin sọ pe nigba ti o n bọ lati oko rẹ lopópónà Keffi sí Abuja ni wọ́n tí dáa lọ́nà tí wọ́n sí dá ẹ̀mí rẹ̀ légbodò.
Ibojì tí ó yanu sílẹ̀ ni ọ̀nà ọ̀fun wọn, ẹ̀tàn kún ẹnu wọn;oró paramọ́lẹ̀ wà létè wọn;
Afomo ti omidan Abdel Wahab fi sawada ohun je kokoro kan ti n gbe ninu omi , ti o si maa n dagba lara eniiyan.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Larisa: Má jẹ́ kí ọjọ́ orí rẹ dí ẹ lọ́wọ́ láti bẹ̀rẹ̀ ohunkóhun to wù ọ New Moni Tọpe Ọshin lo ṣe fiimu yii sita ninu eyi ti Jemima Osunde ti kopa olu ẹda itan rẹ akọkọ.
Lẹyin ti ijọba apapọ yọ owo iranwọ ori epo tan lo ṣe afiukun owo epo bẹntiro lati N145 si N161 to wa bayii.
Olori ile sọ pe awọn arakunrin kan tawọn ko mọ ri darapọ mọ wọn lati yi ọkọ oun ka eyi lo si mu ki awọn ẹsọ yin ibọn soke.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ta ni yoo jẹ akọn Ẹgbẹ agbabọọlu naa ki Mourinho fun iṣẹ to ṣe nigba ti o fi ṣe olukọni Manchester United.
Oríṣun àwòrán, ICIR Ohun to lo mu iwa bẹẹ wa ni pe wọn ko tete fun oun ni iwe irinna pasipọọti lẹyin ti oun ti kọwe lati gbaa.
O ni o tẹ́ oun lọrun lati gbiyanju wo boya oun a wọle tabi bẹẹ kọ ju ki oun kan fọwọ lẹran lasan lọ lasiko yii.
Lasiko ta n wi yii, Stationery Stores ti orukọ ipilẹ rẹ jẹ Adebajo Babes jẹ ẹgbẹ agbabọọlu Naijiria akọkọ ti yoo kopa ninu idije African Champions Cup ti a mọ si CAF Champions League lonii.
Àwọn ni Ọlọrun yàn bí ọmọ rẹ̀.
Gege bi awon ile-ise akoroyin miran, won ni, Bush ti n ba aisan okan fin ra lojo to ti pe, leyi ti o le sokunfa iku re.
Eto arinyanjiyan yii yoo fun awon oludije naa ni anfaani lati faju awon oludibo mora.
Orile-ede Botswana ti ro Aare orile-ede Democratic Republic of Congo (DRC), Joseph Kabila, lati fi ori alefa sile.
’ Lórí ìmọ̀ràn Sunday Igboho, Ẹlẹbubọn ní yóò dára kí Yorùbá padà sí àmúlò èròjà ìbílẹ̀ fún ààbò Sowore takú, kò jẹun ní àgọ́ ọlọ́pàá torí májèlé - Deji Adeyanju Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, ''Ọjà ẹran àgbò kò yá bí ti ọdún tó lọ'' Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Oro Festival: Àwọn olórò ní ọdún Màgbó ló ń gba ibi lọ, kó ire wọlé ní Ikorodu Buhari iwa apanle ni ipenija to tobi julọ to n koju ẹsin musulumi lagbaaye bayii, aarẹ ni ọna kan gbogi lati din ipa buruku iwa yii ku ni pe koni kaluku yago fawọn waja awọn ti ko mọ wọ ti mẹ sẹ.
Ni ayajọ ọjọ nla ninu itan America to jẹ ọjọ isin ọpẹ tọdun 2019 ni Trump ti ṣabẹwo sawọn ọmọ ogun naa.
O ṣapejuwe Kabiyesi bayii, “Baba jẹ akikanju olori ti iṣakoso wọn ti mu ọpọ oriire ba ipinlẹ yii, ti a ko le gbagbe lae ninu itan orilẹ-ede yii ni gbogbo ipele iṣakoso, ni ti ọrọ-aje, aabo ilu ati awọn miiran.
Àwọn ọmọ Ana ni, Diṣoni ati Oholibama.
Oríṣun àwòrán, Twitter/aminuyaro_ O ni awọn yoo gbe igbimọ araalu atawọn alẹnulọrọ kalẹ lati pese anfani fawọn araalu lati maa foju gaani ati lati maa gba awọn alaṣẹ ileeṣẹ ọlọpaa lori awọn ọrọ nla to kan araalu.
Ṣugbọn Jesu kọ̀ fún un, ó sọ fún un pé, “Lọ sí ilé rẹ, sọ́dọ̀ àwọn ẹbí rẹ, kí o sọ ohun tí Oluwa ti ṣe fún ọ ati bí ó ti ṣàánú rẹ.
Cedar College, Lagos: Ilé ìwé wa kọ́ ni Favour kú sí
Kò sí ìgbàlà lọ́dọ̀ ẹlòmíràn; bẹ́ẹ̀ ni kò sí orúkọ mìíràn tí a fi fún eniyan lábẹ́ ọ̀run nípa èyí tí a lè fi gba eniyan là.
yóo pàṣẹ pé kí wọn yọ àwọn òkúta tí àrùn wà lára wọn, kí wọ́n kó wọn sí ibìkan tí kò mọ́ lẹ́yìn ìlú.
00 ) ni wọ ́ n bá ní ilé Àṣàkẹ ́ , ìyẹn ìyá bándélé nígbà tí àwọn akin Ọlọ ́ fìn-íntótó yẹ ilé rẹ ̀ wò .
A ti fa ògo yín ati ohùn hapu yín sinu isà òkú.
Asimafeti, ará Bahurumu, ati Eliaba ará Ṣaaliboni; 
Ẹni ọgọrin ọdun ni baba Haruna Igboro.
àṣírí míì tú síta 7 Agẹmo 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 12 Agẹmo 2020 Oríṣun àwòrán, @officialEFCC Igbimọ ti aarẹ Buhari gbekalẹ fun iṣewadii gbigba awọn owo ilu ti wọn lu ni ponpo pada (PCARA) ti fẹsun kan pe orukọ pasitọ ni alaga ajọ EFCC ti wọn jawe lọ sinmi fun fi na awọn owo ti wọn lọ ẹsun rẹ mọ ọ lẹsẹ loke okun.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ondo: Dejí sun ọmọ méje àtagbalagba meji mọ́lé nítorí pé ó ń bínú Nigba ti ikọ iroyin BBC Yoruba kan si olori eto iroyin fun ipolongo ibo gomina Seyi Makinde, Ọmọọba Dọtun Oyelade, o sọ fun wa pe ijọba yoo fi akọsilẹ iroyin nipa igbesẹ rẹ ọhun sita laipẹ.
Nígbà tí wọ́n gbé e fún ọ̀mọ̀wétí wọ́n ní, “Jọ̀wọ́ bá wa kà á.
Nígbà tí ó jẹun tán, ó ní agbára nítorí pé kò tíì jẹun, kò sì mu omi fún ọjọ́ mẹta sẹ́yìn.
 láìmọ ̀ pé ère arárọ ̀ míre tí ó maa ń gbé ire fún ènìyàn tí ó bá ri fún ọdún meje pẹlú ìyà ọdún méje míràn tí ó tẹ ̀ le .
Ní ìdàkejì, Dele Adeleke tó jẹ́ àbúrò Ademọ̀la Adeleke bu ẹnu àtẹ lu ẹ̀sùn náà ó sì gba àwọn tó kọ̀ láti wá àrídájú ìwé ẹ̀rí Sẹ́nétọ̀ náà níyànjú wí pé ṣé ẹ rò wí pé ẹgbẹ́ òṣèlú APC kò ti ní gbé ọ̀rọ̀ náà síta bí kò bá ní àwọn ìwé ẹ̀rí tó dájú?"
Aisaya bá tún bèèrè pé, “Kí ni wọ́n rí ninu ààfin rẹ?
Àkọlé àwòrán, Nguma ni awọn soja orilẹede Cameroun se asemase pelu oun ati awon obirin miran.
Atakumosa East Ọjọ Iṣẹgun 25/08/2020 4.
Awọn agba ijoye naa, ti wọn tẹle owe Yoruba to ni ọba meji kii wa ni aafin, bi o tilẹ jẹ pe ijoye lee pe mẹfa laafin, ni wọn de fila lasan ati ilẹkẹ sọrun lai de ade sori, to si jẹ pe Olubadan nikan ni ade wa lori rẹ.
Awon iko omo-ogun ofurufu LAFIYA DOLE ti orile ede Niger pelu iko omo –ogun ofurufu orile ede Naijiria ti ju ado oloro ofurufu sibi ti awon iko olote Boko  Haram fi se ibugbe  ni Arege ati Tumbun rago ni ipinle Borno to je ariwa orile ede Naijiria.
Wo àwọn irọ́ ti ọ̀pọ̀ ń pa nípa Coronavirus!
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Kloe: Èmi kìí mu òògùn olóró, àmọ́ mo fẹ́ràn láti máa wà lẹ́bà omi Enidem wa fidi rẹ mulẹ pe awọn agba amofin to to ogun niye ni yoo maa soju Atiku ati PDP ninu ẹjọ naa pẹlu afikun pe ọjọ Isẹgun oni ni ofin pa lasẹ pe ko si anfaani mọ fun oludije lati pẹjọ lẹyin ikede esi ibo.
Rape cases in Nigeria: Ọmọ ọdun 5 àti 14 ni Kalu wà nígbà tí obìnrin fipá ba lòpọ̀
 bákan náà bí a bá ń sin òkú àgbàlagbà ó lè jẹ ́ ìyá , bàbá , tàbí ẹ ̀ gbọ ́ n ẹni .
àánú rẹ̀ sì wà láti ìran dé ìranfún àwọn tí ó bẹ̀rù rẹ̀.
Lẹyin ti ẹgbẹ agbabọọlu Lille ta Pepe ni Osimhen darapọ mọ ikọ ọhun lati ikọ Charleroi, to wa lorilẹ-ede Belgium.
Ènìyàn kán kú, méje farapa nínú ìjàmbá afárá Otedola ní Eko Àwọn ìbejì mi kò le rìn dáadáa nítorí ọgbẹ́ tí wọ́n dá sí wọn lára ní ìgbèkùn - Akeugbagold Àfi ìgbà tí mo bọ́ sọ́wọ́ ọ̀tá mí nínú ìrìnàjò ìfẹ́- Roshan Àgbéyẹ̀wò àṣà: Ìdí tí Yorùbá kìí fí tufọ ikú òjìji fún èèyàn Ẹgbẹ oṣelu APC, lati ipasẹ akọwe Alakoso ẹgbẹ, Emma Ibediro, wa tun kede pe, oludije to ba nifẹ lati kopa ninu idije abẹnu fun ipo gomina naa ni Ipinlẹ mejeeji, yoo san miliọnu mejilelogun ati abọ naira, owo fifi ifẹ lati dije han ati owo fọọmu idije.
Kò tíì sí àrùn Coronavirus ní ìpínlẹ̀ Oyo, a ṣi ń retí èsì àyẹ̀wò - Ijọba Oyo Ni ọjọru ni ijsba apapọ kede pe ko ni si aye fun awọn arinrinajo lati orilẹede mẹtala kan lati wọ orilẹede Naijiria.
Àkọlé àwòrán, Ọbọ yi lo ṣeku sibi igbafẹ ilu Ikogosi, lẹyin ti ijọba ologun paṣe pipa awọn ẹranko to wa nibẹ, lẹyin ti kiniun ṣe'kupa arinrinajo to wa gbafẹ.
Ẹgbẹ Afenifere, to duro lori pe atunto orile-ede yii ni ojutu si iṣoro to n koju Naijiria, sọrọ yii lẹyin ipade awọn olori ẹgbẹ naa lọjọ Aje labẹ alaṣẹ Oloye Reuben Fasoranti.
Oríṣun àwòrán, @bukolasaraki Àkọlé àwòrán, Ajọdun Dubar nilu Ilọrin Lara awọn to peju sibi ajọdun naa ni Waziri ilu Ilọrin to tun jẹ aarẹ ile aṣofin agba lorilẹede Naijiria, Sẹnetọ Bukọla Saraki.
Bakan naa lo tun kede ọjọ kọkanlelogun, oṣu Kẹsan an, ọdun 2020 gẹgẹ bi ọjọ ti awọn ile iwe rẹ yoo di ṣiṣi pada.
Ẹ̀rọ-ayàwòrán amóhùnmáwòrán ká ìṣẹ̀lẹ̀ náà sílẹ̀.
Olùdíje ipò gómínà ní Ekiti jáde láyé Rẹ́díò Fayose di títìpa l'Ekiti Ekiti election appeal: Fayẹmi 2, Ẹlẹka 0 Atọmọde ati agba jade fun idibo ni Ekiti Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ekiti Election: Kọmisana feto idibo ni ibo kika si n lọ lọwọ Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Wayii, awọn afọbajẹ ọhun ti ke gbajare si ile ẹjo giga ipinlẹ Osun, lati dẹkun Oluwo ninu yiyẹ aga oye mọ awọn nidii.
Ẹgbẹ oṣiṣẹ n pe fun iwọde gbankọgbi kaakiri orilẹede Naijiria lati tako igbesẹ ti ijọba gbe laipẹ yii lati fi owo kun owo epo bẹntiro ati ina mọnamọna.
Imọran ikéyin lori covid 19 Nitootọ ni ilẹ Afirika ko ni iku ati iṣẹlẹ Coronavirus yii bii tawọn orilẹ-ede agbaye miran ṣugbọn ko tii yẹ ki wọn sinmi.
Jude Ogomegulem Nnabuife Okwuwadiegu Chukwuka ni baba agbalagba ti ayelujara gbe jade to n kọ orin Naira Marley lori Instagram.
O yá fi àmì sí Ayekofẹnifọrọ Dangote: Mo ti gbà $10m ri ní bánkì kí n lè mọ bí o tí ṣé rí lójú Nàìjíríà ló wà nípò kẹfà nínú ewu ikú àìtọ́jọ́ l'ágbàáyé nítorí nkan mímú tó ní ṣúgà Ìdíje bọ́ọ̀lù fa ìtàjẹ̀ sílẹ̀ ní Poly Ibadan Afojusun rẹ ni lati jẹ iwuri fun ọpọlọpọ obinrin si i, lati maa gba bọọlu.
- Trump Soyombo to ti kọ́kọ gba ẹkọ nípa bi ẹni to ni ààrun ọpọlọ nípasẹ òògun olóró ko to wọ ibẹ lọ ṣàlàye pé, ogun ki alaisan to ri àaye bẹẹdi ni ilé iwosan náà, gẹ́gẹ́ bi o ṣe ṣàlaye, lẹyin ọ̀sẹ̀ mẹta to ti lọ ni wọn to ri ààye bẹẹdi fún un ti wọ́n si san ẹgbẹ̀run meje naira gẹ́gẹ́ bi owo àbẹtẹlẹ ki o to ri ààye lati gba bẹẹdi.
Ọjọ mọkandinlọgbọn abi ọgbọn ni wn fi n ka ọjọ osupa.
 Ó gba ìwé ẹ ̀ rí àkọ ́ kọ ́ nínú ìmọ ̀ òfin láti university of lagos .
Hana bá OLUWA jẹ́jẹ̀ẹ́ ó ní, “OLUWA àwọn ọmọ ogun, bí o bá ṣíjú wo ìyà tí èmi iranṣẹ rẹ ń jẹ, tí o kò gbàgbé mi, tí o fún mi ní ọmọkunrin kan, n óo ya ọmọ náà sọ́tọ̀ fún ìwọ OLUWA ní gbogbo ọjọ́ ayé rẹ̀, abẹ kò sì ní kàn án lórí.
D Tuluen ṣe kongẹ awọn agbebọn nigba to n lọ si olu ilu ipinlẹ Benue, tii ṣe Makurdi lọjọ Satide.
Láìẹ́k yìí ní àwọn kan wọ́n sọ fún Kabièsí láti maa ta ilẹ̀.
Mo wá rò ó wí pé, àwọn ará Filistia tí ń bọ̀ wá gbógun tì mí ní Giligali níhìn-ín, n kò sì tíì wá ojurere OLUWA.
B Joshua-Angel Gomes Wike kìí ṣe dọ́là tí Ganduje leè kó sápò- Agbẹ́nuso ìjọba ìpínlẹ Rivers Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí kan sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
Ọ̀pọ̀lọpọ̀ ọmọ, ọmọ-ọmọ, Ìyàwó, ẹbi àti ará ló gbẹ̀hin rẹ.
“Ẹ sọ fún Hesekaya ọba Juda pé kí ó má jẹ́ kí Ọlọrun rẹ̀ tí ó gbójú lé ṣì í lọ́nà kí ó sọ pé ọba Asiria kò ní fi ogun kó Jerusalẹmu.
Bí mo bá ṣe àṣeyọrí,o óo máa lépa mi bíi kinniun;ò ń lo agbára rẹ láti pa mí lára.
Idà rẹ̀ gé wọn bí eruku,ọfà rẹ̀ sì tú wọn ká bí àgékù koríko.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Nigba ti i a bi awọn onimọ ẹsin bi i : Sheikh Abdullahi Garangamawa, imaamu mọsalasi Jafar Adam ni Kano; o ni awọn eeyan ti sọ eto ẹkọ alimajiri di idakuda.
Dokita yii ni fun apẹẹrẹ, irun pipa le jẹyọ latara aisan òróòro.
"Kikun oju iwọn ẹni ti wọn yan: ""Iwe ofin ko sọ pe ki wọn maa lẹ orukọ eeyan kan mọ ipo kan ni pato."
Wọ́n ní kí ẹ má fi iṣẹ́ ọwọ́ yín mú un bínú, kí ó má baà ṣe yín ní ibi.
Kí alufaa yẹ̀ ẹ́ wò, bí wúwú tí ó wú yìí bá jìn ju awọ ara rẹ̀ lọ, tí irun rẹ̀ bá sì funfun; kí alufaa pè é ní aláìmọ́; àrùn ẹ̀tẹ̀ ni, ẹ̀tẹ̀ ni ó jẹ jáde gẹ́gẹ́ bí oówo.
Lizzy Anjọrin: Inú mi dùn láti di Bọ̀rọ̀kínnì Àdínnì
Ó ṣe ohun burúkú níwájú OLUWA gẹ́gẹ́ bí àwọn baba rẹ̀ ti ṣe.
Igbejọ Ipob: Ileẹjọ yoo gbọ ẹjọ Nnamdi Kanu lọtọ
Oriṣiriṣi ọrọ aṣiri si ni awọn eniyan maa n lo ilu lati sọ, ẹni to ba si ni eti ilu nikan ni ọrọ naa le ye.
O kawe ni Ghana ati ni Uk ko to jẹ minista fun fasiti, ati minista fun ọrọ ile ewọn, ọrọ itọju awọn ọmọde ati bẹẹ bẹẹ lọ.
Sisitá ìjọ Kátólíkì méjì wá ṣe iṣẹ́ ìhìnrere l‘Afirika, lóyún bá dé Èèyàn mẹ́fá tó n bọ̀ láti ìpàgọ́ àdúrà kú nínú ìjàmbá ọkọ̀ ojú pópó l'Osun Biṣọọbu agba patapata ti ijọ Katoliki ni ipinlẹ Eko, Arch bishop Adewale Martins sọ fun BBC pe ipade awọn Biṣọọbu ti wọn ṣe kọminu gidi gan lori iṣoro aabo lorilẹede Naijiria.
Kì báà jẹ́ ibùsùn rẹ̀ ni, tabi ohunkohun tí ó fi jókòó ni eniyan bá fi ara kàn, ẹni náà yóo jẹ́ aláìmọ́ títí di ìrọ̀lẹ́.
Ilu Ikorodu ni ọkọ naa morile lati agbegbe Ajah lasiko ti ijamba naa fi ṣẹlẹ.
Àwọn pàápàá yóo lọ sí ìgbèkùn.
Ẹwẹ, orileede Faranse ti ti awọn ileẹkọ to wa ni agbegbe Paris pa.
Igbesẹ naa waye lẹyin ti igbimọ to n ri si alekun owo oṣu oṣiṣẹ
Election Update 2019: Iléeṣẹ́ ológunní Wike gbówó ńlá fáwọn láti da ìbò rú
Mo lọ sibẹ láti de àwọn ẹlẹ́sìn yìí kí n sì mú wọn wá sí Jerusalẹmu láti jẹ wọ́n níyà.
Ninu ọrọ rẹ nibi ijoko itagbangba naa, sẹnatọ Olurẹmi Tinubu pe fun idaduro awọn ọgba ẹwọn fun awọn obinrin eleyi to ni o ni lati jina gedengbe si ti awọn ọkunrin.
Ọlọ́pàá Adamawa ni #30,000 ni wọ́n fi bọ́ igún látìmọ́lé Facebook yóò bẹ̀rẹ̀ ìnáwó orí ayélujára Theresa May bú sẹ́kún, ó ní òun kò ṣe olóòtú ìjọba UK mọ́ Ọwọ́ ọlọ́pàá tẹ ọmọ Britain tó ń ta kẹ́míkà gẹ́gẹ́ bi omi ìyanu Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Abdulfatah Ahmed: Àwọn Kwara fẹ́ dán ilé ọkọ kejì wo ni lásìkò yí Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Fi fìlà náà dé e lórí, kí o sì gbé adé mímọ́ lé orí fìlà náà.
Lásìkò tó ń dáhun ìbéèrè lórí ọ̀nà ti yóò gbà láti kóju àwọn agbààgbà nílé iṣẹ́ tí yóò maa darí pàápàá jùlọ àwọn àdari àti akọwe àgbà ilé iṣẹ́ náà tí òmíràn tilẹ̀ le bíi lọ́mọ́.
Àwọn iranṣẹ Saulu wí fún un pé, “Wò ó!
Goolu mejilelogun ni Kane gba sawọn ninu ifẹsẹwọnsẹ mẹrindilogoji to gba, goolu mẹrindinlọgbọn ni Salah gba sawọn ni tirẹ ninu ifẹsẹwọnsẹ mọkandinlaadọta to gba.
Ìjọba ìpínlẹ̀ Ondo kéde òfin konile-o-gbele ní Ode ati Ishinigbo lẹ̀yìn rògbòdìyàn tó wáyé níbẹ̀ Wo àwọn tó ti dákú bíi Maina níwájú ìjẹ́jọ́ Wọ́n ti rí Ọ̀pá Àṣẹ ilé aṣòfin ìpínlẹ̀ Ogun tí àwọn jàndùkú jí gbé nípinlẹ̀ Eko o!
Ẹ wò ó, ẹni tí ó ju Solomoni lọ ló wà níhìn-ín.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ẹ̀yin Marlians, ṣẹ mọ̀ pé Naira Marley kìí ṣe aláàbọ̀ ẹ̀kọ́, ó kàwé jáde ní fásitì?
Ajọ amuṣẹya naa yoo ma a woye igbesẹ ti wọn yoo gbe lori ofin konile-o-gbele to n lọ lọwọ ni ipinlẹ Eko, Ogun ati ilu Abuja.
Àwọn ọmọ-ẹ̀yìn mọkanla lọ sí Galili, sí orí òkè tí Jesu ti sọ fún wọn.
Gbogbo ìjọ eniyan Israẹli ni ó gbọdọ̀ ṣe ìrántí ọjọ́ yìí.
Kíni àwọn ọmọ orílẹ̀-èdè yìí ń sọ lórí àwọn tí Obasanjọ ti yàn tẹ́lẹ̀ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Kínì ìdí tí Obasanjọ fí sàbẹ̀wò sí adarí Afẹ́nifére Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Kínì ìdí tí Obasanjọ fí sàbẹ̀wò sí adarí Afẹ́nifére Ó gbóríyìn fún Afẹnifẹre fún àdúrótì, ìgbàgbọ́ nínú Yorùbá àtí ìlọsíwájú orílẹ̀-èdè Nàìjíríà Bákannáà, ni Fasoranti dúpẹ́ lọ́wọ́ Obasanjọ fún ìgbìyánjú rẹ̀ láti mú orílẹ̀-èdè Nàìjíríà dé èbúté ogo, o fi ẹ̀dùn ọkan rẹ hàn sí bí wọn ṣe ń darí rẹ̀.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Abule Ado explosion: Irọ́ ńlá ní NNPC pa lórí ìbúghbàmù Abule Ado níbí tí ẹ̀mí èèyàn 23 Koo to wa tẹ oju opo iforukọsilẹ, wo ohun marun too ni lati mọ.
ṣugbọn bí afẹ́fẹ́ bá ti fẹ́ kọjá lórí rẹ̀,á rẹ̀ dànù,ààyè rẹ̀ kò sì ní ranti rẹ̀ mọ́.
Lọdun 1963 si 1973 ni orukọ rẹ yipada di papa iṣere ilu Eko, Lagos City Stadium.
" Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Hospital Wedding: Oṣù kan péré ni Tash fi ṣe ìgbéyàwó pẹ̀lú Simon kó tó kú Afíkún owó láti bẹ̀rẹ̀ ilé iṣẹ̀ ìfẹrù ránṣẹ́, yóò mú kí fífí ẹrù ránṣẹ́ láti ibì kan sí omíran gbé owó lórí síi ní orílẹ̀ -èdè Nàìjíríà.
eye fun awon ti o ti se gudu gudu meje, yaya mefa lori aseyori ati ipa pataki
 E sa maa ba wa kalo tabi ki e lo si ikanni ero ayelujara wa: www.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Nigeria-China Loan: Afenifere korò ojú sí ìjọba Buhari, bó ṣe ń yáwó kiri 11 Ẹrẹ̀nà 2018 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 1 Ògún 2020 Oríṣun àwòrán, @MBuhari Ẹgbẹ ọmọ bibi ilẹ Yoruba, Afenifere ti kede pe ko si ilẹ kankan ti ilẹ Yoruba yoo gbe jalẹ fun awọn tijọba apapọ jẹ ni gbese, ti wọn wa sin owo wọn.
Ti igbesẹ naa ko ba si tẹ awọn asaaju ẹgbẹ lọrun, ọkọ tiwọn nikan, to jẹ ẹtahoro ni wọn yoo gbe kuro loju popo, tori ko si awakọ to ya owo ra ọkọ ara rẹ, ti yoo gbọrọ si wọn lẹnu.
Bàbá Wande fikùn pé Mo fẹ́ sọ ere 'Tí Olúwa Ni Ilẹ̀' di sinima, máa si parọ àwọn oṣere tó kopa ninu rẹ, tí yóò fi bá ìlànà tode òní mú."
Ẹ óo máa yọ̀ níwájú OLUWA Ọlọrun yín, níbikíbi tí ó bá yàn pé kí ẹ ti máa sin òun, ẹ̀yin, àwọn ọmọ yín lọkunrin ati lobinrin, ati àwọn iranṣẹbinrin ati iranṣẹkunrin yín, ati àwọn ọmọ Lefi tí wọn ń gbé àwọn ìlú yín; àwọn àlejò, àwọn aláìníbaba, ati àwọn opó, tí wọ́n wà láàrin yín.
- Ààrẹ Akufo-Addo Gẹ́gẹ́ bí Aarẹ àgò àṣà àti ìṣẹṣe Yoruba ní ìpínlẹ Osun àti Agbásàgà gbogbo ilẹ̀ Yoruba, Oloye Babatundre Bakare sàlàye pé èèwọ ni kí Ọba kọ ìyàwó rẹ̀ sílẹ̀ nítori pé ní ilẹ̀ Yoruba gẹ́gẹ́ bi àṣà àti ìṣẹ̀ṣe Yoruba, kò si ẹni to gbọdọ gorí ìyàwó ti Ọbá ba ti kọ sílẹ̀.
Àgbẹ́kọ̀yá yarí; Afẹnífẹ́re ní ilé ẹjọ́ ló kàn lórí ọ̀rọ̀ Àmọ̀tẹ́kùn Ilé ẹjọ́ rán ọmọ ìjọ lẹ́wọ̀n ọdún 18 lórí ẹ̀sùn pé ó jí ₦ 15m owo ìjọ Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Wọ́n ní ẹni tó da omi sí’wájú, ẹnítọ̀hún yó tẹ ilẹ̀ tútù.
fesi si oro aare, o seleri pe ojuse omo ilu Daura ati omo orile ede Naijiria,
Ilé ẹjọ Kano wọ́gilé ìdájọ́ tó ní kí Oshiomhole lọ rọọ́kún nílé Lẹ́yìn ò rẹyìn, Amotekun dòhun, gbogbo ilé aṣòfin nílẹ̀ Yorùbá fòǹtẹ̀ lu Kí nìdí táwọn olùkọ́ ilé ìwé Federal Girls College Akure ṣe fí òkúta fọ́ ẹ̀rọ ìbánisọ̀rọ̀ àwọn akẹ́kọ̀ọ́ Amọṣa ṣe a kii mọọ gun, mọs tẹ ki iyan ewura o maa ni koko.
Bẹẹ ba gbagbe, ọpọ igba ni ẹnu kun Ajimobi tẹlẹ pe o ni arun Coronavirus amọ ti amugbalẹgbẹ rẹ, Tunji Bolaji n sẹ pe irọ ni ọrọ naa.
Awọn ti iṣẹlẹ naa ṣoju wọn sọ fun BBC pe awọn janduku to ja iwọde naa gba, ti gbogbo ọna to jade si ọgba ẹwọn naa, ti wọn ko si jẹ ki ẹnikẹni kọja abi wọle si agbegbe ọgba ẹwọn naa.
Apẹẹrẹ fún àwọn òbí ní èyí.
4+4 ko ni ṣe pupọ pẹlu ọrọ bi kii ṣe nina ika mẹrin owo mejeeji soke lati fi han pe lẹyin ọdun mẹrin ti APC lo ni ijọba,wọn yoo lo mrin miran si.
O tẹsiwaju pe gbogbo kudiẹkudiẹ to ṣokunfa isunsiwaju ibo ni ijọba ti ṣe atunṣe rẹ bayii, bẹrẹ lati ori igba ibo ati awọn iwe to n ṣe akẹsilẹ esi ibo.
Gbọnka Ebiri ni tiẹ kii lo ọfa lati jagun amọ o ni oogun ju Arọni lọ, eyi to maa n lo lati fi sẹgun ọta.
Jamb ni awọn yoo fi oju wọn han ti wọn si le padanu anfaani iwe ẹri wọn koda ko jẹ wi pe wọn ti pari Ẹkọ sẹyin laarin ọdun 2009 si 2019.
Gẹgẹ bi atẹjade ajọ ilera agbaye, WHO, lootọ orilẹ€de China ni arun yii ti gbera ṣugbọn awọn orilẹede to ti ran de ti pọ, leyi ti orilẹede Naijiria naa si ti wa darapọ mọ wọn bayii.
Ninu ikede ti ajọ NCDC fi sita l'Ọjọbọ lo ti fojuhan pe , awọn to ti ni aarun naa ti pe 30,249 bayii.
Bakanna lo ni awọn yoo dawọn loko owo ti wn yoo si gba owo ọkọ pada si ilu wọn.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Saraki kò mú ohun rere wọ Kwara bí i olórí asòfin àgbà - Adedoyin Ebi sọ ìyá àgbà di awa kẹ̀kẹ́ Maruwa 'Oun tí Kunle Afolayan ṣe sí mi, mi ò lè ṣeé sí i' ‘Àgbàlagbà ọkùnrin fi tipá bá ọmọdékùnrin mi lòpọ̀’ Hubert Ogunde rèé, baba àwọn òsèré tíátà Jide Kosọkọ tun n fẹ ki ijọba gbe isẹ tiata larugẹ, nipa kikọ abule ere sise, taa mọ si Film Village fun wọn.
Tottenham já Ajax dànù 8 Èbibi 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 9 Èbibi 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Wábiwọ́sí ìyà ni Ajax fi ṣe Tottenham lálejo ni Amsterdam Agbo to tadi mẹyin , agbara lo lọ muwa lọrọ Tottenham ati Ajax ri ninu idije UEFA Champions League.
Ati pe oun ti pe fun iwadii akọtun lati mọ ohun to ṣokunfa iku ẹlẹwọn mẹrinlelogoji naa ni pato.
Ẹnikẹ́ni kò gbọdọ̀ sọ̀rọ̀ rárá títí di ọjọ́ tí n óo sọ pé kí ẹ hó, nígbà náà ni ẹ óo tó hó.
“Nígbà tí wọ́n bá sọ ẹni tí nǹkan dà lára rẹ̀ yìí di mímọ́ kúrò ninu ohun tí ó dà lára rẹ̀, kí ó ka ọjọ́ meje fún ìwẹ̀nùmọ́, kí ó fọ aṣọ rẹ̀, kí ó sì wẹ̀ ninu odò tí ó ń ṣàn; yóo sì di mímọ́.
Ìlú Tirisa ni ó gbé fún ọdún mẹfa àkọ́kọ́.
K1 De Ultimate: Bí Barrymade bá ní alágbàfọ̀ bàbá òun ni mí, oríire ni mo ṣe
Mo ti ń ṣe àmúlò ìtẹ̀wé yìí ní kété tó jáde, kí n lè fún un yín lábọ̀ nípa rẹ̀ ní ẹ̀kúnrẹ́rẹ́.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Aisha Buhari, ìyàwó ààrẹ Gambia Fatoumatta Bah-Barrow ṣe ọjọ ìbí níléèwòsàn l'Ábújá 5 Ògún 2018 Oríṣun àwòrán, @Laurestar Àkọlé àwòrán, Ni ọjọ karun oṣu kẹjọ ọdun 1974 ni wọn bi Fatoumatta Bah-Barrow ni ilu Banjul Iyawo aarẹ orilẹede Naijiria, Aisha Buhari ti darapọ mọ iyawo aarẹ orilẹede Gambia, Fatoumatta Bah-Barrow lasiko ayẹyẹ ọjọ ibi ọdun kẹrinlelogoji rẹ nilu Abuja.
OPC New Era ni awọn ọmọ ẹgbẹ awọn yoo bẹrẹ si ni le awọn Fulani darandaran to n hu iwa ọdaran ni gbogbo awọn ipinlẹ to jẹ ti ẹya Yoruba jade, tawọn ile iṣẹ eto aabo ko ba foju awọn to ṣeku pa arabinrin Funke Olakunrin han.
"Ìpàdé àpérò kọ́ ló kàn, àdánìkànjẹ ẹ̀yà kan ni ká dẹ́kun ní Nàíjíríà - Òǹwòye Spaghetti, mílíìkì, Chivita àti Àǹkàrá sọ Rabiu dèrò ẹ̀wọn ni Eko A ti rí akẹ́kọ̀ọ́ ABU tí wọ́n jígbé lọnà Kaduna-Abuja gbà -Ọlọ́pàá ""Bi mo tilẹ̀ jẹ́ apárí síbẹ̀ kò tìmí lójú"", Liliya Kukushkina Agbẹnusọ ile, John Bercow ni ko si orukọ meji fun igbesẹ yii ju ""aibọwọ fun ofin"" lọ."
 “ko ye ki a yo ara wa lenu lori awon ti won ko lo si Ekiti, bi ki I se pe ki a maa fi adura  ran won lowo pe ki  won maa padanu awon eniyan lasiko eto idibo.
 kò fẹ ́ rẹ ̀ sí ìtọ ́ jú kan ní pàtó , bí ó tilẹ ̀ jẹ ́ pé ìsinmi tí ó tó àti lílo òògùn ní bí a ṣe kọ ọ ́ fún ní gẹ ́ lẹ ́ n ṣiṣẹ ́ fún ọkàn-rìnrìn tàbí ìgbẹ ́ -gbuuru .
Awọn musulumi kaakiri agbaye lo maa n sami ayajọ opin aawẹ Ramadan yii ṣugbọn ko i tii si ọjọ kan ni pato fun un lọdun 2020 nitoripe igba ti wọn ba ri oṣù ni aawẹ Ramadan yoo pari.
 ajagun díḿkà sì túń kópa nínu ìgbìmọ ̀ láti gba ìjoba lówo àrẹ oríléèdè , Ọgágun murtala ramat mohammed ní ọj ̣ ́ o kẹtàlá , osù kejì , ọdún 1976 .
Nígbà tí ó yá, Johanu Onítẹ̀bọmi dé, ó ń waasu ní aṣálẹ̀ Judia.
Igali, ọmọ Natani, ará Soba, Bani, ará Gadi; 
Ni ose yii, Wilder ko àádọ́ta milionu owo dola ($50m) sile fun Joshua lati figagbaga pelu re, ti o si fi gbegede ojobo(Thursday) sile lati se pinnu.
Ibi tí ó ti ń ṣa owó yìí ni ó ti gbọ́ gìrìgìrì ẹ̀sẹ̀, ó sá kúrò ní sàkàní ibojì ọ̀rẹ́ rẹ̀, ó ṣáà ti ṣa owó dání tán, ṣùgbọ́n kò tíì gbọ́n yẹ̀pẹ̀ ibojì pàdà!
Èmi ni OLUWA Ọlọrun rẹ láti ilẹ̀ Ijipti; n óo tún mú ọ pada gbé inú àgọ́, bí àwọn ọjọ́ àjọ ìyàsọ́tọ̀.
Eto naa wa lati mu eto sisan owo lori ikanni igbalode ṣeeṣe lawọn orilẹ-ede mejila kan nigba ti a o ba fi ri oṣu mẹta akọkọ lọdun 2020.
Àwọn ọba ati àwọn ọmọ ogun wọn yóo kọlù ú,wọn yóo pa àgọ́ yí i ká,ẹgbẹ́ ọmọ ogun kọ̀ọ̀kan yóo pàgọ́ sí ibi tí ó wù ú.
”Ó bá sọ fún wọn pé, “Èmi náà kò ní sọ irú àṣẹ tí mo fi ń ṣe nǹkan wọnyi fun yín.
Amọṣa diẹ niyi lara awọn ọmọ Yoruba to n da bi ẹdun, rọ bi owe.
    Ogunlọ́gọ̀ ènìyàn ló sìn wá sí ojú ọ̀nà, ìpínyà náà sì ṣòro gidigidi: ẹlòmíràn ń pòṣé, ọ̀pọ̀lọpọ̀ ń mi ìmí ọ̀dùn, ojú àwọn ọmọbìnrìn sì dàbí orísun omi nínnú èyí tí omije ti ń lo ìbòrùn láti fi nu òógùn ti ń ṣàn bí àgbàrá òjò kúrò lára rẹ̀, ṣùgbọ́n àwọn àgbàlagbà kò sí nínú àwọn ẹlẹ́kún wọ̀n-ọnnì, wọn ń pè wá ní òkọ̀ọ̀kan bí a ti ń lọ, wọn ń fún wa ní ìmọ̀ràn, wọn n fi etí kò wá létí, wọ́n sì ń sọ onírúurú ọ̀rọ̀ àṣírí fún ni bí a ti ń lọ.
Oríṣun àwòrán, LARISSA DIAKANUA Àkọlé àwòrán, Kii se gbogbo aworan ti eniyan ba fi si oju opo ikansiraẹni ni o jẹ otitọ tabi ki awọn eniyan ma a sọ oun ti oju wọn kori Sọ́ra fún gbájúẹ̀, BBC kò ṣètò owó ẹ̀kọ́ ọ̀fẹ́ Àlàyé rèé lórí ìdí tí Atiku fi yan Peter Obi ní igbakejí ààrẹ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ìyá àkàndá ẹ̀dá: Àwọn ẹbí mi fẹ́ kí n pa ọmọ mi torí ó jẹ́ àkàndá ẹ̀dá Lẹyin eyi ni Arlene wa gbe igbese lati kilọ fun awọn eniyan lori ẹrọ ayelujara wi pe, gbogbo ohun to dan ko ni wura, nitori ọrẹ lasan ni awọn mejeeji, ti ko si si ohun to jọ igbeyawo ninu aye oun bayii.
Adajo paṣẹ bakannaa pe ki wọn lọ fi si ahamọ titi di igba ti wọn yoo fi gbẹjọ rẹ.
Ìgbórinsétí nkọ́, kòsí ẹ̀rọ míì mọ́n àf'òun.
lati maa dibo nibikibi ti won ba wa lati ilu okeere”.
O gba ijọba ni iyanju lati ri wi pe wọn wo bi wọn ṣe le lo eto oselu lorilẹede Amẹrika ati ni Ilẹ Gẹẹsi lọna ati mu igbelarugẹ ba iṣejọba lorilẹede Naijiria.
“Ẹnikẹ́ni tí ó bá fọwọ́ kan òkú yóo jẹ́ aláìmọ́ fún ọjọ́ meje.
Abike Dabiri Erewa  lati gba ipinnu aare
Minisita fun amojuto iṣẹlẹ ajalu lorilẹede Naijiria, Sadiya Farouq lo sọ bẹẹ.
Iroyin to tẹwa lọwọ so pe niṣe ni awọn oṣiṣẹ naa yan iṣẹ lodi ni ile asofin ohun lọjọ aje tii ṣe ọjọ kẹtadinlogun oṣu kejila ọdun 2018.
Idi ni pe ẹni naa yoo ni lati lọ si orileede mii to ba wa ni tosi to ni ileeṣẹ Naijiria lati lo gba pali tuntun mi ni.
Ẹ jẹ́ kí á tà á fún àwọn ará Iṣimaeli yìí.
Là mí lójú, kí n lè rí àwọn nǹkan ìyanutí ó wà ninu òfin rẹ.
Oluwa rẹ̀ wí fún un pé, ‘O ṣeun, ìwọ olóòótọ́ ẹrú, eniyan rere ni ọ́.
Hameed Ibrahim Ali gbé Muhammed Abba-Kura ga si ipo oludari àgbà ní agbègbè Apapa.
Nítorí ẹ óo la odò Jọdani kọjá láti lọ gba ilẹ̀ tí OLUWA Ọlọrun yín fi fun yín.
"O ni ""Ẹgbẹ yii bẹrẹ lati ara pe awa ti a jẹ ọmọ ẹgbẹ ma n ba ara wa pade ni ode tabi ariya."
Mose bá dúró ní ẹnu ọ̀nà àgọ́, ó ní, “Ẹ̀yin wo ni ẹ̀ ń ṣe ti OLUWA, ẹ máa bọ̀ lọ́dọ̀ mi.
Ẹgbẹ agbabọọlu Arsenal naa ti tẹle Manchester United lọ si idije Europa.
"Ileesẹ BBC ni orisun iroyin to jẹ ajaabalẹ, bii ẹmu ogidi, iroyin otitọ, ti ko ni ẹja n bakan ninu, ojulowo iroyin ti kii se ẹbu atawọn iroyin ti wọn ko bu omi la, ti ko si ni ẹlẹgbẹ.
George ni ọmọ ilẹ Adulawọ ti ọlọpaa alawọfunfun, Derek Chauvin fi orukun tẹ lọrun pa loṣu to lọ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Lassa Fever: Dokíta mẹrin àti àwọn mẹ́tàdinlólogun ti kú ni Kano àti Ondo.
bi o se towobo iwe adehun ni eyi ti  yoo
Àwọn ará ìlú Ṣekemu lọ sinu oko wọn, wọ́n ká èso àjàrà, wọ́n fi pọn ọtí fún wọn.
Lẹ́yìn náà, ọba ati gbogbo àwọn eniyan rúbọ sí OLUWA.
A gbọ pe eyi ri bẹẹ nigba ti asẹ kan wa lati olu ileesẹ ọlọpaa ilẹ wa nilu Abuja pe atunto kanmọ-n kia gbọdọ bẹrẹ ni ẹka Sars yii.
Àwọn ọmọ Nàíjíríà: Bùhárí gbọdọ̀ sọ́ ẹnu rẹ̀ l‘Ámẹ́ríkà
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù BBC ṣe ìwadìí lórí bí ìrẹ̀wẹ̀sì ọkàn ṣe ń mú kí àwọn ọkùnrin lórílẹ̀èdè Kenya ó máa gb'ẹ̀mí ara wọn Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ BBC ṣe ìwadìí lórí bí ìrẹ̀wẹ̀sì ọkàn ṣe ń mú kí àwọn ọkùnrin lórílẹ̀èdè Kenya ó máa gb'ẹ̀mí ara wọn 29 Ìgbé 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 30 Ìgbé 2019 Ni ẹnu lọwọlọwọ yii, iwadii ti fi idi rẹ mulẹ pe iṣẹlẹ dida ẹmi ara ẹni legbodo ti wọpọ bayii laarin awọn ọkunrin lorilẹede Kenya.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ademọla Ogunbanjo: A nílò bàbá ìsàlẹ̀ nínú òsèlú Ọwọ tẹ akẹkọ to fowo ileewe rẹ ta MMM Gbọ̀ngàn Mapo, ọ̀kan lára ibi àmúyangàn n'Ibadan rèé Àgbálùmọ̀, ohun mẹ́fà tó ń ṣe lára tí o kò mọ̀ Odo ni wọn fi pa ọdọkunrin naa nigba naa ki wọn to ko oku rẹ si inu odo ninu ibi ti wọn ti n gun un.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ọọ̀ni obìnrin, Lúwòó Gbàgídà rèé, akọni tó ń gun ọkùnrin ní ẹṣin rìn Ipa tí Fathia Balogun kó nínú bí mo ṣe dèèyàn lágbo òṣèré fíìmù Yorùba rèé - Baba Ijesha Ìtàn tó rọ̀ mọ́ òwe ‘aṣọ kò bá Ọ́mọ́yẹ mọ́.
Bi a ko ba yanju eyiun naa, a ko le sọ pato ọjọ ti eto ẹkọ yoo gberasọ pada.
Oríṣun àwòrán, senatorishakuabbo Yatọ si awọn aṣofin awọn tara ilu dibo yan gẹgẹ bi Gomina naa a maa hu iru iwa yi.
“Ni bayii, o farahan gbangban-gbangban pe, idije agbaye to n bo yii ni yoo je ikeyin ti ma kopa ninu re fun Spain ,” Iniesta je okan lara agbaboolu iko Spain ti o saaseyori julo ninu itan iko ohun, leyin ti o ran won lowo lati gba ife-eye European Championship ni saa 2008 ati 2012, beesini O tun kopa fun iko naa ninu idije agbaye lodun 2010, ti o si tun gba ife-eye idije naa.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Kò sí ìwé ìrìnnà 'VISA' fáwọn ọmọ Naijiria tó hùwà àìtọ́ nígbà ìdìbò Ìtàn tó rọ̀ mọ́ òwe Ẹni tí kò ṣe bíi aláàárù l‘Oyingbo."
00 Ọrọ to jẹ mọ ayika - 38,997,548,726.
Ọlọ́pàá Eko ní kí olùkọ́ UNILAG Boniface wá sọ tẹnu rẹ̀ lórí ẹ̀sùn ìfipábánilòpọ̀ A ti mọ òbí 40 nínú 108 t'ọ́mọ wọn bọ́ ní ayédèrú ibùdó atúnwàṣe Ilorin - Ọlọ́pàá Kwara O di dandan fawọn ọdọkunrin ti ọjọ ori wọn wa laarin ẹni ọdun mejidinlogun si mẹtadinlọgbọn lati darapọ mọ awọn ọmọ ogun ninu alakalẹ eto ilẹ Russia.
Nígbà tó tún ya mo tún ń wo nkankan lókèrè tó fẹ jọ òjòlá ńlá.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, End SARS, End SWAT: Ó pé mi bí SARS kò ṣe sọ mí dolówọ́- Fulani Kwajafa Nigba to n sọ iru eeyan ti Iya Rainbow jẹ si, Oloye Toyin aya Adegbọla, ti gbogbo eeyan mọ si Aṣẹwo to re Mecca salaye pe, Iya Rainbow jẹ ẹni to ko ni mọra, oludamọran fun awọn ọdọ, ati awokọse rere ni agbo isẹ tiata nitori pe kii fi oju pa ọmọde rẹ.
Ohun ìríra ni èrò ọkàn ẹni ibi lójú OLUWA,ṣugbọn ọrọ̀ àwọn ẹni mímọ́ jẹ́ dídùn inú rẹ̀.
Wọn óo wá mọ̀ nígbà tí mo bá gbẹ̀san lára wọn pé èmi ni OLUWA.
Nibi ipade naa,o fi da wọn loju pe oun ko ni ifoya nipa sise eto idibo eleyi toyanrantin ''Eru idibo ti ko lẹjanbakan ninu ko ba mi nitori iru idibo bẹẹ lo gbemi wọle'' Loju opo Twitter iile isẹ ijọba orileede Naijiria ni fọnran fidio ti Aarẹ Buhari ti sọ ọri yi wa.
Bí Mendez-Liang ṣe side gbígbá bọ̀lù sáwọn fún Cadiff lásìkò to gbá wòmí-ń-gbáa sí ọ̀ ti Diogo Dalot mú balẹ̀, sùgbọ́n ó si tún jẹ lẹ́yìn ti wọn wọlẹ́ sáà kejì.
Coronavirus in Nigeria: Ìjọba àpapọ̀ kéde pé káwọn òṣìṣẹ́ ìpele 12 àti 13 padà s'ẹ́nu iṣẹ́
Èèyàn kan tún jáláìsí nínú ìjàǹbá ọkọ̀ lọ́nà márosẹ̀ Ibadan sí Eko Mr Latin, Jide Kosọkọ àti Mama Rainbow sọ̀rọ̀ lórí ìjà Toyin ati Lizzy Èèyàn mẹ́ta kú nígbà tí ọkọ̀ bọ́ọ̀sì jábọ́ sí ódò Ọ̀ṣun Ìkọlù ibùdó epo rọ̀bì Saudi Arabia yóò kóbá jíjẹ-mímu àwọn èèyàn rẹ̀ - Buhari Oríṣun àwòrán, Getty Images Bakan naa ni ikọ Dotmund yoo gba ikọ Barcelona lalejo loni.
Ó dá ẹni tí wọ́n ní àwọn fẹ́ sílẹ̀: ẹni tí wọ́n jù sẹ́wọ̀n nítorí pé ó paniyan.
Ọga Mohammad Babandede fikun wi pe o le ni ẹgbẹrun mọkanla eniyan ti wọn ti ọwọ ti tẹ lasiko ti wọn wa ọna lati kuro lorilẹede Naijiria lai ni Iwe Irinna to peye.
Elija dìde, ó jẹun, ó sì tún mu omi.
Oloṣelu ni Ọba Olateru, Koda, iroyin sọ pe ninu ààfin rẹ ni wọn ti da ẹgbẹ oṣelu Action Group ti Obafemi Awolowo silẹ.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Atiku ni àgbàgbà Yorùbá ń bá lọ fún ipò Ààrẹ Sọ́ra fún gbájúẹ̀, BBC kò ṣètò owó ẹ̀kọ́ ọ̀fẹ́ Kí lo fẹ́ mọ̀ nípa D.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Akomolede àti Aṣa: Ọ̀rọ̀ Ẹ̀yán ni Bunmi Femi Amao ń kọ́ wa lórí ètò Akọ́mọlédè àti Àṣà lóri BBC Yoruba Ilé ìjọsìn lè bẹ̀rẹ̀ ìsìn àárín ọ̀sẹ̀ padà, Mọ́sáláṣí àti Ṣọ́ọ̀ṣì lé gba iye èèyàn tó wù wọ́n ṣùgbọ́n.
Nítorí pé ní tiwa, ọ̀run ni ìlú wa wà, níbi tí a ti ń retí Olùgbàlà, Oluwa Jesu Kristi, 
Ọọni pe fun ifọwọsowọpọ Naijiria Faari Buhari Asiri ibudo igbafẹ ẹranko ni Naijiria Ọmọ Ààrẹ lẹ́tọ̀ọ́ láti ṣe ìgbéyàwó yálà àwọn ará ìlú fẹ́ràn ìjọba bàbá rẹ̀ tàbí bẹ́ẹ̀ kọ́ - Aisha Buhari Tafa Balogun: Ọga ọlọpaa Naijiria ni Tafa lasiko isejọba Oluṣẹgun Ọbasanjọ ki wọn to fi panpẹ ofin gbe lori ẹsun pe o se owo to din diẹ ni biliọnu mẹfa naira baṣubaṣu (N5.
Ọjọ kọkandinlọgbọn Oṣu kọkanla, ọdun 2020 Lati ọjọ kọkandinlọgbọn oṣu kọkanla ni awọn ileeṣẹ to n pin ina ọba lorilẹede Naijiria ti fi ọrọ ilanilọyẹ sita lati fi to awọn araalu leti.
Boko Haram: obìnrin tórí kó yọ ní omi àti ewé ńi òun jẹ nínú igbó
Bí Jesu ati àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ ti ń jáde kúrò ní Jẹriko, ọ̀pọ̀ eniyan tẹ̀lé e.
Ìnágijẹ oyè wọn ni Ìlúfẹ́milóyè I.
Ijoba ti fofin de iwakusa kekeke lodun to koja, gege bi ona kan lati se adinku iwakusa lona aibofin mu.
"Lasiko idibo ọdun 1993, ""Alhaji Bashir Tofa ati Oloye MKO Abiola lo jọ figagbaga lọjọ naa."
Ẹ óo fi ojú rí Jerusalẹmu, ibùgbé alaafia, tí àgọ́ rẹ̀ kò ní ṣídìí,tí èèkàn tí a fi kàn án mọ́lẹ̀ kò ní hú laelae,bẹ́ẹ̀ ni okùn tí a fi so ó mọ́lẹ̀ kò ní já.
PENGASSAN Strike: Bí ìjọba bá dá wà lohùn lórí IPPIS láàrin wákàtí mẹ́rìnlélógún, a o so ìyanṣẹ́lódì rọ̀
A kò mọ̀ọ́mọ̀ pa ọlọ́pàá mẹ́ta, aráàlú kan, ó ṣèèsì ni, ajínigbé la pè wọ́n - Iléeṣẹ́ ológun Sowore àti àwọn ọmọ ẹgbẹ Revolution Now kò ṣẹ̀ ṣófin lórí ìwọ́de, ẹ tú wọn sílẹ̀ - NLC Òṣùká kékeré kò rẹrùn àgbà, orílẹ́èdè Nàìjíríà ṣòro púpọ̀ láti darí - Ibrahim Babangida Sowore ṣèpàdé pẹ̀lú Nnamdi Kanu láti dojú ìjọba Nàíjíríà bolẹ̀ - Àjọ DSS Ilé-isẹ́ Ológun gbọdọ̀ sèwádìí bí ọmọogun se pa ọlọ́pàá - Buhari Amọ awọn obinrin to ba wa sọrọ lori ọdun oro naa lo faraya pe, ọdun naa n tẹ ẹtọ awọn mọlẹ lasiko ti wọn ba n se e, to si maa n sọ awọn si igbekun ati ẹwọn.
Ṣugbọn ò ń hùwà bí àwọn ọba Israẹli, o sì ti fa àwọn Juda ati Jerusalẹmu sinu aiṣododo, bí ìdílé Ahabu ti ṣe fún Israẹli.
Salah fi idunnu re han lasiko ayeye igbami eye ohun pe, “O je ohun ti o bu ola pupo fun mi.
Ogoni 9 execution anniversary: Ta ni Ken Saro-Wiwa tí ìjọba ológun sekúpa?
Gbogbo àwọn tí wọ́n mọ Òfin, tí wọ́n sì dẹ́ṣẹ̀, òfin náà ni a óo fi ṣe ìdájọ́ wọn.
Mata ní arabinrin kan tí ó ń jẹ́ Maria.
Jamilu Shehe ni tirẹ salaye pe lati igba toun ti wa ni kekere ni ohun kii bẹrẹ awẹ ayafi ti ohun ba foju ri oṣu.
Oríṣun àwòrán, khaosod Àkọlé àwòrán, Ajá naa, Ping Pong di ẹlẹsẹ kan lẹyin ti ọkọ̀ gba a.
Leyin eyi ni ọgbẹni Kucha kede esi pe APC ni 6, 885 ibo ti apapọ ibo APC fi jẹ 247, 752.
Naijiria ji giri si aabo awọn ọmọ orilẹ-ede wa ni ilẹ okeere gẹgẹ bi
Lakotan, o sọ pe ẹni ti oun n fẹ kii ṣe oṣere, ṣugbọn o mọ pe ere ni oun n ṣe , kii ṣe pe oun n fẹ obinrin ti ọrọ ifẹ ba jọ dawọn pọ ninu ere.
Eliṣa dáhùn pé, “Gbọ́ ọ̀rọ̀ OLUWA, ní àkókò yìí lọ́la, ní ẹnubodè Samaria, àwọn eniyan yóo ra òṣùnwọ̀n ìyẹ̀fun kíkúnná kan, tabi òṣùnwọ̀n ọkà baali meji ní ìwọ̀n ṣekeli kan.
Bakan naa, ti o fi mo awon ipago ti awon agbesunmomi ohun tun sa si nipinle Zamfara, ipinle ti o kogun si eka ila oorun orile-ede Naijiria.
Iwo oorun-Gusu– igbakeji alaga egbe (SW),igbakeji oludari eto egbe, oludari alamojuto eto ofin, oludari eto inawo, igbakeji oludari eto awon odo.
Àmọ́ púpọ̀ nínú àwọn ilé wọ̀nyí ni ó ti wó láti ọjọ́ pípẹ́.
Alaga igbimo to n mojuto eto idibo ohun, asofin Danjuma Goje, lo sagbekale iwe isuna ohun lasiko ipade awon asofin to waye lojo isegun(Tuesday), niluu Abuja.
Awon Agbaboolu owo-iwaju(Forwards): Ahmed Musa (CSKA Moscow, Russia); Kelechi Iheanacho (Leicester City, England); Moses Simon (KAA Gent, Belgium); Victor Moses (Chelsea FC, England); Odion Ighalo(Changchun Yatai, China); Alex Iwobi (Arsenal FC, England); Junior Ajayi (Al Ahly, Egypt) ati Gabriel Okechukwu (Akwa United).
Oríṣun àwòrán, Seyi Makinde Ẹni iyì àti akíkanjú tó ṣe gbẹ́kẹ̀lé làwọn èèyàn Akure, ilú ìyá mi - Seyi Makinde Seyi Makinde fún olórin Fuji Taye Currency lẹ́bùn ọkọ̀ bọ̀kìnnì Toyota Prado 2020 Aáwọ̀ oyè PDP gbé Fayose àti Seyi Makinde kọlu ara wọn, ìjà ń bọ̀ Mo parí iṣẹ́ àṣepatì 239, iṣẹ́ 236 míì ń lọ lọ́wọ́- Seyi Makinde Oríṣun àwòrán, Seyi Makinde Ninu ọrọ ti o sọ nibi ipejọpọ naa, Makinde ṣe alaye wipe oun ti ṣe ileri lati ri iya oun ni opin ọsẹ ti o tẹle eto idibo si ipo gomina ti o waye nipinlẹ Ondo, ṣugbọn oun ko ri aye lati gbe awọn ipe iya oun nitori ibẹru wi pe oun ko ni le ri iya oun saaju asiko ti wọn jọ da fun ara wọn.
oakoroyin pe oun ko siyemeji rara, nitori egbe oselu APC ni yoo jawe olubori
O wa fa gbogbo awọn to ba n ṣe ayederu iwe esi ayẹwo Covid-19 pe bi wọn ba gba wọn mu, wọn yoo gba gbogbo iwe irina wọn silẹ.
” Ṣugbọn kì í ṣe gbogbo nǹkan tí a lè ṣe ni ó ń mú ìdàgbà wá.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Mama Arsenal: Màmá àgbà yìí máa ń lọ sí ìbùdó tí wọ́n ti ń wo bọ́ọ́lù láti wòran Oladeinde fi kun un pe ijọba yoo pese awọn ọkọ akero lọpọ yanturu ki awọn eeyan le fi ọkọ wọn silẹ nile lọna ati ṣadinku ba sunkẹrẹ-fakẹrẹ loju popo.
1 90305 Orilẹede Oman 1463 30.
Ṣe ki n lọ si Dubai pẹlu awọn temi ni?
Lọwọlọwọ, o ti pe ẹgbẹrun kan din mẹsan to ti ni aarun naa ni Naijiria.
Ṣugbọn Serubabeli, Jeṣua, ati àwọn baálé baálé tí wọ́n ṣẹ́kù ní Israẹli dá wọn lóhùn pé, “A kò fẹ́ kí ẹ bá wa lọ́wọ́ sí kíkọ́ ilé OLUWA Ọlọrun wa.
Bádérù ti dé Èkó, ilẹ̀ ta sí i.
Asa bí Jehoṣafati, Jehoṣafati bí Joramu, Joramu bí Usaya.
Lẹ́yìn ìṣẹ̀lẹ̀ náà ni wọ́n ní awakọ Benz náà bẹ́ sínú ọkọ̀ míràn pẹ̀lú alábarin rẹ̀ tí wọ́n si sálọ.
Ni èrò tiẹ̀, ọmọ igbimọ Agbaagba ilẹ Yoruba, Yoruba Council of Elders, Kunle Olajide sọ pe, o da oun loju pe Aarẹ Muhammadu Buhari n wa nkan nla ti yoo fi sọ ori Oloye Obasanjo ni, kii se pe o mọọmọ ma ṣe e.
Ọfọ sẹ lagbo osere tiata, awọn osere kan n tahun sira wọn tori Oríṣun àwòrán, https://www.
Ẹnu ní wọ́n ń bọ n'ife Èdùmàrè ò ní jẹ́ kí ẹnu wá pa wa oooo Orin Ọmọ kékeré ẹnu lẹbọ ooo Ẹnu lẹbọ Àgbàlagbà ẹnu lẹbọ ooo Ẹnu lẹbọ Ẹnu ló wọ́lé e bàbá kan Ẹnu lẹbọ 
Bakan naa, ni ti ọmọde ati arugbo, Babatunde ni wọn a fi wọn ṣe akọkọ bi wọn ba n boju to awọn alaisan ti wọn ba jọ wa lori ila.
Ajayi lo fi ọrọ naa lede nigba to ba BBC Yoruba sọrọ lori aago.
Ọkunrin kan wà ninu àwọn Farisi tí ń jẹ́ Nikodemu.
Nibayii, ibeere to wa lẹnu ọpọlọpọlọ awọn eeyan ni pe nibo lo kan fun gomina obaseki abi ṣe o ti gba fun Ọlọrun naa niyẹn.
Kí olúwarẹ̀ súnmọ́ tòsí mi,kí á jọ kojú ara wa?
Àwọn ará Ijipti lé wọn wọ inú òkun, tàwọn ti gbogbo ẹṣin Farao ati gbogbo kẹ̀kẹ́ ogun rẹ̀ ati gbogbo ẹlẹ́ṣin rẹ̀.
Ọmọ mi, pa òfin baba rẹ mọ́,má sì ṣe kọ ẹ̀kọ́ ìyá rẹ sílẹ̀.
Bẹrẹ lati ori Ayaworan ile to n gbero lati tun orilẹede Syria kọ, titi de ori alakoso isẹ ajọ NASA to n mojuto ọkọ ofurufu to n lọ si inu ofurufu Mars, ọpọ awọn obinrin to wa ni akọsilẹ ọgọrun naa ni wọn ti pegede ninu isẹ ti wọn yan laayo, ti wọn yoo si sọ asọtẹlẹ fun wa nipa bi ayeyoo se ri ti yoo ba fi di ọdun 2030.
Ààrẹ ni wọ́n kò ní agbára láti gba ìlú kankan lórilẹ̀-èdè Nàìjíríà dé bi ti wọ́n yóò ni àànfani láti ta àsíà tàbi dúkoko mọ́ ẹnikẹni ju wákàtí mẹ́rìnlélógun lọ.
Eyi lo wa mu ki ajọ kan to n lepa igbayegbadun araalu ati igbogun ti iwa ijẹkujẹ lawujọ, SERAP, ti ke sijọba apapọ lati gbe iwe orukọ awọn alajẹbanu sita.
Ẹyin náà mọ̀ pé àbùkù àwa Yorùbá ni èké ṣíṣe, àti sọ òdodo a máa ṣòro fún ni.
ipaniyan to n hu ni orile ede Sudan ati ekun ila Ariwa ti Darfur.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Akomolede ati Asa lori BBC: Olùkọ́ Kikelomo Ogunboye tan ìmalẹ̀ sí ìwà olè ọ̀gá ọlọ́pàá Iya ọlọmọ mẹrin ọhun sọ pe, ọsẹ mẹrin sẹyin ni oun fi iṣẹ abẹ bimọ tuntun.
" Kamilu ni ọdún 1996 ni òun kọ́kọ́ kópa nínú eré sinima, tí òun sì ti ṣe fíìmù méjìlá jáde, pẹ̀lú afikún pé gbogbo eka tó nii ṣe pelu fíìmù ṣíṣe ni òun mọ nípa rẹ.
O ni nkan to daju ni pe Christina yoo si di nọọsi, bose lẹni ọgọta ọdun, lẹyin ti awọn ọmọ rẹ ba ti pari ẹ̀kọ́ wọn, ti gbogbo àwọn yoo si le pese owo fun ẹ̀kọ́ rẹ""."
Obasanjo tẹsiwaju pe, oun beere pe bawo ni ẹni ti ko kunju osunwọn yoo ṣe wọle ibo Gomina.
A ti ẹ gbọ pe wọn maa n gbakoso oju agbo mọ oninawo lọwọ ni, ti gbogbo elere ti wọn ba pe sibi ayẹyẹ si gbọdọ maa fi orin to wu wọn sinu rẹkọọdu.
Nítorí oníyọ̀ọ́nú ati aláàánú ni Oluwa.
Ile igbimọ asofn ti fonte lu alaga ati ọmọ   igbimọ  ti yoo maa mojuto ile-isẹ  ọlọpaa lorile ede Naijiria.
Ẹgbẹ ́ dẹmọkrátíkì ni ikan ninu awon egbe oloselu ninla meji igba oni ni amerika , po mo egbe republikani .
Ijọba Eko ko danu duro lori ikinni nikan, wọn tun ni ko ma gbagbe lati san owo ori rẹ fun ọdun 2021 ninu owo to jẹ naa.
" Nǹkan mẹ́wàá tó yẹ ní mímọ̀ nípa fásitì ẹ̀kọ́ ìrìnnà òní $50m ní Nàìjíríà Kíni ẹ mọ̀ nípa Ọmọ́táyọ̀ Olútóyè, Ọ̀jọ̀gbọ́n obìnrin àkọ́kọ́ nínú ẹkọ́ èdè Yorùbá lágbàyé Ọpọlọ ọmọ mi kò pé, ó ní àìsàn ọ̀nà ọ̀fun, wárápá, tí kò sì rìn lọ́mọ́ ọdún méje àmọ́ pẹ̀lú ìgbàgbọ́, ayọ̀ ló já sí"" Boko Haram tún ṣọṣẹ́ ní Adamawa, ọ̀pọ̀ òkú ṣùn, àìmọye dúkìá jóná Lasìkò to n sàlàyé lóri ìmọ tuntun tó gbékalẹ̀, ó ṣàlàyé pé orin tàkasúfèé tí òun pè ní MATMusic, ni àwọn orin tó ni àwọn ìmọ̀ ìṣìrò ti jẹ ki ó rorùn nínú."
Ṣugbọn Jesu sọ fún un pé.
Eyi ko ṣẹyin ijamba ọkọ to waye agbegbe Ibaka ni Akungba Akoko, nipinlẹ Ondo, to si pa eniyan mẹrindinlogun.
kí olúwarẹ̀ mú iyawo rẹ̀ wá sọ́dọ̀ alufaa, kí ó sì mú ọrẹ rẹ̀ tíí ṣe ìdámẹ́wàá òṣùnwọ̀n efa ìyẹ̀fun ọkà baali wá fún alufaa.
Oríṣun àwòrán, Facebook/SEyi Makinde Ipade naa gẹgẹ bi agbẹnusọ fun olori awọn gomina ilẹ Yoruba, Rotimi Akeredolu to tun jẹ gomina ipinlẹ Ondo, Smart Oyeyemi, yoo jẹ ijiroro lori ọrọ eto aabo Amọtẹkun ti awọn gomina naa gbe dide fun abo ẹkun Iwọ-oorun Naijiria.
 Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, #EndSARS : Àwọn ọ̀dọ́ dáná sun tírélà akẹ́rù tẹrùtẹrù ní Ekiti Lẹyin naa, ko tun fi da wọn loju pe gbogbo awọn to lọwọ ninu ikọlu naa ni ijọba yoo fi imu wọn danrin.
"Àwọn ọ̀nà láti dẹ́kun ìwọ́de ọ̀dọ́ lọ́jọ́ iwájú nìyí Èèyàn 229 ló ti wà ní gbaga òfin fún wàhálà tó wáyé l'Eko Ìdílé ọba Akinsemoyin fáwọn jàǹdùkú lọ́jọ́ kan péré láti dá ọ̀pá àṣẹ tí wọn gbé padà ""Apena fẹ́gbẹ́ Oṣugbo, Opa, Akala àtẹ̀yin awo, ẹ wa ọ̀pá àṣẹ Ọ́ba Akiolu jáde"" Idile ọba Akinsemoyin ti Lagos Island ti dide si ọrọ ọpa asẹ Ọba Eko, Rilwan Akiolu ti awọn janduku kan ji gbe lọ lọjọru."
atunse si awon ti won fesun kan pe won hu iwa lati se atako ninu egbe won.
Ọgbẹni Adisa ni ijọba ipinlẹ Oyo ti ṣi owo to fi ra gbogbo eroja atawọn irinṣẹ naa, o si jẹ miliọnu mejilelọgbọn Adisa ni ijọba tun ra eroja ati irinṣẹ to to miliọnu mẹrindinlaadọrun un(N86m) fun ẹka ẹkọṣẹ nipa awọn kokoro aifojuri (Department of Virologyy).
Àwọn oníṣòwò ayé yóo sunkún, wọn yóo ṣọ̀fọ̀ lé e lórí, nítorí wọn kò rí ẹni ra ọjà wọn mọ́; àwọn nǹkan bíi: 
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ado Ekiti Blind Couple: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú Ko tan sibẹ, o ni wọn tun ri pali oogun Uniplex Codein, ti iye rẹ to miliọnu mẹwaa naira, pali Pandeen mẹrin, pali emzoline meji, atawọn ohun ija oloro bii aake, ada ati ogun abẹnu gọngọ.
Ó jẹ́ alágbára ati akọni lójú ogun, ó ní ọ̀rọ̀ rere lẹ́nu, ó lẹ́wà, OLUWA sì wà pẹlu rẹ̀.
Wo bí o ṣe leè lo èròjà agbohùnsílẹ̀ tuntun tí Twitter gbé dé 8.
Ṣugbọn, oṣiṣẹ ajọ Unicef kan, Charlotte Gornitzka sọ pe irọ ni iroyin naa.
A sinmi díẹ̀ nígbà tí a gba gúsù erékùṣù kékeré kan tí ó ń jẹ́ Kauda kọjá.
Ilé aṣòfin Amẹ́ríkà yarí August Agboola Brownie, ọmọ Yorùbá tí wọ́n n wárí fún ní Poland Bí gbogbo ayé ṣe wá n ronu lórí àwọn èròjà ara tó le gbógun ti ààrun covid yìí, àwọn oníwàdìí ìmọ̀ sáyẹnsì míràn ti ri pé, èròjà kan wà nínú ara ti o le wúlò.
Mose pe gbogbo àwọn ọmọ Israẹli jọ, ó sọ fún wọn pé: “Ẹ ti rí gbogbo ohun tí OLUWA ṣe sí Farao ati àwọn iranṣẹ rẹ̀, ati gbogbo ilẹ̀ rẹ̀, ní ilẹ̀ Ijipti.
Ṣaaju akoko naa, awọn janduku kan ti rapala wọn saarin awọn oluwọde, ti wọn si kọlu ọọfisi ileeṣẹ ọlọpaa to wa ni Orile, ti wọn si dana sun.
 nípa lílo ìwé yìí , èdè-ìperí á kúrò ní àkọ ́ sórí nìkan : kódà , á á di ohun tí akẹ ́ kọ ̀ ọ ́ àti olùkọ ́ mọ ̀ dénú , tí wọ ́ n sì lè ṣàlàyé rẹ ̀ fún ẹlòmíràn .
Atẹjade kan ti ẹgbẹ oselu PDP fisita lọjọ ayajọ aarẹ naa wa kesi Buhari lati tete wa aforijin lọwọ awọn ọmọ orilẹede yii dipo ko maa se ajọyọ ọjọ ibi.
Ilé náà sì wó lu gbogbo àwọn ọba Filistini ati gbogbo àwọn eniyan tí wọ́n wà ninu rẹ̀.
Hadi Sirika, Chris Ngege, Rotimi Amaechi, Babatunde Fashola, Ogbonnaye Onu, Lai Mohammed Adamu Adamu, Geofrey Onyema, Zinab Ahmed ati Osagie Ehimere ni awon minisita to ba aare sise ni saa to koja Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Yato si olokan-o-jokan ayeye ti won ti la kale lati sami ayajo ojo eto isakoso ijoba tiwa-n-tiwa fun odun 2018 ti a wa yii, Aare Muhammadu Buhari yoo tun ba awon omo orile-ede Nigeria soro lojo-Isegun ni deedee agogo meje owuro.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Abuja Protest: À ń ṣe ìwádìí lórí àwọn obìnrin tí wọn mú nítorí aso péńpé 4 Èbibi 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 5 Èbibi 2019 Àkọlé àwòrán, Abuja Protest: À ń ṣe ìwádìí àwọn lóri àwọn tí wọn mú obìnrin nítorí ìwọsọ wọn Ilé iṣẹ́ ọlọ́pàá ti fẹ̀sì lórí ìfẹ̀honu han tí awọn kan ń ṣe lárọ satide oni lóri mímú ti àwọn ọlọpàá mu awọn obinrin ti wọn ni wọn wọ aṣọ pénpé lọ si ode ijo ní ìlú Abuja.
 Ìmọ ̀ lára-àìsàn yìí máa n wá lemọ ́ lemọ ́ lára bí i ìdá mẹ ́ wàá sí mẹ ́ ẹ ̀ dógún ninu ọgọ ́ rùn ún ènìyàn láàrin oṣù mẹ ́ fà lẹ ́ hìn tí àìsàn náà bá ti kọ ́ kọ ́ kọluni .
Àmọ́ nígbà tí mo wo ibi ọwọ́ rẹ̀ wà, mo rí kiníkan pẹlẹbẹ tó gbé lé itan, tí ó nfi àwọn ìka ọwọ́ rẹ̀ kan.
Kò sí àbùkù kankan rárá lára rẹ̀ bí ti í wù kó mọ, láti orí títí dé àtẹ́lẹsẹ̀ rẹ̀.
Ewe, iko Naijiria yoo maa fojusona lati tun fitan miran bale ti yoo koja eyi ti orile-ede ohun ni tele ninu irufe idije naa ti o waye lodun 1994 ni  Canada, leyin ti won gba ami-eye mẹ́tàdínlógójì  ninu idije naa.
Lẹyin naa lo pada wale lati ṣiṣẹ ni ileeṣẹ Oando.
Omo Naijiria, Ayodele Balogun, ti opo eniyan mo si Wizkid ti gbarada.
Nígbà tí wọ́n dé ilé èrò kan ní ojú ọ̀nà Ijipti, OLUWA pàdé Mose, ó sì fẹ́ pa á.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù India: Ọkùnrin kan yọ kindinrin ìyàwó rẹ 8 Èrèlè 2018 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 25 Èbibi 2020 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Obinrin naa ni wọn yọ kindinrin oun lai sọ fun oun Ọwọ awọn ọlọpaa ti tẹ ọkọ obinrin kan to jẹ ọmọ India ati aburo ọkọ rẹ ọkunrin kan lẹyin to sọ fun awọn ọlọpaa wi pe awọn mejeeji ji kindinrin ohun lati fi rọpo owo ori.
Ajọ iṣọkan agbaye, United Nations ni pe o to ida mẹfa ninu ọgọrun un awọn eniyan orilẹ-ede Uganda lo ni arun kogboogun HIV.
odun ti a wayii, lati ropo Ibrahim Idris, ti o feyin ti lenu ise leyin ti o pe
Amọ ko sai yan pe, arọwa oun fawọn ọkunrin lati maa tẹ jẹjẹ pẹlu awọn aya wọn ko tumọ si pe, oun n fun awọn obinrin lasẹ lati maa siwahu, sugbọn ohun ti oun n sọ ni pe awọn obinrin nilo ikẹ ọkunrin.
Nínú àtẹjáde ti àgbẹnúsọ ọlọ́pàá ìpińlẹ̀ Ajayi Okasanmi fọ́wọ́sí sàlàyé pé kọmísọnà ọlọ́pàá ló paá láṣẹ pé ki wan lọ rọkún nile wọ́n.
Nígbà mìíràn, àwọn èsùn náà àti ìjìyà ẹṣé máa wá láti ọ̀dọ̀ mọ̀lébíi wọn.
Oríṣun àwòrán, @lasemasocial Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Sidibe tenumo pe, yiyan sipo abileko Buhari yoo salekun akitiyan ijoba orile-ede Naijiria lati ji giri si ojuse re lori oro aarun  kogbogun HIV lorile-ede Naijiria.
Bi o se n gbiyanju lati wa ọkada naa kuro nibẹ, ni ko le lọ mọ, to si subu lati ori ọkada.
Àwọn àgbàgbà òkè ọya ń fẹ́ kí Ààrẹ Buhari kọ̀wé fipò sílẹ̀ Irọ́ ni, abẹ́rẹ́ àjẹsára Covid-19 kò lè ṣàyípadà DNA rẹ Báwo ní gbogbo àgbáyé ṣe lè gba abẹ́rẹ́ ajẹ́sara àrún Coronavirus?
Sáájú ni àwọn onímọ̀ sáyẹ́nsì sàkíyèsí pé, ẹni ti ko ni ààrùn covid-19, tabi tó si rùú là, kò ní èròja to n bá kòkòrò wọ ìyájà lára.
Awọn ipinlẹ yii lee ṣe pataki to bẹẹ ti awọn oṣiṣẹ ajọ eleto idibo ti ni kika rẹ le to ọjọ melo kan.
“igbejo ko le seese lojuna iku, eyi si se pataki nitori ti nkan ba se, orun awon osise alaabo ni yoo wa.
Minisita fun eto iroyin ati asa lorile-ede Naijiria  , Alhaji Lai Mohammed, so wi pe ohun iyalenu ,ti o si tabuku ba eto abo  ni eyi je.
Ó fojú tẹmbẹlu gbogbo ohun gíga,ó sì jọba lórí gbogbo àwọn ọmọ agbéraga.
Kò pẹ́ lẹ́yìn èyí wọ́n gbọ́ àkùkọ kan kọ́, wọ́n sì mọ̀ pé etí ìlú kan ni àwọn wà.
Mo ń wẹ̀ ṣùgbọ́n ewé ni kànìnkàn mi; èyí tí ó burú jùlọ lára mi pátápátá ni irun orí mi ti ó kún àti ’rùngbọ̀n mi ti ó kún tó bẹ́ẹ̀ ti òun àti irun ori mi pàdé ara ti wọ́n bò mi lójú tó bẹ́ẹ̀ tí ó fi jẹ́ pé ṣe ni ojú mi ń dán yinrinyinrin nínú lọ́hùn-ún tí ó sì dàbí ẹni pé irun kọ́ ilé fún ojú mi ni.
Ǹjẹ́ fáàrí àáké lè pọ̀ ju ti ẹni tí ó ń fi gégi lọ?
A gbàgbọ́ pé nípa oore-ọ̀fẹ́ Jesu Oluwa ni a fi gbà wá là, gẹ́gẹ́ bí a ti fi gba àwọn náà là.
Nítorí náà Dafidi kó àwọn ọmọ Israẹli jọ láti Ṣihori ní Ijipti títí dé ẹnubodè Hamati láti lọ gbé Àpótí Majẹmu Ọlọrun láti Kiriati Jearimu lọ sí Jerusalẹmu.
wàrà tí yóo máa rí fún yóo pọ̀ tóbẹ́ẹ̀ tí ó fi jẹ́ pé wàrà ati oyin ni yóo máa fi ṣe oúnjẹ jẹ.
Odunlade Adekola, Femi Adebayo, Jenifa ṣi aṣọ lójú àwọn fíìmù tuntun tẹ́ẹ tiń retí Àwọn ọmọ Naijiria ṣèdárò gbajúgbajù agbábọ́ọ̀lù Super Eagles tó dolóògbè Ọmọ Ààrẹ lẹ́tọ̀ọ́ láti ṣe ìgbéyàwó yálà àwọn ará ìlú fẹ́ràn ìjọba bàbá rẹ̀ tàbí bẹ́ẹ̀ kọ́ - Aisha Buhari Aya gómìnà Kwara gba ilé fún Risikat olójú búlúù àti ọkọ rẹ̀ Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Fídíò, Àṣìṣe ọlọ́pàá àti Adájọ́ sọ mí di ẹni tí wọ́n dájọ́ ikú fún, ọpẹ́lọpẹ́ Fayoṣe tí ko buwọ́lù ú5 Owewe 2020 Fídíò, Akomolede: Bolaji Faleke ni Olùkọ́ tó ń kọ́ wa ní àṣà oge ṣiṣe lórí BBC Yorùbá1 Owewe 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 3 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 5 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Àwọn ìwádí fi hàn pé ìabáṣepọ̀ wà láàárín elé yìí àti ọpọ ìrọ̀nú, sísanra jù, àìsan sug àìsàn ọkàn àti àìsàn jejere .
Aarẹ Buhari wa pe gbogbo ọmọ Naijiria lati wa ni isọkan lodi si awọn agbesunmọmi yii ki wọn ma si faaye gba awọn ọrọ to le ran ẹgb agbesunmọmi Boko Haram ati ISWAP lọwọ.
 Ìdàgbàsókè tí ń dé bá ohun èlò eré àpíìrì .
Koda, idanilẹkọ wọn gan ko ni orogun.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ìròyìn Yàjóyàjó : Donald Trump àti ìyàwó rẹ́ ti lùgbàdì àrùn CoronaVirus Ìfẹ́ Yorùbá ló mú mi fi ẹ̀mí wéwu láti kojú ajínigbé ní Kishi - Sunday Igboho Buhari, ayẹyẹ kí là ń ṣe gan, ṣé ti ìpànìyàn àbí ìjínigbé?
Ṣugbọn Jesu fúnrarẹ̀ kò gbára lé wọn, nítorí ó mọ gbogbo eniyan.
Pataki ayajọ 'Ma wọ kọmu' fawọn obinrin Naijiria: Ọjọ 'Ma wọ kọmu' yii lo n seto itaniji fawọn obinrin nipa aisan jẹjẹrẹ ọyan, nitori a gbọ pe kọmu awọju gan lee fa aisan jẹjẹrẹ ọyan Ọjọ yii ni wọn tun fi maa n seto ikowojọ fun isẹ iwadi lati gbogun ti aisan jẹjẹrẹ ọyan Bakan naa tun ni ọjọ 'Ma wọ kọmu' wa lati ran awọn obinrin leti pe ki wọn lọ se ayẹwo ọyan wọn aibaamọ, aisan jẹjẹrẹ ti lee ba wọn ni alejo laimọ Ọjọ 'Ma wọ kọmu' yoo tun jẹ ki awọn obinrin ti wọn ba tete kẹẹfin aisan jẹjhẹrẹ lara wọn lasiko ayẹwo lee tete ri itọju gba lati ka ọwọja ọsẹ aisan naa ko Awọn igbesẹ to yẹ lati tete ka ọwọja aisan jẹjẹrẹ ọyan ko: Igbesẹ akọkọ ni sise ayẹwo ọyan obinrin loore koore, paapa ni ẹkan losu kan, igba to si dara julọ lati se ayẹwo ọyan ni ọjọ kẹwa lẹyin ti obinrin ba pari nkan osu rẹ Asiko ta n se ayẹwo ọyan losoosu ko gbọdọ yatọ, to si gbọdọ bara dọgba eyi ti yoo se iranwọ lati tete ri esi ayẹwo to daju Awọn obinrin ti ko ba se nkan osu gbọdọ mu ọjọ kan losoosu ti wọn yoo maa se ayẹwo ọyan wọn Lasiko ayẹwo osoosu yii, o mọ bi ọyan rẹ se tobi si, bo se se mulọ-mulọ si ati bi awọ rẹ se ri, eyi ti yoo jẹ ko tete mọ bi ayipada kankan ba de sara ọyan rẹ To ba lọ se ayẹwo agọ ara rẹ nile iwosan, obinrin gbọdọ ri daju pe awọn osisẹ eleto ilera se ayẹwo ọyan fun oun lọna to peye, ti ẹnikọọkan si gbọdọ mọ baa ti se ayẹwo ọyan funra ẹni Buhari ti fòfin de àwọn mínísítà láti rìnrìn àjò lọ sí ilẹ̀ òkèrè Àbà ètò ìṣúná 2020 tó kéré yóò mú kí ètò ààbò mẹ́hẹ síi ní Nàìjíríà-Onwoye Ìjọba, ẹ yé fi ẹ̀tọ́ ọmọnìyàn dun ọmọ Nàìjíríà mọ́- SERAP Kìí ṣé òjò àrọ̀rọ̀ọ̀dá nìkan, ọkọ̀ aképo tó dànù náà fà súnkẹrẹ-fàkẹrẹ l'Eko Nibayii ti ayajọ ọjọ 'Ma wọ kọmu' tun ko loni, a n rọ gbogbo obinrin lati se ayẹwo ọyan wọn nitori ijafara lewu, ati okeere si ni oloju jinjin ti n mu ẹkun sun.
Amọ laipẹ yii ni ijọba apapọ kede pe ko sewu loko afi giri aparo nipa gbese ti orilẹede wa Naijiria jẹ silẹ okeere.
Ki ijọba ni gboogbo ipele mu opin wa si eyi, ki Eleduwa to rọjo ibinu rẹ le orilẹede lori.
Sibẹsibẹ ó ru ẹ̀ṣẹ̀ ọpọlọpọ eniyan,ó sì bẹ̀bẹ̀ fún àwọn ẹlẹ́ṣẹ̀.
12 Sẹ́rẹ́ 2019 Àkọlé àwòrán, Níbo láyé kọjú Àwọn alejo lori eto 'Níbo láyé kọjú' ti BBC Yoruba jẹ ko di mimọ pe ibi ti o ba kọ si onikaluku ni yoo fi mọ ohun ti o fẹ lara ẹni ti o ba fẹ fẹ.
3 245789 Orilẹede Kazakhstan 2882 15.
Ko si ikini ayẹyẹ ọjọ ibi, paapaa fun Oba Adeyemi nibẹ, nitori ọsẹ mẹta sẹyin ni ọjọ ibi Kabiesi, ti ko si han pe Olori Anu ki Kabiyesi ku ayẹyẹ ọjọ ibi rẹ gẹgẹ bi awọn olori yoku ti se.
Nigba ti o BBC Yoruba sọrọ, akọwe agba ẹgbẹ awọn agbẹ to jẹ ọdọ(Young Farmers Association of Nigeria - YFAN), Adeleke Opeyemi jẹri sii pe iyan n bọ lorilẹede Naijiria lẹyin ti aarun coronavirus ba kasẹ nlẹ.
Ninu ọrọ to fi tẹle fnran fidio ati aworan boti ṣe farapa yi han, Mide sọ pe ''Igbesi aye awa oṣere tiata ko dẹrun!
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Amugbalẹgbẹ fun Gomina Akeredolu, Ọmọwe Doyin Ọdẹbọwale koro oju si Bakan naa, agbẹnusọ igbakeji gomina ni irọ patapata ni gbogbo rẹ.
nitori iwa yii le ṣalekun ipenija airiṣẹṣe to n koju orilẹ-ede yii bayii.
Bí ẹ bá ṣe èyí, ẹ óo sọ ilẹ̀ yín di aláìmọ́ nítorí pé ìpànìyàn a máa sọ ilẹ̀ di àìmọ́.
O kò gbọdọ̀ jáde lọ sí ibìkankan.
àwọn ìbaaka wọn jẹ́ ojilerugba ó lé marun-un (245), 
awon omode nitori laisi oju gbogbo eya ara yooku lo wa ninu okunkun.
Saraki lo saa meji gẹgẹ bi gomina ipinlẹ Kwara, ti i ṣe ọdun mẹjọ.
O ni ijoba to wa nikale bayii ti gbiyanju lori abo.
Nígbà tí ó fẹ́rẹ̀ tó àkókò Àjọ̀dún Ìrékọjá àwọn Juu, Jesu gòkè lọ sí Jerusalẹmu.
”Àwọn eniyan náà dáhùn pé, “Bẹ́ẹ̀ ni, OLUWA ni ẹlẹri wa.
Nigba to jẹ pe awaye ku ko si, Bamidele Olumilua jẹ ipe Ọlọrun ni owurọ kutu hai Ọjọru, ọjọ Kẹrin oṣu Kẹfa ọdun 2020 lẹni ọgọrin ọdun nilu rẹ, Ikere Ekiti.
Ìbò kan ṣoṣo ló Serah Jibril ní nínú ìbò ọdun 2011.
"Awọn ọmọ olowo, oniwakuwa, ti wọn o lẹkọọ lo da ẹgbẹ ti wọn ti wọn n pe ni ""Fraternity""."
Ọgbẹ́ni Rice sọ pe ìdí si niyii ti awọn alamojuto eto owó nina nilẹ Europe ṣe n lo ilana 'ka wo ibi ti yoo ja si'.
Ọrọ di boo lọ, ko ya fun mi nibi iwọde l’Eko Àwọn ọlọpaa ti fi afẹfẹ taju-taju tu awọn olufẹhonuhan Revolution Now ka nipinlẹ Eko.
Amọ, ile ẹjọ kotẹmilọrun nipinlẹ naa ati ipinlẹ Kaduna da ẹjọ naa nun, eyi lo jẹ ki Aliyu mori le ile ẹjọ to ga julọ l'Abuja.
Awọn agbofinro ni ẹkun Jos ni awọn ko tii le sọ ohun to ṣokunfa ile to wo naa.
Oloogbe Ishola jẹ ẹni ti o gbajumọ fun iṣẹ iwe-kikọ rẹ ati igbega ede Yoruba.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Donald Trump gbìyànjú nípa ètò àlááfíà ló jẹ́ kí n fàá kalẹ̀ fún àmì ẹ̀yẹ Nobel Peace Prize- Christian Tybring- Gjedde 9 Owewe 2020 Oríṣun àwòrán, Reuters Wọn ti fa Aarẹ ilẹ Amerika, Donald Trump kalẹ fun ami ẹyẹ Nobel Peace Prize ti ọdun 2021.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Akure: Deji Akure, Oba Aladelusi Ogunlade ti pàṣẹ kí gbogbo ọjà wà ní títì pa fún ọjọ́ méjì nítorí àjọ̀dún ìṣẹ̀mbáyé méjì 21 Ògún 2020 Oríṣun àwòrán, DEJI of AKURE Kingdom Deji ilu Akurẹ, Ọba Aladelusi Ogunlade ti kede pe ki Ọja gbogbo ni ilu Akurẹ o wa ni titi pa fun awọn ọjọ meji kan bayii.
O ni eyi to fi mọ sise iranlọwọ fun awọn alagbata ati awọn olokooowo to n ta fiimu wọn sita a tun jẹ ki iṣẹ naa rọrun sii.
Atundi ibo naa yoo waye lati rọpo aaye to gbofo lẹyin ti Sẹnetọ Adebayo Osinowo papoda ninu oṣu kẹfa ọdun yii.
“Kí ó jẹ́ ìlànà fun yín títí lae pé, ní ọjọ́ kẹwaa oṣù keje, ati onílé ati àlejò yín, ẹ gbọdọ̀ gbààwẹ̀, ẹ kò sì gbọdọ̀ ṣe iṣẹ́ kankan.
O ni agbekalẹ igbimọ tẹẹkoto naa yoo wa lati wa ọna ti ẹkunwo oṣu tuntun naa yoo fi waye laisi pe awọn ẹka ijọba gbogbo n ti ọrun bọ oko gbese Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
18 Òkùdu 2019 Oríṣun àwòrán, WIKIPEDIA Àkọlé àwòrán, Awọn Yoruba mọ ẹgbẹ Agbẹkọya gẹgẹ bi ẹgbẹ tó jẹ́ àgbà fun ẹgbẹ OPC tó ń jà fun ẹtọ́ awon ọmọ Yoruba.
Eniyan kò lè máa gbé ninu ọlá rẹ̀ títí ayé,bí ẹranko tíí kú, ni òun náà óo kú.
  Ajẹ́pé àwọn ẹyìn ti pọ́n, tí wọ́n sì rẹ̀ dà sílẹ̀ káàkiri.
Nigba to di osu Kẹrin, ọdun 1949, igbimọ olugbẹjọ dide ni gbọngan Obokunbusi to wa nilu Ilesa, eyi ti adajọ Majisireti WO Egbuna ko sodi.
A ti tẹsẹ̀ bọ inú ìgboro rẹ, Jerusalẹmu.
wọ́n kígbe pé, “Ọ̀gá, Jesu, ṣàánú wa.
Apapọ owo isuna naa si lo le diẹ ni igba biliọnu naira (208,802,972,878.
"Fún àpẹẹrẹ lójú òpò Twitter, ènìyàn kan sọ pé ""bí ó bá jẹ́ lóòótọ́ ni Mínísítà fún ètò ìsúná kò ṣìnrú ìlú tí ó sì mú ayédèrú ìwé ẹ̀rí jáde, kò tọ́ sí ipò tí ó wà bẹ́ẹ̀ sì ni wọ́n gbúdọ̀ rọ̀ọ́ lóyè."
    “Òkè Ìrònu jìnà púpọ̀, bí ènìyàn bá  bá tilẹ̀ dé Igbó Elégbèje tán, Olúwarẹ̀ níláti rìn jìnà dáadáa kí ó tó le dé ìlú náà.
Eeyan 46,577 ni apapọ ni arun naa ti fara kan labẹ ayẹwo, ti awọn 33,186 si ti ri iwosan gba lọwọ ajakalẹ arun ọhun.
Ohun tí a óo ṣe nìyí, gègé ni a óo ṣẹ́ láti mọ àwọn tí yóo gbógun ti Gibea.
Ẹkọ ti Omotara ti kọ bayii Motara ni laye oun, oun ti kọ ẹkọ pe kii ṣe gbogbo nkan ni yẹyẹ teeyan gbudọ maa fi rẹrin.
Haliru Bello Haliru, to jẹ alagba ẹgbẹ oṣelu PDP tẹlẹ ni ajọ EFCC fẹsun mẹrin to jọ mọ didari owo ijọba si apo ara rẹ kan lọdun 2015.
Sofari, ará Naama bá dáhùn pé,
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ipaniyan Zamfara: Ile isẹ ọlọpaa kede mimu afurasi meta 19 Èrèlè 2018 Oríṣun àwòrán, @PoliceNG Àkọlé àwòrán, Ọga patapata ile isẹ ọlọpaa ti se abewo silu Zamfara.
eto isejọba to see mu yangan , ni eyi ti ẹni to ba n bọ lẹyin mi , ko se ni
Pinnick fehonu re han lasiko abewo re si olu ile-ise ile ifowopamo naa.
Ogbeni Adamu Edward Lametek lo ṣoju fun gomina Godwin Emefiele, oun lo wa sọ bi banki apapọ yoo ṣe naa owo iṣuna naa.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Mí ò ya wèrè, mí ò burú, ọ̀nà àtijẹ là ń wá' Ẹyin iku ọkọ rẹ, si ni Mama Rainbow bẹrẹ ere siṣe ni ẹkunrẹrẹ.
lati asuwon ile okeere sọdọ rẹ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Seun Kuti: Seun, ọmọ Fela, lóòtọ́ lóun yìnbọn níbi yánpọnyánrin pẹ̀láwọn tó wa ọkọ̀ dí ilé òun, àtipé bó jẹ́ ìjọba àpapọ̀ ló ṣ'àìtọ́ nílé òun ìbọn á sọ 13 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 14 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Seun Kuti, ọmọ agba ojẹ olorin Fẹla Kuti ti ṣalye faraye gbọ pe nipa wahala to ṣẹlẹ ni agbegbe rẹ lalẹ ọjọ Satide to fa yanpọnyanrin.
Ṣùgbọ́n, àwa ènìyàn lápapọ̀ mọ ìwúlò ìbágbépọ̀.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Ǹkan tó jẹ́ kí iṣẹ́ ọ̀nà tèmi yàtọ̀ lágbàáyé ni ǹkan tí mò ń lò' Nigba to ya, baba baba rẹ gbọ si ẹbẹ rẹ o si mu u lọ forukọ silẹ ni ileewe alakọbẹrẹ kan ni ilu to n jẹ Woreta.
Àwọn tí wọ́n pada ti oko ẹrú dé gba ìmọ̀ràn yìí.
Ẹ sọ ọ́ ní òkúta pa nítorí tí ó ti gbìyànjú láti fà yín kúrò lọ́dọ̀ OLUWA Ọlọrun yín, tí ó mu yín jáde kúrò ní oko ẹrú ní ilẹ̀ Ijipti.
" Nkrumah tẹsiwaju pe ọrọ ti Lai sọ nipa ibasepọ Naijiria pẹlu Ghana lo kọ awọn lomiinu julọ.
Ninu Atejade kan ti aare egbe osise,lorile ede Naijiria , Ayuba Wabba gbe jade , pe inu oun baje  nipa isele buruku to waye ni awon  ijọba ibile Barkin-Ladi,Riyom, ati agbegbe to wa ni ipinle Plateau,nibi ti awon eniyan to le ni  mẹ́rìndínláàdọ́rùn ún padanu emi won, ni eyi ti awon eniyan so pe awon odaran lo seku pa awon eniyan naa lojo isinmi.
Oró ejò ni ọtí wọn,àní oró paramọ́lẹ̀ tíí ṣe ikú pani.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Kí ló ma n fa Àkúfà nílẹ̀ Yorùbá, àti ọ̀nà àbáyọ?
Ogbeni Ibn Ouf so pe “Won yọọ kuro lori aleefa” 
Ilé isẹ́ ààrẹ ní ọgá àgbà ilé iṣẹ́ tó n ri sí owó orí lórílẹ̀-èdè Nàìjíríà, Babatunde Fowler ko si lábẹ́ ìwádìí kankan lódi si bi àwọn ilé iṣẹ́ ìròyìn kan ṣe ń tan kiri.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Tani Winnie Mandela tó d'olóògbé?
Gẹgẹ bi atjade naa ti ṣe sọ, o ni ọba Vajiralongkorn  ti pinu lati mu agbega ba ọgagun Suthida Vajiralongkorn Na Ayudhya, to jẹ ẹni ayo rẹ si ipo olori ti yoo si di ipo yi mu gẹgẹ bi olori laafin'' Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Oluwo: Mo lè jẹ Ọba ní Ile Ife O ti pẹ ti awọn ara ilu ti mọ olori Suthida gẹgẹ bi wọlewọde Oba bo ti lẹjẹ wi pe wọn ko sọ sita pe awọn n fẹ ara wọn."
    Mo ba ko àwọn èso méjéèjì, mò ń bọ̀, bí mo sì ti j;ade sí ilú òké Ìrònú ni mo pàdé iwin kan tí ó ni ojú méje, tí ojú wọ̀n-ọnnì tò yi gbogbo agbárí rẹ̀ ká, òun ni ó mú ìwé kan fún mi.
Àbí gbogbo yín ni ẹ lè túmọ̀ àwọn èdè àjèjì?
Oríṣun àwòrán, AFP Àkọlé àwòrán, O ni oun ko lọwọ ninu ẹsun iwa ole ninu ibo Lọdun to tẹle e, Bouteflika gbe apoti ibo fun saa kẹta o si ni ida aadọrun ninu ọgọrun ibo eyi si tun mu ki ẹgbẹ oṣelu alatako tun ri wi nipa iwa ole idibo.
Kí ló yẹ kí ílẹ̀ India se sí ẹkùn tó pa ènìyàn márùn ún?
Kí ahọ́n mi lẹ̀ mọ́ èrìgì mi,bí n kò bá ranti rẹ,bí n kò bá sì fi Jerusalẹmu ṣe olórí ayọ̀ mi.
"Ta ba wo iwọde naa, a ri pe awọn ọdọ ti gba akoso orilẹede yii, lati ọjọ akọkọ iwọde, si ni wọn ti se afihan pe awọn ni abuda asaaju rere.
Atẹjade naa fi kun pe ile iṣẹ ba ẹbi oloogbe oun kẹdun o si bẹ eedua ko fun wọn ni opre ofẹ lati bori iṣẹlẹ ajalu yii Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 3 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 5 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Nibi ti wọn ti n lọ, ni wọn ba awọn ẹlẹyẹ lọna to n ṣe ipade.
Nigba ti alukoro ajọ onidanwo aṣekagba girama, WAEC, Ọgbẹni Damian ba ileeṣẹ BBC News Yoruba sọrọ, o ni ohun ti awọn n reti bayii naa ni awọn ilana ti ijọba apapọ atawọn ijsba ipinlẹ ba fẹnuko le lori.
Ẹlẹ́wọ̀n Kirikiri tó ń wọ́ke, olùdarí ọgbà ẹ̀wọ̀n ló ṣe onígbọ̀wọ́ fun - EFCC Akẹ́kọ̀ọ́ mẹ́fà tó lu akẹẹgbẹ́ wọn ní fásitì FUTA dèrò ilé Ìdájọ́ Dikko bófin mu, kò sẹ́ni tí kò lè bẹ̀bẹ̀ láti dá owó tó jí padà"" Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí kan sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn."
Kò fi ìgbà kankan ronupiwada bí baba rẹ̀ ti ṣe níwájú OLUWA.
ko tọọ, o si lodi si ofin to gbe Olubadan ile Ibadan, Oba Saliu Adetunji, Aje
Kí ló le è mú kí agbábọ́ọ̀lù subú, kó sì kú lásìkò ìfẹsẹ̀wọ̀nsẹ̀?
Ni orilede India aṣọ ti wọn n pe ni Sari tabi sikẹẹti gigun bulaosi àti sikafu ni wọn maa n wọ gẹgẹ bi aṣọ igbeyawo.
Ileesẹ iroyin PRNigeria sọ wipe ẹda-iwe ẹsun ti wọn kọ si Magu ati Keyamo ti tẹ oun l'ọwọ.
Ẹyẹ yìí bẹ̀rẹ̀ sí fò káàkiri títí tí omi fi gbẹ lórí ilẹ̀.
1 1125 Ọkọ oju omi Diamond Cruise 13 712 Erekusu Bermuda 12 19.
síbè a gbódò lè sàlàyé bí ( 55 ) se wáyé .
Duncan Mighty: Ọlọ́pàá fi pampẹ́ mú olórín tàkasúfèé lórí ẹ̀sùn jíbítí mílíọ̀nù mọ́kànlá
N óo tú ẹ̀mí mi sórí àwọn ọmọ yín,n óo da ibukun mi sórí arọmọdọmọ yín,
Ní ti àwọn ọ̀tá mi wọnyi, àwọn tí kò fẹ́ kí n jọba, ẹ mú wọn wá síhìn-ín, kí ẹ pa wọ́n lójú mi!
Gẹgẹ bi iroyin ṣe sọ ọ, nigba ti wọn de ibudo idibo, eeyan mọkandinlaadọrun ni wọn ba to ti dibo ṣugbọn wọn ko tilẹ ri arakunrin kan nibẹ bẹẹ si ni ko buwọ̀ rẹ luwe idibo.
Wolii náà bẹ̀rẹ̀ sí sọ̀rọ̀ ìkìlọ̀ sí pẹpẹ náà, ó ní, “Ìwọ pẹpẹ yìí, ìwọ pẹpẹ yìí, gbọ́ ohun tí OLUWA wí, ó ní, ‘Wò ó!
Ọkunrin náà bá ń wò wọ́n, ó ń retí pé wọn yóo fún òun ní nǹkan.
Awọn oluworan ba yanu lẹẹ bi aja mi lo paa nitori ko si ẹni to ro pe nnkan yoo yi biri fun Bryan to jẹ alako Kingston.
Wọn fi ẹsun kan an pe o lọwọ ninu iṣekupani awọn ọmọ ile iwe to to ọgọrun un lasiko iṣejọba rẹ.
Wọ́n Mú Jeremaya Lọ sí Ijipti.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ṣẹ̀ s’ófin ìrìnà l‘Eko, ko fi ẹ̀wọ̀n ọdún mẹ́ta jura - Ìjọba Eko Iṣẹ́ bẹ̀rẹ̀ ní òpópónà Eko si Abeokuta Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Awakọ̀ 3rd Mainland Bridge: Ìjọba ko yanjú súnkẹrẹ fàkẹrẹ ọ̀nà Apapa Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Wọ́n sìn wọ́n jáde, wọ́n bá rọ̀ wọ́n pé kí wọ́n kúrò ninu ìlú.
De Bruyne gba ami ẹyẹ naa mọ Trent Alexander-Arnold, Jordan Henderson ati Sadio Mane lati Liverpool, Danny Ings ti Southampton, ẹlẹsẹ ayo Leicester, Jamie Vardy ati aṣọle Burnley Nick Pope lọwọ.
Nítorí pé, a óo yọ àwọn tí wọ́n bá ṣe àwọn ohun ìríra kúrò láàrin àwọn eniyan wọn.
Àwọn ọmọ onílẹ̀ àti ọlọ́pàá jọ gbìmọ̀ pọ̀ láti gba ilẹ̀ mí- Guru Maharaj Ji Ó ṣeéṣe kí àrùn Coronavirus tànkálẹ̀ gba inú afẹ́fẹ́- WHO Àwọn ilé ìwé Unity School kò ni kópa nínú ìdánwò WAEC nítorí Coronavirus - Ìjọba àpapọ̀ Nǹkan tí ojú rí rè é bí pápákọ̀ òfurufú ṣe di ṣíṣí padà ní Nàìjíríà Oni ọjọ kẹjọ, oṣu Keje, ni irinajo oju ofurufu labẹle yoo bẹrẹ pada ni Naijiria.
Ó ní ihamọra bàbà ní ẹsẹ̀ rẹ̀, ó sì gbé ọ̀kọ̀ bàbà kan sí èjìká rẹ̀.
Kí ẹ mọ̀ dájú pé mo wà pẹlu yín ní ìgbà gbogbo, títí dé òpin ayé.
India: Ọmọ ọdun méje gbé bàbá rẹ̀ lọ àgọ́ ọlọ́pàá nítori ilé ìgbọ̀nsẹ̀
Ọjọ Iṣẹgun ni Gomina Gboyega Oyetola tun kede afikun ọjọ mẹrinla si isede naa.
Yatọ si bi awọn ti isaaju ni orilẹ-ede Naijiria, wọn lo ọjọ mọkandinlọgọrun un ninu ile naa.
Gomina naa fi ero rẹ han lẹyin ti o ri esi iwadii ti ijọba gbekalẹ lati ṣe ayẹwo awọn oṣiṣẹ ijọba ibilẹ naa.
Iroyin so pe, ile-ise ipese ina nipinle Benin ni o ni iko ti o poju lo fun awon ara-ilu, tori pe ipinle naa ni o ni iko mokandinladorin ninu ida ogorun mita fun awon ara-iluIroyin ohun tun safinhan pe, ipinle Eko ni o tun tele ipinle Benin pelu iko ogota ninu ida ogorun mita, eyi agbegbe ikeja nipinle naa ni iko merindinladota ninu ida ogorun mita ti awon ara-ilu n lo.
Nigba to n ba BBC Yoruba sọrọ, Murphy ni lootọ ni ọmọ isẹ gbajumọ olorin Fuji , Wasiu Ayinde, to pe orukọ rẹ ni KC gba oun leti, ti Wasiu Ayinde funra rẹ gan si fi bata tẹ oun ni ori ati ẹnu mọlẹ.
awọn orilẹ-ede yooku ṣe n ṣe.
Ijoba nígbàgbọ́ pé nígbà tí àjàkalẹ̀ ààrùn náà bá dé góńgó àwọn yóò nílò tó ọgbọn ẹgbẹ̀rún Fẹntílàtọ̀, wọn tí pé fún àwọn egberun mewaa tuntun míràn lat ilé ìṣe Dyson.
(Àwọn ọkunrin ninu wọn tó bíi ẹgbẹẹdọgbọn (5,000).
Kẹrẹ-kẹrẹ, lo ba di ọmọ ijọ Celestial.
Ọmọ ẹgbẹ́ òkùnkùn ṣoro ní Ijebu Ode, ọ̀pọ̀ ẹ̀mí sọnù Ara mi rẹwà ló jẹ́ kí n máa ṣí ara sílẹ̀- Victoria Kolawole Èyí ni àwọn aṣíwájú ìjọba tí ajé ìwà ìjẹkújẹ ti ṣí mọ́ lórí láàrin ọdún 1960 sí àsìkò yí Mo ti kúrò ní ààfin Oyo, kí ìròyìn tó ò jáde pé èmi àti Wasiu Ayinde n fẹ́ ara wa - Olori Badirat 6) Ọmọba Damilola Falegan: Damilola ni Adele Ọba ilu Irese, ni ijọba ibilẹ Ifedore, ni ipinlẹ Ondo.
Ìròyìn nípa ìyàwó túntún fún ọkọ mi kò mì mí lọ́kàn rárá-Aisha Buhari Wọ́dà mẹ́jọ lọ rọ́ọ́kún nílé nítorí ikú ẹlẹ́wọ́n márùn ún Uzor Kalu tó jẹ́ àṣojú láti ìpínlẹ̀ Abia rí ẹ̀wọ̀n ọdún méjìlá he Ìbúgbàmú ọ̀pá epo béntíróò mú ẹ̀mí lọ ni Eko Bakan naa ni iwad\\ii ọhun tun fidi rẹ mulẹ pe, ninu gbogbo awọn owo riba ti awọn ọlọpaa, olupẹjọ ijọba, adajọ atawọn ileeṣẹ ologun gba, ida mẹta ninu rẹ lo jẹ wi pe awọn gan an funrawọn lo beere fun un.
Ẹ jẹ́ kí ó da yín lójú pé ẹ kò ní lọ láì jìyà ẹ̀ṣẹ̀ yín.
Ìjọba Ọṣun: Ẹ sowọ́pọ̀ pẹ̀lú wa láti gbé Ọṣun Oṣogbo dé ibi gíga ní 2019
Hazard to ṣe wi pe o ṣẹṣẹ kopa ninu ifẹwọnsẹ mẹta pere lati igba ti saa bọọlu ọdun yi ti bẹrẹ ko lo ju iṣẹju mejidinlọgbọn lọ lori papa ki wọn to gbe e jade.
Ẹkun iwọ oorun ariwa orilẹede Naijiria ni ọwọja kokoro arun naa si ti lọ silẹ julọ.
Orin ọpẹ lo gba ẹnu wn kan.
Ọjọ kejilelogun, Osu Kẹwa ọdun yii ni wọn yoo ma a se idajọ rẹ.
Eyi ni ijọba se lati mọ riri ipa ribiribi to ko si idagbasoke eto okoowo ati ileesẹ nlanla ni Naijiria.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Èmi gan máa ń béèrè lọ́wọ́ ara mi pé ta ni Wole Soyinka gangan' Nǹkan méje tí yóò ṣẹlẹ̀ nìyíí tí ìjọba bá kéde òfin kónílé ó gbélé nítorí coronavirus Oríṣun àwòrán, Getty Images Ofin konile o gbele jẹ ọna kan pataki ti ijọba kaakiri agbaye fi gbogun ti itankalẹ arun coronavirus to n ṣọṣẹ lọwọlọwọ.
Ikú aláìkọlà ni o óo kú lọ́wọ́ àwọn àjèjì, nítorí èmi OLUWA Ọlọrun ni mo sọ bẹ́ẹ̀.
Ikechukwu sọ fun BBC Yoruba pe ni ọjọ Aje, ọjọ keje Osu kinni ni awọn ajinigbe naa gbe awọn oṣiṣẹ ijọba ibilẹ Gbọnhin kan, ati awakọ rẹ gbe, ṣugbọn ileeṣẹ ọlọpaa ti doola awakọ naa lọjọ Aje yii kan naa.
” Ìtumọ̀ èyí ni, “Ọlọrun mi, Ọlọrun mi, kí ló dé tí o fi kọ̀ mí sílẹ̀?
"Afikun ofin yin lo fa ibinu yọ, ti Bisọọbu fi fesi pe: Oyedepo ni: ""Ohun ini Ọlọrun ni ijọ jẹ lorilẹ aye."
"Nigba taa bi dokita ọhun boya o ti ṣe tan bayi bayi ninu asiko arun Coronavirus yii, o dahun pe lọwọ lọwọ, oun n ṣe awọn nkankan lọwọ ṣugbọn ""bi arun Coronavirus wa o tabi ko si, mo ti ṣe tan lati lọ tori lọhun wọn pese gbogbo eto abo fun dokita ju ọdọ wa nibi yii lọ to bẹẹ ti arun naa ko le ran wọn""."
Ọkọ̀ òfúrufú ọlọ́pàá yóò bẹ̀rẹ̀ sí ní káàkiri Naijiria - Ọgá Ọlọ́pàá Àwọn jàǹdùkú pa fadá ní Taraba-Iléeṣẹ́ ọlọ́pàá Ọwọ́ EFCC tẹ ọ̀kan lára àwọn ti FBI fi èsún jìbìtì kàn!
O fikun oro re pe, awon igbese ijoba apapo wonyii ti sadiku iseku-pani ti o n waye nipinle naa.
A ti ṣiṣẹ agbẹ lorilẹede Niajiria ko dẹrun rara nitori aisi iranwọ - Kehinde Olufemi Ọdọ to n ṣiṣẹ Agbẹ lorilẹede Naijiria, Kehinde Olufemi ti wa fesi si ohun ti aarẹ Buhari sọ wi pe, ki awọn ọdọ lọ ma a ṣiṣẹ ọgbin gẹgẹ bi ọna abayọ si airiṣẹse ni Naijiria.
Gege bi ajo ohun se so pe, akosile osuwon ti o jade ninu osu knni odun 2018 din si ti eyi ti o jade ninu kejila odun 2017 .
Ṣugbọn ohun tí OLUWA sọ nípa Sedekaya ọba Juda, ati àwọn ìjòyè rẹ̀, ati àwọn ará Jerusalẹmu tí wọ́n kù ní ilẹ̀ yìí, ati àwọn tí wọn ń gbé ilẹ̀ Ijipti, ni pé òun óo ṣe wọ́n bí èso burúkú tí kò ṣe é jẹ.
4 Òkùdu 2018 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 17 Ìgbé 2019 Gbajugbaja osere tiata Yoruba, Ibahim Chatta ti ni ololufẹ meji to ba ti fẹran ara wọn gbọdọ ni igbagbọ ninu ara wọn.
Gẹgẹ ba se gbọ, ikọ alatilẹyin awọn oloselu ni ikọ naa, eyi ti Mohammed Yussuf ko sodi, amọ nigba to ya lo parada di ijọ ẹlẹsin Islam.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Myanmar: kékeré ni wọ́n ti n kọ́ àwọn ọmọ nípa ọ̀nà oge ṣiṣe Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Ṣugbọn bí o bá ní anfaani láti di òmìnira, lo anfaani rẹ.
Ó dá àwọn ìràwọ̀ sójú ọ̀run:Beari, Orioni, ati Pileiadesiati àwọn ìràwọ̀ ìhà gúsù.
Ọba Samaria yóo parun bí ẹ̀ẹ́rún igi tí ó léfòó lórí omi.
26 Bélú 2020 6:08 Fídíò, Adebola Ademilua: Àìrísẹ́ ṣè lẹ́yìn ìwé kíkà ló sọ mi dí ìyá onírú, mo dúpẹ́ tèmi, Duration 6,0827 Bélú 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Orúkọ agbábọ́ọ̀lù 23 tí yóò lọ Russia 2018 Nàìjíríà n kẹdun Justice Mustapha Akanbi Ọmọ Prof.
Owúrò Ọjọ́bọ̀, Ọjọ Kejidinlọgbọn, Oṣu Karun un ní àdarí ẹ̀ka ètò ìṣúná yóò jáde láyé.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ajayi: ṣé ìwọ mọ irúfẹ́ ọmọ tí Yorùbá ń pè bẹ́ẹ̀?
Supreme Court: Ilé ẹjọ́ gíga jùlọ sún ìgbẹ́jọ́ ìbò Kano, Imo àti Sokoto
"Lyin ti ẹsun yii gbilẹ kan, agbẹnusọ agbabọọlu naa fi ọrọ sita pe: "" gbogbo ẹnu la fi kọ ẹsun yii ailẹsẹ nlẹ yii ati bi awọn oniroyin ṣe fẹ ẹ loju lọna odi."
Ọpọlọpọ ti sa wọ inú ewu ti wọn rò wí pé àwọn sá fún.
Baba-onírùngbọ̀n sì tún dáhùn, ó ní, Họ́wù o, kò mà dára o, kò yẹ kí á ṣè ‘lérí kí á máà mú ‘lèérí wa ṣẹ o, ó yẹ kí á lọ dé ilé ọkùnrin náà lọ́la o.
2 44 Ọkọ oju omi Zaandam 2 9 Orilẹede Burundi 1 0.
Ninu iho ribiti to ni oju mejila, ti mẹfa si koju ara wọn ni wọn ma n lo pẹlu okuta wẹwẹ abi ọmọ ayo mejidinlaadọta.
Pochettino ko ti ṣiṣẹ akọnimọọgba lati igba to ti fi ẹgbẹ agbabọọlu Tottenham silẹ ti Jose Mourinho si rọpo rẹ.
Ilé iṣẹ́ ọlọpaa ti fìdí rẹ múlẹ̀ pé àwọn ọlọpàá mẹ́rìn ti wọ́n pa àwọn afurasí mẹ́jì kan, èyí ti fọnran rẹ̀ ń jà ràìnràìn lórí ẹ̀rọ ayélujára ti pàdánù iṣẹ́ wọn bayii.
Bakan naa ni wọn kesi ijọba aarẹ Buhari lati gba wi pe awọn lo fa rogbodiyan to n ṣẹlẹ lorilẹede Naijria, ki wọn si ṣe ojuṣe wọn fun awọn eniyan.
Nibayii naa, awọn oniṣẹṣe ni ipinlẹ Ọyọ ti ke si gomina ipinlẹ Ọyọ, Seyi Makinde pe ko kede sjọ ajọdun iṣẹṣe gẹgẹ bi ọjọ isinmi lẹnu iṣẹ.
1 1009 Ọkọ oju omi Diamond Cruise 13 712 Orilẹede Mauritius 10 0.
Ṣugbọn Ọṣinbajo ati awọn ti wọn jọ wa ninu baalu naa ko ni ifarapa kankan.
Gbogbo àwọn ọkunrin náà tó mejila.
"Àwọn ọmọ Nàìjíríà ń sáré wálé torí àṣẹ ìjọba tó wọ́gilé ìrìnàjò láti òké òkun Ilé ẹjọ́ dá pásítọ̀ ìjọ Sotitobire padà sọ́gbà ẹ̀wọ̀n, ó sún ẹjọ́ síwájú Ẹgbẹ́ ọmọlẹ́yìn Kristi kéde àdúrà nítórí àrùn Coronavirus ""Ko yẹ ki iwọde naa waye, mo gba pe mo ṣe jẹbi lati gunle iwọde naa."
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Minimum Wage: Ilé ìgbìmọ asofin dájọ ti sísan yóó bẹ̀rẹ̀ Èèyàn mẹ́sàn-án ti kú ní ilé alájà tó wó l'Eko Ohun tó ṣẹlẹ̀ níbi ìgbẹ́jọ́ Alao-Akala lónìí nìyí Nigba ti akọroyin ileeṣẹ BBC to wa nibi ibanisọrọ naa beere boya iyatọ yoo wa lori iwadii ọtẹ yii nitori ọpọ ile lo ti wo ṣaaju ti ijọba ṣe iwadii si ni araalu ko ri abalọ-ababọ rẹ, Ọga agba LASEMA naa ni iyatọ yoo wa lọtẹ yii nitori awọn eekan ilu titi kan aarẹ Buhari ti wọn ti gbọ sii.
Awọn ọmọ Naijiria naa fi ero wọn han loju opo ikansiraẹni Facebook ti BBC News Yoruba, nibi ti ati bere lọwọ awọn eniyan wipe kini imọran wọn fun Aarẹ Buhari gẹgẹbi o ti gunlẹ si Washington, lati se ipade pẹlu Aarẹ Trump.
Àwọn yàrá mẹta mẹta wà ní ẹ̀gbẹ́ kinni keji.
Nígbà tí wọ́n bá ń ṣá ọ lọ́gbẹ́, ṣé eniyan ni o óo wá pe ara rẹ àbí oriṣa.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Prophecy 2020: Adeboye àti Ayọdele sọ nípa ọjọ́ ìwájú 2020 Primate ni Ọlọrun ti fi han oun pe arun coronavirus ni yoo pa ẹnikẹni to ba gbiyanju lati doju ibo ru ni ipinlẹ.
Bákan náà ni ìkìlọ̀ rọ akẹ́kọ̀ọ́ láti fọ́n iṣẹ́-ìjẹ́ òdì-ọ̀rọ̀ ìgbógunti àṣà Òyìnbó ká sí ọ̀rẹ́ àti ojúlùmọ̀ lórí WeChat àti lórí àwọn irinṣẹ́ iṣẹ́-ìjẹ́ ẹ̀rọ-alátagbà mìíràn.
Awọn oṣiṣẹ eleto idibo, awọn aṣoju ẹgbẹ oṣelu kọọkan ni wọn ti wa nikalẹ nibẹ.
Bẹẹ ba gbagbe, ni Ọjọru ni fidio kan gba oju opo ikansira ẹni Twitter eyi to n se afihan ọmọbinrin kan ti ọkunrin kan n ba lopọ, ti oju ọmọbinrin naa si han sita fun araye ri.
"Nnkan ti de ikorita ti eeyan ko ni idaniloju ibi to n lọ, ati ibi ti yoo pari rẹ si.
ile-eko naa yoo wa ni awon ipinle Bauchi, Imo, Lagos, Nasarawa, Katsina,Edo  ati Federal Capital Territory (FCT), niluu Abuja.
Wọ́n rí òkú ọmọ ọdún mẹ́fà tí wọ́n fipá bálopọ̀ nínú mọ́ṣálàáṣí ní Kaduna Bẹ́ ẹ fẹ́, bẹ́ ẹ kọ̀, July ni ẹjọ́ Sotitobire yóò parí - Adájọ́ gbọmú Ẹ̀kọ́ mẹ́jọ tó yẹ kí ilẹ̀ Afirika kọ́ lára àjàkálẹ̀ aàrùn coronavirus Arúfin ni Seyi Makinde pẹ̀lú bó ṣe gbà kí wọ́n sin Ajimobi sí GRA - Amòfin Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Africa Eye: Ọwọ́ tẹ ayédèrú dókítà Abdallah tó ń tà oògùn Coronavirus Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Èyí tí a wò jùlọ 5:03 Fídíò, Omolola Arohunmolase Welder: Mo ti fí iṣẹ́ 'Welder' gbayì láwùjọ, tó mo fi tọ́ ọmọ yanjú, Duration 5,039 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 5:39 Fídíò, Akomolede ati Asa lori BBC: Olùkọ́ Kikelomo Ogunboye tan ìmọ́lẹ̀ sí ìwà olè ọ̀gá ọlọ́pàá Audu gẹ́gẹ́ bí àwòkọ́ṣe àsìkò yìí, Duration 5,398 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 4:11 Fídíò, Oba Adeyeye Ogunwusi: Ojú mi ti rí lọ́pọ̀ lọpọ̀, ọ̀pọ̀ èèyàn ni kò tilẹ̀ gbàgbọ́ pé mo lè jọba- Ooni, Duration 4,117 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 4:43 Fídíò, Promise Akinlade: ọmọ ọdún mọ́kànlá tó ń fi ìlù dárà bíi àgbàlagbà sọ̀rọ̀ nípa tálẹ́ǹtì rẹ̀, Duration 4,437 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 0:59 Gbọ́, Ìsẹ̀lẹ̀ jákèjádò orílẹ̀èdè àgbáyé láàárín ìṣẹ́jú kan, Duration 0,59wákàtí 5 sẹ́yìn 7:03 Fídíò, Olumuyiwa Bolade Adedeji Military Bruitality: Bí arákùnrin onípèníjà ara tí sọ́jà lù ṣe dé, Duration 7,035 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 4:45 Fídíò, Yoruba Films: Ẹ̀ẹ́ bẹ̀ mi kúrò láyé ni, mi ò lè kú - Fadeyi Oloro, Duration 4,4526 Èrèlè 2020 2:48 Fídíò, Esther Ajayi: Èmi náà ti borí ìṣòro rí ló ń mu mi ṣojú àánú, Duration 2,481 Ògún 2019 6:08 Fídíò, Adebola Ademilua: Àìrísẹ́ ṣè lẹ́yìn ìwé kíkà ló sọ mi dí ìyá onírú, mo dúpẹ́ tèmi, Duration 6,0827 Bélú 2020 5:55 Fídíò, Soyinka Cancer: Àṣe ara mi ni iso ti n run gbogbo bí mo ṣe n ṣèrànwọ́ lórí jẹjẹrẹ, Duration 5,5527 Bélú 2019 BBC News, Yorùbá Ìdí tí ẹ fi le è nígbàagbọ́ nínú ìròyìn BBC Ìlànà Lílò Nípa BBC Òfin Àṣírí Cookies Kàn sí.
Awọn mẹwaa lo mori bọ ninu ijamba naa nigba tawọn to farapa si n gba itọju nile iwosan.
gẹ́gẹ́ bí ẹ ti dúró níwájú OLUWA Ọlọrun yín lẹ́bàá òkè Sinai, tí ó fi sọ fún mi pé, ‘Pe àwọn eniyan náà jọ sọ́dọ̀ mi, kí wọ́n lè gbọ́ ọ̀rọ̀ mi, kí wọ́n lè kọ́ láti máa bẹ̀rù mi ní gbogbo ọjọ́ ayé wọn; kí wọ́n sì kọ́ àwọn ọmọ wọn pẹlu.
Ọkọ̀ bá ṣí; Arisitakọsi ará Tẹsalonika, ní ilẹ̀ Masedonia, ń bá wa lọ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Àjẹ́ ké lánàá, ọmọ kú lónìí ni ọ̀rọ̀ Tinubu àti ìṣẹ̀lẹ̀ Lekki Tollgate - Bode George Wọn ni o ti n jẹwọ fun ọlọpaa bayii ohun to mọ nipa bi wọn ṣe fọ agọ ọlọpaa naa.
Ojọ kọkandinlogun, oṣu keje, ọdun 2020 ni awọn eeyan yii wọle sile ẹlẹgbọn ọn agba ni eyi to fihan pe irinajo wọn ṣi ku aadọrin ọjọ nibẹ sii.
Ọlọ́pàá ní àwọn ti gbáradì fún ìdájọ́ ilé ẹjọ́ agba pátápátá Ileeṣẹ ọlọpaa Ipinlẹ Osun naa ti ni awọn ti wa nikalẹ, lati pese aabo fun awọn ara ilu ibikibi to wu ki idajọ ile ẹjọ to ga ju lọ ni Naijiria, lori esi idibo gomina ipinlẹ Osun to waye ni ọdun to kọja ba fi si ni ọjọ Ẹti.
Lassa fever: NCDC késí aráàlú láti máa se ìmọ́tótó Imọtoto bori aarun mọlẹ, bi ọyẹ ti n bori oru, ajọ to n gbogun ti aisan lorilẹede Naijiria(NCDC) ti parọwa fun awọn eeyan lati mu imọtoto lọkunkundun lẹyin ti eeyan kan padanu ẹmi rẹ ninu awọn meji ti wọn lugbadi aarun ọhun.
 o je omiran efuufu kan pelu isupo kan to fi die din ju ikan-ninu-idaegberun ti orun lo sugbon isupo lona meji ati abo gbogbo awon planeti yioku ninu sistemu orun wa lapapo .
Bẹ́ẹ̀ ni alufaa yóo ṣe ṣe ètùtù fún un, tí yóo sì di mímọ́.
Babajide Sanwoolu ni aabo awọn araalu lo jẹ mi logun gẹgẹ bi oluṣọ agba ni ipinlẹ Eko""."
O tun maa maa dunkooko mọ ololufẹ rẹ pe oun a pa ara oun ti ololufẹ naa ba fi oun silẹ.
Mo ra ọpọlọpọ ẹrukunrin ati ẹrubinrin, mo sì ní àwọn ọmọ ẹrú tí wọn bí ninu ilé mi, mo ní ọpọlọpọ agbo mààlúù ati agbo ẹran, ju àwọn tí wọ́n wà ní Jerusalẹmu ṣáájú mi lọ.
Àwọn ìran Kalebu yòókù ni: àwọn ọmọ Huri àkọ́bí Efurata, iyawo Kalebu: ati Ṣobali, baba Kiriati Jearimu; 
si yẹra fun awọn iwa ati ọrọ to le ṣokunfa laasigbo ati rogbodiyan.
 Ati pe wọn ni Sani n fọ́wọ́ sọyà pe ọ̀rẹ tímọtímọ ni òun pẹ̀lú Ibrahim Magu, òun si le ràn wọ́n lọ́wọ́ láti bọ lọ́wọ́ gbogbo ìwádìí àti ijiya ti wọ́n le sálabapade lọ́dọ̀ àjọ EFCC.
Ṣugbọn olu ilu South Korea, Seoul, ko ti fofin d'ẹnu kọlẹ bi awọn ilu nilẹ Yuroopu.
Idi ni pe wọn ko lee pari iwadii wọn ni ọjọ Aje.
“Ṣugbọn bí ẹnìkan bá ṣèèṣì paniyan, tí kì í ṣe pẹlu ìríra, kì báà jẹ́ pé ó fi ohun ìjà gún un, tabi kí ó ṣèèṣì ju nǹkan lù ú, 
Bakan naa lo lu Oba Adeyemi lọgọ ẹnu lori ipa ti o n ko lati rii wi pe iran Yoruba ko gbẹyin lorilẹede Naijiria.
Ipade pelu awon oniroyin to ye ko waye lagogo mejo owuro ko waye, eyi ti iile-ise aare so pe, “ki awon oniroyin duro titi won yoo fi gbo latenu awon ti oro kan”.
Bí ẹ bá ń gbé inú mi, tí ọ̀rọ̀ mi ń gbé inú yín, ẹ óo bèèrè ohunkohun tí ẹ bá fẹ́, ẹ óo sì rí i gbà.
Ọpẹ́lọpẹ́ àwọn nǹkan tí ìyàwó mi sè pọ̀ ló gbà mí lọ́wọ́ coronavirus- Oladapo Famosinpe tó bọ́ lọ́wọ́ àrùn coronavirus Ènìyàn 416 ló ti lùgbàdì àrùn Coronavirus ní Ọjọ́ Ajé ní Naijiria A ó wá àwọn tó ṣekúpa Omozuwa láwàrí - Ọ̀pá Ọlọ́pàá Naijiria Gómínà Kogi pàṣẹ kóníléógbélé ní ìjọba ìbílẹ̀ kan ní Kogi Nigeria Lockdown Updates: Ẹ wo àwọn ìlànà tuntun tí ìjọba là sílẹ̀, ó ṣeéṣe kí ilé ìjọsìn, mọ́sálásí àti ọkọ òfurufú ṣí Oríṣun àwòrán, Nigeria Presidential Taskforce Àkọlé àwòrán, Ó ṣeéṣe kí ilé ìjọsìn, mọ́sálásí àti ọkọ òfurufú ṣí, Ẹ wo àwọn ìlànà tuntun tí ìjọba là sílẹ̀ Ìjọba orílẹ̀-èdè Nàìjíríà ni àwọn ti wọ ipele kéji fún dídẹ ọkùn ìgbéle ni orílẹ̀-èdè Nàìjíríà báyìí.
Sùgbọ́n alága ẹgbẹ́ òṣìṣẹ́ Ade Adesanmi tako ọ̀rọ̀ yìí, ó ní àwọn kò gba owó lásìkò ìsèjọba Fayose àti pé ọ̀rọ̀ ẹgbẹ́ òṣìṣẹ́ kò sí lábẹ́ àkóso ilé ìgbìmọ̀ aṣòfin.
 Ìgbà gbogbo ni àwọn babaláwo máa gbé ẹbọọ lọ si ibẹ ́ , nwọn a máa bu epo lé yangí náà lórí , a máa rin sún nígbà gbogbo .
Ọgbà kan wà tí mo fẹ́ràn púpọ̀.
Bayii, Bianca n lọ ẹni karun un ni agbaye to si n lọ sile pẹlu ẹbun owo $3.
Ṣugbọn ìwọ ni; ìwọ tí o jẹ́ irọ̀ mi,alábàárìn mi, ọ̀rẹ́ mi tímọ́tímọ́.
Awọn ibudo itan inu sinima Black Panther to jẹ ibi ala rere naa fi ara pẹ ila oorun Naijiria ninu ere Black Panther to jẹ kikida alawọ dudu lo ṣee lọdun 2018.
Intersex: Kò dẹrùn láti sọ wí pé kòjako-kòjabo ni mí
Atupalẹ abọ iwadii naa ti ileewosan ikọṣẹ imọ iṣegun oyinbo ni fasiti Harvard fi sita l'oṣu to kọja fihan pe bi nkan mimu ẹlẹrindodo ti eniyan n mu ba ṣe pọ to ni yoo sọ bi iku aitọjọ ṣe sunmọ ẹni naa to.
Ooni Ile Ife: Màmá tó bí ìyá Ọọ̀ni ilé Ifẹ̀ ju awà sílẹ̀ lẹ́ni ọdún 103
Bakan naa, pelu ise takun-takun ati atileyin Olorun, iko yii yoo tesiwaju de ipele ti o kan.
wọn óo fi ẹnu gbo ilẹ̀ bí ìgbín, pẹlu ìbẹ̀rù ati ìwárìrì ni wọn yóo jáde bí ejò, láti ibi ààbò wọn; ninu ìbẹ̀rù, wọn óo pada tọ OLUWA Ọlọrun wá, ẹ̀rù rẹ yóo sì máa bà wọ́n.
O jẹ Òṣèré, olóòtú, olùdarí àti olórin ọmọ Nàìjíríà.
Ẹ̀rù ba gbogbo Ilẹ̀ náà, ati gbogbo àwọn tí ń gbé ibẹ̀,nígbà tí wọ́n gbọ́ bíbú rẹ̀.
Ẹ kígbe sí OLUWA,ẹ̀yin ará Sioni!
N óo ti fara dà á fun yín pẹ́ tó?
Kí ni mo ṣe tí ọ̀rọ̀ mi fi su yín?
Aarẹ Buhari ko yọju si ilu Auno ti iṣẹlẹ ikọlu ti Boko Haram ti pa to eeyan ọgbọn ti waye.
Lẹ́hìn wákàtí mélòókan mo tọ igbó ọ̀hún ja sí ilẹ̀ ọ̀dàn ńlá kan tó lọ gbansasa kọjá ibi tí ojú ẹni ríran dé.
Gẹgẹ bi iroyin ti a gbọ, wahala naa bẹrẹ lẹyin idije bọọlu gbigba to waye laarin awọn akẹkọọ imọ ẹrọ ati awọn akẹgbẹ wọn to n kọ nipa nipa okoowo ati ibaraẹnisọrọ.
Ọjọbọ to kọja ni Aarẹ Muhammadu Buhari fi orukọ rẹ ranṣẹ si awọn aṣofin fun ontẹ lati le mu u ko kuro ni ipo Adele Adajọ Agba.
Àkọlé àwòrán, Awọn eniyan ara ipinlẹ Ọyo farabale lati gbogbo nkan ti awon oludije ni fun won.
Níbo ni àwọn ọlọrun Sefafaimu, ati ti Hena ati ti Ifa wà?
Nípa ìbéèrè yìí, ẹ ti ṣìnà patapata.
Ọrọ kò rí bẹẹ Nínú èsì rẹ sí ọrọ àwọn ẹgbẹ ọdọ náà,Senator Bukola Saraki ti agbẹnusọ rẹ Yusuph Olaniyonu fi atẹjade síta lórúkọ rẹ sọ pé òun ṣe ìkéde náà láti ṣe ìwúrí fún àwọn ọdọ ẹgbẹ òṣèlú PDP ton n gbero láti du ipò ní.
Ko jọ nkan ọmọkunrin, o da yatọ, o dara gan ni.
Mo tún rí àwọn ewé kọ̀ọ̀kan tí àwọ̀ wọ́n tanná niniini, bótilẹ̀ṣepé àwọn ewé ìyókù ti ń panná.
Sugbọn nigba ti yoo fi di ọwọ ọsan ni iroyin miran tun ti gbalẹ kan pe Ọlọrun ti gbe alawore pade Ajirebi, ti onitọun si fun ni ile ti yoo maa gbe.
Biotilẹjẹpe ogun ọdun niyi ti Oyetọla ti n se oselu, igba akọkọ ni yii ti yoo ma a dije du ipo labẹ ẹgbẹ oselu kan kan.
A óo máa pè yín ní, “Eniyan mímọ́”,“Ẹni-Ìràpadà-OLUWA”.
Iroyin fi lede wipe, olori tuntun fun ẹgbẹ oselu ANC, Cyril Ramphosa kuro nibi ipade ẹgbẹ naa, lati lọ sọ fun aarẹ Zuma wipe ki o tete kọwe fipo silẹ, ki wọn ma ba a le kuro lori oye.
Mo ti tẹ̀lé gbogbo òfin rẹ̀,n kò sì ṣe àìgbọràn sí àwọn ìlànà rẹ̀.
Oluwa lo mọ ẹjọ da ni ọrọ ku si ṣugbọn ireti ati igbagbọ koowa ni pe Olọrun a ṣe Gold Kolawọle to dawati ni riri fun gbogbo aye.
Ṣugbọn nigba ti ile ẹjọ kotẹmilọrun do doju ẹjọ naa bolẹ gbe idajọ rẹ kalẹ, igbimọ ẹlẹni mẹta naa lo panupọ kede pe ile ẹjọ giga naa ko yẹ lati dajọ pe Adeleke ko pari ile ẹkọ girama, ati pe, irọ lo pa lori iwe ẹri to ni oun ni.
Dele naa lowo bii baba rẹ, o lọla, to si jogun ileesẹ baba rẹ nilu Eko.
Lakotan, a lee ni eeyan takun-takun, ti ọpọ̀ eeyan lee ri bii ‘Katapila’ ni Bukọla Saraki lagbo oselu Naijiria.
Orí àkìtàn ni wọ́n ti rí ọkùnrin tó ń fi ìgbẹ́ jẹ Búrẹ́dì -Iléeṣẹ́ ọlọ́pàá Oyo Bí mo ṣe mórí bọ́ nínú ọkọ̀ bàálù tí kò bá já - Aisha Buhari Ta ni Lisa Hanna, arẹwà obìnrin tí àwọn ọmọ Nàìjíríà fẹ́ kó di àárẹ wọn?
 látàrí ìwà àgbẹ ̀ yìn-bẹbọ-jẹ ́ tí àwọn ọlọ ́ pàá hù sí yìí ló jẹ ́ kí ó fa ìbínú yọ ní oṣú august 1986 nípa ṣíṣàkọlù sí ilé ìfowó-pamọ ́ ní èyị ́ tí ọlọ ́ pàá kan tí orúkọ rẹ ̀ ń jẹ ́ ( nathaniel egharevba ) àti àwọn mélòó kan pàdánù ẹ ̀ mí rẹ ̀ sínú àkọlù náà ní fọná-fọnṣu .
Ó ní, “Pẹlu ìrànlọ́wọ́ OLUWA, mo ní ọmọkunrin kan,” ó sọ ọmọ náà ní Kaini.
95bn sórí reluwé làti Kano sí Niger Republic- PDP Ayaba naa, tii se arẹwa obinrin, ni o ti fi gbogbo rogbodiyan to waye nipa rẹ laipẹ yii se afisẹyin, tii eegun fi asọ, to si n tẹsiwaju nipa aye ati ọrọ aje rẹ.
Abiodun ati Shinku Godwin ,abbl .
Won ko ti I so nnkankan fun mi”Aida Parra so fun akoroyin pe:”Ara mi o bale bayii gege bi iya.
O wa so fun gbogbo awon arinrinajo to ti foruko sile ni ipinle naa lati san milionu kan ati aabo naira( N1.
A óo kà wá sí olódodo bí a bá pa gbogbo àwọn òfin wọnyi mọ́ níwájú OLUWA Ọlọrun wa, bí ó ti pa á láṣẹ fún wa.
Derin Ẹlẹran - BBC News Yorùbá BBC News, YorùbáFò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Iṣẹ́ ìdọ̀tí ni ẹran títá, ṣùgbọ́n nínú ẹ̀gbin lowó wà - Derin Ẹlẹran Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Iṣẹ́ ìdọ̀tí ni ẹran títá, ṣùgbọ́n nínú ẹ̀gbin lowó wà - Derin Ẹlẹran 15 Agẹmo 2019 Ootọ iṣẹ́ ìdọti ni iṣẹ alapata ṣugbọn èrè wa nibẹ - Derin Ẹlẹran Aderinsọla Taiwo ni ọdọbinrin alapata ti BBC fọrọwalẹnuwo lori iṣẹ ẹran tita lọna igbalode.
Wo ohun tí àwọn ọmọ Nàìjíríà ń sọ lórí dájọ́ ikú Yahaya Sharif-Aminu tó gba ìdájọ́ ikú lórí ẹ̀sùn ọ̀rọ̀ òdì sí Ànọ́bì Ọwọ́ ọlọ́pàá ìpínlẹ̀ Kebbi tẹ bàbá àti ìyàwó rẹ̀ méjì fún pé wọn so ọmọ pọ̀ mọ́ ewúrẹ́ fún ọdún méjì Orílẹ̀-èdè Chad pé ọgọ́ta ọdún, àwọn ara ìlú ń pariwo lábẹ́ Aàrẹ Deby tó gba 'Field Marshal' Ọkọ Risikat ní ojú búlúù tí ìyàwó òun ní gan an lòun ṣe fẹ́ ẹ Ṣùgbọ́n nígbà ti ó di ọdún 2000, àwọn ìpínlẹ méjìlá ní ìhà Àríwá ló ti darapọ̀ mọ́ ètò ọ̀hún, bákan náà ni wọ́n ṣe àfikún láti maa fi òfin Sharia dá ẹjọ́ tó bá níṣe pẹ̀lú ìwà ọ̀daràn.
Ohun tí ó ṣe burú lójú OLUWA Ọlọrun rẹ̀.
- Nkechi Blessing Ọ̀rẹ́ wa ni Lawrence jẹ́, àmọ́ ó gbẹ̀yìn dẹ́nu ìfẹ́ kọ abúrò wa - Joshua àti Damilola Bamiloye Wo oríṣi inú rírun márùn-ún tí o kò gbọdọ̀ pa mọ́ra Kọ́ sí i nípa àwọn oúnjẹ aṣaralóore tó yẹ kí Aláboyún máa jẹ Alakoso apapọ fajọ eleto idibo to n bojuto ipinlẹ Ondo, Ọmọwe Ademola Ogunmola ninu ọrọ tiẹ, wa gboriyin fawọn oludibo, fun bi wọn se jẹ ki ileri ajọ INEC, lati se aseyọri kọja ohun to waye nipinlẹ Edo, di mimusẹ.
Wọ́n pabùdó wọn sí ẹ̀bá ọ̀nà ní òkè Hakila, Dafidi sì wà ninu aṣálẹ̀ náà.
Ajọ UNESCO ni awọn ọmọde ati ọdọ to le ni biliọnu kan ni wọn ko ti ribi lọ si ile ẹkọ lati igba ti ajakalẹ arun coronavirus ti di ẹru jẹjẹ ni gbogbo agbaye.
Ṣùgbọ́n mo níláti sọ  nǹkan kan tí a ri ni nǹkan bi agogo mẹ́sàn-án òwúrọ̀ ọjọ́ kan.
Wo bí odò tó gùn jù l'Áfíríkà, Nile ṣe ń fójúu ilẹ̀ Egypt-Ethiopia han màbo Ikú ti yọ́wọ́ òṣèré Nollywood Yorùbá, Yusuf Satia l'áwo Aarě Trump to maa n pe aarun Coronavirus ni aarun China yọ ibomu kuro lapo ṣugbọn ko fi bo imu.
kì í ṣe nítorí iṣẹ́ rere kan tí a ṣe, ṣugbọn nítorí àánú rẹ̀ ni ó fi gbà wá là, nípa ìwẹ̀mọ́ pẹlu omi tí ó fi tún wa bí, ati Ẹ̀mí Mímọ́ tí ó fi sọ wá di ẹni titun.
 Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Divorcee: Ó sàn kí wọ́n yàgò fúnra wọn ju ki wọ́n ṣe ara wọn léṣe- Fisayo Lai Mohammed tẹsiwaju pe Ko si ijọba kankan to ni ifẹ ara ilu lọkan ti yoo faaye gba ki awọn eeyan maa sọrọ ikorira, ki wọn si tun maa pin iroyin eke lori itakun agbaye.
-Ọlọ́pàá Olori akọnimọọgba wọn, Gernot Rohr, sọ nibi ipade akọroyin kan pe Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, International Day Against Drug Abuse and Trafficking: ìdí ti mo fi ń mu oògùn olóró 'Ireti mi ni pe wọn yoo tete yanju ọrọ to wa nilẹ yii, ka le gbajumọ iṣẹ to wa niwaju wa.
"Gbogbo ẹ ba mi ni ojiji, eyi si mu ki n ro pe ọrọ abuku ni mo sọ ni, lo jẹ ki n bẹ ẹ pe ko ma binu.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Awọn ọmọogun jẹwọ idi ti wọn ko fi lee pa ina Boko haram Ohun ti iroyin sọ ni wi pe, wọn ko awọ ologun kuro lagbegbe naa ni nkan bii ọjọ diẹ saaju isẹlẹ naa.
Lizzy Anjorin vs Toyin Abraham: Kolawole Ajeyemi ní kò dára kí àwọn òṣèré máa bú ara wọn lórí ẹ̀rọ ayélujára
Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Fídíò, Coronavirus in Nigeria: Ǹjẹ àgbo lè ṣe òògùn coronavirus?
Kò mọ ohun tí ó ṣẹlẹ̀.
' Alaafia eniyan Enugu lo jẹ mi logun -Ugwuanyi Oríṣun àwòrán, @ugwuanyi Àkọlé àwòrán, Mo kọ láti gba ẹmi imọ-tara-ẹni-nikan-laaye ni Enugu Gomina Ifeanyi Ugwuanyi lo jawe olubori labẹ ẹgbẹ oṣelu PDP nipinlẹ Enugu ninu idibo ọjọ kẹsan an, oṣu kẹta, ọdun yii.
OLUWA Ọlọrun yín yóo bukun iṣẹ́ ọwọ́ yín lọpọlọpọ, ati àwọn ọmọ yín; àwọn ọmọ mààlúù yín, ati àwọn ohun ọ̀gbìn yín, nítorí inú OLUWA yóo tún dùn láti bukun yín gẹ́gẹ́ bí ó ti ṣe inú dídùn sí àwọn baba yín, 
Eyi ko ṣẹyin bi ẹni to ṣe oniduro fun nile ẹjọ, Abdulrasheed Maina, ṣe salọ.
Ni owurọ ọjọ aje ni gomina ana nipinlẹ Ekiti, Ayọdele Fayose yoo foju ba ile ẹjọ.
Ẹlẹ́wọ̀n 157 yọò kọ WASSCE, méjì fẹ gba PHD Awọn ọmọ ìjọ sàtánì ń bínú sí Nàìjíríà Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ìjẹ̀bú: Àgbàlàgbà ni mo máa ń ṣe nínú eré tẹ́lẹ̀ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Bimpe: Èèyàn bíi tiyín ni àfín, ẹ dẹ́kun dídẹ́yẹsí àfín Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'O yé kí ìbáṣepọ̀ Nàìjíríà àti UK dán mọ́rán síi lẹ́yìn àbẹ̀wò May' Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
- Ìwádìí BBC Èyí tí mo ṣe tó!
Bi àkọ́bi bá kú, ọkùnrin ti ó bá tẹ̀le yio bọ si ipò.
UNO bẹnu àtẹ́ lu ìdàdúró Onnoghen Àjọ NJC fún Onnoghen àti Mohammed ní gbèdéke ọjọ́ méje Onnoghen ní 'mi ò jẹ̀bi olúwa mi' nílé ẹjọ́ CCT Lara ohun ti igbimọ da laba ni pe ki wọn paṣẹ ifẹyinti lẹnu iṣẹ adajọ naa lẹyin ti wọn ṣe agbeyẹwo gbogbo ẹsun ti wọn fi kan an.
Ṣeun Fakorode ṣiṣẹ pẹlu ajọ to n risi idagbasoke ati ohun ini ni ipinlẹ Eko, iyẹn Lagos State Development and Property Corporation.
Amọ awọn ẹlomiran gbagbọ wi pe, ẹkọ iwe lo se pataki gẹgẹ bi ogun ti eniyan le fi silẹ fun ọmọ.
A óo tún gbọ́ ohùn ọkọ iyawo ati ohùn iyawo ati ohùn àwọn tí wọn ń kọrin bí wọ́n ti ń mú ẹbọ ọpẹ́ wá sinu ilé OLUWA wí pé: 107:1; 118:1; 136:1‘Ẹ fi ọpẹ́ fún OLUWA àwọn ọmọ ogun,nítorí pé rere ni OLUWA,nítorí pé ìfẹ́ rẹ̀ tí kì í yẹ̀ wà títí lae!
Adajọ yì ìgbẹ́jọ rẹ̀ padà lóri àtúndi ìbò Adamawa
nígbà tí wọ́n nà wá ati nígbà tí a wà lẹ́wọ̀n, ní àkókò ìrúkèrúdò ati ní àkókò tí iṣẹ́ wọ̀ wá lọ́rùn, tí à ń pa ebi mọ́nú.
Lootọ ni Jesu Oyingbo ti fi aye silẹ sugbọn awọn ohun to gbe ile aye se jẹ manigbagbe, ti yoo wa ni iranti fun igba pipẹ.
Oga agba ajo ti o n ri si oro omi, ati ayika to mo ninu ajo UNICEF lorile-ede Naijiria, Zaid Jurji so pe, “mimu igberu ba omi mimu ati imototo ayika, sise amulo imototo ayika lorile-ede Naijiria je ojuse awon ara-ilu, ijoba, awon ajafeto omo-eniyan , awon eka aladani ati awujo”.
lati kopa ninu abala ipele keta si asekagba Idije Europa League lẹyin ti wọn gbo
''Fun idi eyi, a ti wọgile ti ko si fẹsẹ rinlẹ'' Eeyan to gbajẹ lẹnu eeyan,apaayan ni"" Ọmọ ipinlẹ Ekiti kan to jẹ oṣiṣẹ ijọba to ba BBC sọrọ to ni ki a fi orukọ bo ohun lasiri ti bu ẹnu atẹ lu igbeṣẹ ijọba Kayode Fayemi yii."
   Ninu ọrọ rẹ, o ṣalaye pe Ile Igbimọ Aṣofin
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Sinimá àwòdamiẹnu, àwọn aṣẹ́wó dín dùǹdú ìyà fún Ẹ̀fáńjẹ́líìsì ní àbẹ́tẹ̀ wọn ní Ejigbo 2 Owewe 2020 Oríṣun àwòrán, others Ẹ wa wo sinima lorita o!
Wọn fẹ̀sun kan pé wọ́n ń ṣe iṣẹ́ amí ati iṣẹ ìyanu èké ti wọ́n si n purọ gbówó lọ́wọ́ àwọn olùgbé Lekki àti Epe nípínlẹ̀ Eko.
Lórí gbogbo ìwọ̀nyí, oúnjẹ dáadáa, ommì dáadáa, atẹ́gùn dáadáa, ni ń ṣe ara dáadáa.
Iya ti Chelsea jẹ lonii ko ṣẹyin akitiyan Micheal Obafemi ati Nathan Redmond ninu ifẹsẹwọnsẹ naa to waye ni papa iṣere Stamford Bridge.
 nǹkan tí ó jẹ ́ gẹ ́ gẹ ́ bí àtúnṣe àrùn ara .
Ẹlẹsẹ ayo, Pierre-Emerick Aubameyang lo kọkọ ṣide goolu fun Arsenal ni bii iṣẹju mẹtalelọgbọn ti ere bọọlu naa gberasọ.
Koda, ọrọ yii kanlẹ, o tun kan baale nitori awọn olugbe adugbo Mowe, Ibafo, Asese, magboro ati Arepo, to yẹ ko lọ wọ isẹ ni aarọ yii ni sunkẹrẹ fakẹrẹ ọks mu mọlẹ, ti wọn ko si lee lọ sẹnu isẹ ati okoowo wọn.
Tee-Leo Okoro ni awọn eniyan marundinlogun ni awọn ti fi panpẹ ọba mu kaakiri ipinlẹ Ondo, lẹyin ti awọn janduku ba ile ati dukia jẹ lasiko ifẹhọnuhan tako ifiyajẹni ikọ ọlọpaa Sars.
Iranṣẹ náà bá gbé oúnjẹ náà kalẹ̀ níwájú àwọn ọmọkunrin náà, wọ́n jẹ, ó sì ṣẹ́kù gẹ́gẹ́ bí ọ̀rọ̀ OLUWA.
OLUWA Ọlọrun ní: “Nígbà tí ó bá wọ isà òkú ọ̀gbun ilẹ̀ pàápàá, n óo ṣọ̀fọ̀ rẹ̀, n óo sé àwọn odò n óo sì ti orísun omi ìsàlẹ̀ ilẹ̀ nítorí rẹ̀, òkùnkùn óo bo Lẹbanoni, gbogbo igi inú igbó yóo gbẹ nítorí rẹ̀.
Awọn iroyin miran ti ẹ le nifẹ si: Croatia na Super Eagles pẹlu ami ayo 2 - 0 ‘Nàíjíríà yóò dé Semi-final ti World Cup’ Sọ àsọtẹ́lẹ̀ nípa ikọ̀ tí yóò gba ife ẹ̀yẹ àgbáyé 2018 pẹ̀lú eré ìdárayá tuntun ti BBC Sugbọn báwo ni ẹlẹ́dẹ̀ ṣe ń ríran?
Eliṣa sọ fún Gehasi kí ó bèèrè lọ́wọ́ obinrin náà ohun tí ó fẹ́ kí òun ṣe fún un, fún gbogbo nǹkan tí ó ti ṣe fún àwọn.
#BBCNigeria2019 Day 20:Ṣeyi Makinde jẹ́ oníṣòwò láti ọ̀dọ́ kó tò di olósèlú#BBCNigeria2019 Ti o ba ṣẹlẹ pe awọn adajọ agba mejeeji jẹbi ẹsun ti wọn fi kan wọn ti wọn si da wọn duro, adajọ Ọlabọde Rhodes-Vivour to jẹ adajọ kẹta to ni iriri julọ ni ile ẹjọ to ga julọ ni Naijiria ni yoo gori aleefa gẹgẹ bi adajọ agbajọ tuntun.
Ọmọ náà dàgbà, ó sì já lẹ́nu ọmú, Abrahamu sì se àsè ńlá ní ọjọ́ tí ọmọ náà já lẹ́nu ọmú.
Liverpool lo pupọ ninu anfaani ti wọn ri ninu idije naa bẹrẹ lati aṣiṣe pẹlu Alisson Becker.
”Ó dá a lóhùn pé, “O ti fi ẹnu ara rẹ wí i.
Lẹ́yìn náà, ọba se àsè ní àgbàlá ààfin fún ọjọ́ meje, fún gbogbo àwọn tí wọ́n wà ní Susa, àtàwọn talaka, àtàwọn eniyan ńláńlá.
"Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, ""aba isuna itẹsiwaju ati idagbasoke"" ni akori isuna ipin Eko fundun 2018 Labẹ eto isuna yii kan naa, ijọba ipinlẹ Eko ni owo iyasọtọ wa fun pipari awọn gbọngan asa marun, idasilẹ ibudo isẹmbaye kan ni ile aarẹ tẹlẹ ti ijọba apapọ sẹsẹ fa le ipinlẹ Eko lọwọ; ile ikonkan isẹmbaye si nla kan laarin ile aar tẹlẹ ni Marina."
Máa sọkún, ìwọ ẹnubodè, kí ìwọ ìlú sì figbe ta.
Asiko ti ipolongo ibo bẹrẹ ni Arabinrin Tikhanovskaya, ẹni ọdun mẹtadinlogoji, to ti fi igba kan jẹ olukọ, di oloṣelu.
Gbogbo ẹranko ẹlẹ́sẹ̀ mẹrin ati oríṣìíríṣìí ẹranko tí ó ń fi àyà fà, ati ẹyẹ ojú ọ̀run ni ó wà ninu rẹ̀.
Oòrùn ati òṣùpá dúró ní ipò wọn,nígbà tí ọfà rẹ ń já lọ ṣòòrò,tí àwọn ọ̀kọ̀ rẹ náà ń kọ mànà,bí wọ́n ti ń fò lọ.
Algeria pada ri maaki mẹta gba nitori Naijiria lo agbabọọlu ti wọn ti ni ko lọ rọọkun nile tẹlẹ.
Awon maa n lo igi lati da eran won tabi ki won lo ada lati ge ewe ti eran won yoo je.
Ẹ yẹra fún ibi; ẹ sì máa ṣe rere;kí ẹ lè wà ní ààyè yín títí lae.
Atamatase iko agbaboolu Bayern Munich,  Franck Ribery ti sun asiko re siwaju si ninu lko agbaboolu Bayern leyin ti o bowolu iwe isise po oloodun kan, eleyi ti yoo mu wa ninu iko ohun titi di opin saa idije Bundesliga to n bo.
Ko ti i si aaye fun awọn ibudo igbafẹ bi i ile ọti, ile iworan bọọlu ati ibudo ti wọn ti n ṣafihan sinima lati bẹrẹ iṣẹ pada.
Gẹ́gẹ́ bí ẹ̀ka kò ti lè so èso fún ara rẹ̀ àfi bí ó bá wà lára igi, bẹ́ẹ̀ ni ẹ̀yin náà kò lè so èso àfi bí ẹ bá ń gbé inú mi.
Ẹ̀yin ìdílé Aaroni, ẹ gbẹ́kẹ̀lé OLUWA,òun ni olùrànlọ́wọ́ ati aláàbò yín.
" Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Làáhànmí: Ìwádìí ní èèyàn 219 ni ibà Lassa pa lọ́dún tó lọ́, 29 lọ́dún yìí, tètè dènà rẹ̀ Nigba to n sọrọ lori ipo ilera ti Toyosi Adesanya wa, osisẹ alarena ileesẹ ọlọpa nipinlẹ Kwara ni bi o tilẹ jẹ pe oun ko tii foju kan kan osere ori itage naa, sibẹ oun gbagbọ pe alaafia lo wa.
Wo aworan igbeyawo ọmọ gomina Ọyọ ati ti Kano Oríṣun àwòrán, @GovKaduna Àkọlé àwòrán, Asiwaju Bọla Tinubu ati gomina Kaduna, Nasir El-Rufai jẹ diẹ lara awọn alejo ti wọn lọ si Kano fun igbeyawo naa Ọmọ gomina ipinlẹ Ọyọ, Idris Abiọla, Ajimọbi ti gbe ọmọ gomina ipinlẹ Kano, Fatima Ganduje, niyawo lọjọ Abameta.
 Àwọn èèyàn tí ó rí ìyàtọ ̀ lẹ ́ yìn abẹ ́ rẹ ́ àjẹsára ìkejì lè rí ìyàtọ ̀ tí wọ ́ n bá gba àjẹsára yii sára tàbí Àfikún ìdá àjẹsára yii tàbí ìdá meji Àjẹsára jẹ ̀ dọ ̀ jẹ ̀ dọ ̀ a àti b.
Wọ́n bẹ̀rẹ̀ sí bi ara wọn pé, “Báwo ni eléyìí ti ṣe lè fún wa ní ẹran-ara rẹ̀ jẹ?
Ọpẹ́lọpẹ́ iná tí kìí lọ, tí kìí dákú ní'lẹ̀ yìí.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: 'Pọ́ńbélé Yorùbá ni mí, n ò sì ní tijú rẹ níbikíbi' Ìjọba Nàìjíríà n fẹ́ kí àwọn obìnrin maa fi àláfo sílẹ̀ láàrin ọmọ kan sí kan Fayẹmi ni ipadàbọ̀ òun kìí ṣe láti gbẹ̀san 1.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Àgbà ni Obasanjo, oun tó ń sọ yé e, ìjọba ni kó tají - Wale oke Lara awọn ohun ti awọn osisẹ EFCC ka mọ awọn afurasi naa lọwọ ni ẹrọ ayarabiasa agbeletan mẹsan, foonu alagbeka mẹrindinlogun, pẹ́lu ọkọ Toyota Camry ti nọmba rẹ jẹ EPE 406FN.
Oludasilẹ ile ijọsin kan nilu Eko, Wolii Adegboyega Ajani lo woye ọrọ yii lasiko ipade akọroyin kan to ṣe lati sami ayajọ gbigbe ogun tiwa ajẹbanu lagbayee.
A ti kọ ọ́ sílẹ̀ níwájú mi pé,“N kò ní dákẹ́, ṣugbọn n óo gbẹ̀san.
Wò mí sàn, OLUWA, ara mi yóo sì dá,gbà mí, n óo sì bọ́ ninu ewu.
Ile iṣe BBC Yorùbá naa n duro pẹlu awọn eniyan Naijiria de ikede INEC lori ijọba ibilẹ ọgbọn tidibo naa ti waye ni ipinlẹ Ọṣun.
Bí ó bá jẹ́ pé ilẹ̀ yín kò mọ́ tó láti máa sin OLUWA níbẹ̀ ni, ẹ rékọjá sinu ilẹ̀ OLUWA, níbi tí àgọ́ rẹ̀ wà, ẹ wá gba ilẹ̀ láàrin wa.
O fọn ipe si ijọba pe nibayii, gbogbo ipele ile kikọ ni ki ijọba maa wa yẹwo lati rii daju pe kii ṣe ayederu ohun elo ni wọn n lo.
 bọ ́ tìnì yìí maa jásí ọ ̀ rọ ̀ ojú ewé tí a fẹ ́ parẹ ́ pẹ ̀ lú àyè láti ṣàlàyé ìdí tí ko fi gbọ ́ dọ ̀ dí píparẹ ́ láìrosẹ ̀ .
Orilẹede Liberia ṣe agbekalẹ ifẹsẹwọnsẹ ọlọrẹsọrẹ ọhun lati fi adagba jẹẹsi pẹlu nọmba mẹrinla(14) ti Weah wọ nigba ti o n gba bọọlu rọ.
Ile Igbimọ Aṣofin Ipinlẹ Eko, Aṣofin Mudashiru Ọbasa, ninu ọrọ rẹ dupẹ
oludije méjíléláàdọ́rin, ti o si dibo ni ibudo
tí wọ́n di àmùrè, tí wọ́n wé lawani gbọ̀ọ̀rọ̀ gbọ̀ọ̀rọ̀, tí gbogbo wọn dàbí ọ̀gá àwọn oníkẹ̀kẹ́ ogun, àwọn ọmọ ogun ará Babilonia.
4 - Má à dúró lórí àkọlé ìròyìn nìkan Wọ́n maa n gbé àwọn ayédèrú ìròyìn kan jáde láti fi pa àwọn ènìyàn lẹ́ẹ̀rín.
Àfi obìnrin náà ni ó b á bàbá mi mu nínú ọlá ńlá Igbó Olódùmarè yìí, bẹ́ẹ̀ ni, èmi ni mo wí fún ọ, bàbá mi dára lọ́kùnrin, ẹ̀gàn ló kù; kì í ṣe nítorí pé ó jẹ́ bàbá mi ni mo fi sọ bẹ́ẹ̀, àwọn ará ìlú wa gan-an ní ẹni tí ń fi ọ̀rọ̀ rẹ̀ ṣe orin kọ, wọn a máa wí nípa tirẹ̀ pe’: ‘Olówó-ayé, arẹwà lọ́kùnrin.
Koda, ọba, awọn ijoye ati awọn aṣaaju ilẹ Ẹgba ti gba kamu, ti wọn ko si mọ ohun ti wọn lee ṣe mọ lati gba ara wọn silẹ lọwọ awọn Ilari Ọlọyọ.
Imaamu kan ni ikọja aaye ni igbesẹ naa Nigba to n fesi lori ọrọ yii, Imam Fuad Adeyemi, to je Imam agba fun ẹgbẹ Al-Habibiyah jake jado orilẹẹde Naijiria, to si tun je asoju iwọ oorun guusu ilẹ Yoruba labe ajọ to n seto alalaji lorilẹẹde Naijiria, (NAHCON) ni, looto ni ilu Iwo jẹ ilu to lami laaka nipa ẹsin Islam sugbọn o koja agbara Oluwo lati yan Waziri fun gbogbo ile Yoruba.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ọ̀rọ̀ǹpọ̀tọ̀niyùn, Aláàfin obìnrin àkọ́kọ́ rèé, tó ní nǹkan ọkùnrin Baṣọ̀run Gáà, tó yan ọba mẹ́rin, pa ọba mẹ́rin àmọ́ ọba karùn-ún ló pa á Mọrèmi Àjàṣorò, akọni obìnrin tó gba Ilé Ifẹ̀ sílẹ̀ lóko ẹrú Igbesẹ yii si lo n mu ki ọpọ ero maa ya wa sidi aworan naa, , papaa awọn obinrin ti wọn si n kan saara si Marta Moreiras pe o seun.
Ijọba orilẹ-ede Amerika ti kesi ijọba Naijiria pe awọn ko i ti i ri iwe lati ọdọ ijọba wi pe ẹdikun ti ba owo iwe irinna fun awọn ọmọ ilẹ Amerika to fẹ wa si orilẹ-ede Naijiria.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù House help: Ìgbà márùn ún rèé tí àwọn ọmọ ọ̀dọ̀ ti gé ẹ̀mí ọgá wọn kúrú 19 Èbibi 2020 Oríṣun àwòrán, others Lati ayebaye ni awọn eeyan ti maa n gba ọmọ ọdọ, to le jẹ ẹbi tabi ara ita.
Òkúta tí ó kọlu ère náà di òkè ńlá, ó sì bo gbogbo ayé.
Jọ́wọ́ mo kan fẹ́ bẹ̀ ọ́ síi: Sọ fún ki ó tú àsírí mi atawọn nǹkan ti kò dára tó ṣẹlẹ̀ lọ́dún 1990."
 Èdè inú orin gbọ ́ dọ ̀ fanimọ ́ ra .
Amọ ninu fidio kan ti Ajirebi se pẹlu osere tiata miran, Kunle Afod, o sẹ lori iroyin naa, to si ni Funke Akindele ko fun oun ni ilegbe rara.
Se ni awọn janduku tun pada lati ji nnkan nile itaja naa.
Ẹ̀yin obìnrin, ẹ lọ kọ́ iṣẹ́ káfíńtà torí ó lówó lórí ju iṣẹ́ aránṣọ lọ Àwọn ọmọbíbí ìpínlẹ̀ Ọyọ nìkan ni yóò rí iṣẹ́ àgbàṣe gbà lábẹ́ ìjọba mi - Seyi Makinde Bí Khafi ṣe ní ìbálòpọ̀ ojútáyé tako àṣà Yorùbá - Ìjọba Ekiti Atẹjade naa tun salaye pe, Obono-Obla yoo si maa naju nile naa titi ti ajọ ICPC yoo fi fẹnu ọrọ jona lori iwadi to n se fun-un.
Gẹgẹbi iroyin se sọ, bi wọn se n bọ silẹ lori okada lawon darandaran fulani naa sa dede yọ si wọn pẹlu ibọn.
Donald Trump ti gbà pé Coronavirus yóò burú jáì kí ǹkan tó dára fún Amẹ́ríkà Ṣé lóòtọ́ ni pé Hushpuppi ti kúrò ní ọgbà ẹ̀wọ̀n l'America?
gomina Akinwunmi Ambode ti ipinle Eko , gomina 
Ibinu OLUWA rọ̀jò lé wọn lórí,àní ìbáwí Ọlọrun rẹ.
Ẹni-ọwọ julọ Odubanjọ sọrọ yii nigba ti o n ba awọn oniroyin sọrọ nibi Ajọdun Orin Iyin ati Orin Imisi Ẹmi ti ọdun 2018 (2018 Festival of Hymns and Canticles), eleyii ti o jẹ ajọdun orin kikọ ọlọdọọdun ti ijọ Eleto Orilẹ-ede Naijiria (Methodist Church Nigeria), ẹka ti Ipinlẹ Eko lapapọ maa n ṣe lọdọọdun.
“Ní Taanaki lẹ́bàá odò Megidoàwọn ọba wá, wọ́n jagun,wọ́n bá àwọn ọba Kenaani jagun,ṣugbọn wọn kò rí ìkógun fadaka kó.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Fi owo osu rẹ we ajẹmọnu Sẹnatọ rẹ 22 Ẹrẹ̀nà 2018 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 1 Bélú 2018 Àwọn oṣiṣẹ Naijiria n beere fun ẹkunwo owo oṣu oṣiṣẹ to kere julọ pé kó jẹ ọgbọn ẹgbẹrun naira, bẹẹ ijọba ipinlẹ ati ti apapọ ni awọn ko lee san iye naa.
Wọ́n ní nítorí ìdí èyí ni àwọn kò ṣe kí ń jẹ ata.
ilu , ni eyi ti awon eniyan n se lojoojumọ.
ni eyi ti won yoo fi lee maa daabo bo awon akoroyin lẹnu isẹ.
Wolii kan tọ Ahabu lọ, ó sì wí fún un pé, “OLUWA ní kí n wí fún ọ pé, ‘Nítorí pé àwọn ará Siria sọ pé, “ọlọrun orí òkè ni OLUWA, kì í ṣe Ọlọrun àfonífojì,” nítorí náà ni n óo ṣe fún ọ ní ìṣẹ́gun lórí ọ̀pọ̀ eniyan wọnyi, o óo sì mọ̀ pé èmi ni OLUWA.
Mahili bí ọmọkunrin meji: Eleasari ati Kiṣi, 
Misa sọ nipa bii oun se tako lilo abẹrẹ ajẹsara fun gbogbo ọmọ ti oun bi, ko to di pe ọmọ oun kẹta wa ni arun polio, ti o si rọ apa ati ẹsẹ rẹ.
FUTA: Òfin ti wà nílẹ̀ tó ní ká lé akẹ́kọ̀ọ́ tó bá na akẹẹgbẹ́ rẹ̀
Gbàrà tí àkókò yìí bá dé, ó ti tún sáré tẹ̀ síwájú, ó nbá’bi tiẹ̀ lọ.
OLUWA Ọlọrun ní, “Nígbà tí mo bá sọ ọ́ di ìlú ìparun bí àwọn ìlú tí ẹnìkan kò gbé inú rẹ̀, nígbà tí mo bá mú kí omi òkun bò ọ́ mọ́lẹ̀, tí ibú omi sì bò ọ́ mọ́lẹ̀, 
Mo rù kan egungun,agbára káká ni mo fi sá àsálà.
Ẹ ma ṣe jẹ ki o ya yin lẹnu pe o bọwọ pupọ fun orileede Naijiria ti kii si j'afara lati gbe ogo ilu rẹ ga nibi kibi to ba wa.
O dupo gomina labẹ asia ẹgbẹ oṣelu APC nibi to ti fẹyin alatako rẹ, Ademola Adeleke ti o ṣoju ẹgbẹ PDP ninu ibo naa janlẹ.
Tìbínú-tìbínú ni mo sì fi ń lọ.
Ohun tí a mọ̀ nìyí nípa gbọ́nmi síi omi ò tó lórí ọ̀rọ̀ oyè Babaloja-General ní ìpínlẹ̀ Oyo Ìpínlẹ̀ Osun kéde ọjọ́ táwọn iléèwé yóò ṣí padà YWC yọ Ààrẹ Banji Akintoye nípò àbi Akintoye tú ìgbìmọ̀ aláṣẹ YWC ká Wo àwọn orílẹ́-èdè mẹ́wàá tí kò ní coronavirus lágbàáyé, bá wo ni wọ́n ṣe ṣe é?
nile igbimo asofin leti pe ,ojo kárùndínlọ́gbọ̀n,
Wasiu Jimoh ni oun diidi gbadura fun Risikat lati bi ọmọ oloju buluu ni ki awọn to bimọ ati pe oju yii ni Risikat fi n wu oun.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Lai Mohammed: Ọbasanjọ, bí ìwo bá ṣé réré, Ara kì yóò yà ọ?
Yatọ si ọrọ Adekoya pe ipẹjọ naa mẹhẹ Adajọ Harrison ni ẹjọ naa tọna, o si yanranti, o ba ofin mu, kii si ṣe nkan to yatọ rara si awọn ipẹjọ to ti maa n waye tẹlẹ.
Lori eto ilegbe, o ni ijọba yoo kọ ilegbe ẹgbẹrun lọna ọọdunrun jake jado Naijiria eyi towo rẹ ko ni ju miliọnu meji naira lọ.
Ọpọlọpọ eniyan tẹ́ aṣọ wọn sí ọ̀nà, àwọn mìíràn tẹ́ ẹ̀ka igi tí wọ́n ya ní pápá.
Territory Emergency Management Agency, and Environmental Managers Registration
Eyi ko si fẹrẹ yẹ lori ipenija ọrọ abo to mẹhẹ lorilẹ-ede Naijiria eleyi to ti mu akiyesi awọn orilẹ-ede agbaye lati tan imọlẹ wọn si bi nnkan ṣe nlọ lorilẹede Naijiria paapaa julọ lori ọrọ abo.
Buhari sọ ọrọ yii lasiko ti oun fesi fun igba akọkọ lori bi wọn ṣe yọ Ibrahim Magu kuro ni ipo gẹgẹ bi adari Ajọ to n gbogun ti iwa ibajẹ lorilẹede Niajiria, EFCC.
Àwọn ìwọ́de àti ìfẹ̀hónúhàn irú èyí wáyé ní àwọn ìlú mìíràn ní Russia.
 Ó jẹ ́ èyí tí ó gùn lé sítáì pakọ ́ sàn tí ó gbẹ ̀ rẹ ̀ gẹ ̀ jigẹ ̀ ní òpin ọdún 1930 lọ sókè , ní ìgbà tí wọ ́ n ń lò ó láti jí àwọn olùsìn lẹ ́ yìn ààwẹ ̀ lásìkò oṣù mímọ ́ lámúláánà ti àwọn ìmọ ̀ le .
Akọroyin BBC Yoruba fidi rẹ mulẹ pe apere afefe tajutaju wa ninu afefe sugbon ko le fidi re mule boya won yin lu Gomina Fayose.
Awọn aworan naa wa lati ileesẹ BBC.
Ṣugbọn awọn to ba wa nileewosan, tabi to n lo ẹrọ fẹntiletọ le lo to ọpọ oṣu ki ara wọn to o ya.
Àwọn olùgbé Tarkwa Bay ń fọ́ ọ̀pá epo, jí epo ta, la ṣe lé wọn - Iléeṣẹ́ Ológun Ileesẹ ologun oju omi ti salaye ohun to faa ti wọn fi n fi tipa-tikuuku le awọn olugbe Tarkwa Bay to wa ni erekusu Eko, eyi ti eeyan le gba oju omi nikan wọ ibẹ.
10 Ati nísisìyí, èmi gbọ́dọ̀ mú ẹ̀kúnrẹ́rẹ́ ìhìnrere mi jade wá láti ọ̀dọ̀ àwọn Kèfèrí sí ilé Israeli.
Erongba tuntun banki CBN yii ni ṣiṣe afọmo awọn owo Naijiria si eyi to dun lati wo loju.
Ṣugbọn nisinsinyii ẹ ti kọ Ọlọrun yín sílẹ̀, Ọlọrun tí ó gbà yín kúrò lọ́wọ́ ìṣòro ati ìyọnu.
Ibasepo laarin orile ede Ethiopia ati Eritrea ko dan monran to, lopo igba ni ija si maa n waye  laarin awon iko omo ogun mejeeji naa.
Elizabeth Babalola to jẹ ana oloogbe naa ṣọ wi pe ogbẹni Olaoye a ma ṣiṣẹ oko dida ati ọkada lati le fi kun iye owo to n gba nibi iṣẹ ijọba to n ṣe.
INEC: Ko si ika ti ẹ ko le lo lati dibo INEC fi alaye sita nipa awọn igbesẹ ti oludibo yoo gbe lasiko ibo bẹrẹ lati ibi ayẹwo oruko to fi de ori ika titẹ.
Coronavirus in Nigeria: Ọmọ Italy tó kọ́kọ́ kó Coronavirus wọ Eko tún lọ́ sí ìpínlẹ̀ Ogun nàá
Jehoaṣi, ọba Israẹli mú Amasaya, ọba Juda, ọmọ Joaṣi, ọmọ Ahasaya, ní ojú ogun, ní Beti Ṣemeṣi; ó sì mú un wá sí Jerusalẹmu.
 Ó lọ sí ilé ẹ ̀ kọ ́ pampers private school , ní ìlú sùúrùlérè , àti ilé-ẹ ̀ kọ ́ nigerian navy secondary school , ní ìlú Ọ ̀ jọ ́ .
Ṣugbọn OLUWA nìkan ló mọ ìgbà tí nǹkan wọnyi yóo ṣẹlẹ̀.
yii ati bi won se tun bọwọlu iwe abadofin lati  je ki ojo isinmi lati maa se  ayajo  ayẹyẹ ijoba tiwa-n-tiwa lorile ede yii maa
Ẹ kọrin, ẹ̀yin òkè ńlá, ìwọ igbó ati igi inú rẹ̀,nítorí OLUWA ti ra Jakọbu pada,yóo sì ṣe ara rẹ̀ lógo ní Israẹli.
Awọn iroyin ti ẹ lee nifẹẹ si: Fathia Williams o feyin balẹ lati gba ise tiata Patoranking: Obinrin lo mu mi fẹran orin kikọ Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí kan sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
Ìdààmú yóo bá àwọn tí ó ń hun aṣọ funfun,ati àwọn ahunṣọ tí ń lo òwú funfun.
Nígbà tí omi òkun rí ọ, Ọlọrun,àní, nígbà tí omi òkun fi ojú kàn ọ́,ẹ̀rù bà á;ibú omi sì wárìrì.
Gopep,  je omo odun marundinlaadota , o ku, leyin aisan ranpe ni ojo ketadinlogun , Osu karun un odun 2018.
Ogbeni Niyi Alli , oludari eka to je mo oro ise lo so eleyii lasiko to n ba awon akoroyin soro ni ipinle Eko , nigba ti awon ero fe wo oko oju irin naa, o wa fi idunnu re han bi oko oju irin naa se tun se bere ise naa, o wa ro awon eniyan lati maa wo oko oju irirn ati lati maa fi ko eru won .
"Agbẹjọro agba ni ""ile igbimọ aṣofin ko lagbara kankan labẹ ofin lati gbero rẹ tabi ṣe agbekalẹ eto ti o le pe aarẹ ko wa ṣalaye ọrọ lorii iṣẹ awọn ologun ati bi wọn ṣe n lo wọn."
He called on Muslims and all Nigerians to always remember men and women who are less fortunate than themselves and to help the government in confronting the challenges facing the nation.
Ohun ti ọpọ n woye rẹ lọwọ bayii ni pe boya yoo ko ẹru oṣelu rẹ lọ ba ẹgbẹ oṣelu PDP pẹlu bi o ti ṣe n rin irinajo kaakiri ọdọ awọn gomina ipinlẹ to jẹ ọmọ ẹgbẹ oṣelu PDP bii Wike ti Rivers ati Udom ti ipinlẹ Akwa Ibom.
" Ko tan sibẹ o, Hon Ogunlẹyẹ tunfikun pe ko si aaye mọ fun ẹnikẹni lati maa da oju irin reluwe kọja tabi maa fo oju irin naa laibikita nitori irufẹ ẹni bẹẹ yoo san owo itanran.
’Ẹnìkejì yóo pe ara rẹ̀ ní orúkọ Jakọbu.
Ẹni tí ó jẹ̀bi tì í sẹ́yìn, ó ní, ‘Ta ni fi ọ́ ṣe olórí ati onídàájọ́ lórí wa?
Bí mo bá pàdé rẹ níta,tí mo fẹnu kò ọ́ lẹ́nu,kì bá tí sí ẹni tí yóo fi mí ṣe yẹ̀yẹ́.
Kí o pa olódodo run pẹlu àwọn eniyan burúkú?
Ààrẹ àná, Goodluck Jonathan ló fún mi ní 'oògùn' tí mo fi yọ Sanusi nípò Emir Kano- Ganduje Sanusi wọ gau torí pé o kọrin bù Gómìnà Ganduje Ganduje fi ọwọ́ òsì da ìdájọ́ ilé ẹjọ̀ nù lórí Emir tuntun mẹ́rin!
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Izeowayi gb'ẹ̀bùn ẹ̀kọ́ ọ̀fẹ́ lórí ìdíje àròkọ BBC Pidgin: 8 Ògún 2018 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 23 Ọ̀wàrà 2018 Àkọlé àwòrán, Ìdíje àròkọ̀ ni BBC Pidgin Ọgbẹni Izeowayi Victor lo jawe olubori ninu idije arokọ ni ede Pidgin.
pase fun awon osise alaabo lati se ise won bi ise lojuna ati ri pe won fese
Ìpín àwọn tí ó ní igbẹkẹle asán nìyí,òun sì ni èrè àwọn tí ọrọ̀ wọn tẹ́ lọ́rùn.
Ẹ kò kọ àwọn arakunrin yín sílẹ̀ láti ọjọ́ yìí wá títí di òní, ṣugbọn ẹ fara balẹ̀, ẹ sì ti ń pa gbogbo àṣẹ OLUWA Ọlọrun yín mọ́.
Ọgọjọ ohun amuyẹ bii ounjẹ, ohun mimu, igbokegbodo ọkọ, owo ina atawọn nnkan miran pẹlu owo ile gbigbe ni awọn ajọ naa gbe yẹwo kaakiri awọn ilu mẹtalelaadoje, (133).
Nígbà tí ó di ọ̀gànjọ́, Paulu ati Sila ń gbadura, wọ́n ń kọrin sí Ọlọrun.
Àwọn ọ̀ràn ìwà ọ̀darànmọràn yìí ti mú ọ̀pọ̀lọpọ̀ àwọn obìnrin ní orílẹ̀-èdè Angola dúró gírígírí, èyí sì fa ìpolongo tuntun kan tí ó ń tako ìjìyà abẹ́lé tí wọ́n pe àkóríi rẹ̀ ní “Ẹ Yé é Pa àwọn Obìnrin” tí Ẹgbẹ́ Ondjango tí ó jẹ́ àjọ ajàfúnẹ̀tọ́ obìnrin tí kì í ṣe ti ìjọba ṣe àgbékalẹ̀ẹ rẹ̀.
Wọn ni gbogbo eniyan lo mọ pe ipolongo ṣi le tẹsiwaju ko to ku wakati mẹrinlelogun ki idibo to waye niwọn igba ti wọn si ti sun idibo siwaju di ọsẹ kan, o yẹ ki awọn ẹgbẹ oṣelu tẹsiwaju pẹlu ipolongo wọn""."
"Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ọ̀dọ́mọdé Onímọ̀ ẹ̀rọ rèé tó ń ṣe bàálù, ọkọ̀, ilé àti ọkọ̀ ojú omi ""Bàbá mi kú, kò sówó ni mo ṣe kúrò ní fásitì Ilorin láti fọ gíláàsì ọkọ̀ lójú pópó"" Adúmáadán ni mí; ọmọ pé síbẹ̀!"
Lẹyin ti arun naa wọ ilẹ Naijiria tan ni awọn nkan ti eeyan le fi daabo bo ara rẹ bi ibomu pẹlu hand sanitizer ti di ọwọn gogo.
Ọrọ iranti ree ti aarẹ ana, Olusegun Obasanjo fi ṣapejuwe agba ọjẹ oloṣelu ipinlẹ Oyo nni, Lamidi Adedibu, se arise ni arika.
Ẹ̀rù mú kí àwọn tí wọn ń ṣọ́ ibojì náà gbọ̀n pẹ̀pẹ̀, kí wọn sì kú sára.
Wayii o, ara awon n kan won yii ni, sise agbekale ise akanse nini apo ifowopamo kan soso ti a mo si(TSA), eyi ti o seranwo lopolopo fun ijoba apapo lati maa pa owo wole lotun losi.
Ki lawọn ọdọ maa n ṣe lọjọ yi Lawọn orileede ti wọn ti n ṣe ayajọ yi, awọn ọdọ a maa ṣe iwọde toun ti pọpọsinsin orin ati ijo.
Ileesẹ to n se akoso awsn isẹlẹ pajawiri nipinlẹ Eko ni ifọwọsowọpọ isẹ ajọ panapana nipinlẹ Eko ati ajọ naa lo mu ki wọn tete bu omi pa ijamba ina naa.
Oloye Adedayọ ṣalaye pe Ọba yoo wu to ba dori aleefa ni ilana Bibeli tabi Kurani kii ṣe Ọba gẹgẹ bi ilana Ọba jijẹ ni ilẹ Yoruba.
"Oṣù yìí ni Juwọn bẹ̀rẹ̀ sí ní bá mi ṣiṣẹ́ kó tó ṣàgbákò ikú òjijì Ọ̀gá ọlọ́pàá tó wà ní 'Check Point' kàgbákò ikú òjijì lọ́wọ́ awakọ̀ l'Eko Wo ìgbésẹ̀ tí ìjọba ń gbé láti dènà ààrùn coronavirus ní Nàìjíríà Iná tún ti jó ilégbèé àwọn obìnrin níléẹ̀kọ́ Poly Ẹdẹ, dúkìá ₦10m ṣòfò Ọgbẹ́ ọkàn láéláé ni fún ọmọbìnrin ọdún mẹ́wàá, tí bàbá rẹ̀ dáná sí lábẹ́ - Amòfin ""Mo lu òyìnbó ní jìbìtì $82, 570 lóríí ayélujára, ìyá mi ló bá mi fi owó náà ra ilé"" Iroyin sọ pe ọpọlọpọ araalu ati ọlọpaa meji lo padanu ẹmi wọn lasiko ti awọn adigunjale naa ati awọn ọlọpaa kọju ija ibọn sira wọn."
Màmá Guardiola d'olóògbé lẹ́yìn tó lùgbàdì Coronavirus Àwọn olùgbé ìpínlẹ̀ Ọ̀ṣun ya bo ibùdó ìdìbò láti gba oúnjẹ Coronavirus Òfìfo ṣọ́ọ̀ṣì pa aṣọ dà fún àwọn Páṣítọ̀ Nàìjíríà Ronaldo fi Real Madrid silẹ lọ si Juventus lọdun 2018 lẹyin to ti ṣoju ẹgbẹ agbabọọlu naa lorilẹede Spain fun ọdun mẹsan an gbako.
Wọn ko jẹ ki ẹni kankan mọ bẹẹ si ni wọn ko jẹ ko ni agbẹjọro.
Èròjà ìlànà tí BBC ń gba ṣe ìròyìn: Ọ̀pọ̀ àwọn olólùfẹ́ BBC ní ìfẹ́ nítori pe ìròyìn wa kò ni ẹja n bákan nínú òòtaọ́ yìí si ló jẹ ki wọ́n dúro tìwá gbágbáágbá.
Bẹnaya, ọmọ Jehoiada, ará Kabiseeli, náà tún jẹ́ akọni ọmọ ogun, ọpọlọpọ nǹkan ńláńlá ni ó fi ìgboyà ṣe.
''Wọn fẹ dunkoko mọ wa ni,eyi si lodi sofin to fayegba wiwi tẹnu ẹni.
Àsọtẹ́lẹ̀ burúkú nìkan ni òun máa ń sọ.
Bí wọ́n kò tilẹ̀ ní orírun kan náà.
Ó wà lórí oyè ní Jerusalẹmu fún ọdún mọkanla.
gbiyanju lati se isẹ fun aseyọri aare Buhari lati jawe olubori ninu eto idibo
Tinubu kò ṣékú, kò ṣé ẹyẹ, o n dibọn ní lórí ọ̀rọ̀ ikọ̀ Amotekun - Fani Kayode Ìbẹ̀rù nípa Amotekun ló ń mú káwọn èèyàn kan máa wí ìwíkùwí - Soyinka Ẹwẹ, fun iranti yin: 1.
Akiriyan ijoba lori awon ikolu Gege bi Alhaji lai se so.
ile-ise naa wa ni  Abu Dhabi, , ti won si
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Yoruba Language: Ṣé ẹ mọ ìdí tí ọmọ fi ń jẹ́ orúkọ yìí?
Gbogbo ọba àwọn orílẹ̀-èdè dùbúlẹ̀ ninu ògo wọnolukuluku ninu ibojì tirẹ̀.
Ẹ̀sìn Àláfíà Àìkú s’ógun mi, iná laa lẹ́yìn ọ̀tá
Gbogbo àwọn eniyan tí ó ń gbé Jerusalẹmu ni ó mọ̀ nípa èyí.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Àìsan N30,000 owó oṣu f'óṣìṣẹ́ kò ní rọgbọ o- NLC Iléèṣẹ́ ológun ti ri òkú Ọ̀gágun Alkali tí wọ́n n wá nínú kànga Eyi fa ọpọlọpọ ikunsinu ni ileeṣẹ NHIS, debi pe awọn oṣiṣẹ ileeṣẹ naa ṣe iwọde.
Ikú ti mú ènìyàn pàtàkì lọ!
Bákan náà ni ti èyí, ó nílò kí wọ́n ṣe ìdásílẹ̀ òfin arọ́pò tí yóò mú ẹ̀tọ́ àwọn obìnrin rinlẹ̀.
"Ibeere to beere ni wi pe ""ṣe Ajimobi fẹ ṣe ojúṣáájú ni àbí báwo ni?"
Kò gbọdọ̀ mu ọtí kíkan tí a fi waini tabi ọtí líle ṣe.
“Bí ẹnìkan bá kórìíra arakunrin rẹ̀, tí ó sì fi ohun ìjà gún un, tabi tí ó ju nǹkan lù ú láti ibi tí ó sápamọ́ sí, tí ẹni náà bá kú, 
Bẹẹ si ni ọ̀pọ̀ àwọn akẹẹgbẹ rẹ nínú oselu, pàápàá àwọn igun alátakò lo ń ṣe ìdárò rẹ fún ipa tó ko fún ìlọsíwájú orílẹ̀-èdè Nàìjíríà.
Nítòótọ́, àwọn erékùṣù tí wọ́n wà ninu òkun yóo dààmú nítorí ìparun rẹ.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Wọ́n fi ikú Tunde Braimoh dá wa lóró ni o - Ẹbí pariwo Ìtàn ayé Henry Fajemirokun, olówó tó fi owó mọ Olúwa àti ènìyàn Báwo ni Coronavirus ṣe n tànkálẹ̀ l'Afrika?
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Jiti Ogunye: Ìjọba àkóbá lológun gbé kalẹ̀ ni 1999 Ole jija lori ẹrọ ayelujara: Igbogun ti awọn ti wọn n jale lori ẹrọ ayelujara ti n sọ eto rere, bẹẹ ni Aarẹ wa parọwa si awọn ti wọn n hu iwa bẹẹ lati jawọ nitori owo sinku ijọba ko ni pẹ ẹ mu wọn Sisọ oro kubakugbe lori ẹrọ ayelujara: Aarẹ Buhari ni awọn ọmọ Naijiria gbọdọ bọwọ fun ara wọn, paapaa lasiko ti wọn ba n fi ẹhọnu han lori nkan ti ijọba n se ti ko tẹwọnlọrun.
Ọpọ awọn ọmọ ilẹ Amẹrika lo dabi ẹni pe ikede aisan Trump yii jẹ iroyin ayọ fun wọn, bo tilẹ jẹ pe, ko dun mọ awọn kọọkan ninu.
Ẹ mọ èyí pé bí baálé bá mọ àsìkò tí olè yóo dé, ìbá máa ṣọ́nà, kì bá tí jẹ́ kí olè kó ilé rẹ̀.
Bakan naa lawọn aṣofin naa tun fi sinu ofin naa pe ẹnikẹni to ba gbimsran rẹ ṣugbọn ti ko ṣaṣeyọri lori rẹ yoo lọ lo ọdun mẹrinla roko ọba.
Ninu ọrọ tirẹ, arakunrin Justin lori ẹrọ Twitter sọ wi pe ohun ko ri iṣoro pẹlu ofin tuntun naa, amọ ijọba gbọdọ le fa ala laarin ọrọ kubakugbe ati eto lati sọ ọrọ lawujọ.
Ti awọn eroja DNA yii ko ba ṣiṣẹ bo se yẹ mọ, o le ṣe akoba fun bi awọn sẹẹli ara ṣe n ṣiṣẹ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Kanya Sesser: láti kekere ni ìyá mí ti kọ̀mí sílẹ̀ ṣùgbọ́n n kò ṣagbe Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Kanya Sesser: láti kekere ni ìyá mí ti kọ̀mí sílẹ̀ ṣùgbọ́n n kò ṣagbe 7 Ọ̀wàrà 2018 'Sọ fún ara rẹ pé o lè se ohun too ní lọ́kàn láti se láì sí ìbẹ̀rù' Omobinrin arewa Kanya sesser ti wọn bi lai ni ẹsẹ, ti ni oun se tan lati yi oju ti awọn eniyan fi n wo ẹwa ati arẹwa pada.
Olori Ajọ Ẹṣọ Oju Popo (FRSC) ẹka ti Sango-Ota ni Ipinlẹ Ogun, Akeem Ganiyu ni o fi ọrọ naa lede.
- Trump Amẹ́ríkà ń béèrè ìròyìn facebook, email arìnrìnàjò tó f'ẹ́ gbà'wé àṣẹ Amẹrika ń gbẹ̀san lára Nàíjíríà, owó ‘Visa’ di ọ̀nà méjì láti wọ Amẹrika Àti lọ s'Amẹrika ti yàtọ̀ báàyí Orìlẹ-èdè mẹrindínlọgbọn tí ọmọ Nàìjíríá lè wọ̀ láì ní àṣe ìwé ìgbélùú Ki wa nidi gangan ti US fi bẹgi dina Naijiria atawọn marun mii?
Ilu Lokoja jẹ ọkan lara awọn agbegbe to n lugbadi omiyale nitori aarin gbungun ọdọ River Benue ati Niger lo wa.
Gẹgẹ bi iwe iroyin Punch ti sọ, ọsẹ meji sẹyin ni ija naa ti bẹrẹ, ti apapọ iye eeyan to si ti ba rin ti le ni ogun.
Ìrì sẹ̀ sí i lára títí tí irun orí rẹ̀ fi gùn bí ìyẹ́ idì, èékánná rẹ̀ sì dàbí ti ẹyẹ.
"Amọṣa, mo ki i kaabọ si ẹgbẹ awọn ti EFCC n wa, mo si tun rọ ajọ naa lati maṣe gbagbe Amosun naa.
Amọ iroyin kan gbe e pe o ti n saarẹ fun igba diẹ sẹyin.
Ìyàlẹ́nu ni ó jẹ́ fún ìyá kan nígbàtí ọmọọ rẹ̀ kọ ẹ̀bùn Kérésìmesì.
Igbimọ to n ṣewadi iṣẹlẹ ọhun ṣi wa lẹnu iṣẹ ni lọwọlọwọ.
ati ẹẹdẹgbẹta (500) ìwọ̀n ṣekeli kasia, ìwọ̀n ṣekeli ilé OLUWA ni kí wọ́n lò láti wọ̀n wọ́n.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù NASS: San 2 Mílíọ́nù tàbí lọ ẹ̀wọ̀n ọdún méjì fún ìlòkulò Codeine 23 Èbibi 2018 Àkọlé àwòrán, Àbádòfin òhún ń wá ojúùtú sí òfin ìjọba Nàíjíríà (2004) tó de Oúnjẹ, àti àwọn ǹkan tó jọ mọ́ òògùn, Ilé ìgbìmọ Aṣòfin Nàíjíríà tí buwọ́ lu àtúnṣe àbádòfin lorí ìlòkulò Tramadol tàbí òògùn ikọ́ olómi codeine pẹ̀lú àbá pé ẹni tí igbá ọ̀rọ̀ náà bá ṣí mọ́ lórí yóò fi ẹ̀wọn ọdún méjì jura tàbí kó san mílíónù méjì náìrà.
Oṣù Kínní ọdún 2020 ti pẹ́ jù, ẹ ṣe ìgbẹ́jọ́ mi kíákíaá - Donald Trump Oṣù Kínní ọdún 2020 ti pẹ́ jù, ẹ ṣe ìgbẹ́jọ́ mi kíákíaá - Donald Trump Trump:Lakọ ni mo wa lati koju iwadi ''Òfin tí Ààrẹ Trump ṣe lórí àwọn àlejò ti lágbára jù'' Awọn aṣofin yẹ aga iṣakoso mọ Trump nidii lootọ, ṣugbọn ko fi idi janlẹ patapata.
Ifedayo Abegunde kọ̀wé fipò sílẹ̀ bíi akọ̀wé ìjọba Oríṣun àwòrán, Temidayo Olofinsawo Iroyin to n tẹ wa lọwọ ni yajoyajo ti kede pe akowe ijọba ipinlẹ Ondo, Ifedayo Abegunde ti kọwe fi ipo rẹ silẹ.
O si tun da ilee'sẹ ti wọn ti n jo irin mọ irin, Aluminium Smelter Company of Nigeria, silẹ nilu Ikot Abasi, to wa nipinlẹ Akwa Ibom ode oni.
Awọn ijọba nilẹ Africa naa dabi ẹni ti n jara mọ ọrọ naa.
Tí ó bá di àkókò ajinde, ninu àwọn mejeeje, iyawo ta ni obinrin náà yóo jẹ́, nígbà tí ó jẹ́ pé gbogbo wọn ni wọ́n ti fi ṣe aya?
 O ni arabinrin Zakari kun oju iwọn lati di ipo yii mu nitori ọkan lara awọn ọmọ igbimọ alakoso ajọ INEC ni ti kii sii ṣe oni lo ti wa nibẹ."
“Èyí ni òfin ẹbọ ìmúkúrò ẹ̀bi.
 bákannáà ni àwọn Ẹ ̀ gbádò wà ní Ìbàrà iléwó , onídà àti oníkólóbó bí ó tilẹ ̀ jẹ ́ pé àwọn tí sáájú Ẹ ̀ gbá dó síbẹ ̀ .
Ogbẹni Babtunde Akinbiyi to jẹ́ agbẹnusọ àwọn alabojutó igbokègbodò ọkọ nipinlẹ Ogun (TRACE), ló fìdí ọ̀rọ̀ na múlẹ̀ lowurọ òni (ọjọbọ).
Davido ati Mayorkun naa fi orin da awọn eeyan laraya lori asẹkagba eto naa.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Omotara: Mo kábámọ̀ ìwà tí mo hù sí ọmọ alágbe, mo wá a títí ṣùgbọ́n mi ò mọ ibi tó wà 23 Bélú 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 26 Bélú 2020 Oríṣun àwòrán, MOtara/instagram Gbajumọ ori ayelujara Naijiria tiṣẹ bọ lọwọ rẹ Omotara ti ni oun kabamọ iwa aibowọfọmọlakeji ti oun hu si ọmọde alagbe kan.
 Ẹ ̀ rín ò yàtọ ̀ tó fi délùú Òyìnbó .
Mo dúpẹ́ pé n kò ṣe ìrìbọmi fún ẹnikẹ́ni ninu yín, àfi Kirisipu ati Gaiyu.
Láì pa àṣẹ (yàtọ̀ sí abala kan tí Skinny kọ “fi ọwọ́ọ̀ rẹ hàn mí” àti “wá tẹ̀lé mi”, orin náà dàbí orin ológun.
Láti inú ẹnu kan náà ni ìyìn ati èpè ti ń jáde.
Ijọba apapọ tun gbe igbimọ ẹlẹni meje kalẹ lati wadi awọn ẹsun ti wọn fi kan an.
Orúkọ rẹ yóo fìdí múlẹ̀ sí i, àwọn eniyan rẹ yóo sì máa gbé ọ́ ga títí lae, wọn yóo máa wí pé ‘OLUWA àwọn ọmọ ogun, tí ó jẹ́ Ọlọrun Israẹli ni Israẹli mọ̀ ní Ọlọrun,’ ati pé ìdílé Dafidi, iranṣẹ rẹ, yóo fìdí múlẹ̀ sí i níwájú rẹ.
Babaláwo rèé pẹ̀lú afurasí adigunjalè mẹ́rin láhàmọ́ọ́ ọlọ́pàá Aàrẹ Buhari buwọlu yíyí orùkó àwọn ibùdókọ ọkọ ojú ìrìn bíi ti Apapa padà fi sọrí àwọn èèkàn ìlú Ìyá òòṣà fẹ̀sùn àjẹ́ kan ìyá ẹni ọdún 90, aráàlú bá sọ ọ́ lókò pa Banana Island jẹ ọkan lara awọn adugbo ti awọn ile to jẹ oju ni gbese pọ si julọ, ẹnikẹni ti yoo ba gbé nibẹ, si gbọdọ jẹun kanu daada, nitori pe obitibiti miliọnu ni wọn n ta ilẹ nibẹ.
Ó fi gbogbo ilé ìṣúra rẹ̀, fadaka, wúrà, turari, òróró iyebíye ati gbogbo ohun ìjà rẹ̀ hàn wọ́n.
Sisọ ogidi ọmọ Yorùbá ni orukọ to ni itumọ kikun jẹ ọkan lara àṣà Yorùbá ti BBC kò fẹ ko parun.
eto idibo  lati ilẹ okeere ati orile ede
19 Owewe 2020 Akure Church Kidnap: Òbí ọmọ tí wọ́n jígbé àti asọ́nà ṣọ́ọ̀ṣì 14, lọ́ búra nì'dí imọlẹ̀ l'Akure29 Bélú 2019 Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí kan sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
Gbogbo ará ilú àti àwọn Ìjọ Onigbàgbọ́ pé jọ lati ṣe ayẹyẹ à ṣe pọ̀ fún Ọbabinrin ni ọjọ́ Ìsimi, ọjọ́ kejila, oṣù kẹfà ọdún.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Àwọn aṣofin Nàìjíríà fẹ̀sùn kan Ọṣinbajo lórí ọ̀rọ̀ NEMA 9 Bélú 2018 Oríṣun àwòrán, @profosinbajo Àkọlé àwòrán, Àjọ NEMA to n dide siṣẹlẹ pajawiri ni Naijiria ni àwọn eẹ̀ yan kainkain NEMA sọ pe ọwọ wọn mọ, bi awọn aṣoju-ṣofin ṣe fẹsun kan Yẹmi Ọṣinbajo lori jibiti biliọnu mẹfa din diẹ.
janez drnovsek ( may 17 , 1950 - february 23 , 2008 ) a bí ní ọdún 1950 .
2019 elections; INEC gba ìwé ẹ̀rí lọ́wọ́ olùdíje APC, PDP lẹ́yìn ìdìbò àpapọ̀ 2019
Nigba to ya ni wọn gbọ ẹjọ ẹbẹ ti wọn pada tu awọn mejeeji silẹ nile ẹjọ kan ni Eko.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, R Kelly ń sukun lóri TV bó ṣe kọ ẹ̀sun ìfipábáni lòpọ̀ Kelly sọ fún akọ̀ròyìn CBS Gayle King pé, wọn lo ẹsun ọjọsí gẹgẹ bíi 'gbèdéke fún ẹsun túntún tí wọn wé mọ òun lẹ̀sẹ̀.
Lọdun 2016 ni wọn ni ọfa ikọlu wọn ti ba Abubakar nibi to lapẹrẹ ati pe oku ni ẹlẹja n taa lo maa pari ikọlu ọhun.
"Ọdúnladé Adékọ́lá ra ọkọ̀ Range Rover, kò sẹ́ni tó gbọ́ síi, nítorí pé ó gbọ́n, ó sì ní ọpọlọ ni.
Ohun tí ó ń sọ kò yé wa.
 falciparum  pẹ ̀ lú "" p."
Awọn ara ilu ti fẹjọ rẹ sun awọn alaṣẹ ọlọpaa titi ṣugbọn ko dẹkun lati maa kọ ọrọ ti yoo bi aye ninu lori Twitter.
"Ọwọ́ ọlọ́pàá Eko tẹ ọmọ ọdún 22 tó jẹ́ olórí 'bambam' f'ẹ́gbẹ́ òkùnkùn Berry Boys Àwọn olùfẹ̀hónúhàn ""Occupy Lagos"" ń fẹ́ kí ìjọba Eko dá Okada àti Maruwa padà Ìjọba Eko sọ pé ká má tọrọ bárà mọ́, wọ́n tún fòfin de kẹ̀ẹ̀kẹ́ tá a fi n ṣiṣẹ́ - Àwọn àkàndá ẹ̀dá Ìsọkúsọ ni Olúbàdàn ń sọ, àwa la lè yọ́ lóyè."
Iwe iroyin African Review sọ pe, Biya n gba ọtalelọọdunrun o din ẹyọkan miliọnu CFA francs, owo orilẹede Cameroon, ti afiwe rẹ jẹ ẹgbẹrun lọna ẹgbẹta o le mẹwa Dọla ($610,000) lọdọọdun.
O kọ́ wọn láti máa pa ọjọ́ ìsinmi rẹ mọ́, o sì tún pèsè ẹ̀kọ́, ìlànà, ati òfin fún wọn láti ọwọ́ Mose iranṣẹ rẹ.
Ẹ máa retí ìyè ainipẹkun tí Oluwa wa Jesu Kristi yóo fun yín ninu àánú rẹ̀.
Ààrẹ Gani Adams sọ ẹni tí Yorùbá yóò dìbò fún ní ọdun 2019 #BBCNigeria2019 Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Atunto Naijiria la n fẹ - Aarẹ Onakakanfo, Gani Adams Ṣe ni Adams fesi si Adesina pe ohun to sọ ko ri bẹẹ, o ni ipo ti orilẹede yii wa fihan gedegbe pe ọpọ ọmọ Naijiria lebi n pa ti wọn ko si nireti kankan.
O ni esi ti agbẹnusọ Aarẹ sọ lori iṣekupani naa jẹ eyii ti ko bojumu, ni bo ṣe sọ pe awọn agbẹ ti wọn pa ọhun ko gba aṣẹ lọwọ ileeṣẹ ologun ki wọn to lọ rèé kérè oko wọn.
Olukopa obinrin ti o darajulo lagbaye ninu ere-idaraya boolu afigigba, Simona Halep fagbahan akegbe re Wang Qiang pelu ami-ayo meje si marun-un(7-5), mefa si ookan( 6-1), ni papa isere BNP Paribas lojo Isegun(Tuesday) lati pegede sipele keta idije Indian Wells.
òun ni òun fi agbára ńlá òun dá ayé: ati eniyan ati ẹranko tí wọ́n wà lórí ilẹ̀; ẹni tí ó bá tọ́ lójú òun ni òun óo sì fi wọ́n fún.
Ṣùgbọ́n ó tẹ̀ ẹ́ mọ́ wa létí dáadáa pé agbára ìdajì ṣíbí kan tí a bá mu lóòjọ́ kò ju ọjọ́ kan lọ nítorí náà a kò gbọdọ̀ pa ọjọ́ kan jẹ láì mu egbòogi yìí títí a ó fi dé ilé.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Gabon: Àlááfíà ti padà, a ti mú àwọn ológun tó fẹ́ gba ìjọba 7 Sẹ́rẹ́ 2019 Oríṣun àwòrán, Reuters Àkọlé àwòrán, Ààrẹ orílẹ̀èdè Gabon, Ali Bongo tó ń se àìsàn lọ́wọ́ ti gba ìjọba láti àádọ́ta ọdún sẹ́yìn.
Lola, ojo Bo ni Osinbajo yoo tun se ipade papo pelu awon agba oje  osise ijoba.
Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí BB Naija: Kí ló pa Elisha Abbo, Leycon àti Naira Marley pọ̀, tí àríyá yóò fi wáyé?
Ṣugbọn mo tún ro ti orúkọ mi, nítorí n kò fẹ́ kí wọ́n ba orúkọ mi jẹ́ lójú àwọn orílẹ̀-èdè tí mo ti kó wọn jáde.
Sinima naa da lori ọmọbinrin kan, ''SALAWA'' to sọ ara rẹ nu, to gbagbe ile.
Oni ọjọ Iṣẹgun, ọjọ kẹẹdogun, oṣu kinni, ọdun 2020 lo pe ọdun mẹrinlelaadọrin tawọn ologun ṣekupa Samuel Ladoke Akintola to jẹ Aare Ona Kakanfo kẹtala ilẹ Yoruba.
Àwọn ẹ̀yà Reubẹni, ẹ̀yà Gadi, ti Aṣeri, ti Sebuluni, ti Dani ati ti Nafutali yóo sì dúró lórí òkè Ebali láti búra.
O ni Igbakeji gomina ipinlẹ Ondo ni lọkan lati di gomina ni o ṣe lọ darapọ ẹgbẹ oṣelu ZLP ti yoo fun ni anfaani lati dije dupo, eleyii ti o lẹtọ si labẹ ofin.
Maïza Séremé fi kun pe, awon oga ologun ti won si wa ninu ise ologun meji ati enikan ti won ti le kuro ninu ise ologun, wa ninu awon ti won fi owo sinkun mu naaAwon alase  gbagbo pe,enikan wa ti o je agbateru ikolu mejeeji, eyi ti won so pe, awon alakata-kiti elesin Islam ti a mo si “Islamic  and Muslim Support Group”.
tóbẹ́ẹ̀ tí àwọn alufaa kò lè dúró láti ṣe iṣẹ́ ìsìn, nítorí ògo OLUWA kún inú ilé OLUWA.
Mariam Phiri – The Road To Sunrise
Yorùbá ma nlo òwe yi nigbati èniyàn bá ṣẹ̀ tàbi ṣe nkan burúkú si ẹni keji, ti wọn bẹ̀rẹ̀ si bẹ ẹni ti wọn ṣẹ̀ lai mọ bóyá ẹni ti ó ṣẹ̀ ni àyipadà ọkàn kúrò ni iwà ìbàjẹ́ tàbi iṣẹ́ ibi.
Ẹ dẹ̀kun lílo Sniper àti Dichlorvos fún ìtọ́jú oúnjẹ- NAFDAC kìlọ̀ Oríṣun àwòrán, Getty Images Kini o kọkọ ṣẹlẹ lẹyin ti wọn ji alaga kansu gbe tẹlẹ?
Atejade lati ile-ise asoju orile-ede America ohun wa ro ijoba orile-ede Ethiopia , “lati ni arojinle,  ki won si gbe igbese miiran ti yoo da abo bo awon ara-ilu ati dukia, bakan naa ki won wa ona ti won yoo fi seto idunna dura pelu awon oloselu, eyi ti won ro pe, yoo je ona kan gboogi lati fese eto ijoba-n-tiwa mule lorile-ede naa”.
O ni o tun ma n mu ki obinrin gbadun ibalopọ ju ti tẹlẹ lọ.
"Wo ọmọbìnrin ọdún méjìlá tó ṣè'gbéyàwó pẹ̀lú ọkùnrin méjì láàrin oṣù kan Ohun tí ilé ẹ̀jọ́ rí rèé tí kò fi gba Béélì Hushpuppi Nítorí ǹkan ẹyọkan tí wọ́n rí yìí ni wọ́n fi lọ́ ẹ̀ṣùn m ọ lẹsẹ pé onibalopọ akọsakọ, ""Gay"" ní òun àti pé òun ni àwọn ọ̀rẹ́kùnrin tí àwọn jọ ń ṣe ìwà ìbàjẹ́."
Nígbà tí Jesu gbọ́, ó ní, “Àwọn tí ara wọn le kò nílò oníṣègùn bíkòṣe àwọn tí ara wọn kò dá.
Floyd Mayweather Jnr ṣeleri gbowo kalẹ fun eto isinku George Floyd Oríṣun àwòrán, @ComplexSports Abẹṣẹ ku bi ojo, Floyd Mayweather Jnr.
ikabo gbogbogboo ni gbọngan igbalejo International Conference Centre, to wa
Lodun 2015 ni Erdogan ati Alufaa Francis ti koko ni gbonmisii omi ko too nigba ti o di olori ijo aguda lagbaye ti yoo koko kede ipaniyan 1915 ti o le ni milionu kan abo awon eniyan to gbemi mi ni ipaniyan to buru julo ni eyi to je esun ti Turkey maa n figbagbogbo se.
Ṣùgbọ́n ’rùngbọ́n nìkan náà ni mo lè fi àdá fá mọ.
Àwọn ọmọ Juda bá tọ ẹ̀yà Simeoni, arakunrin wọn lọ, wọ́n ní, “Ẹ bá wa lọ síbi ilẹ̀ tí wọ́n pín fún wa, kí á lọ gbógun ti àwọn ará Kenaani.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Oshiomole: Ilé ẹjọ́ kòtẹ́milọ́rùn wọ́gilé ìyọnípò Oshiomole gẹ́gẹ́ bíi alága ẹgbẹ́ òṣèlú APC 16 Ẹrẹ̀nà 2020 Oríṣun àwòrán, @marketdigestng Ile ẹjọ kotẹmilọrunilu Abuja ti ni Adams Oshiomhole si ni alaga gbogbogbop fun ẹgbẹ oṣelu APC.
Àwọn ọmọbinrin meje kan wá pọn omi, wọ́n jẹ́ ọmọ Jẹtiro, alufaa ìlú Midiani.
Nigbati Oga agba ajo eleto idibo INEC  ni Ipinle Oyo, n soro lori idaduro ranpe to
Mo bá fẹ̀ pẹrẹgẹdẹ sórí àga mo fẹ̀hìntì dáadáa.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Kwara yóò gbàlejò BBC Yoruba Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Ewe, amugbalegbe Pataki fun aare Buhari lori eto iroyin ati igbodegba, ogbeni Femi Adesina so lasiko to n ba awon akoroyin ile-ise aare soro wipe, aare pe ipade naa lati fi ese isokan ati ibasepo mule laarin awon omo egbe APC pata-pata.
Fún ọ̀pọ̀ ọ̀sẹ̀ ni mó fi wà ni àtìmọ́lé nínú ilé ara mi lori àkéte sàìsàn.
 alison-madueke ( ojoibi december 6 , 1960 ) je oloselu ara naijiria .
Ẹ̀wẹ̀, ọ̀pọ̀ àwọn ọmọ yìí ń fi àwọn ìwé náà ṣe àkọsílẹ̀ àwọn ǹkan ti ó ń sẹlẹ̀ àti àṣírí tó ń tú sí wọn lọ́wọ́ nínú àhámọ́ Boko Haram.
 Lara awọn iṣoro naa ni opopo na ti ko dara, bi awọn agbofinro atawọn ọmọ ita ṣe maa n lo igboju lati gba owo lọwọ awọn eeyan wa, ati bẹẹ bẹẹ lọ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fọ́nrán ohùn, House of Rep: Atúndi ilé ìgbìmọ Aṣofin tí gbérasọ ní Kwara Bakan náà ní ìròyín tún tẹ̀wá lọ́wọ́ pé, ẹ̀rọ̀ tó máà yẹ orúkọ àwọn olùdibò wo ti daṣẹ́ sílẹ̀ láwọn ibìkan, tàwọn ọmọ ẹgbẹ òṣèlú PDP si ní INEC mọ̀ọ́mọ̀ ṣe èyí ni nítòrí ibi tí ẹgbẹ àwọn ti láanfàní láti jáwé olúbori ni.
 wọn ni nǹkan bí ẹgbẹ ̀ rún ọdún sẹ ́ yìn ni ọba ọ ̀ hún jẹ ( a.
Nítorí Ọlọrun a máa rẹ onigbeeraga sílẹ̀,a sì máa gba onírẹ̀lẹ̀.
Ìwọ la ọwọ́ rẹ,o sì tẹ́ gbogbo ẹ̀dá alààyè lọ́rùn.
OPC kò láṣẹ láti fipa lé ẹ̀yà kan nílẹ̀ Yorùbá lórí ọ̀rọ̀ ikú Olakunrin - Ọlọ́pàá Fulani DaranDaran di fà kí n fà láàrin Gómìnà Ganduje àtàwọn Gómìnà ilẹ̀ Yorùbá Ẹ wo àwọn ìròyìn tó ṣì ń gbóná fẹli fẹli lọ́sẹ̀ yìí Ẹ wo ìpínlẹ̀ 15 tó faramọ́ ìdásílẹ̀ àbúlé Ruga Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Awọn ọdọ Ondo fẹ̀họ́nù hàn lórí ìṣekúpani Funke Olakunrin O fikun un wi pe ko si ẹni to le e di alafo ati ọgbẹ ọkan ti iku iyawo oun da silẹ fun oun ati awọn ọmọ pẹlu ẹbi ati ara.
Ní ọjọ́ kẹẹdogun oṣù kẹjọ tíí ṣe ọjọ́ tí ó yàn fún ara rẹ̀, ó lọ sí ibi pẹpẹ tí ó kọ́ sí ìlú Bẹtẹli láti rúbọ.
    Ìrìnàjò wa dára lẹ́yìn tí a kúrò ní ìlú àwọn Èdìdàrẹ́, a kò sì rí nǹkan kan títí a fi de inú igbó ńla’kan báyìí tí orúkọ rẹ̀ ń jẹ́ Aginjù Babalórìṣà.
Oríṣun àwòrán, OYSG Bi darandaran ba si ti ri pe ilẹ naa dara, ko ni fẹ kuro nibẹ mọ, tawọn asaaju awujọ gan si maa n gbe ilẹ wọn fun darandaran lai bun awọn mọlẹbi wọn gbọ.
"Gomina ipinlẹ Ọṣun ti amugbalẹgbẹ rẹ lori ọrọ ọgbin ati ipese ounjẹ, Ọgbẹni Biọdun Ajiṣefini ṣoju fun ṣalaye lasiko abẹwo rẹ si ilu Iba pe 'ara wa lawọn eeyan ti adanu nla yii ṣẹ, wọn kii ṣe ajeji"" Davido, Fani Kayode, Kemi Olunloyo, sọ̀rọ̀ lórí ẹ̀sùn jìbìtì Allen Onyeama Pasuma kìí ṣe ọkọ mi o!"
Wo àwọn Gómìnà Naijiria tí àrùn Covid-19 ti bá fínra Àwọn akẹgbẹ́ ẹ̀ṣọ́ àjọ FRSC mẹ́ta tí àrá sán pa l'Ogun gbọdọ̀ ṣ'ètùtù- Elebuibọn Mo mọ̀ pé ibi tó dára ni Ibidun Ighodalo wà báyìí- Adeboye Seyi Makinde ṣí iléèwé padà ní ìpínlẹ̀ Oyo, Cross River pa ọ̀rọ̀ dà lórí ìwọlé akẹ́kọ̀ọ́ Bawo gan ni ọrọ ṣe bẹrẹ?
Nígbà náà ni yóo bi wọ́n pé,‘Níbo ni àwọn oriṣa yin wà,ati àpáta tí ẹ fi ṣe ààbò yin?
Nigba ti Immaculate Okochu n fi ọpọlọpọ fọto rẹ to rẹwa soju opo ayelujara rẹ lọjọ kọkanla oṣu kẹjọ, ko sẹni to mọ pe arimọ rẹ naa niyẹn.
“Wọn óo kó àwọn ọmọ ogun wá bá ọ, wọn óo sọ ọ́ lókùúta, wọn óo sì fi idà wọn gé ọ sí wẹ́wẹ́.
Awọn mẹtẹẹta wa lara awọn ero ti wọn ri sodo Bakana lọjọ kejidinlọgbọn, oṣu keje lasiko ti Blankson gba awọn mẹtala là.
Ó wó odi Jerusalẹmu palẹ̀ láti Ẹnubodè Efuraimu títí dé Ẹnubodè Kọ̀rọ̀.
 Àwọn oríṣiríṣi rẹ ̀ ni ó ti wà fún lílò láti bíi ọdún 2007 .
Oga agba Mike Obiezu ati awon
Ile ẹjọ́ naa si gba oniduro, wọ́n ni nitori ilumọ̀ọ́ká ni, ko le sálọ.
Báyìí ni ọkùnrin sọ, n kò sì rí i mọ́.
Ṣùgbọ́n àwọn onímọ̀ ẹ̀sìn sọ pé ohun àá ṣeé ṣì kù.
" O ni awọn to forukọ silẹ lọna to tọ ko ju ẹgbẹrun mọkanla lọ, ṣugbọn ariwo maa pọ to ba jẹ pe awọn to ṣe e lọna to tọ nikan, ni wọn fun ni anfani lati ṣe ayẹwọ.
”Pẹlu ayọ̀ ni ọpọlọpọ eniyan ń fetí sí ẹ̀kọ́ rẹ̀.
 kó yẹ kó rí bẹ ́ ẹ ̀ , ṣe ló yẹ kó jẹ ọmọ àti bàbá .
Oun naa wa lara awọn ti omi gbe lọ, to si gba ibẹ di ero ọrun.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Oladapo Adu: Nàíjíríà já mi kulẹ̀ torí wọn kò wá gbé mi Bakan naa, Henry Fajemirokun lọ sile ẹkọ girama CMS nilu Eko fun eto ẹkọ girama rẹ.
 bí a bá tún wo ẹ ̀ ka-èdè tí wọ ́ n ń sọ ní Òkè-igbó àti ifẹ ̀ ẹ ́ tẹ ̀ dó , ẹ ̀ yà ẹ ̀ ka-èdè ifẹ ̀ ni .
Ogbeni Onyeama so pe “Nipa ona ti a o gba lati pese eto iranwo ise akanse fun orile ede Sao Tome ati Principe ni aare  se ran mi lo sibe.
Oríṣun àwòrán, Reuters Àkọlé àwòrán, Awọn mọlẹbi wa ninu ibanujẹ Wakati kan lo yẹ ko lo ki o to de papakọ ofurufu Pangkal Pinang ṣugbọn ko pẹ si igba to gbera to ja lulẹ.
Ayé ò fẹ́ á gbé ayé
Ọ̀nà márún-ún láti mú àdín kù bá dátà (Data) lílò rẹ O mẹnuba ipa ti ẹjẹ tuntun n ko ni agọ ara ni eyi to ṣeeṣe fun enikeni to ba n fi ẹjẹ silẹ loorekoore.
Kọmiṣọna fun eto iroyin, Gbenga Omotosho ninu atẹjade to fi sita lọjọ Aiku ṣapejuwe iroyin kan ninu eyi ti ajọ Economist Intelligence Unit (EIU) fi lede pe ilu Eko lo lewu julọ lati gbe lagbaye gẹgẹ bi aimọkan.
Nígbàtí ìwọ Alákọ̀wé bá gbójú wòkè wo ilé gogoro ńlá nì, tí ìwọ ń gbóríyìn fún àwọn ọmọ ènìyàn tí wọ́n kọ́ irúfẹ́ ilé àràmàndà yìí, tí o rò pé nkan ìyanu ni, Èmi Ẹlẹ́dàá rẹ̀, N ó tan ìmọ́nlẹ̀ oòrùn lókè, tí ògo tirẹ̀ yíò borí ògo ilé gogoro náà, tí ìwọ yíò sì mọ̀n dájú pé Tèmi ni iyì gbogbo, Tèmi ni ìyanu, nítorí agbára Tèmi ju ti ọmọ ènìyàn lọ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Awọn oluwọde ya wọ ile-ẹjọ nitori aṣofin Dino Melaye 1 Ẹrẹ̀nà 2018 Oríṣun àwòrán, Dino Melaye/Facebook Àkọlé àwòrán, Wọ́n gbé Dínò Mèláye lọ́ ilé ẹjọ nitori ẹ̀sun ìkuro lorí ìgbìyànju láti paa Ijọba apapọ orilẹede Naijiria ti gbe aṣofin Dino Melaye lọ s'ile-ẹjọ giga ti ilu Abuja lori awọn ẹsun meji to niiṣe pẹlu ijẹri-eke ati irọ pipa wipe awọn eniyan kan fẹ d'ẹmi rẹ legbodo ni oṣu kẹrin ọdun ti o kọja.
Dayo Adeyẹye - Ekiti Ibo sipo Sẹnetọ ti wọn di loṣu keji ọdun yii lo gbe Dayo Adeyẹye wọle sile igbimọ aṣofin l'Abuja.
A kò sì rẹ́ ẹnikẹ́ni jẹ.
Iyatọ ibo laarin awọn oludije mejeeji ni 482.
Iku awọn eeyan naa waye lati ọwọ awọn oṣiṣẹ alaabo nibudo ti wọn ti n ka esi ibo, ati lati ọwọ awọn araalu si ara wọn.
Ọgbẹni Saheed Alatishe ni oludije ẹgbẹ PDP.
Grace Oyin Adejobi: Ẹ̀yin òṣèré tíátà lóbìnrin tẹ́ ǹ bọ́ra sí ìhòhò, ẹ sá fún ìtànjẹ́ ayé
Awọn miran sọ pe iya-iya mi lo wa nidi ọrọ mi.
agbaboolu Roma, ti pinnu lati fiko Roma sile latari iwa aigboraeniye to n jeyo laarin
Awọn to padanu mọlẹbi wọn sinu rẹ n kọ?
Ẹgbẹ YWC tun sọ pe ohun yoo gbe igbimọ ẹlẹni mẹrin dide lati ba Aarẹ ẹgbẹ naa Ọjọgbọn Akintoye ṣiṣẹ pọ titi ti wọn yoo yan awọn mii.
Nígbà tí wọ́n rí angẹli náà, wọ́n sápamọ́.
Naijiria ati Cameroon ti pade nigba mẹwaa ninu idije AWCON, ṣugbọn ẹgbẹ agbabọọlu Naijiria fagba han Cameroon lẹẹmẹjọ ọtọtọ ti Cameroon si jawe olubori lẹẹkan ṣoṣo.
Coronvirus in Nigeria: Àjọ NCDC ti kede pé ènìyàn méji míran ti ni àrun náà
Kò sí ohun tí a lè fi wé láyé,ẹ̀dá tí ẹ̀rù kì í bà.
Oko ogun oju ofurufu iko omo-ogun ile Amerika, F15 ja sinu omi okun Okinawa ti o kogun si ila oorun orile-ede Japan, nibi ti ogoro omo ogun ile Amerika ti o wa lorile-ede Japan tedo si.
OLUWA a máa ṣe oore fún àwọn tí wọn dúró dè é,tí wọn sì ń wá ojurere rẹ̀.
Nígbà tí Saulu bá àwọn ará Filistia jagun tán, wọ́n sọ fún un pé Dafidi wà ní aṣálẹ̀ Engedi.
Ọgbẹni Tillerson wa lori isinmi lẹyin abẹwo rẹ si ile Afirika nigbati ko ro wipe ọgbẹni Trump yoo yọ oun nipo, ati wipe Aarẹ Trump gba aba lati ṣe ijiroro pẹlu olori orilẹede North Korea, Kim Jong-un.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 3 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 5 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Ọmọ ọdún mejilelogun ni Amoni nígbà tí ó jọba, ó sì wà lórí oyè fún ọdún meji ní Jerusalẹmu.
” Angẹli OLUWA náà bá dúró níbi ìpakà Onani ará Jebusi.
Ni ọdun 2016, awọn osisẹ gunle iyansẹlodi ni Ọjọ Kejidinlogun, Osu Karun, ọdun naa, lẹyin ti ijọba fi owo kun owo epo lati Naira marundinlaadọrin si Naira mejidinlogoje.
Ṣugbọn a ti ja àwọn eniyan wọnyi lólè,a sì ti kó wọn lẹ́rù,a ti sé gbogbo wọn mọ́ inú ihò ilẹ̀,a sì ti fi wọ́n pamọ́ sinu ọgbà ẹ̀wọ̀n.
Ṣugbọn angẹli náà sọ fún un pé, “Má bẹ̀rù, Sakaraya, nítorí pé adura rẹ ti gbà.
ọmọ Kainani, ọmọ Afasadi, ọmọ Ṣemu, ọmọ Noa, ọmọ Lamẹki, 
Thai king: Ọ̀nà wo ní ẹ̀ṣọ́ ọba gbà di olorì láàfin?
Láìpẹ́ yìí ni ìyàwó Kanu pari ẹkọ́ láti gba oyè gíga nínú ìmọ̀ òfin MBA rẹ.
Ó pàṣẹ fún wọn pé, “Ẹ lọ fara pamọ́ lẹ́yìn ìlú náà, ẹ má jìnnà sí i pupọ, ṣugbọn ẹ wà ní ìmúrasílẹ̀.
 Ṣé mákọjá mi Olùgbàlà kìí ṣe orin àkúnlẹ̀kọ àbí?
    A rìn tó wákàtí mẹ́ta sí odò Ẹ̀jẹ̀ nígbà tí a rii pé Ọ̀ nà túbi si i ti ojú ọ̀nà náà kún fún yanrìn funfun lọ gbáà, wọ́n gbá ojú ọ̀nà yìí ó mọ tingín tingín àwọn igi ńlá gbogbo ti wọ́n dàbí àràbà mi wọn sì wà ní apá ọ̀tún àti apa òsì lọ, ṣùgbọ́n, àti ewé, àti ẹka igi àti ìtànná àwọn igi wọ̀n-ọnnì, ṣe ni wọ́n funfun balau, inú igbó náà sì mọ́ tó bẹ́ẹ̀ tí ó jẹ́ pé bí ènìyàn bá wo abẹ́ igbó báyìí, ènìyàn lè rí to irin bí wákàtí kan lẹ́ẹ̀kan ṣoṣo.
Mose ati Eleasari sì ṣe bí OLUWA ti pa á láṣẹ fún wọn.
Alaga ajo INEC, ojogbon Mahmood Yakubu  fi oro naa mule lasiko ipade awon toro kan gbongbon ti o waye nilu Ado-Ekiti, ti n se olu-ilu ipinle naa, lojo Aje(Monday).
Wọ́n ní ẹnu, ṣugbọn wọn kò lè sọ̀rọ̀,wọ́n lójú, ṣugbọn wọn kò ríran.
TI ÌJỌ JÉSÙ KRÍSTÌ TI ÀWỌN ÈNÌYÀN MÍMỌ́ ỌJỌ́-ÌKẸ̀HÌN
Ẹwẹ, olootu ijọba UK, Boris Johnson ni abẹrẹ yii lo maa jẹ kí awọn eeyan UK gbaye gbádùn, ohun naa lo si maa jẹ ki ọrọ aje UK gberu síi.
Abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò dágbére fáyé lẹ́yìn ìjà rẹ Háà, ó ṣe!
Otis Hughley to je akọnimọọgba ikọ awọn obinrin yii fi idunnu rẹ han lasiko to n ba BBC sọrọ.
Olorin Kristẹni ni Lawrence Oyor, to jẹ ọkọ Darasimi.
Ninu ọrọ ati iṣe rẹ, awọn eeyan loju opo Twitter ni o fihan pe, olori ti o ni ifẹ ara ilu nii ṣe.
Bí ohunkohun bá kù di ọjọ́ kẹta, sísun ni ẹ gbọdọ̀ dáná sun ún.
Àwọn òkè ńláńlá ń fò bí àgbò,àwọn òkè kéékèèké ń fò bí ọmọ aguntan.
 Àwọn oyè tó kù tó sì se pàtàkì ní apèènà , akẹ ́ rẹ ̀ , baàjíkí , baàlá , baàjítò , Ọ ̀ dọ ̀ fín àti lísa { .
Ṣugbọn àwọn onigbagbọ pagbo yí i ká títí ó fi dìde tí ó sì wọ inú ìlú lọ.
Nibayii, Ẹgbẹ awọn alaga kansu ALGON ni ipinlẹ Ọyọ ti ṣalaye wi pe awọn yoo pe ẹjọ kotẹmilọrun lori idajọ naa niwaju ile ẹjọ to ga julọ lorilẹede Naijiria.
Nínú ìpéjọpọ yìí ní wọ́n ti yàn ènìyàn méjí fún ìdìbò, Asiwaju Bola Ahmed Tinubu àti Ọjọgbọ́n Adebanji Stephen Akintoye.
    Nígbà tí mo tún sún lálẹ́ mo tún lá àlá ri i, mo ri i pe a bẹ̀rẹ̀ si i jà, àti wí pé a túká, òun ń lọ sí apá kan èmi náà ń lọ sí apá kan.
 O menuba ise akanse tawon olojo ori kan bii Regberegbe ti se fun idagbasoke ilu.
Idibo ọhun yo yẹ ki o waye lọjọ kokandinlogun ati ogunjọ oṣu Kẹfa yoo ma waye ni ọjọ kẹtalelogun oṣu Kẹfa bayi.
Oríṣun àwòrán, AFP Ki i gan ni eroja ammonium nitrate to fa ilẹ ya bẹ ẹ?
Ṣe ẹ ranti bi inu kilaasi yin ṣe maa n ri lasiko ti ẹ ba fẹ ka awọn iwe ayọka Yoruba nigba ti ẹ ṣi wa nileewe girama?
O ni lọwọ yii, oun ko tii le fidi rẹ mulẹ pe ẹnikẹni ti lugbadi arun naa nipinlẹ Oyo titi di igba ti esi ayẹwo naa yoo jade.
Oluranlọwọ pataki fun igbakeji gomina lori ọrọ to n lọ, Omoetan Omolere lo sọ bẹẹ ninu ifọrọwerọ kan pẹlu BBC Yoruba.
Bí ènìyàn bá gbin igi náà sí orí omi ní ìlúkílùú ẹnikẹni tí ó bá mu nínú omi ibẹ̀ yóò di ọlọ́gbọ́n pátápátá.
”Gomina  Dankwambo dupe lowo asofin Ekweremadu fun bi o
’“Obinrin náà yóo sì dáhùn pé, ‘Amin, Amin.
lara iwe-ẹri ti asofin Adeleke fi mọ iwe ti o fi ransẹ si ajo eleto idibo(
Ruga: Ọ̀pọ̀ àwọn ìpínlẹ̀ tó ń fẹ́ Ruga ló wá láti apá òkè ọya
Bi Ọdẹ bá ro ìṣẹ́ ro ìyà inú igbó, ti ó bá pa ẹran kòní fẹ́nì kan jẹ
”“Adari orile ede Naijiria wa ro awon adari ijoba agbaye lati tepele mo ilana ti won towobo nibi ipade to waye niluu London lọdun 2016 nipa  gbigbokun ti iwa ibajẹ.
”Jesu wí fún un pé, “Máa tọ́jú àwọn aguntan mi.
A ti setan lati tubo lo ajosepo to dan moran pelu Singapore ki awa mejeeji le jo je anfani fun ara wa ninu idagbasoke”.
Àwọn gbàgede ìtàkùrọ̀sọ ẹ̀rọ-alátagbà ìlú Serbia gbaná lẹ́yìn tí olórin àti òṣèré ìbílẹ̀ Nataša Tasić Knežević, tí ó jẹ́ ọmọ bíbí ilẹ̀ Roma fi ẹ̀sùn kan ilé ìtajà-ìgbàlóde kan tí ó wà ní ìgboro Novi Sad fún ìwà ìyàsọ́tọ̀ ẹ̀yà nínú ìgbóhùnsáfẹ́fẹ́ ojú-ẹsẹ̀ kan lórí Facebook.
fun won ni ile gbigbe,ounjẹ ati awon nnkan ajẹmọnu.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Money laundering: Inú ọ̀pọ̀ páálí oúnjẹ́ Nódù ní afurasí kan kó ọ̀pọ̀ ike ATM sí 14 Ògún 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 11 Owewe 2020 Oríṣun àwòrán, @EFCC Ọkunrin kan, Ishaq Abubakar, ni ọwọ ti ba pe o ko ike ti wọn fi n gba owo lẹnu ẹrọ, ATM to din diẹ ni ẹgbẹrun mẹta rin.
“Oun ni eni akoko to koko ki mi kaabo pada pelu iwe ataranse.
Nigba ti ileṣẹ iroyin BBC kan si ọdọ awọn ọlọpaa ni ipinlẹ Oyo lati fi idi ọrọ yii mulẹ, awọn agbofinro ni ọrọ ko ri bẹẹ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Àṣírí fàyàwọ́ ọmọnìyàn tú nílé ẹ̀kọ́ kan nípìlẹ́ Edo 21 Èbibi 2018 Oríṣun àwòrán, @solomon Àkọlé àwòrán, Okoduwa wá kìlọ̀ fáwọn ọmọ ilé ẹ̀kọ́ òhún láti kíyèsára kí wọn máà bọ́ sọ́wọ́ ìtànjẹ àwọn fàyàwọ̀ ọmọnìyàn Ó tí tó ọmọ ọgọ́rùn ún tí àwọn fàyàwọ̀ ọmọnìyàn ti kó lọ sí orílẹ̀-èdè Libya láti ilé ìwé kan ní ìlú Benin, ní ìpínlẹ̀ Edo, orílẹ̀-èdè Nàìjíárìà láti bíi oṣù mẹ́rin sẹ́yìn.
Ohun ti mo le sọ ni pe Messi lo dantọ julọ laarin gbogbo awọn agbabọọlu to wa lasiki tirẹ,'' Ronaldinho lo woye bayii."
Ó dáhùn pé, “Ó ṣe lè yé mi láìjẹ́ pé ẹnìkan bá ṣe àlàyé rẹ̀ fún mi?
Nítorí pé Ìfẹ́ OLUWA tí kì í yẹ̀ kò nípẹ̀kun,àánú rẹ̀ kò sì lópin;
Blood donation: Kíni àwọn èrò àti ìgbàgbọ́ tí kò tọ̀nà lórí ẹjẹ́?
Bakan naa ni gomina Abiodun tun fun Laycon ni ẹbun ile oni yara mẹta ati owo to to miliọnu marun naira gẹgẹ bii owo iwuri lati mọ riri rẹ.
Má jìnnà sí mi,nítorí pé ìyọnu wà nítòsí,kò sì sí ẹni tí yóo ràn mí lọ́wọ́.
Ariwo yóo sọ ní ọjọ́ ogun, omi òkun yóo ru sókè ní ọjọ́ ìjì; 
Ojo merindinlogun la o  fi se ifehonuhan naa,ojo yii  tun je ojo ti lati fi se ikilo fun awon to n hu iwa ibajẹ si awon obinrin, ki I se ijoba nikan.
Ṣugbọn wọ́n túbọ̀ múra kankan, wọ́n ń kígbe pé kí ó kàn án mọ́ agbelebu.
Agbẹnusọ ile iṣẹ Ọlọpaa ipinlẹ Kano, DSP Abdullahi Haruna sọ fun BBC pe, o to ọmọde mọkandinlogun tawọn tu silẹ nile awọn ọmọ alailobi Du Merci niluu Kano.
Ki gbogbo nkan to da bi o ṣe da yii, omi alafia ni wọn fi wẹ ilu Eko ti ipẹtu saawọ si maa n waye lai ni wahala, o ni alafia ọhun naa si ni yoo pada jọba ti awọn ọdọ to ṣe iṣẹ laabi naa yoo fi pada wa bẹbẹ.
Ó ní, “Mo ṣẹ̀ ní ti pé mo ṣe ikú pa aláìṣẹ̀.
Awọn ẹbi rẹ ni o sun ni ko ji mọ ni ile rẹ to wa ni Bahamas.
Bakan naa lo sọ fun BBC pe pe awọn ajinigbe ọun tun da awọn obinrin meji miiran silẹ yatọ si mọmọ Siasia.
Wọ́n máa ń há ìlẹ̀kùn yàrá Orímóògùnjẹ́ ṣùgbọ́n wọ́n máa ń fi kọ́kọ́rọ ibẹ̀ há orí ìtérígbà.
7 Nítorínáà, ẹ bẹ̀rù kí ẹ sì wárìrì, Áà ẹ̀yin ènìyàn, nítorí ohun tí èmi Olúwa ti pàṣẹ nínú wọn yíò wá sí ìmúṣẹ.
Ọmọwe Johnson Okolie, alakoso iṣẹ gbogbo ni ibudo iwadi ijinlẹ nipa awọn ajakalẹ arun nilẹ Afrika, African Center of Excellence for Genomics of Infectious Diseases, ACEGID ni fasiti Redemmers University, RUN ṣalaye fun BBC News pe ọpọlọpọ awọn ayẹwo kokoro arun naa ti wọn ṣe lagbegbe ipinlẹ Ọṣun lo fihan pe ẹya kokoro arun COVID-19 to n farahan julọ nibẹ atawọn agbegbe miran lorilẹede Naijiria fihan pe eyi to yatọ gedegbe si ẹya kokoro arun naa to gbilẹ kariaye ni.
Bakan naa la tun ri kanga ti wọn gbẹ lọdun 1842, eyi ti ẹru meje pere gbẹ, ti wọn n pe ni omi iye, taa mọ si water of life abi Miracle water.
Opọ n fẹsun kan ijọba orilẹ-ede wọn pe wọn ko pese awọn ohun eelo to peye lati koju ajakalẹ arun coronavirus to n gbẹbọ lọwọ gbogbo agbaye yii.
Lẹsẹkẹsẹ ni mo bá ranṣẹ sí ọ.
Igbese ti awon omo egbe alatako Democratic Alliance ko faramo, ni yoo je ki oke – aimoye awon osise orile ede naa maa gba egberun meta aabo rand owo orile ede naa losoosu($277)  , ekunwo yii ni won yoo bere si maa gba ni osu karunun odun yii,eyi je ona lati mu eto oro aje orile ede naa gbooro.
Wọn óo fọn fèrè ogun, wọn óo múra ogun, ṣugbọn ẹnikẹ́ni kò ní jáde lọ sójú ogun nítorí ibinu mi ti dé sórí gbogbo wọn.
Ipolongo imọtoto lori fifọ ọwọ́ nigba gbogbo ati idanilékọọ lori ṣiṣe ayẹwo Ebola n lọ ni DR Congo sii.
Oríṣun àwòrán, Twitter/PDP Àkọlé àwòrán, Ọrọ lori adajọ agba tẹlẹ Walter Onnoghen Bakan naa ni Atiku tun fẹsun kan Aarẹ Buhari ninu ẹjọ to fi sun pe o n gbe igbesẹ ti ko ba ijọba awa arawa mu.
Ètò ìṣèlú yóò dojú rú lọ́wọ́ irú àwọn aṣòfin bẹ́ẹ̀.
Meghan and Harry: Ohun tó yẹ kí o mọ̀ nípa ọmọ ọba tí wọ́n fẹ́ bí
Nítorí náà àwọn ọdọmọkunrin rẹ̀, yóo kú ní gbàgede rẹ̀.
Gege bi aare YSFON, Nasiru Gawuna se so, O ni yatosi gomina ipinle Kano, awon ti won yoo tun maa reti lati buyi kun asekagba idije naa, eyi ti won sagbekale re lati seranti oloogbe Gen.
 gbogbo àwọn nǹkan wọ ̀ nyí jẹ ́ ànfàní tó wà ní àwùjọ-ẹ ̀ dá tí kò sì ṣe é fi sílẹ ̀ láì mẹ ́ nu bà .
 n óò sọ ohun tí mo rí nibẹ ̀ fún ọ .
Èmí àti Ajimobi ni a ko jọ sin Naijiria ilẹ̀ bàbá wa ṣugbọn.
Agbẹnusọ NFF, Toyin Ibitoye lo sọ fun BBC Yoruba bẹẹ.
Erling Braut Haaland lo kọkọ rẹyin awọn ikọ Schalke ni iṣẹju kọkandinlọgbọn ti ifẹsẹwọnsẹ ọhun bẹrẹ.
Jẹfuta bá rékọjá lọ sọ́dọ̀ àwọn ará Amoni láti bá wọn jagun, OLUWA sì fún un ní ìṣẹ́gun.
O ni awọn fidio to wa kaakiri to ṣafihan bi awọn ọlọpaa ṣe n pa eeyan ju mẹwaa lọ, ṣugbọn Aarẹ sebi ẹni ti nnkankan ko ṣelẹ.
Igbe ẹkun yii ni Iyalufa gbọ ninu ile to wa, to si sare jade lati wa wo ohun to n sẹlẹ si ọmọ naa.
Awọn Mogaji ilẹ Ibadan ti wa sọ fun Gomina Fayemi pe ko maa ko aṣa atọhunrinwa de ilẹ Yoruba.
" O ni ko si ẹni to ṣe ileri ohunkohun fun awọn agbabọọlu saa rẹ ni ọdun 1980, ṣugbọn gbogbo wọn ni wọn ti gba ẹbun ile ti ijọba igba naa fun wọn.
Minisita gbadura si Eleduwa pe ko tu awọn ẹbi awọn agbabọọlu mejeeji ninu, o ni oun naa kẹdun awọn agbabọọlu mejeeji.
Bakan naa, ni lati tun pese opolopo omi fun awon ara ilu lati se itoju awon ohun osin ati ogbin won gbogbo.
Lẹ́hìn eléyìínì ni ọwọ́ bàbá mi bá á ni ọrùn ẹsẹ̀ méjéèjì tóbẹ́ẹ̀ tí ó fi gbé Èṣù-kékeré kọjá àtàrí, nígbà tí ó si jù síwájú pẹ̀lú ìbínú, nírètí àtifọ́ olóríburúkú yìí ni agbárí, ọ̀rọ̀ náà kò bọ́ sí i.
Amọ, bi o ti wu ki o ri, igbeyawo laarin ọmọ tẹgbọn taburo fun apẹẹrẹ maa n jẹ ki ibaṣepọ to dan mọran wa laarin ẹbi.
Ó sọ wá di ìjọba, ati alufaa Ọlọrun Baba rẹ̀.
 Òun nìkan ni obìnrin lààrin ọmọ mẹ ́ ta nínú ẹbí náà .
Nibayii, iroyin sọ pe wọn ti dari wọn lọ si ẹka awọn ọtẹlẹmuyẹ niluu Osogbo.
Oríṣun àwòrán, Mamman Daura Àkọlé àwòrán, Mamman Daura Ṣugbọn o ni fọnran naa kii ṣe ti ọdun yii rara ninu eyi to ti n fesi si awọn ẹbi Daura pe wọn ko jẹ ki oun wọ inu 'ile onidigi' (Glass house villa), Fatima si lo ya fidio naa.
Iwadii lori ikọlu awọn ọdun kọọkan: Lọdun 2015 ni wọn kọkọ bẹrẹ ikọlu ni Durban ati Johanesburg ni eyi tijọba ni lati fawọn ọmọ ogun ranṣẹ lo daabo bo awọn eniyan agbegbe yii.
Ó dájú pé kò rẹ̀ ọ́.
Ó wó ilé ìṣọ́ wọn lulẹ̀;ó sọ ìlú wọn di ahoro.
Sizaltina Cutaia, tí í ṣe ajìjàǹgbara àti ajàfẹ́tọ̀ọ́ obìnrin ní Angola; tí ó jẹ́ ìlúmọ̀ọ́ká fún iṣẹ́ẹ rẹ̀ lórí ẹ̀tọ́ obìnrin béèrè fún ìṣàmúlò òfin náà lórí àwọn gbàgede ìtàkùrọ̀sọ lórí ẹ̀rọ-alátagbà:
Aliko Dangote,ogbeni  Femi OtedolaAwon omo egbe ti yoo tun wa lara
Agbenuso fun Aare Bashir, “a ti gbaradi lati koju awon ipenija ti o le koju orile-ede naa”, amo won ko so ni pato ajosepo ile-ise ologun laarin orile-ede mejeeji naa.
Ṣugbọn bí angẹli Ọlọrun ni oluwa mi, ọba rí; nítorí náà, ṣe ohun tí ó bá tọ́ sí mi ní ojú rẹ.
 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Obasanjo sọ fún Buhari pé kó gbàgbé sáà kejì Ẹ ó rántí pé nínú lẹ́tà rẹ̀, Obasanjo tẹ́ pẹpẹ gbogbo àwọn ǹkan tí ó lérò pé ó ṣe kókó tí Buhari kò tíì yanjú rẹ̀."
to n ta  awon odaran naa  lolobo ati olori ileto
Ilé alájà-mẹ́ta náà “Jahaj Bari” ní àwọn iṣẹ́ ọnà tí ó yàrà ọ̀tọ̀ lára ní ara irin àgbọ́wọ́lé gun àkàsọ̀.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Odumakin: awọn alagbara lo wa lẹyin ijinigbe Dapchi Iku Yusuf ati àná rẹ: Lọdun 2009, awọn ọmọ ẹgbẹ Boko Haram yabo ileeṣẹ ọlọpaa ni ilu Borno ti wọn si bẹrẹ si ni i ṣe ikọlu pẹlu awọn agbofinro.
Àròpọ̀ iye àwọn ọmọ Israẹli, ní ìdílé-ìdílé, láti ẹni ogún ọdún sókè, àwọn tí wọ́n lè lọ sójú ogun, 
Nítorí náà, ẹ̀mí mi kọrin arò bíi ti dùùrù fún Moabu,ọkàn mi kérora, fún Moabu ati Kiri Heresi.
Àwọn ológun ti yọ Omar al-Bashir, olórí ìjọba Sudan nípò Iléẹjọ́ kòtẹ́milọ́rùn ti ní Ajimobi létọ̀ọ́ láti yan ọba l’Ọyọ Ọmọ atàpátadìde ni mí, télọ̀ ni bàbá mi- Abiola Ajimobi Bakan naa ni ilẹ Amẹrika fẹsun kan an wi pe o fi awọn iroyin ijọba ilẹ Amerika to wa ni idakọnkọ si ita.
Ajọ ilera agbaye, WHO ti gbe e sita ninu iwadii kan pe eeyan miliọnu mẹta lo n ku lọdun nitori ọti mimu.
Oríṣun àwòrán, Hushpuppi Instagram Bakan naa ni wọn tun gba awọn nkan yii lọwọ rẹ: Owo to le ni $40.
Ṣugbọn OLUWA wí pé, “Kí ni kí n ti ṣe ọ́ sí, ìwọ Efuraimu?
'Mi ò mọ̀ pé mo lóyún àfìgbà t'ọ́mọ ń rún'ra' Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 67 year old mother: Mo kojú ọ̀pọ̀lọpọ̀ àìsàn fún ọdún 35 lẹ̀yín ìgbéyàwò Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Olúwa rẹ̀ ó wá pàráàró títí yó fi sú u.
Nítorí bí a bá mọ̀ọ́nmọ̀ dẹ́ṣẹ̀ lẹ́yìn tí a ti ní ìmọ̀ òtítọ́, kò tún sí ẹbọ kan tí a lè rú fún ẹ̀ṣẹ̀ mọ́.
Oríṣun àwòrán, @NLCHQ_ABUJA Ninu ọrọ ti wọn, ẹgbẹ oṣiṣẹ ni awọn gbegi le iyanṣẹlodi naa fun ọṣẹ meji, lati fun ijọba apapọ laaye lati gbe igbesẹ to yẹ fun awọn oṣiṣẹ.
Aisan Iba lagbaaye, ni eyi ti won pe akori rẹ 
 a rí Ọ ̀ gbọ ́ ni ní iléṣà bẹ ́ ẹ ̀ náà ni ó wà ní Ìjẹ ̀ bú jẹ ̀ ṣà .
Ìdí abájọ ni pé, gbogbo àwọn èròjà náà, àti ètò bí wọ́n ṣe ń pò wọ́ pọ̀, nǹkan àṣírí ńlá ni.
Oríṣun àwòrán, Other Àkọlé àwòrán, Lẹyin to kẹkọọ gboye tan nilẹ Gẹẹsi gẹgẹ bi agbẹjọro, Akintola pada si Naijiria lọdun 1949.
Ojú ti àwọn alufaa ati àwọn ọmọ Lefi tí wọn kò tíì ya ara wọn sí mímọ́, tóbẹ́ẹ̀ tí wọ́n tètè lọ ya ara wọn sí mímọ́, tí wọ́n sì mú ẹbọ sísun wá sí ilé OLUWA.
 Ọ ̀ pọ ̀ lọpọ ̀ àwọn idoma ni wọ ́ n jẹ agbẹ .
Ọmọ ọdún mẹ́tàdínlógún ni Fólúkẹ́ - Ọmọ Àkàngbé Orímóògùnjẹ́ ni òun náà.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Bolaji Faleke ni Olùkọ́ tó ń kọ́ wa ní àṣà oge ṣiṣe lórí BBC Yorùbá Ki wa ni ijọba apapọ wa sọ lori ṣiṣi ileewe pada fun ẹkọ?
Ayé ń joró, ó sì ń ṣáàwọn ọ̀run ń joró pẹlu.
Ninu lẹta tuntun naa ni alaga igbimọ lọbalọba nipinlẹ Ekiti, tii tun se Alawẹ tilu Ilawẹ Ekiti, Ọba Adebanji Ajibade Alabi, Afuntade Kinni, ti fesi pada fun Alaafin.
Ojukwu  tun so pe awon tun gba ijoba nimoran ninu akọsile
" Daniel ni gbogbo ohun tawọn sisẹ fun laye awọn ni oun ati iya oun ti padanu bayii, wọn jo ile awọn nina, ti ẹgbọn oun si tun fi ẹmi rẹ di.
Ninu atẹjade kan to fi sita, Aisha sọ pe eto idibo naa kun fun fifi ẹtọ ẹni dun ni, pẹlu alaye pe ẹgbẹ yọ orukọ awọn oludije kan to ti ra fọọmu lati dije kuro l'ọjọ idibo.
Mo ti yan ibí yìí, mo sì ti yà á sí mímọ́, kí á lè máa jọ́sìn ní orúkọ mi níbẹ̀ títí lae.
‘Ẹ maa kọ ọmọ yin l'ede Yoruba’ Dino, Wada àti àwọn olùdíje 11 míràn n dù àsíá PDP fún gómìnà ìpínlẹ̀ Kogi Wike kìí ṣe dọ́là tí Ganduje leè kó sápò- Agbẹ́nuso ìjọba ìpínlẹ Rivers Ẹnilari Olabisi to jẹ aṣojuloge ni eto Ẹwatomi yii n ṣafiwe ẹni dudu ati ẹni pupa papọ pe ko si eyi ti ko rẹwa ninu awọn mejeeji.
O ṣiṣọ loju ọ̀rọ̀ naa nile ẹgbẹ APC nilu Eko lasiko ipade awọn ọmọ ẹgbẹ nibi to ti fi ara rẹ ṣe apẹrẹ pe ipilẹ rere ti oun fi silẹ gege bi gomina nipinlẹ Eko lo di òpó oṣelu mu bayii nipinlẹ Eko.
Mí ò bẹ̀bẹ̀ fún oyè igbákejì alága APC kí wọ́n tó ó fún mi - Abiola Ajimobi Gomina ipinlẹ Oyo tẹlẹ, Abiola Ajimobi ti sọ pe awọn alaṣẹ ẹgbẹ oṣelu All Progressives Congress, APC gbagbọ ninu oun ni wọn ṣe fi oun jẹ igbakẹji alaga ẹgbẹ naa.
“Ẹ yé é da ẹlòmíràn, ẹ jọ̀wọ́ a ò fẹ́ aláìṣòdodo aya mọ́.
Gomes bẹ̀rẹ̀ ìrìnàjò bọ́ọ̀lù gbígbá nígbà tó ti wà ni ọmọ ọdún mẹ́fà, wọ́n yan láti gbáradà ní ilé ẹ̀kọ́ ọmọ wẹ́wẹ́ Manchester United tí ó sì lo ọdún mọ́kanlá gbáko kí o tó lé darapọ̀ mọ ẹgbẹ́ agbábọ́ọ̀lù náà lọ́dun 2017.
Ẹ lọ wo ìlú Kane; ẹ ti ibẹ̀ lọ sí Hamati, ìlú ńlá nì, lẹ́yìn náà ẹ lọ sí ìlú Gati, ní ilẹ̀ àwọn ará Filistia.
 o wa ni apaguusu ebado absheron peninsula , baku pin si apa meji : isale ilu ati arin ilu atijo ( 21.
Ẹṣọ oju-popo ti a ba ri ju 500 naira lọwọ re wọ gau
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ẹ sá àwọn akẹ́kọ̀ọ́ sínú òòrùn fún ọgbọ̀n ìṣẹ́jú lójojúmọ́ - Ìjọba Oyo pàṣẹ Òṣìṣẹ́ LASTMA gún olólùfẹ́ rẹ̀ l'ọ́bẹ, ó tún gba ẹ̀mí ara rẹ̀ l'Eko Ikọ̀ ìjọba Ọ̀yọ́ dé lásìkò tí kò yẹ ni wọn kò ṣe wọlé - Ẹ̀bí Ajimobi fèsì Ọ̀pọ̀ èèyàn tí kò yin Ajimobi lojú ayé, tó ń yìn-ín lẹ́yìn ikú, yóò jẹ ìyà - Oníwáàsí Ọ̀pọ̀ ìgbà ní Hushpuppi àtàwọn èèkàn PDP ti ya fọ́tò ní Dubai, EFCC ẹ wádìí wọn - APC ń lọgun Àwòrán rèé nípa àwọn gbajúmọ̀ tó ti bá Hushpuppi ṣe Mo ti bá ọmọ ọwọ́ mẹ́ta lòpọ̀ sẹ́yìn, ọmọ oṣù mẹ́ta ló ṣìkẹrin - Afurasí jẹ́wọ́ O ti le ni ọdun mẹwa ti wọn ti n lo ọkọ ofurufu naa lati gbe awọn ohun eelo iranwọ lọ sọdọ awọn araalu to wa lagbegbe naa, ti laasigbo to n waye nibẹ n ba finra.
O wa fidi rẹ mulẹ pe ọjọ Kọkandinlogun osu Kẹsan ọdun 2020 yii ni wọn ṣe orin náà si ẹ̀yà Igbo àti Hausa fún ànfàni àwọn ti kò gbọ́ Yorùbá.
Ó wọ ihò lọ pa kinniun kan ní ọjọ́ kan tí yìnyín bo ilẹ̀.
 Wo ojú Akeem t'Ọlọ́pàá mú pé ó fipá bá ọ̀dọ́mọbìnrin kan sùn létí odò l'Oṣun Ìdí tí mo fi ń ṣe ayẹyẹ ọjọ́ ìbí 35 lọ́dọọdún rèé- Allwell Ademola Ìjọba Ghana ṣí iléeṣẹ́ àwọn ọmọ Nàìjíríà padà."
À bá wo Babiloni sàn, ṣugbọn a kò rí i wòsàn.
Bi itan ọrẹ laarin ọmọ ọdun meje, Daniel ati gomina ipinlẹ Ekiti ṣe bẹrẹ rèé.
Igbagbọ awọn eniyan Naijiria ni pe ki Aarẹ Buhari sọrọ yanju pẹlu Aarẹ ilẹ South Africa lori bi awọn to ku a ṣe maa gbe ni alaafia.
Ninu ọrọ rẹ pẹlu awọn oniroyin lẹhin ipade bonkẹlẹ ti wọn ṣe, Fayemi ni ipade naa ko ni ohunkohun ṣe pẹlu ọrọ oṣelu, bikoṣe abẹwo lasan.
Bi ẹ ko ba gba gbagbe, Ko din ni maluu mẹtadinlogun ti ara san pa ni ileto kan ti wọn n pe ni Iba ni ijọba ibilẹ Ifẹlodun ni ipinlẹ Ọṣun.
Kó èso àwọn igi eléso ilé ayé jọ, nítorí pé wọ́n ti pọ́n.
Kí inú lè bí mi, kí n lè gbẹ̀san.
Ìbéèrè yìí ló mú ki BBC ṣe ìwádìí ìgbéṣẹ̀ tí ìjọba fẹ́ gbé tí a si pé olubadamọràn pàtàkì fún ààrẹ Buhari lóri ìfìtónilétí Garba Shehu.
Iwájú kinni jẹ́ iwájú Kerubu, ekeji jẹ́ iwájú eniyan, ẹkẹta jẹ́ iwájú kinniun, ẹkẹrin sì jẹ́ iwájú ẹyẹ idì.
”Ó dáhùn pé, “Alàgbà, mo fẹ́ tún ríran ni!
Ẹ yìnbọn pa ọ̀daràn tí ẹ bá rí níbi kíbi, Buhari pàṣẹ fáwọn ológun Wo ọ̀nà tí orin gbígbọ́ fi ń ṣèrànwọ́ f'ọpọlọ ọmọ ìkókó Ọ̀pọ̀ èèyàn bẹnu ẹ̀tẹ́ lu Mercy Aigbe lórí bó ṣe ki Adeniyi Johnson Ike Ekweremadu, igbákejì ààrẹ ilé aṣòfin àgbà tẹ́lẹ́ rí èèmọ̀ he nilùú Germany!
ni ona kan tabi ikeji eto ipese ounje yii tun pese ise fun ogunlogo awon omo
Oko ofurufu Air Peace lo n ko wọn bọ pada sile.
" Ìlú Ondo ló ń gba owó ìná jùlọ ju àwọn ìlú míràn lọ Gomina Rotimi Akeredolu ti sísọ loju rẹ pe owo ti ijọba oun n na silu Ondo kọja iye ti wọn n na silu miran nipinlẹ naa lọ.
Gbogbo àwọn ọmọ Israẹli kúrò ní Kadeṣi, wọ́n wá sí òkè Hori 
” Lẹsẹkẹsẹ ni àrùn ẹ̀tẹ̀ náà bá kúrò lára rẹ̀.
Mo fẹ́ kí ẹ mọ̀ dájúdájú pé, ninu àwọn tí obinrin bí, kò ì tíì sí ẹnìkan tí ó ju Johanu Onítẹ̀bọmi lọ.
Lara awọn olugbe ilu naa ti o ba ikọ BBC Yoruba sọrọ ṣe alaye wi pe ṣa dede ni atẹgun ojo ka ile mọ awọn lori lọjọ Abamẹta, ti ọrọ naa si di boolọ-o-yago fun mi.
fọ́n owó ká fáwọn èrò lẹ́yìn tó pariwo 'Merry Christmas' Bàbá ẹni ọdún 70 san owó iná àwọn aládùúgbò rẹ 36 gẹ́gẹ́ bi ẹ̀bùn Kérésì Ẹ má gbàbọ̀de kankan láti tú Wolii ìjọ Sotitobire sílẹ̀ o!
Ọlọrun jẹ́ kí Daniẹli bá ojurere ati àánú olórí àwọn ìwẹ̀fà náà pàdé.
 “Mo dupe pupo lowo awon akegbe mi, awon olukoni ati awon ololufe mi gbogbo ti a jo sise po lati mu afojusun yii wa si imuse!
Owo ori sisan ko ṣe ajeji sawọn eniyan Naijiria ṣugbọn wọn kii san an lori ọja ayelujara tẹlẹ.
To fi mọ iranwọ lẹka ilera ati ọna titunṣe ni Jegede tẹnumọ to si ni bi wọn ba fun oun laye, wọn o ni ri alebu ninu iṣẹ oun gẹgẹ bii gomina.
Ẹnikẹ́ni tí ó bá fún ọ̀kan ninu àwọn ọmọ-ẹ̀yìn mi yìí tí ó kéré jùlọ ní ife omi tútù mu, nítorí pé ó jẹ́ ọmọ-ẹ̀yìn mi, mo fẹ́ kí ẹ mọ̀ dájúdájú pé kò ní pàdánù èrè rẹ̀.
Àwọn tó jí ọmọ mi gbé nílé ìjọsìn ní ń kò gbọdọ̀ wa tàbí kí ẹ̀mí mi lọ si"" Idije laarin ẹgbẹ agbabọọlu Etuhu ati Sweden ninu idije oni ipele akọkọ ẹgbẹ si ẹgbẹ lọdun 2017."
Favour Onyeoziri sọ pe iku to n pa ojugba ẹni, owe lo n pa fun ni, o ṣalaye pe tawọn ologun ba n yinbọn pa ọlọpaa, a jẹ wi pe kawọn oloṣelu ti wọn maa n lo ọlọpaa ati awọn ologun gẹgẹ ẹṣọ kiyesara.
5 Nítorí-èyí, èmi kò pa àwọn ìdájọ́ èyítí èmi yíó ṣe rẹ́, ṣùgbọ́n àwọn ègbé yíò wá síwájú, ẹkún, ìpohùnréré ẹkún, àti ìpahínkeke, bẹ́ẹ̀ni, sí àwọn tí wọ́n bá wà ní ọwọ́ òsì mi.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Ki lo wa maa ṣẹlẹ lori Brexit?
Laipẹ yi ni ẹgbẹ naa se abẹwo si Ààrẹ àná lórílẹ̀-èdè Nàìjíríà Oluṣegun Obasanjọ lati fọrọ jomitooro ọrọ lori odo ti awọn Yoruba yoo dọra si.
Èéfín bo gbogbo òkè Sinai mọ́lẹ̀, nítorí pé ninu iná ni OLUWA ti sọ̀kalẹ̀ sórí rẹ̀, ọ̀wọ̀n èéfín rẹ̀ sì gòkè lọ bí ọ̀wọ̀n èéfín iná ìléru ńlá, gbogbo òkè náà sì mì tìtì.
A kò yìnbọn lù olùwọ́de Lekki, omi tútù àti ọtí ẹlẹ́rìndòdò la fi pẹ̀tù sí wọ́n - Iléeṣẹ́ ológun Orisirisi lo n jẹyọ nibi iwadii igbimọ to n gbẹjọ ifiyajẹni ati iwa aitọ lati ọdọ ọlọpaa si ara ilu nipinlẹ Eko.
N óo kó àwọn eṣú láti ìhà àríwá jìnnà kúrò lọ́dọ̀ yín,n óo lé wọn lọ sinu aṣálẹ̀ níbi tí kò sí nǹkankan.
Lati igba naa ọpọ ẹlẹyinju aanu ọmọ Naijiria ti n ṣeleri lati fun mama ni ẹbun kan tabi omiiran.
 Sẹnatọ Andy Ubah Fun ẹni to lo ọdun mẹwa lọgba ẹwsn, to wa buse gede, tẹẹ ni irọ ni wọn pa mọọ lẹyin ọdun mẹwa, arọwa wo tabi ẹbun gba maa binu wo lẹ lee se fun.
Nathaniel Mendez- Laing ọmọ agbabọ́ọ̀lù Cadiff ló jẹ àmìn ayò méèjèjìí bótilẹ̀ jẹ pé Cadiff ń ṣe ó digbà ó ṣe fún ìdíje Premier League sùgbọ́n wọn ṣe àmi sílẹ̀ kí wọ́n to lọ, bi wọn se fẹnu Manchester United gbòlẹ̀.
 A ni awon alakitiyan eniyan ati ọrọ lorile ede yii .
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Sola Kosoko: ọlá bàbá mi ni mò n jẹ́ nínú iṣẹ́ tíátà Èrò àwọn ọmọ Nàìjíríà ṣọ̀tọ̀ọ̀tọ̀ lórí ọ̀rọ̀ Faṣọla àti iná Ọba Mo lọ ilé ìwòsàn Gbagada láti ṣe ìrànwọ́ ni- Sanwo-Olu Lọjọ kẹtadinlogun oṣu kẹsan an ọdun 2018 yii ni o bi ọmọ naa silu Atlanta lorilẹede Amẹrika nigba ti o ku ọjọ meji ti oun gan an yoo pe ọmọ ọdun mejidinlogoji.
Èyí wáyé lẹ́yìn tí àjọ tọ gbógun ti àjàkálẹ̀ ààrùn lórílẹ̀-èdè Nàìjíríà (NCDC) fìdí rẹ̀ múlẹ̀ pé ènìyàn méjì tó ni ààrùn coronavirus jẹyọ níjọba ìbílẹ̀ náà, àwọn méjì náà ni Imaamu àgbà ibẹ̀ àti ọmọ rẹ̀.
Ìjọba ìpińlẹ̀ Eko - BBC News Yorùbá BBC News, YorùbáFò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù EndSARS School Resumption: Àwọn akẹ́kọ̀ọ́ lè padà sílé ìwé láti ọjọ́ Ajé - Ìjọba ìpińlẹ̀ Eko 14 Ọ̀wàrà 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 29 Ọ̀wàrà 2020 Oríṣun àwòrán, Lagos state Govt/twitter Ìjọba ìpínlẹ̀ Eko ti kéde pé àwọn àkẹ́kọ̀ọ́ nílé ẹ̀ka ìjọba àti àládàni lé wọle pada sẹ́nu ékọ́ wọ́n láti ọja Aje, ọjọ́ keji, Osu kọkanla, ọdún 2020.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Oyenusi ló mú mi wọ ẹgbẹ́ adigunjalè kó tó di pé mo b'Ólúwa pàdé' Ni Oṣu Kẹjọ, ọdun 2020 ni ileẹjọ ologun da awọn meji silẹ ninu awọn meje naa wi pe wọn ko jẹbi ẹsun ti wọn fi kan wọn.
Ṣugbọn ó sá dákẹ́ ni, kò fèsì kankan.
ẹ̀ báà bú mi di ọ̀la - Ọ̀gá Amotekun l'Osun Kí ló dé t'awọn Gómìnà Nàìjíríà fẹ̀ yá N17trillion nínú owó ìfẹ̀yìntì òṣìṣẹ́?
Gbogbo àwọn ọmọ Israẹli bá pada lẹ́yìn Dafidi, wọ́n tẹ̀lé Ṣeba.
Amọ o sọ pe ko le ṣeeṣe mọ foun bayii lẹyin ti ijọba ti fofin de irinajo si awọn orilẹede mejeeji.
Bi ko ba ṣe bẹẹ, o ni oun yoo gbe lọ ile ẹjọ.
Koda, aarẹ Donald Trump tilẹ Amẹrika fi fidio naa soju oò Twitter rẹ.
Jẹ́ olùṣọ́-aguntan wọn,kí o sì máa tọ́jú wọn títí lae.
Ọmọ ilu Ila ni ipinlẹ Osun ni Abdulraheem to ni oun ti wa ninu iṣẹ yii lati ọdun 1977.
OLUWA bèèrè pé, ‘Ta ni yóo lọ tan Ahabu, ọba Israẹli, kí ó lè lọ sí Ramoti Gileadi, kí ó sì kú níbẹ̀.
BBC ko ribi fidi otitọ fọnran fidio yii mulẹ ṣugbọn iroyin to tẹwa lọwọ lọdọ awọn to wa ni Ogbomosho ni ikọlu waye laarin awọn oluwọde ati ọlọpaa.
''Lati le jẹ ki wọn mọ pe a ko mu ọrọ naa bi awada lo jẹ ki a gbe igbeṣẹ yii, lootọ la dana sun awọn ẹrọ alagbeka ti a gba lọwọ wọn'' Ìdíje bọ́ọ̀lù fa ìtàjẹ̀ sílẹ̀ ní Poly Ibadan Poly ìgbájọ lé gíwá rẹ̀ lórí ẹ̀sùn ayédèrú ìwé ẹ̀rí Wo bí o ṣe lè kọ́ ọmọ rẹ lẹ́kọ̀ọ́ ìbálòpọ̀ Iwa makaruru lasiko idanwo jẹ ipenija to n ba ẹka eto ẹkọ lorileede Naijiria jẹ ti awọn adari eto ẹkọ a si maa wa orisirisi ọna lati dẹkun rẹ.
Ní ọjọ́ keji, ọpọlọpọ eniyan tí ó wá ṣe àjọ̀dún gbọ́ pé Jesu ń bọ̀ wá sí Jerusalẹmu.
Nǹkan tí a kọ́ ṣe àkíyèsí ni ọ̀wọ̀n ńlá kan tí ó bá ojú ọ̀run lọ, tí o ddúró ní ẹnu ọ̀nà igbo náà.
A fẹ rii daju wipe ipejọpọ naa n waye ni ọdọọdun, ki a le fi aye gba awọn eto l'oriṣiriṣi ti yoo sọ Igbo-Ọra di ibudo igbafẹ fun awọn arinrinajo lati ilẹ okeere.
awon olugbe ati awon omo orile-ede Naijiria lati ron awon omo ogun lowo nipase
Bi a bá ṣe akiyesi eré ije “Fi fa Okun” a o ri pé àwọn kan wà ni iwájú, bẹni àwọn kan wà lẹhin.
Nítorí alààyè mọ̀ pé òun óo kú, ṣugbọn òkú kò mọ nǹkankan mọ́, bẹ́ẹ̀ ni wọn kò ní èrè kan mọ́, a kò sì ní ranti wọn mọ́.
Ọga awọn ọmọ ogun ofurufu, Ọgagun Sadik Abubakar, Minisita fun ọrọ awọn obinrin ati idagbasoke awujọ, Dame Paulline Tallen ati ologun obinrin kan, Grace Garba lo mura ẹyẹ fun un lọjọ naa.
Ati ti o ba to o tẹwa lọrun pe ileeṣẹ Apples and Pearsyoo ma ṣe iṣẹ rẹ lọna to ba ofin mu.
Alufaa tí wọ́n bá ta òróró sí lórí, tí wọ́n sì yà sí mímọ́ gẹ́gẹ́ bí alufaa àgbà ní ipò baba rẹ̀ ni kí ó máa ṣe ètùtù, kí ó sì máa wọ aṣọ mímọ́ náà.
Ó bá pàṣẹ pé kí wọ́n mú wọn láàyè, wọ́n ìbáà máa bọ̀ wá jagun, wọn ìbáà sì máa bọ̀ wá sọ̀rọ̀ alaafia.
''Mo ti ṣe àbẹwò sí àwọn oko kan láwọn ìletò kaaakiri ile kaarọ ojiire ti ohun ti a sì rí ní bẹ kọnilominu nitori ijamba ti kòkòrò ajokorun n ṣe.
Wọn yan Akinbade gẹgẹ bii akọwe ijọba Ipinlẹ Ọṣun nigba iṣakosi Olagunsoye Oyinlọla ni ọdun 2003.
Ohun yii gan ni o fa orukọ 'tunfulu' ti wọn n pe e ninu awọn sinimọ ti o ti kopa.
Nítorí OLUWA Ọlọrun àwọn ọmọ ogun ní ń rúbọ,ní ìhà àríwá, lẹ́bàá odò Yufurate.
 sufuru onielimenti je kritali alaralile pipon yanyan ni igbonasi inuyara .
Nítorí pé egbò Samaria kò lè ṣe é wò jinná; egbò náà sì ti ran Juda, ó ti dé ẹnubodè àwọn eniyan mi, àní, Jerusalẹmu.
 Oludari agba ajo NOA, dokita Garba Abari lo soro ohun di mimo lasiko eto idanileko nipa ilana ise ti o waye ni gbongon ajo ohun niluu Abuja.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Ayekofẹnifọrọ: Ó yá, ẹ fi àmì sórí ọ̀rọ̀ náà.
Àwa ọba alayé ń wọ́nà láti ṣẹ́ eegun ẹ̀yin ọ̀daràn Fulani - Ọọ̀ni O ni koko ti oun gba mu ni pe awọn eniyan iran Yoruba kan ti gbabọde ti wọn si n ṣiṣẹ papọ pẹlu àwọn Fulani agbebọn yii.
Usi yìí jẹ́ ọmọ Bani, ọmọ Haṣabaya, ọmọ Matanaya, ọmọ Mika, lára àwọn ọmọ Asafu tí wọ́n jẹ́ akọrin.
 bórọ ̀ nù wọ ́ jọ ní ayé pẹ ̀ lu ìtúsómi àwọn àdàpọ ̀ rẹ ̀ tí wọ ́ n wọ ́ pọ ̀ , èyun ùn àwọn àlùmọ ́ nì bóràtì .
Court of Appeal: Ilé ẹjọ́ ní òfin kò mọ Omo-Agege, Waive gẹ́gẹ́ bíi olùdíje APC ní ìpínlẹ̀ Delta
lọkan, o tun gbe apoti ibo lati ṣoju ẹkun idibo kan naa lọdun 2011 ṣugbọn nibi
OLUWA, Ọlọrun wa,àwọn oluwa mìíràn ti jọba lórí waṣugbọn orúkọ rẹ nìkan ni àwa mọ̀.
Àwọn ìròyìn mìíràn tí ẹ lè nífẹ̀ẹ́ sí: Ọlọpa mu asaaju ẹgbẹ NURTW Ajínigbépawó jí akọ̀wé NURTW gbé l'Óǹdó Àṣà ìbálé lálẹ́ ìgbeyàwó ń dọdẹ àwọn obìnrin òde òní Àfi ìgbà tí mo bọ́ sọ́wọ́ ọ̀tá mí nínú ìrìnàjò ìfẹ́- Roshan Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, afin pupa Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Ikọ to ba lagbara julọ ni yoo fa ekeji subu kuro ni ila ti wọn fa silẹ, eleyii ti yoo mu wọn bori ninu idije naa.
 Ọrọ ti mo sọ jẹ iroyin to wa ni ikawọ mi ni asiko naa.
"Bó tilẹ̀ jẹ́ pé eroja ""T Cell,"" kò jẹ́ ǹkan tuntun ninu ìmọ̀ sayẹnsì, amọ ó jọ pé, inú rẹ̀ ni ojútùú si ìsòrò àrun coronvairus wa."
Ìdíje bọ́ọ̀lù fa ìtàjẹ̀ sílẹ̀ ní Poly Ibadan Oyè Mọ́gàjí àti Báálẹ̀ ti di owó rèé, ọjà rèé ní Ibadan - Lekan Balogun Zamfarakillings: Kò gbọdọ̀ sí ìwakùsà ní Zamfara Ọkọ̀ ojú omi ''fẹri'' kọlu afárá, ọkọ̀ méjì já sódò Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí kan sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
Ko si ẹni to wọ jẹsi rẹ nọmba 10 lati igba naa Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ipenija lilo oogun oloro jẹ iṣoro kan to ba Maradona finra to si mu ki o maa tobi Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Maradona ati Messi lasiko to n ṣe akọnimọọgba Argentina Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Mraadona di aṣọ ti wọn ya aworan rẹ si lasiko ti Argentina n koju Naijiria Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Awọn to ku diẹ kaa to fun ni aayo mi ni ọrọ Oba Abolarin.
Èmi alára kò mọ̀ ọ́n, ṣugbọn kí á lè fi í han Israẹli ni mo ṣe wá, tí mò ń fi omi ṣe ìwẹ̀mọ́.
Kò sí ẹni tí ó bèèrè wọn, bẹ́ẹ̀ ni kò sí ẹni tí ó wá wọn.
Ìwọ ni o gbé ògo rẹ kalẹ̀ lókè ọ̀run.
ninu atẹjade ti Alukoro Agba rẹ, Ọgbẹni Musbau Razak fọwọ si.
Lẹnu ọjọ mẹta yii ni iroyin tan kalẹ pe olori ni aafin Ile Ife, Naomi Silekunola Ogunwusi ti bimọ ọkunrin lanti-lanti fun Kabiyesi Ọọ́ni Adeyeye Ogunwusi.
Ọdún 38 ni ìyá mí fi ṣiṣẹ́ ní UCH, màá kọ́ ibùdó ìtọ́jú àrùn jẹjẹrẹ ní ìrántí rẹ - Ọọ̀ni Okunrin kan kú lójijì lẹ̀yin ọjọ̀ díẹ̀ to jẹ milionu kan dọ́là Wo dókítà ọmọ Nàìjíríà tí àgbáyé ń wárí fún nítorí abẹ́rẹ́ àjẹsára COVID-19 Ọjọgbọn Chukwuneke sọ pe iṣẹ imọ erọ ayarabiaṣa ni Chisom fẹ ṣe to ba dagba, amọ o yi ero rẹ pada lati ṣe iṣẹ imọ iṣegun oyinbo, nitori bi eto ilera ṣe ri ni Naijiria, ati ilera ara rẹ.
Nítorí náà a kà wọ́n kún aláìmọ́, a sì yọ wọ́n kúrò ninu iṣẹ́ alufaa.
Jehoiakimu bí ọmọ meji: Jekonaya ati Sedekaya.
20 Kíyèsíi, ìwọ ni Oliver, mo sì ti bá ọ sọ̀rọ̀ nítorí àwọn ìfẹ́ ọkàn rẹ; nítorínáà fi àwọn ọ̀rọ̀ wọ̀nyí pamọ́ sínú ọkàn rẹ.
Ó ga ju gbogbo àwọn ọlọ́lá ati aláṣẹ ati àwọn alágbára ati àwọn olóye tí wọ́n wà lójú ọ̀run lọ.
Òjò àrọ̀ọ̀rọ̀dá dá wàhálà sílẹ̀ l'Eko Gómìnà márùn ún tó fojú winá ìbínú bàbá ìsàlẹ̀ wọ̀n A kò tíì fi ìdí ẹ̀ múlẹ̀ pé ògùn Dexamethsaone ń ṣiṣẹ́ fún àrùn coronavirus- WHO Ileẹjọ giga l'Abuja ni ohun ti ṣe afikun igba ti Ọgbẹ Giadom yoo nipo adele alaga gbogbogbo APC pẹlu ọsẹ meji.
Bakan naa ni South Africa ti fofin de ipejọpọ eniyan to ba le ni ọgọrun, wọn si tun fẹ ti ilẹkun awọn ileewe.
Ọlọrun ayérayé ni ààbò yín,ọwọ́ rẹ̀ ni ó sì fi ń gbé yín ró.
"Àdúrà ni mo nílò kìí ṣowó - Pa Kasumu Nàìjíríà ṣe bẹ́ẹ̀ padà s'áyé ìjọba ológun t'ọ́pọ̀ wà látìmọ́lé láì sí ìgbẹ́jọ́ - Olubunmi-Okogie 'Penis Fish"", ẹ̀ja tuntun tó rí bí ǹkan ọmọkùnrin lùwẹ̀ jáde lórí òkun Bóo bá yin báńgà l'Ondo lásìkò ọdún, kélé yóò gbé ọ!"
Ṣugbọn Dafidi jagun gba Sioni, ìlú olódi wọn.
Kókó ọ̀rọ̀ tí àwọn olùdíje kọ̀kọ̀ọ̀kan músọ Adekunle Akinlade Àkọlé àwòrán, #BBCOGUNDEBATE: Èrò àwọn oludije ṣe ọtọ̀ọ̀tọ lóri ètò ẹkọ Ofẹ Lori Ile Ekọ TASUED: Ká kó àwọn ọmọ si ile iwe kọ ni pataki bíko ṣe kí ijọba gbéra sọ láti ṣee daradara, irinṣẹ igbalode ni yoo wa nibvẹ ki àwọn ọmọ ti yóò dangajia Ẹto ẹkọ ọfẹ ṣe pataki ní ile ẹkọ alakọbẹre sugbọn ko lowo ninu lókè.
Gbegede gbina alare jagba, iko agbaboolu Barca di eru iya ru Liverpool pada sorile-ede England, ope pataki lowo ami ayo ti atamatase iko Barca Luis Suarez ati Lionel Messi gba wole, eleyi ti o seranwo fun iko Barcelona lati gbegba oroke ninu ifigagbaga naa,Ifesewonse ipele kinni ohun waye ni papa isere Barca, Camp Nou ti ipele keji yoo si waye ni papa isere Anfield lorile-ede England.
A ko ti le sọ ni pato ẹya ara to da wahala tuntun yi silẹ fun botilẹ jẹ pe awọn kan ni kokosẹ rẹ ni.
Mo fẹ́ sáré lọ rí eniyan Ọlọ́run, n óo pada dé kíákíá.
Nígbà tí o bá kígbe,kí àwọn ère tí o kó jọ gbà ọ́.
Ninu ifọrọwerọ pẹlu iwe iroyin abẹle kan lorilẹede Naijiria, ipinlẹ Ogun ati Ekiti ti ni awọn ko kanju lati da akẹkọọ pada si ileewe bayii.
Rúfin kóo san N1M táa bá ṣí òtẹ́ẹ́lì, ilé sinimá, gbọ̀ngàn ayẹyẹ padà - Ijọba Eko Àwa la mọ báa ṣe mú Sunday Shodipe táa fà a lé ọlọ́pàá lọ́wọ́ - Ọlọ́dẹ Soludero 'Bí a kò bá fẹ́ ìbínú Ọlọ́run, a gbọ́dọ̀ jẹ́ kí Tinubu du ipò ààrẹ̀ lábẹ́ àsìá ẹgbẹ́ APC ní 2023' Kọmísọ́nà ètò ìlera ìpińlẹ̀ Eko ọjọ̀gbọ́n Akin Abayomi ti lùgbàdì ààrùn Covid-19 Fidio bi awọn ọlọpaa ṣe yinbọn lu ọkunrin ọhun ti gba ori ayelujara kan, nibi ti ọkunrin naa ti n rin lọ ṣeba ọkọ kan, to si kọyin si awọn ọlọpaa naa ki wọn to yin in nibọn.
2 184 Orilẹede Brunei 3 0.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ibadan Murder: Oyún oṣù méje ló ń bẹ nínú Azeezat, kí wọ́n tó f'òkúta fọ́ ọ lórí Eyi ni iku kẹrin laarin oṣu kan sira wọn lagbegbe yii kan naa.
Baba rẹ, Adebisi Adu jẹ Olukọ ati ọmọ bibi ilẹ Ekiti, ti iya rẹ, Anne Hayes si jẹ oyinbo alawọ funfun, to n ṣíṣẹ Nọọsi.
Gbogbo àwọn odò Juda yóo kún fún omi.
ṣugbọn ẹnikẹ́ni tí ó bá jẹ lára ẹran tí a fi rú ẹbọ alaafia sí OLUWA, ní àkókò tí òun fúnra rẹ̀ jẹ́ aláìmọ́, a óo yọ ọ́ kúrò lára àwọn eniyan Ọlọrun.
Bi ọjọ ṣe n sun mọ'le fun idibo abẹle fun awọn oludije fun ipo gomina Ipinlẹ Eko labẹ ẹgbẹ oṣelu APC, ibeere ni awọn ara ilu n beere nipa awọn ti Gomina Akinwunmi Ambode yoo koju ninu idibo naa.
" a kì í pè é ní ọba ní àsìkò yẹn bí kò ṣe "" Ọmọlójù ' ."
Ṣé ọtí leè dènà àrùn Coronavirus bi?
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìtàn Mánigbàgbé: Diipọ Fagunwa ní a le è pe bàbá òun ní ‘osó’ ìtàn àkọsílẹ̀ 12 Ọ̀pẹ̀̀ 2019 Oríṣun àwòrán, D.
Amọ awọn mii kan ṣaa fẹ ra a lọle gẹgẹ bii t'Eko bọ fun ara wọn tabi ẹlomii.
Ọrẹ sísun ati ẹbọ wọn, yóo jẹ́ ìtẹ́wọ́gbà lórí pẹpẹ mi;nítorí ilé adura fún gbogbo eniyan, ni a óo máa pe ilé mi.
02 bn Ileeṣẹ ijọba to n risi ọrọ ọlọpaa - N441.
" wọ ́ n maa ń pe ransome-kuti ní ògbóntà obìrin ajàfẹ ́ tọ ́ ọmọ ènìyàn látàrí ipa tí ó kó nínu ìjàfẹ ́ tọ ́ ọmọ ènìyàn , tí wọ ́ n sì tún maa ń pèé ní "" Ìyá ilẹ ̀ aláwọ ̀ dúdú "" ."
Buhari: Màá sisẹ́ fún ààbò àti àgbéga ẹkùn wa
Ṣugbọn ó ṣẹ́ àwọn díẹ̀ kù sílẹ̀ ninu àwọn talaka pé kí wọn máa ṣe ìtọ́jú ọgbà àjàrà kí wọn sì máa dá oko.
fa sẹyin ninu ojuse rẹ ninu awujọ, o wa fi asiko ohun seleri pe oun yoo te
Oríṣun àwòrán, @olafare Àkọlé àwòrán, Emi gana an ti setan lati fowosopo pelu gbogbo ori ade ki a tun ogo ile Yoruba se Fasiti Ọbafẹmi Awolowo University pariwo síta pé àwọn èèyàn ilé ifẹ̀ kan da májèlé sómi iléèwé Ọọnirisa pa àwọn aṣàtìpó lẹ́rin ayọ̀ ni Ibùdó Wasa Ani sẹ, Ọọni ran alaabo rẹ simi - Oluwo O fẹ́ yọ wọ́ ààyè ibùsùn àwọn obìnrin lọwọ́ ọlọ́pàá ba tẹ!
O wa fi kun ọrọ rẹ pe o ṣeeṣe lẹyin ti ọrọ naa ba de iwaju adajọ ko jẹ Eko ni wọn yoo ti gbẹjọ naa ṣugbọn ọrọ ku si ọwọ adajọ.
Chelsea run Norwich mọ́ lẹ̀ jégéjégé Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Níwọ̀n ìgbà tí a ní àwọn tí wọn ń jẹ́rìí sí agbára igbagbọ, tí wọ́n yí wa ká bí awọsanma báyìí, ẹ jẹ́ kí á pa gbogbo ohun ìdíwọ́ tì sápá kan, ati àwọn ẹ̀ṣẹ̀ tí ó rọrùn láti jẹ́ kí wọ́n dì mọ́ wa.
Ni Naijiria, awọn ọmọde maa n wọ awọn fila ọdun, jingi oju, atawọn nkan iṣere miran lasiko yii.
Ṣugbọn kaka ki Oshiomole ko awọn adari ẹgbẹ oṣelu naa sodi lati tete pa ina rẹ ki eefin rẹ to ru sita, idakeji rẹ lo waye.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Bùhárí: Gaddafi ló kọ́ darandaran ní ìwà ipá 12 Ìgbé 2018 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Gulegule awọn darandaran ti da oniruuru ipaya silẹ kaakiri orilẹede Naijiria Ààrẹ orílẹ̀èdè Nàìjíríà, Muhammadu Buhari ti dẹ̀bi itankalẹ awọn agbebon darandaran rú Aarẹ̀ àná lorílèèdè Libya, Muammar Gaddafi.
Oríṣun àwòrán, @OUKtweets Àkọlé àwòrán, Orji ni ẹni to jẹ gomina ana nipinle ọhun.
Agbẹnusọ fun ajọ agbaye ṣalaye pe ile ẹjọ to dawa nikan lo laṣẹ lati yọ awọn adajọ nipo.
Plane Crash: Ọkọ̀ báàlù ṣìnà, ó já wọ ilé onílé
Ijoba ati egbe oselu alatako lorile-ede naa so pe, ki Aare naa kowe fipo re sile, gege bi oro olori ijoba lorile-ede naa, ogbeni Pravind pe, ki arabinrin ohun kowe sipo sile leyin ti won ba pari ayeye ayajo odun ominira naa.
Ètò ọmọ wa ni ẹ jẹ́ kó ṣe é ló ń dá ìdàgbàsókè Nàìjíríà dúró -Osinbajo Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Mo fọ kọ́mú, pátá, ògiri ilé lórí 200,000 láìlèfọhùn lórílẹ̀èdè Oman' Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Aarẹ Buhari ninu ikede to fi sita loju opo Twitter lori ọrọ na sọ pe ki awọn ọmọ Naijiria o ma ṣe ṣiyemeji lori igbesẹ atunto ti awọn n ṣe nileeṣẹ ọlọpaa.
 nítrójìn wà nínú ẹbí àwọn pníktójìn .
Oríṣun àwòrán, FURG Àkọlé àwòrán, iwadii ni esunsun ni eroja asaraloore protein ju eran lo Awọn eroja kokoro miran ti awọn eniyan ma n jẹ ni alangba, alantakun, akekee, labalaba ati bẹẹ bẹẹ lọ.
 ti o je akowe egbe oselu fun ekun  gusu ( Southern Highland Zone).
Sùgbọ́n ó ìyawó ọ̀lẹ̀lé ti pada sórí ìkànsiraẹni Instagram láti fún awọn agbọ́yì sọ̀yí lésì lórí ǹkan ti wọ́n ń sọ nipa ọkọ rẹ̀.
Ramadan 2020: Ṣọ́ọ́ṣì kan sí ìlẹ̀kùn rẹ̀ fún àwọn mùsùlùmí láti kírun Jímọ̀ ní Germany
A kò ṣe ẹ̀tọ́ nípa ọ̀ràn rẹ̀.
Àwọn tí ń ṣe àfọwọ́fà ẹ̀ṣẹ̀ gbé!
ati Ila oorun orile ede naa .
Produced by Roland Hughes, David Brown, Tom Francis-Winnington and Sean Wilmott Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
N kò jókòó láàrin àwọn alárìíyá, bẹ́ẹ̀ ni n kò yọ̀.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Igbesẹ n lọ kikankikan lati rii pe aarẹ Omar al-Bashir kọwe fi ipo rẹ silẹ Lẹyin ti awọn ologun yọ nipo ni Ọjọbọ, wọn gbe ijọba alaranṣe kalẹ kalẹ eyi ti yoo wa nipo fun ọdun meji.
Tinubu naa ti dibo rẹ ni Ward F Ikeja,Alausa ni ipinle Eko.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Coronavirus Drugs: Àjọ NAFDAC ti bẹ̀rẹ̀ àyẹ̀wò àgbò mẹ́rin tí wọ́n ṣe ní Nàìjíríà fún Covid-19 25 Ìgbé 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 20 Èbibi 2020 Oríṣun àwòrán, AFP/NAFDAC Ajọ to n mojuto ipese ounjẹ ati oogun ni Naijiria, NAFDAC, sọ pe oun ti bẹrẹ iṣẹ lori oogun coronavirus mẹrin l'orilẹ-ede Naijiria.
Jesu wá rí Ẹ̀mí Ọlọrun tí ó sọ̀kalẹ̀ bí àdàbà, tí ó ń bà lé e.
Nígbà tí ó wo ọ̀kánkán, ó wò, ó rí ọba náà tí ó dúró ní ẹ̀bá òpó, ní ẹnu ọ̀nà ilé OLUWA gẹ́gẹ́ bí àṣà, ó sì rí i tí àwọn olórí ogun ati àwọn afunfèrè yí i ká, tí àwọn eniyan sì ń fi ayọ̀ pariwo, tí wọ́n sì ń fọn fèrè.
Seba ati Salimuna wà ní ìlú Karikori pẹlu àwọn ọmọ ogun wọn yòókù, gbogbo àwọn ọmọ ogun ìlà oòrùn tí wọ́n ṣẹ́kù kò ju nǹkan bí ẹẹdẹgbaajọ (15,000) lọ, nítorí pé àwọn tí wọ́n ti kú ninu àwọn ọmọ ogun wọn tí wọ́n ń lo idà tó ọ̀kẹ́ mẹfa (120,000).
Àṣe ètò ṣíse ní àṣejù nínú!
Kerubu kinni wà ní igun kinni, Kerubu keji sì wà ní igun keji.
Dodai, láti inú ìran Ahohi, ni olórí ìpín ti oṣù keji, iye àwọn tí wọ́n wà ninu ìpín rẹ̀ jẹ́ ọ̀kẹ́ kan ó lé ẹgbaaji (24,000).
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Mama Rainbow: iṣẹ́ tíátà kò ta sánsán mọ́ bíi ti ayé àtijọ́ Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí End SARS protest: Lára àwọn ìlú tí ìwọ́de ti wáyé ní Ibadan, Ado Ekiti, Osogbo, Ado Ekiti ati Eko19 Ọ̀wàrà 2020 Fídíò, Soyinka Cancer: Àṣe ara mi ni iso ti n run gbogbo bí mo ṣe n ṣèrànwọ́ lórí jẹjẹrẹ27 Bélú 2019 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
 won kò nílò láti ní ìdúró kankan .
Makinde: Ẹgbẹ́ òṣèlú PDP ní àwọn kò padà lẹ́yìn Seyi Makinde, gómìnà ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́
Aawo a sanwo ori ni tipatipa ati a ko sanwo ori bere ni ekun Hiran ati aarin gungun Shabelle lodun 2013.
"O ni ""owó ti pọ̀ nísisìyìí ju ìgbà tí mo kọ́kọ́ wà nípò lọ""."
Obinrin kan tí ó fi oòrùn ṣe aṣọ, tí òṣùpá wà lábẹ́ ẹsẹ̀ rẹ̀.
Ṣemu, ẹ̀gbọ́n Jafẹti, náà bí àwọn ọmọ tirẹ̀, òun ni baba ńlá gbogbo àwọn ọmọ Eberi.
eto fun ise iwadii- Ojogbon Abdulrahman  ObaIgbakeji oludari
Ní ọjọ́ náà àwọn eniyan yóo máa wá ikú ṣugbọn wọn kò ní kú; wọn yóo tọrọ ikú, ṣugbọn kò ní súnmọ́ wọn.
Wọn óo gbé ohùn sókè sí ọ,wọn óo sun ẹkún kíkan kíkan.
Ṣugbọn yóo dà wọ́n bo àwọn tí wọ́n kórìíra yín.
EndSARS Protest Update: Ẹgbẹ́ àgbà Yorùbá ní ọwọ́ alágbarà ẹ̀yìn odi ló wà nídi ìkọlù tó wáyé l'Eko
Ajo to n mojuto ipese eto ilera nipinle Cross River(Primary Healthcare Development Agency), ti pese eto ilera ofe fun Egbẹ̀rún lona mẹ́ta ebi ti o n gbe lagbegbe eka ila oorun ipinle Cross River.
Kí igbe ẹkún ó sọ ninu ilé wọn,nígbà tí o bá mú àwọn apanirun wá sórí wọn lójijì;nítorí pé wọ́n wa kòtò láti mú mi,wọ́n dẹ tàkúté sílẹ̀ fún mi.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Orangun: Èdè àti àṣà Yorùba ní láti jọ wá lójú O ni gbogbo awọn ipade igbimọ iṣakoso gbogbo to yẹ ni aba naa yoo de ki wọn to gbee lọ siwaju awọn aṣofin apapọ.
Ìwọ̀n omeri kan jẹ́ ìdámẹ́wàá ìwọ̀n efa kan.
''Ami naa yoo wa nibẹ titi iwadii lori iṣẹlẹ naa yoo fi pari'' Bakan naa ni Ajọ to n risi irina loju popo ti kesi awọn ijọba ibilẹ lati gbe igbesẹ lati ko awọn ọja kuro loju popo.
Ẹ gbọ́ ariwo ọ̀pọ̀ eniyan,wọ́n ń hó bí ìgbì òkun.
Gomina ipinle Zamfara , Abdulaziz Yari,ti o ba awon akoroyin soro leyin ipade naa, lo so pe awon gomina yoo so nipato lonii yii, nibi ipade ti won yoo se lori iye ti won yoo maa san fun awon osise.
Bákan náà àwọn alátìlẹ́yìn AL sọ wípé ilé àtijọ́ náà kò sí lóríi àwọn ibi àjogúnbá tí ó wà nínú àkọsílẹ̀.
Ẹ wo ojú òpó yìí ni aago mẹfa owurọ ọla, ọjọ kejilelogun, oṣu kinni, ọdun 2019 fún fidio to ṣalaye ni kikun lori èrò Obasanjọ sí Buhari.
Wọ́n pọ̀ tóbẹ́ẹ̀ tí ó jẹ́ pé irú rẹ̀ kò sí rí, irú rẹ̀ kò sì tún tíì ṣẹlẹ̀ mọ́ láti ìgbà náà.
Orúkọ ìyá rẹ̀ ni Hamutali, ọmọ Jeremaya ará Libina.
Titi di bi a se n sọrọ yii owo ti llori orilẹede yii naa ko pamọ ti Naijiria ko tii gba n lọ biii Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Lagos: Ojú àwọn ará Èkó rí màbo pẹ̀lú òjò àrọ̀ọ̀rọ̀dá dá wàhálà sílẹ̀ ní Eko Bẹẹ si ni iye owo ti wọn ti gba pada lawọn orilẹede oke okun to ko wọn pamọ si ti to.
13 Nítorínáà, níní àwọn ẹlérìí púpọ̀, nípa wọn ni a ó ṣe ìdájọ́ ayé, àní bí wọn ṣe lè jẹ́ ọ̀pọ̀lọpọ̀ tó lẹ́hìnwá tí wọ́n yíò ní ìmọ̀ nípa iṣẹ́ yìí.
Ọmọ ipinlẹ Rivers ni ẹkun Gusu-Gusu Naijiria ni Victor Giadom, ti wọn ṣẹṣẹ kede ni Adele Alaga ẹgbẹ oṣelu All Progressives Congress, APC.
Wọn ni Amaka ti ba awọn ọdọkunrin kan kẹsẹ bọ ṣokoto kan to si jawe olubori.
 nikẹhìn , ọmọ náà túnúnbá fún bàbá rẹ ̀ ati àwọn ọmọ-ogun rẹ ̀ .
Ajọdun yii wa lati da inu dun ki a si gboriyin fun awọn akọroyin ti o ti padanu ẹmi wọn lẹnu iṣẹ.
"O ni ""Niwọn igba ti a ko tii gba aṣẹ lọwọ ajọ to n ṣakoso ileeṣẹ wa, a ko lee bẹrẹ si ni gba owo ina tuntun ọhun lọwọ awọn eeyan."
Aare Donald Trump panupo pelu aare teleri Barack Obama ati Bill Clinton, lati gboriyin fun oloogbe ohun fun ise takuntakun ti o gbese fun ile Amerika ati ebi re.
akitiyan rẹ lati pese idagbasoke fun  ẹkun
Àwọn eniyan náà ṣe bí Mose ti sọ fún wọn, olukuluku wọn ti tọ àwọn ará Ijipti lọ, wọ́n ti tọrọ ohun ọ̀ṣọ́ fadaka ati ti wúrà ati aṣọ.
Aare ni ologbe naa, je akinkanju eniyan, ti o si fi gbogbo
Bẹẹ ni ọrọ ri pẹlu awọn iroyin gbogbo tawọn eeyan maa n ju sori ayelujara, to fi mọ awọn aworan abi fidio nipa isẹlẹ kan.
Ijọba tún seto idanilẹkọọ ori redio ati tẹlifisan fun awọn akẹ́kọ̀ọ́ lasiko igbele naa.
Ninu oṣù Bulu, ní ọdún kọkanla ìjọba Solomoni ni wọ́n kọ́ ilé ìsìn náà parí patapata, ó sì rí bí wọ́n ti ṣètò pé kó rí gẹ́lẹ́.
Sanwo-Olu sọrọ fun igbakeji lori ipaniyan to waye ni Lekki ati bawọn janduku se soro nilu Eko lọjọru lasiko to n kopa lori eto ori mohunmaworan kan nipinlẹ Eko.
Malikija ọmọ Rekabu, aláṣẹ agbègbè Beti Hakikeremu, ṣe àtúnṣe Ẹnubodè Ààtàn, ó tún un kọ́, ó so àwọn ìlẹ̀kùn rẹ̀ ó sì ṣe àwọn ìdábùú rẹ̀.
PDP sọ pé ẹjọ́ tó fìdí Atiku rẹmi ò tọ̀nà
Agbófinró, tó bá wa ọkada àbí kẹkẹ maruwa l'Eko, o rugi oyin - Sanwo-Olu Ará Yúróòpù ẹ fìdí mọ́lé yín, mo ti gbé ìlẹ̀kùn Amẹ́ríkà tìpa torí Coronavirus - Trump Ìjọba ń ṣe afárá Eko Bridge l'Eko, àwọn ọ̀nà àbùdá tí ẹ lèè gbà nìyí Latari iṣẹlẹ eyi ti o mu iye owo epo rọbi walẹ di bi ọgbọn dọla lati ọgọta dọla, Ọmọwe Chijioke sọ pe ajakulẹ ọrọ aje eleyi ti a mọ si Recession lede oyinbo di dandan.
Ọlọ́run ní kẹ gbé ọkàn yín lé, torí ohun ènìyàn kọ ni ohùn Ọlọ́run.
Nígbà tí àwọn ọ̀tá wa, ní gbogbo àwọn orílẹ̀-èdè tí ó yí wa ká gbọ́ nípa rẹ̀, ẹ̀rù bà wọ́n, ìtìjú sì mú wọn, nítorí wọ́n mọ̀ pé nípa ìrànlọ́wọ́ Ọlọrun ni iṣẹ́ náà fi ṣeéṣe.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ọ̀pọ̀lọpọ̀ ìnira lojú àwọn ọ̀dọ́ ilẹ̀ Áfíríkà t''o ń wá ìgbé ayé rere lọ sí Yúróòpù ń rí Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
D àti Fellowship20 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Inter-tribal Marriage: Bàbá mi kọ̀ láti bá mi sọ̀rọ̀ torí ọ̀kọ akáta tí mo mú wálé20 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Risikat Azeez: Kaosarat àti Hassanat gba ẹ̀bùn ẹ̀kọ́ ọ̀fẹ́ ₦1.
Èwo nínú àwọn àgbàdo yìí ni ẹ fẹ́ràn ju.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Russia 2018: Super Eagles ati Poland yoo dije ọlọrẹsọrẹ 19 Ẹrẹ̀nà 2018 Oríṣun àwòrán, Nigeria Football federation Àkọlé àwòrán, Orilẹede Naijiria ni orilẹede akọkọ to pegede lati kopa ni Russia 2018 lati ilẹ Afirika Wọn ti si ibudo igbaradi ikọ agbabọọlu Super Eagles ti orilẹede Nigeria fun ifẹsẹwọnsẹ ọlọrẹsọrẹ pẹlu orilẹede Poland ti yoo waye lọjọ aje.
Tí ẹ sì ń ṣe làálàá lórí ohun tí kì í tẹ́ni lọ́rùn?
Èèyàn méjọ sí mẹ ́ wàá ni ó sábà máa ń ṣeré àpíìrì , bí ó tilẹ ̀ jẹ ́ pé ènìyàn mẹ ́ rin péré ni í máa ń lu ìlù .
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Wọle Ṣoyinka: Ẹ máṣe gba gbogbo ohun tẹ bá rí lórí ayélujára gbọ́ nípa mi 25 Ògún 2019 Oríṣun àwòrán, @akhirebhulu Ọjọgbọn Wọle Ṣoyinka ti sọ fun ijọba apapọ pe ko ye fi awọn oṣiṣẹ eleto aabo dunkoko mọ awọn Naijiria mọ.
Ó tẹ́ ìwé náà siwaju mi; mo sì rí i pé wọ́n kọ nǹkan sí i ní àtojú àtẹ̀yìn.
Ẹ gbadura pé kí n lè fi ìgboyà sọ̀rọ̀ bí ó ti yẹ.
OLUWA bá sọ fún Mose pé, “Gbé ọwọ́ rẹ sókè sí ojú ọ̀run, kí òkùnkùn lè ṣú bo gbogbo ilẹ̀ Ijipti, òkùnkùn biribiri tí eniyan fẹ́rẹ̀ lè dì mú.
Gómìnà Kini – Ọ̀gágun Àgbà Mobọ́lájí Johnson – Gómìnà fún ọdún mẹjọ – àádọ́ta ọdún si ọdún méjìlélógójì sẹhin
Bakan naa lo darapọ mọ ile ifowopamọ Sterling ni oṣu Karùn-ún, ọdun 2020, ibẹ lo si ti n sisẹ titi di akoko iku rẹ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Èdè Ekiti ni wọ́n fi kí Fayẹmi kú oríire Ninu wẹliwẹli òjò ni awọn agbabọọlu France ti sẹ ajọyọ ife ẹyẹ agbaye gba nile Moscow lọjọ Aiku.
Ẹ mu ọkan kuro lori pe boya awọn eeyan a fi yin ṣe yẹyẹ ti ẹ ba ke gbajare sita lasiko.
Ohun to ṣokunfa ina naa ko tii hande gẹgẹ bi a ko tii gbọ latẹnu awọn alaṣẹ tọrọ kan gan.
Èwo ni o fẹ́, ninu kí òjìji lọ siwaju ní ẹsẹ̀ mẹ́wàá tabi kí ó pada sẹ́yìn ní ẹsẹ̀ mẹ́wàá?
Lẹ́yìn ọdún kan, wọ́n rí Nnamdi Kanu ni Israel Ọọni Adeyẹye; Olorì tuntun ṣe gbogbo nkan tó yẹ́ kó tó wọlé tọ kábíèsí Mínísítà fún ọ̀rọ̀ àyíká lóríllèdè Tanzania, January Makamba tó tún jẹ́ ọ̀rẹ́ tímọ́tímọ́ rẹ̀ fi hànde wí pé òun bá Dewji àti bàbá rẹ̀ sọ̀rọ̀.
Ó sọ fún wọn pè, “Ó wà ní àkọsílẹ̀ pé, ‘Ilé adura ni ilé mi,’ ṣugbọn ẹ̀yin ti sọ ọ́ di ibi tí àwọn ọlọ́ṣà ń sápamọ́ sí!
N óo ranṣẹ sí Nebukadinesari ọba Babiloni, iranṣẹ mi, n óo jẹ́ kí wọn wá dó ti ilẹ̀ yìí, ati àwọn tí ń gbé ibẹ̀.
"N kò gba owó rí lọ́wọ́ olùdíje kó tó dé ipò - Oyedepo Wòlí ní Gbenga Adeboye jẹ nígbà ayé rẹ Èmi kìí se Ọlọ́run, ẹ yé lo fọ́tò mí fún ẹ̀bùn - Adeboye Nàìjíríà bá RCCG, ìyá Folu Adeboye yọ ayọ̀ 70 Alufaa Kumuyi ni, ""Ẹ ma bẹnu ẹ̀tẹ́ lu adari Naijiria."
El-Rufai, lọ tọwọ́ ọmọ rẹ bọ aṣọ!
Jesu dá wọn lóhùn pé, “Ẹ wá gbàgbọ́ nisinsinyii?
Wọn yóo pa àwọn ọ̀tá wọn run,wọn óo wó egungun wọn, wọn óo sì fi ọfà pa wọ́n.
Wọ́n dá wọn lóhùn pé, “Ẹ dìde, ẹ jẹ́ kí á lọ gbógun tì wọ́n nítorí pé a ti rí ilẹ̀ náà, ilẹ̀ tí ó lọ́ràá ni.
Gbogbo àwọn tí Mose ati Eleasari kà ní pẹ̀tẹ́lẹ̀ Moabu lẹ́bàá Jọdani létí Jẹriko nìwọ̀nyí.
Nígbà tí wọ́n mọ̀ pé kì í ṣe òun ni ọba Israẹli, wọ́n bá pada lẹ́yìn rẹ̀.
 O ni awon omo orile ede yii je eni to nifee alejo , o wa seleri pe orile ede Britain yoo tubo maa seto iranwo fun orile ede Naijiria.
Kí ló dé tí ẹ fi fẹ́ ṣe oríkunkun, bí ọba ilẹ̀ Ijipti ati àwọn ará Ijipti.
Ara, ọrẹ, aladugbo ati gbogbo mọlẹbi lo peju lese lati ṣe idaro oloogbe, Moses Ọlaoluwa Adejumọ ni ile rẹ to wa ni Lẹjọka Abiọla Avenue, Ileṣa.
O jẹ ọmọ ọdun mẹwaa to ti n kọrin lati ọdun marun un sẹyin.
Police arrest: 'Ó léwu láti kọ́kọ́ yẹ ọlọ́pàá wò ní Nàìjíríà'
Awọn aṣọbode sọ fun mi pe ijọsin ko waye.
Láti ọmọomún ni ìyá Ajíbógun Ọwá Iléṣà ti kú Ìyá Agígírì tí ó jẹ́ ẹ̀gbọ́n ìyá rẹ̀ ló wò ó dàgbà, ọmún rẹ̀ ló sì mún dàgbà.
Lara awọn eekan to gbe aba yii kalẹ ni gomina Zulum ti ipinlẹ Borno.
Aarẹ ana naa ṣalaye pe ko si ohun meji ti oun ni tako aarẹ ọna kakanfo ilẹ Yoruba naa ju igbe aye rẹ atẹyinwa lọ ti ko ba iṣe oun mu.
Adájọ pàṣẹ kí wọn fí ọlọ́pàá tó lọwọ nínú ikú Kolade Johnson si àhámọ́ #EndSARS lu ayélujára pa lórí ikú Kolade Johnson Dokita Stephen Urueye to jẹ akẹkọọ imọ iṣegun oyinbo lo n ṣiṣẹ pẹlu ile ẹkọ iwosan LUTH nilu Eko, ko to o padanu ẹmi rẹ lẹyin ti awọn eeyan kan gun ni ọbẹ pa.
Àwòrán ìwọ́de NLC, TUC, ULC lónìí Kíni ìdí tí NLC fi kọ N27,000 owó osù òsìsẹ́?
jado orile ede Naijiria ni eyi ti yoo fi dena gbigbeoogun oloro ati awon isẹ
Adajo Oladipo Abimbola ni ọna alùmọkọ́rọ́yí ni Ọba yii gba de ipo naa.
Ninu idajọ to fi sita nilu Abuja laarin Gomina Gboyega Oyetola ati Sẹnetọ Ademọla Adeleke,Adajọ Bode Rhodes-Vivour fọwọ rọ ẹjọ ti Adeleke gbe wa lati tako idajọ ile ẹjọ kotẹmilọrun.
Ọdun 1964 lo bẹrẹ ere ṣiṣe gẹgẹ bi ọmọde pẹlu ere Makanjuọla ti wọn n ṣe lori mohunmaworan nigba naa.
Ni ẹgbẹ PDP ba ke si ajọ eleto idibo, INEC pe ki wọn wa yọ orukọ ẹgbẹ APC kuro ni akọsilẹ awọn ẹgbẹ to wa ki wọn si yọ iwe ẹri iforukọsilẹ wọn kuro toripe wọn o ni aato to yẹ labẹ ofin.
Àbọ̀ ìpàdé bòńkẹ́lẹ́ láàrin Tinubu àti Buhari rèé Pásítọ̀ pe Naira Marley ní ẹlẹ́mìí èṣù, Marley fèsì padà pé kí pásítọ̀ gan tẹ èṣù mọ́lẹ̀ Ẹ́ gba fóónù, ẹ pe ẹbí yín pé a fẹ́ dáná ṣun yín - Aráàlú sọ fún adigunjalè méji Díẹ̀ lára àwọn ìṣẹ̀lẹ̀ tí yóò mi ìgboro tìtì l'ọ́dún 2020 rèé Magu ṣalaye pe awọn ṣi rọ awọn eniyan ti wọn ba ri awọn aṣebajẹ ni awujọ, ki wọn fi oju wọn han pẹlu ipese to wa fun awọn ti wọn ba ṣe ofofo awọn aṣebajẹ, iyẹn whistleblower policy.
Bakan naa lawọn miran n ke si ileeṣẹ ọlọpaa atawọn ẹka agbofinro miran lati tọwọ ọmọ awọn mejeeji yii bọ aṣọ ki wọn to da omi alaafia ipinlẹ Ọyọ ru.
Ọkọ oloogbe naa ṣe ajuwe Funkẹ gẹgẹ bi obinrin to mọ itọju ẹbi ati ara, ti o si ni ifọkansin lati se aseyori lori ohun gbogbo to ba fi ọkan si lati ṣe.
O wa rọ won pe ”Inu
ati àdàbà meji tabi ọmọ ẹyẹlé meji, èyíkéyìí tí apá rẹ̀ bá ká.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Oríṣun àwòrán, Getty Images Oríṣun àwòrán, Getty Images Oríṣun àwòrán, Getty Images Oríṣun àwòrán, Getty Images George Floyd wọ káà ilẹ̀ lọ nílùú Houston l'Amẹrika Eto isinku George Floyd ti wọ kaa ilẹ lọ niluu Houston lorilẹede Amẹrika nibi ti wọn ti bi i.
Ṣugbọn Paulu sọ fún wọn pé, “Wọ́n nà wá ní gbangba láì ká ẹ̀bi mọ́ wa lọ́wọ́, bẹ́ẹ̀ ọmọ-ìbílẹ̀ Romu ni wá.
Dokita aarẹ Trump Sean Conley fi ọrọ sita pe alaafia ni aarẹ ati iyawo rẹ wa ti wọn si gbero lati duro si ile ijọba lasiko iyasọtọ wọn Loju opo Twitter awọn eeyan ti n fesi si iṣẹlẹ yi.
Ọgagun Sani Usman to jẹ agbẹnusọ fun ileeṣẹ ologun ni lọdun 2014 ni fọnran fidio naa jade ati wi pe ohun ti o wa ninu rẹ kii ṣe atọna bi nnkan ti ṣe ri lasiko yi.
₦ jọwọ fi owo osu re sibi BBC koni fi iroyin to fi sọwọ si wa pamọ, ori ero re nikan ni yoo wa.
Ooni ti Ile Ifẹ ati Wole Soyinka ni ki onikaluku ni ẹlẹkunjẹkun ṣe agbekalẹ aato ijọba to faaye gba ifikunlukun ati ijiroro ṣaaju igbesẹ to ba kan ara ilu.
BBC Yoruba wa gbadura pe ọba oke yoo dẹ ilẹ fun ẹni re to lọ.
Wọ́n bá pada lọ jíṣẹ́ pé, 
Eto eyawo je erongba ijoba apapo lati fun awon olokoowo keekeeke bi i milionu meji ni eyawo ki odun yii to pari.
Update on school resumption in Nigeria: Iléèwé tó bá tẹ̀lẹ́ ìlànà ìjọba lórí àbò COVID-19 nìkan ni yóò ṣí- ìjọba ìpínlẹ̀ Oyo Oríṣun àwòrán, Twitter Ijọba ipinlẹ Oyo ti sọ pe ipinnu oun lati ṣi awọn ile iwe pada lọjọ kọkandilọgbọn oṣu kẹfa ọdun 2020 ṣi wa ni digbi.
 Ọmọ ilẹ ̀ scotland ni .
Gbígbọ̀n ni àwọn àgbààgbà ìlú bẹ̀rẹ̀ sí gbọ̀n bí wọ́n ti ń lọ pàdé rẹ̀.
Bí wolii kan tabi alufaa kan tabi ẹnikẹ́ni ninu àwọn eniyan wọnyi bá wí pé òun ń jẹ́ iṣẹ́ OLUWA, n óo jẹ olúwarẹ̀ ati ilé rẹ̀ níyà.
 Oshuntokun ko I ti fi igbakankan yi iwa re pada lati ma a se atako isejoba aare Muhammadu Buhari, sugbon lati tun lo sori ero amohun-maworan lo kede iroyin ti ko sooto ninu re yii, je ohun ti o buru jai.
’ rèé Iṣu ló wà nínú mọ́tò mi, kìí ṣe èèyàn ni mo sọ di iṣu - Afurasí Ajínigbé figbe ta Adeleke ló ní ọmọ ẹgbẹ́ tó pọ̀jù l‘Ọṣun, nipò gómìnà ṣe tọ́ si ní 2022 - PDP Ọṣun Poly Ibadan: Ọjọ́ iwájú la rò táa fí dáná sún fóònù àwọn akẹ́kọ̀ọ́ Nigba to n mu u wa si iranti nipa ọpọ iya to jẹ oun ati mama oun, Lizzy Anjọrin ni osu Kẹfa si Ikeje ọdun ni iya jẹ oun ati iya oun julọ gẹgẹ bii alarinkiri ti ko nile lori.
Paulu Ní Àníyàn fún Àwọn Ará Galatia.
ati gbogbo àwọn ọkunrin tí wọ́n wà ninu ilé rẹ̀, ati àwọn tí wọ́n bí sinu ilé rẹ̀, ati àwọn tí wọ́n fi owó rà, gbogbo wọn ni wọ́n kọ nílà abẹ́ pẹlu rẹ̀.
Adams Oshiomole ni, oun yoo rii daju pe eto oṣelu tiwantiwa fẹsẹ rinlẹ laarin ẹgbẹ oṣelu naa, eleyii ti yoo fun awọn ọmọ ẹgbẹ lẹnu ọrọ ninu bi nnkan ṣe n lọ si laarin ẹgbẹ oṣelu naa.
"abdullah ii bin al-hussein ( , "" al-malik ʿabdullāh aṯ-ṯānī bin al-Ḥusayn "" ibi ni amman , 30 january 1962 ) ni oba hashemite ileoba jordani ."
Ẹ kú àmúmọ́ra tí ọkọ àti ọmọ yín
Ẹni ọgbọn ọdun ni arabinrin Hapiness ti ọrẹkunrin rẹ pa tori ibalopọ.
Awọn miran ti ẹ n sọ lori ayelujara pe awọn lero pe opin aye ti de ni.
O tun wa a ni ṣe pẹlu ibi ti o ba wa - aaye si le wa lati ṣatunṣe.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Àlàyé rèé lórí ilé kẹ̀ta tó wó l'Eko Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Lagos building collapse: Àwọn òbí ń kérora lórí ikú àwọn ọmọ wọn nínú ìjàmbá ilé tó wó Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé àwọn olórí wọn ti lọ sí Soani,tí àwọn ikọ̀ wọn sì ti dé Hanesi.
Titi di asiko yii, iye awọn ti Covid 19 pa nilẹ̀ Adulawọ jẹ́ bii egberun metadinlogoji, 37, 000 ni eyi to kere niwọn si egberun lona ogorun mẹ́fa din ogun, 580, 000 ni America Bẹẹ eniyan ọgbọ̀n le ni igba ẹgbẹ̀run 230, 000 lo ti ba a rin ni Yuroopu ati ẹgbẹ̀run marun le ni igba ni Asia, 205, 000.
Bí ẹnikẹ́ni bá fọwọ́ kan ohun àìmọ́ kan, ìbáà ṣe ohun àìmọ́ ti eniyan, tabi ti ẹranko tabi ohun ìríra kan, lẹ́yìn náà tí ó wá jẹ ninu ẹran tí a fi rú ẹbọ alaafia sí OLUWA, a óo yọ ẹni náà kúrò lára àwọn eniyan Ọlọrun.
Kii ṣe ifipabanilopọ labẹ ofin ilẹ Gẹẹsi, ṣugbọn oluwadii kan ti sọ pe o yẹ ki wọn o ka a si ifipabanilopọ.
Fun alaye kikun, wo awọn orukọ ti awọn ibudokọ ọkọ oju irin naa n jẹ tẹlẹ ati orukọ tuntun ti ijọba Aarẹ Muhammadu Buhari fun wọn bayii: Ìyá òòṣà fẹ̀sùn àjẹ́ kan ìyá ẹni ọdún 90, aráàlú bá sọ ọ́ lókò pa Sábàbí ire ní ikú Barakat padà já sí - Ẹ̀bí fẹ̀mí ìmoore hàn sọ́mọ Nàíjíríà Ìjọba ti wọ́gilé, ètò ìgbéyàwó tó le ni 4000 nítori Covid-19 Sunday Igboho yarí, ó fohùn ránsẹ́ sáwọn èèyàn tó ń pẹ̀gàn rẹ̀ Ibi ti ibudokọ ọkọ oju irin naa wa Orukọ ti ibudokọ ọkọ oju irin naa n jẹ tẹlẹEni ti Buhari fi orukọ ibudokọ ọkọ oju irin tuntun naa sọri bayiiOrukó tuntun ti a o maa pe ibudokọ ọkọ oju irin naa lati isinyii Opopona Eko si Ibadan Ibudokọ ọkọ oju irin Kajọla Ọjọgbọn Yemi Osinbajo (Igbakeji Aarẹ Buhari) Ibudokọ Yemi Osinbajo Agbegbe Apapa ni ilu Eko Ibudokọ ọkọ oju irin Apapa Oloye Bola Ahmed Tinubu (Agba ẹgbẹ o'selu APC) Ibudokọ Bola Tinubu Agbegbe Ebute Metta Ibudokọ ọkọ oju irin Ebute Metta Ogagun Mobolaji Johnson ( gomina ologun ipinlẹ Eko ri) Ibudokọ Mobolaji Johnson Agbegbe Agbado Ibudokọ ọkọ oju irin Agbado Alhaji Lateef Jakande ( gomina ipinlẹ Eko ri) Ibudokọ Lateef Jakande Agbegbe Agege Ibudokọ ọkọ oju irin Agege Babatunde Raji Fashola (minista isẹ àti iléègbé bayii) Ibudokọ Babatunde Fashola Agbegbe Abeokuta Ibudokọ ọkọ oju irin Abeokuta Ọjọgbọn Wole Soyinka (agba ọjẹ onkọwe) Ibudokọ Wole Soyinka Agbegbe Papa-Lantoro Ibudokọ ọkọ oju irin Papalanto Funmilayo Ransome-Kuti (Oloogbe akinkanju obinrin Égba) Ibudokọ Funmilayo Ransome-Kuti Agbegbe Kila- Olodo Ibudokọ ọkọ oju irin OlodoOloye Olusegun Osoba (to ti jẹ gomina ipinlẹ Ogun ri) Ibudokọ Segun Osoba Agbegbe Omi Adio nitosi IbadaN Ibudokọ ọkọ oju irin Omi-Adio Oloogbe Ladoke Akintola (to ti jẹ Olootu guusu Iwo Oorun Naijiria ri) Ibudokọ Ladoke Akintola Agbegbe Ibadanibudokọ ọkọ oju irin Ibadan Oloogbe Obafemi Awolowo (Baba iran Yoruba ninu oselu) Ibudokọ Obafemi Awolowo Agbegbe aarin gbungbun akoso Ibudokọ akoso Operation Control CentreOloogbe Alex Ekwueme (to jẹ igbakeji aarẹ akọkọ ti a dibo yan ni Naijiria)Alex Ekwueme Operation Control Centre Agbegbe Agbor Ibudokọ ọkọ oju irin Agbor Omowe Goodluck Jonathan (Aarẹ Naijiria tẹlẹ) Ibudokọ Goodluck Ebele Jonathan Agbegbe Itakpe Ibudokọ ọkọ oju irin Itakpe Adamu Attah (Gomina Kwara akọkọ ti wọn dibo yan) Agbegbe Ajaokuta ni ipinlẹ Kogi Ibudokọ ọkọ oju irin Ajaokuta Oloogbe Olusola Saraki (agba oje oloselu ni Kwara) Ibudoko Olusola Saraki Agbegbe Itogbo Ibudokọ ọkọ oju irin Itogbo Augustus Aikhomu (Igbakeji aarẹ labẹ ologun tẹlẹ) Ibudoko Augustus Ahikomu Agbegbe Agenebode Ibudokọ ọkọ oju irin AgenebodeGeorge Innih (to jẹ gomina ologun ipinle Bendel/ Kwara latijọ) Ibudokọ George Innih Agbegbe Uromi Ibudokọ ọkọ oju irin Uromi Oloogbe Anthony Enahoro (Ajijangbara oselu awa ara wa) Ibudokọ Anthony Enahoro Agbegbe Akehen Ibudokọ ọkọ oju irin Ekehen Tom Ikimi (to jẹ minista ọrọ ilẹ okeere tẹlẹ) Ibudokọ Tom Ikimi Agbegbe Igbanke Ibudokọ ọkọ oju irin Igbanke Samuel Ogbemudia (To jẹ gomina ologun ipinlẹ Bendel latijọ) Ibudokọ Samuel Ogbemudia Agbegbe Abraka Ibudokọ ọkọ oju irin Abraka ni ipinlẹ Delta David Ejoor (to jẹ ọga agba adari ologun tẹlẹ) Ibudokọ David Ejoor Agbegbe Opara Ibudokọ ọkọ oju irin OparaMichael Ibru (to je gbajugbaja onisowo) Ibudokọ Michael Ibru Agbegbe Ujevwuibudokọ ọkọ oju irin Ujevwu Oloogbe Alfred Rewane (to je igbakeji aaré lasiko ologun ri) Ibudokọ Alfred Rewane Agbegbe Agboribudokọ ọkọ oju irin ni abule Reluwe ni AgborMike Akhigbe (to ti je agba ologun ri) Ibudokọ Mike Akhigbe Ileeese ijọba apapọ to kede yii salaye pe awọn eeyan wọnyii jk akọni ni Naijiria ti wọn ti gbe ogo ilẹ yii ga daadaa lati ọdun pipẹ sẹyin titi di asiko yii.
Awọn agba ọjẹ oṣere bii Jaiye Kuti, Fathia Williams, Abdulateef Adedimeji sọrọ ni kikun lori ipenija iṣẹ sinima ṣiṣe ni Naijiria.
" Awọn ikọ Gunners fi'dirẹmi ninu idije ligi ilẹ Gẹẹsi ni Brighton lọjọ Aiku, lẹyin igba ti Manchester City na wọn lẹmẹji ọtọtọ pẹlu ami ayo mẹta si odo.
Yomi Otubela, to jẹ aarẹ ẹgbẹ naa sọ pe igbesẹ ijọba yoo fun awọn ni itura diẹ kuro ninu inira ti itankalẹ aarun Coronavirus mu ba wọn.
Ibi tí o bá dágbére fún ẹbí àti ará ní kí wọ́n ti ba ọ lásìkò ọdún Kérésì yìí- Akọ́ṣẹ́mọ́ṣẹ́ Ohùn dùn ju ara wọn lọ!
Kí ni eniyan ẹlẹ́ran ara lè fi mí ṣe?
Kí OLUWA mú àsọtẹ́lẹ̀ tí o sọ ṣẹ, kí ó kó àwọn ohun èlò ilé rẹ̀ ati gbogbo àwọn eniyan tí a kó lẹ́rú lọ sí Babiloni pada sí ibí yìí.
Èèyàn 562 tuntun ló tún ti lùgbàdì COVID-19 ní Nàìjíríà ní àná Wo ohun tó yẹ kí o mọ̀ nípa Laycon, akẹ́kọ̀ọ́jáde UNILAG tó ń kópa nínú BBNaija 2020 Gbogbo ohun tí Godswill Akpabio sọ níbi ẹ̀sùn ìnákùnàá tí wọ́n fi kàn án rèé Bí ẹgbẹ́ One Million Boys ṣe bẹ̀rẹ̀ rèé àti ọṣẹ́ tó ṣe n'Ibadan Wo àwọn nkan tó yẹ́ kí o mọ̀ nípa 'Awawa Boys', ọ̀kan lára ẹgbẹ́ òkùnkùn tó n dá Eko rú Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Adele Ọga Agba ajọ NBC, Ọjọgbọn Armstrong Adachaba, kede eyi nibi ipade oniroyin kan to waye nilu Abuja lọjọ Aje.
“orile ede Naijiria , paapaa julo aare  Buhari  ti pinnu pe ,lasiko yii ni won yoo tọwọbọ  iwe adehun ti yoo lee wulo fun orile ede
O ni igba ti oun kọkọ rii to n ja rain lori ẹrọ ayelujara, ẹru kọkọ ba oun, amọ oun ti faramọ ilumọọka ti fidio naa ti jẹ ki awọn da bayii.
Nígbà tí ó rọ́ àlá náà fún baba rẹ̀ ati àwọn arakunrin rẹ̀.
Awọn iroyin ti ẹ lee nifẹ si: 'ẹ̀bùn ọkọ̀ #75m fún Fayose kìí ṣe tuntun' Ìpàdé ìtagbangba ní Ọṣun, ṣẹ́ ti fi orúkọ sílẹ̀ ?
naa fun gudu gudu meje , yaya yaya mefa lori ipa ti won n ko lati kọ awon ọdọ
5 owó naira ni ọọfiisi àjọ INEC ni Zamfara Awọn ti wọn tori igbeyawo Buhari ya mọṣalaṣi Aso Rock ni inu wọn ko dun to pe igbeyawo naa ko waye bi ayelujara ṣe kede rẹ.
Oríṣun àwòrán, boliandgrills Àkọlé àwòrán, Ayipada ti de ba inawo ṣiṣe bayii Oriṣiriṣi awuyewuye lo n waye lori iru awọn ounjẹ 'tuntun' yi.
Bi wọn ṣe jọ jẹyọpọ ninu fidio naa di ọrọ ijiroro lori ẹrọ ayelujara ni eyi ti awọn eeyan mii ṣi n sọrọ le lori di isinyii.
Nàìjíríà ń ṣọ́ pápákọ̀ òfurufú tórí Ebola Ebola sẹ́yọ ní DR Congo 'Mi ò mọ̀ pé mo lóyún àfìgbà t'ọ́mọ ń rún'ra' Fayoṣe lo òpin ọ̀sẹ̀ lọ́gbà ẹ̀wọ̀n Ikoyi ìpínlẹ̀ Eko Oríṣun àwòrán, Google Oun nikan kọ ni o n ranti Dokita Stella Adadevoh ati ipa ribi ribi to kọ nigba ti itankalẹ aarun Ebola ṣẹlẹ ni Naijiria.
Tí a fiṣọwọ́ ní 12:43 11 Òkùdu 201912:43 11 Òkùdu 2019 Ìkíni àwọn ọmọ Nàìjíríà View more on twitterView more on twitter Article share tools Facebook Twitter ṢàpínlòView more share options Share this post Copy this linkKà síwájú síi nípa àwọn ìtọ́kasí wọ̀nyí.
Ijọba naa ni awọn ti mu eeyan mẹta ti wọn n ta awọn pọnmọ yii ni ijọba ibilẹ Ọjọ ati Iba ti wọn si tun ko awọn pọnmọ oloro wọnyii lori igba wọn.
    Ìgbà tí ó ṣe sá, a dé ọ̀run Àpáàdì ní ibi tí Èṣù ti ń ṣe ọba wọn.
Oun ti ẹ le fẹ mọ sii nipa awọn to n figagbaga ree Pernille Harder Oríṣun àwòrán, Reuters Àkọlé àwòrán, Pernille Harder Ọjọ́ orí: 26 Orílẹ̀èdè: Denmark Iye ìgbà tí ó ṣójú orílẹ̀èdè rẹ̀: 110 Ẹgbẹ́ agbábọ́ọ̀lù: VFL Wolfsburg Ipò: Ọwọ́ iwájú (Forward) Ada Hegerberg Oríṣun àwòrán, RONNY HARTMANN Àkọlé àwòrán, Ada Hegerberg Ọjọ́ orí: 23 Orílẹ̀èdè: Norway Iye ìgbà tí ó ṣójú orílẹ̀èdè rẹ̀: 66 Ẹgbẹ́ agbábọ́ọ̀lù: Olympique Lyonnais Ipò: Ọwọ́ iwájú (Forward) Lindsey Horan Oríṣun àwòrán, MARK RALSTON Àkọlé àwòrán, Lindsey Horan Ọjọ́ orí: 24 Orílẹ̀èdè: USA Iye ìgbà tí ó ṣójú orílẹ̀èdè rẹ̀: 62 Ẹgbẹ́ agbábọ́ọ̀lù: Portland Thorns Ipò: Ọwọ́ àárín (Midfielder) Sam Kerr Oríṣun àwòrán, DANIEL POCKETT Àkọlé àwòrán, Sam Kerr Ọjọ́ orí: 25 Orílẹ̀èdè: Australia Iye ìgbà tí ó ṣójú orílẹ̀èdè rẹ̀: 67 Ẹgbẹ́ agbábọ́ọ̀lù: Perth Glory and Chicago Red Stars Ipò: Ọwọ́ iwájú (Forward) Saki Kumagai Oríṣun àwòrán, FRANCK FIFE Àkọlé àwòrán, Saki Kumagai Ọjọ́ orí: 28 Orílẹ̀èdè: Japan Iye ìgbà tí ó ṣójú orílẹ̀èdè rẹ̀: 102 Ẹgbẹ́ agbábọ́ọ̀lù: Olympique Lyonnais Ipò: Agbá 'wájú ilé mọ́ ọwọ́ ààrín (Defender/defensive midfielder) Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
ẹni tí ó fi mana tí àwọn baba yín kò jẹ rí bọ́ yín ninu aṣálẹ̀, kí ó lè tẹ orí yín ba, kí ó sì dán yín wò láti ṣe yín ní rere níkẹyìn.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Láàrín ìdílé ẹlẹ́ni márùn ún yìí, ọmọ kan ṣoṣo ló léè sọ̀rọ̀ Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 3 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 5 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Asiko tun ti to lati bẹrẹ iwọ o ju mi, emi o ju ọ lẹẹkan si, aago mẹta ọsan ọjọ Aiku ni ifẹsẹwọnsẹ naa yoo bẹrẹ ni papa iṣere Wembley niluu London.
Omowe Babajide Adelekan to n tuko ile ikoni nise agbe tijoba apapo l’Abeokuta nipinle Ogun ni iyanselodi awon osise iwadii jakejado orile-ede Naijiria n sakoba fun ilosiwaju eto ogbin atipese ohun jije.
Bakan naa lo tun woye pe iye awọn eeyan ti arun Coronavirus pa kere jọjọ si iye awọn eeyan ti ijamba ọkọ ati nkan miran n pa lọ.
Ọpọ èèyàn a má fí ọwọ yẹpẹrẹ mú isẹ Hajj bíi pé wọn n lọ naju ni.
Nígbà tí Ọ̀dọ́ Aguntan náà tú èdìdì keje, gbogbo ohun tí ó wà ní ọ̀run parọ́rọ́ fún bí ìdajì wakati kan.
Nigba ti BBC bere nipa fidio to ṣafihan Ayisha to n binu lori ayelujara, pe:  ."
Atẹjade ọhun tun salaye pe iṣẹ atunse yoo bẹrẹ lọgan loju ọna Alaka, tijọba si tun gboriyin fáwọn araalu fun atilẹyin ati suuru wọn lasiko ti isẹ atunse naa n lọ lọwọ.
Bakan naa, adele oludari  ajo to n mojuto sise owo ilu kumo-kumo EFCC, ogbeni Ibrahim Magu salaye pe ajo EFCC lo kowe si ile-ise igbakeji aare lati fun awon oga agba mefa naa ni iwe gbele re, fun igba die lati le je ki won ri awon iwe to se koko ti won fe lo fun iwadii won.
Niwọn igba ti o ba ti jẹ pe orilẹ-ede Naijiria naa lo wa, o di dandan ki o tẹle ilana ati ofin ibẹ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Stolen phone: Fóònù mi ni mo lọ́ tún ṣe lọlọ́pàá bá he mí pé mo jí fóònù Lọjọ Aje, ọjọ kẹsan an oṣu yii ni ijọba Ireland wọgile iwọde ayajọ ọjọ St.
Oye ati ifarajin Dokita Stella lo mu u sọ wi pe oun ko ni jẹ ki wọn tu arakunrin na silẹ kuro nile iwosan naa nitori pe o fura si i pe o ni aarun Ebola.
BBC Yoruba: Àwọn ìròyìn tó tayọ lọ́sẹ̀ yìí
Ìjì tí yóo ti ọ̀dọ̀ mi wá yóo le jù bẹ́ẹ̀ lọ.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Wo àwọn nǹkan tí o kò mọ̀ nípa 'Church of Satan' Àwọn afurasí ajínigbé tó tan oníṣòwò jáde ní ṣọ́ọ́sì wọ gàù Ọlọpaa Eré ìtàgé lórí ayélujára, àbíkẹ́yìn faraya pé iṣẹ́ ilé ń pá òun lórí, ó gbé òfin kalẹ̀ fún ẹbí Boko Haram 601 parí iléẹ̀kọ́, ìjọba yóò san ₦20,000 lóṣù fún ẹnì ìkọ̀ọ̀kan Aráàlú faraya torí èèyàn 63 tó dèrò ọ̀run ní Gúúṣù Kàdúná láàrin ọ̀sẹ̀ kan Bi o tilẹ jẹ pe Ọba Ogunwusi gba pe ọwọja arun Coronavirus si n peleke si, sibẹ o rọ awọn ọmọ Naijiria lati tẹle awsn igbesẹ to yẹ fun idena itankalẹ arun naa.
Awọn onisowo gbìyànjú lati ṣaajo awọn ọja wọn lati ko wọn kuro ninu awọn ile itaja wọn ṣugbọn ẹpa ko boro mọ.
Ó dá wọn lóhùn pé, “Ẹni tí ó fúnrúgbìn rere ni Ọmọ-Eniyan.
Ta ló lè yẹ̀ mí lọ́wọ́ wò?
Ó pàṣẹ fún iranṣẹ meji kí wọ́n bá Gehasi gbé wọn lọ.
Ìbẹ̀rẹ̀ irin àjò sí òkè ìrònú ti ń bẹ́ nínú igbó elégbèje
Oríṣun àwòrán, @Chadwick Iya iya Ledward pẹlu sọ si ọrọ ifẹ aarin awọn mejeeji yii to si ni ifẹ wa laarin wọn, inu awọn mejeeji si dun si ara wọn.
Ọgbẹni Sanwo-Olu sọ pe awọn ri diẹ lara wọn tọka si, ti ileeṣẹ ọlọpaa yoo si tọpasẹ wọn de ibuba wọn lati ri i pe wọn jẹ iya ẹṣẹ wọn.
 Àti wí pé , òun ni ó fà á tí ó fi jẹ ́ pé , bí àwọn ọmọ odùduwà ṣe tàn kálẹ ̀ , orílẹ ̀ -èdè kan ni wọ ́ n , èdè kan náà ni wọ ́ n ń sọ níbikíbi tí wọ ́ n lè wà .
"Èèyàn 196 míràn tún ti ní àrùn Coronavirus ní Nàíjírìa Wo àwọn èèkàn ìlú Kano tó kú láàrín ọjọ́ mẹ́rin sí ara wọn Ẹ wo àwọn gbajúmọ̀ òṣèré tíátà tó jogún eré ṣíṣe lọ́dọ̀ òbí wọn O kò leè wọ inú ilé mi lẹ́yìn ìrìnàjò láti Eko, lai ṣe àyẹ̀wò Coronavirus - Bàbá yari fún ọmọ Ni oṣu to kọja ni wolii kan to jẹ gbajugbaja lagbegbe ila oorun orilẹ-ede Naijiria, Chukwuemeka Odumeje to jẹ oludasilẹ ijọ Holy Ghost Intervention Minisitry kede pe oun yoo fi han arun coronavirus idi ti wọn fi n pe oun ni ""opin aisan ati ailera gbogbo"" Bakan naa ni eekan wolii miran, bii, Apositeli Suleiman Johnson to jẹ adari ijọ Omega fire Ministries Worldwide n bẹ ijọba pe ko gba oun laaye lati lọ sawọn ibudo ayẹwo ati itọju awọn alaarun Coronavirus."
Ọba bá búra fún un pé, “Mo ṣe ìlérí fún ọ ní orúkọ OLUWA Alààyè, tí ó gbà mí ninu gbogbo ìyọnu mi, 
lakoko ti awọn ọjọgbọn gbagbọ lori itan-mimọ ti agbelebu , wọn yatọ lori idi ati ipo fun rẹ .
Establishment Act, FCT Management Board and Health Insurance, Suppression of Piracy
Bayii ni awọn ipinlẹ yooku ṣe to tẹle ara wọn lori atẹ awọn ayẹwo gbe sita lọjọ Abamẹta: Nínú èèyàn 600 tó ní coronavirus lọ́jọ́ Ẹtì, 275 ló wá láti agbègbè ilẹ̀ Yorùbá Ẹgbẹta eeyan ni ayẹwo tun ti fihan pe o tun ti kun iye awọn eeyan to ni arun COVID-19 lorilẹ-ede Naijiria lọjọ kẹtadinlogun, oṣu keje, ọdun 2020.
Wọ́n sin ín sí ìlú Dafidi, ṣugbọn kì í ṣe inú ibojì àwọn ọba.
Oṣu Kinni, ọdun 2019 ni eto naa yoo waye.
Ajọ ere bọọlu ni ilẹ Afirika, CAF lo sọ eyi di mimọ lẹyin ipade kan eyi to ṣe ni ilu Accra lorilẹede Ghana ni ọjọ ẹti.
'Ọmọ ọdọ sàlàyé bó ṣe pa Ọpe Bademosi' Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Parental Guidance: Ọdún méjì ni kí ẹ ti bẹ̀rẹ̀ kíkọ́ ọmọ nípa ìbálòpọ̀ Èrò àwọn ọmọ Naijiria ṣotọọtọ lori èyí Bakan naa, awọn ọmọ Naijiria ti bẹrẹ si ni fun Atiku lesi lori ẹrọ ikansiraẹni Twitter rẹ lẹyin ti o fi ẹsun naa lede.
Inu ọgba ile ẹ̀kọ́ ni awọn ọmọ naa n gbe.
Ní ọjọ́ náà, àwọn ọ̀run yóo parẹ́ pẹlu ariwo ńlá bí ìgbà tí iná ńlá bá ń jó ìgbẹ́.
’’“Ijọba aare Muhammadu  Buhari maa n tele ilana eto ofin , nitori naa, ko ni  gba ile-ise tabi ajo kan laaaye lati tapa si ilana eto ofin.
” Wọ́n bá yipada láti bá a jà; ṣugbọn Jehoṣafati kígbe.
Odumakin sọrọ yii lẹyin ti aworan bi Tinubu ṣe joko, nigba ti Ooni dide lati ki i, gba oju ẹrọ ayelujara kan.
Ọ̀pọ̀ òjò lo ti rọ láàrin emi àti Olúwòó- Olorì chanel Alága ẹgbẹ́ NURTW tó gún ọlọ́pàá pá, gba ìdájọ́ ikú Ọ̀pọ̀ òjò lo ti rọ láàrin emi àti Olúwòó- Olorì chanel Àwọn àràmọ̀ndà ìbomú-bẹnu tó gbòde lásìkò Coronavirus yìí Gbogbo ìpàdé yóò maa wáye lóri ayélujára bakan náà ni ko ni sí ààye fún àlejò láti wọlé àfi ti o ba pọ́n dandan.
Wọ́n pa àwọn ọba Midiani maraarun pẹlu.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Sunday Igboho yarí, ó fohùn ránsẹ́ sáwọn èèyàn tó ń pẹ̀gàn rẹ̀ Àwọn iléesẹ́ abáni fi ẹrù ránṣẹ bẹ̀rẹ̀ ìyaṣẹ́lódì tako àfikún owó Nipost Ìkúnlẹ̀ ló bá dé fún Oshiomole, Ize-Iyamu láti bẹ̀bẹ̀ fún ìbò aráàlú ní Edo Sunday Igboho yari, o fohun ransẹ sawọn eeyan to n pẹgan rẹ Ikú Barakat Bello ní Akinyele gbé aláàánú pàdé ẹ́bí rẹ̀ A ṣe ọdún Ọ̀ṣun lásìkò yìí láti kó Coronavirus lọ ni - Ooni ṣàlàyé Wo àwọn nǹkan tí o kò mọ̀ nípa 'Church of Satan' Ni afikun, Dokita Afeez ṣalaye ni kikun lori awọn ọna ti eeyan ko fi le ko arun jẹdọjẹdọ yii ati nipa ki a maa ma dẹyẹsi awọn to ti nii.
Àwọn ọmọ Hasenaa ni wọ́n kọ́ Ẹnubodè Ẹja, wọ́n ṣe àwọn ẹnu ọ̀nà, wọ́n so àwọn ìlẹ̀kùn rẹ̀, wọ́n sì ṣe ọ̀pá ìdábùú sí àwọn ìlẹ̀kùn náà.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Ọmọdebinrin naa lo ti n gbe lọdọ baba agba ọhun lati igba ti iya rẹ ti jade laye, to si ti n fi ẹjọ sun anti rẹ pe baba agba maa n ba oun lopọ ni gbogbo igba, ti ooyi si n kọ oun.
King Millie: Mo mọ ọsàn hó ní ìyàwó mí ṣe bá mi ṣọrẹ ní kékeré, a sì padà fẹra
“Nígbà tí àwọn ọ̀tá bá ṣẹgun àwọn ọmọ Israẹli, eniyan rẹ, nítorí pé wọ́n dẹ́ṣẹ̀ sí ọ́, lẹ́yìn náà, tí wọ́n bá tún yipada sí ọ, tí wọ́n jẹ́wọ́ orúkọ rẹ ninu ilé yìí, tí wọ́n gbadura sí ọ, tí wọ́n bẹ̀bẹ̀, 
Ó kọ́ ilé rẹ̀ sórí òkè gíga-gíga,ninu pàlàpálá àpáta.
Nípa ti eégún olóòlù, kò sí ǹka tó fi yàtọ̀ si àwọn eégún tó kù ní Ibadan, nítorí náà, kò ni sí ààyè fún láti jáde.
Àwọn aṣekúpani tún ti pa ọmọ ọdún 16 ní Akinyele nípìnlẹ̀ Oyo 'Coronavirus ló mú mi fẹ́ ọkọ mi tí a sì ṣèyàwó lóríi ‘Zoom’ A yìnbọn lu Precious láti dáa dúró ni, akò mọ̀ pé o máa kú- Ọlọ́pàá Èèyàn 576 míràn tún kún àwọn tó ní àrùn COVID-19 ní Nàìjíríà Adarí àjọ NDDC, Pondei ṣetán láti sọ ohun tó mọ̀ nípa ìwàdíì tó bá ti gbádùn- NDDC Ẹwẹ, orilẹ-ede Egypt ti n gbero asiko ti yoo pẹ fun iṣẹ naa tori ki ipele omi naa ma sare wọlẹ paapaa ni ipele akọkọ ti wọn ba n di i.
Aro lori eekana ika ọwọ yii lo ṣafihan ẹni to ti dibo.
Nínú ìpàdé ti wọ́n ṣe kẹ́yin, wọ́n kò fẹ́nu ọ̀rọ̀ jóná lóri ọ̀nà ati dáwọ́ agbékalẹ ọ̀rọ̀ ǹkan ìjà ogun ti North Korea n gbèrò láti ṣe.
O yẹ́ ki ilé iṣẹ́ ọlọ́pàá san owó gbà mábínú fún ẹbi àti àwọn ènìyàn ti ọ̀rọ̀ náà kàn, bákan náà lo fi kun un pe o yẹ ki àwọn ọlọpàá bá awọn oluwọ́de sọ̀rọ̀ láti mọ ǹkan ti wọ́n ń fẹ́ kí orílẹ̀èdè le ni ìlọsíwájú.
Nígbà tí Jeroboamu gbọ́ ìkìlọ̀ tí wolii Ọlọrun yìí ṣe fún pẹpẹ náà, ó na ọwọ́ sí wolii náà láti ibi pẹpẹ, ó sì pàṣẹ pé kí wọ́n mú un.
 Àkóràn nị ́ e pẹ ̀ lú iye bacteria , a sì gbàgbọ ́ wípé ọ ̀ pọ ̀ lọpọ ̀ àkóràn maa ń bẹ ̀ rẹ ̀ pẹ ̀ lú gardnerella vaginalis tí ó maa ń fa biofilm tí ó maa ń jẹ ́ kí opportunistic bacteria dàgbà .
Toi sì fi oríṣìíríṣìí ohun èlò wúrà, fadaka, ati idẹ ranṣẹ sí Dafidi.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Àwọn agbófinró ń wá ọlọ́pàá tó yìnbọn lu olólùfẹ̀ẹ́ méjì, lẹ́yìn tí wọ́n gbé akẹgbẹ́ẹ̀ rẹ̀ 14 Ìgbé 2019 Oríṣun àwòrán, Segalink Àkọlé àwòrán, Ọlọpaa ni awọn n wa ọkan lara awọn to wa nibẹ nigba ti wọn yinbọn naa.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ẹfunsetan Aniwura, obìnrin tó ju ọkùnrin lọ Hubert Ogunde rèé, baba àwọn òsèré tíátà Kí lo fẹ́ mọ̀ nípa ‘Ajala Travels’?
Ẹ ranti pé àwọn tí ó bá ní ìfaradà ni à ń pè ní ẹni ibukun.
Gbogbo wọn ni wọ́n la òkun kọjá.
Ẹ lọ sọ fún àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ wéré, pé ó ti jí dìde kúrò ninu òkú.
 o ni gbogbo iwa abuda eniyan rere, o je oloooto lenu ise, mo si feran re.
O gba mi to ọdun mẹwaa ki n to pinnu lati sọ ọrọ aye mi sita.
Oriṣi mẹta ni Yorùbá ka igbà ẹ̀dá si.
Àwọn eniyan orílẹ̀-èdè náà ń bọ̀ kíákíá.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Benue: Ọwọ ologun tẹ darandaran mẹwa to n ba oko jẹ 27 Èrèlè 2018 Oríṣun àwòrán, @HQNigerianArmy Àkọlé àwòrán, Ohun ija lorisirisi ni wọn ka mọ awọn afunrasi naa lọwọ Ọwọ awọn ologun ti tẹ awọn darandaran Fulani mẹwa kan ti wọn n ba oko oloko jẹ nipinlẹ Benue, lẹkun aringbungbun ariwa orilẹede Naijiria.
Oguntola lo soro yii lasiko ti ile ise naa ati agbasese
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Amotekun: Toogun ní àwọn sá fún ariwo ni wọ́n ṣe ń ṣàyẹ̀wò fún ọ̀dọ́ 47,000 tó bèèrè iṣẹ́ 11 Sẹ́rẹ́ 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 10 Owewe 2020 Alakoso ikọ Amọtẹkun ni ipinlẹ Ọyọ, Ajagunfẹyinti Ajibọla kunle Togun ti ṣalaye pe, aisi iṣẹ fun awọn ọdọ, lo mu ki iye awọn eeyan to forukọ silẹ lati darapọ mọ ikọ Amọtẹkun pọ yanturu.
Ọlọ́run nìkan ló mọ bí ìrìnàjò ìfẹ́ ẹ̀dá á ṣe rí láyé, ọ̀dọ́ Aláàfin ní orí gbémí yà sí, ó sì tẹ́milọ́rùn- Olorì Aanu Wo àwọn olorì àgbà mẹ́rin tí Aláàfin ń wárí fún Yatọ si eyi, niṣe ni awọn ọmọ naa jọ ara wọn bi ìmumu, to si maA n ṣoro nigba mii lati da wọn mọ yatọ.
Lẹ́hìn èyí ọba náà béèrè lọ́wọ́ ọkùnrin yìí ibi tí ìyàwó àjẹ́ náà wà ó si dá a lóhùn báyìí pé: Ọ̀rẹ́ mi n kò mọ ibi tí ó wà gan-an, ṣùgbọ́n nǹkan tí mo rí ni pé nígbà tí ó ti yí mi padà sí bi o ti bá mi yìí ni o ti fi àjẹ́ rẹ̀ yí ìlú tí mo jọba lé ló’ri padà tí ó sọ ọ́ di adágún odò tí ìwọ rí lọ́hùn-ún nì.
"Gẹgẹ bi ọrọ to fi lede loju opo Instagram rẹ, Funke yoo mu tọkọtaya mẹta lọ jẹ igbadun eto ""Dubai Shopping Festival"" lorilẹ-ede United Arab Emirates."
" wọ ́ n tún lè pa "" h ' gan-an jẹ ; kí wọ ́ n pe "" ahéré "" ní "" aéré ."
Láti ìgbà yìí ni ó ti di òwe ìpàsamò fún àwon erú pé; ENI TÓ LERÚ LÓ LERÙ.
Bi wọn da ewé si ilẹ́, yio da ilẹ́ padà, bi wọn da sinú omi/odò, kò léwu fún ẹja àti ohun ẹlẹmi inú omi/odò, bi  ọ̀rá àti ike igbàlódé ti ó ḿba àyiká jẹ́.
Alápinni: Ìjọba kò gbárùkù tì wá nínú iṣẹ́ tíátà
Kí ló dé tí o fi dúró lẹ́yìn láàrin àwọn agbo aguntan?
'À ń lọ ilé-ẹjọ́ kòtẹ́milọ́rùn fún ẹ̀kúnwó owó oṣù ẹlẹ́wọ̀n' Ile ẹjọ ọhun sọ pe, gẹgẹ bi ofin ṣe gbee kalẹ, ẹni ti o ba ka iwe alakọbẹrẹ, to le kọ, to si le ka ni ede Gẹẹsi le dije ninu idiibo.
Laarọ kutu oni, ọjọ abamẹta, ọjọ ketadinlogun, oṣu kẹwaa ni iṣẹlẹ yii ṣẹlẹ.
Wọ́n ti yan ọ̀nà tí ó wù wọ́n,wọ́n sì ń fi tọkàntọkàn sin ohun ìríra wọn.
Ni irọlẹ ọjọ Aiku lawọn ajinigbe yi da ọkọ rẹ lọna ni opopona Isan Iludun ni Ekiti.
O wù mí gidigidi, mo fẹ́ kí o jẹ́ baálé mi, mo fẹ́ kí á jọ máa wọlé, kí á jọ máa jáde.
Apẹẹrẹ iru ounjẹ bẹẹ ni mọinmọin tabi ọlẹ, ti igbagbọ wa pe yoo pẹ ko to jinna tabi ko ma jinna laelae ti obinrin to n ṣe nnkan oṣu ba se e.
Lẹyin ti oju rẹ ati awọn ọrẹ rẹ ti wọn jọ jijangbara ri to loko ẹru, o jijangbara, o jajabọ o si yọ awọn eniyan rẹ (Òkò) kuro ninu iṣoro yii ti wọn si gba ominira nigbẹyin kuro lọwọ Olumoko.
Aṣoju aṣa fun Olori Moremi, Ọmọọba Ronke Ademiluyi lo fi igbesẹ yii lede ni ipo Ọba Adeyeye Ogunwusi.
Koda, wọ́n ti tumọ̀ rl si ede oyinbo ti wọ́n si pe akọ́le rẹ̀ ni: The Forest of Thousand Demon Ṣé òtítọ́ ni pé nǹkan oṣù obìnrin le ba òògùn ìbílẹ̀ jẹ́?
lati seto ofin ti yoo mojuto awon isoro wọnyi.
Lóòtọ́ ofin Naijiria ko sọrọ kankan nipa idasilẹ ikọ alaabo ẹlẹkun jẹkun pe ọwọ Ọlọpaa nikan ni aabo araalu wa, ha, awọn eeyan ilu si ni ipa Ọlọpaa ko ka aabo ilu pẹlu gbogbo ohun tawọn n ri.
Hamzat, wa pelu Gbajabiamila lati maa tewogba awon alejo naa.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, O fẹ jọ bi ẹnipe awọn ẹranko ni awọn eeyan n fi ẹsun kọ lọrun bayii Awọn ọlọpaa naa ni eku lo ya bo agọ ọlọpaa awọn to si jẹ awọn idi ewe oogun oloro naa ti wọn n pe ni 'Bhang' Amọsa, kayeefi ọrọ naa ni wi pe eku to jẹ idi oogun oloro to wa ninu apoti ko da iho lu tabi jẹ ibikibi lara apoti ti wọn ko o si.
CCC Genesis Global: Ǹkan mẹ́wàá tí ẹ ò gbọ́ rí nípa Israel Oladele, Woli ìjọ Genesis Global Báyìí ni olùwọ́de EndSARS, Eremosele Adene ṣe gba òmìnira lọ́wọ́ ọlọ́pàá Nàìjíríà Ìpànìyàn orí ayélujára lásán lẹ̀ ń pariwo, ìbọn òfifo làwọn sọ́jà yìn sínú afẹ́fẹ́ - Lai Muhammed Ẹ̀tanú pé Olùṣọ́ Genesis kò fẹ́ Laide Williams-Oni ló ṣe rán an lọ́ sí ẹ̀wọ̀n ọdún kan - CCC Genesis Global Isẹlẹ yii waye nigba ti olori ileasojusofin kuro ni ọfisi rẹ.
O ni ijọba Naijiira ko kọbi ara si arun naa ko to di pe o di tọrọfankale bayii ti ẹru ti n ba tonile talejo.
''Mi o fi ọrọ idupẹ lọwọ awọn ọmọ Naijiria kankan si oju opo naa bẹ si ni mi o kan si ẹnikẹni lati wa sowo sogundogoji kankan.
Ooni ni oriade akọkọ ti yoo gbaruku ti awọn oluwọde ENDSARS ni Naijria lati igba to ti bẹrẹ ni nkan bi ọjọ marun un sẹyin.
Soyinka Cancer: Àṣe ara mi ni iso ti n run gbogbo bí mo ṣe n ṣèrànwọ́ lórí jẹjẹrẹ
OLUWA sì sọ fún Mose pé, 
Awon minisita to le logbon lo wa nibi ayeye ajodun agbaye yii, ojo meta agbako ni won yoo fi se ayeye yii.
kí o wí pé, ‘Ẹ gbọ́ bí OLUWA ti wí, ẹ̀yin ọba Juda, ati gbogbo ẹ̀yin ará Juda ati gbogbo ẹ̀yin tí ẹ̀ ń gbé Jerusalẹmu, ẹ̀yin tí ẹ̀ ń gba ẹnu ọ̀nà wọnyi wọlé.
Ninu ọrọ tirẹ, Gomina ipinlẹ Eko, Babajide Sanwo-Olu ni ki awọn ọmọ Naijiria lo asiko yii lati fi wa ilọsiwaju orilẹede Naijiria, ki wọn si sọra fun ọrọ agan to le fa iyapa ati ẹlẹyamẹya lorilẹede Naijiria.
Oríṣun àwòrán, Gbajabiamila Àjọ agbófinró DSS ń àwọn ti bẹ̀rẹ̀ ìwadìí ẹ̀ṣọ́ olórí ilé aṣòfin-ṣojú, Femi Gbajabiamila tó yìnbọn pa Fẹndọ l'Abuja Ileeṣẹ agbofinro ọtẹlẹmuyẹ DSS lorilẹede Naijiria ni awọn ti bẹrẹ iwadii lori iṣẹlẹ ibọn yinyin to ṣekupa fẹndọ kan ti orukọ rẹ n jẹ Ifeanyi Okeke latọwọ ọkan lara awọn oṣiṣẹ ileeṣẹ agbofinro naa.
Ó ní, “OLUWA àwọn ọmọ ogun, Ọlọrun Israẹli ní kí n sọ fún gbogbo àwọn tí a ti kó ní ìgbèkùn láti Jerusalẹmu lọ sí Babiloni pé, 
Ti eeyan ba gbọrọ tawọn Democrats n sọ,wọn ni lootọ ni pe awọn le ma ri Trump yọ ṣugbọn ohun to ṣe koko fawọn ni pe ki o kawọ pẹyin rojo ẹsun ti wọn fi kan.
CAN: Ìjọ tó bá bá àwọn èèyàn láramu ni kí wọ́n lọ̀
Lẹ́yìn tí a bá gé koríko, tí koríko tútù mìíràn sì hù,tí a bá kó koríko tí a gé lára àwọn òkè wálé,
Èyí jẹ́ ẹbọ sísun olóòórùn dídùn fún OLUWA.
“Jobu, tẹ́tí sílẹ̀ nisinsinyii kí o gbọ́ ọ̀rọ̀ mi.
Ninu atẹjade naa, Baba Adeboye bu ẹnu atẹ lu iroyin wi pe, ko si itakurọsọ kankan to waye laarin Tinubu ati oun.
"Ninu ifọrọwerọ kan ti wọn dijọ se lori isẹlẹ yii, tọkọ taya naa ni ""A dijọ n wa ọkọ igbeyawo wa lọ ni, a dijọ ku papọ ni, titi aye laa ma lo igbeyawo wa lọ, ko baa ma dara."
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Oyo Attack: Ilé ìwòsàn UCH ni Kọmíṣọ́nnà náà ti ń gba ìtọ́jú 21 Bélú 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 22 Bélú 2019 Àkọlé àwòrán, Iṣẹlẹ iku awakọ kọmiṣọnna ṣeni laanu Kọmiṣọnna fawọn ọlọpaa ni ipinlẹ Oyo ni awọn maa gbe awọn ọmọ janduku to ṣe iṣẹ buruku yii ri.
Ọmọ Adésànmí ì bá fi gbòǹgbò jọ Baba Wọlé Ṣóyínká
Oríṣun àwòrán, @akandeoj Lara awọn ọja ti igbakeji aarẹ si ti pin owoya naa ni Ketu ati Bariga, nibi to ti fara kinra pẹlu awọn ontaja bii ẹlẹran, alata atawọn olokoowo alabọde miran.
Oloye Richard Akinjide ti figbalan ri jẹ minisita feto idajọ lasiko iṣejọba Aarẹ Shehu Shagari.
 iṣẹ yìí ni a gbọ ́ wípé Ọbàtálá kùnà láti jẹ ́ lẹ ́ ni tí a ti fún ní ìkarahun ìgbín , iyẹ ̀ pẹ ̀ , àti igi tíyóò fi tàn án ká fún iṣẹ ́ pàtàkì náà .
Ṣugbọn, Maina si ti kuna lati pada yọju sile ẹjọ lẹyin ti wọn gba oniduro rẹ.
com Ẹrọ isiro fi lede wipe owo apo irẹsi kan jẹ ₦15,000 Pin oju ẹrọ yii Pin oju ẹrọ yii twitter facebook email Minimum wage: Kí ló fàá tí owó oṣù tuntun fi ṣòro?
" Ọ ̀ pọ ̀ lọpọ ̀ owóníná ilẹ ̀ ̀ argẹntínà tí wọ ́ n tí ná kọjá ni woṇ ́ n ti pè ní "" peso "" ."
"Agbẹnusọ ileesẹ naa tun sọ wi pe : ""Baalu naa gbera leyin isẹju mẹjọ si igba ti o yẹ ko gbera nitori wi pe a fi asiko diẹ kọ awọn ero nipa bi wọn yoo ti daabo bo arawọn nigba ti baalu ban mi ti-ti."
Lórí àtẹjisẹ twitter, oníruuru ẹri ti a ko ti le fi idi rẹ múlẹ̀ lo súyọ bi olúkúlúku se n sọ ǹkan to o sẹlẹ̀ ládùgbò wọ́n, ti wọ́n si n sọ idí ti wọ́n fi rò pe àwọn ènìyàn n jale ni irú àsìkò yii.
fun igboya ati igbagbo re lati da alaafia ati aabo ti o ti sonu latari iwa odaran
Johanu ń sọ fún àwọn eniyan tí ó jáde lọ ṣe ìrìbọmi lọ́dọ̀ rẹ̀ pé, “Ẹ̀yin ìran paramọ́lẹ̀, ta ni ó kìlọ̀ fun yín láti sá fún ibinu tí ń bọ̀?
Ni orilẹede Ghana loni, owo ori lita epo kan le ni dọla kan owo orilẹede Amẹrika lọ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Rashidi Yekini: Ijọba Kwara ti ṣetán látí má ṣèrántí gbajúgbajà agbábọ́ọ̀lù tó ti dolóògbé 11 Owewe 2020 Oríṣun àwòrán, Others Gomina ipinlẹ Kwara, AbdulRahman AbdulRazaq ni eto ti n lọ lọwọ lati yi orukọ papaa iṣere wọn ni Ilorin si orukọ gbajugbaja agbabọọlu Rashidi Yekini to doloogbe.
Ìpínlẹ̀ méjìlá ni Sharia tí ń ṣiṣẹ́ ni Naijiria, àwọn musùlùmí nìkàn ní wọ́n le ṣe ìdájọ́ wọ́n níbẹ̀.
Ọlọrun, má jìnnà sí mi;yára, Ọlọrun mi, ràn mí lọ́wọ́!
Anania dáhùn pé, “Oluwa, mo ti gbọ́ ọ̀rọ̀ ọkunrin yìí lẹ́nu ọpọlọpọ eniyan: oríṣìíríṣìí ibi ni ó ti ṣe sí àwọn eniyan mímọ́ rẹ ní Jerusalẹmu.
Èmi Oluwa Ọlọrun óo pa yín.
O ni lais ani-ani, Ndigbo ni yoo je anfaani awon ise akanse  lati odo aare Muhammadu Buhari , nitori naa, ohun idunnu ni yoo je fun omo Ndigbo , yala okunrin tabi obinrin to ba je aare lodun 2023, nitori pe yoo tesiwaju ise akanse ti aare Buhari ba se ku.
O fi kun oro re pe, “A ni lati gbaradi fun idabobo ara eni ati lodo awon omo-ogun eleto abo, eyi ti yoo faye gba ofin ati ilana ile-ise olopaa”.
Wọ́n mú ẹẹdẹgbẹrin (700) mààlúù ati ẹẹdẹgbaarin (7,000) aguntan ninu ìkógun tí wọ́n kó, wọ́n fi rúbọ sí OLUWA Ọlọrun baba wọn.
O je ohun iyalenu lati ri Aare Mnangagwa ti ko ranse ikini ku ori-ire fun Nelson Chamisa  ti egbe oselu Movement for Democratic Change (MDC- T) lori ero ayelujara, bi apapo egbe oselu“Mo fe ki Nelson Chamisaku ori-ire, gege bi o se di adari egbe oselu MDC, a n foju sona fun ifiga-gbaga ninu ipologo eto idibo alaafia, ninu eyi ti awon omo orile-ede Zimbabwe yoo ti dibo yan eni ti won nife si lati dari won”.
Nitori ìdí èyí ni àdán ṣe bẹ̀rẹ̀ si sá pamọ́ lati fi òkùnkùn bora ni ọ̀sán fún eku àti ẹyẹ títí  di òní.
Bí ó bá yọ eyín ẹrukunrin tabi ẹrubinrin rẹ̀, yóo dá ẹrú náà sílẹ̀ lọ́fẹ̀ẹ́, nítorí pé ó ti yọ ọ́ léyín.
Àwọn tí ó wà ninu ọkọ̀ júbà rẹ̀, wọ́n ń sọ pé, “Lóòótọ́, Ọmọ Ọlọrun ni ọ́!
Lori ọrọ owo ori sisan lori ọja, VAT.
"Florence Ajimobi tahùn sí igbákeji gómìnà Oyo lórí ikú ọkọ rẹ̀, ""Gbogbo wa làó kú"" Bakan naa ni ọpọ dukia ati ile ba omi lọ ni marosẹ Eko si Ibadan lawọn agbegbe bii Isheri, Warewa, Arepo, Magboro ati Ibafo ni ipinlẹ Ogun."
Ajọ to n ri si iṣẹlẹ pajawiri ni ipinlẹ Eko, LASEMA sọ pe arugbo kan ati ọmọbinrin to ha sabẹ ile naa fara pa diẹ ṣugbọn wọn ri wọn doola ti wọn si ti kọkọ n tọju wọn ninu ọkọ ilera to n jẹ LASAMBUS.
Awọn mejeeji yii lo si jẹ oṣere tiata pẹlu.
Aarẹ Muhammadu Buhari sọ pe, iṣẹlẹ omiyale naa to waye ni ipinlẹ Katsina dun oun pupọ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ohun mẹ́jọ tóo ní láti mọ̀ bí o bá fẹ́ lọ ilé ọdun Ta a ni Baba Keresi gan an gan?
Otunba Segun Runsewe, Alakoso agba fun ile iṣẹ to n ri si ọrọ aṣa ati iṣe lorilẹ-ede Naijiria, National Council for Arts and Culture (NCAC), lo fi ọrọ yi lede.
Egypt President: Aàrẹ Morsi torílè-èdè Egypt dákú,ó gba ibẹ̀ derò alákeji
Lílépa àwọn nǹkan ti ẹran-ara nìkan a máa yọrí sí ikú, ṣugbọn lílépa àwọn nǹkan ti Ẹ̀mí a máa fúnni ní ìyè ati alaafia.
Won ni saaju ki Aregbesola to de ori aleefa, ipinlẹ Osun ko ni awọn ileewe igbalode to se fi yangan.
Ọjọ Aiku ọjọ kẹta oṣu kinni ọdun 2021 yii ni Pochettino yoo bẹrẹ iṣakuso rẹ ni PSG.
Àrinrìnàjò fo sànlẹ̀ kù lẹyìn tó gbà ìpe ní pápákọ̀ ofurufú ìlú Èkó Ikú mú Steven tó lọ dẹ́nu ìfẹ́ kọ olólùfẹ́ rẹ̀ lábẹ́ omi lọ Bóò ṣe lè yẹra fún ikú nígbà òjò - Onímọ̀ Ehi Iden Ìpínlẹ̀ Ọ̀ṣun kò le è sanwó o ọmọ́gọ̀ lórí LAUTECH- Gómìnà Oyetola Ẹni to ti ku ti ku; amọ a gbọdọdu ẹmi ati alaafia ẹni to ṣẹku: Oloye Adegbenga Akani Adeoye to jẹ Kabiesi Onisọkan, ẹgbẹ isọkan ọmọ Oduduwa ṣalaye fun BBC Yoruba pe nilẹ Yoruba a kii deede tufọ feeyan.
Gómìnà Ortom yọ amúgbálẹ́gbẹ́ 28 nípò Buhari ti gba fọ́ọ̀mù láti dupò ààrẹ ọdún 2019 Ààrùn onígbá méjì mú ẹmí ènìyàn mẹ́rìnlá Oríṣun àwòrán, Ondo APC Àkọlé àwòrán, Ọmọ ẹgbẹ́ òsèlú APC tako Oshiomole Ìpínu àwọn ọmọ ẹgbẹ́ ìpínlẹ̀ Ondo yìí lòdì sí ìdarí ilé ẹgbẹ l'Abuja tí Adams Oshiomole jẹ́ ààrẹ.
Àwọn Farisi bá jáde lọ láti gbèrò nípa rẹ̀, bí wọn óo ṣe lè pa á.
”OLUWA dá wọn lóhùn pé, “Ó ti farapamọ́ sí ààrin àwọn ẹrù.
Mike Ipinlẹ Eko naa ni baale ile yi to jẹ elere idaraya to si tun jẹ olokoowo aladani ti wa.
Bí Joabu ti rìn siwaju bẹ́ẹ̀ ni idà yìí bọ́ sílẹ̀.
Ọkọ ni oludari agba ati alaga ileeṣẹ Nigus Enfinity to jẹ ileeṣẹ kan to dowo pọ pẹlu BYD ti China.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ǹjẹ àgbo lè ṣe òògùn coronavirus?
Ezekwesili ṣalaye ọrọ yii loju opo Twitter, toun ti bi awọn ọmọ Naijiria kan ṣe n bẹnu atẹ́ lu pe ko yẹ ko lọ nitori ikọlu Xenophobia to n ṣẹlẹ.
Jesu ní, “Baba, dáríjì wọ́n, nítorí wọn kò mọ ohun tí wọn ń ṣe.
Awọn olukopa naa ti n jẹ ẹbun owo ati awọn ẹbun nla miran ṣaaju asiko yii.
Ayẹwo ti fi han pe eeyan 328 mii tun ti ni aarun Coronavirus ni Naijiria.
Hailemariam so pe,”laasigbo oloselu ti seku pa ogunlogo awon eniyan, ni eyi ti pupo si tun ti di alainile-lori”.
Fatimah funra rẹ fi ọrọ mulẹ ninu ifọrọwanilẹnuwo tirẹ pe, awo ọjọ pipẹ ni baba oun, iyẹn Mamman Daura pẹlu aarẹ Muhammadu Buhari, ti ẹnikẹni ko si lee ri aarin wọn.
 Bii igba mẹta bayii ni Gomina
Nígbà náà ni mo bi angẹli náà pé, “OLUWA mi, Kí ni ìtumọ̀ àwọn kinní wọnyi?
Gbajugbaja osere sinima, Kate Henshaw ati onkọrin takasufe, Banky W naa bu ẹnu ẹ̀tẹ́ lu aṣofin naa eleyi to ṣakawe gẹgẹ bii ojuti nla.
Gẹgẹ bi ajọ to n gbodun ti ajakalẹ aarun, NCDC, ṣe sọ ninu ikede to fi sita lalẹ ọjọ Satide, ipinlẹ mejila, ati ilu Abuja ni awọn esi ayẹwo naa ti wa.
Mamman Daura: Ohun tó yẹ kóo mọ̀ nípa ìbátàn Buhari tó ń bá a gbé l'Abuja
Lẹ́yìn náà yóo rú ẹbọ sísun tirẹ̀ ati ẹbọ sísun ti àwọn eniyan náà, yóo sì ṣe ètùtù fún ara rẹ̀ ati fún àwọn eniyan náà.
Wúrà ati fadaka kún ilẹ̀ wọn,ìṣúra wọn kò sì lópin.
 O wa fi kun oro re pe,
Ìjàpá fi kún ọ̀rọ̀ rẹ̀ pé ìgbín fúnra rẹ̀ ló wá sọ fún òun pé òun ni òun pa abuké Ọsìn.
Ti onibara kan ba si tọ obinrin naa wa pe oun fẹ ra ẹwa sise rẹ ni awin, iya ẹlẹwa yii yoo sọ fun pe ko ma ra ẹwa lawin, se ni ko ra iye ẹwa ti owo rẹ ka lai jẹ gbese.
níwọ̀n ìgbà tí ẹ mọ̀ pé ẹ óo rí ogún gbà gẹ́gẹ́ bí èrè láti ọ̀dọ̀ Oluwa.
Oborududu ko lanfaani lati ba awon akegbe lo lojo Aiku(Sunday), lataari idojuko iwe irin ajo ti o ni.
Ẹja yóo pọ̀ ninu rẹ̀; nítorí pé omi yìí ṣàn lọ sí inú òkun, omi tí ó wà níbẹ̀ yóo di mímọ́ gaara, ohunkohun tí ó bá sì wà ní ibi tí odò yìí bá ti ṣàn kọjá yóo yè.
Eto 'idokoowo' naa lo bẹrẹ laipẹ yii, to si jẹ pe ori ẹrọ ayelujara Facebook ati Whatsapp ni awọn ọmọ ẹgbẹ ti n ṣe 'kata-kara.
Nibi igbẹjọ aarẹ orileede Amẹrika naa, nile aṣofin agba ti ni pe ko ma ijọba rẹ lọ nitori pe ko jẹbi ẹsun ti wọn fi kan.
Adarí àjọ NDDC, Pondei ṣetán láti sọ ohun tó mọ̀ nípa ìwàdíì tó bá ti gbádùn- NDDC Wọ́n ní Pondei ń ṣàìsàn ló ṣe dákú níwájú ìgbìmọ̀ olùwádíì Adari Ajọ Niger Delta Commission, Ọjọgbọn Kemebradikumo Pondei n ṣe aisan ni o ṣe daku lasiko ti ile igbimọ aṣofin n fi ọrọ wa lẹnu wo lori iwa ajẹbanu to n waye ninu ajọ naa.
Mo gbiyanju lati doola ẹmi rẹ kuro nibẹ ṣugbọn ọrẹ mi kọ̀.
Ìró ọ̀pá tí OLUWA yóo fi nà wọ́n yóo dàbí ìró aro ati dùùrù.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Nikesuliat: Ọ̀dọ́mọdébìnrin akéwì tó n fi ẹ̀ṣà kìlọ̀ ìwá lásìkò yìí Wo àwọn irọ́ tí wọ́n ń pa fún ọ nípa àrùn Coronavirus Ojoojumọ ni arun coronavirus n farahan si l'awọn orilẹ-ede kaakiri agbaye, ko si ti i si iwosan kankan to daju fun.
Mummy Calm Down di aṣojú iléeṣẹ́ ńlá kan l'Abuja Dabiri-Erewa sàlàyá ọ̀rọ̀ yìí lásìkò ti adájọ́ Aminu Bello, ìyá Ibrahim Khaleel ti wọ́n pa láì nidìí lórílẹ̀-èdè náà kọ́wọ́rín sàbẹ̀wò si ọfíísì rẹ̀.
Idije Africa Cup of Nations 2019 Àtẹ idije ati Esi Ìpèlè Komẹsẹoyọ Ìpèlè pipin si ìsọ̀rí Ìpèlè Komẹsẹoyọ Ìpele ikọ̀ mẹrindinlogun 05/07/2019, 17:00 Morocco 1 - 1 Benin (Gbee silẹ koo gbaa sile (penalties)) 1 - 4 Ere pari (Papa iṣere Al Salam, Cairo) 05/07/2019, 20:00 Uganda 0 - 1 Senegal (Gbee silẹ koo gbaa sile (penalties)) - Ere pari (Papa iṣere Cairo, Cairo) 06/07/2019, 17:00 Nigeria 3 - 2 Cameroon (Gbee silẹ koo gbaa sile (penalties)) - Ere pari (Papa iṣere Alexandria, Alexandria) 06/07/2019, 20:00 Egypt 0 - 1 South Africa (Gbee silẹ koo gbaa sile (penalties)) - Ere pari (Papa iṣere Cairo, Cairo) 07/07/2019, 17:00 Madagascar 2 - 2 Congo DR (Gbee silẹ koo gbaa sile (penalties)) 4 - 2 Ere pari (Papa iṣere Alexandria, Alexandria) 07/07/2019, 20:00 Algeria 3 - 0 Guinea (Gbee silẹ koo gbaa sile (penalties)) - Ere pari (Papa iṣere 30 June Air Defence Stadium, Cairo) 08/07/2019, 17:00 Mali 0 - 1 Côte d'Ivoire (Gbee silẹ koo gbaa sile (penalties)) - Ere pari (Papa iṣere Suez, Suez) 08/07/2019, 20:00 Ghana 1 - 1 Tunisia (Gbee silẹ koo gbaa sile (penalties)) 4 - 5 Ere pari (Papa iṣere Ismailia, Ismailia) Ìpele to ṣaaju eyi to kangun si aṣekagba 10/07/2019, 17:00 Senegal 1 - 0 Benin (Gbee silẹ koo gbaa sile (penalties)) - Ere pari (Papa iṣere 30 June Air Defence Stadium, Cairo) 10/07/2019, 20:00 Nigeria 2 - 1 South Africa (Gbee silẹ koo gbaa sile (penalties)) - Ere pari (Papa iṣere Cairo, Cairo) 11/07/2019, 17:00 Côte d'Ivoire 1 - 1 Algeria (Gbee silẹ koo gbaa sile (penalties)) 3 - 4 Ere pari (Papa iṣere Suez, Suez) 11/07/2019, 20:00 Madagascar 0 - 3 Tunisia (Gbee silẹ koo gbaa sile (penalties)) - Ere pari (Papa iṣere Al Salam, Cairo) Ìpele to kangun si aṣakagba 14/07/2019, 17:00 Senegal 1 - 0 Tunisia (Gbee silẹ koo gbaa sile (penalties)) - Ere pari (Papa iṣere 30 June Air Defence Stadium, Cairo) 14/07/2019, 20:00 Algeria 2 - 1 Nigeria (Gbee silẹ koo gbaa sile (penalties)) - Ere pari (Papa iṣere Cairo, Cairo) Ipo kẹta ati ikẹrin 17/07/2019, 20:00 Tunisia 0 - 1 Nigeria (Gbee silẹ koo gbaa sile (penalties)) - 67' (Papa iṣere Al Salam, Cairo) Aṣekagba 19/07/2019, 20:00 Senegal 0 - 1 Algeria (Gbee silẹ koo gbaa sile (penalties)) - Ere pari (Papa iṣere Cairo, Cairo) Ìpèlè pipin si ìsọ̀rí Ìsọ̀rí A | B | C | D | E | F | GBA - O ti gba ATB - Awọn to bori Ọ̀MÌ - Awọn to fidirẹmi ATF - Awọn to ta ọ̀mì IYT - Iyatọ to wa laarin igba ti wọn gba bọọlu sinu àwọ̀n AYO - Aami Ayo Isọri A Orílẹ̀èdè GBA ATB Ọ̀MÌ ATF IYT AYO Egypt 3 3 0 0 5 9 Uganda 3 1 1 1 0 4 Congo DR 3 1 0 2 0 3 Zimbabwe 3 0 1 2 -5 1 21/06/2019, 21:00 Egypt 1 - 0 Zimbabwe (Gbee silẹ koo gbaa sile (penalties)) - Ere pari (Papa iṣere Cairo, Cairo) 22/06/2019, 15:30 Congo DR 0 - 2 Uganda (Gbee silẹ koo gbaa sile (penalties)) - Ere pari (Papa iṣere Cairo, Cairo) 26/06/2019, 18:00 Uganda 1 - 1 Zimbabwe (Gbee silẹ koo gbaa sile (penalties)) - Ere pari (Papa iṣere Cairo, Cairo) 26/06/2019, 21:00 Egypt 2 - 0 Congo DR (Gbee silẹ koo gbaa sile (penalties)) - Ere pari (Papa iṣere Cairo, Cairo) 30/06/2019, 20:00 Uganda 0 - 2 Egypt (Gbee silẹ koo gbaa sile (penalties)) - Ere pari (Papa iṣere Cairo, Cairo) 30/06/2019, 20:00 Zimbabwe 0 - 4 Congo DR (Gbee silẹ koo gbaa sile (penalties)) - Ere pari (Papa iṣere 30 June Air Defence Stadium, Cairo) Isọri B Orílẹ̀èdè GBA ATB Ọ̀MÌ ATF IYT AYO Madagascar 3 2 1 0 3 7 Nigeria 3 2 0 1 0 6 Guinea 3 1 1 1 1 4 Burundi 3 0 0 3 -4 0 22/06/2019, 18:00 Nigeria 1 - 0 Burundi (Gbee silẹ koo gbaa sile (penalties)) - Ere pari (Papa iṣere Alexandria, Alexandria) 22/06/2019, 21:00 Guinea 2 - 2 Madagascar (Gbee silẹ koo gbaa sile (penalties)) - Ere pari (Papa iṣere Alexandria, Alexandria) 26/06/2019, 15:30 Nigeria 1 - 0 Guinea (Gbee silẹ koo gbaa sile (penalties)) - Ere pari (Papa iṣere Alexandria, Alexandria) 27/06/2019, 15:30 Madagascar 1 - 0 Burundi (Gbee silẹ koo gbaa sile (penalties)) - Ere pari (Papa iṣere Alexandria, Alexandria) 30/06/2019, 17:00 Madagascar 2 - 0 Nigeria (Gbee silẹ koo gbaa sile (penalties)) - Ere pari (Papa iṣere Alexandria, Alexandria) 30/06/2019, 17:00 Burundi 0 - 2 Guinea (Gbee silẹ koo gbaa sile (penalties)) - Ere pari (Papa iṣere Al Salam, Cairo) Pada si oke to-top Isọri C Orílẹ̀èdè GBA ATB Ọ̀MÌ ATF IYT AYO Algeria 3 3 0 0 6 9 Senegal 3 2 0 1 4 6 Kenya 3 1 0 2 -4 3 Tanzania 3 0 0 3 -6 0 23/06/2019, 18:00 Senegal 2 - 0 Tanzania (Gbee silẹ koo gbaa sile (penalties)) - Ere pari (Papa iṣere 30 June Air Defence Stadium, Cairo) 23/06/2019, 21:00 Algeria 2 - 0 Kenya (Gbee silẹ koo gbaa sile (penalties)) - Ere pari (Papa iṣere 30 June Air Defence Stadium, Cairo) 27/06/2019, 18:00 Senegal 0 - 1 Algeria (Gbee silẹ koo gbaa sile (penalties)) - Ere pari (Papa iṣere 30 June Air Defence Stadium, Cairo) 27/06/2019, 21:00 Kenya 3 - 2 Tanzania (Gbee silẹ koo gbaa sile (penalties)) - Ere pari (Papa iṣere 30 June Air Defence Stadium, Cairo) 01/07/2019, 20:00 Kenya 0 - 3 Senegal (Gbee silẹ koo gbaa sile (penalties)) - Ere pari (Papa iṣere 30 June Air Defence Stadium, Cairo) 01/07/2019, 20:00 Tanzania 0 - 3 Algeria (Gbee silẹ koo gbaa sile (penalties)) - Ere pari (Papa iṣere Al Salam, Cairo) Isọri D Orílẹ̀èdè GBA ATB Ọ̀MÌ ATF IYT AYO Morocco 3 3 0 0 3 9 Côte d'Ivoire 3 2 0 1 3 6 South Africa 3 1 0 2 -1 3 Namibia 3 0 0 3 -5 0 23/06/2019, 15:30 Morocco 1 - 0 Namibia (Gbee silẹ koo gbaa sile (penalties)) - Ere pari (Papa iṣere Al Salam, Cairo) 24/06/2019, 15:30 Côte d'Ivoire 1 - 0 South Africa (Gbee silẹ koo gbaa sile (penalties)) - Ere pari (Papa iṣere Al Salam, Cairo) 28/06/2019, 18:00 Morocco 1 - 0 Côte d'Ivoire (Gbee silẹ koo gbaa sile (penalties)) - Ere pari (Papa iṣere Al Salam, Cairo) 28/06/2019, 21:00 South Africa 1 - 0 Namibia (Gbee silẹ koo gbaa sile (penalties)) - Ere pari (Papa iṣere Al Salam, Cairo) 01/07/2019, 17:00 Namibia 1 - 4 Côte d'Ivoire (Gbee silẹ koo gbaa sile (penalties)) - Ere pari (Papa iṣere 30 June Air Defence Stadium, Cairo) 01/07/2019, 17:00 South Africa 0 - 1 Morocco (Gbee silẹ koo gbaa sile (penalties)) - Ere pari (Papa iṣere Al Salam, Cairo) Pada si oke to-top Isọri E Orílẹ̀èdè GBA ATB Ọ̀MÌ ATF IYT AYO Mali 3 2 1 0 4 7 Tunisia 3 0 3 0 0 3 Angola 3 0 2 1 -1 2 Mauritania 3 0 2 1 -3 2 24/06/2019, 18:00 Tunisia 1 - 1 Angola (Gbee silẹ koo gbaa sile (penalties)) - Ere pari (Papa iṣere Suez, Suez) 24/06/2019, 21:00 Mali 4 - 1 Mauritania (Gbee silẹ koo gbaa sile (penalties)) - Ere pari (Papa iṣere Suez, Suez) 28/06/2019, 15:30 Tunisia 1 - 1 Mali (Gbee silẹ koo gbaa sile (penalties)) - Ere pari (Papa iṣere Suez, Suez) 29/06/2019, 15:30 Mauritania 0 - 0 Angola (Gbee silẹ koo gbaa sile (penalties)) - Ere pari (Papa iṣere Suez, Suez) 02/07/2019, 20:00 Mauritania 0 - 0 Tunisia (Gbee silẹ koo gbaa sile (penalties)) - Ere pari (Papa iṣere Suez, Suez) 02/07/2019, 20:00 Angola 0 - 1 Mali (Gbee silẹ koo gbaa sile (penalties)) - Ere pari (Papa iṣere Ismailia, Ismailia) Isọri F Orílẹ̀èdè GBA ATB Ọ̀MÌ ATF IYT AYO Ghana 3 1 2 0 2 5 Cameroon 3 1 2 0 2 5 Benin 3 0 3 0 0 3 Guinea-Bissau 3 0 1 2 -4 1 25/06/2019, 18:00 Cameroon 2 - 0 Guinea-Bissau (Gbee silẹ koo gbaa sile (penalties)) - Ere pari (Papa iṣere Ismailia, Ismailia) 25/06/2019, 21:00 Ghana 2 - 2 Benin (Gbee silẹ koo gbaa sile (penalties)) - Ere pari (Papa iṣere Ismailia, Ismailia) 29/06/2019, 18:00 Cameroon 0 - 0 Ghana (Gbee silẹ koo gbaa sile (penalties)) - Ere pari (Papa iṣere Ismailia, Ismailia) 29/06/2019, 21:00 Benin 0 - 0 Guinea-Bissau (Gbee silẹ koo gbaa sile (penalties)) - Ere pari (Papa iṣere Ismailia, Ismailia) 02/07/2019, 17:00 Benin 0 - 0 Cameroon (Gbee silẹ koo gbaa sile (penalties)) - Ere pari (Papa iṣere Ismailia, Ismailia) 02/07/2019, 17:00 Guinea-Bissau 0 - 2 Ghana (Gbee silẹ koo gbaa sile (penalties)) - Ere pari (Papa iṣere Suez, Suez) Pada si oke to-top Awọn akoko ti a lo jẹ (GMT+1), o si ṣeeṣe ko yipada.
Sùgbọ́n ó ni gbogbo ètùtù ti wọ́n maa n ṣe láti so ìyàwó pọ mọ ẹmi àìrí ti yóò fi nira fun ẹnikẹni láti gun orí ìyawo Ọba (orisa).
Bí mo sì ti ní ìfẹ́ fún ọdún pupọ láti wá sọ́dọ̀ yín, mo lérò láti ṣe bẹ́ẹ̀ lọ́tẹ̀ yìí.
Baba rẹ, Dave ba awọn akọroyin sọrọ ni iwaju ile ọmọ rẹ ẹni ọdun mọkanlelọgbọn ni Castle Eden, County Durham.
Lẹ́yìn èyí, Nasiri náà lè máa mu ọtí waini.
" Ẹwẹ, Boss Mustapha ni, awọn nkan to ba jẹyọ ni awọn ọsẹ to n bọ yii, ni yoo sọ inu odo ti igbimọ naa yoo da ọrunla si lori pe, boya ki ìjọba kede igbele gbogboogbo miran.
Oríṣun àwòrán, @others Àkọlé àwòrán, Nọ́mbà 17: Eyi jẹ ọkan lara awọn telifiṣọn ti wọn n pe telifiṣọn òmíì ran niṣẹ ninu ile ọlọla.
iko agbaboolu ti asole naa tun ti kopa fun yato si Arsenal ati Chelsea ni,  Chmel Bisayn nibi ti o ti bẹrẹ ere bọọlu lọdun
Sanai Agunbiade ba awọn oniroyin sọrọ.
Ó ní òun ti fi orúkọ sílẹ̀ láti inú oṣù kẹfà ọdún yìí to sì san ẹgbẹ̀rún mẹ́tàlélọ́gbọ̀n náìrà tí wọ́n si fi àtẹ̀jíṣẹ́ ránṣẹ́ pé ètò náà yóò wáyé ní ọjọ́kẹrìnlá, oṣù kẹfà, ọdún 2020.
Olori ile tuntun yii lo fi ẹyin alatako rẹ, Umar Bago janlẹ ninu eto idibo to waye ni irọlẹ ọjọ Iṣẹgun naa.
Jannat Ali Pẹ̀lú àwọn alágbèékalẹ̀ láti ilé-iṣẹ́ Sathi àti Track-T.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Òṣìṣẹ́ Bánkì ni mí l'Amẹ́ríkà kí n tó bẹ̀rẹ̀ Tíátà' Atinukẹ Ogungbe ni iyawo rẹ akọkọ oṣere tiata Yoruba ni.
Gẹgẹ bi ọrọ ti ẹgbẹ oṣẹlu APC ti ẹka Ilẹ Gẹẹsi fi lede loju opo Twitter rẹ, Osinowo dagbere faye nile iwosan kan ni ilu Eko.
Madimena ń sá lọ,àwọn ará Gebimu ń sá àsálà.
Ṣugbọn aile sọrọ awọn obi rẹ lo mu ko lọ kọ bi wọn ṣe n ba awọn odi ati aditi sọrọ.
di, nitori , bi mo se n baa yin sọrọ bayiimo ti kede ibo aare ati ti ile igbimo
Ṣugbọn òun óo gba ìjọba náà kúrò lọ́wọ́ ọmọ Solomoni, òun óo sì fún ọ ní ẹ̀yà mẹ́wàá.
Ẹrú tí ó bá mọ ìwà hù, yóo di ọ̀gá lórí ọmọ tí ń hùwà ìbàjẹ́,yóo sì jókòó pín ninu ogún bí ẹni pé ọ̀kan ninu àwọn ọmọ ni.
Nígbà tí Baba-onírùngbọ̀n kí wọn tán tí ó béèrè bí wọn ti ṣe rìn tí wọ́n fi dé ibẹ̀ tí wọ́n sì là á yé wí pé àwọn ṣìnà sí inú Igbó Olódùmarè ni, ó tún kí wọn dáadáa ó sì fún wọn ní àyè ní ilé rẹ̀.
O sọ nipa aya didun, inu rirun, oju wọn maa ni awọ pupa rẹsurẹsu, ati ki wọn maa padanu ẹjẹ pupọ ṣugbọn awọn ohun ti ẹ le ma mọ ree.
“Nipasẹ awọn ofin yii, a ti fi han ninu Ile Igbimọ Aṣofin yii pe a mu ọrọ idagbasoke ilu pẹlu aabo ilu ni ọkunkundun.
Ẹ̀rù ń ba àwọn ẹlẹ́ṣẹ̀ tí ó wà ní Sioni;ìjayà mú àwọn ẹni tí kò mọ Ọlọrun.
Mo ṣebí ẹ̀mí yín ju oúnjẹ lọ; ati pé ara yín ju aṣọ lọ.
Trump yọ Tillerson kuro nipo Trump bu ẹnu atẹ lu FBI ‘Buhari, kó ara rẹ ní‘jánu lọ́dọ̀ Trump’ Nàìjíríà ń wá ẹlẹ́dẹ̀ aríran Òwò ẹrú pé irinwó ọdún tó bẹ̀rẹ̀, àwọn Amẹrika tó jẹ́ dúdú wá sí Afirika láti bẹ ilé wò Joe Biden to jẹ igbakeji aarẹ ilẹ Amẹrika lo si n siwaju ninu awọn to fẹ dije fun ipo aarẹ fẹgbẹ Democrat, nigba ti Sẹnẹtọ Bernie Sanders ati Elizabeth Warren si n tẹ le e.
Ṣafati, ọmọ Adila, ni ó wà fún àwọn agbo mààlúù tí wọ́n wà ní àwọn àfonífojì.
Iṣẹlẹ yi waye lasiko to pe Dorathy wa si inu iyara ijiroro ''Diary Room'' Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Akomolede ati asa Yoruba: Ẹ wá kọ́ nípa àpòtí ìṣura èdè wa lórí BBC Yorùbá Iná sọ nínú ilé Big Brother tó ń lọ lọ́wọ́ ní Cameroon Ina kan ṣẹyọ ninu ile ti wọn ti ṣe eto Biggy 237 ni Cameroun, ṣugbọn ẹnikẹni ko ṣeṣe.
Afurasí Fulani ṣekú pa ọmọ olórí ẹgbẹ́ Afẹ́nifẹ́re, Fasoranti Àwa ọba alayé ń wọ́nà láti ṣẹ́ eegun ẹ̀yin ọ̀daràn Fulani - Ọọ̀ni Ẹ yàgò fún ìwà adìẹ dàmí lóògùn nù, màá fọ lẹ́yin lásìkò ìjà - Buhari Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Àgbà ni Obasanjo, oun tó ń sọ yé e, ìjọba ni kó tají - Wale oke Lasiko to n fi idi isẹlẹ naa mulẹ fun BBC Yoruba, agbẹnusọ fun ẹgbẹ Afẹnifẹre, Yinka Odumakin salaye pe lootọ ni isẹlẹ naa waye, asiko ti Ọlakunrin n bọ lati ilu Akurẹ si lo se alabapade iku ojiji naa.
’ rèé Derin ni oun n yọ wahala lọrun awọn ti ko ri aaye lọ si ọja ni, eyi dẹ n pese owo fun oun ni èrè.
August 13, 2019 Sheikh Zakzaky de Delhi, orilẹede India fun itọju ara, Awọn oṣiṣẹ eto ilera si gbee wọ ileewosan lori aga alaaarẹ August 14, 2019 Ninu ohun kan to fi ranṣẹ to si tan ka, El-Zakzaky fẹdun sọ pe ipo ti ile iwosan orilẹede India naa wa buru ju ti ibi ti oun wa ni Naijiria lọ.
E̩nì kò̩ò̩kan tí ó bá ń s̩isé̩ ní è̩tó̩ láti gba owó os̩ù tí ó tó̩ tí yóò sì tó fún òun àti e̩bí rè̩ láti gbé ayé tí ó bu iyì kún ènìyàn; a sì lè fi kún owó yìí nípasè̩ orís̩ìí àwo̩n ètò ìrànló̩wó̩ mìíràn nígbà tí ó bá ye.
Bakan naa, Onuachu, Balogun, Ogu, Simon, Ezenwa, Awaziem ati ajayi naa yoo wa ni ikalẹ.
NAFDAC: Ojú wa wà lára ìpara Blac Chyna náà Boko Haram pa ọmọ ogun Nàìjíríà 53 ‘70% ọ̀dọ́ àti obìnrin ní yóò bàmi ṣisẹ́’ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ọ̀pọ̀ òṣìṣẹ́ elétò ìlera ló ti n lo tọ̀nà ìgbàlódé láti fiṣe àkọsílẹ̀ Ipade mii ti wọn fẹ ṣe lọjọ kejilelogun, oṣu kọkanla.
Àwọn ọkùnrin mẹ́tẹ́ẹ̀ta yìí gbọ́ ọ̀rọ̀ bàbá wọn, olúkúlùkù bá ilé rẹ̀ lọ, gbogbo wọn mú apó àti ọfà, ó di ẹ̀yìn kùnlé baba wọn.
Káyòdé akòwé Ọmọ́tọ́ṣọ̀ọ́ sùn ní ẹnu iṣẹ́ Ìgbà tí wọ́n bi í pé kí ló dé tí ó fi sùn ni ó dáhùn pé olè ajẹ́rangbe tí àwọn ń lé ní òru ni kò jẹ́ kí àwọn sùn dáadáa.
9 9300 Orilẹede South Sudan 62 0.
Ṣùgbọ́n ipó tí ó fún mi kko tíì tẹ́ mi lọ́rùn, ipó tirẹ̀ gan-an ló wù mi.
Igbimọ naa faake kọri wi pe awọn ko ni bu owo lu eto isuna toto biliọnu mọkandinlaadọwa ti wọn gbe wa si waju wọn, ayafi ti wọn ba gbe iye eyi ti Aarẹ Muhammadu Buhari koko gbe ka iwaju wọn ni alakọkọ.
Orin yii ni awọn agbabọọlu Madagascar mu bọ ẹnu nigba ti wọn gba ami ayo wọ ile Guinea lọjọ Satide Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Eewọ.
Nahaṣi, ọba Amoni, kó àwọn ọmọ ogun rẹ̀, wọ́n lọ gbógun ti ìlú Jabeṣi Gileadi.
Aṣojukọroyin BBC ni Onitsha jabọ pe, lẹyin wakati mẹta ti ina ọhun bẹrẹ ni ọkọ panapana kan ṣoṣo ṣẹṣẹ yọju sibi iṣelẹ naa.
Elétù Òdìbò Èkó ni ó máa ń fi Báálẹ̀ jẹ.
Àwọn apẹja yóo dúró létí òkun láti Engedi títí dé Enegilaimu, ibẹ̀ yóo di ibi tí wọn yóo ti máa na àwọ̀n wọn sá sí.
Kayode Ogundamisi@ogundamisi ni bi fatimah se gba lootọ ni oun ya aya aarẹ nibi to ti n pariwo ni bonkẹlẹ kii se nkan kekere rara, o ti tapa si ofin eto aabo, o si yẹ ki aarẹ lee to ile rẹ.
“Bí àlejò kan bá wà ní ààrin yín tí ó sì fẹ́ ṣe Àjọ̀dún Ìrékọjá, yóo ṣe é gẹ́gẹ́ bí òfin ati ìlànà rẹ̀.
O ṣeeṣe ki esi wọn yi jẹyọ nitori ẹkunwo oṣu ti ẹgbẹ́ oṣiṣẹ ni Naijiria, NLC, n beere fun.
Ẹ kò sì ní lè dúró níwájú àwọn ọ̀tá yín títí tí ẹ óo fi kó àwọn ohun ìyàsọ́tọ̀ kúrò láàrin yín.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Baby abandoned on dunmpsite: Mo ti bímọ mẹ́rin tẹ́lẹ̀ fún bàbá méjì nínú òṣí- Dupe Ogbomos Bakan naa ni ileeṣẹ ọlọpaa gbe afurasi afiniṣowo naa lọ si ile iwosan lẹyin tawọn eeyan ti lu u ni alubami.
: Ipa ti  awon olori elesin musulumi  n ko, ni eyi to waye lojoBo niluu Abuja.
A fẹ́ wá ibi ti wọn yóò ti máa gbìn igbó, ti àjò to ń gbógun ti oogun oloro yóò sì mọ nípa rẹ, a máa sọ ibẹ tọsan toru, a gba àṣẹ láti ṣe bẹ́ẹ̀, tí yóò si dohùn, torí òpó anfaani lo wá nìdí rẹ.
Ìdí nìyí tí àwọn Juu fi mú mi ninu Tẹmpili, tí wọn ń fẹ́ pa mí.
Àrà meriiri ni ki àwọn eniyan pinnu lati ṣe nkan to wu wọn bii ọkada gigun lati ilẹ̀ kan si ikeji laarin ọpọlọpọ orilẹ-ede.
O ni ki awọn eeyan fun ijọba ni asiko diẹ sii nitori pe ijọba ko fẹ ṣi ẹsẹ gbé lori gbigba ọmọbinrin naa silẹ lakata awọn ISWA ni.
Àwọn ẹ̀yà Bẹnjamini ni wọ́n ń gbé ìlú náà.
Wọ́n pé ọdún méjìlá báyìí Kílódé tí Ọọni Ife, Oba Ogunwusi kò fi gbọdọ̀ rí ọmọ rẹ̀ tuntun ti Olorì Naomi bí títí di bíi ẹ̀yìn oṣù mẹ́fà?
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ramadan Fast: wo àwọn orílẹ̀èdè tí wákàtí ààwẹ̀ wọn gùn ju ti Nàìjíríà lọ àti àwọn èèwọ̀ oúnjẹ lásìkò ààwẹ̀ 6 Èbibi 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ounjẹ Àkókò: Oòrùn ràn: :Oòrùn ràn Oòrùn wọ̀: :Oòrùn wọ̀ Afghanistan Australia Brazil Canada Chile China Egypt France Greenland Iceland India Indonesia Kenya Libya Morocco Nigeria Russia Saudi Arabia Senegal South Africa Tanzania UK USA Àkókò: Oòrùn ràn: :Oòrùn ràn Oòrùn wọ̀: :Oòrùn wọ̀ Àkókò: Oòrùn ràn: :Oòrùn ràn Oòrùn wọ̀: :Oòrùn wọ̀ Afghanistan Àkókò: 15hrs 31mins Oòrùn ràn: 04:45 Oòrùn wọ̀: 18:55 Australia Àkókò: 11hrs 25mins Oòrùn ràn: 06:46 Oòrùn wọ̀: 16:58 Brazil Àkókò: 11hrs 57mins Oòrùn ràn: 06:37 Oòrùn wọ̀: 17:29 Canada Àkókò: 17hrs 2mins Oòrùn ràn: 05:15 Oòrùn wọ̀: 20:28 Chile Àkókò: 11hrs 25mins Oòrùn ràn: 07:33 Oòrùn wọ̀: 17:46 China Àkókò: 16hrs 11mins Oòrùn ràn: 04:51 Oòrùn wọ̀: 19:30 Egypt Àkókò: 15hrs 5mins Oòrùn ràn: 04:57 Oòrùn wọ̀: 18:47 France Àkókò: 17hrs 44mins Oòrùn ràn: 05:59 Oòrùn wọ̀: 21:37 Greenland Àkókò: 20hrs 48mins Oòrùn ràn: 03:44 Oòrùn wọ̀: 23:06 Iceland Àkókò: 20hrs 47mins Oòrùn ràn: 03:46 Oòrùn wọ̀: 23:06 India Àkókò: 14hrs 58mins Oòrùn ràn: 05:26 Oòrùn wọ̀: 19:10 Indonesia Àkókò: 12hrs 50mins Oòrùn ràn: 05:55 Oòrùn wọ̀: 17:44 Kenya Àkókò: 13hrs 17mins Oòrùn ràn: 06:27 Oòrùn wọ̀: 18:32 Libya Àkókò: 15hrs 48mins Oòrùn ràn: 06:03 Oòrùn wọ̀: 20:05 Morocco Àkókò: 15hrs 28mins Oòrùn ràn: 05:21 Oòrùn wọ̀: 19:28 Nigeria Àkókò: 13hrs 29mins Oòrùn ràn: 06:30 Oòrùn wọ̀: 18:57 Russia Àkókò: 18hrs 35mins Oòrùn ràn: 04:04 Oòrùn wọ̀: 20:50 Saudi Arabia Àkókò: 14hrs 38mins Oòrùn ràn: 05:06 Oòrùn wọ̀: 18:34 Senegal Àkókò: 14hrs 12mins Oòrùn ràn: 06:40 Oòrùn wọ̀: 19:34 South Africa Àkókò: 11hrs 50mins Oòrùn ràn: 06:43 Oòrùn wọ̀: 17:26 Tanzania Àkókò: 13hrs 3mins Oòrùn ràn: 06:39 Oòrùn wọ̀: 18:29 UK Àkókò: 18hrs 1mins Oòrùn ràn: 04:57 Oòrùn wọ̀: 20:58 USA Àkókò: 15hrs 29mins Oòrùn ràn: 05:46 Oòrùn wọ̀: 19:54 Kókó ọ̀rọ̀: Wíwo àkókò dá lórí olú ìlú orílẹ̀èdè kọ̀ọ̀kan Orísun: aladhan.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Wo àwọn ọ̀nà tí o lè gbà láti di ọjọ́ ogbó pẹ̀lú olólùfẹ́ rẹ Lẹyin ipade naa, aarẹ ile aṣofin apapọ, Sẹnetọ Ahmad Lawan ṣalaye fun awọn akọroyin pe, ijọba apapọ ti tẹwọ gba gbogbo ẹhonu awọn ọdọ to n wọde naa.
Eyi je eleekefa iru re nile Adulawo nibi ti won ti fi  ami eye lorisirisi da awon eeyan lola pelu idiyele oniruuru.
Oríṣun àwòrán, Bashir Ahmad Ẹwẹ, Aarẹ Buhari lo anfaani apero TICAD7 niluu Yokohama lati bere iranwọ ilẹ Asia lati dẹkun awọn ole oju ni ọgbun Guinea atawọn to n pẹja lọna aitọ ninu ọgbun naa.
Wọ́n daṣọ bò ó lójú, wọ́n wá ń bi í pé, “Sọ ẹni tí ó lù ọ́?
Mo gbẹ́ kànga mo sì mu omi ninu wọn.
Lati ọwọ Nita ni Maidstone Iroyin BBC Ikọ eleto ilera Lara awọn eeyan mẹrin ninu marun un awọn to ni Covid- 19 ko ni mọọ lara pupọ, o kan maa dabi otutu lasan lara wọn Diẹ lara àmì ẹ ni iba, ikọ ẹgbẹ ati ailera fun ọjọ diẹ ti waa si gbadun laarin ọsẹ kan ti awọn apẹẹrẹ yii yoo lọ Ti o ba ti wọ ẹ lara ni yoo kọle si inu ẹdọ-fooro rẹ nibi ti yoo ti jẹ ki eemi mimi rẹ ko nira pẹlu otutu aya.
Ó kẹ́ ọfà, ó fa ọrun rẹ̀,ó sì fi mí ṣe ohun ìtafàsí.
O ni, o yẹ ki ijọba gba awọn lọwọ pasan awọn eeyan to n se ayederu isẹ awọn.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Tomomewo Favour: olóṣèlú kìí ṣe ọ̀daràn tàbí alágbèrè Agbodemu ni ọwọ awọn ti ba afẹsunkan kan ti orukọ rẹ n jẹ Sola Saliu.
‘Ìṣúnsíwájú ìbò: Àdínkù yóò bá owó epo bẹntiróòlù Ààrẹ Buhari pọ́n ọ̀dọ́ Nàíjíríà lé, ó ya Nov 1st sọ́tọ̀ fún àyájọ́ ọ̀dọ́ Àṣírí tú!
Ṣe Saraki yoo tun jẹ lọ bi, ni agbo oselu Naijiria lẹẹkan sii, paapaa nibayi ti ẹnu n kun-un pe o fẹ du ipo aarẹ?
23%, nigba ti oludije Svetlana Tikhanovskaya gba ida ibo 9.
Oríṣun àwòrán, REUTERS Àkọlé àwòrán, Ọpọlọpọ awọn eniyan ni wọn ti wọ awọ ẹgbẹ oṣẹlu African National Congress, eyiti o fa ija si apartheid.
Ní ọjọ́ náà, àwọn Sadusi kan wá sọ́dọ̀ rẹ̀.
Samuẹli wí fún wọn pé, “Ẹ jẹ́ kí á lọ sí Giligali, kí á lè túbọ̀ fi ìdí ìjọba Saulu múlẹ̀.
Amọṣa adajọ ni ki wọn gbẹsẹ kuro lori aṣuwọn ifowopamọsi rẹ eyi ti wọn ti sọ agadangodo si lati igba ti igbẹjọ naa ti bẹrẹ.
Ọpọ eniyan lo gboriyin fun akọnimọọgba tuntun Tottenham, Jose Mourinho pẹlu bi ikọ rẹ se na West Ham pẹlu ami ayo mẹta si meji.
Dokita yọ góòlù àti owó ṣílè nínú obìnrin kan Etí ìjọba Buhari di sí ìmọ̀ràn àwọn ará ìlú -Jiti Ogunye Ẹ ṣọ́ra fún ìròyìn ẹlẹ́jẹ̀ lórí ètò ààbò - Ọlọ́pàá Esi yii si n fi Liverpool silẹ loke tente tabili liigi ilẹ Gẹẹsi.
Ọpọ isẹlẹ adiitu lo maa n waye lalẹ ọjọ igbeyawo, , ti ko ba si ẹjẹ lori asọ ibusun lalẹ ọjọ igbeyawo, iyawo naa ru igi oyin, to si seese ki wọn le pada sọdọ awọn obi rẹ.
Lẹyin ayẹwo , o sọ pe awọn to n tọju ohun ni ko sewu ki oun maa lọ sile laayọ ati alaafia.
Ajọ CAN pẹlu pa ohun rẹ da: CAN ti saaju sọ fun BBC pe awọn ko mọ nkankan nipa ilana ti ijọba gbe kalẹ lori isin oru aisun ọdun sugbọn wọn yi ohun pada ninu atẹjade kan.
Akonimoogba Iko agbaboolu orile-ede South-Afrika(Bafana Bafana), Stuart Baxter ti pe agbaboolu owo aarin iko SBV Vitesse FC, Thulani Serero si ara iko ti yoo koju iko agbaboolu Super Eagles ninu ifesewonse ipegede fun idije boolu ile Afrika (2019 Africa Cup of Nations, Afcon), ti yoo waye lojo ketadinlogun osu kokanla odun yii.
Ọlọrun sọ̀rọ̀, eṣinṣin sì rọ́ dé,iná aṣọ sì bo gbogbo ilẹ̀ wọn.
Latin/facebook Lẹyin ọdun marundinlogoji to pari ẹks girama ni Bọlaji Amusṣan ti ọpọ mọ si Mr.
Àwọn ologun dóòlà akẹ́kọ̀ọ́ mẹ́fà lọ́wọ́ àwọn ajínigbé ní Kaduna A fẹ́ kí a máa tẹ àwọn afipábánilòpọ̀ lọ́dàá ni báyìí - Ìjọba Ekiti Ọjọ Iṣẹgun ni Aarẹ Muhammadu Buhari gbe aba eto iṣuna fun ọdun 2020 to le ni tiriliọnu mẹwaa lọ siwaju ile aṣofin agba l'Abuja.
INEC:Ìròyìn òfégè ní pé ilé ẹjọ pàṣẹ fún wa láti dáwọ àkójọ èsì ìbò Gómìnà Rivers dúró
Nígbà tí ó di àfẹ̀mọ́jú, àwọn angẹli náà rọ Lọti pé, “Dìde, mú aya rẹ ati àwọn ọmọ rẹ mejeeji tí wọ́n wà níhìn-ín kí o sì jáde, kí o má baà parun pẹlu ìlú yìí.
Iléẹjọ́ rán ajìjàǹgbara 7 lọ sẹ́wọ̀n ní Cameroon Wilfred Ndidi, ọmọ Nàìjíríà pa iná ògo Chelsea ní Stamford bridge Yàtọ̀ sí Ọ̀ṣun Òṣogbo, Ṣàǹgó pẹ̀lú a máa ní arugbá lóde Ọ̀yọ̀ Fowler kò sí lábẹ́ ìwádìí kankan-Garba Sheu Lọdun 2010 si ọdun 2011 ni Siasia fi ṣe akọnimọọgba fun ikọ agbabọọlu ti wọn ko kọja ogun ọdun si ọdun mẹtalelogun lọ.
Ladi Adebutu, Sẹnetọ Ademola Adeleke ati alaga ẹgbẹ PDP ni Eko, amojuẹrọ Deji Doherty ti n di fa ki n fa a tipẹ lorii tani yoo ṣakoso idari ẹgbẹ PDP nilẹ Yoruba.
O ni bi awọn kan ṣe n sọ wi pe bayii ni ọrọ ri, ni awọn miran n sọ wi pe ọrọ ko ri bẹẹ.
 Awọn onimọ nipa eto abo sọ pe, awọn ilu nlanla ni iru nkan bẹ ẹ ti wulo, kii ṣe ni igberiko."
" O sọ pe eyi yoo si waye ni gbagede ileeṣẹ ajọ wọn wa to wa lẹyin ile itaja Shoprite, ni Ikeja.
Ipo keji lapapọ ni wọn gbe ninu ẹlẹekejila idije ilẹ Adulawọ ọhun ni Rabat ni Morocco.
olubori ninu eto idibo lati lọ sile ẹjọ.
Iye àwọn ọmọ Lefi tí ó kó jọ láti inú ìdílé kọ̀ọ̀kan nìwọ̀nyí: láti inú ìdílé Kohati: ọgọfa (120) ọkunrin, Urieli ni olórí wọn; 
Ni bayii, iko agbaboolu orile-ede méjídínláàdọ́ta ni yoo maa kopa fun igba akoko ninu idije boolu agbaye.
Wọn ni ẹni ọdun mẹtadinlogun si mẹẹdọgbọn nikan lo ni anfani lati kopa ninu eto naa.
Nígbà tí àwọn tí kì í ṣe Juu gbọ́, inú wọn dùn.
O tun ni iru apero yii ko tilẹ nilo lasiko yii bikoṣe pe ki ijọba ṣe ohun ti awọn ọdọ Naijiria n ja fun.
àgbèrè, ojúkòkòrò, ìwà ìkà, ẹ̀tàn, ìwà wọ̀bìà, owú jíjẹ, ọ̀rọ̀ ìṣáátá, ìwà ìgbéraga, ìwà òmùgọ̀.
 látàrí èyí , ilẹ ̀ austria-hungary kéde ogun lé serbia lórí ní ọjọ ́ kejìdínlọ ́ gbọ ̀ n osù kẹjọ ọdún 1914 [ 28 / 8 / 1914 ] .
Ekun Ila-oorun,Ariwa– Akowe agba,igbakeji akowe agba (NE),olori awon odo, igbakeji amojuto iwe owo.
Ẹ fún wa ní akọ mààlúù meji, kí àwọn wolii Baali mú ọ̀kan, kí wọ́n pa á, kí wọ́n sì gé e kéékèèké.
Àbíìbá: Ọmọ tí a bí lẹ́yìn ikú baba rẹ̀, pàápàá bí ó bá pẹ́ díẹ̀ tí baba rẹ̀ ti kú kí a tó bi i
Azikwe kawe ni iiẹ Amẹrika ni Fasiti Columbia, Fasiti Pennsylvania ati Faisiti Howard.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ sí: 'Àwọn èèyànì ń fi orúkọ mi lu àwọn obinrin ní jìbìtì' Ǹjẹ́ o mọ̀ pé Baba Sala ló kọ́ Sunny Ade nísẹ́?
AFCON 2019: Idíje Egypt ati Zimbabwe, ọ̀rọ̀ kọ sísọ
Gbogbo àwọn olóyè ní ẹnu ọ̀nà ààfin ọba a sì máa foríbalẹ̀ láti bu ọlá fún Hamani, gẹ́gẹ́ bí àṣẹ ọba, ṣugbọn Modekai kò jẹ́ foríbalẹ̀ kí ó bu ọlá fún Hamani.
Ẹni ọdun mejilelogun ọhun bori awọn eeyan mejila ọtọtọ nibi idije arẹwa afin akọkọ ti wọn se lati din oju yẹpẹrẹ ti awọn eeyan n fi n wo awọn afin ku.
Aládǔgbò wa kan tí í ṣe ọ̀rẹ́ ìyá mi pàtàkì ni ó wá kó wa lọ sí ilé rẹ̀, tí ó fún wa ní àmàlà àti ewédú jẹ.
Ǹjẹ́ mo kí yín lórúkọ àwọn ẹgbẹ mi, àwọn akíkanjú ènìyàn ti ń lọ sí òkè Ìrònú ó dìgbà o, bí ikú bá pa wá, kí ẹ ṣe òkú wa dáadáa, kí ẹ ṣe òkú wa bí òkú ọlọ̀lá, kí ẹ ṣe ọ̀fọ̀ wa bí ọ̀fọ̀ ènìyàn pàtàkì, kí ẹ má sì ṣe jẹ́ kí nǹkan ìwọ̀í dé sàkání ohun ìní wa – ó dìgbà o.
wo àwọn nọ́mba ọlọ́pàá tí o lé pé láti mọ ọ̀nà àbáyọ Wọ́n kí irún Jimọ àkọ́kọ́ ní Hagai Sophia lẹ́yìn ọdún 85 ní Turkey Ẹwẹ, eeyan 16,948 lo ti ri iwosan gba ti wọn si ti ja ajabọ lọwọ ajakalẹ arun naa.
Nígbà náà ni àwọn ọ̀dọ́ aguntan yóo máa jẹ oko ninu pápá oko wọnàwọn àgbò ati ewúrẹ́ yóo sì máa jẹko ninu ahoro wọn.
 Lara awọn ohun ti awọn agbarijọpọ ẹgbẹ osisẹ naa tun n beere fun, ni owo osu kejila fawọn osisẹ ijọba ibilẹ ati ajọ Subeb."
Bí gbogbo ara rẹ̀ patapata bá ti di funfun, ó di mímọ́.
Sanwo-Olu, Jimi Agbaje yọ kúrò nínú ìfọ̀rọ̀wérọ̀ ìtagbangba BBC ní Eko Àwọn àwòrán ẹ̀yìn ìtàgé níbi ìpàdé ìfọ̀rọ̀wérọ̀ BBC Yorùbá l'Eko Ṣé INEC yóò tún ìwé ìdìbò tẹ̀ nítorí Banky W?
Ó kọjá nínú igbó, òórùn gba ‘gbó kankan;
Wọ́n tẹ̀dó sí òdìkejì àwọn eniyan wọn.
 Àwọn ohun ìgbàlódé tí ó wà ní ilé ìtura yìí maa ń jẹ ́ kí àwọn ènìyàn láànfàní sí àwọn ilé iṣẹ ́ ńláńla .
Ọmọbìnrin ìbejì, ọmọ ọdún mẹẹdogun naa ku ni Kumasi Eyi kii si se igba akọkọ ti irufẹ ìṣẹlẹ bẹẹ yóò wáyé ni orílèèdè Ghana.
Yatọ si iwadii lori ọrọ SARS igbimọ naa yoo tọ pinipin iṣẹlẹ to waye ni Lekki ni ilu Eko nibi tawọn eeyan ti padanu ẹmi wọn.
Àwọn onímọ̀ ọpọlọ ní to bá gbé ìgbésẹ̀ yìí, aṣeyege dájú ní ìdánwò
Laipẹ yi ni Covid-19 mu Kọmisana feto ilera ipinlẹ Ondo, Dokita Wahab Adegbenro lọ.
Ẹwẹ lonii idaji iye awọn to wa ni orilẹede naa lo nira fun lati ri ounjẹ jẹ, ọwọn gogo to tun wa ba ọrọ aje wọn jẹ ni o le lọdun mẹwaa sẹyin.
Wọ́n lè jẹ́ iranṣẹ ninu ibi mímọ́ mi, wọ́n lè máa ṣe alákòóso àwọn ẹnu ọ̀nà tẹmpili, wọ́n lè máa ṣiṣẹ́ ninu tẹmpili, wọ́n lè máa pa ẹran ẹbọ sísun ati ẹran ẹbọ àwọn eniyan, wọ́n lè máa ṣe iranṣẹ fún àwọn eniyan.
COMOROS: O le rin irin ajo lọ si orilẹ ede yii lai gba iwe aṣẹ irinna ṣugbọn ti o le ri iwe naa gba ni aadọta dọla.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Lagos traffic: Ohun márùn ún tó ń fa súnkẹrẹ-fàkẹrẹ nílùú Eko Aletilapa awakọ àti iwa tani-o-mu-mi: Ọpọ igba ti sunkẹrẹ fakẹrẹ ba wa loju popo ni ipinlẹ Eko lo maa n jẹ afọwọfa awọn awakọ.
O wa ran awon akegbe re leti ofin   abala kẹ́tàlélógójì ti odun  2015 ti atunse wa lori re, pe, ti ile- igbimo asofin agba ko ba gba oruko awon eniyan naa wole, yoo dekun ise ti o ye ki ile- ifowopamo ti ijoba apapo na maa se ku.
Oluranlowo aare fun iroyin ati ikede,Femi Adesina lo gbe atejade yii sita niluu Abuja.
Eliṣa dé sí Giligali nígbà tí ìyàn wà ní ilẹ̀ náà.
Àwọn ọmọ ogun Filistini jà fitafita, wọ́n ṣẹgun Israẹli, olukuluku àwọn ọmọ Israẹli sì sá pada lọ sí ilé rẹ̀, ọpọlọpọ ló kú ninu wọn.
Nkan tí a mọ̀ nìyíì Ariwo lásán ni Dádì àti Mọ́mì rò pé mó ń fi ike pa tẹ́lẹ̀, ṣùgbọ́n ó ti sọ mi di èèyàn ńlá báyìí Mo ti kúrò ní ààfin Oyo, kí ìròyìn tó ò jáde pé èmi àti Wasiu Ayinde n fẹ́ ara wa - Olori Badirat Kìí ṣe gbogbo èèyàn ló lè máa jẹ irú mi- Adebola, Iya Adigun onírú ìgbàlódé fárígá Ara mi rẹwà ló jẹ́ kí n máa ṣí ara sílẹ̀- Victoria Kolawole Ìwà ìbàjẹ̀ bíi olé jíjà, ìjínigbé àti rìbá gbígbà ní Okediji fi ṣàpèjúwe ǹkan tó ń ṣẹlẹ̀ ní Nàìjíríà Wo oríṣìí oúnjẹ márùn ún tó lè dẹ́kun ikùn yíyọ àti ara àsanjù Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí 3 sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 2:23 Fídíò, Water Generator: Ó leè ṣiṣẹ fún wákàtí mẹfà, kó tó sinmi, Duration 2,2310 Òkùdu 2020 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
Gbogbo àwọn olùṣọ́nà tí wọ́n yàn láti máa ṣọ́ ẹnu ọ̀nà àbáwọlé jẹ́ igba ó lé mejila (212).
"o ni iyẹn bi tirela ko ba gba aarin wa""."
Wayii o, Iko agbaboolu Tottenham yoo maa gbalejo Ajax ni papa isere Spurs lorile-ede England lati mo iko ti yoo lo koju Liverpool Nipele keyin idije  UEFA Champions  League.
Ṣugbọn obinrin tí ó bá ń gbadura tabi tí ó bá ń waasu láì bo orí rẹ̀ fi àbùkù kan orí rẹ̀.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù South Africa: Ìyàtọ̀ tó wà láàrin ìṣesí Nàìjíríà àti South Africa Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ South Africa: Ìyàtọ̀ tó wà láàrin ìṣesí Nàìjíríà àti South Africa 17 Ògún 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 8 Òkùdu 2020 Wọn idalu ni iṣelu, bẹẹ gẹgẹ lọrọ ti ri pẹlu iyatọ to wa laarin aṣa ilẹ Naijiria ati ti orilẹede South Africa.
Bi i ti Obaseki, Ganduje sabẹwo si Aarẹ Buhari lati petu si aawọ laarin oun ati Gomina Ganduje sugbọn pabo lo ja si.
Kò sí Ààrẹ tàbí Gómìnà tó lè dá ìfẹ̀họ́núhàn àwọn Nàìjíríà lórí #EndSARS dúró- Monday Ubani Ẹ wo èrò bìbà níbi ìwọ́de #EndSARS ní ìlú Ibadan Ìwọ́de 'End SARS' lè tan àjàkálẹ̀ arùn coronavirus lẹ́ẹ̀kejì ní Nàìjíríà- Ọjọ̀gbọ́n Faduyile Mọ̀ sí i nípa díẹ̀ lára àwọn èèyàn tí ikú wọn 'láti ọwọ́ ọlọ́pàá' milẹ̀ tìtì ní Nàìjíríà Lara ohun ti ipade naa ni ki wọn ṣe ni kiakia lẹyin ti ileeṣẹ ọlọpaa tu SARS ka ni: Mimu opin ba lilo ipa lati koju awọn oluwọde Titu gbogbo awọn ti ọlọpaa ba mu lori iwọde silẹ ni kiakia Ṣiṣi oju opo ibaraẹnisọrọ laarin ọlọpaa ati ara ilu ki wọn ba le ni igbagbọ ninu wọn.
Bi ọrọ yi ti ṣe n ja rainrain la ba ni ki a kan si oju opo ajọ naa lati mọ pato itunmọ ati iyatọ to wa laarin awọn ọrọ bi NIN,nọmba idanimọ ati E-Card to jẹ kaadi idanimọ ti ajọ naa n fun awọn eeyan.
 Àwọn tí ọwọ rẹ ̀ sì tẹ ̀ , wọ ́ n mọ wọ ́ n mọ ́ odi láàyè ni ìdí nìyẹn tí wọ ́ n fi ń ki àwọn ọmọ Òkè-Òpó ní oríkì-.
Nítorí náà, ẹnikẹ́ni tí ó bá tijú èmi ati ọ̀rọ̀ mi ní àkókò burúkú yìí, tí àwọn eniyan kò ka nǹkan Ọlọrun sí, Ọmọ-Eniyan yóo tijú rẹ̀ nígbà tí ó bá dé ninu ògo Baba rẹ̀ pẹlu àwọn angẹli mímọ́.
Lẹ́yìn náà, ó mú mi wá sí ẹnu ọ̀nà tí ó kọjú sí ìhà ìlà oòrùn.
Majeobaje: Gómìnà, ẹ gbé owó ńlá fún Amotekun kó le dábírà lẹ́ka ètò ààbò
Bẹẹ ba gbagbe, nibi ipade pajawiri ti aarẹ se pẹlu ẹgbẹ oselu rẹ, APC, lo ti kede pe ẹnikẹni to ba ji apoti ibo gbe lasiko eto idibo to n bọ, yoo fi ẹmi ara rẹ di nitori ijọba ti pasẹ fawọn osisẹ agbofinro lati gbe igbesẹ to yẹ.
33 Àti pé òṣì ni ìwọ yíò gbà bí ìwọ kò bá ka àwọn ìmọràn wọ̀nyìí sí, bẹ́ẹ̀ni, àní ìparun tìrẹ àti ohun ìní rẹ.
phasianidae jẹ ́ àwọn ẹyẹ tí ó ń gbé inú ilẹ ̀ bi àwọn ẹyẹ àparò , ẹye ìgà , adìyẹ igbó , àwọn adìyẹ , ẹyẹ bí adìyẹ awó , àti ẹyẹ pòpòndò .
tabi nígbà tí ọkunrin kan bá ń ṣiyèméjì nípa ìdúró iyawo rẹ̀, ọkunrin náà yóo mú iyawo rẹ̀ wá siwaju OLÚWA, alufaa yóo sì ṣe gbogbo ohun tí mo pa láṣẹ yìí.
"Wasiu Ayinde funra rẹ gan ti n bẹ mi, to si ti pe mi pe, ki n ranti pe oun ni ẹgbọn oun.
tun salaye akitiyan ijoba rẹ lati fopin si eleyii.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù May 29 Inauguration: Minista mẹ́fà tí kò tẹ́ àwọ ènìyàn lọ́rùn 25 Èbibi 2019 Àkọlé àwòrán, ẹ ko gbiyanju tó ni saa kinni Buhari loju wa Aarẹ Buhari to n tukọ Naijiria lati 2015 ti ṣeto idagbere fawọn minista ti wọn jọ ṣiṣẹ.
John McCain to fi aye silẹ ni Ọjọ Satide, Osu Kẹjọ, ọdun 2018 ni aisan jẹjẹrẹ ọpọlọ ba finra fun ọpọlọpọ ọdun.
Wọ́n ń yọ iná, ati èéfín ati imí-ọjọ́ lẹ́nu.
Ilaka wa rawọ ẹbẹ sawọn araalu lati maa ba isẹ oojọ wọn lọ pẹlu alaafia laisi ifoya kankan, pẹlu afikun pe ijọba ipinlẹ Ọyọ ti gba akoso awọn ibudokọ gbogbo yika ipinlẹ Ọyọ, ti eegun awọn asaaju ẹgbẹ ọlọkọ ero ko si gbọdọ sẹ mọ nibẹ.
Bí ó bá jẹ́ pé OLUWA ni ó sọ fún un pé kí ó máa ṣépè lé mi, ta ló ní ẹ̀tọ́ láti bèèrè pé, kí ló dé tí ó fi ń ṣe bẹ́ẹ̀?
Ṣajẹ tó mókè, àwọn ènìyàn gbé e gbà lọ́wọ́ ara wọn
Mo ṣe bí OLUWA ti pàṣẹ fún mi.
Chacha Mwita to da ejo naa so pe Miguna kii se omo orile
Ọdun díẹ̀ sẹ́yìn ní o wá di pe àwọn eniyan n ku tabi ki wan yarọ nítori àìsàn rọmọ́lápa rọ́mọ́lẹ́sẹ̀, sùgbọ́n níbayii ọ̀rs náà ti di afiẹyin ti eegun fisọ.
Ó pàṣẹ fún Hilikaya, Ahikamu, ọmọ Ṣafani, Abidoni, ọmọ Mika, ati Ṣafani, akọ̀wé, ati Asaya, iranṣẹ ọba, pé, 
Ọjọ́ náà jẹ́ àmì ayérayé tí ó wà láàrin èmi ati àwọn eniyan Israẹli, pé ọjọ́ mẹfa ni èmi Ọlọrun fi dá ọ̀run ati ayé, ati pé ní ọjọ́ keje, mo dáwọ́ iṣẹ́ ṣíṣe dúró, mo sì sinmi.
O rọ awọn eeyan ipinlẹ Ọṣun lati tuyaya jade lọjọ kejilelogun oṣu kẹẹsan ọdun yii, ki wọn si fi ibo wọn le ijọba ajigbese kuro ni ipinlẹ Ọṣun.
“Ṣugbọn ẹ̀yin fúnra yín, ẹ kíyèsára.
Ghana f'ofin de gbogbo ọ̀rọ̀ eré bọ́ọ̀lù torí rìbá lásìko yìí
4 Ẹrẹ̀nà 2019 Oríṣun àwòrán, Kamaru Usman Àkọlé àwòrán, Ọmọ bibi ilu Benin ni Kamaru Usman Orukọ Kamaru Usman lo gba ẹnu awọn ololufẹ ẹṣẹ kikan bayii lẹyin to di ọmọ ilẹ Afirika akọkọ lati gba igbanu ẹyẹ fun ẹṣẹ kikan ninu idije Ultimate Fighting Championship.
Lẹyin ti awọn agbofinro fi si ta pe wọn doola ẹmi awọn akẹkọọ ABU mẹta ti awọn ajinigbe ji gbe lọna Kaduna ni iroyin jade pe irọ ni pé awọn ọlọpaa lo kan kede riri wọn ni.
Seyi Makinde, fún mi ní ₦156m lórí iṣẹ́ ọpọlọ mi to lò láì tọ́ - Agbaṣẹ́ṣe Ki lo ti ṣẹlẹ sẹyin ni ariwa?
O ti ba gbajugbaja oṣere bii Odunlade ADEKOLA, Tunde Usman, Kelvin Ikeduba ati Femi Adebayo laarin ọpọ awọn osere miran.
Ó wá ń rò ninu ọkàn rẹ̀ pé, ‘Kí ni ǹ bá ṣe o, nítorí n kò rí ibi kó ìkórè oko mi pamọ́ sí?
kan, ti won pe oruko re ni ‘Alhaji Hamisu.
asoju-sofin, ogbeni Yakubu Dogara ti ro awon omo orile-ede Naijiria lati panupo
O ni nibi ti awọn duro si yii naa lawọn ti n sọ fawọn ọkọ miran to n bọ pe ki wọn mase lọ siwaju nitori ewu to wa lọna.
Ẹni ọmọ ọdun méjìdínlogun ti fẹsùn kan IAAF lóri ìpínnu rẹ̀ láti mú àdínku ba okún nínú àwọn obinrin to n sáre fún eré ijé to bá ti jú irínwo mítà lọ.
Pẹlu esi ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ yí, àmì méjì ló kù kí Chelsea fi ba Tottenham.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Alexis Sanchez: Man Utd faramọ asorọ ẹwọn lori jibiti owo ori 7 Èrèlè 2018 Àkọlé àwòrán, Santes jẹ ọkan lara awọn agbabọọlu to n gbowo julọ ti yoo jin sọfin aisan owo ori Agbabọọlu fun ikọ Barcelona tẹlẹ naa lo nkoju igbẹjọ lorilẹede Spain nitori bo se gbokiti ipakọ si owo ori sisan eyi toto miliọnu kan Euro.
Wike, to jẹ oludije fun ipo
Lionel Messi gba ami-ayo meji wole, besini O se iranwo ami-ayo kan fun akegbe re Ousmane Dembele, lati fagbahan Chelsea pelu ami-ayo meta sodo(3-0), lojoRu(Wednesday).
” OLUWA Ọlọrun ni ó sọ bẹ́ẹ̀.
Àwọn tí ẹ ti mọ̀, tí ẹ sì ti ń gbọ́ nípa wọn pé, ‘Ta ni ó lè dúró níwájú àwọn ìran Anaki?
N ò kìí ṣe dókítà tí yóò yan ògùn fún ẹnikẹ́ni, n kò lo ògùn fún Coronavirus-Makinde ''O lè kó coronavirus nípa ṣíṣe eré ìdárayá, ẹ gbélé yín lásìkò yìí,''- onímọ̀ ètò ìlera Kí ló mú àwọn aládùúgbò Mọ́ṣáláṣí Alhaja kọlu àwọn ọlọ́ọpàá?
O ni Ninu ọdun 2018, Niyi dele lọjọ kan, lo ba sọ fun mi pe wọn riran si oun pe oun gbọdọ ni ibalopọ fun ọjọ meje gbako, lai fi pa ọjọ kankan jẹ."
"Isẹ lila oju ọna Metroline ti Buhari wọgile naa lo jẹ adanu fawọn eeyan ipinlẹ Eko, eyi towo rẹ to miliọnu lọna mejidinlọgọrin Dọla.
Amasa kú lẹsẹkẹsẹ, láì jẹ́ pé Joabu tún gún un ní idà lẹẹkeji.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Dino Melaye ní ọlọ́pàá ti fẹ́ wó ilẹ̀kùn ilé mi lulẹ̀ báyìí o Ṣé ó tọ̀nà kí obìnrin máa bímọ sílé?
Lẹyin o rẹyin, atawọn ti wọn fi iwe pe, atawọn ti wọn ko fi iwe pe lo kọ lati yọju sibi ipade naa.
Ògo Lẹbanoni yóo di tìrẹati iyì Kamẹli ati ti Ṣaroni.
Ó ní kí wọn má gbọ́ ohun tí ó ń sọ rárá, nítorí pé kò sí oriṣa orílẹ̀-èdè kan tí ó tó gba àwọn eniyan rẹ̀ lọ́wọ́ òun tabi lọ́wọ́ àwọn baba òun, kí á má wá sọ pé Ọlọrun tiwọn yóo gbà wọ́n lọ́wọ́ òun.
Gbogbo eniyan ni yóo kórìíra yín nítorí orúkọ mi.
Ó bá dá wọn lóhùn pé: “Heberu ni mí, ẹ̀rù OLUWA ni ó bà mí, àní Ọlọrun ọ̀run, tí ó dá òkun ati ilẹ̀ gbígbẹ.
Àjọ Elétò ìdìbò INEC ti sọ̀rọ̀ lórí iná tó jó àwọn káàdì ìdìbò ní Ondo Ajọ to n ri si eto idibo lorilẹ-ede Naijiria, INEC, ti sọ pe Ina to ṣẹyọ ni ọfiisi rẹ to wa ni ilu Akure ko ni ṣakoba fun eto idibo to n bọ ni ipinlẹ ọhun loṣu kẹwaa ọdun yii.
Ozor Àkọlé àwòrán, Wàhálà ti wáyé lórí ọ̀rọ̀ ẹ̀kúnwó oṣù tuntun fún òṣìsẹ́ láàárín ìjọba àti àwọn adarí òṣìṣẹ́ Aarẹ Muhammadu ti ni oun yoo gbe igbimọ kalẹ lori eto owo oṣu tuntun fawọn oṣiṣẹ lorilẹede Naijiria.
Àkókò tí a bá sì ní í inú ayé yìí, mo bẹ̀ yín ẹ má ṣáìjẹ́ kí á lò ó dáadáa: kí á lò ó pẹ̀lú ayọ̀, kí a lò ó pẹ̀lú ẹ̀rín kí á sì fi inú dídùn bo ìbànújẹ́ mọ́lẹ̀ batakun.
Ẹni ti èèyàn tó sún mọ́ ṣẹ̀ṣẹ̀ kú fún, ìkọ̀sílẹ̀ nínú ìgbéyàwó, ẹni to ni àìsàn kan to buru, ẹni ti iṣẹ bọ́ lọ́wọ́ rẹ̀, tàbi tó ni ìṣòro owó ńla kan yóò fẹ́ pa ara rẹ̀.
Wọn gba pe eyi ko ṣẹyin iwa ijẹgaba ti awọn kan fẹ tun maa jẹ le iran to ku lori bii amunisin ni eyi ti ko le ṣeeṣe.
Iroyin lati orilẹ-ede Amẹrika ni, awọn okunrin meji ọhun ni wọn jẹ ọmọ ogun ilẹ Amẹrika.
Àkọlé àwòrán, Àdá, àáké, ati fila pupa jẹ́ diẹ lara ami idanimọ awọn ẹgbẹ okunkun ni Naijiria Ara adugbo naa kan to ba awọn akọroyin sọrọ, ṣugbọn ti ko fẹ ki wọn darukọ rẹ sọ pe, ọkunrin kan t'awọn ko mọ orukọ rẹ naa tun ku lọjọ ìṣẹgun lẹyin t'awọn agbofinro pẹtu sí aawọ náà tan.
Nigba miran si ni yii, aarẹ Trump ti sọ wi pe oju ọjọ ṣe pataki si oun.
Wéré tí ó wí báyìí, ṣe ni àbúrò rẹ̀ rá mọ́ wa lójú, nígbà tí o sì fi máa tó ìsẹ́jú mẹ́ta ṣe ni mo rí i tí o ń fò bọ̀ lófurufú tí ó gbé fìlàsayépọ̀ lé èjìká, tí ó gbé e kalẹ̀ lọdọ wa.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ìsọ̀ oníwe ìròyìn àtàwọn tó ń kà a lọ́fẹ̀ẹ́ Oríṣun àwòrán, AFP Àkọlé àwòrán, Ogbontarigi osere ọmọ South Africa yii n fayọ ya fọto nipasẹ odo Gbajugbaja oṣere, Candice Swanepoel to wa lati orilẹ-ede South Africa lo duro ya fọto ninu omi yii.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Biafra at 51: Ikọ̀ Boko Haram, ìbò June 12, ìwọ́de EndSARS wà lára ìṣẹ̀lẹ̀ tí kò bá sọ Nàíjíríà sójú ogun 1 Ọ̀wàrà 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 15 Sẹ́rẹ́ 2021 Oríṣun àwòrán, Getty Images Orilẹede Naijiria jẹ orilẹede to n san fun wara ati oyin, ti ọba oke si fi ọpọ ohun alumọọni jinki rẹ, ki ogun abẹle to wọle de lọdun 1967.
Yóo wá dá wọn lóhùn pé, ‘Mo fẹ́ kí ẹ mọ̀ dájúdájú pé, níwọ̀n ìgbà tí ẹ kò ti ṣe é fún ọ̀kan ninu àwọn tí ó kéré jùlọ wọnyi, èmi ni ẹ kò ṣe é fún.
Bẹẹni ẹnu ko tun sin lara Wenger saaju ifẹsẹwọnsẹ Arsenal pẹlu AC Milan eyiti yoo waye lọjọbọ ninu idije Europa League.
Èdè Yorùbá ti di kíkọsílẹ̀ ó sì jẹ́ ọ̀kan nínú àwọn aṣíwájú èdè káàkiri Afirika nípa kíkọsílẹ̀.
Kii ṣe nilẹ Afirika nikan ni wọn ti ma n fi oju buruku wo o, bakan naa ni ọrọ ri ni awọn apa ibikan nilẹ India ati Asia.
Àkúntúnkú, ìgbà márùn ún rè é tí Shekau kú tí wọ́n ní kò kú mọ Olóòtú ìjọba Gẹ̀ẹ́sì yan ọmọ Yorùbá ní Mínísítà Iléẹjọ́ fún Seyi Makinde láṣẹ láti yan adelé alága ìbílẹ̀ ní ìpínlẹ̀ Oyo Ọkùnrin méjì, obìnrin mẹ́ta jáde láyé ní Mecca lásìkò Hajj 2019 - NAHCON Opo awon omo Naijiria lo n fokan si i pe aare yoo se ifilole awon omo igbimo re lojo Isegun lasiko ipade awon alase ijoba.
Lọrọ awọn akọṣẹmọṣẹ, bi ara rẹ ba ti gbona ju iwọn onka igbona ara to to metadinlogun celcius tabi ọgọrun Farenheit lọ?
Kanu jẹ asojú UNICEF, asoju Startimes, bákan náà lo gba àmì ẹ̀yẹ OON.
Àjẹsára ikọ ́ ọfe jẹ ̀ àjẹsára tí ń dáàbò bo ni lọ ́ wọ ́ ikọ ́ ọfe .
Bakan naa ni awọn ẹgbẹ kan, bi ẹgbẹ awọn dokita sọ pe o lewu lati ṣi awọn ile iwe pada lasiko naa.
Sẹẹli ti ko ji pepe mọ naa le ṣe akoba fun awọn sẹli to ku, o si le fa a ki gbogbo ara o wu.
ORÚKỌ tí a ń sọ àti àwọn ìdí tí a fi n sọ wón (orúkọ àmútorúnwá).
Nítorí pé ọjọ́ meje ló kù tí n óo bẹ̀rẹ̀ sí rọ òjò sórí ilẹ̀ fún ogoji ọjọ́ tọ̀sán-tòru, gbogbo ẹ̀dá alààyè tí mo dá ni yóo sì parun lórí ilẹ̀ ayé.
Ohun tí mò ń sọ ni pé àwọn nǹkan tí àwọn abọ̀rìṣà fi ń rúbọ, ẹ̀mí burúkú ni wọ́n fi ń rúbọ sí, kì í ṣe Ọlọrun.
O tesiwaju pe laarin odun meta
Àwọn náà wá sọ fún un pé, “Wò ó ná, arakunrin, ṣé o mọ̀ pé ẹgbẹẹgbẹrun ni àwọn Juu tí ó gba Jesu gbọ́, tí gbogbo wọn sì ní ìtara sí Òfin Mose.
Awon oluko, igbakeji oga agba ile eko naa mejeeji, Ali Musa Mabu ati Abdullahi Sule Lampo; ati oga agba ile eko ohun, Adama Abdulkarim pelu adari eka amojuto oro ile iwe nipinle Yobe, Musa Abdulsalam, naa wo akosile oruko naa wo pe o pe.
Rachael Oniga: Oríṣun àwòrán, Rachael Oniga Bakan naa, agba ọjẹ oṣere tiata ni ede Yoruba ati oyinbo, Racheal Oniga jẹ ọmọ bibi ipinlẹ Delta.
Adajọ Umar Abubakar ni yoo lewaju awọn adajọ meji mii ti yoo gbẹjọ ọhun bẹrẹ lati ọjọ Kẹjọ oṣu Kejila ọdun 2020.
Nigba to n ba BBC Yoruba sọrọ lati fesi si ohun ti Fayose sọ naa, Bode George ni aigbọn ati aimọ lo n se Fayose nitori ko yẹ ko jẹ oun lo yẹ ki Fayose ri fin.
Ni ipari mo fe ki obi, alagbato ati awon osise eleto aabo dide si ise ti won naa nitori ojo iwaju rere ni awon ewe Naijiria ni”Aare Buhari dupe lowo awon agbofinro gbogbo fun pipa ofin fun awon ewe ti a la kale ninu iwe ilana ofin Naijiria todun 1999 to daabo boa won omode ati ominira eto won ti odun 2003.
Ayinde Barrister: Òní ló pé ọdún mẹsan an ti ọba orin jáde láyé
Wo ọkùnrin ẹni ọdún 55 tí wọ́n ká agbárí èèyàn mẹ́rin, àti àwọn ẹ̀yà ara mìí mọ́ lọ́wọ́ ní Ogun Gbọ́yì-sọ̀yí àti ìròyìn èké láti ọ̀dọ̀ àwọn olólùfẹ́ wa ló ṣáábà ma ń da ìgbéyàwó àwọn òṣèré rú- Ọpẹ Ayeola Ǹkan tí ó yẹ ki o mọ̀ nípa Burna Boy Ilé ẹjọ́ dájọ́ ẹgba mẹ́ẹ̀dóògún fún ọ̀daràn tó jí Iphone ní Kaduna Ọlọ́pàá tó dúró yìí gbá mi létí lẹ́ẹ̀mẹrin-Ajẹ́rìí ìwà ipá níwájú ìgbìmọ̀ SARS Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Kegel: Eré ìdárayá tí àwọn onímọ̀ sọ pé ó n fikún adùn ìbálòpọ̀ fún obìnrin, tó tún n fún ọkùnrin ní agbára24 Bélú 2020 10:17 Fídíò, Oba Adedokun Abolarin ti Oke Ila: Ó ya ọ̀pọ̀ tó súnmọ́ mi lẹ́nu bí mo ṣe ń kọ́ àwọn akẹ́kọ̀ọ́ pẹ̀lú ipò Ọba, Duration 10,1723 Bélú 2020 Ooni of Ife: Àwòrán ọmọ mi kọ́ lẹ ń rí lórí ayélujára o, ọmọ ọ mi ń ṣètùtù lọ́wọ́- Ọba Adeyeye Ogunwusi24 Bélú 2020 Ọwọ́ ọlọ́pàá tẹ àwọn méji tó jẹ ẹran ara ọlọ́pàá tí wọ́n pa n'Ibadan24 Bélú 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 3 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 5 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Ikolu ojo-Abameta yii ni igba akoko ti awon ologun naa so pe, won se ni apa gusu Ubari, eyi ti o to edegberin ibuso si apa gusu ilu Tripoli, enu ona ibode orile-ede Libya si orie-ede Algeria.
 Ọ ̀ rò orúkọ náà , tó máa n jé olùkópa , kìí ṣe ÒsÈrÉ tàbí ÀkÓso tí òrò kò bá fún wọn ní irú ipa béè .
Ẹsun ti wọn fi kan an ni wipe o fẹ ba ọmọdebinrin naa ṣe ere ifẹ, to si fi ẹnu ko o ni ẹnu.
Oríṣun àwòrán, Reuters Gomina ipinlẹ Minnesota ni ifẹhọnu han naa ti koja bo ṣe yẹ nitori ọpọlọpọ dukia si ti sọfọ si ifẹhọnu han naa.
Lẹhinnaa, awọn to ni arun naa bẹrẹ si ni pọ si.
 murtala ò lówó sí bí ìfipá-gbà-joba tó mu gorí oyè .
Ṣe àwọn Darandaran ajoji lo n ṣọṣẹ́ ni Naijiria?
Ẹ̀yin gómìnà Yorùbá, ẹ wá ṣàlàyé ìdí tẹ fi ṣèfilọ́lẹ̀ ètò Àmọ̀tẹ́kùn - Iléeṣẹ́ ààrẹ A móyè yìí jẹ.
O se ni laanu wi pe, ibi ti opo awon ololufe boolu afesegba jake-jado agbaye fokan si ninu ifigagbaga iko agbaboolu Liverpool ati Barcelona ninu idije Uefa Champions League ona ko gba be rara.
Lọwọ bayii, ohun gbogbo n lọ leto-leto nilu Ibadan, ti ọfọn kankan ko si fi iru na igba.
Ṣugbọn ko gbọdọ si irinajo laarin ipinlẹ kan si omiran lasiko isede fun awọn arinrinajo loju popo.
CBN: A ń pariwo tó lórí MMM fáwọn ọmọ Nàíjíríà Iṣẹ́ ẹ̀mí ẹ̀tàn ló bàlemi lasiko tí mo sọ àṣọtẹ́lẹ̀-Simeon Ononogbu Mo gbàgbé sùnlọ sìnú ọkọ̀ òfurufú, ẹ̀rù ikú bà mí -Tiff Báwo ni ọkùnrin tí ọlọ́pàá bá òkú rẹ̀ nínú àgbá ní Oyingbo ṣe kú?
Omi bò mí mọ́lẹ̀,mo ní, ‘Mo ti gbé.
Atẹjade naa ni awọn osisẹ ajọ EFCC to wa nilu Eko, lo ya bo ileẹkọ naa, to wa ni ojule Kẹrinla, opopona Animasaun, ladugbo Ojodu-Berger nilu Eko, lasiko ti awọn akẹkọ ileẹkọ naa n gba idanilẹkọ lọwọ.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Lẹyin ọdun mẹrindinlogun ti ijọba ologun fi dari Naijiria,eto iselu alagbada pada lọdun 1999.
kí ó má baà hàn sí àwọn eniyan pé ò ń gbààwẹ̀, àfi sí Baba rẹ tí ó wà ní ìkọ̀kọ̀.
 Wayi o,ile-ise to n ri si eto ibanisoro (Mater Dei Communication Centre) pelu ifowosowopo ajo NOA lo se agbekale eto idanileko naa ti won pe akori re ni:“Eto ilana lenu ise, kopa pataki ninuilosiwaju ati idagbasoke orile-ede.
Ìdí rẹ̀ ni pé kí ibukun Abrahamu lè kan àwọn tí kì í ṣe Juu nípasẹ̀ Kristi Jesu, kí á lè gba ìlérí Ẹ̀mí nípa igbagbọ.
Ọba Akadir wa ni ilu yoo ṣe pade pẹlu awọn agbaagba lati mọ ọna abayọ.
”Àwọn mìíràn ní, “Ó jọ pé òjíṣẹ́ oriṣa àjèjì kan ni!
Kórira mí to ba wù ọ, fẹ́ràn mi tó ba wù ọ, sùgbọ́n lo ọpọlọ ẹ'' ''Báwọ ni mó ṣe ya asìwere tó pẹ̀lú bí ǹkan ṣe ri láti ẹ̀yìn wá, àti gbogbo ǹkan ti mo ti là kọja, ṣe mó fẹ́ di aṣerubani ni, tí maa wá mú ọmọ obinrin lọ de wọn mọlẹ sí inú ilé kan?
Yatọ si awọn ilana tuntun yii, gomina tun kede pe o ti le ni ẹgbẹrun mẹẹdogun eeyan to ti ni coronavirus ni ipinlẹ Eko.
Wọn fikun un wi pe gbogbo awọn ẹsọ alaabo ni o ti fi ọwọ sowọpọ loti ri wi pe awọn adigunjale ati awọn oniwakiwa miran ko ni ba dukia awọn eniyan ati ọrọ aje orilẹ-ede Naijiria jẹ.
Á dá wọn lọ́wọ́ kọ́ gẹ́gẹ́ bí ọba sí ará ìlú
Arabinrin Temitọpẹ Adeṣegun to jẹ igbakeji oludari ajọ HAI lo sọrọ fun Ọọnirisa to wọ ìléèdí ọlọjọ meje fun tọdun 2018.
Ọkan gboogi lara awọn alatako ẹgbẹ oselu APC ati Aarẹ Muhammadu Buhari ti fi lede pe ẹgbẹ oselu to wa ni ijọba ji asia Next Level"" ti wọn n lo fun ipolongo idibo sipo aarẹ lọdun 2019."
Atẹjade ọhun tun sọ pe Odumosu ṣeleri lati ran ileeṣẹ ọlọpaa Ogun lọwọ ninu ṣiṣewadii iṣẹlẹ to fa sababii riri ọpa aṣẹ ọhun.
Oríṣun àwòrán, @TalbertSwan Àkọlé àwòrán, Igba meje ni wọn yinbọn lu Jacob Blake ni Kenosha O tun fẹran ibọn lọpọlọ nitori bo ṣe maa n fi aworan ibọn soju opo ikansiraẹni rẹ lori ayelujara.
' Siwaju si, ẹgbẹ naa wipe fun ọdun mẹrin ti aarẹ Buhari fi wa lori aleefa, ko si ipa idagbasoke kakan ni agbegbe Niger Delta.
Ajọ EFCC fẹsun kan Fayose pe, o gba owo to le ni biliọnu kan naira lọwọ oluranlọwọ ijọba lori eto aabo, ajagun fẹyinti Sambo Dasuki.
Desalegn je omo-egbe oselu Ethiopian People’s Democratic Movement (SEPDM), nigba ti olori ijoba ti o di ologbe Meles Zenawi je omo egbe oselu Tigrayan People’s Liberation Front (TPLF), apapo egbe oselu ohun ni gbogbo omo ile-igbimo asofin orile-ede naa , orile-ede Ethiopia yoo seto idibo ni odun 2020 Ronke Osundiya.
 orin náà ní ẹjẹ ́ wọ ̀ n-ọ ́ n bí a bá fẹ ́ kó dùn , kó dún , kó sì pẹ ́ lọ ́ kàn ẹni .
Gege bi, ogbeni Ali Kolo, ti o oun je olode lagbegbe naa soro ohun di mimo pe, awon meje miiran farapa yanayana ti o fi mo omo kekere kan.
Tí ó rí bí ibùgbé àwọn ọ̀dọ́ kinniun?
Ẹ óo fi ojú ara yín rí i ẹ óo sì sọ pé, “OLUWA tóbi lọ́ba, kódà títí dé ilẹ̀ tí kì í ṣe ilẹ̀ Israẹli!
Bi a ko ba gbagbe awọn alaga ẹgbẹ naa ni ipinlẹ Edo, ti o jẹ ipinlẹ Oshiomole ti sọ pe, awọn ko ni igbagbọ ninu iṣakoso Oshiomole gẹgẹ bi alaga ẹgbẹ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Osun Osogbo Shrine Porn Video: Wo ìgbà méjì láàrín ọdún méjì tí ojúbọ Osun Osogbo ti mú ìròyìn àìtọ́ lọ́wọ́ 14 Owewe 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 16 Owewe 2020 Oríṣun àwòrán, @kingtblakhoc/twitter Àkọlé àwòrán, Tobi Jolaosho 'King Tblak' ni awọn kan gbagbọ pe o pilẹ sinima ibalopọ ni Naijiria Ni aipẹ yii ni iroyin kan jade pe awọn ọdọ kan lọ ṣe aṣemaṣe ni ojubọ Oṣun oṣogbo ni ilu Osogbo.
Ni ti obinrin, o ṣalaye pe bi irun ti wọn maa n ṣe ba ti le ju to si yọ lati ibi gbongbo rẹ, obirin naa ti di apari niyẹ ti ko si si ohun ti onimọ iṣegun oyinbo kankan le ṣe si i.
Kọmisana feto ilera nipinlẹ Ondo naa, Dokita Wahab Adegbenro la tun gbọ pe o ṣalaisi si ibudo ti wọn ti n tọju awọn alarun Coronavirus nilu Akure.
Àwọn tí wọn ń gbé Nẹgẹbu yóo gba òkè Edomu,àwọn tí wọ́n wà ní ẹsẹ̀ Ṣefelayóo gba ilẹ̀ àwọn ará Filistia;wọn yóo gba gbogbo agbègbè Efuraimu ati ilẹ̀ Samaria,àwọn ará Bẹnjamini yóo sì gba ilẹ̀ Gileadi.
Makiri, baba Gileadi, tí ó jẹ́ àkọ́bí Manase ni wọ́n fún ní ilẹ̀ Gileadi ati Baṣani nítorí pé ó jẹ́ akọni ati akikanju eniyan.
Yóo sọ àwọn eniyan di yíyẹ lọ́dọ̀ Oluwa.
Lati tu awọn eniyan ipinlẹ naa lara, ijọba kede pe oun yoo pin oúnjẹ ọ̀fẹ́ fun eniyan rẹ.
Ninu àìlera rẹ ni agbára mi di pípé.
Lai fà ọ̀rọ̀ gùn àwọn ọmọ Ẹkùn gbọ́ igbe Kìnìún, wọn ri ti ó ré kọja, àwọn ọmọ Ẹkùn ti ẹ̀rù ba ti kò ṣe bi iyá wọn ti ṣe ìkìlọ̀, ìjáyà bá wọn, wọ́n sá.
Buruji Kashamu jẹ́ ènìyàn tó nífẹ̀ àráàlú - Gómínà Dapo Abiodun Makinde ni gómìnà, èmi ni igbákejì rẹ̀; kò sí ìjà láàrin wa-Rauf Adeniyan, igbákejì gómìnà ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́ Wo àwọn àìsàn ti ìwọ́ ọmọ tuntun le wòsàn Ipa tí Fathia Balogun kó nínú bí mo ṣe dèèyàn lágbo òṣèré fíìmù Yorùba rèé - Baba Ijesha Tí ẹ ò bá gbàgbé, Lilo to jẹ́ ọ̀rẹ́bìnrin Eric ni wọ́n lé kúro nílé ẹlẹ́gbọ̀n-ọ̀n àgbà lọ́sẹ̀ tó kọja.
Jẹfuta ará Gileadi jẹ́ akikanju jagunjagun, ṣugbọn ọmọ aṣẹ́wó ni; Gileadi ni baba rẹ̀.
Nitori bi awọn ọmọ orilẹ ede Naijiria se n tako igbesẹ ti ile-isẹ ọlọpaa gbe lati sọ pe ki abẹnugan ile igbimọ asọju-sọfin Bukọla Saraki  yọju si agọ wọn, ni awọn ọlọpaa se yi ipinnu wọn pada lọjọ Aje ọsẹ yii.
 “O pon dandan ki awon ipele ijoba gbogbo pese eyawoti ko lere-lori fun awon agbe, latari ati le mu igberu ba ipese ounje lorile-ede Naijiria.
7 4498 Orilẹede Sao Tomẹ́ and Principe 17 8.
kí n lè fara mọ́ ọn péó sàn kí á lọ́ mi lọ́rùn pa,kí n sì lè yan ikúdípò pé kí n wà láàyè.
Bi Yorùbá bá wọ aṣọ ìbílẹ̀ fún òde ojoojúmọ́ tàbi fún ayẹyẹ, wọn ni lati wé gèlè ki imúra lè pé.
Ṣugbọn Isaaki ni Abrahamu kó gbogbo ohun ìní rẹ̀ fún.
Ọlọrun bá Mose sọ̀rọ̀, ó sì pàṣẹ fún un pé kí ó ṣe àgọ́ yìí gẹ́gẹ́ bí àwòrán tí òun ti fihàn án tẹ́lẹ̀.
Lónìí ọjọ́ kọkànlá, oṣù kẹrin sí ọjọ́ kẹtàdínlógún, oṣù kan náà ni ìdánwò àṣewọlé ìwé gíga UTME yóò wáyé jákè jádò Nàìjíríà.
Lórí bóyá igbákejì gómìnà Ondo yóò fipò sílẹ̀ tàbí rárá, ohun tó lu sí wa lọ́wọ́ nìyí Igbakeji gomina ipinlẹ Ondo, Agboola Ajayi ti sọ pe oun ṣi ni igbakeji gomina ipinlẹ naa nitori bi oun ṣe kuro ninu ẹgbẹ oṣelu APC lọ si PDP ko lodi si ofin.
Nigba to yẹ ko sọ pe ni '.
Iroyin fi idi rẹ mulẹ pe awọn ọmọ ẹgbẹ oṣelu PDP fi ẹhonu han niluu Abuja, ti wọn si fi ẹsun kan iṣakoso Aarẹ Muhammadu Buhari pe o fẹ ẹ ba eto oṣelu awaarawa jẹ ni Naijiria nitori eto idibo sipo gomina to waye nipinlẹ Ọṣun, nibiti ẹgbẹ oṣelu APC ti jawe olubori.
Orile-ede Uganda, Rwanda ati orile-ede South Africa ni won ni awon asoju obinrin to poju nile-igbimo asofin nile Africa.
Kí ló dé tí o kò lè wẹ̀ gẹ́gẹ́ bí ó ti wí, kí o sì rí ìwòsàn gbà?
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Action Against Hunger: Ẹgbẹ́ agbésùmọ̀mí ISWAP ṣekú pa àláànú kan 25 Owewe 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Action Against Hunger: Ẹgbẹ́ agbésùmọ̀mí ISWAP ṣekú pa àláànú kan Ẹgbẹ agbesunmọmi Islamic State in West Africa, ISWAP ti pa ọkan lara awọn oṣiṣẹ ẹlẹyinju aanu mẹfa ajọ Action Against Hunger ti wọn mu loṣu Keje ọdun yi.
O ṣalaye pe iwadii si n lọ lọwọ lati mọ ohun to ṣe okunfa iku awọn mejeeji gan an.
Ṣugbọn Josẹfu tẹnumọ́ ọn pé, “Bí mo ti wí gan-an ni ọ̀rọ̀ rí, amí ni yín.
Ẹgbẹgbẹrun eniyan lo ti sọ ẹmi wọn nu nitori arun Coronavirus to bẹ silẹ lorilẹede China, lati Osu Kejila, ọdun 2019.
Bí gbòǹgbò rẹ̀ tilẹ̀ di ògbólógbòó ninu ilẹ̀,tí kùkùté rẹ̀ sì kú,
Ọ̀pọ̀ abánikẹ́dùn ti ṣetán láti yọjú síbi ayẹyẹ ìkẹyìn George Floyd lónìí Oríṣun àwòrán, Getty Images Isin idagbere waye fun George Floyd ni Minneapolis Oríṣun àwòrán, Getty Images Ọpọ awọn abanilkẹdun lo n ṣọfọ George Floyd ni Houstin to n gbe tẹlẹ ko to lọ si Minneapolis ti wọn ti pa.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Àìríṣẹ́ṣe ló mú àwọn ọ̀dọ̀ fẹ̀mí wọn wéwu Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ẹtàn ni àwọn ọ̀rẹ́ fi ń tan èèyàn lọ si Libya pé iṣẹ́ gidi wà níbẹ̀ O fi kun un pe awọn yoo mu adinku ba iye eeyan to n ṣiṣẹ ni ile iṣẹ Naijiria to wa ni orileede Ukraine tori pe ko si owo.
Dán mi wò, o kò ní rí ohun burúkú kan;n kò ní fi ẹnu mi dẹ́ṣẹ̀.
'Pẹ̀lú ìpèníjà ara mi, mo kọ̀ láti ṣagbe' Leprosy Day: 'Kọ̀ńgílá ni mí kí ń tó di adẹ́tẹ̀ ni 1996' ''Kìí bá ṣe Egypt tàbí South Africa, àyà kò fò wá'' Ìdí tí mo fi fẹ́ di Gómìnà Kogi - Dino Melaye Steph ni gbogbo nkan ti awọn dokita ni oun ko le ṣe ni oun pada wa le ṣẹ nitori oun pinnu lọkan oun.
Ifẹhonuhan Lẹkki lori ẹkun owo irinnọ
Ọpọlọpọ awọn ero lati ṣe alaye awọn ipo ti iku ti jésù lori agbelebu ti a ti dabaa nipasẹ awọn onisegun ati awọn ọjọgbọn bibeli .
Dangote kasẹ ọrọ rẹ pẹlu pe ohunn banujẹ nipa wahala gbigbe nkan gba ibode kan si omiran nilẹ Afrika.
Adedeji Shoyebi naa wa nibe lati bojuto eto naa ni gbongan Ile Itura Premier to
"Lọdun 2013 ni awọn kan wa ba mi pe ki n kalọ si orilẹede Russia.
A kò tètè bẹ̀rẹ̀ iṣẹ́ ní ọjọ́ kejì yìí nítorí àwọn àbúrò mi ọkùnrin, ìbátan mi ní ìdí ìyá mi mú ọ̀rọ̀ kékeré kan báyìí wá sí ọ̀dọ̀ mi mo sì tọrọ àyè lọ́wọ́ ọ̀rẹ́ mi náà kí ó jẹ́ kí n dá wọn lóhùn tán.
Oríṣun àwòrán, @ovieali Àkọlé àwòrán, Aworan darandaran Femi Adeshina, to jẹ oludamọran agba fun aarẹ feto iroyin nigba to n ṣalaye fun BBC sọ pe, ọna ati dẹkun wahala laarin agbẹ ati darandaran lawọn ṣe gbe igbimọ kalẹ lori ọrọ yii.
O fikun oro re pe, awon ti sawari irufe ado-oloro yi ti o to oorundinladota niye lodun mejo seyin.
Ileeṣẹ ọlọpaa ni ipinlẹ Ọyọ ti kede pe, arakunrin naa ti sa lọ kuro ni ahamọ awọn ọlọpaa nibẹ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Childbirth in Nigeria: Dokita àti Nọ́ọ̀sì ń fìyà jẹ àwọn alaboyún lásìkò ìbímọ!
Oluwo sọ fun BBC Yoruba pe oun si duro lori ọrọ ti oun sọ pe covid-19 ko le wọ ilẹ Iwo, ṣugbọn oun n lo ibomu nitori ipo olori ti oun wa ni.
 Mó kéré lásìkò náà àwọn òbí mi ǹkan yìí dára fún mi láti ṣe, ìṣòro pọ̀ gàn ni lágbàyé báyìí tó yẹ kí a mójú tó"" Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?"
Ó kọ́kọ́ bàmí lẹ́rù ná, ṣùgbọ́n ó tún pamí ní ẹ̀rín nígbà tó múnmi rántí orin tí olóòtú ètò Tiwa’n’tiwa Alàgbà Oyèkúnlé Azeez máa ń kọ lẹ́ẹ̀kọ̀kan.
ni saa keji  ti yoo lo fun ọdun merin
Nítorí ìyìn ni ó yẹ kí n gbà lọ́dọ̀ yín.
”O tesiwaju pe, awon adajọ gbodo mura sile lati se ojuse won bi o se to ati bi o se ye pelu owo ti o ga ju ara lo.
Títí di ìgbà wo ni o óo fi ojú pamọ́ fún mi?
Oríṣun àwòrán, GEMMA PURKISS Àkọlé àwòrán, Awọn ọmọ ijọ naa gbagbọ pe awọn n ja lati ma jẹ ki orilẹ-ede America di ti ẹlẹ́sìn kan ṣoṣo Ati nnkan ti yoo mu ki awọn eeyan ni ominira lati lo agbara okunkun fun ifẹ ara wọn.
- Òǹwòye ìdìbò YIAGA Gẹgẹ bi ohun ti a gbo,awọn akẹkọ ati olukọ ile ẹkọ yoo pada si iṣẹ lọla.
Wọn óo máa gbé ní àìléwu, nítorí yóo di ẹni ńlá jákèjádò gbogbo ayé.
Sibe orile ede South Sudan fe bu ninu omi ogbon ati imo wa, nitori naa , a o satileyin fun won, paapaa julo  lori eto iselu.
Gege bi awon olutoju alaisan ni ile iwosan  ilu Cape Town  se so, aisan pneumothorax, eyi ti o ni se pelu alafo ti ko faye gba ategun  ni aisan ti o nse aare ana naa pelu ireti wi pe yoo pada sile ni ose to n bo Abiodun Popoola.
Eeyan eeyan mẹtadinlogoje lo ko aarun naa lọjọ Iṣẹgun.
Lati ọmọ ọwọ ni iya rẹ ti pa ọkan pọ pẹlu idunu pe yala ọmọ lẹsẹ tabi ko ni, ko ni jẹ idiwo kankan fun igbe aye rẹ.
Ẹnìkan ninu àwọn eniyan sọ fún un pé, “Olùkọ́ni, sọ fún arakunrin mi kí ó fún mi ní ogún tí ó kàn mí.
Latari eyi, Ọna Kumba ọhun lewu lti gba ti wọn si n ṣe ikọlu si awọn oṣiṣẹ ajọ eleto idibo Cameroon.
Gbé ohùn rẹ sókè pẹlu agbára Jerusalẹmu,ìwọ tí ò ń kéde ìyìn rereké sókè má ṣe bẹ̀rù;sọ fún àwọn ìlú Juda pé,“Ẹ wo Ọlọrun yín.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Nkan ti awọn eeyan nsọ lori BBC Yoruba Lori iroyin kan tawọn iwe iroyin abẹle kan gbe ni ọjọ iṣẹgun pe awọn agbofinro DSS ti gbe ọkan lara awọn kọmiṣọna rẹ, Ọjọgbọn Yakubu ni pe ko si ootọ ninu iroyin naa.
Ọ̀rọ̀ ẹnu rẹ̀ kún fún ibinu;ahọ́n rẹ̀ dàbí iná tí ń jóni run.
Ko si tun si irinajo oju ofurufu lọ si awọn orilẹ-ede kan mọ.
Ile-ẹjọ kotẹmilọrun ti kọkọ da ẹjọ rẹ lẹyin to tako bi ajọ eleto idibo INEC ti kede gomina Emeka Ihedioha gẹgẹ bi ẹni to jawe olubori ninu eto idibo naa.
Nígbà tí wolii Eliṣa wà ninu àìsàn tí ó le, tí ó sì ń kú lọ, Jehoaṣi, ọba Israẹli lọ bẹ̀ ẹ́ wò, nígbà tí ó rí Eliṣa, ó sọkún, ó sì ń kígbe pé, “Baba mi, baba mi!
Kíni ẹ mọ̀ nípa Mama Rainbow tó jẹ́ àgbà òṣẹ̀ré tíátà Yoruba?
Amọ, agbaọjẹ naa sọ di mimọ pe oun ko tọrọ jẹ, bẹẹ ni oun ko ṣe agbẹ, ohun ti oun nilo lọwọ awọn ọmọ Yoruba ni iranlọwọ lati ra irinṣẹ ti yoo mu ohun pada si ipo.
IRAN: Joe Biden ti ni oun ṣetan lati ṣe adehun miran papọ pẹlu awọn orilẹede agbaye lati le mu idẹrun ba orilẹede Amerika lori ọrọ aje wọn ti aarẹ Donald Trump fofin de.
Ìyá yìí a máa ṣe àlàyé síse oúnjẹ oníkanòjọ̀kan.
Oríṣun àwòrán, Dino/twitter Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Fídíò, Dino Melaye nánwó fún Ayefẹlẹ lójú agbo16 Agẹmo 2019 Dino Melaye: Ki lo tun ku ti o sọ?
Gege bi adele adari  agbenusọ fun ile-ise ologun orile ede yii Colonel
Mo mọ̀ pé kò sí ohun tí ó yẹ wọ́n ju pé kí inú wọn máa dùn, kí wọ́n sì máa ṣe rere ní gbogbo ọjọ́ ayé wọn; 
"Ọlọfinsawo ni "" Ohun itiju gbaa ni ki ọmọ ilẹ Kaarọ ooojire ma lee sọ ede Yoruba to dangajia lẹnu."
Àwọn méjì míràn tún sálọ, kí àwọn mẹ́ta míràn tó tún di àwaátì lálẹ́ àná.
Igbẹ ti ko ni ẹya kankan ree, a kọkọ fọn ka a tun di pọ.
Nítorí náà gbogbo wọ́n gba ohun tí OLUWA pa láṣẹ, wọ́n sì pada sí ilé wọn bí OLUWA ti wí.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù EndSARS Protest Update: Iléèṣẹ́ ọlapàá sọ pé Ọlọ́pàá mẹ́fà ni jàndùkú pa, wọ́n tún kọlù àgọ́ ọlọ́pàá márùn-ún lásìkò ìwọ́de 20 Ọ̀wàrà 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 28 Ọ̀wàrà 2020 Awọn janduku pa ọlọpaa mẹfa, wọn ṣe akọlu si agọ ọlọpaa marun un lasiko ifẹhonuhan #EndSARS nipinlẹ Ọyọ Ileeṣẹ ọlọpaa ipinlẹ Ọyọ ti ṣe afihan awọn afurasi ọdaran to dana sun agọ ọlọpaa nilu Isẹyin.
-Shittu 10 Owewe 2019 Ajimobi da ilẹ̀ APC ni -Adebayo Shittu Minista fun ọna ibaraẹnisọrọ tẹ́lẹ̀, Amofin Adebayo Shittu ṣi aṣọ loju eegun ohun to ṣẹlẹ laarin oun ati gomina ipinlẹ Oyo tẹlẹ, Senetọ Abiola Ajimobi.
Wọn ri i pe o jẹbi ẹsun ipaniyan awọn afẹhonu han lasiko iwọde kan.
Igbó sambisa kò ní pe di ibi ìgbàfẹ́ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Èré Ọṣun: Àtáója ní wọn kò jí ère Ọṣun, ó sì wà níbi tó wà Nitori naa, o ni ọkọọkan lara awọn aṣofin mẹrinlelogun to wa ni ipinlẹ naa, ati awọn to jẹ amugbalẹgbẹ oun gbọdọ yan ẹranko ti wọn o maa tọju.
Ẹ má tilẹ̀ bá irú ẹni bẹ́ẹ̀ jẹun.
Àwọn ọmọ mi ti di aláìní,nítorí pé àwọn ọ̀tá ti borí wa.
 Ìtàn ẹbí alátẹnudẹ ́ nu wọn sọ pé ọ ̀ kan lára àwọn tó kọkọ tẹ ̀ dó síbí yìí jẹ ́ awọn to wa láti orífun fulbe .
Obinrin náà bá bi Elija pé, “Eniyan Ọlọrun, kí ló dé tí o fi ṣe mí báyìí?
Gbogbo ilé ọmọ aláìgbọràn nílẹ̀ Yorùbá, Ọlọ́pàá ń bọ̀ wá yẹ̀ yín wò Akẹ́kọ̀ọ́ mẹ́fa, olúkọ̀ méjì ni wọ́n jígbé ní Kaduna O ni awọn kan o tilẹ ni obi mọ tori wọn ti pẹ nibẹ gẹgẹ bi baba agbalagba to ni ile naa ṣe sọ pe obi lo ko gbogbo wọn wa.
Àmọ́ àléébù ibẹ̀ ni ọpọ èèyàn ń wo, wọn kò wo ọpọ àǹfààní tó wà nibẹ.
 lẹ ́ yìn ìgbàtí ìjọ ̀ ba olósèlú padà dé ní ọdún 1999 Ìgè di alákòóso ìjọba àpapọ ̀ fún ìdájọ ́ àti agbẹjọ ́ rò-Àgbà ìjọba àpapọ ̀ ̀ .
Bí wọ́n bá jẹ ninu ẹran ẹbọ alaafia tí ó bá ṣẹ́kù di ọjọ́ kẹta, ẹbọ náà kò ní jẹ́ ìtẹ́wọ́gbà lọ́wọ́ ẹni tí ó bá rú u, a kò ní kọ ọ́ sílẹ̀ fún un, nítorí pé ohun ìríra ni, ẹni tí ó bá jẹ ẹ́ ni yóo ru ẹ̀bi ẹ̀ṣẹ̀ rẹ̀.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ó dára kí obìnrin níṣẹ́ lọ́wọ́ - Toyin Lawani Sinima to gun ni ọrọ oṣelu Naijiria, ko fẹ ẹ ni opin: Nibi ti ọrọ de e duro yii, ko si ẹni to le sọ pe ibi kan ni yoo ja si nigbẹyin.
Oríṣun àwòrán, Yomi Duro Ladipo Imọran BBC Yoruba lori itan manigbagbe akọni ọmọ Oodua yi: Duro Ladipọ̀ ti wa sile aye, to si ti lọ amọ̀ ko kọ̀ja nile aye gẹgẹ bii ejo to kọja lori apata, ti ko ni ipa kankan.
Nítorí pé wọ́n ti kọ òun OLUWA sílẹ̀, wọ́n sì ń sun turari sí àwọn oriṣa, kí wọ́n lè fi ìṣe wọn mú òun bínú; nítorí náà òun óo bínú sí ibí yìí, kò sí ẹni tí yóo lè dá ibinu òun dúró.
Ìbànújẹ́, ìpòrúru ọkàn àti ìgbìnyànjú láti lókun wà lára àwọn ohun tó ń fa àwọn ọmọ Nàíjíríà lọ sí ìdí mímu oògùn ikọ́ olómi tó ní èròjà codeine.
Bí àwọn ìjòyè Juda ati àwọn ìjòyè Jerusalẹmu, àwọn ìwẹ̀fà, àwọn alufaa ati gbogbo àwọn eniyan ilẹ̀ náà ṣe bẹ́ ẹgbọ̀rọ̀ mààlúù sí meji, tí wọn sì gba ààrin rẹ̀ kọjá láti bá mi dá majẹmu, ni n óo ṣe bẹ́ àwọn náà.
Ile akede Naijiria gbọ pe o deede ṣubu lọjọ Abamẹta ki wọn to gbee lọ sile iwosan to ti dagbere faye pe o digboṣe lọjọ kẹwaa, osu keje, ọdun 2018.
Aarẹ ilẹ Amẹrika ti wọn ṣẹṣẹ dibo yan, Joe Biden ni iroyin ayọ ni abẹrẹ ajẹsara naa jẹ fun gbogbo eniyan ni agbaye.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Osun cow death: Iṣẹ̀lẹ̀ tó wáyé kò ni dá wàhálà sílẹ̀ láàrin àwa àti àwọn Fulani.
Ṣugbọn àkókò yín ati ti aláṣẹ òkùnkùn nìyí.
O ya mi lẹnu gan an ni pe o si wa laye lasiko ti mo setan lati ṣe igbeyawo, ọrọ rẹ ree Ọkọ rẹ, ọgbẹni Mahajan ninu ọrọ rẹ, salaye pe oun ko tilẹ ro o pe iyawo oun yoo wa sibi igbeyawo pẹlu sokoto ati kootu.
"Igbesẹ to daraju lọ lati fi opin si ija laarin awọn daran-daran ati agbẹ niyi.
 nigbà tí olódùmarè retí rẹ ̀ títí tí kò rí i , ó rán odù tó dá ìwà tí í ṣe odùduwà .
N kò fẹ́ tú wọn ká pẹlu ebi ninu, kí òòyì má baà gbé wọn lọ́nà.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Lagos School reopening: Ìjóba ìpínlẹ̀ Eko kéde ṣíṣí àwọn ilé ìwé padà 29 Òkùdu 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 4 Agẹmo 2020 Oríṣun àwòrán, others Ìjọba ìpínlẹ̀ Eko tí kéde pé kí àwọn ipele ikẹ́kọ̀ọ́ jáde, ipele àkọ́kọ́ girama (JSS3) àti akẹ́kọ̀ọ́ jáde girama (SSS3) kí wọ́n wọlé pade silé ẹ̀ká wọ́n láti ọjọ́ kẹta ọsù kẹjọ ọd'un yìí lọ.
- Bode George Ariwo ijẹ ti ẹ jẹ tẹtẹ Bola Ige, aye ẹ maa jẹ dagunro mí bẹẹ ni Ayodele Fayose mu bẹnu.
Oríṣun àwòrán, @TheMbuhari Àkọlé àwòrán, Aarẹ Buhari ti n bura fobinrin meje to yan ni minista Bakan naa ni Adamu Adamu, lati ipinlẹ Bauchi, ẹni ti o jẹ minisita fun eto ẹkọ nigba naa.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Òsèré tíátà Aisha Abimbọla jáde láyé O di gbére, Jlloyd Samuel lọ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ọ̀nà àbáyọ sí àìrọ́mọbí tọkùnrin tobìnrin Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Kí ẹni tí ń jalè má jalè mọ́.
Awọn ara meeriri ile ounjẹ, ibusọ, ati ibi igbafẹ kaakakiri le mu ki ololufẹ gbogbo gbagbe ile ile.
 Kò gba ẹnu Buhari láti tàbùkù ará Abuja - PDP Ọba Adesoji Aderemi, Ọọ̀ni Ifẹ̀ tó gba ipò ọba mọ́ tòṣèlú Air pollution: Nàìjíríà ni orílẹ̀ède kẹrin tí atẹ́gùn búburú ti ń pa ènìyàn jù làgbáyéé Owó wọgbó!"
Awọn koko aba mii ti ẹgbẹ APC gbe kalẹ: Oríṣun àwòrán, APC Ipinlẹ kọọkan ni yoo maa san iye owo osu ti agbara rẹ ba ka fawọn osisẹ rẹ Gbogbo awọn ohun alumọọni bii epo rọbi ati afẹfẹ gaasi, iwakusa, kanga epo ati agbeyẹwo ayika fun awari ohun alumọọni, ni yoo jẹ ojuse awọn ijọba ipinlẹ bayi Awọn ijọba ipinlẹ yoo ni ileesẹ ọlọpa tiwọn labẹ ofin idasilẹ wọn ti yoo di ofin atigbadegba Eto akoso ọgba ẹwọn naa yoo di ẹru awọn ijọba ipinlẹ Ofin idasilẹ ileesẹ nilẹ yi naa yoo wa labẹ ofin atigbadegba kawọn ipinlẹ lee maa gba owo ori ọja labẹle Awọn ọmọ ipinlẹ mii to ba n gbe nipinlẹ ti kii se tiwọn lee di ọmọ ipinlẹ naa Oludije to da duro yoo wa lati kopa ninu idibo laisi ninu ẹgbẹ oselu kankan.
Ẹni to bori: Madagascar Egypt vs Algeria.
Gomina Sanwoolu fi idaniloju han pe awọn ti y a ipinlẹ Eko sọtọ lati faaye gba awọn igbesẹ awọn oluwọde tori pe nkan to tọ ni wọn n ṣe.
ni pẹru niluu AbujaLonii yii ni won yoo maa bura fun aare Muhammadu
wa ninu iwe-ofin orilẹ-ede Naijiria, ni pe Gomina kan ni lati pese eto iṣuna
Oríṣun àwòrán, Getty Images Lara awọn oniburẹdi to ba awọn oniroyin sọrọ ni bi o tilẹ jẹpe awọn yoo fopin si iyanṣẹlodi naa, o pọn dandan ki owo burẹdi wọn si.
Nkan tí a mọ̀ nìyíì Mo ti kúrò ní ààfin Oyo, kí ìròyìn tó ò jáde pé èmi àti Wasiu Ayinde n fẹ́ ara wa - Olori Badirat O wa yan pe ko si ohun to jọ mọ ọrọ oselu rara ninu ijiroro awọn agba oselu mejeeji naa lasiko abẹwo ọhun .
Ọjọ́ ọ̀la èdè Yorùbá ti ń kùnà, nítorí nàá ni a ṣe gbé ìdíje kalẹ̀ fún àwọn ọmọ iléèwé l'édè Yorùbá.
”Ó ní, “Èmi kì í ṣe Elija.
Àkọlé àwòrán, Ọ̀pọ̀lọpọ̀ gbàgbọ́ pé irọ́ ni Fayose n pa Joseph Ọlanrewaju sọ lórí Facebook pé ''nkan ti wọ́n ṣe fún Fayose ati ẹgbẹ́ òṣèlú rẹ̀ kò dára rárá.
Ṣaaju ni Aarẹ ilẹ Madagascar, Andry Rajoelina ti kede agbo kan to ni o lagbara lati wo arun Covid-19 to n ba gbogbo aye finra, leyi ti ọpọ orilẹ-ede nilẹ adulawọ si ti ni ko fi ṣowọ si wọn.
Oniṣowo ni Ẹmiọla, bakan naa lo si jẹ agbẹ ọlọsin adiyẹ.
Ṣugbọn Femi Adeniji, to gbẹnusọ fun ileeṣẹ Tropical Arctic Logistics sọ fun BBC wipe, oun ko mọ idi ti ọrọ naa fi fa yanpọn-yanrin.
Mi o mọ ilé iṣẹ́ ti mo ni ti mo fẹ́ fi gba iṣẹ́ kọngila ìjọba níbì kankan ni aye yìí.
Aisha ni ẹnikẹni to ba tasẹ agẹrẹ si ofin yii gbọdọ lọ si iyasọtọ ọlọjọ mẹrinla lati le mọ boya o ko arun naa tabi ko ni.
Wọn ko si ni i ma lọ kaakiri igboro.
Lalẹ ọjọ Aiku lojo ọhun bẹrẹ ti o si rọ fun wakati mẹta gbako.
’Nítorí pé òun ló jẹ̀bi ọ̀rọ̀ yìí,
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ọkùnrin tó fẹ́ fipábámilòpọ̀ fín ǹkan sí mi lójú ló ṣe rọ́nà wọlé sí mi lára Olorì Anu ni Ọba Adeyemi ń halẹ̀ máwọ̀n ẹbí òun torí kò mọ ibi tí òun wà Oríṣun àwòrán, Instagram/queen__aanu Yoruba ni ba ba dakẹ, tara ẹni maa n bani dakẹ ni, igi gogoro ma gun mi loju, ati okeere si la tii lọ ọ.
Iroyin so pe eto idibo ti bere ni pẹrẹu ni  jake jado orile ede  Naijiria bayii, sugbon ni awon ibomiran , a n gbọ pe ero irinse to n se ayẹwo kaadi ibo n se mọna mọna.
Lati ọdun 2009 ni ẹgbẹ́ BokoHaram ti ngbiyanju lati se agbekalẹ ijoba tara won ni ẹkun ila oorun-ariwa Naijiria labe esin Islam.
Bí ẹnikẹ́ni bá bi í pé, ‘Àwọn ọgbẹ́ wo wá ni ti ẹ̀yìn rẹ?
O gbódọ ga ju ìwọ̀n bàtà 1.
Ìran òmìrán, ará Gati ni àwọn mẹtẹẹta; Dafidi ati àwọn eniyan rẹ̀ ni ó sì pa wọ́n.
Oríṣìíríṣìí ìtàn àtẹnudẹ́nu ni a ti gbọ́ nípa ìlú Ìjẹ̀bú-Jẹ̀ṣà, ọ̀rọ̀ òkèèrè sì nìyí, bí kò bá lé yóò dín.
 tí wọn bá ń ṣe ìpàdè awo tàbí tí wọn bá ń ṣọdún ifá , irú bátànì orin ifá yìí ni a sáábà máa ń lò jù .
Ìwé ìròyìn Punch ṣe ìfojúsùn “ìpèsípò” gẹ́gẹ́ bí “àìròtẹ́lẹ̀ ” àti pé ó ti pín ìlú yẹ́bẹyẹ̀bẹ.
Oró agbọ́n leè wo àìsàn jẹjẹrẹ ọmú sàn, wo ohun tí wàá lò pọ̀ mọ́ra wọn Daniel Prude: Ìbòjú tí àwọn ọlọ́pàá New York fi bo ọkunrin ọhun ló ṣe ikú pà á Lara awọn ohun to fa ẹhonu naa ni sisan owoona fun eto dokita abẹnu nileeṣẹ ẹkọṣẹ iṣegun Residency funding, owo gba ma binu fun ajakalẹ arun COVID-19, sisan owo ewu ẹnu iṣẹ (hazard allowance) pẹlu owo ajẹẹlẹ owo osu ọdun 2014, 2015 ati 2016.
Adari Ajọ JAMB naa wa parọwa si awọn akẹẹkọ naa lati wo esi idanwo wọn ti wọn ba ti tẹ atẹjisẹ 'RESULT' si '55019' lori ẹrọ ilewọ wọn, lai lọ si ori ẹrọ ayelujara lati lọ wo o.
Oríṣun àwòrán, @thenff Àkọlé àwòrán, Asisat Oshoala wa pẹlu ẹgbẹ agbabọọlu Dalian Quanjian lorilẹede China.
Onisegun oyinbo kan, Dokita Kunle Obilade, tile iwosan ijọba ipinlẹ Ọyọ salaye fun BBC wi pe ewu n bẹ loko longẹ ni oogun oloro Tramadol ninu agọ ara.
Bakan naa ni Alaafin tun da si ọrọ aawọ ija agba to n waye nipinlẹ Ekiti, to si kọ lẹta si gomina ipinlẹ naa, Kayode Fayemi, lati pe akiyesi rẹ si ọrọ naa ati ọna atunse nipa rẹ.
Abisola, aya wòlíì Babatunde ti ń jẹrìí nípa bí ọmọ ọdún kan ṣe sọnù Ninu awọn ẹlẹri ogun ti yoo jẹri gbe wolii ati olori ijọ Sotitobire, Alfa Babatunde lonii, mẹta ti yọju sile ẹjọ.
Oríṣun àwòrán, Others Akinlami ni ika to ba ṣẹ naa lo yẹ ki ọba ge, nitori naa ti ko ba ti jẹ obi lo wuwa ibajẹ, obi ko gbọdọ jẹya ẹsẹ ti ko ṣe.
Wọ́n ni ǹkan ti ó dun àwọn jùlọ ni pé, Ifeanyi ti rí iṣẹ́ sí ilé iṣẹ́ Labour & Productivity to si ti n múra láti lọ bẹ̀rẹ̀ iṣẹ́ kí ó tó kú Oríṣun àwòrán, Gbajabiamila Níbo ni SSS tó pa Ifeanyi wà?
Awọn kan ti ẹ sọ pe irọ ni mo n pa, pe ọna lati le awọn lọ ni mo ṣe sọ bẹ ẹ.
O ni iku ọkunrin naa dun ileesẹ ọlọpa, nitori pe ko ba ran wọn lọwọ lati jẹ ji ọwọ tẹ awọn akẹgbẹ rẹ to salọ.
Nígbà tó yá mo kúkú dé òkè pátápátá bíótilẹ̀jẹ́pé ńṣe ni mò ń mín hẹlẹhẹlẹ lọ.
5M ti pọ̀ jù fún owó fọ́ọ̀mù ìdìbò abẹ́lẹ́ sípò gómìnà APC - SERAP 'Ọkọ mi yọ kíndìnrín mi láti fi rọpò owó ori' Pásítọ̀ ń sanwó wáàsí mi lórí rédíò, ó fi ń ṣe ìwàásù ní ṣọ́ọ̀ṣì - Akeugbagold Ọ̀kan lára àwọn ọba tọ́jọ́ orí wọn dàgbà jù ní ìpínlẹ̀ Oyo ti wàjà Ìdáhùn Umar tó fi ṣọwọ́ padà sí olórí òṣìṣẹ́ níbi tó ti fèsì pé irọ́ pọ́nbélé ni gbogbo ọ̀rọ̀ náà tún jẹ jáde lórí ayélujára bakan náà.
Lowurọ ọjọ aje ni Adajọ ile ẹjọ giga ni Ikoyi, Onidajọ Nicholas Oweibo ni o di ọgbọnjọ osu kaarun ọdun 2019 ki wọn to le gbẹjọ lori ẹbẹ fun gbigba oniduro rẹ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Baby abandoned on dunmpsite: Mo ti bímọ mẹ́rin tẹ́lẹ̀ fún bàbá méjì nínú òṣí- Dupe Ogbomos Amọ awọn eeyan kan ti n kede loju opo ayelujara pe ileẹjọ kan ti da awọn ẹgbẹ osisẹ ọhun lọwọkọ lati mase gunle iwọde ti wọn n gbero naa.
to n sejoba lọwọ , ti won jigbe lojo Abameta to kọja , ni won so pe won rii
Ni bayii, ẹgbẹ agbabọọlu Arsenal ti yege lati kopa ni idije Europa.
Idije ọjọ Isẹgun yii lo maa bẹrẹ ni bii agogo meje abọ aṣaalẹ lori papa iṣere nla ti ilu Dnipro.
Nígbà ayé Eliaṣibu ati Joiada, Johanani ati Jadua, àwọn ọmọ Lefi ati àwọn alufaa ṣe àkọsílẹ̀ àwọn baálé baálé ní ìdílé baba wọn títí di àkókò ìjọba Dariusi ọba Pasia.
Ṣugbọn ó wí fún wọn pé, “Ọ̀kan ninu ẹ̀yin mejeejila ni, tí ó ń fi òkèlè run ọbẹ̀ pẹlu mi ninu àwo kan náà.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Irú iṣẹ́ wo ní Funke Akindele rán sí Bukunmi Oluwasina, tó fa ariwo lórí ayélujára?
Odidi ọjọ́ mẹta ni wọ́n fi kó ìkógun nítorí pé ó ti pọ̀ jù.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Àwọn amọkòkò kò fẹ́ fi iṣẹ lé ọmọ lọ́wọ́ mọ́ Ìjàmbá afárá Ọ̀tẹ́dọlá: Ọwọ́ ọlọ́pàá tẹ ọlọ́kọ̀ epo tó fa ìjàmbá iná Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ilu Kano ni wọn ti mu arakunrin to ni ọkọ ajagbe akepo naa Ni ǹkan bí oṣù díẹ̀ sẹ́yìn ni irú ìṣẹ̀lẹ̀ aburú yìí ṣẹlẹ̀ ní orí afárá Ọtẹdọla ní ìpínlẹ̀ Eko.
O ni ileeṣẹ Pfizer ati BioNTech ti wọn pawọpọ gbe abẹrẹ ajẹsara naa jade ti n beere fun iwe aṣẹ latọwọ ijọba orilẹede Amẹrika eleyii ti wọn n reti pe yoo bọ sii titi ipari oṣu kọkanla.
Ni ojo karun-un osu keta odun 2017, afunra si omo-ogun olote IRSAD dode ipago awon omo-ogun ijoba ti o wa leba enu ibode pelu orile-ede Burkina Faso ni eyi ti o seku pa awon omo-ogun ijoba orile-ede Mali mokanla.
Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Tunde Bakare: Ìjà àgbà méjì!
fi aidunnu re han lori isele yii, o wa  ba
Leon van Biljon dí èrò ọrun nípasẹ̀ Kìnìún rẹ̀ Iṣẹ́ ṣẹ̀ṣẹ̀ bọ́ lọ́wọ́ Seth Ator tó yìnbọn pa ọ̀pọ̀ èèyàn ní Texas ni- ọlọ́pàá 11.
Jokitani ni ó bí Alimodadi, Ṣelefu, Hasarimafeti, ati Jera; 
Daura ni ipinle  Katsina , ekun ila
Àwọn ẹ̀dá alààyè mẹrin kan wà ní ààrin, wọ́n yí ìtẹ́ náà ká.
Dokita Ọlalekan, lasiko to sọrọ lori aawẹ gbigba ni ko si ohun to buru ninu rẹ eyiun ti o ba ti ba ara wa mu.
Akonimoogba agba iko agbaboolu Bafana Bafana, Stuart Baxter so pe oun ati awon agbaboolu re ko beru lati koju iko agbaboolu Naijiria bi o se le wu ko mo saaju ifesewonse ipegede fun idije boolu ile Afrika( 2019 Africa Cup of Nations qualifier), ti yoo waye ni papa isere FNB,  niluu Johannesburg, lojo Abameta(Saturday).
Matt Grimes lo akọkọ naa wọle nibi ogun iṣẹju ti wọn bẹrẹ ere bọọlu ọhun.
Ati wipe ki awọn panapana to pa ina naa, ẹmi ti bọ lara awọn ololufẹ mejeeji.
"Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Bee farming: Oyin sínsìn lérè lórí ṣùgbọ́n ó tún gbé ikú karí Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Bee farming: Oyin sínsìn lérè lórí ṣùgbọ́n ó tún gbé ikú karí 1 Èbibi 2019 ""N20,000 naira ni mo fi bẹrẹ, o ti sun mi debi ire bayii."
Àwọn kan tò lọ ní apá ọ̀tún odi náà lọ sí Ẹnubodè Ààtàn, 
Orukọ Ọmọwe Nnamdi Azikwe to jẹ aarẹ alagbada akọkọ lorilẹ-ede Naijiria ni wọn fi sọ papakọ ofurufu naa eyi to wa ni olu ilu orilẹ-ede Naijiria.
Fulani darandaran: Ẹ ma wa ija Yoruba - Odumakin Ikọlu darandaran: Fayọṣe ṣe abẹwo si Ortom ni Benue Gani adams ti o sapẹẹrẹ bi awọn Fulani darandaran se jo oko oloye Olu Falae ti o jẹ ọkan gboogi ninu awọn ọjọgbọn nilẹ Yoruba, wa a fikun un wipe awọn ọmọ Yoruba ni ohun gbogbo ti wọn nilo lati fi daabo bo ara wọn, ati wipe awọn ko nii f'aaye gba iru rẹ mọ.
 Titi lai ni maa maa yin o.
Àwọn ọmọ wẹ́wẹ́ tó dín díẹ̀ ni mílíọ̀nù méjì ń gbé nínú aìjẹun-kanu làwọn agbègbè ìwọ oòrùn ilẹ̀ Áfíríkà.
"Ninu ọrọ ti arabinrin Dabiri-Erewa sọ fun ile iṣẹ iroyin Naijiria kan, o ni ""iṣẹlẹ to ṣe ni laanu ni, ṣugbọn kii ṣe iṣẹlẹ to juwe iru eniyan ti a jẹ""."
Sibẹ mo fẹ́ràn Jakọbu, mo sì kórìíra Esau.
Ibi ti wọn yoo ti ribi du ipo lọkan wọn a ma wa.
Awon miiran tun ni: adari agba teleri fun ile-eko ija nipinle Makurdi, AVM John Baba, bee si ni, AVM Napoleon Bali, AVM Charles Oghomwen, AVM AS Liman,  Commodore BB Okunola, Commodore James Gwani.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Baba Legba: Foluke Daramola ní òun kò ní gbàgbé àdúrà òwúrọ̀ tó máa ń gbà fún òun 7 Owewe 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 8 Owewe 2020 Gomina ẹgbẹ TAMPAN ni ipinlẹ Ogun, Owolabi Ajasa ti ṣapejuwe Baba Lẹgba to di oloogbe, gẹgẹ bi baba awọn oṣere nigba aye rẹ to ko awọn eniyan mora.
O fikun pe iwadi kikun ti n waye lori isẹlẹ naa, ti wọn ko si ni pẹ gbe wọn lọ sile ẹjọ.
Josẹfu sì ń gbé ilẹ̀ Ijipti, òun ati ìdílé baba rẹ̀, ó gbé aadọfa (110) ọdún láyé.
Edgal ni ile isẹ eto idajọ ni ipinlẹ Eko ti gba ile isẹ ọlọpaa ni imọran wi pe ohun itiju ati ohun to ba ni loju jẹ ni ki akọ ati abo ma a ba ara wọn ni ibalopo ni ita gbangba.
 niwon 1930 barifiera del levante ti waye ni bari , laarin awọn iṣowo iṣowo pataki ni italy .
Barcelona yóò kojú Man U nínú ìdíje Champions League Chelsea pòkọ ìyà fún Dynamo Kiev pẹ̀lú 5-0 Kí ló mú kí Aubameyang fi Black Panther dáwọ̀ọ́ ìdùnnú?
3tn naira, tabi ki o din owo isuna ẹka miiran ku.
Oluranlọwọ pataki fun Aarẹ Muhammadu Buhari lori eto iroyin ati ipolongo, Garba Shehu ṣalaye pe ipinlẹ mejila lo ti fi erongba ọkan wọn lati darapọ mọ eto naa to ba bẹrẹ.
Ohun tí OLUWA sọ nípa gbogbo àwọn aládùúgbò burúkú mi nìyí, àwọn tí wọn ń jí bù lára ilẹ̀ tí mo fún Israẹli, àwọn eniyan mi.
Láti ọ̀run wá ni o ti ń ṣe ìdájọ́,ẹ̀rù ba ayé, ayé sì dúró jẹ́ẹ́;
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Kogi Coronavirus Status: Kìí ṣe ààrùn Covid-19 ló pa adájọ́ àgba ìpínlẹ̀ Kogi-Kọmísọ́nà ìlera 9 Èbibi 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 28 Òkùdu 2020 Oríṣun àwòrán, Othrers Kọmísọna fún èòì ìlera ní ìpínlẹ̀ Kogi Saka Audu Haruna ní kìí ṣe ààrùn coronavirus lo pa adájọ agbà to jẹ́ Ọlọrun nipe ni ibudó ìtọ́jú àwọn aláàrùn coronavirus ní ìpínlẹ̀ Kogi.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Tọpẹ Adebayọ: Isẹ́ Tíátà tí mò ń se ti tó mi jẹun Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Tọpẹ Adebayọ: Isẹ́ Tíátà tí mò ń se ti tó mi jẹun 30 Èbibi 2018 Temitọpẹ Adebayọ jẹ ọmọ Ọga Bello, àgbà olósèré Yoruba òun gan sì ti ń m'ókè nínú isẹ́ tí baba fi lé e lọ́wọ́.
Ẹwẹ, Gomina Makinde ṣalaye pe, igbogun tiwa ibajẹ yoo fawọn oludokowo ni igboya lati da okoowo silẹ nipinlẹ Oyo.
Bí mo ṣe ń dàgbà ni ǹkan ọmọkùnrin mi ń tóbi síi àmọ́ obìnrin ni mi' Ẹ̀wọ̀n ni wàá gbẹ̀yìn sí, kò sí bóo ṣe dọ́gbọ́n tó - Seyi Makinde wa ègúná ọ̀rọ̀ lé Fayose Ẹ̀yin ọ̀tá mi, ẹ lọ dì mọ́ òpò ina lọ́dún 2020- Ayodele Fayose Aáwọ̀ oyè PDP gbé Fayose àti Seyi Makinde kọlu ara wọn, ìjà ń bọ̀ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Fayose sọrọ lori lẹta oloye Ọbasanjọ.
Olówó-ayém bàbá rẹ wí pé kí n ṣe ọ́ pẹ̀lẹ́, ó ní kí n kí ọ dáadáa, òun wà nínú ìsinmi, lórí ibùsùn àǹfààní wọn dáradára.
O ni 'Sultana ati ọkọ rẹ akuṣẹ, to si jẹ pe ko aworan ayẹwo ko to o bi ọmọ akọkọ.
OLUWA ìwọ yóo fún wa ní alaafia,nítorí pé ìwọ ni o ṣe gbogbo iṣẹ́ wa fún wa.
Ko ni nilo lati gba itọju ile iwosan akọsẹmọsẹ.
Awọn ti iṣẹlẹ naa ṣoju wọn ṣalaye pe tirela naa n lọri lọwọ ni ọkọ akero ọhun lọ kọ lu u lati ẹyin.
Bi o tilẹ jẹ pẹ ọ̀pọ̀ àwọn ọmọ Nàìjíríà ló tí n fi èrò wọ̀n hàn lórí ikú tó pa Ibídun.
75 ni ipin idokoowo ni  yoo waye ni osu kerin lodun 2023”.
Aboderin, ti ọpọ eeyan mọ si Esabod abi iya ewe, lasiko to n kopa lori akanse eto loju opo BBC Yoruba dahun ọpọ ibeere awọn ololufẹ BBC Yoruba.
Gbajumọ osere tiata naa fikun pe Koda, iru oloselu bẹẹ ko ba a jẹ mọlẹbi tabi ọrẹ mi tori a nilo agbekalẹ orilẹede Nigeria tuntun.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Eid celebrations in Africa: Báyìí láwọn mùsùlùmí ti ṣe ọdun ìtúnu ààwẹ̀ káàkiri ilẹ̀ Afirika lásìkò covid-19 yìí 24 Èbibi 2020 Awọn musulumi ṣe ayẹyẹ ọdun itunu awẹ, Eid al-Fitr kaakiri ilẹ Afirika, eyi tii ṣe ipari oṣu Ramada.
Ṣugbọn kí ẹ lè mọ̀ pé Ọmọ-Eniyan ní àṣẹ ní ayé láti dárí ẹ̀ṣẹ̀ ji eniyan ni.
Prophet Israel Oladele: Wo díẹ̀ lára àwọn ìwàásù mánigbàgbé tí wòlíì ìjọ CCC Genesis Global ti ṣe
"- Olùkọ́ Bolaji Owasanoye ni: ""A woye pe wọn dọgbọn si ọna ti wọn fi gbe owo naa jade nipa lilo sub-TSA ki oju kankan ma lee se abojuto bi owo naa se n ajde ati ibi to n gba lọ."
"Fifi ero han lai si wahala ni irinṣẹ awọn akọroyin.
Ọpọlọpọ lo ti fi ohun wọn sita loju opo Twitter lọjọ isinmi lati fi aidunnu wọn han si bi ọpọlọpọ eniyan ṣe ti padanu ẹmi wọn ni ipinlẹ Zamfara lati igba ti ọdun 2018 ti bẹrẹ."
Iroyin to n tẹ wa lọwọ ni pe ko sẹni to tii le mọ iye eeyan to ba iṣẹlẹ naa rin bayii Oríṣun àwòrán, others Ọkọ agbepo meji ti gbina lori afara Otedola ni agbegbe Berger ni ipinlẹ Eko ni idaji oni.
Ó bá sọ fún mi pé, “Èèwọ̀!
Nítorí, kíyèsíi, èmi jẹ́ àìnípẹ̀kun, àti pé ìbáwí èyí tí a fi fúnni láti ọwọ́ mi jẹ́ àìlópin, nítorí Àìnípẹ̀kun ni orúkọ mi.
Ssọ́ra nípa ojúkòkòrò, máa sá fún un, ó búru ju májèlé lọ.
Amọ ṣa, wọn iyanrin lati ibi ti baalu naa ja sinu ọra dipo oku awọn ẹbi wọn.
663m O gbọdọ pé lẹ́mìí àti ni àra.
Aarẹ orilẹ-ede Naijiria tẹlẹ, oloye Olusegun Obasanjo ti sọ pe itankalẹ arun Coronavirus lo mu ki oun ṣe atunṣe si bi oun ṣe fẹ ki ayẹyẹ ọjọ ibi oun waye.
ile-ise CRCC maa n se ni: Opopona oko ojurin, ise okoowo kara-kata, opopona
Láti Ritima wọ́n lọ sí Rimoni Peresi.
Awon omo ogun ile Amerika ti o to egberun meji lo wa nilu Syria fun ise akanse ipenija lati satileyin fun awon omo ogun Kurdish ati Arab ti n se omo ogun ijoba Syria SDF lati gbogun ti awon omo ogun olote to n da ilu ohun laamu.
Ise akanse ijoba ipinle Akwa-Ibom lori kikowo le papa isere ipinle ohun lati le gberu si ati fifigagbaga laarin awon akegbe re yooku nipinle kookan lorile-ede Naijiria, paapajulo lagbaye ti so eso rere, leyin ti papa isere ohun gba ami-eye National Sports Summit Award, leyi ti o je papa isere ti o ni awon ohun elo idaraya igbalode ti o poju lo laarin awon akegbe re lorile-ede yii.
Asofin Boris Johnson lo wa loke tente, ti Micheal Gove ati Jeremy si tẹle lọwọọwọ, lẹyin ti Sajid Javid kuna nitori oun lo ni ibo to kere ju ninu idibo abẹnu to waye.
Ninu ọrọ rẹ, ko ti lẹ ro wi pe olorin kankan le ba Micheal Jackson táákà rara.
Ó ń mú kí òkè Lẹbanoni ta pọ́núnpọ́nún bí ọmọ mààlúù,ó sì mú kí òkè Sirioni máa fò bí akọ ọmọ mààlúù-igbó.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Oyo Schools: Onírúurú ìbòmú ló gbòde, bí àkẹ́kọ̀ọ́ ṣe wọlé padà 7 Agẹmo 2020 Lọjọ Aje ni awọn akẹkọjade ni ipinlẹ Oyo wọle pada si ile ẹkọ kaakiri ipinlẹ naa.
Àjọ Ìlera Àgbáyé àti ilé-iṣẹ ́ Ìṣàkóso àti Ìdènà Àrùn fọwọ ́ sí ìmúlò rẹ ̀ .
Ǹjẹ́ Ọlọrun kò ní ṣe ẹ̀tọ́ nípa àwọn àyànfẹ́ rẹ̀ tí wọn ń pè é lọ́sàn-án ati lóru?
Wọ́n sin ín sí ibojì àwọn ọba ní ìlú Dafidi nítorí iṣẹ́ rere tí ó ṣe ní Israẹli fún Ọlọrun ati ní ilé mímọ́ rẹ̀.
Ọpọlọpọ ariyanjiyan lo tẹle Alaafin to yan Maiyegun tuntun sọ pe Wasiu ti ọpọ mọ si KWAM 1 ko ni dọbalẹ f'awọn ọba kan mọ lati oni lọ.
Bí olúwarẹ̀ bá tún pè ọ́, dá a lóhùn pé, ‘Máa wí OLUWA, iranṣẹ rẹ ń gbọ́.
Alága NURTW gba ìdájọ́ ikú 'torí ẹ̀sùn pípa ọlọ́pàá
Viral Diarrhea: Òjò ló lè mú kí ìtànkálẹ̀ àrun ìgbẹ́ ọ̀rìn má tètè dópin ni Eko- Iléeṣẹ́ ìlera
Idi si ni wi pe o yabọ rara ju ki wọn kan kọ owo gọbọi sinu rẹ lọ.
Obinrin mẹsan ni mo ba sọrọ.
Ọjoọ́ mélòó ni Coronavirus ń lò lára kí ènìyàn tó gba ìwòsàn?
Funmi ni awọn kọ wọn bi wọn ṣe n ṣe oriṣiriṣi nkan ipanu atawọn iṣẹ ọwọ mii.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, COZA: Ọpọ èrò ló jáde ṣe lòdì sí ẹ̀sùn ìfipábánilòpọ̀ Fatoyinbo Ọmọbinrin naa ati ajafẹtọ ati amofin kan ni wọn jọ kopa lori eto wa, Nibo Laye Kọju Si naa.
El Rufai ni : ''Ni Kaduna, eto ẹkọ alimajiri ko tun ni gberi mọ nitori a ṣe lodi sii bayii' Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Coronavirus: BBC News Yorùbá ní kí ẹ dúró nílé bí ẹ kò bá ní ìdí láti jáde Tani awọn ọmọ Almajiri gan an?
O ni ohun ti ofin sọ ni pe ki ẹni naa kawe, yala o ni iwe ẹri tabi ko ni iwe ẹri.
Ó kó wọn kalẹ̀, ó ń bọ wọ́n, ó sì ń rúbọ sí wọn.
Bí ìgbà ayé Noa ni Ọ̀rọ̀ yìí rí sí mi: mo búra nígbà náà, pé omi Noa kò ní bo ayé mọ́lẹ̀ mọ́.
Oríṣun àwòrán, Instagram/realmercyaigbe Bakan naa ni Mercy tun sọ ninu ọrọ rẹ pe ki Adeniyi jẹ ki ohun to ti kọ ja lọ di afisẹyin t'eegun fi aṣọ, ko si jẹ ki ifẹ bori.
dokita omode to mo nipa itoju oju, awon nọọ to mo nipa itoju oju, awon baba ati
Oríṣun àwòrán, Getty Images Lẹyin o rẹyin, Manchester United jawe olubori ninu idije naa, o si gba miliọnu meje Euro.
Wọ́n fún obìnrin kan lọrùn pa, awuyewuye ti ń wáyé Tolulope Arotile: Ikú dóró!
Kí ìjọ eniyan gba ẹni tí ó paniyan náà lọ́wọ́ olùgbẹ̀san, kí wọ́n mú un pada lọ sí ìlú ààbò rẹ̀.
Arakunrin ẹni tí ó pa ni yóo pa apànìyàn náà nígbà tí ó bá rí i.
Àkọlé àwòrán, Loṣu kẹwaa, ọdun 2015 ni NCC bu owó itanran to le ni tiriliọnu kan naira fun ileeṣẹ MTN.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìwé ìrìnnà 'VISA' Amẹ́ríkà: PDP láwọn faramọ ìgbésẹ Amẹ́ríkà 24 Agẹmo 2019 Àkọlé àwòrán, Awa PDP a kò lẹ́bọ lẹ́ru rara, ipinnu Amerika yii tẹ PDP lọrun Awọn ẹgbẹ oṣelu meji to gbajumọ lorile-ede Naijiria ti n sọ ero wọn nipa igbesẹ Ilẹ Amẹrika lati fofin de fifun awọn ọmọ Naijiria kan ni iwe irinna 'Visa'.
“Nisinsinyii, Oluwa, dá ọmọ-ọ̀dọ̀ rẹ sílẹ̀ ní alaafia,gẹ́gẹ́ bí ọ̀rọ̀ rẹ.
Ìròyìn fihàn wí pé ìṣẹ̀lẹ̀ náà lu síta ni nítorí ẹbí sọ wí pé àwọn fẹ́ kí ohun gbogbo wà ní bòńkẹ́lẹ́.
Gideoni bá tẹ́ pẹpẹ kan níbẹ̀ fún OLUWA, ó pe orúkọ rẹ̀ ní “OLUWA ni Alaafia.
 Ó túnmọ ̀ sí pé , láìsí iṣẹ ́ àgbẹ ̀ tó jẹ ́ orísun ìpèsè fún ohun àmúlò ilé-iṣẹ ́ ńlá àti kékeré , láìsí àwọn ohun àmúlò wọ ̀ nyí kò le ṣe é ṣe fún ilé iṣẹ ́ lati máa ṣiṣẹ ́ .
aisan kan tabi omiran, eleyi to si je okan ninu ohun to n fa iku ogo weere lati
Wọn á máa fẹsẹ̀ wọ́lẹ̀, wọn á máa wá oúnjẹ kiri,bí wọn ò bá sì yó wọn á máa kùn.
Má bú ọba, kì báà jẹ́ ninu ọkàn rẹ,má sì gbé ọlọ́rọ̀ ṣépè, kì báà jẹ́ ninu yàrá rẹ,nítorí atẹ́gùn lè gbé ọ̀rọ̀ rẹ lọ,tabi kí àwọn ẹyẹ kan lọ ṣòfófó rẹ.
Awon miiran ti yoo ma tun maa
Ijọba Naijiria si fi eyi to ijọba Saudi leti ti wọn fi da ọmọ obinrin naa silẹ.
Adedoyin di oloogbe losu ti o koja lojo kejidinlogbon odun ti a wayii, nipinle Kwara.
Awọn ẹṣọ alaabo rẹ fi tipatipa mu Moeketsi ni 1989, ti wọn si pada ri oku rẹ.
Kà nípa ìròyìn mánigbàgbé tí BBC News Yorùbá ṣe láàárín ọdún kan Ẹwẹ, Ọmọbabinrin Taiwo ni bi ọrọ tabi iṣẹlẹ ba waye, atoun atawọn oloye lawọn yoo jokoo gbe e yẹwo lati wo ohun to dara lati ṣe, o ni ijọba oun kii ṣe bii eyi ọba a ṣaa maa ba lori ohun gbogbo gẹgẹ bi wọn ṣe maa n sọ.
Wọ́n ti ń gbé ibẹ̀, wọ́n sì ti kọ́ ibi mímọ́ sibẹ fún ìjọ́sìn ní orúkọ rẹ, 
Kò sí oúnjẹ, kò sí omi, burẹdi fẹ́lẹ́fẹ́lẹ́ yìí ti sú wa.
Ọṣun Decides:'Màá san gbogbo owó oṣù òṣìṣẹ́ lékunréré'-Akinbade
Wọn yóo di àwọn ohun èlò ìsìn yòókù sinu aṣọ aláwọ̀ aró kan, wọn yóo sì fi awọ ewúrẹ́ tí ń dán bò wọ́n, wọn óo gbé wọn ka orí igi tí a óo fi gbé wọn.
’’“Ki i se iwa odaran ni pe, e wa si orile ede Russia, ki o wa je iwa odaran lati pada sile.
Gbogbo wọn jẹ́ ọmọ Jediaeli; àwọn tí wọ́n jẹ́ baálé baálé ní ilé baba wọn ati akọni jagunjagun ninu ìran wọn tó ẹẹdẹgbaasan-an ó lé igba (17,200).
Ọ̀kan nínú àwọn gbólóhùn tí mo fẹ́ràn láti ma kà nínú ìwé Alawiye rẹ.
Ẹ̀dá burúkú ni Ikú, kò sì ní ẹran kan ṣoṣo lára, ó kún fún kìkì egungun, ojú rẹ̀ tóbi tó àwọ oúnjẹ, ó dà bí òṣùpá, ó ń pupa bí iná, ó sì ń yí bí ìgbà tí èèso igi tí ó tóbi bá doríkodò tí atẹ́gùn kékeré ń fẹ́ ẹ sí ihìn àti sí ọ̀hún.
UK students Phone ban: A fẹ́ bẹ̀rẹ̀ òfin má lo fóònù mọ́ fàwọn ọmọ wa -Òbí
Bi Timi Agbale Ọlọfa Ina se jade laye ree, ti inu ọrẹ rẹ ko si dun si isẹlẹ naa rara, eyi to mu ko ransẹ si Alaafin Sango pe ko fi ori apere silẹ tabi ko ṣí igba wo, eyi to tumọ si pe ko ku nitori iku to n pa ojugba ẹni, owe nla lo n pa fun ni.
Tí ọ̀dọ́ bá ni okoòwò kan ti ó ṣe kówólé, àwọn ilé ifowópamọ́ kéèké to wà lọ́bẹ́ Banki àpapọ̀ Naijiria (CBN) yóò fún wan lọ́wọ́ láti bẹ̀rl okoòwò náà.
 Ìdí nìyí ti ilé yìí fi ńjé ilé elékuru .
Agboole Ayan, tii ṣe onilu ni Sikiru ti wa, kekere si ni baba rẹ, Oloye Ayanleke Adepoju ti kọ ni ilu lilu.
Amugbalegbe aare lori eto iroyin, ogbeni Bashir Ahmad lo jabo idagbasoke ohun lojo Aiku(Sunday).
O fi kun un pe oun ti ya ara oun sọtọ gẹgẹ bi ilana ajọ NCDC eyi to ni ṣe pẹlu awọn to ko arun naa ṣugbọn ti ko ni ami ifara han rẹ.
Nigba to n ba BBC Yoruba sọrọ, Ajihinrere Mike Bamiloye, tii se ẹni to gbe awọn sinima awodamiẹnu naa sita ni ọdun gbọọrọ sẹyin, salaye nipa awọn asiri aseyọri rẹ.
Ǹjẹ́ fífi omi àti iyọ̀ yọnu leè dènà àrùn Coronavirus?
"Ẹ̀yin ọmọ Yorùbá lókè òkun, ẹ má bẹ̀rù mọ́ láti wálé - Akeredolu Ẹ̀yin ẹkùn yókù, ẹ fi ikọ̀ àbò ""Amotekun ṣe àwòkọ́ṣe rere - APC Imam tó fẹ́ ọkùnrin míì níyàwó forí kó ìjìyà òfin Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'A rí wàhálà táwọn èèyàn ń kojú nilẹ̀ẹ̀ Yorùbá la ṣe fi ""Amotekun"" fi ọkàn wọn balẹ̀' Lori Owo Oṣu Ikọ Amọtẹkun ""Bẹẹ ba ri iye owo kan ti awọn eeyan kan n tan kalẹ bii N13,500 abi nkan mii pe ohun ni owo oṣu wọn, irọ nla ni o."
Wọ́n sì pàgọ́ sí etí odò Meromu.
Gbogbo ẹ̀yin ará Filistini,ẹ má yọ̀ pé a ti ṣẹ́ ọ̀pá tí ó lù yín;nítorí pé paramọ́lẹ̀ ni yóo yọ jáde láti inú àgékù ejò,ejò tí ń fò sì ni ọmọ rẹ̀ yóo yà.
Babaláwo rèé pẹ̀lú afurasí adigunjalè mẹ́rin láhàmọ́ọ́ ọlọ́pàá Ninu fido naa ni Dokita Stella Immanuel, tii se onisegun alabọde nilu Houston kede nibi ipade akọroyin kan pe, oun ti fi oogun Hydroxychloroquine wo alarun Coronavirus to to ọtalelọọdunrun o din mẹwa.
Tí ẹ bá dá mi lóhùn, èmi náà yóo wá sọ irú agbára tí mo fi ń ṣe nǹkan wọnyi.
6 197998 Orilẹede Canada 12688 34.
Ó bá ń gbé ààrin àwọn eniyan náà.
Oríṣun àwòrán, OTHERS Àwọn nkan yìí ni ọpọ eniyan ko mọ nipa rẹ Chukwuemeka Ohanemere ni orúkọ abisọ rẹ O bẹrẹ lati ijọ Charismatic Movement, sugbọn ọpọ awọn ọrẹ rẹ si ma fi n ṣe yẹyẹ nigbati o ni oun fẹ da ijọ ti oun kalẹ Ọpọ lo maa n rò pe ọmọ bibi ilú Anabra ni, sùgbọ́n ọmọ Orlu ni ipnlẹ Imo ni iya ati baba rẹ.
Gomina ohun , eni ti igbakeji re omowe Idiat Adebule soju fun so pe, erongba ipade ohun ni lati la awon ara-ilu loye lori eto-oselu lorile-ede Naijiria, ibara-eni gbe po ati ilana eto oro-aje.
O ni otitọ ni pe awọn ọlọpaa n gbiyanju lati maa mawọn eeyan ti wọn ko tẹ le ilana ti ijọba la kalẹ lori at i dena itankalẹ aarun covid-19.
Wo ìmọràn tó lè jẹ kóo gbádùn ṣíṣe iṣẹ láti ilé lásìkò kónílé-ó-gbélé COVID 19 yìí Kọ́ sí i nípa àwọn oúnjẹ aṣaralóore tó yẹ kí Aláboyún máa jẹ Duro Ladipọ lo bẹrẹ lilo awọn ilu isẹnbaye ninu ijọ ọmọlẹyin Kristi, ti wọn si le e kuro ninu ijọ nitori wọn ri iwa yii gẹgẹ bii eewọ nla, Amọ lati akoko naa, asa yii ko parun, ti wọn si n lo ilu abalaye lasiko ọdun Keresi.
Ọpọ tiẹ fi ṣe yẹyẹ fun aṣiṣe rẹ papaa julọ pẹlu iriri rẹ ninu iṣẹ iriyin.
Ta ló fi í ṣe alákòóso ayé,ta ló sì fi jẹ olórí gbogbo ayé?
"Kemi Afolabi joyè ìmọ́lẹ̀ Adinni Diẹ lara awón to ti ki wọn: Bimbo Oshin sọ pe ""Ẹ ku oriire o, ṣugbọn bawo ni mi o se gbọ nipa igbeyawo naa?"
Ohun tí ó sọ ni pé, “Oluwa yóo bá ọ wí.
Ṣe awọn obi yoo fi iṣẹ silẹ ati gbogbo ohun ti wọn ba n ṣe lọna ati ri i pe wọn bojuto ọmọ?
Aiku nibi ipade apero ti ajo isokan agbaye to n lọ lọwọ
atundi ibo yoo gbe waye  lati lee
Kábíyèsí, ayé ṣòro, ẹ̀yin àgbàlagbà sì ti wí pé ilé ni a ti ń ko ẹ̀sọ́ ròde, ilé ni ikú wa, orúkọ ẹran àjàyí, ayanmopin ẹran olugbode, ará òde kò mọ ni gẹgẹ bí ẹrú, ara ilé níí tọ́ka sí ni.
Orin Ayinla Ọmọwura tun maa n kun fun ijinlẹ ọrọ Yoruba, owe, akanlo ede ati imọran.
Olori ile aṣofin naa, Bukọla Saraki fi ẹsun kan oluranlọwọ fun Buhari lori ọrọ ile aṣofin, Ita Enang pe oun lo ji iwe owo iṣuna ọhun, to si fi omiran rọpo rẹ.
Aṣofin Ipinlẹ to waye kaakiri Orilẹ-ede Naijiria ni ẹgbẹ oselu All
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Akinyẹmi: Ọgbun mẹrin to wa niwaju aarẹ tuntun ni South Africa 15 Èrèlè 2018 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Omi n laamu fun Cyril Ramaphosa Pẹlu bi ọgbẹni Jacob Zuma ti se kọwe fi ipo rẹ siẹ bayii, ibeere lẹnu ọpọlọpọ lorilẹede SouthAfrica ati kaakiri agbaye ni wipe, ki lo kan bayii nibẹ?
Ọ̀tá ti lé mi bá,ó ti lù mí bolẹ̀;ó jù mí sinu òkùnkùn,bí ẹni tí ó ti kú tipẹ́tipẹ́.
"Ọlatunbọsun ni ""Alafia ni a wa ni olu ile ise egbe wa, ti a si n ba ise wa lo ni iroworose."
Alhaji Usman Daura: Oun ni olori ẹṣọ alaabo fun Aarẹ Shehu Shagari, Ọgagun Muhammadu Buhari ati Ọgagun Ibrahim Babangida laarin ọdun 1981 si 1989.
Lara Ise akanse ohun ni kiko ibudo awon ero fun eto irinna ipinle naa.
Koda awọn kan rọ Trump pe ko maa lọ mu 'bleech' o, gẹgẹ bo se gba awọn eeyan to ni arun Coronavirus niyanju.
Àwọn ni wọ́n tẹ gbogbo pẹ̀tẹ́lẹ̀ àwọn oníṣẹ́ ọwọ́ dó.
"Asiko kan tiẹ wa to se ọjọ ibi, ti oun ati Alaafin dijọ n gbe ife ọti si ara wọn lẹnu, to si fesi loju opo ayelujara pe ""Ta ni ẹlẹ daddy ati oxygen ti Alaafin fi n mi bayii?"
“Bí mo tí ń rékọjá lọ lẹ́gbẹ̀ẹ́ rẹ, mo rí ọ tí ò ń ta ẹsẹ̀ ninu ẹ̀jẹ̀.
Bee si ni, iko ohun tun dipo kerin won mu nile Afrika.
Ọọ̀ni: Àwọ̀ méje bíi pupa, aró, ewéko ni omi àjèjì náà ní
Àwọn ọmọ Aṣeri nìwọ̀nyí: Imina, Iṣifa, Iṣifi ati Beraya, ati ọmọbinrin kan tí ń jẹ́ Sera.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, John Amanam: Ìfẹ́ tí mo ní sí àbúrò mi ló sọ mi dí ẹni tó ń ṣe 'Prosthetic' báyìí Ọ̀pọ̀ ẹ̀mí ló ṣòfò nibi ìjàmba tó wáye ni Akungba nìpińlẹ̀ Ondo Ọ̀pọ̀ ènìyàn ló ti ba ìjàmbá alẹ́ ọjọ́ Abámẹ́ta rin ní ìlú Akungba Akoko, ìjọba ìbílẹ̀ Iwọ oorun-Gúúsú nípìnlẹ̀ Ondo.
Àwọn Ọmọ-ẹ̀yìn Jesu Ń Já Ọkà ní Ọjọ́ Ìsinmi.
O to ọjọ mẹta ti aawọ yi ti n rugbo bọ eyi to pada wa kangun si pe igbimọ ayẹwo ẹgbẹ sọ pe Gomina Obaseki ko tọ lẹni to yẹ ko gbe apoti ibo labẹ asia ẹgbẹ.
Oríṣun àwòrán, Instagram/Bashir Ahmad Irinajo si orilẹ-ede Japan Aarẹ Buhari rinrin ajo lọ si ilẹ Japan loṣu kẹjọ fun apero lori idagbasoke fun awọn orilẹ-ede ilẹ Adulawọ, TICAD7.
Ọba ni ó gbọdọ̀ máa pèsè ẹbọ sísun, ẹbọ ohun jíjẹ, ati ẹbọ ohun mímu ní gbogbo ọjọ́ àjọ̀dún, ati àwọn ọjọ́ oṣù tuntun, àwọn ọjọ́ ìsinmi ati àwọn ọjọ́ àjọ̀dún tí a yà sọ́tọ̀ fún àwọn ọmọ Israẹli.
Ṣeun Kuti fi òyìnbó àwọn ọ̀gá ọlọ́pàá ṣe yẹ́yẹ́ tí wọ́n kọ tako ẹgbẹ́ bàbá rẹ̀ tó jíǹde padà lẹ́yìn EndSARS Kí ló ṣokùnfà iná tó sọ ọjà Shasha dahoro n'Ibadan?
Wọ́n ti sin òkú Kazeem Tiamiyu tí wọ́n sọ pé SARS pa ní Sagamu Àṣìta ìbọn pa èèyàn kan lásìkò tí SARS ń kojú adigunjalè l'Eko Ọjọ́ burúkú, èṣù gbomi mu ní Ṣagamu nígbà tí agbábọ́ọ́lù kan dèrò ọ̀run Makinde ni iwọde ENDSARS ṣafihan bi nkan ko ṣe rọgbọ lawujọ mọ to si tun ni o mu ki eeyan maa ṣeemọ bi agbara ko ti ṣe si lọdọ Gomina ti wọn pe ni alaṣẹ ijọba ipinlẹ.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ibà yọ Serena Williams ní Madrid open Orí ló mọ iṣẹ́ àṣelà Mo lòdì sí jíjọ gbàlejò ife àgbáyé-Blatter Serena ti gba ife ẹyẹ Italian Open nigba mẹrin ọtọọtọ.
Ṣugbọn Ahasi dáhùn, ó ní: “Èmi kò ní bèèrè nǹkankan, n kò ní dán OLUWA wò.
ọmọ Aminadabu, ọmọ Adimini, ọmọ Arini, ọmọ Hesironi, ọmọ Pẹrẹsi, ọmọ Juda, 
wọ́n gbé e jù sinu kànga kan tí kò ní omi ninu.
BUSA19: Bí ètò ìgbéyàwó ààrẹ Buhari kò bá ṣe lọ rèé -àwọn ènìyàn Nàíjíríà
Ìlú yìí lè ṣàì dára lójú ẹlòmmíràn, ṣùgbọ́n èmi ni tèmi, mo gbáduǹ ìlú yin n kò sì sí nínú àwọn ẹlòmíràn tì ń sọ̀rọ̀ yín lẹ́yìn pé ìlú yìí kò dára.
Nítorí pé àtọlọ́gbọ́n, àtòmùgọ̀, kò sẹ́ni tíí ranti wọn pẹ́ lọ títí.
ofin orile ede Naijiiria, eyi ti yoo faye gba awon ipinle ati ijoba ibile ni
'Oyún ìju ni mo bá dé ilé ìwòsàn; abẹ́rẹ́ Formalin ni wọ́n gún mi' Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí kan sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
Ọmọ China ni mí n kò sì kí ń ṣe àjọyọ̀ Òyìnbó.
Obìnrin 200 gbé ìléeṣẹ́ tó ń ṣètò ìfètòsọ́mọbíbí lọ ilé ẹjọ́ Wo ohun mẹ́wàá tó yẹ kóo mọ̀ nípá ọmọ ọdún mẹ́wàá Emmanuella tó kọ́ ilé ńlá fún ìyá rẹ̀ Bàbá àádọ́rin ọdún fún ọmọ-ọmọ rẹ̀ ọdún mẹ́ẹ̀dógún lóyún, lọ̀rọ̀ bá pèsì jẹ Ara meriri, mo ri ori olongbo lori atẹ ni ọna ti iwa ifipabanilopọ pẹlu awọn majesin tun gba yọ bayii.
Eeyan 1,147 si ni aarun coronavirus ti ṣekupa lorilẹede Naijiria bayii.
Pé kò ní yà òun lẹ́nu tí àwọn jàgùdà olè bá tẹ̀lé àwọn ọkùnrin náà láti jàwọ́n lólè, tí wọ́n á sì gba gbogbo owó ọwọ́ wọn.
Lẹyin ti idibo aarẹ ba ti pari nilẹ Amẹrika, o lee to ọpọlọpọ ọjọ koda o lee to ọsẹ melo kan lati wadii boya Donald Trump tabi Joe Biden lo jawe olubori.
Mo dì í mú, n kò sì jẹ́ kí ó lọ,títí tí mo fi mú un dé ilé ìyá mi,ninu ìyẹ̀wù ẹni tí ó lóyún mi.
Ẹ gbọ̀n jìnnìjìnnì, ẹ̀yin obinrin tí ara rọ̀,kí wahala ba yín, ẹ̀yin tí ẹ wà ninu ìdẹ̀ra,ẹ tú aṣọ yín, kí ẹ wà ní ìhòòhò;kí ẹ sì ró aṣọ ọ̀fọ̀.
Ẹlẹ́wọ̀n Kirikiri tó ń wọ́ke, olùdarí ọgbà ẹ̀wọ̀n ló ṣe onígbọ̀wọ́ fun - EFCC Ilé aṣòfin Amẹrika gbọnmú lórí ìtìmọ́lé Sowore, ó ní ìjọba Nàíjíríà tako òmìnira aráàlú Ẹ wo ìpínlẹ̀ táwọn gómìnà tẹ́lẹ̀ àti igbákejì wọn ń gba dúkìá ìfẹ̀yìntì tabua Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
gígé ni kí ẹ gé ọwọ́ rẹ̀, ẹ kò gbọdọ̀ ṣàánú rẹ̀ rárá.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù World Autism Day: Ojojúmọ ní mọ ń kẹ́kọ̀ọ́ lára ọmọ mi to jẹ akanda Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ World Autism Day: Ojojúmọ ní mọ ń kẹ́kọ̀ọ́ lára ọmọ mi to jẹ akanda 2 Ìgbé 2019 Gẹ́gẹ́ bi ọjọ òní ṣe jẹ ọjọ àwọn àkanda ọmọ lágbàyé, Ilaniloye tí ń tàn kálẹ̀ láti ríi dáju pe kò si ìdẹ́yẹ si gbogbo àwọn to ba jẹ àkanda ní àwùjọ wa.
Agbára ìrònú pọ̀, òun ni ìyàtọ̀ tí ó wà láàrin àwọn ọmọ ènìyàn àti àwọn ọmọ ẹranko.
Isẹ asofin tí mo ń ṣe tó mi, àmọ́ ìlú ko le è pé mi, kí n má jẹ́, ní mo ṣe dù ipo gómìnà, mo sì gbà pé Ọlọ́run fẹ ki n se ni.
Oriade Adebisi, ọmọ ọdún méjìlélógún kan tó jẹ́ ọmọ fásiti Olabisi Onabanjo tó wà ní Osu, Ipínlẹ̀ Ogun ń lọ kí ọ̀rẹ́ rẹ̀ ní Oru-Ijebu pẹ̀lu olólùfẹ́ rẹ̀ Julian Imaga, nigba tí àwọn mẹéjééji di àwáti.
Ọ̀kan dáhùn, ó ní, Ó mà ṣe o,  ọkùnrin yìí kò lè fura ní ọjọ́ kan láée wí pé oògùn ni ìyàwó òun ń fi sí omi fún òun mu ni alaalẹ́!
“Majẹmu tí Èmi bá wọn dá nìyí: Ẹ̀mí mi tí mo fi le yín lórí, ati ọ̀rọ̀ mi tí mo fi si yín lẹ́nu, kò gbọdọ̀ kúrò lẹ́nu yín, ati lẹ́nu àwọn ọmọ rẹ, ati lẹ́nu arọmọdọmọ yín, láti àkókò yìí lọ ati títí laelae.
Ẹni tí ó kẹ́gàn ìmọ̀ràn yóo parun,ṣugbọn ẹni tí ó bá bẹ̀rù òfin yóo jèrè rẹ̀.
Ma ṣe jẹ ounjẹ tabi eso ti eku ti fi ẹnu kan.
"O gba wa ni akoko gan lati ṣe bẹẹ fun eeyan miliọnu mẹsan ti a ni bayii nitori naa iṣẹ nla ni lati ṣẹṣẹ maa tun un ṣe""."
Lara ohun ti wn la kalẹ lati ṣe ni ọjọ Keresi ni pe wọn yoo dana orisisi ounjẹ mejila ti wọn yoo si jijọ ṣere kaadi tita nitori iṣede to wa nita Kini kan ti Mohammad ni o n jẹ iyalẹnu fun oun ni bi awọn eeyan ṣe n duro lati tu ẹbun wọn ti wn ko kalẹ ''Diduro de asiko ti a o tu ẹbun wa n ṣemi bakan.
Àwọn ikọ̀ mẹ́fà tí kò lè jẹ́ kí ìwọ́de #End SARS, #End SWAT wa sópin lásìkò yìí Oríṣun àwòrán, others Wo ìsọ̀rí àwọn tó jẹ́ kí ìwọ́de End SARS lárinrin àti ìtumọ̀Iwọde End SARS to n lọ lọwọ kaakiri awọn ilu nla ni Naijiria ni ọpọ awọn onwoye ohun to n lọ ti sọ pe o jẹ ọkan Pataki lara awọn iwọde to ni eto julọ ni Naijiria.
Nítorí náà, n óo fún un ní ìpín, láàrin àwọn eniyan ńlá,yóo sì bá àwọn alágbára pín ìkógun,nítorí pé ó fi ẹ̀mí rẹ̀ lélẹ̀ fún ikú,wọ́n sì kà á mọ́ àwọn ẹlẹ́ṣẹ̀.
Nítorí ò ń sọ pé: Mo lówó, mo lọ́rọ̀.
gbe sita lọjọ Ẹti pe: “Aare Buhari ba awon omo ipinle Eko ati ijoba kẹdun lori ijamba
Nigba to n sọrọ lori isẹlẹ naa, ọga agba ọlọpa ilẹ wa, M.
 Titi ti mo fi ri, mi o tilẹ ro nkan ti yoo wọ, sugbọn eyi ko tilẹ ni itumọ nitori mo mọ pe gbogbo nkan to ba tilẹ wọ gbogbo rẹ lo ṣe rẹgi lara rẹ Oríṣun àwòrán, Sanjana Rishi Bi ọpọ eniyan ṣe wa n bere oniruuru ibere, ni Rishi salaye pe oun ko ṣetan lati sọ ohunkohun ti awọn eniyan yoo maa sọ ka, sugbọn ti oun ba ṣe igbeyawo naa ni kọrọ ko si nkan ti yoo ṣẹlẹ.
2019 elections: Kíni ó ń fa èdèàìyedè lẹ́gbẹ́ APC ìpínlẹ̀ Eko
Ipade ohun ni yoo da lori awon isoro to n koju eto aabo, ikolu awon omo-ogun olote abbl.
Ile itura iko agbaboolu Super Eagles, Radisson Blu Hotel gbalejo repete lojo Isegun(Tuesday), leyin ti agbaboolu mejilelogun bale sipago iko naa tin se Wroclaw, fun igbaradi ni kikun saaju ifesewonse olorejore ti yoo waye lojo Eti(Friday) pelu orile-ede Poland.
Aare  Muhammadu Buhari  ti seleri lati je ki awon odo ati obinrin lọwọ
Ẹ tú yáyá jáde dìbò f'ẹ́ni tó wù yín lọ́la- Buhari Owo itanran to din diẹ ni ẹẹdẹgbẹta miliọnu pọn-un ni ajọ FIFA ni ki Chelsea san.
" Agbára wa kò ká àrùn Covid-19 mọ́ - Ìjọba ilẹ̀ Amẹrika Ṣé Biden lè fẹ̀yìn Trump kó di ààrẹ America tó kàn?
Ṣé ẹ kò mọ̀ pé OLUWA ni ìwọ ati àwọn ẹlẹgbẹ́ rẹ ń ṣọ̀tẹ̀ sí, nígbà tí ẹ̀ ń fi ẹ̀sùn kan Aaroni?
Ẹfunsetan Aniwura, obìnrin tó ju ọkùnrin lọ Ọ̀rọ̀ǹpọ̀tọ̀niyùn, Aláàfin obìnrin àkọ́kọ́ rèé, tó ní nǹkan ọkùnrin Taiwo Akinkunmi, ọmọ Ibadan tó ya àsìá Nàíjíríà Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Sùgbọ́n àwọn tọ jẹ́ pé, olá ìjọba ni wọ́n fi n mí, àti àwọn òṣìṣẹ́ ìjọba, ìdẹnukọlẹ̀ ètò ọ̀rọ̀ ajé pa wọ́n lára gidi ni.
Ọba aláde o gbọdọ kọ iyàwó rẹ̀ sílẹ̀- Bakare, Iba àṣà Yorùbá Ọ́nà láti di gbajúmọ̀ olówó ló sọ mi di aṣẹ́wó ni India- Grace Ọmọ Nàìjíríà bu ẹnu ẹ̀tẹ́ lu iléeṣẹ́ Netflix lórí fíìmù tó ní Jesu ní ìbálòpò akọ s'ákọ Folajogun to da ẹgbẹ arannilọwọ silẹ ati Arabinrin Ruth Olowo okere to jẹ iyaloja Akure naa sọrọ lori bi ijọba ati ẹlẹgbẹjẹgbẹ ṣe le maa ran awọn akanda ẹda lọwọ lasiko yii.
Ọpọ awọn alaarun Covid-19 lo si ti n lo ibomu ti ẹrọ naa n pese nile iwosan to wa ni Johannesburg.
Ẹni tí ó gba òmùgọ̀ tabi ọ̀mùtí sí iṣẹ́dàbí tafàtafà tí ń pa eniyan lára kiri.
Ṣe ọpọlọpọ yàrá sinu rẹ̀, kí o sì fi ọ̀dà kùn ún ninu ati lóde.
Nígbà tí ilẹ̀ ọjọ́ kẹta yóo fi ṣú, gbogbo àwọn ọkunrin tí wọn ń gbé agbègbè Bẹnjamini ati Juda ni wọ́n wá sí Jerusalẹmu.
Amọ eyi ti fa ariyanjiran ni oju ọpọ ikansiraẹni Twitter ti ọpọlọpọ eniyan si n bere pe ki lo n ṣẹlẹ ni ipinlẹ Kano.
Ẹgbẹ́ yìí ń gbìyànjú láti gbé ìlànà tí ọmọ Yorùbá yóò fi ní ìrírí àṣà, ìgbéga fún sísọ àti kíka èdè Yorùbá, wọ́n sì fẹ́ ṣe àwárí ìmúpadàbọ̀sípò àti tí tẹ́wọ́ gba ìwà ọmọlúàbí l'áwùjọ.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Olatunji ati awọn ọrẹ rẹ tilẹ ma n wọ aṣọ alaranbara ilẹ Yoruba lati wọ awọn ọkọ igboro naa.
” Jakọbu bá dáhùn pé, “Èmi ni.
Ma ṣe fi ara kan ara pẹlu ẹni to ba ni aisan yii.
Jakọbu bí Josẹfu ọkọ Maria, ẹni tí ó bí Jesu tí à ń pè ní Kristi.
O pasẹ fun wọn pe ki wọn da awọn foonu ati irinsẹ wa ti wọn gba pada, ti wọn si le wa jade kuro ninu agbala wọn.
Yọ apákan sílẹ̀ fún OLUWA lára ti àwọn tí wọ́n lọ sójú ogun, ninu ẹẹdẹgbẹta tí o bá kà ninu eniyan ati mààlúù ati kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ ati ẹran ọ̀sìn, ọ̀kan jẹ́ ti OLUWA.
finish : n ; ( the story was a lie from start to finish .
Bí Ọmọ Ọlọrun bá ni ọ́, sọ̀kalẹ̀ kúrò lórí agbelebu.
“Lẹ́yìn náà, ẹni tí ó gba àpò kan wá, ó ní, ‘Alàgbà mo mọ̀ pé eniyan líle ni ọ́.
Wọ́n wọlé, wọ́n dúró lẹ́gbẹ̀ẹ́ pẹpẹ idẹ.
Aare gboriyin fun awon alakoso ile-ise LADOL fun sise amulo ofin ati ilana ti isakoso ijoba re fi kale lati fi tuko ile-ise won, bee si ni mimu awon olokoowo lolokan-o-jokan nile yii ati loke okun wole lojuna ati mu igberu ba eto oro aje orile-ede yii.
”“mi o mọ erongba yin lori aare ana,Abacha sugbon mo gba lati baa sise papo .
Àkọlé àwòrán, Ile Abiọla kun pitimu fun ero lati se ayajọ June 12 Àkọlé àwòrán, Ọdọọdun ni awọn ajafẹtọ ẹni maa n se iranti MKO Abiọla Àkọlé àwòrán, Ero ko gbẹsẹ ni ile Abiọla fun ayajọ June 12 Àkọlé àwòrán, Haa, ilẹ n jẹ eeyan.
 apis ni a máà ni a máa ń pò ní kókó gbólóhùn nínú àwon ìwé tètèdé onígírámà nítorí pé ó ní òrò-ìse nínú .
Wọ́n ya Ramoti tí ó wà ní Gileadi sọ́tọ̀ ní agbègbè ti ẹ̀yà Gadi, ati Golani tí ó wà ní Baṣani, ní agbègbè ti ẹ̀yà Manase.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù #EkitiDecides: Kayọde Fayẹmi ní wíwọ ẹ̀wù agbọta kò lòdì sí òfin Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ #EkitiDecides: Kayọde Fayẹmi ní wíwọ ẹ̀wù agbọta kò lòdì sí òfin 10 Agẹmo 2018 Olùdijé fún ipò gómìnà lábẹ́ àsìá ẹ́gbẹ́ òṣèlú APC sọ nípa bí ó ti ṣe se ètò ìjọba rí àti èyi tí yóò ṣe bó bá wọ́le.
Ó ní, “Bí inú rẹ bá dùn sí mi nítòótọ́, OLUWA, jọ̀wọ́, máa wà láàrin wa, nígbà tí a bá ń lọ, bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé olóríkunkun ni àwọn eniyan náà; dárí ẹ̀ṣẹ̀ ati àìṣedéédé wa jì wá, kí o sì gbà wá gẹ́gẹ́ bí eniyan rẹ.
Iwe ẹri to n ṣafihan iye ọjọ ori rẹ.
OAU kò fààyè gba kí olùkọ́ fi tipá bá akẹ́kọ̀ọ́ lòpọ̀ A fẹ́ gbé ìgbìmọ̀ kan kalẹ̀ láti wòó bóyá nǹkan tí a gbọ́ lórí ìkànnì ayélujára jẹ́ òòtọ́ tàbí irọ́."
Lẹyìn tí mo figbe ta, INEC mú PVC mi wá bá mi nílé - Gani Adams Kíni itunmọ ọrọ 'body bag' tí Gómìnà El-Rufai sọ?
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Mo máa n forin mi kìlọ̀ ìwà ìbàjẹ́ láwùjọ ni -Hameen 'Mo mọ pe awọn agbabọọlu naa ti gbaradi nipa ti ara, lai fi ti pe wọn n ṣaisan tabi farapa ṣe.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Owu Water Fall: Ọba Oyewole ni ibùdó ìrìn àjò afẹ́ gidi ni àmọ́ ọ̀nà ibẹ̀ burú jáì Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 3 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 5 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Ṣé ohun tí ẹ ṣe sí ìdílé Gideoni tọ́?
Wo oríṣìí oúnjẹ márùn ún tó lè dẹ́kun ikùn yíyọ àti ara àsanjù Wo àwọn oúnjẹ márùn ún tó ń mú kí àtọ̀ ọkùnrin dára síi Koda, o mẹnuba irufẹ ifẹ ti oun ni lati maa ṣe iṣẹ to lagbara, to le to jẹ iṣẹ ti a mọ ọkunrin mọ ni eyi ti oun fi lọ ka sii nipamiṣẹ afi-irin-dara sii ni Institute of Technology.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Adeboye: Màá fi ọlọ́pàá gbé ẹni tó bá lo fọ́tò mí sára kàlẹ́ńdà 9 Ọ̀pẹ̀̀ 2018 Oríṣun àwòrán, @rcgchristchurch Olusọagutan Adejare Adeboye ti n fi ewe ọmọ mọ awọn ọmọlẹyin ijọ Redeem lagbaye pe ki wọn pinwọ iwa fifi aworan oun ati aya oun sara awọn ẹbun ti wọn ba n pin.
‘Ọkùnrin yóò máa bá iṣẹ́ tàbí ìwé rẹ lọ, ṣùgbọ́n obìnrin parí tirẹ̀ síbẹ̀ nìyẹn o.
Bẹẹ naa ni Reuben Abati to jẹ agbẹnusọ aarẹ ana, Goodluck Jonathan fi iroyin naa sori atẹ Twitter rẹ pee Akindele ti bimọ ni tootọ.
Trump ni: “Mo fe ki eyin Asofin ti awon ara ilu dibo yan gbe abadofin sita ni eyi ti asoju egbe oselu mejeeji yoo ti fenuko fimosokan lori ona abayo si ibon lilo ni Amerika.
( a ) aféré : - Ìlù nla ni afẹrẹ .
Àkọlé àwòrán, Samuel nikan kọ lo n ṣe iru iṣẹ yii ninu ile ti obinrin naa n gbe.
Niṣe lo yẹ ki onikaluku maa fọwọ wọn loorekoore ki wọn si tẹle gbogbo imọran ajọ WHO lori didẹkun itankalẹ ajakalẹ aarun coronavirus laisko yii.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Lọ́gán tí mo bá di ààrẹ, mo máa bẹ̀rẹ̀ iṣẹ́' Olusegun Mimiko yóò du ipò àarẹ Nàìjíríà Àkọlé àwòrán, Mimiko kéde láti dupò Ààrẹ ni 2019 Wọn ko fẹ ọ nilu o ń da orin,toba da tan tani yoo ba o gbe?
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Chow Chows Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Africa in Pictures: Àwọn àwòrán tó jojú ní gbèsè láti Africa
Funke Akindele, Toyin Abraham, Bimbo Oshin ṣe Kérésìmesì lọ́nà àrà Èyí ni ìdí tí a kò fi yọ̀nda El-Zakzaky pẹ̀lúù Sowore àti Dasuki- Malami Lori iwọkuwọ ati awọn aṣa ti ko fi bẹ ẹ bojumu ninu sinima Yoruba lode oni, Afod sọ wi pe ọwọ ajọ ti ijọba gbe kalẹ lati maa yẹ sinima wo, Censors Board lo yẹ ko mojuto ojulowo sinima.
Oríṣun àwòrán, @Seyi Àkọlé àwòrán, Kini orisun owo Seyi Makinde ni ibeere awọn kan?
Yóo gbé ọwọ́ lé orí ẹbọ ìmúkúrò ẹ̀ṣẹ̀ yìí, yóo sì pa á, níbi tí wọ́n ti ń rú ẹbọ sísun.
Ó ṣe ohun tí ó burú lójú OLUWA, ó tẹ̀lé ọ̀nà baba rẹ̀, ó sì dá irú ẹ̀ṣẹ̀ tí baba rẹ̀ mú kí Israẹli dá.
Ọdun mejidinlogun si lo fi gba bọọlu, ko to fẹyin ti Chichi ni isan, idi ati egungun lile ju awọn ọkunrin miran lọ , ti irisi rẹ ko si yatọ si tawọn ọkunrin amọ obinrin ni.
Àwọn tí wọn tí ń jẹ oúnjẹ àdídùndi ẹni tí ń ṣa ilẹ̀ jẹ kiri ní ìgboro.
Adaari agba ile-ise naa, Mark Zuberberg sọ wipe esi atunto naa se pere ju ohun ti wọn fojusọna fun ati wi pe atunse naa yoo ran itakun Facebook lọwọ lọjọ iwaju.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù NLC: Ìjọba ti gbà láti san owó oṣù mẹ́rin fáwọn òṣìṣẹ́ l'Ọ́ṣun 10 Ògún 2018 Oríṣun àwòrán, Nigeria Labour Congress Àkọlé àwòrán, Ijọba ni lootọ ni wọn yoo san owo oṣu mẹrin ninu mẹtalelọgbọn ti ijọba jẹ awọn oṣiṣẹ ati oṣiṣẹfẹyinti nipinlẹ naa Ẹgbẹ oṣiṣẹ nipinlẹ Ọṣun ni ijọba ipinlẹ naa ti gba lati san ajẹẹlẹ owo oṣu mẹrin ninu owo oṣu mẹtalelọgbọn ti wọn jẹ awọn oṣiṣẹ.
Wọn fi ọrọ naa to awọn ọlọpa leti, tawọn naa si fi isẹlẹ ọhun to olu ileesẹ wọn leti nitori igba akọkọ ree ti iru isẹlẹ ijọmọgbe bẹẹ yoo waye Iwadii ti ileesẹ ọlọpaa se lati se awari bi Adediwura se poora: Ọrọ yii ko lojutu titi di ọjọ Kẹwaa, osu Keji, ọdun 1949, iyẹn nigba to pe osu kan gbako ti Adediwura poora.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Abiyamọ fi ọmọ sínú ọkọ̀ wọlé lọ, lọ̀rọ̀ yíwọ́ 25 Èbibi 2018 Oríṣun àwòrán, LAGOS STATE POLICE COMMAND Àkọlé àwòrán, Ọkọ Hyundai náà ń lọ fúnra rẹ̀ títí fò tí ó fi já sí inú kòtò ńlá kan nítórí pé arábinrin náà kò fa ìjanu ọkọ̀ ti ọlọ́wọ́.
Kí ni ìtumọ̀ ohun tí o sọ pé dandan ni kí á gbé Ọmọ-Eniyan sókè?
Nisisiyi, BBC n ṣiṣẹ ni ede Gẹẹsi, Hausa ati pidgin ni orilẹede Naijiria.
Sugbọn ṣa, igbesẹ naa ko sisẹ ni asiko yii nitori pe awọn oyin naa ko duro si oju kan.
Ni nnkan bi ọsẹ mẹta sẹyin ni adajọ agba kan ni ki wọn gbẹsẹ le akoto owo ti biliọnu mẹsan naira wa ninu rẹ, eleyi ti wọn fura si pe o ni ohun ṣe pẹlu Ambode.
Maryam Sanda: Toyin Abraham, Femi Adebayo, Tayo Sobola barajẹ́ lórí ìdájọ́ ikú
Iwe mo mọ si ti wọ́n ti tọ́wọ́bọ̀ náà gbọ̀dọ̀ wá láti ọ̀dọ́ òbí tàbi alágbà tọ́ rẹ Oríṣun àwòrán, Nigerian Air Force Àwọn ǹkan ti o gbọdọ ni O gbọ́dọ jẹ́ ọmọ Naijiria nípa ìbí.
Oríṣun àwòrán, Lateef Adedimeji Àkọlé àwòrán, Ọmọde ọjọun, o n dagba ree o, kori jẹ o pẹ laye, ko to agba da.
, ẹgbẹ́ òṣèré tíátà pàṣẹ fún Lizzy àti Toyin O ni iwa jẹgudujẹra naa gan an ti wa n dojukọ awọn to n gbogun tii bayii, bi o tilẹ jẹ wi pe o fi idi rẹ mulẹ pe iṣejọba aarẹ Buhari ko ni sun, bẹẹ ni ko ni wo lori ilakaka rẹ lati dẹkun iwa ibajẹ ati ajẹbanu lorilẹ-ede Naijiria.
Ṣaaju ni Madrid ti gbiyanu lati ra agbabọọlu naa lọdun to kọja ṣugbọn idunadura ọhun fori ṣọpọn.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Notre-Dame Cathedral: ilé ìjọsin jù ara wọn lọ 16 Ìgbé 2019 Oríṣun àwòrán, PA Àkọlé àwòrán, Ilé ijọsin to kun fun itan Ilé ijọsin aguda Notre-Dame to jona yii ti wa láti aadọta le ni ọgọrun mẹjọ ọdun sẹyin.
Oloyun ati ẹni to n fọmọ lọyan ko le fi ẹjẹ silẹ.
Lásìkò tó ń fi ìdí ìsẹ̀lẹ̀ yìí múlẹ̀ fún BBC Yorùbá, àgbà òsèré tíátá ni, Adebayọ Salami, tí gbogbo èèyàn mọ̀ sí Ọ̀gá Bello sàlàyé pé lóótọ̀ ni wọ́n pe òun ní ààrọ̀ ọjọ́rú pé ìlúmọ̀ọ́ká òsèrè tíátá obìnrin náà ti tẹ́rí gba asọ̀.
Aare Buhari fi n da Aare Putin loju pe, orile-ede Naijiria yoo tunbo ni ajosepo to muna doko pelu orile-ede Russia labe isakoso ijoba re.
ó wá ń pada lọ sílé.
Awọn ọlọpa ba wa kẹdun, wọn si farabalẹ gbọ ọrọ wa.
Eniyan lè máa rẹ́rìn-ín, kí inú rẹ̀ má dùn,ìbànújẹ́ sì le gbẹ̀yìn ayọ̀.
Àkọlé àwòrán, Ọpọ ile àti nnkán ìní ló ṣòfò nínú ìjàmbá omíyalé naa Bakannaa ni ọpọlọpọ ilé ìgbé to wa lagbegbe Totoro ni Ipinle Ogun ní o farakasa ìṣẹlẹ náà ti omi sí gbé òpó ọkọ ayọkẹlẹ lọ.
Igi ni wọ́n fi ṣe igun rẹ̀, ati ìtẹ́lẹ̀ rẹ̀ ati ara rẹ̀.
Oríṣun àwòrán, Instagram/abiola ajimobi O fi ẹyin gomina to wa lori aleefa nigba naa, Otunba Christopher Adebayo Alao Akala janlẹ lati gbegba oroke, to si fi ibo perete moke ninu ibo naa.
"Oríṣun àwòrán, SUNDAY MICHEAL OGWU Àkọlé àwòrán, Adugbo CMS ni Sunday Micheal Ogwu ti fi aworan yi sọwọ Oríṣun àwòrán, Sunday Micheal Ogwu Àkọlé àwòrán, Ojo naa mu sunkẹrẹ fa kere ọkọ wa Àkọlé àwòrán, Bi oju ọjọ ṣe ri re ki ojo naa to bẹrẹ ladugbo Ogudu Àkọlé àwòrán, Ọrọ di boo lọ o ya n mi ladugbo Ikoyi Oríṣun àwòrán, Ayanfhe Eledumare Ololade Àkọlé àwòrán, ""Ọlọrun lo n dara."
Àwọn ọmọ Ilara-mọkin yarí,wọn gbé'jà lọ bá Ọba láàfin Aya Fayemi lẹ́jọ́ jẹ́ lórí ikú àwọn akẹ́kọ̀ọ́ Fuoye - Segalink Ẹ ṣèwádìí ikú Ọ̀jọ̀gbọ́n Gideon Okedayọ - ASUU Àwọn ṣẹ̀ṣẹ̀dé South Africa yóò gba ìrànwọ́ owóyàá àti káádì ìpè - Dabiri Ká má parọ́, ojora mú mi lórí àbọ̀ ìgbìmọ̀ olùgbẹ́jọ́ ìbò ààrẹ - Buhari jẹ́wọ́ Ọọ̀ni obìnrin, Lúwòó Gbàgídà rèé, akọni tó ń gun ọkùnrin ní ẹṣin rìn Họnọrebu Biọdun Oyebanji, to jẹ akọwe ijọba ipinlẹ Ekiti pẹlu Họnọrebu Biọdun Ọmọlẹyẹ, to jẹ olori awọn oṣiṣẹ to n ba gomina ipinlẹ Ekiti ṣiṣẹ, lo ṣiwaju ikọ olubanikẹdun naa.
Awọn iroyin ti ẹ lee nifẹẹ si: Ijọba Naijiria tu akọroyin ti wọn mu silẹ ‘Ejo kọ lo mi 36m, Ọga mi lo gbaa’ Amọsa, awọn onwoye kan ti n kun lori iroyin yii paapaa julọ anfani ti o sodo sinu rẹ.
O tẹsiwaju wi pe epo to wọn ki i ṣe ẹbi awọn onile epo bikoṣe awọn alaṣẹ to n be loke.
Àwọn agbébọn jí alága ẹgbẹ́ òsèlú PDP gbé ní Kogi
Olubadamọran pataki fun gomina ọhun lori ọrọ to n lọ, Crusoe Osagie sọ pe ijọba ipinlẹ naa ti ṣetan lati dabo bo gbogbo eeyan ti yoo peju sibi ifẹsẹwọnsẹ ọhun.
Awọn ipinlẹ kan fara kaasa arun iba Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ogundiya: Àṣìṣe Dókítà ló sọ mi di aláàbọ̀ ara lórí kẹ̀kẹ́ Iyanṣẹlodi Òsìsẹ́ ìlera fẹ́ náa tán bíi owó pẹ̀lú ìjọba ni oriṣii ẹka eto ilera Naijira pọ pupọ lasiko iṣejọba rẹ gẹgẹ bii minista ni NaijiriaJohesu sẹ́wé lé ìyanṣẹ́lódì.
Tí ó bá wá jẹ́ pé nítorí oore-ọ̀fẹ́ ni Ọlọrun fi yàn wọ́n, kò tún lè jẹ́ nítorí iṣẹ́ ọwọ́ wọn.
Drug Trafficking: Ọmọ Yorùbá 16 ló wà nínú 23 tíjọba Saudi fẹ pa
UNO bẹnu àtẹ́ lu ìdàdúró Onnoghen Onnoghen jẹ̀bi ẹ̀sùn tí wọ́n fi kàn án, ó pàdánù owó rẹ̀ Ìgbìmọ̀ NJC sún ìgbẹ́jọ́ Onnoghen síwájú Sibẹsibẹ, o da ẹjọ naa nu nitori ile ẹjọ CCT ti pari igbẹjọ naa eyi to gbe idalẹbi fun adájọ́ àgbà Naijiria tẹ́lẹ̀rí naa.
Bí Ọbadaya ti ń lọ, lójijì ni ó pàdé Elija.
Demasi ti fi mí sílẹ̀ nítorí ó fẹ́ràn nǹkan ayé yìí.
O le ni àádọ́jọ ibi ti awọn  ọbayejẹ kan ti n wa epo robi lona aito , ti  Ikọ ọmọ-ogun oju omi, orile ede Naijria, ti  pa bayii, ti won si tun ti mu awon afurasi to le ni àádọ̀rún,ni ila oorun.
Ẹ fún ọ̀já kó le, lítà epo kan le tó ₦250 àbí ju ₦300 lọ Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Sotitobire: Adájọ́ sọ̀rọ̀ nípa ọjọ́ ìdájọ́ fún Wòlíì Sotitobire Alfa Babatunde18 Owewe 2020 Fídíò, Taiwo Bamidele Ondo Dwarf Judge: Ọlọ́run kò ṣe àṣìṣe pé ó dá mi ní aràrá14 Owewe 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 3 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 5 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Oluwa rẹ̀ wí fún òun náà pé, ‘Mo fi ọ́ ṣe aláṣẹ lórí ìlú marun-un.
Ọjọ Aje ni ile aṣofin naa fẹnuko ninu idibo pe ijiya yoo wa fun awọn olori ijọba to lọwọ ninu lilo ipa lori awọn oluwọde alaafia naa, ni ogunjọ, oṣu Kẹwaa.
O ni eyi ni awọn da titi ti owo naa fi wọ miliọnu kan Naira, ti wọn lo ra ọkọ naa.
Agbegbe Iju ni ọkọ naa ti gbera, to si n lọ si Ebute-Mẹtaa.
Mo fọ́n wọn ká sáàrin àwọn orílẹ̀-èdè mìíràn, wọ́n sì tú káàkiri orí ilẹ̀ ayé.
Èmi gan-an yóo kẹ̀yìn sí olúwarẹ̀, n óo sì yọ ọ́ kúrò lára àwọn eniyan rẹ̀; nítorí pé ó ti fi ọ̀kan ninu àwọn ọmọ rẹ̀ fún oriṣa Moleki, ó sì ti sọ ibi mímọ́ mi di aláìmọ́, ati pé ó ti ba orúkọ mímọ́ mi jẹ́.
O fikun ọrọ rẹ pe ikọlu laarin awọn agbẹ ati darandaran di nla nitori ijọba kọkọ fọwọ yẹpẹrẹ mu ọrọ naa.
Jonatani bá dáhùn wí pé, “Má ṣe ní irú èrò bẹ́ẹ̀ lọ́kàn.
Àti pé sísá tí àwọn èèyàn naa sá nílé ìwòsàn jẹ́ ìpèníjà ńlá fún àwọn òṣìṣẹ́ ètò ìlera tó n là kàkà láti fòpin sí ìtànkálẹ̀ Ebola ní orílẹ̀-èdè DR Congo.
67 biliọnù owó òúnjẹ àwọn akẹkọọ tí ICPC ní wọn se makumọku Saaju ni wọn ni alaga ajọ ICPC to n gbogun ti iwa jẹgudujẹra ni Naijiria, Ọjọgbọn Bolaji Owasanoye ti fẹsun kan awọn èèkàn osise nile isẹ ijọba to n mojuto ọrọ eto ọgbin ati awọn miran pe wọn lu biliọnu meji ati abọ to yẹ ki wọn fi bọ awọn akẹkọọ ni ponpo.
Oríṣun àwòrán, @cenbank O ni ileẹjọ kotẹmilọrun ti kọkọ gbe idajọ kalẹ saaju pe owo naa ko tọna, to si jẹ iwa aibọwọ fun ofin fawọn banki naa lati tẹsiwaju maa yọ ninu owo toun ba fi pamọ sọdọ wọn.
Gnassingbe ṣeleri pe oun ṣetan lati tun ọrọ aje orilẹede Togo ṣe ti oun ba wọle.
naa lati ni emi ifarajin lati koju ipenija to wa lawujo.
    Nígbà ti mo máa ṣe ètò ogun náà, fún àwọn ènìyàn mi, mo fi àwọn ti mo rò pé wọ́n jẹ́ akọni sí apá ọ̀tún, mo sì fi àwọn akoni sí apá òsì, àwọn tí mo rò pé wọn kò lágbára jù bẹ́ẹ̀ lọ ni mo ni kí ó dúró sí aarin èrò mi ni pé àwọn tí o wà lápá ọ̀tún àti apa òsì yóò ṣẹ́gun nígbà tí àwọn ẹranko ba gbá iwaju àti ẹ̀yìn yọ, kí wọ́n sì ti ipa bẹ́ẹ̀ yí àwọn ọmọ ogun ẹranko po, kí wọ́n fi àwọn ẹranko sí aarin.
Nígbà tí ó jẹ́ pé,Ọlọrun kò gbẹ́kẹ̀lé àwọn iranṣẹ rẹ̀,a sì máa bá àṣìṣe lọ́wọ́ àwọn angẹli rẹ̀;
NAPTIP: Babalawo to n fọmọ sowo lugbadi ofin
Yoruba si ni o n bọ, o n bọ awọn laa dẹ de amọ lode oni, oju ni wọn n mu to.
Ondo PDP Primaries: Ìjà bẹ́ sílẹ̀ làsikò àyẹ̀wò àwọn olùdìbò láti yan ẹni tí yóò díjé fún PDP nií Akurẹ Akọroyin BBC to wa nibi eto idibo naa to n waye ni Dome ni ilu Akurẹ ni ipinlẹ Ondo ti fidiẹ mulẹ pe edeaiyede bẹ silẹ nibudo idibo naa.
ti won yoo gba lati fi wa owo ti won yoo maa lo fun eto isuna odun 2019, ni eyi
Koda, o na to biliọnu kan dọla.
Ẹni tó tún tòlé èyí ní Adekunle ti wọn kakọ́ yàn ní ìbò ẹgbẹ̀rún mẹ́tàlélógún àti ẹ̀tàlélógójìlénírinwó, Sẹnatọ Adegbenga Kaka ní ẹgbẹ̀rún mẹ́tàd'inlógún àti ọ̀kanléláàdọ́rinlélẹ́ẹ̀dẹ́gẹ̀rin àti Abayomi Semako0 Koroto tó ní ẹgbẹ̀rún mẹ́sàn àti mẹ́wàálélẹ́gbẹ̀ta Ogun 2019: APC fà Adekunle Akínlàdé silẹ loludije ipò Gómìnà ajumọyan Oríṣun àwòrán, Facebook/Adekunle Abdulkabir Akinlade Àkọlé àwòrán, Asoju fun ẹkun idibo guusu Egbado ati Ipokia ni Adekunle Abdulkabir Akinlade Awọn agbagba ẹgbẹ oselu APC nipinlẹ Ogun ti kede orukọ ẹni ti yoo jẹ oludije fun ipo Gomina labẹ asia ẹgbẹ wọn .
Àwọn mìíràn tí wọ́n tẹ̀lé irú ọ̀nà yìí ti ṣìnà kúrò ninu igbagbọ.
Lẹ́yìn náà Samuẹli mú kí àwọn ìdílé ìdílé tí ó wà ninu ẹ̀yà Bẹnjamini tò kọjá, gègé sì mú ìdílé Matiri.
Amọṣa n ṣe ni wọn pa ọrọ mọọ lẹnu nibẹ ti awọn fidio tawsn kan ya nibi eto naa ṣe afihan bi awọn eeyan kan ṣe n fi ibudo naa silẹ.
Wọn fa ẹjọ naa titi to fi de ile ẹjọ to gaju ni Naijiria lọdun 2014, ti ile ẹjọ ọhun si ṣedajọ pe kii ṣe Falabi ni oye naa tọ si, bikoṣe Olarewaju.
bi awon eniyan se maa n so nipa oloye Obasanjo ,pe lati igba ti o ti kuro lori
sì pàṣẹ fún wọn pé kí wọ́n sọ fún wọn pé OLUWA àwọn ọmọ ogun, Ọlọrun Israẹli ní 
 lo so oro ohun di mimo.
Kí Ọlọrun tí ó ń fúnni ní ìrètí fi ayọ̀ tí ò kún ati alaafia fun yín nípa igbagbọ yín, kí ẹ lè máa dàgbà ninu ìrètí tí ẹ ní ninu Ẹ̀mí Mímọ́.
David Beasley to jẹ adari eto ounjẹ lagbaye (WFP) labẹ aṣia ajọ iṣọkan agbaye ni igbesẹ kanmọkanmọn yẹ ko waye lori ọrọ yii lati lee dena ajalu to n rọ dẹdẹ naa.
 Ọ ̀ kan nínú àwọn ìtàn wọ ̀ nyìí sọ pé Ọ ̀ báńta ni ó kó àwọn Ìjẹ ̀ bú kúrò ní ilé-ifẹ ̀ wá tẹ ̀ dó sí Ìjẹ ̀ bú-Òde Ìtàn mìíràn fi ìdí rẹ ̀ múlẹ ̀ pé orísun àwọn Ìjẹ ̀ bú ni wàdáì .
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Yollywood: E wo bí àwón òṣèré tíátà Yoruba ṣe ṣàjọyọ̀ ọdún Kérésìmesì 26 Ọ̀pẹ̀̀ 2019 Oríṣun àwòrán, @others Àkọlé àwòrán, Bi awọn oṣere tiata Yoruba ṣe ṣajọyọ ọdun Keresi ṣọtọtọ Keresimesi ọdun yii o yẹ, o dun, o si larinrin pẹlu.
Èyí tí kò lọ sí inú odò nínú eérú náà pẹ̀lú yìpadà ó di àkeekèé, n ó sì fi irú àkeekèé náà hàn ọ́ ní ọjọ́ tí mo bá rí i.
Èyí yóo jẹ́ ìlànà fún àwọn ọmọ Israẹli ati fún àwọn àlejò tí ó wà láàrin wọn títí lae.
24 Òkùdu 2019 Àkọlé àwòrán, Akọ̀wé ẹgbẹ́ CAN ní ìpínlẹ̀ Ebonyi nígbà kan ri tí wá rọ ọmọ Nàìjíríà láti fi ori jí òun ati pé òun yóò ma kíyèsára ní ìgbà míràn.
Ipade naa yoo waye laago kan(1pm), niyara ipade ọ́ọ̀dúnrún le kan nile igbimo ohun niluu Abuja.
 níba tí wọ ́ n ti ń kọ ́ ni nímọ ̀ iṣẹ-ọwọ ́ tó fi mọ ́ ìmọ ̀ iṣẹ ́ àgbẹ ̀ , aṣọ ́ gbó , ìṣègùn , ìtọ ́ jú ohun ọ ̀ sìn , ìwọnlẹ ̀ , àti ìmọ ̀ iṣẹ ́ àmúṣe-múlò ìmọ ̀ ẹ ̀ rọ .
 O ni: “Mo ti ri iwe ida owo pada fun awon ise akanse bii ti oju ona Jos-Buruku-Mararaba Jena atawon miran ni eyi tijoba ti bere igbese ayewo kikun lati le san owo naa pada”.
Ọkàn ọlọ́gbọ́n wà ní ilé àwọn tí ń ṣọ̀fọ̀, ṣugbọn ọkàn òmùgọ̀ wà ní ibi ìgbádùn.
Ó ranṣẹ jákèjádò ilẹ̀ Manase, wọ́n pe ara wọn jáde, wọ́n sì tẹ̀lé e.
Yatọ si pe o rin kaakiri ibi iṣẹlẹ yi, o tun nawọ gan kamẹra kan nibẹ ti eleyi si mu kawọn eeyan maa fi ṣe yẹyẹ pe o n ṣebi ọlọpaa ọtẹlẹmuyẹ.
Ni ọjọ kọkandinlọgbọn oṣu kẹsan kan naa ni wọn ri ọkọ ayọkẹlẹ Toyota Corolla ti o wa rinrinajo naa ninu adagun odo kan lagbegbe Dura-Du.
Nígbà tí wọ́n bá parí ẹ̀rí tí wọn níí jẹ́, ẹranko tí ó jáde láti inú kànga tí ó jìn tóbẹ́ẹ̀ tí eniyan kò lè dé ìsàlẹ̀ rẹ̀, yóo wá bá wọn jagun.
O so fawon oniroyin pe” Mo ti baa won alase soro, mo ti ko eko sii lori awon ohun ti mo se to ku die kaato nitori awokose rere ni mo fe je fawon odo”Awon alase ile naa ti gbe awon ofin bii sisan owo igbawole ogorun unmesan dola fawon to fe maa sise pelu iroyin ayelujara ni eyi ti awon ajajangbara n kun pe o ti poju pe awon akoroyin Tanzania ko ni ominira oro rara.
 Òhun tí ó selè ni pé a ti pa apor olùwa won je .
Ni àwọn ọmọ-ẹ̀yìn náà bá gbọn eruku ẹsẹ̀ wọn sílẹ̀ bí ẹ̀rí sí àwọn ará ìlú náà, wọ́n bá lọ sí Ikoniomu.
Bẹ́ẹ̀ owó ni gbogbo wọn ó san, kìí ṣe ọ̀fẹ́.
Iwe iroyin atigbadegba kan, Healthline ni oorun ati bi igbẹ onikaluku ṣe ri yatọ sira wọn ni eyi to si lee sọ ọpọlọpọ nkan nipa onikaluku.
Nígbà tí Elija gbọ́ ohùn náà, ó fi ẹ̀wù rẹ̀ bojú, ó jáde, ó sì dúró ní ẹnu ọ̀nà ihò àpáta náà.
Akeredolu yan ọmọ Ilajẹ gẹ́gẹ́ bíi igbákejì rẹ̀ tí wọ́n yóò jọ díje dupò ní Ondo Toke Makinwa ti sọ̀rọ̀; Amcon náà dá a padà fún un pé.
Inu mi si dun pupọ nigba ti ẹ pe mi lana ọjọ Satide.
Nitori naa, o rọ ijọba lati fun awọn ọmọ naa laaye lati jọkọ sile fun oṣu kan si meji lati woye bi arun naa yoo ṣe lọlẹ si, ki wọn to pada si ileewe.
Rehumu, olórí ogun, ati Ṣimiṣai, akọ̀wé, ni wọ́n kọ ìwé ẹ̀sùn sí ọba Atasasesi, nípa Jerusalẹmu ní orúkọ 
- Aregbesola Èyí tí a wò jùlọ 5:03 Fídíò, Omolola Arohunmolase Welder: Mo ti fí iṣẹ́ 'Welder' gbayì láwùjọ, tó mo fi tọ́ ọmọ yanjú, Duration 5,039 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 5:39 Fídíò, Akomolede ati Asa lori BBC: Olùkọ́ Kikelomo Ogunboye tan ìmọ́lẹ̀ sí ìwà olè ọ̀gá ọlọ́pàá Audu gẹ́gẹ́ bí àwòkọ́ṣe àsìkò yìí, Duration 5,398 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 4:11 Fídíò, Oba Adeyeye Ogunwusi: Ojú mi ti rí lọ́pọ̀ lọpọ̀, ọ̀pọ̀ èèyàn ni kò tilẹ̀ gbàgbọ́ pé mo lè jọba- Ooni, Duration 4,117 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 4:43 Fídíò, Promise Akinlade: ọmọ ọdún mọ́kànlá tó ń fi ìlù dárà bíi àgbàlagbà sọ̀rọ̀ nípa tálẹ́ǹtì rẹ̀, Duration 4,437 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 0:59 Gbọ́, Ìsẹ̀lẹ̀ jákèjádò orílẹ̀èdè àgbáyé láàárín ìṣẹ́jú kan, Duration 0,59wákàtí 6 sẹ́yìn 7:03 Fídíò, Olumuyiwa Bolade Adedeji Military Bruitality: Bí arákùnrin onípèníjà ara tí sọ́jà lù ṣe dé, Duration 7,035 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 4:45 Fídíò, Yoruba Films: Ẹ̀ẹ́ bẹ̀ mi kúrò láyé ni, mi ò lè kú - Fadeyi Oloro, Duration 4,4526 Èrèlè 2020 2:48 Fídíò, Esther Ajayi: Èmi náà ti borí ìṣòro rí ló ń mu mi ṣojú àánú, Duration 2,481 Ògún 2019 6:08 Fídíò, Adebola Ademilua: Àìrísẹ́ ṣè lẹ́yìn ìwé kíkà ló sọ mi dí ìyá onírú, mo dúpẹ́ tèmi, Duration 6,0827 Bélú 2020 5:55 Fídíò, Soyinka Cancer: Àṣe ara mi ni iso ti n run gbogbo bí mo ṣe n ṣèrànwọ́ lórí jẹjẹrẹ, Duration 5,5527 Bélú 2019 BBC News, Yorùbá Ìdí tí ẹ fi le è nígbàagbọ́ nínú ìròyìn BBC Ìlànà Lílò Nípa BBC Òfin Àṣírí Cookies Kàn sí.
Bẹẹ ni ọrọ ri fun Ọgbẹni Bisi Alimi, tii se ọkan lara awọn isẹda eeyan kan, ti wọn ko nifẹ lati se igbeyawo pẹlu irufẹ isẹda wọn.
Eniyan meje ninu awọn mẹrindinlogun to n dije dupo ninu idibo abẹle ẹgbẹ oselu PDP, saaju idibo sipo gomina ni ipinlẹ Kogi, ti fi ipo silẹ.
Olórí Alufaa pàápàá lè jẹ́rìí mi, ati gbogbo àwọn àgbààgbà.
Gomina Ipinlẹ Ọyọ, asofin  Abiola Ajimobi naa ti se ojuse re gege bi oludibo
O ṣalaye pe oun gbe igbesẹ naa lati polongo alaafia ati irẹpọ, ati lati mu ki alaafia jọba laarin awọn ẹlẹsin mejeeji.
Onimọ nipa eto ilera, Abilekọ Grace Oluwatoye, sọ fun BBC Yoruba pe 'o yẹ ki obinrin fun ọmọ ni ọyan fun oṣu mẹfa akọkọ ti wọn ba bi'.
Nigeria 2019 Elections: INEC kéde pé àwọn ẹgbẹ́ òṣèlú lé tẹ̀síwájú pẹ̀lú ìpolongo
Amọ ko si iwadii imọ sayẹnsi tabi ẹri to daju, to fi igbagbọ yii mulẹ.
Igbagbọ ninu rẹ̀ ni ó fún ọkunrin yìí ní ìlera patapata, gẹ́gẹ́ bí gbogbo yín ti rí i fúnra yín.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Boko Haram: Ejò lọwọ nínú lórí ikọlù àwọn ọmọ ogun Nàìjíríà 1 Owewe 2018 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 3 Owewe 2018 Oríṣun àwòrán, BBC/Boko Haram Àkọlé àwòrán, Awọn Adunkoko mọni Boko Haram sefilọlẹ idunkuku laja wọn lọdun 2009 ''Boya o jẹ ootọ tabi irọ, emi ko mọ sugbọn ti o ba jẹ wi pe ikọ Boko Haram n da awọn omoogun Naijiria lọna ti wọn si n seku pawọn,ọrọ yi fe amojuto ni kiakia'' Esi ọrọ ti ajagunfẹyinti nigba kan,ọgagun Ayo Olaniyan sọ fun ileesẹ BBC Yoruba rẹ ninu ifọrọwanilẹnuwo kan nipa ọrọ ikọlu awọn omoogun orileede Naijiria ti Boko Haram pa to aadọta ninu wọn.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Xenophobia: South Africa gbọ́dọ̀ dá owó ìtanràn padà kí wọ́n si fìyà jẹ àwọn ti ọ̀rọ̀ kàn -Sen Basiru 8 Owewe 2019 Oríṣun àwòrán, @others Àkọlé àwòrán, Won tun gbodo san owo gba ma binu fun awon omo Naijiria Senatọ Basiru ni koda wọn gbọdọ san owo gba-ma-binu fawọn ti wọn ba nkan wọn jẹ.
O ní lati igba ìwásẹ wọ́n maa n fi iyawo ta Ọba lọ́rẹ ni nítori náà o lé fẹ́ iye ìyàwó to ba wùú, nítori náà ìyàwo kò lẹ́tọ láti jowú nítori Ọba o jáde yóò si ṣaye.
Ileeṣẹ akoroyin jọ NAN, jabọ pe Aarẹ ile ẹjọ naa, Ọgbẹni Kayode Koledoye, ninu idajọ rẹ sọ pe o fi oju han lati ara ọrọ ti ọkọ sọ, ati bi iyawo ti wọn fi ẹsun kan ṣe kọ lati yọju sile ẹjọ ni gbogbo asiko ti igbẹjọ n waye, pe igbeyawo naa ti fi ori ṣọnpọn.
Bí ó ti ń jáde kúrò ninu Tẹmpili, ọ̀kan ninu àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ wí fún un pé, “Olùkọ́ni, wo òkúta wọnyi ati ilé yìí, wò ó bí wọn ti tóbi tó!
Ẹ̀wẹ́, àwọn ẹgbẹ́ ajafẹ́tọ̀ọ́ ní ìpínlẹ̀ Rivers ti ro àwọn ọlọdẹ ni àdúgbò Rumuodara láti rii dáju pé wọ́n o tẹ ofin ati ẹtọ àwọn ti wọn ba mú lóju mọ́lẹ̀.
iye ibo ti won fagile jẹ  89,101 ,
Awon olukopa wa lati ijoba ibile metadinlogota tipinle Eko ni.
Iwẹ wiwẹ, Tiro lile, Irun didi, Irun fifa, Eyin lile, Ila kikọ, Ayika titunṣe, Ilẹ gbigba ati bẹẹ bẹẹ lọ wa lara oge ṣisẹ laye atijọ.
Ó ní, “Kọ gbogbo ọ̀rọ̀ tí mo ti sọ fún ọ sinu ìwé, 
Lara awọn filmu rẹ ni ''Ori, Ilẹ, J.
 orílẹ ̀ -èdè germany rú òfin yìí .
Aare orile ede Naijiria, Muhammadu Buhari ni yoo je alejo Pataki ti aare orile ede Amerika ,Donald Trump yoo maa ri  ni, ogbon ojo, osu kerin ,ni Washinton , gege bi White house se kede re lojo Aiku.
Ileeṣẹ aarẹ ko tii sọ ohunkohun lori ọrọ yii bẹẹ ni igbimọ alaṣẹ orilẹede Naijiria pẹlu.
Saaju la ti mu iroyin wa fun yin pe isẹlẹ aramanda to n waye lori ayelujara lọwọ lọwọ bayii ni ti aworan kan ti gbajugbaja osere tiata, Ibrahim Chatta fi soju opo Twitter rẹ.
Yóo mú akọ mààlúù náà wá sí ẹnu ọ̀nà Àgọ́ Àjọ níwájú OLUWA, yóo gbé ọwọ́ lé e lórí, yóo sì pa á níwájú OLUWA.
Ẹgbẹ́ òṣèlú PDP f'ẹ̀sùn kan Ààrẹ Muhammadu Buhari pé wọ́n fẹ́ ba ètò ìṣèjọba àwaarawa jẹ́ ní Nàìjíríà.
Lẹyin eyi lo ṣe ipade pọ pẹlu aarẹ Ashraf Ghani to n tukọ orilẹ-ede naa.
Níbo làwọn òṣèré apanilẹ́rìn ín wọ̀nyí tó pilẹ̀ sínima àgbéléwò Yorùbá wà?
Dele Momodu mu ni ranti pe nigba ologun wọn ko ki n fẹ ki ẹnikẹni maa gbo wọ lẹnu ẹni ba dan an wo gbigbe tabi pipa ni.
Alaga ẹka to n risi ajakalẹ arun ni ileewosan ẹkọṣẹ ti ileewe giga fasiti eto ilera ni Naijiria, UNIMED ni ipinlẹ Ondo, Dokita Ayodeji Akinbodewa lọ sọ bẹẹ fun BBC.
APC fẹ́ fa ìṣọwọ́-ṣiṣẹ́ ẹ̀rọ káàdì ìbò sẹ́yìn - Atiku INEC ṣèpàdé pẹ̀láwọn alẹ́nulọ́rọ̀ nípínlẹ̀ Oyo ìyà ń bẹ fún ẹni tó bá kó àbẹ́rẹ́ tó ń dènà lùkúlùkú wọ Nàíjíríà - Onímọ̀ Kini Boko Haram?
Ẹyẹ aláwọ̀ eérú-àti-pupa-rẹ́súrẹ́sú náà, tí à ń pè ní Kaande Bhyakur ní èdè ìbílẹ̀ Nepali, ń fi igbó ṣe ìtẹ́ a sì lè fi ojú bà á bí ó bá ń fò lókè lálá láti ìwọ̀n mítà 500 sí mítà 2135.
Agbenuso fun ibudo mimojuto isele pajawiri ni orile ede Paupau New Guinea, Isaac Lupari  ba awon akoroyin soro lori ero ibanisoro pe ko tii seese fun ile ise yii lati soro ni kikun lori awon ohun to baje sugbon a mo pe ko si eni to gbemi mi ninu isele naa bayii.
ilé ti ìsàlẹ̀ fẹ̀ ní igbọnwọ marun-un; àgbékà ti ààrin fẹ̀ ní igbọnwọ mẹfa, àgbékà ti òkè patapata fẹ̀ ní igbọnwọ meje.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ṣugbọn bi wọn ṣe n kọlu awọn oṣiṣẹ eto ilera n fa idiwọ fun pinpin abẹrẹ ajẹsara.
Ó búra pé kí Ọlọrun pa òun bí òun kò bá ṣe bẹ́ẹ̀.
Àṣírí yìí ni pé àwọn tí kì í ṣe Juu ní anfaani láti pín ninu ogún pẹlu àwọn Juu, ara kan náà sì ni wọ́n pẹlu àwọn tí wọ́n jọ ní ìlérí ninu Kristi Jesu nípasẹ̀ ìyìn rere rẹ̀.
"Awakọ̀ bàálù ológun òfurufú obìnrin àkọ́kọ́ ní Nàìjíríà rè e Obìnrin awakọ̀ Bàálù àkọ́kọ́ láti Ọffa rèé 'Ìdí tí pápákọ̀ ofurufú l'Ekiti kò fi m'ógbọ́n wá' ""Nigba ti mo fẹ iyawo mi, awọn obi rẹ sọ fun mi pe o fẹran lati maa rinrinajo""."
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Toyin Abraham: Òṣèré Nollywood ti daya Kolawole Ajeyemi.
“China tun n pese eto iranwo fun awon alaini.
Ehanire rawọ ẹbẹ yìí lásìkò ìpàdé pẹlu awọn akọroyin n'ilu Abuja.
Yemi Mustapha ṣalaye pe arakunrin naa, Yemi Adeniran lo wa ọkọ ti wọn wa ninu rẹ ti wọn n gbe bọ lati Abuja wọn si ti baba wọ inu ilu Ibadan nigba ti iṣẹlẹ naa ṣẹ.
Ó tún pe àwọn eniyan, ó ń wí fún wọn pé, “Gbogbo yín ẹ fi etí sílẹ̀, kí ọ̀rọ̀ mi ye yín.
okeere lorile ede Najiria , ti o tun je oluranlowo aare Muhammadu Buhari, Abike
Lẹ́yìn náà ni ó da òróró sí i lórí láti fi jọba.
Minisita to n ri si eto ẹkọ, Emeka Nwajuiba lo kede awọn ọjọ idanwo naa lẹyin ipade ọlọjọ meji to waye pẹlu awọn alakoso ajọ to n dari awọn idanwo ọhun ni Naijiria.
Iwadi tuntun yii wa lati ọdọ ajọ Barcelona Institute for Global Health (ISGlobal) l'orileede Spain.
Ajọ to n ri si iṣẹlẹ pajawiri ni ipinlẹ Eko, LASEMA ni nkan bii aago mẹsan an abọ alẹ ana (ọjọ Aiku) ni awọn gba ìpè sori aago wọn lori iṣẹlẹ naa.
Ìjọba Eko bẹ̀rẹ̀ sísan N35,000 owó oṣù tuntun ní November Ẹ wo ìpínlẹ̀ táwọn gómìnà tẹ́lẹ̀ àti igbákejì wọn ń gba dúkìá ìfẹ̀yìntì tabua Mẹ̀kúnnù 80,000 l'Ọṣun ti j'ànfàaní ètò ìlera láìsan kọ́bọ̀ - Oyetola Ṣugbọn Saraki sọ ninu atẹjade to fi sita pe owo ifẹyinti ati owo ara oun loun fi kọ ile to wa ni ilu Ilorin, ati wi pe lẹyin toun ṣe gomina tan nipinlẹ Kwara loun kọ ile naa.
Lagos: Ohun mẹ́fà tó yẹ́ kí o rántí nípa Gómìnà Ambode
Alaga, ẹgbẹ ASUU ni fasiti Ọbafẹmi Awolọwọ, Ọmọwe Adeọla Ẹgbẹdokun lo kede eyi nibi ipade awọn olukọ fasiti naa lori bi awọn ajinigbe ṣe ji ọkan ninu awọn olukọ fasiti naa gbe ni aipẹ yii.
Pé òun Jin ni yó yan gbogbo nkan tí màá jẹ.
Kiriataimu, Sibima, ati Sereti Ṣahari, tí ó wà ní orí òkè àfonífojì náà; 
Bayii, ile iṣẹ́ apoògùn Bioraj naa ti fi atẹjade sita pe oun ti ni ki Ogbeni Junaid Hassan ti gbogbo eniyan n pe ni Baba Ibeji lọ rọọ́kún nílé ná.
 bóyá ìdí nìyí tí wọ ́ n fi máa ń ki àwọn Òwu ní.
Ṣé ẹ mọ̀ pé nkan tiwa ò kí ń jọ wá lójú lọ lo títí.
Nínú ìfẹsẹwọnsẹ mẹ́rìdínlógóji to ti kópa, Aubameyang náà ti gbá bọ́ọ̀lù méjìlélógún sáwọn Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Awọn gomina awọn ipinlẹ to wa ni Iwọ-oorun Naijiria yoo ṣe ipade pọ pẹlu ileeṣẹ aarẹ loni, Ọjọbọ.
O ni awọn eeyan ti ri oṣu lawọn ipinlẹ bii Kaduna, Kebbi, Yobe, Borno, Jigawa ati Sokoto.
Ṣugbọn nisinsinyii tí ẹ ti bọ́ lóko ẹrú ẹ̀ṣẹ̀, tí ẹ ti di ẹrú Ọlọrun, èrè tí ẹ óo máa rí, ti ohun mímọ́ ni.
Ṣugbọn ní tiwa, a kò ní lérí ju bí ó ti yẹ lọ.
Obinrin náà fi ìkòkò omi rẹ̀ sílẹ̀, ó lọ sí ààrin ìlú, ó sọ fún àwọn eniyan pé, 
Nítorí anfaani wo ni ó ṣe eniyan, tí ó bá jèrè gbogbo ayé yìí, tí ó pàdánù ẹ̀mí rẹ̀?
Dayọ kẹ́kọ̀ọ́ gboyè ní ilé ẹ̀kọ́ gbogbo nìṣe ti Moshood Abiọla nínú ìmọ̀ ẹkọ́ Sáyẹ́nsì àti ìmọ̀ ẹ̀rọ oúnjẹ.
Yatọ si igbesẹ ijọba apapọ, àwọn ipinlẹ ti aarun naa ti de gbé igbesẹ tí wọn naa.
Premiership league: Liverpool fẹ́rẹ̀ ẹ́ forígbá níwájú Southampton ṣùgbọ́n orí kó o yọ
Mose bá sọ fún àwọn ọmọ Israẹli kí wọ́n ṣe Àjọ̀dún ìrékọjá.
Kínni ó ń fa ilé wíwó?
Ni gbogbo wọ́n bá mú Sositene, olórí ilé ìpàdé àwọn Juu, wọ́n ń lù ú níwájú kóòtù.
Olori Folashade sọ pe, ẹru kọkọ ba iya oun nigba ti oun sọ fun pe Alaafin ni oun fẹ ẹ fi ṣe ade ori.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù AFCON 2019: Àwọn ikọ̀ Super Eagles ti gbà lára owó àjẹmọ́nú wọn 25 Òkùdu 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 26 Òkùdu 2019 Oríṣun àwòrán, AFP Aarẹ Muhammadu Buhari ti buwọlu sisan lara owo ajẹmọnu awọn ẹgbẹ agbabọọlu Super Eagles ti Naijiria.
Nítorí OLUWA Ọlọrun yín ni Ọlọrun àwọn ọlọ́run, ati OLUWA àwọn olúwa, Ọlọrun tí ó tóbi, tí ó lágbára, tí ó sì ní ẹ̀rù ni Ọlọrun yín, kì í ṣe ojuṣaaju, kì í sì í gba àbẹ̀tẹ́lẹ̀.
Mo lọ siwaju, kò sí níbẹ̀,mo pada sẹ́yìn, n kò gbúròó rẹ̀.
Ṣugbọn báwo ni wọn yóo ṣe ké pe ẹni tí wọn kò gbàgbọ́?
O yá fi àmì sí Ayekofẹnifọrọ Gẹgẹ baa se mọ pe ede Yoruba jẹ ede to ni ami, ami ori awọn ede kọọkan lo si n jẹ ka mọ iro wọn leti, bẹẹ si lọrọ ri pẹlu awọn ede ti akọsilẹ wọn jọ ara wọn.
Kiní ọ̀hún ò tiẹ̀ ta rárá, ó wá rí ràṣì-ràṣì lẹ́nu.
Ogbontarigi oṣere-binrin, Ṣọla ọmọ Jide Kosọkọ aya Abina ba BBC Yorùbá sọ̀rọ̀ lori iṣẹ tiata ti o yàn laayo.
Wọn fi ẹsun kan oloogbe Abba Kyari nigba naa pe o gba owo ẹyin to to ẹẹdẹgbẹta miliọnu naira lọwọ ileeṣẹ naa lati lee din iye owo itanran ti wọn ni ki ileeṣẹ naa san nigba naa.
Ninu atẹjade kan ti Adegbenro Adebanjo to jẹ igbakeji adari eto ibaraẹnisọrọ fasiti naa fi sọwọ sita, wọn ni iwa bẹẹ lodi si ofin ati ilana ile ẹkọ awọn.
Nítorí àwọn wolii ati àwọn alufaa ń lọ káàkiri gbogbo ilẹ̀ náà,wọn kò sì mọ ohun tí wọn ń ṣe.
Amọ, ikọ ọmọogun ni ko si otitọ ninu ọrọ ti Sanwo-Olu sọ, ati wi pe awọn ko pa ẹnikẹni ni Lekki Tollgate.
Ọgagun Evariste Ndayishimiye jẹ akẹkọ imọ ofin ni ile iwe giga fasiti Burundi nigba ti ogun abẹle dide lọdun 1993 lẹyin ti wọn pa aarẹ ijọba awaarawa akọkọ ti Burundi ni, Melchior Ndadaye.
N óo rú ẹbọ ọrẹ àtinúwá sí ọ,n óo máa yin orúkọ rẹ, OLUWA,nítorí pé ó dára bẹ́ẹ̀.
"Emi ko mọ pe Ọlọrun n lo ohun asiwere lati da Ọlọgbọn mi laamu ni, lati ẹnu Luminee si ni Ọlọrun ti fun mi ni ẹri ile tuntun.
Nítorí ìwọ ni ògo ati agbára wọn;nípa ojurere rẹ sì ni a ti ní ìṣẹ́gun.
Kò ní sí ẹni tí yóo sin òkú wọn, ati ti àwọn iyawo wọn, ati ti àwọn ọmọ wọn lọkunrin ati lobinrin.
O ṣeeṣe ki Ọmọọba Harry ati Omidan Markle o pa orukọ da lẹyin igbeyawo wọn Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Orukọ oye tuntun, Duke of Sussex"" ni o ṣeeṣe ki wọn fun Ọmọọba Harry lẹyin igbeyawo yii Gẹgẹ bii aṣa ilẹ Gẹẹsi, o ṣeeṣe ki orukọ ọkọ iyawo ati iyawo rẹ o yi pada lẹyin igbeyawo wọn."
ohun ti iru ifitonileti bayii wa fun” Olori
Ebola Virus: ìdí tí Ebola fi ń tàn kálẹ̀
CNN ni gbogbo awọn ẹri wọnyii ni wọn ko jọ pọ ki wọn to gbe iwadii wọn jade.
Ẹ̀wọ̀n ni wàá gbẹ̀yìn sí, kò sí bóo ṣe dọ́gbọ́n tó - Seyi Makinde wa ègúná ọ̀rọ̀ lé Fayose INEC kéde agbègbè ẹsẹ̀ odò 270 ti èrú ìbò ti le wáyé ní ìpínlẹ̀ Ondo Ààrẹ Donald Trump ti padà sí ilé ìjọba lẹ́yìn ọjọ díẹ̀ tó lùgbàdì ààrùn coronavirus Ẹ̀yin olùkọ́, ìlànà àkànṣe owó oṣù tuntun dé fún yín Naira Marley tun beere lọwọ alukoro ileeṣẹ ọlọpaa bo ya o tọnu lati kamẹra ọlọpaa to ba n ṣiwa wu.
gbogbo ilẹ̀ Nafutali, ilẹ̀ Efuraimu, ilẹ̀ Manase, ati gbogbo ilẹ̀ Juda, títí dé etí òkun ìwọ̀ oòrùn, 
Yẹ ọkàn mi wò; bẹ̀ mí wò lóru.
Ṣé olùkọ́ fásitì OAU míràn tún ti kó sí gbaga ìbálòpọ̀-fún-máàkì ni?
Fásítì Babcock lé akẹ́kọ̀ọ́bìnrin tó hàn nínú fídíò ìbálòpọ̀ lọ sílé Láti ọdún 2025 lọ, to bá ṣe ìgbọ̀nsẹ̀ sigboro, o rugi oyin - Buhari Kìnìhún nìkan kọ́ ló burú, àwọn ajá mẹ́wàá yìí náà kò fararọ!
Ekeji ni pe ko si ẹni to mọ igba ati akoko ti ọlọjọ yoo de ati pe ko si ẹda ẹni to mọ ibi ti o maa ku sii.
Àwọn ọmọ Juda tún lọ gbógun ti àwọn ará Kenaani tí wọn ń gbé ìlú Heburoni, (Kiriati Araba ni orúkọ tí wọn ń pe Heburoni tẹ́lẹ̀); wọ́n ṣẹgun Ṣeṣai, Ahimani ati Talimai.
Ṣugbọn Ọlọrun yóo san án pada fún ọ nígbà tí àwọn olódodo bá jí dìde kúrò ninu òkú.
Ogunlọ́gọ̀ yín ti fẹsẹ̀ kọ, wọ́n sì ṣubú,wọ́n wá ń wí fún ara wọn pé,‘Ẹ dìde, ẹ jẹ́ kí á pada sọ́dọ̀ àwọn eniyan wa,ati sí ilẹ̀ tí wọn gbé bí wa,nítorí ogun àwọn aninilára.
Àgbà òṣèré Fasasi Olabankẹwin tí gbogbo ènìyàn mọ̀ sí Dagunro ti dágbérejẹ fàyè ni Òwúrọ̀ yìí.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ondo: Sísá Gààrí síta ń fa àtúnṣẹ̀ àrùn ibàa Lassa 6 Ẹrẹ̀nà 2018 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 27 Bélú 2018 Oríṣun àwòrán, Twipu.
Awọn ipinlẹ miran bi Enugu,Gombe ati Rivers ko ti kede ọjọ tawọn akẹkọọ wọn yoo wọle ti ọpọ awọn onwoye si n beere pe ṣe awọn ileekọ wọn yi ti gbaradi kalẹ pẹlu gbogbo eto to yẹ ṣaaju iwọle awọn akẹkọọ.
Adugbo Oloro ni agbegbe Akinyẹle nilu Ibadan ni Baraka n gbe pẹlu awọn obi rẹ lati igba naa.
Mane lo kọkọ gba bọọlu wọn awọn Southampton to jẹ iks to ti n gba bọọlu jẹun tẹlẹ ki Firmino to fọba lee nigba ti ifẹsẹwọnsẹ naa wọ iṣẹju mọkanlelaadọrin.
Ṣùgbọ́n kòkòrò kò jẹ ká gbádùn obì tó gbó, ọdún mẹta péré ni Yar'adua náà lo lórí aleefa, tí ikú fi pá ojú rẹ dé, tí kò sì dúró de asiko ìbò gbogbo gbòò miran.
Ẹwa Agọnyin ni aayo ounjẹ Badagry Njẹ ẹ mọ pẹtẹsi akọkọ ni Naijiria?
O fikun ọrọ rẹ pe oriṣiiriṣii iṣẹlẹ ti ko fi ogo Ọlọrun han lo ti n ṣẹlẹ lorilẹede Naijiria tẹlẹ, nitorinaa awọn onigbagbọ gbọdọ gbadura lati tako apero ọhun.
Atejade kan ti ajọ naa fi sita lati ẹka to n ri si ọrọ iroyin sọ pe ọpẹlọpẹ awọn panapana to yara pa ina naa, ọtọ ni nnkan ti a ko ba máa sọ.
Niṣe ni arun ọhun n fi ojoojumọ pọ si papaa julọ nipinlẹ Eko, eeyan mẹtadinlaadọrun lo lugbadi covid-19 lati ipinlẹ Eko nikan l'Ọjọbọ.
Nibi ipade ifọrọwerọ awọn oludije gomina ni ipinlẹ Eko eyi ti BBC Yoruba ṣe agbekalẹ rẹ, awọn oludije ṣalaye lọlọkan o jọkan.
Isọri meji ni Asiko ni ninu ede Yoruba.
Awọn ọmọ Naijiria gbo orin naa sugbọn kaka ki wọn gboriyin fun wọn lori orin tuntun naa,iriwisi ọtọọtọ lo ba de.
5 FM ni Naijiria àti ni oke okun.
Oluwo: Inú ìwé kíkà ni ọja ọ̀la àwọn Fulani wà
Ọpọlọpọ kii ti lẹ gbagbọ pe, iru awọn eniyan bẹ ẹ wa, ṣugbọn obinrin kan re e ti aṣiri ọkọ rẹ tu si lọwọ lẹyin igbeyawo ogun ọdun.
Wọn ditẹ lati gbajọba rẹ lọdun lọjọ kẹtala oṣu karun un ọdun 2015 nigba ko si nile.
Imam ni awọn ẹlẹsin ibilẹ ko laṣẹ lori oku rẹ, bi o tilẹ je pe o pa ara rẹ, amọ wọn ko ri iwe idagbere faye ni ibi to ku si.
ajo INEC to n mojuto ibo nipinle Ekiti, ojogbon Idowu Olayinka, oga agba ile
Àwọn tí wọ́n mú Jesu fà á lọ sọ́dọ̀ Kayafa Olórí Alufaa, níbi tí àwọn amòfin ati àwọn àgbà ti pé jọ sí.
Kí wọn má máa lo àkókò wọn lórí ìtàn àròsọ àwọn Juu ati ìlànà àwọn eniyan tí wọ́n ti yapa kúrò lọ́nà òtítọ́.
Oríṣun àwòrán, IRT Àkọlé àwòrán, Musa Umar lẹyin ti awọn ọlọpaa gba silẹ Awọn alaṣe ni wọn gba Magajin Garin naa silẹ, wọn tun mu awọn afurasi kan pẹlu ibọn.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Àgùnbánirọ̀ t'ọ́lọ́pàá yìnbọn pa wọlẹ̀ sùn Iléeṣẹ́ aṣọ́bodè gba nǹkan ìjagun àìtọ́ Ọgbẹni Busuyi Fagoriọla to jẹ ẹgbọn rẹ ṣalaye pe awọn agbebọn ọhun ti wọn to meje niye wọ iboju lasiko ti wọn ji ọgbẹni Dele fagoriọla gbe.
Bí nǹkan oṣù rẹ bá dáwọ́ dúró, àwọn ohun tí yóò ṣẹlẹ̀ sí ọ rèé Agbabọọlu Samson Tijani dayo naa pada nigba ti ifẹsẹwọnsẹ ọhun pe ogun iṣẹju.
"Oríṣun àwòrán, Aketi Àkọlé àwòrán, Owó gọbọi wá nídìí oko-owo igbó gbingbin, Ìpínlẹ̀ Ondo kò ní pẹ gba àṣẹ láti gbin - Akeredolu ""Bí àwọn ènìyàn ṣe ń wọ Ondo kò yẹ wá, a ti bá àwọn ọlọ́pàá ṣe ipade pé àwọn ènìyàn wọn ń gba owó láti jẹ ki awọn eniyan wọlé, tí wọn si ti ṣèlérí láti ja ọrọ náà kunra si, ọ̀rọ̀ tí aarẹ Buhari sì sọ lọ́jọ́ Aje sì ti mú kó nira bayii láti rinrin àjò láti ìlú kan si òmíràn."
" Ibùdó ìyàsọ́tọ̀ ni mo wà, ló fi pẹ́ kí ń tó sọ̀rọ̀ lórí tírélà tó já l‘Eko - Omotola Jalade Ekeinde Ìdẹra dé fún Nàíjíríà!
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Imoyosola Adetoro: Àwọn èèyàn sọ fún ìyàwó mi pé mo ti jẹ́ẹ̀jẹ́ nínú awo pé ń kò ní bímọ Maryam, iya rẹ ati awọn ẹbi yoku to wa nile ẹjọ si lo mu igbe bọnu ni kete ti adajọ naa gbe idajọ rẹ kalẹ.
8 Àti nísisìyí, kí ẹnu máṣe yà ọ pé mo ti pè é fún ètò tèmi, ètò èyítí ó jẹ́ mímọ̀ nínú mi; nítorí èyí, bí òun yíò bá jẹ́ aláìṣèmẹ́lẹ́ ní pípa àwọn òfin mi mọ́ òun yíò di alábùkún fún sí ìyè ayérayé; àti pé orúkọ rẹ̀ ni Joseph.
O sọrọ lori ajọṣepọ awọn olori keekeeke ati agba pe ibọwọfagba ati irẹlẹ ni oun n kọ sii lojoojumọ ni aafin.
O ni bayi ti awọn ti ri ipa ti awọn oludije ọdo ko,iṣoro ko ni si lọjọ iwaaju fun awọn ọdọ lati de ipo oṣelu.
Ojogbon Olufemi Obafemi je eniyan mẹ́rìndínlọ́gọ́rin ti o ti gba ami ohunbayii(76th recipient).
Èrè kí ni ó wà ninu ère?
Ọdun mẹta pere ni Samuel lo nileewe girama to fi ṣe idanwo JAMB bọ si Fasiti Ahmadu Bello to wa ni Zaria.
Pàṣán ń ró, ẹṣin ń yan,kẹ̀kẹ́ ogun ń pariwo!
Covid 19: Ìjọba ìpínlẹ̀ Ogun pàṣẹ kí wọ́n ṣí gbogbo ilé ìjọsìn, ilé ìgbafẹ́ padà lẹ́kúnrẹ́rẹ́
Ó ka ìwé láti ilé ìwé alákọ̀ọ́bẹ̀rẹ̀ títí tó fi kẹ́kọ̀ọ́ gboyè ní Fásitì Ibadan nínú ìmọ̀ iṣẹ́ akàròyìn.
Èwe tí a bá wà rí pé enikan ń fi àmì hàn èyí túmọ̀ sí pé kí ó fún ẹni náà láàyè tí oloyinbo ń pè ní Social Distancing kí ẹni náà sì wà ní igbele laarin ilé yín náà ni, ní ìlànà tó kofin ja ó yẹ kí olúkúlùkù máa fún ara wọn ní ààyè ìwọ̀n mita méjì sí ara ẹni,sugbon a rí pé èyí lè nira díè.
Kò ní já yín kulẹ̀, bẹ́ẹ̀ ni kò ní fi yín sílẹ̀.
Ṣugbọn Geṣuri ati Aramu gba Hafoti Jairi lọ́wọ́ rẹ̀, ati Kenati ati àwọn ìletò tí ó wà ní àyíká rẹ̀; gbogbo wọn jẹ́ ọgọta ìlú.
Ìpàdé ẹgbẹ́ alátakò l'Oyo yóò tẹ̀síwájú lórí bí wọn ṣe fẹ́ fẹ̀yìn APC gbá lẹ̀ APC pàṣẹ lọ rọ́ọ́kún nílé fún Amosun, Okorocha Àwọn oun àjòjì tó ṣẹlẹ̀ nígboro níbi àjọyọ̀ ìṣẹ́gun Buhari Ǹjẹ́ o mọ̀ pé ọdọ 43m ló wà lára olùdìbò?
”Iyyafin Aisha wa gbosuba fun ajo NDE fun ipa ribi-ribi  ti won ko lati mu igbe aye irorun ba awon odo ati obinrin lorile ede Naijiria.
Ọba wa ri pe ko si abuja miran lẹyin ọpẹ mọ, idi ree to fi wọlẹ lọ, ti wọn si n bọ Alaafin Sango ni ọrọọrun, taa mọ si ọjọ marun marun, ta mọ si ọjọ Jakuta.
Ijiya to ṣe e ṣe ko waye fun awọn alakoso ijọba ati eleto aabo, ni fifi ofin de irinajo wọn silẹ okeere, ati gbigbẹsẹ le dukia wọn.
Majẹmu náà yóo wà títí ayérayé pé, èmi ni n óo máa jẹ́ Ọlọrun rẹ ati ti atọmọdọmọ rẹ.
merinlelogoji aarun to lee fa oju fifo ni ile -itoju oju lee wa ojutuu si.
Small Doctor wà lára àwọn ọ̀dọ́ olókìkí tí ileeṣẹ ọlọpaa yàn gẹgẹ bii awokọṣe nilu Eko.
Oríṣun àwòrán, FIFA Àkọlé àwòrán, Ikọ Flying Eagles fidi rẹmi Gbagbagba ni ẹgbẹ agbabọọlu Amẹrika ati Naijiria n tele ara wọn ni isọri kẹrin ti wọn wa pẹlu ami ayo mẹta mẹta, bo tilẹ jẹ pe Naijiria lo wa ni ipo keji.
Ohun gbogbo tí mo ní, tìrẹ ni; ohun gbogbo tí ìwọ náà sì ní, tèmi ni.
Eyi ṣeeṣe ko fa wahala nla lorilẹede China nibi ti iwadii ti fihan pe nnkan bi ida mejilelaadọta ninu ọgọrun awọn ọkunrin wọn lo n ṣana si siga ti o si jẹ pe iwọn perete ida mẹta nini ọgọrun awọn obinrin lo n mu siga nibẹ.
Sanwo-olu gbé ìwé ẹ̀dùn ọkàn olùwọ́de ENDSARS lé Buhari lọ́wọ́ Ìwọ́de 'End SARS' lè tan àjàkálẹ̀ arùn coronavirus lẹ́ẹ̀kejì ní Nàìjíríà- Ọjọ̀gbọ́n Faduyile 3.
Coronavirus: Gómìnà Wike ìpínlẹ̀ Rivers wó ilé ìtura méjì lulẹ̀ torí wọ́n tàpá s'ófin kóńlé-ó-gbélé Àwọn nǹkan tí obìnrin lè ṣe pẹ̀lú olólùfẹ́ oníwà ipá lásìkò ìgbélé Coronavirus yìí Coronavirus: Ǹjẹ́ àwọn dókítà tó ń tọ́jú eyín ń ṣisẹ́ lásìkò pàjáwìrì?
àwọn ọmọ Nesaya ati àwọn ọmọ Hatifa.
Alámójútó àjọ tó ń mójú tó ìṣẹ̀lẹ̀ àjálù lórílẹ̀èdè Nàìjíríà, NEMA lẹ́kùn ìwọ̀ oòrùn gúúsù Nàìjíríà, Alhaji Yakubu Suleiman ló tẹ́wọ́ gba àwọn àbọ̀dé Libya náà, tó sì gba wọ́n níyànjú láti di olùfọnrere wàhálà àti ewu tó wà nínú sísá gba ọ̀nà ẹ̀bùrú r'òkè òkun .
Covid-19 ti pa akọni afúnfèèrè Sax ilẹ̀ Africa Ṣoyinka pari ọrọ rẹ pe o yẹ ki ijọba pe awọn ṣọọṣi ati mọṣalaṣi to tapa si aṣẹ rẹ lẹyin to wọgile ipejọpọ ti eeyan rẹ ju aadọta lọ lẹjọ.
Ìjáfáfá rẹ̀ farahàn lásìkò tí ó di òpó òṣèlú tí ọkọ rẹ̀ gbékalẹ̀ mú nígbà tí wọ́n jù ú sí ẹ̀wọ̀n gbére ní 1964.
Òun ṣá ni àkọ́bí rẹ̀, òun sì ni ẹ̀tọ́ àkọ́bí tọ́ sí.
Gomina Godwin Obaseki ti wọn ko fun ni tikẹẹti, ti darapọ mọ ẹgbẹ PDP, yoo si fẹ ẹ nira lati gba ipo naa lọwọ rẹ.
Olórí ìgbìmọ̀ tó ń rí sí yíyan akọ́nimọ̀ọ́gbá míràn fún orílẹ́-èdè Cameroon, Djomo Kelvin, sọ pé àwọn yóò se àyẹ̀wò fínífíní kí awọ́n tó yan akọ́nimọ̀ọ́gbá tuntun fun égbẹ́ agbábọ́ọ̀lù ọ̀hún.
Ní ti Iṣimaeli, mo ti gbọ́ ìbéèrè rẹ, wò ó, n óo bukun òun náà, n óo sì fún un ní ọpọlọpọ ọmọ ati ọmọ ọmọ, yóo jẹ́ baba fún àwọn ọba mejila, n óo sì sọ ọ́ di orílẹ̀ èdè ńlá.
Ó ní kí àwọn eniyan náà dúró, kí wọn máa ṣọ́ ọba, olukuluku pẹlu ohun ìjà lọ́wọ́.
Bí àpẹrẹ̀ ti olùdíje náà bá ní ìdìbò ìdá àádọ́tà àti ọ̀kan nínú ìdá ọgọ́rùn un ni Texas, wọ́n yóò fún ẹni náà ni gbogbo ìbò 38 tó tọ́ si lati ìpínlẹ̀ Texas Nítori náà ó ṣeése ki ènìyàn di ààrẹ tó ba jáwe olúbori nínú ìdìbò to díjú ní àwọn ìpińlẹ̀ kan, kódà ti kò bá ni ìdìbò tó pọ̀ tó ti alátakò rẹ̀, ó sì le di ààrẹ orílẹ̀-èdè Amẹrika.
Fayemi dọbalẹ gbalaja, Alaafin naa si fọwọ mejeeji gbe e dide pe kare, ọmọ daada."
Àwa mọ̀ dájú pé Ọlọrun a máa mú kí ohun gbogbo yọrí sí rere fún àwọn tí ó fẹ́ràn rẹ̀, àwọn tí ó ti pè gẹ́gẹ́ bí ìpinnu rẹ̀ láti ayébáyé.
Odunlade, Toyin, Ijebu dásí ìwọ́de #EndSARS, Mercy Aigbe gbébọn Ọkọ̀ akẹ́rù tí ìjánu rẹ̀ já ló kọlù ọkọ̀ agbépo tó fa ìjàmbá iná ní Otedola- LASEMA Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí 7:03 Fídíò, Ogbomosho shooting, End Sars, End SWAT: Isiaka Jimoh fi ọmọbìnrin kan àti ìyàwó tó lóyún sínú sílẹ̀ ló- Òbí Isiaka, Duration 7,0317 Ọ̀wàrà 2020 5:55 Fídíò, Soyinka Cancer: Àṣe ara mi ni iso ti n run gbogbo bí mo ṣe n ṣèrànwọ́ lórí jẹjẹrẹ, Duration 5,5527 Bélú 2019 Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí 2 sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
Ounjẹ ko ni da ninu: Omi maa n jẹ ki ounjẹ da ni kiakia, bakan naa ni o maa n jẹ ki eniyan maa lọ ile igbọnsẹ loorekoore.
Minisita si ṣeleri lati san owo naa pada.
Ọdun 2013 si 2014 ni o sisẹ gẹgẹ bi akapo owo agba fun ile iwe Meadow Hall School ni ilu Eko lorilẹ-ede Naijrira Ọdun 2013 si 2016 ni o ṣiṣe gẹgẹ bi akapo owo agba fun ile iṣẹ KPMG lorilẹ-ede Naijiria Boyle-Komolafe ni oludasilẹ ile ounjẹ Ojoro Kitchen lati ọdun 2015 titi di asiko yii Oun naa ni oludari ile iṣẹ Capture Solutions Limited lati ọdun 2018 titi di asiko yii.
Awọn ẹbi mejeeji yoo maa ki ara wọn ku oriire pe ọja to dara ni awọn ra, ọkọ pe ni ọmọkunrin, iyawo naa si pe ni obinrin, kii se korofo isana, igba yii si ni ayẹyẹ igbeyawo to wa sopin.
Ọpọ awọn eeyan to n kọja lati ipinlẹ Nasarawa to wa lẹba ilu Abuja ni ko raye kọja, ni bi awọn agbofinro ọhun ṣe n da awọn ti ko ba wọ ibomu pada lẹnu ibode ilu naa.
Kí láwọn ohùn àmúyẹ tí kọmẹńtátọ̀ tó dáńtọ́ gbọ́dọ̀ ní?
"Gẹgẹ bi alaye, ohun ti fidio orin Falz n sọ ni pe ""a ti de ibi ti to yẹ ka ti yi iwa pada si ara wa ki a si mọ ohun to tọ yatọ si eyi ti ko tọ."
Oríṣun àwòrán, @HQNigerianArmy O kere tan eeyan mejidinlogun lo ku ninu ikọlu taa n wi yii.
Ti wọn ba ti n ṣiṣẹ kiṣẹ, o le ṣe akoba fun DNA.
Olori agbegbe Loko, Abubakar Hamed Sabo sọ fun BBC pe wọn gbe Emir Sanusi wa si ilu Loko London, ṣugbọn wọn ti pada gbe e kuro lọ si ilu Awe nipinlẹ Nasarawa bakan naa.
“Ẹ̀ ń retí ọ̀pọ̀ ìkórè, ṣugbọn díẹ̀ ni ẹ̀ ń rí; nígbà tí ẹ sì mú díẹ̀ náà wálé, èmi á gbọ̀n ọ́n dànù.
-‘kí ni ọba gbọ́ bẹ́ẹ̀ ṣe Òmùgọ̀diméjì gbé iré dà sílẹ̀, ìyàwó fi tẹ̀lé e, ọ̀ràn di ‘Bóò lọ yá fún mi, nígbà ti gbogbo wa sì ń wo ìpàkọ́ ọba báyìí ẹ̀rín la bú sí, a rẹ́rìn-ín títí àrín-tàkìtì ni- bẹ́ẹ̀ ni ìpàkọ́ Òmùgọ́diméjì ṣe bí ẹnií gùn díẹ̀ báyìí, ó sì tún wá tẹ̀ díẹ̀, ó rí kọnkó.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Peter Fatomilola ní àìsí ẹ̀kọ́ ń mú káwọn òṣèré tíátà ó máá ṣe oun tí kò tọ́.
Wo dókítà ọmọ Nàìjíríà tí àgbáyé ń wárí fún nítorí abẹ́rẹ́ àjẹsára COVID-19 Taa ni Ọọni àná tí Ọba Ogunwusi forúkọ ọmọ rẹ̀ sọ?
“Ni deede aago mefa ku ogun iseju ni awon obinrin  meji ti won di ado oloro mora wo adugbo Ajilari ni Bama , to wa ni  ijoba ibile Bama lo, ti won si fi ado oloro to wa lara won pa awon to wa se adura ni owuro ojo naa.
Nítorí náà, Ọmọ-Eniyan ni Oluwa ohun gbogbo ati ti Ọjọ́ Ìsinmi pẹlu.
Nítorí náà nípa èso wọn ni ẹ óo fi mọ̀ wọ́n.
 Á gbọ ́ dọ ̀ mò wípé ẹmi ní ó gbé ìwá ró .
Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí US Presidential Election Debate 2020: Trump àti Biden bínú sọ̀rọ̀ síra wọn lásìkò ìtàkurọ̀sọ30 Owewe 2020 10:43 Fídíò, Wole Soyinka sọ ìdí tó fi ni òun a fi màálù Fulani ṣe súyà fáwọn èèyàn abúlé, Duration 10,4323 Owewe 2020 Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí 2 sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
Àwòrán ìwọ́de NLC, TUC, ULC lónìí Saraki gbé N16.
Ìgbà tí iwin náà rí obìnrin yìí kò ṣe é ní nǹkan kan, ṣùgbọ́n ó mú u sí ọdọ rẹ nínú ihò ó sọ ọ́ si ìyàwó.
Awọn ọmọ ẹgbẹ agbabọọlu Newcastle ati Inter Milan paapa n wa ki Daniel Sturridge darapọ mọ ẹgbẹ agbabọọlu wọn.
Nibayi naa, awọn ẹlẹgbẹjẹgbẹ lorisirisi lo ti n bu ẹnu atẹ lu igbesẹ tawọn ologun naa gbe ati igbiyanju wọn lati le awọn olugbe erekusu Tarkwa Bay ni erekusu Eko.
Ní ọjọ́ kẹwaa oṣù kẹwaa, ní ọdún kẹsan-an tí Sedekaya gorí oyè, Nebukadinesari, ọba Babiloni, dé sí Jerusalẹmu pẹlu gbogbo àwọn ọmọ ogun rẹ̀.
N óo dá a dùbúlẹ̀ àìsàn.
Ọmọbìnrin ọdún 25 gún ọ̀rẹ́kùnrin rẹ̀ pa nítorí ó ní ko lọ ṣẹ́ oyún Èèyàn 125 míràn ṣẹ̀ṣẹ̀ kó COVID-19 ní Nàìjíríà Ìjọba Nàìjíríà ti kéde pé kí ilé ìtura ṣí padà, kí ìlé ìwé máa palẹ̀mọ́ ìwọlé àwọn akẹ́kọ̀ọ́ Ó tó gẹ́ẹ́!
Lara awọn ọmọ igbimọ naa ni Monsurat Sunmọnu, Mulikat Adeola Akande, Bọlaji Ayọrinde, Samson Ọlaoye, ati Sarafadeen Abiọdun Alli.
Igbesẹ yii nijọba gbe lati fun awọn minisita lanfaani lati ṣiṣẹ pọ pẹlu ile aṣofin agba lori eto isuna ọdun 2020 fun orilẹede Naijiria.
Eyi lo mu ki Emir tilu Ilorin, Alhaji Ibrahim Zulu Gambari, fi da si ọrọ aawọ to wa laarin tọkọtaya Abdulwasiu ati Risikat Azeez, ti iyawo ni oju buluu , to n ja ranin-ranin nilẹ lẹnu ọjọ mẹta yii.
Gómìnà Ayọ̀délé Fáyóṣe ti ìpínlẹ̀ Èkìtì ti sọ pé ìdójútì ńláǹlà ni Ààrẹ Mùhámádù Bùhárí ń fún orílẹ̀èdè Nàìjíríà pẹ̀lú bí ó ṣe lọ ń di ẹ̀bi gulegule àwọn darandaran lórílẹ̀èdè Nàìjíríà ru Ààrẹ Gaddafi ti ilẹ̀ Libya tó ti di olóògbé .
Ní ọjọ́ keji tí àwọn ará Filistia wá láti bọ́ àwọn nǹkan tí ó wà lára àwọn tí wọ́n kú, wọ́n rí òkú Saulu ati àwọn ọmọ rẹ̀ mẹta ní òkè Giliboa.
Ọ̀kọ̀ ojú omi dànù, ènìyàn méjì kù, ẹnìkan di àwátì Ọkọ oju omi to danu ti mu ẹmi eniyan meji lọ ti eniyan kan si ti awati.
Wo ohun to yẹ koo mọ nipa bi eto idibo ṣe n lọ Lagos Ọkan ni idibo atundi to n waye ni Eko.
Nathaniel Oke (SAN) ti tako idajọ ti adajo  Musa da pe ko tọna rara.
Daniẹli bá lọ sí ilé, ó sọ fún àwọn ẹlẹgbẹ́ rẹ̀: Hananaya, Miṣaeli, ati Asaraya, 
Ìlú yìí kò ní jẹ́ ìkòkò fun yín, bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò ní jẹ́ ẹran ninu rẹ̀; ní ààlà ilẹ̀ Israẹli ni n óo ti ṣe ìdájọ́ yín.
" Dokita Ryan sọ bẹẹ nibi ipade awọn akọroyin to waye ni Geneva.
 nípa bẹ ́ ẹ ̀ Ọwá ajíbógun àti agígírì jọ dàgbà pọ ̀ .
Awọn aare orile ede mejeeji naa wa fohun sokan lati gbokun ti iwa fayawọ.
Iroyin naa fidi rẹ mulẹ wipe ẹni to jẹ ẹgbọn ọkunrin fun awọn mejeeji lo dari eto isin igbeyawo naa, to si tọka si awọn ẹsẹ Bibeli kan lati fi gbe igbeṣẹ rẹ ọhun lẹsẹ.
Èmi náà bá dá a lóhùn pé mo fara mọ́n ọn bẹ́ẹ̀.
Bakan naa ,ni aare Muhammadu Buhari ti fowo si akanse owo kan lati tete  fi ra awon irinse ogun fun iko omo ogun orile ede yii lati odo awon to n se irinse naa, sugbon rira naa yoo je lati odo ijoba kan si ijoba.
O fi kun un pe ni gbogbo igba ti oun ba ti fẹ jade lọ paniyan ni babalawo naa maa n fun oun ni oogun ati ajẹsara ibilẹ gbogbo pẹlu ọfọ ati ayajọ ti oun yoo pe lati di afẹẹri ni ibi ti oun ti fẹ lọ ṣe ọṣẹ naa.
 murtala se àtúnyèwò ètò ìdàgbàsókè elekéta orílè èdè .
Má ṣe gbèrò ibi sí aládùúgbò rẹtí ń fi inú kan bá ọ gbé.
Oríṣun àwòrán, ololufe BBC Àkọlé àwòrán, Baba agba yii naa rọra wa ewe to fẹ daada lati daabo bo ara rẹ lọwọ coronavirus Oríṣun àwòrán, others Àkọlé àwòrán, Kìí ṣe imú ati ẹni ni eyi n bò, o bfi bori náà ai baa mọ ti kokoro naa bá fẹ́ gba ori wọle Oríṣun àwòrán, others Àkọlé àwòrán, Orin wo ni ka kọ si gbẹdu ibomu-bẹnu onike yi?
Nígbà tí ó dé iwájú Ahabu, Ahabu bèèrè lọ́wọ́ rẹ̀ pé, “Mikaya, ṣé kí á lọ gbógun ti Ramoti Gileadi tabi kí á má ṣe lọ?
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Fuel Price Hike: Onímọ̀ ní oṣooṣù ni owó lítà epò kan yóò máa yàtọ̀, ó le léwó tàbí dínwó 22 Ẹrẹ̀nà 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 16 Owewe 2020 Oríṣun àwòrán, The guradian nigeria Ẹgbẹ oṣiṣẹ lorilẹede Naijiria ti ni yẹkini kan ko lee yẹ iwọde apapọ jakejado orilẹede Naijiria ti yoo waye lọjọ kẹtalelogun oṣu kẹsan an.
gẹ́gẹ́ bí ìlérí tí ó ti ṣe fún àwọn baba wa:fún Abrahamu ati fún ìdílé rẹ̀ títí lae.
Deboye Oyewole loju opo Facebook ni, o dara ki ijọba apapọ bẹrẹ si gba owo oju opopona, nitori yoo jẹ afikun owo abẹle fun ijọba yatọ si owo epo bentiro.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: INEC dá òsìsẹ́ lẹ́kọ̀ọ́ láti yọ Melaye Gẹ̀ẹ́sí gbé £1m kalẹ̀ láti tako Boko haram Ọbásanjọ́, Fálaè sè‘pàdé lóríi Bùhárí Ilé ní gbogbo àwọn ẹ̀ka agbófinró ló gbọdọ̀ dúrú sí ìhà ìlànà tó tọ́ lórí ọ̀rọ̀ yìí, kí wọn sì se kóríyá fáwọn òsìsẹ́ wọn láti gba ọ̀pá àsẹ ilé padà, kí wọn sì tún mú àwọn èèyàn tó wà ní ìdí ìsẹ̀lẹ̀ yìí.
Wakanda Forever : Aubameyang fi 'Black Panther' dáwọ̀ọ́ ìdùnnú lórí pápá
Ẹsẹ̀ mi kò ranlẹ̀ mọ́ nítorí ààwẹ̀ gbígbà,mo rù kan egungun.
Ilé ẹjọ́ gba béèlì Sẹ́nétọ̀ Adeleke ‘Gómìnà Amosun kò fẹ́ràn àwọn ará Ìjẹ̀bú’ Naira Mailey àti ikọ̀ rẹ̀ tí wà látìmọ́lé EFCC ‘Gómìnà Amosun kò fẹ́ràn àwọn ará Ìjẹ̀bú’ Ìyá 73 rọ ọmọ ní oúnjẹ dèrò ẹ̀wọ̀n l'Ámẹ́ríkà Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, African in Greenland: Kí ló sún ilẹ̀ Afirika dénú gbígbé inú yìnyín?
Eyi ko ṣẹyin abajade ipade pajawiri ti ijọba apapọ ati awọn oṣiṣẹ ṣe lati aago mẹjọ alẹ Ọjọ Aiku, titi di afẹmojumo Ọjọ Aje, ti o yẹ ki iyanṣẹlodi naa bẹrẹ.
com Àkọlé àwòrán, Àwọn ọlọpàá sọ wípé ọmọ̀ ọ̀dọ̀ Sunday Adefonou Anani ti jẹ́wọ́ pé òun ló pa ọ̀ga rẹ̀, Ọpẹ Bademọsi, tó wà nínú àwọran yìí Nigba ti iyawo oloogbe dele ti ori Oloye ninu agbara ẹjẹ ti wọn ti gun pa, ni o kigbe sita.
Bo tilẹ jẹ pe o ti kuro ni Naijiria, ileeṣẹ naa ṣi wa lawọn orilẹ-ede miran ni Afrika.
padanu ẹmi wọn, ni eyi ti o waye ni  Gusu
Ènìyàn mẹ́ta wọ gbaga ọlọpàá nítori ajílẹ̀ Àwọn òṣèré tíátà kan rèé, tí wọn fẹ́ ara wọn, tí ìgbeyàwó wọn sì pẹ́ Nàìjíríà bí ìkókó 26, 039 lónìí ọjọ́ kíní, oṣù kínií, ọdún 2020- UNICEF Akinyibi, tọ́ka si pé ìjàmba ọkọ náà ṣẹlẹ̀ ní ààgo mẹrin ààbọ ìdáji pẹlu ọkọ ajagbe dísù pẹlu nọmba ọkọ TKP 653 XA àwọn èèyàn to si ko iṣu.
Agbenuso fun ile-igbimo asoju sofin lorile-ede Libya, Aguila Issa, ti fesun kan orile-ede Turkey pe, o n satileyin fun awon omo-ogun olote lorile-ede naa.
Petermeyer, oludari eka to n mojuto oludari eto aabo ati ilera eka, dari won
Lẹ́yìn náà, ó bi Seba ati Salimuna pé, “Níbo ni àwọn ọkunrin tí ẹ pa ní Tabori wà?
Koda, aworan ti wsn lo jẹ aworan osere tiata kan ti ara rẹ ko ya, amọ to ti jalaisi bayii, Adeshina Adesanya, ti ọpọ eeyan mọ si Pasitọ Ajidara.
Ogun Flood: Wákàtí méjìdínlógún ni òjò fi rọ̀ èyí tó mú ẹ̀kún omi lọ́wọ́
Nisinsinyii, a ti tún un gbìn sinu aṣálẹ̀,ninu ilẹ̀ gbígbẹ níbi tí kò sí omi.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Àwọn àwòrán tó làmìlaaka níbi ayẹyẹ àpéjẹ ìdúpẹ́ Aisha Buhari 3 Ẹrẹ̀nà 2019 Àwọn ènìyàn jàǹkàǹjàǹkàǹ ló pé jú síbi ayẹyẹ àpéjẹ ìdúpẹ́ Aisha Buhari tó wáyé nílé ìjọba l'Abuja.
Falana, ẹni ti o gboriyin fun akitiyan lati ṣagbekalẹ Ikọ Alaabo yii, wa
Orúkọ rere dára láti yàn ju ọrọ̀ pupọ lọ,kí á rí ojurere sì dára ju kí á ní fadaka ati wúrà lọ.
Lati kekere ni ọrọ yii ti ṣẹlẹ o nigba ti mo wa ṣi wa nile iwe girama.
Iṣẹlẹ kayeefi miran tun ṣẹ ni ipinlẹ Ondo lori pe àrá tun san pa maalu mẹjọ ni agbegbe Ikarẹ/ Akoko ni Ijọba ibilẹ Ila oorun ariwa Akoko ni ipinlẹ Ondo.
Bashir ri owó pọun ẹgbẹrun mẹtadinlogoji he ni eyi to to miliọnu mejila naira lasiko ti o n ṣọde ninu apo kan.
] Bí ẹ bá wádìí lẹ́nu òun fúnrarẹ̀, ẹ óo rí i pé òtítọ́ ni gbogbo ẹjọ́ rẹ̀ tí a fi sùn yín.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Johnson & Johnson san biliọnu 8 dọ́là fún ẹni tóògùn gbòdì lára rẹ̀!
“Wundia kan yóo lóyún, yóo bí ọmọkunrin kan; wọn yóo pe orúkọ rẹ̀ ní Imanuẹli.
Oríṣun àwòrán, Instagram Àkọlé àwòrán, Aburo Indimi ni Zarah, ọmọ ààrẹ Muhammadu Buhari fẹ Ohun to jẹ kawọn eeyan mii maa pa owe pe olowo n ṣọrẹ olowo ni wipe ẹgbọn Adama Indimi lo fẹ ọmọbinrin aarẹ Muhammadu Buhari, Zarah Buhari.
O ni ti ko ba si awọn akẹgbẹ oun, ko lee ṣeeṣe fun oun lati pegede gbami ẹyẹ naa mọ Messi ati Ronaldo lọwọ.
Oríṣun àwòrán, Rotimi Akeredolu Aketi facebook Gomina Akeredolu ẹni to kede bẹẹ loju opo Facebook rẹ ninu fidio kan to fisita nibẹ fikun pe laarọ ọjọ Isẹgun ni oun gba esi ayẹwo oun.
ni awon ti fi kun wakati to yẹ ki eto idibo pari ni awon agbegbe ti won ko tete
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, No reception wedding: Adewale ni àpèjẹ kò ṣe pàtàkì sí òun ''Nitori iru awọn eeyan nla nla ti yoo wa sibi igbeyawo ọhun ati titori a ni lati tẹle ofin ijọba, a o ṣe bi a ṣe le din ero ku.
Adebayo ni abajade ipade ẹgbẹ ni wi pe ti ijọba ba kọ lati san owo oṣu awọn kan, gbogbo awọn ni awọn yoo da iṣẹ silẹ.
arọmọdọmọ wọn tí wọ́n ṣẹ́kù, tí àwọn ọmọ Israẹli kò lè parun, ni Solomoni kó lẹ́rú pẹlu ipá, wọ́n sì wà bẹ́ẹ̀ títí di òní yìí.
O ni ọpọ ko ka a kun nitori ede Yoruba lo fi kọ orin naa.
Yemi Omo Elesho Yemi Elesho to jẹ ọmọ Adewale Elesho ni tiẹ sọ pe, lati kekere loun ti bẹrẹ ere tiata, ''mama mi lo maa n gbe mi kaakiri ori itage.
Wo ojú àwọn tó na ìka máa lọ ilé sí Praise nilé ẹlẹ́gbọ́n àgbà BBNaija Àwọn òṣèré Nollywood tí wọn ò sí lóri amóhùmáwòrán mọ́ Kìí ṣe torí ìbèérè ni mo ṣe bẹ́ Fani-Kayode, àwọn akẹẹgbẹ́ mi ló kó mi láyà jẹ - Eyo Charles Tunde Idiagbon, ọ̀gágun kògbagbẹ̀rẹ́ tó ní ẹ̀ẹ̀kan lóṣù ló yẹ kí ológun máa rẹ́rìín Wo ojú àwọn afurasí tó fipá bá Uwaila, akẹ́kọ̀ọ́ Uniben sùn tí wọ́n tún pa á sínúu ṣọ́ọ̀ṣì Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Oyenusi ló mú mi wọ ẹgbẹ́ adigunjalè kó tó di pé mo b'Ólúwa pàdé' Kíákíá lọ daṣọ bo igbá àyà rẹ to ṣí kalẹ̀!
Wọ́n mú wọn wá siwaju ìgbìmọ̀.
Aarẹ orilẹ-ede Naijiria ti kesi awọn ọmọ Naijiria sọra fun iwa radarada ti ko ba ofin mu, ki iyipada, ‘change’ le waye.
nítorí pé bí a kò bá fi ìrìn àjò yìí falẹ̀ ni, à bá ti lọ, à bá sì ti dé, bí ẹẹmeji.
Bí ìgbẹ́jọ́ wòlíì Sotitobire ṣe ń lọ lọ́wọ́ nílé ẹjọ́ lónìí rèé Ìròyìn Yàjóyàjó: Kí ló pa Ogun Majek tó jáde láyé?
Orisabunmi ti jáde láyé, ohun tí a mọ̀ nípa ayé àti ikú rẹ̀ nìyí Èèyàn 32,720 kó ààrun COVID-19 l'Eko nìkàn, Sanwo-Olu bá figbe ta Wo ọ̀nà tí Yoruba ń gbà dá ọmọ àlè mọ̀ nínú ìdílé- Elebuibon Èèmọ̀ wọ̀lú, Ọmọ ẹ̀kọ́ṣẹ́ gbé ọmọ ọ̀gá rẹ̀ àti káàdì ìgbowó ATM sálọ l'Ondo!
Ó ń bọ̀ bí ìkùukùu,kẹ̀kẹ́ ogun rẹ̀ dàbí ìjì.
Aare orile ede Naijiria Muhammadu Buhari ti so pe ijoba yoo satunse to monya lori, lorile ede Naijiria yato si bi o se wa tẹlẹ.
Tipa tikuku ni wọn fi yanju ipade naa Ifẹsẹwọnsẹ naa kun fun ikọlu ohun gbigba ara ẹni ni nipa.
Tí a fiṣọwọ́ ní 4:41 10 Ọ̀pẹ̀ 20204:41 10 Ọ̀pẹ̀ 2020 Àlàyé rèé lórí ìdí tí mo fi lọ sílé Tinubu - Rashidi Ladoja Rashidi Ladoja salaye pe oun lọ sile Tinubu lati ba kẹdun lori ọpọ dukia to padanu lasiko rogbodiyan EndSARS nilu Eko ni.
Ọpọlọpọ ìgbà ni wọ́n ti ń pọ́n mi lójú láti ìgbà èwe mi.
Awakọ̀ àti ọmọ mẹta mọribọ nínú ìjàmbá ọkọ l'Eko
Yóo bá gbogbo àwọn eniyan burúkú wí fún gbogbo ìwà burúkú tí wọ́n ti hù, ati gbogbo ọ̀rọ̀ líle tí àwọn ẹlẹ́ṣẹ̀ tí kò bẹ̀rù Ọlọrun ti sọ sí òun Oluwa.
ati pé bí àwọn ará Ijipti bá ti fi ojú kàn ọ́, wọn yóo wí pé, ‘Iyawo rẹ̀ nìyí’, wọn yóo pa mí, wọn yóo sì dá ọ sí.
Wọn si ti tẹ ọrọ yii Eligio Summum Pontificem"" (""Mo dibo yan Alufaa to tobi ju lọ""), si apa oke."
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Èmi gan máa ń béèrè lọ́wọ́ ara mi pé ta ni Wole Soyinka gangan' Chip Whip: A ò mọ̀ nípa àṣìkọ orúkọ nọ́mbà ọkọ̀ aṣòfin ìpínlẹ̀ Kano - FRSC Ajọ ẹka oju popo, FRSC ti ni awọn ko mọ nkankan nipa aworan nọmba idanimọ ọkọ ‘CHIP WHIP’ ti awọn eniyan n tan kalẹ ka lori ẹro ayelujara ni opin ọsẹ.
Oluranlowo gomina naa tun sọ pe
Bakan naa la gbọ pe wọn ko mọ ile tabi ọna alase ọhun to ti salọ bayii.
Àwọn ọmọ Ṣimei ni Ṣelomoti, Hasieli, ati Harani; àwọn ni wọ́n jẹ́ olórí ìdílé Ladani.
" Gba lati fẹ ọkunrin to ba nifẹ rẹ denu, jẹ ki ọkunrin naa bu iyì fun ẹ, ki o si ṣetan lati lo gbogbo igbesi aye rẹ pẹlu rẹ,"" ọrọ ree lati ẹnu Genevieve."
O ni orile ede Morocco yoo  tepele  mọ ipinnu re lati tubo fowosowopo pelu aare
"Mo fun wọn ni oogun Hydroxychloquine mu pẹlu Zinc ati Zithroma, ti ara gbogbo wọn si da.
Orúkọ ìnagijẹ mẹ́jọ tí wọ́n fi ń pe Abiola Ajimọbi nígbà ayé rẹ̀ Bakan naa lo tun ṣẹ pe, idile Ajimobi ko ran ẹnikẹni si ijọba gẹgẹ bi gomina Makinde ti sọ.
Nígbà tí mo wí pé,‘Ibùsùn mi yóo tù mí lára,ìjókòó mi yóo sì mú kí ara tù mí ninu ìráhùn mi’.
Ẹnikẹni to ba fẹ ẹ gba owó Bitcoin gbọdọ kọkọ ni adirẹsi Bitcoin - eyi ni asopọ nọ́mbà ati lẹta mẹtadinlọgbọn si mẹrinlelọgbọn.
Àwòrán mánigbàgbé BBC news Yorùbá fún ọ̀sẹ̀ yìí
6bn padà A kii mọ rin, kori o ma min, eyi ni awọn kudiẹkudiẹ ti ile igbimọ aṣofin agba kẹjọ ni, bi wọn ti kogba sile lonii.
 The staff at the Essentuki Team Base Camp offered him a cake and bouquet of flowers to celebrate his day.
 isé won sì ni àgbè , ode àti igbá fínfín .
Ìsẹ̀lẹ̀ àìbalẹ̀ ọkán yìí wá sé gẹ́gẹ́ pẹ̀lú sùnmọ̀mí tó ńwáyé ní ìhà àríwá orílẹ̀èdè Nàìjíríà látọwọ́ ẹgbẹ́ Boko Haram.
Kò sí ẹni tí ó wà nínú àwọn Èdìdàrẹ́ tí ó fẹ́ kí òun pàápàá kú, ṣùgbọ́n olúkúlùkù ní inú dídùn sí ikú ọmọnìkejì rẹ̀.
Èyí ni ẹwà tí kò lè ṣá, èyí tí ó ṣe iyebíye lójú Ọlọrun.
Ní oṣù kẹta ni wọ́n bẹ̀rẹ̀ sí kó àwọn ìdámẹ́wàá náà jọ, wọ́n kó wọn jọ tán ní oṣù keje.
Bí ẹ gbìmọ̀ pọ̀ ìmọ̀ yín yóo di òfo.
pe ,oun dupe fun ife ti awon eniyan fi han oun ni gbogbo ibi ti won ti lo se
ó ní: “Ìwọ ọmọ eniyan, àwọn ọkunrin wọnyi kó oriṣa wọn lé ọkàn, wọ́n sì gbé ẹrù ẹ̀ṣẹ̀ tí ń múni kọsẹ̀ siwaju wọn.
Amẹ́ríkà UK, France kọlu àwọn ọmọ ogun al-Assad
Ó jẹ́ olóòótọ́ sí OLUWA, kò yapa kúrò lọ́dọ̀ rẹ̀, ṣugbọn ó fi tọkàntọkàn pa àwọn òfin tí OLUWA fún Mose mọ́.
Nígbà tí ìpayà bá dé ba yín bí ìjì,tí ìdààmú dé ba yín bí ìjì líle,tí ìpọ́njú ati ìrora bò yín mọ́lẹ̀.
'Ọdún méjì sẹ́yìn ni òbí àwọn ọmọbinrin Chibok gbọ́ láti ọ̀dọ́ ìjọba kẹ́yìn' Àwọn tó ń wojú ọjọ́ rí ihò dúdú tó tóbi jù láyé àtọ̀run Nàìjíríà wà ní ìsọ̀rí kejì pẹ̀lú Burundi, Madagascar àti Guinea Oun tí ẹ lè má mọ̀ nípa Omar al-Bashir, olórí Sudan ti wọ́n yọ nípò Ni ilẹ Yoruba, oriṣiriṣi nkan ni wọn fi n wọn ounjẹ latori ọwọ, abọ, agolo, ọ̀rá ati bẹẹ bẹẹ lọ.
Micheal Jackson Vs Beyonce: Àwọn èèyàn sọ ẹní tó jẹ ọgá láàrín olórin méjèèjì
Ọkọọkan lọmọ ọwọ maa n yọ, lo difa fun bi awọn oludije mejeeji ṣe dagbere fun ile ẹlẹgbọn loni tii ṣe ọjọ keji, oṣu Kẹjọ.
Awọn oṣiṣẹ to n ri si iṣẹlẹ pajawiri atawọn adoola si gbyanju lati doola ẹmi awọn ti ijamba naa ba.
”Tabi kí nǹkan tí eniyan dá sọ nípa ẹni tí ó dá a pé:“Kò ní ìmọ̀.
 o je elimenti alaije-metali afagbarapupodimu to po repete .
làti ọdún 2003 ni nneka ti ń ṣíṣé pọ ̀ pẹlu alátò orin hip-hop tórúkọ rẹ ̀ ń jẹ ́ dj farhot tíí tún ṣe agbórin jáde tí ó fi ilẹ ̀ hamburg ṣe ibùgbé .
Fairstein ni aṣaaju olupẹjọ ọrọ ifipabanilopọ to ṣẹlẹ ninu ẹjọ Central Park Five ni New York.
Iléeṣẹ́ google gbé àǹfàní internet ọ̀fẹ́ wọ Eko
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ghana: Nurudeen Adam ní a jẹ́ bíi idán ni Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Ghana: Nurudeen Adam ní a jẹ́ bíi idán ni 19 Òkùdu 2019 Ni abule Pantam Nyame Koro ti orilẹede Ghana ni Ọgbẹni Nurudeen Adam ti n ṣe iṣẹ gbigbẹ ẹda ohun elo orin àmútọ̀hún wá Xylophone.
Dipo ko yi pada oorun ni aṣfin Akinniyi maa n sun niwọnba akoko perete to ba farahan nile aṣofin yii ti gbogbo awọn eeyan ti wa fun un ni inagijẹ 'Aṣofin oloorun' nitori eyi."
 kódà nígbà tí wọn kò bá ní ìtumọ ̀ àdámò wọ ́ n wúlò .
"Àkọlé àwòrán, Ẹ gbẹ oṣiṣẹ TUC n fi ẹsun ifiya jẹ oṣiṣẹ kan ileeṣẹ to n pin ina ọba lorilẹede Naijiria, TCN ""awọn oṣiṣẹ ni ileeṣẹ yii ko fara mọ apapọ ẹgbẹ oṣiṣẹ naa lori ifẹhonu han wọn naa."
Igbakeji Aarẹ Orilẹede Naijiria, Yemi Osinbajo ti se ipade pọ pẹlu Akarigbo ti ilu Remo, Oba Babatunde Ajayi, ati Awujale ti ilu Ijebu, Oba Sikiru Adetona, lori eto aabo to mẹhẹ lorilẹede Naijiria.
25 Òkùdu 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 27 Òkùdu 2020 Oríṣun àwòrán, Abiola Ajimobi Abiola Ajimobi Central Mosque ni Oke Ado ni ilu Ibadan ni ipinlẹ Oyo ni ile ijọsin kẹyin ti ara Abiola Ajimobi yoo wọ gbẹyin.
Ṣugbọn Samuẹli wí fún un pé, “Kí lo dánwò yìí?
Akojọpọ awọn Naijiria mii to ba ọdun 2020 lọ: Abba Kyari: Oríṣun àwòrán, others Ọjọ Ẹti, Ọjọ Kẹtadinlogun, Oṣu Kẹrin, ọdun 2020 ni Abba Kyari d'oloogbe ni ipinlẹ Eko lẹyin ọsẹ diẹ toni aarun coronavirus.
NLC, TUC, ULC yóò ṣe ìwọ́de l'ónìí Lẹ́tà Obasanjo: Àjálù ń bọ̀ bíi ti Rwanda, tí Buhari kò bá ṣàtúnṣe ètò ààbò Oyo TUC: A ṣì fa ìjọ̀ba léti ni pẹ̀lú ìyanṣẹ́lódì NLC pẹ̀lú ẹ̀bùn ọ̀dún tuntun fún Nàìjíríà Amoṣa o ni ijiroro ṣi n tẹsiwaju lori awọn ato ti yoo kan awọn oṣiṣẹ ti owo oṣu wọn ju ẹgbẹrun lọna ọgbọn naira lọ.
 O ni “ọlọpaa abẹle dara gẹgẹ bi ọna ati fi ẹsẹ aabo mulẹ”Gomina Akinwumi Ambọde ti Ipinlẹ Eko, ninu ọrọ rẹ gbe oṣ̣uba o-kare fun Ile Igbimọ Aṣofin Ipinlẹ Eko fun ifọwọsowọpọ aarin wọn ati iṣẹ idagbasoke to n lọ ni gbagede Ile Igbimọ Aṣofin naa.
Ṣáájú àsìkò yìí, Ọbásanjọ́ ti bá ìjọba Goodluck Jónátánì wí nínú ìwé àpilẹ̀kọ tí ó kọ ránṣẹ́ sí i ní ọdún 2013, Ọbásanjọ́ fi ẹ̀sùn kan Jónátánì wípé ó ń darí orílẹ̀-èdè Nàìjíríà lọ sí oko ìparun pẹ̀lú bí ó ṣe fi àyè gba ẹ̀tàn, ìjẹ́gùdùjẹrà, ìbápín àìgbẹ́kẹ̀lé láti fa aṣọ iyì àti ìtẹ̀síwájú orílè-èdè náà ya pẹ́rẹpẹ̀rẹ.
Ẹlẹ́wọ̀n 44 kú sọ́gbà ẹ̀wọ̀n nítorí ooru tó mú púpọ̀ Wo àwọn iléèwé gíga tó ti bẹ̀rẹ̀ sí ní ta fọ́ọ̀mù JAMB post UTME screening ní Naijiria Ṣaaju ni ijọba ipinlẹ Eko ti kede pe awọn ileeṣẹ ọkọ aladani bii Uber ati Bold yoo maa san ida mẹwaa owo ti wọn ba n gba lọwọ awọn onibara wọn.
Dokita Musa ni niwọn igba ti arun kan tabi omiran ti wa ninu ẹbi, yoo maa ran lọ ni, tawọn ọmọ iru ẹbi bẹẹ ba n fẹ ara wọn.
ẹ̀dá ayé pàápàá yóo bọ́ lóko ẹrú, kúrò ninu ipò ìdíbàjẹ́, yóo sì pín ninu ọlá àwọn ọmọ Ọlọrun.
Ki eeyan to le yọ alaga ẹgbẹ lapapọ tabi ki wọn to le kọwe lọ joko sile fun-un, igbimọ alaṣẹ ẹgbẹ lo le se bẹẹ.
Iru igbẹ yi n ṣafihan pe eeyan ko mu omi to inu iru ẹni bẹẹ si kun diẹ.
Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí 5:47 Fídíò, Akomolede ati Asa: Mọ̀ si nípa àwọn ọ̀nà tí Yorùbá ń gbà ran ara wọn lọ́wọ́, Duration 5,4722 Ọ̀wàrà 2020 End SARS Protest: Babangida ní ejò lọ́wọ́ nínú lórí ìsẹ̀lẹ̀ rògbòdìyàn tó ń wáyé káàkiri Nàìjíríà22 Ọ̀wàrà 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Fayemi ṣe tán láti náa bí owó pẹ̀lú Eleka n'ílé ẹjọ́ Fáyẹmí n wa awawi ₦117bn kalẹ ko tó dé orí ìjọba-Fayose Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Fayẹmi bá BBC sọ̀rọ̀ ní kété tó di gómìnà Ekiti Minisita tẹlẹri ọhun fi kun ọrọ rẹ wipe ana oun ni Omisore, bẹẹ sini ko si ohun to buru ninu ki a ṣe abẹwo si ana ẹni.
Oríṣun àwòrán, others Amọ, ileeṣẹ ọlọpaa sọ fun ileeṣẹ iroyin BBC ni ko si otitọ kankan ninu iroyin pe awọn adigunjale n ṣọṣẹ kaakiri, Iroyin ofege to n kaakiri lori ẹrọ ayelujara lo jẹ ki awọn eniyan gbagbọ ninu iroyin ti kii se otitọ naa.
Nígbà kan ìwò ti ẹ̀dá ni à ń wo Kristi, ṣugbọn a kò tún wò ó bẹ́ẹ̀ mọ́.
Ta ni yóò kojú Akeredolu fún ipò gómìnà Ondo?
Ẹ̀yin ọdọmọkunrin, mò ń kọ ìwé si yín, nítorí pé ẹ ti ṣẹgun Èṣù.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Afcon 2019: Super Eagles ti wa gba owó àjẹ́mọ́nú wọn báyìí 29 Òkùdu 2019 Àkọlé àwòrán, Super Eagles Awọn ọmọ ikọ agbabọọlu Naijiria ti gba owo ajẹmọnu wọn lẹyin ti wọn fi fi aidunu han lori ọrọ naa.
Adarí ẹgbẹ́ JOHESU, Josiah Biobelemoye, sọ ní Abuja lọ́jọ́bọ́ pé, àwọn so yanṣẹ́lódì náà rọ̀, láti lè jẹ́ kí ìfọ̀rọ̀wérọ̀ lọ déédé lórí àwọn oun tí wọ́n n béérè.
Adele alaga fun ajọ EFCC to n gbogun ti iwa ibajẹ lorilẹede Naijiria, Ibrahim Magu ti ni oun gbagbọ pe iwa jẹgudujẹra lo fa arun Coronavirus to n ja rain lorilẹede China.
Ninu atejade kan ti aare orile
Ninu idibo gbogbogbo ọdun 2019 papaa julọ idibo gomina, ọpọ ninu awọn baba isalẹ oloṣelu lo gbere itiju.
Nígbà tí ẹ bá súnmọ́ ilẹ̀ àwọn ọmọ Amoni, ẹ má ṣe dà wọ́n láàmú, ẹ má sì bá wọn jagun, nítorí pé n kò ní fun yín ní ilẹ̀ wọn gẹ́gẹ́ bí ohun ìní, nítorí pé, àwọn ọmọ Lọti ni mo ti fún.
Bẹẹ naa ni awọn eniyan lori ẹrọ Twitter naa ki awọn eniyan ipinlẹ Ondo ku oriire fun aṣeyori ofin to rọ mọ ikọ Amọtẹkun.
Minisita fun Ọrọ Ilera, Ọjọgbọn Isaac Adewole, sọ ni Abuja ni ọjọ Ẹtì, wi pe, oun ti fun ajọ ti ó ń gbogun ti ilokulo oògùn, ti a mọ si NAFDAC, ni àṣe lati ri i pe wọn kò fun ẹnikẹni ni iwe aṣẹ lati gbe oògùn naa wọle lati awọn orile-ede miran mọ́.
O ti ta àwọn eniyan rẹ lọ́pọ̀,o ò sì jẹ èrè kankan lórí wọn.
Wò ó ẹrú ni wá lónìí lórí ilẹ̀ tí o fún àwọn baba wa pé kí wọ́n máa gbádùn àwọn èso inú rẹ̀ ati àwọn nǹkan dáradára ibẹ̀.
Olójú àánú yóo rí ibukun gbà,nítorí pé ó ń fún talaka ninu oúnjẹ rẹ̀.
Ọpọ loju opo twitter lo ń beere ibere yii bakan naa pe, ki ayẹyẹ ti a n se gan-an?
Nígbà tí ó rí Ẹsita tí ó dúró ní ìta, inú rẹ̀ dùn sí i, ọba na ọ̀pá oyè tí ó wà ní ọwọ́ rẹ̀ sí i, Ẹsita sì na ọwọ́, ó fi kan ṣóńṣó ọ̀pá náà.
Kí ló wà ní ìdí igbá tí àwọn olorì Aláàfin máa ń tí lóde Ọ̀yọ̀ Kíni ìjọba ń ṣe lórí ewu ẹkọ Almajiri àti covid 19 ní Nàìjíríà?
Bakan naa ni orilẹede Amẹrika yoo pada si Ajọ Eto Ilera lagbaye, ki wọn si saaju igbogun ti aarun Coronavirus.
Iroyin naa ti lẹ ni wọn ji awọn eeyan miiran gbe.
Ọfiisi, ile igbọnsẹ, atawọn akaba to yẹ ko da wa fun ile iṣẹ naa ni wọn ti pa ti wọn sọ di ọgba ẹwọn.
"Ohun to se koko nipe iwa ti wọn hu yii buru jai, ẹnikẹni to wu ko jẹ, ti ọwọ sinku wa ba fi tẹ wọn, a o fi oju wọn ba ileeẹjọ.
Nípa ti ọba tí ó jókòó lórí ìtẹ́ Dafidi, ati gbogbo àwọn tí ń gbé ìlú yìí, àní àwọn ará yín tí wọn kò ba yín lọ sí ìgbèkùn, 
Lẹyin naa lo kuro nibẹ lọ si ile iwe awọn oluko to wa ni Ikẹré Ekiti, lati tẹsiwaju ninu iṣẹ olukọ, ni ọdun 1979 si ọdun 1980.
Premier League: Nàn sẹ́ni ọ́ gọ̀ ni Chelsea fi ṣe fún Watford
Hajiya Amina Mohammed ni Ọjọ kẹrinlelogun, Oṣu keji, ọdun 2017 ko iwe fi ipo rẹ silẹ gẹgẹ bi minisita fun ọrọ agbegbe, lẹyin ti Ajọ Isọkan Agbaye (UN) yan an si ipo gẹgẹ bi igbakeji akọwe gbogboogbo fun ajọ rẹ.
Akosemose yii soro lori awon ewu to ro mo dida idoti soju agbara yato si omiyale agbara ya soobu.
Okunrin naa wa ṣe aisan fun bi ọdun marun un, eyi si mu ki o ta gboogbo nkan ini rẹ lati ri iwosan gba.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Champions League: Chelsea yoo waako pẹlu Barcelona 20 Èrèlè 2018 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Apapọ Messi ati Suares jẹ iṣoro fun awọn agbabọọlu ti wọn ba koju lori papa Ẹgbẹ agbabọọlu Chelsea ati Barcelona yoo gbe'na wo'ju ara wọn nigbati idije Uefa champions league ba pada sori afẹfẹ lalẹ ọjọ isẹgun.
Àṣà Yorùbá ma ńri ọpẹ́ ninú ohun gbogbo, nitori eyi ni àjọyọ̀ àti ayẹyẹ ṣe pọ ni ilẹ̀ Yorùbá.
Awọn oṣere tiata Yoruba ṣi n dara papaa julọ loju opo Instagram wọn.
Àdó olóró pa èèyàn méjìlélọ́gọ́ta ní Mọ́ṣáláṣí Afganistan ní àsìkò Jimoh Àgbo ṣiṣẹ́ fún mi l'asìkò tí mò ń wojú Olúwa fún ọmọ- Toyin Abraham Irú ọjà wo ni wọ́n kò ti lè yan Ìyálọ́jà?
Amọṣa eleyii to mu kawọn ọmọ orilẹ-ede Naijiria o pariwo julọ ni ti olori ijọ Synagogue Church of All Nations, Wolii TB Joshua.
 The theatre, which is the first of its kind in NW Nigeria, was completed in furtherance of his resolve to ensure personnel/families have access to world-class medical services pic.
“N óo pàṣẹ pé kí wọ́n gbo gbogbo Israẹli jìgìjìgì láàrin gbogbo orílẹ̀-èdè, bí ìgbà tí wọ́n bá fi ajọ̀ ku èlùbọ́, ṣugbọn kóró kan kò ní bọ́ sílẹ̀.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Salah, Mane fi àmì tuntun lélẹ̀ ní Premiership SERAP fẹ́ pe UI, AAUA lẹ́jọ́ lórí àfikún owó iléẹ̀kọ́ Aláwàdà ni Buhari - Fáyóṣé Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 3 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 5 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
EndSARS: Olatunde Abolarinwa London Tailor ní òun á ṣe baba fún mi, kò tilẹ̀ dúró ṣe bàbá àwọn ọmọ tirẹ̀ tóríi ìwà Ọlọ́pàá Mopol A kò lọwọ́ sí ìwé ìpẹ̀jọ́ tó tako ìdásílẹ̀ ìgbìmò ìwádìí aṣemáṣe ikọ̀ SARS- ọlọ́pàá Nàìjíríà Àwòrán àwọn afurasí tí a fi léde kìí ṣe òfegè, ṣùgbọn a dọ́gbọ́n síi - Iléeṣẹ́ ọlọ́pàá Àwọn Ọba alayé ní Naijiria ṣàbẹ̀wò sí Ọba Eko, Gómìnà Eko àti Bola Tinubu lẹyin ìwọ́de EndSARS Nitori o salọ ni igbẹjọ rẹ ko fi waye fun oṣu kan nitori ko yọju si ileẹjọ.
Ó bu ìyẹ̀fun díẹ̀, ó pò ó, ó gé e ní ìwọ̀n àkàrà bíi mélòó kan, níbi tí Amnoni ti lè máa rí i.
 lẹ ́ yìn èyí awólọ ́ wọ ̀ di alákòóso Ìjọba Àpapọ ̀ fún Ọrọ okòwò .
Ileeṣẹ ọlọpaa nipinlẹ Ondo ni awọn ti bẹrẹ iwaadi lori iṣẹlẹ naa.
54 Àti lati ríi pé kò sí àìṣedẽdé nínú ìjọ, tàbí ìṣòro pẹ̀lú ẹnìkan sí ẹlòmíràn, tàbí irọ́ pípá, tàbí sísọ ọ̀rọ̀ ẹ̀ni lẹ́hìn, tàbí sísọ̀rọ̀ búburú;
Láti inú ẹ̀yà Sebuluni, a yan Elisafani ọmọ Parinaki.
Èmi náà óo sì máa fi yín rẹ́rìn-ínnígbà tí ìdààmú bá dé ba yín,n óo máa fi yín ṣe ẹlẹ́yànígbà tí ìpayà bá dé ba yín.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Hushpuppi: Ìròyìn sọ pé ó ṣiṣẹ́ olórin rí, ta àlòkù àṣọ àti Kọ̀ńpútà 5 Agẹmo 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 6 Agẹmo 2020 Oríṣun àwòrán, Instagram/Hushpuppie Hushpuppi lorukọ ti ọpọ mọ si ti o si jẹ pe isọwọ fi ọla rẹ han sọ di ilumọọka loju opo ayelujara.
Lásìkò tí ajakale àrùn náà wáyé, kò tíì sí abẹrẹ ajesara tí ń dènà kòkòrò aifojuri tàbí oogun tó ń pá kòkòrò tó lewu nínú ara, èyí tó mú kí ọwọja àrùn òtútù aya ohun burú jáì.
51 Bẹ́ẹ̀ni, pé kí ó lè jẹ́ ọ̀fẹ́ sí gbogbo èyíkéyìí orílẹ̀ èdè, ìbátan, èdè, tàbí ènìyàn tí wọ́n lè jẹ́.
Ni abala kejii ifẹsẹwọnsẹ naa, Bukayo Saka jẹ aramọnda goolu lati fi sọ di mẹta sodo.
Ninu esi ayẹwo naa, ipinlẹ Eko ni eeyan mẹtalelaadoje, Oyo ni mẹtalelọgbọn, Edo si ni mejidinlọgbọn.
Lagos Killings: Ọ̀gá àgbà ọlọ́pàá ṣèkìlọ̀ pàtàkì fún àwọn ọlọ́pàá
 ( akinmuwagun 2001 : 1-3 ) .
Wọ́n ni kí Ìnàkí-ìbẹ̀rù jókòó sí ìparí tabili ni apá kan, wọ́n ní kí emi náà jókòó sí ìparí ní apa kejì ki ń kọjú si i.
Ìgbà tí mo ti rí àkàrà-oògùn ni mo ti mọ̀ pé iṣẹ́ ńlá bẹ̀rẹ̀, mo kọjú sí ìyàwó mi, mo ni, “ Ìyàwó mi ò, n ǹkan dé” òun náà si dá mi lóhùn ó ní ‘Nǹkan kan kò dé baálé mi, múra sí i, Ọlọ́run ọba náà yóó sì ràn ọ́ lọ́wọ́.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ọdun ń lọ sópin, ariwo 'ń sọ̀ ní ilé ńlá l'Abuja Ẹjọ́ Sowore bọ́ sọnù lọ́wọ́ àjọ DSS Ẹ́ wo ojú àwọn òṣèré tíátà tó péjú sí Ibadan fún ìpàdé ọlọ́dọọdún Ìtàn Àrọ̀gìdìgbà jẹ́ kí ń rò pé bàbá mi yan Yemọ̀ja ní àlè - Ọmọ Fagunwa Ajọ LASEMA fidi rẹ mulẹ pe ṣe ni àgbá epo to wa lara ọkọ naa yọ danu, to si f'ori dolẹ, ti ìdá meji ninu mẹta epo diisu to gbe si tu danu saarin ọna.
Tabi tí Ọlọrun ṣe ìpín wọn ní ìrora ninu ibinu rẹ̀?
 Adari ere sinima, Joël Tchédré, jẹ ọkan pataki lara awọn ọdọ yii.
O Abiola’ Àwọn ọmọ Nàìjíríà tahùn sí SERAP lórí ẹjọ́ Onnoghen Àwọn òṣèré, olórin Yorùbá gbàdúrà fún MC Oluomo Kini awọn agba amofin n sọ?
Ṣé àwa mejeeji ni yóo jọ wọ inú erùpẹ̀ lọ?
Nítorí ìlú olódi ti di ahoro,ó di ibùgbé tí a kọ̀ sílẹ̀, tí a sì patì bí aginjù;ibẹ̀ ni àwọn ọmọ mààlúù yóo ti máa jẹko,wọn óo dùbúlẹ̀ níbẹ̀, wọn óo sì máa jẹ àwọn ẹ̀ka igi rẹ̀.
 nínú Ìrìnkèrindò nínú igbó elégbèje , a ìbẹ ̀ rẹ ̀ ìrììnàjò sí òkè ìrònú , alábàá pàdé ẹlẹ ́ gbára , ìtàn òmùgọ ́ diméjì àti Òmùgọ ́ dimẹ ́ ta ìtàn wèrédìran àti ìgbéyàwó Ìrìnkèrindò.
Ọ̀kan ninu wọn dáhùn pé, “Kò sí ẹnìkan ninu wa tí ń sọ àṣírí fún ọba Israẹli.
Bakan naa ni ajọ naa tun sọ pe araalu le fi ẹjọ iru ẹni bẹ ẹ sun lori nọmba ibaraẹnisọrọ 08157691214 tabi 08157691071.
Igbẹ lile to pẹ ki eeyan to ya a tan maa n ṣe kọndọrọ bi kokoro tata n ṣafihan inu kikun diẹ.
Balogun iko agbaboolu Super Eagles, John Mikel Obi ti kede pe, iko re le gba ife eye agbaye ni Russia.
Pèpéle pẹpẹ náà yóo ga ní igbọnwọ kan, yóo fẹ̀ ní igbọnwọ kan.
Ọ̀wọ́ EFCC tẹ ayédèrú Babaláwo pẹ̀lú òògùn abẹnugọ̀ǹgọ̀ Oríṣun àwòrán, EFCC Amọ lara awọn ọmọ Niajiria to fesi si ọrọ yii bu ẹnu atẹ lu iṣẹlẹ naa, ati wi pe EFCC ko lee sọ wi pe gbogbo awọn ti wọn fi panpẹ ọba mu naa ni afurasi 419.
Ọmọbinrin abikẹyin naa ni isẹ oun kọ ni titun yara igbalejo awọn se, amọ oun yoo maa tan ẹrọ amunawa wọn ni alaalẹ, ẹnikẹni ko si gbọdọ wa ji oun lati wa pa, ti oun ba ti lọ sun.
Wọn ni ẹni ọdun mẹtadinlọgọta ọhun, to jẹ oṣiṣẹ eto ilera ti ni aisan itọ ṣuga ati ẹjẹ riru lara tẹlẹ ki ọlọjọ to de lọjọ Abamẹta.
Erongba abẹṣẹ ku bi ojo ọmọ ile Gẹẹsi ati Naijiria, Anthony Joshua, lati fi irawọ kun irawọ rẹ nilẹ Amẹrika lo ti ja si pabo.
23 Ògún 2019 Oríṣun àwòrán, @Alternative Africa Àkọlé àwòrán, Agba ọjẹ Alakada to wọnu oṣelu Ọjọgbọn Adebanji Stephen Akintoye lo jawe olubori ninu idibo ti wọn ṣe fi yan olori tuntun fun iran Yoruba.
Bàbá tí ó bí emi yìí ni akọ̀wédìran, baba Akọ̀wédìran sì ni Ìdákẹ́rọ́rọ́-òde, Ìdákẹ́rọ́rọ́ tó baba fún Àkọ́wédìran, Akọ̀wédìran tó baba fún èmi, Olówó-ayé, nítorí náà, kò sí baba tí ó jẹ́ baba tí ó tóbí tí ó ju baba tí ó ju baba tí ó bí mi, nítorí náà èmi bẹ̀ ọ́ tọkàkntọkàn, má ṣàìjẹ́ kí n mọ baba tí ó tóbí náà tí ó jẹ́ baba tí ó bí ọ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Lagos gas explosion: Afẹ́fẹ́ Gáàsì tó rọra ń yọ́ọ́ jò pa Ajibola lẹ́nu iṣẹ́ jórin-jórin 4 Ògún 2020 Oríṣun àwòrán, LASEMA Ajọ to n ri si iṣẹlẹ pajawiri ni ipinlẹ Eko, LASEMA ti ri oku olukṣẹ kan latarii ibugbamu gaasi to ṣẹlẹ ni agbegbe ibudokọ Alafia ni Orile Iganmu, ipinlẹ Eko.
Idaji ni iṣẹlẹ naa waye, ti ko si tii si ẹni to mọ ohun to fa iṣẹlẹ naa.
gege bi omo orile ede Naijiria, ti a ba fẹ ki idagbasoke ba ara wa,a gbọdọ  gbiyanju lati yan awon eniyan to koju osuwọn
Koda, Abiola Ajimobi sọ ni ọjọ kan ti awọn osisẹ fẹyinti n beere ajẹsilẹ owo ajẹmọnu wọn pe: Se wọn ko ni ọmọ to wulo to lee maa tọju wọn lọjọ ogbo ni eyi ti ko ni jẹ ki wọn gbe ara le owo ajẹmọnu ifẹyinti lati ọdọ ijọba."
 Ẹni ti abajade esi ibo naa ko ba tẹ lọrun
Alukoro fun ile-ise awon omo-ogun ofurufu, ogagun Olatokunbo Adesanya lo so eleyii di mimo ,pe aseyori ikolu naa waye nipa itanu-lolobo ati iwadii  ti iko omo-ogum ofurufu se nipa ibi awon iko Boko haram ti n se ise ijamba ni Arege ati Tumbun rago.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Àìsàn ìtọ̀ súgà kò túmọ̀ sí pé èèyàn ti gba ọjọ́ ikú- Dókítà 14 Bélú 2019 Oríṣun àwòrán, facebook/wilson ikubese Àkọlé àwòrán, Aisan itọ ṣuga ma n jina rere si ẹni to ba n ṣe ere idaraya Wilson Ikubese, to jẹ dokiita ati onimọ nipa eto ilera ti sọ pe, aisan itọ suga ko tumọ si pe eeyan ti gba ọjọ iku Ikubese lo sọ ọrọ yii ninu ifọrọwerọ kan pẹlu BBC layajọ aisan itọ ṣuga tọdun 2019, eyi ti gbogbo agbaye n ṣe.
Headies yii ni won mo si ami eye takasufe lati odun 2006 lo ti bere lati fi yonbo ise awon onkorin ni Naijiria.
Olori ikọ FIFA nibi ayẹyẹ naa, Ọgbẹni Peter Njonjo ni awọn ilu mọkanlelaadọrun ni ife ẹyẹ naa yoo de ni orilẹede mọkanlelaadọta.
Oríṣun àwòrán, EPA Àkọlé àwòrán, Awọn ọmọogun wa nikalẹ lagbegbe naa lẹyin ibugbamuohun Aworan tawọn eeyan fi sọwọ loju opo ayelujara ṣe afihan awọn ọmọogun ti wọn gbe ọkọ ijagun di oju ọna ile ijọsin naa.
Ọjọ Black Friday yii ni awọn ile itaja maa n ta awọn ọja wọn ni ẹsinwo.
Yóo ṣe ìdájọ́ àwọn orílẹ̀-èdè,ọpọlọpọ òkú ni yóo sì sùn ninu wọn;yóo sì run àwọn ìjòyè káàkiri ilẹ̀ ayé.
Lati ọdun 1962 si 1965, Shagari wa ni ipo Minisita fun ọrọ abẹle.
Iwadii ti fihan wi pe o ti le ni ọgọrun un eniyan to ti padanu ẹmi wọn si awọn ẹranko to ṣekupa wọn, lati Osu Kẹrin, ọdun 2014 si Osu Karun un, ọdun orilẹ-ede India to ni ẹkun to poju lagbaye.
Nígbà náà ni ẹ óo tó mọ̀ pé èmi ni OLUWA Ọlọrun yín.
Eyi ni afojusun si mimojuto ifonrere ero pupo ati eya orisiirisii ti Naijiria ni.
- iléeṣẹ́ ológun kìlọ̀ Ninu iṣẹ ikini to fi ranṣẹ si baba, Oloye Alli sọ pe Alaafin jẹ ọba to n lepa alaafia, idagbasoke ati ilọsiwaju ilẹ Yoruba to fi mọ gbogbo orilẹede Naijiria.
2019 Elections: Àjọ tó ń wo bí ìdìbò se ń lọ ní ìsẹ̀lẹ̀ náà léwu
Má ṣe kanra nítorí àwọn aṣebi,má sì ṣe jowú eniyan burúkú,
Gomina ipinlẹ Ekiti tun sọ fawọn eeyan to wa nibi ipade naa wi pe Aarẹ Muhammadu Buhari ṣetan lati gba ọrọ awọn to n beere fun iyipada iwa awọn ọlọpaa Naijiria.
Mi o kan ti ẹ mọ nkan ti mo fẹ se bayi.
”Nígbà náà ni gbogbo ọ̀gá àwọn awakọ̀ ojú omi, ati gbogbo àwọn tí ó ń wọ ọkọ̀ ati àwọn atukọ̀ ati àwọn tí iṣẹ́ wọn jẹ mọ́ ojú omi òkun lọ dúró ní òkèèrè.
Aarẹ Buhari ṣeleri pe ijọba ṣetan lati pese ohun elo ijagun ti wọn nilo lati ṣiṣẹ to wa lọwọ wọn.
Bí àwọn kan tí ń ní àtimọ̀lé tí wọ́n sọ olorin Nazir sí ní Kano ni ọwọ́ kan òṣèlù ní àwọn mii ní.
"Buhari sọ pe ""ootọ ni pe orilẹ-ede Naijira mọ erongba awọn orilẹede to yi wa ka ati ajọ ECOWAS lori ibode ti a gbe agadagodo si, ṣugbọn a o wa ojutu si ọrọ naa laipẹ."
Ekiti Election: Kọmísánà fétò ìdìbò ní jàǹdùkú já àpótí gbà ní wọ́ọ́dù mẹ́fà
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́ búra fún àwọn alága tuntun Ọ̀rọ̀ gbina, ó ti ń ràn nítori àwọn ọmọ Yahoo Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ọ̀nà ọ̀fun lọ̀nà ọ̀run - omi ò jẹ́ ká ta ọjà Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 3 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 5 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Aarẹ kootu naa, Ọmọba Adewale Adegoke sọ fawọn mejeeji lati jọ sọ asọyepọ laarin ara wọn.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Nígbà tí mò ń wà Awolowo, Gowon, Babangida, mo fi ara mi sípo ọ̀wọ̀ tóri .
Ko ṣe maa sọ ni pataki ati jawe olubori ni ifẹsẹwọnsẹ yii fun ikọ Chelsea lẹyin ti wọn ti jẹ ajẹranju iya lọwọ Manchester united ati Liverpool laarin ọjọ mẹrin sirawọn.
Ekiti APC: Kíkọ ọjà tàbí afárá sí Ekiti kọ́ ni ìdàgbàsókè
Jesu sọ fún un pé, “O wí ire.
Akẹ́kọ̀ọ́bìrin kan tí ó jẹ́ ọmọ Tibet-Canada rí ìkọlu lórí ayélujára lẹ́yìn tí ó já ewé olú borí nínú ìdìbò àjọ-ìgbìmọ̀ akẹ́kọ̀ọ́.
Ìfẹ́ mà burú o, o burú púpọ̀.
Jesu kígbe, ó ní, “Baba, ní ọwọ́ rẹ ni mo fi ẹ̀mí mi lé.
"O ni ""mo ṣakiyesi pe igi Keresimesi ṣe pataki si gbogbo Kristiẹni kaakiri agbaye, lo jẹ ki n ṣe bẹ ẹ fun alufa, ati lati ki gbogbo Kristiẹni ku ọdun ati imurasilẹ fun ọdun tuntun""."
Ni afẹmọjumọ lawọn oṣiṣẹ naa ti lọ ti abawọle ileeṣẹ naa pa, ti wọn si ni Ọjọgbọn Yusuf ko lẹtọ lati wa si ibi iṣẹ nitori wọn ti ni ko lọ rọọkun nile naa.
“Lara eto iranwo ti won pese
Ni kete ti o kuro ni agọ ọlọpaa, lo lọ dara pọ mọ awọn ajegbọrọ lọja Elewure lagbegbe Moniya.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Christmans celebrations: Alaafin Oyo gba àdúrà ọdún fún àwọn ọmọ Nàìjíríà, pẹ̀lú ìmọ̀ràn lórí ààrùn COVID-19 25 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 26 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Oríṣun àwòrán, facebook/Alaafin Oba Adeyemi III Bi awọn eekan gbogbo ṣe n dawọ idunu pẹlu oniruuru ara ati ọrọ lọjọ Keresimesi, kabiyesi Alaafin ti ilu Ọyọ, Ọba Lamidi Adeyẹmi Ọlayiwọla kẹta pẹlu ti sọrọ.
Awọn onimọ ninu ọrọ eto aabo ni o ṣeeṣe ki iyatọ maa ba eto aabo to mẹhẹ lọdun 2020 nitori owo ti ijọba ya sọtọ fun ileeṣẹ ọlọpaa atawọn ologun ti kere ju.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Amotekun: Àwọn olóṣèlú, àwọn tó kùnà jíjẹ́ ọmọ ikọ̀ Amotekun ló ń gbé ìròyìn ìbàjẹ́ kiri O sọ ọrọ yii ninu iwe to kọ si Ẹgbẹ ọmọ Yoruba l'agbaye, to ṣe agbatẹru ipade apero akọkọ lori eto aabo nilẹ Yoruba.
Ṣebí Samaria ni olú-ìlú Efuraimu, Ọmọ Remalaya sì ni olórí Samaria.
je pe oun ni lokan lati sabewo sile igbimo ohun koun o to gbele sile sugbon ti
Wọn kò ní wọ ohunkohun tí a fi irun aguntan hun nígbà tí wọ́n bá ń ṣiṣẹ́ iranṣẹ lẹ́nu ọ̀nà ati ninu gbọ̀ngàn inú.
Eyi waye tori bo ṣe ni iwa ko ṣa a ma a ko owo shile meji ti baba rẹ maa n fun un gẹgẹ bii owo ti yoo fi ra nkan awọn aburo rẹ meji nigba ti baba wọn ba ti ṣe iṣẹ lọ si Ghana gẹgẹ bii awakọ.
Airport/Ikeja Bridge, Ijọba ibilẹ Ikeja 4.
Ṣe lootọ ni pe o ta bọsikọrọ l'Eko?
Ẹkún sísun ti sọ ojú mi di bàìbàì,ìdààmú bá ọkàn mi;ìbànújẹ́ sì mú kí ó rẹ̀wẹ̀sìnítorí ìparun àwọn eniyan mi,nítorí pé àwọn ọmọ wẹ́wẹ́ati àwọn ọmọ ọwọ́ ń dákú lójú pópó láàrin ìlú.
Ẹ ti yapa kúrò ní ọ̀nà oore-ọ̀fẹ́.
23 Ọ̀wàrà 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Orilẹede Russia lo n gbalejo ipade apapọ awọn asaaju orilẹ-ede Áfíríkà lọsẹ yii, eyi to n fihan pe agbega ti n ba ipa to n ko nilẹ Áfíríkà.
Abisirim soro yii nibi iforowanilenuwo to se pelu awon oniroyin pe: “Ti eniyan ba n jeun pupo ju, o di dandan ki eya ara maa se ise to po ju ni eyi to le je ki won maa sanra lainidi ti o le di akoba fun ara lojo ola.
sugbon pabo lo jasi, eleyi ti o si se pataki fun won lakoko yii lati so isuna ati
Wọ́n ní iléeṣẹ́ Emzor nàá jẹ̀bi: Ṣíṣe ìdíwọ́ tó fi mọ́ kíkó ẹ̀rí pamọ́ lásìkò tí ikọ̀ NAFDAC ṣe àbẹ̀wò sí ọgbà iléeṣẹ́ nàá.
Gomina Sanwo-Olu ṣalaye pe, o jẹ oun to ba oun ninu jẹ pe pẹlu ọpọ ilanilọyẹ, awọn ero ko dawọ kikun awọn banki atawọn ọja gbogbo lọpọ yanturu .
"Iṣẹ́ amòfin tí mo kọ́ ni Fáṣítì kò mú owó wọlé fún mi bíi iṣẹ́ tíátà - Femi Adebayo ""Nigba ti awọn onimọ iṣegun oyinbo to n wo aarun, awọn oṣiṣẹ ni yara ayẹwo ati awọn akọṣẹmọṣẹ mii to n bẹ ninu ọgba fasiti ilẹ Ibadan ba ṣe agbeyẹwo awọn ọna abayọ nilana ibilẹ, a o ṣe agbekele ogun ibilẹ ti yoo ṣe anfani fun gbogbo agbaye""."
"Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Bolaji Faleke ni Olùkọ́ tó ń kọ́ wa ní àṣà oge ṣiṣe lórí BBC Yorùbá Adekoya ni Ogu ko tẹle ilana iwe ofin ti ""Sheriff and Civil Process Act"" ko to kọ iwe ipẹjọ naa."
Aare sọrọ yii ,nile aarẹ to wa niluu Abuja, nigba to n gba awon ọmọ egbe to n satileyin fun aare ,Buhari Support Organisations (BSO)  , ni eyi ti oludari ajo awon eso onibode lorile ede Naijiria, Colonel Hameed Ali n dari soro.
Oríṣun àwòrán, Facebook/Daniel Elombah Àkọlé àwòrán, Ìpínlẹ̀ Anambra ni àwọn ọlapàá ti kọlu ọ̀gbẹ́ni Daniel Elombah Awọn ọlọpaa tun dunkoko mọ ọbinrin akọroyin Michaela Moye ti o n ba iwe iroyin Daily Times ṣiṣẹ wi pe o n ya fọto bi wọn ti n wole nilu Abuja lọdun 2011.
Ughamadu wa gba awọn to n wa ọkọ lati maa ṣe ra epo pamọ, nitori pe, ileeṣẹ naa yoo ṣe gbogbo nkan to ba le ṣe lati ri i daju pe, iyanṣẹlodi naa ko ni ipa buruku lara bi wọn ṣe n pin epo kaakiri Naijiria.
Jesu bá dúró, ó ní kí wọ́n lọ fà á lọ́wọ́ wá sọ́dọ̀ òun.
Alukoro ọlọ́pàá ní òun kò ní le máa sàlàyé àwọn ǹkan míràn tí àjọ náà tí n ṣe nítori pé, gbogbo àwọn ọ̀daran yìì náà ló n tẹtí sí ǹkan tó n lọ lórí ayélujára láti mọ ibi ti ọlọ́pàá báṣẹ́ dé.
Gomina Fayemi jáwé lọ gbé ilé rẹ fún adarí fasiti Ekiti 'Ẹnu lásán kò lè sàn owó oṣu oṣiṣẹ l'Ekiti' Ìgbẹ́jọ́ EFCC kò ní jẹ́ kí ń péjú sí ìbúra Fayemi - Fayose Fayemi jẹ Gomina ipinlẹ Ekiti lọdun 2010 labẹ asia ẹgbẹ oṣelu Action Congress of Nigeria (ACN).
Àárẹ̀ mú àwọn ọmọ rẹ,wọ́n sùn káàkiri ní gbogbo òpópó,bí ìgalà tí ó bọ́ sinu àwọ̀n.
Ọlọ̀tẹ̀ ni àwọn ìjòyè rẹ, ati ẹgbẹ́ olè;gbogbo wọn ni wọ́n fẹ́ràn àbẹ̀tẹ́lẹ̀,tí wọn sì ń wá ẹ̀bùn káàkiri.
Oríṣun àwòrán, Twitter Ki lo ti kọkọ ṣẹlẹ ni ipinlẹ Kaduna laipẹ?
Ṣugbọn o ni oun si fẹ gbaju mọ ẹgbẹ agbabọọlu Manchester United ti oun wa bayii.
E gbọ naa, ẹgbẹ wo ni Akpabio fi silẹ lati lọ darapọ mọ omiran?
Àwọn ẹlẹ́rìí mẹta ni ó wà: 
 Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Oyedepo àti ìjọba ń tahùn síra lórí bí ìjọba ṣe ń gba àkóso àwọn ilé ìjọsìn EFCC tún gbé Mompha lórí ẹ̀ṣùn lílu jìbìtì lórí ayélujára Ọlọ́pàá méjì wọ gàù lóri bí afurasí apanìyàn l‘Akinyele ṣe sá lọ Ìrìnna ọkọ́ òfúrufú s'ílẹ̀ òkèèrè bẹ̀rẹ̀ padà ní Nàìjíríà Jegede (PDP) ti yan Aṣojúṣòfin Ikengboju gẹ́gẹ́ bí ìgbákejì rẹ̀ tí wọ́n yóò jọ díje dupò Kabiesi ni, Fun apẹrẹ, ti eeyan buburu kan tabi ọdalẹ ba bami lalejo ni aafin mi, awọn onilu yoo fi ilu wọn ki mi nilọ, bo tilẹ jẹ pe ẹni naa ko ni mọ oun ti ilu naa n sọ, ṣugbọn o ye mi.
Awọn ẹjọ wọn yi ti mu ki awọn eeyan padanu owo to le ni biliọnu meji dọla.
Nítorí ó dájú pé, kì í ṣe àwọn angẹli ni ó wá ṣe ìrànlọ́wọ́ fún bíkòṣe àwọn ọmọ Abrahamu.
Ṣebí àna rẹ ni, ó sì jẹ́ olórí àwọn ọmọ ogun tí wọn ń ṣọ́ ọ ati eniyan pataki ninu ilé rẹ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Yoruba Culture: ọjọ́ méje ni wọ́n fí n rẹ ẹ̀kú Danafojura kó tó jáde Kilode ti wọn fi pa Ken Saro Wiwa?
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Yemen Water Child: Ọmọdé 44 ni Sọ́jà pa, tí 100 míì sì kú látọwọ́ ohun ìjà olóró Ipele keje ni wọn ṣẹṣẹ de nigba ti Israel ti lu Costa, ti ori rẹ si bẹjẹ eyi to mu ki alakoso ija gbọwọ rẹ soke pe, o ti jawe olubori.
Oríṣun àwòrán, Getty Images O maa n fihan pe oun fẹran awọn ounjẹ ibilẹ Naijiria gan Bi o ṣe fẹran Naijiria to, o ko ounjẹ ranṣẹ sile fun awọn idile ti Coronavirus ṣakoba fun.
Lizzy Jay to jẹ adẹrinposọnu to n ṣakoso ọmọ Ibadan coaching center sọ bo to lọrọ, ẹ fun oju lounjẹ ayọ ninu fọnran fidio yii.
Jakọbu ati gbogbo àwọn eniyan tí wọ́n wà pẹlu rẹ̀ bá wá sí Lusi, tí ó wà ní ilẹ̀ Kenaani, èyí nnì ni Bẹtẹli.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Buhari: ọmọ ni Lai Mohammed lóri lẹ́tà Ọbásanjó 27 Ìgbé 2018 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ààrẹ ní òun kọ́kọ́ sọ pé wọn kò gbọ́dọ̀ fèsì sí lẹ́tà Obasanjọ Ààrẹ Muhammadu Buhari ṣàlàyé lóri èrò rẹ̀ lóríi lẹ́tà Ọbásanjọ́.
'Àwọn oníṣòwò lẹ̀ka ètò ẹ̀kọ́ nìkan ló lè forúkọ sílẹ̀ báyìí fún ìrànwọ́ ìjọba àpapọ̀ Nàìjíríà' Èèyàn 176 ní àrùn Coronavirus tún ṣẹ̀ṣẹ̀ ràn ní Nàìjíríà ní Ọjọ́ Ìṣẹ́gun Ilé iṣẹ́ ọmọogun òfurufú sọ orúkọ Tolulope Arotiba di mánigbàgbé lórílẹ̀-èdè Nàìjíríà Daniel ń bọ̀ wá wò mí nítori mo ṣàìsàn ló dàwátì- Baba Daniel OPC láwọn mú afurasí agbébọn ajínigbé mẹ́rin l'Oyo, ọlọ́pàá ní àpapọ̀ òṣìṣẹ́ elétò aàbò ló ṣiṣẹ́ náa Awọn wo ni yoo kopa ninu iyanṣẹlodi yii ati fun igba wo?
'Tó bá jẹ́ ìfẹ́ Ọlọ́run ni kí ń di ààrẹ orílẹ̀èdè Nàíjíríà, kò sí ẹnikẹ́ni, tó fí mọ́ Ọbásanjọ́ tó leè pe Ọlárun ní ìjà.
Ibeere ti o n gba ẹnu ọpọ ni pe abi meji ninu awon oludije yii fẹ tẹ fun ni ọkan ninu wọn ni?
Oríṣun àwòrán, Lasema/Facebook Adari ikọ LASEMA, Olufemi Oke-Osanyintolu lasiko to n ba awọn ẹbi ati ara awọn ti ijamba ọkọ naa kẹdun, parọwa si awọn eniyan lati ṣọra ṣe loju popo.
Kolawole so pe, ile-eko ICSAN ni ile-eko akosemose nikan nijoba fun lase lorile-ede Nigeria lati seto idanwo iwe eri akowe ati alamojuto.
Solomoni dúró níwájú pẹpẹ níwájú àwùjọ àwọn ọmọ Israẹli, ó gbé ọwọ́ rẹ̀ mejeeji sókè.
Bi oloselu kan ba wa dije sipo torukọ rẹ si n jẹ Adolf Hitler njẹ ẹyin yoo dibo fún ùn?
Ìkébé mi tóbí ju ohun tí mo lè dọwọ́ bò lọ, n kìí fí ṣakọ- Nkechi Blessing Ẹ jẹ ki a wo bẹbẹ tawọn ọmọluabi mẹtẹẹta ọmọ Naijiria yii ṣe lagbaaye: Israel Adesanya - Igba ogun lo ti figa gbaga, ti ko si fidi rẹ́mi ninu ikankan Oríṣun àwòrán, Getty Images Ko si ẹni to le kọ iyan Israel Adesanya kere lagbo ẹṣẹ kikan ti UFC, ti wọn tun maa n pe ni MMA.
Nígbà náà ni OLUWA wí fun Joṣua pé, “Dìde.
Ṣaaju ni igbakeji gomina ọhun ti bu ẹnu atẹ lu kọmiṣọna naa lẹyin to dena rẹ nigbato fẹ jade kuro ninu ọgba ile ijọba to wa ni Alagbaka, ni ilu Akure.
10 Ọ̀wàrà 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 24 Ẹrẹ̀nà 2020 Oríṣun àwòrán, @others Àkọlé àwòrán, Dokita àti Nọ́ọ̀sì ń fìyà jẹ àwọn alaboyún lásìkò ìbímọ!
duro si orile ede yii , ki a se atileyin fun ijoba lati mu idagbasoke ba orile
Ó bá dìde, ó sáré tọ Eli lọ, ó ní, “Ìwọ ni o pè mí; mo dé.
Ẹgbẹ yii tu bẹnu atẹ lu bi erongba ijọba lati ọdun 2012 ko ṣe tii so eso rere di asiko yii.
Laarin ewọn ọdun mẹta si mẹẹdogun lẹni to ba bu Ọba le fi gbara Venezuela Lọdun 2013,ile ẹjọ giga buwọlu ofin to sọ pe ẹṣẹ ni ki eeyan kọ nkan tabi sọrọ aarẹ laburu.
Ni igba naa lọhun,awọn ọmọ ile fọwọ rọ iwaadi ti igbimọ ile lori ina ọba gbe jade ti wọn si tẹnbẹlu abajade iwaadi naa.
 Koda, bi a se n kuro ni papako, awon omo Niaijiria eniyan jankan-jankan meji otooto setore àádọ́ta millionu(N50m) ati  millionu márùndínlọ́gbọ̀n (N25m) fun iko yii.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Police arrest: 'Ó léwu láti kọ́kọ́ yẹ ọlọ́pàá wò ní Nàìjíríà' 14 Èbibi 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ọrọ eto aabo lorilẹede Naijiria Eewọ, ma danwo!
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Osun : Ilé ẹjọ́ tó ga jù lọ fi òǹtẹ̀ jan Oyetola gẹ́gẹ́ bíi Gómìnà Osun 5 Agẹmo 2019 Oríṣun àwòrán, @Oyetola Gboyega Ilé ẹjọ́ tó ga jù lọ ní ìlú Abuja ti dá Gboyega Oyetola láre gẹ́gẹ́ bíi Gómìnà Osun.
Ẹ̀rù ba àwọn tí ó kù, wọ́n sì fi ògo fún Ọlọrun ọ̀run.
Nitori naa adajọ agba fun pe si EFCC lati gba beeli agbẹjọro agba tẹlẹ ri ko le lọ tọju ara rẹ tori o ni ohun to gbe e lọ si ilu Dubai naa ni ọrọ ilera.
Ohun Marun un too ni lati mọ nipa ofin to da abo bo awọn akanda Ẹnikẹni to ba hu iwa ti ko tọ si akanda yoo fi ẹwọn oṣu mẹfa gbara tabi ko san faani ẹgbẹrun lọna ọgọrun naira; bi o ba wa ṣe ile iṣẹ lo dẹyẹ si akanda, miliọnu kan naira ni yoo fi gbara.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ikú ni fífi oògùn 'Paracetamol' bọ ẹran tàbí se ẹ̀wà- Iléeṣẹ́ ìlera Afunrasí jàǹdùkú 22 lọ́wọ́ ọlọ́pàá ti tẹ̀ lórí wàhálà ìdìbò ní Kogi-Iléeṣẹ́ Ọlọ́pàá Ogun ló ń wáyé ní Kogi, kìí ṣe ìbò dídì - Olùdíje gómìnà Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
bọwọlu ni : lati da Fafiti ile-eko awon oluko ti  ijoba apapo( Adeyemi Federal University of
Oríṣun àwòrán, Adegboyega oyetọla Ìpínlẹ̀ Osun kéde ọjọ́ táwọn iléèwé yóò ṣí padà Ijọba ipinlẹ Ọṣun ti kede eto iwọle tuntun fun ṣiṣi awọn ileewe ni ipinlẹ naa pẹlu mimu ọjọ kọkanlelogun oṣu kẹsan ọdun 2020 fun ṣiṣi awọn ileewe nibẹ.
Nígbà tí Baba-onírùngbọ̀n sọ̀rọ̀ yìí, ọ̀rọ̀ náà jọ mí lójú, ẹ̀rù sì túbọ̀ bà mí, gbogbo nǹkan burúkú ilé ẹ̀dá náà sì ń sọ kẹ́lẹ́kẹ́lẹ́ sí odò inú mi.
Aláàfin ń se ọgọ́rin ọdún, àwọn àwòrán mánigbàgbé Ninu ọrọ rẹ, Dangote seleri lati wa wọrọkọ fi ṣada lori ohun ti Alaafin beere, pẹlu afikun pe oun ṣetan lati mu anfaani ile iṣẹ ati idokoowo wa si agbegbe rẹ, eyi ti yoo mu adinku ba iye awọn ọdo ti ko niṣẹ lọwọ.
Afẹ́fẹ́ ń fẹ́ sí ibikíbi tí ó bá wù ú; ò ń gbọ́ ìró rẹ̀, ṣugbọn o kò mọ ibi tí ó ti ń bọ̀, tabi ibi tí ó ń lọ.
Ninu oṣu Kẹfa nikan, eeyan bi i marun un ni wọn pa, lara eyi ti ọmọdekunrin, ọmọ ọdun marun un kan wa.
Solomoni ka gbogbo àwọn àjèjì tí wọn ń gbé ilẹ̀ Israẹli gẹ́gẹ́ bí Dafidi baba rẹ̀ ti ṣe.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Dele Momodu : Lẹ́yìn Buhari àti Atiku, èrò ọjà làwọn olùdíje yóòkù ní ìdìbò 2019 Iléeṣẹ́ ọlọ́pàá Èkó ní àwọn kò mọ ohunkohun nípa ìwadìí ẹjọ́ Dakolo àti pásítọ̀ COZA mọ́ Ìlú ò rẹ́rìn ín rárá, Alaafin Adeyemi III fárígá fún Buhari nínú lẹ́tà tuntun Mo mọ̀ọ́mọ̀ dá €37,000 ti mo rí he padà ni -Ọmọ ogun Bashir Ẹwẹ, iroyin naa sọ pe awọn ẹyẹ Igun kan to ko si panpẹ apopọ yii ja bọ si ọja ilu Enugu, awọn to maa n ko wọn ko si tete ri wọn ko kọ̀rọ̀ naa to di tọrọ̀ fọn kalẹ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Chelsea vs Leicester city: Lẹ́yìn àjẹranjú ìyà lọ́wọ́ Man United àti Liverpool, Wilfred Ndidi tún pa fìtílà Chelsea ní Stamford bridge 18 Ògún 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Gbogbo nnkan lo lọ lodilodi ni ibi ifẹsẹwọnsẹ Chelsea ati Leicester city ni ọjọ Aiku.
Nítorí ohun tí à ń retí yìí ni àwọn Juu fi ń rojọ́ mi, Kabiyesi!
Mo fojú mi pamọ́ fún ọ,fún ìgbà díẹ̀ nítorí inú mi ń ru sí ọ,ṣugbọn nítorí ìfẹ́ àìlópin mi, n óo ṣàánú fún ọ.
Lọwọ lọwọ, ẹka mẹrindinlogun ni IS sọ pe oun ni ẹka jakejado agbaye ati pe Iṣẹ ti ẹka kọọkan n ṣe si yatọ.
 kókó yìí lè yípadà sí ọgbẹ ́ -inú .
Ṣugbọn wọn kò lè fèsì sí irú ọgbọ́n ati ẹ̀mí tí ó fi ń sọ̀rọ̀.
"Wọn maa n sọ eyii fun awọn ọmọde naa, itan igbesiaye mi a si maa fun wọn ni ireti.
 Awọn iroyin ti ẹ lee nifẹẹ si: Àwọn onímọ̀ Islam àti Oluwo takora lórí oyè Wàzírì Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fọ́nrán ohùn, Imam Fuad tako Oluwo lori wiwe lawani Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!"
Akoda Awo sọ pe, eto to dara ni idasilẹ Amọtẹkun, amọ ko le si aṣeyọri kankan nibẹ, ayafi ti awọn babalawo ba daa si ọrọ naa lati ṣe atọna ijọba.
Akanda ọmọbinrin naa wa parọwa si awọn ọdọ lati ni igbagbọ ninu ara wọn pe ko si ohun kankan to soro lati se fẹni to ba ni afojusun.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, ''Ẹ̀mí ọ̀pọ̀lọpọ̀ ṣì n sọnù ni orilẹ̀-ede Burundi' Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Arakunrin Nasiru Suleiman ni Babalade ni laipẹ ki o to ku ni o ṣi fẹran aworan ti oun fi sita nigba ti oun ṣe ayẹyẹ ọjọ ibi ọmọ rẹ akọkọ.
Wo dókítà ọmọ Nàìjíríà tí àgbáyé ń wárí fún nítorí abẹ́rẹ́ àjẹsára COVID-19 Fatai Rolling Dollar, Ọmọ ìdílé oyè tó gbé igbá orin tí Ebenezer Obey ń ṣiṣẹ́ lábẹ́ rẹ̀!
Ìgbà tí mo tilẹ̀ wá tún wọ inú igbó ibi ti igi ìrònú wà, nǹkan túbọ̀ le.
“Lọ sọ fún Dafidi pé mo fi nǹkan mẹta siwaju rẹ̀; kí ó yan ọ̀kan tí ó fẹ́ kí n ṣe sí òun ninu mẹtẹẹta.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Petrol price in Nigeria: Ìjọba àpapọ̀ ti kéde àdínkù owó epo bẹntiróòlù sí N162.
“Àwọn àlejò tí wọ́n wà láàrin yín yóo máa níláárí jù yín lọ, ọwọ́ wọn yóo máa ròkè, ṣugbọn ní tiyín, ẹ óo di ẹni ilẹ̀ patapata.
Ní àkókò yìí kan náà, Ṣimei, ọmọ Gera, ará Bẹnjamini, láti ìlú Bahurimu, sáré lọ sí odò Jọdani láti pàdé Dafidi ọba pẹlu àwọn eniyan Juda.
Nítorí náà, ẹ jẹ́ kí á rán àwọn ọkunrin kan pẹlu ẹṣin marun-un tí ó kù láti lọ wo ohun tí ó ṣẹlẹ̀.
" Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ọ̀nà tí àwọn olùdíje ipò gómínà ní Ìpínlẹ̀ Ọyọ fẹ̀ gbà yànjú ọ̀rọ̀ ààbò rèé Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Agbegbe Ọsẹ ati Ọwọ ni ipinlẹ Ondo ni aisan naa ti n ja rainrain nilẹ.
Wọ́n ṣìnà ní ti òdodo nítorí mò ń lọ sọ́dọ̀ Baba, ẹ kò sì ní rí mi mọ́.
” Esau bá bèèrè lọ́wọ́ baba rẹ̀ pé, “Ṣé o kò wá fi ẹyọ ìre kan pamọ́ fún mi ni?
Rehoboamu lọ sí Ṣekemu, nítorí pé gbogbo Israẹli ti péjọ níbẹ̀ láti fi jọba.
Nígbà náà ni Eliakimu, tí ń ṣe àkóso ààfin ati Ṣebina, akọ̀wé ọba, ati Joa, tí ń ṣe àkóso ìwé ìrántí fa aṣọ wọn ya láti fi ìbànújẹ́ wọn hàn, wọ́n sì lọ sọ ohun tí olórí ogun náà wí fun ọba.
Ọjọ buruku esu gbomi mu 'Èèwọ̀!
Ní Ọjọ́ Ìsinmi, wọ́n sinmi gẹ́gẹ́ bí òfin ti wí.
Ẹ óo jẹ ẹṣin ati àwọn tí wọn ń gùn wọ́n, àwọn alágbára ati oríṣìíríṣìí àwọn ọmọ ogun níbi àsè tí n óo sè fun yín.
Hilikaya sọ fún Ṣafani akọ̀wé, ó ní, “Mo rí ìwé òfin ninu ilé OLUWA.
 O ni milionu meji ati ida meta ni won ti fi san gbese ajemonu fawon osise feyinti.
james weldon johnson ( june 17 , 1871 june 26 , 1938 ) je ara amerika to je olukowe , oloselu , diplomat , olugbewo , oniroyin , akoewi , onimoeda-eniyan , oluko , agbejoro , ako-orin , ati alakitiyan awon eto araalu .
gbogbo awon eso alaabo, olori elesin ati awon ori-ade gbogbo fun ise takun-
O ni afaimọ ki orilẹede agbaye o maa fi oju wina iyan to lagbara bii ti inu Bibeli nigba ti a o ba fi ri oṣu diẹ sasiko yii.
“Ègún ni fún ọmọ inú rẹ, ati fún èso ilẹ̀ rẹ ati fún àwọn ọmọ mààlúù rẹ ati àwọn ọmọ aguntan rẹ.
 Alamojuto ile awọn ọmọ orukan naa, arabinrin Victoria Adeleke dupe lọwọ Ọba Ogunwusi fun idasilẹ ajo ẹlẹyinju aanu naa, gẹgẹ bi o ṣe parọwa si ọgọrọ awọn eeyan to lowo lọwọ lati se awokọṣe Ọọni Ile-Ife."
“Ọmọ àlè kankan kò gbọdọ̀ bá ìjọ eniyan OLUWA péjọ, arọmọdọmọ rẹ̀ títí dé ìran kẹwaa kò gbọdọ̀ bá ìjọ eniyan OLUWA péjọ.
Ọna wo ni awọn ọmọ ogun n gba ṣe iṣẹ wọn?
August Alsina: Ohun tó ṣẹlẹ̀ rèé láàrin wa àti àlè ìyàwó mi
"Àkọlé àwòrán, Tọkunrin tobinrin lo ṣe ajọyọ lagbo faaji tori wọn ni awọn ti fi ohun gbobo le Oluwa Eleduwa lọwọ Àkọlé àwòrán, ""Onilu yii ma pa mi o, owo rọọbu ti wọn."
(APC), jake-jado orile-ede Naijria lowe pe, ki won se rawon bi osusu owo lati
Ajẹ́pé enítọ̀hún a yẹra fún àwọn àìsàn tó rọ̀mọ́ sísanra bíi ẹ̀jẹ̀-ríru àti ọ̀rá-ẹ̀jẹ̀.
Ni oru ọjọ kẹrinla si ikẹẹdogun oṣu kẹrin ọdun 2014 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Orilẹede Naijiria ti wa labẹ ikọlu Boko Haram fun ọdun diẹ Awọn agbebọn ikọ Boko Haram kan ji awọn akẹkọ obinrin gbe ni ileewe girama ijọba to wa ni ilu Chibok ipinlẹ Borno.
Lẹ́yìn èyí, o ní ki ń jẹun, mo ni kò jẹ, o fi dandan lé e, ìgbà ttí ó pẹ́ sá, mo bu òkèlè díẹ̀.
22 Ẹrẹ̀nà 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Nibi idajọ ileeẹjọ to n gbọ ẹjọ idibo gomina nipinlẹ Ọṣun, igbimọ idajọ naa ni oun yoo yọ ibo ẹgbẹrun meji o le mọkandinlogun ninu ibo APC ati ẹgbẹrun kan o le igba ati mẹrindinlaadọta ninu ibo PDP lawọn ibudo idibo mẹtadinlogun ti wọn ko ti tẹle ilana idibo lorilẹede Naijiria.
Láìpẹ̀ yìí ni ìjọba orílẹ̀-ède Amerika polongo àfikún owó ìrìnna fún àwọn ọmọ Naijiria tí ó bá fẹ́ wá sí Amerika.
Atẹjade kan ti Amugbalẹgbẹ rẹ feto iroyin, Sọla Fasure fisita ni, lasiko ton sọrọ lori iwa isekupani awọn Fulani, Gomina Arẹgbẹsọla ni o se pataki ki ọmọ orilẹede yi kọọkan sisẹ papọ fun alaafia orilẹede yi nipa tita kete sawọn ohunkohun to ba lee sokunfa ogun ati ọtẹ.
Njẹ a le fọkan tọ akojọ ero ara ilu taa pe ni 'poll' yi?
Nígbà tí ó di àfẹ̀mọ́jú Abrahamu lọ sí ibi tí ó ti dúró níwájú OLUWA, 
esi ibo gomina to waye ni ọjọ kẹ́sán án   ni
Oyeyemi sọ pe awọn oluwọde naa gbe ifẹhonuhan wọn debi ayẹyẹ Owu Day nibi ti wọn si ti fọ gilaasi ọkọ igbakeji gomina ipinlẹ Ogun, Amoju ẹrọ(Arabinrin)Noimot Salako -Oyedele.
Oríṣun àwòrán, @NGRSenate Àkọlé àwòrán, Wahala ọwọn gogo epo lo mu ile asofin agba ilẹ Naijria bẹrẹ si nii tan ina wadi bi owo epo se nlọ Oniruuru awuyewuye lo ti waye lori ọrọ owo iranwọ epo rọbi lorilẹede Naijiria pẹlu ọkan-o-jọkan iwadi to ti waye saaju asiko yii.
Amọ awọn ẹlomiran yoo ko arun Covid-19 to lagbara ju bayi lọ.
" Kọmiṣọnna eto ilera to ni coronavirus kii ṣe tuntun, ni kopẹ kopẹ yii lawọn oṣiṣẹ ileeṣẹ ìjọba ipinlẹ Eko mẹwaa ko coronavirus,"" Ọgbẹni Omotosho lo woye bẹẹ Lọjọ Aje ni kọmiṣọnna eto iroyin kede ninu atẹjade kan to fi sita pe Ọjọgbọn Abayomi ti lugbadi aarun covid-19."
Àtùpà pọ̀ ninu iyàrá òkè níbi tí a péjọ sí.
Iyalẹnu lo jẹ fun wa pé ọpọ ninu awọn ti a fi ọrọ wa lẹnu wo ko fi bẹẹ gba idahun iru ọmọ ti Olugbodi jẹ.
    Ìgbà tí ilẹ̀ ọjọ́ kejì mo tí mo lọ sí ọdọ̀ oníbodè, o ránṣẹ́ sí ọ̀gágun àwọn ẹranko ẹni ti ń jẹ Ìnàkí-ìbẹ̀rù.
5 523486 Orilẹede Phillippines 9876 9.
Gẹgẹ bi a ti ṣe pẹlu ileeṣẹ ọlọpaa ipinlẹ Eko lori ọrọ Badoo to n paayan.
Ṣugbọn Ọlọrun rán kòkòrò kan ní àárọ̀ ọjọ́ keji, ó jẹ ìtàkùn náà, ó sì rọ.
Gundogan lo jẹ goolu kẹrin pẹlu gbe silẹ gba sile to gba wọ ile Brighton.
#U17WC: Mínísítà ní orí ìdúró l'òun ti wo ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ Nàìjíríà àti Hungary tán
Tottenham will hope to apply more pressure on the top two, while London rivals
Oríṣun àwòrán, Ekiti state government Fun ipinlẹ Oyo, Agbẹnusọ Gomina, Taiwo Adisa sọ pe awọn ti fi ofin de ọkọ lati ipinlẹ miran si ipinlẹ Oyo ko tiẹ to o dipe ẹgbẹ awọn gomina ṣe bẹ ẹ.
Oluwa bá sọ fún un pé, “Dìde.
Gbogbo awọn ọmọ ẹgbẹ oṣelu Democrats yatọ si meji lo dibo fun yiyọ Trump nipo, bẹẹni awọn Republicans to jẹ ẹgbẹ oṣelu Trump dibo tako o.
Awon asofin naa tenumo pe, ijoba apapo gbodo mu atunse ba ofin ati ilana, papaajulo isuna ti o n lo sori eto ilera, ni ona lati wa ni ibamu pelu ida marundinlogun ninu ida ogorun (15%) ti ajo AU fikale lati tele, ati lilo isuna ohun lona ti o lapere lati mu idagbasoke ba ile-iwosan wa gbogbo.
Awọn ẹlẹsin Hindu yii ma n woye bii nkan yoo ṣeri pẹlu arojinlẹ,ti wọn si maa n jẹun, sun ati ni ibalopo laarin awọn oku ti wọn n jo ni ina ni itẹ iboji.
marun un miiran lojuna ati mu igberu ati imuse de ba ofin ati ilana ijoba apapo
Nígbà tí ó bá fi ojú pamọ́,orílẹ̀-èdè tabi eniyan wo ló lè rí i?
 Ó dá mọ ́ tọ ̀ dúró ni kí ó tó lọ mú un nígbà tí wọ ́ n dé ojà , dírébà jẹ ẹ ̀ bà , ilésanmí jẹ iyán ó sì ra òòyà ní irinwó náírà ( 400.
Àkọlé àwòrán, ọ̀dọ́ ni agbara orilẹ-ede nibi ti eto ẹkọ ti ṣe koko Lọjọ kẹẹdọgbọn, oṣu yii ni wọn ṣe ipade gbẹyin ni eyi ti wọn ko fẹnu ọrọ jona si.
Àwọn Juu wí fún un pé, “Aadọta ọdún ó dín mẹrin ni ó gbà wá láti kọ́ Tẹmpili yìí, ìwọ yóo wá kọ́ ọ ní ọjọ́ mẹta?
Eleyii ko si ni fun wọn laaye lati woo finifini.
 nígbà tí ó yá , ó wá bèrè sí ní pa àwon erúré tó bá ti won ú ogbà a rè .
Oríṣun àwòrán, Facebook/Atiku Abubakar Oludije fun ipo aarẹ fẹgbẹ oṣelu PDP, Atiku Abuabakar lo fọrọ yii lede loju opo Twitter rẹ lalẹ ọjọ Aiku.
springbok jẹ ́ alábọ ́ dé ẹtu tí wọ ́ n ń rí ní gúúsù áfríkà àti gúúsù-wọ ̀ orùn áfríkà .
 Ọ ̀ pọ ̀ kíkó àìsàn náà yoo ti wà fún bí ọdún díẹ ̀ kí ó tó di pé àpá tó dá sí ìpéǹpéjú náà yoo pọ ̀ débi pé irun-ìpéǹpéjú yoo bẹ ̀ rẹ ̀ sí ní pa ẹyinjú lára .
Ọ̀kan ninu àwọn aṣọ́nà tí ó wà ninu ilé ìṣọ́ ní Jesireeli rí i tí Jehu ati àwọn ọkunrin rẹ̀ ń bọ̀.
Oludari ibudo yii, Chike Ihekweazu sọ eyi di mimọ pe afikun iṣẹlẹ mẹẹdọgbọ́n yii ti sọ gbogbo rẹ laarin oṣu kinni si isisiyii di ọọdunrun o le marun le laadọta ni ipinlẹ mọkandinlogun to fi mọ olu ilu orilẹede yii.
Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Eniola Badmus: Ẹ má se ọ̀fọ̀ mi, alaàyè ní mí, ń kò kú - Eniola Badmus21 Ọ̀wàrà 2020 Lekki Tollgate shooting: Fídíò táa ní lọ́wọ́ kò ṣàfihàn gbogbo ohun tó ṣẹlẹ̀ nírọ̀lẹ́ ọjọ́ náà - LCC3 Bélú 2020 Fídíò, Akomolede Yoruba: Kí ni ìdí tí aṣọ fi máa ń pọ̀ lára Egúngún ju Orò lọ́?
O ni ẹtahoro ọmọ Naijiria lo n na owo wa, ti eyi ba si tẹsiwaju, ewu si n bẹ loko longẹ.
Ki ẹbi ma ba parẹ́, ọmọ bibi jẹ ikan ninú ohun pàtàki ni igbéyàwó.
Soleimani ń gbìmọ̀ràn láti kọ lù wá l'Amerika la ṣe kọ́kọ́ yára mú u balẹ̀ - Trump Ìdí rè é tí a fí wó ìlè arúgbó ní ìdàjí -ìjọba ìpínlẹ̀ Kwara Àwọn fóònù wọ̀nyìí kò ní lè ṣe WhatsApp láti ọdún 2020 Ẹ̀kọ́ ọ̀fẹ́, ètò ilera ọ̀fẹ́ àti iná ọba ló jẹ wá lógún- ọmọ Nàìjíríà Ọrọ yii ti di iṣu ata yan-an yan-an loju opo Twitter nibi ti ọpọ ti bẹrẹ si ni fi Ole ati Van Persie we ara wọn nigba ti wọn gba bọọlu fun ikọ Man U.
" Adaobi Tricia Nwaubani: Oríṣun àwòrán, ADAOBI TRICIA NWAUBANI Igbeaye irọrun oun funraarẹ f'orisanpọn nigbati obi rẹ tuka"" Ipinnu rẹ yanilẹnu, ti a ba ni k'awo awọn idojukọ ti Okina ti ni pẹlu idasilẹ Street Priests."
OLUWA kígbe láti Sioni,ó sọ̀rọ̀ láti Jerusalẹmu;ọ̀run ati ayé mì tìtì,ṣugbọn OLUWA ni ààbò fún àwọn eniyan rẹ̀,òun ni ibi ààbò fún Israẹli.
“Bí ẹ bá ń rò ninu ọkàn yín pé, báwo ni ẹ óo ti ṣe mọ ìgbà tí wolii kan bá ń jẹ́ iṣẹ́ tí Ọlọrun kò rán an.
Ọ̀wọ́ngógó epo bẹntirò: NNPC ni 'ìròyìn ẹlẹ́jẹ̀' ni Oladejo Okediji àti ìgbé ayé ìtàn kíkọ rẹ̀ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Parental Guidance: Ọdún méjì ni kí ẹ ti bẹ̀rẹ̀ kíkọ́ ọmọ nípa ìbálòpọ̀ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, JAMB 2019: A ó fagi lé ìdànwò ẹni tó bá ṣe aṣemáṣe Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Ati pe, aṣẹ ti oun gba lọwọ kọmiṣọna ni lati wa nibi ayẹwo naa fun idẹra awọn akẹkọọ to ba wa ṣe ayẹwo nibẹ.
Awọn oṣiṣẹ ileeṣẹ akoroyinjọ apapọ Naijiria, NAN gunle iyanṣẹlodi niwaaju olu ileeṣẹ naa nilu Abuja.
O kere tan awon omo-ogun marun-un gbemi mi ti awon mewa miran si farapa ninu ikolu awon omo ogun olote Taliban ti o waye lenu ibode awon omo-ogun naa lorile-ede Afghanistan.
Bakan naa, wọn ni ki INEC kede aaye awọn aṣofin ẹgbẹ APC gẹgẹ bi eyi to ṣofo ki wọn si bẹrẹ igbesẹ atundi ibo lati fi ẹlomii sipo wọn gẹgẹ bo ṣe wa labẹ ofin.
Amọ eyi ko ri bẹẹ ninu ẹgbẹ oselu to n se ijọba lọwọ lorilẹede Naijiria nitori akọtun laasigbo to n da omi alaafia ẹgbẹ oselu naa ru bayii.
“Bí ẹnikẹ́ni bá fẹ́ mú ọkà wá siwaju OLUWA láti fi rúbọ, ó gbọdọ̀ jẹ́ ìyẹ̀fun dáradára, kí ó da òróró ati turari sórí rẹ̀.
Amọ wọn se itẹbọmi fun un, to si yipada di Kristiẹni, orukọ rẹ si n jẹ Susan Oríṣun àwòrán, Twitter/YorubaHistory Lara awọn ọmọ ti Ọba Oke fi jinki Samuel Ajayi Crowther ni Dandeson Coates Crowther, tii se Bisọọbu agba fun agbegbe Niger Delta, Abigail Crowther, ẹni to fẹ Thomas Babington Macaulay, tii se baba Herbert Macaulay.
Ni batiiri ọkọ baalu ba kọ iṣẹ to si doju kọ orule ile kan lẹba ibi to n lọ.
Yàtọ̀ sí Olúwó, wo àwọn Ọba alayé tó ti kọ ìyàwó rí láìpẹ́ nílẹ̀ Oodua Èèwọ!
O n beere fun ifọwọsowọpọ gbobo eniyan Faranse nile ati loke okun ki wọn le jọ yanju ọrọ naa.
Kí aráyé má rí mi gbé ṣe
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Agba Inaki sọ pé làásìgbò to ń wáyé ní South Africa pẹ̀lú àwọn ẹ̀yà mìí kò tó bí wọ́n ṣe ń pariwo rẹ̀ 23 Èbibi 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 24 Èbibi 2020 Oríṣun àwòrán, Lekan King-kong/Instagram Ilumọọka adẹrinposonu nni, Olalekan Olaleye, ti ọpọ eeyan mọ si Agba Inaki ti salaye pe, ọmọ lile ni oun ni kekere, ti oun si korira ki ẹnikẹni pa oun lẹnu mọ.
 ní ilẹ ̀ amẹrika , jẹnotaipu 1 n fa ìdá àádọ ́ rin ninu ọgọ ́ rùn ún àwọn àìsàn , jẹnotaipu 2 n fa ìdá ogún ninu ọgọ ́ rùn ún àwọn àìsàn , tí ìyòókù ìdá kan ninu ọgọ ́ rùn ún n fa àwọn àìsàn míràn .
Ọba ranṣẹ pe Absalomu, ó sì wá sọ́dọ̀ ọba.
O si dun mi pe n ko beere fun iranlọwọ, mo n da se gbogbo nkan ni pẹlu fifun ọmọ lọyan.
Ṣugbọn onídàájọ́ òdodo ni ọ́, OLUWA àwọn ọmọ ogun, ẹni tí ó ń dán ọkàn ati èrò eniyan wò, jẹ́ kí n rí i bí o óo ṣe máa gbẹ̀san lára wọn; nítorí pé ìwọ ni mo fi ọ̀rọ̀ mi lé lọ́wọ́.
Ethiopia: Bíi ti Zimbabwe, àdó olóró mìíràn bú ní Ethiopia
Ọpọ iwe iroyin papaa julọ lori ayelujara lo sọ pe, Magu ti wa ni gbaga DSS lori ẹsun pe o kojẹ ninu owo ti ajọ EFCC gba lọwọ awọn jẹgudujẹra ti wọn kowo Naijiria jẹ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Oba Adedokun Abolarin ti Oke Ila: Ó ya ọ̀pọ̀ tó súnmọ́ mi lẹ́nu bí mo ṣe ń kọ́ Onyeama ni ohunkohun to ba wu aṣofin kọọkan lo le fi ẹnu ara rẹ sọ nigba to ba wu u ṣugbọn kii ṣe lati sọ ero ara rẹ lorukọ ijọba UK.
Meje ti ku, ṣugbọn mẹwaa wa laaye bayii.
OsunElection 2018: EU, US, Uk ní ominú ń kọ òun lórí àbọ̀ ìròyìn nípa àtúndì ìbò Ọ̀sun
Oluwo ni ko ni boju mu ki oun maa lo ibomu lawujọ gẹgẹ bi olori.
Ní gbolohun kan, ẹni tí ó bá gbé wundia rẹ̀ ní iyawo kò ṣe nǹkan burúkú.
Àmọ́ láti ìgbà tí ìjọba tí ṣe ìkéde konile ó gbele láti dènà itankalẹ àrùn Coronavirus ni osu kẹta ọdún, adinku tí bá ìṣẹ̀lẹ̀ náà sì idà méjì nínú mẹta, èyí tíì ṣe ẹgbẹ̀rún méjìlá péré.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Èmi ò kí ń lu ìyàwó mi' Àwọn ọmọ Nàìjíríà fèsì sí ìkíni Saraki, Fayose nípa Kérésì Àkójọpọ̀ àwòrán ọdún Kérésìmesì lágbáyé Lẹ́yìn tó rúfin, àjọ NBC ṣí iléèṣẹ́ ìgbóhùnsáfẹ́fẹ́ Ekiti padà Aquaman Lati igba ti Justice League ti jade lawọn eeyan ti n poungbẹ fun fiimu omiran bẹẹ.
Igbagbọ wọn ni pe awọn to n lọ si awọn ijọ naa maa n ṣe oogun, ati awọn nkan ti ko tọ gẹgẹ bi Kristiẹni to jẹ atunbi.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Wọn ṣi aworan Obama ati Michelle 13 Èrèlè 2018 Oríṣun àwòrán, AFP Àkọlé àwòrán, Inu Aarẹ America tẹlẹri dun si aworan wonyi Ayẹyẹ ṣiṣi awọn aworan aarẹ America tẹlẹri, Barrack Obama ati iyawo rẹ Michelle Obama ti waye ni Smithsonian's National Portrait Gallery nilu Washington DC l'Amerika.
Aare soro naa di mimo lasiko abewo oba Obol Ofem Ubana ati awon emewa re lati afin Ugep, nipinle Cross River.
Mo yìn yín nítorí pé ẹ̀ ń ranti mi nígbà gbogbo, ati pé ẹ kò jẹ́ kí àwọn ẹ̀kọ́ tí mo fi kọ yín látijọ́ bọ́ lọ́wọ́ yín.
Awọn ọlọpaa gbe Sẹnetọ Adeleke atawọn mẹrin miran lọ siwaju Onidajọ I.
Omi ati àwọn olùgbé inú rẹ̀ pẹlu ń gbọ̀n rìrì.
FBI List: A tí mú obinrin kan lára àwọn gbájuẹ̀ ti FBI ń wá- EFCC
Mo bá la ẹnu, ó sì fún mi ní ìwé náà jẹ.
Bí igbo bá gbẹ yan, eṣú á ya lọ.
Ó dá wọn lóhùn pé, “Ọkunrin tí wọn ń pè ní Jesu ni ó po amọ̀, tí ó fi lẹ̀ mí lójú, tí ó sọ fún mi pé kí n lọ bọ́jú ní adágún Siloamu.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, China - Rògbòdìyàn bẹ sílẹ lọjọ òmìnira àádọ́rin ọdún ilẹ China Iroyin fi ye wa pe, ọta ibọn ba ọkan lara awọn akọroyin to wa nibi ifẹhonu han naa.
o kọ ẹkọ lati yunifasiti ti london ni 1963 pẹlu b.
Wọn tun yan Bouteflika gẹgẹ bi aarẹ lọdun 2004 ti o si fi ẹyin oludije marun un janlẹ lati gba ibo to pọ ju.
Igbimọ majẹ ko bajẹ ni ipinlẹ naa, lasiko ipade wọn ni awọn rọ gomina lati gbe igbese iyọni nipo naa, lẹyin ti wọn se abẹwo si awọn ọgba ile-ẹko giga ọhun ati si awọn ile-isẹ ti ọrọ naa kan.
Ẹmi ko mọ ibi ti ọmọ mi wa.
3bn Gbajue ń lọ orúkọ mi láti gba owó- Mama Rainbow Kò sí arúgbó ní Kano, Bàbá 74 gbé ìyá 84 ní ìyàwó ''Lootọ ni Fayose wa ba mi ki n buwọlu iwe kan ṣugbọn mo sọ pe mi o le buwọlu nitori yoo dabi pe mo n fi ọbẹ ẹyin jẹ ẹgbẹ PDP niṣu ni'' O tẹsiwaju pe ''A ko tii ta olu ileeṣẹ ẹgbẹ wa.
Llamo sọ̀rọ̀ nípa ìrìnàjòo rẹ̀ lọ sí Canada, ọmọ kékeré akẹ́kọ̀ọ́ tuntun kan tí ó wá láti Tibet tí ó bá wá sí ìyàrá ìkẹ́ẹ̀kọ̀ọ́.
Gẹgẹ bi akọsilẹ onka agbaye kan, Worldometer, eniyan ti ko din ni ẹgbẹrun maarun o le ẹgbẹrin ati marundinlaadọta eniyan ni aarun naa ti ṣekupa.
Wọ́n ń sọ lemọ́lemọ́ fún àwọn tí wọn kò ka ọ̀rọ̀ OLUWA sí pé, yóo dára fún wọn.
Wo ohun mẹ́wàá nípa gomina tuntun tí wọ́n dìbò yàn ní Bayelsa Wada: Alága àjọ ìdìbò INEC àti ọgá ọlọ́pàá, mò fà yín lè Ọlọrun lọ̀wọ́ Ohun mẹ́fà tó yẹ ní mímọ̀ nípa Yahaya Bello Adedimeji ní àdìtú layé, Toyin Abraham sọ pé kò sẹ́ni tó lè táyé lọ́rùn Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Àwa akódọ̀tí táà ń gba £1,500 lóṣù níbi sàn ju Sẹ́nétọ̀ lọ ní Nàìjíríà' Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Russia 2018: Ọjọ́ 11 ní à ò fí jẹun tí kò rí ibi sùn
Gẹ́gẹ́ bí ìṣẹ lọ́dọọdún,  àjọ̀dún Notting Hill ló gbọ̀de lọ́jọ́ Àìkú àti ọjọ́ Ajé tó kọjá.
Burna Boy n gún òke àgbà, wọ́n fà á kálẹ̀ fún àmì ẹ̀yẹ̀ Grammy Kìnìhún nìkan kọ́ ló burú, àwọn ajá mẹ́wàá yìí náà kò fararọ!
Ọjọ́-orí ọkùnrin náà a jẹ́ nkan bíi ọdún mẹ́ẹ̀ẹ́dọ́gbọ̀n sí ọgbọ̀n.
Wọn kò bọ̀wọ̀ fún OLUWA rárá.
kò tún níláti bọ̀wọ̀ fún baba rẹ̀ mọ́.
Amọ, atẹjade awọn ọlọpaa ko sọ bi ọkọ ofurufu yii yoo ṣe gbogun ti ijinigbe ni awọn agbegbe yii, tabi ọna ti awọn olopaa yoo gba lati ṣe iṣẹ wọn.
Olalekan Alli, oludari osise ile-ise ijoba ipinle Oyo, arabinrin  Hannah Ogunesan,alaga egbe oselu  APC fun ipinle Oyo, oloye Akin Oke, ati awon
Ìjọba Nàìjíríà ti sún ọjọ́ tí ìrìnàjò bàálù sílẹ̀ òkèèrè yóò bẹ̀rẹ̀ padà síwájú 'Mi o fọ́wọ́ sí bí ọmọ mi, Kiddwaya ṣe lọ fún BBNaija - Terry Waya Ọlọ́pàá Funso ló fi ààyè sílẹ̀ fún mi láti sá kúrò ní àgọ́ ọlọ́pàá tó wà ní Mokola - Sunday Shodipe Kìí ṣe torí ìbèérè ni mo ṣe bẹ́ Fani-Kayode, àwọn akẹẹgbẹ́ mi ló kó mi láyà jẹ - Eyo Charles Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ilé orin wa tí Ajimobi tun kọ́ dára púpọ̀, ṣùgbọ́n a kò ní dẹ́kun òtítọ́ Bẹẹ ba gbagbe, o ti le ni ogun ọdun ti gbajumọ akọrin ẹmi naa ti padanu ọ̀pá ẹyin rẹ, ti ko si lee rin mọ nitori ijamba ọkọ to waye.
Lẹ́hìn tí ó sọ ìtàn yìí tán ọkùnrin náà ká aṣọ sí òkè, nígbà tí ọba yìí wò ó lóòótọ́, láti ìdí títí dé orí nìkan ni ó jẹ́ ara tí ó ní ẹran, egungun àti ẹ̀jẹ̀.
Mo ti sọnù, nítorí pé ọ̀rọ̀ ẹnu mi kò mọ́, ọ̀rọ̀ ẹnu àwọn tí mò ń gbé ààrin wọn náà kò sì mọ́.
 Ó wà lára àwọn tí ó jà fún òmìnìra ilẹ ̀ nàìjíríà .
13 Nítorí ó ti fi sí ọkàn wọn láti ṣe èyí, pé nípa irọ́ pípa wọn yíò lè sọ pé àwọn ti mú ọ nínú àwọn ọ̀rọ̀ tí ìwọ ṣe bí ẹni pé o túmọ̀.
"Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Osun tribunal: Oyetọla ní òun kò bẹ̀rù ìdájọ́ ilé ẹjọ́ lórí èsì ìbò ìpínlẹ̀ Ọṣun 24 Ẹrẹ̀nà 2019 Oríṣun àwòrán, @OSUN_APC ""Emi o bẹru idajọ yii rara."
“Kì í ṣe oòrùn ni yóo máa tan ìmọ́lẹ̀ fún ọ mọ́ ní ọ̀sán, bẹ́ẹ̀ ni kì í ṣe òṣùpá ni yóo máa tan ìmọ́lẹ̀ fún ọ mọ́ ní òru:OLUWA ni yóo máa jẹ́ ìmọ́lẹ̀ ayérayé fún ọ,Ọlọrun rẹ yóo sì jẹ́ ògo rẹ.
Spaghetti, milíìkì, Chivita àti Àǹkàrá sọ Rabiu dèrò ẹ̀wọn ni Eko
Jẹtiro, baba iyawo Mose, mú iyawo Mose, ati àwọn ọmọ rẹ̀ mejeeji tọ̀ ọ́ wá ní aṣálẹ̀, níbi tí wọ́n pàgọ́ sí níbi òkè Ọlọrun.
Kí ló dé tí o kò mú ìlérí rẹ fún OLUWA ṣẹ, tí o sì rú òfin mi?
O woye pe, orile-ede ti o wa ni apa aarin gbun-gbun ile Afrika ohun ko ni ni ajosepo nkankan  pelu awon omo-ogun ti won yapa naa, ni eyi ti ojuse won ko ju didun-koko mo awon eleto-abo, ti won si n da laasigbo sile ni apa ariwa iwo-orun ati apa gusu iwo-orun orile-ede naa, ti o je ti awon elede geesi.
Adari ijọ Àgùdà ni agbaye naa wá gbadura fun awọn ẹlẹsin Kiristi lati ri itunu ati ibagbepọ rere lasiko yii.
Ọkunrin tí ó dúró láàrin àwọn igi mitili náà bá dáhùn pé, “Àwọn wọnyi ni àwọn tí OLUWA rán láti máa rin ilẹ̀ ayé wò.
N óo tú ẹ̀jẹ̀ rẹ̀ dà sórí ilẹ̀ ati sórí àwọn òkè, gbogbo ipadò yóo sì kún fún ẹ̀jẹ̀ rẹ̀.
Wọn fikun pe iwadii ti bẹrẹ lori iṣẹlẹ naa.
Koda wọn ni kii se Buhari ti awọn dibo fun lo wa lori aleefa amọ o ti ku lasiko to se aisan, to si lọ gba iwosan nilu London lọdun 2017.
Àwọn eniyan yòókù, àwọn alufaa, àwọn ọmọ Lefi, àwọn aṣọ́nà, àwọn akọrin, àwọn iranṣẹ tẹmpili ati àwọn tí wọ́n ti ya ara wọn sọ́tọ̀ kúrò lọ́dọ̀ àwọn eniyan ilẹ̀ náà gẹ́gẹ́ bí òfin Ọlọrun, àwọn iyawo wọn, àwọn ọmọ wọn ọkunrin, àwọn ọmọ wọn obinrin, gbogbo àwọn tí wọ́n gbọ́njú mọ ohun tí ó ń ṣẹlẹ̀, 
Ọlọrun tí ó gúnwà láti ìgbàanì yóo gbọ́,yóo sì rẹ̀ wọ́n sílẹ̀,nítorí pé wọn kò pa ìwà wọn dà,wọn kò sì bẹ̀rù Ọlọrun.
Bí ilẹ̀ ti mọ́, ọba dìde, ó sáré lọ sí ibi ihò kinniun náà.
O ni eyi yoo tun din ole ori ayelujara ati gbajuẹ pẹlu ẹrọ ayarabiaṣa kọmputa ku diẹ lagbaye lasiko yii.
Ṣugbọn, ọjọ kẹsan-an, oṣu Kọkanla, ni ireti wa pe ajọ naa yoo kede erongba rẹ.
EndSars Protest: Ǹkan mẹ́ta ti Gómìnà Babajide Sanwo-Olu pinu fún àwọn ọlọ́pàá ìpińlẹ̀ Eko
 lẹ ́ hìn tí àmì jẹyọ , dìgbòlugi sábà máa ń jásí ikú .
Nígbà tí ó gbé ara eniyan wọ̀, ó wó ògiri ìkélé tí ó wà láàrin wọn tí wọ́n fi ń yan ara wọn lódì.
Iroyin to n tẹ BBC News Yoruba lọwọ ṣalaye pe owurọ ọjọ aje ni Sẹnetọ Adeleke lọ yọju si ileeṣẹ ọlọpaa gẹgẹ bi awọn ọlọpaa ṣe paa laṣẹ fun.
Kò tọ́ sí Ọlọ́pàá láti ti ọmọ mi mọ́lé tórí ore tó ṣe lásìkò ìwọ́de EndSARS - Iya Eremosele Èmi ni mò ń jóko sórí ìtẹ́ Ọlọrun alààyè nílé ayé - Oluwo Wo ìdí tí wọ́n fi ta ẹyẹlé kan ṣoṣo ní ₦893,000,000 Àwọn ọmọ Naijiria kó owó wọn kúrò ní Access Bank lẹ́yìn tó gbẹ́sẹ̀lé àpò owó àwọn olùwọ́de EndSARS Ogbontarigi oṣere-binrin yii ṣalaye idi ti oun fi n jẹ Joke Silva dipo Jacob orukọ ọkọ rẹ.
Naijiria ti ko ipa Pataki lasiko eto idibo lorile ede Guinea Bissau, nitori naa
Nígbà tí àwọn kan tí ó dúró níbẹ̀ gbọ́, wọ́n ní, “Ọkunrin yìí ń pe Elija.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Àwọn dọkítà ní bó tilẹ̀ jẹ́ pe àṣìlò òògùn kìí ṣe ẹ̀bi awọn ará ìlú, ó mú ewu púpọ̀ dání Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àwọn dọkítà ní bó tilẹ̀ jẹ́ pe àṣìlò òògùn kìí ṣe ẹ̀bi awọn ará ìlú, ó mú ewu púpọ̀ dání 18 Owewe 2018 Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí 2 sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 2:23 Fídíò, Water Generator: Ó leè ṣiṣẹ fún wákàtí mẹfà, kó tó sinmi, Duration 2,2310 Òkùdu 2020 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
Gẹgẹbii iroyin to tẹ BBC Yoruba lọwọ ṣe sọ, alaga ẹgbẹ akọroyin ere idaraya, SWAN nipinlẹ Ọṣun, ọgbẹni Adeyẹmi Abọdẹrin pẹlu alaga ẹgbẹ awọn oniroyin obinrin, NAWOJ nipinlẹ naa, arabinrin Tunrayo Ayegbayo wa lara awọn olukọ tuntun ti ijọba ṣẹṣẹ taare sawọn ileewe rẹ.
Eleyi jẹ́ ki ilú nlá bẹ̀rẹ̀ si fẹ si.
Wọ́n níláti jẹ́ mímọ́ fún Ọlọrun wọn, wọn kò sì gbọdọ̀ sọ orúkọ Ọlọrun wọn di aláìmọ́, nítorí pé àwọn ni wọ́n ń rú ẹbọ sísun sí OLUWA; èyí tíí ṣe oúnjẹ Ọlọrun wọn, nítorí náà wọ́n gbọdọ̀ jẹ́ mímọ́.
Mò ń kígbe arò bí ajáko,mo di ẹgbẹ́ ẹyẹ ògòǹgò.
Láti January lọ, gbogbo ẹni tó bá ra ọjà lórí ayélujára yóò máa sanwó orí - FIRS A kò tí ì gbọ́ ǹkankan lórí owó ìwé ìrìnnà sí Naijiria - U.
bi wọ́n ṣe dí ojú pópó ti àwọn jàndùkú sì bẹ̀rẹ̀ sí ni gba owó lọ́wọ́ ará ilú tó ǹkan ti gómìnà fi lé pé sójà láti wá ran oun lọ́wọ́ Ààrẹ ti kọ̀wé fipò sílẹ̀ torí èèyàn méjì t'ọ́lọ́pàá pa níbi ìfẹ̀hónúhàn lòdì sí ìjọba Wo ohun tí Fashola rí níbi ìṣẹ̀lẹ̀ Lekki Tollgate tó ń fa ariwo lórí ayélujara Iléẹjọ́ mú ọjọ́ kejìdínlógún, oṣù kọkànlá fún ìgbẹ́jọ́ àwọn tó jí ìbejì Àáfà Akeugbagold ní Ibadan Ó kéré tán ọmọdé 142,000 sí 160,000 ní àìsàn otútú àyà ń pa lọ́dọọdún ní Nàìjíríà Ipa tí mo kó lágbègbè mí lásìkò ìwọ́de EndSARS ló dènà làásìgbò - Alaafin O ní sááju ni gọmìnà Babajide sanwo-Olu ti pé Commader 9 Brigade.
mu won lati satileyin fun oludije fun  ipo gomina labe asia egbe  APC , Inuwa Yahya ni ipinle  Gombe.
Àwọn ará ilẹ̀ Midiani ati ti Amaleki ati àwọn ará ilẹ̀ tí ó wà ní ìlà oòrùn pọ̀ nílẹ̀ lọ bí eṣú àwọn ràkúnmí wọn kò níye, wọ́n pọ̀ bí iyanrìn etí òkun.
Àkọlé àwòrán, Iriri wa fi idi ọrọ mulẹ pe pupọ ninu awọn adugbo yii ni ko dun un wo nipasẹ awọn panti ti o kun gbogbo opopona.
A la agbami lọ sí apá èbúté Silisia ati Pamfilia títí a fi dé ìlú Mira ní ilẹ̀ Lisia.
Ọpọlọpọ iṣẹlẹ ifipabanilopọ lo ti n waye laipẹ́ yii kaakiri awọn ipinlẹ Naijiria to si n waye nibikibi yala ninu ile, ẹyin ile atawọn ile ijọsin.
2019 Election: Olasunkanmi Okeowo ní òun kò díje fun ipo ààrẹ mọ
Umar ni yoo ma tukọ ajọ ọhun lẹyin ti wọn jawe lọ gbele ẹ fun Ibrahim Magu, to jẹ alaga ajọ naa tẹlẹ.
Aisha Buhari: Ìyawó ààrẹ padà délé láyọ̀ láti Dubai
Wọn ni oke ọya ni awọn ti lee fi ọwọ sọya lori ẹmi wọn ati maluu wọn.
Sola Sobowale Àkọlé àwòrán, MVCA Award: Ronke Odusanya, Oyebade Adebimpe, Funke Akindele àti Toyin Abrham tani ami ẹyẹ yoo já mọ lọ́wọ́?
2 Bẹ́ẹ̀ni, kíyèsíi, èmi yíò sọ fún ọ nínú ọkàn rẹ àti ní inú ẹ̀mí rẹ, lati ọwọ́ Ẹ̀mí Mímọ́, èyí tí yíò wá sí orí rẹ àti èyí tí yíò máa gbé nínú ọkàn rẹ.
Bí ojú rẹ bá mú ọ kọsẹ̀ yọ ọ́ sọnù.
Awon egbe yooku ti won ko ni
Ikede orukọ awọn ọmọ ajọ naa ti Aarẹ ile asofin Bukola Saraki kede ni wọn fi sita loju opo Twitter ile asofin lọjọ aje kannaa ti awọn oṣiṣẹ ohun da iṣẹ silẹ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Hospital Wedding: Oṣù kan péré ni Tash fi ṣe ìgbéyàwó pẹ̀lú Simon kó tó kú Kọmiṣana fun eto iroyin ni ipinlẹ Borno, Babakura Jatau ni, lati ipinlẹ Gombe ni ijọba yoo ti ko wọn wa si ipinlẹ Borno, ti wọn yoo si ko wọn si ibugbe ti wọn yoo ti ma a gba idanilẹkọ.
 ní ọdún 2oo9 , ó jọ ̀ wọ ́ ẹran jíjẹ tí ó sì jádé fún ìpolongo peta , tí ó ń jẹ ́ kí àwọn èèyàn mọ ̀ ìlera tí ó rọ ̀ mọ ̣ ́ eẃ jíjẹ .
"O ni, ""boya owo dollar lo gbẹnusoke ni o tabi nnkan."
Ọkunrin tí ń kọ́ àwọn eniyan nígbà gbogbo láti lòdì sí orílẹ̀-èdè wa ati Òfin Mose ati ilé yìí nìyí.
gba ara rẹ sílẹ̀ bí àgbọ̀nrín tíí gba ara rẹ̀ sílẹ̀ lọ́wọ́ ọdẹ,àní, bí ẹyẹ tíí ṣe, tíí fi í bọ́ lọ́wọ́ pẹyẹpẹyẹ.
Ìyà jẹ Efuraimu, gbòǹgbò wọn ti gbẹ, wọn kò sì ní so èso mọ́.
Koda, eyi ni wọn lo se akoba fun ijọba rẹ lati ri owo osu awọn osisẹ san fun ọpọlọpọ osu, ti awọn osisẹ ni Ọsun si n ba idaji owo osu wọn.
Ipá Moabu ti pin, a sì ti ṣẹ́ ẹ lápá.
Ó bí ọmọ ti ẹrubinrin nípa ìfẹ́ ara, ṣugbọn ó bí ọmọ ti obinrin tí ó ní òmìnira nípa ìlérí Ọlọrun.
Bẹ́ẹ̀ ni wọ́n fún wa ní ounjẹ ní oríṣiríṣi lọ́jọ́ náà ṣùgbọ́n ẹnikẹ́ni kò jẹ oúnjẹ wọn-ọnnì nínú wa.
Diẹ lara ẹsun ti wọn tun fi kan awọn mẹtẹẹta ni pe: Wọn ko wa si ipade to igba to yẹ, Gbigba riba tabi ẹbun lọna aitọ lori iṣẹ tabi igbesẹ ile.
Ó rọ gbogbo olórin láti so ewe agbéjẹ́ mọ́wọ́ lórí bi wọ́n ṣe máa n huwa sí àwọn akọròyìn, ìwà ìyànjẹ to fi mọ ìwà àitọ sí àwọn akọròyìn ní Naìjíríà.
Ọlọrun, mo yìn ọ́ fún ọ̀rọ̀ rẹ,ìwọ ni mo gbẹ́kẹ̀lé láìbẹ̀rù;kí ni eniyan ẹlẹ́ran ara lè fi mí ṣe?
 Àwọn mìíràn le lòdì sí èyí pé Àyìnlá Ọmọwúrà ni wọ ́ n mọ ̀ jù , tí ó sì jẹ ́ olórin àpàlà tí ó soríire jùlọ .
Ẹni mọ́kànléláàdọ́fà 111 ló lùgbàdì àrùn covid-19 ní Nàìjíríà lọ́jọ́ Àìkú Ènìyàn méjì pàdánù ẹ̀mí wọn nínú ìjàmbá ọkọ̀ tó wáyé ní Abúlé Ẹ̀gbá, ní ìpínlẹ̀ Eko Oluwo ti ìlú Iwó kìí ṣe ẹgbẹ́ Àtaọjà Osogbo - Alaafin ìlú Ọ̀yọ́ Ẹ̀ gbọ́ ọ̀rọ̀ lẹ́nu Adelé Ọba Alade Idanre ló rí ohun tó ṣẹlẹ̀ láàárín òun àti Ọba Aroloye Wumi Toriọla ti sọ̀rọ̀ sóke láti fi idí rẹ̀ múlẹ̀ pé òun àti ọ̀rẹ́ òun níjà Ọlọpaa mẹta atawọn sọja ṣagbako iku ninu rogbodiyan naa.
Pẹlu esi yi, Nàìjíríà ti tẹsiwaju si ìpele tó kágun sí àṣekágbá nínú ìdíje AWCON.
A gbiyanju lati ba alukoro ilẹẹṣẹ ọlọpaa ipinlẹ Ọyọ sọrọ lorii ẹsun naa lasiko ti a ṣe akojọpọ iroyin yii, ṣugbọn Arakunrin Olugbenga Fadeyi to n ṣoju ajọ naa ko gbe ipe ago rẹ.
Coronavirus: 'Mo sáré padà sí Nàìjíríà láti Uk lẹ́yìn t'íjọba fòfin de ìrìnàjò sílẹ̀ òkèrè' Ninu ọrọ tiẹ, Arabinrin kan toun naa ṣẹṣẹ de lati ilẹ Gẹẹsi bayii to ba BBC Yoruba sọrọ ṣalaye pe erongba oun tẹlẹ ni lati gba ilẹ Geẹṣi lọ si orilẹede Amẹrika.
17 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Oríṣun àwòrán, Bsip Àkọlé àwòrán, Aworan oyun iju Iwadii imọ ijinlẹ kan ti fihan pe obinrin mẹta ninu mẹwaa, ti ọjọ ori wọn wa laarin ọdun mẹẹdọgbọn si ọgbọn ọdun, lo ma n ni oyun iju ni Naijiria.
Àwọn aláṣẹ n wa àwọn tó ṣalabapade Mínísítà féto ìlera ilẹ̀ Gẹ̀ẹ́sì tó lùgbadì Coronavirus
Ṣeun ni bakan naa ni awọn to wa nibi apejẹ naa wa ọkọ di gbogbo ile ti awọn to n gbe ladugbo naa ko si ri aye ati wọle tabi jade.
Ọmọọba Alfred Olabode Akanni Thomas ku togo-togo, ko gbe ile aye lati da awọn ara to wa ninu rẹ nitori ọdun mẹrinlelọgbọn pere lo se nile aye.
 Eyi je okan lara igbese akin tijoba n gbe lati rii pe Ebola ko pada wo orile-ede yii mo.
"Orilẹede Naijiria n sọ ẹlẹwọn di ẹranko Igbakeji Aare orilẹede Naijiria ti bu ẹnu ẹtẹ lu ile isẹ ti o ns'eto awọn ile-ẹwọn lorilẹede yi - wi pe awọn ipo ẹwọn buru jayi - ti o sọ awọn ẹlẹwọn ""ẹranko""."
Ṣugbọn àwọn ọmọ Israẹli wí fún àwọn ará Hifi náà pé, “Bóyá nítòsí ibí ni ẹ ti wá, báwo ni a ṣe lè ba yín dá majẹmu?
"O ni ""ọrọ igbeyawo mi pẹlu Alaafin ni, ko kan ẹnikẹni, ọrọ ara mi ni."
Gbọ̀ngàn Mapo, ọ̀kan lára ibi àmúyangàn n'Ibadan rèé Link Kini ọna abayọ si aisan jẹjẹrẹ Ẹ ṣọra fun fifi taba Ẹ jẹun ti ohun ṣe ara loore Ẹ jẹ ọpọlọpọ eso ati ẹfọ.
Àwọn àwòrán mánigbàgbé nípa Ààrẹ Muhammadu Buhari Èrò àwọn ọmọ Nàìjíríà ṣọ̀tọ̀ọ̀tọ̀ lórí ọ̀rọ̀ Obi àti Ọṣinbajo Goodluck Jonathan kí Ààrẹ Buhari kú ọjọ́ ìbí Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Tayọ̀tayọ̀ ni mó fẹ́ ṣiṣẹ́ pẹ̀lú INEC ki ìdìbò 2019 lé dára' Bakan naa ni awọn ajinigbe gbe ọdọmọbinrin kan nilu Akurẹ lẹnu irinajo rẹ si ilu Ondo ninu oṣu Kọkanla, ko to o di pe awọn ọlọpa doola rẹ nigba ti olobó ta wọn.
Igbimo ajo FIFA to n mojuto sise afihan ife-eye agbaye yoo safihan ife-eye idije boolu agbaye todun 2018 lojo Aiku(Sunday) nilu Moscow.
Àbí kí a wí pé, ‘Láti ọwọ́ eniyan ni?
Oríṣun àwòrán, @OvieSheikh Agbajọwọ awọn ọmọ Naijiria atawọn eeyan orilẹ-ede miran ni Dubai korajọ, wọn ri miliọnu mẹrin din diẹ da fun un, ṣigbọn ko to nnkan.
Elija gbé ọmọ náà sọ̀kalẹ̀ pada sọ́dọ̀ ìyá rẹ̀, ó sì wí fún un pé, “Wò ó!
"Bi wọn ṣe n ṣe oogun apakokoro ""Sanitizer""."
Òwe Nípa Àwọn Alágbàro Ọgbà Àjàrà.
Arabinrin Oluwatobi sọ pe adura ki oun o ma jẹbi gbogbo irọju oun ni oun n gba, ki wahala o ma ja si asan.
a Daddy Freeze: Laipẹ yii ni fidio kan gba ori ayelujara, eyi to ṣafihan agbohunsafẹfẹ, Daddy Freeze, ati ọrẹbinrin rẹ, nibi ti wọn ti kopa nibi ayẹyẹ ọjọ ibi Hushpuppi, nilu Dubai.
"Ọba ti wọn ko ba ṣoro fun, ti ko tẹfa ti ko ṣe gbogbo nnkan ibilẹ to jẹ ọba le lori, ko yatọ si eeyan lasan.
O ni owo ti ẹgbẹ APC n bere lọwọ to fẹ gbe apotyi idibo naa ti pọ ju.
Irú wọn ni Sara tí ó gbọ́ràn sí Abrahamu lẹ́nu tí ó pè é ní “Oluwa mi.
Ọgbẹni Melaye ni nigba toju ṣokunkun loun fi sọ kobakungbe ọrọ si aarẹ naa ṣugbọn bayi ti oju oun ti la, aforiji loun n wa lọdọ Jonathan.
Anas ni o seese ki o fa egbo inu iho eti eyi ti o le waye lataari idoti ati awon kokoro afaisan ti o le mu ariwo dani ninu iho eti.
Bàbá mi fi ìyà jẹ ṣànpọ̀nná; ó fi àbùkù kan òè-ilẹ̀: ó ba làkúrègbé lórúkọ jẹ́; inúrírun di èrò ẹ̀hìn; orí-fífọ́ di ẹni kékeré: ẹ̀hìn-dídùn kò le sọ̀rọ̀; ikọ́ ti sápamọ́; aràn àyà bá ẹsẹ̀ rẹ̀ sọ̀rọ̀; jẹ̀díjẹ̀dí dákẹ́ mini-mini; ibà ń rìn tìrònù-tìrònù; ìgbẹ́ ọ̀rìn doríkodò; kúrúnà ń sọkún;egbò ń pòṣé; ifọ̀n fa ojú ro, otútù si ń káàánú.
Ṣùgbọ́n ọ̀kánkán ibi tí wọ́n ti ja ìjà yìí kò hu koríko mọ́, dípò èyí, àwọn ará Igbó Olódùmarè kọ́ ilé kan sí ibẹ̀, nínú èyí tí oníbodè tuntun ti wọ́n yàn ń gbé, oníbodè yìí kò sì dàbí ti àtijọ́ọ́, nítorí ó fẹ́ràn ènìyàn ó sì fẹ́ràn ẹranko, ó fẹ́ràn aráyé, ó sì fẹ́ràn ará ọ̀run.
 iṣẹ ́ àgbẹ ̀ ni ń mú oúnjẹ wá ; óunjẹ ní sì ń mú ìlera wá , ara-líle sì ni ogùn ọrọ ̀ .
Ó bá wọn wí fún aigbagbọ ati ọkàn líle wọn, nítorí wọn kò gba àwọn tí wọ́n rí i, tí wọ́n sọ pé ó ti jinde gbọ́.
Kí alẹ́ ọjọ́ náà di òfo,kí á má ṣe gbọ́ ìró ayọ̀ ninu rẹ̀ mọ́.
Ninu ikoko kerin, England, Paraguay, Haiti ati orile-ede Netherland ni won yoo jo maa figagbaga.
O tun ṣalaye pe ko si atunṣe popona pẹlu gbogbo ọna aarin ilu ti o ti bajẹ ti ko si si ohun kan pato ti wọn le ri tọka si.
Coronavirus: Ọkùnrin kan kú lẹ́yìn tí wọ́n lù ú nítorí ìbẹ̀rù coronavirus
Ṣugbọn kì í ṣe gbogbo eniyan ni ó ní ìmọ̀ yìí.
Awọn alaṣẹ ileeṣẹ baalu naa ni iṣeju mẹta pere ti baalu naa gbera ni o ja lulẹ Àkọlé àwòrán, Baalu naa ko eero mọkandinlaadọjọ, to fi mọ awọn oṣiṣẹ baalu mẹjọ.
Oni jẹ ọkan lara awọn ọjọ ti inu mi dun ju l'aye.
Oju agbo si ni awọn ọlọpaa ti lọ mu pe ko yọju si agọ awọn, ti gbogbo alejo to wa nibi ikomọ naa si n gba ẹri Gbadero jẹ pe ko jade lọ sibi kankan lọjọ naa.
Gẹgẹ baa si se mọ, osu kẹwa yii kan naa ni awujọ agbaye ya sọtọ fun ayajọ gbigbogun ti aisan jẹjẹrẹ ọyan, lọwọ-lọwọ bayii, ori ayelujara si ti kun fun aworan awọ̀n obinrin to n yan kọmu lodi lonii lati dena arun jẹjẹrẹ ọyan.
Oríṣun àwòrán, Reuters Agbara, iwa jẹgudujẹra ati irọ?
Ninu ọrọ ti Huawei gbe jade, o ni awọn ko ni dawọ pipese ''security updates'' ati awọn iṣẹ miran fawọn alabara awọn lori ọja tawọn fẹ ta,tabi ti wọn ti ta tẹlẹ kaakiri agbaye.
Wọ́n lọ sápamọ́ sí abẹ́ ààbò Farao,wọ́n lọ wá ààbò ní Ijipti.
Ninu ìpọ́njú mi, mo ké pe OLUWAmo ké pe Ọlọrun mi,ó gbọ́ ohùn mi láti inú tẹmpili rẹ̀;ó sì tẹ́tí sí igbe mi.
Israel Adesanya fẹ́ gbéná wojú Romero Coronavirus dòjú ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ PSG àti Strasbourg bolẹ̀ Bojú bojú o.
Gbogbo àwọn ọkunrin tí a kà ninu wọn láti ọmọ oṣù kan sókè jẹ́ ẹgbaata lé igba (6,200).
O ni iṣoro to gogo ju ninu gbogbo idojukọ Naijiria lọwọ yii naa ni iwa jẹgujẹra ni ẹka iṣẹ ọba.
Ọba jókòó níbi tí ó máa ń jókòó sí ní ẹ̀gbẹ́ ògiri, Jonatani jókòó ní iwájú rẹ̀.
 Arabinrin Malaka sọ pe awọn dẹkun lati sọ ohunkohun lori ọrọ naa, nitori pe awọn wo o pe ko bojumu lati ma a sọrọ lori iṣẹlẹ ti iwadii n lọ lori rẹ."
Bákan nàá ló kéde lójú òpó Twitter rẹ̀ pé ọjọ́ kọkàndínlógún, oṣù Kọkànlá ni ìgbẹ́jọ́ yóò maa tẹ̀síwájú.
Nibẹ lo ti kan oku Sukurat to lefo sinu omi.
Wahala eyi to waye kẹhin lọsẹ to kọja mu ki awọn eniyan kan padanu ẹmi wọn, t'ọpọlọpọ si di alainilelori nitori bi awọn onikupani naa ṣe dana sun awọn ile wọn l'awọn abule kan mejidinlogun nijọba ibilẹ Zurmi.
Taa ni Jọkẹ Silva, òsèré tíátà tó ń se ọjọ́ ìbí ?
Aye ode oni, ọgbọọgba ni wọ́n fẹ́ máa pin iṣẹ; ida aadọta si aadọta ni wọn fi n ṣe ninu ọgọrun.
"Nigba ti akọroyin BBC Yoruba kan si i, ti wọn si ba ọrọ de ibi ija Toyin Abraham ati Lizzy Anjorin, esi ti Madam Saje fọ ni wi pe ""Haa, mo dẹ wa wa lori itage lọwọ lọwọ bayii o, ẹ pe mi pada ni bii wakati meji""."
Ní ọjọ́ tí wọ́n dá ońjẹ tí ìyá mi gbé lọ sí ilé- ìwòsàn padà láìjẹ́ pé ènìyàn fọwọ́kàn àn ni ẹrù ti bà mí, ṣùgbọ́n mo sọ́ ọ́ sí ọkàn mi pe mo sá ti gbàdúrà ná.
Síbẹ̀-síbẹ̀, àwọn nkankan a máa mú inú ẹni dùn.
Ọjọ́ OLUWA ń bọ̀ tí wọn yóo pín àwọn ìkógun tí wọ́n kó ní ilẹ̀ Jerusalẹmu lójú yín.
ati ikede , Garba Shehu ti so pe ija ilẹ lo n sabaa maa n waye laarin awon
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Aarẹ Ọna Kakanfo:Isẹ rẹ ni ko dena idunkoko ajeji nilẹ Yoruba 28 Sẹ́rẹ́ 2018 Àkọlé àwòrán, Ojuse Aarẹ Ọna Kakanfo ni lati daabo bo ilẹ Yoruba lọwọ ikọlu awọn ajeji Akọwe apapọ fun ẹgbẹ agbaagba ilẹ Yoruba (YCE), Dokita Kunle Ọlajide ti kede pe omi n bẹ lamu fun Oloye Gani Adams, tii se Aarẹ Ọna Kakanfo ti wọn sẹsẹ yan fun ilẹ Yoruba.
Sùgbọ́n agbẹnuso fún àwọn ọlọ́pàá nìlú Abuja Anjuguri Manzah kọ̀ láti sọ̀rọ̀ lórí ìsẹ̀lẹ̀ náà.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Buhari wa ẹnu si àwọn ọdọ Nàìjíríà Johesu: Òsìsẹ́ ìlera ti bẹrẹ iyanselodi Ẹlẹ́wọ̀n gba máákì 248 ni ìdánwò Jamb Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Tí a fiṣọwọ́ ní 10:55 11 Òkùdu 201910:55 11 Òkùdu 2019 Díẹ̀ lára àwọn sẹ́nétọ̀ lẹ́yìn ìdìbò BBCCopyright: BBC lẹ́yìn ìdìbòImage caption: lẹ́yìn ìdìbò BBCCopyright: BBC Bi idibo ṣe n lọ lọwọImage caption: Bi idibo ṣe n lọ lọwọ BBCCopyright: BBC lẹ́yìn ìdìbòImage caption: lẹ́yìn ìdìbò BBCCopyright: BBC Bi idibo ṣe n lọ lọwọImage caption: Bi idibo ṣe n lọ lọwọ Article share tools Facebook Twitter ṢàpínlòView more share options Share this post Copy this linkKà síwájú síi nípa àwọn ìtọ́kasí wọ̀nyí.
O ni ''ṣe ni mò ń lọ láti ya sinimá kan ní Ikorodu tí àwọn òṣìṣẹ́ SARS sì dá wa dúró, wọ́n sì ní ká san owó láì nídìí.
Ẹyinjú rẹ dàbí ti àdàbà lábẹ́ ìbòjú rẹ,irun orí rẹ dàbí ọ̀wọ́ ewúrẹ́,tí wọn ń sọ̀kalẹ̀ láti gẹ̀rẹ́gẹ̀rẹ́ òkè Gileadi.
Nkurunziza subu lori papa l'alamojuto meji ba rẹwọn he
Àwọn mààlúù ati kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ tí ẹ fí ń ṣe iṣẹ́ lóko yóo máa jẹ oko tí a fi iyọ̀ sí; tí a ti gbọn ìdọ̀tí kúrò lára rẹ̀.
irinna oko, ogbeni Rotimi Amaechi soro di mimo fun awon akoroyin ni agbegbe
Kò sí Nnamdi Kanu nílùú wa o - Ìjọba Orílẹ̀èdè Israel Lawọn àdúgbò bi Kasuwan Magani àti Kujama wọn yóò máa wà lábẹ́ kóníléógbélé fún wákàti méjìlá.
Atẹjade kan ti o wa lati
Femi Fani Kayọde to ti figbakan jẹ minista fun ọrọ ọkọ ofurufu ni Naijiria loun àti awọn ọmọ ìjọ Satani ti n tahun sira wọn lori ayelujara.
Ṣebí àwọn ọlọ́rọ̀ níí máa fìtínà yín, tí wọn máa ń fà yín lọ sí kóòtù!
Ẹni tó jí ọ̀pá aṣẹ ń bọ̀ wá túbá fúnrarẹ̀, mo fi dáa yín lójú gẹ́gẹ́ bí ìyá - Erelu Kuti ''Mo nigbagbọ pe iyipada yoo waye fun idi meji.
Àwọn ọmọ yorùbá ń jẹ ẹ ̀ yà tó ń gbé ní gúúsù ìwọ ̀ oòrùn àti àríwá apa àrin nàìjíríà , àti gúúsù pẹ ̀ lú apa àrin benin .
Opọlọpọ awọn eniyan ti kii ṣe iran Igbo ni iṣu ẹni lo ti ọwọ ẹni bọ epo ni ọrọ yii nitori ile kan naa ni gbogbo wọn ti wa ni ila oorun guusu Naijiria Wo àwọn eléré ìdárayá mẹ́ta tí àjọ FIFA ti fòfin dè títí ayé Fowler kò sí lábẹ́ ìwádìí kankan-Garba Sheu Ìjìyà ń bẹ fún àwọn ti adé ọ̀rọ̀ náà bá ṣí mọ́ lóri -Ọga àgbà FRSC Ambode ní kò sí gìrì, eré ọwọ́ lásán ni EFCC ń ṣe Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Ọmọ Risikat olójú búlúù méjèéjì jẹ̀bùn oríire àti ìfà ńlá Èdè àìyedè láàrin Seyi Makinde àtàwọn aṣòfin yanjú, àbá ọdún 2021 dòhun Ẹ má bínú pé mo kọ́kọ́ ní akẹ́kọ̀ọ́ mẹ́wàá péré ni wọn kó nílé ìwé Kankara - Garba Shehu Àìmọ̀kan ló mú mi hu ìwà tí mo hù kọjá sẹ́yìn, Jonathan dárí jì mí - Dino Melaye Ẹ́ tú èékánná lọ́rùn Sowore, ẹ kò ní ẹ̀rí láti ba ṣẹjọ́ - Ẹgbẹ́ Amòfin Amẹ́ríkà Irú iṣẹ́ wo ní Funke Akindele rán sí Bukunmi Oluwasina, tó fa ariwo lórí ayélujára?
òkùnkùn gan-an kò ṣú jù fún ọ;òru mọ́lẹ̀ bí ọ̀sán;lójú rẹ, ìmọ́lẹ̀ kò yàtọ̀ sí òkùnkùn.
Oríṣun àwòrán, @juwon2017 Nigba to n bawọn akọroyin sọrọ lasiko yiyọju ọba sita naa, Ojumu tilu Ọwọ, Oloye Ọlanrewaju Famakinwa salaye pe o se dandan ki awọn se awọn etutu naa gẹgẹ bii asa ati ise ilu Ọwọ ti laa kalẹ.
Josẹfu dàbí igi eléso tí ó wà lẹ́bàá odò,àwọn ẹ̀ka rẹ̀ nà mọ́ ara ògiri.
Akoda awo ṣalaye siwaju sii pe, bi ọkunrin ba ni iyawo to si ṣakiyesi pe awọn ọkunrin miran ko jẹ ko sinmi, yoo wa nnkan to ba mọ lati fi ṣọ iyawo rẹ.
O ni orilẹede kọọkan lo n gbe igbeṣe ti wọn mọ wi pe yoo ṣe awọn ọmọ ilẹ wọn ni anfaani, nitorinaa loun ṣe woye wi pe ayẹwo to peye ni awọn papakọ ofurufu Naijiria yoo ko ipa to dara lati kapa arun naa.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ìmáàmù yiì dóólà ẹ̀mí 262 Krìstìẹ́nì ni Plateau Ìgbà wo ni Buhari yóò simi àwáwí?
kìnìhún pẹ̀lú àgbọ̀rín n fi ọwọ́ kó ara wọn lọ́wọ́, wọ́n ń siré kiri, ológbò àti èkúté ń ṣe ọ̀rẹ́ tí a ń yọ̀ pé àwọn fẹ́ di àna.
"Ètò RUGA wọn kò lè ká Fulani 500,000 tó wà nínú igbó ilẹ̀ Yorùbá - Oluwo Ìdí tí Bàbá Leah Sharibu fi yarí pé ọmọ òun kò kú Ooni Ife fohùn ránṣẹ́ sí Boris Johnson, ó ní, ""bóo bá joun gbé, má johùn gbé"" Ẹwẹ niwọn igba to ṣe pe ọkan lara awọn ọlọrọ ninu eyi gan ni Yinka Ayefele funra rẹ, BBC Yoruba kan si i latiṣalaye ọrọ."
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Gbajugbaja oṣere tiata, Motilọla Adekunle ló fi aya gbangba rẹ han lori èto ṣé o láyà.
Nítorí pé, n óo fi àwọn onírẹ̀lẹ̀ ati aláìlera sílẹ̀ sí ààrin yín, orúkọ èmi OLUWA ni wọn yóo gbẹ́kẹ̀lé.
Ọkan lara awọn adari ẹgbẹ Afẹnifẹre, Oloye Korede Duyile, ṣalaye fún BC Yoruba ni kikun lori bi wọn se kọwe lọ gbe ile rẹ fun Sẹnetọ Omisore fun ọdun kan.
Jẹ́ kí àwọn òkú ó sọ ìtàn nípa Hong Kong
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: 'Àṣírí ọkọ mi tú sími lọ́wọ́, ṣé mo le dáríjì í?
naa fun oludije fun ipo gomina ni ipinle Rivers ninu egbe PDP, Nyesom Wike.
“Ojú ọ̀nà oke Ìrònù ti n bẹ
Iléèṣẹ́ ọlọ́pàá: A ṣe nkan tó yẹ lórí ajínigbé tó tojú orun dójú ikú' Tá ló pá olùrànlọwọ Segun Oni ?
Oríṣun àwòrán, ENIOLABADMUS Oriṣiriṣi aworan ni Eniola ko soju ikanni Instagram rẹ lati fi sami si ọjọ ibi naa.
Lasiko yii ni ijọba ẹkun ìwọ oorun Naijiria to jẹ ẹya Yoruba, pinnu lati fi owo kun owo ori awọn agbẹ.
Atiku sọ pe ''o sunmọ miliọnu merindinlogun eeyan ni ko nisẹ ni Naijira, ti eyi si fi miliọnu mesan ju iye awọn ti ko nise lọwọ lodun 2014 lọ.
Saudi Arabia: Kíni ìdí ti àwọn ọmọ ogun fi n ṣọ́ àwọn Imaam ni Mecca?
Alaga awọn ọlọdẹ naa labẹ aṣia Hunters Guild of Nigeria, Nurein Hameed koro oju si bi awọn janduku kan ṣe n fi iwọde naa boju lati hu iwa ibi.
Gbígbé Àpótí Ẹ̀rí Wá sinu Tẹmpili.
Kò sóhun tó ń jẹ́ ‘Captivus’ nílẹ̀ Oodua, mágùn ni mágùn ńjẹ́ - Babaláwo Wo àwọn obìnrin abúlé kan tó dáwó ra ọkọ̀ láti máa gbé aláboyún lọ ilé ìwòsàn Ìtàn rèé nípa bí Ogbomoso ṣe pa ọba, yọ nǹkan ọkùnrin rẹ jó kiri ìlú Alámì ẹ̀yẹ Scrabble Paul Sodje àti ọ̀rẹ́ rẹ́ kú lásìkò tó fẹ́ lọ́ sanwó ìdóòlà ẹ̀mí àbúrò rẹ̀, tí afurasí darandaran jí gbé Ẹwẹ, yatọ si awọn gbese ti Naijiria ti jẹ, ọrọ aje ti dẹnukọlẹ, bẹẹ ni nnkan ko ṣenu ire fun ọpọ ọmọ Naijiria nitori ajakalẹ arun Coronavirus to n ba gbogbo agbaye finra.
 ida marun le logorin lo mooko mooka nigbati ida meedogbon ko le ko tabi ka .
Bí ẹnìkan bá ń kọ́ àwọn eniyan ní ẹ̀kọ́ mìíràn, tí kò mọ ẹ̀kọ́ tí ó yè, ẹ̀kọ́ ti Oluwa wa Jesu Kristi, ati ẹ̀kọ́ ẹ̀sìn tí ó pé, 
OLUWA ní, “Àwọn tí ń ran Ijipti lọ́wọ́ yóo ṣubú,ìgbéraga rẹ̀ yóo sì wálẹ̀;láti Migidoli títí dé Siene,wọn ó kú ikú ogun láàrin ìlú.
Nígbà tí ó dé, ó waasu ìyìn rere alaafia fún ẹ̀yin tí ẹ wà ní ọ̀nà jíjìn, ó sì waasu ìyìn rere alaafia fún àwọn tí ó wà nítòsí.
O ni ajọ naa ti da ẹni to ṣafiwe ọrọ pe ejo gbe owo JAMB to to miliọnu mẹrindinlogoji mi duro lẹnu iṣẹ.
Abubakar Yahaya to ni awọn ti jọ n gbe papọ fun ọgbọn ọdun ni aarẹ kankan ko ṣe Idris ni ọpọlọ.
Àwọn ọmọ Israẹli sì tẹ̀dó sí ilẹ̀ àwọn ará Amori.
Iṣẹ́ ọpọlọ ló yẹ ká ṣe nínú tíátà, kìí ṣe àfihàn ara bíbó àbí ìhòòhò wa - Binta Mọgaji Toyin Abraham ní 'gbogbo wa loníbárà', Ijebu ta sí Odunlade Ọ̀nà kan ò wọjà fáwọn òṣèré tíátà, bí wọn ṣe ń ta ìpara ìbóra ni wọ́n ń ta aṣọ ẹbí Funke Akindele, oníròyìn, agbẹjọrò àti òṣèré; ohun tí ẹ kò lérò nípa rẹ̀ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Lateef Adedimeji: Owó wa kò bá máa jóná ṣùgbọ́n aàyè ọpẹ́ ń yọ fún wa Ẹwẹ, bi Jaiye ṣe wa fi sita gbangba gbangba bayii pe Lanre Kuti lorukọ ọkọ toun o kii ṣe Pasuma fun ọpọlọpọ eeyan ni ifọkanbalẹ lori ohun to ti n ja nilẹ kiri tẹlẹ yii.
"Itumọ ""international passport"" l'ede Yoruba ni iwe irinna Agbaye."
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Okóòwò àgbo tí Toyin Abraham gbé sílẹ̀, Lizzy Anjorin ti bẹ̀rẹ̀ tiẹ̀!
“Ya gbogbo àwọn àkọ́bí sí mímọ́ fún mi, ohunkohun tí ó bá ti jẹ́ àkọ́bí láàrin àwọn eniyan Israẹli, kì báà ṣe ti eniyan, tabi ti ẹranko, tèmi ni wọ́n.
Ọgagun Amadou Haya Sanogo si lo lewaju iditẹ gbajọba naa.
Ẹjọ naa to ti wa nile ẹjọ lati ọdun 2015, ni wọn gbe idajọ rẹ kalẹ lọjọ kẹfa, oṣu Kọkanla,.
Ṣebí bíi Kakemiṣi ni Kalino rí,tí Hamati rí bíi Aripadi,tí Samaria kò sì yàtọ̀ sí Damasku?
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Shina Rambo: Ọmọ Sọ́jà tó di adigunjalè tíí fi ahọn eeyan 100 mu ẹ̀kọ tó wá di Mathew Oluwafemi tó ń gbé Bíbélì 6 Ògún 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 15 Ògún 2020 Oríṣun àwòrán, OTHERS Ìtàn ayé Shina Rambo, adigunjale tó fi oyún 27 gún ọṣẹ Yoruba ni bi ọmọ ko ba jọ sokoto, yoo jọ kijipa, ẹni to ba bi ni laa jọ.
Lẹ́yìn tí odò yìí ṣàn kọjá ọgbà Edẹni, ó pín sí mẹrin.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Mayowa Omoniyi: Kò sí orin Obey, Sunny Ade abí tàkasúfèé tí ń kò le ta gìtá sí Nínú fọ́nran náà ni Terrywaya ti sàlàyé pé, gbogbo ìṣẹ̀lẹ̀ tó ṣẹlẹ̀ si Erica nínú ilé kò ṣẹ̀yìn ìfẹ́ to ni sí ọmọ òun Kiddwaya, nítori náà, ó yẹ kó ni ìpin nínú owó ẹlẹ́gbọ̀n àgbà.
Awọn iroyin kan sọ pe wahala naa waye nitori pe ile aṣofin kọ aba kan tileeṣẹ aarẹ buwọlu lati fi owo kun owo fun ajọ DSS ninu owo iṣuna 2018.
Ninu ọrọ tiẹ, aarẹ Iṣẹṣe Foundation nipinlẹ Oyo, Baale Olukanmi Egbelade sọ pe ohun ti awọn fẹ ni pe ki ijọba fi awọn si ipo to yẹ k'awọn wa lawujọ.
Iṣẹlẹ naa waye lẹyin idibo gomina ni ọjọ Àbámẹ́ta tó kọjá nipinlẹ naa.
Ṣebí Ọlọrun kan náà ló dá wa?
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Christmas: Ìdí tí Bàbá Kérésì fi máà n wọ aṣọ pupa àti funfun nígbà gbogbo 25 Ọ̀pẹ̀̀ 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ìdí tí Bàbá Kérésì fi máà n wọ aṣọ pupa àti funfun nígbà gbogbo Ọpọlọpọ gbagbọ pe Baba Keresi maa n wọṣọ ni ibamu pẹlu aàwọ̀ pupa ati funfun to wa lara agolo nkan mimu ẹlẹrindodo Coke.
atunse n lo lowo lori re yoo wa si ipari nipari osu kefa odun ti a wayii.
Yemi Osinbajo: Ẹgbẹ́ àwọn àgbààgbà Yorùbá ní Osinbajo kò gbọdọ̀ kọ̀wé fipò sílẹ̀
Nígbà tí ó di ọjọ́ keji, ó yọ sí àwọn kan tí wọn ń jà.
Igbakeji aare to n tuko orile-ede Naijiria lowolowo, Ojogbon Yemi Osinbajo ti tepelemo ipinnu ijoba apapo lati dokowopo pelu awon aladani ki erongba ijoba yii fun idagbasoke eto oro aje Naijira le bureke sii lasiko Aare Muhammadu Buhari yii.
Ṣé ò ń jowú nítorí mo ní inú rere ni?
Ṣugbọn bí ó bá jẹ́ pé lẹ́yìn ọdún Jubili ni ó ya ilẹ̀ rẹ̀ sọ́tọ̀ fún OLUWA, alufaa yóo ṣírò iye tí ó tó, gẹ́gẹ́ bí iye ọdún tí ó kù kí ọdún Jubili mìíràn pé bá ti pẹ́ sí, ẹ óo ṣí iye owó ọdún tí ó dínkù kúrò lára iye ilẹ̀ náà.
 Oríṣun àwòrán, Alaafin Oba Adeyemi III Ojuse Alaafin ni lati da si awọn ọrọ to ba nii se pẹlu asa to ba suyọ nilẹ Yoruba.
Osinbajo ati Gowon sọrọ yii nibi ijọsin to waye lọjọ Aiku fun ayajọ ominira orilẹ-ede Naijiria niluu Abuja.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Jawahir Roble: Hijab tí mò n lò kọ́kọ́ jẹ́ ìyàlẹ́nu fún àwọn agbábọ́ọ̀lù mi Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Jawahir Roble: Hijab tí mò n lò kọ́kọ́ jẹ́ ìyàlẹ́nu fún àwọn agbábọ́ọ̀lù mi 6 Ìgbé 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 19 Èbibi 2020 Lọdun 2004 ni ẹbi JJ Roble fi ilu abinibi wọn, Somali silẹ nitori ogun, ti wọn si ṣe ibugbe tuntun mi i si Wembley ni ilẹ Gẹẹsi.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ẹ wo àrà àwọn ọmọ kékeré ń fi ẹ̀kọ́ kọ̀mpútà dá Amọ, O ni gbogbo ojude ti wọn ti se magomago ninu idanwo naa ni awon ti ti pa, ti ko si ni si idanwo ni ojude naa mọ.
Yóo fi ògo mi hàn nítorí láti ọ̀dọ̀ mi ni yóo ti gba àwọn ohun tí yóo sọ fun yín.
Awọn abanikẹdun si ti n bọwọlu iwe iforukọsilẹ ikẹdun nile Oloogbe to wa ni agbegbe Park view, Ikoyi niluu Eko.
kí angẹli tí ó yọ mí ninu gbogbo ewu bukun wọn;kí ìrántí orúkọ mi, ati ti Abrahamu, ati ti Isaaki, àwọn baba mi, wà ní ìran wọn títí ayé,kí atọmọdọmọ wọn pọ̀ lórí ilẹ̀ ayé.
Pinnick so pe, “A mu ikinni wa fun O lati owo ijoba, ajo NFF lapapo, lati wa sabewo mo ibi ti  awon dokita ba itoju de.
Falana ti kọwé sí ìjọba ìpińlẹ̀ Eko ọdún 2012 pé ki wọn sọ ìdájọ naa di ẹwọn gbére nítori ti gomìnà tó wá nipò lásìkò náà bá tọwọ́ bọ iwe ikú rẹ̀, ó ti lodí sí ofin ẹtọ ọmọniyan.
Idi ni pe eto isuna lọpọ igba a ma se idiwọ fun eto isejọba lorilẹẹde Naijiria.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù #Russia 2018: Ta ni yóò gba ''golden boot'' ní Russia?
O fin yóò de e̩nì kò̩ò̩kan láti fi ò̩wò̩ àti ìmo̩yì tí ó tó̩ fún è̩tó̩ àti òmìnira àwo̩n e̩lòmíràn nígbà tí e̩ni náà bá ń lo àwo̩n è̩tó̩ àti òmìnira ara rè̩.
Ẹ má jẹ́ kí wọ́n pada wọnú ìlú wọn, nítorí pé OLUWA Ọlọrun yín ti fi wọ́n le yín lọ́wọ́.
Titun ni àwọn awọ ìpọnmi wọnyi nígbà tí a kó wọn jáde tí a sì pọn omi sinu wọn.
Nítorí náà ṣe akiyesi ìyọ́nú Ọlọrun ati ìrorò rẹ̀.
Olusola ni awọn ti pinu lati tẹsiwaju lọ si ile ẹjọ to ga ju ni Naijiria lati ri pe Olusola Eleka gba ẹtọ rẹ pada.
Àwọn ọmọ rẹ yóo máa borí àwọn ọ̀tá wọn.
Ọmọ ẹgbẹ oṣelu PDP ni awọn olupẹjọ mejeeji naa.
" Àwọn ọmọ orílẹ ̀ -èdè únpe ara wọn bíi "" batswana "" ( ẹyọìkan : motswana ) , sugbon awon elede miran unpe won bi "" ara botswana "" ."
O ni ile, oko, ẹbi ati ọrẹ nibẹ.
O ni awọn agbofinro yi sọ pe ọgbọn lawọn agbofinro yi lo lati fi yin ibọn yi sugbọn nigba ti yoo fi ya lawọn gbọ pe asiyin ibọn ba arakunrin kan iyẹn Ifeanyi.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: ‘Buhari ti gbàbọ̀dè fún Nàìjíríà’ Ọlọ́pàá mú 115 ẹlẹ́sìn Shiite Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Shiite: Tinúbú, bá Buhari sọ̀rọ̀ kó tú ZakZaky sílẹ̀ kó tó pẹ́ jù Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Mo fi oogun sínu omi fun un lẹ́ẹ̀mejì, ko mu ú, mo fi májèlé sínú ẹmu, kò mu ẹmu náà.
Akonimọọgba Aguirre ti kọ wọn ni Japan ati Mexico sẹyin ko to di pe o wa gba ipo Hector Cuper.
"koda o ni ṣe ni o fẹ ba oun lorukọ jẹ, ṣugbọn lẹyinorẹyin, o jẹwọ lẹyin ti o ri ara rẹ ninu CCTV.
Festus ṣalaye fun BBC pe ọrọ idaduro oun laarin wakata mejidinlaadọta lẹyin ti wọn yan oun ko dun oun ju.
nígbà náà eniyan óo gbadura sí Ọlọrun,Ọlọrun óo sì gbọ́ adura rẹ̀.
Oyetola ṣalaye pe ohun to ku fun ijọba oun bayii ni lati mojuto eto ẹkọ imọ ẹrọ eleyi ti yoo pese iṣẹ fawọn araalu.
Ọ̀nà tí a fi lè pa ẹ̀ṣẹ̀ Jakọbu rẹ́,tí a fi lè mú ẹ̀ṣẹ̀ rẹ̀ kúrò ni pé:Kí ó fọ́ gbogbo òkúta àwọn pẹpẹ oriṣa rẹ̀ túútúú,bí ẹfun tí a lọ̀ kúnná;kí ó má ku ère oriṣa Aṣera tabi pẹpẹ turari kan lóòró.
Ó sọ fún ọkunrin náà tí ọwọ́ rẹ̀ rọ pé, “Dìde kí o dúró ní ààrin.
Ni àwọn olú ilú ilẹ̀ Yorùbá yókù bi Ìbàdàn, Òṣogbo, Abẹ́òkúta, Àkúrẹ́ àti Adó-Èkìtì, kò si sún-kẹrẹ fà-kẹrẹ ọkọ̀ bi ti Èkó ṣùgbọ́n iná mọ̀nàmọ́ná kò ṣe déédé bi ti ilú Èkó.
giga fafiti Kashere, lo kede asofin Alkali ti egbe oselu, All Progressive
O jẹ ipele kan ninu igbiyanju agbaye gbogbo lati dẹkun arun iba apọnju ni ọdun 2026; eyi yoo bẹrẹ ni orilẹ ede Naijiria ni ipinle Kogi, Kwara ati Zamfara.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Oluwo: Mo lè jẹ Ọba ní Ile Ife Siyanbade salaye pe ni ipinlẹ Oyo,''ijọba ipinlẹ ko jẹ ju owo oṣu kẹrin to ṣẹṣẹ pari lọ amọ fawọn oṣiṣẹ ijọba ibilẹ, a ri ibi ti wọn ti jẹ oṣu kan,oṣu meji,ati oṣu mẹta'' ''Ko si ohun ti ẹni to n ṣiṣẹ ọba fẹ gba lọwọ ẹni to gba ṣiṣẹ to yatọ si owo oṣu'' Nipinlẹ Kwara, ọmọ ko sọri bakan naa nibi ti alaga ẹgbẹ oṣiṣẹ ọgbẹni Issa Ore ti ni isẹ ti eeyan ko baa ti ṣe ko yẹ ki o gba owo rẹ.
Kokoro ko si jẹ ka gbadun obi Ayinla to gbo, ti iku ko jẹ ka gbadun ohun aladun ti Ẹlẹda fi jinki Ayinla Ọmọwura.
Ó ti pa èèyàn 172 ni Nàìjíríà - WHO Àwọn agbègbè tí àtùndi ìbò yóò kàn lọ́jọ́ Àbámẹ́ta nípìnlẹ̀ Eko rèé Àwọn ohun tó bá lè fa ìwà ọ̀daràn bíi aṣọ ìwọ̀kuwọ̀ ló yẹ ká ti ọwọ́ rẹẹ̀ baṣọ - Amotekun Osun 'Àfi kí ìjọba gbẹ̀san àwọn Ọlọ́pàá Mopol tó pa Ọkọ mi, London Tailor lásìkò ìwọ́de EndSARS bí kẹ́ẹ̀ kọ́.
Ẹ̀rọ ayàwòrán mi ò ní paṣẹ́tì o.
Wọ́n óo máa ṣe gbogbo ohun tí OLUWA tíí ṣe Oluwa wọn paláṣẹ, wọn ó sì máa tẹ̀lé ìlànà ati òfin rẹ̀.
Aare egbe awon osise (Nigeria Labour Congress), Ayuba Wabba, akowe agba egbe naa ati awon toro kan gbongbon miiran ninu egbe Trade Union Congress, alaga ajo to n mojuto owo osu awon osise naa o gbeyin ninu ipade naa.
kì báà ṣe àwòrán ohunkohun tí ń rìn lórí ilẹ̀, tabi àwòrán ẹjakẹ́ja tí ń bẹ ninu omi.
Kí ẹ̀yin náà sì ka ìwé tí a kọ sí àwọn ará Laodikia.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Kwara Assembly: Ilé Arúgbó Saraki la fẹ́ lò fún ilé ìwòsàn àwọn òṣìṣẹ́ 6 Ọ̀wàrà 2019 Oríṣun àwòrán, @NGRSenate Àkọlé àwòrán, Ile Asofin Kwara ni ijọba lo ni ilẹ ati ohun ini ti awọn gbe ẹsẹ le,kii se gomina tẹlẹri, Bukola Saraki.
Jìnádù sọ pé Ògúndélé fi òrùkọ ẹ̀rẹ na òun.
Bàntẹ́ Ó tún padà wá múni 
Tí a fiṣọwọ́ ní 13:30 10 Sẹ́rẹ́ 202113:30 10 Sẹ́rẹ́ 2021 Wo àwọn Ọ̀jọ̀gbọ́n fásitì tí àrùn Coronavirus gbẹ̀mí wọn Ibudo iyasọtọ fun itọju awọn eeyan to ni arun Coronavirus la gbọ pe awọn ọjọgbọn fasiti ọhun ti dagbere faye.
Nígbà tí o bá ń rìn, o kò ní rí ìdínà,nígbà tí o bá ń sáré, o kò ní fi ẹsẹ̀ kọ.
Oríṣun àwòrán, Brenda Biya /Facebook Oríṣun àwòrán, Brenda Biya/Facebook Ẹ wo Daniel tí wọ́n fẹ́ yẹgi fún lẹ́yìn tí US kò ṣe irú ẹ̀ fún odidi ọdún 17 Nigeria Police recruitment 2020: Bàyìí ni o ṣe leè di ọlọ́pàá Nàìjíríà Kò sí ìfòyà, ọkọ̀ bààlù wà tí ìjọba ba ti afárá 3rd Mainland lósù yìí Wole Soyinka rèé láti kékeré Sugbọn sebi Yoruba sọ pe oun to kọjú si ẹnikan, ẹyin lo kọ sí ẹlòmíràn.
Tẹ ba si fẹ mọ siwaju si nipa itan igbe aye Ọba Adeyemi, ẹ ka itan igbe aye rẹ nibi lati mọ bo se lo aye rẹ ko to jọba ati bo se dori oye.
Buhari lo si orile ede Niger ni iyawo aare orile ede Naijiria , Aisha Buhari,gomina
O jẹ́ kí ìrandíran wọn pọ̀ sí i bí ìràwọ̀ ojú ọ̀run, o sì kó wọn dé ilẹ̀ tí o ti ṣèlérí fún àwọn baba wọn pé wọn yóo lọ gbà.
Luis Suarez to darapọ mọ Barcelona lati Liverpool ni ikọ Barca gbọdọ ṣọra ni papa iṣere ki wọn maa ba yọ ṣubu.
Láti Tire, a bá ń bá ìrìn àjò wa lọ títí a fi dé Tolemaisi.
Àwọn ọmọ Adini jẹ́ irinwo ó lé mẹrinlelaadọta (454)
Ọ̀nà tí ó gbà wá ni yóo gbà lọ láìwọ ìlú yìí nítorí èmi OLUWA ni mo sọ bẹ́ẹ̀.
Ṣugbọn ọrọ bẹyin yọ nigba ti Crystal Palace gbayo mii wọ le Man U nigba to ku diẹ ki ere bọọlu naa pari.
Nibayii ti eto idibo gomina ipinlẹ Ọsun, ti yoo waye lọjọ kejilelogun osu kẹsan ọdun 2018, ku fẹẹrẹfẹ ko waye, oniruuru awuyewuye lo ti n su yọ, paapa eyi to nii se pẹlu bi olusiro owo agba nipinlẹ naa, Ọgbẹni Alaba Akintayọ se kọwe fipo silẹ.
“Nítorí pé wọ́n ti ṣi àwọn eniyan mi lọ́nà wọ́n ń wí fún wọn pé, ‘Alaafia’ nígbà tí kò sí alaafia.
Nigba ti iyawo aarẹ, Aisha Buhari sọ loju opo Twitter rẹ pe awọn eeyan kan lo n tukọ iṣejọba ọkọ rẹ to jẹ aarẹ, pupọ ninu awọn ọmọ Naijiria lo n sọ pe Kyari lo n sọ nipa rẹ.
kí olukuluku dá ẹrú rẹ̀, lọkunrin ati lobinrin, tí wọ́n jẹ́ Heberu sílẹ̀, kí wọn máa lọ ní òmìnira; kí ẹnikẹ́ni má sì fi Juu arakunrin rẹ̀ ṣe ẹrú mọ́.
 wọ ́ n pe rògbòdìyàn yìí ní sabinada .
mélòó mélòó wá ni eniyan tí a fi amọ̀ mọ,tí ìpìlẹ̀ wọn jẹ́ erùpẹ̀,tí a lè pa bíi kòkòrò lásánlàsàn.
Meraiotu bí Amaraya, Amaraya sì bí Ahitubu.
” Ó wá bi wọ́n pé, “Báwo ni a ti ṣe kọ nípa Ọmọ-Eniyan pé ó níláti jìyà pupọ, kí a sì fi àbùkù kàn án?
Nítorí tiwọn ni mo ṣe ya ara mi sí mímọ́, kí àwọn fúnra wọn lè di mímọ́ ninu òtítọ́.
Ṣugbọn obinrin náà wá, ó kúnlẹ̀ níwájú rẹ̀, ó ní, “Oluwa, ràn mí lọ́wọ́.
Ilẹ Iran naa gbẹsan pẹlu bi wọn ti se yin ado oloro lu ibudo awọn ọmọ ogun Amẹrika to wa ni Iraq.
O ni oun mọ ọṣẹ́ buruku tawọn alakatakiti ẹsin Islam Boko Haram ti ṣe ni ẹkun yii to ti sọ eto ẹkọ wọn di nkan miran.
Wo àwọn oúnjẹ márùn ún tó ń mú kí àtọ̀ ọkùnrin dára síi Wo oríṣìí oúnjẹ márùn ún tó lè dẹ́kun ikùn yíyọ àti ara àsanjù Bóo ṣe lè sọ iṣẹ́ láti ilé lásìkò Coro” di ìgbádùn fún ara rẹ Ìgbésẹ̀ wo ní aláboyún lé gbé láti dẹ́kun ìjẹkújẹ nínú oyún?"
Ko tan sibẹ o, ofin naa tun faaye gba pe ki wọn o fi kẹmika tẹ ẹni to ba fi ipa ba eeyan lopọ lọdaa.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ogundamisi: Ọbasanjọ ni ko jẹ k'awọn ọdọ de'po Iroyin ti a gbọ ni pe wọn ni eniyan mẹwaa lo ti ku ninu ẹbi wọn lati ọdun 2000 ni eyi ti wọn gbagbọ pe baba yii lo n ṣe iku pa wọn.
Ati pe awọn ti ṣe tan lati koju wọn ti ijọba ba le fun wọn ni aaye lati ṣe bẹẹ.
Wo àwọn orílẹ̀-èdè márùn ún tó fún àwọn obìnrin làńfàní tuntun sí ẹ̀tọ́ wọn EFCC ti ri mílíọ̀nù 65.
ún(88,016) ninu abajade esi idibo ohun.
O fojuhan pe Sanusi Lamido ti kọ lati tẹle abala ofin kẹtala ninu iwe ofin ipinlẹ Kano ti ọdun 2019.
Oríṣun àwòrán, NAira marley/instagram Ni ọjọ kẹwa oṣu karun un ọdun 2019 lawọn oṣiṣẹ ajọ EFCC mu Naira Marley niluu Eko.
Nigba ti wọn n ba wa sọrọ, awọn ọmọ ẹgbẹ Yoruba dun lasa salaye pe, ko si bo ti wu ki awọn mura daada to, awọn ọkunrin ni Egypt yoo papa tẹ awọn lọyan, gba awọn ni idi, ti wọn yoo si tun da awọn laamu.
Emery gba iṣẹ lọwọ Arsene Wenger loṣu karun un ọdun 2018 lẹyin to gba ife ẹyẹ Europa mẹta tẹlera pẹlu Sevilla ati ife ẹyẹ liigi ilẹ France pẹlu PSG.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ìtàn tó wà nídi òwe ‘Sebótimọ Ẹlẹ́wà Sàpọ́n’ Ọba Adesoji Aderemi, Ọọ̀ni Ifẹ̀ tó gba ipò ọba mọ́ tòṣèlú MKO Abiola, iṣẹ́ aṣẹ́gità ló fi bẹ̀rẹ̀ okoòwò Iṣọla Oyenusi rèé, ẹnití ìfẹ́ obìnrin ṣun dé ìwà ìdigunjalè Taiwo Akinkunmi, ọmọ Ibadan tó ya àsìá Naijiria Ayinla Ọmọwura, orin èébú àti oríyìn lo fi di ọ̀rẹ́ àwọ̀n obìnrin Ọba Lamidi Adeyẹmi, òṣìṣẹ́ adójútòfò àti Abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò kó tó jọba A si le pe itan yii ni apa keji Ogun Agbekoya nitori ara afikun owo ori tawọn agbẹ n ja fun lo fa sababi iṣẹlẹ yii, gẹgẹ ba ṣe ka a loju opo itakun agbaye.
Awọn iwe rẹ pupọ lo da lori iwa ibajẹ ati ọna idajọ to ye kooro fun awọn oniṣẹ ibi ninu eyi to ti maa n ṣafihan awọn iwa ibi to wọpọ lasiko naa.
won ni osu kan pere lati se  isẹ won gege
Tabi kì í ṣe ọ̀nà kan náà ni a jọ ń ṣiṣẹ́?
O gba awọn eniyan nimọran pe 'E ma fi ọ̀bọ lọ àfín mọ́ nitori pe ìbí kò ju ìbí'.
Báálẹ̀ ni oyè tí ó tó bi jù lọ ni Abúlé Ọjà, ọdún 1944 ni wọ́n bẹ̀rẹ̀ sí ní jẹ oyè báálẹ̀ ni ìlú yìí.
Fraud Allegations: Abike Dabiri-Erewa rọ àwọn tọ́rọ̀ kàn láti yọjú sí FBI
owo ori won le ni adofa Bilionu naira ti won ri gba laarin osu kinni si osu
Nile aṣofin ti wọn ti n ṣe ijiroro lori ofin naa, awọn aṣofin ti ka abadofin naa ni igba ẹlẹẹkeji.
wa bayii lori tabili idije Premier league ti Arsenal ati Manchester United si n
Bí wọ́n ti gbé àpótí ẹ̀rí náà wọ inú ìlú Dafidi, Mikali ọmọ Saulu yọjú wo òde láti ojú fèrèsé, ó rí Dafidi ọba tí ó ń jó tí ó sì ń fò sókè níwájú OLUWA, Mikali sì kẹ́gàn rẹ̀ ninu ọkàn rẹ̀.
Ohun ti pupọ awọn ọdọ bii @iykimo, @bolanle_cole, @julietkego, @YarKafanchan ati bẹẹbẹẹ n sọ ni pe iyalẹnu ni bi awọn eeyan kan ni ipinlẹ Eko ti ṣe lee sa kuro lẹyin Ambọde lẹyin ti wọn ti fi ọdun mẹta yin in lawo 'fun iṣẹ takuntakun' ti o nṣe.
Ní ìsàlẹ̀ ni àwòrán-eré ránpẹ́ ìrìnàjò afẹ́ ọdún-un 2017 ní oríi YouTube
Kò rí oòrùn rí, kò sì mọ nǹkankan, sibẹsibẹ ó ní ìsinmi; nítorí náà ó sàn ju ẹni tí ó bí ọgọrun-un ọmọ tí ó kú láìrí ẹni sin òkú rẹ̀ lọ.
Wọ́n dajọ́ ikú fún òṣeré Kannywood Rahama Sadau, eré àbí òótọ́?
Gẹgẹ bi iwe iroyin The Nation ṣe jabọ, ibi ipade apero kan to waye l'Ọjọru, lori Iwa ipa si awọn obinrin, nilu Ado-Ekiti, lo ti sọ ọrọ yii.
Ọjọ naa gan an ni ọjọ ibi agba oṣere, Aina Gold.
Ní ọdún keji tí Peka ọmọ Remalaya, jọba ní Israẹli, ni Jotamu, ọmọ Usaya, jọba ní Juda.
Kí ló mú ọlọ́pàá wú òkú géńdé nínú sàréè l'Ondo Ọmọbìnrin ti ọ̀rẹ́kùnrín ọmọ Yahoo yahoo rẹ́ dáná sún l'Èkó tí dì èrò ọrùn Èèwọ̀!
Àkọlé àwòrán, Liliya náà gbà pé o nira láti gba pé bi òun ṣe ri rèé Kíkà nípa àrùn náà àti bíbá àwọn míràn ti wọ́n ni irú àìsàn bẹ́ẹ̀ pàdé jẹ́ ǹkan tó ràn lọ́wọ́ láti ni ìwúrí nínú ara rẹ̀.
Níbi tí o kò fi nǹkan sí ni o máa ń wá a sí; níbi tí o kò fúnrúgbìn sí ni o ti máa ń kórè.
Ẹni tí ó kó àwọn ìràwọ̀ sójú ọ̀run bí ọmọ ogun,tí ó ń pè wọ́n jáde lọ́kọ̀ọ̀kan,tí ó sì mọ olukuluku mọ́ orúkọ rẹ̀.
Ọkunrin náà mú wọn wọ inú ilé Josẹfu, ó fún wọn ní omi, wọ́n fọ ẹsẹ̀ wọn, wọ́n sì fún àwọn kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ wọn ní oúnjẹ.
Meji ninu awọn ọlọpaa to n sọ wọn ni wọn pa.
Àwọn ọmọ ogun tí a kà ninu wọn jẹ́ ẹgbaa mẹtadinlogoji ó lé ẹgbẹta (74,600).
Ó ní, òun óo pada sí Sioni, òun óo máa gbé Jerusalẹmu, a óo máa pe Jerusalẹmu ní ìlú olóòótọ́, òkè OLUWA àwọn ọmọ ogun, ati òkè mímọ́.
"Iléeṣẹ́ Instagram wọ́gilé App ""Augmented Reality filters"" lórí ẹ̀rọ rẹ̀ Ìgbẹ́jọ́ Naira Marley sún síwájú bí àwọn agbẹjọ́rò ń jà sí àga ìjókòó Kí ló dé tí Ilé ẹjọ́ sún ìgbẹ́jọ́ Naira Marley sí ọ̀la?"
Akonimoogba agba iko agbaboolu Fulham, Claudio Ranieri so lojobo(Thursday) pe akonimoogbaiko Manchester United, Jose Mourinho je eni akoko ti o ki oun kaabo pada sinuidije EPL gege bi olukoni tuntun fun iko Fulham.
Won yoo bura fun aare ati
Lọ́jọ́ keji, ọ̀gágun náà tú Paulu sílẹ̀.
Gomina Ganduje ṣalaye pe ni wọn igba tawọn Fulani ẹlẹran ọsin ba n dẹran lati apa ariwa Naijiria lọ si aarin gbungbun ati guusu, ọrọ ruga ati isọro eto aabo to mẹhẹ ko le dopin.
Ìdíje bọ́ọ̀lù fa ìtàjẹ̀ sílẹ̀ ní Poly Ibadan Kìnìhún joko jẹ ẹran ara afurásí ọdẹ tí kò gbààyè kó tó ṣọdẹ Ìpànìyàn Zamfara: Kò gbọdọ̀ sí ìwakùsà ní Zamfara Kí ló kàn olórí ọmọ ilé aṣòfin Osun pẹlú ìdájọ kòtẹ́milọ́rùn Sẹnẹtọ Adeleke?
Ebi Bush so ninu oro re lojo Aiku(Sunday) pe, oloogbe ohun jade laye latari ailera re, eleyi ti aisan agba le sokunfa.
OLUWA sọ fún Samuẹli pé, “Ṣe ohun tí wọ́n fẹ́, kí o sì yan ọba fún wọn.
"Ní ìlànà abá àwọn ọmọ ilé ìgbìmọ aṣòfin ní ọjọ kejidinlogun oṣu kẹfa, emi Abdurahaman Abdulrazaq to jẹ gomina ipinlẹ Kwara ti dá gbogbo awọn alaga ijọba ibilẹ mẹrẹrindinlogun duro lẹnu iṣẹ́ wọn fún oṣù mẹ́fà tabi titi èyìn àbájade ìwádìí ìwà jẹgudujẹra ti awọ́n ọmọ ilé ìgbìmọ ìpínlẹ̀ Kawara fi kan wọ́n.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Omiyalé Àkútè: N50 si N100 làwọn èèyàn fi ń kọjá lórí ẹ̀kún omi l‘Ákútè Titi di bi a ti ṣe n kọ iroyin yi, a ko tii gburo pe wọn ti ri oku awọn elomiran lẹyin awọn ti LASEMA ti kede saaju.
Bí o bá pè wọ́n, àwọn náà yóo pè ọ́ wá jẹun níjọ́ mìíràn, wọn yóo sì san oore tí o ṣe wọ́n pada fún ọ.
 Ko ju wakati diẹ sigba naa lọ ni iṣẹlẹ to ṣẹlẹ ni Lẹkki ṣẹlẹ."
Ko si ẹni to lee sọ iru ipo ti ilera Kọmiṣọna funra rẹ wa bayii nile iwosan UCH ti wọn gbe lọ, Tabi idi ti wọn se kọ luu, bẹẹ ni awọn agbebọn naa tun mu ibọn ọlọpa to n sọ kọmiṣọnna naa lọ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìbẹta, Oba Lamidi Adeyemi, Alaafin Oyo pé ọdún méjìlá; nkan tó yẹ kí o mọ̀ nípa wọn nìyíì 26 Bélú 2020 Oríṣun àwòrán, Ayaba folashade/instagram Ọjọbọ, ọjọ kẹẹdọgbọn, oṣu Kọkanla, ọdun 2020, ni ibẹta to wa ninu gbogbo ọmọ ti Alaafin ilu Oyo, Ọba Lamidi Adeyemi Kẹta bi, pe ọdun mejila.
Láti ìlà oòrùn títí dé ìwọ̀ oòrùn,kí á máa yin orúkọ OLUWA.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Awọn ọdọ Ondo fẹ̀họ́nù hàn lórí ìṣekúpani Funke Olakunrin Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Oríṣun àwòrán, @atiku Àkọlé àwòrán, Atiku ni iṣẹ nla lo wa niwaju ohun ''Pipese isẹ ṣe pataki lati maṣe jẹ ki awọn ọdọ darapọ mọ ẹgbẹ kẹgbe ati ti a ba fẹ mu adinku ba awọn ikunsinu to n fa gbọnmisi omi o too lawujọ'' Fun idi eyi,o sọ wi pe oun yoo ṣe ''agbekalẹ eto idanilokowo eleyi ti o muna doko ti yoo si pese pese miliọnu mẹta iṣe ati ọna ise lẹka aladani lọdọọdun'' Yatọ si ọrọ iṣe ti iwe naa mẹnuba,Atiku sọ pe ọun yoo mu idagbasoke ba ipese awọn ohun amayederun ati wi pe ohun yoo mu adinku ba iṣẹ oun oṣi lawujọ.
'Ọ̀la la máa mọ̀ bóyá Jonathan tako òfin PDP pé ó gbàlejò APC ní Bayelsa' Ọ̀daràn tó wà lẹ́wọ̀n tún wọ́'ke $100miílíọnu - EFCC Aṣọgba ile naa sọ fun ajọ LASSESSO pe ẹnu ẹnu ni ga oun fi ni oun fẹ tun ile naa ṣe daadaa ko le dun gbe ṣugbọn ko tii tun un ṣe di oni.
Ọmọ́ Yorùbá korò ojú sí Buhari bí kò ṣe fi orúkọ Obasanjo sọ ibùdókọ̀ ojú'rin Ìjọba Nàìjíríà kéde ìsinmi ọlọ́jọ́ méjì f'ọdún Iléyá Ìyá Barakat fi ẹ̀mí ìmoore hàn sí gbogbo àwọn tó nawọ́ síi lẹ́yìn ikú ọmọ rẹ̀ Wọ́n kí irún Jimọ àkọ́kọ́ ní Hagai Sophia lẹ́yìn ọdún 85 ní Turkey Kini Toke Makinwa funra rẹ sọ lori iṣẹlẹ yii?
Ìdí ti kò tẹ́ àwọn obìnrin lọ́rùn ń jẹ́ ki iṣẹ́ abẹ rán wọn sọrun.
Ní ọ̀pọ̀ ìgbà àwọn ènìyàn yìí máa ń rápálá wọ Libya lójúnà àti kọja lọ sí orílẹ̀-èdè Italy.
Ta ni Ọjọgbọn Adebanji Akintoye tó borí Tinubu láti di olórí àwọn Yoruba?
O ti gbé mi ró nítorí ìwà pípé mi,o sì fi ẹsẹ̀ mi múlẹ̀ níwájú rẹ títí lae.
Awọn ọlọpaa sọ fun BBC Gujarati pẹ Dokita Lakhani pe awọn lori agọ lati ddabo bo ohun nitori pe awọn mọlẹbi obinrin naa le pa ohun.
Jesu bi í pé, “Obinrin, kí ní dé tí ò ń sunkún?
Bode George: òòtọ́ ni ìkìlọ̀ Obasanjọ ati Soyinka
"- Ma ṣe gbe ọkọ rẹ si ẹgbẹ ọkọ miran ti wọn ti paaki silẹ ki o ma baa jẹ ""Double Parking"" - Nitosi awọn to n tun ọna ṣe."
Oríṣun àwòrán, others Àwọ̀ ojú pọ̀ bíi àwọ̀ òṣùmàrè, àmọ́ ojú búlúù Risikat kò nílò àtúnṣe- Dókítà Feyi Adepoju Lori ọrọ oju buluu Risikat Moromoke Azeez atawọn ọmọ rẹ meji naa la si wa.
Ní tiwa, a kò lè ṣe aláìsọ ohun tí a ti rí ati ohun tí a ti gbọ́.
Ni ipari, aare wa ro gbogbo omo orile-ede yii pe, laipe-laijina opin yoo de ba gbogbo ikolu ipaniyan naa.
Koda, iroyin naa ni wọn ti gbe afurasi apaayan naa lọ tọju nile iwosan alarun ọpọ to wa ni Aro ri, amọ to sa kuro nibẹ pada silu Ogere, to si n ṣe wọn bi ọsẹ ti n ṣe oju.
Ogunjọ, Osu kọkanla, ọdun 2015 ni awọn osisẹ kọkọ bẹrẹ si ni faake kọri wi pe, awọn ko lee maa gba ẹgbẹrun mejidinlogun gẹgẹbi gbedeke owo osu awọn osisẹ.
Mo ní, “Nígbà wo ni o óo tù mí ninu?
Samuel Ajayi Crowther, òjíṣẹ́ Ọlọ́run tó gbé èdè Yoruba lárugẹ Mọrèmi Àjàṣorò, akọni obìnrin tó gba Ilé Ifẹ̀ sílẹ̀ lóko ẹrú Ọ̀rọ̀ǹpọ̀tọ̀niyùn, Aláàfin obìnrin àkọ́kọ́ rèé, tó ní nǹkan ọkùnrin Ẹ jẹ ki awa naa sa ipa wa, lati fi ipa tiwa han lawujọ agbaye nitori arise ni arika, ohun ta ba si se ni oni, ọrọ itan ni yoo da, bo ba di ọla.
Bi wọn ṣe n yẹ kaadi idibo awọn olukopa ninu idibo abẹle ọhun wo naa ni wọn n dibo lẹsẹkẹsẹ.
Alukoro ile isẹ ọlọpaa ni ipinlẹ Ọyọ, Olugbenga Fadeyi lo fi ọrọ yii lede, lasiko to n ba BBC Yoruba sọrọ lori ibi ti wọn ba isẹ de lori iwadii itọpinpin lori ijinigbe ọmọ minisita naa.
Oríṣun àwòrán, BBC Sport Àkọlé àwòrán, Omí pọ̀ ju ọkà lọ fún Unai Emery, ìfìdírẹ̀mi mí ló bade fún lọ́wọ́ Frankfurt Ninu awọn ifẹsẹwọnsẹ ti wọn gba sẹyin, eyi ni yoo jẹ igba kẹje ti wọn yoo pade ijakulẹ.
Ronaldo gbáyò sáwọ̀n fún ìgbà àkọ́kọ́ Ṣé £99m kò pọ̀jù láti ra Ronaldo?
Ruiz di ọmọ orilẹede Mexico akọkọ ti yoo aṣaaju ninu awọn agbaọjẹ akẹṣẹ lagbaye lẹyin to na Joshua bi aṣọ ofi to si gba igbanu mẹta ti Joshua ko wa.
Wo bó se ń lọ nínú ìdíje Russia 2018 ‘Ọlọ́kọ̀ epo to jóná yóò fojú balé ẹjọ́’ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Àyàn: Ti mo bá ti gbọ́ ohùn ìlù ni àárẹ́ mi ma ń lọ!
”Ṣugbọn wọ́n sá tún kígbe pé, “Kàn án mọ́ agbelebu!
"Àgbo tí mò ń lò láti jò kó bá mi, ìdí mi ti yọ́ tán - Nkechi Blessing figbe ta ""Ni gbogbo agbaye, tàwọn eeyan ba gbọ nipa iwa ajẹbanu, owo jiji nikan ni wọn maa n ro si eyi to jẹ asise."
Fraser Anning ti kọkọ kọ iwe kan sita, nibi ti o ti sọ pe ko si ohun to buru ninu ipaniyan to waye ni New Zealand.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Òfin tí yóò mú àtúnṣe bá ìlànà ìsìnkú ọba ní ìpínlẹ̀ Ògùn ń bọ̀ lọ́nà 5 Ẹrẹ̀nà 2020 Oríṣun àwòrán, Twitter/dabiodunMFR Abadofin ti yoo mu atunto ba ilana isinku awọn lọbalọba ni ipinlẹ Ogun ko ni pe dofin.
Ìbànújẹ́ ni ọdún Orò ma ń jẹ́ fún àwọn obìnrin ní ìlú Ikorodu 'Ẹ wo iye tí wọ́n ń ta ẹran àgbò lọ́dún yìí ' Fulani kò leè dúró, táa bá lo ohun ta jogún lọ́dọ̀ àwọn bàbá wa - Sunday Igboho Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí kan sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
Amọṣa loju opo Twitter ajọ to n gbogun ti ajakalẹ arun lorilẹede Naijiria, NCDC to jẹ ajọ kan ṣoṣo to laṣẹ lori eto ayẹwo fun kokoro arun naa, ọfẹ ni wọn kọ pe wọn n ṣe ayẹwo fun kokoro arun naa lorilẹede Naijiria.
Gẹ́gẹ́ bi ọlọ́dani o ti dídandan láti dẹ́kun jíju ìke àti ọ̀rá sí ojú àgbàrá: Ní ọ̀pọ̀ ìgbà àwọn ìgbòkegbòdò ará ìlú náà maa ń dẹ́kun omiyalé àgbàrá ya sọ́ọ́bù, ọ̀pọ̀ àwọn ènìyàn ti wọ́n ba ti gbọ́ kíkù òjò ní wọ́n ti lọ da gbogbo ìdòtí ilé wọ́n sí ojú ibi ti ó yẹ kí àgbàrá gbà, èyí jẹ ọkan lára ǹkan ti ó ń fa ẹkún omi, bákan náà o ye ki ará àdúgbò maa kóra jọpọ̀ láti ṣe ìtóju ojú àgbàrá Ìjọba ní láti gbé ìgbésẹ̀ lóri bí ojú ọjọ sé ń yí: Ọ̀rọ̀ àyí padà ojú ọjọ́ jẹ ǹkan pàtàki tí gbogbo ìjọba gbe lọ́wọ́ ní àgbàyé, èyí jẹ ǹkan ti o yẹ ki ọlọdani náà mọ, àyípada ojú ọjọ́ ló faa ti omi fi kú kọjá ibi tó yẹ, nítori ìdí èyí ọ̀rọ̀ náà kìí ṣe ti ìjọba nìkan bíkoṣe pe àti ará ìlú àtí ìjọba ló yẹ ko saapa láti dẹkun omiyale Ìjọba gbọdọ sẹ àtúnṣe àwọn ojú àgbàrá àti ibi ti omí to ba ń jade lati ojúle kọ̀ọ̀kan yóò maa dari si: Ọ̀pọ̀ àwọn awọn orilẹ̀-èdè lo ti ṣe àwọn ètò yìí nígbà ti wọ́n bá n ṣètò àdúgbò síbẹ, ìjọba orilẹ̀-èdè, pàápàá jùlọ ìjọba ìpínlẹ̀ kìí ṣe àwọn ètò yìí, bí ìjọba bá le ṣe àdínkù yóò ba ẹkun omi yale àgbàrá ya sọọbu.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Messi kọ lati ṣe ayẹwo coronavirus lọsẹ to kọja lẹyin ti Barca ni ki gbogbo agbabọọlu lọ fun ayẹwo ki wọn le bẹrẹ igbaradi fun saa bọọlu tuntun.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Iṣẹ́ Kudirat Abiọla ṣì ń fọhùn síbẹ̀, lẹ́yìn ọdún 23 tó papòdà Ṣé ìwọ mọ odò adágún Adó Àwáyè tí kò ní òpin ní ìsàlẹ̀?
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ẹgbẹ CAN ni awọn ko laṣẹ lati ba ẹnikẹni wi nitori Ajọṣepọ laarin awọn onigbagbọ ati ijọba lo jẹ awọn logun Ninu ọrọ rẹ pẹlu BBC Yoruba, olubadamọran fọrọ iroyin fun aarẹ apapọ ẹgbẹ CAN lorilẹede Naijiria, Ẹni-ọwọ Bayọ Oladeji ṣalaye pe, ko si ni ikawọ CAN lati sọ boya ijọ kan lẹtọ lati beere fun owo lọwọ ọmọ ijọ tabi rara.
 Àwọn mìràn máa ń ní ìrora àti pípọ ́ n lójú ibi tí wọ ́ n gba abẹ ́ ẹ ́ rẹ ́ sí .
Bakan naa ni ẹgbẹ oṣiṣẹ naa fikun wi pe awọn naa ni atilẹyin ileẹjọ lati tẹsiwaju ninu iyanṣẹlodi tako ọwọngogo owo epo bẹnitirol ati ina ọba.
Adajọ Olusegun Odusola, tile ẹjọ giga ilu Akure ti kede pe asaaju ijọ Sotitobire, Wolii Alfa Babatunde jẹbi ẹsun ijọmọgbe.
 awon amioro ti won je fiforukosile je ti gbogbo awon ede agbaye koko .
Olubadan sọ ninu atẹjade to fi sita l'Ọjọbọ pe, awọn Ọba mọkalelogun yaju si itẹ oye Olubadan, ninu lẹta ti wọn kọ ranṣẹ si oun lọjọ kẹtadinlọgbọn oṣu kinni ọdun.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù New Emirates: Ilé ẹjọ́ dá Gómìnà Ganduje dúró yíyan àwọn Emir tuntun ní Kano 11 Èbibi 2019 Oríṣun àwòrán, Facebook/Abdullahi Ganduje Àkọlé àwòrán, Ọrọ awọn emir tuntun ni ipinlẹ Kano Ile ẹjọ giga kan niluu Kano ti paṣẹ fun gomina Abdullahi Ganduje lati sẹ mẹdọ lori igbesẹ rẹ lati yan awọn ọba miiran yatọ si Emir ilu kano Sanusi Lamido Sanusi.
Aare Muhammadu Buhari ti pinnu lati sabewo sawon ipinle ti wahala sele si laipe bii Benue, Yobe, Zamfara, Rivers ati Taraba.
 idiboyan aipe , ikewa iru re , waye ni ojo 16 osu kewa 2009 .
Láti Esiongeberi wọ́n lọ sí aṣálẹ̀ Sini, tíí ṣe Kadeṣi.
Oríṣun àwòrán, @PeaceCorpsNG Àkọlé àwòrán, Lẹyin ti aarẹ Muhammadu Buhari ti da abadofin idasilẹ ajọ Peace Corps nu, iporuru ọkan ti de ba ọpọlọpọ ọdọ.
Benue Fire: Ọkọ̀ akérò 18 àtàwọn tó ń gbọ́n epo ló forí ṣọta ìjàmbá iná
Mo yí ọgbọ́n àwọn ọlọ́gbọ́n pomo sì sọ ọgbọ́n wọn di òmùgọ̀.
Ninu gbogbo àwọn ọlọrun èké tí àwọn orílẹ̀-èdè ń sìn,ǹjẹ́ ọ̀kan wà tí ó lè mú kí òjò rọ̀?
Àkọlé àwòrán, Ariwo to pa nitori idunnu mu ki awọn eniyan o pe le wọn lori, wọn si doola aburo rẹ.
Ọ̀kọ̀ọ̀kan ninu àwọn òpó náà ga ní igbọnwọ mejidinlogun, àyíká wọn jẹ́ igbọnwọ mejila, wọ́n nípọn, ní ìka mẹrin, wọ́n sì ní ihò ninu.
Ogunwusi nigba to n dupẹ lọwọ Gomina Wike to gbawọn lalejo, sọ pe apejọpọ awọn ọba naa wa fun wiwa ọnọ lati jẹ ki isọkan ati ifọwọsowọpọ awọn ọba o f'idi mu'lẹ sii lorilẹede yii.
Igbesẹ lati yọ aarẹ Zuma naa ko sẹyin ọpọlọpọ ipade idakọnkọ ti awọn olori ninu ẹgbẹ oselu naa se titi di afẹmọjumọ ọjọ iṣẹgun oni.
Ó kó àwọn alufaa ati àwọn ọmọ Lefi jọ sí gbàgede tí ó wà ní apá ìlà oòrùn ilé Ọlọrun.
Ọ̀rọ̀ púpọ̀ irọ́ ní ń mú wa, nítorí náà ọ̀rọ̀ mi kò nì í gùn gbọọrọ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìjọba àpapọ̀: A óò dá ẹnikẹ́ni tó bá gbé ìwé àti àṣírí ìjọba síta lórí ayélujára lọ́nà àìtọ́ dúró 19 Owewe 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 26 Èbibi 2020 Oríṣun àwòrán, @eniola_opeyemi Àkọlé àwòrán, Folashade Yemi-Esan ló fi ìpè naa síta pé ẹnikẹ́ni tí ìjọba ba mú yóò fẹnu fẹ́ra Ìjọba àpapọ̀ ni ìwé ìdáró ni òun yóò fún ẹnikẹ́ni tí aje ìwà ìbàjẹ́ gbígbé ìwé àti àṣírí ìjọba síta lórí ayélujára lọ́nà àìtọ́ Ó ní ìwé ìjọba kan tó fara han lórí ayélujára láìpẹ́ yìí níbi tí o ti fi ìwé wa wí tẹnu rẹ sọwọ́ sí akọ̀wé ilé iṣẹ́ àpapọ̀ kan jẹ́ èyí tó tini lójú gidigidi.
Eeyan mejidinlogun lo laarun naa lati Abuja, mẹtala lati Rivers, marun un lati ipinlẹ Kaduna nigba ti eeyan mẹrin wa lati Oyo.
Seun Egbegbe lo ọdún méjì àti oṣù méje lẹ́wọ̀n láì tìí san béèlì rẹ̀ Géńdé agbébọn jí adájọ́ gbé lọ ní ìpínlẹ̀ Ondo Kí ni àwọn olórí Áfíríkà ń wá lọ sí Russia?
Gẹgẹ bi minisita feto iroyin, Alaaji Lai Mohammed ṣe sọ ọ lasiko to fi n kopa lori eto ileeṣẹ Mohunmaworan apapọ Naijiria, NTA, inu òṣuwọn ajọni fun idokoowo, Sovereign Investment Fund ni wọn ti fa owo naa yọ lati fi yanju akanṣe iṣẹ marun kan kaakiri ibu ati oro orilẹede Naijiria.
" Ode Alujo orin: Ilee itaja orin The Jazzhole tun maa n gbalejo ode alujo orin.
Àwọn ọmọ ogun Siria ṣá ọba Joramu lọ́gbẹ́.
Àìsàn tó ń ṣe mí kìí ṣojú lásán!
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Mo máa n forin mi kìlọ̀ ìwà ìbàjẹ́ láwùjọ ni -Hameen O fikun pe oju awọn akọroyin si ni ohun fa awọn ibọn AK 47 naa le awọn ọlọpa lọwọ, ti awọn ohun ijagun yoku si wa ni ipamọ nile ijọba ipinlẹ Ogun, eyi to wa labẹ abojuto awọn agbofinro.
Àkọlé àwòrán, Alhaji Gboyega Oyetola ni gbese daa, ti a ba mọ nkan ti a fi ṣe Oludije si ipo gomina labẹ ẹgbẹ oselu APC, Alhaji Gboyega Oyetola lasiko to n fesi si ibeere nipa eto ẹko to da ẹnu kọlẹ ni ipinlẹ Osun, ni wi pe ijọba to wa ni ipo lọwọlọwọ n gbiyanju lati mu ibugbooro ba eto ẹkọ ati pe o ti dara si i ju ti atẹyinwa lọ.
Nígbàkúùgbà tí Àpótí Majẹmu OLUWA bá ṣí, Mose á wí pé, “Dìde, OLUWA, kí o sì tú àwọn ọ̀tá rẹ ká, kí o sì mú kí àwọn tí ó kórìíra rẹ sá.
Ahasi kú, wọn sì sin òkú rẹ̀ sinu ibojì àwọn ọba ní ìlú Dafidi, Hesekaya, ọmọ rẹ̀ sì jọba lẹ́yìn rẹ̀.
 Sugbon otito oro ti foju han pe Kanu ko si ni ahamo ijoba apapo, nigba ti awon eniyan bere si n fi esun kan omo –oogun orile ede Naijiria pe awon lo gbe Kanu pamo lasiko to sa kuro lorile ede Naijiria.
Ẹ pada, ẹ̀yin ọmọ mi, ẹ máa bá tiyín lọ.
Ó ní, “Ìhòòhò ni wọ́n bí mi, ìhòòhò ni n óo sì pada lọ.
Bí Gideoni ọmọ Joaṣi, ti ń pa ọkà ní ibi tí wọ́n ti ń pọn ọtí, tí ó ń fi í pamọ́ fún àwọn ará Midiani, 
Sise ibudo ayẹyẹ ni ọṣọ - Decoration: Oríṣun àwòrán, Istagram/malivelihood A gbọ pe ẹgbẹrun meji apo ododo ni ọkọ nla mẹfa wa ja sibi ayẹyẹ naa, eyi ti wọn lo lati fi se ibudo igbalejo fun ayẹyẹ igbeyawo ọhun ni ọṣọ to rẹwa.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ikire Tussle: Ìdí tí àwọn ọ̀dọ́ Ikire fí ni dandan ọba gbọdọ̀ kúrò lórí àpèrè 26 Ọ̀wàrà 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 27 Ọ̀wàrà 2020 Oríṣun àwòrán, daily trust Iroyin to n tẹ BBC Yoruba lọwọ ni pe awọn ọdọ kan nilu Ikire nipinlẹ Osun, gbiyanju lati ji ọba ilu naa gbe.
Brexit: UK fẹ́ so ìjókòó ilé rọ̀, kíni èyí túmọ̀ sí?
''Ko jẹ iyalẹnu fun mi pe awọn eeyan n sọ pe ohun to ṣẹlẹ si mi ko ṣee maa sọ.
Eyi ni iru igbẹ to dara ju gẹgẹ bi awọn dokita ṣe sọ ọ.
Oludamọran Aarẹ lori ọrọ iroyin, Garba Shehu ṣalaye pe aarẹ n lọ fun apero kan lori eto idokowo fun ọjọ iwaju ti wọn pe akori rẹ ni ''Ki lo kan ninu idokowo lagbaaye.
Coronavirus in Nigeria: Àwọn alárùn Coronavirus l'Eko gbé fídíò síta láti ṣí aráàlú létí Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Coronavirus in Nigeria: Àwọn alárùn òrónà l'Eko gbé fídíò síta láti ṣí aráàlú létí Awọn eeyan kan ti wọn ti ko arun COVID-19 ti wọn wa ni ibudo iwosan ajakalẹ arun IDH ni Yaba nilu Eko ti gbe fidio kan sita lati ṣe itaniji fun awọn ọmọ orilẹede Naijiria ati lati fi ẹmi imoore han si awọn olutọju wọn nibẹ.
O óo níyì jù wọ́n lọ; o óo ní òkìkí jù wọ́n lọ, o óo sì lọ́lá jù wọ́n lọ.
Ẹ̀kọ́ ńlá: Ìtàn Gbọnka àti Timi, akọni méjì tó borí Aláàfin Ṣango Àgbẹdọ̀!
OLUWA fi wọ́n lé Israẹli lọ́wọ́, àwọn ọmọ ogun Israẹli sì bẹ̀rẹ̀ sí pa wọ́n.
Eyi waye lẹyin ti Maina gbiyanju lati sakuro lorilẹede Naijiria lẹyin ti wọn gba beeli rẹ.
Aláàfin ti Ọ̀yọ́, Ọba Lamidi Adeyemi Ọba Adeyemi, lásìkò to ń ṣe ifilọlẹ ìwé kan tí ẹnikan kọ nípa Ayinla Ọmọwúrà, kéde pé òògùn ìbílẹ̀ wa dáadáa tó lè wo ajakalẹ-arun Coronavirus, èyí tó ti sẹ orunkun àwùjọ àgbáyé.
Nítorí náà, mo ti pada sí Jerusalẹmu láti ṣàánú fún un: a óo tún ilé mi kọ́ sibẹ, a óo sì tún ìlú Jerusalẹmu kọ́.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Miyetti Allah ní kí wọn wọ́gilé Amotekun, Sunday Igboho yarí Boko Haram gbọ̀nà àrà yọ, kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ ló so àdó olóró mọ̀ láti kọlu Gómìnà Borno Ìṣòro jíjẹ́ ìyá n dáàgbé ló sọ mí di àtúnbí krístíẹ́nì - Remi Tinubu Kí ló ń fa wàhálà láàrín Kunle Afolayan àti Mike Ezuruonye lórí ayélujára?
Ninu ọrọ rẹ, o ni ''aarẹ kuku sọ nipa dida eto ọrọ aje pada diẹ diẹ.
Awọn nkan to ti bajẹ ninu eroja ajogunba, DNA, yoo ma pọ si Awọn nkan ti a jogunba latara obi, DNA, jẹ akojọpọ awọn eroja ti o n lọ lati sẹẹli ara kan si ikeji.
ó bá bẹ̀rẹ̀ sí sọ fún wọn pé, “Lónìí ni àkọsílẹ̀ yìí ṣẹ ní ojú yín.
Obadiah wọ ọgba DSS lọ lati lọ wi ti ẹnu rẹ pẹlu awọn agbẹjọro rẹ meji ti orukọ wọn n jẹ Pius Akubo (SAN) ati Yakubu Bawa.
Bẹ́ẹ̀ sì lèèdì kan kìí móòrún
Oríṣun àwòrán, Others A rọ gbogbo ọmọ Naijiria lati maa foju s'ọri bi alakan, yala o jẹ olowo tabi talaka."
Mo ta gbòǹgbò lọ síbi omi,ìrì sì ń sẹ̀ sí ẹ̀ka mi ní alaalẹ́.
Nigba ti awọn ọmọ ogun Naijira dawọpọ kọlu ikọ agbesunmọmi Boko Haram.
FUTA: Àwọn mẹ́jọ ló ṣíná ìyà fún Bolu ní FUTA
"Bi a se n sọrọ yii, ọgọrun ninu awọn ọmọbinrin ti wọn ji gbe ni Chibok ni a si n wa, latun ri ti awọn ti Dapchi ti wọn ji gbe.
Loju opo Twitter ajọ naa ni wọn ti kede eyii lalẹ ọjọ Aiku.
Àkọlé àwòrán, ìfọ̀rọ̀wérọ̀ BBC Yorùbá Fun apẹrẹ, lasiko yii, oludije fun ẹgbẹ oṣelu APC, Adebayo Adelabu ni kò ṣe oun lara bakan bakan pe gbogbo awọn kọkọ jọ wa ninu yara kan naa tori baba, ẹgbọn ati ọrẹ ni awọn toku jẹ si oun.
 Siwaju si,  o se pataki ki egbe oselu PDP mo awon ohun ti won ti baje lorisirisi lorile-ede yii fun odun mẹ́rìndínlógún ti won fi wa lori aleefa.
World Event: Wo ohun tó ṣelẹ̀ ní àgbáyé lọ́sẹ̀ tó kọjá
Obesere tun mẹnu ba awo rẹ to jade laipẹ to pe akori rẹ ni ''Standout,'' o ṣalaye pe oṣu meje gbako loun fi ṣiṣẹ lori awo naa.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ìtàn ayé Ọba Seriki Abass ti Badagry, tó ní aya 128, ọmọ 144 Kò sí ọ̀nà láti jáde tàbí wọlé sí Mali, ikọ̀ ológun ọlọ́tẹ̀ kéde ìṣéde Wo ibùdó arẹwà tí ọ̀pọ̀ èrò ń ya lọ ní Abuja Obìnrin kan dèrò ilé ẹjọ́ lórí ẹ̀sùn pé ó fi ọ̀bẹ rẹ́ ọmọ rẹ̀ lọ́rùn Adamu Adamu, Minista ètò ẹ̀kọ́ ti fi òfin àátẹ̀lẹ́ síta kí àwọn ilé ìwé lè wọlé Makinde ti sọ̀rọ̀ lẹ́yìn tí asekúpani Akinyele sálo mọ́ àwọn ọlọ́pàá lọ́wọ́ ní àhámọ́ Olólùfẹ́ mi ṣèèsì fi ọkọ́ gbá mi sí gọ́tà, mo rò pé ọlọ́jọ́ dé ni - Iya Osogbo Ohun to ba ni ninujẹ ni bi awọn alakoso idanwo WAEC to n gba iwe idanwo lọwọ wa, se n lọ si awọn idanwo naa lẹyin ni oju ọlọmọ ko to."
Falconets bú sẹ́kún bí Spain ṣe nà wọ́n wálé Ta ni ẹlẹ́sẹ̀ ayò Megan Rapinoe tó gba ife ẹyẹ àgbáyé tàwọn obìnrin?
Bẹ́ẹ̀ ni ẹ óo ti ṣe ní ẹ̀tọ́ láti rìn gaara wọ ìjọba ayérayé ti Oluwa wa, ati Olùgbàlà Jesu Kristi.
salaye nipa ohun ini rẹ, lojo Aje nile aare to wa niluu Abuja.
(Lusi ni orúkọ ìlú náà tẹ́lẹ̀.
Ó fi iranṣẹ kọ̀ọ̀kan ṣe olùtọ́jú agbo ẹran kọ̀ọ̀kan.
Lẹhin ti Bilbao kede pe ọmọ ẹgbẹ agbabọọlu naa nlọ, Laporte se afiranṣẹ pe adabọ fun awọn ololufẹ rẹ lori ẹrọ ayelujara twitta - pe o da'bọ.
Ti wọn ba si kọ lati gba wa laaye pe ka ra nkan awin lọwọ wọn, se la maa n lọ he igbin abi eesan.
sir john bertrand gurdon ( jbg ) , frs ( ojoibi 2 october 1933 ) je aseoroalaye onidagbasoke ara britani .
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Amotekun: Ìjọba ìpínlẹ̀ Oyo, Ogun, Ondo ní ìyókù kù sí ọwọ́ asòfin ìpínlẹ̀ 12 Èrèlè 2020 Oríṣun àwòrán, Tolu ogunlesi Ijọba ipinlẹ Oyo, Ondo ati Ogun ti buwọlu abadofin ọdun 2020 to gbe ikọ amọtẹkun kalẹ ni ipinlẹ naa.
Bí ibi tí OLUWA Ọlọrun yín bá yàn pé kí ẹ ti máa sin òun bá jìnnà pupọ sí yín, ẹ mú mààlúù tabi aguntan láti inú agbo ẹran tí OLUWA fi fun yín, kí ẹ pa á bí mo ti pa á láṣẹ fun yín, kí ẹ sì jẹ ohunkohun tí ọkàn yín bá fẹ́ láti jẹ láàrin àwọn ìlú yín.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Buhari ní yóò wolé ìbò ààrẹ 2019 - Guru Dino Melaye ṣubú lulẹ̀, ó d'èrò ilé ìwòsàn Mi ò tan mọ́ ààrẹ Buhari rárá o!
Akomolede àti Asa lórí BBC Yorùbá: Mọ̀ síi nípa ẹ̀kún ìyàwó níbí
Ilẹ̀ ń ṣọ̀fọ̀, gbogbo nǹkan ń rọ.
Nigeria: Awọn asofin nwadi ibiti owo ẹyọ lọ
Ọwọ́ ọlọ́pàá tẹ àwọn olè tó kó góòlù àti ẹgbẹ̀lẹ́gbẹ̀ mílíọ̀nù lọ nílé MKO Abiola l'Eko Kí ló mú Obasanjo ti ilẹ̀kùn mọ́ ẹbí, òṣìṣẹ́, ojúlùmọ̀ ní ibi òkú àna rẹ̀?
17 Ìgbé 2020 Lẹyin ti arun Coronavirus di tọrọ fọnkale lọpọ orilẹede kaakiri agbaye, ọpọ awọn eeyan lo ti bẹrẹ si n wa abẹrẹ ajẹsara arun naa.
Bo tilẹ jẹ pe akọwe ijọba ko sọ ọjọ kan pato ti wọn yoo ko agbo naa wọ Naijiria, o ni gbogbo eto ti to lati lọ ko agbo naa lati Equitorial Guinea.
Fọnran fidio kan ti a ko le fidi rẹ mulẹ ti jẹyọ nibi ti agbebọn naa ti n yinbọn lu awọn eeyan.
 Àjẹsára náà dàbí èyí tó má a ń dín ewu ikú tó ti ipasẹ ̀ ìgbẹ ́ gbuuru wáyé kù láàárín àwọn ọmọdé .
Kano: Ọkùnrin mẹrin wọ gàù 'torí ìgbéyàwó orí Facebook
O fikun un wi pe adari rere lo le e tukọ orilẹede Naijiria lasiko ti a wayii, nitori iru iṣẹlẹ bayii ni o ma n fihan boya eniyan jẹ adari rere abi bẹẹ kọ.
Àbí òun nìkan ni ó ṣègbé nítorí ẹ̀ṣẹ̀ rẹ̀?
Aare wa gbadura pe ki Olorun te oloogbe naa si afefe ire.
Àmì ohùn ṣe pàtàkí nínú èdè Yoruba púpọ̀
Ilẹ̀ ṣú, ilẹ̀ sì tún mọ́, ó di ọjọ́ kẹrin.
Aisan naa lo pada pa a , lẹyin to wọ ipele kẹrin.
O sọ pe imọ ijinlẹ nipa ẹrọ ayelujara si ni yoo wu oun lati kọ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù John Blake: Wo ohun tó yẹ kí o mọ̀ nípa ọmọ ọdún 17 tí wọ́n ní ó pa èèyàn méjì níbi ìwọ́de Black Lives Matter ní Kenosha 24 Ògún 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 28 Ògún 2020 Oríṣun àwòrán, Getty Images Lẹyin ti awọn ọlọpaa alawọ funfun yinbọn lu jacob Blake, to jẹ alawọ dudu ni l'Amẹrika, lawọn eeyan ilẹ naa bẹrẹ si ni tu sita lati ṣe ifẹhonuhan lori iṣẹlẹ naa.
Àwọn agbébọn jí alága ẹgbẹ́ òsèlú PDP gbé ní Kogi Samuel Okwaraji: Ó pé ọgbọ̀n ọdún tí lónìí ti akọni àgbábọ̀ọ̀lù papo dà Jẹjẹrẹ ní ìwà akakítí ẹ̀sìn, ẹ yàgà fún ẹ̀kọ́ òdì -Ààrẹ Buhari Ẹ̀yin mùsùlùmí, ẹ yàgò fún ìwà ipá- Buhari Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
EndSARS Protest Update: Aisha Yesufu ní Buhari jẹ́wọ́ pé òun kò láànú aráàlú nínú ọ̀rọ̀ rẹ̀
N óo sọ àṣírí obinrin náà fún ọ ati ti ẹranko tí ó gùn, tí ó ní orí meje ati ìwo mẹ́wàá.
Ohun to yẹ ko mọ nipa idibo South Africa 26.
Ọlọrun a máa fún ẹni tí ó bá ṣe ìfẹ́ rẹ̀ ní ọgbọ́n, ìmọ̀, ati inú dídùn; ṣugbọn iṣẹ́ àtikójọ ati àtitòjọ níí fún ẹlẹ́ṣẹ̀, kí wọ́n lè fún àwọn tí ó bá wu Ọlọrun.
Inú bí OLUWA sí Mose, ó ní, “Ṣebí Aaroni, ọmọ Lefi, arakunrin rẹ wà níbẹ̀?
ati awon osise soro lati rii pe enikeni ko da idoti soju popo.
Obinrin kan ni yii to n fayọ han lẹyin to dibo yan ẹni to wuu.
Gomina ni oun ṣe eyi lati ṣe moriya ati lati gba awọn akẹkọọ toku niyanju lati ṣe ju bẹẹ lọ tori o ni iṣejọba oun mu eto ẹkọ lọkunkundun.
com/6o5xLxyntO— 🇳🇬 Super Eagles (@NGSuperEagles) June 20, 2018Lasiko iforowanilenuwo ti o waye lojoRu(Wednesday), Rohr salaye idi pataki ti o oun se n lo balogun iko naa, John Mikel Obi seyin akegbe re Odion Ighalo ti oun gba owo iwaju.
Ninu ọrọ to sọ lasiko to fi n gbalejo igbimọ awọn eekan ọmọ ipinlẹ Niger kan ni ile aarẹ, Aso rock villa to wa nilu Abuja, aarẹ Buhari ni awọn aṣeyọri iṣejọba oun lẹka ipese ina ọba, opopona ati oju irinna fun ọkọ oju irin waye lai naani awọn ifasẹyin to n waye latọdọ awọn aṣofin apapọ.
ede yii, Mansur Dan-Ali, alakoso eto aabo ,ogagun Gabriel Olanishakin ati
Ó mú gbogbo ọfàtí ó wà ninu apó rẹ̀ó ta wọ́n mọ́ mi lọ́kàn.
June 12: Àjọ eléto ìdìbò gbọdọ̀ kéde MKO Abiola bí ààrẹ Nigeria
 iye owó àjẹsára mmr lójú pálí jẹ ́ 0.
àwọn ìlú tí ó jẹ́ tiwọn ní ìpẹ̀kun apá ìhà gúsù lẹ́bàá ààlà Edomu nìwọ̀nyí: Kabiseeli, Ederi, Jaguri, 
Ọmọ ilu Kano ni Umar Abba jẹ ohun si ni yoo ma dari EFCC titi ti Minisita feto idajọ Abubakar Malami yoo fi kede adele alaga ajọ naa A ko tiribi fidi ọrọ mulẹ lori ọdun ti wọn bi Umar tabi ileẹkọ to ti kẹkọ jade ṣugbọn lọpọ igba lo ti lọ ṣoju adele alaga Magu lawọn aaye to ba ni ko ṣoju ohun.
Ìwà òdodo àwọn olóòótọ́ yóo gbà wọ́n,ṣugbọn ìfẹ́kúfẹ̀ẹ́ àwọn ọ̀dàlẹ̀ yóo dè wọ́n nígbèkùn.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ebola: Àwọn aláìsàn mẹ́ta sá kúrò níléwòsàn ní DR Congo 24 Èbibi 2018 Oríṣun àwòrán, AFP Àkọlé àwòrán, Ó lé ní ẹgbẹ̀rún mọ́kànlá ènìyàn tí àìsàn Ebola pa ní ẹkùn Ìwọ̀ Oòrùn Afrika láàrin 2014 sí 2016 Àwọn aláìsàn Ebola mẹ́ta sá kúrò ní ibùdó ìtọ́jú gba ṣọ́ọ̀sì lọ ní orílẹ̀-èdè Democratic Republic of Congo.
Ìwọ tí o sọ pé kí eniyan má ṣe àgbèrè, ṣé ìwọ náà kì í ṣe àgbèrè?
Zlatan Ibile n beere ninu orin naa pe ''ki lo n run, ṣe Tacha ti wọ le?
Ẹ ṣe ọdún kan tán, ẹ tún ṣe òmíràn sí i,ẹ máa ṣe àwọn àjọ̀dún ní gbogbo àkókò wọn.
Samson Siasia: Orí ti kó ìyá Siasia yọ lọ́wọ́ àwọn ajínigbé lẹ́yìn oṣù méjì ààbọ̀
ó ń ṣe oríkunkun sí i,ó sì gbé apata tí ó nípọn lọ́wọ́ láti bá a jà;
Diẹ lara awọn oṣere tiata to ti di ara ilẹ ree, ta si n ranti iṣẹ ọwọ wọn, a wa gbadura pe ki Ọlọrun tubọ dẹ ilẹ fun gbogbo awọn oṣere tiata to ti dagbere faye.
" gẹ ́ gẹ ́ bí ọ ̀ rọ ọgbọ ́ n kan se wí pé "" ni àtètékọ ́ ṣe ni ọ ̀ rọ ̀ wà "" , bẹ ́ ẹ ̀ náà ni ètò ti wà fún ohun gbogbo láti ìpilẹ ̀ sẹ ̀ wá ."
ati láti fún ẹ̀yin tí wọn ń pọ́n lójú, ati àwa náà ní ìsinmi, nígbà tí Oluwa wa, Jesu, bá farahàn láti ọ̀run ninu ọwọ́ iná pẹlu àwọn angẹli tí wọ́n jẹ́ alágbára.
Oríṣun àwòrán, MEDIAMAFIA Maina to jẹ alaga igbimọ atunto ọrọ owo ifẹyinti ni Naijiria ni wọn fi ẹsun pe o lu biliọnu meji owo ijọba ni ponpo.
Shehu se afikun wipe inu aarẹ Buhari dun si itusilẹ yi, o si ke pe awọn ọmọogun Naijiria ati ileese DSS wipe ki wọn mura si se lati ri wipe awọn akekọbirin Chibok ti Boko Haram jigbe padawa si ile.
Oríṣun àwòrán, @BashirAhmaad Gbogbo igbiyanju Gomina Obaseki lọ si ile aarẹ ni Aso Rock lọdọ aarẹ nigba ti ẹgbẹ APC fẹ yọwọ rẹ lawo lati dupo Gomina lo ja si.
Ijọba ni ohun gbe igbesẹ yii lati dena mọ awọn ole to lee fẹ ji nkan ninu ibojì naa.
siwaju si ojo Abameta to n bọ yii.
12 Nípa bẹ́ẹ̀ Ó nfi hàn pé Òun kannáà ni Ọlọ́run ní àná, ní òní, àti títí láé.
Àwàdà tàbí óótọ́, kì lò f'ẹkún Kọmíṣọ́nnà ìlera Kogi lórí amóhùnmáwòrán?
Ninu atẹjade kan ti ile ifowopamọ naa fi lede loju opo rẹ ti awọn alaṣẹ rẹ si fọwọ si lo ti sọ ọrọ ọhun.
lasiko to n fesi si iroyin ti ile ise asoju ti orile ede Britan gbe jade lori
sílè fún ọdún 2019 láti jé kí èdè, àṣà àti ìṣe wá
Kike si adajọ agba lati gbe igbimọ oluwadi kalẹ ni igbesẹ keji ti ofin orilẹede Naijiria la kalẹ fun yiyọ awọn to ba di ipo mu bii aarẹ, igbakeji aarẹ, gomina ati igbakeji gomina ipinlẹ lorilẹede Naijiria.
A gbo bakanna pe wọn ti bẹrẹ si ni wo awọn ile ni Adugbo Freeman nilu Eko.
Nígbà tí ó pẹ́ òjò yìí dá mo sì múra mo kọ orí sí ibùdo mi, nígbà tí mo máa dé ibẹ̀, igi ńlá kan báyìí ti wó sí ọ̀kánkán ihò mi, igi náà sì ti yí òkúta kúrò lẹ́nu ihò mi.
Nígbà náà ni alufaa yóo mú kí obinrin náà búra, yóo wí fún un pé, ‘Bí ọkunrin kankan kò bá bá ọ lòpọ̀, tí o kò sì ṣe aiṣootọ sí ọkọ rẹ, ègún inú omi kíkorò yìí kò ní ṣe ọ́ ní ibi.
''Buhari àti Tinubu ṣ'àdéhùn pé Yorùbá ni yóò jẹ́ olùdíje ipò ààrẹ APC lọ́dún 2023'' Igbo Olodumare rèé, níbi tí Ìgbín ti tóbi ju Ìjàpá lọ Kí gan ló pa Dapo Ojora, ẹ̀gbọ́n ìyàwó Bukola Saraki l'Eko?
Simoni Peteru, ati Tomasi tí wọn ń pè ní Didimu (èyí ni “Ìbejì”) ati Nataniẹli ará Kana, ni ilẹ̀ Galili, ati àwọn ọmọ Sebede ati àwọn meji mìíràn ninu àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ wà ní ibìkan.
Ọlọ́run nìkan ló mọ bí ìrìnàjò ìfẹ́ ẹ̀dá á ṣe rí láyé, ọ̀dọ́ Aláàfin ní orí gbémí yà sí, ó sì tẹ́milọ́rùn- Olorì Aanu Wo ọ̀nà tí àwọn ‘ẹ̀lẹ̀ Daddy’ gbà dé ààfin Ọyọ Ko tan sibẹ o, iroyin naa sọ pe fun bi ọsẹ kan ni Olori Damilola, to bi ibeji fun alaafin, fi wa ninu ẹwọn naa, to si jẹ pe gbogbo dukia rẹ ni wọn gba lọwọ rẹ.
Ní àkókò ìbẹ̀rẹ̀ ìkórè ọkà baali ni wọ́n dé sí Bẹtilẹhẹmu.
Favour - BBC News Yorùbá BBC News, YorùbáFò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Covid19 Benefit: Àsìkò Coronavirus yìí jẹ́ kí n di télọ̀ tó mọṣẹ́ gidi - Favour Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Covid19 Benefit: Àsìkò Coronavirus yìí jẹ́ kí n di télọ̀ tó mọṣẹ́ gidi - Favour 13 Agẹmo 2020 Ko tilẹ to pe ọdun mẹwaa rara ni Favour ti maa n lọ ba awọn obi rẹ pe oun fẹ kọ iṣẹ ranṣọranṣọ.
Ni bayii aarẹ Trump ni awọn idojukọ bi o se n gbiyanju lati tubọ di aarẹ ilẹ Amẹrika ni ẹlẹẹkeji ni inu oṣu kọkanla ọdun yii, yoo ma koju Joe Biden ti ẹgbẹ Democrat.
O sọ pe ikọlu ati ipanilara t'o sẹlẹ si awọn olukọ ile-iwe meji ninu Ile-ẹkọ akọbẹ ti Atọla ni agbegbe ijọba ibilẹ Ewekoro ti n d'ẹru ba awọn eniyan ti ipinlẹ naa.
Wọn ni awọn yoo pa wa lai si ohunkohun ti yoo sẹlẹ, ti wọn si si irun atọwọda ti mo de sori.
CBN ni ẹnikẹni to ba fi owo rẹ pamọ si ibikibi ti CBN ko lọwọ si wa ninu ewu jibiti.
OLUWA bá wí fún mi pé, 
Uganda ti bẹrẹ ìgbésè láti fi ikú ṣefàjẹ fún ẹní bá ṣe ìgbéyàwó akọ si akọ ati abo si abo Wo ìdí to fi gbọdọ̀ yàgò fún Bobrisky, akọ tó ń ṣe bíi abo Àwọn obìnrin yarí, wọ́n kò fẹ́ àwọn ọkùnrin ní òde ijó wọn Ariwo kò jẹ́!
Ẹjọ ti Ajimọbi fi sun ni wi pe Kọla Balogun kọ ni awọn eeyan dibo fun ninu eto idibo to waye loṣu keji ọdun yii.
Amọṣa, ijọba ipinlẹ Ogun ni awọn eleto ilera kan lawọn fẹ lo ati pe awọn ti ba awọn eleto ilera naa sọrọ lati pese ayẹwo ọhun fun wọn ni ẹdinwo.
Ko pe si asiko yii ti iya rẹ naa dubulẹ aisan, ti oun naa si dagbere faye.
 O ti se opolopo ere fiimu bii: Tinsel, ‘Gidi Blues’, ‘Battleground’, ‘Maroko’ ati ‘Bariga Boy’.
Opọlọpọ ile itaja lo jona mọ ile itaja afẹfẹ gaasi ti iṣẹlẹ naa ti ṣẹlẹ bayii.
Ààrẹ Buhari yóò sàbẹ̀wò sí ìlú Eko Buhari dára ju Ọbasanjọ lọ - Ọba Èkó Buhari takó Ambọ̀de Inu fo aya fo lawọn ara ilu Eko kan wa lati igba ti ijọba kede titi awọn oju ọna kna pa nitori abẹwo Aarẹ Buhari sipinlẹ naa.
" Ninu ọrọ rẹ, Ọgbẹni Toye Arulogun jẹjẹ atilẹyin ileesẹ naa lati ri daju pe asa ọdun Ọsun Osogbo ko yinjẹ, ti awọn yoo si tun fi akọtun ọgbọn si ọna ti wọn n gba se ọdun naa.
Eyi ni igba kẹta ti ile iwosan ijọba to wa ni Yola ti ṣiṣẹ abẹ lori awọn ibeji ti wọn bi bẹẹ ti wọn lẹpọ gẹgẹ bi adari ile iwosan naa, Ọjọgbọn Auwal Abubakar ṣe sọ ọ.
Lai Mohammed: A kò ní bojú wẹ̀yìn lórí àbádòfin ìṣàkóso ẹ̀rọ ayélujára Wo ìlú tí wọ́n tí ń ta ọmọ ọ̀dọ̀ kan fún #1.
Ajọ to n nmojuto iwaadi to da lori iṣuna lorilẹede Naijiria, NFIU ti gbe aṣẹ kalẹ fun gbogbo awọn banki lorilẹede Naijiria lati ṣọra fun gbigbe owo jade fawọn gomina lati inu aṣuwọn naa lai jẹ pe irufẹ owo bẹẹ kọkọ wọ inu aṣuwọn ifowopamọsi ijọba ibilẹ ti ọrọ kan.
Àfi ìgbà tí mo bọ́ sọ́wọ́ ọ̀tá mí nínú ìrìnàjò ìfẹ́- Roshan Ṣé ìnàkí tún gbé owó tó lé ní mílíọ̀nu mẹ̀fà Náírà mì ni?
Fẹntilatọ to n da ṣiṣẹ funra rẹ: Ẹni ogun ọdun kan ni Naijiria, Usman Dalhatu lo ṣe fẹntilatọ kekere naa lati ran awọn to ṣoro fun lati mi funra wọn latari arun ọhun.
A bi Gbajabiamila,ni ojo kárùndínlọ́gbọ̀n, osu kẹ́fà,odun 1962, o lọ si ile –eko alakọbẹrẹ
Ṣé irúfẹ́ oúnjẹ tí ò ń jẹ́ lè jẹ́ kí o gbádùn ìbálòpọ̀ rẹ síi?
Nigba ti ẹnikan beere lọwọ rẹ pe ṣe nitori awuyewuye pe oun ati Wasiu Ayinde n fẹ ara wọn, lo ṣe kuro ni aafin, Badirat sọ pe oun ti kuro ni aafin ṣaaju iroyin naa.
Fun Naijiria, Aarẹ Buhari ṣeleri pe oun yoo pari awọn oju ọna, kọle fun araalu, ati awọn nkan miran l'ọdun 2020.
” Nítorí náà, OLUWA ní, “Ẹ dúró dè mí di ọjọ́ tí n óo dìde bí ẹlẹ́rìí.
Gbogbo rẹ lo si wọ wo.
Akoroyin  ile ise  BBC, Mohamed Arezki Himeurlo so eleyii nipa
Koda, o pari ni ọrọ ti ọpọ ọmọ Naijiria n kọ loju opo Twitter wọn, to si foju han pe, ohun to wa ninu ọrọ aarẹ naa ti toju su wọn.
Oríṣun àwòrán, Joshua Paul for the BBC Àkọlé àwòrán, 'Aṣọ Adajọ ti mo wọ yi a ma ran mi leti ojuṣe nla ti mo ni gẹgẹ bi adajọ Sharia' Amọ ṣa, dida ẹjọ to nii ṣe pẹlu gbigba ọmọ sọdọ laarin lọkọ laya ti wọn ba pinya tabi ki ọkunrin fẹ ju iyawo kan lọ jẹ eleyi ti Adajọ Shushaidah ni imọ nipa rẹ daadaa.
Ó ní, “Iyawo mi kò gbọdọ̀ máa gbé ààfin Dafidi, ọba Israẹli; nítorí pé ibikíbi tí àpótí OLUWA bá ti wọ̀, ó ti di ibi mímọ́.
Ààrẹ Nàìjíríà tẹ́lẹ̀ rí Goodluck Jonathan ní òun ó ni ọrọ̀ kankan nílẹ̀ Òkèrè
Tí a fiṣọwọ́ ní 11:26 10 Sẹ́rẹ́ 202111:26 10 Sẹ́rẹ́ 2021 Àwọn olorì Aláàfin fi oríkì awúnilórí yẹ́ ọkọ wọn sí fún àádọ́ta ọdún tó gorí ìtẹ́ Iwadi fi ye wa pe, ọpọ ninu awọn olori to n ki Alaafin ku oriire aadọta ọdun to gori itẹ, ni wọn ko tii bi lasiko ti Ọba Adeyemi gori itẹ.
Ṣugbọn yóo sọ pé, ‘Èmi kì í ṣe wolii, àgbẹ̀ ni mí; oko ni mò ń ro láti ìgbà èwe mi.
Naijiria, ojogbon Yemi Osibanjo ti rọ awọn to n kẹkọọ gboye jade lati fafiti
Kì í ṣe òun ni oyè yóo tọ́ sí, ṣugbọn yóo dé lójijì, yóo sì fi àrékérekè gba ìjọba.
A máa lọ wá irun aguntan ati òwú ìhunṣọ,a sì máa fi tayọ̀tayọ̀ hun aṣọ.
 Eyi ni ọrọ ti Fayoṣe kọ si ori opo twitter rẹ, ṣugbọn ko daju pe ileeṣẹ aarẹ tabi aarẹ Buhari funrarẹ ṣetan lati dahun si ibeere rẹ."
Nítorí kò ní rí ààyè dá ọ lóhùn lọ́jọ́ mìíràn, òun ni Mọ́gàjí ilé wa.
OLUWA tún wí fún mi pé, “Àwọn ọmọ Juda ati àwọn tí wọn ń gbé Jerusalẹmu ń dìtẹ̀.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Àwọn omidan Naijiria ni wọ́n fi ń ṣerú ní Lebanon- Ọmọlọla Ọ̀rọ̀ rírùn ni ìjọba àpapọ̀ ń sọ lórí ìdásílẹ̀ ikọ̀ Amotekun - Itse Sagay Ìjàmbà ọkọ̀ akẹ́rù ní Ikòròdú fa súnkẹrẹ-fàkẹrẹ ọkọ̀ ní Márosẹ̀ Ọ̀pọ̀ àwòrán tó ń ṣeni láàánú rèè nípa ogun abẹ́lé Nàíjíríà Irọ̀ ni ìjọba ń pa, Ikọ Amọtẹkun ba ofin Naijiria mu- Ìgbìmọ̀ Yoruba Bẹẹ ba gbagbe, oju awọn araalu ri mabo lopin ọdun 2019 nigba ti ileeẹ to n se oju sna ọhun ti abala kan pa ladugbo Kara si Berger, eyi to nira fun ọpọ eeyan lati gba oju ọna ọhun wọ ilu Eko.
Oṣu to kọja ni wọn fi ẹsun kan Don Jr toripe o sọ ootọ nipa awọn eeyan to ti ku latari Covid-19 l'Amẹrika.
Ó ń waasu pé, “Ẹnìkan tí ó jù mí lọ ń bọ̀ lẹ́yìn mi, n kò tó bẹ̀rẹ̀ láti tú okùn bàtà rẹ̀.
Kí wọn gbé e ga láàrin ìjọ eniyan,kí wọn sì yìn ín ní àwùjọ àwọn àgbà.
Ọpọ awọn ajafẹtọ ọmọniyan lo ti n sọ fun ijọba apapọ lati fi orukọ Abiola sọ nnkan kan to jẹ ti ijọba apapọ ko le jẹ iranti nitori pa rẹ ninu eto oṣelu Naijiria.
Ni Ghana, Minisita feto iroyin, Kojo Oppong Nkrumah sọrọ lori koko yii lasiko tawọn alasẹ n salaye ọrọ nipa ọrọ yi wi pe ijọba ko ni erongba lati si ile ẹkọ pada lasiko yi.
Ẹ yin OLUWA, nítorí pé ó ṣeun;ẹ kọrin ìyìn sí i,nítorí pé olóore ọ̀fẹ́ ni.
Opọlọpọ oṣiṣẹ lo maa n fọwọsowọpọ ki eré sinima to di odindin.
Ó sọ fún wọn pé, “Ó lẹ amọ̀ mọ́ mi lójú, mo lọ bọ́jú, mo bá ríran.
Awọn mejeeji ni yoo jọ waako lalẹ oni ọjọ Aiku ti wọn yoo fi mọ ẹni to n lọ si ipele aṣekagba idije ifẹsẹwọnsẹ tilẹ Adulawọ fun ọdun 2019.
Fadaka ni wọ́n fi ṣe àwọn ìkọ́ ati àwọn ọ̀pá tẹ́ẹ́rẹ́tẹ́ẹ́rẹ́, fadaka ni wọ́n sì fi bo àwọn ìbòrí òpó náà.
Jehoahasi kò ní àwọn ọmọ ogun mọ́ àfi aadọta ẹlẹ́ṣin, ati kẹ̀kẹ́ ogun mẹ́wàá ati ẹgbaarun (10,000) àwọn ọmọ ogun tí wọn ń fi ẹsẹ̀ rìn.
Nigba to n ba BBC Yoruba sọrọ, Oloye Lekan Alabi ni Iyalode Abiọdun jẹ onisowo lati kekere, to si ri ja jẹ.
Ṣugbọn ó ń sin Ọlọrun àwọn baba rẹ̀, ó pa òfin Ọlọrun mọ́, kò sì tẹ̀lé ìṣe àwọn ọmọ Israẹli.
Ibi ọ̀rọ̀ dé dúró lórí ṣíṣí àwọn ilé ìwé padà ní Naijira rèé àti nílẹ̀ Afrika Òpópónà àti afárá 19 níjọba fẹ́ ṣe nínú àbá ìṣúná ọdún 2020 A wà nínú igbó tí a ti ń wá àwọn arinrìnàjò mẹ́jọ láti Abuja sí Eko tí wọ́n jígbé lọ- Ọlọ́pàá Ondo E wo ọmọ Yorùbá àkọ́kọ́ tó jà fún ẹ̀tọ́ àwọn aláwọ̀dúdú ní America!
Ajọ UNO sọ pe igbesẹ yii tako ẹtọ ọmọniyan lagbaaye.
Ooni Ile Ife: Ooni Adeyeye Ogunwusi àti Olòrì Naomi gbé Àrẹ̀mọ tuntun wọ ṣọ́ọ̀ṣì
Kí o sì fi ikú wèrewère mọ lórí èyí
" Bakan naa ni agbẹnusọ fun aarẹ Muhammadu Buhari, Garba Shehu, fi atẹjade kan sita lọjọ ọdun Ileya.
aago mẹ́jọ owurọ eto idibo naa si n lọ ni irọwọ ati irọsẹ ; a
Àbí Sioni ti di ohun ìríra lọ́kàn rẹ?
 won ko sọ koko ipade naaKo si gomina Kankan  to so nipato lori ohun ti ipade naa da lori fun awon akoroyin, nigba ti won fe foro wa won lenu wo.
Ni Simeoni bá gbé ọmọ náà lọ́wọ́, ó yin Ọlọrun lógo, ó ní,
Bawo lo ṣe ṣẹlẹ Ohun ta mọ ni pe ọkọ akero naa ti o jọ iru eleyi ti wọn fi n ko awọn ọmọ akẹkọ nikan lo fa ijamba yi.
Ẹnu kun un lọdun 2012, nigba to sọ ni gbangba pe oun faramọ igbeyawo ọkùnrin si ọkunrin, koda ki Aarẹ Obama to o sọrọ nipa atilẹyin rẹ fun iru igbeyawo naa.
Jesu wí fún wọn pé, “Ẹ wá jẹun.
Nígbà náà ni n óo lọ sí ibi pẹpẹ Ọlọrun,àní, sọ́dọ̀ Ọlọrun, ayọ̀ ńlá mi.
Nígbà tí wọ́n gbé ojú wọn sókè, wọn kò rí ẹnikẹ́ni mọ́, àfi Jesu nìkan.
Oniruuru iha lawọn eeyan, lẹgbẹlẹgbẹ, ati lajọlajọ ti sọ lori igbesẹ yii.
Ninu ọrọ rẹ, Makinde sọ pe ipapoda rẹ ba oun lọkan jẹ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fọ́nrán ohùn, Ọ̀gá Bello: Ikú Aisha Abimbọla ká wa lára Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Tunde Bakare: Kaka ko san lara iya ajẹ Ilé Aṣòfin àgbà gba Omo-Agege padà sílé Àwọn aṣòfin gba àyẹ̀wò àbá ìṣúná 2018 Ọ̀pọ̀ àwọn ọmọ Nàíjíríà ló ti ń se ìdárò ikú àgbà òsèré tó dará ilẹ̀ náà ní ojú òpó Twitter wọn.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù World Aniti-Corruption day: Awolowo, Azikwe, Abacha àtàwọn olórí ìjọba tí aje ìwà ìjẹkújẹ ti ṣí mọ́ lórí rí ní Nàìjíríà 9 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 14 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Oríṣun àwòrán, others Èyí ni àwọn aṣíwájú ìjọba táje ìwà ìjẹkújẹ ti ṣí mọ́ lórí láàrin ọdún 1960 sí àsìkò yí Ọrọ iwa ijẹkujẹ kii ṣe ajeji lorilẹede Naijiri.
Bóò bá ní nọ́mbà ìdánimọ̀ NIN, à tí kọ ìdánwò rẹ yóò ṣòro Iṣẹ́ ti bẹ̀rẹ̀ lórí àfikún owó oṣù tuntun- Keyamo Awọn elomiran a tun ma a da idoti si oju omi ati panti si oju odo, eyi ti o fa ki odo máa dagun ati ẹkun omi.
(Sí ọ̀gá akọrin; pẹlu àwọn ohun èlò orin olókùn.
Ó ní àìsàn ìtọ̀ ṣúgà, ojú rẹ̀ kò sì ríran dáàda mọ́.
Ọmọdekunrin naa ni ọkunrin naa n dunkoko mọ oun pe, ti oun ba fi pariwo, oun yoo sọ oun di isu.
Jesu pada sí Galili pẹlu agbára Ẹ̀mí Mímọ́.
Àkọlé àwòrán, aju ara wa lọ, ijakadi kọ Bẹẹ, ko si eegun ti yoo joo re ti atọkun rẹ ko ni ṣai fidunnu han ni ọrọ awọn ololufẹ Liverpool lori ikanni BBC Yoruba pe: Àkọlé àwòrán, Igba iponju lawọn aladuroti n rẹ ni Bẹẹ lawọn mii gba pé o dabi pe papa iṣerẹ naa kii ṣe fun Arsenal lasiko idije naa ni Dandan ní kí a mú Dino sí àhámọ wa- Ọlọ́pàá Àwọn ohun tó yẹ kí o mọ̀ nípa Shehu Shagari tó d'olóògbé Àwọn ìmúra tó lààmìlaka ní Nàìjíríà lọdún 2018 Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Saba Gul: Ọmọbìnrin aláìlápa tí o fẹ̀ dì agbẹjọro Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 3 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 5 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Beer Belly: Wo ohun tó yẹ ko mọ̀ nípa ikun rẹ tó ń to tobi
Ọ̀pá afẹ́fẹ́ gáásì NNPC tó dálu ló fa ìbúgbàmù l‘Eko, ilé 50 àti ọ̀pọ̀ ẹ̀mí ṣòfò Ìpele tuntun ló kàn nínú ìrìnàjò ayé mi, ń kò pe ẹjọ́ lóri ìrọ̀lóyé - Sanusi Kò sẹ́ni tó fẹ́ pa Buhari o, ọkùnrin tó pakuru mọ́ ààrẹ kàn fẹ́ bọ̀ọ́ lọ́wọ́ ni - Femi Adesina Ọmọ ti lọ kí baba, Fayemi bẹ Aláàfin wo l‘Ọyọ, wọ́n jírórò lórí lẹ́tà Ẹ́ gbaradì, to bá lo jẹnẹrátọ̀ àbí tà á, ò ń fi ẹ̀wọ̀n ọdún mẹ́wàá ṣeré - Sẹ́nétọ̀ ń dábàá Láì lo Kakulétọ̀, mo ní ọpọlọ ìṣirò, tábìlì ìṣirò wà lórí mi - Human Calculator ''Aarun a ti dupo lọdun 2023 n ṣe ọpọ lagbo oṣelu atawọn alatilẹyin wọn laarin awọn akọroyin'' Tinubu lo woye bẹẹ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Àmì ohùn ṣe pàtàkí nínú èdè Yoruba púpọ̀ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àmì ohùn ṣe pàtàkí nínú èdè Yoruba púpọ̀ 16 Ìgbé 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 22 Èbibi 2020 Ede, aṣa, àti ìtàn orirun wà lára nkan to ya ogidi ọmọ Yorùbá sọtọ ni gbogbo agbaye.
Gege bi okan gbogi lara awon ololufe ere-idaraya ohun, Mitsuko Sakai se so leyin ifigagbaga naa “Osaka fi ara bale kopa ribiribi ninu ifigagbaga yii, eleyi ti o mu Serena binu, ti o si sokunfa idi ti ko fi se daradara to bi awon ololufe re se lero.
O ni araalu yoo tun lanfaani lati maa wo bi ijororo ile ati gbogbo idibo yoo se maa waye, bakan naa ni yoo maa lọ si ipamọ fun itan ọjọ iwaju.
Nibi ayẹyẹ iṣide ipolongo idibo APC nipinlẹ Ondo ni Tinubu ti pe fun atunto lori bi ijọba apapọ se n pin owo to n wọle labẹle nilẹ yii.
Naijiria (Independent National Electoral Commission ,INEC) ati awon oludibo fun
Nígbà tí wọ́n sé ààfin ọba Igbó Olódùmarè ọ̀rọ̀ pa èsì jẹ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Coronavirus: Ìjọba Osun ní àìlo ìbòmú aráàlú ló mú kí Corovirus peléke si 30 Òkùdu 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 1 Agẹmo 2020 Oríṣun àwòrán, Facebook/Omipidan Ismail Ijọba ipinlẹ Osun ti gbe igbesẹ lati fi titẹle awọn ilana aabo lasiko Covid -19 mulẹ, to si pọn idanilẹkọ ni dandan fawọn to ba tasẹ agẹrẹ sofin yii.
Anthony Ẹkundayọ si ni oludari fun ikọ agbefọba Lọjọ Isẹgun, ọjọ Kejidinlogun, osu Kejila, ọdun 1971 ti wọn da ẹjọ naa, gọngọ sọ.
Nígbà tí ẹ bá ń wá ìmọ́lẹ̀,yóo sọ ọ́ di ìṣúdudu,yóo sọ ọ́ di òkùnkùn biribiri.
Ṣé lóòtọ́ ni Lateef Adedimeji àti Adebimpe Oyebade ṣe ìgbéyàwó?
Àwọn ni yóo máa ṣe ìtọ́jú ibi mímọ́ ati Àgọ́ Àjọ, aṣọ ìbòrí rẹ̀, ati aṣọ tí wọ́n ń ta sí ẹnu ọ̀nà àbáwọlé rẹ̀; 
Ọdun mejidinlogoji re e ti Aarẹ Biya ti wa nipo, àwọn kan si n sọ pe ọmọ rẹ, Brenda n tun ọjọ iwajuu ara a rẹ ṣe ni, torí ti baba rẹ ba fi ipo silẹ.
Inú sì bí OLUWA sí àwọn mejeeji, ó sì kúrò lọ́dọ̀ wọn.
22 Bélú 2020 4:26 Fídíò, Akomolede Yoruba: Kí ni ìdí tí aṣọ fi máa ń pọ̀ lára Egúngún ju Orò lọ́?
Bí o tilẹ̀ kọ́ ìtẹ́ rẹ sí ibi gíga, bíi ti ẹyẹ idì,n óo fà ọ́ lulẹ̀ láti ibẹ̀.
1 10635 Orilẹede Malta 236 53.
Joṣua sọ fún àwọn eniyan náà pé, “Ẹ ya ara yín sí mímọ́ nítorí pé OLUWA yóo ṣe iṣẹ́ ìyanu láàrin yín ní ọ̀la.
Awọn eniyan to n fesi si iṣẹlẹ naa n kesi awọn afẹhọnuhan EndSars lati dawọ duro lori ifẹhọnuhan naa nitori awọn janduku ti gba a mọ wọn lọwọ bayii.
Coronavirus lè tara òkú Abba Kyari ran àwọn tó péjú síbi ìsìnkú rẹ̀- Ààrẹ ẹgbẹ́ dókítà ní Nàìjíríà Ìyàwó mi ṣẹ̀ṣẹ̀ bímọ tuntun, kò si oúnjẹ fún wa torí ìgbélé Coronavirus- Yakubu Bawo wa ni o ṣe le da ami coronavirus mọ?
Ondo: Òjọ̀ àrọ̀rọ̀dà pa ènìyàn kàn, wó ìlé 50 ní Akure
Lẹyin ọjọ kẹta ti ọdun Ọṣun Oṣogbo bẹrẹ si ni eto naa yoo waye.
Ijọba ni eyi ri bẹẹ ki idagbasoke nla lee ba ọrọ aje lorilẹede Naijiria ni.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Pneumonia: Dókítà ní kòkòrò àìfojúrí ló ń fàá Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 3 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 5 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Oloye Adegbenga ni ko ba oju mu ki a ma tufọ fun eeyan lori foonu rara.
Gbogbo eniyan lo mọ pe wakati mẹrinlelogun ṣaaju idibo ni ipolongo lee duro.
Dìde, Baraki, máa kó àwọn tí o kó lógun lọ,ìwọ ọmọ Abinoamu!
-O ni ohun yoo sapa bi Naijiria yoo ti ṣe ma ta igbo lọ si ilẹ okere lati le mu ọrọ aje Naijiria gboro si.
Ilé aṣòfin Amẹ́ríkà yarí Ìwádìí BBC rèé lórí ìjà APC tó fẹ́ gbẹ̀mí Sẹ́nátọ̀ l‘Osun Ìlú tuntun tó kún fún ohun àdáyébá láìsí ọkọ̀ tàbí òpópónà ń bọ̀ ní Saudi Arabia Mo ti gba ọmọ Igbo tó ń wá bàbá rẹ̀ bí ọmọ, kó má ba à pa ara rẹ̀ - Iba Oluyole Lẹ́yìn ọgọ́rùn ún ọjọ́ tí wọn ti Lekki Toll Gate pa, ẹ wo owó gọbọi tíjọba Eko ń pàdánù Ẹ́ ràgà bo ìṣọ̀kan Nàíjíríà, ìyàpà le mú ìṣẹ́ àwọn akọni wa já sásán - Osinbajo Ó ní wọ́n sàlàyé pé àwáwí tí wọ́n ń sọ ni pé, kò si ọgá kankan nitòsí láti mójú tó ọ̀rọ̀ náà.
Mourinho padà sí Manchester United lónìí!
Ẹ o maa gbọ ile akede Niajiria lati ikanni 31m 9690khz ni deede aago  mọ̀kànlá  aabọ owurọ titi di aago mọ̀kànlá  koja iseju   márùndínláàdọ́ta (11:30am-11:45am) ati ni irole ni deede  aago  màrún  koja iseju màrúndínlógún titi di aago  màrún  aabo(5:15pm-5:30pm)Ademola Adepoju.
Jẹtiro, alufaa àwọn ará Midiani, baba iyawo Mose, gbọ́ gbogbo ohun tí Ọlọrun ti ṣe fún Mose ati fún Israẹli, àwọn eniyan rẹ̀, ati bí ó ti mú wọn jáde kúrò ní ilẹ̀ Ijipti.
“Nítorí ta ni ninu yín tí yóo fẹ́ kọ́ ilé ńlá kan, tí kò ní kọ́kọ́ jókòó kí ó ṣírò iye tí yóo ná òun, kí ó mọ̀ bí òun bá ní ohun tí òun yóo fi parí rẹ̀?
Awọn iroyin ti ẹ lee nifẹẹ si: Sé kí Nàíjíríà máa lo igbó fún ìwòsàn?
púpọ ̀ lára àwọn orílẹ ̀ -èdè tó tí ní ìtẹ ̀ síwájú àti ọ ̀ pọ ̀ lára àwọn orílẹ ̀ -èdè tó ṣì ń tẹ ̀ síwájú a má a fikún ara ètò àjẹsára wọn , nígbà púpọ ̀ , ní ìdàpọ ̀ pẹ ̀ lú àjẹsára àrùn ìta ( measles ) àti ti rubella ( àrùn ìta ti jamini ) tí a mọ ̀ sí mmr .
Mo ni itara fun ipenija tuntun yi.
yii leyin ipade bonkẹlẹ ti o  se pelu  aare Muhammadun Buhari nile aare to wa niluu
 Gomina naa ni: “A gbagbọ pe, pẹlu aduro ero ti ani ni ipinlẹ Eko ati irufẹ ọja ti o kun ibẹ o di dandan ki irin ajo afẹ ta bẹrẹ lati papakọ ofurufu lọ si awọn afara ti a ni de Eko Atlantic City tuntun.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Claudiah: ìrẹ̀wẹ̀sì ọkàn bá mi fínra fún ọpọlọpọ ọdún Egypt: Gẹgẹ bi orilẹ-ede Morocco, orilẹede Egypt ko faye gba ki ọkunrin ati obinrin maa fara kan ara lawujọ.
Awọn ọlọpaa to kede ijinigbe naa ni Mohammed Dewji n lọ fún ifaralokun to ma n se laarọ ní àwọn ajinigbe ṣadede gbé sálọ.
Ìdí nìyí tí kò jẹ́ kí wọ́n ta ilẹ̀ wọn.
Nigba to pada de, mo ni ko lọ ya ara rẹ sọtọ fun ọjọ mẹwaa tabi sẹ meji""."
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Aremu: Eré ìtàn nípa ìbí, àti jéèyàn pẹ̀lú ìpèníjà Olusegun Aremu Obasanjo Olajide ni oun ko i tii ri ẹni to fẹran orilẹede Naijiria gẹgẹ bi ọkan soso to Baba Obasanjọ nitori wọn ja fitafita lati ri wi pe orilẹede Naijiria wa papọ lai si ipinya.
Oríṣun àwòrán, Reuters Àkọlé àwòrán, Egbẹgbẹrun lo lọ ibi iwode naa fun Abiy Minisita fun Eto Ilera ni Ethiopia sọ pe eniya bii mẹrinlelogoji ni o wa ni ile iwosan bayi ti eniyan marun si wa ni ẹsẹ-kan-aye-ẹsẹ-kan-orun.
ijoba yooku niyanju lati mu ise won lokun-kundun ki awon naa le gba igbega
Àkọlé àwòrán, Ni Osu Kẹsan an, Ile-ẹjo to gaju ni orilẹ-ede India da ẹjọ to nii se pẹlu ki wọn iyinbọn pa ẹkun naa nu, eleyii to faaye gba ki wọn bẹrẹ si ni wa ẹkun naa pada.
Ó ní, “Nítòótọ́, ọ̀rọ̀ ìbáwí tí OLUWA pàṣẹ pé kí ó sọ sí pẹpẹ Bẹtẹli, ati gbogbo pẹpẹ ìrúbọ tí ó wà káàkiri ní àwọn ìlú Samaria yóo ṣẹ.
Ohun tí ó ṣe ẹni tí ń yá ni lówóni yóo ṣe ẹni tí à ń yá lówó.
Bakan naa ni awọn miran rọ ajọ EFCC lati ri i wi pe awọn ṣe iwadii finifini lori awọn ti wọn mu, ki wọn ma baa fi iya jẹ alaiṣẹ.
ogbon egberun naira ekunwo to je pe awon osise ti ipo won kere nikan ni yoo
Wo ohun tó yẹ kí o mọ̀ nípa akínkanjú obìnrin alága àjọ elétò ìdìbò Ghana 2020 Buhari, pàṣẹ f'àwọn Gómìnà pé kí wọ́n jáwọ́ nínú èróǹgbà láti ná N17trillion owó ìfẹ̀yìntì òṣìṣẹ́ Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Ọmọ náà bẹ̀rẹ̀ sí dàgbà, OLUWA sì bukun un.
"Manga ni ""wọn rọ ara wọn wa ni pẹlu nkan ija ti wọn si kọlu awọn ẹṣọ to wa lẹnu iṣẹ"" Ṣugbọn o salaye pe gbogbo nkan ti pada sipo t'awọn si ti fikun agbara awọn to n pese aabo lawọn ọgba ẹwọn jakejado Naijiria."
Ìbéèrè Nípa Àṣẹ Tí Jesu Ń Lò.
Agiripa bá bi Paulu pé, “Kíákíá báyìí ni o rò pé o lè sọ mí di Kristẹni?
kíni wọn yóò máa ṣe ní ìpínlẹ̀ - DAWN Commission Lẹyin idije yii ni oun ati ọrẹ rẹ Caroline Wozniacki ajọ dije ẹlẹni meji nibi ti wọn ti le jawe olubori ninu idije Auckland Tennis Center.
Mo kìlọ̀ fún yín pé, èmi ni OLUWA Ọlọrun yín, ati pé ẹ kò gbọdọ̀ bọ oriṣa àwọn ará Amori tí ẹ̀ ń gbé ilẹ̀ wọn, ṣugbọn ẹ kò gbọ́ tèmi.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Kí ló mú olùdìbò ní India ge ìka rẹ̀ lẹ́yìn tó ṣèṣì dìbò fún ẹgbẹ́ mìíràn?
”Laipe yii ni ijoba se iwadii lori eto agbe, eto irinna ati ile-ise gaasi ati inamona-mona.
O ti tun bori ninu ididbo apapọ araalu to ti ni ibo to le ni ọgọrin miliọnu si ibo adọrin miliọnu o le diẹ ti Trump ni.
Ijọba ilẹ Gẹẹsi ni 'ko si ami kan gboogi' to fihan pe awọn obirin to ba loyun lee fara kaasa arun coronavirus ju awọn ti ko loyun lọ.
Ṣugbọn alaye yii ko dabii pe o tẹ awọn ileeṣẹ to n ṣe ọti ẹlẹrindodo ti Motara fi n la ọmọ naa loju lọrun.
"W) ti sọ pé: ""Àwẹ ọjọ rana Arafat máa ń pa àwọn ẹṣẹ ọdún tó kọja àti ti ọdún tó ń bọ."
Angẹli náà bá sọ fún àwọn tí wọ́n dúró tì í pé, “Ẹ bọ́ aṣọ tí ó dọ̀tí yìí kúrò lọ́rùn rẹ̀.
 awon atunse okowo to waye ti fun ni idamo tuntun kariaye .
McWen Bridge (Bonny camp) Ijọba ibilẹ Ikeja Eti-Osa.
Bí ó tilẹ̀ gbé ẹgbaa (2,000) ọdún láyé kí ó tó kú, tí kò sì gbádùn ohun rere kankan, ibìkan náà ni gbogbo wọn ń pada lọ.
Gẹgẹ bi Minisita fun eto iṣẹ ọgbin, itọju ẹranko ati ọsin ẹja, Vincent Ssempijja, ṣe sọ, awọn orilẹede to n pese ounjẹ fun ẹja nilẹ Yuroopu gbọdọ fi ẹri ibi ti ounjẹ naa ti wa han.
Nibẹ lo tun ti gba imọ kun imọ nipa iṣiro owo, to si ni iwe ẹri imọ ijinlẹ keji, taa mọ si Masters.
Lórí ilẹ̀ náà ni àwọn ìlú wọnyi wà: Jesireeli, Kesuloti, Ṣunemu; 
Dagrin: Òní ló pé ọdún mẹ́sán án ti Dagrin dágbére fún ayé
Oríṣun àwòrán, Seyi makinde/twitter Bakan naa lo tun ṣalaye pe ileeẹ eto idajọ ni ipinlẹ Ọyọ ti fa gbogbo iwe ifisun ti wọn fi kan awọn oluwọde #EndSARS ni ipinlẹ naa ya, bẹẹni wọn si ti tu gbogbo awọn ti wọn fi si atimọle silẹ.
Ethiopian Airlines crash: Èèyàn 157 dèrò ọ̀run nínú bàálú tó já
 fún àpẹẹrẹ , olè kan jé ̣ òṣèré , olùkópa tí ó bá kópa níhìnìn tàbí òhún láti mú àpíyadà wá .
N óo yí ọ pada, n óo lé ọ siwaju, n óo mú ọ wá láti òpin ìhà àríwá, o óo wá dojú kọ àwọn òkè Israẹli.
Lẹ́yìn tí wọ́n ti jẹ, tí wọ́n sì ti mu, wọ́n pada sọ́dọ̀ oluwa wọn.
Ẹkọ Bibeli  ti igbakeji aare ka ni iwe Genesis 1:1-4,pe“Olorun da ọrun ati aye,aye si wa ni
Nígbà tí wọ́n wọ Bẹtilẹhẹmu, gbogbo ìlú mì tìtì nítorí wọn.
N óo máa yọ̀ ninu OLUWA, ọkàn mi yóo kún fún ayọ̀ sí Ọlọrun mi.
Lootọ ọpọ le sọ pe ẹsẹ wọn ti wa ni ita ṣaaju ibọsipo Adams Oshiomole gẹgẹ bii alaga ẹgbẹ oṣelu APC.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Claudiah: ìrẹ̀wẹ̀sì ọkàn bá mi fínra fún ọpọlọpọ ọdún Lọwọlọwọ ni Naijiria, awọn aṣoju jẹ mọkandinlaadọfa nile igbimọ aṣofin agba nilu Abuja lati ipinlẹ mẹrindinlogoji ati FCT.
láti gé oríṣìíríṣìí òkúta iyebíye ati láti tò wọ́n, bẹ́ẹ̀ náà ni igi gbígbẹ́ ati oríṣìíríṣìí iṣẹ́ ọnà ṣíṣe.
tíọ ́ rì soṣiọ ́ lọ ́ jì tó tẹ ̀ lé ìlànà àti èrò karl marx kì i ṣe tíọ ́ rì oni , ó ti pẹ ́ ti ó tí dáyé .
Olórí ẹ̀yà Bẹnjamini sì ni Abidani ọmọ Gideoni.
Ìbẹ̀rẹ̀ ni n ko ti tètè kó ara mi ní ìjánu ṣe ni mo bẹ̀rẹ̀ ní ibi kékeré ṣùgbọ́n díẹdíẹ ni ìwá búrúkú mi ń bi si i tó bbẹ́ẹ̀ tí ó jẹ́ pé, lónìí yìí, tí ó ti tó ẹgbẹẹgbẹ̀rún ọdún sẹ́yìn tí mo ti ń hùwà ibi wọ̀nyí, ó ti di àṣà mi gan-an ó ti di oúnjẹ fún mi, èmi pàápàá mọ̀ pé ìwà tí mò ń hù kò lè ṣe mi ní ànfàání, ṣùgbọ́n àti fi ìwà wọ̀nyí sílẹ̀ kò ṣe e ṣe.
Soyinka tun da awọn ẹgbẹ mii silẹ to ni ṣe pẹlu ere Tiata, Aṣa ati iṣe Yoruba.
Ife ẹ̀yẹ keji ti ẹgbẹ agbabọọlu Arsenal yoo gba ree labẹ akọnimọọgba tuntun, Mikel Arteta lẹyin ti wọn ti kọkọ gba ife ẹyẹ FA CUP.
"Mo ti dàgbà sì nínú ọgbọ́n, òye àti ìrírí, mo sì ti di obìnrin tó ní òye sii""."
Ọ̀fọ̀ ṣẹ̀ Donald Trump, àbúrò rẹ̀ Robert, dèrò ọrun Ibùdó ìyàsọ́tọ̀ ni mo wà, ló fi pẹ́ kí ń tó sọ̀rọ̀ lórí tírélà tó já l‘Eko - Omotola Jalade Ekeinde Bo tilẹ jẹ pe ero ko fi bẹẹ pọ nibi ayẹyẹ naa bi ti ọdun to kọja, iye awọn eeyan to yọju sibi ọdun ọhun kan n ṣajọyọ ni, lai bikita nipa ajakalẹ arun to wa lode.
A kó dúnkoòkò mọ́ Ambode, isẹ́ wa là ń ṣe - Ilé Aṣòfin Eko Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, U.
 wọn ń sọ èdè yí náà ni benue congo .
Ẹ kò gbọdọ̀ jẹ ẹran ara wọn, bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò gbọdọ̀ fara kan òkú wọn.
Ní ọjọ́ keji tí wọ́n gbéra ní Jọpa ni wọ́n dé Kesaria.
 Kenyatta de si Addis Ababa ni  Ẹti  lọjọ
Simoni ati àwọn tí ó wà pẹlu rẹ̀ bá ń wá a kiri.
Ogbeni Okechukwu ati awon akegbe re yooku, Charlie Chime ati Maureen Anosike gbegba oroke lai figagbaga pelu oludije kankan lasiko eto idibo igbimo ohun ti o waye lagbegbe ijoba ibile Udi ti ko jina si ipinle Enugu.
Rere ni obinrin náà máa ń ṣe fún unkò ní ṣe é níbi, ní gbogbo ọjọ́ ayé rẹ̀.
Nítorí ibinu eniyan kì í yọrí sí ire tí Ọlọrun fẹ́.
Awọn ere idaraya yii ni wọn kopa ninu rẹ lati mu inu ara wọn dun si ki wọn mọ pe ko si nkan ti awọn naa ko le ṣe lọna ara ọtọ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Nkurunziza subu lori papa l'alamojuto meji ba rẹwọn he 4 Ẹrẹ̀nà 2018 Aarẹ Pierre Nkurunziza ni ẹgbẹ agbabọọlu ati ẹgbẹ akọrin to jẹ tirẹ Oríṣun àwòrán, AFP Àkọlé àwòrán, Aarẹ Pierre Nkurunziza ni ẹgbẹ agbabọọlu ati ẹgbẹ akọrin to jẹ tirẹ Awọn alamojuto ere bọọlu meji ni wọn ti r'ẹwọn he lorilẹede Burundi lori ẹsun pe wọn se aarẹ nisekuse lori papa lasiko ti idije n lọ lọwọ.
“Nítorí náà, àkókò ń bọ̀,tí n óo jẹ́ kí wọn da Moabu nù, bí ẹni da ọtí nù.
to n gbe ni orilẹ-ede South Africa O ni:“Lati bi ọdun merin, marun-un ṣẹyin ni a ti n gbọ
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ijinigbe: BBC ṣe ìwádìí bí ikọ̀ IRT ṣe ń gbéjà ko awọn ajinigbe lójú Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Aarẹ Buhari parowa yìí nigba to n ṣe ìpàdé pẹlú awọn alenuloro ni ìpínlè náà lọjo ìṣẹgun.
 Ahmed Musa lo gba ami ayo meji ohun wole ni ipele keji ere ifese-wonse naa.
Àwọn eniyan ibẹ̀ yóo ṣọ̀fọ̀ rẹ̀, àwọn babalóòṣà rẹ̀ yóo pohùnréré ẹkún lé e lórí, nítorí ògo rẹ̀ tí ó ti fò lọ.
Lẹ́yìn náà, kó gbogbo àwọn eniyan náà jọ sí ẹnu ọ̀nà Àgọ́ Àjọ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ilé Aṣòfin: Buhari ni yoo dahun fun awọn to yan sipo 5 Òkùdu 2018 Oríṣun àwòrán, @NG_Police Àkọlé àwòrán, Idris kọ̀ láti yọjú sí ilé aṣòfin l'Abuja lórí ètò ààbò Lẹyin ìpàdé ijiroro alátìlẹ̀kùn mọ́rí se oní wakati mẹta, ile aṣofin àpapọ̀ l'Abuja ti fẹnu ko pe, awọn ko ni igbẹkẹle mọ́ ninu Ọga Ọlọpaa lorilẹede Naijiria, Ibrahim Idris.
Nítorí èyí, Ọlọrun rán agbára ìtànjẹ sí wọn, kí wọ́n lè gba èké gbọ́, 
Ó ṣàlàyé pé, ẹgbẹ́ náà tan ẹgbẹgbẹ̀rún àwọn ọ̀dọ́ wọ inú rẹ̀, nígbà tó sì mú àwọn kan ní dandan lẹ́yìn tí wọ́n jí wọn gbé, tí wọ́n sì ń fi ikú dẹ́rù bà wọ́n tí wọ́n bá gbìyànjú àti jáde.
"Oríṣun àwòrán, @BleacherReport A kò mọ ẹni tó pa ọlọ́pàá Ondo àti ìyàwó rẹ̀, òun kọ́ ló pa ara rẹ̀- ọlọ́pàá Nàìjíríà bèèrè ìrànwó lọ́wọ́ àjọ àgbáyé láti kápá Coronavirus ""Owó oṣù òṣìṣẹ́ yóò di gbèsè, oúnjẹ yóò wọ́n, ìlú yóò le, bí ọrọ̀ ajé Náíjíríà bá dagun"" Ẹ́ gbaradì, to bá lo jẹnẹrátọ̀ àbí tà á, ò ń fi ẹ̀wọ̀n ọdún mẹ́wàá ṣeré - Sẹ́nétọ̀ ń dábàá Ọkan lara awọn adari ikọ Arsenal, Vinai Venkatesham sọ fun awọn akọroyin pe ilera awọn oṣiṣẹ ẹgbẹ agbabọọlu naa ati awọn ololufẹ wọn lo jẹ ikọ naa logun."
Lowurọ kutu ọjọ Iṣegun to ṣe rẹgi pẹlu ayajọ ominira Naijiria ni wọn gunlẹ si papakọ ofurufu ipinlẹ Eko.
Seyi Makinde: Gbogbo iṣẹ́ àgbàṣe tí Ajimọbi ṣe lẹ́yìn ìbò ní màá gbéyẹ̀wò
Lọjọ kọkanla, ọṣu kinni ti wọn gun-un pa, awọn oniṣegun Ilẹ Gẹẹsi ja fitafita lati doola ẹmi rẹ ṣugbọn pabo lo jasi.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Kogi vs Bayelsa: Primate Ayodele sọ àsọtẹ́lẹ̀ Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Awọn iroyin kan ti a ko le e fidirẹmulẹ ti ẹ sọ pe awọn ọmọbinrin naa ni wọn fi maa n dẹ ọkunrin ti wọn ba fẹ ẹ kọlu.
Ninu atẹjade kan ti ajọ NNPC fi sita lọjọ Aiku ni wọn ti kede rẹ pe Ọmọwe Ibe Kachickwu lo yan Kyari si ipo tuntun yii.
Yemi Alade fi ọrọ sita loju opo Twiiter lati tọrọ aforijin.
Laarin asiko ti a n sọrọ rẹ yii naa, ọkọ ọlọpaa bii marundinlogun ni awọn eeyan kan ti bajẹ, pẹlu ileeṣẹ ọẹọpaa meji ni Katsina ati Abia ni awọn eeyan kan ti dana sun.
Bí OLUWA bá ń sàmì ẹ̀ṣẹ̀,ta ló lè yege?
Báwo ni yóo ti burú tó fún àwọn ẹni ibi, tí wọ́n pa aláìṣẹ̀ sórí ibùsùn ninu ilé rẹ̀?
''Inu mi dun pe mo lọ si Manchester United.
Makinde ré àwọn alága káńsù lẹ́fásẹ̀ nílé ẹjọ́ kòtẹ́milọ́rún n'Ibadan Oríṣun àwòrán, twitter/Seyi makinde Ile ẹjọ kotẹmilọrun ni ilu Ibadan ti gbe idajọ kalẹ pe ko sohun to buru ninu igbesẹ Gomina Seyi Makinde lati tu awọn ijọba ibilẹ ka ni ipinlẹ Ọyọ.
Fọnran aworan kan fi ọ̀kan nínú àwọn obinrin náà, Clary to jẹ ọmọ ọdun mọ́kànlélógún hàn, bó ṣe ń sunkún lásiko tó ń satilẹyin fun olokiki akọrin náà.
Àkọlé àwòrán, Ibo abẹlẹ APC ti bẹrẹ ni Kano Bayii ibudo idibo bii Hotoro North, Unguwa Uku Cikin Gari àti Gyadi Gyadi ti n mu esi idibo wọn wa si Kano.
July 25, 2014 Ìròyìn sọ pé ọmọlẹhin El-Zakzaky márùndínlógójì ni àwọn ológun yìnbọn pa lásìkò ìwọde kan ní ìlú Zaria, Kaduna.
Gẹ́gẹ́ bí àṣà àwọn Èdìdàrẹ́, ọmọdé ló ni ayé, àwọn àgbàlagbà kò jámọ́ nǹkan kan.
Eyi ko ṣẹyin ipade to waye laarin Minisita fun eto Ẹkọ,Malam Adamu Adamu ati awọn kọmisọnna fun eto Ẹko ni ilu Abuja.
 gege bi enikan to se pataki larin awon onimo-ogbon , godel ni ipa to se koko lori ironu sayensi ati imo-oye ni orundun 20 , asiko ti opolopo eniyan bi bertrand russell , a.
Kò tó bẹ́ẹ̀, kí ó ri i
Ọrẹ tirẹ̀ ni: àwo fadaka kan, tí ìwọ̀n rẹ̀ jẹ́ aadoje (130) ṣekeli, pẹlu abọ́ fadaka kan tí ìwọ̀n rẹ̀ jẹ́ aadọrin ṣekeli.
"Ìjọba ìpínlẹ̀ Osun tí búwọlù ìlànà àyẹyẹ Ọṣun-Oṣogboo ọdún 2020 ""Mi ò ní wọ Uber mọ́ tí wọ́n bá leè fi owó lée nítorí àfikún owó orí tí Sanwo Olu ṣe"" Ilé ayé mi ti d'ojú bolẹ̀ pẹ̀lú ikú àfẹ́sọ́nà mi- àfẹ́sọ́nà Immaculate Okochu Báwo ni wọ́n ṣe ń lo òfin Sharia?"
Bakna naa ni awọn ọkunrin naa n yinbọn ti wọn sin da epo sawọn eniyan lara ti wọn n sun wọn nina.
Àkọlé àwòrán, Ogun 2019: APC fà Dapọ Abiọdun silẹ loludije ipò Gómìnà ajumọyan ‘Aawọ abẹnu lee koba APC ni 2019’ Ọmọ ẹgbẹ́ òsèlú APC tako Oshiomole Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, APC Primaries: A ṣi n lọ sílé ẹjọ́ lóṣù tó m bọ̀ lórí ọ̀rọ̀ yìí Akinlade to jẹ́ ọmọ ilé ìgbàmọ aṣofin l'Abuja ní wọn ti fà kalẹ̀ tẹ́lẹ̀, sùgbọn lẹ́yìn ti àwọn ọmọ ìgbìmọ̀ amúṣẹ́ṣe tí Adams Oshiomhole ń dari dé láti wá tun ìbò dí làwọn ọmọ ẹgbẹ́ APC ipínlẹ̀ Ogun bẹ̀rẹ̀ sí ni ké gbàjarè pé ilé ẹgbẹ́ àpaps frẹ́ yàn lé àwọn lọ́wọ́.
Òtítọ́ ni o sọ pé, ‘Ọlọrun kan ni ó wà.
Eyi si mu ki gbogbo awọn to tẹle e wa sibẹ o ma a fẹ ẹ l'oju, fẹ ẹ nimu, rọ omi si i l'ori.
Ojú alágbe ni wọ́n fi ń wo alága ìdúró- Ayo Oladokun Ìpanu ‘Cheese ball’ ni wọ́n fi jí Ikimot gbé, àmọ́ ó padà sílé lẹ́yìn ọdún márùn-ún ìfipábánilòpọ̀: Má dákẹ́ - Oluwaseun Wọn ni akoko ti to ki Naijiria ni ipese ina ọba ti ko sẹju, omi ẹrọ to se mu, oju popo to ja gaaraga ati bẹẹ bẹẹ lọ.
2m ọmọdé kò ṣe lọ sílé ẹ̀kọ́ - SERAP ké tọ iléẹjọ́ àgbáyé Gẹgẹ bi iroyin ti a gbọ ṣe sọ ọ, ọpọlọpọ lo ti fara pa yanayana ti ẹmi si ti lọ si i ṣugbọn awọn Ọlọpaa ko tii le sọ aridaju eyi.
Kọmiṣọnna iṣẹ akanṣe Arabinrin Funke oyedun Juliana ni kọmiṣọnna tuntnun fun ile iṣẹ ijọba to n ṣakoso akansẹ iṣẹ.
orile ede Naijiria nigbagbọ ninu awon adari wọn fun eto idajọ ti ko ni oju
Bishop Wale Oke: Ìjọba kò gbọ̀dọ̀ gbè lẹ́yìn ẹ̀sìn kan
omi ni Ipinle Oyo, Gabriel Oguntola ti tọrọ fun ifowosowopo gbogbo iyaloja,
Bẹ́ẹ̀ ni wọ́n ṣe ìdájọ́ Joaṣi ọba.
O jọ pe ọrọ ti a fi sita ni ko ye wọn nitori a ni a da wọn lna nii kii ṣe wi pe a tiu ri wọn mu.
Ẹgbẹ Boko Haram jẹ ọkan lara awọn agbesumọmi to n doju ija kọ awọn ọmọ ogun Naijria.
Nibayii, ẹgbẹ JOHESU ni awọn ọmọ ẹgbẹ yoo ṣe ipade lati ri wi pe awọn wa wọrọkọ fi sada lori igbesẹ ijọba yii, eleyii ti ko dun mọ wọn ninu.
 Mustapha Suleiman akowe agba , to tun soju fun oludari ile ise  to n sakoso gbogbo ile-ise ati ajo ti ijoba apapo tanna imole si ilana to ro mo ijiya to wa labe ofin awon osise ijoba,  fun eni to ba tapa si ofin naa.
Gege bi akoroyin egbe ajafeto-omoniyan lorile-ede Syria,”Awon omo-ogun ijoba Syria ati apapo awon omo ogun miran ti gba ile lowo awon omo-ogun olote, ninu ikolu ti o waye ni arin gungun ila oorun ilu Ghouta, ti o sun mo Damascus.
Ibukun Ọlọrun sì wà lórí ọmọ inú rẹ.
Wọn óo fọ́n wọn dà sílẹ̀ ninu oòrùn, ati lábẹ́ òṣùpá ati àwọn ìràwọ̀ tí wọ́n ní ìfẹ́ sí, tí wọ́n sì sìn; àwọn ohun tí wọn ń wá kiri, tí wọn ń ṣe ìwádìí lọ́dọ̀ wọn, tí wọ́n sì ń bọ.
Níwọ̀n ìgbà tí OLUWA wà láàyè, OLUWA yóo pa á; tabi kí ọjọ́ ikú rẹ̀ pé, tabi kí ó kú lójú ogun.
22 Ìgbé 2020 Oríṣun àwòrán, Twitter/Ministry of Humanitarian Affairs Ajọ iṣọkan agbaye ti ke gbajare sita pe bi ọrọ ṣe n lọ yii ajakalẹ iyan yoo waye lagbaye nipasẹ ọwọja arun Coronavirus.
Ọpọ awọn ololufẹ rẹ lori ikan Instagram lo ti n fi erongba wọn lede lori ọrọ naa.
Enọku bí ọmọkunrin kan, ó sọ ọ́ ní Iradi.
Nítorí Coronavirus, àjọ Olympics lágbayé kéde ọjọ́ tuntun fún ìdíje Tokyo 2020 Idije ere idaraya Tokyo Olympic games yoo bẹrẹ ni ọjọ kẹtalelogun oṣu keje ọdun 2021 bayii yoo si pari ni ọjs kẹjọ oṣu kẹjọ ọdun kan naa.
“Nítorí náà, ẹ bẹ̀rù OLUWA, kí ẹ sì máa sìn ín tọkàntọkàn pẹlu òtítọ́ inú.
Ó sàn fún ọ pé kí ọ̀kan ninu àwọn ẹ̀yà ara rẹ kí ó ṣègbé jù pé kí á sọ gbogbo ara rẹ sí ọ̀run àpáàdì lọ.
Ìbàlòpọ̀ pẹ̀lú ọ̀rẹ́kùnrin kìí ṣe ìfẹ́, bẹ́ẹ̀ ni ìfẹ́ kọ́ ni ìbálòpọ̀ - Genevieve Nnaji Agbaọjẹ oṣere tiata, Genevieve Nnaji sọ erongba rẹ lori ọrọ ibalopọ larin awọn ọdọ.
Mose wí fún wọn pé, “Àṣẹ tí OLUWA pa nìyí: ‘Ẹ fi ìwọ̀n omeri kan pamọ́ láti ìrandíran yín, kí àwọn ọmọ yín lè rí irú oúnjẹ tí mo fi bọ́ yín ninu aṣálẹ̀ nígbà tí mo ko yín jáde láti ilẹ̀ Ijipti wá.
Ife wúrà ni Babiloni jẹ́ lọ́wọ́ OLUWA, ó ń pa gbogbo ayé bí ọtí;àwọn orílẹ̀-èdè mu ninu ọtí rẹ̀,wọ́n sì ń ta gbọ̀n-ọ́n-gbọ̀n-ọ́n.
Juda ati Sila, tí wọ́n jẹ́ wolii fúnra wọn, tún fi ọpọlọpọ ọ̀rọ̀ gba ẹgbẹ́ onigbagbọ náà níyànjú, wọ́n tún mú wọn lọ́kàn le.
O ni aifimọsọkan ni ọta to wa lorilẹede Naijiria, o si rọ awọn adari ijọba Naijiria pe ki wọn gbọ ohun tawọn eeayan n wi.
Mà á fún àwọn ọba alayé ní ojúṣe nínú ìjọba mi - Seyi Makinde Lẹ́yìn ọlọ́pàá, VIO nìkan ló láṣẹ láti dá ọkọ dúró láìṣẹ̀ - Ọ̀gá VIO Eko Àwọn àṣà àti ìse tó yọ obìnrin sílẹ̀ nílẹ̀ Yorùbá Aisha Buhari sàtìlẹyìn fáwọn ọ̀dọ́ tó fọnmú lórí ìyànsípò àwọn alátakò sínú ìjọba APC Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
A jẹ́ pé nígbà tí ó ṣèṣì jábọ́ lọ́wọ́ mi níjọ́kan, tí ó sì balẹ̀ sórí àwọn òkúta, iwájú rẹ̀ tí í ṣe dígí kàn fọ́ ni.
Ìran ẹni tí ó ń gbọ́ ọ̀rọ̀ Ọlọrun,tí ó ní ìmọ̀ ẹni tí ó ga jùlọ,tí ó sì ń rí ìran láti ọ̀dọ̀ Olodumare.
Ẹ má jẹ́ kí ẹ̀rù àwọn alátakò bà yín rárá ninu ohunkohun.
Gọngọ sọ, ẹlẹ́há pàdé àwọn tó lùú ní jìbìtì nílùú Eko lọ́jà Ibadan Ǹjẹ́ ẹ mọ ohun tí igbákejì ààrẹ Yemi Osinbajo sọ nílé bàbá Fasoranti Kí ló mú àwọn adarí Nàìjíríà tako ra wọn lórí ikú ọmọ alága ẹgbẹ́ Afenifere?
O di dandan ki awọn ọmọ ile igbimọ kọkọ ṣi jokoo ni ọjọ Iṣẹgun to m bọ ki wọn to bẹrẹ isinmi ti ẹnu ba kò.
Ó dìgbà o baba Oríṣun àwòrán, @Ladapo Àjànàkú sùn bí òkè, erin wó kò le dìde.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Seyi Makinde gbàlejò Abdulsalami Abubakar ní Ibadan 11 Agẹmo 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 12 Agẹmo 2019 Oríṣun àwòrán, Oyo state Gomina ipinlẹ Ọyọ, Seyi Makinde ti se apejuwe adari orilẹede Naijiria nigba kan ri, Abdusalami Abubakar gẹgẹ bi baba to ni ifẹ si ilosiwaju orilẹẹde Naijiria.
Akowe agba ajo isokan agbaye, ogbeni Antonia Guterres so pe oun nireti pe ibasepo tuntun naa yoo mu iyipada otun de ba orile-ede mejeeji ati ile Afrika.
Shiite kọ̀wé pe àwọn pásítọ̀ láti darapọ̀ mọ́ ìwọ́de wọn Ó yẹ kí àwọn asòfin yọ Buhari - Shiite N3.
Èèyàn 38,344 ló ti ní COVID-19 ní Nàìjíríà lẹ́yìn tí 543 kún un lọ́jọ̀rú Àwọn alágbára ni mo bá díje ṣùgbọ́n mo ti gbà f'Olọrun- Agboola Ajayi Bàbá mi Aláàfin, ẹ ṣeun ẹ̀bùn owó tí ẹ fún èmí àti ọkọ mi- Lizzy Anjọrin Wo àwọn Gómìnà Naijiria tí àrùn Covid-19 ti bá fínra Ṣé lóòtọ́ ni pé Hushpuppi ti kúrò ní ọgbà ẹ̀wọ̀n l'America?
N-Power Agro: ₦25,000 - si ₦30,000 loṣu.
Wo àwọn ìbejì tó mú ẹ̀dọ̀ àti egungun àyà kan ṣoṣo wá látọ̀run Wo àwọn orílẹ́-èdè mẹ́wàá tí kò ní coronavirus lágbàáyé, bá wo ni wọ́n ṣe ṣe é?
Igba akọkọ si ree ti osere tiata naa yoo sisọ loju ololufẹ rẹ ọhun, Michael, ti gbogbo eeyan ms si Razor Ray, ti oun naa jẹ osere tiata to fi orilẹede Amẹrika se ibujoko.
Òhun tó ṣe kókó tó yẹ ko mọ̀ nípa Davido àti Chioma Bẹrẹ lati agbo oṣelu, sagbo faaji, Naijiria si Cameroon, Ghana, ati gbogbo agbaye.
Àwọn eniyan náà fi òtítọ́ inú ṣe iṣẹ́ náà.
Coronavirus dòjú ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ PSG àti Strasbourg bolẹ̀ Bojú bojú o.
Nipinlẹ Kano nikan ni Buhari ti ni o lé diẹ ni ọ̀rùn-dín-ni-miliọnu-mẹta ibo pe kó tésiwaju lẹẹkeji.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Wo oríṣìí àrùn márùn ún tí ìgbéyàwó láàrin ìbátan si ìbátan máa ń fà Iléeṣẹ́ epo rọ̀bì ná ₦116m lórí báírò, ìwé ìkọ̀wé, àwọn aṣòfin fìka hánu Àádọ́ta Náírà tí báńkì ń yọ nínú owó ìpamọ́ oníbàárà kò tọ̀nà - Iléejọ́ Agbébọn tún gbẹ̀mí àgbẹ̀ míì lọ́nà oko lágbègbè Ibarapa Adeboye sọ itan kan fun awọn eeyan to wa nibi ipade adura naa pe, ni ọpọ ọdun ṣeyin, oun nilo ẹgbẹrun marun un naira pere lẹyin ti oun pe ọpọ ero sibi ipade adura pẹlu ileri pe oun yoo gbọ bukata jijẹ ati mimu wọn.
Igba to wa ni Chelsea, o gba ife ẹyẹ mọkanla ọtọtọ laarin ọdun mẹtala to lo ni ẹgbẹ akọnimọọgba naa.
Ọpọ awọn ti n fi ẹhonu han yii lojẹ ọdọ, ọmọ ile iwe ti o si ni atilẹyin awọn eekan ilu ninu.
 O ni pe ilana naa ko ni faaye gba ọna aitọ, yoo da lori otitọ ati iwa rere.
'Kòkòrò covid-19 kékeré gbé mọ́ṣálááṣí tìpa, há àwọn èèyàn mọ́lé' Coronavirus ti di ara wa, kò le è kúrò mọ láéláé - WHO A kò tíì lè sọ ti ìfipabánilòpọ̀ àmọ́ òkúta ni wọ́n fi fọ́ orí Azeezat - Ọlọ́pàá Oyo #JusticeforTina: Àwọn obi Tina Ezekwe ń bèrè fún ìdájọ́ òdodo pẹ̀lú omijé lójú Nàìjíríà kò ní olórí, ẹ pín sí ẹlẹ́kùnjẹkùn - Soyinka Ìdí rèé tí ilẹ̀ Afirika fi gbọdọ̀ kópa nínú dídán abẹ́rẹ́ coronavirus wò Afipábánilòpọ̀ méjì tún ṣọṣẹ́ lára ọmọ ọdún 17 l'Ekiti Kọmisọna tọka si wi pe tori ọda ibudo iyaraẹnisọtọ yii wọn nilo lati bẹrẹ itọju alaisan nile laarin ọsẹ kan si meji ti wọn yoo si yọnda ibudo iyaraẹnisọtọ fun awọn ti ailera wọn lagbara gan.
Aare seleri lati tubo sa ipa re fun aabo emi ati dukia awon eniyan orile ede yii.
56k, ni awọn ọmọ Naijiria yoo bẹrẹ si ni lo nibẹrẹ oṣu Kẹsan an, ọdun 2020.
35) owuro, iko omo ogun ko awon omo ogun
"china shipbuilding corporation , keelung , taiwan kọ ́ "" alva maersk "" ni iye ẹsẹ ̀ bàtà ẹgbẹ ̀ rú méjì àti mẹ ́ rìnlélógún , ó sì di ìfilọ ́ lẹ ̀ ní ọdún 1998 ."
wonu idije NWPL naa ti ni adehun to fese mule bayii pelu ilumooka akonimoogba
ibo ẹgbẹrun mejidinlogun-le-ọọdurun ati marun-un (18,305) ti akẹgbẹ rẹ
O wa gba won niyanju lati ri I pe, won n se itoju awon irinse won loore-koore, ki won si maa tele eto ilana ilera ni ayika won.
Àwọn iròyin tì ẹ leè nífẹ̀ síí: Irú Kọ́mú wo lò ń lò?
Joramu ọba ati Ahasaya, ọba Juda sì jáde lọ pàdé Jehu, olukuluku ninu kẹ̀kẹ́ ogun rẹ̀.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Àyà mi kọ́kọ́ máa ń já nígbà ti mo ṣẹ̀ṣẹ̀ bẹ̀rẹ̀ -Alaga iduro ọkùnrin Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àyà mi kọ́kọ́ máa ń já nígbà ti mo ṣẹ̀ṣẹ̀ bẹ̀rẹ̀ -Alaga iduro ọkùnrin 3 Ìgbé 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 5 Ìgbé 2020 Aṣà igbeyawo nilẹ Yoruba ni igbesẹ oriṣiiriṣii to n mu ayọ wọnu igbeyawo.
N ṣe ni Joyce mu bileedi, to si fi la ara a rẹ ni ikun, ko to o gbe ọmọ tuntun naa jade.
Ṣugbọn irun orí rẹ̀ ti bẹ̀rẹ̀ sí kún lẹ́yìn ìgbà tí wọ́n ti fá a.
O ni eto eko ni o jẹ ki oun ni  gbogbo aseyori oun.
Nítorí náà Mose fi ilẹ̀ Gileadi fún àwọn ọmọ Makiri láti inú ẹ̀yà Manase, wọ́n sì ń gbé ibẹ̀.
Orúkọ iyawo rẹ̀ ni Elisabẹti, láti inú ìdílé Aaroni.
Àwọn ọmọ Juda ṣẹgun ìlú Gasa ati àwọn ìlú tí ó wà ní agbègbè rẹ̀.
Eyi tumọ si pe ogún miliọnu Naira ni ẹni kọọkan wọn yoo san.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ijamba baalu Syria: Ẹmi ọmọ Russia mejilelọgbọn sọnu 6 Ẹrẹ̀nà 2018 Oríṣun àwòrán, AFP Àkọlé àwòrán, Ọkọ ofurufu An-26- bii iru eleyi lo jẹ onipele meji fun kiko awọn ọmọogun ati awọn araalu O le ni eniyan bii ọgbọn to padanu ẹmi wọn nigbati baalu akero kan to jẹ ti orilẹede Russia jabọ ni Syria.
pé kí ó sọ fún ìjọ eniyan Israẹli pé “Ẹ jẹ́ mímọ́, nítorí pé, mímọ́ ni èmi OLUWA Ọlọrun yín.
Wọ́n rí irinwo (400) ọdọmọbinrin tí kò tíì mọ ọkunrin lára àwọn tí wọn ń gbé ìlú Jabeṣi Gileadi, wọ́n sì kó wọn wá sí àgọ́ ní Ṣilo, tí ó wà ní ilẹ̀ Kenaani.
ile-ise oko oju irin orile ede China (Chinese Railway Rolling stock
Oríṣun àwòrán, Getty Images Bi wahala yii si se n waye lẹkun ariwa, paapaa lawọn ipinlẹ to wa ni ẹkun aarin gbungbun Naijiria bii Plateau ati Benue, naa lo n waye ni guusu Naijiria.
Àwọn ìran Anakimu yìí kò kù sí ibikíbi ninu ilẹ̀ àwọn ọmọ Israẹli, àfi ní ìlú Gasa, ìlú Gati, ati ìlú Aṣidodu ni àwọn díẹ̀ kù sí.
'Awọn obinrin nilo ajọ iranwọ fun oṣelu' Ohun ìwòsàn pàjáwìrì ti di dandan 'Ìwà ìdòjútì láwọn olólùfẹ́ Chelsea hù' Omoyele Sowore: Èrù ló ń ba àwọn NEDG láti pè mí Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí 2 sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
Alaga igbimọ naa, Ọmọwe Wale Babalakin lo dari ipade ọhun l'Abuja.
Kí ẹ máa wádìí ohun tí yóo wu Oluwa.
“Ṣugbọn ẹnikẹ́ni tí ó bá mọ̀ọ́nmọ̀ ṣẹ̀, kò náání OLUWA, ìbáà ṣe ọmọ Israẹli tabi àjèjì tí ń gbé láàrin wọn, a óo yọ olúwarẹ̀ kúrò láàrin àwọn eniyan rẹ̀; 
Ọlọgbọ́n ènìyàn ni ọkùnrin náà gbogbo wa la si fẹ́ràn rẹ̀ ni ilé wa.
 kékeré ni ojú rẹ sì ti là sí ìyànjẹ tí ìyá rẹ ̀ máa n takò nígbà ayé rẹ ̀ .
Awọn ni olupese ounjẹ, omi ati ohun irinsẹ fun awọn oluwọde, bi awọn kan ṣe parapọ da owo burẹdi ni awọn miran parapọ da owo DJ ti yoo da wọn laraya.
Earlene Peterson, ẹni ọdun mọkanlelọgọrin, ti wọn pa ọmọ rẹ obìnrin, ọmọ-ọmọ rẹ, ati ọkọ ọmọ rẹ, lo tako idajọ iku naa.
Ó ku Ọdún kan kí ó jáde ìwé mẹ́wàá.
Atẹ́gùn ń gbé àwọn ìkúùkù funfun kọjá bí èéfín, mo sì rí òjiji ilé gogoro náà tó fà lé àwọn ìkúùkù ojo náà.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ọ̀ògùn ikọ́ codeine ń pa iran kan run lọ ní Nàíjíríà 2 Èbibi 2018 Àkọlé àwòrán, Oògùn ikọ́ olómi tó ní èròjà codeine ń se àkóbá fún ọ̀pọ̀ ọmọ Nàíjíríà ní ìsọ̀rí ń sọ̀rí Nígbà tí àbúrò Ruona Meyer to jẹ́ ọkùnrin, di ẹni tó kúndùn oògùn ikọ́ olómi tó ní èròjà codeine nínú, ló mú kí Ruona bẹ̀rẹ̀ sí ní se ìwádìí àwọn ọkùnrin tó ń se oògùn ikọ́ olómi yìí ní ìgboro ìlú Èkó.
9 Ṣùgbọ́n bí kò bá tọ́ ìwọ kì yíò ní irú ìmọ̀lára bẹ́ẹ̀, ṣugbọ́n ìwọ yíò ní ìraníyè ti ìrònú èyí tí yíò mú kí o gbàgbé ohun tí ó jẹ́ àìtọ́; nítorínáà, ìwọ kò leè kọ ohun náà tí ó jẹ́ mímọ́ àfi bí a bá fi fún ọ láti ọ̀dọ̀ mi.
O wa ro gbogbo omo orile ede
ise ohun, lati tepa mo ise won si nipase mimu igberu ba eto aabo, paapaa julo
Wolii Sọtitobirẹ n pada si ile ẹjọ lẹyin ti igbẹjọ ti bẹrẹ ti awọn ẹlẹri gbogbo si ti n wi tẹnu wọn niwaju ile ẹjọ lati mọ boya ọwọ iranṣẹ Ọlọrun naa mọ tabi ko mọ lori ọrọ naa.
Fire: Táńkà epo méjì tó forí gbárí ló fa sábàbí iná ọ̀hún
Yóo kọlu àwọn orílẹ̀-èdè káàkiri yóo sì bò wọ́n mọ́lẹ̀ lọ bí àgbàrá òjò.
14 Ògún 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 3 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 5 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Oríṣun àwòrán, Yinka Alaya/Facebook Ile iṣẹ ọlọpaa ipinlẹ Kwara fi panpẹ ofin mu ibudo atúnwàṣe yii ti wọn ti ko eniyan ọgọrun o le mẹjọ sigbekun lọna aitọ ni agbegbe Ọlọrunṣogo, Ilorin, ipinlẹ Kwara.
maa la awon ọdọ lọyẹ lori ijamba ti biba nnka jẹ maa n koba eto ọrọ aje.
Láàárin orí rẹ̀ ni ihò kékeré kan ń bẹ èéfin kan sì ń rú látti ààrin ibẹ̀ jáde.
'Báyìí la ṣe rìn ín láti pápákọ̀ òfurufú Abuja sí Eko bí ìrìnà òfurufú abẹ́lé ṣe bẹ̀rẹ̀' August Alsina ti fèsì sí ọ̀rọ̀ ìyàwó oníyàwó tó ń bálòpọ̀ Ọmọ Ibadan, Peace Busari tí wọ́n fẹ́ tà lórí Facebook ti dé sí Naijiria láti Lebanon Àlùbami ní Kamuru na Jorge Masvidal láti dí Àmí Ẹ̀yẹ UFC Welterweight Champion rẹ mú!
Lẹ́yìn àwọn onífèrè ni a rí àwọn ọmọdé tí wọn tó bí ọgaọ́ta tí wọ́n wọ aṣọ òkúta olówó iyebíye, lẹ́yìn àwọn wọnyí sì ni ogunlọ́gọ̀ wúndíá tí wọ́n wọ aṣọ aláràbarà dé.
dag hjalmar agne carl hammarskjöld ( ) ( 29 july 1905 - 18 september 1961 ) je diplomati , onimo oro-okowo ati oludako ara swidin .
Ona kan gboogi ti a tun le fi se odiwon bi aleku se n ba owo ori oja nipa mimo iye owo ori oja kookan ati awon onibara re.
Obinrin ayé òde òní kàwé, ṣùgbọ́n bi wọn kò ti ẹ kàwé, gbogbo ẹni ti ó bá ni làákàyè fún àṣà, kò gbọdọ̀ já obinrin si ipò kankan ni ilé nitori obinrin ló ni gbogbo ilé.
Bàbá mi kọjá sí ilé ìwẹ̀, mo ní èrò pé ó lọ tọ̀ ni, ṣùgbọ́n ó pẹ́ kí ó tó jáde, ó ní kí n bu omi fún òun kí òun mú, ṣùgbọ́n kàkà kí ó mu omi náà, ojú ni ó fi bọ́, ó sì dámi lójú pé ó ti sọkún.
Òun ló wí fún wa pé òun ni òun yọ Àkàrà-oogùn nínú ìtìmọ́lé Àgbákò, òun lo sì fún wa ní ìmọ̀ràn bí a ó tì ṣe tí a kò fi ní dé ìlú àwọn ẹyẹ ní ibi tí ògòngò ti n ṣe ọba wọn.
Agbẹjọro taa n wi yii, Malcolm Omirhobo tun fẹ ki ile ẹjọ paṣẹ fun ileeṣẹ ologun Naijiria lati yọ alifabẹti ati ọrọ keu to wa lara ami idanimọ wọn.
8 359415 Orilẹede Switzerland 5824 68.
Bí ó bá tún tẹ̀ wọ́n ní ẹ̀rìn kejì, sààárè ń sún mọ́ nìyẹn.
Nigba ti aarun naa kọkọ bu jade ni China ni ipari ọdun 2019, sise ofin konile o gbele dabi aseju.
Ṣaaju bibọ si ipo gomina, Ajayi ni igbakeji gomina ipinlẹ naa, Rotimi Akeredolu.
 “Fifigagbaga, afojusun ati ilana eto ile-ise yin lo n fun yin ni aseyori.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Adinku igboke-gbodo ọkọ Ijọba maa n din igboke-gbodo ọkọ ku lasiko ti fin konile o gbele ba wa nita.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ifipabanilopọ ma n fa ọgbẹ ọkan Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Ifipabanilopọ ma n fa ọgbẹ ọkan 11 Ẹrẹ̀nà 2018 Emili jẹ eni ti o ti ri iriri ikọlu ẹni ibi, lati igba naa lo ti n kọ awọn obinrin bi wọn ti se le gbeja ara wọn.
Ó ní, “Ẹ má ì tíì ṣe ilẹ̀ ayé ati òkun ati àwọn igi ní jamba títí tí a óo fi fi èdìdì sí àwọn iranṣẹ Ọlọrun wa níwájú.
Nítorí náà, mo níláti kú ní ìhín yìí, n kò gbọdọ̀ rékọjá sí òdìkejì Jọdani, ṣugbọn ẹ̀yin óo rékọjá sí òdìkejì rẹ̀, ẹ óo sì gba ilẹ̀ dáradára náà.
Yóo máa pín ìkógun rẹ̀ fún wọn.
Ni tirẹ, ẹgbẹ oṣelu APC ṣe apejuwe iku rẹ gẹgẹ bii ajalu nla fun gbogbo olugbe ipinlẹ Ọyọ.
Mo wá fẹ́ mọ ìdí rẹ̀ tí o fi ranṣẹ sí mi.
Ami ẹyẹ yii wa ni iranti onkọ ere oniṣe ni, Harold Pinter.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Mama Rainbow: Toyin Adegbola àti Razak Olayiwola ní ìyá rere àti àwòkọ́ṣe gidi ní Iṣẹ nọọsi ni agba oṣere yii n ṣe fun ogun ọdun o le diẹ, ko to dara pọ mọ ẹgbẹ oṣere tiata.
Wọ́n bẹ̀rẹ̀ sí dààmú, ọ̀kọ̀ọ̀kan wọn ń bèèrè pé, “Àbí èmi ni?
Èyí ni àwọn ìdí tí ìjọba ìpínlẹ̀ Kano ṣe rọ Emir Sanusi Lamido l'óyè Ilé ẹjọ́ Kano: Ganduje kò lẹ́tọ̀ọ́ láti yan Emir Buhari, ìjọba rẹ ń jọ bí ègún f'órílẹ̀èdè Nàìjíríà-Oyedepo Ganduje Video - Ìwádìí ilé aṣòfin foríṣánpọ́n Ìdá 90% nínú àwọn olówó Naijiria lo n lọ ilé babaláwo- Mr Latin O ni ''Inu mi dun mo si dupẹ.
Awọn ọrẹ rẹ ti tu sori ayelujara ti wọn n ṣelede lẹyin rẹ Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Osun-Osogbo Festival 2020: Àwọn ẹlẹ́sìn àdáyébá rú òfin Covid-19 níbi àṣekágbá ọdún Osun Osogbo16 Ògún 2020 Blasphemy against Mohammed: Olórin Kano Yahaya Shariff-Aminu tí wọ́n dájọ́ ikú fún ti pe ẹjọ́ kòtẹ́milọ́rùn5 Owewe 2020 Unilag VC: Folasade Ogunsola ni obìnrin àkọ́kọ́ tó jẹ ọ̀gá àgbà fún ibùdó ẹ̀kọ́ṣẹ́ ìṣègùn Fáṣítì Eko24 Ògún 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Coronavirus symptoms in Nigeria: Pẹ̀lú èròjà olùgbèjà ara 'Antibodies' Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Ṣugbọn ìwọ OLUWA ń fi wọ́n rẹ́rìn-ín,o sì ń fi gbogbo orílẹ̀-èdè ṣe yẹ̀yẹ́.
Ọ̀pọ̀ eniyan ni yóo wẹ ara wọn mọ́, tí wọn yóo sọ ara wọn di funfun, wọn yóo sì mọ́; ṣugbọn àwọn ẹni ibi yóo máa ṣe ibi; kò ní sí ẹni ibi tí òye yóo yé; ṣugbọn yóo yé àwọn ọlọ́gbọ́n.
Dapọ Abiọdun, máa bá iṣẹ́ rẹ lọ ní ìpínlẹ̀ Ogun- Ilé ẹjọ́ tó ga jùlọ Wọn pa ọlọ́pàá kan níbi tí wọ́n ti dáná sun ìjọ Sotitobire l'Akurẹ - Police PRO Kò sí arúgbó ní Kano, Bàbá 74 gbé ìyá 84 ní ìyàwó Èyí ni àwọn ìdí tí wọ́n fi fẹ́ ẹ̀ fi 37 Billion Naira tún ilé aṣòfin Nàìjíríà ṣe Ṣugbọ lọwọ yii, awọn ọmọ ẹgbẹ oṣelu Republican ti Trump jẹ ọkan lara wọn lo n dari ile aṣofin agba ilẹ Amẹrika, leyi ti yoo mu ki yiyọ aarẹ Trump ṣoro diẹ.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Iroyin ni awọn eeyan naa fẹran Trump to bẹ ti o fẹẹ jọ bi pe wọn lee fi ẹmi wọn lelẹ fun ọkunrin ọhun.
” Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Ni ọdun 2019 yii, awọn eniyan to ti papoda ninu isẹlẹ omiyale to igba eniyan, ti ọgọọrọ si ti di alairile gbe.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Moroccan Journalist: Hajar Raissouni de èrò ẹwọn lórí ẹ̀sùn àgbèrè àti oyún ṣíṣẹ́ 1 Ọ̀wàrà 2019 Oríṣun àwòrán, Reuters Àkọlé àwòrán, Awọn ajafẹtọ pẹlu aworan Hajar Raissouni nibi iwọde kan ti wọn ṣe losu to kọja Akọroyin ọmọ orile-ede Morocco kan ti fẹwọn ọdun kan gbara lori ẹsun pe o ni ibalopo ṣaaju ki o to lọkọ ati pe o ṣẹyun.
”Jehu bá bèèrè pé, “Ta ni ninu wa?
Fún àpẹrẹ, Yorùbá ni “Ẹni bá jalè ló bọmọ jẹ́”, lati gba òṣiṣẹ́ ni ìyànjú pé ki wọn tẹpámọ́ṣẹ́, ki wọn má jalè.
Lẹ́yìn táwọn agbébọn ja Aborode lólè tán ní wọ́n tún gbébọn fún un- Iléeṣẹ́ Ọlọ́pàá Wo àwọn Adelé-Ọba aládé méje tó jẹ́ obìnrin nílẹ̀ Yorùbá Mi ò le tòṣì láéláé!
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Black women live matters: Ọdún 2015 ní àwọn ọlọ́pàá pa India Kager láìní ìdí- Gina Best Lojumọ nigbamiran, Ibrahim ni oun a maa pa to ẹgbẹrun meji naira, tabi ẹgbẹrun kan abọ naira nigba ti ọja ko ba ya.
Ki lo pa Ogun Majek to jade laye?
Ọmọ tí a bá ṣẹ̀ṣè bí tí a kò kọ́ ní èdè, àti àwùjọ jẹ́ kòríkòsùn.
Ó bá yipada sí àwọn eniyan tí ó ń tẹ̀lé e, ó ní, “Mò ń sọ fun yín, n kò rí irú igbagbọ báyìí ní Israẹli pàápàá!
- Ooni Ile Ife Ìwé àkàgbádùn láti ọwọ́ Fagunwa, Faleti, Iṣọla, Ogunniran àti Okediji tó yẹ kí o kà lásìkò yìí.
Salima, baba Bẹtilẹhẹmu, ati Harefu baba Betigaderi.
Oríṣun àwòrán, Twitter/Osagie Ize-Iyamu Osagie Ize-Iyamu naa dupẹ lọwọ awọn lọbalọba to wa ni bẹ fun atilẹyin wọn, ti o si bẹ wọn lati ṣe atilẹyin fun oun nigba ti asiko idibo ba de ni Osu Kẹsan.
Coronavirus: updates: ìlú kan rèé l'Abuja tí kò mọ̀ rárá nípa Covid-19
O kere tan o to igba mẹfa ti ado oloro mẹfa dun lawọn ile ijọsin ati ile itura naa.
Oríṣun àwòrán, Others Awọn mejeeji bi ibeji ni ọdun 2015 lẹyin ti igbeyawo akọkọ Damola fi ori sapọn ni ọdun 2014.
Ọmọ Naijiria bii okoolerugba o din diẹ (219,665) lo fi ọwọ si iwe ẹsun naa lọ sọdọ ijọba UK.
Oshisko twins, àwọn 'ìbejì' tó ń dẹ́rìn ín p'òṣónú Funkẹ to ye arun ikọ ife la, wa rawọ ẹbẹ sawọn eeyan to ba ti n wukọ lemọlemọ, lati lọ se ayẹwo nile iwosan, tori o lee jẹ arun ikọ ife.
Clemence Westerhof ni olukọni Super eagles ni igba naa nigba ti Peter Rufai jẹ balogun ikọ Super eagles.
Aṣoju awọn olugbe agbegbe Lekki, Ọgbẹni Olorogun James Emadoye sọ pe ofin naa ko tọna rara, o ṣalaye pe ki wọn da owo-ori naa pada si bi o ṣe wa tẹlẹ.
Bákàn náà ni, onílara pọ̀ púpọ̀ nínú ayé wa yìí kò sì sí ọ̀nà tí wọn kò lè gbè láti fi ìlara wọn hàn.
Àkọlé àwòrán, Nígbàtí aféfé wàhálà náà yóò fi rọlẹ̀, ọ̀pọ̀ àwọn òṣìṣẹ́ ni wọ́n ti farapa.
Mi ò gbèrò láti lọ fún sáà kẹ́ta gẹ́gẹ́ bí ààrẹ - Buhari Iléẹjọ́, ẹ sọ fùn ọ̀gá DSS kó fún wa ní ₦1bn torí àhámọ́ lọ́nà àìtọ́ - Sowore àti Bakare Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Money transfer: Òdíwọn iye owó tí èèyàn n fi rànṣẹ́ sílé ń dínkù púpọ̀ jù Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Ẹfunsetan Aniwura, obìnrin tó ju ọkùnrin lọ Ọ̀rọ̀ǹpọ̀tọ̀niyùn, Aláàfin obìnrin àkọ́kọ́ rèé, tó ní nǹkan ọkùnrin Apidan ọmọ India yii lo n gbiyanju lati tun ọgbọn Harry Houdini dá, lọ̀rọ̀ bá yiwọ!
Ati wipe pataki ni isọkan laarin gbogbo ẹya ilẹ yi, ki idagbasoke le e waye lorilẹede yi.
Obinrin ọlọ́gbọ́n kan wà ninu ìlú náà, tí ó kígbe láti orí odi, ó ní, “Ẹ tẹ́tí, ẹ gbọ́!
Nígbà tí ó pẹ́ díẹ̀ ó gbé mi sọ̀kalẹ̀ sí ojú ọ̀nà Igbó Elégbèje, ó sì wí fún mi pé a ti kúró ní àgbègbè ibi tí Ẹlẹ́gbára máa ń dé, ṣùgbọ́n ó wí fún mi ki n má kúrò nibi tí òun gbé mi s’’i nítorí òun ń lọ máa gbé àwọn yòókù lọ́kọ́ọ̀kan wá.
Awọn miran o yẹ ki awọn mejeeji yii pe aro ati ọdọfin inu wọn ati pe ko yẹ ki ọrọ bayii pin awọn mejeeji yii niya nitori pe 'ọmọ iya lawọn mejeeji yii' o Sunday Igboho rán agbénipa sí mi láti gb'ẹ́mi mi-Auxilliary Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Auxilliary : Sunday Igboho kìí ṣe ọmọ ìbàdàn, òun gan ló ń dá Ibadan ru Alaga ẹgbẹ àwọn Alakoso gareji ọkọ nipinlẹ Ọ̀yọ́, Alhaji Mukaila Lamidi, tí ọpọ èèyàn mọ sì Auxiliary, tí sọ̀rọ̀ lórí rògbòdìyàn tó wáyé ládùúgbò Soka, nílùú Ibadan laipẹ yìí.
Ṣugbọn Cech ni ko si ootọ kan nibẹ nigba naa.
Ọkọ tirela naa kọlu ọkan lara awọn ọkọ Toyota Hilux to n ba a kọwọrin lọ silu Usen nibi ti oun ati Pasitọ Ize-Iyamu to jẹ oludije fun ipo gomina lẹgbẹ oṣelu APC yoo ti ba awọn araalu naa sọrọ lori idi ti wọn fi gbọdọ di ibo wọn fun APC.
“Kéde láàrin àwọn orílẹ̀-èdè,ta àsíá, kí o sì kéde.
NFF fi #30,000 kún #10,000 owó ìrànwọ́ oṣooṣù fún ìyá Rashidi Yekini àti Samuel Okwaraji Olorì Aláàfin, Memunat Adeyemi, fohùn ránṣẹ́ sí ikú bàbá yèyé Coronavirus: Ǹjẹ́ àwọn dókítà tó ń tọ́jú eyín ń ṣisẹ́ lásìkò pàjáwìrì?
Awọn ẹgbẹ kan buru ju ara wọn lọ ti kii si ṣe gbogbo ọmọ ẹgbẹ lo ma n wuwa ọdaran.
O ni lati jẹ akẹkọọ jade fasiti tabi ile iwe gbogboniṣe.
Ni kete ti wọn yin oogun akuniloorun meji to lagbara lu Kinihun yii to si moorun lọ ni wọ́n gbe e kuro nile naa ti wọn si gbe e lọ si ọgba ti wọn n ko ẹranko inu igbo si.
Kò ní jẹ́ tèmi, kò sì ní jẹ́ tìrẹ.
Ọba Lamidi Adeyemi pé ọdún 48 lórí ìtẹ́
Láti inú ẹ̀yà Isakari, a yan Palitieli ọmọ Asani.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ekiti Election: Ǹkan mẹ́wàá tó yẹ kí o mọ̀ nípa Kayọde Fayẹmi 9 Agẹmo 2018 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 15 Agẹmo 2018 Oríṣun àwòrán, @kfayemi Àkọlé àwòrán, O jẹ minista fun ìwakùsà ati irin tutu laarin 2016 si 2018 labẹ iṣakoso Aarẹ Buhari John Olukayọde Fayẹmi to dije fun ipo gomina labẹ asia ẹgbẹ oṣelu APC ni ajọ INEC kede gẹgẹ bi gomina tuntun fun ipinlẹ Ekiti.
Àrọ́bá June 12: Ó yẹ MKO Abiọla, ẹ̀gàn ni hẹ̀ẹ̀
Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí 5:55 Fídíò, Soyinka Cancer: Àṣe ara mi ni iso ti n run gbogbo bí mo ṣe n ṣèrànwọ́ lórí jẹjẹrẹ, Duration 5,5527 Bélú 2019 11:51 Fídíò, EndSARS, EndSWAT Protests: Òbí agbábọ́ọ̀lù Kazim Tiamiyu Kaka àtàwọn míì tí ọlọ́pàá pa sọ̀rọ̀, omijé bọ́ lójú, Duration 11,513 Bélú 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Ọjọ meji lẹyin tawọn kan n gbe iroyin ofege pe aarẹ Buhari fẹ ṣegbeyawo pẹlu obinrin mii ni Aisha pada si orilẹ-ede Naijiria.
Mohammed ni ko yẹ ki ọmọ Yoruba tun maa san owo ileewe titi di fasiti mọ.
Nígbà tí ọpọlọpọ òkú bá sùn ní Ijipti,tí a kó ọrọ̀ rẹ̀ lọ,tí a sì wó ìpìlẹ̀ rẹ̀ lulẹ̀.
Ayédèrú Lọ́yà tó ń díbọ̀n gbowó lọ́wọ́ aráàlú bọ́ sí gbaga ọlọ́pàá Ayẹyẹ ìgbaniwọlé sínú ẹgbẹ́ òkùnkùn bẹ́yìn yọ, wọ́n lu ọmọ ẹgbẹ́ tuntun pa Àwọn alága ìbílẹ̀ tún wọ́ Seyi Makinde relé ẹjọ́ Ki gaan ni Aarẹ Trump sọ?
Ẹwẹ, wọn tun fi ẹsun jijale lori ẹrọ ayelujara kan an eyi ti wọn ni o lodi si abala ofin 24 (1) (b) ninu ofin Naijiria.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Larisa: Má jẹ́ kí ọjọ́ orí rẹ dí ẹ lọ́wọ́ láti bẹ̀rẹ̀ ohunkóhun to wù ọ Transmission, Transmission - Ibrahim Idris / Oṣu karun un, 2018 Yoruba ni, aṣiwi ko to aṣisọ.
Bi awada bi ere ni ifẹsẹwọnsẹ naa bẹrẹ eleyi ti ọpọ olololufẹ ere bọọlu si lero pe Man City ni yoo jawe olubori.
Idi ni pe, bi awọn eeyan ṣe n ra nkan yoo dinku, Banki Apapọ naa yoo si ma a gbiyanju lati ko owo jade lati fi ẹsẹ ọrọ aje mulẹ.
Kí ni ó ń mú iyè meji wá sí ọkàn yín?
Ẹ yọ mí látìmọ́lé DSS, ó lòdì s'ẹ́tọ̀ọ́ mi- Ṣowore Èèyàn mẹ́rìnlá tí ọpọlọ wọ́n pé la buwọ́lù bíi kọmísọ́nà l‘Oyo - Olórí ilé aṣòfin kan sáárá Àwọn ọmọ Nàìjíríà kan ń dá ẹ̀bi, òmíràn ń dárò, lórí bí ológun ṣe pa ọlọ́pàá mẹ́ta Ẹgbẹ́ òṣèlú AAC fi ọwọ́ òsì júwe ilé fún Ṣowore!
Lara awọn aṣeyọri rẹ ni bo ṣe mu Gomina ipinlẹ Delta nigba kan, James Ibori, to ji obitibiti owo ipinlẹ rẹ ko.
"Oríṣun àwòrán, Getty Images Minisita fún ọrọ ọlọ́pàá, Bheki Cele, tí ọ̀pọ̀ èèyàn mọ fún sísọ ọ̀rọ̀ kobakungbe àti iwanwara rẹ lórí amusẹ òfin to de ọtí tita, lo sí ti fi ikilọ síta laipẹ yìí pé, àwọn ikọ òun ""yóò ba àwọn ohun èlò ti wọn ba fi ń ta ọtí jẹ""."
Àwọn tí ń bá mi ṣọ̀tá láìnídìí lágbára,àwọn tí ó kórìíra mi láìtọ́ sì pọ̀.
Ọpọ igba si ni itorin ti sọ nipa oniruuru ọsẹ ti wọn n se fawọn agbẹ, yatọ si pe wsn n ba ire oko wọn jẹ, wọn yoo tun sa wọn lọgbẹ tabi gba ẹmi wọn.
Ninu fọnran fidio ti aarẹ fi si oju opo rẹ ni Twitter, o ni atuntọ iṣẹ ọlọpaa n bọ lẹyin ti ijọba tu FSARS ka.
Àwọn ẹni ibi yóo tẹríba fún àwọn ẹni rere,àwọn eniyan burúkú yóo sì tẹríba lẹ́nu ọ̀nà àwọn olódodo.
Ìwọ tóò forúkọ sílẹ̀ lórí ẹ̀rọ ayelujára, owó ìfẹ̀yìntì rẹ lo fi ń ṣeré Ológun mú àwọn sọ́jà tó kọ́wọ̀ọ́ fipá bá akẹ́kọ̀ọ́ fásitì AAUA lò pọ̀ Bakan naa ni olubori yoo gba ẹbun ẹẹdẹgbẹta Dọla (five hundred Dollars) lati fi ra iwe lori eto ẹkọ t'oun kọ.
 bí àwọn ohun tí ó wa nínú ìwé náà ṣe lọ ní olóríjorí nì yí :.
Ilẹ n jẹ eeyan Oríṣun àwòrán, Twitter/abiola ajimobi Àkọlé àwòrán, Senato Ajimobi pẹlu gomina Kayode Fayemi ti ipinlẹ Ekiti, ọmọ iya ẹgbẹ oṣelu APc ni awa mejeeji Oríṣun àwòrán, Twitter/ajimobi Àkọlé àwòrán, Sẹnetọ Ajimọbi pẹlu awọn eekan agbabọọlu orilẹ-ede Naijiria nigba kan ri, Ikẹ Sorunmu, Mutiu Adepoju Yobo Joseph, Emmanuel Amokachi pẹlu minisita fun ere idaraya, Oríṣun àwòrán, Twitter/ajimobi Àkọlé àwòrán, Abiola Ajimobi, Aarẹ Muhammadu Buhari ati Adams Oshiomole ti wọn ṣẹṣẹ yọ kuro nipo alaga ẹgbẹ oṣelu APC.
Oríṣun àwòrán, @RotimiAkeredolu Àkọlé àwòrán, Gomina Akeredolu sọ bi ipinlẹ Ondo se gbaradi lati tọju awọn alaisan iba Lassa Gomina Akeredolu sọ nipa eto ti wọn ti se kalẹ fun awọn to ba lugbadi aisan naa: ·Awọn alaisan wa ni ile iwosan ijọba to wa ni Ọwọ fun ayẹwo gẹgẹ bi wọn se nse ni ile iwosan to wa ni Irrua, ipinlẹ Edo · Ile iwosan mẹtadinlaadọrin ati ibudo ọọdunrun le mẹjọ kaakiri awọn ilu lo wa fun awọn ijọba ibilẹ ti aisan naa ti nja ·Igbaradi fun isẹlẹ pajawiri pẹlu ikọ fun eyi ti tunramu lawọn ijọba ipinlẹ lati kapa aranka aisan naa nipinlẹ Ondo ·Ipolongo ati ilanilọyẹ ti nlọ ni ipinlẹ naa nipa aisan iba Lassa ·Wọn ti gbe ọk silẹ ti yoo maa ko ayẹwo kiri atawọn alaisan ti wọn ba gbe lọ si ile iwosan Irrua ni ipinlẹ Edo.
Ipalẹmọ maa n bẹrẹ lati ori aṣọ wiwọ, gbọngan ayẹyẹ, olorin ti yoo kọrin ati ounjẹ jijẹ fun awọn alejo.
Tẹlẹ ri, ẹni to ba wa lori aleefa ni wọn yoo gbe aṣia ẹgbẹ le lọwọ.
Bí nǹkan oṣù rẹ bá dáwọ́ dúró, àwọn ohun tí yóò ṣẹlẹ̀ sí ọ rèé Adigunjalè fa ìjàmbá ọkọ̀ lọ́nà Ijẹbu Ode sí Ṣagamu, èèyàn mẹ́wàá dèrò ọ̀run Ambode, wá sọ tẹnu rẹ lọ́jọ́rùú lórí owó àwọn àkànṣe iṣẹ́ to ná - Ilé aṣòfin Eko Adájọ́ Dogo tí wọ́n jí gbé ti gba ìtúsílẹ̀ O fikun pe nigba ti awọn obi oun ko lee setọju oun bo se yẹ ni oun sa kuro nile, ni kete ti wọn si ri oun pada, lawọn obi oun mu ohun lọ sile alaigbọran naa, ti Mallam Abdulraheem Owotutu da silẹ.
Nígbàtí ìyàwó ilé bá gbọ́, wọn a pa òfo lọdọ ìyàwó ilé, wọn a tún tẹ́ lọ́dọ̀ àlè.
Laipẹ yii si ni Dayo gbe awo orin tuntun kan jade eyit o milẹ titi, to si pe akọle rẹ ni Mosorire.
Awọn eniyan Naijiria ti wọn na owo wa lati Cairo ati agbegbe rẹ wa ṣe koriya fún awọn Super Eagles ni Cairo ti fi aidunnu wọn han.
Kò sí òògùn kankan tó ń mú mi bí ìbejì bíkòṣe oúnjẹ ìbílẹ̀ - Aláàfin Ọyọ Àwòrán bí ẹ̀kún omi ti ṣọṣé l'Eko àtàwọn ìlú míì nílẹ̀ Yorùbá rèé Ṣé ìpèsè iná ọba yóò wà lọ̀dún 2020 torí ₦9bn nìjọba fẹ́ ná fún ẹ̀rọ amúnáwá?
Adájọ́ pàṣẹ kí wọ́n fi ọlọ́pàá tó lọ́wọ́ nínú ikú Kolade Johnson sí àhámọ́ “Kò sí àgbègbè Nàìjíríà kánkan tó wà lábẹ́ àkóso Boko haram” Kí ló kàn olórí ọmọ ilé aṣòfin Osun pẹlú ìdájọ kòtẹ́milọ́rùn Sẹnẹtọ Adeleke?
Bí Abrahamu kò tilẹ̀ mọ̀ wá,tí Israẹli kò sì dá wa mọ̀.
Ètò RUGA wọn kò lè ká Fulani 500,000 tó wà nínú igbó ilẹ̀ Yorùbá - Oluwo Alábàárù ni mò ń ṣe lọ́jà Ketu àti Mile 12, kí ń tó bẹ̀rẹ̀ Fuji - Atawẹ́wẹ́ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, N100,000 Nairà mà ni Dino gbé dání lójú agbo, kò náwó yàlà-yòlò - Ayefele Lẹyin naa ni akọnimọọgba Stéphane Jobard yoo gbe igbesẹ bo ya Enyeama yoo dara pọ mọ ikọ Dijon.
Ìrètí yìí ni àwọn ẹ̀yà mejila tí ó wà ní orílẹ̀-èdè wa ní, tí wọ́n ṣe ń fi ìtara sin Ọlọrun tọ̀sán-tòru.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ekiti election appeal: Ìpèníjà ráńpẹ́ ni èsì ilé ẹjọ́ kòtẹ́milọ́rùn jẹ́ fún wa -PDP 29 Ẹrẹ̀nà 2019 Oríṣun àwòrán, @solaeleeka Àkọlé àwòrán, Anfaani ile ẹjọ giga lo ṣẹku fun ọgbẹni Olusola Ẹlẹka lati tako esi ibo Gomina ipinlẹ Ekiti Ẹgbẹ oṣelu Peoples Democratic Party nipinlẹ Ekiti ti fesi pe ''ipenija ranpẹ'' ni esi ile ẹjọ kotẹmilọrun to fagile ẹjọ ti oludije wọn ninu idibo gomina, Olusola Eleka gbe wa si iwaju rẹ.
Ó dìde, ó kó gbogbo ohun tí ó ní, ó sá gòkè odò Yufurate, ó doríkọ ọ̀nà agbègbè olókè Gileadi.
“Kí àwọn ọmọ Israẹli máa ṣe Àjọ̀dún ìrékọjá ní àkókò rẹ̀.
Èwo ni ó rọrùn jù, láti sọ pé, ‘A dárí ẹ̀ṣẹ̀ rẹ jì ọ ni,’ tabi láti sọ pé, ‘Dìde, kí o máa rìn?
Bẹẹ si ni ninu fídíò kan tó gbé sójú òpó Facebook rẹ, ní ọba Ogunwusi tí ń ṣe àfihàn àwọn egboogi ìbílẹ̀ kan tó lè wo àrùn Coronavirus san, àti bí àwọn èèyàn ṣe leè lo.
Tirẹ̀ ni ọlá ati agbára tí kò lópin.
-Ẹgberun lọna ọgorun Naira lo ni ohun yoo ma san fun awọn agunbanirọ ti wọn ba yan ohun gẹgẹ bi Aarẹ Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Kí èmi àti ẹ̀yin ọ̀rẹ́-ẹ̀ mi sì gbàdùn ìtàn náà bí Ìbàdàn ṣe ńgbádùn ọkà àti ọ́ọ́yọ́ tòun ti gbẹ̀gìrì.
A máa fọ́ nǹkan túútúú, á jẹ ẹ́ ní àjẹrun, á sì fi ẹsẹ̀ tẹ àjẹkù rẹ̀ mọ́lẹ̀.
Amọ arun coronavirus to n ja rain naa ko i tii de orilẹede Naijiria, nitori naa ni awọn eniyan ṣe n woye lori ọrọ ti Magu sọ.
Èrò ọmọ Nàìjíríà ṣé ọ̀tọ̀ọ̀tọ̀ lóríi ìkéde Rélùwéè ọ́fẹ́ Èkó sí Ìbàdàn Onyeama, jọ̀ọ́ má bínú ìdẹ́yẹsí tá a ṣe torí pé o jẹ́ adúláwọ̀ - Ilé ẹ̀kọ́ Eton Ilẹ̀ UAE ti n fún àwọn arìnrìnàjò ní ìwé ìrìnnà ọlọ́dún márùn ún Wo àmúyẹ kí o tó lè di ọmọ ogun ilẹ̀ Nàìjíríà pẹ̀lú fọ́ọ́mù tó jáde yìí Lọpọ igba Naijiria a maa fi jẹ ki o ye awọn ilẹ wọnyi pe awọn ko gba gberẹ.
Lori ọrọ owo oṣu oṣiṣẹ ti wọn beere lọwọ awọn oludije, gbogbo wọn pa ẹnu pọ lati sọ pe awọn yoo san N30,000 gẹgẹ bi owo oṣu oṣisẹ to kere ju.
Ninu ọrọ ti wọn fi sita, ajọ EFCC ni ile iṣẹ P&ID kuna lati jabọ iye owo dollar marundinlaadoje sinu asuwọn owo tilẹ yii.
Nítorí Kristi kò ṣe nǹkan tí ó tẹ́ ara rẹ̀ lọ́rùn.
"Computare ni ọ̀rọ̀ yí gan-gan ó sì túmọ si ""kíkà"" tàbí ""sísírò"" ní Yorùbá."
"Daju daju kii ṣe oni ni iho yii ṣẹṣẹ ṣi silẹ ni agbegbe naa eyi lo mu ki wọn ""pariwo fun ọlọkada naa pe ojo n rọ, ojo n rọ ṣugbọn to kọ ti ko gbọ""."
A óo lé ọ jáde kúrò láàrin àwọn eniyan, o óo sì máa bá àwọn ẹranko inú igbó gbé; o óo máa jẹ koríko bíi mààlúù, ìrì yóo sì sẹ̀ sí ọ lára fún ọdún meje, títí tí o óo fi mọ̀ pé Ẹni Gíga Jùlọ ní àṣẹ lórí ìjọba eniyan, ẹni tí ó bá wù ú níí sì í gbé e lé lọ́wọ́.
tí ẹ bá ń búra pẹlu òtítọ́ pé, ‘Bí OLUWA ti wà láàyè,’ lórí ẹ̀tọ́ ati òdodo, àwọn orílẹ̀-èdè yòókù yóo máa fi orúkọ mi súre fún ara wọn, wọn yóo sì máa ṣògo ninu mi.
Nígbà tí mo wà lọ́dọ̀ yín, tí mo ṣe aláìní, n kò ni ẹnikẹ́ni lára, àwọn arakunrin tí ó wá láti Masedonia ni wọ́n mójútó àwọn ohun tí mo ṣe aláìní.
ó rán wọn sí Oluwa láti bi í pé, “Ṣé ìwọ ni ẹni tí ń bọ̀ ni, tabi kí á máa retí ẹlòmíràn?
nítorí pẹ ́ ọ ̀ pọ ̀ lọpọ ̀ ìtàn ìṣẹ ̀ dá àwọn ìlú yorùbá jẹ ́ àtẹnudẹ ́ nu , ó máa ń sòro láti sọ ní pàtó pé báyìí-báyìí ni ìlú kan ṣe ṣẹ ̀ .
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù HIV/AIDS: Ìjọba Nàìjíríà gbé èsì ìwadìí tuntun jáde lóríi ọwọ́jà HIV/AIDS 17 Ẹrẹ̀nà 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Iye awọn to ni kokoro arun naa ti dinku lorilẹede Naijiria, gẹgẹ bii iwadii ajọ NACA naa ṣe sọ Eeyan to din diẹ ni miliọnu meji lo ni kokoro arun HIV/AIDS lorilẹede Naijiria, ṣugbọn njẹ o mọ pe obinrin lo pọ ju laaarin wọn?
Ọọni tun fi idaniloju rẹ han fun araalu pe ijọba ati ẹgbẹ ASUU ti fẹẹ pari yiyanju awọn ibi ti fa ki n faa wa lori ọrọ yii.
Ní ọjọ́ kẹta, nígbà tí wọ́n sọ fún Labani pé Jakọbu ti sálọ, 
 O tun so pe “Ile igbimo asoju-sofin si ti n pariwo pe ki won yo awon adari ajo  eleto aabo latari awon wahala to n sele lapa ekun iwo oorun ati ila oorun orile ede Naijria, ni eyi ti won ko eti ikun si ipe naa.
Isaaki bá pe Abrahamu, baba rẹ̀, ó ní, “Baba mi.
Minisita: Ileeṣẹ apòògùn 20 lo jẹbi síse òògùn ikọ́ Codeine
  “O je ohun iwuri fun mi pe, Naijiria je orile-ede adulawo akoko ti o koko pegede fun idije agbaye yii,” “Ijoba apapo yoo ri daju lati satileyin, sepese awon ohun elo fun iko Super Eagles lati kopa daradara ninu idije naa, lorile-ede Russia.
Ó wọlé, ó jókòó pẹlu àwọn ẹ̀ṣọ́ láti rí ibi tí gbogbo rẹ̀ yóo yọrí sí.
Wọn yóò gbẹ́ ihò kéékèèkéé méjì síwájú ilé náà.
Akeredolu salutes Buhari at 76Ondo State governor, Arakunrin Oluwatotimi Akeredolu, SAN, joins millions of Nigerians to congratulate President Muhammadu Buhari on his 76th birthday.
Ife-eye ohun ni Coca-Cola yoo tun gbe kaakiri awon orile-ede yooku miran, ki o to pada sorile-ede Russia fun ifigagbaga re.
Eka to n mojuto epo-robi ati afefe gaasi lorile ede Naijiria, ti gboriyin fun awon olokoowo epo robi ati afefe gaasi fun  ipa pataki ti won n ko nibi ti won ti n wa epo-robi lorile-ede Naijira.
Iroyin sọ pe arakurin oniṣowo kan lo sọ pe ori ilẹ oun ni wọn kọ ileeṣẹ Naijiria yii si ni Ghana.
Ọjọ́ iwájú ni ẹ̀ ń rò tí ẹ fi ń ṣe èyí nígbà gbogbo.
Èyí ẹ̀karùn-ún wà ní orí àkàsọ̀ kan tí ó ní ọ̀pọ̀lọpọ̀ àtẹ̀gùn, ó jókòó lórí àtẹ́gùn tí  ó wà lóké pátápátá nígbà tí a wọlé.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Lagos building collapse: Ìjọba ìpínlẹ̀ Èkó bẹ̀rẹ̀ ilé wíwó ní Lagos Island 15 Ẹrẹ̀nà 2019 Iroyin to n tẹwa lọwọ ni pe ijọba ipinlẹ Eko ti bẹrẹ si ni wo awọn ile ti ko duro daada ladugbo ibi ti ile ti wo pa eeyan to to mejidinlogun.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Scientific Reports: Ìgbẹ́ ọmọdé ní àǹfààní púpọ̀ lára 7 Ògún 2018 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 28 Ògún 2018 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Awọn dokita lati ilẹ Amẹrika naa fikun wipe o seese ki igbẹ ọmọde jẹ ọna abayọ si gbogbo aarun ti n pa awọn eniyan lai to ọjọ.
Ti alaboyun ba si n rọbi, inu irora ni wọn yoo ti gbe jade lọ si ilu miran lati lọ bimọ.
Ọbasanjo sọ eyi lasiko to n ba awọn akọroyin sọrọ ni ile rẹ to wa ni Abeokuta ni ipinlẹ Ogun.
‘Buhari ti wọnu ẹmi lọ’ Ẹ̀rò àwọn ènìyàn se ọ̀tọ̀ọ̀tọ̀ lórí lẹ́tà Ọbasanjo sí Buhari Faari Buhari Day 30: Ṣé o mọ Ààrẹ Buhari délé délé?
Elédùmarè ló rán mi sí gbogbo Ọba Yorùbá - Oluwo Akọ ìbẹ́pẹ ni Yorùbá yóò pè é, ẹ wo bí òṣèré yìí ṣe ń ní ọgbẹ́ ọkàn pé kò tíì r'ọ́mọ bí Ààrẹ Buhari ti ṣàlàyé ìdí tí kò ṣe tíì ṣí ibodè tó tì pa Bákan náà ni ìwádìí fi hàn pé ti awọn ọmọde ba fẹ́ràn orin ti wọ́n gbọ́, wọ́n maa n ranti àwọ́n ọ̀rọ̀ inú orin náà, nítori náà ti gbogbo àwọn ìlàna àti òfin inu ìsìrò ba di orin, èyi yóò ràn wọ́n lọ́wọ́ láti mọ̀ ọ́.
Nibo ni Fatai Rolling doller kawe de?
Imoyosola Adetoro: Àwọn èèyàn sọ fún ìyàwó mi pé mo ti jẹ́ẹ̀jẹ́ nínú awo pé ń kò ní bímọ A ti gbé ìlẹ̀kùn ìjọba ìbílẹ̀ tìpa láti dẹ́kun wàhálà l‘Ọyọ - Àwọn òṣìṣẹ́ ìjọba ìbílẹ̀ Ọ̀daràn tó bá ta féle-fèle yóò bọ́ sọ́wọ́ Amọtẹkun - Ìjọ́ba Ekiti Agbábọ́ọ́lù alápẹ̀rẹ̀, Kobe Bryant àti ọmọ rẹ̀ dèrò ọ̀run nínú ìjàmbá ọkọ̀ òfurufú Bakan naa ni wọn fi ẹsun kan awọn oṣiṣẹ ijọba pe wọn lọ gba ẹyin ba ẹbọ jẹ lori eto isanwo oṣiṣẹ eto IPPIS.
 alárè fi omobìnrin rè kan gbórowó , fún odùduwà láti fi se aya .
Ó tanná ràn án lọ́tùn-ún lósì, sibẹ kò yé e;iná jó o, sibẹsibẹ kò fi ṣe àríkọ́gbọ́n.
Eléyìí ni a ṣe tí a padà wá sí ilé.
Yóo gbọn àwọn èso rẹ̀ tí kò tíì pọ́n dànù, bí àjàrà,yóo sì gbọn àwọn ìtànná rẹ̀ dànù, bí igi olifi.
"Ọgbẹni Aziegbem ni bayii ohun to mumu lọkan oun gẹgẹ bi alaga ẹgbẹ oṣelu PDP ni ipinlẹ Edo ni ""lati rii daju pe gomina Ọbaseki darapọ mọ ẹgbẹ oṣelu naa."
Gẹgẹbi ohun to sọ fun BBC News Yoruba, ko si ara ti omidan iwoyi n da ni oge ati ẹṣọ ti awọn arugbo ko tii fi lo gba nigba tiwọn.
"Láàrin àwọn ọmọ kéékèèké ti wọn n gba ẹmi ara wọn, ọ̀pọ̀ lo ni àrun ti wọ́n n pè ni ""Schizopherenia"" Schizopherenia jẹ́ àìsàn to maa n jẹ́ ki ènìyàn gba ohùn ti yóò ma dá ẹni náà lẹbi fún ǹkan ti wọ́n ṣe, ohun náà a ma jẹ́ ki aye ṣú wọ́n, yóò si ma sọ pe aye ko já mọ́ ǹkankan."
Lati igba yii lo ti n ṣedaro pẹlu awọn ẹbi awọn eeyan to ku ninu ijamba baalu ọhun nigba kuugba ti wọn ba wa sibi ti baalu naa ja si.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Pásítọ̀ ló sọ fún mi pé Ọlọ́run pè mí láti di Olokun tó ń bọ omi' Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí 5:58 Fídíò, Yeye Olokun of Lagos Omolara Fasola Fanimokun: Pásítọ̀ ṣọ́ọ̀ṣì ló sọ ìran pé kí n di Olókun, Duration 5,5821 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Nigerian doctor shoots wife: Dr Benjamin Okigbo pa ìyàwó rẹ̀, pokùnso lẹ́yìn tó gbìyànjú láti pa ọmọ21 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Funke Akindele: Bukunmi Oluwasina ní ọ̀kan lára àlá òun ló wá sí ìmúṣẹ18 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Muyiwa Ademola: A ó jọ rọ́ọ̀kì ọdún 2021 papọ̀ ni lágbára Ọlọ́run26 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 3 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 5 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
BBC: Ìrọ́ ní, a kò ṣètò owó ẹ̀kọ́ òfẹ fún akẹ́kọ̀ọ́ gboyè fásítì
Kọmisọna ọhun jẹ ko di mimọ pe awọn ipinlẹ mẹtẹta yii sun mọ bebe idigunjale to si ni ipinu yii ṣe pataki lati dena ikọlu mii si awọn ileewe ọhun.
Shittu: Máà ṣiṣẹ́ tako olùdíje fún ipò gómìnà l'ábẹ́ APC ní ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ̀
Arsenal fidirẹmi lẹẹkẹta laarin ọjọ mẹjọ
Amọ awọn oṣiṣẹ panapana lo fi ipa ṣi ilẹkun naa ki awọn ọlọpaa to raye wọle.
E̩nì kò̩ò̩kan ló ní è̩tó̩ pé kí a kà á sí gé̩gé̩ bí ènìyàn lábé̩ òfin ní ibi gbogbo.
Lati ipinlẹ Ekiti lawọn ọkọ nla ti n bọ, ilu Akure ni wọn n lọ ki ijanu ọkọ wọn to ja ti ko si le mu un mọ.
Wọ́n jẹ́wọ́ pé àlejò tí ń rékọjá lọ ni àwọn ní ayé.
Ó dára bí o kò bá jẹ ẹran, tabi kí o mu ọtí, tabi kí o ṣe ohunkohun tí yóo mú arakunrin rẹ kọsẹ̀.
2 Àwọn òfin èyítí a fi fún Joseph Smith, Kékeré, ẹnití a pè láti ọwọ́ Ọlọ́run, àti tí a yàn gẹ́gẹ́bí àpóstélì ti Jésù Krístì, láti jẹ́ alàgbà àkọ́kọ́ ti ìjọ yìí;
•Ti eniyan ba n gbe iroyin jade ju bo ṣe yẹ lọ lori ikanni rẹ, o ṣeese ki wọn gbegile, nitori o ti ni iye nkan ti eniyan le gbe jade laarin wakati ti ko tako alakalẹ ikanni naa lọ, amọ ti eniyan ba n gbe iroyin jade lemọlemọ kọja alakalẹ, wọn a gbẹsẹle oju opo naa.
Sedekaya ọba bá kìlọ̀ fún Jeremaya pé, “Má jẹ́ kí ẹnikẹ́ni mọ gbogbo nǹkan tí a jọ sọ, o kò sì ní kú.
Cancer: àpọ̀jù ṣúgà nínú ẹ̀jẹ̀ ń ṣàkóbá fún àgọ́ ara èèyàn
Agbẹnusọ aarẹ ti sọ ọ́ lójú òpó Twitter pé igbakeji aarẹ, ọ̀jọ̀gbọ́n Yẹmi Oṣinbajo ni yóò máa sisẹ́ ààrẹ fún àsìkò tí ààrẹ fi lọ sinmi ni Ilẹ Gẹẹsi.
Awọn ede Yoruba ti iro wọn jọ ara wọn amọ ti akọsilẹ wọn yatọ: OGÚN: Ogún ni awọn oloyinbo n pe ni Twenty, ti ami rẹ si jẹ re mi.
Gbade Ojo sọ ọrọ yii lori ẹrọ redio ni ilu Ibadan, nigba to n ba awọn eniyan fọrọ jomitoro ọrọ lori iku Abiola Ajimobi ati ipa ti ijọba Seyi Makinde ko.
Ẹ̀yin ẹ jẹ́ kí ohun tí ẹ gbọ́ láti ìbẹ̀rẹ̀ máa gbé inú yín.
Àkọlé àwòrán, Lẹyin ti inu papa iṣere Adamasingba kún fọfọ tan, ẹsẹ ko gba ero nita Lekan Salami nitori kaluku wa woran ayẹyẹ ayajọ ominira Naijiria bi ijọba ipinlẹ Oyo ṣe n sami rẹ nilu Ibadan BBC News, Yorùbá Ìdí tí ẹ fi le è nígbàagbọ́ nínú ìròyìn BBC Ìlànà Lílò Nípa BBC Òfin Àṣírí Cookies Kàn sí.
Agbọn jẹ ọkan pataki lara ohun ti Eledaa jogun fawon ọmọ Badagry ni ipinlẹ Eko ni guusu Naijiria.
Eyi waye lẹyin ti wọn tu wọn ka pe ki wọn ma ṣiṣẹ mọ lasiko iwọde EndSARS jakejado Naijiria iyẹn Special Anti-robbery Squad.
fi gbosuba kare lai fun afojusun isakoso egbe oselu APC nipinle naa.
Pasitọ Ogundipe naa dupẹ lọwọ K1 De Ultimate pẹlu idọbalẹ, bakan naa lo tun gbadura fun olorin naa.
 Adedoyin fikun pe  A ni awọn isọri Amotekun ta pe ni 'Irunmọlẹ', ti wọn yoo maa gun ọkada kiri lati agbegbe kan si omiran nibi ti ọkọ ayọkẹlẹ ko lee de, eyi ti yoo mu ki isẹ ipese abbo jẹ alatagba lati adugbo kan si omiran.
Dokita Ogunbayo kede bẹẹ lasiko to n kopa lori eto kan ni ikanni BBC Yoruba eyi to n sami ayajọ imọtoto nnkan oṣu lagbaaye.
Ijọba ipinlẹ EkitiIgbesẹ ijọba ipinlẹ Ekiti ko fi bẹ ẹ yatọ.
Amọ eruku tun sọ lala nigba to ku diẹ ki ipele akọkọ ifẹsẹwọnsẹ naa pari lẹyin ti Harry Kane gbayo mii wọle Arsenal.
Asa orisirisiAlhaji Mohammed ni orile ede Naijiria fidi mule ninu ede ati asa ni eyi ti awon asa miiran tun ti jẹyọ bi I Durbar, isu tuntun , Eyo ati odun egungun abbl.
Ìjọba ìpínlẹ̀ Osun tí búwọlù ìlànà àyẹyẹ Ọṣun-Oṣogboo ọdún 2020 Ẹ̀gbọ́n àti àbúrò wà ní ilé ẹ̀jọ́ lórí ikú Tolulope Arotile Ọlọ́run nìkan ló mọ bí ìrìnàjò ìfẹ́ ẹ̀dá á ṣe rí láyé, ọ̀dọ́ Aláàfin ní orí gbémí yà sí, ó sì tẹ́milọ́rùn- Olorì Aanu Ogunṣola ní láti ọdún tó kọjá ní ọ̀rọ̀ náà ti bẹ̀rẹ̀ láti igba ti Omowe Babalakin to jẹ́ alága ìgbìmọ̀ Kánsù tó ń mójútó ọ̀rọ̀ Fásítì náà ]ati Ogundipe ti n ni kudiẹ-kudié.
Ẹni ọdún mọkanlelogoji ni Rehoboamu ọmọ Solomoni nígbà tí ó gun orí oyè ní ilẹ̀ Juda, ọdún mẹtadinlogun ni ó fi jọba ní Jerusalẹmu, ìlú tí OLUWA yàn láàrin gbogbo ilẹ̀ Israẹli fún ìjọ́sìn ní orúkọ rẹ̀.
 a máa ń lo fíìmù láti ṣẹ ̀ fẹ ̀ , láti dá àwọn ènìyàn lára yá , gẹ ́ gẹ ́ bí irinṣẹ ́ ńlá tí a fi ń kọ àwọn ará ìlú ní nǹkan tuntun .
Nigba to n salaye bi isẹlẹ naa se waye fun awọn akọroyin, Ajagunode tilu Ode, Ọba Sunday Boboye ni oun ti gba idajọ lori ilẹ naa lọdun 2017 ati 2019, tawọn eeyan Isinigbo ko si gbe igbesẹ lati tako idajọ ọhun nile ẹjọ Kotẹmilọrun.
Ọgbẹni Adeṣina beere lọwọ wọn bo ya wọn o tọrọ aforiji lọwọ Aarẹ Buhari ati aw\\pm ọmọ orilẹede Naijiria nibayii ti aarẹ ti pada si Naijiria.
Ajọ ọhun tun kede ọtalenigba le mẹta (263) eeyan to gbawosan, ti wọn si ti ni ki wọn maa lọ sile wọn layọ ati alaafia.
Wọ́n run gbogbo àwọn ará ìlú náà patapata: atọkunrin, atobinrin, àtọmọdé, àtàgbà, àtakọ mààlúù, ataguntan, ati kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́; gbogbo wọn ni wọ́n fi idà parun.
Bí mo ṣe ṣẹ́gun Coronavirus rèé - Seyi Makinde Coronavirus: Ọmọ márùn ún ni mo ní, ṣùgbọ́n kò sí oúnjẹ fún wa lásìkò ìgbélé yìí -Olùgbé ìlú Eko Èèyàn mẹ́fà míràn tún ti ní àrùn Coronavirus ní Naijiria Kí ló mú àwọn aládùúgbò Mọ́ṣáláṣí Alhaja kọlu àwọn ọlọ́ọpàá?
  Awon atundi ibo naa yoo waye
Balogun iko agbaboolu orile-ede Portugal, Cristiano Ronaldo, leni ti o tun gba ami-eye agbaboolu ti o darajulo lagbaye keyin, ti darapo mo iko agbaboolu Juventus lati inu iko Real Madrid pelu owo ti o to millionu márùndínláàdọ́fà owo pounds(105 million pounds).
O óo fi kún ọlá mi,o óo sì tún tù mí ninu.
 gbigba ominira orílẹ ̀ -èdè guinea-bissau mozambique àti angol kò sàì lọ ́ wọ ́ ipa ti orílẹ ̀ - èdè brazil kó nínú .
Ọlọ̀tẹ̀, aláìgbọràn ni gbogbo wọn,wọn á máa sọ̀rọ̀ eniyan lẹ́yìn.
 Bakana naa, ni won yoo maa se ipade pelu alaga igbimo ijoba Duma,ogbeni  Vyacheslav Volodin, ati igbakeji minisita fun ile okeere lorile ede Russia,ogbeni Mikhail Bogdanovlai  lati jroro nipa ibasepo laarin orile ede Naijiria ati Russia.
Hall sọ pe, eto naa yoo fi aye silẹ fun awọn akoroyin mẹta to jẹ akanda lati ṣiṣẹ fun oṣu mẹta, bẹrẹ lati ọsun kẹrin ọdun 2020.
Oríṣun àwòrán, Ooni Palace Àkọlé àwòrán, Awọn ọba wipe pataki ni isọkan laarin gbogbo ẹya ilẹ lorilẹede yi O fi kun ọrọ naa wipe awọn ọmọ orilẹede yi gbọdọ fimọ sọkan lori isọkan orilẹede yii.
Alaafin: Wo arẹwà mẹ́jọ̀ tó ń ṣìkẹ́ Ọba Adeyemi
Oronpoto Animation: Akin Alabi ní kò dára bí eré aláwòrán fáwọn ọmọdé ṣe jẹ́ aláwọ̀ funfun Ẹyìn tí Hydroxychloroquine, Zinc ati Zithromax da lára yá,ẹ bọ síta wà jẹrìí mí-Dr Stella Emmanuel Ọ̀pọ̀ òkú ṣùn, dúkìá jóná nínú àkọ̀tun ìṣẹ̀lẹ̀ ìbúgbàmù gáàsì l‘Eko Tí ìjọba kó bá dẹ́kun ìpànìyàn ní Gúúṣù Kaduna, aráàlú yóò jà fúnra wọn - CAN Daura ni ọpọlọpọ eniyan n sapejuwe bii ọkan lara awọn to lagbara ju ninu iṣejọba aarẹ Muhammadu Buhari.
Ààrẹ Biya ree tó ń gba $610,000 owó osù lọ́dún, ó ti sèjọba fún ọdún 35 Èéfín gẹnẹratọ gbé ayálégbé délé ẹjọ́ Ìyansẹ́lódì ASUU mú káwọn akẹ́kọ̀ọ́ kan dunnú Ọsinbajo kó Ambọde, Sanwo-Olu lẹ́yìn láti pín owóyàá l‘Eko Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Minimum wage: Àwọn ọmọ Nàìjíríà sọ èrò wọn lórí ìyanṣẹ́lódì àwọn òṣìṣẹ́ Lara awọn ohun ti wọn si fi pẹtu sawọn osisẹ lọkan pe iyansẹlodi naa ko wulo mọ ni pe, igbimọ tijọba gbe kalẹ ati ẹgbẹ osisẹ yoo joko sepade, ti wọn yoo si fẹnu ọrọ jona.
Ipade naa ni yoo da lori ona ti ibasepọ orile ede Naijiria ati Britain yoo se tubo fese mule sii.
Aláàfin ní tí kìí bá ṣe òṣèlú ni, Ìwó ló yẹ kó jẹ́ olú ìlú ìpínlẹ̀ Osun
Ọjọgbọn Otubusin to jẹ baba ìkókó naa jẹ ọmọ aadọrin ọdún.
Sotitobire: Ọlọ́pàá ní ₦800,000 ní àfurasí náà ń bèèrè láti fi ọmọ tí wọn ń wá sílẹ̀
A jẹ́ ohun ìríra fún àwọn eniyan.
Ninu ọ̀rọ̀ rẹ̀, Àarẹ Muhammadu Buhari sọ pé, wàhálà àwọn darandaran níí se pẹ̀lú làáṣìgbò tó ṣẹlẹ̀ nílẹ̀ Libya lẹ̀yìn iku ààrẹ Muammar Ghaddafi.
Eleyi jẹ ki èrò fẹ́ràn rẹ púpọ̀.
ti iroyin kan sọ pe osupa ti yọ, ni eyi ti o tumọ  si pe awẹ Ramadhan
Bi awọn olowo ba le san owo nla, ki wọn fi le ri ina ọba lo, ki ni ki awọn mẹkunnu ṣe?
Àwọn ológun ti mú ààrẹ orílẹ̀èdè Mali, Boubacar Keita Awọn ologun ti mu aarẹ orilẹede Mali ni ọjọ Iṣẹgun lẹyin wakati diẹ ti wọn bẹrẹ iditẹ mọ ijọba ni ibudo ologun Kati Camp.
Ó wá bi Jesu pé, “Ta ni ọmọnikeji mi?
Ọ̀kan lára àwọn mọ̀lẹ́bí olóògbé náà kan tí kò fẹ́ kí wọ́n dárúkọ rẹ̀ ló fi ọ̀rọ̀ yìí tó aṣojúkọ̀ròyìn BBC Yorùbá, Rótìmí Ọ̀kédáre létí nílùú Ìbàdàn.
"Sùgbọ́n gbogbo ǹkan to wà nínú ìgò náà tó ń jẹ́ jìínì ti fójú hàn báyìí nígbà ti Adebimpe kédé pé, ọbẹ̀ ti àwọn ń se ti jina tan O ní àkọlé eré ti àwọn ṣe pọ̀ náà ni ""Resentment'' Oríṣun àwòrán, Adebimpe Ọ̀pọ̀ ọmọ Nàìjíríà ló ti ń ṣe sàdánkáta kare sí wọ́n lóri sinimọ agbélé wò náà."
Ọ̀pọ̀lọpọ̀ òkú ẹyẹ igún ré bọ́ lọ́jà Eke-Ihe Àwa ò mọ ẹgbẹ́ kankan tó ń jẹ́ fijilanté fulani l'Ondo- Ìjọba ìpínẹ̀ Ondo Ilé ẹjọ́ sún ìgbẹ́jọ́ Sẹ́nétọ̀ Elisha Abbo tó lu obìrin Oṣiṣẹ LASTMA yii yombo ajọ LASTMA ati ohun gbogbo ti wọn ṣe fun un ki inu rẹ le dun lẹnu iṣẹ oojọ rẹ.
Ikọlu naa gẹgẹ bi ohun ta ri gbọ waye nigba tawọn ikọ ipolongo mejeeji pade ni ilu Oba Akoko ni ijọba ibilẹ Akoko West.
perry dúró sí iwájú yàrá ààbò pẹ ̀ lú ọbẹ lọ ́ wọ ́ , tí ó sì ń dúró de àwọn ajalèlókun tí wọ ́ n n wá àwọn ẹgbẹ ́ atukọ ̀ lati gba ṣakóso ọkọ ̀ lọ ̣ ́ wọ ́ wọ ́ n pẹ ̀ lú ìgbàgbọ ́ pé wọn á wa ọkọ ̀ náà lọ sí somalia .
Ta ló sọ èyí láti ìgbà laelae?
O bawọn kopa ninu agbekalẹ awọn eto bi abadofin igbejọba kalẹ ọdun 2012,atunto iwe ofin Ghana ọdun 1992 ati abadofin to n risi bi wọn ṣe n ṣagbatẹru ẹgbẹ oṣelu.
Aṣofin Sanai Agunbiade ṣoju fun sọ pe ijọba ni lati wa owo lati fi ṣiṣẹ
Àwọn ọkunrin náà lọ títí dé odò Jọdani.
BBC Yorùbá tún rí owó táwọn ẹrú yìí ń ná nígbà náà àti ẹ̀wọ̀n tí wọ́n ń so mọ́ wọn lẹ́sẹ̀ pẹ̀lú irin ọrùn wọn.
"Nigba ti awọn akọroyin bere idi ti o fi ti ile pa, aṣofin Oloyelogun ni ""ofin ilana ile fun oun laṣẹ lati ṣe bẹẹ."
Jehoiada yan àwọn aṣọ́nà fún ilé OLUWA, lábẹ́ àkóso àwọn alufaa, ọmọ Lefi, ati àwọn ọmọ Lefi tí Dafidi ti ṣètò láti máa rú ẹbọ sísun sí OLUWA bí a ti kọ ọ́ sinu ìwé òfin Mose, pẹlu àjọyọ̀ ati orin, gẹ́gẹ́ bí Dafidi ti ṣètò.
Kò sí bí ìlú tàbí orílè-èdè kan kò se ní ní ọ̀kan nínú àwọn àwọn ìṣòro wọ̀nyí.
"Ẹkẹta, Ẹ gbee lọ sile ẹjọ"" Oríṣun àwòrán, Kate Henshaw Òkú èèyàn mẹ́jọ ni wọ́n yọ níbi ìṣẹ̀lẹ̀ ìjàmbá ọkọ̀ nílùú Eko lọ́jọ́ Aje Ẹ̀mí ogójì ṣòfò, ọgọ́ta míràn farapa nínú ìjàmbá ọkọ̀ epo tó jóná Ẹwẹ, agba ọjọgbsn lori ọrọ oṣelu ati imọ ofin, Akin Oyebọde ti ke si igbimọ to n mojuto ẹtọ ati eto nile asofin agba, (Senate Ethics and Privileges Committee) lati tete gbe igbesẹ to tọ lori ọrọ ọhun."
O ni:’’iru isẹlẹ bayii ko jẹ ohun tuntun nitori pe o ti sẹlẹ lọdun 1947 ri, sugbọn iyipada oju-ọjọ lo tun jẹ ki wahala yii tun pọ si, nitori ilẹ ati awọn ohun alumọọni ilẹ ti ko tun to.
Ó ní kí wọ́n tún ṣe bẹ́ẹ̀ lẹẹkẹta, wọ́n sì tún ṣe bẹ́ẹ̀.
 Àbá ti ń wáyé nípa pé kí àtúnṣe wà fún àkọtọ ́ yìí .
 ibi tí ó tan yanrìn náà de ni òkun , ibi tí odùduwà wá tẹ ̀ dó sí ni ilé-ifẹ ̀ .
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Cbocbo oju wà lára Theresa May bayii Ki ni Theresa May yoo ṣe to ba ni ijakulẹ Awọn ti o n ba May ṣiṣẹ ni awọn gan ko mọ oun ti olori ijọba naa yoo ṣe to ba ja kulẹ.
Mo gbójú sókè wo àwọn òkè,níbo ni ìrànlọ́wọ́ mi ti ń wá?
28,757 ni agbegbe ti idibo yoo ti ma a waye.
Agba ilu kan, to fi idi eewọ naa mulẹ ni, ohun kan lo fọ lati ọrun si awọn baba nla awọn pe awọn ko gbọdọ bi ọmọ, sin oku tabi ẹran sinu ilu naa, tori ilu mimọ ni.
Awọn afurasi ọdẹ ẹgbẹ rẹ ṣalaye fawọn mọlẹbi ọkunrin naa pé bi erin ṣe tẹẹ nibi ti awọn ti n ṣọdẹ ni àwọn kinihun kan yabo awọn ti wọn si jẹ ẹran ara ẹ.
“Ní sùúrù fún mi díẹ̀, n óo ṣe àlàyé fún ọ,nítorí mo ní ohun kan tí mo fẹ́ gbẹnusọ fún Ọlọrun.
NIMC Mobile App: Wo bí o ṣe lè gba nọ́mbà NIN rẹ tàbí so ó pọ̀ mọ nọ́mbà fóònù rẹ lórí App tí NIMC ṣẹ̀ṣẹ̀ ṣe Oríṣun àwòrán, Nimc Awọn ọmọ Naijiria ti le lo ẹ̀rọ ibanisọrọ alagbeka wọn bayii lati gba nọ́mbà idanimọ NIN, lai ṣẹṣẹ ma a to.
Wọn tun pada dibo yan an ni 1997.
O ni ninu gbogbo ohun wọnyii eleyi ti wọn ni ijọba apapọ gbe kalẹ yii lo kere ju ati pe kii tilẹ n ṣe gbogbo fasiti lo kan.
Àwọn ọmọkunrin Iṣimaeli nìwọ̀nyí bí a ti bí wọn tẹ̀lé ara wọn: Nebaiotu, Kedari, Adibeeli, 
Awọn obinrin si ni isẹlẹ naa maa n kan julọ, ti kii si saba wọpọ pe ki obinrin fipa ba ọkunrin lopọ.
Ó tún rán ẹyẹ àdàbà kan jáde láti lọ wò ó bóyá omi ti gbẹ lórí ilẹ̀, 
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ọ̀pọ̀lọpọ̀ ǹkan ni àwọn ènìyan ń bèèrè lọ́wọ́ Buhari lásìkò yí Busayo Akogun Broadcast Journalist, BBC Yoruba 9 Bélú 2018 Oríṣun àwòrán, @MBuhari/Twitter Àkọlé àwòrán, Awọn kan n fẹ ki Aarẹ Buhari din iye ti wọ̀n n ta jaala epo bẹtiro ku.
” Bẹ́ẹ̀ ni ó ṣe sọ̀rọ̀ ìtùnú fún wọn, tí ó sì dá wọn lọ́kànle.
Samuel Abdulraheem ko ranti ọjọ tabi bi wọn ṣe ji i gbe nile awọn obi rẹ nilu Kano nigba o wa ni ọmọ ọdun meje.
Ìjàmbá oríṣi ni ó máa ń ṣẹlẹ̀ nínú ẹbí ní ìlú, pàápàá jù lọ ní àárín àwọn tí ó ń ṣiṣẹ́.
O ni yoo dara ki onitọun maa bu ọwọ to tọ fun awọn ilumọọka nitori ko mọ ohun ti awọn n la kọja, ọpọ nkan si lo wa lori ero awọn, idi si ree ti esi aọn si isẹlẹ kọọkan fi n yapa nigba miran.
Àkọlé àwòrán, Rene fi ibi toti f'arapa han olukoroyin BBC 'Awọn Sọja tu mi sihoho' Ọpọ ninu awọn atipo naa sọ wipe awọn soja orilẹede Cameroon fi ilọkulọ lọ awọn.
Ìsọníṣókí Ẹ̀mí márùn-ún bọ́ nínú ìjàmbá ọkọ̀ ní márosẹ̀ Eko sí Ibadan l‘Ọ́jọ́rùú Nàíjíríà jẹ gbèsè ₦6tr láàrin ọdún kan ṣoṣo - NBS Nǹkan yan!
Àwọn arẹwà obinrin Yollywood, tá ló mọ iṣẹ́ rẹ̀ jù?
Ẹwẹ, agbẹnusọ ileeṣẹ ọlọpaa ni ipinlẹ ọhun, Daniel Ndukwe ti sọ fun BBC pe kọmiṣọna ọlọpaa ipinlẹ naa ti paṣẹ pe ki iwadiii bẹrẹ lori ọrọ ọhun.
Ẹni ti wọn f'ẹsun kan naa, nigba ti o de'waju adajọ, ti orukọ rẹ n jẹ A.
"O damiloju wipe ijọba Buhari ni wọn fẹ fi ijinigbe yii koba.
Àwọn alákatakítí pa ènìyàn 19 ní Borno Oríṣun àwòrán, AFP Àkọlé àwòrán, Ikọlu yi n waye lẹhin ti ile isẹ ọmọogun orilẹede Naijiria ti figa gbaya wipe awọn ti bori Boko Haram.
”Osinbajo ni oun mo pe awon omo
Ọlọ́run nìkan ló mọ bí ìrìnàjò ìfẹ́ ẹ̀dá á ṣe rí láyé, ọ̀dọ́ Aláàfin ní orí gbémí yà sí, ó sì tẹ́milọ́rùn- Olorì Aanu Wo ọ̀nà tí àwọn ‘ẹ̀lẹ̀ Daddy’ gbà dé ààfin Ọyọ Olori Anu, ninu igbe to fi bọnu naa, tun tẹsiwaju pe a kii dakẹ ku, ẹnikan kii si wo sun daran, idi si ree ti oun ko fi ni panumọ nitori ewu to n rọ dẹdẹ lori oun.
O ni: Bayii kọ ni wọn ṣe bi i, ọta ibọn awọn ọlọpaa lo sọ ọ di bayii latọdun 1996 ni Ibadan""."
Sugbon a ko ni agbara lati dekun bi oja se n wole si orile ede wa, bakan naa , ni orile ede wa ki i se orile ede ti iresi fayawọ pari si.
Ẹ̀rù kò ní bà á nígbà tí ẹ̀ẹ̀rùn bá dé,nítorí pé ewé rẹ̀ yóo máa tutù minimini.
Ọ̀nà alùmọkọ́rọ́yí ni wọn n gbe e gba.
 Àwọn ònà tóóró tí ó ń jẹ ́ kí wọn mọ ònà ibi tí ọkọ ̀ ojú omi gbà ń fa ààyè fún ìjalèlókun , tí ó tún ń fa ààfàní fún idigun ja ọkọ ̀ ojú omi àti oníṣowò ojú omi .
Awọn oluwadii si ni o ṣeeṣe ki wọn lo awọn apani-gbowo.
Nígbà tí àwọn ọmọ Israẹli rí i pé ilẹ̀ ti ká àwọn mọ́, nítorí ọwọ́ àwọn ọmọ ogun Filistini dùn wọ́n, wọ́n bá ń farapamọ́ káàkiri; àwọn kan sá sinu ihò ilẹ̀, àwọn mìíràn sì sá sinu àpáta, inú ibojì ati inú kànga.
Bí ojú ohun tí wọ́n ṣe bá tì wọ́n, ṣe àlàyé Tẹmpili náà, bí o ti rí i, ẹnu ọ̀nà àbájáde ati àbáwọlé rẹ̀.
Wọn n ṣe eto yii ni iranti Imam Hussein, ọmọ ọmọ Anọbi to ku ninu ogun Karbala.
Lẹyin iṣẹju mẹta ti wọn bẹrẹ abala keji ere bọọlu ọhun ni adilemu, Marcos Alonso gba ayo keji sawọn Tottenham Chelsea.
BBC Yorùbá gba àmì ẹ̀yẹ akọni nídìí àgbéga àṣà àti èdè abínibí Bakan naa ni olukọ salaye pe, iye igba ta ba ni imọ afẹfẹ latinu ẹdọ fooro wa, lo n sọ iye Silebu to wa ninu ọrọ kan.
10 Àlàyé rèé lórí ìdí tí mo fi lọ sílé Tinubu - Rashidi Ladoja BBC News, Yorùbá Ìdí tí ẹ fi le è nígbàagbọ́ nínú ìròyìn BBC Ìlànà Lílò Nípa BBC Òfin Àṣírí Cookies Kàn sí.
Ijọba ipinlẹ Eko sọ pe ki awọn eniyan o yago fun ipejọpọ to ba ti le ni aadọta eniyan.
Iroyin ọsẹ diẹ ṣẹyin ni iya awọn ọkunrin mejeeji ku.
Dolapo Badmus: Abayomi Shogunle, Dolapo Badmus ṣì wà lẹ́nu iṣẹ́ ọlọ́pàá-PSC
Àwọn ọmọ àti ọmọ-ọmọ yi o ṣe oriṣiriṣi ẹ̀yẹ ìbílẹ̀ fún ọ̀pọ̀lọpọ̀ ọjọ́ lati gbé ìyá tàbi àgbà bàbá àgbà relé.
Ìṣẹ́ ló jẹ́ kí n sọ ọmọ nù sórí ààtàn- Dupẹ, Ìyá Muiz Adebayo Ojo ni lati Ilawẹ Ekiti lọ si ọgba SARS ni Ado Ekitit ko to di ero Maximum Security Prison ni eko ni irinajo yii O ni lọdun 2003 ni oun ti ko sii ko to bọ ni 2019.
Makinde ni ajumọṣe ijọba atawọn araalu ni idagbasoke awujọ.
Àwọn angẹli meje tí wọ́n ní àjàkálẹ̀ àrùn meje níkàáwọ́ jáde láti inú Tẹmpili náà wá, wọ́n wọ aṣọ funfun tí ó ń tàn bí ìmọ́lẹ̀.
Ni bayii, yoo bọ si abe eka to n mojuto ise akanse Department of Operations  FSARS pẹlu iyipada tuntun yii.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Kwara: Agbófiró mu àwọn ajọ́mọgbé méjì 27 Ẹrẹ̀nà 2018 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Alamí ló ta àwọn agbóòfiró lólobó nípa ìwà láabi àwọn amòkùnṣìkà yii Ọwọ́ àwọn agbóòfiró ti tẹ àwọn èèyàn kan fún ẹ̀sùn ìjínigbépa ńìpínlẹ̀ Kwara.
Ọrọ kan ṣoṣo maa n tumọ si nkan mẹrin nigba mii tabi ju bẹẹ lọ ni eyi ti ami ori wọn maa n fi iyatọ han bii ìgbà, igbà, ìgbá, àti igba.
Tribunal: Ẹ wo márùn ún lára àwọn tí ilé ẹjọ́ dá dúró lẹ́yìn ìdìbò ọdún 2019
''Ohun ti mo fi sọrọ ni pe awọn ọmọ ọdun mẹta ati ọdun meje miiran tun le ni iru iriri buruku ti mo ni yii lọpọ ọdun sẹyin.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, O le ni ẹgbẹrun meji eeyan to ti di atipo nitori Boko Haram Ṣe ikọlu Boko Haram ti dinku?
Aishat Lola: Kò s'óhun tí mo ṣe tó tẹ́ ìyá mi lọ́rùn
ile igbimo asofin tun ro ijoba apapo lati se atunse lori ilana eto-ẹkọ ti awon
Ìjọba ló ń ṣe kóríyá fún àlàfo ńlá láàrin ọlọ́rọ̀ àti mẹ̀kúnnù - Oxfam Dúkìá àti ọkọ̀ jóná, ọlọ́pàá mẹ́sàn-án fara gbọta lásìkò ìwọ́de Shiite Gba owó lọ́wọ́ àkẹ́kọ̀ọ́ ìjọba, ko rugi oyin - Seyi Makinde Iṣu ló wà nínú mọ́tò mi, kìí ṣe èèyàn ni mo sọ di iṣu - Afurasí Ajínigbé figbe ta Ẹ yé irọ́ pa, mí o fún Super Eagles ní ẹbùn owó kánkan -Sanwo Olu Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí kan sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
"Iṣakoso ti wa yoo mu ipese ohun elo amayedẹrun lọkunkundun""."
Ọmọ Hẹrọdiasi obinrin bá wọlé, ó bọ́ sí agbo, ó bẹ̀rẹ̀ sí jó, inú Hẹrọdu ati ti àwọn tí ó wà níbi àsè náà dùn.
Mliswa so pe :“Aare ana, olola julo, Cde RG Mugabe ni ko lee yoju sile igbimo asofin ni wakati ti a fun un,sungbon leyin ijiroro pelu abenugan ile igbimo asofin , won ti fi sile  lati maa yoju mo.
Ẹmi mẹrin ṣ'ofo, mẹrindinlogun f'arapa ninu ijamba ọkọ ni Lekki
Lizzy Anjorin sun ẹkún ìyàwó, èèyàn kan fún un lẹ́bùn aṣọ funfun láti mọ ìbálé rẹ̀ Wo àwọn Gómìnà Naijiria tí àrùn Covid-19 ti bá fínra Èèyàn 576 míràn tún kún àwọn tó ní àrùn COVID-19 ní Nàìjíríà Eeyan Ọrinlelẹẹdẹgbẹta o din mẹrin ni ajọ to n gbogun ti ajakalẹ arun lorilẹede Naijiria, NCDC tun kede ni alẹ ọjọ Iṣẹgun, ọjọ kọkanlelogun oṣu keje pe ayẹwo tun fihan pẹlu arun coronavirus.
Ṣugbọn bí o bá kọ̀ láti jọ̀wọ́ ara rẹ ohun tí OLUWA fihàn mí nìyí: 
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsèjẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọ Ọgbẹni Gbadamosi tun sọ pe, Naijiria ko ni agbara lati pese gbogbo nnkan ti araalu nilo, paapa awọn nkan ti ẹnu n jẹ bi irẹsi ati ẹja.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Akomolede àti Aṣa: Ọ̀rọ̀ Ẹ̀yán ni Bunmi Femi Amao ń kọ́ wa lórí ètò Akọ́mọlédè àti Àṣà lóri BBC Yoruba Bakan naa ni ijọba gbe oriyin fun awọn to ṣe daadaa ninu idanwo naa,paapaa awọn olukọ ti ko fi aaye gba iwa magomago ni agbegbe wọn lasiko idanwo naa.
O wa ke sawọn ọmọlẹyin Kirisiti lati lo anfani ajọdun ajinde Jesu Kiriisiti lati fi wolẹ adura fun orilẹ-ede Naijiria ki orilẹ-ede yii lee la afonifoji to wa lọwọ yii kọja.
Iranṣẹ náà dá a lóhùn, ó ní, “Dúró ná, eniyan Ọlọrun kan wà ní ilẹ̀ yìí, tí gbogbo eniyan ń bu ọlá fún, nítorí pé gbogbo ọ̀rọ̀ rẹ̀ níí máa ń ṣẹ.
Aarẹ orilẹ-ede Malawi, Peter Mutharika ni awọn eniyan ti di ibo yan fun saa keji pẹlu ibo to le ni ida mejidinlogoji.
meje,aaago ọwọ meta, kaadi idanimọ ati egberun merindinlogun naira.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù #EndSARS: Shogunlẹ ní ẹ̀sùn ìdigunjalẹ̀, ìjínigbé ni FSARS yóò mójútó 11 Òkùdu 2018 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 19 Ògún 2018 Oríṣun àwòrán, POLICENG_PCRRU/TWITTER Ileeṣẹ ọlọpa Naijiria ti ṣetan lati maa ṣe ayẹwo ọpọlọ ati awọn ayẹwo ara mi i fun awọn oṣiṣẹ FSARS.
Lẹyin naa lo tun lọ tẹdo silu Badagry laarin ọdun 1830, nibiti owo ẹru ti gbilẹ, to si mọ ilu naa bii atẹlẹwọ rẹ nitori o sunmọ ilu Porto Novo to ti se ẹru tẹlẹ.
Ajọ to n risi ọrọ to niṣe pẹlu gbigbogun ti lilo ogun oloro, NDLEA ṣe iwadii lori ọrọ Zainab ti wọn si ni ọwọ ti tẹ eeyan meje to n ṣiṣẹ ni papakọ ofurufu Aminu Kano.
Ile igbimo ohun wole pada loni lati olude olojo gboro, eleyi ti won ti wa ninu re fun osu meji latari olokan-o-jokan idibo abele awon egbe oselu patapata ti o sese pari.
Ipo ate iko agbaboolu orile-ede mewa nile Afrika ni itele n tele lori tabili.
wọ́n ń kígbe pé, “Ẹ̀yin eniyan Israẹli, ẹ gbani o!
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Air Canada: Obìnrin to jí nínú òkùnkùn nínú ọkọ̀ òfurufú 24 Òkùdu 2019 Oríṣun àwòrán, others Àkọlé àwòrán, Air Canada: Obìnrin to tají nínú òkùnkùn nínú ọkọ̀ òfurufú Irinajo lati Quebec lọ si Toronto di a-lọ-di-oru -Tiffani Adams.
Nígbà náà ni ọ̀kan ninu àwọn mejila, tí ó ń jẹ́ Judasi Iskariotu, jáde lọ sọ́dọ̀ àwọn olórí alufaa.
Ilẹ Gẹ̀ẹ́sì le è ní olóòtú ìjọba tuntun láìpẹ́ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Lagosollapsedbuilding: Àwọn èèyàn ìpínlẹ̀ Eko ní ìjọba, aráàlú lọ́wọ́ nínú bí ilé ṣe ń wó Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
kí ó lè sọ ọ́ di mímọ̀ ní àkókò yìí láti ọ̀dọ̀ ìjọ, kí ó sì lè fihan àwọn alágbára ati àwọn aláṣẹ tí ó wà ninu àwọn ọ̀run bí ọgbọ́n Ọlọrun ti pọ̀ tó ní oríṣìíríṣìí ọ̀nà.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Yoruba Stars in Hollywood / Europe: Sade Adu, Chamillionaire, Sikiru Adepoju wà lára ọmọ Oodua tó jẹ́ àmúlùúdùn níbẹ̀ 23 Agẹmo 2020 Yoruba ni ti ọmọ ẹni ba dara, o yẹ ka wi, kii ṣe pe a fi ṣe aya.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Oyenusi ló mú mi wọ ẹgbẹ́ adigunjalè kó tó di pé mo b'Ólúwa pàdé' Aarẹ orilẹede Ghana ni ẹka eto ẹkọ ti ṣe gbogbo eto ti ko ni jẹ ki awọn akẹkọọ padanu nkankan to yẹ pẹlu bi wọn ko ṣe lọ sileewe lọdun yii.
Ènìyàn 653 míràn tún kún iye àwọn tó ní COVID-19 ní Nàìjíríà Akeredolu yan ọmọ Ilajẹ gẹ́gẹ́ bíi igbákejì rẹ̀ tí wọ́n yóò jọ díje dupò ní Ondo Ìjọba àpapọ̀ ti gba 800 bílíọ̀nù padà lọ́wọ́ àwọn tó jí owó ìlú kó, àwọn 1,400 ti wà nínú ẹ̀wọ̀n -Lai Mohammed Toke Makinwa ti sọ̀rọ̀; Amcon náà dá a padà fún un pé.
Ijoba orile-ede Naijiria yoo pe ile ise iroyin Kankan to ba n satileyin tabi to n fon rere oro alufansa ati oro ikorira lejo.
Laipe yi ni iroyin kan ti awọn kan si bẹnu atẹ lu bi Aarẹ Buhari ti se fẹ gba ẹ̀yáwó $328 million lọ́wọ́ orílẹ̀èdè China.
Ó kó gbogbo àwọn ọmọ Juda ati àwọn ọmọ Bẹnjamini jọ, ati àwọn tí wọ́n wá láti Efuraimu, Manase ati Simeoni, tí wọ́n jẹ́ àlejò láàrin wọn.
“Mo fe dupe lowo awon osise, awon agbaboolu, oludari gbogbo, ati papajulo awon ololufe iko yii,  fun atileyin ati ife won ti o legbe ti won fi han si mi lati igba ti mo ti n tuko iko yii.
Bakan naa, ki Macron to di aarẹ ile Faranse, o sisẹ fun ọdun mẹrin pẹlu ile ifowopamọ ni orilẹede naa.
Awọn akọwe ile ẹjọ naa ni ṣe aajo rẹ lẹyin to fidijanlẹ sori aga.
Ó bá rán wọn pada, ó ní: “Ẹ lọ sọ fún ẹni tí ó ran yín sí mi pé, 
Ìdí rèé tí ẹ̀mí mi kò fi bọ́ sínú ìdìtẹ̀ gbàjọba tó pa Muritala Muhammed - Obasanjo Oríṣun àwòrán, Olusegun Obasanjo Presidential library Saaju la ti mu iroyin wa fun yin pe, Aarẹ orilẹede Naijiria tẹlẹri, Ọgagun Oluṣẹgun Obasanjọ, ti salaye bo ṣe jajabọ lọwọ ogun iditẹ gbajọba to waye lọdun 1976, ti ọgagun Buka Dimka dari rẹ.
Orí rẹ̀ dàbí ojúlówó wúrà,irun rẹ̀ lọ́, ó ṣẹ́ léra wẹ́lẹ́wẹ́lẹ́ó dúdú bíi kóró iṣin.
Gege bi adari ile ise olopaa se sọ, leyin
Lara awọn afurasi tile ẹjọ ni ki wọn gbe ni tipa tikuuku lori ọrọ epo Malabu ni minisita fọrọ epo rọbi nigbakan, Dan Etete, Adajọ ati agbẹjọro agba tẹlẹ fun ilẹ wa, Mohammed Adoke pẹlu awọn eeyan miran ti wọn fi ẹsun kan pe ọwọ wọn ko mọ nidi katakara ibudo epo Malabu.
Insecurity: Ọọ̀ni ni báwọn ọba alayé ṣe lọ́wọ́ nínú àgbékalẹ̀ Amotekun, ni yóò ṣe tọ́jọ́
ati Bakibakari, Hereṣi, Galali ati Matanaya ọmọ Mika, ọmọ Sikiri, ọmọ Asafu, 
ti  odun 2018 to koja yii, ni eyi ti yoo
Nigbà tó bá BBC Yorùbá sọ̀rọ̀, agbẹnusọ fún ọgbà ẹ̀wọ̀n ìpínlẹ̀ Eko, Rotimi Oladokun ni kò sí ẹyọ òótọ́ kankan nínú ìròyìn òfégè tí àwọn ilé iṣẹ́ ìròyìn kan ń gbé jáde pé ọmọ ọ̀dọ̀ náà ti kú.
Ṣugbọn ẹni tí ó bá forítì í títí dé òpin, òun ni a óo gbàlà.
Bakan naa, ajo to n ri si sise agbekale ile-iwe giga fafiti Nigerian Universities Commission ni yoo se abewo ise akanse ohun ti o ba pari.
iru ni ohun ti a mọ si locust beans ni ede gẹẹsi .
‘Daily Trust fi àsírí ìgbógun tí Boko Haram jáde la se tì í’ 'Boko haram kọ́ ló fa ìbúgbàmù Mubi' 'Mo mọ bí Boko Haram ṣe bẹ̀rẹ̀' Bi awọn ọmọogun ti ṣe n de ibi iṣẹlẹ naa lati doola ẹmi ni ibugbamukeji waye nibi aye ti awọn eeyan wa ọkọ si.
"'Ìdí tí kámẹ́rà táa rí ní Lekki Tollgate kò fi ká gbogbo ìṣẹ̀lẹ̀ tó wáyé rè é' ""Àwọn sójà ní mo káàbò sí ilé ìṣerun àgbáyé tí wọ́n tí ń ṣerun bó ṣe wu wọ́n"" Ìjọba ti buwọ́lu lílo hijab láwọn iléèwé ní ìpínlẹ̀ Osun Ọwọ́ ọlọ́pàá ti tẹ afurasí mẹ́ta tó lọ́wọ́ nínú ìjínigbé alága Iganna l'Oyo Awọn ijọba ibilẹ ti igbesẹ yii ta ba ni: Akinyele East LCDA; Ido LG; Oluyole LG; Ibadan North East LG; Lagelu West LCDA; Soro LCDA ati Ogbomosho Central LCDA."
Wọn ni ninu igbo Kodunga lawọn ti paa nigba ti awọn ọmọ ogun Naijiria gbena woju awọn agbesunmmi naa.
Folashade ni igbakeji ẹka idagbasoke fun giwa to wa nibẹ tẹlẹ, Oluwatoyin Ogundipe.
Ṣugbọn ṣá, ẹ di ohun tí ẹ ní mú ṣinṣin títí n óo fi dé.
Juda yẹ̀ wọ́n wò, ó sì mọ̀ wọ́n, ó ní, “O ṣe olóòótọ́ jù mí lọ, èmi ni mo jẹ̀bi nítorí pé n kò ṣú ọ lópó fún Ṣela, ọmọ mi.
14) Maa fi igbagbogbo pa Blutooth ti a fi n fi nkan ranṣẹ ati ayelujara wi-fi ti o ko ba nilo wọn nigba gbogbo tabi ki o fi si ti o ba wa lori afẹfẹ.
O nira fun awọn arugbo laarin wa lati rin bi awa ọmọ de ti n se, ti awọn ọta yii si n dunkoko pe awọn yoo ge ori wọn bọ silẹ, haa, ọjọ buruku, esu gbomi mu ni.
Lọjọ Ẹti si Abamẹta iye awọn tuntun to ni Covid-19 ja wa silẹ lati 462 si 386.
Ó sàn fún ọ kí o wọ inú ìyè pẹlu ojú kan jù pé kí o ní ojú meji kí á sọ ọ́ sinu iná ọ̀run àpáàdì lọ.
Orílẹ̀èdè Amẹrika ti bẹ̀rẹ̀ sí ní wo wọlé-wọ̀de Atiku, àwọn ìyàwo rẹ̀ lórí owó tí wọ́n kó lọ sí òkèèrè Lawuyi Ogunniran, àgbà ọ̀jẹ̀ òǹkọ̀wé Eégún Aláré dágbére fáyé!
Wọ́n ní “Àṣejù ni bábá àṣetẹ́”.
00) níbi tí kò ti sí ẹni tí ó tún fún un ju náírà márùn-ún lọ.
Nígbà tí ó ṣe o lé mi dé ibi odo ńlá jíjìn kan, ibẹ̀ lo sì ti ní ìrètí àti mú mi.
Àwọn òbí ni ó yẹ kí ó pèsè fún àwọn ọmọ.
Oríṣun àwòrán, @HQNigerianArmy Àkọlé àwòrán, Ọpọ awọn afyrasi lọwọ tẹ ti aimọye si jajabọ mọ awọn alaṣẹ lọwọ Wọn salaye pe lẹyin ifọrọwanilẹnuwo pẹlu eeyan to to igba tawọn ṣe, awọn ri wi pe idaji awọn iku naa waye ni ọdun yi nikan.
Ahabu, ọba Israẹli bèèrè lọ́wọ́ rẹ̀ pé, “Ṣé o óo bá mi lọ gbógun ti Ramoti Gileadi?
Nítorí nǹkan ti yí padà, n kò dàbí ti àtẹ̀yìnwá, ojú mi ti là bí ojú ẹni ti ń kiri ẹ̀yìn odi, ìwà mi ti di gbajúmọ̀, n kò hùwà bí òmùgọ̀ mọ́, mo ti kúrò ni ipò ará oko.
Ìwọ ìrètí Israẹli,olùgbàlà rẹ̀ ní ìgbà ìṣòro.
Lori ẹsun yii, ileeṣẹ aarẹ ti sọ pe ko si ipinnu tabi erongba kankan lati fi ipa gba ilẹ lọwọ ẹnikẹni, to si fẹsun kan pe awọn kan lara awọn ipinlẹ ti ko nifẹ si eto naa lo n ṣi awọn araalu lọna.
Ó lọ pàdé Asa, ó wí fún un pé, “Gbọ́ mi, ìwọ Asa, ati gbogbo ẹ̀yin ọmọ Juda ati ti Bẹnjamini, OLUWA wà pẹlu yín níwọ̀n ìgbà tí ẹ̀yin náà bá wà pẹlu rẹ̀.
Tolla gate to wa ni Lekki-Ikoyi Ile itaja ShopRite Oríṣun àwòrán, TVC Ile itaja Cash n Carry, ni Lagos Island Ile itaja Spar ni Surulere Afin Ọba ilu Eko Oríṣun àwòrán, @jidesanwoolu Ileeṣẹ ọkọ oju omi ni Marina Ile iya Gomina ipinlẹ Eko, Babajide Sanwo-Olu to wa ni Akerele Bakan naa ni wọn tun jo ọọfisi awọn VIO ni Ojodu.
Ṣebí ohun tí wọ́n bá fẹ́ ninu ẹrù rẹ ni wọn óo kó?
Boniface yii ni awọn ọmọ igbmọ ni fasiti UNILAG yoo ṣe iwadii to yẹ lori ẹsun fidio naa ki fasiti Eko to mọ ohun to kan.
 níbẹ ̀ , ó ṣàwárí ìyàtọ ̀ ara rẹ ̀ gẹ ́ gẹ ́ bíi olóore ọ ̀ fẹ ́ àti abínibí òsèré àti olórin.
Ni ibẹrẹ ọdun yii ni Mercy ke gbajare pe o wu oun lati pada si igbeaye oun tẹlẹ nitori oniruuru ojuse lo wa ninu ki eniyan jẹ ilumọọka.
Iko agbaboolu obinrin orile-ede Naijiria, Super Falcons fagba han iko akegbe won Shepolopolo ti orile-ede Zambia pelu ami ayo merin sodo(4-0), ninu ifesewonse idije boolu obinrin tile Afrika ti o waye niluu Cape Coast, lorile-ede Ghana.
Apapọ awọn to ti ni arun naa kaaakiri orilẹ-ede Naijiria ti wa di 18,480 bayii.
Òkú ọmọ ọdún mẹ́ta tó kó sí kàǹga ní Ipaja ni wọ́n yọ' Ilé ẹrù míì tó jábọ́ l‘Eko tún mú ẹ̀mí obìnrin méjì lọ Ọkọ̀ rélùwéè 16 yóò ná Eko sí Ibadan láti oṣù tó ń bọ̀ lọ - Iléeṣẹ́ Rélùwéè kéde Ọba Ilorin ló pàṣẹ pé kí ń padà sọ́dọ̀ ọkọ mi - Risikat olójú búlúù Yatọ sí ìròyìn kan to sọ pé gbájúgbaja olùtaja àwọn èròjà àṣara àti irun lóge ni ọkùnrin náà to sì ni ṣọ́ọ̀bù ńlá ńlá ni àdúgbo Sango nílùú Ibadan àti pé o ṣẹ̀ṣẹ̀ ra ilé ńla kan ni, ilé iṣẹ́ ọlọ́pàá ni ọjọ́ sátide, ọjọ́ kejìlélógun ni ìṣẹ̀lẹ̀ náà wáye, àjọ ọlọ́pàá si ṣẹ̀ṣẹ̀ bẹ̀rẹ̀ ìwádìí lori ọ̀rọ̀ náà ni.
Ẹwẹ, loju opo instagram Ronke Oshodi Oke yii kan naa, awọn ọmọ Naijiria fesi si adura rẹ.
Gbogbo ijọ Olorun ni o ti n gbadura pe ayọ ati alaafia inu odun naa ni ko jẹ ipin awọn eniyan.
Ipinlẹ Sokoto to wa ni ẹkùn Iwọ oorun Ariwa ni oṣi pọ si julọ, pẹlu ìdá mọkanlelọgọrin, nigba ti ipinlẹ Eko, ni ẹkun Iwọ oorun Gusu wa ni ìdá mẹrinlelọgbọn.
Ibanuje d'orí agbà k'odò, Ruiz fi ẹ̀ṣẹ́ sọ Anthony Joshua di ọmọ ológo àná Liverpool da ata gúngún sójú Tottenham gba ife ẹ̀yẹ Champions League Ẹwẹ, agbẹnusọ fun Neymar fi ọrọ sita pe agbabọọlu naa fi gbogbo ẹnu kọ ẹsun naa pe oun ko mọ nipa rẹ.
O mà dára o, olólùfẹ́ mi;o lẹ́wà pupọ.
Ooni Ile Ife: Ooni Adeyeye Ogunwusi àti Olòrì Naomi gbé Àrẹ̀mọ tuntun wọ ààfin Ilé Oòduà
Ìyẹn ni pé kì í ṣe ìwọ ni ará Ijipti tí ó dá rúkèrúdò sílẹ̀ láìpẹ́ yìí, tí ó kó ẹgbaaji (4000) àwọn agúnbẹ lẹ́yìn lọ sí aṣálẹ̀?
Àwọn agbègbè tí àtùndi ìbò náà yóò kàn nípìnlẹ̀ Eko rèé Ilé iṣẹ́ ọlọ́pàá ìpínlẹ̀ Eko ti fi òfin de àwọn ìjọba ìbílẹ̀ Márùn-ún kan tí àtúdì ìdìbò sẹnatọ yóò ti wáyé lọ́ja àbámẹ́ta.
12 Sẹ́rẹ́ 2020 Fídíò, Oshiomole: Elijah Ayodele ti sọ̀rọ̀ ní ìbẹ̀rẹ̀ ọ̀dún lórí ohun tó ń ṣẹlẹ̀ lọ́wọ́ lẹ́gbẹ́ APC17 Òkùdu 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 3 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 5 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Ọgbà yìí rẹwà púpọ̀ ó sì máa nṣábàá dákẹ́ rọ́rọ́.
Iṣẹ́ rẹ̀ lọ́lá, ó sì lógo,òdodo rẹ̀ sì wà títí lae.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Fulani Kidnapping: Owó púpọ̀ la san kí wọ́n tó fi mi sílẹ̀ Bi Iyalufa ṣe n pẹyinda lati wọnu ile, ni Ọmọyẹ bẹrẹ si ni bọ asọ lara titi to fi wa ni ihooho ọmọluabi, to si ki ere mọlẹ, to n sare lọ sinu ọja to sun mọ adugbo wọn.
Oṣu mẹtala ni orilẹ-ede naa fi pin yẹlẹ-yẹlẹ, nitori awuyewuye to waye lori esi idibo ọdun 2019, ile ẹjọ fagile esi idibo naa.
River Niger to wa ni Iwọ-oorun ariwa ati River Benue tó n ṣan wa lati Ila oorun Cameroon.
Adams Oshiomole: Idí tí mo fi faramọ́ ìpinu NEC- Oshiomole
Ní ti àwọn ẹ̀yà Israẹli yòókù, láti ìlà oòrùn títí dé ìwọ̀ oòrùn, Bẹnjamini yóo ní ìpín kan.
Àwo ati abọ́ náà kún fún ẹbọ ohun jíjẹ.
o ba won wọya ijakadi , lati mu gbogbo wọn” .
5 6603540 Orilẹede India 140573 10.
Wọn óo sì mọ̀ pé èmi ni OLUWA.
Yatọ si awọn ti a ka silẹ yii, awọn ẹka oriṣiriṣi lo tun wa ninu ijọ CCC Genesis Global, to ma n ko ipa lasiko isin.
"Bí ẹ bá pa Dino, ẹ ti pa ìjọba tiwantiwa nìyẹn""@NnadiEdwin25 ""Big Brother ti tán, gbogbo nkan ti ń padà bọ̀ sípò, tó fi mọ́ bí wọn se mú Dino Mélayé""@Bolanle_AA."
Agbẹnusọ fún Ẹ̀ka Ìjọba tí ó ń ṣe àbójútó ètò ìforúkọsílẹ̀, Valdemar José, sọ fún àwọn akọ̀ròyìn ìbílẹ̀ Angola pé ìdíyelé fún ìwé ìrìnnà ìwọ̀lú lásán-làsàn lọ sí òkè nítorí owó gegere ni ó ń jẹ láti ṣe ìwé náà:
Lara awọn iwe ti akọroyin BBC foju kan ṣafihan pe awọn alaisan kan le san iye owo to to #300,000 si #750,000 naira ki awọn ati ẹbi wọn le ri aaye ni iyara ti wọn ya sọtọ, nibi ti wọn yoo ti gba itọju to peye.
”Bakan naa, alukoro fun egbe APC Mallam Bolaji Abdulmalihi naa baa won ebi oloogbe Mustapha Akanbi kedun.
Bí bẹ́ẹ̀ kọ́, ògbólógbòó àpò awọ náà yóo bẹ́; ati ọtí ati àpò yóo sì ṣòfò.
O ni ohun to n ṣẹlẹ lawujọ ni oun n sọ ko siyẹ ki awọn eeyan ma ka awọn olorin lọwọ ko Irori Wilson Israel ati ti Chinex papọ pẹlu ti Olamide.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, NLC: Àwọn olósèlú ń la títì láì sanwó osù torí owó tí wọn yóò rí lórí àkànse isẹ́ Èwẹ̀, alága ẹgbẹ́ àwọn ẹgbẹ́ òṣìṣẹ́ lábẹ́ àbùradà NLC Ayuba Wabba sọ pé ó sàn kí àwọn gómìnà lọ tún ìpàdé wọn ṣe, bíbẹ́ẹ̀kọ́ àwọn yóò gùn lé ìyanṣẹ́lódì míràn ni ọ́jọ́ kẹfà, Oṣù Kọkànlá.
O ní: 'ti ó ba ti di bárakú fún ẹnìkan, yóò má a wa owó kiri ni.
Akọroyin fun ọrọ eto aabo pẹlu BBC Africa, Tomi Oladipo ti figba kan toka ọrọ ijoba orilẹede Naijiria to sọ wipe awon ti bori ikọ Boko Haram.
Amọsa, ileesẹ epo rọbi orilẹede Ghana ti sọ wipe ohun ko lagbara lati sọ iye ti owo epo bẹntiroolu yoo ba de atipe gbogbo igbesẹ to yẹ ni gbigbe ni wọn ti gbe lati rii pọ ipa ẹkunwo naa dinku lara araalu.
Mo sùn ṣugbọn ọkàn mi kò sùn.
Amẹrika ni fun iyalẹnu, bi Bagudu se de silẹ Naijiria, ni wọn wẹ ẹ mọ kuro ninu awọn ẹsun naa, to si n du ipo oselu lọ, lati ile asofin agba de ipo gomina, to si n gbadun ofin mafọwọ kan mi lọ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù David Adiatu oníṣẹ́ ọnà pẹ̀lú ìṣó àti òwú Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ David Adiatu oníṣẹ́ ọnà pẹ̀lú ìṣó àti òwú 12 Ọ̀wàrà 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 12 Èbibi 2020 Mo fẹ kọ awọn ọdọ sii nipa iṣẹ ọna ìṣó- David David Adiatu jẹ oniṣẹ ọna to n fi iṣo ati owu da ara to wuu.
Wọn fi kun un pe akitiyan ti n lọ lọwọ lati tun fi ọwọ ofin mu awọn mii sii to lọwọ ninu ikọlu si ile aṣofin naa.
Ìlànà ayérayé ni èyí fún arọmọdọmọ yín, wọn kò tún gbọdọ̀ ní ohun ìní kan mọ́, láàrin àwọn ọmọ Israẹli; 
Awọn oludije mejidinlaadọta ni wọn figa gbaga jọ du ipo gomina nipinlẹ Ọṣun lọjọ Abamẹta, ọjọ kejilelogun, oṣu kẹsan an, ọdun 2018.
Yọ ẹran inú rẹ̀ kúrò lọ́kọ̀ọ̀kan, sá máa mú èyí tí ọwọ́ rẹ bá ti bà.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Jawahir Roble:Hijab tí mò n lò kó jẹ́ kọ́kọ́ jẹ́ ìyàlẹ́nu fún àwọn agbábọ́ọ̀lù mi Ẹlẹsin musulumi kan, Samer Hamdoun ni ''o kọkọ ri bakan lara nigba ta wa nibẹ nitori awọn ohun eelo orin, ati aworan to yi wa ka.
Béèyàn kú àfi kí n kíi pé ó dìgbà ó ṣe
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, SS3 ní mo wà báyìí, mo sì ti gba àmì ẹ̀yẹ̀ púpò nílé-lóko gẹ́gẹ́ bí onílù - Ayansike O ni oriṣiiriṣii ẹbun ni Eleduwa fi jinki Laycom eyi to jẹ ko ni ọpọlọpọ ololufẹ to n fẹran rẹ bi oju.
Ẹ gbọ́ Jide Kosọkọ siwaju si: Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fọ́nrán ohùn, World theatre Day: Kosọkọ ní ètò adójútòfò wà fọ́jọ́ alẹ́ àwọm onítíátà Kosọkọ ni amọ irufẹ eto adojutofo yii ko ba ti waye tipẹ fawọn osere tiata Yoruba, bi kii ba se ọpọ wọn to pagi dina eto naa nigba naa, apẹyinda iwa aidaa yii si ni ọpọ wọn to n saisan n jẹ loni yii.
Bakan naa lo sọ pe o jẹ ọmuti paraku, eyi to maa n mu ki o ṣi iwa hu.
Ó ti dáwọ́lé ohun tí ó fẹ́ ṣeta ni lè ká a lọ́wọ́ kò?
Oyemade sọ pe awọn agbofinro naa fi panpẹ ofin mu iyawo oun, Toyin, lọdun 2019 lai si idi kan pato.
Wọn óo tì ọ́ sinu ọ̀gbun; o óo sì kú ikú ogun láàrin omi òkun.
Ta ni yóo mú mi wọ inú ìlú olódi náà?
Sugbọn o seni laanu pe ọwọja iku ja meje oniroyin Naijiia gba laarin ọjọ meje.
Eyi si da lori bi ẹni naa ba ṣe le dahun awọn ibeere ti wọn ba bi i.
O ni idi niyi ti wọn fi rii pe wọn lẹ orukọ ati nọmba idanimọ ọkọọkan wọn mọ aya aṣọ ti wọn ba wọ.
Olubadan of Ibadan: Olóye Ọ̀tún ní ìjà ti parí ṣùgbọ́n àwa ò gbé adé sílẹ̀ o!
Mo bá bèèrè pé, “OLUWA mi, kí ni ìtumọ̀ kinní wọnyi?
Ọ̀rẹ́ wa ni Lawrence jẹ́, àmọ́ ó gbẹ̀yìn dẹ́nu ìfẹ́ kọ abúrò wa - Joshua àti Damilola Bamiloye Ó sàn fún mi kí n má tíì lọ́kọ báyìí ju kí n lọ́kọ ṣùgbọ́n.
Ó ní, Ṣugbọn òun yóo ya àwọn ẹran ọ̀sìn àwọn ọmọ Israẹli sọ́tọ̀ kúrò lára àwọn ẹran ọ̀sìn àwọn ará Ijipti, ẹyọ kan ṣoṣo kò ní kú ninu gbogbo àwọn ẹran tíí ṣe ti àwọn ọmọ Israẹli.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Pátá Jíjí : Agbẹnusọ ọlọ́pàá ní àwọn olè ajípátá ń gbìdánwò ìpànìyàn ni 5 Sẹ́rẹ́ 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 6 Sẹ́rẹ́ 2019 Oríṣun àwòrán, Tori.
Ọmọ ilẹ Ethiopia, Sintayehu Legese lo jawe olubori ninu idije ipinlẹ Eko, Lagos City Marathon pẹlu ẹbun owo $50,000.
“O kò jámọ́ nǹkankan tẹ́lẹ̀, kí n tó fi ọ́ ṣe olórí àwọn ọmọ Israẹli, eniyan mi.
Àwọn Farisi bá lọ forí-korí wọ́n ń wá ọ̀nà tí wọn yóo fi ká ọ̀rọ̀ mọ́ Jesu lẹ́nu.
Makinde ni ọna kan gbogi lati jẹ ki awọn araalu mọ pe ọrẹ ni ọlọpaa jẹ si wọn ni nipa ihuwa ọmọluabi lẹni iṣẹ.
Iroyin sọ pe ọmọbìnrin náà, Uwaila Omozuwa, ni awọn kan fi ipa balopọ, ti wọn si tun fi agolo afẹ́fẹ́ ti wọn fi n pa ina, 'fire extinguisher' fọ ọ lori, ninu ile ijọsin Redeemed Christian Church of God kan to wa ni adugbo Ikpoba Hill nilu Benin.
"Ìjìyà síse ayédèrú isẹ́ onísẹ́ kò kún tó - Jide Kosọkọ Ọpẹmipọ ní ọkùnrin kò jẹ́ kí òun sinmi nínú tíátà Gbajúgbajà òṣèré tíátà, ""Ijẹwuru"" ti jáde láyé Kosọkọ ni amọ irufẹ eto adojutofo yii ko ba ti waye tipẹ fawọn osere tiata Yoruba, bi kii ba se ọpọ wọn to pagi dina eto naa nigba naa, apẹyinda iwa aidaa yii si ni ọpọ wọn to n saisan n jẹ loni yii."
 Ó díje dupò gómìnà ní ìpínl ̀ ẹ Èkìtì ní ọdún 2007 ṣùgbọ ́ n ó pàdánù ìbò náà lábẹ ́ ẹgbẹ ́ òṣèlú ncp ( national conscience party ) tí ó ti fìgbà kan jẹ ́ alága ẹgbẹ ́ náà jákè-jádò nàìjíríà ní ọdún 2011 .
Èyí ẹ̀kẹfà jókòó lórí àga dáradára, ó da aṣọ bora, ojú rẹ̀ ń dán, ara rẹ̀ tutù, eyín rẹ̀ funfun, ọkàn rẹ̀ balẹ̀, aṣọ tí ó fi bora náà sì dára púpọ̀, bẹ́ẹ̀ ni òun náà lẹ́wà gidigidi.
ti awon enu ibode to wo orile- ede yii, ko se orile-ede Naijiria ni anfaani
Ṣemi Ajayi ni tirẹ fakọyọ fun ẹgbẹ agbgabọọlu, Rotherham United nibi to ti n gba bọọlu jẹun nilẹ Gẹẹsi ṣugbọn awọn agbaọjẹ agbabọọlu ti wọn jọ n gba aye kan naa ni ko jẹ ko raye.
Adajọ Stephen Adah nigbati o n ka idajọ naa mẹnu ba pe ko yẹ ki igbẹjọ naa waye pẹlu ifunrasi ati ọna aitọ ti awọn olupẹjọ fi gba aṣẹ idaniduro ranpẹ.
Arabinrin Siddiqi sọ pe ọdun 2016 ni oun fẹ ọkunrin naa, lẹyin ti awọn pade ni ileewe Federal Urdu University, nilu Karachi, nibi ti Ọgbẹni Siddiqi ti n ṣiṣẹ.
Wọn dá a dúró sile iwosan lati maa woye boya yoo ye e.
2015 ni Akpabio pari saa keji rẹ gẹgẹ bii Gomina, ti o si tun bọ si ile aṣofin agba Naijiria gẹgẹ bi Sẹnẹtọ.
Oríṣun àwòrán, others Iná sọ nínú ilé Big Brother tó ń lọ lọ́wọ́ ní Cameroon Mo ti buwọ́lu àdínkù owó orí nítorí ìrọ̀rùn àwọn èèyàn ìpínlẹ̀ Ogun lásìkò Covid 19- Dapo Abiodun Obasanjọ dúró lórí ọ̀rọ̀ tó sọ lẹ́yìn ikú Kashamu- Kehinde Akinyemi Àwọn adarí lágbàyé ṣèpàdé láti ṣèrànwọ́ fún Lebanon lẹ́yìn ìbúgbàmù tó pa ènìyàn 158 Buruji Kashamu: Olusegun Obasanjo ní ohun tí òun sọ nípa Kashamu lẹ́yìn ikú rẹ̀ kìí ṣe àṣìsọ Aarẹ Naijiria nigba kan ri, Oluṣegun Obasanjo ti sọ pe oun ko ṣi sọ ninu atẹjade ti oun fi lede lẹyin iku Sẹnatọ to n ṣoju ẹkun idibo ila oorun ipinlẹ Ogun tẹlẹ, Buruji Kashamu.
Bí òṣìṣẹ́ Amotekun bá fi orúkọ sílẹ̀ lórí ayélujára, àwọn ọ̀daràn yóò tètè fojú hàn - Oludari Amotekun l'Oyo Ǹjẹ́ o mọ iye ẹ̀bùn owó tí olúborí BBNaija yóò gbà lọ́dún yìí?
Eid-il Kabir: Iléẹjọ́ f'òfin de Oluwo pé kò gbọdọ̀ darí ìrun ní 'EID' lọ́dún Iléyá
Àkọlé àwòrán, Ita kun fofo awon olopaa naa si wa ni digbi Oríṣun àwòrán, Ajimobi Lives on Àkọlé àwòrán, Orin ó digberé gb'ọkàn àwọn èèyàn níbi ìsìnkú Abiola Ajimobi Àkọlé àwòrán, Ko ju eeyan ogun pere ti wọn jẹ ko wa ni ibi isinku naa, ni ṣe lawọn eniyan duro sita.
Wo ìdí tó fi tọrọ àforíjì fún ọ̀rọ̀ ẹ̀gbin tó sọ sí Pásítọ̀ David Oyedepo Iru ololufẹ wo ni Alaafin?
Bakan naa, ni ijọba Ajimobi tun wo awọn ile kan to wa lẹba odo ati awọn to wa lẹba oju popo ki anfaani lee wa lati fẹ oju popo yika ipinlẹ Oyọ.
Ilana ofin ati ṣi ileewe naa wa ninu atẹjade ti ijọba fi le de ti wọn pe ni 'Guidelines for schools and learning facilities reopening after COVID-19 pandemic closures: Taking responsibility for safe schools and quality learning.
Nígbà tí Ṣimei gbọ́ pé àwọn ẹrú rẹ̀ yìí wà ní Gati, 
Wọ́n pọn omi kún ọpọ́n ìmumi àwọn ẹran, láti fún àwọn agbo ẹran baba wọn ní omi mu.
Oludije fẹgbẹ APC nipinlẹ Ọyọ naa ni, o wa ni akọsilẹ pe oun seto ipolongo ibo nibamu pẹlu awọn erongba oun fun ipinlẹ Ọyọ, to si da awọn eeyan ipinlẹ naa loju pe oun kaato lati sisẹ naa, idi si niyi ti wọn se dibo rẹpẹtẹ fun oun .
O see se ki ọti ati siga gbowoleri Owo ifẹyinti tan fawọn gomina ana ni Kwara Gẹgẹbi ofin naa ti wi, ẹnikẹni to ba tapa si ofin naa yoo san owo itanran ti ko din ni ẹgbẹrun lọna ọgọrun naira tabi ko fi ẹwọn osu mẹfa jura.
" Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Mi o fẹẹkan ni mo fẹ dupo aarẹ' Pasitọ agba fun ijọ Latter Rain naa ni laarin awọn ọdọ to fẹ se aarẹ lorilẹede yii, ko si eyi to ni ọgbọn agba to Oby Ezekwesili, tii se oludije ACPN.
ṣugbọn kì í ṣe òun ni yóo kọ́ ilé ìsìn náà, ọmọ bíbí rẹ̀ ni yóo kọ́ ọ.
Lẹ́yìn náà, ó mú gbogbo ọ̀rá tí ó bo àwọn nǹkan inú mààlúù náà, ati ẹ̀dọ̀ rẹ̀, ati kíndìnrín rẹ̀ mejeeji, pẹlu ọ̀rá tó wà lára wọn, ó sun wọ́n lórí pẹpẹ.
Lẹ́hìn èyí ni àwọn aládùúgbò náà wá sí oko ṣùgbọ́n bákan náà ni.
Lagos rain: Ilé méjì, ọ̀pọ̀ igi àti òpó iná wó lẹ́yìn òjò tó rọ̀ nílùú Eko
Èrò àwọn ọmọ Naijiria ṣọ̀tọ̀ọ̀tọ̀ lórí Tinubu àti Abbo Àgùnbánirọ̀ gbẹ́mìí mì látàrí 'Snipper' tó fi fọ irun rẹ̀ Ṣé o ti gbọ́ ohun ti Ọọni Ifẹ́ àti Soyinka parí ọ̀rọ̀ Yorùbá sí?
A ti kọwé sí ìjọba àpapò làti pe agbaṣèṣe odò Asa padà- Gomina Kwara Àwòrán bí ẹ̀kún omi ti ṣọṣé l'Eko àtàwọn ìlú míì nílẹ̀ Yorùbá rèé Òjò àrọ̀ọ̀rọ̀dá dá wàhálà sílẹ̀ l'Eko Ki awọn Gomina yii ba le tete maa mura kalẹ, ajọ naa sọ pe, awọn ti kọ iwe sawọn Gomina ti ọrọ yii kan .
Nàìjíríà -orílẹ̀-èdè tí ǹkan márùn ún yì yà sọ́tọ̀!
Momodu fikun pe, asiko kan tiẹ wa ti awọn mejeeji dijọ joko sepade pẹlu awọn ologun ọmọ ilẹ Germany ti wọn fẹ fi owo gba, lati wa gbe Abiọla kuro lẹwọn, ti Tinubu si se gudugudu meje ati ya ya ya mẹfa lati yọ Abiọla kuro nigbekun.
Ikoro ni wọn ti doola ẹmi eniyan kan ninu awọn ti wọn jigbe naa, ti wọn si ti ri ọkọ naa gba pada.
Ìkà ni ibinu, ìrúnú sì burú lọpọlọpọ,ṣugbọn, ta ló lè dúró níwájú owú jíjẹ?
 iru jẹ eronja ọbẹ ni ilẹ yoruba ati ni agbegbe miran .
BBC: Iroyin sọ pe ni igba pipẹ sẹyin, ẹ fẹ gbiyanju lati gba ẹmi ara yin, ki lo fa a?
Eyi si le mu ki ẹni naa di eero ileewosan.
Orúkọ wo ni ẹ̀yin mo ǹkan ìṣeré yìí sí.
Champions League: Ronaldo ní Tottenham yóò jẹ moyó ìyà lọ́wọ́ Liverpool
Ọdún mọ́kànlá sẹ́yìn ni K1 ti ń béèrè fún oyè Mayegun lọ́wọ́ mi - Alaafin Ẹ̀bùn ọdún tuntun tó yááyì ni ikọ̀ Amotekun - Soyinka Ìjọba Nàìjíríà ti rí obìnrin tó wà l'óko ẹrú ní Lebanon gbà Imam tó fẹ́ ọkùnrin míì níyàwó forí kó ìjìyà òfin O ni titi di asiko yii, Harry ati Meghan ko i tii fi to ijọba ilẹ Canada leti nipa ohun gbogbo to rọmọ ki awọn Ọmọọba naa wa ma a gbe ni orilẹede wọn.
Bí àwọn ara Filistia ti rí wọn, wọ́n ní, “Ẹ wò ó!
Gomina Akeredolu to gbalẹjọ aarẹ Buhari ni ipinlẹ naa ṣi ile itaja nla ni ilu ọrẹ ati afara to la ilu naa kọ ja ni ọjọ kẹẹdọgbọn, Osu Keji, ọdun 2020.
Wọ́n Fa Jesu Lọ Siwaju Pilatu.
Ninu oro  ikinni naa, aare  Biya ni: ‘‘Gege bi eni to jawe olubori ninu
Gẹ́gẹ́ bí àsà ìlù náà, wọ́n fún un ni àyè kí ó bá àwọn ará ìlú sọ̀rọ̀ kí ó tóo’kú.
7 Àti pé fún ìdí èyí mo sọ pé ó jẹ́ ènìyàn búburú, nítorí òun ti wá ọ̀nà láti kó àwọn ohun tí a fi sí ìpamọ́ rẹ lọ; àti bákannáà òun ti lépa láti pa ẹ̀bùn rẹ run.
Oríṣun àwòrán, EPA Aarẹ Alexander Lukashenko ni esi idibo gbe jade pe, o ti bori ida ọgọrin ninu ọgọrun ida ibo ti awọn oludibo di.
Sibẹsibẹ OLUWA kò pa Juda run nítorí ó ti búra fún Dafidi iranṣẹ rẹ̀ pé ìran rẹ̀ yóo máa jọba ní ilẹ̀ Juda.
Dino Melaye sọ èyí di mímọ̀ lọ́nìí ọjọ́ satide pé bí àwọn ọlọ́pàá ṣe yabo ilé oun kò ní ìtumọ̀ rárá.
Bákan náà ni àkọ́bí mààlúù rẹ ati ti aguntan rẹ, tí wọ́n bá jẹ́ akọ.
Sẹ́nétọ̀ Ademọla Adeleke ń jẹ́jọ́ aṣemáṣe lásìkò ìdánwò
Àwọn ará Fedani ati Jafani láti Usali a máa wá fi ọtí waini pààrọ̀ ohun tí ò ń tà; wọn a kó àwọn nǹkan èlò irin wá, ati igi kasia.
Tọ̀sán-tòru níí máa kígbe láàrin àwọn ibojì ati lórí òkè, a sì máa fi òkúta ya ara rẹ̀.
Pẹlu ìtara ati ìrúnú ni mo fi ń sọ pé ilẹ̀ Israẹli yóo mì tìtì ní ọjọ́ náà.
Ẹ jẹ́ kí wọ́n mọ̀ pé òtítọ́ ni àwọn nǹkan tí a sọ fún wọn, tí a sì fi ọwọ́ rẹ̀ sọ̀yà nípa yín.
O ni ẹru wi pe wọn le yinbọn ti yoo si ba alaiṣeẹ kún ìdí ti wọn ko fi jáde Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù NURTW: Makinde kò tíì yí àṣẹ rẹ̀ padà lórí i gbígbẹ́sẹ̀ lé NURTW ní ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́ 9 Owewe 2019 Oríṣun àwòrán, @ibcityannouncer Àkọlé àwòrán, NURTW: Makinde kò tíì yí àṣẹ rẹ̀ padà lórí i gbígbẹ́sẹ̀ lé NURTW ní ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́ Ijọba ipinlẹ Ọyọ ni ko sohun to yipada lori ofin to gbẹsẹ le iṣẹ awọn ẹgbẹ awakọ ero, NURTW ni ipinlẹ Ọyọ.
Ẹ̀yin ọmọ mi, ara ń ni mí nítorí yín, bí obinrin tí ń rọbí lọ́wọ́, títí ẹ óo fi di àwòrán Kristi.
Champions league: Real Madrid jẹ wábiwọ́sí ìyà lọ́wọ́ PSG, Di Maria ló hun pàṣán ìyà wọn Champions league: Athletico bomi paná ayọ̀ Juventus ní ìpadàbọ̀ Ronaldo sí ìlú Madrid Champions League: Balógun ní England, akéwejẹ̀ ní Italy, Liverpool yọ̀ ṣubú níwájú Napoli pẹ̀lú àmì ayò méjì sí òdo Ìyà tí 9-0 tí Manchester United ṣe fún Ipswich l'ọ́dún 1995 sì ni ìṣẹ́gun tó ga jù nínú ìtàn ìdíje Premier League, ṣùgbọ́n City jẹ́ ẹgbẹ́ agbábọ́ọ̀lù keèje tó na ẹgbẹ́ míràn ní 8-0 ní àsìkò tí a wà yìí.
Mò ń ṣe iṣẹ́ alufaa láàrin àwọn orílẹ̀-èdè wọnyi nípa wiwaasu ìyìn rere Ọlọrun, kí wọ́n lè jẹ́ ọrẹ ìtẹ́wọ́gbà fún Ọlọrun, ọrẹ tí Ẹ̀mí Mímọ́ ti yà sí mímọ́.
Àwọn ọba ni yóo máa tọ́jú rẹ bíi baba,àwọn ayaba yóo sì máa tọ́jú rẹ bí ìyá,ní ìdojúbolẹ̀ ni wọn óo máa tẹríba fún ọ,wọn óo sì máa pọ́n eruku ẹsẹ̀ rẹ lá.
Oríṣun àwòrán, Olakunle Arthur Falayi Awọn iròyìn mìíran tí ẹ lè nífẹ̀ẹ́ sí: Ọlọ́pàá mú afẹ̀sùnkàn Boko Haram tó ti pa ju ènìyàn 200 Oju àwọn tó gbẹ̀mí awọn olólùfẹ́ OOU rèé Saraki pè fún ìwádìí ikú olórí ikọ̀ adigunjalè tó ṣọsẹ́ ní Offa Ọ́lọ́pàá mú 'Rambo' ní àríwá Naijiria Ogedengbe Agbógun Gbórò, Akọni tó ń dẹ́rù ba ikú.
Wo o boya sanitaisa ọhun ni iye ọti to to ida ọgọta nin.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Primate Ayodele: Àwọn pásítọ̀ tó ń lo bàálù pẹ̀lú èrò rẹpẹtẹ ń tan aráàlú jẹ ni Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Primate Ayodele: Àwọn pásítọ̀ tó ń lo bàálù pẹ̀lú èrò rẹpẹtẹ ń tan aráàlú jẹ ni 5 Bélú 2019 Oluṣọaguntan agba Ayodele ni oludasilẹ ijọ INRI Evangelical Spiritual Church ti a si mọ ọ fun ọpọlọpọ asọtẹlẹ lorilẹede Naijiria.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Oga Isah salaye pe kete ti awọn ọlọpaa gburo ijinigbe naa ni wọn tọ awọn ajinigbe naa lọ titi ti wọn fi de ikorita Kwosanda nibi ti wọn ti doju ija ko wọn.
Coronavirus:: Òògùn ìtura dé fún Covid-19!
Ogun robbery: Ọlọ́pàá ní àwọn afurasí adigunjalè náà ló ń ṣe ọṣẹ́ ní Abeokuta
Iyì ati ọlá ńlá ń bẹ lọ́dọ̀ rẹ̀;agbára ati ẹwà kún inú ilé mímọ́ rẹ̀.
Ipinlẹ Eko lo ṣi le tenete nipinlẹ ti ọwọja aarun yi ti peleke ti Bauchi si ni iye eeyan to kere julọ.
Òtútù ikú Ajimobi sì ń mú mi, ń kò le sọ̀rọ̀- Akala, Ayefele Àjọ NCDC kéde ènìyàn 594 tó tún ṣẹ̀ṣẹ̀ ní Coronavirus ní Nàìjíríà Aworan ree nipa bí Abiola Ajimobi ṣe lo ayé rẹ̀ Abiola Ajimobi, Gómìnà tí ọ̀rọ̀ kìí kú mọ lára, à fi kó fèsì Akinwumi Ambode Gomina ipinlẹ Eko tẹlẹ, Akinwumi Ambode naa ko gbẹhin lara awọn eekan ìlú to ti ṣedaro Ajimobi to ku.
Tani olóṣèlú tó ṣewọn ọjọ mẹta torí pé o ní orí ààrẹ dàrú
Ó bá gbadura sí OLUWA, ó ní: “OLUWA, ṣebí ohun tí mo sọ láti ìbẹ̀rẹ̀ nìyí, nígbà tí mo wà ní orílẹ̀-èdè mi?
Awọn obi rẹ ni awọn gbẹri rẹ jẹ gẹgẹ bi smọ ti kii rin irinkurin.
Àwọn ọmọ Lefi wọnyi: Jeṣua, Bani, Ṣerebaya, Jamini, Akubu, Ṣabetai, Hodaya, Maaseaya, Kelita, Asaraya, Josabadi, Hanani, ati Pelaaya ni wọ́n ń túmọ̀ àwọn òfin náà tí wọ́n sì ń ṣe àlàyé rẹ̀ fún àwọn eniyan wọn, gbogbo àwọn eniyan dúró ní ààyè wọn.
Fadairo ni a ko le sọ ibi ti idibo naa yoo fori sanpọn si nitori Gomina ipinlẹ Edo, Godwin Obaseki ti kuro ni ẹgbẹ oselu APC, Bakan naa ni wọn ko ni alaga ẹgbẹ oselu ẹyọkan nitori ẹniyan mẹta ni wọn ti kede pe awọn ni alaga ẹgbẹ oṣelu APC.
Ikede ilu-o-fara ro ohun waye lojo keji ti olori ijoba Hailemariam Desalegn kowe fipo re sile, amo yoo si wa nibe titi di igba ti apapo egbe oselu to n sejoba lorile-ede naa ba fimo-sokan yan eni ti yoo dipo re nibi ipade apero won laipe.
Bakan naa ni wọn sọ pe awọn ti ṣe agbeyẹwo akọsilẹ orukọ awọn to wọ baalu pẹlu rẹ, ti wọn si ti n wa wọn.
Ó pàṣẹ fún wọn pé, “Ìdámẹ́ta yín tí ó bá wá sí ibi iṣẹ́ ní ọjọ́ ìsinmi yóo máa ṣọ́ ààfin.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Erin fara gbọgbẹ̀, ó ṣekú pa ènìyàn méjì Àwọn alága ìbílẹ̀ tún wọ́ Seyi Makinde relé ẹjọ́ Agbekoya: Bí a bá na oògùn abẹnugọ̀ngọ̀ s'ókè, ìjínigbé á d'ópin!
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù US Election 2020: Biden jẹ́jẹ̀ẹ́ láti gbé ìgbìmọ̀ amúṣẹ́yá kalẹ̀ fún ìtọ́jú Coronavirus 3 Bélú 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 8 Bélú 2020 Aarẹ tuntun ti wọn sẹsẹ dibo yan ni orilẹede Amẹrika, Joe Biden ti fọwọ sọya pe oun yoo mu irẹpọ ba orilẹede naa.
ninu ijamba omiyale ati iji omi lile to waye ni orile ede Zimbabwe,nigba ti  ijamba  iji omi to sẹlẹ ni orile ede Malawi ko ba wọn,
Gomina Yahaya Bello ti ẹgbẹ APC ni gomina ẹya Ebira akọkọ ti yoo de ipo naa ti ko si jọ wi pe o fẹ fi ipo naa silẹ bayi.
Omozoje ti je ki o di mimo pe anfaani ti wa bayi fun obinrin lati je adari iko
o jọ wipe o npọ sii : wiwaye ni awọn ọdun 1980 sunmọ 20 ninu 100,00 l ' ọdun , nigbati o di awọn ọdun 1990 o jẹ 50 ninu 100,000 l ' ọdun .
Kí ló dé tí o óo fi jẹ́ kí àwọn ará Ijipti wí pé, o mọ̀ọ́nmọ̀ fẹ́ ṣe wọ́n níbi ni o fi kó wọn jáde láti pa wọ́n lórí òkè yìí, ati láti pa wọ́n rẹ́ kúrò lórí ilẹ̀ ayé?
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ọmọdebinrin kan lati Sudan naa n ju asia kekere rẹ bi awọn eniyan ṣe tu si igboro fun ajọyọ ni Khatourm, olu ilu orilẹede Sudan.
Àwọn àgbààgbà Moabu ati Midiani mú owó iṣẹ́ aláfọ̀ṣẹ lọ́wọ́, wọ́n tọ Balaamu wá, wọ́n sì jíṣẹ́ Balaki fún un.
Awọn to n ta ounjẹ, ọmọde to wọle lọ kirun, awọn oṣiṣẹ to n kọle gan gbogbo wọn lo ku sabẹ ile naa."
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Defence HQ: Ilé iṣẹ́ ológun Nàìjíríà fèsì sí awuyewuye pé wọ́n yọ́lẹ̀ sìnkú 2 Ògún 2019 Oríṣun àwòrán, AFP Àkọlé àwòrán, Isinku awọn ologun Ile iṣẹ awọn ọmọ ogun alaabo Naijiria ti bu ẹnu at lu iroyin to n tan kalẹ pe wọn ni saree ikọkọ ni iha Ila Oorun-Ariwa Naijiria.
Pa Kasumu tó ni ohùn ló lọ,ohùn tó fi sílẹ̀ kò ní parẹ́ Irinajo kan ti Barrister lọ si England lọdun 1974, ti gbogbo awọn ọmọ ẹgbẹ si duro de e la i ri nkankan ṣe, lo ru Wasiu Ayinde soke lati bẹrẹ ẹgbẹ akọrin rẹ.
Nítorí pé wọ́n kọ̀ láti tẹ̀lé e,wọn kò náání ọ̀nà rẹ̀ kankan,
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Olaitan Olamide: mò lè má nílò ìwé ẹ̀rí mi tí mo bá parí ní LASU Ko buru ti eniyan ba lọ si ori ayelujara lati wo fidio ibalopọ, ṣugbọn o jẹ nkan iyalẹnu pe orilẹ-ede Naijiria lo n leke, paapa bi a ṣe maa n fi ara wa han bi 'ẹni mimọ'.
Dafidi dá wọn lóhùn pé, “Bẹ́ẹ̀ ni, nígbà tí ó wà láàyè, mo gbààwẹ̀, mo sì sọkún, pé bóyá OLUWA yóo ṣàánú mi, kí ó má kú.
Ṣaaju, Sẹ́nétọ̀ Dino Melaye tó ń ṣojú ẹkùn Iwọ̀ Oòrun ìpínlẹ̀ Kogi ti jọ̀wọ́ ara rẹ̀ fún àwọn ọlọ́pàá.
Lautech: Ìjọba Ọ̀ṣun ní òun kò jẹ òṣìṣẹ́ fásitì náà lówó oṣù
Wọ́n dáhùn pé, “Ọkunrin náà wọ aṣọ tí wọ́n fi awọ ẹranko ṣe, ó sì di àmùrè awọ mọ́ ẹ̀gbẹ́.
Kí ìwọ, náà máa kíyè sára o, jẹ́ẹ́jẹ́ ni kí o máa rìn lọ; ọmọ onílẹ̀ tẹ̀ ẹ́ jẹ́ẹ́jẹ́ẹ́, àjèjì tẹ̀ ẹ́ gìrìgìrì, má ṣe jẹ́ kí pàkúté mú ọ o.
" Òfìfo ṣọ́ọ̀ṣì pa aṣọ dà fún àwọn Páṣítọ̀ Nàìjíríà Ṣé ìrètí wà pé coronavirus yóò dínkù lásìkò ooru?
Nígbà tí Jotamu gbọ́, ó gun orí òkè Gerisimu lọ, ó bẹ̀rẹ̀ sí kígbe pé, “Ẹ fi etí sílẹ̀, ẹ̀yin ọkunrin Ṣekemu, kí Ọlọrun lè gbọ́ tiyín.
Ààrẹ Buhari wọ́gilé kí àwọn òṣìṣẹ́ ìjọba máa wọ ọkọ̀ bàálù olówó gọbọi World Food Day: Wo àwọn oúnjẹ ìṣẹ̀mbáyé Yorùbá tó ti ń di àpatì Akẹ́kọ̀ọ́ Ilaro Poly tó pegedé jù jẹ ẹ̀bùn iṣẹ́ ọ̀fẹ́ lọ́wọ́ Gómìnà Abiodun Njẹ́ o mọ pé N3000 ló o sàn láti gbà kaadi ìdánimọ̀ míì bí tí tẹ́lẹ̀ bá sọnù?
Ṣugbọn n kò ní jẹ àwọn ọmọbinrin yín níyà nígbà tí wọ́n bá ń ṣe aṣẹ́wó, tabi kí n jẹ àwọn aya yín níyà nígbà tí wọ́n bá ṣe àgbèrè; nítorí pé, àwọn ọkunrin yín pàápàá ń bá àwọn aṣẹ́wó lòpọ̀, wọ́n sì ń bá àwọn aṣẹ́wó ilé oriṣa rúbọ.
Koda, Aarẹ Buhari ni ọmọ rẹ kẹtalelogun.
 O tun se alaye pe, gege bii igbimo
- Yinka TNT Bi ọwọ agbofinro ṣe tẹ Shina Rambo, ijiya ẹṣẹ rẹ ati bo ṣe di ajihinrere: Lẹyin ti aya, ọmọ ati ohun gbogbo ti Shina Rambo ṣiṣẹ fun tan, ti gbogbo rẹ poora loju aye rẹ, lo ba lọ fi ara rẹ silẹ fawọn ọlọpaa.
Ko ṣai ṣalaye pe awọn okowo oun loun gbajumọ bayii lati igba ti ajakalẹ aarun covid-19 ti ṣakoba fun gbogbo nkan to fi mọ ere ori itage naa.
Ẹwẹ, agbabọọlu fun ikọ Real Madrid to jẹ ọmọ orilẹede Croatia Luka Modric lo gba ami ẹyẹ FIFA gẹgẹ bi ọkunrin agbabọọlu to pegede julọ ni tootọ, ṣugbọn awọn kan ni oun kọ ni ami ẹyẹ naa tọsi.
O ni arun coronavirus ko lee parẹ mọ laye, o kan lee wawọ lọ silẹ bi awọn aṣiwaju rẹ bii Ebola ni ati pe ẹrin gbaa lawọn wolii kan to n sọ pe ọjọ bayii ni arun naa yoo parẹ n pa oun.
Jesu Oyingbo rèé, pásítọ̀ tó láṣẹ ìbálòpọ̀ lóri ọmọ ìjọ obìnrin Yorùbá kìí ṣe egúngún oníhòhò, ìwà wèrè ni sinimá oníhòhò táwọn òṣèré kan ń ṣe- Lere Paimo Mo fẹ̀ lọ gba owó oúnjẹ lọ́wọ́ bàbá mí ni mo bá wọn tí wọ́n ti pokùnso- Ọmọ Oloogbe Eyín ọ̀ọ́kán mi ni Barakat tí wọ́n pa lẹ́yìn tí wọ́n fipá bá a lòpọ̀- Ìyá Barakat IGP ti jọ̀wọ́ Hamisu Wadume fún aádájọ́ àgbà Nàìjíríà Èmi ni Ààrẹ tó ṣe rere fún ilẹ̀ adúláwọ̀ jù - Donald Trump Ọmọdé yóò máa sọnù ládùúgbò, arúgbó leè kú láì tọ́jọ́, tí wọn bá jókòó sílé lásìkò ìjọsìn - CAN Kí ni ìdí tí ilé ẹjọ́ tún ti sún ìgbẹ́jọ́ Alfa Babatunde Sotitobire síwájú Ohun mẹ́fà tí àgbáyé kò mọ̀ nípa Majek Fashek tó d'olóògbé nìyí Ọwọ́ ọlọpàá tí tẹ ọ̀kan nínú àwọn ọ̀daràn tó ṣekú pa Uwaila Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí 3 sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 2:23 Fídíò, Water Generator: Ó leè ṣiṣẹ fún wákàtí mẹfà, kó tó sinmi, Duration 2,2310 Òkùdu 2020 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
Ko si si iru ariya ti mi o ti i lọ lati bi ogun ọdun, amọ iru eyi ti awọn eeyan naa fẹ ṣe kan fẹ ba orukọ rere ti iru awọn eeyan bi temi to n fi iwa ọmọluabi jaye ori wa, jẹ ni.
Wọ́n sì lè mú kí àjàkálẹ̀ àrùn oríṣìíríṣìí bá ayé, bí wọ́n bá fẹ́.
Abiyamọ ni mi sùgbọ́n mo pa òbí àwọn ọmọ ọlọ́mọ lásìkò ìpìniyàn abéle Rwanda Wo ojú ọmọbìnrin 4 tí afipa báni lòpọ̀ pa ní Nàìjíríà Wọ́n ti gbé òkú Ibidunni Ighodalo sílé ìgbókúpamọ́sí l'Eko Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Grace Oshiagwu: Gómìnà Makinde ké sáwọn ọlọ́pàá, àwọn lọ́balọ́ba lágbègbè Akinyele Ó ní ìyàlẹ́nu ló jẹ́ bí òun se ri pé pé ọkọ tó yẹ kí ó gbéra ni ọjọ́ kẹrìnla ọsù kẹfa, gbéra ni ọjọ́ kẹtàlá oṣù kẹfa láti pápákọ̀ òfurufú Muritala Muhammed to si balẹ̀ sí pápákọ̀ òfurufú Nnamdi Azikwe Abuja ni aago mẹ́fà ọjọ́ náà, ìyàlẹnu ni èèrò inú rẹ̀ tún jẹ́ pẹ̀lú.
Èyí ni ìbéèrè tí ọ̀pọ̀lọpọ̀ ọmọ Yorùbá n bèérè.
O ni ko ju bayẹn lọ.
Kíni ǹkan to ti n ṣẹlẹ̀?
Lẹ́yìn náà, Àgọ́ Ẹ̀rí yóo ṣí, pẹlu àgọ́ àwọn ọmọ Lefi.
Gbòǹgbò rẹ̀ gbẹ nísàlẹ̀,ẹ̀ka rẹ̀ sì gbẹ lókè.
ati awon akoroyin nile igbalejo International Conference Centre to wa niluu
Amọsa, o si ku akẹkọ kan ni ahamọ awọn ikọ yii.
Ní ọjọ́ tí ó bá lọ sí ibi mímọ́, tí ó bá lọ sinu gbọ̀ngàn inú láti ṣiṣẹ́ iranṣẹ ní ibi mímọ́, ó gbọdọ̀ rú ẹbọ ìmúkúrò ẹ̀ṣẹ̀.
Akufo-Addo ni Ààrẹ ẹlẹ́keeta tí to sọ ní gbangba pé òun kò fọwọ́sí ibalopo ọkùnrin sí ọkùnrin tàbí obìnrin sí obìnrin.
Láti ayé àwọn baba ńlá yín ni ẹ ti yapa kúrò ninu ìlànà mi, tí ẹ kò sì tẹ̀lé wọn mọ́.
Sayẹnsi ati imọ ẹrọ - 28,272,741,669.
Nítorí náà, Rehoboamu ṣe apata bàbà dípò wọn, ó sì fi wọ́n sábẹ́ àkóso olùṣọ́ ààfin.
alatileyin egbe  naa soro lati gba
Ni aṣalẹ ọjọ Iṣẹgun ni ajọ to n ṣe kokari eto iforukọsilẹ kaadi idanimọ lorilẹede Naijiria, NIMC kede loju opo Twitter rẹ pe gbajugbaja akanjẹ agbaye ni to jẹ ọmọ Naijiria ṣugbọn to n ja fun orilẹede Gẹẹsi pẹlu ti gba forukọsilẹ fun kaadi idanimọ gẹgẹ bi ọmọ Naijiria, o si ti gba nọmba idanimọ rẹ, NIN.
Àwọn ẹran tí ẹ lè jẹ nìwọ̀nyí: mààlúù, aguntan, 
Ṣugbọn ṣa, eniyan 14292 ti ri iwosan, awọn 769 si ti ku.
Sugbọn awọn ọrọ ti awọn osere kan n sọ lori iku ọkunrin naa ati awọn eeyan to n sọfọ rẹ, n kọ ni lominu.
se  dibo tan, ni won ti lọ sile.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Makinde fẹ́ san ₦30,000 fáwọn òṣìṣẹ́ l’Oyo, yóò tún kọ́ ọjà ìgbàlódé sí Akẹ̀sán Ṣo mọ̀ pé J.
mọkanla-le-ọjileẹẹdẹgbẹrun ati meje (11,947) ni ẹkun idibo Alimoṣọ
Ọmọkunrin Majek Fashek tun fidi rẹ mulẹ pe idile Majek Fashek nikan ni yoo ṣe eto isinku fun un.
Lawọn igberiko lorileede India, iku ọwọọwọ nipasẹ mimu ọti ayederu ko jẹ nkan tuntun.
Ṣugbọn Hamori bá wọn sọ̀rọ̀, ó ní, “Ọkàn Ṣekemu, ọmọ mi, fà sí arabinrin yín, ẹ jọ̀wọ́, ẹ fún un kí ó fi ṣe aya.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ifa Priest: ọdún mọ́kànlá ni mo fi ṣe iṣẹ́ agbejọ́rọ̀ kí n tó gbọ́ràn si Ifá lẹ́nu Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Ifa Priest: ọdún mọ́kànlá ni mo fi ṣe iṣẹ́ agbejọ́rọ̀ kí n tó gbọ́ràn si Ifá lẹ́nu 13 Sẹ́rẹ́ 2020 Emi naa ko kọkọ gba pe Ifa ni mo ṣi maa jokoo ti- Oludari Ifadiwura Tempili Iyanifa Popoọla Ella Agwu to fi ilu oyinbo ṣe ibujoko to n dari tẹmpili Ifadiwura ni ilu Ọba sọrọ ni kikun lori igbesi aye rẹ fun BBC.
Humanitarian Affairs, Disaster Management and Social Development).
Kí olukuluku sá àsálà, kúrò lọ́wọ́ ibinu gbígbóná OLUWA!
Ọmọ yìí jẹ́ ọmọ ẹ̀gbọ́n rẹ̀, ṣugbọn kò ní òbí mọ́.
Wọn kogba wọle lọdun 2008, ọpọ si ti n gbagbe orukọ wọn, koda, awọn ọmọ aye ode oni ko mọ orukọ to n jẹ Dunlop tabi Michelin.
Àwọn èèyàn tó ń tako ètò Amotekun ni kò ní àròjinlẹ̀ - Tinubu Oríṣun àwòrán, Facebook/Bola Tinubu Lẹyin o rẹyin, asaaju ẹgbẹ oselu APC ati gomina tẹlẹ nipinlẹ Eko, Oloye Bola Ahmed Tinubu ti sọrọ lori eto alaabo Amotekun tawọn gomina ilẹ Yoruba gbe kalẹ.
Ó sọ ìyàngbẹ ilẹ̀ náà ní ilẹ̀, ó sì sọ omi tí ó wọ́jọ pọ̀ ní òkun.
“ ‘O kò gbọdọ̀ jẹ́rìí èké sí aládùúgbò rẹ.
Ṣugbọn gbogbo àwọn kòkòrò yòókù tí wọ́n ní ìyẹ́ tí wọ́n sì ní ẹsẹ̀ mẹrin, ìríra ni wọ́n jẹ́ fun yín.
Ìtumọ̀ rẹ̀ sì nìyí: MENE, Ọlọrun ti ṣírò àwọn ọjọ́ ìjọba rẹ, ó sì ti parí rẹ̀.
Fi nǹkan bojú rẹ kí o má baà rí ilẹ̀, nítorí pé ìwọ ni mo ti fi ṣe àmì fún ilé Israẹli.
Àkọlé àwòrán, Aarẹ Buhari BBC Yorùba balẹ̀ bàgẹ̀ s'ílée MKO Abiola l'Eko Ẹ̀yin aṣòfin túntun, ẹ má gbàgbé ẹni gbé'ṣẹ́ fún ni o - Saraki Ta ni Femi Gbajabiamila tó di Olórí tuntun nílé Asojú-sòfin Nàìjíríà?
Ojúlówó wúrà ni wọ́n fi bo gbogbo ibi mímọ́ náà; wọ́n sì fi pákó igi kedari ṣe pẹpẹ kan sibẹ.
Ọlọrun Pe Aisaya láti jẹ́ Wolii.
Awọn to mọ Soworẹ ni bi ọrọ ba niiṣe pẹlu jija fun ẹtọ omoniyan,Sowore kii gbeyin.
Ọkùnrin náà sì dáhùn, ó ní, Dandan ni.
Ẹ́ni ọdun mọkandilọgbọn ni Seyi Makinde nigba to kọkọ da ile iṣẹ epo ati afẹfẹ gaasi aladani tirẹ silẹ lọdun 1997, lẹyin to ti ṣiṣẹ fun ọdun marun un nile ati lẹyin odi.
Lagos-Ibadan: Ìjọba àpapọ̀ pàṣẹ pé kí gbogbo ọkọ̀ agbépo kúrò ní òpòpónà márosẹ̀ Eko si Ibadan- Fasola
D) lati ile iwe giga fasiti kan naa.
Àwọn ọmọ-ẹ̀yìn Jesu yìí sọ ohun tí Ẹ̀mí Mímọ́ fihàn wọ́n fún Paulu pé kí ó má lọ sí Jerusalẹmu.
Ariwo ''Executive Order'' lawọn eeyan n mu bẹnu pe ki aarẹ buwọlu aṣẹ ti yoo fofin de FSARS patapata.
Bẹẹ ba gbagbe, Adams Oshiomole lati ẹkun guusu Naijiria ni alaga tẹlẹ fun ẹgbẹ oselu APC, ko to di pe ileẹjọ yẹ aga mọ nidii.
Gómìnà ìpínlẹ̀ Kaduna fún Sanusi ní ipò tuntun Bayero Emir ìlúu Kano, ìyá rẹ̀ ọmọ Emir Kẹjọ ni ìlú Ilorin!
Jesu Wo Iranṣẹ Ọ̀gágun Kan Sàn.
Saudi Arabia: Ìjọba ti fàyé gba òbinrin lati rìnrinajo lọ orilẹ̀-èdè to wù wọ́n
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Dino Melaye Marriage Proposal: Se lóòtó ni sẹ́nátọ̀ Dino Melaye fẹ́ gbé ìyàwò tuntun 19 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Oríṣun àwòrán, Bishopoftruth Wọ́n ni ọ̀ba kìí wà láì ni olòrì láàfin, sùgbọ́n kìí ṣe ọba aláde tó wà nípò nikan lọ̀rọ̀ yìí bá wí o.
Ẹni to bori: Ghana Ìpele to kangun si aṣakagba Morocco vs Nigeria.
Ìtùnú ni wọ́n jẹ́ fún mi.
Gẹgẹ bi ọrọ ti agbẹjẹro agba ni ipinlẹ Kwara, Kamaldeen Ajibade, sọ niwaju ile ẹjọ lọjọru ni ilu Ilọrin, ọga ọlọpaa ikọ to ṣe iwaadi idigunjale naa, Abba Kyari lo fi to oun leti pe Adikwu ti ku.
 A wa n ro awon to  n wa oko oju ofurufu lati orile ede India ati
Wọn dira pẹlu ibọn, ada ati oogun."
n óo ranti majẹmu tí mo bá Jakọbu, ati Isaaki, ati Abrahamu dá, n óo sì ranti ilẹ̀ náà.
Hajj 2020: ìjọba Saudi ní kò sí ààyè fáwọn alálàájì láti fi ọwọ́ kàn Ka'aba
Kà Síwájú Síi next Article share tools Facebook Twitter ṢàpínlòView more share options Share this post Copy this linkKà síwájú síi nípa àwọn ìtọ́kasí wọ̀nyí.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ilé ẹjọ́ tó ga jù ní kí gómìnà tẹ́lẹ̀, Jolly Nyame lọ fẹ̀wọ̀n ọdún 12 ṣara rindin 7 Èrèlè 2020 Oríṣun àwòrán, EFCC Àkọlé àwòrán, Jolly Nyame jẹ gomina ipinlẹ Taraba laarin ọjọ kọkandinlọgbọ̀n, oṣu karun, ọdun 1999 si ọjọ kọkandinlọgbọn, oṣu Karun, dun 2007.
Asaheli, arakunrin Joabu, ni balogun fún oṣù kẹrin.
O ni arakunrin ẹni ọdun mẹtalelogoji naa lo fun oun pe ki oun fi si ipamọ.
Ẹsun ti wọn fi kan awọn mejeeji ti wọn yọ nipo naa ni iwa ibajẹ lẹnu iṣẹ.
”“Gege bi adari , mo gbodo
Ṣugbọn láti jẹ́ Juu tòótọ́ jẹ́ ohun àtinúwá; ìkọlà jẹ́ nǹkan ti ọkàn.
Wọ́n kó àjẹkù jọ, ó sì kún apẹ̀rẹ̀ mejila.
Mo gbàgbọ́ pé òtítọ́ wà ninu ìròyìn yìí.
 adu ni o dinwoju lati se adalu mo idẹ sugbon a tun le lo adalu awon apilese miran manganisi , kromiomu , banadiomu ati wolframu .
Bakan naa , ni ijoba apapo ti so pe awon yoo tele ilana “ko sise, ko si owo osu” lasiko iyanselodi.
Ìjì líle mú ẹ̀mí èèyàn 1000 lọ, odidi ìlú kan bàjẹ́ Seyi Makinde figbe ta lórí bí Ajimobi ṣe ń ná owó ìlú Iléeṣẹ́ asọ́bodè ṣe agbéga fún òṣìṣẹ́ rẹ̀ tó kọ̀ rìbá Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Collapsed Building: Ayálégbé ló dára bí ìjọba ṣe wólé àmọ́ wọ́n fẹ́ ìrànwọ́ ilé míràn Nigba naa, Alimikhena fí ọkan àwọn ọmọ Nàìjíríà balẹ̀ pé ìgbìmọ̀ náà yóò múṣẹ́ ṣe ni wàràńṣesaà láti mu àbájade to ni ìtumọ lọ́sẹ̀ tó ń bọ Ọkan nínú àwọn ọmọ ìgbìmọ̀ náà Sẹnatọ Solomon Adeola pe àwọn yóò ṣe àtúngbéyẹ̀wò snà ti wọn ń gbà pín owó sí ìpínlẹ̀ lójúnà àti sàn ẹgbẹ̀rún náírà gẹ́gẹ́ bi owó òṣìṣẹ́ tó kéré jùlọ jákejádò ẹka ìjọba Adeola faramọ àgbékalẹ̀ tó wà nínú àbádofin owó òṣìṣẹ́ tó kére jùlọ, ó fi kun pé ti ilé ìgbìmọ fẹ́nukò pé gbogbo ìpele ìjọba ló gbodo san owo náà.
Ẹ̀yin eniyan mi,àwọn olórí yín ń ṣì yín lọ́nà,wọ́n sì ti da ọ̀nà yín rú.
Wọ́n ṣe àmúlò Facebook gẹ́gẹ́ bí ohun èlò ìkórajọ wọn, èròńgbà wọn ni láti jẹ́ kí àwọn ènìyàn mọ̀ nípa àwọn ìjìyà obìnrin ní orílẹ̀-èdè Angola:
Bí kì í bá ṣe pé OLUWA ràn mí lọ́wọ́,ǹ bá ti dákẹ́ jẹ́ẹ́ ní isà òkú.
Wọ́n kọ ìwé náà ní orúkọ Ahasu-erusi ọba, wọ́n sì fi òrùka ọba tẹ̀ ẹ́ bí èdìdì.
Wọn yóo máa gun ẹṣin ati kẹ̀kẹ́ ogun àtàwọn, ati àwọn ìjòyè wọn, ati àwọn eniyan.
Ṣugbọn nisinsinyii, wọ́n ti rí àwọn iṣẹ́ mi, sibẹ wọ́n kórìíra èmi ati Baba mi.
awọn ti wọn ṣe ayẹwo wọn naa jẹ mẹẹdọgbọn, eleyii ti wọn bẹrẹ ni ỌjọBọ
odun 2019 yoo je ipenija fun awon eto ti a ni,paapaa julo nipa sise atunse si
''Emi ko gba pe o wọle.
Eré bọ́ọ̀lù: Musa gbá bọ́ọ̀lù sáwọ̀n fún ikọ̀ tuntun
Awọn eero naa fa aṣọ Asif Rafiq Siddiqi ya, wọn gba a ni ẹṣẹ, wọn gba a leti, wọn si tun gba ṣokoto nidi rẹ lẹyin ti wọn gbọ pe o ti gbeyawo tẹlẹ.
Mi o reti iru ọrọ lile to jade lẹnu minisita , pẹlu nkan ti awọn akẹẹgbẹ mi sọ.
wọ ́ n bí lọlá ní ojo ketala osu kesan odun 1975 ( september 13 , 1975 ) ní ilú new york city àmọ ́ àwọn òbí rẹ ̀ méjèjì jẹ ́ ọmọ orílẹ ̀ èdè nàìjíría ̀ .
Lọ́lá Ọlọ́run Ọba, a r’ẹ́ni tó lórí kẹ̀dẹ̀rẹ̀-kẹdẹrẹ, tó tún kó fìlà jọ bí ilẹ̀ bí ẹní.
N-power Agro wa fun awọn to nifẹ lati kọ nipa iṣẹ agbẹ, ti wọn yoo si le da wa laye ara wọn lẹyin ti wọn ba ti pari eto naa tan.
Àwọn àyípadà wọ̀nyí ni a ti ṣe láti mú ohun èlò náà wá sí ìbámu pẹ̀lú ìwífúnni onítàn tí ó péye jùlọ.
A jẹ́ pé àwọn ò tíì pá lórí, wọn kò tíì h’ewú lára.
Ẹ yipada kúrò ninu iṣẹ́ ibi yín, ẹ̀yin ọmọ Israẹli, kí ló dé tí ẹ fi fẹ́ kú?
“Ti won ko ba gbe igbese lati samulo awon ilana ofin ti yoo je ki o rorun lati pese awon ohun eelo agbelero nile, o seese ki o ma bi eso alaafia ni awujo”Ezeemo ro gbogbo eniyan lati bere si ni ra awon ohun ti a se ni Naijiria funra wa ni eyi to gba pe yoo mu anfaani ba awon eniyan ekun guusu ila oorun Naijiria ti won je olupese awon ohun eelo agbelero julo lorile-ede yii.
Kò sáyè iwọ́de mọ́ l'Eko ẹ lọ tọwọ́ yín bọṣọ - Ọlọ́pàá N kò ní buwọ́ lu ìṣúná tí kò pèsè owó fún ẹ̀bí àwọn tó kú nínú ìwọ́de EndSARS - Gbajabiamila Ìwọ́de #EndSARS rán èèyàn méjì sọ́run n‘Ibadan, Seyi Makinde da ikọ̀ Operation Burst sígboro Tẹ́ bá fẹ́ lo ìwọ́de láti gba àkóso ìjọba, wọn yóò dá yín lẹ́kun - Tinubu Ko pẹ si asiko naa ti awọn ologun ṣina ibọn bolẹ ni Lekki, eyii to jẹ ojuko kan gboogi ti ifẹhonuhan End SARS ọhun ti milẹ julọ ni ilu Eko, ti ibọn si ba ọpọ eeyan.
Ìjókòó ọmọbìnrin yìí ju ti ọba kọba nínú ayé wa, ẹwà rẹ̀ pàápàá sì tayọ ti ọmọ ènìyàn, ara rẹ ń dán bí ara ọmọ tuntun òòjọ́, àti apá àti ẹsẹ rẹ̀ yó bọ́rọ́bọ́rọ́ bí ẹni pé kò sí egungun níbẹ̀, ọmọ ìka ọwọ rẹ̀ yoo dàbí ara kòkòrò orí ọ̀pẹ, àtẹ́lẹwọ́ rẹ̀ mọ́ tónítóní ó dàbí ọjẹ̀lẹ ewé ọ̀gẹ̀dẹ̀, ìlẹ̀kẹ̀ ọrùn rẹ̀ dàbí òòrùn ọ̀sán gangan ti ń tan ìmọ́lẹ̀ púpọ̀, iroyin ọmọbìnrin náà rékọjá ohun sísọ.
Èmi kò forí ṣọta ìjàmbá ọkọ̀ òfúrufú kankan - Obasanjo Mà á ṣiṣẹ́ bí i gómìnà tó ní èrò aráàlú lọ́kàn - Seyi Makinde Aṣọ ń pe aṣọ ránṣẹ́ ni lásìkò ìbúra gómìnà àti ààrẹ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Nigeria Population: Báwọn ọmọ Nàíjíríà ṣe ń pọ̀ si jẹ́ ìpèníjà fún Buhari Ninu atẹjade ti oludamọran agba fun aarẹ lori ọrọ iroyin, Garba Shehu sita, Aarẹ Buhari yoo sọrọ nibi apero ọhun.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Igbese ti ajo ERA gbe lati koju tita siga lagbegbe ile ẹkọ Ti eti ba n dun eniyan, wọn yoo fi eefin taba sinu eti naa, wọn si gbagbọ pe ara rẹ yoo da.
Awon mejila ni yoo je agba omo igbimo nitori pe igbakeji won ree sugbon ko si eni omo odun marundinlogoji kankan ninu won.
Àmọ́ ọ̀rọ̀ burúkú òhun ẹ̀rín kọ́ rèé ni ẹ̀yin èèyàn mi?
O to iwọn kilomita mẹtadinlaadọfa ni Harare.
Nínú ọ̀rọ̀ tó fi ránṣẹ́ sí ayẹyẹ ìfàmì ẹ̀yẹ dánilọ́lá tí ìwé ìròyìn kan lórílẹ̀èdè Nàìjíríà ṣe nílùú Èkó, ni ìyàwó ààrẹ orílẹ̀èdè Nàíjíríà ti sọ èyí di mímọ̀.
abanirojo tabi agbejoro lowo lati le yanju awon kudie-kudie to ba wa laarin
Bi a bá tori ẹni burúkú fọ́jú, a kò ni ri ojú ri ẹni rere
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Travel Ban List: Muhammed ní Amẹ́ríkà kò bùn Nàíjíríà gbọ nípa ìgbésẹ̀ náà 28 Sẹ́rẹ́ 2020 Oríṣun àwòrán, @nigimmigration Minisita feto iroyin lorileede Naijiria, Lai Mohammed ti sọ pe, o ku diẹ kaato bi orileede Amẹrika ṣe fi orukọ Naijiria kun awọn orileede ti wọn gbegi dina irina awọn ọmọ ilẹ wọn lọ si Amẹrika.
Mi o gbadura ki ọta mi gan an koju iṣoro airilegbe.
Ṣugbọn sibẹsibẹ, ẹ óo kú bí eniyan,ẹ ó sùn bí èyíkéyìí ninu àwọn ìjòyè.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fọ́nrán ohùn, Imam Abdulsalam Olayiwola Oye Waziri, gẹgẹ bi ohun ti awọn onimọ so, jẹ oye ''Olubadamọran.
" Mo n ṣe Alakoso eto ayẹyẹ taa mọ si MC, mo tun n kopa ninu okoowo epo robi, mo tun n da oko ọgbin alada nla ni Naijiria ti ẹgbọn mi n ba mi mojuto, mo n ṣe ere tiata, ti mo si tun maa n sọrọ iwuri nibi agbekalẹ eto.
 Aya Elebuibon fikun pe, lootọ ni awọn se ipade ajọdun akọkọ nile Araba awo nilu Osogbo, nibi ti Baba Awo Ifayemi Elebuibon to bawọn sọ ọrọ apilẹkọ."
Ènìyàn 653 míràn tún kún iye àwọn tó ní COVID-19 ní Nàìjíríà Báwó ni òògùn dexamethasone ṣe ń ṣiṣẹ́ lára Wo àwọn òṣìṣẹ́ kólẹ̀-kódọ̀tí tó ń fi ẹ̀mí wọn wéwu kí Abuja leè mọ́ tónítóní Akanbi mi, má fọ̀ ọ́, mo wà pẹ̀lú ẹ; ẹni tó ṣe ìgbéyàwó olórùka ló l'ọkọ- Lizzy Anjorin Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ṣẹ́ lóòtọ́ ní ginger àti garlic lè pa àrun Coronavirus?
Akọsilẹ lori ayelujara Wikipedia sọ pe, Faleti, jẹ sọja nileesẹ ọmọ ogun ilẹ America, laarin ọdun 1998 si 2004.
NNPC n ronu afikun owo epo bentirolu
Lẹsẹkẹsẹ lawọn agbebọn naa si yin in nibọn.
Ede olóhùn ni èdè Yorùbá jẹ.
O ni oun nilo ki Aarẹ Trump fi ipo silẹ ki awọn le gbogun ti arun Coronavirus to n gbẹmi awọn eniyan lọgọọrọ.
Àwọn jàǹdùkú sọ Ààrẹ Buhari, Dapọ Abiọdun lókúta nílùú Abẹokuta
Orukọ odo yii si ni wọn fi n pe ipinlẹ kan nilẹ Yoruba taa mọ si ipinlẹ Ogun, eyi to sunmọ ilu Eko pupọ.
Bí wọ́n ti jí ní òwúrọ̀ ọjọ́ keji, iranṣẹ Abrahamu wí fún wọn pé, “Ẹ jẹ́ kí n lọ jíṣẹ́ fún oluwa mi.
Ó ní Yorùbá kíkọ̀ èmi Alákọ̀wé fẹ́ jọ èdè Lárúbáwá lójú òun nítorí àwọn àmì ọ̀rọ̀ tí mo máa ń fi sí i.
Ojo arọrọda Eko ṣe idiwọ fún káràkátà
Mo mú ọ̀gbẹlẹ̀ wá sórí ilẹ̀, ati sórí àwọn òkè, ati oko ọkà, ati ọgbà àjàrà ati ọgbà igi olifi.
Gbogbo ìyọnu tí a kọ sinu òfin Mose ti dé bá wa, sibẹ a kò wá ojurere OLUWA Ọlọrun wa, kí á yipada kúrò ninu ẹ̀ṣẹ̀ wa, kí á sì tẹ̀lé ọ̀nà òtítọ́ rẹ̀.
Ṣugbọn bí a bá fi mí ṣe ohun ìrúbọ ati ohun èèlò ninu ìsìn nítorí igbagbọ yín, ó dùn mọ́ mi, n óo sì máa yọ̀ pẹlu gbogbo yín.
“Ṣugbọn òkè ńlá ṣubú, ó sì rún wómúwómú,a sì ṣí àpáta nídìí kúrò ní ipò rẹ̀.
Nitori pe ko yẹ ki ajakalẹ arun Coronavirus gba asiko awọn akẹkọọ tan lodun 2020.
O daju pe ọjọ ti lọ lori wọn Àkọlé àwòrán, Ọwọ lo n tun ara se.
Igbimọ ọdọ Yoruba koro oju si bi ijọba Ọyọ se wo redio Ayefẹlẹ Igbimọ awọn ọdọ nilẹ Yoruba ti koro oju si igbesẹ ijọba ipinlẹ Ọyọ lori ileesẹ redio Yinka Ayefẹlẹ, Fresh FM.
Ṣugbọn má jẹ́ kí eniyan burúkú tilẹ̀ ta òróró sí mi lórí,nítorí pé nígbàkúùgbà ni mò ń fi adura tako ìwà ibi wọn.
ile-ejo tun so pe won yoo kede igba ti eto idibo naa yoo waye.
Ẹgbẹgbẹrun awọn ọmọbirin ni wọn maa n ko jade kuro ni orilẹede Naijiria to ni eeyan julọ nilẹ Afrika lọdọdun.
Olu ileeṣẹ ilẹ Amẹrika ti fesi si si iroyin to lu oju ayelujara pa laarọ ọjọ Ẹti pe wọn o fun oludasilẹ ijọ Living Faith Church ti ọpọ mọ si Winners, Bisọọbu David Oyedepo.
Bí wọ́n ti dé ibi ìpakà Kidoni, àwọn mààlúù tí wọn ń fa kẹ̀kẹ́ náà kọsẹ̀, Usa bá di Àpótí Majẹmu náà mú kí ó má baà ṣubú.
O ni: ''Nkan mẹta lo máa n ṣe atọna ibi ti a ti le gbẹjọ ọdaran.
Balaamu dáhùn pé, “Wíwá tí mo wá yìí, èmi kò ní agbára láti sọ ohunkohun bíkòṣe ohun tí OLUWA bá sọ fún mi.
Ó jẹ́ pé ìgbàtí ó ngbé níbẹ̀ ní ìgbà ìrúwé 1820, nígbàtí ó jẹ́ ẹni ọdún mẹ́rìnlá ní ọjọ́ orí, ni ó ní ìrírí ìran rẹ̀ àkọ́kọ́, nínú èyítí Ọlọ́run, Bàbá Ayérayé, àti Ọmọ Rẹ̀ Jésù Krístì bẹ̀ẹ́ wò fúnra wọn.
Fọláṣadé ni ó yí orúkọ padà tí ó di fìlísíà.
O ni ki awọn le jọ wa ọna abayọ naa loun ṣe pe ipade naa ati pé abọ iṣẹ ti a fun ẹnikọọkan nile iṣẹ ijọba ni a ṣẹṣẹ n to pọ ki a le mọ ọna abayọ.
Inú mi dùn sí iwọ́de EndSARS tàwọn ọdọ́ Nàìjíríà ń ṣè - Ooni Ogunwusi EndSARS protest in Nigeria: Mr Macaroni, Falz, Wizkid, Tiwa Savage àtàwọn míì ṣe ìwọde Ìfẹ́hònúhàn 'End SARS' ń tẹ́síwájú láì jẹ́ pé Buhari ṣe.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Eegunjobi Omotanbaje Ajobiewe- Èébú ní wọ́n kọ́kọ́ ń bù mí nígbà tí mo bẹ̀rẹ̀ ẹ̀ṣà pípé ní Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Kò ní sí òkúta kan lórí ekeji níhìn-ín tí a kò ní wó lulẹ̀.
Awon omokunrin ti won paO so pe lara awon omokunrin ti won pa ninu osu kerin odun yii, paapaa julo niluu London  ni Oluwadamilola Odeyingbo , omo odun mejidinlogun, Taofeek Lamidi, omo ogun odun, ati  Harry Uzoka,omo odun merindinlogbon.
Ile iwosan Kitwe Central Hospital to wa ni agbegbe Copperbelt nilẹ naa jẹ ọkan lara awọn ile iwosan to tobi julọ.
OLUWA, gbogbo àbá tí wọn ń dá ni o mọ̀,o mọ gbogbo ète tí wọn ń pa láti pa mí.
O tesiwaju pe ipinnu ijoba yii ni lati ri i pe alaafia joba ni awon agbegbe ti ikolu de ba ni jake –jado orile ede yii.
O ni Sanwo Olu funra rẹ ko ni kaadi idibo eyi to jẹ ko kuna lati dibo tabi ki wọn dibo fun un.
Akọròyìn Natalia Ojewska ti n ba awọn obinrin kan to kopa ninu isẹlẹ naa sọrọ ni ọgba ẹwọn.
Irọ funfun báláwú ni, Boko Haram kò dawa lọnà rárá -Ọmọ ogun Naijiria Ìdúnàdúrà ṣì n lọ láti dóòlà ọmọ Ọffa mẹ́fà lọ́wọ́ ajínigbé- ODU Ọlọ́pàá Nàìjíríà àti Ẹgbẹ́ IMN n ṣé fakinfa lórí ikú àwọn olùwọ́de ìdárò Ashura Ajímọ̀bí lè pe Ọlọ́run lẹ́jọ́ bí ìdájó kò bá tẹ́ ẹ lọ́rùn -Kọla Balogun Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, APC: òfin NYSC ti APC fi mú mi ni wọ́n kò lò fi mú Ajimọbi tí a kò jọ sìnrú ìlú Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
O fi kun un pe, ni ikọlu awọn agbebọn to waye ni ileewe girama awọn obinrin ni ilu Moriki, nijọba ibilẹ Zurmi, ipinlẹ Zamfara, awọn alase meji atawọn akẹkọ mẹrin ni awọn agbebọn naa ji gbe salọ.
Ipade igbimọ adari  ẹgbẹ APC n lọ lowo niluu Abuja .
“Ọkàn rẹ balẹ̀ ninu iṣẹ́ ibi rẹ,o ní ẹnìkan kò rí ọ.
Títí di àkókò tí a fi ń ko ìròyìn yìí jọ, a kò tíì mọ ẹbi arábìnrin yìí ṣùgbọ́n àwọn ará àdúgbò ibi tí ìṣẹ̀lẹ̀ yìí tí wáyé ní, ó ṣeé ṣe kí àwọn ẹbí rẹ yọjú sì ibi igboku sì ni ilé ìwòsàn gbogboogbo tí ìlú Àkúré.
Ninu ọrọ to fi ranṣẹ si BBC, Nkiru to farapa ninu ibugbamu Beirut eyi to mu ẹmi awọn to le lọgọrun un lọ sọ pe ṣe ni wọn ti oun atawọn mẹrin mii mọ inu yara kan ti wọn ko jẹ kawọn ba ọkọ baalu wa si Naijiria toripe wọn ni ọga Madaamu awọn wa fi ẹjọ awọn sun.
OLUWA ní,“N óo kó wọn pada láti Baṣani,n óo kó wọn pada láti inú ibú omi òkun,
Bi o ti lẹ jẹ pe akẹgbẹ rẹ ninu ẹgbẹ Republican to jẹ olori ile aṣofin agba Mitch McConnel ko fi taratara gba ti asiko yi gẹgẹ bi igba ti wọn yoo bẹrẹ igbẹjọ Trump,o ṣeeṣe ki o pada faramọ.
Oríṣun àwòrán, Hushpuppi/instagram Ṣé lóòtọ́ ni pé Hushpuppi ti kúrò ní ọgbà ẹ̀wọ̀n l'America?
Iru awọn eeyan wo lo n sisẹ ijinigbe yii?
Amọ ṣa bi wọn ti ṣe n sọ nkan nuu naa ni awọn to ri n da pada fun wọn.
60,000 àwakọ ló ń lo iwé ìrinà ọ̀kọ̀ tí kò k'oju oṣùwọn ní ìpínlẹ̀ Eko - FRSC Ọba Saudi fìwé pe Ààrẹ Buhari fún ìjọ́sìn Umrah Sùgbọ́n nígbà ti ó ri pe òun ko le lo ọwọ oun, ló ba bẹ̀rẹ̀ si ni kọ́ bi wọn se n fi ẹsẹ se orisirisi ǹkan; o le fi jẹun, tẹ fóònù, bákan náà lo fi n ya aworan.
Ta wa ló fún ará Ṣáínà lẹ́nu ọ̀rọ̀?
Bawọn kan ṣe faramọ orin ọhun lawọn mii ni o ku diẹ kaato.
Lasiko to n fọwọ idaniloju sọya fawọn akọroyin, agbẹnusọ fun ileesẹ ologun, Sagir Musa salaye pe, ẹni to ba ran ni nisẹ laa bẹru, a kii bẹru ẹni ti a jẹ fun.
Inú òun ati gbogbo ìdílé rẹ̀ dùn pupọ nítorí ó ti gba Ọlọrun gbọ́.
Lẹ́yìn náà, ó dojú kọ Jerusalẹmu, 
Aare tun ti fowosi  eto idagbasoke lori igbaye –gbadun ati owo ajemonu fun awon omo ogun orile ede yii paapaa julo awon ti o wa ni agbegbe ti ikolu wa nibe lorile ede yii.
Egbe a-ja-fominira kan, association Una Ventana a la Libertad (A Window on Freedom)to n samujoto awon ogba ewon so ninu atejade won pe,leyin ti won dana sun ibusun , ni ina naa bere si n ran kaakiri ko to wa di pe okan ninu awon ti won timole naa ,yin ibon lu olopaa  kan lese.
ỌJỌ́ KEJÌ LỌ̀DỌ̀ BABA-ONÍRÙNGBỌ̀N-YẸ́ÚKẸ́ Ẹ́NI TÍ Ń GBÉ IBI GEGELE ÒKÚTA
Ọ̀nà àbáyọ fún olóyún lásìkò àjàkálẹ̀ ààrùn Covid-19 Ẹnìkan ṣoṣo nínú ìdílé kan ni yóò gbà N20, 000 owó ìdẹ̀rùn igbele Covid-19 - ìjọba àpapọ̀ Lórí ọ̀rọ̀ Ogun Majek, mi ò lọ́rọ́ láti sọ, ẹ lọ pe ẹni tára rẹ̀ kò yá- Mr.
 a ṣe ìfilọ ́ lẹ ̀ rẹ ̀ àkọ ́ kọ ́ ní ọdún 1963 .
 pẹ ̀ lú olùgbé bíi 230 ẹgbẹgbẹ ̀ rún ènìyàn , òhun ni orílẹ ̀ -èdè olólùgbéjùlọ kẹrin láyé , ó sì ní olùgbé àwọn mùsùlùmí tótóbijùlọ láyé .
"Nitori ati maa ta orin Jazz ati orin ilẹ Adulawọ ni a ṣe ṣi ile itaja rẹkọọdu yii silẹ.
Ṣugbọn Ọjọgbọn Faduyile ni aridaju gbọdọ wa pe bi o ṣe yẹ ki oogun ibilẹ ṣiṣẹ lo ṣe n ṣiṣẹ ko to le di wi pa awọn eeyan yoo maa kẹkọọ gboye lori rẹ ni ileewe giga fasiti.
Bi awọn ipinlẹ to ni Coronavirus ṣe lọ ni yii: FCT-96 Eko-89 Plateau-68 Ogun-49 Edo-44 Rivers-43 Oyo-25 Osun-23 Delta-15 Enugu-11 Kano-7 Kaduna-7 Bauchi-2 Bayelsa-1 Yobe-1 Èèyàn 5 kú, 404 míràn tún kó COVID-19 ní Nàìjíríà l'Ọ́jọ́rú Eeyan 404 ni wọn kede pe ayẹwo tun fihan pe o laarun COVID-19 lorilẹede Naijiria bayii.
Bakan naa ni Ọjọgbọn Oluwatoyin Ogundipe saaju awọn to n fẹhọnu han lori bi wọn ṣe dede yọ kuro nipo.
ṣe Ijebu ko ti ṣe igbeyawo tẹ́lẹ̀ ni?
Oríṣun àwòrán, Getty Images Ẹwẹ, akọnimọọgba ẹgbẹ agbabọọlu Naijiria, Gernot Rohr sọ ṣaaju ifẹsẹwọnsẹ alẹ Ọjọru pe lẹyin ere bọọlu pẹlu Tunisia l'oun yoo kede bo ya oun yoo tẹsiwaju pẹlu ikọ agbabọọlu Naijiria.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Hepatitis: A kò leè kóo nípa dídìmọ́ ara ẹni Atiku ni: ''Niwọn igba ti ipenija ipinlẹ kọọkan lori eto aabo ti yatọ si ra wọn, o tumọ si pe eto aabo ti ijọba apapọ nikan pese ko le dẹkun iwa ọdaran ati rogbodiyan ni Naijiria, O ni idi eyi ni idasilẹ ẹṣọ eleto aabo bii Amọtẹkun fi ṣe pataki ni Naijiria.
Akosile ohun safihan pe, osuwon naa ja wale lati iko merindinlogun o  le 16.
, ti gbogbo ilu si n tuba tusẹ lasiko rẹ."
Oríṣun àwòrán, Abiola ajimobi Nkan miran ti o tun mẹnuba ni ki ọkunrin ko ba ọmọ rẹ obìnrin ni ajọsepọ, tabi aburo ati ibatan iyawo rẹ ni ibalopọ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ààrẹ Nàìjíríà tẹ́lẹ̀ rí Goodluck Jonathan ní òun ó ni ọrọ̀ kankan nílẹ̀ Òkèrè 12 Èbibi 2019 Oríṣun àwòrán, PHILIP OJISUA Àkọlé àwòrán, Aarẹ Jonathan ko jẹjọ kankan lori ọrọ to jọ mọ ajẹbanu Aarẹ Naijiria tẹlẹri Goodluck Jonathan ti ni, ati ile ati ileeṣẹ to fi mọ akoto ikowopamọsi nilẹ okere, ohun ko nikankan ninu wọn.
Mose ati Aaroni ati Huri bá gun orí òkè lọ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Budget 2019: Wo àwọn aṣíwájú àgbáyé míràn táwọn èèyàn dẹ́yẹsí lágbayé 20 Ọ̀pẹ̀̀ 2018 Oríṣun àwòrán, Ahmad Bashir Àkọlé àwòrán, Diẹ lara awọn to ti ba irufẹ itiju ati ariwo idẹyẹsi bayii pade ni Donald Trump, Theresa May, Jacob Zuma ati George Bush Idarudapọ ti ko kere lo waye nigba ti aarẹ Muhammadu Buhari tọ awọn aṣofin apapọ lọ lati gbe aba eto iṣuna orilẹede Naijiria ọdun 2019 kalẹ niwaju wọn fun agbeyẹwo.
Oríṣun àwòrán, Others Iwaadi awọn ọlọpaa fihan pe wọn yin oloogbe lọrun pa, ti wọn si ju oku rẹ sinu kanga to wa ninu ile rẹ.
A fẹ ki won fun wa ni ọkọ oju irin mẹ́wàá  ninu ọkọ oju irin mẹ́rìnlélọ́gọ́ta(64)
Bi ede Ijesha ṣe sun James Omiyinka de bi ire to di gbajugbaja alawada oṣere Yoruba.
Kò ní pada sí ilé rẹ̀ mọ́,bẹ́ẹ̀ ni ibùjókòó rẹ̀ kò ní mọ̀ ọ́n mọ́.
Àwọn nǹkan yòókù tí Solomoni ṣe: gbogbo iṣẹ́ rẹ̀, ati ọgbọ́n rẹ̀, ni a kọ sinu Ìwé Ìṣe Solomoni.
Oríṣun àwòrán, Dagrin Fimilejo Ileewe alakọbẹrẹ Meiran Community Primary school, Roseille nursery and primary school, Meiran Community High school, ati Egbado College lo lọ.
ní osù kẹrin ọdún 1917 ni ile america náà kéde ogun lé ilẹ ̀ germany lórí látàrí bí wọn ṣe kọlu àwọn ara ilẹ ̀ america nínú ọkọ ̀ ojú-oni ti èyí si tako ìlànà ogun jìjà .
Àkọlé àwòrán, Ile Baba Sala Nínú àtẹ̀jáde tí olùrànlọ́wọ́ pàtàkì rẹ̀ fọwọ́ sí, mínísítà fi ìbanújk hàn lórí ìpapòdà Bàbá Sala.
Ọjọ Satide, ọjọ kọkanla, oṣu Keje, ni ijọba ti ṣi oju opo itakun agbaye fun eto igbani sisẹ naa.
"Aarẹ Trump dupẹ lọwọ ọgbẹni Tillerson fun iṣẹ rẹ lori opo ayelujara Twitter rẹ, o sọ pe akọwe titun yoo ṣe ""iṣẹ ti o tayọ""."
"Àmọ́ ẹ ríi pé ẹ dáàbò bo ẹ̀mí yín - Ọ̀gá àgbà ọlọ́pàá Wumi Toriọla ti sọ̀rọ̀ sóke láti fi idí rẹ̀ múlẹ̀ pé òun àti ọ̀rẹ́ òun níjà Ojúmọ́ kan, ìdàmú kan ni mo fi lo ogún ọdún àkọ́kọ́ lórí oyè - Alaafin Tí iye iná tí ẹ rí gbà bá kéré ju owó tí ẹ rà á lọ, ẹ ti jẹ gbèsè tẹ́lẹ̀ ni - Iléeṣẹ́ apínnáká Wo ojú àwọn òṣèré yìí láì lo ""Make-up"" orí ìtàgé bó ṣe rí gẹ́lẹ́ Alukooro ileeṣẹ ọlọpaa ipinlẹ Oyo, Olugbenga Fadeyi sọ fun awọn akọroyin pe,l lootọ nio ọkunrin naa ti gba ominira, o si ti darapọ mọ awọn ẹbi rẹ."
Gbogbo ohun èlò tí ó bá wà ninu àgọ́ náà tí wọn kò fi ọmọrí dé di aláìmọ́.
"Oríṣun àwòrán, others Miracle Igbokwe: Olubori lọdun 2018 Ọdun 2018 ni wọn ṣe apa kẹta eto BBNaija pẹlu akọle ""Double Wahala""."
Àwọn ẹbọra kò jẹ́ fi àwo ẹlòmíràn jẹun.
Ìgbà tí mo sì dìde, mo ri i ó di bàbá mi.
O óo fi ọ̀kan rú ẹbọ ìmúkúrò ẹ̀ṣẹ̀, o óo sì fi ikeji rú ẹbọ sísun sí OLÚWA, láti ṣe ètùtù fún àwọn ọmọ Lefi.
 murtala kó pa pàtàkì nínú ogun abélé .
OLUWA tún sọ fún Jobu pé,
Iya n da gbe ni Balaraba fúnra rẹ jẹ, pẹlu awọn ọmọ rẹ.
A ti sún ìgbẹ́jọ́ Ganduje, Tambuwal àti Ihedioha sí ọ̀la Imam tó fẹ́ ọkùnrin míì níyàwó forí kó ìjìyà òfin Owó orí VAT di 7.
Iṣẹ́ ọwọ́ agbẹ́gilére ni wọ́n,ati ti àwọn alágbẹ̀dẹ wúrà.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: 5:30 p.
Ìjọba Naijiria: À ń se ìwádìí lórí àwọn oníwàásù Sokoto tó ń gbé ìbọ̀n
Èèyàn mẹ́tàdínláàdọ́fà ló móríbọ́ lọ́wọ́ Covid-19, 443 míì tún lùgbàdì rẹ̀ lọ́jọ́ Ẹtì Èèyàn 16 kú lẹ́yìn tí bàálù Air India já lulẹ̀ , tó sì kán sí méjì ní Kerala Ìtàn ayé Shina Rambo, adigunjale tó fi oyún 27 gún ọṣẹ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ohun tẹ́ẹ gbúdọ mọ nípa kókó orí ọyàn yín lásìkò fífọ́mọlọ́yàn Kí ló mú Aisha Buhari figbe bẹnu pé kí Ọ̀gá Ọlọ́pàá tú àwọn ẹ̀sọ́ rẹ̀ sílẹ̀?
Ṣùgbọ́n òun lè sọ̀rọ̀ jù, bí olúwaarẹ̀ ní ki òun dúró ìṣẹ́jú méjì aá’jẹ́ kí ó dúró iṣẹ́jú mẹ́rin; ìgbà tí mo sì dúró títí tí Olóhùn-dùùrù ń fi ọ̀rọ̀ dè mí mọ́lẹ̀, mo ń lọ láì tọrọ gááfárà lọ́wọ́ àwọn ènìyàn náà.
" Oríṣun àwòrán, Ajimobi lives on Bello, ẹni to sọ pe Ajimobi leri lati kọ mọsalasi nla ti yoo gba gbogbo eeyan, to si mu ileri naa sẹ tun fikun pe, mọsalasi ti Ajimobi kọ silẹ ni iwe ẹri Aljanna to gba laye.
Jeremaya ní, “OLUWA sọ fún mi pé, 
Seun Fakorede ti awọn eniyan mọ si Phakoo"" kẹkọọ jade ni ile iwe Fasiti olododo ti Ọbafẹmi Awolọwọ, Ile Ifẹ, ni Ọdun 2017."
Wo díẹ̀ lára àwọn ọ̀rọ̀ ìkẹyìn ti Alexander Akinyele fi léde kó tó papódà Olùdíje 24 ni yóò kópa ní ìdìbò Kogí Ọlọpàá gba owó ilé ìwé #150,000 lọ́wọ́ akẹ́kọ̀ọ́ DELSU kan Ẹ̀rù kò bà mí láti padà sí Bolivia- Evo Morales Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Ile-igbimo asofin ti sun ipade re siwaju latari iku okan lara awon asofin ohun, Olufunke Adedoyin omo bibi ipinle Kwara.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Pásítọ̀ ló sọ fún mi pé Ọlọ́run pè mí láti di Olokun tó ń bọ omi' Bẹẹ ba gbagbe, iroyin gbalẹ ni osu kẹjọ ọdun 2020 nipa arabinrin Risikat, ti ọkọ rẹ Abdulwasiu le jade pẹlu ọmọdebinrin meji nitori pe tiya tọmọ ni oju buluu.
O rí i pé igbagbọ ń farahàn ninu iṣẹ́ rẹ̀, ati pé iṣẹ́ rẹ̀ ni ó ṣe igbagbọ rẹ̀ ní àṣepé.
Ó jẹ́ kí alaafia wà ní ààlà ilẹ̀ rẹ,ó sì fi oúnjẹ tí ó dára bọ́ ọ lábọ̀ọ́yó.
O sọ pe awọn arinrinajo ni lati ṣalaye fun awọn oṣiṣẹ aṣọbode pe iṣẹ wọn ṣe koko ki wọn to le gba wọn laye lati wọ orilẹ-ede ọhun.
 owó te àwon òlòtè tó pa á , sùgbón kì lé tó pa òsìkà ohun rere á tí bà jé .
Ó mọ ọ̀nà rìkíṣí lọ́pọ̀pọpọ̀, o sì mọ̀ ọ́ tó bẹ́ẹ̀ tí ó jẹ́ pé bí o ń pa ènìyàn lọ báyìí olúwarẹ̀ yóò máa wí pé kò sí ọ̀rẹ́ òun tí ó to o.
Òkìkí rẹ̀ kàn ká gbogbo Siria.
Bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé àlàyé wọn kò fìdí èyí múlẹ̀ tó:
Èèyàn 104 kó covid-19 ní iléeṣẹ́ kan ṣoṣo ní Sagamu- Ìjọba Ogun Wèrè tí mò ń ṣe ní Facebook ló pawó fún mi-Esabod Kónílé-ó-gbélé Covid 19 ló tú àṣírí àwọn àfipábánilòpọ̀ láwùjọ- Mínísítà ọ̀rọ̀ àwọn obìnrin Fọ́ọ̀mù ìgbanisíṣẹ́ ikọ̀ Amotekun ti jáde - Ìjọba ìpínlẹ̀ Ondo O ni nigba ti wọn fẹ fi ofin de Naijiria ni awọn pinnu lati ko owo pamọ silẹ okeere, ki iya maa ba jẹ orilẹ-ede Naijiria nigba ti ofin idẹyẹsi naa ba de.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Joke Silva: Alágbàtọ́ ló gbà á nílé ọmọ aláìníyá, tó sì wò ó dàgbà 29 Owewe 2018 Oríṣun àwòrán, joke/instagram Àkọlé àwòrán, Joke Silva: Modupe lọ́wọ́ àwọn algbatọ mi fún itóju wọn Joke Silva jẹ́ ọ̀kan pàtàkì nínú àwọn gbajúmọ òṣèré tíátà ní orílẹ̀-èdè Nàìjíríà, adarí eré àti onisòwò.
Eyi waye nile iṣẹ ikọni ti Nigeria Immigration Service (NIS) to wa ni Kano.
Asán ni àwọn tí ń gbẹ́ ère, ohun tí inú wọn dùn sí kò lérè.
Màá gbé ASUU lọ'lé ẹjọ́ bí wọ́n bá dí mi lọ́wọ́ iṣẹ́ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Èmi kìí ṣe ọmọ ẹgbẹ́ ASUU' Ajeje ọwọ kan ko gbẹru dori, agbajọ ọwọ ni aa fi n sọya ni Yoruba maa n wi.
Ọdún jubili ni ọdún tí ó gbẹ̀yìn aadọta ọdún yìí yóo jẹ́ fun yín.
Oluranlọwọ pataki fun Aarẹ Buhari Garba Shehu, lo fọrọ naa lede lẹyin ti Obasanjo kede pe oun ti dariji Atiku, ati pe oun ṣetan lati ṣatilẹyin fun-un lati di aarẹ Naijiria.
Awọn nkan diẹ ti o le ṣe lati dena iba Lassa 1.
Ó tún sọ fún mi pé, “Má ṣe fi èdìdì di àwọn ọ̀rọ̀ àsọtẹ́lẹ̀ ìwé yìí nítorí àkókò tí wọn yóo ṣẹ súnmọ́ tòsí.
Wọ́n gbé Akọ̀ròyìn ní Morocco lọ sílé ẹjọ́ lórí ẹ̀sùn àgbèrè àti oyún ṣíṣẹ́ Àwọn ọ̀dọ́ kan ń ṣèwọ́de láti pè fún lílé àwọn àjòjì kúrò ní South Africa Ẹ̀kúnrẹ́rẹ́ ìdí tí àwa Shiite fí ń fẹ̀hónúhàn ní Abuja -Zakariyah Òní ni Shi'ite fẹ́ ṣe ìwọ́de ikú ọmọ ọmọ Anọ́bì ní èyí tí ó lòdí sí àṣẹ agbófinró O ni nipa aisinru ìlú NYSC, APC ṣe oun to wu wọn ni APC yọ orúkọ Shittu kúrò láti kópa nínú ìdìbò abẹ́lé .
Eyi to si mu ipaya ba awọn eeyan kaakiri orilẹ-ede yii ki aarẹ Muhammadu Buhari to paṣẹ wi pe ki wọn tọpinpin iṣẹlẹ naa.
Yewande bí'mọ tuntun jòjòló, Mercy Aigbe pàdánù èèyàn rẹ̀, Toyin Abraham fèsì lórí aṣoju NCDC Kí lo mọ̀ nípa fẹntilétọ̀, ohun èlò aṣèrànwọ́ èémí Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Coronavirus: Àwọn ọ̀nà tí ẹ le fi dun ara yín nínú lásìkò yìí Bákan náà lo fikùn pé, àwọn èèkàn ọmọ ẹgbẹ́ osere tiata kan náà tí ń sá ipa wọn láti ṣe itọju Ogun Majek, àmọ́ ìyànjú wọn yìí kò tíì tó láti wo àìsàn baba náà sàn pátápátá.
Wọn fi ẹsun kan Omah Lay atawọn ẹmẹwa rẹ nile ẹjọ majistrati Makidye pe wọn mọọmọ wu iwa to le mu ki arun Covid-19 burẹkẹ si lorilẹ-ede naa.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Fulani Heardsmen: Afenifere ní àṣẹ tó bá wu àwọn àgbàgbà agbègbè àríwá Nàìjíríà ni Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Àkójọpọ̀ àwòrán Òjò òwúrọ̀ Ọjọ Àjé l'Eko Èèmọ̀ rèé o!
Agbẹjọrọ to tun jẹ ajafẹtọ fun awọn ọmọde, Arabinrin Elizabeth Udeh ni ko si ofin kankan to sagbatẹru igbese ti ijọba ipinlẹ Eko fẹ gbe naa.
,ni o fi iwe ipẹjọ ranse si ile-ejo to ga julo lorile ede yii, (Apex court)
com/qT5ypZGvgDAS IT STANDSMan City back on top…#BHAMCI #LIVWOL pic.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Man U dero Europa Ẹgbẹ agbabọọlu Man U kuna bayii lati yege fun idije Champions League ni saa ere bọọlu to n bọ.
Oríṣun àwòrán, Twitter/RotimiAkeredolu Lọjọbọ ni iroyin kan gbode pe, iyawo Gomina ti ko arun Covid -19, ti atẹjisẹ kan ti awọn eeyan n pin kaakiri si sọ pe, ki gbogbo awọn eeyan to kopa nibi eto ti iyawo Gomina se ni Idanre ati Odigbo, tara lọ se ayẹwo.
Ìyá rẹ̀ kú ní ọdún mẹ́ta sẹ́yìn, ìyẹ̀n ni pé ó kú ní ọdún mẹ́ta ṣáájú bàbá rẹ̀.
Bí wọ́n ti ń lọ lọ́nà, tí wọn ń gòkè lọ sí Jerusalẹmu, Jesu ṣáájú, àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ tẹ̀lé e.
Arun naa tun ti mu gbajugbaja oṣere tiata, Omotola Jalade Ekeinde, to si kede loju opo Twitter ati Facebook rẹ pe, ojojo arun ọhun ni ko jẹ ki oun yọju sita lati ọjọ yii wa.
Sí ìpàdé, o pe edé sí ìpàdé, ó pe ìlá sí ìpàdé, ó tún pewéédú sí ìpàdé, bẹ́ẹ̀ ni o gberaga bẹ́ẹ̀ ni, àjejù kò sunwọ̀n, ìwọ̀ntunwọ̀nsì ló dára.
Ọgbẹni Kayode Egbetokun sọ fun BBC Yoruba pe ọjọ Ẹti ni awọn ọlọpaa ri wọn doola ninu igbo kanA óò wá àwọn ọmọ ilẹ̀ Turkey mẹ́rin tí wọ́n jígbé rí láàyè- Ọlọ́pàá Kwara.
Nibi eto kan ti a pe ni: “ona ipese ise/riro awon alainise lagbara”,  ti o waye nipinle Eko,oludasile egbe naa, omooba Chukwunwike Moses Esiole so pe, egbe ohun n sakitiyan lati pese ise nipase eto ogbin.
Palali, ọmọ Usai ṣe àtúnṣe ibi tí ó kọjú sí Igun Odi ati ilé ìṣọ́, láti òkè ilé ọba níbi ọgbà àwọn olùṣọ́.
Ó tún fi kún un fún wọn pé “Orílẹ̀-èdè kan yóo máa gbógun ti ekeji, bẹ́ẹ̀ ni ìjọba kan yóo sì máa gbógun ti ekeji.
Bí o ti ṣe sí Jẹriko ati ọba rẹ̀, bẹ́ẹ̀ gan-an ni kí o ṣe sí Ai ati ọba rẹ̀.
Oríṣun àwòrán, Others Deede aago kan oru ni isẹlẹ naa waye , tawọn afurasi ọdaran naa si gba ẹrọ ibaraẹnisọrọ alagbeka meji .
Ní sáà yìí, ilé ìwòsàn to wà fún ìtọ́jú àwọn alárùn ọpọlọ ní ìpińlẹ̀ Eko Federal Neuropsychiatric Hospital ti gbogbo ènìyàn mọ si YabaLeft lo ṣe àbẹ̀wò si láti le mọ ǹkan ti ó ń sẹ̀lẹ̀ níbẹ̀.
"Ó ti tó wákàtì mẹ́rìnlélógun ti Ibiyeomie ti sọ̀rọ̀ ìdúkokò yìí, àwọn ọlọ́pàá Nàìjíríà kò sì ṣe ǹkankan si"" Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Temitope Akinnusi: Ọ̀pọ̀ iléeṣẹ́ ló takú láti gbà mí síṣẹ́ torí mo ní ojú kan Ó wa pé àwọn ọmọ Naijiria pe, ṣe bi wọ́n yóò kan ṣe maa wò ọ̀rọ̀ yìí ko lọ bẹ́ẹ̀ rèé, nítorí pé Ibiyeomie jẹ́ èèyàn ńla?"
Ó gùn ju ayé lọ,Ó sì fẹ̀ ju òkun lọ.
Tí a bá kì f’awo, awo á kì f’ọ̀gbèri .
Ìlú kan yóo wà níbẹ̀ tí yóo máa jẹ́ Hamoni.
Koda owe to jẹ ẹṣin ọrọ naa wa nibẹ Àkọlé àwòrán, Awọn ori ade ile Oodua ko ṣee fọwọ rọ sẹyin rara ninu gbigbe asa ati iṣe Yoruba ga.
O kò gbọdọ̀ bá arabinrin ìyá rẹ lòpọ̀, nítorí pé, ẹbí ìyá rẹ ni ó jẹ́.
Oga Oloopa ni Ipinle Oyo, Shina Olukolu ti so di mimo pe
8 legbegberunkeji ni november 2009 .
Ni oṣu keji ọdun 2014 Oríṣun àwòrán, AFP Àkọlé àwòrán, An agbebọn Boko Haram kọlu ileewe Government Girls Secondary School, Dapchi, Yobe Awọn agbebọn kan ti wọn jẹ ọmọ ikọ Boko Haram dana sun akẹkọ mọkandinlọgọta ni ileewe girama kan ni ilu Buni Yadi nitosi Damaturu tiiṣe olu ilu ipinlẹ Yobe.
 gẹ ́ gẹ ́ bí àkọsílẹ ̀ ètò ìkànìyàn ọdún 2006 , àpapọ ̀ iye enìyàn tó wà ní Àgbádárìgì jẹ ́ 241,093 .
Osun Tribunal Judgement: 'Àwa ènìyàn Ọṣun kọ ìdájọ́ tó ní Oyetọla kọ́ ló wọlé sípò gómìnà'
Bí ọ̀rọ̀ kan bá délẹ̀ nípa iṣẹ́ ìlú, wọn máa ń rúnpá-rúnsẹ̀ sí i, wọ́n á sì mú sòkòtò wọn wọ̀ láti yanjú irú ọ̀rọ̀ náà.
Nítorí náà, OLUWA Ọlọrun ní, mo fi ara mi búra, bí ẹ ti fi ìrúnú ati owú ṣe sí wọn nítorí pé ẹ kórìíra wọn, bẹ́ẹ̀ gan-an ni èmi náà óo ṣe sí ọ; n óo sì jẹ́ kí ẹ mọ irú ẹni tí mo jẹ́ nígbà tí mo bá dájọ́ fun yín.
Ẹ wo ǹkan to sẹlẹ̀ sí ọmọ àti ìyàwó ọmọ Atikú tó lùgbàdì ààrun Coronavirus Àrùn Coronavirus ti gba ẹ̀mí ẹni àkọ̀kọ̀ ní Zimbabwe Dokita àti Nọ́ọ̀sì fìyà jẹ mí lásìkò tí mò ń rọbí- Alaboyún Ìjọba ti pápákọ̀ òfúrufú Eko àti Abuja pa nítorí coronavirus Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí kan sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
Oníṣẹ́ àdáni 250,000 ni ìjọba ṣe ìlànà yìí fún Ẹ gbọ́ ohun tí Desmond Elliot sọ lórí ayélujára tó bí àwọn ọmọ Nàìjíríà nínú Àwàdà tàbí óótọ́, kì lò f'ẹkún Kọmíṣọ́nnà ìlera Kogi lórí amóhùnmáwòrán?
ọ̀kan fi òun sílẹ̀, òun sì wí pé, dájúdájú, ẹranko kan ti fà á ya pẹ́rẹpẹ̀rẹ, òun kò sì tíì fi ojú òun kàn án láti ìgbà náà.
Ramadan: Kíni ǹkan tó ń ṣẹlẹ̀ si àgọ ara rẹ̀ ti o bá n gbààwẹ
Lea bá ní, “Mo láyọ̀, nítorí pé àwọn obinrin yóo máa pè mí ní Ẹni-Ayọ̀,” nítorí náà ó sọ ọmọ náà ní Aṣeri.
Nítorí náà àwọn ohun tí wọ́n ní lọpọlọpọati ohun ìní tí wọn ti kó jọ,ni wọ́n kó lọ sí ìkọjá odò Wilo.
Ni ọ̀pọ̀lọpọ̀ ọdún sẹhin, Adájọ́ àti Agbẹjọ́rò ki i ṣe iṣẹ́ nitori àgbà ni ó ndá ẹjọ́ bi ijà bá bẹ́ silẹ̀ ni ilẹ̀ Yorùbá.
Kò tán síbẹ̀, Gómìnà ìpińlẹ̀ Rivers, Nyesom Wike náà wa lára àwọn to kọ́kọ́ ki Obaseki ku oríire ìjáwé olúborí.
sugbọn ikilọ wa fawọn akikaju onwẹ to ba fẹ re sinu omi, awọn olugbe ibẹ ni o kun fun awọn ohun eelo iwakusa lorisirisi ti omi ti bo mọl.
 a má a nṣe iṣẹ ́ -abẹ nígbà mìíràn láti yọ àpò tí omi gbè sí náà kúrò .
Wọ́n gbéra láti Efuraimu lọ sí àfonífojì náà,wọ́n tẹ̀lé ọ, ìwọ Bẹnjamini pẹlu àwọn eniyan rẹ.
Ìwọ́de náà bẹ̀rẹ̀ láti ọ́ọ́fìsì àwọn ẹgbẹ́ ọ̀ṣìṣẹ́ ní agbègbè Yidi, lọ sí Gate àti Mọkọla nílú Ìbàdàn.
Àwọn ìròyìn mìíràn tí ẹ lè nífẹ̀ẹ́ sí: Ilé ẹjọ́ dajọ ikú fun ọkunrin tó pa olólùfẹ́ rẹ̀ Alápatà lu ìyàwó rẹ̀ pa ní Ogun Ọmọ ọdun méje gbé bàbá rẹ̀ lọ àgọ́ ọlọ́pàá Kí ló mú àwọn obìririn meji yìí pa bàbá wọ́n?
Eyi si ti fa ọpọ ipe da ina ogun, da ina ọtẹ lataọdọ awọn eekan kan ni ilẹ Yoruba lori lemọlemọ iṣẹlẹ ijinigbe ati igbenipa to n waye lapa iwọ oorun guusu orilẹ-ede Naijiria.
Ki ijọba gba awọn ajagunta lati ṣe afọmọ agbegbe Sambisa.
Yorùbá tone mark: Fífi àmì ohùn sí orí ọ̀rọ̀ Yorùbá ṣe pàtàkì Àwọtẹ́lẹ̀ ọkùnrin àti Ìdọ̀tí Kilo méje ṣekú pa Ìgalà Ẹ wo iye t'óúnjẹ dà báyìí lọ́jà lẹ́yìn tí ìjọba ti ibodè Eku gba ìjọba ní Estonia, ìjọba pàdánù owó gọbọi Bakan naa lo ni wọn tun bura nipa ẹnikẹni to ba mọwọ mẹsẹ si iṣẹlẹ naa pe ki imọlẹ foju ẹ han sita, ko ṣee bi ọṣẹ ṣe n ṣe oju.
Tomije-tomije ni ọgọrọ eeyan to tẹle posi oloye naa fi n sin in lọ si itẹ ikẹyin pẹlu orin aro lọlọkan-o-jọkan lẹnu wọn.
Àbí omi tútù tí máa ń ṣàn láti inú òkè rẹ̀ a máa gbẹ?
Ẹ̀yin ará, ní ìparí ọ̀rọ̀ mi, a fi Jesu Oluwa bẹ̀ yín, a sì rọ̀ yín pé gẹ́gẹ́ bí ẹ ti gba ẹ̀kọ́ lọ́dọ̀ wa ní ọ̀nà tí ó yẹ, kí ẹ máa rìn bí ó ti wu Ọlọrun.
Boasi bá ṣú Rutu lópó, Rutu sì di aya rẹ̀.
Ẹwa lo n ta tẹlẹ ko to maa se ẹwa ta lọdun 1951.
Awọn eniyan ati lọbalọba lo ti n kesi awọn janduku naa lati da ọpa aṣẹ pada ki oju wọn ma ba ri ibi.
Alẹ Ọjọbọ ni ina ọhun deede ṣeyọ ni yara idana, ṣugbọn awọn olukopa ninu eto naa korajọ lati tete pa a.
Mo ti kìlọ̀ fún àwọn ọdọmọkunrin wọnyi pé wọn kò gbọdọ̀ yọ ọ́ lẹ́nu.
Aarẹ Buhari ni, oun nigbagbọ wipe ifẹ ilẹ baba ẹni, ifaraẹnijin ati itẹpamọsẹ awọn ọmọ Naijiria naa, ti mu wọn dide duro pẹlu asia orilẹede Naijiria ni South Korea.
 baale o ríi wí pe ogunlọlá gbé àdùtú àrokò náà lọ sí ọ ̀ dọ ̀ aláàfin .
aare lati mu ileri ti o se fun awon obinrin sẹ, nipa yiyan won, sinu ipo ijoba.
Iraq, Palestine wà nínú orílẹ̀-èdè mẹ́wàá tí ìwádìí BBC ti wáyé
Lára ohun ti ẹni ti ó bá ni àròkàn lè ṣe ni: ki ó ni igbàgbọ́, ìtẹ́lọ́rùn, ro rere, ṣe iṣẹ rere,  jinà si elérò burúkú tàbi oníṣẹ́ ibi àti lati fẹ́ràn ẹni keji.
Lẹ́yìn náà, ó gbadura sí OLUWA fún ìrànlọ́wọ́ Israẹli; OLUWA sì gbọ́ adura rẹ̀.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Odebiyi: ìgbà gbogbo ni Bàbá mi ń polówó iṣẹ́ mi fáráyé Ẹjọ naa da lori pe ileeṣẹ naa ko fi to awọn awakọ ofurufu leti awọn ewu to rọ mọ awọn irinṣẹ tuntun ti wọn fi n rinna ofururu to wa ninu Max 8 naa.
Ri i daju pe eku ko si ni ile rẹ.
 o jẹ agbejoro agba ati alabojuto eka idajo ti ipinle eko lati ọdun 2007 titi odun 2011 .
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Buhari: Kò sí àyè wíwọ ọkọ̀ bààlú olówó gọbọi mọ́ fún àwọn òṣìṣẹ́ ìjọba 17 Ọ̀wàrà 2019 Oríṣun àwòrán, @thesignalng Ajọ ajafẹtọ ẹni, SERAP ti sọ pe arumọjẹ lasan ni igbeṣe ti aarẹ Muhammadu Buhari gbe lati fi adinku si owo ti awọn oṣiṣẹ ijọba n na lori irinajo silẹ okere.
'Jollof, Iyan, Asaro, Ewa Alagbado kìí wọ́n n'ílé oúnjẹ wá ní Egypt' Ẹwa Agọnyin ni aayo ounjẹ Badagry Ta lo ni igbo?
Ile-ise ohun ni won fun ni ami eye Wura (Gold) fun sisan owo-ipin ikodowo fun awon onibara re lore-koore.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: NAFDAC ń wádìí ílé iṣẹ́ apoògùn mẹ́rin Codein lọ, DXM wọlé, kinni iyatọ?
Ọrọ odi to sọ yii lo sọ ọ di ẹni to n kawọ pọn rojọ niwaju adajọ ile ẹjọ Sharia ki wọn to dajọ iku fun un.
Bí ẹ bá mọ̀ pé olódodo ni, ẹ mọ̀ pé gbogbo ẹni tí ó bá ń ṣe òdodo ni ọmọ rẹ̀.
Bakan naa ni ileẹjọ ohun pàṣẹ ki ẹgbẹ NLC ma di awọn ọmọ Naijiria lọwọ lati ṣe iṣẹ oojọ wọn.
Hana dá a lóhùn, pé, “Rárá o, oluwa mi, n kò fẹnu kan ọtí waini tabi ọtí líle.
Ni aaye iko nkan pamọ si ni ibudoko ọkọ oju omi to wa ni Beirut ni ibugbamu yi ti ṣẹlẹ.
Yemi Shodimu lẹni taa n wi to si kopa ninu awọn ere sinima bi Ò le kù (1997), Ti oluwa ni ile (1993) ati Kòseégbé (1995).
Ẹ sẹ́ ẹni Ọlọrun ati olódodo, ẹ wá bèèrè pé kí wọ́n dá apànìyàn sílẹ̀ fun yín; 
Wọ́n gbé Àpótí Majẹmu Ọlọrun kalẹ̀ ninu àgọ́ tí Dafidi ti tọ́jú sílẹ̀ fún un, wọ́n sì rú ẹbọ sísun ati ẹbọ alaafia níwájú Ọlọrun.
US Embassy: Ọ́fíìsì Amẹrika ni Nàìjíríà kéde ìyípadà ètò ìwé ìrìnna Abiyamọ ò!
Láti inú ayé ni àwọn yìí ti wá; nítorí náà, wọ́n ń sọ nǹkan ti ayé, àwọn aráyé sì ń gbọ́ tiwọn.
    “Mo ti sọ lánà-án bí o ti jẹ́ pé ọba ìlú wa rán mi ní iṣẹ́ wí pé ki n ṣe olórí àwọn ọdẹ pàtàkì ti wọn n lọ sí ìlú pàtàkì kan ti orúkọ rẹ̀ ń jẹ òkè Ìrònú níbi tí wọn o ti ká èso Ìrònú lórí igi ìrònú nínú Igbó Elégbèje.
Botilẹ jẹ wipe iwe ofin sọ wipe ile igbimọ asofin lo lagbara ju ni China- gẹgẹ bi oti wa ni awọn orilẹede yoku.
I kanna, Nsikak Edet ati ọgagun Francis Omata to n dari 81 Division Garrison.
Coronavirus Vaccine: Ṣé abẹrẹ àjẹsára ti wà fún àrùn COVID-19?
Mo dáhùn mo sì wí pé: “Àkàrà-oògùn,” òun náà fèsì ó ní, “Èmi náà nù-un.
Wọ́n fi aṣọ aláwọ̀ aró, ati ti elése àlùkò, ati aṣọ pupa, rán ẹ̀wù aláràbarà tí àwọn alufaa yóo máa wọ̀ ninu ibi mímọ́ náà fún Aaroni gẹ́gẹ́ bí OLUWA ti pàṣẹ fún Mose.
Victoria Adeyele AKA Vee Timmy Sinclair AKA Trikytee Terseer Kiddwaya Praise Nelson Florence Wathoni Anyansi Tochukwu Okechukwu AKA Tochi Kate Jones AKA Ka3na Eric Akhigbe Ngozi Nlewedim AKA Erica Ezekiel Bright Osemudiame AKA Brighto Aisha Umaru AKA Kaisha Emuobonuvie Akpofure AKA Neo Tolani Shobajo AKA Tolanibaj Olamilekan Agbeleshe AKA Laycon Rebecca Hampson AKA Nengi Lucy Ẹ̀wẹ̀, àwọn ọmọ Naijiria gẹ́gẹ́ bi ìṣe wọ́n, wọ́n ti sọ bí ǹkan yóò ṣe ri láàrin Lilo àti Eric nígbà ti wọ́n bá fi ojú kan ara wọ́n.
Ohun tí Ọlọrun pè ọ́ fún nìyí, òun sì ni ẹ̀rí rere tí o fi ẹnu ara rẹ jẹ́ níwájú ọpọlọpọ ẹlẹ́rìí.
4 142344 Orilẹede Japan 2277 1.
Mò ń rán ọ sí wọn kí o lè sọ ohun tí èmi OLUWA Ọlọrun wí fún wọn.
Arsenal tun fidirẹmi Arsenal ja bi ẹlẹṣẹ - Wenger Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 3 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 5 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Ẹ jẹ́ kí àwọn mejeeji jọ dàgbà pọ̀ títí di ìgbà ìkórè.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ileesẹ ọmọogun Nàìjìríà: A ò fipá bá ẹnikẹ́ni lò ní ìpàgọ́ 24 Èbibi 2018 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Sùgbọn agbẹnusọ fún àjọ ọmọogun sọ pé irọ́ pátápátá ni ọrọ náà pé àwọn ń fi tipátipá báwọn aṣàtìpó lájọṣepọ̀ Ìròyìn tuntun tún jáde pé àwọn ọmọogun orílẹ̀-èdè Nàìjìríà ń ṣe àwọn ọ̀dọ́mọbìnrin àti àwọn abilékọ to sá fún ìkọlù Boko Haram báṣubàṣu.
"O ṣee ṣe ko jẹ pe ọna lati gbadura fun alaafia lori arun Coronavirus lo mu ki awọn gomina kan kede pe ki awọn musulumi lọ kirun ọdun itunu aawẹ, ti wọn si tun fun awọn Kristẹni laaye lati ṣe isin.
Adébáyọ̀ Fálétí, ògúná gbòngbò ti ó gbé èdè àti àṣà Yorùbá lárugẹ jade láyé.
OLUWA ti fi ògo Jakọbu búra; ó ní, “Dájúdájú n kò ní gbàgbé ẹyọ kan ninu iṣẹ́ ọwọ́ yín.
“Ẹni tí ó bá kọ̀tí kò ṣàánú ọ̀rẹ́ rẹ̀kò ní ìbẹ̀rù Olodumare.
Awọn aworan miran re lati ibi ipade naa: Oríṣun àwòrán, @NGRPresident Àkọlé àwòrán, Aworan yi se afihan Aarẹ Buhari pẹlu awọn ọmọ Naijria ni China to n kẹkọ nipa irinajo ọkọ oju irin Oríṣun àwòrán, @NGRPresident Àkọlé àwòrán, Asisat Oshola agbabọọlu OBINRIN Naijiria to n gba bọọlu jẹun ni China naa sọrọ nibi ipade oun Sẹnetọ mẹrin ati Gomina Ipinle Akwa Ibom tẹlẹri, Godswill Akpabio to sẹsẹ kuro ni ẹgbẹ oselu APC lọ si PDP wa lara awọn to tẹle Aarẹ Muhammadu Buhari lọ si China.
Brazil police brutality: Awuyewuye ti n wáyé lórí bí ọlọ́pàá ṣe fún obìnrin kan ní ọrùn pa
Omotola sọ pe, ohun to buru jai ni iru iṣẹlẹ yii, o wa ke si Gomina Babajide Sanwo-Olu lati wa nnkan ṣe si ọrọ awọn ọkọ tirela to da ẹmi awọn araalu, papaajulọ awọn ọdọ, legbodo.
Níbẹ̀ ni ó ti fi Iṣiboṣẹti jọba lórí gbogbo agbègbè Gileadi, Aṣuri, Jesireeli, Efuraimu, Bẹnjamini, ati lórí gbogbo ilẹ̀ Israẹli.
Ẹ̀rí eniyan kan kò tó fún ẹjọ́ apànìyàn.
Ninu iwe ipẹjọ kan ti ẹka eto idajọ gbe siwaju ileẹjọ District Colombia ti Washinton, ni akara ọrọ naa ti tu sepo, gẹgẹ bi iwe iroyin ilẹ Amẹrika kan ti gbe jade, ti ijọba apapọ ko si ti fesi le lori.
Ó ní bí ǹkan ṣe ń lọ yìí mímú ètò náà wá sí ìmúṣẹ yóò mọ́wọ́ró díẹ̀ títí di ìgbà ti mínísítà bá le sàlàyé ara rẹ̀ lẹ́kunrẹ́rẹ́ fún àwọn ọmọ ilé ìgbìmọ̀ aṣòfin àgbà."
Awọn eeyan to n bọ orisa ogun pọ aja, si ni eroja kan gboogi ti wọn fi n bọ Awọn eeyan to jẹ olorisa Ogun lo maa n jẹ Ogungbemi, Ogunlana.
Awọn ti wọn jọ n ṣe agunbanirọ ni ile iwe ikọni Tai Solarin lo ti pari ẹkọ rẹ ko too wa sin ilẹ̀ baba rẹ, ko to o jade laye.
Ìlú Ilé-Ifẹ̀ lo gbé to fi kú.
Di ẹ ninú àwọn iwà burúkú wọnyi ni ki òṣiṣẹ́ ìjọba ji ẹrù àti owó Ìjọba fún ara wọn tàbi sọ ara wọn di alágbàtà ti o nsọ ọjà di ọ̀wọ́n nipa gbi gba àbẹ̀tẹ́lẹ.
Ẹ̀yin ẹlẹ́gbẹ́ òkùnkùn tẹ fẹ́ ṣe àjọ̀dún lónìí, lákọ la ń dúró dè yín - Iléeṣẹ́ ọlọ́pàá Ìjọba Akeredolu kò ní omi àánú lójú, a kò tọ́jú alárùn Coronavirus mọ́ - Dókítá Ondo Kòṣẹlẹ̀rí ni Hajj ọdún 2020, wo ìyàtọ̀ tó wà nínú rẹ̀ sí ti tẹ́lẹ̀ Ṣé lóòtọ́ ni Lateef Adedimeji àti Adebimpe Oyebade ṣe ìgbéyàwó?
tabi lára aṣọkáṣọ, kì báà jẹ́ olówùú tabi onírun, tabi lára awọ, tabi lára ohunkohun tí a fi awọ ṣe.
Ìgbà tí ó lọ tan ni Adéforítì sọ fún wa tí ó wí pé ìránṣẹ́ Olódùmarè ni àti pé ṣe ni ọba ọ̀run ránṣẹ́ wá sọ fún òun pé òun kò gbọdọ̀ jẹ́ kí àwọn lébìrà tí òun mú ti ọ̀run Àpáàdì wọ̀n-ọnnì dé ibi ilé Ìgb éga-ọ̀run rárá nítorí ìrańṣẹ́ Èṣù kò gbọdọ̀ dé sákání Ọlọ́runn ọba.
Amọ Chelsea gbọnranu ti wọn si jẹ goolu keji.
Aare egbe  NLC tun wa ro ijoba apapo lati wa ona miiran
Akọle to wa labẹ aworan naa lo ni wọn n se iwọde lati se atilẹyin fun iwọde EndSARS ni.
ọwọ ijoba tẹ awọn eniyan ibi naa.
Ìròyìn tí ó jáde ní àìpẹ́ sọ pé “ìfọ̀mọ́” náà le gidi gan-an ni, pẹ̀lú ikú èèyàn méjì ó kéré tán àti ogunlọ́gọ̀ àwọn tí ó wà ní àtìmọ́lé tí ó lòdì sí òfin.
"Lori eyi, Adams sọ fun wa pe ""Ọlọpaa to ba mọ pe oun fẹ ṣe aṣeyọri kun aseyọri gbọdọ ba ẹgbẹ OPC ṣe papọ."
Baba tí ó rán mi níṣẹ́ ti jẹ́rìí mi.
Bí o ti bẹ̀rẹ̀ sí gbadura ni àṣẹ dé, òun ni mo sì wá sọ fún ọ́; nítorí àyànfẹ́ ni ọ́.
Ile iwosan Virtua Our Lady of Lourdes yii nikan ni wọn ti n ṣe iṣẹ abẹ paṣipaarọ kindinrin, ọkan ati awọn iṣẹ abẹ bẹẹ miran ni guusu New Jersey.
Kí wọn tó yọjú jáde rárá,ni mo ti sọ fún ọ nípa wọn.
S nítorí wọ́n bí ọ síbẹ̀ mọ́’ A kò tí ì gbọ́ ǹkankan lórí owó ìwé ìrìnnà sí Naijiria - U.
Ọdun kan pere ni Seedorf ṣi lo nipo gẹgẹ bii oluksni ẹgbẹ agbabọọlu Indomitable lions.
 africanus jẹ ́ tẹ ́ ẹ ́ rẹ tí wọ ́ n rí ní apá gúúsù Áfíríkà nìkan : taung ( 1924 ) , sterkfontein ( 1935 ) , makapansgat ( 1948 ) àti gladysvale ( 1992 ) .
Lẹ́hìn èyí mo lọ sí ibi omi kékeré kan báyìí tí ó ṣán la’ti orí àpáta kan wá sí ìsàlẹ̀ mo sì fi ewé títóbi bu omi mu.
Ṣugbọn bí wọn kò bá lè mú ara dúró, wọ́n níláti gbeyawo.
Ta ló kéde rẹ̀ láti ìbẹ̀rẹ̀ wá, kí á lè mọ̀,ta ló sọ nípa rẹ̀ láti ìbẹ̀rẹ̀ pẹ̀pẹ̀kí á lè sọ pé, ‘Olóòótọ́ ni?
Ikọ Super Eagles ti Naijiria lo yọ ọwọ kilanko Cameroun kuro lawo idije AFCON 2019 to n lọ lọwọ ni orilẹede Egypt eleyi lo si mu ki minisita fere idaraya ni orilẹede Cameroun o ni ko wa maa lọ.
Jakọbu sọ fún Josẹfu pé, “Ọlọrun Olodumare farahàn mí ní Lusi ní ilẹ̀ Kenaani, ó sì súre fún mi.
Kí ẹ̀ṣẹ̀ lè fara rẹ̀ hàn bí ẹ̀ṣẹ̀, ó lo ohun tí ó dára láti pa mí kú, báyìí, ó hàn gbangba pé ibi gan-an ni ẹ̀ṣẹ̀ í ṣe, nítorí ó kó sábẹ́ òfin láti ṣe ibi.
Ọdún kọ̀ọ̀kan yóo dípò ọjọ́ kọ̀ọ̀kan ninu ogoji ọjọ́ tí àwọn amí fi wo ilẹ̀ náà.
Ọbasanjọ: O dun mi pe awọn obi mi ko ri aseyọri mi
Orúkọ yìí fi ìgbàgbọ́ Yorùbá nínú àjínde múlẹ̀
Gẹgẹ bi iroyin ti a tun gbọ, o ti fẹ gbajugbaja olorin Naijiria, DBanj ri.
Ẹ̀gbọ́n mi ni wọ́n ń sọ̀rọ̀ rẹ̀ yìí.
Ohun to faa ni awon isele to ni i se pelu eto oselu  ipinle naa.
Bí ẹgbẹ́ afẹ́nifẹ́re ṣé ń sọ pé àwọn ò mọ̀ nípa ìyànsípò náà ní asojú àwọn tó gbé ètò náà kalẹ̀ ní tí ẹgb afẹnifere o ba mọ ǹkan to yẹ ki wọ́n ṣe àwọn míràn yòó ṣe.
Ilẹ̀ tí ó kù nìwọ̀nyí: gbogbo agbègbè àwọn ará Filistia ati ti Geṣuri; 
Bi o tilẹ jẹ pe lọjọ Ileya, o yẹ kawọn olugbe ilu naa maa fọkan balẹ jẹran ọdun wọn ni, amọ ojo ado oloro lo n rọ leralera nilu naa, bẹrẹ lati ọjọ Ẹti.
Yolllywood: Ọlọ́run ló kọọ pé àwọn ọmọ mi yóò ṣiṣẹ tíátà, èmi kọ lo kàn-án nípa fún wọn
Ọmọ ọdún mẹ́sàn kan àti bàbá Ọdún márùndínlọ́gbọ̀n ní Erin ti pa ní abújé Bajama tó sún mọ́ Yankari Reserve àti ti Safari lẹ́yìn tí wọn pejọ lati wòran erin àti láti ya fótò.
Usieli ọmọ Hariaya alágbẹ̀dẹ wúrà ló ṣiṣẹ́ tẹ̀lé wọn.
23 Ìgbé 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 4 Èbibi 2020 Asa fifi ami si ori ọrọ ti n lọ si okun igbagbe nilẹ Yoruba, paapaa laarin awọn ọdọ wa lode iwoyi.
Gómìnà ìpínlẹ̀ Kaduna fún Sanusi ní ipò tuntun Coronavirus ti na'wọ́ gán Mínísítà fétò ìlera nílẹ̀ẹ Gẹ̀ẹ́sì Nínú ọkùnrin àt'obìnrin, ta ni Coronavirus yóò tètè ṣe lọ́ṣẹ́?
N óo fìyà jẹ oriṣa Bẹli ní Babiloni,n óo jẹ́ kí ó pọ ohun tí ó gbé mì.
Díẹ̀ lára àwọn òṣèré Nollywood ti wọ́n ti ṣe ìgbéyàwó lẹ́ẹ̀kejì À ṣé olóòrùn ni ayálégbé mi tó ń fojóojúmọ́ ṣakọ lórí ayélujára- Onílé Lisa Li Orìlẹ-èdè mẹrindínlọgbọn tí ọmọ Nàìjíríá lè wọ̀ láì ní àṣe ìwé ìgbélùú Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Awọn ọmọ wa paapa ko gbọ nkankan nipa ọrọ na, nitori pe mi o fẹ ki wọn maa fi oju buruku wo baba wọn.
 hill chisholm ( november 30 , 1924 - january 1 , 2005 ) je oloselu , oluko ati olukowe ara amerika .
“Ìyìn ni fún OLUWA, tí ó fún àwọn eniyan rẹ̀ ní ìsinmi gẹ́gẹ́ bí ìlérí rẹ̀.
Igbimọ Aṣofin naa reti eto iṣuna-owo titi ninu oṣu
O ni nipa lilo ibomu ni eeyan ko le ko aarun coronavirus lara awọn oluwọde miiran.
9 1194550 Orilẹede Indonesia 17867 6.
kilode ti wọn se ṣe bẹẹ?
'A sọ fún ọlọ́kadà pé omi kún, omi kún, ṣùgbọ́n ó kọ etí ikún' #Adewura Ẹ̀rò àwọn ènìyàn se ọ̀tọ̀ọ̀tọ̀ lórí lẹ́tà Ọbasanjo sí Buhari Èmi àti Ọbasanjọ leè yapa nínú òṣèlú, àmọ́ mo ń bọ̀wọ̀ gidi fun - Buhari Wale Oke ni Obasanjo kii ṣe ọmọde rara ninu iriri nipa orilẹede Naijiria nitori naa, ohun to ba sọ, ohun to ri ni.
Ijoba tile n so pe awon yoo bere si n gbe igbese “ ko si ise , ko sowo”, sugbon awon egbe naa so pe ijoba kan n  hale lasan ni , awon ko ni dawo iyanselodi duro, ayafi ti ijoba ba mu erongba won se.
Ninu esi ẹkun idibo meje ti ajọ EC ti kede, Aarẹ Akufo-Addo gbegba oroke ninu mẹrin nigba ti Mahama bori ninu mẹta to ku.
 Lati kekere lo ti maa n kowe nipa ounje nipa ibikibi to ba ṣabẹwo si.
Al Shabab ṣe ìkọlù sí ibùdó ogun America ní Kenya, ẹ̀mí mẹ́ta lọ síi Ó ṣeésẹ kí ọkùnrin tó n mu àmujù ọtí ó maa lo ìwà ipá pẹ̀lú ìyàwó rẹ̀ Soleimani Killing: Ẹgbẹ́ Shiites wọ́de l'Abuja, wọ́n jó Àsìá Amẹ́ríkà CAN rọ ìjọba àpapọ láti tú àwọn òǹdè Krìstẹ́nì silẹ̀ lọ́wọ́ Boko Haram Ní ọjọ ọdún kérésìmesi, afurasi ọ̀daran kan lẹ́yìn to jalè tán, tún fipa bá ẹni to kamọle lòpọ̀ ni àgbègbè Okoro Agbor ní Calabar.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, #Sweetsweetcodeine: Ẹ wo bí ìròyìn BBC nípa oògùn ikọ́ Codeine ṣe ń tún ayé tó ti bàjẹ́ ṣe Ọmi odo sodo ni Super Eagles ta pẹlu Zimbabwe ninu ifẹsẹwọnsẹ ọlọọrẹsọọrẹ ti wọn jọ gba lọjọ Abamẹta ni papa iṣere Stephen Keshi niluu Asaba.
Ọkà yóo sọ àwọn ọdọmọkunrin di alágbáraọtí waini titun yóo sì fún àwọn ọdọmọbinrin ní okun.
21 Agẹmo 2020 Baba Ọlọfa ina ló ba wa ṣide ètò fun toni pẹlu owe yii.
Ọpọ àwọn ọmọ Yoruba to wa ni Naijiria ni awọn ọmọ wọn ko gbọ ede Yoruba daadaa ni eyi to ti n kọ awọn onwoye ede lominu lasiko yii.
Kọmisọnna fun eto ilera nipinlẹ Eko, Akin Abayomi lo fi iroyin naa lede pe iwadii lo jẹ ki wọn tete mọ wi pe arun Coronavirus lo n ba awọn akẹkọọ naa fihan.
Nǹkankan tí ó dàbí aṣọ tí ó fẹ̀, tí wọ́n so ní igun mẹrin ń sọ̀kalẹ̀ bọ̀ láti ọ̀run títí ó fi dé ọ̀dọ̀ mi.
Bẹẹ ni wọn ni o ṣeṣe ki pupọ ninu awọn ọmọ ẹgbẹ Republican ti yoo dibo lojukoju pọ ju ti Democrat lọ.
Lórí ìtàkùn ayélujára àjọ to n gbógunti ààrùn Coronavirus ni Naijira NCDC náà, wọ́n sàlàyé àwọn ìlànà ti àwọn elétò ààbò àti ará ilú gbọdọ̀ mọ̀ ti wọ́n bá ri ẹni tó ni ààrùn Coronavirus.
Ajọsepọ awọn ikọ ọlọpaa kogberegbe mẹfa lati ọdọ awọn ọlọpaa Dubai, lo tu asiri awọn ọdaran yii, bi wọn ti ṣe n gbero lati ji owo awọn eeyan kaakiri agbaye.
Pelu bi Ta Lou se gbe igba oroke ninu ere ije ogorun mita yii, yoo tun maa fojusona lati fakoyo ninu idije IAAF Diamond league ti yoo maa waye ki odun yii o to pari.
Fadeyi Oloro kẹnu bọ ọfọ tan ni pẹrẹwu gẹgẹ bo ṣe maa n ṣe ninu ere lai fi ọkan pe meji rara.
Mikel kéde ìfẹ̀hìntì fún Nàìjíríà O fọwọ rẹ sọya pe ko si ẹni kankan ti o n ṣe ẹfẹ niluu Ibadan nigba ti oun fi bẹrẹ titi ti ohun fi wa di ẹni ti wọn mọ kaakiri Naijiria bayii.
Gẹ́gẹ́ bí ìlànà tí Dafidi fi lélẹ̀, Solomoni pín àwọn alufaa sí ìsọ̀rí-ìsọ̀rí láti máa ṣe iṣẹ́ ìsìn, ó sì pín àwọn ọmọ Lefi sí ìsọ̀rí-ìsọ̀rí láti máa kọ orin ìyìn ati láti máa ṣe ìrànlọ́wọ́ fún àwọn alufaa ninu iṣẹ́ wọn ojoojumọ.
SIM Card ni nkan kékeré kan tó wà nínu ẹ̀rọ ìbánisọ̀rọ̀ alágbèéká tó sì jẹ́ ọ̀kan nínú àwọn èròjà ti nmú ẹ̀rọ náa ṣiṣẹ́.
 Ọmọ tí ó kú kí ó tó di pé ó pé ọmọ ọdún méjìlá ni a lè pè ní àbíkú ọmọdé , bẹ ́ ẹ ̀ kẹ ̀ , ẹni tí ó kú nígbà tí ó dàgbà tí àwọn òbí rẹ ̀ kò ní agbára láti bí òmíràn mọọ ́ ni wọ ́ n ń pè ní àbíkú àgbà.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Obasanjo: Atiku kìí se Áńgẹ́lì, àmọ́ yóò se dáadáa ní ìlọ́po méjì ju Buhari lọ Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Iroyin jade paapa nipa awọn mi i to gbẹmi ara a wọn nitori òfò wọn.
Itọju iru awọn bẹẹ si da le jijẹ ki wọn wa laaye titi ti ohun amuṣagbara ninu agọ ara wọn le fi le arun naa lọ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Benin: UK ṣetán láti dá Adìyẹ 'Àkùkọ' Nàíjìrìa ti wọ́n gbé padà 30 Bélú 2019 Oríṣun àwòrán, PA Media Àkọlé àwòrán, Adiye 'Akukọ' ti won mo ni egberun odun seyin ni won se setan lati da pada ba yii.
 ní bíi protein amino acid jẹ ́ ẹ ̀ yà kejì tí ó tóbi jùlọ nínú iṣan ( omi ni o poju ) ninu isan , sẹ ́ ẹ ̀ lì àti tíṣ ́ ù .
Manchester United ko ri anfani to tọ lara Alexis Sanchez
Isele omiyale naa lo je ki awon
Kò sí àníàní, ọ̀pọ̀lọpọ̀ ni kò lé gbàgbé ádẹ́rìnposónu sọ̀rọ̀sọ̀rọ̀ náà nítori àwọn iṣẹ́ to ti gbése kí ó to gbà fún ikú lọgbọ̀n ọjọ oṣù kẹrin, ọdún 2003.
"Gbogbo awọn ileesẹ alaabo gbogbo lo ni lati dide ni kia lati koju itankalẹ awọn ọrọ ikorira ikanni ayelujara (social media), paapaajulọ laarin awọn ọtọkulu ọmọ orilẹede Naijiria.
Bákan náà ní a mọ pé ọ̀pọ̀ àwọn olólùfẹ́ wà ló fẹ́ ní òye bí BBC ṣe ń gbé ìròyìn wọ́n jáde.
Bakan naa lawọn agbofinro naa wa ni sẹpẹsẹpẹ lati rii pe ẹkọ ṣoju mimu lori abo ẹmi ati dukia nibẹ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Idibo Burundi: Ijọba n yọ'wo osu oṣiṣe lati ṣeto l'ọdun 2020 2 Èrèlè 2018 Oríṣun àwòrán, AFP Àkọlé àwòrán, Awọn ajọ aseranwo lagbaye ti ko lati fun Burundi lowo fun ẹto idibo lọdun 2020 Ẹgbẹ osisẹ nilẹ Burundi n pariwo pe ki ijọba dẹkun yiyọ owo ninu owo oṣu awọn oṣiṣẹ.
Ko din ni ọgbọn ero ọkọ kan tun pa lagbegbe Auno nitosi Maiduguri loṣu keji ọdun 2020.
Nítorí iná ibinu mi ń jó,yóo sì jó títí dé isà òkú.
mọ ekun Ariwa gege bi ibudo ti iko Boko Haram fi se ile, ohun ti a kọkọ n gbọ
Ó fi ọ̀kọ̀ rẹ̀ pa ọọdunrun eniyan, nípa bẹ́ẹ̀ òkìkí tirẹ̀ náà súnmọ́ ti àwọn akọni mẹta náà.
Ní ti ilé ìgbìmọ aṣòfin àti ilé ìgbìmọ aṣofin ìpínlẹ̀ ti ko mu wahala dani, bio se ti gomina, A ni láti wo àwọn ti o pọ jùlọ tó si jẹ Bello Mutawalle lo jáwe olubori.
Mo fẹ́ kí ẹ mọ̀ dájúdájú pé ẹni tí ó bá gbà mí gbọ́ yóo ṣe àwọn iṣẹ́ tí mò ń ṣe; yóo tilẹ̀ ṣe àwọn iṣẹ́ tí ó ju ìwọ̀nyí lọ, nítorí mò ń lọ sọ́dọ̀ Baba.
Ọgbẹni Makoda rọ ijọba lati ṣeranwọ fawọn ti ko rile gbe ki wọn le maa gba ile olowo pọọku.
O ni oun ati Ajimọbi ko jọ kọ ile oṣelu lati ìpìlẹ̀ ni eyi ti ko le jẹ ko rọrun ki awọn jọ wa kan ilé naa ninu idibo 2019 yii.
Ẹnìkankan ò sì tí ì já wọn.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù US-North Korea: Trump ati Kim John-un padé ni DM Zone 30 Òkùdu 2019 Oríṣun àwòrán, Reuters Àkọlé àwòrán, US-North Korea: Trump ati Kim John-un padé ni DM Zone lati bere ìpàdé US-North Korea: Trump ati Kim John-un ti ṣe ìpàdé.
OLUWA bá sọ pé, ‘Àwọn eniyan wọnyi kò ní olórí.
Lawọn ọdun diẹ sẹyin, ọwọja ijinigbe ati iṣekupa awọn ọmọde gogo sii lorilẹede Uganda, ti igbagbọ ọpọ si da lori pe wọn fi wọn ṣetutu ọla ni.
Ìjọ Satani dá MI lóhùn lórí ọ̀rọ̀ Fatoyinbo 'A fẹ́ kúrò ní Larubawa nítorí à kò gba ẹ̀sìn' 'A fẹ́ kúrò ní Larubawa nítorí à kò gba ẹ̀sìn' Donald Trump kéde pé ìpàdé òun pẹ̀lú Kim já si rere Ọpọ ololufẹ Super Eagles ni inu awọn ko dun si ipa ti wọn kó ninu idije wọn pẹlu Madagascar to jẹ pe igba akkọ ti wọn maa kopa ninu AFCON ni tọdun yii.
Ṣugbọn ṣa, kii ṣe awọn mejeeji nikan lo ti jẹ ẹran ifẹ ni ori eto Big Brother Naija 2020.
Àwọn ọmọ Nàìjíríà sì ti ń gba ọ̀rọ̀ náà bí ẹni gba igbá ọtí.
Ọ̀do mẹ́rin rẹ́wọ̀n he lórí ikú ọmọ Naijiria n'ílẹ̀ Gẹ̀ẹ́sì
 Bakan naa, gbajugbaja olorin takasufe to tun jẹ mọlẹbi Adeleke ni imọlẹ lo de si ipinlẹ Ọṣun bayii."
Àkọlé àwòrán, Operation Àmọtẹkùn: Ọ̀rọ̀ Tinubu ko ni ohun arigbámu kankan- Afẹ́nifẹ́re Ọ̀rọ̀ Tinubu kò ní ohun àrígbámú kankan Ni ti asiwaju ẹgbẹ oṣelu APC, o ti p ti awọn eeyan ti n duro de ọrọ ti yoo sọ ṣugbọn ko tete fọhun ayafi to di ọjọ kejilelogun oṣu kinni.
Ọmọ mi, bẹ̀rù OLUWA ati ọba,má ṣe àìgbọràn sí ọ̀kankan ninu wọn;
Kọmisọna fun eto ilera nipinlẹ naa sọ pe ''gaari ti wọn tẹ kalẹ loju titi marose lewu ni mumu.
Alukoro fun ẹgbẹ oṣelu naa ni ipinlẹ Ọṣun, Amofin Oyatomi sọọ ninu atẹjade kan to fi sita lori ikanni WhatsApp awọn oniroyin nipinlẹ Ọsun pe arọwa ọmọluabi ti ẹgbẹ APC fẹ gba awọn aṣofin naa ni pe ki wọn kọwe fi ipo ti wọn wa gẹgẹ bíi aṣofin silẹ nitori aya ọlẹ laa gba, ẹni kan kii gba ọmọ ọlẹ.
Ní ọjọ́ kẹrin, wọ́n gbéra ní òwúrọ̀ kutukutu wọ́n fẹ́ máa lọ.
Olùfẹ́ mi ti lọ sinu ọgbà rẹ̀,níbi ebè igi turari,ó da ẹran rẹ̀ lọ sinu ọgbà,ó lọ já òdòdó lílì.
Ọṣẹ òògùn mi kò ní iyr, àgúnmu ko ṣe e kà , mo sín gbẹ́rẹ́ ẹ̀rẹ̀kẹ́, mo sin si àtẹ́lẹwọ́, mo sin sí àtẹ́lẹsẹ̀, mo sín sí ori ọmú, mo sin sí orí ìdodo, mo sín sí ihò imú, mo sín sí ojú ilà àtẹ́lẹwọ́ mi, bẹ́ẹ̀ ni ọ̀tátèlégbèje gbẹ́rẹ́ ni ń bẹ ní àtàrí mi.
Ọjọ buruku esu gbomi mu si ni ọjọ naa lopopona Tsafe si Gusau nigba ti Tirela ati ọkọ ayọkẹlẹ mẹrin kọlu ara wọn ni deede aago mẹrin abọ irọlẹ.
"Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Huawei wan sign ""no-spy agreements"" wit foreign goments Koda nilu ọba to jẹ kan lara awọn alabaṣepọ Amẹrika timọtimọ wọn ṣi n jiroro lori boya ki wọn lo irinṣẹ Huawei lati ṣe itakun 5G tiwọn."
Wọn yan an ri gẹgẹ bi oludari ikọ to n ko alatilẹyin jọ nigberiko fun iyansipo aarẹ Buhari lọdun 2019.
com/6OcPqOTG2O— APC Nigeria (@OfficialAPCNg) 18 July 2018Ninu atejade kan ti egbe ohun gbe jade lojoRu(Wednesday), eleyi ti akowe agba egbe ohun Mallam Bolaji Abdullahi bowolu so pe, ipade yoo waye nilu Oshogbo ti n se olu-ilu ipinle naa, laarin igbimo to n sakoso idibo abele egbe ohun, eyi ti gomina ipinle Zamfara, Abdul’aziz Abubakar Yari yoo dari re.
 Ẹ jẹ́ ká jó ẹ jẹ́ ká yọ̀ orílẹ̀ èdè Nàìjíríà pé ọdún MÉJÍDÍNLLỌ́GỌ́TA
Ṣe MC Oluomo di ipo oṣelu kan mu ni?
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Mali: O kéré tán, ẹ̀mí 95 ti sọnù ní Mali 10 Òkùdu 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, ọpọ ìgbà ni ìkọlu ti maa n waye laarin Fulani atawọn ara Dogon ni aaring gbungbun Mali Eniyan mọkandinlogun tun ti dawati ni Mali.
Abule Zokutu ko ju bi irin wakati meji fun ọkọ lati aarin gbungbun ilu Abuja nibi ti ikọ amuṣẹya ti aarẹ yan to n ṣiṣẹ ojoojumọ nipa fifun awọn eeyan niroyin nipa Coronavirus wa.
Ṣebí yẹ̀yẹ́ ni ò ń fi Sodomu arabinrin rẹ ṣe ní àkókò tí ò ń gbéraga, 
Pe awọn ọmọ rẹ ki wọn wa kọ e\\kọ loni lori eto Akomolede ati Asa lori BBC Yoruba Oríṣun àwòrán, others Ẹ ṣúnmọ́ bí láti kọ́ ẹ̀kọ́ nípa ìsọ̀rí ọ̀rọ̀ nínú gbólóhùn Yorùbá Wo àfipábánilòpọ̀ ẹni ọdún 51 tí ìjọba ìpínlẹ̀ Ekiti tú làṣirí ní gbangba Olùkọ́ Bunmi Femi Amao ló ń kọ́ wa ní Ọ̀rọ̀ Ẹ̀yán lonìí Àwọn Olùkọ́ ìpínlẹ̀ Eko dárà lórí Akọ́mọlédè àti Àṣà lórí BBC Lawuyi Ogunniran, àgbà ọ̀jẹ̀ òǹkọ̀wé Eégún Aláré dágbére fáyé!
"Joao Teixeira de Faria, tawọn eeyan mọ si ""John of God"", ni adajọ sọ pe o jẹbi ifipabalopo awọn obinrin meji ti o si laṣepọ lọna aitọ pẹlu awọn meji miran ni ile iwosan rẹ to wa ni Abadiania."
Lẹyin ayẹwo awọn minista ki lo ti ṣẹlẹ?
Wọ́n ní “Ará ibí yìí kọ́ ni ó ń pa àwọn tí ó ń pe orúkọ yìí ní Jerusalẹmu, tí ó tún wá síhìn-ín láti fi ẹ̀wọ̀n dè wọ́n, tí ó fẹ́ fà wọ́n lọ sọ́dọ̀ àwọn olórí alufaa?
Ìdí abájọ ni pé òní ọjọ́ kọkànlélógún oṣù keje ọdún ni ojúmọ́ gígùnjùlọ lọ́dún ní ìhà àríwá àgbáyé.
9th Assembly: Ìdìbò ilé ìgbìmọ̀ aṣòfin àpapọ̀ Nàìjíríà
Abidani ọmọ Gideoni ni yóo jẹ́ olórí láti inú ẹ̀yà Bẹnjamini.
Ninu oro oludari egbe GOGAN, ogbeni Felix Idiga so pe isokan je ohun kan pataki ti o se koko fun idagbasoke orile-ede.
Nitori idi eyi lati nkan bi ọmọ ọdun mẹrin lo ti n tiraka lati kawe lati ile iwe alakọbẹrẹ lọdun 1951.
Lati igba naa ni o si ti wa ni ahamọ ajọ naa ni ilu Abuja.
Ó wù mí kí n jẹ́ aṣọ́nà ninu ilé Ọlọrun miju pé kí n máa gbé inú àgọ́ àwọn eniyan burúkú.
N ó fi agbárí rẹ se ọbẹ̀ ẹ̀fọ́, bẹ́ẹ̀ ni ìbàdí rẹ yóò máa ṣe ọ̀rá ṣìnkìn nínú ọbẹ̀ ata.
Gba àwọn ọmọ Lefi fún mi dípò awọn àkọ́bí ní Israẹli, sì gba àwọn ẹran ọ̀sìn wọn, dípò àwọn àkọ́bí ẹran ọ̀sìn àwọn ọmọ Israẹli.
"Gbajúgbajà òṣèré tíátà, ""Ijẹwuru"" ti jáde láyé Samuel Ajayi Crowther, òjíṣẹ́ Ọlọ́run tó gbé èdè Yoruba lárugẹ Àkọlé àwòrán, Ambode Adari Ile Asofin, Modashiru Obasa ni inu oun dun bayii si bi Gomina Ambode gbe aba isuna 2019 silẹ."
O kede ipinnu rẹ lati gbe apoti ibo fun gomina ni ọdun 2010 laarin awọn oludije mẹrinla miiran, ṣugbọn ipinnu naa f'ori sanpọn.
Kọmísọ́nà fún eré ìdárayá àti ìdàgbásókè àwọn ọ̀dọ́ nípínlẹ́ Ondo, Saka Yusuf Ogunleye ti kéde pe wọn ti tu gbogbo ìgbìmọ̀ eléré ìdárayá ka nípínlẹ́ Ondo.
Gege bi akowe agba ijoba apapo, Boss Mustapha, ro awon osise ati oluko ile-iwe giga fafiti patapata lati maa samulo ogbon ati imo won lati mu idagbasoke orie-ede Naijiria.
Ọrọ Adene lu ori ayelujara pa lẹyin tawọn ọlọpaa gbe e nile rẹ nitori o wa lara awọn to kopa ninu ifẹhonuhan EndSARS.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Èèmọ̀ Ìnàkí tún gbé Mílíọ̀nu méje Náírà mì Ta ni yóò borí láàrin Aisha Buhari àti ọkọ rẹ̀ lórí ọ̀rọ̀ ‘First Lady’?
”Losu to koja yii( Osu kesan an), ni awon egbe osise se iyanselodi lati fehonu han lori iha ti ijoba ko si ekunwo ti won fe.
Kí ló dé tí o fi fi ara pamọ́ fún mití o kà mí kún ọ̀tá rẹ?
Ṣe Aarẹ Donald Trump ni yoo tun wọle fun saa keji ni tabi Joe Biden ni yoo yẹ aga mọ nidii?
O ṣalaye pe inu ifa ni ipilẹ Ọba jijẹ ati isesi awọn ọba alaye ti jade wa ninu.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Man United vs Chelsea: Man U fí han Chelsea pe ajá to wọlé ti ẹkun yóò fẹ̀jẹ̀ wẹ̀ Ìyàlẹ́nu ní abájáde ìfẹsẹwọnsẹ̀ ọ̀hun jẹ́ nítori ó jọ bi ẹni pé Chelsea yóò ṣe dáradár jú Manchester United lọ ní sáà àkọ́kọ́, bọ́ọ̀lù ṣe gbá àwsn pada ní ẹ̀ẹ̀mejì bi Emerson àti Tammy Abraham ṣe gbìyànjú tó.
" Músá ni ọ̀rọ̀ ti àwọn sọ kẹ́yìn ni ìgbà tí òun kọ apìlẹ kan nípa ààrùn Coronavirus ni Kano ti Tolu si fẹesi si ǹkan ti òun kọ.
Ijebuu Aarin ọsẹ yii kan naa ni Olatayo Amokade, ti ọpọ mi si Ijẹbu polongo loju opo Instagram rẹ pe awọn ololufẹ oun ti le miliọnu kan ati abọ lori ikanni naa.
Agodi niluu Ibadan, Ipinle Oyo ni ekun Gusu Iwo oorun Orile-ede Naijiria.
Juda yóo rí ìgbàlà ní ìgbà tirẹ̀, Israẹli yóo sì wà láìléwu.
Ọ̀gá àgbà iléèṣẹ́ ọlọ́pàá dín wákàtí iṣẹ́ ọlọ́pàá kù Báyìí ni ayẹyẹ wíwé láwàní Mike Zhang ọmọ China ṣe lọ Bakan naa, Ọgagun F.
Ni ọjọ Abamẹta ni okiki kan nipa ayẹyẹ ọjọ ibi Bobrisky to waye lagbegbe Lekki Phase 1 nilu Eko.
Bí ó bá ku eniyan mẹ́wàá ninu ìdílé kan, gbogbo wọn yóo kú.
‘Bi Gomina Ajimobi se yan adarí òsìsẹ́ tuntun ní Oyo kò dí wa lọ́wọ́’ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Jiti Ogunye: Ìjọba àkóbá lológun gbé kalẹ̀ ni 1999 Abiola Ajimobi Bi o tilẹ jẹ wi pe Gomina Abiola Ajimobi ni gomina akọkọ ti yoo wọle lẹẹmeji gẹgẹ bi gomina ipinlẹ Oyo, o kuna lati wọ le ibo sile igbimọ aṣofin agba l'Abuja.
Ko tan sibẹ, Wolii Ayodele ni laipẹ laijinna ni ọwọ palaba asaaju ikọ Boko Haram, Abubakar Shekau yoo segi, ti ina yoo si dilẹ lẹyin asunsunjẹ rẹ.
Nitori naa ni wọn ṣe ke si ijọba lati dakun si ju aanu wo awọn eniyan lagbegbe naa nitori ile iwosan ti wọn niyẹn.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Odion Ighalo: Ó di 2021 kí Ighalo tó fi Manchester United 2 Òkùdu 2020 Oríṣun àwòrán, Twitter/Man U Ẹgbẹ agbabọọlu Manchester United ti sọ idi ti wọn fi ṣe adehun tuntun pẹlu ẹlẹsẹ ayo, Odion Ighalo eyi ti yoo mu un di oṣu ọdun 2021 pẹlu ikọ naa.
Bákan náà lo tún sọ nipa àjọ INEC.
Awọn iroyin miran ti ẹ le nifẹ si: BBC ṣe'filọlẹ Yoruba, Igbo ati Pidgin Akẹkọ Dapchi 101 lo pada de BBC koro oju si ikọlu ijọba ipinlẹ Eko Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 3 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 5 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ìdílé tí ọkọ da ọmọ síta tóríi ojú Búlùú tí wọ́n ní bá BBC sọ̀rọ̀ Ninu fidio naa si ni o ti ṣe afihan awọn olutọju alaisan bii oninabi, to n ni ibalopọ lẹnu iṣẹ pẹlu awọn alaisan ti wọn n tọju.
Afẹnifẹre koro oju si ikọlu 'awọn ọmọ Yobe' Ọsinbajo pe fun ọlọpa agbegbe Mo sọ̀rọ̀ tako ọkọ mi torí òtítọ́ - aya Bùhárí Ko ti daju ibi ti Lawal Musa Daura wa bayi sugbọn iroyin kan so wi pe ọkọ re to gbe wa si ile ijọba ko lo gbe pada kuro nibe nigba ti wọn wa jade.
inu egbe akoroyin obinrin dun si ipa ti ile -ise ologun nipinle Oyo n  ko lasiko ti awon egbe naa ke gbajare lo si
Alukoro fun ileesẹ ologun orilẹ lorilẹede Naijiria naa tun jẹ ko di mimọ pe awọn ọmọogun naa tun ba awọn ọkọ meje to jẹ ọkọ agbebọn, alupupu, aba ati awọn ọkọ miran jẹ nibẹ Oríṣun àwòrán, @HQNigerianArmy Àkọlé àwòrán, Ara ohun ti Boko Haram n polongo ni wipe awọn lodi si ẹkọ iwe Ni ọgbọnjọ osu kinni ọdun yi, awọn ọmọ ogun fi ija pẹẹta pẹlu awọn ọmọ ikọ Boko haram, ti wọn si gba ọkọ ijagun EMBT kan, ibọn AK-47, ibọn afẹfẹ tajutaju ati awọn iwe ẹsin lorisirisi pẹlu agolo afẹfẹ idana gaasi pẹlu ajilẹ."
Gomina Babajide Sanwo-Olu lo kede awọn ilana tuntun yii, pẹlu boṣe jẹ pe ipinlẹ Eko ni aarun coronavirus pọ si julọ ni Naijiria.
Awọn ibeji ti ọkan ninu wọn jẹ afin ko wọpọ nilu.
Nítorí èmi wà láàyè, ẹ̀yin náà yóo wà láàyè.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ojú mi ti rí lọ́pọ̀ lọpọ̀, àmọ́ mo dúpẹ́ pé mo ti pé ọdún márùn ún lórí oyé- Ooni Alaga igbimọ fidihẹ ati igbimọ alakanṣe eto to fi mọ gomina ipinlẹ Yobe, Mai Mala Buni lo dari awọn ọmọ igbimọ alaṣẹ ẹgbẹ to ku pẹlu Aarẹ Buhari ninu ipade naa.
yan awon adari ile igbimo asofin.
to n mojuto ọrọ gbigba awon eniyan si ile- ise lorile  ede Naijiria ,ile –ise ti yoo maa mojuto ẹya
o fi ipinle Eko se ibugbe ti o si sise nibe pelu, ki o to di igbakeji aare
O ní gẹ́gẹ́ bi àjọ NNPC ṣe ti kéde láti ìgbà tí ọ̀rọ̀ epó bẹntiro tí n já wálẹ̀ l'Ágbàyé pé oṣooṣù ni àwọn yóò ma sọ iye ti àwọn ará ilú yóò maa ra epo.
Wọ́n sọ ohun tí ó ṣẹlẹ̀ fún un.
Ẹka ijọba imọ ijinlẹ ati imọ ẹrọ lorilẹede China lo sọ pe, oogun Chloroquine ṣiṣẹ daadaa lara awọn to ni aarun naa tawọn ti danwo lara wọn.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Minimum Wage: Buhari ló kù tí yóò fẹnu ọ̀rọ̀ jóná lóri owó oṣù tuntun 24 Ògún 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Ọrọ gbogbo to nii se pẹlu sisan owo osu tuntun fawọn osisẹ orilẹede Naijiria ni ko tii ni ojutu bayii nitori ijiroro lori bi owo osu tuntun naa yoo se jẹ sisan lo ti dẹnu kọlẹ bayii.
BBC Yoruba ati BBC Igbo yoo bẹrẹ iṣẹ ni pẹrẹwu lẹyin ifilọlẹ wọn ni ọsẹ to n bọ nipinlẹ Eko.
Lẹyin ọ rẹyin, ileẹjọ dajọ ẹwọn oṣu mẹfa fun Mallet pẹlu iṣẹ ilu fun ọjọ diẹ.
” Nítorí náà ninu àwọn ohun tí ó jẹ́ àìlera fún mi ni mo ní ayọ̀ pupọ jùlọ, àwọn ni n óo fi ṣe ìgbéraga, kí agbára Kristi lè máa bá mi gbé.
Ẹ wọ inú ihò lọ, kí ẹ lọ máa gbébẹ̀!
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ojúde Ọba: Ayẹyẹ tó ń ṣàfihàn àṣà àjogúnbá Yorùbá 13 Ògún 2019 Oríṣun àwòrán, Ojude Oba Facebook Ninu awọn ọdun to gbajugbaja nilẹ Ijẹbu, eyi ti tọmọde-yagba, ti onile-talejo maa n kopa ninu rẹ ni ọdun Ojude Ọba jẹ, to si tun gbajugbaja nilẹ Yoruba.
Aisi eto aabo ati awọn onwoye idibo lasiko idibo naa ti fi agbara fun ẹsun magomago lasiko idibo ti wọn fi kan ijọba.
Jẹtiro dáhùn, ó ní, “Ẹni ìyìn ni OLUWA, tí ó gbà yín kalẹ̀ lọ́wọ́ àwọn ará Ijipti ati lọ́wọ́ Farao.
to le ni ọ́ọ̀dúnrún  milionu naira sọtọ  fun ile-ise to n samojuto irin ati ohun alumọọni
Ọlọrun pàṣẹ pé kí ìmọ́lẹ̀ wà, ìmọ́lẹ̀ sì wà.
N óo dá ire Israẹli, àwọn eniyan mi, pada,wọn yóo tún àwọn ìlú tí wọ́n ti wó kọ́,wọn yóo sì máa gbé inú wọn.
ti ijo Catholic niluu Abuja, John Cardinal  Onaiyekan ti ro ijoba apapo
Wí fún àwọn eniyan Israẹli pé, ẹnikẹ́ni tí ó bá ṣépè lé Ọlọrun rẹ̀ yóo ru ẹ̀bi ẹ̀ṣẹ̀ nítorí rẹ̀.
O ni awon ijoba to kogba wole lo bere kiko ibudo ayewo onibusun eedegbeta naa ni eyi ti ise ori re yoo pari titi odun to m bo.
Gbenga Abimbola - BBC News Yorùbá BBC News, YorùbáFò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ondo 2020 Election: Ọmọlúwàbí ṣọ̀wọ́n láàrín àwọn òlóṣèlú ló jẹ́ kí wọ́n má a lọ láti ẹgbẹ́ òṣèlú kan sí òmìràn - Gbenga Abimbola 22 Agẹmo 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 12 Ògún 2020 Oríṣun àwòrán, Others Onimọ nipa eto oṣelu lorilẹede Naijiria, ọmọwe Olugbenga Abimbola ti ni aini iwa ọmọluwabi lo n mu ki awọn oloṣelu ma a kuro ni ẹgbẹ oṣelu kan lọ si omiran.
Mo mọ̀ dájú pé, kò sí agbára kan ninu èmi eniyan ẹlẹ́ran-ara, láti ṣe rere, n kò lágbára láti ṣe é.
 Ijọba ṣeleri pe oun yoo san owo awọn oṣiṣẹ wa, a ṣi n reti ko gbe igbesẹ lori ileri rẹ ṣugbọn a ko tii gbọ nkankan.
N30,000 ni mo gbà fún orí, ọwọ́ àti ẹran ara wòlíì Bosede - Kayeefi Ẹ kọ́ nípa ohun tí Yorùbá ń pè ní Àrígiṣẹ́gi Wọ́n ta ère Ọ̀ṣun Osogbo sí Togo - Bàbá Ọṣun figbe ta Baṣọ̀run Gáà, tó yan ọba mẹ́rin, pa ọba mẹ́rin àmọ́ ọba karùn-ún ló pa á Awọn ileeṣẹ iroyin kan sọ pe, agbẹnusọ ajọ DSS, Afunaya sọ pe awọn gbe igbesẹ naa ni ibamu pẹlu ojuṣe wọn l'abẹ ofin.
Ajọ WHO ni titakete si ara ẹni lo ṣe pataki bayii lati dena aarun covid-19.
O ni Kunle Afọlayan ti n fihan ni ọpọlọpọ igba pe, oun korira ẹya Igbo ati pe, ọjọ idẹyẹsi rẹ si awọn ẹya naa ti pẹ.
" Iroyin tun ṣalaye pe nṣe lawọn janduku lo anfani wahala to bẹ silẹ naa lati fi ja ọpọ awọn eeyan to wa fun ipolongo naa lole awọn ohun ini wọn.
ẹni tí ó jẹ́ olórí àwọn ayaba.
DSS ti fi igbákejì gómìnà CBN tó ní gómìnà kan ní Àríwá Naijiria ní Ọ̀gá Boko Haram silẹ Ileeṣẹ otẹlẹmuyẹ lorilẹede Naijiria, DSS ti fi silẹ lẹyin ẹsun to fi kan gomina kan ni ẹkun ariwa Naijiria.
'Oògùn olóró máa ń jẹ́ ki n bá ara mi jà, ti màá ṣerami léṣe' Gèlè ìyàwó láàrín ìṣẹ́jú mẹ́ta kẹ̀?
Eje ká ní Ìṣọ̀kan ni ìlú wa, agbègbè wa àti àdúgbò wa pẹ̀lú èyí Ìṣọ̀kan yoo le wà láàrin àwa Yorùbá, Haúsá ibo
Oríṣun àwòrán, @HQNigerianArmy Àkọlé àwòrán, Boko Haram méje faragbá àdó olóró tí wọ́n fi sí ẹ̀bá ọ̀nà!
Nítorí kì í ṣe nítorí pé Abrahamu pa Òfin mọ́ ni Ọlọrun fi ṣe ìlérí fún òun ati ìran rẹ̀ pé yóo jogún ayé; nítorí ó gba Ọlọrun gbọ́ ni, Ọlọrun sì kà á sí ẹni rere.
Mo ní, “Gbé ẹnu sókè kí o sọkún nítorí àwọn òkè ńlá,sọkún tẹ̀dùntẹ̀dùn nítorí àwọn pápá inú aṣálẹ̀,nítorí gbogbo wọn ti di ahoro, láìsí ẹnìkan tí yóo la ààrin wọn kọjá.
Rahul Gandhi to jẹ olori alatako ẹgbẹ oṣelu Congress to n ba Modi to jawe olubori ni India dupo ti gba fun Ọlọrun.
Èsì tí U Ye Ni fún àwọn ọmọ ajagun rè é  :
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Dino Melaye nánwó fún Ayefẹlẹ lójú agbo Ọgbẹni Aremu sọ pe o ṣe pataki lati wo fọnran finifini nitori ọpọ eeyan lo n fi ọgbọn alumọnkọrọi gbe fidio jade lori ayelujara.
5 5183 Orilẹede Liberia 83 1.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Abikẹ Dabiri: Iṣẹ́ pọ̀ lọ́wọ́ Naptin àti àwọn aṣọ́bodè Nàìjíríà Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Abikẹ Dabiri: Iṣẹ́ pọ̀ lọ́wọ́ Naptin àti àwọn aṣọ́bodè Nàìjíríà 21 Èbibi 2018 Omo Naijiria lo n ta ara wọn nile okeere Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí kan sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
Nítorí, bí mo ti sọ ṣáájú, ẹ ṣe ọ̀wọ́n fún wa tóbẹ́ẹ̀ tí ó fi jẹ́ pé bí ó bá kan ti ikú, kí á jọ kú ni, bí ó bá sì jẹ́ ti ìyè, kí á jọ wà láàyè ni.
Mercy Aigbe bu èpè jó àwọn tó ní gómìnà kan ló ra ilé fún-un Ìgbín ní èmi àti ìyá mi máa ń he kiri, ká tó lee jẹun - Lizzy Anjọrin Ìtàn tó rọ̀ mọ́ òwe ‘aṣọ kò bá Ọ́mọ́yẹ mọ́.
INEC sọ pé ki ẹgbẹ́ PDP fi ọkan balẹ, pe wọ́rọ́wọ́ ni eto idibo 2019 yoo lọ, ti ko si ni i si mago-mago kankan.
Oun àti ọkọ rẹ tẹlẹ, Nelson Mandela ni awọn eniyan South Africa ko le tete gbagbe.
a maa ń wo ẹ ̀ tẹ ̀ sàn nípa ìtọjú .
Hijab Crisis: Fásitì Ibadan ní kò sí ohun tó yípadà pẹ̀lú ìwọṣọ akẹ́kọ̀ọ́ ISI
Segun Olufemi; iyaafin Adelaja Abosede Omobolanle ati dokita Lawal Lateef
”Aare wa toro aforijin lowo egbe naa pe, oun ko tọ wọn wa lasiko to fe fi ipinnun re han lati dije fun ipo aare leekeji lodun 2019, ni eyi to se lasiko ipade  awon oloye egbe APC ni ojo kesan an, odun 2018.
APC ni wọn gbee fun Yahaya Bello tori oun lo ṣe ipo keji Audu laisko idibo abẹlẹ ninu ẹgbẹ APC.
Iyabọ kọ lẹta gbọọrọ kan to pe ni 'Lẹta gbangba si baba mi.
nitori pe iye awon eniyan to jade  ni
Kii ṣe Tikhanovskaya nikan lo díje tako Aarẹ Lukashenko.
Kò ṣọ̀wọ́n ká rí ṣóòṣì àti mọ́ṣáláṣí tí wọ́n kọ́ si ẹ̀gbẹ́ arawọn.
Nigba ti o n sọrọ lori akori ọrọ Ipade Apero awọn Alẹnulọrọ naa fun ti saa yii, “Nigbaradi fun Eto Idibo ti yoo waye ni irọwọ Irosẹ, ti yoo si jẹ Ojulowo” , Aṣofin Bisi Yusuf ṣalaye pe erongba Ile Igbimọ Aṣofin yii ni lati tubọ le jẹ ki awọn ara ilu le mọ riri eto idibo ninu iṣakoso Ijọba Tiwa-n-tiwa.
8 Àti pé Ó fún un ní agbára láti òkè wá, nípa ọ̀nà èyítí a ti pèsè saájú, láti ṣe ìtumọ̀ Ìwé Ti Mọ́mọ́nì.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Working religious women: Ẹ̀lẹ́hàá kìí ṣe ọ̀lẹ- Aminat Adegoke Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Óyá ẹ jẹ́ ká gbé e yẹ̀wò.
Igbesẹ wọn yi ni EFFC sọ pe o ṣi ọna fun Aroke lati hu orisirisi iwa gbajuẹ lasiko to yẹ ko wa lọgba ẹwọn pẹlu iranwọ awọn ọdaran mii.
Ati pe o kan wu awọn ẹni ibi yii lati tu ọra ajọ ICPC si ọna miran ni ti wọn si doju ẹsun naa kan ileese ijọba to jẹ Ministry of Humanitarian Affairs.
Lara awọn eeyan Pataki to wa nibi idanilẹkọ naa ni aṣoju ilẹ Gẹẹsi si Naijiria nipa eto ọrọ aje, Helen Grant, ati alaga ẹgbẹ awọn ọmọ Naijiria nilẹ okere, Abike Dabiri-Erewa.
Orílẹ̀-èdè tabi ilẹ̀ ọba tí kò bá sìn ọ́ yóo parun,wọn óo di àwópalẹ̀ patapata.
Amọ, iwadii ni erin ti pa eniyan bi aadọta le lẹgbẹrun, nigba ti ẹkun ti sekupa eniyan mejilelaadọrun.
Jesu orí ayélujára kan rèé tó wa fun isoji ni Afirika Èèkànlú ní ìpínlẹ̀ Ogun lọ kí Buhari l‘Abuja torí ẹ̀yẹ tó fi dá Abiọla lọ́lá Arẹ́májà kò sí, Olubadan fi tìlù-tìfọn kí àwọn ìjòyè káàbọ̀ lẹ́yìn ọdún méjì Òṣèré tíátà, Kemi Afolabi dùbúlẹ̀ àìsàn ní ìlú Mecca Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Ambode ní kò sí gìrì, eré ọwọ́ lásán ni EFCC ń ṣe ''Àwọn ọmọ wa ma ń wọ ọkọ̀ ojú omi láìsí ẹ̀wù ìdàábòbò nítorí àti kàwé'' Ìjìyà ń bẹ fún àwọn ti adé ọ̀rọ̀ náà bá ṣí mọ́ lóri -Ọga àgbà FRSC Ta ni Seun Fakorede, ọmọ ọdún 27 tó fẹ́ di kọmiṣọna?
To si jẹ pe niṣe ni awọn ọlọpaa n da ọkọ ati eero to ba fẹ ẹ wọ ipinlẹ naa pada si ibi ti wọn ba ti n bọ.
Jíjẹ oúnjẹ tó ní Ṣuga pupọ ninu: Ọ̀pọlọpọ wa la jẹbi esun yii.
Ọmọ ẹgbẹ agbebọn kan jẹwọ pe oun lo pa akọroyin naa.
O ni eeyan le lowo lọwọ ṣugbọn ko ma lori oye."
Bakan naa, minisita fun ere idaraya ati idagbasoke ọrọọdun, Sundare Dare ni awọn agbabọọlu Naijiria fi da oun loju pe didun lọsan yoo so fun Naijiria ninu ifẹsẹwọnsẹ pẹlu Brazil.
Lara wọn ni yìí lasìkò tó sọ bí yóò ṣe ná owo náà Àkọlé àwòrán, Mahassin ṣe àgbékalẹ̀ ohun elo ìmọ ẹ̀rọ fún àwọn ìyálajé àti àwọn onísòwò láti mú ìdàgbàsókè bá ètò ọ̀rọ̀ àjé wọn tí o ń pè ní MadamCash.
Corporation Limited (CRCC), ogbeni Fenjian Chen.
Kò si iyàtọ̀ laarin ọlọ́tí pẹ̀lú ẹni ti ó mu egbò igi olóró àti wèrè, nitori ihùwà ọlọ́ti àti ẹni lo oògùn olóró kò yàtọ̀ si ti wèrè bi wọn bá ti yó.
Oríṣun àwòrán, @RemoStarsSC Agbẹnusọ fun ileesẹ ọlọpaa ipinlẹ Ogun, Abimbola Oyeyemi sọ fun awọn akọroyin pe, ikọ SARS kọ lo pa Kazeem, o ni lootọ ni ikọ naa kan fi pampẹ ofin mu pe o wọ aṣọ ṣọja.
Nígbà tí ó wà lórí oyè ní Susa tíí ṣe olú-ìlú ìjọba rẹ̀, 
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Èṣù kìí ṣe sàtànì bí ẹ ṣe máa ń pè é' Ọkan lara awọn ara abule, Ibrahim sọ pe awọn oyin ọhun ko yọ awọn ẹran ọsin to wa ninu abule silẹ.
Ojo Ketala, Akorede, Maami, Apaadi, Aje Meta 1 and 2, Asiri Nla, Apaadi 1 and 2, Koosefowora, Iro Funfun, Taiwo Taiwo, Omo Ghetto, Agbara ife, Agbefo, Iro funfun, Awa Obinrin.
Lẹyin naa ni wọn fi panpẹ ofin mu nile iya rẹ ni Antioch, ni ipinlẹ Illinoi, to jẹ nnkan bi ọgbọn iṣẹju si Kenosha nibi ti iṣẹlẹ naa ti waye.
Igba akọkọ kọ niyi ti iroyin ati awuyewuye ti n waye lori pe boya Tinubu fẹ ẹ dije du ipo aarẹ Naijiria ni ọdun 2023.
Ní àkókò ìjọba Jehoramu, Edomu ṣọ̀tẹ̀ sí Juda, wọ́n sì yan ọba fún ara wọn.
Wayii o, ipo ate ajo FIFA/Coca-Cola miiran yoo tun jade lojo keje, osu
Ilé tí ẹ kọ́ fún mi dà?
Oṣu kẹjọ 2018: Awọn ẹbi Daphne Caruana Galizia beere fun iwadii kikun lati wo boya Malta i ba le dena iku rẹ.
Jehieli, Asasaya, ati Nahati; Asaheli, Jerimotu, ati Josabadi; Elieli, Isimakaya, ati Mahati ati Bẹnaya ni àwọn alabojuto tí wọ́n ń ṣiṣẹ́ lábẹ́ Konanaya ati Ṣimei, arakunrin rẹ̀.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Èmi àti Kolington kò fẹ́ra padà o, ọba Wákà kò fẹ́ ọba Fuji mọ́ - Salawa Abeni Èmi sì ní Oluwo tilẹ̀ Iwo, kò sí ìgbìmọ̀ ọba kankan tó lè ní kí ń rọ́ọ́kún nílé - Oluwo Toyin Abraham ọkọ rẹ̀ àti Ire ní London, Odunlade 'kòlábò' pẹ̀lú Mercy Aigbe Èlé owó iná ọba kọ́ ló kàn, ẹ kọ́ ṣàtúnṣe sí ìlànà àdánú tẹ́ ń ṣe fún wa - Iléeṣẹ́ apínná sọ fún ìjọba Niwọn igba to jẹ pe ti ko ba si ẹsẹ, ẹsẹ kii dede sẹ, ohun ti wọn lo fa sababi ni bi ijọba ilẹ Naijiria se n gbero lati yọ miliọnu lọna ọgọrun ninu owo naa fun gomina Atiku Bagudu, tipinlẹ Bauchi.
Koda, n ko tun nifẹ lati maa jade lọ mọ si ibikibi nitori mo n bi ara mi leere pe ki ni awọn aladugbo yoo lero nipa mi, tabi ki ni awọn ọrẹ mi yoo sọ.
Amọṣa ọrọ ni gomina ṣi n ba awọn oluwọde naa sọ to fi di pe awọn janduku kan bẹrẹ si ni kọlu ti wọn si n yinbọn pẹlu okuta si ọkọ gomina naa.
juujuu, okunkun si wa lori ilẹ.
Àtúndì ìbò Kwara: Ọmọ ẹgbẹ́ wa kò fowó ra ìbò - APC Àkọlé àwòrán, Atúndì ibo bere ni láwọn ìjọba ìbílẹ̀ Kwara Iroyin to n tẹ wa lọwọ ti fidi rẹ mulẹ pe ibo kika ti bẹrẹ lawọn agọ idibo gbogbo to wa ni ẹkun idibo Irẹpọdun, Isin Ekiti àti Oke Ẹrọ, nibi ti atundi ti n waye lọjọ Satide.
Ni owurọ ọjọ Iṣẹgun lawọn janduku kan nibi iwọde ENDSARS l'Eko kọlu agọ ọlọpaa kan lagbegbe Orile ti wọn si dana sun un.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Àṣìṣe ọlọ́pàá àti Adájọ́ sọ mí di ẹni tí wọ́n dájọ́ ikú fún, ọpẹ́lọpẹ́ Fayoṣe tí ko buwọlu Igbesẹ tuntun to yẹ lati tẹlẹ fun onibara to ba fẹ tẹ nọmba atẹsanwo gba ina niwọn yii: 1.
Adesina ni, yatọ si aarẹ orilẹede Ghana, Nana Akufo-Addo, Buhari nikan lo wa lori eto lati ba awọn eniyan sọrọ nibi ayẹyẹ ọun, eleyi ti ireti wa pe yoo sokunfa ibasepọ to dan mọọran sii laarin orilẹede mejeeji.
Brọda Shaggi oun n fi isẹ apanilẹrin lori Instagram bọ ẹbi ati ara, to si tun rọ awọn ọmọ Kaarọ OOjire lati maa tẹti gbọ BBC Yoruba.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Mohammed Adoke: EFCC dájọ́ wíwà láhàmọ́ ọjọ́ mẹ́rìnlá fún Mínísítà ètò ìdájọ tẹ́lẹ̀ 20 Ọ̀pẹ̀̀ 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 21 Ọ̀pẹ̀̀ 2019 Oríṣun àwòrán, OTHER Adajọ agba orilẹede Naijiria, Mike Ozhekome to tun jẹ agbẹjọro fun Agbẹjọro -Agba Naijiria tẹlẹ ri Mohammmed Adoke ti ta abuku ajọ EFCC lori pe wn fi panpẹ mu onibara rẹ.
'Ẹlẹyamẹya ti ohun waye labẹ iṣejọba aarẹ Buhari ko ṣẹyin ihuwasi aarẹ fun ara rẹ, ati awọn igbesẹ ati eto ti aarẹ n ṣe ti ko mu itẹsiwaju ba orilẹede Naijiria.
"Pásítọ̀ Enoch Adeboye darapọ̀ mọ̀ #ENDSARS, ó fún ìjọba Nàìjíríà ní ìmọ̀ràn ọ̀nà àbáyọ Mo ṣèlérí láti ṣe ju ohun tí mo ti ṣe lọ fún ẹbí àwọn tó kú torí EndSARS - Seyi Makinde Bàbá ọlọ́mọ méjì fi ipá bá ọmọ ọdún mẹ́rin lò pọ̀; Adájọ́ rán an ní ẹ̀wọ̀n gbére Ọlọ́pàá mú afurasí 31 tó ń dúnkokò máwọn ọmọdé lórí ayélujára Oríṣun àwòrán, APple Àkọlé àwòrán, Diẹ lara awọn àwọ̀ ti iPhone 12 ní Awọn nkan to fi da i phone naa yatọ ree: Ko nilo ohun amugbagbara ""Charger""."
Mo ní ànító nígbà tí mo rí ohun tí ẹ fi rán Epafiroditu sí mi gbà.
OLUWA wí fún Mose pé, “Mo dá majẹmu kan, n óo ṣe iṣẹ́ ìyanu níwájú àwọn eniyan náà, irú èyí tí ẹnikẹ́ni kò rí rí ní gbogbo ayé tabi láàrin orílẹ̀-èdè kankan.
" Oríṣun àwòrán, Unique Foundation Schools Amofin naa ṣalaye pe ọpa aṣẹ naa ni yoo ṣaaju abẹnugan ile naa to be fẹ wọ inu ile igbimọ aṣofin naa lọ.
Àwọn ohun ọ̀gbìn inú rẹ tí ń sọ dàbí ọgbà pomegiranate,tí ó kún fún èso tí ó dára jùlọ,àwọn bíi igi hena ati nadi;
Ipese iṣẹ miliọnu kan lẹka iṣẹ aladani.
Ṣugbọn lọjọ kan, ọkunrin kan to jẹ ibatan mi kan to n gbe lẹgbẹ ile wa ṣaadeede fa mi lọ si inu ile rẹ nibi to ti fipa bami lopọ.
O fikun pe Toyin naa si fesi pada fun oun pe awọn nifẹ, tawọn si ms riri oun pẹlu.
Esi yii fihan pe ọti ẹlẹrindodo ni nkan ṣe pẹlu arun jẹjẹrẹ lara ẹda.
Ọjọ́ Ìsẹ́gun di ọjọ́ ìbànújẹ́ fún ọ̀pọ̀ ìdílé ní Nàíjíríà torí òkú tó ṣùn Oríṣun àwòrán, @jidesanwoolu Yika orilẹede Naijiria ni awọn araalu ti n se ọfọ awọn eeyan wọn to dagbere faye lojiji lati ipasẹ iwọde EndSARS to di rogbodiyan.
Eleyii ni ọrọ Agbẹnusọ Ile Ipinlẹ Eko lati fi saami ayajọ awọn oṣiṣẹ, ti ọpọ eniyan mọ si ‘May Day’ tọdun 2018, eleyii ti alukoro Agbẹnusọ naa, Ọgbẹni Musbau Rasak fọwọ si.
Ọ̀rọ̀ náà rú mi lójú; mo bá bi ọkunrin náà bí ó bá fẹ́ lọ sí Jerusalẹmu, kí á ṣe ìdájọ́ ọ̀rọ̀ náà níbẹ̀.
Ija laarin Aarẹ Trump ati orilẹede China, to fi mọ ọrọ aje Aarẹ Trump lati igba to ti gori oye ni o ti wọ iya ija pẹlu orilẹede China nipa ọrọ aje.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ifọrọwanilẹnuwo pẹlu Ọjogbọn Wọle Soyinka Soyinka ni ojuse ile isẹ to n koju iwa ajẹbanu ni lati gba awọn owo ti awọn asebajẹ ji ko pada lati fi mu ibugboro ba ọrọ ajẹ orilẹede Naijiria.
Ajibade Ogunoye di Ọlọ́wọ̀ tuntun fún ìlú Ọwọ Wole Soyinka ni ọmọ ilẹ Afirika akọkọ to kọkọ gba ami ẹyẹ Nobel Prize ninu imọ Litiresọ lọdun 1986.
Láti Iyimu wọ́n lọ sí Diboni Gadi.
Wọ́n wá ńbẹ àwùjọ àgbáyé láti gba àwọn nítorí àìlásọ lọ́rùn pààká ni àwọn ìsẹ̀lẹ̀ ìkọlù darandaran yìí jẹ́, ó sì ti di àpérò fún gbogbo àwọn ọmọ̀ eríwo báyìí.
Oríṣun àwòrán, others Iyansẹlodi naa n waye lori sisan owo ajẹmọnu fun ewu ti wọn la kọja lasiko ajakalẹ arun COVID-19 atawọn ẹdun miran.
 Nipa awọn iṣẹ ti yoo ṣe gẹge bii Mayegun, o ni ""Ituluṣe ni mo wa fun."
Lẹyin eyi ni wọn ju oku arabinrin ọmọ ọdun mejilelọgọta naa sinu kanga ti jinjin rẹ to iwọn ẹsẹ bata ẹgbẹrun kan, ti wọn si gbe ẹrọ amunawa lee lori.
Kogi àti Bayelsa: Irọ́ ni pé wọ́n sèkọlù sí Gómìnà Seyi Makinde
Ronaldo ní Tottenham yóò jẹ moyó ìyà lọ́wọ́ Liverpool Ajimobi tako àṣẹ iléẹjọ́ pẹ̀lu ìbò ìjọba ìbílẹ̀ tó ṣe - Ìjọba Ọyọ Àrà kengé!
fi rọ orile ede naa lọrun lati da ile-ise won sile lai jẹ pe won sa owo ori.
Nígbà tí èmi náà wo inú àpò mi, mo wọ ṣòkòtò kan tí ó jẹ́ ti baba mi tẹ́lẹ̀ tí mo jogún lẹ́yìn ikú rẹ̀, àwọ̀ rẹ̀ náà ni, ti búlúù ni -  nígbà tí òárún là, àwọ̀ sánmọ̀ mọ́lẹ̀ kedere, àwọ̀ ojú ọ̀run sì jẹ́ búlúù.
Mà máa sọ igi tútù di gbígbẹ,má sì máa mú kí igi gbígbẹ pada rúwé.
Ògo àwọn wolii yóo wọmi, òkùnkùn yóo sì bò wọ́n.
OLUWA yóo fa ìwọ ati Israẹli lé àwọn ará Filistia lọ́wọ́.
Aare sapejuwe ikunwo naa gege bi aami orile-ede yii lati maa gbe papo ni isokan.
"Kò yẹ kí ìjọba máa ní àwọn mẹ̀kúnú lára lásìkò Coronavirus yìí- Rewane Àwọn àwòrán ìrántí tó ń sàmì ogójì ọdún tí Ọba Adesoji Aderemi jáde láyé Wo awọn Aàrẹ nílẹ̀ Áfríkà to ti gba oyè ""Field Marshal"" rí Khorasan: Oṣu Kinni, ọdun 2015, ni IS kede pe oun ti da ẹka silẹ ti yoo ma a ṣíṣẹ ni Afghanistan, Pakistan, ati awọn agbegbe to yi wọn ka."
Bí ẹni fi òkúta sinu kànnàkànnà,ni ẹni tí ń yẹ́ òmùgọ̀ sí rí.
OLUWA sì ti kó ìyọnu bá ìwọ náà lónìí.
Asiko ọtọọtọ lawọn oniruuru ipinlẹ ma n pari idibo wọn.
Wọn óo bọ̀wọ̀ fún Ẹni Mímọ́ Jakọbu;wọn óo sì bẹ̀rù Ọlọrun Israẹli.
Bakan naa ni agbegbe yii kan naa, wọn yinbọn pa awọn ọmọ ẹkọṣẹ meji, Odude Amos Adeleke ati Azeez Yekini nigba ti wọn kọlu ilu wọn ti ọpọlọpọ si fara pa yana yana.
Ẹ̀yin ọmọde, ẹ má jẹ́ kí ìfẹ́ wa jẹ́ ti ọ̀rọ̀ ẹnu tabi ti ètè lásán; ṣugbọn kí ó jẹ́ ti ìwà ati ti òtítọ́.
Saraki: Àwọn aṣòfin àpapọ̀ ṣ'àfihàn ìṣọ̀kan lásìkò tí jàǹdùkù jí ọ̀pá àṣẹ ilé gbé
Kí OLUWA fúnrarẹ̀ jẹ́ ẹlẹ́rìí tí yóo takò yín,àní OLUWA, láti inú tẹmpili rẹ̀ mímọ́.
Ó sì ń bọ àwọn ìràwọ̀.
Keyamo ni ajọ WAEC ti jẹri si i pe Aarẹ Buhari ni iwe ẹri girama, ṣugbọn o ni ọrọ ko ri bẹẹ pẹlu Adeleke l'Oṣun.
 Òun ni ó se èkejì móósè gégé bí olórí fún àwon ara isiréélì nígbà tí wón n la aginjù kojá tí wón n lo sí ilè ìlérí láti Íjíbíìtì .
Ṣaaju ni ajọ to n gbogun ti iwa ibajẹ ni Naijiria, EFCC ti fi ẹsun kan Naira Maley lori ọrọ to jọ mọ lilu jibiti lori ẹrọ ayelujara.
 Ọ ̀ pọ ̀ lọpọ ̀ nínú wọn ló tún wá láti Èsìé ̣ , Ílúdùn , Ìpetu ( kwara ) , rorẹ ́ àti Òmu-àrán .
Nítorí pé o ṣọ̀wọ́n lójú mi, o níyì, mo sì fẹ́ràn rẹ,mo fi àwọn eniyan rọ́pò rẹ;mo sì fi ẹ̀mí àwọn orílẹ̀-èdè dípò ẹ̀mí rẹ.
Ipo yi ko ki n se oye idile ,ko si  pon dandan ki won gbe oye naa fun Omo oba-kunrin naa ti Oba-birin naa ba papoda.
Nibi igbẹjọ to waye l'Ọjọbọ, awọn olupẹjọ pe ẹlẹri lara awọn oṣiṣẹ ajọ DSS atawọn ẹlẹri miran.
Awọn ohun to yẹ ko mọ nipa Mọremi Ajaṣoro: Ọmọ bibi ilu Ọffa, lẹba Ilọrin, nipinlẹ Kwara bayii, ni Mọremi, igbeyawo lo si gbe de ilu Ile Ifẹ Ọranmiyan, tii se ọmọ bibi Oduduwa, to tun jẹ Ọba nilu Ile Ifẹ ni ọkọ Mọremi, eyi to mu ki Mọremi jẹ olori abi Ayaba Arẹwa obinrin, akikanju to ni igboya ni Mọremi, to si setan lati fi ohunkohun to ni, gba ilu Ile ifẹ silẹ lọwọ awọn Igbo Idi ree ti Mọremi se tọ odo Ẹ̀sìnmìrìn lọ pe oun yoo fun ni ohunkohun to ba fẹ, niwọn igba to ba fi asiri agbara awọn Igbo naa han oun Mọremi fi ara rẹ silẹ lati jẹki wọn ko oun lẹru, ti ẹwa rẹ si wọ oju Ọba awọn igbo, ẹni to fẹ bii aya, to si di aayo olori rẹ Mọremi farakinra pẹlu awọn Igbo, to si mọ asiri wọn, lẹyin eyi lo yọ pada si Ile Ifẹ lati tu asiri awọn Igbo fun wọn Ọmọ ogun Yoruba bori awọn ọmọ ogun Igbo, ti Mọremi si pada sọdọ ọkọ rẹ tii se Ọba Ọranmiyan lati di ayaba Mọremi fi ọmọkunrin rẹ kansoso, Oluorogbo, rubọ fun odo Ẹsinmirin, nigba ti odo naa beere ọmọ ọhun lọwọ Mọremi, lati fi san ẹjẹ to jẹ fun Oniruuru ibudo awọn obinrin lawọn ileẹkọ fasiti nilẹ wa, bii fasiti Eko ati Ọbafẹmi Awolọwọ, ni wọn fi sọri akikanju obinrin yii Lọdun 2017, Ọba ogunwusi mọ ere kan to ga julọ lorilẹ ede Naijiria, lati fi seranti Mọremi ni aafin Ọọni tile Ifẹ Ọpọlọpọ ere ori itage si ni wọn ti se lati fi se iranti akikanju obinrin naa lede oyinbo ati Yoruba Ọpọlọpọ itan ni igbesi aye Mọremi Ajasoro kọ wa, to si yẹ ki awa eeyan iwoyi, ati obinrin, ati ọkunrin fi se arikọgbọn.
Fídíò yìí ló ṣàfihàn Lizzy níbi tó ti n jó sí orin àwọn alága ìdúró/ìjókòó níbi ayẹyẹ nàá.
”Wọ́n dáhùn pé, “Jesu ará Nasarẹti ni.
com Àkọlé àwòrán, Oloye Bode Akindele lo si yi fun ijọba ipinlẹ Oyo lowo to pọju lati fi koju arun Covid-19 Saaju la ti mu iroyin wa fun yin pe iku tun ti doro nilẹ Ibadan pẹlu bi iroyin iku Oloye Bode Akindele ṣe gbagboro kan.
Ṣugbọn nígbà tí ó rí Modekai ní ẹnu ọ̀nà ààfin, tí kò tilẹ̀ mira rárá tabi kí ó wárìrì, inú bí i sí Modekai.
Ṣugbọn jẹ́ àpẹẹrẹ fún àwọn onigbagbọ ninu ọ̀rọ̀ rẹ, ati ninu ìṣe rẹ, ninu ìfẹ́, ninu igbagbọ ati ninu ìwà pípé.
Amọṣa awọn eeyan kan lori ayelujara ti ṣalaye pe irọ nla gbaa ni iroyin ti ẹgbẹ oṣelu naa gbe.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ni ọjọ isinmi ni Kẹmi Adeosun foju ọrọ ọun lede Adeosun tun sọ pe aleekun ọun kii se oun ti yoo ku giri lọ soke, o ni ijọba ti gbe igbesẹ lati rii pe aleekun owo ori yii ko gun awọn ileese tọrọ naa kan lapa, nidi eyi, wọn ti seto ki owo ori ọun maa lekun diẹdiẹ lati asiko yii titi di ọdun 2020.
Oríṣun àwòrán, BABAJIDE SANWO-OLU/TWITTER Iwadii ti ileeṣẹ iroyin CNN ṣe fi han pe awọn ọmọ ileesẹ ologun Naijiria dana ibọn ya awọn oluwọde EndSARS ni Lekki Toll Gate.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Afárá já sódò lẹyìn tí ọkọ̀ ojú omi kọlùú ní Brazil 7 Ìgbé 2019 Aworan afara to ja sodo Oríṣun àwòrán, Handout/Reuters Àkọlé àwòrán, Afara to ja sodo Ọkọ oju omi agbero 'fẹri' kan ti kọlu afara kan nipinlẹ Pará lagbegbe ariwa orileede Brazil.
Osu meji ni mo lo ni Iseyin, ti wọn si ta mi fun eeyan mẹta ọtọstọ, amọ ti wọn n da mi pada, ko to wa di pe wọn ta mi fun mi fun obinrin ara Popo kan, ẹni to ta mi fun eebo Pọtugi, ki wọn to gbe mi lọ soke okun.
Nítorí ìdí èyí, àwọn ọ̀dọ́mọkùnrin tí wọ́n ń tan àwọn obìnirn jẹ pé àwọn ó fẹ́ wọn láìjẹ́ pé o ti inú ọkàn wọn jáde, àti àwọn oníyèmejì ọ̀dọ́mọbìnrin tí wọ́n ń tan ogunlọ́gọ̀ ọkùnrin jẹ lójoojúmọ́ ayé wọn apànìyan ni gbogbo wọn, Olódùmarè ṣe ayé ní iyọ̀ òyìnbó fún àwọn ọmọ ènìyàn, ṣùgbọ́n àwọn wọ̀n-ọnnì ńn fẹ́ sọ ọ́ di ewúro.
Amọṣa ni ibudo itọju awọn alaarun naa lo ti ṣe idanwo ọhun.
 Àṣìṣe ló ṣẹlẹ̀ níbi ètò ìsìnkú Abba Kyari- FCTA Ìtàn Manigbagbe: Àwọn àjakalẹ-àrun to ti wáyé rí ṣáájú Coronavirus Àwọn Ìpínlẹ̀ tí coronavirus kò tíì dé ní Nàìjíríà, àti ìgbésẹ̀ tí wọ́n ń gbé láti dènà rẹ̀ O tẹsiwaju lati sọ pe ipo Olori awn oṣiṣẹ fun aarẹ yatọ si ti gomina, nitori naa mi o lero pe Gomina Nasir El-Rufai wa lara awọn ti aarẹ le yan.
Oríṣun àwòrán, @MBuhari Secondus ni ikede Buhari ọhun lo fara pẹ ikede ogun jija lori awọn oludibo ati iwa riru ọkan awọn agbofinro soke si wọn.
Lọ́jọ́ kejì, o fi ẹrù iṣu méjìlá ránṣẹ́ pẹ̀lú ṣago ẹmu ogidi mẹ́wàá, ó gbé àpò ìdọ̀họ gaàrí kan, àpó èlùbọ́ méjì, garawa epo mẹ́jọ pẹ̀lú àpó iyọ̀ ńlá kan.
Dino Melaye fìdí rẹmi, Smart borí nílé ẹjọ́ kòtẹ́milọ́rùn Ọpẹ́ o!
Orúkọ wọn dúró lẹ́hìn àwọn èrò ẹhìn si ń ìje nítorí wọn pé kí àwọn kí ó le dabi wọn.
Ẹẹdẹgbẹsan (1,700) ẹlẹ́ṣin ni Dafidi gbà lọ́wọ́ rẹ̀, ati ọ̀kẹ́ kan àwọn ọmọ ogun tí wọ́n ń fi ẹsẹ̀ rìn.
Iwe iroyin Forbes mu alaye wa pe aiṣedeede eto ọrọ aje ati owo ti ko gbe pẹli lo mu ki iye awọn to lowo to to biliọnu dinku di ogun nilẹ afrika lati mẹtalelogun ti wọn jẹ lọdun to kọja.
Mo ní àwọn akọrin lọkunrin ati lobinrin, mo sì ní ọpọlọpọ obinrin tíí mú inú ọkunrin dùn.
Kazeem ki o to ku ni igbakeji balogun ikọ agbabọọlu Remo Stars.
Mo bá gbọ́ tí ó sọ̀rọ̀, nígbà tí mo gbọ́ ohùn rẹ̀, mo dojúbolẹ̀, oorun sì gbé mi lọ.
Ọọni Adeyẹye Ogunwusi ni idunnu nla lo jẹ fun awọn ọbalaye lasiko yii lati rii pe ajinde n de ba awọn aṣa ilẹ Yoruba.
loju pe orile-ede Naijiria setan lati sagbateru idije boolu afesegba titi awon
Ìwọ́de 'End SARS' lè tan àjàkálẹ̀ arùn coronavirus lẹ́ẹ̀kejì ní Nàìjíríà- Ọjọ̀gbọ́n Faduyile Owó oṣù tuntun fáwọn olùkọ́ tí Buhari kéde yóò dá aáwọ̀ sílẹ̀- Wike Wo ìgbà mẹ́rin tí ìjọba ti tú ikọ̀ ọlọ́pàá SARS ká sẹ̀yín ṣùgbọ́n.
Gẹgẹ bi ọrọ ti kọmiṣọna feto ilera Eko sọ, awọn eeyan mọkandinlọgọjọ lo wa ninu ọkọ baalu naa, awọn mẹfa si ṣalabapade rẹ nile itura to wọ si, ti awọn marundinlogoji mii tun ṣalabapae rẹ nile iṣẹ to ṣabẹwo si ni ipinlẹ Ogun.
Aburo rẹ naa lo si fi awọn mejeeji mọ ara wọn.
Wọn buwọlu u lọjọru lẹyin eto ayẹwo ti awọn aṣofin kan ṣe fun un.
Ẹni tí ó bá ṣe onídùúró fún àlejò yóo rí ìyọnu,ṣugbọn ẹni tí ó bá kọ̀ tí kò ṣe onídùúró yóo wà láìléwu.
” Ṣugbọn Jakọbu dá a lóhùn pé, “Mo dúpẹ́, má wulẹ̀ ṣe ìyọnu kankan.
Abenugan naa wa bu ẹnu atẹ lu
"Ọkan lara awọn tisẹlẹ naa soju wọn, to ba BBC sọrọ ni ""Nkan kan lo mu ki ọkọ epo naa bu gbamu fun ina, to si pa gbogbo ero to wa ninu ọkọ bọọsi kan atawọn eeyan to n gbọ epo, koda awọn ile ati sọọbu to wa nitori ibiti isẹlẹ naa ti waye, lo jona raurau."
Naijiria, Independent National Electoral Commission (INEC),ti kede omo egbe
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ilẹkun Baalu Dana fo yọ nilu Abuja 7 Èrèlè 2018 Oríṣun àwòrán, Dapo Sanwo Àkọlé àwòrán, Ilẹkun ẹyin lawọn ero inu baalu Dana naa gba jade nigbati ilẹkun iwaju ja bọ Ọpọ ero to wa inu baalu Dana lọjọbọ lo n se ọpẹ pe ori ko wọn yọ lọwọ ewu nigbati ilẹkun iwaju baalu B45 to ko awọn ero lati ilu Eko lọ si Abujas sadede fo yọ ni kete ti baalu naa balẹ tan nilu Abuja.
Kò gbọdọ̀ ti ipasẹ̀ wọn sọ ara rẹ̀ di aláìmọ́ nítorí ìyàsímímọ́ Ọlọrun ń bẹ lórí rẹ̀.
Ṣugbọn mo kórìíra rẹ̀, nítorí pé àsọtẹ́lẹ̀ rere kan kò ti ẹnu rẹ̀ jáde sí mi rí, àfi kìkì burúkú.
ede yii  loju pe eto aabo yoo wa fun
Ronaldo si ni ọdun meji ṣii ninu iwe adehun to buwọlu pẹlu Juventus.
Oríṣun àwòrán, Government of Ekiti State, Nigeria.
Ẹ mú àwọn eniyan mi jáde,àwọn tí wọ́n ní ojú, ṣugbọn tí ojú wọn ti fọ́,wọ́n ní etí, ṣugbọn etí wọn ti di.
Asa ọba, yọ Maaka ìyá rẹ̀ àgbà pàápàá kúrò ní ipò ìyá ọba, nítorí pé ó gbẹ́ ère ìríra kan fún oriṣa Aṣera.
Aarẹ Buhari lara ipinu rẹ nigba to gba ijọba, sọ wi pe ohun yoo koju Boko Haram sugbọn lẹyin ọdun mẹta ti o de ori alefa,kaka ki ewe agbọn Boko Haram de,niṣe ni o n le koko si.
World Cup 2018: Salah yóò kópa nínu ìdíje Russia vs Egypt lọjọ Iṣẹgun
 bẹ ́ ẹ ̀ ṣi ni a kìí dára ka ma kù ṣíbì kan .
" Awọn eeyan to peju sibi eto isinku naa, ti iroyin ọhun ba lojiji, si ti n pada lọ sile lọọkọkan.
Ohun tó yẹ kẹ́ẹ mọ nípà olùdíje mèjì tó lágbára nínú ìdìbò Ghana rèé
Njẹ o ni nkan to le fa Akufa nilana iṣegun oyinbo?
Ko fi pamọ wipe oun ni baba isalẹ rẹ.
Mo ní owó kún owó mo sì  ní ọ̀pọ̀lọpọ̀ oògùn tó bẹ́ẹ̀ tí mo níláti wá aláàárù kí wọ́n bá mi máa gbé ẹrù mi ni.
Ó bá kó gbogbo àwọn eniyan rẹ̀ jọ, wọ́n pàgọ́ sí Jahasi, wọ́n sì gbógun ti àwọn ọmọ Israẹli.
Sadoku ati Abiatari bá gbé àpótí ẹ̀rí pada sí Jerusalẹmu, wọ́n sì wà níbẹ̀.
Yóo fi yàrá ńlá kan hàn yín, ní òkè pẹ̀tẹ́ẹ̀sì, tí wọn ti tọ́jú sílẹ̀.
Amọṣa, lẹyin asiko diẹ ni ikede tun waye pe ijọba apapọ ti da a pada si ipo rẹ.
Akọroyin BBC, Adedayo Okedare ti o jade pẹlu awọn ogunlọgọ eniyan ti o tu jade fẹhonuhan sọ wipe inu awọn ko dun si afikun ti ijọba se fun owo irinna yii ati wipe o jẹ ipalara fun awọn olugbe adugbo lekki ati Ajah ti wọn maa nlo awọn ibusọ wọn yii lojoojumọ.
 Oríṣun àwòrán, @justempower Amọ Otuji ko sai fikun pe bi o tilẹ jẹ pe kii se gbogbo awọn eeyan to n pe ni agbegbe naa lo n ji epo ta, sugbọn ẹni to gbe epo laja ko jale, bi ẹni to gbaa silẹ, nitori ti wọn ko ba tu asiri awọn eeyan to n ji epo fa lọna aitọ ni ayika wọ, gbogbo wọn ni wọn jọ jẹbi."
Oríṣun àwòrán, TWITTER Awọn eniyan eniyan to fesi si oun ti gomina naa sọ gboriyin fun Akeredolu fun ipa ribiribi to ko nipa ifilọlẹ ikọ amọtẹkun fun eto aabo ipinlẹ naa ati ilẹ Yoruba lapaapọ.
Ó dọ́gbọ́n fi àwọn ọmọ rẹ̀ ṣe olórí káàkiri, ó pín wọn káàkiri jákèjádò ilẹ̀ Juda ati Bẹnjamini ní àwọn ìlú alágbára.
Bioraj dá òṣìṣẹ́ dúró torí fídíò BBC 'Àìbọ̀wọ̀ fẹ́tọ̀ọ́ ọmọnìyàn ló ń fa wàhálà Bokoharam, Shiite' Ibẹẹta ati ọmọ iya wọn jona ni jigawa Donald Trump kéde pé ìpàdé òun pẹ̀lú Kim já si rere Abba Kyari ni ko si ẹni to maa n fẹ ki ọwọja ofin gba oun mu pẹlu ijiya to tọ ni ọrọ ẹsun naa.
"Koda, bi a ko ba fi alukurani bura, ka fi bibeli bura, amọ̀ ki awa ati ọ̀ga ọlọpa to ni Oluwo ko na mi, ka jọ̀ da ibọ̀n kọ̀ja, ko wa sọ̀ pe ko ri bẹẹ Bi ọga ọlọpa fẹ ni oun ko sọrọ tori ọrọ ijọba ki wọn jẹ ka da ibọn kọ ja, emi nikan kuku kọ ni mo wa nibẹ, awa ọba to wa nibẹ pọ, ẹlẹri mi si ni wọn.
Wọ́n ní ọ̀ps wọ́n lo ti sọ ilé ìgbìmọ̀ aṣòfin àgbà di ilé ìfẹ̀yìnti àti ìfọ̀kànbálẹ̀.
Awọn orile-ede ta n wi yi ni owo, wọn ni eto imayegbadun farailu to munadoko bẹẹ ni wọn tun gbe igba-oroke ti ọrọ ba kan ki a mu idagbasoke ba awujọ.
wọn ìbáà hù lọ́jọ́ tí ẹ gbìn wọ́n,kí wọ́n yọ òdòdó ní òwúrọ̀ ọjọ́ tí ẹ lọ́ wọnsibẹsibẹ kò ní sí ìkórèní ọjọ́ ìbànújẹ́ ati ìrora tí kò lóògùn.
Wọn ko fẹ ki ododo jade ni'' Oríṣun àwòrán, Reuters Trump wa poinu pe bẹrẹ lati ọjọ Aje to n bọ, oun yoo gba ileẹjọ lọ lati ri pe wọn tẹle ofin idibo ti ẹni to jaweolubori si fidi sori aga.
Olugbe adugbo naa kan fi inu iho ti wọn ni Adediwura ko si han akọroyin BBC Yoruba.
Wọn si sọ fun ẹnikẹni ti o ba ni àmì kankan lati lo íretí fi ṣe ayẹwo orisirisi aarun.
Àwọn oní Bókobòko níwá, Èbólà lẹ́hìn.
kefa lati fi sami ayeye ayajọ eto ijoba tiwa-n-tiwa lorile ede yii fun igba
Àwọn ọmọ Nàìjíríà ṣe ìwọ́de l'Osogbo lórí àfikún owó epo bẹntiróò Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí 12:46 Fídíò, Àṣìṣe ọlọ́pàá àti Adájọ́ sọ mí di ẹni tí wọ́n dájọ́ ikú fún, ọpẹ́lọpẹ́ Fayoṣe tí ko buwọ́lù ú, Duration 12,465 Owewe 2020 6:18 Fídíò, Akomolede: Bolaji Faleke ni Olùkọ́ tó ń kọ́ wa ní àṣà oge ṣiṣe lórí BBC Yorùbá, Duration 6,181 Owewe 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Joaṣi ni ó wà fún ibi tí wọ́n ń kó òróró olifi pamọ́ sí.
O le ni orile-ede ogoji to ti fofinde awọn olugbe UK, bi awon EU se n pinu lati se agbekale ilana kan lasiko yii.
Agbẹnusọ fun Ile-iṣẹ Ọlọpaa ipinlẹ Eko Chike Godwin Oti to ba BBC Yoruba sọrọ fidi rẹ mulẹ pe gbogbo eto ti to lati gbe Aafa naa lọsi ile-ejọ bayii.
O Fagunwa, Adebayo Faleti, Akinwumi Iṣọla, Lawuyi Ogunniran àti Oladejo Okediji ṣiṣẹ silẹ ki wọn to lọ3 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Overweight and pot belly: Wo oríṣìí oúnjẹ márùn ún tó lè dẹ́kun ikùn yíyọ àti ara àsanjù8 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Death During Sex: Àwọn nǹkan mẹ́ta tó le ṣekú pa ọkùnrin lásìkò ìbálòpọ̀ rèé9 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Akomolede Oyo round up: Àwọn Olúkọ ìpínlẹ̀ Oyo fakọyọ lórí ètò Akọ́mọlédè àti Àṣà púpọ̀27 Bélú 2020 Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí 2 sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
Oríṣun àwòrán, Reuters Àkọlé àwòrán, Awon obi n beree omo won lowo ijoba Ikọlu naa ti n mu irufẹ isẹlẹ bẹẹ to sẹlẹ si awọn ọmọbinrin akẹkọ to le ni igba ti awọn Boko Haram ji gbe ni ile-iwe kan ni ilu Chibok ni ọdun 2014 wa si iranti.
 ní àwọn ọ ̀ pọ ̀ ìgbà ( 60-80 % ) ni kòní àwọn ààmì .
Bẹrẹ lati dahun ibeere to wa ninu idanwo rẹ nipa ki koju si awọn eleyi ti o mọ daada ki o si ṣe iyoku lẹyin rẹ Lakotan, ti o ba ri wi pe ko si ọna abayọ si ibẹru-bojo ti o ma n mu o lasiko idanwo, ri wi pe o koju si ile iwosan lati gba itoju lọwọ dokita ati onimọ nipa ihuwasi eniyan.
Ohun èlò fún ìwé ẹ̀rí ọmọ-ìlú-fún-ìrìnnà máa ń gbọ́n owó mì, nítorí iṣẹ́ ìdáàbòbò oríi rẹ̀, tí àjọ ọba ń kówó lé lórí tẹ́lẹ̀ kí ó tó di ìgbà yìí.
20 Ọ̀wàrà 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Bẹẹ naa ni obinrin tun lee kopa ninu idibo ati lati gbe apoti idibo, eyi ti ko ri bẹẹ tẹlẹri.
Ọpọ nkan imọ ẹrọ lo ti wa bayii to si jẹ pe ko gba wọn ni iṣẹju pupọ lati lo o mọ ara wọn bi wọn ba fẹ ya fọto.
    Mo wí fún oníṣẹ́ tí ọba rán wá wí pé kí ó máa lọ síwájú dè mi, àti pé mo ń bọ̀ lẹ́yìn rẹ̀, lẹ́yìn èyí, mo yi aṣọ mi padà: mo wọ àwọ̀tẹ́lẹ̀ fẹ́lẹ́fẹ́lẹ́ sí ìsàlẹ́, mo wa wọ tógò mi titun tí mo ṣẹ̀ṣẹ̀ dá lé e, lẹ́yìn èyí ní ni mo wa gbé ẹ̀wù agbádá ẹtù bàbá mi mo kìí bọ ọrun, mo sì mu ṣòkòtò ẹtù pẹ̀lú mo wọ̀ ọ́, mo wá dé fìlá abetí-ajá sán-ányán mi kan báyìí mo ta á hanha.
Ṣugbọn bí ọmọ-ọ̀dọ̀ náà bá rò ní ọkàn rẹ̀ pé, ‘Yóo pẹ́ kí oluwa mi tó dé,’ tí ó wá bẹ̀rẹ̀ sí lu àwọn iranṣẹkunrin ati iranṣẹbinrin, tí ó ń jẹ, tí ó ń mu, tí ó tún ń mutí yó, 
Kí á má tilẹ̀ sọ ti iyùn tabi Kristali,ọgbọ́n ní iye lórí ju òkúta Pali lọ.
Nígbà tí wọ́n bí Jesu ní Bẹtilẹhẹmu ní ilẹ̀ Judia, ní ayé Hẹrọdu ọba, àwọn amòye kan wá sí Jerusalẹmu láti ìhà ìlà oòrùn.
” OLUWA bá sọ pé: “Òpin ti dé sí Israẹli, àwọn eniyan mi, n kò sì ní fojú fo ẹ̀ṣẹ̀ wọn mọ́.
 Iroyin to tẹ BBC news Yoruba lọwọ ṣalaye pe nibi ijoko ile naa to waye ni ọjọ ẹti lawọn aṣofin mejidinlogun to wa nile aṣofin naa."
Oshonaike ṣalaye pe bi wọn ti fipa ba Omozua lopọ ran ohun leti bi ọkunrin kan to fi ọdun mẹwaa ju oun lọ ṣe fipa ba oun lopọ nigba t'oun wa lọmọ ọdun mọkandinlogun.
“Kúrò lọ́dọ̀ àwọn eniyan wọnyi kí n lè pa wọ́n run ní ìṣẹ́jú kan.
Aarẹ Buhari sọrọ yii ninu ọrọ apilẹkọ rẹ to sọ nibi ayajọ ọjọ ijọba awarawa akọkọ iru rẹ l'Abuja lonii.
Nigba ti awọn ọlọpaa gbe Adeyemi de ile ẹjọ, ṣe ni ero ya bo yara igbẹjọ lati wo afurasi naa.
Amọ, ọga agba ọkọ ero BRT ipinlẹ Eko ko ṣai ṣalaye pe ijọba ni lati roo daadaa ki wọn to gbe ilana mii kalẹ nitori akoba ti coronavirus ti ṣe fun ọrọ aje tẹlẹ.
Oríṣun àwòrán, Osinbajo/twitter Àkọlé àwòrán, Osinbajo dúpẹ́ lọ́wọ́ Mummy G.
Masari ni ikọ darandarn labẹ ẹgbẹ Miyetti Allah ati Macaban lo seranwọ lati gba idande awọn akẹkọọ naa.
Lọjọbọ ni ijọba orile-ede Naijiria fi ikede sita pe awọn orile-ede to ba gbegi dina irinajo baalu lati Naijiria sọdọ wọn, Naijiria naa ko ni gba ki baalu wọ ilẹ rẹ lati ọdọ wọn.
Abdulaziz, lati wa se  Umrah (lesser
Wo àwọn báńkì tó wà lẹ́yìn àwọn olówó èlé bí MMM Ẹ̀yin òṣìṣẹ́ elétò ìlera, ẹ padà sẹ́nu iṣẹ́- JOHESU Wo bí Sunday Shodipe ṣe pa Funmilayo tó pa kẹ́yìn l' Akinyele Ìjọba Kaduna kéde ọjọ́ mẹ́ta fún ìdárò Emir Zazzau, Buhari, Tinubu, Babangida náà ń ṣèdárò Sudan tí bẹ̀rẹ̀ ìjìròrò lórí bí US yóò ṣe yọ òrúkọ̀ wọn kúrò nínù ikọ̀ agbẹ́sùnmọ̀mí àgbáyé Bákan náà ni kò si ẹ̀rí láti fi hàn pé ilé iṣẹ́ ẹlikọ́pítà náà kọ ìwé fún àjọ NCAA lati yọnda ọkọ ọ̀hun fún ìrìnàjò lẹ́yìn ti àsìkò to le rìn ti parí.
Yahaya fí kún pé ti àwọn ba wa mú ẹnikẹni to si lé mú àrídaju jáde pe òun kìí ṣe aṣẹ́wó tàbí ọ̀daràn, àwọn ó dáa silẹ̀ láti maa lọ.
2 mílíọ́nù owó ìtanràn Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
O óo sì mọ̀ pé èmi OLUWA, ni olùgbàlà rẹ,ati Olùràpadà rẹ, Ẹni Ńlá Jakọbu.
"Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Olumuyiwa Bolade Adedeji Military Bruitality: Bí arákùnrin onípèníjà ara tí sọ́jà lù ṣe dé Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Olumuyiwa Bolade Adedeji Military Bruitality: Bí arákùnrin onípèníjà ara tí sọ́jà lù ṣe dé 5 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 ""Bi mo ṣe ni ipenija ara yii, mi o ro pe o yẹ ki sọja naa lee ṣiwọ lu mi rara amọ."
Awọn aṣẹ miran ti ijọba ipinlẹ Ekiti pa lori kikapa arun yii niwọnyii: Àrùn Coronavirus ti tàn dé orílẹ̀èdè Eritrea Orilẹede Eritrea ti fi lede wi pe awọn ti ni ẹni akọkọ to ni Coronavirus lorilẹede naa.
Kí aráyé baà leè mọ̀ pé eré kọ́ làwọn wá ṣe, àgọ́ ọlọ́pàá tó wà ní Owódé làwọn alọkólóhunkígbe yìí ti kọ́kọ́ kí wọn kú ilé níbẹ̀, tí wọ́n sì rán àwọn ọlọ́pàá tó wà lẹ́nu iṣẹ́, àwọn èèyàn tó ní ẹjọ́ ní tésàn náà àtàwọn èèyàn míì tó wà níbẹ̀ sọ́run ọ̀sángangan.
O ṣalaye pe ''Iroyin to tẹ wa lọwọ pe wọn ṣe apejẹ ọjọ ibi ọkan lara wọn lo mu ki awọn eeyan wa tara ṣaṣa lọ si bẹ.
“Ẹ má ṣe kó ìṣúra jọ fún ara yín ní ayé, níbi tí kòkòrò lè bà á jẹ́, tí ó sì lè dógùn-ún.
Lekki Toll Gate: Ìjọba ìpínlẹ̀ Èkó fajúro lórí ìpolówó tó ṣe àfihàn obìnrin ní ìhòòhò
Kete ti o fi ọrọ yi sita lawọn eeyan ti n kan sara si ijọba fun igbesẹ yi Owo yi,ta lo wa fun Gẹgẹ bi alaye ti aarẹ ASUU Biodun Ogunyemi ṣe lalaye, o ni ọna orisirisi ni ijọba ma n gba na owo fun idagbasoke eto ẹkọ ni Naijiria.
Alukoro ileeṣẹ ọlọpaa nipinlẹ Ondo,Femi Joseph lo fidi ọrọ na mulẹ fun BBC Yoruba.
Kì í ṣe pé mo ní ẹjọ́ kankan láti bá orílẹ̀-èdè wa rò.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù EndSARS Protest Update: Aisha Yesufu ní Buhari jẹ́wọ́ pé òun kò láànú aráàlú nínú ọ̀rọ̀ rẹ̀ 15 Owewe 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 23 Ọ̀wàrà 2020 Oríṣun àwòrán, Ibrahim Usman Ọkan lara awọn oju to gbajumọ julọ lasiko iwọde #EndSARS, Aisha Yesufu ti ṣe apejuwe aarẹ Muhammadu Buhari, gẹgẹ bi aṣiwaju ti ko laanu ọmọ Naijiria loju.
Bí kò bá ṣe bẹ́ẹ̀, ìwọ kì bá tí wá sí ibi tí ìwọ wà ní àkókò yìí.
Ṣugbọn ile ẹjọ ni kí ajọ NBC lọ ni suuru titi di igba ti wọn yoo fi dajọ lori ẹjọ ti DAAR Communications fi ta ko igbeṣẹ ajọ naa.
Ọlọgbọndiyan ninu atẹjade to fi sita lorukọ ẹgbẹ PDP sọ pe mimi kan ko le mi ẹgbẹ naa ohun to wu ki ẹgbẹ APC ṣe.
Ṣugbọn Jesu kígbe tòò, ó mí kanlẹ̀ ó bá dákẹ́.
Má dúró tì wa, ma dúró ti wa, àwa kò fẹ́ ọ, àwa kò bá ọ ṣe àjọpín, Ìgbéraga, àbàwọ́n inú ayé, Ìgbéraga, ìfàsẹ́yìn ọmọ ènìyàn, Ìgbéraga, má kó tìrẹ ràn wá, máa lọ, máa lọ, máa lọ jọ̀wọ́ máa lọ o:-:-: jọ̀wọ́ máa lọ o:-:-:-: jọ̀wọ́ máa lọ o:-:-:-:
Lẹyin eyi ni Ọba Seriki Abass Williams tun da awọn ilu meji miran silẹ nilẹ Yoruba, awọn ilu naa ni Ayetoro ati Idogo, ti wọn wa nipinilẹ Ogun titi di oni.
Lasiko to n ba BBC Yoruba sọrọ, Agbowu ni igbesẹ ti igbimọ lọbalọba nipinlẹ Ọsun gbe lori ọrọ naa, eyi to ni ki Oluwo lọ rọọkun nile na fun osu mẹfa ko tu irun kankan lara rẹ, tabi jẹ ko kabamọ nina to na oun.
Nítorí iṣẹ́ tirẹ̀ burú, ṣugbọn ti arakunrin rẹ̀ dára.
Oga ajọ NDLEA ni okinrin naa yoo foju ba ile ẹjọ ni kete ti iwadi ba ti pari Gbajabiamila balẹ̀ sí Ghana láti pẹ̀tù sááwọ̀ láàrin Nàìjíríà àti Ghana Ẹgbẹ́ òṣìṣẹ́ NLC, PDP, MAN fọnmú lórí epo bẹntiró tó dí N162 Kí ló wá nínú àbádòfin pínpín omi àti àwọn ǹkan inú omi tó ń mú awuyewuye wa?
Abdullahi yii la gbọ pe odu rẹ kii se aimọ fun oloko awọn obi Aisha ati Aisha funra rẹ, nitori pe o sunmọ mọlẹbi naa tipẹtipẹ ni.
“Ẹnikẹ́ni tí ó bá fẹ́ rú ẹbọ alaafia sí OLUWA, yóo mú ẹbọ náà wá fún OLUWA.
Gomina ipinlẹ naa, Seyi Makinde lo kede bẹ ẹ ninu atẹjade kan to fi sita loju opo Twitter rẹ lọjọru.
Bi a ba tibi orukọ rẹ to yi pada si Raymond wo, o ti le fi ẹsin Islam silẹ ṣugbọn o le jẹ inagijẹ lasan ni Raymond, ki o ma se wi pe o pa ẹsin da.
Má mú mi kúrò nítorí ojú àánú rẹ.
Idibo Osun: Yusuf Lasun ní wọn ń dìtẹ̀ mọ òun nínú ẹgbẹ́ APC Oríṣun àwòrán, @Lasun4Governor Ìgbákejì olori ilé ìgbimọ aṣojú-sòfin, Ọgbẹ́ni Yusuf Lasun ní, òun kò ṣetán láti fí ẹgbẹ́ òṣèlú All Progressives Congress (APC) sílẹ bó tilẹ̀ jẹ́ pé, òun fìdí rẹmi nínú ìdìbò àbẹlé ẹgbẹ́ lati dupò gómìnà tó wáyé nílu Oṣogbo lóṣù keje ọdun 2018.
Oríṣun àwòrán, Osun Defenders Nipa eto ẹkọ rẹ, a ri akọsilẹ pe: Seneto Ademola Adeleke lọ si ile ẹkọ alakọbẹrẹ niluEeko ati ile ẹkọ Nawarudeen nilu Ikire.
Ṣugbọn njẹ o mọ pe sisun lai wọ nkankan ni anfaani to le ṣe fun ọ?
Nigba to n ba BBC Yoruba sọrọ, Osisẹ alarena fun ileesẹ ọlọpa nipinlẹ Kwara, Geffrey Okasanmi Ajayi salaye pe aarọ ana ni isẹlẹ naa sẹlẹ, nigba ti awọn agbebọn kọlu awọn osere tiata kan, eyi ti awọn kan fi to ileesẹ ọlọpa leti.
Sibekai, láti inú ìdílé Huṣati, ati Ilai, láti inú ìdílé Aho; 
Nítorí lọ́dọ̀ rẹ̀ ni ohun gbogbo wà, láti ọwọ́ rẹ̀ ni ohun gbogbo ti ń wá, nítorí tirẹ̀ sì ni ohun gbogbo ṣe wà.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Shiite: Ẹ̀mí àti ara wa kọ ohun tí ìjọba ń ṣe sìwa láti 2015 Lọjọ Iṣẹgun, ọgbẹni Ilesanmi yoo fi iwe ẹhonu sọwọ si ileeṣẹ ijọba eleyi ti awọn eeyan fọwọsi lati le daabo bo awọn to n ṣe iwaasu nita gbangba.
Ẹ kò lè sin Ọlọrun, kí ẹ tún máa bọ owó.
Jọ̀wọ́ mo bẹ̀ ọ́, ìrẹ̀lẹ̀ ṣe pàtàkì nínú ìwà, má ṣe fi ara rẹ wé àwọn ẹlòmíràn, ìgbà tí wọ́n bá lo ẹ̀bún tí Olódùmarè fún wọn tán, wọn a gbé ìgbéraga wọ̀ bí ẹ̀wù wọn a wí pé àwọn nìkan ṣoṣo ní ń bẹ.
Bakan naa lo sọ pe akọnimọọgba Unai Emery ko tii mu iyatọ kankan to ba Arsenal lati igba to ti gori aleefa lẹyin ti Arsene Wenger kuro.
Lati ọjọ keji, iwe idibo meji ni wọn yoo mu dani owurọ, ati meji ni ọsan.
Meji ninu ọmọ rẹ, Oloye Yomi Akintola and Dokita Abimbola Akintola naa jẹ minisita keji fun eto inawo.
Ajọ naa loju opo Twitter rẹ sọ pe atunto ti ọga ọlọpaa kede gbọdọ tumọ si fifi opin si ifiyajẹni, fifini si ihamọ lọna aitọ, iwa ilọnilọwọgba, ati iṣekupani 'ti awọn oṣiṣẹ SARS ti hu jakejado orilẹede Naijiria fun ọpọlọpọ ọdun.
Mummy Calm Down di aṣojú ilésṣẹ́ ńlá kan l'Abuja Lootọ, Aisha Buhari lọ Dubai Iroyin to n ja rayin-rayin lori ayelujara ni wi pe iyawo aarẹ orilẹede Naijiria ti rinrinajo lọ si Dubai ni orilẹede United Arab Emirate fun idi pato ti a ko mọ.
Ninu awọn to ṣe ọrọ yi ni aaya bẹ silẹ o bẹ sare ni Oby Ezekwesili to jẹ oludije fun ẹgbẹ oselu ACPN.
" INTERACTIVE Tap or click to interact Moshood Olalekan Adeoti Action Democratic Party (ADP) < Padà lọ sí ọ̀dọ̀ Olùdíje Kíni ọjọ́ ìbí yin?
Òye mi ju ti àwọn àgbà lọ,nítorí pé mo gba ẹ̀kọ́ rẹ.
“Nítorí náà, ẹ̀yin ẹ má máa páyà kiri nítorí ohun tí ẹ óo jẹ.
 A n se awon atunse kan ki a le tele ilana ofin bi o ti ye ki ina esisi ma le jo wa leemeji ni.
Bó tilẹ̀ jẹ́ wípé BBC Yorùbá kò lè fìdí ọotọ mulẹ pe inaki mi owo náà, àmọ̀ awọn akọròyìn Freedom radio ní ìpínlẹ̀ Kano royìn lọ́jọ́bọ pé, ọkan nínú àwọn oṣìṣẹ́ ní ẹ̀ka akoso owó ló sàlàyé pé, ìnàkí ńla kan lo wọ inú ọfíísì àwọn láti gbé owó náà.
adẹ́tẹ̀ ni ọkunrin náà, kò mọ́; alufaa sì gbọdọ̀ pè é ní aláìmọ́.
Oríṣìíríṣìí ìkìlọ̀ ló ti bọ́ sí etí i wọn nípa ewu tí nbẹ nínú epo-rọ̀bì, ṣùgbọ́n ó dàbí ẹni pé bí ọ̀rọ̀ ọ̀hún ṣe ngba etí ọ̀tún wọlé ni ó ngba etí òsì jáde.
Ohun ta gbo ni pe awọn obi rẹ ati awọn ẹgbọn rẹ okunrin ni wọn pa ninu ile wọn nirole ọjọ naa.
Obaseki kéde òfin kónílé-ó-gbélé ní Edo torí ète jíjá ọgbà ẹ̀wọ̀n Ijọba ipinlẹ Edo ti kede ofin konile-o-gbele oni wakati merinlelogun, bẹrẹ lati irọlẹ oni lọ.
Oríṣun àwòrán, Instagram/ Ajimobi Aseyọri ati akude Ajimobi bii gomina ipinlẹ Oyo: Lasiko ti Abiola Ajimobi wa lori aleefa bii gomina nipinlẹ Oyo fun odindi ọdun mẹjọ gbako, ọpọ aseyọri ati iṣẹ ribiribi lo ṣe lori aleefa, Eyi je ki aimọye iṣẹlẹ Kosẹlẹri ni rere si waye nipinlẹ Oyo ni saa isejọba ọlọdun mẹjọ rẹ.
Ẹ̀yin ará, ẹ má ṣe bá ara yín wí, kí á má baà da yín lẹ́jọ́.
Agbẹnusọ fun ileeṣẹ ọlọpaa naa ni Danjuma Uba kan lo fi ipa ba oun lopọ ni Oṣu Kini, ọdun yii to si ti salọ.
Ní ọdún náà gan-an ní oṣù keje, ni Hananaya wolii kú.
O ti to bi ọdun kan bayii ti a ti gbọ pe Saheed kọrin ba Pasuma tabi Pasuma kọrin ba Saheed.
Saudi fẹ́ gbẹ̀mí 23 ọmọ Nàìjíríà tó gbé òògùn olóró Irọ́ ló pa, a kò mọ̀ ọ́ rí tàbí fún ọ ní ₦13m - APC tako afurasí ajínigbé Àlàyé rèé lórí bí wọ́n ṣe mú mi lẹ́rú ní 1837 - Ajayi Crowther Ọpọ lo ti n ri igbesẹ ọjọ Aje naa gẹgẹ bii eyi ti o n ṣe afihan pe, alaafia ti n pada si aarin igbimọ lọbalọba ilu Ibadan.
O bẹ̀rẹ̀ èré ori itage ni ọdun 1971 ṣùgbọ́n nínú agbélewò Omolasan ni ìràwọ rẹ ti tàn sita, bakna naa lo tun tàn sii lẹ́yin to fara han ninu eré Iru Esin eyi ti Olaiya Igwe gbé jáde lọ́dun 1997.
Nigba to n fesi si ọrọ yii, Pasitọ Ajifowowe sọ pe iwe mímọ ní kí a maa bọwọ fun awọn alaṣẹ.
Ó fi kun pé, wọ́n ti ri ibi ti afẹ́fẹ́ gáásì ti n jáde wan si ti dii pa, sùgbọ́n ìwádìí àwọn ǹkan míran to báàjẹ́ níbẹ̀.
Ìpínlẹ̀ Eko ní èèyàn 136 nínú èèyàn 152 lápapọ̀ tó lùgbàdì àrùn Coronavirus ní Nàìjíríà Ọlọ́pàá fìyà jẹ mí lọ́dún 2014, mò wà lẹ́yìn àwọn ọ̀dọ́ lórí ìwọde EndSARS- Fayemi Awọn ọlọ́pàá gbòde kan ní Ajah, ọwọ́ tẹ àwọn afurasi tó ń jalè Iléeṣẹ́ ológun ní ó bàwọn lọ́kàn jẹ́ bí Sanwo-Olu ṣe ni kìí se òun ló pe sójà si Lekki O tẹsiwaju pe ọna ti awọn ọmọ Naijiria le fi sọ fun banki naa pe ohun to ṣe ko dara to ni ki wọn ko owo wọn kuro nibẹ.
Wọn ni bi wọn ko ba dẹkun iru iwa bayii, awọn oludibo le maa jade sita lasiko ibo nitori ibẹru bojo.
Wọn ìbá sì ṣú ìyá mi lópó fún ọ̀kan nínú àwọn ará ilé bàbá mi.
OLUWA kìí wo nǹkan bí eniyan ti ń wò ó, eniyan a máa wo ojú, ṣugbọn OLUWA a máa wo ọkàn.
Koda, ko to o di pe wọn gba a wọle si Fasiti ilu Benin.
BBC Yoruba bá díẹ̀ lara àwọn to n lo oogun oloro nibudokọ 'Under Bridge' ni Ojuẹlẹgba nipinlẹ Eko sọrọ lori àṣilo oogun oloro.
Ibi kékeré ni nǹkan ti í lọ, ẹni tí a rán ní iṣẹ́ tí ó ń ṣiré lójú ọ̀nà, aláfojúdi ẹ̀dá ni; ẹni tí a fún ní nǹkan kékeré tí kò dúpẹ́ lọ́wọ́ ẹni, aláìmoore ni, nítorí náà mo ń fẹ́ẹ́ lọ, ojú ń kán mi, bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé ọ̀rọ̀ rẹ jọ bí àbẹ̀tẹ́lẹ̀, tí ìwọ sì ṣe ìlérí àti fi oko ìla hàn mí, síbẹ̀ n kò ní i lè dúró fún ọ ní ímọ̀ràn kan.
Abajade iwadii yii ko ya ni lẹnu pe awọn obi ati alagbatọ ko fẹ ki awọn ọmọ wọn lo ẹrọ ibanisọrọ mọ lasiko ti wọn ba wa nile iwe.
Niwọn igba to si jẹ pe alatise ni yoo mọ atise ara rẹ, eyi lo mu ki ẹlẹwa Ṣapọn da ọgbọn ti awọn onibara rẹ ko fi ni gba igba lori rẹ, nipa rira ọja rẹ lawin.
Ẹ ṣe akiyesi bóyá ilẹ̀ náà dára tabi kò dára, ati pé bóyá àwọn eniyan ibẹ̀ ń gbé inú àgọ́ ninu ìlú tí ó tẹ́jú tabi ìlú olódi ni ìlú wọn.
Awọn eeyan naa sọ pe, kii ṣe lasiko ti iwọde n lọ kaakiri Naijiria, pe ki ijọba wọgile ẹka ileeṣẹ ọlọpaa, SARS, lo yẹ ki Toyin o polowo sinima naa.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ọbanikoro: Àjọṣepọ̀ tó wà láàárín èmi àti Fayose kò ní jẹ́ ki ń tú àṣírí 4 Èrèlè 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 5 Èrèlè 2019 Àkọlé àwòrán, Ọbanikoro ni inu oun ko dun lori igbẹjọ naa Igbẹjọ gomina ana ni ipinlẹ Ekiti, Ayọdele Fayoṣe lori ẹsun ṣiṣe owo to le ni biliọnu meje naira (N7.
Alakinyẹle ti ilu Akinyẹle, Ọba James Ọdẹdiran ti pariwo sita pe bi afurasi ti wọn mu fun iṣẹlẹ iṣekupani naa ṣe sa mọ ọlọpaa lọwọ fihan pe ẹmi awọn olugbe agbegbe naa ko de.
Abilekọ Madikizela-Mandela polongo fun idasilẹ rẹ lai kaarẹ, o si di alatako fun iṣejọba awọn alawọ funfun.
Dubai: Wo nkan tó yẹ kí o mọ̀ nípa ìwé ìrìnnà ọlọ́dún márùn ún tí UAE n fún arìnrìnàjò
1999,ni o yi ero rẹ pada lati tun  dije
Ẹ̀wọ̀n ni wàá gbẹ̀yìn sí, kò sí bóo ṣe dọ́gbọ́n tó - Seyi Makinde wa ègúná ọ̀rọ̀ lé Fayose Aawọ oṣelu to n ṣẹlẹ laarin awọn ọmọ ẹgbẹ oṣelu Peoples Democratic Party ni iha Guusu-Iwọ Oorun Naijiria eyi to jẹ awọn ilu Yoruba da bii pe o tun ti n gbona bii ogun bayii gẹgẹ bi itahunsira ni gbangba ṣe bẹ silẹ laarin gomina Oyo, Seyi Makinde ati gomina ipinlẹ Ekiti tẹlẹ, Ayodele Fayose.
Agbẹnusọ fun gomina Zailani Bappah lo fidi ọrọ̀ yii mulẹ fun BBC.
Angẹli OLUWA náà bá rá mọ́ ọn lójú.
lehin ogun àgbáyé alakọkọ ogbe ni ilu poznani lati ọdún 1931 títí di ọdún 1936 orin , ogun kẹkẹ jake jado ilu aláẁọ dúdú .
 O tun ni idagbasoke nipa ise agbe  ti won tun fẹ se ,yoo  je ki ounje tun  tubo po si lorile ede Naijiria Adari tootoGomina Udom Emmanuel ti ipinle Akwa Ibom wa ro awon omo leyin kirisiteni lati tubo sunmo Olorun nipa adura won, ki won si tun maa so otito oro nigba gbogbo ati  pe ki won si tun maa wa idagbsoke esin igbagbo lorile ede Naijiria.
Kò sì bá a lòpọ̀ rárá títí ó fi bímọ.
O tun so pe  “Awọn  eniyan mi ko ni kọja aaye wọn , nitori naa ki awọn  eniyan jade wa dibo.
Òòró ilé tí ó wà ní ìhà àríwá náà jẹ́ ọgọrun-un (100) igbọnwọ (mita 50), ìbú rẹ̀ sì jẹ́ aadọta igbọnwọ (mita 25).
Àwọn ọmọ àwọn iranṣẹ rẹ̀ yóo jogún rẹ̀;àwọn tí ó fẹ́ràn orúkọ rẹ̀ yóo sì máa gbé inú rẹ̀.
Ó jẹ́ akọni jagunjagun, ṣugbọn adẹ́tẹ̀ ni.
Koda ninu awọn to ṣeto isinku, to si gbalejo Gomina Eko, Babajide Sanwoolu nile aṣofin agba, Adebayo Osinowo ta mọ si Pepperito, lasiko to jade laye ni Braimoh wa.
Ẹ̀rù kò ba odò Joshua, ojora kò mu, kó tó ríyà he lọ́wọ́ Ruiz Ko si otitọ kankan ninu ọrọ to n tan kalẹ lori ayelujara pe, Abẹṣẹkuojo, Anthony Joshua ni ipaya ọkan tawọn oloyinbo n pe ni ''panic attack'', ki o to kọ lẹta si iya lọwọ Andy Ruiz lopin osẹ to ja.
Koda, o tun ni iye osisẹ́ ti koowa ba ni ati iye owo to ba n san fun wọn lasiko Covid 19 yii ni ki wọn san owo ori wọn le lori lai jẹ gbese.
Ile-ise iroyin L’Express so lose to koja pe, Fakin na egbelemukun owo rupees fun ara re, nipa lilo kaadi Platinum ti ajo kan ti kii se ti ijoba, ti a mo si Planet Earth Institute (PEI) fun-un.
Ọdọmọkunrin yìí sì kọ orúkọ wọn sílẹ̀, wọ́n jẹ́ ọkunrin mẹtadinlọgọrin.
Adari agba NAFDAC, Ọjọgbọn Mojisola Adeyeye ni kii ṣe ohun to bojumu ki awọn oniṣowo maa fi Sniper ati DDVP ṣetọju awọn ounjẹ bii agbado, ẹwa ati ẹja gbigbẹ.
Koko nnkan ti o ṣe okunfa ede aiyede lasiko abẹwo naa ko han si ẹnikẹni, eyii lo si mu ibẹrubojo de ba awọn olugbe adugbo naa, paapaa julo lasiko ti wọn ṣe akiyesi wi pe wọn fi ipa gbe 'Ajanaku' lọ si ile itura 'Auxiliary' to n bẹ ni agbegbe Alakia nilu Ibadan, gẹgẹ bi awọn aladugbo ṣe sọ.
Àwọn tí wọn ń ṣòwò aguntan, tí wọn ń wò mí, mọ̀ pé èmi OLUWA ni mo ṣe ohun tí ó ń ṣẹlẹ̀.
Ohun tí o kò mọ̀ nípa Ebila One Million Boys"" àti Ekugbemi, olórí ẹgbẹ́ òkùnkùn méjì tó da ìlú Ibadan rú Ṣaaju ni Akeredolu ti kede loju opo Twitter rẹ kan naa pe ọkan gboogi lara awọn to n ba du ipo gomina ninu ẹgbẹ oṣẹlu naa, Olusegun Abraham ti yọwọ rẹ kuro lawo idibo ọhun."
eto ilana ti o ba fẹ lo wa  ni ibamu pelu
Si eyi, agbẹjọro alatako ni ẹtọ eeyan ṣee bo mọlẹ to ba jẹ pe nitori ifẹ ilu ni.
Èsì ìdánwò òhun tí a ṣé síwájú là n bá fínra báyìí ní Nàìjíríà- Yemi Shodimu Ninu awọn ohun ta ri ka loju opo Twitter wọn, ileeṣẹ ilera ko sọ pato boya awọn ti gba abẹrẹ ajẹsara ti wọn n pe orukọ rẹ nui Sputnik lọwọ Russia.
"Kìí ṣe ebi, ìyà tàbí ìṣẹ́ ló mú kí wọ́n yabo àwọn ilé ìkẹ́rùsí - Femi Adeshina Àkùkọ dojú ìjà kọ ọlọ́pàá, ikú ló já sí fún agbófinró Ìjọba Eko kọ orúkọ sí ""Palliatives"" tiwọn lára o, mo ní ẹrù tèmi f'ọjọ́ ìbí mi tí wọ́n jí - Họ́nọ́rébù Agunbiade Dokita Tunde Adeife jẹ ko di mimọ pe o le niṣe pẹlu ajogunba idile nigba miran."
Enọku wà ní ìrẹ́pọ̀ pẹlu Ọlọrun, nígbà tí ó yá, wọn kò rí i mọ́ nítorí pé Ọlọrun mú un lọ.
Oríṣun àwòrán, @mko_abiola Bi onirese MKO Abiọla ko ba wa fin igba mọ, eyi to ti fin ko lee parun laelae, idi si ree to fi yẹ ka mọ nkan kan, abi meji nipa igbe aye oloore yii, gẹgẹ ba ṣe ka loju opo itakun agbaye Wikipedia, ẹni to fi ẹmi rẹ lelẹ fun ifẹsẹmulẹ ijọba alagbada ati idagbasoke orilẹede Naijiria.
bẹrẹ iṣẹ kikọ mọṣalaṣi lati le ni imọlara pe awa naa wa si Ile Igbimọ Aṣofin yii.
Atiku FinCEN Files: Atiku ní iró ni pé orílẹ̀èdè Amẹrika ń ṣọ́ wọlé-wọ̀de òun àti ìdílé rẹ̀
Ọga àwọn ologun náà bu ẹnu àtẹ lu gbogbo àwọn ẹri tó wà nígboro pé ìrọ́ lásán ni wọ́n.
Gende agbebọn yabo ileesẹ ọlọpaa nibadan, ẹmi ọlọpaa kan bọ Oríṣun àwòrán, Others Awọn gende agbebọn kan ti ya bo agọ ọlọpaa to wa ni agbegbe Ikolaba nilu Ibadan nirọlẹ ọjọ Ẹti, ti wọn si mu ẹmi Kọburu ọlọpaa kan lọ.
Nípasẹ̀ mi ni àwọn ọba fi ń ṣe ìjọba,tí àwọn alákòóso sì ń pàṣẹ òdodo.
Mo şe ìşe tani á múmi, mo sì şe é ní àşekún.
Ó sàn kí eniyan pàdé ẹranko beari tí a kó lọ́mọ,ju kí ó pàdé òmùgọ̀ ninu agọ̀ rẹ̀ lọ.
" Ki oto dagbere faye, Alhaji Oyerinde Fẹlẹ ni alaga ẹgbẹ awakọero NURTW lẹkun iwọ oorun gusu orilẹede Naijiria.
Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí New Covid-19 Strain UK : Atiku ní kí ìjọba dì ìrìnnà ọkọ̀ òfurufú láàrin ilẹ̀ Gẹ̀ẹ́sì sí Nàìjíríà kú nítorí Covid-1921 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 1:15 Fídíò, Fuji Music: Kollington Ayinla sọ ẹni tó dá orin Fuji sílẹ̀ gan an ní Nàiìjíríà, Duration 1,1516 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Ede Poly Rector suspension: Wọ́n ní kí ọ̀gá àgbà Pólì Ede lọ rọ́kún ńlé lórí ẹ̀sùn pé 'ó kan bẹ́ẹ̀dì sí ọ́fíìsì'15 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Sex party: Ìjọba gbé ilé ijó oníhòhò tì pa lórí ẹ̀sùn títàpá sí ìlànà àti dẹ́kun coronavirus15 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 3:16 Fídíò, Ọgbà ẹ̀wọ̀n ni wọ́n ti já ìbálé Esra lábẹ́ àwáwí àyẹ̀wò wúndíá, Duration 3,1613 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Ganduje: Gòmìna Ganduje ni yíyọ Sanusi nípò Emir Kano wà fún àtúnṣe ètò oyè jíjẹ ní ìlú Kano16 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí kan sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
Bí eniyan burúkú bá sì yipada kúrò ninu ibi tí ó ń ṣe, tí ó bẹ̀rẹ̀ sí ṣe ohun tí ó dára tí ó sì tọ́, yóo yè nítorí rere tí ó ṣe.
Ṣugbọn Mose dá Ọlọrun lóhùn pé, “Ta ni mo jẹ́, tí n óo fi wá tọ Farao lọ pé mo fẹ́ kó àwọn ọmọ Israẹli kúrò ní ilẹ̀ Ijipti?
Sáájú àsìkò yìí ni ààrẹ Muhammadu Buhari ti buwọ́lu gbígba ènìyàn ẹẹ́dẹ́gbẹ̀rin o lé mẹ́rìnléláàdọ́rin ènìyàn lọ́bẹ́ ètò náà.
Ile ẹjọ Myanmar ran akoroyin Reuters méjì lẹwọn labẹ ofin mẹnumọ
 Valentine tun salaye pe ọpọ dukia lo ti sofo nitori isẹlẹ ina ọhun, ti ileẹkọ, ilegba ati awọn ibudo ijọsin loniran nran si dawo lulẹ tabi padanu orule ile wọn."
Nana Akufo-Addo lati ẹgbẹ oṣelu NPP ati John Mahama lati ẹgbẹ oṣelu NDC ni wọn n sọ nipa wọn ju, eyi lo si fa nkan mẹrin to ya eto idibo yii sọtọ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Coronavirus in Nigeria: Esì àyẹwò ọmọ ati ìyáwọ ọmọ Atiku ti jáde 23 Ẹrẹ̀nà 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 24 Ẹrẹ̀nà 2020 Oríṣun àwòrán, Others Àkọlé àwòrán, Mò n lọ fun ìgbélé nítori mo ṣe alábapàdé ọmọ Atiku- Gomina Bauchi Ninu atẹjade ti ileeṣẹ ijọba ipinlẹ Bauchi fi sita ni a ti rii pe oun nikan ni aarun naa mu laarin awọn mẹfa ti wọn jọ kọwọrin.
Èyí ni iṣẹ́ tí Ọlọrun rán Sefanaya, ọmọ Kuṣi, ọmọ Gedalaya, ọmọ Amaraya, ọmọ Hesekaya ní àkókò ìjọba Josaya, ọmọ Amoni, ọba Juda.
Wí fún wọn báyìí pé, ‘Ẹ gbọ́ ohun tí OLUWA Ọlọrun wí; nítorí pé ẹ̀ ń yọ̀ nígbà tí wọ́n sọ ibi mímọ́ mi di aláìmọ́, ati pé ẹ̀ ń yọ ilẹ̀ Israẹli, nígbà tí wọ́n sọ ọ́ di ahoro, ẹ sì ń yọ ilẹ̀ Juda, nígbà tí wọ́n kó o lọ sí ìgbèkùn; 
Ọkan lara awọn odu asọrọdorin lorilẹede Naijiria, Ruggedman pẹlu sọ si ọrọ naa ninu eyi to ti ni ko dara ki awọn olorin, gẹgẹ bi awokọṣe lawujọ o maa gbe lẹyin awọn oni yahooyahoo.
Pẹlu àṣẹ ọba, àwọn iranṣẹ gun àwọn ẹṣin ọba, wọ́n sì yára lọ.
Láti ìgbà náà, ilé obinrin yìí ni Eliṣa ti máa ń jẹun ní Ṣunemu.
Nígbà tí o rí i inú rẹ dùn.
Bayii ni ileeṣẹ ọmọ-ogun ori ilẹ ṣe kilọ fawọn to n ṣe iwọde #EndSARS kaakiri Naijiria.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ṣina Peters bú sẹ́kún lórí ikú Ras Kimono, pé ẹni rere lọ 10 Òkùdu 2018 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 11 Òkùdu 2018 Oríṣun àwòrán, OFFICIALRASKIMONO/INSTAGRAM Àkọlé àwòrán, Ẹni ọgọ́ta ọdún ni olóògbé Ras Kimono Gbajúgbajà olórin Reggae ni, Ras Kimono, tí órúkọ rẹ̀ gangan ń jẹ́ Ekeleke Elumelu ti papòdà ní ẹni ọgọ́ta ọdun Ààrẹ ẹgbẹ́ àwọn olórin ti orílẹ̀-èdè Naijiria (PMAN), Pretty Okafor, ní ikú nàá jẹ́ ìbànújẹ́ ńlá fún àwọn àwùjọ olórin.
Amọ, ija waye laarin wọn pẹlu bi aaṛẹ Trump ṣe ni China lo n pin arun Coronavirus kaakiri lagbaye, ati bi China ṣe n gba ọrọ aje wọ Amẹrika lọwọ.
Minisita eto irinna to sọrọ yii nigba to lọ ṣe ayẹwo ibi iṣẹ de duro ni fasiti naa ṣalaye pe ọfẹ ni ileeṣẹ onimọ ẹrọ (Technics Engineering Architectural Marketing (TEAM) naa yoo ṣiṣẹ ni fasiti ọhun.
Ori oke yii si ni wọn ti sọ pe igbin tobi ju ijapa lọ, aarin gbungbun Igbo Olodumare si ni Oke langbodo wa.
Ẹnikẹ́ni tí ó bá jókòó lórí ohunkohun tí ẹni tí nǹkan bá dà lára rẹ̀ bá fi jókòó, kí ó fọ aṣọ rẹ̀, kí ó sì wẹ̀; yóo jẹ́ aláìmọ́ títí di ìrọ̀lẹ́.
Oluwa yàn mí láti jẹ́ kí àwọn àyànfẹ́ Ọlọrun lè ní igbagbọ ati ìmọ̀ òtítọ́ ti ẹ̀sìn, 
UEFA: Real Madrid yóò kojú Bayern, Arsenal àti Athletico yóò wáákò
Bàbá mi mura, ó ń lọ, ó ń kọrin, ó ń súfèé, ó si ń rìn bí jagunjagun.
N óo sọ ọ́ di orílẹ̀-èdè ńlá, n óo bukun ọ, n óo sì sọ orúkọ rẹ di ńlá, tóbẹ́ẹ̀ tí o óo jẹ́ ibukun fún àwọn eniyan.
Bakan náà lo ni, àwọn yóò dá eyi ti wọ́n yọ lọ́jọ́ Sátidé àti ọjọ́ àìkú pada fun àwọn oníbara ti ọ̀rọ̀ náà kan.
Eliṣa jókòó ninu ilé rẹ̀ pẹlu àwọn alàgbà.
ifesewonse akoko 7′0 – 1  Hakim Ziyech18′0 – 2  David Neres26′  Noussair Mazraoui 30′Daniel Carvajal  62′0 – 3The night Dušan Tadić made the world sit up and take notice.
A fi oṣu Kẹwa ọdun yi ṣe iwadi awọn iroyin to sọrọ nipa iku awọn obinrin lọjọ kini oṣu naa.
Àwọn tafàtafà bẹ̀rẹ̀ sí ta ọfà sí wa láti orí ògiri wọn, wọ́n sì pa ninu àwọn ọ̀gágun rẹ, wọ́n pa Uraya náà pẹlu.
Ninu atejade kan, ajo EU ohun so pe, o je iroyin ayo lati gbo pe, won tit un pupo awon akekoo naa sile.
mulẹ ninu ọrọ rẹ kan pe ‘orilẹ-ede Naijiria gan-an ni ilẹ Afirika, bi
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fọ́nrán ohùn, PDP: A fẹ́ gba odindin Imo padà ni lọdún tó m bọ Ogbeni Deji Doherty tọ jẹ́ ọmọ ìgbìmọ̀ amúṣẹ́ṣe ẹkùn ìwọ̀ oòrùn Naijiria ṣalaye ìpinnu ẹgbẹ́ PDP pé ìdìbò àpapọ̀ ló jẹ PDP lógún bayìí, kìí ṣe tìjoba ìbílẹ̀.
Ó pe àwọn eniyan Ọlọrun ati àwọn opó, ó bá fa Dọkasi lé wọn lọ́wọ́ láàyè.
2019 Guber election: Adelabu pe Makinde, INEC l'ẹ́jọ́
Èyí jẹ́ kí ara mi fúyẹ́ díẹ̀.
Pẹlu eyi, o si tun boju wo ọ̀na tiṣẹ rẹ le fi yatọ si awọn mii to n pa adiyẹ ta bii tirẹ.
Wọ́n pa àwọn ìlú wọn run, gbogbo ilẹ̀ oko tí ó dára ni wọ́n da òkúta sí títí tí gbogbo wọn fi kún.
 Àwọn ìní oníṣeẹ ̀ dá kárbọ ̀ nù yàtọ ̀ gẹ ́ gẹ ́ bí irú álótrópù bá ṣe rí .
"Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ebila of Ibadan: Ikọ̀ Operation Burst"" ní àwọn ló pa Ebila, olórí àwọn ""One million boys"" n'Ibadan 12 Agẹmo 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 14 Agẹmo 2020 Oríṣun àwòrán, others Ọga agba ikọ agboguntiwa ọdaran ni ipinlẹ Ọyọ eyi taa mọ si Operation Burst, Kọnẹẹli Ọladipọ Ajibọla ti ṣalaye pe ikọ naa lo ṣekupa olori awọn ọmọ ẹgbẹ okunkun One million boys ni ipinlẹ Ọyọ, Abiọla Ebila lọjọ Aiku."
"Gẹgẹ bo ṣe sọ, o ni ""ko si owo oṣu ti a gba ri lẹnu iṣẹ yii ayafi ti ba kọkọ pariwo."
" Òun ni ó dá ilé-èkó tí ó n jé "" school of individual psychology ' sílè ."
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Fífí ọmọdé ṣ'ẹrú Ẹwẹ, alabojuto ẹka to n gbogun ti fifini ṣ'owo ẹru ni ajọ to n ri si iwọle wọde lorilẹede Naijiria, Foluso Akintola ni orilẹede Naijiria nikan n ṣe iṣẹ gẹgẹ bii orisun, ọna ati ebute abode ifini ṣ'owo ẹru.
Oyo, Ogbeni Ola Ajayi dupe lowo oga ọlọpaa fun abewo re, o si mu da a loju pe
Bí Hamani tí ń wọlé ni ọba bi í pé, “Kí ló yẹ kí á ṣe fún ẹni tí inú ọba dùn sí?
niluu Uyo ni ipinle Akwa Ibom ni Gusu orile ede Naijiria.
Àwọn tí ń gbé ìpẹ̀kun ayé sì ń bẹ̀rùnítorí àwọn iṣẹ́ ìyanu rẹ;o mú kí àwọn eniyan, láti ìlà oòrùn títí dé ìwọ̀ rẹ̀, hó ìhó ayọ̀.
Bí ẹ̀yi náà kò bá tàn káàkiri, tí irun ibẹ̀ kò sì pọ́n, tí ẹ̀yi náà kò sì jìn ju awọ ara rẹ̀ lọ, 
Mo fẹ́ kí ẹ mọ̀ dájúdájú pé àwọn eniyan ìran yìí kò ní tíì kú tán títí gbogbo nǹkan wọnyi yóo fi ṣẹlẹ̀.
Bí ẹnikẹ́ni bá gbọ́ ọ̀rọ̀ mi, tí kò bá pa á mọ́, èmi kò ní dá a lẹ́jọ́, nítorí n kò wá sí ayé láti ṣe ìdájọ́, ṣugbọn mo wá láti gba aráyé là.
Kí ló dé tí ẹ̀yin gbé ara yín ga ju gbogbo àwọn eniyan OLUWA lọ?
Agba ọjẹ oloselu ni Akintọla, to si tun jẹ agbẹjọro to moye, bakan naa lo tun jẹ ẹni ti yoo sọrọ, ti yoo dabi ki a pọn ni ete la, tori ọrọ da saka lẹnu rẹ, boya ni ede Yoruba ni, abi Gẹẹsi.
Koda, ipo kẹrin lo ṣe ninu idibo gomina naa nipinlẹ Ogun.
Nítorí kí á tilẹ̀ wí pé a ti mọ ara wa tẹ́lẹ̀ rí ni, o kò lè gbà mí tọwọ́tẹsẹ̀ jù bi o ti gbà mi yìí lọ.
Laye ode oni, awọn asa ati ise aye atijọ naa ni ofin ode oni tako, ti a ko si fi bẹẹ naani wọn mọ.
"Oríṣun àwòrán, Facebook/Femi Adesina ""Aarẹ Buhari, nigba to jẹ olori Naijiria labẹ ijọba ologun, da ọkan awọn eeyan ẹkun naa laamu, to si tun kẹyin si ẹkun yii lasiko to jẹ alaga igbimọ apo asunwọn ẹdawo epo rọbi, PTF lasiko ijọba Sani Abacha."
Apákan wọn ni o óo rí, o kò ní rí gbogbo wọn, níbẹ̀ ni o óo ti bá mi ṣépè lé wọn.
Ninu ọrọ rẹ, awọn adari ni iye wọn yoo di ẹni ana.
Ninu ìfẹ́ rẹ tí kì í yẹ̀, pa àwọn ọ̀tá mi,kí o sì pa gbogbo àwọn tí ń ṣe inúnibíni mi run,nítorí pé iranṣẹ rẹ ni mí.
Bẹ́ẹ̀ ni Abramu ṣe jáde kúrò ní Ijipti, ó pada lọ sí Nẹgẹbu pẹlu aya rẹ̀, ati Lọti ati ohun gbogbo tí ó ní.
Amọ, o sọ pe kii ṣe ọta gidi lo wa ninu ibọn tawọn sọja yin soke ni Lekki lati tu awọn oluwọde EndSARS ka.
 O ro won ki won tesiwaju lati tubo fi awon eeyan saaju ninu ipinnu won gbogbo.
Erin tí ó jẹ́ ọkùnrin gba ilé kan ó ń sánwó o ṣooṣù lé e lórí ibẹ̀ ni àwọn méjéèjì sì ti máa ń pàdé lọ́jọ́ mẹ́sàn-án mẹ́sàn-án ọjọ́ ọjà.
Algeria naa ti ṣokọ fun Naijiria lẹẹmeje ninu ifẹsẹwọnsẹ wọn latẹyin wa.
Bakan naa lọgbẹni Ọlawale jẹ ko di mimọ pe ile ti oun fi ọwọ, owo ati oogun oun kọ wa lara awọn ile to jona ninu ijamba ina naa.
Koda, lati inu ere lo si ti ni ifẹ oun, odindi ọdun mẹta si lo fi n wa nọmba aago ipe oun.
 Àjọ náà tún ṣèrànwọ ́ nípa sísan owó fún àwọn ihun ìṣura ti ó jẹ mọ ́ ilẹ ̀ gíríkì , louvre ní ilẹ ̀ paris àti ilé ìṣura fitzwilliam tí ó wà ní ilé ẹ ̀ kọ ́ àgbà cambridge university , àti àwọn mìíràn gẹ ́ gẹ ́ bí ìjábọ ̀ ọdọdún wọn ti wí .
13 Bí ìwọ yíò bá ṣe rere, Bẹ́ẹ̀ni, tí ìwọ yíò sì jẹ́ olõtọ́ títí dé òpin, a ó gbà ọ́ là ní ìjọba Ọlọ́run, èyí tí ó tóbi jùlọ nínú gbogbo awọn ẹ̀bùn Ọlọ́run; nítorí kò sí ẹ̀bùn kan tí ó tóbi ju ẹ̀bun ìgbàlà lọ.
Ti a ko gbagbe pe, lojo ketadinlogun osu keta, ajo UNAIDS yan Buhari gege bi asoju pataki lori ipolongo dideku atagba aarun HIV latara iya si omo inu re, ati lati polongo sise itoju awon omode ti won ni aarun kogbogun HIV naa lorile-ede Naijiria.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, France pegede de ipele aṣekagba World Cup 2018 Àwọn orilẹ-ede ilẹ Adulawọ maraarun ni wọn ti já ti onikaluku ti pada sile.
Bakan naa, Oludije si ipo gomina labẹ ẹgbẹ oṣelu ADP, Moshood Adeoti ninu ọrọ tirẹ fikun wi pe eto ẹkọ se pataki o ṣe koko si ìjọba òun, ati pe ọna abayọ si isoro eto ẹkọ ni ipinlẹ Osun ni gbigba awọn olukọ to dangajia lati bu iyi kun eto ẹkọ lọna to yẹ.
Èsi ibò yi ya gbogbo àgbáyé lẹ́nu nitori àwọn ọ̀rọ̀ ti Donald Trump (Olóri ẹgbẹ́ GOP)  ti sọ siwájú nigbati ti ó polongo lati dé ipò.
Ṣugbọn di bi a ṣe n sọrọ yii, wọn ko tii mọ ipo tabi ibi ti Dayo Adewole to fi mọ awọn to ji i gbe wa.
Ó sọ fún wọn pé, “Lódodo ẹ óo mu ninu ife mi, ṣugbọn láti jókòó ní ọwọ́ ọ̀tún mi ati ní ọwọ́ òsì mi kò sí ní ìkáwọ́ mi láti fi fún ẹnikẹ́ni, ipò wọnyi wà fún àwọn tí a ti pèsè rẹ̀ sílẹ̀ fún láti ọ̀dọ̀ Baba mi.
2 billion laarin ose keji odun si osu keta odun 2018 ti a wa yii,O salaye pe, owo to wa ni ipamo naa duro gbari ni ibere odun 2018 yii si bilionu mokandinlogoji o le $39.
AD,LP, fìdírẹmii lórí ẹ́jọ́ tí wọn fí takò iyansipo Sanwo Olu
- Madam Saje Owó ilé ìwé gbígbà ní ìpínlẹ̀ Ogun ti di ìtàn - Gómìnà Dokita yọ góòlù àti owó ṣílè nínú obìnrin kan Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Yollywood: Kò sí ẹni ti òbí mi kò lè sọ̀rọ̀ sí -Sisi Quadri Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Ni kete tawọn obi Aisha ri pe o ti di awati, ni baba rẹ fi isẹlẹ naa to ileesẹ ọlọpa leti, tawọn onitọun naa si bẹrẹ isẹ lọgan nibamu pẹlu asẹ ọga agba ọlọpa ni orilẹede yii.
Coronavirus lockdown updates in Nigeria: Adeboye ni ọpọ nǹkan ńlá ńlá ni yóò ṣẹlẹ̀ lẹ́yìn ìgbélé Coronavirus
Ó ní kí wọn nà án kí wọn fi wádìí ọ̀rọ̀ lẹ́nu rẹ̀, kí ó lè mọ ìdí tí àwọn eniyan ṣe ń pariwo lé e lórí bẹ́ẹ̀.
Òtítọ́ inú ni mo fi fẹ́ sọ̀rọ̀,ohun tí mo mọ̀ pé òdodo ni ni mo sì fẹ́ sọ.
Báyìí ni mo sọ sí ìyá mi, bí mo sì ti ń sọ̀rọ̀ wọn-ọnnì ni àwọn abàmì ẹ̀dá wọn-ọnnì bẹ̀rẹ̀ sí lọ ní ọ̀kọ̀ọ̀kan, nígbà tí mo sì wo ojú ìyá mi ó bẹ̀rẹ̀ sí sọkún, omi tí ó jáde lójú rẹ sì dà bí ìró ẹ̀jẹ̀ ńlá, ìyá mi ń sọkún ọmọ.
Gbogbo ọ̀nà ìríra tí àwọn ará Amori ń gbà bọ oriṣa ni Ahabu pàápàá ń gbà bọ oriṣa rẹ̀, bẹ́ẹ̀ ni lílé sì ni OLUWA lé àwọn ará Amori jáde kúrò ní ilẹ̀ Kenaani fún àwọn ọmọ Israẹli nígbà tí wọn ń bọ̀.
“Ṣugbọn mo sọ fun yín pé gbogbo ọ̀rọ̀ tí eniyan bá ń sọ láì ronú ni yóo dáhùn fún ní ọjọ́ ìdájọ́.
Bí ẹnikẹ́ni bá jáde kúrò ninu ilé rẹ lọ sí ààrin ìlú, ẹ̀jẹ̀ rẹ̀ yóo wà lórí ara rẹ̀, kò sì ní sí ẹ̀bi lọ́rùn wa.
Awọn igbimọ ti wọn yan lati Ile Igbimọ Asofin ipinlẹ naa n sewadii lori fidio ti akọrọyin kan fi lede to fi han pe gomina naa n gba riba.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Coronavirus: Ewu wo làwọn òṣìṣẹ́ elétò ìlèra ń kojú ní Nàìjíríà?
O ṣalaye pe kete ti ijamba ọhun ṣẹlẹ ni ọkunrin to ni alabahun naa gbe digba-digba lọ si ile iwosan kan niluu Argungu.
O ni owon gogo owo wewe yii n je ki nkan won sii ni lorile ede Naijiria lasiko yii pelu igbagbo pe Banki Naijiria ni ko te owo tuntun sita.
Amọṣa awọn ọmọlẹyin ijọ Shiite lorilẹ-ede Naijiria, IMN ni o ṣeeṣe ki o jẹ pe awọn eeyan kan ni ijọba aarẹ Buhari n fi orukọ aṣiwaju ẹsin Shiite naa, El-Zakyzaky gba owo si apo ara wọn.
Báwo ni ọwọ́n ṣe mú igún náà satimọlẹ ṣaaju iwadii?
Adájọ́ ní Seun Egbegbe ṣì lẹ́jọ́ láti jẹ́ lórí ẹ̀sùn gbájúẹ̀ Genesis Global: Ṣé lóòtọ́ ni pásítò ìjọ Celestial, Israel Oladele Ogundipe rẹ́wọ̀n hẹ?
án : Limpopo, Guateng, Free State, Northern Cape,
Níbẹ̀ bàbá mi bá kìnnìún jà ó fi àáké pa kìnnìún, bàbá mi bá ẹkùn jà ó fi kùmọ̀ pa ẹkùn, bàbá mi bá òjòlá jà ó fi pàṣán pa òjòlá, ọjọ́ méje ni òun si gbà ní àìjẹun.
"Ọwọ́jà coronavirus yóò ṣì wà pẹ̀lú àgbáyé fún ìgbà pípẹ́- Ngozi Okonjo-Iweala Ìjọba àpapọ̀, ẹ so ifilọlẹ ẹ̀rọ alatagba 5G rọ na - ilé asofin àgbà Wo àwọn to ti rí ìwòsàn lọ́wọ́ àrùn coronavirus àti ibi tí wọ́n ti wá káàkiri Nàìjíríà Mẹ́rin nínú àwọn mọ́kànlá tó ń bọ̀ láti Sokoto tí wón mú l'Oyo ló ní Coronavirus Oyedepo tún wà ń béèrè pé"" irú ilé ìwòsàn wo ló ń ṣe àṣeyọrí ìwòsàn bíi èyí táwọn ìjọ Ọlọ́run ńṣe?"
Idi ree ti BBC fi tiraka lati wa okodoro ọrọ nileesẹ aarẹ lati mọ ibi ti Mamman Daura wa, ati pe se lootọ ni o n se aisan.
Baba-baba rẹ ko kọja ọdun mẹsan lori oye ti wọn rọ ọ l'oye.
Paulu tún dúró fún ìgbà díẹ̀ sí i.
O si yi orúkọ ẹgbẹ rẹ to ti kọkọ da silẹ pada si Jama'at Ahl al-Sunna lil-Da'wah wal-Jihad (Boko Haram).
Ìdí tí a fi pa àwọn àgbẹ̀ onírẹ̀sì ní Borno, Boko Haram ṣàlàyé nínú fídíò tuntun 'Àwọn ọmọ 5 kọ́ ló sọnù, ọmọ 28 ló sálọ síléeṣẹ́ foyúngbowó nípinlẹ̀ Ogun' Ṣé ẹ rántí àkọ́lé àwọn ìwé àkàgbádùn yìí?
Ó fi ojúlówó wúrà ṣe ohun tí wọ́n fi ń tún òwú fìtílà ṣe ati àwọn àwo kòtò; àwọn àwo turari, ati àwọn àwo ìmúná.
Ninu ọrọ tirẹ, Aarẹ orilẹede Naijiria, Muhammadu Buhari ni idi ti oun fi gbe igbesẹ naa ni lati fi opin si iwa jẹgudujẹra ni ẹka mejeeji, ki idagbasoke ba a le ba ọrọ ajẹ ni Niajiria.
Jumoke Odetola: Ọ́pọ̀ òṣèré koro ojú sí àṣehàn lásán lẹ́yìn ikú akẹẹgbẹ́ wọn, Williams Aanuoluwapo, Kumbalee
Bakan naa lo ni wi pe ọjọ keje ati ikarundinlogun ọdun oro naa ni awọn yoo gbe oro naa.
ABBA Isah - Ọmọ ẹgbẹ́ 6.
 Ìtan wolof ti wà láti bí ẹgbẹ ̀ rún ọdún méjìlá tàbí métàlá sẹ ́ yìn .
Wo àfiwé owó oṣù Ọlọ́pàá Nàìjíríà pẹ̀lú akẹgbẹ́ wọn lókè òkun Wo àwọn Ṣọ́ọ̀ṣì Nàìjíríà àti l'Áfíríkà tó ń wólẹ̀ àdúrà kí Trump lè wọlé ìbò ààrẹ America Cristiano Ronaldo ti fara kásá àrùn Coronavirus Mo sì ń gba ìtọ́jú lọ́wọ́ lẹ́yìn tí Fury fẹ̀ṣẹ́ já iṣan ọwọ́ mi loṣù mẹ́jọ sẹ́yìn- Deontay Wilder Omi alayo kọn yii ni wọn gbe wọ isinmi aarin ifẹsẹwọnsẹ naa ki Liverpool to tun fi goolu kan sii nigba to di iṣẹju kejilelaadọrin lati ẹsẹ Mo Salah.
Bi eeyan gbe aṣia orilẹede Naijiria dani, ko daabo bo lọwọ ikọlu ologun Ahesọ ọrọ yii jade pe ṣọja ko lee yinbọn pa ẹnikẹni to ba n mu aṣia orilẹede Naijiria dani.
" Oríṣun àwòrán, IDRIS IBRAHIM Ṣugbọn lọjọ Abamẹta, ọjọ kọkandinlọgbọn, oṣu Keji, ọdun 2020, ni ọkunrin kan bu ẹnu atẹ lu awọn ọmọ ẹgbẹ Tijjaniya ti Yahaya jẹ ọkan lara wọn lori ikanni WhatsApp ọhun lẹyin ti Yahaya sọrọ abuku si Anọbi, o si tun ka ọrọ Yahaya silẹ lor tẹlifoonu rẹ.
Sìgá mímu ń di èèwọ̀ oògùn ìlera pípé lagbaye Kini Pásítọ̀ Kumuyi fi ṣẹ ọmọ Naijiria?
Wọn kò fọ èdè kankan, wọn kò sì sọ ọ̀rọ̀;bẹ́ẹ̀ ni a kò gbọ́ ohùn wọn;
Ọga agba ọlọpaa ni Naijiria Mohammed Adamu lo ṣalaye pe gbogbo ẹbi ọlọpaa to ba rogbodiyan iwọde EndSARS lọ nijọba yoo ṣeranwọ fun.
Gómìnà Oyetọla tìpínlẹ̀ Ọ̀ṣun leè fipò sílẹ̀ nítorí ìbúra Wo ǹkan mẹ́jọ tó yẹ kóo mọ̀ nípa Alex Badeh táwọn agbébọn pa Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Oríṣun àwòrán, Isho Pepper Junior Olusola ni abigbẹyin ninu ọmọ mẹrin ti awọn obi rẹ bi, abule Olokuta, ni ẹba Alahọ to wa nijọba ibilẹ Oluyole nilu Ibadan si lo ti lo igba kekere rẹ, ibẹ si lo ti lọ sile ẹkọ alakọbẹrẹ Christ School, Olokuta.
Ẹ kò ní máa gbé e lé èjìká kiri mọ́.
Hataki pada lọ ròyìn ohun tí Modekai sọ fún Ẹsita.
Ẹ̀ ń ya oríṣìíríṣìí ọjọ́ sọ́tọ̀, ẹ̀ ń ranti oṣù titun, àkókò ati àjọ̀dún!
Nínú fídíò náà, arábìnrin Knežević sọ pé alábòójútó ilé ìtajà náà bẹ̀bẹ̀ lẹ́yìn tí òun ṣe àròyé nípa ìwọ̀sí náà, ṣùgbọ́n pé inú òun kò dùn sí bí àwọn èrò tí ó pé jọ lé òun lórí ṣe yẹ̀yẹ́ òun.
O sọ pe ẹjọ ti oun pe sọdọ awọn ọlọpaa ṣi n tẹsiwaju.
Ni deede ago mejila ọsan ni adura idagbere fun oloogbe bẹrẹ ni Mọṣalaṣi Sẹnetọ Ishaq Abiola Ajimobi to wa ni Oke Ado, Ibadan.
Ileri ti aarẹ ṣe lọdun 2015 ni pe oun yoo mu iwe ofin aparo kan o ga jukan laarin akọ ati abo (National Gender Policy) Bakan naa ni ọmọ ṣe ori ni ile aṣofin apapọ nibi ti o jẹ pe awọn obinrin meje pere ni ile aṣofin agba ati mọkanla ni ile aṣoju-ṣofin.
Ọdún yìí kii ṣe ọdun ti ènìyàn n wá èrèọjà rẹpẹtẹ bíko ṣe, asíkò láti wà láàlafíà."
'Nàìjíríà, ṣọ́ra, ogun ń sọ ilé ọlá di ahoro!
 juan ponce da sílè ní odún 1521 .
Oba Adeyemi ko to jọba jẹ osisẹ adojutofo ati akansẹ to dantọ, to si ni iriri ba se n se akoso eyi to wulo pupọ fun lasiko to di ọba alaye.
Nile Busola Dakolo ati ọkọ rẹ Timi nilu Eko ni wọn ni iṣẹlẹ yi ti waye.
Oríṣun àwòrán, Others Àkọlé àwòrán, Ijọba ipinlẹ Ọyọ ti bẹ awọn oniṣegun ibilẹ lọwẹ lori aarun Corona Amọ ajọ NAFDAC ninu atẹjade wọn sọ wi pe, ileeṣẹ ẹyọkan pere lo ti gbe oogun wa labẹle fun agbẹyẹwọ bọya lootọ ni oogun naa le ṣe awotan arun Coronavirus.
Farting offense: Ọkùnrin yasó nínú ọkọ̀ Uber rí ẹ̀wọn he ní ilẹ̀ Gẹ̀ẹ́sí
Agbede ni orukọ awọn ajinigbe ti ọwọ tẹ naa ni Bright Chinonso, Eze Ernest, Chisom Godwin and Chinoyerem Chineye.
" Nigba ti BBC Yoruba beere pe ṣe awọn eeyan ko ni maa fi oju ọgbọn oṣelu wo sisan owo naa lasiko yii ti ibo gomina ipinlẹ naa ku ọsẹ meji, alaga ẹgbẹ oṣiṣẹ NLC nipinlẹ Ọṣun naa ni ohun yoo wu ti awọn eeyan ba tumọ rẹ si, eyi to jaju fun oun ni ki awọn oṣiṣẹ ti oun n ṣoju o gba ẹtọ wọn.
Wo àmúyẹ kí o tó lè di ọmọ ogun ilẹ̀ Nàìjíríà pẹ̀lú fọ́ọ́mù tó jáde yìí Làásìgbò òṣèlú wáyé nílùú Ondo, ọ̀pọ̀ èèyàn fara pa Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Akomolede ati asa Yoruba: Ẹ wá kọ́ nípa àpòtí ìṣura èdè wa lórí BBC Yorùbá Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Ondo Governorship Election: Ọ̀pọ̀ dúkìá àti mọ́tò bíí 15 làwọn jàǹdùkú bàjẹ́21 Ògún 2020 5:58 Fídíò, Akomolede ati asa Yoruba: Ẹ wá kọ́ nípa àpòtí ìṣura èdè wa lórí BBC Yorùbá, Duration 5,5820 Ògún 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Iroyin naa salaye pe awọn ọdọ ilu Ikire lo anfaani rogbodiyan lori iwọde ENDSARS to n lọ lọwọ lati ji oriade naa, Akire tilu Ikire, ọba Falabi gbe lọ.
 O fikun ọrọ rẹ pe oriṣiriṣi ijọ ni oun wa Ọlọrun de."
Bi ẹko ẹ ko ba gbagbe, lati nkan bi ọsẹ kan sẹyin ni ija kan ti n waye laarin Toyin ati Lizzy lori ẹrọ ayelujara, eyi to ti mu ki Lizzy sọ ọpọlọpọ ọrọ kobakungbe si Toyin.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Lagos -Ibadan Express: Súnkẹ́rẹ fakẹrẹ ọkọ òpópónà marosẹ̀ tòní tún kọ sísọ 26 Èrèlè 2020 Oríṣun àwòrán, Goldmyne Àkọlé àwòrán, Lagos -Ibadan Express: Súnkẹ́rẹ fakẹrẹ ọkọ òpópónà marosẹ̀ tòní tún kọ sísọ Òpópónà Eko si Ibadan ni àwọ́n ènìyàn tún ji si pe o ti di pa ni òwúrọ̀ oni, ti ọ̀ps ko si ni ìrèti àsìkò ti wọ́n yóò de ẹnu iṣẹ́ wọ́n.
Ozo-Eson ni ijọba apapọ ko lasẹ lati yii adehun ti igbimọ onigun mẹta gbe le Aarẹ Buhari lọwọ pe ẹgbẹrun lọna ọgbọn Naira ni awọn fẹ ma a gba gẹgẹ bi gbendeke owo osu.
Fatma Samoura to jẹ akọwe agba fun FIFA ni wọn yan pe ko lọ mojuto ọrọ CAF.
Awọn olupẹjọ fidi rẹ mulẹ fun igbimọ olugbẹjọ ibo aarẹ naa pe, ẹrọ kọmputa ajọ INEC fihan pe, Atiku lo leke pẹlu ibo to le ni miliọnu mejidinlogun ti aarẹ Buhari si ṣe ipo keji pẹlu ibo to leni miliọnu merindinlogun ati aabọ.
Oríṣun àwòrán, @Ooni Kini Ọba to ba fẹ tete fi oju kan ọmọ rẹ le ṣe?
A ò ní ri àpadà sí burúkú láí-láí o.
Anthony Joshua lori Twitter ni nkan miran lo n ṣẹlẹ lorilẹede Naijiria, nitori pẹlẹ putu ni awọn afhọnuhan naa fi n ṣe iwọde wọn.
O fikun un pe, sise agbeyewo ati ijiroro po lori iwe eto isuna naa, ni o sokunfa idi ti sise agbekale re fun aare se pe di isin yii.
Ẹni ibi ń yí ninu ìrora ní gbogbo ọjọ́ ayé rẹ̀,àní, ní gbogbo ọdún tí a là sílẹ̀ fún ìkà.
Bakan naa ni wọn darukọ Gbenga Ololade to jẹ adari Prime FC nigba naa, gẹgẹ bi ọkan lara awọn to mọ nipa owo ti wọn fi ra Ighalo lọ nigba naa.
Nígbà náà, ẹ óo ṣe àsè àjọ ọ̀sẹ̀, tíí ṣe àjọ̀dún ìkórè fún OLUWA Ọlọrun yín; pẹlu ọrẹ àtinúwá.
A o ri I pe eto idibo yii lo ni irọwọ-irọsẹ.
Àwọn ilé Jerusalẹmu ati àwọn ààfin ọba Juda, gbogbo ilé tí wọn ń sun turari sí àwọn ogun ọ̀run lórí òrùlé wọn, tí wọn sì ti rú ẹbọ ohun mímu sí àwọn oriṣa mìíràn, gbogbo wọn ni yóo di aláìmọ́ bíi Tofeti.
Awon egbe oselu Coalition for Change ati Grand National Coalition meji ti won sese da sile lorile-ede naa,ko ijokoo mejo ati ijokoo merin, nigba ti awon egbe-oselu aladani merin yoku tun ni lara ijokoo naa, amo ijokoo meje yoku ni ajo eleto abo koi ti kede re.
Bakan naa lo tun ṣeleri pe oun yoo fi fidio mii sita, nibi ti ọmọ oun fun'ra rẹ yoo ti sọrọ laijẹ pe oun gba ẹnu rẹ sọrọ.
Oríṣun àwòrán, Instagram/ronkeoshodioke Ọmọ bibi ipinlẹ Ondo ni Ronke Oshodi-Oke, amọ ilu Eko lo ti lọ si ileewe alakọbẹrẹ ati girama, to si ni nitori idi kan tabi omiran ni oun ko fi le tẹsiwaju ni idi ẹkọ oun, lọ si ileewe giga.
Oríṣun àwòrán, Press Association Àkọlé àwòrán, Iwadi fihan lọdun 2014 pe ida kan ninu mẹrin obinrin lorilẹede Naijiria lo ti fara kaasa iwa ipa labẹle Amọsa, Gomina Ambọde ni isẹ ku sọwọ awọn agbofinro lati rii wi pe wọn n se iwadi to kuna nitori ko si ani-ani wi pe awọn gan-an laraalu kọkọ maa n kan si ti irufẹ iwa ọdaran bẹẹ ba waye.
Ọ̀gbéni Kunu ní kò sí àǹfàní nínú dídá orukọ nígbà tí àwọn èèyàn kan tí aráyé mọ̀ pé aṣọ àlà wọn kò mọ́ rọ̀gbà yí ààrẹ Mùhámádù Bùhárí fúnrarẹ̀ ká .
Ẹ̀rù wá ba ọ̀gágun náà nígbà tí ó mọ̀ pé ọmọ-ìbílẹ̀ Romu ni Paulu, àtipé òun ti fi ẹ̀wọ̀n dè é.
Bí ọ̀pọ̀ ènìyàn bá n gbé papọ̀, ó rọrùn lati jọ parapọ̀ dojú kọ ogun tàbí ọ̀tẹ́ tí ó bá fẹ́ wá láti ibikíbi.
Àbúrò Saraki ní APC ló ni Kwara lọ́jọ́ Abamẹta tó m bọ̀ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Election Update 2019: Lẹ́yìn lílọ Saraki, Kwara yóò ṣún síwájú ni Bukola Saraki ti jẹ gomina ipinlẹ Kwara ri ko to di aarẹ ile igbimọ aṣofin agba.
Èyí sì túmọ̀ sí onírúurú ǹkan to lágbára fun ọ̀pọ̀ èniyàn nílé àti nílẹ̀ òkèèrè.
Sedekaya ọba Juda ni ó sọ Jeremaya sẹ́wọ̀n, ó ní, kí ló dé tí Jeremaya fi sọ àsọtẹ́lẹ̀ pé OLUWA ní òun óo fi Jerusalẹmu lé ọba Babiloni lọ́wọ́, yóo sì gbà á; 
EFCC fẹ̀sùn kan ọmọ ilẹ̀ Britain méjì Bi a ko ba gbagbe, laipẹ yi ni iroyin kan pe ọgbẹni Hope Aroke ti wọn tun un pe ni H Money n wọke lati inu ọgba ẹwọn ti wọn fi si.
Àkàrà-òògùn bẹ̀rẹ̀ sí ọ̀rọ̀ í dọ.
Ile-igbimo asofin  fi ipinnu  re mule lojo-Eti, botile je pe, , ojuse won ku die kaato, lati ni iye ibo ti won n fe, agbenuso ile-igbimo asofin ohun toro aforiji lori idapo ti o waye lasiko ti won n se akojopo ibo lori ero computa.
Sani Abacha: Olórí ológun tí ìjọba rẹ̀ ga ju ilé ẹjọ́ lọ
Àwọn ọmọ Pahati Moabu láti inú ìran Jeṣua ati Joabu jẹ́ ẹgbẹrinla lé mejila (2,812)
Adeleye ni ọkan pataki lara nkan ti oun yoo ṣe ni láti mu aabo ilu ati Ounjẹ rọrun fun ara ilu, nitori ọna yii nikan ni ilu fi le tuba ko tunṣẹ Adeleye ni o se pataki lati gbaruku ti isẹ ti eniyan ba ba nílé O fi kun un pe eto Mother and Child ti Mimiko ti se seyin ati awọn opopona ti gomina Akeredolu n se.
Mo dé ìwọ̀-oòrùn níbi tí agbami òkun ti lọ kánrin-kése kọ́já ibi ojú rí.
Gomina ipinlẹ naa, Godwin Obaseki lo kede bẹẹ loju opo Twitter rẹ lẹyin ti awọn janduku darapọ mọ awọn oluwọde End SARS ti wọn si gbiyanju lati tu awọn ẹlẹwọnm ka silẹ ni ahamọ.
Ẹ̀yin ará Etiopia, n óo fi idà mi pa yín.
Asọ̀ tí ó wáyé láìpẹ́ yìí láàárín Ààrẹ àná, Olúsẹ́gun Ọbásanjọ́ àti Ààrẹ tí ó wà lórí àlééfà, Ààrẹ Muhammadu Buhari – tí àwọn méjèèjì jẹ́ ajagun fẹ̀yìntì afipásèjọba ológun –ní ipa tí ó pọ̀ lórí ètò ìdìbò oṣù tí ó ń bọ̀.
Yóo jọba lórí ìdílé Jakọbu títí lae, ìjọba rẹ̀ kò ní lópin.
Ayọ̀ ń bẹ fún gbogbo àwọn tí ó fi ọ́ ṣe agbára wọn,tí ìrìn àjò sí Sioni jẹ wọ́n lógún.
Mi o kawe mi o si fẹ gbe ibọn ki n maa jale kiri, ọsẹ meji pere lo ku ki n fi kere oko yii, ẹ jọwọ ẹ saanu mi, mi o lọna miran.
Joshua ni alagbatọ Leah Sharibu to jẹ ọmọ ọdun mẹrinla to wa ni panpẹ Boko Haram lati oṣu keji, ọdun to kọja lasiko ti wọn ji eniyan to ju ọgọrun un gbe lo nile iwe rẹ ni ilu Dapchi, ni ipinlẹ Yobe.
Pedro goes agonisingly close, only just dragging his effort the wrong side of the post…0-0 [42'] #EVECHE pic.
O ni igbadun, owo ati iriri to wa lori eto naa ni oun wa wa to si ni oun fẹran ounjẹ pupọ.
Eredi ni pe iyọnipo ọhun si ku abala kan, leyi to wa lọwọ ile aṣofin agba orilẹ-ede ọhun nitori ọna meji ni yiyọ aarẹ nipo lorilẹ-ede Amẹrika pin si.
'Àwọn SARS ló yìnbọn pa ìyá mi' SARS já wọ ilé àwọn akẹ́ẹ̀kọ́ fásitì Akungba Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, ọ̀gá ọlọ́pàá sọ̀rọ̀ lórí SARS Nibayii, ileeṣẹ ọlọpaa sọ pe awọn afurasi ọhun ti wa ni atimọle, ati pe wọn yoo fi iya to tọ jẹ wọn labẹle tabi gbe wọn lọ sile ẹjọ ti iwadi ba fi le fihan pe wọn jẹbi ẹsun naa.
Òun ni ó mú kí gbogbo ilé dúró dáradára, tí ó sì mú un dàgbà láti di ilé ìsìn mímọ́ fún Oluwa.
Olufemi naa wa gba ijọba ni imọran lati maṣe daamu awọn ọdọ nitori iya ni yoo jẹ ki awọn ọdọ ṣe iṣẹ agbẹ lai fun wọn ni ohun iranwọ.
Ju gbogbo rẹ lọ, mo dupẹ fun ọfiisi tuntun ti o ṣi fun mi gẹgẹ bi ẹ̀bùn ayẹyẹ ọjọ ibi ọgọta ọdun ti mo pe.
Nítorí náà, ẹ ranti pé nígbà kan rí, ẹ jẹ́ abọ̀rìṣà gẹ́gẹ́ bí ipò tí a bi yín sí.
Òjò kò sì rọ̀ sórí ilẹ̀ fún odidi ọdún mẹta ati oṣù mẹfa.
Oríṣun àwòrán, @Ransome-Kuti Àkọlé àwòrán, Awon obinrin Ẹ̀gbá fariga Ọba Alake igba naa, Ọba Samuel Ladapọ Ademọla ati awọn Oyinbo Ajẹ́lẹ̀ gbogun ti aya Ransome-Kuti.
Ẹ má pe ẹnìkan ní ‘Baba’ ní ayé, nítorí ẹnìkan ṣoṣo ni Baba yín, ẹni tí ó wà ní ọ̀run.
Igbe wọn ta sókè bíi híhó omi òkun ńlá
Tolani jẹ oṣiṣẹ ileeṣẹ Illusions Imagery ki o to di pe igbakeji aare, Yemi Osibanjọ yan si ipo tuntun yi.
Ayé rẹ yóo mọ́lẹ̀ ju ọ̀sán gangan lọ;òkùnkùn rẹ yóo sì dàbí òwúrọ̀.
"Yahoo Yahoo oní 'Millitary Dating' lèmi ń ṣe""."
Ranti dibo ni ibudo idibo to wa ni 
Oríṣun àwòrán, Facebook/Barrister Fans page Àkọlé àwòrán, Opo ko kọkọ gbagbọ nigba ti wọn kede iku Barrister Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, ''Ẹ̀mí ọ̀pọ̀lọpọ̀ ṣì n sọnù ni orilẹ̀-ede Burundi' Ololufẹ Barrister mii gbadura ni pe ki Alhaji Agba maa sinmi laya Allah titi di ọjọ agbende.
Ẹni tí ó sàn jùlọ ninu wọn dàbí ẹ̀gún, ẹni tí ó jẹ́ olódodo jùlọ láàrin wọn sì dàbí ẹ̀gún ọ̀gàn.
Ẹwọn ọdun maarun ni awọn ọmọbinrin naa yoo fi jura ti ile ẹjọ ba fi le fidi rẹ mulẹ pe wọn jẹbi.
” Aare Buhari,tun wa dupe lowo
ṣalaye pé oun nigbagbọ ninu agbara oludibo ati ireti awọn eniyan Naijiria lati ni ọjọ iwaju rere ti ko ṣẹyin awọn adari to bẹru Ọlọrun.
Ilu Kishi ni iroyin tan kalẹ pe awọn afurasi agbesunmọmi ati afẹjẹwẹ ti n huwa laabi ninu igbo igbafẹ Old Oyo National Park to wa nilu naa.
Ondo marijuana: Naijiria kò fẹsẹ̀rinlẹ̀ tó láti gba igbó láàyè fún ìtọ́jú àìsàn- Onímọ̀ ìlera
Olubadan sọrọ yi lọjọbọ nibi ipade kan ti gomina Ajimọbi pe awọn ọba alaye kan si jakejado ipinlẹ Ọyọ eyi to wa lati beere fun atilẹyin wọn fun ifẹsẹmulẹ alaafia ati eto aabo nipinlẹ Ọyọ.
Wọ́n ń tẹ̀lé ìmọ̀ ara wọn, wọ́n ń ṣe oríkunkun, dípò kí wọ́n máa lọ siwaju, ẹ̀yìn ni wọ́n ń pada sí.
O ni igbesẹ yii yoo mu ki ẹka ileeṣẹ o gbooro si ni ida ogun ninu ọgọrun.
Sugbọn, awọn ọmọbinrin ọlọpa ti iko Boko Haram ji gbe, n sunkun kikoro ninu fọnran na.
Ikọ adunkoko mọni ni Boko Haram, to si kọlu ijọba orilẹede Naijiria lọdun 2009 pẹlu erongba lati se agbekalẹ isejọba ẹlẹsin Islam lagbegbe iwọ oorun Afrika.
Cameroon lo wa ni ipo mẹrindinlaadọjọ ninu orilẹede mẹrindinlaadọsan to n hu iwa ijẹkujẹ.
Ilẹ̀ tí ó kún fún ọkà ati baali, ọgbà àjàrà ati igi ọ̀pọ̀tọ́, ati igi pomegiranate, ilẹ̀ tí ó kún fún igi olifi ati oyin.
Ogun yii sọ ọpọ ẹmi ati dukia nu ni eyi ti NAijiria n ṣe iranti aadọta ọdun to waye.
Nígbà tí a mú ìyìn rere wá sí ọ̀dọ̀ yín, a kò mú un wá pẹlu ọ̀rọ̀ ẹnu nìkan; ṣugbọn pẹlu agbára ninu Ẹ̀mí Mímọ́ ni, ati pẹlu ọpọlọpọ ẹ̀rí tí ó dáni lójú.
Rev Fr Nike Onyanofoh to jẹ alagba ijọ aguda fun ẹkun Benin naa so wi pe wọn ti gbe awọn alufa naa lọ si ile iwosan ni Benin fun itọju to peye.
Iroyin ti o bani-ninu je ni wi pe, awon omo ogun merin farapa lasiko ikolu ohun, ti won si n gba itoju lowo nile iwosan iko omo ogun naa.
’ Mo ní n ó lọ gbàdúrà kí ó má kǔ.
Wọn óo pada sábẹ́ ààbò mi,wọn óo rúwé bí igi inú ọgbà;wọn óo sì tanná bí àjàrà,òórùn wọn óo dàbí ti waini Lẹbanoni.
Afọnja, ẹni tó finú wénú ní Ilọrin, àmọ́ tó jẹ iwọ Ṣé ìwọ mọ odò adágún Adó Àwáyè tí kò ní òpin ní ìsàlẹ̀?
Oludamọran kan lati ile Ẹkọ fasiti Joseph Ayo Babalola, ọmọwe Olaniyi Cecilia Mosunmola sọ pe pupọ ninu awọn obi lo lẹbi bi awọn ọdọ ṣe n gba ẹmi ara wọn.
Eleduwa si ti fi eso ọmọ si aarin wọn.
Angẹli OLUWA tún pe Abrahamu láti òkè ọ̀run ní ìgbà keji, 
Ọkunrin kan ti orukọ rẹ n jẹ @omo_billionaire loju opo Twitter, lo bi awọn eeyan leere pe kin ni idajọ lori ọrọ pasitọ Omashola ati Naira Marley.
Ẹlomiran ni lati ọdun to kọja ni oun ti fi ọjọ ibo sọkan, tawọn si ti ya sọtọ fun ijọba, ki lo wa de ti wọn tun se yẹ ọjọ yii lati di awọn lọwọ.
Fi wọ́n sọ́kàn nígbà gbogbo,kí o sì so wọ́n mọ́ ọrùn rẹ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ṣe wahala wá ti ọkọ bá kọ̀ láti fún aya tó ti kọ̀ silẹ lára ogún rẹ?
Nínú àtẹ́jáde rẹ̀, òlúùlú orílẹ̀-èdè Nàìjíríà Abuja ló ń léwájú pẹ̀lú ènìyàn 128, ìpínlẹ̀ Eko tẹ̀lée pẹ̀lú 86, Kaduna ni 26 nígbà ti Katsina náà ni 20 Àwọn ìpińlẹ̀ tó kù ni Rivers 19, Oyo 7, Benue, Edo, jigawa àti Ogun ní 5 tí Bayelsa ati Kano sì ni 2.
Bó tilẹ̀ jẹ́ pé, agbẹnusọ ọlọ́pàá, Bala Elkana sọ fún àwọn akọ̀rọ̀yìn pé, kò tii sí àrídájú pé òkú Adewura ní wọn ri àfi ti ìwádìí ba parí níwọ̀n ìgbà to jẹ́ pe òkú rẹ̀ ti ń jẹra.
“Dìde nisinsinyii, kí o lọ sí ìlú Sarefati, ní agbègbè Sidoni, kí o sì máa gbé ibẹ̀.
Báwo ló ṣe wá di ìjẹ fún àwọn ọ̀tá rẹ̀.
Oríṣun àwòrán, @PoliceNG Sugbọn niwọn igba to jẹ pe oku ni eeyan pa irọ mọ ti kii lee fọhun, ẹgbẹ oselu APC ti wa kigbe sita fun Wadume pe, yoo dara ko tete sọ awọn to ran nisẹ ibi nitori APC kii fun awọn apaayan ati ajinigbe ni owo.
ati ifira-ẹni-jin gẹgẹ bi awokọsẹ laarin ara wọn.
" Ìpínlẹ̀ Eko ń bá àwọn iléètura sọ̀rọ̀ fún ìpèsè ibùsùn fáwọn aláàrùn Coronavirus Ìpínlẹ̀ Eko ń bá àwọn iléètura sọ̀rọ̀ lọ́nà àti kojú ìpèníjà ibùsùn láwọn ibùdó ìtọ́jú àwọn aláàrùn COVID-19 Ijọba ipinlẹ Eko ni awọn ti n ba awọn ileetura sọrọ l'Eko fun iranwọ lori iṣoro aisi ibusun to to lawọn ibudo itọju awsn alaarun coronavirus ni ipinlẹ Eko.
INEC ni ipinle Bauchi, ọjọgbọn Kyari Mohammed lo kede naa lọjọ  Aiku .
 Ati pe kikida awọn to ba n kirun deedee
Kí Oluwa wà pẹlu gbogbo yín.
Mo máa n forin mi kìlọ̀ ìwà ìbàjẹ́ láwùjọ ni -Hameen Àwọn elétò ààbò ń fìyà jẹ àwọn èèyàn púpọ̀ jù ni Nàìjíríà Buhari san lára owó àjẹmọ́nú Super Eagles!
Adele Oludari ẹka ibaṣepọ araalu nileeṣẹ ologun Ọgagun Sagir Musa, lasiko to n fesi si atẹjade kan lati ileeṣẹ ọlọpaa pe, salaye pe awọn ọmọogun lo gba ipe lati wa doola ẹnikan ti awọn ajinigbe ji gbe, loju ọna Ibi-Wukari nipinlẹ Taraba.
Baba Obasanjo kii fi ọwọ rọ ẹnikẹni sẹyin tabi da ọrọ wọn nu.
soro niluu Minna , ti o je olu-ilu Niger , ni ekun aarin gbungbun orile ede
Ó sọ fún un pé “Èmi ni OLUWA tí ó mú ọ jáde láti ìlú Uri, ní ilẹ̀ Kalidea, láti fi ilẹ̀ yìí fún ọ ní ohun ìní.
Oríṣun àwòrán, Others Àkọlé àwòrán, Awọn alaṣẹ ẹgbẹ APC ni ipinlẹ Rivers ti kọkọ da Giadom duro, fun pe o tako ilana ati agbakalẹ ẹgbẹ""."
Idaduro Daura ko sẹyin bi awọn ọmọ ile isẹ ọtẹlẹmuyẹ se dina wiwọle mọ awọn asofin agba l'owurọ ọjọ Iṣẹgun.
vasco da gama ni ó ṣe àwárí mozambique ní 1498 .
Atẹjade ti wọn fi sita fun BBC ni: Eyi ni igba akọkọ ti a ni lati gba awọn nkan iranlọwọ wa pada nitori abuku kan.
Ṣugbọn iresi ti gbowo lori lẹyin ti ijọba ti ibode tan, baagi irẹsi kan ti di ẹgbẹrun lọna ogun naira si ẹgbẹrun lọna mejidinlọgbọn bayii, koda awọn irufẹ irẹsi mii maa ju bẹẹ lọ.
Ewe, o salaye pe, won yoo ka awon akekoo ohun lati mo awon yoku ti won si wa ninu ihamo awon ajini-gbe naa.
Àwọn aṣekúpani tún ti pa ọmọ ọdún 16 ní Akinyele nípìnlẹ̀ Oyo A yìnbọn lu Precious láti dáa dúró ni, akò mọ̀ pé o máa kú- Ọlọ́pàá Èèyàn 576 míràn tún kún àwọn tó ní àrùn COVID-19 ní Nàìjíríà Sotitobire Latest news: Adájọ́ yarí lórí bí àwọn ẹlẹ́rìí ṣe ń fi ẹjọ́ falẹ̀ Ile ejọ giga tipinlẹ Ondo, to kalẹ si ilu Akure, ti fari ga lori bi igbejọ Alfa Babatunde se n fa nilẹ bii igbin.
Oríṣun àwòrán, Twitter/miraclenaija Bakan naa ni Miracle gba ẹbun owo miliọnu kan naira lati ọdọ Payporte Arena Games ati ẹgbẹrun lọna igba naira lati ọdọ Final Wager.
Àwọn ni ẹ óo fi rú ẹbọ sísun sí OLUWA; pẹlu ẹbọ ohun jíjẹ, ati ẹbọ ohun mímu, ẹbọ tí a fi iná sun, olóòórùn dídùn, tí OLUWA gbádùn ni.
Àwọn kan tí wọ́n ti jókòó níbẹ̀ bi wọ́n pé, “Kí ló dé tí ẹ̀ ń tú kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́?
47 Àti láti ṣe àbẹ̀wò sí ilé ọ̀kọ̀ọ̀kan ọmọ ìjọ, kí ó sì gbà wọ́n níyànjú láti máa gbàdúrà lóhùn òkè àti ní ìkọ̀kọ̀, àti láti máa ṣe gbogbo àwọn ojúṣe ẹbí.
N óo da àwọn ẹranko burúkú sáàrin yín, tí yóo máa gbé yín lọ́mọ lọ, wọn yóo run àwọn ẹran ọ̀sìn yín, n óo dín yín kù, tí yóo fi jẹ́ pé ilẹ̀ yín yóo di ahoro.
“Ṣé tàkúté a máa mú ẹyẹ nílẹ̀, láìṣe pé eniyan ló dẹ ẹ́ sibẹ?
Nígbà tí Saulu gbọ́ pé Dafidi ti sá àsálà lọ sí Gati, ó dẹ́kun láti máa wá a kiri.
Akinyẹmi: Ọgbun mẹrin to wa niwaju aarẹ tuntun ni South Africa
O ni PDP kọ esi idibo to gbe Fayẹmi wọle patapata nitori pe àjọmọ̀ INEC ati APC atawọn oṣiṣẹ eleto aabo lo bi madaru to ṣẹlẹ l'Ekiti.
Awọn akanda ẹda ọhun to wa lati ijọba ibilẹ mẹtalelọgbọn kaakiri ipinlẹ Oyo lu oju opo ileeṣẹ ijọba to wa lagbegbe Agodi n'Ibadan pa.
Ìdí mẹ́ẹ́rin tí sísùn ní ìhòhò lé gbà ṣe ara a rẹ l'óore Mo lóbìnrin tó bímọ fún mi, ṣùgbọ́n ọ̀rọ̀ ìyàwó kò tíì yọ fún mi báyìí-Pasuma Ènìyàn lásán ní ọba ilẹ̀ Yoruba tí kò bá ṣe ètùtù, ẹ má tẹ ìṣẹ̀ṣe mọ́lẹ̀ - Elebuibon Ìdá 90% nínú àwọn olówó Naijiria lo n lọ ilé babaláwo- Mr Latin Irinajo si Saudi Arabia Awọn ẹlesin Musulumi ti wọn ti n gbaradi lati goke Arafa lọdun yii ko le ni anfani ati ṣe bẹ nitori ọwọja arun Coronavirus yii kan naa.
Dafidi bá kó àwọn ọmọ ogun rẹ̀ jọ, ó lọ sí Raba, ó gbógun tì í, ó sì ṣẹgun rẹ̀.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Nigeria Swearing in 2019: Kà nípa gómìnà tuntun ni Kwara 1 Èrèlè 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 29 Èbibi 2019 Ìlú Ilọrin ni a ti bí Abdulrahman Abdulrazaq tó jẹ́ onísòwò epo pàtàkì tí bàbá rẹ̀ sì jẹ́ agbẹjọ́rò pàtàkì ní àríwá Nàìjíríà.
Ogagun agba Muhindo Akili Mundos, ti o je alatileyin fun Aare Joseph Kabila, je okan lara awon meta ti orile-ede America fofin de naa.
" Oríṣun àwòrán, Hamisu Mallamawa Àkọlé àwòrán, Musa joko s'aarin awọn to wa ba yọ pe ori ko yọ lọwọ ajinigbe ''Lapapọ, eeyan mejila ni wọn ji gbe ni abule Mallamawa'' O tẹsiwaju pe ''awọn obinrin mẹrin wa laarin wa, ọmọge mẹta ati adelebo kan.
Oloye Ẹlẹbuibọn sọ pe ọrọ naa dabi orin Yoruba kan to sọ pe iya lo jẹ iya agba, to ko owo lọ ọ ra ajẹ."
Wọ́n gbé ẹ̀wù dáradára kan wọ̀ ọ́; Hẹrọdu bá tún fi ranṣẹ pada sí Pilatu.
Ṣaaju ninu ifọrọrọwanilẹnuwo kan pẹlu BBC Yoruba lori eto aabo, Gani Adams sọ fun wa pe ẹgbẹ OPC ko le da si ọrọ aabo Naijiria ti ijọba ko ba pe e si.
’ Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí kan sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
Nínú ọ̀rọ̀ rẹ̀ lásìkò tó bá BBC Yoruba sọ̀rọ̀, ní ààrẹ ẹgbẹ́ FIBAN Desmond Nwachukwu sàlàyé pé, àwọn ṣì ń dúró de Ọjọ́rú ọjọ keje, ọdún yìí kí àwọn tó gbé ìgbẹ́sẹ̀ tó kan lórí ọ̀rọ̀ náà.
Eko Agbegbe Maza-maza ni awọn eeyan kọkọ kọlu lati ji ounjẹ iranwọ Covid-19 to wa nibẹ.
CAF Champions League: CAF pàṣẹ àtúngbá ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ àṣekágbá CAF Champions League
Iṣẹ́ Oluwa ni èyí,ìyanu ni ó jẹ́ lójú wa.
Ni ipari, idije Commonwealth ohun ti o bere lojoRu(Wednesday), ni ireti wa pe yoo pari lojo karundinlogun osu kerin odun ti a wa yii.
Oríṣun àwòrán, @Thegistday Eemọ ti ṣẹlẹ ni ile igbimọ aṣofin ipinlẹ Ogun gẹgẹ bi awọn afurasi janduku ṣe ya bo ibẹ l'Ọjọbọ ọsẹ.
Àmọ́ lóde òní, ẹ̀rù ò ṣábà á ba’ni mọ́n.
Àwọn ọmọbinrin Moabu dúró létí odò Anoni,wọ́n ń rìn síwá, sẹ́yìn,wọ́n ń lọ sókè, sódò,bí ọmọ ẹyẹ tí a lé kúrò ninu ìtẹ́.
Ọba Babiloni lù wọ́n, ó sì pa wọ́n sórí ilẹ̀ Hamati.
Nilẹ Afrika, orilẹ-ede Naijiria ni wọn ti n lo eroja ibora julọ.
Wo àwọn ìlérí tàwọn Gómìnà tuntun ṣe nínú ìbúra wọn Boko Haram àti àwọn Fulani daran daran jẹ́ ọgbọ́n áti sọ Nàíjíríà di ìlú mùsùlùmí - Wale Oke Irú ọmọ wo ni Yorùbá máa ń pè ní Ìgè?
    Ẹ ó ríí pé mo fi ìwé náà júbà ọ̀pọ̀lọpọ̀ àwọn ènìyàn tí wọn wà láyé lónìí, mo gba àṣẹ lọ́wọ́ àwọn wọ́nyí wọ́n sí ti àṣẹ náà fún mi pé ki n fi júbà àwọn, ṣùgbọ́n ó ní ìdí pàtàkì tí mo fi fi ìwé yìí júbà wọn.
Ipade yii waye ni alẹ ojo Ru , leyin ti pupo ninu awọn asofin ti egbe APC yapa lo sinu egbe alatako  iyen PDP lọjọ Isegun.
Iṣẹlẹ naani yoo si jẹ ẹkẹta iru ẹ ti yoo maa waye laarin oṣu mẹta ni ilẹ Yoruba.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ibanuje d'orí agbà k'odò, Ruiz fi ẹ̀ṣẹ́ sọ Anthony Joshua di ọmọ ológo àná Ilé alájà mẹ́ta wó pa onímọ̀ ẹ̀rọ́ tó ń kọ́ ọ lọ́wọ́ Amẹ́ríkà ń béèrè ìròyìn facebook, email arìnrìnàjò tó f'ẹ́ gbà'wé àṣẹ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Collapsed Building: Ayálégbé ló dára bí ìjọba ṣe wólé àmọ́ wọ́n fẹ́ ìrànwọ́ ilé míràn Iroyin to tẹ BBC News Yoruba lọwọ ṣalaye pe awọn aladugbo gbe e lọ si ileewosan kan ni agbegbe Oke-Baalẹ ṣugbọn ti awọn oṣiṣẹ ileewosan naa ni ọrọ rẹ kọja agbara awọn.
Gbogbo àwọn tí wọn rí wọn ń pa wọ́n jẹ, àwọn ọ̀tá wọn sì ń wí pé, ‘A kò ní ẹ̀bi kankan, nítorí pé wọ́n ti ṣẹ OLÚWA, tí ó jẹ́ ibùgbé òdodo wọn, ati ìrètí àwọn baba wọn.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Èyí ni àwọn ìdí tí INEC fi sún ìdìbò aarẹ síwájú Ẹnikẹ́ni tó bá ṣáájú láti jì àpótí ìbò, ẹ̀mí rẹ̀ ló fi ń ṣeré - Buhari Ihalẹ Buhari: PDP na ìká àbuku sí Buhari lẹyìn ìpàdé wọn O ṣeéṣe ki iṣẹ́ bọ́ lọ́wọ́ ọlọ́pàá inú àwòrán 4+4 APC, PDP, CUPP kọ etí ikún sí òfin INEC Àwọn ìgbà tí ẹ̀ṣọ́ aṣọ́bodè ti pànìyàn lọ́nà àìtọ́ Àjọ aṣọ́bodè gba Codeine N200m Iléeṣẹ́ aṣọ́bodè gba nǹkan ìjagun àìtọ́ Lasiko ti wọn n ba BBC Yoruba sọrọ, awọn eeayan kan ni ọpọ onibara awọn ni awọn ti ja kulẹ nitori ibo yii, ti ko si yẹ ki ajọ eleto idibo maa fi tiwọn da awọn araalu duro.
View more on twitterView more on twitter Article share tools Facebook Twitter ṢàpínlòView more share options Share this post Copy this linkKà síwájú síi nípa àwọn ìtọ́kasí wọ̀nyí.
Gbogbo ibi tí yìnyín ti ń rọ̀, ó yẹ kí ó ti máa dáwọ́ dúro.
25 Kí gbogbo ọ̀pọ̀lọpọ̀ àwọn tí wọ́n bá gbàgbọ́ tí wọ́n sì ṣe ìrìbọmi ní orúkọ mímọ́ rẹ̀, àti pé tí wọ́n fi orí tìí nínú ìgbàgbọ́ títí dé òpin, nílati di ẹni ìgbàlà—
Nǹkan burúkú kò ní ṣẹlẹ̀ sí wa.
Marcus the Pig: Kini ẹlẹ́dẹ̀ aríran fi ṣẹ Naijiria?
Yóo wá sọ gbangba níwájú àwọn eniyan pé,‘Mo ti ṣẹ̀, mo sì ti yí ẹ̀tọ́ po,ṣugbọn Ọlọrun kò jẹ mí níyà ẹ̀ṣẹ̀ mi.
Gomina ipinlẹ naa lorileede Amẹrika ni iṣẹlẹ yi jẹ eleyi to buru julọ ti yoo ṣẹlẹ ni ibẹ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Anthony Joshua vs Andy Ruiz: DJ Cuppy ní ìgbà gbogbo ni ọlọ́kàn bí Joshua maa ń borí 7 Ọ̀pẹ̀̀ 2019 Oríṣun àwòrán, Instagram/Cuppy Oni lonii jẹ, ẹni a bẹ lọwẹ.
 Ìgbà yìí ni mozart ti bẹ ̀ rẹ ̀ síí kọ orin fún ara rẹ ̀ .
O n lo bi milionu meje awon eniyan lorile-ede Sierra Leone, amo,o le ni milionu meta awon eniyan ni won foruko sile, eyi to je pe, awon ni won yoo dibo ni awon ipago idibo ti o le ni egberun mokanla kaakiri orile-ede naa.
Gege bi oba Ofem ‘‘A n padanu awon odo wa lopolopo lataari rogbodiyan to n waye lotun losi.
DSS fi ipá mú Ṣowore padà s'átìmọ́lé l'Abuja Mo ṣetán láti kojú Andy Ruiz ni Saudi lọ́jọ́ Sátidé- Anthony Joshua Uzor Kalu tó jẹ́ àṣojú láti ìpínlẹ̀ Abia rí ẹ̀wọ̀n ọdún méjìlá he O pe akori eto naa ni 'Nolly veteran SOS Project 2019' lara awọn to ti n janfani eto naa bayii ni Sadiq Daba, Barbara Soki, Kareem Adepoju a.
O gba ọta ibọn ni aya rẹ.
Àwọn ará Ai bá pe gbogbo àwọn eniyan tí wọ́n wà ní ìlú jọ, wọ́n bẹ̀rẹ̀ sí lé àwọn ọmọ Israẹli lọ.
“Ní tiwa, a ti gbìyànjú níwọ̀n bí agbára wa ti mọ, a ti ra àwọn arakunrin wa tí wọ́n tà lẹ́rú fún àwọn orílẹ̀-èdè mìíràn pada, ṣugbọn ẹ̀yin tún ń ta àwọn arakunrin yín, kí wọ́n baà lè tún tà wọ́n fún wa!
Ẹ forí jì mí fún àṣìṣe yìí!
"Tyson Fury d'ẹ̀ṣẹ́ bo Deontay Wilder lórí, ó gbadé WBC mọ́ ọ lọ́wọ́ A n ṣé àyẹwò ẹni tá fúnra sí pé o ní Coronavirus l'Eko-Kọmísánà ìlera Ighalo tẹsiwaju pe ""Ohun ti ẹnikẹni ba sọ ko kan mi, afojusun wa ni Man United ni lati tẹsiwaju ninu saa bọọlu yii."
6 mílíọ̀nù ni-APC Ni ọjọ kejilelogun oṣu kẹsan ọdun 2018 ni eto idibo ati yan gomina fun ipinlẹ Ọṣun waye.
Gbogbo ohun tí ẹ bá gbọ́, kí ẹ máa rán wọn sí mi.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Uber Lady: Bùkátà pọ̀ lọ́rùn mi ní mo ṣe ń wa taxi akérò Ṣiṣe ayederu idi ni ọpọlọpọ aida ninu ti o si ṣeku pa awọn obinrin ilẹ Britain meji ti wọn rin irin ajo lọ si ilẹ Turkey.
Children's Day: Èwe ni ọjọ́ ìwájú ìran ènìyàn-Adeyeye Enitan Ogunwusi
Ikú ọmọ D'banj: Àwọn mọ̀lẹ́bí sọ̀rọ̀ lórí ikú ọmọ rẹ̀
Pẹlu ijo ati ilu ni Zlatan fi kọ orin ọhun, koda oun atawọn akẹgbẹ rẹ ni wọn jọ kọ ọ́.
Gbogbo ọlọpaa lo gbọdọ le wa ọkọ pẹlu iwe aṣẹ iwakọ to pe.
Awọn Eewọ: Awọn akọroyin BBC lorilẹede Russia, Olesya Gerasimenko ati Svetlana Reiter beere lọwọ awọn obinrin ni Russia, idi abajọ ti wọn n fi pa ọmọ ti wọn bi.
Dé ibi pé ẹnikẹ́ni tí ó bá fẹ́ tọrọ ibukun ní ilẹ̀ náà,yóo máa tọrọ rẹ̀ ní orúkọ Ọlọrun òtítọ́,ẹnikẹ́ni tí yóo bá sì búra ní ilẹ̀ náà,orúkọ Ọlọrun òtítọ́ ni yóo máa fi búra.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Scrabble: Yorúbà Scrabble ni àkọ́kọ́ ní èdè abínibí nílẹ̀ Afrika Nitootọ lawọn obi ni lilo foonu nile iwe yii kii jé ki ọkan awọn akẹkọọ papọ si oju kan nibi ẹkọ wọn.
Iliev so oro ohun fun gomina ipinle Plateau, Simon Lalong, lasiko abewo re si papa isere naa, O si fikun-un pe gbogbo ohun elo ni ipese re ti wa nile bayii lati ko papa isere ohun ni ibamu pelu ilana ti ajo CAF fi sile.
Coronavirus Cases in Africa: Gómìnà Makinde yan tíṣà rẹ̀ sí ipò òṣèlú ní ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́ Oríṣun àwòrán, others Yoruba ni ẹyin lo n di akukọ, ibi ti agba ba si dagba de, ni ọmọde yoo ba, awọn ọmọde si lo ni ọjọ ọla.
 nígbà tí ilẹ ̀ france náà da si ní osù kọkànlá ọdún 1914 .
Ninu atẹjade kan ti oluranlọwọ aare lori iroyin ati ikede , Femi Adesina
Abẹrẹ-ajẹsara ni aabo to péye 2.
Ọpọ eeyan si lo gba pe akikanju akọrin ni Ayinla Ọmọwura, bẹẹ si ni ọjọ ko lọ lori awọn awo orin to ṣe lati ọpọ ọdun sẹyin, to si fi aikawe rẹ jẹ amuludun fun iran Yoruba.
Ati pe iṣẹ iroyin jati-jati ni ileeṣẹ iroyin agbaye yii ṣe.
A kò gbo̩dò̩ dá è̩bi è̩s̩è̩ fún e̩nìké̩ni fún pé ó hu ìwà kan tàbí pé ó s̩e àwo̩n àfojúfò kàn nígbà tó jé̩ pé lásìkò tí èyí s̩e̩lè̩, irú ìwà bé̩è̩ tàbí irú àfojúfò bé̩è̩ kò lòdì sí òfin orílè̩‐èdè e̩ni náà tàbí òfin àwo̩n orílè̩‐èdè àgbáyé mìíràn.
 Èdè máa ń yàtọ ̀ láti ibìkan sí òmíràn .
- Sowore Adigunjalè ń bèérè ẹyin, ouńjẹ ati aṣọ lọ́wọ́ àwọn tí wọ́n ń jà lólè Faṣola ni àwọn ọ̀nà Nàìjíríà kò bàjẹ́ tọ bí wọ́n ṣe ń pariwo Garba Shehu ni awọn ipo oloṣelu kan lawọn ti yọ kuro ti wọn ko si tun awọn eeyan miran yan si ipo mii bi buhari ṣe wọle lẹẹkeji.
  “Laipe yii ni a o mọ
Nígbà tí ó dé ọ̀dọ̀ Eliṣa, ó wólẹ̀ níwájú rẹ̀, ó sì di ẹsẹ̀ rẹ̀ mú.
ti pe akiyesi wa si iroyin kan ti o so pe, iko omo ogun ,  Operation
Òfin nìkan ló lè gbadé lórí àwa Ọba ìlú lbadan- Oba Lekan Balogun Aṣojú Seyí Makinde lásan ní mo jẹ, òṣìṣẹ́ gbọdọ̀ bọ̀wọ̀ fún mi - Ọ̀dọ́mọdé Kọmísánà Biodun Fatoyinbo fi ipò sílẹ̀ lorí ẹ̀sùn ìfipábánilòpọ̀ COZA: Mi ò fípá bá obìrin lò pọ̀ rí láyé mi - Pásítọ̀ Fatoyinbo PFN: Fatoyinbo kọ̀ láti yọjú ni ìwádìí wa kò ṣe parí Ó ṣeeṣe kí Fatiyinbo pẹ́ díẹ̀ ní ibá ìfọ̀rọ̀wánilẹ́nuwò yìí lágọ̀ọ́ ọlọpàá nítori irú ìfọ̀rọ̀wánilẹ̀núwò yìí gba àwọn Dakólò ní wákàti mẹ́jọ gbáko kí wọ́n to pari.
Ṣugbọn kò pa àwọn ọmọ wọn, gẹ́gẹ́ bí ìwé òfin Mose ti wí, níbi tí OLUWA ti pàṣẹ, pé, “A kò gbọdọ̀ pa baba nítorí ẹ̀ṣẹ̀ ọmọ, tabi kí á pa ọmọ nítorí ẹ̀ṣẹ̀ baba; olukuluku ni yóo kú nítorí ẹ̀ṣẹ̀ ara rẹ̀.
Eyi ni aṣedanwo yoo fi han ni eyikeyi ibudo CBT ti ajọ JAMB ti fọwọ si fun iforukọ silẹ.
Nítorí láti ìgbà tí o ti wà ní ọmọde ni o ti mọ Ìwé Mímọ́, tí ó lè sọ ọ́ di ọlọ́gbọ́n, tí o fi lè ní ìgbàlà nípa igbagbọ ninu Kristi Jesu.
Igi ìdáná díẹ̀ ni mò ń wá níhìn-ín, kí n fi se ìwọ̀nba oúnjẹ díẹ̀ tí ó kù, fún èmi ati ọmọ mi; pé kí a jẹ ẹ́, kí a sì máa dúró de ọjọ́ ikú.
Bakan naa ni o so pe, awon akekoo yoku,ti won koi ti ri, ko le ju marun-un lo, tori pe, pupo awon obi ni won ti ri awon omo won.
"Fatima ṣalaye kikun pe: ""nibẹrẹ ni Aarẹ Buhari ti fun baba mi, Mamman Daura ni Glass House yii pe ki a maa gbe ti a si ti n gbe fun ọdun bii mẹta."
”Gbogbo àwọn tí wọ́n wà ní àpéjọpọ̀ náà sì ṣe “Amin”, wọ́n sì yin OLUWA.
Jehaleli sì ni baba Sifi, Sifa, Tiria, ati Asareli.
Ninu ilẹ̀ ẹ̀yà Isakari; wọ́n fún wọn ní Kedeṣi ati Daberati; 
Oríṣun àwòrán, @Alhaja Adeola Agoro Loru mọju oni ọjọ Aiku, ọjọ kinni, oṣu kọkanla, ọdun 2020 ni Wolii naa jẹ Olorun nipe.
Ogbẹni Femi Adesina to jẹ oludamọran fun aarẹ Mohammadu Buhari lori ọrọ iroyin ni kii ṣe pe ijọba fẹ tako aṣẹ ofin ile ẹjọ rara.
 } f ' enuko sí nomba pàtò gidí kan .
Bi Isẹlẹ naa se waye Gbajabiamila to sapejuwe iku fẹndọ naa gẹgẹ bi ohun to fọwọ kan ni lẹmi sọ pe awọn kuro ni ọfisi bi ise awọn ni tawọn si duro lati ki awọn to n ta iwe iroyin .
Alága méjì láàrín ọjọ́ kan, sinimá oríta láàrín àwọn adarí APC Ìdílé márùn-ún tó gbajúmọ̀ fún òwò ẹrú nílẹ̀ Yorùbá A kò tíì fi ìdí ẹ̀ múlẹ̀ pé ògùn Dexamethsaone ń ṣiṣẹ́ fún àrùn coronavirus Premier League gbìnàyá padà, ọ̀gá àti ọmọṣẹ́ fìjà pẹ̀ta Wo gómìnà márùn ún tí wọ́n ti fojú winá pẹ̀lú bàbá ìsàlẹ̀ wọ̀n Saaju idibo sipo gomina ni ipinlẹ Edo ni Osu Kẹwaa, Odun 2020, ohun to gba ẹnu awọn eniyan kan ni ija to bẹ silẹ laarin Adams Oshiomọlẹ ati Gomina ipinlẹ Edo, Godwin Obaseki.
Iroyin fihan pe abajade naa ti tẹ aarẹ lọwọ lati oṣu kejila, ọdun 2018.
Àwọn àgbààgbà Gileadi dá a lóhùn pé, “OLUWA ni ẹlẹ́rìí láàrin àwa pẹlu rẹ pé, ohun tí o bá wí ni a óo ṣe.
Yóo pada sídìí òwò aṣẹ́wó rẹ̀, yóo sì máa bá gbogbo ìjọba tí ó wà lórí ilẹ̀ ayé ṣe òwò àgbèrè.
Báwo ni n óo ṣe pada dé iwájú baba mi láìmú ọmọ náà lọ́wọ́?
Femi Gbajabiamila( adari gbimo asojue )Alaga
O ni bótilẹ̀ jẹ́ pé ìlànà àwọn iṣẹ́ abẹ ti ouhn ṣe jẹ́ eyi to wọ́n gidigidi ni ti Miílíọnu naira, síbẹ̀ oun yọlẹ se lábẹlẹ nótori àwọn ọmọ Niajiria ti yoo ma bẹ́nu atẹ lu oun.
Ẹ má ṣe jẹ́ kí ẹnikẹ́ni tàn yín jẹ lọ́nàkọnà nípa ọ̀rọ̀ yìí.
Ohun to bani ninu jẹ ju ni pe bi awọn eniyan ṣe n mu nkan ẹlẹrindodo jake-jado agbaye ti pọ si ju ti tẹlẹ lọ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù US presidential election 2020: Àwọn àkọ́lé ìròyìn tó leè jáde lẹ́yìn ìdìbò Ààrẹ Amẹrika 3 Bélú 2020 Oríṣun àwòrán, Getty Images Ni bayii ti idibo sipo Aarẹ ilẹ Amẹrika ti bẹrẹ ni pẹrẹwu, ibeere ti ọpọ awọn eeyan atawọn onwoye ohun to n lọ n bere ni pe ta ni yoo gbegba oroke ninu idibo naa?
Olori awọn oṣiṣẹ rọ awọn oṣiṣẹ nipinlẹ Eko lati jara mọ iṣẹ wọn, ki wọn si ṣiṣẹ wọn lai ṣọlẹ.
Obìnrin kò gbọdọ̀ jáde alẹ́ mọ́ ní Kano Atiku ni àgbàgbà Yorùbá ń bá lọ fún ipò Ààrẹ Sọ́ra fún gbájúẹ̀, BBC kò ṣètò owó ẹ̀kọ́ ọ̀fẹ́ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ṣọla Allyson: Obìnrin tí kò bá rẹwà ni yóò máa ṣí ara sílẹ̀ Ṣùgbọ́n, ìgbéyàwó kò ti lee sí ní ọkàn rẹ̀ rárá, nítorí pé ó n kẹ́kọ̀ọ́ láti gba oyè ìmọ̀ ìjìnlẹ̀ kejì nínú iṣẹ́ tó yàn láàyò ní fásitì Oxford, tó wà ní ilẹ̀ Gẹ̀ẹ́sì.
Orílẹ̀-èdè Togo gbe òfin tuntun silẹ̀ lórí ìwọ́de ìfẹ̀hónu hàn
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Sotitobire: Ọkọ mi kò mọ̀ Jegede PDP rí, kódà kò fa ẹnikẹ́ni kalẹ̀ dípò Akeredolu- Bisola Lara awọn to du ipo naa ni Arẹmọ Sanni Gbadegẹsin, Ọmọọba Ọlanitẹ Ajagba, Ọmọọba Afọnja Ilaka, Ọmọọba Sanda Ladepo Ọranlọla ati bẹẹ bẹẹ lọ Ọjọ Kẹrinla, osu Kinni, ọdun 1971 ni Ọba Lamidi Ọlayiwọla gun ori itẹ awọn baba nla rẹ, to si di Ọba Lamidi Ọlayiwọla Adeyẹmi kẹta Alaafin maa n sọla laarin awọn aya rẹ, paapaa awọn to jẹ ọdọ, ti wọn si tun jẹ oju ni gbese ni ọdẹdẹ, o si maa n mu wọn yangan lọ si ọpọ ibi to ba n lọ Lara awọn arẹwa aya Alaafin ni Olori Ola, Memunat, Badrat ati bẹẹ bẹẹ lọ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Eegunjobi Omotanbaje Ajobiewe- Èébú ní wọ́n kọ́kọ́ ń bù mí nígbà tí mo bẹ̀rẹ̀ ẹ̀ṣà pípé ní Ni ẹni ọdun mejilelọgọrin, Ọba Adeyẹmi ni okun ati agbara to ju tawọn ewe miran lọ, to si bi ibeji ni ẹẹmeji ati ibẹta Onkọtan, Onpitan ati ọlọpọlọ pipe ni Alaafin, ti ko si gbagbe ọpọ itan ilẹ Yoruba ati Naijiria lai naani ọjọ ori rẹ Lara awọn ọmọ Alaafin to gbaju-gbaja ni Amofin Babatunde, Ọmọọba Fọlasade, Taibat, Nurudeen Adesẹgun, Akeem Adeniyi (Skimmeh), Adebayọ Fatai ati bẹẹ bẹẹ lọ.
Ooni Ile Ife, Oba Adeyeye Enitan Ogunwusi lo sọrọ yii nigba to n dupẹ lọwọ Eleduwa fun anfaani ti o ni lati pe ọdun marun un lori itẹ baba rẹ.
Amọ, o ni oun n gbero lati gbe sinima kan jade ni bii oṣu meji si asiko yii.
Mo ka gbogbo nǹkan wọnyi sí àdánù nítorí ohun tí ó ṣe iyebíye jùlọ, èyí ni láti mọ Kristi Jesu Oluwa mi, nítorí ẹni tí mo fi pàdánù ohun gbogbo, tí mo fi kà wọ́n sí ìgbẹ́, kí n lè jèrè Jesu.
94, èyí só di ohun tómọ́lẹ̀jùlọ kẹta ní ojúsànmọ̀ àṣálẹ lẹ́yìn Òsùpá àti Àgùàlà.
Ẹni ọdun ọgọrin ọdun ni Arabinrin Beauty to n gbe ni ilu Odoni ni ijọba ibilẹ Sagbama ipinlẹ Bayelsa ti wọn si ji i gbe lọ gba ori omi lọ si ibi ti ẹnikẹni kò mọ̀.
Sùgbọ́n ní báyìí ènìyàn tó díẹ̀ ní ẹgbẹ̀rún mẹ́jiléláàdọ́ta ènìyàn lo ti ni ààrùn náà ní Nàìjíríà tí ènìyàn to dín díẹ̀ ni ẹgbẹ̀rún mọ́kàndínlógójì ló ti gbádun ti wọ́n sì ti pada si ilé wọ́n.
" O wa gba Laycon nimọran lati lo agbara rẹ fun didẹkun awọn iwa kotọ lawujọ, awọn iwa ti kii se ti ọmọluabi atawọn iwa ibi miran.
Ajakalẹ arun coronavirus yii lo n gba ẹbọ lọwọ gbogbo agbaye lati oṣu kejila, ọdun 2019 to ti bẹrẹ ni China.
Inú mi ìbá dùn bí OLUWA bá lè fún gbogbo àwọn eniyan rẹ̀ ní ẹ̀mí rẹ̀ kí wọ́n sì máa sọ àsọtẹ́lẹ̀.
Ki ijọba ati osisẹ jọ joko lati soro lo se pataki.
Eyi waye lẹyin ti ẹgbẹ agbesunmọmi Islamic State West Africa Province (ISWAP) ṣekupa awọn Kristẹni atawọn Musulumi kan ni ilu Borno gẹgẹ bi iroyin ṣe sọ ọ.
’ Nígbà tí ó lọ tán ni mo rí i pé ó fi ẹ̀wù àti ṣòkòtò dídára kan sílẹ̀ fún mi mo sì wọ̀ wọ́n, mo ká aṣọ mi tí ó tutù mo fi í sínú àpò mi.
Champions league: Chelsea gbélé fọrùn rọ́ ní Stamford Bridge, àwìn ni Valencia fi ṣẹ Lampard lọ́wọ́
“Nítorí náà, ẹ̀tọ́ ni kí á yan ẹnìkan ninu àwọn tí ó ti wà pẹlu wa ní gbogbo àkókò tí Jesu Oluwa ti ń wọlé, tí ó ń jáde pẹlu wa, láti àkókò tí Johanu ti ń ṣe ìrìbọmi títí di ọjọ́ tí a fi mú Jesu kúrò lọ́dọ̀ wa, kí olúwarẹ̀ lè jẹ́ ẹlẹ́rìí ajinde Jesu, kí ó sì di ọ̀kan ninu wa.
Idi eyi ni pe ko si ajẹsara kankan ninu agọ ara to lee dena arun yii nitori ko si ẹnu to lugbadi rẹ ṣaaju asiko yii ri.
O fikun wi pe awọn oloselu lorilẹede Naijiria lo wa ni idi isekupani ati ijinigbe to n waye ni awọn ilu to wa ni orilẹede naa lẹyin idibo gbogboogbo to kọja.
Ẹ má ṣe da ara yín pọ̀ mọ́ àwọn alaigbagbọ.
Nítorí pé wọ́n ti kọ̀ mí sílẹ̀, wọ́n ń sun turari sí àwọn oriṣa láti mú mi bínú nítorí iṣẹ́ ọwọ́ wọn.
“ko si nkan ti o se pataki larin emi pelu Obi; o kan je pe mo nife re pupo gege bi agbaboolu.
Ọ̀rọ̀ gbina, ó ti ń ràn nítori àwọn ọmọ Yahoo Bákan náà ni ikọ̀ IRT mú éni ogójì ọdún kan Shehu Abdullahi tí wọ́n pe ní ọ̀kan lára awọn ọmọlẹ́yìn Barau.
Lẹyin ti wọn gbe oku obinrin naa pada sile ni wọn ranṣẹ pe awọn to n lo ilana ibilẹ lati mu ejo.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ẹtàn ni àwọn ọ̀rẹ́ fi ń tan èèyàn lọ si Libya pé iṣẹ́ gidi wà níbẹ̀ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Abikẹ Dabiri: Iṣẹ́ pọ̀ lọ́wọ́ Naptin àti àwọn aṣọ́bodè Nàìjíríà Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Gẹgẹ bi Ọmọwe Olufemi Oke-Osanyintolu ṣe sọ ọ, awọn janduku yii ti ṣaaju ko epo sinu ọkọ akepo ti iwọn rẹ to lita ẹgbẹrun lọna mẹtalelọgbọn ti wọn si tun ti n ji omii ko sinu iru ọkọ akepo yii miiran nigba ti awọn agbofinro ya lu wọn.
Ẹrú kì í gbé inú ilé títí, ọmọ níí gbé inú ilé títí.
Koda ijọba rẹ tun tan ka de awọn apa kan lorilẹede Senegal, Mauritania, Burkina Faso, Gambia, Guinea Bissau, Guinea ati orilẹede Ivory Coast.
Ní gẹ̀rẹ́gẹ̀rẹ́ Luhiti, wọ́n ń sọkún bí wọ́n ti ń gòkè lọ,wọ́n sì ń kígbe arò bí wọ́n tí ń lọ sí Horonaimu.
Ṣé kò yẹ kí ẹ mọ̀ nípa ìdájọ́ òtítọ́?
Àkọlé àwòrán, LASEMA n ke gbajare lori awọn ile ti o ti daagun Igba akọkọ kọ ni yii ti ile a da wo nipinlẹ Eko, koda, ọkan ṣẹlẹ loṣu kéfa ọdun 2019 ni adugbo Mafoluku lasiko ti wọn n tun un ṣe lọwọ.
 kò pẹ ́ púpọ ̀ lẹ ́ jìn èyí ni ó bá lọ jà ogun kan , ṣùgbọ ́ n kí ó tó padà dé , ọmọ rẹ ̀ kan gbà òtẹ ́ ńlá kan jọ tí ó fi jẹ ́ wí pé agígírì kò lè padà sí ilée bajimọ mọ ́ .
Kí gbogbo nǹkan ẹlẹ́mìí yin OLUWA!
Ọlọrun fi ipá gba aṣọ mi,ó fún mi lọ́rùn bí ọrùn ẹ̀wù àwọ̀tẹ́lẹ̀ mi.
Awọn isẹ akanṣe yoku ni ọkọ bọọsi bọginni tuntun ati opopona tuntun to lọ si papakọ ofurufu.
Oguntuase ni ''bi nnkan o ba ku,ki n jinde,Eleka yoo jinde pada bi Lasaru inu Bibeli.
Gbẹ́kẹ̀lé OLUWA, sì máa tọ ọ̀nà rẹ̀,yóo gbé ọ ga, kí o lè jogún ilẹ̀ náà;nígbà tí a bá pa àwọn eniyan burúkú run, o óo fojú rẹ rí i.
Ọpọ́n orí ọ̀kọ̀ọ̀kan ga ní ìwọ̀n igbọnwọ marun-un (mita 2¼).
    Kí ìjà tó bẹ̀rẹ̀, Ìnàkí-ìbẹ̀rù ti wí fún ni pé ìgbà tí ìjà bá parí lálẹ̀ ọjọ́ náà, àwọn ẹranko ń fẹ́ kí a bá àwọn jẹun.
Ó kú ní ọ̀san àná ọjọ́ kẹ́jọ oṣù kẹjọ, ọdún 2018, ní ilé ìwòsàn Zenith Medical Kidney Hospital Abuja lẹ́yìn àìsàn kídìrín.
A ó ṣèrànwọ́ fáwọn ẹbí ọlọ́pàá tó bá rògbòdìyàn EndSARS lọ láti inú N500m tí a yà sọ́tọ̀- Makinde Kàyééfì!
Sambisa: Yóò di ibi ìgbàfẹ́ láìpẹ́ ọjọ́
Lanre Kuti ni mo fẹ́ - Jaiye Kuti Kìnìhún Manchester City tó bú ramúramù, ó fẹ́ pa Chelsea jẹ ni?
Ó di k’ó máa sun abẹ́ ewé, abẹ́ igi kiri.
Nàìjíríà bí ìkókó 26, 039 lónìí ọjọ́ kíní, oṣù kínií, ọdún 2020- UNICEF Ẹ̀kọ́ ọ̀fẹ́, ètò ilera ọ̀fẹ́ àti iná ọba ló jẹ wá lógún- ọmọ Nàìjíríà Ògo tuntun yóò sọ ní ọdún 2020!
 O ye ki a wa nkan se si ona kiko ohun jije pamo sii.
Awon apaniyan kolu awon eniyan ijọba ibile Riyom ati Barkin-Ladi ni Ipinle  Plateau to wa ni  aarin gbungbun orile ede Naijiria  nibi ti won ti fi emi opolopo awon  eniyan ati dukia sofo.
Sugbọn ọpọ Naijiria lo n woye pe ijọba orilẹede yii ko tii se ohun to yẹ, to ba si fẹ dẹkun ikọlu yii, o gbọdọ san sokoto rẹ ko le ni.
Ẹranko Ewèlè náà fún un ní agbára rẹ̀, ati ìtẹ́ rẹ̀ ati àṣẹ ńlá rẹ̀.
“Bí ọkunrin kan bá fẹ́ iyawo, tí iyawo náà kò bá wù ú mọ́ nítorí pé ó rí ohun àléébù kan ninu ìwà rẹ̀ tí kò tẹ́ ẹ lọ́rùn; tí ó bá já ìwé ìkọ̀sílẹ̀ fún un, tí obinrin náà jáde kúrò ní ilé rẹ̀, tí obinrin náà sì bá tirẹ̀ lọ; 
 Fun idi, ko ni dara ki wọn ṣe e ni dandan fun awọn ara ilu.
egbe oselu , All Progressives Congress (APC)wọle, ti won si ni ki gbogbo
Jesu bèèrè pé, “Ṣebí àwọn mẹ́wàá ni mo mú lára dá.
Bí a bá ya ìyẹ̀fun tí a kọ́kọ́ rí ninu ìkórè sí mímọ́, a ti ya burẹdi tí a fi ṣe sí mímọ́.
Israẹli bá wí fún Josẹfu, ó ní, “Níwọ̀n ìgbà tí mo ti fi ojú kàn ọ́ báyìí, tí mo sì rí i pé o wà láàyè, bí ikú bá tilẹ̀ wá dé, ó yá mi.
O ní lati ìgbà ti àwọn ti wà ní ilé ìwé alákọbẹ̀rẹ̀ ni Tolu ti fi hàn pé òun fẹ́ràn iṣẹ́ ọmọogun ojú òfurufú, ti ó si lọ si girama ọmọ ojú òfurufú bákan náà Musa gbadúrà pé ki ọlọrun dẹlẹ̀ fún Tolu ki o sì ran ẹbí rẹ̀ lọ́wọ́ ni àsìkò ìnira yìí."
Bẹ́ẹ̀ ni n kò sì fẹ́ kí irú nǹkan bẹ́ẹ̀ ṣẹlẹ̀ si yín.
Elere sisa merindinlogbon nipinle Kwara ti ko lo sipago fun igbaradi de idije orisi ere idaraya mewaa ti yoo waye ni ere odo ile Adulawo ni Algiers ni orile–ede Algeria laipe.
Gẹgẹ bi wọ́n ṣe sọ, iyanṣẹlodi naa jẹ ọna lati fẹhonu han lori ipo ti awọn fasiti orilẹede Naijiria, nitori bi ijọba ko ṣe maa nawo le wọn lori daada.
Bakan naa lo sọ pe ko si ẹni to le gba ijọba gbọ lori ọrọ to ba n sọ nipa Ibrahim El-Zakzaky.
Rwanda Sex: Wo bí àwọn obìnrin yìí ṣe máa ń gbáradì ojú abẹ́ wọn fún ìbálòpọ̀
Ó bá mú burẹdi, ó dúpẹ́ lọ́wọ́ Ọlọrun, ó bù ú, ó bá fún wọn.
Nígbà tí a sún díẹ̀, wọ́n tún sọ ìwọ̀n sinu òkun, wọ́n rí i pé ó jìn tó ọgbọ̀n mita.
Ikú òjijì kò jìnnà àmọ́ ọ̀nà méje rèé láti dènà rẹ̀ Ẹ̀yin gómìnà Yorùbá, ẹ wá ṣàlàyé ìdí tẹ fi ṣèfilọ́lẹ̀ ètò Àmọ̀tẹ́kùn - Iléeṣẹ́ ààrẹ Fásitì ìpínlẹ̀ Ekiti dá òṣìṣẹ́ 355 padà sẹ́nu iṣẹ́ Ilẹ̀ UAE ti n fún àwọn arìnrìnàjò ní ìwé ìrìnnà ọlọ́dún márùn ún Iran ní àwọn ṣe èyi láti gbẹ̀san ikú igbákeji ọgágun Iran Qasem Soleimani to wáyé lọ́sẹ̀ to kọja Ikọlu ilẹ̀ Amerika to wáye lọ́sẹ̀ to kọ́ja yìí lo ga júlọ láti dá ibáṣepọ ti ko dánmọràn láàrin orilẹ̀-èdè méjèèji tẹ́lẹ̀ rú pátápátá.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Winter Olympics: Saraki kan saara si awọn ọmọ Naijiria mẹta to ndije 22 Sẹ́rẹ́ 2018 Àkọlé àwòrán, Eyi jẹ igba akọkọ ti awọn ọmọ orilẹ ede Naijiria yoo dije ninu isọri ere yi lagbaye Awọn ọmọbinrin mẹta ti yoo soju ilẹ Naijiria nibi idije Olimpiiki ori yinyin, (Winter Olympics) fun igba akọkọ.
Awọn kan sọ pe wọn ma n lo Tramadol naa lati le ni okun fun ifipabanilopọ, to jẹ ọkan pataki lara iṣẹ buruku ọwọ wọn.
''Mi o fẹ itajẹsilẹ awọn alaiṣẹ nitori ki n le wa nipo agbara,'' Aarẹ Keita lo sọ bẹẹ.
Ni ọjọ abamẹta ni ikọ agbabọọlu Liverpool ati Manchester United yoo maa waako lati mọ ẹni ti yoo se ipo keji ninu atẹ igbelewọn liigi Premiership ilẹ Gẹẹsi.
Dafidi sì sọ fún Akiṣi pé, “Bí mo bá rí ojurere rẹ, jọ̀wọ́ fún mi ní ààyè ní ọ̀kan ninu àwọn ìletò agbègbè yìí kí n máa gbé.
Eyii to n tumọ si pe ninu idiyele tuntun naa, iye akoko ti eeyan fi n lo ina ni yoo ṣe odiwọn bi wọn yoo ṣe maa san owo ina si, eyii ko si ni nkan ṣe pẹlu iye owo ti wọn ra ina ọhun.
Lagos-50 FCT-24 Kwara-9 Edo-4 Kaduna-3 Ondo-2 Plateau-2 Apapọ awọn to ti ni ti pe 64,184, lara si ni 60,069 ti ri iwosan.
Ki ede Yoruba ma baa parun ni BBC Yoruba ṣe n ṣeto ibeere nipa 'Bawo lo ṣe gbọ ede Yoruba to?
"A gbiyanju takun-takun ninu idije yii, pẹlu wipe lile ti wọn le Bakayoko jade jẹ ohun ti o se ikunọ fun ẹgbẹ agbabọọlu Chelsea.
OLUWA ní, “Nítorí náà, wò ó, n óo jẹ́ kí wọn mọ̀;àní sẹ́, n óo jẹ́ kí wọ́n mọ agbára ati ipá mi;wọn yóo sì mọ̀ pé orúkọ mi ni OLUWA.
Minisita fun ọrọ obinrin ati idagbasoke, Sẹnatọ Aisha Alhassan, ti awọn eniyan ma n pe ni Mama Taraba, fi ipo rẹ silẹ ninu ẹgbẹ oselu APC lori ẹsun wi pe wọn ko fun oun laye lati dije dupo gomina labẹ ẹgbẹ oselu APC ni ipinlẹ Taraba.
Ẹni ọdun mejidinlogun ni Musfau saaju iku rẹ.
Lẹ́yìn ọ̀pọ̀lọ́pọ̀ oṣù tí òjò kò rọ̀ ní orílẹ̀èdè Cuba, Ọba ilẹ̀ Yorùbá ló pàṣẹ kí òjò rọ̀ níbẹ́ tó sì rọ̀-Elebuibon Olorì Aláàfín tẹ́lẹ̀, Anuoluwapo Adeyemi gba àmì ẹ̀yẹ lórí ipa tó kó nínú oge ṣíṣe Ṣé àwọn ìjayà ajaguntà ilẹ̀ òkèrè leè bá Nàìjíríà fòpin sí ìṣòro àbò?
Ìjọba ti pápákọ̀ òfúrufú Eko àti Abuja pa láti dènà àrùn coronavirus nípasẹ̀ wọléwọ̀de Ina ti jo dori koko bayii lori ọrọ ajakalẹ arun coronavirus lorilẹede Naijiria, ajọ to n ri si igbokegbodo ọkọ ofurufu, NCAA ti kede pe papakọ ofurufu ilu Eko ati Abuja yoo di titi pa lọna ọjọ Aje, ọjọ kẹtalelogun oṣu kẹta yii.
Lẹ́hìn eléyìí ọkùnrin kan tún wá síwájú Aṣojú-Olódùmarè, akọ̀wé kan báyìí ni, nígbà tí ó dé pẹ̀lú ìtara ni ó fi ń sọ̀rọ̀, tí ó ń fi orí sọ tí óo ń fi ọrùn sọ, ó ní, ìwọ ìránṣẹ́ Ẹlẹ́dàá ayé, ìwọ iranṣẹ́ Ẹlẹ́dàá ọ̀run, bá mi wí fún Ọlọ́run Ọba pé, kí Ó ba mi yí àwọn aláṣẹ ní ibi iṣẹ́ mi lọ́kàn padà, kí wọ́n yéé ṣí mi ní ipò padà lọ́dọọdún: kí n máa ti ìlú dé ìlú, kí n máa tí ìletò dé ìletò, kí n máa bá hílàhílo kiri; bí wọ́n tí ń ṣe mi yìí kò dára.
O kere tan o ni lati de papakọ ofurufu ni wakati mẹta ṣaaju ki baalu rẹ to gbera O ni lati tẹle ilana ijinasiraẹni nipa diduro lori awọn aaye ti wan ti ṣe ami si ti awọn oṣiṣẹ ilera yoo si yẹ bi ara rẹ ti ṣe gbona si Ti ara rẹ ko ba gbona pupọ, wọn ma ni ki o tẹsiwaju lati lo ọṣẹ ifọwọ lẹyin ti wa lọ gba iyọnda lati wọ baalu Ti ara rẹ ba gbona ju bo ti ṣe yẹ lọ, wọn ma da ẹ pada tabi ki wọn fi ọkọ agbe alaarẹ gbe ọ kuro ni kiakia Oríṣun àwòrán, FAAN Ri wi pe awọn aaye ti wọn ṣami si ni o duro si Bi o ba ti wọ inu ọkọ ti yoo gbe yin lọ sinu baalu, joko sọtọ si awọn ti ẹ ba jijọ wọ ọkọ Ki ẹ to wọ inu baalu,ri wi pe o jina si ẹni to wa ni iwaju rẹ Ri wi pe ẹni to fẹ wọ baalu ṣaaju rẹ wọle tan ki o to wọle Ninu baalu wọn ko ni fun yin lounjẹ kankan bi tatẹyinwa Ri wi pe o fi aaye ijoko to wa laarin kalẹ laarin iwọ ati ẹlomiiran Wọn yoo fi omi kalẹ si aye ijoko to wa niwaju rẹ ki o ba le muu fun ara rẹ O gbọdọ wọ ibomu lopin igba to ba wa ninu baalu Ti baalu ba ti balẹ,ri wi pe o dide lati gbe ẹru rẹ lẹyin ti ẹni to wa niwaju rẹ ba ti gbe ẹru rẹ sọkalẹ Aaye ibi ti wọn ṣe ami si ni ko gba lati lọ gba ẹru rẹ Duro si oju ibi ti wọn ṣe ami si lati gbe ẹru rẹ Ti o ba ti gbe baagi rẹ tan, to sẹyin awọn to wa niwaju rẹ ki awọn oṣiṣẹ ileeṣẹ ọkọ ofurufu baa le ṣe ayẹwo ẹru rẹ boya iwọ lo ni lootọ.
kí o lè ṣe ẹ̀tọ́ fún àwọn aláìníbabaati àwọn ẹni tí à ń pọ́n lójú,kí ọmọ eniyan, erùpẹ̀ lásánlàsàn, má lè dẹ́rù bani mọ́.
Awọn ọmọde lo pọju ninu awọn to dero ọrun naa.
 Àkọtọ ́ amharic ni wọ ́ n fi kọ ọ ́ sílẹ ̀ .
Ẹkẹta ni Absalomu, ọmọ Maaka, ọmọ Talimai, ọba Geṣuri.
Àwọn èèyàn jàǹkànjàǹkàn l'Akure bí Funke Olakunrin ti wọ káà ilẹ̀ lọ 'Kò sí ohun tó burú nínú bí Ajimobi ṣe dá Yewande tó pa ọkọ rẹ̀ sílẹ̀' Èèwọ̀!
BBC kò mọ̀ nípa àwọn ohun tí ó wà ní àwọn ojú òpó tí ó wà ní ìta.
Bí ògo Ọlọrun bá wá yọ lára rẹ̀, Ọlọrun fúnrarẹ̀ yóo mú kí ògo Ọmọ-Eniyan yọ; lọ́gán ni yóo mú kí ògo rẹ̀ yọ.
Lara awọn to ti fi ohun silẹ lori rẹ ni Sẹnetọ Shehu Sani.
 Ṣugbọn lẹyin isẹ abẹ ti wọn ṣe fun mi, ara mi ti ya."
Ṣugbọn àníyàn mi rí bí ọ̀rọ̀ tí ó wà ní àkọsílẹ̀ pé, “Àwọn ẹni tí kò gbọ́ nípa rẹ̀ rí, yóo rí i.
Ọ̀pọ̀lọpọ̀ ènìyàn ni kò sì mọ ìdí rè tí a fi máa ń ko ilà.
 ohun tí a máa ń rí nínú gbólóhùn gan-an ni ( 5 ) .
Bakan naa, ni awon ololufe re ti o wo orin ohun lojo kannaa ti o jade lori ero ayelujara YouTube ti le ni egberun lona ogorun eniyan bayii.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Sri Lanka Attacks: Ìbúgbàmù pa èèyàn 207 ní ilé ìjọsìn àti ilé ìtura lọ́jọ́ Àjíǹde 21 Ìgbé 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ipaniyan nilu ṣọọṣi Aarẹ Muhammadu Buhari ti ranṣẹ ibanikẹdun si awọn ẹbi eeyan to le lugba ti ṣagbako iṣẹlẹ ikọlu pẹlu ado oloro to waye lawọn ile ijọsin ati ile itura lọjọ Ajinde lorileede Sri Lanka.
Oríṣun àwòrán, edufuntechniknig Àkọlé àwòrán, Eyi ni igba akọkọ ti ikọ oludije ọjẹwẹwẹ Naijiria kankan yoo di abala asekagba idije naa .
Mo ti rù láàrin ọ̀sẹ̀ kan, iṣẹ́ Eko kò dẹ́rùn - Sanwo-Olu Ìdílé Pius Adesanmi ti gbé Boeing lọ sílé ẹjọ́ Àwọn àwòràn ilẹ̀ Afíríkà: Bí ètò àdúra ọdún musulumi àti àwọn ayẹyẹ miràn ṣe lọ Láti ìgbà díẹ̀ sẹyin ni ààrin Gomina ipinlẹ Kano Ganduje àti gómìnà ilé ifowopamọ apapọ tẹ́lẹ̀ri Sanusi Lamido Sanusi kò ti gún.
Ní abala ìrìnàjò afẹ́ yìí, amọ̀nà ṣe ìbéèrè: ṣé àwọn ọ̀gá obìnrin náà kò jẹ̀bi bí?
Ẹni tí ó bá ń dáko yóo ní ọ̀pọ̀ oúnjẹ,ṣugbọn ẹni tí ó bá ń lo àkókò rẹ̀ lórí ohun tí kò lérè, kò lọ́gbọ́n lórí.
Fayose fi ẹ̀sùn kan ìjọba àpapọ̀ Nàìjíríà pé ó rán àwọn ọlọ́pàá sí ìpínlẹ̀ Ekiti láti pá òun ṣáàjú ètò ìdìbò gómìnà tí yóò wáyé lọ́jọ́ kẹrìnlá, òṣù Keje.
"Gẹgẹ bi atẹjade naa ti wi, orukọ̀ awọn afurasi onijibiti naa ni Kazeem Agbabiaka Ajetumobi, Alhaji Femi Oyebode, ti gbogbo eeyan mọ si ""Atona"", Abdul Rassheed Ojonla, to tun n jẹ ""Apase Oodua"", Babatunde Oluajo ati Adebiyi Kehinde Oseni ti adape rẹ́ tun n jẹ ""Jagun""."
"Ẹ̀yin ẹlẹ́gbẹ́ òkùnkùn tẹ fẹ́ ṣe àjọ̀dún lónìí, lákọ la ń dúró dè yín - Iléeṣẹ́ ọlọ́pàá Àlàyé rèé lórí bí wọ́n ṣe pa Ebila, olórí àwọn ""One million boys"" n'Ibadan Ìsìpẹ́kítọ̀ d'àwátì, jàndùkú fara gbọta nínú ìjà ọlọ́pàá ati aráàlú ní Ogun Àwọn àádọ́ta ọ̀dọ́ wọ gàù nítorí ilé ijó ní Ilorin Ènìyàn 653 míràn tún kún iye àwọn tó ní COVID-19 ní Nàìjíríà Oríṣun àwòrán, others Àkọlé àwòrán, Aworan wahala to bẹ silẹ ni ọja kan nilu Eko lasiko ti awọn ọmọ ẹgbẹ Awawa yabo ọja naa."
6 5316 Orilẹede Liberia 84 1.
Afẹ́nifẹ́re kìí ṣe asọju ọmọ Yorùba ẹgbẹ́ lásàn ní wọ́n Èmi àti Saheed kìí ṣe ọmọdé, a ti jọ ṣe Sinimá papọ̀, èyí túmọ̀ sí pé ìjà ti parí - Fathia Balogun Ọ̀pọ̀ èèyàn bẹnu ẹ̀tẹ́ lu Mercy Aigbe lórí bó ṣe ki Adeniyi Johnson Àjẹ́ àti Aṣẹ́wó ní ìyá Rainbow - Òjòpagogo Nitootọ ni ìdìbò míràn á wáyé ní Kogi, mo máa di gómínà ni -Dino Ọgbẹni Oyeyemi ni iwadii si n lọ lọwọ lori awọn ajinigbe to fara gbọta nitori ko sẹni to tii sọ ohun kan fun ileeṣẹ ọlọpaa di akoko yii.
Èémí Ọlọrun níí pa wọ́n run,ninu ibinu rẹ̀, wọ́n a sì ṣègbé.
Awọn afurasí náà ní póńpó àti ìbọn ni àwọn fi pa wọ́n.
Sẹ́nátọ̀ àti Gómìnà àná, ẹ dá owó ìfẹ̀yìntì yín padà sápò ìjọba- Adájọ́ Ọwọ́ EFCC tẹ káńsẹ́lọ̀ olórí adigunjalè tó ń jí ọkọ̀ ní Kwara Njẹ́ ó mọ àwọn àìsàn aṣeku pani to rọ mọ ooru?
Ni imurasile fun eto idibo odun 2019 to n bo bayii, ni awon
"Bakan naa o mẹnu ba a pe lootọ ni ija wa laarin oun ati Alhaji Ayinde Barryster sugbọn bii ti iku kọ tori ""bi kii ba ṣe Barry ni iṣẹ aṣọle ni mi o ba maa ṣe""."
Ẹgbẹ́ agbábọ́ọ́lù AS Roma dá sí awuyewuye jọ̀lọ́fù
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Codeine: Àjọ aṣọ́bodè gba ògùn ikọ́ N200m lọwọ awọn onífàyàwọ́ 25 Agẹmo 2018 Oríṣun àwòrán, Nigeria Customs Service Àkọlé àwòrán, Ọga agba ajọ aṣọbode ni iwọ oorun gusu Naijiria Muhammad Garba sọ pe awọn ara ilu lo ta wọn lolobo nipa oogun naa Àjọ aṣọbode Nigeria ti já ogun ikọ olomi Codeine to owo rẹ to igba miliọnu naira gba ni Ijẹbu Ode, ni Ipinlẹ Ogun.
OLUWA tí ó gbà mí lọ́wọ́ kinniun ati beari yóo gbà mí lọ́wọ́ Filistini yìí.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Ọpọ lo ti n sọ pe asiko ti to lati le akọnimọọgba Ole Gunnar Soljskaer lọ lẹyin ti Man U ti n rakoro bi ọmọ ọwọ fun bi igba diẹ bayii.
Àkọlé àwòrán, Awọn eniyan to lati ra epo ni awọn ilu nla nla ni Naijiria Amọ ọpọlọpọ ara ilu ni Eko, Ondo, Abuja ati bẹẹ bẹẹ lo lo koju owongogo epo bẹntiro, ti o si fa sunkẹrẹ fakẹrẹ ọkọ lawọn ile epo kaakiri.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Champions league: Real Madrid jẹ wábiwọ́sí ìyà lọ́wọ́ PSG, Di Maria ló hun pàṣán ìyà wọn 19 Owewe 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Ode ko dara fun olukọni ikọ agbabọọlu Real Madrid, Zinedine Zidane atawọn agbabọọlu rẹ ni alẹ Ọjọru nigba ti wọn lọ koju Paris St-Germain ni idije Champions League.
wọ ́ n bi ní ìlú auchi , tí ó jẹẹ ́ ìlú kan ní town in ìpínlẹ ̀ Ẹdó ní orílẹ ̀ -èdẹ nàìjírìà .
kí ẹ lè mọ bí ìfẹ́ Kristi ti tayọ ìmọ̀ ẹ̀dá tó, kí ẹ sì lè kún fún gbogbo ẹ̀kúnrẹ́rẹ́ Ọlọrun.
Oríṣun àwòrán, others Àkọlé àwòrán, Ọdun 2014 ni Sanusi Lamido Sanusi jẹ oye Emir lẹyin ti wọn gba iṣẹ lọwọ rẹ gẹgẹ bi gomina banki apapọ Naijiria Gẹgẹ bi onimọ nipa ọrọ aje, Emir sọ pe ko si oore kankan ti ipinlẹ Kano fẹ ri lara owo yiya nitori pe iṣẹ akanṣe naa ko le so eso kankan.
Awọn to wa ni Naijiria ti wọn ba ri pe wọn ti ṣalabapade ẹni to ni arun ọhun lee pe nọmba 0800-970000-10 tabi 112.
Ati wi pe ki awọn ara ilu fi to ileeṣẹ ọlọpaa leti ti wọn ba gbọ ohunkohun tabi mọ ibi ti arakunrin Mustapha Adekunle ti wọn fi ẹsun kan wa.
OLUWA bá sọ fún Mose pé, “Mú ninu àwọn àgbààgbà ilẹ̀ Israẹli lọ́wọ́, kí ẹ jọ la ààrin àwọn eniyan náà kọjá, kí o sì mú ọ̀pá tí o fi lu odò Naili lọ́wọ́, bí o bá ti ń lọ.
BBNaija: Mercy ló gbadé BBNaija ọdún 2019
N óo wọ́n omi mímọ́ si yín lórí, àìmọ́ yín yóo sì di mímọ́.
Ìbáwí a máa dun ọlọ́gbọ́nju kí wọ́n nà òmùgọ̀ ní ọgọrun-un pàṣán lọ.
Ènìyàn 182 ni àjọ NCDC kéde pé ó tún ṣẹ̀ṣẹ̀ ní Covid-19 ní Nàìjíríà Ayálégbé wa tó fi tipá já àbálé mi ṣe àkóbá fún ìgbé ayé mi - Foluke Daramola Ìwọ́de bẹ̀rẹ̀ ní Minnesota lórí àwọn ọlọ́pàá mẹrin to pa ọmọ adulawọ ni Amẹ́ríkà Buhari buwọ́lu ẹkùn iléeṣẹ́ ọlọ́pàá márùn ún tuntun káàkiri Nàìjíríà Ìjọba fẹ́ ṣe ìwádìí ohun tí kò jẹ́ kí ìpínlẹ̀ Kogi àti Cross River tíì ní covid-19 Oríṣun àwòrán, Twitter Minisita eto ilera ni Naijiria, Dokita Osagie Ehanire sọ pe ijọba yoo ṣe iwadii ohun to faa gan an ti ipinlẹ Kogi ati Cross River ko fi tii ni akọsilẹ aarun coronavirus.
11 Ìjìyà ayérayé jẹ́ ìjìyà ti Ọlọ́run.
 kò sí ẹ ̀ rí tó tó láti so àjẹsára náà pọ ̀ mọ ́ ìnira tó jẹ mọ ́ àwọn àìsàn inú iṣan-ara .
Ohanaeze ni amọ awọn tako Osinbajo lori ọrọ rẹ wi pe adura ni ọna abayọ.
milionu marun un owo Euros fun
Oríṣun àwòrán, Big Brother Naija / Twitter Laycon yóò san owó orí tó súnmọ́ N8.
Ọgagun Soleimani padanu ẹmi rẹ lẹba papakọ ofurufu Baghdad nigba ti awọn ọmọ ogun Amẹrika yin ado oloro Drone kan lu to si ṣeku pa.
Ìjọba ayérayé ni ìjọba rẹ,yóo sì máa wà láti ìran dé ìran.
Lagos Prince: Ilé ẹjọ́ ṣèdájọ́ ikú f'ọmọ Ọba ìlú Eko tẹ́lẹ̀ lórí ẹ̀sùn ìpànìyàn
”Mo bá dáhùn, mo ní, “OLUWA, ìwọ nìkan ni o mọ̀.
Minisita ọrọ ilẹ Yuropu lorilẹede Faranse, Amélie de Montchalin ni esi ibo ilẹ Gẹẹsi ti tan imọlẹ si ọrọ BREXIT.
Bẹnaya, ọmọ Jehoiada, láti ìlú Kabiseeli, jẹ́ ọmọ ogun tí ó ti ṣe ọpọlọpọ ohun ìyanu, ó pa àwọn abàmì eniyan meji ará Moabu.
Àjẹ́ àti Aṣẹ́wó ní ìyá Rainbow - Òjòpagogo Wo àwọn ojúṣe àti èèwọ̀ fún ikọ̀ ọlọ́pàá SWAT tó gba iṣẹ́ lọ́wọ́ SARS Mi ò mọ̀ nípa àwọn tọ́ọ̀gì tó da ìwọ́de EndSARS Alausa rú, mo ṣì wà lẹ́yìn yín digbí!
Ṣùgbọ́n kíní òfin sọ nípa ṣíṣe àyẹwò fínífíní fún àwọn tí wọn bá yan sí ipò àti wí pé kí ni ìlànà tí wọn là kalẹ kí èèyàn tó lè di ipò mú ní Nàìjíríà?
Bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé ó ń kó fadaka jọ bí erùpẹ̀,tí ó sì to aṣọ jọ bí amọ̀;
Oríṣun àwòrán, EFCC/Fayose/Twitter Àkọlé àwòrán, Ẹ̀nu kun EFCC lórí ìkéde tó fi síta nípa Fayose níkété tí wọ́n kéde èsì ìbò gómìnà Ekiti EFCC sọ ninu ikede naa pe 'pọpọṣinṣin ti tan.
Kò séni tí kò ní jẹ́ ìpe Olódùmarè.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Sri Lanka áti India níkan ni irù ològbó yì wá O sọkalẹ oke odo naa pẹlu ọkọ oju omi ko to wa bẹ sinu odo naa to ti dawati di asiko yii.
Awọn iṣẹlẹ yii ati awọn miran to n waye jakejado Naijiria, lo mu ki awọn ara ilu gba oju opo Twitter lati sọ pe, awọn ko fara mọ bi aarẹ Buhari ko ti ṣe mu ọrọ aabo ni koko.
Bẹ ẹ si ni o le to ọjọ diẹ tabi ọsẹ melo kan ki ẹni to ba ni i to ni alaafia.
"A mo wi pe ara yoo ni awọn ara ilu lori idasẹsile nitori re ni alaga wa fi ni ki idasesile naa mo ni awọn ile iwosan ijọba apapo nikan bayi.
Ileẹjọ naa si paṣẹ ki Mabinuori san ẹgbẹrun marun un Naira ni oṣooṣu lati ma a fi tọju ọmọ rẹ.
Wọ́n wí fún wọn pé, “Ìtìjú gbáà ni ó jẹ́, pé kí a fi ọmọbinrin wa fún ẹni tí kò kọlà abẹ́, a kò gbọdọ̀ ṣe bẹ́ẹ̀ rárá.
Páro-páro ni àwọn mọ́ṣálááṣí dá káàkiri Nàìjíríà lásìkò ìrun Jímọ̀ nítorí coronavirus Ìjọba ìpínlẹ̀ Eko bẹ̀rẹ̀ oúnjẹ pínpín fún àwọn èèyàn lásìkò ìgbélé Coronavirus Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Coronavirus: Àwọn ìlana to tọ̀nà lati tọ ti o ba fún pe o ni ààrun Eeyan meloo ni o ti lugbadi arun yi Ibeere kan to jọ pe ko le ṣugbọn eleyi to si ṣe pataki nipa arun yi leyi jẹ Jakejado agbaye lati ka nipa ọkẹ aimọye eeyan to ko arun naa ṣugbọn lotitọ,diẹ leleyi jẹ lara awọn to ni gaan.
Genort Rohr: A ò ní já ẹ̀yin alátìlẹ́yìn wa kulẹ̀ lónìí
Ẹni tí ó bá kọ Ọmọ kò ní Baba.
Inú àgọ́ kan ni mo ti ń dé inú àgọ́ mìíràn, tí mo sì ń lọ láti ibìkan dé ibòmíràn.
Ninu ọrọ ti wọn sọ fun awọn oniroyin ni ajọ naa ti sọrọ lori bi orilẹede Naijiria ṣe ri lọwọlọwọ, ati ọna abayọ si ohun to dẹnukọlẹ ni Naijiria.
‘A kò jáde ṣe ìwọ́de ìtagbangba mọ́, inú ọkàn wa lá ti máa ṣe ìfẹ̀hónú hàn’ Yoruba ni taa ba ni eegun baba ẹni yoo jo, amọ ti ko ba jo mọ, ko si ẹni to lee mu ni si.
O fikun oro re pe, ile igbimo yoo tun joko sepade miiran lati duro de esi latenu minisita ohun, ti minisita ba si ko lati fesi, a o gba oro ohun bi eni n gba igba oti.
Ètò ìwọ̀n wúrà fún tabili àkàrà ìfihàn kọ̀ọ̀kan ati ìwọ̀n fadaka fún tabili fadaka kọ̀ọ̀kan, 
  Wọn kò ka igi yìí kún nǹkanan níbẹ̀.
Tori naa lọwọlọwọ, ko sẹni to bọ, tori eyi lao fi tẹsiwaju ni ṣiṣe ayẹwo lati mọ awọn to ni.
Wọ́n ni nibi ti ó ti ń kigbe ni awọn ara abule ti wa ti àwọn oniṣẹ́ ibi yii sa lọ.
Ṣugbọn gbogbo àwọn ará ilẹ̀ Juda pa àwọn tí wọ́n pa Amoni ọba, wọ́n sì fi Josaya ọmọ rẹ̀ jọba.
 Àwọn ènìyàn koin ní wọ ́ n sì ń sọ ọ ́ .
Arabo Ibrahim Bayo, ni awon wa  si orile
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìjọba Nàìjíríà; Ohun burúkú ni láti pa àwọn olùjọ́sìn 2 Èbibi 2018 Àkọlé àwòrán, Ènìyàn tó lé lọ́gọ́ta lo fara káasa nínú ìṣẹ̀lẹ̀ náà.
Nítorí ní àkókò Noa, wọ́n ń jẹ, wọ́n ń mu, wọ́n ń gbeyawo, wọ́n ń fi ọmọ fọ́kọ, títí di ọjọ́ tí Noa fi wọ inú ọkọ̀, ìkún-omi bá dé, ó bá pa gbogbo wọn rẹ́.
Aliyu Sadiya Umar Faruk Ìdí ti a fi kọ̀ láti fi El-ZakZakky sílẹ̀ -Ileeṣẹ Aarẹ Buhari Òkìtì iyanrìn wó pa èèyàn méjí nílùú Ibadan Èèmọ̀!
Ilé ẹjọ́ Èkìtì d'ájọ́ ikú f’ọ́kùnrin tó jí ọtí méje áti páálí sìgá
àwọn tí nǹkan wọnyi ṣojú wọn, tí wọ́n sì sọ fún wa.
Hubert Ogunde rèé, baba àwọn òsèré tíátà Ẹ̀wọ̀n tí mo lọ ni ẹ̀san ìwà tí mo hù gẹ́gẹ́ bíi olórí ológun- Buhari Pervez Musharraf, Àarẹ ológun Pakistan nígbà kan rí gbọ́jọ́ ikú Yàtọ̀ sí Olúwó, wo àwọn Ọba alayé tó ti kọ ìyàwó rí láìpẹ́ nílẹ̀ Oodua Oríṣun àwòrán, Empics Àkọlé àwòrán, Tenientertainer: Olórin obìnrin tí kìí ṣi ìhòhò rẹ silẹ̀- Olólúfẹ Teni Ọ̀rọ̀ yìí wá di gbigbà bi ẹni gba igbá ọti nígba ti @Benita_Fairy kọ pé Teni fí han pé àwọnn obinrin ọlórin lé ṣe àṣeyori lái ṣí ìhòhò wọ́n sílẹ̀ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Iná PHCN tó dé lójijì ṣàkóbá ńlá ní Ibadan Ní kété to sọ èyí tan ni àwọn ènìyàn bẹ̀rẹ̀ si ni gbàá bi ẹni gba igbá oti, bi àwọn kan ṣe ni kìí ṣe oun nikan ni kìí ṣí ìhòhò rẹ̀ sílẹ̀ ní àwọn míràn ni iṣe ọkunrin lo n ṣe ni kìí ṣe ṣi ara silẹ̀.
Ó ní, “Ẹ kó àwọn olùfọkànsìn mi jọ sọ́dọ̀ mi,àwọn tí wọ́n ti fi ẹbọ bá mi dá majẹmu!
Adajọ́ náà ni wọ́n yóò tú Ndume sílẹ̀ ni ọgbà ẹ̀wọ̀n Kuje, ní kété tí o bá ti ṣètò gbogbo, tó sì san owó tó yẹ ki ó sàn.
Èrè rẹ̀ ń bẹ lọ́wọ́ rẹ̀, ẹ̀san rẹ̀ sì ń bẹ níwájú rẹ̀.
Ọbasanjọ fi kun pe ireti wa pe laipẹ yii ni ilẹ Naijiria yoo ni aarẹ ti yoo buwlu iwe adehun naa.
 Kọmisana naa, ti ọpọ eeyan mọ si Banik sọ pe, ijọba ipinlẹ Osun ko tii gbe igbesẹ kankan lori iwe ẹhonu ọhun."
Láti ibẹ̀ ni ó ti lọ sí Beeriṣeba.
Gẹgẹ bi akọsilẹ ajọ Unicef ṣe sọ ọ, ida marundinlogoji ọmọbinrin Afghan lo ti maa wa nile ọk nigba ti wọn ba fi pe ọdun mejidinlogun, ida mẹsan wọn si lo ti ṣeyawo ki wn to pe ọdun mẹẹdogun.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Say no to rape: Àwọn òṣèré tíátà Yorùbá pariwo síta lórí wàhálà ìfipábánilòpọ̀ Koda iroyin ti sọ ọ ri pe oun ati iyawo ti wẹ ẹsẹ awọn eeyan laarin ero pupọ ri eyi si jẹ ki awọn eniyan nigbagbọ ninu rẹ.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Dókítà aláwọ̀ dúdú kéde òògùn Chloroquine fún ìwòsàn Coronavirus, Facebook yọ fídíò náà dànù Òtítọ́ lékè!
Oluwa rẹ̀ sọ fún un pé, ‘O ṣeun, ìwọ olóòótọ́ ẹrú, eniyan rere ni ọ́.
Eeyan mẹta lo ti jalaisi bayii nibi irin idaro Ashura ti awọn ọmọlẹyin Shite ṣe nilu Kaduna.
won ti n ka apapọ ibo .
Jomanex Kasaye náà ṣe ìrántí ìwàyáìjà ọpọlọ tí ó ní í ṣe pẹ̀lú ìrònú ìfìlú Ethiopia sílẹ̀ kí wọ́n ó tó fi ọwọ́ òfin mú àwọn ọ̀rẹ́ẹ rẹ̀  ìrora àìlágbára  ìlàkàkà ọkàn àti àìfẹ̀dọ̀lórí òróòró àti ìbẹ̀rù wípé àwọn ọ̀rẹ́ òhun ò ní jáde láàyè.
APC ni awọn ko ni fi ṣọwọ nitori ko nilo mọ.
El Rufai: Ìjọba kò ní pẹ́ fi àwọn tó dá wàhálà sílẹ̀ jòfin Gomina ipinlẹ Kaduna, Mallam Nasir El-Rufai ti fi ẹdun ọkan rẹ han si ija ẹsin to waye nipinlẹ naa lọsẹ to kọja, ninu eyi ti ọpọlọpọ eniyan ti padanu ẹmi wọn.
Bawọ ni o ti ṣe ma n ṣe ti awọn akẹgbẹ r to ku ba n jẹ ounjẹ ni ile iwe?
Ninu ọrọ rẹ, alaga igbimọ to n ṣe iwadii ileeṣẹ DSTV, Unyime Idem sọ pe ile bẹrẹ iwadii lẹyin tawọn ọmọ fi ẹhonu han lori afikun owo tariifu DSTV.
Laipẹ yii ni iroyin kan jade sita pe awọn kan n lo kẹmika naa lati fi ṣe ounjẹ wọn lọjọ, ko ma ba a bajẹ, ṣugbọn ajọ NAFDAC ti sọ pe o lewu fun ilera ara.
Tó bá dínkù dé'bìkan tí kòsí àjẹára fún ènìà mọ́, 
A o maa jabo awon esi miran ti
Ìyá dú ọmọ rẹ̀, o yíi láta, ó sì tún jòkó jẹ ẹ́ Ki o to di asiko yii, awọn ara agbegbe naa gbagbọ pe ti awọn ba gba abẹrẹ ajẹsara fun ọmọ wọn, awọn oyinbo naa n gba nkankan ninu ẹjẹ ati egungun awọn ọmọ wọn ni.
Awọn ologun ati ikọ ọmọogun WAI si wa nitosi lati fi iya jẹ ẹnikẹni to ba tapa si ofin naa.
O fi kun oro re pe, apapo iye esi idanwo ti won gbese le fun ayewo n lo bi ogofa, 111,981 , (One Hundred and Eleven Thousand, Nine Hundred and Eighty-One )Gege bi oro ajo naa pe, “leyin ti won wo aworan ori ero CCTV lasiko ti idanwo naa n lo, ti a si wo akosile iroyin latodo awon alamoju idanwo naa ati awon omo orile-ede Naijiria rere ti won nife si eko to yanranti lorile-ede Naijiria, ajo JAMB ti gbe abajade esi idanwo ti iye re n lo bi milionu meji jade 1,502,978, (One Million, Five Hundred and Two thousand, Nine Hundred and Seventy-Eight, eyi ti won jokoo fun idanwo abawole ile-eko giga fun ti odun 2018.
Kunle Afolayan, òṣìṣẹ́ báńkì tẹ́lẹ̀ kó tó di gbajúgbajà òṣèré Ilé ẹjọ́ kọ̀ láti tú Omoyele Soworẹ sílẹ̀ Nǹkan kò tíì ṣẹnu ire fún àwọn ọmọ orílẹ̀-èdè yìí - Atiku Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Nigeria Independence Day: Sé ẹ mọ̀ pé ọdún 1956 ló yẹ́ ká ti dòmìnira ṣùgbọ́n.
Ninu ọrọ rẹ, Infantino gbe iṣejọba tirẹ wo lẹgbẹkẹgbẹ ohun to jogun ba.
Ṣugbọn o ti wa ni iyasọtọ bayii fun itọju, Fellaini ni agbabọọlu akọkọ ni idije liigi ilẹ China to gbajugbaja julọ ti yoo kọkọ ko arun naa.
Ọmọ Nàíjíríà: Eré ìtàgé lágbo òsèlú bẹ̀rẹ̀ lẹ́yìn BB Naija
Mi o ro pe o ni ṣe pẹlu rẹ nitori gbogbo awọn agba ẹgbẹ lo wa nibi ti a ti sọ pe awa Yoruba ko faramọ Ruga Settlement ni ilẹ Yoruba.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Àwa àti fijilanté pẹ̀lú ọdẹ́ ìbílẹ̀ ló dojú kọ adigunjalè ní First Bank Okeho - Iléeṣẹ́ ọlọ́pàá Ìtàn ọba Yorùbá tí wọn yẹgi fún torí ó jí ọmọ gbé ṣe ètùtù Ẹ káàbọ̀ sọ́jọ́ Arafat, tí Ọlọ́run yóò fi ààwẹ̀ Mùsùlùmí pa ẹ̀ṣẹ̀ wọn rẹ́ Akẹ́kọ̀ọ́ Babcock tí wọn bá lòpọ̀ nínú fídíò rí ẹ̀kọ́ ọ̀fẹ́ ní fásitì òkè òkun Aláwàdà ni ọmọ mi láti kékeré, kò ṣẹ̀ṣẹ̀ máa gbé mi mọ́ra- ìyá ‘Mummy calm down’ (Toluige Olokoobi Babalola) Wo ìyàtọ̀ tó wà láàrin Bíbélì Yorùbá tí Kumuyi kọ sí èyí tó wà ńlẹ̀ Ìkúnlẹ̀ abiyamọ, ìkókó mẹ́jọ kú nílé ìwòsàn lálẹ́ ọjọ́ kàn Dayo Amusa gbarata lórí bí agbófinró ṣe ń pa ọ̀dọ́ láì nídìí Bakan naa lo ni ọmọ oun kii fi ero rẹ pamọ, o ma n sọ bi o ba ṣe ri ni ọkan rẹ ni.
Jẹ́ kí ọjọ́ náà ṣókùnkùn biribiri!
Eleyi jẹ ki imúra Yorùbá gbayì ni gbogbo àgbáyé.
ni gbolohun ti Israel Adesanya fi da awọn alatako rẹ lohun lẹyin to da bantẹ iya fun Paulo Costa ninu ija wọn to waye ni Dubai.
Ti ija ba waye laarin ileto si ileto, tabi ipinlẹ si ipinlẹ, ẹtọ Maiyegun ni lati ri wi pe wọn wa opin si aawọ naa laarin ilu mejeeji.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Arsenal: Emery ní òun fẹ́ kí agbábọ́ọ̀lù tí kò fakọyọ bínú 16 Owewe 2018 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Arsenal fìyà jẹ Newcastle mọ́lé Akọnimọọgba ikọ Arsenal Unai Emery sọ oju abẹ niko nigba to sọ pe ko kan oun ti awọn agbabọọlu ikọ naa ba binu ti oun ba parọ wọn ninu ifẹsẹwọnsẹ kankan.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Mí ò le nífẹ̀ẹ́ obìnrin Nàìjíríà kankan mọ lẹ́yìn ti mo ti tọ́ obìnrin òyìnbó wò- Issa 21 Sẹ́rẹ́ 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 22 Sẹ́rẹ́ 2020 Àkọlé àwòrán, Issa, ẹni ọdún mẹ́rìndínlọ́gbọ̀n fẹ́ ẹ́ fẹ́ ọmọ America, Janine Sanchez, tó jẹ́ ẹni ọdún mẹ́rìndínláàdọ́ta.
Eleyii ya ni lẹnu pupọ ju.
Amọ ijọba ko laa kalẹ boya eto ọgbin oni ọkọ ati ada ni tabi ti ọna igbalode.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Ṣugbọn awọn kan ninu ile naa faake kọri pe ko si ohun to buru ninu ki Aarẹ wa ṣo fun awọn ọmọ Naijiria awọn ohun to n ṣe lori eto abo ẹmi ati dukia wọn.
idigunjale; ifipabanilopo; ati fifi eya ara eniyan setutu ọla.
’Lóòótọ́ o ti sọ bẹ́ẹ̀ tẹ́lẹ̀,ṣugbọn o ti ṣe ìwọ̀n ibi tí o lè ṣe.
Nisinsinyii ó ti yé wọn pé láti ọ̀dọ̀ rẹ ni ohun gbogbo tí o fún mi ti wá.
Ìkádìí A bí Moshood Olalekan Adeoti ni Ilú Ìwo, ijọba ibilẹ Iwo ní ìpínlẹ̀ Osun lọjọ́ kẹ́tàdínlogun oṣù kejì ọdún 1953 Ó bẹ̀rẹ̀ ilé ìwé alákọbẹ̀rẹ̀ ní District Council Primary Schoollọdun 1959 àti Aipate Day School lọdun 1964, lẹ́yìn náà ló lọ ilé ìwé Grammer lọdun 1974 Moshood Adeoti gboyè ìmọ ìṣòwò láti Fasiti Benin lọdún 1984 Moshood Olalekan Adeoti jẹ alága ẹgbẹ́ òṣèlú Alliance For Democracy 1998-2003, alága ẹgbẹ́ òṣèlú Action Congress 2006-2010 àti alága Action Congress of Nigeria ti alaga àkọkọ fún ẹgbk oselu APC 2010-2011 Isiaka Oyetola All Progressives Congress (APC) < Padà lọ sí ọ̀dọ̀ Olùdíje Kíni ọjọ́ ìbí yin?
Igbimọ naa kede idaduro Ọjọgbọn Ogundipe nibi ipade wọn to waye ọfiisi igbimọ to n mojuto ọrọ awọn fasiti ni Naijiria, NUC niluu Abuja.
Buhari sisọ loju ọrọ naa lọjọ isẹgun nibi opin ipade agbeyẹwo awọn minisita to waye nile ijọba nilu Abuja.
Ajà-fún-ẹ̀tọ́-ọmọnìyàn yìí ń jáde lábẹ́ àsíá African Action Congress.
Nípa igbagbọ ni ó fi ń gbé ilẹ̀ ìlérí bí àlejò, ó ń gbé inú àgọ́ bíi Isaaki ati Jakọbu, àwọn tí wọn óo jọ jogún ìlérí kan náà.
Òfin to gbe àjọ NYSC kalẹ̀ lorilẹde Naijiria sọ pe o di dandan fun gbogbo ẹni to ba kàwé gboyè ni ile ẹ̀kọ́ giga, yálà lorilẹede Naijiria tabi loke òkun lati sinlẹ̀ baba wọn fun ọdun kan.
Ọ̀dọ̀ fásitì jànkàn Oxford ló ti jáde Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí kan sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
Bi sisun ni ihoho ba wa le ran ọ lọwọ lati ni eyi, o o ri pe iyẹn tun dara.
Sarumi Ni obìnrin àkọ́kọ́ tí yóò gbégbá ipò gómìnà l'Ọyọ
Marie Josee Ta Lou lojoBo(Thursday), gba ami-eye goolu ninu ere ije ti o sa fun wakati mokanla ati iseju marundinlogun, saaju akegbe re omo ile Ghana  Janet Amponsah ti oun sa ere naa ni wakati mokanla ati iseju mẹ́rìnlélọ́gọ́ta; bee si ni Udo Joy-Gabriel omo orile-ede Naijiria se ipo keta ni wakati mokanla ati iseju mẹ́rìndínláàdọ́rin.
Kí Òjòlà-ìbínú tóó kú, ó mọ̀ pé àwa ni, ó sì kígbe wa lọ sí ọ̀run.
“Aaroni yóo pada wá sinu Àgọ́ Àjọ, yóo bọ́ àwọn aṣọ funfun tí ó wọ̀ kí ó tó wọ inú ibi mímọ́ lọ, yóo sì fi wọ́n sílẹ̀ níbẹ̀.
Wọ́n dá a lóhùn pé, “Ọlọrun àwọn Heberu ni ó farahàn wá; jọ̀wọ́, fún wa ní ààyè láti lọ sí aṣálẹ̀ ní ìwọ̀n ìrìn ọjọ́ mẹta, kí á lè lọ rúbọ sí OLUWA Ọlọrun wa, kí ó má baà fi àjàkálẹ̀ àrùn tabi ogun bá wa jà.
Mo dúró de ìgbàlà rẹ, Oluwa.
Ni ọdun 1997 lo kan lu agbami oowo sise.
"Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, RAMADAN: Onímọ̀ ẹ̀sin sọ nípa isẹ́ láádá àti làádà ""Eniyan mẹtadinlogoji lori yọ - arinrinajo mẹtalelọgbọn ati oṣiṣẹ mẹrin"" lohun ti ọkan lara awọn igbimọ aṣewadii, Yelena Markovskaya sọ."
Ẹwẹ, ninu atẹjade ti oludari agba ajọ LASEMA, Ọmọwe Olufemi Damilola Oke-Osanyintolu fọwọ si, wọn gba gbogbo araalu nimọran lati maa moju to awọn ọmọde gidi gan lawọn agbegbe ti iṣoro omiyale n da laamu.
Alaga egbe ohun, Adamson Momoh, fi idunnu re han bi eto naa se lo, bee si ni o fi da awon omo egbe ati awon torokan gbongbon ninu egbe naa loju pe oun yoo sa ipa re lati ba awon omo egbe sise papo.
'Ọdún 2019 pẹ̀lú àwọn àsọtẹ́lẹ̀ tó kó lọ́wọ́ dé' Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ṣọla Allyson: Obìnrin tí kò bá rẹwà ni yóò máa ṣí ara sílẹ̀ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, New year message: Buhari, Jonathan, Atiku, kí àwọn ọmọ orílẹ̀èdè Nàìjíríà Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Ọpọ awọn orukọ si ni wọn maa n pe ara wọn bii 'Ẹlẹ Daddy' abi 'Oxygen' Alaafin, ti ariyanjiyan si tun maa n wa lati mọ ẹni ti oriki naa tọ si.
Ọmọ ilẹ̀ Kenya gbé ‘búrọ́ọ̀ṣì ìfọyín’ mì nígbà tó ǹ fọyín
Shekau to jẹ olori igun kan lara ikọ Boko Haram ṣekilọ pe irufẹ ipaniyan bẹẹ lawọn yoo maa fi bẹ gbogbo awọn to ba n lẹdi apo pọ pẹlu ileeṣẹ ọmọogun Naijiria.
Kì bá wù mí kí ẹ jọba nítòótọ́ kí àwa náà lè ba yín jọba!
“Ohun ti o baa le mu ki igbimo toro kan gbongbon ninu egbe oselu APC fowo soya bowolu enikan gege bi oludije dupo aare, ko si ohun ti o le ye oro naa.
Ó gbé àpótí ẹ̀rí náà sinu àgọ́ náà, ó sì ta aṣọ ìbòjú rẹ̀ dí i gẹ́gẹ́ bí OLUWA ti pàṣẹ fún un.
Ọrọ yii ti n mu ki awọn eeyan maa sọ orisirisi ero wọn nipa rẹ lori ayelujara.
Boasi bá dáhùn, ó ní, “OLUWA yóo bukun fún ọ, ọmọ mi, oore tí o ṣe ní ìkẹyìn yìí tóbi ju ti àkọ́kọ́ lọ; nítorí pé o kò wá àwọn ọdọmọkunrin lọ, kì báà jẹ́ olówó tabi talaka.
Báyìí ni gbogbo àwọn tí kì í ṣe Juu yóo máa wá Oluwa,ati gbogbo àwọn orílẹ̀-èdè mìíràn tí mo ti pè láti jẹ́ tèmi.
Ó yàn wá kí á lè jẹ́ ẹni tí a yà sọ́tọ̀, tí kò ní àléébù níwájú rẹ̀, tí ó sì kún fún ìfẹ́.
 lọ ́ gán tí àkóràn àrùn náà bá ti bá ènìyàn kan , àrùn náà lè tàn káàkiri bákan náà láti ara ènìyàn kan sí èkejì .
Lọjọọru ọsẹ to kọja ni ileesẹ ọtẹlẹmuyẹ apapọ orilẹede Naijiria, DSS ransẹ pe ọgbẹni Tony Ezimakor, lati igbayii ni ẹnikẹni ko si ti rii.
Ọpọ awọn oloufe Aramide lo ti n selede lẹyin rẹ loju opo facebook.
Okechukwu  so pe “ise akanse ohun amayederun ti aare  Buhari gunle   bi i oju –popo, oju oko irin, ise agbe ati ina mona-mona lo pọ julo lorile ede Naijiria.
Eto ẹkọ Imugbooro eto ilera fawọn akẹkọọ girama ileewe adani lawọn agbegbe ti ko ni iru anfaani bẹẹ.
ó bẹ̀ wọ́n pé, “Ẹ jọ̀wọ́, ẹ̀yin arakunrin mi, ẹ má hu irú ìwà burúkú yìí.
Mose bá na ọ̀pá rẹ̀ sójú ọ̀run, Ọlọrun sì da ààrá ati yìnyín ati iná bo ilẹ̀, Ọlọrun sì rọ̀jò yìnyín sórí ilẹ̀ Ijipti.
Wọ́n ń kọ lálá sí àwọn ìlú Juda.
Àwọn ará Kiriati Jearimu ati Kefira ati Beeroti jẹ́ ọtadinlẹgbẹrin ó lé mẹta (743).
Bẹ́ẹ̀ ni Mose ṣe ṣàlàyé àwọn Àjọ àjọ̀dún tí OLUWA yàn, fún àwọn ọmọ Israẹli.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Anatomy Book: Ọjọgbọn nílé ìwòsàn UCH àti UI gbé ìwé orúkọ ẹ̀yà ara lédè Yorùbá jáde 21 Bélú 2019 Àkọlé àwòrán, Awọn orukọ ẹya ara ọkunrin niwaju ati feremu ara lede Yoruba yii kamọmọ Àkọlé àwòrán, Ojogbon Durotoye Adeleke salaye ni kikun nipa iwe eya ara yii ni eyi ti egbe Atunbi Yoruba ati Oasis Health Foundation se agbateru re ni UCH ni fasiti Ibadan.
Ìyàwò lárìnlọọ̀dù mi pè mí ní akálòlò ni mo ṣe paa - Afurasí Ìpàdé àpérò kọ́ ló kàn, àdánìkànjẹ ẹ̀yà kan ni ká dẹ́kun ní Nàíjíríà - Òǹwòye Spaghetti, mílíìkì, Chivita àti Àǹkàrá sọ Rabiu dèrò ẹ̀wọn ni Eko A ti rí akẹ́kọ̀ọ́ ABU tí wọ́n jígbé lọnà Kaduna-Abuja gbà -Ọlọ́pàá Van Dijk ni agbabọọlu adiẹyin mu akọkọ ti wọn yoo maa wo boya o le gba ami ẹyẹ naa.
Oríṣun àwòrán, Getty Àkọlé àwòrán, Lootọ ni ko ṣeeṣe ki a ma darugbo, ṣugbọn gbigbe igbeaye ilera to peye le dinku 8.
Parí iṣẹ́ tí ò ń ṣe níta,tọ́jú gbogbo nǹkan oko rẹ,lẹ́yìn náà kọ́ ilé rẹ.
Ikọ awọn osisẹ ọba naa, ti Oludari kan nileesẹ ọrọ ayika, Awoniyi Joshua ko sodi, lo pasẹ pe ki wọn ti ibudo atọkọse naa pa.
"Bi o tilẹ jẹ pe mọlẹbi aran ni wọn, o wọpọ ki wọn maa pe wọn ni ""ẹja Penis""."
“Ẹ̀yin olóríkunkun, ọlọ́kàn líle, elétí dídi wọnyi!
Ilu Ọwọ ni ileewosan nla ti ijọba apapọ, FMC to wa nibẹ ni Olori Naomi Silekunola ti lọ bimọ rẹ si.
ni won da awon eniyan naa si, o ni  balu akọkọ
awon akekoo yii ti iye won le ni egberun lona àádọ̀rún ,ti won n je anfaani eto yii nile iwe naa .
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Suicide Prevention: ìwọ́de yìí wáyé láti gbógun ti pípa ara ẹni Uwem sọ pe oriṣiriṣi idi ni awọn eeyan ṣe le fi ipa banilopọ, bi arun ọpọlọ ati awọn awọn idi miran.
Ọsẹ to kọja ni Gomina Ipinlẹ Ọyọ, Seyi Makinde sọ wi pe eto isuna ti gomina ana, Abiola Ajimobi se kii se isuna ti awọn le e sisẹ le lori.
Nibayi to pe ọdun mejidinlọgbọn ti Olusola Isola Ogunsola jade laye, to si fi ọpọ ọmọ silẹ saye lọ, a si n gbadura pe ki ọba oke tẹ si afẹfẹ rere, ko si di idile to fi silẹ saye lọ mu sinsin.
“Mo pàṣẹ fún àwọn adájọ́ yín nígbà náà, mo ní, ‘Ẹ máa gbọ́ ẹjọ́ àwọn arakunrin yín, kí ẹ sì máa ṣe ìdájọ́ òdodo láàrin eniyan ati arakunrin rẹ̀, tabi àlejò tí ó wà lọ́dọ̀ rẹ̀.
Mahrez dá Super Eagles dùbúlẹ̀ lórí pápá oko tútù Pípè fún ìfẹ̀hónú hàn túmọ̀ sí ìdìtẹ̀ gbàjọba àti ìgbésùnmọ̀mí - Ọlọ́pàá Abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò dágbére fáyé lẹ́yìn ìjà rẹ Èmi kò gbé pọ̀ pẹ̀lú Kollington Ayinla àmọ́ ọjà t'ọ́mọ ti wọ̀ lọ̀rọ̀ àwa méjééjì - Salawa Abẹni Ó tó gẹ́ẹ́!
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Buhari ti sofin aleekun owo ori ileese ọti ati siga 11 Ẹrẹ̀nà 2018 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Minisita fun eto isuna sọ pe orilẹede Naijiria ni wọn ti n gba owo ori to kere julo lori tobacco Ijọba apappọ orilẹede Naijiria ti mu aleekun ba owo ori ti awọn ile ise to n pon ọti ati awọn ti o n se siga yoo maa san gẹgẹ bi owo ori.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù 'Mo ti gba kádàrá lórí bí Ọlọrun ṣe dá mi' Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ 'Mo ti gba kádàrá lórí bí Ọlọrun ṣe dá mi' 13 Ọ̀pẹ̀̀ 2018 Folaṣade Adeyẹmọ jẹ àkàndá ẹ̀dá ti ojú rẹ fanimọra pupọ.
Gẹgẹ bi ohun ti akọroyin wa jabọ ati ohun ti awọn ara adugbo sọ, eeyan mẹrindinlogun lo n ṣiṣẹ nibẹ nigba ti ile naa dawo.
Idile oloogbe sọ ninu ikede to fi sita fun eto adura naa pe, ẹbí Ajimobi nikan ni yoo kopa nibi eto adura , nitori ofin to rọ mọ itankalẹ coronavirus.
Oríṣun àwòrán, Babcock O ti kọkọ fi lede ni Osu Kẹfa wi pe gbogbo eto ti n to lati ri wi pe arabinrin naa lọ si ileewe giga lai si idẹyẹsi fun wọn.
Awọn miiran tiẹ ni aṣọ iwọkuwọ lawujọ gan an lo sẹ okunfa iwa ifipabanilopọ to ti pọ si ni Naijiria bayii.
Atẹjade kan ti alukoro ileeṣẹ ọlọpaa ipinlẹ naa, Olugbenga Fadeyi fi sita, gẹgẹ bi iwe iroyin Punch sẹ sọ, fihan pe ọjọ Aje ni Kọmisanna ọlọpaa nipinlẹ Oyo, Nwachukwu Enwonwu fi ikede naa sita.
Ko jọ bi ẹni pe kata kara ounjẹ tiwa n tiwa Yoruba lọhun nira fun wọn pẹlu ifọrọwanilẹnuwo akọroyin BBC Yoruba.
Adeyemi Afolayan (Ade Love): Oríṣun àwòrán, Premium times Ọdun 1940 ni wọn bi Adeyemi Afolayan, ti ọpọ eeyan mọ si Ade Love, to si jade laye lọdun 1996 lẹni ọdun mẹrindinlọgọta.
Akọ mààlúù nìwọ̀nyí, tí o lè fi rú ẹbọ sísun sí OLUWA.
Ilé ẹjọ́ ní kí ''Yahoo boy'' lọ darí ọkọ̀ f'óṣù mẹ́ta pẹ̀lú N50,000 owó ìtanràn Ọlọ́pàá méjì wọ gàù lóri bí afurasí apanìyàn l‘Akinyele ṣe sá lọ 'Àwa ọmọ Nàìjíríà tó farapa fẹ́ wálé láti Lebanon, ìjọba kó wa pamọ́' Ọlọ́pàá gbọ́dọ̀ wá àwọn tó gbàbọ̀dè láàrín wọn nítorí ẹ̀mí wa ò dè ní Akinyele Ẹ ṣetò ìbò gómìnà míràn ní Bayelsa kó tó di Nov - Adájọ́ pàṣẹ Lẹyin atotonu agbẹjọro rẹ, Gboyega Oyewole (SAN), adajọ Mohammed Liman ti paṣẹ tẹlẹ lọjọ kẹrinlelogun oṣu keje wi pe, ki EFCC jọwọ awọn nkan rẹ fun un.
Wọn yan an gẹgẹ bii amugbalẹgbẹ fun ijọba ipinlẹ Ogun lasiko iṣejọba Ọtunba Gbenga Daniel.
Kọmisọna feto iroyin nipinlẹ Adamawa, Ahmad Sajoh fidi iṣẹlẹ naa mulẹ.
Lára ewu wọnyi ni, ki i si ifọ̀kànbalẹ̀ nitori ijà àti ariwo ti owú ji jẹ laarin àwọn iyàwó ma nfà pàtàki ni agbo ilé nlá tàbi ilé Ọlọ́rọ̀ àti Olóyè.
Kí oore-ọ̀fẹ́ ati alaafia láti ọ̀dọ̀ Ọlọrun Baba wa ati Oluwa Jesu Kristi kí ó máa wà pẹlu yín.
Wo iṣẹ́ tó wà nínú rẹ̀ kó tó dé'lẹ̀.
Ó sì tẹ́ pẹpẹ kan sibẹ fún OLUWA.
Ó ṣẹlẹ̀ bẹ́ẹ̀ ní ọpọlọpọ ìgbà.
”Ọkunrin náà gba ọ̀rọ̀ tí Jesu sọ fún un gbọ́, ó bá ń lọ sílé.
Wolii náà sáré tu aṣọ tí ó fi wé ojú, lẹsẹkẹsẹ ọba sì mọ̀ pé ọ̀kan ninu àwọn wolii ni.
Awọn oṣiṣẹ náà, paapa julo, àwọn tó n ṣiṣe ni awọn ile ìwòsan ìjọba àpapọ, ni yóò kọ̀kọ̀ bẹrẹ iyansẹlodi náà.
egbe APC to lẹdi apo  pọ mọ ọmọ egbe
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: 'Tàpá sófin ojú pópó kóo ṣọdún lẹ́wọ̀n' Ẹ sọ́ra fún ayé deru òògun nípìnlẹ̀ Eko 'Buhari sọ fún wa pé ipò tí ọ̀rọ̀ ajé Nàìjíríà wà kò dára' Ọga ajọ to n ri si ọrọ pajawiri nipinlẹ Eko Adesina Tiamiyu ṣalaye pe ọkan ninu awọn ọkọ ọhun tiẹ tun gbina.
O fikun pe, ẹgbẹ arẹwa to sẹyin Buhari ko ba lee rọrun fun lati pada wa se afikun awọn aseyọri to ti se tẹlẹ ni saa akọkọ rẹ.
Wọn ni ìṣẹ̀lẹ̀ náà wáye ni DR Congo àti France.
Pa òwe yìí fún àwọn ọlọ̀tẹ̀ wọnyi kí o sì wí fún wọn pé, ní orúkọ èmi OLUWA Ọlọrun: Gbé ìkòkò kaná;bu omi sí i.
"Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: ""Àhámọ́ ajínigbé ni ń bá wà lónìí, ọ̀pẹ́ awakọ̀ mi"" Saheed tí wọ́n dáná sun ní OkeAdo, Ibadan, ajínigbé ni àbí àrìnfẹsẹ̀sí?"
Olùrànlọ́wọ́ pàtàkì fún mínísítà, Shola Kolawole lo sọ èyí lásìkò tó sàbẹ̀wò si ìyá àwọn ọmọ náà Risikat tí òun pẹ̀lú ni ojú búlúù.
Eto idibo si ipo alaga ẹgbẹ oselu yii gan lo fa dukuu laarin Cyril Ramaphosa ati Jacob Zuma.
Ìbúrawọlé Nàìjíríà ṣojú àgbáyé Lori ọrọ yii naa ni Alhaji Sayeed Osupa fi ero tirẹ hàn si fun BBC Yorùbá.
Amọ Ofori ti wa lẹwọn bayii nibi ti wọn ti fẹsun apayan kan an.
Bẹ́ẹ̀ ni kí ẹ̀yin gan-an mú sùúrù.
Wuraọla kọ, ko fun Ọrunmila ni ounjẹ ati omi, sibẹ Ọrunmila ko fọhun, ti ko si binu pẹlu.
Èmi alára kò mọ̀ ọ́n, ṣugbọn ẹni tí ó rán mi láti máa ṣe ìrìbọmi ti sọ fún mi pé, ẹni tí mo bá rí tí Ẹ̀mí bá sọ̀kalẹ̀ lé lórí, tí ó bá ń bá a gbé, òun ni ẹni tí ó ń fi Ẹ̀mí Mímọ́ ṣe ìwẹ̀mọ́.
'MC Oluọmọ kò kú o, kò sí ikú lójù rẹ̀' Aàrẹ Buhari gbóríyìn fún BBC fún ìròyìn òótọ́ 'Ọkùnrin tí kò bá sanwó iléèwé ọmọ, kó lọ wẹrí' Lara wọn ni ẹgbẹ oṣelu PDP, APC, ẹgbẹ MURIC, àwọn obinrin oloṣo, àwọn ọmọ Yahoo atawọn oloṣelu lapapọ.
kathryn ryan cordell thornton ( ph.
Atunse lori omi mimuOga agba naa tun se ayewo si omi ti iko omo oogun ofurufu to wa ni Makurdi  naa n mu, ni eyi ti won ti se opolopo atunse si, lati tun lee maa je ki awon to n gbe ni ayika yii je anfaani re.
Ọ̀rọ̀ ọmọlúwàbí ni kí ó máa ti ẹnu yín jáde nígbà gbogbo, ọ̀rọ̀ tí ó bá etí mu, kí ẹ lè mọ bí ó ti yẹ láti dá ẹnikẹ́ni tí ẹ bá ń bá sọ̀rọ̀ lóhùn.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù June 12: Lekan Alabi ní kí ọmọ Naijiria rántí àwọn akọni ìjọba àwa-arawa Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ June 12: Lekan Alabi ní kí ọmọ Naijiria rántí àwọn akọni ìjọba àwa-arawa 12 Òkùdu 2019 Agbaakin Olubadan, Oloye Lekan Alabi ti ṣalaye bi ọrọ June 12 ṣe ri ni ọkan rẹ ati ọpọ ọmọ Naijiria lẹyin ti Aarẹ Muhammadu Buhari sọ June 12 di ayajọ ọjọ ijọba awa-arawa ni Naijiria lati yẹ MKO Abiola si.
Nítorí òkè Sioni tí ó di ahoro;tí àwọn ọ̀fàfà sì ń ké lórí rẹ̀.
"Kàyééfì tuntun rèé lórí #EndSARS, ọ̀rọ̀ pọ̀ nínú ìwádìí BBC Akinwumi Isola dárà nínú ìwé ""Nítorí Owó"" lórí Akomolede Yoruba Ìbẹ̀rù-bojo gbalẹ̀ ní Oyigbo lẹ́yìn tí ọlọ́páà mẹ́ta àti sọ́jà kú nínú rògbòdìyàn EndSARS Ènìyàn méjì pàdánù ẹ̀mí wọn nínú ìjàmbá ọkọ̀ tó wáyé ní Abúlé Ẹ̀gbá, ní ìpínlẹ̀ Eko Ẹ̀gbọ́n mi tán ìṣòro mi nípasẹ̀ ṣíṣe ẹ̀ya ara àtọwọ́dá fún mi- Ubokobong Sunday Ṣugbọn awọn akẹkọọ 1,003, 668 lo pegede ninu iṣẹ marun un to fi mọ ede Gẹẹsi(English Language) ati Iṣiro(Mathematics)."
OLUSEGUN OBASANJO Oríṣun àwòrán, others Wo díẹ̀ nípa ohun tí Walter Carrington gbé ṣe nígbà ayé rẹ̀ Walter Carrington aṣojú America sí Nàijíríà tó fẹ́ ọmọ Nàìjíríà tó dolóògbé àti ohun ti Arese aya rẹ̀ sọ Àwọn nkan tó yẹ kí o mọ̀ nípa aṣojú ilẹ̀ America tẹ́lẹ̀ sí Nàìjíríà, Walter Carrington tó kú Walter Carrington, to jẹ aṣojú America ní Nàìjíríà nígbà kan ri ti di olóògbé Iyawo rẹ to jẹ ọmọ orilẹ-ede Naijiria, Arese Carrington lo fi ikede sita pe ọkọ oun kú ni ọjọ Iṣẹgun, ọjọ kọkanla, oṣu Kẹjọ, lẹni aadọrun ọdun.
“Wò ó, mo ti pe Besaleli ọmọ Uri, ọmọ ọmọ Huri, láti inú ẹ̀yà Juda.
Ẹni tí ó ṣi olódodo lọ́nà lọ sinu ibi,yóo já sinu kòtò tí òun fúnrarẹ̀ gbẹ́ sílẹ̀,ṣugbọn aláìlẹ́bi eniyan yóo jogún ire.
Nígbà kan rí kò wúlò fún ọ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Jemimah: Wàhálà àwọn òbí mi pọ̀ ló jẹ́ kí n gbé ara mi níyàwó 12 Ọ̀wàrà 2018 Oríṣun àwòrán, Lulu Jemimah Arábìnrin kan tó ti sú láti maa dáhùn ìbéèrè lori ìdí tí kò fi tì i l'ọ́kọ, ti gbé ara rẹ̀ níyàwó.
Saudi Arabia mosque: Wo àwòdamiẹnu àwòrán Mọ́ṣáláṣí Ànọ́bì ní Medina!
Pẹlu ipade ti a ṣe pẹlu awọn ọlọpaa yii, ao kọkọ maa dọgbọn ba wọn ṣiṣẹ papọ ki ọrọ awọn ajinigbe yii to wọ wa lara tan, nitori pe ọrọ ijọba kii ya bọrọ.
Bẹ́ẹ̀ ni o kò gbọdọ̀ bẹ̀rù ohun tí wọn ń bẹ̀rù.
Oríṣun àwòrán, FURG Àkọlé àwòrán, Èròjà Búrẹ́dì Brazil ni kokoro to ni protein to dára fún agọ ara ènìyàn Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Ilé ẹjọ́ dá pásítọ̀ ìjọ Sotitobire padà sọ́gbà ẹ̀wọ̀n, ó sún ẹjọ́ síwájú Àwọn tó jí ìbejì mi gbé ti pè mí ṣùgbọ́n N50 mílíọ̀nù tí wọ́n ń béèrè pọ̀ ju agbára mi lọ-Akeugbagold Afurasí darandaran jí èèyàn mẹ́rìnlá gbé ní Ọ̀ṣun Àwọn ajínigbé bèèrè N20m fún ìyàwó ọba Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Kayeefi: Àkójọpọ̀ ìṣẹ̀lẹ̀ kàyéèfì tó wáyé lásìkò ààrùn coronavirus Gẹgẹ bi ileeṣẹ ọlọpaa ṣe sọ, Akpan jẹwọ pe ọmọ ẹgbẹ okunkun ni oun, awọn si ti ji awọn eeyan gbe lẹẹmeji.
 abímbọ ́ lá ( 1969 : 26 ) ṣe ìtọ ́ kasí èyí nínú Ọ ̀ yẹ ̀ kú méjì .
O ni awọn eeyan to wa ninu ọkọ akero funfun naa n rin irin ajo lati ipinlẹ Eko lọ ipinlẹ mii ni.
Obinrin kan wà tí nǹkan oṣù rẹ̀ kọ̀, tí kò dá fún ọdún mejila.
Ìyá Siasia kúrò lákàtà àwọn ajínigbé lẹ́yìn oṣù méjì ààbọ̀ 'Èmi àti Toyin Abraham ṣẹ̀ sọ̀rọ̀ fún ìgbà àkọ́kọ́ láti ọdún méjì torí ìjà òun àti Lizzy' Ẹ yéé purọ́ kiri!
omoladeoluwateru Àkọlé àwòrán, Oju bọrọ ko ṣe gbọmọ lọwọ ekurọ South Afrika Nigba ti a beere boya Naijiria le gbe awọn ọmọ ilẹ rẹ to wa ni South Afrika pada wa sile, Otunba Oluwateru ni o ṣeeṣe ṣugbọn kii ṣe gbogbo eeyan naa ni yoo fẹ pada wa sile.
Kò bá jù bẹ́ẹ̀ lọ, ọpẹ́lọpẹ́ àwọn olùkọ́ ti wọn ṣe takun-takun làálàá láti dáàbò bo àwọn ọmọdé.
Nítorí pé, bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé ara wa ti òde ń bàjẹ́, ṣugbọn ara wa ti inú ń di titun sí i lojoojumọ.
Ninu ipade awọn oniroyin to waye lopin ọsẹ yii niluu Ibadan, awọn ẹgbẹ naa gbarata lori iwa ọdaran ti awọn amokunṣeka kan n hu si ọmọde ati awọn agba to jẹ obinrin, paapa julọ lori ọrọ iṣekupani ati ifipabanilopọ.
O tẹsiwaju pe, ẹkọ ọfẹ ti Ijọba Fayoṣe kọ lati fun awọn akẹẹkọ Ipinlẹ naa ni Fayẹmi fun wọn lai gba owo kọọkan bo ti wu ki o kere mọ.
Odòlayé ni ń wí ìbà yìí o
Èmi iranṣẹ yín ti rí ojurere lọ́dọ̀ yín, ẹ sì ti ṣe mí lóore ńlá nípa gbígba ẹ̀mí mi là, ṣugbọn n kò ní le sálọ sí orí òkè, kí ijamba má baà ká mi mọ́ ojú ọ̀nà, kí n sì kú.
Bàbá yìí bẹ̀rẹ̀ síí wá ọ̀nà àti mú ọmọ rẹ̀.
 ipadade oseluaraalu ni 1991 mu itoro ati idagbasoke okowo wa .
Ko ti foju han boya ẹnikẹni ti ẹ fi to wọn leti nipa aarun naa.
Onírúirú èso àti nkan ọ̀gbìn ni wọ́n nta tí wọ́n npọ́n tí wọ́n sì nrẹ̀ ní àsìkò yìí.
Ọmọwe Abimbola sọ eyi lasiko to n fesi si bi eto oṣelu ṣe n lọ ni ipinlẹ Edo ati Ondo saaju idibo sipo gomina ti yoo waye nibẹ.
Bakan naa ni wọn maa n lo nibi awọn ayẹyẹ loriṣriṣi gẹgẹ bii oriki koriya.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Temitope Akinnusi: Ọ̀pọ̀ iléeṣẹ́ ló takú láti gbà mí síṣẹ́ torí mo ní ojú kan ijọba ni oun gbe igbesẹ naa, ki awọn ọlọja yii fun ara wọn gbe owo le awọn ọja yii, lọna ti yoo pe awọn ara ilu.
Godwin yoo tun ni anfaani lati lo odun marun un miiran, ni eyi ti yoo pari
Awọn ileewe, banki, ọfiisi ati ọpọlọpọ okoowo lo di titi pa lẹyin ti ẹgbẹ oṣiṣẹ NLC bẹrẹ iyaṣẹlodi kaakiri Naijiria.
Èmi náà óo máa fi hapu yìn ọ́,nítorí òtítọ́ rẹ, Ọlọrun mi;n óo máa fi ohun èlò orin yìn ọ́,ìwọ ẹni mímọ́ Israẹli.
Jẹ́ kí ilẹ̀ lanu, kí ìgbàlà lè yọ jáde.
Nígbà tí mo bá ń ranti rẹ ninu adura mi tọ̀sán-tòru, èmi a máa dúpẹ́ lọ́wọ́ Ọlọrun tí mò ń sìn pẹlu ẹ̀rí-ọkàn mímọ́, gẹ́gẹ́ bí àwọn baba-ńlá mi ti ṣe.
Sugbọn ọpọ lara awọn ọmọ aye ode oni ni ko mọ abari yii.
kí ẹ lè mọ àwọn ohun tí ó dára jùlọ.
Osun, Olusegun Agbaje ti ni  ahesọ ọrọ ti
Ile-igbimo asofin ti sun ipade re siwaju lati buyi fun awon omo ogun Naijiria mẹ́rìnlélógójì ti o padanu emi sowo awon omo ogun olote boko haram lose ti o koja, nipinle Borno.
Orilẹede ti awọn ologun yoo ti ni iwuri lati fi ẹmi wọn lelẹ fun orilẹede Naijiria.
Ọlẹ́gbọ́n ni ọkùnrin náà, o sì jẹ́ oníwà rere.
O salaye pe, “awon agbegbe tuntun ohun ni eka to ogbin ati irinna, awon ile-ise ipese nnkan ati eka amuna wa ati afefe gaasi”.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Wiwa ọkọ Baalu da bi ki ẹ lọ da duro sori apata' Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Ìjọba yóò lo BVN àtàwọn ọ̀nà méjì míràn láti pín owó ìrànwọ̀ fún aráàlú Wọn dupẹ lọwọ awọn ọmọ Naijiria to ya fọnran naa ati awọn to pin in titi ti ọwọ ijọba fi tẹẹ.
Àmọ́ o, ẹni tó bá tẹra mọ́n’ṣẹ́, ó di dandan kó jẹ̀rè iṣẹ́ ọwọ́ rẹ̀.
Oríṣun àwòrán, Fasola/Twitter Àkọlé àwòrán, Akoba yoo ba ọrọ aje Naijiria ti a ko ba tete se atunse marosẹ Ibadan silu Eko.
Adajo agba  Akanbi so eyi di mimo lakoko ti awon oniroyin nforoworo pelu re leyin eto adura Pataki eyi ti egbe  awon obirin aseranwo (Muslim Charitable Women Association of Nigeria) eyi ti aya Emir ti ilu Ilorin , Hajia Rafat  Zulu Gambari se agbekale re se, ti o si waye ninu ogba Adajo agba naa ni Asa-Dam, G.
Níbo ni àwọn baba ńlá yín ati àwọn wolii wà nisinsinyii?
Labẹ abala kẹtadinlogun si ikọkanlelogun ofin lori ọrọ irinajo oju ofurufu lagbaye lọdun 1944, gbogbo ileeṣẹ baalu lo ni orilẹ-ede to forukọ silẹ si, to si le ma ju ẹyọkan lọ, ofin orilẹ-ede naa lo si de ileeṣẹ ọkọ ofurufu naaa.
tí ẹ bá jẹ ninu oúnjẹ ilẹ̀ náà, ẹ óo mú ọrẹ wá fún OLUWA.
À şé ohun tí a bini á kúkú bini.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù May 29: Àwọn ọmọ Nàìjíríà sọ irú àwọn adarí tí wọ́n ń fẹ́ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ May 29: Àwọn ọmọ Nàìjíríà sọ irú àwọn adarí tí wọ́n ń fẹ́ 22 Èbibi 2019 Ṣaaju eto ibura wọle ti yoo waye ni ọjọ kọkandinlọgbọn oṣu karun ọdun 2019 lorilẹede Naijiria, awọn araalu ti n sọ iru awọn adari ti wọn fẹ ki aarẹ yan lati ba a ṣiṣẹ.
Ori awọn obi rẹ si lo di ẹbi igbe aye buburu to gbe naa le, eyi to yẹ ko jẹ ẹkọ fun awa obi pe, o yẹ ka kọ ọmọ wa, ko lee fun wa ni isinmi.
Gbogbo nǹkan wọnyi ni mo ti fi ọgbọ́n wádìí.
Nítorí náà, nígbà tí Kristi wọ inú ayé wá, ó sọ fún Ọlọrun pé,“Kì í ṣe ẹbọ ati ọrẹ ni o fẹ́,ṣugbọn o ti ṣe ètò ara kan fún mi.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Okiki kan nigba naa kakiri agbaye lori bi ijọba to wa lode lorilẹede Naijiria lasiko naa ṣe kuna lati daabo bo awọn akẹkọ naa Ninu ọrọ to fi sita lori ikanni twitter rẹ, aṣiwaju ikọ to n pe fun itusilẹ awọn akẹkọ naa, BBOG, Ọmọwe Oby Ezekwesili ni 'awọn ti ṣeleri pe ko ni si idaduro ni ipe awọn titi di igba ti ijọba apapọ yoo ko awọn ọmọ naa pada.
Aare Muhammadu Buhari sepade po pelu awon toro kan gbongbon nile ise omo ogun Naijiria lojo Aiku(Sunday), nile ise aare, niluu Abuja.
Lara awọn eekan to bawọn peju-pesẹ sibi aṣekagba ipolongo ibo naa ni igbakeji aare orilẹese yi tẹlẹri, Atiku Abubakar, aare ile igbimọ asofin tẹlẹri, David Mark.
Obili, ará Iṣmaeli, ni ó wà fún àwọn ràkúnmí.
O fikun pe, wọn se agbekalẹ ikọ Amotekun lati ba okoowo awọn ara oke ọya jẹ ni, ko si tun lee da wọn lọwọ kọ lati se ọrọ aje wọn lẹkun iwọ oorun guusu Naijiria.
Sanwo-Olu ni o si jọ bi ẹni wipe oun yoo ṣi tun ru si lori ohun ti oju oun n ri gẹgẹbi ẹni to n tukọ Eko.
O Fagunwa; Ǹkankan máa ń darí wọn lọ ibi tí a kò mọ̀22 Ọ̀wàrà 2018 Ìtàn Mánigbàgbé: Diipọ Fagunwa ní a le è pe bàbá òun ní ‘osó’ ìtàn àkọsílẹ̀12 Ọ̀pẹ̀̀ 2019 Àtẹ Àwòrán, D.
Gẹgẹbi ẹnikan to sọrọ nipa odo naa ti wi, tiyale-tiyawo (Awọ ati Awẹle) ni wọn di omi Ikọgọsi.
Bo tilẹ jẹ pe wọn ṣejọ rẹ, ile ẹjọ si ti ni ki wọn tu silẹ, o ṣeni laanu pe inu ẹwọn ni ọdun tuntun yoo ba okunrin ọhun.
Ni bayii, AC Milan ko ni anfaani lati gba ife eye idije kankan ni saa yii.
Oluranlowo Aare ile-igbimo asofin  agba lorile-ede Nigeria, Bamidele Omishore so pe, ile-ise Aare ati ile-igbimo asofin yoo fowosowopo lati mu atunto ba iwe eto kara-kata, eyi ti orile-ede Nigeria fowo si.
O gba ami ẹyẹ Nigeria Media Merit Awards gẹgẹ bii sọrṣo-sọrọ ori redio to dantọ ju ni ọdun 2003, 2004 ati 2005.
Ologbondiyan ni ẹgbẹ PDP ko tako ojuurin ti ijọba yii ṣe lati Eko si Ibadan nitori awọn mọ pe anfaani lo wa nibẹ fun araalu.
"Pe wọn kọ ọ si ori iwe pe wọn ti tu u silẹ, ko tumọ si pe o ti di ominira.
- Ìwádìí BBC Afọnja, ẹni tó finú wénú ní Ilọrin, àmọ́ tó jẹ iwọ Nigba to n sọrọ lorukọ awọn oriade to ku nilẹ Yoruba, Ọọni tun tẹnumọ pe, ominu n kọ awọn ọba alaye to wa nilẹ Kaarọ Oojire lọwọlọwọ bayii, nitori ipenija eto aabo naa ti di irawọ ọsan, to n ba awọn agba lẹru.
akẹgbẹ rẹ lati ẹgbẹ oṣelu PDP ti o ni ẹgbẹrun mẹta-le-ọjilelọọdurun
 Èyí náà rí bẹ ́ ẹ ̀ fún ẹ ̀ ka-èdè Ìgbómìnà .
kí ẹ fi inú kan ati ohùn kan yin Ọlọrun ati Baba Oluwa Jesu Kristi.
Black Che to jẹ ọmọ ipinlẹ Enugu ni inu ile iṣẹ ni awọn wa loru ọjọ ti ibọn n ro, ṣugbọn nigba ti wọn yoo fi jade sita lowurọ, oku eniyan marun un ni wọn ba nilẹ.
Ni kiakia, Stella Damasus to jẹ gbajugbaja oṣere naa ti jade bere ibeere nla pe ṣe awọn eeyan ko ṣì tii gba ọrọ ẹsun yii gbọ?"
Aare tun ro igbimo naa lati ri daju pe atunse ba awon ise akanse bi, ile-iwe, ile-iwosan abbl, eleyi ti awon omo ogun olote ti baje koja afojuri.
O tun dupẹ lọwọ awọn ara ilu lẹẹkan sii fun ifọwọsowọpọ ati atilẹyin wọn.
Kọmisana ni ki wọn ma jẹ ko di wọn lọwọ iṣẹ oojọ wọn ki wọn si jẹ araalu to n pa ofin mọ tori awọn ṣi n ṣe iwadii boya ẹran maalu kan ti wọn pa ti wọn si n ta lọja Eke-Ihe lo fa iku wọn.
Àkọlé àwòrán, Bolanle Sarumi to n dije dupo gomina ni gbogbo awon ọmọ wẹwẹ ti ọjọ ori wọn ko ju marun lọ yoo gba eto ilera ofe.
Bi o ti le je pe, awon adari egbe oselu APC ti mu lokunkundun wi pe awon oludije won lo gbodo jawe olubori lati tuko ile-igbimo asofin mejeeji.
Bayelsa, Kogi Election: APC ní yóò jáwe olúbori
Àjànàkú nipò adarí rere, ó kúrò lẹ́rù ọmọdé Fadá méji, ọmọ ìjọ 13 kú nínú ìkọlù darandaran Ipò àgbà ló yẹ́ kí a ti bá olórí - Fani-Kayode Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ sí Àwòrán àṣekágbá ìpolongo ìdìbò PDP l'Ékìtì FFK: Ẹ̀jẹ̀ Fulani ti dàpọ̀ mọ́ ti Yorùbá lára mi Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí kan sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
May his gentle soul rest in perfect peace.
Ori ni ọmọ maa n saaba fi wa si aye ṣugbọn awọn kan maa n fi ẹsẹ wa ti Yoruba n pè ni Ìgè Àdùbí.
Àkọlé àwòrán, Ijegun Gẹgẹ bi ohun ta a gbọ, aarin oru ni iṣẹlẹ naa bẹrẹ, ti awọn ara adugbo bẹrẹ si ni i gbọ ariwo ibugbamu nla.
Boko Haram kii ye ji awọn akẹkọ gbe eleyi to mu ki oju orilẹede agbaye ṣi si ọdọ rẹ lọdun 2014, lẹyin to ji nnkan bii ọọdunrun akẹkọbinrin gbe nileewe kan to wa ni ilu Chibok nipinlẹ Borno, ipinlẹ ti Boko Haram ti kọkọ di agbebọn.
Ọ̀rọ̀ LAUTECH gba àpérò f'áwọn Olúdíje Ọṣun Ìpínlẹ̀ méjìlá nínú ewu àgbárá òjò ní Nàìjíríà Kíni ẹ mọ̀ nípa àwọn gbajúgbaja Yollywood?
 Nigba ti aare n fi ẹdun ọkan rẹ
Ó bèèrè pé, “Ṣé ìwọ gan-an ni Esau, ọmọ mi?
Àwọn àgbàlagbà naa ma ndá aṣọ ẹgbẹ́ fún idúpẹ́ ọdún, ṣùgbọ́n ki owó epo rọ̀bi tó gba igboro, ki ṣe aṣọ olówó nla bi ti ayé òde òni.
O yẹ ka tun ile rẹ se ju bayi lọ Àkọlé àwòrán, Iroyin ko to afojuba.
Àsìkò tó láti fi ìwọ́de gba ara wa sílẹ̀ lọ́wọ́ ebi àti oko ẹrú - Sowore Ìjọba Buhari ń wùwà bíi ìjọba Abacha lórí ọ̀rọ̀ Ṣoworẹ- Ṣoyinka Agbẹnusọ fun ajọ DSS, Peter Afunaya sọ fun BBC pe, awọn lọ ọ gbe oludasilẹ iwọde naa, ti wọn pe 'Revolution Now' ni owurọ ajọ Abamẹta to kọja, nitori pe oun n pe fun iditẹ gba ijọba.
Ìtàn ayé Henry Fajemirokun, olówó tó fi owó mọ Olúwa àti ènìyàn Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Iléesẹ́ ológun: Àwọn ọmọ-ogun ṣi wá gbọ́ lórí ìsípò-rọpò wọn ni
Wọ́n sọ èyí di mímọ̀ nínú àtẹ̀jáde tí kọmísọ́nnà àsà àti ìrìnàjò afẹ́, Obawale Adebisi fọ́wọ́sí.
Oríṣun àwòrán, Facebook/Alaafin Oyo Bakan naa ni Minisita fun idagbasoke awọn ọdọ ati ere idaraya ni Naijiria, Sunday Dare ti ki Alaafin ku oriire aadọta ọdun lori itẹ.
Laolu Akande ti o je agbẹnusọ fun Ọṣinbajo jeri rẹ fun BBC pe awọn mọ si ẹsun naa ati pe awọn yoo fesi si iroyin naa láipẹ̀.
Gẹgẹ bi agbẹnusọ wọn Ibrahim Musa ti ṣe ṣalaye fun BBC, o ni awọn ọlọpaa pa eeyan mẹfa ni Bauchi,mẹta ni Kaduna ,meji meji ni Sokoto ati Gombe ati ẹnikan ni Katsina.
Gbogbo igbiyanju ati jẹ ki ekuru ọrọ Sẹnetọ Elisha Abbo to lu obinrin abilekọ kan ni ile itaja eroja ibalopọ ni ilu Abuja tan lawo, pabo lo ja si tori ọrọ rẹ ti de ile ẹjọ bayii.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Nàìjíríà kéde orúkọ àwọn agbábọ́ọ̀lù Falconets fún ìdíje àgbáyé 27 Agẹmo 2018 Oríṣun àwòrán, FIFA.
Naijiria to wa ṣe eyi gan lo wa ni awọn fẹ rii daju pe awọn pe ipade awọn tọrọ kan na labẹle ki wọn to le tọwọ bọ iwe adehun naa.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Serena Williams: Mọ̀ sínú, mọ̀ síkùn ni ìdí tí mo fi kọ̀ 5 Ògún 2018 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Williams to pada si ni gbabọọlu ẹlẹyin lẹyin ti o bi ọmọbinrin rẹ, fi idi rẹmi nigba to n figagbaga pẹlu Briton Johanna Konta pẹlu ami ayo 6-1 6-0.
"Mummy Calm Down di aṣojú iléeṣẹ́ ńlá kan l'Abuja Bí ẹ ṣe mọ̀wé tó, ẹ wá dánrawò níbí pẹ̀lú ""Àpólà Ọ̀rọ̀ Orúkọ - Noun Phrase Ariwo ""arabinrin yii ti lọ"" ni oun funrarẹ gbọ ninu eti rẹ lọhun to fi laju."
Oríṣun àwòrán, PIUS UTOMI EKPEI Àkọlé àwòrán, MMM ṣeleri lati fun awọn oludokowo ni ele ìdá ọgbọn (30%) lori iyekiye ti wọn ba fi dokowo.
Adari egbe APC , Ahmed Bola
O fi kun un pe ṣaaju asiko yii ẹgbẹrun kan ati ẹẹdẹgbẹta naira lawọn n gba fun ibalopọ ọlọwọ kukuru Short time ti awọn si n gba ẹgbẹrun marun un fun di ilẹ mọ kẹlẹlẹ daybraek.
Ṣugbọn ẹni tí ó bá sọ̀rọ̀ àfojúdi sí Ẹ̀mí Mímọ́ kò lè ní ìdáríjì laelae, ṣugbọn ó jẹ̀bi ẹ̀ṣẹ̀ títí lae.
 Bee si ni, A ti seto sile lopolopo fun gbogbo orile-ede ati awon ololufe iko kookan ti yoo wa si Russia.
ẹ̀yin tí ẹ̀ ń jọ́sìn ninu ilé OLUWA,tí ẹ wà ní àgbàlá ilé Ọlọrun wa.
Ajọ UNICEF sọ pe o fẹ to awọn ọmọ miliọnu mẹwaa le diẹ to wa laarin ọdun marun un si mẹrinla ti ko si nile iwe ni Naijiria.
29 Àti pé bí èyí bá rí bẹ́ẹ̀, mo pàṣẹ fún ọ, ìránṣẹ́ mi Joseph, pé kí ìwọ ó sọ fún un, pé òun kì yíò ṣe ohunkóhun mọ́, tàbí kí ó yọ mí lẹ́nu mọ́ nípa ọ̀rọ̀ yìí.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Imam Fuad tako Oluwo lori wiwe lawani Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Imam Fuad tako Oluwo lori wiwe lawani 28 Ẹrẹ̀nà 2018 Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí 2 sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 2:23 Fídíò, Water Generator: Ó leè ṣiṣẹ fún wákàtí mẹfà, kó tó sinmi, Duration 2,2310 Òkùdu 2020 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
Lonii ni ireti wape, Aare Zuma yoo so si ipinnu egbe oselu re bi won se pe pada lana.
Ṣugbọn ní oṣù keje Iṣimaeli, ọmọ Netanaya, ọmọ Eliṣama, láti ìdílé ọba, pẹlu àwọn ọkunrin mẹ́wàá dojú kọ Gedalaya, wọ́n sì pa òun, ati àwọn Juu ati àwọn ará Kalidea tí wọ́n wà pẹlu rẹ̀ ní Misipa.
13 Ògún 2020 US Elections 2020: Primate Ayodele ní òun ti sọ àsọtẹ́lẹ̀ pé Trump yóò fìdírẹmi, tí kò bá ṣọ́ra ṣe8 Bélú 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Èsi ibò ti wọn di ni ilú Amẹ́rikà ni oṣù kọkànlá, ọjọ́ kẹjọ jade ni òru ọjọ́ kẹjọ mọ́jú ọjọ́ kẹsan ọdún Ẹgbàálémẹ́rindinlógún.
"Omo Ghetto: Funke Akindele ṣàlàyé bí àwọn agbébọn ṣe kọlù wọn làsíkò tí wọ́n ń ya fíìmù ""Ojojumọ ni mo n pada lọ si ibi ti mo ti ri ọmọ yẹn boya maa ri i."
Eléyìí ni ọ̀rọ̀ tí mo lè sọ fún yín, mo ṣetán láti lọ sí ibi tí ẹ rán mi, ẹ jẹ́ ki n lọ sílé kí n lọ máa múra.
Ọ̀ṣun Oṣogbo 2019: Ìyán gbígbóná ní wọn kọ́ fi bẹ̀rẹ̀ ọdún
Ọ̀rọ̀ èké kankan kò sí ní ẹnu wọn.
Papa iṣere Wembley to jẹ ti Chelsea ni idije na ti waye.
 Ọkùnrin mẹ ́ rin ni àwọn òbí rẹ ̀ bí .
Akọkọ ni iwe iforukọsilẹ awọn eeyan to ku diẹ kaato fun lawujọ (Social register), ọna keji ni wiwo awọn akuṣẹ ni ilu nla nipa lilo nọmba idanimọ asuwọn igbalode (BVN) lati ṣawari awọn ti owo inu aṣuwọn wọn ko ba ju ẹgbẹrun marun lọ.
Koda wọn ko awọn akoroyin meji lọ ni ileeṣẹ naa to wa ni Maiduguri.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Mo leè di ààrẹ láì lọ sí Amẹ́ríkà - Àtíkù Ìgbésẹ̀ láti yọ Dino Melaye forí sánpón Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí kan sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
Bi o tilẹ jẹ pe awọn eeyan maa n kaanu rẹ lawọn oju opo ayelujara sugbọn ibẹ lo mọ.
O ni: “Ti a ba sa ipa tiwa gege bi onimottoo orile ede ti gbogbo eniyan Naijiria dekun dida idoti soju agbara, o di dandan ki omi ti a n lo lati orisii orisun tubo dara sii ki aisan maa re awon eniyan ni kete.
Adajọ naa kilọ fun gbajugbaja olorin naa lati fara han ni ọjọ naa aṣẹ ẹ lọ gbe wa ni wiwọ ni dide (Bench warrant) loun yoo pa fawọn agbofinro lori rẹ.
Oríṣun àwòrán, @Alaafinofoyo Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Fídíò, EndSars, EndSwat: Ọlọ́pàá ti fi ìbọn lù mí láyà rí torí mó ní 'extra tyre' méjì- afẹ́hònúhàn15 Ọ̀wàrà 2020 Fídíò, Soyinka Cancer: Àṣe ara mi ni iso ti n run gbogbo bí mo ṣe n ṣèrànwọ́ lórí jẹjẹrẹ27 Bélú 2019 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
 “Ki olorun ki o tE si afefe rere.
ti o gba boolu sagbon julo, leyin ti o gba boolu mẹ́rìnlélógójì  sagbon ninu apapo ifesewonse  méjídínllọ́gọ́ta ti o
Ni ọdun 1996 ni ọdunlade Adekọla bẹrẹ ere tiata ṣiṣe, ni ọdun 2018 ni Ọdunlade Adekọla kẹkọ gboye ijinlẹ ninu imọ akoso okoowo, (Business Administration) ni fasiti ilu Eko, Unilag.
Ó bá dá ọ̀rọ̀ sílẹ̀, ó ń fi tẹ̀dùntẹ̀dùn ṣe àlàyé ìjọba Ọlọrun fún wọn, ó sì ń fi ẹ̀rí tí ó wà ninu ìwé Òfin Mose ati ìwé wolii nípa Jesu hàn wọ́n láti òwúrọ̀ títí di ìrọ̀lẹ́.
Ero yii ti pọju Oríṣun àwòrán, Reuters Àkọlé àwòrán, Haa, awọn obinrin lo n luwẹ bii ẹja yii, ohun ti ọkunrin lee se, awọn obinrin naa le se e.
Ọkan lara awọn ara abule naa ni arakunrin kan ti wọn n pe ni Raji Oba, o mọ ọrọ sọ, to si laya bii Kinihun, ko bẹru Eji Gbadero rara, to si sọ bẹẹ loju rẹ Sabitu sare lọ sọ fun ọkọ rẹ pe oun ma kofiri Gbadero ni aarin abule ni alẹ yii, ti ẹnu si ya onitọhun pe ki lo n wa nibẹ lọwọ alẹ.
Ìrìnàjò lọ sí òkè òkúta Robin Hood
Ọjọ ti pẹ ti awọn to n mu igbo ti fẹ ki wọn ṣọ mimu ati tita rẹ di ohun ti ofin faaye gba.
O sọ itan ọrẹ rẹ kan to ni o ṣalaye fun oun ni igba kan sẹyin pe darandaran kan pa arakunrin rẹ, ẹjẹ rẹ si kan si ori koriko ti maalu jẹ, iwọ pẹlu ti kopa ninu iku arakunrin rẹ niyi lọna kan abi omiran.
"Tori eyi, akọroyin BBC Yoruba to ṣabẹwo si ilu Peckham ni London ba wọn ni gbolohun awọn kan ""lailai ajo ko le da bii ile, ile koko n tagbe"" bi awọn ba ti ko ọrọ̀ jọ tan ni ilu London."
Ẹsun pe Soworẹ ń déte láti dìtẹ̀ gba ìjọba Nàíjíríà, ẹsun lilo owo baṣubaṣu atawọn ẹsun mii ni wọn fi kan an.
Saulu tún rán àwọn iranṣẹ náà lọ wo Dafidi, ó sọ fún wọn pé, “Ẹ gbé e wá fún mi ti òun ti ibùsùn rẹ̀, kí n pa á.
‘Koda, ọpọlọ rẹ pe debi wi pe kii gbagbe ohunkohun ti ẹ ba kọ ọ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Akure Kidnap: Àwọn abiyamọ fẹ̀hónúhàn lórí ọmọ tí wan jígbé nílé ìjọsìn Akurẹ Agbejoro àwọn ọ̀daràn náà, John Saliu ṣàlàyé pé, ọlọ́pàá kò ní aridaju tí ó péye pé àwọn onibara oun ni wọn jó ilé ìjọsìn náà àti wí pé, kii ṣe àwọn ni wọn pá ọlọ́pàá tí ó kú sínú ìṣẹ̀lẹ̀ náà.
Gomina tesiwaju pe, pupo ninu awon ile to wa ni agbegbe naa ni won ti paale
“OLUWA yóo tu Sioni ninu,yóo tu gbogbo àwọn tí ó ṣòfò ninu rẹ̀ ninu;yóo sì sọ aṣálẹ̀ rẹ̀ dàbí Edẹni, ọgbà OLUWA.
Bí àpẹẹrẹ ìró èdè /a/ /b/ /d/ /e/ /ẹ/ kò dá ìtumọ̀ ní, àfi tí abá kàn wọ́n papọ̀ lọ́nà orísirísi.
Mo ń lọ sí ọ̀run lónìí, Ọlọ́run Ọba si tún fún mi ní aṣẹ wí pé kí n fi yín sí ipò yín àtijọ́.
Jasisi, ará Hagiri, sì jẹ́ alabojuto àwọn agbo aguntan.
N óo san ẹ̀san iṣẹ́ wọn àtẹ̀yìnwá fún wọn.
Gẹgẹ bi ohun ti a ri ka, ile isẹ to bẹrẹ eto yi salalye pe awọn gbe awọn kẹẹkẹ naa kalẹ ki awọn ara ilu ba le mọ riri eto irina orisi miran yatọ si eleyi ti wọn n lo tẹlẹ.
Ó pẹ́ tí mo ti mọ̀ ọ̀ láì jẹ́ pé ìwọ mọ̀ mí, ó pẹ́ tí mo ti ri ọ láì jẹ́ pé ìwọ mọ̀ pé mo rí ọ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Buruji Kashamu: Gómínà Dapo Abiodun tí lọ ṣàbẹ̀wò ìbánikẹ́dùn sí àwọn ẹbí Kashamu 8 Ògún 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 10 Ògún 2020 Gomina ipinlẹ Ogun, Dapo Abiodun ti sapejuwe Sẹnetọ Buruji Kashamu gẹgẹ bi ẹni to ni ifẹ ọmọniyan.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù World Day for Cultural Diversity: Bí àwọn òṣìṣẹ́ Ìpínlẹ̀ Oyo ṣe f'aṣọ ìbílẹ̀ dárà lati gbé àṣà lárugẹ 21 Èbibi 2019 Ọjọ́ kọkànlélógun, oṣù karùn ún ní ọdọọdún ni àyájọ́ ọjọ́ àṣà ní àgbáyé, bí àwọn olùgbé Ipinlẹ̀ náà ṣe rántí ọjọ́ náà rèé.
Ewe, alekun owo ohun ni a o lo lati fi mu idagbasoke tun de ba, ajo osise ati ina monamona, eto ogbin, eto eko, eto ilera ati eto aabo to mehe lorile-ede yii fun igbayegbadun awon ara-ilu patapata.
Labani bá pe gbogbo àwọn ọkunrin ibẹ̀ jọ, ó se àsè ńlá fún wọn.
Nítorí òye kò yé àwọn eniyan wọnyi rárá;nítorí náà, ẹni tí ó dá wọn kò ní ṣàánú wọn,Ẹni tí ó mọ wọ́n kò ní yọ́nú sí wọn.
Àwọn ọmọ Bebai jẹ́ ẹgbaata ó lé mẹtalelogun (623)
Bakan naa ni awọn agbabọọlu gbọdọ maa lo í ọmú ni gbogbo igba ti wọn ba wa ni papa.
Insecurity: Monguno ní àsìkò ti tó láti f'òpin sí Almajiri ní Nàìjíríà
Igbaju igbamu ni arabinrin naa fi ṣe ọga ọlọpaa naa lọjọ.
Ajọ eto ilera l'agbaye, WHO, sọ pe lootọ ounjẹ aṣaraloore ni galiiki, to si le ni awọn eroja apa kokoro aifojuri ninu, ko si aridaju pe jijẹ galiiki le daabo bo awọn eniyan lọwọ arun tuntun coronavirus.
Wọn darukọ rẹ pe, Usman Khan ni, ati wi pe o ti se ẹwọn ri lori ẹsun to jẹ mọ igbesumọmi ni ọdun 20-12.
Lagos police: Wọ́n ti gba'ṣẹ́ lọ́wọ́ ọlọ́pàá ọ̀mùtí
Àbí n kò ní gbẹ̀san ara mi lára irú orílẹ̀-èdè yìí?
“Ṣugbọn ìwà àgbèrè tirẹ̀ ju ti ẹ̀gbọ́n rẹ̀ lọ.
john dramani mahama ( ; ojoibi 29 november 1958 ) je aare ile ghana ati igbakeji-aare orile-ede ghana tele .
”Ọ̀rọ̀ yìí bà wọ́n ninu jẹ́ pupọ.
Mo yí ààlà àwọn orílẹ̀-èdè pada,mo kó ẹrù tí ó wà ninu ilé ìṣúra wọn.
Eyi ko ṣẹyin bi fọto 'igbeyawo' oun ati arẹwa oṣerebinrin, Adebimpe Oyebade, ṣe jade sori ayelujara.
Alukoro ajọ naa, Ikechukwu Ani ṣalaye fun awọn iwe iroyin abẹle kan lorilẹede Naijiria pe iroyin ofege ni iroyin naa nitori pe ajọ naa ko tii joko ṣe ipade debi ti yoo maa le ẹnikẹni ni iṣẹ.
Báwo ni mo ṣe lè dáríjì àwọn tí ń lo òṣùnwọ̀n èké; tí àpò wọn sì kún fún ìwọ̀n tí kò péye?
"Fun ọpọlọpọ ọsẹ, a mọ pe ileeṣẹ ọlọpaa ranṣẹ pe kọmisana naa, nkan ti mo ro ni pe iwa ibajẹ ti fẹ ẹ gbakoso ẹjọ naa.
Jesu mọ̀ pé wọ́n ń fẹ́ bi òun léèrè ọ̀rọ̀ yìí.
O tẹsiwaju pe awọn gende agbebọn yoo kọlu awọn sọọsi pupọ ninu ọdun 2021, ti wọn yoo si tun maa ji awọn asaaju ijọ gbe lọ pẹlu.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ọdún Orò ń sọ àwa obìnrin sí ìgbèkùn, ẹ̀wọ̀n, tó sì ń tẹ ẹ̀tọ́ wa lójú - Àwọn obìnrin Ikorodu faraya Èèyàn mẹ́rìnlá tí ọpọlọ wọ́n pé la buwọ́lù bíi kọmísọ́nà l‘Oyo - Olórí ilé aṣòfin kan sáárá Èmi àti Saheed kìí ṣe ọmọdé, a ti jọ ṣe Sinimá papọ̀, èyí túmọ̀ sí pé ìjà ti parí - Fathia Balogun Mo fẹ́ pa ara mi torí ojú àbùkù tí wọn ń fi wò mí pé mo fi iṣẹ́ abẹ bímọ"" Fulani kò leè dúró, táa bá lo ohun ta jogún lọ́dọ̀ àwọn bàbá wa - Sunday Igboho Alaye ree lori bi 'Iyawo' se wọ inu ede Yoruba: Ni igba iwasẹ, nigba ti oju si wa ni orunkun, ilu kan wa ti wọn n pe ni ilu Iwo lẹba ilu Osogbo, eyi to si wa titi di aye ode oni."
O ni lẹyin igba ti olori Aanu ti jẹ owo Alaafin tan, ko le ṣadede sa kuro.
Domestic violence: ‘Ẹ̀rù ayé mi sì ń bà mí’ – obìnrin tí ọkọ gé imú rẹ̀
Ibadan Obaship Tussle: Mọ́gàjí Ibadan ní ìjoba ló da ọ̀rọ̀ lọ́balọ́ba rú
Ẹ fi ìfẹnukonu alaafia kí ara yín.
Akitiyan ọmọ'ṣẹ́ mi tó wà lára àwọn tó jí ìbejì mi gbé kò kéré nígbà tí á n wá wọn- Akeugbagold Àmọ̀tẹ́kùn bẹ̀rẹ̀ iṣẹ́ pẹrẹu l'Ọ́ṣun Kí ló wà ní ìdí igbá tí àwọn olorì Aláàfin máa ń tí lóde Ọ̀yọ̀ Wo bí o ṣe lè jẹ́ kí bátììrì fóònù rẹ pẹ́ síi Awọn kan lara wọn maa n gba ile wọn wa a ṣiṣẹ, ti awọn miran si maa n gbe pẹlu idile to ba gba wọn siṣẹ.
    Ìwà iwin àti ti ènìyàn kò lè bá ara ṣe déédéé àsẹ̀ypinwá àsẹ̀yìnbọ̀, tọkọtayà yìí jà, ọkọ́ lé aya jade ṣùgbọ́n níwọ̀n bí ọmọ tí wọn bí kò ti tíì dágbà tó bẹ́ẹ̀, kò lè fi ìyá rẹ̀ sílẹ̀, nígbà tí obìnrin náà sì máa kúrò nínú ihò òkúta ni bàbá rẹ̀ fi eyín erin ta ọmọ rẹ̀ lọ́rẹ títóbi ni eyín erin náà, ó lu ihò láti apá kan dé apá kejì bí ènìyàn bá tì wù ti ibẹ̀ jìnà tó.
Lóòtọ́ọ́ ní ilé iṣẹ́ ọlọpàá ọtẹlẹ̀múyẹ tí mú Sowore sí àhámọ nítori pé wọ́n mí ò ń dún ìkokò mọ aláfíà, àtí ìbágbépọ̀ àrà-ẹni tó ń jọba lórilẹ̀-èdè Nàìjíríà Since wey dem arrest Sowore, na so many ogbonge Nigerians dey condemn di move, some don say di protest must go on, but who be dis man wey dey dinger Revolution Now across Nigeria?
Aburu kekere kọ ni awọn ọmọ ẹgbẹ okunkun naa n ṣe ni awọn agbegbe bi i Agege, Ogba, Ifako-Ijaiye, Iyana-Ipaja, ati Abule Egba.
Ó ti fi ibinu fà mí ya,ó sì kórìíra mi;ó pa eyín keke sí mi;ọ̀tá mi sì ń fojú burúkú wò mí.
Wọ́n fi Ipá bá Dina Lòpọ̀.
Lẹ́yìn náà, ebi wá ń pa á.
Ọpọ ́ n máa ń tẹ ́ pẹrẹsẹ tí ó sì máa ń sáábà jẹ ́ roboto láàrin íṣí-ǹ-ìṣí mẹ ́ fà sí méjìdínlógún ní títóbi rẹ ̀ , pẹ ̀ lú àwòrán ère tàbí ọnà ( àpéjúwe ) .
Oríṣun àwòrán, Getty Images Riyad Mahrez lo da ẹgbọ si ara Chelsea, ti o si fi ami ayo keji si inu awọn ti ifẹsẹwọnsẹ naa fi pari.
paapaa si awọn ọta rẹ, ti o si n waasu ifẹ ati alaafia.
Olufisun ọ̀hún ni oun gba ipe lati ọdọ Ebenezer pe ẹnikan ti oun ko mọ ri jalẹkun wọ ile ijọsin Holy Ghost Sanctuary to je ti 'Penticostal' kan ni agbegbe Vita Foam, opopona oja tuntun ni Makurdi.
Bẹ́ẹ̀ ni ó sì rí láàrin ẹ̀yin náà láti ọjọ́ tí ẹ ti gbọ́, tí ẹ sì ti mọ oore-ọ̀fẹ́ Ọlọrun nítòótọ́.
Amọ, minisita fun eto iroyin naa ni ijọba ko ni naani gbogbo ọrọ ti awọn to ba tako ofin naa ba sọ, ati wi pe awon gbe ofin tuntun naa kalẹ fun idagbasoke Naijiria, eleyii o mu ki ijọba laṣẹ labẹ ofin lati ṣe atunṣe ofin to rọmọ iroyin lorilẹede Naijiria loore-koore.
"Ninu ọrọ ti wn fi sita lẹyin iku Soleimani, adari Ayatollah Ali Khamenei sọ pe "" wi pe o faye silẹ lọ ba Ọlọrun kii ṣe opin ọna rẹ tabi iṣẹ ti a fi ran an, ṣugbn ẹsan a ke kikan kikan lroi awọn to lọwọ ninu ẹjẹ rẹ atawọn akinkanju mii ti wọn pa lana."
''Mo gba ọkọ naa laye nitori idi yi'' Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Tani otutu ma n mu ju laarin Ọkunrin ati Obinrin?
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Lagos collapsed building: Àwọn èèyàn ìpínlẹ̀ Eko ní ìjọba, aráàlú lọ́wọ́ nínú bí ilé ṣe ń wó Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Lagos collapsed building: Àwọn èèyàn ìpínlẹ̀ Eko ní ìjọba, aráàlú lọ́wọ́ nínú bí ilé ṣe ń wó 30 Ẹrẹ̀nà 2019 Ile ko ṣẹsẹ maa wo ni ipinlẹ Eko ati kaakiri Naijiria, ṣugbọn gbọnmọgbọnmọ rẹ ni ẹnu ọjọ mẹta yii ti fa ọpọ si ajọ to nironu.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Christmas: Jesu ni ọjọ́ ọ̀la àti ibi ìyanu mi- Jaga Ọjọ ọhun tun jẹ ọjọ ti awọn eeyan ma jẹ ajẹyo ati ajẹṣẹku ounjẹ ti wọn se lasiko ọdun.
     Lara awon ti o lo pade aare Buhari ni papako ofurufu Maiduguri International Airport ni gomina ipinle Borno Kashim Shettima, oga agba yanyan fun iko omo-ogun, Lieutenant Tukur Yusuf Buratai  ati awon osise omo ogun naa.
Bẹ́ẹ̀ ni ọba ati gbogbo àwọn eniyan náà ṣe ya ilé Ọlọrun sí mímọ́.
  Òun ló ń fún wa ní àdí èkùọ́ àti òrí.
Ileeṣẹ ọlọpaa ninu atẹjade ti wọn fi sita gba ọwọ agbẹnusọ wọn, DSP Ahmed Wakil sọ wi pe arakunrin naa wu iwa buruku yii nitori nipa ifipabanilopọ ni ọmọ rẹ obinrin fi loyun ọmọ tuntun jojolo naa.
Mẹfiboṣẹti bá dáhùn pé, “Jẹ́ kí Siba máa mú gbogbo rẹ̀, kìkì pé kabiyesi pada dé ilé ní alaafia ti tó fún mi.
Mama rẹ Comfort Bamidele Awojobi si jẹ onisowo to jẹ ọmọ bibi ilu Modakeke Ile Ifẹ nipinlẹ Osun.
Nínú oṣùu Ẹrẹ́nà ọdún-un 2019, a gbé ìgbésẹ̀ kan láti da ilé náà wó lulẹ̀.
Awọn kan lara wọn gba pe akọnimọọgba wọn, Gernot Rohr n ṣe iṣẹ rẹ daada, nigba ti awọn kan sọ pe ko lo awọn agbabọọlu naa boṣeyẹ ko lo wọn.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Bode George s'ọrọ lori abadofin tuntun ipinlẹ Eko Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Bode George s'ọrọ lori abadofin tuntun ipinlẹ Eko 9 Ẹrẹ̀nà 2018 Oloye Bọde George bu ẹnu ẹtẹ lu aleekun owo ori lori ile ati ilẹ nipinlẹ Eko.
Sugbọn bi o ti se gba bọọlu wọ inu awọn kọ lo gba ori afẹfẹ.
APC ní yóò jáwe olúbori ni Bayelsa ati Kogi- Tinubu Òní nilé ẹjọ́ tó ga jùlọ yóò gbẹ́jọ́ ẹ̀sùn ayédèrú sabuké tí wọ́n fi kan Buhari Ìfẹ̀hónúhàn l'Abuja lórí ìdájọ́ ilẹ̀ Gẹ̀ẹ́sì tó gbẹ́sẹ̀ lé $9.
Sugbọn ṣe iwadii tuntun ni ireti ninu ?
Ìdí rẹ̀ nìyí tí a fi ní ìtùnú.
Olarewaju so pe, “ awon osise ijoba ti won n sise ni awon eni-ibode ko se amulo ilana ti o ye, nipa sise awon ohun ti ko le je ki eto kara-kara ti ko ni idiwo fese mule ni ekun naa, latari bi won n se n bere owo ti ko lese n le lori oja won.
Ẹ má ṣe tìtorí oúnjẹ ba iṣẹ́ Ọlọrun jẹ́.
Lẹ́yìn wọn ni Sadoku, ọmọ Baana náà ṣe àtúnṣe abala tiwọn.
Ẹgbẹ awọn olukọ lorilẹede Naijiria lo tu aṣiri eyi sita to si ṣakawe eyi gẹgẹ bii ohun to buru jai to si bani ninu jẹ lọpọlọpọ.
''Orileede Naijiria lagbara ti o si setan lati san gbogbo owo ti wọn ba ya pada nigba to ba yẹ ni ibamu pẹlu eto inawo to yanranti.
Nisinsinyii, wọ́n ń dẹ́ṣẹ̀ kún ẹ̀ṣẹ̀, wọ́n yá ère fún ara wọn; ère fadaka, iṣẹ́ ọwọ́ eniyan, Wọ́n ń sọ pé, “Ẹ wá rúbọ sí i.
Bẹẹni, nibayii wọn ti wa ni ipinlẹ Ondo; ijọba ipinlẹ naa si ti gbe aṣẹ kalẹ pe gbogbo ọmọ ẹgbẹ fijilante naa ni ki awọn agbofin o fi panpẹ ofin mu ni kiakia.
Ewe, Drogba tun fiko agbaboolu Marseille sile, ti o si tun lo darapo mo iko agbaboolu Chelsea, nibi ti o ti gba ife-eye idije EPL ati idije Uefa Champions League.
Asoju ohun salaye pe, ipade apero lori eto idokowo elekefa yoo waye ni ilu Tehran ti n se olu ilu orile-ede naaOrile-ede Iran n sami ayeye odun mokandinlogoji ti orile-ede ohun bo lowo isejoba ibile, eyi ti o sokunfa ijoba elesin Islam.
a ó mú lò nínú isé yìí .
O wa  ro gbogbo awon to n gbe ni
Ṣugbọn kete ti Mompha ti gba awọn nnkan yii tan to si ọfiisi EFCC silẹ ni wọn tun gba a mu.
Awọn  miiran tun ni:Muhammad  Najatu to n soju fun Ila- Iwo oorun, Braimaoh  Austin lati Ila Gusu, agbejọro Rommy Mom lati Aarin Gbungbun  orile ede  Naijiria ati Nkemka Oshimiri Jombo-Ofo lati Ila oorun Gusu ati awọn  osisẹ ile isẹ ajo naa.
Ọ̀pọ̀ ènìyàn sọ pé ìgbéṣẹ̀ ẹgbẹ òṣèlú APC kò fí ti mẹ̀kúnù àti t'àwọn ọ̀dọ́ ṣe.
” Ọkunrin náà bá yà, ó sì jókòó.
’Awọn sọja Cameroun tu mi sihoho' Italy dá àwọn aboyun àt'ọmọ wẹ́wẹ́ pada Kí ló dé tí obinrin tó ní HIV/AIDS fi pọ̀ ju ọkunrin lọ ní Nàìjíríà?
Ẹ̀kẹta tí ó jjù bá mi ni góńgó imú mi, mo rọra fi ọwọ́ ra inú mo dákẹ́ jẹ́jẹ́.
" Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Naming of Railway stations in Nigeria: Afenifere, YCE, Akitoye, Fani-Kayode ní ẹ̀tanú Obasanjo ni Buhari ṣe28 Agẹmo 2020 Fídíò, Gani Adams: Ẹni ba fe pẹ laye, maa ra aye gbe ni20 Èrèlè 2018 Buhari: Òpùrọ́ àti òjòwú ni Olusegun Obasanjo21 Sẹ́rẹ́ 2019 Fídíò, Obasanjo: Eré ìtàn nípa ìbí, àti jéèyàn pẹ̀lú ìpèníjà Olusegun Aremu Obasanjo5 Ẹrẹ̀nà 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Bẹ́ẹ̀ ni Esau ṣe di ẹni tí ń gbé orí òkè Seiri.
Jokiṣani ni baba Ṣeba ati Dedani.
Mo kúrò ni òde ọ̀run mo bá ìsàlẹ̀ ilẹ̀ lọ, bẹ́ẹ̀ ni mo gbé ọgọ́rùn-ún ọdún láàárin àwọn òkú tí ń bẹ ni ìssàlẹ̀ ilẹ̀ mo si kọ́ onírúurú ọgbọ́n lọdọ wọn, àti ìgbà náà ni mo sì ti mọ̀ pé, nínú ikú ti gbogbo àwọn ọmọ aráyé ń kú, ìba díẹ̀ni ó jẹ́ àtọ̀run wwá nínú wọn – àwọn aráyé a máa fi ọwọ́ ara wọn ṣe ara wọn; òmùgọ̀ a máa pa ẹlòmíràn láìròtẹ́lẹ̀, àṣejù iṣẹ́ a máa pa ẹlòmíràn láìròtẹ́lẹ̀, ọ̀lẹ-ṣíṣe a máa pa ẹlòmíràn láìròtẹ́lẹ̀, wọ̀bìà a máa pa ẹlòmíràn láìròtẹ́lẹ̀, ojúkòkòrò a má pa ẹlòmíràn láìròtẹ́lẹ̀.
Àkókò ń bọ̀ tí a óo tún Jerusalẹmu kọ́ fún mi láti ilé ìṣọ́ Hananeli títí dé Bodè Igun.
Simi gba àmì ẹyẹ to dára ju lọ nínú RnB nínú orin adako rẹ 'Smile For Me' 'Joromi' bákan naa lọ gba Aliboomu tí dára julọ.
Nínu ìkọ́ni rẹ̀, Michel sàlàyé ìrú òunjẹ tó yẹ kí ènìyàn máà jẹ, tó sì fí kún-un pé àdín àgbọn kò dára rárá fún mimu tabi jijẹ.
Ijà fún ẹ̀tọ́ lati ṣe irú igbeyawo yi ti wà lati bi ọdún mẹrindinlãdọta sẹhin, ṣùgbọ́n ni oṣù kẹfà, ọdún Ẹgbãlemẹ́tàlá, Ilé Ẹjọ́ Àgbà fi àṣẹ si pé ki Ìjọba Àpapọ̀ gba àṣà ki ọkùnrin fẹ́ ọkùnrin tàbi ki obinrin fẹ́ obinrin, lati jẹ ki àwọn ti ó bá ṣe irú igbéyàwó yi lè gba ẹ̀tọ́ ti ó tọ́ si igbéyàwó àdáyébá – ohun ti ó tọ́ si ọkùnrin ti o fẹ́ obinrin, nipa ogún pinpin, owó ori tàbi bi igbéyàwó ba túká.
“Ọba Ijipti ní ìhà gúsù yóo lágbára, ṣugbọn ọ̀kan ninu àwọn ìjòyè rẹ̀ yóo lágbára jù ú lọ, ìjọba rẹ̀ yóo sì tóbi ju ti ọba lọ.
Ọmọ ọdún mẹ ́ fà ni mozart nígbà tí ó bẹ ̀ rẹ ̀ iṣẹ ́ orin gan-an .
Lẹyin naa, wọn gbe e digba digba lọ sile iwosan ko to di pe o gbẹmi mi.
 orúko yìí nì ò sì mo àdúgbò náà lòrí dì onì yìí ni pàtàkí fún ìdamò ìta-eko ojóun .
Ojú wọn kún fún àgbèrè, kì í sinmi fún ẹ̀ṣẹ̀.
Ọmọbinrin ti orukọ rẹ n jẹ Motunrayọ Seun Ajila ni o ṣetan lati Ile-Iwe Giga, Adeyemi College of Education, Ondo ti awọn kan si fi ipa baa lopọ ni adugbo Sunday Bus Stop, Akure.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù End Sars, End SWAT, Aisha Yesufu: Ó ní ìdí tí mo fi ń wọ Hijabu lọ ṣe ìwọ́de- Aisha 15 Ọ̀wàrà 2020 Oríṣun àwòrán, other Ọpọ eeyan lagbaye lo mọ Aishaa Yesufu gẹgẹ bi ajafẹtọ araalu ṣugbọn ohun ti o ṣokunkun si ọpọ ni idi ti o fi jẹ pe ẹwu hijab lo yan laayo lati maa wọ fun ti iwode #ENDSARS to gbode kan lọwọ yii.
Dá odi ìlú lu níṣojú wọn, kí o sì gba ibẹ̀ jáde.
Kí ibú omi tó wà ni mo ti wà,nígbà tí kò tíì sí àwọn orísun omi.
Àwọn afurasí márùn-ún tó ń jẹjọ fún ẹsun idigunjale ati ipaniyan naa yabo awọn ile ifowopamọsi nìlú Ọ̀ffà nibi ti wn ti pe eeyan ọgbọn lOsu kẹrin ọdún tó kọjá .
Ogbẹ́ni Trump ko si ọmọ ilẹ̀ Amẹrika kankan to farapa nínú ìṣẹ̀lẹ̀ náà àwọn ǹkan díẹ̀ si lo bàjẹ́ ni ibùdó náà.
Olori ilu Lousville ti paṣẹ agbeyẹwo ileeṣẹ ọlọpaa nibẹ.
Ajọ JAMB fun osisẹ n'iwe lọ gbe'le ẹ Ohun marun t'ejo n jẹ Iṣẹlẹ yii waye ni ile ifiweranṣẹ alabọde kan to wa ni agbegbe Cibitoke ni iwọ oorun orilẹede Burundi.
Kò tún nílò kí n sọ fún ọ pé ìwọ fúnrarẹ, o jẹ mí ní gbèsè ara rẹ.
Khadijah, obìnrin àkọ́kọ́ tó dẹnu ìfẹ́ kọ àyànfẹ́ rẹ̀ Ilé ẹjọ́ rán àwọn mérìndínlógún lẹ́wọ̀n gbére fún dídáná-sun Nusrat Ọwọ ṣìkún òfin ti tẹ Maina, alága àná fún ọrọ owó ìfèyìntì - DSS Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Wọn n ṣe eyi lati fun wọn anfani lati le maa mu ọti lile bi o ba ṣe wu wọn.
Ní ọ̀sẹ̀ to kioja nígba ti ọ̀rọ̀ náà kò yanju ni ọlọpàá gbé Alfa Babatunde lọ si agọ wọ́n fun ifọ̀rọ̀wánilẹnuwo.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ladoja: Àwọn èèyàn Oyo fì ìbò sọ̀rọ̀ pé ìjọba Ajimobi kò dára Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Ladoja: Àwọn èèyàn Oyo fì ìbò sọ̀rọ̀ pé ìjọba Ajimobi kò dára 4 Òkùdu 2019 Osi Olubadan ti ilẹ Ibadan, to tun jẹ gomina tẹlẹ ni ipinlẹ Oyo, Senetọ Rashidi Ladọja ti salaye pe, inu Ajimọbi dun pe o fidi rmi ninu ibo sile asofin agba to kọja.
Eyi tumọ si wi pe o ṣeeṣe ki Femi Gbajabiamila naa jawe olubori gẹgẹ bi adari ile igbimọ aṣojuṣofin nitori pe fun igba pipẹ bayii, abajade ohun to ba ṣẹlẹ nile igbimọ aṣofin agba lo maa n sọ bi yoo ṣe ri nile igbimọ aṣojuṣofin.
Amnesty International: Àwọn agbófinró ń fìyà jẹ àwọn èèyàn púpọ̀ jù ni Nàìjíríà
O yẹ ìrìn ẹsẹ̀ mi ati àbọ̀sinmi mi wò;gbogbo ọ̀nà mi ni o sì mọ̀.
Èyí ni bí èèyàn 538 ṣe ń yan ààrẹ lé èèyàn mílíọ̀nù 331 ní Amẹ́ríkà Ṣé ìwọ́ mọ Àrànmọ́ Fáwẹ́ẹ̀lì Yorùbá dáadáa?
Wọ́n ti pàṣẹ lọ rọọ́kún nílé fún òṣìṣẹ́ káńsù tó lú obìnrin kan ní ìpínlẹ̀ Ogun Àjọ Lasema rí òkú èèyàn nínú èèrù iná àwọn ọkọ̀ agbépo tó jóná ní afárá Kara Wo àwọn àsọtẹ́lẹ̀ ìgbà tó yẹ kí ayé parẹ́ àtàwọn tó sọ àsọtẹ́lẹ̀ náà Wo àwọn oníròyìn méje tó kú láàrin ọjọ́ méje ní Nàìjíríà O ni ẹdun ọkan nla lo jẹ fun oun pe awọn obi atawọn aburo oun ko le sọrọ, ṣugbọn itọju ti wọn fun oun jẹ ohun iwuri.
 látàrí ogun yìí ló jẹ ́ kí ó gbéra ọ ́ un àtàwón ọmọlẹ ́ yìn rẹ ̀ tíbwọ ̀ n sìbfi rẹ ̀ dó sí ìwọ ̀ oòrùn ilẹ ̀ nàìjíríà tí tí dònìí .
Ọjọ ikọkandilọgbọn oṣu ikarun un ọdun 2019 ni aarẹ Buhari ṣe iburawọle ṣugbọn lati igba naa, ko tii yan awọn minisita rẹ.
12 Àti pé nígbàtí ìwọ bá jọ̀wọ́ ohun náà èyí tí Ọlọ́run ti fún ọ ní ìríran àti agbára láti túmọ̀, ìwọ jọ̀wọ́ ohun náà èyí tí ó jẹ́ mímọ́ sí ọwọ́ ènìyàn búburú,
Seidu Adeyemi to jẹ ọrẹkunrin Khadijat Oluboyo ni wọn fẹsun kan wi pe o pa a, ti o si tun rii mọle si inu yara rẹ ni Aratusi, Oke-Aro ni Akure, nipinlẹ Ondo.
Lásìkò tó ń ka iwé fún ìmọ̀ ofin oní pele kejì ló bẹ̀rẹ̀ si ni gbá bọ́ọ̀lù fún NK Dinamo Zagreb, VfB Stuttgart àti SSV Ulm 1846 níbi to ti fọmọ yọ ninu iṣẹ́ to yàn láàyò.
Lai Muhammed lo sọ ọrọ naa nigba to n ṣayẹwo ibi iṣẹ de duro loju ọna oju irin Ibadan si ilu Eko.
Mo túbọ̀ múra mo kọ́ ifa mọ́ ifá, mo mọ pàtàkì nínú àwọn odù, mo mọ ìtàn ayébáyé, mo mọ ìjìnlẹ ògèdè, bẹ́ẹ̀ ni ẹ̀mí mio fẹ́rẹ̀ ẹ bọ́ nibi ti mo ti ń jẹ ataare.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Àyájọ́ ọjọ́ àwọn èwe lónìí Ní ọdún 1954 ni ìpàdé ìgbìmọ̀ àjọ ìsọ̀kan àgbáyé kéde rẹ̀, wọ́n se ìfilọ́lẹ̀ rẹ̀ kí gbogbo orílẹ̀-èdè lè yan ọjọ́ kan fún ti wọn.
 “Bo tile je pe a nilo irawo lati orile ede China sibe, a gbodo lee sakitiyan lati mu atunse ba eto oro aje tiwa naa.
Láti ìtẹ́lẹ̀ kékeré títí dé ìtẹ́lẹ̀ ńlá jẹ́ igbọnwọ mẹrin (mita meji).
Àbájáde èsì ayẹwò to jáde lánáà kan ìpińlẹ̀ méjìdin lógun Ènìyàn mẹ́ta lo tun bá ààrùn náà rin láná, eyí si ti mú iye ènìyàn tó ti kú wá si ẹgbẹ̀run kan àti méje.
Ahmed Lawan: Àwọn ohun tó yẹ ko mọ̀ nípa ààrẹ aṣòfin àgbà tuntun
Ẹranko tí o rí yìí ti wà láàyè nígbà kan rí, ṣugbọn kò sí láàyè mọ́ nisinsinyii.
Wọ́n fẹ́ ba dáadáa ààrẹ Buhari jẹ́ ni wọ́n ṣe ń lọ́ kíkojú ìṣòro àbò mọ́ ikú àwọn àgbẹ̀ Koshebe Ẹ wo ọmọ Yoruba, Adewale Adeyemo tí yóò jẹ igbákejì akọ̀wé akápò ní ilẹ̀ Amẹrika Iyè àwọn àgbẹ̀ tí Boko haram dúmbú ní Borno ju ohun tẹ́ẹ gbọ́ lọ - UN Ṣe lóòtọ́ ní ọmọ Nàíjíríà mílíọ́nù 25 yóò má ló ìná Solar látí Dec 1, 2020?
Àwọn Eniyan náà Ṣe Ìrònúpìwàdà Èké.
Oríṣun àwòrán, Usman Okai Austin Àkọlé àwòrán, Kódà, ìpàdé nàá kò yọ àwọn olórí ẹ̀sìn sílẹ̀ O fi kun ọrọ pe, Aarẹ Buhari ti kọ eti ikun si ọrọ Obasanjo ati Atiku nitotri o n tẹsiwaju ninu eto igbogun ti iwa ibajẹ ati ṣiṣe owo ilu kumọkumọ Ẹyin l'ohùn,tó bá ti jabọ kìí ṣe ko mọ Rẹgi ni ọrọ yi ṣe ti a ba wo ọrọ ti Aarẹ ana l'orileede Naijiria, Olusẹgun Oríṣun àwòrán, @atiku Àkọlé àwòrán, Ṣaaju ni Ọbasanjọ sọ pe Ọlọrun ko ni dari ji oun ti oun ba gbe lẹyin Atiku Abubakar.
Bakan naa ni BBC kan si ileesẹ ilẹ ọrọ abẹle ati eyi to wa fun ọrọ ilẹ okeere nilẹ Gẹẹsi, awọn naa ko setan lati sọ ohunkohun l'ori ọrọ naa .
Benue,Plateau,Zamfara, ijoba ibilẹ Kuje ati  Bimji ni ipinle  Sokoto, Awon ibi yii ni Ajo eleto idibo ko
Ó sọ fún àwọn tí ń ta ẹyẹlé pé, “Ẹ gbé gbogbo nǹkan wọnyi kúrò níhìn-ín, ẹ má ṣe sọ ilé Baba mi di ilé ìtajà!
Èmi kò gbé pọ̀ pẹ̀lú Kollington Ayinla àmọ́ ọjà t'ọ́mọ ti wọ̀ lọ̀rọ̀ àwa méjééjì - Salawa Abẹni Barrister ló sọ mí di èèyàn ńlá - Ayinla Kollington Ìtàn tó wà nídi òwe ‘Sebótimọ Ẹlẹ́wà Sàpọ́n’ Ìtàn tó rọ̀ mọ́ òwe ‘aṣọ kò bá Ọ́mọ́yẹ mọ́.
A ti yẹ ọ̀rọ̀ rẹ wò fínnífínní, ó dúró ṣinṣin,mo sì fẹ́ràn rẹ̀.
Agùnbánirọ̀ mẹ́sàn-án ló ti ṣe pẹ̀kí ọlọ́jọ́ wọn lẹ́yìn tí wọn lo si odo Moyo Salva fún ìgbáfẹ́ ní ìjọ̀ba ìbílẹ̀ Gashaka ìpínlẹ̀ Taraba.
Akole ipade ohun yoo da lori,“Mimu Ibasepo jeyo pelu ile okere je kokoro kan gbogi lati koju idojuko ati pipese igbe aye alafia.
Ifọrọwerọ BBC Yoruba ati Akorede Okunnu ree: Ọgbẹni Akorede ni iṣẹ oun ni ko fun oun naa lanfaani lati maa gbe oke okun pẹlu idile oun.
Igbimo Academy yii lo n sagbateru ami eye agbeye ninu idanilaraya, Oscars .
Mose ṣe ọ̀pá fìtílà náà gẹ́gẹ́ bí àpẹẹrẹ tí OLUWA fi hàn án.
 nínú àwọn isẹ ́ owọ ́ rẹ ̀ ni a ti lè rí  orin ololufe j."
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Falz f'ohùn lẹ̀ fún PDP, APC, MURIC, àwọn ọmọ Yahoo 11 Sẹ́rẹ́ 2019 Oríṣun àwòrán, YOUTUBE Àkọlé àwòrán, Folarin Falana Gbajugbaja olorin nni, Folarin Falana ti gbogbo eniyan mọ si Falz tun ti gbe iṣe rẹ de pẹlu orin bi owe bi owe rẹ̀.
Ní ibikíbi tí ẹ bá ń gbé, àwọn ìlú yín yóo di ahoro, àwọn ibi ìrúbọ yín yóo di òkítì àlàpà, tóbẹ́ẹ̀ tí àwọn pẹpẹ oriṣa yín yóo di ahoro ati àlàpà.
Awọn ipo ti Ọjọgbọn Ibrahim Gambari ti di mu ri Olori orilẹede Ọgagun Muhammadu Bahuri nigba naa lọhun yan Ọjọgbọn Ibrahim Gambari gẹgẹ minisita fun ọrọ okeere laarin ọdun 1984 si 1985.
TCN, ní kò s'óhun tí yóò ṣe iná mànàmáná ní Nàìjíríà lóní
Mo wá ń bèèrè, “Ṣé wọn kò ì tíì gbọ́ ni?
Ìgbà tó yá tó dàbí ẹni pé wọn fẹ́ fi azonto di olúwarẹ̀ létí, ni mo bá kọrí'lé ní tèmi o jàre.
O kò gbọdọ̀ bá aya arakunrin baba rẹ lòpọ̀, nítorí pé, ẹ̀gbọ́n ni ó jẹ́ fún ọ.
Wọ́n fún Àwọn Juu Láṣẹ láti Bá Àwọn Ọ̀tá Wọn Jà.
Aṣoju ẹka idajọ Amẹrika mii, Robert Hammer sọ ninu atẹjade naa pe Onyema ṣe ọpọlọpọ eto lati ra oniruuru nnkan lorilẹ-ede Amẹrika, amọ o ni jibiti naa ni gbogbo rẹ ba de.
Ewe, aare gbagbo pe, bi ogagun Onoja se pe àádọ́rin odun leni, ti O tun dagba lojo ori si ni O tun kun ogbon ori bakan naa, eyi ti o mu gba iwe eri dokita ni eka amofin, eleyi ti o lo lati fi si n orile-ede ti o nife si pupo.
Lori ayelujara Twitter ni Toyin Abraham ti polowo sinima naa lowurọ ọjọ Ẹti, tawọn ọdọ si koro oju si igbesẹ naa tori iwọde a ko fẹ SARS mọ ti wọn n se.
Ọjọ Ẹti , ọjọ kẹtalelogun, osu Belu ni ẹbi, ara ati ojulumọ pejọ pọ ti wọn si sin oku oloye naa ni Ipinlẹ Ondo, tii ṣe ilu oloogbe naa.
Buhari tún sọ pé léhìn tí òun lọ́ra láti gbà síi lẹ́nu, Lai Mohammed ní ó yẹ kí a fèsì, ṣùgbón nínú èsì náà, wón kò gbọ́dọ̀ dárúkọ Obasanjo.
“Ṣugbọn tí ẹ bá sọ fún mi pé ẹ gbẹ́kẹ̀lé OLUWA Ọlọrun yín, ṣebí àwọn ibi ìrúbọ ati àwọn pẹpẹ Ọlọrun náà ni Hesekaya ti bàjẹ́, tí ó sì sọ fún àwọn ará Juda ati Jerusalẹmu pé, ‘Níwájú pẹpẹ tí ó wà ní Jerusalẹmu nìkan ni kí ẹ ti máa sìn.
Olukuluku wọn sọ ọ̀pá rẹ̀ sílẹ̀, ọ̀pá wọn sì di ejò ṣugbọn ọ̀pá Aaroni gbé gbogbo ọ̀pá tiwọn mì.
Lái fí ti ọmọluabi ṣe Gekpe sàlàyé El-Zakzaky bẹ̀rẹ̀ ìfọ̀rswérs pẹ̀lú àwọn agbẹjọrò ti Ali Zia Kabir Chaudary àti Gunjan Singh soju fún ni orilẹ̀-èdè náà.
Asofin tẹlẹri, Honourable Mojeed Olaiya sọ wi pe orilẹ-ede Naijiria ni ohun gbogbo bi alumọni ati owo ni akunwọsile lati se atunse ile iwe ẹgbẹwa lọdọọdun.
“Ní tiyín, ẹ̀yin agbo ẹran mi, èmi OLUWA Ọlọrun ni n óo ṣe ìdájọ́ láàrin aguntan kan ati aguntan keji, ati láàrin àgbò ati òbúkọ.
Ati pe oniruuru oko ni awọn ti ri ti wọn si gbin igbo si aaye to to papa isere bọọlu.
láti inú ìdílé Geriṣomu, aadoje (130) ọkunrin, Joẹli ni olórí wọn; 
Mẹtala ninu wọn lo wa lati ipinlẹ Eko, mẹrin lati Abuja, meji lati ipinlẹ Kaduna ti gomina ipinlẹ Ọyọ, Seyi Makinde si kun iye wọn.
Àwọn ẹranko wọ ihò wọn lọ,wọ́n dákẹ́ sibẹ, wọ́n sá pamọ́.
nítorí mo mọ̀ pé àyọrísí rẹ̀ ni pé a óo dá mi sílẹ̀ nípa adura yín ati nípa àtìlẹ́yìn Ẹ̀mí Jesu Kristi, 
00), ile-ise osise otelemuye Department of State Services (DSS) yoo gba “bilionu mewaa le ni okòólénígba dín meje owo naira (=N=10,213,282,455.
Mo bùn ọ́ ní adúrú gbèsè nnì nítorí o bẹ̀ mí.
 O wa salaye siwaju pe, ti eyi ba ti wa bo
Awon ile-ise meji ni won n figa gbaga lati ra Etisalat, amo ajo NCC ni ireti pe, gbogbo re yoo niyanju bi o ba fi maa di ipari osu keta.
Saheed Osupa fi eyi lede lasiko to n ba BBC Yoruba fọrọjomitoro ọrọ lori oju opo ikansiraẹni Facebook ti BBC News Yoruba.
O ti gbé ẹ̀ṣẹ̀ wa kalẹ̀ ní iwájú rẹ;àwọn ẹ̀ṣẹ̀ ìkọ̀kọ̀ wa sì hàn kedere ninu ìmọ́lẹ̀ ojú rẹ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, COZA: Ọpọ èrò ló jáde ṣe lòdì sí ẹ̀sùn ìfipábánilòpọ̀ Fatoyinbo Eyi si mu ki wọn o tun bẹrẹ si ni ṣọ ọrọ nipa ẹsun ifipabanilopọ ti ayaworan, to tun jẹ iyawo gbajugbaja akọrin, Timi Dakolo, Busola, fikan Fatoyinbo.
Dókítà t'ọ́mọ kú lọ́wọ́ rẹ̀ bọ́ nínú ẹjọ́ ní Leicester
eto  iranwọ imọ ẹrọ ati eto ilana fun
 Ọ ̀ pọ ̀ lọpọ ̀ ogun ni napoleon ṣẹ ́ .
Ṣugbọn yóo dìde sí ìdílé àwọn aṣebi,ati àwọn tí ń ti àwọn oníṣẹ́ ẹ̀ṣẹ̀ lẹ́yìn.
Lagos Lion: BBC ṣèwádìí ibi tí aráa India tó ń sin Kìnìhún wà
” Ni ó bá bá wọn wọlé, ó dúró lọ́dọ̀ wọn.
Irọ́ lásán ni, ṣe ni NCDC ń fi Coronavirus tan àwọn ọmọ Naijiria jẹ- ìjọba ìpínlẹ̀ Kogi Coronavirus in Nigeria: Ní ṣe ni NCDC ń fi Coronavirus tan àwọn ọmọ Naijiria jẹ- ìjọba ìpínlẹ̀ Kogi Oríṣun àwòrán, Getty Images Ijọba ipinlẹ Kogi ti sọ pe ko si ẹnikẹni to ni arun Coronavirus ni ipinlẹ naa.
Joṣua bá múra, ati gbogbo àwọn ọmọ ogun rẹ̀, wọ́n lọ sí ìlú Ai.
nígbà tí ó ṣe awọsanma lọ́jọ̀,tí ó fi ìpìlẹ̀ orísun omi sọ ilẹ̀,
Ṣaaju alaga ẹgbẹ NEF, Ọjọgbọn Ango Abdullahi ti sọ pe idi ti awọn fi ke si awọn Fulani Darandaran ki wọn dari pada si iha Ariwa waye latari ẹsun pe o le ma si abo fun ẹmi wọn tori ọrọ ti awọn gomina iha Guusu sọ.
Ẹ ranti ọ̀rọ̀ tí mo ti sọ fun yín, pé, ‘Ọmọ-ọ̀dọ̀ kò ju ọ̀gá rẹ̀ lọ.
Ayẹyẹ kankan ko si waye titi di ọdun 2014, lẹyin iku Emir Ado Bayero.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Kunle Afolayan: èmi kò fẹ́ fi ogún sílẹ̀ fún ọmọ mi A tun gbọ pe awọn osisẹ panapana meji lo farapa ninu ijamba ina naa, lasiko ti wọn n tiraka lati pa ina ọhun, ti wọn si ti gbe wọn lọ sile iwosan.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Fayemi: Àwọn àwòrán tó jẹ ojú ní gbèsè níbi ìbúra 16 Ọ̀wàrà 2018 Awọn awọran to joju ni gbese nibi ayẹyẹ iburawọle sipo Fayemi ni Ado Ekiti Àkọlé àwòrán, Awọn eeyan n duro ki ayẹyẹ naa bẹrẹ Àkọlé àwòrán, Awọn lọbalọba ko gbẹyin nibi ayẹyẹ naa Àkọlé àwòrán, Oni nkan laa jẹ o ṣẹ e .
Wọ́n gbé oúnjẹ wá fún un pé kí ó jẹ, ṣugbọn ó wí pé, “N kò ní jẹun títí n óo fi jíṣẹ́ tí wọ́n rán mi.
Heṣiboni ati Jaseri, pẹlu àwọn pápá oko àyíká wọn.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Amnesty International: Àwọn agbófinró ń fìyà jẹ àwọn èèyàn púpọ̀ jù ni Nàìjíríà 26 Òkùdu 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Amnesty International: Àwọn agbófinró ń fìyà jẹ àwọn èèyàn púpọ̀ jù ni Nàìjíríà Ajọ to n mojuto ọrọ alaforijin ni agbaye ti a mọ si Amnesty International ni awọn eleto aabo Naijiria ṣi n fiya ti ko tọ jẹ awọn eeyan.
Ó mú ìwé majẹmu náà, ó kà á sí etígbọ̀ọ́ gbogbo àwọn eniyan, wọ́n sì dáhùn pé, “Gbogbo ohun tí OLUWA wí ni a óo ṣe, a óo sì gbọ́ràn.
Òun nìkan ni ó dá wà, inú rẹ̀ sì bàjẹ́ pupọ.
Ọmọ Ẹgbẹ Oṣelu to pọju ninu Ile Igbimọ Aṣofin naa, Aṣofin Sanai
 awon adari elesin kan n  so pe wahala yoo sẹlẹ lasiko eto idibo.
Ilu Ibadan ni awọn mejeeji, eyi ti o fi han pe a lee pe wọn ni tẹgbọn taburo.
Magu wi pe, Ajọ EFCC ti ni ifọwọ sowọpọ pẹlu ajọ ọtelẹmuyẹ ilẹ Amẹrika, FBI, lati foju awọn afurasi naa lede.
Agbenuso fun molebi Gaddafi so ninu osu kejila odun 2017  pe, Saif ni atileyin ebi naa lati fopin si laasigbo ti o sele lorile-ede naa latigba ti won ti fipa yo baba re kuro lori alefa.
Kano Chained Man: Ìdáǹdé dé fún bàbá táwọn ẹbí rẹ so mọlẹ fun ọgbọn ọdun
Akọsilẹ fihan pe awọn oṣiṣẹ eleto ilera ni Naijiria lo lugbadi aarun coronavirus julọ nilẹ Adulawọ yatọ si orilẹede South Africa.
"Shina ni asiko yii ni oun wa bi baba oun pe ""Ṣe ẹjẹ eeyan niyi ni abi ẹjẹ ẹranko?"
Wọ́n ti gbé òkú Ibidunni Ighodalo sílé ìgbókúpamọ́sí l'Eko 'Àìjáfáfá àwọn panápaná ló mú kí ọṣẹ́ iná Akure pọ̀' Wòlíì Sotitobire gúnlẹ̀ sí ilé ẹjọ́ ní ìtẹ̀síwájú ìgbẹ́jọ́ rẹ̀ Osinowo ti figba kan jẹ ọmọ ile igbimọ aṣofin ipinlẹ Eko fun saa mẹrin ọtọtọ, nibi to ti ṣoju ẹkun idibo Kosofe.
Ile isẹ ikansiraẹni Facebook ti ni ogunlọgo oju opo to jẹ ayederu ni awọn ti wọgile nitori wọn fẹ lepa ilẹ Afirika.
Naijiria ojogbon, Yemi Osinbajo, ti ni pupọ ninu awon onisowo lo ti nifẹẹ lati
Tí àsìkò bá ti tó láti bímọ, ó ṣe pàtàkì kí ó bere àwọn ìbéèrè tí ó bá wù ọ Cadee sọ pé ó lè béèrè àwọn ìbéèrè wọ̀nyìí: Ǹjẹ́ ewu àti kó ààrùn Coronavirus ń bẹ fún mi níbi tí mo wà yìí, ṣe ó ní ẹni tí ó ti wà ní ààyè yìí tó ní ààrùn Coronavirus tẹ́lẹ̀?
A tilẹ̀ ṣe ànìyàn pé kí Àpáta-ìgbẹ̀yìn ṣú Ìlábùrù ní opó, ṣùgbọ́n kò fẹ́, a wí títí, ṣùgbọ́n ó kọ̀ jálẹ̀ o ní kò wu òun, àti pẹ̀lú pé òòrùn ara rẹ̀ kòì tíì tán, nígbà tí ó kọjá lọ́dọ̀ òun o ń rùn sí òun.
Sọ wí pé,“Òkú eniyan yóo sùn lọ nílẹ̀ bí ìgbọ̀nsẹ̀ lórí pápá tí ó tẹ́jú,ati bíi ìtí ọkà lẹ́yìn àwọn tí wọn ń kórè ọkà,kò sì ní sí ẹni tí yóo kó wọn jọ.
Bẹ́ẹ̀ ni ẹ óo ṣe mú ibi yìí kúrò láàrin yín.
 Àkosílẹ ̀ àpẹẹrẹ ìjalèlókun tí ó pẹ ́ jù ṣẹlẹ ̀ ní bíi orundún mẹ ́ rìnlá sẹ ́ yìn , nígbà tí àwọn ẹgbẹ ́ ajalè lórí òkun dojú kọ ọkọ ̀ ojú omi ti aegean àti mediterranean tí kò digun .
“Láti ọ̀dọ̀ Atasasesi ọba, sí Ẹsira, alufaa, tí ó tún jẹ́ akọ̀wé òfin Ọlọrun ọ̀run.
JAMB post UTME screening: UNN, MAPOLY, Auchi poly, AKSU àtàwọn míì ti bẹ̀rẹ̀ ìgbésẹ̀ àtiwọlé ní Naijiria
Lamẹki bí Noa, Noa bí Ṣemu, Hamu, ati Jafẹti.
Àwọn Obinrin Tí Wọn Ń Ran Jesu Lọ́wọ́.
Nítorí Mose wí pé, ‘Bọ̀wọ̀ fún baba ati ìyá rẹ’ ati pé, ‘Kí á pa ẹni tí ó bá sọ̀rọ̀ àbùkù sí baba tabi ìyá rẹ̀.
" Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Gomina Ambọde kede ọjọ idije Lagos City Marathon ọdun 201911 Èrèlè 2018 Quilox: Ìjọba ìpínlẹ̀ Èkó ti Quilox, ilé ijó Shina Peller pa nítorí ariwo23 Ọ̀pẹ̀̀ 2019 Shina Peller: Afojúsùn mi ni kí gbogbo ènìyàn jẹ mùdùn-múdùn ìjọba3 Òkùdu 2018 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
“Lẹ́yìn náà, mo mú omi, mo wẹ̀ ọ́; mo fọ ẹ̀jẹ̀ kúrò lára rẹ, mo sì fi òróró pa ọ́ lára.
Gẹ́gẹ́ bi Tony Orilade tó jẹ agbẹnusọ EFCC ṣe sọ, ó ni kìí ṣe pe àwọn yabo ilé rẹ̀ gẹ́gẹ́ bi ìròyìn tó ń lọ nígboro.
Ẹ yé irọ́ pa, mí o fún Super Eagles ní ẹbùn owó kánkan -Sanwo Olu Sanwo-Olu kò lè tori ìjà Ọjọta fòfin de NURTW ní Eko - Agbẹnusọ gómínà Háà!
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Amugbalẹgbẹ fun Gomina Akeredolu, Ọmọwe Doyin Ọdẹbọwale koro oju si Ojogo sọ pe ijọba yoo pasẹ ofin konileogbele patapata to ba jẹ dandan, ṣugbọn o ti gbe agadagodo ṣenu gbogbo ibode to wọ ipinlẹ ọhun bayii.
Awọn naa lọ n gbọ́n iyẹpẹ fi di awọn ibi ti omu ti gba opopona to si ti n ya wọnu ile.
Ninu awọn akọmọna, pupọ eeyan lo gbagbo pe o to gẹẹ lo fakọyọ.
Abenugan ile igbimo asofin kekere lorile ede
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Lagos Prince: Ilé ẹjọ́ ṣèdájọ́ ikú f'ọmọ Ọba ìlú Eko tẹ́lẹ̀ lórí ẹ̀sùn ìpànìyàn 18 Ọ̀pẹ̀̀ 2019 Oríṣun àwòrán, @TeamAfroNaija Àkọlé àwòrán, Wọn ni Adewale bẹ Lateef lọwẹ lati gba ẹmi arabirin Sikirat to si fun ni ẹgbẹrun un mẹfa naira owo iṣẹ Ile ẹjọ giga kan nipinlẹ Eko ti ṣe idajọ iku fun Adewale Oyekan, to jẹ ọmọ ọba ilu Eko tẹlẹ, Ọba Adeyinka Oyekan.
Ṣugbọn ẹyọ nǹkankan ni ó jẹ́ koṣeemani.
Ijoba orile-ede Naijiria ti fokan awon ara ilu bale wi pe eto -abo to nipon yoo  wa fun won latari ikolu eyi to waye latowo awon omo egbe elesin Islam kan ti a mo si Islamic Movement of Nigeria,ti gbogbo eniyan mo si Shiites, to waye nilu Abuja ,ti n se olu-ilu orile-ede Naijiria .
Bo ti lẹ jẹ wi pe oludasilẹ ijọ naa ti saaju bẹnu atẹ lu idena akojọpọ ijọsin, amọ Bisọọbu David Oyedepo ni oun yi ipinu pada nitori isin tawọn maa n se kii kọja ago mẹwa si ago mẹrin owurọ ni gbogbo ọjọ Kọkanlelọgbọn osu Kejila ọdọọdun.
 President for finding me versatile enough to move around.
Ìpínlẹ̀ Ondo ti ní gómìnà tuntun Òyìnbó sísọ di èèwọ̀ ní ìpínlẹ̀ Ekiti Yàtọ̀ sí Ọ̀ṣun Òṣogbo, Ṣàǹgó pẹ̀lú a máa ní arugbá lóde Ọ̀yọ̀ Falana àtàwọn míì péjú síbi àpérò #RevolutionNow l'Eko Ambọde ni titi di bi a ṣe n sọrọ yii, ko si igba kan ti ajọ EFCC ba oun ni gbolohun lori ohunkohun yoo wu.
Wo ìyàtọ̀ tó wà láàrin Bíbélì Yorùbá tí Kumuyi kọ sí èyí tó wà ńlẹ̀ Ìpínlẹ̀ Oyo kéde àdínkù owó orí nítorí Covid 19 Ìjọba àpapọ̀ kéde ọjọ́ tí ìdánwò NECO, NABTEB àti BECE yóò bẹ̀rẹ̀ Keisha sàlàyé ìdí tó fi sunkún ní ìyàrá ìrántí nílé ẹlẹ́gbọ̀n ọ́n àgbà, ayé pariwo Ni bayii, Babalola ti ṣi oju opo Instagram fun Oreoluwa lẹyin ti fidio Mummy calm down"" naa sọ ọ di gbajumọ tan."
Amọ o fun mi ni owo lati gba ilegbe miran ti maa gbe titi ti ojo yoo fi lọ, mo si n dupẹ pupọ lọwọ rẹ.
Ṣe akọnimọọgba yoo nipa lori bi awọn agbabọọlu yoio ṣe maa huwa?
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Lórí ìrìnàjò Buhari sí London: Garba Shehu ni ààrẹ lè ṣe ìjọba níbikíbi 28 Ìgbé 2019 Amofin agba Femi Falana ati amofin Mike Ozhekome wa lara awọn onimọ to ti bẹnu atẹ lu bi Aarẹ Muhammadu Buhari ṣe gbori le ilu London lai sọ idi ti oun fi n lọ fun Ile Igbimọ Aṣofin.
jẹ Gana, o jẹ ọkan lara  omo ise Boko
Visions (Shaitan, Buruja, Brood) – Nigeria
Huramu, ọba Tire, bá dá èsì lẹta Solomoni pada, ó ní, “OLUWA fẹ́ràn àwọn eniyan rẹ̀, ni ó ṣe fi ọ́ jọba lórí wọn.
O sọ pé ìwọ ni o óo máa jẹ́ ayaba títí lae,nítorí náà o kò kó àwọn nǹkan wọnyi lékàn,o kò sì ranti ìgbẹ̀yìn wọn.
waye, lara iwadii ti won yoo maa se ni  “iwa ibajẹ,iwa ifipa gba ohun ini, gbigba ilẹ lọna aitọ.
wọ́n fi ṣe adé, ati fìlà ati ṣòkòtò.
Gbogbo orílẹ̀-èdè ńláńlá sì fi ìbòòji abẹ́ rẹ̀ ṣe ibùgbé.
Ọsinbajo, asaájú tílù fẹ́ jùlọ, kò leè di ààrẹ lásìkòyí Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Aarun ọpọlọ kii se idajọ iku Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Wo fidio ikede iku Hawking to ku lẹni ọdun mẹrindinlọgọrin (76) Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Nígbà tí a ti kó nǹkan ìjà wa jọ tán tí a sì kó àwọn oògùn wa pàtàkì fún Ewédayépọ̀ a bẹ̀rẹ̀ sí pa èrò ọ̀nà àtilọ.
"Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Coronavirus in Nigeria: Ìwádìí fihàn pé ọ̀pọ̀ aráàlú ni kò gbà pé àrùn Covid-19 wà Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Palmwine Tapping: Ọ̀dọ́mọdé àdẹ́mu ní ìṣẹ́ náà kò wú òun lórí Lọjọ Ẹti, iroyin to kọkọ gbode ni eyi to ni ṣe pẹlu awọn eeyan mẹwa to ku lẹyin ti wọn mu ọti ti wọn fi ""Hand sanitiser"" po pọ ni ipinlẹ Andra Pradesh to wa ni guusu orileede India."
Ohun tí Sodomu arabinrin rẹ ṣe tí kò dára ni pé: Òun ati àwọn ọmọ rẹ̀ obinrin ní ìgbéraga.
 Ó jẹ ́ bíbí bíi aláìnídèkùn ní norfolk , virginia , usa , roberts kó lọ sí làìbéríà ní 1829 nígbà tó jẹ ́ ọ ̀ dọ ́ .
Ki gbogbo Nigeria tó gba ominira ni àwọn Òṣèlú lábẹ́ olùdari Olóyè Ọbáfẹ́mi Awolọwọ ti fi owó kòkó àti iṣẹ́-àgbẹ̀ dá nkan ṣe fún gbogbo ilẹ̀ Yorùbá.
Ọdun 2019 ni Busola Dakolo jade si gbangba pẹlu ẹsun pe Pasitọ Biodun fi ipa ba oun lopọ ninu ile awọn obi oun nilu Ilorin, ni ọdun diẹ sẹyin.
Ajo to n mojuto boolu afesegba nile Afrika, CAF ti yan aare ajo NFF Amaju Pinnick gege bi igbakeji aare ajo CAF.
Lasiko to n ba BBC Yoruba sọrọ, Ọladapọ ni oun ko fẹ ki ayẹyẹ naa tete su awọn eeyan ni oun se da ara to to bẹẹ.
Kò yá wà lẹ́nu pé Dogara lọ sí PDP Ambọde: Kò sí ìjà láàrin èmi àti Tinubu Igbákejì Àárẹ Nàìjíríà, Ọ̀jọ̀gbọ́n Yẹmi Ọṣinbajo ló gba iṣẹ́ lọ́wọ́ Daura l'ọ́jọ́ keje, oṣù Kẹjọ, 2018, lásìkò tó fi delé fún Ààrẹ Buhari tó lọ fún ìsìnmi ẹnu iṣẹ́ nílẹ̀ Gẹ̀ẹ́sì.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ìgunnukó: Àwọn Tápà gbà pé ẹni tó bá ń sin Ìgunnukó kò ní ráùn ohun rere Ohun ti wọn n sọ ni pe, ko tọna labẹ ilana pin in re-la a re, ọkan ko gbọdọ jukan lọ pe, ki ibatan oludije kan tun lọwọ ninu eto kika ibo ti o ti n kopa.
Ọba Adesoji Aderemi, Ọọ̀ni Ifẹ̀ tó gba ipò ọba mọ́ tòṣèlú Ìpínlẹ̀ Oyo gba ipò ìkíní mọ́ Edo lọ́wọ́ nínú fífí ọmọdé ṣ'ẹrú Háà!
Oríṣun àwòrán, @followlasg Gẹgẹ bo se wi, ohun keji ni pe wọn ko fi ami ẹyẹ ilẹ wa kankan da Jakande lọlka ri nigba to jẹ pe awọn eeyan lasan ti ko to nidi aseyọri ti gba ami ẹyẹ orilẹede yii.
Kii ṣe aṣọ nikan ni wọn ta nibi itaja ojule ọhun to waye ni New York.
Ṣe Saulu yóo wá gẹ́gẹ́ bí mo ti gbọ́?
Ijọba Kaduna ni bi o tilẹ jẹ pe oun maa n bọwọ fun ẹtọ ọmọniyan lati wa itọju fun ara rẹ ni ibikibi lagbaye amọ nibamu pẹlu aṣẹ ileẹjọ naa, awọn igbesẹ kan gbọdọ wa ti olori ẹsin naa gbọdọ tẹle, ki oun to lọ.
Lẹ́yìn náà, gbé ọ̀pá fìtílà náà wọ inú rẹ̀, kí o sì to àwọn fìtílà orí rẹ̀ sí ààyè wọn.
" Ojojumo là ń fi ara wa se oogun owó, a ń fi ojú rí apá àti ẹsẹ, tó fi mọ orí èèyàn nigboro, táwọn ọmọ Badoo sì ń fọ orí àwọn èèyàn kiri, èyí tí kò dun mọ Ọlọ́run nínú.
Ẹ o ranti pe Senegal fiya jẹ Naijiria pẹlu ami ayo meji sodo ninu idije WAFU lọdun 2018 naa.
Ewe, Bi a se n tesiwaju lati tun mu igberu ba eto idibo lorille-ede yii, bee si ni lati maa faye gba ojusaaju ninu awon idibo wa gbogbo, egbe oselu APC gbosuba fun isejoba aare Muhammadu Buhari, papaajulo fun akitiyan re lati je ki eto idibo waye nirowo-rose, bee si ni lai figba kan bo kan ninu.
Aarẹ Buhari pàsẹ ki wọn si awọn bode Naijiria pada kiakia Oríṣun àwòrán, Getty Images Aarẹ orilẹede Naijiria, Muhammadu Buhari ti paṣẹ pe ki wọn ṣi awọn ẹnu ibode mẹrin loni wara n ṣesa.
Oríṣun àwòrán, Mercy Aigbe/Instagram Oríṣun àwòrán, Toke Makinwa/Instagram Kinni ibimọ Akindele ṣe jẹ ọrọ nla laarin awọn ololufẹ rẹ?
Oludari ajọ NAFDAC sọ pe o san ki ijọba o nawo lori agbo ti wọn ṣe ni Naijiria, ju ti orilẹ-ede Madagascar lọ.
Oríṣun àwòrán, realmercyaigbe Àkọlé àwòrán, A see ẹbun akara oyinbo lasan lee pa owe nla fun ẹda kan Mercy Aigbe ni n se ni oun rẹrin iyangi, to si lọra lati se amin.
Ohun ati Asiwaju Bola Ahmed Tinubu ni wọn jijọ du ipo yi ki o to ja mọ lọwọ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Boko Haram: Ọlọ́pàá mú afẹ̀sùnkàn olójú kan tó ti pa ju igba ènìyàn 21 Ọ̀pẹ̀̀ 2018 Oríṣun àwòrán, NIGERIA POLICE Idunnu ṣubu layọ awọn ikọ IRT l'Ọjọbọ bi iroyin ṣe kan wipe ọwọ ti tẹ Abdulmalik Umar to jẹ ọkan lara awọn ogbologbo apaniyan ati ọgagun ninu Boko Haram.
Gomina naa mu wa si iranti pe ọpọlọpọ n ro pe tori ati wọle gomina lẹẹkan sii lo n san ọna nigba ti o darapọ mọ awọn gomina ti wọn jọ wa nibi ifilọlẹ ikọ Amotekun nilu Ibadan ninu oṣu kinni ọdun yii.
Diego Maradona: Ohun mẹ́wàá pàtàkì nípa Maradona àti ìbáṣepọ̀ rẹ̀ pẹ̀lú ẹlẹ́sẹ̀ ayò Diego Costa rèé
Oshodi Tapa fi ọpọ aya ati awọn ọmọ to to mẹrindinlaadọta sile aye lọ, ti wọn si sin oku rẹ si aarin gbungbun opopona Oshodi ni Epetedo nilu Eko, bẹẹ ni wọn ri ọwọn iranti soju saare rẹ titi di oni.
Oríṣun àwòrán, Others Idile Henry Fajemirokun: Baba ọlọla yii fẹ iyawo, oloogbe Comfort Oseboade Fajemirokun, ẹni to papoda lọdun 2019.
Minisita feto ìlera ni Mo ń rọ àwọn ọmọ Nàìjíríà láti gbé ilegbee wọn kalẹ fún ibùdó iyasọtọ fún ìgbà díẹ̀."
0Atẹjade kan ti ajọ to n ri si igbogun ti ajakalẹ arun lorilẹede Naijiria, NCDC fi sita loju opo Twitter rẹ ṣalaye pe, mẹtalelogoji ninu awọn eeyan naa wa ni ipinlẹ Eko, mẹjọ wa lati Sokoto, mẹfa lati Taraba, marun un ni Kaduna, marun un ni Gombe, mẹta ni Ondo, mẹta ni ilu Abuja.
Ìjọba ìpínlẹ̀ Oyo kéde pé kí àwọn òṣìṣẹ́ ìjọba dáwọ́ iṣẹ́ dúró nítorí coronavirus Èèèyàn márùn ún péré ló leè lọ ayẹyẹ ìgbéyàwó ní Australia báyìí nítorí Coronavirus Ilé ìgbìmọ̀ Aṣòfin Nàìjíríà kó igbá wọlé l'Abuja nítorí coronavirus Ẹwẹ àwọn ọja tó máa ń kún fòfò náà yóò kogbasile afi àwọn èyí tí wọn tí ń tà oúnjẹ jíjẹ Ní ose tó kọjá ní aare ni kí wọn tí gbogbo ilé ìwé, ilé ọtí, àti àwọn ibi igbafe, gbogbo ilé ìworán àti pé ipejopo kò gbọ́dọ̀ ju ènìyàn méjìlélọ́gbọ̀n lọ.
idibo, Bakan naa,ajo INEC ko ni foju rere wo awon janduku to ba fẹ da wahala
Lẹ́yìn náà, kí àwọn ọmọ Aaroni, alufaa, to àwọn igẹ̀ ẹran náà ati orí rẹ̀ ati ọ̀rá rẹ̀ sórí igi tí wọ́n dáná sí, lórí pẹpẹ náà.
Marley ni oun o jẹbi gbogbo ẹsun ti wọn fi kan an.
Isaaki kúrò níbẹ̀, ó lọ tẹ̀dó sí àfonífojì Gerari.
Àsìkò tó láti dóòlà Nàíjíríà, a ti gbé ẹ̀ṣùn ìbò lọ sílé ẹjọ́ tó ga jùlọ - PDP Ilẹ̀ Gẹ̀ẹ́sì yóò kúrò pátápátá lára àjọ EU ní Jan 31 ọdún 2020 Lẹ́yìn ìpàdé òní l‘Abuja, ṣé ASUU yóò yanṣẹ́ lódì àbí bẹ́ẹ̀kọ́?
Bo tile je pe awon kan tile tele oro gomina naa lati  wa  oko won lo gunle  si ile gomina nibi ti  gomina ti n se ipolongo eto idibo .
Ṣebí mo ti sọ fún ọ tipẹ́,mo ti kéde rẹ̀,ìwọ sì ni ẹlẹ́rìí mi:Ǹjẹ́ Ọlọrun mìíràn wà lẹ́yìn mi?
lọ́jọ́ tí a dé ibẹ̀ gan-an, àpótí ọti kan ló wá gbé fún ni, ó sì fi màlúù méjì lé e.
Orúkọ àwọn tí wọ́n bí fún un ní Jerusalẹmu nìwọ̀nyí: Ṣamua ati Ṣobabu, Natani, ati Solomoni; 
Idahun wa lẹkunrẹrẹ ninu fidio yii.
"Ilana itọju alaisan nile""Fun awọn ti ailera wọn ko le ti wọn yoo maa tọju nile, a maa pe wọn lori ẹrọ ibanisọrọ, oṣiṣẹ wa yoo lọ bẹ wọn wo, a o ri i daju pe wọn gba ilana itọju ara ẹni lori ẹrọ ibanisọrọ wa, a o si ma mojuto ayipada wọn."
NAFDAC: A ń se ìwádìí pínpín oògùn ikọ́ Coedine délẹ̀ Oríṣun àwòrán, @nafdactwitter Àkọlé àwòrán, NAFDAC ti ṣetan láti wádìí àwọn ilé iṣẹ́ apoògùn fínnífínní lórí ọ̀rọ̀ coedine Fídíò Coedine BBC ṣí ojú NAFDAC sí iṣẹ́ ìwádìí tó yé kí wọ́n ṣe Ní kété tí BBC ti gbé fídíò àwón ọ̀dọ́ ti wọ́n n mu òògùn ikọ́ olómi Coedine síta ní ó ti n so èso rere fún iṣẹ́ ìwádìí àti òfin ìlera túntún.
Aare yanana oro naa pe, ohun ti o baa ba oju, o di dondon ki imu mo lara lataari ibasepo ti o wa laarin orile-ede kookan.
Lizzy Anjori ṣèyàwó, àwọn òṣèré púpọ̀ ṣọjọ́ ìbí f'ọ́mọ lọ́sẹ̀ yìí Ègún ọ̀dá owó yóò jà yín, tẹ́ ẹ̀ bá san ìdá mẹ́wàá - Oyedepo 'Coro' wà 'Coro' ò sí o, èmi á lọ́ sókè òkún bí mo bá ríṣẹ́ - dókítà Wo bí ètò ìsìnkú Tolulope Arotilẹ yóò ṣe lọ nílùú Abuja lọ́sẹ̀ tó ń bọ̀ NCDC ni eeyan ẹgbẹrun marundinlogoji ati ọtalenirinwo o din mẹfa, (35, 464) ni ayẹwo ti fihan pe o larun naa ni Naijiria.
Àlàyé rèé lóríi ìdí tí wọ́n fi ń pe aya ní ìyàwó Khafi wọ gàu lẹ́nu iṣẹ́ lórí ẹ̀sùn ìbálòpọ̀ ní BB Naija Àlàyé rèé lóríi ìdí tí wọ́n fi ń pe aya ní ìyàwó Bakan naa lo tun rọ awọn awọn araalu pe eto idẹrun wọn lo mumu julọ ni aya ijọba oun, ti oun yoo si tukọ ipinlẹ Ọyọ pẹlu ibẹru Ọlọrun.
atileyin  nipa sise ohun iwuri fun un yin.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Coronavirus : Idris Elba ti lùgbàdì àrùn Coronavirus 16 Ẹrẹ̀nà 2020 Oríṣun àwòrán, Getty Images Gbajugbaja oṣere ọmọ ilẹ Gẹẹsi Idris Elba ti kede pe oun ti lugbadi arun Coronavirus.
Bakan naa lo kesi aarẹ Muhammadu Buhari lati jade wa bawọn ọmọ Naijiria sọrọ, ko si sọ awọn ọna ti yoo gba wa ojutu sawọn ẹhonu oluwọde.
Nítorí náà n óo tún ṣe ohun ìyanu sí àwọn eniyan wọnyi, ohun ìyanu tí ó jọni lójú.
Ẹ wo irú ilẹ̀ tí ilẹ̀ Kenaani jẹ́, àwọn eniyan mélòó ló ń gbé ibẹ̀ ati pé báwo ni wọ́n ṣe lágbára sí.
Linda Ikeji: Gbájugbaja àkọ̀ròyìn ẹ̀rọ alátagbà bímọ tuntun
Bẹ́ẹ̀ ni wọn yóo ṣe fọ ilẹ̀ náà mọ́.
Agbẹnusọ Ile Igbimọ Aṣofin naa tun rọ awọn ọmọ orilẹ-ede yii lati jawọ ninu aawọ ati awọn iwa tabi igbesẹ ti o le fa laasigbo laarin ilu.
Ijọba Nàìjíríà pinnu láti dá àwọn èèyàn lókowò N10,000
Ile ijọsin mẹta to wa ni Kochchikade, Negombo ati Batticaloa ni awọn alaburu ti yin ado oloro lasiko ijọsin Ajinde lorileede Sri Lanka.
"Eto idibo lawọn agbegbe yii, paapa eto idibo sile asoju-sofin ati asofin agba ni ko lee waye, ti ajọ INEC yoo si pinnu to ba ya nipa akoko ti atundi ibo yoo waye lawọn agbegbe naa, lẹyin tawn ba ti gbọ ẹkunrẹrẹ alaye.
Ẹ̀yà Aṣeri ni yóo pàgọ́ tẹ̀lé ẹ̀yà Dani; Pagieli, ọmọ Okirani, ni yóo sì jẹ́ olórí wọn.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Dòkítà tó ṣe iṣẹ́ abẹ fún oyún inú l‘Amẹrika ló ń sọ Yorùbá yìí, bíi ẹní la oyin Àrà méèrírí!
Omokunrin Uzbek kan, ti o je awako oko ero bogini kan lo kolu awon eniyan marun un , ni eyi ti won padanu emi won ni Sweden, lodun to koja, ni won ti ju si ewon gbere , pe o  jebi iwa olote.
Ohun tí o kò mọ̀ nípa Hosni Mubarak, Ààrẹ Egypt tó papòdà Ààrẹ Buhari ṣí ilé iṣẹ́ àti afára ní ìpínlẹ̀ Ondo Tiamiyu Kazeem ni ọkọ oju popo kọlu, leyi to yọri si iku rẹ lẹyin ti iroyin ni awọn ọlọpaa SARS ti i jabọ kuro ninu ọkọ wọn ni ọna Abeokuta-Sagamu lọjọ Satide.
Arabia fesun kan pe o n gbe ogun oloro, Zainab Aliyu ti bale si papako ofurufu Malam
Ṣùgbọ́n àwọn èèyàn míràn yí ọ̀rọ̀ náà si ibòmíràn, tí wọ́n sì ni torí owó tí àwọn ìjọ Ọlọ́run kò rí pa wọlé mọ, ní ojisẹ Ọlọ́run náà ṣe ń pariwo lórí bí ìjọba ṣe tí ilé ìjọsìn pá.
Ó rọ àwọn ọmọ ìgbìmọ tẹ̀ẹ́koto lóri ètò ìsúná láti dá èsì pada titi ọjọ Jimọ, bákan náà lo'tún rọ wọn láti mú àbájáde wọn silẹ̀ láàrin ọjọ kẹsan an sí ọjọ kọkanla, oṣù kẹ́rin.
Orúkọ rẹ̀ ní èdè Heberu ni Abadoni; ní èdè Giriki orúkọ rẹ̀ ni Apolioni.
Ìgbà wo ni o óo tají lójú oorun?
Oludari ile-ise akoroyin Voice of Nigeria (VON), ogbeni Osita Okechukwu ti jawe olubori lati darapo mo awon asoju ti yoo kopa ninu eto idibo egbe oselu ti o wa lori alefa lowo bayii, ti n se All Progressives Congress (APC).
Mercy Aigbe: Àwọn òṣèré tíátà Yorùbá mẹ́wàá tí kìí ṣe Yorùbá
O ṣeeṣe ki Ayew o pẹlu awọn agbabọọlu Swansea City ti yoo fẹsẹwọnsẹ pẹlu Burnley lọjọ abamẹta.
Wọ́n ní ẹgbaa mẹẹdogun (30,000) kẹ̀kẹ́ ogun, ati ẹgbaata (6,000) ẹlẹ́ṣin, àwọn ọmọ ogun wọn sì pọ̀ bí eṣú.
Ó ní: “Àwọn ará Tire ń dẹ́ṣẹ̀ kún ẹ̀ṣẹ̀, dájúdájú, n óo jẹ wọ́n níyà; nítorí wọ́n kó odidi orílẹ̀-èdè kan lẹ́rú lọ tà fún àwọn ará Edomu.
Aleku yoo ba eto isuna orile-ede naa si trillion meji o le ni odun 2018 si odun 2019 ju ti odun 2017 lo.
idibo naa ,,awon agbofinro ati awon osisẹ aabo ara ni aabo ẹmi(Nigeria Security
A tun ti mu okan wa le , lati tubo gbokun ti iwa ibaje, bo se wu ki o buru to.
Nigba ti wọn beere lọwọ rẹ idi ti ko fi fẹ oṣere bi ti ẹ, Ronke sọ pe afojusun oun ni lati fẹ oṣere nigba ti oun wa ni ọmọge.
Gbogbo òkú tí ó wà níkàáwọ́ ikú ati àwọn tí wọ́n wà ní ipò òkú ni wọ́n tún jáde.
Amọ awọn eniyan lori Twitter bere si ni rẹrin ni lẹyin ti ẹni to sọrọ nipa bi bọọlu ṣe n lọ(commentataor) ṣe aṣiṣe pẹlu bi o ṣe sọ pe Alex Iwobi n gba bọọlu ni Arsenal.
 Ijoba ti ke gbajere pe kawon eniyan din omi ti won n lo ku.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Kílódé t'íjọba kò ṣe tíì pe àwọn darandaran ní agbésùmọ̀mí?
O Adaraloye sọ pe Ifeanyi atawọn miran ti wọn ti na papa bora huwa ọdaran naa ni nnkan bi aago mẹta oru ni adugbo Femi Oni, to wa ni opopna Arinko, ni Otta, iyẹn ni ipinlẹ Ogun.
A gbagbọ pe ajọ FBI yoo ṣe iwadi fini fini lori ọrọ naa, ti gbogb wa si maa mọ okodoro ibẹ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Beckham: Èdè mẹ́sàn-án ni Beckham fi gbógun ti àrùn ibà 9 Ìgbé 2019 Oríṣun àwòrán, @malariamustdie Gbajugbaja agbabọọlu ọmọ ilẹ Gẹẹsi tẹlẹ, David Beckham tun ti gba ọna ara miran yọ sawọn eeyan agbaye, paapa awọn ololufẹ rẹ.
0 145495 Agbegbe Palestine 910 18.
Ẹwẹ, o ni ireti, ninu ohun gbogbo pe yoo ri iṣẹ to dara.
Ẹni tí ó kọ etí dídi sí igbe talaka,òun náà yóo kígbe, ṣugbọn kò ní rí ẹni dá a lóhùn.
Lati igba ti aarẹ Buhari ti de ori oye ni ariwo pe awọn alagbara kan wa to n paṣẹ ni ijọba rẹ ti bẹrẹ.
com/BpLNz8AW6uOle's at the wheel…What a photo 😍 pic.
Lọwọlọwọ bayii, Lizzy tun ti mu okoowo ilẹ ati ile tita mọ katakara lati ri taje se.
Giadom ni ẹgbẹ awọn yoo bọwọ fun aṣẹ ti ile ẹjọ pa pe ki Oshiomole yẹba ṣẹgbẹ kan titi ti wọn yoo fi gbẹjọ lori yiyọ nipo.
Oríṣun àwòrán, @officialasanlu Àkọlé àwòrán, Abdulsalam lo ede rẹ lati fi gba awọn ọmọ ogun Afọnja, ti wọn si gba ẹmi Afọnja lọdun 1817 Ìtàn tó wà nídi òwe ‘Sebótimọ Ẹlẹ́wà Sàpọ́n’ Ọba Adesoji Aderemi, Ọọ̀ni Ifẹ̀ tó gba ipò ọba mọ́ tòṣèlú MKO Abiola, iṣẹ́ aṣẹ́gità ló fi bẹ̀rẹ̀ okoòwò Iṣọla Oyenusi rèé, ẹnití ìfẹ́ obìnrin ṣun dé ìwà ìdigunjalè Ibẹrẹ iṣubu Afọnja nilu Ilọrin: Afọnja gbagbọ pe awọn ọmọ ogun Fulani ati awọn ẹru to jẹ Hausa jẹ akikanju jagunjagun, ti wọn si sangun ju awọn ọmọ ogun toun lọ, idi niyi to se ba Shehu Alimi, tii se Alafa Fulani da ọrẹ, Afọnja si tu awọn ọmọ ogun tiẹ ka, to si ko awọn ẹya Hausa, Fulani atawọn ẹya miran sinu ikọ ọmọ ogun rẹ Lẹyin ti Alimi ku, Abdulsalam tii se ọmọ Alimi lo anfaani ohun ti Afọnja se yii, to si loo lati kọlu Afọnja.
Bakan naa awọn ipara, nkan ikunra, atike ati ikunte ti wọn maa n lo gan n ṣe iṣẹ agbara.
Àkọlé àwòrán, Tayotayo ni Kabiesi gbalejo awon ogo weere Baba gbogbo ọmọ Oodua wure aṣeyọri fun gbogbo awọn ọmọ ti wọn wa sibi eto naa atawọn ti wọn ko le wa lapapọ.
Ǹkan tí a mọ̀ nípa kọ́lẹ̀jì olùdìbò tó ń fìdì ẹni ti yóò jẹ ààrẹ ilẹ̀ Amérika múlẹ̀ Koda, wọn dana sun agọ ọlọpaa mẹta ni agbegbe naa.
Ẹ̀yin èrò inú ọkọ̀ lójú agbami òkun,ati gbogbo ohun tí ó wà ninu omi òkun;ati àwọn erékùṣù ati àwọn tí ń gbé inú wọn.
Bakan naa lo sọ pe ọjọ kẹwa, oṣu Kẹrin ni awọn akẹkọọ naa yoo to pada si ọgba ileewe.
si eto Iroyin, Aabo ati Ọgbọn Imuṣẹṣe ninu Ile Igbimọ Aṣofin Ipinlẹ Eko
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Igboora: Wòlíì ni mí, ṣùgbọ́n àwọn ọ̀gá tó kọ́ mi níṣẹ́ òògùn owó ní kí n má dárúkọ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Igboora: Wòlíì ni mí, ṣùgbọ́n àwọn ọ̀gá tó kọ́ mi níṣẹ́ òògùn owó ní kí n má dárúkọ 26 Agẹmo 2019 Hmmmmn.
Fásitì ìpínlẹ̀ Ekiti dá òṣìṣẹ́ 355 padà sẹ́nu iṣẹ́ Ọmọ ilẹ̀ Iran 82 ló kú nínú bàálù tó já lórílẹ̀èdè naa Ilé ìwòsàn l'Àbuja ti ya àwọn ìbejì tí wọ́n sọpọ̀ láyà lọ́fẹ̀ẹ́ Gómìnà mẹ́ta àtí ènìyàn 1,242 ló kó sí panpẹ EFCC ni ọdún 2019 Ẹ́ gba fóónù, ẹ pe ẹbí yín pé a fẹ́ dáná ṣun yín - Aráàlú sọ fún adigunjalè méji Diẹ ree lara awọn eeyan ti aarẹ ti da pada lẹyin ti wọn ti rọ wọn loye lati igba ti aarẹ Buhari ti de ipo ni ọdun 2015: Oríṣun àwòrán, Tetfund Àkọlé àwòrán, Kí ló dé tí Ààrẹ Buhari tún ń dá àwọn tó fúnrarẹ̀ yọ nípò pàdà Ọjọgbọn Suleiman Bogoro, akọwe agba ajọ iṣuna eto ẹkọ giga ni Naijiria, TETFUND: Ni ọdun 2014 ni aarẹ ana, Goodluck Jonathan kọkọ yan an sipo ṣugbọn oṣu keji, ọdun 2016 ni ijọba aarẹ Buhari yọọ kuro nipo.
Èyí wáye lẹ́yìn tí wọn ni Fayose sọ̀rọ̀ tó lé dá ẹgbẹ́ rú tó sì lè dá wàhalà sílẹ̀ láàrin àwọn ọmọ kéèkèé àti àgbà ẹgbẹ́.
Ó fún Nàìjíríà l'èsì àwọn ẹ̀sùn tó fi kàn-án Ọba ni mí, mi ò le b'ọ̀rìṣà, Olorì tuntun tó ń bọ̀ já gbogbo ''scale''- Oluwo ti Iwo Èèyàn méjì kú, méjìdínlógóje míì ṣẹ̀ṣẹ̀ kó COVID-19 lọ́jọ́ Àìkú O ni oun ko fẹ iranwọ ẹgbẹ awọn oṣere ni Niajiria ati wi pe awọn ọmọ Yoruba ni oun fẹ ki wọn ran oun lọwọ lori iṣẹ oun.
Opolopo awon eniyan lo kedun iku Daniel pelu DBanj baba re.
Èmi a sọ fún àwọn tí ń fọ́nnu pé, ‘Ẹ yé fọ́nnu’;èmi a sì sọ fún àwọn eniyan burúkú pé, ‘Ẹ yé ṣe ìgbéraga.
Onimọ nipa ọrọ eto aabo, Ọgbẹni Richard Amuwa ti gba awọn orilẹede Naijiria n'imọran pe o lewu lati kọkọ yẹ ọlọpaa wo ti o ba fẹ yẹ wọn wo.
Gomina wa dupẹ lọwọ Deji ti Akure fun abẹwo rẹ, to si fi da wọn loju pe, awọn ara ilu Akure yoo ko ipa ribiribi ninu eto isinku iya oun.
Wọn a máa sùn ní ìhòòhò ní gbogbo òru,wọn kìí sìí rí aṣọ fi bora nígbà òtútù.
Ẹgbẹ naa si lo ṣe ikọlu akọkọ ni orilẹ-ede naa.
Wọ́n ń kùn ninu àgọ́ wọn,wọn kò sì fetí sí ohùn OLUWA.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Kayeefi: Facebook ni Wolii Arole Jesu fi tàn an wọ agbo, orí rẹ̀ ni wọ́n fi s'owó Awọn kan fẹsun kan ologun pe wọn n ran ẹgbẹ okunkun lọwọ Ni ọdun 1999 wọn pa awọn ọmọ ẹgbẹ igbimọ akẹkọọ fasiti Obafemi Awolowo nilu ile Ife nipinlẹ Osun.
Ọpọlọpọ eniyan ni yóo bá wọn kẹ́gbẹ́ ninu ìfẹ́kúfẹ̀ẹ́ wọn; nítorí ìṣe wọn, àwọn eniyan yóo máa gan ọ̀nà òtítọ́.
Báyìí ni àwọn ọmọ aráyé bẹ̀rẹ̀ sí ṣe tí wọn ń sọ̀rọ̀ tí wọn ń dárúkọ orí kékeré àti ọwọ́ títóbi, bẹ́ẹ̀ náà ssì ni aṣojú-Olódùmarè fi etí sílẹ̀ tí ó ń gbọ́ àròyé wọn.
Gbogbo awọn ọmọ Yoruba yoku wa salọ.
Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí kan sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
“Ogún òṣùnwọ̀n gera ni yóo wà ninu òṣùnwọ̀n ṣekeli kan.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Àbọ̀dé Libya: Èeyàn 218 padà dé sí ìlú Èkó 8 Èbibi 2018 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ó lé l'ẹ́gbẹ̀rún mẹ́jọ àwọn ọmọ orílẹ̀èdè Nàíjíríà tí wọ́n ti kó padà dé láti orílẹ̀èdè Libya Okòólénígba ó dín méjì làwọn ọmọ Nàíjíríà tí wọ́n kó padà dé láti orílẹ̀èdè Libya ni ọjọ́ ìṣẹ́gun.
Ẹwẹ, o jade ninu abọ igbimọ PCARA to n bojuwo owo ijọba ti ajọ EFCC ri gba pada pe laarin oṣu karun ọdun 2015 si oṣu karun ọdun 2020, orukọ Emmanuel Omale to jẹ Pasitọ ijọ kan, Hand of God Prophetic Ministry ni Magu fi n ko owo jẹ.
Ẹri láti ara àwọn ayàwòràn kọ̀rọ̀ ti wọn ń lẹ mọle fi han pe Adeleye jẹ alágbàtọ ọmọ tó n ba wọn gbéle, O gbiyanju láti fún ọmọ náà lóunjẹ, sùgbọ́n ti ó kọ láti gba ounjẹ náà ti obinrin yii si da ọmọ náà dubulẹ láti fún un lóunjẹ.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Iroyin lati agbegbe naa so pe awọn eeyan kan n sun lọwọ nigba ti ogiri naa ya lu wọn.
Má jẹ́ kí ìwà ìṣòótọ́ kí ó fi ọ́ sílẹ̀,so àánú ati òtítọ́ mọ́ ọrùn rẹ,kọ wọ́n sí oókan àyà rẹ.
Oríṣun àwòrán, @paadcofficial Àkọlé àwòrán, Ile ẹkọ fasiti ilu Eko ṣe agbekalẹ idije imọ ẹrọ fun awọn akẹkọ fasiti ni iranti Ọjọgbọn Awojobi Lasiko igbesi aye rẹ, o jẹ alaga igbimọ ile ẹkọ nipinlẹ Eko ti o si kọ ọpọ iwe fun awọn akẹkọ ile iwe girama ati ile ẹkọ giga.
Abrahamu bá sọ pé òun yóo búra.
Eliṣa sọ fún un pé kí ó múra láti ta ọfà náà, ó sì ṣe bẹ́ẹ̀.
Oríṣun àwòrán, Alaafin Oba Adeyemi 111 Facebook Koda, Alaafin funra rẹ gan an sisọ loju rẹ nigba kan pe, oun maa n ran awọn olori yii lọ sile iwe lẹyin ti wọn ba de ọdọ oun tan, ki wọn le tẹsiwaju lẹnu ẹkọ wọn.
Nígbà tí Dafidi rí angẹli tí ó ń pa àwọn eniyan náà, ó wí fún OLUWA pé, “Èmi ni mo ṣẹ̀, èmi ni mo ṣe burúkú.
N óo fún àwọn alufaa ní ọpọlọpọ oúnjẹ,n óo sì fi oore mi tẹ́ àwọn eniyan mi lọ́rùn.
Aare Buhari tun ba ebi, ọrẹ ati awon akẹgbẹ rẹ,dupe lowo
Fun ti oga eka ti ko  o si ile –eko iko Ologun ofurufu  ni, Shuaibu Yusuf ,Samanja Ishaya, Alabi David,Adeleke
Agbẹnusọ naa wa fi da gbogbo awọn akopa to sọrọ ninu ipade ijiroro naa loju pe gbogbo imọran wọn ni awọn yoo gbe yẹwo.
nneka tí bàbá rẹ ̀ jẹ ́ ọmọ bíbí ìpínlẹ ̀ anambra tíí ṣe ẹ ̀ yà ìgbò tí ìyá a rẹ ̀ sì jẹ ́ ọmọ orílẹ ̀ èdè jamani .
Amọ ọba alayeluwa naa ni oun rọ awọn Ndigbo lati sọ fun awọn Igbo to ku pe wọn ko ṣẹ wa lati ilẹ Juu bi kii ṣe pe Ile Ifẹ ni orisun wọn.
O ni eeyan mẹta ni ọwọ wa ti tẹ, fun pe wọn lọwọ si ipago orin ita gbangba, ni Ddungu Resort, ni ilu Kampala, lọjọ Satide."
ẹ o rii pe eto idibo naa lọ ni irọwọ ati irọsẹ.
" Agba Alfa náà, tó dúpẹ́ lọ́wọ́ àwọn tó jí ọmọ rẹ gbe nítorí wọn fi tí ọmọlúwàbí kun, tún ṣàlàyé pé àwọn èèyàn náà bá òun sọ ọ̀pọ̀lọpọ̀ ọrọ nípa ipò tí Naijiria wá àti nípa ti ara òun gan-an.
Tohun ti pe iye eeyan orile-ede rẹ ko ju 360,000 lọ; Iceland ko jafara rara.
Laipẹ yii ni ijọba Saudi kede pe, wọn gbẹsẹle gbogbo irinajo okere si orilẹ-ede wọn fun igba diẹ titi ti arun ọhun yoo fi kasẹ nile.
Sadoku, ọmọ Ahitubu, ati Ahimeleki, ọmọ Abiatari ni alufaa, Seraaya ni akọ̀wé gbọ̀ngàn ìdájọ́ rẹ̀.
mo kórìíra wíwà pẹlu àwọn aṣebi,n kò sì jẹ́ bá àwọn eniyan burúkú da nǹkan pọ̀.
Eyi yoo satileyin to dan moran ati eyi ti ko ni kolofin ninu, nipa gbigba owo wole sapo ijoba, ni iyanju ati le ni aseyori erongba won”.
Aviation Strike: Ẹ̀gbẹ́ àwọn òṣìṣẹ́ pápákọ̀ òfurufú bẹ̀rẹ̀ ìyanṣẹ́lódì
Bí o bá ń fi irú ọ̀rọ̀ báyìí siwaju àwọn arakunrin, ìwọ yóo jẹ́ òjíṣẹ́ rere ti Kristi Jesu, tí a tọ́ dàgbà ninu ọ̀rọ̀ igbagbọ ati ẹ̀kọ́ rere tí ò ń tẹ̀lé.
Ṣugbọn Jehoṣafati bèèrè lọ́wọ́ Ahabu pé, “Ṣé kò sí wolii OLUWA mìíràn mọ́ tí a lè bèèrè lọ́wọ́ rẹ̀?
 Ti a ba n sọrọ okoowo ati isẹ aje, bi kanhun se jẹ ọga ni awujọ okuta, naa ni Henry Fajemirokun jẹ ọga lawujọ ọrọ aje lorilẹede Naijiria."
 Ọjọ ́ kẹwàá , oṣù kínní ọdún 1988 ni wọ ́ n ṣe àwárí plánẹ ́ tì kékeré yìí , ní agbègbè kushiro ni orílẹ ̀ -èdè japan .
Okan lara awon alaaanu Samaria kan lo gbe Joy Chioma wa
Lọwọlọwọ ti a n sọrọ yi, awọn
“Iko omo ogun ise akanse Operation LAFIYA DOLE pelu ifowosowopo iko omo ogun to n mojuto aabo ilu dojuko awon omo ogun olote ohun lojoBo(Thursday).
Àwọn eniyan yóo dáhùn pé, ‘Nítorí pé wọ́n kọ OLUWA, Ọlọrun àwọn baba wọn sílẹ̀, tí ó mú wọn jáde kúrò ní ilẹ̀ Ijipti, wọ́n ń lọ bọ oriṣa, wọ́n sì ń foríbalẹ̀ fún wọn.
Nígbà tí àwọn aládùúgbò rẹ̀ ati àwọn tí wọn máa ń rí i tẹ́lẹ̀ tí ó máa ń ṣagbe, rí i, wọ́n ń bi ara wọn pé, “Ǹjẹ́ ọkunrin yìí kọ́ ni ó ti máa ń jókòó, tí ó máa ń ṣagbe rí?
Ṣebí àwọn onigbagbọ ara yín ni ẹ̀ ń dá lẹ́jọ́?
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ọlọ́pàá àti Shiites tún fìjà pẹ́ẹ́ta 24 Ìgbé 2018 Oríṣun àwòrán, @OfficialPDPNig Àkọlé àwòrán, Wahala tún bẹ́ sílẹ̀ nílùú Àbúja láàrin àwọn ọlọ́pàá àti àwọn ọmọ ìjọ ẹ̀sìn shi'ite Àwọn ọlọ́pàá tún kọlu àwọn ọmọ ìjọ ẹlẹ́sìn shi'ite níwájú olú ilé ẹgbẹ́ tó wà fún ẹ̀tọ́ ọmọnìyàn (National Human Rights Commission) nìlú Abuja, nígbàtí wọ́n ń fi ẹ̀hónú wọn hàn nítorí olórí wọn tó wà ní áhámọ́.
Bakan naa Seyilaw sapejuwe rẹ gẹgẹ bii ọrọ ti wọn jumọ lọ si ile iwe ti iṣẹ amuludun si tun pa wọn pọ daro rẹ.
Bí ó ti dé, ó sọ̀kalẹ̀ lọ sinu odò, ó pọn omi rẹ̀, ó sì jáde.
"Iru eeyan ti mo jẹ ree, ohun ti mo ba foju sun, o gbọdọ tẹ mi lọwọ"" Adetutu ni ẹkọ imọ ofin (law) lo wu oun lati lọ ka ni fasiti, amọ oun ko tilẹ sopo gba fọọmu lati joko se idanwo Jamb, nitori ẹsin ti wọn fi oun se nile ẹkọ alakọbẹrẹ ati girama ti to gẹẹ, idi si ree ti oun fi lọ kọ isẹ ọwọ."
sọ fún wọn pé ẹ̀bẹ̀ ni ò ń bẹ̀ mí pé kí n má dá ọ pada sí ilé Jonatani; kí o má baà kú sibẹ.
Ọgba ẹwọn ko wa lati fiya jẹ ẹnikẹni, sugbọn o tun jẹ ibi ti wọn ti n tun aye awọn eniyan ti o wa ni ahamọ se pelu.
   Bakan naa ni o tun so pe ikolu ohun “safihan lakotun iru igbese to ye lati kapa ikolu awon omo-ogun olote ni ekun Sahel, ni eyi ti o ro awon ajo lagbaye lati satileyin fun akitiyan awon orile-ede ti won wa ni ekun naani kia kia”.
Obasanjọ sabẹ̀wò sí Akurẹ́ lórí ìbo 2019 Àtẹ̀jáde náà ní, àwọn aláṣẹ ilé ìjọ́sìn náà wòye pé, ọ̀pọ̀ lààsígbò ló ń mi ìgbeyàwó lògbò-lògbò nítorí irọ́ pípa, pàápàá láti ipasẹ̀ àìjẹ́wọ́ ipò tí àgọ́ ara ìkọ̀ọ̀kan lọ́kọ-láya wà àti ìlera ìbísí wọn.
O ni ko gbe ọrun rẹ lọ si idi Eṣu.
NCDC lo fi ikede naa lede loju opo ikansiraẹni Twitter rẹ, ti apapọ awọn to ti ni arun naa ti wa di 12233 bayii.
Nítorí òṣùnwọ̀n tí ẹ bá lò fún ẹlòmíràn ni a óo lò fun yín.
 wọ ́ n ní ìgbàgbọ ́ nínú òrìṣà àkúnlẹ ̀ bọ , asòdì sí ẹ ̀ kó kristiẹni ni ìjọba wọn tẹ ́ lẹ ̀ , wọn kò ní àǹfààní láti gbọ ́ nípa orúkọ jesu .
Ọna si jin paapa fun awa to ku.
Makinde fi orúkọ ọmọ ọdún 27 kan ránsẹ́ sílé aṣòfin ní ìpìnlẹ̀ Ọ̀yọ́
O tesiwaju pe iwa rere ati otito nikan ni ὸpό to n gbe orile ede leke.
 oríṣìíríṣìí èrò ló ń gba ọkàn mi bí mo ti ń wo díńgí yìí lọ .
Àwọn ni: Asaraya, ọmọ Jerohamu, Iṣimaeli ọmọ Jehohanani, Asaraya ọmọ Obedi, Maaseaya ọmọ Adaya ati Eliṣafati ọmọ Sikiri.
Amọ Joshua to gba ami ẹyẹ wura fun ilẹ Gẹẹsi ninu idije Olympics lọdun 2012 ti n ṣe igbaradi pẹlu awọn abẹṣẹ ku bi ojo miiran ṣaaju ija rẹ pẹlu Ruiz Jr.
10 Ọ̀wàrà 2019 Wo díẹ̀ lára àwọn àṣà àti ìṣe tó ya Yorùbá sọ́tọ̀ nínú gbogbo àgbáyé!
Wo ohun tó mú kí Ṣèyí Makinde ó tẹ̀síwájú pẹ̀lú ìpàdé ìtagbangba níbàdàn láàrín ìṣẹ̀lẹ̀ àrùn Coronavirus Èyí ni ipa tí àdínkù owó epo bẹtiró yóò mú bá ọ̀rọ̀ ajé Nàìjíríà Wòlíì Sotitobire padà sílé ẹjọ́ lónìí Nílé ijó Fẹla Anikulapo, àrùn Coronavirus dá fàájì dúró O ni sáàju àsìkò yìí ni òun ti gbe ilẹ̀kun ofí'si oun ti ni nkan bi ọ̀ṣẹ̀ meji sẹyin ti oun si ti paṣẹ fun àwọn òṣìṣẹ́ to ba pọ́ndandan láti maa ṣiṣẹ́ láti ilé.
Mo wá gbọ́ ohùn ẹnìkan tí ó ń sọ fún mi pé, ‘Saulu!
Èyí ni àwọn tí òfin kónílé-ó-gbélé tí ààrẹ Buhari pa l'áṣẹ kò kàn ní Eko, Ogun àti Abuja Èèyàn mẹ́rìnlà míràn tún ti ní àrùn Coronavirus ní Naijiria Ṣé òògùn Chloroquine lè dènà ààrùn Coronavirus bí?
Mourinho kò ọ́rọ́ rẹ̀ jẹ,o padà wá dì akọ́nimọ̀ọ́gbá tuntun fún ikọ̀ Tothenham
Alufaa Adeboye ni iroyin to ba ni ninu jẹ ju iroyin iku Ibidunni Ighodalo.
Bawo ni wọn ṣe de ibẹ?
Èmi ni mo wí fún ọ, Òmùgọ́diméjì, bí etí rẹ kò bá di, gbọ nǹkan tí a máa bá ọ sọ lónìí: Ìlú rẹ yìí bàjẹ́ tó bẹ́ẹ̀ tí n kò rí irú rẹ̀ rí.
Ninu fidio ti a ri wo lori ayelujara, Iginla ni oun ati iyawo oun ti n ja lori ọrọ naa fun bi ọdun meje.
Ronkẹ Oṣodi: Mo kórira ki aya má ni ìtẹríba fún ọkọ nínú ilé
''Wọn tọ lati ile ifowopamọ lọ si ọfisi rẹ ni.
Bi ko ba dun un wo loju, wọn ti gba ọ niyẹn o!
Ọdun meje ni afikun ọdun ti wọn yoo lo ju awọn ọkunrin ti wọn ko gbe igbese aye to dara lọ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Akomolede ati Aṣa lori BBC:Wo ìrúfẹ́ ìgbeyàwó méje tó wà nílẹ̀ Yorùbá àti ojúṣe Alárinà Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Fídíò, Soyinka Cancer: Àṣe ara mi ni iso ti n run gbogbo bí mo ṣe n ṣèrànwọ́ lórí jẹjẹrẹ27 Bélú 2019 Fídíò, Grandma Maruwa: Ó yẹ kí obìnrin sisẹ́ láì wojú ọkọ kó tó jẹun11 Bélú 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Ni bayii, amule iko agbaboolu Juventus, leni ti o tun je balogun iko ohun, Gianluigi Buffon  ni o  ti farahan bayii pe ko ni kopa fun Juventus mo leyin ti saa yii ba pari,Awon ololufe Juventus patewo lopolopo fun Balogun naa lasiko to n rin jade leyin ti o gba kadi pupa lati jade kuro lori papa latari asemase re.
Ilééṣẹ́ Facebook leè mọ ìgbà tí àwọn tó wà lójú òpó wọn ń ní ìbálòpọ̀ Dokita àti Nọ́ọ̀sì fìyà jẹ mí lásìkò tí mò ń rọbí- Alaboyún Ọmọde kan wà ní ẹsẹ̀ kan aye ẹsẹ kan ọ̀run lẹ́yìn ìṣẹ̀lẹ̀ ilẹ̀ rírì ní Croatia Wo àwọn irọ́ ti ọ̀pọ̀ ń pa nípa Coronavirus!
Nígbà tí ó di ọjọ́ kẹrin, wọ́n wá bẹ iyawo Samsoni pé, “Tan ọkọ rẹ kí ó sọ ìtumọ̀ àlọ́ náà fún wa, láì ṣe bẹ́ẹ̀, a óo sun ìwọ ati ilé baba rẹ níná.
Gbogbo atotonu to n waye lori nọmba yi ko sẹyin bi ajọ NCC ṣe gbe gbendeke ọlọsẹ meji kale Wo ìjìyà tó wà fún àwọn ọmọ Naijiria tí kò bá fi nọ́mbà NIN kún ìforúkọsílẹ̀ Siimu wọn láàrin ọ̀sẹ̀ méjì Jide Kosoko forin sẹ́nu sọ pé òun ni igi lẹ́yìn ọgbà Mr Latin lórí ipò ààrẹ TAMPAN tó wà Ilé ẹjọ́ da ìpèjọ́ pé Akeredolu kọ ló yẹ kó wọlé ìdìbò ìpińlẹ̀ Ondo nù Wọ́n ti dí ọ̀pá afẹ́fẹ́ gáàsì tó bẹ́ lópópónà márosẹ̀ Ibadan sí Eko pa Àìmọ̀kan ló mú mi hu ìwà tí mo hù kọjá sẹ́yìn, Jonathan dárí jì mí - Dino Melaye O ti di dandan bayii ki gbogbo awọn to n lo foonu Alagbeka o pese nọmba yi bi won ko ba fẹ ki wọn wọgile opo ibaraẹnisọrọ wọn.
A ti gbé ìwádìí dìde lórí ìpànìyàn tó wáyé lásìkò ìwọ́de EndSARS- Ilé ẹjọ́ àgbáyé, ICC A kó ní sanwó oṣú ASUU láìjẹ́ pé wọ́n gba IPPIS- Ìjọba Àpapọ̀ Oṣú mẹ́fà ni òṣìṣẹ́ ìjọba tó bá bímọ yóò máa lò nílé kó tó wọṣẹ́ padà- Seyi Makinde DPO ọlọ́pàá ju télọ̀ sátìmọ́lé, gbé e lọ sílé ẹjọ́ n'Ibadan torí ''ó ba aṣọ rẹ̀ jẹ́'' Aṣoju ẹṣọ aabo oju popo naa tẹsiwaju pe ijanu ọkọ akero naa to dẹnukọlẹ lo fa ijamba naa, pẹlu alaye wi pe awọn ọdọ kan ti inu bi lori iṣẹlẹ naa ni wọn dana sun ọkọ akero naa loju ẹsẹ.
Iru iṣẹlẹ yii kan naa tun waye ni agbegbe Owode-Yewa nipinlẹ Ogun nibi ti wọn ti ọta ibọn ẹṣọ aṣọbode ti ta pa akẹkọọ ile iwe giga fasiti Tai Solarin, Ijẹbu Ode nibi ikọlu laarin wọn ati awọn ọlọja irẹsi.
Inú àwọn eniyan dùn pupọ ní ìlú náà.
Ọdun 2016 ni ijọba bẹrẹ eto naa ti eeyan to to ẹgbẹrun lọna ẹẹdẹgbẹta si ti jẹ anfaani nibẹ.
Yàtọ̀ sí ife ẹ̀yẹ AFCON, orílẹ̀èdè wo ló tún leè mókè lẹ́ka míràn l‘Afirika Amuneke fipò sílẹ̀ gẹ́gẹ́ bí akọ́nimọ̀ọ́gbá Tanzania Asamoah Gyan: O ṣeéṣe kí èyí jẹ́ ìdíje AFCON ìkẹyìn mi Èrò àwọn ọmọ Naijiria ṣọ̀tọ̀ọ̀tọ̀ lórí Tinubu àti Abbo Gba owó lọ́wọ́ àkẹ́kọ̀ọ́ ìjọba, ko rugi oyin - Seyi Makinde Amọ, agbaọjẹ agbabọọlu Algeria, Riyad Mahrez ṣẹ ikọ agbabọọlu Naijiria leegun ẹyin lẹyin to gbayo keji wọ le fun Algeria ni iṣẹju ti ere bọọlu naa pari.
Gẹgẹ bi ọmọ ẹgbẹ Democrat ti ko ni alatako kankan, Chukwuocha bori ninu idibo ọhun pẹlu ibo 7,640.
Nítorí náà, ẹ jẹ́ kí á pa iṣẹ́ òkùnkùn tì, kí á múra gẹ́gẹ́ bí ọmọ-ogun ìmọ́lẹ̀.
Àjẹkù burẹdi marun-un náà kún agbọ̀n mejila, lẹ́yìn tí àwọn eniyan ti jẹ tán.
“Lọ sí ilé àwọn ọmọ Rekabu kí o bá wọn sọ̀rọ̀, mú wọn wá sinu ọ̀kan ninu àwọn yàrá tí ó wà ninu ilé OLUWA, kí o sì fi ọtí lọ̀ wọ́n.
"Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Peters Ijagbemi dá àrá lórí ètò 'Ṣé o láyà' ti BBC Yorùbá lọ̀sẹ̀ yìí Omojokun lorukọ awọn ọmọ ogun naa ṣalaye pe: ""Awọn agbebọn naa ti beere ọgbọn miliọnu Naira lọwọ ọkọ abilekọ Afogun ki wọn to fi wọn silẹ."
 Ni paapajulo lati so fun O pe a ko gbagbe re nigba Kankan, beesini O si duro digbi ninu iko Super Eagles.
Ọ̀rọ̀ tí Dafidi sọ yìí, mú kí àwọn eniyan Juda fara mọ́ ọn, wọ́n sì ranṣẹ sí i pé kí ó pada pẹlu gbogbo àwọn iranṣẹ rẹ̀.
Ami ayo meji sẹyọkan ni Spain fi fagba han wọn ninu ifẹsẹwọnsẹ ọhun ni ipele komẹsẹ-ọ-yọ onikọmẹjọ (quarter finals).
 Àwọn ìwọ ̀ n ìdẹ ́ kun míìrán ni ọwọ ́ fífọ ̀ àti síse oúnjẹ dáradára .
O tun wa gboriyin fun ijoba apapo  ati awon osise eleto –ilera bi won se n tete  toju awon eniyan ti isele naa sele si.
Aare Muhammadu Buhari gbosuba kare lai fun iko agbaboolu Super Falcons fun ipa ribiribi, eleyi ti iko naa ko lati gba ife-eye idije 2019 West African Football Union-WAFU.
 Èdùmàrè má jẹ́ kí á sí nílé lọ́jọ́ tebi ń 
Bí mo bá sọ fún eniyan burúkú pé dájúdájú yóo kú, ṣugbọn tí o kò kìlọ̀ fún un pé kí ó yipada kúrò ní ọ̀nà ibi tí ó ń rìn kí ó lè yè, eniyan burúkú náà yóo kú sinu ẹ̀ṣẹ̀ rẹ̀; ṣugbọn lọ́wọ́ rẹ ni n óo ti bèèrè ẹ̀jẹ̀ rẹ̀.
Wọn ni awọn ko tii le sọ pe ajọṣepọ kankan n bẹ laarin awọn ẹgbẹ alaabo yii, ju eyi to wa laarin ọlọpaa ati araalu lọ.
1982 (Ipele ẹlẹgbẹjẹgbẹ) Benghazi Algeria 2-1 Nigeria 11.
Ní ọjọ́ kẹwaa lẹ́yìn náà, OLUWA pa Nabali.
Mo si sọ ọ kan l'oju pe oun ṣe agbere.
Nígbà tí àwọn ọmọ-ẹ̀yìn mẹ́wàá yòókù gbọ́, inú wọn ru sí àwọn tẹ̀gbọ́n-tàbúrò meji yìí.
Ọlọrun sọ fún un pé, ‘Àwọn ọmọ rẹ yóo jẹ́ àlejò ní ilẹ̀ àjèjì.
Awon ipinle ti won n san owo kekere lori oko wiwo laarin ilu ni ipinle Bauchi (N96.
Nígbà tí ó di ọjọ́ tí ọba dá fún wọn, Hẹrọdu yọ dé pẹlu aṣọ ìgúnwà rẹ̀, ó jókòó lórí ìtẹ́ rẹ̀.
akẹgbẹ won  sọrọ dipo pe ki won maa hu
Ikú òjijì kò jìnnà àmọ́ ọ̀nà méje rèé láti dènà rẹ̀ Gomina ni ijọba oun ti sefilọlẹ igbimọ kan ti yoo dunadura pẹlu awọn osisẹ lori agbekalẹ owo osu tuntun naa pẹlu afikun pe oju opo kanna ni ijọba ati awọn ẹgbẹ osisẹ n tọ lori ọrọ yii.
Ninu atẹjade kan eyi ti amugbalẹgbẹ fun Oloye Ọbasanjọ lori ọrọ iroyin, Kẹhinde Akinyẹmi fi sita lọrọ yii ti jẹyọ.
Isola kọ iwe akọkọ rẹ, Efunsetan Aniwura, ni ọdun 1961 ati 1962 nigbati o jẹ ọmọ ile iwe ni Ile-ẹkọ giga fasiti ti Ibadan.
Òbìnrin mánigbàgbé mẹ́ta nínú ìjọba tiwantiwa láti 1999
Ọgbẹni Ologbindiyan sọ pe kii ṣe asiko ti ijọba ṣe afikun owo ina ati owo epo bẹntiro yii lo yẹ ki ijọba tun maa na ẹgbẹlẹgbe biliọnu owo dọla sori ojuurin reluwee lati Kano si orilẹede Niger.
"Ọlọ́pàá, adájọ́ àtàwọn aṣọ́bodè ló gba rìbá jùlọ ní Nàìjíríà- NBS Kò yé káwọn Gómìnà fẹ̀yìntì máa gbowó gọbọi mọ́- Èrò ọmọ Nàìjíríà ""Ọlọjọ ibi kii ṣe ọrẹ mi, ọrẹ mi lo ni ki n sin oun kalọ."
Ibura sipo rẹ la gbọ wi pe o n waye ni ile igbimọ asofin nibi ti yoo ti ba awọn asofin sọrọ.
Oun naa sọ fun BBC pe, nkan buruku gba a ni bi ìjọba apapọ ko se fi orukọ Obasanjo si ara awọn eeyan naa.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Tomomewo Favour: olóṣèlú kìí ṣe ọ̀daràn tàbí alágbèrè Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Tomomewo Favour: olóṣèlú kìí ṣe ọ̀daràn tàbí alágbèrè 24 Òkùdu 2019 Ìbẹ̀rù, owó, ìpè pàjáwìrì fún mítìnì lóru kìí jẹ ki òṣèlú rọrùn fún obìnrin - Favour Honorebu Tomomewo Favour to jẹ ọdọbinrin to n sọju ẹkun Ilajẹ Constituency sọ pataki ipa ọkunrin gẹgẹ bi oluranlọwọ fun obinrin to n ṣe iṣelu.
Gbogbo ẹni tí Ọlọrun bá fún ní ọrọ̀ ati ohun ìní, ati agbára láti gbádùn wọn, ati láti gba ìpín rẹ̀ kí ó sì láyọ̀ ninu iṣẹ́ ọwọ́ rẹ̀, ẹ̀bùn Ọlọrun ni.
ati Sokoto ni awon yoo ri i pe o di afiseyin ti eegun n fi aso.
Bianca júwe ilé fún Serena Williams nínú ìdíje l'America Ọkùnrin kan sálọ lẹ́yìn tó gbẹ̀mi ènìyàn mẹ́ta Àwọn akọni Nàìjíríà padà sílé pẹ̀lú àmì ẹ̀yẹ 121 láti Morocco A fẹ́ bẹ̀rẹ̀ òfin má lo fóònù mọ́ fàwọn ọmọ wa -Òbí Ni ipari Gomina Sanwo Olu rọ awọn ajeji to nileeṣẹ lati gbiyanju igbe aye alaafia pẹlu awọn eniyan adugbo wọn.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìsẹ̀lẹ̀ Ghana: Òògùn ẹ̀fọn pa ìbejì àti ẹ̀gbọ́n wọn 24 Ìgbé 2018 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Awon òbí náà paapaa, fara kasa nínú ìṣẹlẹ ọhun Awon aláṣẹ ni orílèèdè Ghana ti bẹrẹ iwadi nípa ìṣẹlẹ ikú ọmọ mẹta, lẹyìn tí wọn fa oogún oloro sínú.
Sugar gba iwe ẹri olukọni onipo kini ni ileewe ẹkọṣẹ olukọni NCE Federal College of Education, to wa ni Osiẹlẹ nilu Abeokuta, ipinlẹ Ogun, ki o to lọ si ileewe giga fasiti Ibadan lati gba iwe ẹri imọ ijinlẹ akọkọ, B.
 Bawo ni wọn se lee maa gba ẹmi awọn ọmọ ilẹ yii ni gbogbo igba, ti a ko si tii ri ẹnikẹni mu lati fi jofin.
Gẹgẹ ba se mọ pe ipo pataki ni ipo Alaafin ninu itan Yoruba, to si se asaaju ninu odiwọn ipo awọn oriade nilẹ kaarọ Oojire.
Atẹ́gùn lásán ni yóo gbé gbogbo wọn lọAfẹ́fẹ́ ni yóo fẹ́ wọn lọ.
Ọdọmọde onimọ ẹrọ naa salaye pe oun maa n fun awọn ọmọde ni awọn isẹ ọwọ oun naa lati fi sere ni, amọ eyi to ba jẹ agbayanu ninu awọn isẹ ẹrọ naa, ni oun maa n fi pamọ.
Orúkọ wọn kì bá tí parẹ́ títí ayé,bẹ́ẹ̀ ni kì bá tí parun lae níwájú mi.
Akanṣe eto idibo yii ti aj eleto idibo orilẹ̀ede ghana ṣe agbekalẹ rẹ jẹ fun awọn oṣiṣẹ koṣeemani ti yoo maa ṣiṣẹ fun awọn ara Ghana lọjọ keje oṣu kejila ọdun yii.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Àwòrán mánigbàgbé BBC news Yorùbá fún ọ̀sẹ̀ yìí 3 Èbibi 2019 Eyi ni akojọpọ awọn aworan ohun oju rii lọsẹ yii.
Alukoro fun isẹ ọlọpaa ni ipinlẹ Kaduna, Muktar Aliyu salaye fun BBC wi pe, ileesẹ ọẹọpaa si wa lẹnu iwadi lati mọ ohun to sokunfa wahala naa.
com/g5qfwui3HpBio ti le je pe, iko Manchester United padanu ifesewonse ikolu ese kinni sowo PSG pelu ami ayo meji sodo(2-0), apapo esi ifesewonse mejeeji safihan iko agbaboolu ti o jawe olubori.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Olanrewaju Akojede to jẹ ọkan lara awọn ọmọ ọmọ oloogbe sọ pe iku awọn mejeeji dabi ere ori itage awọn gbajugbaja ololufẹ meji, ''Romeo and Juliet'' ti wọn fẹ ara wọn bi oju.
 A dupẹ fun atilẹyin ati ifọwọsowọpọ yin si wa.
" o ti ṣeto nipasẹ mawjoudin , ngo tunisia , ti orukọ rẹ tumọ si "" a wa be "" ."
Èrò àwọn ọmọ Naijiria ṣọ̀tọ̀ọ̀tọ̀ lórí àwọn ti Sanwo Olu yàn sípò Ọwọ́ ti tẹ ọlọpàá mẹ́rìn to pa afurasí Agbẹnusọ fun awọn ọlọpaa, Connie Moganedi, si ti fi idi ọrọ naa mulẹ.
Awọn ọba meejeji naa lo mẹnuba baa pe ilana ibilẹ ti wọn n gba sinku ọba ni ko ba igba mu mọ, o si yẹ ki ayipada de baa.
Ó mú mi jáde wá síbi tí ó láàyè,ó yọ mí jáde nítorí tí inú rẹ̀ dùn sí mi.
ṣugbọn tí ẹ bá pada sọ́dọ̀ mi, tí ẹ pa òfin mi mọ́, tí ẹ sì ń tẹ̀lé e, bí ẹ tilẹ̀ fọ́nká lọ sí ọ̀nà jíjìn réré, n óo ṣà yín jọ, n óo sì ko yín pada sí ibi tí mo ti yàn pé ẹ óo ti máa sìn mí kí orúkọ mi lè máa wà níbẹ̀.
Awọn aworan awodamiẹnu latilẹ Afrika lọsẹ yi CAN kò rán ẹnikẹ́ni lọ ṣọ́ọ̀ṣì COZA, iṣẹ́ ara wọn ní wọ́n lọ jẹ́ -Samson Ayokunle Yinka Ayefele di bàbá ìbẹta A ó gbé'gbésẹ̀ lẹ́yìn ìwádìí fídíò tí Dino ti ń náwó lójú agbo- Ọlọ́pàá Ẹgbẹ awọn agba apa oke Ọya orilẹ-ede Naijiria naa ni ilu ogun tawọn kan n lu lapa guusu ilẹ yii lori wọn n kọ awọn lominu.
Bakan naa ni gomina ipinlẹ Eko tẹlẹ naa sọ pe kii ṣe oun lo ni ileeṣẹ Lekki Concession Company, to n mojuto bi Toll Gate naa ṣe n pa owo wọle fun ijọba Eko.
 O tun wọn rọ awọn ọmọ orilẹ-ede Naijiria lati ṣe
Omidan Dorcas Dienda, to jẹ́ aṣoju orilẹede Congo lo jawe olubori nibi eto naa.
O ni o ba oun lojiji pe lẹyin wakati kan soso pere ti ipade naa pari, lawọn osisẹ ileesẹ naa wa lati ti abule mẹkaniki yii lai jẹpe wọn fun awọn ni anfaani tabi akoko diẹ si lati ko lọ si ibudo mii.
Èmi ò r'óhun tó burú kí obìnrin opó fẹ́ ọkọ míì sínú ilé ọkọ rẹ̀ UNILAG ní kí olùkọ́ míì, Samuel Oladipo to ń bèèrè ìbálòpọ̀ lọ́wọ́ akẹ́kọ̀ọ́ lọ fìdí mọ́lé Òpópónà àti afárá 19 níjọba fẹ́ ṣe nínú àbá ìṣúná ọdún 2020 Ará ìlú fárígá, wọ́n wọ́ alàkóso ìlú nilẹ́ pẹ̀lú ọkọ̀ Omo-Agege ṣalaye pe gẹgẹ bi abiyamọ, oun ko faramọ bi awọn olukọ Fasiti sẹ n dẹnu ifẹ kọ awọn akẹkọbinrin.
Kò si ẹ̀ri fún ìbò ọmọ kékèké ni Kano — Ganduje
"Sugbọn bi mo se sọkalẹ ni mo gbọ gba leti mi, ti wọn si da mi dọbalẹ, ti wọn n fi bata tẹ mi lori mọlẹ.
Wayii o, Pinnick tun dupe lopolopo lowo ile ifowopamo naa fun atileyin won ni gbogbo igba lojuna ati mu igberu ba boolu afesegba ati ere idaraya lapapo ni orile-ede Naijiria.
Oju opo Instagram ti kun pitimu bayii fun fọto awọn oṣere tiata, ti wọn parada di arugbo, amọ ṣe ewu kankan wa ninu lilo ẹrọ yii?
Ati pe baba oun san 'owo iṣẹ agbere'' fun iyawo oun nipa gbigbe ọpọlọpọ iṣẹ akanṣe fun ileeṣẹ rẹ, Bowen and Brown, nileeṣẹ to n mojuto ipese epo rọbi ni Naijiria, NNPC.
Orúkọ OLUWA jẹ́ ilé-ìṣọ́ tí ó lágbára,olódodo sá wọ inú rẹ̀, ó sì yè.
Ohun kejì tí ó yà mí lẹ́nu ni àwọn ènìyàn méje tí mo bá nínú ilé náà ní torí bí mo ti ṣe rí wọn jọ mí lójú gidigidi.
Ó bá dá mi lóhùn pé, “Àwọn ìwo wọnyi dúró fún àwọn alágbára ayé tí wọ́n fọ́n Juda, Israẹli, ati Jerusalẹmu ká.
    Níbgà tí àkókò ẹkún kọjá tán tí mo wọ ilé ti wọ́n ti ń ta nǹkan báyìí, ọkùnrín kan wọlé, o kó ọ̀pọ̀lọpọ̀ owó lọ́wọ́.
Ó wí fún mi pé nṅkan ńlá ni ìgbéyàwó, ayẹyẹ ńlá sì ni ọjọ́ ìgbéyàwó pẹ̀lú.
Nitori naa ni ajọ ti o n moju to irinna ni ipinlẹ naa (LASTMA) ṣe fi atẹjade sita lori awọn ọna ti aarẹ yoo fẹsẹ tẹ.
Ẹ má máa yọjú sí nǹkan oní-ǹkan.
- Olùkọ́ yarí Miyetti Allah ní kí wọn wọ́gilé Amotekun, Sunday Igboho yarí Lẹ́yìn ọgọ́ta ọdún tí Nàíjíríà gba òmìnira, wo ipò tí àṣà àti èdè Yorùbá wà Ọwọ́ ọlọ́pàá tẹ tọkọ-taya àti èèyàn méjì míì tó gé orí òkú ní Ibojì Ẹ kíyèsára!
Ààrẹ, o ye kí ẹ tí bá ọmọ Naijiria sọ̀rọ̀ nípa àrùn Coronavirus Ẹ wo àwọn olówó tí wọ́n ti ṣe ìrànwọ́ fún Naijiria láti kojú àrùn Coronavirus Coronavirus updates : Covid-19 tún ti pọ̀ si l'Eko àti Abuja, ó di èèyàn 65 tó níi ní Nàìjíríà Oríṣun àwòrán, Getty Images Ajọ to n gbogun ti itankalẹ aarun ni Naijiria, NCDC ti kede pe eniyan mẹrinla miran tun ti ni coronavirus ni Naijiria.
Mí ò tíí ní ìpinnu lóri ìdíje ààrẹ ọdún 2023 Kìí ṣe ẹ̀bi wa pé ètò ìsìnkú Abiola Ajimobi falẹ̀ - ìjọba ìpínlè Oyo O ni daamu naa ti kere ju iye omi to lee gba lasiko ti wọn ṣẹṣẹ kọ lọ.
awon osise ile ise ijoba to n  ri si oro
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Risikat Moromoke Azeez: Inú èmí àti Òbí mi dùn nígbà ti Risi bí ọmọ olójú búlù- Wasiu Bakan naa lo tun sọ pe baba oun fẹran oloogbe naa ju oun lọ, nitori naa ni oun ṣe ti ọmọ naa sinu kanga ṣugbọn oun ko mọ pe yoo mu ẹmi rẹ lọ.
Ẹ kéde èyí láàrin gbogbo orílẹ̀-èdè.
Dafidi bá lọ wádìí ọ̀rọ̀ náà lọ́dọ̀ OLUWA.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Hagia Sophia ibudo iṣembaye to di mọṣalaṣi ni Turkey O ni eyi fihan pe Aarẹ ko ka aṣa si mọ laye ode oni nitori ibudo iṣembaye naa ti wa fun ọpọlọpọ ọdun sẹyin.
Ọmọ ọkọ tàbi ẹbi ọkọ ọkùnrin lè fi àṣà yi kẹ́wọ́ lati fẹ opó ni tipátipá, omiran lè pa ọkọ lati lè jogún iyàwó.
Ẹlẹ́rìí gbọdọ̀ tó meji tabi mẹta, kí ẹ tó lè dá ẹnikẹ́ni lẹ́bi lórí ẹ̀sùn kan.
Danfo Driver: Mad Melon' ọ̀kan lára àwọn akọrin Danfo Driver
Nígbà tí wọ́n dé Jerusalẹmu, Jesu wọ àgbàlá Tẹmpili lọ, ó bá bẹ̀rẹ̀ sí lé àwọn tí wọn ń tà ati àwọn tí wọn ń rà jáde.
kí ìjọ eniyan Israẹli ṣe ìdájọ́ láàrin ẹni tí ó ṣèèṣì paniyan ati arakunrin ẹni tí wọ́n pa, tí ó fẹ́ gbẹ̀san, gẹ́gẹ́ bí ìlànà yìí.
Ilu Orlando nipinlẹ Florida ni ọkunrin ọhun n gbe, nibi to ti n ṣe bii Jesu.
    “Nígbà tí gbogbo wa pada dé pátápátá láti ibi tí ọba rán wa ni ó sọ fún mi pé kí á dá ọjọ lílọ wa a sì dá itadógún.
Omi mú kí ó dàgbà,ibú omi sì mú kí ó ga.
Nibayi, Gomina ipinlẹ Kaduna, Malam Nazir El-Rufai ti pasẹ fun awọn eleto aabọ ipinlẹ naa lati se ofin toto isẹlẹ naa, ki wọn si fi awọn to wa nidii ọrọ naa jofin.
Àyọkúrò láti inú ìwé ìtàn ti Joseph Smith tí ó ṣe àpéjúwe ìlànà ìfinijoyè ti Wòlíì náà àti Oliver Cowdery sí oyè àlufáà ti Aarónì ní itòsí Harmony, Pennsylvania, ọjọ́ kẹ̃dógún Oṣù karũn 1829.
Ìjọba gbé ilé ijó oníhòhò tì pa lórí ẹ̀sùn títàpá sí ìlànà àti dẹ́kun coronavirus Ìdí tí àwọn èèyàn kan kò fí le ni àrùn Coronavirus Asiko oṣelu ni a wa yii, awọn to n gbe iru iroyin yii n wa bi okele wọn yoo ṣe pọn lọdọ gomina ni,"" igbakeji gomina lo sọ fun BBC bẹẹ."
Agbábọ́ọ̀lù Liverpool Sadio Mané ló kọ́kọ́ gbá bọ́ọ̀lù sínú àwọ̀n nínú ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ ìdíje Premier League tí wọ́n gbá lajọ́ Àìkú.
“Àwọn eniyan mi dàbí aguntan tí ó sọnù, àwọn olùṣọ́ wọn ti ṣì wọ́n lọ́nà.
Nígbà tí wọ́n jíṣẹ́ ọba fún Aisaya tán, 
Won soro ohun di mimo, nibi eto idanilekoo olojo meji fun awon akoroyin eka eto-ilera nilu Abuja.
Ọga ọlọpaa naa ni, gbogbo eto lo ti to lati ọdọ ajọ naa fun iranlọwọ to nipọn fun ikogoja igbimọ alaabo alajumọse naa.
Ṣugbọn nígbà tí àpótí Ọlọrun náà dé Gati, OLUWA jẹ ìlú náà níyà, ó mú kí gbogbo ara wọn kún fún kókó ọlọ́yún ati àgbà ati èwe wọn, ó sì mú ìpayà bá gbogbo wọn.
OLUWA ti fi mí léàwọn tí n kò lè dojú kọ lọ́wọ́.
Wọ́n bá bọ́ sinu ọkọ̀ ojú omi kan, wọ́n fẹ́ yọ́ lọ sí ibi tí kò sí eniyan.
"O ni ""gbogbo igba ni wọn n fi to mi leti lori igbesẹ atunsẹ to n lọ lati fi opin si bi awọn ọlọpaa ṣe ma n fi iya jẹ ni, ati awọn iwa ti ko tọ miran."
Supplementary Election: Àwọn jàndùkú yìnbọn fún òṣìṣẹ́ Inec, Ọ̀jọ̀gbọ́n Tuluen, ní Benue
9m kalẹ̀ fún owó oṣù òṣìṣẹ́ ní Kwara Àwòrán ìwọ́de NLC, TUC, ULC lónìí Gẹgẹ bii minisita fọrọ oṣiṣẹ ati igbanisiṣẹ, Dokita Chris Ngige ni ijọba apapọ yoo gbe aba ofin ẹkunwo osu tuntun naa ṣọwọ sọdọ awọn aṣofin apapọ ni ọjọ kẹtalelogun oṣu kini ọdun 2019 bi awọn aṣofin naa ba wọle pada sẹnu iṣẹ.
Àwọn ọmọ Nàìjíríà fèsì sí ìkíni Saraki, Fayose nípa Kérésì 'EFCC mo dé' àti àwọn àṣà míì táwọn olóṣèlú fi dagbo rú ní 2018 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ọdọọdun ni gbogbo ẹlẹsin Kristẹni lagbaye ma n parapọ lati se ayẹyẹ Ọjọ ibi Jesu Kristi.
Ko si ohun to ni ibẹrẹ ti ko l'opin, lo difa fun gudugbẹ to ja lọjọ Iṣẹgun nigba ti iroyin jade pe elegee ara, Lionel Messi ti kọwe si ẹgbẹ agbabọọlu Barcelona pe oun ṣetan lati dagbere fun ẹgbẹ agbabọọlu naa pe o digba o ṣe.
6 1422320 Orilẹede Indonesia 25484 9.
Ọlọrun ń lépa mi,ẹ̀yin náà sì tún ń lépa mi!
Wọn jẹ ko di mimọ pe bi o tilẹ jẹ wi pe ajọ eleto idibo, INEC sọ pe iroyin naa waye ni irọwọ ohun irọsẹ.
Gege bi ababo ipade naa: won ni yoo fi aaye ifigagbaga loju oja pasipaaro sile fun awon onisowo.
Nígbà tí a súnmọ́ nkan náà dé ibi pé kò sí nkankan tó díwa lójú, tí a sì nwòó kedere ní iwájú wa, ìyanu gbáà ló jẹ́ fún wa.
" Ayobami Oladokun sọrọ lori ayipada ti oun fẹ ko ba iṣẹ alaga iduro bii ki awọn alaga ma maa gba asiko awọn oninawo pupọ ati pe ki wọn ma maa mu nkan ti kii ṣe ti wọn loju agbo.
OLUWA yóo fún àwọn eniyan rẹ̀ ní agbára;OLUWA yóo fún wọn ní ibukun alaafia.
O wa ṣàlàyé pé Ọlọ́run ran iya mi sì mi."
Lọ́dọ̀ rẹ̀ ni a dé sí.
Kuatu arakunrin wa náà ki yín.
Eyii to n tumọ si pe Victor ni agbabọọlu lati ilẹ Afrika ti iye owo ti wọn ra a pọ julọ.
lati ẹgbẹ oṣelu PDP ni esi ibo ẹgbẹrun kan-le-okolelẹgbẹrin ati ookan
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Jose Mourinho: Iṣẹ́ bọ́ lọ́wọ́ akọ́nimọ̀ọ́gbá Man United 18 Ọ̀pẹ̀̀ 2018 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Jose Mourinho fi Manchester United silẹ Iroyin to n tẹ wa lọwọ ni yajoyajo sọ pe iṣẹ ti bọ lọwọ akọnimọọgba ikọ Manchester United Jose Mourinho.
Ọdún meje ni ó gba Solomoni láti parí rẹ̀.
Eyii n tumọ si pe o ṣeeṣe ki ile ẹjọ naa fi ọjọ ti yoo ṣe idajọ rẹ lede lọjọ naa.
Oríṣun àwòrán, Facebook/Femi Adesina To ba jẹ pe Buhari ko wọgile akanse isẹ oju ọna naa ni, sunkẹrẹ fakẹrẹ ọkọ to n lu igboro ilu Eko pa bayii ko ba ti waye, ti irọrun ko ba si bawọn olugbe Eko nidi igbokegbodo ọkọ.
Ẹbora ìgbéraga – ìbánújẹ́ àti Ahọ́ndiwúrà ìyàwó rẹ̀
Ọpọlọpọ àwọn afọ́jú ni ó jẹ́ kí wọ́n ríran.
 Ogagun Azinta wa so pe, ohun yoo sa ipa re lati pese isuna fun awon osise re ati ebi won lati se amulo ababo eto naa.
 Zagreb 🇭🇷🇮🇹 Inter 0-1 (0-1) Frankfurt 🇩🇪🇨🇿 Slavia 4-3 (6-5) Sevilla 🇪🇸🇪🇸 Villarreal 2-1 (5-2) Zenit 🇷🇺#UEL Last 16 = Done.
Báyìí ni Arotile náà ṣe bẹ̀rẹ̀ ìrìnàjo to sọ di olókìkí nìgbà to fi orúkọ silẹ̀ láti ṣe iṣẹ́ yìí ni ọdún díẹ̀ sẹ́yìn.
“O óo ya igẹ̀ ẹbọ fífì náà sí mímọ́ ati itan tí ó jẹ́ ti àwọn alufaa lára àgbò ìyàsímímọ́, nítorí pé, ti Aaroni ati àwọn ọmọ rẹ̀ ni.
Nígbà tí mo dé ibẹ̀ mmo rí ọ̀nà kékeré kan tí ó bá inú ihò òkúta náà lọ.
Ṣugbọn ibeere kan ti ọpọ ololufẹ ere bọọlu n beere lori ayelujara ni pe ta gan an ni yoo gba ẹgbẹ agbabọọlu Liverpool lọwọ elege-ara Lionel Messi.
Alukoro ileeṣẹ ọlọpaa, DCP Frank Mba ṣalaye ninu atẹjade kan to fi sita lorukọ ọga ọlọpaa Naijiria pe awọn ọlọpaa SARS ko gbọdọ duro soju titi mọ dabi dari igbokegbodo ọkọ loju popo mọ.
"Mo ti ní kí ọmọ mi má ṣe wá sí Ado Ekiti àmọ́ kò gbọ ọrọ si mi lẹ́nu.
Oríṣun àwòrán, BIG BROTHER NAIJA Nengi ni olukopa kẹta to ja kuro lori eto naa ni aṣekagba.
Iná ẹ̀lẹ́ńtíríkì pa ẹlẹ́wọ̀n márùn ún lọ́gbà ẹ̀wọ̀n l'Eko Dino ní ìyàwó ni Adeyemi jẹ́ f'óun lágbo òṣèlú, Adeyemi l'ọ́mọ ọ̀dọ̀ ni Dino jẹ́ Èso Apple tuntun tí ẹ lè fi pamọ́ fún ọdún kan ti wọ ọjà Kò sí súnkẹrẹ-fàkẹrẹ mọ lópópóna márosẹ̀ Eko si Ibadan Oyedele ni aworan Trump to lu ayelujara pa yii ni ikeji iru rẹ ti oun maa fi ya aarẹ ilẹ̀ America.
Gbogbo ibi tí wọn ń ṣe, kò jẹ́ kí wọ́n lè pada sọ́dọ̀ Ọlọrun wọn, nítorí pé ọkàn wọn kún fún ẹ̀mí àgbèrè, wọn kò sì mọ OLUWA.
Ni oṣu kẹsan an ọdun 2018 lawọn eeyan ipinlẹ Ọṣun dibo lati yan gomina to wu wọn.
 Won se lalaye wi pe eroja kan ninu ohun elo ti won po po ni odi calcium carbonate ,ti o je ohun elo kan Pataki ninu ohun elo ipese biriki ti a mo si limestone ,ti o so awon eroja naa paapo.
Àwọn ẹni tí ó wà pẹlu mi bá fà mí lọ́wọ́ lọ sí Damasku.
Ẹnu ya àwọn òbí ọmọ náà.
 Ọba Oyedọtun ni, awọn lee kilọ fun ara awọn, lawọn se ni ki Oluwo lọ sinmi laarin awọn naa ninu igbimọ lọbalọba fun osu mẹfa, awọn ko si yọ Oluwo gẹgẹ bii ọba tori ileẹjọ nikan lo lasẹ lati yọ ọba."
Àwọn orílẹ̀-èdè yóo parapọ̀ láti kojú wọn, nígbà tí wọ́n bá ń jìyà fún ọpọlọpọ ẹ̀ṣẹ̀ wọn.
Ọlóyè ẹgbẹ́ Afẹnifere Ayo Adebanjo àti Sẹnatọ Femi okunronmu nínú iwé ìròyin Punch lọ́jọ Aiku ti kswé pe ki Tinubu sọ àyè to tò si lórí ọ̀rọ̀ Amọtẹkun lẹ́yin ti àgbẹjẹ́rò àgbà Naijiria ti sọ pé ìdásílẹ̀ rẹ̀ kò bá òfin mu.
Fulani darandaran naa ti awọn akọroyin ko le e fidi orukọ rẹ mulẹ, fi ẹsẹ fẹẹ lẹyin isẹlẹ naa lagbegbe Road Block, ni Akure.
Coronavirus dá rúkè-rúdò sílẹ̀ ní pápákọ̀ òfurufú l'Amẹrika, ọ̀pọ̀ ń forí gbárí Awọn papakọ ofurufu ilẹ Amẹrika ti wa ni idarudapọ bayii nitori eto ayẹwo ilera lori arun Coronavirus to bẹrẹ, fun awọn eniyan to n de lati ilẹ Yuroopu.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù UNGA: Tijjani Bande jẹ́ àgbà ọ̀jẹ̀ nípa ìbásepọ̀ àwọn orílẹ̀èdè 8 Èbibi 2019 Oríṣun àwòrán, TWITTER Àkọlé àwòrán, Àjọ Ìsọ̀kan Àgbáyé UN ti yan Ọ̀jọ̀gbọ́n Tijjani Bande gẹ́gẹ́ bí adarí ẹ̀ka Àjọ United Nations General Assembly.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù South Africa: Awọn adoola ẹmi ti muse se ni ibudo iwakusa 2 Èrèlè 2018 Oríṣun àwòrán, AFP Àkọlé àwòrán, ọ̀kan lára àwọn ti orí kó yọ Wọ́n ti n sisẹ́ lori ọ̀nà lati doola ẹ̀mí awọn tó tó eeyan marundinlọ́gọ́rùn tío há sínú ihó ilẹ́ níbìkan ti wọ́n ti n wa alumọ́ọ́nì goolu ni orílẹ̀èdè South Africa.
Niṣe ni gbajumọ oṣere Iyabo ko sinu aṣọ alaranbara to ni awọ dudu ati funfun ninu eyi to ti n ṣakọ ninu fọto to ya.
Àfonífojì Sidimu kún fún ihò tí wọ́n ti wa ọ̀dà ilẹ̀.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Lẹnu ijọ mẹta yi ọrọ asa idaranjẹ n mu ariyanjiyan wa inu awujọ ni Naijiria.
Ẹ̀wẹ̀, o ní àláífìà ti jọba báyìí sùgbọn àjọ ọmọogun kábàmọ pé irú ǹkan bẹẹ waye bí o ṣe kó ìpayà bá àwọn ará ìlú ní pápákọ̀ òfurufú.
O wa bẹbẹ pe ẹ saanu mi, Ọlọrun ko ni fi aarẹ ṣe yin, a ti nawo sẹyin lai ri iwosan, amọ mo sẹṣẹ wa ri ibi ti wọn yoo ti tọju mi daadaa bayii ni, sugbọn ko si owo mọ.
"Oríṣun àwòrán, @MBuhari O ni ""ele ori owoya ti China fẹ gba kere jọjọ si tawọn orilẹede alagbara lagbaye yoku, ni ijọba apapọ se n gbe igbesẹ lati gba a."
Ó bá di ọ̀kan ninu àwọn aposteli mọkanla.
ṣe kò rán ọ níṣẹ́ mìíràn sí mi?
Àti àwọn ìbéèrè míràn Àwọn nǹkan tí obìnrin lè ṣe pẹ̀lú olólùfẹ́ oníwà ipá lásìkò ìgbélé Coronavirus yìí O fikun pe, koda gan bi wọn ba ṣe awari abẹrẹ ajẹsara fun Covid-19, iṣẹ nla ni akoso arun naa yoo si tun jẹ.
Ọpọ ninu awọn ọmọ South Africa to jẹ alawọ dudu ti n gbe ninu ìṣẹ́ lati atọdun-mọdun, ta a ba ni kafiwe awọn to jẹ Asia ati awọn ọmọ South Africa to jẹ alawọ funfun.
Kii wa a ṣe Regina nikan lo da ni ọjọ naa o.
" Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Borno Zabarmani massacre: Ípànìyàn tó wáyé ní Borno fihàn pé omi n bẹ lámù fún ètò ààbò - Tinubu3 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Assistant Commissioner of Police: Àwọn afurasí ṣá ìgbákejì kọmísọ́nà ọ̀gá ọlọ́pàá láàké dójú ikú2 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 D.
Igbesẹ  asẹ ijọba yii ni yoo jẹ  ikẹfa rẹ lati igba ti ijọba yii ti de ori aleefa, kin lo de ti won fe tapa si eyọ kan yii, nigba ti won gba marun un yooku wọle.
Ninu alaye re, olori osise ijoba ni gomina  ti yan awon igbimo ti yoo maa mojuto  imototo agbegbe  lati dena aisan , ni eyi ti won yoo tun rii pe
Agbẹnuso Ile Igbimọ Aṣofin Ipinlẹ Eko, Aṣofin Mudashiru Ọbasa ti rọ awọn oniroyin ati awọn ẹlẹgbẹjẹgbẹ lati gbiyanju fi ojuṣe wọn daabo bo eto oṣelu tiwantiwa lorilẹ-ede Naijiria.
Ahabu bá ranṣẹ pada sí Benhadadi ọba pé, “Mo faramọ́ ohun tí ó kọ́kọ́ bèèrè fún, ṣugbọn n kò lè gba ti ẹẹkeji yìí.
Ti wọn ba pa a pọ mọ owo oṣu awọn ti iṣẹ wọn jọ mọ ti ọlọgun (164bn naira), apapọ owo naa ko tii to iye owo ti ijọba n lo fi san owo oṣu awọn oṣiṣẹ ni ẹka eto ẹko, ti ko si to 1tn naira ti Atiku Abubakar sọ wi pe wọn n na.
Akinkanju ni wa, a kii se ojo.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Okorocha àti ẹgbẹ́ APC ń gbéná wojú ara wọn Ẹgbẹ́ ajàfẹ́tọ̀ọ́ ẹni yóò bẹ túbú ọlọ́pàá wò Gómìnà àná míì, Joshua Dariye, tún rẹ́wọ̀n he Aṣofin yii kii ye sa nibi ijoko ile; paapaa lasiko ti ọrọ to kan ẹkun idibo to n ṣoju fun ba wa fun ijiroro."
Ẹ̀rù yóo ba ọba Asiria, yóo sálọ.
OLUWA fi sí Kirusi lọ́kàn, ó sì pàṣẹ jákèjádò ìjọba rẹ̀.
Gègé ni wọ́n ṣẹ́, tí wọ́n fi pín in fún ẹ̀yà mẹsan-an ati ààbọ̀ ninu ẹ̀yà àwọn ọmọ Israẹli, gẹ́gẹ́ bí OLUWA ti pàṣẹ fún Mose.
da ojo ti o ro lojo isegun(Tuesday) ohun, ni o dena ise awon alaabo naa.
Irú ẹ̀dá wo tilẹ̀ ni tèmi yìí!
Orúkọ àwọn ẹ̀yà Israẹli nìwọ̀nyí: Ààlà ilẹ̀ náà ní ìhà àríwá bẹ̀rẹ̀ láti etíkun, ó lọ ní apá ọ̀nà Hẹtiloni dé àbáwọ Hamati títí dé Hasari Enọni, tí ó wà ní ààlà Damasku, ní òdìkejì Hamati.
Ọwọ́ tẹ afurasí 8 tó jí akẹ́kọ̀ọ́ Chibok gbé ‘Alaafia ni akẹẹkọ Dapchi wa pẹlu ọmọ mi’ Àkúntúnkú, ìgbà márùn ún rè é tí Shekahu kú tí wọ́n ní kò kú mọ Abule Girgir ni Jakusko ni ipinlẹ Yobe ariwa ila oorun Naijiria ni wọn ti bi Yusuf lọdun 1970.
títí tí OLUWA yóo fi fún àwọn arakunrin yín ní ìsinmi bí ó ti fún yín, tí àwọn náà yóo wà lórí ilẹ̀ tí OLUWA Ọlọrun yín fun wọn ní òdìkejì odò Jọdani.
Haiti ni ti wọn sọ wi pe, awọn arinrinajo naa gbọdọ ni iwe ilera lati wọ orilẹede wọn, eleyii ti wọn yoo fihan awọn ẹṣọ aṣọbode lati Ọgbọnjọ, Oṣu Kẹfa.
9 Agẹmo 2018 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 10 Agẹmo 2018 Oríṣun àwòrán, @NGRSenate Àkọlé àwòrán, Ile Asofin agba lagbara lati buwọlu tabi tapa si ẹnikẹni ti Aarẹ ba fi orukọ re sowo si wọn Kí èèyàn tó gbà isẹ gẹgẹ bí Mínísítà lorílè-èdè Nàìjíríà, o ní àwọn ìlànà kàn tó gbọdọ tẹle.
Operation Amọtẹkun: Ilé iṣẹ́ ààrẹ ránṣẹ́ pe àwọn gómìnà ilẹ̀ Yorùbá lórí ọ̀rọ̀ Àmọ̀tẹ́kùn
Oríṣun àwòrán, @NNPCgroup O ni eleyi lo n fi aye silẹ fun awọn ti o n ṣe fayawọ epo lati maa tẹsiwaju ninu iwa ibajẹ wọn atipe, atilẹyin ile aṣofin apapọ ni ajọ NNPC n wa lati dẹkun iwa fayawọ epo rọbi naa.
62 Bẹ́ẹ̀ni, èmi yíò sì mú ìhìnrere mi wá sí ìmọ́lẹ̀ bákannáà, èyí tí a ṣe iṣẹ́ ìránṣẹ́ rẹ̀ fún wọn, àti, kíyèsíi, wọn kí yíò sẹ́ àwọn ohun náà èyítí o ti gbà, ṣùgbọ́n wọn yíò gbé e ró, wọn yíò sì mú un wá sí ìmọ́lẹ̀ àwọn kókó òtítọ́ ẹ̀kọ́ mi, bẹ́ẹ̀ni, àti ẹ̀kọ́ kansoso tí ó wà nínú mi.
Jemide ni owo ti awọn ọmọ ẹgbẹ n ra Suga ati iyẹfun lasiko yii ti kuro ni keremi lati nkan bii oṣu mẹfa sẹyin lo ti n gbowo lori siii lọsẹẹsẹ.
"Lo ba ki ọwọ bọ apo , o si mu iwe pelebe kan jade pe ""nkan ti wọn yoo maa ka niyi ti ofin konile o gbele yoo fi kasẹ nilẹ - ko to o kuro lọdọ mi lati fi 'isan ti geeti gbau."
Tani yóò gba ife ẹ̀yẹ UEFA Champions League ti saa yi?
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ondo Governorship Election: Ọ̀pọ̀ dúkìá àti mọ́tò bíí 15 làwọn jàǹdùkú bàjẹ́ 21 Ògún 2020 Oríṣun àwòrán, Others Ileesẹ slọpaa nipinlẹ Ondo ti fidi rẹ mulẹ pe laasigbo oselu waye lọjọbọnilu Ondo nipnilẹ Ondo Nigba to n ba BBC Yoruba sọrọ, agbẹnusọ fun ileesẹ ọlọpa nipinlẹ Ondo, Tee-Leo Ikoro ni ninu aawọn naa ni ọpọ eeyan ti fara pa amọ ko si ẹni to ku ninu laasigbo naa.
Aàrẹ Muhammadu Buhari ti ẹgbẹ́ oṣèlú APC fi ẹyìn Atiku Abubakar janlẹ̀ nínú ìdìbò tó wáye lajọ́ kẹtàlélogun osu Keji ti ó si pinu láti ṣejọ lóri abajáde èsì ìdíbò ọhun láti gba ẹtọ òun pada.
O fikun pe, pẹlu ohun gbogbo ti a ri ka ninu iroyin ati ofin ilẹ Naijria, ko yẹ ki Gomina Makinde gba ki wọn sin Ajimobi si GRA Oluyole, to wa ni Ibadan.
Ẹni ọdun marundinlaadọta ni Israel Oladele Ogundipe.
Minisita fun eto iroyin ati asa, Alhaji Lai Muhammed lasiko to n ba awọn oniroyin sọrọ ni ilu Ilorin, sọ wi pe iroyin ofege ni awọn eniyan n gbe kaakiri lori ẹrọ ayelujara lati le pe ijọba to wa lode loruko buburu saaju idibo gbogboogbo ti yoo waye ni Satide, ọsẹ yii.
Ohùn rẹ̀ nìkan ni ẹ̀ ń gbọ́.
 agbejade ni ori afefe kompini ipolongo amerika ( abc ) ni ojo kerindinlogbon osu kesan odun 2012 .
Nígbà meje lojoojumọ ni mò ń yìn ọ́nítorí òfin òdodo rẹ.
Ìfẹ́kúfẹ̀ẹ́ ara wọn ni wọ́n ń lépa.
Atẹjade naa ni Tinubu ko mọ awọn to n pe lori aago ri, sibẹ, o gbe ipe wọn, to si salaye fun wọn pe oun kọ ni oun ni ileesẹ LCC to n gba owo bode ni iloro Lekki.
Buhari: Iṣẹ́kíṣẹ́ ni awọn akọ́lé ń ṣe pẹ̀lú ilé tó ń dàwó ní Eko lemọ́lemọ́
Ṣugbọn wọn kò gbọdọ̀ nà án ju ogoji ẹgba lọ, ohun ìtìjú ni yóo jẹ́ fún un ní gbangba, bí wọ́n bá nà án jù bẹ́ẹ̀ lọ.
Bẹ́ẹ̀ ni OLUWA ṣe máa ń bá Mose sọ̀rọ̀ ní ojúkoojú, bí eniyan ṣe ń bá ọ̀rẹ́ rẹ̀ sọ̀rọ̀.
Ezekwesili jáwọ́ nínú ìdíjé sípò aàrẹ Nàìjíríà #BBCNigeria2019 Ààrẹ Buhari ti buwọ́lu òfin tí yóò dáàbò bo àwọn àkàndá ẹ̀dá Ìbòòsí!
AFCON 2021: Orílẹ̀-èdè Cameroon tí yóò gbàlejò ìdíje nàá yí ọjọ́ padà
Nígbà tí àwọn ẹ̀mí èṣù bá rí i, wọ́n a wolẹ̀ níwájú rẹ̀, wọ́n a máa kígbe pé, “Ìwọ ni Ọmọ Ọlọrun.
Aisha Raheem ati Victor Boyle-Komolafe ti wọn jẹ ọmọ Naijiria ti wọn n gbe ohun ribibiri ṣe ni wọn ti pegede ninu awọn ti wọn fi orukọ wọn silẹ fun ami ẹyẹ 2020 Africa Prize.
OLUWA, n óo máa dúpẹ́ lọ́wọ́ rẹ láàrin àwọn eniyan,n óo sì máa kọrin ìyìn sí ọ láàrin àwọn orílẹ̀-èdè.
Oríṣun àwòrán, others Ninu ọrọ rẹ, Oloye Arabinrin Oyelola Elebuibon sọ wi pe pataki ipade naa ni lati fihan gbogbo agbaye pe, jijẹ oṣo tabi ajẹ kii ṣe nkan ibi, gẹgẹ bi awọn ẹlẹsin kan ṣe n wo o.
Slave Trade: Olórí ilé aṣòfin Amẹrika lọ Ghana láti bẹ ilé wò fún ayẹyẹ irinwó ọdún òwò ẹrú
Sibẹ awọn orilẹ-ede alamuleti DR Congo n ṣayẹwo to yẹ lori eeyan to ni Ebola ati Covid 19.
"Dino, èyí o ṣe yìí kù díẹ̀ káàtó"" Agolo akẹ́rù Apapa kò pa ènìyàn ṣùgbọ́n ó ba ọ̀pọ̀ ọkọ̀ jẹ́- Ọ̀ga RRS Olè gbé òrùka ìgbéyàwó mì ní Eko Àdó olóró dáhùn lára èèyàn mẹ́ta ní ìlú Konduga O fikun ọrọ rẹ pe Germany ti na Naijiria ni 8-0 ri lọdun 2011 ṣugbọn wọn se e ki wọn to jẹ ẹ nigba tawọn mejeeji pade ninu idije ife ẹyẹ agbaye."
Agbaọjẹ abẹṣẹ ku bi ojo, Deontay Wilder lo sọ pe oun si n gba itọju lẹyin oṣu mẹjọ ti Tyson Fury ti fẹṣẹ dara si oun lara.
A dé ọ̀hún ní déédéé agogo mẹ́jọ-àbọ̀ gan-an, a rí ẹnìkan ti o ń bọ̀ láti aafin a sì wí fún un pé ọba wi fún wa kí á wá rí òun, ẹni náà bá padà wọ aafin lọ láti lọ sọ fún ọba, ṣùgbọ́n nígbà tí o máa padà dé, ó wí fún wa pé, ọba òmùgọ́diméjì ti lọ sí oko.
Àwọn ẹ̀yà Reubẹni ṣiyèméjì,ìmọ̀ wọn kò ṣọ̀kan láti wá.
Gẹgẹ bo se wi, awọn yoo tẹle ilana to dena arun Coronavirus naa, ti adinku yoo si ba iye eeyan ti yoo tẹle aarẹ wa sile asofin apapọ, ki ile maa baa kun akunju.
Bakan naa lo fikun pe ijọba yẹ ki wọn sa ipa wọn fun awọn obi nipa lila wọn lọyẹ nipa bi wọn ṣe le tọ ọmọluwabi lawujọ.
Ẹ wo àbájáde ìwádìí wa Ṣé Akpabio ṣetán láti dárúkọ àwọn Aṣòfin tó gba iṣẹ́ àkànṣe lọ́wọ́ NDDC?
mo wipe awon omo orile-ede Naijiria nife ere boolu afesegba lopolopo, inu mi si
Nígbà tí Ẹranko Ewèlè náà rí i pé a lé òun jáde sinu ayé, ó bẹ̀rẹ̀ sí lé obinrin tí ó bí ọmọkunrin nnì kiri.
(Kò sí ẹni tí ó fi ara rẹ̀ fún iṣẹ́ burúkú lójú OLUWA gẹ́gẹ́ bíi Ahabu, tí Jesebẹli aya rẹ̀, ń tì gbọ̀n-ọ́n-gbọ̀n-ọ́n láti ṣe iṣẹ́ burúkú.
Alufa ijo naa ti kowe lati gbawe ase fun ile-ijosin naa ti awon eniyan ti n josin lati bi odun meedogun, leyin ti won ti sofin fifi ile se ile-ijosin ni odun 2016.
Ọjọgbọn Akin Abayomi fidi ọrọ yi mulẹ nigba ti o n sọ fawọn oniroyin ibi ti wọn ba iṣẹ de lori kikoju itankalẹ aisan Coronavirus.
Ewe Lettuce: Ewe yii wulo fun mimu ki isan ara rọ, ko si ni ilera to peye.
Minista soro yii nibi apero lori wto ilera agbaye to n lo lowo ni Geneva, eyi to je alaadorin iru re pe  “Ise ayewo lorisiirisii la n se lati ekun kan si ikeji ati laarin awon aala ile kookan sira won lekun Lake Chad lati fi gbogun ti WPVI.
Awọn agbabọọlu kan ni ọmọ tuntun nile, bẹ ẹ làwọn kan si n gbé pẹlu arugbo wọn.
Gbẹdu/Ogido: Eyi tumọ si ilu to tobi, boya nítorí eti ni ọpọ se maa n pe orin ati ilu to dun ni 'Gbẹdu'.
”Gege bi Okechukwu se so:”ohun ti aare se ni lati kede esi ibo , ki awon to fagile esi idibo naa si ri ara won bi i olutako si eto ijoba tiwa-n-tiwa”.
Ẹlomiran le fa a simu, tabi ti o ba fi ọwọ kan ibi ti ikun tabi itọ naa ba bọ si.
Kíni ẹ mọ̀ nípa Tolani Alli, ayàwòrán tí igbákejì ààre Osinbajọ ṣẹ́ṣẹ́ yàn?
 ogun mohammed tí ó jà láàrin kèfèrí àti mùsùlùmí ìgbà náà ló ká lámúrúdu mọ ́ .
Bí òkú eṣinṣin ṣe lè ba òórùn turari jẹ́;bẹ́ẹ̀ ni ìwà òmùgọ̀ kékeré lè ba ọgbọ́n ńlá ati iyì jẹ́.
Ninu ìdílé Heburoni, Jerija ni baba ńlá gbogbo wọn.
Oríṣun àwòrán, Facebook/Nigeria Police Force Alukoro ileeṣẹ ọlọpaa sọ fawọn akọroyin pe, ọrọ oun ko ju bayii lọ lori erongba ẹgbẹ awọn oṣiṣẹ lati gunle iyanṣẹlodi lọla.
Ṣugbọn mo ní ẹ̀rí tí ó tóbi ju ti Johanu lọ.
Ẹnikẹ́ni tí wọ́n bá rí, wọn óo fi ọ̀kọ̀ gún un pa,ẹni tí ọwọ́ bá tẹ̀, idà ni wọ́n ó fi pa á.
Are niluu Ibadan, ekun Gusu ni ipinle Oyo.
Ti ènìyàn bá n jẹ ẹ púpọ̀ o le ṣe ikú pa ẹni náà, ó sàn ki ènìyàn má jẹe rárá.
Bí mo sì ti ń fẹ́ sọ fún yín yìí, mo fẹ́ ki ẹ jẹ́ kí ó wọ ibi kọ́lọ́fín agbárí yin lọ, kí ẹ̀yìn tí ẹ n gbọ ọ̀rọ̀ yìí, fi ọ̀rọ̀ náà ṣe oúnjẹ, àti pàápàá ẹ̀yin ọmọ ilé ìwé, kí ẹ gbádùn rẹ̀ bí ọbẹ adìẹ pàtàkì, tí gbajúmọ̀ obìnrin se, tí o dín tí ó gbẹ tíkẹ́tíẹ́.
 efúnróyè tínubú nì orúko rè .
“Nítorí òun ni Ọlọrun Alààyètí ó wà títí ayérayé.
O ti to ọjọ mẹta ti ọrọ naa ti n ja ranyin ṣugbọn ẹnikankan ko ti lẹ́ sọ pato boya ootọ ni.
Bí àwọn Kerubu náà bá fẹ́ fò, tí wọ́n bá na ìyẹ́ apá wọn, àwọn àgbá náà kìí kúrò lẹ́gbẹ̀ẹ́ wọn.
UK Recession: Ètò ọ̀rọ̀ ajé ilẹ́ Gẹ̀ẹ́sì ti dẹnukọlẹ̀ fún ìgbà akọ́kọ́ láti ọdún 2009: wo bí ipa tí yóò ní lórí rẹ̀
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Mo n wa'yawo - Falz 'Àwa ò tẹ́ pẹpẹ ǹkan táa ní sórí ẹ̀rọ̀ ayélujára' FFK: Ẹ̀jẹ̀ Fulani ti dàpọ̀ mọ́ ti Yorùbá lára mi Ìpanu ‘Cheese ball’ ni wọ́n fi jí Ikimot gbé, àmọ́ ó padà sílé lẹ́yìn ọdún márùn-ún Bákan náà ló ní kíláásì kìnní-ní, ní ilé ẹ̀kọ́ girama àgbà, SS1, ni òun ti bẹ̀rẹ̀ orin kíkọ, tí kò sì rọrùn rárá láti se àwo orin tí yóò jẹ́ ìtẹ́wọ́gbà.
Awọn oṣiṣẹ eleto aabo ni ibọn wa fun ni Naijiria bii Ọlọpaa, ọmọ ogun, awọn ẹṣọ alaabo ẹnu bode àti bẹẹ bẹẹ lọ.
(…) Àti pé “iṣẹ́ ìdàgbàsókè ọrọ̀ Ajé orílẹ̀-èdè Angola” kò lé wáyé nípasẹ̀ àfilé owó orí, nítorí wípé àwọn ọmọ ìlú ni ó ń fi orí kó o, àwọn tí ó wà ní ipò ìjọba ní àǹfààní tí ó pọ̀ ní ìkáwọ́ọ wọn, tí ó ṣe pé àpò ará ìlú tí ó ń rùnpà ni wọ́n ti ń mú owó tí wọ́n ń ná.
''Iwé ìrìnà ọkọ̀ tó lé ni ẹgbẹ̀rún lọ́nà ọgọ́ta ló wà ni ilé iṣẹ́ wá ti kò si ẹni to bèrè fún.
Ìdáǹdè mi súnmọ́ tòsí,ìgbàlà mi sì ti ń yọ bọ̀.
Awọn ni alasẹ ere bọọlu, akọnimọọgba ati oluranlọwọ akọnimọọgba, bẹẹ si ni awọn ọkunrin lo nha mọ awọn obinrin ju fun ibalopọ.
Nígbà tí ilẹ̀ ọjọ́ kejì mọ́ láàótọ́ mo rí ìwé rẹ̀, ohun tí o sì kọ ni èyí:
ni igbesẹ si n lọ lọwọ lati sedasile ile ifowopamo iroyin ati ero igbalode
28 Tí Bàbá, Ọmọ, àti Ẹ̀mí Mímọ́ jẹ́ Ọlọ́run kan, àìlópin àti ayérayé, ti kò ní ìparí.
Ṣùgbọ́n bí gbajúmọ̀ mejì tọ̀tọ̀ ti ṣe de inu aginjù yí kò le ṣàì ya ẹnikẹ́ni lẹ́nu.
Boseman jade laye lẹyin idojukọ ọdun mẹrin pẹlu aisan jẹjẹrẹ.
Ti OLUWA ni òṣùnwọ̀n pípé,iṣẹ́ ọwọ́ rẹ̀ ni gbogbo ohun tí à ń wọ̀n.
Ile-ise kerin ti o gba ami eye fadaka ohun wa lori, bi o se n san owo-ipin idokowo fun awon onibaara re lore-koore lati bi ogun odun seyin.
Lara awon to tele aare Buhari lo si orile ede Morocco ni gomina ipinle Ebonyi, Dave Umahi ,gomina ipinle Jigawa Abubakar Badaru ati awon oludari ile-ise ijoba apapo.
Àwọn eniyan Ọlọrun bá dáhùn pé,“Kí ló dé tí a fi jókòó jẹ̀kẹ̀tẹ̀?
Oríṣun àwòrán, @waecngr Àkọlé àwòrán, WAEC f'ofin de ile'we mẹtadinlaadọta Wayi o, bi awọn akẹkọọ oniwe mẹwa si se n gbaradi lati joko se idanwo naa, ni ọkan awọn obi ati olukọ n poruru lori bi idanwo naa yoo se lọ.
Òtítọ́ làwọn sọ́jà gbé ìbọn tó lọ́ta gidi nínú lọ sí Lekki Toll Gate lásìkò ìwọ́de EndSARS- Ọ̀gágun Taiwo O si tun satilẹhin fun ayederu iroyin to ti n lọ tẹlẹ nipa iṣẹlẹ naa.
Gbogbo àwọn eniyan náà bá fi ohùn ṣọ̀kan pé, “Ẹnikẹ́ni ninu wa kò ní pada sí àgọ́ rẹ̀ tabi ilé rẹ̀.
Awon omo-ogun apetusaawo ajo isokan UN so ninu atejade kan pe, won salaye iwadii lori isele naa fun adari omo-ogun UNMISS, David Shearer ati awon adari awon omo-ogun miiran , ninu eyi ti won ti fenu ko lati ko awon omo-ogun naa kuro ni ipag naa.
Ẹ gbọ́ ohun tí OLUWA wí,OLUWA tí ó dá ọ̀run.
Nko mọ pe o lee gba ọna yi yọ.
Mo kan ń tiraka láti ṣe ojúṣe mi ni bí ọmọ ṣe ń satileyin fún òbí, àwọn èèyàn yìí ní àwọn ọmọ gidi tó ń tọju wọn.
Àwọn adigunjalè pa èèyàn mẹ́fà ní báńkì kan nìpínlẹ̀ Ondo Wo bí o ṣe lè kọ́ ọmọ rẹ lẹ́kọ̀ọ́ ìbálòpọ̀ 'Ọkọ̀ la rí, a ò tíì rí adárí Ilé iṣẹ́ pána-panà Eko àtàwọn mẹ́fà' - Ọlọ́pàá Akọroyin BBC fi aridaju han pe ina naa pọ jọjọ to bẹẹ ti wọn dari irinajo pẹlu baalu lọ si ilu Portharcourt.
Wọ aṣọ rẹ tí ó dára jùlọ, kí o sì lọ sí ibi ìpakà rẹ̀, ṣugbọn má jẹ́ kí ó mọ̀ pé o wà níbẹ̀ títí di ìgbà tí ó bá jẹ tí ó sì mu tán.
Nǹkan kò tíì ṣẹnu ire fún àwọn ọmọ orílẹ̀-èdè yìí - Atiku A ti ní mílíọ̀nù 11 Naira láti se ẹjọ́ pẹlú ilé-isẹ́ ọlopaa Naijiria!
Alaga ajọ to n gbogun ti  sise owo ilu basu-basu lo soro yii nibi  ayẹyẹ eto naa nigba ti o n  fa olu ile-ise naa le ile akede Naijiria Voice
Pius Adesanmi ní kò bá rọ́pò Wole Soyinka tí kò bá kú - ọmọ Naijiríà Awakọ̀ òfúrufú Ethiopian Airlines pariwo 'lọ sókè!
Nítorí náà ni ó ṣe sọ ọ̀wọ̀n náà ní orúkọ ara rẹ̀; ọ̀wọ̀n Absalomu ni wọ́n ń pe ọ̀wọ̀n náà, títí di òní olónìí.
Amọ awọn miran tako ọrọ rẹ to sọ nipa yiyan akowe obinrin Awọn ẹlomiran tilẹ mu amọran tiwọn to yatọ si ti Pasito Adeboye wa lọna ati dẹkun ifẹkufẹ oju Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
’ Kò sí òfin mìíràn tí ó tóbi ju èyí lọ.
ti o darapo mo iko Barca lati inu iko agbaboolu Dalian Quanjian F.
"Ẹru yoo si baa eeyan ti a ba ka bi Orowọle ti se apejuwe ija Esu Kekere Ode ati Olowo aye, to fi ms ija Igbo Elegbeje to waye laarin awọn eeyan ati awọn Iwin, tẹ sai ro pe ẹyin gan wa nibi ija naa, tẹ ba ka akọsilẹ rẹ Ọpọ si lo n kaanu nipa bi Kumọdiran se jade laye, ti Pasitọ kan si n waasu nipa ọjọ idajọ nigba to gbọ nipa bi awọn arinrinajo se n lọ si oke Ironu titi de Odo Ẹjẹ nibiti Ayederu ti ku ""Igbakuugba ti mo ba si ka nipa Igbagbọ Ounjẹ ni ebi maa n pa mi, ti ọpọ eeyan si n sọ ahesọ ọrọ ladugbo pe Fagunwa n ba awọn ẹmi airi sọrọ nigba ti wọn ka itan Jaaniini nipa Arọgidigba Koda, emi gan sin iya mi ni gbẹrẹ ipakọ pe mo ro pe baba mi n yan Yemọja kan ni ale ninu okun, nigba ti mo ka itan Arọgidigba."
Lara awọn nkan ti awọn ọlọpaa ka mọ awọn afurasi naa lọwọ ni ibọn AK47 marundinogoji, ẹẹdẹgbẹta ọta ibọn, to fi mọ aṣọ ọmọ ogun mẹwaa, ọkọ ijagun meji ati awọn nkan ija oloro mi i.
Ẹgbẹ́ òṣèlú PDP, ẹ̀ka ìpínlẹ̀ Eko fún Fayose lọ́jọ́ méje láti bẹ àwọn adarí ẹgbẹ́ Ikọ̀ Boko Haram àti gbogbò àwọn tó ń sàtìlẹyìn fún wọn kò ní rí ọdún 2021 - Pásítọ̀ Adeboye Yoruba wo ló fẹ́ gbé Oduduwa Republic tẹ́ n pariwo?
“Ẹni tí ó bá jẹ́ aláìmọ̀kan, kí ó máa bọ̀!
Àwọn Wolii Èké ati Olùkọ́ni Èké.
Ọmọ-ẹ̀yìn náà ni ó jẹ́rìí sí nǹkan wọnyi.
nítorí bí ahọ́n ti í máa ń tọ́ oúnjẹ wò,bẹ́ẹ̀ ni etí náà lè máa tọ́ ọ̀rọ̀ wò
Àfikún ọ̀sẹ̀ méjì la tún fun yín láti kúrò l‘Apapa - Ọsinbajo Àṣà ìbálé lálẹ́ ìgbeyàwó ń dọdẹ àwọn obìnrin òde òní Awọn miran to wa ni ibudo ẹjẹ gbigba yii naa sọrọ lori idi ti awọn ṣe jade wa fi ẹjẹ silẹ fun BBC.
“Ìgbà tí mo tún kọjá lọ́dọ̀ rẹ, tí mo tún wò ọ́, o ti dàgbà o tó gbé.
Ọga ọlọpaa Adegboye to ṣafihan awọn ọdaran naa nile ẹjọ majisireeti ọhun ni, wọn gba miliọnu mẹrin owo itanran lọwọ baba awọn ibeji naa, ki wọn to fi awọn ọmọ naa silẹ.
Àwọn eniyan náà yóo máa fìyà jẹ ara wọn,olukuluku yóo máa fìyà jẹ ẹnìkejì rẹ̀,àwọn aládùúgbò yóo sì máa fìyà jẹ ara wọn.
"O ni ""mi o ṣe mọ o!"
Riri daju pe awọn orilẹede to yi agbegbe naa ka bii Chad, Niger ati Cameroun ṣiṣẹ lori wiwagbo dẹkun sawọn isọmọgbe ikọ agbebọn naa to wa letido adagun omi Chad 3.
Mo rí i pé Tẹmpili náà ní pèpéle tí ó ga yíká.
Bẹ́ẹ̀ ni kí wọ́n má ṣe gbára lé ọrọ̀ tí kò lágbẹkẹ̀lé, ṣugbọn kí wọ́n gbẹ́kẹ̀lé Ọlọrun tí ó ń fún wa ní gbogbo ọrọ̀ fún ìgbádùn wa.
Irú èèyàn bíi igbákejì ààrẹ to jẹ́ ọ̀jọ̀gbọ́n nínú ìmọ̀ nípa òfin yẹ kó mọ̀ pé nǹkan báyìí kọjá ká máa pariwo orúkọ kiri .
Oluwo tun sọ pe o lodi ki Ọba alaye maa bọ oriṣa laafin, nitori naa, ko ṣeeṣe fun oun lati maa bọ oriṣa.
Bi igba pe eeyan de oju agbami ni idanwo a ma jẹ fun ọpọ eeyan-kii si ṣe awa nikan lagbegbe wa lọrọ yi kan.
Bí ilẹ̀ bá ti mọ́, sọ fún ọba pé kí ó so Modekai kọ́ sí orí igi náà.
Omegie ni ẹrọ ‘speed limiter’ naa ko ni jẹ ki awọn awakọ wa ọkọ loju popo ju kilomita aadọrun un ni wakati kan (90/km per hour) ti wọn ba n wa ọko lo loju popo.
"Ko tilẹ fi akoko ṣofo rara pẹlu ọrọ oko rẹ to kọkọ ju to sọ wi pe ""Brother Muri shout finish, we no see am for court"", eyi lo fi n ba ẹgbẹ to nja fun ẹtọ awọn musulumi (MURIC) to ni awọn yoo gbe lọ ile ẹjọnitori orin rẹ, ""This is Nigeria"" nibi to ti lo awọn ọmọbinrin to lo Hijab."
Ilé ẹjọ́ wọ́gilé ìgbẹ́jọ́ Olalekan 'Woodberry' Pọnle Òru òní ní ìjọba á ti afárá 'Third Mainland' ní Eko; Wo àwọn ọ̀nà míràn tí o leè gbà lẹ́yìn tí wọ́n bá tìí Ọlọ́lá jù lọ Terry Waya ni Bàbá Terseer Kiddwaya tó ń kópa nínú BBNaija 2020 Wo ohun tí Adájọ́ sọ nípa ìgbẹ́jọ́ Wòlíì Sotitobire l'Ondo Amofin agba, Malami fi awọn ẹsun agbọ-gbọnti kan Magu ninu eyi ti a ti ri ẹsun ṣiṣe owo baṣubaṣu, jiji awọn ẹru ti wọn ri gba ko ti wọn si n ta wọn fawọn ọrẹ ati ojulumọ wọn.
Ibadan, ekun Gusu ni ipinle Oyo.
Igbà ènìyàn ló wà ní ilé iṣẹ asojú Nàìjíríà ní Russia nítorípé wọn o rí owó ọkọ̀ léyìn ìdíje ife ẹ̀yẹ àgbáyé 2018.
50 ní Nàìjíríà báyìí- Àjọ PPPRA Fuel Price: Àjọ PPPRA epo bẹntiró ti di N121.
Odo Adagun Sogidi ni BBC lọ ṣe iwadii rẹ nitori ti ọmọ ko ba ba itan, o gbọdọ ba arọba to jẹ baba itan.
Amọṣa, ni ọjọ Aje ni ọwọ awọn ọtẹlẹmuyẹ ọlọpaa tun ra Wadume mu pada ni ilu Kano ti o lọ farasinko si.
Beard Woman: Irungbọ̀n mi máa ń dójú tì mí láti jáde lọ ra nǹkan ní ọ̀sán gangan
85 ti o si pajude si N59.
Ni idaji ọkọ kan, ni ijọba Ajimobi ko ẹrọ katakata lọ bi ile naa wo, eyi to bọ si ibinu ọpọlọpọ eeyan.
“OLUWA yóo jẹ́ kí àwọn ọ̀tá rẹ ṣẹgun rẹ.
Àwọn ọlọ́pàá kò kọbiara si ọ̀rọ̀ ìwà ipá lásìkò ìgbéle Covid -19 ni ìwà ipá ṣe pọ̀ - Ajàfẹ́tọ obìnrin Àwọn ọlọ́pàá kò kọbiara si ọ̀rọ̀ ìwà ipá lásìkò ìgbéle Covid -19 ni ìwà ipá ṣe pọ̀ - Ajàfẹ́tọ obìnrin Láti ọ̀sẹ̀ díẹ̀ sẹ́yìn ni ìròyìn aburu nípa ìwà ipá nínú ilé àti ifipábánilòpọ̀ ti n peléke síi lágbàyé tí kò sì yọ orílẹ̀-èdè Nàìjíríà sílẹ̀ pẹ̀lú.
Eyi lo fa alaafia ti a n jẹgbadun ni agbegbe
Eleyii jẹ ọkan lara awọn adehun ti aarẹ Donald Trump tako, to si yọ orilẹede Amerika kuro ninu adehun naa.
àwọn tí wọ́n jẹ́ akọni ninu wọ́n lọ sí Beti Ṣani lóru, wọ́n sì gbé òkú Saulu ati ti àwọn ọmọ rẹ̀ kúrò lára odi Beti Ṣani, wá sí Jabeṣi Gileadi, wọ́n sì sin wọ́n sibẹ.
, Duration 8,0016 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 6:56 Fídíò, Wòlíì Kasali sọ̀rọ̀ nípa awuyewuye pé ó lé ìyàwó rẹ̀ jáde nílé, Duration 6,5628 Ọ̀pẹ̀̀ 2018 5:57 Fídíò, LASTMA Yesufa: Àwọn dókítà gbìyànjú lórí ojú mi ṣùgbọ́n.
Babalwa wa parọwa si awọn to jẹ iru eda bii ti ti oun wi pe ti o ba rọrun fun wọn, ki wọn ma tiju pe kojako-kojabo ni wọn.
OLUWA Ọlọrun yín yóo da àwọn ègún wọnyi sórí àwọn ọ̀tá yín tí wọ́n ṣe inúnibíni si yín.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Nibi ipade kan pẹlu awọn aṣofin ẹgbẹ oṣelu Conservative party to waye ni May ti ṣalaye pe 'Mo ṣetan lati fi ipo yii silẹ ṣaaju asiko to yẹ lọna ati lee ṣe ohun to ba tọ fun orilẹedee wa.
Opolopo iwode lo waye titi ti o fi fipo aarẹ naa silẹ fun awọn ologun.
Àwọn bàbá ìsàlẹ̀ òṣèlú tó bá ìtìjú bọ̀ nínú ìbò Gómìnà rèé Afurasi tó fa ìpayà nílé ìwé Port Harcourt ti wọ gàù Ọ̀rọ̀ Aisha Buhari sí Ramaphosa wú ọ̀rọ̀ síta lẹ́nu àwọn ọmọ Nàìjíríà Kí ló ṣe ikú pa Adediwura Lateefat Bello lẹ́yìn ọ̀sẹ̀ méjì tí wọ́n ń wá a?
Ọwọ́ ọlọ́pàá tẹ afurasí ajínigbé 93, àti ìbọn 'AK47' márùndínlógójì 'Irọ ni, ko si ologun kankan ni Dapchi' Fayemi ṣetán láti ṣáájú àwọn gomina láti mójútó ètò ààbò Bàbá pokùnso ní àhámọ́ lórí ẹ̀ṣùn pé ó bá ọmọ rẹ̀ lòpọ̀ Oríṣun àwòrán, AFP Àkọlé àwòrán, Eto aabo to peye ti jẹ ipenija nla fun orilẹede Naijiria Ipinlẹ Jigawa lo ni iku to kere ju pẹlu eniyan meje.
Awọn ohun ti eeyan nilo ni ethanol tabi Isopropyl, methylated spirit, ewe aloe vera, ati lọfinda.
Jordaan ti wọn ṣẹṣẹ yan yoo wa ni ipo kẹta.
Ìgbàlà jìnnà sí àwọn eniyan burúkú,nítorí wọn kò wá ìlànà rẹ.
Gbajugbaja oṣere ti wọn ti dojuti fun iwa ibajẹ, Harvey Weinstein ti ri ẹwọn ọdun mẹtalelogun he fun ẹsun ifipabanilopọ ati wi wu iwa aitọ si obinrin.
Gbogbo wọn jẹ, wọ́n yó, àjẹkù sì kún apẹ̀rẹ̀ mejila.
Gbogbo kànga tí àwọn iranṣẹ Abrahamu baba rẹ̀ gbẹ́ ní àkókò tí Abrahamu wà láyé ni àwọn ará Filistia rọ́ yẹ̀ẹ̀pẹ̀ dí.
"\""Àlùfàá méjì wà lára àwọn mẹ́rin tó fi ipá bámilòpọ̀\"""
Moderna, ileeṣẹ apogun miran lorilẹ-ede Amẹrika naa ti kede pe ida mẹrinlelaadọrun atabọ (94.
Amọ iriri wa fi idi ọrọ mulẹ pe, pupọ ninu awọn adugbo yii ni ko dun un wo nipasẹ awọn panti ti o kun gbogbo opopona kaakiri eyi ti ko wu oju ri rara.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Igbẹ to gun to tun ni ila tẹẹrẹ tẹẹrẹ lo maa n nira lati ya, a lefo ori omi, bẹẹ domi sii ko tun ni lọ bọrọ.
" Nnamdi Kanu ti ṣàlàyé bí ó ṣe rìn lẹ́yìn ọdún kan tó dàwátì Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Nnamdi Kanu ti ṣàlàyé bí ó ṣe rìn lẹ́yìn ọdún kan tó dàwátì Olórí ẹgbẹ́ tó ń polongo fún ìdásílẹ̀ orílẹ̀édé Biafra, IPOB, Nnamdi Kanu ti sọ̀rọ̀ lẹ́yìn ọdún kan tó dàwátì.
Wọ́n ní, “Ilẹ̀ tí ń jẹ àwọn eniyan inú rẹ̀ ni ilẹ̀ náà, gbogbo àwọn tí a rí níbẹ̀ ṣígbọnlẹ̀.
Ẹni ọdun mẹtadinlọgbọn ọhun to gbajugbaja lori ayelujara pẹlu orukọ to n lo, TBlak"" ni wọn fi ẹsun kan pe o dan nkan eewọ wo ninu igbo Osun Osogbo nibi to ti lọ ya fiimu ibalopọ pẹlu obinrin kan ni ihoho."
Nígbà tí ó pẹ́ díẹ̀, mo já sí ọgbà igi eléso kan tí ó kún fún onírúurú èèso dídùn irú èyí tí n kò tí ì rí jẹ láti ọjọ́ tí mo ti ṣìnà yìí.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Yoruba Films: Àwọn òṣèré tó bímọ s'Amẹrika lọ́dún 2019 rèé kí Trump tó f'òfin dèé 24 Sẹ́rẹ́ 2020 Oríṣun àwòrán, Instagram Bi awada, bi ere, ọrọ naa ti di otitọ bayii.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Trump picture: ọjọ́ tí Trump kí mi kú iṣẹ́ lórí 'twitter' ní inú mi dùn jù- Oyedele Awọn ijọ ajihinrere alawọfunfun naa n gbaruku ti Trump bo tilẹ jẹ pe awọn eeyan dudu to jẹ ọmọ ijọ aye ode oni to n pẹlu ẹgbẹ Democrat bu ẹnu atẹ lu igbesẹ aarẹ Trump pọ.
" Wọnyii ni ọ̀rọ̀ to jade lẹnu Dokita Manuel Serrano, to n sisẹ ni ileewosan National Centre for Oncological Investigations, ni Spain.
Loṣu keje ọdun 2020 lẹgbẹ oṣelu Democrat yoo kede nibi apero wọn niluu Wisconsin ẹni to yoo ṣoju ẹgbẹ naa ninu idibo aarẹ ti yoo waye loṣu kọkanla.
Bí àjálù ìbúgbàmù tó gb'ẹ̀mí ọ̀pọ̀ nìlùú Eko ṣe wáyé nìyí Àjọ NYSC sé ilẹ̀kùn ibùdó ìfinimọlé nítorí Coronavirus Buhari fárígá, ó ní kò s'óṣìṣẹ́ ìjọba tó gbọ́dọ̀ rìnrìnàjò sílẹ̀ òkèèrè lọ́wọ́ yìí Àwọn ọba Yorùbá kan rèé tí wọ́n rọ̀ lóyè, tí ọba míràn jẹ lójú ayé wọn Ilé ẹjọ́ ti sún ìgbẹ́jọ́ pásítọ̀ ìjọ Sotitobire si Ọjọ́bo̩ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Elebuibon: Àwọn àṣà àtọ̀húnrìnwá ló fa títa ẹ̀jẹ̀ nítorí ògùn owo Awọn orilẹede ti ọrọ kan naa ni orilẹede China, Italy, Iran, South Korea, Spain, Japan, Faranse, Germany, Amẹrika, Norway, ilẹ Gẹẹsi, Netherlands ati orilẹede Switzerland.
Awọn to ku ti won n kopa ninu ipele ṣikeji si àṣekagba ni: Uruguay, France, Brazil, Belgium, Sweden, England, Russia ati Croatia.
pẹ ̀ lú àwo orin rẹ ̀ ti ọdún 2000 ( tí ó pe ní ' sóyòyò ) músílíù ti ṣe àṣeyọrí nípa mímú kí orin àpàlà fẹjú síi , sí etíìgbọ ́ àwọn ọ ̀ dọ ́ , ó ṣe bẹ ́ ẹ ̀ mí èémì ọ ̀ tun sí inú ẹ ̀ yà orin yìí bẹ ́ ẹ ̀ náà ni ó mú àṣà ( iṣẹ ́ takuntakun bàbá rẹ ̀ ) wà láàyè .
Agba ọjẹ elere idaraya tẹniisi sọ eleyi di mimọ, lẹyin ọjọ marun un ti aìsàn ibà yọwọ́ rẹ láwo ìdíje Madrid Open.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Valentine: Ọkùnrin ní kí obìnrin má fún àwọn ní àwọ̀tẹ́lẹ̀ mọ́ bíi ẹ̀bùn ọjọ́ olólùfẹ́ Nigba ti ounjẹ ko ba si da bo se ni kiakia gẹgẹ bo se maa n se tẹlẹ lasiko ti eeyan wa ni ọdọ, itumọ eyi ni pe onitọhun ko sisẹ asekara to yẹ, ti yoo si maa ba ikun rẹ ja.
Orò kan wọ́pọ̀ ní ibi púpọ̀ ní ilẹ̀ Yorùbá.
Ètò ìjọba fún pínpín owó ìrànwọ́ yóò bẹ̀rẹ̀ ni 21/09/2020 Asiwaju BolaTinubu sọ̀rọ̀ lóríi ìròyìn ẹlẹ́jẹ̀ pé òun gbà pé APC fìdí rẹmi ní Edo Wo bí Sunday Shodipe ṣe pa Funmilayo tó pa kẹ́yìn l' Akinyele Obaseki la Ize-Iyamu mọ́lẹ̀ wọlé ìbò gómìnà lẹ́ẹ̀kejì ní ìpínlẹ̀ Edo Bakan naa ni ọdun 2017, ileeṣẹ ofintoto HBLNY ati SAR fi lede wi pe Atiku fi owo ranṣẹ si banki mẹtadinlọgbọn pẹlu iye owo to to $11,140,357 si banki Deutsche Bank Trust Company Americas, DBTCA ni orilẹede Amerika.
Stefanu bá tẹnu bọ̀rọ̀, ó ní, “Ẹ̀yin arakunrin ati baba mi, ẹ gbọ́ ohun tí mo ní sọ.
Nṣe ló nyí birir bí òkòtó.
Ọmọ yín yìí, ọmọ ńlá ni.
O gboroyin fun isajoba gomina Ganduje, eleyi ti o mu ipese eto ilera ti o peye lokunkun-dun nipinle Kano, papaa julo fun akitiyan re lati kun awon osise eleto ilera lowo lati tan eto abere ajesara kaakiri awon ijoba ibile patapata.
Awọn eeyan ṣi n kaakiri laisi ibomu Lara ofin ti ijọba ipinlẹ ati apapọ gbe kalẹ ni pe ibomu facemask di ọranyan fun gbogbo eeyan to ba fẹ jade kuro ninu ile wọn.
ti ko ipa pataki lenu ise  je ohun iwuri lati
Ọpọ awọn obinrin ni o si maa n woo gẹgẹ bi arimalee lọ ọkunrin eleyii ti o farahan ninu awọn ti o n tẹ lee lori ikanni instagram rẹ.
tí àwọn ọdọmọkunrin bá rí mi, wọn á bìlà sẹ́gbẹ̀ẹ́ kan,àwọn àgbà á sì dìde dúró;
Ẹ̀jẹ̀ bo àpò náà bámúbámú, ihùúhù ẹyẹ sì lẹ̀ mọ́ ẹ̀jẹ̀ wọ̀n-ọnnì lára bẹ́ẹ̀ ni oní rúurú òògùn ni wọ́n so mọ́ ọn ni ẹ̀gbẹ́; àdó àti atọ́, egungun ejò àti ìkó oódẹ, ìyẹ́ agbe àti ìyẹ́ àlùkò, pẹ̀lú ẹyọ owọ ayé àtijọ́, àti onírúurú ìwo ẹranko, àti kékeré àti títóbi, àti ìwo àgbọ̀nrín tí ń ká ilá jẹ nínú oko, pẹ̀lú ìyẹ́ àparò tí ń rìn kiri ní inú aginjù, gbogbo àwọn wọ̀nyí péjọ bámúbámú sí ara àoò ńlá ẹbọra kékeré inú ọ̀gán, orúkọ ẹni tí ń jẹ́ Èsù-kékeré-òde.
Oyedele ni odiwọn aworan naa to 24 X 21 ni eyi to lo to wakati aadọrin lati fi ya.
Àbí, ẹ kò mọ̀ pé ara yín ni ibùgbé Ẹ̀mí Mímọ́ tí ó wà ninu yín, tí ẹ gbà láti ọ̀dọ̀ Ọlọrun?
Ọmọ Yorùbá míràn tún dé ipò gíga l‘Amẹrika Sowore àti àwọn ọmọ ẹgbẹ Revolution Now kò ṣẹ̀ ṣófin lórí ìwọ́de, ẹ tú wọn sílẹ̀ - NLC Samuel Okwaraji: Ó pé ọgbọ̀n ọdún tí lónìí ti akọni àgbábọ̀ọ̀lù papo dà Ilé-isẹ́ Ológun gbọdọ̀ sèwádìí bí ọmọogun se pa ọlọ́pàá - Buhari Bí ọlọ́pàá bá mú ọ, kí ló yẹ kí o ṣe?
Àwọn nìkan ninu ìran Lefi ni wọ́n lè súnmọ́ OLUWA láti rúbọ sí i.
Eyi si mu ki awọn dokita ileewosan naa maa dunkooko lati bẹrẹ iyanṣẹlodi tijọba ko ba wa nkan ṣe si ijinigbe to n waye ni gbogbo igba loju ọna naa.
Kí ló wá dé tí ẹ fi dìde sí mi lónìí láti bá mi jà?
Awẹ́ meji meji tí ó ṣe é ṣí láàrin ni ìlẹ̀kùn kọ̀ọ̀kan ní.
Ṣugbọn bí ẹ bá kọ̀, tí ẹ kò gbà láti kọlà abẹ́, a óo mú ọmọbinrin wa, a óo sì máa lọ.
 o ní àrànmọ ́ tí ó ga .
Akọwe agbegbe fun ẹgbẹ awọn nọọsi nilẹ naa, Khaya Sodidi, sọ pe A ko le fi ẹmi awọn nọọsi sinu ewu nitori awọn oṣiṣẹ to n gbalẹ nile iwosan ti daṣẹ silẹ."
Ile ijọba ilẹ America ni tootọ ni eto wa lati maa gbe ọrọ jade loju opo twitter Trump ki ara ma baa fu awọn oniṣẹ ibi lori irin ajo rẹ.
Nítorí náà, n óo tàn án lọ sinu aṣálẹ̀, n óo bá a sọ̀rọ̀ pẹ̀lẹ́pẹ̀lẹ́.
Coronavirus: Ẹ wo àwọn ìròyìn èké tó gbòde ní Áfíríkà torí àjàkálẹ̀ àrùn
Ati lati ri wi pe wọn mu awọn janduku to n da ilu ru laipẹ.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Iroyin ni wọn ti pa o le ni ẹgbẹrun ọgọrun un eniyan ki ogun naa to pari lọdun 2009.
ofin – Emeka Ngige, SANIgbakeji oludari-
Ṣìṣeṣìṣe Troost-Ekong ṣokùnfà ìyà àjẹsùn fún Nàìjíríà lọ́wọ́ Algeria Obasanjo ẹru n ba oun pe ija ẹlẹyamẹya le bẹ silẹ tawọn ẹya miiran ba kọju ija si awọn Fulani eyi to le buru jai bi ipaniyan to ṣẹlẹ lorilẹ-ede Rwanda.
Tani Akeredolu tó ń díje dupò gómìnà fún ìgbàkejì nípìnlẹ̀ Ondo?
ún , sugbon ti o tun sun eto idibo naa siwaju di osu to n bọ.
nínú àwọn ìtàn òkè yí àwọn méjì ló sọ bí a ṣe sọ ìlú náà ní ijẹ ̀ bú ṣùgbọ ́ n ó dàbí ẹni pé a lè gba ti irúfẹ ́ èyí tí ó sọ pé Ìjẹ ̀ bú - Òde ni Ọba ijẹ ̀ bú jẹ ̀ ṣà ti mú orúkọ náà wá ní eléyìí ti ó bójú mi díẹ ̀ .
Dafidi bá ranṣẹ pe Tamari ninu ààfin, ó ní kí ó lọ sinu ilé Amnoni, kí ó lọ tọ́jú oúnjẹ fún un.
Bí ọ̀wọ̀n ìkùukùu tí ó wà ní ẹnu ọ̀nà Àgọ́ Àjọ ti gbéra sókè ni ẹ̀tẹ̀ bo Miriamu, ó sì funfun bí ẹ̀gbọ̀n òwú.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ina: Ibudo idalẹsi Olusosun-Ọjọta njona Nibayi, gbogbo aayan ileesẹ wa lati gbọ ti ẹnu ijọba ipinlẹ Eko ni ko si so eso rere.
“Ọpọlọpọ obinrin ni wọ́n ti ṣe ribiribi,ṣugbọn ìwọ ta gbogbo wọn yọ.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Kàkà k‘éwé àgbọn dẹ̀ lágbo òṣèlú l‘Ondo, akọ̀wé ìjọba tún kọ̀wé fipò sílẹ̀ Mà á gbẹ̀san bàálù àjọ UN tó já ní Borno - Buhari yarí Ẹ̀kún omi ṣọṣẹ́ ní Ogun, ìjọba yarí láti wó ilé ojú odò Ẹ sá àwọn akẹ́kọ̀ọ́ sínú òòrùn fún ọgbọ̀n ìṣẹ́jú lójojúmọ́ - Ìjọba Oyo pàṣẹ Òṣìṣẹ́ LASTMA gún olólùfẹ́ rẹ̀ l'ọ́bẹ, ó tún gba ẹ̀mí ara rẹ̀ l'Eko Ohun to fa ogun naa ni pato l'ọdun 1966 ni ija ẹlẹyamẹya ati ẹsin to waye ni apa Ariwa Naijiria, iditẹ gbajọba, ati bi awọn kan ṣe gbogun ti awọn ẹya Igbo to n gbe ni apa Ariwa Naijiria.
Ẹ bẹ̀rẹ̀ sí kùn ninu àgọ́ yín, ẹ ní, ‘Ọlọrun kò fẹ́ràn wa, ni ó ṣe kó wa jáde láti ilẹ̀ Ijipti, kí ó lè kó wa lé àwọn ará Amori lọ́wọ́, kí wọ́n sì pa wá run.
" Bakan naa lo tun ṣafihan awọn ọta ibọn to ri ṣa lagbegbe ti iṣẹlẹ naa ti waye.
 dúró orímóògùnjẹ ́ nìkan ni ọmọ tí Àdùnní bé .
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ojúdé Ọba 2018: Asọ ń pe asọ ránsẹ́ Tìlù tìfọn ni wọ̀n kí Arsène Wenger kàábọ̀ sí Liberia Wọ́n ní àwọn ọlọ́pàá SARS ọ̀hún na pápá bora kúrò níbi tí ìṣẹ̀lẹ̀ náà ti wáyé lẹ́yìn tí wọ́n yìnbọn pa arákùnrin náà.
2)Oorun sísun nita gbangba Muzdalifa: Gẹgẹ bí àwọn onimọ ẹsin ti ṣàlàyé, ni kete ti oorun ba tí fẹ lọ wọ lọjọ Arafat, ní àwọn Alalaaji yóò gbéra lọ sún laaye kan ti wọn n pé ni Muzdalifa.
Ẹgbẹ oṣelu PDP wa funpe si awọn adari ẹgbẹ oṣelu APC ti wọn tuka lati gbaradi fun esi wọn si idahun awọn ọmọ Naijiria fun iwa ti wọn pe ni aṣemaṣe pe ki wọn ma ro pe wọn lee mu u jẹ gbe nipa didarapọ mọ ẹgbẹ oṣelu mii.
'Obinrin lo mu mi fẹran orin kikọ' Fọlọrunṣọ Alakija: Obinrin nilo imọ 'Awọn obinrin nilo ajọ iranwọ fun oṣelu' Angelique kidjo pe fun anfani f'awọn obinrin Opọ gba pé asiko ti to ki a faaye gba ibadọgba larin ọkunrin ati obinrin paapaa ninu oṣelu Naijiria ki idagbasoke le jẹ jade.
Awọn olupẹjọ sọ pe Buhari parọ ninu ibura to kọ silẹ ninu iwe to fun ajọ eleto idibo INEC lasiko to fi erongba rẹ lati dupo han.
ẹ̀mí mi yọ̀ sí Ọlọrun, Olùgbàlà mi,
ofin mu,ki won si daabo bo awon eniyan nipa didena iwa janduku.
Nítorí èrè rẹ̀ dáraju èrè orí fadaka ati ti wúrà lọ.
Gbogbo àwọn àgbààgbà ni wọ́n pésẹ̀ sibẹ.
Ọba Babiloni rí i pé òun ń pèsè ohun tí ó nílò ní ojoojumọ fún un, títí di ọjọ́ ikú rẹ̀.
Ninu atẹjade kan eyi to fi sita, Sẹnetọ Ajimọbi ni kete ti oun gbọ iroyin ni oun ti fi iṣẹ ma foya abo Ọlọrun wa pẹlu rẹ ranṣẹ si Gomina Makinde ni kete lẹyin to kede rẹ.
Ladọja jare n'ilẹ ẹjọ lori bi o ti lodi si awọn ijoye pẹlu awọn baalẹ ti ijọba sọ di ọba.
(Marca) Everton naa ti sọ fun Crystal Palace pe awọn ṣetan lati san ọgọta miliọnu Pọun fun rira atamatase orilẹ-ede Turkey, Cenk Tosun ni igba kan naa pẹlu Wilfred Zaha.
Idà olójú meji tí ó mú yọ jáde lẹ́nu rẹ̀.
O wa lara awọn to da iwe iroyin Nigerian Daily News silẹ, lọna lati tẹsiwaju ninu ipo oṣelu.
Yóo wá, yóo pa àwọn alágbàro wọ̀n-ọn-nì, yóo sì fi ọgbà àjàrà rẹ̀ fún àwọn alágbàro mìíràn.
Obinrin onínúrere gbayì,ṣugbọn ọrọ̀ nìkan ni ìkà yóo ní.
 O ti le ni odun kan bayii ti mo ti kopa gbeyin latari pe mo sese bimo.
Ayaba Faṣiti Rí Ahasu-erusi Ọba Fín.
Ó bi wọ́n léèrè pé ǹjẹ́ baba òun ṣì wà láàyè.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ondo Politics: Eyitayo Jegede gbé Akeredolu lọ síwájú ìgbìmọ̀ tó n gbọ́ ẹ̀sùn ìdìbò 30 Ọ̀wàrà 2020 Oríṣun àwòrán, Twitter/Eyitayo Jegede/Rotimi Akeredolu Oludije fun ẹgbẹ oṣelu Peoples Democratic Party, ninu idibo gomina ipinlẹ Ondo, to waye laipẹ yii, Eyitayo Jegede, ti pe ẹjọ tako iyansipo Gomina Rotimi Akeredolu.
Amọ, ọkan lara ikọ Amọtẹkun naa ṣeṣi yinbọn to si pa Tosin Thomas lasiko ti wọn fẹ pari ija to n ṣẹlẹ.
BBC Yoruba tubọ bere lọwọ rẹ boya igbesẹ lati yọ niṣe pẹlu ọrọ to sọ fun BBC Yoruba nipa pe awọn Yoruba lodi si dida agọ Fulani silẹ nilẹ Yoruba ṣugbọn o ni oun ko ro bẹ.
Gbogbo ohun tí Ọlọrun ṣe sí Farao ati sí àwọn ará Ijipti nítorí àwọn ọmọ Israẹli ni Mose ròyìn fún baba iyawo rẹ̀.
N ó ṣàròyé ìdí abájọ, àti ìdí tí wọ́n fi ń pe igbó náà ní Igbó Funfun.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ekiti: Ìyàwó gómìnà Èkìtì rọ àwọn obìnrin lóríi gbígbẹ̀bí sílé 2 Sẹ́rẹ́ 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Awọn ajọ agbaye fi idi rẹ mulẹ pe iku ọwọọwọ laarin awọn obinrin ati ọmọ wẹwẹ pọ lorilẹede Naijiria Oniruuru iburdo ìrọbí ni awọn obinrin n gba bimọ sí.
Lọdun yii, ibeere tawọn obinrin ọgọrun naa n beere ni pe: Bawo ni ọjọ ọla yoo ti ri to ba jẹ pe awọn obinrin lo dari rẹ?
O tesiwaju pe, awon ti setan lati se amulo ero VAR naa ninu olokan-o-jokan ifesewonse CAF ti yoo maa waye.
Ìdí tí mo fi rán an si yín ni pé kí ẹ lè mọ bí gbogbo nǹkan ti ń lọ sí lọ́dọ̀ wa, kí ọkàn yín lè balẹ̀.
Wọn fẹ fi tipatipa gba akoso ile igbimọ aṣofin ipinlẹ naa eleyii ti wọn n tun ṣe lọwọlọwọ.
Ṣugbọn pàṣẹ fún Joṣua, mú un lọ́kàn le, kí o sì kì í láyà; nítorí pé, òun ni yóo ṣiwaju àwọn eniyan wọnyi lọ, tí wọn yóo fi gba ilẹ̀ tí o óo rí.
lorile ede yii ni o gbọdọ ni awọn asoju , o kere tan asoju kan lati ipinle kan.
Fi àìmọ̀kan sílẹ̀, kí o sì yè,kí o máa rin ọ̀nà làákàyè.
O ni yara iya oun niwe naa wa, ti oun si ba awọn iwe ti wọn fi gba oun wo ninu iwe naa, lasiko ti iya oun ko si nile, eyi to fidi rẹ mulẹ pe tọkọ-taya Silva gba oun wo ni.
Láti ìgbà yìí si ni ọ̀pọ̀ àwọn égbẹ́ ajàfẹ́tọ́ ọmọniyan ti ń rọ ijọba láti dá sí ìgbésẹ̀ àwọn to ṣe àgbékalẹ̀ yìí nítori ní ọ̀pọ̀ ìgbà ní ìdájọ Sharia máa n tẹ òfin ẹtọ ọmọniyan lójú mọ́lẹ̀.
Gomina Oluwarotimi Akeredolu ti ipinle Ondo pin omo eso koko to le ni egberun irinwo ati egberun meedogbon ti kasuu fawon agbe ipinle Ondo.
Ṣé ọjọ́ kan ṣoṣo ni wọ́n fẹ́ parí rẹ̀ ni?
1 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Asiko ati Iba Iṣẹlẹ"" ni akori Akomolede ati Aṣa tọsẹ yii."
Ninu iwoye wọn wọn woye wipe igbesẹ naa yoo ta abuku ba orilẹede Naijiria ni awujọ agbaye.
Dafidi tún bèèrè pé, “Ǹjẹ́ àwọn alàgbà Keila yóo fà mí lé e lọ́wọ́?
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Coronavirus: Àìsàn yíì ti ràn dé Amẹrika, Thialand àti South Korea 21 Sẹ́rẹ́ 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 22 Sẹ́rẹ́ 2020 Oríṣun àwòrán, Getty Images Ijọba orilẹ-ede China ti kilọ fawọn eeyan dawọ lilọ-bibọ si ilu Wuhan nibi ti aarun Coronavirusti ti ṣekupa eeyan mẹsan an.
ti o si ye ki o pari isẹ rẹ ni ojo keji ,osu kefa odun yii.
Lọ́dún 2008 ni ilé ìgbìmọ̀ aṣojúsòfin ṣàpéjúwe bílíọ́nù mẹ́rìndínlógún tí ìṣàkóso Ọbasanjọ ná lórí iná ọba gẹ́gẹ́ bí ànádánù, tí wọ́n sì di ẹ̀bi ru àìsètò tó yẹ́ nínú àgbékalẹ̀ òwó ìṣúná, tó fí mọ́ àìní àfojúsùn ọjọ́ iwájú látọ̀dọ̀ àwọn iléèṣẹ́ tó yẹ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Akurẹ Kidnap: Èmí kò ṣetán láti gbọ́ ẹ̀jọ yín lónìí, ó di 2020- Adájọ́ Adeyanju 24 Ọ̀pẹ̀̀ 2019 Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Akurẹ Kidnap: Èmí kò ṣetán láti gbọ́ ẹ̀jọ yín lónìí, ó di 2020- Adájọ́ Adeyanju Èmí kò ṣetán láti gbọ́ ẹ̀jọ yín lónìí, ó di 2020- Adájọ́ Laarọ oni, ọjọ Iṣẹgun, ọjọ kẹrinlelogun, oṣu kejila ni awọn olopaa ipinlẹ Ondo ko awọn eeyan yii lọ sile ẹjọ.
Ẹ má jẹ́ kí ọkàn yín lọ sọ́dọ̀ irú obinrin bẹ́ẹ̀,ẹ má ṣèèṣì yà sí ọ̀dọ̀ rẹ̀.
El-Rufai ninu , lati tete fi awon adari Adara ti won mu ,lasiko ipaniyan  ni awon agbegbe naa silẹ.
Jesu tún bi í ní ẹẹkẹta pé, “Simoni ọmọ Johanu, ǹjẹ́ o fẹ́ràn mi?
#BBCNigeria2019 Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Yinka Ajia: ìbẹ̀rù Ọlọrun ni mo fẹ́ fi tukọ̀ Kwara ti mo ba wọlé Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí 2:51 Fídíò, Buhari gbọ́dọ̀ yọ àwọn mínísítà tí kò wúlò ní sáà kejì yí-Ogundamisi, Duration 2,513 Ẹrẹ̀nà 2019 Ó tó gẹ́ ní àṣà ìpolongo tó fakọyọ lásìkò ìbò 20193 Ẹrẹ̀nà 2019 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
díẹ̀ ni yóo sì kù ninu àwọn tafàtafà alágbára ọmọ Kedari; nítorí OLUWA Ọlọrun Israẹli ló sọ bẹ́ẹ̀.
Àwọn eniyan náà sì ń dá àwọn ẹran ọ̀sìn náà jọ níwájú Dafidi, wọ́n ń sọ pé, “Ìkógun Dafidi nìyí.
O ni awon igbimo egbe ti gbe awon igbese to ye ki won gbe, ko to di ojo kẹ́tàlélógún, osu kefa, odun 2018 , ti idibo egbe naa yoo waye.
Wọ́n wá bẹ̀rẹ̀ sí wádìí láàrin ara wọn pé ta ni ìbá jẹ́ ninu wọn tí yóo dán irú rẹ̀ wò.
Kíá ni Ọba ránṣé pé kí wọ́n ó lọ mú ìgbín wá.
Kí irú ẹni bẹ́ẹ̀ má ṣe rò pé òun óo rí nǹkankan gbà lọ́dọ̀ Oluwa: ọkàn rẹ̀ kò papọ̀ sí ọ̀nà kan, ó ń ṣe ségesège, ó ń ṣe iyè meji.
Títí di ìgbà ìdìbò, kò gbó-òórùn inúnibíni kán rí láti ọ̀dọ àwọn akẹgbẹ́ẹ rẹ̀ tí wọ́n jẹ́ ọmọ China.
Ọba Ìjẹ̀bù - Jẹ̀ṣà ni ó máa ń gbé Ọwá lésẹ̀ tí ó sì máa ń ṣúre fún un kí wọn tó gbà á gẹ́gẹ́ bí ọwá àti olóri gbogbo ọba ilẹ̀ Ijẹ̀ṣà.
Ṣebí àwọn ni ẹ fún ní ọ̀rá ẹran ìrúbọ yín,àwọn ni ẹ sì rú ẹbọ ohun mímu yín sí?
Ṣugbọn ìwọ fi àtàtà ọtí yìí pamọ́ di àkókò yìí!
Ẹ̀yin fúnra yín mọ̀ pé ọwọ́ ara mi yìí ni mo fi ṣiṣẹ́ tí mo fi ń gbọ́ bùkátà mi ati ti àwọn ẹlẹgbẹ́ mi.
Dafidi ti lòdì sí mi báyìí, ó sì ti ba dè mí, láti pa mí.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Èmi ò kí ń lu ìyàwó mi' Nibi igbẹjọ to waye loni naa ni adajọ Senchi ti gbọ adura ajọ EFCC, to si ni ki wọn lọ di awọn eeyan naa wa sile ẹjọ ni tipa tipa, to si sun igbẹjọ ọhun siwaju di ọjọ Kọkanla osu Keje ọdun 2019.
Amọ, kii ṣe orilẹede Russia nikan ni iru iṣẹlẹ bayii ti n ṣẹlẹ.
Ẹni tó bá ń bínú kàn ń bínú lásán ni- Oyedepo Lóòtọ́ ni mo yìnbọn níbi yánpọnyánrin tó wáyé ládúgbò mi-Seun Kuti Wo àwọn ohun tí Amotekun kò ní le è ṣe mọ́ ní ìpínlẹ̀ Oyo.
Ibineaya, ọmọ Jerohamu, Ela, ọmọ Usi, ọmọ Mikiri, Meṣulamu, ọmọ Ṣefataya, ọmọ Reueli, ọmọ Ibinija.
Òkun rí i, ó sá,Jọdani rí i, ó pada sẹ́yìn.
tesiwaju ninu ipile to ti wa nilẹ.
Ẹni to bori: Morocco Kenya vs Uganda.
OLUWA Ọlọrun ní, ‘Wò ó, mo lòdì sí ọ, ìwọ Sidoni.
hillary diane rodham clinton ( ; ojoibi october 26 , 1947 ) je oloselu ara orile-ede amerika .
O so pe “ti o ba n gbe oko bo lati shagamu wa siluu Eko,kilomita metadinlogun akoko ti wa kan ti pari.
O wá rọ awọn ọdọ lati dide ja fun agbekalẹ eto iṣejọba tiwantiwa ti ko lẹjanbakan ninu, eto idari to see fi ọkan tan ati idajọ ododo fun mutumuwa, ki Naijiria lee tẹ siwaju.
Nítorí pé ẹ kò ní fi ìkánjú jáde,bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò ní sáré jáde.
àwọn ará ìlú kan yóo máa rọ àwọn ará ìlú mìíràn pé, ‘Ẹ jẹ́ kí á lọ kíákíá láti wá ojurere OLUWA, ati láti sin OLUWA àwọn ọmọ ogun; ibẹ̀ ni mò ń lọ báyìí.
Kọmiṣọna fọrs ayika atohun alumọni ni ipinlẹ Ọyọ, Kẹhinde Ayọọla dakẹ si ileewosan aladani kan lagbegbe Iyaganku ni ilu Ibadan, gẹgẹ bi awọn iwe iroyin abẹle ṣe sọ.
Governorship Election Update: Àfikún ìdìbò yóò wáyé nìpínlẹ̀ mẹ́fà lọ́jọ́ kẹtàlélógún oṣù yìí
sise owo ilu basu-basu lati koju iwa ibaje ati ajẹbalujẹ.
O ni oun n ṣiṣẹ pọ pẹlu ajọ to n ri si ọrọ ọlọpaa lati rii pe gbogbo eto yii di ṣiṣe.
Ọdúnnìí, á sàn wá s’ówó, sàn wá s’ọ́mọ, sàn wá sí àláfíà – tí í ṣe baálẹ̀ ọrọ̀.
4 Òkùdu 2019 Oríṣun àwòrán, @BashirAhmaad Àkọlé àwòrán, Ààrẹ Buhari, Saraki, Dogara àtàwọn gómìnà kan tí ránṣẹ́ ìkíni kú ọdún sí àwọn mùsùlùmí Aarẹ Muhammadu Buhari ti fi da awọn ọmọ orilẹede Naijiria loju pe opin ko ni pẹ de si iwa ijinigbe, igbesunmọmi atawọn iwa miran to n tigi boju alaafia lorilẹede Naijiria.
O yà si idi iṣẹ́ to yàn láàyo nítori bi awọn akẹgbẹ rẹ se máà n dẹyẹ si ni kékére, o ti ja ni Honkong, Australia, àti China o si ti de ipele ti o gba 11-0 O wọ adéhun pẹ̀lú Utimate Fighting Championship ni ọdun 2017.
Kọmísọ́nà ètò ìlera ìpińlẹ̀ Eko ọjọ̀gbọ́n Akin Abayomi ti lùgbàdì ààrùn Covid-19 'Bí a kò bá fẹ́ ìbínú Ọlọ́run, a gbọ́dọ̀ jẹ́ kí Tinubu du ipò ààrẹ̀ lábẹ́ àsìá ẹgbẹ́ APC ní 2023' Iròyìn àyọ, àdínkù tún bá iye ènìyàn tó lùgbàdì Covid -19 ní Nàìjíríà lọ́jọ́ Àìkú Ilé ẹrù míì tó jábọ́ l‘Eko tún mú ẹ̀mí obìnrin méjì lọ Awọn ilana tuntun naa niyii: Alejo ti wọn o maa gba ko gbọdọ ju ìdá ọgọta lọ ti wọn o gba lẹẹkan naa.
Olè gbé òrùka ìgbéyàwó mì ní Eko Àwòrán àjọyọ̀ ìjọba ológun ní Sudan Wahala iyan rọ dẹdẹ sori South Sudan Àwọn òṣìṣẹ́ aláàbò kọlu àwọn tó n ṣe ìwọ́de ní Sudan Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Olórin ọmọ Nàìjíríà kan gbà ìdájọ́ ikú fún bíba orúkọ Anọbi Muhammed jẹ́ Ilẹ́ ẹjọ́ Sharia kan ni ìpińlẹ̀ Kano ti dájọ ikú fún olórin kan to jẹ́ ẹni ọdún méjìélógún nítori pé o bá orúkọ Anọbi Muhammed jẹ́ nipa gbigbe orukọ Imaamu kan ga ju ti Anọbi Muhammed lọ ninu orin rẹ.
Amọ lẹyin o rẹyìn, alaafia jọba, ti ilu Ogbomoso si pada tuba tusẹ titi di oni, bi o tilẹ jẹ pe nnkan to dara ti bajẹ saaju.
Oṣiṣẹ fidihẹ to ba INEC ṣiṣẹ to kọwe ẹsun yii ṣalaye pe ajọ eleto idibo Zamfara kọ lati san owo ọya awọn oṣiṣẹ wọnyii.
Ẹgbẹ oselu The African Action Congress ti le Ọmọyẹle Sowore ati awọn mejidinlọgbọn miran fun ẹsun wi pe wọn dojuti ẹgbẹ oselu naa.
- Àjọ ajàfẹ́tọ̀ọ́ ọmọdé Al Shabab ṣe ìkọlù sí ibùdó ogun America ní Kenya, ẹ̀mí mẹ́ta lọ síi Buhari, Osinbajo, ẹ̀yin gómìnà, ẹ kéde dúkìá yín kọ́jọ́ méje tó pé-SERAP Pẹsẹ́ ní Ọlọ́pàá Nàìjíríà wà látàrí ìṣekúpani Ọ̀gágun Iran- Ọ̀gá Ọlọ́pàá Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Inu mi bàjẹ́ nígbà tí mo bí i, odidi oṣù mẹ́ta, mi ò lè gbàdúrà s'Ọ́lọ́run' Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Eliṣa bá gbadura pé kí OLUWA jọ̀wọ́ ṣí ojú rẹ̀, kí ó lè ríran.
Materials Research and Development Council (RMRDC) ile-ise imo sayensi ati imo
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Coronavirus: Àwọn ìlana to tọ̀nà lati tọ ti o ba fún pe o ni ààrun 2.
2m dọlà ni obìnrin yìí ń gbà tó bá kọ ǹkan sí ojú òpó Instagram rẹ̀ Kí ló mú ọlọ́pàá ilẹ̀ Gẹ̀ẹ́sì san owó gbà má bínú £2500 fún pásítọ̀ yí?
Àwọn baba wa ni wọ́n dẹ́ṣẹ̀, àwọn sì ti kú,ṣugbọn àwa ni à ń jìyà ẹ̀ṣẹ̀ wọn.
Ta ni yóo wá bá mi rojọ́?
 Ó sì jẹ ́ kí tàgbà tọmọdé , akẹ ́ kọ ̀ ọ ́ àti olùkọ ́ , kòfẹ ́ sọ ̀ àti àgbẹ ̀ rí ẹ ̀ kọ ́ kan tàbí òmíràn dìmú nínú fíìmù wọn .
 fún àkóràn ojú , kìí ṣe nípasẹ ̀ ojú bíbó lásán .
O ti di ènìyàn Mẹrinlelógóji to ti ni ààrun Coronavirus ni Naijiria Èṣi àyẹ̀wò jáde, Gómìnà Bauchi ti ní aàrùn coronavirus báyìí Ilé ìgbìmọ̀ Aṣòfin Nàìjíríà kó igbá wọlé l'Abuja nítorí coronavirus Nibayii, eeyan mẹrindinlaadọta lo ti lugbadi arun covid-19 ni Naijiria ninu eyi ti ẹnikan ti di oloogbe ti awọn meji si ti kuro nile iwosan lẹyin ti wọn gbadun tan.
Ẹ̀yin tẹ́ẹ tako àgbékalẹ̀ àgọ́ Fulani, ìkórira ló ń yọ yín lẹ́nu - Ìjọba àpapọ̀ Thomas John: Kí ló yẹ kóo mọ̀ nípa adelé alága NNPC tuntun?
Ó wí fún wa pé bí wọ́n bá rí ni, wọn ó fi ojú wa rí nǹkan nítorí ohun ti àwọn Àkàrà-oogun ti sẹ si wọn.
Ó ti ṣe igbá-kejì gómìnà Ilé Ìfowópamọ́ Àgbà ti Nàìjíríà láti ọdún 2009 sí 2014, níbi tí “ó ti tukọ̀ ọ àwọn àgbà iṣẹ́ àtúnṣe nínú ètò ìkówóoamọ́ orílẹ̀ èdè Nàìjíríà lẹ́yìn ìgbà tí ọrọ̀ Ajé àgbáyé ti ṣe òjòjò tán.
O maa n din ooru ku lati sun daada Ti ooru ba mu, o dara ki o jẹ ki atẹgun o fẹ si ọ lara.
Mohamud Ibrahim fikun un pe, awon agbesunmomi agbebon kan lo sekupa lasiko to n lo ile itaja.
 Ise ijoba ni lati pese abadofin atilana ofin ti yoo mu ise aladani rorun sii fun idagbasoke.
"Ipinlẹ Eko yoo bẹrẹ si ni dan chloroquine wo lati mọ bi yoo ṣe ṣiṣẹ si.
Ó ní kò sí ìjáfara mọ́.
Chelsea kọ́wọ̀ọ́ rìn pẹ̀lú Arsenal lọ àṣekágbá Europa Gbà fọ́gà ẹ!
Osoba ní lẹ́yìn tí ìjọba pé àwọn, àwọn ọmọgun náà ríi dájú pé, ìlànà tó tọ́ àti èyí tó yẹn láti bá ará ìlú ṣe ni àwọn lò, ìbọ̀n yínyìn tàbí ìpànìyàn kankan kò sì wáye.
 Eyi tumo si pe isele kan le ran opolopo ero.
Ẹkun omi ati ilẹ mimi lo ti n waye nibẹ lọwọ lọwọ.
(VON) ,Shade Olatunbosun ati Ngozi kan si ni ipinle Nasarrawa.
Bi awọn ẹgbẹ ajafẹtọ bii Coalition in Defence of Nigerian Democracy and Constitution, CDNDC ṣe n lọgun pe, aṣilo ipo lo n da aarẹ Buhari laamu, bi bẹẹ kọ, ko laṣẹ lati gbe ile ijọba kalẹ fun Mamman Daura.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù America: Àìsàn jẹ̀jẹ̀rẹ̀ pa Sẹ́nétọ̀ John McCain l'ọmọ ọdún 81 26 Ògún 2018 Oríṣun àwòrán, AFP Àkọlé àwòrán, Obama ṣọfọ McCain ti wón jọ du ipo aare America John Mc Cain ni o ba Obama jọdu ipò aarẹ America lọdun 2008.
Trump ati Jong-un ṣe ileri nibi ipade naa lati fọwọ ṣowọpọ lori ibaṣepo titun.
Mi o le sọ; Amọ, o le jẹ AFCON ti maa gba kẹyin ree'' Idije AFCON ti Egypt yi ni igba ẹlẹẹkeje ti Gyan yoo kopa, ọdun 2008 ti Ghana gbalejo idije naa lo kọkọ kopa ninu AFCON.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ogun Election: Ilé ẹjọ gbé àga lọ rèé jókòó jẹ sílé fún Ọsunsanya.
Ẹ tají kí ẹ máa kọrin,ẹ̀yin tí ó sùn ninu erùpẹ̀.
Ọpọlọpọ awọn ọmọ ile iwe rẹ ni a gbọ wipe, o maa n rin irin bii maili mẹrin ki wọn to de ile iwe.
lee jẹ ki awon ile igbimo asoju ati ile-ejo ipinle lee da duro lori inawo won ,
Ó bẹ̀rẹ̀ sí sọ̀rọ̀ sí àwọn olórí ogun tí wọ́n wà pẹlu rẹ̀; ó ní, “Ẹ gbọ́, ẹ̀yin ará Bẹnjamini, ṣé ọmọ Jese yìí yóo fún olukuluku yín ní oko ati ọgbà àjàrà?
Nígbà tí ilẹ̀ mọ́, ó tún lọ sí Tẹmpili.
Ó ní òun óo fi ẹ̀mí kan sinu rẹ̀, tí yóo mú kí ó sá pada sí ilẹ̀ rẹ̀ nígbà tí ó bá gbọ́ ìròyìn kan, òun óo sì jẹ́ kí wọ́n pa á nígbà tí ó bá dé ilẹ̀ rẹ̀.
Fẹntílàtọ̀ yìí bákan náà ni afẹ́fẹ́ kosooru-kosotutu tí yóò máa fẹ́ gbígbóná sínú afẹ́fẹ́ ìsẹ̀gùn láti lè bá àgọ́ ara ènìyàn mu.
Lóòótọ́ ni mo rí pé gbogbo yín ni ó fajúro, bẹ́ẹ̀ ni ọkàn mi le koko bí òkúta dídán inú omi, ìlọsíwájú jìnná sí oníyèméjì, n kò si ṣiyèméjì bí mo ti ń lọ, lágbára Ọlọ̀run Ọba tí ó dá mi n ó padà dé ilé dandan.
Rí dájú pé ebi rẹ ń fọwọ́ wọn pẹ̀lú omi àti ọṣẹ lóòrèkóòrè.
OLUWA, ayé kún fún ìfẹ́ rẹ tí kì í yẹ̀;kọ́ mi ní ìlànà rẹ.
Ìdí nìyí tí mo fi ń rán ọ létí pé kí o máa rú ẹ̀bùn-ọ̀fẹ́ Ọlọrun sókè, tí a fi fún ọ nípa ọwọ́ mi tí mo gbé lé ọ lórí.
Ẹ̀mí èṣù náà bá gbo ọkunrin náà jìgìjìgì, ó kígbe tòò, ó sì jáde kúrò ninu ọkunrin náà.
 O maa n fa aisan sara ni ni eyi to maa n je ki ara wuwo sii nitori pe ara maa n fe sinmi lale ni eyi ti ko ni si agbara lati je ki oolo inu lo ounje naa daadaa.
Eyi bẹrẹ lẹyin gbedeke wakati mejidinlaadọta ti wọn fun ijọba lati yanju owo oṣu ti ijọba jẹ wọn ati awọn ọrọ mi i to n jẹ awọn oṣiṣẹ niya.
Ajiboye tẹsiwaju wipe aifi aye silẹ fun ijọba ipinlẹ Ọyọ lati tọwọ bọ eto ile iṣẹ redio naa loṣokunfa igbeṣe ati lo ọwọ agbara."
Ẹ máa pa àwọn ọjọ́ ìsinmi mi mọ́, kí wọ́n lè jẹ́ àmì láàrin èmi pẹlu yín, kí ẹ lè mọ̀ pé èmi OLUWA ni Ọlọrun yín.
 Àpapọ ̀ iye àwọn ènìyàn tí ó wà níbè gẹ ́ gẹ ́ ètò ìkànìyàn ọdún 2006 sọ jẹ ́ 645,000 .
"Gẹgẹ bi ẹ ṣe mọ bi iwa ijẹkujẹ ṣe gbilẹ ninu iṣejọba yii, eyi fihan pe nṣe ni wọn n gbọn owo kuro ninu apo araalu lorukọ Sheikh El-Zakyzaky nitori, lai fọta pe, irọ nla ni wọn n pa.
Àwọn Yorùba kò fi ọwọ́ yẹpẹrẹ mú ètò ìsọmọlórúkọ nítorí pé a ka orúkọ sí ǹnkan pàtàkì.
Lẹyinorẹyin, ile ẹjọ naa ni ki wọn rẹ ipo rẹ silẹ lati Major General si Brigadier General, ki wọn si tun fi ọwọ osi juwe ile fun.
Alufaa yóo mú àgbò ẹbọ ìmúkúrò ẹ̀bi ati ìwọ̀n ìgò òróró náà, yóo fì wọ́n bí ẹbọ fífì níwájú OLUWA.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Femi Odekunle: Àwọn ohun mánigbàgbé ti ọ̀jọ̀gbọ́n náà gbé ile ayé ṣe rèé 30 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Oríṣun àwòrán, @agbahor_aghogho Iroyin iku Ọjọgbọn akọkọ lori imọ nipa iwa ọdaran lorilẹede Naijiria, Femi Odekunle, lo ja ranyin-ranyin lori ayelujara, lẹyin to lugbadi arun Coronavirus.
Ṣé o ní igbagbọ pé yóo pada,ati pé yóo ru ọkà rẹ̀ wá sí ibi ìpakà rẹ?
Babatunde Fashola: Àwọn alájẹbánu gba owó fún isẹ́ iná mọ̀nàmọ́ná
Onitsha market fire: Buhari kẹdùn pẹlu ẹbí obìnrin tó kú àti ọmọ rẹ.
Bí baba ti máa ń ṣàánú àwọn ọmọ rẹ̀,bẹ́ẹ̀ ni OLUWA máa ń ṣàánú àwọntí ó bá bẹ̀rù rẹ̀.
Gẹ́gẹ́ bí OLUWA ti ṣe fún àwọn ọmọ Esau tí wọn ń gbé òkè Seiri nígbà tí ó pa àwọn ará Hori run fún wọn, tí àwọn ọmọ Esau gba ilẹ̀ wọn, tí wọ́n sì tẹ̀dó sibẹ títí di òní olónìí, ni ó ṣe fún àwọn ará Amoni.
A-dú máa dán, ọrẹ ìmùlẹ̀ lórí Òpópónà 'Facebook'
Ninu ọrọ tiẹ, balogun ẹgbẹ agbabọọlu Brazil, Thiago Silva bu ẹnu ẹtẹ lu ihuwasi Messi si Tite.
Àwọn ọmọ Israẹli yòókù yóo wà láàrin àwọn orílẹ̀-èdè ati ọ̀pọ̀ eniyan, bíi kinniun láàrin àwọn ẹranko igbó, bíi ọ̀dọ́ kinniun láàrin agbo-aguntan, tí ó jẹ́ pé bí ọwọ́ rẹ̀ bá tẹ ẹran, yóo fà á ya, kò sì ní sí ẹni tí yóo lè gbà á lọ́wọ́ rẹ̀.
 'Ni aye isinyii to jẹ wi pe bi ọkọ ṣe n gbe bukata ẹbi naa ni iyawo n fi owo silẹ, o pọn dandan ki obinrin ni irẹlẹ, ki ọkọ rẹ naa si fẹran rẹ."
65 Nítorí, kíyèsíi, èmi yíò kó wọn jọ bí àgbébọ̀ ti íràdọ̀ bò àwọn ọmọ rẹ̀ sí abẹ́ ìyẹ́ rẹ̀, bí wọn kò bá sé ọkàn wọn le.
Nnkan bi ọsẹ diẹ sẹyin ni awuyewuye ṣiṣe owo baṣubaṣu jẹyọ ni ajọ ọhun, koda wọn fi ọwọ osi juwe ile fun adari ajọ naa tẹlẹ, Joy Nunieh.
Ẹ̀yin ọmọ Israẹli, ẹ pada sílé yín,kí Dafidi máa bojútó ilé rẹ̀!
Ile iṣẹ naa wa pa ọwọ pọ pẹlu ile iṣẹ ijọba lpinlẹ Eko ti o wa fun igboke gbodo ọkọ oju omi ati ti ilẹ okeere ti o wa ni Texas .
Ilana ti a n sọ wọn yi nii se pẹlu bi awọn arinrinajo yoo ti se ma se nibẹ, ṣaaju ki wọn to wọ inu baalu ati nigba ti wọn ba ti wọ inu rẹ.
Ajọ NNPC ni, gbogbo awọn to wa ni ibi iṣẹlẹ naa ni awọn ti fi orukọ wọn sita, ti ko si si ẹni to sọnu.
Gbogbo wọn yóo wí fún ọ pé,‘Àárẹ̀ ti mu yín gẹ́gẹ́ bí ó ti mú àwa náà.
a Scorpion, ti wọn fura si pe oun ni ọga patapata fun ẹgẹ naa.
Ori akitan lo ju ọmọ si, lẹyin to ru ẹru oyun fun oṣu mẹsan-an.
Isọri ounjẹ marun un ree ti o le jẹ lati maa sanra asanju tabi yọkun 1.
''O ṣeeṣe ki n ma kopa ninu AFCON imiran mọ.
Òun ni a sì rí ní òpin ìwé pé òun ni ó jí owó Orímóògùnjẹ́ gbé.
Ìfihàn tí a fi fúnni nípasẹ̀ Wòlíì Joseph Smith sí John Whitmer, ní Fayette, New York, Oṣù Kẹfà ọdún 1829.
Àṣepọ̀ mọ́ ìtẹ́ àánú ni kí o ṣe àwọn Kerubu náà, kí ọ̀kan wà ní ìsàlẹ̀, kí ekeji sì wà ní òkè rẹ̀.
A dẹ okùn sílẹ̀ fún un,a sì dẹ pańpẹ́ sí ojú ọ̀nà rẹ̀.
Bakan naa ni Ahmed fi oju awọn alaṣẹ ijọba ti wọn fi ẹsun titẹ ẹtọ ọmọniyan mọlẹ wina ofin.
Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí US Presidential Election Debate 2020: Trump àti Biden bínú sọ̀rọ̀ síra wọn lásìkò ìtàkurọ̀sọ30 Owewe 2020 10:43 Fídíò, Wole Soyinka sọ ìdí tó fi ni òun a fi màálù Fulani ṣe súyà fáwọn èèyàn abúlé, Duration 10,4323 Owewe 2020 Èyí tí a wò jùlọ 5:03 Fídíò, Omolola Arohunmolase Welder: Mo ti fí iṣẹ́ 'Welder' gbayì láwùjọ, tó mo fi tọ́ ọmọ yanjú, Duration 5,039 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 5:39 Fídíò, Akomolede ati Asa lori BBC: Olùkọ́ Kikelomo Ogunboye tan ìmọ́lẹ̀ sí ìwà olè ọ̀gá ọlọ́pàá Audu gẹ́gẹ́ bí àwòkọ́ṣe àsìkò yìí, Duration 5,398 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 4:11 Fídíò, Oba Adeyeye Ogunwusi: Ojú mi ti rí lọ́pọ̀ lọpọ̀, ọ̀pọ̀ èèyàn ni kò tilẹ̀ gbàgbọ́ pé mo lè jọba- Ooni, Duration 4,117 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 4:43 Fídíò, Promise Akinlade: ọmọ ọdún mọ́kànlá tó ń fi ìlù dárà bíi àgbàlagbà sọ̀rọ̀ nípa tálẹ́ǹtì rẹ̀, Duration 4,437 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 0:59 Gbọ́, Ìsẹ̀lẹ̀ jákèjádò orílẹ̀èdè àgbáyé láàárín ìṣẹ́jú kan, Duration 0,59wákàtí 5 sẹ́yìn 7:03 Fídíò, Olumuyiwa Bolade Adedeji Military Bruitality: Bí arákùnrin onípèníjà ara tí sọ́jà lù ṣe dé, Duration 7,035 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 4:45 Fídíò, Yoruba Films: Ẹ̀ẹ́ bẹ̀ mi kúrò láyé ni, mi ò lè kú - Fadeyi Oloro, Duration 4,4526 Èrèlè 2020 2:48 Fídíò, Esther Ajayi: Èmi náà ti borí ìṣòro rí ló ń mu mi ṣojú àánú, Duration 2,481 Ògún 2019 6:08 Fídíò, Adebola Ademilua: Àìrísẹ́ ṣè lẹ́yìn ìwé kíkà ló sọ mi dí ìyá onírú, mo dúpẹ́ tèmi, Duration 6,0827 Bélú 2020 2:36 Fídíò, Sotitobire: Ìdájọ́ òdòdò ló fẹsẹ̀ múlẹ̀ lórí ọ̀rọ̀ Pásítọ̀ Sotitobire - Agbẹjọ́rò fún ìjọba, Duration 2,367 Ọ̀wàrà 2020 BBC News, Yorùbá Ìdí tí ẹ fi le è nígbàagbọ́ nínú ìròyìn BBC Ìlànà Lílò Nípa BBC Òfin Àṣírí Cookies Kàn sí.
" NLC ní Gómìnà tí kò bá san ẹ̀kúnwó oṣù gbọdọ̀ fipò sílẹ̀ Irun 'Miss Congo' gbaná lẹ́yìn tó gbadé 'Miss Africa 2018 Ta ló já bàlúù ogun Nàìjíríà ni Damasak?
Oríṣun àwòrán, Wumi Toriola/Twitter Oríṣun àwòrán, Wumi Toriola/Instagram Ṣùgbọ́n lówúrọ̀ ọjọ́ Ẹti ni Wumi Toriola tún bọ́ sọjú òpó instagram rẹ̀ láti sọ pé, Bí èèyàn bá ṣe aburú fún ọ, má rẹ́rin ti kò dénú pẹ̀lú irú ẹni bẹ́ẹ̀ bi o bá gáání wọ́n."
Ẹ níláti ní ìfaradà títí dé òpin, kí ẹ lè di pípé, kí ẹ sì ní ohun gbogbo lẹ́kùn-únrẹ́rẹ́, láìsí ìkùnà kankan.
Ẹka to n se iwadii ni Ajọ Isọkan Yuroopu, EU EOM ni ofo ni idibo sipo aarẹ, ti ipo gomina ati si ile igbimọ asofin apapọ lorilẹede Naijiria.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Olaitan Olamide: mò lè má nílò ìwé ẹ̀rí mi tí mo bá parí ní LASU Iran ni pe eyikeyi ninu wọn ti wọn ba lo lati fi ṣina ikọlu si Iran yoo fara kaaṣa ibinu Iran.
Amọ iroyin miran ti ko fẹsẹ mulẹ ni, awọn ọmọogun akẹgbẹ rẹ, lo yinbọn paa.
Aaroni ati àwọn ọmọ rẹ̀ yóo sì jẹ ẹran àgbò náà, ati burẹdi tí ó wà ninu agbọ̀n, ní ẹnu ọ̀nà àgọ́ àjọ.
Ó bọ oriṣa Baali, ó sì mú OLUWA Ọlọrun Israẹli bínú ní gbogbo ọ̀nà bí baba rẹ̀ ti ṣe.
Ọkùnrin kan pa ara rẹ̀ sínú ọgbà àjọ TRACE tó n mójútọ ìrìnnà ọkọ̀ nípìnlẹ̀ Ogun Ipade oniroyin naa lo waye lẹyin ti awọn ọmọ Naijiria kan n bere pe ki ijọba ṣe iwadii kikun lori iku jagun jagun na.
Nítorí nàá, kà á dáàda láti mọ̀ bóyá wọ́n kàn fẹ́ ẹ́ fi gbọ́ tẹnu rẹ ni.
Òun ni yóo rẹlẹ̀ jù láàrin àwọn orílẹ̀-èdè, kò ní lè gbé ara rẹ̀ ga láàrin àwọn orílẹ̀-èdè mìíràn mọ́.
 Àpẹẹrẹ ni eyínfúnjowó , eyínafẹ ́ , ajíláran , ajíṣafẹ ́ , Ọ ̀ pẹ ́ lẹ ́ ńgẹ ́ , arikúyẹrí , agbọ ́ tikúyọ ̀ , awẹ ́ lẹ ́ wà , ìbàdí àrán àti bblọ.
Suhaila kasẹ ọrọ rẹ ninu fidio naa pe, ''ẹni to fi atẹjade sita pe awọn wọgile iwọde ko ni nnkankan ṣe pẹlu awọn to n ṣagbatẹru iwọde to n lọ lọwọ ni Abuja, ti iwọde naa ko si ni dopin ayafi ti wọn ba tu olori awọn silẹ'' Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Shiite: Ẹ̀mí àti ara wa kọ ohun tí ìjọba ń ṣe sìwa láti 2015 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
9m) 'A kò ní w'ojú olóṣèlú kankan lóríi ìwádìí àpapín owó N5bn ní Kwara' Dino ní ìyàwó ni Adeyemi jẹ́ f'óun lágbo òṣèlú, Adeyemi l'ọ́mọ ọ̀dọ̀ ni Dino jẹ́ Ilé ẹjọ lé Ọba Èrúwà kúrò lórí Àpèrè lẹ́yìn ọdun 21 Missing Child: Òbí àti asọ́nà ṣọ́ọ̀ṣì 14, lọ́ búra nì'dí imọlẹ̀ l'Akure Ní àsìkò yìí, àwọn àgbẹ̀ láti Washington nìkan lo ní ànfàni lati gbìn èso náà títí dí ọdún mẹ́wàá si àsìkò yìí.
Ta ni yóò gba ₦60m lónìí láàrin olùdíje márùn-ún tó kù nílé BBNaija?
Tanker Accident: Ọ̀pọ̀ èèyàn tó ń lọ sẹ́nu iṣẹ́ àti okoòwò ló tàn sílẹ̀
Oni ọjọ Aje gan si lo pe ọdun mẹtalelaadọta ti ogun abẹle Baifra naa bẹrẹ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Awọn ọmọ Naijiria n sọ ọrọ oriṣii nípa ọrọ Buhari ati Shagari 29 Ọ̀pẹ̀̀ 2018 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 31 Ọ̀pẹ̀̀ 2018 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ko si ẹni ti kò lè ṣẹ ara wọn laye, aforijin lo dara julọ Iku alumuntu looṣa to n kọ ẹbọ nigba ti asiko ba tó.
Ṣugbọn, ẹgbẹ ti da a duro l'ẹnu iṣẹ rẹ tẹlẹ.
Ọmọdé yóò máa sọnù ládùúgbò, arúgbó leè kú láì tọ́jọ́, tí wọn bá jókòó sílé lásìkò ìjọsìn - CAN Àwọn afunrasí lórí ikú Funke Olakunrin ti wà nílé ẹjọ́ ní Akure Ikú mú Steven tó lọ dẹ́nu ìfẹ́ kọ olólùfẹ́ rẹ̀ lábẹ́ omi lọ Iṣẹlẹ yii waye ni St John's Episcopal Church ni isọda ọna to wa lọgangan iwaju ile Aarẹ.
1 triliọnu to yẹ ki o san fun idagbasoke fasiti ni Naijiria.
Láìsì nọ́mbà ìdánimọ̀ NIN ní 2020; kò sí ìdánwò- JAMB Ènìyàn 721 fi ayédèrú ìwé ẹ̀rí gba iṣẹ́ ìjọba àpapọ̀ - ICPC Kò sí ìfoyà, mò ṣetán láti sàn jù ₦30,000 fáwọn òṣìṣẹ́ l‘Eko - Sanwo-Olu Ẹ gbà mi o!
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Russia 2018: Awọn alátilẹyin àgbabọọlu kò le pada sílé O ní nígbà ti ọ̀rọ̀ náà sẹlẹ̀ obinrin kan tó ń mójú to àwọn ti irú ìṣẹ̀lẹ̀ bẹ́ẹ̀ bá sẹlẹ̀ sí, Yulia Siluyanova ló ti kọ̀kọ̀ bẹ̀rẹ̀ ìtọ́jú wọn kí ó tó pe òhun.
” Mose nawọ́ mú un, ejò náà sì pada di ọ̀pá ní ọwọ́ rẹ̀.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Orílẹ̀èdè Canada fọwọ́ sí kí wọ́n máa fi igbó sararindin 24 Òkùdu 2018 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ọ̀pọ̀lọpọ̀ló ń fara pamọ́ mu igbò Ní ìbẹ̀rẹ̀ ọ̀sẹ̀ yìí ni orílẹ̀èdè Canada di orílẹ̀èdè tí yóò f'òfin se àtìlẹ́yìn kí àwọn ènìyàn rẹ̀ máa fi egbòogi olóró igbo se fàájì ara.
Lagos Fire Service: Ẹ máse tan àbẹ́là lórí ike tàbí pákó
awon Fulani fi n dunkoko mo won ni ile won.
ohun tí òǹkọ ̀ wé ṣiṣẹ ́ lé lórí nínú ìwé yìí ìpín èdè aáfíríkà sí ẹbí .
Oríṣun àwòrán, Catholic Diocese of Otukpo Àkọlé àwòrán, Oṣu kẹfa ọdun 2016 ni wọn ji alufaa Adeyi to jẹ alufaa agba fun diọsisi Otukpo ni Ipinlẹ Benue gbe Awọn mẹrin ni ọlọpàá mu nigba ti iṣẹlẹ naa ṣẹlẹ.
Ìwé onídùró náà sọ wí pé ó ní se pẹ̀lú bí wọ́n se ti Dino mọ́le láti ọjọ́ yìí, lèyí tó ní ó le sàkóbá fún ìlera rẹ̀.
Tinubu, oju ti ẹ, o ta ilẹ Yoruba fun ọta rẹ nitori adanikanjẹ- Femi Fani-Kayode Oloselu Femi Fani Kayode ti kọ lẹta ranṣe si Asiwaju Bola Ahmed Tinubu lẹyin ti Aarẹ Muhammadu Buhari yan Alaga fidiẹ tuntun fun ẹgbẹ oṣelu APC.
Otedola Bridge accident: Èèyàn méjì bá ìjàmbá ọ̀kọ̀ tó ṣẹlẹ̀ lórí afárá Otedola lọ
"Mo fi igbeyawo mi silẹ nigba ti ọmọ mi wa ni oṣu mẹta pere.
Joṣua sọ fún àwọn ọkunrin meji tí wọ́n lọ ṣe amí ilẹ̀ náà pé, “Ẹ wọ ilé aṣẹ́wó náà lọ, kí ẹ sì mú obinrin náà wá ati gbogbo àwọn eniyan rẹ̀, gẹ́gẹ́ bí ẹ ti búra fún un.
Oríṣun àwòrán, @tosinsammy_s Ileeṣẹ ọlọpaa ni apa awọn agbofinro to n ṣọ banki naa ko ka wọn, nitori bi wọn ṣe pọ wa, ti gbogbo wọn si wọle lẹẹkan naa.
Alága NURTW gba ìdájọ́ ikú 'torí ẹ̀sùn pípa ọlọ́pàá Àwọn àmì tó fi mọ̀ pé wọn ń fipá bá ọmọdébìnrin rẹ lòpọ̀ Mo fẹ́ sálọ torí ìpèníjà àkójọpọ̀ èsì ìbò gómìnà Ọyọ - Kọ̀misánà INEC l‘Ọyọ Oṣu karun un ọdun 2017 ni igbẹjọ bẹrẹ lori ọrọ naa ti ile ẹjọ fi ẹsun alabala mẹrin kan ọmọdekunrin naa Nigba ti ile ẹjọ si ṣe agbeyẹwo gbogbo ẹri, adajọ ni olujẹjọ naa jẹbi mẹta ninu ẹsun mẹrin naa, sugbọn ikọ olupẹjọ ko mu aridaju wa wipe, afẹsunkan naa fipa ba oloogbe naa lo.
Nítorí gbogbo ohun tí ó ṣẹlẹ̀ wọnyi, a dá majẹmu, a sì kọ ọ́ sílẹ̀, àwọn ìjòyè wa, ati àwọn ọmọ Lefi ati àwọn alufaa fi ọwọ́ sí i, wọ́n sì fi èdìdì dì í.
ofin nitori naa, o jawe olubori gege bi aare orile ede Naijria.
England kéde ìséde ọ̀sẹ́ mẹ́rin míràn láti dẹ́kun ìtànkálẹ̀ Covid 19 Ènìyàn méjì pàdánù ẹ̀mí wọn nínú ìjàmbá ọkọ̀ tó wáyé ní Abúlé Ẹ̀gbá, ní ìpínlẹ̀ Eko Ẹ̀ gbọ́ ọ̀rọ̀ lẹ́nu Adelé Ọba Alade Idanre ló rí ohun tó ṣẹlẹ̀ láàárín òun àti Ọba Aroloye Ta ni Wolii Olapade Agoro tó re ibi àgbà ń rè tí ayé ń pariwo rẹ̀ yìí?
“Nigba ti inu wa ba bajẹ, ti ọkan wa gba ọgbẹ, ẹ jẹ ki a fi orin iyin, orin ẹmi sinu ọkan wa dipo ti a o fi maa ṣepe tabi ro irokuro, tabi sọ nnkan mii, ki a jẹ ki orin ẹmi mimọ Ọlọrun Eledumare ki o ba aye wa lọ.
 akin àti ilésanmí sun ọ ̀ dọ fìlísíà mọ ́ jú .
Ko da bi ẹni pe iyatọ wa ninu iye ipo ti wọn fun awọn obinrin ninu iṣejọba yii.
Wọn yóo fi ìbẹ̀rù wá sọ́dọ̀ OLUWA, wọn yóo sì gba oore rẹ̀ ní ọjọ́ ìkẹyìn.
Ti o ba wa laye ni, Okwaraji ko ba ti pe ọmọ ọdun mẹrinlọgọta lati ọjọ kọkandinlogun, oṣu karun ọdun 2020 yii.
Lagos State: Ìjọba ìpínlẹ̀ Eko ní irọ́ ni àjọ EIU ń pa pé ìlú Eko ló léwu jùlọ láti gbé lágbàáyé
 ní ti ìjọba Ìbílẹ ̀ isis , a rí ìlú bíì Òkè-onigbin-in , Òwù-isis , Èdìdi , Ìjárá , Ọwá kájọlà , Ìsánlú-isis , Ọ ̀ là àti bẹ ́ ẹ ̀ bẹ ́ ẹ ̀ lọ .
Nígbà tí àwọn adẹ́tẹ̀ mẹrin náà dé ìkangun ibùdó ogun, wọ́n wọ inú àgọ́ kan lọ.
Gbogbo wọn ni ó ti yapa;tí wọn sì ti bàjẹ́,kò sí ẹnìkan tí ń ṣe rere,kò sí, bó tilẹ̀ jẹ́ ẹnìkan ṣoṣo.
 A gḅdọ gbọra wa ye, ki a bọwọ funra wa, ki a si ni ifarada funra wa ki alaafia ati aabo le jọba.
Tola Oyediran: Buhari, Makinde, Sanwo-Olu ń ṣèdárò Tola Oyediran ọmọ Obafemi Awolowo tó papòdà
O ni mo ti rọ Aarẹ Buhari ni taara lati pèsè aabo fún ẹmi."
''Ko ba ṣe wa lanfaani ti ijọba ba ṣe amulo aba ti wọn da lẹyin ipade apero to waye lasiko ijọba aarẹ Goodluck Jonathan, nitori pe awọn olori pipe lo joko se apero naa'' Oríṣun àwòrán, Getty Images Ajibola ni iru iwa ki a maṣe tẹsiwaju pẹlu iṣẹ ti ijọba kan ba ṣe ku, lo n foju han lawọn ẹka ijọba lorisirisi ni Naijiria.
sibẹsibẹ Ọlọrun fẹ́ràn àwọn baba yín tóbẹ́ẹ̀ tí ó yan ẹ̀yin arọmọdọmọ wọn, ó yàn yín láàrin gbogbo eniyan tí ó wà láyé.
Bóyá bí a ti ń sọ̀rọ̀ yìí, ninu ihò ilẹ̀ níbìkan ni ó wà tabi ibòmíràn.
Àwọn orílẹ̀èdè àjọ ECOWAS yóò máa ná owó kan nàá l'ọ́dún 2020 'A fẹ́ kúrò ní Larubawa nítorí à kò gba ẹ̀sìn' Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí kan sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
Wọn óo máa kéde ìgbàlà rẹ̀ fún àwọn ọmọ tí a kò tíì bí,pé, “OLUWA ló ṣe é.
Ọlọrun yàn mí láti jẹ́ akéde ati aposteli ati olùkọ́ni.
Déédé aago mẹ́jọ ààbọ̀ ni wọ́n gbé Zakzaky àti ìyàwó rẹ̀ wá sílé ẹjọ́, tí ètò ààbò sì gbópọn gidi.
Ó ní, “Má bẹ̀rù, nítorí mo ti rà ọ́ pada;mo ti pè ọ́ ní orúkọ rẹ, èmi ni mo ni ọ́.
Ìyekan ni Ìrèké àti Olóhùn-iyọ̀ tí ó ba àwọn Àkàrà-Òògùn lọ sí òkè-Láńgbòdó ni ijọ́sí, ọkùnrin yìí lè jó ju òkòtó lọ, bẹ́ẹ̀ ni tí ó ba ń fọn fèrè rẹ̀ kí tẹranko tènìyàn máa jó ni.
Abimeleki lọ sọ́dọ̀ Isaaki láti Gerari, òun ati Ahusati, olùdámọ̀ràn rẹ̀, ati Fikoli olórí ogun rẹ̀.
"O ni ""Ọmọ tó bá lanu gbàgà sọ̀rọ̀ sí àgbà"", bí ẹni fọwọ osi juwe ile baba rẹ ni nitori naa, ""baba ati iya rẹ lo n ba wi""."
Mo ti ri yín; èmi OLUWA ni mo sọ bẹ́ẹ̀.
Ninu atẹjade kan ti ileeṣẹ asoju orileede Amẹrika to wa ni Naijiria fisita, ni ọrọ yi wa.
Arabinrin Talatu Nafa naa tun ro ijoba lati pese awon eso gbingbin fun awon agbe ni iwonba owo ti owo won le ka.
Kete ti wọn gba aba ofin naa wọle lo ti fo esi si igbesẹ naa loju opo Twitter rẹ: Saaju, ki o to di aarẹ ile asofin agba,Saraki jẹ gomina nipinlẹ Kwara fun ọdun mejọ.
Báwo ni obìnrin ṣe ń ní ìtura ìbálòpọ̀?
Elija dáhùn pé, “Gbé ọmọ náà fún mi.
Nigba to n dahun ibeere yii, oludamọran lori ọrọ ilu ati ilẹ okeere, Olukayode Ogundamisi ni nkan arikọgbọn pọ lorisirisi ninu ere Big Brother Naija.
"Olùkọ́ fásitì méjì ń bèèrè ìbálòpọ̀ lọ́wọ́ akẹ́kọ̀ọ́ fún máákì Iléeṣẹ́ BBC fi ètò ""Aim High"" lọ́lẹ̀ fún àwọn àkàndá ẹ̀dá Ko si ọrọ naa ni ede oyinbo tabi ni ede kankan ti Yoruba ko ni ọrọ ti wọn fun un nitori pe ki agbado to daye, kini kan ni adiyẹ n jẹ."
Ẹ pọ́n àwọn ọ̀kọ̀ yín,kí ẹ gbé ihamọra irin yín wọ̀!
Wọ́n bá ka ẹ̀sùn sí Mose lẹ́sẹ̀, wọ́n ní, “Fún wa ní omi tí a óo mu.
Bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé n óo pa gbogbo orílẹ̀-èdè run,gbogbo orílẹ̀-èdè tí mo fọn yín ká sí ni n óo parun patapata,ṣugbọn n kò ní pa ẹ̀yin run.
Lara awọn eekan ilu to peju síbi adura ọjọ mẹjọ to waye nile Ajimobi to wa ni Oluyole nilu Ibadan ni Gomina Ipinlẹ Kano, Abudullahi Ganduje ati aya oloogbe, Florence Ajimobi.
Ó ní “ẹja l’ẹja íjẹ sanra”.
Àwọn ọmọ Paṣuri jẹ́ ẹgbẹfa ó lé mẹtadinlaadọta (1,247).
níwájú OLUWA, nítorí pé ó ń bọ̀ wá ṣe ìdájọ́ ayé.
Ṣugbọn obinrin keji dáhùn pé, “Rárá!
Àkókò ìyọnu yóo dé, irú èyí tí kò tíì sí rí láti ọjọ́ tí aláyé ti dáyé; ṣugbọn a óo gba gbogbo àwọn eniyan rẹ, tí a bá kọ orúkọ wọn sinu ìwé náà là.
Koda, o le ṣe nibi ti ko si ni gbangba nibi iṣẹ rẹ.
 Ó tún gba àwon onísé àdáni níyànjú láti máa sesé tí àwon òsìsé gbogbo-o-gbo ti je gàba lé lórí .
Bẹẹ naa ni ọgbẹni Wray fẹmi imoore rẹ han si ileeṣẹ ọlọpaa Dubai, bi wọn ti se gba lati fi awọn ọdaran yii ranṣẹ si ọdọ awọn, ki wọn ba le kawọ pẹyin rojọ ẹṣẹ wọn.
Oriṣiriṣi ìdí si ló máa n fà ki wọn rọ Kabiesi loye, diẹ nibẹ ni ọ̀tẹ̀, ogun, iwakiwa, ati bẹẹ bẹẹ lọ, lo maa n mu ki wọn o rọ ọba loye.
Ọga ọlọpaa naa fikun ọrọ rẹ pe awọn ọlọpaa to ṣọ ileewe ọhun kọju ija sawọn janduku naa nibi ti ọlọpaa kan ti farapa.
Ṣugbọn OLUWA yóo rẹ ìgbéraga wọn sílẹ̀, ọwọ́ wọn yóo sì rọ.
Ṣé Jeremaya ni ó sọ ọ́, tí ìwọ fi ń kọ ọ́ ni, àbí báwo?
Àṣé ọmọbìnrin yìí ti kúrò ní ilé, òun àti ẹgbọn rẹ̀, wọ́n si ti fi igbó Olódùmarè ṣe ibùgbé wọn, ìgbà tí bàbá mi sì ṣe ìbéèrè yí ni ọran náà tó yé e.
Shekau wọ ijabu lati bọ lọwọ ologun Iwa-ipa Fulani darandaran: ọlọpa fi panpẹ ọba mu eniyan meji Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Wọn ko awọn eeyan jade lẹyin ikọlu ibọn naa Ikọlu yii jẹ ọkan lara iyibọn paniyan ni ile-iwe to buru ju lati igba ti wọn ti paa eniyan mẹridinlọgbọn ni ile-iwe Connecticut kan ni ọ̀dun 2012.
Ninu rẹ leyi ta ti gbọ pe awọn kan korajọ fipaba ọmọbìnrin ẹni odun mọkandinlogun kan lopọ ti wọn si re bọ lati oke ile alaja mẹfa ni Mogadishu loṣu Kẹsan an.
#Zamfarakillings: Ààrẹ Buhari bínú sí àwọn afẹ̀họ́nú hàn Wike ti PDP ló borí ìdìbò sípò gómìnà Rivers Dokita Abraham ṣalaye pe nkan pataki to n fa bi ooru naa ṣe pọ to bẹẹ ko ṣẹyin bi eroja to yẹ ko maa daabo bo awọn eniyan lọwọ oorun ti dinku pupọ, eyi lo si fa a ti oorun fi n mu to bẹẹ.
O sọ fun BBC Yoruba pe 'measles' ti Yoruba n pe ni tita tabi igbona lo mu oun nigba naa, abajade rẹ ni pe o rọ lẹsẹ.
Oríṣun àwòrán, @mavel Idi ree ti BBC Yoruba fi wọ inu itan lọ lati se agbeyẹwo igba meje ọtọọtọ ti ẹpọn agbo Naijiria ti mi, amọ ti Ọlọrun ko jẹ ko ja.
 O tun tesiwaju pe awon ti se atunse ni awon
Dandan ni kí o dé iwájú Kesari.
Ó kó agbo-ilé Sera wá, wọ́n sì fa àwọn ọkunrin ibẹ̀ kalẹ̀ ní ọ̀kọ̀ọ̀kan, wọ́n bá mú Sabidi.
Bákan náà ní BBC Yorùbá tún bá ọmọ Nàìjíríà kan tó fi orílẹ̀-èdè Russia ṣe ibùgbé Kehinde Oluremi sọ̀rọ̀, ó sàlàyé pé Akinwumi Ambode ló sanwó ìrìnà àwọn ènìyàn ààdọ́ta láti pada sílé láàná.
Àwọn ọkunrin náà sì fún un ní èsì bíi ti iṣaaju.
Oríṣun àwòrán, IFAAS/USF Àkọlé àwòrán, Awọn onimọ sayẹnsi n se akọsilẹ ti yoo wulo lọjọ iwaju ti wọn ba n se iwadi nipa iwa ipaniyan Afojusun dida oko naa silẹ ni lati mọ bi oku se n jẹra ati ohun to n sẹlẹ si ayika ti iru oku bẹẹ ba wa.
Lara awon igbimo toro kan gbongbon nile igbimo asofin ti yoo sepade po pelu alaga ajo INEC ni: abenugan ile igbimo ohun, Dr.
Àwọn mẹ́rin t'íjọba Buhari k'etí ikún s'àṣẹ òmìnira iléẹjọ́ lórí wọn rèé Ilé ẹjọ́ kọ̀ láti tú Omoyele Soworẹ sílẹ̀ Ọwọ́ tẹ babaláwo àti adigunjalè márùń ni Imo - Olọpàá Ilé yá!
Awọn iroyin ti ẹ lee nifẹ si: Ogbologbo ijapa l'aafin Ṣọun Ẹwa Agọnyin ni aayo ounjẹ Badagry Ibikunle Amosun: Owo adani ni'ṣẹ ẹran dida, ko kan ijọba Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Ibudo idibo 3,010 ni wọn fi sita fun ètò idibo naa nipinlẹ Osun pẹlu ọlọpaa 18, 426 gẹgẹ bi ọga agba ọlọpaa, Idris Ibrahim ṣe fi sita.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, BIAFRA at 50: Ìhàlẹ̀ ológun ni Gowon ni ká kọ́kọ́ fi bẹ̀rẹ̀- Aladejẹbi Ikẹta ni pe a gbọdọ maa wa ọrẹ kun ọrẹ ni, kii se ka maa wa ọtọ kun ọta lẹnu isẹ abi ni ilu abinibi wa Itan igbe aye Bode Thomas tun kọ wa pe ninu gbogbo ohun ti a ba n se, ka fi suuru kun nitori ibinu maa n ba nkan jẹ ni O tun kọ wa pe ka maa sọ ẹnu wa, ẹnu lẹbọ tori ọrọ rere lo n fa obi lapo, ọrọ buruku si lo n fa ida lakọ.
Ninu atẹjade kan ti ileeṣẹ ologun fi sita, wọn ni Gomina Wike gbe owo banta-banta lọ fun awọn ọmọ ogun Ẹkun kẹfa ileesẹ ologun, lati da eto idibo ru fun anfaani ara a rẹ, to si tun n fi ẹsun ṣiṣe ègbè kan awọn ọga ileeṣẹ ologun.
Oríṣun àwòrán, BBNAIJA Ki ni Kaisha sọ lẹyin to kuro ni ile ẹlẹgbọn agba?
June 12: Ilé Aṣòfin rọ INEC ko kéde èsì ìbo àarẹ 1993
Aaroni fẹ́ Eliṣeba ọmọbinrin Aminadabu tíí ṣe arabinrin Naṣoni.
Elija tún dáhùn pé, “Bí mo bá jẹ́ eniyan Ọlọrun, kí iná wá láti ọ̀run, kí ó sì jó ìwọ ati àwọn aadọta ọmọ ogun rẹ!
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, End SARS, End SWAT: Ó pé mi bí SARS kò ṣe sọ mí dolówọ́- Fulani Kwajafa Toyin ni awọn o tilẹ ko firi awọn ọlọpaa pe ki wọn wa bẹ ẹ wo de bi ti wọn yoo san owo itọju rẹ, ọdun kan gbako si lo fi wa nileewosan.
Gomina naa tun so pe lati bi odun meta ti aare Muhammadu Buhari ti wa lori aleefa , omo orile ede Naijiria , ko ti i jẹ anfaani Kankan.
Mark wa ro ijoba apapo lati gbe igbese to nipon lori eto-abo orile-ede yii ati lati mu atunto ba eto oselu.
Ọbásanjọ́ tẹnumọ́ọ wípé “ipasẹ̀” Abacha ní ọjọ́ kínní àná náà ni Buhari ń tọ́ báyìí “láì wo ẹ̀yìn wò.
Yoo ya yin lẹnu iru awọn owo yii to kogba wọle lọsẹ kini, oṣu kẹjọ ọdun 2020: Bọọsi/Ọkọ ofurufu Ọlọkọ/Agbero: Wọle pẹlu ṣenji ẹ o, N1500 lọkọ, wọle pẹlu ṣenji ẹ o.
Ṣugbọn Ọlọrun sọ fún wolii Ṣemaaya, 
"Bákanna ni ìhùwàsí àwọn òṣìṣẹ́ aláàbò rẹ̀ tí wọ̀n n pè ni ""Mandela United Football Club."
38 Àti nísisìyí, lõtọ́ ni mo wí fún ọ, pé àkọsílẹ̀ àwọn ohun wọ̃nnì tí ìwọ ti kọ, èyítí o ti lọ kúrò ní ọwọ́ rẹ, wà ní fífín sí orí àwọn àwo ti Néfì;
Oríṣun àwòrán, Osun Osogbo Festival Atẹjade kan ti Tunde Muraina, tii se oludari ileesẹ naa salaye pe ajọ OSUCCIMA tun ti se agbekalẹ ajọdun miran ti wọn pe ni Community Day Cultural Festival eyi ti yoo wa fun ipese isẹ ati agbelarugẹ awọn olokoowo aladani.
Awọn aloku taya ọkọ lo fi n ṣe iṣẹ ọna tirẹ.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Ki ni yoo ṣẹlẹ to ba di pe wọn o gba esi idibo yii tọwọ tẹsẹ?
Ọlọpaaa ni awọn ti fa ọmọdekunrin naa le ẹka ijọba to n ri si itọju ọmọde lọwọ.
Oríṣun àwòrán, @Fredick_Leonard Amugbalẹgbẹ fun aarẹ lori okoowo alabọde pẹlu ọọfisi igbakeji aarẹ ati alakoso eto naa, Tola Adekunle sọ fawọn akọroyin nilu Abuja pe eto sisan owo naa yoo bẹrẹ lọsẹ yii.
Bẹ́ẹ̀ ni ẹ má jẹ́ kí ẹnikẹ́ni pè yín ní ‘Ọ̀gá,’ nítorí ọ̀gá kanṣoṣo ni ẹ ní, òun ni Mesaya.
Man U tún ṣubú dàánù bí City ti dìgbájú rù wọ́n 24 Ìgbé 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 25 Ìgbé 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Manchester City ti da ori Liverpool kọja lati bọ si ipo ikini lori afara liigi Premiership pẹlu bi wọn pegede lori Man Utd pẹlu goolu meji si ọkan.
Gomina ipinle Nasarrawa, Umaru Tanko Al-Makura ti ni eto
A kò ní gbọ́ ìró ọlọ ninu rẹ mọ́.
O ti pa majẹmu tí o bá iranṣẹ rẹ dá tì,o ti ba adé rẹ̀ jẹ́, o ti fi wọ́lẹ̀.
Oni iṣẹlẹ yii mu ki oun ko aarun HIV.
Nítorí náà ta ló lè mọ títóbi agbára rẹ̀?
Bàbà ìyàwó ló yẹ kí ọkùnrin dọ̀bálẹ̀ fún, kìí ṣe ìyàwò tó fẹ́ fẹ́ - Yemi Elebuibon Ènìyàn lásán ní ọba ilẹ̀ Yoruba tí kò bá ṣe ètùtù, ẹ má tẹ ìṣẹ̀ṣe mọ́lẹ̀ - Elebuibon Ọ̀nà tó fi le è mọ gbájúẹ̀ babaláwo - Ẹlẹ́buìbọn 'Ìbọn dún láàfin Ọ̀ọ̀ni ilé ifẹ̀ lóòtọ́, ṣùgbọ́n kò séwù' Yéèpà, òfin ìtakété síra ẹni forí ṣánpọ́n lásìkò ọdún Osun Osogbo Àwòrán àwòdamiẹnu rèé lásìkò ọdún Ọ̀ṣun Osogbo Ẹsẹ̀ kò gbèrò ní ọdún Ọ̀ṣun Òṣogbo BBC Yoruba ba Araba ilu Oṣogbo to tun jẹ onimọ nipa aṣa ati ẹsin adayeba nilẹ Yoruba, Oloye Yẹmi Ẹlẹbuibọn, sọrọ lati jẹ ka mọ iyatọ laarin awọn eeyan mẹtẹẹta naa.
Kò sì ní sí agbára fun yín láti dúró níwájú àwọn ọ̀tá yín.
Ibẹ̀ ni iná yóo ti jó yín run, idà yóo pa yín lọ bí eṣú.
Nígbà tí mo bá iyawo mi, tí òun náà jẹ́ wolii lò pọ̀, ó lóyún, ó sì bí ọmọkunrin.
Bamidele Oleyelogun ti Ile Igbimọ Aṣofin Ipinlẹ Ondo ṣalaye idi ti
Awọn ọba kan binu pe wọn fi ọwọ rọ wọn sẹyin nitori pe wọn ko pe wọn si ipade naa.
O ni: “O ye ki iwe iroyin atigbadegba Vogue to da lori ile Afrika bere lasiko yii.
OLUWA tìkalárarẹ̀ ni ààbò yín, ati idà yín,òun ní ń dáàbò bò yín, tí ó sì ń fun yín ní ìṣẹ́gun.
Egbe osise ti faake kori pe ọgbọ̀n egberun naira ni awon yoo maa gba gege bi owo osu to kere julo fun awon osise, ni eyi ti Ngige so pe awon ko ti i fenuko lori iye naa.
''Rara,rara rara,iroyin ẹlẹjẹ ni,ko si nnkankan to jọ bẹ lati ile ẹjọ nipinlẹ Rivers'' Oyekanmi salaye pe ''loni lo yẹ ki a gbe ilana kalẹ, ki ilẹ oni si to ṣu a o gbe jade'' Àkọlé àwòrán, Darudapọ waye nidibo Gomina ati awọn asoju ile asofin nipinlẹ Rivers Ọrọ yi n waye lẹyin ti ile ẹjọ paṣẹ ki Inec dawọ kika ati akojọ esi idibo ni Bauchi.
Lara awọn to farahan niwaju igbimọ naa loni ni ajọ elepo rọbi ni Naijiria, NNPC, ajọ to n mojuto idiyele owo epo rọbi ni Naijria, PPPRA, ileesẹ olusiro owo agba ni ilẹ Naijiria, ẹgbẹ awọn alagbata epo to jẹ aladani, IPMAN ati awọn alẹnulọrọ mii ni ẹka epo rọbi ni orilẹede Naijiria.
Oríṣun àwòrán, Fathiabalogun Àkọlé àwòrán, Ọ̀kan lára àwọn oṣèrè kan náà tún rèé, tó wọ aṣọ ti àwọn ènìyàn ń wári fún lọdun 2018 Oríṣun àwòrán, @bammybestowed Àkọlé àwòrán, Ẹnu kò sìn lára Bambam tó jẹ́ ọ̀kan lára àwọn olùdíjé Big Brother Naija l'ọ́dún 2018 nítorí aṣọ aláràmbarà tó wọ́ Ifilọlẹ̀ aṣọ Star Boy Gbajúgbajà olórin tàkasúfe, Wizkid lásìkò tó fọwọ́sowọ́pọ̀ pẹ̀lú Nike lati ṣe aṣọ jersey jáde.
Wọ́n fi ojúlówó wúrà ṣe ìgbátí adé mímọ́ náà, wọ́n sì kọ àkọlé kan sí ara rẹ̀ bí wọ́n ti ń kọ ọ́ sí ara òrùka èdìdì, pé, “Mímọ́ fún OLUWA.
OLUWA bá Jona ọmọ Amitai sọ̀rọ̀, ó ní, 
OLUWA sọ fún un pé, “Sọ̀kalẹ̀ lọ, kí o sì kìlọ̀ fún àwọn eniyan náà, kí wọ́n má baà rọ́ wọ ibi tí OLUWA wà láti wò ó, kí ọpọlọpọ wọn má baà parun.
Yan Jehu, ọmọ Nimṣi, ní ọba Israẹli, kí o sì yan Eliṣa, ọmọ Ṣafati, ará Abeli Mehola, ní wolii dípò ara rẹ.
Kí wọ́n ṣubú, kí wọ́n sì kú ní ilẹ̀ Kalidea,kí wọ́n gún wọn ní àgúnyọ láàrin ìgboro.
Kini yoo tẹyin igbesẹ yi bọ?
Jẹ́ kí n bọ́ sí ààrin àwọn ẹran ọ̀sìn rẹ lónìí, kí n sì ṣa gbogbo ọmọ aguntan dúdú, ati gbogbo ọmọ ewúrẹ́ ati aguntan tí ó ní dúdú tóótòòtóó lára, tí ó dàbí adíkálà, irú àwọn ẹran wọnyi ni n óo máa gbà fún iṣẹ́ tí mò ń ṣe fún ọ.
Ṣe o mọ pe elegungun lile ni ẹ, mo fẹ ki o lo egungun yii daradara Ni kete ti Omokharo wọle lo ti kan agbabọọlu Algeria kan leegun ti wọn si gbe onitọhun jade wọn ko si lee rọpo rẹ mọ nitori iye irọpo to yẹ ni ṣiṣe ni ikọ Algeria ti ṣe tan nigba naa ki o to ṣẹlẹ.
Ní ọjọ́ kẹrin a dé Miletu.
Kò sí ohun kan láti òde wá tí ó wọ inú eniyan lọ tí ó lè sọ ọ́ di aláìmọ́.
Olukuluku yóo dàbí ibi ààbò nígbà tí ẹ̀fúùfù bá ń fẹ́ati ibi ìsásí nígbà tí ìjì bá ń jàWọ́n óo dàbí odò ninu aṣálẹ̀,ati bí ìbòòji àpáta ńlá nílẹ̀ olóoru.
Eyi ni owe ti Oloye Aderẹmi Adedeji, agba ọjẹ oṣere ti gbogbo eeyan mọ si Babab Olọfa ina fi ba BBC Yoruba ṣide eto tuntun to da lori atupalẹ owe ati awọn akanlo ede Yoruba Eto yii ni BBC Yoruba gbe kalẹ ki ede Yoruba ma baa parun, ki awọn ọdọ le mọ sii nipa akoonu ede Yoruba.
''Olóde'' ni Yorùbá ń pe coronavirus, iléeṣẹ́ Yemkem ti rí òògùn rẹ̀ báyìí- Olùdásílẹ̀ Yemkem Bàbá mi fún mi ní kíndìnrín rẹ̀ láti dóòlà ẹ̀mí mi- Sam Ṣé ìwọ leè wa kẹ̀kẹ́ lórí ìgò?
Dafidi pè é kí ó wá bá òun jẹ oúnjẹ alẹ́ ọjọ́ náà, ó sì fún un ní ọtí mu yó, ṣugbọn Uraya kò lọ sí ilé rẹ̀.
Ọkunrin kan ti orukọ rẹ n jẹ Christian Tybring- Gjedde, to jẹ ọkan lara awọn ọmọ ile igbimọ aṣofin orilẹ-ede Norway lo fa Trump kalẹ fun ami ẹye naa.
Báwo ni ìtànkálẹ̀ ààrun coronavirus ṣe ya si?
amọ oun gbọ wipe wọn fi tipa ba awọn obirin miran lọpọ.
" Ọ̀pọ̀ àbùkù lo máa ń bá ilumọọka àmọ́ ọpọ ìgbéyàwó lo ń dàrú yàtọ̀ sí ti àwọn onitiata.
Iye owo iranwọ epo yii yoo kọ iru ile iwosan yii mejidinlogoji.
Tesiwaju sii,”Emi ni mo je olori odo lasiko igba naa, ni eyi ti won fagile abajade ibo naa.
 Àwọn èdè kan tún wà tí wọ ́ n ń sọ níbẹ ̀ .
“Ẹ̀yin pàápàá fi ojú rí i, Bẹnjamini arakunrin mi náà sì rí i pẹlu pé èmi gan-an ni mò ń ba yín sọ̀rọ̀.
1 1,125 Diamond Princess cruise ship 13 712 Bermuda 12 19.
Oríṣun àwòrán, Channels Ki eleyii to waye ni awọn sọja ti kọkọ di ọna to wa ni Aya ni ilu Abuja, ki awọn afẹhọnuhan naa ma ba a kọja.
Ọkọ to bọ ha sinu gọta Elomiran ti ọrọ ọhun ṣoju rẹ sọ pe ọkọ kan to bọ ha sinu gọta lo fa ṣababi ọpa epo to fọ.
O ni àwọn ọlọ́pàá maa n sọ fún àwọn ènìyàn wọ́nyìí pé ki wọ́n padà wá lẹ́yìn ti aàrùn Coronavirus ba ti kásẹ̀ nilẹ̀, tábi kí wọ́n lọ yànjú rẹ̀ nílé.
Wọ́n rí nǹkankan tí ó dàbí ahọ́n iná, tí ó pín ara rẹ̀, tí ó sì bà lé ẹnìkọ̀ọ̀kan wọn.
Bẹ́ẹ̀ gan-an ni tí ẹ bá ń lo èdè àjèjì, tí ẹ kò lo ọ̀rọ̀ tí ó yé eniyan, báwo ni eniyan yóo ṣe mọ ohun tí ẹ ń sọ?
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Afẹ́nifẹ́re kìí ṣe asọju ọmọ Yorùba, ẹgbẹ́ lásàn ní wọn Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Afẹ́nifẹ́re kìí ṣe asọju ọmọ Yorùba, ẹgbẹ́ lásàn ní wọn 23 Ògún 2019 Ọ̀rọ̀ asíwájú ilẹ̀ Yorùbá túntún ti wọ́n ṣẹ̀ṣẹ̀ yàn lánàá òdé yìí túbọ̀ n dá èdè aìyede sílẹ̀ láàrin àwọn ọmọ Yorùbá.
Ẹwẹ, nipa ti ina ti wọn ni o dede ku ni Lekki Tollgate, o ni ko sẹni to pa ina.
Ogbeni Shehu tenumo oro re pe, kosi aseyori kankan ti egbe oselu PDP ti gbese fun
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Coronavirus: Ọmọ ilẹ̀ Italy tó kó Coronavirus wọ Naijiria kò ní àrùn náà mọ́ 19 Ẹrẹ̀nà 2020 Oríṣun àwòrán, Getty Images Ayẹwo ti fi han pe ọmọ orilẹde Italy to ko arun Coronavirus wọn Naijiria ko ni arun naa mọ.
Se bi ounjẹ aarọ la n dana lọwọ ni bii deede aago mẹsan aarọ, sadede la gbọ igbe pe ogun ti wọn ilu, tawọn ọmọgun to maa n mu eeyan lẹru fun tita si ti ya de.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù El-Zakzaky: Ṣé lóòtọ́ ni ìjọba ń ná N3.
Ọba Babiloni yóo fi idà pa wọ́n, kò ní ṣàánú wọn, kò sì ní dá ẹnikẹ́ni sí.
Ṣebí Ìwé Mímọ́ ti sọ pé láti inú ìdílé Dafidi, ní Bẹtilẹhẹmu ìlú Dafidi, ni Mesaya yóo ti wá?
O ni ọmọ awọn yii lo tubọ di okun ifẹ wọn mu pẹlu alaafia ni awujọ.
”Èmi ni agbọ́tí ọba ní àkókò náà.
Òun ni yóo rí ibukun gbà lọ́dọ̀ OLUWA,tí yóo sì rí ìdáláre gbà lọ́wọ́ Ọlọrun, Olùgbàlà rẹ̀.
Ijọba Eko lo kọkọ wọgile ìsìn oru mojumọ naa, to sì ni awọn ṣe bẹẹ nitori aṣẹ ijọba apapọ lori isede ago mejila oru sí aagọ mẹrin afẹmọjumọ.
Eyi ni ero adari ile iṣe idokowo nipinlẹ Eko, Muda Yusuf nigba ti o n woye nipa bi aarẹ Muhammadu Buhari ti ṣe buwọlu adehun okowo kan naa ni Afrika.
O ro pe a ko laju, o n sọ fun wa pe ka lọ wa isẹ mii se nitori Ọba nikan lo ni owo tijọba n fun wa losoosu, o ro pe a ko mọ bo se n lọ, ẹrin rẹ pa mi nitori ko tii mọ nnkan kan.
Nítorí náà, bí ọ̀rọ̀ oúnjẹ ni yóo bá gbé arakunrin mi ṣubú, n kò ní jẹ ẹran mọ́ laelae, kí n má baà ṣe ohun tí yóo gbé arakunrin mi ṣubú.
Yatọ si eyi, ijọba tun fun ni ami ẹyẹ apapọ, CFR, lọdun 1975.
Erékùṣù ni ilẹ̀ Patimosi, ó wà láàrin omi.
Kí ó da yín lójú pé,nǹkan burúkú ni, ìgbẹ̀yìn rẹ̀ kò sì ní dùn,pé ẹ fi èmi OLUWA Ọlọrun yín sílẹ̀;ìbẹ̀rù mi kò sí ninu yín.
Kaakiri awọn orilẹ-ede agbaye bii Ghana, UK, Cameroon atawọn mii ni wọn ti maa n sami ọjọ yii.
Èrongbà wa: Èròngbà wà ní láti gbé ìgbésẹ̀ láti ṣe ǹkan ti yóò ṣe àǹfàní fún ará ìlú, ṣíṣe ìṣẹ́ fún àwọn alábara wa nípa pípèsè ìròyìn tó yàtọ̀, tó kú ojú òṣùwọ́n, tí ko sì ni ẹjańbakàn ńinú, bákan náà ni à n kọ́ àwọn ènìyàn lẹ́kọ̀ọ́, à n fí ohun tó ń lọ to wọ́n leti bákan náà ni àn dáwọn lára yá.
Ifẹsẹwọnsẹ mẹfa ọtọtọ ni wọn ti fidi rẹmi rẹmi bayii bayii ninu mọkanla ti wọn ti gba ni saa bọọlu tuntun yii.
Àwọn ipò obinrin ni ‘Ìyáálé’, eyi jẹ́ iyàwó àgbà tàbi iyàwó àkọ́fẹ́ ninú ẹbí, pàtàki ni ilé o ni iyàwó púpọ̀ ṣùgbọ́n ọkùnrin ni ‘olóri ẹbí’.
Yóo ṣe ètùtù fún Àgọ́ mímọ́ náà, ati Àgọ́ Àjọ, ati pẹpẹ náà, kí ó sì ṣe ètùtù fún àwọn alufaa pẹlu ati ìjọ eniyan náà.
Kíni ẹ mọ̀ nípa àwọn gbajúgbaja Yollywood?
O ni nigba ti oun yoo fi jade ni ọjọ Aje, 'igboro ti daru' loun lee fi we nitori iye awọn to wa nigboro lati ṣe ere idaraya.
Ewe, okan lara ami-ayo ti Japan gba wole, lo wa lati oju boolu agbesile gba ti a mo si(Penalty kick).
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù NAFDAC gbẹ́sẹ̀ kúrò lórí òfin tó fi de àwọn iléeṣẹ́ apòògùn 12 Èbibi 2018 Àkọlé àwòrán, Àṣìlò òògùn ikọ́ olómi tó ní èròjà codeine nínú máa ń fa ki kíndìrín bàjẹ́, gìri, ọpọlọ dídàrú àti orí yíyí.
Kò yẹ ki enia fi àkókò ṣòfò, nitori ẹni kò gbin nkan, kò ni ẹ̀tọ́ àti kórè ni igbà ikórè.
Nígbà tí wọn jí ní àfẹ̀mọ́júmọ́ òkú kún ilẹ̀ lọ kítikìti.
Ẹ̀sín wa kò ní bọ́ sọ́wọ́ ọ̀tá, Arsenal gbọdọ̀ na Chelsea lónìí - Lacazette Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Mama Arsenal: Màmá àgbà yìí máa ń lọ sí ìbùdó tí wọ́n ti ń wo bọ́ọ́lù láti wòran Ẹgbẹ agbabọọlu Chelsea lo kọkọ gba bọọlu wọle, lati ọwọ ọmọ ilẹ America, Christian Pulisic.
“Sọ fún Aaroni ati àwọn ọmọkunrin rẹ̀ pé, kí wọ́n máa fi tọ̀wọ̀tọ̀wọ̀ lo àwọn nǹkan mímọ́ tí àwọn eniyan Israẹli yà sọ́tọ̀ fún mi, kí wọ́n má baà ba orúkọ mímọ́ mi jẹ́.
Gege bi oro re, asiko ti awon ajegudu-jera oloselu, ti won n fi laasigbo ati modaru yii idibo ti koja lorile-ede Naijiria, ni eyi ti o so pe, akoko bee ti di ohun igbagbe, ati afiseyin teegun n fiso.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ǹjẹ́ ààrùn ni coronavirus bí?
Nanny: Èèyàn làwa náà, ẹ yé ṣe wá bí ẹranko
OLUWA àwọn ọmọ ogun ní:“Ẹ ṣa àwọn ọmọ Israẹli yòókù jọ,bí ìgbà tí eniyan bá ń ṣa èso àjàrà tókù lẹ́yìn ìkórè.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Alaafin, MC Oluomo, Ejiogbe àti ọmọ Tinubu wà lára àwọn tí yóò pèsè iṣẹ́ 774,000 Baba Suwe bọ́ lọ́wọ́ àìsàn, ó bẹ̀rẹ̀ tíátà padà Jàndùkú yabo ilé ìwòsàn ìjọba sáájú ìpàdé akọ̀ròyìn táwọn dókítà pè Ojú Shagbada Erigga rèé lẹ́yìn tó pa ọ̀rẹ́bìnrin rẹ̀ l'Akinyele ní Ibadan Ìdí tí lílọ Yúrópùù fi di èèwọ̀ fún Nàìjíríà àti àwọn orílẹ̀-èdè adúláwọ̀ míì Arúfin ni Seyi Makinde pẹ̀lú bó ṣe gbà kí wọ́n sin Ajimobi sí GRA - Amòfin O ni ọwọ tẹ Elijah lẹyin ti agbẹjọro kan kọ iwe ẹhonu si ọga ọlọpaa Ajuwon wi pe, Ojo ti parọ gba owo lọwọ awọn eeyan pupọ, to si n dibọn pe agbẹjọro ni oun .
Àwọn ọmọ Israẹli yòókù kò gbọdọ̀ súnmọ́ Àgọ́ Àjọ náà, kí wọn má baà dẹ́ṣẹ̀, kí wọn má baà kú.
O salaye pe, “igberu ba eto oro aje ohunni saa kerin odun 2017 si 1.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Shiite: Ẹ̀mí àti ara wa kọ ohun tí ìjọba ń ṣe sìwa láti 2015 Ileeṣẹ aarẹ ni ijọba ko ni kọ ohun ti yoo na oun lati sọ ọrọ awón agbesunmọmi di ohun igabgbe ni Naijiria.
Aare orile ede Naijiria Muhammadu Buhari ti kede  ipinnu rẹ lati dije fun ipo aare lẹẹkeji.
Má kọ iṣẹ́ ọwọ́ rẹ sílẹ̀.
Angẹli OLUWA ní, “Ìlú ègún ni ìlú Merosi,ẹni ègún burúkú sì ni àwọn olùgbé rẹ̀,nítorí pé wọ́n kọ̀, wọn kò wá ran OLUWA lọ́wọ́;wọn kò ran OLUWA lọ́wọ́ láti gbógun ti àwọn alágbára.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Joy Nunei dá awuyewuye silẹ̀, Buhari pinnu láti túṣu dé ìsàlẹ̀ ìkòkò lórí ìdàgbàsókè Niger Delta 1 Òkùdu 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 17 Agẹmo 2020 Oríṣun àwòrán, Others Aarẹ Muhammadu Buhari ti sọ pe gbogbo ohun ti yoo gba ni oun fun lati tuṣu de isalẹ ikoko idi ti ko fi si idagbasoke ni agbegbe Niger Delta lẹyin ẹgbẹlẹgbẹ owo ti ijọba apapọ n rọ s'agbegbe ọhun lọdọdun.
Ṣugbọn nígbà tí ẹ kọ̀ ọ́, tí ẹ kò ka ara yín yẹ fún ìyè ainipẹkun, àwa ń lọ sọ́dọ̀ àwọn tí kì í ṣe Juu.
Wọn yóo fi ọfà pa àwọn ọdọmọkunrin,wọn kò ní ṣàánú oyún inú,bẹ́ẹ̀ ni wọn kò ní ṣàánú àwọn ọmọde.
Ó ní ogoji ọmọkunrin ati ọgbọ̀n ọmọ ọmọ lọkunrin, tí wọn ń gun aadọrin kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́.
Ó ta ọpọlọpọ ọfà, ó sì tú wọn ká.
 Oríṣun àwòrán, Seyi Makinde Makinde tun salaye pe, ayipada rere ti n ba owo ti ijọba Oyo n pa wọle labẹle, o si ti di irọrun lati gba iwe aṣẹ emi ni mo nilẹ bayii, toun si tun ṣe atunṣe awọn oju popo to ti bajẹ."
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Bode George: òòtọ́ ni ìkìlọ̀ Obasanjọ ati Soyinka Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Iroyin naa, ti ko sọ ibi ti Obasanjọ n rinrin ajo lọ ṣalaye wipe, inu ọkọ ofurufu Ethiopian Airlines ni ori ti ko Obasanjọ yọ.
nítorí pé ó sanra tóbẹ́ẹ̀ tí ojú rẹ̀ yíbò,ẹ̀gbẹ́ rẹ̀ sì jẹ́ kìkì ọ̀rá.
“Ìwọ ọmọ eniyan, bí orílẹ̀-èdè kan bá ṣẹ̀ mí, tí wọ́n ṣe aiṣootọ, tí mo bá run gbogbo oúnjẹ wọn, tí mo mú kí ìyàn jà ní ilẹ̀ náà, tí mo sì run ati eniyan ati ẹranko inú rẹ̀, 
Ìfẹ́ tí mo ní sí aráàlú ló gbé mi wọlé lẹ́ẹ̀kejì - Gomina Akeredolu Gomina ipinlẹ Ondo, Oluwarotimi Akeredolu ti ni ifẹ ti oun ni si awọn araalu lo jẹ ki wọn dibo fun oun gẹgẹ bi gomina fun saa keji.
Olalekan kawe alakọbẹrẹ nile ẹkọ ti Bishop Oluwole ni Agege, to si tun lọ sile ẹkọ girama nilu Iwo.
Lórí ìmọ̀ràn Sunday Igboho, Ẹlẹbubọn ní yóò dára kí Yorùbá padà sí àmúlò èròjà ìbílẹ̀ fún ààbò Ọkan lara awọn agbaagba ilẹ Yoruba Ifayemi Ẹlẹbubọn sọ pe, imọran gidi ni Sunday Adeyemo ti ọpọ mọ si Sunday Igboho gbekalẹ lasiko to ba BBC Yoruba sọrọ, lori ọna lati gbogun ti awọn Fulani to n da eto aabo wa ru lawọn ipinlẹ Yoruba.
Eyi mu ko lo anfaani ẹbẹ rẹ si awọn ọmọ ẹgbẹ oṣelu Republican ti inu n bi, lasiko idibo gbogboogbo.
O ni  idanwo lati ọdọ Ọlọrun ni awon
Ilé ìwòsàn gba àwọn aláìsàn ibà ẹ̀fọn 403 tí ó pọ̀ jù lọ ní ọjọ́ 22 osù Agẹmọ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Food Festival: Ìbọn pa èèyàn mẹ́ta níbí ayẹyẹ Oúnjẹ ní Carlifornia 29 Agẹmo 2019 Oríṣun àwòrán, EPA Eeyan mẹta lo ti gbẹmi mi gẹgẹ bi agbebọn kan ṣe ṣina ibọn bolẹ nibi ayẹyẹ ọdun ounjẹ kan to n waye niluu Carlifornia.
Awọn miran ti lẹ fi awọran bi awọn eniyan ṣe pejọ si papakọ BRT ti awọn eniyan ti fẹ wọ ọkọ ni agbegbe Ikorodu, ti wọn si tun fihan pe ko si yiyago fun ara ẹni laaarin awọn eniyan to n tiraka lati wọ ọkọ.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ọmọ ọdún méjìlá ni mo ti ń ṣe bàálù, ọkọ̀, ilé àti ọkọ̀ ojú omi - Ọdọ́mọdé ‘Engineer’ Ajé ò!
OLUWA sọ fún Joṣua pé, “Má ṣe bẹ̀rù wọn, nítorí pé ní ìwòyí ọ̀la, òkú wọn ni n óo fi lé Israẹli lọ́wọ́.
Àgbèrè ò fi wọ́n sílẹ̀ nígbà kan
Ìgbà tí iwin náà rí èyí, ó yípadà ó bẹ̀rẹ̀ síí le Ayédèré-ẹ̀dá lọ èmi náà tún ń sá gba ọ̀nà tèmi lọ.
Nítorí àwọn nǹkan tí yóo wà fún ìgbà díẹ̀ ni àwọn nǹkan tí a lè fi ojú rí.
tete  mu  idagbasoke ba awujo ni agbaye.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù DR Congo Park: Olùdarí ìbùdó náà ní wọ́n ń fi fọ́tò yíyà sín olùtọ́jú wọn jẹ ni 22 Ìgbé 2019 Oríṣun àwòrán, Ranger Mathieu Shamavu Inaki nla meji to wa ni ibudo igbafẹ nla kan, Virunga National Park, ni orilẹede DR Congo, lo fẹran lati maa ya aworan adaya, ti wọn yoo si duro bii eeyan ninu fọto ti awọn olugbafẹ to ba wa sibẹ ya.
”Abdulallahi so pe “ o seni laaanu pe ,lasiko to ye ki awon eniyan maa bu omi ogbon re mu, ni iku mu un lo, ki Olorun te e si afefe ire.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ẹ̀yin obìnrin, ẹ jáde du ipò ààrẹ láti gbàjọba lẹ́yìn Buhari - Amina Muhammed Sina Jesu ní orúkọ́ mi báyìí, ń kò jẹ́ Shina Rambo mọ́ - Adigunjalè tẹ́lẹ̀ kìlọ̀ Agbẹjọ́rò wọ́ ìjọba lọ sílé ẹjọ́ pé kó yọ kéú kúrò lára owó Náírà Mọ̀ síi nípa Shina Rambo tó pàdé Jesu lọ́gbà ẹ̀wọn lẹ́yìn tó ti jalè Abẹ́rẹ́ àjẹsára tó dájú fún ìdènà àrùn Coronavirus ti jáde Wàhálà míì dé!
Aare ana fun orile ede Naijiria
Ìyìn ni fún OLUWA tí ó sì fa èmi iranṣẹ rẹ̀ sẹ́yìn kúrò ninu ṣíṣe ibi.
 O wa ro awon omo ipinle naa lati tu yaya, tu yaya sita ,
Ohun tí ó jẹ́ kí n tẹ̀lé e ni pé mo fẹ́ẹ́ wò ó dáadáa bóyá ibi tí ẹ̀fúùfù ti fẹ́ ẹ wá kò jìnnà, nípa bẹ́ẹ̀ mo sì lè rí àmì láti fi hàn mí pé síbẹ̀síbẹ̀ mo lè yọ nínú ìhámọ́ mi.
Ẹ̀mí ń kọ́ àwa ati ẹ̀yin papọ̀ ní ìṣọ̀kan pẹlu Kristi kí á lè di ibùgbé Ọlọrun.
Xenophophia: Lizzy Anjorin, Yinka Ayefele, Mercy Aigbe sọ̀rọ̀ ìtùnú
Josẹfu dojúbo òkú baba rẹ̀ lójú, ó sọkún, ó sì fi ẹnu kò ó lẹ́nu.
Awọn mejeeji sọ pe ọrẹ timọtimọ ni awọn, ti ko si si ọrọ ifẹ laarin awọn.
Joke Silva ni àdari àkọkọ fún abúlé òṣèré (film Village) ti ile ẹkọ Fasiti Kwara (KWASU) dá sílẹ̀ lọdún 2014.
“Ṣé nítòsí nìkan ni mo ti jẹ́ Ọlọrun ni, èmi kì í ṣe Ọlọrun ọ̀nà jíjìn?
Abrahamu ya abo ọmọ aguntan meje ninu agbo rẹ̀ sọ́tọ̀.
Ohun gbogbo ni wọn fi tẹ ẹ lọrun tọkan oun gan naa si yọ mọ wọn lai ronu ipo ti o wa pẹlu ibinujẹ.
Jakọbu ní kí Josẹfu búra fún òun, Josẹfu sì búra fún un.
Uganda: Tata ni ounjẹ awọn ara Uganda, eleyii ti wọn ti yii lata.
Ọpọlọpọ ninu àwọn Juu ni wọ́n wá láti Jerusalẹmu sọ́dọ̀ Mata ati Maria láti tù wọ́n ninu nítorí ikú arakunrin wọn.
àwọn darandaran ará Gerari bá àwọn tí wọn ń da ẹran Isaaki jà, wọ́n wí pé, “Àwa ni a ni omi kànga yìí.
A gbọ pe awọn oluwọde naa n jo sọọbu, taya, ti wọn si di gbogbo ọna gboogi nilu Akure pa.
tipẹ sibe awon orule rẹ ko jo rara.
Natani bá lọ sí ilé rẹ̀.
O kórìíra mi; nítorí pé o pa àlọ́ fún àwọn ará ìlú mi, o kò sì sọ ìtumọ̀ rẹ̀ fún mi.
A ṣẹṣẹ kuro labẹ wahala ajakalẹ arun corona pẹlu awọn igbele gbogbo.
Ọ̀pọ̀ ìgbà ni mò ń gbààwẹ̀.
Oríṣun àwòrán, @Lance commons Àkọlé àwòrán, Wọn ṣẹṣẹ n laju ni abule Tarahumara ti Daiz ti jade ni Ni oju opo Twitter wọn, Ijọba ilẹ Mexico to ba obinrin naa yọ sọ wi pe obinrin naa ti setan lati lọ si ile-iwe girama lati pari ẹkọ rẹ.
Ọgọọrọ ẹmi ati dukia lo ti ba isekupani ati ado oloro ti ikọ Boko Haram fi n sekupa awọn ọmọ Naijiria lẹkun iwọ Ariwa orilẹede Naijiria.
Awon oluko ile-eko giga fafiti ijoba orile-ede Kenya bere iyanse-lodi gbogbogbo, lori iwonba owo ti ijoba n san fun won, iyanse-lodi yii bere leyin osu kan, ti won fopin si ifehonu-han to waye lorile-ede naa.
Lai si ìbáwí tàbi ijiyà fún ẹ̀ṣẹ̀, ẹlẹ́sẹ̀ tàbi ọ̀daràn kò ni yi padà.
Igbesẹ rẹ lati rọpo Oshiomole ti bẹrẹ lati igba ti Oshiomole ti n koju wahala idaduro ninu ẹgbẹ nibẹrẹ ọdun 2020.
Nígbà tí Jesu mọ̀ bẹ́ẹ̀, ó bá kúrò níbẹ̀.
láti inú ẹ̀yà Dani: Asareli, ọmọ Jerohamu.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù D.
Ko tan sibẹ, amiẹyẹ olukọni ere bọọlu to pegede ju lọkunrin bọ si ọwọ Kennedy Boboye ti ẹgbẹ agbabọọlu Plateau United nigbati Ann Chiejinne gba ami ẹyẹ fun olukọni agbaọọlu to pegede ju lobirin.
Gege bi iko omo ogun naa se so, lori ero ayelujara won,”A mu awon agbesunmomi ohun lasiko iwode wa lojo Aiku(Sunday), ti  a si gba orisirisi ohun elo ija ogun bi: ibon, ogun ibile ati awon nkan miiran lolokan-o-jokan.
APÁ KÌÍNÍ Yorùbá ni kíkí fún gbogbo àsìkò ọjọ́, ìṣẹ̀lẹ̀ àti èto.
 Ifigagbaga n la ni ifesewonse ohun yoo je fun iko agbaboolu orile-ede mejeeji, leyin ti a fojusona lati gba ifesewonse akoko ninu ni Russia.
 Lati odun 1959 ni awon Castro ti n tuko orile ede yii titi di asiko yii.
OLUWA yóo sì fi òjò ibukun sí orí èso tí ẹ gbìn sinu oko, nǹkan ọ̀gbìn yín yóo sì so lọpọlọpọ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Toyin Ibietan: Àlòkù táyà ọkọ̀ ló mú mi rí nǹkan ṣe lásìkò ìgbélé COVID-19 Ẹkọ ti itan igbe aye Eji Gbadero kọ wa: Ẹkọ akọkọ kọ wa pe ti aye ba yẹ wa tan, ka ma ṣe hu iwa ibajẹ.
Nigeria: Kiniun pa olusọ ọgba ẹranko
Ẹ̀yin amòfin ati ẹ̀yin Farisi, ẹ̀yin aláṣehàn wọnyi!
" Àkọlé àwòrán, Tinubu ni ko sọrọ mọ lori yiyọ Ambọde nipo Lara awọn to wa nibi ipade naa ni Tinubu, aṣiwaju ẹgbẹ oṣelu APC lẹkun aringbungbun ipinlẹ Eko, Ọmọba Tajudeen Olusi, Gomina Ambode, Igbakeji rẹ, Adebule, olori ile aṣofin ipinlẹ Eko Mudashiru Obasa, ati igbakeji rẹ, Wasiu Esinlokun.
Nigba ti BBC ba ọkan lara awọn to ni ile itaja naa sọrọ o fi idi rẹ mulẹ pe lootọ ni wọn fọ ṣọọbu awọn lasiko laasigbo naa ni South Africa, amọṣa awọn ti pada si ẹnu owo bayii.
Awọn ọmọ rẹ ni ọrẹ rẹ timọ-timọ."
Máa pa wọ́n lọ ní ọwọ́ ọ̀tún, ati ní ọwọ́ òsì, níbikíbi tí ó bá sá ti kọjú sí.
A tilẹ̀ rí àwọn òmìrán ọmọ Anaki níbẹ̀, bíi tata ni a rí níwájú wọn.
Lars Lagerback ni olukọni fun Super eagles nigbati Diego Maradona jẹ olukọni ikọ Argentina.
Ní àkókò ìjọba Jehoiakimu ni Nebukadinesari, ọba Babiloni gbógun ti Jerusalẹmu, Jehoiakimu sì di iranṣẹ rẹ̀ fún ọdún mẹta.
Ó fihàn pé alágbára ni òun níwájú àwọn ọ̀tá rẹ̀.
O ṣalaye pe ẹbi Majek Fashek wo awọn nnkan to rọ mọ eto aabo lo jẹ ki wọn gbe igbesẹ lati sin in silu oyinbo.
Lábẹ́ ọ̀pẹ kan, tí wọ́n sọ ní ọ̀pẹ Debora, tí ó wà láàrin Rama ati Bẹtẹli ní agbègbè olókè ti Efuraimu ní í máa ń jókòó sí, ibẹ̀ ni àwọn ọmọ Israẹli tií máa ń lọ bá a fún ìdájọ́.
Oríṣun àwòrán, Omoyele Sowore Ènìyàn 26,000 ni àìsàn jẹjẹrẹ ń pa lóòjọ́ kíni ọ̀nà àbáyọ sí àìsàn Lassa Fever?
O safihan awon eri igberu ti o ba eto oja owo ori idokowo, ni odun 2017, eyi ti o je US$12,228 milionu pelu amugberu 138.
5 143685 Orilẹede Ethiopia 1747 1.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ogun Flood: Wákàtí méjìdínlógún ni òjò fi rọ̀ èyí tó mú ẹ̀kún omi lọ́wọ́ 8 Ògún 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 6 Agẹmo 2020 Ọwọja omiyale, agbara ya sọọbu to n waye nipinlẹ Ogun, ti mu ki ijọba ipinlẹ naa kede pe oun yoo wo ile kile to ba wa loju agbara ati ojusan omi lati dena ijamba ẹkun omi.
- Kemi Afolabi Ẹbí Buhari lásán ni Mamman Daura kò nípò òṣèlú kankan Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Mama Rainbow: Toyin Adegbola àti Razak Olayiwola ní ìyá rere àti àwòkọ́ṣe gidi ní O ni igbagbọ awọ́n ni pe ọmọ to ba kawe rẹ daadaa ko kan ni wulo fun ara rẹ nikan bikoṣe ko lọwọ si idagbasoke ipinlẹ rẹ.
Ìdí tí mo fi fẹ́ di Gómìnà Kogi - Dino Melaye Kí ló mú ọmọ Nàìjíríà mẹ́sàn án forí la ikú nínú ìkọlù Libya?
6 % gbogbo àwọn ènìyan tí ó wá sí ilé ìwòsàn dùbúlẹ ̀ .
"Ipinlẹ Eko ti bẹrẹ igbesẹ lati mu ayipada nla jade wa lori eyi.
Èdè Akurẹ àti Ibadan ni wọ́n fi fà mí léti pé ẹni re kìí 'se òṣèlú - Seyi Makinde Ìyá tó lu ọmọ ọdún mẹ́rin pa l‘Akurẹ bọ́ sọ́wọ́ ọlọ́pàá A padà san owó ìtanràn fáwọn ajínigbé kí wọ́n to fi àwọn mẹ́tẹ̀ẹ̀ta sílẹ̀- Ẹbí Spaghetti, mílíìkì, Chivita àti Àǹkàrá sọ Rabiu dèrò ẹ̀wọn ni Eko Oríṣun àwòrán, @others Àkọlé àwòrán, Awọn eniyan Kogi a dibo gomina loṣu kọkanla ọdun Ọjọ kẹrindinlogun, oṣu kọkanla, ọdun 2019 ni eto idibo si ipo gomina ni ipinlẹ Kogi yoo waye.
Ìlérí Fayemi lati san owó oṣù oṣìṣẹ́ l'Ekiti: ẹnu lásán kò lè ṣe é
Àwọn tí wọ́n jọ ń jẹun bà bẹ̀rẹ̀ sí sọ láàrin ara wọn pé, “Ta ni eléyìí tí ó ń dárí ẹ̀ṣẹ̀ ji eniyan?
Eyi lo n fa ibeere ati ọpọlọpọ esi ti awọn ọmọ Naijiria n fi sita lori ẹrọ ayelujara lati igba ti ọrọ yii ti ti ẹnu ẹgbẹ oṣelu APC jade si Atiku Abubakar.
Ọpọlọpọ awọn eniyan lo bá wọn dunnú ti orukọ ọmọkunrin jòjòló naa pọ loriṣiiriṣii.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ojú mi ti rí lọ́pọ̀ lọpọ̀, àmọ́ mo dúpẹ́ pé mo ti pé ọdún márùn ún lórí oyé- Ooni Lori iyanṣẹlodi ẹgbẹ ASUU, Ọọni fi aridaju han pe yoo wa sopin laipẹ tori awọn lọba lọba ti da si i.
 O bere ise ere itage ni sise pelu ile ise Wale Adenuga ninu ere oloso-ose Super story.
 Àkànṣe owó oṣù lá wa olùkọ́ ń fẹ́ yàtọ̀ sí tàwọn òṣìṣẹ́ ìjọba míì - NUT A gbẹ́sẹ̀ lé ilé kan tó jẹ́ ti Bukola Saraki, torí àpò ìjọba ló ti mú owó sanwó ilẹ̀ - Ilé aṣòfin Irọ́ ni Cameron pa mọ́ mi lórí ọ̀rọ̀ àwọn akẹ́ẹ̀kọ́ Chibok- Jonathan figbe ta Bẹẹ ba gbagbe, awọn oludije mẹrindinlọgbọn lo bẹrẹ eto BB Naija fun tọdun yii, ti wọn pe akọle rẹ ni 'Pepper Dem', ti oludije mọkanlelogun si ti ja kulẹ lasiko kan tabi omiran."
Ninu ọrọ rẹ to sọ fawọn oniroyin, alaga ẹgbẹ ASUU nileẹkọ fasiti Ilọrin, UNILORIN, ọmọwe Usman Raheem ni 'wọn ti sọ ẹgbẹ ASUU di ẹgbẹ awọn alagbara kan.
Gege bi o tun se so pe, lara iko omo ogun olote Boko Haram ti o fe salo ni ado oloro naa tun kolu.
Oríṣun àwòrán, Others Laarin ago mọkanla owurọ si aago kan ọsan ọjọ Iṣẹgun ni iṣẹlẹ yii ṣẹlẹ si Okochu gẹgẹ bi ọrẹ rẹ Lucy ṣe sọ.
Lẹyin ọpọlọpọ iṣẹlẹ to ti waye, wọn da awọn ẹlẹwọn kan silẹ pẹlu ileri lati mu ayipada ba aye wọn.
Ààfá mẹ́ta réwọ̀n hé nípa ṣíṣe ìrànlọ́wọ́ òjijì fún obìnrin kan pẹ́lù 36 mílíọ̀nù náìrà Wo àwọn krìstíẹ́nì tó n wẹ̀ nínú odò tó ní yìnyín láti ṣàjọyọ̀ ìrìbọmi Jesu Ìgbéyàwó ọkùnrin s'ọ́kùnrin, obìnrin s'óbìnrin ti di òfin ní Northern Ireland Ẹ má mu gaarí mọ́ nítorí ìbà Lassa- Dókítà Boniface Arabinrin Modupe Kolawole ni àwọn aṣọna to wa lẹ́nu iṣẹ́ lọ́jọ́ náà àti igbakeji oludari lo lọ sibẹ ṣùgbọ́n oludasilẹ ijọ ko dasi ọ̀rọ̀ náà.
O ni lẹyin ti wọn ba gbe faili ẹsun ọkọọkan wọn yẹ wo tan, awọn to ba lẹjọ lati jẹ ninu wọn yoo kọri si ile ẹjọ lọjọ Aje.
Olatunji ni òun sọ fún pé, kò jẹ ki awon ṣe àyípadà pátápátá bá ìtàn ayé rẹ tó bá fẹ́, tó sì gba sí òun lẹ́nu, ó ní bẹ́ẹ̀ lo bọ aṣọ ìgbéraga silẹ, tó sì ń ṣiṣẹ́ náà.
Saaju la ti kọkọ mu iroyin wa fun yin nipa ikede ti Olori naa gbe soju opo Twitter rẹ, nibi to ti pariwo pe ẹmi oun si wa ninu ewu tori pe oun kọ Alaafin.
Ó sì mọ odi sí wọn.
Oríṣun àwòrán, Premium Times - Evelyn Okakwu A gbọ pè aisan to n ba a finra ni ṣe pẹlu ifarapa egungun ẹyin to si ti mu u farahan nile ẹjọ lọpọ igba lori ibusun alaisan.
“Igbimo ohun tun tenumo mumu igberu ba igbe aye Alafia ati eto aabo laarin awon ekun ajo  ECOWAS, nipase sise amulo ofin ati ilana egbe naa,” “Bakan naa, apapo egbe naa tun tenumo mumu igberu ba ibasepo ti o wa laarin ajo mejeeji(ECOWAS ati  EU).
Èyí ló mú kí Adajọ Olusegun Odusola pé àkíyèsí ilé ẹjọ́ pé, tí àwọn Ẹlẹ́rìí kò bá pè dáadáa lọ́nà, olórí ẹni afesunkan ni yóò ṣe ẹlẹ́rìí ara rẹ.
Ohun ti Ajani sọ si gbogbo awọn ẹsun tawọn eeyan fi n kan Amọtẹkun ni pe, wọn n lo ẹsun ẹlẹyamẹya lati fi doju ija kọ Amọtẹkun lọna a ti bawọn jẹ.
Gomina Sanwo-Olu kede ibuwolu yii ninu ipade pẹlu awọn olori onisowo ati onise Aladani keekeeke (MSMEs) ni Lagos Corporate Assembly to jẹ́ ile okowo ijọba, ni Alausa .
Solomoni ọba ati gbogbo ìjọ Israẹli dúró níwájú àpótí majẹmu, wọ́n ń fi ọpọlọpọ aguntan ati ọpọlọpọ mààlúù tí kò níye rúbọ.
Ẹgbẹ osisẹ fasiti naa n beere fun owo isuna to gbooro fun ile ẹkọ giga ati sisan owo ajẹmọnu awọn olukọ fasiti.
Balogun ọ̀rún náà bá mú un lọ sọ́dọ̀ ọ̀gágun.
O salaye pe,aye wa lati jiroro lori owo yiya, amo, ele ori re ko gbodo ju iko meji si meta ninu ida ogorun, ni eyi ti o fi kun oro naa pe, ipo ile-ise ile-kiko tun satileyin fun sisan owo naa.
Ikọlu awọn alakatakiti ẹsin Islam ti wọn n pe ni Al Qaeda ati Islamic State Group ti n wọpọ sii ni Mali bayii.
Ebun Adegboruwa, SAN Agbẹjọrọ agba ni Ebun Adegboruwa, ṣugbọn ko to de ipo naa, o ṣiṣẹ miran bii iṣẹ agegẹdu ni inu igbo ipinlẹ Ondo, Edo ati Delta.
Iṣẹlẹ awọn agbebọn ti wọn a kan deede maa pa awọn ero lorilẹ-ede Amerika ti n gba ẹbọ bayiiẸ̀sùn apànìyàn ni wọ́n fi kan Robert Bowers'.
Ẹfọ Àkọlé àwòrán, Akwụkwọ nri na-acha ndụ ndụ dịka ụgụ na ndị ọzọ na-enyekwa aka Awọn ẹfọ to ba jẹ alawọ ewe ni awọn eroja ara bii folate, eleyii to n ran obinrin lọwọ ni ati tete loyun, ti o si ma n jẹ ki atọ ọkunrin duro ni ara obinrin.
Aare  Buhari, wa rọ awon adari  ile-ise ijọba ati ile-ise aladaani lati fọwọsowọpọ
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Femi Falana: Ojú Elzakzaky kan ti fọ́ nítorí àìsí ìtójú tó 22 Sẹ́rẹ́ 2019 Oríṣun àwòrán, Google Àkọlé àwòrán, Agbẹjọ́rọ̀ fún Elzakzaky, Femi Falana ní ọdún 2015 tí wọn ti wà látìmọ́lé ni wọ́n kò tíì ní ìtọ́jú tó péye.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Mo fẹ́ gbé ògo ìdílé ìyá àti bàbá mi ga pẹ̀lú iṣẹ́ Mọkálìíkì' Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
O sọ pe ko dara to lati kan ni àlá lai sisẹ to tọ.
"Nínú ọ̀rọ̀ rẹ̀ láti dúpẹ fún ìwàláàyè rẹ̀ ninú ọdún túntun, òṣèré náà kọọ́ pé, "" ẹbùn ni ìwàláàyè wá jẹ́ láti ọdọ̀ adáni wáyé' Zainab Habib tí ilẹ̀ Saudi Arabia pa irọ́ mọ́ pé o gbé cocaine tí gba sabuké NYSC!"
” Olórí àwọn ẹ̀ṣọ́ ọba bá fún un ní owó, oúnjẹ, ati ẹ̀bùn, ó ní kí ó máa lọ.
O mẹnuba ominira lati sọrọ ti ara ilu yẹ ko ni ni Naijiria bayii.
Evra ni oun ko fi tabuku wọn, nigba ti oun sọ pe awọn agbabọọlu Arsenal n gbabọọlu bi ọmọ ọwọ, o ni otitọ loun n sọ.
Ilé ẹjọ́ kọ̀ láti tú Omoyele Soworẹ sílẹ̀ Ọwọ́ tẹ babaláwo àti adigunjalè márùń ni Imo - Olọpàá Ilé yá!
O ni oun gbagbọ pe ko le si ninu ofin South Africa lati maa fiya jẹ awọn ajeji ni ilu wọn rara.
Kínni ìtàkùn ayélujára 5G nííṣe gan na pẹ̀lú ààrùn coronavirus?
ni: Ahmed Musa, Paul Onuachu, Leon Balogun, Troost Ekong, Kenneth Omeruo,
Èwo nínú àwọn amóhùnmáwòrán yìí lẹ rántí?
Dino to n ṣoju ẹkun idibo Iwọ Oorun ipinlẹ Kogi nile igbimọ aṣofin agba sọ oko ọrọ si Omo Agege to jẹ igbakeji adari ile aṣofin agba.
Bí Mose ti gbé ejò sókè ní aṣálẹ̀, bẹ́ẹ̀ gan-an ni a óo gbé Ọmọ-Eniyan sókè, 
Awọn wo lo n sun un?
Gbogbo ẹran ati àwọn tí wọ́n mọ́ ati àwọn tí wọn kò mọ́, àwọn ẹyẹ ati gbogbo ohun tí ń fàyà fà lórí ilẹ̀, 
Ko si ohun to jọ yiyọ ẹnikẹni nipo.
Ni Afikun, wọn ti n ko awọn eeyan ti ọrọ kan bi awọn oṣiṣẹ ni iboji oku naa si igbele fun ọjọ mẹrinla, lẹyin ti wọn yoo ṣe ayẹwo to yẹ fun wọn.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Justice For Uwaila: Ọlọ́pàá ìpínlẹ̀ Edo fojú àwọn aṣebi tó pa Uwaila Omozuwa hàn 27 Ògún 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 28 Ògún 2020 Oríṣun àwòrán, Twitter Àkọlé àwòrán, Ọjọru, ọjọ kẹtadinlọgbọn, oṣu Karùn-ún, ọdun 2020 ni àwọn kan fipá bá ọmọbìnrin ẹni ọdún 22 lopọ̀ nínú sọ́ọ́sì.
Ajo naa so pe iwe ti awon ri gba lati odo awon egbe oselu ti won fẹ foruko sile jẹ mẹ́rìnlélógóje.
Ni ọdun 1990, ajọ WHO woye pe ida mejidinlogoji ninu ọgọrun awọn eeyan lo lanfani si ohun elo imọtoto, eyi si ti di ida marundinlọgbọn lọdun 2015.
Kò sí ibìkan tí wọ́n dásí ní gbogbo orí rẹ̀.
Ninu ifọrọwerọ pẹlu BBC News Yoruba, Iba Gani Adams funrarẹ ṣalaye pe, awọn ọyọmesi gangan lo fun oun laṣẹ lati yan igbimọ oloye ni kete ti oun ba de ori oye.
Mo ni igbagbo pupo lori awon agbaboolu wa, bee si ni ti a ba sowopo ti a si ni afojusun kan naa, a gba iko yii de bi giga.
Àrùn Ẹ̀yi di ilọ́po mẹ́ta jákèjádò àgbáyé lọ́dún 2019 - UN Ẹ̀yin Onínúfùfù ẹ wo ìdí tí ìbínú fi dára púpọ̀ Ta ló gé orí ọkùnrin mẹ́ta ní Lekki?
Bobrisky dárò pé EFCC gbé Mompha, ọ̀dọ́mọdé olówó tó ń lo aago ₦20m Mò ń dókòòwò láti pín ọrọ̀ mi yíká Nàíjíríà kí àdínkù leè bá ìṣẹ́ - Dangote Ìdí tí abiyamọ yìí kò fi jàǹfàní ètò ìlera ọ̀fẹ́ kí gómínà Makinde tó fún un ní N50,000 Ẹ̀kún omi mú ọ̀pọ̀ ẹ̀mí lọ l‘Eko torí adágún odò tí wọn ṣí ní Abẹokuta Oríṣun àwòrán, @ibcityannouncer O tẹsiwaju pe, ọpọ awọn oṣiṣẹ OYRTMA lo farapa nibi iṣẹlẹ ọhun.
Àgbò náà kò lágbára láti dúró níwájú rẹ̀.
Gbogbo àwọn tí wọ́n bẹ̀rù ọ̀rọ̀ Ọlọrun rọ̀gbà yí mi ká nítorí aiṣootọ àwọn tí wọ́n ti oko ẹrú dé.
 wọn a má a dín iye ọjọ ́ tí àwọn ènìyàn kò fi níí lè lọ sí ibi-iṣẹ ́ kù sí bíi ìdajì ọjọ ́ bí a bá wòó lápapọ ̀ .
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Saa bọọlu tuntun bẹrẹ Man City tun gba ife ẹyẹ FA, bẹẹ ni wọn ti Carabao Cup, awọn kan tiẹ sọ pe ife mẹrin ni wọn gba lẹyin ti wọn ṣina iya fun Chelsea ninu ifẹsẹwọnsẹ Community Shield ti saa bọọlu to lọ.
Dokita Musa tun sọ pe, awọn arun ajogunba lo maa ṣaa ba jẹ ki oyun bajẹ lara obinrin.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ta ni agbábọ́ọ̀lù tó fakọyọ jù lọ ní Afcon 2019?
N óo ko yín jáde láàrin àwọn orílẹ̀-èdè, n óo ko yín jọ láti gbogbo ilẹ̀ tí mo ti fi tipátipá fọ́n yín ká sí, pẹlu ọwọ́ líle, ati ibinu.
3 Ṣe sùúrù, ọmọ mi, nítorí ó jẹ́ ọgbọ́n ní inú mi, àti pé kò tọ́nà pé kí o túmọ̀ ní àkókò yìí.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù EndSARS Protest Update: Ọ̀gá àgbà ọlọ́pàá àti ọ̀gá àjọ ọlọ́pàá ń késí àwọn òṣìṣẹ́ wọn 21 Ọ̀wàrà 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 31 Ọ̀wàrà 2020 Oríṣun àwòrán, Nigerian Police Force Ọga agba awọn ọlọpaa, Muhammed Adamu ti ni ki awọn ọlọpaa maa daabo bo ara wọn lodi si ikọlu.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: 'Buns ni ọmọ mi jẹ tán ní ṣọ́ọ̀ṣì, ló bá di àwátì' Ibodè tí a tì ló fa ọ̀wọ́ngógó owó ọjà - Ìjọba Naijiria Ẹ wo ìpínlẹ̀ táwọn gómìnà tẹ́lẹ̀ àti igbákejì wọn ń gba dúkìá ìfẹ̀yìntì tabua Mẹ̀kúnnù 80,000 l'Ọṣun ti j'ànfàaní ètò ìlera láìsan kọ́bọ̀ - Oyetola Iná mọ̀nàmọ́ná lọ fún wákàtí 24 ní Ghana, lariwo bá sọ!
“OLUWA Ọlọrun wa bá fi Ogu, ọba Baṣani, lé wa lọ́wọ́, ati gbogbo àwọn eniyan rẹ̀.
Jesu jáde kúrò níbẹ̀, ó lọ sí ìlú rẹ̀.
gege bi adari ijoba tuntun lorile ede naa.
Babalọla ni ayafi ti a ba gbe igbesẹ akin lati mu ayipada ba ofin ọdun 1999 naa, se ni ọps aayan wa lati se aseyọri yoo maa ja si asan.
Ipade naa waye lati jiroro lori ọna abayọ si eto aabo to dẹnukọlẹ lorilẹede Naijiria, lasiko ti awọn ọdọ ṣe ifẹhọnuhan tako ifiyajẹni lati ọwọ awọn ọlọpaa.
Presidency: Aarẹ Buhari kẹdun ikú àwọn eniyan to kagbako Boko Haram
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Obìnrin tó lágbára láti yan ìyàwó míì fún ọkọ 'Abẹ́ dídá f'óbìnrin ṣì wọ́pọ̀ ní Cameroon' 'Awọn obinrin nilo ajọ iranwọ fun oṣelu' Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ṣe wahala wá ti ọkọ bá kọ̀ láti fún aya tó ti kọ̀ silẹ lára ogún rẹ?
Oríṣun àwòrán, Reuters Àkọlé àwòrán, Mané gbá bọ́ọ̀lù náà wọlé ní ìsẹ́jú mẹ́rìnlélógún sí ìgbà tí wọ́n bẹ̀rẹ̀ eré Ṣaaju ifẹsẹwọnsẹ idije Premier League laarin Liverpool ati Manchester United nirọlẹ ọjọ Aiku, akọnimọọgba Liverpool Jurgen Klopp ni oun fẹ ki awọn agbabọọlu ikọ Liverpool fi'binu gba bọọlu pẹlu Man U ni.
Bí àwọn ọmọ Nàíjíríà kan se ń tàbùkù ìjọba lórí [bó se gbé Dino, ni àwọn mìíràn ń kan sáárá sí ìjọba pé bẹ́ẹ̀ ni ọmọkùnrin ń se.
Ipinlẹ Eko ni Gbọ̀gan olúlu ètò ọ̀rọ̀ ajé tí o si ní ìgbòkegbodo ọkọ̀ to pọ̀ju lọ ní orílẹ̀-èdè Naijiria Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
OLUWA àwọn ọmọ ogun ní, “N óo rán ègún náà lọ sí ilé àwọn olè ati sí ilé àwọn tí wọn ń búra èké ní orúkọ mi.
Ní ìrìnàjò yìí, a o dé ìlú kan ní ibi tí àwọn ẹranko ń gbé tí ó jẹ ìlú wọn gan-an, ibi tí ìwọ ó ti máa rí to àádọ́ta àgbọ́nrín fún oúnjẹ àárọ̀, ọgọ́ta ìmàdo fún oùnjẹ ọsán, àti ẹ̀ẹ́dẹ́gbẹ̀ta kọ̀lọ̀kọ̀lọ̀ fún ounjẹ alẹ́.
Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí EndSars Protest: A kò lọwọ́ sí ìwé ìpẹ̀jọ́ tó tako ìdásílẹ̀ ìgbìmò ìwádìí aṣemáṣe ikọ̀ SARS4 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Seyi Makinde: Gbogbo ìgbà ni ìyá mi máa ń sọ fún mi pé díẹ̀ ló kù kí àwa méjèjì kú lọ́jọ́ tó bí mi4 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Obasanjo: Mo lòdì sí ìgbé ayé tí Gani Adams ń gbé látẹ̀yìnwá, ṣùgbọ́n n kò bá a jà - Obasanjo3 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Fídíò, EndSARS: Olatunde Abolarinwa London Tailor ní òun á ṣe baba fún mi, kò tilẹ̀ dúró ṣe bàbá àwọn ọmọ tirẹ̀ tóríi ìwà Ọlọ́pàá Mopol5 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Ìbejì wù mí láti kékeré ṣùgbọ́n mí ò mọ̀ pé ìbẹfà lorí kọ mọ́ mi- Ifeoma Ìyá Ìbẹfà Ṣé ìrànwọ̀ ni Kamala, ìgbákejì tí Biden yàn yóò jẹ́ fún un tàbí ìpalára?
’ Kí ẹ dáhùn pé, ‘Oluwa fẹ́ lò ó ni, lẹsẹkẹsẹ tí ó bá ti lò ó tán yóo dá a pada sibẹ.
Wo àwọn òṣìṣẹ́ kólẹ̀-kódọ̀tí tó ń fi ẹ̀mí wọn wéwu kí Abuja leè mọ́ tónítóní Mo ti bẹ̀rẹ̀ sí ń bá àwọn tí a jọ díje nínú ìdìbó abẹ́lé sọ̀rọ̀ kí àláàfíà léè jọba - Akeredolu Wo àwọn nkan tó yẹ́ kí o mọ̀ nípa 'Awawa Boys', ọ̀kan lára ẹgbẹ́ òkùnkùn tó n dá Eko rú Adarí àjọ NDDC, Pondei ṣetán láti sọ ohun tó mọ̀ nípa ìwàdíì tó bá ti gbádùn- NDDC Ọpọlọpọ iṣẹlẹ yii waye ni awọn gbegede ariya orin kikọ ọlọdọọdun.
  Ọ̀pọ̀lọpọ̀ àwọn ère ọ̀hún ni wọ́n ti máa bẹ̀rẹ̀ sí yòòrò nígbàtí ènìà bá rí wọn nítorípé yìnyín ò kí npẹ́ yòòrò tí òtútù bá káwọ́ nlẹ̀ díẹ̀ àbí tí òrùn bá ràn síi.
 Oríṣun àwòrán, @NGRpresident Àkọlé àwòrán, Bill Gates ati Aliko Dangote rọ Buhari lati dokowo ninu araalu Ni awọn orilẹede towo to nwọle fun wọn ti gbe pẹẹli, ọjọ ori ọpọ awọn eeyan ibẹ ki wọn to ku, maa nwọ ọdun marundinlọgọrin, lawọn orilẹede ti owo to nwọle fun wọn ko ti gbewọn to bẹẹ, ọjọ ori ọpọ wọn ki wọn to ku maa nwọ ọdun mejidinlaadọrin sugbọn lorilẹede Naijiria, ọdun mẹtalelaadọta lọpọ ọmọ Naijiria ndagbere faye.
Ogun ebi ni Nàìjíríà ń bá fínra lọ́wọ́, ogun coronavirus kò gbọdọ̀ kún un-Oluwo Ṣé ẹ̀yin mọ idí ti Abass Akande fi n jẹ Obesere?
Idije àṣekágbá Russia 2018 Croatia ati France ni wọn jọ waako lati mọ ẹni ti yoo gba ife ẹyẹ lọ.
O tun salaye pe ki eto yi ba lee kẹsẹjari, ni CBM ti se
Orukọ Ijẹwuru to fi silẹ si lo di manigbagbe titi di oni yii, tawọn eeyan fi n ranti rẹ.
Mo gbìyànjú láti ṣe àlàyé àwọn kan láti dáhùn ìbéèrè tí ẹnìkan bi mí lórí Twitter.
Ekiti Election: Àwòrán bí ètò ìdìbò gómìnà ṣe lọ ní Ekiti
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Immaculate Okochu: Arẹwà orí ìpolówóo Cold Stone Creamery ṣàgbàkò ikú nínú ìjámbá ọkọ̀ nígbèéyàwó ku díẹ̀ 13 Ògún 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 14 Ògún 2020 Oríṣun àwòrán, @i_amloveday Ọkọ afẹsọna ọmọbinrin ti ọkọ akẹ́rù tẹ̀ pa nipinlẹ Eko lọjọ kọkanla, oṣu Kẹjọ, Imaaculate Okochu, ti sọrọ lori iku rẹ.
Àwọn obìrin àsìkò kì í wọ́n lọ́dọ̀ rẹ̀.
Akojọpọ re e lori igba mẹrin ti ikọ ọlọpaa ti tu SARS ka lorilẹede Naijiria.
Ìṣẹ́ tó mu ọmọ Nàíjíríà lómi ti gba oorun lójú mi - Osinbajo Ètò sogúndogójì 'MMM' tún ti padà dé, rọ́bọ́ọ̀tì ni yóò maa ṣàkóso Ta ni awàdà rẹ̀ wúu yín lórí jù ní Yollywood?
Isẹlẹ náà waye lẹyin wakati diẹ ti Ọ̀gá àwọn ọmọ ogun oríilẹ̀ orílẹ̀èdè Nàìjíríà, Ọ̀gágun Tukur Buratai ní kí àwọn ènìyàn apá ìlà oòrùn àríwá padà sí ilé wọn.
Gígùn aṣọ títa kọ̀ọ̀kan jẹ́ igbọnwọ mejidinlọgbọn, ìbú rẹ̀ sì jẹ́ igbọnwọ mẹrin, gbogbo wọn rí bákan náà.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Hepatitis: A kò leè kóo nípa dídìmọ́ ara ẹni Awọn ti wọn n ṣe atilẹyin fun awọn obinrin meji naa ti bẹrẹ iwe ipẹjọ fun ajọ to n ri si ẹtọ awọn ọmọ ilẹ South Africa lati ri si iṣẹlẹ naa.
Ileeṣẹ ọlọpaa ti kọkọ doola awọn mẹta ti wọn jigbe lọsẹ to lọ.
Ṣugbọn nítorí àwọn àyànfẹ́ tí Ọlọrun yàn, ó dín àkókò rẹ̀ kù.
Ṣugbọn ọrọ náà gbà àlàyé Àlàyé akọkọ ti Kayode Ajulo ṣé ní pé ''ẹnikẹni tó bá fẹ ṣé iṣẹ ní Nàìjíríà tí o sí parí ilé ẹkọ gíga yunifásítì tàbí ilé ìwé gbogbo n'isẹ (poly) gbọdọ sìn ìlú fún ọdún kàn.
Iku Marie-Amélie waye lọjọ ti ijọba orileede France ṣe agbejade ofin tuntun lati koju iwa ipa laarin lọkọ laya.
Aarẹ ni ijọba ''da ẹgbẹ ọmọogun yii silẹ lati daabo bo apa iwọ oorun ariwa orilẹede Naijiria lọwọ awọn janduku ti wọn da ilu ru kiri, ati pe iṣẹ wọn ni lati daabo bo orilẹede Naijiria lapaapọ.
Ṣugbọn ìmọ́lẹ̀ wà ní gbogbo ibi tí àwọn ọmọ Israẹli ń gbé.
Èèyàn mọ́kànléláádọta ló wá láti ìpínlẹ̀ Eko nínú èèyàn 72 tó kó ààrùn covid-19 lọ́jọ́ Ajé 'Ṣọ́ọ́ṣì ni mọ ti ń bọ̀ kí n tó pàdé àwọn sójà tó fi abẹ gẹ irun fún mi' Ti ẹ o ba gbagbe, ọjọ kẹrinla oṣu keji ọdun 2013 ni ẹgbẹ musulumi nipinlẹ Osun gbe ijọba ipinlẹ naa lọ si ileẹjọ pe ki ijọba faye gbawọn akẹkọọ to jẹ musulumi lati maa wọ hijab nile iwe.
O níláti kó gbogbo wúrà ati fadaka tí o bá rí ní gbogbo agbègbè Babiloni, ati ọrẹ àtinúwá tí àwọn ọmọ Israẹli ati àwọn alufaa bá fínnúfẹ́dọ̀ dá jọ fún Tẹmpili Ọlọrun wọn ní Jerusalẹmu.
O ni oun le jẹ ẹni to ni lọwọ sugbọn nkan maa n tete dun oun lọkan.
Nítorí pé ogun OLUWA ni ò ń jà, o kò sì hùwà ibi kan ní gbogbo ọjọ́ ayé rẹ.
Àdúrà ni mo nílò kìí ṣowó - Pa Kasumu Wo ohun tó 'sun Sẹ́nétọ̀ Dino Melaye dé ìdí tíátà Bóo bá yin báńgà l'Ondo lásìkò ọdún, kélé yóò gbé ọ!
Bàálú náà yẹ ko kó èrò lọ sí Beni to jẹ kilomita ààdọtadinirinwo tó n lọ sí ìhà àríwá Goma.
Ẹjẹ riru: Obinrin to ba ni aisan ẹjẹ riru naa le ni oyun iju Awọn obinrin to ba ni aisan PCOS: Aisan to l'agbara ni PolyCystic Ovarian Syndrome (PCOS) fun awọn obinrin kan Awọn ami oyun iju: Bi oyun iju naa ba ṣe tobi to, iye to jẹ, ati ibi to wa ninu ile ọmọ, ni yoo sọ ami ti obinrin yoo ri.
Nínú ọdún tuntun, ènìyàn 1,031 míràn ló tún ṣẹ̀ṣẹ̀ lùgbàdì ààrùn Covid-19 ní Nàìjíria Oríṣun àwòrán, NCDC Bi a ti ṣe n wọ inu ọdun tuntun loni, Ajọ to n gbogun ti ajakalẹ aarun lorilẹ-ede Naijiria, NCDC ti kede pe eeyan 1,031 miran ti kun iye awọn to ti ni aarun COVID-19 ni Naijiria.
Adebimpe Adebiyi to jẹ ọga ẹka ile iwosan ileeṣẹ ilera sọ pe anfaani nla re fun Naijiria lati fikun agbara ipese abẹrẹ ajẹsara wọn.
O ni won ko ni fi kun ojo ti won ti da naa,o wa ni”o ku ojo marundinlogundinlẹgbẹ̀wàá, ti eto idibo yoo waye lorile ede yii’’.
Àyà bẹ̀rẹ̀ sí pá a, ó bẹ̀rẹ̀ sí dààmú.
Atiku fìdí rẹmi nílé ẹjọ́ tó ga jùlọ, kò sọ́rọ̀ mọ́ lórí ìbò ààrẹ Oríṣun àwòrán, @atiku Ile ẹjọ to ga julọ lorilẹede yii ti tun fi idi ibo to gbe aarẹ Muhammadu Buhari mulẹ gẹgẹ bii aarẹ ti ilu dibo yan lọjọ Kẹtalelogun osu Keji ọdun 2019.
Ọmọ Yorùbá mẹ́wàá tó jẹ́ àmúlùúdùn ní Amẹ́ríkà àti Yúróòpù Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Filipi sọ fún un pé, “Bí o bá gbàgbọ́ tọkàntọkàn, ẹ̀tọ́ ni.
"Ọlọ́pàá méjì dèrò ọ̀run nínú ìjàmbá ọkọ̀ l'Akure lẹ́yìn tí wọ́n kúrò níbi tí Akeredolu ti gba ìwé-ẹ̀ri moyege Ẹ wo èrò bìbà níbi ìwọ́de #EndSARS ní ìlú Ibadan Mo fẹ́ ìdájọ́ òdodo lórí ikú tó pa ọmọ mi- Baba ọmọ ti SARS pa Àwọn aṣòfín ní ìpínlẹ̀ Edo ti yọ Abẹnugan Ilé, Francis Okiye bí jìgá Wọ́n kò pa ẹnikẹ́ni sí ààfin Ṣọun Ogbomosọ, òkú tí àwọn ọdọ́ gbé wa ni ọlọ́pàá wọ́ jáde- Agbẹnusọ Ṣọ̀un ""Alaafia ti pada si aafin Ṣọun Ogbomọṣọ, koda aafin ni gbogbo wa sun mọju."
Níkeyín, orí rè gbé e ko àgbà dáadáa kan tí ó làá lóye pé erú tí baba rè fún lógún n gan ni kí ó mú, nípa báyìí gbogbo dúkìá bàbá rè yóò padà di tirè nítorí pé eni tí ó ni erú ni ó ni gbogbo ohun ìní erú; eni tó lerú ló lerù.
Nítorí náà, àwọn ọmọ Israẹli bọ́ gbogbo ohun ọ̀ṣọ́ wọn kúrò, ní òkè Horebu.
  Gẹ́gẹ́ bí ojúlówó ọmọ Oòduà, mo wá ibìkan tó tẹjú pẹrẹsẹ, mo wá òkúta kan, mo ṣa èkùọ́ mélòókan, mo pa wọ́n, mo dà wọ́n sẹ́nu, mo jẹnu wọ̀mù-wọ̀mù, mo gbé e mì kàló.
O gun iyawo rẹ lọbẹ ki o to jọwọ ara rẹ fun awọn ọlọpaa.
Ewe, odun 1987 nile ejo lorile-ede Kenya ti dajo iku gbeyin, bee si ni lọdun meji seyin ni aare Uhuru Kenyatta ropo ejo iku ogunlogo awon elewon si ewon egbere.
89bn lọ́wọ́ ìjọba’ Ènìyàn márùn-ún kú nínú bàlúù ogun tó já ni Damasak Ilé ẹjọ́ fagilé ìpè Dino láti wá kó Ọlọ́pàá kúrò nílé rẹ̀ Ilé ẹjọ́ fagilé ìpè Dino láti wá kó Ọlọ́pàá kúrò nílé rẹ̀ Fabiyi fi kun un wi pe gbogbo ẹṣẹ ti Toyin ṣẹ oun ni oun ti dariji, ki Toyin naa ṣe bakan naa, ki ohun gbogbo si pada si ipo laarin wọn.
 jìnádù bínú nítorí pé ó sọ pé Ògúndélé sin òun ní owó ní àárí àwùjọ .
"Oluwo ti ìlú Iwó kìí ṣe ẹgbẹ́ Àtaọjà Osogbo - Alaafin ìlú Ọ̀yọ́ Ẹ̀yin ọlọ́pàá, ẹnikẹ́ni tó bá fi ọwọ́ kàn yín, ẹ dojú ìjà kọ ọ́ padà- Ọ̀gá Àgbá Ọlọ́pàá Wo awọn iroyin manigbagbe to waye ni ọsẹ yii Wo ojú àwọn òṣèré yìí láì lo ""Make-up"" orí ìtàgé bó ṣe rí gẹ́lẹ́ Nibayii, kele ofin ti gbe awọn aṣoju ikọ ""Operation Burst"" ti wọn fi ẹsun kan."
male gbagbe fun ikọ ti o ba lọ.
"Latin lórí àìsàn Ogun Majek Wo àwọn ọmọbìnrin tó mu ìtọ̀ ara wọn nítorí òùngbẹ aṣálẹ̀ Sahara 'Dokita ilé ìwòsàn ló gba ẹsẹ̀ lọ́wọ́ mi' Ìtàn Manigbagbe: Àwọn àjakalẹ-àrun to ti wáyé rí ṣáájú CoronavirusToyin ni ""Ìrírí tuntun ni ìgbéyàwó jẹ fún mi, tó sì ti yí igbe ayé mi padà sí rere."
Wọn si fi si ihamọ fun bi i wakati mejidinlaadọta lai fi ẹsun kankan kan-an.
Aare ni:”oni ni ayeye ijoba tiwa-n-tiwa je ikokandinlogun iru re ati ajodun odun keta lori ijoba yii.
"Ko si nkan to kan ijọba pẹlu ohun to nlọ lori ikanni ayelujara (social media); yala ni isiinyi tabi ni ọjọ iwaju.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Yankari Reserve: Erin pa ènìyàn méjì ní ìlú Bajama 13 Agẹmo 2018 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 14 Agẹmo 2018 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, O ní erin náà lọ sí Gwartanbali níbi ti àwọn ará ìlú ti pé bòó tí wọn si ń ya fọto pẹ̀lú rẹ̀.
Awọn obinrin naa kopa ti wọn pe ara wọn ni obinrin Rwanda ti wọn si n saabo fun awọn obinrin.
Awọn kan lara wọn ti jẹ to miliọnu marun Naira.
Ọ̀rẹ́ tí kò jẹ́ ròyìn ẹni tí o sọ̀rọ̀ ọ̀rẹ́ òun ní rere àfi ẹni  tí o bú u, irú àwọn báwọ̀n-ọnnì ni adíjàálẹ̀-takété, ọ̀bàyéjẹ́ ènìyàn.
Adajo agba, Hussein Baba- Yusuf wa sun ejo naa si ojo kẹ́rìndínlógún , osu karun un.
Big Brother Naija 2020 housemates: Ọlọ́lá jù lọ Terry Waya ni Bàbá Terseer Kiddwaya tó ń kópa nínú BBNaija 2020 Oríṣun àwòrán, Others Ọmọ Terry Waya to jẹ ọkan lara olowo to gbajumọ lorilẹ-ede Naijiria n kopa ninu Big Brother Naija 2020 ti ọtẹ yii ti wọn pe akọle rẹ ni 'Lockdown Season'.
 Bakan naa, nigba ta kan si gbajugbaja olorin ẹmi kan nilu Ibadan, Yinka Ayefele, oun naa ni jinni jinni iku Ajimobi si wa lara oun, oun ko si tii setan lati sọrọ."
Tọpẹ ni ojoojumọ ni oun maa n gba imisi orin lati ọdọ Ọlọrun, to ba si jẹ pe bẹẹ ni oun se n se awo orin jade ni, ilẹ yoo ti kun.
OLUWA óo dáàbò bò ọ́ lọ́wọ́ gbogbo ibi,yóo pa ọ́ mọ́.
O kò mọ̀ pé kí o lè ronupiwada ni gbogbo oore tí Ọlọrun ń ṣe, 
pajawiri lati gba awon eniyan sile lasiko isele ile riri.
Toyin Ibietan: Àlòkù táyà ọkọ̀ ló mú mi rí nǹkan ṣe lásìkò ìgbélé COVID-19
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Africa Eye: Wo ìtàn ìyá kan ìyá kan àtàwọn olè ajọ́mọgbé tó n ta ọmọ ní Kenya Fun awọn ọdun diẹ sẹyin, igbesẹ loriṣiriṣi ti n waye lati mu ayipada ba eto igbimọ agbaọjẹ oludibo alaṣẹ (Electoral System) ṣugbọn awọn to gbe lẹyin ilana naa ni oun gan lo n mu ki eto idibo aarẹ lorilẹede Amẹrika o rinlẹ kaakiri orilẹede naa, ati wi pe awọn to n dibo tabi dije ti mọ eyi ṣaaju.
Bí Ismail ṣe ja fitafita tó pé oun kò ni ǹkan ṣe pẹ̀lú ohun ti wọ́n ri lóri fọọnu oun tó àti pé ọ̀rk oun ló kọ síbẹ̀ àwọn ọlọpàá aṣọbode ní àwọn kò le gbà ki o wọle si ilẹ̀ Amẹrika.
Gẹgẹ bii iroyin ṣe sọ, Ọgbẹni Ajayi Shuaib to pe ara rẹ ni ẹni ọrọ n dun labẹ ẹgbẹ oṣelu PDP ni wọn pe o pe ẹjọ naa.
O pada sọ ero rẹ lori kẹkẹ wiwa di iṣẹ ṣiṣe lẹyin to pada wa sile.
Lílò: Ìkìlọ̀ pé ó dára kí a yára gbọ́ ṣùgbọ́n kí a lọ́ra láti fèsì; nínú ísọ̀rọ̀ púpọ̀ ju bí ó ti yẹ ni a lè ká ọ̀rọ̀ mọ ‘ni lẹ́nu.
O sisọ loju rẹ pe awọn oyinbo ti nkọ ede Yoruba bayi ki wọn lee pada wa kọ awọn ọmọ wa.
Hauwa Mohammed, oṣiṣẹ ajọ aṣeranwọ Red cross Oríṣun àwòrán, Getty Images Oṣiṣẹ agbẹbi ni Hauwa Mohammed pẹlu ọkan ninu awọn ileewosan ajọ aṣeranwọ alagbelebu pupa, Red cross, ICRC ti wọn n ṣiṣẹ iranwọ lawọn agbegbe ti wahala ti n waye ni ẹkun ila oorun ariwa orilẹede Naijiria.
Opebi Link Bridge, Ikeja Ijọba ibilẹ Ikeja 27.
Oṣu karun-un, ọdun 2019 ni fidio kan jade sori ayelujra, to si ṣafihan bi Sẹnetọ Abbo ṣe n ko igbaju, igbamu fun obinrin kan ni ṣọọbu ti wọn ti n ta awọn eroja ibalopọ nilu Abuja.
Oun ati iyawo rẹ ni wọn jijọ n rinrin ajo lasiko ti awọn ajinigbe naa ṣọṣẹ.
Aarẹ ni ìgbesẹ yìí ko ṣẹyin ọna láti ri dáju pé àwọn agbẹ àti awọn oníṣẹ oojọ ko padanu ọna ati jẹ wọn, bákan náà ni ijọba ti ṣepade pọ pẹlu awon to n ri si eto ọ̀rọ̀ aje naijiria ti wọn si ti pese awọn imọran yìí.
Buhari: Ọ̀págun ìjìjàgbara fún South Africa ni Winnie
Akéde bá kígbe sókè, ó kéde pé, “Ọba ní kí á pàṣẹ fun yín, gbogbo eniyan, ẹ̀yin orílẹ̀, ati oniruuru èdè 
Se iru eeyan bayi laa mọ ba gbe, ta maa wo pe ọba ree, ti ko si isinmi fun ẹni kankan ta jọ wa ladugbo.
OLUWA bá sọ fún mi pé, “Ìwọ ọmọ eniyan, àwọn ọmọ Israẹli ni àwọn egungun wọnyi.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, È gbọ òun ti ojú awọn ara ipinle Ogun rí lọwọ ìṣẹlẹ omiyale Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Olukọ ile iwe alakọbẹrẹ ti Women Society nile iwe giga fasiti UNILAG niluu Eko, Charity Madumere ni wọn ti da duro bayii pé ko lọ rọọkun nile na lori ẹsun pe awakọ ile iwe naa, Abiodun Matthew ba akẹkọọ ọmọ mẹrin tage lọna aitọ.
Bakan naa ni Jon Snow ninu fiimu ‘Game of Thrones’ naa ba awọn abamiẹda ẹranko ja bii ‘Dragon’.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ẹ kọ́ nípa ohun tí Yorùbá ń pè ní Àrígiṣẹ́gi Gẹgẹ bi ọrọ ti ile iṣẹ ogun fi sita, wọn awọn ni aṣa ati ilana ti awọn maa n tẹle lati ṣe isinku awọn akọgun to ba ku lara awọn nitori naa awọn ko yọ nkankan ṣe.
Adúmáadán ni mí; ọmọ pé síbẹ̀!
Iṣẹlẹ naa waye ni ile orẹbinrin rẹ naa to wa ni agbegbe Inikpi, ni Makurdi to jẹ olu ilu ipinlẹ Benue.
 Àwọn àtúnbọ ̀ tán díẹ ̀ díẹ ̀ lè wáyé ní ojú ibi abẹ ́ rẹ ́ náà .
O ti kọja osu meji bayi tawọn akẹkọọ ni orile-edeto le ni aadọwa kio ti lọ sile iwe mọ.
Bakan naa lo ni wọn ti paṣẹ fun awọn agbofinro lati ri daju pe ofin konile-o-gbele naa mulẹ.
Gun control in Nigeria: Wo ọ̀nà márùn ún tí o lè gbà dábòbò ara rẹ lọ́wọ́ ìjàmbá!
”Gege bi oludije dupo gomina egbe naa, Gboyega Oyetola fi idunnu re han, bee si ni O dupe pupo lowo aare Buhari fun atileyin re, O si tun fi kun oro re pe, isakoso ijoba egbe oselu APC ti se daradara nipinle Osun ati ni ijoba apapo, ti o si tun setan lati tesiwaju tepa-mose si ninu aseyori ohun.
(Nítorí pé ọlọ̀tẹ̀ kúkú ni wọ́n), ṣugbọn wọn yóo mọ̀ pé Wolii kan ti wà láàrin wọn.
Ọjọ Abamẹta to tẹle ni Joe ku.
Johanu fèsì pé, “Kò sí ẹni tí ó lè rí ohunkohun gbà àfi ohun tí Ọlọrun bá fún un.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Kano-Niger rail line: PDP ní àìmèyí tó kàn n'ìgbèsẹ̀ ìjọba láti ná $1.
Ninu idibo naa ni ti Biden gbegba oroke pẹlu ibo awọn igbimọ agbaọjẹ oludibo alaṣẹ ni ilu Amẹrika, Electoral college nibi to ti ni ibo 306 ti Trump si ni 232.
milionu meji eniyan ti won je anfaani eto yii.
"Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Mo ti kó kúrò nílé Olu Jacobs rí lẹ́ẹ̀mejì- Joke Silva ""Mo fẹ́ pa ara mi torí ojú àbùkù tí wọn ń fi wò mí pé mo fi iṣẹ́ abẹ bímọ"" Èmi àti Saheed kìí ṣe ọmọdé, a ti jọ ṣe Sinimá papọ̀, èyí túmọ̀ sí pé ìjà ti parí - Fathia Balogun Àrà méèrírí!"
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Idije Premier League Ọdun kọkandinlọgbọn ree ti ikọ Liverpool ti gba ife ẹyẹ ere Ilẹ Gẹẹsi kẹyin, ipo keji ni wọn si wa bayii lori tabili idije Premier League nigba ti Manchester City wa loke tente.
Àwọn ọmọ ogun Filistini ni wọ́n kọ́ kọlu àwọn ọmọ ogun Israẹli, nígbà tí àwọn mejeeji gbógun pàdé ara wọn, tí wọ́n sì jà fitafita; àwọn ọmọ ogun Filistini ṣẹgun Israẹli, wọ́n sì pa nǹkan bíi ẹgbaaji (4,000) ninu wọn.
Lọwọlọwọ, apapọ awọn to ti ni aarun naa ti pe 72,140, eeyan 65,722 ti ri iwosan, 1,190 si ti ku.
ẹni tí ó fẹ́ rúbọ yóo tọ́jú ìdámẹ́wàá òṣùnwọ̀n efa ìyẹ̀fun kíkúnná tí a fi idamẹrin òṣùnwọ̀n hini òróró kan pò fún ẹbọ ohun jíjẹ; 
Eré ìtàgé tí ó ní àkójọpọ̀ orin abínibí, ijó àti ewì ni a mọ Thangyat mọ́.
Fífẹ́ tí ó fẹ́ràn àwọn eniyan rẹ̀ tó wà láyé yìí, ó fẹ́ràn wọn dé òpin.
Ọkan ninu atupalẹ eto iṣuna naa ti awọn eeyan n pariwo bayii lori ayelujara ni ti owo to le ni biliọnu mẹwaa naira ti Aarẹ Buhari ni wọn fẹ fi tun àwọn wáyà ina ati inu ile Aso Rock se ni Abuja.
‘Ayédèrú ìròyìn ni pé EFCC yabo ilé mi’ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Woli Kasali: Angẹli mi ni orékelẹ́wà Dọlapo Awoṣika Wọn fikun wi pe, o yẹ ki ijọba o mu eto aabo ni okunkundun ni, ki wọn si pese ohun to tọ, to yẹ fun aabo awọn ara ilu.
Aare  Muhammadu Buhari ti gboriyin fun iwa akin ti oloogbe Tunde Idiagbon hu lasiko ti  o je igbakeji aarẹ nigba ti o je ogagun ati adari  orile ede yii.
Egbe oselu APC ni apapo ibo òjìlénígba dín mẹ́sàn án le  ẹ̀gbẹ̀rún okòólénígba dín
14 Àti pé nígbànáà ni ìwọ yíò mọ̀, tàbí nípa èyí ni ìwọ yíò mọ̀, gbogbo ohun èyíkéyìí tí ìwọ bá fẹ́ lati ọ̀dọ̀ mi, èyítí ó níí ṣe pẹ̀lú awọn ohun ti òdodo, nínú ìgbàgbọ́ pẹ̀lú ìgbàgbọ́ nínú mi pé ìwọ yíò rí gbà.
Àwọn ọmọ Israẹli bá kúrò níbẹ̀, gbogbo wọ́n sì pada sí ilẹ̀ wọn, olukuluku pada lọ sí ìlú rẹ̀, sí ààrin ẹbí rẹ̀.
Wo àgbáríjọpọ̀ àwọn Arugbá Ọ̀ṣun Òṣogbo látìgbà tó ti bẹ̀rẹ̀ Buhari júwe ọ̀nà ilé fún Obono-Obla lórí ẹ̀ṣùn ayédèrú ìwé ẹ̀rí Facebook fi kọ́kọ́rọ́ ti àwọn ojú òpó ayédèrú ìròyìn léde Yorùbá àti Igbo Ayọ̀ abara bíńtín!
Bakan naa, awon asofin tun ro aare Muhammadu Buhari lati san gbogbo eto ti o ba to si oloogbe Moshood Abiola, gege bi aare teleri ati adari awon iko omo-ologun orile ede Naijria(GCFR), ti o fi mo igbakeji re naa, Baba Gana Kingibe lai ku iye kankan sile.
Ninu atẹjade ti ẹgbẹ agbaboolu rẹ Bold FC fi lede wọn ni Promise jade laye lẹyin ti o ti lo Ookanlelọgbọn lori eepẹ.
0 430 Orilẹede Cambodia 0 0.
"Lara awọn ẹdun ọkan wọn ti wọn kọ sara awọn akọle naa ni pe "" A n beere fun ohun ti a sisẹ fun, Inu fifo la fi n sisẹ, ti a ko si mọ igba ti ounjẹ miran yoo wa, Dokita ti ebi n wa jẹ ewu fun awujọ, ẹtọ wa ni owo osu wa, kii se ẹbun, ẹ jọwọ, ẹ san owo osu ti ẹ jẹ wa, ki lo de tile iwosan tiwa yatọ , ati bẹẹ bẹẹ lọ."
 Ó ti ṣiṣẹ ́ lábẹ ́ ìjọba àti aládàáni rí , tí ó sì jẹ ́ kọmíṣánà àkọ ́ kọ ́ fún iṣẹ ́ àti ilégbèé ní Ìpínlẹ ̀ Èkó.
Nítorí bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé àwọn nǹkan tí à ń pè ní oriṣa wà, ìbáà ṣe ní ọ̀run tabi ní ayé, gẹ́gẹ́ bí oriṣa ti pọ̀, tí “àwọn oluwa” tún pọ̀, 
Iya to bimi ko fẹki n sere tiata Afeez Ọwọ, nigba to n salaye irinajo rẹ laye sọ pe iya to bi oun ko fi taratara gba pe ki oun maa ṣe ere tiata.
Samuẹli bá sọ fún un pé, “Bí idà rẹ ti sọ ọpọlọpọ ìyá di aláìlọ́mọ, bẹ́ẹ̀ ni ìyá tìrẹ náà yóo di aláìlọ́mọ láàrin àwọn obinrin.
Ijọba apapọ lorile-ede Naijiria ti kede pe igbokegbodo ọkọ laarin ipinlẹ kan si omiran le bẹrẹ pada lati ọjọ Kini oṣu Keje.
Wo àwọn báńkì tó wà lẹ́yìn àwọn olówó èlé bí MMM Ẹ̀yin òṣìṣẹ́ elétò ìlera, ẹ padà sẹ́nu iṣẹ́- JOHESU Bí PDP ṣe na APC lálùbami ní Edo, bẹ́ẹ̀ ni yóò ṣẹlẹ̀ ní Ondo- PDP Wo ìdí tí ètò ìdìbò gómìnà ìpínlẹ̀ Edo ṣe lọ ní ìrọwọ́-rọsẹ̀ Wo àwọn ìlúmọ̀ọ́ká tó ṣe ìgbéyàwó ní ọdún 2020 yìí Ẹwọ́n ọdún méjìlá ni wọ́n fún àwọn Ṣója mẹ́rin tó pa ìyá àti ọmọ méjì ní Cameroon Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí 6:25 Fídíò, Akomolede Yoruba: Ìtàn ọ̀rẹ́ tó fi ògùn gba ọkọ ọ̀rẹ́ rẹ̀ nílùú òyìnbó rèé, Duration 6,2515 Owewe 2020 6:18 Fídíò, Akomolede: Bolaji Faleke ni Olùkọ́ tó ń kọ́ wa ní àṣà oge ṣiṣe lórí BBC Yorùbá, Duration 6,181 Owewe 2020 Èyí tí a wò jùlọ 5:03 Fídíò, Omolola Arohunmolase Welder: Mo ti fí iṣẹ́ 'Welder' gbayì láwùjọ, tó mo fi tọ́ ọmọ yanjú, Duration 5,039 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 5:39 Fídíò, Akomolede ati Asa lori BBC: Olùkọ́ Kikelomo Ogunboye tan ìmọ́lẹ̀ sí ìwà olè ọ̀gá ọlọ́pàá Audu gẹ́gẹ́ bí àwòkọ́ṣe àsìkò yìí, Duration 5,398 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 4:11 Fídíò, Oba Adeyeye Ogunwusi: Ojú mi ti rí lọ́pọ̀ lọpọ̀, ọ̀pọ̀ èèyàn ni kò tilẹ̀ gbàgbọ́ pé mo lè jọba- Ooni, Duration 4,117 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 4:43 Fídíò, Promise Akinlade: ọmọ ọdún mọ́kànlá tó ń fi ìlù dárà bíi àgbàlagbà sọ̀rọ̀ nípa tálẹ́ǹtì rẹ̀, Duration 4,437 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 0:59 Gbọ́, Ìsẹ̀lẹ̀ jákèjádò orílẹ̀èdè àgbáyé láàárín ìṣẹ́jú kan, Duration 0,59wákàtí 5 sẹ́yìn 7:03 Fídíò, Olumuyiwa Bolade Adedeji Military Bruitality: Bí arákùnrin onípèníjà ara tí sọ́jà lù ṣe dé, Duration 7,035 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 4:45 Fídíò, Yoruba Films: Ẹ̀ẹ́ bẹ̀ mi kúrò láyé ni, mi ò lè kú - Fadeyi Oloro, Duration 4,4526 Èrèlè 2020 2:48 Fídíò, Esther Ajayi: Èmi náà ti borí ìṣòro rí ló ń mu mi ṣojú àánú, Duration 2,481 Ògún 2019 6:08 Fídíò, Adebola Ademilua: Àìrísẹ́ ṣè lẹ́yìn ìwé kíkà ló sọ mi dí ìyá onírú, mo dúpẹ́ tèmi, Duration 6,0827 Bélú 2020 5:55 Fídíò, Soyinka Cancer: Àṣe ara mi ni iso ti n run gbogbo bí mo ṣe n ṣèrànwọ́ lórí jẹjẹrẹ, Duration 5,5527 Bélú 2019 BBC News, Yorùbá Ìdí tí ẹ fi le è nígbàagbọ́ nínú ìròyìn BBC Ìlànà Lílò Nípa BBC Òfin Àṣírí Cookies Kàn sí.
Ọpọlọpọ awọn to ni covid-19 ni yoo gbadun lẹyin ti wọn ba fun ara ni isinmi, ati oogun ara riro (bi i paracetamol).
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Boko Haram: Ọmọ 37,000 yóò jànfani ẹkọ́ ọ̀fẹ́ ní ìjọba ìbílẹ̀ mẹ́ta ní ìpínlẹ̀ Borno 28 Ẹrẹ̀nà 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Awọn ile ẹkọ ti Boko Haram ti ṣe ọṣẹ́ Àjọ ilẹ Yuroopu tó ń ri si ipese ìrànwo ati idaabo bo ètọ ara ilú tí a mọ si European Commision's Civil Protection and Humanitarian Aid (ECHO ) pẹluu ajọṣepọ ajọ ẹlẹyinju aanu kan lorilẹede Naijiria, Plan international Nigeria ti ní àwọn ṣetan láti dáhun si ìṣòrò etò ẹkọ ti kò si fún àwọn ọmọ ìhà ìlà-òòrun ilẹ Nàìjíríà nibi ti ogun boko Haram ti gbe n ṣọṣẹ.
Ó bá pada lọ sọ ohun tí ó ṣẹlẹ̀ fún wolii Eliṣa.
Fifi ẹnu ootọ ọrọ yanju irọ to wa nibẹ Ṣe ootọ ni pe oju ọjọ to dara ṣe iranlọwọ fun Afrika?
Ìjọba àpapọ̀ sì ti gba àṣẹ ilé ẹjọ́ látọ̀dọ̀ ilé ọjọ́ tó ń rí sí ọ̀rọ̀ ilé iṣẹ́ lọ́jọ́ ẹtì láti dẹkun gígùn lé ìyanṣẹ́lódì àwọn òṣìṣẹ́.
Sugbọn nigba ti wọn gbe e de ile ẹjọ wọn ko jẹ ki adajọ mọ pe oniroyin ni.
Pasitọ Bakare pe ipe yii lasiko to n bawọ̀n ọmọ Naijiria sọrọ lori ipo ti orilẹede yii wa lọwọ-lọwọ bayii, eyi to se lasiko isin ọjọ isinmi ninu ijọ rẹ.
6m ni mo fi borí Buhari, ojú òpó INEC gan leè jẹ́rì si - Atiku Atiku: Ó dá mi lójú pé mi ò le fìdí rẹmi nínú ètò ìdìbò ààrẹ Àwọn ìdí márún ti Atiku kò fi wọlé ààrẹ Atiku n ṣé iranran lórí ìbò 1.
Waidi Ayinla Ọmọwura fori sọlẹ si adugbo Itoko, ni ilu Abẹokuta lọdun 1933, bi o tilẹ jẹ pe ko sẹni to mọ ọjọ ti wọn bii, nitori ko si akọsilẹ nipa ọjọ ibi rẹ lasiko to de ile aye.
Ní ọdún kẹẹdọ́gbọ̀n tí wọ́n bí mi ni mo fẹ́ wúndíá kan láti ìlú ìyá mi, òun ni ó sì dúró tì mi yìí, Ahọ́ndiwúrà ni orúkọ rẹ̀ ń jẹ́, òun sì ni àkọ́bí ọmọ tí Àjàkálẹ̀- àrùn bí fún Ikú ní ìlú ìyá mi.
 Àwọn ló jẹ ́ àjẹsára àkọ ́ kọ ́ tí a lò káàkiri júlọ , tí a ṣe àgbéjáde rẹ ̀ ní yàrá tí a tí ń ṣe àgbéjáde àwọn egbògi .
“N óo gbá àwọn oriṣa kúrò ní ilẹ̀ náà débi pé ẹnikẹ́ni kò ní ranti wọn mọ́; bákan náà ni n óo mú gbogbo àwọn tí wọn ń pe ara wọn ní wolii kúrò, ati àwọn ẹ̀mí àìmọ́.
Sani to gba pe lootọ ni kii se asa ati ise ẹgbẹ Arẹwa lati pọn sẹyin oludije ẹgbẹ oselu kan fikun pe, awọn ti fi iroyin nipa oludije si etigbọ awọn oludibo, ki wọn si se idajọ fun wọn.
BBC Yoruba ṣèwádìí lórí àwọn ohun tó yẹ ka fojú sùn kí a tó lé pè wọn ní agbésùmọ̀mí Àwọn kan ṣàlàyé àwọn ìdí tí ìjọba kò ṣe tíì lè kéde wọn nígbà tí àwọn mìíràn sọ pé ọ̀rọ̀ òṣèlú ni kò tíì je ki a kéde wọn gẹ́gẹ́ bíi agbésùmọ̀mí.
Gba ẹ̀wù ẹni tí ó bá ṣe onídùúró fún àlejò,kí o sì gba nǹkan ìdógò lọ́wọ́ rẹ̀,tí ó bá ṣe onídùúró fún àjèjì obinrin.
Ẹ ti gbàgbé bí wọ́n ti ṣe pa Abimeleki ọmọ Gideoni?
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Kidnapped Girl: Iyá Ikimot ní lẹ́yìn ọ̀pọ̀ ìdààmú àti owó láti wá ọmọ náà, òun sọ ìrètí nù Aarẹ orilẹede Naijiria naa wa pa a lasẹ fun awọn ẹgbẹ awọn akọle lati ri daju wi pe, wọn kọ ile lọna igbalode to ba ofin mu, lati mu ibugbooro ba ọrọ aje lorilẹede Naijiria.
Bakan naa ni ọga agba ọlọpa tun pasẹ fun Kọmisana ọlọpa nipinlẹ Ogun pe awari ti obinrin n wa nkan ọbẹ ni ko fi ọrọ awọn pasitọ naa se, nipa dida awọn agbofinro sigboro lati wa awọn ajinigbe to sisẹ ibi ọhun.
Mà á gbẹ̀san bàálù àjọ UN tó já ní Borno - Buhari yarí Ẹ̀kún omi ṣọṣẹ́ ní Ogun, ìjọba yarí láti wó ilé ojú odò Ẹ sá àwọn akẹ́kọ̀ọ́ sínú òòrùn fún ọgbọ̀n ìṣẹ́jú lójojúmọ́ - Ìjọba Oyo pàṣẹ Òṣìṣẹ́ LASTMA gún olólùfẹ́ rẹ̀ l'ọ́bẹ, ó tún gba ẹ̀mí ara rẹ̀ l'Eko Lẹyin ti awọn ọlọpaa Dubai mu tan la bẹrẹ si ni ri aworan orisirisi, to se afihan iru iṣẹ to kọkọ bẹrẹ si ni ṣe ki o to kuro ni Naijiria.
Awọn alatako kan sọ pe, pipa lo yẹ ki wọn pa ẹnikẹni ti wọn ba ri to jẹbi ẹsun ifipabnilopọ, bi o tilẹ jẹ pe, awọn ọmọ ile igbimọ aṣofin agba Naijiria ti lodi si igbesẹ yii.
Wasiu Adewale Olatubosun Ọmọwe Ọlatubosun ni itaniji ti bẹrẹ lori iwa kotọ yii, lati mu ki araalu mọ wahala to rọ mọ irufẹ iwa didana sun awọn afurasi.
Ṣugbọn lẹyin ti ijọba doola ẹmi awọn ọmọ ile iwe naa, ti iye awọn akẹkọọ to le ni ọọdunrun si gba idande, ni Shehu ko ọrọ rẹ jẹ pe aṣiṣe ni oun ṣe nipa iye awọn akẹkọọ ti oun fi lede ṣaaju.
Wọn yóo fi ṣe ẹlẹ́yà, wọ́n yóo tutọ́ sí i lára, wọn yóo nà án, wọn yóo sì pa á.
Umahi , lo soro yii lojoRu nile aare ,leyin ipade  ti igbimo alase to n yanju wahala laarin awon
ariwa ilu Nampula lose to koja.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ladoja Loju opo Twitter, igbakeji kọmisọna ọlọpaa Tunji Disu fi fọnran bi iṣẹ ṣe n lọ sita to si ni wọn ti ri agola nla ẹru naa gbe kuro.
Ìyàwó mi ló ṣì ń dáná, bu oúnjẹ mi, gé èékáná fún mi - Pásítọ̀ Adeboye Ọkùnrin kan fipá bámi lòpọ̀ lọ́mọ ọdún mọ́kàndínlógún- Funke Oshonaike Ẹ wo ọ̀nà tí ìjọba Nàìjíríà fẹ́ ẹ́ gbà san owó fún àwọn olùkọ́ iléèwé aládàni tí kò rówó oṣù gbà Ààrùn Coronavirus tún ti ran ènìyàn 595 l'órílẹ̀-èdè Nàìjíríà Kii kuku ṣe pe ko loyun lataarọ dalẹ ri, o n loyun, ọmọ a dagba de ibi kan ṣugbọn ile ọmọ funrarẹ ko dagba tẹle ọmọ ninu - Kayefi.
Nígbà tí mo bá wà láàrin àwọn Juu, èmi a máa di Juu kí n lè jèrè wọn.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ikọlu darandaran: Fayọṣe ṣe abẹwo si Ortom ni Benue 8 Èrèlè 2018 Oríṣun àwòrán, Lere Olayinka Àkọlé àwòrán, Fayọṣe ni gbọin gbọin loun wa lẹyin ofin ipinlẹ Benue to fopin si fifẹran jẹ Gomina Ayọdele Fayọṣe ipinlẹ Ekiti ti ṣe abẹwo si akẹgbẹ rẹ Gomina Samuel Ortom ti ipinlẹ Benue.
Ninu awọn eeyan mẹrinlelọgọrin lara awọn to baa wọ baluu pọ ni wọn wa ni ilu Eko.
Ta ló jáwé olúborí nínú eré ìdíje ní Eko?
Oríṣun àwòrán, Ogun State Governor's office Àkọlé àwòrán, Ni aye atijọ, awọn ọba ìlú nilẹ Yoruba ati kaakiri ilẹ Afrika maa n lo ìlù lati ba awọn ẹmẹẹwa wọn sọrọ.
Kí ènìyàn mu kí ayé ọmọ ẹlòmíràn dára lágbára ju ohun gbogbo .
Yobe: Obi awọn akẹkọ Dapchi nbeere ọmọ wọn
O ni igbelarugẹ ati ipese iṣẹ fun awọn ọdọ lawujọ ni yoo mu ki iwa ibajẹ dinku lorilẹede Niajiria.
"Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Oyenusi ló mú mi wọ ẹgbẹ́ adigunjalè kó tó di pé mo b'Ólúwa pàdé' Baba awọn ọmọ ọhun ni ""nigba ti iyawo mi bi awọn ibeji yii, mo ro o pe kilode ti eyi ṣẹlẹ si mi ni ọjọ ori mi yii ṣugbọn nibayii mo ti dupẹ lọwọ Ọlọrun""."
Osun Election Tribunal: Èyí ni òkodoro ìdájọ tí àwọn eniyan ìpínlẹ̀ Ọsun ti ń reti- Oyetola
"Gẹ́gẹ́ bí oníròyìn kan tí kò fẹ́ dárúkọ ara rẹ̀ ṣe sọ ọ́, ""akẹ́kọ̀ọ́ ni ẹni tí wọ́n pa yìí ṣùgbọ́n mi ò le sọ ilé ìwé rẹ̀."
Ṣugbọn diẹ lo n nipa lara eeyan bii ti Covid 19 yii Awọn coronavirus kọọkan maa n fa ailera ti ko lagbara pupọ bii ọfinkin, iba ṣugbọn ti Covid 19 lagbara pupọ lati fa ailera nla bii otutu aya Niumoníà Awọn to ba ti kagbako rẹ le ni awọn apẹrẹ bii iba, ara riro paapaa tọwọtẹsẹ ati ikọ.
N óo gbà ọ́ lọ́wọ́ àwọn eniyan Israẹli ati àwọn orílẹ̀-èdè yòókù tí n óo rán ọ sí.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, SS3 ní mo wà báyìí, mo sì ti gba àmì ẹ̀yẹ̀ púpò nílé-lóko gẹ́gẹ́ bí onílù - Ayansike Iṣẹ́ tí kò ní àlébù la ó ṣé fún Ondo tẹ́ẹ bá fún mi láyè Araale kan bere pe lọdun mejọ ti Eyitayo Jegede fi ṣiṣẹ gẹgẹ bi agbẹjọro agba ipinlẹ Ondo labẹ iṣejọba Olusegun Mimiko, ki ni iṣẹ apẹrẹ rere to ṣe tawọn le wo mọ ọ lara lati dibo yan an lọtẹ yii.
Olódodo a máa jẹ àjẹtẹ́rùn,ṣugbọn eniyan burúkú kì í yó.
débọ ̀ Ògúndoyin jẹ ́ olóṣẹlú ọmọ orílẹ ̀ èdè < nowiki > nàìjíríà < / nowiki > kan .
 Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Adájọ́ kọ̀ láti gba oniduro Dino Melaye Ọ̀gá àgbà Ọlọ́pàá kọ̀ láti yojú sí àwọn asófin Àwọn agbófinró tún ti'mú Dino Melaye Mi kò rí orílè-èdè tí wọ́n ti ń gbé aláìsàn tó wà lórí kẹ̀kẹ̀ aláìsàn lọ sí ilé ẹjọ́, ti ẹni bẹ́ẹ̀ kò leè dáhùn ìbéèrè Adájọ́ láti sọ bóyá òun jẹ̀bi tàbí òun kò jẹ̀bi.
ọgọ́ta ọjọ́ ni mo sì ṣe ki n tó jáde.
Iyipada ti wọn mu ba papakọ naa waye lẹyin ti ile iṣẹ aladani kan raa lọwọ ajọ to n ṣamojuto rẹ BAA niye owo biliọnu pọun kan le diẹ lọdun 2009.
Bákare fikun pe kò sí ẹnikẹ́ni, bí ó ti wù kó ní ipò tàbi lọ́la, tó tí ó le sọ pé òun ni àsírí kankan ni ìpamọ́.
Ṣaa deede ni wọn rii pe gbogbo nkan dojuru nigba ti ajọ State Information System Agency (RIA) si bẹrẹ iwadii ni pẹrẹwu.
"Fẹrẹẹ, nigba to fi di ọdun 1957, o ti da ẹgbẹ́ ""Fatai Rolling Dollar & African Rhythm Band"" silẹ."
Ope Bademosi: Ọmọọ̀dọ̀ tó pa Ope Bademosi ti rí ẹ̀wọ̀n gbére he!
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ooni: Ayẹyẹ ọdún Moremi yóò wà fún ìtẹ̀síwájú àwọn obìnrin 20 Ẹrẹ̀nà 2018 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 8 Bélú 2018 Oríṣun àwòrán, ooniadimulaife Àkọlé àwòrán, Ọ̀ọ̀ni Ilẹ̀ Ifẹ̀ n gbaradi de ọdun Mọremi Ọọni ti Ile -Ife, Ọba Adeyẹye Ogunwusi, Ọjaja Keji ti fẹ ṣe afihan orin kikọ ati ere itage lati bu ọla fun Olori Moremi Ajaṣoro to ja fun ominira awọn ẹru nigba aye rẹ.
Lẹ́yìn náà igi yìí di igi ìdáná: Eniyan óo gé ninu rẹ̀, yóo fi dáná yá; yóo gé ninu rẹ̀ yóo fi dáná oúnjẹ; yóo gé ninu rẹ̀, yóo fi gbẹ́ ère, yóo máa bọ ọ́.
" Sanyeri ni oju Ijẹbu ri diẹ ko to da duro amọ ọpẹ ni fun Ọlọrun pe oun naa ti jana bayii.
Nítorí náà ni OLUWA Ọlọrun rẹ fi pa á láṣẹ fún ọ láti ya ọjọ́ ìsinmi sọ́tọ̀.
OLUWA Ọlọrun ní, “Àwọn ará Moabu ń wí pé ilẹ̀ Juda dàbí àwọn orílẹ̀-èdè mìíràn, 
Nígbà tí ó ti parí wíwọn inú Tẹmpili, ó mú mi gba ẹnu ọ̀nà tí ó kọjú sí ìlà oòrùn jáde, ó sì wọn ẹ̀yìn Tẹmpili yíká.
Bẹẹ ba gbagbe, a ti mu iroyin wa fun yin saaju pe, obinrin to ni oju buluu naa, Risikat Azeez, ni ọkọ rẹ le jade nitori o bi ọmọbìnrin meji ti oju wọn buluu bi i ti iya wọn.
Kidnap cases in Nigeria: Iléeṣẹ́ ọ̀lọ́pàá ní ọwọ́ tẹ afurasí méjì, méjì míì sálọ
Ohun ni emi naa ṣe n jẹ Adekunle Afod.
Eniyan burúkú ń mú nǹkan burúkú jáde láti inú ọkàn burúkú rẹ̀.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Yoruba Culture: ọjọ́ méje ni wọ́n fí n rẹ ẹ̀kú Danafojura kó tó jáde Ọ̀rọ̀ di bóòlọ-o-yàámi ni Ẹ̀gbá, ominira dé f'awọn obinrin, Alake kọwe fipo rẹ silẹ Kete tijọba ti mu Funmilayọ lori ẹsun pe kò san owó orí ara rẹ, ni awọn obinrin ti pe bo ilé ẹjọ naa.
“Ó fi wọ́n jọba lórí àwọn òkè ayé,ó sì fún wọn ní èso ilẹ̀ jẹ.
Ẹ máa dáríjì eniyan, Ọlọrun yóo sì dáríjì yín.
Simoni Peteru sọ fún wọn pé, “Mò ń lọ pa ẹja.
 owó ti yarọ sí i lọ ́ wọ ́ .
Láti orí 'Our Mumu don do' sí 'Revolution Now' Buhari yóò búra wọle fún àwọn mínísítà Àwọn obinrin wa lè máa rìrìnàjò lọ orilẹ̀èdè míì báyìí - Ìjọba Saudi Mo fẹ́ pa ara mi torí ojú àbùkù tí wọn ń fi wò mí pé mo fi iṣẹ́ abẹ bímọ"" Gbígba onídùròó Zakzaky ṣàfihàn àṣeyọrí ìfaradà wa lásìkò ìfìyajẹni - Shiite Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí kan sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn."
Eyi lo fa a ti awọn alaṣẹ ileewe naa fi paṣẹ pe ki gbogbo akẹkọọ fi ọgba ileewe naa silẹ ni kiakia, ki wọn o si lọ fun isinmi idaji saa ni tipa-tipa.
Tirẹ̀ ni n óo jẹ́, n óo sì dúró tì í.
OLUWA Ọlọrun ní, “Wò ó, n óo gbé ọwọ́ mi sókè sí àwọn orílẹ̀-èdè.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìyansẹ́lódì MMA2: Alẹ́ Ọjọ́bọ ni ìyansẹ́lódì náà wá sópin 10 Ọ̀wàrà 2018 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 12 Ọ̀wàrà 2018 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Àwọn arìnrìàjò ní pápákọ̀ òfúrufú MMA2 Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Àwọn òṣìṣẹ́ pápápọ̀ òfurufú ní Ìpínlẹ̀ Eko fi ẹ̀honú wọn hàn Àwọn ẹgbẹ́ òṣìṣẹ́ lẹ́kàa ètò ìrìnà òfúrufú ti fagile iyanṣẹlodi ti wọn gun le.
Ó gbẹ́ kòtò kan yí pẹpẹ náà ká, kòtò náà tóbi tó láti gba òṣùnwọ̀n irúgbìn meji (nǹkan bíi lita mẹrinla).
Dúró tì mí, má sì ṣe bẹ̀rù, nítorí pé Saulu tí ó fẹ́ pa ọ́, fẹ́ pa èmi pàápàá, ṣugbọn o óo wà ní abẹ ààbò níbí.
Ni osu keje odun 2018, ni won  kede aarun Ebola ni orile ede naa , ni eyi ti
Ninu atejade kan ti oluranlowo gomina fun eto iroyin  alhaji Bello Muhammed Zaki gbe jade lati toro aforijin fun bi won se sun ojo naa siwaju.
Lẹ́yìn ọjọ́ kẹwaa, OLUWA bá Jeremaya sọ̀rọ̀.
agbẹnusọ ti o ko pa nibi ipade naa ni agbẹnusọ lati ile igbimọ aṣofin Ipinlẹ
Ìgbà tí iwin yìí sọ̀rọ̀ síi kò le dáhùn, inú bí iwin nítorí èyí, ó na irin mọ́ ọ lórí, orí fọ, ìmùdùnmúdùn hàn gbangba, ikú dé.
” Isaaki ní, “Wò ó, a rí iná ati igi, àgbò tí a óo fi rú ẹbọ sísun dà?
"Jakande pé 90 láì gba àmì ẹ̀yẹ kankan ní Nàíjíríà -Osoba Ìbọn ọlọ́pàá ló pa èèyàn, ẹgbẹ́ wa kìí lo ìbọn - Shiite fárígá Ìtàn tó rọ̀ mọ́ òwe ""Ẹni tí kò ṣe bíi aláàárù l‘Oyingbo."
 Àìmoye ènìyàn tí a kò lè fi ojú da iye wọn ni ó ń sọ èdè yìí gẹ ́ gẹ ́ bí èdè kejì , ìyẹn èdè àkọ ́ kún-tẹni ní pàtàkì ní àwọn orílẹ ̀ -èdè tí ẹ ̀ sìn mùsùlùmú ti gbilẹ ̀ .
Àwọn ọlọ́dẹ darapọ̀ mọ́ ìwọ́de #EndSARS l'Osogbo, wọ́n ní kò sáyè fún jàǹdùkú mọ́ Oríṣun àwòrán, Amiloaded news Awọn ọdẹ nipinlẹ Ọṣun ti darapọ mọ awọn oluwọde #EndSARS ni ilu Oṣogbo pẹlu ikilọ fawọn janduku pe ki wọn rin jinna si iwọde naa.
Lẹyin wakati mẹta lawọn oṣiṣẹ ọgba ẹranko naa ko oku ọmọ erin kan ati atawọn marun un miiran nitosi ara wọn.
Nítorí náà, san ẹ̀san ẹ̀ṣẹ̀ wọn fún wọn;ninu ibinu rẹ, Ọlọrun, ré àwọn eniyan yìí lulẹ̀.
Lati ipasẹ okoowo to burẹkẹ yii ni Fajemirokun ti da ileesẹ olokoowo Henry Stephens silẹ, ti ileesẹ naa si gbọrẹgẹ-jigẹ Henry yapa sidi oniruuru okoowo bii tita simenti ati eroja ikọle, imọ ẹrọ, ile ifowopamọ, eto adojutofo, kiko ọja lọ soke okun ati gbigbe ọja wọle Awọn okoowo miran to tun dawọle ni eto irinna ọkọ oju omi, ati epo rọbi, to si jẹ gbajugbaja laarin awọn olokoowo nigba naa Laarin ọdun mẹwaa, Ileesẹ Fajemirokun ti gbooro debi pe o n se katakara pẹlu awọn ileesẹ ilẹ okeere nilu Ọba, Amẹrika, Poland, Japan, Belgium, Egypt, Germany and Brazil.
"Oríṣun àwòrán, Queen_Aanu/Instagram ""Mo mọ pe awọn eeyan ti ni ero wọn nípa mi, boya o tọ tabi ko tọ, lori idi ti mo fi fẹ ọba alaye naa tabi kuro ninu igbeyawo ọhun."
"Ti mo ba wa n fi dukia mi han, ti mo n ṣe afẹfẹyẹyẹ, yoo da bi pe mo n sọ fun awọn eeyan pe wọn o jara mọ iṣẹ to mi.
Ṣugbọn nítorí pé àwọn baba wa mú Ọlọrun ọ̀run bínú, ó fi wọ́n lé Nebukadinesari ọba Babiloni, ní ilẹ̀ Kalidea lọ́wọ́, òun ni ó wó tẹmpili yìí palẹ̀, tí ó sì kó àwọn eniyan ibẹ̀ lọ sí ilẹ̀ Babilonia.
Agency (NASRDA),ile –ise to n se iwadii lori  ohun alumooni ile ati ohun ogbin (Raw
4 2,767 Central African Republic 63 1.
Ẹwẹ, agbẹjọro ati ajafẹtọ ọmọniyan kan, Dele Farotimi sọ pe, isọkusọ ni ọrọ ti Aarẹ ba awọn ọmọ Naijria sọ ninu igbohunsafẹfẹ to ṣe.
Ko tan sibẹ o, onitọun tun fikun pe, saka ni ara Daura ya, ti ko si se ojojo kankan.
Má ṣe ìlara àwọn ẹni ibi,má sì ṣe bá wọn kẹ́gbẹ́,
Ó fi ìwé náà rán Elasa, ọmọ Ṣafani ati Gemaraya, ọmọ Hilikaya: àwọn tí Sedekaya, ọba Juda, rán lọ sọ́dọ̀ Nebukadinesari, ọba Babiloni.
'Ọjọ́ mẹ́fà lọ́sẹ̀ ni mo fi ń gbáradì láti tayọ àwọn ẹlẹgbẹ́ mi táá jọ ń wẹ odò' Ẹ̀ wo bí àwọn ẹ̀ṣọ́ ojú etí òkun ṣe ń ṣiṣẹ́ l'Eko Eyi tun mu ki Crystal Chiagbu bẹrẹ si ni ba awọn ọmọ ti wọn bi lai lẹsẹ tabi ti ẹsẹ ati apa wọn ba ti ge ṣiṣẹ lati maye rọrun fun wọn ati lati kọ wọn pe idunu la fi n gbe 'le aye.
Minisita to n ri si ere-idaraya ati idagbasoke awon odo lorile-ede Naijria, Solomon Dalung so pe isuna to muna-doko se pataki lati mu igberu de ba ere-idaraya nipinle wa kookan.
 Ẹwẹ, wọn wa beere fun ṣiṣe awọn ọna to wọ inu awọn adugbo sira wọn.
Kọmiṣona naa fi kun pe, iye ti ijọba maa n ri lori afara Lekki-Ikoyi loṣu ko din ni ọọdunrun miliọnu naira, nigba ti oju ọna Lekki-Epe maa n pa nnkan bii ẹẹdẹgbẹta miliọnu naira loṣu fun ijọba.
7) Ọlọ́fà ti Ọffa - Ọba Wuraola Isioye: Wọn fi Ọba Isioye jẹ lọdun 1957 Ó si dari ẹkùn Ọffa fun ọdun meji ko to o di pe ijọba ẹkùn nla ni Ariwa Naijiria yọ ọ loye.
Oluwatoyin Bayegun: Nígbà tí mo di gbájúgbajà tán ni mo bẹ̀rẹ̀ sinimá
O Fagunwa nile rẹ to wa ni Oke Igbo ree.
OLUWA sọ fún Mose pé, “Sọ fún àwọn ọmọ Israẹli pé, 
Atọ ọmọkunrin Reyes, ati ẹjẹ rẹ ba eyi ti wọn ri lara obinrin alawọ funfun naa mu ni eyi ti wọn fi fidi otitọ mulẹ.
Ikú Dagunro: Sajẹ ní èèyàn tó ṣe gbáralé ni Dagunro, ọ̀pọ̀ èèyàn ló dìde láti ara rẹ̀
Nígbà tí ọdún yípo, Nebukadinesari, ọba Babiloni ranṣẹ lọ mú un wá sí Babiloni pẹlu àwọn ohun èlò olówó iyebíye tí ó wà ninu ilé OLUWA.
Àsìkò tó láti fi ìwọ́de gba ara wa sílẹ̀ lọ́wọ́ ebi àti oko ẹrú - Sowore Aáwọ̀ ọ̀dọ́ Yorùbá àti Hausa ló dá wàhálà sílẹ̀ ní Ṣásá - Ṣeriki Hausa Asiko ti igbẹjọ n lọ lati gba oniduro rẹ lori ẹsun ti wọn fi kan an ninu oṣu Kẹrin, ọdun 2017, ni ileeṣẹ ijọba to n mojuto ọrọ mọlẹbi ti kọkọ sọ fun pe, o ti padanu ẹtọ to ni lati maa gbe ni South Africa.
Ọkunrin náà bá dìde lẹsẹkẹsẹ, ó gbé ibùsùn rẹ̀, ó bá jáde lọ lójú gbogbo wọn.
Wo àwọn olùdíje < Padà lọ sí ọ̀dọ̀ Olùdíje Ìkádìí Àkọlé àwòrán, Akinbade: ''Due Process'' ni awa yoo fi se ijọba Akinbade ni Ile-iwe giga fasiti LAUTECH ti awọn olukọ ko ki n ye da isẹ silẹ nitori ijọba kò san owo oṣu wọn, sọ pe òun yoo rii daju pe wọn da eto ẹkọ pada si ipo to yẹ ki o wa.
 Ko tan sibẹ o, Toyin tun tẹsiwaju pe ọpọ awọn ololufẹ oun lo n poungbẹ lati wo sinima naa lagbegbe Ikeja, eyi ti oun ya nigba ti oun wa ninu oyun osu mẹfa."
Dokita Akerele ni ti ijọba ba gba awọn eniyan laaye lati maa lo igbo, ilokulo oogun ni yoo mu wa ti yoo si jẹ ki aarun ọpọlọ wọ pọ.
He was such a committed humanitarian who did not just talk about peace-building but lived his life building peace and trying to make the world more wholesome.
Aare Emmerson Mnangagwa ti orile-ede Zimbabwe ti daruko oga-agba ile-ejo giga orile-ede naa, adajo Priscilla Chigumba  gege bi oga-agba ajo eleto-idibo,  gege bi oro re ninu iwe akosile kan saaju eto idibo ti yoo waye ninu odun ti a wa yii, eyi ti erongba re da lori ati mu ajosepo to dan moran mule laarin awon orile-ede lagbaye.
Ògùṣọ̀ meje tí iná wọn ń jó wà níwájú ìtẹ́ náà.
Orilẹede Naijiria wa lara awọn orilẹede ti ina ọba rẹ ko fẹẹ ṣe dede to lagbaye, eleyi ti o si ti gba ọpọ ọrọ abuku laaarin awọn ọmọ orilẹede Naijiria ati loke okun.
Oríṣun àwòrán, Instagram/itslaycon Laycon, ẹni to salaye pe oun ko ni lero rara pe oun le jawe olubori ninu idije naa, fikun pe oun naa gbero lati kopa lori eto naa, ki oun lee se agbelarugẹ orin ti oun n kọ ni.
Agbẹnusọ fun ileesẹ ọlọpaa nilu Kano, abdullahi Haruna naa fidi idoola ẹmi yii mulẹ fun BBC, to si ni iwadi n lọ lọwọ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Olaitan Olamide: mò lè má nílò ìwé ẹ̀rí mi tí mo bá parí ní LASU Ninu ifọrọwanilẹnuwo wọn pẹlu Adeeko lo ti ṣalaye pe, pasitọ fun oun ni ọmọ odo lati fi lu u lori, ki oun pasitọ to o fi ọbẹ yọ ọkan rẹ, eyi to fi se asejẹ fun Adeeko ati iya rẹ.
 Ṣùgbọ ́ n , lọ ́ nà kìíní ná , kò fẹ ́ rìn jìnnà púpọ ̀ sí àbúrò rẹ ̀ gẹ ́ gẹ ́ bi ìpinnu wọn pé àwọn kò gbọdọ ̀ jìnná sára wọn bí ó ti lẹ ̀ jẹ ́ wí pé àwọn méjèè jì kò jọ fẹ ́ gbé ibùdó kan náà .
"O ni, ""Fun ọ̀pọ̀ ọdun ni wọ̀n ti ri Gashaka gẹ̀gẹ̀ bi igbo to ni awọn ìnàki to pọ̀ jùlọ lorilẹede Naijiria ati Cameroon, eleyi to sọ̀wọ́n jọjọ."
Lẹ́yìn náà, àwọn Kerubu bá gbéra, wọ́n fò, pẹlu àgbá, ní ẹ̀gbẹ̀ẹ̀gbẹ́ wọn; ìtànṣán ògo OLUWA Ọlọrun Israẹli sì wà lórí wọn.
Àwọn tí wọ́n túká bá ń lọ káàkiri, wọ́n ń waasu ọ̀rọ̀ náà.
Ẹ̀yin lẹ kọ́mi lódù, tẹ sìnmí wálé ayé
Ewe, opo eniyan lo ti bu enu ate le erongba ijoba lati da ikolu si iko omo ogun Taliban duro lataari isinmi odun Ramadan, eleyi ti o sokunfa bi iko Taliban se sekolu si agbegbe iko omo ogun ohun.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, ''Ẹ gbudọ̀ ṣe àwọn ǹkan wọ̀nyí lọ́jọ́ ìdìbò gómìnà l'Ondo bí bẹ́ẹ̀ kọ́ .
Bakan naa ni Arabinrin Akosa tun rọ Ile naa lati ṣe agbekalẹ ofin ti yoo fun obinrin ni ẹtọ kan naa ni kikun pẹlu ọkunrin ati pe o se pataki ki Ile naa maa pese abadofin iṣuna owo ilu sori ẹrọ kalekako ki awọn ẹlẹgbẹjẹgbẹ le maa foju sunnukun wo o ki o to di ofin.
Oluwapamilerin Mihael Ayanlere (NAIJIRIA) Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Àyàn: Ti mo bá ti gbọ́ ohùn ìlù ni àárẹ́ mi ma ń lọ!
Ẹ̀yin ọlọ́pàá, ẹ di ìhàmọ́ra kẹ́ẹ já àlàfíà ìlú gbà padà - Ọ̀gá àgbà ọlọ́pàá Àwọn ọ̀nà láti dẹ́kun ìwọ́de ọ̀dọ́ lọ́jọ́ iwájú nìyí Èèyàn 229 ló ti wà ní gbaga òfin fún wàhálà tó wáyé l'Eko Bi kii ba ṣe oun, ta lo paṣẹ naa?
Ìtìjú ni ó jẹ́ fún mi láti bèèrè fún ọ̀wọ́ ọmọ ogun ati àwọn ẹlẹ́ṣin tí yóo dáàbò bò wá ninu ìrìn àjò wa, nítorí mo ti sọ fún ọba pé Ọlọrun wa a máa ṣe rere fún àwọn tí wọ́n bá ń gbọ́ tirẹ̀; Ṣugbọn a máa fi ìyà jẹ gbogbo àwọn tí wọn kò bá tẹ̀lé e.
Agba agbẹjọrọ, Alex Izinyon SAN, lo n ṣoju fun sẹnetọ Adeleke, nigba ti Nathaniel Oke SAN, ati Abdusalami Abdufatai n gbẹjọro fun awọn olujẹjọ keji ati ikẹta.
Àwọn agbébọn jí nọ́ọ̀sì ará Germany yìí gbé ní ọgbà ilé isẹ́ ẹgbẹ́ alágbèlébù pupa lálẹ́ ọjọ́rú ọ̀sẹ̀.
Ẹgbẹ Shiite tun sọ siwaju si ninu atẹjade ti wọn fi sita pe awọn ile iwosan ni Naijiria ko le ṣetọju El-Zakzaky ati iyawo rẹ ninu oniruuru aarun lo ṣe wọn latimọle ti wa lati ọjọ yii.
Àwọn ará ìlú ń da àwọn to bọ́yọ lọ́wọ́ Boko Haram padà si àgọ́ wọ́n Pẹ̀lú bí gbogbo àyé ṣe gbe ìfẹhonu han lóri ìjínigbé àwọn ọmọ Chibok síbẹ̀ àwọn kan o bikítà ti wọ́n sì ń dá àwọn tí wọ́n sá kúrò ni àhámọ Boko Haram pada si bẹ̀.
Ikede yii si lo n waye ni oni ọjọ Isẹgun, ọjọ Karun osu kẹwaa, tii se ayajọ ọjọ awọn olukọ lagbaaye.
com/B7pfbgSYBk— JuventusFC (@juventusfc) July 16, 2018“Mo feran idojuko lopolopo, bi o ti le je pe, Mo mo daju wi pe ko ni rorun fun mi.
Ninu ọrọ rẹ, Alaafin ni kani ilana iṣẹṣe ati itan abalaye ni wọn tẹle ni, ilu Iwo lo yẹ ko jẹ olu ilu ipinlẹ Ọsun dipo Osogbo ti wọn fi ṣe olun ilu ipinlẹ Ọsun.
Alaafin: Ọ̀sán ọjọ́ Àìkú ní Ọba Adeyemi gbalejo Kayode Fayemi
Olamide ni ọpọlọ oun ni oun n lo, ko si si ẹnikẹni to kọ oun nisẹ naa, bi oun ba si ti ri mọto tuntun, abi orisi ọkọ ofurufu tuntun, ni oun yoo se sita.
‘Ọlọrun sọ pé:Ẹnu lásán ni àwọn eniyan wọnyi fi ń bọlá fún mi,ọkàn wọn jìnnà pupọ sí mi.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ṣé ẹ̀yin mọ idí ti Abass Akande fi n jẹ Obesere?
Bú ààrẹ láwọn orílẹ̀èdè márùn-ún yìí kí o rugi oyin Irọ́ ni, mi ò sọ pé mọ fẹ di Ààrẹ ní 2023- Tunde Bakare Osinbajọ: Ọlọrun ṣetán láti mú Nàìjíríà d'élẹ̀ ìlérí, TUC ní Nàìjíríà ti kùnà lẹ́ni ọdún 59 ‘Omoyele Sowore tí dé ilé ẹjọ́ ní Abuja!
Wo àwọn oúnjẹ márùn ún tó ń mú kí àtọ̀ ọkùnrin dára síi 'Iléèṣẹ́ ọlọ́pàá ló gbégbà orókè nínú ìwà jẹgudujẹra ní Nàìjíríà' Buhari, pàṣẹ f'àwọn Gómìnà pé kí wọ́n jáwọ́ nínú èróǹgbà láti ná N17trillion owó ìfẹ̀yìntì òṣìṣẹ́ Nkechi Blessing vs Toyin Abraham: Nkechi tí tọrọ ìdáríjí ẹ̀ṣẹ̀ lọ́wọ́ akẹgbẹ́ rẹ̀, Toyin Abraham Ìbálòpọ̀ ọ̀lọ́jọ́ méje mú kí ilé ẹjọ́ tú ìgbéyàwó ọdún mẹ́wàá ká ní Ibadan Ki a to wi, ki a to fọ, ẹlẹsẹ ayo, Heung-Min Son ṣi gbada lori Eṣu lẹyin to gba goolu goolu aramọnda kan wọle Arsenal ni bii iṣẹju mẹtala.
Daura ni ilu to ti pẹ ju ninu itan ẹya Hausa, koda, awọn oluwadii kan tilẹ gbagbọ pe Daura ni orisun ede Hausa.
'A sọ fún ọlọ́kadà pé omi kún, omi kún, ṣùgbọ́n ó kọ etí ikún' #Adewura NURTW l‘Abuja yóò kàn sí Makinde láìpẹ́ lórí bó ṣe fòfin dè wá l‘Ọyọ - Ejiogbe Lasiko to n sọ ohun ti oju rẹ ti ri lọgba ẹwọn, Obasanjo sàlàyé pé, òhun kò ni ìrètí mọ ninu ọgba ẹwọn, nítori àṣẹ Abacha ni pé a fi ti òun ba kú ni òun àti àwọn méjì míràn to lé jáde lẹ́wọ̀n.
Ìlérí tí òun fúnrarẹ̀ ṣe fún wa ni ìyè ainipẹkun.
’ Kò ṣẹ̀ṣẹ̀ nílò alágbára tabi ọ̀pọ̀ eniyan, láti fà á tu tigbòǹgbò tigbòǹgbò.
Homepage Accessibility links Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Ìrànlọ́wọ́ Ìwọlé News Sport Weather Radio Arts Ààtò BBC News Yorùbá BBC Yoruba ÀkọléÀkọlé abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Àkọlé bọ̀tìnnì síwájú síi Olùmúdọ́gba bọ́tìnnì síwájú síi Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Media player Close player Close player Close player Inú APC ń dùn nígbà tí ayọ̀ PDP kò kún lórí ìdájọ́ náà 11 Owewe 201911 Owewe 2019 Òní lòní ń jẹ́ ti Adájọ́ yóò dájọ́ ẹ̀sùn ìgbẹ́jọ́ èsì ìdìbò Aarẹ Naijiria láàrin Muhammadu Buhari àti Abubakar Atiku I'll sign in later And we'll keep you signed in.
Oríṣun àwòrán, @others Àkọlé àwòrán, Afi ki wọn tu Zakzaky silẹ ni ariwo ti awọn Shiite n pa O ni ijọba Buhari gbà pé o ni idi ti Adajọ Abubakar Malami (SAN) N3.
Wíwó laá wó àwọn ilé ìkẹ́rùpamọ̀sí tó wà láwọn ibodè wa Ẹ̀yin ọkọ̀ epo tó wà ní Ogere, ẹ kó àásá yín ká leè tún ọ̀nà márosẹ̀ ṣe dé Eko - Ìjọba Àpapọ̀ Kò yẹ kí ààrẹ fi ìlú silẹ̀ láì gbé ìjọba lé ẹnikẹ́ni lọ́wọ́ -Agbẹjọ́rò Latẹnu ọna igbo ti ẹ o gba wọ ile baba lẹ o ti ro pe inu igbo irumọlẹ tẹẹ maa n ka ninu itan gan lẹ ti de yii ayafi bi ẹ ba wọle tan.
Amọ ṣa a ti bẹrẹ iwadi ti ko si ni pẹ ti ọwọ wa yoo fi tẹwọn.
Gbigbe ọmọde ni iyawo: Ajọ to n risi ọrọ awọn ogo wẹẹrẹ lagbaye, UNICEF ti ni orilẹede Naijiria jẹ kan lara awọn orilẹede to gba laaye ki awọn awọn ọkunrin fi ọmọdebinrin ti ko ba ti i pe ẹni ọdun mejidinlogun ni iyawo.
Àwa ẹ̀dá ọmọ aráyé, a wá dúró gẹ́gẹ́ bí kábiíòsí láàrin gbogbo àwọn ẹ̀dá tí Olódùmarè dá sí ilé-ayé.
Àrùn Coronavirus fa'lẹ̀ya láwọn ìletò aláwọ̀dúdú ní Amẹ́ríkà Kí lo mọ̀ nípa fẹntilétọ̀, ohun èlò aṣèrànwọ́ èémí Kí làwọn ìdàmú tí Coronavirus n mú bá àgọ́ ara?
Amọ, o ti ṣekupa eeyan 1,168.
O wa gbe ilana ti eto idibo ọjọ abamẹta yoo ba jade kalẹ.
Aarin Yusuf ati Minisita fun Eto Ilera, Ọjọgbọn Isaac Adewole ko wọ lẹyin ti minisita ni ko lọ rọkun nile lori ẹsun jẹgudujẹra owo to din diẹ ni biliọnu kan naira ti wọn fi kan Yusuf.
Oríṣun àwòrán, Trace Amọ ko si ẹmi kankan to bọ ninu ijamba naa, ti awọn sisẹ alaabo atawọn araalu si ti pa ina ọhun.
Nígbà tí wọ́n dé ọ̀dọ̀ rẹ̀, ó sọ fún wọn pé, “Ẹ mọ̀ bí mo ti lo gbogbo àkókò mi láàrin yín láti ìgbà tí mo ti kọ́kọ́ dé ilẹ̀ Esia.
Bí mo tí ń wò, mo gbọ́ ohùn ọpọlọpọ àwọn angẹli tí wọ́n yí ìtẹ́ náà ká ati àwọn ẹ̀dá alààyè ati àwọn àgbààgbà mẹrinlelogun.
Mo mọ̀ pé ìran Abrahamu ni yín, sibẹ ẹ̀ ń wá ọ̀nà láti pa mí, nítorí ọ̀rọ̀ mi kò rí àyè ninu yín.
Èyí ni pé nípa ohun meji tí kò ṣe é yipada, tí Ọlọrun kò sì lè fi purọ́ ni àwa tí a sá di Ọlọrun fi lè ní ìwúrí pupọ láti di ìlérí tí ó wà níwájú wa mú.
Agba akọrin Juju miliki naa ṣalaye siwaju pe ohun kii ye ṣe afẹri iyawo oun to jade laye ti oun si maa n rii loju ala.
Awọn ọlọpaa ba ibọn agbelẹrọ mẹrin ati ọta ibọn mejidinlogoji ninu ọkọ bọọsi naa.
Kódà tí kìí bá ṣe àsìkò òdòdó rárá.
so pe, okere tan orile-ede Naijiria yoo niloo iye owo tiye re le lọ́ọ̀dúnrún bilionu owo dola(337
Ọda owo n ba wa finra, agbara owo orilẹede wa ti dinku, ti awọn ọja si gbe owo gege lori.
Arabinrin alaboyun kan, Zainab Aliyu Balarabe ti ku lẹyin ti ejo bu u jẹ nile iyagbẹ kan to wa nile rẹ nilu Kaduna.
Ìwọ máa wò ó, n óo fi ẹ̀mí kan sí inú rẹ̀,yóo gbọ́ ìròyìn èké kan,yóo sì pada lọ sí ilẹ̀ rẹ̀.
Àkọlé àwòrán, Number ti LASEMA fi sita lati maa pe fun ifitonileti iṣẹlẹ pajawiri ni 767 / 112.
Ẹ̀bùn tí a fúnni ní kọ̀rọ̀ a máa paná ibinu,àbẹ̀tẹ́lẹ̀ tí a tì bọ abẹ́ aṣọ a máa paná ìjà.
Nigeria vs Algeria: Mahrez dáná sun Super Eagles!
Ẹnikẹ́ni kò sì gbọdọ̀ wá sí iwájú mi ní ọwọ́ òfo.
Adari ijọba Scott Morrison lo kede igbeṣẹ yi lẹyin ipade to ṣe pẹlu awọn minisita orilẹ-ede ọhun.
Eyi tumọ si pe ọkunrin naa ti di orisun ounjẹ wọn fun asiko pupọ.
Kò sì sí ẹlòmíràn tí OLUWA rán láti ṣe ọpọlọpọ iṣẹ́ ìyanu lára Farao ati gbogbo àwọn iranṣẹ rẹ̀ ati gbogbo ilẹ̀ rẹ̀, ní ilẹ̀ Ijipti.
“Kò sí àgbègbè Nàìjíríà kánkan tó wà lábẹ́ àkóso Boko haram” Kìnìhún joko jẹ ẹran ara afurásí ọdẹ tí kò gbààyè kó tó ṣọdẹ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Àyà mi kọ́kọ́ máa ń já nígbà ti mo ṣẹ̀ṣẹ̀ bẹ̀rẹ̀ -Alaga iduro ọkùnrin Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Bẹ́ẹ̀ ni Oluwa wà fún ara.
Àti pé irúfẹ́ àwọn ìbọn tó lò mú kó lè pààyàn kíákíá nítorí àwọn ìbọn alágbára ni ó lò.
" Àkọlé àwòrán, Àfikún owó ilé ìwé leè dákún ìsòro Nàíjíríà Bákannáà ni àjọ SERAP tún ké sáwọn aṣòfin àpapọ̀ lórílẹ̀èdè Nàìjíríà láti gbé òfin kalẹ̀ láti dẹ́kun bí àwọn ilé ẹ̀kọ́ gíga ṣe ń fowó kún owó wọn.
A o le jade lọ ba ọrẹ ṣere afi ka ṣaa ma de oju mo ile ka si wa layika wọn.
Ninu awon minisita metalelogoji ti aare yan, obinrin meje pere lo wa ninu won.
Ìtàn Mánigbàgbé: Ìtàn tó rọ̀ mọ́ ìdí tí wọn ṣe ń pe aya ní ìyàwó
Àpatán òwe yìí ni, ‘Afàgò kẹ́yin àparò, ohun ojú ń wá lojú ń rí.
Sanusi Adebisi Idikan rèé, olówó tó ń san owó orí fún gbogbo ọkunrin ilẹ̀ Ibadan Ẹfunsetan Aniwura, obìnrin tó ju ọkùnrin lọ Idi si ree ti wọn se ya ọjọ kan sọtọ nilu Abẹokuta lati maa fi ṣe iranti akọni baba Ẹgba to ti lọ naa, ti wọn n pe ni Lisabi Day.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Pa Kasumu: Lere Paimo ní àìrìríjẹ́, àìrímú tàbí ìrònú má a ń jẹ́ kí ọjọ́ ogbó dagun Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 3 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 5 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
“Ẹ gbọ́, ilé Israẹli, ǹjẹ́ ẹ mú ẹbọ ati ọrẹ wá fún mi ní gbogbo ogoji ọdún tí ẹ fi wà ninu aṣálẹ̀?
Ọrọ imọran agbẹnusọ Ile Igbimọ Aṣofin naa lo wa ninu ọrọ ikini rẹ fun aawẹ Ramadan to wọle yii, eleyii ti alukoro rẹ, Ọgbẹni Musibau Rasak fọwọ si.
 Ààrẹ Buhari ṣí ilé iṣẹ́ àti afára ní ìpínlẹ̀ Ondo Ìdí ti mo fi ṣe iṣẹ́ àmúrelé mi lábẹ́ ATM rèé - Dele Ẹ̀wọ̀n ọdún méje gbáko ni Olisa Metuh yóò fi ṣara ridin!"
''Ohun to jẹ wa logun kii ṣe awọn to n pa owo nidi tita gaasi, bi ko ṣe didaabo bo ẹmi wọn ati ti awọn eeyan to rọgba yika wọn.
 O tesiwaju pe ipinle Carabobo si wa ninu ofo sibe.
Lọṣu to kọja ni awọn ọmọ ile igbimọ aṣofin Chad buwọlu ofin ti yoo sọ aarẹ wọn di oloye to ga julọ ninu iṣẹ ologun ni gbogbo agbaye.
Ọpọ alawọfunfun gan an lo gbaruku ti awọn alawọdudu ninu iwọde ti wọn n ṣe lati tako iwa idẹyẹsi ati ẹlẹyamẹya.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Waste to Wealth: Ẹ̀gbin tìrẹ ni èròjà táwọn èèyàn míràn fi n ṣiṣẹ́ ajé, okoòwò ńlá ni Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
"Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Chris Daizell: Ọ̀pọ̀ èèyàn ló ń bú mí, wọ́n ní mo dàbí ọ̀daràn 7 Bélú 2018 ""Igbakuugba ti mo ba n wẹ, ti mo ba si ri alafo ni ara mi laisi Tattoo nibẹ, o maa n bi mi ninu - Mo gbọdọ lọ fi Tattoo bo."
'Kwara nílò ìsọ̀kan àti ìtẹ̀síwájú' - Adedoyin Níbo lowó ìrànwọ́ ẹ̀kọ́ wa wà?
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ayinde Barrister: Òní ló pé ọdún mẹsan an ti ọba orin jáde láyé 16 Ọ̀pẹ̀̀ 2018 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 16 Ọ̀pẹ̀̀ 2019 Oríṣun àwòrán, Facebook/Barrister fans page Àkọlé àwòrán, Iku mu ọba orin Fuji lọ Iku n pani, ilẹ n jẹyan.
Bakan naa, aare tun gbosuba fun awon omo-ogun orile ede Naijiria ati awon ajo eleto aabo lati pese aabo to peye lori emi ati  dukia ni jake-jado orile ede yii.
Twin Festival 2019: Ṣé ọbẹ ìlasa àti àmàlà ló ń ṣokùnfà bíbí ìbejì ní ìlú Igboọrà?
Wọ́n ba ọjọ́ ìsinmi mi jẹ́ patapata.
Ìwà wa kò yé àwọn eniyan, sibẹ gbogbo eniyan ni ó mọ̀ wá.
Àwọn orílẹ̀ èdè ti gbọ́ nípa ìtìjú yín,igbe yín ti gba ayé kan;nítorí àwọn ọmọ ogun ń rọ́ lu ara wọn;gbogbo wọn sì ṣubú papọ̀.
Àwọn Gómìnà ilẹ̀ Yoruba lẹ́tọ̀ọ́ láti dá ikọ̀ Amotekun sílẹ̀ - Itse Sagay Àkọlé àwòrán, Ọrọ Amọtẹkun ti di ija gbogbo eeyan to fe eto aabo to peye Ẹgbẹ Agbẹkọya ti sọrọ lori awuyewuye ti Agbẹjọro agba fun ijọba apapọ sọ pe Amọtẹkun ko ba ilana ofin Naijiria mu.
Àmì òróró ayọ̀ ni ó fi gbé ọ gaju àwọn ẹlẹgbẹ́ rẹ lọ.
A kò ní ṣí olódodo ní ipò pada lae,títí ayé ni a óo sì máa ranti rẹ̀.
Ọpọ awọn ara ilu Ikarẹ Akoko lo tu yahaya lọ si aafin lati kọkọ rii pe ṣe lotọ ni Kabiesi waja ki nitori wọn ni awọn ko fẹ gbagbọ pe ki Baba papoda lasiko yii.
Bí kò bá wá rí bẹ́ẹ̀, ànfàní rèé láti bẹ̀rẹ̀ sí ní kọ́ èdè Yorùbá lórí bbc.
Alákòóso United Nations fún ìsásàálà ti ṣe àkọsílẹ̀ àwọn asásàálà tí ó wá láti Burundi tí wọ́n lé ní 347,000 ní oṣù Èrèlé 2019, UNHCR fìdí ẹ̀ múlẹ̀:
Dájúdájú, eniyan ń káàkiri bí òjìji,asán sì ni gbogbo làálàá rẹ̀;eniyan a máa kó ọrọ̀ jọ ṣá,láìmọ ẹni tí yóo kó o lọ.
Ó ń wò ọ́ bí o tí ń ṣe gbogbo nǹkan wọnyi bí alágbèrè tí kò nítìjú!
Àwọn ọlọ́gbọ́n jùlọ ninu àwọn obinrin tí wọ́n wà lọ́dọ̀ rẹ̀ dá a lóhùn,òun náà sì ń wí fún ara rẹ̀ pé,
Amọ, asoju fun awọn akẹẹkọ naa, Anthony Ifediba sọ wipe oseese ki fasiti Alabama o jẹ ijọba Naijiria ni iye owo toto ẹgbẹrunlọnaẹgbẹrin owo okeere, $800,000.
O de 'bẹ tan lorin ba yipada.
Ogbeni Segun Adekola ti o fi ipinle Ekiti se ibugbe, fi erongba re han pe, awon eyan Naijiria naa owo ti o to bilionu kan dola owo ile-okere ninu odun kan, leyi ti isiro re ni naira to ọ́ọ̀dúnrún o le logota bilionu naira, lati lo gbawosan nile okere.
A ti fa ara wa kalẹ̀ fún àwọn ará Ijipti ati àwọn ará Asirianítorí oúnjẹ tí a óo jẹ.
Wasiu Ayinde: Ó pọn dandan fún Mayegun láti ri pé àláfíà jọba
Ṣugbọn nígbà tí àwọn Juu ní Tẹsalonika mọ̀ pé Paulu ti tún waasu ọ̀rọ̀ Ọlọrun ní Beria, wọ́n wá sibẹ láti ṣe màdàrú ati láti dá rúkèrúdò sílẹ̀.
 ikin ifá jẹ ́ mẹ ́ rìndínlógún .
Nigba to ti jẹ wipe awọn ere wa da lorii ki idile toro, bibọ lọwọ ogun eṣu ati bẹẹ bẹẹ lọ ko si sẹni ti ko fẹ bọ lọwọ ogun tabi ti ko fẹ ki idile oun to.
Lẹ́hìn èyí mo kúrò ní ibẹ̀ mo wá sí ilé mo bọ́ sí orí ibùsùn mi mo sùn lọ.
Ṣugbọn dandan ni pé kí ó kọ́kọ́ jìyà pupọ, kí ìran yìí sì kẹ̀yìn sí i.
" Saraki: Adura fun orilẹede Naijiria gbọdọ tẹ siwaju Oríṣun àwòrán, @bukolasaraki Àkọlé àwòrán, Adura fun orilẹede Naijiria gbọdọ tẹ siwaju Ninu ọrọ tirẹ, aarẹ ile aṣofin agba, Bukọla Saraki rọ awọn musulumi lati ma ṣe rẹyin ninu iwa ikoraẹni nijanu, ati ifẹ ọmọnikeji wọn.
Ní ọjọ́ keje, ọmọ náà kú, ẹ̀rù sì ba àwọn iranṣẹ Dafidi láti sọ fún un pé ọmọ ti kú.
EndSARS: Fayemi ní ọlọ́pàá ti fìyà jẹ òun náà rí, gbọin-gbọin lòun wà lẹ́yìn àwọn ọ̀dọ́ lórí ìwọde EndSARS
“Ẹ ṣọ́ra, kí ẹ má gbàgbé OLUWA Ọlọrun yín, nípa àìpa àwọn òfin ati ìlànà rẹ̀ mọ́, ati ìdájọ́ rẹ̀ tí mo fun yín lónìí, 
Mose gbéra láti pẹ̀tẹ́lẹ̀ Moabu, ó gun orí òkè Nebo lọ títí dé ṣóńṣó òkè Pisiga, tí ó wà ní òdìkejì Jẹriko.
Ẹ ranti àwọn àrùn burúkú tí ẹ fi ojú ara yín rí, àwọn àmì ati àwọn iṣẹ́ ìyanu ati iṣẹ́ agbára tí OLUWA Ọlọrun yín ṣe kí ó tó kó yín jáde.
irúfẹ ́ ọ ̀ rọ ̀ kejì ni ọ ̀ rọ ̀ aṣẹ ̀ dá .
F Kumuyi lo ni ile ẹkọ naa, ti oriṣiriṣi akọle bi #justicefordondavis #deeperlifehighschool ati Pastor Kumuyi ni ariwo rẹ n lọ lori Facebook ati Twitter.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Onimọ eto ilera nipa fifun ọmọ lọyan naa sọ awọn ohun tẹ́ẹ gbúdọ mọ nípa kókó orí ọyàn yín lásìkò fífọ́mọlọ́yàn ati bi ẹ ṣe lee gbe ọmọ si aya.
Kí ló dé tí àìsàn àwọn eniyan mi kò sàn?
Geoffrey Onyeama, ni yoo tele ojogbon Osinbajo lo South Africa.
Iyawo ni ijọ jẹ si Jesu.
Ọjà Àgbáláta ní Badagry rèé, níbití ẹran ejò ti dùn ju ẹran adìẹ lọ Ọlọ́run yóò ṣe ìdájọ́ nkan tó wà láàrin èmi àti Ireti Ajanaku - Tope Alabi A kò jáde ṣe ìwọ́de ìtagbangba mọ́, inú ọkàn wa lá ti máa ṣe ìfẹ̀hónú hàn - Revolution Now Agbébọn yìnbọn pa ọlọ́pàá kan níbùdó àyẹ̀wò ọkọ̀ lójú pópó Nigba to n mẹnuba awọn iṣoro to n ba ẹgbẹ Akọmọlede ati Aṣa Yoruba finra, aarẹ ẹgbẹ naa beere fun atilẹyin awọn ẹlẹyinju aanu, oninu rere, awọn eeyan ti Ọlọrun bẹ igi ọla fun lawujọ ati awọn ileeṣẹ nlanla, lati wa yọ ẹgbẹ naa ni ọfin awọn iṣoro to jin si, nipa aini irinṣẹ to pegede.
Àkọlé àwòrán, Àwọn olóye ní báyìí ló ṣe yẹ kí kànga maa wà ní dídé Àmọ́ nínú ọ̀rọ̀ rẹ̀, agbẹnusọ fún gómìnà ìpínlẹ̀ Kano, Dókítà Abdullahi Ganduje, Aminu Yassar, sọ pé ohun tó ṣẹlẹ̀ kò ní nkankan ṣe pẹ̀lú pé ìyà omi n jẹ ìpínlẹ̀ naa."
Yàrá tí ó kọjú sí ìhà àríwá jẹ́ ti àwọn alufaa tí wọn ń mójútó pẹpẹ; àwọn ni àwọn ọmọ Sadoku.
Bí ẹnikẹ́ni kò bá gbé inú mi, a óo jù ú sóde bí ẹ̀ka, yóo sì gbẹ; wọn óo mú un, wọn óo sì fi dáná, yóo bá jóná.
O ni bayi, ẹlẹwọn ẹgbẹrun meji din meje lawọn ri ka pe wọn ríbi salọ kuro lẹwọn mejeeji to wa ni ipinlẹ Edo.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Disability: Àwọn òbí mi gbìyànjú títí ní kékeré mi ṣùgbọ́n .
“Nítorí náà àwọn ẹranko ìgbẹ́ ati ìkookò ni yóo máa gbé inú Babiloni, ẹyẹ ògòǹgò yóo máa gbé inú rẹ̀.
Ninu oro re, o so pe PDP ni awon ba ja.
Èdùmàrè yìí tún ṣe iṣẹ́ ẹ̀ l’áṣepé, ó fi làákáyè jíìnkí ọmọ ẹ̀dá.
Aare soro naa di mimo ninu iwe ataranse ti o fi sowo si agbenusoro ile igbimo asoju-sofin, ogbeni Yakubu Dogara.
A gbọ́ ohùn kan lórí àwọn òkè gíga,ẹkún ati ẹ̀bẹ̀ àwọn ọmọkunrin Israẹli ni.
Àwọn ológun dojú ìjà kọ ara wọn ní Khartoum Rélùwéè tẹ alágbe kan pa ní Eko Beckham, àgbábọ́ọ́lù tẹ́lẹ̀ rèé tó ń sọ èdè Yorùbá Arabinrin He ni oun n wọ jingi kekere ti wọn n wọ fi bo ẹyinju (Contact lense) ni eyi ti ko jẹ ko ṣeeṣe fun oun lati fọwọ gbo ẹyinju oun ki oun to de ilé iwosan.
Agbẹjọro rẹ, Toyin Ojaomo fi to ileeṣẹ iroyin abẹle kan leti pe Ọgbẹni Magu ko si ni ahamọ mọ.
Koda wọn tun maa n fi agadagodo pa ete mejeeji ẹnu ẹru de mọra wọn, ki wọn ma baa sọrọ si ara wọn, Gbogbo awọn eroja ìnira ti wọn si n lo fawọn ẹru yii lo wa ninu ibudo ise nnkan isẹnbaye lọjọ si ni iranti owo ẹrú, eyi to wa lagbo ile Mobee nilu Badagry, titi di oni oloni.
Bakan naa, ọmọ Naijiria mii wa lara awọn eeyan kan ti wọn fẹsun kan pe wọn ka egboogi oloro ''cocaine'' mọ lọwọ niluu Jeddah.
Ọgbẹni Miller lo ma n kọ awọn ọrọ apilẹkọ ti Trump ma n sọ ni gbangba - o si jẹ gbajugbaja fun ọwọ lile to fi mu ọrọ bi awọn atipo ṣe n wọ ilẹ amẹrika.
Mo ní n óo máa jẹ́ Ọlọrun wọn, àwọn náà óo sì máa jẹ́ eniyan mi; mo ní kí wọn máa tọ ọ̀nà tí mo bá pa láṣẹ fún wọn, kí ó lè dára fún wọn.
O ni dipo oogun orun ṣaaju iṣẹ abẹ ni wọn ba ṣe aṣiṣe gun oun labẹrẹ Formalin ti wọn maa n fun òkú ko ma baa bàjẹ́.
Lẹ́yìn ò rẹyìn, Seyi Makinde bori arun Coronavirus Kí lo mọ̀ nípa fẹntilétọ̀, ohun èlò aṣèrànwọ́ èémí Èyí ni ìdí tí coronavirus ṣe n pa àwọn kan, tí kò sì pa àwọn kan Coronavirus- Atọ́nà bí nkàn ṣe ń lọ ní Afirika Ni apapọ ẹniyan mejilelọgbọnlenigba lo ti ni arun Coronavirus ni Naijiria, ti ẹniyan mẹtalelọgbọn si ti ri iwosan gba, amọ ti ẹniyan marun si ti ku.
Ohun akọkọ ni lati lọ si ile iwosan lati gba itọju Ki o to sun ni ale, ẹ kọkọ wẹ naa.
Ó sọ pé bàbá òun kò tilẹ̀ mọ nkankan tó n lọ ní agbègbè rẹ̀ mọ́.
Ogbeni Shifeta ti ro awon eniyan lati maa pon omi lo sile won fun wiwe tabi fo  aso won , ki o le dekun ikolu burku yii.
Tiger Woods ló borí ní ami ẹ̀yẹ Masters ti 2019 ní Augusta
fi da aabo bo awọn ara ilu nitori pe ijọba apapọ ko le da gbogbo ẹ ṣe.
adari iko omo ogun gege bi awon akegbe won okunrin.
Ninu fidio BBC News Yoruba fun ayajọ yii, awọn obinrin ni oriṣiriṣi ilana iṣẹ aje gbogbo sọrọ lori ipenija ti wọn n dojukọ; paap julọ laarin awọn ọkunrin lẹnu iṣẹ aje gbogbo.
Ọlọrun ni ó ti yàn án bẹ́ẹ̀ láti ilẹ̀ wá.
Ẹ yé irọ́ pa, mí o fún Super Eagles ní ẹbùn owó kánkan -Sanwo Olu Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Fulani Kidnapping: Owó púpọ̀ la san kí wọ́n tó fi mi sílẹ̀ Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Gẹ́gẹ́ bí ọ̀rọ̀ọ Debjani, a f’ẹ̀sùn-un ìgbẹ̀mí ènìyàn púpọ̀ kàn án ní abúlée Cherekali tí ó wà ní kìlómità 180 láti Guwahati, olú-ìlúu India ti apáa ìlà-oòrùn.
Ẹmu mímu kìí jẹ́ kí ènìyàn ní ìtọ̀ súgà Harrison Omonhinmin ní bótilẹ̀ jẹ́ pé ẹmu ni súgà, síbẹ̀ kìí fún ènìyàn ni ìts súgà bi àwọn ọti míràn ṣe máa n ṣe.
“Nítorí náà, gbogbo bí ẹ bá ti fẹ́ kí eniyan ṣe si yín, bẹ́ẹ̀ gan-an ni kí ẹ̀yin náà ṣe sí wọn.
Pẹlu iye awọn eeyan tuntun yii, o ti le ni ẹgbẹrun mẹtalelaadọta eeyan to ti larun naa lorilẹede Naijiria bayii.
Lọ sí Befrienders fún ojú òpó ìbánisọ̀rọ̀ ìdènà ìparaẹni ní orílẹ̀-èdèe rẹ.
O wà ninu Edẹni, ọgbà Ọlọrun.
Sibẹ, ẹ tún ń rú òfin ọjọ́ ìsinmi, ẹ̀ ń fa ìrúnú Ọlọrun sórí Israẹli.
" A ri inaki gẹ̀gẹ̀ bii ara ẹranko to se pataki jù, ìdí niyi ta fi nílò lati kà wọn, ka si ri ipò tawọn ìnàkí ọhun wa lọ́wọ́lọ́wọ́, eyi yoo se afihan iyatọ̀ to wa laarin ohun taa mọ̀ nipa awọn inaki yii tẹ́lẹ̀ rí""."
Awa kò ní Oludije bíi o ba o pa kánkan.
Bí àpamọ́ àlọ́ àti ìtàn àtọwọ́dọ́wọ́ ṣe mú ọ̀rọ̀ àyíká di mímọ̀ ní Mekong
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Mummy calm down: Ìyá Ore sọ pé gbogbo ìgbà tí óun bá n bá a wí ló ma n ṣe àwàdà Ajagunfẹyinti Olayinka Olayanju ni ko si ohun to nira ninu fifi orukọ silẹ lori ayelujara nitori ko si ibudo itakun agbaye ti wọn ba lọ lati fi orúkọ silẹ, ti wọn ko ni seranwọ lati ba wọn ṣe e.
Sí Timoti ọmọ mi tòótọ́ ninu igbagbọ.
Bí ó ti ń sọ̀rọ̀, àwọn kan wá láti ọ̀dọ̀ alákòóso ilé ìpàdé, wọ́n ní, “Ọdọmọdebinrin rẹ ti kú.
Ẹ masẹ pa ara yin nitori ipenija yii.
N óo dúró, n óo máa retí ohun tí yóo sọ fún mi, ati irú èsì tí èmi náà óo fún un.
Ni odun mọkanla sẹyin ni wọn da ileeṣẹ Tesla silẹ, ki o to wa di gbajugbaja ileeṣe to n ṣe ọkọ ẹlẹntiriki lagbaye lọdun 2019.
Àwọn àgbààgbà Sioni jókòó lórí ilẹ̀, wọ́n dákẹ́ rọ́rọ́,wọ́n ku eruku sórí,wọ́n sì wọ aṣọ ọ̀fọ̀.
“Mo n gbiyanju lati ma se owo orile ede yii basu –basu,Mo n jade nigba ti o ba je dandan.
Ẹ fójú lóúnjẹ níbi African Drum Festival 2019 A fa ọmọ ọdún márùn-ún f'ọ́kọ a sì fẹ́ ṣe bẹ́ẹ̀ fáwọn àbùrò rẹ̀ Ọ̀gá àgbà iléèṣẹ́ ọlọ́pàá dín wákàtí iṣẹ́ ọlọ́pàá kù Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Kò bá mi lára mu kèèyàn máa gbé ayé ẹ̀ sáfẹ́fẹ́' Ajafẹtọ ọmọniyan naa ni ohun to buru jai ni ki wọn fi owo to yẹ ki wọn fi tun ilu se, lọ maa fi se ipade ti wọn ṣi wà lori alefa.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Kayeefi: Facebook ni Wolii Arole Jesu fi tàn an wọ agbo, orí rẹ̀ ni wọ́n fi s'owó Ogunye ni awọn aṣofin kuna ninu isẹ wọn, bakan naa ni awọn ti wọn yan si ipo naa ko le e se ohun to tọ, nitori wọn ko loye lbi ti wọn ti fẹ ṣe iṣẹ naa.
Àkọlé àwòrán, Leah Sharibu wa lara awọn ọmọbinrin ile iwe Dapchi ti ikọ agbesunmọmi Boko Haram jigbe ni Osu Keji, ọdun 2018.
lo sẹburu awon  ikọ ọlọpaa lasiko ti won
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ẹgbẹ́ IMN:ọmọ ẹgbẹ́ wa mẹ́tàlá ní ọlọ́pàá yìnbọn pa níbi ìwọ́de ìdárò Ashura 10 Owewe 2019 Oríṣun àwòrán, Google Àkọlé àwòrán, Aarẹ Buhari ati Sheikh Ibrahim El-Zakzakky Fakinfa laarin ọlọpaa Naijiria ati ẹgbẹ ọmọ Shiite( IMN) tun ti gbọna mi yọ pẹlu bi ẹgbẹ naa ti ṣe ni ọlọpaa yinbọn pa ọmọ ẹgbẹ awọn mẹtala.
Eruku sọ lálá níbi ayẹyẹ ìgbéyàwó Lizzy Anjorin, àwòrán àti fídíò nìyíì Èèmọ̀!
Rafiu nigba to n ba BBC Yoruba sọrọ wi pe igbese naa ku die kaato nitori ijọba ko gbe igbese to yege lati yanju isoro ọna apapa ti awọn ọkọ nlanla ma n pejọ pọ si ni oju ọna.
Tori naa afi ko ra a lati ilu Oyinbo nipasẹ awọn ọrẹ rẹ.
 Ìlànà àti ètò wà tí wọ ́ n ń tẹ ̀ lé láti sin ara wọn tó papòdà .
monamona to n se seke-seke lorile ede yii.
Wo ibi fún èsì ìdìbò yíyan aàrẹ tuntun ní orílẹ̀-èdè Ghana Ọlọ́pàá, sójà yabo Lekki Toll Plaza láti dènà ìfẹ̀hónúhàn míràn Ìdí rèé táwọn àkàndá ẹ̀dá fi dí iwájú iléeṣẹ́ ìjọba ìpínlẹ̀ Oyo pa l'Agodi n'Ibadan A kò ní padà sílé ìwé àyàfi t́i ìjọba bá san owó oṣù tó jẹ wá - ASUU Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ojú mi ti rí lọ́pọ̀ lọpọ̀, àmọ́ mo dúpẹ́ pé mo ti pé ọdún márùn ún lórí oyé- Ooni Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
igbesẹ ti ẹ gbe, pupo ninu awon eniyan lo rin irinajo lati lọ dibo, mo tun gbọ
Àwọn òbí mí kọ́kọ́ tako kí n má lu ìlú gẹ́gẹ́ bí obìrin - Ayansike Oluwo kọ̀ láti sọ̀rọ̀ lórí àwọn afọbajẹ tó fẹ́ yọ ọ́ nípò, aráàlú fọ́n síta láti fẹ̀hónú hàn Owó ilé ẹ̀kọ́ Fáṣítì Ìpínlẹ̀ Ondo ló kéré jùlọ ní Nàìjíríà - Akeredolu Ọgbẹni Kalejaye sọ ninu atẹjade ọhun pe Wike ko mọ bi eto idibo ṣe maa n lọ ni irọwọ-rọsẹ lo jẹ ko sọ pe idibo gomina ipinlẹ Edo to waye laipẹ yii lo lọ ni irọwọ rọsẹ julọ.
O man n sọ eroungba rẹ lai woju ẹnikẹni Muhammadu Sanusi jẹ ẹni kan ti kii bẹru ati sọ ohun to ba wa ninu ọkan rẹ fun ijọba lai bikita ohun to le tẹyin rẹ jade.
Linda Fairstein jẹ onkọwe ọmọ ilẹ̀ Amẹrika.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Odumakin sọrọ lori Fulani darandaran Babandede sọ ọrọ yii lasiko ikẹkọọ-jade fun awọn ọmọ ogun mẹrindin ni irinwo lori ọrọ ẹṣọ aabo fun iwọle-ijade awọn eniyan ni Naijiria.
Ìdí rèé tí Aisha Buhari kò tíì padà sí Nàìjíríà- Iléeṣẹ́ ààrẹ Osinbajo kò lẹ́tọ́ lábẹ́ òfin láti yọ amúnitì ara rẹ̀ - Amòfin Ajulo Ọpẹ́ o!
Wòlíì Kasali sọ̀rọ̀ nípa awuyewuye pé ó lé ìyàwó rẹ̀ jáde nílé
Lakọkọ, oju opo naa ni https://www.
Ṣé o óo fún Israẹli ní ìṣẹ́gun?
Ede Yoruba dùn púpọ̀ ṣugbọn laisi àmì ohùn, o ṣeéṣe kó ma yé èèyàn dáadáa.
36 Nítorí-èyí, ẹ̀yin le jẹ́rìí pé ẹ ti gbọ́ ohùn mi, ẹ̀yin sì mọ àwọn ọ̀rọ̀ mi.
Bákan náà ni o má n dà bi gírísiì tí gbogbo ríkèé-ríkèé ojú ńlo láti ṣiṣẹ́ ati omi to n ran oju lọ́wọ́ láti ṣẹ́.
Láti ìṣẹ̀dálẹ̀ ayé, takọ-tabo ni Ọlọrun dá wọn.
Cameroon, Tanzania, Uganda, Ethiopia, Nigeria, àti Benin ti ní Ìtìpa Ẹ̀rọ-ayélujára, ìjọba ti fi owó-orí lé lílo búlọ́ọ̀gù àti ẹ̀rọ-alátagbà, wọ́n sì ti fi ọwọ́ ṣìgún òfin mú oníròyìn.
Biṣọbu ọhun sọ fun BBC Yoruba pe adura nikan ṣoṣo lo le dẹkun arun Coronavirus, kiiṣe titi ile ijọsin pa.
Lẹyin ọpọlọpọ iṣẹ iwadii yii lo mu abajade ihuwasi mẹjọ wọnyii jade to yẹ ki onikaluku woye daadaa.
O lọ sile iwe Christs'School ni Ado Ekiti to jẹ olu ilu ipinlẹ Ekiti lọdun 1975 si 1980.
O sọ fun BBC pe ipọnju ati idaamu lo mu ki oun gbe ọmọ ẹlẹẹkarun sọnu.
Ni Ọjọ Satide lorilẹ-ede Lẹbanon, ẹgbẹlẹgbẹ eniyan lo korajọ lati fẹhonuhan takọ aibikita ijọba si iṣẹlẹ to waye naa.
Olugbe ijọba ibilẹ Tangaza kan nipinlẹ Sokoto ti o ba BBC Hausa sọrọ ṣalaye pe nnkan bi oṣu meji sẹyin ni awọn ẹgbẹ naa wọn awọn ileto kan ni ijọba ibilẹ naa.
Àkọlé àwòrán, Inú ọgbà MMA2 Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ sí: Ademọla Adeleke: Kò sí èròngbà láti yọ Bukola Saraki 'A gbọ́dọ̀ gbé ìgbésẹ̀ tí ìpínlẹ̀ Eko gbé nípa èdè Yoruba’ Atiku ń wá igbákejì, ta ni yóò jẹ́?
Ohun taa gbọ ni pe o fi aṣọ kan ṣe okun ti o si so o mọ ọrun rẹ eleyi to sokunfa iku rẹ.
Yóo pa àgbò ẹbọ ìmúkúrò ẹ̀bi, yóo sì mú díẹ̀ ninu ẹ̀jẹ̀ rẹ̀, yóo fi kan ṣóńṣó etí ọ̀tún ẹni tí wọ́n fẹ́ sọ di mímọ́ ati àtàǹpàkò ọwọ́ ọ̀tún rẹ̀, ati àtàǹpàkò ẹsẹ̀ ọ̀tún rẹ̀.
Òkúta ńlá ńlá ni wọn tò si ẹ̀bá ọ̀nà náà apá ọ̀tun àti apá òsì.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Francisca Ordega nigba to n gba bọọlu fun ikọ Sydney FC Ọjọ ẹsan Super Falcons lara France Ordega ranti bi France ṣe lu Naijiria ni alubami ni bii ọdun sẹyin, nitorinaa, ohun kan ṣoṣo to wa lọkan rẹ ni eṣan.
Bẹtani kò jìnnà sí Jerusalẹmu, kò ju ibùsọ̀ meji lọ.
Kò sí ẹnikẹ́ni tí ó lè já a gbà mọ́ Baba mi lọ́wọ́.
Lẹ́yìn èyí ló bẹ̀rẹ̀ sí ní ráńṣẹ́ sí àwọn ènìyàn lórúkọ ayá ààrẹ Muhammadu Buhari.
Agbẹnusọ Ile naa tun fi da awọn oṣiṣẹ loju pe gbgbo ipa ni ijọba n sa ki aye le rọrun fun awọn oṣiṣẹ yii.
‘Bùhárí kùnà láti gbógun tìwà ìjẹkujẹ’ 'Èrò ọ̀dọ́ Kwara ṣọ̀tọ̀ọ̀tọ̀ lórí ọ̀rọ̀ Saraki' Ṣé lóòótọ́ ni ọkọ̀ gba àárín Tinubu àti Ambọde l'Eko?
2019 Election Update: Ìgbìmọ̀ ìgbẹ́jọ́ fún Atiku láyè láti ṣàyẹ̀wò ohun èlò ìdìbò ààrẹ
Niwọn igba to si jẹ pe isu atẹnumọran kan kii jona, eyi lo sokunfa bibi oju opo BBC Yoruba bii ọmọ tuntun jojolo.
Tó bá jẹ́ pé orísun kan nàá ni gbogbo ìwádìí rẹ̀ n tọ́ka sí, a jẹ́ wí pé ó ṣeéṣe kó ní bayo-báyó nínú.
Modele Fatoyinbo, ìyàwó Biodun Fatoyinbo ti wọn fẹ́sùn kàn ni COZA ni kò ṣeéṣe fún ọkọ òun láti fipá bá ẹnikeni lòpọ̀.
”Àwọn oníṣẹ́ náà pada lọ jíṣẹ́ fún Benhadadi ọba.
Mo mọ ohun tí n óo ṣe, kí àwọn eniyan lè gbà mí sinu ilé wọn nígbà tí wọ́n bá gba iṣẹ́ lọ́wọ́ mi.
Eyi tumọ si pe kaka ki ẹlulu ma dun ọbẹ, tapa titan rẹ ni yoo run si Oríṣun àwòrán, AFP Àkọlé àwòrán, Inu ẹni kii dun, ka pa mọra.
Àwọn nǹkan wọnyi ni wọ́n ń sọ eniyan di aláìmọ́; kí eniyan jẹun láì wẹ ọwọ́ kò lè sọ eniyan di aláìmọ́.
Eyi ko tilẹ jẹ ki n fura pe nkankan ṣajoji ninu igbeyawo wa.
Àwọn orílẹ̀-èdè mìíràn yóo rí ìhòòhò rẹojú yóo sì tì ọ́.
Àwọn eniyan yóo sì máa gbé ìlú yìí títí ayé.
 Ẹ ̀ tẹ ̀ ni ó rọ ̀ mọ ́ àbùkù ìbálópọ ̀ fún ọ ̀ pọ ̀ ìtàn , tí ó jẹ ́ ìdènà fún ìfi-ara-ẹni sùn àti ìtọjú lọ ́ gán .
13 Èmi yíò fún wọn ní agbára pé kí wọn le kíyèsíi kí wọn sì wo àwọn nkan wọ̀nyí bí wọn ṣe ri;
Cisse bẹ́ sí Kàǹga nítori fóònù N3,000 Ẹyin ni wọ́n fi n gba ìbále ẹlòmiran lára wa ki a to lọ pàde àwọn oníbara Ọmọ melo ni awọn ara orilẹede mii rinrinajo lọ bi si ilẹ Amẹrika?
Iṣẹ́ bọ́ lọ́wọ́ ọlọ́pàá tó pa Kọ́pà l'Abuja Àwọn onífàyàwọ́ ń lo Whatsapp láti ta heroin Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Stella Akinsọ: Àwọn Ìwé Mímọ́ fi àsẹ sí ìfètòsọ́mọbíbí Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ekiti Election: Ìjọba ìbílẹ̀ làwọn òsìsẹ́ Inec yóó sùn mọ́jú ọjọ́ ìbò Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, #EkitiDecides: Sẹgun Adewale ní ìpèsè ohun ìdẹ̀rùn yóò bá ìfẹ́ aráàlú mu Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ekiti Election: Àwọn ohun èèlò ìdìbò ń dé síjọba ìbílẹ̀ Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
40 Àti nísisìyí, nítori àkọsílẹ̀ èyí tí a fín sí orí àwọn àwo ti Néfì ṣe pàtàkì jùlọ nípa àwọn ohun tí, nínú ọgbọ́n mi, èmi yíó mú wá sí ìmọ̀ àwọn ènìyàn nínú àkọsílẹ̀ yìí—
Igba ti a ri iyawo aarẹ kẹyin ni ita gbangba ni asiko adura ọdun Eid-el-Kabir pẹlu awọn idile rẹ nile Aso Villa nilu Abuja.
Bẹ́ẹ̀ gan-an ni OLUWA yóo ṣe sí ìjọba yòókù tí ẹ óo gbà.
Bi awọn kan ti ṣe n ṣe n bu ẹnu atẹ lu iwa yi lawọn miran n ni kii ṣe oun toju o riiri.
Akojọpọ aworan yii wa lati ileesẹ BBC Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Ọna marun un lati dèna Lassa Fever Aisan iba ọrẹrẹ jẹ aisan ti ko ni ẹrọ, amọ ti o ni itọju ti ẹni to ba ni aisan naa ba tete lọ si ile iwosan lati fi ara rẹ han.
Eji Gbadero: Ó pa Raji Oba nítorí ilẹ̀ nìjọba bá yẹgi fún un
Lagos-Ibadan Express: Ènì mẹ́rin kú, mẹrin míràn farapa nínú ìjàmbá ọkọ̀
 Àwọn oríṣi méjì pàtakì ni ó wà : àjẹsára ẹlẹ ́ ẹ ̀ kún sẹ ́ ẹ ̀ lì àti àjẹsára aláìní sẹ ́ ẹ ̀ lì .
" SERAP ni ofin CAMA ni ofin ijẹgaba le ni lori to tii buru julọ ninu itan orilẹede Naijiria, eyi ti wọn yoo tun lo lati tẹ ẹtọ araalu loju mọlẹ.
O salaye pe ahesọ ọrọ ni pe onibara mi beere owo gba ma-binu lati ọwọ Pasitọ Biodun Fatoyinbo."
 nígbà tí ó sì ṣe ó wọ káà lọ .
"Àwon ìsòrí olè métèèta wònyí kìí lo ohun ìjà kankan, àwon gan ni òwe ""Ìjànbá solè oníléjí"" bámu nítorí pé ó rorún fún Olóhun tí ó bá gbóyà láti mú èyíkéyìí nínú àwon olè wònyí."
Ipinnu iyansipo naa ni orile-ede China fi mule pe, ki akonimoogba tuntun ohun ran iko naa lowo lati pegede fun boolu afesegba ninu idije Olympiki  ti yoo waye lodun 2020 (2020 Olympic Games football tournament).
O ni ki a ri asiko idejumọle yi bi eleyi ti a o fi jẹ ki irẹpọ tubọ rinlẹ ninu mọlẹbi wa.
Emi ni mo maa n kọ ọrọ awọn orin ere mi, ki n to o gbe fun aburo mi Amin mi to n kọrin lati kọ ọ.
Gbogbo inú ilé ìsìn náà patapata ni wọ́n fi wúrà bò, ati pẹpẹ tí ó wà ninu Ibi-Mímọ́-Jùlọ.
Wọn ke si ijọba lati ri si ọrọ awọn obinrin to n ta paraga lawọju ki adinku le de ba ipa buburu ti imukumu n ko laarin wa.
O fọn rere Walter Carrington pe o gbiyanju ipa rẹ lati rii pe isejọba awa ara wa ni Naijiria fi ẹsẹ mulẹ nigba naa.
Báwo ni wọn yóo ṣe gbúròó rẹ̀ láìsí àwọn tí ó ń kéde rẹ̀?
Lara wọn lati ri ojọgbọn Shuaib Oba Abdulraheem to o fi igba kan jẹ Alakoso Yunifasiti ilu Ilorin.
''O dabi ẹni pe ajoji ni awọn agbebọn to hu iwa yi.
" Alfred ṣalaye pe awọn akẹkọọ ọhun gun lara awọn infijilatọ naa ni 'compass' lẹyin ọrun.
O ti mú kí á sá fún àwọn ọ̀tá wa lójú ogun;àwọn tí ó kórìíra wa sì fi ẹrù wa ṣe ìkógun.
Asán ni wọ́n, ohun ìṣìnà sì ni wọ́n;ní àkókò ìjẹníyà wọn, wọn yóo parun ni.
Bakan naa ni awọn kan ni asiko tun ti to lati ji ipolongo #EndSARS dide pada nitori igbesẹ ti ọga ọlọpaa gbe yii, nitori pe fifi opin si SARS patapata ni awọn ọmọ Naijiria n fẹ.
Ṣé o rí i bí ó tí ń lọ ṣe àgbèrè lórí gbogbo òkè ati lábẹ́ gbogbo igi tútù?
Hushpuppi naa ko gbẹyin ninu iranti Dagrin.
Super Eagles yoo koju iko agbaboolu Poland laale oni, ni ona lati gbaradi ni kikun fun ifesewonse idije boolu agbaye todun ti a wa yii.
Kí n wà ninu oyún ninu ìyá mi títí ayé.
Ó ń sọ fún àwọn eniyan pé kí wọ́n gba ẹni tí ó ń bọ̀ lẹ́yìn òun gbọ́.
Facebook wọ gau lori aawọ data
Ó kọ́kọ́ ju àwọran òun àti ọmọbìnrinkan sórí àtagbà ìkànsiraẹni Instagram rẹ pẹlu àmì ifẹ́ láì kọ àkọlé kankan si.
Ó rán Eliakimu tí ń ṣàkóso ààfin, ati Ṣebina akọ̀wé ilé ẹjọ́ ati àwọn àgbààgbà alufaa, wọ́n da aṣọ ọ̀fọ̀ bora, wọ́n lọ sọ́dọ̀ wolii Aisaya, ọmọ Amosi.
Láti ibẹ̀ wọ́n wọ ọkọ̀ ojú omi lọ sí Kipru.
Kii ṣe iroyin tuntun mọ bayii pe Eyitayọ Jẹgẹdẹ ni wọn dibo yan gẹgẹ bii ẹni ti yoo gbe aṣia ẹgbẹ oṣelu naa lasiko idibo gomina ipinlẹOndo ti yoo waye lọjs Kẹwaa oṣu kẹwaa ọdun 2020.
pé yóo gbà wá lọ́wọ́ àwọn ọ̀tá wa,ati pé yóo fún wa ní anfaani láti máa sìn ín láì fòyà,
Ọgbẹni Aremu sọ pe o ṣe pataki lati wo fọnran finifini nitori ọpọ eeyan lo n fi ọgbọn alumọnkọrọi gbe fidio jade lori ayelujara.
Ọ̀nà tí a óo fi mọ̀ pé a jẹ́ ẹni òtítọ́ nìyí; níwájú Ọlọrun pàápàá ọkàn wa yóo balẹ̀.
Nítorí ẹni tí ó bá wá sọ́dọ̀ Ọlọrun níláti gbàgbọ́ pé Ọlọrun wà, ati pé òun ni ó ń fún àwọn tí ó bá ń wá a ní èrè.
Àsikò tó lati dáwọ́ àṣà ṣì ṣúpó dúró nitori obinrin ki ṣe ẹrú tàbi ẹrù ti wọn njẹ mọ́ ogún.
Ẹ̀mí burúkú láti ọ̀dọ̀ OLUWA ń dà ọ́ láàmú; 
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, #JusticeforTina: Àwọn obi Tina Ezekwe ń bèrè fún ìdájọ́ òdodo pẹ̀lú omijé lójú Ọkan lara awọn ọkunrin to jẹ aṣoju ẹgbẹ naa, Arakunrin Hamzat Kọlawọle so wi pe iwa ti ko bojumu t ko si yẹ awujọ ni iwa ifipabanilopọ.
Bi àwọn mọ̀lẹ́bí ṣe ń rẹ ìyàwò olóògbé lẹ́kún, bẹ́ẹ̀ ni awọn ọmọ olóògbé ń ṣe ìdárò rẹ̀.
Genevieve fikun ọrọ rẹ pe ewu n bẹ loko longẹ fun igbeyawo ti ọkunrin ba fẹ obinrin nitori Ibalopọ."
koju lowo bayii, paapaajulo ni eka eto aabo.
Nítorí náà, ìwọ ọ̀rẹ́ mi ojú fèrèsé, ti inú Ẹlẹ́dàá yé Ẹlẹ́dàá kí ó tó dá ènìyàn bí ó ti dá a.
"O fun pe si awọn to wa ni ijọba pe ""ẹ bẹrẹ ẹkọ ọfẹ, ilera ọfẹ, owo ẹ wa bayii""."
Orílẹ̀ède Ghana fí Asamoah Gyan jẹ Balogun káàfàtà ikọ Black Stars
ni o seese ki o tun fara gba isele ijamba naa bi o owo re se n lo.
“Nisinsinyii, Ọlọrun mi, bojúwò wá kí o sì tẹ́tí sí adura tí wọ́n bá gbà níhìn-ín.
Ọjọ́ náà yóo dé bí ọjọ́ ìparun láti ọ̀dọ̀ Olodumare.
 tí ẹni tí ó bá kọ àyọkà bá pa ojú ewé rẹ ( tí kìí ṣe ojú ewé oníṣẹ ́ tàbí ojú ewé ẹ ̀ ka ) , a lè kaa sí ìbeerè fún píparẹ ́ a ó gbẹ ́ , { { db-blanked } } sí ojú ewé náa ( wo g7 ) .
Lagos Jumat Mosques: Títì pa ni ìlẹ̀kùn àwọn mọ́ṣáláàṣí kan wà ní ìpínlẹ̀ Eko lásìkò ìrun Jímọ̀
Atupalẹ ẹbun fun ẹni to ba gbade BBNaija ọdun yii ni ọgbọn miliọnu naira(N30m), ile pẹtẹẹsi oni yara meji, ọkọ SUV kan, irinajo afẹ si ilu Dublin lorilẹede Scotland atawọn ọpọlọpọ ohun elo ninu ile Wo nkan ti awọn olukopa to ti já kuro lori eto naa jẹ: Triky tee O jẹ N3,359,000 Ohun elo inu ile Irinajo silu Dubai fun ayẹyẹ One Africa Music Fest Ọ̀dà Ẹẹdẹgbẹta Dọla owo Bitcoin Ozo O jẹ N2,780,000 gẹgẹ bi ẹbun owo Ọkọ ayọkẹlẹ Irinajo silu Abuja Ẹẹdẹgbẹta Dọla owo Bitcoin Irinajo silu Dubai fun ayẹyẹ One Africa Music Fest Prince Oun naa jẹ N2,570,000 Ohun elo inu ile Irinajo silu Abuja Ẹẹdẹgbẹta Dọla owo Bitcoin Irinajo silu Dubai fun ayẹyẹ One Africa Music Fest Kiddwaya O jẹ ẹbun owo: N1,720,000 Foonu tuntun Ọ̀dà Ẹẹdẹgbẹta Dọla owo Bitcoin Wathoni O jẹ ẹbun owo: N1,250,000 Eroja iṣaraloge Ẹẹdẹgbẹta Dọla owo Bitcoin Brighto O jẹ ẹbun owo: N970,000 Ọ̀dà Ẹẹdẹgbẹta Dọla owo Bitcoin Tolanibaj O jẹ ẹbun owo: N825,000 Irinajo silu Abuja Ẹẹdẹgbẹta Dọla owo Bitcoin Praise O jẹ ẹbun owo: N770,000 Ẹẹdẹgbẹta Dọla owo Bitcoin Lucy O jẹ ẹbun owo: N570,000 Ọ̀dà Ẹẹdẹgbẹta Dọla owo Bitcoin Kaisha O jẹ ẹbun owo: N570,000 Ọ̀dà Ẹẹdẹgbẹta Dọla owo Bitcoin Tochi O jẹ ẹbun owo: N220,000 Ẹẹdẹgbẹta Dọla owo Bitcoin Eric Ẹẹdẹgbẹta Dọla owo Bitcoin Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Ìtara OLUWA àwọn ọmọ ogun ni yóo ṣe èyí.
EFCC fẹsun jiji owo ilu lọ silẹ okeere kan Diezani Alison-Madueke: Ara awọn gbajugbaja ẹjọ ti ajọ EFCC ṣe lasiko ti Ibrahim Magu jẹ adele alaga ajọ naa ni ẹjọ minisita epo rọbi tẹlẹ, Diezani Alison-Madueke.
Ilé náà kún fún ọpọlọpọ eniyan, lọkunrin ati lobinrin; gbogbo àwọn ọba ilẹ̀ Filistini ni wọ́n wà níbẹ̀.
O tun ni awọn to n pẹgan oludije ẹgbẹ oṣelu Republican to n gbe apoti ibo fun saa keji ko fẹran awọn alatilẹyin rẹ.
"A pa di dandan fun gbogbo olukopa lati fọ ọwọ wọn l'ẹnu ọna, ati lati fi ọṣẹ apakokoro pa ọwọ ki wọn o to o wọle, lai yọ ẹnikẹni silẹ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ẹ wo àwọn ọmọ tí bàbá wọn fi s'ílẹ̀ sálọ ní Ghana Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Ẹ wo àwọn ọmọ tí bàbá wọn fi s'ílẹ̀ sálọ ní Ghana 13 Ìgbé 2018 Ọ̀pọ lo mọ ipalara ti iwakusa ni,wọn ko mọ ipa ti lilọ awọn ara China kuro ni Ghana lodun 2013, ni lori ihuwasi awọn ọmọ ti won fi silẹ.
Awọn ibeere wa lorisirisi ti ko tii si idahun si.
Ní ọdún kẹtadinlogun tí Jehoṣafati, ọba Juda, gun orí oyè ni Ahasaya, ọmọ Ahabu, gun orí oyè ní ilẹ̀ Israẹli, ó sì jọba ní Samaria fún ọdún meji.
Ni Ọjọ Ẹ̀ti, eniyan to le ni ẹgbẹrun (1,074) lo tun ṣẹṣẹ lugbadi arun ohun kaakiri orilẹede Naijiria.
Awọn mẹwaa miiran ti wọn jọ mu ni wọn n duro fun idajọ bayii.
Olówó-ayé kò wí ju báyìí lọ, Olódùmarè sì gbọ láti ọ̀run alákeji, nítorí kò sí ènìyàn ksn tí ó da bi màlákà, bẹ́ẹ̀ ni kò si aláfẹ̀hìntì kan tí o da bi Ọlọ́run Ọba.
Ẹ gun òkè odò Jọdani wá sí Jẹriko, àwọn ará Jẹriko sì gbógun tì yín, ati àwọn ará Amori, àwọn ará Perisi, àwọn ará Kenaani, àwọn ará Hiti, àwọn ará Girigaṣi, àwọn ará Hifi, ati àwọn ará Jebusi, mo sì fi wọ́n lé yín lọ́wọ́.
O din ni ida marun awọn eeyan ipinlẹ bii Borno, Zamfara, Kano, Abia ati ipinlẹ Eko ti wọn n ṣe igbọnsẹ si itagbangba.
 “Mi o ni ko lati towobo iwe ibasepo olojo pipe pelu iko yii, ti mo ba ri
Ile naa ko jina si papakọ ofurufu to fẹ ba si rara.
Ejò lé àwọn aṣòfin ìpínlẹ̀ Ondo kúrò nípàdé Ìjọba ti bẹ̀rẹ̀ sí báwọn tó gbé òṣìṣẹ́ aláàánú mẹ́fà sọ̀rọ̀- Garba Shehu Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Kayeefi: Facebook ni Wolii Arole Jesu fi tàn an wọ agbo, orí rẹ̀ ni wọ́n fi s'owó Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Bakan naa ni Sanwo-Olu ni olori ileesẹ ọmọ ologun ilẹ wa ti pe oun lori isẹlẹ to waye lọjọ Isẹgun ọhun.
Ṣùgbọ́n ní alẹ́ ọjọ́ tí ètò náà ku ọ̀la, Shabuyeva sọ̀rọ̀ pé òun gba ìpè àjèjì láti orí òpó ẹ̀rọ-ìbánisọ̀rọ̀ kan tí kò ṣe é dámọ̀, ẹni náà sì sọ fún òun pé bí òun bá tẹ̀síwajú pẹ̀lú ètò náà bí ó ṣe ti pinnu, wọ́n máa fi igi ìgbábọ́ọ̀lù-afọwọ́jù pàdé àwọn àlejò rẹ ní ìta ilé-iṣẹ́ náà.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Africa Eye: Coronavirus di adákẹ́jà ní Somalia, ikú ọ̀wọ́ọ̀wọ́ ń peléke si Gbogbo awọn isẹlẹ yii si ni olori ana nile asoju-sofin fi ni o mu ki oun ko aasa oun kuro ninu ẹgbẹ oselu PDP lọ si APC.
Lara awọn iṣẹ ti yoo maa ṣe lẹnu ipo tuntun yii ni lilewaju ikọ orilẹede Naijiria lọ si igbimọ ọrọ aje lajọ OPEC.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ìgbeyàwó túka nígbà tí afipábánilópọ̀ fi fídíò aya àfẹ́sọ́nà sórí ayélujára Sotitobire: Ojú àwọn Wòlí tó tí lọ sẹ́wọ̀n lórí ẹ̀sùn ọdaràn tẹ́lẹ̀ rèé Tí wọ́n bá kó owó wá fun yín lásìkò ìdìbò, owó tí wọ́n jí ni o, ẹ gbà á àmọ́.
Àṣepọ̀ ni wọ́n ṣe òun ati ìtẹ́dìí rẹ̀.
Nnamdi Azikwe Oloye Benjamin Nnamdi Azikwe ti gbogbo eeyan mọ si Zik, ni wọn bi ni ọjọ kẹrindinlogun, oṣu kọkanla, ọdun 1904.
Moabu wá di ẹni yẹ̀yẹ́ ati ẹni àríbẹ̀rù fún gbogbo àwọn tí wọ́n yí i ká.
Àwọn eniyan ti gbọ́, wọ́n wárìrì,jìnnìjìnnì sì dà bo gbogbo àwọn olùgbé ilẹ̀ Filistini.
'Ọkọ mi yọ kindinrin mi lati rọpo owo ori' Ope Aiyeọla: Nkan to pa emi ati Baba Suwe pọ O jẹ ọkan lara awọn oserebirin India diẹ ti wọn se awọn fiimu to milu titi lai ri atilẹyin akikanju ọkunrin kankan.
Ẹgbẹrun meji ololufẹ ẹgbẹ agbabọọlu Arsenal to wo ere bọọlu naa lo fi aidunnu wọn han sawọn agbabọọlu ati akọnimọọgba wọn, Mikel Arteta lẹyin ifẹsẹwọnsẹ naa.
O wa tun fi kun pe ara ilu ni lati fowosowopo pelu ijoba
Ìlérí tó dájú ni ìlérí OLUWA,ó dàbí fadaka tí a yọ́ ninu iná ìléru amọ̀,tí a dà ninu iná nígbà meje.
Wọ́n mọ òpó sí ara ògiri Tẹmpili yíká, kí wọn baà lè gba àwọn yàrá dúró kí ó má baà jẹ́ pé ògiri Tẹmpili ni óo gbé wọn ró.
Ọwọ awọn to ju idọti silẹ la ba nibẹ: Lọjọ kẹẹdọgbọn, oṣu kọkanla, awọn oṣiṣẹ to n para inu ọgba naa ba oku igala naa ti ọjọ ori rẹ́ to ọdun mẹwaa nibi to ku si.
Inú Abrahamu baba yín dùn láti rí àkókò wíwá mi, ó rí i, ó sì yọ̀.
Gẹ́gẹ́ bí ìpínlẹ̀ to ni epo robi àti eto eto idokowo, gomina ni ipo karùn-ún ni ìpínlẹ̀ Ondo wá, isẹ ribiribi tí àwọn sí ń gbé ṣe lo ń fà àwọn olokoowo wá sí Ondo.
Ẹfunsetan Aniwura, obìnrin tó ju ọkùnrin lọ Hubert Ogunde rèé, baba àwọn òsèré tíátà Ida mẹjọ ninu mẹwaa owo oṣu rẹ ni wọn ni o ya sọtọ lati maa fun awọn ọmọ alaini ni ile iwe Keriko to wa ni abule Pwani ni Nakuru.
Neymar: Agbábọ́ọ̀lù Brazil kọ ẹ̀sùn ìfipábanilòpọ
Ẹnu ya àwọn onigbagbọ tí wọ́n jẹ́ Juu tí wọ́n bá Peteru wá nítorí àwọn tí kì í ṣe Juu rí ẹ̀bùn Ẹ̀mí Mímọ́ gbà lọ́fẹ̀ẹ́ ati lẹ́kùn-únrẹ́rẹ́.
Ileeṣẹ ọlọpaa nilu Dubai lo kọkọ mu Ramoni Igbalode(Hushpuppi), Olalekan Jacob Ponle (Woodberry), ati awọn miran.
Ní ọjọ́ kan, ọmọdé yìí gbàgbé bàntẹ́ sí oko, ó dé ilé tán kí ó tó rántí pé òun kò mú bàntẹ́ wá sí ilé, ṣùgbọ́n kìn ni ó bá pàdé lóko?
Lọwọlọwọ, eniyan mejila ni ijọba fidirẹmulẹ pe o ni coronavirus ni Naijiria.
Gbogbo ẹni tí ó bá ní ìrètí yìí ninu Jesu yóo wẹ ara rẹ̀ mọ́ gẹ́gẹ́ bí Jesu fúnrarẹ̀, ti jẹ́ mímọ́.
Ọkan lara awọn afurasi ti ọwọ ọlọpaa tẹ lori iku ọdọmọbinrin, to jẹ akẹkọọ Fasiti ilu Benin, ti wọn pa laipẹ yii, sọ pe obinrin kan to jẹ ọmọ ijọ kan naa pẹlu rẹ lo ni ki awọn pa a.
5 5887 Orilẹede Namibia 158 6.
Eyi ni a fi lee se apejuwe igbe aye ọgbẹni Etu Sodiq Omotayo ẹni to ni ipenija oju amọ to n sisẹ gbogbo elere lati wa ounjẹ oojọ jẹ.
Afi ti ijọba Buhari ati awọn alaranlọwọ rẹ ba ni a ko si ni ijọba awarawa mọ lo ku."
Balaamu dá angẹli náà lóhùn pé, “Mo ti dẹ́ṣẹ̀, n kò sì mọ̀ pé o dúró lójú ọ̀nà láti dínà fún mi.
0 1,103 Cayman Islands 2 3.
Aare Buhari tenumo pe, ise takuntakun, atileyin, fifarajin, ati isera-eni re lowosi bi idagbasoke se n ba ile-ise idanilaraya lorile-ede yii jake-jado.
Ó mú marun-un ninu àwọn arakunrin rẹ̀, ó fi wọ́n han Farao.
Lọ ta gbogbo ohun tí o ní, kí o pín owó rẹ̀ fún àwọn talaka, ìwọ yóo wá ní ìṣúra ní ọ̀run.
Ohunkohun tí o bá dè ní ayé, ó di dídè ní ọ̀run.
Omololu Olunloyo Kọmíṣọnnà lẹẹmẹfà tó gbé ọpá àṣẹ fún aláàfin Oyo àti Ṣọun Ogbomọṣọ Wo àwọn ohun tó yẹ kí o mọ̀ nípa àrùn Coronavirus àti ìbálòpọ̀ akọ àt'abo Kí làwọn ìdàmú tí Coronavirus n mú bá àgọ́ ara?
Awọn Emir tuntun mẹẹrin naa wa ni agbagbe Gaya, Karachi, Bichi ati Rano.
Kí ló dé táwọn ọ̀dọ́ dìbò 140m fún BBNaija àmọ́ tí ìbò ààrẹ Nàíjíríà jẹ́ 28m?
Ni ọdun 1968, aworan awọn ọmọde ti ebi n pa, ti awọ wọn si ri rada-rada gba ori awọn amohunmaworan nilẹ alawọ funfun kan.
Ayoola ka aṣẹ naa jade lọjọ Ẹti pe Ọba AbdulRasheed Adewale Akanbi ko gbọdọ dari eto irun lọjọ Jimọh tabi nibi ayẹyẹ ọdun awọn musulumi kankan fun asiko yii.
APC- àjòjì ọkùnrin kan gbàsàkóso iìkànì Twitter rẹ̀
"Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Hakeem: Mo lè sọ arúgbó dí ọmọge nígbà tó bá wù mí ""Walahi ọdaju abiamọ ni Aarẹ Muhammadu Buhari yi sá."
Lẹyin eyi ni K1 naa dahun pe agba ko kan ọgbọn.
Oríṣun àwòrán, Twitter/NigerianCAA Ni awọn ibudo ayẹwo kokoro arun ti ijọba faṣẹ si ni ipinlẹ Kano, nnkan bi ẹgbẹrun marundinlogoji naira le diẹ ni owo ayẹwo arun Coronavirus nibẹ.
Bakan naa nigba ti ina nla kan sọ ni ileeṣẹ ipese ina orilẹede ẹgbẹ wọn, Ukraine ati Chernobyl, Belarus fara gba gidi gan.
O ni inu wọn dun pe ajọ CAN ti ni iṣẹ ẹgbẹ kọ́ ni awọn to lọ ijọ COZA lọ jẹ bikoṣe iṣẹ ara wọn.
Gbogbo Juda ati Jerusalẹmu ṣe ọ̀fọ̀ rẹ̀.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ahmed Musa ati Alex Iwobi Naijiria naa kopa ninu ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ naa Aaron Ramsey palemo ètò ni iṣẹju igbeyin ifẹ̀sẹ̀wònse náà.
Akọkọ ni iroyin ti awọn alatako rẹ n gbe ka pe, o lọwọ ninu aṣemase kan nigba ti o n ṣiṣẹ gẹgẹ bi agbẹjọro nilẹ Amẹrika.
Ọjọ kẹsan oṣu Kẹta ni idibo si ipo Gomina ati ti awọn asoju ile asofin ipinlẹ naa waye nipinlẹ naa.
Ni Joannesburg to jẹ olu ilu orilẹ-ede South Africa ni awọn alagbara ti n dan ara wo ti wọn n ja fawọn onworan paapaa awọn ololufẹ.
 mo fẹ́ lùú ni marun si odo, mo fẹ wẹ ki n yan kankan, ki n náà ni alubolẹ, bo ba le ku ko kú, ìyẹn kii ṣe isoro temi Adesanya pe Romero nija láti báa ja, nigbati àwọn alaṣẹ fori ko wọ́n ko fààye gba Paulo Coasta lati koju rẹ bákan náà nitori o farapa ni ọdun to kọja.
O tọka si ijamba ina to waye ni awọn ileeṣẹ ajọ naa to wa ni ipinlẹ Anambra, Abia ati Plateau.
 Bakan naa , ni a ti ya awon opolopo eto sile fun igbadun awon to n gbo wa, paapaa julo ilẹ Afirika.
Sanwó Olú búra fún ìgbìmọ̀ ìṣàkóso rè níbi tó ti yan àwọn 38 sípò
Abuja Bank Robbery: Inú oṣù kẹwàá ni mo ti ń ṣètò jíja olè ní Báǹkì mi- Larry Ehizo Orílẹ̀èdè Amẹ́ríkà ti ṣekú pa olórí ọmọ ogun Iran tó lágbara jù Ẹ̀mi arákùnrin yìí kò gbé e, ó bá aláṣẹ́wò lò dórí ìgbà ìkéje ló bá ré sálákeji Ẹ̀yin ọmọ Kwara, ẹ seun fún àtilẹ́yìn yin lórí ilé Arugbo - Bukola Saraki Ati pe gbese lo maa n ja si fun awọn gẹgẹ bi ileewosan.
Kí ló dé, tí o fi sá, ìwọ òkun?
Lẹyin ipejọpọ awọn gomina ilẹ Yoruba - ipinlẹ Oyo, Ogun, Ekiti, Osun, Eko ati Ondo - lori ọrọ aabo, ni paapaa, ọrọ ijinigbe to ti n gbilẹ ni agbegbe wọn, onimọ nipa ọrọ aabo kan, Patrick Agbamu ti ni wahala ti idasilẹ ọlọpaa ipinlẹ yoo dasilẹ le ju ogun ti wọn fẹ ko ṣẹ lọ.
” Absalomu rọ ọba títí, ṣugbọn ó kọ̀ jálẹ̀.
"Èmi àti Zulaiha la jọ wà lábẹ́ igi tó wà nínú ọgbà ilé wa lọ́jọ́ nà, ló bá sọ pé ooru n mú òun, ni mo bá ní kó lọ pọn omi kó fi wẹ̀.
OLUWA àwọn ọmọ ogun, Ọlọrun Israẹli ní, ‘Bí ẹ bá gbójú lé àtilọ sí Ijipti, pé ẹ óo lọ máa gbé ibẹ̀, ogun tí ẹ̀ ń sá fún yóo bá yín níbẹ̀; 
À ń fẹ́ aṣojú tí yóò rí i wípé à ń rí ẹtọ wa gbà lóòrèkóòrè.
Nígbà náà ni Abrahamu tẹríba níwájú gbogbo wọn.
Ṣùgbọ́n bí èrò mi bá jẹ́ òtítọ́, ó ń fò kiri níbi ní gẹ̀rẹ́gẹ̀rẹ́ òkè Rekcha.
Ṣugbọn adajọ Aboki ni Atiku ko ni lanfani lati ṣe ẹda awọn ohun idibo naa nitori ofin ko faye gba a.
Eeyan 35 miran ko aarun iba Lassa 'Àwọn Dókítà fẹ́ kẹ́yin s'awọ̀n alárùn lassa' L'ọ́dun 2014, ó lè ní ẹ̀ẹ́dẹ́gbẹ̀fà ènìyàn tí ó bá ààrùn náà lọ ní Guinea, Sierra Leone àti Liberia.
Okanlawọn ni o padanu ẹmi rẹ nigba ti ọkọ oju omi ti wọn wọ pada si ibugbe wọn doju de lẹyin idibo ọjọ nirọlẹ ọjọ Satide.
Naby Keita ati Roberto Firmino gba goolu meji sawọn FC Porto bi Liverpool ṣe bori.
Kí ẹ fi kọ́ àwọn ọmọ yín dáradára, ẹ máa fi ṣe ọ̀rọ̀ sọ nígbà tí ẹ bá jókòó ninu ilé yín ati ìgbà tí ẹ bá ń rìn lọ lójú ọ̀nà, ati ìgbà tí ẹ bá dùbúlẹ̀ lórí ibùsùn yín ati nígbà tí ẹ bá dìde.
O ni ko si ẹni to si n yọ awọn naa lẹnu nibi iṣẹ ati ilana ẹsin wọn.
Wọn sọ pe, ajọdun naa ti n so eso rere nitori ọpọ awọn ọmọ ijọ ti wọn ti kuro ninu ijọ naa lọ si awọn ijọ miiran ni wọn ti n pada sinu ijọ yii bayii nigba ti wọn ko lanfani si awọn orin ẹmi bayii n awọn ijọ ti wọn lọ.
OLUWA ti wí fún mi pé, n kò ní gun òkè odò Jọdani yìí.
Ko pẹ ni wọn fi ọlọpaa mu Abiola lẹyin ti ijọba to wa lori oye da ibo naa ru lasiko Ibrahim Babangida.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ọlọ́pàá: Ọmọ ìyá méjì gé orí ọmọ ọdún mẹ́wàá nítorí N200,000 29 Bélú 2018 Oríṣun àwòrán, Lagos State Police Command Àkọlé àwòrán, Ayodeji ati Saheed salaye fun awọn ọlọpaa pe ọgbẹni kan ti orukọ rẹ njẹ Sodiq Abefe ni o ni ki awọn lọ wa ori eniyan kan wa Ọwọ ileṣẹ ọlọpaa ti tẹ ọmọ iya meji kan pẹlu ori ọmọdekunrin ti wọn ṣẹṣẹ ge nilu Eko.
Oríṣun àwòrán, Facebook\\Alhaji Taofeek Oyerinde Àkọlé àwòrán, Ni ọsan ọjọ iṣẹgun ni Alhaji Fẹlẹ jade laye nileewosan Zenith Kidney Hospital nilu Abuja Alhaji Fẹlẹ, gẹgẹbi aarẹ ẹgbẹ NURTW lorilẹede Naijiria ṣe sọ, ti wa ni ile iwosan lati nnkan bii ọsẹ mẹta sẹyin, nibi ti o ti n gba iwosan fun aisan kidinrin to ba n finra.
Jesu bá dúró, ó ní, “Ẹ pè é wá.
Awọn ẹgbẹ oselu ti bu ẹnu ẹ̀tẹ́ lu igbese ti ijọba ipinlẹ Kwara gbe lati fagile iwọde itagbangba fun awọn ẹgbẹ oselu ni ipinlẹ naa.
Jerusalẹmu, Ìlú Sioni dára, ó sì lẹ́wà,ṣugbọn n óo pa á run.
Ṣugbọn OLUWA ni Ọlọrun tòótọ́,òun ni Ọlọrun alààyè, Ọba ayérayé.
Deede aago mẹwa owurọ ni gbajumọ onilu naa mi kanlẹ nile rẹ ladugbo Keesi nilu Abeokuta.
Wọn kò ní ṣẹ́ nǹkankan kù fun yín ninu ọkà yín, ọtí waini yín, ati òróró yín, àwọn ọmọ mààlúù tabi ọmọ aguntan yín; títí tí wọn yóo fi jẹ yín run.
Naijiria  Tukur Buratai,fun iranwọ ati itọsọna
Ẹ bá Jerusalẹmu sọ̀rọ̀ pẹ̀lẹ́pẹ̀lẹ́ẹ ké sí i pé, ogun jíjà rẹ̀ ti parí,a ti dárí àìṣedéédé rẹ̀ jì í.
orile ede Senegal fun saa keji .
Oríṣun àwòrán, Reuters Àkọlé àwòrán, Eyi ni aworan apa kan nibi ina to n jo ni ìgbẹ́ Amazon ni Rio Pardo ni orilẹ-ede Brasil.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Wolf Hybrid Chow Chows: O jẹ ẹya aja to fẹ̀ran olowo wọn, ti o si ma n kọju ija si ẹnikẹni to ba gbẹna woju olowo rẹ.
Ó gba ààrin àwọn ìlú tí wọ́n wà ní orí òkè lọ ní apá ìwọ̀ oòrùn, ó sì pin sí aṣálẹ̀ Betafeni.
Eyi lo mu ki aya gomina ana nipinlẹ Oyo, Florence Ajimobi tete pakiti mọlẹ lati se atunse ibudo itaja rẹ to jona.
Ni ọdun mẹfa sẹyin, a gbọ pe David, ati awọn aburo rẹ meji ti wọn jẹ ibeji, Joseph ati Jonathan wa ninu ọkọ kan nigba ti agbebọn kan yinbọn sinu ọkọ naa ni ẹẹmẹta.
A fi ìwé pe Wakabi kí ó wá á sọ̀rọ̀ níbi ètò Àyájọ́ Àwọn Olùgbèjà Ẹ̀tọ́ Ọmọnìyàn ní Tanzania ọlọ́dọọdún tí Àgbáríjọ Olùgbèjà Ẹ̀tọ́ Ọmọnìyàn ti Tanzania (THRDC) jẹ́ olùgbàlejò.
Àwọn tí wọ́n ṣẹ̀ láti ọ̀dọ̀ Geriṣoni nìwọ̀nyí: Libini ni baba Jahati, Jahati bí Sima, 
Mo kó wọn lọ sinu yàrá àwọn ọmọ-ẹ̀yìn Hanani, ọmọ Igidalaya eniyan Ọlọrun, yàrá náà wà lẹ́gbẹ̀ẹ́ yàrá àwọn ìjòyè, lókè yàrá Maaseaya ọmọ Ṣalumu, aṣọ́nà.
ona lati doju ija ko ipenija eto aabo ni ekun ohun.
Sọ fún ọgbọ́n pé, “Ìwọ ni arabinrin mi,”kí o sì pe ìmọ̀ ní ọ̀rẹ́ kòríkòsùn rẹ,
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ọkọ̀ tírélà epo forí sọ ọkọ̀ tírélà tó kó ẹja l‘Osun, ẹ̀mí èèyàn méjì sọnù Ọkọ̀ rélùwéè 16 yóò ná Eko sí Ibadan láti oṣù tó ń bọ̀ lọ - Iléeṣẹ́ Rélùwéè kéde Àwọn ọmọ orílẹ̀èdè Mali ń fò fáyọ̀ pé ológun gba ìjọba mọ́ alágbádá lọ́wọ́ Ìròyìn ayọ̀!
Ko ti ẹ tẹ lati jẹ iru nakn bẹ lẹyin ọjọ kan ti ọjọ ori rẹ ba ti kọja.
Wo àwọn oúnjẹ márùn ún tó ń mú kí àtọ̀ ọkùnrin dára síi Wo àwọn Ọba aládé méje tó jẹ́ obìnrin nílẹ̀ Yorùbá Lóòtọ́ ni mo yìnbọn níbi yánpọnyánrin tó wáyé ládúgbò mi-Seun Kuti Àṣeyọrí Anthony Joshua fi hàn pé owó tí à ń ná lórí eré ìdarayá kò lọ lásán - Dapo Abiodun Nítorí kò sí ọ̀nà àbáyọ nínú ìṣẹ́ ní mo ṣe fẹ́ ta ọmọ mi- Sarah ọmọ òrukàn Ọpọ awọn ọkunrin ati obinrin to wa nihoho lawọn ọlọpaa ri lati oju ferese, bakan naa ni wọn paaki ọkọ sita rẹgẹdẹ.
Gbogbo àwọn ẹranko àti ẹyẹ tí ó wá sí ibẹ̀ ni ó lè sọ̀rọ̀ kí ènìyàn gbọ́.
Siwaju si, aare tun kedun pelu
Ohun tí ó dára ni a fẹ́ máa ṣe nígbà gbogbo.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Africa Eye: Ọwọ́ tẹ ayédèrú dókítà Abdallah tó ń tà oògùn Coronavirus Ṣé òògùn Chloroquine lè dènà ààrùn Coronavirus bí?
Nítorí kì í ṣe nǹkan rere tí mo fẹ́ ṣe ni mò ń ṣe, ṣugbọn àwọn nǹkan burúkú tí n kò fẹ́, ni mò ń ṣe.
Iroyin ni o kere tan awọn marun un ni wọn ti dologbe nibi iṣẹlẹ ọhun nigba ti ọpọlọpọ si farapa.
Àjẹsára náà kò ní ewu kankan rárá , ó sì ṣeé lò bí ènìyàn bá lóyún àti bí ènìyàn bá ní àrùn hiv / aids .
Eero awọn ọmọ Naijiria ṣọtọọtọ lori orukọ ti wọn fun ileeṣẹ tuntun naa.
Paapaa julo lati maa se ojuse awon alakoso  egbe ti won dibo yan.
Coronavirus lockdown: Àwọn ọ̀nà tí ẹ le fi dun ara yín nínú lásìkò ìgbélé
Wọ́n dé ìlú olódi ti Tire, títí lọ dé gbogbo ìlú àwọn ará Hifi, ati ti àwọn ará Kenaani.
Alukoro ileesẹ ọlọpa ni ipinlẹ Ogun, Abimbọla Oyeyẹmi lo kede eyi nilu Abẹokuta.
Ife yìí ni ọ̀gá mi fi ń mu omi, ife yìí kan náà ni ó sì fi ń woṣẹ́, ọ̀ràn ńlá gan-an ni ẹ dá yìí.
Mana náà sì dàbí èso korianda, tí àwọ̀ rẹ̀ dàbí kóró òkúta bideliumi.
Ṣugbọn bi idunkoko mọni lati odo àwọn ọlọpa ti ṣe peleke ló mú kí Seneto Dino yí èrò pada láti fagile eto ìsìn idupẹ ati apejẹ to yẹ ko waye ni Aiyetoro Gbede Nígbà tí BBC bẹrẹ lọwọ Gideon boya Seneto Dino ṣì wà ní ipinle Kogi,o kọ láti fèsì.
Nígbà tó ń sọ̀rọ̀ lórí ipò tí ìyà ìbejì wá, Akeugbagold ni ṣe ni ìyàwó òun kan ń dákú ni gbogbo igba ni, kódà, ó ni wọn tun ṣẹ̀ṣẹ̀ fi silẹ nile ìwòsàn ni, eyiun bí kò bá tún dákú kí ilẹ tó sú.
Ẹnu ya Jakọbu náà ati Johanu, àwọn ọmọ Sebede, tí wọ́n jẹ́ ẹlẹgbẹ́ Simoni.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Retirement Benefits: Èyí ni mùdùnmúdùn tó wà nínú owó ifẹ̀yìntì àwọn Gómìnà tẹ́lẹ̀ ní Nàìjíríà 27 Bélú 2019 Oríṣun àwòrán, Google Ko jẹ tuntun mọ pe awọn aṣofin ipinlẹ Zamfara ti wọgile owo ifẹyinti tabua ti awọn Gomina to fi ipo silẹ n gba.
Ọjọ ikẹrinlelogun oṣu kẹjọ ọdun 1977 ni wọn bi Funke Akindele ni idile Akindele, baba rẹ jẹ adari ile iwe girama ti iya rẹ si jẹ dokita.
” Bí ọmọ náà ti ń sáré lọ, Jonatani ta ọfà siwaju rẹ̀.
Mu alekun agbara ba ọrọ aje awọn eeyan ipinlẹ Borno.
Fi aṣọ aláwọ̀ aró ṣe ojóbó sí etí ẹ̀gbẹ́ tí ó wà ní òde ninu aṣọ àránpọ̀ kọ̀ọ̀kan.
 ní ọjọ ́ kejì sí èyí ni ilẹ ̀ ni ilẹ ̀ france náà kéde ogun lé ilẹ ̀ germany náà lórí .
Mò ń làkàkà láti dé òpin iré-ìje mi tíí ṣe èrè ìpè láti òkè wá: ìpè Ọlọrun ninu Kristi Jesu.
Gbaju-gbaja akorin omobibi orile-ede Senega, ti o fi orile-ede America se ibujokoo, Akon wa lorile-ede Ethiopia bayii lati kopa nibi ayeye ayajo isami ogun Adwa ti o waye ni nnkan bi ogofa odun seyin.
Ó gbọdọ̀ kọjá sí òdìkejì odò lẹsẹkẹsẹ kí ọwọ́ má baà tẹ̀ ẹ́ ati àwọn eniyan tí wọ́n wà lọ́dọ̀ rẹ̀, kí wọ́n sì pa wọ́n.
Ẹ fi arokọ ranṣẹ si bbcpidgin.
Corona virus: Ibi àyẹ̀wò mẹ́ta ló wà fún Coronavirus ní Naijiria
Mo kígbe fún ìrànlọ́wọ́ títí ilẹ̀ fi mọ́ó fọ́ gbogbo egungun mi bí kinniun ti máa ń fọ́ egungun.
Ọkọ̀ táńkà agbépo tó gbiná lójú ọ̀nà mọ́rosẹ̀ Eko sí Ibadan dá súnkẹrẹ fàkẹrẹ sílẹ̀ Yatọ si Germany, orilẹ-ede England naa ti n gbaradi fun ofin konile-o-gbele tuntun, lẹyin ti awọn alasẹ Austria, France, ati Ireland, kede ti wọn.
Philippe kọkọ parọ pe emi ni mo ko ran oun, sugbọn a pada ri obinrin kan to sọ fun wa pe ọdun 1997 ni Philippe ti ko aarun naa ran oun.
Ṣugbọn lati igba ti ọrọ naa ti wa lori ẹrọ ayelujara ni ọmọbinrin naa ti n bẹbẹ lati yi pada.
Gẹgẹ bi ọrọ ti Florence Ajimọbi sọ, ko si ohun meji ti ọkunrin n ri nidi ale yiyan ju ibalopọ lọ, bi wọn ba si ti ni ibalopọ naa tan, ọrs pari niyẹn ọkan wọn kii si pẹlu ẹni ti wọn n yan lale.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Zamfara Bandits: Kò sí ẹni tó mọ iye ènìyàn tí àwọn adigunjalè gbé lọ 2 Èbibi 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Zamfara Bandicts: Ko si ẹni to mọ iye ènìyàn ti àwọn adigunjale gbé lọ Awọn afurasi adigunjale kàn ti kọlu ilé iwé Government Girls Secodary School Moriki, ni ijoba ibilẹ Zuru ipinlẹ Zamfara láárọ̀ oni, ọjọru nibi ti wọn ti da ibọn bolẹ nígbà ti wọn pa ènìyàn kan ti ko si ẹni ti o mọ iye eniyan ti gbé lọ.
8 15535 Orilẹede Uruguay 90 2.
Wọ́n pàgọ́ sí Refidimu, ṣugbọn kò sí omi fún wọn láti mu.
Oríṣun àwòrán, Yemi0ke/Twitter Ki nidi ti ọrọ a yọ ọ́ lẹgbẹ fi kọkọ waye?"
Diego Milito to gba ife ẹyẹ Champions League pẹlu Inter Milan lọdun 2010 ni tirẹ sọ pe Tottenham loun dibo fun.
A bí i ní ọjọ́ karùn-ún, osù kẹsan, ọdún 1984 sùgbọn ìlú Ibadan ní ìpínlẹ̀ Ọyọ ló gbé dàgbà.
“Bí ẹnikẹ́ni bá ṣẹ̀ láìmọ̀, yóo fi abo ewúrẹ́ ọlọ́dún kan rú ẹbọ ìmúkúrò ẹ̀ṣẹ̀.
Àwọn ọmọ Nàìjíríà ń kérora àdánù tí àṣẹ ìjọba tó wọ́gilé ìrìnàjò láti òké òun mú bá wọn Ṣé òògùn Chloroquine lè dènà ààrùn Coronavirus bí?
Ẹ yé gba owó orí níbi ìdána ìyàwó mọ́, sísọmọbìnrin s'óko ẹrú ni- Daddy Freeze A kò fòfin de owó naira tó ti pẹ́ ní Naijiria -CBN ‘Àti fi àwọ̀n ọlọ́kadà 123 láti Jigawa sílẹ̀’ Irú ọmọ wo ní Yorùbá ń pè ní Olúgbódi?
Egbe WANEP  tun tesiwaju pe opolopo awon eniyan ni eru ti n ba nitori eto idibo to n bo , paapaa julo nipa eto aabo ti ko fese mule , bi awon oloselu se n bu ara won ati bi won se n dun ikooko mo ara won .
N óo lọ sọ́dọ̀ àwọn eniyan pataki pataki,n óo sì bá wọn sọ̀rọ̀;nítorí àwọn mọ ọ̀nà OLUWA,ati òfin Ọlọrun wọn.
0 34278 Orilẹede Norway 517 9.
Nítorí náà, kí ẹ̀yin náà wà ní ìmúrasílẹ̀, nítorí ní wakati tí ẹ kò rò tẹ́lẹ̀ ni Ọmọ-Eniyan yóo dé.
Wọn ni ohun to de ba idajọ ti awọn ọmọ ẹgbẹ PDP kan gbe lọ si ile ẹjọ kotẹmilọrun Lakure naa lo de ba ti Bwari latari pe awọn to gbejọ naa wa ko gbe ẹjọ naa wa lasiko ti ofin fi aye kalẹ fun igbẹjọ ọrọ idibo.
Atẹjade naa ni salaye pe awọn oluwọde mejila ni awọn agbofinro yinbọn pa ni Lekki lọjọ Isẹgun.
Papalolo ní ìlépa owó ni ìyàtọ̀ tó wà láàárín àwọn òṣèré tíátà àtijọ́ àti ìsisìnyí
ẹni tí ó sọ ayé di aṣálẹ̀,tí ó sì pa àwọn ìlú ńláńlá rẹ̀ run,ẹni tí kì í dá àwọn tí ó bá wà ní ìgbèkùn rẹ̀ sílẹ̀?
Oríṣun àwòrán, Getty Images Iku akọroyin naa si mu ọpọlọpọ ibinu wa laarin Saudi ati Turkey.
Àwọn àpọ́n ọmọ Yorùbá olówó Marun tí kò tíì laya Bàbá Leah Sharibu ti fẹ̀si lorí ìròyìn pe ọmọ rẹ ti bímọ fún ọga Boko Haram Human trafficking: Iṣẹ́ irun ṣíṣe ló di iṣẹ́ aṣẹ́wó mọ́ Adeola lọ́wọ́ ní Cote D'ivoire Amọ ẹgbẹ oṣiṣẹ ASUU fi ẹsun kan ijọba pe wọn ko duro lori ọrọ wi pe ki wọn gbe ajọ UTAS yẹmọ, amọ ti ijọba paṣẹ pe oṣiṣẹ ti ko ba si lori eto isuna IPPIS ko ni gba owo Oṣu Kini, ti ọdun 2020 ti o n pari ni ọṣẹ yii.
Mo ti wẹ̀wọ̀n nígbà pupọ jù wọ́n lọ.
Igba akọkọ kọ niyi ti imọran yii jade si Buhari.
naa si sa wọnu igbo lọ.
ẹ gbọ́ ọ̀rọ̀ OLUWA, ẹ̀yin tí ẹ ṣẹ́kù ní Juda.
Lẹ́yìn ìrìn ọjọ́ mẹta ninu aṣálẹ̀ Etamu, wọ́n pàgọ́ sí Mara.
Olukuluku àwọn tí wọ́n tó ọmọ ogún ọdún tabi jù bẹ́ẹ̀ lọ, tí wọ́n kà dá ìdajì ìwọ̀n ṣekeli kọ̀ọ̀kan tí òfin wí, ìwọ̀n tí wọn ń lò ní ilé OLUWA ni wọ́n sì fi wọ̀n ọ́n, iye àwọn eniyan tí wọ́n kà jẹ́ ọgbọ̀n ọ̀kẹ́, ati ẹgbẹtadinlogun ó lé aadọjọ (603,550).
pé kí ẹ jìnnà sí irú ìwà àtijọ́ tí ẹ ti ń hù, ìwà ìfẹ́kúfẹ̀ẹ́ ara tíí máa tan eniyan lọ sinu ìparun.
Ó dùbúlẹ̀ láàrin àwọn ọ̀dọ́ kinniun,ó ń tọ́jú àwọn ọmọ rẹ̀.
Eyi tumọ si pe ida mẹta ninu mẹrin ọmọ orilẹede Naijiria ni ko lanfani si ile igbọnsẹ to mọ Aisan igbẹ gbuuru ti o ṣee dena nipasẹ omi to mọ gaara ati ile igbọnsẹ to mọ wa lara ohun to n gba ẹmi awọn ọmọde julọ lorilẹede Naijiria.
Arabinrin Omobolanle Sarumi Aliyu ni obinrin akọkọ ti yoo jade lati dije ipo gomina ipinlẹ Ọyọ.
Mo mọ̀ pé ọkàn rẹ fà sí ilé ni o fi sá, ṣugbọn, èéṣe tí o fi jí àwọn ère oriṣa mi kó?
Ajẹsilẹ owo osu awọn oṣiṣẹ ati oṣiṣẹ fẹyinti: Ẹnu tun kun Abiola Ajimobi lasiko ti ko san owo oṣu awọn oṣisẹ ati oṣisẹ fẹyinti.
Ounjẹ jijẹ lasiko yii le jọ ohun ti ko lera, sugbọn eniyan gbọdọ sọra nipa ounjẹ ji jẹ lasiko aawẹ.
Oríṣun àwòrán, @others Àkọlé àwòrán, Lati kekere ni mo ti bẹrẹ ere ṣiṣe- Jide Kosokọ Diẹ lara awọn ere ti Ọmọọba Kosọkọ ti ṣe ni Aṣiri nla, The Department, Gidi Up, Last Flight to Abuja, The Figurine, Jenifa ati bẹẹ bẹẹ lọ.
Merari bí ọmọkunrin meji: Mahili ati Muṣi.
3rd mainland / Oworonshoki Bridge Ijọba ibilẹ Ikeja Kosofe 36.
Lọjọru to kọja ni Iman ara Somalia to n rirnrin oge wọ aṣọ alarabra yii.
Gẹgẹ bi ohun to sọ, o ni ohun fẹ di aarẹ orileede Ghana ni ẹni ogoji ọdun lọjọ iwaju.
Wọ́n ṣe ìfẹ́kúfẹ̀ẹ́ ní aṣálẹ̀,wọ́n sì dán Ọlọrun wò.
O le ni eeyan ẹgbẹrun lọna ọọdunrun ti aisan Coronavirus yii si ti mu lọ jakejado agbaye.
Oríṣun àwòrán, EPA Àkọlé àwòrán, Awọn ọmọbinrin Mandela, Zanani ati Zindzi, wa ni pẹsẹ.
Bayern Munich gbẹyẹ mọ Sevilla lọwọ ti ori si ko Real Madrid yọ ki wọn to ri Juventus bì ṣubu.
O ni ẹbi ti gbiyanju titi lati ya awọn mejeeji ṣugbọn Saidi a tun wa bẹ Bọsẹ pada ni.
Àwọn obinrin tí wọn ní ojú àánú ti fi ọwọ́ ara wọn se ọmọ wọn jẹ, wọ́n fi ọmọ wọn ṣe oúnjẹ jẹ,nígbà tí ìparun dé bá àwọn eniyan mi.
Rán marun-un ninu àwọn aṣọ náà pọ̀, lẹ́yìn náà, rán mẹfa yòókù pọ̀, kí o ṣẹ́ aṣọ kẹfa po bo iwájú àgọ́ náà.
Kí eniyan ṣe òdodo ati ẹ̀tọ́,sàn ju ẹbọ lọ lójú OLUWA.
Iya Waziri kẹnu bọ ọrọ pe lẹyin Ọlọhun, ọmọ yii nikan lo ku fun oun.
Meji meji yóo tọ̀ ọ́ wá ninu oríṣìíríṣìí àwọn ẹyẹ, ati oríṣìíríṣìí àwọn ẹran ọ̀sìn, ati oríṣìíríṣìí àwọn ohun tí ń fàyà fà lórí ilẹ̀, kí o lè mú kí wọ́n wà láàyè pẹlu rẹ.
Ní ọjọ́ ibinu rẹ ni o pa wọ́n,o pa wọ́n ní ìpakúpa láìṣàánú wọn.
Èmi ìbá mọ̀ ki ń yára sọ̀ kalẹ̀ kí n wa ibòmíràn sá sí!
Ko tan sibẹ, agbẹnusọ fun ileesẹ ọlọpaa nipinlẹ Rivers tun fikun pe, awọn yoo se abẹwo ibanikẹdun sile mọlẹbi oloogbe onikẹkẹ Maruwa naa.
Ọgbẹni sọ pe gbogbo ti ijọba ni gbogbo ẹsun ifipabanilopọ, ti ko si ni faaye gba idasi lati ọdọ ẹnikẹni.
Fela Durotoye, olùdíje ipò ààrẹ ẹgbẹ́ òṣèlù ANN #BBCNigeria2019 Kíni igbimọ NJC fẹ́ jíròrò lè nípa Onnoghen?
Michel Sidibe, ti o je oga agba ajo naa soro yii ninu atejade kan, ti apapo iko ti o n ri si oro aarun HIV/AIDS ninu ajo UN gbe jade lojo-Aje nilu Abuja.
Edo governorship election: Ẹ̀kọ́ márùn ún tí a rí kọ́ nípa eré tíátà tó ń wáyé l'ágbo òṣèlú ìpínlẹ̀ Edo
“ Yiyapa kuro ninu egbe t I je ka  mo awon ọrẹ , ọta ati awon afoju –feni ,maa fọkan – fẹni eniyan  bayii , ao beru iwa agabagebe won,  sugbon awa wa ni isokan pelu okan lile .
Ìfẹ̀hónú gbọ̀nà míràn yọ ní Benin Oríṣun àwòrán, royzkingin / Twitter Ọna ara ni iwọde a ko fẹ ọlọpaa SARS mọ gbayọ lopopona marosẹ ilu Benin nipinlẹ Edo, nigba tawọn ọdọ di oju popo pa.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Lóṣù mẹ́ta sẹ́yìn, mò ń wa ọkọ̀ taasín, ṣùgbọ́n wọ́n sọ mí di afọ́jú lọ́san gangan' Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Lórí iṣẹ́ ikàn yìí, a ti kọ́ ilé, ọmọ ti lọ ilé ìwé' Omoyele Sowore tii ṣe oludije fun ipo aarẹ ati alaga igbimọ ẹgbẹ oṣelu African Action Congress (AAC) fesi pé òun ṣi ni alaga ẹgbẹ oṣelu AAC.
Ogunlọgọ eeyan l'Amẹrika ati nilẹ Gẹẹsi ni wọn ti n ṣe ifẹhonuhan lati ọsẹ to lọ lori ọmọ ilẹ Afirika Ọgbẹni George Floyd to ku lẹyin ti ọlọpaa alawọfunfun kan, Derek Chauvin fi orunkun fun un lọrun.
Wọ́n ta ère Ọ̀ṣun Osogbo sí Togo - Bàbá Ọṣun figbe ta Baṣọ̀run Gáà, tó yan ọba mẹ́rin, pa ọba mẹ́rin àmọ́ ọba karùn-ún ló pa á Ọbasanjọ sọ àsírí sàgbàdèwe rẹ̀ Jesu Oyingbo rèé, pásítọ̀ tó láṣẹ ìbálòpọ̀ lóri ọmọ ìjọ obìnrin Ọgbọn ti itan Afọnja kọ wa: Itan Afọnja kọ wa lati maa mu ẹjẹ wa si ẹnikeji sẹ boya onitọun wa laye abi o ti jade laye O tun kọ wa lati jẹ olootọ si ẹni to ba se wa loore Itan naa tun kọ wa lati mase ta ara ile abi ẹya wa lọpọ, nitori o seese ka ma ri ra ni ọwọn gogo mọ A tun ri kọ pe tẹni n tẹni, ekisa n taatan, ara ile ẹni ko seni, eniyan ẹni ko seniyan, ko ni jọ alaroo lasan, ẹbi ẹni ni ẹbi ẹni Itan naa tun jẹ ka mọ pe ka maa fura, ka si maa kiyesara nipa awọn alejo to ba wọle tọ wa, ka si mase tete dara de wọn, nitori ewu lee wa loko Longẹ, Longẹ gan ewu ni.
Mọ̀ sí i nípa díẹ̀ lára àwọn èèyàn tí ikú wọn 'láti ọwọ́ ọlọ́pàá' milẹ̀ tìtì ní Nàìjíríà Àwọn aṣòfín ní ìpínlẹ̀ Edo ti yọ Abẹnugan Ilé, Francis Okiye bí jìgá Inú mi dùn sí iwọ́de EndSARS tàwọn ọdọ́ Nàìjíríà ń ṣè - Ooni Ogunwusi Àìbìkítà yíì gbọ́dọ̀ dópin, ìjọba gbọdọ̀ mú ẹ̀dùn ọkàn àwọn aráàlú lọ́kùnkúndùn- Agbẹjọ́rò Àgbà Àìbìkítà yíì gbọ́dọ̀ dópin, ìjọba gbọdọ̀ mú ẹ̀dùn ọkàn àwọn aráàlú lọ́kùnkúndùn- Agbẹjọ́rò Àgbà Agbẹjọro agba lorilẹ-ede Naijiria, Wahab Shittu ti kesi ijọba apapọ lati mu ibeere awọn ọmọ Naijiria lọkunkundun nitori awọn eeyan lo gbe wọn de ipo ti wọn wa loni.
Ọkan lara awọn oluranlọwọ rẹ sọ fawọn akọroyin pe ẹni ọdun mẹtalelọgọta ti sẹnẹtọ Oko jẹ ki o to dagbere faye.
Ooni ile Ife, Oba Enitan Ogunwusi, Ojaja 2 naa fi asiko
O tun kilọ pe “A ti kansi gbogbo wọn , wọn  yoo si wa si aagọ wa , ki wọn  to bẹrẹ eto idibo.
Ọgbọn wo ni baba n da si kini ọhun?
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ibadan Murder: Oyún oṣù méje ló ń bẹ nínú Azeezat, kí wọ́n tó f'òkúta fọ́ ọ lórí Èèyà 315 ló lùgbàdì àrùn Coronavirus ní Naijiria ní ọjọ́ Ajé Ìrántí Sani Abacha, apàṣẹ wàá tó tún kó owó Nàìjíríà mì APC ni Auxilliary ṣiṣẹ́ fún lásìkò ìdìbò gómìnà 2019 kìí ṣe PDP-Oyo NURTW Ṣé lóòtọ́ ni òjòjò dá Abiola Ajimobi wólẹ̀?
Esiri, ọmọ Kelubu, ni alabojuto fún gbogbo iṣẹ́ oko dídá.
Ifọrọwerọ ori ikanni ayelujara Twitter naa ti wọn pe ni #AskThePolice #ReformSARS ni wọn gbe kalẹ lati fun araalu ni anfani lati fi ẹhonu wọn han lori ise awọn ọlọpa FSARS lorilẹede Naijiria.
Apo aṣọ aransilẹ Aga ati ohun elo ile idana meje.
Bẹ́ẹ̀ náà ni igi àti àwọn ejò ròyìn ìwà búbburú yin.
Adigunjalẹ̀ fìbọn fọ́ ojú ọmọ tó fẹ́ lọ sìnrú ìlú nílùú Èkó 'Ohun ẹ rí, ẹ wí, ẹ ò lè fipá mú wa fáwọn darandaran nílẹ̀ ní ìpínlè wa' Toyin Abraham ní 'gbogbo wa loníbárà', Ijebu ta sí Odunlade Ohun ti a gbọ ni pe ile epo meji pere lo n ta epo ninu awọn ile epo to ju meje lọ nibode Seme.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Naijiria:Iwadi bẹrẹ lori owo iranwọ epo 29 Sẹ́rẹ́ 2018 Oríṣun àwòrán, AFP Àkọlé àwòrán, Aisi an ibudo ifọpo lo sokunfa sisan owo iranwọ ori epo fun awọn ti o nko epo wọle Owo toto trilliọnu mẹwa naira lorilẹede Naijiria ti nsan lori owo iranwọ epo, taa mọ si subsidy.
Wo ìdí tí àwọn obìnrin kan fi n yọ ilé ọmọ wọn kúrò Èyí ni ọ̀nà tí àwọn obìnrin n gbà kó ara wọn sí wàhálà nítorí ara bíbó Mo sọ Dókítà dí òpùrọ́ lórí ayé mi - Steph Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí kan sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
Onimọ nipa ẹsin musulumi Alhaji Taofeek Akeugbagold lo sọrọ yii lori ẹrọ amohun-maworan.
Ẹrù ẹ̀ṣẹ̀ rẹ̀ wọ̀ ọ́ lọ́rùn,ó wó lulẹ̀, kò ní dìde mọ́.
Ọkunrin náà lọ, ó bẹ̀rẹ̀ sí ròyìn ohun tí Jesu ṣe fún un ní agbègbè Ìlú Mẹ́wàá, ẹnu sì ya gbogbo eniyan tí ó gbọ́.
Ẹ̀yin ará, àyànfẹ́ Ọlọrun, a mọ̀ pé Ọlọrun ni ó yàn yín.
Amọ wọn korira ibalopọ laarin akọ si akọ, wọn rii gẹgẹ bi ohun irira.
"orile-ede olominira sosialisti ile kroatia ( "" socialist republic of croatia "" to unje kikekuru bi sr croatia ; ede kroatia : "" socijalistička republika hrvatska "" , "" sr hrvatska "" ) je orile-ede sosialisti ati orile-ede alabagbepo alaselorile ti orile-ede olominira sosialisti apapo ile yugoslafia tele ."
Eyi jade nibi atejade kan ti ile-ise adele aare gbe jade pe “íwa ibajẹ, ti won hu lai je pe aare mọ nipa  rẹ,buru jai.
Anjorin-Lawal, ẹni to sẹsẹ se igbeyawo laipẹ yii sisọ loju ọrọ yii lasiko to n ba akọroyin kan sọrọ.
O ni ibọn ba Ọlakunrin ati awọn ọmọ ọdọ rẹ, amọ obinrin naa ni ẹjẹ ko tete da lara rẹ titi to fi gbe ẹmi mi, ti awọn ọmọ ọdọ rẹ si wa nile iwosan nibi ti wọn ti n gba itọju lọwọ.
Àkọlé àwòrán, Ileeṣẹ ọlọpaa ipinlẹ Ọyọ sọ pe oṣiṣẹ ọlọpaa ti Sunday fi ẹsun kan wi pe o ṣi awọn silẹ ti n foju wina ibawi.
"mi o le gba ohunkohun to ba ti ẹnu rẹ jade gbọ.
Bí Khafi ṣe ní ìbálòpọ̀ ojútáyé tako àṣà Yorùbá - Ìjọba Ekiti Seyi Awolowo, ọmọ-ọmọ Awolowo, kí ló ń wà lórí ètò BB Naija?
Ọpọlọpọ iranṣẹ ni ó wà nisinsinyii tí wọn ń sá kúrò ní ọ̀dọ̀ oluwa wọn.
Nígbà tí wọ́n gbé àpótí ẹ̀rí dé ibùdó, gbogbo Israẹli hó ìhó ayọ̀, tóbẹ́ẹ̀ tí ilẹ̀ mì tìtì.
Ninu alaye rẹ, o ṣalaye wi pe ọjọ ọjọbọ mimọ yii ninu bibeli jẹ ọjọ irubọ Jesu Kristi lati pa ẹsẹ araye rẹ nitori oru mojumọ ọjọ yii ni ọjọ ẹti rere ti Jesu ku fun ẹsẹ araye.
amọ ti wọn lọ si ile, ti wọn si padawa si Eko ni ibi ti wọn ti n ṣe iṣẹ ojo wọn.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Florida: Ọ̀ọ̀nì àléègbà dé ba Mary lálejò lọ́gànjọ́ òru Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Oludari eka to n ri si ise iwadii lori eto ẹkọ ati idagbasoke, arabinrin Chioma Nwadei  naa wa so pe eto ẹkọ ni gbongbo to le mu idagbasoke ba igbe aye iderun lorile ede Naijiria.
n mojuto oro abele, ogagun Abdulrahman Dambazau so pe; “A ti pinnu lati sise pelu ijoba
Juda di ilé mímọ́ rẹ̀,Israẹli sì di ìjọba rẹ̀.
Muhammadu Buhari jẹ oloṣelu a si le ṣe apejuwe rẹ gẹgẹ bi ọkan lara awọn gbajugbaja oloṣelu tẹsẹ wọn rinlẹ ni iha Ariwa orilẹede Naijiria.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ọdun meje ni Gyan ti fi jẹ Balogun ikọ Black Stars Ghana yoo gba ifẹsẹwọnsẹ wọn akọkọ ninu idije Afcon pẹlu Benin lọjọ kẹẹdọgbọn, Osu Kẹfa.
''O ṣe Ọlọrun mi, eyi pọju.
Bi eniyan ba n wuks tabi sin, iwọn omi diẹ to ba n jade ni imu tabi ẹnu wọn lee ni koko arun yii.
Ìtàn tó wà nídi òwe ‘Sebótimọ Ẹlẹ́wà Sàpọ́n’ Owó wọgbó!
Awọn abanikẹdun ko dawọ ikini duro ni ile oloogbe Moses Adejumo Olaiya ti gbogbo eeyan mọ si Baba Sala ni ilu Ilesa.
Bákan náà ni ẹni tí ó bá wà lóko kò gbọdọ̀ pada sílé.
Ogbeni Femi Odusanya, ti o je agbenuso fun egbe awon oloja ewe-be loja Mile 12 so pe, o pon dandan ki awon ipele ijoba meteeta mu alekun baa won agbe elewe-be, lati mu igberu ba ipese ounje, ni eyi ti o n ro ijoba apapo lati kowo lori gbigbe odo kaakiri orile-ede Naijiria, lati le mu igberu ba eto ogbin lasiko ogbele.
Dino Melaye fìdí rẹmi, Smart borí nílé ẹjọ́ kòtẹ́milọ́rùn Araale: Ẹgbẹ agbabọọlu wo lẹ n ja fun?
Ṣugbọn Peteru dáhùn pé, “Èèwọ̀ Oluwa!
Ìdí nìyí tí mo ṣe ní kí gbogbo ọmọ ẹgbẹ́ pọ́n ọn lé nítorí pé ojúkójú ni ẹnikẹ́ni lè fi wo ilé tí kò ní olórí.
Uganda: de pẹlu iwe aṣẹ igbelu Vanuatu: de pelu iwe aṣẹ.
Ṣugbọn Paulu ní kí á fi òun sílẹ̀ ní ìtìmọ́lé títí Kesari yóo fi lè gbọ́ ẹjọ́ òun.
Àkọlé àwòrán, Ilumọka oloseelu ni Bunmi Ojo jẹ nipinlẹ Ekiti Àwọn agbebon kan tí ṣeku pá arákùnrin Bunmi Ojo nílu Ado Ekiti, níbi tí ọ ti n wò bọọlu lójó ẹtì.
ijoba apapo ti fọwọsi rira awọn oka lati fi kun awon oka ti a ko pamọ.
Ninu iroyin miran ẹwẹ, ijọba Ipinlẹ Eko ti fofin de iwa tita ẹran agbo l'awọn oju opopona kan nipinlẹ naa, nibayii ti bi ọdun ileya wọle de tan.
 Bi ẹni wa ninu ahamọ ""Ti idawa opin ọsẹ ba le mu ki ọkunrin lu eeyan, ẹ ro ohun ti iru ọkunrin bẹ le ṣe ti eeyan ba wa pẹlu rẹ fun oṣu."
Ọmọ ọdún mẹ́rìnlá kàwé gboyè jáde ni Oxford Àwọn kànga ìṣẹ̀ǹbáyé rèé ní Badagry tó ń pa ẹrú níyè Èmi àti Bọla Tinubu fẹ́ lo ‘German Mercenaries’ láti gbé MKO Abiọla kúrò lẹ́wọ̀n - Dele Momodu Bakan naa lo ni bi awọn iṣinwẹẹrẹ akẹkọọ ti ko tii mọ ọwọ ọtun yatọ si osi ṣe n jade nileewe girama bayii lai ni iṣẹ ọwọ kankan ti wọn mọ kun ara ohun ti o n kun wahala aisi iṣẹ lorilẹ-ede Naijiria.
Àwọn ti ọ̀rọ̀ náà sojú ni, bí awakọ̀ náà ṣe kọ̀ láti san owó òun ti ọmọogun ọ̀hún si fọọ léti, ó ní ko máa fò bi ọ̀pọ̀lọ́, bákan náà ló tún tún gba ọkọ̀ lọ́wọ́ rẹ̀.
Òun náà sì tún fésí, ó ní ‘De ilé tani ìbá tún ṣe?
Bí afọ́jú bá ń fọ̀nà han afọ́jú, àwọn mejeeji yóo jìn sinu kòtò.
"Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: ""Àhámọ́ ajínigbé ni ń bá wà lónìí, ọ̀pẹ́ awakọ̀ mi"" Ẹ wo nkan tí Deeper Life High School tún sọ lórí Don Davis, akọ́kọ̀ọ́ JS1 tí wọ́n fi ipá bálòpọ̀ Àjọ NIMC ti gbé ìlànà tuntun jáde fún gbígba NIN lọ́nà ìrọ̀rùn Wo ọ̀pọ̀ mílíọ̀nù fóónù tí Whatsapp kò ní bá ṣiṣẹ́ mọ́ lọ́dún 2021 Ibodè àgbáyé ní Saki, ìbẹ̀ ni agbébọn ń gbà wọ ilẹ̀ Káàrọ̀ Oòjíire - Makinde gbarata ""Pẹlu ọpọ ohun alumọni to wa lorilẹede yii, ko yẹ ki Naijiria wa lara awọn otosi orilẹede, bẹẹ si ni ko yẹ ki awo ijọba abi ọmọ Naijiria kankan sun ninu ebi."
"Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Toyin Atoyebi mechanic: Ẹ wo Toyin, ọmọbinrin ọdún 16 tó ń tún skadà àti gẹnẹrátọ̀ ṣe ní ""Ko si aniani, owo wọle si apo owo Osun United, sugbọn wọn ko tilẹ bun awọn alaṣẹ Osun United to ni akanti naa leti rara."
Ẹwẹ, akòwé àgbà fún ìgbìmọ̀ ìlé ìwòsàn ní ìpínlẹ̀ Ondo Dr Niran Ikumọla ti bu ẹnu atẹ lu bi awọn ẹgbẹ awọn nọọsi nipinlẹ Ondo ti ṣe 'wọde lẹyin ti alarun ọpọlọ kan lu nọọsi ati dokita to n tọju rẹ nilu Akure.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Mà á gbẹ̀san bàálù àjọ UN tó já ní Borno - Buhari yarí Ẹ sá àwọn akẹ́kọ̀ọ́ sínú òòrùn fún ọgbọ̀n ìṣẹ́jú lójojúmọ́ - Ìjọba Oyo pàṣẹ Òṣìṣẹ́ LASTMA gún olólùfẹ́ rẹ̀ l'ọ́bẹ, ó tún gba ẹ̀mí ara rẹ̀ l'Eko Ikọ̀ ìjọba Ọ̀yọ́ dé lásìkò tí kò yẹ ni wọn kò ṣe wọlé - Ẹ̀bí Ajimobi fèsì Ojo arọrọda yii ṣe akoba fun ọpọ dukia ti ogunlọgọ awọn eeyan si di alainile lori nitori rẹ.
Mú burẹdi mẹ́wàá, àkàrà dídùn díẹ̀, ati ìgò oyin kan lọ́wọ́ fún un, yóo sì sọ ohun tí yóo ṣẹlẹ̀ sí ọmọ náà fún ọ.
Ọpẹ́ ni f’Ólúwa fún àwọn àyípadà rere wọ̀nyí.
Idi ni pe ọpọlọpọ ọdaran yoo maa lo anfaani pe ileeṣẹ ọlọpa faaye gba sisan owo fun ajinigbe lati maa ṣiṣẹ ibi.
Ẹ̀rù àti oríkunkun ló mú kíjọba máa fi ọlọ́pàá, ológun halẹ̀ mọ́ aráàlú - Ṣoyinka Toyin Abraham kìí bá èmi náà yọ̀, ni kò jẹ́ kí ń gbé e lárugẹ fún ayọ̀ ọmọ - Lizzy Anjorin Iṣẹ́ ọpọlọ ló yẹ ká ṣe nínú tíátà, kìí ṣe àfihàn ara bíbó àbí ìhòòhò wa - Binta Mọgaji Èmi àti Saheed kìí ṣe ọmọdé, a ti jọ ṣe Sinimá papọ̀, èyí túmọ̀ sí pé ìjà ti parí - Fathia Balogun Ọ̀pọ̀ èèyàn bẹnu ẹ̀tẹ́ lu Mercy Aigbe lórí bó ṣe ki Adeniyi Johnson Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Jumoke Odetola: Ọ́pọ̀ òṣèré koro ojú sí àṣehàn lásán lẹ́yìn ikú akẹẹgbẹ́ wọn, Williams Aanuoluwapo, Kumbalee19 Ògún 2020 Boko Haram, ISWAP in Borno: Islamic State West Africa Province ni àwọn mọ̀ọ́mọ̀ pa ṣọ́jà méje náà ni20 Ògún 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Ijọba Orilẹ-ede South Africa ko ri akọsilẹ kankan fi sita lori odiwọn iye igba ti ikọlu ti waye ni South Africa sawọn ajoji.
Àwọn orin kán wà ni ilẹ ̀ yorùbá tí wọ ́ n ń kù lọ .
Nítorí náà, ẹ̀yin àyànfẹ́, nígbà tí ẹ ti ní àwọn ìlérí yìí, ẹ wẹ gbogbo ìdọ̀tí kúrò ní ara ati ẹ̀mí yín.
Lasiko to fi n sọrọ nibi ayẹyẹ ṣiṣi awọn akanse iṣẹ to ṣe ni ipinlẹ naa ni gomina Okorocha ti ṣe ijẹwọ yii.
Idahun Ogunbanjọ: Iriri ninu oselu ko ni nnkan n se pelu ibi ti oro de duro bayii.
Ní ọjọ́ keji, Johanu rí Jesu tí ó ń bọ̀ wá sọ́dọ̀ rẹ̀, ó ní, “Wo ọ̀dọ́ aguntan Ọlọrun, tí ó kó ẹ̀ṣẹ̀ aráyé lọ.
"Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Murphy Elégungun Rọba: Mo fẹ́ di ẹnití egungun rẹ rọ jùlọ ní àgbáyé ""Ẹnikẹni ko gbọdọ dẹyẹ si akanda ẹda ni ibudo idikọ, awọn to ni ileeṣẹ irinna gbọdọ ṣeto to yẹ fun awọn ti ko le rin, rina tabi gbọrọ, ati awọn akanda to ku."
Awakọ naa ti orukọ rẹ n jẹ Moses Palmer ni iṣẹlẹ naa waye ni owurọ Ọjọ Satide.
Arabinrin naa japoro iku titi ki o to de; ki awọn eeyan to raye de ọdọ rẹ lo ti dagbere faye ninu agbara ẹjẹ.
Sotitobire Church: E túbọ̀ ní sùúrù, a máa wá ọmọ náà rí- Alukoro ọlọ́pàá
O ti mú kí òkìkí Israẹli kàn nípa àwọn nǹkan ńláńlá, ati nǹkan ìyanu tí o ti ṣe fún wọn, nípa lílé àwọn eniyan orílẹ̀-èdè mìíràn jáde tàwọn ti oriṣa wọn, bí àwọn eniyan rẹ ti ń tẹ̀síwájú.
Fun apẹẹrẹ, ileewosan fun awọn aboyun kan ni Johannesburg di titi pa tori iroyin pe wọn ni oṣiṣẹ wọn kan lọ sunmọ alaisan Coronavirus.
Ikú ọmọ Dbanj: Ohun ti awọn òṣeré n sọ
com/kAy9oPwBUHwon ti  bura fun aare Muhammadu Buhari bayi gege bi aare orile ede Naijiria fun saa keji fun odun merin.
Ilana yii ko sọ iye akọ ati abo ti wọn gbọdọ lo si ile iwe ni igba kan naa, ṣugbọn lorilẹede Naijiria bayii, awọn ọkunrin n lọ si ile iwe ju awọn obinrin lọ.
Koda, ọrọ ẹlẹsinjẹsin ati ẹlẹya mẹya gan wa lara ohun to n mi ẹsẹ isọkan ati irẹpọ Naijiria , tawọn klẹsin Kristiẹni ati Musulumi si n fi ojoojumọ tutọ si ara wọn loju.
Buhari ní ìdìbò 2019 kìí ṣe tikú-tìyè US Shut down: Embassy Nàìjíríà kógbá nílé 'Ori kó awakọ̀ àti ọmọ mẹta yọ nínú ìjàmbá ọkọ' 'Ootọ ní fídíò ọmọogun Nàìjíríà tí kò fẹ́ kojú Boko Haram ṣùgbọ́n.
Iko akoroyin lori faye somo-bibi sagbekale ilana ojo kukuru kan, pelu erongba ati se adinku iku alaboyun ati omo-wewe nipinle Kaduna ati ni orile-ede Naijiria lapapo.
Ǹjẹ́ o lè máa wò wá níran báyìí títí tí a óo fi kú?
Oríṣun àwòrán, Others Lẹyin ti Adajọ gbọ ẹjọ awọn agbẹjọrọ mejeeji, Adajọ Benjamin Hassan gba beeli wọn pẹlu miliọnu kan naira pẹlu onidurọ to n gbe ni agbegbe naa.
“Lẹ́yìn náà yóo pa ewúrẹ́ ìrúbọ ìmúkúrò ẹ̀ṣẹ̀ tí ó jẹ́ ti àwọn eniyan Israẹli, yóo sì gbé ẹ̀jẹ̀ rẹ̀ lọ sinu ibi tí aṣọ ìbòjú wà, yóo sì ṣe é bí ó ti ṣe ẹ̀jẹ̀ akọ mààlúù, yóo wọ́n ọn siwaju ìbòrí ìtẹ́ àánú, yóo sì tún wọ́n ọn siwaju Àpótí Ẹ̀rí.
Òjòlá-ìbínú tí i ṣe olórí ejò ayé gbogbo
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Orílẹ̀ède Ghana fí Asamoah Gyan jẹ Balogun káàfàtà ikọ Black Stars 24 Èbibi 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Balogun meji ni ikọ Black Stars ni bayi Balogun meji ni yoo dari ikọ agbagbọọlu Ghana,Black Stars lọ si idije Afcon 2019 ti yoo waye ni Egypt.
Oríṣìíríṣìí onjẹ ni ènìyàn lè rí ràjẹ pẹ̀lú, pàápàá láti ìlú Jamani.
Nítorí náà, ààyè wa ni o, òkú wa ni o, ti Oluwa ni wá.
Aarẹ Sudan, Omar Al-Bashir ni awọn ologun Sudan le kuro lori alefa lẹyin iwọde ifẹhonu han fun ọpọlọpọ oṣu to waye lodi si iṣejọba rẹ fun ọgbọ̀n ọdun.
Oríṣun àwòrán, Fellipe Abreu Àkọlé àwòrán, O yẹ ka se ẹyẹ ikẹyin fun oku wa tilu tifọn.
Oríṣun àwòrán, Getty Images ''Idunnu lo jẹ fun mi lati de ipo akọnimọọgba ẹgbẹ agbabọọlu yii.
Lẹ́yìn náà, yóo pada lọ sí ilé rẹ̀, ní Rama, nítorí pé a máa dájọ́ fún àwọn eniyan níbẹ̀ pẹlu.
Bakan náà ni ọ̀gá àgbà àjọ NCDC ni òun kò ní ìpinu kankan láti máa wá àwọn tó péju síbi ayẹyẹ náà kíri Ta ni Naira Marley jẹ́ gan an?
A o ṣe àpẹrẹ àṣà ìsìnkú ìbílẹ̀ fún arúgbó pẹ̀lú ni Ìbòròpa Àkókó ilú Yorùbá ni ẹ̀gbẹ́ Ìkàrẹ́-Àkókó ti Ipinle Ondo, orile-ede Nigeria.
Nígbà tí ó dé ọ̀hún tán ó ń wò káàkiri bóyá óun lè rí ènìyàn nínú rẹ̀, ibi tí ó sì tí ń ṣe èyí ni ó ti bẹ̀rẹ̀ sí gbọ́ igbe ẹni kan nínú ìyàrá kan báyìí, ó ń sọkún.
 Àwọn orílẹ ̀ -èdè míràn ṣe é ní dandan pé kí àwọn ọmọdé àti àwọn tí àìsàn yìí lè tètè kọlù máa gbà àjẹsára yìí lóòrèkórè .
Eyadema fipa gbajọba lorilẹede Togo lọdun 1967, o si jẹ aarẹ ilẹ naa to fi di ọdun 2005 to ku.
àwọn Juu ati àwọn aláwọ̀ṣe ẹ̀sìn Juu; àwọn ará Kirete ati àwọn ará Arabia, gbogbo wa ni a gbọ́ tí wọ́n ń sọ àwọn iṣẹ́ ńlá Ọlọrun ní oríṣìíríṣìí èdè wa.
Ó dé ìlú Samaria kan tí ń jẹ́ Sikari, lẹ́bàá ilẹ̀ tí Jakọbu fún Josẹfu, ọmọ rẹ̀.
Lẹ́yìn tí ó ti sá lọ ni àwọn iranṣẹ ọba pada dé.
Stella fi ibinu pa Stella alabagbe rẹ, o gba idajọ iku Orukọ kanna ni wọn jijọ njẹ ṣugbọn arabirin Stella Gilbert ko wo eyi mọ alabagbe rẹ, Stella Godwin lara, ko to fi ibinu gun lọbẹ pa.
OLUWA sọ fún mi pé, kí n lọ sí ilé ọba Juda kí n sọ fún un níbẹ̀ pé, 
Ẹ máa dáríjì ara yín bí ẹnikẹ́ni bá ní ẹ̀sùn kan sí ẹnìkejì rẹ̀; gẹ́gẹ́ bí Oluwa ti dáríjì yín bẹ́ẹ̀ gan-an ni kí ẹ̀yin náà máa ṣe sí ara yín.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Kara bridge explosion: Àjọ Lasema sọ pé wọ́n rí òkú nínú èèrù iná tó jó nítòsí Berger 21 Òkùdu 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 22 Òkùdu 2020 Oríṣun àwòrán, lasema Ajọ to n mojuto iṣẹlẹ pajawiri nipinlẹ Eko, Lasema, sọ pe oun ri oku ninu eeru ina awọn ọkọ agbepo to gbina lori afara Kara, nitosi Berger nilu Eko loru ọjọ Abamẹta.
“Dájúdájú, ibìkan wà tí wọ́n ti ń wa fadaka,ibìkan sì wà tí wọ́n ti ń yọ́ wúrà.
Ẹwẹ, oludije ipo aarẹ f'ẹgbẹ oṣelu Democrat l'Amẹrika, Joe Biden ti pe fun Iwadii kikun lori iṣẹlẹ naa.
”Gomina ipinle Kogi Yahaya Bello , ti o tun pe ara re ni odo, dupe lowo aare lati se onigbonwo eto apeje yii fun awon odo.
“Ẹ má jẹ́ kí ìdílé Kohati parun láàrin ẹ̀yà Lefi, 
Amoo gba ami-ayo kinni wole ni saa akoko ifesewonse naa, ki Oluwasegun o to gba ami-ayo keji wole niseju méjídínllọ́gọ́ta saa keji ifesewonse naa.
Pilatu wá sọ fún wọn pé, “Ẹ wò ó, ọkunrin náà nìyí.
Bẹẹ ba gbagbe, laipẹ yii ni iroyin kan tan kalẹ pe olori naa ni ajọṣepọ ikọkọ pẹlu gbajumọ akọrin Fuji nni, Wasiu Ayinde Kwam I, bi o tilẹ jẹ pe awọn mejeeji ti ṣẹ lori ahesọ ọrọ naa.
Ọ̀rọ̀ ti ń gba ibòmíràn yọ lórí ẹ̀ṣùn ìfipábánilòpọ̀ - Timi Dakolo Pariwo Àjọ ọlọpàá Eko kédé pé ìbalòpọ̀ nítà kò bójúmu Iwadii to ṣẹṣẹ ṣe pẹlu ifọrọwanilẹnuwo fun awọn ọkunrin ọgbọn laarin oṣu Karun un, ọdun 2018 si oṣu Keje, ọdun 2019, lati mọ bi awọn ọkunrin ṣe n koju ibalopọ tipatipa.
Ọlọrun tí ń gbani là ni Ọlọrun wa;OLUWA Ọlọrun ni ń yọni lọ́wọ́ ikú.
O ni oun fi ẹgbẹ oṣelu APC silẹ nitori idojuti ati inuni-bini nla ti oun doju kọ ninu ẹgbẹ naa.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, BBC ṣe'filọlẹ ami ẹyẹ Komlar Dumor Ile iṣẹ BBC ṣe agbekalẹ ifoye yẹnisi ami ẹyẹ Komla Dumor lati buyi fun atọkun ile iṣẹ BBC World News to sa dede ku lọdun 2014 lẹni ọdun mọkanlelogoji.
Oríṣun àwòrán, LASEMA O ni laago meji oru oni ni LASEMA gba ipe nipa ijamba ina naa lopopona Eko si Ibadan.
Nítorí ìjì náà sá túbọ̀ ń le sí i ni.
Nigeria ministers: Wo ohun tó yẹ kí o mọ̀ nípa àwọn obìnrin méje ti Buhari forúkọ wọn ránṣẹ
Gẹgẹ bi Abdulrasheed Adeoye to jẹ oludari agba ẹka iṣẹ ọna to si ti jẹ oludari ẹka imọ Tiata ni fasiti Ilorin eyi tii ṣe ipo meji ọtọọtọ ti oloogbe Ayo Akinwale naa ti kuro to gbe eku ida le e lọwọ, wọn bi Ayo Akinwale ni ilu Ibadan, ọmọ bibi ilu Ibadan si ni pẹlu.
 Àwọn wọ ̀ nyìí ni ó ń gbé ní Àgọ ́ -Ìwòyè .
ohun ìbànújẹ́ ńlá ati ẹ̀dùn ọkàn ni ọ̀ràn àwọn eniyan mi jẹ́ fún mi nígbà gbogbo.
 Buhari júwe ọ̀nà ilé fún Obono-Obla lórí ẹ̀ṣùn ayédèrú ìwé ẹ̀rí Àjẹ́ àti Aṣẹ́wó ní ìyá Rainbow - Òjòpagogo Bí Khafi ṣe ní ìbálòpọ̀ ojútáyé tako àṣà Yorùbá - Ìjọba Ekiti 'Ejò lọwọ nínú lórí ikọlù àwọn ọmọ ogun Nàìjíríà' Bakan naa lo tun rọ awọn eeyan agbegbe naa lati joye oju lalakana fii n ṣọ ori nitori pe gbogbo igbesẹ ti awọn agbebọn naa n gbe ko ṣẹyin alami ti awọn kan lara araalu n ṣe fun wọn.
" Abbas fi kun pe wọn ti n gbiyanju lati na owo naa, ati pe wọn ko ni i dẹkun iwa jibiti wọn ti ile ẹjọ ko ba gbẹsẹ le apo asuwọn naa.
Káàkiri àgáyé ni àwọn èèyàn dá ọjọ́ òní sí ní ọlọ́kan-òjọ̀kan nítorí bí ònkà ọjọ́ náà ṣe báramu rẹ́gí-rẹ́gí.
O din diẹ ni ẹgbẹrun lọna ọgbọn obinrin kaakiri agbaye ti wọn n doloogbe lati ọwọ ololufẹ wọn ti wọn n fẹ lọwọ tabi ti wọn ti fẹ sẹyin lọdun 2017.
School reopening: Ìjọba ìpínlẹ̀ Rivers kéde ọjọ́ tí àwọn iléèwé yóò wọlé padà
Kí wọn máa fi òye kọ́ àwọn ọdọmọbinrin wọn láti fẹ́ràn ọkọ wọn ati ọmọ wọn.
Jedeaya, ará Meronoti, ni ó wà fún àwọn abo kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́.
End bad government: Wọn rò pé a maa jà tàbí ba ǹkan jẹ́ ni ṣùgbọn ọmọlúwàbí ni wa-Afẹ̀hónúhàn Onikaluku sọ diẹ nipa ohun ti oju wọn ti ri lọwọ awọn agbofinro Naijiria.
“ ‘Bọ̀wọ̀ fún baba ati ìyá rẹ gẹ́gẹ́ bí OLUWA Ọlọrun rẹ ti pa á láṣẹ fún ọ; kí o lè pẹ́ lórí ilẹ̀ tí OLUWA Ọlọrun rẹ fún ọ, kí ó sì lè máa dára fún ọ.
Èmi àti Saheed kìí ṣe ọmọdé, a ti jọ ṣe Sinimá papọ̀, èyí túmọ̀ sí pé ìjà ti parí - Fathia Balogun Mo fẹ́ pa ara mi torí ojú àbùkù tí wọn ń fi wò mí pé mo fi iṣẹ́ abẹ bímọ"" Fulani kò leè dúró, táa bá lo ohun ta jogún lọ́dọ̀ àwọn bàbá wa - Sunday Igboho Ọjà Àgbáláta ní Badagry rèé, níbití ẹran ejò ti dùn ju ẹran adìẹ lọ Bakan naa lo gba pe, ko si ohun ti awọn ọkunrin n se, ti awọn obinrin ko lee se ju bẹẹ lọ, idi si ree ti awọn obinrin fi yẹ ko kọ awọn isẹ miran tawọn ọkunrin n se, lọna ati maa pawo wọle, yatọ si isẹ aransọ."
Ó pé ọdún 17 tí Bọla Ige kú; àwọn nkan tó yẹ́ kí o mọ̀ nípa rẹ̀ rè é Rwanda: Àjẹ́ tó dóòlà ẹmí àwọn ènìyàn rèwàlẹ̀ àsà 7) Davido - Nwa Baby Orin yii jẹ ọkan lara awọn orin to wọnu ipele nkan ti wọn wá julọ lori google ni Naijiria lọdun 2018.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ajá dóòlà ọmọ tuntun tí ìyá rẹ̀ bò mọ́lẹ̀ láàyè ni Thailand 18 Èbibi 2019 Oríṣun àwòrán, khaosod Àkọlé àwòrán, Ajá naa bẹrẹ si ni i gbo nigba to ṣakiyesi ẹsẹ̀ ọmọ naa to yọ sita Ni Ariwa orilẹede Thailand ni Aja kan ti doola ọmọ tuntun jojolo kan lẹyin ti iya ọmọ naa to jẹ ọdọ bo o mọlẹ ni aaye.
Amọ, agbenusọ fun ile isẹ ọlọọpa ni ipinlẹ Ondo, Femi Joseph sọ pe iwadii ti bẹrẹ ni pẹrẹwu lori isẹlẹ naa.
Ẹsẹ̀ rẹ ti dára tó ninu bàtà,ìwọ, ọmọ aládé.
Sugbọn eyi to jẹ iyalẹnu ni ajọsepọ to wa laarin ayaba Ọyọ naa ati ilumọọka ọkunrin kan to maa n mura bi obinrin, tọpọ eeyan mọ si Bobrisky.
Bakan naa lo wọ koto to ni aworan Satani si ori, to si ka oriṣiriṣi ọrọ lati jẹjẹ atilẹyin ati ifọkansi fun Satani.
Olórí ilé asòfin l‘Ọ́sun pàdánù N38m sọ́wọ́ gbájúẹ̀ 'A fẹ́ dojú kọ ìṣòro Nàìjíríà' Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Ilé ìwòsàn ṣi abẹ́rẹ́ Formalin gún mí; n kò lè dá ìgbẹ́ àti ìtọ̀ dúró mọ́' Ò sòro láti bímọ sí Nàíjíríà - Bill Gate Ẹ o ranti wipe, ni oṣu kẹta ọdun 2018 ni Ọgbẹni Bill Gates sapejuwe ilana imupadabọsipo ati agbega ọrọ aje tijọba apapọ dawọle gẹgẹ bii eyiti ko ba aini awọn araalu pade.
Taní Ibidunni Ighodalo tí gbogbo ọmọ Nàìjíríà ń selédè lẹ́yìn rẹ̀ 'Ọlọ́pàá ló ń pa wá, kìí ṣe coronavirus' Òjò àrọ̀ọ̀rọ̀dá dá wàhálà sílẹ̀ l'Eko Gómìnà márùn ún tó fojú winá ìbínú bàbá ìsàlẹ̀ wọ̀n A gbọ wi pe bi ara yii ṣe san lo pa awon ẹṣọ meta naa loju ẹsẹ, to si jan awọn mii mọlẹ, ti gbogbo agbegbe naa si di erujeje.
Níbẹ̀ ni mo ti rí obinrin tí ó gun ẹranko pupa kan, tí àwọn orúkọ àfojúdi kún ara rẹ̀.
Àwọn onigbagbọ níláti fẹ́ràn ara wọn.
Ninu ẹẹdẹgbẹsan ó lé marundinlọgọrin (1,775) ìwọ̀n ṣekeli fadaka ni ó ti ṣe àwọn ìkọ́ fún àwọn òpó náà, ara rẹ̀ ni ó yọ́ lé àwọn ìbòrí wọn, tí ó sì tún fi ṣe àwọn ọ̀pá tẹ́ẹ́rẹ́tẹ́ẹ́rẹ́ fún aṣọ títa wọn.
2 104442 Ilẹ Australia 908 3.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ṣé ó láyà?
ṣugbọn gbé mi kúrò ní ilẹ̀ Ijipti kí o sì sin mí sí ibojì àwọn baba mi.
com/voiceofnigeria/status/1133654961764671488Aare Muhammadu Buhari naa ti de si papa isere  Eagles Square niluu Abuja Alufaa Rev Dr.
Nibayii, ijoba to wa lori aleefa si n se
Awon alakoso egbe to n sejoba lowo bayii, Egbe All Progressives Congress (APC)  ti se ipinnu lati fi odun kan kun  iye odun ti awon alakoso egbe won  maa n lo lori ipo  tele, bakan naa ,ni awon egbe to n mojuto ise akanse yoo maa gbe oro naa wo.
Omijé ń dà pòròpòrò lójú mi,nítorí ìparun àwọn eniyan mi.
Aare Muhammadu Buhari,  ti kedun pelu ebi, ore, ara ati awon ololufe fun iku oloogbe Ted Mukoro, ti o kopa ninu ere ero amohunmaworan Village Headmaster, leni ti o jade laye lomo odun mokandinlaadorun.
 Àkọlé àwòrán, BBC n wo awọn iroyin ni fini-fini Olubayọde Alebiosu: Isẹ akoroyin jẹ ara igbe aye mi.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Maryam Sanda: Femi Adebayo, Bimbo Akinsanya sọ̀rọ̀ lórí ohun tó ń kóbá ìgbèyàwó 1 Èrèlè 2020 Oríṣun àwòrán, Instagram Bi awọn eeyan ṣe n fesi si ọrọ idajọ ti ile ẹjọ da fun Maryam Sanda ti ile ẹjọ ṣẹṣẹ da ẹjọ iku nipa yiyẹ igi fun tori wi pe o pa ọkọ rẹ, Bilyaminu Bello ṣi n fẹ loju sii.
Awọn iroyin ti ẹ lee nifẹ si: CAN ni ki Bello t'ọwọ ọmọ rẹ basọ 'Kristẹni lo n fara kaaṣa ikọlu fulani ju' Ileẹjọ f'ofin de ọdun oro nipinlẹ Ogun Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
tun sọ pe “Mo fe fi daa yin loju pe eni ti ẹ nifẹẹ si
Ọmọ mi, fetí sí ọ̀rọ̀ mi,tẹ́tí sílẹ̀ sí ohun tí mò ń sọ.
Mo kí gbogbo Mùsùlùmí lọkunrin àti lobinrin, ní orílè èdè Nàìjíríà àti ní gbogbo àgbáyé pé, a kú ìdásẹ̀ wọ oṣù alápoǹlé nii tí ṣe oṣù Ramadana, oṣù yọ́ ẹ̀sẹ̀ yọ́ ẹ̀sẹ̀, ẹ̀mí gbogbo wa tí a bẹ̀rẹ̀ rè ni yíò gbájá nínú ìlera tó péye àti àlàáfíà.
” Ẹ̀ ń yínmú sí mi.
Gbogbo ilẹ̀ẹ wọ́n ni àwọn onílẹ̀ fi odi yípo.
Ninu atẹjade ti adari igbokegbodo ile isẹ Victor Ayetoro fọwọsi lo ti salaye pe akasọ naa kuna ti ọkọ to n gbe eniyan lọ soke sodo si ja lulẹ.
 Ààbò lo ko nǹkan ìlò ọkọ rẹ lo ta ni ọjà ejigbomekan ní owó pọ ́ ọ ́ kú ó ra ounjẹ wọn ṣi tójú àwọn àlejò wọn .
Ilẹ̀ lanu, ó fa omi tí Ẹranko Ewèlè náà tu jáde lẹ́nu mu.
Ṣugbọn ibeere ti oun gbọdọ wa idahun si ni pe kilode ti oun fi sọrọ yii lasiko yii ti oun ti sun mọ ọgọrin ọdun laye?
 O ni o yẹ ki ẹgbẹ naa ni ẹni ti yoo maa ṣoju fun wọn ninu igbimọ alaṣẹ igbimọ eto Madanidofo ẹka eto Ilera yii.
bí mo ti ṣe sí Ṣilo ni n óo ṣe ilé tí à ń fi orúkọ mi pè, tí ẹ gbójú lé; ati ilẹ̀ tí mo fún ẹ̀yin ati àwọn baba ńlá yín.
Koda, ni ilẹ yii ati loke okun ni awọn eeyan ti bu ẹnu ẹtẹ lu iṣẹlẹ naa.
Ó tún fi wúrà tí a fi òòlù lù ṣe ọọdunrun (300) apata kéékèèké.
Bẹ́ẹ̀ ni wọ́n bẹ̀rẹ̀ si yí padà sí onírúurú ǹkan títí wọ́n fi di ejò ọkà.
Ọ̀rọ̀ wọn dùn mọ́ Hamori ati Ṣekemu, ọmọ rẹ̀ ninu.
Sugbọn o ni awọn miran to jọ bẹẹ bi apẹrẹ Marine Le Pen ilẹ Faranse.
Mo wá rí ẹranko kan tí ń ti inú òkun jáde bọ̀.
Oríṣun àwòrán, @CAPRITOLU Ibẹ tutu mini mini lootọ, to si dabi ẹni pe ojo sẹsẹ rọ ni nigba ti awọn agbegbe yoku ninu igbo naa si gbona.
"Otinubu ni "" Ẹ ti gbọ ohun ti Buhari sọ nipa jiji apoti ibo gbe."
O ni ajọ naa yoo bẹrẹ si maa
Ìgbà tí mo dé ilé, ìyá mi tún ti ku.
Arabinrin to fẹsun kan yari kanlẹ ti ọ̀rọ̀ naa si di tọrọ fọn kalẹ.
" Wo àmì márùn-un tí o fi le mọ ẹni tó fẹ́ gbẹ̀mí ara rẹ̀ Típà tẹ dẹ́rẹ́bà pa ní Epe Lẹ́yìn ọ̀pọ̀ ọdún, ìjọba Kwara fẹ́ sọ orúkọ Rashidi Yẹkini di mánigbàgbé Ọwọ́ tẹ ọkùnrin kan ní pápákọ̀ òfurufú l‘Eko tó ń kó ike ATM 2,886 lọ si Dubai Eniuola Badmus Eniola Badmus ti ọpọ awọn ololufẹ rẹ mọ si gbogbo Bis girls naa ṣọjọ ibi laarin ọsẹ yii.
Lara awon to wa nibi ayeye ajodun naa ni, Sylvester Nsofor,asoju orile ede Naijiria ni United States ati iyawo re, ati ojogbon, Uzodimma Nwala, aare  egbe to n mojuto eto  idagbasoke  Ala-Igbo .
Wọ́n dúró fún ìgbà díẹ̀, ni àwọn ìjọ bá fi tayọ̀tayọ̀ rán wọn pada lọ sọ́dọ̀ àwọn tí ó rán wọn wá.
Òun ni ó wá gẹ́gẹ́ bí ẹlẹ́rìí, kí ó lè jẹ́rìí sí ìmọ́lẹ̀ náà, kí gbogbo eniyan lè torí ẹ̀rí rẹ̀ gbàgbọ́.
Ọlọrun lágbára láti tún lọ́ wọn pada sí ibi tí ó ti gé wọn.
Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Ibadan Divorce: Abílékọ Idowu faraya ní kóòtù kọkọ-kọkọ n'Ibadan, Ó ní òun ò leè pín ọkọ òun pẹ̀lú ẹnikẹ́ni18 Ògún 2020 Akure shooting: Àlááfíà ti padà sí ìlú Akure, ẹnikẹ́ni kò kú - Deji ilu Akure7 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Divorce in Ibadan: Iléẹjọ́ tú ìgbéyàwó ọdún méjé ká nítorí àìnáání ara ẹni6 Bélú 2020 Fídíò, Promise Akinlade: ọmọ ọdún mọ́kànlá tó ń fi ìlù dárà bíi àgbàlagbà sọ̀rọ̀ nípa tálẹ́ǹtì rẹ̀7 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Overweight and pot belly: Wo oríṣìí oúnjẹ márùn ún tó lè dẹ́kun ikùn yíyọ àti ara àsanjù8 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Aisha Buhari: Aya Ààrẹ Buhari ké sí àwọn aya gómìnà pé kí wọ́n lọ paná ìdàrúdàpọ̀ ágbègbè kóówá7 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Male Fertility: Wo àwọn oúnjẹ márùn ún tó ń mú kí àtọ̀ ọkùnrin dára sí i7 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
 Lara awon eniyan naa ni awon ajafetomoniyan , awon osise ni ile-ise eepo robi.
Shehu sọrọ lori oriṣii awọn awakọ to wa loju popo ni Naijiria bii atawọn ero to n ronu rinlọ loju titi.
Ajọ awọn gomina lorilẹede Naijiria yoo kede igbesẹ to kan lori ọrọ RUGA"" ni ọrọ Garba Shehu fi da ileeṣẹ wa lohun."
Iṣẹ aje ati ọna lati la lo gbe Temitope lọ si ilẹ okeere lẹyin to sinru ilu tan, ko to o di pe o bọ sọwọ awọn to fi awọn to sọ pe awọn yoo ba wa iṣẹ olukọ nilu Dubai, ti yoo si maa gba owo gọbọi.
Sibẹ o rọ awọn eeyan ipinlẹ Eko lati maṣe jafara pẹlu eto imọtoto wọn o nitori o daju pe iṣẹgun n bọ laipẹ.
si awon ekun oselu Ipolongo yoo bere pelu sise abewo si awon ekun oselu mefa  kookan jake-jado orile-ede yii.
Dúkìá àti ọkọ̀ jóná, ọlọ́pàá mẹ́sàn-án fara gbọta lásìkò ìwọ́de Shiite Òkìtì iyanrìn wó pa èèyàn méjí nílùú Ibadan Èèmọ̀!
Nígbà ti àkọròyìn BBC Yoruba bèèrè nípa gbogbo àwọn ọ̀rọ̀ tí wọn ń tẹ̀ ránṣẹ́ loju opo twitter Dino, ó sàlàyé pé kò sí àrídájú pé sẹnátọ Dino fúnra rẹ̀ ló ń tẹ jáde.
Ó lọ sí ẹnu ọ̀nà ààfin, ṣugbọn kò wọlé nítorí ẹnikẹ́ni kò gbọdọ̀ wọ àkísà wọ inú ààfin.
Idi ni pe baba wọn pẹlu nigba aye rẹ kii ṣe oburẹwa rara.
Eyi ti sun iye awọn to ti lugbadi arun naa siwaju di ẹgbẹrunleniejilelọgọsan.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù LASEMA Lagos Accident: Ọkọ̀ akóyanrìn tẹ èèyàn kan pa ní Epe 2 Agẹmo 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 11 Owewe 2020 Oríṣun àwòrán, Lasema/Facebook Ijamba ọkọ kan to waye lagbegbe oju ọna marosẹ Lekki si Epe ti ran eeyan kan lọ sọrun Gẹgẹ bi atẹjade kan ti ajọ LASEMA fi sita, wọn doola ẹmi eeyan kan bẹẹ ni wọn gbe oku eeyan miran kan jade nibi ijamba naa.
"A rọ àjọ elétò ìdìbò INEC láti wọ́gile ìdìbo náà ti wọn bá wa kọ̀ láti wọ́gile a jẹ́ wípe ilé ẹjọ ni à ó ti gba ẹ̀tọ́ wa"" Akọwé ẹgbẹ́ òṣèlú All Progressives Congress (APC) nípinlẹ̀ náà Ibrahim Sarina sọ pé ọ̀rọ̀ ẹgbẹ́ alátakò lásan ní èyí nítori ní ibi ti òun wà ní ijọba ìbílẹ̀ Takai kò si ǹkan to jọ irú ǹkan bẹ́ẹ̀ bí ìdìbò ṣe ń lọ ni ìrọwọ́rọsẹ̀."
Ó ní, “Pẹpẹ yìí yóo wó lulẹ̀, eérú orí rẹ̀ yóo sì fọ́n dànù.
" Aarẹ ẹgbẹ naa ṣalaye pe ti ijọba ko ba san owo naa ni akoko ti gbendeke ti wọn fun ba ti pari, awọn yoo gbe igbesẹ to kan.
Wọn kò bìkítà fún ọjọ́ ìsinmi mi, mo sì ti di aláìmọ́ láàrin wọn.
Bo ṣe n mu wọn nibi ti ooru ti n mu, lo n mu wọn nibi ti otutu wà.
Ultimate Cyclers Ọmọ ilẹ Amẹrika kan niroyin sọ pe o ni eto 'idokowo' yii, ti eto naa si ti pa orukọ da laimọye igba.
o ye kì a tètè menu ba ìyàtò kan ti ó wà láàrin bíbá òfin mù àti jíjé àtéwógbà .
O ni ijọba Amẹrika ṣetan lati daabo bo ẹka ile iṣẹ ifowopamọ lọwọ awọn onijibiti ti wọn n fi ọrọ owo ṣiṣe boju wa si Amẹrika.
Òwúrọ̀ ọjọ́ keji lẹ́yìn àjọ ìrékọjá ni ìgbà kinni tí wọ́n fi ẹnu kàn ninu èso ilẹ̀ náà, wọ́n jẹ àkàrà tí kò ní ìwúkàrà ati ọkà gbígbẹ.
Owó gọbọi wá nídìí oko-owo igbó gbingbin, Ìpínlẹ̀ Ondo kò ní pẹ gba àṣẹ láti gbin - Akeredolu Mo ṣetán láti ta ilé tí mo ń gbé, kí n le rí àwọn ìbejì mi padà - Akeugbagold Gómìnà Ṣèyí Mákindé ó ní ìdí tí òun kò fi leè ti ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́ pa nítorí COVID-19 Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Kini Yoruba international passport""?"
Alhaji Lai Mohammed so oro ohun di mimo lasiko sise ifilole ero igbalode “Digital Terrestrial Television Switch Over project “ nipinle Osun, ti o kogun si gunsu orile-ede Naijiria lojo eti(Friday).
Kawu sọ pe ko tọ fun ile-isẹ igbohunsafẹfẹ lati maa ka lẹta ipolonlogo ẹgbẹ oselu nigba ti akoko idibo ko tii sunmọ'le.
Ṣugbọn àwa tìkarawa yóo di ihamọra ogun wa, a óo sì ṣáájú ogun fún àwọn yòókù títí wọn yóo fi gba ilẹ̀ ìní tiwọn.
àwọn nìkan ni a fún ní ilẹ̀ náà,àlejò kankan kò sì sí láàrin wọn).
    Nígbà tí mo mọ̀ pé gbogbo wọ́n ti lọ tán pátápátá mo wí fún àwọn ẹlẹgbẹ́ mi kí wọ́n sọ̀ kalẹ̀ kí wọ́n dúró dè mí, lẹ́yìn náà mo yà sí inú igbó ní apa ọ̀tún mi, nígbà tí mo dé ọ̀hún, mo ké pe Olódùmarè pé kí ó jọ̀wọ́ ṣe alátìlẹ́yìn wa bí a ti ń lọ, mo ra ọwọ sí ojú ọ̀run mo sì wí fún Olódùmarè pé, Ṣìgìdì kò lágbára níwájú Ọlọ́run, Àǹjọ̀nnú kò gbọdọ fi ọwọ pa ìdà Ẹlẹ́dàá lójú, ọgbọ́n orí ẹni kò tó gba nì là láìfi ti Ọlọ́run ọba si i.
Ọ̀rẹ́kùnrin pa ọmọ igbákeji gómínà tẹ́lẹ̀rí 'Fayẹmi ṣì ní ẹ́jọ́ láti jẹ́ ní Ékìtì' Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ekiti Election: Idibo ti bẹrẹ ni pẹrẹwu!
Lẹyin ipade aarẹ Amerika, Donald Trump ati Kim Jong Un ni ori ilẹ North Korea ni Trump ti ki ara rẹ ku iṣẹ takuntakun ti o ṣe.
O wa sun igbẹjọ ọhun si ọjọ kejidinlogun, oṣu kẹjọ.
O da oko ọgbin Abiọla farms silẹ, ibudo itawe Abiola Bookshops, ileesẹ ti wọn ti n ta eroja fun agbekalẹ ileesẹ redio, ileesẹ burẹdi Wonder bakeries, ileesẹ iroyin Concord Press, ileesẹ ofurufu Concord Airlines, ileesẹ elepo Summit oil, ileesẹ ọkọ oju omi Africa Ocean Lines, ile ifowopamọ Habib, ileesẹ to n gbe awo orin jade Decca W.
Nígbà ti BBC Yorùbá kàn sí ilé iṣẹ́ Turkish Airline ti àwọn ènìyàn ọ̀hún fẹ̀sún kan, aṣojú wọn sàlàyé pé lọ́ọ̀tọ́ ní àwọn èrí to wà níwájú àwọn fí han pé ọks òfurufú àwọn ní wọn bá rin ìrìn àjò, sùgbọ́n àwọn kò tí le fídí ọ̀rọ̀ múlẹ̀ òṣíṣẹ́ tó wà ní ìdí ọ̀rọ̀ náa.
Láti ibùgbé rẹ lókè ni o tí ń bomi rin àwọn òkè ńlá.
Ó bá ní kí wọn kéde fún àwọn ará Ninefe, pé, “Ọba ati àwọn ìjòyè rẹ̀ pàṣẹ pé, eniyan tabi ẹranko, tabi ẹran ọ̀sìn kankan kò gbọdọ̀ fi ẹnu kan ohunkohun.
 Follow @voiceofnigeria  for live coverage, reports and commentaries.
 Ni bayii, a ni lati lo gbaradi fun ifesewonse to tun bo lona.
Ó ti mú odì yíyàn dópin lórí agbelebu.
Idi ni pe ile asofin kẹfin pe owo naa ti wọ apo aladani kan.
Sibẹ o kò ṣe bí àwọn alágbèrè, nítorí pé o kò gba owó.
O le ni bilionu mẹ́rìndínlógún dola
Dide to de si Eko, o yipada di ẹlẹsin Kristiẹni.
Oríṣun àwòrán, @HQNigerianArmy Àkọlé àwòrán, Laipẹ yii ni ọwọ awọn ọmọogun tẹ awọn darandaran fulani kan ni ipinlẹ Benue nibi to ti n ba oko oloko jẹ Ọwọ tẹ mẹfa ninu awọn darandaran fulani naa nigba ti awọn ọmọogun naa tọpinpin wọn de ileto miran ti orukọ rẹ n jẹ Garigiji nibi ti wọn ti n gbimọran ati salọ mọ awọn ologun naa lọwọ.
🚨 [BREAKING NEWS] 🚨✍ Agreement for loan of @AsisatOshoala ▶ https://t.
Àwọn agbókùú fẹ́ fàá lọ ilé ẹjọ́
“Erongba wa lati gbogun ti iwa ibajẹ ti n so eso rere.
Wọ́n sì bù u ṣàkà báyìí lójú mi, bẹ́ẹ̀ ni òun ni yóò dá ẹjọ́, o sì yà mi lẹ́nu pé ojú gbogbo wa báyìí ni ọba ṣe ń bẹ wọ́n kí wọ́n padà sí ọ̀dọ̀ òun.
Lẹyin naa lo lọ sileewosan Anglogold Ashanti, fun itọju.
Ṣé lóòtọ́ ni ìgbìmọ̀ olùwádìí dábàá kí Ààrẹ Buhari yọ alága EFCC, Ibrahim Magu nípò?
Oríṣun àwòrán, Ile oodua Lati ọjọ pipẹ lawọn igbagbọ kan ti waye nipasẹ iroyin tawọn eeyan ti gbọ nipa jijẹ ọba nilẹ Yoruba.
Èmi ni Ikú, èmi pàtàkì tí í ṣe ìránńṣẹ́ Olódùmarè, àáké Ọlọ́run Ọba, tí ń gbé àwọn ènìyàn lulẹ̀, tí ń hú gbòǹgbò ẹni ńlá, tí ń gba baba lọ́wọ́ oníbaba, tí ń gba ìyá lọ́wọ́ oníyàá, mo ti gba ọmọ lọ́wọ́ ọlọ́mọ; mo ti gba ènìyàn lọ́wọ́ elénìyàn; mo ti gba ọkọ lọ́wọ́ ọlọ́kọ; mo ti gba ìyàwó lọ́wọ́ oníyàwó, mo ti pín olùfẹ́ ní ìyà; mo ti gba ọ̀rẹ́ lọ́wọ́ ara wọn; mo ti sọ gbajúmọ̀ lẹ́rù kalẹ̀; mo ti mú àyípadà bá olówó; mo ti fẹ́ ojú bọ̀ọ̀kinní kù; àkùkọ ti kọ lẹ́hìn alágbára; mo ti mú arẹwà kúrò lórí ilẹ̀; mo ti sọ àwọn ọlọgbọ́n di èrò inú pósí; mo ti pa ojú àwọn ènìyàn pàtàkì dé, àti gèǹdè, àti àgbàlagbà, ọkùnrin, obìnrin, dúdú, funfun, pupa; gbogbo wọ́n tí ṣubú níwájú mi.
Akawe yi ṣe rẹgi pẹlu arakunrin kan ti súnkẹrẹ-fàkẹrẹ ọkọ ló kó o yọ lọwọ ìjàmbá ọkọ òfurufú' kan to ja lorile-ede Indonesia.
Wọ́n sọ ilẹ̀ wọn di ohun ẹ̀rù ati ohun àrípòṣé títí lae.
Bakan naa lo tun ke si awọn ololufẹ rẹ lati maa wo awọn fiimu to ba gbe jade, paapaa lojo opo YouTube rẹ ki awọn owo diẹdiẹ le maa wọle fun un.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Barister lo bi gbogbo oníṣẹ́ fújì -Oṣupa Igba ti ọmọ to ran niṣẹ pada de, lo ba iya rẹ ati ọmọ tuntun ninu ile, eyi lo si mu ko pariwo 'ẹ gba mi' si awọn alajọgbelepọ wọn fun iranlọwọ.
Jíjáde tí ènìà jáde yìí, á bọ́ sí oko nlá kan tí wọ́n fi odi òkúta yípo bíi ti àwọn oko abúlé Youlegrave tí ìrìnàjò ti bẹ̀rẹ̀.
Jesu bá pe ọmọde kan, ó mú un dúró láàrin wọn, 
Ofin naa ti adape rẹ n jẹ CAMA, si lo fun awọn asoju ijọba lagbara lati gba akoso awọn ile ijọsin, ki wọn si yọ igbimọ oludari ibẹ lai lọwọ ile ẹjọ ninu.
OLUWA wí fún Mose pé, “Kí ló dé tí o fi ń ké pè mí, sọ fún àwọn ọmọ Israẹli pé kí wọ́n tẹ̀síwájú.
Eyi lo mu ki wọn pinnu lati se afihan ile ounjẹ ti ko wọpọ lawujọ si awọn gbagede kan, eleyii to bẹrẹ ni Malmo, lorilẹede Sweden ni Ọjọ Kọkanlelọgbọn, Osu Kẹwa, ọdun 2018.
Mo baa sọrọ l'ọjọ Aje lọgan ti a pari eto idibo nipinlẹ Ondo, mo si sọ fun iya mi wi pe a o rira ni opin ọsẹ.
Bani Jackreece ti oun naa n gbe lagbegbe Oyigbo sọ fun BBC pe laago mẹrin idaji loun sa kuro nile nitori ẹru n ba oun lori eto aabo to mẹhẹ nibẹ.
Eyi ko sẹyin bi ọkọ agbepo to ja lati ara ọkọ ti naa ṣe da sunkẹrẹ fakẹrẹ ọkọ silẹ ni afara ọtẹdọla ni ipinlẹ Eko.
kí ó lè ra àwọn tí ó wà lábẹ́ òfin pada, kí á lè sọ wá di ọmọ.
Ipinlẹ Eko lo ni eeyan to poju pẹlu eeyan 128 lọjọ Aje nikan soso.
Kò sí ewu lóko, àfi gìrì àparò, Ọ̀rẹ̀ ni Akọgun Tola Adeniyi jẹ́ si Akọgun òun si ló mu wọ́n mọ Kila.
Mata dá a lóhùn pé, “Mo mọ̀ pé yóo jí dìde ní ajinde ọjọ́ ìkẹyìn.
Tiamiyu Kazeem gbẹmi mi lọjọ kejilelogun, Oṣu keji ọdun 2020 lẹyin ti wọn sọ pe ọkan lara awọn oṣiṣẹ SARS ti lati inu ọkọ, ti ọkọ mii to n bọ si kọluu, leyi to mu ko njẹ Ọlọrun nipe.
O fikun ọrọ pe, iru nnkan to mu ki orilẹede Amẹrika se ayipada ofin rẹ leyi, lati le ri pe awọn ọmọ orilẹede naa wa lailewu.
 Yato si owo bilionu meta le nida meta ti won san nibere odun yii fawon towo won ko po to ogorun un milionu.
Ta ló pa ọgágun Borgi, ọ̀rẹ́ ni tàbí ọ̀tá?
“Alaafia ni mo fi sílẹ̀ fun yín.
N óo pa gbogbo àwọn tí ń lọ tí ń bọ̀ níbẹ̀.
Ẹnikẹ́ni tí ó bá fẹ́ jẹ́ pataki láàrin yín níláti jẹ́ iranṣẹ yín; 
Nítorí ẹni tí OLUWA bá fẹ́ níí báwí gẹ́gẹ́ bí baba tí máa ń bá ọmọ rẹ̀ tí ó bá fẹ́ràn wí.
Ẹ mọ̀ dájúdájú pé mo kìlọ̀ fun yín lónìí 
Fún ogoji ọdún gbáko ni ọ̀rọ̀ wọn fi sú mi,tí mo sọ pé, “Ọkàn àwọn eniyan wọnyi ti yapa,wọn kò sì bìkítà fún ìlànà mi.
Ẹ̀yin ọmọ Yorùbá lókè òkun, ẹ má bẹ̀rù mọ́ láti wálé - Akeredolu Ko tan sibẹ, gomina Fayemi sọ pe oun ti gbe gbe agbara wọ igbakeji oun lati ma a ba iṣakoso lọ lori awọn igbesẹ to ṣe koko, ti oun yoo si maa ṣe iṣẹ diẹdiẹ lati ile.
Ko si ẹrí to dájú láti dá Ajimobi láre gẹgẹ bí olúborí - Ilé Ẹjọ́ Wo nkan tó yẹ́ kí omọ̀ nípa Victor Giadom tó já ipò adelé alága ẹgbẹ́ APC mọ́ Ajimobi lọ́wọ́ Ìgbésẹ̀ míràn ṣúyọ lórí ọ̀rọ̀ Abiola Ajimobi O tun sọ ninu ikede naa pe D'banj fi ipa ba oun lopọ.
Mo fẹ́ kí o mọ̀ pé, o kò ní jáde kúrò níbẹ̀ títí o óo fi san gbogbo gbèsè tí o jẹ, láìku kọbọ!
Elija tún sọ fún wọn pé, “Èmi nìkan ṣoṣo ni wolii OLUWA tí ó ṣẹ́kù, ṣugbọn àwọn wolii oriṣa Baali tí wọ́n wà jẹ́ aadọtalenirinwo (450).
Ẹni kẹta wọn to wa ọkọ naa ni wọn ni o fi ọkọ naa ja iloro kini ati ikeji pẹlu erongba lati wọ iloro kẹta nibi ti Kabiyesi arole Oodua, Ọọni Ogunwusi n gbe ṣugbọn awọn agbofinro to n ṣọ aafin naa ba ya boo.
Nígbà tí mo wà lẹ́wọ̀n, ẹ wá sọ́dọ̀ mi.
lasiko ti  egbe awon ọgọ́rùn ún obinrin
Ipa tí ìyànsípò Olóòtú ìjọba Gẹ̀ẹ́sì tuntun yóò mú bá ‘Brexit’ Háà, ó ṣe!
Nítorí náà, èmi OLUWA Ọlọrun óo tú ibinu gbígbóná mi sórí ibí yìí, n óo bínú sí eniyan ati ẹranko, ati igi oko ati èso ilẹ̀.
Ohun to si tun yani lẹnu julọ ni pe, nigba to ku ọdun kan pere ki Dapọ yii pe ẹni ọgọta ọdun, ni ori gbe e de ipo gomina, to si bura wọle ni ọjọ yii kan naa.
Ó bá fa ọmọde kan dìde ní ààrin wọn, ó gbé e sí ọwọ́ rẹ̀, ó wí fún wọn pé, 
" Eyi ni awọn ọrọ Senator Rashidi Ladọja, tii se gomina tẹlẹ nipinlẹ Oyo, eyi to jẹ ipinlẹ kan lẹkun iwọ oorun guusu Nigeria, tọpọ eeyan ti n sọ ede Yoruba.
Nítorí náà, jẹ́ kí ọmọ mi lọ, kí ó lè sìn mí.
Ìtàn Aláàfin Aole rèé, tó gbé ìran Yòrùbá ṣépè Wèrè tí mò ń ṣe ní Facebook ló pawó fún mi-Esabod Kónílé-ó-gbélé Covid 19 ló tú àṣírí àwọn àfipábánilòpọ̀ láwùjọ- Mínísítà ọ̀rọ̀ àwọn obìnrin Ilu Dangora ti iṣẹlẹ yii ti waye jina si Kano niwọn kilomita marunlelọgọrin.
Àbí o fi ojú tẹmbẹlu ọpọlọpọ oore Ọlọrun ni, ati ìfaradà rẹ̀ ati sùúrù rẹ̀?
Iru awọn iroyin ti ẹ le nifẹ si: Fọlọrunṣọ Alakija: Imọ ṣe koko 'Ara sisan kii ṣe arun' Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Bakan naa lo tun fi orukọ ati nọmba idanimọ awọn ọkọ ti wọn fẹ lu ni gbanjo naa lede pẹlu.
Olori ekun naa, Habitegeko Francois so fun awon oniroyin pe, ara tun san pa omo ile-eko kan lojo-Eti ni agbegbe ohun.
Oríṣun àwòrán, AFrican Drum Festival Àkọlé àwòrán, Ajodun ilu Àkọlé àwòrán, Ajodun ilu Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Idi ti aarẹ fi jawọ ni lati duro de igba ti ijiroro gbogbo yoo mu ki awọn ẹgbẹ osisẹ ati ẹka idokoowo o se ohun to tọ."
 fágúnwà ( 1903 - 9 december , 1963 ) je akowe omo naijiria ti won bi ni okeigbo ni ipinle ondo .
Ìlọsíwájú ẹgbẹ́ ló jẹ wá lógún'' Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Gomina Ambode ko ti ṣọrọ lori nnkan ti PDP sọ Labẹ òfin ètò ìdìbò, anfààní ṣì wà fún ẹgbẹ́ òṣèlú láti parọ orúkọ oludije kí gbedeke ọjọ ti INEC fi sílẹ tó pé Ohùn tá gbọ ní pé Gómìnà Ambode ti n palẹmo láti kẹrú rẹ kúrò ní Alausa lẹyìn tí ọ pàdánù tikẹti ẹgbẹ́ APC lati du ipo Gomina lọdun 2019.
Ọlọrun pè yín sí ipò yìí nípa iwaasu wa, kí ẹ lè jogún ògo Oluwa wa Jesu Kristi.
Manoa bá sọ fún iyawo rẹ̀ pé, “Dájúdájú, a óo kú, nítorí pé a ti rí Ọlọrun.
Nnkan bi eeyan 420,000 lagbo wipe wọn ko ti ri owo osu gba laisun ọdun tuntun.
Onídàájọ́ òdodo ni Ọlọrun,a sì máa bínú sí àwọn aṣebi lojoojumọ.
 ilu nri je gbigba gege bi ipilese asa igbo .
 Ìgéjẹ yii maa ń mú àwọn kòkòrò àkóràn láti itọ ́ ẹ ̀ fọn sínu ẹ ̀ jẹ ̀ ènìyàn .
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ẹniọla Badmus: Bí mo ṣe fẹ́ wà nìyìí 19 Òkùdu 2018 Oríṣun àwòrán, ENIOLA BADMUS/FACEBOOK Àkọlé àwòrán, Ẹniọla Badmus jẹ́ mọ̀lúmọ̀ká òsèré Eniola Badmus jẹ́ òsèré Nollywood ọmọ Nàìjíríà.
PDP: Àrà tó bá wu Gomina Ajimobi kó dá lọ́sẹ̀ kan tó kù yìí
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Iroyin ni papakọ ofurufu Kyiv ni Ukraine ni ọkọ ofurufu naa n lọ bo ṣe gbera kuro ni Iran Wọn ni Kyiv to jẹ olu ilu Ukraine ni ọkọ ofurufu ọhun morile ko to jabọ Okọ ofurufu naa gbe ero ọgọsan an ati awọn oṣiṣẹ ọkọ ofurufu Awọn akọroyin Iran ni ọkọ ofurufu Boeing 737 -800 naa jabọ ni agbegbe Parand to wa ni guusu iwọ oorun Tehran to jẹ olu ilu Iran.
Fifi ilọkulọ lọ awọn obinrin elere ori papa ti wa tipẹ Ile isẹ iroyin BBC ba obinrin oniroyin kan sọrọ (ko fẹka da orukọ rẹ), o ni ootọ ni pe wọn nfi ilọkulọ lọ awọn obinrin daa daa ni Naijiria nitoripe oun gaan funra rẹ ti gbọ ọ o si ti sẹlẹ si i ri.
Gomina sọ fún wọn pé wọn kò gbọdọ̀ jẹ ninu àwọn oúnjẹ mímọ́ jùlọ, títí tí wọn yóo fi rí alufaa kan tí ó lè lo Urimu ati Tumimu láti wádìí lọ́wọ́ OLUWA.
Agbẹnusọ fun ileeṣẹ ọlọpaa nipinlẹ Ogun ni, Kọmisọna ọlọpaa ni ipinlẹ naa, Edward Ajogun ti paṣẹ ki wọn gbe awọn afurasi naa lọ si ẹka to n ṣewadii iwa ọdaran, fun iwadii ẹkunrẹrẹ.
Wọn óo gé ọ ní etí ati imú, wọn óo sì fi idà pa àwọn eniyan rẹ tí wọ́n kù.
Nígbà tí àwọn ará Samaria dé ọ̀dọ̀ rẹ̀, wọ́n bẹ̀ ẹ́ kí ó dúró lọ́dọ̀ wọn.
Samuẹli ṣe bí OLUWA ti pàṣẹ fún un, ó lọ sí Bẹtilẹhẹmu.
Titi di bi a ṣe n sọrọ yii ko tii dẹkun, koda ti ẹnu lọwọlọwọ yii wa peleke sii paapaajulọ lorilẹede Naijiria.
Awọn kan ni ootọ ọrọ ti ko ni ki a ma sọ ohun ni ọrọ Babab Kumuyi Amẹ́ríkà ń béèrè ìròyìn facebook, email arìnrìnàjò tó f'ẹ́ gbà'wé àṣẹ Ibanuje d'orí agbà k'odò, Ruiz fi ẹ̀ṣẹ́ sọ Anthony Joshua di ọmọ ológo àná Sultan pàṣẹ fún àwọn mùsùlùmí láti ṣ'ọdẹ òṣùpá lónìí 'Ọmọ SS 1 mu èso olómi, ṣùgbọ́n ilé ìwé wa kọ́ ló kú sí' Àwọn ìròyìn mìíràn tí ẹ lè nífẹ̀ẹ́ si: N kò gba owó rí lọ́wọ́ olùdíje kó tó dé ipò - Oyedepo Leah Sharibu pé ọmọ ọdún 16 ní àhámọ́ Boko Haram Pápà mímọ́ gbarata lóríi ìpànìyàn Benue Pásítọ̀ bẹ́'rí ọmọ ìjọ ní ìpínlẹ̀ Ògùn Ààwẹ̀ gbẹ̀mí ọmọ Naijiria ní orílẹ̀èdè Amẹ́ríkà Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Ó ní,“Ẹni ègún ni Kenaani,ẹrú lásánlàsàn ni yóo jẹ́ fún àwọn arakunrin rẹ̀.
Ifẹ̀sùn kan, ẹ̀rí nípa àfojúrí nìkan àti àwọn ǹkan míràn ti a kò le fìdí rẹ̀ múlẹ̀ gbọ̀dọ̀ jẹ́ bi àfiwé pẹ̀lú ǹkan ti ẹlòmíràn ti fi ìdí rẹ̀ múlẹ̀ Tí a ba ṣe aṣìṣé, a máá n jáde si gbangba láti tọrọ àforíjì, bákan náà ni a ma ní a máá n gba àwọn ènìyàn níyanjú láti kọ àṣà kíkọ́ ẹ̀kọ́ lára elòmíràn.
Nítorí náà ni OLUWA ṣe san án fún mi, gẹ́gẹ́ bí òdodo mi,ati gẹ́gẹ́ bí mo ti jẹ́ mímọ́ níwájú rẹ̀.
Bashir, tii se darandaran nipinlẹ Adamawa lo kede pe oun ti yofẹ pẹlu ọmọ aarẹ ati awọn aworan fọto to n ya.
mu awon to pa adari ana fun  iko-omo ogun
aseyori ti o se laarin odun meta aabo ti o ti lo lori aleefa, ni won n so awon
Nítorí pé ọba Babiloni ti dúró sí oríta, ní ibi tí ọ̀nà ti pínyà; ó dúró láti ṣe àyẹ̀wò.
Ẹ má ṣe fi iṣẹ́ náà jáfara, nítorí tí ẹ bá fi falẹ̀, ó lè pa ọba lára.
Oríṣun àwòrán, @Ahmedmusa718 Àkọlé àwòrán, abiyamọ ni gbogbo aye n gbadura ko duro jẹun ọmọ Àwọn ìròyìn mìíràn tí ẹ lè nífẹ̀ẹ́ sí: Fela Durotoye, olùdíje ipò ààrẹ ẹgbẹ́ òṣèlù ANN #BBCNigeria2019 America àti Ilẹ̀ Gẹ̀ẹ́sì ní àwọn kò ní ààyò olùdíje ní Naijria #BBCNigeria2019 Tani Kingsley Moghalu tó ń duipò ààrẹ?
Ọjọ kọkandinlọgbọn oṣu kẹta ọdun 1944 ni wọn bi Akufo-Addo ni Accra tii ṣe olu ilu orilẹede Ghana.
 Ó fẹ ́ olóṣèlú tí a mọ ̀ sí obafemi awolowo láti Ọjọ ́ kẹrìndínlọ ́ gbọ ̀ n oṣù kejìlá Ọdún 1937 di ìgbà tí olóṣèlú náà fi kú ní ọdún 1987 .
Àwọn ará Asiria pàápàá ti dara pọ̀ mọ́ wọn;àwọn ni alátìlẹ́yìn àwọn ọmọ Lọti.
Alaga tẹlẹri fun ileeṣẹ to n sakoso eto iroyin ni Naijiria (National Broadcasting Corporation), Tony Iredia ti bu ẹnu atẹ lu ofin tuntun naa, to si sọ wi pe o tako ofin to de eto iroyin ni Naijiria.
Alukoro ileeṣẹ ọlọpaa lorilẹede Naijiria ni lootọ ni awọn ṣe ifimufinlẹ to munadoko ṣaaju idibo naa lati ms ibi ti eefin wahala lee ti ru lasiko idibo naa sibẹ ohun to waye kii ṣe eyi ti wọn lee maa dẹbi rẹ ru awọn agbofinro bi o ti wulẹ o mọ.
Wọ́n la ẹnu, wọ́n ń pariwo lé mi lórí,wọ́n ń wí pé, “Ìn hín ìn, a rí ọ, ojú wa ló ṣe!
Ẹ ju ọkunrin yìí sẹ́wọ̀n, kí wọ́n sì máa fún un ní omi ati burẹdi nìkan títí òun óo fi pada dé ní alaafia.
Ọjọ́ OLUWA dé tán,tìkàtìkà pẹlu ìrúnú ati ibinu gbígbóná láti sọ ayé di ahoro,ati láti pa àwọn ẹlẹ́ṣẹ̀ inú rẹ̀ run.
"Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Khadijat Oluboyo: Ilé ẹjọ́ sọ ọ̀rẹ́kùnrin rẹ̀ sí gbaga Khadijat Oluboyo n mura lati jade fasiti ni ile iwe giga fasiti Adekunle Ajasin ni Akungba Akoko ni ipinlẹ Ondo ki o to jade laye Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Baba Khadijat Oluboyo jẹ́rìí ọmọ rẹ̀ Seyi Makinde, yé é sọ̀rọ̀ mi láìdà - Gomina Ajimobi ""Ẹ sinmi ariwo Saraki, ẹnikẹ́ni ló le è di ààrẹ aṣòfin àgbà"" Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!"
Gbogbo pápá oko kún fún ẹran ọ̀sìn,àwọn ẹ̀gbẹ́ òkè sì kún fún ohun ayọ̀,
 Alaafin tun salaye pe Ọlọrun lo fun mi ni abuda ati oore ọfẹ lati ko awọn obinrin jọ, paapaa awọn arẹwa obinrin, emi kii si sọ ọrọ tabi ajọṣepọ emi ati olori kan fun omiran, mo maa n fi ọrọ gbogbo ṣe mẹnumọ laarin ọkọọkan wọn ni.
Oríṣun àwòrán, yinka ayefele Bakan naa ni Yinka Ayefẹlẹ funrarẹ ti kede rẹ loju opo Facebook rẹ pe orin ijo ọmọ mo ji fowurọ mi jo ti oun kọ ninu awo orin oun kan lọjọ ọjọsi ti di otitọ bayii.
Pasitọ ijọ Sotitobire, Alfa Babatunde njẹjọ lori ọmọ ọdun kan to poora ninu ile ijọsin rẹ lọdun 2019.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: England ti le Sweden kúrò ní Russia Èrò àwọn ènìyàn nípa ikú Khadijat Olubọyọ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, CUPP: JJ Ọmọjuwa sọ ohun tí ìdàpọ̀ àwọn ẹgbẹ́ yìí yóò jẹ́ Orilẹede Faranse naa fagba han ẹgbẹ agbabọọlu Uruguay pẹlu ami ayo meji sodo ki wọn to pegede fun ipele to kangun si aṣekagba.
Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí US election 2020 polls: Taa ló ń léwájú- Trump tàbí Biden?
Ènìyàn 26,000 ni àìsàn jẹjẹrẹ ń pa lóòjọ́ Àgbálùmọ̀, ohun mẹ́fà tó ń ṣe lára tí o kò mọ̀ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Femi Falana: kò yé kí ìdájọ́ òfin yàtó síra wọn ni Naijiria Oludari ẹka ato ilu nipinlẹ Ekiti lo buwọlu Iwe aṣẹ ti wọn fi ti ileeṣẹ rẹdio naa pa.
Ẹni tí ó ń bá mi sọ̀rọ̀ mú ọ̀pá ìwọnlẹ̀ wúrà lọ́wọ́ láti fi wọn ìlú náà ati àwọn ìlẹ̀kùn rẹ̀, ati odi rẹ̀.
O ti ṣaaju gbiyanju ikọlu si ijọba ni ọdun 2008, eleyii ti o si sọ ọ di ero ẹwọn gbere.
Ó ní òun ó máa fi tọkàntọkàn pa majẹmu tí a kọ sinu ìwé náà mọ́.
Ìbẹ̀rù-bojo gbalẹ̀ ní Oyigbo lẹ́yìn tí ọlọ́páà mẹ́ta àti sọ́jà kú nínú rògbòdìyàn EndSARS Ẹni mọ́kànléláàdọ́fà 111 ló lùgbàdì àrùn covid-19 ní Nàìjíríà lọ́jọ́ Àìkú Oluwo ti ìlú Iwó kìí ṣe ẹgbẹ́ Àtaọjà Osogbo - Alaafin ìlú Ọ̀yọ́ Wo iye owó tí ìjọba Amẹrika ń na sí ìdìbò Ààrẹ àti ibi tí owó náà ti ń wá 6) Esther Agbaje: Ni ipinlẹ Minnesota, Arabinrin Esther Agbaje, naa n dije fun ile igbimọ aṣofin, lati ṣoju ẹkun idibo 59B.
Wọn óo sì dáhùn pé, ‘Ìdí tí OLUWA fi ṣe bẹ́ẹ̀ ni pé, àwọn eniyan náà kọ OLUWA Ọlọrun wọn, tí ó kó àwọn baba ńlá wọn jáde láti ilẹ̀ Ijipti sílẹ̀, wọ́n sì lọ ń forí balẹ̀ fún àwọn oriṣa, wọ́n ń sìn wọ́n; nítorí náà ni OLUWA fi jẹ́ kí ibi ó bá wọn.
ikede lorile ede Naijiria, Alhaji Lai Mohammed lo soro yii fun awon akoroyin
Wareham ni lati ilẹ lo ti yẹ ki ọkan eeyan gba kamu ohun to delẹ ki o si ri i gẹgẹ bii ''asiko ti eeyan yoo mu idagbasoke ba ara rẹ ati mọlẹbi rẹ.
Aare ni “O je iyalenu fun mi pe awon kan  tile lee sun, nigba ti won kuna lati san owo osu osise fun won .
Oríṣun àwòrán, @MKO_Abiola10 Awọn ẹlẹgbẹjẹgbẹ ajafẹtọ ẹni nilẹ yii ati ni awujọ agbaye lapapọ ni wọn gbọnmu lori igbesẹ naa ti oniruuru iwọde ati atako si n waye.
Loju opo ajọ aladani iyawo Gomina Ajike Support Centre ni Facebook,wọn fi aworan ibi ti Risikat ti n gba idanilẹkọ.
15 Àti pé ẹ̀rí àwọn ẹlérìí mẹ́ta ni èmi yíò rán jade nípa ọ̀rọ̀ mi.
Amọ, ajọ naa sọ wipe isunsiwaju lọjọ iwaju le e mu ijiya kan tabi omiran lọwọ, fun awọn akẹkọ ti ko ba f'orukọ silẹ lasiko ti o yẹ.
Oríṣun àwòrán, WIKIPEDIA Igbesẹ yi mu ki ọkọ na ti o pe orukọ rẹ ni Autonov 1 ni anfaani lati fi ẹyin sare (reverse) laarin iṣẹju perese ju awọn ọkọ miran lọ O tun ṣe akitiyan pupọ nipa eto ẹkọ ti awọn to ba ranti ko ni gbagbe pe o jẹ atkun eto tanmọ fun awọn akẹkọ lori ẹrọmounmaworan ti wọn pe ni Mastermind.
26 Bélú 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 27 Bélú 2020 Oríṣun àwòrán, Google Àkọlé àwòrán, Fatai Rolling Doller, àgbà ọ̀jẹ̀ olórin tí ọ̀dọ́ ń wò ní àwòkọ́ṣe rere Fatai Rolling Dollar: Baba 70 jayé kọjá 70 kó tó dágbére Wọn kere si Number, Ori wa a dara, Saworo, Eko Akete, Baba Wa, To ba fe mo Dollar, Aduke, Feso Jaiye, Iyawo Ma pa mi.
Majẹmu náà ni pé mo ti yan òun ati arọmọdọmọ rẹ̀ láti máa ṣe alufaa ní Israẹli títí lae nítorí pé ó ní ìtara fún Ọlọrun rẹ̀, ó sì ṣe ètùtù fún ẹ̀ṣẹ̀ àwọn eniyan Israẹli.
wọ́n to bẹrili ati onikisi ati Jasperi sí ẹsẹ̀ kẹrin, wọ́n sì fi ìtẹ́lẹ̀ wúrà jó wọn mọ́ ìgbàyà náà.
Bakan naa ni ibudo igbafẹ yii npa owo ribiribi wọle fun ijọba ipinlẹ Ekiti.
Owo ori sisan lori owo ati owo ori sisan lori dukia.
"O fesi pe ""inú mi dùn pé mi o ní ìrírí nínú òṣèlú nítori òṣèlú Nàìjíríà kò ṣe é mú yangàn,"" o ni ọna ati ṣejọba gangan lo yẹ kii ṣe ka fi oṣelu wọle ka tun tẹsiwaju ninu oṣelu ti a ba de ipo."
Awakọ ati oṣiṣẹ ile iṣẹ kan lawọn afurasi meji ọhun tọwọ sinkun ofin ti ba bayii.
Ogunye lasiko to n ba BBC sọrọ ni ọja okunkun ati ọja ẹtan ni Ile Igbimọ Asofin ati ijọba Aarẹ Muhammadu Buhari n ṣe.
Awọn oṣiṣẹ ijọba ni afẹhọnuhan kan ti ku nigba ti ado oloro to mu dani bugbamu mọ ọ lọwọ, to si gba ibẹ lọ.
Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Fídíò, Sunday Igboho: Kò bójúmu bí wọn ṣe ní ká wá fi orúkọ́ sílẹ̀ bíi ọmọ ẹgbẹ́ Àmọ̀tekún lórí ayélujára20 Ògún 2020 5:58 Fídíò, Akomolede ati asa Yoruba: Ẹ wá kọ́ nípa àpòtí ìṣura èdè wa lórí BBC Yorùbá, Duration 5,5820 Ògún 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 3 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 5 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Àkọlé àwòrán, Ìyanṣẹ́lódì míràn ń kànlẹ̀kùn lẹ́yìn t'áwọn gómìnà sọ pé àwọn kò lè san ju #22,500 lọ fún 'Minimum wage.
Ojú kò ní tì í nígbà tí ó bá ń bá àwọn ọ̀tá rẹ̀ rojọ́ lẹ́nu bodè.
” Bẹ́ẹ̀ ni OLUWA Ọlọrun wí.
o kú ní ọdún 1998 .
Ki Toure to kuro nilẹ Mali, si lo ti se isẹ abẹ kan nilu Bamako, eyi to nii se pẹlu aisan ọkan.
Awọn Biṣọọbu ijọ Aguda ni Naijiria ati iwọde EndSARS Ọkan lara awọn iroyin to jade loju opo Twitter ti ọpọlọpọ si gba bi ẹni gba igba ọti ni iroyin kan to tọka si awọn Biṣọọbu ijọ Aguda kan pe awọn naa wọde lati ṣatilẹyin fun iwọde EndSARS.
Kìí pe wọ̀bìà, Bí ó pajá ẹ̀ kó wá jẹun
Mò ń rọ̀ yín, mo tún ń jẹ́rìí pé oore-ọ̀fẹ́ Ọlọrun tòótọ́ nìyí.
Yoòbá ní àìrìnjìnnà ni kò jẹ́ ká rí abuké ọ̀kẹ́rẹ́.
Iṣẹ́ Kudirat Abiọla ṣì ń fọhùn síbẹ̀, lẹ́yìn ọdún 23 tó papòdà Ọ̀nà márún-ún láti mú àdínkù bá dátà (Data) lílò rẹ Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Eyi kii jẹ ki awọn eeyan gbe ọmọ lọ si ileewosan.
Luis Suarez ati Lionel Messi ni wọn jẹ goolu meji ti aṣeyọri yi fi waye ti o si jẹ ki o dabi pe Barcelona yoo gba ife ẹyẹ karun un lera laarin saa meje.
ninu iwa akin won fun itesiwaju ile-ise naa.
"Aarẹ si nilo lati mu ọrọ awọn alaidaaa ni ijba rẹ kuro ko si yi ọna ara toun funrarẹ gan kuro.
Oríṣun àwòrán, @ComrMuhammad12 Wọn bi Baru ni ọjọ keje, oṣu keje ọdun 1959.
Wo àwọn ojúṣe àti èèwọ̀ fún ikọ̀ ọlọ́pàá SWAT tó gba iṣẹ́ lọ́wọ́ SARS Pásítọ̀ Enoch Adeboye darapọ̀ mọ̀ #ENDSARS, ó fún ìjọba Nàìjíríà ní ìmọ̀ràn ọ̀nà àbáyọ Mọ̀ nípa iPhone 12, fóònù ológo 5G tí kìí lo Charger” tó ṣẹ̀ṣẹ̀ jáde Àṣé àṣírí wà nínú Hijabu tí Aisha Yesufu ń wọ̀ lọ ìwọ́de Ṣé Èdùà dá ààtàn isó ni?"
“Ègún ni fún ọ nígbà tí o bá wọlé, ègún sì ni fún ọ nígbà tí o bá jáde.
Ìròyìn Yàjóyàjó - Àwọn agbébọn kọlu Kọmísánà fọ́rọ̀ ilẹ̀ àti ilégbèé ní Ọyọ, awakọ̀ dèrò ọ̀run Àbá ìsúná N1.
Ọga ajọ eleto idibo ilẹ Ghana, Jean Mensa lo kede pe Akufo-Addo la alatako rẹ, John Mahama mọlẹ ninu eto idibo naa.
igbinmo asofin agba pe ki won se atunse si abala iwe ofin meji kan ninu iwe
Ìjọba Buhari ń lo agbára láti jà ìjà ẹsìn- Jiti Ogunye Òpópónà márosẹ̀ Eko sí Ibadan tún dí pa lásìkò tí ọkọ̀ epo dànù A kò ní ṣe ìwọ́de mọ́ torí a ti gbé ìjọba lọ sílé ẹjọ́ - Shiite kéde fáráyé Ofin yii lo nkan nipa fun awọn ọlọsin ẹran lati ye da ẹran lati agbegbe kan si omiran, amọ wọn ni asẹ lati fi ọmọlanke abi ọkọ gbe awọn ẹran naa lati ibudo kan si ekeji, ẹnikẹni ti ọwọ ba si tẹ pe o n ko ẹran kiri pẹlu ẹsẹ yoo san ẹgbẹrun lọna aadọta naira owo itanran tabi ko lọ si ẹwọn ọdun kan abi ko se mejeeji papọ.
” Aare Buhari tun ni eto ti ijoba oun gunle lati maa sofofo awon to ba ji owo ilu, ti so eso rere nipa pe opolopo owo bilionu ni won ti ri gba pada lowo awon obayeje yii, ni eyi ti won ti lo lati pese awon ohun amayederun ti awon omo orile ede Naijria si n je anfaani re.
“Sọ fún Aaroni ati àwọn ọmọ rẹ̀ pé, èyí ni òfin tí ó jẹmọ́ ẹbọ ìmúkúrò ẹ̀ṣẹ̀, níbi tí wọ́n ti ń pa ẹran fún ẹbọ sísun, ni kí wọ́n ti máa pa ti ẹbọ ìmúkúrò ẹ̀ṣẹ̀ pẹlu, níwájú OLUWA; ó jẹ́ ohun mímọ́ jùlọ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Osun poly: Ọ̀pọ̀ òògùn, àti ohun eèlò ni àwọn akẹ́kọ̀ọ́ tó ṣèwọ́de náà dá iná sun 1 Òkùdu 2019 Oríṣun àwòrán, citymirror news Àkọlé àwòrán, Ọ̀pọ̀ òògùn, àti ohun èlò ni àwọn akẹ́kọ̀ọ́ tó ṣèwọ́de náà dá iná sun.
Ìdí tí Joṣua fi kọ ilà abẹ́ fún wọn ni pé, gbogbo àwọn ọkunrin tí wọ́n lè jagun, tí wọ́n jáde láti ilẹ̀ Ijipti, ti kú lójú ọ̀nà ninu aṣálẹ̀ lẹ́yìn tí wọ́n ti jáde láti ilẹ̀ Ijipti.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Sanwo-Olu, El-Rufai fara pamọ́ torí COVID-19 lẹ́ẹ̀kejì Àwọn agbófinró Nàíjíríà yóò rojọ́ níwájú iléẹjọ́ àgbáyé ICC Wo ìgbéyàwó olówó iyebíye tí awakọ̀ Kabúkabú ti jẹ̀bùn ọkọ N3.
Meji din ni aadoje(128) ni ile igbimọ aṣofin keje le ṣiṣẹ le lori, nigba ti ile kẹfa ṣiṣẹ ofin mejilelaadọrin (72).
Bóò ṣe lè yẹra fún ikú nígbà òjò- Onímọ̀ Ehi Iden Aisha Buhari, ohun mẹ́fà tò fi yàtọ̀ sí àwọn aya ààrẹ tó ti jẹ kọjá!
 ilé ìgbìmọ ̀ aṣòfin yìí wà lábẹ ́ ìṣàkóso ẹgbẹ ́ òṣèlu all progressives congress tí ó ń ṣe ìjọba Ìlú Èkó lọ ́ wọ ́ lọ ́ wọ ́ .
Ẹ gbọ́ ìròyìn ayọ̀ lórí àrùn Coronavirus Coronavirus: Wo ohun tí o ní láti ṣe láti dáàbò bo ara rẹ Ǹjẹ́ mo tílẹ̀ ti ní àrùn Coronavirus?
Ẹ ní inú kan sí ara yín.
ibile, paapaa julo pelu awon torokan gbongbon lojuna ati fese alafia gboro si
Kò si iná mọ̀nàmọ́ná ti ó ṣe deede, kò si omi mimu fún ará ilú pàtàki fún àwọn agbègbè titun.
Ṣugbọn o ni inu mama oun ti dun bayii nitori oun ti di araba ninu bọọlu gbigba.
Ẹgbẹ awọn ololufẹ rẹ ''DExplora'' n dibo fun Dorathy witi-witi, koda awọn ni igi lẹyin ọgba rẹ ti ko ti fi di ero ile.
Iya rẹ ko jade n'ile, ṣugbọn baba rẹ fi dandan gba oun ati awọn arakunrin rẹ mejeeji silẹ.
Iko Super Eagles sa gbogbo ipa won lati da ami ayo ohun pada, sugbon kaka ko san lara ewe ogede pipele lo n peleke si, leyin ti won pada fori bale fun iko Madagascar ni gbeyin-gbeyin.
Bakan naa, wọn mnu ba ọna ti wọn yoo gba lati ri owo ọhun san.
A gbọ́ pé ọ̀gẹ̀dẹ̀ Fìkì, táa mọ̀ sí ọ̀gẹ̀dẹ̀ wẹ́wẹ́ tàbí páráǹtà tó pọ́n, ni wọ́n fi máa se Dòdò Ìkirè.
Ọmọ Yoruba ni Oluremi Adeleye, dídá ọmọ kilẹ̀ sì jẹ aṣà láàrin awọn abiyamọ láti rii dáju pe ebi ò pa ọmọ.
Nígbà tí ìyàwó yìí sì gbọ́ ìbéèrè náà ó bú sẹ́rìn-ín ó ni, ‘A!
Ẹ̀yin kò mọ̀ pé Ẹni tí Ó ṣe àwọn nǹkan wọnn-ọnnì ta àwọn ẹ̀dá ìyókù yọ!
Opposition (egbe alatako) : Ẹgbẹ alatako ni ẹgbẹ ti
Nigba to di ọdun 2015, o kọwe fi ipo rẹ silẹ nibi to ti n ṣiṣẹ lati maa ṣetọju awọn eeyan ti iya n jẹ nitori awọn ẹbi wọn ba ogun lọ.
Solomoni ọba ní ọrọ̀ ati ọgbọ́n ju gbogbo àwọn ọba yòókù lọ lórí ilẹ̀ ayé.
Ìtúsílẹ̀ Sheikh ni a ń béèrè, ṣùgbọ́n ìjọba kò fẹ́ tẹ̀lé ìdájọ́ ilé ẹjọ́ pé kí wọ́n dáa sílẹ̀.
"Ẹfunsetan Aniwura, obìnrin tó ju ọkùnrin lọ ""Bàbá mi kú, kò sówó ni mo ṣe kúrò ní fásitì Ilorin láti fọ gíláàsì ọkọ̀ lójú pópó"" Adúmáadán ni mí; ọmọ pé síbẹ̀!"
Lasiko to n ba BBC Yoruba sọrọ, Bisi Alimi salaye pe, ọrọ akọ to n fẹ akọ, tabi abo to n fẹ abo ko nii ohunkohun se pẹlu ẹsin rara, isẹ ọwọ Olodumare ni.
Ilé iṣẹ́ ọlọ́pàá ń ṣe ìpàdé pẹ̀lú Naira Marley lọ́wọ́lọ́wọ́ Ibadan ń jó àjórẹ̀yìn láàrin ẹgbẹ́, ẹ fún wa ní ìpínlẹ̀ tiwa - Kola Balogun bẹ ilé aṣòfin Fayose tó gbé òkú bàbá rẹ̀ pamọ́ fún ọdún kan láì sin, kò tó sọ̀rọ̀ sí mi - Bode George Tani Akeredolu tó ń díje dupò gómìnà fún ìgbà kejì nípìnlẹ̀ Ondo?
Samuẹli bá bèèrè lọ́wọ́ Jese pé, “Ṣé gbogbo àwọn ọmọ rẹ ọkunrin nìyí?
Siwaju sii, ọmọ alaga naa Onimọẹrọ Nurudeen Adejumo sọ fun awọn oniroyin pe oun gba ipe pajawiri ni irọlẹ ọjọ naa wi pe agbara ojo ti gbe baba oun lọ ti o si ti di awati bayii.
" Bẹẹ ba gbagbe, laipẹ yii ni ọwọ awọn ọlọpaa Dubai tẹ Hushpuppi ati awọn akẹgbẹ rẹ kan ti wọn n lu awọn eeyan ni gbajuẹ lori ẹrọ ayelujara, to si ti farahan nile ẹjọ lorilẹ ede Amerika.
Aare tun salaye pataki ibasepo pelu awon orile-ede ile okere to n koju isoro kan naa lati ri daju pe akitiyan ijoba lojuna ati gbogun ti iko omo ogun olote boko haram ja si aseyori.
 dìgbòlugi wà ní orílẹ ̀ èdè 150 ní àwọn ojú ilẹ ̀ ayé yàtọ ̀ sí antarctica .
aare yoo maa lo ni ilu naa.
mu awon apaniyan naa wa sabẹ ofin.
4 Ẹrẹ̀nà 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 5 Ẹrẹ̀nà 2019 Ẹgbẹ awọn olukọ fasiti to jẹ ti ijọba l'orilẹede Naijiria ti sọ pe awọn ko gberero lati tun lọ fun iyanṣẹlodi oloṣu mẹta mi i.
Comrade Funmi-Sessi lasiko to n ba BBC Yoruba sọrọ ni ohun ti ijọba apapọ n ṣe ni lati pana iyanṣẹlodi naa lasiko yii.
 Igbimo ẹlẹnu márùn ún naa ni ọsẹ kan lati pari
Oga ile ise asobode ekun ohun wa fi asiko naa dupe lowo awon osise ile
N-Power Community Education: ₦10,000 - si ₦30,000 loṣu.
Àṣà ìbálé lálẹ́ ìgbeyàwó ń dọdẹ àwọn obìnrin òde òní 'Ẹ dẹkun didabẹ fun ọmọbinrin' 'Ǹkan ìṣeré ìbálòpọ̀ mi ńpaná iṣẹ́ mọ́ mi lára' Awọn obinrin mẹrin to ba BBC sọrọ lori asa yii salaye pe alẹ ọjọ ti ọkọ awọn fẹ gba ibale awọn, amọ ti ko mu ẹjẹ lọwọ, lo mu ko gbagbọ pe oun kii se ojulowo ọmọge eyi ti ko ri bẹẹ.
Lásìkò ìdìbò ọdún 2016, ìjọba ìbílẹ̀ náà fún gómìnà tó wà lórí àléfà Rotimi Akeredolu ni ìbò tó dín díẹ̀ ni ẹgbẹ̀rún mẹ́rrìndílọ́gbọ̀n, èyí ló ga jùlọ ní gbogbo àwọn ìjọba ìbílẹ̀ tó kù.
Itọju gboogi to wa fun ni 'hysterectomy'; eyi ni ilana ti wọn n gba lati yọ ile ọmọ obinrin kuro ninu ara.
Chelsea sáré kọjá kádàrá, góòlù kan ṣoṣo ní Vanlencia fi lù wọ́n ‘A ó gbé ìdílé Kayọde Fayẹmi ṣépè tí àwọn akẹ́kọ́ tó ṣèṣe bá kú!
Ẹni tí kò bá máa bá mi kó nǹkan jọ, ó ń fọ́nká ni.
Solomoni jọba lórí gbogbo àwọn orílẹ̀-èdè, láti odò Yufurate títí dé ilẹ̀ Filistia, títí dé ààlà ilẹ̀ àwọn ará Ijipti.
Lakọkọ mo fẹ dupẹ lọwọ Ọlọrun"" ni ọrọ ti Joshua fi bọnu nigba to n ba awọn oniroyin sọrọ lẹyin ija naa."
Yìnyín yóo bọ́, yóo bo gbogbo ilẹ̀,a óo sì pa ìlú náà run patapata.
Ṣugbọn ẹnikan ti ọrọ naa ṣoju rẹ sọ fun BBC pe lootọọ lawọn agbebọn ji awọn akẹkọọ lọ ni ileewe naa.
Láìpẹ́ láìjìnnà, wọ́n á yipada kúrò ní ọ̀nà tí àwọn baba wọn ń rìn.
Naira Marley koju ija si Ruggedman Kii ṣe Simi nikan ni Naira Marley ba wọ iya ija lori ọrọ boya jibiti ori ayelujara, yahooyahoo tọna paapaa julọ lẹyin orin 'Am I a yahoo boy?
Ijọba orilẹede naa ni ko ti si ẹni to le sọ pato oun to fa ina na to ran de awọn apa ibomiiran ninu ọgba rẹ.
Saulu bá fọn fèrè ogun jákèjádò ilẹ̀ náà, wí pé “Ẹ jẹ́ kí àwọn Heberu gbọ́ èyí.
Wọn yóo pe àwọn àgbẹ̀ pàápàá, ati àwọn tí wọn ń fi ẹkún sísun ṣe iṣẹ́ ṣe, láti wá sọkún àwọn tí wọ́n kú.
Wọn óo dáná sun àwọn ilé rẹ, wọn óo sì ṣe ìdájọ́ fún ọ lójú àwọn obinrin pupọ.
Òtítọ́ kò sí mọ́ ninu ìṣe yín, bẹ́ẹ̀ ni, kò sì sí ninu ọ̀rọ̀ ẹnu yín.
Iwẹ ni arabinrin naa fẹ lọ wẹ pẹlu iro nigba ti awọn oniṣẹ ibi naa kaa mọ ti wọn si ṣe isẹ ibi naa.
Ẹgbẹ́ Boko Haram pa àwọn òṣìṣẹ́ UN márùn ún tó wá ṣiṣẹ́ ìrànwọ́ ní Nàìjíríà Awọn alakatakiti ẹsin Islam ti pa awọn oṣiṣẹ ajọ agbaye marun to wa ṣe iṣẹ iranwọ ni Naijiria.
Awọn Emir mẹrin naa yoo wa ni Rano, Gaya, Karaye ati Bichi.
Tí ó fi ẹsẹ̀ rẹ̀ rìn lọ sí ilẹ̀ òkèèrè,tí ó ṣe àlejò lọ sibẹ!
Ǹ jẹ́ o mọ̀ pé iṣẹ́ ń dúró de akẹ́kọ̀ọ́ tó yan iṣẹ́ olùkọ́ láàyò ní fásitì?
Laipẹ yii ni minisita fun eto ilera, Osagie Ehanire kil fun awn dokita Naijiria nigba to n sọ̀rọ̀ nibi ipade igbimọ amuṣẹya ti ijọba lori ọrọ Covid-19 pe ki wọn tun ero wọn ro.
Yátọ si ẹ̀sún pe o beere ibalopọ lọwọ akẹkọọ rẹ, wọn tun fi ẹsun kan pe o ṣe magomago ọjọ ori rẹ.
Won fura pe o seese kawon onise ibi ju ado oloro laipe.
Ẹ kéde iṣẹ́ rẹ̀ láàrin àwọn orílẹ̀-èdè!
Ajisebutu ti o kọ lati fi idi rẹ mulẹ wipe laasigbo naa waye laarin awọn ẹgbẹ OPC, wipe ọwọ sikun ọlọpa ti mu awọn afurasi mẹrindinlaadọta to fa wahala lagbegbe Oke-Ado ni Ibadan, lẹyin ti awọn ọlọpa yara lọ si ibi isẹlẹ naa.
Oluwadi kan ni Fasiti Moi ni Kenya, to n tọ pinpin awọn ẹgbẹ naa lori Facebook fun ọdun mẹta, Duncan Omanga, sọ pe, 'awọn ọlọpaa ti wọn furasi maa n gba ọna ẹburu lati ṣewadi awọn ti wọn fẹ ẹ pa lori ayelujara.
Iya Rainbow: Olùtọ̀jú aláìsàn ni kó tó di òsèré
Ẹ má fòyà, ẹ má sì jẹ́ kí ọkàn yín rẹ̀wẹ̀sì, Ẹ lọ kò wọ́n lójú lọ́la, OLUWA yóo wà pẹlu yín.
Eyi ko sẹyin ọrọ ikọlu to waye ni ilu Kushebe Zabarmani nibi ti ikọ Boko Haram ti dumbu ọpọlọpọ awọn agbẹ onirẹsi to bẹẹ ti ko tii ni pato onka iye awọn to fori fa iku naa.
Nítorí náà, kinniun inú igbó ni yóo wá kì wọ́n mọ́lẹ̀.
 O ni Lootọ gbogbo wa la mọ pe aye ko tọ lọ bii orere, binti laye sugbọn ṣe ojoojumọ la n ranti ọrọ yii, taa si n ṣíṣẹ tọ ọ?
Ilegbe fawọn dokita ati nọọsi lawọn ẹkun to ko ni ile iwosan.
''Eyi ni lati sọ fun gbogbo eniyan pe wọn ti pe akiyesi Aarẹ ẹgbẹ CAN, Ẹni Ọwọ Samson O.
Ibinu gbígbóná OLUWA kò ní yipada,títí yóo fi mú èrò ọkàn rẹ̀ ṣẹ.
Nígbàa ti ó ṣe tí mo lọ sí ibi tí omi kan báyìí wà kí n baà wo ojú mi nítorí odò ni mo fi ń ṣe dígí, nígbà tí mo dé odo yìí tí mo wo ìsàlẹ̀ tí mo rí ara mi ẹ̀rù bà mí púpọ̀ nítorí kò sí ìyàtọ́ láàrin èmi àti ìnàkí rárá.
Lati ọwọ Lorraine Smith in Harlow James Gallagher Akọroyin eto ilera Iyaraẹnisọtọ ni ilu kọọkan ati konile-o-gbele nipọn nitootọ ṣugbọn laiṣe eyi, araun naa a maa tankalẹ sii ni Ko tii si oogun tabi abẹrẹ ajẹsara fun coronavirus bo ṣe wa fun otutu ọginiti ni eyi to n jẹ ko ni ipa pupọ lara arugbo ati awọn to ni ailera ara tẹlẹ Ṣe ki n wọ iboju lati daabo bo ara mi ati ẹlomii?
Ọgbẹni Trump fi ọrọ ṣọwọ lori oju opo ayelujara twita rẹ pe ohun ti oun gbọ lati ọdọ Kim Jong-un nii ṣe pẹlu didẹkun amulo ado oloro ṣugbọn o ni ijiya ti awọn gbe le North Korea yoo ṣi wa ni lẹ titi di igba ti ọrọ yoo fi wọ.
N-Power Creative: ₦10,000 - si ₦30,000 loṣu.
Ènìyàn méjìlá lọ tí ni aarun Coronavirus ni Ethiopia Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Coronavirus: Gbogbo igbá ti ṣófo láwọn ilé ìtajà káàkiri London Uganda fofin de ọkada wiwọ laarin ọjọ mẹrinla Aarẹ orileede Uganda,Yoweri Museveni tí fi ofin de ìgbòkègbodò ọkọ jákèjádò orile náà fún òjò mẹ́rìnlá láti dekun ìtànkalẹ aarun Coronavirus.
Ta òróró sí wọn lórí, gẹ́gẹ́ bí o ti ta á sí baba wọn lórí, kí àwọn náà lè máa ṣe alufaa mi.
Irẹwẹsi ninu agọ ara: ti eniyan ko ba mu omi to, eyi maa n jẹ ki omi dinku ni agọ ara nitori naa ara yoo maa rẹwẹsi, nitori pe iṣẹ pupọ ni fun ọkan gẹgẹ bi a ṣe mọ pe oun lo pọn ẹjẹ si ara, omi maa n pese afẹ ninu ara pẹlu, nitori naa ti iṣẹ ba ti poju fun ọkan irẹwẹsi yoo baa.
#2019NigeriaDecides Ìká wò ló lérò wí pé o yẹ láti fí dibo?
Akorin naa ti toro iforiji fun asise re ti won pe ni “awada alufansa”Ninu oro idariji re, “Eyin omo orile-ede mi lokunrin ati lobinrin, mo  toro aforiji lowo yin fun oro ti mo so, ona ti mo gba fi bi yin ninu ati akoba ti o je fun yin”.
Wọ́n sọ fún àwọn oníṣẹ́ tí wọ́n wá láti Jabeṣi-Gileadi pé, “Ẹ sọ fún àwọn eniyan yín pé, ní ọ̀sán ọ̀la, a óo gbà wọ́n kalẹ̀.
Wọ́n jẹ́ ẹ̀dá tí ó mọ ti ara rẹ̀ nìkan tó bẹ́ẹ̀ gẹ́ẹ́ tí kò sí irú wọn ṣáájú wọn tí kò sì lè sí irú wọn lẹ́yìn wọn.
Ko tan sibẹ, wn tun gba ọta ibọn, foonu alagbeka mẹrindinlọgbọn ati siimu foonu mejilelogun, lọwọ awọn afurasi yi.
Oríṣun àwòrán, Fellipe Abreu Àkọlé àwòrán, Posi ẹrọ amohunbugbẹmu (microphone) ree, awọn akọrin tabi akọroyin ni wọn fi n sin, eyi to safihan isẹ oojọ ti wọn yan laayo nigba ti wọn wa laye.
Ẹni tí ó ń fi kún ọrọ̀ rẹ̀ nípa gbígba èléati èrè jíjẹ ní ọ̀nà èrú,ń kó ọrọ̀ náà jọ fún ẹni tí yóo ṣàánú àwọn talaka.
O ni ki wọn gbiyanju ipa wọn pẹlu adura lọwọ Olorun fun aṣeyọri.
Ṣàájú ni wọ́n ti fi ẹ̀sùn lílu owó tó n lọ sí bi i mílíọ́nù máàrùn Naira, tó jẹ́ owó ìlú ní pónpó kàn án àti àwọn méjì mì í.
Ṣugbọn bí o bá kìlọ̀ fún olódodo náà pé kí ó má dẹ́ṣẹ̀, tí kò sì dẹ́ṣẹ̀, dájúdájú yóo yè, nítorí pé ó gbọ́ ìkìlọ̀; ìwọ náà yóo sì gba ẹ̀mí ara rẹ là.
Wọn bi Zeinab ni ariwa orileede Iran sinu idile talika ti orisun wọn jẹ iran Kurdish.
Ondo 2020 Election: Ọmọlúwàbí ṣọ̀wọ́n láàrín àwọn òlóṣèlú ló jẹ́ kí wọ́n má a lọ láti ẹgbẹ́ òṣèlú kan sí òmìràn
Àwọn ọmọ wọn mejeeji, Ahimaasi ati Jonatani wà lọ́dọ̀ wọn.
Araale: Ṣe ẹ maa n lọ si ilu Ikenne daadaa.
Àbí ojú kọ́ la fi nkàwé ni?
Apá kan ninu ilẹ̀ ẹ̀yà Juda jẹ́ ìpín ti ẹ̀yà Simeoni.
Alẹ ọjọ idibo ni wọn maa n saba kede eyi to si jẹ pe ti ọdun yii, ọjọ Isegun ọjọ kẹta oṣu kọkanla ọdun 2020.
Inú wa yio dùn ti ẹ bá lè darapọ̀ mọ́ wa lati kọ nipa àṣà ati itàn àdáyébá ni agbègbè yin ni ilẹ̀ Yorùbá fún àkọọ́lẹ̀ ki èdè àti àṣà Yorùbá ma ba parẹ́.
Idi niyi ti mo se fẹ mojuto
Ìpín ti Efuraimu yóo wà lẹ́gbẹ̀ẹ́ ti Manase, láti ìlà oòrùn títí dé ìwọ̀ oòrùn.
 A ni lati lo gbaradi fun ifesewonse wa pelu iko agbaboolu Leicester ti yoo waye lojo Aiku(Sunday) bayii.
Orílẹ̀-èdè meje ni ó parẹ́ ní ilẹ̀ Kenaani nítorí tiwọn, ó sì jẹ́ kí wọ́n jogún ilẹ̀ wọn, 
O ni awon Adari orile-ede nile Afriika ti kuna lati mu idagbasoke to ye ba ona ola awon eniyan won.
UK: Ọjọ́ kejilelogun, oṣù keje, ọdún 2019 ni wọ́n yóò ṣe ìkéde
Lẹyin ti awọn agbebọn pa Funke Olakunrin to jẹ ọmọ adari ẹgbẹ Afẹnifẹrẹ lorilẹ-ede Naijiria, iṣẹlẹ naa wu ọpọlọnu irunu jade lọdọ awọn ọmọ Naijiria.
Iwin burúkú ni, bí o bọ̀ àwọn ọmọ rẹ̀ tí à ń pè ni ni ọmọ ẹlẹ́gbára ni ó máa ń ṣáájú tí wọ́n má ń kéde bíbọ̀ rẹ̀ fún gbogbo ohun alaàyé.
ipinle to ba nifẹẹ si i.
A padà lẹ́yìn Ezekwesili, Buhari là ń bá lọ #BBCNigeria2019 Ààrẹ DR Congo tuntun Tshisekedi ṣàárẹ̀ nígbà ìbùra Festus keyamo: Lẹ́tà Obasanjọ sí Buhari ti di ìrégbè 'Kọ ọkọ rẹ sílẹ̀ kí o lọ fẹ́ Buhari' #Elections2019 INEC ni orúkọ ẹgbẹ́ òṣèlú Ezekwesili yóo hàn lórí ìwé ìdìbò #BBCNigeria2019 Wọn fẹnuko pe ti ọpọlọ obinrin naa ba pe, ko si ohun to buru ninu gbigbe agabra adari le won lọwọ paapaa lasiko yii to dabi pé awọn ọkunrin ti kuna ninu iṣẹ ìlú ni NAijiria loju ti wọn.
Ohun tí èmi ti rí lọ́dọ̀ Baba mi ni mò ń sọ, ohun tí ẹ̀yin ti gbọ́ lọ́dọ̀ baba yín ni ẹ̀ ń ṣe.
A óo fún ọ, títí dé ìdajì ìjọba mi.
" Àwọn ará ìlú Àkúrẹ ́ fún Àjàpadá ní orúkọ "" aṣọdẹbóyèdé ' ."
Àwọn greek ni ó dá naples sílẹ ̀ ṣùgbọ ́ n ó bọ ́ sí abẹ ́ àṣẹ róòmù ní sẹ ́ ńtúrì kẹ ́ rin ṣáájú ìbí kírísítì .
Kí ni eniyan lè fi ṣe pàṣípààrọ̀ ẹ̀mí rẹ̀?
’ Àwọn ẹrú rẹ̀ ní, ‘Ṣé kí á lọ tu wọ́n dànù?
ó ní, “Ninu ìpọ́njú mi, mo ké pe OLUWA,ó sì dá mi lóhùn,mo ké pè é láti inú isà òkú, ó sì gbóhùn mi.
ÀWỌN ÀPÓSTÉLÌ MÉJÌLÁ SÍ ÒTÍTỌ́ TI 
Babiloni ìlú ńlá náà kò bọ́ lọ́wọ́ ìdájọ́ Ọlọrun, Ọlọrun jẹ́ kí ó mu ninu ìkorò ibinu rẹ̀.
Wọn fi ẹsun idigunjale kan George Floyd lọdun 2007 Ni ọdun 2007, wọn ẹsun idigunjale kan George Floyd.
O ti fi ìfẹ́ rẹ tí kì í yẹ̀ṣe amọ̀nà àwọn eniyan rẹ tí o rà pada,o ti fi agbára rẹ tọ́ wọn lọ sí ibùgbé mímọ́ rẹ.
Joṣua pín ilẹ̀ wọn fún àwọn ọmọ Israẹli gẹ́gẹ́ bí ìpín ẹ̀yà kọ̀ọ̀kan.
Ibuwọlu naa waye lọjọ Aje lẹyin ti idibo aarẹ lorilẹ-ede naa ti waye ni ọjọ kẹta, oṣu kọkanla, ọdun 2020.
Ijamba ọkọ: Ẹmi 18 bọ ni marosẹ Ibadan si Eko
Alufaa yóo sì fi rúbọ níwájú OLUWA, yóo ṣe ètùtù fún un; nígbà náà ni yóo di mímọ́ kúrò ninu ìṣàn ẹ̀jẹ̀ rẹ̀.
Awọn olukopa nibi ayẹyẹ naa sọ pe asiko Bayajjida lo bẹrẹ lati le mu ki iṣọkan wa laarin awọn Ọba ilẹ Hausa, ṣugbọn atunṣe ba a lẹyin ti ẹsin Islam de.
”Jehoṣafati dáhùn, ó ní, “Má sọ bẹ́ẹ̀.
Hassan ló yìbọ̀n pa Ifeanyi nítori wan ń sá tẹ̀lé mọ́to Femi Gbajabiamila ti wọn si n kíi.
Nibi tero ba pọ si o ṣeeṣe ki eeyan sọ nkan nu tabi ko gbagbe nkan si eeyan mii lọwọ.
Àtẹ̀jíṣẹ́ náà tun fi kun pe, BBC ń fẹ́ láti ran ọ̀gọ̀run lọ́nà ẹgbẹ̀rùn àkẹ́kọ̀ọ́ jáde fásitì lọ́wọ́ láti tẹ̀síwáju nínú ẹ̀kọ́ wọn ní Fásítì tó wù wọn lágbàyé.
US election results: Wo ìdí márùn-ún tí Biden fi bórí nínú ìdìbò ààrẹ America
Àlá tí o lá, ati ìran tí o rí ní orí ibùsùn rẹ nìyí:
"Ipinlẹ Eko yii kan naa lo ti ṣe iṣẹ miran pẹlu ẹgbẹ alarokọ to kọ itan ""Village Headmaster"" to di fiimu agbelewo lori ikanni ileeṣẹ NTA lọjọ naa lọhun."
Ọ̀dọ́mọkùnrin ẹni ọdun mẹ́rìndínlọ́gbọ̀n ṣá bàbá rẹ̀, ẹni ọdún àádọ́rin pa
Kunle Afolayan, òṣìṣẹ́ báńkì tẹ́lẹ̀ kó tó di gbajúgbajà òṣèré Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Nigeria Independence Day: Sé ẹ mọ̀ pé ọdún 1956 ló yẹ́ ká ti dòmìnira ṣùgbọ́n.
Ọmọbinrin arinrinoge nigbakan ri, ti fi ẹsun kan aarẹ ana lorilẹede Gambia, Yahaya Jammeh pe, O fi ipa ba oun lopọ lasiko to fi wa ni ipo aarẹ.
Ọlọrun bá bi Jona pé, “Ǹjẹ́ o lẹ́tọ̀ọ́ láti bínú nítorí ìtàkùn yìí?
" Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí 4:32 Fídíò, Fulani Kidnapping: Owó púpọ̀ la san kí wọ́n tó fi mi sílẹ̀ lẹ́yìn ọjọ́ mẹ́fà, Duration 4,328 Agẹmo 2019 Kidnapping: Ọwọ́ ọlọ́pàá ba Pásítọ̀ olórí ikọ̀ ajínigbé tó pa èèyàn márùn ún30 Agẹmo 2020 Kidnapping in Nigeria: Ara sọ́ọ́bù oníṣòwò ni wọn ti rí nọ́ńbà ìpè rẹ̀, tí wọn sì tàn-án jáde lásìkò ìsìn26 Agẹmo 2020 Osun Kidnapping: Àwọn afunrasí darandaran jí èèyàn mẹ́rìnlá gbé nńú bọ́ọ̀sì Osogbo sí Abuja23 Owewe 2019 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 3 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 5 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
''A ko ni tori wi pe a n dije ninu ibo ki a wa fi aabo ara ilu ṣere'' Nibi ipade naa la tun ti ri awọn eekan ẹgbẹ bi igbakeji Aarẹ Yemi Osinbajo ati alaga ẹgbẹ oṣelu APC, Adams Oshiomọlẹ to peju sibẹ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Sunday Ayẹni: Damilọla, aya ọmọ mi fìgbónára sọ mi sókùnkùn alẹ́ Awọn aladugbo sọ wipe idi ti baba naa ko fi fẹ ki ọmọ rẹ jade ni wipe o ni oun fẹ ki o tẹle oun lọ ṣiṣẹ kan.
Ìtàn ìgbé ayé Abdulrahman Abdulrazak, gómìnà Kwara Aṣọ ń pe aṣọ ránṣẹ́ ni lásìkò ìbúra gómìnà àti ààrẹ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Nigeria Population: Báwọn ọmọ Nàíjíríà ṣe ń pọ̀ si jẹ́ ìpèníjà fún Buhari Awọn agbẹ naa sọrọ lori awọn ipenija ti wọn n dojuko nitori aisi awọn ohun elo amayedẹrun, paapa ọna to ja gara lasiko ti wọn ba fẹ ko ere oko.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ẹ wo fídíò Kìnìhún ní ibùgbé rẹ̀ tuntun ní Bogije, Lekki Ẹ wọ orukọ awọn aja ti ẹ gbọdọ yẹra fun: Aja Bullmastiff: O jẹ ẹya aja ti yoo le eniyan lere nitori bi o se tobi to, ẹrujẹjẹ ni, to si le pa eniyan.
 Ìjoba àpapò gba àkóso ilé isé ìròyìn méjì tí ó tóbi jù lo lórílè èdé yìí .
A kìí mọ, bí o ba dé tí o bá sì gbọ́ pé mo ti kú, máṣe ba ara jẹ́, ṣu òṣùká pàtàkì kí o gbé ẹrù mi bí ọkùnrin.
A kò lè fi ipá mú e̩nìké̩ni dara pò̩ mó̩ e̩gbé̩ kankan.
39 Bẹ́ẹ̀ni, kí o sì rantí pé a ti sọ nínú àwọn ìwé kíkọ pé àwọn àkọsílẹ̀ pàtàkì kan ni a ti fi fúnni nípa àwọn ohun wọ̀nyí ní orí àwọn àwo Néfì.
Idi ti Aisha Umaru ọmọ Hausa obinrin kan soso to wa ni BBNaija se fọ sẹkun.
Mi o ni ṣatilẹyin fun ọkọ mi to ba fẹ lọ fun saa keji Igba keji ti Aisha Buhari tun sọrọ lodi si iṣakoso ọkọ rẹ ni ọdun 2017 nigba to sọ pe oun ko ni ṣatilẹyin fun ọkọ oun to ba dije fun saa keji gẹgẹ bi aarẹ l'ọdun 2019.
“Nígbà tí o bá fi ohun ẹlẹ́mìí rúbọ sí mi, burẹdi tí o bá fi rúbọ pẹlu rẹ̀ gbọdọ̀ jẹ́ èyí tí kò ní ìwúkàrà ninu, ọ̀rá ẹran tí o bá fi rúbọ sí mi kò sì gbọdọ̀ kù di ọjọ́ keji.
Ààrá bá bẹ̀rẹ̀ sí sán, mànàmáná ń kọ, ilẹ̀ bẹ̀rẹ̀ sí mì tìtì.
Wo àwọn tó ń jí owó Covid-19 tí Ìjọba ní wọ́n yóò káwọ́ pọ̀nyìn rojọ́ Ajọ pajawiri ni ipinlẹ Eko, LASEMA naa fikun un pe awọn awakọ loju popo, paapaa tirela gbọdọ ma a wakọ jẹjẹ loju popo, ki wọn si ye sare asapajude.
 Okunnu ni ọmọ bibi ìlú Ogbomoso ni Ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́ ni oun, tó sì ni gbogbo olórin ni òun féràn àmọ́ orin Fuji olóògbé Sikiru Ayinde Barrister ni òun máa ń gbọ́ julọ."
obinrin to ti to ọgọta ọdun ni iru emi bayii n wa, nigba ti mo ba si ṣe e laipẹ, gbogbo aye ni yoo ri.
Ẹgbẹ ASUU fi ikede yi sita loju opo Twitter wọn Ohun ta gbo ni pe ipinu lati mu iyanṣẹlodi naa wa si opin waye lẹyin ipade kan laarin ijọba ati awọn ọmọ gbẹ naa labuja.
Ilẹ̀ ayé wárìrì, ó sì mì tìtì,ìpìlẹ̀ àwọn òkè mì jìgìjìgì;wọ́n wárìrì nítorí tí ó bínú.
Igi ìyè kan wà ní ẹ̀gbẹ́ ọ̀tún, ọ̀kan wà ní ẹ̀gbẹ́ òsì odò náà.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Boko Haram: Ẹ̀mí kan bọ́, èèyàn 16 míì farapa nínú ìṣẹ̀lẹ̀ àdó olóró ní Maiduguri 5 Èrèlè 2018 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 31 Agẹmo 2020 Oríṣun àwòrán, @___FAREED Aifararọ ati idarudapọ waye nilu Maiduguri, tii se olu ilu ipinlẹ Borno lasiko ti ọpọ eeyan n se ọdun Ileya.
Ní àkókò ẹkùn ní ìlú wọn.
Ọọni gbe Arẹmọ Tadenikawo Adesoji Aderemi Ogunwusi wọ inu aafin Ile Ife fun igba akọkó.
4 Kíyèsíi, iṣẹ́ tí a pè ọ́ láti ṣe ni láti kọ ìwé fún ìránṣẹ́ mi Joseph.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Muhammadu Buhari: Falana ní ilé ìwòsàn ti di mọ́ṣúárì ní Nàìjíríà nígbà tí Buhari ń gbàtọ́jú nílẹ̀ òkèrè 10 Èrèlè 2020 Oríṣun àwòrán, Facebook/Femi Falana Ẹyin ọmọ Naijiria, ẹtọ yin lati beere fun eto ilera to peye lọwọ ijọba aarẹ orilẹede Naijiria, Muhammadu Buhari.
Gbogbo wọn dira ogun pẹlu idà,akọni sì ni wọ́n lójú ogun.
Esi ipinlẹ kọọkan re e: Eniyan 6,879 ti ri iwosan, ti 518 si ti ku.
Àwọn ìjòyè bá sọ fún Baruku pé kí òun ati Jeremaya lọ sápamọ́, kí wọn má ṣe jẹ́ kí ẹnikẹ́ni mọ ibi tí wọ́n wà.
samojuto ọrọ to jẹ mọ ounjẹ lorile ede Naijiria Abubakar Atiku-Bagudu,lo soro
" Kí ló ń fa ikùn yíyọ láàárín àwọn ọlọ́pàá?
Ṣugbọn kí àkọsílẹ̀ lè ṣẹ ni èyí ṣe rí bẹ́ẹ̀.
( October 11, 1962)O gba imo ijinle ninu ede Geesi  Bachelor of Arts (English) lodun 1983; o
Abijamu jáde láyé, wọ́n sì sin ín ní ìlú Dafidi, Asa, ọmọ rẹ̀ sì gorí oyè lẹ́yìn rẹ̀.
Ideyẹsi ni nitori idile yii gbọdọ dopin - Oge MaduagwuNibayii, awọn ẹbi to wa lati idile ẹru yii wa lara awọn to ni ọrọ julọ ni agbegbe wọn, amọ ko si bi wọn ṣe le ṣe oriire to, awọn eniyan si ma n dẹyẹsi wọn gẹgẹ bi ẹni ti ko jamọ nkankan.
Nígbà tí ó yá, ó rí i pé òun lóyún, ó sì rán oníṣẹ́, pé kí wọ́n sọ fún Dafidi ọba.
Yóo ràn mí lọ́wọ́, yóo fún mi ní ìfẹ́ ọkàn mi.
Bákan náà ní Australia, puerto Rico, Poland àti Czech Republic, Croatia ti Macedonia, wọ́n ń lò ó gẹ́gẹ́ bí ògùn òyìnbó.
Àwọn mẹ̀kúnù jόkòό sí àyé wọn pẹ̀lú ìrẹ̀lẹ̀ láì b’Ólúwa wíjọ́.
OLUWA bá wí fún mi pé, “Òtítọ́ ni ohun tí o rí, nítorí mò ń sọ ọ̀rọ̀ tí mo sọ, n óo sì mú un ṣẹ.
Iru ewu wo gan an ni o le wu awọn awọn oṣiṣẹ eleto ilera lorilẹede Naijiria?
Má dìtẹ̀ bí àwọn ọmọ ìdílé ọlọ̀tẹ̀ wọnyi.
Amo, igbiyanju wa lati beere iha ti ijọba ipinlẹ̀ Ọ́yọ̀ ko si iyansẹ̀lodi ọlọ̀jọ̀ mẹ̀ta naa jasi paabo, nigba ti oludamoran fun Gomina ipinlẹ̀ Ọ́yọ̀ lori eto iroyin, Ogbeni Yemi Olayinka ko gbe ipe erọ ibanisọ́rọ́ wọn.
Bayii ni wọn yoo ṣe titi ti oludije kan yoo fi ni ibo to pọ ju.
Israel sọ pe o ṣe oun bi ki ija naa ti bẹrẹ nitori oun ko le duro mọ lati da ẹṣẹ bo Costa lori.
to wa lati awon agbegbe wonyii.
Òpè eniyan a máa gba ohun gbogbo gbọ́,ṣugbọn ọlọ́gbọ́n a máa kíyèsí ibi tí ó ń lọ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìtàn Mánigbàgbé: Kí lo fẹ́ mọ̀ nípa ‘Ajala Travels’?
APC ati PDP n gbena woju ara wọn ninu atundi ibo Kwara Bi awọn ẹgbẹ oṣelu ṣe n gbaradi fun atundi ibo sile aṣoju-ṣofin lẹkun ijọba ibilẹ Ekiti, Oke Ero, Isin ati Irẹpọdun ni ipinlẹ Kwara, eleyi ti yoo waye ni ọjọ abamẹta, awọn agbebọn kan lo ṣaa dede kọlu awọn ọkọ ti o ko oludije fun ẹgbẹ oṣelu APC, Tunji Ajulo Opin ati ikọ ipolongo rẹ pẹlu ibọn.
Òun ni olùdarí ìsìn ninu ilé Ọlọrun.
”Ó dáhùn pé, “Èmi kò mọ̀.
Àwọn àgbà tí wí pé ọgbọ́n ọlọ́gbọ́n kì í jẹ́ kí a pa àgbà ní wèrè.
Àwọn aṣọ́de rí mibí wọ́n ti ń rìn káàkiri ìlú;wọ́n lù mí, wọ́n ṣe mí léṣe,wọ́n sì gba ìborùn mi.
Ṣaṣa ni obinrin ti yoo ri Ọgbẹni Bọlanle Ninalowo ti ko ni ki Ọlọrun ku iṣẹ nitori ẹwa rẹ.
 Àwọn eléré àpíìrì tí ó tì ń ṣeré ní Ìjerò báyìí ni Èyéọwá Ọmọyẹyè , s.
Ibadan NURTW: Àwọn ti Auxilliary àtàwọn tí Ajanaku gangan ló ń dàgboro rú
Small Doctor gba òmìnira n'ílé ẹjọ pẹ̀lú ìkìlọ̀ Wo àwọn àwòrán ìgbà ayé Aretha Franklin Fun ẹyin ti ẹ ko ba ti laanfaani lati dasi, boya ki ẹ ka diẹ lara ohun ti wọn n sọ ki ẹ to mọ iha ti ẹ o kọ si ọrọ yi.
Aare Muhammadu Buhari kẹdun pelu aare orile-ede Amerika, Donald Trump ati awon eniyan re lataari ikolu omiyale ati iji ti o kolu awon eka ati ipinle kookan lorile-ede naa.
 Ọ ̀ kán kú èkejì sì wà láàyè .
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Sudan: Omar al-Bashir, oníyàwó méjì tí kò bí'mọ kankan 11 Ìgbé 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 12 Ìgbé 2019 Oríṣun àwòrán, ASHRAF SHAZLY Àkọlé àwòrán, Omar al-Bashir Lẹyin ọgbọ̀n ọdun, orilẹede Sudan yoo ni adari tuntun latari bi awọn ologun orilẹede naa ṣe gba ijọba lọwọ Omar al-Bashir.
Àwọn tí wọ́n kú ninu àjàkálẹ̀ àrùn náà jẹ́ ẹgbaa mejila (24,000).
Arsenal ti padà júwe ilé fún Unai Emery N kò mọ̀ pé ojú mi ṣì lè là mọ́ lọ́wọ́ ìgbájú- Boluwatifẹ FUTA Dino ní ìyàwó ni Adeyemi jẹ́ f'óun lágbo òṣèlú, Adeyemi l'ọ́mọ ọ̀dọ̀ ni Dino jẹ́ Erin mẹ́fa wó níbi tí wọ́n ti fẹ́ dóòlà ẹ̀mí ara wọn Ronaldo lo tun tẹle Messi lẹyin t'oun naa ti gba ami ẹyẹ Ballon D'or fun igba marun un ọtọọtọ.
A Mú Peteru ati Johanu Wá siwaju Ìgbìmọ̀ Àwọn Juu.
Ninu igbes tuntun yii, ẹrọ ATM gan ko gbudọ maa pọ owo to dọti mọ, bi o ba wa ri pe o pọ eyi ti o dọti jade, o le fi ẹjọ rẹ sun ile ifowopamọ to ga ju lọ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù US presidential election 2020: Ta a ni Joe Biden tó ń díje fún ipò aárẹ America 2 Bélú 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 4 Bélú 2020 Oríṣun àwòrán, Getty Images Wo ǹkan tó yẹ kí o mọ̀ nípa Joe Biden, tó ń kojú Trump nínú ìbò America.
Ggẹ́gẹ́ bí ọ̀rọ̀ àwọn àgbà tí ó wí pé ẹni tí ó bá ọwọ́ í wẹ̀ á bá àgbàlagbà jẹun, inú ẹ̀gbọ́n rẹ̀ dùn ó si wí pé: mo dúp púpọ̀ pé ìyá mi bbí ọ pẹ̀lú mi.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ọrọ lori Brexit O ṣalaye pe ọpọ ọmọbibi Naijiria ti wọn n gbe ni Ilu Ọba ko ba ti wa nibẹ to ba jẹ pe nnkan fararọ lorilẹ-ede Naijiria.
Kudirat Abiola jẹ apẹrẹ ajijangbara fun ijọba awarawa Naijiria to bẹẹ to jẹ pe ọdun mọkandinlogun, wọn ṣi n ṣe iranti igbesẹ yii eti iboji rẹ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, EndSars, EndSwat Protest: Òbí agbábọ̀ọ̀lù Gbenga Tiamiyu Kaka àtàwọn míì tí ọlapàá pa sọ̀r Bayii ni o ṣe le wo esi idanwo WAEC rẹ Lọ si oju itakun ayelujara www.
Ẹ wo iriri rẹ ati amọran to ni fawọn miran to ba n gba awẹ.
Mike Tyson ti oun naa ti fẹyin ti kilọ pe afaimọ ki ẹru ijakulẹ ninu ija akọkọ maa mu Joshua padanu lẹẹkan si ni Saudi.
Bi awọn ọmọ Naijiria si ṣe n poungbẹ adẹrinposonu naa, lo mu ka fi ọrọ wa Baba Suwe lẹnu wo, ki ọkan araalu le balẹ pe, alaafia ni baba wa.
Aṣeyọri nla ni eyi jẹ nitori ọpọ lo gbagbọ pe, orilẹ-ede Naijiria ko koju oṣuwọn to nipa iwaadi ijinlẹ nipa eto ilera.
  Àwòrán kan wà tí ó lè ba ẹlòmíràn lẹ́ rù.
Wọn ni awọn yoo pese ọna abo lati ma fi lo ẹrọ ilewọ tabi kọmputa eleyi ti yoo ṣe anfaani fawujọ.
Aarẹ gan lo yẹ ko gbe igbesẹ lori pipẹtu si aawọ gbogbo lẹgbẹ oselu naa."
Kí o máa rí arọmọdọmọ rẹ.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Kí ló mú Olorì Badrat Ajoke kúrò ní ààfin Oyo lọ́jọ́ Iléyá?
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Brọ̀dá Shaggi: Shagidon ni mo gé kúrú sí Shaggi bíi ìnagijẹ nínú eré Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Brọ̀dá Shaggi: Shagidon ni mo gé kúrú sí Shaggi bíi ìnagijẹ nínú eré 13 Ìgbé 2018 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 9 Ọ̀pẹ̀̀ 2018 Gbajugbaja apanilẹrin loju opo ikansiraẹni Instagram, to tun jẹ osere tiata, Samuel Animasahun Perry salaye pe, ẹnu awọn agbero ni gareji ọkọ ero ni ero lilo inagijẹ ninu ere ti kọkọ gba ọkan oun.
Ó bi mí pé, ta ni mí; mo dá a lóhùn pé, ‘Ọ̀kan ninu àwọn ará Amaleki ni mí.
Iṣẹ́ wo ni Ayo Akinwale ṣe sílẹ̀ kó tó rọ̀run àrèmabọ̀ lẹ́ni ọdun 69?
50 Àti báyìí ni, wọ́n fi ìbùkún sílẹ̀ sí orí ilẹ̀ yìí nínú àwọn àdúrà wọn, pé kí ẹnikẹ́ni tí ó bá gba ìhìnrere yìí gbọ́ ní ilẹ̀ yìí lè ní ìyè ayérayé;
Àwọn ọmọ ogun Israẹli sì ń lé wọn lọ.
Ajọ NDLEA nipinlẹ Ondo lo kede bẹẹ nibi ipade akọroyin kan to se nilu Akure lọjọ Ẹti.
    Ìgbà tí ó lọ tán ni ara wa tó padà bọ̀ sí ipò tí a tó lè sọ̀rọ̀ tíi a tó lè rẹ́rìn-ín sí ara wa.
Ọbasanjọ figbe ta pé Buhari fẹ́ gbé òuń Iwe Aarẹ Ọbasanjo si Buhari: nibọ ni ọrọ naa yoo jasi?
Ahabu, ọba Israẹli, ati Jehoṣafati, ọba Juda, bá lọ gbógun ti ìlú Ramoti Gileadi.
MTN àti BBC World Service bẹ̀rẹ̀ àjọṣepọ̀ lórí ìròyìn ìṣẹ́jú kan BBC Wo àwọn èèyaǹ jàǹkàn mérin tí àrùn Coronavirus ti sọ dèrò ọ̀run ní Naijiria Àwọn èèyàn ìpínlẹ́ Ondo kò gbàgbọ́ pé Coronavirus wà lọ jẹ́ kó máa pọ̀ síi - ìjọba Wo bí ọwọ́ orílẹ̀-èdè Dubai ṣe tẹ Ramoni Igbalode tí gbogbo ayé ń pè ní Hushpuppi Gẹgẹ bi iroyin lati oju opo naa ti se sọ, iforukọsilẹ to ba waye saaju asiko yi jẹ otubantẹ ni yoo ja si fẹni ba se iru rẹ.
Ìwà ìṣẹ̀dá ẹ̀gbọ́n náà yàtọ̀ ṣá, bí bàbá rẹ kò bá sọ́ra yóò pa a, nítorí ọ̀gbọ́n mi náà ba nì lẹ́rù lọ́pọ̀lọpọ̀, bẹ́ẹ̀ ni kì í fẹ́ kí ẹnikẹ́ni bẹ̀rù òun, ẹni tí ó bá bẹ̀rù rẹ̀ a na irin mọ ọ lórí, á pa á dànù wéréwéré.
Bakan naa lo tun ke sawọn eeyan ilu Iwo lati mu lilo ibomu lọkunkundun pẹlu arọwa sawọn to n ni afihan awọn aisan to rọ mọọ lati lọ ṣe ayẹwo ara wọn nitori arun naa kii ṣe opin ẹmi.
“Nítorí Efuraimu ti tẹ́ ọpọlọpọ pẹpẹ láti dẹ́ṣẹ̀ níbẹ̀, wọ́n ti di pẹpẹ ẹ̀ṣẹ̀ dídá fún un.
OLUWA bi Satani pé, “Níbo ni o ti ń bọ̀?
Sultan náà bá àwọn akọ̀ròyin sọrọ ni ààfin rẹ̀ ni Ọjọ́rú, nibi tí ó ti rọ àwọn Musulumí jákèjádò agbaye pé, kí wọn lo àǹfàní ààwẹ̀ ọgbọn'jọ́ náà, láti fi ọkàn wọn jì fún àlàáfía.
Ni aarọ ọjọ Aje lawọn akansa ẹda yabo ibujoko ijọba ipinlẹ Eko ni Alausa, ti wọn si n fẹhonu han sijọba lori bo se fofin de ilo ọkada ati kẹkẹ Maruwa lawọn agbegbe kan.
Èsì ìdìbò tí yóò gbé aàrẹ tuntun wọlẹ́ ní Ghana rèé.
Fífòfinde àwọn ọkọ̀ yìí kò ṣẹ̀yìn àjàkálẹ̀ ààrun coronavirus to wọ orílẹ̀ èdè Naijiria nínú oṣù kẹta ọdún 2020.
"Iléeṣẹ́ Instagram wọ́gilé App ""Augmented Reality filters"" lórí ẹ̀rọ rẹ̀ Ìjà ìgboro rèé o, ṣe bí ọkùnrin ni Bobrisky ṣe bá ọkùnrin ẹgbẹ́ rẹ̀ jà ní?"
Àkọlé àwòrán, Maa ṣiṣe pẹlu Hamzat igbakeji mi lati mu gbogbo ileri wa lasiko ipolongo ṣẹ fun ẹyin eeyan ipinlẹ Eko Sanwo Olu ki àwọn eniyan ipinlẹ Eko fun ifarada si bi igba ti ri lasiko yii.
Ọba Ogunwusi fi eyi lede lori itakun ikansiraẹni Instagram rẹ wi pe isẹ Odumare ati awamaridi ni bi oun se fẹ olori naa, ti ọba si ki i kaabọ si aafin ọba.
Nígbà tí ó bá ń gbé àwọn fìtílà náà sí ààyè wọn ní àṣáálẹ́, yóo máa sun turari náà pẹlu, títí lae ni yóo máa sun turari náà níwájú OLUWA ní ìrandíran yín.
O ni ko yẹ ki iyawo jẹ ko maa ṣe bi ọtẹlẹmuyẹ fun ọkọ rẹ.
Kí o má baà kọ́ ìwà rẹ̀,kí o sì fi tàkúté mú ara rẹ.
“Sugbon a ko ni gba ipolongo ti o lee fa wahala laaye ni ipinle yii.
Ń kó sì gbàdúrà irú iriri báyìí fún ọ̀tá mi rárá, ọkàn àwọn ọmọ mi ń fà mí.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Amẹ́ríkà UK, France kọlu àwọn ọmọ ogun al-Assad 14 Ìgbé 2018 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, America,UK, France gbèjà orílẹ̀èdè Syria Látàrí bí wọ́n se kọlu orílẹ̀èdè Syria láìpẹ́ yìí, orílẹ̀èdè Améríkà, ilẹ̀ Gẹ̀ẹ̀sì ati orílẹ̀èdè Faransé ti koná ogun wọ́n sì ti gbé e ko ibi mẹ́ta kan tí wọ́n fojú sùn wípé àwọn ló kọlu orílẹ̀èdè Syria.
Jesu sọ fún un pé, “Simoni, mo fẹ́ bi ọ́ léèrè ọ̀rọ̀ kan.
Fun idi eyi,orileede Naijiria kuna lati mu ileri Abuja ọdun 2001 to ṣe pẹlu awọn orileede miran lafrika pe ohun yoo na o kere ju ida mẹẹdogun 15% ninu ida ogorun owo isuna rẹ lori ọrọ ilera.
Omi ni Sisera bèèrè, wàrà ni Jaeli fún un,àwo tí wọ́n fi ń gbé oúnjẹ fún ọbani ó fi gbé e fún un mu.
Àwọn ọmọ Israẹli pàápàá bẹ̀rẹ̀ sí sọkún àìrẹ́ran jẹ.
Amọ kini ki a ti wi si ti arakunrin to ge ika ara rẹ nitori pe o ṣeṣi fi ika naa dibo fun ẹgbẹ to yatọ si eleyi to yan laayo.
àwọn kan lọ sí apá ọ̀nà Beti Horoni, àwọn yòókù lọ sí ẹ̀bá ìpínlẹ̀ àtiwọ àfonífojì Seboimu ní ọ̀nà aṣálẹ̀.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, BBC Africa Eye: ìwádìí ìkọ̀ks BBC fihàn pé àwọn kan ń jí ohun èèlò ìdáàbòbò ìjọba tà nígbo Uloma ni tirẹ sọ pe iwa iṣerubalu ni ki wọn maa mu eeyan fun ẹsun isọro odi.
Ọpọlọpọ ọkọ nla pọ kaakiri Apapa nitori ibudokọ oju omi to pọ si agbegbe naa.
Ìró ìyẹ́ wọn dàbí ìró ọpọlọpọ ọkọ̀ ẹlẹ́ṣin tí wọn ń sáré lọ sójú ogun.
Ohun tí mo fẹ́ kí o mójútó ni oúnjẹ tí èmi ati ìdílé mi óo máa jẹ.
Ó ṣe nǹkan burúkú lójú OLUWA.
lori awon ohun amayederun , nitori pe epo rọbi ko wa titilai,” .
Nítorí à ń gbé ìgbé-ayé wa ninu àìlera ti ara, ṣugbọn a kò jagun gẹ́gẹ́ bí ẹni tí ó ń wá ire ara wa, 
"Oríṣun àwòrán, fathiawilliams instagram Nigba to n kede iroyin ayọ naa loju opo ikansira ẹni Instagram rẹ, toyinabrahamnews, osere tiata naa ni ""Oluwa dara, Ọmọọba wa ti de"", to si fi ijo sii."
4 7320 Orilẹede Somalia 130 0.
Ẹ kó ara yín jọ kí ẹ pọ̀ bí eṣú!
" Oríṣun àwòrán, Getty Images Lati oṣu kẹsan, ọdun 2017 ti awọn ọlọde to n koju awọn agbesunmọmi pelu awọn ologun ti jọ fọwọ siwe lati dẹkun lilo awọn ọmọde, 1,727 jẹ iye awọn ọmọde ti wọn ti tusilẹ.
S - Liverpool Agboyi Ketu - Five Cowries Agboyi Ketu - Marina/C.
Ọdun 1958 ni wọn bi Babatunde Omidina, ti ọpọ mọ si Baba Suwe ni ilu Eko.
Ikolu ohun tan titi kakaakiri awon orile-ede ti o fara pe orile-ede naa bi Niger ati Burkina Faso, eleyi ti o mu ki orile-ede France ati Amerika ran awon omo ogun re lati da si rogbodiyan naa.
Ẹ má banújẹ́ tabi kí ẹ sọkún.
Aṣẹ́wó rán awakọ̀ ajàfẹ́tọ̀ọ́ l'ẹ̀wọ̀n Bakan naa lo ni ọkọ kan tawọn janduku fẹ fi lọ hu iwa laabi wọn lagbegbe kan ni Kogi lọwọ awọn ọlọpaa tun tẹ.
Mose ati Eleasari gba àwọn ohun ọ̀ṣọ́ wúrà ati àwọn ohun ọ̀ṣọ́ mìíràn náà lọ́wọ́ wọn.
Àwọn ni ó fi ògo rẹ̀ hàn fún.
Amọ iwadii wa fihan pe irọ gbaa ni , ti agbẹnusọ obinrin naa si ni lootọ ni SARS gbe Ugochukwu lọdun 2018 amọ ko si ohun to se.
Ti o ba ti jẹ wipe Fayose lo sọrọ a kii fẹ fesi."
lasiko ti o n yan awon minisita senu ile-ise ti won yoo maa tuko re lojoRu(Wednesday),
Paroparo ni agbegbe naa da ti iwọnba awọn eeyan melookan to n wọle si n kọ ọrọ idaro wọn si iwe ibanikẹkun ti wọn ṣi pẹlu aworan oloogbe naa.
ati àwọn arakunrin wọn: Ṣebanaya ati Hodaya, Kelita, Pelaaya, ati Hanani, 
Nígbà náà ni wọ́n ké pe OLUWA ninu ìpọ́njú wọn,ó sì gbà wọ́n ninu ìṣẹ́ wọn.
Diẹ ninu ohun ta mọ nipa rẹ ree Kii ṣe ọmọ Naijiria ni Dokita Stella Ọpọ awọn to n ṣalabapin fidio yi lo lero wi pe ọmọ Naijiria ni Dokita Stella.
Bí ẹ bá gbin ohun ọ̀gbìn, òfò ni yóo jásí, nítorí pé àwọn ọ̀tá yín ni yóo jẹ ẹ́.
Ẹ gba àjàgà mi sí ọrùn yín, kí ẹ sì wá kẹ́kọ̀ọ́ lọ́dọ̀ mi, nítorí onírẹ̀lẹ̀ ati ọlọ́kàn tútù ni mí, ọkàn yín yóo sì balẹ̀.
Bóyá bí àwọn ará Juda bá gbọ́ nípa ibi tí mò ń gbèrò láti ṣe sí wọn, olukuluku lè yipada kúrò ninu ọ̀nà ibi rẹ̀, kí n lè dárí ẹ̀ṣẹ̀ ati àìdára wọn jì wọ́n.
Iṣẹ ẹni kankan ko ni di iṣẹ o.
 Sise eto ogbin anamo lalada nla ni eyi ti Banki idagbasoke ile Adulawo n pese iranlowo fun to ti n bi eso ipese ise ati ounje fawon ara ilu”.
Ṣugbọn ninu ifọrọwanilẹnu wo kan ti ileeṣẹ amohunmaworan ijọba ipinlẹ Ondo, OSRC, ṣe, pẹlu awakọ ọkọ akẹru naa, lo ti fojuhan pe o ṣeeṣe ko jẹ otitọ ni ọrọ ti kọmisana ọlọpaa sọ.
Yoruba ni ti ko ba si ina, eefin kii ru, ibeere awọn ọmọ Naijiria ko sẹyin iroyin kan to jade laipẹ yii pe ara ibatan aarẹ naa ko da, ti wọn si ti gbe digbadigba lọ sile iwosan.
Òróró tí o bá ta sí wọn lórí ni yóo sọ àwọn ati gbogbo ìran wọn di alufaa títí lae.
Ọjọ Ẹti, ọjọ kẹrin, oṣu Keje, ni ajọ to n daabo bo ẹtọ oníbàràá ni Naijiria, FCCPC, kede pe oun ti mu Anu, to ni ileewosan Medcontour.
Arabinrin Maimuna sọ pe ọna ti ko tọ ni FIRS n gba ta ontẹ naa ko ba ofin mu.
Ọgbọnjọ, oṣu Kẹrin, ọdun 1966 ni wọn da ijọ Satani silẹ, lati ọwọ Anton Szandor LaVey, nilu San Francisco l'orilẹ-ede America.
Esther Agbẹjọro ni Esther Agunbiade to wa lati ipinlẹ Eko.
Iroyin naa tẹsiwaju pe o san ki eeyan ni Covid-19, nitori o lanfaani lati ri iwosan gba ju ki o gba abẹrẹ ajẹsara arun naa lọ.
Pataki lara awọn alatako Kenyatta ni Odinga jẹ, koda ni ibẹrẹ ọdun 2018 ni Odinga se ijẹjẹ fun ara rẹ gẹgẹbii aarẹ orilẹede Kenya leyin wọlukọlu to waye nibi idibo apapọ nibẹ.
Lara awọn ilana naa ni pe awọn oṣiṣẹ ijọba to wa ni ipele 'Level 15' soke nikan ni yoo pada sẹnu iṣẹ.
Àìmọye irú ìṣẹ̀lẹ̀ yìí ló nṣẹlẹ̀ káàkiri orílẹ̀ wa.
GarcíaAlmagrojẹ onkọrin ilẹ Spain to jẹ ọmọ ọdun mejilelọgbọn.
Akure Kidnap: Wọ́n ti dáná sun ilé ìjọsìn Sọtitobirẹ nílú Akure Iroyin to n tẹwa lọwọ ni yajoyajo sọ pe awọn eeyan ti dana sun ile ijọsin Sọtitobirẹ Miracle Centre nilu Akure ni ipinlẹ Ondo.
eniyan ti o fara kaasa, awon omobibi ipinle Sokoto ati apapo ijoba ipinle naa kedun
Obinrin kan wà níbẹ̀ tí ó ń jẹ́ Lidia, ará Tiatira, tí ó ń ta aṣọ àlàárì.
Mo bá mú Jaasanaya ọmọ Jeremaya ọmọ Habasinaya ati àwọn arakunrin rẹ̀ ati gbogbo àwọn ọmọ rẹ̀ ati gbogbo ìdílé Rekabu, 
“Bí àwọn tí kò yẹ kí wọ́n jìyà bá jìyà, ṣé ìwọ wá lè lọ láìjìyà?
Aisha ati Fatimọ si ni wọn ti salaye ohun to kan wọn nipa fidio naa, ti ọkọọkan wọn si n naka aleebu si ara wọn.
 brazil ni ikan ninu awon okowo gbangba to unsare dagba julo lagbaye .
Ìránṣẹ́ Ọlọ́run ni ó jẹ́ fún àwọn Kìrìstẹ́nì àti àwọn Júù (Yawúdí) pẹ̀lú.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ọla Adedibu ní Ladoja jẹ̀ tó fi wọlé Gómìnà l‘Oyo labẹ ẹgbẹ́ PDP - Obasanjo Àwọn gómìnà nílẹ̀ Yorùbá ti kùnà láti pèsè ààbò tó péye fún aráàlú - Ẹgbẹ́ Majeobaje Ọ̀fẹ́ ló bá dé, Boko Haram kọ́ ló jí akẹ́kọ̀ọ́ gbé, a kò san kọ́bọ̀ fún ìdáǹdè wọn - Masari Ṣé lóòtọ́ ni Bimpe Oyebade lóyún fún Lateef Oladimeji?
ede Naijiria ko ni afiwe laarin akẹgbẹ wọn lagbaaye” .
Wọ́n ríran lẹsẹkẹsẹ, wọ́n bá ń tẹ̀lé e.
Nígbà tí ó ṣe tí ariwo náà túbọ̀ ń súnmọ́ wa ni a bẹ̀rẹ̀ si i gbọ́ ohun tí wọn ń wí.
Ọpọlọpọ nkan to maa n ṣẹlẹ lọfiisi lo ti poora lasiko isede.
Bí mo bá sọ pé èmi kò mọ̀ ọ́n, èmi yóo di òpùrọ́ bíi yín.
Fún ìgbà àkọ́kọ́ nínú ìtàn ìlúu nì, àwọn Abódiakọ-akọ́diabo kò bẹ̀rù láti jáde síta nínú ibi ìkòkọ̀ wọn àti fún ìjọba láti mú òfin Ààbò Ẹ̀tọ́ Abódiakọ-akọ́diabo Ènìyàn ọjọ́ 24, oṣù Èbìbì 2018.
Bakan naa lo fikun pe wahala yii buru to bẹẹ to fi n mu awujọ agbaye lomi, ti aarẹ Donald Trump tilẹ Amẹrika si bi oun nigba kan ri pe ki lo de toun fi n pa awọn Kristẹni.
Ọmọ ọgbọ̀n ọdún ni ṣùgbọ́n ó dàbí ọmọ ọdún mọ́kànlélógún.
Ó kéré tán, ẹ̀mí méjì míì ti lọ lórí ìfẹ̀hónú han Sagamu láàrin Ọlọ́pàá àti aráàlú Ọga ọlọpaa patapata lorilẹede Naijiria, Mohammed Adamu ti paṣẹ fun ọga ọlọpaa to wa lẹka iṣewaadi iwa ọdaran, Anthony Ogbizi lati ṣewadi ohun to fa iku Tiamiyu Kazeem to d'oloogbe nipinlẹ Ogun.
Jesu bá sọ fún àwọn ọmọ-ẹ̀yìn pé, “Nítorí èyí ni mo ṣe sọ fun yín pé kí ẹ má máa páyà nípa ẹ̀mí yín, pé kí ni ẹ óo jẹ, tabi pé kí ni ẹ óo fi bora.
Gbogbo alààyè ni wọ́n gbọdọ̀ máa fi èyí sọ́kàn.
Àwọn nǹkan tí Solomoni ń lò fún ìtọ́jú oúnjẹ ní ọjọ́ kọ̀ọ̀kan nìwọ̀nyí: Ọgbọ̀n òṣùnwọ̀n ìyẹ̀fun tí ó kúnná dáradára, ati ọgọta òṣùnwọ̀n ọkà tí wọ́n lọ̀; 
Ọjọgbọn Adewọle ni alafo oun ọgbun ibanisọrọ to wa laarin awọn ijọba ipinlẹ ati awọn eeyan wọn lo n ṣokunfa bi wahala aarun iba lassa ṣe n fẹ oju sii lorilẹede Naijiria.
Ní ọjọ́ kẹrin, oṣù keje, Orilẹ̀-èdè South Africa ń ṣe àyẹwò ọgbọ̀n nínú ènìyàn ẹgbẹ̀run kan, ká fi wé àyẹ̀wò ènìyàn méjìléláàdọ́rin nínú ẹgbẹ̀run kan ni UK àti márùnlélọ́gọ́run nínú ẹgbẹ̀run kan ni US.
Eérú náà ni àwọn ọmọ Israẹli yóo máa lò fún omi ìwẹ̀nùmọ́, fún ìmúkúrò ẹ̀ṣẹ̀.
 igba re pari ni august 31 , 2011 .
Kò lè sọ̀rọ̀ jáde lẹ́nu ju bẹ́ẹ̀ lọ, gbogbo ilé a máa dákẹ́ minimini.
Obasanjo, Gowon, Muhammed- wo àwọn olóri Nàìjíríà lọ́dọ̀ọ́ Ọ̀pọ̀ èèyàn ló sá fún mi nígbà tí mo dùbúlẹ̀ àìsàn- Ògògó Bí ọwọ́ ọlọ́pàá Sharia Kano ṣé tẹ ọkùnrin 26 tó mura bi obìnrin Àwọn abiyamọ figbe ta lórí ọmọ ọdún kan ti wọn wá nílé ìjọsìn l'Akure Ọrọ ede aiyede laarin awọn ontaja ọmọ orilẹ-ede Naijiria ati akẹgbẹ wọn ni Ghana ti bẹrẹ kaakiri gbogbo ọdun 2019.
Pasipaaro owo Dola si Naira loju oja nipinle Eko, eka gusuu iwo oorun orile-ede Naijiria duro soju kan.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù US Open 2019: Bianca júwe ilé fún Serena Williams nínú ìdíje l'America 8 Owewe 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Bianca gba ami ẹyẹ mọ agba ọjẹ Serena lọwọ ni New York Idije to gbogo fun Bianca Andreescu naa waye ni Flushing Meadows ni New York laarin ọjọ kẹrindinlọgbọn, oṣu kẹjọ si ọjọ kẹjọ, oṣu kẹsan an, ọdun 2019.
Kọmiṣọnna fun eto ilera naa ni awọn ijọba ibilẹ bii marun un ni Eti-Osa, Ajeromi, Surulere, Amuwo- Odofin ati Mushin ni awn eniyan to lugbadi arun naa ti pọ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Àràfá 2018: 100,000 òsìsẹ́ aláàbó ni Saudi lò fún ààbò tó péye 17 Ògún 2018 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 20 Ògún 2018 O le ni eeyan miliọnu meji jake-jado agbaye, to fi mọ awọn ọmọ Naijiria to to ẹgbẹrun lọna marundinlọgọta, ti wọn n gun oke Arafa lọjọ Aje, eyi to jẹ ohun to se pataki julọ ninu eto haji sise.
Gbogbo ohun tí ọba pa láṣẹ ni wọ́n ṣe.
Coronavirus: Fífi nkan bo ìmú rẹ kò tòó dènà kíkó coronavirus
4 291 Erekusu Turks and Caicos Island 6 15.
Àwọn míràn jẹ́ èyí tí ó jade nípasẹ̀ díẹ̀ nínú àwọn àtẹ̀lé rẹ̀ nínú Àjọ Ààrẹ (wo àwọn àkọlé sí Ẹ&M 135, 136, àti 138, àti àwọn Ìkéde Lábẹ́ Àṣẹ 1 àti 2).
Gege bi atejade kan lati ile-ise abenugan ile igbimo asofin, igbimo asofin yoo tun maa sepade po pelu igbimo ijoba orile ede Russia.
Lori igbesẹ yii, awọn olugbe lati diẹ lara awọn ipinlẹ ti ọrọ yi kan si ti fi ero wọn han.
Ni afikun un, ti a ko ba gbagbe pe iko agbaboolu South Africa fagbahan iko agbaboolu Super Eagles ni ifesewonse akoko pelu ami-ayo meji sodo(2-0), eyi fi han gbangba pe ifigagbaga naa yoo lagbara pupo.
Kí ẹ má ṣe gba owó ìtanràn lọ́wọ́ ẹni tí ó jẹ̀bi ẹ̀ṣẹ̀ ìpànìyàn, pípa ni ẹ gbọdọ̀ pa òun náà.
Oríṣun àwòrán, El-Zakzaky Awuyewuye ṣi n waye lori bi irinajo aṣiwaju ijọ Shiite ni Naijiria, Ibrahim El-Zakzaky ṣe ní kọnu n kọhọ ninu lasiko to lọ gba itọju ni orilẹede India, eyi ti o n ṣokunfa ipadabọ rẹ wa sile.
ó sì dà á sinu àwo kan, ó gbé e fún un.
Tata ni ounjẹ awọn ara Uganda.
Pẹ̀lu gbogbo anfani wọ̀nyii, o si ni awọn kan paapa julọ ninu ẹgbẹ alatako to ni awọn ko ri anfaani kankan ninu irinajo Buhari lọ si ipade naa.
"Awa mejeji jọ kere ti a ko si mọ ohunkohun nipa ifẹ nigba ti mo kọkọ pade rẹ, odo ifẹ kun a si luwẹ lai bẹruu ko gbe ni lọ.
Asofin Wasiu Ehinlokun to je igbakeji agbenuso lo soju fun agbenuso ile igbimo asofin nibi ipade naa.
Àwọn olùdámọ̀ràn rẹ̀ ati iyawo rẹ̀ sọ fún un pé, “Bí Modekai, ẹni tí o ti bẹ̀rẹ̀ sí wólẹ̀ níwájú rẹ̀ bá jẹ́ Juu, o kò ní lè ṣẹgun rẹ̀, òun ni yóo ṣẹgun rẹ.
Òwe Yorùbá ni “Bi èniyàn bá ni kò si irú òhun, àwọn ọlọ́gbọ́n a máa wòye”.
Eyi ko ṣẹyin bi awọn ọdọ ni ipinlẹ Eko ṣe pariwo fun gomina ipinlẹ Eko, Babajide Sanwo-Olu lati ''sọrọ soke'' lasiko to n ba awọn ọdọ afẹhọnuhan sọrọ nipinlẹ Eko.
O ni ki a maa ba oun gbadura.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Alápinni: Kò sí ẹni to fẹ́ kọ́kọ́ kọ́ iṣẹ́ òṣèré bíi ti àtẹ̀yìnwá Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Gbogbo ènìyàn ló wọ agbádá ikú, ẹni tó kàn lẹnìkan kò mọ̀ Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Ẹ gbé e jáde kí n máa báṣẹ́ lọ jàre!
Awọn ipinlẹ yoo le ṣamojuto ni aarin ipinlẹ wọn ṣugbọn labẹ ofin ijọba apapọ.
Corruption in Nigeria: Ojíṣẹ Ọlọ́run kan ní báwọn òbí ṣe ń jí owó ìlú kò, ní wọ́n ń fi lé ọmọ lọ́wọ́
Ẹniọwọ Ayọkunle ni 'ki ijọba fi ofin de ẹgbẹ awọn darandaran Fulani, Miyetti Allah to n ṣe agbodegba fun awọn darandaran fulani to n gbẹmi eeyan kiri ilu.
OLUWA bá dá àwọn ọmọ Israẹli lóhùn, ó ní, “Ṣebí èmi ni mo gbà yín lọ́wọ́ àwọn ará Ijipti ati àwọn ara Amori, ati àwọn ará Amoni ati àwọn ará Filistia.
Wọ́n dá a lóhùn pé, “Ohun tí o óo wí fún àwọn tí wọ́n ní baba rẹ di ẹrù wúwo lé àwọn lórí, ṣugbọn kí o bá àwọn dín ẹrù yìí kù ni pé ìka ọwọ́ rẹ tí ó kéré jùlọ tóbi ju ẹ̀gbẹ́ baba rẹ lọ.
Ayodele Fayoṣe kò ṣì lórí wíwá ọ̀rọ̀ láti sọ sí ohunkóhun ti Ààrẹ Muhammadu Buhari bá sọ.
Ọrọ iwuri, ifẹ, ati adura lo fi ki ku ọjọ ibi.
Ó bá a níbi tí ó jókòó sí lábẹ́ igi Oaku kan, ó bi í pé, ṣe òun ni wolii tí ó wá láti Juda?
Àwọn Àtúnṣe: Ilé iṣẹ́ BBC ń a fi ara ji fun aseyori ise to n lo geere .
Ọ̀tá wí pé,‘N óo lé wọn, ọwọ́ mi yóo sì tẹ̀ wọ́n;n óo pín ìkógun,n óo sì tẹ́ ìfẹ́ ọkàn mi lọ́rùn lára wọn.
Ẹ yin OLUWA, ẹ̀yin ẹ̀dá ọ̀run,ẹ yìn ín lókè ọ̀run.
Nibayii, ohun gbogbo ti pada bọ sipo ti igbokegbodo ọkọ si ti bẹrẹ pada.
Coronavirus in Oyo: Ìjọba ní gbogbo ìpéjọpọ̀ tí kò bá tẹ̀lé òfin ìdènà àrùn ni òun yóò tìpa
Lé wọn kúrò níwájú mi, kí wọ́n máa lọ!
Minisita fun ọrọ Ilẹ Afirika ni Ilẹ Gẹẹsi, Harriet Baldwin lo sọ eyi lasiko ti Olootu Ilẹ Gẹẹsi, Theresa May n se abẹwo si orilẹ-ede Naijiria, gẹgẹ bi ara eto lati se abẹwo si Afirika.
O sọ fun awọn ọlọpaàá pe awọn ti n gbàwẹ̀ nàá fun ọjọ mẹ́rìnlelogoji ki ọmọ wọn to gbẹ́mìí mi.
Oni & ati àwọn ọmọ-kunrin rẹ ni Ìbàdàn ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́, Oṣinọwọ oníṣòwò ọkọ̀ irinna ni Èkó, Mobọ́láji Bank-Anthony, Asábọ́rọ̀, ọmọ Ìkárọ̀ ni ẹ̀gbẹ́ Ọ̀wọ̀ ni ìpínlẹ̀ Ondo àti bẹ́ ẹ̀ bẹ́ ẹ̀ lọ ti wọn ti gbàgbé wọn pẹ̀lú ọrọ̀ ti wọn fi silẹ̀.
Ilé-ẹjọ́ Gíga Dhaka ti fi àṣẹ pe Ọ̀gá Àgbà Ètò Ìlera ti ìjọba.
Àwọn olórí ogun náà bínú sí i gidigidi, wọ́n ní, “Sọ fún un, kí ó pada síbi tí o fún un, kí ó má bá wa lọ sójú ogun, kí ó má baà dojú ìjà kọ wá.
Bakan naa o ṣalaye awọn nkan to gbagbọ ninu rẹ nipa aṣa ati iṣẹṣe Yoruba fun idagbasoke orilẹede pẹlu igbelẹyin imọ ofin.
Àwọn àgbààgbà Juu ń kọ́ ilé náà, wọ́n sì ń ṣe àṣeyọrí pẹlu ìdálọ́kànle tí àsọtẹ́lẹ̀ tí wolii Hagai ati Sakaraya, ọmọ Ido ń fún wọn.
Lọjọ Aiku to kọja niroyin ni o jade laye lẹyin igbiyanju rẹ lati pa iná orí to wa ninu irun rẹ.
Salwa Eid Naser - Elere idaraya to jẹ ọmọ Naijiria ati Bahrain Salwa Eid Naser lo sare julọ nilu Doha, to si jẹ asaaju laarin awọn obinrin to ti n kopa ninu idije ere sisa oni irinwo mita, lati ọgbọn ọdun sẹyin.
Ẹ má ṣe bá a da nǹkankan pọ̀, kí ó lè yí pada.
Bẹẹ, eto ilera orilẹ-ede Adulawọ ko dabi ti awọn orilẹ-ede agbaye to ti goke agba.
A kò fòfin de owó naira tó ti pẹ́ ní Naijiria -CBN Ẹ yé gba owó orí níbi ìdána ìyàwó mọ́, sísọmọbìnrin s'óko ẹrú ni- Daddy Freeze Ọwọ́ ọlọ́pàá ti tẹ ọkùnrin kan tó pa ọ̀rẹ́ rẹ̀ nítorí N40 ní Kano Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, VAT: Kò sí àǹfàní kankan tí ìjọba ti ṣe fún mi sẹ́yìn Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
 bí orò bá ti ń ké ní oru yóò máa bọ ̀ lákọlákọ .
Ní ọdún keje ìjọba Atasasesi, díẹ̀ ninu àwọn ọmọ Israẹli tí wọ́n ti ìgbèkùn dé: àwọn alufaa ati àwọn ọmọ Lefi, àwọn akọrin, àwọn aṣọ́nà ati àwọn iranṣẹ ninu Tẹmpili, 
eniyan : awọn irufẹ bi ọwọ, ifarada, alaafia ati igbọra eniye.
nítorí ó wí pé:“Ṣebí ọba ni gbogbo àwọn olórí ogun mi!
Ogbeni Junnian  ti o je oga agba fun ile-ise  , CRRC Tangshan Co ti orile ede China salaye
Leyin idajo iku iyegi fun-ni ti o waye keyin lorile-ede Botswana, ajo isokan ile-Europe ti o tako idajo iku te atejade kan, eyi ti o bu enu ate lu igbese orile-ede Botswana ohun.
”iyafin Buhari tun wa gbosuba fun
N óo wá sinu ilé rẹ pẹlu ọrẹ ẹbọ sísun;n óo sì san ẹ̀jẹ́ mi fún ọ.
 O ni:“Bi awọn ara ilu ba n sọ pe
O ni Laycon yoo san owo ori lori ẹbun owo to jẹ ati awọn dukia to jẹ bii mọto, ile atawọn dukia miran ṣugbọn ko sohun to kan an pẹlu owo ori lori awọn irinajo afẹ silẹ okeere gbogbo ti wọn yan fun diẹ.
Ko ju eeyan ogun pere to wa ni bẹ gẹgẹ bi a ṣe gbọ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù EndSars, End SWAT, Nigeria protest: Buharii ní àkókò tó táwọn ọ̀dọ́ yóò fòpin sí ìwọ́de náà 13 Ọ̀wàrà 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 18 Ọ̀wàrà 2020 Oríṣun àwòrán, Senatengr Aarẹ Muhammadu Buhari ti n ba awọn aṣiwaju ile igbimọ aṣofin apapọ jiroro nibi ipade kan lori ipo ti Naijiria wa bayii.
Eyi ni ohun mẹwaa to yẹ kẹ ẹ mọ nipa Arabinrin Asofin Mojisola Alli-Macaulay; Oríṣun àwòrán, Mojisola Alli-Macaulay Ọrukọ rẹ ni Mojisola Kehinde Alli-Macaulay AKA Mama Amuwo Abilẹko to si ti bi awọn ọmọ ni Ọmọ ọdun mẹtalelogoji ni arabinrin naa Ọjọ Kẹwaa, Oṣu Kẹwaa, ọdun 1977 ni wọn bi Agbegbe Surulere, ni ipinlẹ Eko ni wọn ti bi O lọ si ile iwe alakọbẹrẹ Festac Primary School V (1984-1990), Subola Nursery And Primary School Festac (1982-1984), Arabinrin Mojisola Alli-Macaulay lọ si ileewe Girama Festac Girls' Secondary School (1990-1993)ati Navy Town Secondary School (1993-1995) Àwọn olóṣèlú Nàìjíríà márùn ùn tó sọ̀rọ̀ tí ará ìlú fà ìbínú yọ Ìrànwọ́ ikú fàwọn tó bá wà lórí àkéte àìsan tó leè já sí ikú ti di òfin tuntun tí wọ́n fẹ́ fọwọ́ sí!
Iwà ni Yorùbá kàsí ni ayé àtijọ́ ju owó ti gbogbo ilú bẹ̀rẹ̀ si bọ ni ayé òde òni.
Àwọn tí ọ̀rọ̀ náà ṣe ojú wọn ròyìn ohun tí ó ṣẹlẹ̀ sí ọkunrin náà ati àwọn ẹlẹ́dẹ̀.
Iroyin tun so pe , bo tile je pe won ri oku awon eniyan kan legbe odo , sibe opolopo awon eniyan lo ti di awati bayii.
Láti Moserotu wọ́n lọ sí Bene Jaakani.
Ó dà wọ́n lọ láìléwu, ẹ̀rù kò bà wọ́n;òkun sì bo àwọn ọ̀tá wọn mọ́lẹ̀.
Bi ere, bi ere awọn eeyan ti Ọlọrun fun ni ẹbun ilu lilu nilẹ Yoruba ti n lọ tan, ko si si awọn eeyan to maa gba ipo wọn.
Sisera bá bẹ̀ ẹ́ pé, “Jọ̀wọ́ òùngbẹ ń gbẹ mí, fún mi lómi mu.
Oríṣun àwòrán, Olubayode Alebiosu Ki ni ọlọpaa sọ?
Obinrin yii jẹ ọmọ orilẹ-ede Taiwan ni eyi ti awọn oniṣegun oyinbo rii pé awọn oyin ti wọn fẹran ilaagun eniyan sọ oju rẹ di ilé.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Majeobaje: Gómìnà, ẹ gbé owó ńlá fún Amotekun kó le dábírà lẹ́ka ètò ààbò 15 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 18 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Oríṣun àwòrán, Others Ẹgbẹ kan to jẹ ti ọmọ bibi ilẹ Yoruba, Majeobaje ti ke sawọn gomina lẹkun iwọ oorun guusu Naijiria lati wa ojutu si ipenija eto aabo.
o to wa je oludari isejoba tiwa-n-tiwa miiran bayii.
Mo tìí bọ'tí pé kí ng máa gbádùn orin lọ ni apá ọ̀tún rẹ̀ bá ṣàdédé bẹ̀rẹ̀ sí í ṣe dákú-dájí.
Mose ṣe gbogbo ohun tí OLUWA pa láṣẹ fún un patapata.
Ìyá ọmọ náà, Mallama Haddaniya Bashir, tó bá BBC Pidgin sọ̀rọ̀ ní , òun kò le gbàgbé ìṣẹ̀lẹ̀ na títí láí.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ijọba ipinlẹ Ondo gbe agadagodo sẹnu ọna awọn ile ijọsin to tapa sofin konileogbele Coronavirus lockdown: Síńimá kòṣewòtán, Pásítọ̀ fo fẹ́ǹsì láti sá mọ́ agbófinró lọ́wọ́ ní Àkúrẹ́ Oniruuru ọbẹ nijọ iku erin.
Oṣu kẹsan an ọdun 2012 ni Moses gba ifẹsẹwọnsẹ akọkọ nigba to de Chelsea Ẹgbẹ agbabọọlu mẹta - Liverpool, Stoke City ati West Ham United - lo ti ya Moses lo lọwọ Chelsea laarin ọdun 2013 si 2016.
Wọ́n bá bèèrè pé, “Ẹ̀yà wo ninu Israẹli ni kò wá siwaju OLUWA ní Misipa?
Alukoro ajọ ọlọpa ipinlẹ Ondo naa sọ siwaju wi pe, awọn yoo gbe Usman rele ẹjọ, nitori pe ohun ni o sokunfa ija naa, ti wọn ko ba ri Fulani darandaran ti o na papa bora.
Àwọn tí ó pàṣẹ péwọn kò gbọdọ̀ dé àwùjọ àwọn eniyan rẹ̀.
O ni: mo ri bi wọn ṣe n yinbọn pa ọpọ eniyan koda, ado oloro ba ọrẹ mi timọtimọ.
“Nítorí èmi ni OLUWA, Ọlọrun rẹ,ẹni tí ó rú òkun sókè,tí ìgbì rẹ̀ fi ń pariwo;OLUWA àwọn ọmọ ogun ni orúkọ mi.
Wọn ko awọn olorin iyin jọ lati gbe ohun iyin soke si Ọlọrun nitori oloogbe aya pasitọ Ituah Igbhodalo.
ṣugbọn ẹ kò gbàgbọ́, nítorí ẹ kò sí ninu àwọn aguntan mi.
n se olu-ilu orile-ede Naijiria  ti bowọ
Ninu atẹjade ti wọn fi lede ni wọn ti fi lede wi pe wọn fẹ fi eyi ṣe atunto ẹka to n risi idagbasoke ọrọ aje ni ipinlẹ naa.
Osere ori itage ni Baba Rainbow naa, ko to di olukọ ni fasiti Eko, UNILAG.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Saudi Arabia: Jí foonu ọkọ rẹ̀ wò, kóo fi ẹ̀wọ̀n jura 3 Ìgbé 2018 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Kí ìyàwó sẹ́bùrú ìròyìn láti ipasẹ̀ ìtàkùn àgbáyé láì gba àsẹ jẹ́ ìwà ọ̀daràn Ẹ̀wọ́n ọdun kan tàbí owó ìtanràn ẹgbẹ̀rún lọ́nà mẹ́tàlẹ́láàádóje dọ́là ni aya tó bá jí foonu ọkọ rẹ̀ wò yóò san ní orílẹ̀èdè Saudi Arabia.
Owó oṣù òṣìṣẹ́ yóò di gbèsè, oúnjẹ yóò wọ́n, ìlú yóò le, bí ọrọ̀ ajé Náíjíríà bá dagun"" Arìnrìn àjò tó bá ṣẹ̀ṣẹ̀ dé gbé, ábẹ́ ààbò ọjọ́ mẹ́rìnlá ni wọn yóò wà torí Covid19 - Uganda Ǹ jẹ́ o mọ̀ pé ìdọ̀tí rẹ le è sọ ẹ́ di olówó?"
Jasoni sì ti gbà wọ́n sílé.
Nigeria Swearing in 2019: Makinde ní omi tuntun rú, ìgbà ọ̀tun dé sí ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́
 wọn a sì máa sín ìlẹ ̀ kẹ ̀ gan-an .
 Minisita soro yii lasiko to n  jabọ awon akitiyan rẹ laarin odun merin ti o ti
Lagos Lockdown: Èrò àwọn èèyàn ṣọ̀tọ̀tọ̀ lẹ̀yìn tí ìjọba kéde pe ó ṣeṣe ki òfin kónílé-ó-gbélé mìí wàyé Oríṣun àwòrán, Sanwo-olu/ Twitter Àkọlé àwòrán, Èrò àwọn èèyàn ṣọ̀tọ̀tọ̀ lẹ̀yìn tí ìjọba kéde pe ó ṣeṣe ki òfin kónílé-ó-gbélé mìí wàyé Awọn olùgbé ìpínlè Eko atawọn ọmọ Naijiria mìí ti bẹrẹ sí ń fi èròngbà wọn léde lẹyin ti ìjọba ìpínlẹ̀ náà ní o ṣeṣe ki òfin kónílé-ó-gbélé bẹrẹ lọtun tawọn èèyàn ba tẹsiwaju kikọ etí ikún sí alakalẹ ìjọba.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 2020: Ọdun 2020 yii ko nìí nira fún àwọn tó bá bẹ̀rù Olorun Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Abiola Ajimobi: Ikọ̀ ìjọba Oyo sọ pé àwọn ẹ̀ṣọ́ ilé Ajimobi ní ọwọ́ aya olóògbé ni kọ́kọ́rọ́ géètì wà
O la adiyẹ naa si meji, wọn si ki ẹnu wọn bọ ara wọn.
Ṣugbọn eléyìí kò lè jẹ́ Mesaya, nítorí a mọ ibi tí ó ti wá.
O ni ọdun keresimesi ti 2020 yoo yatọ si ti awọn to ti n waye sẹyin.
Oríṣun àwòrán, Facebook/Kwankwansiya Àkọlé àwòrán, Lọdun 2015, Kwankwaso dije nibo abele APC sugbọn o fidiremi lọwo Buhari.
O ṣalaye wi pe, ṣe ni wọn fi kóńdó ọlọ́pàá náà lori ati lara.
Lọ́pọ̀ ìgbà ni ìjọba ti kéde pé àwọn yóò ṣi òpópònà ní Osù Kẹ́rin, ọdun 2020 tí yóò bẹ̀rẹ̀ ìṣẹ́.
Nínú gbogbo àwọn ìlú tí ó wà ní Ilẹ̀ Ìjẹ̀ṣà, àdè tàbí ohùn ti Iléṣà àti ti Ijẹ̀bú-Jẹ̀ṣà ló bá ara wọn mu jù lọ.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Yaya Toure,Samuel Etoo ati Riyadh Mahrez O gba ni ọdun 2003-2005 o si tun gba pada ni ọdun 2010.
awon alamojuto eto idibo lati ilẹ okeere ati orile ede yii fun ifowosowopo won,
”Eliṣa dáhùn pé, “Ó dára, ẹ máa lọ.
Láti ọdún 1930 títí dé ọjó òní, awo ńlá ló jẹ́ láàrin wọn.
Ṣobaki tí ó jẹ́ balogun àwọn ọmọ ogun Hadadeseri, ni aṣiwaju wọn.
Nítorí náà ó mú kí ọjọ́ ayé wọn pòórá bí afẹ́fẹ́;wọ́n sì lo ọjọ́ ayé wọn pẹlu ìjayà.
 Iroyin lẹkunrẹrẹ  lori bi ipade naa se n lọ, yoo waye laipẹ.
EFCC fẹ́ gbẹ́sẹ̀ lé ilé tí mo fi owó ìfẹ̀yìntì kọ́ nílùú Ilorin- Saraki Eku gba ìjọba ní Estonia, ìjọba pàdánù owó gọbọi Ilé ìwòsàn New Jersey ṣ'àṣìṣe ṣiṣẹ́ abẹ kìndìrín fún aláìṣàn l'Amẹrika 'Kìí ṣe gbogbo ohun tí dókìtà ni kí n má jẹ torí àìsàn jẹjẹrẹ ni mo tẹ̀lé' Wọn mẹnuba asọtẹle Wooli ṣaaju iku rẹ, bo ṣe bẹrẹ iṣẹ iranṣẹ rẹ lati ilu Eko ati awọn iṣẹlẹ kayeefi to ba irinajo Alagba naa rin.
Ile isẹ ọlọpaa naa wa fi da awọn eniyan loju pe ọrọ naa ki i se igbesunmọni tabi ikọlu, sugbọn aigboraẹniye laaarin awọn akẹẹkọ lo fa wahala.
Ajoji to ba niwe igbelu nikan ni yoo wọ Kenya: Awọn ọmọ orilẹ-ede Kenya nikan, ati awọn ajoji to ba ni iwe igbelu ti ọjọ ko ti i lọ lori rẹ nikan, ni wọn yoo faaye gba lati wọle si Kenya.
Oríṣun àwòrán, Bolasarumialiyu/Instagram Àkọlé àwòrán, Ọmọ Ilẹ̀ Gẹ̀ẹ́sì ni Ìyá rẹ̀ Abẹ ẹgbẹ oṣelu Nationla Interst Party (NIP) ni arabinrain naa ti n dije gẹgẹ bi gomina.
"Nigba to n sọrọ nipa iyawo rẹ, Rambo ni ""Igi lẹyin ọgba ni iyawo mi jẹ fun mi, mo si maa n pada sile lọ sun ti, lẹyin ti mo ba jale tan."
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Oba Abdulrasheed Akanbi sọ ìrẹ́pọ̀ tó wà láàrin Iwo àti Ife Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Oba Abdulrasheed Akanbi sọ ìrẹ́pọ̀ tó wà láàrin Iwo àti Ife 2 Èbibi 2019 Ìran Ọba Iwo kò gbúdọ̀ dé adé àfi tó bá rí ìlú tí Odídẹrẹ́ wà bí bẹ́ẹ̀ kọ́.
Mahassin Quadri ló gbà ìrànwọ $5,000 Tony Elumelu Ìgbà méje ti ọ̀fọ̀ ti ṣẹ̀ lágbo eré bọ́ọ̀lù Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Somalia: 'Wọ́n pàṣẹ fún mi láti dá Ramla dúró ká tò lè ṣe igbeyàwó' Amọ, awọn ẹlomiran dáhùn pe kani bi wọn ṣe n ṣe ayẹwo lojoojumọ fun Atiku ni yii, ko ni ke gbajari si ta wi pe wọn ṣe oun baṣubaṣu ni papakọ ofurufu Abuja.
Alaga ẹgbẹ oṣiṣẹ NLC nipinlẹ Ọṣun, Jacob Adekomi lo sọ eleyi ninu ifọrọwerọ rẹ pẹlu BBC Yoruba.
Asa wó ère náà lulẹ̀, ó gé e wẹ́lẹwẹ̀lẹ, ó sì dáná sun ún ní odò Kidironi.
Amọṣa o ni nigba ti oun wo awọn igbesẹ ti ijsba gbe kalẹ bii pe ki awọn eeyan to ba ju aadọta lọ o maa korajọ pọ si oju kan naa fun ohunkohun, ẹrin fẹ maa pa oun bi o tilẹ jẹ wi pe ajalu ni nnkan to n ṣẹlẹ.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Tí kìí bá ṣe ti Barrister, iṣẹ́ ‘Gateman’ ni ń bá máa ṣe - Ayinla Kollington Buhari gbà wá, àwọn àjèjì ti gbàkóso ilẹ̀ Yorùbá - Ọọ̀ni figbeta Afọnja, ẹni tó finú wénú ní Ilọrin, àmọ́ tó jẹ iwọ Òpin ọ̀ṣẹ̀ dé, ẹ jẹ́ ká jọ fi àwòrán aláyọ̀ ṣararindin Àwọn ìròyìn BBC tó tayọ lọ́sẹ̀ yìí Agbẹnusọ fun ile iṣẹ ọlọpaa ni, ofin Naijiria faye gba ẹyakẹya lati lọ si ipinlẹ miiran, bakan naa lofin faye gba wọn lati ni dukia nibi kibi ti wọn ba wa lorilẹede Naijiria.
Èyí ni bí àwọn agbébọn ṣe gbé òṣìṣẹ́ Shell méjì, wọ́n tún pa àwọ̀n aláàbò wọ̀n ní Rivers
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Wọ́n dóòlà ẹ̀mí èèyàn mẹ́rin níbi ilé mííràn tó wó l'Eko Iléeṣẹ́ asọ́bodè ṣe agbéga fún òṣìṣẹ́ rẹ̀ tó kọ̀ rìbá Owó dé!
Wọn fẹsun kan awọn ara ilu naa pe awọn ni wọn ṣe iku pa ọlọpaa kan ti o gbẹmi mi lasiko ti wọn dana sun ile ijọsin Wolii So titobi rẹ.
Minisita eto ẹkọ, Emeka Nwajiuba lo fi ọrọ naa lede nigba ti igbimọ amuṣẹya ijọba apapọ n jabọ ibi iṣẹ de duro lori ọrọ Covid-19 ni Naijiria.
Aarẹ si ti fi da wọn loju pe, oun yoo dẹkun awọn agbebọn to n dun mọhurumọhuru mọ awọn ọmọ orilẹede Naijiria.
OLUWA, Ọlọrun mi, o ti ṣe ọ̀pọ̀ iṣẹ́ ìyanu fún wa,o sì ti ro ọ̀pọ̀ èrò rere kàn wá.
 Awa ko ni yaju wa sile ,ki talubo ko wọọ , a o tele otito , a o si ri I pe otito bori”.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Coronavirus: Oṣù kan gbáko lèèyàn 16 mílíọ̀nù yóò fi wà lábẹ́ ìséde ni Italy 8 Ẹrẹ̀nà 2020 Oríṣun àwòrán, Reuters Àkọlé àwòrán, Awọn ọlọpaa ati ọmọ ogun tṣetan lati ti ilu Milan pa Minisita feto ilera orileede Italy sọ pe o keere tan eeyan miliọnu mẹrindinlogun lofin konileogbele yoo kan ni agbegbe Lombardy ati awọn ileto mẹrinla miran f'osu kan gbako.
Oríṣun àwòrán, Nigeria Police Àkọlé àwòrán, Àwọn ikọ̀ IRT nínú igbó tí wọ́n ti bá òkú àwọn olólùfẹ́ náà A gbọ́ pé àwọn ọlọ́pàá ri ọkọ̀ Crosstour olóògbé náà, bàtà rẹ̀ àti fónù rẹ̀ gbà lọ́wọ́ àwọn afurasí nàá.
Báwo ni o ṣe le mọ̀ pé o ní àrùn Coronavirus?
Wo àwọn ẹranko tí wọ́n máa figagbaga ni Egypt Ìgbà Marún-un ti Aisha Buhari ti tako ìjọba Buhari 'BBC Yoruba gan gan lara' Oko òkú rèé, níbití òkú ti ń jẹrà mọ́lẹ̀ fún àyẹ̀wò Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí kan sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
A gbọ pe Ọba Olayode da ọjọ fawọn agbẹ lati wa ba se ipade laafin lati dijọ fẹnuko lori iye owo ori ti wọn yoo san.
Awọn ọlọpaa ko kọkọ raye wọle lẹyin ti wọn ti ilẹkun ile ijo onihoho naa.
"Báyìí ni 50 Kobo ṣe dá ìfẹ̀hónú ""Ali Must go"" sílẹ̀ tó mú ọ̀pọ̀ ẹ̀mí akẹ́kọ̀ọ́ lọ Ẹ̀kọ́ ọ̀fẹ́ déé fáwọn ọmọ Ọlọ́pàá tó kú lásìkò EndSARS, Gómìnà Sanwo-Olu kéde Ìjọba Eko kọ orúkọ sí ""Palliatives"" tiwọn lára o, mo ní ẹrù tèmi f'ọjọ́ ìbí mi tí wọ́n jí - Họ́nọ́rébù Agunbiade Àbájáde ìdìbò náà ni wọ́n kéde lọ́jọ́ Eti ti ènìyàn tó dín díẹ̀ ni ẹ̀ẹ́dẹ́gbẹ̀ta sì tún di ìbò ọ̀tọ̀ tó fi mọ́ àwọn míràn tó wà ni ilẹ̀ òkèrè, ṣùgbọ́n yóò tó ọjọ́ kẹfa kí wọ́n tó ṣe ikédé àṣeyọri rẹ̀."
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù UI- Ìwádìí àyẹwò nìkan ló lè sọ ohùn tó pá olùkọ́ tó kù nínú ilé to jo 6 Ìgbé 2019 Oríṣun àwòrán, Tunji Oladejo Àkọlé àwòrán, Ori ibusun ti awọn panapana ti gbe ọgbẹni Othman Zubair lọ si ile iwosan Ile Ẹkọ fasiti ilu Ibadan,ti ọpọ mọ si UI ti fesi si iku arakunrin kan to ku mọ inu filati kan to jona laaye ibugbe awọn oṣiṣẹ agba ile Ẹkọ naa .
Ọrọ orin Davido Risky Ọrọ orin Soapy Naira Marley Woske Lọdọọdun ni ile iṣẹ Google ma n gbe orukọ ati awọn ọrọ tawọn eeyan n bere nipa rẹ julọ loju opo rẹ jade .
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ẹlẹ́wọ̀n: Ọgbà ẹ̀wọ̀n ni mo ti kàwé yege ní ìdánwò Jamb Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Ẹlẹ́wọ̀n: Ọgbà ẹ̀wọ̀n ni mo ti kàwé yege ní ìdánwò Jamb 22 Ìgbé 2018 Ẹlẹ́wọ̀n kan ti ní inú ọgbà ni òun ti s‘orí rere nítori ibẹ̀ ni òun ti kàwé yege ìdánwò Jamb.
"Ni ọjọ ti aarẹ gunlẹ sorilẹede Naijiria lati London to ti lọ gba iwosan, ọjọ naa ni olori ẹka alaabo ilẹ wa, Ọgagun Abayomi Olonisakin n fi ọmọbinrin rẹ lọkọ.
O sọ fun BBC pe''Niṣe o n ṣe mi igba pe Harry Porter ni mi'' Ọgbẹni Hussain to ba wọn ṣe gbogbo pọpọsinṣin ọdun keresi- bi ka ba wọn ṣe apejẹ Keresi ni ọfisi tabi lilọ si ile ọrẹ rẹ laisun Keresi- ko lanfaani ati ṣe iru rẹ ri nitori idile musulumilo ti wa.
Benjamin wi pe, o ti gba iwe lọ gbele ẹ, o si ti n fi oju winaa ibaniwi pẹlu bi iwadi ṣe n lọ lori ọrọ naa."
lo síle ; dínkù agbára mi ti n dúnkù .
Pupọ ninu awọn Gomina ipinlẹ Naijiria ni o n gba owo yi ti awọn ile aṣofin la kalẹ ṣaaju ki wọn to kuro lori oye.
O kẹkọọ jade lọdun 2018, o si lọ sinru ilu gẹgẹ bi Ọba alade akọkọ ti yoo ṣe agunbanirọ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Obìrin kògbérégbè mẹ́ta nínú òṣèré Yorùbá 21 Ọ̀pẹ̀̀ 2018 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 22 Ọ̀pẹ̀̀ 2018 Oríṣun àwòrán, Instagram/Lola_Idije Oríṣìríṣi àwọn òṣeré ló wà nínú àwọn òsèré sinimá àgbéléwó tí wọ́n sì ń kópa ọlọ́kan ò jọ̀ kan níbẹ̀.
Ẹnìkan ní igbagbọ pé kò sí ohun tí òun kò lè jẹ, ṣugbọn ẹni tí igbagbọ rẹ̀ kò tíì fẹsẹ̀ múlẹ̀ rọra ń jẹ ẹ̀fọ́ ní tirẹ̀.
Ko fẹẹ si ipinlẹ kan kan to bọ lọwọ ikọlu awọn Fulani darandaran yii, ti wọn n wa oko tutu fawọn maalu wsn lati jẹ.
O wa fun sisami bi Anabi Ibrahim ṣe pa ẹran agbo dipo Ismail ọmọ rẹ.
Ọkọ kọ̀ mí, mo fẹ́ jẹ májèlé torí mo bímọ tó ní ojú ara takọtabo Àlàyé rèé lóríi ìdí tí wọ́n fi ń pe aya ní ìyàwó Thai king: Ọ̀nà wo ní ẹ̀ṣọ́ ọba gbà di olorì láàfin?
Má ṣe alaigbagbọ mọ́, ṣugbọn gbàgbọ́.
Ní Damasku, baálẹ̀ tí ó wà lábẹ́ Ọba Areta ń ṣọ́ ẹnu odi ìlú láti mú mi.
Ẹ̀yin eniyan, ẹ dákẹ́ jẹ́ẹ́ níwájú OLUWA, nítorí ó ń jáde bọ̀ láti ibi mímọ́ rẹ̀.
Ni ọsan ọjọ Ẹti ni baaluu ilẹ Gẹẹsi ko igba o le aadọrin awọn ọmọ Naijiria kan pada si orilẹede Naijiria.
BBallot box (Apoti idibo) : Eyi ni apoti idibo ti
Ó képe OLUWA, ó ní, “OLUWA, Ọlọrun mi, kí ló dé tí o fi jẹ́ kí irú ìdààmú yìí bá obinrin opó tí mò ń gbé ọ̀dọ̀ rẹ̀ yìí, tí o jẹ́ kí ọmọ rẹ̀ kú?
Akọkọ, odun ni iyalode taa ba n sọrọ eto oselu, kii se aimọ fun oloko awọn oloselu, tori pe o jẹ ọkan gboogi lara awọn to lẹnu lori bi eto oṣelu ṣe n lọ nipinlẹ Ọyọ.
Awọn ọdọ naa, ninu fọnran aworan ti wọn fi sita, eyi to n ja rainrain lori ayelujara, tun salaye pe kii se iyansipo ti aarẹ ile asofin agba se laipẹ yii nikan ni awọn n mẹnuba, amọ awọn n sọ nipa gbogbo eto iyansipo to n waye gan ni labẹ ijọba apapọ.
O óo jèrè iṣẹ́ ọwọ́ rẹ,ayọ̀ ń bẹ fún ọ, yóo sì dára fún ọ.
O ni ati wọọdu leyan ti le darapọ mọ ẹgbẹ, ati pe alaga ẹgbẹ PDP nipinlẹ Edo ko sọ ohun to jẹ bẹẹ f'oun nigba tawọn mejeji jọ sọrọ.
”OLUWA, ọba wọn dáhùn pé,“Kí ló dé tí wọn ń fi ère wọn mú mi bínú,pẹlu àwọn oriṣa ilẹ̀ àjèjì tí wọn ń bọ?
A ti n gbe gbogbo igbese tó yẹ lati fopin si iwa fayawọ epo rọbi -Mele Kyari Ọga agba ajọ elepo rọbi orilẹ-ede Naijiria, (NNPC) Mele Kyari ti kede pe iye agba epo ti wọn n gbe lawọn ibudo ikepo si lorilẹ-ede Naijiria ti dinku lati nnkan bii ọjọ kejilelogun, oṣu kẹjọ ọdun.
 Èyí nipé àrùn yíì gbọ ́ dọ ̀ wáyé lọ ́ dọ ́ ọdún lára àwọn ènìyàn láti wá ní agbegbè .
Bí ẹgbẹ́ One Million Boys ṣe bẹ̀rẹ̀ rèé àti ọṣẹ́ tó ṣe n'Ibadan Afurasí tí Ọlọ́pàá ní ó pa Barakat, Grace àtàwọn míì l'Akinyele ti sọ̀rọ̀ pé.
Ati pe ni kiakia ni awọn lọ si ile naa, ti awọn ati awọn agbebọn naa si jọ doju ija kọ ara wọn, amọ wọn papa ri gbe lọ.
Ibeere loriṣiriṣi ni o dojukọ lori eto tọtẹ yii, bi o tilẹ jẹ wi pe ẹnu yii naa ko jẹ ki Yẹmi o gbadun sibẹ, o jẹwọ ara rẹ pe ẹnu nikan kọ loun ni o, oun mọ nipa aṣa ati iṣe Yoruba daadaa.
 Sise ayeow loorekoore maa n je ki awon onisegun oyinbo tete gbe igbese to ye lasiko fun itoju nipa oogun lilo, ise abe ni sise atawon itoju miran.
Abramu ṣá ń lọ sí ìhà gúsù ní agbègbè tí à ń pè ní Nẹgẹbu.
Buhari yóò tẹ́'wọ́ gba fọ́ọ̀mù rẹ̀ l'Abuja Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Ilé ìwòsàn ṣi abẹ́rẹ́ Formalin gún mí; n kò lè dá ìgbẹ́ àti ìtọ̀ dúró mọ́' Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Tẹniọla: Pè mí láago tí o bá mọ iyán gún pẹ̀lú ọbẹ̀ ilá tó dùn Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Kí ni ẹ̀ ń gbọ́ ọ̀rọ̀ rẹ̀ sí?
Ọ̀kan ninu wọn ni Dionisu, adájọ́ ní kóòtù Òkè Areopagu, ati obinrin kan tí ń jẹ́ Damarisi ati àwọn ẹlòmíràn pẹlu wọn.
Orukọ ẹlẹwa Ṣapọn ni Amudat Janeth Ewusi Ọdẹsọla.
Ṣugbọn kí á tó bí àwọn ọmọ náà, àní sẹ́, kí wọ́n tó dá ohunkohun ṣe, yálà rere ni tabi burúkú, ni Ọlọrun ti sọ fún Rebeka pé, “Èyí ẹ̀gbọ́n ni yóo máa ṣe iranṣẹ àbúrò rẹ̀.
Yatọ si pe ifigagbaga laarin ẹgbẹ agbabọọẹu mejeeji yii a maa larinrin, ohun kan ti yoo tun tayọ ninu ifẹsẹwọnsẹ wọn tọtẹ yii ni awọn akọnimọọgba mejeeji ti yoo maa leawju awọn ikọ mejeeji; Pep Guardiola ati Mikel Arteta.
Awọn oluwọde naa tun mu ibọn AK-47, ati ọta ibọn marundinlọgbọn.
Nigba ti o n fi ọrọ wa wọn lẹnuwo, agbẹjọro fun ọkan lara awọn olujẹjọ naa, Abdul Aminga ke si awọn ọlọpaa naa lati salaye ohun to sokunfa bi awọn idi oogun oloro naa se dinku si ẹẹdẹgbẹsan o le mẹwaa.
Kete ti ọkọ ba ti mọ ojú aya tán ni alarinna a ti yẹba.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù EL-Zakzaky: DSS ti fi El-zakzaky sílẹ̀ láti lọ sí India fún ìwòsàn 12 Ògún 2019 Oríṣun àwòrán, Others Àkọlé àwòrán, Agbẹjọ́rọ̀ fún El-Zakzaky, Femi Falana ní lóòtọ́ ni Àjọ DSS tí fún adarí IMN ní Naijiria náà láàyè láti lọ gba ìwòsàn.
O ni oun ko ni gba ki agbẹjọro ijọba tabi agbẹjkọro Sotitobire da oju ẹjọ ọhun ru nitori pe idajọ odo ni ou n fẹ lori ọrọ na.
Àwọn irúgbìn mìíràn bọ́ sórí ilẹ̀ olókùúta tí kò ní erùpẹ̀ pupọ.
Baraki bá pe àwọn ọmọ Sebuluni ati Nafutali sí Kedeṣi; ẹgbaarun (10,000) ọkunrin ninu wọn ni wọ́n tẹ̀lé Baraki, Debora náà sì bá wọn lọ.
 tosin kàwé gboyè àkọ ́ kọ ́ ní unifásítì ti nottingham nibi tí ó ti kọ ́ nípa ìmọ ̀ bí a ṣe lè pèlò nka .
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Black women live matters: Ọdún 2015 ní àwọn ọlọ́pàá pa India Kager láìní ìdí- Gina Best Oyeyemi sọ pe iwadii ṣi n lọ lọwọ lati mọ otitọ ọrọ naa, ati lati mọ awọn ẹbi ọkunrin naa.
’’Oludari agba ile-ise VON, ogbeni Osita Okechukwu gboriyin fun awon ti o setore gbagede naa, O si tun so pe, ile-ise Von setan lati tun  fowosowopo pelu awon ajo miiran lati le mu awon afojusun re wa si imuse.
(19,028) tayọ akẹgbẹ rẹ lati ẹgbẹ oṣelu PDP, Arabinrin Elizabeth
Oríṣun àwòrán, @ijebu_official Àkọlé àwòrán, Ọkan lara awọn ọdọ lagbo oṣere ni Olatayo Omokade ti gbogbo eniyan mọ si Ijebu.
Igbakeji gomina ipinlẹ Ọyọ naa ni ọga oun, iyẹn gomina ipinlẹ Ọyọ ti tẹkọleti lọ si orilẹede Denmark bayii lati lọ ree gba imọ kun imọ lori eto dida papa ijẹko silẹ ki o lee bu mu ninu omi ọgbọn ati iriri wọn nibẹ.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Lati kekere ni wọn ti maa n fi Ruiz ṣe yẹyẹ nitori bo ṣe sanra.
Ìgbà wo ni a óò kọ́ ẹ̀kọ́, tí a ó fi gbọ́n?
Gbogbo nǹkan wọnyi sì ṣẹ mọ́ Nebukadinesari ọba lára.
fun awọn osisẹ won losoosu .
Èsì ìdìbò tó gbé aàrẹ tuntun wọlẹ́ ní Ghana rèé.
"West to fi ikede naa sita loju opo ayelujara Twitter rẹ lalẹ ọjọ Abamẹta tun sọ pe ""Asiko ti to fun wa lati ranti ileri ilẹ Amẹrika, nipa gbigbẹkẹle Ọlọrun, ka si sowọpọ fun ìran ati kikọ ọjọ ọla wa""."
Fi wúrà ṣe òrùka mẹrin, kí o jó wọn mọ́ ẹsẹ̀ rẹ̀ mẹrẹẹrin; meji lẹ́gbẹ̀ẹ́ kinni, meji lẹ́gbẹ̀ẹ́ keji.
Àkọlé àwòrán, MKO Abiọla, ọ̀pọ̀ eniyan lo n ṣelédè lẹyin rẹ Ikú Abiọla ni ọpọlọpọ gba pe kìí ṣe àmúwá Ọlọrun rara nitori pe wọn ni wọn paá satimọle ni.
Ṣaaju ni Comfort Lamptey to lewaju ikọ naa ti kan saara si ajọ INEC fun ipa takuntakun to n ko ni idagbasoke iṣejọba awara.
Ajo to n mojuto isele pajawiri lorile-ede Naijiria, National Emergency Management Agency (NEMA), ti sabewo si okan lara ile ise ajo ohun ti o wa nipinle Benue, (Benue State Emergency Management Agency) (BSEMA) lati se ipade pajawiri laarin awon toro kan lojuna lati dena ikolu omiyale ti o seese ko waye nipinle Benue.
Saka jẹ ọmọ ẹgbẹ́ agbábọọlu Kwara United, o kú ni ori papa lásìkò ìgbáradi pẹlu àwọn akẹgbẹ́ rẹ ní ilú ìlọrin tii ṣe oluulu ipinlẹ Kwara.
Lasiko yii kan naa lo tun fi sita han faraye pe ipasẹ ifipabanilopọ ni iya fi bi oun.
Mo rí wọn láti òkè gíga,mò ń wò wọ́n láti orí àwọn òkè.
Nítorí náà, OLUWA sọ fún àwọn ará Jerusalẹmu pé,“Ẹ wò ó, n óo gba ẹjọ́ yín rò,n óo sì ba yín gbẹ̀san.
ilu bi ose to ati bo se ye, bee si ni lati pese awon eto won fun won pata-pata.
Koko to wa ninu abọ iwadii igbimọ Orosanye: Ko si ofin kankan to ti idasilẹ aadọta ninu awọn ileeṣẹ lajọ-lajọ kan to jẹ tijọba lẹyin, ó si yẹ ki wọn pa rẹ Ipenija ati iṣoro nla wa ninu sise akoso awọn ileesẹ ijọba, nitori bi wọn ṣe ko awọn ẹka kan ati lajọ-lajọ kuro labẹ wọn, ti isẹ tawọn ẹka naa si n ṣe ti yọ silẹ.
Mo dúpẹ́, Orí ṣe mí lólùkọ́.
Nigba ti wọn ba pari iṣẹ adagun odo nla eyi ti Ethiopia n kọ, ohun ni yoo jẹ ibudo amunawa to tobi ju ni Afirika.
Wo ohun tí Fashola rí níbi ìṣẹ̀lẹ̀ Lekki Tollgate tó ń fa ariwo lórí ayélujara Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Egbò tó ti fẹ́ẹ̀ jiná ni ìtàn bí wọ́n ṣe pa Soun Ogbomoso, Ọba Olayode tẹ ń bèrè' Oríṣun àwòrán, Oluwo Facebook Osemawe ti Ondo Oríṣun àwòrán, Osemawe/Alchetron Osemawe ti ilu Ondo jẹ ọkan lara awọn ọba alaye ni Ilu Ondo, ipinlẹ Ondo.
Báyìí ni a ṣe dé Romu.
Bolatito Ogunsola Bolatito ni iyawo kekere to gbẹyin ninu awọn iyawo Isho Pepper, Aina Orosun si ni ọpọ eeyan mọ si.
Má dá èmi ọmọ-ọ̀dọ̀ rẹ lẹ́jọ́,nítorí pé kò sí ẹ̀dá alààyè tí ẹjọ́ rẹ̀ lè tọ́ níwájú rẹ.
Lootọ ni iroyin jade nipa bi MMM ṣe da iyẹpẹ si gaari awọn eniyan ni awọn orilẹede kan, eyi ko da awọn ọmọ Naijiria duro lati ma ko owo wọn le e lori nitori ireti pe 'ẹyẹ awọn yoo ti fo ki igi o to o da'.
Àkọlé àwòrán, Awọn afẹhonuhan taku sẹnu ọna ile aṣofin ipinlẹ Eko lati ma jẹ́= ki ẹnikẹni wọle tabi jade sita ayafi bi wọn ba gbọ tiwọn.
Shippers Council), Ogbeni Hassan Bello ati awon ti won jo koworin pelu
Eleyi mu ki o jẹ agbabọọlu ti o jẹ goolu julọ fun Naijiria ninu idije naa.
Ayọọla sọọ di mimọ pe lọjọ melo kan sẹyin ni gomina ipinlẹ Ọyọ, Onimọ-ẹrọ Ṣeyi Makinde gba iṣẹ lọwọ ileeṣẹ aladani to n ṣiṣẹ kolẹkodọti tẹlẹri nipinlẹ Ọyọ, ti o si yan adari tuntun fun ileeṣẹ to mojuto imọtoto ilu.
"Ọba Abdulrasheed fi si oju opo instagram rẹ pe ""ki Ọlọrun tunbọ fun aarẹ ni oye lati ṣe aṣeyọri ni gbogbo ọna""."
15 Ọ̀pẹ̀̀ 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 16 Ọ̀pẹ̀̀ 2019 Oríṣun àwòrán, @others Àkọlé àwòrán, Wọn kọ ara wọn silẹ latari awọn ohun kan to ṣelẹ laarin wọn Kabiesi Oluwo ti ilu Iwo, Oba Abdulrosheed Adewale ti kọ olori rẹ Chanel Chin silẹ.
Oloye Raufu Yesufu to jẹ mọ́gàjí ilé Delesolu ti wọn ti n sin ọọni yii ni Ibadan ṣalaye fun BBC Yorùbá pé àwọn baba nla wọn lo bẹrẹ sinsin ọọni naa bi ẹran ọ̀sìn ninu ilé ni 1940.
"Oríṣun àwòrán, Instagram/abiola ajimobi Ọpọ eeyan si lo n ṣe apejuwe oloogbe naa bii ẹni ti ọrọ kii ku mọ lara nigba aye rẹ, Nitori gbogbo ọrọ lo ni esi lọdọ Abiola Ajimobi, to si maa n sọ pe ""ọmọ Ibadan ni mi, mo si mọ esi ọrọ""."
ara èdè sẹ ̀ mítíìkì ni èdè Àrábíìkì ( arabic ( Èdè lárúbááwá ) ) .
Eniyan burúkú ni yóo forí gba ibitíì bá dé bá olódodo.
Wo ohun tó yẹ kí o mọ̀ nípa àwọn obìnrin méje ti Buhari forúkọ wọn ránṣẹ Kò sí ìwé ìrìnnà 'VISA' fáwọn ọmọ Naijiria tó hùwà àìtọ́ nígbà ìdìbò Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Jollof, Iyan, Asaro, Ewa Alagbado kìí wọ́n n'ílé oúnjẹ wá ní Egypt' Wọn gbee lọ sileewosan ni ọjọru bi o tilẹ jẹ pe awọn alaṣẹ ilẹ naa ko sọ idi to fi lọ gba itọju nileewosan.
Èèyàn 38,344 ló ti ní COVID-19 ní Nàìjíríà lẹ́yìn tí 543 kún un lọ́jọ̀rú Kí ló pa Bobrisky àti Olorì Aláàfin Oyo pọ̀?
5 metres ( 34 in ) tí grubb telescope company.
Ọkunrin kan wà ní ìjókòó ní Listira tí ó yarọ.
Wo ìdí tí Osun fi kede ìsinmi fún ọdún ìṣẹ̀ṣe, tàwọn ìpínlẹ̀ yókù kò dáhùn, Ọdún Hijri mùsùlùmí tuntun wọlé dé, ẹ wo kókó pàtàkì nípa rẹ̀ Ṣé o fẹ́ ṣiṣẹ́ ológun?
Eeyan ẹẹdẹgbẹta o le aadọta lo wa fun iṣẹ naa ṣugbọn lẹyin ayẹwo ọpọlọ ati ilera, wọn yọ awọn igba o le ọgbọn kuro ti irinwo le ogun si yege.
Níbo ni n óo ti rí olùtùnú fún ọ?
Ọjọ yii jẹ eyi ti awọn onigbagbọ maa fi n sami iku Jesu Olugbala lori igi agbelebu nibi agbari.
Wọn si fi si atimle ileegbe ni ileewosan awọn ologun ni Cairo.
Awọn iyalọmọ yii yoo wa fi ika hanu pe ko ba dara ki awọn ti loye pe fifun ọmọ lọyan kii kan waye lasan, o ni ilana kan to yẹ ki awọn tọ, ko si dara ki awọn maa se 'eyi jẹ, eyi ko jẹ' nipa fifun ọmọ ni ọyan, bẹẹ si ni bi wọn ba se n fun ọmọ lọyan si, ni oye yii yoo ma ye wọn si, to si lee mu irora lọwọ nigba miran.
Aare orile-ede Naijiria ohun ni ireti wa pe, yoo fowo si iwe adehun ifenuko anfaani idokowo ti ko lowo-ori ninu naa ni ojo kokanlelogun osu keta odun 2018, nibi ipade apero ajo isokan ile-Afrika ti yoo waye nilu Kigali lorile-ede Rwanda.
”Obinrin yìí bá dáhùn pé, “A óo ju orí rẹ̀ sílẹ̀ sí ọ, láti orí odi.
'Óṣeéṣe kí ọ̀rẹ́kùnrin Khadijat fẹ́ fi ṣowó' Ìyá lu ọmọ rẹ̀ pa nítorí 21,000 Naira Agbébọn jí alága káńsù tẹ́lẹ̀ gbé Tá ló pá olùrànlọwọ Segun Oni ?
Ṣugbọn bí o bá sọ ohun tí a wá ṣe fún ẹnikẹ́ni, ẹ̀bi ìlérí tí a fi ìbúra ṣe yìí kò ní sí lórí wa mọ́.
Iléeṣẹ́ aṣọ́bodè yarí, kò gba ìrẹsì tó bàjẹ́ padà lọ́wọ́ Ṣeyi Makinde Ileeṣẹ Aṣọbode fún ẹkùn Oyo ati Osun, tí ibùjókòó rẹ wà n'ilu Ibadan, tí kọ láti gba ẹgbẹsan irẹsi ti wọn lo bajẹ padà lọ́wọ́ ìjọba Ìpínlẹ̀ Oyo.
Amofin Niyi Akintola woye ọrọ naa nigba to nwoye lori bi ile ẹjo kan nilu Abuja se yi idajo pada lori ẹsun ikowoje ti wọn fi kan osise kan nileesẹ to nsakoso owo ifẹyinti awọn ọlọpaa kan, ogbẹni Yakubu Yusuf.
Akíkanjú obìnrin Algeria tó kojú ogun Lárúbáwá fáwọn ènìyàn rẹ̀ Ọlọpa kan yinbọn mọ ọga rẹ nitori obinrin Tani otutu ma n mu ju laarin Ọkunrin ati Obinrin?
Ẹni tí ó bá eniyan wí,yóo rí ojurere níkẹyìn,ju ẹni tí ń pọ́n eniyan lọ.
Ọgbẹni Trump ti sọ fawọn Kristẹni alatilẹyin ninu ọpọ atẹjade Twitter pe bi oun ko ba wọle ninu oṣu kọkanla, ẹtọ ṣiṣe ẹsin ara ẹni ati ofin to de oyun ṣiṣẹ wa lewu.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, New year message: Buhari, Jonathan, Atiku, kí àwọn ọmọ orílẹ̀èdè Nàìjíríà O ni ko si ohun meji ti ẹgbẹ oṣiṣẹ n fẹ bayii ju ki aarẹ fi aba lori ẹkunwo oṣu naa ṣọwọ sawọn aṣofin apapọ fun bibuwọlu ki iṣẹ lee bẹrẹ lori sisan rẹ.
3% to wa laarin aarẹ Donald Trump ati Joe Biden.
Bakan naa ni Ọbasanjọ bu ọwọ lu oludije fun ipo aarẹ labẹ ẹgbẹ oṣelu Peoples Democratic Party, PDP, Atiku Abubakar.
Mercy Eke lo jawe olubori eto naa lọdun to koja, oun ni obinrin akọkọ to jawe olubori ninu eto BBNaija lati gba ti won ti bẹrẹ.
Ifẹhonuhan ti suyọ loni ni ilẹ China to jẹ ayajọ ọjọ ominira ilẹ naa ni eyi ti pupọ ninu awọn ọmọ ilẹ naa ti tu jade lati féhonuhan ti o si jasi wahala.
Ṣugbọn ọpọlọpọ ololufẹ ere bọọlu lo ti n sọ pe owo naa pọ lati na lori agbabọọlu to ti pe ọmọ ọdun mẹtalelọgbọn.
Nítorí wọn óo jèrè iṣẹ́ ọwọ́ wọn.
Ìpínlẹ ̀ Ábíá je ikan ninu awon ipinle 36 ni orile-ede naijiria .
aleefa bayii ni iye ibo  21,960, to fi
OLUWA Ọlọrun bi obinrin náà pé, “Irú kí ni o dánwò yìí?
Nígbà tí Jesu wà ní Bẹtani, ninu ilé Simoni tí ó dẹ́tẹ̀ nígbà kan rí, 
 O menuba ipinnu ijoba re lati mu igbe aye rorun fawon eniyan ile.
Ajọ to n gbogun ti iwa ibajẹ lorilẹede Naijiria, EFCC ti ni awọn yoo ri daju pe Minisita fun epo rọbi, Diezani Allison-Madueke to n jẹjọ iwa jẹgudujẹra yoo pada wale, ki ọdun to pari lati wa jẹjọ rẹ.
 lo mu ki aare Muhammadu Buhari fi ookan kun eeji lati bere awon akanse ise  ni –oju-popo, oju irin, eto ogbin ati ina mona-mona-atunse loju popo ona egberun marun run kilomita to je ti ijoba apapo, pelu ina mona-mona ati ounje lopo janturu.
Oṣu riri ṣe pataki nitori ohun ni yoo ṣe atọna igba ti awẹ yoo bẹrẹ ati igba ti yoo pari.
alatako Chadema , o si tun je okan gboogi ninu awon  to n tako isejoba aare  John Magufulilori lori ero ayelujara.
Ó ní bí wọn ò bá sọ́ra, ìkọlùkọgbà ńrúgbó bọ̀ pàápàá pẹ̀lú ọ̀pọ̀lọpọ̀ ọ̀dọ́ tí kò nísẹ́ lọ́wọ́ tí ètò ẹ̀kọ́, ìlera, àti àmúlò ohun àlùmọ́nì kò sì sí lárọ́wọ́tó wọn.
Ṣugbọn ọ̀kan ninu àwọn tí ó dúró fa idà yọ, ó fi ṣá ẹrú Olórí Alufaa, ó bá gé e létí.
Sani ni ti Ile Igbimọ Asofin to wa ni aleefa bayii ba gba lati jẹ ki Aarẹ Buhari ya owo naa, owo ti Naijiria je yoo aadọta biliọnu dọla owo ilẹ okeere, eleyii ti yoo fa ipalara fun idagbasoke orilẹ-ede Naijria.
Awọn mẹtẹẹta naa ni Bisọọbu David Oyedepo, ti see alakoso agba fun ijọ Winners pẹlu gbajugbaja onwoye awujọ kan, Ifedayo Olarinde ti ọpọ eeyan mọ si Daddy Freeze.
OLUWA ni olùṣọ́ àwọn àlejò,òun ni alátìlẹ́yìn àwọn opó ati aláìníbaba,ṣugbọn a máa da ète àwọn eniyan burúkú rú.
ẹ tà á, kí ẹ sì gba owó rẹ̀ sọ́wọ́, kí ẹ kó owó náà lọ sí ibi tí OLUWA Ọlọrun yín bá yàn pé kí ẹ ti máa sin òun.
Ohùn kan ti inú ìkùukùu náà wá, ó ní “Èyí ni àyànfẹ́ ọmọ mi, ẹ máa gbọ́ tirẹ̀!
Bakan naa ni wọn tun ni ki ẹni to jẹ alaga ẹgbẹ awọn alaga kansu (ALGON) tẹlẹ, Ọgbẹni Dapọ Ọlagunju, kọmiṣọna tẹlẹ fun ọrọ ijọba ibilẹ, Ọgbẹni Kọla Kọlade pẹlu gbogbo awọn alaga kansu mẹrẹẹrindinlogun tẹlẹ ni ipinlẹ naa o yọju ni wara-n-ṣeṣa niwaju ile naa.
Aare orile-ede America, Donald Trump, ti kede pe orile-ede Egypt loun a koko sabewo si nile Adulawo.
Ní tèmi, èmi ó máa ní ìrètí nígbà gbogbo,n óo sì túbọ̀ máa yìn ọ́.
Wo ọ̀nà àbáyọ sí bo ṣe ń han‘run Ọ̀làjú sọ àṣà nù, wò ó báwọn obìnrin ṣe ń wà ọkọ kiri lórí ayélujára Nínú akànṣẹ́ mẹ́ta ọmọ Nàìjíríà tó dáńtọ́ lágbàáyé, Yorùbá méjì wà nínu wọn Gomina Zulum lo n bọ lati ilu Baga to ti lo ṣe ayẹwo agbegbe naa, ti ogun Boko Haram ti jẹ ki ọpọlọpọ eniyan kuro nibẹ, tijọba ipinlẹ naa si woye pe, asiko ti to fun awọn eniyan lati pada sibẹ.
Oṣiṣẹ ajọ UNICEF Awọn agbebọn Boko Haram ji Saifura Hussaini Ahmed Khorsa, ọmọ ọdun marundinlọgbọn gbe wọn si paa ni ọjọ kẹtadinlogun oṣu kẹsan ọdun 2018.
Ẹgbẹ oselu PDP wa ke si awọn ileesẹ alaabo lorilẹede Naijiria lati dide ji giiri si ojuse wọnki awọn akẹkọ naa lee di riri.
Mo sì tún máa ń tẹle mama mi lọ sí ọdọ mama wọn ní Mọsalasi Jimoh.
Ohun tí yóo kù ninu àwọn igi igbó rẹ̀kò ní ju ohun tí ọmọde lè kà, kí ó sì kọ sílẹ̀ lọ.
Agiripa bá dìde pẹlu gomina ati Berenike ati gbogbo àwọn tí ó jókòó pẹlu wọn.
Laarọ ọjọ Ẹti ni Linda fọrọ naa lede loju opo Instagram ati opo ayelujara tirẹ gan an, Lindaikejisblog.
Awọn ololufẹ meji ti iru rẹ ti ṣẹlẹ si sọ wi pe o yẹ ki awọn ẹya Igbo yii mọ wi pe bi a ṣe bi ẹru la bi ọmọ, Olorun ko si fẹran ẹnikan ju omiran lọ, amọ aimoye ati igbagbọ ninu iṣẹṣe lo n mu ki awọn ẹbi ma a ṣe bi wọn ti n ṣe.
Wọ́n dáhùn pé, “Rárá, a kò mọ̀ ọ́n, sọ fún wa.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Canada: Kò sí ẹ̀sẹ̀ nínú igbó mímu àti títà, ẹ tẹ́síwájú 17 Ọ̀wàrà 2018 Oríṣun àwòrán, AFP Contributor Igbó mímu àti títà ti di gbẹ̀fẹ́ l'orilẹede Canada bayii lai bẹ̀rù agbofinro.
A gbé mi ga láàrin àwọn orílẹ̀-èdè,a gbé mi ga ní ayé.
Inu awon to n wa gusa ko dun bi isele naa se n sele lera-lera.
N óo wá kó wọn pada wá sí ibí yìí nígbà náà.
Gbogbo ọrọ to si n sọ l'ọjọ naa lo dun mọ mi ninu.
Oríṣun àwòrán, CBN Gov Akinsola Àkọlé àwòrán, Tinubu ni Next level kìi ṣe ọrọ akọmọna ipolongo idibo lasan, ilana ìdagbasoke ti ijọba APC gbọdọ mulo ni Ninu ọrọ to fi ran igbakeji rẹ si ibi apero naa, Aarẹ Muhammadu Buhari ni oun ko ni kọ ipakọ si ileri oun lati gbe awọn ọmọ orilẹede Naijiria de ipo ati aaye ti o yẹ wọn.
O ni eyi ribẹ nitori pe awọn eeyan kan ti wọn fi ipa ba ọmọ tabi ibatan wọn lopọ ma n lọ si agọ ọlọpaa pe awọn ko ṣe ẹjọ mọ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Brexit: Àpẹẹrẹ́ burúkú ni ìjọba gẹ̀ẹ́sì ń fi lílẹ̀ -Ọ̀jọ̀gbọ́n Wole Soyinka 3 Owewe 2019 Oríṣun àwòrán, @soyinka Àkọlé àwòrán, Brexit: Àpẹẹrẹ́ burúkú ni ìjọba gẹ̀ẹ́sì ń fi lílẹ̀ -Ọ̀jọ̀gbọ́n Wole Soyinka Ọ̀jọ̀gbọ́n Wole Soyinka tí ke pé àgbárijọ àwọn orilẹ̀-èdè tí o gba ominira lọ́wọ́ ìjọba gẹ̀ẹ́sì láti gbe ìjgbìmọ ti yóò lọ si ilẹ̀ gẹ̀ẹ́si láti lọ ṣe ìwádìí lóri àṣẹ̀ ti aṣòjú ìjọba ilẹ̀ gẹ̀ẹ́si Boris Johnson pa lọ́sẹ̀ to kọjá láti dá àwọn ilé ìgbìmọ asọfin duró lẹ́yìn iṣẹ́ wọ́n.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Abẹnugan ilé aṣòfin ìpínlẹ̀ Ọyọ jáde láyé PDP lè má kópa nínú ìdìbò oṣù keje ní Imo 'Kọ́ ọgbà fún ẹran ọ̀sìn rẹ' Iniesta: Mò ṣetán láti fi Barcelona sílẹ̀ Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
8 104002 Orilẹede Panama 3193 76.
O Fagunwa, Adebayo Faleti, Akinwumi Iṣọla, Lawuyi Ogunniran àti Oladejo Okediji ṣiṣẹ silẹ ki wọn to lọ
Bakan naa ni iwadii awọn iyansipo lawọn ajọ ati ileeṣẹ ijọba bii EFCC, ICPC, igbakeji banki apapọ orilẹ-ede Naijiria atawọn ipo miran ko ni i ṣeeṣe.
Ọ̀nà wo wá ni àwọn Juu fi sàn ju àwọn orílẹ̀-èdè yòókù lọ?
Oluwo lo sọ ọrọ naa ninu atẹjade kan tó fi ṣọwọ́ sí BBC Yoruba.
Wo àwọn ìbejì tó mú ẹ̀dọ̀ àti egungun àyà kan ṣoṣo wá látọ̀run Èèyàn mẹ́tàlélógóje míì ṣẹ̀ṣẹ̀ kó COVID-19 ní Nàìjíríà Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Oyenusi ló mú mi wọ ẹgbẹ́ adigunjalè kó tó di pé mo b'Ólúwa pàdé' Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Fídíò, Akomolede: Bolaji Faleke ni Olùkọ́ tó ń kọ́ wa ní àṣà oge ṣiṣe lórí BBC Yorùbá1 Owewe 2020 Fídíò, Yoruba Language: Akomolede ati Asa Yoruba tọ̀sẹ̀ yí rèé lẹ́nu olùkọ́ wa30 Ògún 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Ó bá ń bá ọ̀nà rẹ̀ lọ pẹlu ayọ̀.
Jahaj Bari wà nínú àwọn ilé àkọ́pọ̀ Waqf (mortmain) tí kò ṣe é tà.
Yóo máa ṣe ìtọ́jú ibi mímọ́ ati gbogbo ohun tí ó wà ninu rẹ̀ ati àwọn ohun èlò ibẹ̀.
Iwe adehun yii yanana ọrọ igbega lẹnu iṣẹ, owo oṣu ati dida owo oṣu ti wọn yọ pada.
Ìgbà tí a simi díẹ̀ lẹ́hìn óunjẹ, a bẹ̀rẹ̀ iṣẹ́ wa.
Òmùgọ́diméjì gorí oyé Ṣọ̀pọ̀nná gbé òmùgọ́dimejì lọ
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Fayemi: Gbèsè tí mo bá nílẹ̀ ni kò jẹ́ kí n ti yan kọmíṣọ́nà 18 Ọ̀pẹ̀̀ 2018 Oríṣun àwòrán, Fayemi /twitter Àkọlé àwòrán, Ijọba ipinlẹ Ekiti f'ofin de Fayemi fun ọdun mẹwaa losu to koja Gomina ipinlẹ Ekiti, Kayọde Fayẹmi sọ pe ko si owo lati yan kọmiṣọna kankan fun ipinlẹ naa.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Adesoji Aderemi: Ọba Yorùbá tó tiraka láti dí àlàfo láàrin olówó àti olòṣì 5 Òkùdu 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 3 Agẹmo 2020 Oríṣun àwòrán, Adesoji Aderemi Family Àkọlé àwòrán, Adesoji Aderemi: Ọba Yorùbá tó tiraka láti dí àlàfo láàrin olówó àti olòṣì Ti a ba n sọrọ awọn oriade nilẹ Yoruba, ọkan pataki ni Ọba Ọlọla Titus Martins Adesọji Tadeniawo Aderẹmi, Atọbatẹlẹ Kinni, tii se Ọọni tilu Ile Ifẹ.
Ní ọdún mélòókan sẹ́hìn, ẹni bá fẹ́ràn àwọn ẹ̀rọ ìgbàlódé, nṣe ni ó ń kó wọn ká lóríṣìíríṣìí ni.
Afẹ́fẹ́ yóo gbá wọn lọ, ojú ìsìn ìbọ̀rìṣà wọn yóo sì tì wọ́n.
Daniẹli dáhùn pé, “Kabiyesi, kí ọba pẹ́, 
OLUWA Ṣèlérí láti Gba Àwọn Eniyan Rẹ̀ Là.
Oludari ajọ naa, Osai Ojigho sọ pe awọn fi ikilọ naa sita, nitori pe awọn iṣẹlẹ to n waye bayii fihan pe ijọba fẹ ẹ bo aṣiri iṣẹlẹ naa, gẹgẹ bi iṣe rẹ ni gbogbo igba ti ileeṣẹ ologun ba paayan lọna ti ko ba ofin mu ni Naijiria.
Lẹ́yìn náà, Balaki, ọmọ Sipori, ọba Moabu, dìde láti bá Israẹli jagun, ó ranṣẹ sí Balaamu, ọmọ Beori, láti wá fi yín gégùn-ún.
"Koda, ""ọjọ to wa mi wa sile, ti a si jọ n lọ loju ọna lo to o mọ nitori bi ọpọ eeyan ṣe n wo mi, ti wọn si n naka si mi""."
12/08/2018 (Ifọrọwerọ pẹlu Iwe Iroyin This Day newspaper) Agbeyẹwo Ọrọ Ni ọdun 2018, ijọba apapọ fi owo to to 650bn naira si ẹka eto ẹko, ti ida meji lọna mẹta (407.
O ń gba €126m (£108m) ni owó ọ̀yà rẹ̀ báyìí ní èyí tó ti ju €94m tí Cristiano Ronaldo ń gbà lọ.
Oríṣun àwòrán, @others Àkọlé àwòrán, O sọ fun awọn eniyan South Africa pé ijọba oun a pese aabo to peye fun ileeṣẹ wọn ati awọn okowo wọn.
Oríṣun àwòrán, Google Àkọlé àwòrán, Kí láwọn ohùn àmúyẹ tí kọmẹńtátọ̀ tó dáńtọ́ gbọ́dọ̀ ní Awọn to mọ ọ nigba aye rẹ kan sara sii ti wọn si fun un ni orisirisi inagije to jọ mọ bi o ti ṣe maa n hun ọrọ lalai dena pẹnu.
Igbe àwọn òṣìṣẹ́ tí wọ́n ba yín kórè oko yín sì ti dé etí Oluwa Ọlọrun Olodumare.
Ole nikan kọ ni wọn ja, wọn tun ṣekupa awọn araalu atawọn ọlọpaa.
Ọdun meji ni ajọ WAEC yoo fi fi ofin de wọn, gẹgẹ bi ibawi fun ṣíṣe mago-mago lasiko idanwo.
Gẹgẹ bi Akọwe iroyin ati ikede fun Gomina Sanwo-Olu, Gboyega Akosile ṣe sọ, Gomina ipinlẹ Ondo, to tun jẹ olori awọn gomina nilẹ Yoruba, Rotimi Akeredolu ṣapejuwe iṣẹlẹ to waye nipinlẹ Eko, gẹgẹ bi ibudo ogun.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ooni Ile Ife: Àwọn ohun tó yẹ kí o mọ̀ nípa Ọ̀ọ̀ni Ilẹ̀ ifẹ̀ to pe Ọdún mẹ́ta lórí ìtẹ́ Òdùduwà 7 Ọ̀pẹ̀̀ 2018 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 8 Ọ̀pẹ̀̀ 2018 Oríṣun àwòrán, Ooni ile ife Àkọlé àwòrán, gomina ipin#sun nigba naa, Rauf Arẹgbẹṣọla gbe ọpa aṣẹ funi tuntun nibi ayẹyẹ nla to waye ni gbagede Ẹnuwa ni aafin Oodua ni ilu ile Ifẹ Ṣaaju ọjọ kejidinlogun oṣu keje ọdun 2015, ko si ẹni to leero pe Adeyẹye Ogunwusi lee gun ori itẹ Oodua gẹgẹ bii Ọọni ile ifẹ nitori bi ọba kan ko ba ku, omiran kii jẹ.
Ìbejì Oníbẹ̀mbẹ́ Òru tí kò yara wọn lẹ́yìn ọgọ́ta ọdún Ohùn ìjálá lásán ni mo fi ń pa ẹran nínú igbó - Ọdẹ Oníjàálá Mo fẹ́ ọkọ mi torí bó se ń kọrin, kìí se torí owó - Ìyàwó Aràrá Mo fẹ́ kí àyẹyẹ ìgbeyàwó mi dùn ni mo se bú sẹ́kún - Ọkọ ìyàwó ẹlẹ́kún Awọn Iyalode to ti jẹ ni ilẹ Ibadan Iyalode Subola, 1850-1867 Iyalode Efunsetan Aniwura, 1867-1874 Iyalode Iyaola, 1874-1893 Iyalode Lanlatu Asabi Giwa, 1894-1913 Iyalode Isale Osun, 1914-1917 Iyalode Ronilatu Ajisomo, 1917-1934 Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Abayọmi Aranmọlatẹ, Dr Laser: Vagino Plasty àti iṣẹ́ abẹ ẹwà Obìnrin ló jẹ mí lógún Iyalode Rukayat Awosa Akande, 1935-1948 Iyalode Abimbola, 1948-1961 Iyalode Adebisi Abeo, 1961-1974 Iyalode Wuraola Esan, 1975-1985 Iyalode Hunmani Alade, 1985-1995 Iyalode Aminatu Abiodun, 1995-2018 Iyalode Theresa Oyekanmi to wa lori oye lọwọ-lọwọ.
Gbajabiamila wa tẹsiwaju pe ’’ Ile igbimo asoju jẹ  ile kan, ile-isẹ kan, nitori naa inu mi bajẹ
Ahieseri ọmọ Amiṣadai ni olórí wọn.
Ẹ̀gbọ́n Ilẹ́sanmí ni Àdùnní ìyá Dúró Orímóògùnjẹ́.
Yàtọ̀ sí Ọkada tí í ṣe kẹ̀kẹ́ akérò alùpùpù ní Naija, kẹ̀kẹ́ Marwa – kẹ̀kẹ́ ẹlẹ́sẹ̀ mẹ́ta ní í ṣe.
Muhammed Buhari ti ki aare Macky Sall ku ori ire lati jawe olubori gege bi aare
Eyi jade ninu atẹjade to sọ nipa iyansipo naa ti Ọgagun agbnusọ ile iṣẹ ologun, Sagir Musa fọwọ si pe yoo gba eku ida lọwọ Ọgagun S.
Bi awọn ipinlẹ to ni Coronavirus ṣe lọ ni yii: Eko-106 FCT-54 Rivers-48 Plateau-40 Edo-29 Enugu-21 Oyo-20 Kano-18 Ondo-15 Ogun-10 Ebonyi-9 Ekiti-8 Kaduna-6 Cross River-5 Kwara-4 Anambra-3 Delta-3 Imo-2 Nasarawa-2 Borno-1 Èèyàn 624 míràn tún kó COVID-19 ní Nàìjíríà l'Ọ́jọ́ Iṣẹ́gun Eeyan 624 ni wọn kede pe ayẹwo tun fihan pe o laarun COVID-19 lorilẹede Naijiria bayii.
Chelsea niṣẹ to pọ lati ṣe lalẹ lalẹ Ọjọbọ nigba ti wọn ba koju Liverpool ninu idije UEFA Super Cup.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Lẹ́yìn oṣù márùn ún, Buhari kọ̀ láti yọ ọga NHIS bí ìgbìmọ̀ ṣe sọ 16 Ìgbé 2019 Oríṣun àwòrán, NHIS Nigeria Àkọlé àwòrán, Inu awọn oṣiṣẹ NHIS ko dun si bi ọga agba ajọ naa ko ṣe tẹle aṣẹ lọ rọọ kun nile ti wọn fun un Lẹ́yin oṣu karun un ti igbimọ kan ti ijọba apapọ gbe dide lati wadii ẹsun aṣemaṣe ati jẹgudujẹra ti wọn fi kan ọga ajọ NHIS Usman Yusuf Usman Yusuf, Aarẹ Muhammadu Buhari ko ti i gbe igbesẹ lori abajade iwadii igbimọ naa.
Nylon ati rọba ki n kere ju bi o ba se wa nigba ti wọn se e fun ẹgbẹẹgbẹrun ọdun, eleyii ti o le ko aisan mọra lẹyin ọpọ ọdun loju kan naa.
Oríṣun àwòrán, @sgyemikale Àkọlé àwòrán, Ìpínlè Èkìtì wà lára àwọn ìpínlẹ̀ tí o n gba owó tó kéré jù láti ọdọ ìjọba àpapọ̀ ''Nnkán rọrùn díẹ fún àwa ti a n ṣé iṣẹ àgbẹ diẹdiẹ ṣugbọn fún àwọn tí kò ní ọnà míràn ìnira nlá ní àìrí owó oṣù gbà je'' Ìwádìí ilé iṣé BBC ṣé àfihàn pé oṣù kẹwa ọdún tó kọjá ní Gómìnà Fayoṣe san owó oṣù oṣiṣẹ ijoba ibile àti àwọn olùkọ kẹyìn.
JAMB Result 2019: 34,120 akẹ́ẹ̀kọ́ ni kò ní èsì ìdańwò JAMB
Siwaju si, wọn ni ki awọn agbalagba lọ wa bi joko si ki awọn ọdọ le raye sejọba.
Ọlọ́run tóbi lỌba, ojú bàbá mi rí nǹkan, Oówó-ayé pọ̀ lọ́kùnrin.
Lọjọ ru ni EFCC kede pe awọn ri owo naa ninu ibi ifowopamọ si ninu ọọfiisi ọga agba to n ṣamojuto inawo ajọ INEC ni Zamfara ni apa ariwa Naijiria.
Ó da òrùka mẹrin, ó jó ọ̀kọ̀ọ̀kan mọ́ igun kọ̀ọ̀kan ayanran idẹ náà, àwọn òrùka wọnyi ni wọ́n máa ń ti ọ̀pá bọ̀ láti fi gbé pẹpẹ náà.
Àkọlé àwòrán, Oriṣiriṣi ọna ni eto igbani wọle maa n gba ninu awọn ẹgbẹ okunkun Ọpọ eeyan niroyin naa lo ku iku aimọdi lati ipasẹ wahala naa ni gareeji Epe, Road, Adefisan, Gareeji Ibadan, Onirugba, Tatina ati oju ọna Benin si Ondo.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Àwọn kan fẹ́ da Naijiria rú torí ààbò tó mẹ́hẹ - Osinbajo gbarata Abúlé tí wọn kìí ti sọ ọmọ ní orúkọ, ohùn arò ni wọ́n fi ń pè wọ́n Ọ̀rọ̀ ti ń gba ibòmíràn yọ lórí ẹ̀ṣùn ìfipábánilòpọ̀ - Timi Dakolo Pariwo Barrister ló sọ mí di èèyàn ńlá - Ayinla Kollington Armstrong, lasiko to n rin lori ofurufu naa sọ wi pe ‘igbesẹ akọkọ niyii fun eniyan, ipa pataki fun ara aye’.
Oga agba ajo FAO José Graziano da Silva so pe, “eka eto ogbin lara eyi ti a ti ri eto ohun osin osin eja, awon osin inu-omi n koju ewu lopo-lopo bi: ayipada oju ojo, kokoro ajeniru, aarun, oorun mimu ati awon isele miiran, ni o n sakoba fun awon agbe wonyii”.
O Fagunwa, Adebayo Faleti, Akinwumi Iṣọla, Lawuyi Ogunniran àti Oladejo Okediji ṣiṣẹ silẹ ki wọn to lọ3 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí 2 sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
Awon miran tun ni gomina ti
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Wọ́n fi agídí sé ọmọ Naijiria mọ́lé ní China nítorí àrùn Coronavirus Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Wọ́n fi agídí sé ọmọ Naijiria mọ́lé ní China nítorí àrùn Coronavirus 16 Ìgbé 2020 Ọmọ Naijiria kan to wa ni orilẹ-ede China sọ ohun toju rẹ n ri nilẹ ọhun nitori arun Coronavirus.
Awon egbe meji ọtọtọ ti won n dije fun ipo gomina ninu  egbe All Progressives Congress (APC) ati oludije
Lati mu aridaju wa fun yin la fi ṣe ifọrọwanilẹnuwo yii pẹlu baba ibẹta gan funra rẹ to si ṣalaye gbogbo ọrọ.
Bo tilẹ jẹ pe ijọba Amẹrika ko ti sọ ni pato ohun ti yoo wa ninu iwe aṣẹ naa, ṣugbọn o ṣoro lati sọ igbesẹ ti aarẹ Trump lee gbe lori ọrọ to ni ṣe pẹlu oju opo ikansiraẹni lai ṣe pe ile igbimọ aṣọfin ilẹ naa fọwọ si.
Nibi ti ayẹyẹ ti n waye ni wọn yoo ti se iṣu, ti wọn yoo si fi ẹrọ lọ ọ.
" Ẹ̀mí márùń bá ìjà àwọn jàǹdùkú lọ ní Ìjẹ̀bu Ìkọlù Ọ̀ffà pa èèyàn mẹ́tàdínlógún — Ọlọ́pàá A gbọ́ wípé àwọn ará ilé olóògbẹ́ náà funra pé ìkan kò ṣe déédé pẹ̀lú rẹ̀ l'Ọjọ́rú, ṣùgbọ́n ó fi yé wọn wípé kò sí wàhálà rárá.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Seyi Makinde: PMS kò ní ohun ṣe pẹ̀lú NURTW, ìṣẹ́ rẹ̀ ni láti pawó wọlé fún ìjọba 11 Ọ̀pẹ̀̀ 2020, 07:19 WAT Oríṣun àwòrán, Facebook/ The Park management Oyo state Gomina ipinlẹ Oyo, Seyi Makinde ti sọ pe ọna lati dena wahala ni ẹka igboke-gbodo ọkọ, lo mu ki oun ṣe ayipada ẹgbẹ NURTW.
Bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé o mọ̀ pé n kò lẹ́bi,ati pé kò sí ẹnikẹ́nití ó lè gbà mí lọ́wọ́ rẹ.
Ni kete ti idajọ naa hande ni awọn ọtọkulu ti n fi sita lori ẹrọ ayelujara.
Ṣé ẹ kò tíì bèèrè ọ̀nà lọ́wọ́ àwọn arìnrìnàjò?
Bakan naa lo ni Daura bawọn peju sibi eto isinku agbẹnusọ tẹlẹ fun aarẹ Buhari to jade laye, Wada Maida lọjs Isẹgun.
 O tun sọ ninu ifọrọwanilẹnu kan lọdun 2017 pe, lasiko ijiroro pẹlu Ọlọrun ni oun tun ka iwe Ẹ́ksódù ninu Bibeli, nibi ti Ọlọrun ti farahan Mose, to si sọ fun un pe ko dari awọn ọmọ Ísrẹ́lì jade kuro ni Egypti."
O ni eyi ku diẹ kaa to ninu iwa awọn adari orilẹ-ede South Africa lori iṣẹlẹ yii.
Ijoba apapo orile ede Naijiria ti pase fun awon eso alaabo  lorile ede yii lati tubo je ki eeto aabo tubo fese mule si i ni awon agbegbe Mubi ati Adamawa.
Aarẹ wa gbadura pe ki Ọlọrun tẹ adajọ naa si afẹfẹ rere, ki o si tu awọn  ẹbi rẹ ninu.
O fi fidio nipa ariya naa sita lọjọ Satide.
Agbenusọ fun ìpín Kẹfa ileesẹ ologun to wa nilu Port Harcourt, Ọgagun Charles Ekeocha, sọ fun ileesẹ Radio Nigeria pe lootọ ni oun mọ pe awọn ni àkànṣe isẹ ni Oyigbo, sugbọn irọ ni pe awọn kọlu awọn eeyan.
to wa ni ipinle naa, ni eyi ti awon gbofinro ati asoju egbe kọọkan si tẹle wọn.
Àkọlé àwòrán, Awọn ẹgbẹ okunkun fasiti Naijiria: Buccaneers,Black Axe ati awọn ẹgbẹ ijaiya mìíràn Ẹsun ipaniyan, igbimọ pọ, ṣíṣe ẹgbẹ okunkun, ati níní nkan ija lai gba iwe àṣẹ, ni wọn fi kan Kingsley.
O ni lati agogo kan oru lọjọ kejidinlọgbọn oṣu kejila, gbogbo arinrinajo to ba n bọ lati orilede mejeeji gbud ṣafihan iwe aṣẹ irina meji ati esi ayẹwo ilera pe wọn ko tii lugbadi arun naa.
Mismari fi kun-un pe, “oko oju-omi naa n lo si odo Muslim Brotherhood ati al-Qaida, kii se Misurata”.
Ẹni tí ó bá ń ṣe ìtọrẹ àánú, kí ó ṣe é pẹlu ọkàn kan.
"Mercy Aigbe ti oun funra rẹ naa kopa ninu fiimu to si tun jẹ igbakeji adari ere ni awoṣifila ni sinima naa to pe akọle rẹ ni ""Kini Igbeyawo"" yoo jẹ."
Àwọn ọmọ Nàíjíríà kan fàbínú yọ lórí ọ̀rọ̀ Buhari Awọn ọmọ orilẹede yii, ninu eyi ti a ti ri awọn oloselu, ajafẹtọ ẹni, awọn agbẹjọrọ, agbarijọpọ ẹgbẹ oselu ati awọn eekan ilu kan ti foju laifi wo ọrọ to jade lẹnu aarẹ Mohammadu Buhari lasiko ipade ẹgbẹ APC lọjọ Aje.
Fifa sọ wí pé níbi ìpàdé gbogboògbò tí àwọn yóò se ní Moscow, lorílẹ̀ède Russia ni àwọn yóò ti se ìpolongo náà lọ́jọ́ kẹtàlá, Osù Kẹfà, ọdún yìí.
Ẹ máa ṣọ́nà, kí ẹ máa gbadura nígbà gbogbo pé, kí ẹ lè lágbára láti borí gbogbo àwọn ohun tí ó ń bọ̀ wá ṣẹlẹ̀, kí ẹ sì lè dúró níwájú Ọmọ-Eniyan.
Ikọ wiwu naa le ma le lakọkọ, amọ to baya, wọn yoo ba wukọ ti yoo ma tu nkan jade.
Also a huuuuge thank you and love to my family ♥️, my Personal Team for supporting me all my career during all the ups and downs no matter what.
Oríṣun àwòrán, lizzy anjorin/instagram sceenshot Awọn agba ni ibi taa ti n ṣe la ti njẹ.
N óo mú kí odò Naili gbẹ, n óo ta ilẹ̀ náà fún àwọn eniyan burúkú; n óo sì jẹ́ kí àwọn àjèjì sọ ilẹ̀ náà ati gbogbo ohun tí ó wà ninu rẹ̀ di ahoro.
Ẹni tí ó yẹ kí ẹ bẹ̀rù ni Ọlọrun tí ó lè pa ẹ̀mí ati ara run ní ọ̀run àpáàdì.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Ẹsun Obinrin mẹjọ lo jade sita lọdun to kọja lati fi ẹsun kan Biden pe o fi ọwọ kan awọn, o di mọ wọn tabi fi ẹnu ko wọn lẹnu bkẹ si ni ileeṣk iroyin ilẹ Amẹrika ṣafihan bi o ṣe maa n ki awọn obinrin timọ timọ nita gbangba eyi to maa n fi han ni ọpọ igba bo ṣe n fi imu fi irun wọn.
Wọ́n kó àwọn aya Dafidi mejeeji, Ahinoamu ará Jesireeli ati Abigaili opó Nabali lẹ́rú pẹlu.
Bi ijamba ṣe lee da wahala sunkẹrẹ-fakẹrẹ silẹ niwọnba lo jẹ wi pe aijafafa awọn ajọ gbogbo to yẹ lati tete palẹ oju popo mọ gan an ni ogunnagbongbo ohun gan an to n ṣẹlẹ.
 AminAṣofin Micheal Adeyẹmọ jẹ Ọlọrun nipe ni ọjọ Ẹti (Friday), ọjọ kẹtadinlọgbọn  oṣu kẹrin ọdun 2018 lẹni ọdun mẹtadinlogoji.
com/yoruba Ileeṣẹ agbohunsafẹfẹ ti ijọba ilẹ Gẹẹsi (BBC) ti ṣetan lati ṣe ifilọlẹ awọn ẹka iṣẹ iroyin meji tuntun lorilẹede Naijiria lọjọ aje.
Niṣe ni Odunlade gbe gbohungbohun dani to fi n sọrọ nibi iwọde naa.
Gibeoni tóbi ju ìlú Ai lọ, akọni sì ni gbogbo àwọn ọkunrin ibẹ̀.
Wọ́n kọ́ Magawa lati ma fi imú finlẹ̀ fún àwọn ǹkan bíi kẹ́míkà, àdó olóró, èyí túmọ̀ si pé, o le ṣe àwárí ìjìnlẹ̀ lórí imo\\-ilẹ ki o sì wá jáde ni kíákíá.
Wọ́n gbé òkú ọgá iléẹ̀kọ́ àti òṣìṣẹ́ méjì míì tó kú nínú ìbúgbàmù lọ sílé ìgbókùsí ológun ojú omi l‘Eko Mo kó àrùn Coronavirus lẹ́yìn tí mo ṣalábapàdé ẹni tó ní àrùn náà lára - Idris Elba Ọmọ ti lọ kí baba, Fayemi bẹ Aláàfin wo l‘Ọyọ, wọ́n jírórò lórí lẹ́tà Oríṣun àwòrán, others Ki ni ohun to ṣẹlẹ?
"Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Èmi àti Saheed kìí ṣe ọmọdé, a ti jọ ṣe Sinimá papọ̀, èyí túmọ̀ sí pé ìjà ti parí - Fathia Balogun ""Mo fẹ́ pa ara mi torí ojú àbùkù tí wọn ń fi wò mí pé mo fi iṣẹ́ abẹ bímọ"" Fulani kò leè dúró, táa bá lo ohun ta jogún lọ́dọ̀ àwọn bàbá wa - Sunday Igboho Ọjà Àgbáláta ní Badagry rèé, níbití ẹran ejò ti dùn ju ẹran adìẹ lọ Oloye Roga ni ti awọn oloro ba ti se etutu wọn tan, ni igi yii yoo tun ruwe pada, ti ohun gbogbo yoo si tuba tusẹ."
Ọ̀nà isà òkú tààrà ni ilé rẹ̀,ilé rẹ̀ ni ọ̀nà àbùjá sí ìparun.
Oríṣun àwòrán, Sen Bala Muhammed Wayi o, ajọ eleto idibo ko lee tii kede ẹni to jawe olubori ninu ibo gomina nipinlẹ Bauchi bayii nitori ibo ijba ibilẹ Tafawa Balewa to wa nile ẹjọ.
Oyeyemi ni awọn eeyan lo ta ikọ ọlọpaa to n gbogun tiwa idigunjale SARS lolobo nipa irinsi awọn afurasi naa ati ibuba wọn to wa lagbegbe Odeda.
"Akeugbagold tún wà bẹbẹ, ó ní ""mo bẹbẹ lọwọ gbogbo àwọn èèyàn ti mo ba ṣẹ tàbí àwọn tí wọn ró pé mo ṣẹ àwọn, àbí àwọn tí ìyà àwọn ọmọ náà bá ṣẹ, kí wọn dakun, jọwọ forí jin mi, mo bẹbẹ ni""."
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Atiku gba ‘Fisa’ Amẹrika, àwọn ọmọ Nàíjíríà sọ̀rọ̀ Buhari: Ipa pàtàkì ni Fasheun kó nínú ẹgbẹ́ NADECO Samuel Ladoke Akintọla jẹ́ Agbẹjọ́rò àti Akọ̀ròyìn tí ọ̀rọ̀ dá lẹ́nu rẹ̀ Hubert Ogunde rèé, baba àwọn òsèré tíátà Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ọkọ ìyàwó ẹlẹ́kún: N kò bá tí ba ẹnu jẹ́ lọ́jọ́ ìgbeyàwó, àwàdà ni mo se O tun fikun pe ẹgbẹ oselu PDP ti se iwọn to lee se fun ọdun mẹrindinlogun, ẹgbẹ oselu to wa lori aleefa lọwọlọwọ ni ko mura lati sa ipa tiẹ naa.
Ati pe wọn si gbọdọ maa tẹle awọn ilana ti igbims amuṣẹya naa ba fi silẹ.
Ẹwẹ, ileeṣẹ ologun jẹ ko di mimọ pe iyatọ gedegbe wa laarin iṣẹ ni papakọ ofurufu ati ibomiran.
Ajọ isọkan orilẹ-ede agbaye naa, to ni bi ara ile ẹni ba n jẹ kokoro buruku, ti a ko ba tete wi fun-un, hẹrẹ-huru rẹ ko ni jẹ ka sun loru, lo mu ki oun tete maa kigbe sita bayii pe, ẹni to ba ni eti ko gbọ, ohun ti ẹmi n sọ fun awọn ijọ.
Ṣugbọn iwọde wọn naa di wahala, debi i pe wọn kọlu awọn ọlọpaa.
‘Ẹ sọ fún Josẹfu pé, dárí àṣìṣe ati ẹ̀ṣẹ̀ àwọn arakunrin rẹ jì wọ́n, nítorí wọ́n ṣe ibi sí ọ.
Fun apẹẹrẹ, Ọba kii ri oku, Ọba kii jẹun ni ita gbangba, ati bee bee lọ.
Bobrisky ni Runṣewe n dunkooko mọ oun.
Ẹ ranti OLUWA ní ilẹ̀ òkèèrè,kí ẹ sì máa ronú nípa Jerusalẹmu pẹlu.
Baba rẹ̀ dá a lóhùn pé, ‘Ọmọ mi, ìwọ wà lọ́dọ̀ mi nígbà gbogbo, gbogbo ohun tí mo ní, tìrẹ ni.
Oniyide, ẹni to kede pe iṣẹ ọpọlọ oun ni ilana tuntun ọhun, ti wa wọ ijọba ipinlẹ Oyo lọ sile ẹjọ lori amulo iṣẹ ọpọlọ naa, eyi to ni wọn lo lai jẹ ki oun mọ nipa rẹ.
Ọlọrun yóo gba gbogbo agbára ọwọ́ àwọn eniyan burúkú kúrò;ṣugbọn yóo fi agbára kún agbára fún àwọn olódodo.
Bakan naa ni gbajugbaja afẹsẹkubiojo, Anthony Joshua, pẹlu ajafẹtọ ọmọniyan, J.
Ọga agba Ọlọpaa naa ti o tun jẹ Alaga Igbimọ Tẹẹkoto fun Ọrọ Aabo Eto Idibo, rọ awọn oloṣelu lati yago fun jagidijagan ni ṣaaju, ni asiko ati lẹyin idibo ọdun 2019 yii.
“Gba àwọn ọmọ Lefi dípò gbogbo àwọn àkọ́bí ninu àwọn ọmọ Israẹli, ati ohun ọ̀sìn àwọn ọmọ Lefi dípò ohun ọ̀sìn wọn.
Ẹ̀yà adúláwọ̀ ni ọkùnrin náà jẹ́.
OLUWA ní, “Israẹli dàbí aguntan tí àwọn kinniun ń lé kiri.
”Croatia ti pegede sipele ti o kan ninu idije ohun, leyin ti won jawe olubori ninu ifesewonse meji ti won gba seyin, pelu ami mefa lori oke tente tabili.
"O sọ pe ""Ijọba Osun ti pinu lati jẹ ki awọn eeyan korajọ fun isin yii sugbọn ile ijọsin ti yoo ba se isin gbọdọ ri pe awọn eeyan pari rẹ lasiko, ti wọn ko si ni kọja aago kan oru'' Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Baruwa Gas Explosion: Àwọn tó forí sọta ìjàmbá iná ń bẹ ìjọba láti dìde ìrànwọ́ Isin Cross over ori ayelujara: Ijọ RCCG (Redeemed) Ohun ti ile ijọsin Redeemed Christian Church sọ fun awọn ọmọ ijọ rẹ ni pe lori ayelujara lawọn yoo ti se isin tọdun aisun dun tawọn."
nile igbimo asoju-sofin lasiko ti won fe yan  awon adari ti yoo maa sakoso won.
Bakan naa ni wọn tun n gbe isẹ agbase sita lai bikita, lai naani owo ilọpo meji ti wọn n na lori rẹ lai tẹle abala ofin to yẹ.
" Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Genotype: Kí làwọn àǹfàni àti ewu tí ẹ̀yà jínótáìpù rẹ le mú bá ìgbé ayé rẹ̀ Eji Gbadero pada soju agbo ayẹyẹ ikomọ rẹ, to si n ba ọpọ eeyan ya fọto loju agbo, asiko yii si ni awọn ara abule lọ sọ fun awọn ọlọpaa Alimoso pe Eji Gbadero ti pa Raji Oba.
onírúiyepúpọ ̀ kan le jẹ ́ òdo , tàbí kó jẹ ́ kíkọ bíi àròpọ ̀ ìkan tàbí ọ ̀ pọ ̀ àwọn ọ ̀ rọ ̀ aláìjẹ ́ òdo .
Wọ́n bọ́ ihamọra Saulu, wọ́n gé orí rẹ̀, wọ́n sì rán àwọn oníṣẹ́ káàkiri gbogbo ilẹ̀ Filistini láti ròyìn ayọ̀ náà fún àwọn oriṣa wọn ati àwọn eniyan wọn.
Ṣugbọn bí ẹnikẹ́ni kò bá gba ohun tí a wí yìí, a kò gba òun náà.
Nígbà tí Eliabu, ẹ̀gbọ́n rẹ̀ àgbà gbọ́ tí ó ń bá àwọn ọkunrin náà sọ̀rọ̀, ó bínú sí Dafidi, ó ní, “Kí ni ìwọ ń wá níbí?
Nígbà tí ó dé ibi tí ó ti ń gbọ́ igbe yìí ó rí ọkùnrin arẹwà kan tí ó jókòó lé orí àga.
Bí wọn bá wí pé,“Tẹ̀lé wa ká lọ,kí á lọ sápamọ́ láti paniyan,kí á lúgọ de aláìṣẹ̀,
EFCC ń wádìí iléeṣẹ́ Bola Tinubu,' Alpha Beta Consulting Ltd' Kí ló mú àwọn adarí Nàìjíríà tako ra wọn lórí ikú ọmọ alága ẹgbẹ́ Afenifere?
Bakan naa ni wọn sọ wi pe yiyago fun ara ẹni ṣe pataki ni asiko yii.
Standard Chartered Bank, Stanbic-IBTC, Citibank, ati Diamond Bank wa lara awọn banki ti CBN lo padi apopọ pẹlu ile isẹ MTN lati tapa sofin idunadura to de pasiparọ owo lorileede Naijiria.
Wọ́n bá wẹ̀ ẹ́, wọ́n tẹ́ ẹ sí yàrá lókè ní ilé pẹ̀tẹ́ẹ̀sì kan.
Bakan naa ni awọn kan n sọ pe, kii ṣe gbogbo aṣọ lo yẹ ka maa ṣa l'oorun nipa iṣakoso ọkọ gẹgẹ bi aya arẹ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Kini Yoruba international passport""?"
Kí ló ń ṣẹlẹ̀ láàfin Oyo táwọn èèyàn fi ń ki Alaafin ní mẹ́sàn án mẹ́wàá?
Ronaldinho rinrin ajo lọ si orilẹede Paraguay tẹlẹ lati ṣe ifilọlẹ iwe rẹ ati ipolongo fawọn ọmọ ti obi wọn ko ri ọwọ họri.
Oludari ajo to n mojuto isele pajawiri lorile ede Naijiria, Mustapha Maihaja, so pe isele omiyale to waye ni awon apa kan lorile ede Naijiria ti gbemii awon eniyan  mọ́kànlélọ́gọ́rùn ún.
Olukuluku wọn ti ṣìnà lọ,kò sí ẹni tí yóo gbà ọ́ sílẹ̀.
Ó gbà wọ́n là lọ́wọ́ àwọn tí ó kórìíra wọn,ó sì kó wọn yọ lọ́wọ́ àwọn ọ̀tá wọn.
1 29989 Orilẹede Belize 280 73.
afurasi odaran ohun ni oniruuru ibon ilewo ati sakabula merinlelogun(24); ohun
Àwọn onigbeeraga ti gbẹ́ kòtò sílẹ̀ dè mí,àní, àwọn tí kì í pa òfin rẹ mọ́.
Seyi Makinde: ₦60m ní mo gbé kalẹ̀ fún ìtọ́jú àwọn akẹ́kọ̀ọ́ ìmọ̀ òfin fún ọdún kan
Lootọ ni ọpọ wọn ti re iwalẹ asa, amọ awọn miran si wa loke eepẹ, ti ko si yẹ ka tete gbagbe wọn.
Wọ́n ti fẹ̀sùn kan Agboola Ajayi pé ó tẹ ayédèrú ìwé ìdìbò níbi ìdìbò abẹ́lé PDP ní Akure Awọn ọmọleyin ọkan lara awọn oludije, Eyitayo Jegede, ti sọ pe awọn alatilẹyin rẹ fariga pe, igbakeji gomina, Agboola Ajayi tẹ ayédèrú ìwé idibo wọle.
Akọwe ẹgbẹ oṣelu APC ni ipinlẹ Ondo, Alex Kalejaiye lo fi idi ọrọ naa mulẹ fun BBC Yoruba.
Oluwa rẹ̀ wí fún un pé, ‘Ọ̀rọ̀ ẹnu rẹ gan-an ni n óo fi ṣe ìdájọ́ rẹ, ìwọ ọmọ-ọ̀dọ̀ burúkú yìí.
Wayi o, opo ololufe ere boolu
Odidi ilu marun un ni ọrọ to kan iku Favour rọ mọ kaakiri - Eko, Abeokuta, Mowe, Ikoyi Ile, Osogbo.
Nígbà tí Natani wọlé, ó wólẹ̀ níwájú ọba, ó sì dojúbolẹ̀.
Nibayii, ọpọ ọmọ Naijiria ni wọn ti n koro oju si iwa isekupani to n fi ojoojumọ waye ni ẹkun Guusu Kaduna naa ati ikọlu awọn agbegbọn to n waye loore koore nibẹ.
Fun apẹẹrẹ, ni ipinlẹ Rivers, ti epo rọbi sodo si julọ lorilẹede Naijiria, ọpọ olugbe ipinlẹ naa lo ni ko si owo lọwọ, ko si isẹ lati se, ti ebi si n pa awọn.
Ọmọ ọdún mẹ́rìnlá kàwé gboyè jáde ni Oxford Alaga igbimọ gbohun-gbaroye araalu ni ile aṣofin naa, Họnọrebu Adegoke Ọlajide ṣalaye pe lasiko ti awọn alaga kansu naa fi ara han niwaju ile ni wọn jẹwọ pe loṣooṣu lawọn maa n da owo ijọba ibilẹ wọn gba ọna miran, eyi ti wọn ni o wa ni ibamu pẹlu aṣẹ ti wọn ri gba latọdọ gomina ana ni ipinlẹ naa, Ayọ Fayoṣe.
Nisinsinyii, ẹ̀yin ìran ẹlẹ́ṣẹ̀ yìí dìde gẹ́gẹ́ bí àwọn baba ńlá yín láti mú kí inú bí OLUWA gidigidi sí Israẹli.
 Ìtọjú àwọn tí ó ní àkóràn nípa egbòògi náà ivermectin ní gbogbo oṣù mẹ ́ fà-mẹ ́ fà sí méjìlá .
Ìlú náà kò sí ní gbańgba, ibi ìkọkọ̀ kan báyìí ni ó wà, ẹnikẹ́ni kò tilẹ̀ gbúròó ọkùnrin náà mọ́.
Oju ọjọ naa ti fa ki wọn da ọkọ ofurufu duro lati ma se isẹ, bẹẹ si ni wọn ti ọgọọrọ ile iwe pa, eleyii ti o dina awọn eniyan lati ma le e lọ lati ibi kan si ibomiran.
Àkọlé àwòrán, Mai Mala Buni, alaga fidihẹ fẹgbẹ oselu APC ati gomina ipinlẹ Yobe Nibayii, lẹyin ti atẹgun ti fẹ si saa to yẹ ki alaga fidi hẹ ti wọn yan lẹyin Oshiomole lo nipo, ni awọn ọmọ ẹgbẹ oselu PDP kan tun ti n lọgun pe, ki wọn se agbekalẹ ojulowo ikọ oludari fẹgbẹ oselu naa.
Ọmọde meje, agbalagba mẹrin ni mo n gbọ, ti mo si ni osisẹ mẹtalelogun to n ba mi sisẹ.
"Ọwọ tẹ awọn kan naa laarin igboro, a si ti fa gbogbo wọn le awọn agbofinro lọwọ.
Ìlú tí a ó gbé yẹ̀wò lọ́sẹ̀ yìí ni Abúlé Ọja.
Ẹ kò mọ ohun tí yóo ṣẹlẹ̀ si yín lọ́la.
Wọn tun ni wọn fi agidi mu awọn ọmọde ati agba jagun lọna ti ko yẹ.
Obayi tun je ko di mimo pe ipin merin ni eto yii wa jake-
to kọja, lo ti ye ki eto idibo mejeeji aare ati ile igbimo asoju-sofin yii waye
Florence fi orin ọpẹ si Oluwa pari rẹ pe lẹyin igbesẹ to yẹ oun pada bi ọmọkunrin lantilanti to ti pe ọdun mẹwaa bayii ki eledumare baa woo ni awoye.
lusegun Obasanjo jẹ ajagunfẹyinti to jẹ aarẹ Naijiria laarin ọdun 1999 si 2007 fun saa meji.
Ìkamọ̀dù jagun náà, wọ́n sì m’ẹ́rú wálé.
 Àjọ Ìlera Àgbáyé gbani nímọ ̀ ràn láti fúnni ní àjẹsára náà bí ènìyàn bá ti pé ọmọ oṣù mẹ ́ ẹ ̀ sán ní àwọn agbègbè ibití àrùn náà ti wọ ́ pọ ̀ .
Ta ló tìlẹ̀kùn mọ́ òkun,nígbà tí ó ń ru jáde,
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Hushpuppi: Ó di ẹlẹ́wọ̀n tó ní nọ́ńbà l‘Amẹrika, orúkọ̀ rẹ̀ wà lórí ayélujára 2 Agẹmo 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 8 Agẹmo 2020 Oríṣun àwòrán, Hushpuppy/SCREENSHOT/BOP.
Kedemotu ati Mefaati pẹlu àwọn pápá oko àyíká wọn.
Kìí ṣe ẹjọ́ àlejò yìí rárá.
Oríṣun àwòrán, Instagram/gloriabamiloye Fun igba akọkọ, Mike Bamiloye ṣalaye ọrọ kan to jade ninu fiimu Agbara Nla to ṣe, ninu eyi ti obinrin kan, Bose to gba agbara okunkun lọwọ ọrẹ rẹ, Paulina, ti maa n kigbe Ayamatanga"", ki agbara Ọlọrun to tu u silẹ."
Ní gbogbo ọjọ́ tí ó ya ara rẹ̀ sọ́tọ̀ fún OLUWA, kò gbọdọ̀ súnmọ́ òkú: 
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Fake News: Ayédèrú Dino fẹ́ fún èèyàn mẹ́wàá ní mílíọ̀nù mẹ́wàá náírà tí Atiku bá wọlé 17 Èrèlè 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 18 Èrèlè 2019 Oríṣun àwòrán, Instagram/dinomelaye Àkọlé àwòrán, Ilumọka oloṣelu ni Sẹnẹtọ Dino Melaye Ibeere ''ki lo yẹ ki a fi ṣajọyọ ti Atiku ba pegede ninu ibo Aarẹ?
Ọrọ naa bi awọn ọrọ miran to nii ṣe pẹlu igbe aye awọn eeyan orile-ede yii, ti n mu ariwisi ọtọọtọ wa lati igba ati ijọba ti kede pe awọn fẹ ya aaye sọtọ fun un.
''Mama mama mi ko tilẹ beere ohun kan lọwọ mi, o kan ṣaa tọju mi ni.
Bi wọn ba wa yan lati pa koko yii ti, o lewu.
“Wọn kò ní ní ilẹ̀ ìní nítorí èmi ni ìní wọn, ẹ kò ní pín ilẹ̀ fún wọn ní Israẹli, èmi ni ìpín wọn.
Ogunlọgọ eeyan lo ti wo fidio ọhun, lẹyin to jade lori ayeluhara, koda gomina ipinlẹ Eko, Babajide Sanwo-Olu gan ko gbẹyin.
Wọn ń wí pé, “Ẹ jẹ́ kí á fa ẹ̀wọ̀n tí wọ́n fi dè wá jákí á sì yọ ara wa kúrò lóko ẹrú wọn.
Má ja talaka lólè, nítorí pé ó jẹ́ talaka,má sì dájọ́ èké fún ẹni tí ara ń ni.
Lẹyin eyi lo wa ni ko lọ fi asọ penpe roko ọba fun ọdun mọkanlelogun gbako.
Ariwa-iwọ oorun ati Guusu-iwọ oorun ẹkun naa ni agbegbe meji ti wọn ti n sọ ede Gẹẹsi lorilẹ-ede naa.
Mo sọ̀na bi iṣẹ́ yóò ṣe de ìhàn ìlàoorùn Imo nípinlẹ Imo, nítori pe o wa lára àwọn ibi ti NDDC ń mójú tó, nítori náà gẹ́gẹ́ bi asojú ẹkùn náà ni mó ṣe gbé iṣk lọ si bẹ̀.
A bíi ní ọjọ kẹtadínlogun oṣù keji, ọdun 1971, ó jẹ ajàfẹ́tọ ọmọniyan, pàápàá jùlọ ìjọba awa-ara wa.
Ajàfẹ́tọ̀ọ́ obìnrin Cecelia Kitombé sọ̀rọ̀ sí àwọn tí ó ń ṣe àtìlẹyìn ìbáṣepọ̀ tí ó níyà nínú:
Alaye mii ti Ẹmiọla ṣe fun BBC Yoruba ni pe awọn ikọ yii tun lu obinrin ni agbegbe Ogunpa nilu Ibadan nitori pe aṣọ to wọ ko tẹ wọn lọrun.
"Oludari fún àwọn alakoso gareji ọkọ ti jọba yàn, Mukaila Lamidi - Auxiliary lọ ń jà káàkiri ìlú, nígbà ta si ti mọọ tẹ́lẹ̀, a kò sì fẹ́ kí orúkọ wa bajẹ, là ṣe ni sùúrù fún""."
Fasiti Ahmadu Bello lo ti kẹkọọ gboye ko to lọ gba iṣẹ ọkan lara awọn igbimọ Commonwealth of Learning.
Bakibukaya ati Uno arakunrin wọn a máa dúró kọjú sí wọn ní àkókò ìsìn.
  Èyí máà nmú kí gbogbo wọn bárawọn mu dáadáa kí wọ́n sì gúnrégé lójú, bíótilẹ̀jẹ́pé púpọ̀jù nínú wọn ti fẹ́ẹ̀ẹ́ bàjẹ́ tán.
 bí àrùn náà ti nle síwájú síi , ó lè ran egungun .
Akanse adura Fidau ọjọ mẹjọ naa lo waye nile oloogbe Ajimọbi nilu Ibadan nilana ẹsin Islam.
Ẹ̀yin ń fẹ́ da ètò aláìní rú,ṣugbọn OLUWA ni ààbò rẹ̀.
Ìbáṣe pé ọmọ ènìyàn kì í fi ojí idà wọn gbolẹ̀, díẹ̀ ni Ẹlẹ́dàá pàápàá ìbá fi jù wọn lọ, ipò tí ó fẹ fi wọn sí pọ̀, ó fẹ́ràn wọn.
Wọ́n fi ìtìjú wọlẹ̀ lọ, wọ́n lọ bá àwọn tí wọ́n wà ní ipò òkú.
Ẹ̀sìn Ọlọ́run Ikú tí yóò pamí, ikú ire
Afara tuntun já, Gómìnà rè sodò nì Kenya Afárá 3rd Mainland di ṣíṣí ní ìlú Eko Afárá Third mainland gb’ẹ̀gbọ́n Ako ti le sọ pato iye eeyan to farapa ninu iṣẹlẹ naa ṣugbọn awọn awẹdo ti n gbiyanju lati doola ẹmi.
Ile ijo naa ni oun yoo tubọ maa bẹju wo bi nnkan ba ṣe n lọ si lori arun naa ki wọn to tun lee sọ igba ti faaji yoo pada bẹrẹ nibẹ.
Ọba bi Daniẹli, tí wọ́n sọ ní Beteṣasari ní èdè Babiloni pé, “Ǹjẹ́ o lè rọ́ àlá mi fún mi, kí o sì sọ ìtumọ̀ rẹ̀?
Ogbeni Gidado so fun gomina ipinle Bauchi, Muhammed Abubakar lojo kẹ́rìndínlógún, osu kárùn ún lati fi ipinnu re han pe oun yoo fise sile.
Ẹ kò gbọdọ̀ dá irú ẹ̀ṣẹ̀ yìí ní ilẹ̀ tí OLUWA Ọlọrun yín fun yín.
Ẹni tí ọkàn rẹ̀ kò ṣe déédéé ninu OLUWA yóo ṣègbé; ṣugbọn olódodo yóo wà láàyè nípa igbagbọ.
Gbọ́, àwọn aṣọ́de rẹ gbóhùn sókè,gbogbo wọn jọ ń kọrin ayọ̀,nítorí wọ́n jọ fi ojú ara wọn rí i,tí OLUWA pada dé sí Sioni.
nígbà tí gbogbo àwọn ọmọ Israẹli bá wá sin OLUWA ní ibi tí ó yàn pé kí wọ́n ti máa sin òun, o gbọdọ̀ máa ka òfin yìí sí etígbọ̀ọ́ gbogbo wọn.
''Ti ẹni to n ṣe ere idaraya ba mi, eemi naa yoo maa jade leralera, ti ẹni naa ba si ni aarun coronavirus, ẹlomiiran ti wọn jọ n ṣe ere iadaraya le ko aarun naa lara rẹ,'' Dokita Wilson lo woye bẹẹ.
Awọn miran se apẹrẹ orilẹẹde okeere ti o fun awọn eniyan laaye lati se ifẹhọnu, lai si ọlọpaa ti yoo kan ilẹkun wọn ni ọganjọ oru.
Bi o tilẹ jẹ pe baba naa ni ipenija ara, ti ko si le da rin, sibẹ eyi ko ṣe idiwọ fun lati fi ipa rere lelẹ, ko to jade laye.
Ọmọbinrin ti wọn fi ṣe owo ẹru naa kuro ni ile ni Osu Kẹwa ni ọdun 2017, ti oju rẹ si ri to loju ọna ko to de Cote D‘ivoire, ti ẹni to mu lọ si faa le obinrin kan lọwọ nibẹ.
Ní ọjọ́ náà gan-an ni àwọn iranṣẹ rẹ̀ wá sọ fún un pé àwọn kan omi ninu kànga kan tí àwọn gbẹ́.
Ṣugbọn ọ̀rọ̀ atukọ̀ ati ẹni tó ni ọkọ̀ wọ ọ̀gágun létí ju ohun tí Paulu sọ lọ.
Láìpẹ́ ọjọ́, ìwà tìrẹ gan-an yóo burú ju tiwọn lọ.
Sergio Aguero lo pegede julọ ninu ifẹsẹwọnsẹ to waye ni alẹ Ọjọ Àìkú.
 Ó ṣe alábápàdá ikú rẹ ̀ ní ibi ìjàmbá ọkọ ̀ òfurufú ní odò bárẹ ́ ǹtì .
Wo ohun to yẹ koo mọ sii nipa awọn eroja amu-adun ibalopọ pọ sii lori ibusun: Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Oriṣa Aphrodite ti wọn tun n pe ni Venus to wa lati inu odo ti nkan adun ifẹ ti jade Ona mẹta ni a le pin awọn nkan adun ibalopọ yii si gẹgẹ bi iṣẹ won lara.
awon eekan jake jado nile Yoruba.
Ṣùgbọ́n àsẹ̀hìnwá-àsẹ̀hìnbọ̀ ọ̀rọ̀ yìí, àwọn ẹranko àti àwọn ẹyẹ mu ọtí yó, wọ́n bẹ̀rẹ̀ sí ṣe réderède, Àjànàkú bẹ̀rẹ̀ sí wó igi lulẹ̀, kìnnìún bẹ̀rẹ̀ sí pa àwọn ẹranko, Kọ̀lọ̀kọ̀lọ̀ pa ọ̀kan nínú àwọn àgbébọ̀, Àṣádì ń lé àwọn ẹyẹ kiri.
Aarẹ ẹgbẹ awọn Dokita, Dokita Adedayo Faduyile lasiko to ba BBC sọro ni, awọn dokita ko to ni Naijiria nitori wi pe dokita kan lo n tọju si ẹgbẹta eniyan lo yẹ kojẹ , amọ o le ni ẹgbẹwa eniyan to n lo dokita kan.
Lẹhin idibò, ni òwúrọ̀ kùtùkùtù ọjọ́ keji idibò, ni ọjọ́ Ẹti, ọjọ́ kẹrinlélógún, oṣù kẹfa, èsi ibò jade pé ibò bẹ́ẹ̀kọ́ ju ibò bẹni lọ, eyi ti ó túmọ̀ si wi pé, ará ilú ti ó fẹ́ ki wọn ‘kúrò’ ni ẹgbẹ́ Ilú-Oyinbo pọ̀ ju àwọn ti wọn ó fẹ́ ki wọn ‘dúró‘ ninú ẹgbẹ́.
Ọga ileesẹ Naijiria to n boju to awọn ọmọ ilẹ yi nilẹ okere(NIDCOM) iyẹn Abike Dabiri-Erewa sọ pe iku ọmọ ọdun mọkandinlogun Oluwatoyin yi jẹ iwa ika to buru to si tun bani lọkan jẹ.
Ní àkókò náà Hẹrọdu ọba bẹ̀rẹ̀ sí ṣe inúnibíni sí àwọn kan ninu ìjọ.
Awọn ti iṣẹlẹ naa ṣoju wọn ni arakunrin Nomyange naa lọ si ile afẹsọna rẹ pẹlu galọọnu epo bẹntiroo, to fi dana sun ile naa.
”Wọn kò sì lè túmọ̀ àlọ́ rẹ̀ fún ọjọ́ mẹta.
Pẹlu iranlọwọ ọkan lara awọn ti mo ti kọkọ ba sọrọ, ti oun naa ti ṣayẹwo to si ni aarun HIV, to bẹrẹ si ni ṣọ ọkọ ayọkẹlẹ ti gbogbo awọn obinrin to n wa Philippe wa n gbe e wa.
 Funmi Jokotade: Ala to wa si imusẹ ni bi mo se darapọ mọ ileesẹ BBC yi.
Arọwa mi si wọn ni ki ijọba wa ọna lati ṣayipada wọn ki wọn baa le di eeyan daada lawujọ'' Lati ọdun 2001 ni ofin Sharia ti fẹsẹ rinlẹ ni Kano ti awọn ọlọpaa Hisbah si ni agbara lati mu awọn to ba ṣe ohun to tako ofin Islam.
ati Adaaya, ọmọ Jerohamu, ọmọ Paṣuri, ọmọ Malikija ati Maasai ọmọ Adieli, ọmọ Jasera, ọmọ Meṣulamu, ọmọ Meṣilemiti, ọmọ Imeri.
Gbogbo ìdè tí wọ́n fi dè é já kúrò ní ọwọ́ rẹ̀.
Nínú ọ̀sẹ̀ yìí ní Dino Melaye ké gbànjarè pé ọgá àgbà ọlọ́pàá fẹ mú òun láti gún òun lábẹ́rẹ́ ikú Ilé iṣẹ́ ọlọ́pàá wá ni ǹkan tí àwọn sọ fún Dino Melaye lásìkò náà ní pé tó bá mọ p'\\e òun ti ṣẹ̀ sófin kò wá jẹ́wọ́ Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 3 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 5 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Ẹlẹ́rìí tòótọ́ a máa gba ẹ̀mí là,ṣugbọn ọ̀dàlẹ̀ ni òpùrọ́.
"Mo tako gbogbo irọ to yi igbeyawo mi pẹlu ọkọ mi ka.
”Gehasi ní, “Kò bímọ, ọkọ rẹ̀ sì ti di arúgbó.
'Buhari, ṣé ìkíni ọdún níyìí tàbí ìpolongo ìdìbò?
Olukuluku lo ni ẹtọ lati se ẹsin to ba wu u."
" Aluko pari ọrọ rẹ pe ko wu awọn awọn dokita lati daṣẹ silẹ ṣugbọn ọrọ naa ti sun wọn.
Àsìkò tó láti fi ìwọ́de gba ara wa sílẹ̀ lọ́wọ́ ebi àti oko ẹrú - Sowore Ọsẹ meji ni wọn fi maa n se ọdun Ọṣun Oṣogbo, eyi to maa n kun fun oniruuru eto to jẹ mọ aṣa ibilẹ lati gb ajọdun naa larugẹ.
Nitori naa, ẹkọ nla re e f'ẹnikẹni to ba fẹ sa lọ ba aarẹ lati gbeja rẹ.
Ko ti i si alaye lẹkunrẹrẹ lori bi wọn yoo ti ṣe ṣeto yi amọ owo ti wọn fẹ naa ni wọn ti ṣe atupalẹ rẹ.
Ọjọ Iṣẹgun ni iṣẹlẹ naa waye ni abule Kibundani ni agbegbe Kwale l'orilẹ-ede Kenya, ni nkan bi agogo mẹsan alẹ.
Yóo jẹ́ mímọ́ fún OLUWA ní gbogbo ọjọ́ ìyàsọ́tọ̀ rẹ̀.
Ni kete ti wọn yan Fayẹmi tan lo ti parọwa fawọn akẹgbẹ rẹ lati tubọ mojuto ọrọ eto aabo Naijiria to ti n gbẹbọ lọwọ koowa bayii.
Ileeṣẹ iroyin Naijiria ni ọpọ ninu awọn to ya wa kirun Jimọ nibẹ naa lo n ṣepe fawọn to bẹrẹ iroyin ofege naa lori ayelujara.
Dafidi gba ẹgbẹrun (1,000) kẹ̀kẹ́ ogun, ẹẹdẹgbaarin (7,000) ọmọ ogun ẹlẹ́ṣin, ati ọ̀kẹ́ kan (20,000) ọmọ ogun lọ́wọ́ rẹ̀.
Ìgbà tí mo ti ká èso kan, mo padà pẹ̀lú ayọ̀ mò ń lọ.
Ṣugbọn Mose dáhùn pé, “OLUWA, akólòlò ni mí; báwo ni ọba Farao yóo ṣe fetí sí ọ̀rọ̀ mi?
Ninu oro ti olugbani-nimoran pataki fun aare lori oro ifitonileti ati igbodegba, ogbeni Femi Adesina gbejade lojoBo(Thursday) so pe, gege bi oro ti Oshuntokun so, iro nla ni oro naa je, bee si ni ayeye odun Eid-el Kabir  lo nirowa-rose lai si wahala rara.
Mata ń ṣe ètò gbígbé oúnjẹ kalẹ̀; Lasaru wà ninu àwọn tí ó ń bá Jesu jẹun.
Ọjọ Abamẹta tii ṣe ogunjọ oṣu kẹfa ọdun 2020 ni arẹwa Ibidunni Ighodalo wọ kaa ilẹ lọ niluu Eko.
Ramadan wa lati se atunse nipa ti ẹmi, nitori naa, mo rọ awon musulumi lati lo
Inú wáá bí mi, mo ní, ‘Orí rẹ ni yóò dé ilé Ikú, àyà rẹ ni yóò dé ilé Ikú, ìwọ abi ‘rùngbọ̀n yẹ̀ùkẹ̀yẹukẹ yìí.
Orile ede Naijiria yoo maa koju Cote d’ Voire ati Burkina Faso ninu ipele ti won wa.
Fún àwọn ohun tí ó ṣẹ́kù ní okun, nítorí àwọn náà ń kú lọ.
Ruga ko tumọ si ki eeyan jẹ gaba lori ẹlomiran.
Nígbà tí Hesekaya ati àwọn ìjòyè wá wo àwọn ìdámẹ́wàá tí wọ́n kójọ bí òkítì, wọ́n yin OLUWA, wọ́n sì dúpẹ́ lọ́wọ́ àwọn ọmọ Israẹli.
Bí ẹ bá fẹ́ yapa sí apá ọ̀tún tabi apá òsì, ẹ óo máa gbọ́ ohùn kan lẹ́yìn yín tí yóo máa wí pé, “Ọ̀nà nìyí, ibí ni kí ẹ gbà.
Ìjà náà pọ̀ gidigidi, nítorí bàbá mi kò yéé ròyìn ọ̀ràn yìí títí ó fi kú.
Àwọn ará Ijipti bá ń kán àwọn eniyan náà lójú láti tètè máa lọ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Yoruba Film: Baba Ijesha sọ bí ọ̀tá ṣe sún un bá iré gẹ́gẹ́ bíi aláwàdà òṣèré Yorùbá 8 Ògún 2020 Oríṣun àwòrán, @BabaIjesha Wọ́n gba Scene"" mẹ́ẹ̀dọ́gbọ̀n lọ́wọ́ mi, wọ́n gbé òfo lé mi lọ́wọ́ ni mo fi di òṣèré fíìmù Yorùba."
Manchester United vs Tottenham: Man United ré Mourinho àti Tottenham lẹ́pa lórí pápá Old Trafford
nítorí pé irọ́ ló wà nídìí àwọn àṣà wọn.
Àwọn ologun dóòlà akẹ́kọ̀ọ́ mẹ́fà lọ́wọ́ àwọn ajínigbé ní Kaduna Funke Akindele: Funke Akindele fi fiimu to ṣẹṣẹ dari sita lori oju opo Instagram rẹ, eyi ti o pe akọle rẹ ni #Your Excellency.
“Mo ni iberu olorun, bee si ni o ye ki awon akoroyin maa bi awon oludije to ba n seponlogo fun won lati so ipinnu won, ki won si beere awon ona ti won yoo gba lati mu ileri naa se.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Yoruba Films: Bó ṣe ń lọ́ lágbo Yollywood lópin ọ̀sẹ̀ yìí 31 Sẹ́rẹ́ 2020 Oríṣun àwòrán, Instagram Akọ ẹja pataki meji lawọn BBC Yoruba lori bo ṣe n lọ lopin ọsẹ gbe jade lonii.
6 74246 Orilẹede Serbia 1949 27.
8 1053 Orilẹede Antigua ati Barmuda 4 4.
Inú igbó yìí jẹ́ ọ̀kan nínú ibùgbé Robin Hood àti àwọn ọmọ ogun rẹ̀ wọ̀nyí.
Ganiyat tó fi irin gbígbóná àti àdá ya ara ọmọ àbúrò ọkọ rẹ ti dèrò àgọ́ ọlọ́pàá l' Ogun Bakan naa ni Carrot ni awọn eroja ara bii beta-carotene ti kii jẹ awọn sẹẹli ara ti ko dara ṣe aṣemaṣe.
Loju opo facebook BBC Pidgin lati ṣe alabapade ọrọ arakunrin kan Al Hassan III to sọ pe, Beyonce wa ni ipo kini ti Bob Marley tele ki o to wa kan Micheal Jackson.
Ninu ọrọ rẹ, O ni idi ti awọn fi fi oju wọn lede ni lati fi ọkan awọn eniyan balẹ wi pe ko si ewu loko longẹ, ati pe awọn ọlọkada to wa ni ọgọọrọ si ipinlẹ Eko, wa ṣiṣẹ ounjẹ ọjọ wọn.
Lara akiyesi awọn alẹnulọrọ ninu ipade naa ni ki awọn alaami ẹyẹ naa ma ma yan ara wọn fun igbimọ to n moju to ami idanilọla bayii, eleyii ti akọwe agba Ile-iṣẹ ijọba fun ọrọ iṣẹ ilu Pataki kan, Ọmọwe Jẹmilade Longẹ woye rẹBakan naa Akọwe Agba fun Ile-iṣẹ Ijoba to n ri Isuna-owo ni Ipinlẹ Eko, Arabinrin Olufunmilayọ Balogun sọ pe ko si abala ti yoo maa gba aami idanilọla naa pada lọwọ ẹni ti wọn ba fun, bi iru ẹni bẹẹ ba ṣe aṣemaṣe lọjọ iwaju.
Yóo ti ìka rẹ̀ bọ inú ẹ̀jẹ̀ náà, yóo sì wọ́n ọn sílẹ̀ nígbà meje níwájú OLUWA, níwájú aṣọ ìkélé tí ó wà ní ibi mímọ́.
gẹgẹ bi awọn ọmọ ijọ rẹ gbogbo ṣe maa n pe e, iyẹn Pasitọ Adeboye ni: niwọn igba ti awọn eeyan ba ṣi n jẹ ẹran maalu, awọn fulani yoo ṣi maa ṣe ohun to ba wu wọn.
Nigba to n se ifilọlẹ igbimọ naa, Makinde ni afojusun agbekalẹ igbimọ naa ni lati se afikun imọ ati iriri awọn asaaju ijọba oun, nipa gbigbe imọran pataki kalẹ fun ijọba.
Wọn a tun maa pe oṣu yi ni Rabi Al Thani.
inú rẹ ni tọmọdé tàgbà ti ń játùbú.
Ekiti: Àwọn ọmọ ilé ìgbìmọ̀ aṣòfin yọ abẹnugan ilé
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù EFCC: Pàṣípáàrọ̀ owó ni Mompha fi ń bojú láti ṣe gbájúẹ̀ àti 419 23 Ọ̀wàrà 2019 Oríṣun àwòrán, Instagram Àkọlé àwòrán, Orí ẹ̀rọ ayélujára ń gbóná lala láti ìgbà tí ọwọ́ sìnkú àjọ EFCC ti tẹ Ismaila Mustapha tí wọ́n ń pè ní Mompha.
Báwo lọ̀rọ̀ Tafsir, ìdanilẹ́kọ̀ọ́ lásìkò Ramadan yóò ṣe jẹ́ pẹ̀lúu Coronavirus tó gbòde yìí?
Irú ìyà kan náà tí ẹ rí ninu ìgbé-ayé mi, tí ẹ tún ń gbọ́ pé mò ń jẹ títí di àkókò yìí ni ẹ̀yin náà ń jẹ báyìí.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù EndSars Protest Update: Àwọn òṣìṣẹ́ ọgbà ẹ̀wọ̀n ń bẹ jàńdùkú àmọ́ wọ̀n kò gbọ́ 19 Ọ̀wàrà 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 22 Ọ̀wàrà 2020 Oríṣun àwòrán, Adetomi Akin Ileesẹ to n se akoso ọgba ẹwọn nilẹ wa, ẹka tipinlẹ Ondo ti salaye bi awọn janduku se ja ọgba ẹwọn Okitipupa laarọ Ọjọbọ.
Awọn eniyan mẹtalelọgọfa naa ni ile-isẹ eto aabo ayika ni ipinlẹ Eko fi panpẹ mu, ti wọn si fi ọrọ wa lẹnu wo, lẹyin ti awọn eniyan ta ile-isẹ aabo naa lolobo pe, awọn eniyan wọ ipinle Eko ni ọgọọrọ.
Ṣugbọn Jesu mọ èrò inú wọn; ó bá bi wọ́n pé, “Kí ló dé tí ẹ fi ń ro èrò burúkú ninu ọkàn yín?
Ọmọ iya kan naa ni Bidemi ati Sola Kosoko, wọn padanu iya wọn lọdun 1993.
Awọn ọmọ ẹgbẹ́ ṣe ìpinnu láti lo ìdìbo àbẹnu láti yan olùdíje sípò gẹ́gẹ́ bii àṣà ẹgbẹ́ tẹ́lẹ̀lẹ́yìn ìpàdé bònkẹ́lẹ́ pàjáwìrì tí àwọn ìgbìmọ amúṣẹ́ ṣe ṣe pẹ̀lú gomìnà ìpínlẹ̀ Ondo Rotimi Akeredolu lónìí.
Bi wọn se se eyi tan ni awọn agbebọn yii tun gba ọja abule naa lọ nibi ti wọn tun ti da ina ibọn bolẹ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Okeho Robbery: Ó tó 60 mílíọ̀nù tí àwọn olè jí ṣùgbọ́n a kò rí kọ́bọ̀ gbà padà- Òṣìṣẹ́ banki 19 Bélú 2018 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 10 Ògún 2020 Oríṣun àwòrán, Others Ileeṣẹ ọlọpaa ni ipinlẹ Oyo ti ni iwadii ti bẹrẹ ni pẹrẹwu lori ibi ti ọwọ ti awọn adigunjale gbe ni banki to wa ni ilu Okeho wọlẹ si.
Lílo nkan ìbomú kò tóò láti dènà pé kóò má á nìí coronavirus Èṣi àyẹ̀wò jáde, Gómìnà Bauchi ti ní aàrùn coronavirus báyìí Èèèyàn márùn ún péré ló leè lọ ayẹyẹ ìgbéyàwó ní Australia báyìí nítorí Coronavirus Ìjọba àpapọ̀ fẹ́ f'òfin dé irina ọkọ̀ akero jakejado Nàìjíríà Awọn onimọ iṣegun oyinbo si ti sọ pe wọn ko ti i fidirẹmulẹ pe Chloroquine le dena tabi wo aarun coronavirus.
Bayii wọn ti fi ẹsun kan obinrin naa ṣugbọn awọn kan gba pe awọn ofin ile Saudi mii yoo to di igbagbe labe Omoba Mohammed bin Salman.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Mimu ẹ̀jẹ̀ ejò máa ń fún ọkùnrin lágbára Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Mimu ẹ̀jẹ̀ ejò máa ń fún ọkùnrin lágbára 13 Owewe 2018 Àwọn tó ti jingíri nínú ẹran ejò jíjẹ ní ẹni tó ti ju àádọ́ta ọdún lọ ló leè mu ọtí wáìnì tí wọ́n ń ṣe látara ẹran ejò.
Ẹ̀mí Ọlọrun sì bà lé e, 
Eyi si ti mu ki awọn alasẹ o gba awọn araalu ni imọran láti fi ile wọn silẹ, titi ti wahala naa yoo fi wa sopin.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ajọ eto ilera ni agbaye, WHO, si sọ pe iye ṣuga ti eniyan yoo jẹ ni ojumọ ko gbọdọ ju aadọta giramu lọ.
Alaga fẹgbẹ awọn gomina, to tun jẹ gomina ipinlẹ Zamfara, Abdulaziz Yari, to ka abọ ipade pajawiri ti awọn gomina naa ṣe l'Ọjọru nilu Abuja, sọ pe ''wọn yoo gbe igbimọ kan dide lati ṣepade pẹlu Aarẹ Muhammadu Buhari lori ọrọ naa.
Nítorí wọ́n dẹ àwọ̀n sílẹ̀ fún mi láìnídìí,wọ́n sì gbẹ́ kòtò sílẹ̀ dè mí láìnídìí.
" Awọn ọmọ Naijiria yoo lanfaani lati yan eyi to ba wu wọn.
 Oríṣun àwòrán, others Nigba ti a beere taa ba wo ọjọ ori, ṣe alaafin ko lẹtọ lati dasi ọrọ naa, Fatomilọla sọ pe, agba ko kan ọrọ yii, kii si se ti ọjọ ori pẹlu."
Lai Mohammed ni:”Adura mi nipe ki Olorun re idile yii lekun lasiko yii.
agbofinro ati oludari ile-isẹ ọtẹlẹmuyẹ, pe abajade esi ibo ti rgbr PDP ni awon
O lẹ́wà bíi Jerusalẹmu,O níyì bíi ọ̀wọ́ àwọn ọmọ ogun tí ń gbé ọ̀págun.
Bi mo tilẹ̀ jẹ́ apárí síbẹ̀ kò tìmí lójú, Liliya Kukushkina A kó dúnkoòkò mọ́ Ambode, isẹ́ wa là ń ṣe - Ilé Aṣòfin Eko Ijọba tí júwọlẹ̀ fún Amẹrika lóri iwé ìrìna!
Nítorí náà ó sọ̀rọ̀ títí dòru.
Agbẹnusọ fun Ile Igbimọ Aṣofin nipinlẹ Eko, Mudashiru Obasa to fi idi ẹ mulẹ wi pe lootọ ni wọn n gbe abadofin naa yẹwo.
Bo ṣe ku ki wọn tu u silẹ lọjọ keje, oṣu keje, ọdun 1998 ni Moshood Kashimawo Abiola jade laye.
 gbogbo ohun tó sì ti sẹlẹ ̀ sí àwọn baba ńlá wọn ni wọ ́ n máa ń mú lò nínú orin wọn pàápàá .
”Mose bá wí pé, “Bí o ti wí gan-an ni yóo rí, kí o lè mọ̀ pé kò sí ẹlòmíràn tí ó dàbí OLUWA Ọlọrun wa.
 omo egbé náíjá kongò ( niger-congo ) ni wón .
 ) ( the solders were on guard all night.
Awọn ọmọ eeyan ma n lẹ oko mọ ọmọ ẹyẹ, wọn ma n pa wọn.
"lẹ ́ yìn tí ó parí ẹ ̀ kọ ́ rẹ ̀ ni wọ ́ n gba bámijí Òjó sí ilé iṣẹ ́ ìròyìn ní ọdún 1970 , Àlhàájì lateef jákàńdè ni ó gbà á sí iṣẹ ́ ìròyìn ní ilé-iṣẹ ́ "" tribune "" ní ìlú Èkó , gẹ ́ gẹ ́ bí igbá kejì olóòtú Ìròyìn yorùbá ."
#BigBrotherNaija g'ori afẹfẹ Khafi wọ gàu lẹ́nu iṣẹ́ lórí ẹ̀sùn ìbálòpọ̀ ní BB Naija Seyi Awolowo, ọmọ-ọmọ Awolowo, kí ló ń wà lórí ètò BB Naija?
Igbẹ adiyẹ naa a ma a lẹ mọ oju ara wọn.
Pẹlu eyi iye awọn eeyan ti ajakalẹ aarun coronavirus ti ran jade laye ti di ẹgbẹrun kan o le mẹtala.
Bakan naa ni dukia ti ile ẹjọ ba beere lọwọ rẹ, ile ẹjọ kọ lo ni i, ile ẹjọ yoo gba a ni ti ẹni naa ba sa lọ.
Lootọ awọn ẹgbẹ Bisọbu Aguda fi atẹjade sita ti wọn fi fi atilẹyin han fun iwọde awọn ọdọ lori wahala awọn ọlọpaa to waye ṣugbọn ko si igba kankan ti wọn jade sita lati darapọ mọ iwọde naa.
Shittu jere ẹgbẹ ni, nitori pe oun nikan kọ lo wa ni ipinlẹ Ọyọ, ka to o fi jẹ minisita.
sọjí bẹ ̀ rẹ ̀ ẹ ̀ kọ ́ rẹ ̀ ní ilé-ẹ ̀ kọ ́ alákọọ ́ bẹ ̀ rẹ ̀ st.
Nígbà tí à ń ṣẹ̀dá egungun mi lọ́wọ́ ní ìkọ̀kọ̀,tí ẹlẹ́dàá ṣẹ̀ṣẹ̀ ń ṣọnà sí mi lára ní àṣírí,kò sí èyí tí ó pamọ́ fún ọ.
Amọṣa, abajade iwadii naa ko ṣai tun ṣe e lalaye pe iye awọn eeyan to ku sinu ikọlu igbesunmọmi ti dinku lọdun 2019 yii si ọdun 2018 lorilẹ-ede Naijiria.
"Lóòótọ́ ni mo dù ipò òṣèlú mú rí, mo sì ti kúrò nibẹ láti May 2019, bóyá wọn wa ro pe owo oselu si ku nílé ni, kò ye mi, mo roo, roo, n kò rí ro, èmi kò ṣe ibajẹ si ọdọ ẹnikẹ́ni, n kò sì ba ti ẹnikẹ́ni jẹ́, ṣùgbọ́n mo mọ pe, ibi tí ọ̀rọ̀ aje Naijiria de dúró rèé.
Dafidi ṣe ohun tí Ọlọrun pa láṣẹ fún un, wọ́n pa àwọn ọmọ ogun Filistini láti Gibeoni títí dé Gasa.
Awọn alaṣẹ ilu Minneapolis gbẹsẹ le fifi ẹsẹ fun afunrasi lọrun mọlẹ tofimọ awọn ọna miran tawọn ọlọpaa n lo lati fi mu awọn afunrasi mọlẹ.
ati gaasi lorile ede Naijiria Leemon Ikpea ku ori ire odun  méjílélọ́gọ́ta ti  o pe ni ojo mọ́kàndínlógún, osu kejila odun
Amọ, o ni ijọba orilẹede Naijiria yoo ri wi pe iye ti wọn ta a, ko kọja agbara awọn ti yoo ra a.
Fulani kò leè dúró, táa bá lo ohun ta jogún lọ́dọ̀ àwọn bàbá wa - Sunday Igboho Ẹ̀yin ọ̀tá mi, ẹ lọ dì mọ́ òpò ina lọ́dún 2020- Ayodele Fayose Ó ti tán fún mí lọ́dún 2023- Ààrẹ Muhammadu Buhari Bàbá akẹ́kọ̀ọ́ LASU tí ọ̀rẹ́kùnrin rẹ̀ àti pásítọ̀ fi ṣ'oògùn owó ń bèèrè fún ìdájọ́ òdodo Fayemi ṣalaye pe awọn ẹṣọ 'Amọtẹkun' yoo maa ṣe iranwọ fun awọn agbofinro ni gbogbo ipinlẹ mẹfa nilẹ Yoruba.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ẹ wá dánrawò níbí pẹ̀lú Àpólà Ọ̀rọ̀ Orúkọ, Noun Phrase"" Ẹ̀yin tí ẹ kò gbọ́ Yorùbá, ẹ ṣúnmọ́ bí láti kọ́ lítíréṣọ̀ èdè Yorùbá lórí BBC Olùkọ́ Bunmi Femi Amao ló ń kọ́ wa ní Ọ̀rọ̀ Ẹ̀yán lonìí Ẹ ṣúnmọ́ bí láti kọ́ ẹ̀kọ́ nípa ìsọ̀rí ọ̀rọ̀ nínú gbólóhùn Yorùbá Àṣà Oge Ṣíṣe ní Akọ́mọlédè BBC Yorùbá ń gbé yẹ̀wò lónìí, Ó yá, iṣẹ́ ti bẹ̀rẹ̀."
Òsèré Tíátà ọmọ nàìjíríà, olórin, olùdarí àti olóòtú.
ati ile igbimo asoju-sofin lati tun fowosowopo lati mu awon kudiẹ- kudiẹ to wa
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Bolaji Faleke ni Olùkọ́ tó ń kọ́ wa ní àṣà oge ṣiṣe lórí BBC Yorùbá Adeniyi sàlàyé pe, èyí tó burú jùlọ ni pé, ọjọ́ kan ti o yẹ ki ìpàdé wáyé, ni bàbá lọ ko àwọn ènìyàn bi ogún kan wa, ti wọ́n si da ìpàdé rú, lẹ́yìn náà ni wọ́n gbe abájáde ìpàde lọ fun àwọn oní ìwé ìròyìn.
Gomina Abubakar Badaru ti ipinlẹ Jigawa, Abdullahi Ganduje tipinlẹ Kano, Ibrahim Geidam ti ipinlẹ Yobe, Abdullahi Abubakar ti ipinlẹ Bauchi, pẹlu Aminu Masari lati ipinlẹ Katsina, ni wọn wa nikalẹ lati gba Aarẹ Buhari lalejo ni papakọ ofurufu ilu Dutse.
Gẹgẹ bii Ọba ilu naa, Ọba Isaac Ayẹni, Akila ti Ẹrin Ijẹṣa ṣe sọ, ọjọ meje ni o gba awọn baba bla wọn lati rin kuro ni ile Ifẹ deibudo ti omi naa wa.
Huspuppi arrestgedi: Hushpuppi l'ẹ́jọ́ láti jẹ́, Invictus Obi gbà pé òun jẹ̀bi ẹ̀sùn gbájúẹ̀ ẹgbẹ̀lẹ́gbẹ̀ owó lágbáyé
Ẹ̀ṣẹ̀ mìíràn wà tí ó la ti ikú lọ.
17 Àti pé bí Ọlọ́run bá fún un ní agbára lẹ́ẹ̀kan síi, tàbí bí òun bá ṣe ìtúmọ̀ lẹ́ẹ̀kansíi, tàbí, ní ọnà míràn, bí òun bá lè mú awọn ọ̀rọ̀ kannáà jáde wá, kíyèsíi, a ti ní àwọn ọ̀rọ̀ wọ̀nyí ní ọwọ́ wa, àwa sì ti pààrọ̀ wọn;
Ẹ̀yin ará, ẹ wo ọ̀nà tí Ọlọrun gbà pè yín.
O lee jẹ onisowo ata nigba aye rẹ, tabi ko jẹ ẹda kan ti ko gba gbẹrẹ, to tete maa n binu, ata wẹwẹ ẹda.
Ko si ẹnikan kan to le yè.
Ó sì fẹ́ iyawo fún gbogbo wọn.
tilekun , ile itaja re, ki o si maa fi ebi pa awon eniyan, ki o wa ni ko ni si
Amọṣa, nigba ti BBC News Yoruba kan si ileeṣẹ ọẹọpaa ni ipinlẹ Ondo lati mọ bi ọrọ ti jẹ, alukoro ileeṣẹ ọlọpaa nibẹ, ASP Tee Leo-Ikoro ṣalaye pe lootọ ni awọn gbọ si ikọlu naa ti awọn ọtẹlẹmuyẹ si ti bẹrẹ iṣẹ lori rẹ ni pẹrẹu.
Àwọn jàǹdùkú ṣe ikú pa ẹnìkan n'ílùú Eko Wọ́n fi agídí sé ọmọ Naijiria mọ́lé ní China nítorí àrùn Coronavirus Àwọn Ìpínlẹ̀ tí coronavirus kò tíì dé ní Nàìjíríà, àti ìgbésẹ̀ tí wọ́n ń gbé láti dènà rẹ̀ Wo àwọn ọmọbìnrin tó mu ìtọ̀ ara wọn nítorí òùngbẹ aṣálẹ̀ Sahara Ta ló ga jù lábà?
Ta ni ṣubú sinu ẹ̀ṣẹ̀ tí ọkàn mi kò bàjẹ́?
O fikun oro re pe,“pataki atunto ipo ohun ni lati ri daju pe, onikaluku n se ojuse ise re bi o se to ati bi o se ye.
Ṣugbọn ifarapa leralera lori ookun rẹ ko jẹ ko le gba bọọlu pẹ.
Nígbà tí Sakaraya rí i, ó ta gìrì, ẹ̀rù bà á.
Amọ o ṣe ni laanu pe, kokoro iku ko jẹ ki awọn tọkọtaya tuntun naa gbadun ara wọn, nitori osu meji lẹyin igbeyawo ni Morohunfolu jade laye.
Ní ọjọ́ kan bí Jesu ti ń kọ́ àwọn eniyan, àwọn Farisi ati àwọn amòfin jókòó níbẹ̀.
Èyí tí ó wáá yà mí lẹ́nu ni èyí pé ibikíbi tí mo bá yà sí ni àwon ẹranko eọ̀nyí ń yà sí àfi bí ẹni pé èmi ni wọ́n ń wá kiri ni, bẹ́ẹ̀ ni wọ́n ń lọ tiwọn ni, ṣe ló jọ bẹ́ẹ̀ lójú mi.
FIFA: Infantino máa bá'ṣẹ́ rẹ lọ
Ijipti ni ó bí Ludimu, Anamimu, Lehabimu, Nafutuhimu, 
Boko Haram tún pa èèyàn mẹ́ẹ̀dógún lágbègbè Maiduguri
Ninu atẹjade ti Ọjọgbọn Ogundipe fi ọwọ si fun ra rẹ, o ṣalaye pe ki gbogbo awọn ti ọrọ fasiti UNILAG kan kọ eti ikun si iroyin ofege ọhun.
Ọkunrin náà dá a lóhùn pé, “Láti Bẹtilẹhẹmu ti Juda ni a ti ń bọ̀, a sì ń lọ sí ìgbèríko kan ní òpin agbègbè olókè Efuraimu níbi tí mo ti wá.
 awon abule pelu awon adako bere ni arin odun 3600 ati 2600 sk .
Mo ti ròyìn òdodo ninu àwùjọ ńlá.
Ọkọ rẹ̀ a máa rẹ̀ ẹ́ lẹ́kún, a máa bi í pé, “Kí ní ń pa ọ́ lẹ́kún?
Nigba to bẹrẹ igbẹjọ ọhun, agbẹjọro fun ikọ olujẹjọ, Olusola Oke salaye pe ogun ẹlẹrii ni yoo ma jẹri gbe onibara oun.
Yahaya Bello ni ìgbélé náà yóòràn ìjọba lọ́wọ́ láti lé jẹ ki wọ́n rí àwọn tó ti ní ǹkan ṣe pẹ̀lú imaamu náà ati ọmọ rẹ.
Gbedeke ọsẹ meji pere si ni ajọ naa fi silẹ lati sẹ bẹ ẹ.
Lẹyin ti ọlọpaa mu awọn afẹsunkan naa, ni wọn mu awọn oluwadii lọ ibi ti wọn sọ iyoku ara ọmọdekunrin naa si ninu ile kan ti wọn ko ti i kọ tan ni Sapati.
Kí ìwọ tóó wọ inu igbó náà pàápàá ẹ̀rù oníbodè ibẹ̀ ń bà mi, nítorí iwin burúkú ni, Àǹjànnú-ìbẹ̀rù ni orúkọ rẹ̀ ń jẹ́.
Olóore ati olódodo ni OLÚWA,nítorí náà ni ó ṣe ń fi ọ̀nà han àwọn ẹlẹ́ṣẹ̀.
Àwọn yòókù yóo gbọ́, ẹ̀rù yóo bà wọ́n, wọn kò sì ní ṣe irú nǹkan burúkú bẹ́ẹ̀ mọ́ láàrin yín.
Ewe, Sergio Aguero naa darapo mo won, sugbon ko kopa latari ifarapa ti o ni.
Naomi Campell omo Liberia lo muu wo ori itage nibi ti awon eekan bii Drake, Beyounce ati Adele ti sere seyin.
Bí a bá yọ ti agbègbè ààbò kúrò, nígbà mìíràn pípa ẹyẹ yìí fún oúnjẹ, ní òkè kékeré tí ó yí àfonífojì Kathmandu ká ti mú kí ẹyẹ Spiny Babbler dínkù ni iye.
Fayoṣe: Mi ò jẹ̀bi ẹ̀sùn kankan Agbẹjọ́rò: Ẹsun pe Ọgbẹni Ayọ Fayoṣe ni ọjọ kẹtadinlogun oṣu kẹfa ọdun 2014, tẹwọ gba owo ti iye rẹ jẹ miliọnu marun dọla owo ilẹ amẹrika lọwọ Sẹnetọ Musiliu Obanikoro, ẹni to jẹ minisita abẹle feto abo nigba naa.
 ohun tí à ń sọ ni pé àwọn obìnrin nìkan ló ń kópa nínú àgbékalẹ ̀ ewì ayaba .
Ayé kò lè gbà á nítorí ayé kò rí i, bẹ́ẹ̀ ni kò mọ̀ ọ́n.
Wasiu Ayinde: Ìrìnàjò ọdún kẹtàlélọ́gọ́ta rẹ̀ rèé, títí tó fi di Máyégún ilẹ̀ Yorùbá
Lara awọn to jẹ anfani eto yii, Ọgbẹni Afọlarin Lateef ẹni ti o gba ẹrọ amunawa ati ẹrọ igẹrun fi ẹmi imoore han si eto ironilagbara yii ati aṣofin to ṣgbatẹru rẹ gẹgẹ bi ara ere Ijọba Tiwantiwa lorilẹ-ede Naijiria.
NASS media coverage: À n ṣe àgbéyẹ̀wò ìlànà túntún fún àwọn akọ̀ròyìn
Adeosun wa sọ pe, orilẹede Naijiria lo n gba owo ori to kere ju lọwọ awọn ile isẹ to n pese ọti ati siga.
gẹ́gẹ́ bi o ṣe sọ pé nígbà ti ìgbákeji ààrẹ lọ ilú rẹ̀ ni ọrọ naa ṣẹlẹ̀, ati pe ki o pésé fọnràn aworan tàbi ohùn ti wọ́n gbà silẹ̀ bí ẹ̀rí.
Bẹ́ẹ̀ ni ọ̀pá fìtílà tí a fi ojúlówó wúrà ṣe, ati àwọn fìtílà orí rẹ̀, pẹlu gbogbo àwọn ohun èlò rẹ̀, ati òróró ìtànná rẹ̀.
Ni orilẹede Ghana lọjọbọ, nṣe lawọn adigunjale kan ya bo agọ ọlọpaa kan lolu ilu orilẹede naa.
Baba onile to n sun ita ni Biya Oríṣun àwòrán, Intercontinental Hotel Àkọlé àwòrán, Ile itura to gbayi ni Switzerland ni Biya n gbe ju Awọn kan maa n ṣapejuwe Aarẹ Biya gẹgẹ bi baba onile, ṣugbọn ti kan-in-kan-in ile rẹ kii ta nidi, nitori pe ọpọlọpọ akoko lo maa n wa ni awọn ile itura to gbayi, to si wọ́n pupọ ni orilẹede Switzerland.
Adebola, tii ṣe ọmọ bibi ilu Ile-Ife ni oun n ṣe awada naa, nigba ti ọwọ oun dilẹ ni, lai mọ pe o lee di nkan nla, ti awọn eeyan kii si jẹ ki oun gbadun, ti oun ko ba ṣe.
Chukwu so pe iko omo oogun orile ede Naijiria tun ri ibọn AK 47, to lee yin ọta ọgọ́ta leekan naa papọ.
Lẹyin naa to ba di irọlẹ, wọn a pejọ si ile ijọsin lati jẹ oujẹ alẹ Oluwa eyi ti Jesu Kristi jẹ pẹlu awọn ọmọ ẹhin rẹ lọjọ naa.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Òkè Ìdànrè: Òkè tó kéré jùlọ jẹ́ ẹsẹ̀ bàtà 3000 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 3 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 5 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Adesina ni, bí wọ́n ṣe n sọ pé, orílẹ̀-pedpe Nàìjíríà ni olú-ilú àwọn òtòsì lágbàyé, kìí ṣe orí ìjọba yii ni òṣì náà ti bẹ̀rẹ̀, bí kìí ṣe bi àwọn adarí ti ṣe ṣe owó ìlú mákumaku láti ààdọ́ta ọdún sẹ́yìn, kìí ṣì ṣe ǹkan ti ìjọba tọ n bẹ lóde le ṣe láàrin ọdun méjì Nínú ọ̀rọ̀ rẹ̀, ó ni àwọn ìgbẹ́sẹ̀ ààrẹ Buhari yóò mú ènìyàn ọgọ́rùn mílíọ̀nù kúrò nínú òṣì ni ọdún mẹ́wàá síbí.
 Àwọn ohun ẹlẹ ́ ẹ ̀ mí ṣe é tòsọ ́ tọ ̀ bíi oníàhámọ ́ kan ( consisting of a single cell ; èyí kàkún ọ ̀ pọ ̀ àwọn baktéríà ) tàbí oníàhámọ ́ púpọ ̀ ( èyí kàkún àwọn ọ ̀ gbìn àti ẹranko ) .
Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí AfCFTA: Orilẹẹde 44 t'ọwọ bọ'we ilana okoowo tuntun fun Afrika21 Ẹrẹ̀nà 2018 Toxic Cream: Uk ní kí tọkọtaya san £17,000 owo itanran ati ṣíṣe iṣẹ́ ìlú fún ọgọ́ta wákìtí9 Ọ̀wàrà 2019 Online VAT: Sísan owó orí ọjà lórí ayélujára yóò mú kí ọrọ̀ ajé rú gọ́gọ́ si27 Ògún 2019 Bitcoin: Wo àwọn nkan tí ó yẹ kí o mọ̀ nípa Bitcoin, kí o tó ó dáwọ́ le e16 Agẹmo 2020 Buhari jawọ ninu ilana okoowo tuntun fun Afrika19 Ẹrẹ̀nà 2018 AfCFTA: Buhari gbe igbimọ kalẹ lori adehun okoowo ọfẹ22 Ẹrẹ̀nà 2018 Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí kan sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
Bi awọn orileede to n fofin de UK lati ma rinrin ajo wa ilu wọn se n peleke sii ajọ isọkan agbaye (WHO) n gbiyan lati se afiwe iru ewu to wa nibẹ.
Bẹ́ẹ̀ ni yóo ti ṣe ètùtù fún ibi mímọ́ náà, nítorí àìmọ́ àwọn eniyan Israẹli, ati nítorí ìrékọjá ati gbogbo ẹ̀ṣẹ̀ wọn, bẹ́ẹ̀ gan-an ni yóo sì ṣe sí Àgọ́ Àjọ tí ó wà láàrin wọn, nítorí àìmọ́ wọn.
Oríṣun àwòrán, NCDC Àwọn tó bọ́ lọ́wọ́ Coronavirus ni ìpínlẹ̀ Eko àti Kaduna lé díẹ̀ ni ọ̀ọ́dúnrún O lé ni ẹgbẹ̀rún ènìyǹ to ti bá ààrùn Covid-19 rìn lọ́dún yìí.
Ó ṣe agbada omi ńlá kan ati àwọn ère mààlúù mejila tí wọ́n wà ní abẹ́ rẹ̀.
Láti ọjọ́ náà ni wọ́n ti ń gbèrò ọ̀nà tí wọn yóo fi pa Jesu.
Ọ̀ṣun Oṣogbo 2018: Ulrich Salazar wálé ọdún láti New York
Obìnrin Mùsùlùmí ṣe ilé àlúfà ní ọ̀ṣọ́ fún Kérésìmesì Àwọn gómìnà nílẹ̀ Yorùbá ti kùnà láti pèsè ààbò tó péye fún aráàlú - Ẹgbẹ́ Majeobaje Apo asunwọn banki: Awọn banki ni Naijiria ma n gba NIN gẹgẹ bi ami idanimọ, ki wọn o to le ṣi apo asunwọn pẹlu wọn, tabi bẹrẹ si ni lo asunwọn ti o ko lo fun igba pipẹ pada.
Ojọgbọn yii fẹyinti, o si fi ilẹ America ṣe ibujoko fun ọpọlọpọ ọdun ko to o pada waye Ilé iṣẹ́ márùn ún tí wọ́n dárukọ kìí ṣe túntun- Garba Shehu FRSC dá N443,180 padà fún ẹbí ẹni to ní ìjàmbá mọ́tò Ọlọ́pàá Germany ń wádìí àfurasí mẹ́rin nínú àwọn tó kọlu Ekweremadu ni Germany Iṣẹ́ bọ́ lọ́wọ́ ọlọpàá mẹ́rìn to pa afurasí, wọ́n tún dèrò ẹ̀wọ̀n Iwe tuntun to ṣe yii gbe iwadii tuntun jade lori ero Samuel Johnson (1846-1901) nipa ilẹ Arab bii orisun Yoruba.
Ṣugbọn ara òkúta ni gbòǹgbò rẹ̀ rọ̀ mọ́,òun gan-an sì ń gbé ààrin àpáta.
N kò ṣe ibi sí ẹnikẹ́ni ninu wọn bẹ́ẹ̀ ni ń kò gba kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ ẹnikẹ́ni wọn.
O ni aṣiwere ni gbogbo awọn to n ṣatilẹyin fun ẹgbẹ APC ti wọn n sọ oko ọrọ si PDP nitori ipade itagbangba ti wọn ṣe ni Ibadan.
Ẹ yìn ín, ẹ̀yin ọba ayé ati gbogbo orílẹ̀-èdè,ẹ̀yin ìjòyè ati gbogbo onídàájọ́ ayé;
Building Collapse: Wọ́n yọ èèyàn mẹ́rin níbi ilé mííràn tó wó l'Eko
Arsenal gbiyanju lati da goolu naa pada, ṣugbọn pabo ni gbogbo igbiyanju ja si.
O ni bayii, inu baba oun dun si oun nitori oun ti n ri owo mu wale.
Ìṣẹ̀lẹ̀ ìpànìyàn: Iléeṣẹ́ aṣọ́bodè ní àṣìta ìbọn ló fa sábàbí
O pa àwọn ọ̀tá run patapata, o sọ ìlú wọn di ahoro,o sì sọ wọ́n di ẹni ìgbàgbé.
Ṣugbọn a pada gbọ wi pe ọrọ naa ti yanju laarin agba oloṣere mejeji yii ti wọn si ti n mura igbesẹ itẹsiwaju fiimu 'Ti Oluwa nilẹ'.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìkọlù Afghanistan: Akọ̀ròyìn BBC àti èèyàn mẹ́jọ jáláìsí 1 Èbibi 2018 Àkọlé àwòrán, BBC sọ wipe Shah jẹ akọroyin ti awọn eniyan buyi fun, nitori o gbajugbaja, o si mọ isẹ rẹ ni isẹ Akọroyin BBC kan ni wọn ti pa ni ila oorun agbeegbe khost, ni orilẹ́ede Afghanistan lọjọ ti wọn se ikọlu to pa eniyan ogoji, ti akọroyin mesan si wa ninu wọn.
"Oríṣun àwòrán, @victoryomogiate ""Ko si to ba mi ni ajọsepọ, ni mo ti sọ fun pe emi kii se oninabi, amọ to seleri fun mi pe oun ko ni ja mi kulẹ laelae."
9 219652 North Macedonia 1924 92.
Gómìnà Sanwo-Olu pàṣẹ pé kí wọn tú ẹléwòn 6 sílẹ lásìkò Kérésìmesì Funke Akindele, Toyin Abraham, Bimbo Oshin ṣe Kérésìmesì lọ́nà àrà Èyí ni ìdí tí a kò fi yọ̀nda El-Zakzaky pẹ̀lúù Sowore àti Dasuki- Malami Bi àwọn kan ṣé n jẹ àsun ní àwọn míì n ṣeré lórí omí láti gbádùn Kérésì àná Bournemouth lo kọkọ gba goolu wọle nigba ti ifẹsẹwọnsẹ naa wọ iṣẹju karundinlogoji pẹlu Dan Gosling.
Àwa nìyí, a kò pọ̀ jù báyìí lọ.
Ṣugbọn mo dàbí ọ̀dọ́ aguntan tí wọn ń fà lọ sọ́dọ̀ alápatà.
Ó rí wọn, ó sì mú àwọn mejeeji pada wá sí ilé.
Látẹ̀yìn wá, nígbà tí Saulu pàápàá wà lórí oyè, ìwọ ni o máa ń kó àwọn ọmọ Israẹli lọ sógun.
" Koda, o ni oun n bẹbẹ fun oogun orun, ṣugbọn oyun inu rẹ ko faaye gba lilo iru oogun bẹ ẹ.
tí wọn ń ṣe iṣẹ́ ibi.
Àròsọ àti ìgbàgbọ́ àwọn ènìyàn lórí gbígba ẹ̀jẹ̀ Ọmọ isaac Adewọle gba ìdáǹdè lọ́wọ́ ajínigbé Ìṣẹ́ tó mu ọmọ Nàíjíríà lómi ti gba oorun lójú mi - Osinbajo A kò fẹ́ Festus Adedayo ní ìjọba Buhari - Àwọn olólùfẹ́ APC yarí Wọn ma n ki awọn Aina pe: Aina Ogunyunmọla A dá ilá ọkọ re A se ọbẹ̀ ọkọ lọ́tọ̀ Ebi kìí pa ọkọ Aina òrósùn rara Iná dídá kìí ni wọn lára nitori ọkọ."
Olówó ni ọkùnrin náà ó sì ní tó ilé méjì sí ìletò yìí, ọ̀kan nínú ilé náà lo ń gbé nígbà tí a báa, gbogbi nǹkan ti o fi ń rránṣẹ́ si wa wọ̀n-ọnnì ọkùnrinn kan báyìí tí orúkọ rẹ̀ ń jẹ́ Ojuayédùn lo ń tẹ̀lé wọn wá, òun ni olórí àwọn to ń ṣiṣẹ́ lábẹ́ Ayédèrú-ẹ̀dá.
Aarẹ awọn dokita naa ni ẹka ile iwosan ijọba apapọ, FMC, to wa ni Abeokuta, Adekunle Akeem Jimoh sọ fun BBC pe ijọba apapọ ko ṣe awọn ohun to yẹ ni ṣiṣe lo jẹ ki wọn daṣẹ silẹ.
Iṣẹ wọn ni lati ṣagbeyẹwo awọn ẹri ti awọn eeyan fi ranṣẹ ki wọn si ṣe ohun to yẹ lori ipaniyan lọna aitọ gbogob to ti waye sẹyin ni ipinlẹ Eko.
Ìlú náà yóo di àlàpà títí lae, ẹnikẹ́ni kò sì gbọdọ̀ tún un kọ́ mọ́.
Ifeanyichukwu Chiejine: Agbábọ́ọ̀lù Chiejine jáde láyé lẹ́yìn ààsàn ráńpẹ́
Damasus, Omotola, Ezekwesili, Funmi Iyanda dá sí ẹ̀sùn ìfipábánilòpọ̀ Fatoyinbo
Saraki ni ki ile lo ida ogoji lati ṣeranwọn feto ẹkọ awọn ọmọ sẹnẹtọ to ku nigba to jẹ adari ile lati ọdun 2015 si 2019.
Isamotu Rafiu Olasunkanmi, Kọmisana ilera ni Osun ni awọn ara ilu kii fẹ lo ibomu ati pe, iye awọn to n ko arun Covid-19 n peleke si ni.
Alufaa yóo pàṣẹ pé kí wọ́n pa ọ̀kan ninu àwọn ẹyẹ náà sinu ìkòkò amọ̀, lórí odò tí ń ṣàn.
Oríṣun àwòrán, @Ajoku Àkọlé àwòrán, Irẹsi alasepọ Jọlọọfu lounjẹ to tun n gbayi ni gbogbo inawo awọn Yoruba lasiko yii.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Nigerian Traffic Laws: Ohùn tó yẹ ní mímọ nípa òfin ojú pópó 30 Bélú 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Lilọ bibọ loju popo jẹ ohun ti a ko le sa fun gẹgẹ bi ọmọ eniyan.
Ní àkókò tí àwọn adájọ́ ń ṣe olórí ní ilẹ̀ Israẹli, ìyàn ńlá kan mú ní ilẹ̀ náà.
Kí o tó ṣẹ́jú pẹ́, owó rẹ lè ti lọ,ó le gúnyẹ̀ẹ́ kí ó fò,bí ìgbà tí ẹyẹ àṣá bá fò lọ.
Oríṣun àwòrán, Facebook/Bauchi State Government ''Lawọn ibi ta baa ri pe ofin yi ku diẹ kaato, awa naa yoo ṣatunse rẹ bi Kaduna ti ṣe ṣe ti wọn'' O ṣalaye pe ''A o fi aye silẹ ki titẹ lọda wa ninu ofin wa gẹgẹ bi ijiya ifipabanilopọ'' Mohammed ni oun mọ pe titẹle ofin yi le fẹ le diẹ ṣugbọn awọn yoo ṣe ni ibvamu pẹlu aṣa ati iṣẹṣe awọn eeyan Bauchi.
 Àwọn ọmọdé ní í máa n sáábà tan àìsàn náà kálẹ ̀ ju àwọn àgbà lọ .
N81m pọ̀ lóòtọ́ láti fi gé koríko Stadium, Ọ̀gá Mínísítà,èló lẹẹ́ san fáwa ọ̀dọ́ láti gè e?
Nítorí ara tíí bàjẹ́ yìí níláti gbé ara tí kì í bàjẹ́ wọ̀; ara tí yóo kú yìí níláti gbé ara tí kì í kú wọ̀.
Ninu àwọn ọmọ Ṣefataya, Sebadaya, ọmọ Mikaeli, ni olórí;orúkọ ọgọrin eniyan ni wọ́n kọ sílẹ̀ pẹlu rẹ̀.
Ijọba rọ awọn ileeṣẹ redio ati amohunmaworan to fi mọ awọn ileeṣẹ iroyin mii pe ki wọn darapọ mọ ileeṣẹ tẹlifisan ijọba apapọ, NTA lati le ṣafihan ọrọ fawọn eeyan.
Wọ́n dá a lóhùn pé, “Àbí ará Galili ni ìwọ náà?
Oriṣiiriṣii orukọ ni Yoruba maa n sọ ọmọ bii orukọ abisọ, orukọ to fi ẹsin ẹni hàn, orukọ to fi iṣẹ idilẹ ẹni han ati bẹẹ bẹe lọ.
Ẹwẹ, o fi kun un pe wọn san owo idasilẹ lọwọ awọn mejeeji ki wọn to gba itusilẹ, awakọ ati olokoowo ni awọn mejeeji.
Amọ ni bayii, ajọ NIMC ti fi ikede sita pe ẹṣẹ ni fun ẹnikẹni lati gba iru owo bẹ ẹ, nitori pe ọfẹ ni eto iforukọsilẹ ati gbigba NIN.
Olùrànlọ́wọ́ pàtàkì fún ọ̀rọ̀ ibojì òkú, àti àwọn ipò òṣèlú mìíràn tó jẹ́ kàyééfì ní Nàìjíríà Buruji Kashamu jẹ́ ènìyàn tó nífẹ̀ aráàlú- Gómínà Dapo Abiodun Baba Obasanjọ kò ní àrùn Coronavirus- NCDC Kí ló mú Obasanjo ti ilẹ̀kùn mọ́ ẹbí, òṣìṣẹ́, ojúlùmọ̀ ní ibi òkú àna rẹ̀?
Ó ní wọ́n bèèrè fún gbígba onídúró tọkọ-taya náà, àmọ́ adájọ́ tó ń gbọ́ ẹjọ́ náà, Gideon Kurada ní kí òun kọ̀ ìbèèrè náà sínú ìwé.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ogun Police: Àwọn jàǹdùkú kọlu ọlọ́pàá, DPO faragbọta, ọlọ́pàá mẹ́rin di àwátì 6 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Oríṣun àwòrán, AFP Àkọlé àwòrán, Ìgbà àkọ́kọ́ kọ́ nìyí tí irú ìṣẹ̀lẹ̀ bẹ̀ yòó wáyé Bi awọn to n ṣọ araalu ba di ẹni ti awọn janduku wa bẹrẹ si ni jigbe, kini ki ara yooku wa a ṣe?
Àwọn onímọ̀ Islam àti Oluwo takora lórí oyè Wàzírì Ija eerin meji: Oluwo ati Ọọni Ọba alade naa lopin ọsẹ we lawani fun Waziri gbogbo ilẹ Yoruba.
Bojú wo àpáta wa, Ọlọrun,fi ojú àánú wo ẹni àmì òróró rẹ.
Ni ọjọ́ keji ọ̀sẹ̀, ọjọ́ keje oṣù kẹfà, ọdún Ẹgbàá-lémẹ́rìndínlógún, ilé-iṣẹ́ Amóhùn-máwòrán Kẹrin ni Ilú-Ọba fi àpẹrẹ hàn bi àwọn ọmọ Ọlọ́rọ̀ lati Nigeria ti mba owó ninú jẹ́ ni Ilú-Ọba.
Ẹfọ tabi ewebẹ Oríṣun àwòrán, Getty Images Nọọsi Adanna ni jijẹ ewe ''pumpkin'' ati amunututu dara fun agọ ara.
Àyà mi ń lù kìkìkì,n kò sì lè dákẹ́;nítorí mo gbọ́ ìró fèrè ogun, ati ariwo ogun.
"Kii ṣe Yewande nikan ni ijọba da silẹ, oun ati awọn ẹlẹwọn mi ti apapọ wọn kẹ ẹẹdẹgbẹta ni wọn da silẹ.
 Dokita Vahwere, to sọ eyi fun BBC tun sọ pe ""awọn miran tiẹ maa n sọ pe iwosan ti wọn n fun awọn to ni aarun naa gan an lo n pa wọn."
Ko si akọsilẹ fun Orilẹede Benin, Namibia, Tunisia ati Zimbabwe Orilẹede wo ni ọrọ aje rẹ dara julọ?
Agenda 2050: Wo ohun tó yẹ kí o mọ̀ nípa ìgbìmọ̀ tuntun tí Buhari gbé kalẹ́ lórí ìdàgbàsókè Nàìjíríà Ileeṣẹ to n ri si ọrọ owo yiya ni Naijiria, Debt Management Office, DMO, ti sọ pe iye gbese ti Naijiria jẹ lapapọ bayii ti le ni tiriliọnu mọkanlelọgbọn.
aabo fun arinrinajo oko ofurufu ati igbaye-gbadun awon arinrinajo.
Nítorí náà, pàṣẹ kí wọ́n ṣọ́ ibojì náà títí di ọjọ́ kẹta.
“Bẹ́ẹ̀ ni, ìwọ ọmọ rẹ̀ Beṣasari, o kọ̀, o kò rẹ ara rẹ sílẹ̀, bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé o mọ̀ nípa ìṣẹ̀lẹ̀ yìí.
fun awon ere idaraya miran ni ede geesi  kan si.
Ó wá wí fún ọkunrin náà pé, “Na ọwọ́ rẹ.
Awọn ẹgbẹ naa ni awọn aramanda ẹja agia (Dolphins) to wa ninu rẹ lo tin dinku lati mejidinlaadọjọ si mẹtadinlaadọta pere.
CBN gbé ọ̀nà àbáyọ dé sí owó tó dọ̀tí
Ọgbẹni Blankson, ni ọpọlọpọ ti gboriyin fun gẹgẹ bi akọni to ṣubu loju ija lasiko to n doola awọn eniyan ti ọkọ oju omi ti wọn wọ doju de sinu odo nilu Port Harcourt.
"Gẹgẹ bi alakoso ipinlẹ Oyo, ohun gbogbo to ba bajẹ o (gomina) ni lati ni atunṣe si i, boya o wa ran eeyan lati ri Kabiyesi ni kọrọ lati ṣe iyẹn, mi o le sọ""."
Òun ni alága àkọ́kọ́ ìgbìmọ̀ tó ń ṣe àkóso Security Trust Fund Ipinlẹ Eko.
Bí wọ́n bá pa wá, a jẹ́ pé ikú yá, bí wọ́n bá sì dá wa sí, a óo wà láàyè.
Bàbá ìyàwó ní ìfẹ́ wà láàrin ọmọ́ òun àti ọkọ rẹ̀, inú àwọn sì dùn sí ìgbeyàwó náà
Bakan naa, orisirisi oro lo ti tan kale pe orile-ede China tun gba ile-ise akoroyin orile-ede naa ZNBC, ati papako ofurufu ti won sese ko si olu ilu orile-ede ohun, Lusaka, lati fi di owo ti ile China ya orile-ede Zambia.
Lóòótọ́ ọ̀rọ̀ tí ẹ̀dá yìí wí ṣẹ: ní ọjọ́ kejì ni nǹkan gbogbo ti rí bí ó tí wí tí olúkúlùkù bá ara rẹ̀ ní ipò tí ó béèrè.
Ọpọlọpọ awọn eniyan ni wọn n gbiyanju lati mọ Ta ni Sadiya Umar Farouq tí ìròyìn ẹlẹ́jẹ̀ ń gbé pé òun ló fẹ́ dí ìyàwó tuntun Buhari?
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Yoruba Culture: ọjọ́ méje ni wọ́n fí n rẹ ẹ̀kú Danafojura kó tó jáde Awọn Ọyọmesi gba Alaafin Sango nimọran pe ko tako ija ti awọn ọrẹ meji naa ja ni Ẹdẹ, ko si pasẹ pe ki wọn tun ija naa ja nilu Ọyọ niwaju Ọba ati awọn Ọyọmesi Ọjọ Akẹsan ni wọn tun ti fija pẹẹta, Timi ta ọfa rẹ, to si tase Gbọnka, ti onitọun naa si lo oogun lati fi mu ki Timi sunlọ fọnfọn, to si bẹ ori rẹ.
00) tí wọ́n bá níbi ìgbèré Orímóògùnjẹ́ fún Yéwándé láti tójú.
Ìjọba ń gbèrò láti fẹ̀sùn ìgbésúnmọ̀mí kan Sowore bíi Nnamdi Kanu- Falana Obasanjo, Gowon, Muhammed- wo àwọn olóri Nàìjíríà lọ́dọ̀ọ́ Àgbékalẹ̀ ètò tó ń ṣàmójútó ìnáwó ìjọba á gbógunti ìwà àjẹbánu- APC Ọ̀pọ̀ èèyàn ló sá fún mi nígbà tí mo dùbúlẹ̀ àìsàn- Ògògó Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Silas Robotic Engineer: Kò sí ǹkan rere tí ọmọ Nàìjíríà kò lè ṣe Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Ó jẹ́ eniyan rere ati olódodo.
O ni: Igbesẹ yi n sagbega orukọ rere ti BBC ti ni nipa iroyin to gbamuse ti yoo si de ọdọ awọn ọdọ lorile-ede Naijiria'' Àwọn èèyàn ìpínlẹ́ Ondo kò gbàgbọ́ pé Coronavirus wà lọ jẹ́ kó máa pọ̀ síi - ìjọba Ẹbí Abiola Ajimobi kéde bí ètò ìsìnkú rẹ̀ yóò ṣe rí pé.
Peteru bá ti gbogbo wọn jáde, ó kúnlẹ̀, ó gbadura.
O ṣapejuwe Ọlọpaa Hisbah ti Kano ti ẹnikẹni ko le ni ki wọ́n kasẹ rẹ nilẹ bẹẹ si ni o ṣalaye pe awọn Ọlọpaa ibilẹ yii nikan lo le mọ bi ajoji ba wọ ilu.
Odò Arinoni jẹ́ ààlà ilẹ̀ Moabu, ó wà láàrin ilẹ̀ Moabu ati ilẹ̀ Amori.
‘Àwọn ọba ńlá mẹrin tí yóo jẹ láyé ni àwọn ẹranko ńláńlá mẹrin tí o rí.
Amọsa awọn ẹgbẹ osisẹ lorilẹede Naijiria ti sọ wipe eyi ko lee so eso rere fun ọrọ aje orilẹede Naijiria ati wi pe yoo fa ọpọlọpọ idaduro lẹnu isẹ.
Àwọn eniyan á dákẹ́ jẹ́ẹ́, wọn á farabalẹ̀ gbọ́ tèmi,wọ́n sì ń gba ìmọ̀ràn mi pẹlu.
" kí ó to rin ìrìnàjò yìí , ó sọ wípé oun kò fẹ ́ ran us , tí ó sì kọ ̀ láti ta "" september morn "" fún olùtẹ ̀ jáde ìwé ìròyìn us , lẹ ́ yìn tí rògbòdìyàn nípa àwòrán yìí bẹ ̀ rẹ ̀ ."
Alamojuto ekun ti ilu Warii Antai Asuquo soro iwuri yii, nibi ipade olodoodun ti eka DPR ti odun 2018, to waye nile-ise won to wa  niluu Warri ,ni ipinle Delta.
    Báyìí ni ọmọbìnrin yìí sọ, ìgbà tí ọkùnrin náà dá a lóhùn pé òuun kò yẹ ní ẹni tí ìbá gbọ́ irú ọ̀rọ̀ yìí lẹ́nu ọlọ́lá bẹ́ẹ̀ ọmọbìnrin náà tún dáhùn ó ni:
Ní gbogbo ìgbà tí bàbá bá gbé ẹran ka orí, ewé díẹ̀ , ni ó ma fi bò ó, yóò wá fi ọ̀bẹ ìgéran rẹ̀ lé e.
Foláṣádé: Òun ni ó jí owó Orímóògùnjẹ́ kó.
“lorile ede Naijiria idagbasoke nipa eto iselu ni I se pelu igbaradi fun eto idibo aare ati ile-igbimo asofin ti yoo waye ni osu keji odun 2019.
 ohùn ẹni tí ń dárin le pin nígbà tí alágogo bá lé e láré kọjá ibi agbára rẹ ̀ mọ .
Ilé ọ̀hún ga tó bẹ́ẹ̀ gẹ́, n kò lè fojú rí òkè rẹ̀ láti ìsàlẹ̀.
 mitchell ṣe atunyẹwo lori awọn agbejade 40 lori koko-ọrọ pẹlu awọn ero ti o wa lati inu ijakalẹ ọkàn si iṣan apọn .
Ilé ẹjọ́ tú ìgbéyàwó ọdún mẹ́wàá ká nítorí ẹ̀sùn ìbálòpọ̀ ọlọ́jọ́ gbọọrọ àti òògùn owó
Bẹ́ẹ̀ ni yóo rí ní ọjọ́ tí Ọmọ-Eniyan bá yọ dé.
’ Rhoda Owolabi to jẹ ololufẹ Toyin naa ko gbẹyin, o sọ pe ki Toyin fi ija f'Ọlọrun ja, nitori ija kii bi ọmọ ire.
OLUWA ní,“Ẹ wò ó, mo dojú ìjà kọ yín,ẹ̀yin tí ẹ̀ ń gbé àfonífojì,tí ó dàbí àpáta tí ó yọ sókè ju pẹ̀tẹ́lẹ̀ lọ,ẹ̀yin tí ẹ̀ ń wí pé,‘Ta ló lè dojú ìjà kọ wá?
Ninu ọ̀rọ̀ ti alukoro ile iṣẹ ọlọpaa, DCP Frank Mba fi sita, wọn ni ki gbogbo ara ilu fi ara balẹ pe ohun gbogbo yoo rọlẹ.
“Nígbà tí o bá ń kórè oko rẹ, o kò gbọdọ̀ kórè títí kan ààlà.
"Iyabo ni ""Emi Alice Iyabo Ojo, ko ni ṣe atilẹyin, polongo tabi dibo fun ọmọ ẹgbẹ oselu APC tabi PDP mọ laelae laye mí."
Oríṣun àwòrán, STREET PRIESTS Àkọlé àwòrán, Okina ni erongba lati fẹ ajọ rẹ loju si Ajọ Street Priests ti na iyẹ rẹ de ọdọ awọn ọmọde ti o ṣeeṣe ki o sọ ojupopo di ile, fun apẹẹrẹ: awọn t'ohun gbe ni awọn ibudo ifiniwọsi awọn ogunlende.
" Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Afáárá òpópónà Mokwa sí Jebba wó lulẹ̀ Àwọn Gómìnà Gúúsù-Ìwọ̀ Oòrùn kéde June 12 Lai Mohammed fèsì sí ọrọ Obasanjo O ni awọn agbofinro ti ṣawari ẹbi awọn ọeeyan naa.
Ṣugbọn Elimasi, tí ìtumọ̀ orúkọ rẹ̀ jẹ́ onídán, takò wọ́n.
Minisita fun eto ẹkọ Ọgbẹni Adamu Adamu lo fọrọ naa lede lẹyin ipade igbimọ alaṣẹ ijọba apapọ l'Ọjọru nilu Abuja.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ejo abami to n mu owo ni ajọ Jambu Oludari yii ṣalaye pe banki CBN ni banki kọọkan a gba owo idapada N200:000:00 fun odiwọn oṣu mẹta ti wọn a fi maa ṣe eto yii.
Gbogbo awọn nkan to ri nipa ipalẹmọ Keresi yi lo fi soju opo rẹ ni Twitter, kia lawọn eeyan ti ṣalabapin rẹ niye igba to le ni 100,000 Lẹyin ti awọn eeyan bẹrẹ si ni pin ọrọ to kọ yi ni ọrẹ rẹ kan mu imọran wa pe ki o fi oju opo awọn ajọ ẹlẹyinju aanu sibẹ ki awọn eeyan baa le da owo fun wọn.
Awon to wa nibẹ ni awon ri
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Hosni Mubarak: Ààrẹ́ Egypt tẹ́lẹ̀ jáde láyé 25 Èrèlè 2020 Oríṣun àwòrán, Getty Images Aarẹ orilẹede Egypt tẹlẹ, Hosni Mubarak ti awọn ologun le kuro niluu lọdun 2011 ti dagbere faye ni Cairo lẹni ọdun mọkanlelaadọrun.
awọn eroja to wa ninu fiimu mejeeji lo jẹ ki a wo ifarajọra to wa ninu wọn.
Lock down: Ṣé Irọ ni pé àwọn adigunjalà ń ṣọṣẹ ní ìpínlẹ Eko àti Ogun?
 Alarina ileesẹ ọgba ẹwọn l'Ondo ni awọn janduku naa wa pẹlu ibọn, ada atawọn ohun ija oloro lati kọlu ọgba ẹwọn naa."
Bakan naa, Ajo eleto idibo INEC yoo tun maa fun awon asoju ( House of
Ile ejo kan ni orile ede Somaliland to sese kede lati gba ominira fun  orile ede tire, ni  o ti ju arabinrin akewi kan si ewon odun meta.
Èmi Tatiu tí mò ń bá Paulu kọ ìwé yìí ki yín: Ẹ kú iṣẹ́ Oluwa.
Nitori naa,ti a ba ni agbejoro mewaa, a o  ri meji to n se daadaa, ti won le gbe ejo won kale lona to ye.
''Irọ patapata ni iwe iroyin gbe.
Lara awọn ọta ibọn ti wọn yin lo ba Kabiesi.
 Ó jé Òkan lára àwon olórin àkókó ti ilè adúláwò láti ní àseyorí kákìjádò ayé , a ti pè e ní òkan lára àwon olórin tó níyì jùlo ní gbogbo àsìkò .
Oríṣun àwòrán, others Àkọlé àwòrán, Ara ọtọ ni ibomu-bẹnu yii ti wọn sẹ bi i kọmu obinrin.
Ìwà èérí rẹ̀ hàn níbi ìṣẹ́tí aṣọ rẹ̀,kò sì bìkítà fún ìparun tí ń bọ̀.
Kí ẹ máa fi ọ̀dọ́ akọ mààlúù meji, ati àgbò kan ati ọ̀dọ́ àgbò meje ọlọ́dún kọ̀ọ̀kan, tí wọn kò ní àbààwọ́n rú ẹbọ sísun sí OLUWA.
Pẹlu bi ọrọ seri yii, ibeere ọpọ ni pe, ṣe adajọ agba yoo tẹle ilakalẹ iwe ofin Naijiria ati oun ti awọn amofin agba n sọ pe ko si idi fun un lati fi oju han nile ẹjọ naa.
Ẹni tí ó tẹ̀lé e ni Ipò-òkú.
Ó si to èèyàn mílíọ̀nù lọ́nà àádọ́ta tó tí ipaṣẹ ajakale àrùn yìí jé Ọlọ́run nipe.
E̩tó̩ yìí sì gbani láàyè láti pààrò̩ e̩ sìn tàbí ìgbàgbó̩ e̩ni.
“Lẹsẹkẹsẹ lẹ́yìn ìpọ́njú ọjọ́ wọ̀n-ọn-nì, oòrùn yóo ṣókùnkùn, òṣùpá kò ní tan ìmọ́lẹ̀ rẹ̀, àwọn ìràwọ̀ yóo jábọ́ láti ọ̀run.
Wọn á di tírà pàlàbà-pàlàbà mọ́ iwájú.
Agbára mi ha rí bí ti òkúta bí?
O ti le ni ọdun mẹwaa ti wọn ti n ṣọṣẹ ni ariwa ila oorun Naijiria atawọn orilẹ-ede miran.
Ṣe ni Woods, akọni ọmọ ọdun mẹtalelogoji naa fi igbe ta nigba to jawe olu bori.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ọjọ́ kìí pẹ́, àlàyé àti fídíò rèé lóríi bí èèyàn ṣe rìn lórí Òsùpá ní ààdọ́ta ọdún sẹ́yìn Àwọn kan fẹ́ da Naijiria rú torí ààbò tó mẹ́hẹ - Osinbajo gbarata Abúlé tí wọn kìí ti sọ ọmọ ní orúkọ, ohùn arò ni wọ́n fi ń pè wọ́n Ọ̀rọ̀ ti ń gba ibòmíràn yọ lórí ẹ̀ṣùn ìfipábánilòpọ̀ - Timi Dakolo Pariwo Bakan naa ni wsn tun n kọminu pe ti orukọ awọn minisita naa ba tiẹ de siwaju ile asofin apapọ lọsẹ yii, n jẹ asọ si lee ba ọmọyẹ mọ, nidi ikede awọn tile asofin ba fi ontẹ lu ninu wọn.
Ẹsun kikowo ilu jẹ ni ajọ EFCC n wa ọga agba DSS ọhun fun.
Nítorí ojú kò tì mí bí mo bá ń ṣe ìgbéraga ní àṣejù nípa àṣẹ tí a ní, tí Oluwa fi fún mi, láti lè mu yín dàgbà ni, kì í ṣe láti fi bì yín ṣubú.
Wọ́n fi ojúbọ àwọn oriṣa wọn bí i ninu;wọ́n sì fi ère wọn mú un jowú.
Ifeanyi Ubah United 16:00Nasarawa United ?
Mo rán wọn lọ sọ́dọ̀ Ido, olórí àwọn eniyan ní Kasifia; mo ní kí wọ́n sọ fún Ido ati àwọn arakunrin rẹ̀ tí ń ṣiṣẹ́ ninu tẹmpili pé kí wọ́n fi àwọn eniyan tí yóo máa ṣe iṣẹ́ ìsìn ninu ilé Ọlọrun wa ranṣẹ.
Àwọn tí ó ń kọjá lọ ń bá a wí pé kí ó panu mọ́.
3 Ọ̀wàrà 2019 Àkọlé àwòrán, Awon ajoji ile South Africa ni won n kolu Aarẹ Muhammadu Buhari bẹrẹ irinajo abẹwo si orilẹ-ede South Africa lọsẹ yii lati ṣatunṣe to yẹ ninu ajọṣepọ orilẹ-ede mejeeji.
"A o lọwọ ninu ikọlu naa.
Òwe yi ni a lè fi ṣe àpẹrẹ iṣẹ́ ribiribi ti Olóògbé, Olóyè Hannah Ìdòwú Dideolú ṣe fún Olóògbé Olóyè Ọbáfẹ́mi Awólọ́wọ̀, ògúná gbongbo Òṣèlú ni ilẹ̀ Yorùbá àti fún orilẹ̀ èdè Nigeria.
 Besini, gbogbo ipago Camp Nou  lapapo ko le gbagbe ise rere ti o ti gbese ninu iko agbaboolu yii.
Gẹgẹbi awọn onimọ iṣegun ṣe sọ, ko din ni alaisan mẹẹdogun ti wọn ti ri iwosan kuro lọwọ aisan foniku-fọla dide ni Naijiria nipasẹ imọ lilo iwọ ati olubi ọmọ fi ṣe iwosan yii, eleyii ti a mọ si Stem cell.
Àfilé iye owó fún gbígba ìwé ẹ̀rí ọmọ-ìlú-fún-ìrìnnà mú àwọn ọmọ Angola fi ẹ̀hónú hàn
Ipade olojo kan ti o waye laarin awon adari eka ijoba Lake Chad niluu N’djamena, ti n se olu ilu orile-ede Republic of Chad, eleyi ti aare Muhammadu Buhari tuko ipade ohun ti fenuko lati kun awon iko omo ogun lowo nipase pipese awon ohun elo ija ogun.
Ó wí èyí nípa Ẹ̀mí tí àwọn tí ó gbà á gbọ́ yóo gbà láì pẹ́, nítorí nígbà náà ẹnikẹ́ni kò ì tíì rí ẹ̀bùn Ẹ̀mí gbà nítorí a kò ì tíì ṣe Jesu lógo.
Ariwo àwọn eniyan náà sì pọ̀ pupọ.
Kí laà bá wá pe Computer yìí ní Yorùbá tí kò bá tọ̀nà, tí kò bá bá ìtunmọ̀ mu rẹ́gí-rẹ́gí?
Awọn to wa nibi ipade naa ni Aarẹ ẹgbẹ oṣiṣẹ, Ayuba Wabba ati akẹgbẹ rẹ ni ẹgbẹ TUC, Quadri Olaleye.
Ó ti dáná sun àwọn ọlọrun wọn; ṣugbọn wọn kì í ṣe Ọlọrun tòótọ́, ère lásán tí a fi igi ati òkúta gbẹ́ ni wọ́n, iṣẹ́ ọwọ́ ọmọ eniyan.
''Ko si iyatọ ninu nkan to n ṣẹlẹ niwaju ile ẹgbẹ.
Ó ti fi wọ́n sílẹ̀ fún ìparun, ó sì ti fà wọ́n kalẹ̀ fún pípa.
Ni ṣe ni awọn agbebọn naa pasẹ fun awọn olukọ ati akẹkọọ, lati bọ ara wọn si ihoho, ki wọn si sa asala fun with ẹ̀mí wọn.
Chelsea kọ́ láti fìyà panu bíi Arsenal àti Man U
Lojiji ni ilẹkun si mọ wa lori, ti mo si ri mama mi, iya ọkọ mi, ibatan baba mi meji, ati ẹbi ọkọ mi kan, wọn fẹ mọ boya ọkọ mi ba mi nile, to si ja ibale mi.
 gbogbo ibi tí ifá ba ti dé lo ti ń yan ìyàwó , èyí lo mu ifá rí àríṣá àwọn obìnrín .
''Ni ile ijọsin Gabola, o maa gbe ọti rẹ wa ti pasitọ yoo si ba ọ ya si mimọ ki o fi ma ṣe akoba f'ara rẹ'' O ni nigba ti ofin yi si ti bẹrẹ niṣe lawọn ko duro loju kan ṣe ijọsin ki awọn agbofinro ma baa mu awọn.
Ẹnìkan fọhùn láti orí ìtẹ́ náà, ó ní, “Ẹ yin Ọlọrun wa, gbogbo ẹ̀yin ìran rẹ̀, ati gbogbo ẹ̀yin tí ẹ bẹ̀rù rẹ̀, ẹ̀yin mẹ̀kúnnù ati ẹ̀yin eniyan pataki.
OLUWA ń yẹ àwọn olódodo, ati eniyan burúkú wò,ṣugbọn tọkàntọkàn ni ó kórìíra àwọn tí ó fẹ́ràn ìwà ipá.
Iṣẹlẹ yii lo n waye lẹyin ti adajọ agba ipinlẹ naa, Nasir Ajanah dagbere faye nile itọju awọn to ni arun Coronavirus ni ilu Abuja.
Jesu wá bi baba ọmọ náà pé, “Ó ti tó ìgbà wo tí irú èyí ti ń ṣe é?
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù 'Obìnrin ló ni ilé àti àdúgbò fún ìdí èyí wọ́n lè ṣe ìlú dáadáa' Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ 'Obìnrin ló ni ilé àti àdúgbò fún ìdí èyí wọ́n lè ṣe ìlú dáadáa' 25 Sẹ́rẹ́ 2019 Iṣẹ́ ìlú yàts gidigid si iṣẹ́ ilé ni igbagbọ ẹlomii.
O ni ijọba ti ṣetan lati kọkọ fi aadọta miliọnu le lugba silẹ, nigba to rọ awọn ẹlẹyinju aanu ọmọ Naijiria fikun owo naa ko le pe.
O ṣalaye pe eleyi ṣẹlẹ nitori ofin iṣede to wa kaakiri agbaaye ko fawọn eeyan lanfaani lati ri ti ọrọ ibalopọ ro.
Eyi ni igba akọkọ ti aarẹ Buhari yoo rinrinajo kuro lorilẹede Naijiria lati igba ti ajakalẹ arun Coronavirus ti bẹ silẹ.
Láàrín ọjọ́ mẹ́jọ péré, ibà Lassa kan èèyàn 25 Oyo TUC: A ṣì fa ìjọ̀ba léti ni pẹ̀lú ìyanṣẹ́lódì Lẹ́yìn ọdún mẹ́wàá, Tokyo àti Auxillary ṣèpàdé bòńkẹ́lẹ́ Aláàfin Ọyọ pé ọdún 48 lórí àpèrè Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ijó Bàtá ti Yorùbá gb'oríyìn ní Calabar Festival 2018 Ti a ko ba gbagbe, ni Ọjọru, ọsẹ yii ni gomina Abiola Ajimobi yan abileko Ololade Agboola gẹgẹ bi adari awọn osisẹ tuntun, lẹyin ti abileko Hannah Ogunnesan ko iwe fi ipo silẹ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Bisi Alimi: Ìyà mi rò pé n kò leè ṣe ni àmọ́ n kò ní ìfẹ́ abo ni mo ṣe fẹ́ akọ Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Bẹ́ẹ̀ ni èmi ni mo kọ́ Efuraimu ní ìrìn,mo gbé wọn lé ọwọ́ mi,ṣugbọn wọn kò mọ̀ pé èmi ni mo wo àwọn sàn.
Awọn agbẹ figbe ta pe wọn ko tii dẹkun kikọlu oko awọn, o ni awọn si ti bẹ wọn tititi ti wọn ko gbọ.
Loju opo ẹni to pe ni ọmọ iya rẹ obinrin@ rawflesh_may_9, ko si nkankan nibẹ lori Instagram, lati le fi tọkasi ẹni to n jẹ bẹẹ.
Gba ẹjọ́ àwọn tí kò ní ẹnu ọ̀rọ̀ rò,ati ti àwọn tí a sọ di aláìní.
Aarẹ Trump, ti ọrọ yii kan sọ loju opo Twitter rẹ pe oun yoo fesi si iṣẹlẹ yii lọjọbọ.
Ọ̀gá NIMASA tẹ́lẹ̀ fi ẹ̀wọ̀n ọdún 42 jura Ìgbájú ìgbámú ni Senegal fi lé Nàìjíríà kùrò ní ìdíje ife àgbáyé FIFA U-20 Kí ni àwọn ẹ̀ṣẹ̀ àti ẹ̀sùn tó ń da Oshiomole láàmú?
Pípín Ilẹ̀ Náà láàrin Àwọn Ẹ̀yà Israẹli.
Nítorí pé mò ń pe gbogbo àwọn orílẹ̀-èdè tí ó wà ní ìjọba àríwá, èmi OLUWA ni mo sọ bẹ́ẹ̀, àwọn ọba wọn yóo sì tẹ́ ìtẹ́ wọn kalẹ̀ ní ẹnubodè Jerusalẹmu, ati yíká odi gbogbo ìlú Juda.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù BBNaija: Khafi la Mercy àti Cindi mọ́lẹ̀ nínú abala tó kẹ́yìn ìdíje ọ̀rọ̀ nípa Nàíjíríà 25 Ògún 2019 Oríṣun àwòrán, Instagram/khafikareeem Khafi Kareem to jẹ ọkan lara awọn to n kopa ninu eto agbelewo kan, Big Brother Nigeria, taa mọ si BBNaija ti gba ẹbun ọkọ ayọkẹlẹ lori eto naa.
Seyi Makinde kò leè gba adé lórí àwa ọba 21, iléẹjọ́ ni yóò là wá níjà - Lekan Balogun Àwọn àdúgbò Ibadan gborúkọ tuntun látẹnu Ajimobi Laduntan Oyekanmi di ìyálóde tuntun fún ilẹ̀ Ibadan Èèyàn 2,040 làwọn agbésùnmọ̀mí ti pa ní Nàìjíríà lọ́dún yìí- Ìwádìí Adajọ Usman Na'abba to lewaju awọn adajọ to gbe idajọ naa kalẹ, fidi ọrọ mulẹ pe wọn ko tẹle iyana to tọ pẹlu iyansipo awọn ọba naa.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Belarus: Ààrẹ orílẹ̀èdè Lukashenko tún wọlé lẹ́yìn ọdún 25 lórí oyè!
Oda, ko yọ ọmọ rẹ silẹ.
 rainat jẹ ẹni ti o mu eto gbigbaradi fun ọmọ tuntun jojolo ni okunkundu ati ṣiṣeowo .
awon agbejoro mejeeji naa, alaga ile –ejo tẹẹkotọ wa ran agbejoro olufisun naa
“Bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé ò ń ṣe àgbèrè ẹ̀sìn, ìwọ Israẹli, má kó ẹ̀bi bá Juda.
“Nígbà tí mo bá kó àwọn ará ilé Israẹli jọ kúrò láàrin àwọn orílẹ̀-èdè tí mo fọ́n wọn ká sí, tí mo sì fi ìwà mímọ́ mi hàn láàrin wọn, lójú àwọn orílẹ̀-èdè yòókù, wọn óo máa gbé ilẹ̀ tiwọn, ilẹ̀ tí mo fún Jakọbu iranṣẹ mi.
Ọba Adeyẹmi, ninu ifọrọwanilẹwo kan to ṣe pẹlu iwe iroyin Punch sọ pe, o wu awọn iyawo oun lati fi oun ṣọkọ nitori pe oun ran wọn lọ sileewe.
Aarẹ Buhari kede bẹẹ lasiko to n bawọn akọroyin ile ijọba sọrọ nile ijọba Aso Rock nilu Abuja lati sami ọdun Ileya.
Akọkọ ni pe ti a ba fi orukọ abinibi rẹ wo, tii se Ramoni, idile musulumi lo ṣeese ki o ti jade.
Ekiti Ghost Workers: Gómìnà Fayemi ní N400m ló ń sọnù ní ọdọọdún nítorí àwọn tó ń gba owó òṣù láì ṣiṣẹ́
O tun so pe, awon alakoso ile-ise epo robi Eland Oil and Gas, ti won fi ile biritiko se ibugbe, ti ni ile-ise lorilsirisi eyi ti owo ori re je bilionu owo dollar lorile-ede Naijiria, o wa fikun pe,“eleyi yoo tun safihan igboya ti ile-ise won ni lorile-ede yii.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Blind Couples: Pẹ̀lú ìpèníjà ojú, tọkọtaya bímọ mẹ́ta, tí wọn sì tún ń ṣiṣẹ́ olùkọ́ Koda, awọn oluwọde ri ikede ileesẹ ologun lati bẹrẹ operation Crocodile Smile bii ara ọna lati da awọn ologun sita, ki wọn lee bomi pa ina iwọde to n lọ lọwọ.
Ọgbẹni Eyo ṣalaye pe kii ṣe nitori ibeere to bi Fani-Kayode ninu ni oun ṣe bẹbẹ.
Koda, wọn ti fun Hushpuppi ni nọmba idanimọ l'ọgba ẹwọn, 54313-424, eyi ti yoo fun awọn eeyan l'anfaani lati ka nipa rẹ lori itakun agbaye naa.
Se ni Funke Etti naa n tara poro pe iru ki ni eyi, to si n rọ aarẹ Buhari lati tete dẹkun bi wọn se n pa awọn ọmọ Naijiria ni South Africa.
Olori yi wa lara awọn Olori to kere julọ ni aafin ti ọpọ maa n pe ni òló ẹlẹjẹ tutu ti Baba fi n mi lasiko yii.
Oríṣun àwòrán, Wellcome Collection Àkọlé àwòrán, Awọn oniṣegun alawọ funfun bẹrẹ si ni lo taba gẹgẹ bii oogun Ati pé nigba miran, wọn n fi le kokoro to n fa aisan kuro ni agbegbe wọn.
Ọkunrin kan wà tí wọn máa ń gbé wá sibẹ, tí ó yarọ láti inú ìyá rẹ̀ wá.
Wọ́n ń já nǹkan gbà lọ́tùn-ún, wọ́n ń jẹ ẹ́,sibẹ ebi ń pa wọ́n.
Pẹlu bi o ṣe han gbangba gbangba pe ewu n bẹ lori orule, Kudirat ṣi huwa adari lasiko yii ti gbogbo ẹ doju ru.
yii  fihan pe, o jẹ ẹni ti o ni iwa adari
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Kiiling of Nigerians: Ijọba Nàìjíría fá orílẹ̀-èdè South Africa létí 7 Ògún 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Abike Dabiri pè fún ìwádìí tó péye lórí gbogbo àwọn tí wan ti pa kí wan si fi ẹni ti igbá ba ṣí mọ lóri jófin Ìjọba orílẹ̀-èdè Nàìjíríà tí kìlọ̀ fún South Africa, pé òun kò ní faramọ pípà ọmọ Nàìjíríà ní ìpakúpa, àti ni àìni ìdí tó n wáye lórílẹ̀-èdè South Africa lójoojúmọ mọ, nítorí pé oni sùùrú Nàìjíríà ti gbẹ lórí ọ̀rọ̀ náà Adarí àgbà àjọ tó ń ri sí ọ̀rọ̀ àwọn ọmọ Nàìjíríà ní òkè òkun (NIDCOM) Abike Dabiri, tó fi ìkìlọ̀ náà sọwọ́ ní ìlú Abuja ní ọ̀sán òní ọjọ́ru, sàlàyé pé ìwà ìpani ni yiìí ti kọjá afaradà fún ọmọ Naàìjírìà.
Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Fídíò, Akomolede ati Asa Yoruba: Kí ni Future tense"" lédè Yorùbá?"
Jesu bá sọ fún un pé, “Mú ọwọ́ kúrò lára mi, nítorí n kò ì tíì gòkè tọ Baba mi lọ.
Oríṣun àwòrán, @Buhari Àkọlé àwòrán, Kókó ọ̀rọ̀ tí Buhari sọ ní àyájọ́ June 12 Gbagede Eagle Square nibi ti Naijiria ti n sami ayẹyẹ iṣejọba Awa ara wa ni Abuja, ni aarẹ Buhari ti wa ba awọn ọmọ Naijira sọrọ.
Helesi, láti inú ìdílé Peloni, Ira, ọmọ Ikeṣi ará Tekoa, ati Abieseri, láti Anatoti 
OLUWA, Ọlọrun Alágbára ti sọ̀rọ̀:ó ké sí gbogbo ayéláti ìlà oòrùn títí dé ìwọ̀ oòrùn.
Báwo ní àwa óo ṣe wá là báyìí?
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Shiite: Ilé ẹjọ́ gíga Kaduna sún ìgbẹ́jọ́ adarí Shiite síwájú 29 Agẹmo 2019 Ijoko ile ẹjọ giga ni Kaduna ko waye lonii lori gbigbọ ẹjọ lati gba oniduro adari ẹgbẹ Shiite, El-Zakzakky.
"Ni nkan bi aago maarun si mẹfa owurọ ni oorun gbe mi lọ.
Ẹran ọ̀sìn díẹ̀ ni o ní kí n tó dé ọ̀dọ̀ rẹ, díẹ̀ náà ti di pupọ nisinsinyii OLUWA ti bukun ọ ní gbogbo ọ̀nà nítorí tèmi.
Ṣugbọn Jesu sọ fún wọn pé, “Kò sí wolii tí kò níyì àfi ní ìlú baba rẹ̀ ati ní ilé rẹ̀.
Tolani Alli kẹkọọ jade ni Fasiti Michigan, ni orilẹ-ede Amẹrika, nibi ti o ti kẹkọọ nipa imọ sayẹnsi.
Ọjọ Satide, ọjọ kẹtalelogun, oṣu Karun, ni oriade naa darapọ mọ awọn baba nla rẹ ni ipo oku, lẹyin aisan ranpẹ.
1) Gbiyanju lati tẹle ipinnu rẹ dopin.
Oríṣun àwòrán, Olayomi Koiki Ninu fidio kan to gba ori ayelujara kan, lo se afihan Sunday Igboho ati awọn ẹlẹgbẹjẹgbẹ miran nilẹ Yoruba, ti wọn kora jọ siwaju ile Igboho, pẹlu asọ ẹgbẹ Yoruba ati akọle lọwọ wọn.
Ta ni mo ní lọ́run lẹ́yìn rẹ?
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Sekinat Quadri ọmọ ọdun meje ajẹsẹ to fẹ dabi Anthony Joshua Umar Kremlev to jẹ akọwe agba ajọ naa ni o dabi pe ejo iku Maxim fẹ lọwọ ninu.
Lẹyin ipade bonkẹlẹ to waye laarin awọn mejeeji, Tinubu sọ fun awọn ọmọ Naijiria pe asaaju Naijiria naa jẹ oniwa rere ati onigboya eniyan, ti ko si lee fẹ se saa kẹta lori aleefa laelae.
Ọọni ti Ilé-Ifẹ̀, ọba Adeyeye Ogunwusi Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Wo bí o ṣe leè ṣe ìjìnàsíraẹni ní ibiṣẹ́ lásìkò Coronavirus yìí Arole Oodua, ọba Ogunwusi kéde síta Laipẹ yìí pé òun ti ṣe àwárí ìwòsàn fún àrùn Coronavirus.
Coronavirus Update in Nigeria: 'Ewu ń bẹ pẹ̀lú bí àwọn ọmọ iléèwé ṣe wọlé padà lásìkò àrùn Coronavirus'
ng Awọn oludije pe fun isunsiwaju idibo abẹle naa Nibayii, iroyin n sọ pe meje ninu awọn oludije naa ni wọn ti n pe fun isunsiwaju idibo abẹnu naa.
Iléeṣẹ́ ọlọ́pàá ní Kano tí ṣe àyẹ̀wò àwọn 13, 048 tó fẹ́ darapọ̀ mọ́ wọn Bí mo bá wọlé padà, mí ò lè yàn Ize Iyamu tàbí Osagiobare sípò olùbádámọ́ràn- Obaseki Wo ọ̀nà ìsanwó tuntun fún àwọn oníbárà iná mọ̀nàmọ́ná ní Eko (EKDC) Oríṣun àwòrán, Other Wiwo awọn fidio yii tabi fifun ara ẹni ni adun ibalopọ, ma n mu adinku ba bi ibalopọ ṣe ma n wu ọkunrin si pẹlu iyawo tabi ọrẹbinrin wọn.
Dípò òjò, eruku ni yóo máa dà bò ọ́ láti ojú ọ̀run, títí tí o óo fi parun patapata.
 Gẹ́gẹ́ bí ọ̀dọ́ náà ṣe sọ."
Nítorí náà, mo bẹ àwọn àgbà láàrin yín, alàgbà ni èmi náà, ati ẹlẹ́rìí ìyà Kristi, n óo sì ní ìpín ninu ògo tí yóo farahàn.
Wyclef Police Ibadan: Kí ni Ọ̀gá Ọlọ́pàá yóò ṣe fàwọn Ọlọ́pàá Ibadan tó ṣe obìnrin bó ṣe wù wọ́n nínúu fídíò?
Ki ni Ileeṣẹina mọnamọna, IBEDC sọ nipa iṣẹlẹ naa?
Ṣugbọn bi onirese onirese Oyinkan ko ba fingba mọ, eyi to ti fin silẹ ko le parun.
"Ida ẹgbẹta ni iye awọn ọmọbinrin Naijiria to n gunlẹ si orilẹede Italy nikan.
Ni wọ́n bá dá àwọn angẹli mẹrin náà sílẹ̀.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù RCCG: Àwọn Pásítọ́ ijọ Redeem márùn ún bọ́ sọ́wọ́ ajínigbé ní Ijebu Ode 2 Ògún 2019 Oríṣun àwòrán, @NigerianPolice Ọga agba ọlọpaa lorilẹede Naijiria, M.
Nínú oro tìrẹ Alowonle Olajide ni, oro igbele yìí kò bá òun lára mú rárá, àti pé ó jọ bí ẹni pé ènìyàn wá nínú ewọn ni, ó wá rọ ijọba pé kí wọn dín ọjọ igbele yóò kú tí ó bá ṣeeṣe ọsẹ kan péré tí to kí olúkúlùkù sì padà sí ẹnu isẹ rẹ.
Ẹni tí ó bá wí pé òun wà ninu ìmọ́lẹ̀, tí ó kórìíra arakunrin rẹ̀, wà ninu òkùnkùn sibẹ.
Ọ̀nà meje ni wọn yóo pín ilẹ̀ náà sí, àwọn ẹ̀yà Juda kò ní kúrò ní àyè tiwọn ní apá ìhà gúsù, bẹ́ẹ̀ náà ni àwọn ẹ̀yà Josẹfu tí wọ́n wà ní agbègbè tiwọn ní apá ìhà àríwá.
Ní ọjọ́ keji gbogbo àwọn ọmọ Israẹli bẹ̀rẹ̀ sí kùn sí Mose ati Aaroni pé, “Ẹ pa àwọn eniyan OLUWA.
Báyìí ni 50k ṣe dá ìfẹ̀hónú Ali Must go"" sílẹ̀ tó mú ọ̀pọ̀ ẹ̀mí akẹ́kọ̀ọ́ lọ Ẹ̀kọ́ ọ̀fẹ́ déé fáwọn ọmọ Ọlọ́pàá tó kú lásìkò EndSARS, Gómìnà ìpìnlẹ̀ Eko kéde Aago mẹ́fà òwúrọ̀ sí mẹ́jọ alẹ́ ni ọ̀kadà yóò láǹfàní láti máa ṣiṣẹ́ ní Osun - Gómìnà Oyetola Ẹ má gbìyànjú láti bo àṣírí ìpànìyàn tó wáyé ní Lekki, á ní ẹ̀rí tó dájú - Amnesty International Bọ́ọ̀sì ìrìnà 106 tuntun yóò máa ná Ibadan sí Eko àtàwọn ìpínlẹ̀ míì - Seyi Makinde Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Kété tí wọ́n bá ti báa yín sùn tàn torí pé ẹ tóbi, ẹ gbà pé ìfẹ́ yẹn ti parí - Auntie Remi Ọlọ́yàn ńlá Abẹ ti wọn so mọ akukọ naa lẹsẹ lo bẹ kasan arakunrin Christine Bolok nigba tawọn ọlọpaa fẹ lọ mu awọn to n fi akukọ ja."
Ìkọ̀kọ̀ ni ìdìbò nàá ti n wáyé: Wọn maa n ṣe eto idibo naa ni ayika to pamọ.
Badmos sisọ loju rẹ pe iranwọ tawọn ọmọ Naijiria se fun ileeṣẹ ọlọpaa nigba ti iṣẹ iwadii n lọ lọwọ lo mu ki ọwọ ọlọpaa tete tẹ obinrin naa.
Ìràwọ̀ òṣèré orí-ìtàgé ìlú Serbia Nataša Tasić Knežević, àwòrán láti ọwọ́ọ Dzenet Koko, a lò ó pẹ̀lú àṣẹ.
Isiaka Busari, Mighty Joe tó jẹ́ adigunjalè tó rọ́pò Ọyenusi lẹ́yìn tí wọ́n pa á Ọmọ Nàìjíríà kan gbé Fásitì Oxford lọ sílé ẹjọ́ tàko oríkí ọrọ 'Mortgage' nínú ìwé àtúmọ̀ ọrọ Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí 12:46 Fídíò, Àṣìṣe ọlọ́pàá àti Adájọ́ sọ mí di ẹni tí wọ́n dájọ́ ikú fún, ọpẹ́lọpẹ́ Fayoṣe tí ko buwọ́lù ú, Duration 12,465 Owewe 2020 Fídíò, Akomolede: Bolaji Faleke ni Olùkọ́ tó ń kọ́ wa ní àṣà oge ṣiṣe lórí BBC Yorùbá1 Owewe 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Peter Adeeko helping military widows: Wo bí ọkùnrin ọmọ òrukàn yìí ṣe ń ran àwọn opó tí ọkọ wọn kú sójú ogun lọ́wọ́ 21 Ògún 2020 Oríṣun àwòrán, OTHERS Wo bí ọkùnrin ọmọ òrukàn yìí ṣe ń ran àwọn opó tí ọkọ wọn kú sójú ogun lọ́wọ́ Kekere ni Peter Adeeko wa ti ibọn fi ba baba rẹ loju ogun, eyii to sọ baba rẹ di ẹni ti ko le e dide kuro lori ibusun rẹ ko to di pe o dagbere faye lẹyin ọdun diẹ si.
Ọkunrin kan wà tí kò ní ẹnìkan,kò lọ́mọ, kò lárá, bẹ́ẹ̀ ni kò ní ìyekan,sibẹsibẹ làálàá rẹ̀ kò lópin,bẹ́ẹ̀ ni kò ní ìtẹ́lọ́rùn ninu ọrọ̀ rẹ̀.
Wọn óo jẹ́ aláìmoore; aláìbọ̀wọ̀ fún Ọlọrun, 
”Wọ́n á sì máa sọ fún àwọn wolii pé,“Ẹ má sọ àsọtẹ́lẹ̀ òtítọ́ fún wa mọ́,ọ̀rọ̀ dídùn ni kí ẹ máa sọ fún wa,kí ẹ sì máa sọ àsọtẹ́lẹ̀ ẹ̀tàn fún wa.
Idahun si ibeere naa ni: Kó ń kó-jabele eyi to jẹ: mi mi mi re re re Ede Yoruba ko ni parun o!
Ẹ óo gba ọkàn yín là nípa ìdúróṣinṣin yín.
Agbẹjọro Pissetzky ni awọn FBI ji Ramoni gbe ni Dubai ni lai tẹlẹ awọn ofin ati ilana to yẹ ni kikun ki wọn to maa gbee bọ ni America.
Àjọṣe Eré Ẹ̀tọ́ Ọmọnìyàn, tí ó jẹ́ àjọṣepọ̀ àjọ̀dún eré ajàfẹ́tọ̀ọ́  ọmọnìyàn 40 kárí ayé, fi lẹ́tà ṣọwọ́ sí ìjọba:
Komisona Singapore ninu oro tire fi idunu re han si Naijiria pelu ileri pe Singapore yoo tubo maa se idanilekoo fawon osise ati awon ona miran lori idagbasoke orile ede mejeeji.
Ijọba orile-ede Naijiria ti kede ojo isegun(Tuesday) ojo kokanlelogun ati ojoRu(Wednesday) ojo kejilelogun osu kejo odun ti a wayii, gege bi ojo isinmi lati fi se ajoyo odun awon Musulumi todun ti a wayii, ti  a mo si, 2018 Eid-Al-Adha.
Buhari paṣẹ pe ki Naijiria sọ asia kalẹ fọjọ mẹta nitori Shagari Ẹni ti ọla ba tọ si ni a n bú ọla fún ni ọrọ iku aarẹ Shehu Shagari to ti wọ káà ilẹ̀ sùn bayii.
"Akomolede ati Asa Yoruba: Kí ni ""Present tense"" lédè Yorùbá?"
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Farms to You: Irú ajílẹ̀ wo ló yẹ fún lílò lásìkò yìí- Aisha Wọn fikun pe ikọ alaabo Amotekun ko wa lati dojukọ ẹya Fulani abi ẹnikẹni, sugbọn gbogbo ẹni to ba n huwa ọdaran ni Amotekun yoo maa doju ija kọ, onitọun ko baa jẹ ẹya Yoruba.
Ẹni to bori: Guinea Guinea-Bissau vs Mauritania.
Ooru mú mi nítorí mo rí iná yá.
Àmọ́ ṣá ìgbà àti àkókò ni yóò sọ ohun tí yóò ṣẹlẹ̀ sí àwọn ẹyẹ ìlú Nepal tí kò sí ní ibòmíràn.
Lorile-ede Kenya, awon ajafeto omo eniyan ti benu-ete lu ikolu awon obinrin nipa fifi ipa ba won lo po, ati awon iwa odaran miiran tako awon obinrin leyin eto idibo.
Nínú mẹ́tàlá yìí, Mọkanla nínú àwọn mẹtala yìí jẹ́ láti ipinlẹ Eko, ẹyọkan ni ìpínlẹ̀ Delta, ẹyọkan ni ipinlẹ Kano Ajọ to n gbogun ti ajakalẹ arun lorilẹede Naijiria, NCDC lo kede eyi loju opo twitter rẹ lalẹ ọjọ Ẹti.
Nigba ti ohun ẹlẹgbọn ọn agba fọ si i pe kini ero rẹ nipa awọn ọmọ ile to ku ati pe bawo lo se n ṣe pẹlu wọn.
Má ṣe fà wá sinu ìdánwò.
Nígbà tí ó yá, Kaini mú ninu èso oko rẹ̀, ó fi rúbọ sí OLUWA.
Bakan naa ni awọn eeyan to peju síbi eto naa yonbo iwa rere oloogbe naa, bẹẹ ni wọn ṣe apejuwe rẹ bii Araba nla to n mi igbo kijikiji lagbo oselu ipinlẹ Oyo ati lorile-ede Naijiria lapapọ.
Gẹ́gẹ́ bí mo ti sọ fún ọ lóru àná, ó pẹ ti mo ti ń gbúròó rẹ nítorí àti ajá àti ẹran a máa wí nípa tìrẹ pé, ‘Ọlọ́gbọ́n ni Ìrìnkèrindò i ṣe.
”“iwe yii se atupalẹ awon itan ilu  bi i: Ila-Orangun, Erin-Ijesha, Ile-Ife, Iwo, Ilesha, Osogbo, Ikirun, Ejigbo, Ede, Ikire, Orile-Owu, Okuku, Irabiji ati Ijebu-Jesa.
) Nígbà tí Jesu sọ báyìí tán, ó wí fún un pé, “Máa tẹ̀lé mi.
Aya wolii ṣalaye lẹkunrẹrẹ fun BBC Yoruba lori ohun to ṣẹlẹ gangan ati igbesẹ ti ọkọ rẹ gbe.
Bakan naa ni aarẹ orilẹede Amerika, Donald Trump ko da yatọ ninu awọn aarẹ wọn yii.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Neha Sharma: obìnrin tó ń múra bíi ọkùnrin láti leè ṣiṣẹ́ gẹrígẹrí Rape: Oluwaseun Osowobi ní Commonwealth fún lámì ẹ̀yẹ ọ̀dọ́ tó pegedé jùlọ ní 2018 Àkọlé àwòrán, Rape: Oluwaseun Osowobi ní Commonwealth fún lámì ẹ̀yẹ ọ̀dọ́ tó pegedé jùlọ ní 2018 Oluwaseun Osowobi la laalaa ifipabanilopọ kọja lati di ajafẹtọ awọn ti wọn ti la iru iṣẹlẹ bẹẹ kọja.
A kò mọ ohun tí ó ṣẹlẹ̀ sí Mose tí ó kó wa jáde láti ilẹ̀ Ijipti.
Ni àṣà igbéyàwó Yorùbá, èèmọ̀ ni ki ọkùnrin fẹ́ ọkùnrin tàbi ki obinrin fẹ́ obinrin.
Ilé yìí yóo di òkìtì àlàpà, yóo sì di ohun àwòyanu ati ẹ̀gàn fún gbogbo ẹni tí ó bá ń rékọjá lọ.
Ìdí rẹ̀ nìyí tí ẹni tí ó ń fi èdè àjèjì sọ̀rọ̀ fi níláti gbadura fún ẹ̀bùn láti lè túmọ̀ rẹ̀.
Orile-ede Naijiria ti sefilole ajo tuntun
Kii ṣe afikun owo ori ni a nilo bayii.
Ọmọlanke la papa fi gbe ẹgbọn mi lọ sile iwosan lẹyin o rẹyin, nibi to ti dakẹ.
Nígbà náà ni Finehasi dìde, ó bẹ̀bẹ̀ fún wọn,àjàkálẹ̀ àrùn sì dáwọ́ dúró.
Eyi ko seyin idajọ ileejọ kotẹmilọrun ni ilu Abuja to fi ontẹ lu u pe ki wọn yọ Adam Oshiomọlẹ gẹ̀gẹbi Alaga ẹgbẹ oṣelu naa.
Ẹ jẹ́ kí á yan ohun tí ó tọ́,kí á jọ jíròrò ohun tí ó dára láàrin ara wa.
Ó ku nǹkankan: Tọ́jú ààyè sílẹ̀ dè mí, nítorí mo ní ìrètí pé, nípa adura yín, Ọlọrun yóo jẹ́ kí wọ́n dá mi sílẹ̀ fun yín.
Gomina Akeredolu bori ni ijọba ibilẹ mẹẹdogun, ninu mejidinlogun to wa ni ipinlẹ Ondo, eyi to mu ko fi ẹyin Jegede janlẹ pẹlu esi ibo to pọ.
" Mo bẹ awọn eniyan lati maa ṣe akiyesi gbogbo awọn ti wọn ṣe alabapin pẹlu ati nigba gbogbo lati maa ṣe ayẹwo awọn ara adugbo wọn pẹlu loore-koore lati dẹkun irufẹ ijamba bayii lawujọ""."
Ilé-iṣẹ́ ààrẹ àti àjọ tó ń rí sí ìdánwò àṣekágbá ní ìhà ìwọ̀-oòrùn Afirika (WAEC) ló ń ṣe gbọ́nmisíi -omi -ò -tó lóri ọ̀rọ̀ ìwé ẹ̀rí ààrẹ Muhammadu Buhari ti àjọ WAEC gbéjade lọ́jọ́ Jímọ tí kọja.
Orúkọ tí Olórí wọn –Agígírì sọ ibẹ̀ ni IJẸLÚ nítorí pe ÌJẸ̀ ni Ìjẹ̀sà máa ń pe Ẹ̀JẸ̀.
Eyi ni awọn ọna abuda fun awọn ọlọkọ lasiko ti atunṣe afara Eko bridge naa yoo maa fi waye: Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 3 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 5 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
ỌJỌ́ ÌTÀN  – Ikọ̀ ọkọ̀ òfuurufú TM
Nígbà tí àkókò igbagbọ ti dé, a kò tún nílò olùtọ́ mọ́.
Jesu wí fún un pé, “Jẹ́ kí àwọn ọmọ rí oúnjẹ jẹ yó ná, nítorí kò dára kí á mú oúnjẹ ọmọ kí á sọ ọ́ fún ajá.
Ewe, ekun ariwa Kivu ni laasigbo ti so di asale , latari iwa isekupa-ni ati jiji eniyan gbe, eyi ti laasigbo to n waye laarin eya meji sokunfa re.
Alágbára ni iyì lójú àwọn ọmọ ènìyàn, ṣùgbọ́n ọ̀lẹ ọkùnrin òtúbáńtẹ́ ènìyàn ni lójú àwọn obìnrin – mo wọlé mo kó ohun ìkọ̀wé jo, mo gbàga mo jókòó ti tábìlì mo sì gbé àga kan si ẹ̀bá tábìlì náà lórí eléyìí sì ni ọ̀rẹ́ mi náà jókòó lé, àkàrà-òògùn, a-bá-olóúnjẹ-kú.
N óo kó àwọn orílẹ̀-èdè tí wọ́n burú jùlọ wá, wọn óo wá gba ilé wọn.
Iroyin to n lọ kaakiri ni pe Kabiyesi, iku baba yey ti le olori to kere julọ laafin rẹ, iyẹn Olori Badirat Ajọkẹ kuro laafin lori ẹsun pe o n ṣe aṣemaṣe pẹlu gbajugbaja olorin Fuji to tun jẹ Mayegun ilẹ Yoruba, Wasiu Ayinde Marshal, ti ọpọlọpọ mọ si KWAM 1, K1 De Ultimate.
Bakan naa ,ni igbimo yoo tun maa tewogba  ijiroro lati ile-ise to n mojuto papa ofurufu ati banki  ayanilowo fun ile kiko lorile ede Naijiria( Federal Mortgage Bank).
Oríṣun àwòrán, Graham Prentice/Alamy N jẹ ẹnikan mọ orukọ ọmọ yii?
    Mo dúró títí bí ẹni pé kí Ẹlẹ́gbára pàápàá kọjá, kò kọjá, àkókò gan-an tí mo sì bẹ̀rẹ̀ síí ronú pé kò níí wá mọ ǹ jẹ́ ki n súfèé pe àwọn yò’kù mi ni mo déédéé ri ti ilẹ̀ ń mi tìtì tí ogunlọ́pọ̀ àwọn ẹranko ń sá kiri, àwọn ẹyẹ pàápàá kò fi ara balẹ̀ mọ́, wọn ń kígbe léra léra, àwọn ejo ń sáré gun igi wọ́n tún ń wọ lulẹ̀, bẹ́ẹ̀ ni igbe àwọn ọ̀kẹ́ẹ́rẹ́ gba agbegbe kankan.
AMAA 2018 Ami eye awon asatunto ise to dara julo
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù OsunDecides: Adeleke kò jáwọn olólùfẹ́ tó fẹ́ wòran ijó rẹ̀ kulẹ̀ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ OsunDecides: Adeleke kò jáwọn olólùfẹ́ tó fẹ́ wòran ijó rẹ̀ kulẹ̀ 19 Owewe 2018 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 20 Owewe 2018 Oludije fun ipo gomina labẹ ẹgbẹ oselu PDP nipinlẹ Ọsun, Sẹnetọ Ademọla Adeleke, kò jáwọn olólùfẹ́, tó fẹ́ wòran ijó rẹ̀ kulẹ̀, lasiko eto ipolongo ibo rẹ to waye nilu Osogbo lọjọ̀ru.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ǹjẹ́ wọn yoo dá awọn ọmọ Chibok tókù sílẹ̀?
Gbogbo àwọn olólùfẹ́ rẹ̀ pẹ̀lú ló si ti n bẹnu àtẹ lu ìwà tó wu.
Oyedele kede atilẹyin rẹ fun Akeredolu lẹyin ifikunlukun pẹlu gomina Akeredolu nileejọba ipinlẹ Ondo ni alẹ ọjọ Aiku.
Aworan yii lasan si ti sọ ohun ti awọn araalu fẹ mọ, eyi to n ṣọ pe ọba alaye naa si nifẹ oun bii oju, to si n gbadun pe oun rẹwa pupọ.
Ní ti Titu, ẹlẹgbẹ́ mi ati alábàáṣiṣẹ́ mi ni ninu ohun tí ó kàn yín.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Child marriage: Wo ọmọbìnrin ọdún méjìlá tó ṣè'gbéyàwó pẹ̀lú ọkùnrin méjì láàrin oṣù kan 15 Agẹmo 2020 Oríṣun àwòrán, Getty Images Eemọ lukutu pẹbẹ.
Àwọn ìjòyè náà bá sọ fún ọba pé, “Ẹ jẹ́ kí á pa ọkunrin yìí nítorí pé ó ń mú ìrẹ̀wẹ̀sì bá àwọn ọmọ ogun tí wọn kù láàrin ìlú, ati gbogbo àwọn eniyan nítorí irú ọ̀rọ̀ tí ó ń sọ fún wọn.
Lẹ́yìn náà, ẹ máa bá tiyín lọ.
Oye mi nipa aye yii ti yatọ ni akoko taa wa yii, haa, o ma dara ki eniyan ni arojinlẹ o.
Ṣugbọn ni bayii, awọn tẹgbọn-taburo naa ti wa ni ihamọ ọlọpaa, nibi ti wọn yoo ti gbe wọn lọ ile ẹjọ.
Chioma Okoye ni: “Mo n parowa yii fun gbogbo iran Igbo lati dide bii omo oko lati mu idagbasoke ba asa ati ede Igbo lagbaye.
Lọ́jọ́ ọdún Kérésìmesì, wàhálà bẹ́ sílẹ̀ l'Osogbo, iná ìbọn sọ Nínú kó o fi omi fọ ìdi tàbí lo tííṣù fi fá a, Èwo ló rọrùn?
Gbajúmọ̀ gbọdọ̀ jẹ́ àwòkọ́ṣé rere torí bí ìràwọ̀ ṣe ń kú, ni òmíràn ń tàn - Foluke Daramola Wo aṣọ òtútù tó wọ́n jùlọ ní àgbáyé!
Òòró rẹ̀ jẹ́ igbọnwọ kan ààbọ̀ (mita 7), ìbú rẹ̀ náà jẹ́ igbọnwọ kan ààbọ̀ (mita 7), ó sì ga ní igbọnwọ kan (bíi ìdajì mita).
Igbakeji aarẹ Barack Obama tẹlẹ ri yii ni wọn yan gẹgẹ bi oludije labẹ asia ẹgbẹ oṣelu Democratic fun idibo inu oṣu kọkanla.
Farao bá dáhùn, ó ní, “Kí OLUWA wà pẹlu yín bí mo bá jẹ́ kí ẹ̀yin ati àwọn ọmọ wẹ́wẹ́ yín lọ.
Oludamọran rẹ, Sean Kampondeni sọ fun BBC pe, eyi lo fihan pe adari le mojuto igbe aye ẹ̀mí ati ti ara, awọn eniyan rẹ.
’ rèé Orí mi wú, Joke Silva kọ ewì ìfẹ́ lọ́jọ́ ìbí Olu Jacobs Ẹ̀yin èèyàn Oyo, ẹ sọ tẹnu yín lórí àbá àjẹbánu tí Makinde dá - SERAP Sanwoolu ṣe é dáa fún wa níbodè Lekki, Ikoyi - Awakọ̀ ní Lekki Soji Adagunodo fikun wi pe, kii se adari ẹgbẹ lo n yan ẹnikẹni lati dije dupo, amọ awọn eniyan to ba ni ọmọlẹyin to pọju, nitori ẹni ti wọn ba di ibo fun ni awọn ma a gbe si iwaju.
Igbesẹ yii si lo waye lẹyin ọsẹ kan pere ti Oluwo lu Agbowu tilu Ọgbaagba nibi ipade alaafia kan ti igbakeji sga agba ọlspa pe nilu Osogbo.
Olumilua: Ọdún kan àti oṣù mẹ́wàá ni Bamidele Olumilua fi ṣe gómìnà ní ìpínlẹ̀ Ondo ijọ́un Oríṣun àwòrán, others Yoruba ni ọjọ taa dele aye ko to ọjọ ta ba ku, nitori iṣẹ ọwọ wa ni yoo sọ nipa ohun ta ba gbe ile aye ṣe.
Igbà Ọba Adéyẹyè Ẹniitàn, Ògúnwùsi á tu ilú lára.
Awon mii ni ko ṣiṣẹ to lori eto ẹkọ ni ko jẹ kawọn eniyan mọ Ọjọgbọn yii bii minista to lagbara.
Yóo sì da ẹ̀jẹ̀ akọ mààlúù yòókù sílẹ̀ nídìí pẹpẹ ẹbọ sísun tí ó wà ní ẹnu ọ̀nà Àgọ́ Àjọ náà.
Atẹjade kan ti alaga fẹgbẹ PDP ni ipinlẹ Ọsun, Sọji Adagunodo fisita wa kesi awọn ileesẹ to n gbogun ti iwa ibajẹ, lati dide tanna imọlẹ wọn si ẹsun yii.
Wọ́n fẹ́rẹ̀ má ì tíì gbìn wọ́n,wọ́n fẹ́rẹ̀ má ì tíì ta gbòǹgbò wọlẹ̀;nígbà tí ó fẹ́ afẹ́fẹ́ lù wọ́n,tí wọ́n fi rọ bí ewéko,tí ìjì sì gbé wọn lọ bí àgékù koríko.
Ninu kí o gbóná tabi kí o tutù, ó yẹ kí o ṣe ọ̀kan.
Ìkéde nípa àwọn dúkìá yìí, tí Ójẹrinde pàdánù sì ọwọ àjọ ICPC ni ilé ẹjọ́ ti tẹ síta, lójú àwọn ewé ìwé ìròyìn kan nilẹ wa .
Ọgba ẹwọn ijọba apapọ nilu Chicago, ni Illinois, lorilẹ-ede Amẹrika ni Ramoni Igbalode, wa lọwọlọwọ.
Oríṣun àwòrán, PA Media Àkọlé àwòrán, Boris ko le da so ijokoo ile rọ lai kàn si Obabinrin Elizabeth Kinni o wa máa ṣẹlẹ bayii ni UK?
Lẹ́yìn èyí, ogun mìíràn tún bẹ́ sílẹ̀ pẹlu àwọn ará Filistia, ní Gobu, ninu ogun yìí ni Sibekai ará Huṣa ti pa Safu, ọ̀kan ninu àwọn ìran òmìrán.
Ìran tí Ọlọrun fihan wolii Habakuku nìyí.
Babcock Sex Video: Ọ̀pọ̀ èèyàn ní kò yẹ kí wọn lé akẹ́kọ̀ọ́bìnrin ọ̀hún torí kìí ṣe ọmọdé
Sibẹ awọn ololufẹ Super Eagles ni ki wọn ṣora fún Adam Ounas ati Mahrez ti wọn jẹ agba ọjẹ agbabọọlu fun Algeria.
“Ẹ gbọdọ̀ ṣọ́ra, kí ẹ sì máa pa gbogbo òfin tí mo fun yín lónìí mọ́, kí ẹ lè wà láàyè, kí ẹ lè máa bí sí i, kí ẹ sì lè lọ gba ilẹ̀ tí OLUWA ti búra láti fún àwọn baba yín.
O wa ṣapejuwe bi awọn ologun se kọju ibọn sawọn ọdọ to n sewọde ni Lekki Eko gẹgẹ bi ikọlu si ilẹ Yoruba.
Ewe, bi a ko ba gbagbe pe, lojo kejidinlogun osu kokanla odun ti a wayii, ni iko olote boko haram sekolu sibudo iko omo ogun Naijiria ti o wa lagbegbe Metele, nipinle Borno, ti won si seku-pa ogunlogo awon omo ogun.
Tí wọ́n bá sọ fún wá ni ọjọ́ àìkú tó kọjá wipe àó wá sòkú Ayodeji ènìyàn yóò jiya Ọdún kẹtalá rẹ̀ẹ́ tí Ituah àti Ibidunni ti wà bíi tọkọtaya kí ó to dédé dolóògbé ní ilú Port harcourt láàrọ̀ kùtù ọjọ́ àìkí Oríṣun àwòrán, others Àkọlé àwòrán, Ibidun Ituah Ighodalo fayé silẹ̀ ìlúmọ̀ọ́ká arẹwà tí fáyésilẹ̀ Wo àwọn òṣèré tíátà Yorùbá tó bí ìbejì Ẹ̀kọ́ mẹ́jọ tó yẹ kí ilẹ̀ Afirika kọ́ lára àjàkálẹ̀ aàrùn coronavirus Alhaja Kudirat Abiola: Odindi géńdé ọkunrin mẹ́fà ni wọ́n gbé iṣẹ́ ikú rẹ̀ fún Mo kábámò pé mo fipá bá Ìyá ẹni ọgọrin ọdún sún ní Kano- Muhammad Zulfara'u Oríṣun àwòrán, @prettypearl Kogi Robbery: Àwọn adigunjalè tó ja báńkì lólè ní Kogi, ya bo àgọ́ ọlọ́pàá,pa ọlọ́pàá mẹ́jọ Awọn adigunjale ti pa ọlọpaa mẹjọ, ti ọga ọlọpaa DPO si wa lara wọn ati obinrin kan ni agbeegbe Isanlu, ni ijọba ibilẹ Yagba ni ijọba ipinlẹ Kogi.
Ǹ bá sìn ọ́ wá sílé ìyá mi,ninu ìyẹ̀wù ẹni tí ó tọ́ mi,ǹ bá fún ọ ní waini dídùn mu,àní omi èso Pomegiranate mi.
Koda gomina ipinlẹ Kano ni oun ti ṣe tan lati tọwọ bọwe iku rẹ ni kete ti ọgbọn ọjọ naa ba ti pe.
Awọn agbofinro sọ pe awọn eeyan yii tawọn ọmọde pọju lara wọn ni wọn ju ṣẹkẹṣẹkẹ si lẹsẹ ninu ahamọ ti wọn wa.
Kí o ti àwọn ọ̀pá náà bọ àwọn òrùka ẹ̀gbẹ́ pẹpẹ, tí ọ̀pá yóo fi wà ní ẹ̀gbẹ́ kinni keji pẹpẹ náà nígbà tí wọ́n bá fẹ́ gbé e.
james mercer langston hughes ( february 1 , 1902 - may 22 , 1967 ) je akoewi , aseiwe-aroso , akoere-oritage ati alaroko .
Dafidi bẹ̀rẹ̀ sí di alágbára sí i, nítorí pé OLUWA àwọn ọmọ ogun wà pẹlu rẹ̀.
 Hiddink, omo odun mọ́kànléláàdọ́rin ohun, ni gbajugbaja akonimoogba ti o lamilaaka lagbaye ti yoo teko leti lo tuko agbaboolu lorile-ede China lati gba ti aare orile-ede China, Xi Jinping, ti fi erongba re han lati mu ayipada otun ba ere boolu afesegba lorile-ede ohun.
Awọn ajafẹtọẹni ni ẹjọ rẹ ti tan imọlẹ si ilakaka ijọba lati dẹgun le awọn akọroyin to n bẹnu atẹ lu u Wọ́n gbé Akọ̀ròyìn ní Morocco lọ sílé ẹjọ́ lórí ẹ̀sùn àgbèrè àti oyún ṣíṣẹ́.
Olumilua: Mimiko ní olóògbé náà kìí ṣe olóṣèlú jẹgúdú-jẹrá, irú rẹ̀ kò sì wọ́pọ̀ mọ́
APC sún ìdìbò abẹ́lé fún ìpò gómìnà síwájú nipinlẹ Imo ati Eko Ẹgbẹ oṣelu APC ti sun idibo abẹle fun ipo gomina ni Ipinlẹ Eko to yẹ ko waye lọjọ Aiku tẹlẹ si ọjọ Aje bayii.
sọ iye tí o bá fẹ́ máa gbà, n óo sì máa san án fún ọ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ekiti Election: Bọ́mọ kò bá bá ìtàn ó di dandan kó bá àrọ́bá 13 Agẹmo 2018 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 14 Agẹmo 2018 Àkọlé àwòrán, Àwọn ènìyàn Ekiti ti ṣetan Àwọn ènìyàn Ekiti yóò pààrọ̀ Fayooṣe sí gómìnà míì lónìí Ọjọ́ kìnní, oṣù kẹwaa, ọdún 1996 nijọba Nàìjíríà dá ipinlẹ Ekiti pẹlu ipinlẹ marun un miran silẹ lábẹ ijọba ologun Sani Abacha.
olufokansin lati ri i pe won tẹle ibo ti won di  lati ile idibo, lọ si ile ikabo.
Ó ranṣẹ sí àwọn ará Kenaani ní ìhà ìlà oòrùn, ati ti ìwọ̀ oòrùn, ati àwọn ará Amori, ati àwọn ará Hiti, ati àwọn ará Perisi, ati àwọn ará Jebusi ní àwọn agbègbè olókè, ati àwọn ará Hifi tí wọ́n wà ní abẹ́ òkè Herimoni ní ilẹ̀ Misipa.
4% ni àwọn tó ti pe ogójì ọdún tó ti kú , tí ìdà 19% sì jẹ́ àwọn tó ti lé ní ọgọ́rin ọdún.
Orilẹ-ede mẹwaa miran ni ilẹ Afirika ni wọn wa laarin ipo ogun akọkọ igbelewọn awọn orilẹ-ede ti iṣẹlẹ igbesunmọmi ti gogo julọ lagbaye.
APC bu ẹnu atẹ lu igbesẹ ijọba Akwa Ibom lori papa iṣere rẹ Agbẹnusọ fun APC ni ipinlẹ naa, Nkereuwem Enyongekere sọ fun BBC Pidgin pe igbesẹ ijọba lati ma jẹ ki awọn lo papa iṣere naa ko bojumu.
Five Fingers For Marseilles – South Africa
Àwọn ọmọ Nàìjíríà láti ilẹ̀ Gẹ̀ẹ́sì wọ̀ gàù l'Eko Coronavirus returnees: Àwọn àbọ̀dé ọmọ Nàìjíríà láti ilẹ̀ Gẹ̀ẹ́sì ní òbítíbitì owó làwọn san ṣùgbọ́n ẹ̀gbin níjọba ń fojú wọn rí Nnkan o rọgbọ fun awsn ọms Naijiria ti ijọba apapọ ko de lati orilẹ€de Gẹẹsi ni ọjọ Ẹti pẹlu bi gbogbo wọn ṣe n pariwo pe nṣe ni ijọba apapọ ru wọn da silẹ ni yanrin ikọle ni papakọ ofurufu ilu Eko.
le jẹ ki a ni awon adari tootọ ti o  lee
O ni oun ni gbogbo nnkan ti o pe fun lati du ipo ọun, sugbọn ti asiko ko tii to loju oun lati se bẹẹ.
Oríṣun àwòrán, @lagosstategov Àkọlé àwòrán, SERAP ní kò yẹ kí mínísítà fún iná ọba ó ṣe orúkọ àwọn kọngílá tó gbowó láì ṣiṣẹ́ ìpèsè iná ọba lóòkú òru Ajs naa ni bi minisita naa ba lee daruks awọn ileeṣẹ naa si gbangba, yoo mu ko di iṣoro fun wọn lati ko owo naa jẹ.
Lóòtọ́ ó lẹtò sùgbọ́n kìí ṣé ni àyíká Nàìjíríà.
Ohun to rọ mọ aṣa yii lo kan yatọ diẹ sira wọn Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Àìle è ka kéú ló sọ mí di Krìstíẹ̀nì - Adewale Ayuba Itan omi gbigbona ati tutu ni Ikọgosi Ekiti Ṣé ìwọ mọ odò adágún Adó Àwáyè tí kò ní òpin ní ìsàlẹ̀?
Ìdí tí mo fi ń ṣe ayẹyẹ ọjọ́ ìbí 35 lọ́dọọdún rèé- Allwell Ademola Yàtọ̀ sí Eko, wo ohun t'áwọn ìpínlẹ̀ meje míràn ń sọ nípa ìwọlé àwọn akẹ́kọ̀ọ́ Wo ojú Akeem t'Ọlọ́pàá mú pé ó fipá bá ọ̀dọ́mọbìnrin kan sùn létí odò l'Oṣun YWC yọ Ààrẹ Banji Akintoye nípò àbi Akintoye tú ìgbìmọ̀ aláṣẹ YWC ká?
ÌLÀNÀ TÍ À Ń GBÀ ṢIṢẸ́ Fún iṣẹ́ to níkìmí nínú, bí iṣẹ́ ìwádìí tàbi kíkọ ìròyìn tó níṣe pẹ̀lú dátà, a máa ń ràn yín lọ́wọ́ láti ni òye bi a ṣe ń se iṣẹ́ wa nípà sísàfihàn bi aṣe ṣe àkójọ dátà àti ìtúpalẹ̀ ohunkohun to ba dabi ẹni pe ó ta kókó, àwọn àròsínú tàbi ìlànà míràn ti a gbà ṣiṣẹ́- bí àpẹẹrẹ, àwọn àpẹẹrẹ ìkẹ́kọ̀ọ́, ìwọ̀n àyẹwò, sisasoju, awọn àlà àìtọ́, báwo ni a ṣe gba dátà, ọ̀nà wo lo gbà báramu lágbàyé, pẹ̀lú ìgbà àti àkókò Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
"Yatọ fun iṣẹ Tiata, ilumọọka ni Ayo Akinwale ninu fiimu lati igba awọn ere atijọ bii: Afonja Sango Ladepo Omo Adanwo Iranse Aje Agbara Obinrin ati bẹẹ bẹẹ lọ pẹlu oniruuru ami ẹyẹ ti Ayo Akinwale gba gẹgẹ bi oṣere, oludari ere, ẹlẹsẹ ijo ati olohun orin - ""gbogbo iha Tiata lo pe lara Ayo Akinwale""."
Ẹ má ṣe jẹ́ kí èyí yà yín lẹ́nu, nítorí àkókò ń bọ̀ nígbà tí gbogbo àwọn òkú tí ó wà ní ibojì yóo gbọ́ ohùn rẹ̀, 
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Tọkọtaya lu ọmọ ni gbanjo fun 400k 20 Èrèlè 2018 Oríṣun àwòrán, PUNCH Àkọlé àwòrán, Baba ọmọ ni ajọmọ oun ati iyawo oun ni lati ta ọmọ jojolo naa Lẹyin iwadi ọse mẹta, ọwọ sinkun awọn ọtẹlẹmuyẹ ba tọkọtaya kan ti wọn ta ọmọbinrin jojolo ti wọn sẹsẹ bi ni ẹgbẹrun lọna irinwo naira, lẹyin wakati diẹ ti wọn bi ọmọ naa.
"Aye ọjọun lawọn kan n parọ, ọba kan kii jẹ ẹdọ, irọ ni wọn n pa.
Kọmiṣọna ọlọpaa ipinlẹ Ondo, Bolaji Salami ni iṣẹlẹ naa waye lọjọ karundinlogun, oṣu Kejila, ọdun 2020.
Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí 8:06 Fídíò, Blind Couples: Pẹ̀lú ìpèníjà ojú, tọkọtaya bímọ mẹ́ta, tí wọn sì tún ń ṣiṣẹ́ olùkọ́, Duration 8,0619 Ọ̀wàrà 2020 6:59 Fídíò, Blind DJ: Etu Omotayo kò ríran àmọ́ ó le to irinṣẹ́ eléré pọ̀ láti kọrin láì sí ìrànwọ́, Duration 6,5917 Ògún 2020 6:56 Fídíò, Wòlíì Kasali sọ̀rọ̀ nípa awuyewuye pé ó lé ìyàwó rẹ̀ jáde nílé, Duration 6,5628 Ọ̀pẹ̀̀ 2018 5:57 Fídíò, LASTMA Yesufa: Àwọn dókítà gbìyànjú lórí ojú mi ṣùgbọ́n.
O se ni laaanu  pe wọn kọlu awon osise ajọ eleto idibo  ati awon agunbanirọ ni ipinle Ọsun.
Iyaafin Agboola lo soro yii di mimo lasiko ti o n ba
N óo gbé ẹ̀mí apanirun kan dìde sí Babiloni,ati sí àwọn ará Kalidea;
Diẹ lara awọn eniyan naa sọ fún BBC pe lasiko ti awọn n tọrọ bara ni awọn agbofinro ko àwọn ni ilu Kaduna, lọjọ Ẹti.
Ohun to dara ni ki iyawo wa pẹlu eniyan, ko si tako ofin Ọlọrun."
AFCON 2019: Báwo ni ìdíje Super Eagles àkọ́kọ́ yóò ṣe lọ?
Wọ́n sọ fún Aaroni pé, ‘Ṣe oriṣa fún wa kí á rí ohun máa bọ, kí ó máa tọ́ wa sí ọ̀nà.
O ni iru awọn ọkunrin to n hu iru iwa ọdaran bẹẹ lo yẹ ki gbogbo awọn ọkunrin to ku pawọpọ lati bawi nitori wọn ba gbogbo ti ko mọwọmẹsẹ loju jẹ.
Ẹlẹ́dàá ló ṣe ètò oyin ṣíṣe, tí Ó sì fi fún kòkòrò abìyẹ́ nì láti máa ṣe.
Falcons morile Abdijan fun idije WAFU NFF sadehun pẹlu Dennerby fun Falcons Oludari eto ibanisọrọ nileeṣẹ ajọ to n mojuto ere idaraya ni Naijiria, NFF, Ademọla Ọlajire ninu ikede kan to fi sita l'alẹ ọjọ Ẹti sọ pe orilẹ-ede Austria nibi ti Super Falcons wa lọwọlọwọ fun igbaradi ni olórí akọnimọọgba wọn, Thomas Dennerby ti kede orukọ naa.
Ẹ kọ orin ìyìn sí Ọlọrun, ẹ kọ orin ìyìn;Ẹ kọ orin ìyìn sí Ọba wa, ẹ kọ orin ìyìn!
Bákan náà lo sàlàyé pé, òun yóò lọ fi ẹjọ sùn ni Bareke Letmack ni agbegbe Mokola gẹ́gẹ́ bi òfin ṣe láásílẹ̀ Bí mo ṣe pàdánù àǹfàní láti rí ìyá mi fún ìfgbà ìkẹ́yìn - Makinde ṣàlàyé A kò lọwọ́ sí ìwé ìpẹ̀jọ́ tó tako ìdásílẹ̀ ìgbìmò ìwádìí aṣemáṣe ikọ̀ SARS- ọlọ́pàá Nàìjíríà Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Seyi Makinde: Gbogbo ìgbà ni ìyá mi máa ń sọ fún mi pé díẹ̀ ló kù kí àwa méjèjì kú lọ́jọ́ tó bí mi4 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 EndSars Protest: A kò lọwọ́ sí ìwé ìpẹ̀jọ́ tó tako ìdásílẹ̀ ìgbìmò ìwádìí aṣemáṣe ikọ̀ SARS4 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Àtẹ Àwòrán, Oluwo, Olúgbò àtàwọn Ọba alayé míì ṣàbẹ̀wò sí Gómìnà ìpínlẹ̀ Eko, Oba ìlú Eko àti Bola Tinubu3 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 11:29 Fídíò, EndSARS: Olatunde Abolarinwa London Tailor ní òun á ṣe baba fún mi, kò tilẹ̀ dúró ṣe bàbá àwọn ọmọ tirẹ̀ tóríi ìwà Ọlọ́pàá Mopol, Duration 11,295 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Sagbokoji, ìlú tó sún mọ́ ọ̀làjú pẹ́kípẹ́kí ṣùgbọ́n tí iná ẹ̀lẹ́ńtíríkì kò sí láti ọgọ́ọ̀rún ọdún Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Sagbokoji, ìlú tó sún mọ́ ọ̀làjú pẹ́kípẹ́kí ṣùgbọ́n tí iná ẹ̀lẹ́ńtíríkì kò sí láti ọgọ́ọ̀rún ọdún 18 Èbibi 2019 Awọn agba bọ, wọn ni nibi ti eeyan kan ti n sunkun airi eyin ni ẹnikan n sun airi ete bo tirẹ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ajimobi ni ìlérí òun láti mú àwọn tó pa 'Ṣuga' kò yí padà 3 Èbibi 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Temitọpẹ Ọlatoye Ṣuga lo ṣoju fun ẹkun idibo apapọ Lagelu/Akinyele ni ipinlẹ Ọyọ ki o to ku Gomina ipinlẹ Ọyọ, Abiọla Ajimọbi ti sọ pe oun ko mọ ohunkohun nipa iku aṣofin apapọ ipinlẹ naa kan, Temitope Olatoye ti ọpọ mọ si Ṣugar.
' O fikun pe oun tẹle aṣẹ ijọba to tako ipejọpọ awọn eniyan ọlọgọrọ lasiko ajakalẹ arun Coronavirus yii.
Ẹ̀yin ẹ̀ṣọ́, ẹ kò gbọdọ̀ fààyè gba jíjí àpótí ìdìbò ní Kogi àti Bayelsa- Buhari A gbé ìgbìmọ̀ kan kalẹ̀ láti ṣiṣẹ́ lórí gbígba àkóso fásitì LAUTECH - Seyi Makinde ‘Ilé ẹjọ́ kò gbé ẹ̀sùn ìfipánílòpọ̀ yẹ̀wò, à ń lọ sí ilé ẹjọ́ - Busola Dakolo Èèyàn méjì farapa nínú ilé tó jóná ní Tejuoso l‘Eko Mohammed ni erongba ijọba apapọ ki n ṣe lati fi ẹtọ awọn Naijiria lati sọrọ du wọn, ṣugbọn o jẹ ọna lati fọ ori itakun ayelujara mọ.
Bakan naa lo fidunnu ẹbi han pe aarẹ Buhari wa yẹ oloogbe naa si.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ẹ wá gbọ bí òwe Yoruba ṣe dùn lẹnu ọmọ Igbo Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Ẹ wá gbọ bí òwe Yoruba ṣe dùn lẹnu ọmọ Igbo 14 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Imado iba ṣe bi ẹlẹdẹ a balu jẹ, ẹru iba j’ọba, eeyan iba ku ọkan.
ọrọ rẹ, Alaga Igbimọ awọn musulumi ninu Ile Igbimọ Aṣofin Ipinlẹ Eko,
Ṣé o ti ká àgbọ̀nrín mọ́ ibi tí ó ti ń bímọ rí?
"Oríṣun àwòrán, others ""Mimu ti a mu awọn meji yii mu so eso rere nitori pe o finna mọ awọn to ku lati le yọnda awọn to wa ni igbekun wọn lai gba owo."
Márosẹ̀ Kaduna di ìbùba fáwọn ajínigbé Ilẹ́eṣẹ́ ààrẹ: Ìkọlù Birnin Gwari dun Buhari Agbebọn pa ọmọ ogun mejila Awọn awakọ ni agbegbe Birnin Gwari lo tun kigbe pe àwọn ajinigbe ji àwọn èrò to to marundinlaadọta to n lọ lati àríwá si gúúsù Nàìjíríà gbé.
N400m ló ń sọnù ní ọdọọdún nítorí àwọn tó ń gba owó òṣù láì ṣiṣẹ́ - Fayemi Wo ọmọ Yoruba tó jáwé olúborí nínú ìdìbò sílé ìgbìmọ̀ aṣòfin ilẹ̀ Amẹrika Wo ǹkan tó yẹ kí o mọ̀ nípa Joe Biden, tó ń kojú Trump nínú ìbò America Arakunrin Nguyen, to n da gbele sọ pe lẹyin apamọwọ kekere kan ati ẹiyẹ oun ti ori ko yọ, awọn ko farapa botilewu ko kere mọ.
Wọ́n pada sí Jerusalẹmu ati ilẹ̀ Juda, olukuluku pada sí ìlú rẹ̀.
Ìpínlẹ̀ Ogun, Eko ti gbáradì fún ẹ̀kún omi yalé Ijọba ipinlẹ Eko ti kesi awọn ara ilu lati sa ipa wọn lórí imọtoto lasiko ojo yii lati dẹkun omiyale-agbara ya sọọbu.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, ''Ẹ̀mí ọ̀pọ̀lọpọ̀ ṣì n sọnù ni orilẹ̀-ede Burundi' Kikopa ninu AFCON latẹyinwa: Orilẹ-ede Burundi ko kopa ri lati ọdun 1957 ti AFCON ti bẹrẹ titi di ọdun 1974.
Ni aipẹ yii ni iroyin kan pe olori Aanu jade si gbangba walia loju opo ayelujara rẹ to si faraya lori awọn ọrọ iwọsi tawọn eeyan kan n sọ sii loju opo ayelujara.
Ó fi ọ̀kan ninu àwọn ọmọ rẹ̀ ṣe alufaa oriṣa rẹ̀.
Ó ní, “Ìwọ tí Ọlọrun fẹ́ràn, má bẹ̀rù, alaafia ni, dá ara yá, kí o sì ṣe ọkàn gírí.
Gbogbo yín, ẹ gbé ọkàn ìrẹ̀lẹ̀ wọ̀, bí ẹ ti ń bá ara yín lò, nítorí,“Ọlọrun lòdì sí àwọn onigbeeraga,ṣugbọn a máa fi ojurere wo àwọn onírẹ̀lẹ̀.
Ó bi mí pé: “Amosi, kí ni o rí?
Yoo wa pe ogoji ọdun ọhun lọla ṣugbọn kii ṣe lorilẹ aye.
Oríṣun àwòrán, Joseph Burke-Monerville/Facebook Àkọlé àwòrán, Joseph jẹ ẹni ọdun mọkandinlogun nigba to ku ni ọdun mẹfa sẹyin Oríṣun àwòrán, Joseph Burke-Monerville Ẹni ọdun mọkandinlogun ni a gbọ pe Joseph ọmọ ile iwe fasiti London Metropolitan nigba naa wa lasiko to ku.
Àjẹ́dìran, ṣe akiyesi ìwà tí Olódùmarè fi jíǹkí rẹ.
Kí ni ó tún kù kí n ṣe?
Bakan naa, adari ile igbimọ asofin nilẹ Yoroopu, European Parliament sọ wipe awọn yoo se iwadi lori bi wọn se si iroyin ti awọn eniyan fi soju opo Facebook lo.
Iroyin fi han wi pe Al-Bashir wa lara olori orilẹede Afirika to lowo ju lọ.
Ẹnikẹ́ni ninu yín kò ní wọ ilẹ̀ tí mo ti búra pé yóo jẹ́ ibùgbé yín, àfi Kalebu ọmọ Jefune ati Joṣua, ọmọ Nuni.
Ileeṣẹ ọlọpaa China ni ifẹhonuhan ti n bi ige ati adubi ni eyi ti awọn agbofinro fi ni lati gbe igbesẹ to yẹ lasiko yii: Ìjà arọ méjì lálẹ́ òní ní pápá ìṣeré Old Trafford Ǹ jẹ́ o mọ àwọn èèyaǹ wọ̀nyí tó jà fún òmìnira Nàìjíríà?
- BBC News Yorùbá BBC News, YorùbáFò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Kaduna Kidnapping - Ọmọ iléèwé mẹfà pẹlú Olùkọ méjì ni wọn jígbé ni Kaduna.
Ó gbadura, sí OLUWA, OLUWA sì gbọ́ adura rẹ̀, ó sì fún un ní àmì tí ó yani lẹ́nu kan, 
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, EndSARS protest in Nigeria: Mr Macaroni, Falz, Wizkid, Tiwa Savage àtàwọn míì ṣe ìwọde O ni ọrọ iwa tani-o-mumi ti awọn ọlọpaa kogberegbe FSARS ti ijọba ṣẹṣẹ tuka yii kọja bẹẹ lori awọn iroyin to lu ayelujara pa lasiko yii.
Awọn mọlẹbi rẹ ni awọn ti lọ fi ọrọ naa lọ ni agọ ọlọpaa Ajiwe to wa ni Ajah ṣugbọn awọn ko tii ri ipa koko kankan niwọn igba ti ọwọ ko tii tẹ awọn ajinigbe ọhun.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Donald Trump: Àwọn obìnrin ilé ìgbìmọ̀ aṣòfin Amẹrika fọnmú sí ọ̀rọ̀ Trump 16 Agẹmo 2019 Àkọlé àwòrán, Àwọn obìnrin ilé ìgbìmọ̀ aṣòfin Amẹrika fọnmú sí ọ̀rọ̀ Trump Awọn obinrin aṣojuṣofin ti aarẹ Donald Trump sọrọ nipa wọn lori ayelujara ni ọrọ rẹ ko dun awọn.
Bakan naa ninu fọnran fidio kan to fi si oju opo Instagram to ti n wẹ ninu omi iluwẹ igbalode, orin iyin ẹsin Kristẹni ni o n kọ ninu rẹ.
Ninu ikede to fi sita, Ọga Agba fun ẹka Ọtẹlẹmuyẹ kan nileeṣẹ ọlọpa, Abba Kyari fi sita l'oju opo Facebook rẹ, ọwọ tẹ afurasi mẹrin nibi ti wọn ti n ṣe ayederu oogun .
wa sapejuwe kikuro ninu egbe APC lo sinu egbe APM gege “Ipenija ati ifiyajẹni’’.
Wọ́n gbéraga, wọ́n sì ṣe nǹkan ìríra níwájú mi.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìdájọ́ ikú: Ààdọ́sàn-án orílẹ̀-èdè ló ti fòfin de ìdájọ́ ìpànìyàn 16 Ọ̀wàrà 2018 Oríṣun àwòrán, AFP Akọwe Agba fun Ajọ Isọkan Agbaye (United Nations), António Guterres ti gbẹ oriyin fun awọn orilẹede to ti fofin de idajọ iku lorilẹede wọn, lasiko to n sami ẹyẹ ayajọ ọjọ to fofin de idajọ iku lagbaye.
“OLUWA yóo lé ẹ̀yin ati ẹni tí ẹ bá fi jọba yín lọ sí orílẹ̀-èdè tí ẹ̀yin ati àwọn baba yín kò mọ̀ rí, ẹ óo sì máa bọ oríṣìíríṣìí oriṣa tí wọ́n fi igi ati òkúta gbẹ́ níbẹ̀.
Ṣugbọn Mose pè wọ́n, Aaroni ati gbogbo àwọn àgbààgbà Israẹli lọ sọ́dọ̀ rẹ̀, ó sì bá wọn sọ̀rọ̀.
Nibayii, orilẹede Morocco tabi South Africa ni ireti wa pe o ṣeeṣe ko ja mọ lọwọ.
’ Ohun tí a sọ nípa mi yóo ṣẹ.
Tolulope tun kẹkọgboye gẹgẹ bii akẹkọọ imọ ogun ofurufu to fakọyọ ju nileewe giga tawọn ologun ofurufu lọdun 2017.
Ilu Eko lo ti lo igba ewe rẹ.
Láti ìgbà náà ni Israẹli ti ń bá ìdílé Dafidi ṣọ̀tẹ̀ títí di òní yìí.
Mo n parowa fun awon ijoba wa lati satileyin to ye nipa ajo to n risi oja to n lo sile okeere NEPC ki won le maa seto idanilekoo fawon aranso ati lilo irin ise oke okun daadaa ju bi won se n se laisiko yii lo”.
Ẹni tí kò dẹ́ṣẹ̀, tí a kò sì gbọ́ ọ̀rọ̀ ẹ̀tàn ní ẹnu rẹ̀ rí.
 nínú ogun eléèkejì yí ni àwon omo kúrunmí márùún kú sí , pèlú bí àwon omo ogun Ìbàdàn ti pa àwon omo re márúún tí wón sì gbé orí òkan nínú won ránsé sí bàbá won ( kúrunmí ) .
Gege bi ogbeni Muhidiin Khalif Aliyow, ti o wa lara awon toro kan gbongbon lagbegbe naa, so fun ile-ise akoroyin VOA pe, “Ibugbamu ado oloro waye laarin oja, eleyi ti won gbin sinu nkan osin, ti o si sekupa eniyan merin ti awon marun un miiran si farapa,”Ewe, awon osise eleto aabo ibile ti bu enu ate lu ikolu ohun, ti won si fi mule pe, iko omo ogun olote al-Shabab ni o wa nidi isele naa.
Mẹsan an ninu awọn eeyan ọhun wa ni ipinlẹ Eko, ti awọn marun un to ku si wa ni Abuja.
" Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Njẹ Chloroquine nipa kankan lati le koju Coronavirus Ki lo n da igbeyawo awọn oṣere ru?
se laarin odun meta ati aabo ti o ti lo.
 Ó tó wákàtí meṛrin kí wọ ́ n to rí àwọn èrò fàyọ níbi tí wọn há sí .
 Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Àṣírí ńlá tó ń bẹ láàrín Alaafin àtàwọn onílù rẹ̀ rèé Wo oríṣìí ìlù Yorùbá, ìwúlò wọn àti ba ṣe ń lò wọ́n Oyedepo àti ìjọba ń tahùn síra lórí bí ìjọba ṣe ń gba àkóso àwọn ilé ìjọsìn EFCC tún gbé Mompha lórí ẹ̀ṣùn lílu jìbìtì lórí ayélujára Ọlọ́pàá méjì wọ gàù lóri bí afurasí apanìyàn l‘Akinyele ṣe sá lọ Ìrìnna ọkọ́ òfúrufú s'ílẹ̀ òkèèrè bẹ̀rẹ̀ padà ní Nàìjíríà Jegede (PDP) ti yan Aṣojúṣòfin Ikengboju gẹ́gẹ́ bí ìgbákejì rẹ̀ tí wọ́n yóò jọ díje dupò O ni ọdun mejila sẹyin ni oun gba imisi lọdọ awọn ẹgbẹ pe ki oun ma a polongo nipa awọn ẹlẹgbẹ ọrun."
Ganiyat tó fi irin gbígbóná àti àdá ya ara ọmọ àbúrò ọkọ rẹ ti dèrò àgọ́ ọlọ́pàá l' Ogun Amọ kinni ọrọ ti ogbontarigi agbabọọlu naa sọ kẹyin ki o to jẹ Eleduwa ni pe.
Awọn amuyẹ Ramadan gbọdọ wa pẹlu wa kọja asiko wẹjẹwẹmu yii lọ.
" O fikun pe o yẹ kawọn eeyan fura si awọn to ba kundun ki wọn maa pẹgan eeyan ẹlẹgbẹ wọn, o ni awọn ti ko jẹ nnkan kan ni, nitori ẹni to ba jẹ nnkan ko ni bawọn pẹgan eeyan laelae.
Ẹni tí ó ṣoore ṣe é fún ara rẹ̀,ẹni tí ó sì ń ṣìkà ó ń ṣe é fún ara rẹ̀.
Eyi ni awọn ohun jijẹ ti a n ko wọ orilẹede Naijiria lati ilẹ okeere gẹgẹ bii ajọ iṣọkan agbaye fun ọdun 2019 ti gbe kalẹ: Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Lẹsẹkẹsẹ tí Judasi ti gba òkèlè náà tán, ó jáde lọ.
O tun je akoko ti a n fife han sira wa, didariji awon to se wa, sise aanu ati ireti ninu oore-ofe Olorun.
 ""Iyawo to ni ìtẹríba ni ọ, abajọ ti awọn ọmọ wa ọkunrin fi gbadura pe ki Ọlọrun fun wọn ni iyawo bi iru rẹ."
” Ẹni tí ń sáré bọ̀ náà túbọ̀ ń súnmọ́ tòsí.
ero fonron lori ero ayelujara(Twitter), o salaye pe, leyin ti oun ba
Inú fun ẹ̀dọ̀ fun ni ó fi bọ́ sọ́nà láti wá a títí tí òun ó fi rí i.
Ṣugbọn ninu ẹgbẹ alatako, PDP, Gomina Ayọdele Fayose nikan ni o ti kede ni gbangba pe ohun fẹ di Aare.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Fuel Price: Ẹ̀dínwó epo bẹntírò ti NNPC kede kò kan ará ilú O fí kún-un pé, gbogbo àwọn ibi ti wọ́n tí n fọ epo lórílède Nàìjíríà náà yóò le ṣiṣẹ́, èyí yóò sì mú àdíkù báa ìbéèrè fún níná owó dọla nígbàgbogbo, nítórí pé èyí gàn ló n kóba ètò ọ̀rọ̀ ajé Nàìjíríà.
Mo ti lo agbára mi ṣòfò, mo ti fi ṣe àṣedànù,sibẹsibẹ ẹ̀tọ́ mi ń bẹ lọ́dọ̀ OLUWA.
Nígbà tí ilẹ̀ mọ́, gbogbo àwọn olórí alufaa ati àwọn àgbà ìlú jọ forí-korí nípa ọ̀ràn Jesu, kí wọ́n lè pa á.
Ṣugbọn jìnnìjìnnì dà bo àwọn arakunrin rẹ̀ níwájú rẹ̀ tóbẹ́ẹ̀ tí wọn kò lè dáhùn.
•Iye àwọn olùdìbò agbègbè náà - 351,146 •Àwọn tí ó fọwọ́ sí ìwé láti yọ Melaye - 189,870 •Àwọn tí ó jáde láti wá ṣe àyẹwò orúkọ - 20,868 •Àwọn tí wọ́n ṣe àyẹ̀wò orúkọ - 18,742 Ọ̀jọ̀gbọ́n Moti ní pẹlú èsì yí, kò sí ọ̀nà míràn lábẹ́ òfin fún àwọn ará ìlú látí ṣe ìpàdé ìta gbangba tí wọ́n fi lè dìbò yọ Dino Melaye.
Titi di bi a ṣe n kọ iroyin yii wọn ko tii sọ igba ti ifẹsẹwọnsẹ naa yoo wa pada waye.
Ìtàn tó wà nídi òwe ‘Sebótimọ Ẹlẹ́wà Sàpọ́n’ Ìtàn tó rọ̀ mọ́ òwe ‘aṣọ kò bá Ọ́mọ́yẹ mọ́.
Bakan naa ni wọn si pe fun ki aarẹ Buahari kọwe lo gbelerẹ fun awọn olori eto aabo ni orilẹede Naijiria.
Ọmọ orilẹede Amerika mejilelaadọta ni Iran jigbe nigba naa ninu ileeṣẹ ijọba orilẹede Amerika to wa ni Iran.
Amọ nkan ti ọpọlọpọ n duro o de ni boya ile aṣofin agba yoo fi ontẹ lu iyọnipo rẹ.
Amọ ṣa ẹgbẹrun meje ati ẹẹdẹgbaarun le ni mẹfa (7,906) ni yoo jẹ anfaani yi ni Abuja.
awon ti pese aabo to peye loju ona naa.
Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Ooni ile Ife: Iná sọ láàfín Ọọ̀ni Ilé Ifẹ̀, Ọọ̀ni ilé ifẹ̀ ní kò sí ẹ̀mí tó báa lọ19 Ògún 2020 5:58 Fídíò, Akomolede ati asa Yoruba: Ẹ wá kọ́ nípa àpòtí ìṣura èdè wa lórí BBC Yorùbá, Duration 5,5820 Ògún 2020 3:13 Fídíò, Mr Macaroni sọ nípa eré tí Freaky Freaky, Sugar Daddy, You are doing well, Freaky Spicy fẹ́, Duration 3,1315 Ògún 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
83 fún ọjọ ́ kan .
Ko da tori eyi wọn ni awọn atawn alaṣẹ jọ pa ẹnu pọ pe ki wọn sun idanwo awọn akẹkọọ to yẹ ko bẹrẹ ni ọjọ kẹtadinlogun oṣu ikẹfa siwaju.
Nítorí náà, nígbà tó yá, Ọlọrun rán àjàkálẹ̀ àrùn burúkú kan sáàrin àwọn eniyan náà, nítorí pé wọ́n mú kí Aaroni fi wúrà yá ère mààlúù fún wọn.
Nítorí ìyàsọ́tọ̀ ẹ̀yà yìí ṣì ń ṣẹlẹ̀ ní orílẹ̀-èdè Mauritania, ìdájọ́ òdodo kò sí ní àrọ́wọ́tó fún àwọn ẹni orí-kó-yọ àti àwọn ìdílé wọn.
Jesu orí ayélujára kan rèé tó wa fun isoji ni Afirika Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Iya Adura Esther Ajayi sọ àṣírí owó rẹ̀ tó fi ń ṣàánú O ni awọn n duro de adajo lati fun awọn ni iwe idajọ rẹ, ki awọn le lọ si ile ẹjọ kotẹmilorun fun igbẹjọ ti wọn naa.
Ní ọdún tí Usaya Ọba kú, mo rí OLUWA: ó jókòó lórí ìtẹ́, a gbé e ga sókè, aṣọ ìgúnwà rẹ̀ sì kún inú tẹmpili.
Ẹnikẹ́ni kò ní gbé ibẹ̀, bẹ́ẹ̀ ni ẹnikẹ́ni kò ní dé sibẹ.
ile igbimo asofin ti ipinle Borno , ogbeni Abdulkarim Lawan, asoju ajo isokan
Ayẹwo ati itọju aisan iba Early diagnosis and treatment yields best results T Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ti tete ṣe ayẹwo ati itọju maa n so eso to dara ju Aisan iba ṣe e tọju - ayẹwo le ṣe afihan aisan iba ninu ara laarin ọgbọ̀n iṣẹju tabi ko maa to bẹ.
Ọpọ lo dunnu si iroyin naa, bakan naa ni wọn ṣe iranti bi wọn ti maa n loogun ọhun fun itọju aarun iba lati ọjọ to ti pẹ.
Mose wọ inú ìkùukùu náà lọ, ó gun orí òkè náà, ó sì wà níbẹ̀ fún ogoji ọjọ́, tọ̀sán-tòru.
Bí ọkunrin kan bá bá ọkunrin ẹlẹgbẹ́ rẹ̀ lòpọ̀ bí a ti ń bá obinrin lòpọ̀, àwọn mejeeji ti ṣe ohun ìríra; pípa ni kí wọ́n pa wọ́n, ẹ̀jẹ̀ wọn yóo wà lórí ara wọn.
 Sinima ki sinima ti won ba gbe sita tabi ti won ba n safihan re ninu amohunmaworan Naijiria gbodo gba iwe ase.
Ipade awon eekan ninu eto aabo Naijiria n lo lowo nile ijoba nilu Abuja.
Tinubu ní kò jẹ́ kí àwọn ọmọ bíbí Eko gbérí nínú òṣèlú Nǹkan kò ṣẹnuure fáwọn obìnrin nínú ìgbìmọ̀ ìṣèjọba Buhari Àwọn ọmọ Yorùbá wo ni mínísítà ní ìjọba Buhari?
Àkọlé àwòrán, Awọn amoju ẹrọ lẹnu iṣẹ ki gbogbo wiwo ati gbigbọ eto le to.
ni Ọlọrun wá mú wà ní ìrẹ́pọ̀ pẹlu ara rẹ̀ nípa ikú ọmọ rẹ̀, kí ó lè sọ yín di ẹni tí ó mọ́, tí kò ní àbùkù, tí kò sì ní ẹ̀sùn níwájú rẹ̀, 
Toluwani Awakan ati awọn ẹbi awọn mii bii Kolade Johnson atawọn ti iroyin tun ni awọn ọlọpaa SARS pa naa sọrọ to pọ.
Ǹkan mẹ́jọ tó máa kọ́kọ́ ṣẹlẹ̀ kí olólùfẹ́ méjì tó pa ara wọn Laipẹ́, ọmọ tí kò bá pé ọdún méjìdínlógún kò ní leè jáde girama l’Ọṣun Wọ́n ti pa ẹni to yìnbọn pa ará Texas márùn ún -ọlọ́pàá Adeboye sọ̀rọ̀ lórí ètò pápá ìjẹko RUGA Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, VAT: Kò sí àǹfàní kankan tí ìjọba ti ṣe fún mi sẹ́yìn Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
“Nígbà tí o bá ka iye àwọn eniyan Israẹli, ẹnìkọ̀ọ̀kan gbọdọ̀ mú ohun ìràpadà ẹ̀mí rẹ̀ wá fún OLUWA, kí àjàkálẹ̀ àrùn má baà bẹ́ sílẹ̀ láàrin wọn, nígbà tí o bá kà wọ́n.
Gẹ́gẹ́ bí Ìwé Mímọ́ ti wí, “Ẹnikẹ́ni tí ó bá ké pe orúkọ Oluwa ni a óo gbà là.
A óo tún ìlú náà kọ́ sórí òkítì rẹ̀,a óo sì tún kọ́ ààfin rẹ̀ sí ààyè rẹ̀ tẹ́lẹ̀.
"Aṣoju ajọ WHO ni Naijiria, Dokita Wondimagegnehu Alemu ni ""titete da awọn ti o ni aisan naa mọ laarin ilu, to fi mọ gbigbe wọn lọ s'ileewosan lasiko to yẹ maa n mu ki o rọrun lati le doola ẹmi alaisan."
N óo tẹ orí àwọn ọ̀tá wọn ba.
 Ó sì ṣílọ sí virginia nígbà tí ó pé ọmọ ogún ọdún , ó kàwé ní college of william and mary , wọ ́ n sì gbàá wọlé bí amòfin .
Nítorí náà ni àwọn ẹ̀yà Lefi kò fi ní ìpín tabi ogún pẹlu àwọn arakunrin wọn.
Nigba to n sọrọ lori afurasi ajinigbe kan to ti n sun fun ọjọ mẹfa lai laju nipinlẹ Ondo nitori oogun Tramadol to mu, Obilade ni to ba jẹ pe wọn tete gbe afurasi naa lọ si ile iwosan, o seese ki wọ́n fa oogun naa kuro lara rẹ, amọ niba yii to ti dapọ mọ ẹjẹ rẹ, boya ni ko fi ni se ipalara fun ẹmi rẹ.
PDP bu ẹnu ẹtẹ lu ijọba Aarẹ Buhari pe ko tete ja ọrọ naa kunra, wọn ni o buru jai pe olu ileeṣẹ Naijiria to wa nilẹ South Africa tun kọ ẹyin si awọn ọmọ Naijiria to sa lọ sibi.
Amọṣa o ni, ijọba ipinlẹ Eko gbọdọ ṣe ohun to tọ lati dena atunṣẹ iṣẹlẹ naa lọjọ iwaju.
Ìfọwọ́sowọ́pọ̀ nìkan ni ọ̀nà abáyọ sí ìṣòro Nàìjíríà- Olusegun Obasanjo Ìtura ìgbà díẹ̀ ni bọ́dà tí ìjọba ṣí padà, kò lóòre nínú - Onímọ̀ ọrọ̀ ajé Wo ìdí tí ààrẹ Buhari kìí fi ṣe ẹ̀dà Jubril láti Sudan Ọkan lara wọn tun ṣalaye pe ibi ti awọn n sun si, naa ni wọn ti n ṣe igbọnsẹ.
Bí mo bá sì wà láàyè kí o fi ìfẹ́ òtítọ́ OLUWA hàn sí mi kí n má baà kú.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fọ́nrán ohùn, Alaafin Ọyọ: Asiri agbara bibi ibeji lọpọ igba Lamidi Ọlayiwọla tun gbe ni ọdọ Alake tilẹ Ẹgba, Ọba Ọladepo Ademọla, ko to di pe wọn tun rọ Alake yii loye O tun lọ gbe lọdọ Ọlọla-binrin Kofoworọla Abayọmi ladugbo Keffi, ni Ikoyi nilu Eko, to si lọ sile ẹkọ Mọda, Ọbalende Modern School Lẹyin eyi lo morile ileẹkọ girama St.
Pẹ̀lú gbogbo bí mo ṣe dán an wò nígbà tí a bá ń lájọṣepọ̀ tó wà níwájú mi, tí mo wà lórí rẹ̀ pẹ̀lú oríṣiríṣi ǹkan ìṣeré ìbálòpọ̀, mo ma ń sábà fẹ́ padà sí ọ̀rẹ́ mi àtijọ́.
”Ni ipari atejade ohun wa sapejuwe iwa-ibaje gege bi, arun jejere, eleyi ti o le dena idagbasoke orile-ede, ti o si tun lee le awon olokoowo ati ile-ise aladaani kuro lorile-ede yii,”Egbe APC wa so pe, awon yoo tun tesiwaju si ninu iwa gbigbogun ti iwa ibajẹ ati awon ohun ibajẹ miiran ti o joba lorile-ede Naijiria.
Mo pinnu lọ́kàn mi láti mọ ohun tí ọgbọ́n jẹ́, ati láti mọ ohun tí ìwà wèrè ati ìwà òmùgọ̀ jẹ́.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Olusegun Obasanjo: Ọmú ìyá mi ti mo fi ń mùkọ ni kekere ló jẹ ki ń lókun Lákọkọ́, wọ́n se ìfilọ́lẹ̀ rẹ̀ láti se ìmúgbòòrò ìgbọ́ra-ẹni-yé láàrín àwọn èwe.
Tí bàbá ẹlẹ́ran bá ní “Yè-è-é, ó wọjú o, ẹ-ẹ̀rẹran, K-ẹ́-ẹ-sẹ́lẹ́ńkẹ́jọ̀”.
“Sọ fún àwọn ọmọ Israẹli pé, nígbà tí ẹnikẹ́ni ninu yín bá fẹ́ mú ọrẹ ẹbọ wá fún èmi OLUWA, ninu agbo mààlúù, tabi agbo ewúrẹ́, tabi agbo aguntan rẹ̀ ni kí ó ti mú un.
 Àpò omi nínú ara náà ni a lè fà jáde láti awọ ara , lílo òògùn sì gbọ ́ dọ ̀ tẹ ̀ lé èyí .
Tìfura tìfura lafi ń bá ayé rìn
Ẹni to bori: Morocco Nigeria vs Cameroon.
Ẹni tí ó jẹ́ igbákejì wọn ni Hanani ọmọ Sakuri, ọmọ Matanaya, nítorí pé wọ́n mọ̀ wọ́n sí olóòótọ́, iṣẹ́ wọn sì ni láti fún àwọn arakunrin wọn ní ẹ̀tọ́ wọn.
Nigba to ya, Ọgbẹni David tun yi ẹnu pada o sọ tẹlẹ pe ọjọ kọkanlelogun oṣu kẹwaa ọdun 2017 tun ni aye yoo parẹ.
ife ẹyẹ ti  African Cup of Nations
Àwọn òkú ninu Jesu ni yóo kọ́kọ́ jinde.
Nítorí Ọlọrun lágbára láti ranni lọ́wọ́ ati láti bini ṣubú.
Dafidi ati àwọn ọmọlẹ́yìn rẹ̀ bá dìde, wọ́n lọ sí ilẹ̀ Filistini, àwọn ọmọ ogun Filistini sì lọ sí Jesireeli.
Aarẹ ajọ NMA fikun ọrọ rẹ pe kikọ oogun ibilẹ nileewe yoo jẹ kawọn ọmọ Naijiria ni itọju to peye eleyi ti yoo jẹ ki alaafia jọba.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ti ọmọ ko ba jọ iya, aa jọ baba; Fẹla Anikulapo Kuti ba awọn iwa kan nile ni.
Maryam Sanda, obinrin ti wọn fẹsun kan pe o pa ọkọ rẹ lọdun 2017, ti ile ẹjọ si dajọ iku nipa yiyẹgi fun un nibẹrẹ ọdun yii, naa wa lara awọn ohun ti wọn n wa loju opo agbaye yii.
Aarẹ Muhammadu Buhari, naa si ti fi ikede sita pe, ki awọn oloṣelu maṣe lo ipo wọn lati fun ẹnikẹni ni isẹ naa.
Yóo kó àwọn ọ̀dọ́ aguntan jọ sí apá rẹ̀,yóo gbé wọn mọ́ àyà rẹ̀.
 odùduwà ni a gbọ ́ pé ó kọ ́ kọ ́ ṣí kúrò ní agbègbè náà wá sí ilẹ ́ -ifẹ ̀ .
Wọn wa parọwa si ijọba lati pesẹ agba nla ti awọn eeyan le ko ilẹ ati idọti si, bakan naa si ni wọn lo pọn dandan fun ajọ kolẹkodọti ni ipinlẹ Ọyọ lati ṣe iṣẹ wọn gẹgẹ bi iṣẹ.
 Ogbeni Adebimpe Quadril ni ajo to n gbogunti iwa ibaje lorile-ede Naijiria, Economic and Financial Crimes Commission ti eka ilu Ibadan fesun kan pe o n se gbajue lori ero ayarabiasa ti awon eleyinbo pe ni, “Internet fraudster,” Ajo EFCC fi oro naa mule pe,
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Bukola Saraki: Àìbọ̀wọ̀ f'áṣẹ ilé-ẹjọ́ n'ìgbẹ́sẹ̀ EFCC láti gba ilé mi ní Ilorin 28 Bélú 2019 Oríṣun àwòrán, Facebook/Bukola Saraki Aarẹ ile aṣofin agba l'Abuja ni saa eto ijọba awarawa to kọ ja, Sẹnẹtọ Bukola Saraki ti fẹsun kan ajọ to n gbogun ti iwa ajẹbanu ati ṣiṣe owo ilu kumọkumọ, EFCC.
Ọpọ dokita lo n fa awọn oṣiṣẹ ile iwosan leti pe ki wọn ye korajọ mọ ninu yara ijẹun.
Ṣùgbọ́n lórí òkè àbí àpáta tí ó bá ga sókè tó,
Ẹfunsetan Aniwura, obìnrin tó ju ọkùnrin lọ Ọ̀rọ̀ǹpọ̀tọ̀niyùn, Aláàfin obìnrin àkọ́kọ́ rèé, tó ní nǹkan ọkùnrin Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Tomomewo Favour: olóṣèlú kìí ṣe ọ̀daràn tàbí alágbèrè Èyí ẹ ṣe tó, England àti VAR júwe ilé fún Cameroon Ọ̀rọ̀ ti yanjú dé ibì kan lórí owó àjẹmọ́nú àwọn Super Falcons Iṣẹ́ ẹ̀mí ẹ̀tàn ló bàlemi lasiko tí mo sọ àṣọtẹ́lẹ̀-Simeon Ononogbu Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Àkọlé àwòrán, Agbegbè ibi ti àwọn arinrinajo naa wa súnmọ Malta ju Italy lọ Ní báyìí èsúrú ọ̀rọ̀ náà ti pàdídà, ó ń lé ajá, bí òrílẹ̀-èdè Italy ṣe fárígá pé àwọn àrinrìnàjò lọ́nà àìtọ́ tí àjọ ẹléyin jú àànú orílẹ̀-èdè Germany kan tí wọn ń pè ni SOS Méditerranée dóòlà kò ni wọlé sí Italy.
fun ibasise po olojo rampe, eleyi ti o si n gbadun asiko re ninu iko ohun.
Osu Keje ree ti awọn akẹkọọ ti wa nile.
Lẹ́yìn bí oṣù mẹta sí i, ẹnìkan wá sọ fún Juda pé, “Wò ó!
Ubani ni awọn araalu ti ofin fun ni anfaani lati gba ibọn ni awọn to n fi ṣe ọdẹ, Koda, o ni irufẹ ibọn ti wọn le lo, amọ kii ṣe bii AK47.
   Aare nigbagbo pe, won yoo maa seranti oloogbe naa fun ise takun-takun, ipolongo igbe aye alafia ati fifopin si aawo laarin ilu abbl, leni ti igbagbo re si tun duro sinsin pe ojo ola orile-ede Naijiria dara pupo.
Inú báyìí ni àwọn méjéèjì rò, nígbẹ̀yìn ṣá, wọ́n pinnu pé bí ọ̀kánjúwàfẹ̀yìntì bá dé kí a wọ̀ọ̀n yìnbọn pa a.
Díẹ̀ nínú àwọn àwòrán tí mo yà ní àárọ̀ yìí ni ìwọ̀nyí.
Gbogbo òru ni ó fi gbadura sí Ọlọrun.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Onnoghen: Ilé ẹjọ́ kòtẹ́milọ́rùn ní ẹjọ́ náà kò lẹ́sẹ̀ ńlẹ̀ 10 Èbibi 2019 Oríṣun àwòrán, Google Àkọlé àwòrán, Walter Onnoghen pè ẹjọ́ yìí láti tako aṣẹ idaniduro ranpẹ̀ ti ile ẹjọ CCT pa láti yọọ́ ni iṣẹ́.
onibara jẹ owo to yẹ ki won san fun ipese ina mona-mona.
Ẹní bá ga tàbí t’ẹ́sẹ̀ rẹ̀ gùn mà wá dáràn o!
Ẹ yìnbọn pa ọ̀daràn tí ẹ bá rí níbi kíbi, Buhari pàṣẹ fáwọn ológun Ike Ekweremadu, igbákejì ààrẹ ilé aṣòfin àgbà tẹ́lẹ́ rí èèmọ̀ he nilùú Germany!
fun ipo aare fun egbe naa pe won jale lati inu inu ẹrọ  ayelujara INEC ,Independent
Ṣugbọn, ọrọ ajẹmọnu yii n da omi tutu si wọn lọkan.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Akiolu Staff of Office: Àwọn ológun láwọn ló dóòlà Ọba Eko àti ìdílé rẹ̀ ṣáájú ìwọ́de EndSARS 23 Ọ̀wàrà 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 15 Bélú 2020 Oríṣun àwòrán, LASG Aṣe ọrọ ikọlu tawọn ọdọ kan ṣe si aafin ọba ilu Eko, Rilwan Akiolu naa lọra pọ mọ awọn iṣẹlẹ iwọde ifẹhonuhan nipinlẹ Eko.
Ǹ bá lọ jìnnà réré,kí n lọ máa gbé inú ijù;
Magun Majẹla: Ọkunrin to ba ba obinrin ti wọn ba le iru Magun yii si lara, ko gbọdọ jẹ ila, ni kete to ba ti le fi ẹnu kan ila, ọrun laala niyẹn.
ati ile-ẹkọ awọn olukọ lorile ede Naijiria (Joint Admissions and
Èyí túmọ̀ sí pé àwọn (Jamb) nàá mọ̀ pé àwọn tí kò ṣe daada ní iléèwé girama ló n fẹ́ kọ́ ẹ̀kọ́ nípa iṣẹ́ olùkọ́.
Omojuwa ni iṣorọ to n koju orilẹede Naijiria ko to lati di ẹbi rẹ ru ẹnikan.
Ọba bá súre fún un, ó ní kí ó máa lọ.
 Awon osise alaabo ti gbe igbese ti o ye lati
Mo bẹ àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ pé kí wọ́n lé e jáde, ṣugbọn wọn kò lè ṣe é.
Ó bá pàṣẹ fún wọn kí gbogbo àwọn eniyan jókòó ní ìṣọ̀wọ́, ìṣọ̀wọ́ lórí koríko.
Ọga INEC sọ pe ajọ naa yoo maa kede igba ti atundi ibo mii yoo waye lawọn ibudo idibo marun un tọrọ kan.
PDP: Buhari gbọdọ̀ tọrọ àforíjìn lọ́wọ́ ọmọ Nàíjíríà fún èdè àbùkù tó pè
Buhari kọminú lórí ìjà ẹ̀sìn tó gbẹ̀mí èèyàn 55 lọ́jà kan nípìnlẹ̀ Kaduna Shehu Sani: Màá kéde ẹgbẹ́ òṣèlú tí mo máa darapọ̀ pẹ̀lú láìpẹ́ Oríṣun àwòrán, Twitter/@elrufai Àkọlé àwòrán, Ní Ọjọ́bọ́ ní ìjá kọ́kọ́ bẹ́ sílẹ̀ ní ìlú Kasuwar Magani ní ìjọba ìbílẹ̀ Kajuru Sùgbọ́n ìjà náà padà tàn dé olú ìlú ìpílẹ̀ náà l'ọjọ́ Àìkú.
    Nǹkan tí mo ṣa fẹ́ kí ẹ mọ̀ ni pé a níláti bá àwọn Èdìdàrẹ́ jagun gan-an lé orí òfin yìí, n kò lè ròyìn ogun náà fún yín, nítorí àkókò ń lọ, ṣùgbọ́n a ṣẹ́gùn, wọn túúbá fún wa, wọ́n ní àwọn di tiwa.
Àwọn ọmọ Lefi ni: Jeṣua, Binui ati Kadimieli; Ṣerebaya, Juda, ati Matanaya, tí òun pẹlu àwọn arakunrin rẹ̀ wà nídìí ètò àwọn orin ọpẹ́.
Laarin ogoji ọdun(1960-2000), ifipagbajọba ṣẹlẹ nigba ogoji laarin ọdun mẹwaa.
Agbẹ́nusọ ẹsọ ìgbòkègbodo ọkọ náà (FRSC) Bisi Kazeem tó fidi ọ̀rọ̀ náà múlẹ̀ sàlàyé wọ́n ti gbé òkú ènìyàn mẹ́ta náà kúrò, nígbà tí wọ́n ti gbe àwọn tó farapa lọ si ilé ìwòsàn gbogbo níṣe Kubwa Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
OLUWA yóo fún ọ ní ọpọlọpọ òjò ní àkókò rẹ̀ láti inú ilé ìṣúra rẹ̀ lójú ọ̀run, yóo sì bukun iṣẹ́ ọwọ́ rẹ.
Ó rún ejò idẹ tí Mose ṣe, tí wọn ń pè ní Nehuṣitani nítorí pé títí di àkókò náà àwọn ọmọ Israẹli a máa sun turari sí i.
Inú wá bí baálé ilé náà.
Ọmọlolu bu ẹnu atẹ lu iṣesi yii lasiko to n ba BBC sọrọ lori bi oludije fun ipo adari Ile Igbimọ Asojusofin, Femi Gbajabiamila ko aṣojuṣofin aadọta ti wọn sẹsẹ dibo yan lọ si Saudi Arabia lati lọ sepade.
Ni ọsẹ to kọja, ọmọogun ikọ Naijiria to le ni ọgbọn ni awọn ikọ agbesunmọmi Boko Haram fi ẹmi wọn sọfo, lẹyin ti wọn wa sigun ba wọn ni ibi ti wọn wa.
Bi o ti le je pe, City gba ami-ayo kinni wole ni kete ti ifesewonse ohun bere, sugbon omi po ju oka lo, leyin ti Liverpool da ami-ayo meji pada gbara ti saa keji ifesewonse naa bere ni papa isere Etihad Stadium.
“Ṣugbọn ohunkohun tí eniyan bá ti fi fún OLUWA, kì báà jẹ́ eniyan ni, tabi ẹranko, tabi ilẹ̀ àjogúnbá rẹ̀, yóo jẹ́ títà tabi kí ó rà á pada.
Aare  Muhammadu Buhari ti parowa fun awon osise eleto aabo gbogbo ni Naijiria ati awon eka ijoba kookan lati tubo fowosowopo pelu re lati fi wa ojutu sisoro eto aabo to fe maa fojoojumo gbebo lowo eniyan Naijiria bayii.
“Àgbà ló ni ọgbọ́n,àwọn ogbó tí wọ́n ti pẹ́ láyé ni wọ́n ni òye.
Abenugan ile-igbimo asofin agba, Saraki so pe”adari gidi gbodo maa feti sile si igbe aye awon eniyan re”.
Ki Ọlọrun dẹlẹ fun awọn eni rere, ọjọgbọn kikun to re iwalẹ àṣà.
Bi o tilẹ jẹ wipe ọpọlọpọ ileeṣẹ iroyin lo n gbe e safẹfẹ pe yatọ fun okuta ti wọn fi fọ ọ lori, wọn tun fipa ba a lo pọ, alukoro ọlọpaa sọ fun BBC Yoruba pe, awọn ko le fi idi eleyii mulẹ ṣugbọn iwadi ti wọn n ṣe ni yoo boya lootọ ni tabi irọ ni pe wọn tun fipa ba oloogbe aboyun yii lajọṣepọ.
Ẹkunrẹrẹ ajọsọ ọrọ pẹlu BBC News Yoruba lori ẹrọ ayelujara lo wa loke iroyin yii.
Amọ ikọ agbabọọlu Tottenham ni Mourinho n ko o lọ koju Man United lọtẹ yii lẹyin to gbaṣẹ akọnimọọgba ẹgbẹ agbabọọlu naa ni kopẹ kopẹ yii.
Èyí ló fi mí lọ́kàn balẹ̀ gbáà pé ibi a wí la dé yìí o.
Dokita Olanrewaju ni, pelu bi nnkan ti ṣe ri lawujọ loni, o di dandan ki ijọba ṣe agbedide awọn oṣiṣe ilera ti yoo maa tọpinpin ibi ti awọn eeyan n ṣe ibẹrẹ si.
Yaa Asantewaa: Ti ẹyin ọkunrin Ashanti kò bá tẹsiwaju, awa obinrin yóò lọ
Satani bá wọ inú Judasi tí à ń pè ní Iskariotu, ọ̀kan ninu àwọn ọmọ-ẹ̀yìn mejila.
Ó mú ère ọmọ mààlúù náà, tí wọ́n fi wúrà ṣe, ó sun ún níná, ó lọ̀ ọ́ lúbúlúbú, ó kù ú sójú omi, ó sì gbé e fún àwọn ọmọ Israẹli mu.
mọ imọ isiro, sayensi imo ẹrọ 
Yemọja kú, ẹja kẹ́ja ò jẹ́ wẹ̀ nínú ibú
Oríṣun àwòrán, @Shittu Àkọlé àwòrán, O wu mi lati tukọ ipinlẹ Oyo Ọpọ gba pe oun naa ko ni iwe ẹri agunbanirọ lati fi sọ pe oun sin ilẹ baba oun bii ti Kemi AdeosunAPC yọ orúkọ Shittu kúrò láti kópa nínú ìdìbò abẹ́lé.
Awọn to kawe gboye fasiti, ile ẹkọ gbogbonise HND tabi OND lẹka eto ẹkọ imọ ilera, Microbiology, Psychology, Midwifery Public Health tabi eto ẹkọ miran lẹka sayensi lo le kopa nibẹ.
Ṣọ́ra kí o má yipada sí ìwà ẹ̀ṣẹ̀,tí ó wù ọ́ ju ìjìyà lọ.
Zsenchi, lasiko to n gba ẹbẹ agbẹjọro ajọ EFCC to gbe ẹsun naa wa siwaju rẹ, salaye pe ibikibi ti wọn ba ti kofiri awọn afurasi naa ni ki wọn ti di wọn ni apanyaka boya lorilẹede yii ni abi loke okun.
Nítorí OLUWA Ọlọrun yín mú kí odò Jọdani gbẹ títí ẹ fi rékọjá sí òdìkejì rẹ̀, gẹ́gẹ́ bí ó ti mú kí Òkun Pupa gbẹ, títí tí ẹ fi là á kọjá.
O ni o yẹ ki ọkọ ati aya maa ni ifarada fun ara wọn.
Mo tún ń wí fun yín pé yóo rọrùn fún ràkúnmí láti wọ ojú abẹ́rẹ́ jù fún ọlọ́rọ̀ láti wọ ìjọba Ọlọrun lọ.
Yala gẹgẹ bii sẹnetọ tabi aṣojuṣofin?
N kò tilẹ̀ dàbí agbowó-odè yìí.
Babachir Lawal bọ lọwọ EFCC Ta ni Naira Marley jẹ́ gan?
Ó ti ń mú èrè pupọ wá fún àwọn olówó rẹ̀ nípa àfọ̀ṣẹ rẹ̀.
Oríṣun àwòrán, EPA Goolu mẹwaa ti wọn gba sawọn ninu ifẹsẹwọnsẹ mejila ti wọn ti gba ni saa bọọlu yii lo kere julọ fun Arsenal lati ọdun 1982.
Á gbẹ́ ihò sinu àpáta,ojú rẹ̀ a sì tó àwọn ìṣúra iyebíye.
Nítorí náà kí ẹ lọ sọ gbogbo orílẹ̀-èdè di ọmọ-ẹ̀yìn mi; kí ẹ máa ṣe ìrìbọmi fún wọn ní orúkọ Baba ati ti Ọmọ ati ti Ẹ̀mí Mímọ́.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Olórin tàkasúfèé pàdánù mílíọ̀nú náìrà kan lori ìfẹsẹ̀wọsẹ̀ Liverpool Vs Barcelona 8 Èbibi 2019 Oríṣun àwòrán, @iam_kcee Olorin takasufẹ ọmọ orileede Naijiria kan ti farakasa miliọnu Naira kan lori ifẹsẹwọnsẹ Champions League to waye laarin ẹgbẹ Liverpool ati Barcelona.
Nítorí náà, mo bẹ̀ yín, ẹ jẹun; èyí ṣe pataki bí ẹ ò bá fẹ́ kú.
"Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ajọ SERAP bu ẹnu ẹtẹ lu owo ifẹhinti f'awọn oloselu Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Ajọ SERAP bu ẹnu ẹtẹ lu owo ifẹhinti f'awọn oloselu 25 Sẹ́rẹ́ 2018 SERAP: ""Owo ifẹhinti ko tọ si ẹni ti o sisẹ gẹgẹ bii gomina ilu fun patapata ọdun mẹjọ"" Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí 2 sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn."
Aṣofin Ọbasa ninu ọrọ ikini ku ọdun rẹ yii
Nitorina, a gbọdọ pejọ, ki a ronu, ki a si sẹ atungbeyẹwo ọna abayọ.
Tí ẹ bá ní ìbéèrè míràn, ẹ má sàìfiránṣẹ́ sí mi ní 
Amọ ki ni Buhari gan funra rẹ sọ lori idibo 2015 ti o mu awuyewuye dani nigba naa?
Oríṣun àwòrán, @OgbeniOlaide Gẹgẹ bi o ṣe wa ni akọsilẹ, odindi gende ọkunrin mẹfa ni wọn gbe iṣẹ iku rẹ fun.
Ninu ọrọ to ba awon akọroyin sọ nilu Abuja, agbarijọpọ awọn ẹgbẹ oṣiṣẹ lẹka eto ilera lorilẹede Naijiria salaye pe ijoba ti n mu awon lọbọ lori ijiroro won.
Yusuf Magaji Bichi di Olùdarí àgbà tuntun
 Ààfin ọba ni a ti ń bá ewì ayaba pàdé .
Ṣaaju lọjọ kẹjọ oṣu kejila ọdun yii ni aarẹ Buhari ti safihan ipinu rẹ lati ṣi awọn ẹnu ibode naa.
Ó fi fadaka ṣe àwọn ẹsẹ̀ ìjókòó rẹ̀,ó fi wúrà ṣe ẹ̀yìn rẹ̀,Aṣọ elése-àlùkò tí àwọn ọmọbinrin Jerusalẹmu hun ni ó fi ṣe tìmùtìmù ìjókòó rẹ̀.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Hubert Ogunde ló m'órí mi yá láti di òṣèré Koko pataki ti Ortagus tun sọ ni pe awọn ti ọrọ kan jẹ awọn ti wọn n hu iwa Tani-o-mumi, ti wọn ko bọwọ fun ẹtọ ọmoniyan rara.
Ẹ̀rù ba Sara, ó sẹ́ pé òun kò rẹ́rìn-ín.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Tíátà ọ́mọdé tí wọ́n ń kọ́ wa ní Bariga ti mú mi lọ Germany, Switzerland, Amsterdam.
O ní ọ̀pọ̀ Ọba ní ìhà ìwọ̀ -òòrun -Guusu ní láti dári jọ ṣe àgbékalẹ̀ ìgbìmọ ti yóò dá ògo Yorùba àti àṣẹ ti Ọlọrun fún wọ́n pada gẹgẹ bii Ọba.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Bọla Tinubu: Ìpínlẹ̀ Ọ̀ṣun kò ní owó mi lọ́wọ́ Wọn ni awọn tun ri pe awọn ọmọ igbimọ n ṣe aṣilo awọn nkan ini ileeṣẹ naa ni eyi ti wọn ti paṣẹ pe ki wọn da pada bayii.
5 9796769 Orilẹede Mexico 112326 89.
" Ariwo ló ń mú owó wọlé fún mi, kò wù mí láti gbé ayé tó dákẹ́ rọ́rọ́ - Lizzy Anjorin Majek Fashek tí wọ káà ilẹ̀ lọ!
Agbẹjọro fun ajọ EFCC, Aliyu Adebayo ileẹjọ lati fiya to tọ jẹ Balogun nitori ohun to ṣe tako ofin orilẹede Naijiria.
Won a ma ṣe baba isalẹ fawọn ọmọ ẹgbẹ okunkun.
Oríṣun àwòrán, STR/AFP/Getty Images Àkọlé àwòrán, Awọn ọlọpaa ti mu Baba omo naa ti o ni ibon to pa ọmọ naa Wọn ní iwadii ti fí hàn pé baba baba ọmọ náà fi ìbon rẹ sì ìbí tí ọwọ ọmọdé ti le tó.
Ojoojúmọ́ ní aàrùn coronavirus ń pọ̀ si i láwọn orílẹ̀-èdè Afirika ti ikú tó ń tibẹ̀ wá náà sì ń pọ̀ si i.
Nítorí náà, ọ̀run ati ayé, ati gbogbo ohun tí ó wà ninu wọn,yóo yọ̀ nítorí ìṣubú Babiloni,nítorí pé apanirun yóo wá gbógun tì í, láti ìhà àríwá,Èmi OLUWA ni mo sọ bẹ́ẹ̀.
Àwọn Afíríkà mẹ́tà to ṣe bẹbẹ nínú EPL sáà 2018/2019 Cardiff tí tiẹ̀ ti jóná kóná ìyà mọ́ Manchester United Àti ilé àti ilẹ̀, mi ò ní ǹkankan ní ilẹ̀ òkèrè-Goodluck Jonathan O ti di ilu ti awọn oniṣowo n gbe ti wọn ti n sun ti wọn ti n ji, jẹun, ṣiṣẹ, ran ọmọ lọ ile iwe ati ọpọlọpọ ohun teeyan n ṣe lati gbe aye.
Oríṣun àwòrán, EPA Laipẹ yi ni ẹgbẹ Arsenal lawọn ti n fimu-finlẹ si ẹni ti wọn yoo fi paarọ rẹ ni eyi ti ireti si wa pe o ṣeeṣe ko jẹ akọnimọọgba ẹgbẹ Wolves, Nuno Espirito ni yoo gba ipo rẹ.
Ni abala tire, dokita ajo WHO Rex Mpazanje ro awon akoroyin lati lo igbese yii lati ji giri ninu gbigbe iroyin eto ilera.
Owọ ọlọ́pàá tẹ̀ẹ́ ni Oró nipinlẹ Kwara lana.
Erelu Kuti mẹnu le ọrọ yii lori eto ifọrọwanilẹnuwo kan lori ẹrọ amohunmaworan kan nibi to ti sọrọ tẹdun tẹdun bi abiyamọ.
Lati kekere lo ti n gba ẹbun ọmọ to yege titi to fi gba oye imọ ijinlẹ akọkọ ninu ẹkọ ile kikọ ni Fasiti olódòdó ti Obafemi Awolowo (1989), ikeji ni Fasiti Eko (1993) ati ọmọwe ni OAU lọdun 2005.
 Ìtàn tó wà lókè yìí náà ni wọ ́ n sọ ṣùgbọ ́ n wọn ṣe àfikún díẹ ̀ .
19 Òkùdu 2018 Agbenusọ fun ile isẹ ọlọọpa ni ipinlẹ Ondo, Femi Joseph sọ pe iwadii ti bẹrẹ ni pẹrẹwu lori isẹlẹ naa.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fọ́nrán ohùn, kíni ìdí tí ìjọba kò ṣe tíì pe àwọn darandaran ní agbésùmọ̀mi Kíni òfin sọ nípa kikede ẹgbẹ́ kan gẹ́gẹ́ bíi agbésùmọ̀mí Ẹgbẹ́ to bá ń dúnkookò mo ìjọba láti gba ẹtọ kan Àwọn egbe tó ní ohun ìjà bíi ìbon, àdó olóró lọ́wọ́ Ìwa ijinigbe àti igbeni-pamọ Bíba nkan ìní ìjọba jẹ́ Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Afẹ́nifére: Àwọn Ọba kò lè júwe ìdìbò 2019 NURTW da ayẹyẹ ọjọ́ òṣìṣẹ́ rú ní Ékó Ijọba àpapọ̀ fòfin de oògùn ikọ́ olómi codeine Davido fi mọ́tò #45 milionu dá Chioma lọ́lá Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Ko tii si abẹrẹ ajẹsara arun naa nitosi, sibẹ omilẹgbẹ awọn ọdọmọkunrin ti wọn n ko idọti lati ojule de ojule ni agbegbe Karu nitosi Abuja lo n fi ọwọ lasan ṣe iṣẹ, laisi ibomu tabi ibọwọ.
Ẹranko Ewèlè yìí dúró níwájú obinrin tí ó fẹ́ bímọ yìí, ó fẹ́ gbé ọmọ náà jẹ bí ó bá ti bí i tán.
Yóo dàbí igi tí a gbìn sí ipa odò, tí ó ta gbòǹgbò kan ẹ̀bá odò.
O ni wọ maa pe idilẹ ti oye bá kan, lẹyin naa ni wọn yoo to bi ifa lere."
Daniẹli sì wà níbẹ̀ títí di ọdún kinni ìjọba Kirusi.
Kí òfin yìí lè di àmúṣẹ, ìjọba China ti ṣe ìfilọ́lẹ̀ àwọn ètò ìpolongo kéékèèké mélòó kan fún ìkọ̀yìn sí àwọn ayẹyẹ tí kì í ṣe ti ìbílẹ̀ China.
Nígbà tí àwọn tí wọn kọ́kọ́ dé ibi iṣẹ́ dé, wọ́n rò pé wọn yóo gbà ju owó fadaka kọ̀ọ̀kan lọ.
O ni laipẹ ni wọn yoo fi ẹ̀rí yii gba ipo PDP pada fun Olusola Eleka to yẹ ko wọle idibo naa l'Ekiti.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Yollywood: Odunlade fijó bẹ́ẹ, Lizzy padà sọ́dún 2012, Lateef gbàmì ẹ̀yẹ tuntun 12 Ọ̀wàrà 2019 Oríṣun àwòrán, Instagram Àkọlé àwòrán, Yollywood Artists: Odunlade fijó bẹ́ẹ, Lizzy padà sọ́dún 2012, Lateef gbàmì ẹ̀yẹ tuntun Wọnyi ni diẹ lara awọn nnkan tawọn oṣere Yollywood ṣe lọsẹ yii ti wọn si gbe sori ayelujara nipa ara wọn.
Nítorí pé ó ń wo gbogbo ayé,ó sì ń rí ohun gbogbo tí ó wà lábẹ́ ọ̀run.
Ninu lẹta naa, Oba Abdulrasheed Akanbi sọ wi pe oun kii kọ lẹta ni gbogbo igba, amọ lati dawọ ipaniyan duro ati ki ogun ma ba a sẹlẹ ni Naijiria ni oun fi kọ lẹta naa si Aarẹ Buhari.
Ninu lẹta kan to kọ si aarẹ ile aṣofin agba Ahmad Lawan, Aarẹ Buhari ni oun fẹ san owo naa fun ijọba ipinlẹ Kogi, ko lee san owo oṣu to jẹ labẹle.
Irú ẹ̀dá wo ni Bukọla Saraki jẹ́ ?
Opopona kan ṣoṣo lo so ijọba ibilẹ Kagara pọ mọ ilu Madaka mọ awọn abule to ku.
0 656 Faroe Islands 1 2.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, ko din nirun a ti n si n wa bayi ni ileewe naa.
Mose ati Aaroni ṣe gẹ́gẹ́ bí àṣẹ OLUWA lójú Farao ati lójú gbogbo àwọn ẹmẹ̀wà rẹ̀.
ninu àgbàlá ilé OLUWA,láàrin rẹ, ìwọ ìlú Jerusalẹmu.
Nigba to n bawọn omilẹgbẹ ololufẹ rẹ sọrọ loju opo ikansiraẹni Twitter ati Facebook rẹ lori itakun agbaye, Atiku ni, ibeere to se pataki to wa niwaju awọn ọmọ Naijiria ni pe ‘N jẹ igbe aye wọn ru gọgọ si lati ọdun mẹrin sẹyin ti ijọba to wa lode ni orilede yii ti gba ijọba’?
Ta ni yóo yà wá kúrò ninu ìfẹ́ Kristi?
Lẹhin oṣù meje, àwọn Ológun tún fi ibọn gbà Ìjọba lọ́wọ́ àwọn Ológun ti wọn fi ibọn gbé wọlé ti Aguiyi Ironsi jẹ olóri rẹ.
Oríṣun àwòrán, AFP Àkọlé àwòrán, Mo di eti mi pa ni si ariwo orukọ Serena ki n to bori!
Oríṣun àwòrán, others Abala keje àti í kejìlá àbá náà ro olùdarí àgbà fun ibùdó tó ń ṣe àkóso ajakalẹ-arun àrùn ni Naijiria, NCDC lágbára, láti gbé àwọn igbesẹ tó ṣe kókó, tó wá nisalẹ yìí, lásìkò tí ajakalẹ-arun bá bẹ silẹ.
ní Sikilagi ati ní Mekona ati àwọn ìletò àyíká rẹ̀, 
Ibo awọn ọmọ ẹgbẹ Republican ti Ààrẹ Trump wa pọ jù ti ẹgbẹ Democrat ti Joe Biden wa lọ pẹlu ida mejilelaadọta, eyii to gbe adajọ Barrett wọlé.
Àwọn ọ̀nà tí obìnrin fi le gbádùn ìbálòpọ̀
Umar ni oun ti ajọ naa mọ ni wi pe ina lo sokunfa rẹ, bọya ina dede gbe wọn ni tabi ara lo san pa wọn, ati wi pe nitori naa ni awọn ṣe bẹrẹ iwadii lori rẹ.
Amọ bi wọn ba ṣe n dagba, ni yoo ma a rẹ ẹya ara naa, eyi ti yoo nipa lori bi wọn ṣe n ni ibalopọ.
Ninu alaye rẹ, o ni wọn le gba ile ẹjọ giga lọ ti wọn ba ri aisedede kankan ninu ohun ti oludije naa ba fi sọwọ.
Adesoji Aderemi, Ọọ̀ni Ifẹ̀ àti gómìnà Adúláwọ̀ àkọ́kọ́ láyé eèbó amúnisìn Ìjọba tó wà lóde yìí kò ní ìfẹ́ aráàlú la ṣe dá ẹgbẹ́ NCF sílẹ̀ - Femi Falana Wo àdúgbò tó ń jẹ́ orúkọ èèbó amúnisìn tí yóò pa orúkọ dà l’Eko Ẹ wo bí ìsìnkú Adegbenro, Kọmíṣọ́nnà l‘Ondo ṣe lọ.
" Emi ti mo n sọrọ yii, mi o ra fọọmu pe mo fẹ dibo, nitorinaa ko si ẹni to lee sọ pe aini anfani ati pada si ile aṣofin lẹẹkan sii lo n faa.
Ní àkókò ogun,yóo gbà ọ́ lọ́wọ́ idà.
Agbẹnusọ ààrẹ náà sàlàyé pé, nítori pé ìwọ́de náà ti pẹ́ ju bi o ṣe yẹ lọ ló mú kí ààyè gba àwọn tó ṣe aburu náà.
Ìfipálówó: Bàbá ọmọ tí wọn gé lórí ní òun rán an láti gbowó lẹ́nu ATM ni
Ṣugbọn aisan to n ṣee ko gbọ bẹẹ si ni mi o le gba ọmọ ti mo ta pada ni iya wi.
Wọ́n ti ní kí Jolaosho TBlak"" wá káwọ́ pọ̀nyìn r'ojọ́ ìdí tó fi ya ""Blue Film"" nínú igbó Osun Osogbo Afurasí kan yin Oloruntoba níbọn nítorí èdèàìyedè nílé oní Sharwama Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ìtàn ọ̀rẹ́ tó fi ògùn gba ọkọ ọ̀rẹ́ rẹ̀ ni Akomolede BBC Yorùbá fẹ́ kọ́ wa lònìí Arabinrin Favour ni ọkọ afẹsọna oun fi oun silẹ lẹyin ti awọn ẹbi rẹ sọ fun wi pe ko lee fẹ oun nitori idile ẹru ni oun ti wa."
"Lọwọ lọwọ bayii, ipinlẹ mejila ti setan lati gba owoya naa, a si lero pe ki ọsẹ yii to pari, a san owo naa fun wọn.
Day jawe olubori ninu ija mẹtadinlogun ninu mejilelogun to kopa ninu rẹ, o fidi rẹmi ninu mẹrin, o si ta ọmi ninu ija kan.
Iyalẹnu lo wa jẹ pe opopona marosẹ ti wọn di pa yii, ni wọn gbe agbada kana si lati se irẹsi ati ọbẹ fun ounjẹ alẹ.
 ní ilẹ ̀ amẹ ́ ríkà , àdán ni ó sábà maa ń fa dìgbòlugi , ó kérésí ìdá 5 % dìgbòlugi lára àwọn ènìyàn ni o ń wá láti ọ ̀ dọ ̀ ajá .
fi onte luu pe ki ogbeni Emefiel tẹsiwaju gege bi adari ile ifowopamo ti ijoba
Ẹfunsetan Aniwura, obìnrin tó ju ọkùnrin lọ Ajá dóòlà ọmọ tuntun tí ìyá rẹ̀ bò mọ́lẹ̀ láàyè Ọ̀kan lára àwọn akẹ́kọ̀bìnrin Chibok kàwé gboyè l'Amẹrika Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Ó ṣojú mi kòró, ẹ wọ bí ìgbà ayé Bàbá Fagunwa ṣe rí' Nínú ọ̀rọ̀ ìdúpẹ̀ rẹ̀ gómìnà Akinwumi Ambode ni inú òhun dùn gidigidi bí àwọn agbábọ̀ọ̀lù náà ṣe ṣe àyẹ́sí fún òhún, o ni àwọn dájọ, ọjọ́ náà sikò àti pe òun dupẹ lọ́wọ́ àwọn to ṣe àgbátẹrùn ètò náà àti gbogbo àwọn to wá si pápá ìṣèré náà láti wa wòran Oríṣun àwòrán, AkinwumiAmbode Àkọlé àwòrán, Akinwumi Ambode: Awọn àgbà ọ̀jẹ̀ agbábọ̀ ọ̀lù lágbàyé yẹ́ Gomina Ambode si Awọn olólùfẹ́ gómìnà Akinwumi Ambode náà ko gbéyin lóri àtẹjiṣẹ́ twitter láti fi ìdùnú wọn han lórí ìfẹsẹwọnsẹ náà.
Ọdún Hijri mùsùlùmí tuntun wọlé dé, ẹ wo kókó pàtàkì nípa rẹ̀ Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí 5:58 Fídíò, Akomolede ati asa Yoruba: Ẹ wá kọ́ nípa àpòtí ìṣura èdè wa lórí BBC Yorùbá, Duration 5,5820 Ògún 2020 World Isese Day: Àwọn oníṣẹ̀ṣe ṣàlàyé pàtàkì ọdún ìṣẹ̀ṣe àti ìdí tí ìjọba fi gbọdọ̀ kéde ìsinmi lẹ́nu iṣẹ́ bí àwọn ọdún ẹ̀sìn míràn20 Ògún 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 3 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 5 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Wọ́n gbọdọ̀ gba ìjẹníyà nítorí ẹ̀ṣẹ̀ wọn, nítorí pé, wọ́n kẹ́gàn ìdájọ́ mi, wọ́n sì kórìíra ìlànà mi.
Kaakiri oju opo ayelujara ni awọran ibi ti Pulev ti fẹnu ko ẹnu akọroyin ile iṣẹ iroyin Vegas Sports Daily,Jennifer Ravalo ti gbode nigba ti o n bere nipa ija rẹ pẹlu Tyson Fury lọwọ rẹ.
” Mose bá gbadura fún àwọn eniyan náà.
Ọpọlọpọ ọmọ Naijiria lo koro oju si iwa ipaniyan yii nigba naa amọ esi ti Idiagbon fọ pada fun wọn ni pe: Ojutu àrà ọ̀tọ̀ ni Naijiria nilo lati wagbo dẹkun fun àṣà nini owo kiakia eyi to n ṣe iwuri fun iwa ọdaran."
Ileesẹ ọlọpaa ni asofin Owoẹyẹ, lati ipasẹ agbẹjọro rẹ, to fi ọrọ naa to ileesẹ ọ̀lọpaa leti, tun fi kun pe, awọn afurasi onijibiti naa tun gbe oun lọ si abule Ọsunjẹla, nibiti wọn ti lu oun ni aludojubolẹ, ti wọn si da apa si oun lara, bẹẹ́ ni wọn tun bọ asọ lọrun oun, ti wọn si ya fọto ihoho oun, eyi ti wọn fi n gba owo lọwọ oun.
Yẹra fún òmùgọ̀,nítorí o kò lè gbọ́ ọ̀rọ̀ ọlọ́gbọ́n lẹ́nu rẹ̀.
Oríṣun àwòrán, Ondo state House of Assembly Lẹyin ti ile se agbeyẹwo abala ofin to yẹ nipa igbesẹ rẹ ọhun lo wa pasẹ pe ki wọn lọ fun igbakeji gomina, Agboola Ajayi ni iwe ifitonileti pe wọn fẹ rọ ọ loye.
Aba tawọn eeyan muwa ni pe ki a fi eto si isẹ wa ki a si faaye kalẹ fun isinmi loore-koore.
Pẹlu ìdùnnú ńlá ni mo fi jókòó lábẹ́ òjìji rẹ̀,èso rẹ̀ sì dùn lẹ́nu mi.
End Sars, End SWAT, Aisha Yesufu: Ó ní ìdí tí mo fi ń wọ Hijabu lọ ṣe ìwọ́de- Aisha
Aare Buhari so pe : “ko si  ijoba to n dari iko  omo- ogun ti inu re yoo dun pe ki awon iko olote maa pa awon omo ologun ati awon ara ilu bo se wu won.
Kiki to jẹ ọmọ ọmọ ọmọ Oloye Obafemi Awolowo gẹgẹ bi Seyi na ṣe jẹ to si jẹ ọkan lara awọn oludije ninu ile BBNaija ni Kiki sọ pe Seyi ti ṣe nnkan iwuri lati igba to ti wa nilu ile.
Ẹ wo àbájáde ìwádìí wa Iléeṣẹ́ ọgbà ẹ̀wọ̀n ìlú Chicago sọ pé Hushpuppi kò sí ní ẹ̀wọ̀n MCC ní Chicago mọ́.
"Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Nigerian Youth Investment Fund: Ijọba àpapọ̀ yóò kó bílíọnù 75 owó ẹyá fún àwọn ilé ìfowópamọ́ kéékèké fún ìṣòwò àwọn ọ̀dọ́ 25 Agẹmo 2020 Oríṣun àwòrán, Sunday Dare Níní ìwádìí àjọ ""International Labour Organization"" tó jẹyọ lọ́dún 2019, ìdá àwọn ọ̀dọ́ tí kò níṣẹ́ lápa ní Nàìjíríà jẹ́ ìdá mẹ́rìnlá Bákan náà ni ìjọba orílẹ̀-èdè Nàìjíríà náà tún fi ìdí rẹ̀ múlẹ̀ pé àwọn ti kò niṣẹ́ lọ́wọ́ ni Nàìjíríà jẹ́ ìdá mẹ́tàlélọ́gbọ̀n àbọ̀ ní ọdún 2020."
Tunde gangan an lo fi aworan rẹ ati aya rẹ pẹlu ọmọ wọn si ori oju opo Twitter.
Nigba to ba ileeṣẹ iroyin BBC News Yoruba sọrọ, Oloye Sunday Igboho sọrọ ilẹ kun.
Ẹni to ba dan iru ẹ wo, le foju ba ile ẹjọ labẹ ofin ilẹ naa, koda awọn eeyan yoo doju bo ẹni to ba dan iru rẹ wo.
Èyíkéyìí ninu àwọn ọmọ rẹ̀ tí ó bá di alufaa dípò rẹ̀ yóo wọ àwọn aṣọ wọnyi fún ọjọ́ meje, nígbà tí ó bá wá sí ibi àgọ́ àjọ.
Ajọ eleto ilera lagbaye, WHO ti sọ tẹlẹ pe ọpọ oṣiṣẹ eleto ilera lagbaye lo ti farakasa aarun covid-19.
Jẹ́ kí Israẹli wí pé,“Ìfẹ́ rẹ̀ tí kì í yẹ̀ wà títí lae.
Oríṣun àwòrán, @WeArePindula Nigba to n gbosuba fun ikọ ọlọpa to se bẹbẹ yii, Kọmisana ọlọpa nipinlẹ Eko, Zubairu Muazu wa pasẹ pe ki wọn gbe ẹsun awọn ole meji ọhun sabẹ ikọ to n gbogun ti iwa idigunjale nipinlẹ Eko fun iwadi kikun.
’ Mose bá bẹ̀rẹ̀ sí gbọ̀n.
Bẹ́ẹ̀ náà ni, ó pa ọkunrin ará Ijipti kan tí ó ṣígbọnlẹ̀, tí ó sì dira ogun tòun tọ̀kọ̀.
Bi o ṣe gbagbe ara nigba to n sọrọ niwaju ero pupọ lo mu opin de ba ipolongo akọkọ rẹ fun ipo aarẹ (eyi si ni igbakẹta) ki o tilẹ to bẹrẹ.
Ko pẹ́ púpọ̀ tí a gòkè tan tí mo ṣe ìpàdé kí a bà yan ènìyàn sí àwọn ipò pàtàkì tí ó ṣófo lẹ́yìn tí ọ̀pọ̀lọpọ̀ ti kú tán.
oṣu kan naa ninu ile kan lagbegbe Oritoke, ni Ojoo, ni ilu Ibadan.
Nítorí pé, ninu ẹ̀jẹ̀ ni ẹ̀mí gbogbo ohun alààyè wà, nítorí náà ni mo fi sọ fún ẹ̀yin ọmọ Israẹli pé, ẹ kò gbọdọ̀ jẹ ẹ̀jẹ̀ ẹ̀dá alààyè kankan, nítorí pé, ninu ẹ̀jẹ̀ ni ẹ̀mí ẹ̀dá alààyè gbogbo wà, ẹnikẹ́ni tí ó bá jẹ ẹ́, a óo yọ ọ́ kúrò.
O sọ pe, awọn eeyan to n lo ọkọ ati awọn to tun n lo epo rọbi fun awọn nkan mii, ko ni ohunkohun lati bẹru nitori pe ileesẹ naa ni anito lati fun wọn ni ohun gbogbo ti wọn nilo.
Adonibeseki bá dáhùn pé, “Aadọrin ọba tí mo ti gé àtàǹpàkò ọwọ́ ati ti ẹsẹ̀ wọn, ni wọ́n máa ń ṣa èérún oúnjẹ jẹ lábẹ́ tabili mi.
Lasiko igba ti Gomina Rauf Aregbesola ṣe ijọba, ọpọ nnkan lo mu ba isejoba ipinlẹ Ọsun, ṣugbọn ohun to kọju si ẹnikan gẹgẹ bi Yoruba ti ṣe n sọ, ẹyin lo kọ si ẹlomiran.
Lefi bí ọmọ mẹta: Geriṣoni, Kohati ati Merari; àwọn ni olórí àwọn ìdílé ẹ̀yà Lefi.
Ṣugbọn o ṣeeṣẹ ki ipa rẹ pọ pupọ lara oloyun nitori agọ ara wọn ati iyatọ ti oyun n mu ba ara ati awọn ailera nipa eemi mimi Mo n fun ọmọ mi to jẹ oṣu marun un lọyan, kini ki n ṣe ti mo ba ti lugbadi coronavirus?
NLC Strike update: Ìná ẹgbẹ́ òṣìṣẹ́ NLC ati ìjọba kò wọ̀ níbi ìpadé
Tí ọ̀kan bá wá bẹ̀ mí wò,ọ̀rọ̀ tí kò lórí, tí kò nídìíni yóo máa sọ;bẹ́ẹ̀ ni ninu ọkàn rẹ̀, èrò ibi ni yóo máa gbà.
Nigba ti BBC beere lọwọ Adesina nipa ọrọ tawọn kan sọ pe, Ruga Settlement yii yoo gba ilẹ lọwọ awọn onilẹ, Adesina fesi pada pe''Ẹnikẹni to ba sọ iru ọrọ yii, ikorira lo fi sọ, o si yẹ ki wọn lọ fọ ọkan iru ẹni bẹẹ mọ kuro ninu ero eleyamẹya gbogbo'' Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Gomina Ortom wa lara awọn Gomina ti ipinlẹ wọn koju ipenija aawọ agbe ati darandaran Lọjọ iṣẹgun ni Gomina ipinlẹ Benue, Samuel Ortom fesi si igbese yii lẹyin ti ileeṣẹ to n risi ọrọ eto ọgbin gbe katakata wa, lati bẹrẹ isẹagbekalẹ agọ Fulani ni ipinlẹ Benue.
’ “Gbogbo eniyan yóo dáhùn pé, ‘Amin.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Papalolo ní ìlépa owó ni ìyàtọ̀ tó wà láàárín àwọn òṣèré tíátà àtijọ́ àti ìsisìnyí Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Papalolo ní ìlépa owó ni ìyàtọ̀ tó wà láàárín àwọn òṣèré tíátà àtijọ́ àti ìsisìnyí 7 Ọ̀pẹ̀̀ 2018 Ti a ba n sọrọ awọn adẹrinpoṣonu to gba muṣe ni ilẹ Yoruba ati ni orilẹede Naijiria, ọkan gboogi ni Ayọ Ogunṣina ti ọpọ mọ si papalolo jẹ.
Gẹgẹ bi O se sọ, O ni akori ipade ọhun yoo da lori,’’ sise ibasepọ ati idagbasoke fun Niger Delta.
Ojilelọọdunrun o din mẹta paali ohun ọṣọ ilẹ iyẹn tiles oke okun ti wọn ṣe lorilẹede China.
Alexis Sanchez: Man Utd faramọ asorọ ẹwọn 'Man Utd ko ri anfani to tọ lara Sanchez' Man United bọ́ si ìpele àsekágbá ninu ìdíje FA Ṣugbọn goolu marun un pere lo jẹ ninu ifẹsẹwọnsẹ marundinlaadọta to kopa ninu rẹ lati igba to de sọdọ wọn lati Arsenal loṣu Kini ọdun 2018.
Bẹẹ naa ni ọpọ ile ati dukia farakasa iṣẹlẹ yi ti ọp si di alainile lori.
 bi ti 2012 , awọn oniwe-olugbe ti a ni ifoju-lati wa ni nitosi 17.
Ọjo Kẹwa, Osu Kọkanla, ọdun 1995 ni ijọba ologun Naijiria se oun to bi ọpọlọpọ eniyan ninu lagbaye lẹyin ti wọn pa awọn ajafẹtọ mẹsan lati ilẹ Ogoni.
o ni awon yoo gba alatako lati darapo mo igbimo ijoba ti yoo maa samojuto idibo
Chelsea n yeruku lala bayii, koda wọn jawe olubori ninu ifẹsẹwọnsẹ meje ti wọn kopa ninu rẹ kẹyin.
Àwọn ni wọ́n fún ní ìlú Ṣekemu, tí ó jẹ́ ìlú ààbò fún àwọn tí wọ́n bá ṣèèṣì pa eniyan, ati àwọn pápá ìdaran rẹ̀ tí ó wà ní agbègbè olókè ti Efuraimu.
Oríṣun àwòrán, BBC Sport Àkọlé àwòrán, Awọn ololufẹ ẹgbẹ agbabọọlu Sfax n fi ina ṣere nigba ifẹwọnsẹ ẹgbẹ agbabọọlu naa pẹlu awọn agbabọọlu ilẹ Faranse ana lati ṣe ayẹyẹ aadọrun ọdun ẹgbẹ agbabọọlu ilẹ Tunisia naa ni papa-isere Mhiri in Sfax Oríṣun àwòrán, AFP Àkọlé àwòrán, Afin to kọkọ gba ami ẹyẹ obirin to rẹwa ju ni Zimbabwe, Sithmbiso Mutukura, gba ododo lẹyin igba ti wọn de l'ade ni Harare.
Igbimọ amuṣẹya ti ijọba ipinlẹ Ọyọ gbe kalẹ lori kikoju ajakalẹ arun coronavirus lo kede igbesẹ ijọba ipinlẹ naa lọjọ Aje.
”Jehu dáhùn pé, “Alaafia ṣe lè wà níwọ̀n ìgbà tí ìwà àgbèrè ati àjẹ́ ìyá rẹ ṣì wà sibẹ.
Ile iwe girama Kings College nilu Eko ni Adebayo lọ ti o si pegede nibẹ.
Gbogbo rẹ̀ wá ń tàn winiwini nínú ìmọ́lẹ̀ oòrun.
Yóo sì wá jẹ́ pé àwa ni a fa ìbànújẹ́ fún baba wa, ní ọjọ́ ogbó rẹ̀, ìbànújẹ́ yìí ni yóo sì pa á.
Deji sọ wi pe ko si ohunkohun ti ẹnikẹni ba n ṣe, ti ko ba ti ba ofin mu, ko tọna.
O ṣalaye pe bi eeyan ba ni dọla bayi, ki o ṣọra lati naa.
Oríṣun àwòrán, Yomi Shogunle/Twitter Àkọlé àwòrán, Onnoghen farahan niwaju ile ẹjọ CCT Onnoghen: PDP so ìpolongo ìbò rọ̀ Iléẹjọ́ òṣìṣẹ́ tún dáwọ́ ìgbẹ́jọ́ Onnoghen dúró lọ́dọ̀ CCT Atiku, Saraki, ẹgbẹ́ àwọn agbẹ́jọ́rò ta ko Buhari nípa Onnoghen Ọjọ karundinlọgbọn, oṣu kinni, ọdun yii ni Aarẹ Muhammadu Buhari ni ki Onnoghen lọ rọkun nile ti o si fi Adajọ Mohammed Tanko rọpo rẹ.
Bí àyẹ̀wò bá ṣe kéré tó, bẹ́ẹ ni iye ènìyàn to ni ààrun náà ti yóò farahàn, bákàn náà ni àwọn ti yóò kú, yóò wá pọ̀ jọjọ.
Àwọn ọmọ Efuraimu ní ìdílé-ìdílé nìwọ̀nyí: ìdílé Ṣutela, ìdílé Bekeri ati ìdílé Tahani.
Àwọn ará ìlú Beti Ṣemeṣi ní, “Ta ló lè dúró níwájú OLUWA Ọlọrun mímọ́ yìí?
Libya: Ọmọ Naijiria mejilelaadoje miran pada sile Àwọn ọmọ Nàìjíríà 320 yóò padà wálé láti South Africa lọ́jọ́rú - Adama 'Ọmọ Nàíjíríà 218 padà dé láti Libya Àtìpó 162 míì dé padà láti Libya O ṣalaye pe ''obinrin mẹ́rìndínlọ́gọ́ta (56) ọkunrin mẹ́tàléláàdọ́rùn ún (93) ati awọn ọmọdekunrin mejila (12) lo wa lara awọn to de naa'' Akọ̀ròyìn Morocco, Hajar gbà ìdájọ́ ẹ̀wọ̀n lórí ẹ̀sùn àgbèrè àti pé o ṣẹ́yún A ti ní mílíọ̀nù 11 Naira láti se ẹjọ́ pẹlú ilé-isẹ́ ọlopaa Naijiria!
Òrò-ìse ( is ) ni olórí fún àpólà ìse ( apis ) .
”Tabi pé, “Ó ṣe, arabinrin mi!
Jehosadaki lọ sí ìgbèkùn nígbà tí Ọlọrun jẹ́ kí Nebukadinesari wá kó Juda ati Jerusalẹmu lọ sí ìgbèkùn.
Bí wọ́n ti wọ inú ọkọ́ ni afẹ́fẹ́ bá rọlẹ̀.
Ami meji gboogi to si maa n fihan ni iba ati ikọ ahugbẹ ti ko dawọ duro.
Absalomu á tún wá fi kún un pé, “A!
Wọn bura fun abẹnugan tuntun ti  wọn sese dibo yan naa , Alhaji  Kabiru Alhassan Rurum, o si bẹrẹ isẹ lesekan naa.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Èmi gan máa ń béèrè lọ́wọ́ ara mi pé ta ni Wole Soyinka gangan' Eyi lo mu ki Alaafin Sango ran Timi Agbale lati lọ dena de awọn agbesunmọmi to wa lati ilẹ Ijẹsa laarin ilu Arà ati Awó, pẹlu igbagbọ pe wọn yoo pa a nibẹ.
Ní ọjọ́ náà, n óo run àwọn orílẹ̀-èdè tí wọ́n bá gbógun ti ìlú Jerusalẹmu.
 Òun ni ó dá fasisti sílẹ ̀ ní italy .
Oríṣun àwòrán, Facebook/Primate Babatunde Elijah Ayodele Bakan naa ni Ayodele sasọtẹlẹ pe o seese ki aarẹ to wa lori aleefa ati ọkan lara awọn aarẹ to ti jẹ tẹlẹ jade laye, ti omiran yoo si fi asọ penpe roko ọba.
 yoo jẹ igba keje ti igbimo alasẹ ti ogbeni
Ó di gberééé Oríṣun àwòrán, Ajimobi Lives on Àkọlé àwòrán, Deede ago mejila ọsan ni wọn yoo ṣe adura idagbere fun un ni Mọṣaaṣi.
Juda dá a lóhùn, ó ní, “Kí ni a rí tí a lè wí fún ọ, oluwa mi?
 láàrín oṣù mẹ ́ ta , aníní ti gbẹ ̀ mí lẹ ́ nu ọlọ ́ pàá mẹ ́ sàán .
Olori egbe odo naa, ogbeni Greig Oluchukwu, so oro ohun di mimo lasiko abewo re si Gomina Samuel Ortom nilu Makurdi.
Èyí ni láti ran àwọn ti o ni ẹ̀hónú kan tàbi òmíràn láti sọ lórí ìdàmú ti wọ́n ń kojú láti fi orúkọ silẹ̀ fún iṣẹ́ ọlọ́pàá.
Ohun ti eyi tumọ si ni pe o ṣeeṣe ki o maa mọ Ọlọrun tabi ki o maa ni igbagbọ ninu rẹ.
"Eniyan kan ti iṣẹlẹ na ṣoju ẹ ni ""iyanu nla lo jẹ"" fun ẹni ti ori ba yọ ninu baalu naa to gbe arinrinajo mẹtaleaadọrin ati oṣiṣẹ marun."
" Fidio naa ṣafihan awọn kan to duro, awọn oṣiṣẹ aṣọbọde, ati arakunrin kan ti ara rẹ kun fun ẹjẹ, to si da bi ẹni to ti ku.
  “Eyi yoo waye ni gbogbo ipinle jake-jado orile ede Naijiria , pelu Abuja lojo Isegun, Ogbonjo, osu kewaa, odun yii.
Wọn a máa kó oúnjẹ jọ fún ẹran wọn ninu oko olókowọn a sì máa he èso àjàrà ní oko ìkà.
Ṣé n kò lágbára tó láti rà wọ́n pada ni;àbí n kò lágbára láti gba ni là?
27 Òkùdu 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, AFCON 2019: Níbo ni ọ̀rọ̀ owó ajẹmọnu ikọ Super Eagles dé dúró?
 Amọ Chris ni oun fẹ ki awujọ gba oun bi oun ti ri."
Bakan naa ni Ẹgbẹ awon ẹya Igbo, Ohanaeze Ndigbo ni o dara bi Osinbajo ṣe sọrọ lori iṣoro to n koju awọn ọmọ Naijiria, ati bi o ṣe le jasi ipinya fun wa.
Kò si ǹkan ti àwọn ènìyàn le sọ, kò si ọ̀rọ̀ to tóbi kankan nínú ọ̀rs to wa nilẹ̀ yìí.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Àwọn òṣìṣẹ́ ilé aṣòfin Nàìjíríà bẹ̀rẹ̀ iyànṣẹ́lódì 17 Ọ̀pẹ̀̀ 2018 Oríṣun àwòrán, @NgrSenate Àkọlé àwòrán, Awọn asofin ṣi n ba iṣẹ lọ ni ile aṣofin lalai si iranlọwọ awọn oṣiṣẹ ile aṣofin Àwọn òṣìṣẹ́ ilé aṣòfin Nàìjíríà tí mú ìlérí wọn ṣẹ láti gbegi dina iṣẹ ni ile náà pẹlu bi wọn ti ṣe bẹrẹ iyanṣẹlodi lọjọ Ajé Lọsẹ to kọja ni wọn leri lati da iṣẹ gbogbo duro lori bi awọn alaṣẹ ile aṣofin naa ko ti ṣe san owo oṣu wọn.
Ninu rẹ̀, wọn yóo ra igi ati òkúta tí wọn yóo lò fún àtúnṣe náà ati láti san owó gbogbo ohun tí wọ́n nílò fún àtúnṣe ilé OLUWA.
Òùngbẹ bá bẹ̀rẹ̀ sí gbẹ ẹ́ gidigidi, ó sì gbadura sí OLUWA, ó ní, “Ìwọ ni o ran èmi iranṣẹ rẹ lọ́wọ́ láti ṣẹgun lónìí, ṣugbọn ṣé òùngbẹ ni yóo wá gbẹ mí pa, tí n óo fi bọ́ sí ọwọ́ àwọn aláìkọlà wọnyi?
Bakan naa ni fun ọkunrin ati obinrin.
Gbogbo wọn óo gbó bí aṣọ.
Bakan naa, gomina fidi ọrọ mulẹ pe oun ti ṣe ibẹwo si aafin Soun ti Ogbomoso to si ni oun ti jẹjẹ lati fun Kabiyesi ni Ọgrun miliọnu naira lati bẹrẹ atunṣe gbogbo nkan to bajẹ lasiko ti awọn olufẹhonuhan yabo aafin.
A gbọ́ dájúdájú pé ìwà àgbèrè wà láàrin yín, irú èyí tí kò tilẹ̀ sí láàrin àwọn tí kì í ṣe Juu.
Ipadabọ agbabọọlu si ẹgbẹ to ti figba kan gba bọọlu fun ri a maa mu ero ọkan orisirisi wa.
Brian ni ti oun yoo gbiyanju lati ṣe e fun oṣu mẹfa sii lẹyin naa oun le ti ile itura ọhun pa.
Iwe iroyin ilẹ naa fi lede wi pe dokita to n ṣiṣẹ ni ileeṣẹ ijba ni ẹni to ku naa lẹyin to pada si orilẹede DRC lati ilẹ Faranse.
Ọba Siria yóo wá pada sí ilẹ̀ rẹ̀ pẹlu gbogbo ìkógun rẹ̀.
Ajọ PFN sọ pe ewu nla wa nibẹ ti awọn ajẹ ba ṣe bẹẹ ṣe apero wọn gẹgẹ bi wọn ṣe n gbero.
wahala se n pọ sii nipa eto aabo ni ẹkun Ariwa.
Awọn ipinlẹ naa ni ipinlẹ Ọyọ, Ogun ati Eko.
”Jesu wá sọ fún un pé, “O wí ire.
What are they and why are they a problem?
BB Naija 2020: Erica ní òbùrẹwà, kìkìdá egungun ní Leycon, òun sì fẹ́ pa á Oríṣun àwòrán, BB Naija Orisirisi ara lo ti n waye nile BB Naija bayii, eyi to n ya ọpọ eeyan lẹnu.
O lọ sile ile iwe alakọbẹrẹ Ansarudeen ni Ijẹbu Igbo ko to o kuro nibẹ lọdun 1972 lọ pari iwe rẹ ni St John Modern School ni ipinlẹ Eko.
Ọ̀rọ̀ ẹ̀tàn ni wọ́n sì wawọ́ mọ́;wọ́n kọ̀, wọn kò pada sọ́dọ̀ mi.
35 San gbèsè tí ìwọ ti jẹ atẹ̀wé.
Wọn tún pe ọmọ ọkùnrin kan ṣoṣo ti Bàbá bi jade pé ó ni ẹ̀tọ́ lati mu ohun kan ti ó bá wu u ninú gbogbo ohun ini Bàbá rẹ, nitori eyi wọn fún ni ọjọ́ meje lati ronú ohun ti ó bá wù ú jù.
“Ẹ̀yìn Apolo ni èmi wà,” tí ẹlòmíràn tún ń wí pé, “Ẹ̀yìn Peteru ni mo wà ní tèmi.
Ni Ọjọru ni ayẹwo fihan pe Onuachu nikan lo ni arun covid-19 ninu gbogbo awon agbabọọlu Genk ti wọn ṣe ayẹwo coronavirus.
ipinle Borno yoo jẹ anfaani iwe adehun ti won tọwọbọ yii , nitori pe yoo mu eto
Ikọ Amọtẹkun ni ipinlẹ Ọṣun ti bẹrẹ iṣẹ ni pẹrẹu bayii pẹlu bi wọn ti ṣe wọ awọ igbo ni ipinlẹ naa lọ lati fi panpẹ ofin gbe awọn ọmọ orilẹede China ati Ghana kan ti wọn n ji kusa wa ni ipinlẹ naa.
Máfọ́ya, mo wà pẹ̀lú ẹ, Ajimọbi kàn sí Makinde lóri Coronavirus to ni Àwòrán ìhòhò: Salawa Abeni ti sọ̀rọ̀, ẹgbọ́ ohun tó wí Woli Babatunde n jẹjọ ijinigbe ti wọọn fi kan oun atawọn ọmọ ijọ rẹ mẹfa lori ọmọde jojolo kan to poora ni ile ijọsin rẹ ni oṣu kọkanla ọdun 2019.
Iná mọ̀nàmọ́ná ti dára di ẹ̀ si, nitori iná kò lọ púpọ̀ mọ́ bi ti tẹ́lẹ̀.
 Àwọn tí ó níí ṣe pẹ ̀ lú ìtàn ìwáṣẹ ̀ tàbí àwon ìtàn akọni .
Small Doctor: Mo kórira igbó, ọtí àti sìgá nítorí màmá mi lòdì si
Patirusimu, Kasiluhimu, (lọ́dọ̀ ẹni tí àwọn ará Filistia ti ṣẹ̀) ati Kafitorimu.
Ṣugbọn lónìí ńkọ́, ò ń fi ẹ̀sùn kàn mí nípa obinrin.
A gbọ pe Oyinkan lo pọn ni dandan fun Dokita naa pe ti yoo ba fẹ oun, o gbọdọ paarọ orukọ rẹ si Abayomi, tii ṣe orúkọ ọkọ rẹ aarọ.
OLUWA dá Mose lóhùn, ó ní, “Ǹjẹ́ nǹkankan wà tí ó ṣòro fún èmi OLUWA láti ṣe bí?
“Won ni anfaani lati tun bere aye won pada.
Ọpọ igba si ni o ma n tọrọ aforijin lọdọ ẹni to to ati ẹni ti ko to-o.
"Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ondo disability: Kò sí ẹni tí àkàndá kò lè ya ilé rẹ̀- Ayọdele ""Ní ti Bunmi Joshua nítirẹ, oun jẹ́ri èké fún àwọn ọmọ ìjọ naa pé ọmọ oun to ti kò gbọ́ran ti ko si lè sọrọ ri ìwòsàn gbà."
Ṣugbọn Jesu mọ ohun tí wọn ń rò.
Sugbọ́n ó ni ikéde yìí yọ àwọn to ṣe àwọn osiṣẹ́ eleto ààbò, awọn panapana àti àwọn onimọ iṣegun.
 Open, leyin ti o fagbahan Juan Martin Del Potro pelu ami-ayo mefa si meta(6-3), meje si mefa(7-6), mefa si meta(6-3) lati gba ife-eye idije naa lojo Aiku(Sunday).
Olasunkanmi Okeowo, tó fẹ́ díje fún ipò ààrẹ orílẹ̀-èdè Nàìjíríà lọ́dún 2019, lábẹ́ àsía African Democratic Congress (ADC) tí sọ pé, òun kò díje fún ipò ààrẹ mọ lẹ́yìn tó sọ̀rọ̀ kan eyi tó bí àwọn ọmọ Nàìjíríà nínú.
awon ologun pẹlu awon akọroyin laye ode oni” to waye ni ipinle
Mélòó-mélòó ni ẹ fi sàn ju àwọn ẹyẹ lọ.
Àwọn ìjòyè ń ṣe inúnibíni mi láìnídìí,ṣugbọn mo bẹ̀rù ọ̀rọ̀ rẹ tọkàntọkàn.
Sa ipá rẹ láti wá kí ó tó di àkókò òtútù.
 Ti ọdun 2018 yii waye ni ọjọ Aiku, Sunday ni Ile-ijọsin Methodist Church City Mission Circuit, ni agbegbe Surulere ni Ipinlẹ Eko.
Dele Momodu: Gbogbo aáyan àwa Nadeco láti tú Abiola sílẹ̀ ni kò hàn sí Kọla Abiọla
Nígbà tí ó ta á lẹẹmẹta, ó dáwọ́ dúró.
Ooni ti ile Ife, Oba Adeyeye Ogunwusi, Ojaja II ni o ṣeni laanu pe lasiko idibo gbogboogbo to waye ni Naijiria ni ọdun 2019, eniyan miliọnu mẹtadinlọgbọn lo jade lati dibo, amọ, eniyan ẹgbẹrun lọna aadọrin lo dibo lasiko eto Big Brother Naija ni ọdun 2019.
Wọ́n tún ṣí kúrò ní àfonífojì Seredi, wọ́n pa àgọ́ wọn sí òdìkejì odò Arinoni, tí ó wà ní aṣálẹ̀ tí ó bẹ̀rẹ̀ láti agbègbè àwọn ará Amori.
Àjọ ọlọpàá Eko kédé pé ìbalòpọ̀ nítà kò bójúmu Ènìyàn 26,000 ni àìsàn jẹjẹrẹ ń pa lóòjọ́ Ẹ wo àwọn ẹlẹ́sìn Hindu tó ń jẹ ènìyàn A ò gba ìbálòpọ̀ akọ ṣákọ tàbí abo sábo Awọn kan gba pé jijẹ ìṣẹ́pe inú odò n ṣiṣẹ́: Casanova ti itan gba pe o gbadun ibalopọ ju ni wọn ni o maa n jẹ to iṣẹpẹ aadọta laraarọ Bẹẹ ko si iwadii to fidi ẹ mulẹ pe iṣẹpẹ ti Casanova n jẹ gẹgẹ bii ounjẹ aarọ rẹ lo n mu u ki ara rẹ maa figba gbogbo dide.
O ni a le ge ọrọ si silebu niye igba ti eemi ba jade.
Kò sí ẹnìkan ninu àwọn tí wọ́n jọ ń jẹun tí ó mọ ìdí tí Jesu fi sọ ọ̀rọ̀ yìí fún un.
Fún àpẹẹrẹ bí a bá ní: ‘àpọ́nlé ni ìyá káà, kò sí ìyá kan ní káà tí kò ní orúkọ’, ohun tí a ń sọ ni pé kò sí ẹni tí kò ní orúkọ.
Kò sì sí ẹyọ ọkunrin kan tí ó kù ní Ai ati Bẹtẹli tí kò jáde láti lépa àwọn ọmọ Israẹli.
Buhari ni awọn to n fi orukọ ọlọrun boju pa eniyan, kii ṣe ẹlẹsin tootọ.
Ipolongo naa de ori ẹrọ ayelujara.
Niwọn igba to jẹ pe idi isẹ ẹni, laa ti n mọ ni lọlẹ, Bukọla ṣiṣẹ ni ile iwosan Rush Green to wa ni Essex gẹgẹ bi oniṣegun oyinbo lọdun 1988 si 1989.
Samson ni ọkunrin ohun ati awọn ẹmẹwa rẹ mu nkan ija lọwọ, ti wọn si fi agidi wọ inu oko naa ti o si da ipaya silẹ laarin awọn eniyan, eyi tumọ si pe wọn da omi alaafia ibẹ ru.
Koda, aimọye igba lati asiko ti iwọde yii ti bẹrẹ lo ti kọ ọrọ sori Twitter rẹ lati ṣe atilẹyin, ati lati bu ẹnu atẹ lu ipaniyan to n waye lasiko iwọde to n lọ.
Ǹjẹ́ fún ẹni tí ó lè pa yín mọ́ tí ẹ kò fi ní ṣubú, tí ó lè mu yín dúró pẹlu ayọ̀ níwájú ògo rẹ̀ láì lábàwọ́n, 
Gomina tẹlẹ rí ni ipinlẹ Ekiti to si tun jẹ agbaọjẹ ninu ẹgbẹ alatako ni Naijiria fi ọrọ yi sita loju opo Facebook.
Guusu orilẹ-ede Mozambique ni ọdọmọkunrin kan ti sin baba rẹ laaye ki baba naa to gbẹmi mi.
Ileeṣẹ ọmọ ogun ilẹ̀ ni Naijiria naa ti fi ontẹ lu igbega awọn ọmọ ogun naa.
Ó ṣe nǹkan tí ó burú lójú OLUWA, ṣugbọn ẹ̀ṣẹ̀ rẹ̀ kò tó ti àwọn ọba tí wọ́n jẹ ṣáájú rẹ̀.
Àwọn mìíràn tún sọ pé ọ̀kan ninu àwọn wolii àtijọ́ ni ó jí dìde.
Ko pẹ ti ijamba naa waye ni Ọṣinbajo fi fidio kekere kan soju opo Instagram rẹ.
Ṣugbọn yẹra fún iyàn jíjà lórí ọ̀rọ̀ wèrè ati ìtàn ìrandíran, ati ìjà, ati àríyànjiyàn lórí ọ̀rọ̀ òfin.
Àkọlé àwòrán, Oro to ba gba ẹkun, a kii fi ẹrin sọọ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Arakunrin Fulani ni aigbede ara eni ni orisun ija pelu agbe Oba kaakiri ilẹ̀ Yoruba lo peju pesẹ sibi apero ọna abayọ yii.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Tribunal: Ẹ wo márùn ún lára àwọn tí ilé ẹjọ́ dá dúró lẹ́yìn ìdìbò ọdún 2019 11 Owewe 2019 Oríṣun àwòrán, @others Àkọlé àwòrán, Ẹ wo márùn ún lára àwọn tí ilé ẹjọ́ ti yọ kúrò nípò lẹ́yìn ìdìbò ọdún 2019 Lẹyin idibo gbogboogbo to waye loṣu keji ọdun yii ni ọpọlọpọ awuyewuye ti n ṣelẹ lori esi idibo naa ti ajọ eleto idibo INEC fi lede.
Òpin burúkú ti dé bá ọ, o kò sì ní sí mọ́ títí ayé.
Oríṣun àwòrán, Deeper Life Àkọlé àwòrán, Kumuyi: Kini adarí ìjọ Deeper Life fi ṣẹ ọmọ Naijiria?
03 bn Owo iranwo fun iṣẹ akanṣe - N355 bn Owo iranwọ fun ilegbe ẹbi - N20 bn Owo iranwọ fun awọn ọdọ - N25 bn Awọn olu ileeṣẹ ijọba bii ọgọta - N336 bn Oríṣun àwòrán, Nigeria Presidency Buhari gbé àbá ìṣúná ₦13.
 nígbà míràn àwọn ibi tí omi ara maa ń gbà lè fi ara gba , tí ó sì lè fa ibà tàbí kí ó maa rẹ ènìyàn .
Awon osise ajo eleto idibo Independent National Electoral Commission, INEC ti de si ago idibo to wa ni Rumuola ,  ni ipinle Port Harcourt ni Ekun Gusu , orile ede Naijiria.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Cedar College, Lagos: Ilé ìwé wa kọ́ ni Favour kú sí 3 Òkùdu 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Oogun Oloro Ariwo ẹkun sọ nile Favour Ekemedili to jẹ akẹkọ onipele ikẹta ni ile iwe girama Cedar College, Baruwa ni agbegbe Ipaja ipinlẹ Eko.
Lara awọn ẹhonu ti awọn oṣiṣẹ naa n beere fun ni atunyẹwo ilana iṣẹ ni ileeṣẹ naa eleyi ti wọn ni wọn ni o ti di ogbo.
Wọ́n tún ní àṣẹ láti sọ gbogbo omi di ẹ̀jẹ̀.
Eyi ni esi ifesewonse idije boolu afesegba orile-ede Naijiria Nigeria Professional Football League (NPFL), ti o waye lopin ose:Nasarawa United 2-0 El-Kanemi Warriors FCHeartland FC 1-1 Kano Pillars FCWikki Tourists FC 1-1 Rangers InternationalMFM FC 3-0 Niger TornadoesKwara United 2-1 Yobe Desert Stars FCLobi Stars 1-0 Sunshine StarsFC IfeanyiUbah 2-1 Go Round FCKatsina United 1-0 Plateau UnitedRivers United 0-0 Abia Warriors.
Àwọn òṣèré tíátà kan rèé, tí wọn fẹ́ ara wọn, tí ìgbeyàwó wọn sì pẹ́ Kògbérèégbè mẹ́ta nínú òṣèré Yorùbá Àwòrán bí ìṣẹ̀lẹ̀ ìjàmbá iná ṣe wáyé ní ọja Balogun l‘Eko rèé Àìráyè dé ibí iná tó ń já ní Balogun jẹ́ ìpèníjà ńlá fún wa –LASEMA Igi to ba dara kii pẹ nigbo lọrọ Funmi Martins Lara awọn nnkan ti Afeez mẹnuba ni iya iyawo rẹ Funmi Martins, ati ipa to ko ninu igbesi aye oun ati iyawo rẹ Mide Martins.
OLUWA mú kí inú àwọn ará Filistia ati ti àwọn ará Arabia, tí wọn ń gbé nítòsí àwọn ará Etiopia, ru sí Jehoramu.
Kristi ti sọ wá di òmìnira.
Yatọ si pe o jẹ obinrin akọkọ oun ni obinrin alawọdudu akọkọ ti yoo dipo yi mu.
Ọwọ wọn lo si ti maa n gba kọkọrọ lati si ilẹkun sọọsi, ti yoo si tun da pada to ba kàwé tán.
Iroyin ni aisan ọkan lo fa iku ojiji to mu u lọ, lẹyin ti o lọ si ile iwosan fun ayẹwo ara rẹ.
Ohun tí wọ́n kọ sinu ìwé náà nìyí, “Ẹni tí ó mú ìwé yìí wá ni Naamani, iranṣẹ mi, mo rán an wá sọ́dọ̀ rẹ kí o lè wò ó sàn ninu àrùn ẹ̀tẹ̀ rẹ̀.
Àwọn adigunjalè pa èèyàn mẹ́fà ní báńkì kan nìpínlẹ̀ Ondo Irinajo ti gbérasọ padà ní pápákọ̀ òfurufú ìpínlẹ̀ Imo lẹ́yìn ìjàmbá iná 'Ọkọ̀ la rí, a ò tíì rí adárí Ilé iṣẹ́ pána-panà Eko àtàwọn mẹ́fà' - Ọlọ́pàá Lara awọn afẹhonu han meje ni wọn ti pa bayii lati ọjọ abamẹta to kọja ti ikọlukọgba yii ti bẹrẹ.
Oni lonii jẹ ẹni a bẹ lọwẹ.
Ọdun 2019 ni idibo gbogboogbo naa ni Babajide Sanwo-Olu naa fi idi Ambode janlẹ ninu idibo abẹlẹ saaju idibo sipo gomina naa, amọ Ambode si wa ni ẹgbẹ oṣelu APC.
Coffee Painter: Adebukola ní kò sí ìrànwọ́ lẹ́yìn ẹ̀kọ́ girama lòun ṣe ń ya àwòrán
Ko sọ ibi ti oun ti koarun naa ṣugbọn o ni ki gbogbo awọn eeyan ipinlẹ rẹ duro nile ki wọn si tle ilana didaabo bo araẹni lọwọ Coronavirus Coronavirus ti mu èèyàn 1 ní Benue, èèyàn 7 mìíràn ní Eko Ipinlẹ Benue ti di ipinlẹ tuntun ti yoo gbalejo arun Coronvirus ni Naijiria pẹlu bi ijọba ti ṣe kede pe eeyan kan ti ni arun naa nibẹ.
”“ojo iwuye naa yoo waye ni ojo kejila, osu kefa , odun 2018 ti a wayii, ojo yii ni yoo dipo ojo kokandinlogbon ti a  maa n gba isinmi lenu ise lati fi sajoyo odun ijoba tiwa-n-tiwa lorile ede Naijiria.
Lara awọn eekan ilu ti ọbẹ ofin yii ge lọwọ ni Fela Anikulapo Kuti, ti ọwọ tẹ pe o ko owo ilẹ okeere nla jade lọ soke okun.
Ember Month Security: Ọwọ́ pálábá àwọn ọmọ ẹlégbẹ́ òkùnkùn 15 ségí ní ìpínlẹ̀ Eko
Wọ́n rìn títí dé ẹnubodè Gedori, ní apá ìlà oòrùn àfonífojì, láti wá koríko fún àwọn ẹran ọ̀sìn wọn.
"Wo awọn Aàrẹ nílẹ̀ Áfríkà to ti gba oyè ""Field Marshal"" rí 6) Awùjàlẹ̀ ti Ìjẹ̀bú - Ọba Sikiru Adetona: Ọdun 1982 ni wọn rọ ọba yii loye lẹyin ti wọn fi ẹsun afojudi, ijọra ẹni loju, ati aibọwọ fun ofin kan an."
O ni oun lo ni ọpọlọpọ iriri, ọgbọn ati imọ lati tukọ ile aṣofin.
US election 2020: Ibú-owó Bloomberg fẹ́ wàákò pẹ̀lú Trump nínú ìbò ààrẹ Amẹrika
Ó dáhùn pé, “Ìwọ Daniẹli, máa bá tìrẹ lọ, nítorí a ti pa ọ̀rọ̀ yìí mọ́, a sì ti fi èdìdì dì í, títí di àkókò ìkẹyìn.
Fayemi gba oye Ọmọwe ni Fasiti Kings College niluu London.
Kí àwọn òyìnbó tó dé, kò sí ètò kíkọ ati kíka èdè Yorùbá.
Bí ìwọ bá ni Mesaya, sọ fún wa pàtó.
Nítorí bí eniyan bá lè di olódodo nípa ṣíṣe iṣẹ́ òfin, a jẹ́ pé Kristi kàn kú lásán ni.
Lara irufẹ awọn bẹẹ ni Brian, Rukiya ati Marcus ti wọn fi Amẹrika silẹ lọ si Namibia, Tanzania ati Uganda lati maa gbe.
Ìbáwí lásán ni mo fi gbẹ́ omi òkun,tí mo sì fi sọ odò tí ń ṣàn di aṣálẹ̀,omi wọn gbẹ,òùngbẹ gbẹ àwọn ẹja inú wọn pa,wọ́n kú, wọ́n sì ń rùn.
- Ọ̀gá àgbà ọlọ́páà Ẹ yé parọ́ kiri!
Gbajugbaja òṣèré ''Toromagbe'' nínú fíìmù ''Arelu'' ti jáde láyé Ẹ wo ọmọ Yoruba, Adewale Adeyemo tí yóò jẹ igbákejì akọ̀wé akápò ní ilẹ̀ Amẹrika Ṣe lóòtọ́ ní ọmọ Nàíjíríà mílíọ́nù 25 yóò má ló ìná Solar látí Dec 1, 2020?
Aṣofi Tunde Braimoh ni o dabaa ọrọ yii nigba ti o n
Oloogbe yii jẹ ọmọ ọdun mejilelọgọta.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Nigeria 2019 Elections: Àwọn aráàlú kan ní ìṣúnsíwájú ìbò ṣàkóbá fún ọrọ̀ ajé Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Nigeria 2019 Elections: Àwọn aráàlú kan ní ìṣúnsíwájú ìbò ṣàkóbá fún ọrọ̀ ajé 19 Èrèlè 2019 Lẹyin ti ajọ eleto idibo ilẹ wa, INEC, kede pe oun ti sun ibo aarẹ to yẹ ko waye ni ọjọ Satide, ọjọ Kẹrindinlogun osu Keji ọdun 2019 siwaju, si Satide, ọjọ Kẹtalelogun osu Keji yii kannaa, oniruuru iha ni awọn ọmọ orilẹede yii kọ si ikede naa.
lojuna ati koju ipenija to n koju eto aabo lorile-ede Naijiria.
Jesu bá mú burẹdi marun-un ati ẹja meji náà, ó gbé ojú sókè ọ̀run, ó dúpẹ́.
Má bá àwọn ọ̀mùtí kẹ́gbẹ́;tabi àwọn wọ̀bìà, tí wọn ń jẹ ẹran ní àjẹkì;
"Ẹwẹ, nigba ti BBC Yoruba kan si kọmiṣọnna fun eto iroyin ni ipinlẹ Ondo, Donald Ojogo, o ni ""a ti yanju ohun ti wọn n bere fun."
Ilẹ ẹjọ fagi lé ìbò ọmọ ẹgbẹ APC lógùn, pè fún àtúndì ìbò.
Oríṣun àwòrán, AFP Àkọlé àwòrán, Awọn onijo si tun da awọn eeyan lara ya nigboro Johannesburg, lorilẹede South Africa, nibi ti wọn ti n ṣẹ ajọdun ọdun tuntun ounka-ọjọ China Oríṣun àwòrán, AFP Àkọlé àwòrán, Wọn si tun s'afihan ijo ibilẹ ẹkun nigba t'awọn eeyan dunnu amojubaa Ọdun Aja Oríṣun àwòrán, AFP Àkọlé àwòrán, Ni orilẹede DRC, nibi ti ogun ti sọ awọn eeyan di atipọ, obirin alasala kan joko.
OLUWA yóo fọn yín káàkiri sí ààrin àwọn orílẹ̀-èdè, àwọn tí wọn yóo sì ṣẹ́kù ninu yín kò ní tó nǹkan láàrin àwọn orílẹ̀-èdè tí OLUWA yóo fọn yín ká sí.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Fídíò codeine: Iléesẹ́ Emzor gba‘sẹ́ lọ́wọ́ òsìsẹ́ 1 Èbibi 2018 Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Fídíò òògùn ikọ́ Codeine: Àpọ̀jù rẹ̀ ń ya ọ̀dọ́ ní wèrè Fídíò lórí títà àti rírà oògùn ikọ́ olómi Codeine tí BBC fi síta ti ń bí oríṣíiríṣíi èrò láàrin àwọn ọmọ Nàìjíríà.
Pẹlu omije loju ọpọ eniyan ni ọdọmọde ajagun ọmọ ogun ofurufu ni, Tolulọpẹ Arotilẹ wọ kaa ilẹ lọ lọjọbọ ni itẹ isinku awọn akọni loju ogun ni ile Abuja.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Number Plate: Ìlànà FRSC rèé láti gba nọ́mbà àdáni fún ọkọ̀ rẹ 4 Bélú 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 11 Òkùdu 2020 Oríṣun àwòrán, Twitter/FRSC Àkọlé àwòrán, FRSC ní àwọn kò mọ̀ nípa nọ́mbà ọkọ̀'CHIP WHIP' Wo ilana ti eeyan gbọdọ tẹle to ba fẹ gba nọmba adani si ọkọ rẹ gẹgẹ bi ajọ ẹṣhọ oju popo FRSC ṣe laa kalẹ: Ṣe iforukọsilẹ ọkọ rẹ Igbesẹ akọkọ ni pe eeyan gbọdọ ṣe iforukọ silẹ ọkọ loju opo ajọ ẹṣọ oju popo, FRSC (http://www.
(Àwọn ará Jabeṣi ti jí àwọn egungun náà kó kúrò ní ìta gbangba, ní ààrin ìlú ní Beti Ṣani, níbi tí àwọn ará Filistia so wọ́n kọ́ sí, ní ọjọ́ tí wọ́n pa wọ́n ní òkè Giliboa.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Funke Akindele jẹ àkàndá ẹ̀dá - Adaku Aarẹ ẹgbẹ CAN, Ẹni Ọwọ Samson O.
Aisan ọkan ni iroyin ti a gbọ ṣọ pe o gbẹmi rẹ.
ati adari won jiroro papọ, laisi ani-ani, mo lee fọwọ sọya pe awon osisẹ orile
Siga tita d‘eewọ lẹba ile ẹkọ Wo oríṣiríṣi ìgbádun ibálòpọ̀ láwọn orílẹ̀èdè mìíràn A yoo ṣe àyẹ̀wò ọpọlọ fàwọn òṣìṣẹ́ FSARS - Iléesẹ́ ọlọ́pàá Òògùn ẹ̀fọn pa ọmọ mẹ́ta ní Ghana Bakan naa lo sọ pe ọna ati da wahala silẹ lorilẹ-ede Naijiria ni ati pe ilẹ Yoruba ko ni gba a.
 ní ñǹkan ẹgbẹ ̀ rún ọdún kẹ ̀ ẹdógún ( prior 15th century ) ìtàn se akọ ̀ sílẹ rẹ pe ọmọọba bìnrin nwe kò àwọn ènìyàn rẹ tọ ́ yẹ kan dí woyo sodí lo sí ojù gbangba níbi tí wọ ́ n gbé wà bayìí .
Buhari maa n sọ pe iku iya oun jẹ ọkan lara awọn iṣẹlẹ ibanujẹ to ti ṣẹlẹ si i laye, nitori pe iya rẹ nikan lo tọ ọ dagba, lẹyin ti baba rẹ ku nigba to wa ni ọmọ ọdun mẹrin.
kí ó fún mi ní ihò Makipela, òun ni ó ni ihò náà, ní ìpẹ̀kun ilẹ̀ rẹ̀ ni ó wà.
Iroyin naa tilẹ fi kun un pe ni ọsẹ to kọja ni wọn gbe Sẹnetọ Ajimọbi digbadigba lọ sileewosan ti a n sọrọ rẹ ọhun nigba ti ọrọ ilera rẹ n ṣebi ẹni fẹ maa mẹhẹ eleyi to si n da aya ja awọn mọlẹbi rẹ.
Ìwọ kì í ṣe àgàbà gebè tí ó fi ẹ̀jẹ̀ sí inú tí ó tu ita funfun jáde, tí ó yin ènìyàn lójú tí ó bú ènìyàn lẹ́hìn, èkúté mi ọ̀wọ́n, jẹ́ kí n sọ ìtàn kékeré kan fún ọ - lẹ́jẹ́ kan, èmi àti alábòsí jọ wà nínú ẹgbẹ́, nígbà tí ó ṣe àkíyèsí pé ọkùnrin kan ń fẹ́ẹ́ ba ẹgbẹ́ jẹ́, gbogbo wa pa ẹnu pọ̀ pé kí ọkùnrin náà kúrò nínú ẹgbẹ́, àfi ìgbà tí a túká ní ibi ìpàdé tán tí alábòsí rọra yọ́ kẹ́lẹ́kẹ́lẹ́ tọ ọkùnrin náà lọ tí ó wí fún un pé òun kò ni ọwọ́ nínú èrò wa.
com/yoruba/45319192 Omi titun ti rú nínú oríṣii ètò ìgbéyàwó Yorùbá lásìkò yí Àkọlé àwòrán, Omi titun ti rú nínú oríṣii ètò ìgbéyàwó Yorùbá lásìkò yí Ṣe wọn ni ibi gbogbo ni ifẹ wa bi a ba lee farabalẹ waa.
 delanọ ní láti ilé-ifẹ ̀ ni Ẹ ̀ gbá tí mú ètò Ògbóni wá .
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Igbaradi Super Eagles for idije AFCON 2019 Naijiria yoo to koju Senegal ninu ere bọọlu ọlọọrẹsọọrẹ miiran lọjọ kẹrindinlogun oṣu Kẹfa lorilẹede Egypt ki idije AFCON 2019 to bẹrẹ.
Oríṣun àwòrán, Others Wọn maa n lo lasiko ayẹyẹ nla, o si ti gbajumọ laarin awọn ọlaju, kii ṣe ohun elo orin abẹle.
Ọ̀tá Nàíjíríà ni Saraki àti Dogara - Buhari Nigeria swearing-in: Ọjọ́ kò!
Ó ti fi ọ̀rọ̀ rẹ̀ hàn ní àkókò tí ó wọ̀ fún un ninu iwaasu tí ó ti fi lé mi lọ́wọ́ gẹ́gẹ́ bí ìlànà Ọlọrun Olùgbàlà wa.
Yóo rí fún un bí ó ti rí fún Sodomu ati Gomora ati àwọn ìlú agbègbè wọn tí ó parun.
Iṣẹ́ Kudirat Abiọla ṣì ń fọhùn síbẹ̀, lẹ́yìn ọdún 23 tó papòdà Háà!
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ètò ẹ̀kọ́: Buhari dín owó fọ́ọ̀mù NECO, JAMB kù 19 Ọ̀wàrà 2018 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 29 Bélú 2018 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ọrọ eto ẹkọ Ijọba apapọ ti kede ẹdinwo owo fọọmu idanwo aṣekagba nile iwe girama ti ajọ National Examination Council n ṣe ati idanwo ṣiṣe wọ ile iwe giga.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Badagry: Ojú ọ̀nà àrèmabọ̀ fáwọn ẹrú tó ń lọ sókè òkun Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Badagry: Ojú ọ̀nà àrèmabọ̀ fáwọn ẹrú tó ń lọ sókè òkun 3 Ìgbé 2018 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 23 Ògún 2018 Ibùdó ojú ọ̀nà àrèmabọ̀ tó wà ní ìlú Badagry rèé, tí áwọn òyìnbó ń kó áwọn ẹrú sí, láti lọ fi se iṣẹ́ agbára sókè òkun.
"Ki o to lee darapọ mọ ajọ yii, eniyan bẹẹ yoo ti wo fọọmu igbaniwọle ninu eyi ti a ti ṣe alaye ohun ti owo ti wọn san wa fun.
Òbúkọ kan fún ẹbọ ìmúkúrò ẹ̀ṣẹ̀.
Bí ẹnìkan bá fẹ́ iyawo, tí ó sì tún fẹ́ ìyá iyawo náà pẹlu, ìwà burúkú ni; sísun ni kí wọ́n sun wọ́n níná, ati ọkunrin ati àwọn obinrin mejeeji, kí ìwà burúkú má baà wà láàrin yín.
 O ni igba gbogbo nijoba ipinle setan lati sisepo pelu ajo NDDC.
Ọmọwe Folashade Yemi-Esan kẹkọọ gboye gẹgẹ bi akẹkọọ to fakọyọ julọ ninu imọ nipa iṣẹ abẹ eyin ni fasiti Ibadan lọdun 1987.
Kọmisana ọlọpaa ni Ipinlẹ Eko, Muazu Zubairu ti ni wọn ti fa awọn afẹsunkan naa le ọwọ agọ ọlọpaa to wa ni Makinde, Oshodi ati ẹka to n ṣe iwadii ẹsun ole.
Àwọn alufaa ati àwọn ọmọ Lefi ya ara wọn sí mímọ́ lápapọ̀, fún ayẹyẹ náà.
Amọ ṣa, o jọwọ ẹri to fi mọ ohun iko nkan elo ẹrọ ayarabiaṣa komputa pamọ si (hard disk) ati awọn nkan miiran.
 O ni idagbasoke ti o ti de ba eto oro aje ati awujo nipa irinna
 Gege bi a se seleri, ohun ti yoo pese ojo iwaju rere fun orile-ede yii ni eto aabo, eto oro aje ti o duro sinsin, bee si ni lati koju iwa ibaje.
Ṣùgbọ́n nínú ọ̀rọ̀ ti ẹ̀, akọ̀wé ìkéde fún ìjọba ìpínlẹ̀ Ekiti, Yinka Oyebọde, sọ fún BBC Yoruba pé, lóòtọ́ ni wàhálà nàá wáyé láàrin àwọn tó fẹ́ yọ alága ẹgbẹ́ NURTW.
Adesanya ko ti fidi rẹmi ri lati igba to ti di agbaọjẹ lagbo UFC.
AFCON 2019: Òde kò dùn fún super Eagles, Madagascar nà wọ́n pẹ̀lú 2-0
Koda bi o ba ṣe asikọ Umar Ibn Khattab to jẹ saabe agba ni wọn wu iru iwa yi, afaimọ ki wọn ma da sẹria ẹgba fun wọn'' Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Omọ Falana yii ti kopa ninu ere fiimu agbelewo ati ere oniṣe loriṣiirisi bii ti Jẹnifa.
fun adajo agba  ati minisita fun eto idajọ
Ni bayii, orile-ede Amerika ti setan lati kun awon omo-ogun Afghan lowo lati koju awon omo-ogun olote Taliban naa, nipa lilo awon ohun ija ogun oju ofurufu, besini lati tun fipa mu awon omo-ogun olote naa lati jo forowero bi igbe aye Alafia yoo se joba.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fọ́nrán ohùn, Iparọwa si gbogbo awọn tọrọ naa kan lati ri wipe aba ofin naa mulẹ lorilẹede Naijiria Adari ipolongo naa wa parọwa si gbogbo awọn tọrọ naa kan lati ri wipe aba ofin naa mulẹ nigbogbo ẹka ati ẹya to wa lorilẹede yi, ki ọjọ iwaju awọn ọdọ le wuyi pẹlu ilọsiwaju to lamilaaka lorilẹede yii.
Òṣìṣẹ́ ìròyìn àti àwọn ọmọ-ìlú ti di èrò àtìmọ́lé lórí ẹ̀sùn àtẹ̀jáde “ìròyìn irọ́” títí kan ìkóròyìn ìkòkọ̀ ìlú sí etí ìgbọ́ ẹgbẹ́ afẹ̀míṣòfò.
Ó sì lọ kó àwọn jàǹdùkú ati àwọn aláìníláárí eniyan kan jọ, wọ́n pe Rehoboamu ọmọ Solomoni níjà.
Mo ti dàgbà ọ̀jẹ̀, n kò ní díje fún ipò gómìnà ìpínlẹ̀ Oyo mọ́ - Alao Akala Ọ̀fẹ́ ni China yóò kọ́ fásítì $50M ètò ìrìnnà sí Daura ìlú Ààrẹ Buhari- Amaechi Irọ́ ni, kò sí olóyún nínú àwọn tí Tírélà pa ní Ondo ṣùgbọ́n awakọ̀ ti sá lọ- Ọlọ́pàá Ondo Ọba ni mí, mi ò le b'ọ̀rìṣà, Olorì tuntun tó ń bọ̀ já gbogbo ''scale''- Oluwo ti Iwo Ta ni ìyàwó Chadwick Boseman, tó jẹ́ àwòkọ́ṣe rere f'áwọn ọ̀dọ́ Adúláwọ̀?
Atiku sọ pé òun wọlé gẹ̀gẹ̀ bí gómìnà ìpínlẹ̀ Adamawa ní ọdún 1999, kí òun tó di igbákejì àarẹ́ Olúsẹ́gun Obásanjọ́ l'ọdún kan náà.
Operation Velvet: Ilé ẹjọ́ alágbéèká bẹ̀rẹ̀ láti fìyà jẹ́ awakọ̀ tó bá rúfin Minimum wage: Kí ló fàá tí owó oṣù tuntun fi ṣòro?
Mo sọ fún ìyá mi pé mo fẹ́ ẹ́ lówó lọ́wọ́ díẹ̀ kí n tó ṣe ìgbéyàwó, nítorí pé mí ò ní nkan tí mo le fi ṣe aya lọ́ọ̀dẹ̀ ọkọ."
3 9516 Orilẹede Malawi 185 1.
Ẹni to bori: Algeria Ìpele to ṣaaju eyi to kangun si aṣekagba Tanzania vs Namibia.
Nígbà tí wọ́n kó wa dé iwájú ọba àwọn ejò, tí òun náà rí wa, inú bí i gidigidi orí rẹ̀ sí yí padà ó túbọ̀ ń tóbi sí i; gbobo àwọn ìjòyè rẹ̀ sí bẹ̀rẹ̀ sí pòṣé wọ́n ń bínú nítorí wa.
Wọ́n tún gbé àpótí Ọlọrun náà ranṣẹ sí ìlú Filistini mìíràn, tí wọn ń pè ní Ekironi.
Fun idi eyi aarẹ Trump ti fẹ bẹgi dina irinajo wọ ilẹ Amẹrika, bakan naa o ti pe fun atunṣe iwe ofin eyi to n sọ ni di ọmọ ilu Amẹrika fun gbogbo ọmọ ti wọn ba bi si Amẹrika.
    Ìgbà ‘ti ó di ọjọ́ kan Ìbẹ̀ǹbẹ́-Olókùnrùn ṣe ìpàdé ńlá kan tó o pe ará ayé àti ará ọ̀run wá jẹun, nítorí ẹran tí o rí kò tó, ó pa àrẹ̀mọkùnrin rẹ̀ ó dín in ní ata, nítorí ọtí ti ó rí kò sì tó, ó pa àrẹ̀mọbínrin rẹ̀ o rọ ẹ̀jẹ̀ rẹ̀ si inú ìgò, ṣùgbọ́n nígbà tí àwọn ará òde ọ̀run dé, wọ́n mọ ohun tí ó ti ṣe, wọ́n bá ṣẹ èpè fún un pé títí ọjọ́ ìrònúpìwàdà rẹ̀, bi ó ti wù kí ó jẹun tó ko níí yó mọ́, bí ó sì mu omi odò gbẹ kò ní ní ìtẹ́lọ́rùn, ìdí rẹ̀ sì nì yí tí o fi di abàmì ẹ̀dé bẹ́ẹ̀ kalẹ̀ láti ọjọ́ náà wá.
Iṣẹ́ tí OLUWA rán wolii Malaki sí àwọn ọmọ Israẹli nìyí.
Laipẹ yii ni ile ẹjọ fi gomina nigba kan ri fun ipinlẹ Taraba ati Plateau si ẹwọn lori ẹsun iwa ibajẹ ti ajọ EFCC fi kan wọn pe wọn na owo ilu ninakuna nigba ti wọn fi wa nipo.
Oríṣun àwòrán, Sreenshot Niṣe ni gbogbo awọn to wa nibi ijoko naa n sare kijokijo lasiko ti Ọjọgbọn Pondei daku lori aga to joko si.
 “Mo ni igbagbo pe, pelu ase Olorun oba, asiko ti awon onijegugu-jera oloselu ati awon jandiku won, ti won n fa laasigbo ati iwa alumokoro yi lasiko idibo ti koja lo lorile-ede Naijiria”.
Lọdun 2018, Izeowayi Victor jáwé olúborí nínú àròkọ̀ BBC Pidgin.
Èmi kì í máa kan ẹ̀ṣẹ́ tèmi ní ìkànkukàn, bí ẹni tí ń kan afẹ́fẹ́ lásán lẹ́ṣẹ̀ẹ́.
" awọn oniwe-c-3 usb ikanni ti gbe "" pinwheel "" ojoojumo lati 7 : 00 emi lati 9 : 00 p."
wọ ́ n bí abass sí ìlú ijoga orile ní ìpínlẹ ̀ ogun , orúkọ àbísọ rẹ ̀ sì ni famerilekun .
Aliyu sọ fun ileesẹ akoroyinjọ nilẹ wa, NAN pe agbegbe mairi, Custom ati Gwange to wa nilu Maiduguri ni wọn ti gbọ ibugbamu awọn ado iku naa.
Pẹlu gbogbo alaye yii, o le mọ iru awọn ilu ti Alaafin Oyo, Oba Lamidi Olayiwola Adeyemi kẹta n sọ nigba ti o fi lede pe, awọn onilu lo maa n tu asiri bi awọn ẹni ibi ba fẹ wọ aafin.
Ile asofin Kwara: Owo ifẹyinti d'opin f'awọn gomina ana
O yan ọrọ naa lasiko to n fi atẹjisẹ dahun oriṣiri'si ibeere ti awọn ololufẹ rẹ n bi i lori ayelujara ibaraẹnidọrẹ Instagram rẹ ni ọjọ Aje.
Baluu oko ofurufu aare ohun bale si papako ofurufu Nnamdi Azikiwe laago mesan an abo nilu Abuja.
igbimo ipolongo naa ni:Oloye  Bisi AkandeOloye John
Iléeṣẹ́ APC, PDP dá páropáro ṣáájú ìdájọ́ ilé ẹjọ́ tó ń gbọ́ ẹjọ́ ìdìbò gómìnà ìpínlẹ̀ Ọṣun Àkọlé àwòrán, Ida yoo waye loni nilu Abuja Paroparo ni ọ́fíìsì ẹgbẹ́ òṣèlú APC àti PDP dá ní Ìpínlẹ̀ Ọṣun ní bí àwọn ẹgbẹ́ òṣèlú méjèèjì náà ṣe ń dúró de ìdájọ́ ilé ẹjọ́ tó ń rí sí èṣùn tó súyọ lórí èsì ìbò gómìnà Ìpínlẹ̀ náà tó wáyé lọ́dún 2018 Lọwọ yii, idajọ ṣi n lọ lọwọ ni ile ẹjọ to n gbọ ẹjọ naa nilu Abuja.
Orile-ede Italy ti gbakoso agbegbe Eritrea ati Somaliland, ni eyi ti won tun n tesiwaju lati gba akoso Ethiopia.
Ṣamua ni baálé ní ìdílé Biliga,
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ipaniyan: Ẹ̀wọ̀n gbére ni adájọ́ fún ọkùnrin náà pé ó jí olólùfẹ́ rẹ̀ gbé 26 Ẹrẹ̀nà 2019 Oríṣun àwòrán, Makawai.
Ó wọ́pọ̀ laarin ẹbi ọkùnrin àti obinrin àfẹ́sọ́nà, ki obi kọ̀ ki wọn fẹ́ra nitori itàn pé idilé tàbi ilú ti ikan ninú ọkùnrin tàbi obinrin ti jade kò dára.
 Igba yii ni Fada Mbaka wa sọ fun wa pe ka maa lọ ki awọn gende oun to pa wa.
"  Loni, akowe agba ilẹ Amerika n fi awọn miran kun awọn ti ofin fisa gbigba de nitori ipa ti wọn ko bi eto idibo inu osu kẹsan ati ikẹwaa ṣe n bọ ni Edo ati Ondo ""Awọn eniyan wọnyi huwa aitọ lai fi ti ipa to ni lara awọn ọmọ Naijiria ṣe ati nkan ti o ṣe fun eto ijọba awa ara wa ni Naijiria."
Èmi nìkan ni ó lọ sí ibi tí mo ti ri i.
Ó dára, nítorí bẹ́ẹ̀ ni mo jẹ́.
Nibẹ si ni awọn agbanisiṣẹ ti maa n wa gbogbo ọna lati yan awọn idile naa jẹ.
 ofurufu lorile ede Naijiria, asofin Hadi
Aare kẹdun pelu awon ebi ti o padanu awon ohun ini won ati eniyan won sinu ikolu omiyale naa.
Ṣugbọn tí ó rí ìbáwí fún ẹ̀ṣẹ̀ rẹ̀.
Ẹ wá rí i, ẹ tún ti gbọ́ pé kì í ṣe ní Efesu nìkan ni, ṣugbọn ó fẹ́rẹ̀ jẹ́ pé ní gbogbo Esia ni Paulu yìí ti ń yí ọ̀pọ̀ eniyan lọ́kàn pada.
Lanre Kuti ni mo fẹ́ - Jaiye Kuti Ènìyàn 27 lo ti bá iṣẹ̀lẹ̀ ọkọ̀ ofúrufú tó já rìnrìn ajò Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Kogi 2019: Àwọn ará ìlú sọ̀rọ̀ lórí ìrètí wọn lọ́wọ́ Yahaya Bello Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Ile ẹjọ naa paṣẹ pe igbẹjọ naa gbọdọ tẹ siwaju, pẹlu aṣẹ pe ki awọn agbẹjọro to wa nivdi ẹjọ naa o mu ọjọ igbẹjọ tuntun ki igbẹjs lee tẹsiwaju, lai naani boya kanu yọju tabi ko ysju.
Ẹni tí ó máa ń ṣàánú fún ẹgbẹẹgbẹrun, tí ó máa ń dárí àìṣedéédé ji eniyan, ó máa ń dárí ẹ̀ṣẹ̀, ati ìrékọjá jì, ṣugbọn kì í jẹ́ kí ẹlẹ́ṣẹ̀ lọ láìjìyà, a sì máa fi ìyà ẹ̀ṣẹ̀ baba jẹ ọmọ ati ọmọ ọmọ títí dé ìran kẹta ati ikẹrin.
Sebi aimose ko omorogun lo se tori bo omi gbigbona, Iko agbaboolu Valencia fara ko ibon sakabula Arsenal, leyin ti won padanu ifesewonse ipele keji asekagba idije EUROPA sowo Arsenal pelu ami-ayo meji si merin(2-4), ti apapo esi ifigagbaga ese mejeeji si je ami ayo meta si meje(3-7).
Kiakia ni awọn eniyan ti n da awọn ohun ini yii pada ni awọn ilu bii Adamawa, ipinlẹ Eko, Oyo, Osun ati bẹẹ bẹẹ lọ.
Ṣugbọn nígbà tí ẹ̀jẹ̀ náà bá dá, kí ó ka ọjọ́ meje lẹ́yìn ọjọ́ náà; lẹ́yìn náà, ó di mímọ́.
Osun Election: Ìbò méje péré ni Adeleke fi fẹ̀yìn Adebiyi janlẹ̀
Kabiesi soro naa di mimo lori ero ayelujara(Twitter) re lana ode yii, ti n se ojo kejidinlogun osu kewaa odun ti a wayii pe,”Ibere ife ati igbe-aye tuntun ni eyi je pelu olori Shilekunola Moronke Oluwaseyi Naomi.
Oríṣun àwòrán, Others Asiko yii ni Ajimobi se ayẹwo fawọn osisẹ, to si tun da pupọ wọn duro tori wọn ko ni iwe ẹri to jinna, tawọn osisẹ naa si ni eyi ko ri bẹẹ.
Lẹ́yìn tí ó ti jókòó, ó pe àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ mejila, ó wí fún wọn pé, “Bí ẹnikẹ́ni bá fẹ́ jẹ́ ọ̀gá, ó níláti ṣe iranṣẹ fún gbogbo eniyan.
Sugbọn Ataoja tilu Osogbo, Ọba Oyetunji Ọlanipẹkun, lasiko to n fesi lori isẹlẹ yii fun BBC Yoruba, o ni irọ to jinna sootọ ni igbe ti baba ati iya Ọsun fi ta, tori ere Ọsun wa ni aafin sugbọn oun ko gbọdọ fi oju ri.
 Tunji Bello ati oluranlowo ijoba ati adari okoowo ati oro to je mo ti ile okeere, ojogbon Ademola Abass.
Amọ, ko si ẹni ti arun naa pa lọjọru.
Esau dá a lóhùn, ó ní, “Ebi ń pa mí kú lọ báyìí, ò ń sọ̀rọ̀ ipò àgbà, kí ni ipò àgbà fẹ́ dà fún mi?
Nígbà tí Iṣiboṣẹti ọmọ Saulu gbọ́ pé wọ́n ti pa Abineri ní Heburoni, ẹ̀rù bà á gidigidi, ìdààmú sì bá gbogbo àwọn ọmọ Israẹli.
Akọwe ilera lorileede Gẹẹsi Matt Hancock ti sọ fún àwọn aṣofin ile naa pe awọn ti ṣawari irufẹ ẹyà kokoro àrùn Covid-19 mi ti a máa yara tan ka.
Ariwo ipaniyan, ijinigbe nihin lọhun atawọn wahala to n da silẹ n kọ ni lominu lorilẹede Naijiria.
Alaga awọn gomina PDP, Seriake Dickson ti ipinlẹ Bayelsa lo sọrọ naa fawọn akọroyin l'Abuja lọjọ Ẹti.
o ni ti bá wo bó ṣe yí ìgbésí ayé Toyin Abraham padà sí rere báyìí, yàtọ̀ sí ipò aláìní tó wà tẹ́lẹ̀.
Mo dúró lórí òdodo mi láìyẹsẹ̀,ọkàn mi kò ní dá mi lẹ́bi,títí n óo fi kú.
Sibẹ, ẹni tí ó kéré jù lọ ní ìjọba Ọlọrun jù ú lọ.
” Urimu bá mú Jonatani ati Saulu, 
Jẹ́ onísùúrù; máa ronújinlẹ̀; wà ní ìwọ̀ntún-wọ̀nsì; ní sùúrù, ìgbàgbọ́, ìrètí àti ìfẹ́ aláìlẹ́gbẹ́.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Blood donation: Kíni àwọn èrò àti ìgbàgbọ́ tí kò tọ̀nà lórí ẹjẹ́?
’ Bí ọba bá bèèrè irú ìbéèrè yìí, sọ fún un pé, ‘Wọ́n ti pa Uraya, ọ̀kan ninu àwọn ọ̀gágun rẹ̀ pẹlu.
Kámáparọ́, nínú ìrìnàjò kékeré lọ sí Shamakhi, n kò rò ó tì tẹ́lẹ̀ pé n ó ṣe àlábàpáàdé Ìyá àgbà Saray.
O gbadura pe ki ọba orin ko maa sun lọ laya Olugbala.
Awon obinrin ile Africa sami ayeye ayajo ojo awon obinrin lagbaye lojo-Bo, pelu ileri sise adinku aidogba tako-tabo, nipa fifi aye gba awon obinrin lati kopa ninu eto oselu ati awon ona miiran.
Ẹwẹ, nigba ti BBC kan si alukoro ile iṣẹ ọlọpaa, Frank Mba lati fi aridaju ọrọ yii lelẹ, ọgbẹni Frank ni iroyin naa ko tẹ oun leti di akoko ti a n sọrọ.
"Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Wo ìdí tí àwọn orílẹ̀èdè fi ń dẹwọ òfin kónílé-ó-gbélé Coronavirus Nígbà tó ń sọ̀rọ̀ lórí bí ọ̀pọ̀lọpọ̀ ìdílé àwọn osere tíátà ṣe máa ń tètè dàrú, Jelili Oniso ṣàlàyé pé, ""ẹni tí yóò bá jẹ ọkọ àbí ìyàwó gbajumọ gbọdọ ni ìfaradà púpọ̀ nítorí tí gbogbo ayé ni ọkọ àti aya tó ń pè ní tiẹ̀ nìkan, kí wọn sì máa bẹ Ọlọ́run pé kí onitohun má sìṣe ."
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Sunday Igboho: Òǹyẹ̀ kankan kò lè yẹ àgbékalẹ̀ Amotekun nílẹ̀ Yorùbá 12 Èrèlè 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 29 Owewe 2020 Oríṣun àwòrán, Instagram/sunday_igboho Ilumọọka olokoowo ati ajafẹtọ awujọ, Oloye Sunday Adeyemo, ti ọpọ eeyan mọ si Sunday Igboho, ti woye pe onyẹ kankan ko le yẹ ikọ alaabo Amotekun.
Ìtàn nípa bí wọ́n ṣe fẹ́ sá kúrò Bí wọ́n ṣe ju ọ̀pọ̀ sínú ọkọ ti wọ́n gbé wá ní wọn ni ki àwọn kan máa fí ọwọ́ kọ́ àra wọn lọ́rùn.
Alhaji Lai Mohammed wa rs awọn ọmọ orilẹede Naijiria lati maa woye gbogbo iroyin ti wọn ba n ri gba lori ayelujara nitori oye lagba n wo.
“ ‘Dá idà náà pada sinu àkọ̀ rẹ̀.
Èmi ni mo ni ààyè ọmọ, òkú ọmọ ni tìrẹ.
Ọkunrin naa, George Kotini Hezron n pada sile rẹ lọjọ buruku, eṣu gbomimu ọhun, lẹyin to ṣe faaji tan nile ọti.
Arẹgbẹ́sọla yan olori osisẹ tuntun Gómìnà ìpínlẹ̀ Ọsun Ọgbẹ́ni Rauf Aregbẹsọla ti yan Ọgbẹ́ni Abdulrasak Salinsile gẹ́gẹ́ bí olorí àwọn oṣiṣẹ ní ile ìjọba ìpínlẹ̀ náà.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Nikesuliat: Ọ̀dọ́mọdébìnrin akéwì tó n fi ẹ̀ṣà kìlọ̀ ìwá lásìkò yìí Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
De Klerk, ti o je omo odun mejidinlaadorun ,ti o si je alawo funfun  ni o gba ami idanilola pelu eni ti o gba ipo lowo re ,oloogbe Nelson Mandela lodun 1993, fun ayipada ijoba latowo alawo funfun si owo alawodudu, ti o si fopin si ija eleyameya.
Sugbọn ṣa, pe ile aṣofin buwọlu aba owo osu naa, ko ti i tumọ si pe yoo di sisan, nitori pe ile asofin mejeeji gbọdọ fi ohun ṣọkan lori rẹ, ki wọn to o gbe pada si ọdọ aarẹ.
Oun ni Ọmọwe akọkọ ti yoo jẹ Soun ti Ogbomoṣo ṣugbọn nigba to di ọdun 1969.
ẹwẹ, o ṣalaye wipe o jọ bii pe obinrin to ni ileeṣẹ foyungbowo ọhun ni nọmba wọn lọwọ lo ṣe ri wọn pe pada ti awọn ọmọ naa fi salọ sọdọ rẹ.
Arsenal naa ta ọmi ayo kọọkan pẹlu ikọ agbabọọlu Brighton ni papa iṣere Emirates, eleyi to tumọ si pe wọn ko le de ipo kẹrin mọ lori tabili idije Premier League fun saa yii.
Ẹ ṣe oun to tọ'' Eeyan kan tilẹ sọ pe iṣẹ nla ni wọn yoo ṣe lati le j ki awọn eeyan ṣa idọti ti wọn ba ju silẹ.
Igbesẹ yi ko ṣẹyin iroyin iwadii kan ti ile iṣẹ BBC gbe jade lori ifipabanilopo lati le fi gba maaki eleyi to ṣafihan Pasito Boniface nibi ti o ti n hu iwa aitọ si akẹkọbinrin kan.
" kí o tó ni ààrùn naa, a jẹ́ pé olúwa rẹ̀ ti koju àwọn kòkòrò tó tó iye èyí tó le fún ènìyàn ni ààrùn náà, pẹ̀lú àwọn ìmọ̀ nípa MERS àti SARS, ìgbàgbọ́ ni pé o gbọ́dọ̀ tó ìwọ̀n ẹgbẹ̀rún kan kòkòrò naa ti yóò wọ àgọ́ ara ki èèyàn to le ni ààrùn naa gẹ́gẹ́ bo se ko sójú òpó ayélujára rẹ̀.
Awon ile-ise to tun pegede naa
Koda gbogbo oju ọna to so ilu Beira papọ mọ awujọ agbaye lo ti bajẹ patapata, sugbọn eto irinna ofurufu ti bẹrẹ pada.
Nítorí pé n óo lé àwọn orílẹ̀-èdè jáde fún yín, n óo sì fẹ ààlà yín sẹ́yìn.
ipaniyan ni ipinle Benue ati Taraba .
O tun wa ro ijoba ipinle naa lati san owo osu mefa ti won n je awon osise eleto ilera.
O ni yala ti wọn pa tabi fi gbowo gọbọi kii ṣe kekere eyi ti iwadii awọn si ti fihan pe awọn to n ṣe iṣẹ yii lọpọ igba maa n fara sinko si Gaa awọn Fulani kaakiri ti wọn kii sii foju wọn han sita.
Nígbà tí a dé ibẹ̀ iná kan bẹ̀rẹ̀ sí jó nínú ibi tí ọkùnrin yìí wà, ó si ń jó o, ọkùnrin náà sì bẹ̀rẹ̀ sí kígbe lẹ́ẹ̀kọ̀ọ̀kan ó ń gbin, ó ń pòṣé, gbogbo àyíká ọ̀dọ̀ rẹ̀ sì mú kí ilé Ikú ba ni lẹ́rù gidigidi.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Bode George: òòtọ́ ni ìkìlọ̀ Obasanjọ ati Soyinka Kante ati Giroud pẹlu awọn agbabọọlu mọkanla lo kọkọ side ifẹsẹwọnsẹ fun ikọ Chelsea, nigba ti Aubameyang ati Lacazette yoo ma a gba fun Arsenal gẹgẹ bi agbabọọlu mọkanla akọkọ.
Jesu wá sọ fún wọn pé, “Ẹ ṣọ́ra, kí ẹ sì ṣe gáfárà fún ìwúkàrà àwọn Farisi ati àwọn Sadusi.
Dafidi dáhùn pé, “Ǹjẹ́ ìwọ kọ́ ni alágbára jùlọ ní Israẹli?
Ọ̀pá ìdábùú ìlẹ̀kùn rẹ̀ yóo jẹ́ irin ati idẹ,bí iye ọjọ́ orí rẹ̀ bá ti tó, bẹ́ẹ̀ ni agbára rẹ̀ yóo pọ̀ tó.
Àrùn parkinson jẹ ́ ààrùn ọpọlọ tí ó ní ṣe pẹ ̀ lú ẹ ̀ yà ọpọlọ tí ó rọ ̀ mọ ́ bí ènìyàn ṣe ń rìn .
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Buns ni ọmọ mi jẹ tán ní ṣọ́ọ̀ṣì, ló bá di àwátì' O ni igbakeji pasitọ, awọn aṣọna ṣọọṣi lẹyọ kọọkan ati awọn obi ọmọ naa bura ni ọkọọkan wi pe awọn ko mọ owo mọ ẹsẹ si iṣẹlẹ naa.
N kò fi tipátipá mu yín rúbọ,bẹ́ẹ̀ ni n kò sọ pé dandan ni kí ẹ mú turari wá.
Àwọn ọmọ tí o bí ní àkókò ìgbèkùn rẹyóo sọ ní etígbọ̀ọ́ rẹ pé,‘Ibí yìí kéré jù fún wa,fún wa ní àyè sí i láti máa gbé.
Bloomberg da ẹgbẹ oṣelu ara rẹ ṣe laarin ọdun 2007 si 2018.
OLUWA rán Jeremaya níṣẹ́, ó ní 
Ẹnikẹ́ni kò ì tíì gbọ́ ohùn rẹ̀ rí, bẹ́ẹ̀ ni ẹnikẹ́ni kò rí i bí ó ti rí rí.
ati awon ohun mayederun lorile ede Naijiria kuro.
Nígbà gbogbo ni nǹkan ń dára fún un.
to wa lori eto aabo ni ekun Ariwa, ki o to di nnkan miiran.
” Ó sì fi kún un pé òun kò ní fi dù ú.
“Saulu ati Jonatani,àyànfẹ́ ati eniyan rere,wọn kì í ya ara wọn nígbà ayé wọn,nígbà tí ikú sì dé,wọn kò ya ara wọn.
kí ó lè sinmi lọ́wọ́ ọjọ́ ìṣòro,títí tí a ó fi gbẹ́ kòtò fún eniyan burúkú.
Ó ti pẹ́ tí wọ́n ti mọ̀ mí.
Má jẹ́ kí ẹwà rẹ̀ wù ọ́,má sì ṣe jẹ́ kí ó fi ìpéǹpéjú rẹ̀ mú ọ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ondo Kidnap: Ọlọ́pàá Ondo ní àwọn ti rí ẹníkan padà nínú mẹ́jọ tí wọ́n ń wà nínú ọkọ̀ 27 Òkùdu 2020 Oríṣun àwòrán, Others Àkọlé àwòrán, Iléeṣẹ́ Ọlọ́pàá ní ìpínlẹ̀ Ondo ti fi ìdí ẹ̀ múlẹ̀ pé lóòtọ́ ní àwọn ajínigbé gbé àwọn arìnrìnàjò láti Abuja sí Eko lọ.
Aarẹ ni oun ti ṣalaye idi ti wọn fi gbe awọn ẹnubode naa ti pa, bẹẹni nisisiyi to dabi ẹni pe awọn orilẹede to mule ti wa ti mọ pataki ohun ti a fẹ bayiisaid, a ti n wo igbesẹ ati ṣii pada."
 wón wà ní apá àríwá ààrin gbùngbùn aáfíríkà lati apá ìlà oòrùn nàìjíríà títí dé ìwò oòrùn sùdáànù .
“Nítorí náà, ẹ ṣọ́ra gidigidi, níwọ̀n ìgbà tí ẹ kò rí ìrísí OLUWA ní ọjọ́ tí ó ba yín sọ̀rọ̀ láàrin iná ní Horebu, 
Labani bá dá Jakọbu lóhùn, ó ní, “Èmi ni mo ni àwọn ọmọbinrin wọnyi, tèmi sì ni àwọn ọmọ wọnyi pẹlu, èmi náà ni mo ni àwọn agbo ẹran, àní gbogbo ohun tí ò ń wò wọnyi, èmi tí mo ni wọ́n nìyí.
Oríṣun àwòrán, @Bashir Ahmad Àkọlé àwòrán, Aarẹ Buhari ati adele ọga ọlọpaa Adamu Ti ọga ọlọpaa Idris ba fẹyinti loni, Abubakar Adamu Mohammed ni a gbọ pe Aarẹ Buhari yoo kede gẹgẹ bi ọga ọlọpaa tuntun.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Egypt gbalejo AFCON 2019 Agbabọọlu Liverpool, Mo Salah fẹẹ gba goolu keji wọle sawọn ṣugbọn Edmore Sibanda to jẹ aṣọle Zimbabwe sọ pe oni kọ.
" Ilé iṣẹ́ ọlọ́pàá ti bẹ̀rẹ̀ ìwádìí sí ọ̀rọ̀ Sẹ́nétọ̀ Abbo Ọwọ́ mi mọ́ lórí eto Gàá darandaran, RUGA- Goodluck Jonathan Àwọn ìbejì yabo Igbó Ọrà fọ́dún ìbejì lágbàáyé Àwọn arẹwà obinrin Yollywood, tá ló mọ iṣẹ́ rẹ̀ jù?
“Ni bayii a ti bere ijiroro sugbon a ko ti fenuko sibi kan.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Sextuplet: Àdúrà Ìbùkún ló kú lẹ́yìn ọmọ mẹ́fà yìí- Ifeoma Thelma àti Onyemaechi Chiaka Kini Fasiti UNILAG ri si eto iyọninipo Ogundipe?
Ẹ ̀ kọ ́ nípa àwùjọ-ẹ ̀ dá jẹ ́ ẹ ̀ kọ ́ kan pàtàkì tí kò ṣe é fọwọ ́ rọ ́ sẹ ́ yìn .
Bakanna lo ni awọn ipinlẹ ti arun naa ti rinlẹ julọ ni Edo, Ondo, ati Ebonyi.
 Ǹjẹ́ ẹ rántí ìtàn yìí nínú ọ̀kan lára àwọn ìwé tí a kà ni ọdún díè sẹ́yìn.
Ṣùgbọ́n nígbà tí ó ṣe díẹ̀ ti eṣinṣin kan bà le oju egbó bàbá mi kékeré kan, ojú ẹsẹ̀ tí ó fi ya igi ní ìgbà ìjà Èṣù-kékeré-òde, ti bàbá mi sì lé eṣinṣin náà kúrò ṣe ni eṣinṣin yí padà tí ó di ejò tí ó bẹ̀rẹ̀ sí lọ́ mọ́ ọn ní ẹsẹ̀, tí bàbá mi si niláti máa sáré kiri.
CAMEROON: Oṣu mẹta ni orilẹ ede yii naa fun gbigbelu awọn ọmọ Naijiria lai gba iwe Aṣẹ igbelu orilẹ ede naa.
Ìfipá gba maersk alabama jẹ ́ àtẹ ̀ léra ìṣẹ ̀ lẹ ̀ orí omi tì ó bẹ ̀ rẹ ̀ pẹ ̀ lú àwọn ajalèlókun merin tí wọ ́ n fi ipá gba ọkọ ̀ ojú omi ẹ ̀ lẹ ́ rù , mv maersk alabama ogòjílénírinwó máìlí ( 440 km ; 280 mi ) gúúsù-ìlàoòrùn eyl , somalia .
Ẹni to bori: Morocco Kenya vs Zimbabwe.
Ni Ile Gẹẹsi, ida eniyan 41 lo gba ti Trump, ida 31 ni Ilẹ Faranse ati ida 26 lorilẹede Germany.
Dafidi dá a lóhùn pé, bí ó bá rí bẹ́ẹ̀ dúró níhìn-ín títí di ọ̀la, n óo sì rán ọ pada.
Akọṣẹ-mọṣẹ nipa ounjẹ jijẹ to tun jẹ nọọsi, Adanna Monday ni o ṣe pataki ki onikaluku maa se ounjẹ to ba fẹ jẹ fun ra rẹ.
N óo sọ ẹran ara rẹ̀ káàkiri sí orí àwọn òkè.
Méjì nínú èròjà mẹta tí mo rí náà, wá lara awon èròjà tí àjọ Nafdac tí fi ọwọ si ṣáájú, pé ó dára fún lilo àwọn èèyàn."
Lẹ́yìn ọdún keji tí àìsàn náà tí ń ṣe é, ìfun rẹ̀ tú síta, ó sì kú ninu ọpọlọpọ ìrora.
Ọpọ awọn osere tiata yii lo n para poro nipa awọn isẹlẹ iwa ipa to n waye lemọlemọ laarin lọkọ laye, ti wọn si n kilọ fun tọkunrin-tobinrin lati sọrase.
Ọdọọdun ni ipade adura naa, ti wọn pe ni 'Emerge2020' maa n waye ni gbagede Tafawa Balewa Square nilu Eko.
Alhaji Adio ni, lati kekere loun ti n gbọ awo orin ti Barrister ti kọ wéré, ko to maa kọ orin Fuji.
Osinbajo  ti dibo  wọn ni Victoria
Àwọn orílẹ̀-èdè tí wọ́n wà ní àyíká yín yóo wá mọ̀ nígbà náà pé èmi OLUWA ni mo tún àwọn ibùgbé yín tí ó wó lulẹ̀ kọ́, tí mo sì tún gbin nǹkan ọ̀gbìn sí ilẹ̀ yín tí ó di igbó.
Lórí rẹ̀ ni wọ́n ń kó àwọn ohun tí wọ́n fi ń pa ẹran ẹbọ sísun ati ti ẹbọ yòókù sí.
Ogunlogo awon elesin Islam lati abule Kafr al-Waslin kolu ile-ijosin kan leyin adura jimo ojo-Eti lojo kejilelogun osu kejila, ninu eyi ti won fo gbogbo ferese, bakan naa ni won ba gbogbo nnkan ti o wa ninu ile-ijosin naa je.
Ẹ rí i pé ó ṣe olóòótọ́ sí Ọlọrun tí ó yàn án gẹ́gẹ́ bí Mose ti ṣe oloòótọ́ ninu gbogbo ìdílé Ọlọrun.
láti gbọ́ ìkérora àwọn ìgbèkùn,ati láti dá àwọn tí a dájọ́ ikú fún sílẹ̀.
Amọṣa, awọn alaṣẹ igbimọ apapọ lori gbigbogun ti arun coronavirus ti ke gbajare sita pe awọn eeyan ko tẹle ofin yii.
Ni ọdun 2007 ni Alhaja Aminat Abiọdun gun ori oye iyalode ilẹ Ibadan, lẹyin iku Iyalode to gbesẹ, Oloye Wuraọla Akintọla.
 revels , to wa bakanna lati mississippi , ni omo afrika amerika to soju ni kongresi u.
Ìjábọ àwọn òṣìṣẹ́ nípà ẹyàmẹya: Mọ̀ nípa bí BBC ṣe ń ṣisẹ́ láti túbọ̀ mú ìwúri ba gbogbo ẹ̀yá, ẹsin àti àwọ̀ BBC's Equality Information Report.
European Union (EU )pelu iranwo awon egbe ti  ki i se ti ijoba (Voluntary Returnees ,AVR) lo
Ó lọ sí ilé ìwé abeokuta grammar school , ó sì kẹ ́ kọ ́ sí ní orílẹ ̀ èdè england .
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ṣé lóòtọ́ ní agbára àti ipá àwọn ọmọ ogun Iran tó ó kojú tí America?
Àlàó kò gbọ́ nípa ẹni tí ó ń fi kọ́kọ́rọ́ dán séèfù wò nítorí pé ó lọ sí ibì òkú ìyá Báyọ̀ ní ọjọ́ náà.
Minisita ṣalaye pe idi ti ijọba fi gbe igbesẹ yii ni pe awọn ajọ idanwo ko wa lati maa pa wo wọle fun ijọba.
Bi ọrọ ṣe jẹ wa ninu fidio yii.
ati gbogbo àwọn ọba Tire, ati àwọn ọba Sidoni, ati gbogbo àwọn ọba erékùṣù tí ó wà ní òdìkejì òkun.
Bí mo bá lọ pèsè àyè sílẹ̀ dè yín, n óo tún pada wá láti mu yín lọ sọ́dọ̀ ara mi, kí ẹ lè wà níbi tí èmi pàápàá bá wà.
oṣu kẹsan an, ọdun 2020, eeyan eeyan ojilelugba o din ẹyọ kan lo tun ṣẹṣẹ ko aarun naa ti eeyan mẹwaa si jade laye lorilẹede Naijiria.
Àwọn ọmọ Israẹli tí wọ́n jáde láti ilẹ̀ Ijipti nìwọ̀nyí:
Awọn ọlọpaa ni agbegbe Allen lo n gbe ni Dallas.
Ṣugbọn o jẹ ohun iyalẹnu pe ọra lasan ni awọn to n ṣeṭoju alaisan fi n dabo bo ara wọn, fun nnkan bi wakati mẹtala ti wọn n lo lẹnu iṣẹ.
Igbakeji rẹ, Ibrahim Lamorde lo si gba ipo rẹ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Tunde Ednut: Ìdí mẹ́fà rèé tí Instagram, Facebook le fi wọ́gilé ojú òpó ìkànsíraẹni rẹ 13 Sẹ́rẹ́ 2021 Oríṣun àwòrán, Tunde ednut Ọpọlọpọ igba ni awọn alaṣẹ oju opo ikansiraẹni lori ayelujara ma n gbegile awọn oju opo awọn eniyan laimọ nkan ti wọn ṣe lai dara, ki wọn to gbegile oju opo wọn.
O ni ọpọlọpọ arinrinajo miliọnu mẹtadinlogun to rin ni ọdun to kọja ni papakọ ofurufu Naijiria, Abuja ati Eko ni wọn ti rinrin ajọ.
'Kaka ki o kin mi lẹyin lori sisọ ẹgbẹ wa ji pada, ni ṣe ni o duro gẹgẹ bi adina si erongba wa.
oríṣìíríṣìí ni àwọn ohun èlò tí àwọn babaláwo fi í da ifá ikin ifá ni àdáyéná nínú wọ ́ n .
Ó p'ọ́dún méjì tí Keshi kú Àwọn Afíríkà mẹ́tà to ṣe bẹbẹ nínú EPL sáà 2018/2019 Ninu iwe ti wọn fi ranṣẹ si aarẹ AFN, Ibrahim Gusau ti oludari agba IAAF, Jee Isram fọwọ si, o ni lọfan ni wọn ti kan si AFN nigba ti aṣiṣe naa waye lọjọ kejidinlogun oṣu kẹta ọdun 2018 pe ki wọn da ẹgbẹrun lọna aadoje dollar ($130,000) pada ninu ẹgbẹrun lọna ọgọjọ ($150,000) ti wọn ṣeesi fi ranṣẹ si wọn pada.
 nígbà tí àwon wònyí tún wúlò níbò mìíràn , a fẹ yán an pé kìí ṣe gbogbo àwọn ẹ ̀ pọ ́ n ló jẹ ́ wọ ̀ fún .
Nigba to n ṣafihan fọnran kan niwaju igbimọ igbẹjọ naa lori bi awọn janduku ṣe kogun ba aafin ọba Akiolu, ọga agba ologun to n ṣalaye ọrọ lorukọ ileeṣẹ ogun Naijiria, Brigadier Taiwo ni ọpẹlọpẹ awọn ni idile ọba fi bọ lọwọ awọn janduku.
Kaduna Rape: Wọ́n rí òkú ọmọ ọdún mẹ́fà tí wọ́n fipá bálopọ̀ nínú mọ́ṣálàáṣí
Agbebọn pa eeyan 35 ni Zamfara Ọwọ́ pálábá ségi fún gbajúgbajà olè méjì tó ń ṣọṣẹ́ lọ́wọ́ l‘Eko Olè gbé òrùka ìgbéyàwó mì ní Eko Olè wọ ilégbèé obìnrin ní fásitì Ibadan, àkẹ́kọ̀ọ́ méjì farapa Wọn ni Rabiu ji awọn nkan wọnyii nile itaja kan ni agbegbe Abule Egba lọjọ kẹrindinlogun, oṣu kẹjọ ọdun yii.
Naijiria fagba han orile ede Cameroon pelu ami ayo meta si meji(3-2)  ninu idije to waye laarin orile ede mejeeji
Amoju-ẹrọ Olaniyan ni awọn oloṣelu kan, ti wọn n wa oju rere Gómìnà ipinlẹ Oyo lo wa nidi ọrọ naa.
Lẹ́yìn náà, ó yipada, ó wọn ìhà àríwá, ó jẹ́ ẹẹdẹgbẹta (500) igbọnwọ (mita 250), gẹ́gẹ́ bí ọ̀pá rẹ̀.
Ninu oṣu Kejila bakan naa, ni ileeṣẹ ọlọpaa sọ pe ọwọ tẹ mẹrinlelogun lara awọn ọmọ ẹgbẹ naa ni Mosafejo, l'agbegbe Oshodi nilu nipinlẹ Eko.
Nítorí iṣẹ́ burúkú wọn, n óo lé wọn jáde ní ilé mi.
Àwọn eniyan mi, Israẹli, ni n óo lò láti gbẹ̀san lára Edomu.
Looto ni pe wọn n se iwadi ẹsun ti wọn fi kan Fayose sugbọn eyi ko tumọ si wi pe yoo wa fẹsẹ fẹ.
Igbesẹ yii waye lẹyin ọjọ melo kan ti awọn aṣofin n beere pe ki lode ti ikọ Boko Haram atawọn janduku mii n fi ẹrọ ibanisọrọ ṣe iṣẹ aburu ti ijọba ko si ri wọn mu.
Dájú, ohun mímọ́ ni Òfin, àwọn àṣẹ tí ó wà ninu rẹ̀ náà sì jẹ́ ohun mímọ́, ohun tí ó tọ́, tí ó sì dára.
" owo fun iko hubble bere sini je kikojo ni ewadun 1970s , pelu ireti pe yio gbera ni 1983 , sugbon o ku seyin nitori isoro isise , inawo ati ijamba "" challenger "" ."
Àwọn wolii yóo di àgbá òfo;nítorí kò sí ọ̀rọ̀ OLUWA ninu wọn.
Donald Trump ti gúnlẹ̀ sí UK fún àbẹ̀wò ọlọ́jọ́ mẹ́ta
Àwọn ọmọ ogun Israẹli tí Amasaya dá pada, tí kò jẹ́ kí wọ́n tẹ̀lé òun lọ sógun bá lọ, wọ́n kọlu àwọn ìlú Juda láti Samaria títí dé Beti Horoni.
isakoso orile ede yii lee tubo fese mule sii.
Àwọn alufaa tí wọ́n tẹ̀lé wọn ni Eliṣama ati Jehoramu.
Wọ́n wí fún un pé, “Àwa lè ṣe é.
Apapo iko onise-akanse naa yoo se osuwon iye owo ati bi won yoo se maa pin ilana ti iko ohun la kale fun awon ti oro kan.
Ondo Assembly: Ejò da ìjókòó ilé rú , l'àwọn aṣòfin bá fẹsẹ̀ fẹ
Bi o tilẹ jẹ pe ọpọlọpọ wọn ko ni ayẹsi nibi ayẹyẹ, awa yoo ṣe afihan diẹ lara awọn ọmọ orilẹede yi paapa julọ awọn ti wọn je ọmọ kaaro o jiire ti wọn nṣe gudugudu meje yaya mẹfa ni Hollywood.
Ẹni to bori: Tanzania Madagascar vs Egypt.
"*""Ìfórísánpọ́n ètò- ẹ̀kọ́ ni ìfórísánpọ́n orílẹ̀-èdè."
Akọwe agba fasiti naa, Ọgbẹni Oladejo Azeez lo fi atẹjade kan sita pe igbimọ alaṣẹ fasiti UNILAG ti yẹ aga mọ Ọjọgbọn Ogundipe nidi.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ko si ilẹ riri, iji lile tabi ikun omi to lee bi afara naa wo Gẹgẹ bi awọn to wa nidi kikọ rẹ ṣe sọ, oṣiṣẹ mejidinlogun lo padanu ẹmi wọn sori kikọ afara naa.
Nígbà tí a jẹun tán, mo ṣe àkíyàsí pé gbogbo ẹni tí ó jẹun ni ó yó pátápátá, ṣùgbọ́n oúnjẹ kò ṣẹ́kù sínú àwo ẹnikẹ́ni.
" Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ajé ò!
Kò rí ìparun ninu Jakọbu,bẹ́ẹ̀ ni kò rí ìpọ́njú níwájú Israẹli.
Lẹyin ajalu gbogbo ohun to pàdánù, Rolling Dollar to ni ọmọ mẹẹdogun láti ọwọ obinrin mẹrin tun foju sọkún marun ninu awọn ọmọ rẹ to fi mọ àwọn iya wọn nitori ìṣẹ́ àti àìsàn.
Kódà, ní àwọn orílẹ̀èdè tó lajú dáadáa, àwọn òfìn kọ̀ọ̀kan wà láti mú ìrọ̀rùn bá àwọn àkàndá ẹ̀dá bí àwọn afọ́jú.
Mr Jeremy wo iwe Guiness Book of World Records gẹgẹ bi ọkunrin to kopa julọ ninu filmu to n safihan ibalopọ, iyẹn ''Blue Film'', ti wọn si ṣe fiimu Porn Star: The Legend of Ron Jeremy fun ni ọdun 2001 lati sọ itan aye rẹ.
Bóò ṣe lè yẹra fún ikú nígbà òjò - Onímọ̀ Ehi Iden 'À ń bẹ Ààrẹ Buhari kó pèsè ààbò fún àwa ọ̀dọ́bìnrin' #U20WC: Flying Eagles fìyà ṣínu ààwẹ̀ lórílẹ́èdè Poland Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Àgbà ni Obasanjo, oun tó ń sọ yé e, ìjọba ni kó tají - Wale oke O ni bi ọlọkada naa ṣe lọ lari mọ ibi iho naa ti arabinrin to gbe si ko sinu rẹ niyẹn, wọn si kilọ fun un ṣugbọn boya o ti mọ bo ṣe n gba na yii tẹlẹ""."
O wa pe gbogbo ẹbun owo to wọle latọdọ awọn Aladani, ileeṣẹ ati ajọ pọ soju kan pe o jẹ N1.
Kí alufaa máa kó igi sí i ní àràárọ̀; kí ó máa to ẹbọ sísun lé e lórí, orí rẹ̀ ni yóo sì ti máa sun ọ̀rá ẹran tí ó bá fi rú ẹbọ alaafia.
Ninu ọrọ ti Ismail Omipidan, agbẹnusọ fun Gomina Gboyega Oyetola fi sita loju opo Facebook rẹ, o ni awọn eeyan kan ti ọwọ tẹ lo ti n gba idanilẹkọ nipa didaabo bo ara wọn lasiko Covid 19.
Olódùmarè kò ní jẹ́, kí o wọ ẹ̀wọ̀n lọ́sàn-án gangan.
Nítorí ó dá mi lójú bẹ́ẹ̀ ni mo ṣe fẹ́ kọ́kọ́ wá sọ́dọ̀ yín, kí ayọ̀ yín lè di ìlọ́po meji.
Jehoṣafati bá bẹ̀rẹ̀ sí kígbe, OLUWA sì gbà á sílẹ̀ lọ́wọ́ àwọn ọ̀tá.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ekiti: Ìtumọ̀ Pelúpelú nínú òyè ọba jíjẹ ní ìpínlẹ̀ Ekiti àti ìpele tí àwọn ọba pín sí 18 Ẹrẹ̀nà 2020 Oríṣun àwòrán, @iam_ademuyiwa Itan oye awọn lọbalọba l'Ekiti ti a mọ si Pelupelu bẹrẹ lẹyin ti ogun Kiriji pari lọdun 1886.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù US election results: Wo ìdí márùn-ún tí Biden fi bórí nínú ìdìbò ààrẹ America 3 Bélú 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 8 Bélú 2020 Oríṣun àwòrán, Getty Images Lẹyin bi aadọta ọdun to ti lo nipo iṣakoso, to si ti n dafun tolo si ipo aarẹ America, ọwọ Jmoe Biden ti tẹ nkan to n wa.
Yoruba: Báwo lo ṣe gbọ́ èdè rẹ sí?
3 93577 Orilẹede Guatemala 4250 24.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ayinla Kollington: ọ̀rẹ́ ni èmí àti Barrister kó tó jáde láyé Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Àìsàn jẹ́ kí àwọ̀ ara Amida dàbí ara ẹja Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Iṣimaeli ọmọ rẹ̀ jẹ́ ọmọ ọdún mẹtala nígbà tí òun náà kọlà abẹ́.
Ipade apero apapo awon minisita naa waye keyin ni odun 2009.
Ìbẹ̀rùbojo gba ọkàn àwọn olùgbé Eko àti Ogun nítorí adágún omi Ọ̀yan tí yóò di ṣíṣí láìpẹ́ Bàbá ẹni ọdún 61 bá ọmọ rẹ̀ lopọ̀, ó fún un lóyún l'Eko Ṣé ó leè jẹ́ ilẹ̀ tí Makinde kò jẹ́ kí Florence Ajimobi gbà ló ń bi nínú?
Nígbà náà ni Solomoni ọba dáhùn, ó ní, “Ekinni keji yín ń wí pé, òun kọ́ ni òun ni òkú ọmọ, ààyè ni tòun.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù IAAF'S $130,000: Ọ̀gọ̀ọ̀rọ̀ èèyàn lórí ayélujára f'èébú ṣe Sunday fún Dalung 26 Èbibi 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 27 Èbibi 2019 Oríṣun àwòrán, Facebook/Solomon Dalung Àkọlé àwòrán, Owo ajọ IAAF Ayelujara n gbona girigiri lori ọrọ ti minisita ọrọ ọdọ ati ere idaraya, Solomon Dalung.
Charlie Boy pè fún ìwádìí ìbò tó gbé gómìnà tuntun wọlé l‘Ọsun Aregbesọla lọ àmọ́ ọ̀pọ̀ isẹ́ rẹ̀ ń fọhùn síbẹ̀ l‘Ọ́sun Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Jide Kosọkọ: Isẹ́ tíátà yóò gòkè tíjọba bá gbówó kalẹ̀ láti seré Gbajugbaja olorin Fuji naa fikun ọrọ rẹ pe ijakunlẹ nigba miran maa n fihan wi pe, eniyan ẹlẹran ara ni oun, ati wi pe Ọlọrun nikan lo ju gbogbo ẹda lọ.
AfCFTA: Buhari gbe igbimọ kalẹ lori adehun okoowo ọfẹ
èso ọ̀pọ̀tọ́ gbígbẹ ati ìdì àjàrà meji.
Mo ti búra, n óo sì mú un ṣẹ,pé n óo máa pa òfin òdodo rẹ mọ́.
Ọkùnrin kan sálọ lẹ́yìn tó gbẹ̀mi ènìyàn mẹ́ta Láìpẹ́, ará ìlú rẹ ni ọlọ́pàá tí yóò máa ṣọ́ ìlú rẹ Ìdajì owó iṣẹ́ àgbàṣe ló ń padà sápò gómìnà àná àti aya rẹ̀ l‘Ọyọ - Seyi Makinde Ohun ti a gbọ ninu awọn iwe iroyin abẹle ni pe ko seeyan to ṣeṣe tabi ku ninu iṣẹlẹ naa.
Rọ́ àlá rẹ fún àwa iranṣẹ rẹ, a óo sì túmọ̀ rẹ̀.
"Awọn osisẹ ileesẹ eto ilera sọ fun wa pe ijọba pẹlu ileesẹ ọlọpa fẹ tanna wadi isẹlẹ naa siwaju ki wọn to fun awa ẹbi lasẹ lati lọ sin oku ọmọ wa pada.
 Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Awọn ọdọ Ondo fẹ̀họ́nù hàn lórí ìṣekúpani Funke Olakunrin Akọwe ijọba ipinlẹ Ondo, atawọn kọmiṣọna ni ipinlẹ Ondo ni wọn ba Aarẹ ana, Goodluck Jonathan kọwọrin."
Iṣẹlẹ yi waye ni ọjọ meji lẹyin ti ile kan dawo lEko l'Ọjọru nibi ti ogun eeyan ti padanu ẹmi wọn.
Jesu bá gbé ọwọ́ mejeeji lé e.
Ìsọníṣókí Àjọ elétò ìdìbò EC yóò kéde èsì ìbò ààrẹ Ghana láìpẹ́ Ọwọja arun Coronavirus n peleke si ni Naijiria Ọwọ́ ọlọ́pàá tẹ èèyàn méjì tó fẹ́ ṣ'èèrú pẹ̀lú ìwé ìdìbò ààrẹ Ghana Ààrẹ Akufo-Addo ati alátakò rẹ̀ Mahama ti dìbò níbi ìbò ààrẹ Ghana tó ń lọ lọ́wọ́ Ọ̀pọ̀ awọn olùdibò ló ti de si ibùdó ìdìbò Mo ṣèlérí láti rí sí ìrẹ́pọ̀ àti ìwòsàn Amẹ́ríkà - Joe Biden Wo ọkùnrin tó dáná sun ọ̀rẹ́bìnrin rẹ̀ torípé kó gbà látí jẹ́ aya rẹ̀ Biden la Trump mọ́lẹ̀ wọlé ìbò ààrẹ orílẹ̀-èdè Amẹ́ríkà Èèyàn márùn-ún kú nínú rògbòdìyàn tó wáyé lásìkò ìdìbò ní Ghana Jíjábọ̀ ohun tí ń lọ lọ́wọ́ Nípasẹ̀ Busayo James-Olufade, Olubusola Afolayan àti Joshua Adetunji Gbogbo àkókò tí a kọ jẹ́ ti UK Tí a fiṣọwọ́ ní 19:0119:01 Ìjọba ìpínlẹ̀ Ondo kéde òfin konile-o-gbele ní Ode ati Ishinigbo lẹ̀yìn rògbòdìyàn tó wáyé níbẹ̀ Ileesẹ ọlọpaa nipinlẹ Ondo to fidi isẹlẹ naa mulẹ ti wọ́n n gbe igbesẹ lati pe alaafia si agbegbe mejeeji naaKà Síwájú Síi next Article share tools Facebook Twitter ṢàpínlòView more share options Share this post Copy this linkKà síwájú síi nípa àwọn ìtọ́kasí wọ̀nyí.
Àkọlé àwòrán, Gomina ipinlẹ Kwara tuntun ati iyawo rẹ wọle.
Ará, mo fẹ́ ran yín létí ọ̀rọ̀ ìyìn rere tí mo fi waasu fun yín, tí ẹ gbà, tí ẹ sì bá dúró.
Wọ́n bá mú un lọ sí ẹnu ọ̀nà Ẹṣin, ní ààfin, wọ́n sì pa á sibẹ.
Alaga igbimọ amuṣẹya fun amojuto coronavirus ni Naijiria, Sani Mustapha, lo kede aṣẹ tuntun yii lọjọbọ.
“Èmi kò wá ọlá láti ọ̀dọ̀ eniyan.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ọmọ ogun Nàìjíríà bẹ̀rẹ̀ lílo 'Drone' láti gbógun tàwọn ajínigbé ni Ondo àti Ekiti Àfi ìgbà tí mo bọ́ sọ́wọ́ ọ̀tá mí nínú ìrìnàjò ìfẹ́- Roshan Wọn ta Tutu ni miliọnu pọun nilẹ Gẹẹsi Wo ǹkan mẹ́jọ tó yẹ kóo mọ̀ nípa Alex Badeh táwọn agbébọn pa Ogagun Lamidi ti ṣiṣẹ ni awọn ẹka iṣakoso ati ni oju ogun fun ọpọlọpọ ọdun.
Àwọn mẹrẹẹrin rí bákan náà, ó sì dàbí ìgbà tí àwọn àgbá náà wọnú ara wọn.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù EFCC: Nítorí ẹ̀sùn 419 laaṣe mú Naira Mailey àti ikọ̀ rẹ̀ 10 Èbibi 2019 Oríṣun àwòrán, EFCC Àkọlé àwòrán, Àjọ EFCC ti fi ẹ̀sùn píparó gba ọwọ́ lọ́wọ́ àwọn ènìyàn lọ́nà ẹ̀bùrú lórí ẹ̀rọ ayélujára kan gbajúgbajà olórin náà.
Nígbà tí ó di ọjọ́ kẹfa, wọ́n kó ìlọ́po meji, olukuluku kó ìwọ̀n Omeri meji meji.
Fayẹmi ni, ojuṣe awọn gomina ni lati rii daju wi pe eto aabo fi ẹsẹ mulẹ ni awọn ipinlẹ wọn, lai ṣe awawi kankan bi o ti n wu, ki o mọ.
Ohun tí ó mú wa ṣe bẹ́ẹ̀ ni pé ẹ̀rù ń bà wá pé, nígbà tí ó bá di ọjọ́ iwájú, àwọn ọmọ yín lè wí fún àwọn ọmọ wa pé, ‘Ọ̀rọ̀ OLUWA Ọlọrun Israẹli kò kàn yín.
20 fún abẹ ́ rẹ ́ kan .
O ni wọn tun le awọn kọmiṣọna meji miran, ati iyawo gomina tẹlẹri ni ipinlẹ ọhun, Alhaja Mutiat Ladoja, to jẹ iyawo ṣẹnatọ Lamidi Ladoja pada lẹnu ọna.
Wọ́n kọ́ ibi mímọ́ kan sí ọwọ́ ẹ̀yìn ilé ìsìn náà, inú ibi mímọ́ yìí ni wọ́n gbé Àpótí Ẹ̀rí OLUWA sí.
Ìgbìmọ̀ tó ga jù lọ tó ń gbọ́ ẹjọ́ ẹ̀sìn Islam lórílẹ̀èdè Nàìjíríà (NSCIA) ṣèbẹ̀wò sí adárí IMN, Ibraheem Zakzaky látìmọ́lé ní Abuja.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ambode sanwo ènìyàn 50 tó há sí Russia Nàìjíríà bá RCCG, ìyá Folu Adeboye yọ ayọ̀ 70 Ilé iṣẹ́ BBC ni Fayẹmi kọ́kọ́ bá sọ̀rọ̀ gẹ́gẹ́ bíi gómìnà tí Ekiti yàn Ìwádìí BBC: Àwọn ará Èkìtì ń sáré gba N4,000 sáájú ìbò Ife Ẹ̀yẹ Àgbáyé kó gbogbo ẹrù rẹ̀ lọ sí France!
A máa fún aláàárẹ̀ ní okun.
Ilé-Iṣẹ́ yìí sì ni àdéhùn tó ṣe é gbójúlé, tó sì fúnni ní ìfọ̀kànbalẹ̀.
Ogbeni Samuel Aruwa,oluranlowo gomina fun iroyin ati ikede lo soro yii ni ojo Aiku ni ipinle Kaduna.
Bakan náà, wọ́n ko le fi òfin de ọmọṣẹ Amotẹkun fún òhun kohun to ba ṣe lásìkò tó ba wà lẹ́nu iṣẹ́.
Kọmiṣọnna eto iṣuna Olasunbo Florence ni kọmiṣọnna tuntun eto inawo Kọmiṣọnna eto idajọ Amofin Ayinla Jawondo ni kọmiṣọnna eto idajọ nipinlẹ Kwara.
Kanú ti gbà àmì ẹ̀yẹ UEFA Champions League, ife ẹ̀yẹ̀ UEFA ó gba ife ẹ̀yẹ FA ní ẹ̀mẹtàa àti ọmọ ilẹ̀ Afirika tó mọ bọọlu gbá jùlọ, ó jẹ ọkan lára àwọn agbábọọlù tó gba Premiere League, àmì ẹ̀yẹ̀ Olympic Gold Medal.
OLUWA Ọlọrun ní, “Ọjọ́ ń bọ̀ tí n óo rán ìyàn sí ilẹ̀ náà; kì í ṣe ìyàn, oúnjẹ, tabi ti omi, ìran láti ọ̀dọ̀ OLUWA ni kò ní sí.
alaafia lasiko eto idibo gomina  to n bọ
akọ mààlúù kékeré kan ati àgbò kan, ọ̀dọ́ àgbò kan ọlọ́dún kan, fún ẹbọ sísun; 
Yàrá kan wà tí ìlẹ̀kùn rẹ̀ wà ninu ìloro ẹnu ọ̀nà, níbẹ̀ ni wọ́n tí ń fọ ẹran tí wọ́n bá fẹ́ fi rú ẹbọ sísun.
8% Gbigba bọọlu si oju ile 4 3 Gba bọọlu 10 8 kọna 10 1 Ṣẹ sofin 13 12 Awọn agbabọọlu ti wọn yan Awọn ti wọn o kọkọ bẹrẹ Nigeria 16 Akpeyi 22 Omeruo 6 Balogun 2 Ola Aina 20 Awaziem 4 Wilfred Ndidi 7 Musa 15 Simon 8 Peter Etebo 18 Iwobi 9 Ighalo Guinea 12 Koné 3 Issiaga Sylla 18 Dyrestam 5 Seka 6 Falette 10 Kamano 13 Cissé 4 Diawara 16 Traoré 8 Naby Keita 21 Kaba Awọn iyipada 78 Iwobi                                                                  down Chukwueze                                                              up 88 Ighalo                                                                  down Paul Onuachu                                                              up 94 Simon                                                                  down Kalu                                                              up 71 Naby Keita                                                                  down Lass                                                              up 73 Dyrestam                                                                  down Sidibé                                                              up 82 Kamano                                                                  down Koita                                                              up Awọn ti wọn paarọ 10 Mikel 5 Troost-Ekong 11 Onyekuru 19 Ogu 17 Kalu 21 Osimhen 23 Uzoho 1 Ezenwa 13 Chukwueze 14 Paul Onuachu 9 Kanté 2 Mohamed Yattara 7 Mohamed Camara 23 Fodé Camara 19 Koita 11 Idrissa Sylla 17 Fofana 20 Lass 1 Naby-Moussa Yattara 14 Sidibé 22 Aly Keita 15 Jeanvier Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Ọ̀kọ̀ọ̀kan ninu àwọn àkànpọ̀ igi náà ní ìkọ́ meji meji láti fi mú wọn pọ̀ mọ́ ara wọn, bẹ́ẹ̀ ni wọ́n ṣe gbogbo àwọn àkànpọ̀ igi àgọ́ náà.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Flying Eagles fàtòrì já ewé bọ̀wọ̀ fágbà 4-0 fún ikọ̀ Qatar 24 Èbibi 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Flying Eagles fàtòrì já ewé bọ̀wọ̀ fágbà 4-0 fún ikọ̀ Qatar Ikọ Flying Eagles orile-ede Naijiria ti jawe olubori ninu ifẹsẹwọnsẹ wọn akọkọ ninu idije fawọn ojẹwẹwẹ tọjọ ori wọn ko ju ogun ọdun lọ.
Omotola ni igbogun ti iwa ajẹbanu lawujọ ṣe pataki ṣugbọn ijọba gbọdọ rii wi pe awọn ọmọ Naijiria gbaye gbadun.
Nítorí òun ni wolii Aisaya sọ nípa rẹ̀ pé, “Ohùn ẹnìkan tí ó ń kígbe ninu aṣálẹ̀ pé,‘Ẹ la ọ̀nà tí OLUWA yóo gbà,ẹ ṣe é kí ó tọ́ fún un láti rìn.
Kí ló dé tí eniyan burúkú fi ń kẹ́gàn Ọlọrun,tí ó ń sọ lọ́kàn rẹ̀ pé, “Ọlọrun kò ní bi mí?
Oshiomole ṣe alaye ọrọ naa nibi asekagba ipolongo idibo ẹgbẹ oselu APC to waye lọjọ iṣẹgun, nilu Oṣogbo .
Ẹ dìde, ẹ kígbe lálẹ́,ní àkókò tí àwọn aṣọ́de ń bẹ̀rẹ̀ iṣẹ́!
Ẹ̀jẹ̀ Lọ́wọ̀–Ninu Rẹ̀ Ni Ẹ̀mí wà.
Eyi to tumọ si pe kii ṣe pe o finu-findọ gba lati ba dokita lo pọ.
Oṣojumikoro ṣe alaye wi pe wọn ṣaa lori ni ọna mẹta ọtọọtọ lẹyin ti wọn fi ipa baa loọ tan.
Aisha sọ̀rọ̀ náà lásìkò tó ń ṣepàdé pẹ̀lú àwọn obinrin kan ni ilé ijọba ní'lú Abuja lọ́jọ́ Abamẹta tí ó sì ń wá ìdáhùn si ọ̀nà ti ìjọba gbà pín owó ti wọ́n ń fún àwọn ìdíle tó tòṣì júlọ láwọn ìpínlẹ̀.
iko akoroyin yoo fun ile ise ọlọpaa ni atileyin to gbohunjẹ fẹgbẹ, gbawo bọ
Omotosho ní ǹkan ti ìjọba ń ṣe yìí kàn jẹ́ ọ̀nà láti fí gbogbo ǹkan to n lọ tó ará ilú léti ni.
Gbogbo awon ti ajere iwa odaran naa simo lori ni won san owo itanran: dida laasigbo sile, sise akoba fun isokan orile-ede ati jiji awon dukia ara-ilu ko, won le pejo kotemilorun bi won ba fe.
Lọ sọ fún wọn pé, kí wọ́n pada sinu àgọ́ wọn.
Àwọn ọmọ Bela nìwọ̀nyí: ìdílé Aridi ati ìdílé Naamani.
Ẹ si mọ pe ṣonṣo meji ni wọn ti ko gbọdọ fojurinju nitori ọkan ni lati tẹ fun ekeji ni.
Àwọn tí ó mọ̀ bí ara ọkunrin náà ti ṣe dá ròyìn ohun tí ó ṣẹlẹ̀ fún wọn.
Sugbọn ni ti Abubakar Bukola Saraki, Ọmọbọlanle ni a ba maa pee, nitori pe o ba ọla nile ni, to si dide lati inu ọla lọ si ipo giga.
"Loju iyawo Adio, o di pe ""agba ti ko lowo lọwọ, ti n fọn ni kaa, akọ aja lasan to n gbo ni""."
O fi kun un pe ọmọ orilẹede Amẹrika ni eeyan kan to ku ninu wọn ati pe kii ṣe ọkọ ofurufu loun ba wọ orilẹede Naijiria ni tirẹ.
Dafidi ọba ranṣẹ sí àwọn alufaa mejeeji: Sadoku, ati Abiatari, láti bèèrè lọ́wọ́ àwọn àgbààgbà Juda pé, “Kí ló dé tí ẹ fi níláti gbẹ́yìn ninu ètò àtidá ọba pada sí ààfin rẹ̀?
Bẹ́ẹ̀ ni ọkùnrin náà sọ, nígbà tí ó si dákẹ́ ọ̀rọ̀ rẹ̀ n kò rí i mọ́.
Àwọn Arabinrin Tí Wọ́n Jẹ́ Ẹlẹ́ṣẹ̀.
", ọ̀rọ̀ ìpínlẹ̀ Ọyọ àtàrí àjànàkú ni, àgbàlagbà bíi tèmi ló nílò""."
OLUWA ní,“Láti ìgbà èwe Moabu ni ó ti ń gbé pẹlu ìrọ̀rùn,kò tíì lọ sí ìgbèkùn rí.
Nítorí ó fẹ́ lati ọ̀dọ̀ mi pé kí òun lè mú àwọn ọkàn wá sí ọ̀dọ̀ mi, ṣùgbọ́n ìwọ nfẹ́ kí o lè yára wá sí ọ̀dọ̀ mi nínú ìjọba mi.
Fẹnikẹni to ba n wakọ, ina ọkọ rẹ ṣe pataki.
Wọ́n yọ́ wúrà bo gbogbo àkànpọ̀ igi náà, wọ́n fi wúrà ṣe ìkọ́ fún àwọn àkànpọ̀ igi náà, wọ́n sì yọ́ wúrà bo àwọn ọ̀pá ìdábùú náà pẹlu.
TUNNGR: Ta ló ṣe móríyá fún ọ jù lọ ní Super Eagles?
 lati odun 2009 ni Orile ede Naijiria ti n woya ija pelu iko olote Boko HaramEka ijoba ipinle labe akoso, Trump lo fowo si tita awon baalu ogun ati irinse igbalode ti iye re je ẹgbẹ̀ta milionu, fun orile ede Naijiria lodun to koja, ni eyi ti ijoba Obama da tita re duro nitori esun ti won fi kan ile-ise ofurufu  orile ede Naijiria pe won n fi ado oloro naa pa awon alaise.
paapaa julo lori eto okoowo, eto aabo ati  isejọba.
Ará, mo ní ẹ̀bẹ̀ kan láti fi siwaju yín.
Ẹni to bori: Algeria South Africa vs Madagascar.
Ìbálòpọ̀ ọ̀lọ́jọ́ méje mú kí ilé ẹjọ́ tú ìgbéyàwó ọdún mẹ́wàá ká ní Ibadan Kí lo mọ̀ nípa ìbẹta kan ṣoṣo tí Alaafin Oyo bí?
Haruna Magashi sọ ọrọ naa gẹgẹ bi esi si ohun ti Minisita fun eto iroyin ati aṣa ni Naijiria, Lai Mohammed sọ ninu fidio kan, pe miliọnu mẹta ataabọ ni ijọba apapọ fi n bọ olori ẹlẹsin Shia loṣooṣu.
ti eniyan lee ri gbamu nibi ọrọ naa ni pe, egbe oselu PDP ti seto abajade esi
Nigeria 2019 Election: Ìwé ẹ̀rí lè ṣe ìjákulẹ̀ fún olùdíje Ààrẹ Kaduna: Ikú Ọ̀ba dá kóníléógbélé padà Mahassin Quadri ló gbà ìrànwọ $5,000 Tony Elumelu Ilé-iṣẹ́ ọmọogun ni sùgbọn o, àwọn ti mú àwọn afura sí kàn ti wọn lérò pé o lọ́wọ́ nínú ìṣẹ̀lẹ̀ náà látari àwọn ìròyìn to tẹ àwọn lọ́wọ́.
”Adari agba ekaa ountaja ile-ise Cadbury nile Afrika, iyaafin Iwadiae Chidinma so pe: “Ise ti Tom Tom se lara ko to n ka.
Nítorí náà, ẹ di ẹni ìfibú; ẹrú ni ẹ óo máa ṣe, ẹ̀yin ni ẹ óo máa ṣẹ́ igi tí ẹ óo sì máa pọnmi fun ilé Ọlọrun mi.
OLUWA, má jẹ́ kí ọwọ́ àwọn eniyan burúkú tẹ ohun tí wọn ń wá;má jẹ́ kí èrò ọkàn wọn ṣẹ.
Wọ́n dìde, wọ́n tì í sẹ́yìn odi ìlú, wọ́n sì fà á lọ sí ibi gẹ̀rẹ́gẹ̀rẹ́ òkè ibi tí ìlú wọn wà, wọ́n fẹ́ taari rẹ̀ ní ogedengbe.
ti ijọba fẹ  se fun awon omo ile-iwe naa
adétoun ( 2003 : 1 ) ṣàlàyé pé orí ìtàn àtẹnudẹ ́ nu ni ìtàn Ìjẹ ̀ bú àti ìṣẹ ̀ dálẹ ̀ wọn dá lé .
Jẹ́ kí ọjọ́ tí o dá tètè pé,kí àwọn náà lè dàbí mo ti dà.
A kò tún ní gbọ́ ohùn fèrè ati ti àwọn olórin tabi ti ohùn ìlù ati ti ṣẹ̀kẹ̀rẹ̀ ninu rẹ mọ́.
Idi ree ti BBC Yoruba ṣe bọ sigboro, ta si ni ki awọn ọmọ Oodua fi ami si ori ọrọ: Ayekofẹnifọrọ.
ati ile-itura to wa ni orile ede  Sri
Nítorí náà mo já ìwé náà ni wéré-wéré, ìgbàtí mo sì rí ìwé yìí búlùú tún ni àwọ̀ rẹ̀.
Bí o bá ti fa òun nìkan ṣoṣo kalẹ̀, n óo kúrò ní ìlú yín.
Awon oloja so pe, awon oja n gbowo lori lasiko odun bayii, latari aleku lowo ori irina-oko ati awon ipenija eto-abo ti won n koju ni apa ariwa ila-orun orile-ede Naijiria.
Awon ti oro kan naa, ni won pe ipe ohun nibi eto idanilekoo olojo kan ti o waye ni ipinle Eko, ninu eyi ti won n ro awon orile-ede ti won je omo egbe ajo ECOWAS, lati fara mo ipade ijiroro ni iyanju ati se agbedide awon anfaani ti o wa ni ekun naa.
Iroyin so pe ipade naa bere ni deede agogo mokanla owuro, lara awon to wa nibi ipade ohun ni,igbakeji aare orile ede Naijiria, ojogbon Yemi Osinbajo,akowe agba fun orile ede yii ogbeni Boss Mustapha,oludari awon osise ijoba , iyaafin Winfred Oyo-Ita,oludari osise aare, Malam Abba Kyari ati awon oluranlowo aare .
Ọwọ́ rẹ̀ bá bọ́ sípò gẹ́gẹ́ bí ekeji.
O salaye pe, won ti seto idanilekoo fun awon mekaniiki merinleladorin, lati le maa toju ati se awon atunse ti o ye si awon ganga-dero naa, ni eyi ti o gba won niyanju lati maa ta awon irin ise omi ero naa, lati le wa ni arowo to bi nnkankan ba baje ninu re.
Ìwà àgàbàgebè wọn ń takò wọ́n;wọ́n ń polongo ẹ̀ṣẹ̀ wọn bíi ti Sodomu:Wọn kò fi bò rárá.
Nítorí ẹ̀bẹ̀ Joseph Knight, Wolíì náà béèrè lọ́wọ́ Olúwa ó sì gba ìfihàn.
Pẹlu bi o ṣe ti jẹ pe kii ṣe afin, koda kii ṣe ilu Ile Ife ni wọn bi Arẹmo si yii, o ṣeeṣe ki gbogbo eyi ko gba akoko diẹ sii.
” Bakan naa, won gbadura pe, ki olorun te oloogbe  Bush si afefe rere.
ng Ninu esi rẹ, Garba Shehu ni aarẹ le lo agbara lati ṣelu nibi to ba wu ko lọ.
11 Ọ̀pẹ̀̀ 2018 Fídíò, Buruji Kashamu: Èmi ṣì ni olùdíje PDP ní Ìpínlẹ̀ Ogun18 Ọ̀pẹ̀̀ 2018 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 3 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 5 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
ti awon olugbe abule naa ti o padanu ile ati awon ohun ini won ti n fi ehonu
    Báyìí ni iwin náà bú wa, bí o sì ti ń sọ̀rọ̀ ni mò ń wo eyín rẹ̀ kíká tí ó mú kí ẹnu rẹ̀ ri foforo.
Wọ́n ṣe fún wọn bí Josẹfu ti wí.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Parental Guidance: Ọdún méjì ni kí ẹ ti bẹ̀rẹ̀ kíkọ́ ọmọ nípa ìbálòpọ̀ Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ọdun 1997 ni Woods kọkọ gba Woods won the first of his five Masters titles in 1997 Isreal Adesanya fàgbàhàn Kelvin Gastelum ni Atlanta Nàìjíríà wà ní ìsọ̀rí kejì pẹ̀lú Burundi, Madagascar àti Guinea Àdúrà mi ni kò jẹ́ kí ìyà Manchester United ó pọ̀ jù lọ́wọ́ Barcelona- Wòlíì Àrólé Fun bii ọdun mọkanla ni Woods n tiraka lati gbe'gba oroke ninu idije gọọfu lẹyin ti wọn ti fi ẹsun aṣemaṣe agbere kan an, eyi to tu idile rẹ ka, to si mu ijakulẹ ba a ninu gbogbo oun to da'wọle.
Akọ́nimọ̀ọ́gbá ikọ̀ agbábọ́ọ̀lù Arsenal, Mikel Arteta náà ti fara káásá àrùn Coronavirus
Alaboyun ko gbọdọ ti ọwọ bọ sokoto ọkọ rẹ lati mu owo - Igbagbọ Yoruba ni pe obinrin to ba ni oyun sinu, to ba mu owo ni apo ọkọ rẹ, yoo bi ọmọ ti yoo maa fẹwọ, tabi jale.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù AFCON 2019: Orílẹ̀èdè wo ló tún leè mókè lẹ́ka míràn l‘Afirika 9 Agẹmo 2019 Idije ife ẹyẹ Afirika (AFCON) fọdun 2019 ti n lọ lọwọ, pẹlu orilẹede mẹrinlelogun to n figa gbaga lati jawe olubori.
Gege bi agbenusoro minisita to n
Makinde gbé ìṣúná ọdún 2020 kalẹ̀, iṣẹ́ òde ló kó ìpín tó pọ̀ jùlọ Saaju la ti mu iroyin wa fun yin pe, Gomina ipinlẹ Ọyọ, onimọ ẹrọ Seyi Makinde ti se agbekalẹ aba eto isuna ọdun 2020, tii se akọkọ iru rẹ ti yoo gbe kalẹ lati igba ti ijọba rẹ ti bẹrẹ, eyi to pe ni eto isuna awọn araalu, fun araalu.
Oyetola to jẹ oludije labẹ ẹgbẹ oṣelu APC naa lo jẹ onimọ nipa eto ìṣúná ati inawo, pẹlu ile isẹ adojutofo ti ti rẹ, Silvertrust Insurance Brokers Limited ti o da silẹ lati ọdun 1991, to si jẹ oludari fun ko o to di adari ajọ osisẹ fun gomina Aregbesola.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Port harcourt Bole: Mi kò mọ́ pé bọ̀ọ̀lì títà lè gbé mi dé ipò yìí láyé mi!
Ilé -ìṣẹ́ ọlọpàá rọ ará ìlú láti máa kọbiara sí àhesọ to gbòde kan láti ba orúkọ ọlọpàá jẹ́ lóri ọ̀rọ̀ náà.
Gomina Tambuwal so pe , oun darapọ mọ egbe PDP lati lee tesiwaju ninu oselu.
”Dafidi ọba bá dáhùn pé, “Mo ṣèlérí fún ọ, ní orúkọ OLUWA Ọlọrun alààyè, pé, ẹnikẹ́ni kò ní ṣe ọmọ rẹ ní ohunkohun.
#Zamfarakillings: Ìjọba pàṣẹ kí wọn dáwọ́ ìwakùsà ní Zamfara
awon akoroyin lati ri i pe won tele ilana to ro mo ise won,ni eyi  to ni se pelu iroyin.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Osun tribunal: Ilé ẹjọ́ sọ Adeleke di gómínà, ṣùgbọ́n kò tó bẹ́ẹ̀ kó kó lọ ilé ìjọba 23 Ẹrẹ̀nà 2019 Ọpọ awọn alatilẹyin Ademola Adeleke to jẹ oludije PDP fun ipo gomina Ipinlẹ Osun ninu idibo to koja ni ipinlẹ naa lo bẹ si ita pẹlu ajọyọ ni ọjọ Ẹti bi ile ẹjọ ṣe ni Ademola Adeleke ni ojulowo gomina.
wọ́n yọ ọrùn sí ẹ̀wù àwọ̀kanlẹ̀ náà bí ọrùn ẹ̀wù gan-an, wọ́n sì fi aṣọ tẹ́ẹ́rẹ́ gbá a yípo kí ó má baà ya.
24 Kíyèsíi, mo wí fún un, òun gbé ara rẹ̀ ga kò sì rẹ ara rẹ̀ sílẹ̀ tó ní iwájú mi; ṣùgbọ́n bí òun bá lè tẹ orí ara rẹ̀ ba ní iwájú mi, tí ó sì rẹ ara rẹ̀ sílẹ̀ nínú àdúrà nlá ati ìgbàgbọ́, nínú òtítọ́ ọkàn rẹ̀, nígbànáà ni èmi yíò fi fún un lati wo àwọn ohun tí ó ní ìfẹ́ láti rí.
Bí mo ti ń ronú, ọkàn mi dàrú;mo bá sọ̀rọ̀ jáde, mo ní:
Ni ọjọ Iṣẹgun ni gomina Rotimi Akeredolu kede pe ki gbogbo iloro ileewe ni ipinlẹ Ondo di titipa lẹyin tawọn janduku ti gba igboro kan pẹlu awọn ohun elo ija loriṣiriṣi ti wọn si ti sọ iwọde di nnkan miran.
Enuduisu Odili sexual Port Harcourt death: Ọkùnrin kan gba ibi ìbálòpọ̀ jásí ọ̀run alákeji
pé, òun yóo gba ìjọba kúrò lọ́wọ́ ìdílé Saulu, yóo sì fi Dafidi jọba lórí Juda jákèjádò, láti Dani títí dé Beeriṣeba.
"Oríṣun àwòrán, Abiola Ajimobi ""Ọrẹ ni wa."
Ọkan lara awọn eeyan tori koyọ ninu ijamba ọkọ naa, Malam Bello Bakada ni bii idan ni isẹlẹ naa waye, eyi to ba ọpọ wọn lojiji.
O ni o jẹ ohun to bani ninu jẹ pupọ wipe ọna ti oselu n gba lorilẹede Naijiria n fun awọn oloselu laaye lati da ẹgbẹ oselu silẹ ki wọn si maa se akoso rẹ bi o ba se wu wọn, eleyi ti ko ri bẹẹ ni orilẹede South Africa.
Ẹka idajọ orilẹ-ede Amẹrika lo kede ọrọ naa loju opo itakun agbaye wọn.
Awon ere re miran ni: Shirley Valentine, The Ten Year Plan, Before You Go ati bee bee lo.
Kò tọ̀nà láti gbé adájọ́ Onnogben lọ síwájú CCT - Adájọ́ fẹ̀yìntì Gani Adams ní Ọ̀yọ́mèsì ló fún òun láṣẹ láti yan olóyè Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fọ́nrán ohùn, Oluwo ti Iwo Ọba AbdulRasheed Akanbi kí Aláàfin Ọyọ kú ọjọ́ ìbí A bí Lamidi Olayiwola Adeyemi III ní ọjọ́ kẹẹ̀dógún oṣù kẹwàá ọdún 1938.
Yóo pàṣẹ pé kí wọ́n ha gbogbo ògiri ilé náà yípo, kí wọ́n kó gbogbo ohun tí wọ́n fi rẹ́ ilé, tí wọ́n ha kúrò, kí wọ́n dà á sí ibìkan tí kò mọ́ lẹ́yìn ìlú.
Ninu atejade kan, eyi ti amugbalegbe aare pataki lori eto iroyin ati igbodegba, ogbeni Garba Shehu te jade lojoRu(Wednesday), o ni, ki egbe oselu PDP lo koju mo ohun ti isakoso ijoba re fun odun mẹ́rìndínlógún ti sokunfa lorle-ede Naijiria, ju ki won o wa maa mu ebi aare gege bi ohun ipolongo idibo lodun 2019.
Aarẹ Ẹgbẹ naa kaakiri agbaye, Ọgbẹni Bọlaji Amuṣan ti ọpọ mọ si Mr.
Joabu, ọmọ Seruaya, ṣe akiyesi pé ọkàn Absalomu ń fa Dafidi pupọ.
A kò tilẹ̀ gbọ́ ọ rí pé nǹkankan wà tí ń jẹ́ Ẹ̀mí Mímọ́.
Ìdìbò Kano kò fararọ, bẹ́ẹ̀ láwọn ìpínlẹ̀ to kù náà kò ní ìfọ̀kanbalẹ̀
Olukuluku àwọn ará Siria dúró ní ipò wọn, wọ́n dojú kọ Dafidi, wọ́n sì bá a jagun.
Nígbà náà ni wọ́n ké pe OLUWA ninu ìpọ́njú wọn,ó sì yọ wọ́n ninu ìṣẹ́ wọn.
Ooni: Mo rọ àwọn àgbẹ̀ àti darandaran láti gba ìrẹ́pọ̀ láàyè
Ija ọhun bẹrẹ ni igba ti Lizzy Anjorin fi fidio kan lede loju opo instagram rẹ, nibi ti o ti fi ọpọlọpọ eebu ṣọwọ si Toyin.
“Bí kò bá ní agbára láti mú aguntan wa, kí ó mú àdàbà meji tabi ọmọ ẹyẹlé meji, ọ̀kan fún ẹbọ sísun, ekeji fún ẹbọ ìmúkúrò ẹ̀ṣẹ̀, alufaa yóo ṣe ètùtù fún un, yóo sì di mímọ́.
Ṣaaju akoko yii, Agbaje ti kọkọ ṣiṣẹ pẹlu ileeṣẹ ijọba ilẹ Amẹrika, US State Department, bẹẹ lo tun ṣiṣẹ nileesẹ awọn amofin kan lẹyin to kọkọ kẹkọọ gboye ni Fasiti Pennsylvania.
Ògì ni wọn fi nṣe Ẹ̀kọ́.
Ileeṣẹ naa lo fi ikede naa sita loju opo Twitter rẹ lọjọ Aje.
Nigbati o n ba awọn akọroyin sọrọ, Kọmisọna fun ọrọ ayika nipinlẹ Eko, Babatunde Durosinmi- Etti sọ pe, o ṣe pataki fun awọn ara ilu Eko lati tọju ayika wọn, bi wọn ṣe n yọ ayọ ọdun.
Má gbẹ́kẹ̀lé àwọn ìjòyè;eniyan ni wọ́n, kò sì sí ìgbàlà lọ́dọ̀ wọn.
”Daramola ni ojo ibọn ti iko omo oogun ofurufu ati omo oogun ori-ile n yin lati dojuko iko olote naa , le won kuro ni agbegbe naa.
Ẹni tí ó bá bú arakunrin rẹ̀, yóo jẹ́jọ́ níwájú àwọn ìgbìmọ̀ ìlú.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Kìí ṣe emí ni mó ràn amúgbálẹ́gbẹ̀ẹ́ mi tó sọ̀rọ̀ abùkù sí FIBAN níṣẹ́- Wasiu Ayinde Wo ọjọ́ tí wòlíì Sotitobire yóò gba ìdájọ́ Iléẹjọ́ gíga Akure kọ̀ láti gba onídùróó olórí ìjọ Sotitobire Pásítọ̀ ìjọ Sotitobire padà yọjú sílé ẹjọ́ lónìí, àbọ̀o rèé.
Buhari ni o to gẹ bayii nitori Naijiria pe alaafia gbọdọ jọba lorilẹede Naijiria.
Bakan naa lo fi kun un pe gbogbo igbesẹ ati ilana to ba yẹ fun idapada irinajo silẹ okeere naa yoo bo si ojutaye laipẹ.
Ninu atẹjade ti wọn fi lede, ọkan ninu awọn agbẹnusọ fun ẹgbẹ oselu PDP, Gabriel Aduku sọ wi pe, awọn mẹjo naa fi ipo silẹ fun Gomina ipinlẹ naa tẹlẹri, Idris Wada to n dije dupo ninu idibo abẹle naa.
Ọ̀pá fìtílà fún iná títàn, ati àwọn ohun èlò tí ó jẹ mọ́ fìtílà rẹ̀ ati òróró fún iná títàn.
Nibo ni wọn wa ati pe ki lo mu wọn faake kọri toun ti aṣẹ olori Musulumi ?
O tẹsiwaju wipe akanṣe iṣẹ naa ko se e da ṣe fun Ọọni Ile-Ife ni kan, labẹẹ bẹẹ lofi keesi gbogbo ẹni ti nnkan rọrun fun lati fi ifẹ han nipa fifọwọ sọwọpọ pẹlu ajọ naa.
Orilẹ-ede Germany ti gba ife ẹyẹ agbaye tawọn obinrin lọdun 2003 ati 2007.
Bakan naa ni ijọba apapọ tun ṣalaye pe aṣẹ yii lo bẹrẹ si ni fi ẹsẹ mulẹ bẹrẹ lati ọjọ Satide, ọjọ kọkanlelogun oṣu kẹta ọdun 2020.
Wọn yóo máa ṣe àfojúdi sí àwọn òbí wọn.
29 Bélú 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Aago mẹjọ abọ lalẹ ọ jọ Bọ ni aarẹ Trump de si Afghan ko to lọ pada laidagbere nitori eto aabo rẹ.
Ahimaasi, (ọkọ Basemati, ọ̀kan ninu àwọn ọmọ Solomoni), ni alákòóso Nafutali.
Wọ́n ní, “Nítòótọ́ Ọmọ Ọlọrun ni ọkunrin yìí.
O ni awọn akẹkọọ to ku diẹ kaato fun ni ileewe naa wa fun.
Kí á má rí i, n kò jẹ́ pè yín ní olóòótọ́;títí di ọjọ́ ikú mi ni n óo dúró lórí ọ̀rọ̀ mi,pé mo wà lórí àre.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Dino Melaye, olùdíje sípò kẹẹ̀ta lábẹ́ àsìá PDP tó gba fọ́ọ̀mù ipò Gómìnà Kogi 5 Agẹmo 2019 Oríṣun àwòrán, dinomelaye Àkọlé àwòrán, Dino Melaye Ilumọka oloṣelu ọmọ ipinlẹ Kogi, Senatọ Dino Melaye ti darapọ mọ awọn to n dije dupo Gomina ni ipinlẹ naa.
Wọn si ti tọrọ aforiji fun igbesẹ wọn.
Adajọ kẹkọọ ile iwe giga fasiti ja ni Fasiti Ahmadu Bello, Zaria.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Coronavirus in Lagos: 'Bí Covid19 bá peléke síi l'Eko, ilé la ó ti máa tọ́jú àwọn kan' 6 Òkùdu 2020 Oríṣun àwòrán, @Rasheethe Ijọba ipinlẹ ti jẹ ko hande pe bi wọn ba n ni iye awọn to lugbadi arun Covid19 to n le ni igba si ọọdunrun lojoojumọ gẹgẹ bo ṣe n sunmọ ọ lẹnu ọjọ mẹta yii, awọn ibudo iyaraẹnisọtọ wọn ko ni to fun itọju mọ.
A lé sọ pé kò sí oúnjẹ kan tí kò dára, ṣugbọn nǹkan burúkú ni fún ẹni tí ó bá ń jẹ oúnjẹ kan tí ó di nǹkan ìkọsẹ̀ fún ẹlòmíràn.
'ilana ofin nipa ẹjọ ti wọn ba ti gbe wọn lo si iwaju adajọ ni wọn gbodo tele.
Eyi lo n sọ bi Oke Olumọ ti se pataki to fun awọn Ẹgba nitori abẹ rẹ ni wọn sa si lasiko ogun, ibẹ si ni ilu Abẹokuta ti gberasọ.
Wọ́n sọ ibẹ̀ ní àfonífojì Eṣikolu, nítorí ibẹ̀ ni àwọn ọmọ Israẹli ti gé ìtì èso àjàrà.
"Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: ""Àhámọ́ ajínigbé ni ń bá wà lónìí, ọ̀pẹ́ awakọ̀ mi"" Bodè àgbáyé ní Saki, ìbẹ̀ ni agbégbọn ń gbà wọ ilẹ̀ Káàrọ̀ Oòjíire - Makinde gbarata Saheed tí wọ́n dáná sun ní OkeAdo, Ibadan, ajínigbé ni àbí àrìnfẹsẹ̀sí?"
Oríṣun àwòrán, Instagram/toyinabrahamnews OTSWC ni o le maa si ohun kankan laarin wọn ṣugbọn ko si ohun tawọn osẹre tiata ko le sẹ.
Oríṣun àwòrán, Reuters Àkọlé àwòrán, Diẹ ninu awọn akẹkọbirin Dapchi nigba ti wọn fẹ wọ baalu nibudo awọn ologun ofurufu ni Maiduguri, Nigeria.
Gbogob nkan ti ẹ ba ri lori iwe ile ẹjọ kọ lo maa n jẹ 'otitọ' delẹ.
Wọn ma n se eyi nitori pe eefin ati ooru ina ma n le àwon kokoro oyin kuro nibi ti wọn ba wa.
Ọmọbinrin naa ni lẹyin ti Cute Abiola ti seleri aye ati ọrun fun oun, lo wa ja oun ju silẹ, lẹyin to ti lo oun tan.
 À n fúnni gẹ ́ gẹ ́ bí abẹ ́ rẹ ́ tí a gún sínú ẹran ara .
S 3 bí wọ́n yóò se kọ ìdáwò wọ́n.
Kíni irúfẹ́ ìgbésẹ̀ kíní tó bẹ̀rẹ̀ ìrìnàjò ńlá ìsọ́jí èdè Yorùbá kíkọ àti kíkà?
Ìdáhùn tí ó fún mi ni pé, “Oore-ọ̀fẹ́ mi tó fún ọ.
, Duration 5,5712 Òkùdu 2020 Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí kan sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
Laiti pe ọsẹ kan ti awọn ajinigbe ji eniyan mẹẹrin ni ipinlẹ Ondo, wọn tun ti ji eniyan mẹta miran gbe lọjọ Abamẹta to kọja.
O wa ro awon oludibo lati tun dibo fun egbe oselu APC ninu eto idibo to n bọ.
Bakan naa lo tun di ipo minisita abẹle fun eto iṣuna labẹ iṣejọba aarẹ Oluṣẹgun Ọbasanjọ titi di ọdun 2003.
Àyájọ́ ọjọ́ àwọn èwe lórílẹ̀-èdè Nàìjíríà jẹ́ ọjọ́ tí wọ́n yà sọ́tọ̀ láti pọ́n àwọn èwe lé.
ẹnu atẹ lu iwa yii patpata.
Ni bayii, Akeredolu ti lọ ṣabẹwo si awọn ti wọn jọ dije ninu idibo abẹle naa, lara awọn ni Olusola Oke, Salo Iji ati D.
Ó bẹ̀rẹ̀ láti Galili lẹ́yìn ìrìbọmi tí Johanu ń sọ pé kí àwọn eniyan ṣe.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, World TB Day: Funkẹ Dosunmu ni ikọ́ ife kìí pani, ta bá lo òògùn rẹ̀ déédé O ni ẹgbẹ oselu APC ti pinnu lati pe ẹjọ kotẹmilọrun pẹlu afikun pe, o da oun loju pe didun ni ọsan yoo so fun oun ni ile ẹjọ kotẹmilọrun.
Nítorí náà n óo sọ iná sí orí odi ìlú Tire, yóo sì jó ibi ààbò rẹ̀ ní àjórun.
Premier League gbìnàyá padà, ọ̀gá àti ọmọṣẹ́ fìjà pẹ̀ta Lati ayebaye lawọn aṣiwaju ti maa n gbadura pe ki ọmọlẹyin wọn o gberi koda ju awọn gan an lọ.
Farao bá tún ranṣẹ lọ pe Mose, ó ní, “Ẹ lọ sin Ọlọrun yín, ẹ máa kó àwọn ọmọ yín lọ pẹlu, ṣugbọn ẹ fi agbo aguntan yín ati agbo ẹran yín sílẹ̀.
“Eleyii yatọ si ọgbọ̀n egberun ti  igbimo
Ó gbà mí lọ́wọ́ ọ̀tá mi, tí ó lágbára;ati lọ́wọ́ gbogbo àwọn tí wọ́n kórìíra mi;nítorí pé wọ́n lágbára jù mí lọ.
Ẹya Ebira, Igala àti Okun ni o pọju nibẹ pẹlu ijọba ibilẹ mọkanlelogun.
Eniyan yoo maa ṣe aisan nigba gbogbo: Omi maa n ran ara lọwọ lati fọ idoyi ati awọn majele to wa ninu ara kuro, o si maa n fun eroja to maa n gbogun ti aarun lara lagbara.
Ti ẹ ko ba gbagbe, ọjọ kẹtadinlọgbọn, oṣu Kọkanla, ọdun 2020, ni ASUU gba pe awọn yoo fopin si iyanlodin ọlọjọ gbọọrọ ti wọn gunlẹ lẹyin ti ijọba apapọ ni oun yoo yọnda 70 biliọnu fun wọn gẹgẹ bi owo ti oun jẹ wọn ṣaaju.
O jẹwọ pe, oun maa n lọ si awọn ile ijo ti awọn eniyan ti maa n bọ ara wọn si ihoho, ti oun si pade ọmọbinrin onijo kan nibẹ.
Jẹ́ kí n gbọ́ ohun tí Ọlọrun, OLUWA yóo wí,nítorí pé ọ̀rọ̀ alaafia ni yóo sọ fún àwọn eniyan rẹ̀,àní, àwọn olùfọkànsìn rẹ̀,ṣugbọn kí wọn má yipada sí ìwà òmùgọ̀.
Dafidi ati irinwo (400) eniyan sì ń lépa wọn lọ, ṣugbọn àwọn igba (200) eniyan tí àárẹ̀ mú kò lè la odò náà kọjá, wọ́n sì dúró sí etí odò.
Aare Buhari yoo lo asiko yii lati tepelemo ajosepo to dan moran to wa laarin orile-ede mejeeji pelu ipinnu sise ileri atileyin to ye, ki idagbasoke le tubo ba orile-ede mejeeji ati ile Adulawo lapapo paapaa ninu oselu.
Bi a bá wo òwe yi, a o ri pe Agbe pọn bi aró, Àlùkò pupa bi osùn nigbati Lékeléke funfun bi ẹfun.
4 2767 Orilẹede Central African Republic 63 1.
Ilé ẹjọ́ kọ̀ láti tú Omoyele Soworẹ sílẹ̀ Oju opo arẹwa Lisa kun fun awọn aworan to rẹwa to le mu ki ẹlomii firu rẹ tọrọ pe ọjọ wo loun naa a ni owo to to bayii.
Gun orí òkè gíga lọ, ìwọ Sioni,kí o máa kéde ìyìn rere.
Wọn fi kun un wi pe awọn ma n se idanimọ ọkọ lorilẹede Naijiria letoleto ni, ti kii si ni abawọn.
Kọmísọ́nà fún ọ̀rọ̀ ìròyìn ní ìpínlẹ̀ Eko, Kehinde Bamigbetan nínú àtẹ̀jáde fún àwọn oníròyìn sọwípé àbẹ̀wò Ààrẹ Muhammadu Buhari fún ní Ọ́jọ́bọ̀ àti Ẹtì ọ̀sẹ̀ yii sí ìpínlẹ̀ náà, ló jẹ́ kí wọ́n fún àwọn ènìyàn ní ìsinmi ọjọ́ kan náà.
Agbẹnusọ ileeṣẹ ọlọpaa nipinlẹ Ọyọ, Gbenga Fadeyi lo fi idi ọrọ naa mulẹ ni ilu Ibadan.
Oríṣun àwòrán, FFK Awọn ẹsun yii ló bọ́ sápọ̀ ìbínú Bakare, tó si fèsì sọ̀wọ̀ si olóyè ẹgbẹ́ Afẹnifẹre, Yinka Odunmakin, tó sì sàlàyé pé ki FFK wá sọ ǹkan tó bá mọ̀ nípa òun.
Kini Pásítọ̀ Kumuyi fi ṣẹ ọmọ Naijiria?
NCDC fikun pe awọn ipinlẹ ti ọrọ naa kan ni ipinlẹ Eko,Katsina, Oyo, Kano, Edo, Zamfara, Ogun, Gombe, Borno, Bauchi, Kwara, Abuja,Kaduna, Enugu ati ipinlẹ Rivers.
Agbára ọwọ́ ọ̀tún rẹ pọ̀ jọjọ, OLUWA;OLUWA, ọwọ́ ọ̀tún rẹ ni ó fọ́ àwọn ọ̀tá túútúú.
Ibi tí o bá kú sí, ni èmi náà yóo kú sí; níbẹ̀ ni wọn yóo sì sin mí sí pẹlu.
Ramadan 2020: Buhari, Ọọni, Sultan Sokoto ní kí àwọn ọmọ Nàìjíríà láti fi ìtúnu àwẹ̀ gbàdúrà fún Nàìjíríà
Ọjọgbọn onimọ nipa ihuwasi eda lati fasiti Heidelberg ni Ohio, USA, Aaron Sell ni, awọn eniyan ma n lo ibinu laye atijọ lati fi han wi pe, awọn ni agbara lati paṣẹ, ati lati jẹ ki awọn eniyan gba ọrọ wọn gẹgẹ bi ohun ti o tọna lati se.
Ti ọtẹ yii si nii ṣe pẹlu ọrọ wahala iwọde EndSARS bo tilẹ jẹ pe o le ti maa sinmi bayii.
Ṣugbọn a mọ̀ pé Ọlọrun ní ẹ̀tọ́ láti ṣe ìdájọ́ àwọn tí ń ṣe irú nǹkan wọnyi.
ati ilaniloye ni ipinle Cross River , Dr.
Ori ẹrọ amohunmaworan ati lori ayelujara ni ot i le wo eto naa bo ṣe n bẹrẹ.
Abajade wọn ti dori igba bayii.
Ninu idajọ ti adajọ Yunusa Musa gbe kalẹ lori ẹhonu ibo gomina ti ẹgbẹ oselu ANDP gbe wa siwaju rẹ, igbimọ olugbẹjọ ẹhonu ibo naa ni ajọ eleto idibo lo yọ orukọ oludije ibo gomina fun ẹgbẹ oselu naa lọna aitọ.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ìjà àgbà méjì!
Ko si da lori amuyẹ ẹni ti wọn ba yan nikan, o tun ni i ṣe pẹlu afojusun ilana iṣejọba aarẹ to wa lori oye.
ede Naijiria ti ọwọ kejo, Major General Hakeem Otiki, ti ni ikọ ‘Harbin
Awọn akẹkọọ mẹfa ti wọn jigbe ni ileewe girama ni Gwagwada, nipinlẹ Kaduna ti gba ominira bayii.
O ni ọrọ awọn janduku agbebọn jẹ ọkan lara ipenija ti iṣakoso rẹ n doju kọ.
Ọba yán gbogbo aṣọ kúrò lára, bí aláìlóye eniyan níwájú àwọn iranṣẹbinrin àwọn iranṣẹ rẹ̀!
àwọn ará Patirusimu ati ti Kasilu tíí ṣe baba ńlá àwọn ará Filistia ati àwọn ará Kafito.
Asiko yii si lo ra ọkọ akẹru to si lọ kọ ọkọ wiwa.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù 2020 Africa Prize:Ẹ wo àwọn ọ̀dọ́mọdé Naijiria tó ń ṣe bẹbẹ níní iṣẹ́ aládaní 21 Bélú 2019 Oríṣun àwòrán, OTHERS Àkọlé àwòrán, Aisha Raheem àtí Victor Boyle-Komolafe ti pegedé nínú àwọ́n orúkọ tí wọ́n fi sílẹ̀ fún àmì ẹ̀yẹ 2020 Africa Prize.
Moeti ni ''a ko le titori pe a n gbogun ti itankalẹ aarun coronavirus ki a padanu ọjọ iwaju wa pẹlu awọn akẹkọọ.
Ọbanikoro: Àjọṣepọ̀ tó wà láàárín èmi àti Fayose kò ní jẹ́ ki ń tú àṣírí
 fọláṣadé náà ni ó yí orúkọ padà sí fìlísíà olówálàgbà .
Iyatọ laarin Emere, Ajẹ ati Oṣo: Awọn ti a n pe ni ajẹ, ni awọn ni ìyà mi, lati ipilẹ aye ni Olodumare ti da wọn.
O fi idaniloju han pe awọn olukọ a fopin si iyanṣẹlodi na laipẹ ati pe awọn akẹkọọ a wọle nibẹrẹ oṣu kinni ọdun 2019.
Funke Akindele fún mi lówó tí mo fi gba ilé, kò ra ilé fún mi o - Ajirebi Alakoso ajọ EFCC tuntun de!
aabo fun igbakeji aare lasiko ijamba oko ofurufu, ni eyi ti ko farapa nibẹ.
“Ẹ da ẹbọ sísun yín pọ̀ mọ́ ẹran tí ẹ fi rúbọ, kí ẹ lè rí ẹran jẹ; Èmi OLUWA àwọn ọmọ ogun, Ọlọrun Israẹli ni mo sọ bẹ́ẹ̀.
Gbajugba olori Don Jazzy naa wa lara awọn to kọkọ farahan pe ọmọ ẹgbẹ ni òun O ṣalaye pẹlu aworan meji pe bi ọkunrin ba kọ lati fun ọrẹbinrin rẹ lowo, ọrẹbinrin naa ko ni fẹyin le lẹ.
Ninu mẹrinla naa, wọn ri awọn mẹfa to ko ẹru wọle lati ori omi, mẹta miran jẹ arinrinajo.
 O ni sibẹ ẹgbẹ awọn ko fara mọ ọn ki wọn ṣe eto madanidofo eto ilera naa ni kannpa.
O ni gba ami ẹyẹ NMMA ni ọdun 2008, 2009, 2010 ati ami ẹyẹ Dame ni lọdun 2009.
Agbaboolu omo orile-ede Algeria, Riyad Mahrez ti o tun kopa fun iko agbaboolu  Leicester ti darapo mo iko akegbe won, Manchester City ninu idije English Premier League lojo isegun(Tuesday), osu meje seyin ti iko naa ko lati san owo idunadura re.
''Mo maa n fẹ gbọ ọrọ lẹnu gbogbo awọn ti ọrọ kan.
BBC Gov Debates: Àwọ́n olùdíje ìpínlẹ̀ Ogun ṣe tan láti jíròrò
Ẹnu ya ọpọlọpọ àwọn tí ó gbọ́ ẹ̀kọ́ rẹ̀.
Walter Onnoghen: UNO bẹnu àtẹ́ lu ìdàdúró adájọ́ àgbà
Oríṣun àwòrán, Ẹ wo àwọn òṣèré àti àwọn ọmọ òṣèré tó sọjọ́ ìbí lọ Ronke Ojo-Anthony Lọ́sẹ̀ yìí bákan náà ni gbájúgbajà òṣèré Ronke Ojo-Anthony tí gbogbo ènìyàn mọ si Ronke Oshodi-Oke náà ṣe ọjọ́ ibí nínú.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìpàdé Commonwealth; Ọbabìnrin fẹ́ kí àrẹ̀mọ rẹ̀ gba àsẹ 19 Ìgbé 2018 Oríṣun àwòrán, EPA Àkọlé àwòrán, Awọn adari mẹtalelaadorin naa parapọ si Aafin Burkingham lati jiroro Ọbabìnrin Ilẹ̀ Gẹ̀ẹ́sì ti késí awọn adarí àjọ Commonwealth lati yan ọmọ oun, Ọbakunrin Charles lati jẹ oye adari lẹhin oun.
Ajọ ajafẹtọ Amnesty International ni idajọ naa ko dara nitori pe o lodi si ofin orilẹede naa.
Sugbon, ti a ba wo sisowo eran dida yii, a ri wipe isowo to niyelori ni, eleyi ti ko si ni n rorun fun awon osise, ti o si tun mo si pe, won le dawole okoowo awon ohun osin miiran.
Ọpọlọpọ ẹmi lo ti sọnu nipasẹ coronavirus ni eyi ti awọn eeyan si ti gba kadara si.
Eyi ko ṣẹyin bi amugbalẹgbẹ rẹ kan ṣe ko arun COVID-19 laipẹ yii.
Sibẹ awọn eniyan kan ninu ipade naa ko ṣai yin ijọba fun iru ipade naa pe o dara, eleyii ti o fun awọn eniyan laaye lati fi ẹdun okan wọn han lori owo-ori ilẹ naa, ki ijọba le mọ ero ọkan ara ilu, ki wọn si le gbe igbesẹ to yẹ.
Loju opo Twitter ipinlẹ Eko ni wọn ti fi lede pe ki awọn eniyan yago fun ara wọn ni ila mita kọọkan nitori naa ki awọn eniyan yẹra fun ibi ti eniyan to pọ ba wa.
Mo ti rù láàrin ọ̀sẹ̀ kan, iṣẹ́ Eko kò dẹ́rùn - Sanwo-Olu Lẹ́yìn àṣẹ ilé ẹjọ́, AIT àti RayPower padà s'afẹ́fẹ́ Gbogbo àwọn gomina yii lo gba pé ti awọn ko ba tete gbe igbesẹ to yẹ lasiko, o ṣeeṣe ki ọrọ yii maa gba ẹbọ lọwọ awọn laipẹ.
Mo mọ ọkunrin yìí, bí ninu ara ni o, bí lójú ìran ni o, èmi kò mọ̀–Ọlọrun ni ó mọ̀.
Ẹ̀yin ará Filipi mọ̀ pé ní ìbẹ̀rẹ̀ iṣẹ́ ìyìn rere mi, nígbà tí mo kúrò ní Masedonia, kò sí ìjọ kan tí ó bá mi lọ́wọ́ sí ọ̀rọ̀ fífúnni lẹ́bùn ati gbígba ẹ̀bùn jọ fúnni àfi ẹ̀yin nìkan ṣoṣo.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Akomolede ati Asa lori BBC: Olùkọ́ Kikelomo Ogunboye tan ìmalẹ̀ sí ìwà olè ọ̀gá ọlọ́pàá Eeyan mẹfa lọwọ ọlọpaa kọkọ tẹ ki wọn to mawọn mẹrin mii ninu eyi ti ọkan lara wọn ti lọ sa pamọ.
Lati igba ti mo ti n sisẹ lati ile bi nkan bi ogun ọdun sẹyin ipenija ti o lagbara ti mo le tọka si ni pe bi maa ti se yanju asọ fifọ, ina dida, ile titunsẹ ki n si tun lee se isẹ mi pẹlu ifọkanbalẹ.
Ilu Eko lo fi ṣe ibugbe, bo tilẹ jẹ pe ilu London ni ni wọn bi si, to si ti dagba.
Oluwo wa ṣapejuwe Alaafin gẹgẹ bi baba fun gbogbo ọba nilẹ Yoruba.
 Ṣùgbọ ́ n ó fi díẹ ̀ lé ni ogóje kìlómítà láti ilé-ifẹ ̀ .
Nígbà tí Peteru wà ní ìsàlẹ̀ ní agbo-ilé, ọ̀kan ninu àwọn iranṣẹbinrin Olórí Alufaa dé.
26 Bélú 2020 Iléèṣẹ́ ọlọ́pàá mú ọkùnrin ẹni ọdún 55 tó gé ẹ̀yà ara èèyàn nílẹ̀ ìsìnkú ṣọ́ọ̀ṣì l'Ogun25 Bélú 2020 Covid 19 vacine updates: America kan sárá si Dókítà Ogbuagbu, ọmọ Nàìjíríà tó ṣàwárí abẹ́rẹ́ àjẹsára COVID-19 àkọ́kọ́25 Bélú 2020 Burna Boy Twice as Tall: Ǹkan tí ó yẹ ki o mọ̀ nípa Damini Ebunoluwa Ogulu Rex (Burna Boy) ti orin rẹ̀ lu ìgboro pa báyìí25 Bélú 2020 Amos Dauda, Iphone: Ilé ẹjọ́ dájọ́ ẹgba mẹ́ẹ̀dóògún fún ọ̀daràn tó jí Iphone ní Kaduna25 Bélú 2020 Grammy awards 2021 - Burna Boy, Beyoncé, àti Dua Lipa, wà lára àwọn ti wọ́n fi orúkọ wọn sílẹ̀25 Bélú 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 3 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 5 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
" Àjọ ìsọ̀kan àgbáyé ní, àwọn ikọ̀ ọ̀daràn lágbàáyé ló ń kó Tramadol wọ ilẹ̀ Afrika láti ẹkùn gúúsù ilẹ̀ Asia.
Ó sọ fún ọmọ náà pé, “Sáré lọ wá àwọn ọfà tí mo ta wá.
’ Òun náà fèsì, ó ní, ‘Olówó-ayé mi ọ̀wọ́n, kọjú sí èyí tí ó bá ọ, mú ojú kúrù ní ‘rùngbọ̀n mi’.
Aarẹ orileede Naijiria Muhammadu Buhari ti pẹlu awọn ọmọ Naijiria lati fi ikini ku orire ranṣẹ si ikọ Super Eagles lori bi wọn ṣe bori ikọ South Africa ninu idije AFCON.
89 million, ti o to  N2.
Àwọn eniyan bá bi mí pé, “Ṣé kò yẹ kí o sọ ohun tí nǹkan tí ó ń ṣẹlẹ̀ yìí túmọ̀ sí fún wa, tí o fi ń ṣe báyìí.
Ẹjọ naa dele ẹjọ, igbẹjọ rẹ si 'fihan pe ko mọọmọ pa ọkọ rẹ.
Ẹ̀rí tí ó fi hàn gbegbe pé àwọn Ìjẹ̀ṣà gba ìlù Ijẹ̀bú - Jẹ̀ṣà gẹ́gẹ́ bi ìlú ti ó tẹ̀ lé Iléṣà ni ilẹ̀ Ìjẹ̀ṣà ni pé ìjókòó àwọn lọ́balọ́ba ilẹ̀ Ìjẹ̀ṣà, Ọwá ìlẹ̀ Ìjẹ̀ṣà ni ọba Ìjẹ̀bú - Jẹ̀ṣà máa ń yàn àn lé.
Naijiria ko tii gba ife eye yii ri ṣugbọn wọn ti kopa ninu idije naa nigba mejila.
Ajọ SERAP bu ẹnu ẹtẹ lu owo ifẹhinti f'awọn oloselu Owo ifẹyinti tan fawọn gomina ana ni Kwara Owó ifẹyìntì àwọn Gómìnà ní ìpínlẹ̀ Zamfara dì àlọrámirámi Ki ọrọ naa ba le ye wa daada, a ni ki a darukọ awọn ipinlẹ miran ti wọn ṣe agbekalẹ ofin owo ifẹhinti fawọn Gomina ati igbakeji wọn, lẹyin ti wọn pari saa ijọba wọn.
Ijakulẹ O ti gbadun ibalopọ, sugbọn oriṣiriṣi ni iriri igbadun rẹ.
Èmi ni mo fi ojú ọ̀run sí ipò rẹ̀,tí mo fi àwọn ìpìlẹ̀ ayé sọlẹ̀,tí mo sì sọ fún ìlú Sioni pé, ‘Ẹ̀yin ni eniyan mi.
NLC ni owo oṣu oṣiṣẹ ti da radarada nitori ọwọngogo to gun owo epo, ina ọba, ati ounjẹ kaakiri Naijiria.
Ṣugbọn, ileesẹ naa ko fun wọn ni iwe ẹri to yẹ lori ilẹ naa.
”Ṣugbọn Paulu ní, “Ní tèmi o, wọ́n bí mi bẹ́ẹ̀ ni.
Àwùjọ-ẹ̀dá ti ṣe àwọn nnkan dáradára báyìí náà ni wọ́n ń ṣe àwọn ohun tí ó lè pa ènìyàn lára.
Amofin ni Cyril Ramaphosa ki o to di ọmọ ileegbimọ asofin to si ko ipa ribiribi ninu kikọ iwe ofin orilẹede South Africa lẹyin igbominira lọwọ awọn alawọ funfun.
Koda wọn din ẹran lati fi jẹ irẹsi jọlọfu ọhun, ti ohun gbogbo si n se yatayoto.
 Ọ ̀ pọ ̀ ìgbà ni mo sì ń yanu tán rẹ ́ rìn-ín .
Ṣé ó yẹ kí á pa alufaa ati wolii, ní ibi mímọ́ OLUWA?
Eyi ni wọn yoo ṣe agbeyẹwo rẹ lati mọ iru iranlọwọ ti o nilo.
“Nítorí náà àkókò kan ń bọ̀, tí wọn kò ní máa búra ní orúkọ OLUWA tí ó kó àwọn ọmọ Israẹli jáde kúrò ní ilẹ̀ Ijipti mọ́, 
Lai ti ẹ ni iyàwó, ọkùnrin ẹbi ọkọ lè ma ni ìfẹ́ si iyàwó ti ọkọ rẹ̀ kú.
Ẹ gbà pé n kò ni yín lára.
Ní ọdún mélòó kan sí i, ẹ óo gbógun ti ilẹ̀ tí ó ṣẹ̀ṣẹ̀ ń bọ̀ sípò lẹ́yìn ìparun ogun, orílẹ̀-èdè tí a ṣà jọ láti ààrin ọpọlọpọ orílẹ̀-èdè mìíràn sórí àwọn òkè ńláńlá Israẹli, ilẹ̀ tí ó ti wà ní ahoro fún ọpọlọpọ ọdún.
Oríṣun àwòrán, Alawe of Ilawe Ekiti Ninu iwe oloju ewe marun ọhun, ni Ọba Alabi ti n kesi gomina ipinlẹ Ọyọ pe igbimọ lọbalọba ni Ekiti koro oju si awọn ohun ti Alaafin mẹnuba ninu lẹta rẹ.
Gomina ọhun sọ pe ijọba yoo ṣe iwaadi finifini lori ọrọ naa lati mọ pato ọhun to ṣẹlẹ gan latari bi ọrọ ẹni ti ọrọ naa ṣoju rẹ ati ọrọ awọn ọlọpaa ṣe yatọ.
 Ó ní kí ti òun má bàa jẹ ́ òfo nílé orímóògùnjẹ ́ ni ó jẹ ́ kí òun jí owó rẹ ̀ gbé .
Mú wa bọ̀ sípò, OLUWA Ọlọrun àwọn ọmọ ogun!
Àṣa ṣì ṣúpó kò wọ́pọ̀ mọ laarin àwọn ti ó jade, àwọn ti ó ngbé ilú nla àti Òkè-òkun tàbi àwọn ti ó kàwé, ṣùgbọ́n ó wọ́pọ̀ laarin àwọn ti kò jade kúrò ni Abúlé àti àwọn ti kò kàwé.
Adari ajọ naa sọ wipe ni ipari osu kẹrin ọdun 2018, lawọn yoo palẹmọ gbogbo igbohunsafẹfẹ lọnọ atijọ, to si kilọ fun awọn ile-iṣẹ igbohunsafẹfẹ lati sapa wọn lati gbe iṣakoso orilẹede Naijiria lọnọ tiwantiwa larugẹ.
Ile igbimo asofin Naijiria ti pe ajo to n mojuto eto idibo lorile-ede Naijiria, (INEC) lati kede esi eto idibo aare ti o waye lojo kejila osu kefaa odun 1993(June 12, 1993), ki awon omo orile-ede yii le mo pato esi idibo ohun.
Odindin ọsẹ mẹfa ni wọn fi dibo yii kaakirir orilẹ-ede India ni eyi ti awọn ajọ eleto idibo ti fẹ ka tan bayii ti Modi si n lewaju ninu esi idibo to ti jade.
 iwe romu orí kẹrin ẹsẹ ikẹtadínlíágun títí de ikọkànlélógún ( romu 4 : 17-21 ) pẹlu fìdí re múlẹ ̀ pe láti inú ẹ ̀ sẹ ̀ àìgbọràn ti Ádámú ati eéfà Ọkùnrin àtì obìnrin akọkọ ṣẹ ̀ ni gbogbo ẹ ̀ dá ọ ̣ mọ ̣ ènìyàn ti di ẹlẹ ́ sẹ ́ , torí láti ara àwon méjéèjì ni gbogbo ọmọ ẹ ̀ dá ti ṣẹ wa .
IVF: Ìyá ìbejì se IVF mẹ́ta lókè òkun, ìkẹrin tó se ní Nàíjíríà, ló fi bímọ
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù 9th Assembly: Gbajabiamila fi èróńgbà rẹ̀ láti jẹ adarí ilé aṣojú ṣòfin hàn 31 Ẹrẹ̀nà 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 1 Ìgbé 2019 Oríṣun àwòrán, Facebook/Femi Gbajabiamila Àkọlé àwòrán, Ibo ile aṣoju ṣofin Aṣoju ṣofin Femi Gbajabiamila ti kede erongba rẹ lati jẹ adari ile aṣofin agba l'Abuja.
Kinni eero awọn ọmọ Naijriia lori ipadabọ konile-o-gbele?
Ojú rẹ ni yóo ṣe tí n óo fi fi àwọn aya rẹ fún ẹlòmíràn, tí yóo sì máa bá wọn lòpọ̀ ní ọ̀sán gangan.
Omidan Monica Dung to je okan lara awon to kopa ninu eto idanilekoo yii ni inu oun dun gan an ni fun anfani yii pelu imoran sawon obinrin lati dekun wiwa ise ti ko si ni igboro lasiko yii.
Orílẹ́-èdè 5 tí takọ-tabo kò gbọdọ̀ fẹnu ko ara wọn lẹ́nu Wo àwọn tó dipò ìlú mú tí wọ́n jẹ́jọ́ lórí dúkìa Ṣé ìwọ láyà ti o mọ òwe Yorùbá dáadáa?
 wọ ́ n yọ abala èyí tí wọ ́ n fi kun kúrò lati dáapadà ( c .
Bákan náà, tẹ̀gbọ́n tàbúrò ni ìyá tí ó bí wọn.
Hesekaya ọba ati Asaraya olórí ilé OLUWA ni wọ́n yàn wọ́n sí iṣẹ́ náà.
O si ti gba to owo to le ni miliọnu marun-un, N5,328,000.
“Kò sí ọmọ-ọ̀dọ̀ kan tí ó lè sin oluwa meji.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ẹrijiyan Ekiti ni Omi Erin wa Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Ẹrijiyan Ekiti ni Omi Erin wa 2 Ẹrẹ̀nà 2018 Omi Erin to wa ni ilu Erijiyan Ekiti jẹ omi ti wọn kii pa ẹja rẹ, nitori ti wọn ba se, ko ni jina gẹgẹ bi ọmọ ilu naa ti sọ.
aabo ti o peye mule si nipinle naa.
ilu, bẹẹ ni wọn gbọdọ na owo naa fun ohun ti wọn fẹ lo wọn fun ni pato.
Wọ́n gba rọ́bà rẹ̀, wọ́n fi ọ̀bẹ rẹ́ ẹ wẹ́lẹ́wẹ́lẹ́.
Dọlapọ, to ṣọrọ yii nibi ipade adura awọn obinrin to waye ni ilu Makurdi ni ipinlẹ Benue ṣalaye pe, adura kikankikan lawọn obinrin nilo bayii fun awọn ọmọ wọn obinrin, ki wọn ma baa pokii.
Lagos gas explosion: Afẹ́fẹ́ Gáàsì tó rọra ń yọ́ọ́ jò pa Ajibola lẹ́nu iṣẹ́ jórin-jórin
Àwa nìkan sì là wà ní àdúgbò náà.
16 Ọ̀wàrà 2020 Fídíò, Abayọmi Aranmọlatẹ, Dr Laser: Vagino Plasty àti iṣẹ́ abẹ ẹwà Obìnrin ló jẹ mí lógún12 Ọ̀wàrà 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Aisan ọpọlọ le wọle ti ọkọ wọn ko ba fi wọn lọkan balẹ.
– ikú rẹ̀ náà dún mi lọ́pọ̀lọpọ̀, nítorí oyíndayépọ̀ kò jẹ́ bẹ́ẹ̀ lára mi, kkìí fi ọ̀ràn mi ṣiré, bí ó ti wà ní ilé rẹ̀ nì, kìí ṣe kí ó ma wá bẹ̀ mí wò ni ààfin lẹ́ẹ̀kọ̀ọ̀kan tórí ìwọ̀nyí ni mo sì ṣe pe ìwọ ọmọ rẹ̀, Ìrìnkèrindò, lónìí wípé kí o má jẹ́ kí orúkọ ilé yín bàjẹ́ o.
Lẹ́yìn náà, ogun bẹ́ sílẹ̀ ní Geseri, láàrin àwọn ará Filistia ati àwọn ọmọ Israẹli.
Síbẹ̀, Abódiakọ-akọ́diabo ènìyàn ní ìtàn mìíràn láti sọ bí ó bá kan ti ẹ̀tọ́ àti ìgbé ayé; wọ́n ti jìyà oró, ìfipábánilòpọ̀, dáná sun wọ́n ní ààyè, bẹ́ wọn lórí àti yin ìbọn pa wọ́n, ìjọba kò fi torí gbogbo èyí ràn wọ́n lọ́wọ́ pẹ̀lú pé Ìjọba ti tari òfin Ààbò Ẹ̀tọ́ Abódiakọ-akọ́diabo Ènìyàn wọlé nínú oṣù Ẹrẹ́nà ọdún 2018.
Aare Muhammadu Buhari n lo si Accra ni orile-ede Ghana loni ojo Aje lati lo ba won sami ayeye odun mokanlelogota igbominira ti yoo waye ni Independence Square lojo Isegun, ojo kefa osu keta odun 2018.
Awọn ẹbi rẹ ni o tun ni arun ọpọlọ naa pelu ẹ, Balasubramanyam fi iyawo kan ati ọmọ meji ati aburo rẹ.
Àwọn àgbààgbà ìlú náà yóo mú ọkunrin yìí, wọn yóo nà án dáradára.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ijamba ọkọ-ofurufu ologun pa 'yan mẹjọ 15 Ẹrẹ̀nà 2018 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ijamba baalu to sẹlẹ lorilẹede naa ni ọdun 1992 pa eeyan mẹrinlelogun Ijamba baalu ologun kan ti pa eeyan mẹjọ lorilẹede Senegal bẹẹni eeyan mejila miran farapa .
Bẹẹ ba gbagbe, ọjọ Kọkanla osu Karun ọdun 2019 ni isẹlẹ naa waye nigba ti fidio kan gba ori ayelujara kan.
padanu emi re sinu isele ohun, ti opo eniyan miiran si farapa yanana.
 NLC ni awọn kọ afikun owo epo yii nitori ara n ni awọn ara ilu Oríṣun àwòrán, others Àkọlé àwòrán, Ọ̀pọ̀ ọmọ ẹgbẹ́ wa ló n tẹpo níye tó kéré sí iye ti PPPRA fi síta- IPMAN IPMAN kéde àfikún iye owó epo bẹntiróòlù di ₦162 wọ́n ni kìí ṣe #151."
“Nítorí náà, àwọn òkú yín tí ẹ dà sí ààrin ìlú yìí ni ẹran, ìlú yìí sì ni ìkòkò, ṣugbọn n óo mu yín kúrò láàrin rẹ̀.
Crystal palace rọ́ àlá burúkú fún Manchester United ní pápá ìṣiré “Theater of dreams” Willian pa itú méje ní ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ rẹ̀ àkọ́kọ́ fún Arsenal Manchester city, Chelsea figagbága ní Wembley Dele Alli ba Tottenham na Chelsea mọ'le Arsenal f'agba han Watford Chelsea wa ni ipo ikẹwa bayi ti Arsenal asi n tọ Everton lẹyin ni ipo keji.
 a ṣe àgbéjáde àwọn àjẹsára tí à ń gba ẹnu lò ní àwọn ọdún 1990 .
Ọlọpa sọ pe afurasi yii jẹwọ pe oun gba ẹ̀gbẹ̀rún lọna ẹ̀ẹ́dẹ́gbẹ̀ta naira lati ṣe iṣẹ ibi naa.
Fayose to jẹ ọkan gboogi ninu awọn alatako aarẹ orilẹede Naijiria, Muhammadu Buhari tun salaye siwaju sii wipe ko si bi awọn ọmọ orilẹede Naijiria yoo se ni igbagbọ to rinlẹ ninu ajọ to n gbogun ti ṣiṣe owo ilu baṣubaṣu lorilẹede Naijiria, EFCC nigbati ajọ yii kan naa to sọ ni osu kẹrin ọdun 2016 wipe ifunrasi ti ko lẹsẹ n lẹ ni ẹsun iwa ibajẹ ti wọn fi kan alagaajọ to n se kokari ijihin dukia oṣiṣẹ ilu, CCT, Umar atipe yoo nira diẹ lati fidi rẹ mulẹ nile ẹjọ yoo ṣe tun wa yipada maa gbe arakunrin kan naa lọ siwaju ile ẹjọ nitori ẹsun yii.
“Ẹnikẹ́ni ninu àwọn eniyan Israẹli, kì báà jẹ́ ọkunrin tabi obinrin, kò gbọdọ̀ sọ ara rẹ̀ di alágbèrè ní ilé oriṣa kankan.
Bakan naa lo tun fikun pe, ajọ eleto idibo gbọdọ fi olupẹjọ naa, eyiun ẹgbẹ oselu ANDP sinu eto idibo tuntun.
8 91922 Orilẹede Afganistan 1945 5.
Ẹ̀jẹ̀ Ríru, Ìfúnpá Gíga, Ìtọ̀ Ṣúgà, Wárápá, Àìsàn Ọkàn, Ọpọlọ Wíwú, Ojú Fífọ́, Ìdákọ́lẹ, Àpọ̀jù Ọ̀rá-Ẹ̀jẹ̀, àti bẹ́ẹ̀ bẹ́ẹ̀ lọ.
”Gege bi akonimoogba ohun, “ Eyi je idojuko tuntun fun mi, bee si ni
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 9ice: Ǹjẹ́ olórin tàkasúfèé yìí ń mu igbó bí àwọn òṣèré mìíràn?
Jesu wá bi wọ́n pé, “Ọpọlọpọ iṣẹ́ rere ni mo ti fihàn yín láti ọ̀dọ̀ Baba.
New Zealand: Lateef Alabi ní òun kò lérò pé agbébọn leè kọlu mọ́ṣálásí ní New Zealand
" Buhari fárígá, ó ní kò s'óṣìṣẹ́ ìjọba tó gbọ́dọ̀ rìnrìnàjò sílẹ̀ òkèèrè lọ́wọ́ yìí Ṣé lóòtọ́ ni Ọọ̀ni ilé ifẹ̀ ti parí aáwọ̀ lọ́balọ́ba l'Ékìtì?
Ninu ọrọ rẹ, Ọga ẹṣọ Amọtẹkun sọ pe lootọọ ni iwe ofin ilẹ Naijiria fawọn eeyan lanfaani lati ba ẹgbẹ k'ẹgbẹ to ba wu wọn ṣe, amọ ko fún àwọn ọdọ lagbara lati maa wọ iwọkuwọ tabi tabuku ede Yoruba."
nipa bi won se lo owo ati ohun alumọọni orile ede yii ni ilokulo.
Ọkan lara awọn aṣoju ẹgbẹ naa, Arabinrin Grace Oluwatoye kesi ijọba ati awọn agbofinro lati bojuto wahala ti awọn ọmọbinrin n dojukọ lasiko yii.
Kí OLUWA Ọlọrun wa ranti adura mi yìí ati gbogbo ẹ̀bẹ̀ tí mo bẹ̀ níwájú rẹ̀ yìí tọ̀sán-tòru, kí ó máa ti èmi iranṣẹ rẹ̀ lẹ́yìn nígbà gbogbo, ati àwọn ọmọ Israẹli, eniyan rẹ̀ pẹlu; máa tì wá lẹ́yìn bí ó bá ti tọ́ lojoojumọ, 
7 661180 Orilẹede Romania 17098 87.
Awọn ọmọ naa ti wọn jẹ ọmọ ọdun meji ni a gbọ pe wọn ku si inu omi adagun ti wọn ṣe lọjọ si inu ile wọn to wa ni ilu Mbala.
Sirajo tun tesiwaju pe , “Mo fẹ ki orile ede Naijiria pada si ibi ti agbègbè, ẹyà ati esin ko ni jẹ ipilẹ fun ohunkohun ti a nilo; Mo fẹ orile ede Naijiria ti won ti le yan ọ sipo tabi dibo fun ọ nile -isẹ tabi ni ilu  lati sin awọn eniyan nibikibi lorile ede Naijiria “.
Lọjọ Kọkanlelọgbọn oṣu Keje ọdun yi ni ajọdun ileya tọdun yi bọ si.
Ẹwẹ, aṣoju Naijiria ni Lebanon, Goni Modu sọ fun BBC pe awọn mọ nipa iṣẹlẹ naa awọn si n gbiyanju lati yanju ẹ.
Ọba mẹ́wàá ìgbà mẹ́wàá, wọ́n l’óun ló ni ilé-ayé.
gbe ati afurasi odaran miran to ja owo oja  egberun lona irinwo naira gba lowo abileko
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Operation Amotekun: Ẹgbẹ́ kan rọ Tinubu, láti sọ èrò rẹ lórí ọ̀rọ̀ Amọtẹkun 18 Sẹ́rẹ́ 2020 Oríṣun àwòrán, Facebook/Asiwaju Bola Tinubu Lẹyin ti ọpọ eekan nilẹ Yoruba ti sọrọ akin lati gbaruku ti eto ẹṣọ Amọtẹkun tawọn gomina ipinlẹ Yoruba ṣe ifilọlẹ rẹ, ẹgbẹ kan to n jẹ 'Save Lagos Group' ti ke pe Asiwaju Bola Tinubu pe ki oun naa sọ ero rẹ faye gbọ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Baby abandoned on dunmpsite: Mo ti bímọ mẹ́rin tẹ́lẹ̀ fún bàbá méjì nínú òṣí- Dupe Ogbomos Awọn banki ati ileeṣẹ aladani ko gbọdọ faaye gba ju ìdá ọgọta oṣiṣẹ wọn lẹẹkan naa, wọn si gbọdọ maa ṣiṣẹ laarin aago mẹsan owurọ si mẹta ọsan.
Badirat Ajoke sọ pé òun fínnú-fíndọ̀ fi ààfìn Oyo sílẹ̀ ni, wọ́n kò lé òun
Ọmọ China j'oyè fún ìgbà àkọ́kọ́ nílùú Kano Ohun mẹ́fà tí kò yẹ́ kí o gbàgbé nípa Gómìnà Ambode Irọ́ ni ò, òjò kìí fa àìsàn ibà - Dokita Ipinlẹ Ondo ni a gbe bi i to si gbe fun igba diẹ lati kekere rẹ.
Ẹgbe alatako ni agbara lopolopo, ti won ko si ni bo iwa ibaje mọlẹ bi o ṣe wọpọ ni isejọba aarẹ.
Nigba ti yoo fi di ọdun 2016, o fi oye ọgagun daa lọla.
Ènìyàn 653 míràn tún kún iye àwọn tó ní COVID-19 ní Nàìjíríà Ọwọ tẹ àwọn ọlọ́pàá tó fìyà jẹ obìnrin kan lọ́nà àìtọ́ n'Ibadan Obìnrin àti ọmọdé tó há sábẹ́ ilé tó wó ní Ebute Meta ti ń gba ìtọ́jú, LASEMA ń ṣàyẹ̀wò ilé náà lọ́wọ́ Nibayii eeyan 845 lo ti ṣe alaisi nipasẹ ajakalẹ arun naa lorilẹede Naijiria.
Bi awọn eeyan kan ṣe n foju aits wo igbesẹ ti wọn gbọ pe agba ọjẹ ẹgbẹ oṣelu naa, Bọla Tinubu gbe ni awọn kan n kan saara sii.
com Ija ọga ati ọmọ iṣẹ lo waye lọjọ Satide nigba ti ẹgbẹ agbabọọlu Manchester City gba alejo Arsenal ni papa iṣire Etihad.
Idà, ati ebi, ati àjàkálẹ̀ àrùn, ni n óo fi pa wọ́n run.
Akowe agba Scotland yoo tun sagbekale awon ohun ti o je ajo naa logun, lara eyi ti a ti ri igbaradi ipade igbimo olori ijoba awon orile-ede labe ajo naa, ti yoo waye losu to n bo nilu London, jijiroro lori awon ona ti a fi le sise papo, nipa eto ilana ofin, eto oro-aje, ayipada oju ojo ati awon oro miiran ti yoo sanfaani fun eto isejoba rere.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Baby abandoned on dunmpsite: Mo ti bímọ mẹ́rin tẹ́lẹ̀ fún bàbá méjì nínú òṣí- Dupe Ogbomos O ní ẹ̀tọ́ rẹ̀ ni gẹ́gẹ́ bi ìgbákejì òun láti dúro ni apá ibi ti òun tò si lásìkò ti òun bá Laycon jà.
Inú mi dùn sí iwọ́de EndSARS tàwọn ọdọ́ Nàìjíríà ń ṣè - Ooni Ogunwusi EndSARS protest in Nigeria: Mr Macaroni, Falz, Wizkid, Tiwa Savage àtàwọn míì ṣe ìwọde Owó oṣù tuntun fáwọn olùkọ́ tí Buhari kéde yóò dá aáwọ̀ sílẹ̀- Wike Kò gbọdọ̀ sí ìfẹ̀họ́núhàn EndSARS ní ìpínlẹ̀ Rivers - Gomina Wike Ọna lati dena itankalẹ coronavirus lasiko iwọde #EndSARS Ọjọgbọn Faduyile ṣalaye pe ko ṣi ṣiṣe ko si ai ṣe lori ọrọ ate dena coronavirus ju pe ki awọn eeyan maa tẹle ilana itakete si ara ẹni lọ bi wọn ti n ṣe iwọde.
Àlejò àpàndodo ni Fayoṣe, a kò fìwé pèé - Afuye Bàbà ọmọ ọdún 75 kó HIV ran ọmọ ọdún 14 lẹ́yìn tó fi ipá báa lò Kìí ṣe gbájúẹ̀ nìkan lọmọ Nàìjá ń ṣe lókè òkun!
John Amanam: Ìfẹ́ tí mo ní sí àbúrò mi ló sọ mi dí ẹni tó ń ṣe 'Prosthetic' báyìí Owatapa ti Itapa Ijesha, Wolii Olapade Agoro jáde láyé Àwọn jàǹdùkú gbá mi lójú, wọ́n lù mí, wọ́n kán apá olóyè mi- Adelé Ọba Alade Idanre Sanwo Olu àti Okowa dẹwọ́ ìséde ní Eko àti Delta pẹ̀lú àlàyé tuntun '' Mo gba yin nimọran lati ṣiṣẹ karakara, ki ẹ si ṣiṣẹ yin gẹgẹ bi iṣẹ, amọ ti ẹnikẹni ba fi ọwọ kan yin, ẹ gba ara yin la.
Ní ọdún 2013 gangan ló gbérasọ.
Ṣugbọn idà OLUWA ṣe lè dákẹ́ jẹ́ẹ́, nígbà tí Oluwa fún un ní iṣẹ́ láti ṣe?
Fún àpẹẹrẹ, wọ́n dájọ́ ẹ̀wọ̀n ọdún méjìlélọ́gbọ̀n fún ajàfẹ́tọ̀ọ́ ènìyàn Germain Rukiki fún “ìdarapọ̀ mọ́ ìgbìyànjú ìrúlùú, “jíjin ètò ààbò ìlú lẹ́sẹ̀, àti ìṣọ̀tẹ̀” ní 2018 nítorí pé ó ṣe àkọsílẹ̀ àwọn ọ̀nà tí ìjọba Nkurunziza ń gbà fìyà jẹni.
igbodegba, Garba Shehu, ti kede wipe won ti ko awon osise alaabo lo si
Ìjọ Hàkíkà: O leè sùn ti ìyàwó mi, kí ń sùn ti tìrẹ
Awọn to ku ni: FCT-27 Oyo-10 Kaduna-5 Ondo-2 Kano-1 Lati bi ọsẹ kan ni iye esi ti ajọ naa n gbe sita ti n lọ soke diẹdiẹ, eyi to n kọ awọn alaṣẹ eto ilera lomiinu pe o ṣe e ṣe ki aarun naa tun burẹkẹ si lẹẹkeji.
Eyi tumọ si pe ogoji ọdun ni awọn olukọ yoo maa lo lẹnu isẹ bayii, ki wọn to fẹyin ti.
Iwọde #EndSARS ti gberasọ niluu Ibadan naa lẹyin ti o ti mulẹ tan niluu Eko.
Ìpàdé Commonwealth; Ọbabìnrin fẹ́ kí àrẹ̀mọ rẹ̀ gba àsẹ
Àwọn èèyàn fi ìtara ba ilé ìjọsìn jẹ́ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Aeroplane House: Látọdún 1999 ni mo ti bẹ̀rẹ̀ kíkọ́ ilé yìí fún ìyàwó mi ọ̀wọ́n Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Coronavirus: Pásítọ̀ Adeboye ní òun faramọ́ ìmọ́tótó, ṣùgbọ́n àwàdà ni ìgbésẹ̀ àwọn ìjọba lágbáyé láti kojú Coronavirus
Njẹ ẹgbẹ APC mọ nipa wahala naa gẹgẹ bi ẹsun ti PDP fi kan an?
Nítorí mo jẹ́rìí pé wọ́n sa ipá wọn, wọ́n tilẹ̀ ṣe tayọ agbára wọn, tìfẹ́tìfẹ́ ni wọ́n sì fi ṣe é.
 Àrùn náà ti wáyé lára àwọn ọmọ ènìyàn jálẹ ̀ ìtàn ẹ ̀ dá .
DSS ti fi igbákejì gómìnà CBN tó ní gómìnà kan ní Àríwá Naijiria ní Ọ̀gá Boko Haram sílẹ̀ ‘Àwọn òlóṣèlú kò ní ìwà ọmọlúwàbí ló jẹ́ kí wọ́n má a lọ láti ẹgbẹ́ òṣèlú kan lọ sí òmìràn’ Wo ọ̀nà márùn ún tí o lè gbà dáàbò bò ara rẹ lọ́wọ́ ìjàmbá láì gbé ìbọn!
Awon eyan jankan-jankan ni o tele gomina Ganduje lo si ipinle Abia fun abewo ohun, ti o fi mo, Emir ilu Kano, Alhaji Muhammdu Sanusi II.
Ìbẹta, Oba Lamidi Adeyemi, Alaafin Oyo pé ọdún méjìlá; nkan tó yẹ kí o mọ̀ nípa wọn nìyíì
lati tete dibo ki aago to re kọja.
O tun gbosuba kare lai fun awon ile-ise aladani, papaa julo igbimo Kano Emirate Council ti o n kun ijoba lowo lati ri daju pe awon omode je anfaani eto ilera to peye nipinle naa.
Rabuṣake bá dìde dúró, ó sì kígbe ní èdè Juda, ó ní, “Ẹ gbọ́ ohun tí ọba ńlá, ọba Asiria wí: 
Jẹ́ kí ojú ó ti àwọn tí wọn ń ṣe inúnibíni mi,ṣugbọn kí ojú má tì mí.
Ajo INEC yoo bẹrẹ  si maa kede abajade esi idibo ni deede aago
Orílẹ̀-èdè Amẹrika kò ṣọ́ wọlé-wọ̀de mi àti ìdílé mi- Atiku fèsì Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Nigeria School resumption Update: Bí àwọn akẹ́kọ̀ọ́ ṣe ń wọlé, wo bí o ṣe lè dáàbò bo ọmọ rẹ níléèwé26 Owewe 2020 Fídíò, Wole Soyinka sọ ìdí tó fi ni òun a fi màálù Fulani ṣe súyà fáwọn èèyàn abúlé23 Owewe 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
 A ti kowe sijoba apapo ki won tun igbimo olubanidamoran yan, pelu igbimo alayewo ise akanse ki ipinnu ijoba si rere lori ekun yii le di mimuse ki a si le fokan tan awon alajosisepo wa.
Akọwe ijọba ipinlẹ naa, Rafiu Ajakaye lo fi ọrọ naa lede ninu atẹjade kan to fi ṣowọ si BBC Yoruba.
O salaye pe, baba iya oun ati ọkọ aburo iya oun, tii se ‘uncle ’ oun maa n fi owo ati ẹbun fa oun loju mọra, lẹyin ti wọn ba se ifẹkufẹ wọn tan.
Aare Buhari ti o je aare lodun 2015 ,ni o kede lojo Aje lose to koja lati dije leekeji fun ipo aare lodun 2019.
Eto Akọmọlede ati Aṣa Yoruba, ti yoo maa waye lẹẹkan lọsẹ loju opo ikanni BBC Yoruba, yoo maa kọ wa ni ede ati asa wa, ko maa ba parun.
Ọlọrun tí ó gbé agbára wọ̀ mí,tí ó sì mú ọ̀nà mi pé.
Eyi jẹ diẹ ninu itan to mu ki June 12 ṣe pataki fun iran Yoruba.
Oluwo tẹsiwaju pe, eto aabo ara ilu jẹ ojuṣe akọkọ fun ijọba.
Amọṣa, awọn aṣaaju ẹgbẹ oṣiṣẹ ti kilọ fun ijọba apapọ pe ko gbọdọ fi ọbẹ ẹyin jẹ awọn oṣiṣẹ niṣu lori adehun naa.
Aya oloogbe Ajimobi, ẹni to gba pe lootọ ko tii yẹ ki oun maa sọrọ síta bayii lasiko ti oun n kẹdun iku ọkọ oun lọwọ, tun salaye pe, o di dandan ki oun sọrọ sita nitori aimọye iṣẹlẹ aidaa to n waye lati ọdọ ijọba ipinlẹ Oyo.
awon omo orile-ede Naijria lati tu yaya, tu yaya sita lola ojo Abameta(Satide)
Bàbá rẹ̀ jẹ́ òṣìṣẹ ilé iṣẹ́ jórin-jórín, nígbà ti ìyá rẹ̀ Bose Ogulu jẹ́ ń ṣe iṣẹ́ ògbífọ̀.
Iku wọn ko gbọdọ ja sasan nipa sise agbekalẹ isejọba rere eyi ti wọn ku fun.
Àwọn tí ó gbàgbọ́ láì rí mi ṣe oríire!
Ondije omo orile-ede Cameroon marun un to n kopa ninu idije Commonwealth Games  to n lo lowo lorile-edei Australia, ni won ko ri mo bayii.
Ija laarin awon ọmọ ẹgbẹ awakọ NURTW ni Idumọta ti gbẹmi eeyan kan
Orílẹ̀-èdè Nàìjíríà tí ní àkọsílẹ̀ àwọn ènìyàn ẹ̀tàléláàdọ́wàá to tún ṣẹ̀ṣẹ̀ ní ààrùn covid-19 ti àpapọ̀ gbogbo ibi tí ǹkan dé dúró ní Nàìjíríà báyìí sì ti di ẹgbẹ̀rún márùn-ún àti méjìlélọ́gọ́jọ.
Ìdí ti a fi kọ̀ láti fi El-ZakZakky sílẹ̀ -Ileeṣẹ Aarẹ Buhari Ìdí ti a fi kọ̀ láti fi El-ZakZakky sílẹ̀ gẹgẹ bi ilé ẹjọ ṣe paṣẹ rẹ - Ileeṣẹ Aarẹ.
Kí ni ẹ óo máa wí nígbà tí OLUWA bá mú àwọn tí ẹ fi ṣe ọ̀rẹ́,tí ó fi wọ́n jọba le yín lórí?
Ìyá àádọ́rin ọdún sọ bí ọkùnrin ọdún márùndínlọ́gbọ̀n ṣe fipá bá òun lòpọ̀ Ẹ wo ìṣẹ̀lẹ̀ nípa ẹ̀sùn ìfipábánilòpọ̀ tí wọ́n fi kan D'banj ní sísẹ̀-n-tẹ̀lé 'Màálù tó bá tàsẹ̀ àgẹ̀rẹ̀ níwájú ilé mi, ó dẹran àsun!
Bẹẹ naa ni o tun sọ pe awọn meji ni o n kawe lati gboye ọmọwe (PhD) ni fasiti NOUN bayii.
“Nítorí pé àwọn eniyan wọnyi kọ omi Ṣiloa tí ń ṣàn wẹ́rẹ́wẹ́rẹ́ sílẹ̀, wọ́n wá ń gbọ̀n jìnnìjìnnì níwájú Resini ati ọmọ Remalaya, 
Buruji Kashamu jẹ́ ènìyàn tó nífẹ̀ àráàlú - Gómínà Dapo Abiodun Mo ti buwọ́lu àdínkù owó orí nítorí ìrọ̀rùn àwọn èèyàn ìpínlẹ̀ Ogun lásìkò Covid 19- Dapo Abiodun Baba Obasanjọ kò ní àrùn Coronavirus- NCDC Bákan náà ni Kolawole fún ẹbi náà lówó bí mínísítà ṣe ran, o ní kò sí ọmọde ti kò yẹ láì lọ sí ilé ìwé.
5M ti pọ̀ jù fún owó fọ́ọ̀mù ìdìbò abẹ́lẹ́ sípò gómìnà APC
Lọpọ igba ni wọn ka oogun oloro mọ ọ lọwọ eyi to jẹ ki wọn fi ọwọ sinkun ofin mu un.
“Pe ẹnìkan nisinsinyii;ǹjẹ́ ẹnikẹ́ni dá ọ lóhùn?
Bí ẹni tí a ti là mọ́lẹ̀, tí kò lè dìde, bá ń kígbe fún ìrànlọ́wọ́ ninu ìnira,dájúdájú o kò tún ní gbé ìjà kò ó?
Ó hàn gbangba pé ẹ̀yin ni ìwé tí Kristi kọ, tí ó fi rán wa.
Nàìjíríà kò nílò sénétọ̀ kankan- Fayemi Jessica Nabongo ni obìnrin àkọkọ nílẹ Adúláwọ tó rin gbogbo àgbáyé.
Agbófinró mú ọ̀dọ́mọkùnrin 57 níbi ètò ìgbaniwọlé fún ìbálòpọ̀ akọ-sí-akọ
Onimọ yii sọ pe o jẹ ilana ọlọgbọn nitori pe iye ti wọn ro pe awọn maa ri lowo ti wọn pa wọle lọdun to kọja pọ kọ ni wọn ri nitori ọrọ aje Naijiria.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ilé ẹjọ́ fún Sẹ́nétọ̀ Adeleke lọ́jọ́ mẹ́rin láti pèsè ìwé ẹ̀rí Fásitì 28 Agẹmo 2018 Oríṣun àwòrán, Ademola Adeleke/Facebook Àkọlé àwòrán, Adeleke ni yóò kojú ọgbẹni Gboyega Oyetola ti ẹgbẹ òṣèlú APC nínú ìdìbò Gómìnà ìpínlẹ̀ Osun Ilé ẹjọ́ gíga ti ìpínlẹ̀ Ọṣun ti ké sí olùdíje fún ipò Gomìnà ni ẹgbẹ́ òṣèlú PDP tó tún jẹ́ Sẹ́nétọ̀ báyìí nílé ìgbìmọ̀ aṣòfinláti wá fi ìwé ẹ̀rí rẹ̀ hàn.
 láìpẹ ́ ó di èyí tí ẹ ̀ sìn kìí ṣe àkòrí rẹ ̀ .
Wọn ko tilẹ jẹ ko fa oludije kalẹ ni ipinlẹ Rivers lasiko idibo to kọja.
O ni owo ti oun ba tọrọ yii ni oun ati iya agba maa jọ fi n jẹun.
"Obìnrin kò gbọdọ̀ jáde alẹ́ mọ́ ní Kano Wo ìdí to fi gbọdọ̀ yàgò fún Bobrisky, akọ tó ń ṣe bíi abo Tasiu fi kun un pe ""Awọn yoo fi wọn si ahamọ titi tawọn obi wn yoo fi yọju siwa."
O ṣeleri fun wọn pe oun maa mojuto ipese igbeaye irọrun sii fun wọn lasiko yii paapaa lasiko igbaradi de idije.
Ẹ̀sùn ìfipábánilòpọ̀: Orí Twitter ló ti bẹ̀rẹ̀, ikú ló já sí Iléẹjọ́ fi Ọ̀jọ̀gbọ́n tó bèérè fún ìbálòpọ̀ ní fásitì OAU pamọ́ sọ́gbà ẹ̀wọ̀n Àwọn aláṣẹ kéde ìséde lọ́gbà fásitì Ibadan Efunjoke Coker: Abiyamọ́ tó ṣé atọna àwọn akẹ́kọ̀ọ́bìnrin Queens College Àkọlé àwòrán, Ọjọ gbogbo ni t'ole.
Èyí ni yóo jẹ́ ààlà ilẹ̀ náà ní apá ìhà àríwá.
A tun ri ka ninu atẹjade ti EFCC fi sita pe nigba tawọn ọmọ ilẹ China yii ri pe awọn oṣiṣẹ ajọ naa ko jawọ ninu iwaadi wọn, ni wọn ba nawọ aba lati fun wọn ni abẹtẹlẹ ọgọrun miliọnu naira ki wọn ba le gbagbe ọrọ naa.
ede Naijiria INEC ti kede abajade idibo aarẹ to waye ni Olu-Ilu Abuja, FCT.
Biṣọọbu Oyedepo ni Ọlọrun sọ fun oun pe ilọrọ ninu Oluwa kii ṣe ileri, kii sii ṣe ọrọ adura ati aawẹ.
"Oríṣun àwòrán, Alamy Stock Photo Àkọlé àwòrán, Ajọ agbaye woye pe ọpọ awọn to n gbe ni igboro ni orilẹede Naijiria lo n gbe awọn agbegbe ti ko bojumu Ìṣẹ́ ati oṣi ""ko parapọ rara"" Ọpọ̀ lo gbagbọ pe aidọgba n pọ si lojoojumọ."
Wọn ko bikita boya onibara ni ọ, tabi bẹẹkọ.
Ki o to di igba naa, a ti paṣẹ pasitọ ti ọrọ yi kan ki o maṣe kopa ninu iwaasu kankan.
Amọ awọn agbẹjọrọ to fi ẹsun kan an sọ wi pe ẹwọn gbere lo tọ si i fun iya ati gbogbo iwa aitọ to wu si awọn obinrin, ti ko si ronupiwaa.
"Adura wa ni wi pe, ki ẹgbẹ oṣiṣẹ ma doju ti awọn ọmọ Naijiria, pẹlu igbesẹ ijọba lori ọwọn gogo owo epo bẹntirol ati ina mọnamọna.
 bí ó bà sì dì ale gbogbo won a pate eko won sì ojú kan .
Sina Rambo ati B red lorukọ awọn ọmọ Ademọla mejeeji tawọn naa n kọ orin.
iwa ọdaran ( International Criminal Court ICC) ti fi iwe ẹsun  ransẹ  si ogbeni Bashir lati tako iwa ogun ati
Rògbòdìyàn bẹ sílẹ lọjọ òmìnira àádọ́rin ọdún ilẹ China - BBC News Yorùbá BBC News, YorùbáFò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù China - Rògbòdìyàn bẹ sílẹ lọjọ òmìnira àádọ́rin ọdún ilẹ China 1 Ọ̀wàrà 2019 Àkọlé àwòrán, China - Rògbòdìyàn bẹ sílẹ lọjọ òmìnira àádọ́rin ọdún ilẹ China Loni, ọjọ kinni, oṣu kẹwaa, ọdun 2019 naa ni orilẹ-ede China n sami ayajọ ominira aadọrin ọdun lẹyin ominira.
Agbẹnusọ fun ijọba orilẹede naa, Guy-Bertrand Mapangou ti sọ fun BBC pe awọn ti mu awọn ọmọ ogun mẹrin ninu marun to gbe igbeṣe naa,to si ni awọn si n wa ẹni ikarun.
Rehoboamu jẹ́ ọmọde nígbà náà, kò sì ní ìrírí tó láti dojú ìjà kọ wọ́n.
Abrahamu jẹ́ ẹni ọgọrun-un (100) ọdún nígbà tí a bí Isaaki fún un.
Lẹ́sẹ̀ kan náà baba ọmọ náà kígbe pé, “Mo gbàgbọ́; ràn mí lọ́wọ́ níbi tí igbagbọ mi kù kí ó tó.
Adajọ agba ile ẹjọ to ga ju lọ lorilede Naijiria ni Ọgbẹni Tanko.
Gomina ipinle Kogi, Yahaya Bello , salaye idi ti awon alakoso egbe se pinnu lati fi kun akoko to ye ki awon alakoso egbe pari.
Aba yi, to nii se pẹlu eto inawo nilẹ Amẹrika, lawọn asofin ilẹ naa gbọdọ buwọlu, ko to di pe aarẹ Donald Trump fọwọsi, eyi si gbọdọ waye ko to di aago mejila oru ọjọ ẹti to kọja, amọ igbesẹ yi ni ko seese, ti ọrọ naa si di kọ, tawọn asofin ko si lee fẹnu ko lori ilana ti aba eto ẹnawo naa yoo gba, eyi to sokunfa bijọba ilẹ Amẹrika se gbe ilẹkun rẹ ti fun igba diẹ na.
Ìwọ ni mo kígbe pè, OLUWA,ìwọ ni ààbò mi, má di etí sí mi.
Oniruru ahesọ ọrọ lo waye lori ohun ti Fatai Akinbade ti ẹgbẹ oṣelu ADC, Moshood Adeoti ti ẹgbẹ oṣelu ADP ati Iyiọla Omiṣore ti ẹgbẹ oṣelu SDP fẹ sọ ni ko ye awon eeyan.
Awọn agbabọọlu naa ko wo ti ojo rara, nṣe ni wọn yọ ti wọn si n jo pẹlu ife ẹyẹ naa lọwọ wọn.
Aworan abẹwo Aarẹ Buhari si ipinlẹ Plateau
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Russia 2018:Super Eagles ti kẹ́kọ̀ọ́ nínú ìdíje tó kọjá Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Lórí ìgbéyàwó mi, ẹ̀ ṣáà jẹ́ kó wà báyìí' Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Abala keji ifẹsẹwọnsẹ laarin Juventus ati Lyon naa to yẹ ko waye lọjọ kan naa ko ni waye mọ.
Àtẹ̀jadé náà sí sọ wipe gbogbo àwọn ti wọn kopa ninú MMM ti mọ nipá ewu to wà nibẹ ki wọ́n ó tó ti ẹsẹ̀ bọọ́.
Wíwọ̀n ni o óo máa wọn oúnjẹ tí o óo máa jẹ, ìwọ̀n oúnjẹ òòjọ́ rẹ yóo jẹ́ ogún ṣekeli, ẹ̀ẹ̀kan lojumọ ni o óo sì máa jẹ ẹ́.
Nipasẹ iṣẹ iwaadi iroyin to rinlẹ ni BBC News Yoruba fi ṣawari ibudo ti wọn ti n fi ẹgbẹrun mẹrin naira ra ibo ni ilu Ado Ekiti.
Laipẹ yii ni Adesina jawe olubori ninu iwadii ẹsun magomago ti wọn fi kan an.
Kí Oluwa alaafia fúnrarẹ̀ fun yín ní alaafia nígbà gbogbo lọ́nà gbogbo.
Kí ẹ gbadura kí ó má jẹ́ àkókò tí òtútù mú pupọ.
Ẹgbẹ́ àwọn òṣìṣẹ́ elétò ìlera, JOHESU bẹ̀rẹ̀ ìyanṣẹ́lódì káàkiri Nàìjíríà Egberin ọtẹ lọrọ iyanṣẹlodi awọn oṣiṣẹ eleto ilera lorilẹede Naijiria yii o.
OLUWA Pàṣẹ Pé Kí Àwọn Eniyan Israẹli Kúrò ní Òkè Sinai.
Ọ̀rọ̀ ẹnu eniyan burúkú a máa mú un bíi tàkúté,ṣugbọn olódodo a máa bọ́ ninu ìyọnu.
Zoom Wedding: Àwọn ọkọ àti ìyàwò ló ní àwọn kò leè sún ọjọ́ ayọ̀ wọn síwájú.
Oríṣun àwòrán, @omotimehinnelso Amọ agbẹjọro rẹ, Ọgbẹni Oyewole sọ pe oun yoo sọ fun ileẹjọ lati paṣẹ pe ki EFCC fi silẹ.
Lara ẹsun naa ni ọkan to ni se pẹlu iku awọn eeyan meje kan, to fi mọ arakunrin kan ati awọn ọmọ rẹ meji ti wọn pa lọjọ Abamẹta, lẹyin ikọlu to waye laarin ikọ Amọtẹkun pẹlu awọn agbebọn ni Aiyete Ibarapa.
Buhari lo fidi ọrọ naa mulẹ nigba to n ṣe ipade pẹlu awọn Aarẹ Naijiria tẹlẹ ri.
Ṣugbọn tí a bá ti yẹ ara wa wò, a kò ní dá wa lẹ́jọ́.
Ó ní, ‘N óo fún ọ ní ọpọlọpọ ọmọ, n óo sì sọ ọ́ di ọpọlọpọ ẹ̀yà, ati pé àwọn ọmọ ọmọ rẹ ni n óo fi ilẹ̀ náà fún, yóo sì jẹ́ tiwọn títí ayé.
Nígbà tí àwọn ati baba wọn rí èyí, àyà wọn já.
Apola Orukọ ni olukọ wa sọrọ ni kikun le lori.
Àwọn ọmọ Elamu jẹ́ ẹgbẹfa ó lé mẹrinlelaadọta (1,254)
BBCCopyright: BBC Ile igbimọ aṣoju-ṣofinImage caption: Ile igbimọ aṣoju-ṣofin Article share tools Facebook Twitter ṢàpínlòView more share options Share this post Copy this linkKà síwájú síi nípa àwọn ìtọ́kasí wọ̀nyí.
Nígbà tí Modekai gbọ́ ìdáhùn yìí láti ọ̀dọ̀ Ẹsita, 
11 Kíyèsíi, ó tọ̀nà nígbàtí o bẹ̀rẹ̀; ṣùgbọ́n ìwọ bẹ̀rù, àti pé àkókò náà ti kọjá, kò sì tọ̀nà mọ́ nísìsìyí;
Òun ni ó bí Dúró fún Orímóògùnjẹ́.
Nítorí náà, sọ fún àwọn ọmọ Israẹli pé, ‘Èmi ni OLUWA, n óo yọ yín jáde kúrò lábẹ́ ẹrù wúwo tí àwọn ará Ijipti dì rù yín, n óo yọ yín kúrò ninu ìgbèkùn wọn, ipá ni n óo sì fi rà yín pada pẹlu ìdájọ́ ńlá.
Nigeria Police recruitment 2020: Ṣé àbáwọle sójú òpó NPF policerecruitment.
Sanwo-Olu pèsè ìpàgọ́ tó wà ní Igando fáwọn tí iná jólé wọn ní Abule Egba láti gbé Ẹ̀yin gómìnà Yorùbá, ẹ gbé òfin kalẹ̀ láti ti Amotekun nídìí, kí àròyé leè dópin - Falana Mọ̀ síi nípa ǹkan tí o lè ṣe láti dènà ibà Lassa Oxford English Dictionary: Ọ̀rọ̀ 28 túntun ti wọ́n fi kún-un lọ́dun 2020 Amọ o fikun pe, ajọ naa ti bẹrẹ si ni lo ọna miran lati fi ṣiṣẹ pọ pẹlu awọn ajọ to n gbogun ti iwa ibajẹ ni ilẹ okeere lati ri wi pe Minisita fun epo bẹntirolu tẹlẹri naa, pada wa sile lati wa jẹjọ ẹsun iwa ibajẹ.
Ẹ̀yin ọmọ ìta tó ní Funke Akindele ra ilé fún mi, irọ́ ni o - Ajirebi FBI jí Hushpuppi gbé ní Dubai ni- Agbẹ́jọ́rọ̀ Ramọni Igbalode Ó di gbéré!
Ní ọjọ́ kan, Jesu lọ sí orí òkè, ó lọ gbadura.
Òun níí ṣe orí fún gbogbo àwọn ẹ̀mí ojú ọ̀run, ìbáà ṣe ìjọba tabi àwọn aláṣẹ.
Ní ọdún jubili, ẹni tí ó ra ilẹ̀ náà yóo dá a pada, ẹni tí ó ni ín yóo sì pada sórí ilẹ̀ rẹ̀.
Ṣugbọn oluranlọwọ fun Aarẹ Buhari Bashir Ahmad fesi sọrọ Omotola, o ni ki o ye ṣaroye mọ nitori awọn ti wọn n ṣiṣẹ rowo lọna totọ ko ṣaroye, bẹẹ ni wọn ko si le sọ pe Naijiria da bi ọrun apaadi.
Gbogbo wọn ni wọ́n súre fún ọba, wọ́n sì pada sílé pẹlu inú dídùn; nítorí gbogbo oore tí OLUWA ti ṣe fún Dafidi, iranṣẹ rẹ̀, ati fún àwọn ọmọ Israẹli, eniyan rẹ̀.
Gẹ́gẹ́ bi ọ̀gá agbẹnusọ ọlọ́pàá ìpińlẹ̀ Eko Muyiwa Adejobi ṣe sọ, ìṣẹ̀lẹ̀ náà wáye ni ọjọ́rú, ọjọ́kejìdínlogún, oṣù kọkànlá ọdún yìí.
Olùkọ́ fásitì méjì ń bèèrè ìbálòpọ̀ lọ́wọ́ akẹ́kọ̀ọ́ fún máákì Fídíò rèé nípa bí Aláké tuntun ṣe ń gba ìwúre lábẹ́ Olúmọ kó tó gba adé Princess salaye pe oun maa bọ ẹnu oun ati ti aburo oun, pẹlu sisan owo ile ati ileewe aburo oun, lo mu ki oun gba idi wiwa ọkọ akero lọ.
Ẹ pada s'ori ise, kẹ si fun gbogbo wa l'oriyin.
“Bẹ́ẹ̀ ni inú mi yóo ṣe máa ru si yín, tí n óo sì bínú si yín títí n óo fi tẹ́ ara mi lọ́rùn.
Láti ayé àtijọ́ ni orílẹ̀-èdè ọ̀hún ti wà,orílẹ̀-èdè alágbára ni.
Iroyin so pe iwe- owo ipinle Benue to wa ni ile ifowopamo meta ni ajo to n mojuto sise owo ilu basu-basu, EFCC ti gbese le lojo Isegun.
Bí o bá ń gbọ́ ti OLUWA, OLUWA yóo pa ìlérí tí ó ṣe nípa mi mọ́, pé arọmọdọmọ mi ni yóo máa jọba ní Israẹli níwọ̀n ìgbà tí wọ́n bá pa òfin òun mọ tọkàntọkàn, pẹlu òtítọ́ inú.
Amasaya ọmọ rẹ̀ sì jọba lẹ́yìn rẹ̀.
5% láti 5% lẹ́yìn tí ààrẹ Buhari buwọ́lu àbá ètò ìnáwó Àwọn sẹ́nétọ̀ Nàìjíríà fa ìbínú yọ 'torí N2Miliọ̀nù owó àjẹmọ́nú Kérésì tí wọ́n fún wọn Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Rebecca Skippage lo le iwaju awọn ti o ṣe iwaadi yi ti o si sọ wi pe bi awọn oniroyin ti ṣe gbe iroyin nipa awọn iku wọn yi jade ṣe afihan iha ti awọn eeyan kọ si iru iwa bayi.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Texas Shootings: Wọ́n ti pa ẹni to yìnbọn pa àwọn ará Texas márùn ún -ọlọ́pàá 1 Owewe 2019 Oríṣun àwòrán, Reuters Àkọlé àwòrán, iku omi lo n pa omuwẹ lọrọ agbofinro to kọkọ ku nibi iṣẹlẹ Texas Ẹni marun un lo ti jẹ Olọrun nipe ninu iṣẹlẹ naa bayii - ọlọpaa.
Oríṣun àwòrán, @thefemifela Àkọlé àwòrán, Funmilayo Ransom Kutijẹ obinrin bi okunrin nigba aye rẹ Ni ọdun 1978 ni awọn ọmọ ologun ti Funmilayọ lati aja kẹta ni ile ọmọ rẹ, Fela Anikulapo ti wọn pe ni Kalakuta Republic.
Liz Da Silva: Oríṣun àwòrán, Liz Da Silva O loju ẹni to lee gbagbọ pe ọmọbìnrin yii kii ṣe ọmọ Naijiria rara, debi pe yoo jẹ ọmọ Yoruba, ọmọ bibi orilẹ-ede Togo nii ṣe.
Ìwọ gbàgbọ́ pé Ọlọrun kan ní ń bẹ.
Se Yoruba bọ wọn, ọjọ kan ni ti ole, ọjọ kan  ni  fun
Ìyá Siasia kúrò lákàtà àwọn ajínigbé lẹ́yìn oṣù méjì ààbọ̀ Ẹ yéé purọ́ kiri!
Coronavirus tún ti ṣe ọṣẹ́ lórí iṣẹ́ líla ojú ọ̀nà relùwe láti Eko sí Ibadan - Ìjọba àpapọ̀ Àrùn Coronavirus fa'lẹ̀ya láwọn ìletò aláwọ̀dúdú ní Amẹ́ríkà Nígbà ogun, gbogbo aráàlú máa ń kó ohun tí wọ́n bá ní síta ni."
Modekai bá lọ, ó ṣe bí Ẹsita ti pàṣẹ fún un.
Ó ń sọ ọ̀rọ̀ yìí fún wọn kedere.
Tí kìí bá ṣe fún ìṣẹ̀dá ara ọmọ ènìà ni, a kò lé gbé ilé-aiyé yìí ju ọjọ́ méjì sí mẹ́ta lọ.
Ìjọba Oyo fẹ́ mọ ikú tó pa akẹ́kọ̀ọ́ UI níléeṣẹ́ tó ń ṣe ọṣẹ Àwòkọ́ṣe ìwà ìrẹ̀lẹ̀, òtítọ́ àti olùfẹ́ mẹ̀kúnnù ni Ayo Fasanmi - Ìjọba Osun Boko Haram da ìbọn bo ọkọ̀ gómìnà Borno, ẹ̀ṣọ́ àláàbò rẹ̀ farapa Ìtàn ọba Yorùbá tí wọn yẹgi fún torí ó jí ọmọ gbé ṣe ètùtù Lẹyinorẹyin, ọrọ naa to ọmọ Ọba Dubai leti, o si ti ṣeleri lati gbe owo naa san.
Awọn obinrin aboyun, ti wọn ti ile-iwosan naa pa ṣe apejuwe awọn owo ti wọn n gba nile iwosan naa bi ohun ibanujẹ ati pe ojẹ ohun irẹjẹ fun ọpọlọpọ ninu wọn.
Irọ́ ni pe a ti pa mẹ́ta nínú àwọn Shiite -Ileeṣẹ ọlọ́pàá Naijiria Lónìí ni Ajimobi yóò mọ bó ṣe ń lọ pẹ̀lú ẹjọ́ kòtẹ́milọ́rùn tó pè Agbejọ́rò Dakolo:Mílíọ́nù mẹ́wàá náírà tí a béèrè kì í ṣe owó gbà má-bínú Fi àwọn ènìyàn mi sílẹ̀ ni South Africa -Buhari Amọ ṣa, o ṣalaye pe lara awọn ti awọn mu to wa ni Naijiria ni awọn yoo ko wọn lọ si ilẹ Amẹrika nitori pe awọn ọmọ Amẹrika wa lara awọn ti wọn lu ni jibiti.
Dapchi: Àwọn akẹgbẹ́ Leah Sharibu padà sí ilé ìwé, ṣùgbọ́n Leah kò bá wọn wọlé
'Coronavirus ló mú mi fẹ́ ọkọ mi tí a sì ṣèyàwó lóríi ‘Zoom’ Gómìnà ìpínlẹ̀ Ekiti, Kayode Fayemi nàá ti ni aàrùn Coronavirus Kí ló dé tí ìjọba ìpínlẹ̀ Oyo kéde fífagilé Sáà ètò ẹ̀kọ́ kẹta fún àwọn akẹ́kọ̀ọ́?
Oun ni ọdọmọde ti ko tii pe ogun ọdun akọkọ to maa gba goolu Grand slam lẹyin Maria Sharapova lọdun 2006.
Elija sì dáhùn pé, “Bí mo bá jẹ́ eniyan Ọlọrun, kí iná wá láti ọ̀run, kí ó sì jó ìwọ ati àwọn aadọta ọmọ ogun rẹ!
Ohun alumọọni ilẹ Russia ni awọn eto afanilojumọra lorisirisi lẹka ọrọ aje eyi ti yoo mu ko fidi kalẹ ni Afirika bi ko tilẹ ni awọn eroja kan lọpọ fun awọn ileesẹ nlanla rẹ.
O ni ọjọ ti oloogbe naa ku, awọn jọ wa ninu yara ni ni ibi ti o sun si, ki o to di pe o gba ipe lori ẹrọ rẹ, ti o si dide.
Ó fi ọ̀tẹ̀ kún ẹ̀ṣẹ̀ tí ó dá;ó ń pàtẹ́wọ́ ẹlẹ́yà láàrin wa,ó sì ń kẹ́gàn Ọlọrun.
Oríṣun àwòrán, Fayoseofficial Àkọlé àwòrán, Gomina ana ní ìpínlẹ̀ Ekiti Ayodele Fayose lásìkò tó ń sàbẹ̀wo si àjọ EFCC Ayẹyẹ àyájọ ìmúra oge nípinlẹ̀ Eko (#lagosfashionshow) Hmmm, lọdun 2018 ni ìpìnlẹ̀ Eko ṣe ayẹyẹ ètò ìmúra oge tó mìlú tiìtì.
Nígbà náà ni ó sọ fún eniyan pé,‘Wò ó, ìbẹ̀rù OLUWA ni ọgbọ́n,kí á yẹra fún ibi sì ni ìmọ̀.
Ninu ọrọ ti wọn, Ẹgbẹ Pan Niger Delta Forum, PANDEF ni atunto ni ọna abayọ si iṣoro Naijiria, eleyii ti yoo fun awọn ijọba ipinlẹ ni agbara lati mu ilọsiwaju ati idagbasoke ba agbegbe wọn.
Ilé ẹjọ́ pàṣẹ kí Sẹ́nétọ̀ Elisha Abbo san N50m fún obìnrin tó fìyà jẹ Mi o fi ìgbà kankan sọ pé Buhari ni yóò jẹ ààrẹ kẹ́yìn ní Nàìjíríà- Akintoye Loju opo Twitter ajọ to n mojuto gbigba owo ori nipinlẹ Eko LIRS ni wọn fi ọrọ yii sọwọ, lati le ran Laycon leti pe, awọn n duro de owo ori rẹ ninu owo to gba.
Bí ẹ kò bá san án fún un, yóo ké pe OLUWA, yóo sì di ẹ̀ṣẹ̀ sí yín lọ́rùn.
Awon omo-ogun Sahel, eyi ti o je apapo awon omo-ogun lati orile-ede Mali, Niger, Chat, Burkina Faso ati orile-ede Mauritania, ni won niloo owo ti o le ni 400 milionu owo ile Euro euros (494 million dollars), lati le je ki won ni atileyin ile-okere.
Hana lóyún, ó bí ọmọkunrin kan, ó sọ ọmọ náà ní Samuẹli, ó ní, “Títọrọ ni mo tọrọ rẹ̀ lọ́wọ́ OLUWA.
Ọpọlọpọ awọn ọkọ to baa kọwọrin ni wọn kọlu ti wọn si bajẹ kọja ala.
Irin arinwọdi si ni ki eeyan to gun oke yii, eyi ti kii se eremọde rara.
Noa ṣí òrùlé ọkọ̀, ó yọjú wo ìta, ó sì rí i pé ilẹ̀ ti gbẹ.
Sùgbọ́n oo àlàyé láti ẹnu olùdarí ìjáde àti ìwọlé epo nínú ẹgbẹ́ IPMAN to tún jẹ́ akọ̀wé ẹgbẹ́ náà tẹlẹ̀ Mike Osatuyi, sàlàyé pé, èdinwó náà ko tii sí fún ará ilú.
Nígbà tí oòrùn wọ̀, tí ilẹ̀ sì ṣú, kòkò iná tí ó ń rú èéfín ati ìtùfù tí ń jò lálá kan kọjá láàrin àwọn ẹran tí Abramu tò sílẹ̀.
Sagir Musa ni awọn ṣe ikede yii nigba ti wọn ri i pe ọkan lara awọn ọmọ ogun toun naa ba wọn kopa ninu idanilẹkọ ọhun ti lugbadi arun Coronavirus bayii.
Ganduje fikun pe ẹru ko ba oun rara, nitori oun mọ pe ẹni to ba wu Ọlọrun l'oun gbe agbara fun.
"Adeniran tẹsiwaju wi pe, "" ni awọn ikorita kan, awọn basejẹ yii ti sọ awọn dukiya ijọba ti ara wọn pẹluu bi o ṣe jẹ wi pe gbogbo awọn ile ẹkọ yii ni ijọba mọ odi yika."
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Kò sí ọ̀nà ti èèyàn kò lè fi pèsè ìrànlọ́wọ́ fún ará ìlú ẹ 15 Ìgbé 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 30 Èbibi 2020 Àkọlé àwòrán, Wo aláànú tó n wa ọkọ̀ tí wan fi n gbé aláìsàn lọ́fẹ̀ẹ́ Abdulkadir Abdirahman Adan ni o fi ara rẹ jin laarin agbami ado oloro ni olu ìlú Somalia.
Ìjà ni ìgbéraga máa ń fà,ṣugbọn àwọn tí wọ́n bá gba ìmọ̀ràn yóo ní ọgbọ́n.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ìyàtọ̀ tó wà láàrin ìṣesí Nàìjíríà àti South Africa Minista fun awọn agbofinro, Bheki Cele naa ti ṣabẹwo si awọn ibudo iṣẹlẹ ọhun.
Láti ibẹ̀, a ṣíkọ̀, nítorí pé afẹ́fẹ́ ṣọwọ́ òdì sí wa, a gba apá Kipru níbi tí afẹ́fẹ́ kò ti fẹ́ pupọ.
ni oju opopona marosẹ, ọlọpaa lee ṣe ayẹwo ọkọ rẹ bi o ba wa ninu rẹ lasiko ti wọn da ọ duro.
bí ó bá sọ̀rọ̀ dáradára, má ṣe gbà á gbọ́,nítorí ọpọlọpọ ìríra kún inú ọkàn rẹ̀.
Dafidi ati Abiṣai bá lọ sí ibùdó Saulu ní òru ọjọ́ náà, Saulu sì ń sùn ní ààrin àgọ́, ó fi ọ̀kọ̀ rẹ̀ gúnlẹ̀ lẹ́bàá ìrọ̀rí rẹ̀.
Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Sunday Igboho: N kò gba kọ́bọ̀ lọ́wọ́ ẹnikẹ́ni láti wá ọ̀daràn jáde nínú igbó Kishi30 Owewe 2020 Seyi Makinde ṣèlérí owó oṣù kẹtàlá fáwọn òṣìṣẹ́ Amotekun l' Oyo10 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Oyo Coronavirus: Makinde ní kò sí ọwọ́jà Coronavirus ẹlẹ́ẹ̀kejì ní ìpínlẹ̀ Oyo14 Sẹ́rẹ́ 2021 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 3 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 5 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Igbakeji minisita kan to pada gba idaduro lo dabaa pe aṣẹwo ni awọn obinrin naa eyi ti ọkan lara wọn jẹ aṣofin.
A sọ fún un nínú ìran yìí pé Ìjọ òtítọ́ ti Jésù Krístì tí a ti gbékalẹ̀ ní àwọn ìgbà Májẹ̀mú Titun, àti tí ó ti ṣe àbójútó ẹ̀kúnrẹrẹ́ ìhìnrere náà, kò sí lórí ilẹ̀ ayé mọ́.
Ishaq Oloyede: Jamb ko nii fi esi idanwo silẹ ni kiakia WHO yoo kapa aisan Lassa Fever Pẹlu abajade tuntun yii, o ti le ni ẹgbẹrun kan ati ọgọfa aisan ti wọn funrasi gẹgẹbii iba Lassa to ti waye lorilẹede Naijiria, ọtalelọọdunrun o din mẹta ninu wọn ni wọn ti fidi rẹ mulẹ nigba ti wọn tun fidi ẹẹdẹgbẹrin o le ogun ati mẹta mulẹ wi pe wọn kii ṣe arun ọhun.
awon obi ati akẹkọọ naa pe ki won sora fun awon onijibiti , ti won a so pe.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Igba akọkọ ni yii ti Manchester United yoo maa fidirẹmi ninu idije liigi ilẹ Gẹẹsi lati oṣu kejila ọdun 2018 Ṣaaju ifẹsẹwọnsẹ yii ọpọ itakurọsọ lo ti n waye laarin awọn onwoye, onimọ ere bọọlu atawọn ololufẹ ẹgbẹ agbabọọlu mejeeji lori pataki ifẹsẹwọnsẹ ọhun fun ati kopa awọn mejeeji ninu idije Champions league ni saa bọọlu to n bọ.
Awọn agbasẹse nilẹ Naijiria ko ni owo to towo lati gbọ bukata akanse isẹ to lowura bii atunse opopona marosẹ Ibadan si Eko.
Dafidi ṣe gbogbo ohun tí OLUWA pa láṣẹ fún un, ó sì pa àwọn ọmọ ogun Filistini láti Geba títí dé Geseri.
Ile ẹjọ ni ilana iṣakoso to ni pe ọga ọlọpaa lo ni aṣẹ lati gba eeyan ṣiṣẹ ko fẹsẹmulẹ, nitori naa igbaniṣiṣẹ yii ko bofin mu.
"O ni ""Irọ nla ni pe ẹda ofin ile Singapore ni abadofin naa, nitori ofin o ṣeeṣe ki ofin orilẹede kan jọ ti omiran, papa ti wọn ba n dojukọ iṣoro kan tabi ni afojusun to ba baramu."
olukọni NCE Federal College of Education, to wa ni Osi-ẹlẹ niluu Abeokuta,
Ìwọ́de bẹ̀rẹ̀ ní Minnesota lórí àwọn ọlọ́pàá mẹrin to pa ọmọ adulawọ ni Amẹ́ríkà Ọdún 38 ni ìyá mí fi ṣiṣẹ́ ní UCH, màá kọ́ ibùdó ìtọ́jú àrùn jẹjẹrẹ ní ìrántí rẹ - Ọọ̀ni Gómìnà Ondo Akeredolu ṣí ilẹ̀kùn ṣọ́ọ̀ṣì àti mọ́ṣáláṣí sílẹ̀ fún ìjọ́sìn Wákàtí mẹ́ta lo gbọ́dọ̀ ti dé pápákọ̀ òfúrufú bóo bá fẹ́ wọ bàlúù báyìí Trump dínà mọ́ Nàìjíríà àtí orílẹ̀èdè márùn ún míì láti má wọ Amẹ́ríkà Oríṣun àwòrán, Getty Images Ilẹ Amẹrika ti fi Naijiria ṣe ọkan lara awọn orilẹede mẹfa ti wọn bẹgi dina fifun wọn ni irufẹ iwe aṣẹ irina kan lọ si orilẹede wọn.
Nítorí ọ̀kan ni yóo ṣe: ninu kí ó kórìíra ọ̀kan, kí ó fẹ́ràn ekeji, tabi kí ó fara mọ́ ọ̀kan, kí ó má sì ka ekeji sí.
Ọ̀rẹ́kùnrin Khadijat Olubọyo gba ọjọ́ ikú!
Oríṣun àwòrán, @kojonyed Tramadol lee wo ara riro san ti eeyan ba mu odiwọn to yẹ ni nilo O maa n kun ọpọ eeyan to ba lo o ni oorun Nigba mii, awọn eeyan miran to lo Tramadol, kii sun Apọju Tramadol kii jẹ ki eeyan mọ ohun to n lọ ni ayika mọ to ba ti denu ara Kii jẹ ki eeyan lee mi jalẹ nigba miran Tramadol lee tete ge ẹmi kuru, ko si pa eeyan Tramadol se e fà kuro ninu ara ti ko ba tii sisẹ́ dapọ̀ mọ̀ ẹ́jẹ Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
 Ó jẹ ́ ìkan gbọ ̀ n tí a maa ń rí tí wọ ́ n bá bí ọmọ tuntun tí ó ní ichthyosis ti irú harlequin ṣùgbọ ́ n ectropion lè wáyé látàrí àìlágbára àwọn ẹran ara ìdéjú ìsàlẹ ̀ .
"Eleyi ti mi o so l'ose to koja, won ni mo so, a so niyen""."
 Eyi fihan pe o ka wa lara pupo ni eyi ti awon osise eleto aabo gbogbo ti n sise pe;u ifowosopo awon obi ati alagbato awon omodebinrin ti o dawati wonyii.
Ọmọ Naijiria toto ẹgberun mefa ati egberin ole mefa(6,806) lo ti pada sile bayi lati orilẹede Libya.
Àkọlé àwòrán, ọpọ ile lo ti di ẹgẹrẹmiti ni ipinlẹ Eko ti ijọba si ti fẹ ṣe ayẹwo lori wọn Agbebọn pa eeyan 17 l'Amẹrika Kíni ọ̀nà àbáyọ si ọ̀rọ omíyale ni Naijiria?
0 14 Orilẹede Anguilla 0 0.
 Ó sí baptist boys ' high school ní ọjọ ́ kẹtàlélógún oṣù kínín Ọdún 1923 , pẹ ̀ lú àwọn akẹ ́ kọ 75 àti olùkọ ́ mẹ ́ rin ( pẹ ̀ lú ìyàwó rẹ ̀ , madora pinnock ) .
Kaakiri aye ni wọn ti maa n wo iwaasu Pasitọ Chris to fi mọ ni Amẹrika.
Àsọtẹ́lẹ̀ nípa aṣálẹ̀ etí òkun nìyí:àjálù kan ń já bọ̀ láti inú aṣálẹ̀,láti ilẹ̀ tí ó bani lẹ́rù,ó ń bọ̀ bí ìjì líle tí ń jà bọ̀ láti ìhà àríwá aṣálẹ̀.
Yatọ si iṣẹ orin raggae, Majek Fashek tun dan agbara wo lagbo sinima nigba to ko pa ninu fiimu agbelewo Mark of the beast to jade lọdun 2000 ati eto apanilẹrin kan ni ọdun 2016.
Ògiri kan wà ní ìta tí ó wà ní ẹ̀gbẹ́ àwọn yàrá ní apá ti gbọ̀ngàn ìta, ó wà níwájú àwọn yàrá náà, gígùn rẹ̀ jẹ́ aadọta igbọnwọ, (mita 25).
 Àwọn jẹsí tó gbajúmọ̀ nínú ìtàn ìdíje bọ́ọ́lù Coronavirus: Arsenal padà sórí pápá, Premier League lè bẹ̀rẹ́ padà lóṣù kẹfa Bí ilumọọka agbabọọlu Drogba ṣe dáwọ ogun dúró ní Ivory Coast Moise Kean: Everton koro oju sí agbabọọlu wọn tó lọ sí òde ijó lásìkò isede ẹ́gbẹ agbabọọlu Lasiko to n ba ileesẹ amohunmaworan El Chiringhito sọrọ, ọmọ orilẹ-ede Argentina ọhun sọ pe: Ẹru n ba mi, sugbọn emi ati ọrẹbinrin mi lajọ wa nibi, mi o si ni i ifarakanra pẹlu awọn eeyan miran.
Wọn a gbe ẹ lori gege koo maa fi owo ranṣẹ ni bii ọsẹ ọsẹ.
darapo mo awon orile-ede ti o ti pegede fun idije ohun saaju,  orile-ede Egypt, Nigeria, Senegal, Morocco,
Òpin ti dé; ó ti dé ba yín.
Bí àwọn ìjòyè bá gbọ́ pé a jọ sọ̀rọ̀, bí wọn bá wá sọ́dọ̀ rẹ tí wọn ní kí o sọ nǹkan tí o bá mi sọ fún àwọn, ati èsì tí mo fún ọ, tí wọn bẹ̀ ọ́ pé kí o má fi ohunkohun pamọ́ fún àwọn, tí wọn sì ṣe ìlérí pé àwọn kò ní pa ọ́, 
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Chloroquine for coronavirus: Njẹ Chloroquine nipa kankan láti kojú Coronavirus?
Aarẹ ọna kakanfo Yoruba Iṣẹ́ Kudirat Abiọla ṣì ń fọhùn síbẹ̀, lẹ́yìn ọdún 23 tó papòdà Oshisko twins, àwọn 'ìbejì' tó ń dẹ́rìn ín p'òṣónú Wọ́n ta ère Ọ̀ṣun Osogbo sí Togo - Bàbá Ọṣun figbe ta Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Olusegun Obasanjo: Ọmú ìyá mi ti mo fi ń mùkọ ni kekere ló jẹ ki ń lókun Bẹẹ si ni wọn yan Họnọrebu Abiodun Muhammed Fadeyi to n ṣoju ẹkun idibo Ijebu North II gẹgẹ bii igbakeji adari ni ipinlẹ Ogun.
Mahrez dá Super Eagles dùbúlẹ̀ lórí pápá oko tútù Barrister ló sọ mí di èèyàn ńlá - Ayinla Kollington Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Yinka Ayefele: Oṣù àwọn ìbẹ́ta mi kò pé ní kò jẹ́ kí n kọ́kọ́ kéde ìbí wọn Ṣugbọn agbabọọlu iwaju fun Tottenham sọ ifẹsẹwọnsẹ ọhun di ọmi alayo mejimeji(2-2) lẹyin to gba bọọlu mii sawọn ni iṣẹju marun din laadọrin.
Ní tèmi o, ó dára láti súnmọ́ Ọlọrun;mo ti fi ìwọ OLUWA Ọlọrun ṣe ààbò mi,kí n lè máa ròyìn gbogbo iṣẹ́ rẹ.
Ṣugbọn ilẹ̀ tí ọkàn yín fẹ́ pada sí, ẹ kò ní pada sibẹ mọ́.
Ẹ wà ninu àwọn tí a óo máa fi wàrà bọ́, ẹ kò ì tíì lè jẹ oúnjẹ gidi.
Wọn ni ki ijọba ṣe ohun to yẹ lati dẹkun iwa buruku awọn Fulani darandaran kan atawọn Myetti Allah kan ti wọn ro pe awọn kọja agbara ofin ko too tun di ọrọ Boko haram mọ wa lọwọ.
Àwọn ènìyàn láti agbègbè náà máa ń pè é ní ‘tigress’.
" knowlesi "" kìí sábà fa ààrùn lára àwọn ènìyàn ."
"Ọlọpàá yìbọn ti wan si pa ènìyàn méje ti wan si ti Sowore móle lori ọ̀rọ̀ náà, sùgbọ́n síbẹ̀ kò dẹyin lẹ́yìn ìfẹhonuhan láti jajagbara fún ètò ẹkọ́ to yanranti lórilẹ̀-èdè Naijiria Sáaju ni ọdun 2018 Sowore, se agbekalẹ ìpolongo ààrẹ pẹ̀lú ""Our Mumu don do"" èyí tó fi sàlayé pé ọ̀pọ́ ọ̀dọ́ ni Naijiria ti yọwọ́ kuro nínú ètò ìjọba Ẹ̀ẹ̀mẹjọ ọtọọtọ ni ó ti wọ ẹwọn lóri ọ̀rọ̀ ìwọde ìfẹ́honuhan ni Naijiria."
Jẹfuta bá àwọn àgbààgbà Gileadi pada lọ, àwọn ará Gileadi sì fi jẹ balogun wọn.
Ó bá tún wọ inú ọkọ̀ ojú omi, ó pada sí ibi tí ó ti wá.
Ileeṣẹ ọmọ ogun ofurufu Naijiria fun Bashir Umar ni igbega ọdun meji lẹyin to gbe owo to ri he ni ọja Hajj pada fun ẹni to ni.
EFCC: Èèyàn 647 la ti rán lọ sẹ́wọ̀n Ajọ ọlọ́pàá nínú ìfọ̀rọ̀wánilẹ́nuwò rẹ̀, ayédèrú agbẹjarò náà ní òun nífẹ̀ sí ìṣẹ́ agbẹjọ́rò nígbà tí ọ̀rẹ́ rẹ̀ kan ran kí ó ṣe bí amòfin láti lọ jáwè fún ayálégbé kan.
Nígbà tí wọ́n wá orúkọ wọn ninu ìwé àkọsílẹ̀ tí wọn kò rí i, wọ́n yọ wọ́n kúrò lára àwọn alufaa, wọ́n sì kà wọ́n sí aláìmọ́.
Iroyin kan ti o n da ẹru ba ọpọ lẹkun ariwa orilẹede Naijiria, paapaa julọ ni ipinlẹ Sokoto ni ti ẹgbẹ agbebọn tuntun kan ti wọn ni wọn n waasu ẹsin Islam tawọn tibọn lọwọ.
Tinubu ní kìí ṣe irú àsìkò ti ààrun Covid-19 ń da ètò ọrọ ajé láàmú yìí, mí ò rí ọjọ́ ìwájú tó bi éyin 'se rii Mí ò sì tíì ṣe ìpinnu kankan láti dupò ààrẹ lọ́dún 2023 nítori pé àwọn ǹkan to n kojú wa ní àsìkò yìí tí lágbára tó.
Buhari nìkan tàbí ilé ẹjọ́ ló le bèrè fún ìwé ẹ̀rí.
Ajo ma-da mi da-gbese ti so pe  àádọ̀rún bilionu naira  ni ijoba apapo  ri ninu oja  ipin idokoowo  to waye ninu osu kerin .
Nígbà tí Mose sọ̀kalẹ̀ pada ti orí òkè Sinai dé, pẹlu wàláà ẹ̀rí meji lọ́wọ́ rẹ̀, Mose kò mọ̀ pé ojú òun ń dán, ó sì ń kọ mànàmànà, nítorí pé ó bá Ọlọrun sọ̀rọ̀.
 bí ò sun ìyẹ ̀ rẹ ̀ -ifá , yóò máa kọ orin ifá .
Udoma salaye pe, erongba koko meta ohun ni lati pese anfaani fun awon oludokowo, ipese ise ati fifowosowopo pelu awon onile-ise aladani.
  Ó ti pẹ́ tí wọ́n ti nfọ́ òkúta níbẹ̀.
 gbajúgbajà òṣèré orí-ìtàgé ọmọ orílẹ ̀ -èdè nàìjíríà , Ìdòwú philip tí gbogbo ènìyàn mọ ̀ sí ' Ìyá rainbow ' ṣàpèjúwe gbenga gẹ ́ gẹ ́ bí adẹ ́ rìín-pòṣónú àti aláwàdà tí ó ma ń tọrẹ àtinúwá fẹ ́ ni tó bá ni lo ìrànlọ ́ wọ ́ .
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, BBC Africa Eye: ìwádìí ìkọ̀ks BBC fihàn pé àwọn kan ń jí ohun èèlò ìdáàbòbò ìjọba tà nígbo Gomina Bala, sọ lati ẹnu agbenusọ rẹ pe iyansipo naa kii ṣe babara, nitori pe Balaraba wulẹ̀ ti n ṣe Alaga ẹgbẹ awọn obinrin to ti kọ ọkọ wọn silẹ ni ipinlẹ Bauchi tẹlẹ.
O ni oun ṣe bẹ ni lati pakiesi awọn eeyan si aṣa iwe kika ati iwe kikọ ni Naijiria.
Ni afikun un, lara awon gbajugbaja ti o wa ye asekagba ife-eye ohun si ni, akonimoogba agba iko agbaboolu Real-madrid teleri Zinedine Zidane.
Ọjọ́ tí mo ti sọ̀rọ̀ rẹ̀ ń bọ̀, yóo dé.
miiran sugbon yoo gbiyanju lati mu igbega ba awon to ti wa nilẹ, lona ati mu
 “Isuna ilu ti o ye ki won fi mu igberu ba eto oro aje, pipese eto eko ti o peye ati eto ilera, ni won ti ko si apo won kookan lataari iwa imotara eni nikan soso.
Ọjọru ni ile naa da wo ni agbeegbe Ita Faaji, Lagos Island ni Isalẹ Eko.
Àwọn ọmọ Lotani ni Hori ati Homami.
“Ẹ̀yin náà mọ̀ bí ayé wa ti rí ní ilẹ̀ Ijipti, ati bí a ti la ààrin àwọn orílẹ̀-èdè tí a gbà kọjá.
Àti báyìí ni òun pọ́n wọn, ó sì wí fún wọn pé kìí ṣe ẹ̀ṣẹ̀ lati pa irọ́ kí wọ́n ba lè mú ènìyàn nínú irọ́, kí wọ́n ba lè pa á run.
Nisinsinyii OLUWA, mo bẹ̀ Ọ́, ro títóbi ìfẹ́ rẹ tí kì í yẹ̀, kí o dárí ẹ̀ṣẹ̀ àwọn eniyan yìí jì wọ́n bí o ti ń dáríjì wọ́n láti ìgbà tí wọ́n ti jáde kúrò ní ilẹ̀ Ijipti.
"Awọn mejeeji tutọ si ara wọn loju lori obinrin naa to jẹ ọrẹbinrin Kọburu Adamu lalẹ ọjọ isẹgun.
Kí ló dé tí ẹ fi ń fi iṣẹ́ ọwọ́ yín bí mi ninu, tí ẹ̀ ń sun turari sí àwọn oriṣa ní ilẹ̀ Ijipti, níbi tí ẹ̀ ń gbé?
Lẹhin oṣù keje ni aadọta ọdún sẹhin, àwọn Ológun fi ibọn gba Ìjọba ni igbà keji.
Peteru bá bi í pé, “Anania, kí ló dé tí Satani fi gbà ọ́ lọ́kàn tí o fi ṣe èké sí Ẹ̀mí Mímọ́, tí o fi yọ sílẹ̀ ninu owó tí o rí lórí ilẹ̀ náà?
Wọn tun ni o kọ lati jọwọ ara rẹ sabẹ iṣakoso ọfiisi adajọ agba ilẹ Naijiria.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Itaniji: Oluwo sọ ìtàn bí Orunmila ṣe jìyà nílùú Iwo àti ayọ̀ tó gbẹ̀yìn rẹ̀ torí sùúrù Inu oko kan naa lawọn Fulani ati agbẹ n gbe.
9 174115 Orilẹede Dominican Republic 2358 22.
s ti sọ wípé àwòrán yìí kò bójú mu ní bíi ogún ọdún ṣ ́ yìn .
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Rochas Okorocha, káàbọ̀ sí àwùjọ àwọn gómìnà tí EFCC ń wá - Fayose Sìgá mímu ń di èèwọ̀ oògùn ìlera pípé lagbaye Ará ìlú dájọ́ oró fún ọkùnrin to bẹ́ orí ẹ̀gbọ́n rẹ̀ ní Cross River Bakan naa lo fikun un pe, ikankan ninu awọn ọmọ igbimọ alasẹ ẹgbẹ ọlọkọ ero naa ko gbọdọ safihan ara wọn mọ laarin igboro jakejado ipinlẹ Ọyọ.
Ó tọ̀nà láti san owó-orí fún Kesari ni, àbí kò tọ̀nà?
Tẹ̀lé ọ̀rọ̀ OLUWA tí mò ń sọ fún ọ; yóo dára fún ọ, a óo sì dá ẹ̀mí rẹ sí.
''Èyí lo mú kí wọn má sare gbogbo ona láti fẹ pajá lọ́bọ fún ara ìlú'' Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ogundamisi: Ọbasanjọ ni ko jẹ k'awọn ọdọ de'po Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ifọrọwanilẹnuwo pẹlu Ọjogbọn Wọle Soyinka Lai Mohammed ni aseyori ìjọba Buhari lo n ko Obasanjo lominu pàápàá jùlọ pẹlu bi ọ ṣe l'ànfààní ati mú ìyípadà bá ètò ilu ṣugbọn tí o kò láti ṣe òhun tó yẹ.
O fagunwa lo nigba aye rẹ, iyalẹnu lo jẹ pe lẹyin ọdun 55 to ti papoda, ijọba tabi ẹlẹgbẹjẹgbẹ kankan ko satunse ile ati dukia to fisilẹ.
Oríṣun àwòrán, @followlasema Ọpọ eroja bii ọpa, silinda gaasi ati awọn nnkan miran to ti jona ni wọn ri nibi isẹlẹ naa, ti ajọ Lasema ko si sọ boya ẹmi kankan sọnu ninu ijamba naa.
Àwọn ìṣẹ̀lẹ̀ mánigbàgbé tó wáyé nibi ìwọ́de ENDSARS Nàìjíríà Ọlọ́pàá mú afurasí 31 tó ń dúnkokò máwọn ọmọdé lórí ayélujára Bàbá ọlọ́mọ méjì fi ipá bá ọmọ ọdún mẹ́rin lò pọ̀; Adájọ́ rán an ní ẹ̀wọ̀n gbére Ẹgbẹ́ Agbẹjọ́rò NBA ti kéde pé àwọn yóò ṣojú awọn Olùwọ́de #EndSARS lọ́fẹ̀ẹ́ nílé ẹjọ́ Ìwọ́de 'End SARS' lè tan àjàkálẹ̀ arùn coronavirus lẹ́ẹ̀kejì ní Nàìjíríà- Ọjọ̀gbọ́n Faduyile Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Sotitobire: Ọkọ mi kò mọ̀ Jegede PDP rí, kódà kò fa ẹnikẹ́ni kalẹ̀ dípò Akeredolu- Bisola Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí 7:57 Fídíò, End SARS, End SWAT: Ó pé mi bí SARS kò ṣe sọ mí dolówọ́- Fulani Kwajafa, Duration 7,5717 Ọ̀wàrà 2020 2021 Nigerian Budget: Àbádòfin ìṣúná 2021 ré kọjá ìpele ìkejì nílé aṣòfin àgbà15 Ọ̀wàrà 2020 EndSARS School Resumption: Àwọn akẹ́kọ̀ọ́ lè padà sílé ìwé láti ọjọ́ Ajé - Ìjọba ìpińlẹ̀ Eko29 Ọ̀wàrà 2020 Fídíò, Wole Soyinka sọ ìdí tó fi ni òun a fi màálù Fulani ṣe súyà fáwọn èèyàn abúlé23 Owewe 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Awakọ kan d'oloogbe ninu ikọlu afurasi darandaran nipinlẹ Ondo
Nítori àwọn àtúgbẹ́yẹ̀wò, o níra láti ṣe àkójọpọ fún àwọn ọkọ́ naa Orisun: Johns Hopkins University atawọn ajọ eto ilera ilu Iye akọsilẹ to waye gbẹyin 7 Oṣù Ọ̀pẹ̀ 2020 14:22 WAT+3  Àárín èmi àti àwọn tó jí ọmọ gbé nìkan ni mo fẹ́ kí idunadura náà wá, mo sì ní ẹtọ láti lo ọna ti mo ba mọ pe o dara, láti dáàbò bo ohun tí Ọlọ́run fún mi."
Dino Melaye tó ń díje dupò gómínà Kogi ni irọ́ ni pé òun ti ju awà sílẹ̀ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Nigeria models: Ẹ má bóra mọ́, ọmọ dúdú dùn lọ́mọbìnrin EFCC ní iṣẹ́ ọdaran òun kí ó maa ji ojú àwọn ènìyàn ti wọn fẹ jà lólè yóò si fi ránṣẹ́ si àwọn akẹgbẹ́ rẹ̀ ni òkè okun.
Awo, gẹgẹ bi ọpọlọpọ eeyan ṣe n pe e, jade laye lọjọ kẹsan an, oṣu karun un, ọdun 1987, ni ọmọ ọdun mejidinlọgọrin, ti wọn si sin in ni Ikenne to jẹ ilu rẹ.
” Nítorí pé wọ́n ti ṣe ìbúra tí ó lágbára nípa ẹni tí kò bá wá siwaju OLUWA ní Misipa, wọ́n ní, “Pípa ni a óo pa á.
 Wayii o, ogbeni Enang so pe ekunwo owo osu ohun yoo ropo owo ti awon osise n gba tele lesekese yala nile ise ijoba tabi ti aladani, lati bere si ni san ogbon ẹ̀gbẹ̀rún(N30,0000) gege bi owo osu awon osise to kere julo, bere loni ojo kejidinlogun, osu kerin odun 2019.
Ṣugbọn àwọn Farisi ń sọ pé, “Agbára olórí àwọn ẹ̀mí èṣù ni ó fi ń lé àwọn ẹ̀mí èṣù jáde.
Agbnusọ fun ajọ naa, Fabian Benjamen, sọ wi pe ajọ naa n gbiyanju lati ri wi pe gbogbo esi idanwo t'awọn eeyan ṣe jade lori opo ayelujara rẹ.
Èyí ni yóo jẹ́ kí gbogbo eniyan mọ̀ pé ọmọ-ẹ̀yìn mi ni yín, bí ẹ bá fẹ́ràn ara yín.
 Èdè wum ( macro-bantu ) ni wọ ́ n n sọ .
Ṣugbọn ṣa, abala kẹta ofin ti awọn orilẹ-ede fẹnuko le lori lọdun 1961 lori iru ọrọ yii labẹ akoso ajọ to n mojuto ọrọ awọn atipo l'agbaye, UNHRC, sọ pe ọmọ ti wọn ba bi loju ofurufu tabi ori omi ti orilẹ-ede agbaye, ni wọn yoo gba gẹgẹ bi i pe orilẹ-ede ti baalu tabi ọkọ oju omi naa forukọ silẹ si ni wọn bi i si.
Aisha Buhari tọrọ ìdáríjì lórí fídìo tó jáde Ọjọ mẹrin ni Day fi wa nile uwosan nibi ti ko ti le gbe apa, gbe ẹsẹ, ko to di pe o wa jẹ Ọlọrun nipe.
O fi kun un wipe wọn tun ti ṣeto lati jawo ayẹwo ojoojumọ soke sii lati ẹgbẹrun kan si ẹgbẹrun mẹta loojọ.
Ajo to n pese iranlowo fun idagbasoke eto ogbin ti a mo si: The International Funds for Agricultural Development (IFAD) ni oun ti ya owo bilionu mejo naira soto fun idagbasoke ise agbe nipinle meje ni Naijiria.
, ni eyi ti won yoo fi gbogun ti ise, osi ati ainimo, ebi ati lati tun le mu
Ofin ti a ba tori ẹru se ni a ko gbọdọ de ori ọmọ ki a wa yii pada.
Ẹnìyàn méjì ti kú nítori àrùn Coronavirus ní ìpínlẹ̀ Oyo Kini 'pen' l'ede Yoruba?
 Eyi ni ile ijọsin akọkọ ti awọn angẹli kọ si ile aye.
Lara orin ti awọn olorin kan fi ṣapejuwe patakii Funke Akindele si wọn ree.
N óo rọ wọ́n lọ́tí yó,títí tí wọn óo fi máa yọ ayọ̀ ẹ̀sín,tí wọn óo sì sùn lọ títí ayé.
’ ” Nítorí ó rò ninu ara rẹ̀ pé, bóyá òun lè fi àwọn ẹ̀bùn tí ó tì ṣáájú wọnyi tù ú lójú, àṣẹ̀yìnwá àṣẹ̀yìnbọ̀, nígbà tí ojú àwọn mejeeji bá pàdé, bóyá yóo dáríjì òun.
Jerusalẹmu, mo ti fi àwọn aṣọ́de sí orí odi rẹ;lojoojumọ, tọ̀sán-tòru, wọn kò gbọdọ̀ panumọ́.
Kayefi nla leyi ṣugbọn ododo ọrọ ni.
Àwọn ni wọn óo máa ṣe oríṣìíríṣìí iṣẹ́ tí ó bá jẹ mọ́ àwọn nǹkan wọnyi.
Iroyin to n tẹ wa lọwọ ni pe awọn janduku ti yabo awọn to n ṣe iwọde #ENDSARS ni ileeṣẹ ijọba ipinlẹ Eko to wa ni Alausa.
Amọ awọn miran parọwa si ẹgbẹ osisẹ lorilẹede Naijiria lati mọkanle nitori ọna ni yii lati ri wi pe won ko se ekunwo owo osu awọn osisẹ naa lasiko to tọ ati eyi to yẹ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Coronavirus in Nigeria: Ǹjẹ́ ṣé òògùn apakòkòrò le pa ààrùn coronavirus?
Àwọn ọba ilé-ayé yóo mú ọlá wọn wá sinu rẹ̀.
Wí fún un pé OLUWA Ọlọrun ní: ‘O ti jẹ́ àpẹẹrẹ ìwà pípé, o kún fún ọgbọ́n, o sì lẹ́wà tóbẹ́ẹ̀ tí o kò ní àbùkù kankan.
Àwọn òbíi rẹ̀ àgbà sá kúrò ní ilẹ̀ẹ wọn pẹ̀lú Dalai Lama ní ọdún-un 1959.
Bẹẹ na lo se ri pẹlu oniruuru imọ ẹrọ sayẹnsi ti oyinbo n se nitori asise lee waye lati ipasẹ ẹrọ naa, paapaa ti ko ba sisẹ bo se yẹ.
Fun awọn olujọsin, wọn ko sin Satani, ṣugbọn wọn ri i gẹgẹ bi apẹẹrẹ to ba iru eeyan ti wọn jẹ mu nipa ìbí.
Latigba ti won ti se agbekale ami eye naa ni odun 2006, won koi ti fun enikankan tori pe, ko si eni ti o koju osuwon lati gba iru ami eye bee.
Ninu atẹjade kan, ẹgbẹ oṣelu PDP ni igbesẹ naa lasiko ti eto idibo gomina nipinlẹ Ọṣun ku ọsẹ kan jẹ iwa idunmọhurumọhuru mọ alatako ati eyi to lee da họwu-họwu silẹ nipinlẹ naa.
Loju opo ayelujara yii ni eeyan yoo ti fọwọ si fọọmu kan lati fihan pe ẹni naa fẹ gba nọmba aladani si ọkọ rẹ.
Gege bi Farah “O si mo niwon, Mo si ni ere-ije miran niwaju ti o to meji iru maili ti mo sa yii, ise sip o fun mi lati se.
“Ẹ ní iyọ̀ ninu ara yín, nígbà náà ni alaafia yóo wà láàrin yín.
Ilẹ ẹjọ kan nilu Akure ti paṣẹ ki arakunrin Adeyemi Alao ti wọn fẹsun kan pe o pa Khadijat ọmọ igbakeji gomina Ipinlẹ Ondo nigba kan ri, Alhaji Lasisi Oluboyo, lọ rọọkun naa lẹwọn.
Arákùnrin tó jí Ese Oruru gbé ti rí ẹ̀wọ̀n ọdún 26 he Wo ìgbà márùn ún tí àwọn ọmọ ọ̀dọ̀ ti gé ẹ̀mí ọgá wọn kúrú Wọn tí fòfin de iléeṣẹ́ ìròyìn Chris Oyakhilome nítorí ó sọ pé 5G ló ṣokùnfà àrùn Coronavirus Femi Adebayo di àgbà àáfà òníláwàní, Iyabo Ojo fi sìgá dárà, Allwell Ademola di ọmọdé padà, tí Wazo si bímọ tuntun Akeugbagold to ni awọn Kristẹni wa lara awọn eeyan to n ṣe onigbowọ waasi oun lori redio, tun tọkasi pe pasitọ kan wa lara awọn onigbowọ waasi naa.
 tí abá ni kí áwòó láti ìgbà ìwásẹ ̀ fún àpẹẹrẹ , ètò ìkọ ́ ni dára ni ilé ẹ ̀ kọ ́ alákọ ̀ bẹ ̀ rẹ ̀ , èdè yorùbá ni afi hún kọ ́ akẹ ́ kọ ̀ láti ilẹ ̀ kí àtó kii èdè òmíràn bọ ̀ ọ ́ , àmọ ́ ni báyìí èdè gẹ ̀ ẹ ́ sì ni afi ń kọ ́ akẹ ́ kọ ̀ tí ọ ̀ pọ ̀ lọpọ ̀ wọn si ń sọ èdè yorùbá nílé .
O ni olupẹjọ ko gbe ẹsun dide lori ayederu iwe ẹri ninu ẹjọ to kọkọ pe; o si kuna lati fi idi rẹ mulẹ pe ayederu ni iwe ẹri to fihan.
Ẹ̀jẹ́ tí mo jẹ́,tí mo sì fi ẹnu mi sọ nígbà tí mo wà ninu ìpọ́njú.
O tun ni Ọgbẹni Jago lo gbọ bukaata bi Ronke ṣe ṣe idi nla, lẹyin ti wọn bẹrẹ si ni fẹ ara wọn.
Aare Adama Barrow bere igbese erongba ipada bo sinu ajo ohun ninu osu keji odun 2017, leyin ti o gori alefa ninu eto idibo ti o waye ninu osu kejila odun 2016.
O ti yan àwọn ọmọ Israẹli fún ara rẹ, láti jẹ́ eniyan rẹ, o sì ti di Ọlọrun wọn títí lae.
Coronavirus dé ọ̀dọ̀ ará ọ̀run, ọdún Egúngún kò ní wáyé nílùú Ibadan nítorí coronavirus Ẹ̀yin Pásítọ̀, ẹ múra fún ìkómọ yanturu lọ́dún tó ń bọ̀ - Adeboye Inú káàdì ìránti tí mo rí he ní mó tí rí fọ́tò ìhòhò Salawa, mó kàn fẹ́ gbà owó díẹ̀ ni- Afurasí Olorì Anu Adeyemi ń ṣe ọjọ ìbí, ẹ gbọ́ ǹkan tò sọ sí Kábíyésì Ninu atẹjade kan eyi to fi sita lọju opo Facebook rẹ, Pasitọ Adeboye ṣalaye pe oun yoo forikori pẹlawọn ajọ agbofinro gbogbo lati rii pe panpẹ ofin tete mu awọn to ṣiṣẹ ibi naa ati pe o digba ti idajọ ododo ba waye lori ọrọ naa ki oun to si lẹyin rẹ.
Asekagba idije ohun ti o waye ni gbagede O2 Arena, Djokovic gbo ewuro si Zverev loju pelu ami ayo mefa si merin(6-4), mefa si ookan(6-1).
Mo fẹ yi ero awọn eeyan pada wi pe Sharia wa lati fi iya jẹ awọn obinrin ni'' ''Gbogbo ẹni to ba fẹ fẹ iyawo miran gbọdọ yoju fun ara wọn ni iwaju ile ẹjọ adajọ Shushaida.
Eto ilana idibo yii ni yoo fun awọn araalu ati oludibo ni agọ idibo kọọkan ni anfaani lati to si ẹyin aworan oludije fun ipo aarẹ to ba wu wọn.
Eniyan burúkú kò wá Ọlọrun, nítorí ìgbéraga ọkàn rẹ̀,kò tilẹ̀ sí ààyè fún Ọlọrun ninu gbogbo ìrònú rẹ̀.
Ẹ dira yín gírí, Èṣù tíí ṣe ọ̀tá yín, ń rìn kiri bíi kinniun tí ń bú ramúramù, ó ń wá ẹni tí yóo pa jẹ.
Ẹgbẹ agbesunmọmi Boko Haram ti n ṣọṣẹ jiju ado oloro, ipaniyan ati ijinigbe lorilẹede Naijiria lati ọdun 2009.
Africa Eye: Wo ìtàn ìyá kan ìyá kan àtàwọn olè ajọ́mọgbé tó n ta ọmọ ní Kenya
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Insecurity: Àwọn aráàlú ní ìpànìyàn àti ìgbéṣùnmọ̀mí ni kò jẹ́ kí ẹnu sìn lára Buhari 13 Èrèlè 2020 Oríṣun àwòrán, Others Nkan ko ṣẹnu re fun aarẹ orileede Naijiria lẹnu ọjọ mẹta yii, pẹlu bi awọn ara ilu ṣe n fi ẹhonu han si iṣejọba rẹ.
T’ó ń fi ẹsẹ janlẹ̀ kiri l’àdúgbò
Bí kinniun tíí yọ ní aginjù odò Jọdani tíí kọlu agbo aguntan, bẹ́ẹ̀ ni n óo yọ sí àwọn ará Babiloni, n óo mú kí wọn sá kúrò lórí ilẹ̀ wọn lójijì; n óo sì yan ẹnikẹ́ni tí ó bá wù mí láti máa ṣe àkóso ibẹ̀.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Sex: Ẹ̀ẹ̀méje ló gorí ọmọ alaṣẹ́wó, ni kò bá bọ̀ mọ́ 3 Sẹ́rẹ́ 2020 Oríṣun àwòrán, Getty Images Arakunrin kan ti orukọ rẹ n jẹ Davy ti gbẹmi mi lasiko ifigagbaga ibalopọ pẹlu obinrin aṣẹwo nile itura kan lagbegbe Ejigbo nipinlẹ Eko.
Amọ, oludije si ipo gomina ni abẹ oselu APC naa ti bu ẹnu atẹ lu ọrọ ti ọpọlọpọ eniyan sọ pe oun ni ẹyinoju Alaga Ẹgbẹ Oselu APC, Asiwaju Ahmed Tinubu ati ti Gomina Ipinlẹ Osun, Rauf Aregbesola.
Ṣebí àwọn ọmọdé ni wọ́n ń gun kẹ̀kẹ́?
kí ó fá irun orí tabi ti àgbọ̀n olúwarẹ̀, ṣugbọn kí ó má fá irun ọ̀gangan ibi tí ẹ̀yi náà wà.
 Àwọn nǹkan wọ ̀ nyí jẹ ́ ara àwọn ìṣòro tó n kojú àwùjọ-ẹ ̀ dá .
Oríṣun àwòrán, @Police Awọn miran lara wọn gbe owo kalẹ fun iwọde naa, bẹẹ ni awọn mii ẹwẹ n ru wọn soke lati tẹsiwaju ninu iwọde ọhun.
Lateef Alabi ni orukọ rẹ, oun si lo n dele bii Imaamu ni mọsalasi naa, to si n lewaju awọn olujọsin ninu adura nigba ti ọkunrin agbebọn kan, Brenton Tarrant kọlu wọn.
Ó tọ̀ ọ́ lọ níbi tí ó jókòó sí lẹ́bàá ọ̀nà, ó ní, “Wá, jẹ́ kí n bá ọ lòpọ̀,” kò mọ̀ pé opó ọmọ òun ni.
Nítorí náà, ẹ̀yin ará, a ní ìgboyà láti wọ Ibi Mímọ́ jùlọ tí ó wà lẹ́yìn aṣọ ìkélé nípa ẹ̀jẹ̀ Jesu, 
Ọkan lara awọn ọmọ rẹ ọkunrin, Olugbenga Ọbasanjọ fi ẹsun kan baba rẹ ni gbangba pe o n ni ibalopọ pẹlu iyawo oun.
Ojú gbogbo wa ń fi ògo Oluwa hàn bí ìgbà tí eniyan ń wo ojú rẹ̀ ninu dígí.
Ìdí tí èyí fi ṣẹlẹ̀ si yín ni pé ẹ sun turari, ẹ sì dẹ́ṣẹ̀ sí OLUWA.
Bayii won ti ti awon ile ise ibudo afefe gaasi ati awon ile ise epo robi pa.
Lẹyin o rẹyin, Abiola Ajimobi fidi rẹmi ninu ibo naa, ti Sẹnatọ Kola Balogun si jawe olubori lati lọ sile aṣofin agba ni Abuja.
Eyi si fa itahunsira laarin oun ati Naira Marley.
Wọ́n dó tì í, wọ́n sì mọ òkítì sí ara odi rẹ̀ yíká.
Ìjìnlẹ̀ ọ̀rọ̀ ni, ó sì nítumọ̀ púpọ̀.
Gusu), ogbeni  Bankole Oluwajana;  agbẹjọro fun egbe naa, Babatunde Ogala; akapo
Mercy Aigbe: Àwọn olólùfẹ́ rẹ̀ kẹ̀yìn sí í pé ó ní káwọn ọmọge gbọ́n àpò baálé ilé tí wọ́n ń fẹ́ gbẹ Iwa nabi tu igbeyawo ọgbọn ọdun ka Ọsinbajo se‘dana ọmọbinrin rẹ nile ijọba Adekunle Gold, Simi tú àṣírí ètò ìgbéyàwó wọn Àṣà ìbálé lálẹ́ ìgbeyàwó ń dọdẹ àwọn obìnrin òde òní Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Omi titun ti rú nínú oríṣii ètò ìgbéyàwó Yorùbá lásìkò yí Fidio kan nipa iṣẹlẹ naa fihan bi ọkan lara ẹbi iyawo tuntun ṣe n beere lọwọ obinrin naa pe 'sista, ki lo ṣẹlẹ, ki lẹ fẹ'?
Mama Boko Haram: Alaafia ni akẹẹkọ Dapchi wa
 wọn wà ni àgbègbè ebira ní ìpínlẹ ̀ kwara , edo , okene àti bẹ ́ ẹ ̀ bẹ ́ ẹ ̀ lọ .
Aare orile ede Naijria  Muhammadu Buhari ati adari ijọba orile ede Britain ,Theresa May se ipade bonkẹlẹ nile aare to wa niluu Abuja.
Ẹ óo wá mi, ṣugbọn bí mo ti sọ fún àwọn Juu pé, ‘Níbi tí mò ń lọ, ẹ̀yin kò ní lè dé ibẹ̀,’ bẹ́ẹ̀ ni mo sọ fun yín nisinsinyii.
Wo àwọn ìjọba ìbílẹ̀ 20 tí àrùn coronavirus pọ̀ sí jùlọ ní Nàìjíríà Ni ọjọ aje ni igbimọ apapọ lori gbigbogun ti ajakalẹ arun coronavirus lorilẹede Naijiria, PTF jade pẹlu awsn ilana tuntun ti aarẹ buwọlu fun didena itankalẹ arun COVID-19.
‘Awọn ọmọ to wa ni fasiti ti dagba to lati mọ iyatọ laarin iwa rere ati iwa buburu.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù World theatre Day: Kosọkọ ní ètò adójútòfò wà fọ́jọ́ alẹ́ àwọm onítíátà Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ World theatre Day: Kosọkọ ní ètò adójútòfò wà fọ́jọ́ alẹ́ àwọm onítíátà 27 Ẹrẹ̀nà 2019 Nigba to n dahun ibeere yii, agba ọjẹ kan nidi isẹ tiata, to jẹ odu, ti kii se aimọ fun oloko laarin awọn osere tiata, Ọmọọba Jide Kosọkọ ni ẹgbẹ awọn osere ori itage lede Yoruba, taa mọ si TAMPAN, labẹ akoso ọgbẹni Bọlaji Amusan, ti gbogbo eeyan mọ si Mr Latin, ti n se gudugudu meje, ati yaya mẹfa fun eto adojutodo fawọn ọmọ ẹgbẹ naa.
Ẹwẹ, ile ifowopamọ Access Bank pada fesi si ọrọ ti Oluwo fi lede loju opo Twitter rẹ, wọn dupẹ lọwọ rẹ wọn si tọrọ aforijin lori ohun ti oju mama rẹ ti ri.
Kiko ọpọ ọmọ ogun lọ si tibu-tooro ipinlẹ Ekiti pẹlu akọsilẹ to fi han pe ẹgbẹrun lọna ọgbọn ọlọpaa, ẹgbẹrun marun ọmọ ogun ati ẹgbẹrun mẹrin ati aabọ osisẹ ọtẹlẹmuyẹ ti wọn fi sọwọ si ipinlẹ Ekiti.
"On d ""ki lo tun ku ti o se"" video I've just seen on @Ayourb's TL, there's plenty Saraki still needs to do."
O ni ijọba kọ̀ lati sọ ireti nu lori ọdọmọbinrin naa.
- Aregbesola Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'N500 dé fún gbogbo ọmọ tuntun lóṣooṣù bí mo bá di gómìnà Ondo - Adeleye AAC Ó ní ìdí tí àwọn fi fẹ́ kí wọ́n gba oyè lọ́wọ́ Máyégún gbogbo ilẹ̀ Yorùbá ní pé ìwà tó hù kò bá ìlànà oyè tó jẹ́ lọ nítorí náà, Aláàfin Ọyọ Ọba Lamidi Adeyemi gbọ̀dọ gbà á lọ́wọ́ rẹ.
Nínú ìṣèjọba yìí, Èmi àti Ààrẹ Buhari lọlọ́rọ̀, kìí ṣe ọmọ Nàìjíríà-Ibrahim Gambari, olórí òṣìṣẹ́ lọ́fíìsì ààrẹ Aláàfin gbé àṣẹ kalẹ̀ láti dènà àtúnṣẹ̀ ìṣẹ̀lẹ̀ 'Soka'nílùú Ọ̀yọ̀ Kókó ohun tó wà nínú àbọ̀ ìwádìí Orosanye, tó le gba iṣẹ́ lọ́wọ́ òṣìṣẹ́ Ẹ yé tako ìjọba lórí iléèjọ́sìn títì pa, ẹ jọ̀wọ́ ṣọ́ọ̀ṣì yín fún ìtọ́jú àwọn tó lárùn coronavirus- Tunde Bakare Ki o to di kọmiṣọna, Ayọọla ni aṣofin to n ṣoju ẹkun ila orun ipinlẹ Ọyọ ni ile igbimọ asofin ipinlẹ naa laarin ọdun 1999 si ọdun 2003.
A n fi asiko yii ronu lori isẹlẹ ibanujẹ jiji awọn ọmọbinrin wa gbe, paapaa julọ ni Dapchi ipinlẹ Yobe.
olubori gege  bi aare orile ede Naijiria
Ikọ̀ aláàbò Nàìjìríà dojú kọ Shiite Kaduna: Ikú Ọ̀ba dá kóníléógbélé padà D.
Nítorí ẹ kórìíra ẹ̀kọ́;ẹ sì ti ta àṣẹ mi nù.
Ẹwọn ọdun mẹrinl;a ni ofin kede fun igbeyawo akọ si akọ tabi abo si abo ni Naijiria.
Tsaigumi ni baluu adanikan fo akọkọ ti ileesẹ ọmọogun ofurufu lorilẹede Naijiria yoo da se fun ara rẹ.
Ọtí tí wọ́n fi Sanitáísà àti Methanol pò pọ̀ ṣekú pá èèyàn 86 A ó san ẹ̀san ire fún ẹbí Richard, a ó sí san owó gbogbo ètò ìsìnkú - Iléesẹ́ ọṣẹ tí akẹ́kọ̀ọ́ UI kú sí Àgbà òṣèré tíátà míràn tún jáde láyé!
Èmi OLUWA Ọlọrun ni mo wí bẹ́ẹ̀.
Oríṣun àwòrán, others Àkọlé àwòrán, Mùsùlùmí tó ń gbèrò láti lọ hajj ni Alhaji, Alhaja - Onímọ̀ Imaam:Imaam ti Yoruba n pe ni Lemọmu ni itumọ rẹ n jẹ asiwaju, amọ o pe meji.
Isaaki dá oko ní ilẹ̀ náà, láàrin ọdún kan ṣoṣo ó rí ìkórè ìlọ́po lọ́nà ọgọrun-un (100) ohun tí ó gbìn nítorí OLUWA bukun un.
“Bí àrùn ẹ̀tẹ̀ bá mú yín, ẹ ṣọ́ra gidigidi, kí ẹ sì rí i pé ẹ ṣe gbogbo ohun tí àwọn alufaa, ọmọ Lefi, bá là sílẹ̀ fun yín láti ṣe, gẹ́gẹ́ bí mo ti pàṣẹ fún wọn.
Ko si nnkan to jọ pe Gomina ipinlẹ Eko fun awọn Super Eagles ni owo moriwu.
    Bí ilẹ̀ ti ń mọ ni ọjọ kejì, ti a ri i pé ó tó àkókò kí ọba tì maa rì àwọn ènìyàn rẹ̀, a tún ránṣẹ́ lọ sí ààfin.
Ninu atẹjade ti Kọmisanna fun eto iroyin ati ilanilọyẹ, Donald Ojogo, fi sita, o fidirẹ iṣẹlẹ sọ pe àràbà nla kan lo wo ninu iṣẹlẹ naa.
Ronaldo fi góòlù mẹ́ta bẹ̀rẹ̀ ọdún 2020 pẹ̀lú Cagliari 6 Sẹ́rẹ́ 2020 Oríṣun àwòrán, Getty Images Ogbontagi agbabọọlu ọmọ orilẹede Portugal, Christiano Ronaldo ti fi goolu mẹta ṣẹwọ ninu ọdun tuntun.
Lẹ́yìn náà, Jese sọ fún Abinadabu pé kí ó kọjá níwájú Samuẹli.
"Adájọ́ pàṣẹ kí wọ́n fi ọlọ́pàá tó lọ́wọ́ nínú ikú Kolade Johnson sí àhámọ́ 'Àwọn SARS ló yìnbọn pa ìyá mi' ""Ileeṣẹ ọlọpaa ti n wa wọn tipẹ fun ẹsun pe wọn pa eniyan mẹfa lasiko idigunjale mẹta ọtọọtọ ti wọn ṣe."
"Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ìdá kan nínú mẹ́ta àwọn eléré ìdárayá tí orílẹ̀-èdè Cameroon kó lọ sí ìdíje Commonwealth ló ti sálọ ""Ìpín mẹ́ta ni àwọ́n eléré ìdárayá tó sálọ náà pín sí."
Ni Sakiu bá sọ̀kalẹ̀, ó sì fi ayọ̀ gbà á lálejò.
Kí kaluku kọrí sí ìlú rẹ̀!
00 Ohun alumọọni ati amusagbara - 32,585,739,585.
Alpha Sy sọ pé ọkọ rẹ̀ tí ó ti di olóògbé wà lára àwọn tí wọ́n pa lọ́dún 1990.
ní ọdún kẹta ìjọba rẹ̀, ó se àsè fún àwọn ìjòyè, ati àwọn olórí, àwọn òṣìṣẹ́, ati àwọn olórí ogun Pasia ati ti Media, àwọn eniyan pataki pataki tí wọ́n wà lọ́dọ̀ rẹ̀ ati àwọn gomina agbègbè rẹ̀.
Àtíkù kéde bẹ́ẹ̀ lásìkò tó ń bá BBC Hausa sọ̀rọ̀ lọ́jọ́ Sátidé nígbà tí wọn bií pé báwo ló se fẹ́ di ààrẹ orílẹ̀èdè Nàíjíríà láì kọ́kọ́ se ẹ ń lẹ́ ń bẹ̀un sí Amẹ́ríkà.
Ile ẹjọ giga kan nipinlẹ Eko ti ran ọdanran naa lẹwọn igbere Iku ọmọ ogun ori omi ati ololufẹ rẹ ni Port Harcourt Ọmọ ọdọ mii tun ṣekupa ọga rẹ to jẹ ọmọ ogun ori omi ati ọrẹbinrin kan ni agbegbe Borokini, ni Port Harcourt, ni ipinlẹ Rivers.
Bakan naa lo dupẹ lọwọ Lucky Ayedatiwa to dije gẹgẹ bi igbakeji gomina, to si rọ ki o maṣe da oun lẹyin o rẹyin.
Gbogbo àwọn eniyan tí ẹ̀ ń gbé ààrin wọn yóo sì rí iṣẹ́ OLUWA, nítorí ohun tí n óo ṣe fún wọn yóo bani lẹ́rù jọjọ.
Bi o tilẹ jẹ pe aṣedanwo lee nilo lati san ẹẹdẹgbẹrun (N500) ni ibudo CBT gẹgẹ bí owo isẹ ṣugbọn wọn gba aṣedanwo nimọran pe ẹnikẹni ko gbudọ san kọja ẹẹdẹgbẹrin Naira (N700) gẹgẹ bi owo iṣẹ.
Attahiru jega kede ọrọ yii lasiko ipade apero ẹgbẹ kan nilẹ Naijiria, ikẹẹdogun iru rẹ, eyi to waye nile ẹkọ fasiti Bayero nilu Kano.
Oríṣun àwòrán, @TVCconnect O ni bo tilẹ jẹ pe o ti pe ọgọta ọdun ti Naijiria gba ominira lọwọ ijọba amunisin oyinbo alawọ funfun, abẹ ijọba amunisin abẹ ile ni Naijiria wa sibẹ.
akinkanju ti won fi han lasiko ifigagbaga naa, eleyi ti o ron iko naa lowo lati
Ìdájọ Ademola Adeleke l'Akure kò túmọ sí pé o kún ojú òṣùwọ̀n-Timothy Owoeye
Asa kú ní ọdún kọkanlelogoji ìjọba rẹ̀.
Nitori naa to ba jẹ pe iwọ kii mu omi bi o ti tọ, bi ọdun ṣe n lọ si opin yii jẹ ki o jẹ ipinu ọdun tuntun rẹ lati maa mu omi bi o ti tọ ati bi o ti yẹ.
Iṣẹlẹ naa, to waye lọsan ọjọ Aje, lo n kọ ọpọ eeyan lominu.
 fún àpẹẹrẹ , a lè rí ẹ ̀ sìn ìbílẹ ̀ àti àwọn ẹ ̀ sìn ìgbàlódé tó jẹ ́ ẹ ̀ sìn kirisitẹẹni àti ẹ ̀ sìn mùsùlùmí .
Oríṣun àwòrán, @A_Salkida Àkọlé àwòrán, Wọn yibọn pa ọkan lara awọn eeyan ọhun, lẹyin naa ni wọn bẹ awọn mẹwaa to ku lori Agbófinró mú ọkùnrin tó ń gun bààlu tó fẹ́ gbéra Ìjọba Kano fi páńpẹ́ òfin mú Ọba àwọn Oṣó lórí ẹ̀sùn jìbìtì Òṣèrébìnrin tí wọ́n bá fi ìbálòpọ̀ lọ̀ 'torí ìṣẹ́, kó bọ́ síta láti sọ̀rọ̀ - Kunle Afod Ó kéré tán, ènìyàn mẹ́rìnlá tí kú nínú àjálù ọkọ̀ òfurufú tó já Aarẹ ni aabo gbogbo ọmọ Naijiria jẹ ojuṣe oun bẹẹ si ni iku alaiṣẹ Kristẹni tabi Musulumi maa n ba oun lọkan jẹ.
Nilu Eko to ṣe pe ọpọ eeyan lo n lo afẹfẹ gaasi yi fun idana ati iṣowo, o di dandan ki ijọba wa wọrọkọ fi ṣada lọna ati dẹkun ibugbamu ni gbogbo igba.
Nígbà náà ni ó wá yé wọn pé kì í ṣe ti ìwúkàrà tí à ń fi sinu burẹdi ni ó ń sọ, ti ẹ̀kọ́ àwọn Farisi ati Sadusi ni ó ń sọ.
Bẹ́ẹ̀ gẹ́gẹ́ ni ẹgbẹẹgbaarun àwọn ọmọ Efuraimu,ati ẹgbẹẹgbẹrun àwọn ọmọ Manase.
Bo tile je pe awon agbejoro so pe , o mo-on-mo se ikolu yii si ipinle naa ni, amosa awon omo ogun olote (IS) ko ti I fesi pe oun lo  wa nidii ikolu naa.
Tatenai, gomina, Ṣetari Bosenai ati àwọn ẹlẹgbẹ́ wọn tẹ̀lé gbogbo àṣẹ tí Dariusi ọba pa fún wọn lẹ́sẹẹsẹ.
Nígbà tí ẹ bá dìde dúró láti gbadura, ẹ dáríjì ẹnikẹ́ni tí ẹ bá ní ohunkohun ninu sí, kí Baba yín ọ̀run lè dárí ẹ̀ṣẹ̀ yín jì yín.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ahmadu Ali Must Go Protest: Àfikún owó oúnjẹ akẹ́kọ̀ọ́ ní Fáṣítì fa ẹ̀hónú tó mú ọ̀pọ̀ ẹ̀mí lọ 29 Ọ̀wàrà 2020 Oríṣun àwòrán, Archive Yoruba ni arise ni arika, arika si ni baba iregun, ohun ta ba ṣe lonii, yoo di itan bo di ọla.
Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Ghana elections 2020 winner: Nana Akufo-Àddo àti John Dramani ló jọ ń díje lọ́là7 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Ghana 2020 election: Jean Adukwei Mensa,Tani akíkanjú obìnrin tí yóò kéde èsì ìbò aàrẹ Ghana?
Ta ni Loucas Moura Ọmọ orileede Brazil ni Loucas Moura ti o si wa si Tottenham lati ẹgbẹ PSG to ta a ni ọdun 2018 niye owo miliọnu mẹtalelogun poun.
Ìran Yorùbá: Àṣà ju àṣà lọ!
Nítorí mo ti pinnu pé n kò fẹ́ mọ ohunkohun láàrin yín yàtọ̀ fún Jesu Kristi: àní, ẹni tí wọ́n kàn mọ́ agbelebu.
naa se lati gba awon ohun ijamba ogun ati ipanilara lowo awon janduku naa.
Meghan fun ra rẹ ti sọ tẹlẹ pe ipari oṣu kẹrin tabi ibẹrẹ oṣu karun un ọdun 2019 ni ọmọ tuntun yii yoo de.
 títí tí gama fi kú ni 1882 , àbá yìí kò tí ì di òfin .
Aworan CCTV to ṣafihan agbebọn naa nibi to ti wọ aṣọ dudu to si ti gbe ibọn dani ni wọn ti ṣe afihan rẹ lori amohunmaworan .
Adarí Ilé ìgbìmọ̀ Asòfin tako ètò ìjọba tiwantiwa- Agbẹjọ́rọ̀ Ǹjẹ́ o mọ ohun tó ń fa súnkẹrẹ-fàkẹrẹ nílùú Eko?
Ẹgbẹ oṣelu Labour ti ni awọn ko ni dibo fun adehun May lori Brexit.
“Ko si ohun ti o kan
OLUWA bá ní, “Ó wà ní ìkáwọ́ rẹ, ṣugbọn o kò gbọdọ̀ fọwọ́ kan ẹ̀mí rẹ̀.
Nígbà tí ó pẹ́ díẹ̀ lẹ́hìn èyí wọ́n mú oúnjẹ wá fún wa ṣùgbọ́n n kò jẹ oúnjẹ náà nítorí nígbà tí wọ́n ń fẹ́ẹ́ mú oúnjẹ náà wá mo gbọ́ ti wọ́n ń ṣe àríyànjìyàn kan wọ́n ń ṣe àròyè nínú ilé oúnjẹ pé bóyá oògùn tí wọ́n fi sí inú oùnjẹ náà tó láti mú kí á sanra tàbí kò tó.
Mo bá pàṣẹ kí wọ́n fi í sílẹ̀ ní ìtìmọ́lé títí tí n óo fi lè fi ranṣẹ sí Kesari.
kí ó tó já 30 Ẹrẹ̀nà 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Awakọ̀ òrúrufú Ethiopian Airlines pariwo lọ sókè!
Wọ́n ń wí pé, “Àìsàn burúkú ti gbé e dálẹ̀;kò ní dìde mọ́ níbi tí ó dùbúlẹ̀ sí.
Ko tan sibẹ, awọn gomina ilẹ Yoruba naa tun fori okoo sọdun pẹlu ọga ọlọpaa nilẹ wa naa, lati gba awọn osisẹ ọlọpa ẹlẹkunjẹkun lati agbegbe kọọkan ti wọn tẹdo si.
Ọlọrun mọ̀ pé mo fẹ́ràn yín.
Wọ́n bá gbéra ní òwúrọ̀ ọjọ́ keji, wọ́n lọ sí agbègbè olókè, wọ́n sì wí pé, “Nítòótọ́ a ti dẹ́ṣẹ̀, ṣugbọn nisinsinyii a ti ṣetán láti lọ gba ilẹ̀ náà tí OLUWA ti sọ nípa rẹ̀ fún wa.
AARE BUHARI N TOWOBO IWE IBURAwon ti bura fun gomina tuntun fun ipinle Gombe, Alhaji Muhammadu Inuwa Yahaya  gege bi gomina kerin ti won dibo yan ni ipinle naa.
Èyí yóo mú ìtìjú bá ẹni tí ó bá fẹ́ ṣe alátakò nígbà tí kò bá rí ohun burúkú kan sọ nípa wa.
Inú bí olówó rẹ̀, ó bá fà á fún ọ̀gá àwọn ẹlẹ́wọ̀n pé kí wọ́n sọ ọ́ sẹ́wọ̀n títí yóo fi san gbogbo gbèsè tí ó jẹ tán.
Poly Ibadan: Ọjọ́ iwájú la rò táa fí dáná sún fóònù àwọn akẹ́kọ̀ọ́ Ẹ fura o, wọ́n ti ń fi orúkọ Adeboye àti Olukọya lu jìbìtì ní Facebook Àwọn olùgbé ilu Ẹdẹ lu akẹ́kọ̀ọ́ pa Òní nilé ẹjọ́ tó ga jùlọ yóò gbẹ́jọ́ ẹ̀sùn ayédèrú sabuké tí wọ́n fi kan Buhari Awọn obi ati alagbatọ kan gab pe nkan ti yipada ati pe ọmọde naa le lo ẹro ibanisọrọ nibikibi nigba to ba wuu.
" Àwọn tí wọ́n jọ díje ni Joseph Olusola Iji, Odimayo Okunjimi, Olayide Owolabi Adelami, Isaacs Duerimini Kekemeke, Olusola Oke Alex, lfeoluwa Olusola Oyedele àti Olajumoke Olubusola Anifowoshe.
Lẹ́yìn ò rẹyìn Seyi Makinde búra fún ìgbìmọ̀ olùgbaninímọ̀ràn Oko òkú rèé, níbití òkú ti ń jẹrà mọ́lẹ̀ fún àyẹ̀wò Ìgbà Marún-un ti Aisha Buhari ti tako ìjọba Buhari Kò dùn mí pé mo sọ̀rọ̀ tako Buhari -Adedayo Festus Odun 2019 ni Burundi ba oogun eewọ máleèkópa wọn jẹ ti wọn si pegede ninu idije kikopa.
Ọpọ wa ni ko bikita nipa ọjọ ọla wa, oni nikan la n naani rẹ, eyi to sọ wa di ẹni ibi pẹlu ọpọ ibanujẹ, ta si joko si kọrọ ile wa lati maa se idajọ lori awọn asise ẹlomiran.
Eyi ti sun iye awọn to ni arun yii siwaju di mọkanlelaadọjọ, 151.
Ó ní, “Ẹ kò gbọdọ̀ fọwọ́ kan ẹni àmìòróró mi,ẹ kò sì gbọdọ̀ ṣe àwọn wolii mi níbi.
Ẹ̀yìn Ilé ìsìn yìí ni ọ̀nà tí ènìàá lè gbà jáde kúrò nínú abúlé, kí ó sì bẹ̀ rẹ̀ ìrìnàjòo lo sí òkè àpáta Robin Hood.
a bí thomas hardy ( 2 june 1840 - 11 january 1928 ) ní 1840 .
MC Oluọmọ ti di Alága àwọn awakọ̀ ní ìpínlè Èko.
Ọpọ lo ti n wode lálẹ ọjọ iṣẹgun niwaju ile iṣẹ ọlọpaa Minneapolis ti awon ọlọpaa si n fi tajutaju tu wọn ka #icantbreathe lọrọ to gba oju opo twitter kan lowuro oni ni Naijiria Bakan naa ni awon miran loju opo twitter ni yiyọ awon ọlọpaa naa nisẹ ko to nitori to ba ṣe pe alawọ dudu lo pa alawọ funfun ní, ẹjọ ipaniyan ni wọn yoo da ti o si le lọ ẹwọn gbere Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Breastfeeding week 2020: Bí ọyàn ṣe tóbi tàbí kéré sí kò ní ǹkan ṣe pẹ̀lú ìfọ́mọlọ́yàn Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Breastfeeding week 2020: Bí ọyàn ṣe tóbi tàbí kéré sí kò ní ǹkan ṣe pẹ̀lú ìfọ́mọlọ́yàn 8 Ògún 2020 Ọsẹ yii ni ayajọ ọjọ ifọmọlọyan lagbaaye oniruuru alakalẹ si ni ajọ eleto ilera ti la kalẹ.
Akowe Oba soun Ogbomosho, Ogbeni Toyin Ajamu naa sọrọ lori ohun to ṣẹlẹ gangan lọjọ yẹn.
Nítorí náà, a jẹ́ aṣojú fún Kristi.
Kí ó má wá jẹ́ pé yóo fi ìpìlẹ̀ lélẹ̀ tán, kò ní lè parí rẹ̀ mọ́.
Defense) nigbaaya  ni  ibudo idibo to wa ni ileto  Santar Amadi ni ijoba ibile Kankara nibi ikọlu
Ògo rẹ̀ tí ń ṣá bí òdòdótí ó wà ní òkè àfonífojì dáradára,yóo dàbí àkọ́so èso ọ̀pọ̀tọ́,tí ó pọ́n ṣáájú ìgbà ìkórè.
Gbogbo wa lẹru ba lori iyipo pada to waye ni Kano nitori a mọ pe wahala yoo wa ni Naijiria bi wahala ba bẹ silẹ ni ilu Kano, ṣugbọn a dupẹ lọwọ Ọlọrun pe alaafia jọba.
Àwọn tí ará ilẹ̀ Israẹli dè ní ìgbèkùn lọ ninu àwọn ará ilé Juda jẹ́ ọ̀kẹ́ mẹ́wàá (200,000) àtàwọn obinrin, àtàwọn ọmọkunrin, àtàwọn ọmọbinrin; wọ́n sì kó ọpọlọpọ ìkógun lọ sí Samaria.
Lọpọ igba, iyatọ ọjọ mọkanla a maa waye laarin ọdun kan si omiran, bakan naa, iye ọjọ oṣu kọọkan le yatọ si ara wọn.
Ọ̀rọ̀ ìyàwó kìí ṣe ọ̀rọ̀ ṣiréṣiré, ohun tí ó bá ilé ẹni lọ kúrò ní ọ̀rọ̀ yẹpẹrẹ.
Kíni àjọ ọlọ́pàá ń ṣe lórí bí agbófinró ṣe ń ṣèèṣì pànìyan lójoojúmọ́?
Bi a ko ba gbagbe awọn ọmọ ikọ SARS pade atako lati ọdọ araalu lori aiṣedede wọn lẹnu iṣẹ ati ifiyajẹni lati ọdọ wọn sí ara ilu.
Akọwe ijọba apapa to tun jẹ akọwe igbimọ naa, Boss Mustapha ṣalaye fawọn akọroyin pe ijọba ti wọgile gbogbo irin-ajo to ti buwọlu tẹlẹ fawọn oṣiṣẹ ijọba.
 Iroyin sọ pe inu ile kan naa ni gbogbo wọn n gbe, to si jẹ pe Adekunle lo maa n fun iyawo Arinze ni owo lati fi fun idile rẹ ni oúnjẹ, ti ọkọ rẹ ko ba ti ṣe ojuṣe."
Ọdun 2018 ni Aarẹ Trump yọ orilẹede Amẹrika kuro ninu adehun ti wọn ni pẹlu Iran lati jẹ ki wọn dẹwọ ipese ija ogun ọlọgọọrọ, Nuclear.
Ẹ̀rò àwọn ènìyàn se ọ̀tọ̀ọ̀tọ̀ lórí lẹ́tà Ọbasanjo sí Buhari Aláàfin Ọyọ pé ọdún 48 lórí àpèrè Soyinka: Ọ̀pọ̀ ìgbà ni ayédèrú ìròyìn ti pa mí Darandaran Fulani kìí lo ìbọn, 'pọ̀pá' la máa ń lò Àwọn kan fẹ́ da Naijiria rú torí ààbò tó mẹ́hẹ - Osinbajo gbarata Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Obasanjo: Atiku kìí se Áńgẹ́lì, àmọ́ yóò se dáadáa ní ìlọ́po méjì ju Buhari lọ Alaafin to mẹnuba awọn iṣẹlẹ haa-hinn to waye lori ọrọ abo to mẹhẹ ni ilẹ Yoruba laipẹ yii ni aarẹ Buhari ti wọn fi joye ko lee gbadiyẹ lori eto abo.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ojú mi ti rí lọ́pọ̀ lọpọ̀, àmọ́ mo dúpẹ́ pé mo ti pé ọdún márùn ún lórí oyé- Ooni Nigba to n sọrọ lori ọpa aṣẹ ti wọn ji gbe ni ipinlẹ Ogun, Kunlere ni ọpa aṣẹ ti wọn ji gbe ko sọ pe iṣẹ ijọba yoo duro.
Iye awọn to ku lọwọ arun naa si ti di 1,103 ti ara awọn 49,606 si ti ya lẹyin itọju.
Ó bá sọ fún mi pé, “Wọlé kí o rí nǹkan ìríra tí wọn ń ṣe níbẹ̀.
Ramadan: Àwọn mùsùlùmí tí kò bẹ̀rẹ̀ àwẹ̀ títí d'ìgbà tí wọ́n tó fojú r'óṣù
Adajọ ni lootọ lawọn afurasi naa ko si nibi isẹlẹ idigunjale gẹgẹ bi awọn ti salaye ayafi Felix nikan, amọ o ni wọn mọ saaju pe isẹlẹ naa yoo waye Ati pe awọn to jẹ ọlọpaa laarin wọn ko si ṣe ohunkohun lati dena rẹ, bẹẹ ni wọn tun pin ninu ere to wa lati idi isẹlẹ idigunjale ọhun Ẹkun iwọ oorun Naijiria nikan lo ni, Kwara kii si Ṣe ara wọn.
Eeyan 39,539 ni apapọ ni arun naa ti fara kan labẹ ayẹwo lorilẹede Naijiria.
Patrick Sawyer ati Dokita Stella Ogunjọ osu kẹjọ odun 2014 ni Dokita Stella Ameyoh Adadevoh se alabapade arakunrin ọmọ orileede Sierra Leone kan ti orukọ rẹ n jẹ Patrick Sawyer nigba ti arakunrin naa ti o ni aarun Ebola fẹ fi tipa kuro ni ile iwosan aladani kan ti Dokita Stella ti n sisẹ ni ilu Eko.
"latipasẹ ijafara, ainironu jinlẹ, imọtaraẹni nikan iwa ika, ati iwa ikorira, o seese ki ilẹ Naijiria tun maa ti ara rẹ sinu ogun abẹle minran, bẹẹ si ni , ogun jẹ okoowo to buru pupọ, o maa ngbọn owo pupọ lọ, o n seku pa ọpọ eeyan, to si tun maa nba ọpọ dukia jẹ, koda, eyi gan kan ẹni yowu ko bori ogun naa.
Marriage dispute: Ìyàwó mi fi mí sílẹ̀ kó lọ sílé ọkùnrin míì nínú báráàkì kan náà, àmọ́ mò sí tún fẹ́ràn rẹ̀
Bakan naa ni obinrin kọkan ko tii jaweolubori ninu idibo sipo Aarẹ ninu itan Amẹrika.
Wo àwọn nkan tí ó yẹ kí o mọ̀ nípa Bitcoin, kí o tó ó dáwọ́ le e Èèmọ̀!
Ìjọba yóò lo BVN àtàwọn ọ̀nà méjì míràn láti pín owó ìrànwọ̀ fún aráàlú Ṣé Irọ́ ni pé àwọn adigunjalè ń ṣọṣẹ́ ní ìpínlẹ̀ Eko àti Ogun?
Ìyanu ńlá ni ó jẹ́ fún mi nígbà tí mo rí obinrin náà.
Gege bi oro iko naa, alakoso tuntun fun ajo ECOWAS lori oro oselu, alaafia ati eto-abo, ogagun agba Francis Behazin ti darapo mo ojogbon Sawyer ti o je adari iko alamojuto ajo ECOWAS gege bi adari igbimo alamoju to ise-akanse fun iko naa.
miiran ni ekun Aarin gbungbun orile ede yii , si ohun ti a mo tele.
Ishola, to je minisita ana fun eroja irin ati irin lorile ede Naijiria wa so pe
Ọdún meje ìyàn sì bẹ̀rẹ̀ gẹ́gẹ́ bí Josẹfu ti wí, ìyàn mú ní ilẹ̀ gbogbo, ṣugbọn oúnjẹ wà ní gbogbo ilẹ̀ Ijipti.
1989 or where it all started!
Ko si ẹri pe ileeṣẹ to n mojuto titẹ iwe aṣẹ iwọle sorilẹede Naijiria naa ni ẹsun iwa ibajẹ kankan tabi boya ẹsun ti wọn fi kan ẹni to nii ni ohunkohun lati ṣe pẹlu iṣẹ iwe aṣẹ irinna ti wọn gbe le wọn lọwọ.
apa ibikan ni ipinle Benue, sibẹ awon eniyan duro jigbi lati dibo .
Saulu bá búra ní orúkọ OLUWA pé, “Bí OLUWA ti ń bẹ, ibi kan kò ní ṣẹlẹ̀ sí ọ nítorí èyí.
Ramla ṣalaye fun BBC pé àwọn òbí oun kò kọ́kọ́ fọwọ si i ṣẹ to wu oun yii nitori pe wọn ko ri ọmọbinrin musulumi to n kan ẹ̀ṣẹ́ rí.
Amọṣa, o ni gbogbo ilakaka oun lasiko ti oun wa nipinlẹ Ekiti ni lati rii pe Fayoṣe di gomina ati pe inu oun bajẹ gidigidi lati wa jẹjọ tako Fayoṣe naa bayii.
Ọ̀yàyà jẹ́ òògùn tí ó dára fún ara,ṣugbọn ìbànújẹ́ a máa mú kí eniyan rù.
Ní ìlú náà ẹrẹ̀ ṣe ìdíwọ́ fún àwọn jagunjagun Ọ̀yọ́ ni wọ́n bá fi ń pe ìlú náà ni Ìjẹ̀bú - Ẹrẹ̀.
 Won si tun kede abajade esi idibo naa niwaju  awon asoju egbe kọọkan ati awon agbofinro.
Bẹẹ ba gbagbe, a ti kọkọ mu iroyin wa fun yin nipa lẹta kan ti Alaafin kọ si Fayemi lọjọ kejila osu kẹta, ati awọn koko to wa ninu rẹ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ẹtàn ni àwọn ọ̀rẹ́ fi ń tan èèyàn lọ si Libya pé iṣẹ́ gidi wà níbẹ̀ Dokita agba Oluyinka Olutoye: Oríṣun àwòrán, BBC Sport Àkọlé àwòrán, Bi a ba fi ọmọ we ọmọ.
Ile aṣofin agba Naijiria ti gbe igbesẹ ri lati fi ofin de ila kikọ lode oni l'orilẹede Naijiria.
Wẹ̀ mí mọ́ ninu àṣìṣe àìmọ̀ mi.
O fi kún pé líla àwọn ènìyàn lọ́yẹ̀ lóri ààrun náà láti mú àdínku bá bí ìdẹ́yẹ sini lórí rẹ̀.
Kí ni èmi ìbá fi ọ́ wé, ìwọ ìyá mi!
“Ó ní bí Hesekaya bá sì sọ fún òun pé, OLUWA Ọlọrun àwọn ni àwọn gbójú lé, òun óo bi í pé, ṣé kì í ṣe ojúbọ OLUWA náà ati àwọn pẹpẹ ìrúbọ rẹ̀ ni Hesekaya wó lulẹ̀ nígbà tí ó sọ fún àwọn ará Juda ati àwọn ará Jerusalẹmu pé, ẹyọ pẹpẹ kan ni kí wọ́n ti máa sin OLUWA?
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Pásítọ̀ ló sọ fún mi pé Ọlọ́run pè mí láti di Olokun tó ń bọ omi' Ẹwẹ, ọkan lara awọn olugbe agbegbe Odo Ọna nibi ti wọn ni Saheed n gbe ṣalaye pe, aisan ọpọlọ lo n ba Saheed finra diẹdiẹ, ati pe kii ṣe ajinigbe gẹgẹ bi wọn ṣe sọ.
Kìí ṣe ààrùn Covid-19 ló pa adájọ́ àgba ìpínlẹ̀ Kogi-Kọmísọ́nà ìlera Eeyan 790 tuntun mii lo ṣẹṣẹ lugbadi arun Coronavirus ni Naijiria.
Gege bi Dalic se so,“O wu mi lati wa loke tente tabili, bakan naa ni, a gbodo tun se atunse si iko wa, lataari awon agbaboolu kookan ti o ti gba kaadi pelebe olomi-osan, eyi ti o si le sokunfa ewu fun wa ti a ko ba fogbon si, fun idi eyi ma a se atunse ranpe si awon agbaboolu mi.
pé kí ó jíṣẹ́ fún Rehoboamu, ọba Juda ati gbogbo ẹ̀yà Juda ati ti Bẹnjamini, 
 Ìmúlò rẹ ̀ mú kí ìwọ ̀ n ìṣẹ ̀ lẹ ̀ àwàlù eyín dín kù pẹ ̀ lú ìwọ ̀ n 95 % .
Hajar ni akọroyin to n ṣiṣẹ pẹlu ileeṣẹ iwe iroyin Akhbar Al-Yaoum.
Àwọn oríṣi àjẹsára náà méjèèjì tó wà , tí à ń gba ẹnu lò , ni a lè lò láìséwu .
Ṣaaju eyi, o ti kọkọ jade loju opo itakun agbaye Al-Watan pe o ku ni ile iwosan awọn ologun ni Cairo.
Wò ó, mo tún fún ọ ní àwọn akọ mààlúù yìí fún ẹbọ sísun, ati pákó ìpakà fún dídá iná ẹbọ sísun, ati ọkà fún ẹbọ ohun jíjẹ.
A gbọ́ràn sí Jonadabu baba ńlá wa lẹ́nu, à ń pa gbogbo àṣẹ tí ó pa fún wa mọ́, pé kí á má mu ọtí ní gbogbo ọjọ́ ayé wa, àwa, àwọn aya wa ati àwọn ọmọ wa lọkunrin ati lobinrin.
Ṣugbọn àwọn eniyan mímọ́ Ẹni Gíga Jùlọ yóo gba ìjọba ayé, ìjọba náà yóo jẹ́ tiwọn títí lae, àní títí ayé àìlópin.
Bí mo ti rí i, ẹ̀rù bà mí, mo dojúbolẹ̀.
ati  ile-ifowopamo ti ijọba orile ede
Lai pari ọrọ rẹ pe afojusun ijọba ni lati ṣakoso bi awọn eeyan ṣe n lo ori ayelujara lai tẹ oju ẹtọ wọn lati sọrọ gẹgẹ bi ọmọ Naijiria mọlẹ.
Oshiomole: Ẹ pe aṣaájú olóṣèlú níjà láti lo ọrọ̀ ìpínlẹ̀ fún àìní òṣìṣẹ́
Nítorí kì í wọ inú ọkàn lọ, bíkòṣe inú ikùn, a sì tún jáde.
26 Ẹrẹ̀nà 2020 Lori alaye awn nkan to yẹ ki o mọ nipa aarun coronavirus fun tonii, a ṣe agbeyẹwo lilo oogun Chloroquine fun itọju aarun naa.
Ìgbà tí ó di ọjọ́ ígbéyàwó bàbá mi, àríyá ńlá gba Igbó Olódùmarè kankan.
Iko agbaboolu Super Eagles bere igbaradi ni kikun fun ifesewonse akoko ti won yoo gba pelu iko agbaboolu orile-ede Croatia.
nítorí mò ń sọ fun yín pé ọ̀pọ̀ àwọn wolii ati àwọn ọba ni wọ́n fẹ́ rí àwọn nǹkan tí ẹ rí, ṣugbọn tí wọn kò rí i; wọ́n fẹ́ gbọ́ ohun tí ẹ gbọ́ ṣugbọn wọn kò gbọ́ ọ.
isinmi olojo kan lojo Eti .
Bi awọn ipinlẹ to ni Coronavirus ṣe lọ ni yii: Lagos-113 FCT-72 Plateau-59 Enugu-55 Kaduna-38 Ondo-32 Osun-26 Ebonyi-20 Ogun-9 Delta-8 Borno-7 Akwa Ibom-6 Oyo-5 Bauchi-1 Kano-1 Ekiti-1 NCDC kéde èèyàn 423 míràn tó ṣẹ̀ṣẹ̀ lùgbàdì Covid-19 ní Nàìjíríà Ajọ to n gbogun ti ajakalẹ arun lorilẹ-ede Naijiria, NCDC ti kede irinwo le mẹtalelogun eeyan to ṣẹṣẹ fara kaasa arun Covid-19 ni Naijiria.
 Mo ranti awọn obinrin ti wọn n gba okuta ti wọn si n fun ọkunrin ti wọn si n lẹẹ mọ wa."
Bákanáà la tún bi wọ́n láti kọ orin ìbílẹ̀ wa kan tí wọn bá mọ̀.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Oyo: Inú òbí dùn sí ìgbẹ́sẹ̀ ìpínlẹ̀ Ọyọ láti bẹ̀rẹ̀ ilé-ìwé tí àwọn akẹkọ̀ọ́ ń gbé 30 Owewe 2019 Oríṣun àwòrán, Google Àkọlé àwòrán, Ìjọba ìpínlẹ̀ Ọyo kéde wí pé àwọn ti setán láti tún bẹ̀rẹ̀ ilé-iwé tí àwọn akẹ́kọ̀ọ́ ń gbé ní ìpínlẹ̀ náà.
Aare Muhammadu Buhari sinu awe Ramadan, pelu adari egbe oselu APC,Asiwaju Bola Tinubu.
agbaboolu Manchester City yoo si maa waako pelu West Ham.
Ọba Adeyemi ati Olori Ramat Adedayo Adeyemi Oríṣun àwòrán, Olori Ramat Adedayo Adeyemi Olori Adedayo ati Ọba Adeyemi kii fi ifẹ aarin wọn pamọ rara titi di akoko yii, paapaa, ti eeyan ba pade wọn ni ode ariya.
Nígbà tí ó tó àkókò tí a óo gbé Jesu lọ sókè ọ̀run, ọkàn rẹ̀ mú un láti lọ sí Jerusalẹmu.
Ìjọba kéde ọjọ́ ìwọlé àwọn àgùnbánirọ̀ sí ìpàgọ́ lẹ́yìn Covid 19- Sunday Dare #EndSARS: Àwọn olùwọ́de kọ etí ikún sí àṣẹ ijọba, wọ́n tẹ̀sìwájú ìwọ́de l'Abuja Ọba Lamidi Adeyẹmi, òṣìṣẹ́ adójútòfò àti Abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò kó tó jọba Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí #ENDSARS: Àṣìta ìbọn ọlọ́pàá ló sọ mọ̀lẹ́bí mi, Adenike di báyìí, wọn ò bí i bẹ́ẹ̀, EndSARS ni dandan o- Toyin Abraham16 Ọ̀wàrà 2020 EndSARS Protest: Àwọn olùwọ́de ní ''májèlè ni oúnjẹ tí MC Oluomo gbé wá fún wa, a ò jẹ''17 Ọ̀wàrà 2020 EndSARS Protest Update: Aisha Yesufu ní Buhari jẹ́wọ́ pé òun kò láànú aráàlú nínú ọ̀rọ̀ rẹ̀23 Ọ̀wàrà 2020 Fídíò, Soyinka Cancer: Àṣe ara mi ni iso ti n run gbogbo bí mo ṣe n ṣèrànwọ́ lórí jẹjẹrẹ27 Bélú 2019 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Lori opo Twitter ọkan ninu awọn ololufẹ Barrister gbadura pe ki olorin naa ko maa sun laya Olugbala lọ Ọmọ ọba Ademolateejay ni ṣe lo dabi ana ti Ayinde Barrister faye silẹ lọdun mẹsan an sẹyin, o ni iku olorin Fuji naa dabi oguta iyebiye to sọnu.
Eyi ni akojọpọ diẹ lara awọn iṣẹlẹ naa.
2 mílíọ́nù owó ìtanràn Àjẹ́ àti Aṣẹ́wó ní ìyá Rainbow - Òjòpagogo Cardi B ṣàlàyé ohun tó gbé fọ́tò ìhòhò rẹ̀ d'órí ayélujára Instagram Ọsan ọjọ Ẹti ni wọn fi ọkọ ko ounjẹ naa lọ sibi iwọde Alausa.
O óo ru ìjìyà ẹ̀ṣẹ̀ wọn fún iye ọjọ́ tí o bá fi dùbúlẹ̀.
Hadadeseri ọba, bá ranṣẹ sí àwọn ará Siria tí wọ́n wà ní ìhà ìlà oòrùn odò Yufurate, wọ́n bá wá sí Helamu.
Iku akọroyin to pọ ju ṣẹlẹ ni ọdun 2006 nigba ti marundinlọgọjọ ku.
Bẹẹ si ni lọdun 2018, o le ni ẹgbẹrun mẹjọ ọmọ Naijiria ti US fun ni iwe aṣẹ irina.
Olukọ bibeli kan, Rabbi Jack Moline ni bi pun ṣe ri iṣesi aarẹ Trump yii lẹyin to ṣẹṣẹ fi ọwọ ofin ijọba ologun tu awọn afẹhonu han ka tan jẹ lilo ẹsin Kristẹni lọna aitọ gbaa.
” Wọ́n dá a lóhùn pé, “Bẹ́ẹ̀ ni.
Igbimọ naa f'ẹnuko pe Inec gbọdọ tun àbá owo isuna ti Aarẹ Muhammadu Buhari fi sọ wọ si wọn pada wa ni ẹẹkan si, ki awọn le wo o finifini.
Agígírì rìn díẹ̀ síwájú kí ó tó dúró.
Àwọn olóyè náà fi tọkàntọkàn fún àwọn eniyan, ati àwọn alufaa ati àwọn ọmọ Lefi ní nǹkan.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Eegunjobi Omotanbaje Ajobiewe- Èébú ní wọ́n kọ́kọ́ ń bù mí nígbà tí mo bẹ̀rẹ̀ ẹ̀ṣà pípé ní Ìfẹ́hònúhàn 'End SARS' ń tẹ́síwájú láì jẹ́ pé Buhari ṣe.
Iroyin ọhun tun fi kun un pe idarudapọ waye ninu gbọngan ile aṣofin ọhun lasiko ti igbesẹ ati yọ olori ile naa ati igbakeji rẹ fẹ waye.
Ìlú tí ó tóbi láàrin àwọn orílẹ̀-èdè tẹ́lẹ̀!
Òun ati àwọn opó àwọn ọmọ rẹ̀ bá gbéra láti ilẹ̀ Moabu, wọ́n ń lọ sí ilẹ̀ Juda.
Oríṣun àwòrán, @lasemasocial Amọṣa ajs naa ni iṣẹ ti n lọ lati ko gbogbo awọn igi ti o wo kuro loju popo.
kò pẹ ́ kò jìnnà , lẹ ́ hìn ikú alárẹ ̀ àti lúwà , ni àjèjì kan tí o múrá pàpà-rẹrẹ wọ ̀ lú .
Wọn se agbekalẹ idije ''Technovation'', lati gba awọn ọmọ obinrin ni iyanju ki wọn baa le se oun eelo to le mu igbayegbadun ba awujọ wọn.
Ninu gbogbo àwọn ìwé rẹ̀, nǹkankan náà ní ó ń sọ nípa ọ̀rọ̀ wọnyi.
Bẹ́ẹ̀ ni, ẹnikẹ́ni tí kò bá gbé agbelebu rẹ̀, kí ó máa tẹ̀lé mi, kò yẹ ní tèmi.
Ẹ kò mọ̀ pé àwọn tí ń ṣiṣẹ́ ninu Tẹmpili a máa jẹ lára ẹbọ, ati pé àwọn tí ń ṣiṣẹ́ níbi pẹpẹ ìrúbọ a máa pín ninu nǹkan ìrúbọ tí ó wà lórí pẹpẹ?
Bornstein ni, awọn ẹ̀sọ́ Trump yabo ile isẹ oun lọdun to kọja, lati palẹ gbogbo iwe ilera Aarẹ Trump to wa ni ipamọ oun mọ nilẹ.
Igba akọkọ ree ti idije AFCON yoo waye ninu oṣu kẹfa si ikeje, bakan naa ikọ agbabọọlu mejilelelogun yoo kopa fun igba akọkọ dipo mẹrindinlogun to ti wa tẹlẹ.
Obaseki: Mi ò ní pẹjọ́ kòtẹ́milọ́rùn lórí bí APC ti yọ mí kúrò lára olùdíje ìbó abẹ́lé fún ipò gómìnà Edo Gomina ipinlẹ Edo, Godwin Obaseki ti tako igbesẹ igbimọ ẹgbẹ oṣelu APC to n ṣayẹwo awọn oludije nipinlẹ Edo ti wọn yọ ọ kuro lara awọn oludije fun ipo gomina ninu idibo abẹle to n bọ.
O jẹ ọmọkunrin kan ṣoṣo ti iya rẹ bi laarin ọmọ mẹta, oun naa tun ni abigbeyin iya wọn.
ASUU ni digbi loun wa lẹyin ipinnu ijọba apapọ lati sun idanwo WAEC ọhun siwaju.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Conjoined Twins: Kìí ṣe ìdájọ́ ikú ṣùgbọ́n gbígbé ayé á nira Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Conjoined Twins: Kìí ṣe ìdájọ́ ikú ṣùgbọ́n gbígbé ayé á nira 20 Agẹmo 2019 Àṣìṣe kan lè ba ohun gbogbo jẹ́ gẹgẹ bi dokita ṣe sọ ọ.
kí ẹ sì pa àwọn òfin ati ìlànà rẹ̀, tí mo paláṣẹ fun yín lónìí mọ́, fún ire ara yín.
Ajọ Eleto idibo lorilẹ-ede Naijiria, INEC ti kede Gomina ipinlẹ Rivers, Nyesom Wike ti ẹgbẹ oselu PDP gẹgẹ bi ẹni to jawe olubori ni idibo sipo gomina ni ipinlẹ Rivers.
Àwọn ọba Yorùbá kan rèé tí wọ́n rọ̀ lóyè, tí ọba míràn jẹ lójú ayé wọn Ìtàn Gbọnka àti Timi, akọni méjì tó borí Aláàfin Ṣango Tun wẹ, aarẹ ọdẹ Asọludẹrọ, Nureni Ajijola Anabi naa kin Igboho lẹyin pe ko yẹ ki ẹnikẹni ti ko ba fi ogun bura wa lara awọn Amotekun nitori wọn yoo ba ẹgbẹ naa jẹ.
Dafidi wí fún un pé, “Sọ ohun tí ó ṣẹlẹ̀ fún mi.
Ọbasanjọ: Ó yẹ kí Amina Zakari kọ̀wé fipò sílẹ̀ ‘Ìjàmbá iná Àbẹ́là kò ló pa ìyá Jimoh Ibrahim’ Lẹ́yìn osù méjì, kò sọ́nà àbáyọ sí ìyanṣẹ́lódì ASUU Àlàyé rèé lórí àìyọjú mi síbi ìjíròrò fáwọn oludijè sípò ààrẹ - Buhari Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Atiku ní òun kò dènà kí ọ̀dọ́ kankan dupò ààrẹ ní Nàìjíríà O fikun wi pe awọn mọ wi pe awọn yoo bori ninu idibo to n bọ, eyi ti yoo si ya awọn ẹgẹ alatako ti Baba Ọbasanjo n satilẹyin fun.
Ikú àwọn ọkùnrin Aláwọ̀-dúdú ni ọwọ́ Ọlọpa ni orilẹ̀ èdè Àméríkà pọ̀ ju pi pa àwọn aláwọ̀ funfun tàbi laarin àwọn ẹ̀yà kékeré miran.
Àwọn ni yóo jẹ́ ààlà ilẹ̀ yín.
Àwọn Ẹ̀yà Apá Ìhà Àríwá Dìtẹ̀, Wọ́n Sì Ya.
00) ni a ti ri apo
Orísirísi ànfàní ni ó wà nínú ìbágbépọ̀ ẹ̀dá.
Ọlọ́pàá Germany ti mú àfurasí mẹ́rin nínú àwọn tó kọlu Ekweremadu ni Germany Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Àwọn ọ̀dọ́ Naijiria ti sọ̀rọ̀ síta lórí ohun ti wọ́n ń retí lọ́dọ̀ minista tuntun Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Wo àwọn ọ̀nà tí o lè gbà láti di ọjọ́ ogbó pẹ̀lú olólùfẹ́ rẹ Ifẹhonuhan naa ti mu ki ijọba apapọ tu ẹka ileeṣẹ ọlọpaa naa ka to si gbe omiran, SWAT, kalẹ, ṣugbọn ọdọ naa ni o ku nibọn n ro.
Oríṣun àwòrán, Seyi makinde Ìjọba Oyo kéde pé láàrín Sept.
Ọna abayọ si ipenija eto oselu ni Naijiria Oríṣun àwòrán, Jiti Ogunye Àkọlé àwòrán, O parọwa si awọn alawọdudu lati fẹran ara wọn nitori awọn ara ilu ni o le yan eniyan ti yoo tukọ wọn lo si ilẹ ileri si ipo.
Èmi àti Ènìyàn-ṣe-pẹ̀lẹ́ àti Olóhùn-un-dùuùrù wwà nínú ààfin lóhùn-ún pẹ̀lú àwọn ènìyàn tí ó kù a ń múra lọ́wọ́.
Wọn le ba o se ọrẹ loni, bo si di lọla, wọn a ṣe ipolongo lati tako ọ.
lataari ota ibon ti o fara gba, ti opo eniyan si farapa yanayana.
Ẹwẹ, aarẹ orilẹede Argentina, Alberto Fernandez ti kede ọjọ mẹta lati kẹdun Maradona.
Mo mọ̀ pé o ní ìṣòro; ati pé o ṣe aláìní, bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé ọlọ́rọ̀ ni ọ́ ní ọ̀nà mìíràn.
Ẹni fojú di ọ́, olúwarẹ̀ kàbùkù.
Se ẹ ri wipe owo naa ki se owo die?
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Wo bí Sunday Orimola ṣe gba ikú ẹranko kú ní Ifon ni Ondo lórí ọ̀nà àtijẹ Iroyin ọhun sọ pe Ọmọwe Amos Akingba, Oloye Tola Adeniyi, Oloye Solagbade Popoola ati Ọjọgbọn Anthony Kila ti wọn da ẹgbẹ YWC silẹ fi atẹjade kan sita ninu eyi ti wọn ti sọ pe iwa tani yoo mu mi, aikoju oṣuwọn ati titapa si ofin ẹgbẹ lo ṣe okunfa yiyọ ọ nipo.
Mose bá dá wọn lóhùn, ó ní, “Ṣé ẹ fẹ́ jókòó níhìn-ín kí àwọn arakunrin yín máa lọ jagun ni?
Wo ìdí tí Osun fi kede ìsinmi fún ọdún ìṣẹ̀ṣe, tàwọn ìpínlẹ̀ yókù kò dáhùn, Ikoro ni ọwọ ọlọpaa ti ba awọn janduku ẹda kan to lọwọ ninu rogbodiyan ọhun, ti iwadii si tun n lọ lọwọ lati mu awọn afurasi ọdaran miran si.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ọ̀gá àgbà Ọlọ́pàá kọ̀ láti yojú sí àwọn asófin Ijọba àpapọ̀ fòfin de oògùn ikọ́ olómi codeine Ipinlẹ wo ni yoo tẹle igbesẹ awọn aṣofin Kwara?
Ó dájú pé kò sí ẹnikẹ́ni tí Ọlọrun yóo dá láre nípa òfin, nítorí a kà á pé, “Olódodo yóo wà láàyè nípa igbagbọ.
Ṣiṣe atunṣe si eto ilera alabọde ati ti ile iwosan ijọba nlanla.
Wọ́n kò pa ẹnikẹ́ni sí ààfin Ṣọun Ogbomosọ, òkú tí àwọn ọdọ́ gbé wa ni ọlọ́pàá wọ́ jáde- Agbẹnusọ Ṣọ̀un Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Abayọmi Aranmọlatẹ, Dr Laser: Vagino Plasty àti iṣẹ́ abẹ ẹwà Obìnrin ló jẹ mí lógún Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí EndSARS Protest Update: Aisha Yesufu ní Buhari jẹ́wọ́ pé òun kò láànú aráàlú nínú ọ̀rọ̀ rẹ̀23 Ọ̀wàrà 2020 Fídíò, Wole Soyinka sọ ìdí tó fi ni òun a fi màálù Fulani ṣe súyà fáwọn èèyàn abúlé23 Owewe 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
" steinman fun "" iwari re lori ahamo dendritiki ati ipa re ninu ajesara alamuye "" ) ."
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Tọkọtaya méjì, ọmọ ìyá mẹ́rin bá ìjàmbá ọkọ̀ ayọ́kẹ́lẹ́ lọ l'Amerika 8 Ọ̀wàrà 2018 Èèyàn ogun ti padanu ẹmi wọn ninu ijamba ọkọ kan to waye nilu New York lorilẹede Amerika.
Jíjẹ ni kí ẹ máa jẹ èso igi wọn, ẹ kò gbọdọ̀ gé wọn lulẹ̀.
Awọn ko yọ ẹnikẹni sil ninu ẹgb oṣelu oun.
Ikede kan ti agbẹnusọ fun aarẹ Buhari, Bashir Ahmad fisita loju opo Twitter rẹ lo sisọ loju eleyii.
Itupalẹ rẹ niyi ni atẹ isalẹ yii: Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Orúkọ agbábọ́ọ̀lù 23 tí yóò lọ Russia 2018 Super Eagles: Ìdúró o sí, ìbẹrẹ o sí fún wà mọ Àwọn ìdíje Nàìjíríà míràn tó kù lóṣù yìí Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 3 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 5 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Sẹnatọ Mishau ni gẹgẹbi ọrọ ti alaga ajọ isakoso ileesẹ ọlọpa lorilẹede Naijiria sọ, ẹgbẹrun lọna ọtalelọọdunrun o din mẹwa (350,000) ni gbogbo ọlọpa to wa lorilẹede Naijiria.
Ati wipe, wọn yoo se agbekalẹ oniruuru ibudo awọn ologun sinu igbo ẹrujẹjẹ naa.
Ọlọrun bá sọ fún Mose pé, “Na ọwọ́ rẹ sórí òkun pupa kí omi lè bo àwọn ará Ijipti ati kẹ̀kẹ́ ogun wọn, ati àwọn ẹlẹ́ṣin wọn mọ́lẹ̀.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Aato ilu kun ara ohun ti ipin Eko yoo mojuto dun 2018 Pẹlu gbogbo ilakalẹ yii, kọmisọna fun eto isuna ni ipinlẹ Eko, Ọgbẹni Akinyẹmi Ashade ni ẹẹdẹgbẹrun biliọnu o din mẹta ni owo ti ijọba nreti ati pa wọle si asuwọn rẹ ni ọdun 2018.
Oríṣun àwòrán, Twitter/@iam_Davido Àkọlé àwòrán, Davido fun Chioma l'oruka nilu London lẹyin to kede pe awọn ti ṣe mọmi-n-mọ ọ Idije ere idaraya l'ọdun 2020: African Nations Championship Oṣu Kẹrin ọdun yii bakan naa ni orilẹede Cameroon yoo gbalejo idije ife ẹyẹ awọn akọni nilẹ adulawọ, African Nations Championship.
Ṣugbọn lẹ́yìn ọjọ́ mẹta yóo jí dìde.
Oríṣun àwòrán, @BashirAhmaad Ọrọ aabọ tabi kikoju awọn agbesunmọmi Boko Haram ati kikoju awọn onijẹgudujẹra ti o jẹ opo pataki ipolongo Aarẹ Buhari lọdun 2015 papọ si abẹ isọri kan ṣoṣo.
Ajo UNICEF gba awọn alaboyun nimọran lati lọ sile iwosan ijọba tabi ti aladani to kun oju owo ti wón ni awọn ohun eelo itọju alaboyun ati ọmọ tuntun.
Nigba to n ba BBC Yoruba sọrọ lori iku Olumilua, Mimiko ni eeyan gidi ati ẹni Ọlọrun ni ọga oun naa, to si jẹ oselu to nifẹ awọn araalu pẹlu ibẹru Ọlọrun.
kí ó má baà gbọ́ ohùn afunfèrè,tabi ìpè adáhunṣe.
Ẹ ti ranṣẹ lọ sọ́dọ̀ Johanu, ó sì ti jẹ́rìí òtítọ́.
Pẹlu imọran pe ki alaboyun maa ṣe ere idaraya ti kò lera pupọ ki o le ran an lọwọ lasiko ìrọbí.
Ìtàn ayé Henry Fajemirokun, olówó tó fi owó mọ Olúwa àti ènìyàn Ó ṣeéṣe kí ènìyàn 12,000 máa kú lójoojúmọ́ lẹ́yìn Covid-19 Orílẹ̀-èdè mẹ́wàá tí ẹgbẹ́ alákatakítí Islamic State n fínna mọ́ ní àgbáyé N kò gba ₦4bn lọ́wọ́ Magu, ẹ má ró àjẹbánu mọ́ mi láṣọ - Osinbajo pariwo Eyi yoo si jẹ ka mọ irufẹ awọn aisan to rọ mọ irufẹ ayẹwo ti itọ wa n mu jade.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Footballers: ìkà láwọn aṣojú agbábọ̀ọ̀lù míì lágbàyé Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Footballers: ìkà láwọn aṣojú agbábọ̀ọ̀lù míì lágbàyé 24 Èbibi 2019 Ireti òbí àti alágbàtọ́ ti n wọ̀ọkùn lórí àṣeyọri ọmọ wọn to n gba bọọlu.
Sugbọn ni ọdun 2019, lasiko ibo gomina to waye ni ipinlẹ Kwara, Abdulrahman Abdulrazaq jawe olubori, gẹgẹ bii gomina ipinlẹ Kwara lọjọ Kẹsan, osu Kẹta.
Wọn yoo pe wọn si ipade ni olu ijọ Aguda, to wa ni Vatican, idibo yoo si tẹle e- 'conclave' ni wọn maa n pe eto idibo naa.
Iroyin to n tẹ wa lọwọ ni yajoyajo n fi ye wa pe Olumilua jade laye ṣugbọn a ko tii lee fi idi iku to paa mulẹ.
paapaa julo lori kamera to gbe  aworan
'Ọkọ mi mú ọ̀bẹ jáde lápò, ó sì gé imú mi jábọ́.
Ṣugbọn Jona gbéra ó fẹ́ sálọ sí Taṣiṣi, kí ó lè kúrò níwájú OLUWA.
Wọ́n ṣe ogún àkànpọ̀ igi fún ẹ̀gbẹ́ àríwá àgọ́ mímọ́ náà, 
Ajọ to n risi idena ati amojuto ajakalẹ aarun ni Naijiria, NCDC lo fi iroyin yin lede ni oju opo ikansiraẹni Twitter wọn.
Àwọn eniyan náà ń pàrọwà fún mi pé, “Má waasu fún wa.
Body Farms: Ṣé ó tọ̀nà láti fi ojú òkú ráre báyìí?
Olu Jacobs: Ipò wo ni gbajúmọ̀ òṣèré tíátà yìí wà?
Jesu bá wí fún un pé, “Máa lọ, igbagbọ rẹ ti mú ọ lára dá.
Iṣẹ́ Kudirat Abiọla ṣì ń fọhùn síbẹ̀, lẹ́yìn ọdún 23 tó papòdà Fulani DaranDaran di fà kí n fà láàrin Gómìnà Ganduje àtàwọn Gómìnà ilẹ̀ Yorùbá Barrister ló sọ mí di èèyàn ńlá - Ayinla Kollington Ẹ wo àwọn ìròyìn tó ṣì ń gbóná fẹli fẹli lọ́sẹ̀ yìí Ta ni Ẹlẹwa Ṣapọn?
Ọkọ rẹ, Pyotr ba oku ọmọ oṣu meje ni baluwẹ lọjọ kan to pada sile, o si ri Alyona iyawo rẹ lẹgbẹ odo kan ni abawọlu Moscow, nibi to ti n mu ọti Vodka.
Agbẹnusọ fun ikọ ologun aditẹgbajọba naa, gagun Ismael Wague lo sisọ loju ọrọ yii lori tẹlifisan orilẹede naa.
Wọ́n dá a lóhùn pé, “Jesu ará Nasarẹti ni.
Nígbà tí wọ́n jíṣẹ́ fún Jehu pé wọ́n ti kó orí àwọn ọmọ Ahabu dé, ó pàṣẹ pé kí wọ́n kó wọn jọ sí ọ̀nà meji ní ẹnubodè ìlú, títí di òwúrọ̀ ọjọ́ keji.
Ondo Coronavirus: Akeredolu ní igbó ìpínlẹ̀ Ondo ló dára jùlọ lágbaye tí kò sì yẹ kó máa ṣòfò Oríṣun àwòrán, other Gomina Ìpínlẹ̀ Ondo, Rotimi Akeredolu tí ṣàlàyé nípa opo anfaani tó wa nídìí ọ̀gbìn igbó.
Bí ààrùn náà ṣe ń kan ọjọ́ orí.
Nítorí láti inú rẹ ni aṣiwaju kan yóo ti jáde,tí yóo jẹ́ olùṣọ́-aguntan fún Israẹli, eniyan mi.
Kí ẹnikẹ́ni tí ó bá ṣèèṣì pa eniyan lè sá lọ sibẹ.
Ọkeowo ṣalaye pe igbakeji Gomina Ondo tun ti yan oun gẹgẹ si ipo gẹgẹ bi akọwe iroyin.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, COZA: Ọpọ èrò ló jáde ṣe lòdì sí ẹ̀sùn ìfipábánilòpọ̀ Fatoyinbo Bukky Shonibare ni awọn agbofinro ti kọkọ ranṣe si oun lati wa ṣalaye nipa iwọde ti wọn fẹ ṣe naa tẹlẹ.
lodun 1959 ni aarẹ Dwight D Eisẹnhowe lo baalu akọkọ, to ni oda pupa ati goolu sugbon laye aarẹ Kennedy baalu naa tun lo oda buluu ati funfun, titi di oni yii.
Ṣugbọn eniyan rere a máa ro èrò rere,ìdí nǹkan rere ni à á sì í bá wọn.
Lagbegbe Alausa ni ilu Eko, gbogbo awọn dokita ati akọroyin to n bọ lati ibi iṣẹ ni awsn ọlọpaa ko da satimọle ti wọn si gbẹsẹle ọkọ wọn.
Oríṣun àwòrán, Twitter /Nigerian Presidency Àkọlé àwòrán, Ireti wa pe idokowo naa yoo mu idagbasoke ba eto ọrọ aje Naijiria Ikunpa fun ọrọ aje laarin Naijiria ati ilẹ Gẹẹsi Awọn onimọ nipa eto ọrọ aje ti tẹnumo pataki ṣiṣe ikunpa fun ọrọ aje laarin Naijiria ati ilẹ Gẹẹsi.
Kó ẹrù rẹ jáde lójú wọn ní ọ̀sán gangan kí ìwọ pàápàá jáde lójú wọn ní ìrọ̀lẹ́ bí ẹni tí ń lọ sí ìgbèkùn.
"Ó lọ sùn lánàá sùgbọ́n nígbà ti olúkúlùkù jí láàrọ̀ òní ni kò jí mọ́ Ọkùnrin náà kò dárúkọ ilé ìtura tàbi àdúgbò ti ìṣẹ̀lẹ̀ náà ti wáyé sùgbọ́n ìlú Port Harcourt lo ti ṣẹlẹ̀.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Akinọla: Ọdún méjì ni kí ẹ ti bẹ̀rẹ̀ kíkọ́ ọmọ nípa ìbálòpọ̀ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Akinọla: Ọdún méjì ni kí ẹ ti bẹ̀rẹ̀ kíkọ́ ọmọ nípa ìbálòpọ̀ 12 Bélú 2018 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 1 Ìgbé 2020 Ìfipá-bọmọdélòpọ̀ jẹ́ ohun tí òbí gbudọ̀ sàkíyèsí Òbí gbọ́dọ̀ ṣe ìwádìí ní kíkùn lóri ibikíbi ti ọmọ bá ń lọ.
Ta ló rí irú rẹ̀ rí?
Ṣugbọn mo wí fun yín pé ẹ̀yin ti rí mi, sibẹ ẹ kò gbàgbọ́.
Nígbà tí Hiramu, ọba Tire, gbọ́ pé Solomoni ni ó gun orí oyè lẹ́yìn baba rẹ̀, ó rán oníṣẹ́ sí i; nítorí ọ̀rẹ́ ni òun ati Dafidi, wọ́n sì fẹ́ràn ara wọn.
Àkọlé àwòrán, Agbègbè Ìkóríta Ọ̀tẹ́dọla ní opópónà márosẹ̀ Ìbàdàn sí ìlú Èkó ni ìsẹ̀lẹ̀ náà ti wáyé.
ni ile gomina to wa ni ilu Ilorin lojo Aje.
Èyí ni ilẹ̀ tí wọ́n pín fún ẹ̀yà Efuraimu gẹ́gẹ́ bí iye ìdílé wọn, 
Bí àwọn gbájugbajà òsèré ṣe ń sọ ti wọ́n bẹ́ẹ̀ ni àwọn tó jẹ́ ilúmọ̀ọ̀ká láwùjọ àti àwọn ọmọ Naijira míràn náà ń sọ bí o ṣe yẹ kí o rí.
Iṣẹlẹ ọhun waye lọsan ọjọ Ẹti ni ile to wa ni nọmba 16, Salvation, ni Opebi to wa ni Ikeja.
tí ọba Sedekaya ní, “Ẹ sọ fún Jeremaya pé kí ó bá wa ṣe ìwádìí lọ́dọ̀ OLUWA nípa Nebukadinesari, ọba Babiloni, tí ó gbógun tì wá; bóyá OLUWA yóo ṣe iṣẹ́ ìyanu rẹ̀ fún wa, kí Nebukadinesari kó àwọn ọmọ ogun rẹ̀ kúrò ní ilẹ̀ wa.
Wọ́n ṣe àjọ̀dún Àgọ́ Àjọ, wọ́n rú ìwọ̀n ẹbọ sísun tí a ti ṣe ìlànà sílẹ̀ fún ọjọ́ kọ̀ọ̀kan.
Nígbà tí àwọn Juu rí ọ̀pọ̀ eniyan, owú mú kí inú bí wọn.
Ọrẹ Arlẹ̀ne kan lo fi iwe ipe ransẹ si i wi pe, oun se igbeyawo ni Kinshaha, to jẹ olu-ilu Democratic Republic of Congo, ti oun ati ọrẹ ọkunrin rẹ si jọ wọ asọ kan naa gẹgẹ bo se wọpọ laarin awọn ẹya ilẹ naa, lati ma a da asọ ẹbi lasiko igbeyawo.
2 Àti pé nípa ìgbàgbọ́ yín ni ẹ̀yin yíò lè rí wọn, àní nípa ìgbàgbọ́ náà èyí tí àwọn Wòlíì ìgbàanì ní.
wọ ́ n bí fọláṣadé Ọláyínká bádérìnwá , tí wọ ́ n mọ ̀ lẹ ́ nu iṣẹ ́ rẹ ̀ sí Ṣadé bádérìnwá ( / ˈʃɑːdeɪ ˈbɑːdərɪnwɑː /  shah-day bah-dər-in-wah "" ) , ní ọjọ ́ kẹrìnlá oṣù kẹ ́ rin , 1969 ."
Ooni Adeyeye: Ọmọ Nàìjíríà Mílíọ̀nù márùn ún yóò jànfàní ẹ̀kọ́ ọ̀fẹ́ látọ̀dọ̀ Arole Oodua ti Ile Ife
Coronavirus Cases in Africa: Agbaṣẹ́ṣe ti ní kí Seyi Makinde fún òun ní ₦156m lórí iṣẹ́ ọpọlọ òun to lò láì tọ́ Oríṣun àwòrán, Twitter Àkọlé àwòrán, Olufemi Oluyide tí í ṣe Agbaṣẹ́ṣe pẹ̀lú ìjọba Ọ̀yọ́ ní, iṣẹ́ ọpọlọ òun ni ìlànà tuntun fún àkóso gáréèjì ọkọ̀ ní Ìpínlẹ̀ náà, tí ìjọba ṣẹ̀ṣẹ̀ ṣe ìfilọ́lẹ̀ rẹ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Mò ń fi lẹ̀kẹ̀ ya àwọnran láti jèrè ǹkan méjì - Olaniyi Olaniyan O wa rọ awọn ọmọ ile igbimọ aṣofin lati wo awọn eto ti awọn oludije fun ipo olori ni fun wọn, ki wọn si dibo fun ẹni to wu wọn.
Ẹni ti ọrọ naa ṣoju rẹ ṣalaye pe awọn ọlọpaa SARS mu ọrẹ Kolade to di oloogbe ni Kolade ba beere lọwọ wọn wi pe ki lo de ti wọn fi mu ọrẹ.
Titi a fi gbá ara wa ní ìyàwó, kò hùwà àbòsí kan sí mi rí, kò wí pé ki n wa kí n dé ibẹ̀ ki n má báa, kò wí pé kí a pàdé ní ibì kan kí n dé ọ̀hún ki n ma rí i, kò yẹ àéhùn lọ́jọ̀ kan ṣoṣo rí, bí mo bá dé ilé wọn ẹni ti ó bá tọ́ kí n kí tí n kò tíì kìí, a tọka rẹ̀ sí mi, bí àwọn òbí rẹ sọ̀rọ̀ kan nípa mi á wí fún mi, bí ojú mi yípadà díẹ̀ kínún, ó ti mọ̀, kò tú àṣírí mi rí, àfi bí ó bò ó, ọ̀rọ̀ tí mo bá fi pamọ́ sí ọwọ́ rẹ̀, kò jẹ́ wí i fún ẹnikẹ́ni, ènìyàn rí i gbẹ́kẹ̀lé.
Awọn miran sọ pe tolotolo pọ ni America nigba ti wọn da orilẹ-ede naa silẹ ni eyi to fi jẹ ki wọn maa pa wọn jẹ lasiko naa.
Loju opo Twitter Buhari lo ti hande pe Jonathan ṣebẹwo si Aso Rock lati jabọ lorii ọrọ gbọnmi si i omi o to ninu oṣelu ati igbesẹ ipẹtu saawọ eyi ti ajọ ECOWAS n gbe lọ si orilẹede Mali.
ti oju ona ma-ro-sẹ to gba  Port
Majẹmu náà tí ó wà láàrin èmi pẹlu rẹ, ati atọmọdọmọ rẹ, tí ẹ gbọdọ̀ pamọ́ nìyí, gbogbo àwọn ọmọkunrin yín gbọdọ̀ kọlà abẹ́.
" Ṣé òótọ ni pé èèyàn leè kó Coronavirus láti ara aṣọ tàbí bàtà?
Buhari: Ẹ̀yin òṣìṣẹ́ aláàbò, ẹ ṣe ohun tó yẹ láti pèsè ààbò tó péye
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù COZA: Lẹ́yìn ìwadìí PFN ni CAN tó leè sọ̀rọ̀ lórí ẹ̀sùn tí wọ́n fi kan Fatoyinbo 16 Agẹmo 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 17 Agẹmo 2019 Oríṣun àwòrán, CAN/Fatoyinbo Apapọ ẹgbẹ ọmọlẹyin Kristi ni Naijiria, CAN, ti sọ pe oun ko mọ nkankan nipa bi awọn kan ṣe ṣe abẹwo a n bẹ lẹyin rẹ si COZA.
Oríṣun àwòrán, Getty Images O rọ ijọba lati mu gbogbo nkan rọrun fun awọn ọmọ Naijiria lasiko yii, ki wọn ba le tọju ara wọn ati ẹbi wọn.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fọ́nrán ohùn, kíni ìdí tí ìjọba kò ṣe tíì pe àwọn darandaran ní agbésùmọ̀mi Ọgagunfeyinti Michael Abiodun Oladeji, tó jẹ́ onímọ̀ nípa eto ààbò, ṣàlàyé pé àwọn darandaran yàtọ̀ sí àwọn Boko Haram àti Niger Delta nítorí pé kò sí ìdí kan pàtó tí wọn fi ń pànìyàn ṣùgbọ́n àìgbọ-ara-ẹni-yé lo ṣokùnfà ìjà àwọn darandaran.
Ijoba ipinle Kwara ti gba ajo alaniloye ni Naijiria, iyen, National Orientation Agency (NOA) atawon ajo to nii se pelu sise idanilekoo fawon ara ilu gbogbo lati bere eto ilaniloye fawon oludibo saaju eto idibo odun 2019.
Oríṣun àwòrán, Bolasarumialiyu/Instagram Àkọlé àwòrán, Ọmọ bíbí ìlú Ibadan ni Ilẹ Ibadan lo ti kawe alakọbẹẹrẹ, ati girama , ko to gba Fasiti Anglia Ruskin Cambridge, ilẹ Gẹẹsi lọ fun iwe giga.
tun so pe “mo tun fi asiko yii ki gbogbo awon osise orile ede yii ku  ayẹyẹ ayajọ ọdun osisẹ lagbaaye” .
Ǹjẹ́ ọdún rẹ rí bíi ti eniyan?
O ni ohun kan tawọn ọlọpaa mọ ni lati maa ge ẹmi awọn ọdọ kuru kaakiri orilẹede Naijiria.
Àwọn ẹṣin ati kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ wọn wà bí wọ́n ṣe so wọ́n mọ́lẹ̀, gbogbo àwọn àgọ́ wọn sì wà gẹ́gẹ́ bí àwọn ará Siria ti fi wọ́n sílẹ̀.
Peter jẹ ẹni to ni ailera ti awọn onimọ n pe ni Obsessive Compulsive Disorder (COD).
- Òǹwòye ìdìbò YIAGA Wo àwọn ìlérí tàwọn Gómìnà tuntun ṣe nínú ìbúra wọn Ọjọ̀gbọ́n Fatunde: Báyìí ni bàbá ìsàlẹ̀ nínú òṣèlú ṣe lè dópìn bí El-Rufai ṣe sọ Sheikh Dahiru Maraya to jẹ oniwaasu agba ninu ẹsin Islam ni Kaduna sọ fun BBC pé ofin naa ṣe lodi si ẹtọ ọmọniyan Naijiria ninu iwe ofin ilẹ wa.
Erongba ijoba ni lati se adinku eto isuna re si iko mefa ninu ida ogorun 6.
Sex for Grade: Ọwọ́ àwọn aṣòfin yóò bẹ̀rẹ̀ sí ní tẹ àwọn olùkọ́ fásitì olójúkòmúòlọ Oríṣun àwòrán, @NGRSenate Ile igbimọ aṣofin orilede Naijiria yoo ṣe ipade lori abadofin kan ti wọn gbero lati fi ṣe ofin ti yoo lodi si ilọkulọ ibalopọ lawọn ile iwe giga fasiti Naijiria.
Apero naa ni wọn ni yóò maa wá ojúútu si òmi ètò ààbò to ti ń dàrú ni ìhà Guusu - ìwọ̀-òòrun Nàìjíríà láti oṣù díẹ sẹ́yìn.
Ọ̀pọ̀ ọmọ ogún Gẹ̀ẹ́sì àtàwọn èèyàn miran ló lugbadi àrùn yìí, tó sì gba ilẹ̀ Yúróòpù, Asia àti Áfíríkà kan.
Inú bí OLUWA sí Usa, OLUWA sì lù ú pa nítorí pé ó fi ọwọ́ kan àpótí ẹ̀rí náà.
Oríṣun àwòrán, Garba Shehu Aarẹ Muhammadu Buhari yoo ba awọn ọmọ orilẹede Naijiria sọrọ ni agogo mẹjọ ọjọ Aje.
“leyin ikolu oniruuru ti o ti waye nilu Ghouta… Eyi ti sokunfa owon gogo ounje, ti awon einyan  si filu naa sile Bakan naa, isinkun awon ti o ti ba isele naa lo, ni ko le waye lataari awon ibugbami ohun ija oloro lotun losi.
Nígbà tí ẹ bá kọ́ fọn fèrè ìdágìrì, àwọn tí wọ́n pa àgọ́ sí ìhà ìlà oòrùn Àgọ́ yóo ṣí, wọn yóo sì tẹ̀síwájú.
Iroyin fi ye wa pe Da Rocha kọle, o kọ aasẹ silu Eko, to si ṣiṣẹ takuntakun lati ri daju pe ilu Eko ni idagbasoke ati awọn ohun eelo amayedẹrun to yẹ nigba to fi wa loke eepẹ.
Arakunrin baba Saulu bá bi í pé, “Kí ni Samuẹli sọ fun yín?
Alaye Ọladapọ ree siwaju si: Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fọ́nrán ohùn, Sokoto ni baba to ba ọmọ rẹ lo lati pokunso Agbẹnusọ fun ajọ NSCDC fikun pe, nigba ti afurasi naa, Razak n sọ tẹnu rẹ, o ni lootọ ni oun n ba Zenab ni ajọsepọ, iṣẹ esu si ni isẹlẹ naa.
Ajax to le Real Madrid ti ife ẹyẹ naa wa lọwọ lọ le yoo maa gbalejo Juventus, ẹgbẹ agbabọọlu Cristiano Ronaldo.
” Masari,ni aare orile ede Naijiria Muhammadu  Buhari ti fun awon gomina “Ni idaniloju pe awon yoo gbe igbesẹ
Oríṣun àwòrán, Mountain of Blessing and Miracle Church of Christ Wooli Faleyimu sọ nigba naa wipe ti ko ba ṣe awọn akanṣe adura kan, ko ni ri ọmọ bi titi to fi maa jade laye.
Awọn ẹbi ati ara ti sin arabinrin Aishat Mustapha ti agbara ojo gbe lọ ni Ọjọ Aje ni agbegbe Surulere ni ipinlẹ Eko.
Oluwateru:Oju bọrọ kò ṣé gbọmọ lọ́wọ́ ekurọ South Afrika lori Xenophobia Ambassador Oluwateru daba yi gẹgẹ bii lọna abayọ nigba to n ba BBC Yoruba sọrọ, nipa ariwo to gbode lori bi awọn ọmọ orileede South Africa ṣe n dẹyẹ si awọn ọmọ Naijiria.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Olusegun Obasanjo: Ìjọba Ààrẹ Buhari kò yàtọ̀ sí ti Abacha 20 Sẹ́rẹ́ 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 21 Sẹ́rẹ́ 2019 Oríṣun àwòrán, Google Àkọlé àwòrán, Ní ilé rẹ̀ ní Oke-Mosan, OOPL ,Abeokuta ni ààrẹ tẹ́lẹ̀rí náà ti bá àwọn akọ̀ròyìn sọ̀rọ lọ́jọ́ Àìkú lórí ipò tí Naijiria wà.
Bí ẹnikẹ́ni bá jẹ ẹ́ ní ọjọ́ kẹta, ohun ìríra ni, kò sì ní jẹ́ ìtẹ́wọ́gbà mọ́.
 O ro awon obi ati alagbato lati maa ko awon omo won ni ede ati asa Igbo ki won le mo orisun won ati awon itan akoni to ti lo seyin ki won le ko eko daadaa.
Nígbà tí ó di òwúrọ̀, ó dìde, ó ṣí gbogbo ìlẹ̀kùn ilé OLUWA, ṣugbọn ẹ̀rù ń bà á láti sọ ìran tí ó rí fún Eli.
Nítorí nípa òfin, mo ti kú sinu òfin kí n lè wà láàyè lọ́dọ̀ Ọlọrun.
Ẹni tí ó bo ẹ̀ṣẹ̀ rẹ̀ mọ́lẹ̀ kò ní ṣe rere,ṣugbọn ẹni tí ó jẹ́wọ́ ẹ̀ṣẹ̀ rẹ̀,tí ó sì kọ̀ ọ́ sílẹ̀, yóo rí àánú gbà.
Adisa ni awọn aṣoju ileeṣẹ to n ri si eto ẹkọ ni ipinlẹ Oyo yoo ma kaakiri awọn ile iwe lati ri pe wọn ni gbogbo oun to yẹ O ni eyi ko ṣẹyin ki wọn baa le ni lọna ati dena itankalẹ arun Covid-19 laarin awọn ọmọ ile iwe.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Donald Trump: Àkọbí ọmọ ààrẹ, Donald Trump Jr ti lùgbàdì Covid-19 2 Ọ̀wàrà 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 21 Bélú 2020 Oríṣun àwòrán, Getty Images Akọbi ọmọ ọkunrin aarẹ orilẹede Amẹrika, Donald Trump naa ti lugbadi aarun Coronavirus gẹgẹ bi agbẹnusọ rẹ ṣe fi sita.
3 Bí èyí kò bá rí bẹ́ẹ̀, gbogbo ilé ayé ni yíò di ìfiṣòfò ní bíbọ̀ rẹ̀.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Obasanjọ-Kufuor: AU, ECOWAS gbọdọ̀ dá sí ọ̀rọ̀ Benin 13 Òkùdu 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images/GEORGES GOBET Aarẹ nigba kan ri lorilẹede Ghana, John Kufuor ati Aarẹ tẹlẹ ni Naijiria Olusẹgun Ọbasanjọ, ti ke pe ajọ iṣọkan awọn orilẹede ni Afirika (AU), ati ajọ ECOWAS, lati da si oṣelu orilẹede Benin to n kọni lominu bayii.
Ìjọba àpapọ̀: A óò dá ẹnikẹ́ni tó bá gbé ìwé àti àṣírí ìjọba síta lórí ayélujára lọ́nà àìtọ́ dúró
 Àwọn odò ọnà ló ni agẹmọ , àwọn ìbarà lo ni gẹ ̀ lẹ ̀ dẹ ́ .
Àṣàkẹ́: Òun ni ó jẹ́rìí sí owó kòkó ti Àkàngbé gbà.
Lọ fọwọ́ kàn án;kí o wo irú ìjà tí yóo bá ọ jà;o kò sì ní dán irú rẹ̀ wò mọ́ lae!
Wo àwọn tó ń jí owó Covid-19 tí Ìjọba ní wọ́n yóò káwọ́ pọ̀nyìn rojọ́ Ìjọba ìpínlẹ̀ Eko ti bẹ̀rẹ̀ àtúnkọ́ ilé tí ẹlikọ́pútà tó jábọ́ bàjẹ́ ní ìlú Eko O fikun pe o ti le ni obinrin ẹgbẹrun mẹrin ti Jeremy ti balopọ, ti wọn si gbadun rẹ lai fi ẹsun ifipabanilopọ kan an.
Ó wọn gígùn ẹnu ọ̀nà náà, ó jẹ́ igbọnwọ mẹtala (mita 6½).
Lọwọlọwọ bayi, Joe Biden lo n lewaju ṣugbọn obiri laye, o le yi pada ki o fi sọdọ Trump.
 Oríṣun àwòrán, Twitter/Foursquare Gospel Church Àkọlé àwòrán, Oludari ile ijosin Four Square Gospel Church Ẹwẹ, awọn akẹkọọ ni fasiti ilu Eko ti o ba BBC sọrọ lawọn ko tii foju kan olukọ naa lẹyin ti BBC gbe fọnran fidio naa jade lọjọ Aje."
Nitori àṣejù yi, olè bẹ̀rẹ̀ si jà ni ibi igbéyàwó, eyi jẹ́ ki wọn gbé àpèjẹ igbéyàwó àti àwọn ayẹyẹ yoku kúrò ni ilé.
 A ti ni Vogue Arabia fun awon ara Larubawa ni eyi to fihan pe tile Adulawo lo ye ki o kan.
Tamaryn Green, lati Paarl ni Western Cape ni won ti de ni ade omobinrin to rewa ju ni South Africa f’odun 2018 ni Sun Arena, Time Square ni Pretoria.
Buhari Nalado Sandamu to jade laye lẹyin to se ounjẹ adidun si ẹnu aarẹ Buhari fun ọgbọn ọdun gbako.
Ṣugbọn nígbà tí ó tó àkókò tí ó wọ̀, Ọlọrun rán Ọmọ rẹ̀ wá.
Ṣugbọn Joabu dá a lóhùn pé, “Rárá o, kì í ṣe ìwọ ni o óo mú ìròyìn náà lọ lónìí, bí ó bá di ọjọ́ mìíràn, o lè mú ìròyìn ayọ̀ lọ.
Ajo naa ti awọn ileeṣẹ DAAR Communications, AIT ati Raypower lori ẹsun aṣemaṣe ni ọjọbọ, eyi to mu ọpọ awọn eniyan bẹnu ẹ̀tẹ́ lu igbesẹ ajọ naa.
Oluwo: Oluwo sọ̀rọ̀ nípa ẹwà rẹ̀ gẹ́gẹ́ bí Ọba alayé tó rẹwà gidigidi
"Oṣu mẹta sẹyin lati ri pe o ṣeeṣe ki ọrọ ko ri bayii, ṣugbọn a ko da ipalẹmọ duro, nitori a tun ro o pe Hajj ṣi le waye, ki ọrọ o ma wa a ba wa ni ojiji.
Ìjọba Nàìjíríà ti mú Dókítà Anu tí àwọn kan f'ẹ̀sùn kàn pé ayédèrú iṣẹ́ abẹ ìdí ló n ṣe Erépá ní bàbá àti ìyá mi ṣe tí wọ́n fi bí mi, wọn kò fẹ́ra wọn- Funsho Adeolu Èyí ni bí Hushpuppi ṣe gbìyànjú láti jí $124m lọ́wọ́ ẹgbẹ́ agbábọ́ọ́lù Premier League kan Àjọ NCDC kéde ènìyàn 454 tó tún ṣẹ̀ṣẹ̀ ní Coronavirus ní Nàìjíríà 2) Eleruwa ti Eruwa - Ọba Adebayo Adegbola: Ọdun 2011 ni ile ẹjọ rọ Ọba Adegbola loye.
yóo máa gbà ọ́ lọ́wọ́ ibi ṣíṣe,ati lọ́wọ́ àwọn ẹlẹ́tàn,
ona atilu won ni jibiti, ti ajo EFCC naa si ba ọpọlọpọ owo to fi ona eru gba
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Kaduna Rape: Wọ́n rí òkú ọmọ ọdún mẹ́fà tí wọ́n fipá bálopọ̀ nínú mọ́ṣálàáṣí 29 Òkùdu 2020 Oríṣun àwòrán, Getty Images Wọn ti ri oku ọmọbìnrin kan, ọmọ ọdún mẹfa, ti awọn kan fi ipa balopọ niluu Kaduna.
ó sì jù wọ́n sí ọgbà ẹ̀wọ̀n ní ilé olórí àwọn tí wọn ń ṣọ́ ààfin ninu ọgbà ẹ̀wọ̀n tí Josẹfu wà.
re ti o ni ile-ise naa ti san owo osu fun un.
Oríṣun àwòrán, @trueNija O tiẹ to akoko kan, ti ẹkun guusu Naijiria n beere pe ti ajọse ko ba see se, ki wsn jẹ ki onikaluku pinya, ki alaafia lee jọba.
O ni ohun to ṣe pataki ni lati rii pe idajọ ti ijọba ba fẹ ṣe ko ṣegbe fẹnikan tabi fi sibi ti ko yẹ ko fi si.
Ìdá meji ninu mẹta asiko ti mo ti lo laye, ni mo fi n wa imọ nipa kokoro aifojuri, bi wọn ṣe le gba ara ẹni kan de ti ẹlomiran, ati bi mo ṣe le kapa wọn.
ó rí aṣọ tí wọ́n fi wé orí òkú lọ́tọ̀, kò sí lára aṣọ-ọ̀gbọ̀, ó dá wà níbìkan ní wíwé.
Pneumonia: Dókítà ní kòkòrò àìfojúrí ló ń fàá òtútù àyà
Ìdí nìyí tí OLUWA fi ṣe àwọn nǹkan wọnyi sí ọ lónìí.
Amọ, awọn onimọ nipa oju ọjọ ti wi pe ojo arọọrọda ni se pẹlu bi oju ọjọ se n yipada (climate change).
Arẹwa obinrin ọmọ Naijiria yii ni a gbọ pe ọkọ akẹru rọ lu to si mu ẹmi rẹ lọ ni ipinlẹ lẹyin wakati diẹ to ṣẹṣẹ to sọ ọrọ kan loju opo Faacebook rẹ.
Nítorí náà OLUWA àwọn ọmọ ogun sọ nípa àwọn wolii pé:N óo fún wọn ní ewé igi kíkorò jẹ,n óo fún wọn ní omi májèlé mu.
Ibugbamu nla to waye ni Lebanon sọ mi soke janto, mo ri ọpọlọpọ oku nilẹ"", ohun ti ọmọ Naijiria kan to moribọ sọ ree."
Abimeleki ati àwọn ọkunrin tí wọ́n wà pẹlu rẹ̀ bá gbéra ní òru, wọ́n lọ ba níbùba lẹ́gbẹ̀ẹ́ Ṣekemu, ní ìsọ̀rí mẹrin.
Orisirisi awuye lo ti ṣẹyọ lẹyin ti abigbẹyin Aarẹ Buhari, Hanan Buhari wọ ọkọ ofurufu, Nigeria Air Force lati lọ ṣe iṣẹ ọwọ rẹ.
Ìyá ìkókó náà yóò wọṣọ tó dára nítorí ọjọ́ ayọ̀ ni ọjọ́ náà fún un.
Nítorí a máa mú kí oòrùn rẹ̀ ràn sórí àwọn eniyan burúkú ati àwọn eniyan rere; a sì máa rọ òjò sórí àwọn olódodo ati sórí àwọn alaiṣododo.
Awọ ara awọn ọmọ Britain n'igba iwasẹ Ìtọ́jú ara di ìrọ̀rùn!
Ó wá wádìí pé apá ibo ni Paulu ti wá.
Atọbatẹlẹ si la lee pe Atanda Alowolodu bii iyere, nitori aati igba ewe lo ti n se bi ọba ati eeyan nla.
Nigba to n salaye nipa ẹni to da orin Fuji silẹ nilẹ Yoruba, Kollington kede pe, oun ati Alhaji Sikiru Ayinde Barrister ni awọn dijọ bẹrẹ orin Fuji ni akoko kan naa tawọn dijọ wa ninu isẹ ologun, bi o tilẹ jẹ pe orin Fuji ti wa tipẹ ki awọn to bẹrẹ si ni gbe larugẹ.
Ṣugbọn Mose sálọ mọ́ ọn lọ́wọ́, ó lọ sí ilẹ̀ Midiani, ó sì jókòó lẹ́bàá kànga kan.
Coronavirus symtoms and cure: Seyi Makinde ní Àmàlà gbígbóná lòun fi àsìkò ìgbélé òun jẹ Aṣe ounjẹ ni gomina ipinlẹ Ọyọ, Seyi Makinde lọ fi asiko igbele rẹ jẹ?
    Ara mi gbóná já gbàà, mo múra mo lọ sí ilé mo lọ pọ́n àdá mi sílẹ̀ pé ìgbà tí ó bá dé n o pa á ni.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Taraba Killings: IGP ti jọ̀wọ́ Hamisu Wadume fún aádájọ́ àgbà Nàìjíríà 20 Ògún 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 3 Òkùdu 2020 Oríṣun àwòrán, others Àkọlé àwòrán, Taraba Killings: IGP ti jọ̀wọ́ Hamisu Wadume fún aádájọ́ àgbà Nàìjíríà Ọ́fíísì agbẹ́jọ́rò àgbà Nàìjíríà tí gbá ẹjọ́ Bala Hamisu ti gbogbo ènìyàn mọ̀ sí Wadume tó jẹ́ gbájúgbajà ajínigbé ní ìpínlẹ̀ Taraba kúrò lọ́wọ́ ọ̀gá àgbà ọlọ́pàá Muhammed Adamu.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù D'banj's rape accusation: Ẹ wo ìṣẹ̀lẹ̀ nípa ẹ̀sùn ìfipábánilòpọ̀ tí wan fi kan D'banj ní sísẹ̀n tẹ̀lé 25 Òkùdu 2020 Oríṣun àwòrán, Dbanj ati Seyitan Lati bi ọsẹ melo kan ni gbajugbaja akọrin takasufe l'orilẹ-ede Naijiria, D'Banj,ti wa ninu iroyin.
Mo ti tọ́jú òkúta ati pákó pẹlu.
Atẹjade naa ni iwọde wọọrọwọ lawọn ọmọ Shiite naa fi boju kọrọ to bẹyin yọ, ti wọn si fẹ fi tipa wọ ile asofin apapọ amọ tawọn ọlọpaa to wa nibẹ ko gba fun wọn.
Kò sí ọ̀ranyàn fún ọkọ tabi aya tí ó jẹ́ onigbagbọ ninu irú ọ̀ràn báyìí.
Níbẹ̀ ni ó kọ́ ibi mímọ́ rẹ̀ tí ó ga bí ọ̀run sí,ó sì fi ìdí rẹ̀ múlẹ̀ bí ayé títí lae.
 a gbọ ́ wí pé ìbáṣepọ ̀ wà láàárin àwọn òrìṣà tàbí òòṣà ilẹ ̀ yorùbá àti olódùmarè , àwọn yorùbá gbàgbọ ́ pe òòṣà wọ ̀ nyí nì wọ ́ n lè rán sí olódùmarè yálà láti tọrọ nǹkankan lọ ́ wọ ́ rẹ ̀ tàbí dúpẹ ́ lọ ́ wọ ́ rẹ ̀ fún ohun ribiribi tí ó ṣe fún wọn .
Èyí ni ìdí tí coronavirus ṣe n pa àwọn kan, tí kò sì pa àwọn kan Lati ara iwadii yii , awọn oluwadii naa ṣe akiyesi pe asiko otutu ni coronavirus lọ soke pupọ, ni asiko kan naa ti aisan otutu maa n wà.
Ọmọ ẹgbẹ ́ èdè tí a ń pé ní iranian ni bàlúṣì .
" Èèyàn mẹ́rìnlá tí ọpọlọ wọ́n pé la buwọ́lù bíi kọmísọ́nà l‘Oyo - Olórí ilé aṣòfin kan sáárá Èmi àti Saheed kìí ṣe ọmọdé, a ti jọ ṣe Sinimá papọ̀, èyí túmọ̀ sí pé ìjà ti parí - Fathia Balogun Mo fẹ́ pa ara mi torí ojú àbùkù tí wọn ń fi wò mí pé mo fi iṣẹ́ abẹ bímọ"" Fulani kò leè dúró, táa bá lo ohun ta jogún lọ́dọ̀ àwọn bàbá wa - Sunday Igboho Iru ipejọpọ bayii ni Munira lo dara pupọ nitori wọn ko fi aaye gba awọn lati maa fara ro ọkunrin."
Lẹyin naa lo rọ awọn eeyan lati ma ṣe imọtoto araẹni gẹgẹ bi ajọ to n gbogun ti ajakalẹ ni Naijiria, NCDC ṣe gbe kalẹ.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, O ko le wọ aṣọ dudu yii mọ Ìdí tí Ọsinbajo, asaájú tílù fẹ́ jùlọ, kò fi leè di ààrẹ báyìí Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ìdíje ayò ọlọ́pọ́n, ta lòpè?
ati nígbàkúùgbà tí wọ́n bá ń rúbọ sí OLUWA ní ọjọ́ ìsinmi, ọjọ́ oṣù titun, tabi ọjọ́ àjọ̀dún, gẹ́gẹ́ bí iye àwọn tí a yàn láti máa kọrin níwájú OLUWA nígbà gbogbo.
Agbẹnusọ Maharaj, ọgbẹni Ojo Peter lo sọ eyi lasiko to ń ba BBC Yoruba sọ̀rọ̀ lórí bí àwọn ọmọ onílẹ̀ àti àwọn ọlọ́pàá ṣe yabo abúlé Maharaj ti àwọn ọlọ́pàá naa sì dúró tìwọn.
Premier league: Góòlù Sterling tún gbé Manchester city borí Arsenal lẹ́ẹ̀kansi
Ìbọn àti afẹ́fẹ́ aláta ní DSS fi tú wa ká lásìkò ìwọ́de fún ìdásílẹ̀ Sowore Òfin ọ̀dájú ni àṣọ́bodè ṣe pé epo kò gbọdọ̀ dé ẹnu bodè Nàíjíríà - Ilé aṣojú-ṣòfin Lara awọn araalu to ba akọroyin BBC Yoruba sọrọ ṣalaye wi pe, obitibiti idọti to gba igboro ilu Ibadan kan lee ṣe akoba fun ilera awọn ara ilu.
Mọ ohun to ma n jẹ ki o paya lasiko idanwo, ki o si ri wi pe gbogbo rẹ lo wa ọna abayọ si Ri wi pe , o sọ ọrọ iwuri si ara rẹ lasiko idanwo .
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Adeboye: Ìkìlọ̀ mẹ́ta tí àgbà ìjọ fi síta nínú ìwàásù f'áwọn Pásítọ̀ ọ̀dọ́ 6 Agẹmo 2019 Oríṣun àwòrán, PASTOR E.
Ohun tí ó bẹ̀rẹ̀ láti àfonífojì Anoni títí dé òkè Herimoni.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Wọ́n ta ère Ọ̀ṣun Osogbo sí Togo - Bàbá Ọṣun figbe ta Baṣọ̀run Gáà, tó yan ọba mẹ́rin, pa ọba mẹ́rin àmọ́ ọba karùn-ún ló pa á Ọbasanjọ sọ àsírí sàgbàdèwe rẹ̀ Jesu Oyingbo rèé, pásítọ̀ tó láṣẹ ìbálòpọ̀ lóri ọmọ ìjọ obìnrin Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí kan sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
Gbogbo àwọn eniyan náà bá pa ohùn pọ̀, wọ́n ní, “Gbogbo ohun tí OLUWA wí ni a óo ṣe.
E gbodo gbajumo ise yin, tori pe idi ise eni lati moni-lole, lati tunbo satileyin fun awon aseyori ti a ti ni tele”.
Màá gba kádàrá tí mo bá fìdírẹmi - Ganduje Bí wọ́n ṣe ń ta káádì ìdìbò ní Kano nìyì Ẹlẹ́rìí 400 ni yóò tako Buhari lórí èsì ìbò - Atiku Atiku n ṣé iranran lórí ìbò 1.
 Ìtàn yìí ṣòro láti gbàgbọ ́ , nítorí kò ri ìdí múlẹ ̀ .
Ó ní òun dúpẹ́ lọ́wọ́ àwọn ènìyàn ìpińlẹ̀ Edo fún àdúrò ti wọ́n àti pé òun ni ìgbàgba pé bí òun ṣe n kúro ni Edo báyìí òun mọ̀ pé, Obaseki yóò ṣe ìtójú wọ́n dáradára.
Wọ́n gé àtàǹpàkò ọwọ́ ati ti ẹsẹ̀ rẹ̀ mejeeji.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ọba Lamidi Adeyemi pé ọdún 48 lórí ìtẹ́ 14 Sẹ́rẹ́ 2019 Oríṣun àwòrán, Alafinofficial Àkọlé àwòrán, Aláàfin Ọyọ pé ọdún 48 lórí àpèrè Òní ló pé ọdún méjìdínláàdọ́ta tí aláfin Oyo, Ọba Lamidi Adeyemi kẹ́ta gori apèrè àwọn bàbá rẹ̀.
Lara awọn iwaasu wolii Israel Oladele Ogundipe ree: Wo àwọn èèkàn, ìlúmọ̀ọ́ka olórin tó ṣàbẹ̀wò sí ijọ Celestial Church ti Genesis Global Wòlíì míì, tún wọ gàù lẹ́yìn tó tàpá sí ìlànà béèlì tí wọ́n fún un nílé ẹjọ́ Ṣé Sanwo-Olu, gómìnà Eko yóò farahàn níwájí ìgbìmọ̀ olùwádìí ìṣẹ̀lẹ̀ Lekki Tollgate?
ran awon gomina lọrun lati tete san ekunwo naa.
gege bi eni ti yoo dije fun ipo gomina legbe oselu Peoples Democratic Party,
Owó ránpẹ́ ni mo san nígbà tí mo ràá.
Wo ìdí tí àwọn obìnrin kan fi n yọ ilé ọmọ wọn kúrò O ni ti awọn asofin agba naa yoo si se ayẹwo fun awọn to fẹ gba ipo minisita ọhun, ko to di pe wọn lọ fun isinmi olosu meji eyiti yoo bẹrẹ lọjọ Kẹrindinlọgbọn osu Keje taa wa yii.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Àjọ Marie Stoppes ma n ta to miliọnu meji kọndọọmu naa l'oṣooṣu Ajọ aladani naa lo n ṣe alagbata kọndọmu ọhun, ko to o di pe ijọba fi opin si tita rẹ lọdun 2019.
Ẹ gbàdúrà kí ogun má bẹ́ sílẹ̀ ní 2020- Primate Ayodele Oludasilẹ Ijọ INRI Evangelical Spiritual Church, Oke-Afa, ni Ejigbo ni ipinlẹ Eko, Primate Babatunde Elijah Ayodele ti sọ asọtẹlẹ nipa ọdun 2020.
Àwọn tí ó bọ́ sáàrin ẹ̀gún ni àwọn tí ó gbọ́, ṣugbọn àkólékàn ayé, ìlépa ọrọ̀, ati ìgbádùn ayé fún ọ̀rọ̀ náà pa, wọn kò lè dàgbà láti so èso.
Ko si irin-ajo kaakiri orilẹede: Oríṣun àwòrán, Getty Images Irin-ajo lati ibi kan si ibo miiran ko si nigba ti ofin konile o gbele ba wa lode lorilẹede kan.
” Nítorí Saulu rò ninu ara rẹ̀ pé, àwọn Filistini ni yóo pa Dafidi, òun kò ní fi ọwọ́ ara òun pa á.
Owó ti ọ̀pọ̀lọpọ̀ Oniṣẹ́-oṣ̀u ngba kò tó lati bọ́ iyàwó kan ki owó oṣù míràn tó wọlé, bẹni kò tó gba ilé nla ti ó lè gba iyàwó púpọ̀ pàtàki ni ilú nla bi Èkó.
Tabi ẹ kò mọ ohun tí Ìwé Mímọ́ sọ ninu ìtàn Elija?
"Iṣẹlẹ naa ba ni lẹru jọjọ"" Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Segalink:ìkùnsínú pọ̀ láàrin àwọn agbófinró bẹ́ẹ̀ wọn kò ni agbẹnusọ Bakan naa, aṣọna kan ni adugbo naa, Kalu Uka ni bi oun ṣe gbọ ibọn lọwọ oru, kia kia l'oun ti ilẹkun ita ile iṣẹ ti wọn gba oun lati maa ṣọ, ṣugbọn iyalẹnu lo jẹ fun un lati gbọ iku eniyan marun un lowuro ọjọ keji."
O ni eyi jẹ imuṣẹ ileri t'oun ṣe lasiko ipolongo idibo k'oun to di gomina ipinlẹ Oyo.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Lockdown the world: Awọn ọmọ Nàìjíríà káàkiri àgbáyé sọ ìrírí lábẹ́ àṣẹ kónílé-ó-gbélé Sola àti Abidemi Kosoko: Oríṣun àwòrán, others Sola àti Abidemi Kosoko, tí àwọn méjèèjì jẹ gbajumọ osere lobinrin ni wọn jogún isẹ náà lọ́wọ́ bàbá wọn, Jide Kosoko, tíì ṣe àgbà ọjẹ osere tíátà.
Láti Hori Hagidigadi wọ́n lọ sí Jotibata.
Obinrin kan , ti ko fe ki won
Gbogbo àwọn ará ìlú náà gba ohun tí Hamori ati Ṣekemu ọmọ rẹ̀ wí, gbogbo ọkunrin sì kọlà abẹ́.
Ẹ kò gbọdọ̀ ro ire kàn wọ́n tabi kí ẹ wá ìtẹ̀síwájú wọn títí lae.
Bakan naa ni gomina tẹlẹ ọhun tun sọ ọ di mimọ pe awọn iṣẹlẹ to n ṣẹlẹ ni ipinlẹ Edo pẹlu n tọka si ipo gba f'Ọlọrun ti awọn eeyan ipinlẹ naa wa Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Láàrín ìdílé ẹlẹ́ni márùn ún yìí, ọmọ kan ṣoṣo ló léè sọ̀rọ̀ Ondo deputy governor: Igbákejì gómìnà ìpínlẹ̀ Ondo Agboola Ajayi ti fẹgbẹ́ APC sílẹ̀ lọ PDP Oríṣun àwòrán, Facebook/Allen Sowore Iroyin to n tẹ wa lọwọ ni yajoyajo sọ pe igbakeji Gomina ipinlẹ Ondo, Agboola Ajayi ti fẹgbẹ oṣelu APC silẹ lọ PDP.
Ó fojú hàn gbangba pé irọ̀ ni wọ́n ń pa, tí olórí wọn, tí wọn wà lọ́dọ̀ rẹ̀ gẹ́gẹ́ bíi fijilante tó ń sọ́ ìlú Maiduguri, sì rọ̀ wọn láti sọ tòótọ́.
Níwọ̀n ìgbà tí ẹ bá ti fínnúfẹ́dọ̀ jẹ́jẹ̀ẹ́ ohunkohun fún OLUWA Ọlọrun yín, ẹ ti fi ẹnu yín ṣèlérí, ẹ sì níláti rí i pé, ẹ mú ẹ̀jẹ́ náà ṣẹ.
Ó wọn ẹnu ọ̀nà náà láti ẹ̀yìn àwọn yàrá ẹ̀gbẹ́ kan títí dé ẹ̀yìn yàrá ẹ̀gbẹ́ keji, ìbú rẹ̀ jẹ́ igbọnwọ mẹẹdọgbọn (mita 12½), láti ìlẹ̀kùn kinni sí ekeji.
láti ìgbà tí àwọn Ẹ ̀ gbá ti dó sí abẹ ́ òkúta ni ètò ìsèlú wọn ti bẹ ̀ rẹ ̀ si yàtọ ̀ .
" Mercy ni lẹyin osu diẹ ti oun gba ẹbun akara oyinbo naa, ni oun ra ile tuntun fun ara oun ni adugbo to rẹwa ni ilu Eko, Ẹ dakun, ẹ ki iya onile tuntun"" ni Mercy sọ, pẹlu afikun pe oun ti ri oore ọfẹ Ọlọrun, ti iyanu rẹ si ti wa oun ri."
Wọn ti bura sipo fun Abiy Ahmed gẹgẹ bi olóòtú ìjọba orilẹẹde Ethiopia.
Wo ipa tí Mayegun yóò ma kó ní ilẹ̀ Yoruba!
O tun so pe “lati le  jẹ ki orile ede Naijiria ni idagbasoke, ko gbodo maa gbokan le awon orile ede miiran , nitori pe isẹ iwadii lori ẹda irin amusẹse ati ọtẹlẹmuyẹ yoo je ki idagbasoke ba imo oju omi.
Ìtàn ayé Ọba Seriki Abass ti Badagry, tó ní aya 128, ọmọ 144 Tunde Idiagbon, ọ̀gágun kògbagbẹ̀rẹ́ tó ní ẹ̀ẹ̀kan lóṣù ló yẹ kí ológun máa rẹ́rìín Yàtọ̀ sí Eko, wo ohun t'áwọn ìpínlẹ̀ meje míràn ń sọ nípa ìwọlé àwọn akẹ́kọ̀ọ́ Iléẹjọ gíga jùlọ da ẹjọ́ Wada (PDP) nù ní Abuja lórí ètò ìdìbò gómìnà ìpínlẹ̀ Kogi Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí 6:18 Fídíò, Natalia Mufutau ìyá Yakub, Kamil àti Adam sọ̀rọ̀ lórí bí wọ́n ń sọ èdè mẹ́rin pàpọ, Duration 6,1831 Ògún 2020 6:10 Fídíò, Yoruba Language: Akomolede ati Asa Yoruba tọ̀sẹ̀ yí rèé lẹ́nu olùkọ́ wa, Duration 6,1030 Ògún 2020 Èyí tí a wò jùlọ 5:03 Fídíò, Omolola Arohunmolase Welder: Mo ti fí iṣẹ́ 'Welder' gbayì láwùjọ, tó mo fi tọ́ ọmọ yanjú, Duration 5,039 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 5:39 Fídíò, Akomolede ati Asa lori BBC: Olùkọ́ Kikelomo Ogunboye tan ìmọ́lẹ̀ sí ìwà olè ọ̀gá ọlọ́pàá Audu gẹ́gẹ́ bí àwòkọ́ṣe àsìkò yìí, Duration 5,398 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 4:11 Fídíò, Oba Adeyeye Ogunwusi: Ojú mi ti rí lọ́pọ̀ lọpọ̀, ọ̀pọ̀ èèyàn ni kò tilẹ̀ gbàgbọ́ pé mo lè jọba- Ooni, Duration 4,117 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 4:43 Fídíò, Promise Akinlade: ọmọ ọdún mọ́kànlá tó ń fi ìlù dárà bíi àgbàlagbà sọ̀rọ̀ nípa tálẹ́ǹtì rẹ̀, Duration 4,437 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 0:59 Gbọ́, Ìsẹ̀lẹ̀ jákèjádò orílẹ̀èdè àgbáyé láàárín ìṣẹ́jú kan, Duration 0,59wákàtí 5 sẹ́yìn 7:03 Fídíò, Olumuyiwa Bolade Adedeji Military Bruitality: Bí arákùnrin onípèníjà ara tí sọ́jà lù ṣe dé, Duration 7,035 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 4:45 Fídíò, Yoruba Films: Ẹ̀ẹ́ bẹ̀ mi kúrò láyé ni, mi ò lè kú - Fadeyi Oloro, Duration 4,4526 Èrèlè 2020 2:48 Fídíò, Esther Ajayi: Èmi náà ti borí ìṣòro rí ló ń mu mi ṣojú àánú, Duration 2,481 Ògún 2019 6:08 Fídíò, Adebola Ademilua: Àìrísẹ́ ṣè lẹ́yìn ìwé kíkà ló sọ mi dí ìyá onírú, mo dúpẹ́ tèmi, Duration 6,0827 Bélú 2020 5:55 Fídíò, Soyinka Cancer: Àṣe ara mi ni iso ti n run gbogbo bí mo ṣe n ṣèrànwọ́ lórí jẹjẹrẹ, Duration 5,5527 Bélú 2019 BBC News, Yorùbá Ìdí tí ẹ fi le è nígbàagbọ́ nínú ìròyìn BBC Ìlànà Lílò Nípa BBC Òfin Àṣírí Cookies Kàn sí.
" Igba ti wn fi ofin yi rinl ni igba ti arakunrin kan lọ si ori Facebook to si ni apaniyan,afipabanilopo ati ole ni Oba Willem-Alexander.
Bákan náà, èmi OLUWA ṣe ìlérí pe n óo fi ìdí ìdílé rẹ̀ múlẹ̀.
ile-iṣẹ naa  ko ni  lee lo owo
Kí ó pa á ní apá ìhà àríwá pẹpẹ níwájú OLUWA, kí àwọn ọmọ Aaroni, alufaa, da ẹ̀jẹ̀ rẹ̀ sí ara pẹpẹ náà yíká.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìjàpá tó wà ni ààfin Ṣọ̀ún Ogbomọṣọ ti jáde láyé lẹ́yìn to ti lo 344 ọdún láyé 3 Ọ̀wàrà 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 4 Ọ̀wàrà 2019 Àkọlé àwòrán, Alagba papoda lẹyin aisan rampẹ Ijapa to wa ni afin Ogbomọṣọ to ti lo ojilelọọdunrun o le mẹrin ọdun loke eepẹ ti jade laye.
Ninu abajade iwadi igbimọ ti wọn ṣe agbekalẹ rẹ sọ, awọn ọmọ ileeṣẹ ologun kan ati awọn janduku to yabo ibudo ti wọn ti n ko esi ibo jọ ni o da eto idibo naa ru.
Russia nìkan ló ṣì ni àmì mẹ́ta nínú ìdíje àgbáyé World Cup 2018: Èsì ìdíje bọ́ọ̀lù tó ti wáyé Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Ilemboye n wa owo, ọmọ rẹ n wa ọkọ.
Opọ awọn onile iṣẹ nlanla bii ilé ifowopamọ ati oni ṣọọbu keekeeke ni wọn ti kogba wọle lasiko yii.
Botilẹ jẹ pe ko si ofin kankan ni Naijiria to tako wiwọ aṣọ penpe, abala karundinlogoji ofin ilu Abuja to tako ìrìn ti ko ba ofin mu ni wọn fi ka ẹsun si wọn l'ẹsẹ.
ti kede pe oun yoo fẹyinti nidi ere bọọlu ni pari idije ile geesi ti saa 2018/2019
Awọn eeyan ti isẹlẹ naa soju wọn sọ fun BBC pe ọkọ epo to gbina naa, lo gbokiti lasiko to n gbinyanju lati pẹ koto kan silẹ loju popo to wọ ilu Markudi, tii se olu ilu ipinlẹ Benue.
Ní ayé àtijọ́, nígbà tí ayé kò ì tí ì rí bàyìí, tí àwọn ọmọ ènìyàn mọ iyì Ọlọ́run ju ti ìwòyí lọ, Olódùmarè a máa ránńṣẹ́ láti ọ̀run wá láti wáá bẹ ará ayé wò, ìrańńṣẹ́ náà a sí máa wá lọ́dúun méje-méje.
Bẹ́ẹ̀ ni ẹrú kò ju oluwa rẹ̀ lọ.
Kò sí ìlú tí ó bá àwọn ọmọ Israẹli dá majẹmu alaafia àfi àwọn ará Hifi tí wọn ń gbé ìlú Gibeoni.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìwọ́de Shiite: Ọrọ̀ ajé dẹnu kọlẹ̀ ní Kaduna 20 Òkùdu 2018 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 21 Òkùdu 2018 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Àwọn mùsùlùmí Shiite kọlu àwọn ọlọ́pàá lọ́pọ̀ ìgbà nibi tí wọ́n ti ṣe ìwóbi pé k'ìjọba tú olórí wọn sílẹ̀ Ọpọ eeyan lo farapa nibi t'awọn musulumi ti wọn jẹ ọmọ ẹgbẹ Shiiite ti kọlu awọn ọlọpaa lasiko ti wọn n ṣe iwọde nilu Kaduna l'Ọjọru.
 david levering lewis to je olukowe itan koole pe ,  nigba ajo ise re fun ojo pipe , w."
Olórin gidi gbọdọ mọ bi wọn ṣe ń lo ohun eelo orin kan.
orile-ede ohun so pe o seese ki o da rogbodiyan sile.
Nígbà tí Naomi rí i pé Rutu ti pinnu ninu ọkàn rẹ̀ láti bá òun lọ, kò sọ ohunkohun mọ́.
Abimeleki bá lọ sí òkè Salimoni, òun ati gbogbo àwọn tí wọ́n wà lọ́dọ̀ rẹ̀.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù EndSars in Portharcourt: Ọjọ́ méjì sẹ́yìn ni aya awakọ̀ Márúwá tí ọlọ́pàá pa bímọ tuntun 7 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 10 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Oríṣun àwòrán, Allwell Ene Bi ijọba se n sanna bi a se jẹ ekuru ọran ko tan nidi ifẹhonuhan tawọn araalu n se tako awọn ọlọpaa, se ni awọn eeyan kan tun n gbọn ọwọ rẹ sinu awo.
A gbọ iroyin pe ile iwe alakọbẹrẹ yii lo wa loke patapata ile alaja ọhun.
nítòótọ́, o gbọ́n ju Daniẹli lọ, kò sì sí ohun àṣírí kan tí ó ṣú ọ lójú.
Amọ, wọn ko i ti sọ iye eniyan to ku sinu ijamba naa.
Gbogbo nǹkan yòókù tí Hesekaya ṣe, ìwà akọni rẹ̀ ati bí ó ti ṣe adágún omi ati ọ̀nà omi wọ inú ìlú ni a kọ sinu Ìwé Ìtàn Àwọn Ọba Juda.
Afẹ́fẹ́ ìlà oòrùn mú kí ó gbẹ,gbogbo èso rẹ̀ sì rẹ̀ dànù.
Kí ẹ̀yin náà sì lè sọ fún àwọn ọmọ ati àwọn ọmọ ọmọ yín, irú ohun tí mo fi ojú wọn rí, ati irú iṣẹ́ ìyanu tí mo ṣe láàrin wọn; kí ẹ lè mọ̀ pé èmi ni OLUWA.
Gbogbo àwọn ọmọ Israẹli lọkunrin ati lobinrin tí ọ̀rọ̀ náà jẹ lógún ni wọ́n mú ọrẹ àtinúwá wá fún OLUWA, láti fi ṣe iṣẹ́ tí OLUWA pa láṣẹ fún Mose.
’’Aare Buhari  wa gbosuba fun ajo eleto idibo lorile ede
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Liverpool lu Tottemham pa Ẹgbẹ agbabọọlu Tottenham gbiyanju, ṣugbọn omi pọ ju ọka lọ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ajínigbépawó jí akọ̀wé NURTW gbé l'Óǹdó 15 Ìgbé 2018 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Mílíọnù máàrún naira làwọn ajinigbepawo náà ń bèèrè láti túu sílẹ Àwọn ajínigbípawó kan ti jÍ akọ̀wé ẹgbẹ́ awakọ̀ èrò, NURTW nipinlẹ Oǹdó, Comrade Kayode Agbeyagi gbé.
Ilẹ̀ yóo sì dáhùn adura ọkà, ati ti waini ati ti òróró.
 wọn wá sí ilẹ ̀ Ìjẹ ̀ ṣa láti dó sí kí wọn lè ni àyè ijọba tiwọn .
Ẹni to bori: Namibia Senegal vs Benin.
Kí ìwọ lọ kí èmi jókòó sáyé àbí nla- Èmi kọ́.
"Ilé iṣẹ́ ọmọogun òfurufú ti bẹ̀rẹ̀ ètò ìgbaníwọlé- Àwọ ìlànà ìforúkọsilẹ̀ rèé Bí o ṣe lè forúkọ silẹ̀ fún ètò ""N75BN Nigerian Youth Investment Fund"" rèé."
Awọn nkan miran nipa rẹ to tun wa nibẹ ni, orukọ, ọjọ ori, ati ẹya rẹ.
”Igbakeji aare,Osinbajo wa gbe bibeli ti won fi awon ede orile ede Naijiria ko fun Bishop Jakes.
Ẹ máa ṣe ohun gbogbo láìsí ìkùnsínú tabi iyàn jíjà, 
Àwọn ọmọ-ogun náà ń bi í pé, “Àwa náà ńkọ́, kí ni kí a ṣe?
Ọpọ atunṣe lo n lọ lọwọ lati rii pe awọn agbofinro gbaye gbadun,'' ọga ọlọpaa lo sọ bẹẹ.
Ijọba Aarẹ Muhammadu Buhari wa fi kun wi pe ki awọn ọmọ Naijiria o fọkanbalẹ nitori idibo naa yoo lọ ni irọwọrọsẹ lai si magomago.
Àwọn tẹ̀gbọ́n-tàbúrò yóo ṣe ikú pa ara wọn; bẹ́ẹ̀ ni baba yóo ṣe sí ọmọ rẹ̀, àwọn ọmọ yóo tàpá sí àwọn òbí wọn, wọn yóo sì pa wọ́n.
Ile asofin Amẹrika gbarata bẹẹ ninu iwe ẹhonu kan to kọ ransẹ si ileesẹ asoju ijọba Naijiria pẹlu afikun pe iwa ifiyajẹni ijọba Naijiria ti n kọ ọpọ eeyan lominu, to si n mu ifura lọwọ.
Ilé iṣẹ́ ọlọ́pàá ní ipínlẹ̀ Edo tí mú ọmọ ologun, kọpora Mose Oguche tí wọ́n fẹ̀sùn kan pe ó gun awakọ pa ní ìlú Okenne ni ipínlẹ̀ Kogi.
Daromosu gba awon eniyan niyanju lati maa sayewo olodoodun fun oju won ni kete ti won ba ti pe omo ogoji odun ati pe ki awon ebi ti arun yii ba ti yo enikeni lenu tele ri maa sayewo lati omo odun meje soke.
" Oríṣun àwòrán, Others Ofin tuntun naa ni yoo risi eto iforukọsilẹ, gbigba ontẹ ijọba, owo ori, ati ilana fun iṣẹ ṣíṣe.
Ó wà ninu Ìwé Mímọ́ pé, “Àwọn tí ó mú ìyìn rere wá mà mọ̀ ọ́n rìn o!
Sanwoolu: Nígbà wo ni mo ṣèlérí mímú òpin bá súnkẹrẹ-fàkẹrẹ Apapa?
gomina to wa ni  Agodi niluu Ibadan , ni ipinle
Ṣugbọn Jesu ní, “Ẹ má sunkún mọ́, nítorí ọmọ náà kò kú, ó ń sùn ni.
Lẹyin naa lo ni bo tilẹ jẹ pe awọn eeyan lẹtọ labẹ ofin lati ṣe ifẹhonuhan, ileeṣẹ ọlọpa ko ni faye gba iru rogbodiyan bayii mọ.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ade Yoruba Ikede ti jade wi pe wọn ti ji Oloye Razak Olaseinde Adamson to jẹ Baalẹ ilu Apese ni ijọba ibilẹ Eti Osa, ipinlẹ Eko.
Oríṣun àwòrán, Soweta/getty Omotosho si sọ nigba naa pe, oun ko jẹbi ẹsun naa.
Lojoojumọ ni mo wà pẹlu yín ninu Tẹmpili tí mò ń kọ́ àwọn eniyan, ẹ kò ṣe mú mi nígbà náà.
Victor Agunbiade ọmọ Baba Ijẹbu ni ipinlẹ Ogun to jẹ Guusu Naijiria to n gbe ogo ilẹ Oodua ga lọwọlọwọ ni idi iṣẹ ọmọ ogun oju omi ni America ni BBC Yoruba gbe wa fun un yin nipa akọni Yoruba lọtẹ yii.
Ni ile ijọba ipinlẹ Eko to wa ni Marina ni Sanwo-Olu ti gba wọn ni alejo.
O fi idunnu re han nipa bi
'Ekute jẹ ogun oloro lagọ ọlọpa' Awọn ipinlẹ kan fara kaasa arun iba Ilé ìwòsàn New Jersey ṣ'àṣìṣe ṣiṣẹ́ abẹ kìndìrín fún aláìṣàn l'Amẹrika EFCC fẹ́ gbẹ́sẹ̀ lé ilé tí mo fi owó ìfẹ̀yìntì kọ́ nílùú Ilorin- Saraki Iṣẹ buruku tawọn eku yii ṣe si awọn waya ni Estonia pọ de ibi pe ko ṣeeṣe fawọn dokita lati kọ oogun fawọn alaisan.
AFCON Qualifier: Kò séwu fún gbogbo àwọn tí yóò kópa nínú ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ Naijiria àti Sierra Leone ní Benin
Oríṣun àwòrán, iSho pepper Junior Lasiko ti Olusola n dabira lati gbe aṣa, ede ati ìṣe Yoruba larugẹ, ni iku ja ẹmi rẹ gba lairo tẹlẹ lasiko aisan ranpẹ lẹni aadọta ọdun, ni ọjọ kejidinlọgbọn, oṣu Kejila, ọdun 1992.
Eléyìí kì í ṣe iná tí eniyan ń yá,kì í ṣe iná tí eniyan lè jókòó níwájú rẹ̀.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Àyájọ́ òṣìṣẹ́: NURTW gba ẹ̀jẹ̀ lára àwọn òsìsẹ Akosile, to jẹ igbakeji oluranlọwọ pataki fun gomina lori ọrọ iroyin sọ fun BBC Yoruba pe gomina Sanwo-Olu ti fa ọrọ naa le awọn ọlọpaa lọwọ lati ṣiṣẹ wọn, MC Oluọmọ, àtàwọn èèkàn míràn sọ̀rọ̀ lórí ikú Fẹ́lẹ́ Ta bá gba àlààfíà láàyè, Makinde yóò tú NURTW sílẹ̀ l‘Ọyọ láìpẹ́ - Yasin Alága NURTW gba ìdájọ́ ikú 'torí ẹ̀sùn pípa ọlọ́pàá NURTW Ekiti fẹgba yọ àwọn adarí kúrò ní gáréèjì!
Ni ọdun 1979 ni ọgbẹni Shittu di ọmọ ile ìgbìmọ̀ asòfin ní ìpínlẹ̀ Ọyọ, to si jẹ pe, ko pọn dandan lati ni iwe ẹ̀rí agunbanirọ lati di ipo naa mú.
Olùdíje méta yẹ̀bá nínú ìbò abẹ́lé APC l‘Ọ́sun Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Àwọn èèyàn àti awakọ̀ ké igbe ìrora bí àwọn ọkọ̀ ńlá ṣe dí ọ̀nà mọ́rosẹ̀ Apapa-Oshodi pa Òwúrọ̀ ọjọ́ ìdìbò náà ni àwọn olùdíje mẹ́ta, Moshood Adeoti, Peter Babalọla àti Senatọ Babajide Ọmọworarẹ sọ pé àwọn kò dìje mọ́ ninu awọn eniyàn mẹtadinlogun ló n dije láti gbé àsìá ẹgbẹ APC sókè bíi olùdíje gómìnà ní ìpínlẹ̀ Osun.
ọ̀rẹ́ ló ṣe’ni l’ọ́ṣẹ́ tó ku s’ára bí iṣu
Àwọn agbábọ́ọ̀lù Naijiria to ti kú sórí pápá Samuel Okwaraji: Samuel Okwaraji kú lórí pápá lásìkò to n gbá bọọlu láti fun pegede ife àgbáye pẹlu Angola.
aràn mùjẹ ̀ mùjẹ ̀ pẹlẹbẹ inú ẹran ẹlẹ ́ dẹ ̀ wọ ́ pọ ̀ púpọ ̀ ní eṣia , gúsù sàhárà afirika , àti amẹrika latini .
A kò tíì rí àrídájú tó tó sùgbọ́n a ó máa mú ìròyìn bó ṣe ń lọ níbi ìṣẹ̀lẹ̀ yìí wá fún un yín.
Oríṣun àwòrán, @hadd1nzarewa O ni ohun ti awọn eeyan to n gbe iwe idanwo naa kiri fẹ se ni lati gba owo lọwọ awọn obi, ti ọmọ wọn wa lara awọn akẹkọọ to fẹ ṣe idanwo naa.
Jonatani ni ó bí Meribibaali; Meribibaali sì bí Mika.
 Ọkọ mi kò le f'ipá bá ẹnikẹ́ni lò pọ̀ láíláí - Modele Fatoyinbo Àdúrà kò le pa ìfipábánilòpọ̀ rẹ́, àtàwọn àkọlé mìí tó jẹyọ lórí ọrọ Fatoyinbo Lẹ́tà Obasanjo: Àjálù ń bọ̀ bíi ti Rwanda, tí Buhari kò bá ṣàtúnṣe ètò ààbò Yinka Ayefele di bàbá ìbẹta O ni ""Atẹjade yii wa lati jẹ ki gbogbo awọn olori ẹsin Kristiẹni, araalu, ati awọn to fẹran otitọ, mọ pe ẹgbẹ CAN tabi Aarẹ CAN ko fi ọwọ si tabi mọ nkankan nipa abẹwo atilẹyin naa."
Ogunlọ́gọ̀ eniyan wọ́ lọ sí ọ̀dọ̀ rẹ̀ nígbà tí wọ́n gbọ́ ohun tí ó ń ṣe.
O ti mu ki isọkan wa laarin gbogbo eniyan''.
Bẹ́ẹ̀ ni Ọlọrun ṣe mú ohun tí ó ti sọ tẹ́lẹ̀ láti ẹnu gbogbo àwọn wolii rẹ̀ ṣẹ, pé Mesaya òun níláti jìyà.
Aare tun ni:’’Mo ni ipinnu fun awon omo orile ede Naijiria.
Gbogbo wa dàbí aláìmọ́,gbogbo iṣẹ́ òdodo wa dàbí àkísà ẹlẹ́gbin.
E jẹ ki a fi eleyi we Italy ti o ni eeyan miliọnu ọgọta ti eeyan ẹgbẹrun mejilelogun si ti ku nibẹ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Salawa Abẹni: ₦50 péré làwọn èèyàn fí ń pè mí fún ayẹyẹ nígbà tí mó bẹ̀rẹ̀ orin kíkọ̀ 2 Ògún 2019 Oríṣun àwòrán, Facebook/Abeni Salawa Gbajugbaja olorin Waka, Alhaja Salawa Abẹni sọ pe, oun ko lọwọ si awuyewuye ta lo da Fuji silẹ tawọn olorin kan n gba bi ẹni n gba igba ọti.
Nibayii to ti di atunbi Kristẹni, ko le rinrinajo lai ko ikọ agbabọọlu tara rẹ, Hallaluya FC ati ẹgbẹ akọrin rẹ dani fun anfani gbigbabọọlu pẹlu awọn agbẹbọọlu igberiko ati ṣiṣe ipolongo ihinrere pẹlu eto adura gẹgẹ bi ileeṣẹ iroyin AFP ṣe sọ ọ.
Premier League: Everton dín'yà fún Chelsea pẹ̀lú àmì ayò 2-0
Mo rí i pé ó ti ba ara rẹ̀ jẹ́, ọ̀nà kan náà ni àwọn mejeeji jọ ń tọ̀.
Ó mọ iṣẹ́ àgbẹ̀dẹ wúrà, ati ti fadaka, ti bàbà, ati ti irin; ó sì mọ òkúta, ati igi í gbẹ́.
 ohun tí èyí èyí ń fi yé wa nip é nibi tí ìtàn akọkọ parí si ni ìtàn kejì ti bẹrẹ .
 O wa tun pase fun adari igbimo naa Asofin Rafiu Ibrahim, lati jabo fun ile igbimo asofin leyin ose meji.
Nítorí òfin níí mú kí eniyan mọ ẹ̀ṣẹ̀ lẹ́ṣẹ̀.
"Kii ṣe nkan ti mo fẹ gbe gbogbo aye mi le lori""."
Lasiko yii, awọn awakọ yoo maa gba ọna kan naa lati aago mejila oru si aago kan ọsan.
Idahun ni: Alagabagebe to tumó si eni to maa n se kebekebe, ami ohun rẹ ni: re mi do do re do Èèmọ̀!
Ìka mi ò ní dá, kò ní ṣẹ́, kò ní gé.
Akanse eto naa lori Facebook BBC Yoruba ree: Arabinrin naa gbera lati ilu Abuja wa si ilu Eko ni ibi ti wọn ti fi aworan awọn ọmọ Naijiria ti wọn n ṣiṣẹ pẹlu oyinbo lọhun han, eyi to mu ki ori rẹ wu lati tẹle wọn lọ silẹ Yuroopu.
Gomina tuntun wa fi asiko ohun tenumo pe, isejoba oun
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Revolution Now: Lẹ́yìn ọdún kan, DSS tún ti mú Olawale Bakare tó jẹ́jọ́ pẹ́lúu Sowore l'Osogbo 5 Ògún 2020 Oríṣun àwòrán, citymirrornews.
' Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Ohùn gooro ló gbé mi dé ọ̀dọ̀ ààrẹ̀ Bush, Obama, Obasanjo, Goodluck, Buhari' Koda wọn le lo lati fi dina mọ ẹrọ alatagba tawọn ti eleyi ṣi le da wahala silẹ.
” ’ Kò burú, ẹ mú ẹ̀jẹ́ yín ṣẹ!
Bí mo bá ní, “N óo sọ̀rọ̀ báyìí,”n óo kó àwọn ọmọ rẹ ṣìnà.
Small Doctor fi kun pé ìyá òun, ‘ìyá Tíṣà’ kò nífẹ́ sí irú ìwà àìdáa yìí,tí òun kìí kọrin nípa rẹ̀ nítorí bó ṣe ń ba ọ̀pọ̀ ọ̀dọ́ láyé jẹ́.
Àjẹsára náà di èyí tó wà fún lílò ní ilẹ ̀ amẹ ́ ríkà fún ìgbà àkọ ́ kọ ́ ní ọdún 2006 .
Ṣugbọn o sọ pe ọja t'ọmọ ba ti wọ, o ti dokuta.
Orin Ìwọ́de Ojúnà gbọdọ̀ ní àwọn èròjà tí ó ṣe kókó nínú kí ó tó lè kópa:
Fidio yii lo ṣafihan bi Odunlade ṣe ko mọlẹ pẹlu Mike Edwards to wa lara awọn marun un to pegede julọ ninu eto BBNaija 2019 to ṣẹṣẹ pari Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, David Adiatu oníṣẹ́ ọnà pẹ̀lú ìṣó àti òwú Femi Adebayo Salami: Femi Adebayo Salami to jẹ ọmọ Ọga Bello fi aworan kan sori oju opo ayelujara rẹ eleyi to fi ṣalaye pe ohun kan to rọ oun lọrun ju lati maa ṣe naa ni ere ori itage.
Akọroyin BBC News Yoruba ti wa nibẹ ni pese, lati ma a fi to yin leti bi o se n lọ.
Gbogbo awọn ile ẹkọ ni Christchurch naa ni wọn ti ti pa.
Pittsburg ni ipinlẹ Pennsylvania niṣẹlẹ yii ti wáyé ni orilẹ-ede Amẹrika.
Oníyèméjì ń ronú ikú sí ara rẹ̀ lówùúrọ̀ òun sì kí lọ́sàn-án bẹ́ẹ̀ ni òun ìbá gbé ọjọ́ mẹ́ta ní inú ayé sí i, ọkàn ẹni ni àlùfáà ẹni.
Zainab Aliyu: A kò mọ́ pé wọ́n kẹ́ òògùn olóró sí àbúrò mi l'ọ́rùn- Hajara
 díè lára àwon èdè tó wà lábé ìpìn yìí ni banda gbanja àti ngbika .
Ẹsun naa gba gbogbo ori ayelujara kan lati aarọ ọjọ Ẹti, ṣugbọn Fatoyinbo ni oun ko fipa ba obinrin kankan lo pọ ri.
Loju opo Instagram rẹ, osere tiata lobinrin, Lizzy Anjọrin, ẹni to han loju rẹ pe inu rẹ ko dun si isẹlẹ naa, lo n kesi awọn ọmọ Naijiria pe ki wọn mase gbẹsan ikọlu awọn ara South Africa naa nitori awa ara wa ni ọrọ yii yoo kan julọ.
“Awon  ti won fi ara pa  ti wa nile iwosan fun  itoju, a si ti  ko awon oku naa kuro nile”.
Kò sí bọ́mọdé ṣe lè tètè jí kúrò nílé, oko ló má a bá kùkùté.
Awọn akẹẹgbẹ rẹ ni Jimoh Alihu, Charles Olumo, ati Afolabi Afolayan (Jagua) to ti papoda.
O fẹ́ olùṣọ́àgùntàn Ituah Ighodalo olórí ìjọ Tirinity House ní ọjọ́ kẹ̀rìndinlógun oṣù kejì ọdún 2007.
Iroyin sọ pe o ṣeeṣe ki awọn to n pọn ọti gbarọgudu yii ti ṣe ọpọ rẹ kalẹ ti wọn si ti n ta fawọn olounjẹ lẹgbẹ titi ati awọn eeyan lawọn igberiko.
N óo kó wọn lọ sí ilẹ̀ àwọn ará Kenaani, ati ti àwọn ará Hiti, ati ti àwọn ará Amori, ati ti àwọn ará Perisi ati ti àwọn ará Hifi, ati ti àwọn ará Jebusi, ilẹ̀ tí ó kún fún wàrà ati oyin.
"Coronavirus Cases in Africa: Adarí àwọn agbóòkú tó ń fi ijọ́ dárà ní ilẹ̀ Ghana sọ bí àwọn ṣe da ìlúmọ̀ọ́ká Arsenal rántí ""Invincibles,"" ó pé ọdún mẹ́rìndínlógún tí Arsenal gba ife Premier League Seyi Makinde, fún mi ní ₦156m lórí iṣẹ́ ọpọlọ mi to lò láì tọ́ - Agbaṣẹ́ṣe Orílẹ̀èdé Naijiria ti gba Àgbo Coronavirus ti ilẹ̀ Madagascar ṣe tọwọ́tẹsẹ̀!"
" Osinbajo daba pe eto lati se atunto si isẹwọn yoo gba akoko pupọ, ṣugbọn ko tilẹ si eto lati mu ipo naa dara rara.
Russia foribale fun Uruguay ninu ifesewonse keyin ipele kinni-in ninu idije boolu agbaye to n lo lowo lorile-ede Russia.
Yóo pa eyín keke, yóo pòórá,ìfẹ́ rẹ̀ yóo sì di asán.
 Iko obinrin otooto mejo yoo maa kopa ninu idije naa fun saa yii lati fi bere eka tawon obinirin ohun.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, EndSars, EndSwat Protest: Òbí agbábọ̀ọ̀lù Gbenga Tiamiyu Kaka àtàwọn míì tí ọlapàá pa sọ̀r SERAP ati awọn ti wọn dijọ pe ẹjọ yii ni awọn fẹ ki ile ẹjọ f'ọwọ rọ afikun owo epo ati ina ọba sẹyin."
OLUWA tún bá mi sọ̀rọ̀ ó ní, 
Ṣugbọn n kò lo anfaani yìí rí.
Mercy Aigbe ninu esi tirẹ ni jẹjẹ oun loun n mura ọjọ ibi to si fẹ ya ọpọlọpọ fọto gẹgẹ bi wọn ṣe n ṣe lode oni ṣaaju ọjọ naa pẹlu oriṣiriṣi aṣọ to rẹwa ti aṣara loge oun si gbe aṣọ ti oun sanwo fun ranṣẹ si oun.
Ṣugbọn ṣa, Akosile kede pe awọn ileewe ijọba yoo ṣi wa ni titi pa.
Aṣofin Muyiwa Jimoh, to jẹ Igbakeji Olori Ọmọ ẹgbẹ oṣelu to pọ ju lọ ninu Ile naa sọ pe iwa naa ko dara rara.
Nígbà tí obinrin náà rí Samuẹli, ó kígbe lóhùn rara pé, “Kí ló dé tí o fi tàn mí?
Minisita fun eto Iwosan, Osagie Ehanire lo fi eyi lede lasiko to n ba awọn eniyan sọrọ lori awọn ohun ti ijọba n ṣe lati koju arun Coronavirus ni Niajiria.
Ninu oro re, aare Macron menu ba bi ijoba re yoo se ran orile-ede Naijiria lowo lati koju iko omo ogun olote Islam ti o n koju awon ipinle kookan ti o kogun sile oorun orile-ede Naijiria, ki o to teko leti lo sile igbafe ohun nipinle Eko.
Ọ̀rọ̀ lè má dùn lẹ́nu mi, ṣugbọn mo ní ìmọ̀, ní ọ̀nà gbogbo a ti mú kí èyí hàn si yín ninu ohun gbogbo.
Awon eto ti won yoo ti maa kopaAwon omooba yii yoo maa kopa ninu awon eto olokan-o-jokan niluu Abuja ati ni ilu Eko.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Poly Ibadan: Ọjọ́ iwájú la rò táa fí dáná sún fóònù àwọn akẹ́kọ̀ọ́ Sanwoolu ṣe é dáa fún wa níbodè Lekki, Ikoyi - Awakọ̀ ní Lekki Ọ̀nà tó fi le è mọ gbájúẹ̀ babaláwo - Ẹlẹ́buìbọn Kí ni Bode Thomas ní ṣe pẹ̀lú ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ Nàìjíríà àti South Afrika?
Orilẹede Naijiria naa si ni ori ikọlu wọnyi ta julọ, ti ikọlu Boko Haram to buru julọ si jẹ tawọn agbebọn.
Tesiwaju si, odu ni aare Macron ki se aimo foloko, O ti fi igba kan sise gege bi asoju orile Faranse lorile ede Naijiria ti o wa nilu Eko lọdun 2004, odun meje ti Fela faye sile.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ere Idaraya: Aáwọ̀ ààrin Wenger àti Mourinho ti parí 20 Èrèlè 2019 Oríṣun àwòrán, Shaun Botterill Akọnimọọgba ẹgbẹ agbabọlu Arsenal nigba kan ri, Arsene Wenger gbami ẹyẹ Laureus ni ọjọ Aje, ṣugbọn ohun to yani lẹnu ju ni ẹni to gbori yin fun, tii se Jose Mourinho Wenger, ẹni ọdun mọkandinlaadorin gba ami ẹyẹ naa nitori ipa to ko lori bọọlu afẹsẹgba ni Ilẹ Gẹẹsi, ni paapaa, fun ọpọlọpọ ọdun to lo gẹgẹ bii olootu ẹgbẹ agbabọọlu Arsenal.
Lẹyin eyi ni o gba oye ọjọgbọn, ti o si jẹ olukọ agba, ni ẹka imọ ede Yoruba, lati ọdun 1983.
Ikú Fẹ́lẹ́: Àwọn olùbánikẹ́dùn ní Fẹ́lẹ́ kò dúró jẹ isẹ́ ọwọ́ rẹ̀.
AFCON 2019: Cameroun yọ Seedorf nípò gẹ́gẹ́ bíi olùkọ́ni Indomitable Lions
Asaraya bí Seraaya; Seraaya sì bí Jehosadaki.
Coronavirus Update: Ebi lé pa ènìyàn 12,000 lójoojúmọ́ lẹ́yìn Covid-19- Oxfam International
Bakan naa lo sọrọ lori idi ti APC ati ijọba Buhari ko ṣe yan oun sipo minista ni saa aarẹ Buhari keji yii.
 Ofin naa lo da ruke rudo silẹ ti awọn ara ilu ti n fi ẹdun ọkan wọn han.
A mọ̀ pé Kristi tí a ti jí dìde kúrò ninu òkú, kò tún ní kú mọ́; ikú kò sì lè jọ̀gá lórí rẹ̀ mọ́.
Trump sọrọ yii lasiko to pada si eto ijabọ lori Coronavirus to maa n ṣe, o si paṣẹ pe ki gbogbo eniyan ilẹ Amẹrika maa lo ibomu O ni Ibomu ni iṣẹ to n ṣe, bakan naa ni eyi tun tumọ si pe wọn wa ni isọkan.
 bákan náà ni ó tún ṣe amúgbá-lẹ ́ gbẹ ́ lórí ètò olósẹ ̀ -ọ ̀ sẹ ̀ pẹ ̀ lú diana williams tí ó ma ń wáyé ní dédé agogo márun ìrọ ̀ lẹ ́ ( eyewitness news ) àti ìròyìn alágo mọ ́ kànlá ( 11.
Nítòótọ́, Ọlọrun kì í ṣe ibi,bẹ́ẹ̀ ni Olodumare kì í dájọ́ èké.
Ń ko dúró ṣe ìdánwò WAEC nílé ẹ̀kọ́ gírámà, kí n tó bẹ̀rẹ̀ tíátà
Ọpọ awọn obinrin to si fi ọrọ wa lẹnuwo sọ pe awọn ko ni ilera pipe lati igba ti wọn ti ṣe iṣẹ abẹ naa.
O wa parọwa si awọn akẹkọ lati ma ṣe ba ọkan jẹ latari ijakulẹ ninu idanwo.
Coronavirus in Lagos: Ayẹwò kò dáwọ́ dúro botílẹ̀ jẹ́ pé èròjà ayẹwò (Reagents) kò si mọ́- Kọmísọ́nà ìròyìn Oríṣun àwòrán, others Àkọlé àwòrán, Ayẹwò kò dáwọ́ dúro botílẹ̀ jẹ́ pé èròjà ayẹwò (Reagents) kò si mọ́ Ìjọba ìpínlẹ̀ Eko ni ẹ̀ẹ́dẹ́gbẹ̀ta ènìyàn ni àwọn n ṣe àyẹ̀wò coronavirus fún lójoojúmọ lójúnà àti mú àdínkù bá ìtànkálẹ̀ ààrùn coronavirus.
orilẹede yii nigba kan laye ijọba ologun, Ajagunfẹyinti Abdulsalam Abubakar naa
Ajọ to n se ilana awọn oniroyin, (Media Council of Kenya) sapejuwe isele naa gẹgẹ bi iwa idukoko tikolafiwe, eleyi ti wọn so pe ko yẹ ko waye ni ijọba tiwantiwa.
Dájúdájú, ọjọ́ ńlá ni ọjọ́ Jesireeli yóo jẹ́.
 Àwọn àbùdá mìíràn máa hàn kedere tí a bá gbé èdè tó yàtọ ̀ sí èyí tí a ti mọ ̀ tẹ ́ lẹ ̀ ỵẹ ̀ wò .
Awọn to wa ni idi ifẹhọnu han naa wa kesi ijọba orilẹ-ede Naijiria ko tọwọ awọn ọlọpaa Naijiria bọsọ, nitori awọn ṣetan lati taatan pẹlu wọn.
Ẹ kú ayẹyẹ ọjọ́ ìbí ooo Ọ̀jọ̀gbón Akinwándé Oluwo̩lé Babátúndé S̩óyinká
Grace Osadebe sọ pe ọna ọtọ ti oun fi n dín ata bọọli oun ni wọn fi sọ oun ni inagijẹ Maleesky ni ilu Port Harcourt to jẹ olu ilu ipinlẹ Rivers to ti n mu taje ṣe.
Láti ìgbà yìí lọgbogbo ìran ni yóo máa pè mí ní olóríire.
Eyi waye nínú ìjàmba ọkọ to dánikan ṣẹlẹ̀ ni àgbègbè pipeline, Ogere ni marosẹ Lagos-Ibadan Express ní ìpínlẹ̀ Ogun.
láti ṣe àyájọ́ ọjọ́ ọmọ wẹ́wẹ́.
" Risikat to jẹ ọmọ agbo ile Ayegbami niluu Ilorin.
Gomina Osun ṣe ìléri ọkọ ogun 20 fún ilè Yorùbá!
Èmi náà kíi, mo sọ oríkì síi, lẹ́yìn náà ó mú mi lọ sí ibi ti o ń gbé ó sì wá oúnjẹ fún mi.
Wọ́n bá pàṣẹ pé kí wọ́n kéde jákèjádò gbogbo ilẹ̀ Israẹli láti Beeriṣeba títí dé Dani, pé kí àwọn eniyan wá sí Jerusalẹmu láti pa Àjọ Ìrékọjá mọ́ fún OLUWA Ọlọrun Israẹli; nítorí pé wọn kò tíì ṣe Àjọ Ìrékọjá náà pẹlu ọ̀pọ̀ eniyan gẹ́gẹ́ bí ìlànà.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Sibahle Zwanen fi ìmọ̀ ìṣìro da orí ayélujára rú Arabinrin He ni ṣaa dede ni atẹgun kan fẹ wa nibi iboji ti oun ti n tu koriko yii ni eyi ti oun fi kọkọ ro pe idọti lo ko si oun loju.
Lara ọhun to ni ijọba yoo fun wn ni kaadi ipe ti wọn fi iye owo ẹgbẹrun lọna ogoji sinu rẹ.
0 6053 Orilẹede Mali 184 1.
Ẹ bẹ OLUWA fún mi nítorí pé yìnyín ati ààrá yìí tó gẹ́ẹ́, n óo jẹ́ kí ẹ lọ, n kò ní da yín dúró mọ́.
Abilekọ Madikizela-Mandela sọ ọrọ apilẹkọ kan to da wahala silẹ, ni bi to ti fi ontẹ lu ẹgba ọrun"", fifi taya kọ awọn ti wọn furasi pe wọn lọwọ ninu iṣejọba asiko naa lọrun, ti wọn si tun n dana sun wọn."
Ẹ ka ẹ̀kúnrẹ́rẹ́ níbí June 12: Ògùn, Ọ̀yọ́ kéde ìsinmi lẹ́nu iṣẹ́ Oríṣun àwòrán, http://ogunstate.
Wọn le sọ nkan to ba wu wọn.
bí Noa, Daniẹli ati Jobu bá tilẹ̀ wà níbẹ̀, èmi OLUWA Ọlọrun fi ara mi búra pé, wọn kò ní lè gba ọmọkunrin tabi ọmọbinrin wọn là.
O tesiwaju pe, igbakeji aare ojogbon Yemi Osinbajo so  fun won nibi ipade to waye niluu Akure to je olu-ilu ipinle Ondo ni osu kesan an pe, ki won tesiwaju lati maa se ipade won loorekoore.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù May Workers day: Ìkáyàsókè bá àwọn òṣìṣẹ́ nítorí àìmọ ọjọ́ ọ̀la lẹ́yìn Coronavirus 24 Ìgbé 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 1 Èbibi 2020 Ọjọ kinni oṣu karun ni ayajọ awọn oṣiṣẹ lorilẹede Naijiria ati lagbaye amọṣa yatọ si iṣoro tawọn oṣiṣẹ n fara gba ni atẹyinwa bii ipenija owo oṣu sisan lasiko, aisi igbega lẹnu iṣẹ lasiko ati oniruuru awọn iwa kotọ miran ti wọn n fi oju wina rẹ lẹnu iṣẹ, lọdun yii, ipenija ajakalẹ arun Coronavirus kun ipenija wọnyi koda o ti mu ẹmi ọpọ ninu wọn lọ.
Eni ta n wi yi sọ pe ninu ibẹrubojo ni awọn eeyan ilu Kọmisana naa ti se Iye wa ti wọn si n rawọ ẹbẹ si Gomina la ti sa gbogbo agbara lati ri pe wọn doola ẹmi ọmọ awọn.
Lasiko to n ba awọn akọroyin sọrọ ni Ile Ijọba Amẹrika, White House ni Aarẹ Trump fesi lori ọrọ yii ni idahun si akọroyin to ni ki lo ri si ọrọ naa.
Olori ẹgbẹ́ naa, Abu-Bakr Al-Baghdadi lo dari ẹgbẹ naa titi to fi ku lọdun 2019, lasiko ti ilẹ America ṣe ikọlu si ibudo wọn ni Ariwa Syria.
8 million) ti awọn to din diẹ lẹgbẹrun lọna ọtalenigba (253,000) si ti gba ibẹ ku.
Awọn ikọ rẹ ti sọ pe, igbagbọ awọn ni pe ọgbọn lati gbẹmi Adams Oshiomhole ni bi o tilẹ jẹ pe awọn ọlọpaa ko tii jade pẹlu iwadii wọn lori iṣẹlẹ naa.
Ijọba ilẹ Gẹẹsi ni ijiya ileeṣẹ tẹlifiṣọn Loveworld ni pe yoo maa sọ ninu igbohunsafẹfẹ rẹ pe oun kede ọrọ ti ko ni otitọ ninu nipa arun Cpvid-19.
Awọn iroyin kan sọ pe ija naa waye nitori pe awọn ọmọ ẹgbẹ million boys mú ọmọ ẹgbẹ alatako, 'indomie' kan, to ji ẹ̀rọ ibanisọrọ, ti wọn si 'ba a wi'.
Nítorí náà, wọn óo ṣẹ̀sín ní ilẹ̀ Ijipti.
Oríṣun àwòrán, Twitter/APC Àkọlé àwòrán, Idibo aarẹ ọdun 2023 Ambode ati Tinubu Ohun itiju lo jẹ fun Gomina ipinlẹ Eko, Akinwumi Ambode lasiko idibo sipo gomina ni ipinlẹ Eko lọdun 2019 nibi ipolongo kan.
Àwọn ni àwọn ọmọ Basemati, aya Esau.
Nípasẹ̀ rẹ̀ ni a ti dá ohun gbogbo, ninu gbogbo ohun tí a dá, kò sí ohun kan tí a dá lẹ́yìn rẹ̀.
Lẹyin ti oorun ba wọ, lawọn alarafa yii yoo morile Muzdalifah, to jẹ idaji irin laarin oke Arafa si ilu Mina, ti wọn yoo si duro di oru.
" Okina ba awọn ọmọde kan to maa n patẹ ere n'ikorita kan to wa ni itosi ile rẹ, o si maa n lo ọpọlọpọ wakati lati ba wọn takurọsọ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Sadiya Umar Farouq: Èmi kò jí nínú owó oúnjẹ àwọn akẹ́kọ̀ọ́, irọ́ ni Bolaji Owasanoye, alága ICPC ń pa 29 Owewe 2020 Sadiya Umar Farouq ti ní pé ọwọ òun mọ lórí N2.
Awon agbaboolu ti o ti bale sipago ni kikun:                                                      Francis Uzoho,
Alfa Jamiu rèé tó lu Kọ̀ráà ní jìbìtì ₦30m àmọ́ tó fi owó ra ìfun Erin àti ẹ̀dọ̀ Ìnàkí Oríṣun àwòrán, Facebook/EFCC Ọwọ awọn agbofinro EFCC ti tẹ alfa kan torukọ rẹ n jẹ Jamiu Isiaka, to sọ ara rẹ di ọga ti n gba aṣọ alaṣọ bora nipa pipe ara rẹ ni alukoro fun aarẹ Buhari, Fẹmi Adeṣina.
Gbogbo àkọ́bí ọkunrin, gẹ́gẹ́ bí orúkọ wọn, lati ọmọ oṣù kan lọ sókè ní iye wọn, lápapọ̀, wọn jẹ́ ẹgbaa mọkanla ó lé igba ati mẹtalelaadọrin (22,273).
Emery so ninu oro re,“Stephan mu iriri ti o po wa sinu iko yii.
Bakan naa lo wa kesi awọn eniyan ti wọn fẹ gba owo wọn pada lati yọju si wọn.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ambode pe fun ijiya ẹwọn ọdun mẹẹdọgbọn fun afipabanilopọ 12 Ẹrẹ̀nà 2018 Oríṣun àwòrán, Lagos state government Àkọlé àwòrán, 'Iwa ifipabanilopọ kii se ohun to yẹ ki a fun ni ijiya yẹpẹrẹ' Gomina ipinlẹ Eko, Akinwunmi Ambode ti sọ wi pe ko si ohun to buru ninu ijiya ẹwọn ọdun mẹẹdọgbọn fun ẹnikẹni to ba jẹbi ẹsun ifipabanilo tabi eyikeyi iwa idunmọhuru mọ obinrin ninu ile.
Seyi Makinde: Gómìnà ìpínlẹ̀ Oyo kéde dúkìá tó tó #48bn
Bakan naa ni Dapọ jẹ odu, ti kii ṣe aimọ fun oloko ni ẹka katakara awọn eroja epo rọbi ati afẹfẹ idana gaasi, to si ni ileeṣẹ aladani tiẹ fun eroja epo rọbi.
Iná tí ó wá láti ọ̀run ni ó pa àwọn ọ̀gágun meji ti iṣaaju ati àwọn ọmọ ogun wọn, nítorí náà mo bẹ̀ ọ́, dá ẹ̀mí mi sí.
Niwọn igba to jẹ pe ọjọ ti pẹ, Iyalode Ẹfunsetan ti wa, to si ti pada sọdọ Eledua, oniruuru itan ni a gbọ nipa rẹ.
Tani Taiwo Ogunjobi, akọ̀wé àjọ NFF tẹ́lẹ̀ tó d'olóògbé?
Ohun ti yoo mu anfani pupọ wa ni bi Aarẹ Naijiria Muhamadu Buhari ti ṣe fi ọwọ si adehun okoowo kan naa nibi ipade apero ajọ iṣọkan ilẹ Afrika to waye ni Niger lọjọ Aiku.
Wo àwọn ohun márùn ún tó yẹ kí o mọ̀ nípa Sanusi Ẹ́ gbaradì, to bá lo jẹnẹrátọ̀ àbí tà á, ò ń fi ẹ̀wọ̀n ọdún mẹ́wàá ṣeré - Sẹ́nétọ̀ ń dábàá Agbófinró, tó bá wa ọkada àbí kẹkẹ maruwa l'Eko, o rugi oyin - Sanwo-Olu Ọgbẹni Ikolo ni ileeṣẹ ọlọpaa ti gbe ọmọ ọwọ ati ọmọ ọdun meji ti iyawo naa n gbe lọwọ to fi ku fun mama iyawo naa.
Bilionu mewaa ni owo ti aare fi sile lati fi tun awon ibi to baje yii se, a  si ti setan lati bere ise bayii.
Ki a to diju ki ato la,Burnley ti fi ikeji si.
Jakọbu alára bá bọ́ siwaju gbogbo wọn, ó wólẹ̀ nígbà meje títí tí ó fi súnmọ́ Esau, arakunrin rẹ̀.
- Ọ̀gá àgbà ọlọ́páà Wo bí ìwọ náà ṣe lè rí gbà nínú owó ìrànwọ́ tí ìjọba Nàìjíríà fẹ́ pín O ṣalaye pe fasiti ipinlẹ Ekiti to wa ni Ifaki-Ekiti ni igbaradi naa yoo ti waye fun ọsẹ mẹta gbako.
 ) ( the books are at my disposal .
 Èyí pẹ ̀ lú ọ ̀ pọ ̀ ti gúúsù Áfíríkà , asia , àti latin amẹ ́ ríkà .
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Akọ́nimọ̀ọ́gbá ikọ̀ agbábọ́ọ̀lù Arsenal, Mikel Arteta náà ti fara káásá àrùn Coronavirus 13 Ẹrẹ̀nà 2020 Oríṣun àwòrán, @Sporf Awọn alakoso idije Premier League ti wọgile ifẹsẹwọnsẹ to yẹ ko waye laarin ikọ naa ati Brighton lọjọ Abamẹta lẹyin ti akọnimọgba ikọ Arsenal, Mikel Arteta lugbadi arun Coronavirus, Iṣẹlẹ yi ti mu ki ikọ ọhun gbe kọkọrọ ṣẹnu ilẹkun papa iṣere ti wọn ti n ṣe igbaradi, lẹyin naa ni wọn ya awọn eeyan to ṣalabapade akọnimọgba naa sọtọ fun ayẹwo ati itọju.
Atunto ohun ni o kunfun: awon igbakeji adari oko ofurufu mẹ́rìndínlógún(16 Air Vice Marshals),  Air Commodores mẹ́rìndínlógún, ogagun mẹ́sán án (9 Group Captains),  Wing Commander méje ati Squadron Leader mẹ́rin .
Olórí orílẹ̀-èdè Azerbaijan tàkùrọ̀sọ àkọ́kọ́ ní orí amóhùnmáwòrán lẹ́yìn ọdún 15 ní orí àlééfà.
Baba Elebuubọn ni o yẹ ki wọn ṣe etutu lati dena ajalu miiran papaa julọ awọn alabaṣiṣẹ pọ awọn to ku.
Ibukun àwọn baba rẹ ju ti àwọn òkè ayérayé lọ,kí ibukun àwọn òkè ayérayé wá sórí Josẹfu,ẹni tí wọ́n yà ní ipá lọ́dọ̀ àwọn arakunrin rẹ̀.
Fawọn ọkunrin, o tumọ sí pe wọn o gbe ọdun mọkanlelọgbọn lai larun kankan.
Lẹ́yìn náà, OLUWA sọ fún Elija pé, 
Òfìfo ṣọ́ọ̀ṣì pa aṣọ dà fún àwọn Páṣítọ̀ Nàìjíríà Dánáfojúrà nìyí, abàmì eégún tí ń gbé inú iná ṣọlá Ìrìnàjò Toyin Abraham, láti orí gbèsè jíjẹ, ó di onílé, onimọto àti aya lọ́ọ̀dẹ̀ ọkọ Àwọn Alákòso gárèjì ló kó ìbọn àti àdá tọ ọlọ́kadà wá ní Soka-Alága ẹgbẹ́ ọlọ́kadà Ọyọ Tikútìyè lọ̀rọ̀ Coronavirus, àdúrà lọ̀rọ̀ gbà lásìkò yìí-Ààrẹ Buhari Coronavirus pandemic: Ààrẹ Buhari ní àdúrà làsìkò yí gbà pẹ̀lú ìfaradà láti ṣẹ́gun Coronavirus, àrùn tikútìyè tó ń da àgbáyé láàmú Aarẹ Buhari ki awọn ọmọ Nàijiria ku afarada bi gbogbo nnkan ṣe n lọ lásìkò Coronavirus yìí Oríṣun àwòrán, Bashir Ahmad Àkọlé àwòrán, Ààrẹ Buhari ní àdúrà làsìkò yí gbà pẹ̀lú ìfaradà láti ṣẹ́gun Coronavirus, àrùn tikútìyè tó ń da àgbáyé láàmú Aarẹ Muhammadu Buhari ti ke sawọn ọmọ orilẹede Naijiria pe ki wọn rọju mu gbogbo inira tabi irora ti igbesẹ gbogbo ti ijọba n gbe lati dẹkun itankalẹ arun Coronavirus ba n mu ba wọn.
Ogbeni Okechukwu soro ohun di mimo lasiko ayeye igba keji ifigagbaga ere itage ni ede faranse laarin awon ile-eko sekondiri lorile-ede Naijiria(2nd Edition of the Voice of Nigeria Annual National Secondary Schools French Drama Competition), ti o waye niluu Abuja.
Nítorí náà Ọmọ Mímọ́ Ọlọrun ni a óo máa pe ọmọ tí ìwọ óo bí.
Dájúdájú, ire ati àánú yóo máa tẹ̀lé mi kiri,ní gbogbo ọjọ́ ayé mi;èmi óo sì máa gbé inú ilé OLUWA laelae.
Iwadii naa si tun fi idi rẹ mulẹ pe iporuru ọkan, (Depression lo n ṣokunfa eyii.
Ǹjẹ́ o mọ ìgbà tí wọ́n bẹ̀rẹ̀,tí wọ́n sì bímọ?
Oríṣun àwòrán, AFP Àkọlé àwòrán, Ọkọ akero miiran niyi, sugbọn lakoko yi nigboro Nairobi, lorilẹede Kenya ni nibi ti Annastacia Wainaina, ẹni ọdun 34, ti jẹ ọkan lara awọn awakọ to n ṣiṣẹ ninu ọkọ akero matatu"" kan - to jẹ tijọba ati ti aladanikan ni."
Wọn ko kọkọ fẹ gba ki gbogbo wa wọle sugbọn lẹyin ọ rẹyin, eeyan mẹrin ninu wa lo ba wọn.
Afiyesi maa n wa fun awọn ti wọn n fẹjẹ silẹ̀ fún ìgbà akọkọ ki wọn le ni oye to yẹ.
Asofin Nnamani so oro naa di mimo fun akoroyin ile-igbimo asofin ohun lojoBo(Thursday), lasiko ti o to awon oludokoowo sile lati ile okeere lati pade igbakeji aare ojogbon Yemi Osinbajo.
Ṣugbọn bí a bá wà ninu ìpọ́njú, fún ìwúrí ati ìgbàlà yín ni.
Oríṣun àwòrán, @Mohammed Jagunma ati Gold Abdulrafiu Risikat, ìyá àwọn ọmọ olójú búlù tí bẹ̀rẹ̀ sí ní kọ́sẹ́ aṣojú lóge Iléeṣẹ́ Ọlọ́pàá dènà ọkùnrin tó fẹ́ pa ara rẹ̀ nítorí ọmọbìnrin Buhari Àwọn ọmọ Naijiria ṣèdárò gbajúgbajù agbábọ́ọ̀lù Super Eagles tó dolóògbè Ó ń bọ̀ lọ́nà!
" O gbọdọ̀ siyè méjì tí o kò bá tí ì gbọ́ nípa orísun nàá rí tàbí bóyá ó ní ìlépa kan.
Àwọn àìṣedede kan dá ìgbẹ́jọ́ Rukiki dúró, ó sì wáyé ní ọ̀sẹ̀ mélòó kan ṣáájú àríyànjiyàn ìdìbò abófinmu náà.
Awọn naa ni: Naijiria, Egypt, Morocco, Tunisa ati Senegal.
Iroyin so pe,Twinamasiko so si bi Aare Yoweri Museveni  se bu enu-ete lu ikolu awon obinrin lasiko ayeye ayajo awon obinrin lagbaye.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fọ́nrán ohùn, Imam Fuad tako Oluwo lori wiwe lawani Sugbọn ko jọ bi pe Oba Rasheed setan lati gbọ arọwa kankan paapa julọ lati ọdọ awọn Imamu.
Oríṣun àwòrán, @ayoadaniel Ta ni Michael Taiwo Akinkunmi: Ọjọ Kẹwa osu Karun ọdun 1936 ni Michael taiwo Akinkunmi fori sọlẹ silu Ibadan, ọmọ bibi Ibadan si nii se pẹlu Taiwo, gẹgẹ bi orukọ rẹ ti salaye, jẹ ibeji, oun si ni akọkọ ninu awọn ọmọ meji to wa saye lasiko kannaa, latinu iya kannaa, a ko si gbọ nipa ikeji rẹ, tii se Kẹhinde, titi di oni oloni, o si seese ko ma si laye mọ Taiwo gbe lọdọ baba rẹ titi to fi pe ọmọ ọdun ọdun mẹjọ, ko to di pe isẹ gbe baba rẹ lọ si ẹkun ariwa Naijiria, nibẹ si lo ti bẹrẹ ileẹkọ alakọbẹrẹ rẹ, lẹyin ti baba rẹ fẹyin ti si ni wọn pada wa silẹ Kaarọ Oojire nihin Lẹyin ti wọn pada de, Taiwo Akinkunmi fi orukọ silẹ nile ẹkọ alakọbẹrẹ onitẹbọmi to wa ni adugbo Idikan nilu Ibadan, to si pari lọdun 1949 Ọdun 1950 lo lọ sile ẹkọ girama Ibadan Grammar School, to si kẹkọ jade kuro nibẹ lọdun 1955, pẹlu iwe ẹri oniwe mẹwa.
Èyí wáyé lẹ́yìn ti ìjọba àpapọ̀ kò yí ẹnu pada lórí ọ̀rọ̀ rẹ̀ láti ti 3rd Mainland fún oṣù mẹ́fa lati ṣe àwọn àtúnṣe yẹ ti yóò sì bẹ̀rẹ̀ lónìí ọjọ́ kẹrìndinlọ́gbọ̀n ọṣù kèje, ọdún 2020.
Ọdun 2016 ni ijọba apapọ Naijiria bẹrẹ eto N-Power, ti eeyan to to ẹgbẹrun lọna ẹẹdẹgbẹta si ti jẹ anfaani rẹ.
Ṣugbọn lójú àwọn tí à ń gbà là, agbára Ọlọrun ni.
Ta ni ẹ óo fi díwọ̀n mi?
Ọ̀wọ́ Eṣú, gẹ́gẹ́ bí Àmì Ìkéde Ọjọ́ OLUWA.
Inu mi yoo dun ti iriri mi ba ti ṣeranwọ fun ẹnikan: Ọpọ lo ti n sọ ero wọn lati igba ti mo ti fi iriri mi sita eleyi to jẹ iwuri fun mi.
Nínú èyínìi pípa ni ọba nílátí pa á.
Umma Getso ti Young Progressive Party ati Khadijah Abdulahi Alliance for New Nigeria.
Ẹgbẹ́ òṣelú All Progressive Congress ti kí Dókítà Kayode Fayemi tó jẹ́ olùdíje ẹgbẹ́ òṣèlú wọn fún àṣeyọrí rẹ̀ gẹ́gẹ́ bíi Gómìnà ìpínlẹ̀ Ekiti.
Ó sì ké sí àwọn ọmọ ogun Saulu ati Abineri pé, “Abineri!
Nítorí náà, títì ni yóo máa wà.
àwọn aṣọ tí wọ́n ṣe iṣẹ́ ọnà sí fún ṣíṣe iṣẹ́ alufaa níbi mímọ́, ati àwọn ẹ̀wù mímọ́ fún Aaroni alufaa, ati ẹ̀wù iṣẹ́ àwọn ọmọ rẹ̀, tí wọn yóo máa fi ṣe iṣẹ́ alufaa.
Lizzy Anjorin: Bo se n polowo okoowo asọ ninu sọọbu rẹ lo tun n ta ilẹ ati ile Ọna lati ri ọwọ mu lọ sẹnu lẹyin isẹ ere sise lo mu ki ilumọọka osere tiata lobinrin, Lizzy Anjorin fi tun si sọọbu asọ.
-Ọlọ́pàá Iṣọla Oyenusi rèé, ẹnití ìfẹ́ obìnrin ṣun dé ìwà ìdigunjalè Àwọn ọmọ ẹgbẹ́ naa, lábẹ àbùrada ẹgbẹ gbogbo olúdije dupò ààrẹ to to ọgọ́ta niye àti àwọn alága ẹgbẹ́ wọ́n (Joint Forum of Sixty Presidential Candidates àn national Chairmen), sọ èyí di mímọ̀, lásiko ti wọ́n pé ìpàdé pẹ̀lú àwọn akọroyin.
O bọ ọ lọwọ o ni Kẹẹ pẹ ọlọla julọ""."
O le ni eeyan ẹgbẹ́run lọna ọgọ́fà to ti ba ikọlu naa lọ.
Oluwo ni àṣà Yoruba lo dára julọ, àmọ́ àwọn ohun tí kò bá dára, ó yẹ ká mú kuro ninu rẹ.
Madam Sajẹ pé eni ọgọ́ta ọdún Ni bayii ti oni ọjọ Kẹtadinlọgbọn osu Kẹta jẹ ọjọ ti ajọ isọkan agbaye ya sọtọ gẹgẹ bii ayajọ ọjọ tiata lagbaye, eyi lo mu ki BBC Yoruba maa beere pe se awọn osere tiata Yoruba n pọnmi silẹ de oungbẹ bi fun ọjọ alẹ wọn abi asiko ti ilera yoo beere?
Ṣàánú mi, Ọlọrun, ṣàánú mi,nítorí ìwọ ni ààbò mi;abẹ́ òjìji apá rẹ ni n óo fi ṣe ààbò mi,títí gbogbo àjálù wọnyi yóo fi kọjá.
Jude ni Ko si ohun to pamọ ninu pe Pan Ocean jẹ Amcon lowo ni eyi ti a mọ si gbese.
Lọdun 1978, Shehu Shagari jẹ ọkan lara awọn ọmọ ẹgbẹ to bẹrẹ ẹgbẹ oṣelu National People's Party.
“Ṣé o lè wá oúnjẹ fún kinniun,tabi kí o fi oúnjẹ tẹ́ àwọn ọ̀dọ́ kinniun lọ́rùn,
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, BBC Africa Eye: Akọroyin fẹ ìdí àwọn oníṣẹ́ ibi ọmọ ogun síta Èyí jẹyọ nínú fọ́ran kan tó jẹyọ lórí ayélujara nínú oṣù kéje ọdún 2018 níbi ti àwọn ọmọ ogun kan ti daṣọ bo awọn obinrin meji lójú pẹ̀lú ọmọbinrin lórí ìkúnlẹ̀ ti wọ́n sì pọ ọmọ sẹ́yìn.
OLUWA ni mo ké pè, nígbà tí mo wà ninu ìpọ́njú,ó sì dá mi lóhùn.
Koda, awọn ni wọn sọ ọmọ tuntun naa ni orukọ: Moraaanugba Oluwaseun Adeyinka bayii.
Ìyá Leah Sharibu ké gbàjarè sí ìjọba Buhari Ṣé ìgbéyàwó òṣèré tíátà leè pẹ́?
 Amaa ṣe atilẹyin to yẹ fun idagbasoke eto yii.
Gbogbo nǹkan yòókù tí Jehoiakimu ṣe ni a kọ sinu Ìwé Ìtàn Àwọn Ọba Juda.
Naijiria; ile ise Oloopa; ile ise aabo  ara eni ,laabo ilu ) Civil Defence ); awon
Gẹgẹ baa se gbọ latẹnu iya agba kan nilu Ogbomoso, Ọba Olayode, lasiko to gori itẹ jẹ ni ti aye n fẹ nitori inu gbogbo ọmọ Ogbomoso lo dun lasiko to jọba lọdun 1967.
Ile ẹjọ kan nilu Eko si ti dajọ iku fun oun naa.
Ọlọ́pàá ti bẹ̀rẹ̀ ìwádìí láti mọ òkodoro bí wọ́n ṣe gbé ọmọ tuntun náà sin láàyè ní India Ìdùnnú ni yóò jẹ fún wa ti wọn bá ṣe àwọn ọnà tí kò dára wọnyíì- Bosun Aguda Ajọ Amnesty International ní kò dín ní 119 ọmọ Nàìjíríà ti wọ́n ti gba ìdájọ́ ikú ní Malaysia Ajọ naa ni wọn ti awọn ibode ọhun lati oṣu kẹjọ, ọdun 2019 latari ati lee jẹ ki ọrọ aje orilẹ-ede yii dagba sii.
Asofin  Hunkuyi lasiko ijiroro lori aba kan pe, bi awon ohun elo amayederun ni awon ile-iwosan ijoba ko seyin, “ daku-daji ina mona-mona, ati aisi oni deedee, eyi ti o sokunfa ailera-ara ati alekun ewu kiko aarun ni awon ile-iwosan”.
Kábíyèsì fẹnu ara rẹ̀ tú àṣírí àwọn Fulani Daran daran tó ń ṣọṣẹ́ nílùú rẹ̀ Matthew Longstaff lo gbayo naa wọle fun Newcastle nigba ti ifẹsẹwọnsẹ ọhun ku iṣẹju mejidinlogun ko pari.
Ọgbẹlẹ ati iyan mu ki Olori Fatimid wọgile eto Hajj lọdun 1048 A.
Nítorí pé ó ti tẹ aláìní mọ́lẹ̀,ó sì ti pa wọ́n tì sí apákanó sì fi ipá gba ilé tí kò kọ́.
 ohun tí òpìtàn ìbá sọ fun wa nip é ìran odùduwà ni Ọbàlùfọ ̀ n jẹ ́ .
Lọjọ Aiku, ọjọ kejidinlogun ni awọn agbabọọlu obinrin ọmọ Naijiria yii fakọyọ ti wọn tun gbe ife ẹyẹ Afrobasket lọ.
Aarẹ Nana Akufo Addo ti orilẹede Ghana lo kede pe ki awọn akẹkọọ onipele keji ati ikaarun ti ileewe Girama ti wọn ti wa nisinmi sile fun ọpọlọpọ oṣu wọle sẹnu ẹkọ wọn pada lọjọ ikarun un, oṣu kẹwaa titi di ọjọ kẹrinla, oṣu kejila pe ki wọn fi pari saa ẹkọ ti wọn wa ki asiko arun Coronavirus to bẹrẹ.
Bí wọ́n ti ń jó, wọ́n ń kọrin báyìí pé, “Saulu pa ẹgbẹẹgbẹrun tirẹ̀,ṣugbọn Dafidi pa ẹgbẹẹgbaarun tirẹ̀.
Agbabọọlu Tennis loun ati ẹgbọn rẹ Obinrin Mari Afiwe kan ti opo ti n sọ nipa Naomi Osaka ati Serena Williams to gbewuro soju rẹ ni pe awọn mejeji ni ẹgbọn obinrin to n gba Tennis.
”Joabu dáhùn pé, “Ǹjẹ́ bí o bá fẹ́, máa lọ.
Oríṣun àwòrán, Getty Images O fikun ọrọ rẹ pe ẹni to ba da iru laṣa yoo jẹ iyan rẹ niṣu nitori ifẹmi ara ẹni wewu gbaa ni.
Ati pé a kò dá ọkunrin nítorí obinrin, obinrin ni a dá nítorí ọkunrin.
O sọ bi iya rẹ ṣe kọkọ sọ ireti nu ninu oun to yan laayo yii to si sọ fun un pe ko le ṣe oriire nibẹ amọ ṣe ni ohun ati ilu ijo mama gan yipada nigba tinkan ti ọmọ rẹ, Erelu elemure n ṣe bayii ti di iwuri nla fun un.
Dájúdájú mo mọ̀ pé o óo gbé mi lọ sí ipò òkú,ilé tí o yàn fún gbogbo eniyan.
"Wọn ko si ni i ṣe ohunkohun lati tako ẹgbẹ wọn.
EFCC ni ikede ori Twitter naa ki i ṣe ipinnu ajọ naa.
Toyin ni pẹlu iranlọwọ awọn oniṣegun ibilẹ to moye ni oun fi mọ ara ti awọn ewe ati egboogi ibilẹ n da eyi ti o si mu lo.
Àkọlé àwòrán, Minisita feto ilera naa ti f'gbakan ri paṣẹ lọ rọọkun nile fun Ọjọgbọn Yusuf ṣugbọn ti aarẹ Buhari daa pada Ina ru ni ileeṣẹ adojutofo ilera lorilẹede Naijiria, NHIS, ina ọhun kii sii ṣẹ kekere.
Oando bọ́ si abẹ́ ìwádìí àjọ eto aàbò okòwò àti pàṣípààrọ̀ Naijiria-SEC
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Operation Amọtẹkun: Ilé iṣẹ́ ààrẹ ránṣẹ́ pe àwọn gómìnà ilẹ̀ Yorùbá lórí ọ̀rọ̀ Àmọ̀tẹ́kùn 8 Sẹ́rẹ́ 2020 Oríṣun àwòrán, Facebook/SEyi Makinde Ile iṣẹ aarẹ ti ranṣẹ pe awọn gomina marun un to wa nilẹ Yoruba lori agbekalẹ eto aabo ''Amọtẹkun'' ti wọn fẹ ṣe ifilọlẹ rẹ l'Ọjọbọ.
Nígbà tí ó bá dé ilé, yóo pe àwọn ọ̀rẹ́ rẹ̀ ati àwọn aládùúgbò rẹ̀ jọ, yóo wí fún wọn pé, ‘Ẹ bá mi yọ̀, nítorí mo ti rí aguntan mi tí ó sọnù.
Gẹ́gẹ́ bí ọ̀kan nínú àwọn tí ọ̀rọ̀ náà ṣe ojú ẹ ṣe sọ, pé àwọn adigunjalè náà wọ àdúgbò nínú ọkọ̀ ayọ́kẹ́lẹ́ Toyota Camry àti bọọsi kan ti wọn gbé sí ẹgbẹ́ báǹkì náà, tí wọn sì bẹ̀rẹ̀ sí ní yìbọn sí inú afẹ́fẹ́ láti dẹ́rù ba àwọn ènìyàn.
Oríṣun àwòrán, twitter/Ajimobi Àkọlé àwòrán, Abiola Ajimobi ninu aṣọ ibilẹ nibi eto kan ni ilu Ibadan Oríṣun àwòrán, Twitter/abiola ajimobi Àkọlé àwòrán, Sẹnetọ Ajimọbi lasiko to n sọrọ lori koko kan to kaa lara nigba to ṣi jẹ Gomina ipinlẹ Oyo Oríṣun àwòrán, Twitter/abiola ajimobi Àkọlé àwòrán, Abiola Ajimobi ati Florence aya rẹ ti ọpọ maa n sọ pe Ajimọbi kii ko iyan rẹ kere ni yii lasiko ipolongo fun ẹgbẹ oṣelu onigbalẹ APC Oríṣun àwòrán, Twitter/ajimobi Àkọlé àwòrán, Oloye Ajimobi n jo lọjọ ajọdun aṣa ni ipinlẹ Oyo Oríṣun àwòrán, Twitter/abiola ajimobi Àkọlé àwòrán, Ajimobi pelu Aarẹ Muhammadu Buhari to n tukọ Naijiria labẹ ẹgbẹ oṣelu APC Oríṣun àwòrán, Twitter/ajimobi Àkọlé àwòrán, Ajimobi pelu gomina ipinlẹ Ekiti tẹlẹ, Ayọdele Fayose, ọrẹ ṣiṣe ko kan iyatọ ninu ẹgbẹ oṣelu ti koowa wa!
Ìyá iyawo Simoni wà ní ìdùbúlẹ̀ àìsàn ibà.
Wọn ni eniyan mẹtala miiran tun ti lugbadi aarun naa ni ipinlẹ Eko ati ẹyọkan ni ipinlẹ Delta.
Bí ẹnikẹ́ni bá ṣe iṣẹ́ iranṣẹ, kí ó ṣe é pẹlu gbogbo agbára tí Ọlọrun fún un.
NCC: Á gbógun ti àwọn èèyàn tí kò bá fi orúkọ nọ́mbà ìpè wọn sílẹ̀
2019 World Happiness: Ìwàdíì sọ pé ìdùnnú ti pọ si ní Nàìjíríà
O ni ida mẹtadinlogoji ninu ọgọrun awọn ile eto ilera lorilẹ-ede Naijiria lo ni ile igbọnsẹ fawọn alaisan.
Ó ní: “Àwọn ará Juda ń dẹ́ṣẹ̀ kún ẹ̀ṣẹ̀, dájúdájú n óo jẹ wọ́n níyà; nítorí wọ́n ti kọ òfin èmi OLUWA sílẹ̀, wọn kò sì rìn ní ìlànà mi.
A maa ṣa awọn taya ti wọn ko lo mọ kiri ilu Eko.
tuntun ni yoo de si orile
Amọ, iroyin mii to tun lu ayelujara pa tun sọ pe ẹgbẹ YWC ti yọ Ọjọgbọn Akintoye gẹgẹ bi aarẹ ẹgbẹ naa.
Nígbà tí mo rí ọ̀rọ̀ rẹ, mo fi ṣe oúnjẹ jẹ.
Se lawọn sọja n tiraka lati le awọn ọkọ nla to n tu afẹfẹ taju taju sita lalẹ ọjọ keji ti iwọde wọn latari pe wọn f ki aarẹ Omar al- Bashir kọwe fipo silẹ.
O ni titi di isinyi ni ọrun ṣi n dun ọmọdebinrin kan ti ọkunrin yii fipabalopọ nitosi ile Oun yatọ si ti iya arugbọ to n gbe ni ẹgbẹ Mọṣalaṣi to tun fipa kọlu.
Wọn ni o pe awọn lati lọwọ si idagbasoke agbegbe naa ju ki awọn maa tọrọ owo kiri lọ.
Isele aseku-pani yii waye, ti o n lo bi ose meji ti ijoba orile-ede Rwanda ti awon ile-ijosin bi eedegberin pa, latari bi won se kuna, lati tele ofin ilana  ile kiko ati bi won se n fi ariwo di ara-ilu lowo.
Mo kabamọ ohun to ṣẹlẹ .
Tóyìn Adégbọlá: Kò yẹ kí obìnrin fi ìdí gba ipò tíátà
Joṣua dúró níwájú angẹli Ọlọrun, pẹlu aṣọ tí ó dọ̀tí ní ọrùn rẹ̀.
“Ẹ wá sọ́dọ̀ mi gbogbo ẹ̀yin tí ń ṣe làálàá, tí ẹrù ìpọ́njú ń wọ̀ lọ́rùn.
Alabi so pe“Ajọ NiBUCAA pelu ibasepo awon oluranlowo ti se gudu-dudu meje,yaya mefa lorile ede Naijiria,lati gbokun ti aarun kogboogun.
Ilẹ isẹ ijọba apapọ lori amojuto ara ilu, mimoju to ajalu idagbasoke eto amuludun ti salaye pe ẹnikẹni ti ko ba tii gba ajẹmọnu tirẹ tumọ si pe orukọ ẹni bẹẹ wa ni ile iṣẹ ijọba apapọ miran ni.
Ọpọ lo n sọ pe nitori o jẹ obinrin ni wọn ṣe da a silẹ.
Awọn oniṣẹ ibi kan ti pa ọmọ ọdun marun un kan ni ijọba ibilẹ Akinyẹle ni ipinlẹ Ọyọ.
Ó jẹ́ aláriwo ati onírìnkurìn obinrin,kì í gbélé rẹ̀.
Yóo jẹ́ ìpín ti ọba ní Israẹli.
Bí ó ti ń bá wọn sọ̀rọ̀ lọ́wọ́, Goliati wá láti pe àwọn ọmọ ogun Israẹli níjà.
Ó bá fi òun ati olùtọ́jú rẹ̀ pamọ́ sinu yàrá kan.
Lẹyin idanwo naa, akẹkọọ mẹrin lo yege lati janfaani eto ẹkọ ọfẹ naa nile ẹkọ girama ati ti alakọbẹrẹ to wa ninu ọgba ile ẹkọ naa Owo yii si ni yoo gbọ bukata owo ileewe akẹkọọ naa, owo ilegbe, asọ ileewe ati awọn iwe ti wọn yoo lo fun ọdun kan.
Bi mo si ti de moscow ni wọn ti gba iwe irinna mi lọwọ mi.
Mò ń bi yín, ǹjẹ́ ẹ mọ ohun tí ó fà á?
 Eyi yoo tun je ki awon to ni aisan ti ko lera pupo duro sigberiko ti won wa nibiti itoju yoo ti wa ba won.
Opó ni mí, ṣùgbọ́n ọ̀pọ̀ ló ń rí opó bíi gbọkọgbọkọ Ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ parí, Germany di ẹrù ìyà aláwẹ́ mẹ́ta lé Najiria lórí Kàyééfì, oyún inú nínú ilé ìgbọ̀nsẹ ọkọ̀ òfurufú Tomomewo gba awọn obinrin to ba fẹ wọnu iṣelu Naijiria lọ ni imọran.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ọwọ tẹ agbofinro meji lori iṣowo ọmọniyan 10 Ẹrẹ̀nà 2018 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, O sọwọn ki wọn ba awọn agbofinro nibi isowo ọmọniyan Ileeṣẹ to n mojutọ iṣiwa ati iṣilọ ni Naijiria ti bẹrẹẹ iwadi lori awọn oṣiṣẹ rẹ meji kan ti wọn furasi wipe wọn fẹ ko awọn ọmọbirin jade kuro ni Naijiria lọna aitọ.
OLUWA àwọn ọmọ ogun,òun ni Ọba ògo náà.
Simoni dáhùn pé, “Alàgbà, gbogbo òru ni a fi ṣiṣẹ́ láì rí ohunkohun pa, ṣugbọn nítorí ọ̀rọ̀ rẹ, n óo da àwọ̀n sí omi.
Àkọlé àwòrán, Ifẹhonu han n lọ lọwọ ni oriko NBA nipa ọrọ Onnoghen Ẹ o ranti wipe ni ọjọ Ẹti, amofin agba Olisa Agbakoba to bẹnu atẹ lu igbesẹ Buhari lati yọ Onnoghen ti ni awọn yoo ṣe iwọde lati fi ẹhonu han lori igbesẹ aarẹ naa.
Ìdí tí a fi ṣàfikún owó ìtanràn ọ̀rọ̀ kòbákùngbé ní Nàìjíríà sí 5 Mílíọ̀nù rèé - Lai Mahammed Aya gómìnà Kwara fẹ́ ran tìyá- tọmọ olójú búlúù lọ́wọ́ Ṣé lóòtọ́ ni aya ààrẹ, Aisha Buhari fò lọ sí Dubai fún ìtọ́jú?
Buhari di alága àjọ Ecowas Àwọn kan fẹ́ da Naijiria rú torí ààbò tó mẹ́hẹ - Osinbajo gbarata Lẹ́tà Obasanjo: Àjálù ń bọ̀ bíi ti Rwanda, tí Buhari kò bá ṣàtúnṣe ètò ààbò Ìlú ò rẹ́rìn ín rárá, Alaafin Adeyemi III fárígá fún Buhari nínú lẹ́tà tuntun Diẹ orukọ awọn to wa nibẹ ni: Rauf Arẹgbẹṣola fun ipinlẹ Osun Goerge Akume fun ipinlẹ Benue Tibi Pre Sylva ipinlẹ Bayelasa Adebayo Adeniyi fun ipinlẹ Ekiti Babatunde Fasola fun ipinle Eko Olorunminbe Mamora fun ipinlẹ Eko Gbemisola Saraki fun ipinlẹ Kwara Lai Mohammed fun ipinlẹ Kwara Tayo Alaṣo Adura fun ipinlẹ Ondo Sunday Dare fun ipinlẹ Oyo Olamilekan Adegbite fun ipinlẹ Ogun.
 Lẹyin o rẹyin, adajọ Oluwatoyin Taiwo sọ pe ki ọdaran naa lọ fi ẹwọn jura fun oṣu mejidilogun lori ẹsun mẹta ti wọn fi kan an, yoo si maa ṣe ẹwọn naa papọ, tabi ko san owo itanran 100,000 naira fun ẹsun kọkan."
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Naira Marley: Ẹ wo bí ìgbẹ́jọ́ ṣe lọ lórí ẹ̀sùn tí wọ́n fi kan Marley 21 Èbibi 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 7 Ògún 2020 Oríṣun àwòrán, Others Ile ẹjọ alagbeka kan nilu Abuja, ti sọ pe ki gbajugbaja akọrin , Azeez Fashola, ti gbogbo eniyan mọ si Naira Marley san ẹgbẹrun lọna igba Naira, owo itanran.
Oluwa mi, gbọ́ ohun tí èmi iranṣẹ rẹ fẹ́ sọ.
Oríṣun àwòrán, @ikeazor Àkọlé àwòrán, Wọn pada yan an sinu awọn ọmọ igbimọ alamojuto ẹgbẹ APC ti aarẹ Buhari ba wọle lati 2015.
Iṣẹlẹ naa mu ẹ̀mí awọn ara adugbo kan lọ.
Ṣé o óo lè sọ pé oriṣa kan ni ọ́ lójú àwọn tí wọ́n bá fẹ́ pa ọ́?
Ọjọ ti pẹ ti wọn ti máa n rọ ọba loye nilẹ Yoruba.
Tó o bá fẹ́ wọ bàálù lásìkò yìí, wo òfin tuntun tó tẹ̀lé Nibayii ti awọn papakọ ofurufu ilu Eko ati Abuja ti bẹrẹ si ni gbe ero pada, o tọ ki a fi diẹ lara awọn ilana to de irina lawọn papakọ ofurufu yii to ara wa leti.
Ko si akọsilẹ ọlọdọọdun fun iye ọmọ ti awọn ajoji si ilẹ Amẹrika bi ṣugbọn oniruuru ajọ lo ni iṣiro tiwọn.
Wárìrì níwájú OLUWA, ìwọ ilẹ̀,wárìrì níwájú Ọlọrun Jakọbu.
Sọ pé ọba Babiloni wá sí Jerusalẹmu, ó sì kó ọba ati àwọn ìjòyè rẹ̀ lọ sí ọ̀dọ̀ ara rẹ̀ ní Babiloni.
Kí gígùn aṣọ títa kọ̀ọ̀kan jẹ́ igbọnwọ mejidinlọgbọn, kí fífẹ̀ rẹ̀ sì jẹ́ igbọnwọ mẹrin, kí àwọn aṣọ títa náà gùn bákan náà, kí wọ́n sì fẹ̀ bákan náà.
National Electoral Commission, INEC) ti kede ,Nyesom Wike,pe oun lo jawe
 a ka àwọn ìwá tí ọwọ ́ wa tẹ ̀ ní agbègbè náà , a sì rí ọ ̀ kọ ́ tó wúlò fún wa lórí orí ọ ̀ rọ ̀ tí iṣẹ ́ wa yìí dá lé .
àwòrán igi ọ̀pẹ ati kerubu sí yíká; wọ́n gbẹ́ igi ọ̀pẹ kọ̀ọ̀kan sí ààrin kerubu meji meji.
Wọn gba awọn oludibo niyanju lati ma ṣe lo atanpako wọn fi dibo.
 Bakan naa , opolopo ileri to se lasiko to n dije fun ipo aare lati mu idagbasoke ba eto ogbin lorile ede yii, lo ti n mu wa si imuse.
Ọlọpaa taa n wi yi wa lara awọn to tẹle awọn to n ṣoju ọlọpaa wa si ibi igbẹjọ igbimọ naa nilu Eko.
’Èmi náà si fèsì mo ní, ìwọ ni mò ń wá, ìwọ ni mo tọ̀ wá gán-an, ọba ìlú mi lo sì ni ki n lọ pè ọ́ wa, nítorí kí a bà jọ lọ sí ìrìn àjò kan.
Ninu oṣu karun un ọdun 2020 ni fidio kan gbode lori ayelujara, eyii to n ṣafihan pe abẹrẹ ajẹsara yoo ṣe paṣipaarọ DNA eeyan, amọ awọn onimọ naa ti sọ pe ko ri bẹ.
Mo nigbagbo pe,a o ni baalu orilẹ ede  tiwa , ni eyi ti yoo fẹgbẹkẹgbẹ pẹlu   awọn  orilẹ ede  lagbaaye, ni eyi ti o tun nifẹẹ  awọn  onibara lọkan.
Nígbà náà ni ọmọ-ẹ̀yìn keji tí Olórí Alufaa mọ̀ jáde, ó bá mú Peteru wọ agbo-ilé.
Lọdọ wọn orin lasan lo kọ, o si ṣe pataki ki awọn eeyan gbo ẹkọ ti orin naa n kọ wọn Awọn kan tun mu Fela Anikulapo wọ inu ọrọ yi.
Lẹ́yìn náà, ó pada sí ilé rẹ̀, ó bèèrè fún oúnjẹ, wọ́n gbé e fún un, ó sì jẹ ẹ́.
Wọ́n lọ fọ kẹ̀kẹ́ ogun rẹ̀ ní adágún Samaria, àwọn ajá lá ẹ̀jẹ̀ rẹ̀, àwọn aṣẹ́wó sì lọ wẹ̀ ninu adágún náà gẹ́gẹ́ bí OLUWA ti sọ tẹ́lẹ̀ pé yóo rí.
Bóbá dú lójú, a dú lénu
Awọn orilẹede to se idajọ iku ni ọdun 2013 si 2017: Afghanistan Bahrain Bangladesh Belarus Botswana Chad China Egypt Equatorial Guinea India Indonesia Iran Iraq Japan Jordan Kuwait Malaysia Nigeria North Korea Oman Pakistan Palestine Saudi Arabia Singapore Somalia South Sudan Sudan Taiwan Thailand (2018) United Arab Emirates USA Vietnam Yemen.
Security state of Nation: Ọ̀rọ̀ ààbò kìí se èyí tí a lé fí gbèdéké sí- Femi Adesina
Bakan naa lo kede pe oun ti se alaye lori owo ti wọn ri ko jọ fun iwọde naa, ti apapọ rẹ jẹ miliọnu mẹtadinlaadọjọ naira.
Iye àwọn ọmọ tó gba abẹ́rẹ́ ajẹ sára kò tìí yi pada gẹ́gẹ́ bi ajọ WHO ṣe sọ ìdá ọgọ́rin ati máruùn nínú ìdá ọgọ́run ni wọ́n wà titi di àsìkò yìí láti nkan bi ọdún díẹ̀ sẹ́yìn.
 Aare wa fi okan asoju naa bale pe orile ede Naijiria yoo tun tepele mo ibasepo to wa laarin awon orile ede mejeeji naa , paapaa julo lori eto oro aje ati aabo.
Ọmọ aadọrin ọdun kan lo ti gbẹmi mi, nigba ti ọkan lara awọn kiniun ti o n ṣe itọju fun se ikọlu sii ni orilẹ-ede South Africa.
 ní àwọn orílẹ ̀ -èdè tó ṣẹ ̀ ṣẹ ̀ ntẹ ̀ síwájú , èyí jẹ ́ ọ ̀ kan nínú àwọn ohun tó má a nsábà ṣe òkùnfà gìrì .
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Èmi gan máa ń béèrè lọ́wọ́ ara mi pé ta ni Wole Soyinka gangan' Arsenal (1991) Aṣọ aláwọ̀ ofeefe yii jẹ ọkan lara awọn aṣọ manigbagbe ni nkan bi ọdun 1990.
N óo wà lórí òkè òjíá,ati lórí òkè turari,títí ilẹ̀ yóo fi mọ́,tí òkùnkùn yóo sì lọ.
Bayii ekun yii gba apapo ida meji le ni merin nigba ti ekun guusu ile Adulawo gba ida perete meji le ni merin ti aarin gbungbun ile Afrika gba ida mefa le ni meta nibi ti iwo oorun si ti gba ida meta le ni meji ni eyi to kere julo.
Mose bá yipada, ó sọ̀kalẹ̀ láti orí òkè, tòun ti wàláà òkúta ẹ̀rí mejeeji lọ́wọ́ rẹ̀, àwọn wàláà òkúta tí Ọlọrun ti kọ nǹkan sí lójú mejeeji.
nítorí pé kíákíá ni wọn yóo gbẹ bí i koríko;wọn óo sì rọ bí ewé.
Ẹni mẹ́ta gbé Buhari lọ sílé ẹjọ́ nítorí pé ó parọ́ ìwé ẹ̀rí rẹ̀ fún àjọ INEC Ilé alájà méjì wó lu ọmọ mẹ́rin ni Bariga Ọlọ́pàá fi páńpẹ́ ọba mú ọmọ ogun ilẹ̀ Naijiria Iléeṣẹ́ ọmọ ogun dá Bashir tó ri owó he lọ́lá O ni nibẹ ni wọn ti ran wọn lọ kìlọ̀ fún àwọn ọmọ wọ́n láti lọ so àgbéjẹ mọ́wọ́.
Mo wò ó láti ibi ìbàdí lọ sí ìsàlẹ̀, ó dàbí iná.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Demilade Adepegba: Mo má a ń gbàgbé fèrè ni, tí mo bá wà nílé ìwé Wọn ni iye ibo ti Atiku ati Buhari ri niyi ni ipinlẹ marunlelọgbọn nitori ko tii si esi idibo aarẹ ti ipinlẹ Rivers lori ẹrọ kọmputa INEC, lọjọ kẹẹdọgbọn oṣu keji.
Lasiko ti baba rẹ n ba BBC sọrọ nibayi to n lọ ọdun mẹwa ti isẹlẹ naa waye, baba Mutallab ni idajọ ‘ma ri oorun’ ti wọn fun ọmọ oun ti lagbara ju, yoo si dara ki awọn alasẹ ba woo se.
Àwọn Ọmọ Israẹli ní Òkè Sinai.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Mo ń retí láti ọ̀dọ̀ bàbá mi nígbà tí mo gbọ́ pé ó bá ìjàmbá bàálù lọ Adesanmi to jẹ ọjọgbọn ni fasiti kan ni orilẹ-ede Canada in rinrin ajọ lọ orilẹ-ede Nairobi lati Addis Ababa nigba ti ọkọ naa ja lulẹ laarin iṣeju mẹfa to gbera.
 Èyí ni ó mú apèbí ( olóyè pàtàkì kan ní ibùdó yìí ) lọ báa bóyá ijà ni ó bá wá ní tòótọ ́ .
Amọ ara wa latipasẹ mọlẹbi, taa si fẹ ara wa.
Absalomu sá lọ ní àkókò yìí.
Wọ́n mú wọn láàyè, wọ́n sì pa wọ́n ní ibi kòtò tí ó wà ní Bẹtekedi.
Bolatito ko ipa manigbagbe ninu iṣẹ tiata lasiko ti ọkọ rẹ, Ishola Ogunsola wa loke eepẹ, sugbọn lẹyin ti ọkọ rẹ ku tan, oju obinrin naa ko han mọ ninu ere tiata.
Ẹwẹ iroyin kan sọ wi pe nigba ti wọn kan si iya ọmọ naa, o ru ẹbi iku ọmọ rẹ le ile iwe pe wọn ko mojuto ọmọ oun to wa ni iṣakoso ni.
Mo kí ọ púpọ̀, o kù ìrìn, o kú làásìgbo òde ayé, o kú ìrìnkiri inú aginjù, o kù ọjọ́ rírí jẹ, o kú ọjọ́ àìríjẹ, àwọn ènìyàn rẹ ńkọ́?
Olukopa to ba ti gba ami ẹyẹ ri nilẹ okeere gbọdọ ti ṣiṣẹ ni Naijiria fun ọdun meji Gbogbo olukopa ti gbọdọ pari eto isinru ilu, NYSC.
Ẹ̀yin ń kọ ilà ní Ọjọ́ Ìsinmi kí ẹ má baà rú òfin Mose, ẹ wá ń bínú sí mi nítorí mo wo eniyan sàn ní Ọjọ́ Ìsinmi!
Gbogbo won kọ lati ba awon akoroyin
Lucinda Evans - Ajafẹtọ ẹni lati South Africa Nibayii ti orilẹede South Africa n koju iwa ipaniyan ati ifipabanilopọ to le pupọ, Lucinda ti dide gẹgẹ bii agbẹnusọ fun awọn obinrin.
Mo ṣe àkíyèsí ìwé kan tí ó wà ní oókan-àyà rẹ̀, ohun tí wọn kọ sí ibẹ̀ sì ni èyí: ‘Bí iré bí iré ẹni tí ó ń jáfara bá ara rẹ̀ láàárin àwọn èrò ẹ̀hìn, bí iré bi iré aláfara bá ara rẹ̀ ní ọ̀run alákejì.
Onyeoziri fikun ọrọ pe, ọpọlọpọ ohun to n lọ lorilẹede Naijiria lo pe fun ki ijọba gbe igbesẹ lori wọn, ki wọn lee dẹkun wọn.
Oun naa bu ẹnu ẹ̀tẹ́ lu awọn to huwa buruku yii pe o ku diẹ kaa to.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Baby abandoned on dunmpsite: Mo ti bímọ mẹ́rin tẹ́lẹ̀ fún bàbá méjì nínú òṣí- Dupe Ogbomos Musa ṣalaye pe lootọ ni awọn papakọ baalu , ati awọn ileeṣẹ ọkọ ofurufu ti ṣetan fun iṣẹ, ṣugbọn awọn ẹ̀ka miran ti ko nii ṣe pẹlu ọkọ ofurufu lo fa afikun ọsẹ kan.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Ọna ajọṣepọ eto ilera to jẹ ti alagboole to dara pupọ: Eyi jẹ idi karun un ti ajakalẹ arun Covid 19 ko fi ṣọṣẹ ju bi o ti yẹ lọ nilẹ Adulawọ.
Koda, ẹbi ti fẹ́nuko pe ninu iboji ti wọn sin ololufẹ Baba si lọ́dun 2014 naa ni itẹ́ oku ti Baba yoo sun si gbẹ̀yin bi o se sọ saaju iku rẹ̀.
“Ọjọ́ ìdájọ́ OLUWA fẹ́rẹ̀ dé sórí àwọn orílẹ̀-èdè;a óo san án fún ọ, gẹ́gẹ́ bí iṣẹ́ ọwọ́ rẹ.
BBC rin ìrìnàjò pẹ̀lú Abba Kyari lórí ìwádìí ìjínigbé 'A fẹ́ kúrò ní Larubawa nítorí à kò gba ẹ̀sìn' Donald Trump kéde pé ìpàdé òun pẹ̀lú Kim já si rere Ọkọ mi kò le f'ipá bá ẹnikẹ́ni lò pọ̀ láíláí - Modele Fatoyinbo Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí kan sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
Ó fi aṣọ àwọ̀lékè tí ó já bọ́ sílẹ̀ lára Elija lu odò, ó sì kígbe pé, “Níbo ni OLUWA Ọlọrun Elija wà?
Nítorí náà, eniyan níláti foríbalẹ̀, kì í ṣe nítorí ẹ̀rù ibinu Ọlọrun nìkan, ṣugbọn nítorí pé ẹ̀rí ọkàn wa pàápàá sọ fún wa pé ó yẹ bẹ́ẹ̀.
Bakan naa ni Ejigbe tun nahun kesi Olubadan ilẹ Ibadan, Ọba Saliu Adetunji Aje Ogungunnisọ Kinni, lati bawọn rawọ ẹbẹ si Makinde pe ko tu okun ofin naa lọrun awsn nitori agba ti ko binu ni ọmọ rẹ n pọ.
Ninu oro tire, gomina fun ipinle Osun , Gboyega Oyetola wa ro awon  akẹkọọ-gboye ohun lati jẹ asoju rere fun
Ọba yìí sọ fún àwọn eniyan rẹ̀ pé, “Ẹ wò bí àwọn ọmọ Israẹli wọnyi ti pọ̀ tó, tí wọ́n sì lágbára jù wá lọ.
Ṣaaju iṣẹlẹ yii, ohun ta a mọ ni wi pe iroyin n tan kaakiri pe o n ṣaisan nitori pe o ti lugbadi ajakalẹ arun COVID-19.
Ikeji ni pe ko fi ẹsẹ naa silẹ bẹẹ, ko san fun'ra rẹ, bo tilẹ jẹ pe, yoo pẹ ẹ ko to o san.
Ijoba orile ede Naijiria ti ro ijoba orile ede UK lati se idajo to ye lori iku omo orile ede Naijiria kan , Ogbeni Abraham Badru ti won yin ibon pa ni ilu LondonOluranlowo agba fun aare lori oro ile okeere ati agbegbe re, iyaafin Abike Dabiri lo pe ipe yii ninu atejade kan ti agbenuso re lori iroyin ,ogbeni  Abdur-Rahman Balogun , gbe jade niluu Abuja.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Animal accident: Arákùnrin kan dóòlà ẹ̀mí Erin tí alùpùpù gbá lójú pópó 23 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Oríṣun àwòrán, Photoshot Ọmọ Erin kan ti alupupu gba loju titi ti ru u la lẹyin ti arakunrin kan doola ẹmi rẹ.
Wọn yóo sì jọ dojú ìjà kọ Edomu ati Moabu.
Àkójopò àwon ède kan ni yí tí wón tó márùn-ún-dín-lógósàn-án ( 175 ) .
Ijọba ipinlẹ Ọyọ ni awọn ti n gbọ finrinfinrin pe awọn eeyan kan ti n ṣe kurukẹrẹ kaakiri lọna ti ko bofinmu ti wọn si n pe ara wọn ni ọmọ ẹgbẹ awakọ ero, NURTW nipinlẹ Ọyọ.
Aare Paul Biya ti orile ede
Ó sì sọ ọ̀wọ̀n náà ní Misipa, nítorí ó wí pé, “Kí OLUWA ṣọ́ wa nígbà tí a bá pínyà lọ́dọ̀ ara wa.
Ṣe wọn o tun wa oludari bọọlu?
Ninu atẹjade ti Ọgbẹni Hakeem Bello to jẹ oludamọran pataki si Minista ẹka naa, Babatunde Faṣọla fi sita lọjọ Aiku lo ti sọ bẹẹ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Lagos building collapse: Àwọn òbí ń kérora lórí ikú àwọn ọmọ wọn nínú ìjàmbá ilé tó wó Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 3 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 5 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Ni a bá ju ikú ati ipò òkú sinu adágún iná.
Ajọ IAAF si n reti ki Naijiria da owo wọn pada ko maa baa di wi pe wọn yoo f'ofin de wọn lati kopa ninu ere eje kaakiri agbaye.
Lara awon ti o kopa ninu ipolongo
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'EFCC ti wá dà bíi ara ẹgbẹ́ òṣèlú APC' O ni ipenija nla ni igbẹjọ Fayoṣe jẹ fun APC ati gbogbo awọn ti wọn ti fi ẹsun ikowojẹ kan labẹ aarẹ Buhari ati iṣejọba rẹ.
Àwọn olùṣọ́-aguntan náà pada síbi iṣẹ́ wọn, wọ́n ń fi ògo ati ìyìn fún Ọlọrun fún gbogbo nǹkan tí wọ́n gbọ́, ati àwọn nǹkan tí wọ́n rí gẹ́gẹ́ bí angẹli náà ti sọ fún wọn.
Díẹ̀ lára àwọn ìṣẹ̀lẹ̀ tí yóò mi ìgboro tìtì l'ọ́dún 2020 rèé Wo àwọn èèkàn tí ikú mú lọ lọ́dún 2019 Gómìnà mẹ́ta àtí ènìyàn 1,242 ló kó sí panpẹ EFCC ni ọdún 2019 Njẹ́ ẹ mọ̀ pé orílẹ̀-èdè Nàìjíríà ló n wo 'Blue film' jù?
Duro Ladipọ, ìlúmọ̀ọ́ká òṣèré tíátà àti ọmọ àlúfà tí kò gbàgbé àṣà ìbílẹ̀ Ọ̀rọ̀ǹpọ̀tọ̀niyùn, Aláàfin obìnrin àkọ́kọ́ rèé, tó ní nǹkan ọkùnrin Ṣé ó ṣeéṣe kò jẹ́ àṣírí ìbejì Aláàfin nìyíì?
Bàbá mi tì ròyìn iwin náà fún mi rí, ìbejì ni pẹ̀lú èṣù, awọn méjéèjì si ni àwọn ọmọ aráyé ń bọ ní ìkoríta.
Awọn meje lo da ẹgbẹ yii silẹ nigba naa.
Oyin lé àwọn ènìyàn kúrò l'ábúlé kan ní Plateau
Bẹ́ẹ̀ ni wọ́n ṣe sí ọpọlọpọ àwọn ẹrú mìíràn, wọ́n lu àwọn kan, wọ́n pa àwọn mìíràn.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Olorí ogun Ethiopia f'arapa nínú rògbòdìyàn tó wáyé ni Addis Ababa 23 Òkùdu 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Lootọ ni Ọgbẹni Abiy pa ina wahala oṣelu, amọ ija ẹlẹyamẹya n pọ si Igbakeji Adari eto aabo lorilẹede Ethiopia ti ni ọgagun to wa ni idi ifipa gba ijọba to waye ni Ethiopia ti sa lọ kuro ni ilu, ti won ko si mọ irin rẹ.
Nígbà tí mo dé ilẹ̀ o rẹ̀ mi púpọ̀ nítorí mo ti pẹ́ púpọ̀ lórí òkè, ebi sì ti pa mí inú mi ti di pẹlẹbe, mo bà rọra jókòó sí apá kan mo ń simi.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Kid boxer: Ọmọọba 'The Buzz' Larbie rèé, ọmọ ọdún méje tó ń fi ẹ̀ṣẹ́ dá bírà Abass ni ọlọyaya eeyan ni sẹnetọ Ajimobi, o si yẹ ki awọn ọmọ Naijiria kọ eti ikun si iru iroyin bẹẹ.
Aarẹ ibẹ ni aarẹ ilẹ Yuroopu to pẹ ju lori oye.
Sowore, ẹni to fi ikede naa soju opo Twitter rẹ tun mu wa si iranti pe o pe ọdun kan bayii ti ikọ agbofinro gbe oun sahamọ.
Bí ó tilẹ̀ rí bẹ́ẹ̀, Ẹ̀kọ́ àti àwọn Májẹ̀mú jẹ́ àrà ọ̀tọ̀ nítorítí kìí ṣe ìtumọ̀ àwọn ìwé àtijọ́, ṣùgbọ́n orírun rẹ̀ jẹ́ ti òde òní a sì fifúnni láti ọwọ́ Ọlọ́run nípasẹ̀ àwọn àsàyàn wòlíì Rẹ̀ fún ìmúpadàbọ̀-sípò iṣẹ́ mímọ́ Rẹ̀ àti ìgbékalẹ̀ ìjọba Ọlọ́run lórí ilẹ̀ ayé ní àwọn ọjọ́ wọ̀nyìí.
Àkọlé àwòrán, Ipade itagbangba BBC Yoruba Awọn opo to di gbọngan Mapo mu lo n ṣe apejuwe oke meje to yi ilu Ibadan ka.
Lara wọn ni idanilọla pẹlu Member of the Order of the Federal Republic (MFR), ti Aarẹ Olusegun Obasanjo fun lọdun 2006.
Ninu ọrọ rẹ, Aarẹ ile igbimọ aṣofin agba, Bukola Saraki yin awọn ọmọ igbimọ naa, o si tun dupẹ lọwọ awọn oṣiṣẹ Naijiria àti awọn ẹgbẹ oṣiṣẹ fun suuru wọn lori ọrọ naa.
Gbogbo sísìn tí ó sìn yín, ǹjẹ́ irú ohun tí ó yẹ kí ẹ fi san án fún un nìyí?
Ṣugbọn àwọn ọmọ Lefi ni kí wọ́n pàgọ́ yí Àgọ́-Ẹ̀rí ká, kí àwọn tí kì í ṣe ọmọ Lefi má baà súnmọ́ Àgọ́ náà, kí n má baà bínú sí àwọn ọmọ Israẹli.
Hassan Dankwambo ti o tun je oludije dupo asofin labe asia egbe oselu, People’s
Ṣùgbọ́n ki wọ́n tóó sùn ní alẹ́, Àjẹ́dìran wi fún bàbá mi pe òun rántí oògùn kan báyìí tí ó wà ní àpò tòbí òun, òróró kan báyìí ni, ó si mu òróró náà ó fi pa ọkọ rẹ̀ tuntun yìí lára ó wí fún un pe nígbà tí ilẹ̀ bá máa fi mọ́ yóò tubọ̀ lágbára sí i.
Kí l'ànfàní àdéhùn okoòwò kan l'Afíríkà, AfCFTA tí Buhari tọ́wọ́ bọ̀?
"Iwadii fihan pe nigba to ku, Fatai Rolling Dollar ko niwe ẹri ọjọ ti wọn bi i sugbọn pẹlu isiro ọpọlọpọ eeyan, ""Baba 70"" jẹ ẹni ọdun mẹrindinlaadọrun un ko to dagbere fàyè."
Gomina Ikpeazu dupe lowo gomina Ganduje fun abewo re, ti O si ro awon omo orile-ede Naijiria lati tun bo maa dawole awon iwa ti yoo mu igberu ba isoknn ati idagbasoke orile-ede yii.
Eyi ni ọfiisi aarẹ sọ lalẹ ana ninu ọ̀rọ̀ oluranlọwọ pataki fun aarẹ lori ọrọ iroyin, Ọgbẹni Garba Shehu.
Oríṣun àwòrán, Super Eagles Àkọlé àwòrán, Awọn oyinbo o gbéyin nínú àwọn to ra aṣọ náà Bó tilẹ̀ jẹ́ pé owó aṣọ náà lé ní ọgbọ̀n ẹgbẹ̀rún lé ọgọ́fà náírà, síbẹ̀ àwọn enìyàn bo asọ náà wìtìwìtì.
lọpọ janturu, isẹ ọwọ, ipese ile gbigbe,eto iwosan ,ipese omi mimu,eto irinna ọkọ,
Fun aridaju eyi, ko tii si ọ̀kan ninu awọn mejeji tọrọ kan to jade lati ni mo tuba o, tabi mo tọrọ aforiji tabi mo gba kamu.
Ijọba gbọdọ gbé igbimọ alaabo kalẹ laarin awọn olugbe awọn adugbo ti agbara ojo ti maa n ṣọsẹ.
“Elamu náà wà níbẹ̀, pẹlu gbogbo àwọn ọmọ ogun rẹ̀, ibojì wọn yí ibojì rẹ̀ ká.
Oríṣun àwòrán, Reuters Ajakalẹ aarun atawọn nnkan miiran ti ko jẹ kawọn musulumi ṣiṣẹ Hajj fun igba mẹjọ to ku: Lọdun 967 A.
Ọna ati wa aabo f'ẹmi rẹ lo wa lọ s'ọdọ ẹgbẹ okunkun Buccaneer ṣugbọn ni kete to darapọ mọ wọn, ibẹru bojo awọn ẹgbẹ okunkun to ku lo jọba lọkan rẹ.
Oluwo ni Ori ni o yẹ ki Ọba maa bọ kii ṣe Orisa, nítori Ọba to n role fun Oodua to tun wá n bọ oriṣa, àwọn ti kò to o gan wọ́n o sọ pe àwọn jù ú lọ.
Wọ́n kúrò ní Salimona wọ́n lọ sí Punoni.
Oríṣun àwòrán, Facebook/Adoration Ministry Enugu Nigeria Eto ifọrọwanilẹnuwo naa ko tete waye ni kete ti wọn de ile ijọsin naa, tori Mbaka n waasu lọwọ.
Awọn orilẹ-ede to sunmọ South Africa ni awọn alejo to wa ni South Africa ti wa iṣẹ aje wa.
10 Nítorí, kíyèsíi, ohun ìjìnlẹ̀ ti ìwà-bí-Ọlọ́run, báwo ni ó ṣe tóbi tó!
Àrùn T’ó Ń Peléke Sí i
Oṣu Karun, ọdun 2019 ni gomina Akeredolu ti kọkọ kede pe, oun ati ọga agba ajọ to n ri si igbogun ti ilokulo oogun (NDLEA), Abdallah ti jọ kọwọrin lọ sorilẹede Thailand, lati kọ nipa aṣeyọri igbo gbingbin.
ni yoo jẹ enikeji ti yoo di ipo naa mu leyin Joseph Garba  ti o je asoju teleri ati eni ti o feyinti
Níbo ni ó ti rí agbára láti ṣiṣẹ́ ìyanu báyìí?
" Ẹ jọ́wọ́ ẹ bá mi sọ fún un pé mo ń dúró dèé.
Bẹ́ẹ̀ sì ni ìwọ OLUWA gúnwà títí lae,ọlá rẹ sì wà láti ìran dé ìran.
Ọdún merin sẹyín ní àwọn oniṣẹ ibi Boko Haram ji àwọn ọmọdebinrin gbe ni Chibok ni ìpínlẹ̀ Borno.
Àwọn ọmọ-ẹ̀yìn yòókù sọ fún un pé, “Àwa ti rí Oluwa!
BBC ṣe akọsilẹ awọn nkan marun un to ṣe koko, to si sọ ilu Daura di gbaju-gbaja kaakiri agbaye.
Awon wonyii a maa rọ igbagbọ wọn mọ ọ ti yoo si ri bẹẹ bi wọn ba tun ayẹwo ṣe.
Òun náà kò ṣiyè méjì, ó gbéra ó tẹ̀lé bàbá rẹ̀.
Awọn obi rẹ, ti wọn jẹ ọmọ bibi ilu Abeokuta, wa isẹ aje lọ silu London, níbi ti oun naa ti bẹrẹ iṣẹ tiata lati ile ẹkọ.
Kí ni mo jẹ́, kí ni ilé mi jámọ́ tí o fi gbé mi dé ipò yìí?
Ajọ Amnesty sọ pe oun ni ẹri to pọ, lati fihan pe awọn ọmọ ogun lo yinbọn mọ awọn oluwọde naa, eyi to pa awọn kan, ti awọn mii si farapa.
Má fi ẹnu rẹ sọ ìsọkúsọ, má sì kánjú sọ̀rọ̀ níwájú Ọlọrun, nítorí Ọlọrun ń bẹ lọ́run ìwọ sì wà láyé, nítorí náà jẹ́ kí ọ̀rọ̀ rẹ mọ níwọ̀n.
oludari agba ajọ DAWN Commission ni kii ṣe eyi ti yoo kasẹ nilẹ kiakia o, o wa lati duro titi ayeraye ni tori pe iye Ọlọpaa to wa ni Naijiria nikan ko to lati ṣe aabo loori gbogbo araalu.
Ṣe òpó igi akasia marun-un fún aṣọ títa sí ẹnu ọ̀nà náà, kí o sì fi wúrà bo àwọn òpó náà; wúrà ni kí o fi ṣe àwọn ìkọ́ wọn pẹlu, kí o sì ṣe ìtẹ́lẹ̀ idẹ marun-un fún wọn.
Kò ní ṣẹ́ ọ̀pá ìyè tí ó tẹ̀,bẹ́ẹ̀ ni kò ní pa iná fìtílà tí ń jò bẹ́lúbẹ́lú,yóo fi òtítọ́ dá ẹjọ́.
Ọ̀kọ̀ọ̀kan àwọn àdúgbò yí ló ní Olórí ọmọ tàbí lóógun kọ̀ọ̀kan tí ó jẹ́ aṣáájú fún ọmọ àdúgbò rẹ̀ òun ní aṣáájú fún iṣẹ́kíṣẹ́ àti tí ó bá délẹ̀ láti ṣe ni àdúgbó, bẹ́ẹ̀ ni, ó sì tún jẹ́ aṣojú ọba fún àwọn ọmọ àdúgbò rẹ̀.
Kí ẹ̀kọ́ mi kí ó máa rọ̀ bí òjò,àní, bí ọ̀wààrà òjò tíí dẹ ewébẹ̀ lọ́rùn;kí ó sì máa sẹ̀ bí ìrì,bí òjò wẹ́rẹ́wẹ́rẹ́ tíí tu koríko lára.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Asigbe awọn ọmọkunrin meji ni India Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Ìyá Jesu ati àwọn arakunrin rẹ̀ lọ sọ́dọ̀ rẹ̀, ṣugbọn wọn kò lè dé ibi tí ó wà nítorí ọ̀pọ̀ eniyan.
Bẹẹ ni awọn miran sọ wi pe, ibẹru bojo mu awọn ara Ekiti nitori Fayemi fẹ yọ Ewi ti ilu Ado-Ekiti, Oba Rufus Adejugbe ati awọn ọba mọkanla miran, to n fapajanu si gomina ipinlẹ naa.
Èdè bijago tabi bidyogo jẹ ́ ọkan pàtàkì lára àwọn orisìírísìí èdè bí i mẹ ́ ẹ ́ dógbọ ̀ n tí wọ ́ n ń sọ láti ilẹ guinea-bissau , orúkọ mìíràn tí a tún mọ èdè yìí sí ni : bigogo , byougout .
Àwọn kan ní omi gbígbóná àti iyọ̀ ni ká fi wẹ̀.
Ìṣẹ́ ọnà gbáà ni ìṣẹ̀dá rẹ̀ jẹ́.
Ó yí àwọn ará Ijipti lọ́kàn pada,tóbẹ́ẹ̀ tí wọ́n fi kórìíra àwọn eniyan rẹ̀,tí wọ́n sì hùwà àrékérekè sí àwọn iranṣẹ rẹ̀.
I Timaya, Olamide, Reminisce àti Wizkid.
“Gbogbo ẹ̀yà Lefi ni alufaa, nítorí náà wọn kò ní bá àwọn ẹ̀yà Israẹli yòókù pín ilẹ̀.
asoju ipinle Ondo lati se awon ofin ti yoo mu igbe aye irorun ba awon ara ilu .
Kókó mẹ́jọ tó jẹyọ nínú ọ̀rọ̀ Ààrẹ Buhari fáwọn ọmọ Nàìjíríà Oríṣun àwòrán, Bashir Ahmad Aarẹ Muhammadu Buhari ti buwọlu wiwa ọwọ ofin konile-o-gbele walẹ diẹ ni ipinlẹ Eko, Ogun ati Abuja bẹrẹ lati Ọjọ Aje, ọjọ kẹrin, oṣu karun ọdun 2020.
Gbajugbaja oṣere tiata, Bolaji Amusan fi hann wa bo se láyà to lori ètò ṣé o láyà.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó O fi kun pe ko si ootọ ninu ọrọ pe awọn n doju ija kọ awọn eeyan ẹya kan ni.
Ọgbẹni Amuṣan ni oun ko lọrọ lati sọ lori rẹ ati pe ki BBC News Yoruba o lọ bi alagba Majek leere ohunkohun ti a ba fẹ.
Oríṣun àwòrán, Oluwo A ri igba to tabuku Alaafin naa nipinlẹ Ọsun, a si mọ bo se maa n wọ Ọọni nilẹ loju wa lasiko ipade awa ọba, awọn eleyi si ti to lati sọ fun Oluwo pe ko lọ sinmi laarin wa, to ba tiẹ ni oun ko na Agbowu, ta si mọ pe eleyi kii se ootọ, a kan bẹ Agbowu ni pe ko mu suuru, ara iya ọba naa niyẹn."
kíni wọn yóò máa ṣe ní ìpínlẹ̀ - DAWN Commission Wọ́n ti mu aṣojú ọmọ Britikó ní orílẹ̀-èdè Iran Ilé ẹjọ́ pàṣẹ kí wọ́n fi àwọn afurasí tó pa àkẹ́kọ̀ọ́ LASU sí ẹ̀wọ̀n Ìjọba Ondo, inú fìfo la fi ń ṣiṣẹ́, ẹ ṣan ọ̀pọ̀ owó oṣù tẹ jẹ wa - Àwọn dókítà fárígá Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Eduardo: Mo ń jí mọ́tò pẹ̀lú àwọn ọ̀rẹ́ mi nítorí pé mo fẹ́ di 'Big boy' Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
O ni ẹ jọwọ ẹ ma gbadura tabi gbero si obinrin pe ko kan jiya lasan.
Ìdíje àwọn àkàndá àti abarapa ẹ̀dá
Òyìnbó sísọ di èèwọ̀ ní ìpínlẹ̀ Ekiti Ìpínlẹ̀ Ondo ti ní gómìnà tuntun SSANU, NASU gbé fásitì Ibadan tì pa O dìgbà tí mo bá dórí àgá kí ń tó sọ ìpinnu mi - Fatai Owoseni Ẹ̀wẹ̀, Garba fi kún un pé, ìyé àwọn ẹni to ti tóójúbọ to sì ń san owó orí ti sún láti mílíọ̀nù mẹ́wàá sí ogun mílíọ̀nù ènìyàn pàápàá jùlọ lábẹ́ ìjọba ààrẹ Muhammadu Buhari.
Paul Pogba náà bá tun fọba lee fun wọn, ni France ati Croatia jọ n waako lori papa fun idije aṣekagba Russia 2018 ti oju gbogbo wa lara wọn.
Dafidi bá bèèrè lọ́wọ́ OLUWA pé, “Ṣé kí n lépa àwọn ọmọ ogun náà?
Ṣùgbọ́n tí àwọn méjéèjì bá jẹ́ ọkùnrin, ọjọ́ mẹ́sàn án ni a ó sọ wọ́n lórúkọ.
Eeyan mọkanlelaadọta lawọn to ko aarun naa nipinlẹ Eko nikan.
Ó ní kí ó bọ́ sóde, kí ó máa lọ.
Oríṣun àwòrán, @hartarmah1 Bakan naa ni agba amofin yii tun woye pe, ba se n pe ofin ilẹ wa naa ni 'ofin apapọ Naijiria' jẹ eyi ti ko bojumu to, nitori ofin to wa fun igun kan ni.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Lateef Adedimeji: Owó wa kò bá máa jóná ṣùgbọ́n aàyè ọpẹ́ ń yọ fún wa Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Lateef Adedimeji: Owó wa kò bá máa jóná ṣùgbọ́n aàyè ọpẹ́ ń yọ fún wa 19 Ògún 2019 Orọ aṣiwere ló n yatọ, bakan naa ni ọrọ ọlọgbọn awọn oṣere yii ri lori wahala to rọ mọ ṣiṣe sinima.
Ẹni tí ó ní wárápá bàbá mi wo wárápá fún un, ẹni tí ó ní sòbìyà bàbá mi wo sòbìyà rẹ̀ sàn, ọ̀kẹ́ àìmoye àwọn adẹ́tẹ̀ ni òun sì sọ di gbajúmọ̀ nínúu ilé wa.
A gbọ́ pe Mavrodi, tíí se ẹni ọ̀dún méjìlélọ́gọ́ta ni wọ́n gbé dìgbà-dìgbà lọ sílé iwòsàn nírọ̀lẹ́ ọjọ́ karùnúndínlọ́gbọ̀n osù kẹta nítorí àyà tó ń roó, àmọ́ tó gbẹ̀mí mì lẹ́yìn wákàtí díẹ̀ tó délé ìwòsàn.
"Pari pari ẹ, ajọ INEC naa ni ""a o gbe igbesẹ ti yoo kasẹ ohun gbogbo nilẹ lonii""."
Ninu atẹjade rẹ fun ọsẹ kẹsan ninu ọdun lo ti gbe eyi jade.
Gomina Ambode so pe “Ofin egbe fi ilana sile boya lati yan awon oludije tabi ki won dibo yan oludije won, ohun to se pataki ni ki a je ki awon omo-egbe lowo ninu eto ijọba tiwa-n-tiwa.
EFCC: A ó ri dájú pé Diezani padà wálé láti jẹ́jọ́ ìwa jẹgúdújẹrá
Ni bayii, jijawe olubori ohun lo mu ki orile-ede Belgium bo si ori oke tente tabili ipele keje(Group G).
Igbimọ Aṣofin Ipinlẹ Eko mẹnu ba bi ijamba yii, paapaa eyi to waye lọjọ
Ogbeni Suleiman wa ro, gomina Aregbesola lati pese ero apoti kulubu isaworan naa fun awon ara-ilu, paapajulo awon alaini, ni ona lati je kan lanfani lati mo ohun to n lo layika won jakejado.
kí ẹ sì fi kọ́ àwọn ọmọ yín dáradára.
Ugbochukwu Michael: Ààrùn kòkòrò HIV kìí ṣe ìdájọ ikú Olorì Aláàfín tẹ́lẹ̀, Anuoluwapo Adeyemi gba àmì ẹ̀yẹ lórí ipa tó kó nínú oge ṣíṣe Gbajugbaja òṣèré ''Toromagbe'' nínú fíìmù ''Arelu'' ti jáde láyé Ṣé àwọn ìjayà ajaguntà ilẹ̀ òkèrè leè bá Nàìjíríà fòpin sí ìṣòro àbò?
Asoju Zarchi tun so pe, orile-ede Nigeria tun ni ajosepo eto oro-aje pelu orile-ede Iran, ati pe, ajosepo laarin orile-ede mejeeji ohun ti goke agba.
Ìdí nìyí tí wọ́n ṣe pe orúkọ ìlú náà ní Babeli, nítorí níbẹ̀ ni OLUWA ti da èdè gbogbo ayé rú, láti ibẹ̀ ni ó sì ti fọ́n wọn káàkiri gbogbo orílẹ̀ ayé.
Àwọn ọmọ ti Jokiṣani ni: Ṣeba ati Dedani.
Hesekaya a máa fa ẹran kalẹ̀ ninu agbo ẹran rẹ̀ fún ẹbọ sísun ti àárọ̀ ati ti àṣáálẹ́, ati fún ẹbọ ọjọ́ ìsinmi, ẹbọ oṣù tuntun ati àwọn ẹbọ mìíràn gẹ́gẹ́ bí òfin OLUWA.
ile-ise ti bẹrẹ isẹ wọn ni  pẹrẹu.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, #NGACMR:Ohùn tí àwọn alatilẹyin Super Eagles sọ lẹyìn tí Nàìjíríà borí Cameroon Hany Abou-Rida kede ikọwefipo rẹ silẹ pẹlu ileri pe oun ati awọn alaṣẹ EFA gbogbo lawọn jọ n lọ ni.
Ẹni kan to soju rẹ koro to wa ni agbo ti Oluwo fi ẹsun kan olori ẹsọ naa wipe itara r ti pọ ju to se ndẹru bolẹ wipe yoo ti Oluwo bi ko ba yago fun Ọọni lati kọja.
Ẹ fọn fèrè ní Gibea, ẹ fọn fèrè ogun ní Rama, ẹ pariwo ogun ní Betafeni, ogun dé o, ẹ̀yin ará Bẹnjamini!
Mo bá ra oko náà lọ́wọ́ Hanameli ọmọ arakunrin baba mi, mo sì wọn fadaka ṣekeli mẹtadinlogun fún un.
Ìtàn Mánigbàgbé: £100, tíí ṣe ₦42,150 àsìkò yìí, nìjọba fun Taiwo Akinkunmi lówó iṣẹ́ lọ́dún 1959
    Nígbà ti ọkùnrín náà dákẹ́ ọ̀rọ̀ i sọ mo fèsì fún un, mo ní: “Ìrìnkèrindò, mo dúpẹ́ lọ́wọ́ rẹ gidigidi.
Ti ọmọde kan ba si dagba si ilẹ Yoruba, yoo ṣe ọkan lara awọn ere idaraya ti awọn ọmọde ma n ṣe, bi o tilẹ jẹ pe ọpọ wọn lo ti n wọọkun lọ lode oni.
Dino Melaye ti dìbò ní àtúndì ìdìbò tó ń lọ lọ́wọ́!
Láàrin iná yìí, mo rí àwọn ẹ̀dá alààyè mẹrin kan, wọ́n dàbí eniyan.
Ọlọ́pàá South Africa rí ẹ̀wọ̀n ọgbọ̀n ọdún re torí ikú ọmọ Nàìjíríà Àwọn ìmúra málegbàgbé Dino Melaye níle aṣòfin àgbà Erin mẹ́fa wó níbi tí wọ́n ti fẹ́ dóòlà ẹ̀mí ara wọn Àwọn agbébọn pa ènìyàn mẹ́rinlá lásìkò ìjọsìn Èso Apple tuntun tí ẹ lè fi pamọ́ fún ọdún kan ti wọ ọjà Ohun ti oṣiṣẹ ajọ ẹlẹwọn kan nibẹ ti a fi orukọ bo laṣiri ṣalaye ni pe ina ọba to ṣa dede lagbara lori awọn waya ina kan lọgba ẹwọn naa lo ṣokunfa iṣẹlẹ buruku ọhun.
"O tun kopa ninu awọn ere agbelewo EbonyLife ati ""Desperate Housewives"" Oríṣun àwòrán, others Michael Efe Ejeba: Oloriirelọdun 2017 O le ni ọdun mẹwaa lẹyin ti wọn se apa kinni, ki wọn to ṣe apa keji ti wọn wa bẹrẹ si ni pee ni Big Brother Naija."
Ni ere bọọlu gbigba atawọn ere idaraya miran, ọpọ igba ni ọga ati ẹni to ti figbakan ri jẹ ọmọṣẹ rẹ ni ere idaraya maa n pada wa figagbaga.
Akẹgbẹ Ronaldo ninu ẹgbẹ agbabọọlu orilẹede Portugal, Jose Fonte lo sọrọ yii nipa ẹlẹsẹ ayo, Ronaldo to wa pẹlu ikọ Juventus bayii.
Àwọn ìdílé àwọn akọ̀wé tí wọn ń gbé Jabesi nìyí: àwọn ará Tirati, Ṣimeati, ati Sukati.
Ẹsita wá sọ fún ọba pé eniyan òun ni Modekai.
Nígbà tí Saulu rí Dafidi tí ó ń lọ bá Goliati jà, ó bèèrè lọ́wọ́ Abineri, olórí ogun rẹ̀ pé, “Ọmọ ta ni ọmọkunrin yìí?
''Ju gbogbo rẹ lọ, ebi n pa araalu ni Naijiria latari bi ọrọ aje orilẹede yii ti dẹnu kọlẹ,'' Fayemi lo sọ bẹẹ.
Marcelo Oríṣun àwòrán, Getty Images Awọn agbablu aarin to pegede 1.
Bakan naa ni awọn kan tun fi ara pa.
Ìwà ìlu-ni ní jìbìtì lórí ìtàkùn àgbáyé, tí àwọn kan tún n pè ní 'yahoo-yahoo' tàbí 419, kìí ṣe tuntun ní Nàìjíríà, bí ó tilẹ̀ jẹ́ wí pé ìwà ọ̀daràn ni.
Bo tilẹ lẹ jẹ wi pe ẹẹkan lọdun ni irinajo naa yoo maa waye, ireti wa wi pe awọn onikarakata to n bẹ ni agbegbe naa yoo maa jẹ ere gọboi lasiko ti irinajo naa ba n waye.
4 Àti èyí gẹ́gẹ́bí oore ọ̀fẹ́ ti Olúwa àti Olùgbàlà wa Jésù Krístì, ẹnití gbogbo ògo jẹ́ tirẹ̀, nísisìyí àti títí lái.
Ohun to máa n mú inú rẹ̀ dùn jùlọ ni pé, ó fẹ̀ràn láti máa kọrin fún àbúrò rẹ̀.
Aarẹ Muhammadu Buhari naa ṣe ifilọlẹ ipolongo rẹ nile ijọba labuja lọjọ aiku pẹlu akori ti o pe ni 'Next Level' Saaju ifilọlẹ yi ni awọn amugbalẹgbẹ rẹ ti n fi orisirisi ipolongo sita loju opo Twitter sugbọn nigba ti yoo fi to ọwọ irọlẹ ni Bashir Ahmad oluranlowo fun Buhari lori ọrọ iroyin lori ayelujara fi aworan ipolongo yi sita.
Bẹẹ iṣẹ awọn agba ọjẹ to ti lọ sinmi pẹlu awọn baba nla wọn a maa tọ wọn lẹyin ti aye a si maa ka wọn sii.
Esi Aisha Buhari ati Fatima Daura gan funrarẹ lo tubọ fina mọ ọrọ naa, eyi to wa di ohun ti gbogbo awọn ọmọ Naijiria n gba bi ẹni n gba igba ọti, lati bii ọjọ diẹ sẹyin.
Lẹyin iṣẹlẹ naa, ni ọwọ awọn ọlọpa tẹ awọn afurasi kan to sọ pe Aarẹ ile aṣofin àgbà Naijiria, Bukọla Saraki ni awọn n ṣiṣẹ fun, botilẹ jẹ wi pe iwadi kankan ko ti i fi mulẹ pe lootọ Saraki ni wọn n ṣiṣẹ fun.
Ni bayii to tun je pe , eto idibo odun 2019 ti n sunmo etile.
Eyi lo mu ki wọn beere fun iyawo baba oun to ṣẹṣẹ bimọ ni ọsẹ meji sẹyin.
Wo àwọn èèkàn, ìlúmọ̀ọ́ka olórin tó ṣàbẹ̀wò sí ijọ Celestial Church ti Genesis Global A kò tíì lè sọ pé ọmọ Ọba tuntun ni yóò jẹ Ooni lọ́jọ́ iwájú - Elebuibọn Ọkùnrin tó pe ìyàwó rẹ̀ lájẹ̀ẹ́ tì í mọ́lé fọ́dún mẹ́rin, fún un lóyún nígbà mẹ́ta!
Gbogbo Israẹli láti Dani dé Beeriṣeba, ni wọ́n mọ̀ pé wolii OLUWA ni Samuẹli nítòótọ́.
Nítorí náà, OLUWA àwọn ọmọ ogun yóo rán àìsàn apanirunsí ààrin àwọn akọni ọmọ ogun rẹ̀.
Igbimọ yii yoo ni agbara lati
 wón wá ilè sí èhìn odi ìlú , wón sì ń pe ibè ní ilè-ekùú .
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Funmi Adewara: Tele Medicine' ní a fi ń ṣàyẹ̀wò èèyàn ìdá ọgọtá láti dènà ìtànkálẹ̀ Covid Bákan náà ni àṣẹ yìí yóò kan àwọn oní físàH-2B, eyí ni àwọn òṣìṣẹ ìgbà dé ìgbà tó fi mọ́ àwọn tó ń ṣiṣẹ nílé ìtura àti ibi ìgbáfẹ́, yàtọ̀ sí àwọn tó ń ṣiṣẹ́ àgbẹ̀, àti àwọn tó wà ni ẹ̀ka ètò ìlera.
Ira ati Garebu, àwọn mejeeji jẹ́ ará Itiri; 
Gbajabiamila kéde èróńgbà rẹ̀ láti jẹ adarí ilé aṣojú ṣòfin l'Abuja #Mothersday2019: Àwọn ìpèníjà obìnrin láwùjọ 'Fashọla, o ò dẹ̀ bẹ̀rù Ọlọ́run!
Àwọn kan lọ sọ fún Tamari pé baba ọkọ rẹ̀ ń lọ sí Timna láti rẹ́ irun aguntan rẹ̀.
Awon wonyi mo iyi eto ijọba tiwa-n-tiwa , nitori naa, won ko ni da si eto ijọba tiwa-n-tiwa orile ede Naijria to wa ni abẹ ominira tirẹ.
Awọn gomina ti wọn bura fun ni awọn ipinlẹ wọn naa ṣe awọn ileri kan fawọn ara ilu ni eyi to maa mu ki ọsan so didun ti wọn ba muu ṣẹ.
Awon to tun soro nibi ipade naa ni minista fun okowo ati akowe agba fun ile ise ijoba apapo to n risi eto isuna ati erongab ilana, Samson Adewale atawon miran.
Sisọ ede Yoruba di ofin nipinlẹ Eko
DSS gbé olùrànlọ́wọ́ Aisha Buhari tì mọ́lé lórí N2.
Bíótilẹ̀jẹ́pé èrò wọn ò tí ì máa rinlẹ̀, Olórin Angola, Gill Slows Allen Russell náà sọ̀rọ̀;
Femi Odugbemi, omo Naijiria to n dari ere ati fiimu agbelewo ni won ti yan pe ko di okan lara awon igbimo ti yoo maa dibo ni Academy of Motion Picture Arts and Sciences nile America.
O ni oun ṣe tan lati ṣe ohun to yẹ lai fi akoko ṣofo ni kete ti igbimọ naa ba ti fi esi wọn ranṣe.
Ajọ NAFDAC wa fi asiko yii kesi awọn apoogun lati ṣiṣẹ karakara lori ati wa ọna abayọ si arun Coronavirus ni Naijiria, ati wi pe awọn ṣetan lati ṣe ayẹwo awọn oogun ti wọn ba ṣe labẹle.
Alákòóso kọ̀ọ̀kan níí máa tọ́jú nǹkan jíjẹ tí Solomoni ọba ń lò fún ara rẹ̀ ati fún gbogbo àwọn tí ń jẹun ní ààfin rẹ̀; alákòóso kọ̀ọ̀kan sì ní oṣù tí ó gbọdọ̀ pèsè nǹkan jíjẹ, láìjẹ́ kí ohunkohun dín ninu ohun tí ọba nílò.
Ọgbọ́n àlùmọ̀kọ́rọ́yí ni a ti fi pète.
A ṣé báyìí nikú burú tó
O tun pin agbara ti ẹmi fun awọn kan ninu ẹgbẹ oṣelu kan to ni pe ki wọn gba agbara lati bẹrẹ iṣẹ Ẹ̀kọ́ ọ̀fẹ́, ètò ilera ọ̀fẹ́ àti iná ọba ló jẹ wá lógún- ọmọ Nàìjíríà Nàìjíríà bí ìkókó 26, 039 lónìí ọjọ́ kíní, oṣù kínií, ọdún 2020- UNICEF Ó ti tán fún mí lọ́dún 2023- Ààrẹ Muhammadu Buhari Idi ti EFCC ṣe mu Sheu Sani S'ahamọ.
BBC ni o ṣeeṣe ki ipinnu May nijakule ti wọn ko ri iru rẹ ri ni ọgọrun un ọdun.
Tú ibinu rẹ sórí àwọn orílẹ̀-èdè tí kò mọ̀ ọ́,ati orí àwọn ìjọba tí kò sìn ọ́.
Àfi gbolohun kan tí mo sọ nígbà tí mo dúró láàrin wọn, pé, ‘Ìdí tí a fi mú mi wá fún ìdájọ́ níwájú yín lónìí ni pé mo ní igbagbọ pé àwọn òkú yóo jinde.
Awọn eniyan tẹ ara wọn pa ni Papa isere Ṣugbọn iwe ti ajọ EFCC fi pe e l'ẹjọ fi ẹsun kan Ọgbẹni Ahmadu, ati awọn miran pe, wọn seto igbani sisẹ to yọri si iku awọn ọmọ Naijiria.
A ni akosile idagbasoke olodoodun ni odun 2017, lati iko0.
Sanwo-Olu fidi ọrọ yi mulẹ ninu ifọrọwerọ pẹlu ileeṣẹ iroyin CNN lọjọ Aje.
"Tí ẹ ba ni ìgbáyawo ni òpin ọ̀sẹ̀ yìí, ẹ wá gbé àkàrà oyinbo yìí"" Tí ẹ ò bá gbàgbé àwọn ọlọpàá yabo ibi ayẹyẹ ọjọ́ ìbí Bobrisky lọ́jọ́ Satide tí ayẹyẹ ọjọ ìbí náà ko fi wáye mọ Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!"
Òṣèré tíátà Yorùbá mẹ́ta gbàmì ẹ̀yẹ pé wọ́n pegedé Kí ni àwọn ayédèrú ìmọ̀ràn ìwòsàn tó rọ̀ mọ́ àrùn coronavirus?
Mo lé wọn jáde fún yín, mo sì fi ilẹ̀ wọn fun yín.
Sheffield faṣọ iyì ya mọ́ Chelsea lára lọ́nà ìrìnàjò sí Champions League Wo agbábọ́ọ̀lù Super Eagles Nàìjíríà àkọ́kọ́ tó lùgbàdì coronavirus Amọṣa, ibi aye fojusi ọna ko gba ibẹ lọrọ ja si fun awọn agbabọọlu Arsenal atawọn ololufẹ ikọ naa.
Ondo election 2020: Àwọn ara ìpínlẹ̀ Ondo ránṣẹ́ sí Akeredolu ohun ti wọ́n ń retí ní báyìí
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Oronpoto Animation: Akin Alabi ní kò dára bí eré aláwòrán fáwọn ọmọdé ṣe jẹ́ aláwọ̀ funfun Tani Baba Ayo Fasanmi to doloogbe yii?
Leyin naa, ni won bere igbese alaafia lati dekun ija olojo pipe to maa n sele laarin orile ede mejeeji naa.
 Ọ ̀ pọ ̀ lọpọ ̀ ènìyàn ló máa ń dá Ọgbọ ́ n jọ fún ìdàgbàsókè ìlú .
Abọ ipade ASUU lọjọ kejilelogun, oṣu kọkanla: Oríṣun àwòrán, Twitter ASUU kọ̀ láti fopin si iyanṣẹlodi ti wọn gunle.
Iwe yii lo tun ti sọ nipa itan iwasẹ to da Yoruba silẹ nibi ti Akitoye ti tumọ Ile Ifẹ nibi ti ojumọ ti n mọ waye.
INTERACTIVE Tap or click to interact Moshood Olalekan Adeoti Action Democratic Party (ADP) < Padà lọ sí ọ̀dọ̀ Olùdíje Kíni ọjọ́ ìbí yin?
" Ni ibi ipolongo naa ni West ti sọ ero rẹ lori bi o ṣe tako oyun ṣiṣẹ, bi o ti lẹ jẹpẹ awọn eniyan ko gba ipolongo rẹ gbọ.
OLUWA fún Dafidi ní ìṣẹ́gun ní gbogbo ibi tí ó lọ.
OLUWA kò ní fi olódodo lé e lọ́wọ́,tabi kí ó jẹ́ kí á dá olódodo lẹ́bi ní ilé ẹjọ́.
Àwọn aposteli mejila bá pe àwọn ọmọ-ẹ̀yìn Jesu yòókù jọ, wọ́n ní, “Kò yẹ kí á fi iṣẹ́ iwaasu ọ̀rọ̀ Ọlọrun sílẹ̀, kí á máa ṣe ètò oúnjẹ.
”Wayi o, asofin Ayo da Silva tun menuba eka eto agbe ati awon eto miiran ti o wa nikawo re, ti yoo gbese fun awon eniyan ni igberiko, papaa julo awon agbe.
Eyi lo mu ki ijọba orile-ede Argentina ṣeto fun igba ọlọpaa ti yoo maa ṣọ iboji agbaọjẹ agbabọọlu tó lọ, Diego Armando Maradona.
Ladani, ọ̀kan ninu ìran Geriṣoni, ní àwọn ọmọkunrin tí wọ́n jẹ́ olórí ìdílé wọn, ọ̀kan ninu wọn ń jẹ́ Jehieli.
“Bí ẹnìkan bá kú lẹ́gbẹ̀ẹ́ rẹ̀ lójijì, tí ó sì ti ipa bẹ́ẹ̀ sọ orí rẹ̀ di aláìmọ́; yóo dúró fún ọjọ́ meje.
Àwọn ìlú wọnyi wà lẹ́bàá ààlà ilẹ̀ àwọn ará Manase: Beti Ṣani, Taanaki, Megido, Dori ati gbogbo ìlú tí ó yí wọn ká.
Wọ́n bá bi í pé, “Ta ló mú ọ wá síhìn-ín?
Awọn oluwọde naa kọkọ lọ si agbegbe Panseke niluu Abeokuta lati ibi ti wọn lọ kaakiri titi wọn fi de aafin Alake ti ilẹ Ẹgba, Oba Adedotun Gbadebo.
Ṣugbọn ni oṣu keje ọdun 2017, ijọba apapọ fofin de iru awọn epo ti ko dara wọn yii nitori ọpọlọpọ iwọn sọ́fọ̀ (sulfur) to wa ninu rẹ.
 Àwọn oríṣi jẹnotaipu hcv méje pàtàkì ní n bẹ .
Ẹfunsetan Aniwura, obìnrin tó ju ọkùnrin lọ Ọ̀rọ̀ǹpọ̀tọ̀niyùn, Aláàfin obìnrin àkọ́kọ́ rèé, tó ní nǹkan ọkùnrin Taiwo Akinkunmi, ọmọ Ibadan tó ya àsìá Nàíjíríà Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí kan sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
Ọpọlọpọ obinrin lo ti wa si gbagba ǹi awọn oju opo ikansiraẹni pẹlu #MeToo movement lati ọdun 2017, lati tu asiri gbogbo bi Harvey Weinstein ṣe n fipa ba awọn obinrin lopọ.
“Àwọn tí wọ́n jẹ́ aláìmọ́ fun yín ninu gbogbo àwọn ohun tí ń rìn lórí ilẹ̀ ni: asín, ati èkúté, ati àwọn oríṣìíríṣìí aláǹgbá ńlá, 
Kò sì sí àní-àní pé ẹni tí Ọlọ́run dá, tí kò ṣe fi ara wé ni ọba Olateru-Olagbegi kejì, tí ìdílé rẹ si wa lara ìdílé tó tóbi ju to tun kàwé julọ n'ilu Ọwọ.
Oríṣun àwòrán, @Toomas Àkọlé àwòrán, Estonia pàdánù owó gọbọi látàri Eku tó gba ìjọba ní Estonia Loru mọju ni wọn ti tete paarọ waya oni mita ọọdunrun ni agbegbe Harju ni olu ilu Tallinna ti wọn si ti bẹrẹ iṣẹ atunṣe awọn Kaido Plovits to jẹ ọga agba fun ajọ RIA ṣalaye pe ko pẹ ti wọn pari atunse yii ni kia ni eyi ti ohun gbogbo dẹ ti bẹrẹ pada.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Àwọn òbí kan tilẹ̀ tún maa n ra ìwé ẹ̀rí fún ọmọ wọn.
Nigba ti wọn fẹsun naa kan Santes, ẹni ọdun mọkandinlọgbọn, lọdun 2016, asoju rẹ ni atamatase agbabọọlu naa ti bọwọ patapata"" fun ofin, to si tun ti kede owo to wọle fun-un ninu adehun ẹtọ si aworan rẹ to se."
ni ẹgbẹ̀ta  lo ti padanu ẹmi
Johanu ọmọ Sakaraya gbọ́ ọ̀rọ̀ Ọlọrun ní aṣálẹ̀ tí ó wà.
"Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Pistachio Green Puppy: Àwọn ẹgbẹ́ rẹ̀ jẹ́ aláwọ̀ funfun, tí òun sì jẹ́ aláwọ̀ ewé ""Mo sọ asọtẹlẹ pe aarẹ ilẹ America yoo sọ awọn ọrọ ti ko tọ ọ, lasiko ipolongo ibo."
Oríṣun àwòrán, @lasemasocial Ajọ to n mojuto iṣẹlẹ pajawiri ni ilu Eko, LASSEMA ṣalaye pe skan lara ile to wo naa wa ni agbegbe Abule ẹgba, ti omiran si tun wo lulẹ lagbegbe Ladipo Busstop, ni Oshodi.
Ṣomeri, arakunrin Jafileti, bí ọmọkunrin mẹta: Roga, Jehuba ati Aramu.
Ile iṣẹ eleto ina ọba nilẹ Ghana, Ghana Grid Company(GRIDCo) sọ pe aisina lawọn agbegbe kan lorileede Ghana ko ṣẹyin apọju ina to pada si ori opo nilẹ naa ti o si mu ki awọn ẹrọ amunawa dakẹ iṣẹ.
Ninu eyi ti a o ri apẹrẹ pe o di ootọ ni iranwọ iṣẹ kikọ ti iyawo Gomina arabinrin Olufolake Abdulrazaq ṣe fun yi jẹ.
Kò sí ìyà oró n Muṣin mọ́ páà
O gba a nimọran pe ki ijọba maa ko owo to yẹ ki ọ̀dọ́ kọọkan o gba ninu eto isinru ilu fun un to ba ti n kẹkọ jade nileewe giga.
Ti àwọn tí wọ́n kú ikú ogun sàn ju àwọn tí wọ́n kú ikú ebi lọ,àwọn tí ebi pa joró dójú ikú,nítorí àìsí oúnjẹ ninu oko.
Ejelonu ni, oun ti lọ wa pata ati kọmu ọmọbinrin naa nibi ti Otema ti fipa baa lo, ṣugbọn nigba ti oun ko ri wọn nibẹ, oun tun lọ wa ile afurasi naa ni Bariga, Ṣugbọn ko ri pata naa nibẹ pẹlu.
Olólùfẹ́ mi dàbí egbin,tabi ọ̀dọ́ akọ àgbọ̀nrín.
O sapejuwe eto ohun gege bi eyi ti o wa fun ojo-aye, pelu ogunlogo awon agbe ti won n kopa ninu eto naa jake-jado orile-ede Naijiria.
fun minisita fun ajo to n mojuto owo lorile ede Naijiria lati wa ọgbọ̀n bilionu ti won
" Oríṣun àwòrán, Agbowu Ọba Akinrọpo ni, se ni, Oluwo tun n sọ kaakiri pe igbesẹ ti awọn lọbalọba gbe naa ko kan oun tori oun si n jọba lọ ni, ti Oluwo ko si gba alaafia laaye lori aawọ naa, oun ko si lee gba ko fi iya jẹ oun gbe.
Jesu wí fún wọn pé, “Mo sọ fun yín pé èmi gan-an nìyí.
Awon ile-ise gbogbo lorile-ede Nigeria ti n koju ipenija latigba ti owo ori epo-robi ti wale ni odun 2014, eyi ti o sokunfa bi eto oro-aje se denu-kole, ti o si so awon ile-ise di onigbese.
Àwọn tí wọ́n ni ilẹ̀ yìí tẹ́lẹ̀ rí ni àwọn ará Hiti ati àwọn ará Amori, àwọn ará Kenaani ati àwọn ará Perisi, àwọn ará Hifi, ati àwọn ará Jebusi.
Ọ̀gọ̀ọ̀rọ̀ agbébọn lo wà nílúù Kishi, National Park - Gani Adams figbe ta O ṣe idasilẹ ilana irinajo Hajj ti Naijiria n lo Lọdun 1990, ijọba apapọ labẹ iṣakoso Ọgagun Ibrahim Babangida yan Ọba Adeyẹmi Olayiwola gẹgẹ bi Amiru Hajj, lati dari awọn musulumi ni gbogbo ipinlẹ mọkanlelogun to wa ni Naijiria nigba naa, fun irinajo Hajj.
Premier League: Ta ni yóò gba Premier League láàrin Man City àti Liverpool?
Bí Jesu ti gbé ojú sókè ó rí àwọn ọlọ́rọ̀ bí wọ́n ti ń dá owó ọrẹ wọn sinu àpótí ìṣúra.
A ti kọwé sí ìjọba àpapò làti pe agbaṣèṣe odò Asa padà- Gomina Kwara Kò sí ìdí láti tọrọ àforíjì lọ́wọ́ Nàìjíríà - Alákòso Johannesburg Folashade Yemi-Esan, ohun tó yẹ kóo mọ̀ nípa adarí ẹ̀ka òṣìṣẹ́ ọba tuntun Ọkọ Toyin Abraham pẹ́ ọ̀rọ̀ sọ lórí aáwọ̀ láàrin ìyàwó rẹ̀ àti Lizzy Anjorin Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Naijiria fi ìgbájú mẹ́ta lé Cameroon kúrò ní AFCON ‘Gómìnà Oyetọla, ẹ má fojú àìda wò wá ní Ẹdẹ, ẹ tún òpópónà wa tó bàjẹ́ ṣe.
Ọjọ́ kẹsàn án ni ti ọkùnrin.
O ni inu ifẹsẹwọnsẹ ipele ẹlẹni mẹrindinlogun ọjọ Aje, ninu idije ife ẹyẹ agbaye FIFA U-20 lorilẹ-ede Poland ni yoo ti ṣẹlẹ.
Sé ọlọ́pàá tasẹ̀ àgẹ̀rẹ̀ tàbí fìyà jẹ ọ́ láìtọ́, wo bó ṣe fi ẹjọ́ rẹ̀ ṣùn l‘Eko Gbogbo ìgbésẹ̀ Aláàfin láti jí mi gbé ló já sí pàbó, n kò le panumọ́ - Olori Anu Ìdàlúrú gbòde, ìjọba kéde ìṣéde torí nǹkan ọ̀pọ̀ ọkùnrin tó ń pòórá Ṣé lóòtọ́ ni olorì méjì míì tún ti kúrò láàfin Oyo?
Gẹ́gẹ́ bímo ṣe máa ń sọ, èmi ni olùṣọ́ fún àwa tó kù."
Lẹyin rẹ ni ti Barakat Bello ti awọn kọlọrọsi mii tun ṣekupa lẹyin ti wọn fipa baa lopọ tan ni ilu Ibadan.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Bí àwọn adarí ìjọba ṣe ń kó Coronavirus, ń kọ wá lóminú - Ìjọba àpapọ̀ Àkójọ́pọ̀ àwòrán rèé lórí bí ìwọlé akẹ́kọ̀ọ́ ṣe lọ sí ní Oyo Bí Hushpuppi ṣe tiraka rèé l‘Eko, kí ọlà ‘òjijì’ tó dé Akẹ́kọ̀ọ́ wọlé padà, ìjọba Oyo kò pèsè ìbòmú lòdì sí ìlérí rẹ̀ Ẹ wo bí ọ̀rọ̀ òṣèlú, ẹ̀sìn àti ẹ̀yà ṣe fa ogun abẹ́lé Biafra Kàkà k‘éwé àgbọn dẹ̀ lágbo òṣèlú l‘Ondo, akọ̀wé ìjọba tún kọ̀wé fipò sílẹ̀ Ẹ wo bí ọ̀rọ̀ òṣèlú, ẹ̀sìn àti ẹ̀yà ṣe fa ogun abẹ́lé Biafra Awọn dokita naa wa n fi ika gun gomina Rotimi Akeredolu nimu lori ọwọ yẹpẹrẹ ti wọn lo fi mu itankalẹ arun naa.
Bí ó bá tọ́ kí n jẹ yín níyà, n óo jẹ yín níyà,kìí ṣe pé n óo fi yín sílẹ̀ láìjẹ yín níyà.
Ọkunrin tí ó bá ń gbadura tabi tí ó bá ń waasu tí ó bo orí fi àbùkù kan orí rẹ̀.
 wọ ́ n ṣèdàá orúkọ ìlú Ìjẹ ̀ bú-Òde láti ara àpapọ ̀ orúkọ ajẹ ́ bu àti olóde tí ó jẹ ́ àtèté tó gbajúgbajà .
Botilẹjẹ wi pe iye awọn to ku ko ti i fojuhan bayii, oṣiṣẹ ijọba kan sọ fun BBC pe o le ni aadọta eniyan to ti ku, ti ọpọlọpọ si farapa.
Bo tilẹ je pe awọn akẹkọọ nile iwe girama to wa ni ipele kẹta akọkọ yoo tẹsiwaju si ipele kinni ẹlẹẹkeji lai ṣe idanwo, wọn yoo ṣe idanwo BECE ninu oṣu Kẹwaa ọdun 2020.
Ọlọ́kadà Jigawa: Ìjọba Eko ti wá mọ́lé lọ́nà àìtọ́, a fẹ́ owó ‘gbà má bínú’
ní àkókò tí àwọn ọmọ ogun ọba Babiloni gbógun ti Jerusalẹmu ati Lakiṣi ati Aseka, nítorí pé àwọn nìkan ni wọ́n ṣẹ́kù ninu àwọn ìlú olódi Juda.
Igbesẹ Keji: Abẹnugan Ile Aṣofin gbọdọ fi iwe ẹsun ranṣẹ si Igbakeji Gomina laarin ọjọ meje, yoo si fi ranṣẹ si awọn ọmọ Ile Aṣofin pẹlu.
Ìyẹn láàrin àwa ọmọ ènìyàn àti ẹranko gbogbo – ẹranko si ewéko, eweko sí ènìyàn, àti bẹ́ẹ̀ bẹ́ẹ̀ lọ.
Arọwa yi waye nigba ti Makinde ati awọn ikọ rẹ ṣabẹwo si Obasanjo nilu Abeokuta.
Dokita Chidinma wa rọ awọn eniyan lati ma a se ayẹwo ara wọn ni ẹẹkan laarin oṣu mẹfa, ki wọn ba le mọ ipo ti ẹya ara wọn wa.
Jesu sọ ọ̀rọ̀ yìí nígbà tí ó ń kọ́ àwọn eniyan ninu ilé ìpàdé wọn ní Kapanaumu.
Afeez Fashola ti gbogbo eeyan mọ si Naira Marley fi lede loju opo Twitter rẹ pe oun yoo dari iwde ifẹhonuhan wọọrọwọ lọjọ Aje ọsẹ yii to si sọ fun awọn ololufẹ rẹ ki wọn darapọ.
Ó súre fún Sebuluni ati fún Isakari, ó ní:“Máa yọ̀ bí o ti ń jáde lọ, ìwọ Sebuluni,sì máa yọ̀ ninu ilé rẹ, ìwọ Isakari.
Nítorí èyí, ilẹ̀ yóo ṣọ̀fọ̀,ojú ọ̀run yóo sì ṣókùnkùn.
Joṣua bá ranṣẹ, wọ́n sáré lọ wo inú àgọ́ rẹ̀, wọ́n bá àwọn nǹkan náà ní ibi tí ó bò wọ́n mọ́, ó fi fadaka tẹ́lẹ̀.
gbaruku ti adinku oja ti won n gbe wole lati oke okun wa si orile ede Naijiria.
Ife oluwa Ogundipe lo lọ kawe gboye imọ ijinlẹ keji lorilẹ-ede Faranse, lo ba kiyesi pe ko wu oun lati fi kẹkẹ wiwa silẹ lẹyin ọdun kan ti o ti n wa a kiri.
O ti gba ọ̀pá àṣẹ lọ́wọ́ rẹ̀;o sì ti wó ìtẹ́ rẹ̀ palẹ̀.
Oríṣun àwòrán, Lagos state Àkọlé àwòrán, Samuel Okwaraji: Kíni ẹ̀yín mọ nípa akọni yìí?
Àwọn tí ọba rán bá bẹ̀rẹ̀ sí lépa àwọn ọkunrin náà lọ ní ọ̀nà odò Jọdani, títí dé ibi tí ọ̀nà ti rékọjá odò náà, bí àwọn tí ọba rán ti jáde ní ìlú, bẹ́ẹ̀ ni wọ́n ti ìlẹ̀kùn odi ìlú náà.
Ìpínlẹ̀ Oyo, Eko àti Ogun fọnmú lórí ìlànà pínpín abẹ́rẹ́ àjẹsára Covid-19 Dókítà tó lé ní ogún ní Covid-19 nílé ìwòsàn Fásitì Ilorin - Álága ẹgbẹ́ dókítà Seyi Makinde ní ọwọ́jà Covid-19 kò rinlẹ̀ bí NCDC se kéde èèyàn 120 tó ní àrùn lọ́jọ́ kan l‘Oyo Èèyàn mẹ́sàn án kú, 1,398 míràn tún lùgbàdì Coronavirus ní Nàìjíria Ìdí tí àwọn èèyàn kan kò fí le ni àrùn Coronavirus Ọmọ olowo ati ọlọla ni Bolu Akin-Olugbade, toun naa si sisẹ lati lowo, bi igbesi aye rẹ si se lọ ree.
Farada ìpín tìrẹ ninu ìṣòro gẹ́gẹ́ bí ọmọ-ogun Kristi Jesu.
ẹkun idibo Badagry kinni, Aṣofin Ibrahim Layọde ti ẹgbẹ oṣelu APC ni esi
Nairijia jawale ninu ipo ate tuntun ajo FIFA, eyi ti igbimo to n ri si boolu afesegba lagbaye gbe jade lojo-Bo(Thursday).
Wo àwọn gómìnà Nàìjíríà tó tí lùgbàdì Covid-19 àti ipò tí ìlera wọ́n wà Ìjọba ilẹ̀ Canada bẹ̀rẹ̀ iṣẹ́ lórí fọ́ọ̀mù àwọn tó fẹ lọ sí orílẹ̀-èdè náà Pásítọ̀ tó bá Ọlọ́run jiyàn kó tó di Ààrẹ Baba Suwe bọ́ lọ́wọ́ àìsàn, ó bẹ̀rẹ̀ tíátà padà O yẹ ki ètò náà bẹ̀rẹ̀ nínú oṣù kẹwàá ọdún yìí ṣùgbọ́n èdè àìyedè to wáye láàrin mínísítà fún ètò iṣẹ́ Festus Keyamo àti àwọn ọmọ ilé ìgbìmọ̀ aṣòfin ní àná ọjọ́ iṣẹ́gun jọ bi ẹni pé ó ti pagidinà ètò náà.
Ó sì bi mí pé, “Ìwọ ọmọ eniyan, ǹjẹ́ o rí ohun tí wọn ń ṣe yìí?
Ibojì náà ni ò fi ṣe ilé.
Awọn ọlọkada naa ni itimọle awọn tako ofin Naijiria to fun awọn ọmọ bibi orilẹede yii ni anfaani lati lọ lati ipinlẹ kan si omiran, lai si ẹru tabi ipalara.
Delila tún sọ fún un pé, “Báwo ni o ṣe lè wí pé o nífẹ̀ẹ́ mí, nígbà tí ọkàn rẹ kò sí lọ́dọ̀ mi.
Wọ́n lọ sọ́dọ̀ Hilikaya, olórí alufaa, wọ́n kó owó tí àwọn eniyan mú wá sí ilé OLUWA fún un, tí àwọn Lefi tí wọn ń ṣọ́ ẹnu ọ̀nà gbà lọ́wọ́ àwọn ẹ̀yà Manase, ati Efuraimu ati gbogbo àwọn ọmọ Israẹli yòókù, ati lọ́wọ́ àwọn tí wọn ń gbé Juda, Bẹnjamini ati Jerusalẹmu.
Ṣugbọn ko ni nkankan ṣe pẹlu opo ayelujara fun iwe iroyin naa ti oju opo gangan jẹ https://www.
Democratic Party, PDP  ni iye ibo to pọju
Nibi pẹnariti ri gan ni Naijiria ti fagba han South Africa pẹlu ami ayo mẹrin si mẹta 4-2.
 Àwọn ọmọ ilé-ìwé gan-an gbọdọ ̀ mọ ̀ pé ká sètò ìnáwó ẹni kì í sohun tó burúkú bí ti í wù kó mọ .
O tun jẹyọ pe awọn alakatakiti ẹsin n gbeero lati lo anfaani bi eto abo ṣe ri, fi mu ki afojusun wọn wa si imuṣẹ.
Mo sì mọ̀ pé, iṣẹ́ mi pàtàkì ni la’ti máa kọ́ ìwà baálé mi, ki ń mọ nǹkan tí ó fẹ́ ki ń mọ nǹka tí kò fẹ́, ki n ṣe nǹkan tí o fẹ́, ki ń yàgò fún nǹkan tí kò fẹ́.
Àwọn ìjọ sìn wọ́n sọ́nà, wọ́n wá gba Fonike ati Samaria kọjá, wọ́n ń ròyìn gẹ́gẹ́ bí àwọn tí kì í ṣe Juu ṣe ń yipada di onigbagbọ.
Nigba ti yoo si fi pe ọdun mẹwaa, o ti di iyawo lọọdẹ ọkọ.
Sùgbọ́n òun kọ̀ lati fún wọ́n ni èsì títí di ẹ̀yìn oṣù kan.
Odunayo ni oun ko mọ pe arimọ awọn ni ere ranpẹ tawọn jọ ṣe ninu ṣọọbu lọ.
Kete ti o fi ikede yi sita lawọn eeyan ti n sọ ti ọkan wọn lori ikede yi.
“Ìwọ náà ronú wò,ṣé aláìṣẹ̀ kan ṣègbé rí?
Nígbá tí ó wí báyìí tán èmi náà dáhùn, mo ní, Mo ti ri wọn, wọ́n jọ ara wọn, wọ́n dàbí ìbejì láàárin gogbo àwọn igi ti ń bẹ lágbègbè ibẹ̀.
 síbẹ ̀ síbẹ ̀ , tropiduridae lè pàwọdà , àwọn ẹ ̀ yà kan náà sí ma ń ní àwọ ̀ ọ ̀ tọ ̀ tọ ̀ ní ibùgbé ọ ̀ tọ ̀ tọ ̀ , tí wọn a sì maa ṣe àfihan àwọ ̀ ọ ̀ tọ ̀ tọ ̀ .
Ojú rẹ̀ wá pọ́n wẹ̀ẹ̀ bí ẹrẹ iná.
Leyin ti Aare Emmanuel Macron se ipade pelu re ni aafin Elysee, Aare oun so pe, won yoo so arakunrin naa di omo orile-ede Faranse.
Àkọlé àwòrán, John ọmọ Fayẹmi sin ilẹ Naijiria ilẹ baba rẹ̀ gẹgẹ bii olukọni ni Police College to wa ni Ṣokoto lapa ariwa Naijiria.
”Wọ́n bá dáhùn pé, “Pa àlọ́ rẹ kí á gbọ́.
Mo tún rí i wí pé wọn kò fún àwọn ọmọ Lefi ní ẹ̀tọ́ wọn, tóbẹ́ẹ̀ tí àwọn ọmọ Lefi ati àwọn akọrin, tí wọn ń ṣe iṣẹ́ náà fi sá lọ sí oko wọn.
Ọba kọ ìmọ̀ràn àwọn àgbà, ó gbójú mọ́ wọn, 
Link Wo àwọn nkan tí o le ṣe gẹ́gẹ́ bi aláboyún lásìkò àjàkálẹ̀ ààrùn Covid-19 Coronavirus: Kíni àwọn àmì tuntun tó n fihàn?
Ẹ wo èyí tí ó bá sanra nínú wọn, ẹ pa á fún mi; oúnjẹ ni mo máa fi gbogbo wọn ṣe, ìparun ní ń gbẹ̀hìn apànìyàn, àwọn tí ń pa mí lọ́mọ dandan ni kí n máa pa wọ́n lọ́mọ, ọjọ́ kan ń bọ̀ tí ilẹ̀ yóò mọ́ bá àwọn tí ń lépa ọmọnìkejì, níwọ̀n ìgbà tí èmí mi bá wà láàyé, n kò ní í fi ojú rí ọmọ ènìyàn kí ọmọ ènìyàn lọ.
 Ṣùgbọ ́ n nígbà tí ẹ ̀ sìn àjòjì dé wọ ́ n bẹ ̀ rẹ ̀ si ń yi padà lati inú ẹ ̀ sìn ìbílẹ ̀ wọ ́ n sí ẹ ̀ sìn mùsùmùmí àti ẹ ̀ sìn kirisitẹni .
Kì í ṣe gbogbo àwọn tí ó jẹ́ ìran Abrahamu ni ọmọ rẹ̀ tòótọ́, nítorí bí Ìwé Mímọ́ ti wí, Ọlọrun sọ fún Abrahamu pé, “Àwọn ọmọ Isaaki nìkan ni a óo kà sí ìran fún ọ.
ninu  omo egbe oselu to kere julo gege bi
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Human Trafficking: Wọ́n fun mi ni omí ìmùlẹ̀ kí wọ́n to sọ fun mi pé iṣẹ́ aṣẹwo ni mo wá ṣe- Adeola 23 Sẹ́rẹ́ 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 24 Sẹ́rẹ́ 2020 Oríṣun àwòrán, others Àkọlé àwòrán, Ẹyin ni wọ́n fi n gba ìbále ẹlòmiran lára wa ki a to lọ pàde àwọn oníbara Arabinrin Adeola,(Kii se orukọ abisọ rẹ gangan) ti sọ itan bi wọn ṣe ta oun si oko ẹru fun ọọdunrun owo ilẹ okeere Cefas ti ilẹ Côte d'Ivoire.
Ẹsita ayaba dáhùn, ó ní, “Kabiyesi, bí mo bá rí ojurere rẹ, bí ó bá sì wù ọ́, dá ẹ̀mí mi ati ti àwọn eniyan mi sí.
" Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Ìgbà tí mo máa fi lajú sáyé padà, ọ̀fọ̀ ikú mi ní wọ́n ń kígbe' Kii ṣe ẹsẹ nikan ni Oluwatobi fi pa, ẹnu rẹ paapa là.
Àkọsílẹ̀ gbogbo nǹkan yòókù tí Hesekaya ṣe, ati iṣẹ́ rere rẹ̀, wà ninu ìwé ìran wolii Aisaya, ọmọ Amosi ati ninu ìwé ìtàn àwọn ọba Juda ati Israẹli.
Ẹni tó bá ń bínú kàn ń bínú lásán ni14 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Fídíò, Akomolede ati Asa lori BBC: Olùkọ́ Kikelomo Ogunboye tan ìmọ́lẹ̀ sí ìwà olè ọ̀gá ọlọ́pàá Audu gẹ́gẹ́ bí àwòkọ́ṣe àsìkò yìí8 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 World Aniti-Corruption day: Awolowo, Azikwe, Abacha àtàwọn olórí ìjọba tí aje ìwà ìjẹkújẹ ti ṣí mọ́ lórí rí ní Nàìjíríà14 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Ọlọpàá sọ pé ọkùnrin ti wọ́n yìn ni ìbọn náà to si kunibi iṣẹ̀lẹ̀ náà ni àwọn àdó olóro to dì mọ́ra.
wa rọ yin lati maa se rẹwẹsi ni ojuse wa, ti a o fi mu eto idagbasoke yii ,yoo
Ọga ọlọpaa lorilẹede Naijiria, Mohammed Adamu ti paṣẹ wi pe awọn ọlọpaa SARS ko gbọdọ kaakiri ilu mọ lati oni lọ.
Lekan kingkong lọmọ Yorùbá tó ń fi òwe dárà lẹ́yìn odi Níbo làwọn òṣèré apanilẹ́rìn ín wọ̀nyí tó pilẹ̀ sínima àgbéléwò Yorùbá wà?
Ahabu sọ fún Jehoṣafati pé, “Bí a ti ń lọ sógun yìí, n óo yí ara pada.
Mo ti rí ọmọ Jese ará Bẹtilẹhẹmu tí ó mọ hapu ta dáradára.
Lasiko abẹwo wọn si agbegbe Lekki Tollgate nibi ti wahala ti ṣẹlẹ laṣalẹ ọjọ Iṣẹgun ni minisita fun akanṣe iṣẹ, Babatunde Raji Fashola ṣadede ṣe awari ẹrọ ayaworan, kamẹra kan eleyi ti wọn ni o ṣeeṣe ko jẹ pe awọn eeyan kan lo fi sibẹ ṣaaju iṣẹlẹ naa.
“Nígbà tí ẹ bá dé ilẹ̀ tí OLUWA Ọlọrun yín fun yín, tí ẹ bá gbà á, tí ẹ sì ń gbé inú rẹ̀, tí ẹ bá wí nígbà náà pé, ‘A óo fi ẹnìkan jọba lórí wa gẹ́gẹ́ bí àwọn orílẹ̀-èdè yòókù tí wọ́n yí wa ká,’ 
Ọrọ yinyin ibọn pa awọn alawọ dudu ni orilẹ-ede America ti di nkan nla lasiko yii.
Ọwọ tẹ ikọ rẹ mẹrin, ti awọn ọlọpaa si ri ibọn AK 47 mẹrin gba lọwọ wọn.
gbọ́ adura wọn láti ibùgbé rẹ lọ́run, dáríjì wọ́n, dá wọn lóhùn, kí o sì san ẹ̀san fún olukuluku gẹ́gẹ́ bí iṣẹ́ rẹ̀, (nítorí ìwọ nìkan ni o mọ èrò ọkàn ọmọ eniyan); 
Se àsọtẹ́lẹ̀ rẹ, kó o sì pin-in pẹ̀lú àwọn ẹlòmíràn nípa lílo eré ìdárayá tuntun ti BBC.
O fikun-un pe, Obi ti kopa daradara ninu iko re nile okere ati iko agbaboolu Super Eagles.
Omisore jẹ igbákejì gómìnà ìpínlẹ̀ Ọṣun, Adebisi Akande láàrin ọdún 1999- 2003.
Lẹyin to ba ti yan orukọ kan, awọn cardinal to ku yoo sun mọ poopu tuntun lati fi ori balẹ fun un.
Ijọba naa ni o lodi si ofin fun ẹnikẹni to jẹ agbofinro, yala ọlọpaa ni tabi ọmọ ologun lati maa ṣe iṣẹ okada tabi wa kẹkẹ ẹlẹsẹ mẹta lawọn agbegbe ti ijọba ti fofin de.
Idi ree ti Alaafin fi jẹ hoo fun awọn agunlẹyinju obinrin yii, ti wọn si di ayaba ni Aafin Ọyọ.
com/rj0fKvzBVc— @omolayoalabi (@omolayoalabi_08) 21 April 2018Ademola Adepoju.
Nígbà náà ni Anderu, ọ̀kan ninu àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ tí ó jẹ́ arakunrin Simoni Peteru sọ fún un pé, 
Ẹnu ya baba ati ìyá Jesu nítorí ohun tí ó sọ nípa rẹ̀.
Ó ní àtẹ̀gùn meje, ìloro rẹ̀ sì wà ninu.
Wọ́n a tún máa to àwọn ẹ̀rọ gboùngboùn agbóùnsáfẹ́fẹ́ sí àwọn òpópónà kàn tí àwọn òṣèré á máa lú onírúirú àwo olórin fún ìgbádùn àwọn èro tí wọ́n péjọ sọ́dọ̀ ọ wọn.
 fún àpeere , ( 27a ) ń so pé rí jé òrò-ìse tí ó máa ń gba apor gégé bí àfikún .
Tinubu fikun pe oun ko ni imọ nipa isẹlẹ naa rara saaju akoko to waye, tabi ko awọn ologun ransẹ.
Wo ohun tó yẹ kí o mọ̀ nípa ikọ̀ Burundi Bí eṣinṣin bá kọ́já, wíwọ́n ní, lásìkò ìṣíde AFCON 2019 Wo àwọn ẹranko tí wọ́n máa figagbaga ni Egypt Wo ohun tuntun tó n ṣẹlẹ̀ lágboolé CAF Opolopo eeyan ni wọn ni eto iṣide naa dun daadaa nibi ti Femi Kuti atawọn olorin miran ti da awọn eniyan lara ya.
 ní ọdún 1966 sí ọdún 1969 , ó jẹ ́ òkan pàtàkì nínú ìgbìmọ ̀ àwọn ọmọ ẹgbẹ ́ akọ ́ mọ-lédè yorùbá orthography .
 lákòókó tí ó fi dúró yẹn , ó rò wí pé òun ti rìn jìnnà díẹ ̀ sí àbùrò òun kò mọ ̀ wí pé nǹkan ibùsọ ̀ mẹ ́ fà péré ni òun tí ì rín .
Lẹyin naa ni wọn wa ṣe ayẹwo fun awọn akẹkọọ, ti o si fihan gbangba pe ọmo.
O ni ko si nnkan ti ko lee ṣẹlẹ ni papa iṣire Camp Nou lorilẹde Spain nigba ti wọn ba lọ pade fun ipele keji ifẹsẹwọnsẹ naa.
Mo ti fi ọ̀rọ̀ rẹ fún wọn.
Nítorí náà, ó gbé ọwọ́ sókè, ó búra fún wọnpé òun yóo jẹ́ kí wọ́n kú sí aṣálẹ̀, 
Ǹ jẹ́ ẹ ní ẹ̀pà náà
Ifigagbaga asekagba idije UCL ohun ni o farahan bayii pe, Spain yoo koju England, ni eyi ti o tunmo si pe, iko agbaboolu Real Madrid CF yoo maa waako pelu iko agbaboolu Liverpool FC.
Àwọn ènìyàn zulu ni ẹ ̀ yà tó pọ ̀ jù ni orílè-èdè gúúsù Áfríkà .
OLUWA ní, “N kò rán àwọn wolii níṣẹ́, sibẹsibẹ aré ni wọ́n ń sá lọ jíṣẹ́.
Nítorí náà, gẹ́gẹ́ bí ó ti wà ní àkọsílẹ̀ pe:“Ẹni tí ó bá fẹ́ ṣe ìgbéraga,kí ó ṣe ìgbéraga nípa ohun tí Oluwa ṣe.
Bí a bá jẹ́ ọlọ́gbọ́n, a jẹ́ ẹ fun yín, 
“Mo fe fi da awon osise loju pe, oro ti lo bi o se ye ko lo, ki onikaluuku lo fokan bale.
Awọn eniyan meji miran tun ku lati ipasẹ ọgbẹ ti wọn ko ninu isẹlẹ naa.
Gbogbo àwọn arabinrin rẹ̀ kọ́ ni wọ́n wà lọ́dọ̀ wa níhìn-ín?
 bẹ ́ ẹ ̀ sì ni odùduwà bá àwọn àgbà awo ní ilé-Ìfẹ ̀ tí odùduwà sì ja ìjà àjàborí tí ó sì borí lọ ́ wọ ́ wọn .
ati ifowosowopo awon osise eleto abo bii ile ise Ologun(Nigeria Army) Orilede
”OLUWA sì dáhùn pé, “Saulu yóo wá.
– ogunlọ́gọ̀ àwọn ejò tí wọ́n tí dúró yí ààfin po wáa mọ̀ pé àwa ló pa ọba wọn kí á sì tóó ṣẹ́ ojú pẹ́ẹ́, Ìjànbáforítì ti jáde, ó tọ̀ wọ̀n lọ, díẹ̀ nínú àwọn ènìyàn wa náà sì tẹ̀lé e lọ.
Nítorí náà, olùdarí níláti jẹ́ ẹni tí kò lẹ́gàn; kò gbọdọ̀ ní ju iyawo kan lọ, ó gbọdọ̀ jẹ́ eniyan jẹ́jẹ́, ọlọ́gbọ́n eniyan, ọmọlúwàbí, ẹni tí ó fẹ́ràn láti máa ṣe eniyan lálejò, tí ó sì fẹ́ràn iṣẹ́ olùkọ́ni.
gomina fun saa keji ni ipinle Sokoto, nigba
Nígbà tí BBC béèrè pé báwo ní ìgbé ayé tí ṣe rọrùn laigba owó oṣù, Suleiman ní ìpeníjà nlá ní eyi jẹ fun awọn oṣiṣẹ.
Àjọ NJC fún Onnoghen àti Mohammed ní gbèdéke ọjọ́ méje Ìkìlọ̀!
O ni awọn alaṣẹ ọgba ẹwọn naa kan sara si ijọba fun bi wọn ṣe tara ṣaṣa dahun si ipe awọn lori ipo ti ẹlẹwọn yii wa.
Awọn ole bi ọgbọn niroyin sọ pe o ya wọ ilu naa, ti wọn si di awọn ọna kan pa ninu ilu ki wọn o to wọ awọn ileefowopamọ naa.
Oríṣun àwòrán, AFP Àkọlé àwòrán, Gomina Ambọde ni Agbekalẹ awọn akanse isẹ tuntun yo kun awọn idagbagbasoke to wanilẹ tẹlẹ Lasiko ti o n se afihan aba isuna odun 2018 fun ile igbimọ asofin ipinlẹ Ẹko, Gomina Ambode jẹjẹ wipe isejọba oun yo sa gbogbo ipa lati yọri awọn akanse isẹ ti o n lọ lọwọ, pẹlu agbekalẹ awọn akanse isẹ tuntun miran ti yo pakun awọn idagbagbasoke ti o n bẹ lakọsile lati bi i ọdun meji abọ sẹyin.
Oríṣun àwòrán, Odunlade Adekola Àkọlé àwòrán, Ọdunlade ọmọ Adekọla, agba n bọ wa kan ọ o Oríṣun àwòrán, Jide Kosoko Àkọlé àwòrán, Agba kii pẹ kan ni Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
 Oríṣun àwòrán, Getty Images ""IBK ti kuna."
Ṣugbọn niṣe ni Leujoe yari, to si wọ ile idana lọ lati mu ọbẹ to fi gun Temidayo pa.
Bayii, iko omo ogun ofurufu Naijiria ti fo kaakiri fun nkan bii igba wakati lati fi maa wa awon omo naa.
Awọn mejeeji ni yoo ṣoju ẹgbẹ oṣelu APC ninu idibo naa to m bọ lọna.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ogbomsho shooting, End Sars, End SWAT: Isiaka fi ọmọbìnrin kan àti ìyàwó tó lóyún sínú síl Gomina Seyi Makinde ipinlẹ Oyo naa ti ṣapejuwe iku mama Oyediran gẹgẹ bi adanu nla fun orilẹede Naijiria.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Àṣìṣe ọlọ́pàá àti Adájọ́ sọ mí di ẹni tí wọ́n dájọ́ ikú fún, ọpẹ́lọpẹ́ Fayoṣe tí ko buwọlu Olórin Kano tí wọ́n dájọ́ ikú fún pe ẹjọ́ kòtẹ́milọ́rùn Owó oúnjẹ ni mo lọ ọ gbà, oyún ọmọ tí mo jù sí àkìtàn ni mó gbé wálé- Dupe, ìyá Muiz Iléeṣẹ́ ọlọ́pàá ní Kano tí ṣe àyẹ̀wò àwọn 13, 048 tó fẹ́ darapọ̀ mọ́ wọn Facebook mú àyípadà bá àtẹ̀jíṣẹ́ síra ẹni lórí òpó Instagram, wo àwọn ǹkan tó kàn ọ níbẹ̀ Wo ohun tó ṣẹlẹ̀ sí Saka, Sunkanmi Omobolanle àtàwọn òṣèré sinimá míràn lọ́sẹ̀ to kọja Eyi ni awọn iroyin nipa awọn oṣere sinima to waye laarin ọsẹ to kọja.
Eyi lo mu wọn fi ẹjọ sun Olodumare.
Igbẹjọ Eni, Shell yoo tẹsiwaju lọjọ kẹrinla oṣu kẹta
Sugbọn gbogbo igbiyanju BBC lati fidi ọrọ yii mulẹ ni ko yọri nitori ọpọ awọn to le sọrọ nipa rẹ nitootọ ni awọn ko fẹ sọrọ lasiko yii.
Oríṣun àwòrán, Nnamdi Nwoye Ṣugbọn o ṣeni laanu pe onimọ-ẹrọ to n mojuto kikọ ile naa ti jẹ Ọlọrun ni pe.
Isọri awọn adari ẹsin kan kaakiri Amẹrika ti lodi si igbesẹ Aarẹ ilẹ Amẹrika, Donald Trump ti o ti gbe bibeli soke niwaju ile ijọsin St.
Bí ìbànújẹ́ bá tún pọ̀ lápọ̀jù kí ó má baà wó irú ẹni bẹ́ẹ̀ mọ́lẹ̀.
Ara ló ń ta àwọn ẹgbẹ́ NURTW tó ń pariwo mi kiri, APC ni wọ́n bá lọ nígbà náà l'Oyo- Auxiliary NURTW: Auxiliary ní ara ló ń ta àwọn ẹgbẹ́ NURTW tó ń pariwo òun kiri, APC ni wọ́n bá lọ l'Oyo Ẹgbẹ awakọ NURTW ẹka ti ipinlẹ Oyo ti ke gbajare lori iwa ipa ti wọn ni Alhaji Lamidi Mukaila ti inagijẹ rẹ n jẹ Auxiliary to n hu sawọn ọmọ ẹgbẹ ajọ naa.
ohun to n sẹlẹ lorile ede yii.
Amọ nibayii, ko si agbeegbe kan kan ti Boko Haram wa mọ, ilu perete to wa lẹkun ibode Naijiria ni Lake Chad nikan ni wọn ti n sọse bayii.
Àwọn olórí tí ó wà ninu wọn dàbí ìkookò tí ń fa ẹran ya, wọ́n ń pa eniyan, wọ́n sì ń run eniyan láti di olówó.
Ẹ má hùwà burúkú sí àwọn àlejò, tabi àwọn aláìníbaba, ati àwọn opó.
Ẹ fi ariwo fèrè yìn ín;ẹ fi fèrè ati hapu yìn ín.
Idà ni a óo fi pa wọ́n.
Nítorí pé Ahasi fẹ́ tẹ́ ọba Asiria lọ́rùn, ó gbé pátákó tí wọ́n tẹ́ fún ìtẹ́ ọba kúrò, ó sì sọ ibẹ̀ dí ẹnu ọ̀nà tí ọba ń gbà wọ ilé OLUWA.
Wọn le abilekọ Madikizela-Mandela lọ si Brandfort, ilu kereje kan lẹkun Free State, fun bi ọdun mẹwa.
Ìfẹ́ kì í jowú, kì í ṣe ìgbéraga, bẹ́ẹ̀ ni kì í fọ́nnu.
Ọpọ olorin takasufe bi Davido, Falz, Wizkid atawọn adẹrinpoṣonu bii Mr Macaroni, Woli Agba lo ti darapọ mọ iwọde #EndSARS.
Irú Ẹni Tí Olùdarí Ìjọ Níláti Jẹ́.
Opọ so fun BBC pe iru rẹ ko ṣẹlẹ ri nigboro ki a to ṣẹṣẹ wa sọ pe ni abule ni Bangladesh.
Ọpa afẹfẹ gaasi to bu gbamu ti ṣekupa ọpọ eeyan niluu Kaduna lọjọ Satide.
Ẹkọ kẹta naa ni pe, ki araalu maa fi suuru huwa lasiko ti iṣẹlẹ kan ba n gbona lara wọn, ko si yẹ ki wọn maa ba dukia ijọba jẹ.
Oríṣun àwòrán, others Àkọlé àwòrán, AFCON 2019: A kò ṣẹ̀ṣẹ̀ jọ máa pàdé ara wa!
 Bi a ṣe wa n ṣọdun aawẹ, ti a fi n saami ipari aawẹ Ramadan yii, ki a ma fi awọn iwa dardara ti a ti kọ ninu oṣu Ramadan silẹ”O ṣalaye siwaju pe oṣu Ramadan jẹ asiko arojinlẹ, lati fi awọn iwa ẹṣẹ wa silẹ, ki a huwa rere, ti o jẹ gbongbo fun awujọ rere kan.
Bẹẹ ko sẹni ti ko ni ku, adura BBC ni pe ki ọjọ jinna sira wọn fun koowa.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'ìjà ṣẹlẹ̀ láàrín èmi àti ọ̀gá mi ní Lebanon tórí mi ò lè dá N300K padà' Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Bí mo bá sọ fún un pé, ‘Wò ó àwọn ọfà náà wà ní ẹ̀gbẹ́ rẹ,’ kí o jáde wá, nítorí bí OLUWA tí ń bẹ, kò sí ewu kankan fún ọ.
‘Buhari kìí fá orí apákan, dá apakan sí’ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Festus keyamo: Ọ̀rọ̀ Obasanjọ sí Buhari ti di ìrégbè Keyamo ni PDP ti ṣeto esi ibo ti wọn fẹ gbe wọ oju opo Inec amọ isunsiwaju ọjọ ibo lo kawọn lọwọ ko.
Atẹjade kan to wa loju opo ikansiraẹni tuwita ti aarẹ orilẹede Naijiria tun kede wipe, aarẹ Buhari ti bẹrẹ igbesẹ lati ri pe awọn adajọ to pegede, fi gbọọrọ jẹka nikan ni igbimọ onidajọ n yan sipo adajọ.
Ṣugbọn, awọn olutọju alaisan sọ pe wọn ko ni i le ṣe e , nitori oyun to wa ninu rẹ.
Jummai sọ fun BBC pe lara awọn ọmọ oun to ti kawe gboye ti wọn si n ṣiṣẹ wa.
Keyamo ní bayìí, àwọn ìgbìmọ̀ kọ̀ọ̀kàn ti bẹ̀rẹ̀ iṣẹ́ ni àwọn ìpínlẹ̀ wọ́n gẹ́gk bí wan ṣe làá silẹ̀ tẹ́lẹ̀.
Ìdájọ́-òdodo yóò dàwátì lọ́wọ́ àwọn agbẹjọ́ro àti adájọ́ bẹ́ẹ̀.
O Fagunwa, Adebayo Faleti, Akinwumi Iṣọla, Lawuyi Ogunniran àti Oladejo Okediji3 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Ẹni kọ̀ọ̀kan níí sábàá máa lò ó lójoójúmọ́, èyí nì ni pé bí àwọn ọmọ ilé náà bá jẹ́ ọgbọ̀n, oṣooṣù ni aṣọ náà ó tó máa kan ẹni kọ̀ọ̀kan, nítorí náà ní àkókò òtútù, ewé ni wọ́n ń lò jù bí aṣọ.
Ìfihàn tí a fi fúnni nípasẹ̀ Wòlíì Joseph Smith ní ọjọ́ kínní Oṣù Kọkànlá ọdún 1831, ní àkókò àkànṣe ìpàdé kan tí àwọn alàgbà ìjọ ṣe ní Hiram, Ohio.
Mo wá di àpẹẹrẹ gbogbo àwọn tí wọn yóo gbà á gbọ́ tí wọn yóo sì ní ìyè ainipẹkun.
Èyíkéyìí ninu àwọn ọmọ Aaroni tí ó bá fi ẹ̀jẹ̀ ati ọ̀rá ẹran náà rúbọ ni ó ni itan ọ̀tún ẹran náà gẹ́gẹ́ bí ìpín tirẹ̀.
Kete ti gbogbo ibo ati kika ba ti le bara mu, yoo bẹrẹ si ni farahan loju opo eyi to jẹ ti orilẹede gangan.
Ọgbẹni Sunday Dare, minista fun ọrọ awọn ọdọ ati ere idaraya atawọn eekan mii nijọba lo wa ni papakọ ofurufu Nnamdi Azikwe lati ki wọn kaabọ sile.
Àwọn awakọ náà tún sàlàyé pé, ibùdókọ meje lo wà láàrin Bẹẹrẹ sì Omi-Adio, èyí tó mú kí owó tí àwọn yóò san ni àárọ̀ àti alẹ fáwọn Auxiliary jẹ́ egbèje náírà lojumọ, tí àwọn yóò sì tún san ọọdunrun náírà fún ìjọba Ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́, àmọ́ àwọn ti yari láti san owó náà.
Akọroyin kan sọ fun BBC pe eniyan mẹta to gbe ado oloro si ara wọn jẹ ki ado oloro naa ro gbamu lara wọn.
Jesu Oyingbo rèé, pásítọ̀ tó láṣẹ ìbálòpọ̀ lóri ọmọ ìjọ obìnrin D.
Ọpọlọpọ tí ó gbọ́ ninu àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ sọ pé, “Ọ̀rọ̀ yìí le, kò sí ẹni tí ó lè gba irú rẹ̀!
Mose gbé òróró ìyàsímímọ́, ó ta á sí gbogbo ara Àgọ́ náà ati ohun gbogbo tí ó wà ninu rẹ̀, ó sì yà wọ́n sí mímọ́.
Oladejo Okediji àti ìgbé ayé ìtàn kíkọ rẹ̀ BBC Yoruba ba ọga agba ile iṣẹ JAMB, Ọjọgbọn Ishiaq Oloyede sọ̀rọ̀ lori awọn ohun to n ru obi ati awọn oluṣedanwo loju lori idanwo JAMB ati gbigbani wọ ile iwe iwe giga lẹyin ti esi ba ti jade.
Ko si ogun lasiko rẹ ṣugbọn itan sọ wi pe, lọna ati lee ri ogun ja, ki o si jẹwọ orukọ rẹ gẹgẹbii aarẹ, Ojo Aburumaku da wahala iditẹ gbajọba kan silẹ ni aarin ilu oun tikalara rẹ.
Ọba dáhùn pé, “Ohunkohun tí ẹ bá ní kí n ṣe náà ni n óo ṣe.
Ṣugbọn ile igbimọ aṣoju-ṣofin ti da igbesẹ naa duro.
Awọn iroyin ti ẹ lee nifẹẹ si: Fọlọrunsọ Alakija: Imọ se koko Naijiria sọkutu wọwọ l'ayajọ awọn obinrin Obi awọn akẹkọ Dapchi nbeere ọmọ wọn Asaaju ẹgbẹ oselu APC naa, to jẹ gomina tẹlẹri nipinlẹ Eko fun saa meji, wa gbadura fun igbakeji aarẹ naa, pe ko lo igbe aye rẹ yoku ninu alaafia, ilera pipe pẹlu ogbọn, imọ ati oye.
Ani, nigbakigba too ba fi aye silẹ, jẹ ki idahun naa wa ninu rẹ.
 kò sí bí ìlú tàbí orílè-èdè kan kò se ní ní ọ ̀ kan nínú àwọn àwọn ìṣòro wọ ̀ nyí .
Ko tan sibẹ, ọmọ naa tun wọn iwọn 9lb 11oz lori iwọn!
Olorun fun aanu ti oloye Ikpea to tun je alaga ati oludari ile-ise Lee
Ọba ní, “Ṣé yóo tún máa fi ọwọ́ pa Ayaba lára lójú mi ni, ninu ilé mi?
Ta ni ó gbe yín ga ju ẹlòmíràn lọ?
Ó kó ọ̀kẹ́ mẹta ati ẹgbaarun (70,000) àwọn òṣìṣẹ́ jọ láti máa ru àwọn nǹkan tí yóo fi kọ́lé, ọ̀kẹ́ mẹrin (80,000) àwọn òṣìṣẹ́ tí yóo máa fọ́ òkúta, ati ẹẹdẹgbaaji ó lé ẹgbẹta (3,600) eniyan láti máa bojútó àwọn òṣìṣẹ́.
NHS sọpe egberun mejo lè díè ni Fẹntílàtọ̀ to wà sugbon wọn gbìyànjú láti ra kun ni kíákíá.
Mama mi ls si Mecca lai sọ fun baba mi amọ nigba to de, baba mi ko jẹ ko wọle, ni ipniya fi de saarin wọn.
50 fún oṣù kan kan .
Rogbodiyan nla bẹ silẹ lasiko idibo ati lẹyin idibo ọhun nipinlẹ Kano lẹyin tawọn ọdọ ti wọn jẹ alatilẹyin oludije ẹgbẹ oṣelu PDP yari pe Kabir Yusuf lo yẹ ko wọle ibo naa.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Sogidi Lake: Kòṣẹja-kòṣèèyàn lá bá nínú adágún odò náà -Ojedele Nafdac sọ pe wọn yoo dan ogun chloroquine naa wo lara awọn eniyan to ba ni aarun naa lati le mọ boya yoo ṣiṣẹ fun.
Ọlọ́gbọ́n lágbára ju akọni lọ,ẹni tí ó ní ìmọ̀ sì ju alágbára lọ.
Ti a ko ba gbagbe, ọmọ ọdún márùn-ún àti àgbà mẹ́rin ló bá ìṣẹ̀lẹ̀ ọ̀pá epo bẹntiróò tó gbiná ní Abule Egba lọ láìpẹ́ yìí.
EFCC gbé ọ̀gá owó ìfẹ̀yìntì tẹ́lẹ̀ lọ sÍ ilé ẹjọ́ fún ìwà ìbàjẹ́!
Oriṣiriṣi iṣẹlẹ lo ti n waye ni agbo oṣelu nipinlẹ Edo, paapa lẹyin ti gomina Godwin Obaseki fi ẹgẹ oṣelu APC silẹ, to si darapọ mọ PDP, nitori pe wọn ko fun ni tikẹẹti ẹgbẹ.
O pe ẹjọ yii nile ẹjọ giga apapọ kan nilu Abuja lọsan ọjọ isẹgun.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Victor Agunbiade ni ojú àlá ni Ọlọrun ti yan iṣẹ́ ọmọ ogun ojú omi fún òun ní America Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Victor Agunbiade ni ojú àlá ni Ọlọrun ti yan iṣẹ́ ọmọ ogun ojú omi fún òun ní America 14 Ògún 2020 Mo ti ṣiṣẹ olutọju arugbo ri ni America- Victor Agunbiade.
"Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ẹ wo adúrú ǹkan tí Softface ma ń tò pọ̀ láti sín àwọn òṣèré, gbajúgbajà jẹ Olorì àgbà mẹ́rin tó jẹ́ igi lẹ́yìn ọgbà fún Aláàfin Adeyemi Bí ẹgbẹ́ One Million Boys ṣe bẹ̀rẹ̀ rèé àti ọṣẹ́ tó ṣe n'Ibadan Àlàyé rèé lórí bí wọ́n ṣe pa Ebila, olórí àwọn ""One million boys"" n'Ibadan Tolulope Arotile: Ọ̀rẹ́ Tolu ṣàlàyé bí ìjàmbá ọkọ̀ tó ṣekúpa á ní Kaduna ti ṣẹlẹ̀ Oríṣun àwòrán, OTHER One Million Boys ni Ibadan Adugbo Kudeti nitosi Molete nilu Ibadan ni a le pe ni ibùba tabi ibùdó àwọn ọmọ ẹgbẹ 'One Million Boys' nilu Ibadan."
Ilẹ̀ àwọn ọmọ Lefi ati ilẹ̀ gbogbo ìlú yóo wà láàrin ilẹ̀ ọba.
Kíkọ Iyawo sílẹ̀ ati Títún Igbeyawo ṣe.
Yóo gba àwọn iranṣẹkunrin ati iranṣẹbinrin yín, ati àwọn mààlúù ati kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ yín tí wọ́n dára jùlọ, yóo máa kó wọn ṣiṣẹ́.
Israel Adesanya fi ẹ̀ṣẹ́ fọ́ Paulo Costa lójú 'Misita Alagidi, emi leleyi!
tí ó gbà wá là, tí ó pè wá láti ya ìgbé-ayé wa sọ́tọ̀.
Iha wo ni ẹgbẹ awọn osisẹ ile-wosan kọ si isẹlẹ yii ?
Lọwọ yii idi olukọni wọn n gbona bayii pẹlu ironu igbesẹ ti awọn alaṣẹ ẹgbẹ agbabọọlu naa lee gbe bi nnkan ko ba ṣe ẹnuure funwọn laipẹ.
 Inu mi dun lati so pe gbese wa n dinku gidi lati odun 2016 titi di isinyii ni eyi to le nida aadota ninu ogorun un.
Erelu Kuti ṣalaye pe Ọpa aṣẹ ti Ọba tuntun yatọ si ọpa aṣẹ amurode.
8 Owewe 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 16 Òkùdu 2020 O ti le ni ọgbọn ọdun ti mo ti n ta bọọli yii - Grace Ko si iṣẹ ti eeyan ko le ṣe là ni igbagbọ awọn Yoruba; ẹni to ba jale lo ba ọmọ jẹ.
“Ó ti pẹ́ tí mo ti dákẹ́ jẹ́ẹ́,mo dákẹ́ jẹ́ẹ́, mo mára dúró.
Nítorí náà, wọ́n fi ara wọn han àwọn ará Filistia.
Yoo si fi abẹrẹ gun iwe kọọkan lati fi okun kan pere de wọn pọ.
Ọmọbìnrin ni, ṣùgbọ́n ó lẹ́wà tó bẹ́ẹ̀ tí n kò bá irú rẹ̀ pàdé rí, ó ró aṣ\p funfun, ó wọ ẹ̀wù funfun, ó di irun orí rẹ̀ wìnnìkìn winnikin, ó pupa fẹ́ẹ́rẹ́, ṣùgbọ́n ó ní ìyẹ́ méjì ńlá ni apá bẹ́ẹ̀ ni bàtà fàdákà wọ́n dá ẹ̀wù tí ó wọ̀ ní ọ̀nà tí ìyẹ́ lè fi rí àyè yọ jáde, ó wọ bàtà fàdákà, ṣùgbọ́n inú àtẹ tí ó gbé ọjà títà rẹ̀ gbogbo sí, góòlù ni.
Ọrọ rẹ pada de ilé ẹjọ ṣugbọn lẹyìn ọpọ atotonu, adájọ gba oniduro rẹ̀.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: 'Ẹ kéde èsì ìdìbo àarẹ 1993' Àwọn ọ̀rọ̀ àyọlò MKO Abiọla Ohun tí Abiola ti gbé ilé ayé ṣe Ipade naa ni akọkọ iru rẹ laarin Aarẹ orilẹede America to wa lori oye pẹlu olori orilẹede North Korea, to si so eso rere fun awọn mejeeji.
“Ẹ jẹ ki a ki awọn   igbimọ  tuntun ti yoo maa mojuto ile-isẹ  ọlọpaa ku ori-ire, bakan naa ni ki a tun gbosuba fun aare nitori oruko awọn eniyan ti o fi ranse si  wa.
Wọ́n sì fi eyín erin bo inú rẹ̀.
Ganduje OFR Eeyan meji mii tun ti jade laye ni ipinlẹ Kano latari ajakalẹ arun Coronavirus.
Baruku Ka Àkọsílẹ̀ ninu Ilé OLUWA.
Ìwẹ̀fà náà sọ pé, “Wo omi.
Ó ké tìbínútìbbínú ó wí báyìí pé:
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Lockdown updates: Naira Marley gbóríyìn fún Jude Chukwuka pẹ̀lú #1 míliọnù Joi Yimebe Nunieh gangan ni apeja orukọ rẹ, ṣugbọn ọpọ eeyan lo mọ ọ si Joy Nunieh.
Nípa ti ajinde àwọn òkú, ẹ kò ì tíì ka ọ̀rọ̀ tí Ọlọrun sọ fun yín pé, 
Lẹ́yìn náà, wọ́n ti pada lọ sí ààrin ìlú, wọ́n sì ń hó fún ayọ̀.
Gbogbo wọn patapata ni wọ́n ṣẹ, ẹyọ kan kò yẹ̀ ninu wọn.
Oríṣun àwòrán, @247NNU Ni ti eto aabo ilu, Owoṣeni sọ pe iṣẹ gbogbo eeyan ni eto abo ilu jẹ, lẹyin naa lo sọ fun awọn eeyan naa pe ki wọn mu eto abo ara wọn lọkunkundun nitori oju ni alakan fi n ṣọri.
Gbogbo ẹ̀gbẹ́ mi ń gbóná fòò,kò sí ibìkan tí ó gbádùn lára mi.
Wọn yọ Kaisha ati lẹyin ti ibo ti awọn ololufẹ eto agbelewo naa to dibo di fun oun atawọ̀n mẹ̀ta miran ko gbewọn to tawọn ẹlẹgbẹ wọn yoku.
Ẹ tọ àwọn alufaa ọmọ Lefi lọ, kí ẹ sì kó ẹjọ́ yín lọ sí ọ̀dọ̀ ẹni tí ó wà ní ipò onídàájọ́ ní àkókò náà.
 Eto okoowo to dara ni adehun naa fun ilẹ Naijiria, ireti si wa pe Naijiria yoo ni aarẹ ti yoo lee fọwọsi iwe adehun ọhun nitori ọwọ aarẹ to wa nipo bayii ko lagbara to.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Yinka Ayefele: Oṣù àwọn ìbẹ́ta mi kò pé ní kò jẹ́ kí n kọ́kọ́ kéde ìbí wọn Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
" Lara awọn agunbanirọ ti ọrọ naa kan ni: Nwachukwu Chimaobi Curtis, Ononuju Amarachi Nwamaka, Francis Joseph Arinze, Chigozie Evidence Chijioke, Iliyasu Usman, Nasiru Yau, Sheu Muktar, Offor Blessing Chinelo, Mezenwa Ngozi Chidinma.
“A ti ka àwọn ọmọ ogun tí ó wà lábẹ́ wa, kò sí ẹni tí ó kú sójú ogun.
Bí ẹ̀mí wọn bá ti bọ́, wọn á pada di erùpẹ̀,ní ọjọ́ náà sì ni èrò inú wọn óo di ègbé.
Ọmọbinrin kan ku si sọọsi lasiko ijẹri Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Mi o fẹẹkan ni mo fẹ dupo aarẹ' Bákannáà ló sọ pé, bàálù náà se pàtàkì nítorí Jesu ko ni gùn Kẹtẹkẹtẹ ka lo si wà láyé.
àwọn ọmọ Besai, àwọn ọmọ Meuni, ati àwọn ọmọ Nefuṣesimu, 
Nipinlẹ Ogun, Ọba ilu Ipokia di ọba alade ilẹkẹ.
 Ó jẹ ́ ìkan lára àwon oògún tí Àjọ Ìlera Àgbáyé ṣàkójọ ẹ ̀ sí oògún tó wúlò jùlọ fún ìlera , oògùn tí ó gbóná ko , tí ó sì wúlò fún ètò ìlera .
Ẹ sọ́ra, ọ̀pọ̀ èèyàn ni yóò lọ sẹ́wọ̀n ní 2019 - EFCC Àwọn òṣèré tíátà Yorùbá tó bá 2018 lọ Ǹjẹ́ o mọ̀ pé Baba Sala ló kọ́ Sunny Ade nísẹ́?
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Alao Akala:Èmi àti Ajimọbi kò ṣe ìlérí kankan fún ara wa Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Claudiah: ìrẹ̀wẹ̀sì ọkàn bá mi fínra fún ọpọlọpọ ọdún Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ronke Oṣodi: òótọ́ ọ̀rọ̀ máa ń korò gan ni f'áwa èèyàn Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Reubẹni bá wí fún baba rẹ̀ pé, “Pa àwọn ọmọ mi mejeeji, bí n kò bá mú Bẹnjamini pada wá fún ọ.
Diẹ ninu awọn eekan Ibadan ti iku mu lọ ree: Oloye Bode Akindele: Ninu ifọrọwanilẹnuwo kan ti BBC Yoruba ṣe pẹlu aarẹ ẹgbẹ ọmọ Ibadan, Oloye Adeyemi Soladoye, o ni iku Parakoyi Ilẹ Ibadan, Oloye Bode Akindele ni ẹlẹẹkeje iru rẹ ti yoo ṣẹlẹ lati ibẹrẹ ọdun yii.
Kò tán sibẹ̀, wọ́n tún bèrè fún ẹgbẹ̀rún lọ́nà ìgbà náírà lọ́wọ́ ẹbí ọ̀daràn náà gẹ́gẹ́ bi owó béèlì kí wọ́n tó fi sílẹ̀.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Esi ti igbakeji aarẹ fọ yi wa ni idahun si ọrọ tawọn kan sọ nipa rẹ ninu iwe iroyin to ni ko si ootọ nibẹ.
Nigba ti yoo fi di ipari oṣu Kẹta, irinajo si awọn papakọ ọkọ ofurufu to tobi ju ti dinku.
“Bẹ́ẹ̀ náà sì ni bí olódodo bá yipada kúrò ninu òdodo rẹ̀, tí ó bá dẹ́ṣẹ̀, tí mo sì gbé ohun ìkọsẹ̀ kan siwaju rẹ̀, yóo kú, nítorí pé o kò kìlọ̀ fún un, yóo kú nítorí ẹ̀ṣẹ̀ rẹ̀, a kò sì ní ranti iṣẹ́ òdodo rẹ̀ tí ó ti ṣe; ṣugbọn n óo bèèrè ẹ̀jẹ̀ rẹ̀ lọ́wọ́ rẹ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Teach your children Yoruba: Wo àwọn òyìnbó tó ń kẹ́kọ̀ọ́ èdè Yorùbá ní Michigan, America Eto naa da lori bi awọn ọmọ orilẹ-ede Cameroun to n sọ ede Gẹẹsi ati ede Faranse ṣe le gbe papọ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ọwọ́ sìkùn ọba tẹ lára àwọn afurasí tó kọlu ilú Òffà 14 Ìgbé 2018 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ọwọ́ ọlọ́pàá tẹ lára àwọn afurasi tó kọlu ilú Òffà Látarí ikọ̀lù tó wáyé láìpẹ́ nílu Ọ̀ffa, Iléeṣé ọlọ́pàá ti ìpinlẹ Kwara ti mú àwọn afurasí méjìlá míì tó ní se pẹ̀lú ìkọlù ilú náà láìpẹ́.
EFCC to fi eyi lede loju opo ikansiraẹni Twitter wọn ni Hushpuppy is ẹni to gajulọ lorilẹede Naijiria ti wọn n wa bayii fun ẹsun iwa ọdaran lori ẹrọ ayelujara.
Sugbọn sa, gomina ológun to pada jẹ lẹyin rẹ, Ọgagun Oladipupo Diya da a pada sipo lọdun 1984.
Ọpọlọpọ gèle ìgbàlódé wá lati òkè òkun.
 léyìn ìgbeyàwó àkókó , ó ti fé ìyàwó mérin mìíràn .
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Libya: Ọmọ Naijiria mejilelaadoje miran pada sile 22 Sẹ́rẹ́ 2018 Oríṣun àwòrán, ABIKJE DABIRI/TWITTER Àkọlé àwòrán, ọmọ Naijiria mejilelaadoje pada sile lati orilẹede Libya Ajọ to n risi eto irinna lati agbegbe kan si ominran lagbaye (IOM) pelu iranwọ ajọ isọkan orillẹede Europe (EU), ti da awon ọmọ Naijiria mejilelaadoje pada sile lati orilẹede Libya, leyin ti Ojilelẹẹdẹgbẹta pada sile lọse to kọja.
Ta ló lè dá a dúró?
”Gomina tun so pe bi May se wa sil ilu Eko ,yoo tun je ki  eto okoowo ati aabo  tun ni idagbasoke si i.
Ní gbolohun kan, ẹ ní inú kan sí ara yín.
Josẹfu bọ́ sinu kẹ̀kẹ́ ẹlẹ́ṣin rẹ̀, ó lọ pàdé Israẹli, baba rẹ̀ ní Goṣeni.
Nígbà tí àwọn àgbààgbà péjọ tán, àwọn ọmọ Lefi gbé àpótí náà.
Oríṣun àwòrán, authenticmuy Ìwádìí tú àṣírí Dókítà tó pa ìyàwó rẹ̀, ó fẹ́ pa ọmọ wọn méjì, òun fúnrarẹ̀ tún pokùnso Àwọn ìgbésẹ̀ tóo lè fi so NIN rẹ̀ pọ mọ́ síìmù MTN, Glo, Airtel ati 9Mobile rẹ Ṣé lóòtọ́ ni pé ọmọ ikọ̀ Amotekun yìnbọn pa èèyàn méjì ní Ibadan?
11 Bélú 2020 Alaafin: Ọ̀pọ̀ èèyàn ń bèèrè pé kí ló dé tí Olorì Badra kò fi sí nínú fọ́tò ọdún Ileya8 Ògún 2020 Queen Badra Olaitan: Ọ̀pọ̀ nnkan tó bàmí nínú jẹ́ ni ojú mi rí lọ́dún 20209 Bélú 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Buhari mọ pe awọn ẹlẹsin Shiite pọ ni Naijiria ti wọn n gbe ni alaafia Aarẹ Buhari to n tukọ orilẹ-ede Naijiria ni Islamic Movement of Nigeria ni ọrọ aṣẹ adajọ n ba wi kii ṣe ẹlẹsin ShiiteIkọ̀ aláàbò Nàìjìríà dojú kọ Shiite .
Atipo Naijiria 50 rigbala lori omi Ilé ẹjọ́ dájọ́ ikú fún èèyàn mẹ́ta nítorí ikú akẹ́kọ̀ọ́ fásitì UNIOSUN Kí lo fẹ́ mọ̀ nípa D.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Kwara Bursary: Àwọn akẹ́kọ̀ọ́ Kwara Poly ṣèwọ́de fún owó ìrànwọ́ ẹ̀kọ́ 5 Ẹrẹ̀nà 2019 Àwọn akẹ́kọ̀ọ́ ileẹkọ gbogbonse Poly tipinlẹ Kwara, ti wọn jé ọmọ bíbí ìpínlè Kwara yà bo ileesẹ eto isuna ìpínlè náà (Kwara State Internal Revenue Service) láti béèrè fún owó iranwọ eto ẹkọ (Bursary) wọn.
Máa ṣe eré ìdárayá èémí, pee nọ́ọ̀sì agbẹ̀bí rẹ tí ó bá kojú ìṣòro kankan.
Ó ní, “Mo fi orúkọ OLUWA alààyè búra, ẹni tí ó gbé mi ka orí ìtẹ́ Dafidi baba mi tí ó fi ìdí mi múlẹ̀, tí ó mú ìlérí rẹ̀ ṣẹ, tí ó sì fi ìjọba náà fún èmi ati arọmọdọmọ mi, lónìí olónìí ni Adonija yóo kú.
Ọlọ́pàá rí òkú ọ̀gá àgbà iléèṣẹ́ ńlá kan tí wọn ń wá, lójú omi l‘Eko A gbé òfin 1960 jáde, màálù tó bá jẹ oko àgbẹ̀, tí olówo rẹ̀ kò sanwó, títà ni - Buhari Ìjọba fẹ́ kọ́lé 300,000, pẹ̀lú ìrànwọ́ fún àgbẹ̀ 4m láti mú àdínkù bá ìṣẹ́ - Osinbajo O ni O yẹ ki awọn igbimọ to n ri si ami ẹyẹ ọhun wo ti awọn akitiyan Trump gẹgẹ bi ohun amuyẹ fun ami ẹyẹ ọhun, kii ṣe iwa rẹ."
maa pese awon ohun elo ipese ounje naa.
Atẹjade kan ti ẹgbẹ APC fisita nilu Ibadan wa rọ gbogbo ẹmọ ẹgbẹ wọn lati gba awẹ ati adura ẹjọ mẹtanaa, eyi to bẹrẹ ni ọjọ Aje, ọjọ kejilelogun oṣu kẹfa ọdun 2020.
" Lẹyin naa lo sọ pe ko si idukoko kankan to le e da omi tuntun to n ru bo duro.
Nítorí pé, ẹ̀yin mejeeji ni ẹ kò hùwà òtítọ́ sí mi láàrin àwọn ọmọ Israẹli, nígbà tí ẹ wà ní odò Meriba Kadeṣi, ní aṣálẹ̀ Sini.
Ijọba Amẹrika gbe igbesẹ naa lẹyin ti adari ikọ al-Qaeda, Osama Bin Laden fi orilẹ-ede naa ṣebugbe lọdun naa lọhun, gẹgẹ bii alejo ijọba.
Mo tún wí lẹ́ẹ̀kan sí i, kí ẹnikẹ́ni má ṣe rò pé aṣiwèrè ni mí.
Ajọ naa sọ wipe awọn ti ile naa wo pa ni Toyin Ogundimu, ẹni ọdun marundinlogoji, ati Sherifat Olalere, ọmọ ọdun mọkanla.
Nígbà tí ó ṣe ó bẹ̀rẹ̀ sí fi owó náà ṣòwò, òwò náà sì lọ síwáju dáradára tó bẹ́ẹ̀ tí ó fi jẹ́ pé ní àkókò tí Aṣojú-Olódùmarè fi máa padà de irin wó ọ̀mọ̀wé ni ó jẹ́ akọ̀wé ní abẹ́ ọmọ yìí bẹ́ẹ̀ ni òun ni ó ni owó tí ó san fún wọn.
O ni pẹlu iriri oun latẹyin wa, o yẹ ki aarẹ Buhari tete da si awn ọ̀rọ̀ to ṣe gboogi to nilo akiyesi kanmọ kanmọ.
Badagry: Erékùṣù tí àwọn ọmọdé ti ń wọ odò ńlá láti lọ sílé ìwé
Ó ṣe agbada omi rìbìtì kan.
Ojúṣe Ẹni sí Arakunrin Ẹni Tí Ó Ṣaláìsí.
O so wipe, ni gbogbo igba naa, oun ko jẹ ounjẹ kankan to ju eso igi lọ atawọn nkan oko min tawọn eeyan pinj sẹba ọna.
garba shehu fikun wipe ijoba naijiria ko ni fi isele yii jafara, amo won yoo kesi awon elebo aabo lati wo bi o se n lo lawon agbeegbe yii.
Ṣugbọn ohun tí ó sọ ni pé, “Ọ̀rọ̀ náà wà nítòsí rẹ, àní, ó wà lẹ́nu rẹ ati lọ́kàn rẹ.
Ṣugbọn o, ofin yii kii ṣaba jẹ mimulo, nitori pe ọmọ tuntun ti ni orilẹ-ede abinibi tẹlẹ (ibi ti awọn obi rẹ ti wa).
Owolabi ni bata kan ti oun ni nile, lo fun oun ni ọgbọn inu pe, oun lee lo asọ oke lati fi se baagi ati bata.
Ológun kan tí ọpọlọ rẹ̀ kò pé, ló pa akẹẹgbẹ́ rẹ̀ tó ṣẹ̀ṣẹ̀ ṣègbéyàwó - Iléeṣẹ́ ológun jẹ́wọ́ Nibayi,awọn to ba arun naa lọ ni Naijiria ti wọ 879.
Kò jẹ́ kí ẹnikẹ́ni tẹ̀lé òun àfi Peteru ati Jakọbu ati Johanu àbúrò Jakọbu.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ẹ gbọ́, èwo ló dára jù nínú 'oníjó' àti 'akówó jẹ'?
Ṣugbọn bawo ni wọn ṣe lee pin abẹrẹ yii ti yo fi kari gbogbo agbaye, ati pe ki ni awọn ipenija to rọ mọ pinpin abẹrẹ naa?
Ẹ gbọ́, ẹ̀yin olórí ilé Jakọbu, ati ẹ̀yin alákòóso ilé Israẹli, ẹ̀yin tí ẹ kórìíra ìdájọ́ òdodo, tí ẹ sì ń gbé ẹ̀bi fún aláre.
BBC Yoruba ṣe akojọpọ awọn ikọlu to ti waye si awọn ileewe lorilẹede Naijiria laarin asiko ti gulegule awọn ikọ Boko Haram bẹrẹ lorilẹede naa.
pé o kò ní pa wá lára, gẹ́gẹ́ bí àwa náà kò ti ṣe ọ́ níbi, àfi ire, tí a sì sìn ọ́ kúrò lọ́dọ̀ wa ní alaafia.
Sanwo Olu sọrọ yii lẹyin to ṣabẹwo si Shoprite ni Sangotedo ati Surulere lati wo bi nkan ṣe bajẹ to si iroyin ti oun n gbọ lori iṣẹlẹ naa.
Èmi fúnra mi yóo jí wọn dìde ní ọjọ́ ìkẹyìn.
Ọgọ́jọ ayo o din mẹta ni awọn agbabọọlu ti gba sawọn ninu ifẹsẹwọnsẹ ọgọta ti wọn gba lati igba ti idije naa ti bẹ̀rẹ̀.
Amọṣa Mimiko ko sọ ọrọ lori boya yiyọ ti ẹgbẹ oṣelu rẹ yọ ọwọ ninu idije aarẹ tumọ si pe wọn yoo gbaruku ti ẹgbẹ oṣelu miran fun idije ipo arẹ lasiko idibo apapọ lọdun 2019.
ologun silẹ lati wa di aarẹ ninu eto iselu, ti o tun wa di eni ti o wa ninu iwe
báwo ni iranṣẹ ti Ẹ̀mí yóo ti lógo tó?
22 Òun sì jìyà àwọn ìdánwò ṣùgbọ́n òun kò fi àkíyèsí rẹ̀ sí wọn.
A bii ni ọjọ kejilelogun, oṣù kẹta, ọdún 1979.
Agbakoba tun fa ijọba apapọ lọ ile ẹjọ lori ọrọ naa.
Àwọn ilé ìwé Unity School kò ni kópa nínú ìdánwò WAEC nítorí Coronavirus - Ìjọba àpapọ̀ Oríṣun àwòrán, legit Saaju la ti mu iroyin wa fun yin pe, ijọba apapọ ni awọn ile iwe girama ijọba apapọ, Unity Schools, ko ni kopa ninu idanwo WAEC ọdun yii titi di igba ti o yẹ.
 Àwọn ìwé àpilẹ ̀ kọ rẹ ̀ dá lórí èdè yorùbá , ̀ ó kó gbogbo ohun àmúyẹ àṣà yorùbá bí tàwọ ̀ n àkoni ìgbà ìwáṣè nínú ọ ̀ pọ ̀ ìwé àpilẹ ̀ kọ rẹ ̀ , ní èyí tí ó ṣàyípadà rẹ ̀ sí àwọn ohun ìgbafẹ ́ , àwòrán àti sinimá àgbéléwò.
Ni ọdun 2010 ni wọn fi oloye Ifayẹmi jẹ oye Araba awo ti ilu Osogbo eyi to fihan pe oun ni olori gbogbo onifa ati alawo ni ilu Oṣogbo.
2 bílíọnù fi tún wáyà iná àti inú ilé Aso Rock ṣe- Buhari Oríṣun àwòrán, Nigerian Police Ọlọ́pàá f'ẹsẹ̀ fẹ́ẹ l'Eko lẹ́yìn tó yìnbọn fún ọ̀rẹ́bìnrin rẹ̀ lẹ́nu Ọlọpaa kan ti wọn n wa bayii ni a gbọ pe o ti juba ehoro lẹyin to yinbọn fun ọrẹbinrin rẹ ni ibudokọ Salvation Bus Stop ni Ikeja niluu Eko.
Osinbajo: Ọmọ Nàìjíríà, nǹkan kò ní pé ṣẹnure fún mẹ̀kúnù
Jẹ́ kí wọn máa yin OLUWA nítorí ìfẹ́ rẹ̀ tí kì í yẹ̀,àní nítorí àwọn iṣẹ́ ìyanu tí ó ṣe fún àwọn ọmọ eniyan.
Ẹ gbà á tọwọ́-tẹsẹ̀ ní orúkọ Kristi gẹ́gẹ́ bí ó ti yẹ onigbagbọ.
Òkú ọmọ tuntun pòórá nílé ìgbókúpamọ́sí nílùú Akurẹ Ọwọ iji lile ti ojo naa, eyi to bẹrẹ ni nnkan bii agogo mẹjọ abọ mu dani, to si jẹ pe, ile meji lo wo, ọpọlọpọ igi ati opo ina lo si wo lulẹ.
Bakan naa ni ijọba kede pe ki gbogbo awọn oniṣẹ ko ṣee mani naa pada si ẹnu wọn.
Gẹgẹ bi a ṣe gbọ, o ti pẹ diẹ ti iroyin sọ pe afurasi ọdaran yii lo wa nidii iku ọwọwọ to n waye lagbegbe ijọba ibilẹ Akinyele nipinlẹ Oyo.
Gbogbo awon igbese yii ni o ti yori si rere, ohun ti a se lonii ni lati wa atileyin ijoba apapo fun ipele ti a wa yii, lori ohun ti a fenuko le lori lonii yii, igbimo ohun ti satileyin fun orile-ede Naijiria lati fowo siwe adehun ifenuko naa tini ipade apero ajo isokan ile Afrika ti yoo waye nilu Kagali lorile-ede Rwanda ni ojo kokanlelogun osu keta odun 2018.
“Ẹ ṣọ́ra fún àwọn wolii èké tí wọn máa ń wá sọ́dọ̀ yín.
(Kí ọ̀rọ̀ tí ó ti sọ lè ṣẹ tí ó wí pé, “Ọ̀kan kan kò ṣègbé ninu àwọn tí o ti fi fún mi.
Aisha Buhari tọrọ ìdáríjì lórí fídìo tó jáde Seyi Makinde, bàtà tí Ajimobi bọ́ sílẹ̀ ni ko tẹsẹ̀ bọ̀ fún àṣeyọrí Ọyọ - APC Irú ọjà wo ni wọ́n kò ti lè yan Ìyálọ́jà?
Amọ lẹyin igba naa, ko ni jọju mọ.
Bí ó bá kọ́kọ́ dè é ni yóo tó lè kó o lẹ́rù.
Ẹnikẹ́ni kò mú un, nítorí àkókò rẹ̀ kò ì tíì tó.
To àwọn òkúta rẹ̀ lérí ara wọn dáradára, lẹ́yìn náà mú akọ mààlúù keji kí o sì fi rú ẹbọ sísun.
ọmọ Haṣabaya, ọmọ Amasaya, ọmọ Hilikaya; 
Ni bayii, iko agbaboolu Super Eagles ti bo sipo keta nilẹẹ Afrika ninu atejade tuntun ipo ate ajo FIFA ti won fi sita lojoBo(Thursday).
Èyí tí ó ń ṣàn lọ sí Òkun Araba tí à ń pè ní Òkun Iyọ̀ gé kúrò, ó sì dá dúró.
Ọmọwe Gomba Fortune Oyor ni baba to bi lọmọ.
Ẹgbẹ agbabọọlu Chelsea padanu ọkan lara awọn igi lẹyin ọgba rẹ, Tiemoue Bakayako lẹhin asesemase lẹẹkeji ti wọn si gba bọọlu fun wakati pẹlu awọn mẹwa.
Lagos train accident: Ọkọ̀ ojú irin pa ènìyàn mẹ́rin ní Eko
SR ni à ń pè ní Wikileaks Ilé Adúláwọ̀.
Ó bá fi ọwọ́ rẹ̀ ṣẹgun fún ara rẹ̀,òdodo rẹ̀ sì gbé e dúró.
PDP fẹ́ gbé ìgbésẹ̀ tuntun Kola Ologbodiyan lorukọ ẹgbẹ oṣelu PDP ni àwọn ti n to gbogbo ẹ̀rí wọn jọ pẹlu gbogbo esi ti awọn oṣiṣẹ PDP ni l'Ekiti papọ .
O so pe ” VOA jẹ ile akede Amerika, ti o ni iwa ootọ, ti o si tun ni opolopo awọn eniyan to n gbọ ọ, paapaa julọ lorile ede Naijiria, nitori naa , wọn ni opolopo ise ti wọn lee se lati dekun oju ti awọn eniyan fi n wo orile ede yii, paapaa julo lori ija to n waye laarin awọn agbẹ ati odaran.
Ko si iru ohunkohun to wu, to lee sẹlẹ.
Ìtàn Mánigbàgbé: Kí ni ẹ rántí nípa Israel Adebajo, gbajúmọ́ oníṣòwò tó dá 'Stationery Stores' sílẹ̀?
Ojogbon Samuel to je omo aadorin odun ati iyawo rẹ ni ọmọ ọgọrun ọdun le di ọlọmọ ti wọn ba ti ni ipinnu to daju lai bẹru pẹlu igbagbọ ninu Ọlọrun alaaye.
O ni ko si ohun ti yoo damu alaafia orilẹ-ede Naijiria ati pe Naijiria ko ni foju kan itajẹsilẹ mọ, bẹẹ ni ko ni si ogun mọ nitori nnkan yoo yipada si rere fun orilẹ-ede Naijiria.
Lẹyin o rẹyin, Kosoko bori Akitoye, to si lee kuro lori oye lọdun 1845, to si jọba ilu Eko nigba ti Oshodi jẹ Balogun rẹ.
Òkú yóo sùn lọ bẹẹrẹ láàrin yín, ẹ óo sì mọ̀ pé èmi ni OLUWA.
Wọn fi ọkọ ofurufu ologun gbe Bashir lati Kano lọ si olu ileeṣẹ ologun ni Abuja lati ṣe koriya fun un.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Ndume tí d'èrò ẹ̀wọ̀n nítori pé ó gba onídùróó Maina tí wọ́n kò rí mọ́ Ilé ẹjọ́ kan nílùú Abuja ti ni kí wan ti Ali Ndume tó jẹ́ sẹnátọ̀ láti Bornu mọ́lé, nítori bi Abdulrasheed Maina to ṣe oníduró fun ṣe pòórá.
Ọgbẹni Ashir Oyegun, Alakoso agba tẹlẹ fun Ọrọ Ayika ati Iṣeto Kikọ ilu ni Ipinlẹ Eko sọ pe ipade awọn alẹnulọrọ naa da dara, o ni.
Ibodè tí a tì ló fa ọ̀wọ́ngógó owó ọjà - Ìjọba Naijiria Sanwo-Olu ń sanwó Eko!
Èerí ara, èérí ibùgbé, èérí aṣọ, èérí oúnjẹ, èérí ẹ̀fúùfù, èérí àpòlòkú ẹni, àìyàgbẹ́ lákòókò, àti ìwà àìbikítà nígbà tí àìsàn bá ṣẹ̀ṣẹ̀ bẹ̀rẹ̀ – àwọn wọ̀nyí ni ó ń mú èyí tí ó pọ̀ jù nínú àwọn ọmọ ènìyàn kúrò ní òde ayé ní ìgbà òwúrọ̀ àti ní ìgbà ọ̀sán gangan wọn.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Wo ọna ti o le gba lati fi daabo bo ara rẹ lori Facebook.
Mo wá rí Ọmọ-Eniyan tí ó dúró lọ́wọ́ ọ̀tún Ọlọrun.
Awọn ìmúra tó dá orí ayélujára rú jùlọ lọ́dún 2018
Awọn eroja ounjẹ ti a ti le ri tryptothan to n mu adun ifẹ dun sii ni ẹyin, adiyẹ, ewedu, eso ati soya.
Àlárùn Coronavirus di 7000 lágbàyéé, ìjọba Nàíjíríà kọjú oro sí ọjà China tó jẹ́ ẹbu 'Mi ò fẹ́ gbé àrùn Coronavirus lọ sí Áfíríkà' Ṣé Coronavirus leè tẹ̀lé ọjà Chinco wọ Nàìjíríà?
Ṣugbọn wọn kò ka àwọn ọmọ Lefi mọ́ wọn, 
Ọba pàṣẹ pé kí wọ́n ṣe bẹ́ẹ̀.
Manoa dá angẹli OLUWA náà lóhùn, ó ní, “Jọ̀wọ́, dúró díẹ̀ kí á se ọmọ ewúrẹ́ kan fún ọ.
Eto-ilera to peye fun awon omode je anfaani ati je ki won koju si iwe won, o je ki awon agbalagba lowo lowo pelu, bakan naa, ni o je ki eniyan bo lowo ise ohun osi, ni eyi ti o si n je ki a le pese awon ohun amayederun fun idagasoke eto oro-aje olojo pipe.
Ọlọ́pàá gbé àwọn tó yìnbọn lu olólùfẹ́ ní Ajegunle Kíni ìdí tí àwọn ẹbí àwọn ọmọ Chibok fi ń tọ woli lọ?
Bí mo bá sì sọ fún òmíràn pé, ‘Wá!
Ninu ifesewonse ti o waye ni papa isere Old Trafford, Iko agbaboolu mejeeji gba ami-ayo kookan(1-1).
Bí àwọn Mùsùlùmí ṣe leè ṣe Ramadan ọdún yìí lásìkò àrùn Coronavirus Ọjoọ́ mélòó ni Coronavirus ń lò lára kí ènìyàn tó gba ìwòsàn?
Àwọn òbí ń fún ọmọ wọn lọ́yàn Ní nkan ti a mọ̀, kò sì ewu nínú kí ọmọ máa mú ọyàn daada, gẹ́gẹ́ bí Cadee ṣe sọ gbogbo ìwádìí tí wọn ti ṣe kó sì àfihàn pé àwọn ọmọ lè kó aarun Coronavirus láti ara ọmú mímú, nítorí náà ìyá leè fún ọmọ lọ́mú Kini mo ní láti ṣe tí mo bá ń gbé ilé Kojú-sí - mi-kín-kojú-sì-ọ?"
" Bí ìjọ́bá bá subú, ó ṣe pàtàkì gbà pé òun súbu kí í tọrọ afórijì kí ó sì kọ́ ẹ̀kọ́ nínú àṣìṣe wọ́n.
Èèyàn 160 ló tún forí kó o Fun ọjọ keji lera bayii, ipinlẹ Plateau ni o n lewaju laarin awọn ipinlẹ ti COVID-19 ti n ṣọṣẹ julọ lorilẹede Naijiria lori onka olojoojumọ awọn to n ni aarun naa eleyii ti ajọ to n gbogun ti ajakalẹ arun lorilẹede Naijiria, NCDC fi sita.
Adeola @Harrdehy fi igbe bọnu ni tiẹ, o ni ẹnikẹni to ba kopa ninu ipade itagangba ẹgbẹ osẹlu PDP gbọdọ ya ara rẹ sọtọ fun ayẹwo arun coronavirus.
Bakan naa lo rọ awọn araalu lati ma foya ki wọn si maa gbe igbe alaafia lọ.
tí ó kó wọn jáde kúrò láàrin àwọn orílẹ̀-èdè wọ̀n-ọn-nì,láti ìhà ìlà oòrùn ati láti ìhà ìwọ̀ oòrùn,láti ìhà àríwá ati láti ìhà gúsù.
Ọdun mejidinlogun sẹyin ni abadofin fun awọn akanda yii ti wa niwaju ile igbimọ aṣofin iyẹn ọdun 1999 ti awọn aṣofin kọkọ da a labaa lakoko iṣejọba aarẹ ana, Oluṣẹgun Ọbasanjọ.
Ìkọ BBC Yoruba rí àwọn oṣiṣẹ pajawiri ipinle Ogun ti wọn n tiraka lati kò àwọn nnkán to bajẹ kúrò nínú omí.
Gígùn àgbàlá náà yóo jẹ́ ọgọrun-un igbọnwọ, ìbú rẹ̀ yóo jẹ́ aadọta igbọnwọ, gíga rẹ̀ yóo sì jẹ́ igbọnwọ marun-un pẹlu aṣọ títa tí a fi aṣọ ọ̀gbọ̀ ṣe ati ìtẹ́lẹ̀ idẹ.
Ó gbadura sí i, ó ní kí àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ pín in fún àwọn eniyan.
Tí ẹni ọ̀hún tún bá ṣoríire tó rí ibọ̀sẹ̀ tó bẹ́sẹ̀ ẹ rẹ̀ mu, bàtà nlá yìí ó tún ṣe aláwọ̀ ọ kàlákìnní bákan.
OLUWA ti mú ẹ̀bi yín kúrò,ó sì ti lé àwọn ọ̀tá yín lọ.
O tun so pe ise ti bere ni pereu loju irin Warri si Itakpe, Alli tun fi idunnu re han si aare orile ede Naijria Muhammadu Buhari lati mu eto oko oju irin ni okunkundun.
Ijọba Cross River goment lawọn ti mura de tawọn si ti se ibomu to pọ pẹlu pe wọn pọn dandan lilo rẹ fara ilu.
Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Fídíò, Soyinka Cancer: Àṣe ara mi ni iso ti n run gbogbo bí mo ṣe n ṣèrànwọ́ lórí jẹjẹrẹ27 Bélú 2019 Professor Wole Soyinka láti kékeré13 Agẹmo 2020 Wole Soyinka: Pańpẹ́ ọba lọ̀nà àbáyọ sí ìwà ìbàjẹ́15 Èbibi 2018 Fídíò, Wọle Soyinka: Ti mo ba dara pọ m'ẹgbẹ Obasanjọ, wọn gbọdọ yẹ mi lọpọlọ wo19 Èrèlè 2018 Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Aisha Buhari: Ọ̀pọ̀ aráàlú ní Aisha ti pariwo ṣáájú pé Buhari kọ ló ń darí ìjọba
Minisita Lai Mohammed ni iṣejọba aarẹ Muhammadu Buhari ti fara rẹ jin fun idagbasoke ohun amayedẹrun gbogbo jakejado orilẹede Naijiria; yoo si tẹsiwaju lati pari awọn apati akanṣe iṣẹ gbogbo dipo bibẹrẹ awọn miran.
Aare Mnangagwa so lose to koja pe, orile-ede ohun to wa ni apa ila-oorun ile Africa yoo seto idibo ti ko ni kolofin ninu ninu osu keje odun ti a wa yii, eyi ti o so pe, oun yoo faramo abajade esi idibo naa, bi o ba je pe egbe oselu alatako ni o jawe olubori.
Wọ́n ń gbé àyíká ilé Ọlọrun, nítorí iṣẹ́ wọn ni láti máa bojútó o, ati láti máa ṣí ìlẹ̀kùn rẹ̀ ní àràárọ̀.
Lo ba ni keṣekeṣe ni wọn ri o, pe kasakasa nbọ lọna, eyi to jẹ baba keṣekeṣe ni daada.
Wo bí wọ́n ṣe sìnkú àwọn àgbẹ̀ 43 tí Boko haram dúmbú ní Borno Kí ló dúdú gan nínú ọjọ́ ''Black Friday'' tí ẹ̀gbẹ́ Hisbah takò ní Kano?
Mo ti di 'Mummy Ire', ìgbéyàwó mi sì ọlọ́gbọ́n ọkùnrin tí mú àyípadà bá mi, mo sì ti kúrò ní Toyin tí àwọn èèyàn mọ tẹ́lẹ̀.
Lẹhin ìsìnkú, àwọn ẹbí àti àwọn ọmọ Olóògbé pé jọ lati pín ogún.
Arẹwà Ibidunni Ighodalo wọ káà ilẹ̀ lọ nílùú Eko Ohun tí a rí nílé Ajimobi rèé lẹ́yìn ìròyìn òfégè pé ó jáde láyé Ìwadìí ti bẹ̀rẹ̀ lórí àrá tó sán pa òṣìṣẹ́ FRSC mẹ́ta nípínlẹ̀ Ogun- Ọ̀gá àjọ FRSC Gómìnà márùn ún tó fojú winá ìbínú bàbá ìsàlẹ̀ wọ̀n Àwọn ohun tuntun tí a mọ̀ nípa ìgbẹ́jọ́ Wòlíì Sotitobire Báwó ni òògùn dexamethasone ṣe ń ṣiṣẹ́ lára Awọn to ku naa ni in: Dan Foster ti ile ise radio Cool FM Hugo Odiogor ti ile ise Vanguard Xiavier Ndayongmong ti Daily Independent Nkirukah Udoh ti ile ise AIT Naomi Uzor ni ileeṣẹ Vanguard Aramide Praise Oikelome Media Project and Independent Newspaper Azeez ozi Sanni ayaworan ni The Nation Nkirukah Udoh Awọn iṣẹlẹ to n ja kiri awọn ile iṣẹ iroyin yii ko yọ ile iṣẹ oroyin AIT silẹ bi wọn ṣe padanu akọroyin to tun jẹ gbanumọ akaroyin lori mohunmaworn ile iṣẹ naa.
Inu awọn obi ipinlẹ Oyo dun lẹyin ti ijọba ipinlẹ Oyo ni gbogbo eto ti to lati ri pe awọn da ile iwe ti awọn akẹkọọ maa n gbe inu rẹ pada si ipinlẹ naa.
Lẹ́yìn náà kí o pada wá rú ẹbọ rẹ.
Iṣejọba Aarẹ Umar Musa Yar'Adua lo yọ ọ nipo lẹyin ọsẹ diẹ to bẹrẹ saa keji gẹgẹ bi alaga EFCC.
A fi oju wa rí ọ̀run àpáàdì
Saaju la ti kọkọ mu iroyin wa fun yin pe Ayodele Fayose ti sọ fun ẹgbẹ oselu PDP nipinlẹ Eko pe ayafi ti oloye Bode George ba yẹba ninu ẹgbẹ oselu naa, ni egbẹ PDP to le moke nipinlẹ Eko.
Saaju la ti kọkọ mu iroyin kan wa fun yin pe ọkunrin kan ti wọn fẹsun kan pe o fipa ba ìkókó ọmọ oṣu mẹta lajọṣepọ ti n foju wina ofin bayii ni ile ẹjọ kan ni ipinlẹ Nasarawa.
 Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Èré Ọṣun: Àtáója ní wọn kò jí ère Ọṣun, ó sì wà níbi tó wà Makinde fikun pe awọn osisẹ ti wọn ni ifẹ ilu lọkan, ti ke gbajare tọ oun wa pe, Ajimọbi ti n dete lati ri daju pe ijọba to n bọ ko ni tete ri ẹsẹ walẹ, nipa gbingbọn owo ilu gbẹ."
    “Súnmọ́ hùn-ín, ìwọ Ìrìnkèrindò ọmọ mí, mo Súnmọ́ iwájú ìtẹ́, mo dọ̀bálẹ̀, ọba sì tún ń bá ọ̀rọ̀ rẹ̀ lọ ó ní; 
Oyo , to wa ni ekun Gusu orile ede Najiria, lara awon to wa nibi ayeye ohun ni igbakeji
Gẹ́gẹ́ bí Prem Chand ṣe ti sọ:
Ṣugbọn ko si ọdun ti eeyan ko ṣi le fi ẹjẹ silẹ bo tilẹ jẹ pe awọn orilẹ-ede kan ni ọdun ọgọta si aadọrin ni tiwọn.
Akonimoogba iko Golden Eaglets, Manu Garba so pe o da oun loju pe iko agbaboolu Falconets le jawe olubori ninu ifigagbaga ipele keta idije FIFA U-20 Women World Cup to n lo lowo lorile-ede France, ti won yoo gba pelu iko agbaboolu Spain.
Ìdájọ́ ikú: Ààdọ́sàn-án orílẹ̀-èdè ló ti fòfin de ìdájọ́ ìpànìyàn
Wọ́n ń sọ pé, “Níbo ni eléyìí ti ní irú ọgbọ́n yìí?
26 Àti pé níwọnbí wọn bá nwá ọgbọ́n kí á lè fún wọn ní ẹ̀kọ́;
Ile iṣẹ yii ni wọn ṣẹ ifilọlẹ eto tuntun yii pẹlu ikopa ajọ to n ri si iṣẹlẹ pajawiri loju omi niluu Eko ni ọjọ Ẹti nigba ti wọn ja awọn ọkọ oju omi tuntun lati fi bẹrẹ eto naa.
Tohun ti bi awọn wonyi ṣe n gbero pé ki wọn fi itan lelẹ, paapaa bi ohun tó n ṣẹlẹ ni orile-ede wọn kò ṣe fararọ nitori ogun abẹ́lé to n gbegi dina alaafia ara ilu.
Ṣugbọn ohun to jẹ ki ọpọ ololufẹ eto BBNaija nipa awọn mejeeji ni pe Ozo nífẹẹ Nengi, amọ Nẹngi ni oun ko fẹ ni ololufẹ ninu ile ẹlẹgbọn agba BBNaija.
 Neyman ti bi omo okunrin kan, David Lucca da Silva Santos (7) lati ọdọ orẹbinrin rẹ Carolina Dantas tẹlẹ.
    Lẹ́yìn è’yi, a padà bá ilé Adéforítì lọ, ṣùgbọ́n mo fẹ́ sọ fún yín pé ìgbà tí mò ń sọ̀rọ̀ ‘Ọjọ́ kejì’ ọjọ́ kan àti bẹ́ẹ̀ bẹ́ẹ̀ lọ awa ti a jẹ́ ọdẹ ni a n kà á bẹ́ẹ̀, ìgbà tí ó bá pẹ́ títí tí oorun ba kun ni ti a sì tún jí ni àwa ń pè ní ọjọ́ kejì, ṣùgbọ́n Adéforítì àti ìyá rẹ̀ kò sùn rárá, ilẹ̀ kìí sí í ṣu ní ibẹ̀ pé kí ènìyàn déédéé rí òkùnkùn, ṣe ni gbogbo ilé ń mọ́lẹ̀ títí ọjọ́ ayé láàárò, lọ́sàn-án, lálẹ́, lọ́gànjọ́ òru.
Bẹẹ ni ọrọ ri pẹlu alagba Kamorudeen Aderibigbe, tii ṣe olukọ lọdun 1979, nile ẹkọ alakọbẹrẹ St Michael to wa ladugbo Yemetu, nilu Ibadan.
Ọlamilkekan Adegbitẹ - Minisita fun idagbasoke Irin tutu ati iwakusa.
Góòlù àrámọ̀ndà ló fi gbẹyẹ lọ́wọ́ LASK fún Manchester United ní ìdíje Europa Páro-páro ni àwọn mọ́ṣálááṣí dá káàkiri Nàìjíríà lásìkò ìrun Jímọ̀ nítorí coronavirus Oríṣun àwòrán, others Ààrẹ Laurent Gbagbo ati awọn ọmọ ogun rẹ ni wọn n se akoso guusu ile naa ti awọn ọmọ ogun ọlọtẹ Guilamme Soro si di agbára mú ni ariwa ilẹ náà.
"Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, SARS: Awọn ará ìlú fi ẹ̀rí síta nípa ìrírí wọn Nínú ìkéde Princess Ife lórí Twitter, ó ní ""dájú dájú pẹ̀lú ìrírí mi ó tọ́ láti pe àwọn ọlọ́pàá SARS ní ọ̀daràn."
Ẹni to bori: Nigeria Nigeria Orilẹede Naijiria ni orilẹede ti eeyan inu rẹ pọ julọ nilẹ Afirika, pẹlu eeyan to le ni igba miliọnu, to si wa ni ipo keje lagbaye.
Kíni ẹ̀yin rántí nínú ǹkan ti o ti ṣẹlẹ lọ́dun díẹ̀ sẹ́yìn àti nísìnyìí Ilé-isẹ́ ìpòogùn Johnson & Johnson san biliọnu 8 dọ́là fún ẹni tóògùn gbòdì lára rẹ̀!
Ọba tí ó dájọ́ ẹ̀tọ́ fún talaka,ní a óo fìdí ìjọba rẹ̀ múlẹ̀ títí.
Ẹ jẹ ka wo diẹ lara awọn eeyan ọhun.
Alayeluwa lo sọ ọrọ naa loju opo Instagram rẹ lẹyin to gbalejo awọn ọdọ kan ninu afin rẹ to wa ni Ife.
Lẹyin ti ijọba ni awọn ti gbọ ti wọn tu SARS ka, awọn ọdọ tun kọ lati dawọ iwọde duro.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ori kan bọ́dì ree o.
Solomoni ọba fi ẹgbaa mọkanla (22,000) mààlúù ati ọ̀kẹ́ mẹfa (120,000) aguntan rúbọ.
Ẹ ranti pé a ti sọ gbogbo èyí fun yín nígbà tí a wà lọ́dọ̀ yín.
Human Calculator: N kò lo idán àbí àlùpàyídà fún ìṣirò ọpọlọ tí mò ń ṣe
Kí wọn má máa ja ọ̀gá wọn lólè.
Lootọ mo maa n ro pe ọjọ ibanujẹ nla gbaa ni sjọ naa, ams nigba ti mo roo nidakeji, mo ri pe ọjọ ibukun ati ọjọ ayọ lo jẹ ninu igbesi aye mi.
Bí o bá fẹ́, èmi yóo pa àgọ́ mẹta síhìn-ín, ọ̀kan fún ọ, ọ̀kan fún Mose ati ọ̀kan fún Elija.
Bí a bá ti wí fún ọ ni kí o ṣe.
Ẹ kò gbọdọ̀ fi ọmọ yín fún àwọn ọmọkunrin wọn láti fẹ́, bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò gbọdọ̀ fẹ́ ọmọ wọn fún àwọn ọmọkunrin yín.
Adájọ́ ti pàṣẹ pé kí wọ́n mú ọmọ Rasheed Maina, Faisal, tó sá mọ́ ilé ẹjọ́ lọ́wọ́: Ọrọ ti Senetọ Ndume la kọkọ gbọ nipa alaga igbimọ ti ijọba Naijiria gbe kalẹ lati ṣatunto eto owo ifẹyinti, Abdulrasheed Maina to sa mọ ile ẹjọ lọwọ.
 ( aládésurú , 1985 ) orúkọ tí a mọ ̀ mọ ́ ewì yìí ní agbègbè Èkìtì ni orin olorì .
Lọ́wọ́ àwọn ará Hiti ni wọ́n ti ra ilẹ̀ náà ati ihò òkúta tí ó wà ninu rẹ̀.
Wọn yóo máa wo ojú wolii fún ìran ṣugbọn kò ní sí, alufaa kò ní náání òfin mọ́, bẹ́ẹ̀ ni kò ní sí ìmọ̀ràn mọ́ láti ọ̀dọ̀ àwọn àgbààgbà.
A kò fipá mú ẹnikẹ́ni láti dá Ruga, aàgọ́ Fulani sílẹ̀ -Iléeṣẹ́ aàrẹ Àdúrà kò le pa ìfipábánilòpọ̀ rẹ́, àtàwọn àkọlé mìí tó jẹyọ lórí ọrọ Fatoyinbo NFF ti san owó àjẹ́mọ́nú Super Eagles Àwòrán apanilẹ́rìn-ín fún ọ̀sẹ̀ yìí, ìtọ́wò rèé Gẹgẹ bii atẹjade kan ti Ọga agba ajọ to n moju to iṣẹlẹ pajawiri nipinlẹ Eko LASEMA, Ọmọwe Oluwafẹmi Oke-Ọsanyintolu fi sita, o ni oku eeyan mẹjọ ni wọn ti fa jade ninu agbami bayii.
Ikubese ni titẹ okunrin lọdaa ko da ibalopọ duro.
A ó ran àwọn àgbẹ lọ́wọ́ ní Ondo oludije ipo gomina ni ipinlẹ Ondo labẹ asia ẹgbẹ oṣelu Peoples Democratic Party, PDP, Eyitayo Jegede ni ọrọ awọn agbẹ ko ṣee fọwọ rọ sẹyin ni ipinlẹ Ondo torinaa oun yoo ṣeranwọ fun wọn.
"’ Ààrẹ Buhari ti lọ sí ìlú Daura fún ọdún Sallah ""Bí Zakzaky yóò bá lọ gba ìtọ́jú ní India, ó gbọdọ̀ ṣe àwọn nǹkan wọ̀nyìí"" Gbígba onídùròó Zakzaky ṣàfihàn àṣeyọrí ìfaradà wa lásìkò ìfìyajẹni - Shiite Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, ''Ọjà ẹran àgbò kò yá bí ti ọdún tó lọ'' Ti oorun ba ti jade ni ọjọ yii, ni awọn musulumi ti wọn lo bi ilẹ mimọ yoo bẹrẹ irinajo lọ si Oke Arafa to wa ni Mecca."
Awọn ajọ naa ni, iṣẹlẹ ẹkun omi naa ti n kankun ni lọwọlọwọ bayii nitori gbogbo awọn ohun atọka to ṣe atọna fun iṣẹlẹ ẹkun omi lọdun 2012 ti farahan bayii.
yege lati gba esi ibo naa bo se wa , ki o si fi ẹmi isejọba han.
Ọwọ́ ọlọ́pàá ti tẹ àwọn 41 ènìyan lórí ìkọlù ní South Africa Iṣẹ́ ṣẹ̀ṣẹ̀ bọ́ lọ́wọ́ Seth Ator tó yìnbọn pa ọ̀pọ̀ èèyàn ní Texas ni- ọlọ́pàá Tàbi Ikorodu/ Itoikin/ Ijebu-Ode-Benin/Ore Akínbiyi ni àtunṣe òpópónà oní kìlómítà ẹgbẹ̀ta náà yóò wáye láti ọjọ́ keji, oṣù kẹsàn an sí ọjọ́ kẹẹ̀dógun, oṣù kejila, ọdún 2019.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Kano rape cases: Muhammad, ẹni ọdún mẹjìlélọgbọn jẹwọ bí òun ṣe ń fipábá àwọn obìnrin ogójì lò pọ 12 Òkùdu 2020 Oríṣun àwòrán, Kano Police Ọpọ awọn eeyan lo ti ṣe iwọde loriṣiriṣi lori ọrọ ifipabanilopọ to n fojoojumọ pọ sii ni Naijiria lasiko yii.
Premier League: Man City ti fàgbà han Fulham pẹ̀lú 2-0
oludamoran  tuntun naa lati maa tẹti silẹ
Mo tún ṣe ilérí lónìí pé, bí ó ti wù tí inú bí mi tó, ọ̀rọ̀ burúkú kò ní ti ẹnu mi jáde si i.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Seyi Makinde: Ìrírí, ọ̀gbọ́n àti ìmọ̀ ìgbìmọ̀ yìí yóò ṣèrànwọ́ fún ìjọba mi 21 Òkùdu 2019 Oríṣun àwòrán, Oyo state Government Igbin tẹnu mọ igi, o gun, ni Gomina Seyi Makinde fi ifilọlẹ igbimọ olugbaninimọran to kede laipẹ yii se.
Eliakimu, ọmọ Hilikaya tí ó jẹ́ alákòóso ààfin jáde lọ bá wọn pẹlu Ṣebina, akọ̀wé ilé ẹjọ́, ati Joa ọmọ Asafu, akọ̀wé ààfin.
Coronavirus in Nigeria: Àjọ NCDC tún ti kéde ènìyàn 148 míràn tó ní ààrùn Covid-19 l'órílẹ̀-èdè Nàìjíríà Esi ayẹwo aarun Covid-19 tun ti fihan pe eeyan mejidinlaadọjọ lo tun ti ni aarun naa l'orilẹ-ede Naijiria.
Ó kọ́ ìlú Tadimori ní aṣálẹ̀, ati gbogbo ìlú tí wọn ń kó ìṣúra jọ sí ní Hamati.
Ṣugbọn ní àkókò yìí ẹ ti bọ́ sinu ìmọ́lẹ̀ nítorí ẹ ti di ẹni Oluwa.
Ọ́pọ̀lọ̀pọ̀ miliọ̀nu ni wọ́n ti sọ di alairilegbe.
 Ẹ ̀ ka-èdè Ìgbómìnà Òrò sì jẹ ́ ọ ̀ kan lára ẹ ̀ yà ẹ ̀ ka-èdè Ìgbómìnà tí wọn ń sọ ni ẹkùn Òrò .
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ki o to binu, ki o to ja.
Sugbọn lẹyin asiko diẹ, egungun naa tobi si i, ni mo ba tun pada ṣenu isẹ.
Aare tun gbosuba fun gomina naa fun aseyori re lori  eto mimu igbe aye iderun  ba awon ara ilu ni ipinle Jigawa, aare wa ro awon ipinle ti won ko ti I maa gba lara  ẹ̀ẹ́dẹ́gbẹ̀ta  bilionu naira ti won ya soto lati fi mu igbe aye iderun ba ara-ilu, tete maa  je anfaani yii.
Alaafin, Ọba Lamidi Adeyẹmi III ni ojumọ kan wahala kan loun koju fun ogun ọdun akọkọ ti oun lo loye.
won n sin, iru asiko bayii ni a maa n fi dupe lowo Olorun , a si n tun n
Ninu ọrọ tirẹ, olori akọnimọọgba Super Eagles, Gernot Rohr, sọ pe o da oun l'oju pe Naijiria ni anfaani lati gba ife.
Linda fi kun un ọrọ rẹ pe o tiẹ buru tan patapata nigba ti oun loyun tan fun Sholaye.
Ìwọ Israẹli, n óo sọ ọ́ di iyawo mi títí lae;n óo sọ ọ́ di iyawo mi lódodo ati lótìítọ́,ninu ìfẹ́ tí kì í yẹ̀ ati àánú.
Ṣugbọn àwọn ọkunrin náà kọ̀, wọn kò dá a lóhùn.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìbálòpọ̀ fún máàkì: Monica fojú hàn níwájú ìgbìmọ̀ OAU 25 Ìgbé 2018 Oríṣun àwòrán, @OfficialOAU Àkọlé àwòrán, Ohùn un ọ̀jọ̀gbọ́n Akindele tí o ń bèèrè fún ìbálòpọ̀ ìgbà lọ́wọ́ akẹ́kọ́bìnrin kan bọ́ sójú agbami ayélujára lọ́sẹ̀ díẹ̀ sẹ́yìn Akẹ́kọ̀ọ́ fásitì Ọbáfẹ́mi Awólọ́wọ,̀ OAU tó wà nílùú Ilé ifẹ̀, Monica Osagie, tí ohùn rẹ̀ wà nínú fọ́nrán ohùn àkásílẹ̀ kan nínú èyí tí ọ̀jọ̀gbọ́n kan ní ẹ̀ka ìmọ̀ nípa ìṣirò owó ní fásitì náà, tó ń béèrè fún ìbálòpọ̀ ìgbà máàrún ọ̀tọ̀ọ̀tọ̀ nítoríi máàkì, ti fìdí rẹ̀ múlẹ̀ pé lóòótọ́ ni ọ̀jọ̀gbọ́n Akíndélé béèrè fún ìbálòpọ̀ láti bá fún òun ní máàkì.
Lẹ́yìn náà, láìpẹ́ ẹ óo sì tún rí mi?
Èèyàn 216 míràn ṣẹ̀ṣẹ̀ kó COVID-19 ní Nàìjíríà Àwọn ará ìlú Ikarẹ Akoko ń ṣọ̀fọ̀ Ọba Adegbite, Ọwá Ale Ikarẹ tó wàjà Bàbá ẹni ọgọ́ta ọdún dèrò ilé ẹjọ́ nítorí ó wọ inú oko Obasanjo láì gba àṣẹ Bí ìjà bá wà láàrin èmi àti Olubadan, a ó yanjú ẹ ní pẹ̀lẹ́kùtù, ọ̀rọ̀ bàbálọ́jà kò lè dìjà Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Baby abandoned on dunmpsite: Mo ti bímọ mẹ́rin tẹ́lẹ̀ fún bàbá méjì nínú òṣí- Dupe Ogbomos Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Ikare Monarch: Ọdún méjìdínláàdọ́ta ní Oba Adegbite-Adedoyin ló lókè èèpẹ̀, kó tó mí kanlẹ̀2 Owewe 2020 6:18 Fídíò, Akomolede: Bolaji Faleke ni Olùkọ́ tó ń kọ́ wa ní àṣà oge ṣiṣe lórí BBC Yorùbá, Duration 6,181 Owewe 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 3 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 5 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Ó wá bi wọ́n pé, “Àwòrán ati àkọlé ta ni ó wà ní ara rẹ̀ yìí?
Ni asiko ti wọn n fi iroyin yii lede, ijọba ni awọn ṣi n tiraka lati kapa awọn jagidijagan naa.
Kòṣẹlẹ̀rí ni Hajj ọdún 2020, wo ìyàtọ̀ tó wà nínú rẹ̀ sí ti tẹ́lẹ̀ Inú wa kò dùn pé Seyi Makinde ṣílẹ̀kùn iléẹ̀kọ́ padà l'Oyo - Àwọn òbí Awọn obi kan tako bi ijọba Seyi makinde se si ileewe pada nipinlẹ Ọyọ.
O tun wa rọ gomina tuntun naa lati kilọ fun awon alatileyin rẹ lati maa
Ta ló fẹ́ fi ẹ̀sùn kàn mí?
Bí kò bá ṣe pé OLUWA àwọn ọmọ ogun dá díẹ̀ sí ninu wa ni,à bá rí bí i Sodomu,à bá sì dàbí Gomora.
Loju Oludije labẹ ẹgbẹ oṣelu Action Democratic Party, ko si ohun to buru ninu yiyan ọmọ iran miran bii Igbo sipo nipinlẹ Eko ṣugbọn ẹni naa gbọdọ kunju oṣunwọn to.
Ẹni tí ń ṣọ́ ilé ẹ̀wọ̀n náà bá bèèrè iná, ó pa kuuru wọ inú iyàrá, ó ń gbọ̀n láti orí dé ẹsẹ̀.
Certificate forgery: Olùpẹ̀jọ́ ni òun kò ṣẹjọ́ mọ pẹ̀lú gómìnà Kwara
O ni èròjà CVD PLUS tó wà nínú rẹ lo ń gbógun ti àwọn kòkòrò àrùn tí a kò leè fojú rí, tó sì tún ń mú agbega bá àwọn ọlọ́pàá tó ń dáàbò bo ara, èyí tó lè ṣe iranwọ láti bá àwọn àrùn to jọ mọ Coronavirus ja.
Nigba ti o n sọrọ nibi eto ilanilọyẹ fun awọn ọmọ ile tuntun niluu Abuja, Dogara sọ fawọn eekan nilu ẹgbẹ oṣelu, lati jẹ ki awọn ọmọ aṣofin mọ igbesẹ wọn lori ati yan olori.
Jehoiada sì fi àwọn olùṣọ́ tí wọ́n wà lẹ́nu iṣẹ́ sí ìtọ́jú ilé OLUWA.
Àwọn Giriki mélòó kan wà ninu àwọn tí ó gòkè lọ sí Jerusalẹmu láti jọ́sìn ní àkókò àjọ̀dún náà.
Ọ̀kọ̀ọ̀kan ninu àwọn ẹ̀dá alààyè mẹrin náà ní apá mẹfa.
Àwọn aláṣẹ rí èyí gẹ́gẹ́ bí ìwọ̀sí gidi tí wọ́n sì lé ọgọọgọ̀rún akẹ́kọ̀ọ́ kúrò ní àwọn ilé ẹ̀kọ́ lóríṣìíríṣi káàkiri orílẹ̀-èdè náà.
Ni ẹni ọdun mkandinlọgbọn ni Sultan yii gbajọba lọwọ baba to bi i lọmọ, Said bin Taimur lasiko itajẹsilẹ buruku kan ti ilẹ Britain ṣatilẹyin fun lọdun 1970.
O kere tan ogun eniyan loti padanu emi won, ti àádọ́rin eniyan miran si farapa yanayana ninu ikolu ti o waye lojo Aiku(Sunday) laarin awon omo-ogun olote ati omo ogun ijoba India.
Pupọ ninu awọn ọmọ ilẹ Yoruba lo maa n gbọ owe oke yii ṣugbọn ti wọn kọ mọ itumọ rẹ.
 Àjọ yí tún ń ṣagbátẹrù fún àwọn ohun tí ó jẹ mọ ́ àṣà , bẹ ́ ẹ ̀ náà ni ó tún ń pèsè ẹ ̀ kọ ́ ọ ̀ fẹ ́ fún àwọn akẹ ́ kọ ̀ ọ ́ tí wọ ́ n ti kẹ ̀ kọ ̀ ọ ́ gboye kúrò ní fàsitì àmọ ́ tí wọ ́ n ṣì ń ṣe iṣẹ ́ ìwádí ìmọ ̀ ìjìnlẹ ̀ nípa ìmọ ̀ akiọ ́ lọ ́ jì àti ìmọ ̀ iṣẹ ́ àgbẹ ̀ .
Itan igbe aye Ẹfunsetan Aniwura: Laarin ọdun 1790 si 1800 ni Oloye Ẹfunsetan Aniwura de ilẹ aye.
eleyi ti o mu ki awon emewa re naa dibo gege bi oludari won.
Iwe iroyin South China Morning Post gbe iroyin jade nipa obinrin kan to ba ara arẹ nileewosan lati gba itọju nitori pe ọfun rẹ wu ju boṣeyẹ lọ lẹyin to jẹ kilogiramu kan aabọ galiiki tutu.
Bẹẹ naa lo tun rọ awọn obinrin lati kan si awọn to sunmọ wọn fun iranlọwọ.
Ó dìde, ó bá gba ìrìbọmi.
Àwọn tí OLUWA rà pada yóo pada,wọn óo wá sí Sioni pẹlu orin,ayọ̀ ayérayé yóo kún inú wọn.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Labẹ ijọba Romu, ẹya Giriki, Juu ati Egipti lo korajọ pọ n jẹ ẹlẹsin kristẹni Coptic.
Ọgbọn Imuṣẹṣe ninu Ile Igbimọ Aṣofin Ipinlẹ Eko ṣe agbateru rẹ ni
ti ro awon eniyan ki won lo dibo won ni irowo-irose, ki won si keyin si oro kunba-kungbeti
Idà ni yóo pa àwọn awoṣẹ́ wọn,kí wọ́n lè di òpè!
Àwọn ọmọ Jafani ni: Eliṣai, Taṣiṣi, Kitimu ati Dodanimu.
O ni awọn pasitọ to n lọ tẹnu bọlẹ kiri lọdọ ijọba tabi oloṣelu n wa ohun ti wọn a jẹ kiri ni amọ oun o ki n ṣe eeyan bẹẹ́.
 kìí se pé àwon òrò-ìse wònyí kò lè yan àfikún mìíràn sùgbón àtúnpínsòrí tí a bá fún òrò kan ni a gbódò tèlé bí béè kó , gbólóhùn tí ó ti je yo kò ní í bófin mú .
OLUWA, mo mọ̀ pé ọ̀nà ẹ̀dá kò sí ní ọwọ́ ara rẹ̀.
Oun ti o ba wa yatọ.
1838 ursa jẹ ́ plánẹ ́ tì kékeré ní ibi ìgbàjá ástẹ ́ rọ ́ ìdì .
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Lekki Shooting: UN, Biden, Clinton àtàwọn gbajúmọ̀ lágbááyé tó korò ojú sí ípànìyàn Lekki 21 Ọ̀wàrà 2020 Oríṣun àwòrán, @JoeBiden Akọwe Gbogboogbo fun ajọ agbaye, United Nations, Antonio Guterres, ti bu ẹnu ẹtẹ lu ipaniyan to waye nipinlẹ Eko ni ogúnjọ, oṣu Kẹwaa.
idaniloju pe o pari ẹkọ rẹ gege bi ohun ti o wa ninu iwe iforukọsilẹ  ile-iwe naa todun  1980”.
Saaju ki Donald Trump to buwọlu aṣẹ yi, orileede US ti lewaju awọn to n fin ina mọ awọn orileede miran lati yago fun ile iṣẹ Huawei.
Eyi si lo mu ki ọga agba ọlọpa nilẹ wa, Mohammadu Adamu fi fi ilu Abuja silẹ, wa se ipade pẹlu awọn gomina atawọn eeyan ti eto aabo gberu lẹkun iwọ oorun guusu Naijiria.
títí di ọjọ́ tí a gbé e lọ sókè ọ̀run lẹ́yìn tí ó ti pàṣẹ ohun tí ó fẹ́, nípa Ẹ̀mí Mímọ́, fún àwọn aposteli tí ó ti yàn.
Ọpẹlọpẹ dokita mii ti o ba nibi to tun wo o pe kawọn tun ṣi lọ lati bẹrẹ ayẹwo lakọtun, lo ba ri bẹbẹ to ju bẹbẹ lọ.
Ọjọ́ kìíní, oṣù kìíní, ọdún 1978 ni a bí òṣèré Tíátà, olùdarí eré àti oníṣòwò yìí.
June 12: Ère tuntun tí Ìpínlẹ̀ Eko mọ fún MKO Abiola
Ọmọ a mi malu ṣ’ọdún ìgbàgbọ́
Ẹ máa yẹ́ irú àwọn bẹ́ẹ̀ sí.
Bí ìṣọ̀kan yoo ṣe dé ilẹ̀ Yorùbá ati ipinlẹ̀ Ọ̀ṣun ni a ń wá.
Ṣugbọn àwọn oníjàngbọ̀n kan dáhùn pé, “Báwo ni eléyìí ṣe lè gbà wá?
Nítorí náà, ẹ̀yin ará mi, nígbà tí ẹ bá péjọ láti jẹun, ẹ máa dúró de ara yín.
Ninu atẹjade ti akọwe fasiti naa, Ọgbẹni Oladejo Azeez fi sita, ṣalaye pe igbimọ naa yọ ọ nipo lori ẹsun aṣẹmaṣe ati iṣowo ileewe kumọkumọ.
 orísun omi lè níí ṣe pẹ ̀ lú títànkáàkiri .
O ni oun ṣe bẹẹ lati lee tubọ jawe sobi irinajo oun nile aye ni.
com/Trem6676 Amọ ọpọ awọn obinrin to ti ni aisan jẹjẹrẹ, amọ ti ori ti ko yọ, ni ko lee se lai ma wọ kọmu nitori wọn nilo lati fi kọmu gbe fukẹfukẹ soke, eyi ti wọn se rọpo ọmu fun wọn lẹyin isẹ abẹ ti wọn fi ge ọyan wọn kuro.
Nítorí pé àìmọye ìdààmú ló yí mi ká,ọwọ́ ẹ̀ṣẹ̀ mi ti tẹ̀ mí,tóbẹ́ẹ̀ tí n kò ríran.
itupalẹ eto iṣuna owo yii, Gomina ṣalaye pe awọn ti ṣamulo iṣuna owo
Ki ni ounjẹ ti ẹ ro pe N117,000 le ra ni ojoojumọ?
Bi a ko ba gbagbe, laipẹ yi ni awuyewuye waye lori bi aarẹ Naijiria ti ṣe paṣẹ lọ rọọkun nile fun adajọ agba orile-ede naa, Adajọ Walter Onnoghen.
Anbua so pe, awon akosile lati awon agbegbe ijoba ibile yoku ni won yoo gbe sita laipe ojo.
Nígbà tí Banaba ati Saulu parí iṣẹ́ tí a rán wọn, wọ́n pada láti Jerusalẹmu, wọ́n mú Johanu tí àpèlé rẹ̀ ń jẹ́ Maku lọ́wọ́.
Ami ohun ṣe pataki pupọ ki a le maa gbọ ara wa ye.
ṣugbọn ó bi Farao ati àwọn ọmọ ogunrẹ̀ ṣubú ninu Òkun Pupa,nítorí pé ìfẹ́ rẹ̀ tí kì í yẹ̀ wà títí lae.
7) Yọ awọn aapu ti o ko nilo tabi ti o kii lo nigba gbogbo Njẹ́ ó mọ àwọn àìsàn aṣeku pani to rọ mọ ooru?
Ijọba apapọ ri kaadi idanimọ bi ohun to wulo fun eto aabo, bakan naa lo ṣe pataki fun eto ọrọ aje Naijiria.
Emi ti n jẹ ki aṣa wa wu awọn eeyan lati ilu Iwo.
Ẹ̀mí ni ó gbé e tí ó fi ń sọ ohun àṣírí tí ó ń sọ tí kò yé eniyan.
"Ẹẹkan ni ọdun mẹta ni ijọba ma n ṣi i tẹlẹ, ti a si ma n gbaradi fun un, amọ lati ọdun mẹrin sẹyin ni wọn ti n ṣi i lọdọọdun.
Àwọn obinrin meji yóo máa lọ ògì, a óo mú ọ̀kan, a óo fi ekeji sílẹ̀.
Nigba to n sọrọ lori idi to fi gbe igbesẹ naa, Sunday Igboho salaye pe oju ko gbọdọ ti ilẹ Yoruba lo mu ki oun fi ẹmi ara oun lelẹ lati lọ koju awọn afurasi apamọ lẹkun jaye naa.
Lori faran Twitter rẹ, ileesẹ FAAN so wipe kiakia ni wọn le awọn maalu naa kuro lojuona ti wọn si fun baalu naa l'ase ati ba.
Awọn iroyin ti ẹ lee nifẹẹ si: Obasanjo, Fayose ṣe'pade pẹlu aare Buhari l'Abuja Tunde Bakare: Idamẹwa kii ṣe dandan fun Kristẹni O dẹrin pẹẹkẹ awọn to ba wa ninu ibanujẹ Adeolu Adeleke (Abẹnugan ile asofin ipinle Ọyọ laarin ọdun 2003-2007) se iranti Arisekola Alao pẹlu ibanujẹ ọkan.
5 biliọnu ni wọn fi ṣeto idibo l'Amẹrika.
Ẹ gbọ́ ohun tí Desmond Elliot sọ lórí ayélujára tó bí àwọn ọmọ Nàìjíríà nínú Wo bí o ṣe le fi orúkọ sílẹ̀ láti gbà nínú N75b tí ìjọba fẹ́ ẹ̀ fún àwọn ọ̀dọ́ láti dá iṣẹ́ sílẹ̀ Kìí ṣe ebi, ìyà tàbí ìṣẹ́ ló mú kí wọ́n yabo àwọn ilé ìkẹ́rùsí - Femi Adeshina Mi ò ṣẹ̀ máa pín ǹkan lọ́wọ́ ara mi fún aráàlù, ilé mi gangan kọ́ ni wọ́n ti jí Palliative"" kó - Họ́nọ́rébù Agunbiade Ohun ati awọn akẹgbẹ rẹ kan ni wọn kọwọrin ṣayẹwo si ile ikẹru irinṣẹ ilera pamọ si ni Lokoja."
irène joliot-curie ( 12 september 1897 - 17 march 1956 ) je onimo sayensi ara fransi , ohun ni omobinrin marie skłodowska-curie ati pierre curie ati iyawo frédéric joliot-curie .
 Ó lè wáyé látàrí àìfọkànbalẹ ̀ tàbí bíbàjẹ ́ ẹṣọ ́ ara .
’’Ogbeni Shittu ni ijoba ti ra
O kò fún aláàárẹ̀ ní omi mu,o kọ̀ láti fún ẹni tí ebi ń pa ní oúnjẹ.
Sheffield faṣọ iyì ya mọ́ Chelsea lára lọ́nà ìrìnàjò sí Champions League 11 Agẹmo 2020 Oríṣun àwòrán, Getty Images Aye ma le o, ẹgbẹ agbabọọlu Sheffield United fi oju Chelsea ri mọ bo lọjọ Satide ninu idije Premier League.
Nigba ti BBC News Yoruba kan si alagba Mustapha Hussein Ọlanrewaju to jẹ akọṣẹmọsẹ iṣuna ati isiro owo, o ni ko souhun to buru ninu ohun ti ajọ naa sọ ati pe labẹ ofin, Laycon gbọdọ san owo ori lori ẹbun tẹtẹ oriire to jẹ naa.
Gẹgẹ bi wọn ti se sọ, awọn ẹsọ Aisha Buhari ko jẹ ki amugbalẹgbẹ yi wọ Aso Rock nitori pe wọn ni o seese ki o ti ko Covid-19 lati ibi to ti n bọ.
Kíni Yorùbá ṣe ń kí èèyàn báyìí: 'Ẹ kú arógun'
Gbogbo wa bá bẹ́ sí eré sísá.
Nigba ti iwadii naa bẹrẹ, ohun ti Ile Igbimọ Aṣofin fẹ mọ ni bi ogoji miliọnu Naira ṣe di awati ni ajọ naa.
oun ti dari awon ajo agbofinro ati ẹsọ eleto aabo lati fọwọsowọpọ pẹlu ipinlẹ to wa lorile ede yii ,
Nigeria 2019 Elections: Àwòrán bí Ilọrin ṣe gbàlejò Yẹmi Ọṣinbajo
Àwọn iròyin tì ẹ leè nífẹ̀ síí: BBOG: Ọdún kẹrin kò láìrí áwọn ọmọ tó sọnù pé Aláwàdà ni Buhari - Fáyóṣé Ọọ̀ni : Oluwo lorukọ oyè tí ọba Ìwó ń jẹ́ Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Igboho, ẹni tó gbé ìmọ̀ràn náà kalẹ lásìkò tó ń sọ̀rọ̀ lórí ìṣẹ̀lẹ̀ kan tó wáyé ládùúgbò rẹ, Soka nílùú Ibadan lọjọbọ tokọjá, tún korò ojú sí Auxiliary, lórí bó ṣe da omi àlàáfíà ìlú rú ládùúgbò Challenge sì Bẹẹrẹ n'ilu Ibadan laipẹ yìí.
Odunlade Adekola, Femi Adebayo, Jenifa ṣi aṣọ lójú àwọn fíìmù tuntun tẹ́ẹ ti ń retí Toyin Abraham pé 40, wo ohun márùn ún tó mú dá yàtọ̀ láàrín ogójì ọdún Bí mo bá wọlé padà, mí ò lè yàn Ize Iyamu tàbí Osagiobare sípò olùbádámọ́ràn- Obaseki Owó oúnjẹ ni mo lọ ọ gbà, oyún ọmọ tí mo jù sí àkìtàn ni mó gbé wálé- Dupe, ìyá Muiz Bákan náà ni ọkọ̀ òfurufú méjì míràn, Delta àti British Airways náà ṣe e ṣe kó bẹ̀rẹ̀ si ni fò láti pápákọ̀ òfurufú náà lónìí.
Àwọn arabinrin mejeeji yìí ranṣẹ lọ sọ́dọ̀ Jesu pé, “Oluwa, ẹni tí o fẹ́ràn ń ṣàìsàn.
" Ó jẹ ́ àpẹrẹ àdàpọ ̀ àìníọ ́ rgánì tó "" únfọ ́ "" ní tẹ ́ mprétọ ̀ tó lọ ́ wọ ́ rọ ́ , láti yípadà sẹ ́ yìn láti polymer sí mólékùlù ."
"A dúro bí iké lẹ́yìn ìròyìn táa gbé jáde nípa Lekki Tollgate; CNN tako Lai Mohammed DSS ṣèlérí iwadìí tí kò rújú lórí bí òṣìṣẹ́ rẹ̀ kan ṣe yìnbọn pa fẹ́ńdọ̀ lẹ̀yìn Gbajabiamila Saka ń wá ọ̀rẹ́ rẹ̀ kan nítorí aṣọ kóòtù ọdún 34 sẹ́yìn Ninu iwaasu rẹ kan to ṣe ninu oṣu Kẹjọ, ọdun 2020, Oladele ni ""okoowo to lamilaaka julọ nile aye ni ki eeyan gbaju mọ iṣẹ rẹ."
Sibẹsibẹ OLUWA, ìwọ ni baba wa,amọ̀ ni wá, ìwọ sì ni amọ̀kòkò;iṣẹ́ ọwọ́ rẹ ni gbogbo wa.
ẹṣọ aṣạbode ati awọn miiran bẹẹ n lo uhun ija, ko si ohun ti yoo da Ile
Ilé ẹjọ́ pàṣẹ kí Sẹ́nétọ̀ Elisha Abbo san N50m fún obìnrin tó fìyà jẹ Oríṣun àwòrán, Punchng Saaju la ti mu iroyin wa fun yin pe, ile ẹjọ giga ilu Abuja, to wa ni Maitama, ti dajọ pe ki sẹnetọ to n ṣoju ẹkun idibo Ariwa Adamawa, Elisha Abbo, san aadọta miliọnu Naira, gẹgẹ bi owo itanran, fun oṣiṣẹ ile itaja kan to fi iya jẹ.
Tesiwaju si, ogbeni Ahaziah salaye pe, ile-ise akoroyin Voice of Nigeria nikan ni ofin fayegba lati ma a safihan aworan ati awon isele lolokan-o-jokan bi o se n sele lorile-ede Naijiria fun awon eniyan lagbaye.
Chief Imam Sheikh Yahaya Oshoala to n dari mọṣalaṣi Oriwu Central, ni Ikorodu ni ipinlẹ Eko ni guusu Naijiria naa gbadura ọdun fun gbogbo wa pe.
O ní gbogbo ìbọ̀n ti wọ́n yìn níbẹ̀ kìí ṣe ìbọn gangan bíkose ọta ìbọn alátìkè Ẹ̀wẹ̀, gbogbo ènìyàn ló tí n bẹ̀nu àtẹ́ lu gómìnà ìpińlẹ̀ Eko Babajide Sanwo-Olu lórí ìṣẹ̀lẹ̀ Lekki Shooting, nílẹ̀ yìí àti lókè Okun.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Coronavirus in Nigeria: K1 de Ultimate ní káwọn ọmọ Nàìjíríà tí kò bá ńidìí láti jáde ó gbé inú ilé wọn 21 Ẹrẹ̀nà 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 4 Ìgbé 2020 Oríṣun àwòrán, k1 de ultimate Agba oye Wasiu Ayinde Ọmọgbọlahan ti ọpọlọpọ eeyan mọ si K1 ti ke sawọn ọmọ orilẹede Naijiria pe pẹlu bi nnkan ṣe n lọ yii lori arun coronavirus, gbogbo ẹni ti ko ba ni nnkan to nṣe ki wọn gbe ile wọn ni.
fi kun owo ti won maa n fun awon ipinle losoosu lorile ede Naijiria, ki o lee
Atiku sọ pe Akinjide gbe igbeaye to ni ipa gẹgẹ bi amofin, oloṣelu ati olori ilu.
Ìbẹ̀rù OLUWA a máa mú kí ẹ̀mí eniyan gùn,ṣugbọn ìgbé ayé eniyan burúkú yóo kúrú.
Nígbà tí o bá dé ibẹ̀, fi àmì òróró yan Hasaeli ní ọba Siria.
Ìmọ́lẹ̀ sì ti tàn sí àwọn tí ń gbé ninu òkùnkùn biribiri.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Yollywood: Bákan náà ni àwòrán Sikiratu Sindodo tó ń ṣọjọ́ ìbi, gba orí ayélujára 21 Èrèlè 2020 Oríṣun àwòrán, ourlovefrotoyinabraham Eyi ni agbeyẹwo awọn nnkan tawọn oṣere tiata Yoruba, Yollywood ṣe lọsẹ yii.
Nitori naa lo ṣe ṣe pataki fun ijọba lati kọkọ mojuto awọn ipenija to wa nilẹ bi eto aabo, to ti mu ki awọn agbẹ fi oko silẹ, ati ina mọnamọna.
Ó ní, “Bí ìjọba ọ̀run ti rí nìyí.
Atọmọde ati agba lo tuyaya jade fun ajọyọ ọdun egungun tọdun yii, gẹgẹ bi iṣe wọn lọdọọdun nilu Iwo.
Folashade ni a fi bi ẹni pe baba oun sọ asọtẹlẹ ni, nitori pe fifẹ ti oun fẹ Ọba Lamidi Adeyemi, ti pari aawọ to wa laarin rẹ ati awọn eniyan Isalẹ Oyo, bo tilẹ jẹ pe awọn kan ṣi n binu.
A gbẹ́sẹ̀ lé ilé kan tó jẹ́ ti Bukola Saraki, torí àpò ìjọba ló ti mú owó sanwó ilẹ̀ - Ilé aṣòfin Saraki: Ìwà àrékérekè ni ilé mi tí EFCC tì pa Bukola Saraki fi 'Gbas Gbos' ọ̀rọ̀ ránṣẹ́ lórí 'ilẹ̀ bàbá rẹ̀' tí ìjọba Kwara gbà padà Fulani kò leè dúró, táa bá lo ohun ta jogún lọ́dọ̀ àwọn bàbá wa - Sunday Igboho Wọ́n ti ti ilé ìjọba Kwara pa ní Ilọrin nítorí ọ̀rọ̀ ilé Arúgbó!
BBC African Footballer 2018: Mohamed Salah wà lára àwọn tí yóò du àmì ẹ̀yẹ Asisat tún gbá bọ́ọ̀lù sí àwọ̀n Equatorial Guinea nígbà tí eré di ìṣẹ́jú mẹ́tàlélógún (23).
Ehuriah, tun wa ro awon oga agba mewaa miiran ti o tun je anfaani igbega lenu
Jakọbu bá fi ẹnu ko Rakẹli lẹ́nu, ó sì bú sẹ́kún.
Saaju la ti mu iroyin wa fun yin pe lonii Ọjọru, ọjọ Kẹẹdọgbọn osu kẹfa ọdun 2020, ni igbẹjọ ẹsun ijọmọgbe tun n tẹsiwaju nile ẹjọ pẹlu olori ijọ Sotitobire, Alfa Babatunde.
Àdó olóró dáhùn lára èèyàn mẹ́ta ní ìlú Konduga Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Éégún tó wà nídí Yoruba Bollywood, Samo Baba f'ojú hàn o!
Israẹli ń gbé ilẹ̀ Ijipti, ní Goṣeni, wọ́n sì ní ọpọlọpọ ohun ìní níbẹ̀, wọ́n bímọ lémọ, wọ́n sì pọ̀ sí i gidigidi.
Lichtsteiner bere ise agbaboolu re ninu iko agbaboolu Grasshoppers Zurich ninu idije orile-ede Switzerland lodun 2001, O tesiwaju ninu iko agbaboolu Lille ni France, O tun darapo mo Lazio lorile-ede Italy, ki o to darapo mo Juventus lodun 2011.
Dájúdájú ẹni ibi kò ní lọ láìjìyà,ṣugbọn a óo gba àwọn olódodo là.
Bakan naa ni ikọ BBC Yoruba ṣe abẹwo si ofisi ẹgbẹ awọn olukọ agba(SSANU) ẹka ti fasiti ilẹ Ibadan, lati le mọ iha ti wọn kọ si iyanṣẹlodi naa, sugbọn awọn ọmọ ẹgbẹ kọ lati ba oniroyin sọrọ nitori alaga wọn ko si lori ijoko.
Ó tẹ́ ẹ sí inú ibojì rẹ̀ titun tí òun tìkalárarẹ̀ ti gbẹ́ sí inú àpáta.
Àwọn aṣòfin ìpínlẹ̀ Ogun pariwo sí Gómìnà wọn Ìdí tí mi ò fi lè parí ìjà pẹ̀lú Ààrẹ Ọ̀nà kakanfò, Gani Adams - Obasanjo Ṣé ẹ rántí àkọ́lé àwọn ìwé àkàgbádùn yìí?
Aseli bí ọmọkunrin mẹfa: Asirikamu, Bokeru, Iṣimaeli, Ṣearaya, Ọbadaya, ati Hanani.
Nigba to nba ileesẹ BBC Yoruba sọrọ, ọmọbinrin Alaafin, Ọmọọbabinrin Olubunmi Labiyi ni inu ounjẹ ti baba oun njẹ ni asiri agbara rẹ wa.
’ rèé MKO Abiola, iṣẹ́ aṣẹ́gità ló fi bẹ̀rẹ̀ okoòwò Irú èpè wo ni Aláàfin Aolẹ ṣẹ́ fún ìran Yorùbá?
lati panupo gbaduro fun orile-ede France ati awon eniyan re.
Ohun tí Dafidi sọ ni pé, ‘Oluwa wí fún oluwa mi pé:Jókòó ní ọwọ́ ọ̀tún mi
Koda, Jose Mourinho gbà pé ikọ mejeeji gbá bọọlu naa nipa agbara wọn.
Olè Lekki: Obìnrin méjì ni wọ́n dá lọ́nà, tọ́wọ́ ọlọ́pàá fi tẹ̀ wọ́n
 Àwọn ilé-iṣẹ ́ ( companies ) ni ó ń darí ilẹ ̀ yìí láti 1891 sí 1942 .
Ṣugbọn, ọrọ bẹyin yọ fun wọn nigba ti awọn ọlọpaa dena de wọn, ki wọn o maa ba ri owo ti wọn jiko gbe lọ.
Mose wí fún OLUWA pé, “Bí o kò bá ní bá wa lọ, má wulẹ̀ kó wa kúrò níhìn-ín.
OAU: Ohùn ọ̀jọ̀gbọ́n Richard Akindele ni wọ́n ká sílẹ̀ OAU fẹ́ wádìí olùkọ́ tó fẹ́ bá akẹ́kọ̀ọ́ lò fún máákì 'Ọ̀jọ̀gbọ́n Akindele kò ṣẹ̀ṣẹ̀ máa bèèrè fún ìbálòpọ̀' Igbọhunsilẹ kan lori ẹrọ ilewọ ti wọn fi ka ọrọ Akindele bi o ti ṣe n beere fun ibalopọ lọwọ ọmọbinrin naa, lo kọkọ ko ọjọgbọn naa si wahala.
Lẹyin naa o tún jawe olú borí nínú idibo tí ó gbé e wo ilẹ̀ igbimọ asofin àgbà n'ilu Abuja ni odun 2003.
Nígba ti BBC kan si àjọ CAN lóri ọ̀rọ̀ náà , wọ́n ni àwọn kò ni ọ̀rọ̀ kankan láti sọ nítori pé Babtunde kìí ṣe ọmọ ẹgbẹ́ Christian Association of Nigeria (CAN).
Owó yìí jẹ́ aṣèdúró fún àwọn irúfẹ́ ìṣẹ̀lẹ̀ báwọ̀nyí.
pẹlu ìdajì òṣùnwọ̀n hini ọtí waini kan, fún ẹbọ ohun mímu, gẹ́gẹ́ bí ọrẹ ẹbọ sísun.
Àna gómínà Ọ̀yọ́, Ganduje yan Emir mẹ́rin ní Kano Ìgbà mélòó ni ikọ̀ Ilẹ̀ Gẹ̀ẹ́sì méjì wọ àṣekágbá Champions League rí?
"O ni ""Niwọn igba ti awọn akẹgbẹ mi, akọnimọọgba mi ati awọn ololufẹ mi ba lee gbagbọ ninu ipa ti mo le ko lori papa, temi ni lati maa ṣe ohun ti mo mọọ ṣe."
antwan wiggins tí wọ ́ n bí ní ọjọ ́ kẹfà oṣù kẹ ́ ta ọdún 1980 ( march 6 , 1980 ) ní ìlú brooklyn.
Ẹgbẹẹdogun (3,000) ọkunrin Juda lọ bá Samsoni ní ibi ihò àpáta tí ó wà ní Etamu, wọ́n sọ fún un pé, “Ṣé o kò mọ̀ pé àwọn ará Filistia ni wọ́n ń ṣe àkóso wa ni?
Ní ọjọ́ kọkanlelogun oṣù keje, ọdún keji ìjọba Dariusi, OLUWA tún sọ fún wolii Hagai, pé: 
" Atẹjade ti Baderinwa fi sita, eyi to sisọ loju ọrọ yii ni, Akintayọ ti sisẹ kara fun ijọba ipinlẹ Ọsun, ti isẹ ọba yoo si mọ ifẹyinti rẹ lara.
Ẹpa / Imumu Oríṣun àwòrán, Instagram/Utakaegbe Orisirisi ẹpa to wa lo dara ni ara to si n mu ki atọ ọkunrin dara si ju tẹlẹ lọ ti wọn ba n jẹ loore-koore.
Wọ́n ti sọ gbogbo ilẹ̀ náà di ahoro,ṣugbọn ẹnikẹ́ni kò bìkítà fún un.
Aarẹ Macron faramọ ki ilẹ Faranse si wa pẹlu Ajọ Isọkan Ile Europe ‘European Union’, lẹyin ti awọn ti Ilẹ Gẹẹsi dibo lati kuro ninu ajọ naa, ti awọn alatako Macron si faramọ igbese naa.
Nígbà tí ó di òwúrọ̀ kutukutu, ó dìde, ó tẹ́ pẹpẹ kan sí ìsàlẹ̀ òkè náà, ó ri ọ̀wọ̀n mejila mọ́lẹ̀, ọ̀kọ̀ọ̀kan fún ẹ̀yà Israẹli kọ̀ọ̀kan.
Ó kọ̀ láti rin ọ̀nà ìyè,ọ̀nà rẹ̀ wọ́, kò sì mọ̀.
Onimọ nipa ihuwasi ẹda, Ọjọgbọn Oni Fagboungbe, ṣalaye idi to le mu ki obinrin ti wọn fi ipa balopọ, tabi hu iwa ipasi pada sọ pe oun ko ṣe ẹjọ mọ.
Sugbọn kii ṣe bi i ki awọn janduku rọ́ wọ aafin.
Minisita naa fikun un wi pe engiini ọkọ ofufuru to yọnu naa, lo ṣe akọba fun ọkọ ofurufu naa to fi jabọ lati oke.
Lori ejo to mi owo: Ajọ JAMB fun osisẹ n'iwe lọ gbe'le ẹ
Ọjọ Kẹta, Osu Kẹsan, ọdun 2019 ni Ile Igbimọ Asofin ipinlẹ Ọyọ buwọlu abadofin ti yoo se agbeyẹwo owo isuna ọdun 2019, ti awọn asofin si gba aba naa wọle.
Wọ́n kó wọn títí ó fi sú wọn.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ẹgbọ́n olóògbé Suga: Wọ́n yìnbọn fún Suga lójú mi, n kò sì lè dá wọn dúró O ni lọ sọ fun Buhari pe Naijiria n ṣẹjẹ o si gbudọ tete doju kọ awọn ohun to n damu ọpọlọpọ ọmọ Naijiria."
- Ilé ẹjọ́ ìpínlẹ̀ Ondo Ilé ìwòsàn kan rèé tó ń fi àtùpà gbẹ̀bí aláboyún Wọn gbe adẹrinposonu naa lọ soke okun, ti lọrun si gbọ adura rẹ, amọ lati bii ọdun meji to ti pada de orilẹ ede yii, Baba Suwe ko kopa ninu ere tiata kankan.
nítorí wọn óo fún ọ ní ẹ̀mí gígùnati ọpọlọpọ alaafia.
Ẹ gbà'wọ̀nyí ẹ fi bẹ̀rẹ̀ ọdún titun.
Ojú àwọn tọ́wọ́ ti tẹ̀ lára àwọn tó jí 'tíá rọ̀bà ọ̀kadà', fíriìjì, ẹ̀rọ ata kó nílée Sẹ́nétọ̀ Teslim Folarin rèé Ẹ wo ojú àwọn jàndùkú tí ọwọ́ ọlọ́pàá tẹ nígbà tí wọ́n lọ kó ọjà ọlọ́jà ní Shoprite Ilorin Wo àwọn ayédèrú ìròyìn tó gbà'gboro kan lásìkò ìwọ́de #EndSARS Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí End SARS Protest: Babangida ní ejò lọ́wọ́ nínú lórí ìsẹ̀lẹ̀ rògbòdìyàn tó ń wáyé káàkiri Nàìjíríà22 Ọ̀wàrà 2020 Fídíò, Ogbomosho shooting, End Sars, End SWAT: Isiaka Jimoh fi ọmọbìnrin kan àti ìyàwó tó lóyún sínú sílẹ̀ ló- Òbí Isiaka17 Ọ̀wàrà 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Ẹsun mọkanla ni wọn fi kan an; gbogbo mẹwẹẹwa lo si fesi si pe oun ko jẹbi wọn.
kí ó gba àwọn ẹbọ náà lọ́wọ́ wọn fún lílò ninu Àgọ́ Àjọ, kí ó sì pín wọn fún olukuluku àwọn ọmọ Lefi gẹ́gẹ́ bí iṣẹ́ ìsìn olukuluku wọn ti rí.
Wọn tun ni ẹka si awọn adugbo bi i Beere, Mapo, Born Photo, Idi-Aro, Isale Asaka, Idi-Arere, Odinjo, Modina, ati bẹẹ bẹẹ lọ.
Inira pọ pupọ ju fun eto idibo o wa mu ki idibo naa maa fa bi igbin.
Inu mi iba dun pupo to ba je pe, a ti se gbogbo eleyii nigba ti a ni owo lowo.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Orlando Owoh: Èmí àti Oladipupo Owomoyela jọ lọ ẹ̀wọ̀n Alágbọn- Caroline Owoh, aya Orlando Ṣaaju ni wọn ti kọkọ yan Chukwuocha lati ṣoju ẹkun kinni ni ile igbimọ aṣoju Deleware lọdun 2018.
A bá já ọmọ náà gbà lọ sọ́dọ̀ Ọlọrun, níwájú ìtẹ́ rẹ̀.
Awọn ọmọ Naijiria n daro Baba Sala Mínísítà fún ìròyìn àti àṣà Alhaji Lai Muhammed lórúkọ ìjọba àpapọ̀ ní aláwàdà tí kò ṣeé fi wé ẹnikẹ́ni ni olóògbé Moses Olaiya jẹ́.
Onimọ ofin ti ni iwe ofin Naijiria naa kesi ẹgbẹ oselu APC lati tun ile ara wọn to, ki wọn le pa ẹnu ko fa eniyan kan silẹ lori ẹni ti yoo soju, ati wi pe ti wọn ko ba tun ile wọn to, ẹgbẹ alatako PDP le gba ipo naa mọ wọn lọwọ.
 Ìlú yìí ni bàbá rẹ ̀ ti ń ṣiṣẹ ́ orin kíkọ ní ààfin archbishop ti salzburg .
“Bí ẹnìkan bá gbé ọmọge níyàwó, ṣugbọn tí ó kórìíra rẹ̀ lẹ́yìn tí ó ti bá a lòpọ̀, 
Bí ẹnikẹ́ni bá wà ninu yín, tí ọgbọ́n kù díẹ̀ kí ó tó fún, kí olúwarẹ̀ bèèrè lọ́dọ̀ Ọlọrun, yóo sì fún un.
Ẹnu mi kún fún ìyìn rẹ,ó kún fún ògo rẹ tọ̀sán-tòru.
Ìjọba, e yé dẹ́yẹ sí wa mọ́, àwọn ẹlẹ́sìn ìbílẹ̀ ṣèwọ́de n'Ibadan Wọ́n ti fa Ààrẹ Amẹrika, Donald Trump kalẹ̀ fún àmì ẹ̀yẹ Nobel Peace Prize Auxiliary gbé èèyàn mẹ́fà tó ń jáwèé ayédèrú fáwọn awakọ̀ lọ sí ilèẹjọ́ ní Ibadan Oríṣun àwòrán, Others Bí ìjà bá wà láàrin èmi àti Olubadan, a ó yanjú ẹ ní pẹ̀lẹ́kùtù, ọ̀rọ̀ bàbálọ́jà kò lè dìjà Ṣeyi Makinde ṣàbẹ̀wò s'áàfin Olubadan, Ó ní tùbí ǹ nùbí ni ọ̀rọ̀ gbà Bi ija ba wa laarin emi ati Olubadan, a o yanju ọrọ ni pẹlẹkutu- Makinde Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Akomolede ati Aṣa lori BBC: Mọ̀ si nípa oríṣìí ẹ̀ka ìsọ̀rí ọ̀rọ̀ àti ìwúlò wọn Gomina ipinlẹ Oyo onimọ ẹrọ Seyi Makinde sabẹwo si aafin Olubadan ti ilu Ibadan, Ọba Saliu Adetunji, Ajenigunuso, nibi to ti tun fidi rẹ mulẹ pe oun ko ni fori ade wọlẹ ati pe gbogbo ọwọ to tọ si wọn l'oun yoo ma fi wọ wọn.
"Obìnrin Mùsùlùmí ṣe ilé àlúfà ní ọ̀ṣọ́ fún Kérésìmesì 'Ẹ sọ́ra fún ""Christmas Carol"", ẹ̀yin tẹ́ẹ sì wà lókè òkun ẹ má wálé o!"
Ojú ẹni tí ó jókòó lórí ìtẹ́ náà dàbí òkúta iyebíye oríṣìí meji.
Pasitọ Idowu Oluyomade to jẹ amugbalẹgbẹ alufaa Enoch Adeboye ijọ Redeem naa wa nibi eto isinku ọhun.
Ìyá rẹ̀ bá dáhùn pé, “Mo ya fadaka náà sí mímọ́ fún OLUWA, kí ọmọ mi yá ère fínfín kan kí ó sì yọ́ fadaka náà lé e lórí.
 Pàṣán ológìnní, kò sí lọ́wọ́ èkúté.
Ni bayii, awon alase orile-ede ohun ti si gbongan ile-iwe, ibi igbafe ati awon aye miiran ti o le gba awon ti isele ohun sele si.
Gomina Akeredolu n tọka si i pe ipinlẹ Ondo lo n gbin igbo julọ ni Naijiria, to si yẹ ki orilẹ-ede yii o lo anfaani naa fun awọn ọmọ Naijiria.
Ó mú un níbi tí ó ti ń tọ́jú àwọn aguntantí ó lọ́mọ lẹ́yìn,kí ó lè máa tọ́jú àwọn ọmọ Jakọbu, eniyan rẹ̀,àní àwọn ọmọ Israẹli, eniyan ìní rẹ̀.
Afurasí afipábánilópọ̀ kàgbákò, obìnrin tó jà lólè fi eyín gé nǹkan ọkùnrin rẹ̀ jábọ́ lásìkò ‘Blow Job’ Àwọn ọba alayé, Mínísítà àti gómìnà nílẹ̀ Yorùbá ṣèpàdé pẹ̀lú ìjọba àpapọ̀, àbọ̀ rèé Iná ṣẹ́yọ nílé ìtajà aya Ajimobi lẹ́yìn ọjọ́ mẹ́ta tó jáde opó Saaju ni o ti fi atẹjade kan sita nibi to ti paṣẹ pe ki gbogbo awọn ọmọ ẹgbẹ ni gbogbo ẹka wọn ti gunle iyanṣẹlodi bẹrẹ lati ago mejila ọjọ Aiku mọjumọ ọjọ Aje.
Buhari: Isa Funtua, Abba Kyari, àti Zulaihat Buhari jẹ́ àwọn tó súnmọ́ Aàrẹ tó papòdà láìpẹ́ Oríṣun àwòrán, others Àkọlé àwòrán, Isa Funtua/Zulaihat Hardo/Zulaihat Buhari/ Abba Kyari Yatọ si ọkan lara awọn eeyan to sunmọ Aarẹ Muhammadu Buhari, Isamaila Isa Funtua, to ku lọjọ Aje, Aarẹ ti padanu awọn eeyan to ṣe pataki si i ni igba diẹ sẹyin.
"Ọwọ ti ọpọ eeyan fi mu ọrọ Amotekun yii fihan pe ọna wa si jin ni Naijiria lati mu ki eto iselu ijọba awa ara wa pegede.
Bakan naa ni wọn fikun wi pe awọn ko le e sọ lọwọlọwọ iye eniyan to ba ijamba ọkọ naa lọ.
Labẹ ofin yii, wọn ko ni gba ẹnikẹni laaye lati maa se ọti lile ta tabi maa taa loju taye tabi ki wọn maa mu ọti laarin igboro lawọn agbegbe kan nigboro ilu Ilọrin.
Ṣugbọn agbara naa maa n dinku bi a ṣe n dagba si.
maa sun tun fa lala, pelu oju won mejeeji ni didi.
Àwọn adigunjalè yabo ṣọ́ọ̀ṣì, wọ́n fipá bá obìnrin kan lòpọ̀, wọ́n yìnbọn fún òmíràn Ìpínlẹ̀ Bauchi àti Kaduna láti máà tẹ àwọn afipábánilopọ̀ lọ́dàá Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Ondo Election 2020: Ẹ wo àwọn olùdíje sípò gómìnà nípínlẹ̀ Ondo tó takò bàbá ìsàlẹ̀26 Owewe 2020 Fídíò, Wole Soyinka sọ ìdí tó fi ni òun a fi màálù Fulani ṣe súyà fáwọn èèyàn abúlé23 Owewe 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Láti ìgbà yìí lọ, kí ẹnikẹ́ni má ṣe yọ mí lẹ́nu mọ́, nítorí ojú pàṣán wà ní ara mi tí ó fihàn pé ti Jesu ni mí.
Ọgbẹni Taiwo n sọ eyi bo ṣe n fi fọnran bi wọn ṣe n gbe Ọba Akiolu ati mọlẹbi rẹ wọ inu ọkọ ologun ki wọn to gbe wọn sa kuro laafin.
 thomson , om , frs ( 18 december 1856 - 30 august 1940 ) je ara britani asefisiksi ati elebun nobel .
Chidi Okoroafor to jẹ agbẹnusọ fun CBN ṣalaye kikun fun BBC pé ajọ NDIC lo maa n ṣeto adojutofo fawọn ibi ifowopamọ si gbogbo ti CBN fọwọ si ni eyi ti MMM ko si nibẹ.
Bẹẹ lo sọ pe ko si mọlẹbi kankan to jade sita lati wa kede pe awọn padanu eeyan kankan lasiko ikọlu to waye logunjọ osu Kẹwa ọdun 2020.
Oríṣun àwòrán, @Nations Wo awọn ọmọ Yorùbá méje, tó ń dupò nínú ìdìbò ilẹ̀ America Mọ̀ sí i nípa àwọn ọmọ Nàìjíríà mẹ́sàn-án tó ń díje nínú ìdìbò ilẹ America lọ́jọ́ Ìṣẹ́gun.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù UN General Assembly: Buhari ní ìgbà ọtun ni ìyànsípò Bande jẹ́ lẹ́ka òṣèlú 4 Òkùdu 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 5 Òkùdu 2019 Oríṣun àwòrán, @BashirAhmad Àkọlé àwòrán, Tijanni Bande Tijanni Muhammed Bande ni wọ́n yan gege bi ààrẹ fún ipejopọ ajọ ìsọ̀kan agbaye ( UN General Assembly).
fi ri ekunwo san, laije pe won ya owo lati fi san owo osu yii.
Ewé Rhubarb Ewé yìí wọ́pọ̀ láàrin àwọn ara ilẹ Gẹẹsì ti wọn maa n fi pètò ounjẹ, ọ̀pọ òunjẹ nilẹ gẹẹsi ni ewé náà wà nínú rẹ̀.
so pe ijoba oun ti se gudugudu, meje , yaya mefa lati pese idagbasoke ni ogba
Bàbà tí Solomoni fi ṣe òpó mejeeji ati agbada omi, pẹlu àwọn mààlúù idẹ mejeejila tí wọ́n gbé agbada náà dúró, ati àwọn ìtẹ́lẹ̀ tí Solomoni ọba ṣe fún ilé OLUWA kọjá wíwọ̀n.
Iro ni ile Amerika pa mo mi lori esun jibiti- Allen Onyema Davido, Fani Kayode, Kemi Olunloyo, sọ̀rọ̀ lórí ẹ̀sùn jìbìtì Allen Onyema 'Kìí ṣe pé ìjánu Ọkọ̀ tó pa Tolulope Arotile já tàbí kò já, ìwádìí wà lọ́wọ́ ọlọ́pàá' Ni nkan bi ọsẹ meloo kan ni ọga agba ileeṣẹ naa Allen onyema ke gbajare pe ki ijọba ṣe iranwọ fawọn to wa lẹka ofurufu ki wọn ba fi le lalauyọ lasiko yii.
Ojú ọ̀nà ìlú àwọn ejò náà ń dán ṣùgbọ́n ìbá dára jù bẹ́ẹ̀ ló níkò ṣe ti ọ̀pọ̀lọpọ̀ àwọ̀ ara wọn tí ó bọ́ sílẹ̀ tí ó sì dá ìpàǹtí sí ojú ọ̀nà lọ.
Women’s World Cup todun 2020 simo lori.
Èmi ti fi ògo fún ọ ninu ayé, mo ti parí iṣẹ́ tí o fún mi ṣe.
Ọja naa to jẹ ọkan lara awọn ọja to tobi ju nipinlẹ Eko.
Aarẹ ilẹ naa, Cyril Ramaphosa ti wa kede pe ọrọ arun Covid-19 kii ṣe ohun ti ijọba ilẹ naa lee fi ọwọ yẹpẹrẹ mu, o si ti pe e ni iji lile.
Èwo ló pàtàkì jùlọ nínú ẹ̀rọ ìbánisọ̀rọ̀ àti ilé ìgbọ̀nsẹ̀?
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Mo máa n forin mi kìlọ̀ ìwà ìbàjẹ́ láwùjọ ni -Hameen Wọn tẹsiwaju pe, lai si eto aabo to fi ẹsẹ mulẹ, yoo nira lati jẹ anfani eto ọrọ aaje to rọṣọmu, bẹẹ si ni awọn oludokowo ti o le mu idagbasoke ba orilẹede yii yoo maa bẹru lati wọle wa.
Evariste Ndayishimiye di ààrẹ tuntun lórílẹ̀èdè Burundi Wọn fi ẹsun kan awọn ọmọ Naijiria ọhun pe wọn maa n dibọn bi oniṣowo ti wọn si maa n parọ gba owo gọbọi lọwọ awọn to ba ko si panpẹ wọn.
    Orí àpáta ńlá kan báyìí ni mo gùn lọ ni tèmi.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Idanre Hills, Ondo: Ogun gan kò láyà láti dédé gun òkè Idanre Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Idanre Hills, Ondo: Ogun gan kò láyà láti dédé gun òkè Idanre 12 Ọ̀pẹ̀̀ 2019 Nibi ti oke naa ga de, ibudo isinmi marun tan yan yan.
Ní àpàpọ, kí àwọn ti yóò sójú fún kọlẹ̀jì ìdìbò yìí tó kúrò nílé ni àwọn àrá ìpińlẹ̀ wọ̀n yóò ti kọ́kọ dìbò láti mọ ẹni ti wọ́n fẹ́ dìbò fún.
Abineri bá àwọn ará Bẹnjamini sọ̀rọ̀ pẹlu.
Ero awọn eniyan ni wipe ijọba to wa lode yii, ko kọ ẹkọ kankan lara isẹlẹ to sẹlẹ lọdun mẹrin sẹhin, atiwipe ọgọrun ninu awọn ọmọ Chibok naa, lo si wa ni ahamọ awọn Boko Haram ti wọn tun fi wa ji awọn ọmọ Daphchi yii gbe.
Nítorí inú tí OLUWA ń bí si yín ati inú rẹ̀ tí kò dùn sí yín bà mí lẹ́rù, nítorí ó ti ṣetán láti pa yín run.
Adari yii lo owo epo rọbi orilẹede naa lati fi san na idagbasoke fun Oman.
Arabinrin Theresa May ni Olootu ijọba ilẹ naa ni lọwọlọwọ yii, saa iṣejọba rẹ ko si tii pari.
Inú bí èyí ẹ̀gbọ́n, ó bá kọ̀, kò wọlé.
Yóo bu ọlá fún àwọn tí wọ́n bá yẹ́ ẹ sí.
“Pa á láṣẹ fún Aaroni, ati àwọn ọmọ rẹ̀ pé, èyí ni òfin tí ó jẹmọ́ ti ẹbọ sísun: ẹbọ sísun níláti wà lórí ààrò lórí pẹpẹ ní gbogbo òru títí di òwúrọ̀ ọjọ́ keji, iná sì níláti máa jò lórí pẹpẹ náà ní gbogbo ìgbà.
Bakanna lo fi ara rẹ jẹ Emir akọkọ fun ilẹ Yoruba.
A fẹ ẹni ti yoo faaye gba ẹtọ awọn onigbagbọ""."
Wọ́n ti gba àwọn ọ̀rọ̀ náà, ó ti wá yé wọn pé nítòótọ́, láti ọ̀dọ̀ rẹ ni mo ti wá, wọ́n sì gbàgbọ́ pé ìwọ ni ó rán mi níṣẹ́.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, BIAFRA at 50: Ìhàlẹ̀ ológun ni Gowon ni ká kọ́kọ́ fi bẹ̀rẹ̀- Aladejẹbi Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Apapa Gridlock: Ààrẹ Buhari ti pàṣẹ kí wọ́n ó kó àwọn ọkọ̀ kúrò láàrin ọjọ́ díẹ̀ 22 Èbibi 2019 Ileeṣẹ aarẹ Naijiria ti paṣẹ pe ki wọn o ko gbogbo awọn ọkọ nlanla to wa ni papakọ oju omi Apapa kuro laarin ọsẹ meji pere.
Báyìí ni gbogbo wa yóo fi dé ìṣọ̀kan ninu igbagbọ ati ìmọ̀ Ọmọ Ọlọrun, tí a óo fi di géńdé, tí a óo fi dàgbà bí Kristi ti dàgbà.
Jakọbu gbọ́ pé àwọn ọmọ Labani ń sọ pé òun ti gba gbogbo ohun tíí ṣe ti baba wọn, ninu ohun ìní baba wọn ni òun sì ti kó gbogbo ọrọ̀ òun jọ.
Àwọn eniyan náà ṣe bí àwọn babalóòṣà ti wí.
 kì í yọ kọ ́ kọ ́ rọ ́ ojú kékeré séèfù .
Losu Kẹta ọdun 2019 awọn akẹkọbinrin mẹta kan wọ gau lori pe wọn ya aworan yẹyẹ aarẹ Pierre Nkuruziza .
Oríṣun àwòrán, others Se lootọ ni idigunjale n waye?
Ni UK, ati awọn ibomiran, akọsilẹ ẹ̀rọ satalaiti ko fihan boya adinku to ba lílọ bibọ lo mu adinku ba titu jade eefin, bo tilẹ jẹ pe awọn kan sọ oun ni.
Aṣọ to wọ fi igba aya Dorothy han pupọ ti gbogbo awọn ohun to fi n ṣe oge si n han kedere fawọn oluworan.
Oríṣun àwòrán, Twitter/diranabiola Awọn aworan bi eyi to wa labẹ yi ṣafihan awọn to ṣe ọjọ ibi ati awọn to pari igbeyawo gẹgẹ bii tọkọtaya tuntun ti a so pọ ti wọn si gba ibẹ lọ si iwọde.
Ohun kan pataki ti awọn sinima bii Aṣiri nla, Ti Oluwa nilẹ, ati bẹẹ bẹẹ lọ lo lati fi fa oju awọn eeyan mọra lasiko naa ni lilo awọn adẹrinpoṣonu ninu awọn sinima wọn nigba naa.
Ẹnikẹni to ba ti gba nọmba idanimọ lee lo fun ohunkohun bii nile ifiwopamọ, ati ririn ajo lọ si oke okun, gbigba owo ifẹyinti, ati bẹbẹ lọ.
Gẹgẹ bi adari awon ileto ati agbegbe wa ati bi ẹlẹsin
Iroyin to n tẹ wa lọwọ ni yajo-yajo lo fi ye ni pe, ijamba ọkọ kan to lagbara waye ni deede aago mẹwa ọjọru yii, ni abẹ afara Fidiwọ, lopopona marosẹ Ibadan silu Eko.
ICPC rọ ààrẹ Buharí láti dá àwọn ọ̀gá àgbá ilé iṣẹ́ tọ́rọ́ ṣí mọ́ lórí dúró
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Hajj 2018: Àwòrán bí àwọn Alálàájì àkọ́kọ́ ṣe ń gbéra l’Abuja 21 Agẹmo 2018 Àwọn alálàájì láti ìpínlè Kogi ni wọ́n ṣíde ìrìnàjò Hajj 2018 ní orílè-èdè Nàìjíríà.
Wọ́n pa wọ́n ní ìpakúpa ní ọjọ́ náà.
US presidential election 2020: Ta a ni Joe Biden tó ń díje fún ipò aárẹ America
Agbẹjọro ni Akin-Olugbade, to si n ṣe idokowo ninu rira ile ati ile kikọ, epo rọbi, ile ifowopamọsi ati bẹẹ bẹẹ lọ.
Ọmọ Nàìjíríà kan gbé Fásitì Oxford lọ sílé ẹjọ́ tàko oríkí ọrọ 'Mortgage' nínú ìwé àtúmọ̀ ọrọ Ó sàn kí ẹ pa mí ju kí ẹ ba oko tí mo gbin igbó sí jẹ́ lọ- Afurasi Clement sí NDLEA Ọwọ́ ọlọ́pàá tẹ àwọn olè tó kó góòlù àti ẹgbẹ̀lẹ́gbẹ̀ mílíọ̀nù lọ nílé MKO Abiola l'Eko A kú oríire!
Awọn ẹbi ti ko ju mẹrinlelogun lọ pẹlu awọn ọrẹ rẹ lo wa nibi ayẹyẹ isinku Maradona l'Ọjọbọ.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Awọn adari mejeeji fi ipinnu wọn han lati gbogun ti iwa ipa lagbaye Awọn ohun ti wọn jiroro ni ọrọ eeto aabo, gbigbe ogun ti iwa ibajẹ lorilẹede Naijiria, idokowo laarin orilẹede mejeeji ati ẹtọ ọmọ eniyan.
"Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, BBC gbalejo ọmọ Ibadan Dele pe awọn oniwe iroyin atawọn mii ni Naijiria wọn si fi da a loju pe pẹlu ohun ti awọn n ri, Abiola ni yoo wọle gẹgẹ bi aarẹ afigba to pe eeyan kan to ni nkan ti ologun fẹ ṣe ree o ""O ni oun ti n wa mi, o ji ọrẹ rẹ Abiola lo mọ da bii pe yo wọle ṣugbọn awọn ologun ko ni gbe ijọba fun un."
Ẹ gbọ́ ọ̀rọ̀ yìí, ẹ̀yin obinrin Samaria, ẹ̀yin tí ẹ sanra bíi mààlúù Baṣani, tí ẹ wà lórí òkè Samaria, tí ẹ̀ ń ni àwọn aláìní lára, tí ẹ̀ ń tẹ àwọn talaka ní àtẹ̀rẹ́, tí ẹ̀ ń wí fún àwọn ọkọ yín pé, “Ẹ gbé ọtí wá kí á mu.
Lẹyin agbekalẹ abọ igbimọ naa, ni alaga ẹgbẹ APC, Oloye Oyegun wa ki wọn ku isẹ takuntakun ti wọn se, to si kede pe pẹlu igbesẹ yi, gbogbo aye ti wa mọ ohun ti ẹgbẹ oselu APC duro fun.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Iroyin naa ni orilẹede Ukraine, Madagascar ati India ni ọwọja arun Ẹ̀yinaa ti mulẹ julọ, ti akọọlẹ si fi han pe ẹgbẹlẹgbẹ awọn eeyan lo ti fara kaasa arun yii nibẹ.
 lẹ ́ yìn tí wọn bá sin òkú tán , àwọn aláwo náà máa sun adìye náà jẹ .
Mo ṣèlérí láti ṣe ju ohun tí mo ti ṣe lọ fún ẹbí àwọn tó kú torí EndSARS - Seyi Makinde Bàbá ọlọ́mọ méjì fi ipá bá ọmọ ọdún mẹ́rin lò pọ̀; Adájọ́ rán an ní ẹ̀wọ̀n gbére Ọlọ́pàá mú afurasí 31 tó ń dúnkokò máwọn ọmọdé lórí ayélujára Ẹgbẹ́ Agbẹjọ́rò NBA ti kéde pé àwọn yóò ṣojú awọn Olùwọ́de #EndSARS lọ́fẹ̀ẹ́ nílé ẹjọ́ Àwọn ìṣẹ̀lẹ̀ mánigbàgbé tó wáyé nibi ìwọ́de ENDSARS Nàìjíríà Oríṣun àwòrán, @jidesanwoolu 'Mo jíṣẹ́ ẹ rán mi'!
Muhammed  ni awon omo orile ede Naijiria yoo maa de si
Adajọ Onyemanam to dárí ẹjọ́ to wáyé lónìí ọjọ́ iṣẹgún lo dá ẹjọ́ náà ló fídí rẹ̀ múlẹ pé ìdájọ́ ilé ẹjọ́ kekere to yọ Adams Oshiohmole gẹ́gẹ́ bi alágá ni inú ọṣù kẹta ọdún yìí ṣe ǹkan to yẹ ati pé, ẹjọ́ kòtẹ́mílọ́rùn ti Oshiomhole pè kò fìdì múlẹ̀.
Owó ìfẹ̀yìntì àwọn Gómìnà ní ìpínlẹ̀ Zamfara dì àlọrámirámi Missing Child: Òbí àti asọ́nà ṣọ́ọ̀ṣì 14, lọ́ búra nì'dí imọlẹ̀ l'Akure Ẹ̀wọ̀n oṣù mẹ́ta àti #3,000 ni awakọ̀ tí kò bá ní ‘speed limiter’ yóò fi jura- FRSC Ẹ wo iye t'óúnjẹ dà báyìí lọ́jà lẹ́yìn tí ìjọba ti ibodè Ọpọlọpọ gba pe iṣẹ rẹ ko dara to ni ẹgbẹ agbabọọlu naa ṣe n ri ijakulẹ Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Arsenal tun fidirẹmi Lyon fìgbájú gba Emirate Cup lọ́wọ́ Arsenal, wọ́n fi pánda rọ́pò Top 4 ta pàù!
 O ni kete tise akanse yii ba pari lopin odun yii ni irorun yoo de fawon agbe ati olugbe agbegbe yii.
Kí wọn jẹ́ eniyan jẹ́jẹ́, kí wọn jẹ́ ẹni tí ó ṣe é gbẹ́kẹ̀lé ninu ohun gbogbo.
Ẹ jẹ́ kí á máa yọ̀, kí inú wa sì dùn nítorí ìgbàlà rẹ̀.
Ṣugbọn wọn kò rí i nígbà tí wọ́n wá a.
Asofin Sharon lo seto ilana  irorun lati maa fi san owo awon osise to ba fẹyinti
 freud ni ó kókó n tè lé sùgbón ó yapa kúrò ní òdò rè 1911 .
Nínú oṣù Igbe 2017, Novaya Gazeta jábọ̀ pé àwọn aláṣẹ ní Chechnya, ti ìlú oníjọba Ìmọ́lẹ̀ tí ó ń rí ìdààmú jù ní gúúsù Russia tí ajagun fẹ̀yìntì Ramzan Kadyrov, ń ṣe olóríi rẹ̀, ń ṣe ìpolongo tí ó rorò tí ó ń tako ìtẹ̀mọ́lẹ̀ àwọn ènìyàn tí í ṣe LGBT tí ó ń gbé nínúu rẹ̀.
" O ni bi idile ti oye kan ko ba ri ọmọ oye to dantọ fa kalẹ, n ṣe ni ki awọn araalu kọ amulumala ọmọ oye ti wọn ba fa silẹ, ki wọn si mu ninu ọmọ oye ni idile to ba kan.
Ẹ̀ ń sọkún, omijé ojú yín ń ṣàn lára pẹpẹ OLUWA, ẹ̀ ń sọkún tẹ̀dùntẹ̀dùn, ẹ sì ń ké, nítorí pé OLUWA kò gba ọrẹ tí ẹ mú wá fún un.
Australia: Lorilẹede Australia, nnkan bii ẹgbẹrun mejilelogoji dola lawọn ọlọpa n gba, wọn kii sii ṣe iṣẹ ju ogoji wakati lọ.
Lónìí, OLUWA fi ọ́ lé mi lọ́wọ́, ṣugbọn mo kọ̀ láti ṣe ọ́ ní ibi, nítorí pé ẹni àmì òróró OLUWA ni ọ́.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Hepatitis: A kò leè kóo nípa dídìmọ́ ara ẹni Aarẹ GMD ni awọn onimọ nipa eto ilera ko tii pari iwaddi wọn lati mọ boya apapọ Hydroxychloroquine, Zinc ati Zithromax lee koju Covid-19.
Ẹnikẹ́ni kò rí irú igi alimugi bẹ́ẹ̀ mọ́ ní ilẹ̀ Israẹli títí di òní olónìí.
O ni Pataki apero naa ni  ki gbogbo won jo forikori lori imo kikun ninu eran ara atawon ilera miran bii aisan iba atawon arun itankale miran.
Nitori naa ko ni ohun se pelu abajade esi ibo”.
Ọkùnrin kan lu ìyàwó rẹ̀ pa"" nítorí ó lọ síbi ayẹyẹ ìsọmọlórúkọ Wo àwọn oúnjẹ márùn ún tó ń mú kí àtọ̀ ọkùnrin dára síi Àwọn Olúkọ ìpínlẹ̀ Oyo fakọyọ lórí ètò Akọ́mọlédè àti Àṣà púpọ̀ Wo ibi mẹ́rìnlá tí o kò gbọdọ̀ gbé ọkọ̀ rẹ sí lásìkò yìí."
Ẹ máa wá alaafia ìlú tí mo ko yín lọ, ẹ máa gbadura sí OLUWA fún un, nítorí pé ninu alaafia rẹ̀ ni ẹ̀yin náà yóo ti ní alaafia.
1–6, Àwọn òṣìṣẹ́ nínú ọgbà ajarà yíò gba èrè ìgbàlà; 7–8, Iyè àìnípẹ̀kun ni ó ga jùlọ nínú àwọn ẹ̀bùn Ọlọ́run.
Bàbá mi náà fèsì o ní, mo ń lọ ṣe ọdẹ.
5million dollars) ni iṣiro owo Naijiria elo lo ro wipe yoo je?
Ta ni obìnrin tó fẹ́ bá Dino Melaye ṣe ìgbéyàwó lọ́jọ́ kejì Kérésì?
Iṣẹ́ bọ́ lọ́wọ́ ọlọ́pàá ọ̀mùtí ní ìlú Eko Dókítà ọmuti ṣe iṣẹ́ abẹ tó pa olóyún àti ọmọ rẹ̀ Ó ṣeésẹ kí ọkùnrin tó n mu àmujù ọtí ó maa lo ìwà ipá pẹ̀lú ìyàwó rẹ̀ Ẹ̀kọ́ mẹ́jọ tó yẹ kí ilẹ̀ Afirika kọ́ lára àjàkálẹ̀ aàrùn coronavirus Ọjọ́ orí wo ló yẹ kí ikùn ẹ̀dá bẹ̀rẹ̀ sí tóbi?
"Oríṣun àwòrán, Olubunmi Labiyi Àkọlé àwòrán, Ayọ ati idunnu ko tan ni aafin Ọyọ ""Eso jijẹ ni asiri agbara baba mi."
Asiko ti wọn pa ọgagun Gamal Abdel Nasser lọdun 1952.
Má fẹ́ràn oorun àsùnjù, kí o má baà di talaka,lajú, o óo sì ní oúnjẹ ní àníṣẹ́kù.
Àwọn Juu tún ṣa òkúta láti sọ lù ú.
Lẹ́yìn náà ó sọ fún gbogbo ìjọ Israẹli pé, “Bí ó bá dára lójú yín, tí ó sì jẹ́ ìfẹ́ OLUWA Ọlọrun wa, ẹ jẹ́ kí á ranṣẹ lọ sọ́dọ̀ àwọn eniyan wa tí wọ́n ṣẹ́kù ní ilé Israẹli, ati àwọn alufaa ati àwọn ọmọ Lefi ní àwọn ìlú tí wọ́n ní pápá oko, kí wọ́n wá darapọ̀ mọ́ wa.
Nígbà tí ó kù dẹ̀dẹ̀ kí Dafidi jáde láyé, ó pe Solomoni, ọmọ rẹ̀, ó sì kìlọ̀ fún un pé, 
Tope fikùn pé òun kò ṣe ère tíátà tí gbogbo-gbòò mọ lásìkò yìí, àmọ́ òun ń ṣe ère tíátà ti ẹ̀mí, tó sì tun fikún pé, òun ń kọ orin fún àwọn Òṣeré tíátà to bá bẹ òun.
Ni Abidjan ni orilẹ-ede Cote D'Ivore ni eto ibura naa ti waye.
"Lẹyin naa lo parọwa si awọn olugbe ipinlẹ Eko lati ""Calm down"" lasiko pọpọṣinṣin ọdun leya."
Ohun ni aṣọ fi ń pọ́n mọ́ wọn lára
Joṣua ati gbogbo àwọn ọmọ ogun rẹ̀ bá jálù wọ́n lójijì ní etí odò Meromu, wọ́n bẹ̀rẹ̀ sí bá wọn jagun.
O wa tẹnumọ pe gomina Sanwo-Olu ti pasẹ pe ki iwadii bẹrẹ lori isẹlẹ naa, to si rọ gbogbo araalu lati bomi suuru mu.
Lẹ́yìn nǹkan wọnyi, Ọlọrun dán Abrahamu wò, ó ní, “Abrahamu!
Bí ó ti lẹ̀ jọ́ pé orílẹ̀-èdè Nàìjíríà tí ta iná mọ̀nànmanà fún aládaní lójùnà ati mú ki ètó amúsagbára rú gọ́gọ́ síi, síbẹ̀ àwọn ọmọ Naijíríà ṣi ń kigbe àìrínà lò.
Jàńdùkú olóṣèlú gbàkóso ilé aṣòfin l‘Ondo Adájọ́ ní kí Ahmed Danladi, tó jẹ́ awakọ̀ tó jalè gbálẹ̀ kóòtù f'ọ́jọ́ méjì ní Abuja Wo àmì márùn-un tí o fi le mọ ẹni tó fẹ́ gbẹ̀mí ara rẹ̀ Ọ̀dọ́ Nàíjíríà fèsì padà fún Buhari lórí ìkéde pé kí wọn padà sóko Wo ìyá ọlọ́mọ mẹ́ta tó ti pé ọdún 48 tó ń ṣe ìdánwò WAEC, kó le di nọ́ọ́sí Ṣaaju ni awọn ọmọ Naijiria kan ti pariwo pe owo burẹdi ti le sii nigboro ati pe kii ṣe ounjẹ mẹkunnu mọ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù IlorinDurbar: Emir Sulu-Gambari léwájú àwọn èèkàn ẹlẹ́ṣin níbi àjọ̀dún Dubar nílú Ilọrin 22 Ògún 2018 Oríṣun àwòrán, @onile050 Àkọlé àwòrán, Ajọdun Dubar nilu Ilọrin Ayẹyẹ durba ilu Ilọrin waye loni pẹlu oniruru ilu, ijo ati ifọn.
safihan awon omo egbe ti yoo maa fun aare ni Muhammadu Buhari ni imọran awon
Suspected ritual killer: Ọwọ́ tẹ afurasí olóògùn owó tó fẹ́ gé ọmú obìnrin nílé ìtura
Ni iṣẹju kẹrinla ifẹsẹwọnsẹ naa ni Virgil, agbabọọlu Liverpool gba goolu kan ṣoṣo to pin awọn ẹgbẹ agbabọọlu mejeeji niya wọle.
Nigba to n ba BBC Yoruba sọrọ, Sheikh Abdulrazak Isola salaye pe, awọn eeyan to n gbero lati lọ si ilẹ mimọ Mecca ni wọn npe ni Alhaji ati Alhaja, apemọ orúkọ lasan si ni pẹlu.
Asamoah Gyan: O ṣeéṣe kí èyí jẹ́ ìdíje AFCON ìkẹyìn mi Kíló burú nínú kí Sanwo-Olu fún Super Eagles lówó Super Eagles kò ní já àwọn ọmọ Nàìjíríà kulẹ̀- Musa Èrò àwọn ọmọ Naijiria ṣọ̀tọ̀ọ̀tọ̀ lórí Tinubu àti Abbo Ọpọ ninu awọn ọmọ Naijiria gba pe ori Aare Buhari maa n gba ife ẹyẹ pe ati pé pẹlu adura, o maa ja si ọpẹ.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Tottenham ati Liverpool yoo koju ara wọn ni ọjọ kini oṣu kẹfa.
Ikọ ọmọogun Amerika ni awọn orilẹede Gbungun lagbaye Ni Oṣu Keji, ọdun 2019 ni Aarẹ Trump sọ wi pe oun yoo pe gbogbo awọn ọmogun ilẹ naa to wa lorilẹede Syria nitori pe ogun ti wọn n ja naa ko nidi mọ.
 Aṣofin Bisi Yusuf ti ẹgbẹ oṣelu APC ni ẹgbẹrun mẹrinlelogoji-le-mẹtadinlọgọjọ
“A gbọ́ ohùn kan ní Rama,ẹkún ati ọ̀fọ̀ gidi.
ni osu kesan an odun to koja.
Oríṣun àwòrán, @Ondo House of assembly Àkọlé àwòrán, Aṣòfin Iroju Ogundeji, Favour Tomowewo àti Williams Adewale ń lọ rọọkún nílé Aṣòfin Iroju Ogundeji lo jẹ igbakeji adari ile, oun naa lo n ṣoju ẹkun idibo Odigbo 1; nigba ti Favour Semiloore Tomowewo n ṣoju ẹkun idibo Ilajẹ keji; àti Williams Adewale to n ṣoju Ondo West keji.
Ayẹwo naa si lo ni o jẹ ki wọn gba oun laaye lati wọ ọkọ ofurufu wa sorilẹede yii ni ana.
Òní ní ààwẹ Ramadan pe ọjọ mẹ́wàá sùgbọ́n ààwẹ ku ọjọ mọ́kandinlogun si ogunjọ ti ààwẹ náà yóò pari ti ọdun itunu ààwẹ yóò si waye.
Ṣeyi Makinde to je gomina ipinlẹ Oyo, labẹ ẹgbẹ oṣelu PDP.
T i a ba fi ni ka ran wọn lọwọ, aṣiri ko ba tu'' Tijo tayọ ni Adamu fi darapọ mọ ẹbi rẹ pada, to si ni yoo ṣe diẹ ki oun to pada soko.
New Covid-19 Strain UK : Atiku ní kí ìjọba dì ìrìnnà ọkọ̀ òfurufú láàrin ilẹ̀ Gẹ̀ẹ́sì sí Nàìjíríà kú nítorí Covid-19
Ó ti wà ṣiwaju ohun gbogbo.
 Àwọn àmì àìsàn náà a má a bẹ ̀ rẹ ̀ lẹyìn ọjọ ́ méjì sí ọ ̀ sẹ ̀ mẹta tí ènìyàn bá ṣe aláàbápàdé kòkòrò àìlèfojúrí afàìsàn náà , pẹ ̀ lú ibà , ọ ̀ fun dídùn , ìrora nínú iṣan ara , àti orí fífọ ́ .
Bí wọ́n bá fà á tu kúrò ní ààyè rẹ̀,kò sí ẹni tí yóo mọ̀ pé ó wà níbẹ̀ rí.
Àwọn ojú meje yìí ni Ẹ̀mí Ọlọrun meje tí Ọlọrun rán sí gbogbo orílẹ̀ ayé.
Idi ni pe igbimọ to n duna dura fẹgbẹ osisẹ, JNPSNC atawọn asoju ijsba apapọ tun ti sun ipade wọn si ọjọ Kẹrin osu Kẹsan ọdun yii fun akstun ijiroro miran.
Ati pe, akoko yi jẹ akoko lati fi ifẹ han si aladugbo ẹni, papa julọ awọn to ku diẹ kaato fun.
Gẹgẹ bo ti wi, ọdun yii ko ni lọ lai jẹ pe Ọlọrun bẹ awọn eeyan to n gbẹmi awọn ọmọ orilẹ-ede yii wo, to fi mọ awọn eeyan to n se atilẹyin fun wọn, tabi awọn to n saanu fun awọn apaniyan.
“Ìwọ ọmọ eniyan, àwọn tí wọn ń gbé ilẹ̀ Israẹli tí ó ti di aṣálẹ̀ wọnyi, ń wí pé, ‘Ẹnìkan péré ni Abrahamu, bẹ́ẹ̀ ó sì gba ilẹ̀ yìí.
tí àwọn eniyan fi ń mú ìdikù tabi aṣọ-iṣẹ́ tí ó ti kan ara Paulu, lọ fi lé àwọn aláìsàn lára, àìsàn wọn sì ń fi wọ́n sílẹ̀, ẹ̀mí burúkú sì ń jáde kúrò lára wọn.
 kí ni o ń ṣe tí o ń pá kọ ́ lọ ́ kọ ́ lọ ́ ní ìta níbẹ ̀ yẹn ?
 A fe je ko kopa lati siso loju eegun kii ifesewonse ohun o to bere.
O ni ti wọn ba ti gbe ọpa aṣẹ naa sọkalẹ kuro lori aga rẹ, o n tumọ si pe igbimọ ti wa ni ijoko lati sọrọ lori abadofin.
"Ìbáwí wá lásìkò tí àwa bẹ̀rẹ̀ orin kíkọ, tí a sì ń gbà ìbáwí àmọ́ ni asiko yii, ọ̀pọ̀ olórin lo ń kọ ẹyin sì ìbáwí.
Àwíjàre iléèṣẹ́ Fresh FM lórí àwọn ẹ̀sùn nàá Ohun elo igbohun safẹfẹ ti owo rẹ ko din ni milliọnu mejidinlọgbọn naira lo da wo lasiko ti ijọba ipinlẹ Ọyọ fi katakata wo ile iṣe redio Fresh Fm ti o jẹ ti gbajugbaja akorin juju, Yinka Ayefẹlẹ lojo Aiku."
Aare oun koko se iroyin naa, amo nigbeyin o so pe, oun ti da gbogbo owo ti oun na ohun pada.
Ko si ẹni to mọ ibi ti awọn aworan meji toku wa.
”“Awon kan tile n so pe ki won tun bu ola  fun Kudirat.
Orúkọ Jesu ati igbagbọ ninu orúkọ yìí ni ó mú ọkunrin tí ẹ rí yìí lára dá.
Iroyin kan sọ pe ilegbe awọn oṣiṣẹ to wa nile iwe naa lawọn ọdaran naa kọkọ lọ ni nibi ti wọn ti ji iyawo ọkan lara awọn gbe.
Asofin melaye fi fidio yi sori opo ayelujara instagramu rẹ lọjọ ẹti.
títí di ìgbà tí òun óo fi ko yín lọ sí ilẹ̀ mìíràn tí yóo dàbí tiyín, ilẹ̀ tí ó kún fún ọkà ati waini, ilẹ̀ tí ó kún fún oúnjẹ ati ọgbà àjàrà, ilẹ̀ tí ó kún fún igi olifi ati oyin, kí ẹ lè wà láàyè, kí ẹ má baà kú.
Amọ ṣa ileeṣẹ ọlọpaa ni Katsina sọ fun BBC pe owo ti awọnklede lati fun ẹni to ba le tawn lolobo nipa ibi ti wọn ti le ri olori naa le ju miliọnu marun un naira lọ.
Ẹ máa yọ̀, ẹ̀yin ará Sioni!
"Àkọlé àwòrán, ìfọ̀rọ̀wérọ̀ BBC Yorùbá O ni ""bí Ọyọ bá dán obìnrin wò, Ọyọ a dùn ún wò, kò ní sí ọ́fíìsì ọkọ gómìnà"" nitori naa, oun yoo ṣe owo ilu ti wọn ko ki n lo daadaa tẹlẹ daadaa bayii."
Àwọn orílẹ̀-èdè kò ní lọ sọ́dọ̀ rẹ̀ mọ́,odi Babiloni pàápàá yóo wó lulẹ̀.
Wọn yoo kede ẹni to jawe olubori nibi eto kan ti yoo waye nilu Eko ni ogunjọ, oṣu Kẹsan, ọdun 2019.
Láìsí àní-àní, èpè ja àwọn ológun 28  yẹn lóru ọjọ́ náà.
Ní ìgbẹ̀yìn-gbẹ́yín gbogbo wọn, ó wá farahàn mí, èmi tí mo dàbí ọmọ tí a bí kí oṣù rẹ̀ tó pé.
Àwọn tí ó ń pọ́n wa lójú sọ pé kí á dá àwọn lárayá, wọ́n ní,“Ẹ kọ orin Sioni kan fún wa.
Nítorí pé ọ̀rọ̀ ìyànjú wa kì í ṣe ohun ìṣìnà, bẹ́ẹ̀ ni kì í ṣe ohun èérí tabi ti ìtànjẹ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù World Teachers Day: Ẹ̀kúnrẹ́rẹ́ àlàyé rèé nípa ìlànà àkànṣe owó oṣù tuntun fáwọn òlùkọ́ 5 Ọ̀wàrà 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 6 Ọ̀wàrà 2020 Oríṣun àwòrán, Google Ni Ayajọ Ọjọ awọn olukọ lagbaye, World Teachers Day ni Aarẹ Buhari kede ilana tuntun fun owo oṣu awọn olukọ ni Naijiria.
Àgbékalẹ̀ Amotekun dára torí agbára òògùn àwọn baba wa kò dínkù tàbí parẹ́ - Peter Fatomilola Iléẹjọ́ gíga Akure kọ̀ láti gba onídùróó olórí ìjọ Sotitobire Mò ń tọ̀ s'ára ni mo fi gba ara à mi l'óko ẹrú ní Oman Ẹ fi èmi àti àwọn alága káńṣù APC sílẹ̀, ká yanjú aáwọ̀ wa nítùbí-ǹnùbí - Makinde bẹ iléẹjọ́ Ọba Balogun ni Olubadan ko lagbara bii ti wulẹ ko mọ, lati le awọn Ọba Ibadan kuro nilẹ Ibadan.
Olu Jacobs: Àwọn gbajúmọ̀ òṣèré márùn-ún tí wọn ti pa irọ́ ikú mọ́ sẹ́yìn rèé
Ọlọrun, láti ìgbà èwe mi ni o ti kọ́ mi,títí di òní ni mo sì ń polongo iṣẹ́ ìyanu rẹ,
    Ní agogo mẹ́sàn-án gééré ni a dé ààfin ní ọjọ́ tí ó tún dá yìí, a tilẹ̀ kọ́ ṣebí a pẹ́ ni, ṣùgbọ́n nígbà tí a dé ọhún ni a mọ pe a dé sí àkókò gan-an.
 O di dandan ki opopona irinna to dara wa, ki ona ibanisoro to ye kooro wa pelu eto ilera alabode ti o kunju owo sugbon ti ko ga ju ara lo wa larowoto awon eniyan.
Wọn ni bi awọn ọmọ orilẹede Naijiria se n bẹ gija sinu idokoowo owo inu afẹfẹ bit-coin n pe fun amojuto to peye.
Aleshinloye wá fikùn pé àwọn tí gbé ọ̀rọ̀ náà lo sílè ẹjọ́, tí àwọn sí ń dúró de idajọ ilé ẹ̀jọ́ lórí ọ̀rọ̀ náà.
Bakannaa ni wọn fún Sane ni àmì ẹyẹ ọjẹ wẹwẹ agbabọọlu to pegede julọ, ni liigi naa fun ọdun 2017-2018.
Ṣòkòtò mi kan péńpé báyìí tí ó jẹ́ àwọ̀tẹ́lẹ̀ mi ni mo tún fi fún àwọn ìránńṣẹ́ ọ̀rẹ́ mi náà ṣùgbọ́n inú Baba-onírùngbọ̀n kò dùn sí gbogbo aájò tímo ń ṣe wọ̀nyí, gbogbo ìtọ́jú wa tí ó ṣe kò jọ ọ́ lójú, òun jẹ́ ọ̀kan nínú àwọn wọn-ọnnì tí wọn kì í ṣe oore nítorí kí ènìyàn baà san án padà, ìrétì àwọn ẹni tí ń bẹ lọ́wọ́ Ọlọ́run Ọba.
Àwọn eniyan náà dákẹ́ jẹ́ẹ́ gẹ́gẹ́ bí ọba Hesekaya ti pàṣẹ fún wọn, wọn kò sọ ọ̀rọ̀ kankan.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Coronavirus pandemic: Ẹgbẹ́ àwọn àgbẹ̀ ní Nàìjíríà ní ìyàn ń bọ̀ lẹ́yìn coronavirus àyàfi.
Wọ́n ti gbé òkú Ibidunni Ighodalo sílé ìgbókúpamọ́sí l'Eko Wo ojú ọmọbìnrin 5 tí afipa báni lòpọ̀ pa ní Nàìjíríà Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Grace Oshiagwu: Gómìnà Makinde ké sáwọn ọlọ́pàá, àwọn lọ́balọ́ba lágbègbè Akinyele Bí o ṣe n lọ lori ti awọn kan bẹrẹ si ni lu awọn ọkunrin meji kan laarin ọna.
"orúkọ ti àwọn obi rẹ ́ sọ o ni "" siddhartha gautama "" ."
Ẹ má páyà lórí àìsí irinṣẹ́ ìṣègùn nílé ìwòsàn torí Covid19, ìmọ́tótó ara yín ló jà jù - NMA Oríṣun àwòrán, Getty Images Aarẹ apapọ fun ẹgbẹ awọn onisegun oyinbo nilẹ wa, Dokita Adedayọ Faduyile ti salaye pe irọ to jinna sootọ ni pe awọn eeyan ti n ya wa sawọn ile iwosan abẹle, lati wa gba iwosan.
Wayi, ki o to di pe o jẹwó ninu iyikoto, Savastano ni a gbọ pe o jẹ kápẹ́ńtà, ti kò si ni owo tó tó lati tọju ara rẹ̀.
Amọ, bi o ti ṣe koko to lati rin irinajo lasiko yii, bakan naa ni o ṣe koko lati kiyesi ilera ara wa lasiko arun Coronavirus yii, nitori ko i tii kuro nilẹ.
“Ofin naa yo ile-ise ti awon osise re ko ju ogun tabi
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Yomi Fabiyi ló ni ki òun àti ìyàwó rẹ̀ yàgò fún ra wọn Wakati kan ataabọ gbako ni mo fi duro de e, ki n to ri ọkọ ayẹkẹlẹ rẹ lọọkan.
Schalke 04France Ligue 1 February 10 17:00 Toulouse ?
Ó sọ fún àwọn ará Penueli pé, “Nígbà tí mo bá pada dé ní alaafia n óo wó ilé ìṣọ́ yìí.
"Ninu alaye rẹ loju opo Instagram rẹ, Lizzy ni ""Se bi emi ni mo dide lati ja fun Toyin Abraham lasiko tawọn eeyan n tabuku rẹ loju opo ayelujara nigba ti isẹlẹ ti Seun Ẹgbẹẹgbẹ waye, amọ titi di asiko yii, Toyin ko ki mi ri ku oriiire lasiko ti mo ba kede pe Ọlọrun se oore nla fun mi."
Ọjọ́ meje ni ẹ óo fi jẹ burẹdi tí kò ní ìwúkàrà, ní ọjọ́ keje ẹ óo pe àpèjọ kan fún OLUWA láti ṣe àjọ̀dún.
Lẹ́yìn ti afuransi náà bọ lọ́wọ́ ọlọ́pàá ló mú ẹjọ́ náà padà wọ́ sí àgọ́ ọlọ́pàá ti ilé iṣk ọlọ́pàá si bẹ̀rl si ni ṣe ìwádìí àwọn ènìyàn náà.
Osisẹ alarina fun ọgba fasiti Ibadan ni ni kete ti iroyin kan awọn osisẹ alaabo to wa lọgba ileeẹkọ naa, ni wọn ti ta mọra, ti wọn si kesi awọn ọlspa lati wa kun wọn lọwọ.
O polongo fidio awọn sẹnetọ kan to tako ọkọ rẹ̀ Igba miran tun ni asiko to fi awọn fidio kan sita.
“Ẹ̀mí Oluwa wà pẹlu minítorí ó ti fi òróró yàn míláti waasu ìyìn rere fún àwọn talaka.
Ta ló lè ṣe ẹ̀fẹ̀ tó Mr Latin láàrin àwọn apanilẹ́rìín fíìmù Yorùbá?
Ọmọ ọdún mẹ́tàdínlógún (17) nì Dúró.
''Bi ẹni wi pe ara ran bọmbu lọwọ ni ti eeyan ba fin in si imu'' Dokita Anthony tun sọ wi pe ''ti eeyan ba mi afẹfẹ yi to yẹ ki a ma mi sita sinu, a maa ṣokunfa iku'' Afẹfẹ Idana gaasi Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Afẹfẹ gaasi idana le mu ina dida ya amọ o le yara pa eeyan O ṣeeṣe ki eefin rẹ naa ṣe iku paniyan ninu ile.
Ṣugbọn OLUWA bínú sí Mose ati Aaroni, ó ní, “Nítorí pé ẹ kò gbà mí gbọ́, ẹ kò sì fi títóbi agbára mi hàn níwájú àwọn eniyan náà, ẹ̀yin kọ́ ni yóo kó wọn dé ilẹ̀ tí mo ti ṣèlérí láti fún wọn.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Àwọn obìnrin orílẹ̀-èdè Iran ti lè wo bọ́ọ̀lù aláfẹsẹ̀gbá báyìí 10 Ọ̀wàrà 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 13 Èbibi 2020 Oríṣun àwòrán, @90min_Football Àkọlé àwòrán, Ọpọlọpọ awọn obinrin Iran lo ti gbaradi loni lati foju ganni idije bọọlu fun igba akọkọ Ọpọlọpọ orilẹ-ede agbaye ni ko fun awọn obinrin lanfani lati ṣe awọn ohun kan ti awọn okunrin lee ṣe.
Báyìí ni Simiri ṣe pa gbogbo ìdílé Baaṣa, gẹ́gẹ́ bí OLUWA ti sọ tẹ́lẹ̀, láti ẹnu wolii Jehu, 
Ò ń fi ọ̀wọ̀n ìkùukùu darí wọn lọ́sàn-án, o sì ń fi ọ̀wọ̀n iná darí wọn lóru, ò ń tọ́ wọn sí ọ̀nà tí ó yẹ kí wọ́n rìn.
Itunmọ eleyi si ni wi pe awọn to yẹ ki wọn gba alejo idije naa ni ọdun 2021 ati 2023 yoo sinmi na.
Kò ì tíì pẹ́ ti ọ̀kan nínú wa pa àgbọ̀nrìn kan, a bá gbé e fún un.
A kò lè rí ohun tí kò dára kí á má sọ nítorí pé abẹ́ rẹ ni a ti ń jẹ; nítorí náà ni a fi gbọdọ̀ sọ fún ọba.
Yollywood: Ẹ wo àwọn gbajumọ òṣèré tíátà tó jogún ere ṣíṣe lọ́dọ̀ òbí wọn
Ni ọjọ karun oṣu karun ọdun 2019 lawọn ajinigbe ji Ọjọgbọn Adeyinka Adegbẹhingbe gbe ti wọn ko si fi silẹ afi igba ti wọn gba miliọnu marun naira lọwọ awọn eeyan rẹ.
Igbakeji aare ojogbon Yemi Osinbajo, loso oro ohun di mimo lasiko abewo ibanikedun re sibi isele naa.
To ba jẹ pe o fẹ ẹ gba kaadi miran ni, ẹgbẹrun márùn-ún lo ba de.
Wọn ni wọn ri awọn ole naa mu lasiko ti ikọ naa ṣe iṣẹ wọn lasiko awọn oju omi naa.
Wikki 3-0 River UtdMFM  3-0 HeartlandRangers 1-0 EnyimbaFCIU 1-1 Abia WarriorsLobi  1-0 Katsina UtdTornadoes 1-0 Plateau UtdYobe Stars 2-0 Kano PillarsKwara Utd 1-1 El KanemiGo Round 1-0 Sunshine.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Kọmíṣọ́nà fétò ẹ̀kọ́ nípínlẹ̀ Ọ̀ṣun ní ibi tó bá wu ìjọba ló leè gbé òṣìṣẹ́ rẹ̀ lọ Bi o tilẹ jẹ wi pe o ni oun ko mọ nipa akọroyin kankan ti wọn da pada, kọmiṣọna feto ẹkọ ni ipinlẹ Ọṣun ni ibi to ba wu efuufulẹlẹ nii dari igbẹ si, ibi to ba wu ijọba lo lee gbe awọn oṣiṣẹ rẹ lọ atipe niwọn igba ti awọn ti wọn gbe lọ si ileewe gẹgẹ bii olukọni wọnyii ba ti ni iwe ẹri olukọni, ileewe lo yẹ ki wọn wa.
Ọmọ mi, bí o bá ṣe onídùúró fún aládùúgbò rẹ,tí o jẹ́ ẹ̀jẹ́ fún àjèjì,
Ìyẹ́ kọ̀ọ̀kan àwọn Kerubu mejeeji gùn ní igbọnwọ marun-un, tí ó fi jẹ́ pé láti ṣóńṣó ìyẹ́ kinni Kerubu kọ̀ọ̀kan dé ṣóńṣo ìyẹ́ rẹ̀ keji jẹ́ igbọnwọ mẹ́wàá.
Lánàá òde yìí ni Gómìnà Babajide Sanwo-Olu sàlàyé pé, òun ń pinu láti kásẹ̀ òfin tó ní kí wan ma san owó ìfẹ̀yìntì fún àwọn gómìnà tó ti jẹ rí àti àwọn ìgbákeji wọ̀n.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, APC Primaries: A ṣi n lọ sílé ẹjọ́ lóṣù tó m bọ̀ lórí ọ̀rọ̀ yìí Gomina Fayose ati ajọ EFCC ki se ajoji ara wọn.
Ọ̀gbẹ́ni Gbénga Olugunna, tó jẹ́ ọ̀kan lára àwọn aṣáájú ẹgbẹ́ òṣìṣẹ́ lawọn ileesẹ tó ń se rọ́bà lórílẹ̀èdè Nàìjíríà, jẹ́ ọ̀kan lára àwọn ọmọ ẹgbẹ́ òṣìṣẹ́ tó fara káásá ìkọlù àwọn ọmọ ẹgbẹ́ ọlọ́kọ̀-èrò ọ̀hún.
Mo gbọ́ ohùn líle kan láti inú Tẹmpili tí ó sọ fún àwọn angẹli meje náà pé, “Ẹ lọ da àwọn àwo meje tí ó kún fún ibinu Ọlọrun sinu ayé.
Ẹ má ṣe sọ nípa rẹ̀ ní Gati,ẹ má ṣe ròyìn rẹ̀ ní ìgboro Aṣikeloni;kí inú àwọn obinrin Filistini má baà dùn,kí àwọn ọmọbinrin àwọn aláìkọlà má baà máa yọ̀.
Èmi OLUWA, tí n óo ṣe bí mo ti wí, èmi ni mo sọ bẹ́ẹ̀.
Nibayii ti ileẹjọ ti dajọ wipe ki ajọ naa tẹsiwaju, ati wi pe o lọtọ lati gbe amofin agba lọ sileẹjọ lori ọrọ naa, Ajọ SERAP ni igbesẹ akọkọ leyi ja si lati rii pe awọn oloselu dẹkun rirọ araalu jẹ.
O ni kani awọn ọlọpaa sọ̀kò ẹyẹ ihuwasi awọn Shiite nibi iwọde yẹn nipa yinyin ibọn ni, ọpọ ẹmi ko ba tun sọnu sii.
”Jesu dá wọn lóhùn pé, “Mo gbọ́.
Lara awọn to ti bu ẹnu ẹtẹ lu igbesẹ ọga ọlọpaa ni ajọ ajafẹtọ ọmọniyan lagbaye, Amnesty International, ẹka ti Naijiria.
"Sùgbọ́n ọ̀pọ̀ àwọn eléré tíátà ló ba adari eré náà dáwọ ìdunnu fún ayẹyẹ ọjọ́ ibí ọmọ rẹ̀ Lóri àtẹ̀jísẹ Instagram rẹ̀, Okiki ni ""Ẹ wo ẹni to ṣe ódìgbòòṣe si ọdun mẹ́fà"" O ní Kí ọdún meje rẹ rẹwa bi ìwọ gan ṣe rẹwa, ọmọbinrin mi ọ̀wọ́n, ìdùnu àti ayọ tọ́ sí ọ, mo gbàdúra ki Ọọ́run fi ààbò rẹ̀ fún ọ ni ọdún méje yìí àti ni gbogbo ọjọ́ aye rẹ̀."
Nkan ti a ṣe akiyesi ni pe, yíyà lati ibi kan si ekeji n fa sunkẹrẹ, fakẹrẹ ọkọ.
Aarẹ Muhammadu Buhari fẹ Aisha Muhammadu Buhari to j obinrin akọkọ ni Naijiria, Ọlọrun si fi ọmọ ati ọmọ ọmọ ta wọn lọrẹ.
Ẹni tí yóo dá mi láre wà nítòsí,ta ló fẹ́ bá mi jà?
Ileese aarẹ orilẹede Naijiria ti sọ pe, ọrọ ko ri bẹẹ; atipe awọn ọbayejẹ ẹda kan lo fẹ ti ibi ohùn mu aarẹ.
Kí ẹ mọ̀ pé ohunkohun tí ẹ sọ ní ìkọ̀kọ̀, a óo gbọ́ nípa rẹ̀ ní gbangba.
Oríṣun àwòrán, TWITTER/LASEMA Iṣẹlẹ to waye laipẹ yi ni Iju Ishaga Ọjọ buruku ẹsu gbomimu ni Ọjọru ọjọ Kẹrinlelogun oṣu Kẹsan jẹ fun awọn eniyan agbegbe Balogun, Iju Ishaga nipinlẹ Eko.
Ibeere yii lo jẹ yọ ni ọjọ Aje bi ọpọ ọmọ Naijiria ṣe n bẹnu ẹ̀tẹ́ lu Adari ijọ Deeper Life, Pasitọ William Kumuyi lori ọrọ rẹ nipa olori Naijiria, Aarẹ Muhammadu Buhari.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Sowore: Ilé aṣòfin Amẹrika ní ìwà ìfìyàjẹni tíjọba Nàíjíríà hù ń kọ àwọn lóminú 27 Bélú 2019 Oríṣun àwòrán, @YeleSowore Ile asofin Amẹrika to wa nilu Washinton DC ti koro oju si bijọba Naijiria se n tẹsiwaju lati fi Omoyele Sowore, Jones Abiri ati Kofi Bartels pẹlu Samuel Ogundipẹ si ahamọ ọlọjọ pipẹ.
 lọ ́ nà kejì , ò lè jẹ ́ wí pé bóyá nítorí pé ẹsẹ ̀ lásán tó fi rín nígbà náà tàbí nítorí pé agìnjù tó fi orí là nígbà náà ló ṣe rò wí pé ibi tí òun ti rìn ti nasẹ ̀ díẹ ̀ sí ọ ̀ dọ ̀ àbúrò òun lo ṣe dúró ni ibi tí a ń pè ní ijẹ ̀ bú - jẹ ̀ ṣà lónìí .
Ẹ foríjìn wá ọmọ Nàìjíríà, mó mọ̀ pé ẹ̀ ń bínú tórí a kò tètè gbé ìgbésẹ̀ lórí ọ̀rọ̀ EndSARS- Osinbajo Oríṣun àwòrán, Instagram/profosinbajo Ẹyin ọmọ Naijiria ẹ jeburẹ o, ẹ forijin wa, lootọọ lo yẹ ki ijọba apapọ ti wa nkan ṣe si ọrọ awọn olufẹhonuhan lori ọlọpaa #EndSARS / End SWAT.
Gẹgẹ bi iroyin naa se wi, agbegbe Ajebọ lopopona Ibadan silu Eko ni isẹlẹ naa ti waye ni deede aago meje alẹ.
Xenophobia: Ohun tójú àwọn ọmọ Nàìjíríà ń rí ní South Africa kọjá àfẹnusọ
"Mo tun maa n fun wọn ni ẹgbẹrun meji naira ẹni kọọkan ni ojoojumọ, wọn yoo sinu aawẹ lọdọ mi, lọdun to kọja, wọn gbe irẹsi, miliki, ororo lọ sile amọ Coronavirus ko jẹ ko ri bẹẹ lọdun yii.
’ Nítorí mo ń sọ fun yín pé Ọlọrun lè gbé ọmọ dìde fún Abrahamu láti inú òkúta wọnyi.
Eyi jẹ ikunọ fun ẹgbẹ agbabọọlu Arsenal lẹyin ti Sam Clucas ti gba ami ayo meji s'ojule.
Ẹ jẹ́ kí inú yín kí ó dùn, kí ẹ wá máa yan, nígbà tí gbogbo nǹkan wọnyi bá bẹ̀rẹ̀ sí ṣẹlẹ̀, nítorí àkókò òmìnira yín ni ó súnmọ́ tòsí.
kí ẹ̀wọ̀n fadaka tó já, kí àwo wúrà tó fọ́; kí ìkòkò tó fọ́ níbi orísun omi, kí okùn ìfami tó já létí kànga; 
Ọlọrun lè fun yín ní oríṣìíríṣìí ẹ̀bùn, tí ẹ óo fi ní ànító ninu ohun gbogbo nígbà gbogbo.
Ninu itan Naijiria, ọpọlọpọ lo gba pe asiko yii SARS já wọ ilé àwọn akẹ́ẹ̀kọ́ fásitì Akungba ni awọn agbofinro ti ṣe iku pa alaiṣe julọ ni eyi ti wọn pe ni àṣìta ìbọn ni ọpọ igbaỌlọ́pàá gbé àwọn tó yìnbọn lu olólùfẹ́ ní Ajegunle .
3 972688 Orilẹede South Africa 22206 38.
Ṣugbọn nkan ti ko ni tabi-tabi ni ibanujẹ ọkan ati ainidaniloju awọn obi awọn akẹkọbirin naa.
Ìkùukùu kún gbogbo inú ilé náà, ìmọ́lẹ̀ ògo OLUWA sì kún gbogbo inú àgbàlá.
Nítorí gbogbo àwọn tí ń sáré ìje a máa kó ara wọn ní ìjánu.
O ni lasiko ti Ọjọgbọn Simon ṣe n gẹ irun lọwọ ni afẹfẹ gaasi naa gbina ṣugbọn gbogbo igbiyanju lati doola ẹmi rẹ ja si pabo ni eyi to ti mu ẹmi Ọjọgbọn naa lọ.
Real Madrid gbadé ògo La Liga, Messi ní Barcelona ò lè ta pútú mọ́ Messi ti juwe ẹgbẹ agbabọọlu Barcelona gẹgẹ bi ikọ ti ko lagbara lẹyin ti ikọ Osasuna gbo ewuro si wọn loju pẹlu ami ayo meji si ọkan ni Nou Camp.
 Àrùn yìí pẹlu a máa wà lára irúfẹ ́ àwọn ẹranko bí i àádọ ́ jọ míràn .
osise tuntun fun ile-ise naa n jade lẹnu ikọsẹ won , ni eyi ti o waye ni ile-ẹkọ
Mama mama mi ni o n ṣe itọju mi nigba naa, bo tilẹ jẹ pe mo kọ lati sọ ohun to ṣẹlẹ fun un.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Èmi gan máa ń béèrè lọ́wọ́ ara mi pé ta ni Wole Soyinka gangan' Ọdọ baba kan, ti wọn n pe ni Daniel Ojo lo gbe nilu Ibadan, to si tun kawe nibẹ Ipo kinni ni Fagunwa maa n gbe nile ẹkọ tori pe ọpọlọ rẹ ji pepe Fagunwa maa n gba itan lẹnu aburo baba rẹ obinrin to n jẹ Fabunmi Nigba miran, o maa n sun si itẹ oku, igbo aginju tabi ko ti ara rẹ mọnu ile lati kọwe.
Koda, ọkọ ọlọpa to wa nikalẹ nibudo ọhun le ni ogun, tawọn agbofinro ti oju wọn ko rẹrin si duro wa wa wa, bi esinsin ba si ta firi nibẹ, wọn yoo wọn.
Iṣẹlẹ naa si tun mu awakọ Uber naa padanu iṣẹ rẹ lẹyin ti ko le lọ sibi iṣẹ nitori o farapa nibi iṣẹlẹ naa.
ninu awon aarun to buru julọ , eyi ni o maa jẹ ikeji iru rẹ  to sẹlẹ lorile ede naa laarin odun 2013-16  , aarun yii lo tun n  fa aarun eebi, aarunsu ( igbẹ gbuuru).
Ọga ọlọpaa Ewonwu ko ṣai jẹ ko di mimọ faraalu, paapaa àwọn eeyan ipinlẹ Ọyọ pe awọn ọlọpaa yoo maa sa ipa gbogbo nigbakugba lati daabo bo ẹmi ati dukia araalu.
Alájọ Ṣómólú: Ó fi ọdún mẹ́ta gba àjọ láì kọ́ sílẹ̀, kò sì si owó san Election 2019 Updates: Atiku pe ẹjọ́ tako Buhari pẹ̀lú 20 àgbà amòfin Election 2019 Updates: Makinde ní Ajimọbi fẹ́ ná owó Ọyọ tán, láti dá ìjọba òun lóró Sugbọn awọn akoroyin BBC, Yusuf Yakasai ati Halima Umar Saleh, ti wọn lọ si Kano lati gbe iroyin imurasilẹ fun idibo naa jade, ti ṣe iwadi lori bi wọn ṣe maa n ṣe owo kaadi ibo tita ati rira.
Lójijì Jesu pàdé wọn, ó kí wọn, ó ní, “Ẹ pẹ̀lẹ́ o!
5M ti pọ̀ jù fún owó fọ́ọ̀mù ìdìbò abẹ́lẹ́ sípò gómìnà APC - SERAP Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Àwọn eniyan tún ń rúbọ, wọ́n sì tún ń sun turari níbẹ̀.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, BBC Africa Eye: ìwádìí ìkọ̀ks BBC fihàn pé àwọn kan ń jí ohun èèlò ìdáàbòbò ìjọba tà nígbo Àwọn alágbára ni mo bá díje ṣùgbọ́n mo ti gbà f'Olọrun- Agboola Ajayi Igbakeji gomina ipinlẹ Ondo, Agboọla Ajayi ti ṣalaye idi ti o fi fidirẹmi ninu idibo abẹle lati yan oludije fun ipo gomina ni ipinlẹ naa lẹgbẹ oṣelu PDP.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Kunle Afolayan: èmi kò fẹ́ fi ogún sílẹ̀ fún ọmọ mi Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Oríṣun àwòrán, @feminist_co Bakan naa ni ẹgbẹ Feminist Coalition tun rawọ ẹbẹ sawọn ọdọ pe ki wọn dẹkun iwọde naa, niwọn igba ti aarẹ ti ba araalu sọrọ, ti ko si mẹnuba ohunkohun to nii se pẹlu ibọn yinyin to waye ni Lekki.
Oríṣun àwòrán, Facebook/Seyi Makinde Amọ, iwadi BBC Yoruba fihan pe ariwo sọ laarin gomina Makinde ati awọn asofin naa lẹyin ọjọ diẹ lori aba isuna ọhun.
Oríṣun àwòrán, Reuters Àkọlé àwòrán, Awọn ara orilẹede China kan n reti awọn eniyan wọn to wa ninu baalu naa Agbẹnusọ ileeṣẹ naa sọ pe ijamba naa waye ni nkan bi aago mẹsan ku iṣẹju mẹrindinlogun lowurọ ọjọ Aiku, laipẹ to kuro ni olu ilu oeillede Thiopia.
Nígbà tí wọ́n bẹ̀rẹ̀ sí kọrin ìyìn, OLUWA gbẹ̀yìn yọ sí àwọn ọmọ ogun Amoni, ati Moabu ati ti Òkè Seiri tí wọ́n wá bá àwọn eniyan Juda jà, ó sì tú wọn ká.
Ileesẹ BBC wa nkesi ijọba lati fun awọn akọroyin lanfaani lati sisẹ wọn pẹlu ominira to peye ati ododo lati atako lati ibikibi.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ijọba pasẹ fawọn agbofinro lati tọpinpin ọrọ ikorira lori ikanni ayelujara 25 Sẹ́rẹ́ 2018 Oríṣun àwòrán, AFP Àkọlé àwòrán, Ọrọ ikorira ti di agbẹdọ ni orilẹede Naijria pẹlu asẹ tuntun lati ọdọ ijọba Ijọba apapọ orilẹede Naijiria ti pa asẹ fun awọn ileesẹ alaabo gbogbo lati ji giri si gbigbogun ti itankalẹ awọn ọrọ ikorira lawọn ikanni ayelujara (social media) gbogbo.
Gbogbo àwọn tí ó ń gbé Lida ati Ṣaroni rí i, wọ́n bá yipada, wọ́n di onigbagbọ.
Niwọn igba to si jẹ pe ko si ohun ti ọkunrin lee se, ti obinrin ko lee se ju bẹẹ lọ, eyi lo mu ki Mọremi fi ara rẹ silẹ lati gba ilu rẹ la lọwọ ikonilẹru.
Gbogbo ẹbi, ará àti ilú yi ó parapọ̀ lati ṣe ẹ̀yẹ ikẹhin fún irú arúgbó bẹ́ ẹ̀.
ní ibi tí aláfà yọ ̀ ọ ̀ da fún arójòjoyè yìí , akọ-iṣu àtí tábà ni àwọn Òkè-òpó ti máa ń gbìn síbẹ ̀ rí .
James Bond: Gbajúgbajà òṣèré, Sean Connery tó ṣe fíìmù James Bond tí jáde láyé lẹ́ní ọdún 90
Tí a bá wo àwọn orílẹ̀-èdè tí wọ́n sẹ̀sẹ̀ bẹ̀rẹ̀ sì ní máa gbérí níwọ̀n ọgbọ́n ọdún sẹ́yìn a ri wí pé púpọ̀ nínú wọn ni wọn fi èdè abínibí kọ́ àwọn akẹ́kọ̀ọ́ wọ́n, kòsí iṣẹ́ìwádìí kan tí wọ́n se tí wọ́n kò kọ ní èdè wọn bí ó tilẹ̀ jẹ́ wí pé èdè gẹ̀ẹ́sì ni wọ́n gbà fi se ìwádìí náà.
Lẹ́yìn ìgbeyàwó ọdún mọ́kànlá àti ọ̀pọ̀ ìjà, Bọsẹ di èrò ọ̀run nílé Saidi Ayọ̀ abara bíńtín!
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Buhari gbé ‘Next Level’ jáde bíi ìwé ìpolongo ìbò rẹ̀ PDP fà Buruji Kashamu kalẹ̀ bíi olùdíje Gómìnà l‘Ogun Ìdìbò 2019 ku ọgọ́rùn-ún ọjọ́, INEC kò rí owó ìsúná rẹ̀ gbà Hubert Ogunde rèé, baba àwọn òsèré tíátà Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, World Toilet Day: Aráàlú ní woléwolé yẹ kó bẹ̀rẹ̀ àyẹ̀wò ojúlé dé ojúlé Bakan naa lo woye pe ọpọ eeyan ni ko ni isẹ lọwọ, ti ẹka awọn ileesẹ to n pese asọ sita si ti dẹnu kọlẹ patapata.
AFCON 2019: Ọmọ Nàijíríà rọ Super Eagles lati tubọ sápa wọn pẹlú Madagascar
Díẹ̀ sì ni àwọn tí wọ́n rí i.
 ' Ọjọ ìbì rẹ ni ọjọ kẹtadínlógún , osu ' ̀ ketàlá , 1907 nì awa , tokushima .
 A ti pinnu lati tun iboji Iwene Tansi se nitori pe irin ajo afe n ta lagbaye nipa mimu owo goboi wole ati nipa ipese ise oojo fawon eniyan.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Oba Adedokun Abolarin ti Oke Ila: Ó ya ọ̀pọ̀ tó súnmọ́ mi lẹ́nu bí mo ṣe ń kọ́ Diego Maradona ìlúmọọká agbábọ́ọ̀lù dágbére f'áyé Iroyin to n tẹ wa lọwọ ni yajoyajo sọ pe gbajugbaja agbabọọlu ni ọmọ Argentina Diego Maradona ti dagbere faye.
 Ìrora lè tẹ ̀ siwajú fún àwọn oṣù díẹ ̀ lẹ ́ hìn tí a yọ aràn kúrò .
Olorin takasufe, Zlatan Ibile lo kọkọ gborin jade pe lori awuyewuye to ṣẹlẹ lori ọrọ ara rirun to maa n waye laarin Tacha ati Mercy.
Coronavirus in Nigeria: Amúgbálẹ́gbẹ́ Gómìnà SanwoOlu kó àrùn COVID-19 ràn án, àmọ́ wọ́n ní àrùn náà kò dá a wólẹ̀
Ọmololu Akinwale naa wa fi kun wi pe ko si ipade kankan ti eniyan fẹ se ti ko le e se ni awọn ilu to lamilaaka lorilẹede Naijiria, ti yoo si yori si rere.
Oríṣun àwòrán, Twitter/todayng Ajọ to n risi idena ati amojuto ajakalẹ arun, NCDC lo fi ikede naa sita loju opo Twitter rẹ.
Lẹ́yìn ọdún mẹ́jọ̀, ìjọba Ọyọ bẹ̀rẹ̀ owó ẹ̀náwò àtìgbàdégbà padà fún àkóso ílé ẹ̀kọ́ Gomina ipinlẹ Oyọ Onimọ ẹrọ Ṣeyi Makinde ti fọwọ si sisan owo to to okoolelẹẹdẹgbẹta ati mẹfa miliọnu naira (₦526) fun gbogbo ile iwe ijọba gẹgẹ bi owo ẹnawo atigbadegba fawọn ileewe ijọba bii ẹgbẹrun meji aabọ.
Eyin Olukọ Yoruba ni ipinlẹ Eko ati alaga ati awọn oloye ẹgbẹ Akomolede to ku, BBC n dupẹ lọwọ yin fun iṣẹ takuntakun ti ẹ ṣe ti ẹ fi kọ wa ni awọn koko ọrọ wọnyii.
Pàápàá jùlọ fún àwọn ìlú tí àwọn ẹlẹ́sìn méjéèjì ti dojú ìjà ko arawọn.
 Sham T Kolo, Oludari ẹka iwadii ati ninu ajọ naa sọ fun BBC pe o ṣeni laanu pe awọn onibaara ọja ni Naijiria kii bikita lati yẹ deeti ọjọ ti nkan ti wọn fẹ ẹ ra yoo ti ẹnu bodo."
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù MI ní 'Òjíṣẹ́ Satani' ni pásítọ̀ kan; ni ìjọ Satani bá da lóhùn 29 Òkùdu 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 30 Òkùdu 2019 Oríṣun àwòrán, @MI_Abaga Àkọlé àwòrán, Ìjọ Satani dá MI lóhùn lórí ọ̀rọ̀ Fatoyinbo Ẹ ma pa orukọ Satani mọ awọn oniṣẹ ibi.
Báwo ni Kristi ti ṣe lè fi ohùn ṣọ̀kan pẹlu Èṣù?
Ó gba gbogbo àwọn ẹran ọ̀sìn pẹlu.
aladaani , won nifẹẹ lati da ile-ise ti yoo maa pese ina mona-mona sile niluu
takun ti won se lati ri pe eto idibo lo leto –leto ni  jake jado Ipinle Oyo.
Àwọn oriṣa tí kò lè ríran, wọn kò lè gbọ́ràn, bẹ́ẹ̀ ni wọn kò lè rìn.
"Dasofunjo tun ni ""laarin ọpọ eniyan, Majek jẹ ẹni to lawọ, ti ko ba ni, o maa n jẹ ibanujẹ ọkan fun un."
A kò rán Elija sí ọ̀kankan ninu wọn.
Iyawo ọba tuntun naa, Shilekunola Naomi jẹ woli ati ajihinrere ni Ijọ En-Herald Ministries to ti jẹ adari ijọ naa.
Ṣugbọn gbogbo ẹ̀yin tí ẹ di OLUWA Ọlọrun yín mú ṣinṣin ni ẹ wà láàyè títí di òní.
Kí ẹ má baà wí pé:Wò ó, a mọ̀ wọ́n.
Mò ń kú lọ, lọ́wọ́ àwọn apànìyàn!
"Ọwọ́ òfin ti tẹ ọ̀pọ̀ ọmọ Nàìjíríà lórí ẹ̀sùn jìbìtì l'Amẹrika- FBI Ọlọ́pàá Germany ń wádìí àfurasí mẹ́rin nínú àwọn tó kọlu Ekweremadu ni Germany Oríṣun àwòrán, @tolanialli Oun naa lo tun se "" Women in the Delta"" ni osu kejila, ọdun 2018."
Fifi ẹgbẹ kan silẹ lọ omiran wọpọ laaarin awọn oloṣelu ninu ipolongo ibo ni Naijiria.
Coronavirus: Kíni àwọn àmì tuntun tó n fihàn?
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Akomolede ati Aṣa lori BBC: Mọ̀ si nípa oríṣìí ẹ̀ka ìsọ̀rí ọ̀rọ̀ àti ìwúlò wọn Awọn eto ti aya gomina ni fun Risikat ati ọkọ rẹ wa nipele ipele, a tun fẹ gba sọọbu fun obinrin oloju buluu naa lati maa ta oogun to kọ isẹ rẹ.
Dokita àti Nọ́ọ̀sì fìyà jẹ mí lásìkò tí mò ń rọbí- Alaboyún Awọn onwonye sọ pe eleyi ko ni fawọn ileeṣẹ ọlọpaa ati ologun lanfaani lati ra awọn nnkan ija ogun, ohun ti wọn lee se ni ki wọn maa san owo ohun ti wọn ba ra diẹdiẹ Ilé ìgbìmọ aṣofin ti dájọ tí wọn ó fọwọsi àbádofin ìsúna 2019.
Mo ké pe OLUWA, ó sì dá mi lóhùn,ó sì gbà mí lọ́wọ́ gbogbo ohun tí ń bà mí lẹ́rù.
Naijiria, ojogbon  Yemi Osinbajo naa lo
5 3,893 Cape Verde 115 21.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Alápinni: Kò sí ẹni to fẹ́ kọ́kọ́ kọ́ iṣẹ́ òṣèré bíi ti àtẹ̀yìnwá PDP bu ẹnu atẹ lu Asiwaju Tinubu pe o fẹsun kan ẹgbẹ oselu PDP ati oludije sipo aarẹ lẹgbe oselu naa, Atiku Abubakar wi pe wọn fẹ fi tipatipa gbe e wọle gẹgẹ bi aarẹ lorilẹede Naijiria.
 Nitori naa,ko si eredi pe ẹnikan tun n sọ
Ọgbẹni Bada wa bu ẹnu atẹ lu iroyin kan to n ja rainrain pe ile ifowopamọ kan ti fun ọmọdebinrin ọjọ naa lẹ́bun owo Ọga ileewe Dele gba awọ́n ọmọ ile to ku ni imọran ki wọn gbiyanju lati maa ṣe gẹgẹ bi Dele ṣe ṣe to lo anfani to ni Ọ̀ọ̀ni kò láṣẹ láti yọ mí nípò, mi ò sì ní ááwọ̀ mọ́ pẹ́lú Aláàfin-Oluwo Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ìlú Eko ló jẹ gbèsè jù ní Nàìjíríà lẹ́yìn ìjọba àpapọ̀ Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Wọ́n ní oró bí oró ejò,wọ́n dití bíi paramọ́lẹ̀ tí ó di etí ara rẹ̀,
Ẹ̀rù OLUWA ba Dafidi ní ọjọ́ náà, ó sì wí pé, “Báwo ni n óo ṣe gbé àpótí ẹ̀rí OLUWA wá sọ́dọ̀ mi?
Oríṣun àwòrán, NIGERIAN IMMIGRATION SERVICE Àkọlé àwòrán, Visa to Nigeria: Ó lé gba Visa láti wá fẹ̀yìntì sí Naijiria Lẹ́yìn ìpàdé òní l‘Abuja, ṣé ASUU yóò yanṣẹ́ lódì àbí bẹ́ẹ̀kọ́?
Keyamo so pe, orile-ede Naijiria ni awon ohun alumoni ati awon ologbon ori lati mu idagbasoke ba orile-ede naaO salaye pe, awon olori wa ni oludena fun idagbasoke orile-ede Naijiria fun ojo-pipe.
Obìnrin Mùsùlùmí ṣe ilé àlúfà ní ọ̀ṣọ́ fún Kérésìmesì Àwọn gómìnà nílẹ̀ Yorùbá ti kùnà láti pèsè ààbò tó péye fún aráàlú - Ẹgbẹ́ Majeobaje Iwọde naa si ni Sowore lo wa lati tako eto isejọba ti ko mọyan lori atawọn iwa aidaa miran ni Naijiria.
ó ranṣẹ sí wọn pé, “Kí OLUWA bukun yín nítorí pé ẹ ṣe olóòótọ́ sí Saulu ọba wa, ẹ sì sin òkú rẹ̀.
moshood káṣìmawòó Ọláwálé abíọ ́ lá ( august 24 , 1937 - july 7 , 1998 ) tí ó túmọ ̀ sí m.
Adebayo Shittu, Esq -Ko yege (ko ni iwe ẹri isinru ilu NYSC ni èyí to ti ni òun kò kọ̀ lati ṣẹṣẹ lọ sin ilẹ̀ baba oun lasiko yii) Ipinlẹ Ogun:1.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Sogidi Lake: Kòṣẹja-kòṣèèyàn lá bá nínú adágún odò náà -Ojedele Ṣùgbọ́n, ó sọ pé Coronavirus kìí se ìṣirò Maasi.
UNILAG Child Molestation: Ọ̀jọ̀gbọ́n Fagbohungbe ní àwọn òbí ayé òde òní kò ṣiṣẹ wọn bí iṣẹ́
  Ogbeni Felix Adolije, ti o je
Bi o tilẹ jẹ pe Gomina Ganduje ti ṣalaye pe oun ko gba owo ẹyin lọwọ ẹnikẹ ri, sibẹ olori ileeṣẹ iroyin to gbe fidio naa sita, Jafar Jafar farahan niwaju ile aṣofin ipinlẹ Kano nibi ti o ti sọ pe ootọ ni gbogbo ohun to wa ninu fidio naa, o si fi ẹsun kan gomina naa pe lootọ lo gba owo ẹyin lọwọ awọn kọngila ti wọn gbe iṣẹ ijọba fun nipinlẹ ọhun.
Nigba ti awon miiran so pe, iku Tsvangirai le mu atunto ba egbe naa pelu adari tuntun, ti o tun je odo langba.
 Ṣíṣe àyẹ ̀ wó ní ojú ibí tí ó bá ràn ṣe pàtàkì bí ọ ̀ pọ ̀ lọpọ ̀ oògùn araríro.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù BREXIT: Kí ni ohun tó fẹ́ yọ Theresa May nípò olóòtú ìjọba Gẹ̀ẹ́sì ṣáájú àkókò rẹ̀ 28 Ẹrẹ̀nà 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Aigbọra ẹni ye lori BREXIT ti n fa ọpọ iwọde ni orilẹede naa.
Nígbà náà ni wọ́n bẹ̀rẹ̀ sí bá ara wọn jiyàn pé, “Bí a bá wí pé, ‘Láti ọ̀run ni,’ yóo sọ pé, ‘Kí ló dé tí ẹ kò fi gbà á gbọ́?
Agbébọn pa ènìyàn 14, ọmọọ̀gun Naijiria sígun ni Kaduna Rohr já Iheanacho àti Semi jùú lẹ̀ lọ Egypt fún AFCON 2019 Ìpínlẹ̀ Oyo gba ipò ìkíní mọ́ Edo lọ́wọ́ nínú fífí ọmọdé ṣ'ẹrú Ẹ̀mí 18 ṣòfò ní Òpópónà Akure sí Ọwọ O ni awọn ti ṣalaye fun ijọba pé ijọ Olorun kọọkan lo ti ṣagbekalẹ ilana ofin ti wọn n tẹle fun alaafia awujọ ti wọn wa koda ki wọn to ṣeto iwaasu.
Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Fatai Rolling Dollar: Baba 70 jayé kọjá 70 kó tó dágbére fáyé pé ó dìgbóṣe!
 Awon alafojuri ni afurasi naa tan aago ikilo ijamba ina ko to bere sini sise fawon eniyan.
Nínú ìtàn ìpińlẹ̀ yìí pẹ̀lú, wọ́n sábà má ń wò ó bóyá ọkàn lára àwọn olùdíje dupò wá láti ìjọba ìbílẹ̀ náà.
Ààrẹ Buhari sún eré ìdárayá àpapọ̀ Edo 2020 síwájú Àwọn ọmọ Ilé Igbimọ Asofin àgbà ti fáríga nítori Coronavirus Ìjọba Somalia gbẹ́sẹ̀ lé ìrìn àjò òkè òkun lẹ́yìn tí Coronavirus báwọn lálejò Ọmọ Nàìjíríà kan ti ní àrùn Coronavirus nípìnlẹ̀ Eko Àwọn ọba Yorùbá kan rèé tí wọ́n rọ̀ lóyè, tí ọba míràn jẹ lójú ayé wọn Bí Fayemi bá tasẹ̀ àgẹ̀rẹ̀, àwọn oníbáwí rẹ̀ wà l'Ekiti-Peter Fatomilọla Ọgbẹni Mustapha ṣalaye pe ijọba ko fẹ ki arun naa tan kalẹ ju eeyan mẹta to ti lugbadi rẹ lọ lorilẹede Naijiria.
Ọ̀dọ́ aguntan tabi àwọ́nsìn ewúrẹ́ náà kò gbọdọ̀ lábàwọ́n, ó lè jẹ́ àgbò tabi òbúkọ ọlọ́dún kan.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ẹjọ́ Walter Onnoghen: NJC nìkan ló lásẹ láti yọ Adájọ́ Ágbá 30 Sẹ́rẹ́ 2019 Àkọlé àwòrán, Ilé ẹjọ́ kòtẹ́milọ́rùn ti fi ọwọ́ òsì di ẹjọ́ tí Adájọ́ Àgbà lórílẹèdè Naijiria pè mọ́ ìjọba àpàpọ̀.
Báyìí ni onígbèsè bá wọlé, ó sì san gbèsè fún Alákàn , ní Alákàn bá kóredélé.
Ọ̀gá INEC náà sọ pe, àwọn tó fọwọ́ sí ìwé láti yọ Dino Melaye dín diẹ̀ ní ẹgbẹ̀rú lọ́na igba (189,870), ṣùgbọ́n ní ọjọ́ Àbámẹ́ta, àwọn tí wọ́n yẹ orúkọ wọn wò dín diẹ̀ ní ẹgbẹ̀rú mọ́kàndínlógún (18,742).
Àṣẹ yìí wáyé lẹ́yìn tí ìgbìmọ̀ olùwádìí tí wọ́n gbe kalẹ̀ lórí ẹ̀sùn aṣemáṣe tó rọ̀ mọ́ ìbáṣepọ̀ tí kò tọ̀nà, èyí tí wọ́n fi kan àgbà ọ̀jọ̀gbọ́n Richard Akíndélé ní fásitì ọ̀hún.
Babiloni dàbí ibi ìpakà, tí a tẹ̀ mọ́lẹ̀ nígbà tí à ń pa ọkà.
Iye eeyan to forukọsilẹ lati jẹ anfaani ilera labẹ iléeṣẹ́ adójútòfò ìlera,NHIS, ṣi kere toun ti bi ko ṣe rọrun lati mọ iye eeyan ti o tiforukọ silẹ Adele akọwe NHIS ti fojuda pe iye eeyan to forukọsilẹ kere si ida maarun ninu ida ọgọrun Gẹgẹ bi iroyin ti ile ifowopamọ agbaye World Bank ko jọ lati ọdun 2009,awọn eeyan to le ni ida mẹta lo ti fi inira bọsi inu iṣẹ́ latari owo gọbọi ti wọn n san lati gba itọju.
Ninu awọn to kopa nibi apero atunto ilẹ Naijiria to waye ni 2014, o jẹ ọkan lara awọn agba ọjẹ to kopa nibẹ.
Ọrọ naa bi ijọba ipinlẹ Kano ninu, lati igba naa si ni wahala ti n rugbo laarin wọn.
Ọ̀gá ọlọ́pàá túntún ṣèlérí láti kojú ipenija ààbò àti ìdìbò 2019 Lori ọrọ pe ko fẹ ẹ si iyatọ laarin ẹgbẹ oṣelu rẹ, PDP ati ẹgbẹ oṣelu APC nipa afojusun wọn ati bi wọn ṣe n ṣe ipolongo ibo ti ko gbajumọ ọrọ to ṣe koko, Atiku ni iru nkan bẹ ko le ṣai waye nitori pe eto oṣelu Naijiria ko ti fẹsẹ rinlẹ daada.
Ọlọ́pàá, sójà yabo Lekki Toll Plaza láti dènà ìfẹ̀hónúhàn míràn Oríṣun àwòrán, Johnpaul/twitter Ní ǹkan tó jọ́ bi ẹni pé ìjọba ń gbìyànjú láti dènà ìwọ́de ìfẹ̀hónúhàn #Endsars àwọn ọlọ́pàá àti sójà lọ sí Toll Gate Lekki nílùú Eko.
Ìjọba Somalia gbẹ́sẹ̀ lé ìrìn àjò òkè òkun lẹ́yìn tí Coronavirus báwọn lálejò Ọmọ Nàìjíríà kan ti ní àrùn Coronavirus nípìnlẹ̀ Eko Mo kó àrùn Coronavirus lẹ́yìn tí mo ṣalábapàdé ẹni tó ní àrùn náà lára - Idris Elba Coronavirus: Wo ohun tí o ní láti ṣe láti dáàbò bo ara rẹ 1.
Ó tẹ́ pẹpẹ oriṣa sinu ilé OLUWA, ilé tí OLUWA ti sọ nípa rẹ̀ pé, “Ní Jerusalẹmu ni ibi ìjọ́sìn tí orúkọ mi yóo wà, tí ẹ óo ti máa sìn mí títí lae.
" Iná ẹ̀lẹ́ńtíríkì pa ẹlẹ́wọ̀n márùn ún lọ́gbà ẹ̀wọ̀n l'Eko Nǹkan mẹ́wàá tó yẹ ní mímọ̀ nípa fásitì ẹ̀kọ́ ìrìnnà òní $50m ní Nàìjíríà Kí ni pàtàkì ọ́fíìsì agbègbè fún aṣòfin?
Ẹni to bori: Madagascar Senegal vs Uganda.
N óo pa gbogbo oriṣa Baali tí ó kù níhìn-ín run, ati gbogbo àwọn babalóòṣà wọn; 
Nítorí nípa oore-ọ̀fẹ́ tí Ọlọrun fún mi, mò ń sọ fún ẹnìkọ̀ọ̀kan láàrin yín pé kí ó má ṣe ro ara rẹ̀ jù bí ó ti yẹ lọ.
Ọba tún bi í pé, “Níbo ni Mẹfiboṣẹti, ọmọ ọmọ Saulu, ọ̀gá rẹ wà?
OLUWA kò ní ta eniyan rẹ̀ nù, nítorí orúkọ ńlá rẹ̀, nítorí pé ó wù ú láti ṣe yín ní eniyan rẹ̀.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Sikiru Ayinde Barrister, Barry wonder gbajúmọ̀ olórin Fuji tó ṣiṣẹ́ sọ́jà, tẹ̀wé-tẹ̀wé àti akọ̀wé iléèṣẹ́ 16 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Oríṣun àwòrán, Twitter/@AyindeBarrister Iku n pani, ilẹ n jẹyan.
Oríṣun àwòrán, AFP Àkọlé àwòrán, Russia 2018: Awọn alátilẹyin àgbabọọlu kò le pada sílé Oluremi ní pé ‘Fan IDs’ wọn ló yẹ kí wọn lò, sùgbọ́n ó jẹ́ ohun tó yani lẹ́nu pé kò sí ọnà láti rìn irìnààjò, bótilẹ̀ jẹ́ pé ọ̀ọ̀fẹ́ ní Fan IDs jé láti orílẹ́-èdè Russia.
Ọpọlọpọ sinima agbelewo lo ti n jade bo tilẹ jẹ wi pe lori ayelujara nikan naa lẹ ṣi ti le ri wọn wo bayii.
Ẹ máa yọ̀ kí inú yín sì dùn gidigidi,ẹ̀yin ará Jerusalẹmu!
Wọn gbe lọ sile ẹjọ, ti adajọ si sọ si ẹwọn ọdun mọkanla ni ọgba ẹwọn Agodi nilu Ibadan.
Ó bẹ̀rẹ̀ láti àgbékà kinni, ó gba inú ti ààrin lọ sí èyí tí ó wà lókè patapata.
 pelu olukuluku eniyan ni gbogbo orile ayafi ni antarctica , awon eniyan je awon iruaraleaye .
ṣugbọn a óo máa pe ẹ̀yin ní alufaa OLUWA,àwọn eniyan yóo sì máa sọ̀rọ̀ yín bí iranṣẹ Ọlọrun wa.
Akọrin takasufe naa to ṣe ayẹyẹ ọjọ ibi ọdun mejidinlọgbọn rẹ lọjọ Aiku, ọjọ kọkanla, oṣu Kẹwaa, sare lati yọ fọto naa kuro lori ayelujara.
Afurasí agbébọn 47 bọ́ sọ́wọ̀ ikọ̀ 'Operation Burst' l'Oyo Oríṣun àwòrán, Facebook/Nigeria Police Force Afurasi agbebọn mẹtadinlaadọta ni ọwọ sinkun ikọ digboluja Operation Burst ti tẹ nilu Igangan, nipinlẹ Oyo.
Oba Adeyemi ni oun ko awọn ẹsọ sita lati ma ṣe fun awọn janduku laaye lati ṣekọlu si awọn agọ ọlọpaa lasiko ifẹhọnuhan EndSars naa.
Àwọn ọmọ Israẹli bá wọn jẹ ninu oúnjẹ wọn, wọn kò sì bèèrè ìtọ́sọ́nà lọ́dọ̀ OLUWA.
Òun náà sì dáhùn, ó ní, Ta ní ń pe èmi èkúté, èmi èrò inú igbó, èmi èrò inú aginjù, èmi tí mò ń bá ayé mi kiri láàárin ìtàkùn àti igi?
 ní ọdún 1921 ni ó dá ẹgbẹ ́ òṣèlú fascist sile .
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Lagos-Ibadan Train: Iléeṣẹ́ Rélùwéè ní ìgbà 16 ní àwọn ọkọ̀ ojú irin náà yóò máa rìn lójúmọ́ 22 Ògún 2020 Oríṣun àwòrán, @Official_NRC Igba ọtun ati eto idẹrun ti de fun awọn arinrin ajo lati ilu Eko si Ibadan, pẹlu ọkọ oju irin reluwe ti yoo bẹrẹ isẹ losu to n bọ.
”Abenugan wa ro ijoba ati awon ti oro kan lati maa segbaradi fun iru isele bayii, ki won si maa se ilaniloye fun awon eniyan  lori ikolu buruku naa.
Buhari wa fọwọ gbaya pe oun yoo ri daju pe aabo wa fun ominira ati ẹtọ araalu, ti oun si setan lati raga bo isọkan orilẹede Nàíjíríà.
N óo ṣí odò lórí àwọn òkè,ati orísun láàrin àwọn àfonífojì;n óo sọ aṣálẹ̀ di adágún odò,ilẹ̀ gbígbẹ yóo sì di orísun omi.
Kí ló dé tí ẹ fi súnmọ́ ògiri tóbẹ́ẹ̀?
Ṣáájú Josaya ati lẹ́yìn rẹ̀, kò sí ọba kankan tí ó fi gbogbo ọkàn rẹ̀, gbogbo ẹ̀mí rẹ̀ ati gbogbo agbára rẹ̀ sin Ọlọrun, gẹ́gẹ́ bí ó ti wà ninu gbogbo òfin Mose.
Èyí ni àkọsílẹ̀ ekinni tí wọ́n ṣe nígbà tí Kureniu jẹ́ gomina Siria.
Olùpọ́njú ké pe OLUWA, OLUWA gbọ́ ohùn rẹ̀,ó sì gbà á ninu gbogbo ìpọ́njú rẹ̀.
Ootọ diẹ wa lara ọrọ yii.
O ni oun nigbagbọ ninu Atiku pe, oun nikan lo lee mu ki irẹpọ ati isọkan pada si orilẹede Naijiria, ti yoo si mu ki gbogbo ẹya ati ede pada wa nisọkan.
Jakọbu bá rúbọ lórí òkè náà, ó pe àwọn ìbátan rẹ̀ láti jẹun, wọ́n sì wà lórí òkè náà ní gbogbo òru ọjọ́ náà.
O ba ni ninu jẹ gan pe ọpọlọpọ ọmọ Naijiria lo n la ọpọlọpọ iwa ipa kọja latọdọ awọn ẹgbẹ bii Boko Haram, ISWAP, awọn Fulani darandaran ati awọn ẹgbẹ agbesunmọmi mii."
Gómìnà ìpínlẹ̀ Kaduna, El-Rufai fi ipò míì dá Sanusi lọ́lá Ẹ wo ọ̀nà márùn ùn tí ọkùnrin ṣì fi ń jẹ gàba lé obìnrin lórí Harvey Weinstein tó jẹ̀bi ẹ̀sùn ìfipábánilòpọ̀ ti rí ẹ̀wọ̀n ọdún mẹ́tàlélógún he!
 Òun ni ó se èrè àgùntàn onígóòlù fún won .
Baba ńlá yín àkọ́kọ́ ṣẹ̀,àwọn aṣiwaju yín náà sì ṣẹ̀ mí.
Àwọn olókìkí mìíràn ninu àwọn ọmọ ogun Dafidi nìwọ̀nyí: Asaheli, arakunrin Joabu; ati Elihanani, ọmọ Dodo, ará Bẹtilẹhẹmu; 
Wo àwọn míniístà mẹ́fà tí ẹnu ń kùn jùlọ Orúkọ àwọn Super Falcons 23 tó ń lọ France ti jáde Wọ́n jí ọmọ yìí gbé láti máa fi tọrọ bárà l'Eko Àjọ ọlọpàá Eko kédé pé ìbalòpọ̀ nítà kò bójúmu Lọjọ ti ayipada maa de ba a, O pade ajọ alaanu kan to ran an lọwọ lati pada si igbe aye ọtun.
Ọdún mẹtadinlogoje (137) ni Lefi gbé láyé.
Marketing & Communications, Oríṣun àwòrán, Mojisola Alli-Macaulay Akọroyin ni ileese Radio Lagos/Eko FM 89.
Jesu wá sọ fún Peteru pé, “Má bẹ̀rù.
Kí ẹ máa hùwà pẹlu ìrẹ̀lẹ̀ ati ọkàn tútù, kí ẹ sì máa mú sùúrù.
Bí ọkùnrin yìí ti sọ ti ẹnu rẹ̀ tán ni ọkùnrin mìíràn tún ti bọ́ síwájú tí ó wólẹ̀ níwájú Aṣojú-Olódùmarè, ó wí pé ìwọ ìránṣẹ́ Ẹlẹ́dàá ayé, ìwọ iranṣẹ́ Ẹlẹ́dàá ọ̀run, bá mi wí fún Ọlọ́run Ọba pé ọmọ tí ó fún mi yìí kò tẹ́ mi lọ́rùn rárá, ki ó ṣe pàṣípààrọ̀ rẹ̀ fún mi, ọmọ tí óo le koko bí òkúta amáa gun igi dé ṣóńṣó orí, a máa ti ibi gegele bẹ́ lé ibi gegele, a máa wẹ̀ nínú odò jíjìn a máa lé ewúrẹ́ káà kiri ilé, a máa sọ òkò lu àgùntàn káà kiri ojú ọ̀nà, a máa lé ọmọ ọlọ́mọ káà kiri òde.
NHIS: Kíni ó ń fa wàhálà fún Ọ̀jọ̀gbọ́n Usman Yusuf lórí ọ̀rọ̀ adójútòfò ìlera?
A ti fi  awon erongba wa ranse si igbimo to n mujoto ise akanse egbe , ni eyi ti yoo fi okan omo egbe bale lori idajo… Idajo ko nii se pe ,o gbodo je olubori.
Ajagun pari ọrọ rẹ pe, iṣẹ ti bẹrẹ lati ṣawari awọn afurasi naa, to na papa bora laipẹ.
Anthony Joshua: Lẹ́yìn ìjà rẹ̀ pẹ̀lú Luiz, Anthony Joshua bẹ Ọba ìlú rẹ̀, Àkárìgbò wò
Oríṣun àwòrán, @CustomsNG Àkọlé àwòrán, • Wo bí àwọn fàyàwọ́ ṣe ń kó ìrẹsì wọ Nàìjíríà Abajade iwadii ajọ aṣeṣiro ode naa jẹ ko di mimọ pe omilẹgbẹ awọn to riṣẹ lo ni awọn san owo ki awọn to ri iṣẹ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Oluwo ni mo mọ̀, n kò mọ orukọ oye míràn -Ọọ̀ni 13 Ìgbé 2018 Oríṣun àwòrán, OLUWO ILU IWO Àkọlé àwòrán, Ọ̀pọ̀ ìròyìn ló ti kàn káàkiri ṣáájú àsìkò yìí pé àárín Olúwó àti Ọọ̀ni ilé ifẹ̀ kò gún Ọọ̀ni ilé ifẹ̀,Oba Adeyeye Ogunwusi Ọ̀jájá kejì ti sọ pé Olúwó ni òhun mọ Olúwó ti ìlú Iwò sí kìí ṣe orúkọ mìíràn.
"Ayédèrú Ọ̀ṣun ni wọ́n ń bọ lónìí, kìí ṣe ojúlówó - Bàbá Ọlọ́ṣun tún figbe ta ""Ojú wa rí tó ní Egypt, bí wọ́n ṣe ń tẹ̀ wá lọ́mú, ni wọ́n ń gbá wa ní ìdí"" Ìdẹ̀ra dé, Gẹnẹrátọ̀ tó ń lo omi dé, a bọ́ lọ́wọ́ òkùnkùn Èmi àti Bọla Tinubu fẹ́ lo ‘German Mercenaries’ láti gbé MKO Abiọla kúrò lẹ́wọ̀n - Dele Momodu Àwọn ọmọ Nàíjíríà ló ṣiṣẹ́ takò mí ní Ireland kí ń má baà wọlé ìbò Káńsélọ̀ - Yemi Adenuga Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?"
Ni ipari, Juventus yoo maa koju iko agbaboolu AC Milan lojo kokanlelogbon osu yii, bee si ni won yoo tun lo gba ifesewonse akoko idije UEFA Champions League pelu Real Madrid lojo keta inu osu to n bo.
Ibrahim ni Giwa fasiti awn ologun to wa ni Biu, o si ni iyansipo naa paṣẹ ki iṣẹ bẹrẹ ni kia kia.
Èmi OLUWA ni mo sọ ọ́ pé n óo fi Farao Hofira ọba Ijipti lé ọ̀tá rẹ̀ lọ́wọ́ ati àwọn tí wọn ń wá ẹ̀mí rẹ̀ gẹ́gẹ́ bí mo ti fi Sedekaya, ọba Juda lé ọwọ́ ọ̀tá rẹ̀, Nebukadinesari, ọba Babiloni, ẹni tí ó ń wá ọ̀nà láti pa á.
Sinima mi, #Elevatorbaby ni wọn n se afihan wọn kaakiri awsn ibudo sinima ayafi ibudo sinima tiyin nikan ni ko gbe sita.
Angẹli kẹrin fun kàkàkí rẹ̀, ìdámẹ́ta oòrùn kò bá lè ràn mọ́; ati ìdámẹ́ta òṣùpá, ati ìdámẹ́ta àwọn ìràwọ̀.
Olúwa á gbé yín ga o.
Ìdí nìyí tí ọgbọ́n Ọlọrun ṣe wí pé, ‘N óo rán àwọn wolii ati àwọn òjíṣẹ́ si yín, ẹ óo pa ninu wọn, ẹ óo ṣe inúnibíni sí àwọn mìíràn.
Ṣugbọn ẹ fi gbogbo ara ṣiṣẹ́, ní ìbẹ̀rù Oluwa.
3 Ìgbé 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 12 Èbibi 2020 Oríṣun àwòrán, dyson Ìjọba ilẹ̀ Gẹ̀ẹ́sì tí pé fún rírà ẹgbẹ́gbẹ̀run ẹ̀rọ fẹntíletọ̀ láti mú irọ̀rùn bá àwọn ilé ìwòsàn nítorí wàhálà ààrùn Coronavirus tó ń bá àgbáyé fíra.
tí ó fi ara rẹ̀ ṣe ìràpadà fún gbogbo eniyan.
Amọṣa iwọde naa ba tun yipada si eyi ti a fi n fẹhonu han lori ọwọngogo , aisi iṣuna to jọju fun ẹka eto ẹkọ ati bẹẹ bẹẹ lọ Ni ọjọ kejidinlogun ni awọn oluwọde naa rin kaakiri fun ayajọ ọdun ti kan iwọde wọn a Awọn ọlọpaa só pe awón ọlọpaa mejidinlogun ni o fara pa nibi iwọde naa.
Gẹgẹ bi iroyin ṣe sọ ọ, Ileẹjọ naa tun paṣẹ wi pe ohunkohun tẹgbẹ Shiite ba ṣe bayii ti di ti ẹgbẹ agbesumọmi.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ojú kan la fí ń sùn, lẹ́yìn ilẹ̀ mímì tó wáyé Òjò òwúrọ̀ ṣèdíwọ́ fún ọ̀pọ̀ olùgbé ìlú Èkó Bakan naa ni wọn tun darukọ Taraba, Benue ati Adamawa gẹgẹ bii ara awọn ipinlẹ ọhun.
Ṣugbọn òùngbẹ ń gbẹ àwọn eniyan náà, wọ́n fẹ́ mu omi, wọ́n bá ń kùn sí Mose, wọ́n wí pé, “Kí ló dé tí o fi kó wa jáde láti ilẹ̀ Ijipti, láti fi òùngbẹ pa àwa ati àwọn ọmọ wa, ati àwọn ẹran ọ̀sìn wa?
Mo bá gbé òkú rẹ̀, mo gé e lékìrí lékìrí, mo bá fi ranṣẹ sí gbogbo ilẹ̀ Israẹli jákèjádò, nítorí pé àwọn eniyan wọnyi ti ṣe nǹkan burúkú ati ohun ìríra ní Israẹli.
Kí wọ́n wí pé, ‘A kò lọ́wọ́ ninu ikú ọkunrin yìí, bẹ́ẹ̀ ni a kò sì mọ ẹni tí ó pa á.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù El-Zakzaky pé ìpàdé pẹ̀lú àwọn àgbẹ́joro India àti àwọn àjọ ti kìí ṣe ti ìjọba 16 Ògún 2019 Oríṣun àwòrán, IMN Àkọlé àwòrán, Lái fí ti ọmọluabi ṣe Gekpe sàlàyé El-Zakzaky bẹ̀rẹ̀ ìfọ̀rswérọ̀ pẹ̀lú àwọn agbẹjọrò ti Ali Zia Kabir Chaudary àti Gunjan Singh soju fún ni orilẹ̀-èdè náà.
Gbajabiamila tun nifẹ si mimu idagbasoke ba ere idaraya ni Naijiria.
Bakan naa Bouteflika ko ribi koju awọn ẹsun iwa ajẹbanu ti wọn fi kan an eyi to tapo si aṣọ ala rẹ pupọ lori alefa.
Akọwe agba ẹgbẹ awọn agbaagba ilẹ Yoruba, Yoruba Council of Elders, Dokita Kunle Olajide lo sọ bẹẹ fun BBC Yoruba.
Lójú òpó twitter gomina ìpínlẹ̀ Kaduna Nasir El-Rufai kabamọ lóri gbogbo ìṣẹ̀lẹ̀ náà.
Magun onilẹpọ: Eyi ni irufẹ Magun ti yoo mu ki ọkunrin ati obinrin lẹpọ bi wọn ba ti n ṣe ere ifẹ, ti wọn ko si ni lee ya.
kí ọlọ́gbọ́n lè gbọ́, kí ó sì fi ìmọ̀ kún ìmọ̀ rẹ̀,kí ẹni tí ó ní òye lè ní ìmọ̀ pẹlu.
1996 Lẹyin igbeyawo ọdun mejidinlogoji, tọkọ-taya naa tuka.
Oyeleye ni ijọba ipinlẹ ni yoo maa mojuto sisan owo oṣu wọn, ẹ si mọ pe ilana fun sisan owo oṣu oṣiṣẹ ijọba wa ni Naijiria, ohun ti wọn yoo tẹle niyẹn.
Àwọn òbí yín, ati àwọn arakunrin yín, àwọn ẹbí yín, ati àwọn ọ̀rẹ́ yín, yóo kọ̀ yín, wọn yóo sì pa òmíràn ninu yín.
Ṣugbọn wọn kò gbọ́ràn, wọn kò sì tẹ́tí sí mi.
Kí á gbé ọ ga ju ọ̀run lọ, Ọlọrun,kí ògo rẹ sì kárí gbogbo ayé.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Tinubu, ojú tì ẹ́, o ta Yorùbá fún ọ̀tá torí àdánìkànjẹ - Fani-Kayode A kò ní fara mọ́ fífi àkókò ṣòfò lórí ẹjọ́ Sotitobire - Ìjọba Ondo Wo bí ọwọ́ orílẹ̀-èdè Dubai ṣe tẹ Ramoni Igbalode tí gbogbo ayé ń pè ní Hushpuppi Abisola, aya wòlíì Babatunde ti ń jẹrìí nípa bí ọmọ ọdún kan ṣe sọnù Ajimobi kìí bá ọ̀lẹ, olè àti ọlọ́pọlọ kúkú ṣe ọ̀rẹ́ - Alaafin Alaafin Oyo wa kan saara si awọn isẹ ati ipasẹ rere ti Ajimobi fi lelẹ, eyi to ni ko ni parẹ laelae.
Babaláwo yarí Kí ni ọkùnrin yìí ṣe tí bàbá rẹ̀ fi só mọ́lẹ̀ fún ọgbọ̀n ọdún?
Obinrin ọhun ti orukọ rẹ n jẹ Obiagelu Onakanse ni wọn sin sinu ile kan lagbegbe GRA ni ilu naa.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ọmọ tuntun gba ominira lẹyin ti wọn san owo itọju rẹ ni Gabon 14 Èrèlè 2018 Àkọlé àwòrán, Ọmọ tuntun, Angel lo oṣu maarun akọkọ aye rẹ nileewosan Idunnu ṣubu l'ayọ fun iyalọmọ kan nigba ti ileewosan aladani kan ni Gabon yọnda ọmọ tuntun rẹ fun, lẹyin ti wọn ti gba ọmọ naa silẹ fun ọpọlọpọ oṣu nitori wipe awọn obi rẹ ko ri owo itọju san.
Àkọlé àwòrán, Ọmọ Ibadan, ki ni so?
tí mo sì ko yín jáde láti ilẹ̀ Ijipti, láti máa jẹ́ Ọlọrun yín.
Kyari ni olori ijọba to kọkọ ni Covid-19 ni Naijiria.
Ó kẹ́kọ̀ọ́ jáde ní ilé ìwé gíga fásitì ti Ilọrin nínú ìmọ̀ ẹ̀kọ́ onírúurú èdè (Lingustics) ó sì tún gboyè Diploma nínú ìmọ̀ ẹ̀kọ́ Tíatà ní Odunfa Caucus.
Igbakeji Olori Ọmọ Ẹgbẹ Oṣelu to pọ ju ninu Ile Igbimọ Aṣofin Ipinlẹ Eko, Aṣofin Muyiwa Jimoh, ti o ṣe atupalẹ Abadofin ṣalaye pe Abadofin naa ti o pin si abala mẹrindinlọgbọn ni yoo jẹ akọkọ iru rẹ paapaa ni awọn ipinlẹ lorilẹ-ede yii, elyii to ni opin si ipele meji, iyẹn Idanilola atu ati Aami Ẹyẹ.
Stonehenge ti pẹ́ ní orílẹ̀ yìí tó jẹ́ pé a kò lè sọ pàtó pé àwọn báyìí ni wọ́n kọ́ ọ síbẹ̀.
Ṣugbọn o ní àwọn díẹ̀ ninu ìjọ Sadi tí wọn kò fi èérí ba aṣọ wọn jẹ́.
Awọn ẹlẹwọn lorilẹede kenya maa n ṣe aga ijoko, tablili fawọn ile iṣẹ ijọba ati ile igbimọ aṣofin.
Orile-ede Thailand wa lara awọn orile-ede to n lo rọba pupọ.
O ni eyi wa ni ilana pẹlu ofin ti ajọ to n ri si ọrọ oṣiṣẹ lagbaye fi le lelẹ.
Ni ti Balkiss Yusuph, ila ti wọn kọ sii loju jẹ ki o padanu anfaani lati jẹ akẹkọ to jafafa, nitori pe oju maa n ti i lati dide soke dahun ibeere olukọ, debi wi pe o fẹ rẹ pa ileewe ti.
Ijoba orile-ede Naijiria n gbero lati gbe igbese ti yoo mu edinwo goboi ba ipese iresi lorile-ede yii.
Bakan naa ni o tun kopa ninu ere idije ifese wọn sẹ ti FIFA ti ọjọ ori wọ ko ju Ogun kọ Promise ni o tun je adari ninu idije ti awọn ọjẹwẹwẹ ti ọjọ ori wọn ko ju mẹtalelogun lọ ni Beijing 2008.
Saulu pa ara dà, ó wọ aṣọ mìíràn, òun pẹlu àwọn ọkunrin meji kan lọ sọ́dọ̀ obinrin náà ní òru, Saulu sì sọ fún obinrin náà pé, “Lo ẹ̀mí abókùúsọ̀rọ̀ rẹ láti pe ẹni tí mo bá sọ fún ọ wá.
Idà ni ó kù tí ẹ gbẹ́kẹ̀lé; ẹ̀ ń ṣe ohun ìríra, ẹ̀ ń bá iyawo ara yín lòpọ̀, ẹ sì rò pé ẹ óo jogún ilẹ̀ yìí?
Kò ní ohun tí yóo fi san gbèsè yìí, nítorí náà olówó rẹ̀ pàṣẹ pé kí á ta òun ati iyawo rẹ̀, ati àwọn ọmọ rẹ̀ ati gbogbo ohun tí ó ní, kí á fi san gbèsè rẹ̀.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Corruption in Nigeria: Ojíṣẹ Ọlọ́run kan ní báwọn òbí ṣe ń jí owó ìlú kò, ní wọ́n ń fi lé ọmọ lọ́wọ́ 10 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 11 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Oríṣun àwòrán, @MBuhari Ojisẹ Ọlọrun kan ti woye pe ogun ti aarẹ Muhammad Buhari n gbe ti iwa ajẹbanu ko tii kun to rara.
Oríṣun àwòrán, @others Àkọlé àwòrán, Nọ́mbà 11: A-wo-dami-ẹnu ni amohunmaworan yii nigba to jade, ile olowo nikan lẹ ti le ri nigba naa Oríṣun àwòrán, @others Àkọlé àwòrán, Nọ́mbà 12: Nigba ti Telifiṣọn ti a n lẹ̀ mọ ogiri jade, ọlaju ti wọle de, igberaga ti bẹrẹ ninu palọ onikaluku to ba ri jajẹ niwọn ba to de tun le fowo pamọ ra a sile.
Ìròyìn náà ní ọ̀pọ̀ ẹ̀mí ló ti bá ìsẹ̀lẹ̀ náà rìn, àmọ́ kò sẹ́ni tó leè sọ iye àwọn tó kú nínú ìsẹ̀lẹ̀ náà lọ.
Ẹrọ ayaworan naa fihan pe, o le ni igba ogun ti George Floyd fi pariwo pe, oun ko le e mi mọ, lẹyin ti wọn fi orunkun fun lọrun, amọ ti ọlọpaa Chauvin jagbe mọ wi pe, ko gbe ẹnu rẹ soun, ko dakẹ ariwo to n pa.
apa kan, da apa kan si’ eleyi to le tabuku won.
'Ẹ ṣọ́ra ní London' Ọwọ́ tẹ afurasí 29 lórí ìpànìyàn Ìjẹ̀bú Igbó Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Ajọ naa ti wa fi ikilọ sita pe ki awọn adari ileeṣẹ ọlọpaa lati tete lọ wa nnkan ṣe si ọrọ awọn ọgọrọ ọlọpaa to yọkun nigboro Naijiria bayii.
A tun gbọ pe awọn osisẹ ileesẹ Julius Berger to n tun oju sna se lo wa nibẹ lati ko awọn epo to danu ọhun, ti ọrọ yii ko si yọ awọn osisẹ panapana silẹ pẹlu aibaamọ ijamba ina lee fẹ waye.
Gẹ́gẹ́ bí àṣà Paulu, ó wọ ibẹ̀ tọ̀ wọ́n lọ.
Jesu orí ayélujára kan rèé tó wa fun isoji ni Afirika Àṣírí mẹ́wàá tí mo mọ̀ nípa Boko Haram-Naomi Adamu Aarẹ Buhari pàṣẹ pé kí wọ́n ṣàwárí àwọn oníṣẹ́ ibi tó pa èèyàn 65 ni Borno Ilé iṣẹ ọlọpàá yóò gba ènìyàn 40,000 sí isẹ Arẹ́májà kò sí, Olubadan fi tìlù-tìfọn kí àwọn ìjòyè káàbọ̀ lẹ́yìn ọdún méjì Aare Buhari ni oun ni igbagbo lati le fun won ni ile ise ti won a ti sise laipe.
Ninu orukọ awọn mẹtalelogoji ti Buhari fẹ ki ile igbimọ ṣe ayẹwo fun, o yani lẹnu pe obinrin meje pere ni o wa ninu orukọ mẹtalelogoji naa.
2 10527683 Orilẹede Mexico 137916 109.
Ni ibẹrẹ ọdun yii, awọn eniyan marundinlaadọta ti salaisi latari arun iba-pọnju, pọntọ.
    Àpèjúwe tí mo ṣe wọ̀nyí yóò fi hàn yín pé ìrìnàjò ti ó léwu ni ìrìnàjò náà, ṣùgbọ́n a kò rí ìyọnu rara, ojú wa kò sì rí nǹkan kan jù bẹ́ẹ̀ lọ títí a fi ibẹ̀ ni ìjàngbọ̀n ti bẹ̀rẹ̀.
”Ó dáhùn pé, “Bẹ́ẹ̀ ni, iye tí a tà á ni.
Ibùdó ìwakùsà Beatrix tó ọgọ́jọ máìlì sí ìlu Johannesburg, ti ihọ̀ tí wọn ti ń wa góòlù ọ̀ún si tó ẹgẹ̀rún mẹ́ta o lé lọ́gọ́jọ níwọ̀n ẹsẹ̀ bàtà.
Ọjọ Keje osu Kejila ọdun 1963 ni Daniel Ọlọrunfẹmi Fagunwa, ti gbogbo eeyan mmọ si D.
Òkúta tí wọn kò gbẹ́ ni kí ẹ fi kọ́ pẹpẹ kan fún OLUWA Ọlọrun yín kí ẹ sì rú ẹbọ sísun sí i lórí rẹ̀.
BB Naija: Yàtọ̀ sí Lecon, àwọn olóríire yòkúù ni Katung Aduwak, Efe Ejeba, Miracle Igbokwe, Mercy Eke
O ni awọn ti wọn ti ri yọ laaye ni wọn ti ko lọ sile iwosan Plateaus Specialist ati Bringham University Hospital.
òun óo mú wọn pada wá sí Jerusalẹmu láti máa gbébẹ̀; wọn óo jẹ́ eniyan òun, òun náà óo sì jẹ́ Ọlọrun wọn, lóòótọ́ ati lódodo.
Lagos-404 FCT-37 Oyo-19 Ondo-14 Abia-13 Enugu-13 Kaduna-13 Edo-12 Kano-12 Kwara-11 Ebonyi-10 Nasarawa-7 Ogun-6 Osun-5 Delta-5 Niger-5 Plateau-4 Bayelsa-4 Katsina-3 Ekiti-2 Imo-2 Ajọ to n gbogun ti ajakalẹ arun lorilẹede Naijiria, NCDC ti kede pe eeyan ọọdunrun le ni ogoji miran ti lugbadi arun Covid-19 ni Naijiria.
Ẹgbẹ agbabọọlu Osasuna to bawọn lalejo lo dẹru iya le wọn lori eleyi lo mu Lionel Messi koro oju ti o si fi ibinu sọrọ.
Ṣugbọn pípa ni kí ẹ pa wolii tabi alálàá náà, nítorí pé ó ń kọ yín láti ṣọ̀tẹ̀ sí OLUWA Ọlọrun tí ó kó yín jáde láti ilẹ̀ Ijipti, tí ó sì rà yín pada kúrò ní oko ẹrú.
O salaye pe ẹgbẹ osere TANPAN duro ti oun lasiko ti oun ṣe aisan, to fi de ori awọn alagbata sinima ati ọpọ eeyan miran, ko to di pe Ọlọrun la oun.
Anuoluwapo si ni aayo ati ẹyinju Alaafin ko to gbe iyawo le e.
Ayaworan: Samuel Agbaje Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí 5:52 Fídíò, Akomolede àti Aṣa: Ọ̀rọ̀ Ẹ̀yán ni Bunmi Femi Amao ń kọ́ wa lórí ètò Akọ́mọlédè àti Àṣà lórí BBC Yorùbá, Duration 5,5224 Owewe 2020 OPC láwọn mú afurasí agbébọn ajínigbé mẹ́rin l'Oyo, ọlọ́pàá ní àpapọ̀ òṣìṣẹ́ elétò aàbò ló ṣiṣẹ́ náa22 Owewe 2020 Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí kan sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
) ewé ewé dára fun àwon eran òsìn ní jíje.
O si daju pe bi onirese ko ba fin igba mọ, eyi to ti fin silẹ ko lee parun mọ laelae.
Gẹgẹ bi ọrọ ti ajọ to n risi eto ilera lagbaye, WHO ṣe sọ, ewe dongoyaro ko le wo aarun covid-19.
Eeyan meje lo ti dero ọrun nipasẹ Covid 19 nipinlẹ Katsina to jẹ ipinlẹ ti aarẹ Naijiria, Muhammadu Buhari ti wa.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Risikat Azeez: Ìyàwó Gómìnà ìpínlẹ̀ Kwara mú ìlérí rẹ̀ ṣẹ, Risikat tí bẹ̀rẹ̀ sí ní kọ́sẹ́ aṣojú lóge 3 Ògún 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 19 Ògún 2020 Oríṣun àwòrán, Facebook/ajikecentre Arabinrin iya awọn ọmọ oloju buluu Risikat Azeez ti bẹrẹ si ni kọṣẹ iṣaraloge latari iranwọ iyawo Gomina ipinlẹ Kwara.
Awon naa ni : Aare tun fowosi  yiyan awon adajo méje  fun ile-ejo ijoba to wa niluu Abuja.
Ahabu sọ fún Ọbadaya pé, “Lọ wo gbogbo orísun omi ati àfonífojì ní gbogbo ilẹ̀ yìí, kí o wò ó bóyá a lè rí koríko láti fi bọ́ àwọn ẹṣin ati àwọn kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́, kí wọ́n má baà kú.
    Eléyìí kò yé mi, ǹjẹ́ kí n la ẹnu kí n bèèrè ohun tí ń wá, ṣe ni òjò ńlá bẹ̀rẹ̀ tí ọkùnrin náà sì kan ìlẹ̀kùn ilè mi, ó ni, “Jọ̀wọ́ ṣílẹ̀kùn fún mi, ọ̀rẹ́ mi,” èmi náà bá ṣí i fún un.
Mo fẹ́ kí ẹ mọ̀ dájúdájú pé, a óo máa sọ ohun tí obinrin yìí ṣe ní ìrántí rẹ̀ níbikíbi tí a bá ń waasu ìyìn rere ní gbogbo ayé.
Àwọn ìjòyè náà kò sì mọ ibi tí mo lọ tabi ohun tí mo lọ ṣe, n kò sì tíì sọ nǹkankan fún àwọn Juu, ẹlẹgbẹ́ mi: àwọn alufaa, ati àwọn ọlọ́lá, tabi àwọn ìjòyè ati àwọn yòókù tí wọn yóo jọ ṣe iṣẹ́ náà.
20 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí kan sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
Eyi tumọ si pe, ẹni ti yoo ba rinrinajo laago meje owurọ, ti gbọdọ de si papakọ laago mẹrin idaji.
Funke Akindele (Jenifa): Ilumọọka oṣere tiata miran to tun bi ibeji ni Funke Akindele, ọkọ rẹ keji, Abddulrasheed Bello ti ọpọ eeyan mọ si JJC Skillz, lo si bi awọn ọmọ naa fun.
"Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù EndSARS protest in Nigeria: Mr Macaroni, Falz, Wizkid, Tiwa Savage àtàwọn míì ṣe ìwọde Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ EndSARS protest in Nigeria: Mr Macaroni, Falz, Wizkid, Tiwa Savage àtàwọn míì ṣe ìwọde 13 Ọ̀wàrà 2020 "" We are looking for answers"" - Mr Macaroni Iwọde ifẹhonuhan lori ọrọ ipaniyan ati ifiyajẹni awọn ọlọpaa Naijiria lọna aitọ lo bi iwọde to bẹrẹ ni Naijiria to ti n tan kaakiri awọn orilẹ-ede miran bayii #End SARS ni wọn fi sọri iwọde naa."
Bakanna la gbo wi pe Gomina Ibikunle Amosun naa ti kede pe oun yoo du ipo asofin agba labe asia APC fun ẹkun arin gbungbun ipinlẹ Ogun.
Kalid wipe wọn sun igbẹjọ naa siwaju fun osu mẹrin ki wọn le e fun awọn alaṣẹ laaye lati se iwadi finifini lori awọn afunrasi ikọ Boko Haram.
BREXIT: Kí ni ohun tó fẹ́ yọ Theresa May nípò olóòtú ìjọba Gẹ̀ẹ́sì ṣáájú àkókò rẹ̀
Ṣugbọn Jonadabu, ọmọ Ṣimea, arakunrin Dafidi, wí fún ọba pé, “Kabiyesi, ẹnikẹ́ni kò pa gbogbo àwọn ọmọ rẹ.
Inira pẹlu mimi eleyi ti ko sẹyin titobi ju ẹdọ foro a ma diwọ bi ara ti se n ri atẹgun mimi sinu gba eleyi to nilo lati le fi wa lalaafia.
75 sita, fun iye owo to din ni ogoji bilionu naira.
A kò tíì lè sọ ti ìfipabánilòpọ̀ àmọ́ òkúta ni wọ́n fi fọ́ orí Azeezat - Ọlọ́pàá Oyo Ìyá àádọ́rin ọdún sọ bí ọkùnrin ọdún márùndínlọ́gbọ̀n ṣe fipá bá òun lòpọ̀ 'Bí Covid19 bá peléke síi l'Eko, ilé la ó ti máa tọ́jú àwọn kan' - Ìjọba ìpínlẹ̀ Eko Níbo ni Sẹ́nétọ̀ Abiola Ajimobi, gómìnà àná ní ìpínlẹ̀ Oyo wà?
Niajiria ti beere fun iralowo lati odo orile ede Amerika lati gbogun ti airisẹ
Ọgbẹni Olowolafẹ ṣalaye pe ọrọ Amọtẹkun ni ipinlẹ Ọyọ ti dọwọ ru koda o ti d'ẹsẹ ru bi ẹsẹ telọ.
"Ejiogbe ni ""lati ọjọ́ tí Mukaila ti ń dá wọn èèyàn láàmú, tó ń ṣe àwọn èèyàn lese, ìjọba ni irọ la n pa, ọ̀pọ̀ ẹ̀sùn si lo wa ni agọ̀ ọlọ́pàá nípa rẹ, àmọ́ ń ko fẹ́ sọ̀rọ̀ pupọ nípa rẹ""."
Wọn kédé Narendra, oludije ẹgbẹ́ BJP ni India pẹ̀lú ariwo ńla Mohammed Adamu ti di Ọ̀gá ọlọ́pàá Nàìjíríà tuntun Fayemi ṣetán láti ṣáájú àwọn gomina láti mójútó ètò ààbò ‘Bi Gomina Ajimobi se yan adarí òsìsẹ́ tuntun ní Oyo kò dí wa lọ́wọ́’ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Abdulfatah Ahmed: Àwọn Kwara fẹ́ dán ilé ọkọ kejì wo ni lásìkò yí Wọn ti fi ofin de omi iyanu naa ni ọpọlọpọ orilẹ-ede, wọn si ni o n fa eebi, ati aisan inu ẹjẹ.
Kò burú tí ẹ bá pe Ààrẹ Buhari ni 'Major General'- Ìjọba Nàìjíríà Ileeṣẹ iroyin BBC Hausa gbiyanju lati ba Garba Sheu sọrọ lori nkan ti iyawo aarẹ sọ ṣugbọn ko gbe ipe rẹ.
Iroyin kan tiẹ sọ pe Messi ti kan si akọnimọọgba rẹ tẹle, Pep Guardiola to wa ni Man City bayii.
O ṣiṣẹ pẹlu ile iṣẹ Daura Native Authority ko to dara pọ mọ ile iṣẹ to n ri si eto igbohunsafẹfẹ Naijiria (NBC) gẹgẹ bi igbakeji alamojuto eto.
Yatọ si eyi, o fikun pe ọkunrin ni gbogbo wọn ma n jẹ, eyi to fi han pe kii ṣe pe wọn fẹ ẹ tẹdo si ipinlẹ Ọyọ gẹgẹ bi arinrinajo ni.
Ọwọ́ EFCC tẹ ọ̀kan lára àwọn ti FBI fi èsún jìbìtì kàn!
idagbasoke  yoo se deba eto ọrọ aje , ti
Atamatase agbaboolu afigigba ti o darajulo sikeji lagbaye, Rafael Nadal ni Spain ti kede bayii pe yoo figagbaga ninu ipele keta si asekagba idije Davis Cup ti won yoo gba pelu Germany nilu Valencia losu to n bo.
 Akọrin Tungba naa fikun pe irọrun de ba mi gidi bayii pẹlu kẹkẹ tuntun naa, Dare Obama tun ti fun mi ni ireti lati rin pada,.
Bí Joṣua ti gbọ́ ariwo àwọn eniyan náà tí wọn ń ké, ó wí fún Mose pé, “Ariwo ogun wà ninu àgọ́.
fun akitiyan won ton sa lati ri pe igberu ba eto ogbin orile-ede yii.
Ṣugbọn nípa oríkunkun ati agídí ọkàn rẹ, ò ń fi ibinu Ọlọrun pamọ́ fún ara rẹ títí di ọjọ́ ibinu ati ìgbà tí ìdájọ́ òdodo Ọlọrun yóo dé.
"Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Collapsed Building: Ayálégbé ló dára bí ìjọba ṣe wólé àmọ́ wọ́n fẹ́ ìrànwọ́ ilé míràn ""O wa ye mi pe apaniyan ni ọkunrin ọhun, ti mo si tete pariwo fun awọn olujọsin to to ọgọrin niye lati doju bolẹ."
Mo si tun wo pe boya mi o rẹwa to l'obinrin ni, nitori pe mo sanra diẹ, a bi mo ti n darugbo ni.
Ninu ipade yi ni Minisita feto ilera Dokita Osagie Ehanire wa pẹlu Alexey L.
Bakanna, olugbe ilu Eko ti ko darukọ ara rẹ sọ fún BBC Yoruba sọ pe, fun anfaani araalu ni ijọba ṣe sọ pe k'awọn eeyan gbe ile wọn lati ago mejila oru si ago mẹrin owurọ.
“Ilẹ̀ Sebuluni ati ilẹ̀ Nafutali,ní ọ̀nà òkun,ní òdìkejì Jọdani,Galili àwọn àjèjì.
Olukọ kan tun bamilopọ pẹlu ipá.
Àwọn ọmọ̀wé tí wọ́n ti ṣo ìwà wọn nù ni àwọn ejò olóró ní inú ayé tí wọ́n ń bu aláìṣẹ̀ jẹ káàkiri òde, bẹ́ẹ̀ ni ojú wọn ti fọ́ wọn kò sì mọ̀, wọ́n wà ní ipò afọ́jú tí ń fi ọ̀nà han ẹni tí ó ríran.
Bẹẹ naa lo sọ pe Aarẹ Muhammadu gbọdọ jara mọṣẹ lori iṣejọba rẹ.
Nítorí pé, iná ńlá yìí yóo jó wa run; bí a bá tún gbọ́ ohùn OLUWA Ọlọrun wa sí i, a óo kú.
4 7303 Agbegbe French Polynesia 79 28.
Àwọn eniyan burúkú ba dè mí,wọ́n fẹ́ pa mí run,ṣugbọn mò ń ṣe àṣàrò lórí òfin rẹ.
Idris Elbar Oríṣun àwòrán, Reuters Ni ọjọ aje ni gbajugbaja oṣere sinima ni ilẹ Gẹẹsi, Idris Elba kede pe oun ti wa ni igbele bayii nitori oun pẹlu ti ko arun COVID-19 ti ọpọ n pe ni Coronavirus.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Gani Adams: Irọ́ ni wọn ń pa, mi ò sálọ sí France nítorí ìwọ́de O ṣalaye pe ọrọ awọn janduku naa ti kuro ni ti ipinlẹ Oyo nikan, nitori pe ibode agbaye lo wa ni ilu Saki, eyi ti awọn janduku lati Mali n gbiyanju lati ma a gba wọle.
Awọn onimọ si ti sọ asọtẹlẹ pe o ṣeeṣe ko jẹ ohun ni eyi ti yoo buru ju lẹyin ti oṣu Kẹjọ, ọdun 2016 lasiko ti owo epo rọbi ja walẹ kaakiri agbaye.
Makinde: Ẹgbẹ́ òṣìṣẹ́ faramọ́ wíwọ́gilé ₦3000 táwọn akẹ́kọ̀ọ́ girama ń san
Bi wọn ṣe n ṣayẹwo gbogbo awọn to ba fẹ kọja naa ni wọn n da ẹnikẹni ti ko ba wọ ibomu pada, tabi ki irufẹ ẹni bẹ jẹ bulala.
Ẹ ṣe bí ọmọ-ọwọ́ tí a ṣẹ̀ṣẹ̀ bí, tí òùngbẹ wàrà gidi ti ẹ̀mí ń gbẹ, kí ó lè mu yín dàgbà fún ìgbàlà.
 Awon alatileyin re naa ti ko ateranse lorisiirisii si oju iwe re legbelegbe.
Lagos, Delta Curfew: Sanwo Olu ní kí àwọn òṣìṣẹ́ ìjọba padà sẹ́nu iṣẹ́ ní Eko, Delta sọ tirẹ̀ dí aago mẹ́jọ alẹ́ sí mẹ́fà ìdájí
O fi sita loju opo Twitter pe aarẹ Buhari ti fọwọ si ṣiṣe agbekalẹ igbimọ awọn adari ilu lati maa bojuto gbogbo iṣẹlẹ iwa ipa tawọn ọlọpaa ba hu.
Inú mi dùn láti darapọ mọ́ ikọ̀ Arsenal -Mikel Arteta Èèyàn méjì kú nínú ìjàmbá ọ̀kọ̀ tó ṣẹlẹ̀ lórí afárá Otedola Lagos-Ibadan Express: Ènìyàn mẹ́rin ti kú nínú ìjàmbá ọkọ̀ Ṣé ẹ ti rí kí èèyàn ní àwọ̀ ara tó ń ṣí bíi ìpẹ́pẹ́ ẹja rí?
" Àwọn irú onírúiyepúpọ ̀ tó tún wọ ́ pọ ̀ ni àwọn onírúiyepúpọ ̀ tó ní àwọn olùsọdipúpọ ̀ oninomba odidi , àwọn onírúiyepúpọ ̀ tó ní àwọn olùsọdipúpọ ̀ alọ ́ jú ( complex coefficients ) , àti àwọn onírúiyepúpọ ̀ tó ní àwọn olùsọdipúpọ ̀ tí wọ ́ n jẹ ́ nọ ́ mbà odidi ìfiwọ ̀ n nọ ́ mbà àkọ ́ kọ ́ "" p "" kan ."
AFCON 2019: Inú mi dùn pé mo jẹ́ ẹni àkọ́kọ́ tó ṣojú Nàíjíríà fún ìgbà 100
Ifenuko ti ipinle Eko waye lehin fifi idunnu won han lati kopa ninu eto akanse naa nipa eyawo iye owo ti o to igba million owo dola.
Oludije dupo labe egbe-oselu alatako kan gboogi lorile-ede Sierra Leone, ti a mo si Sierra Leone Peoples Party (SLPP), Julius Maada Bio, ti da awon omo-ogun eleto-abo lebi, pe, iduro won ni awon ibi ipago idibo, ni ko je ki awon eniyan jade wa dibo lasiko atundi ibo aare ti o waye lojo-AbametaEto-idibo bere ni kutu-kutu owuro ni woorowo, gege bi eni ti oro naa soju re se so pe, biotileje pe, awon miiran saroye  pe, bi ogoro awon olopaa se duro si awon ibi ipago idibo naa deru ba  awon eniyan lati dibo.
com/Insights Ilẹ̀ UAE ti n fún àwọn arìnrìnàjò ní ìwé ìrìnnà ọlọ́dún márùn ún Fásitì ìpínlẹ̀ Ekiti dá òṣìṣẹ́ 355 padà sẹ́nu iṣẹ́ Ọmọ ilẹ̀ Iran 82 ló kú nínú bàálù tó já lórílẹ̀èdè naa Ilé ìwòsàn l'Àbuja ti ya àwọn ìbejì tí wọ́n sọpọ̀ láyà lọ́fẹ̀ẹ́ Nigba to n sọrọ, onimọ nipa ibalopọ, Mmirimmachukwu Ekechukwu sọ fun BBC Igbo pe ko si nkan to buru ninu ki awọn ọmọ Naijiria o maa wo awọn fidio ibalopọ, ṣugbọn ki wọn o ye e dibọn.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: 'A sinmi ìwádìí lóri Kemi Adeosun' Aago méjìlá ọjọ́ Ẹti ni ìséde yóò bẹ̀rẹ̀ ṣáájú ìdìbò náà Fun eeyan bii Kẹmi Adeọṣun to ti fi igba kan ri ṣe kọmiṣọna ni ipinlẹ abinibi rẹ, iyẹn ipinlẹ Ogun ki o to wa di minisita, o fihan pe igba meji ọtọọtọ lo ti la irufẹ awọn igbesẹ iwadi bẹẹ kọja.
Jehoṣafati kó gbogbo àwọn ọmọ ogun rẹ̀ pada sí Jerusalẹmu pẹlu ayọ̀ ìṣẹ́gun, nítorí pé OLUWA ti fún un ní ìṣẹ́gun lórí àwọn ọ̀tá rẹ̀.
Bakan naa, adajọ paṣ pe ki ileeṣ Olisa Metuh, Dextra investment san faani miliọnu mẹẹdọgbn naira ni ibamu pẹlu ẹsun ikarun ati ikẹfa ti wọn si paṣẹ pe ki Olisa Metuh funra rẹ san faani ọọdunrun le marunlelaadọrin miliọnu naira.
Falana tun fi kun ọrọ rẹ pe Buhari naa ni o fa iya to n jẹ ọpọ ara ilu Eko bayii lẹyin ti ijọba f'ofin de ọkada ati kẹkẹ Maruwa nitori o wọgile aba lati ṣe eto igbokegbodo ọkọ ti igbalode oni igba nmiliọnu dọla($200m) eyi ti Gomina Lateef Jakande ṣe agbekalẹ rẹ lasiko to wa lori alefa.
Ika ni awọn oludibo yoo tẹ lati yan oludije to ba wu ọkan wọn fun ipo kipo ti wọn ba n dije fun.
leyin ti o padanu ifesewonse ipele keji si asekagba idije Copa America sowo orile-ede Brazil.
Ṣugbọn nígbà tí ó rí Jesu lókèèrè, ó sáré, ó dọ̀bálẹ̀ níwájú rẹ̀.
Oba Lamidi Adeyemi: Aláàfin àkọ́kọ́ tí yóò lo àádọ́ta ọdún lórí ìtẹ́
O ti to ọjọ mẹta kan ti gbun-gbun-gbun ti n waye laarin gomina ipinlẹ Kano, Abdullahi Umar Ganduje ati Ẹmia Lamido Sanusi.
Titi di bi a ṣe n sọrọ yii, awọn ọmọ ogun ilẹ ko tii sọrọ lori iṣẹlẹ yii.
” Ọba Israẹli bá yíra pada, ó lọ sí ojú ogun.
Nígbà tí Jairi ṣaláìsí, wọ́n sin ín sí ilẹ̀ Kamoni.
Yari  tun so pe awon gomina  “Nifee lati san ekunwo ti awon osise fenuko le lori nibi ipade won , sugbon se won lagbara lati san owo naa .
Aarẹ ki gbogbo wọn ku iṣẹ takuntakun ṣugbọn ọpọ ninu awọn ọmọ Naijiria lo n binu si diẹ ninu awọn minista naa pé wọn ko ṣe daadaa tó.
O dá a, ipò rẹ̀ rẹlẹ̀ díẹ̀ sí ti ìwọ Ọlọrun,o sì ti fi ògo ati ọlá dé e ní adé.
Gboyega Oyetola láre gẹ́gẹ́ bíi Gómìnà ipinle Osun.
Wọ́n fi ìbọ̀rìṣà wọn sọ OLUWA di òjòwú;wọ́n fi ìwà burúkú wọn mú kí ibinu OLUWA wọn ru sókè.
Ileesẹ ijọba Naijiria ni Ghana ni iwe ẹri to ni nọmba idanimọ SCR/LCS 74/VOL.
32 Ṣùgbọ́n ó lè ṣeéṣe kí ènìyàn ṣubú kúrò nínú ore ọ̀fẹ́ kí òun sì yapa kúro lọ́dọ̀ Ọlọ́run alààyè;
Bí ìròyìn yìí bá dé etí gomina, a óo bá a sọ̀rọ̀, kò ní sí ohunkohun tí yóo ṣẹ̀rù bà yín.
Asofin Godswill Akpabio lo sikeji aba Ahmad Lawan .
" APC ni Auxilliary ṣiṣẹ́ fún lásìkò ìdìbò gómìnà 2019 kìí ṣe PDP-Oyo NURTW Ṣé lóòtọ́ ni òjòjò dá Abiola Ajimobi wólẹ̀?
Bi ọdun si ṣe n gun ori ọdun, ti ọpọlọpọ iyawo ile si n ṣiṣẹ, ni iwulo awọn ọmọ ọdọ, tabi oṣiṣẹ abani ṣisẹ ile n pọ si.
Bakan naa lo menuba igbesẹ ijọba Oyo lati pese aga ijokoo yatọ si owo ina awọn ọga ile iwe alakọbẹrẹ ati girama ti ijọba Oyo ṣẹṣẹ san fawọn ọga ile iwe kọọkan.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìtàn Mánigbàgbé: Èyí ni àwọn Ọba ilẹ̀ Yorùbá mẹ́jọ tí wọn lé kúrò lórí oyè 17 Ẹrẹ̀nà 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 10 Ọ̀wàrà 2020 Oríṣun àwòrán, Others Yoruba ni a ko ri iru eyi ri, a fi n dẹru ba ọlọrọ ni nitori ko si ohun ti oju ko ri ri, ẹsin ta ta ta, o ku, eniyan rin, rin, rin, o sọnu.
Ọgbẹni Mana Srivate ṣalaye fun ileeṣẹ akoroyin jọ Reauters pe oniruuru eto adoola ẹmi loun ti ṣe ninu irinajo iṣẹ oun-ṣugbọn oun ko ṣiṣẹ idoola ẹmi erin ri.
Oríṣun àwòrán, @omoh___tee/ Ṣugbọn dokita Anu ti pee lẹjọ fun ibanilorukọjẹ, to si n bere fun owo itanran miliọnu marundinlọgbọn naira.
Spanish flu and other pandemic: Ẹ fokan balẹ, àwọn ajakale àrùn kan rèé to burú ju Coronavirus lọ
Ikanni yii ní oun tó tó ẹgbẹ̀rún lọ́na ọgọ́rùún meje olùtẹ̀le, ti wọ̀n si ti síi lati ọdun 2013.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Seyi Makinde vs ALGON: Àwọn alága káńsù ní ìpínlẹ̀ Oyo fẹ́ pẹjọ́ kòtẹ́milọ́rùn lórí bígómìnà Seyi Makinde ṣe yọ wọ́n nípò 15 Agẹmo 2020 Oríṣun àwòrán, oyoinsight.
RCCG Virtual Convention: Kátàkárà mẹ́wàá tí yóò pàdánù àìsí ìpéjọpọ̀ ńlá RCCG lọ́dún yìí
’’Ogagun Abdulsalami wa gbadura fun orile ede Naijiria pe eto idibo yii
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Human Calculator: N kò lo idán àbí àlùpàyídà fún ìṣirò ọpọlọ tí mò ń ṣe Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Ó máa ń sọ nínú àwọn ìfọ̀rọ̀wánilẹ́nuwò pẹ̀lú àwọn akọ̀ròyin pé, Èmi kìí mu ọtí, sìgá tabi igbó, bẹ́ẹ̀ ni mi kìí ṣe àlágbèrè."
Nigba ti awọn araalu ṣẹṣẹ n simi lori awuyewuye yii, ni iroyin kan tun jade lọsẹ yii pe arakunrinkan ti orukọ rẹ n jẹ Tobilọba Jọlaosho lọ ya sinima onibalopọ ti a mọ si 'Blue film' lojubọ naa.
Pupo awon ilu to wa ni ekun  Oromia ni orile ede Ethiopia  ni won n seto  ifehonu-han onile-gbele  lati bi  ojo meta, eyi ti awon ajafeto omo eniyan ati awon odo pe fun ni ekun naa.
Ìwọ ń bẹ̀rù ọmọ eniyan tí a dá, bíi koríko.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ṣeyi Law: Ọ̀rọ̀ ìlú yìí tó kéèyàn de aago méjì Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Ṣeyi Law: Ọ̀rọ̀ ìlú yìí tó kéèyàn de aago méjì 26 Ọ̀wàrà 2018 Ṣeyi Lawrence ní ní tòótọ̀, ara àmì ìdánimọ̀ òun ni aago méjì tí òun máa ń wọ̀.
 ní àkókò yíì , ó lè nira láti rìn tàbí ṣiṣẹ ́ .
nígbà tí àwọn baba ńlá yín dán mi wò,tí wọ́n dẹ mí, bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé wọ́n ti ríohun tí mo ti ṣe rí.
O jẹ onkọwe, onimọ ninu itan ati alakada.
Àyìnlá n yán apá ká pèlú èrò pé òun yóò di olórò lójó náà, àmó àgbà tí ó kó Adéláyò ti so fún un láti máa fi òye kíyèsí ohun gbogbo.
Awọn kan n fi ṣe oniduro gẹgẹ bi okoowo Awọn kan ti wa to n fi jijẹ oniduro ṣe iṣẹ ṣe.
Awọn alaṣẹ oju opo ikansiraẹni Twitter lo fi idi eyi mulẹ ninu atẹjade kan ti wọn fi sita ni ọjọ Abamẹta.
Ọmọ náà jẹ́ ọmọ pupa, ojú rẹ̀ dára ó sì lẹ́wà.
Äare Buhari dupe lowo awon to wa nidi akoso egbe bii Oyegun fun ise alaafia.
Nígbà kan rí, OLUWA pè ọ́ ní igi olifi eléwé tútù, tí èso rẹ̀ dára; ṣugbọn pẹlu ìró ìjì ńlá, yóo dáná sun ún, gbogbo ẹ̀ka rẹ̀ yóo sì jóná.
Bí baba wundia náà bá kọ̀ jálẹ̀ pé òun kò ní fi ọmọ òun fún un, yóo san iye owó tí wọ́n bá ń san ní owó orí wundia tí kò mọ ọkunrin.
Fadaka kò jámọ́ nǹkankan ní àkókò ìjọba Solomoni.
Gomina bi wọ́n pé, “Ta ni ninu àwọn meji yìí ni ẹ fẹ́ kí n dá sílẹ̀ fun yín?
Beckham, àgbábọ́ọ́lù tẹ́lẹ̀ rèé tó ń sọ èdè Yorùbá Tottenham na Man City bí olè tó jí ike owó Dókítà yọ oyin mẹ́rin tó n gbé nínú ẹyinjú arábìnrin kán Ẹ yàgò fún ìwà adìẹ dàmí lóògùn nù, màá fọ lẹ́yin lásìkò ìjà - Buhari Ṣugbọn Smalling ni ikọ Man U ti koju awọn agbaọjẹ agbabọọlu ni Cristiano Ronaldo ati Kylian Mbappe, o ni Messi naa ko ni yatọ si wọn.
Iwa-ipa Fulani darandaran: ọlọpa fi panpẹ ọba mu eniyan meji Fayose: Awọn darandaran to pa Tunde ko ni lọ lai jẹjọ Sugbọn awọn agbẹnusọ fun aarẹ Buhari ko tii fesi pada lori ọrọ yi.
”A ti jiroro nibi ipade pe ki a tele ilana ajo eleto idibo , ki a si ri I pe gbogbo eto naa lo ni irowo-irose.
Oríṣun àwòrán, Reuters Àkọlé àwòrán, Caster Semenya: kíní ìdájó yìí dà fún obìnrin àti eré ìdáraya Semenya, tó ti jáwe olubori nígbà mọ́kàndínlọgbọ̀n nínú eré ije oni mítà ọgọjọ nítori pé a bíi gẹ́gẹ́ bi ẹni to ni ìṣẹ̀dá okùnrin, wọn sába máa n ni abùdá àdámọ ọkùnrin pàápàá ninu okùn.
O ni iru awọn ọna ti ko tọ ti awọn kan n lo lati kowo jẹ ko ni ṣi silẹ ni ijọba oun.
Ngige ni iṣẹ́ n lọ lọ́wọ́ lórí ǹkan ti ASUU n bèèrè Ṣé Fulani daran-daran ni àwọn tó n jí ènìyàn gbé ní ìpínlẹ̀ Ondo?
Ijọba ipinlẹ naa ni lati gba ti iwọde naa ti bẹrẹ, ẹnu ọjọ mẹta yii ti n mu idiwọ wa fawọn akẹkọọ ati oṣiṣẹ ileewe gbogbo lati de ileewe wọn.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ademọla Ogunbanjo: A nílò bàbá ìsàlẹ̀ nínú òsèlú Ilakaka rẹ ninu jija fun ẹtọ ọmọniyan wa lara awọn ohun to mu ki awọn eeyan Naijiria lero wi pe yoo jẹ Aare ti o le ni aanu mẹkunu loju.
USSD: Ìjọba àpapọ̀ bẹ̀rẹ̀ ìwàdíí lórí owó orí tí MTN fẹ́ yọ̀
Nigba ti Iya ọmọ naa n salaye bi ọrọ ti rin, o ni, ko ju bii ọgbọn isẹju si igba ti oun se abẹwo si Eniola ninu Ile ijosin awon ọmọde ti ẹka ijọ naa, to fi di awati.
''Buhari àti Tinubu ṣ'àdéhùn pé Yorùbá ni yóò jẹ́ olùdíje ipò ààrẹ APC lọ́dún 2023'' Igbo Olodumare rèé, níbi tí Ìgbín ti tóbi ju Ìjàpá lọ Iléeṣẹ́ ológun ti yabo ibùdó àwọn jàndùkú tó jí àwọn akẹ́kọ̀ọ́ gbé níléèwé katsina- Garba Shehu Kí gan ló pa Dapo Ojora, ẹ̀gbọ́n ìyàwó Bukola Saraki l'Eko?
8 547 Papua New Guinea 9 0.
Oludari agba ile-ise akoroyin Voice of Nigeria, ogbeni Osita Okechukwu so pe ile-ise naa yoo tesiwaju lati ma a gbe awon ede ile okere laruge, papaa julo ede Faranse laarin awon akeeko jake-jado orile-ede Naijiria.
Akonimoogba agba iko agbaboolu Super Eagles, Gernot Rohr ti kede awon agbaboolu ti yoo lo soju orile-ede Naijiria ninu idije boolu agbaye to n bo lona lorile-ede Russia.
Nítorí ìmọ̀ OLUWA yóo kún gbogbo ayébí omi ṣe kún gbogbo inú òkun.
Ọgá ọlọpa Ibrahim Idris ti da ẹ̀ka ọlọ́pàá tó ń ṣe ìwádìí sí'ta, ìgbákejì ọ̀gá ọlọ́pàá tó n mójú tó zone 7 sì ló darí ẹgbẹ́ náà.
Ko lee lọ ileewe mọ lọdun 1944 nigba ti baba rẹ ku, lo ba bẹrẹ si ni kọ iṣẹ mọkaliiki.
Bákannáà ni òfin yìí wà láti dáábò bo àwọn ọkọ lọ́wọ́ ìyàwó wọn.
Awọn araalu Agba, lagbegbe Ekwulobia tọka si igbesẹ tẹgbọntaburo naa gẹgẹ bii eewọ.
lo si oja kan naa,ile-iwe kan naa ni won lo.
Koda Maradona wa nibi ifẹsẹwọnsẹ Gimnasia y Esgrima pẹlu Patronato to waye lọjọ Ẹti tii ṣe ọjọ ibi ọgọta ọdun rẹ.
Toyin Abraham wa lara awọn eekan elere sinima taraye n wari fun julọ lori ayelujara.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Fire Eater: Azonto ní àfojúṣùn òun ni láti lọ fi idán iná yìí pa owó lókè òkun Ẹwẹ, amofin naa sọ siwaju sii pe ẹni to ba wọ aṣọ ologun lati fi ṣe ere ori itage, tabi ẹni ti gomina tabi aarẹ ba fun ni aṣẹ lati wọ aṣọ naa ko lẹtọ si ijiya kankan labẹ ofin.
Mo ṣe bí ìgbà tí ọmọ Olódùmarè pàápàá ṣe oorre  fún àwọn adẹ́tẹ̀ mẹ́wàá, ọ̀kan péré ni ó padà wáá dúpẹ́ nínúwọn!
 Àwon mwera , makua àti mabia ni àwon alámùúlégbé won .
Ọba bá lọ sí ààfin rẹ̀, ó fi gbogbo òru náà gbààwẹ̀.
5bn ni okuta iyebiye yii ko wọ apo ijọba orilẹede naa lọdun to kọja nikan.
Gbogbo wọn lo ti peju po si gbagede ti ipade pajawiri lorii wahala awọn ajinigbe, iwa ọdaran ati eto aabo nilẹ Yoruba naa ti n waye.
Ilé-iṣẹ́ Echo ti Moscow ní Yaroslavl tí ó jẹ́ ẹ̀ka ilé-iṣẹ́ Agbóhùnsáfẹ́fẹ́ Echo ti Moscow ìsopọ̀ tí ó ti dá dúró fún ìgbà pípẹ́ ní Russia fagi lé ìfọ̀rọ̀wọ́rọ̀ pẹ̀lú àwọn ajìjàǹgbara LGBT lẹ́yìn tí wọ́n gba ìhalẹ̀ láti ọ̀dọ̀ àwọn tí ó kórìíra-ìbálòpọ̀-láàárín-akọ-àti-akọ, olóòtú ilé-iṣẹ́ náà Lyudmila Shabuyeva sọ̀rọ̀ nínú àkọsílẹ̀ Facebook kan:
fẹ pin si awon ile –iwe ti won yoo maa pese ounjẹ naa.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù 2020 in Retrospect: Abiola Ajimobi, Ibidunni Ighodalo, Buruji Kashamu wà lára àwọn tó bá ọdún yìí lọ 29 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Si ọpọ ọmọ Naijiria, ọdun manigbagbe ni ọdun 2020 jẹ nitori awọn isẹlẹ kasiara to waye ninu ọdun naa.
2 Owewe 2019 Oríṣun àwòrán, Facebook/Wada/Grace Adejoh/Dino Melaye/Musa Wada Àkọlé àwòrán, Ta ni yoo jamọ lọwọ?
Ẹgbẹrun meji Cedi owo ilẹ Ghana ni wọn ti kede gẹgẹ bi ẹbun, fun ẹnikẹni to ba lee ran ọlọpaa lọwọ lati ṣawari wọn.
Iroyin ọhun ni nibẹ ni wọn ti gbe e lọ si agọ ọlọpaa Maitama pẹlu 'erongba ati gbee lọ si ile ẹjọ magistrate ti ko si ẹni to mọ ni ọla' Ki ni ẹgbẹ oṣelu PDP n sọ?
"Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, LASU Ritual: Àwọn akẹẹgbẹ́ akẹ́kọ̀ọ́ LASU tí wọn fi ṣowó sọ̀rọ̀ lórí ìgbé ayé olóògbé Bakan naa o mẹnu ba ọrọ adari ikọ Amotẹkun pe ""ẹ o le ri eeyan kan ko dede jade wa pe oun ni Ọgagun Olori Amọtẹkun fun gbogbo Iwọ Oorun Naijiria""."
Lara awọn ohun to sodo sinu ẹbun miliọnu marundinlaadọrin, N85m.
Ìwọ ni o mú kí àwọn orísun máa tú omi jáde ní àfonífojì;omi wọn sì ń ṣàn láàrin àwọn òkè.
Wọ́n tún ti pa omidan ẹni ọdún 18 míràn l'Akinyele ní ìlú Ibadan Ìjọba ìpínlẹ̀ Eko kéde ọjọ́ tí àwọn iléèwé gígá yóò wọlé Fún ọjọ́ kẹ́ta, ìpínlẹ̀ Plateau gbé ipò kínní lórí àtẹ COVID-19!
Bimbo Oshin Bimbo Oshin naa ko gbẹyin lara awọn gbajugabja oṣere tiata Yoruba to n ki awọn tirẹ ku ọdun Keresi.
Mo sì ti mọ̀ pé ẹ kò tún ní gbà wá sílẹ̀, ni mo ṣe fi ẹ̀mí mi wéwu, tí mo sì kọjá sí òdìkejì lọ́dọ̀ àwọn ará Amoni; OLUWA sì fún mi ní ìṣẹ́gun lórí wọn.
8) Guilty Beatz, Mr Eazi, Patapaa àti Pappy Kojo -Akwaaba Onkọrin ọmọ ilẹ Ghana, Guilty Beatz lo kọ orin naa.
 Won yoo bura fun awon adajo ti won yan si ile-ejo kotemilorun ati alaga fun ile-ejo ijoba apapo ,adajo Walter Onnoghen,ni osu kefa ,ojo kéjìlélógún, Eti, 2018.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Viemens Bamfo: Ọmọ ọdún méjìlá tó gbèlé kẹ́kọ̀ọ́ dì àpéwò bó tí ṣé wọ ilé ẹ́kọ́ fásítì Ghana 29 Ọ̀wàrà 2019 Oríṣun àwòrán, Facebook Ọmọ ọdun mejila kan lorileede Ghana ti di ilumọka lẹyin to pegede idanwo, ti wọn si gba wọle si fasiti orilẹede Ghana.
"Minisita naa ni, ""A ṣe ipade pàjáwìrì pẹlu ajo ti ó ń ṣakoso oògun pípò ni orilẹ-ede yii ati NAFDAC, lati gba awọn oogun ikọ oni codeine pada kaakiri."
Koda a jọ n lọ fun ayẹyẹ Ọdun Ereke laipẹ yii.
kede abajade esi idibo aare niluu Abuja.
gẹgẹ bi igbakeji alaga fun igbimo eto ipolongo.
Nítorí náà, mo lòdì sí Farao, ọba Ijipti.
Kọmiṣọna ọlọpaa ipinlẹ Kaduna, Ali Janga ṣalaye fun BBC pe ileeṣẹ ọlọpaa yabo gbọngan naa lẹyin tawọn ara ilu kan ta wọn lolobo lori ohun to n ṣẹlẹ lagbegbe ọhun.
Ibo ẹgbẹrun mẹrindinlọgbọn ni Yusuf fi n la Ganduje lọwọyii.
Oríṣun àwòrán, Instagram/djswitch_ O kẹkọọ jade ninu imọ Geology ni Fasiti ijọba apapọ to wa ni ilu Port Harcourt, ni ipinlẹ Rivers.
Bákan náà ni Fathia sàlàyé pé òun kò fẹ̀yìn balẹ̀ fún ẹnikẹ́ni rárá, kí òun tó gba isẹ́ tíátà.
Ohùn tí mo gbọ́ ni ti àwọn oníhapu tí wọn ń lu hapu wọn.
Iyabo Ojo house: Iyabo Ojo ṣílé tuntun, Eko mì tìtì
Ilééṣẹ́ Google ṣe ìrántí Funmilayọ Ransome-Kuti!
Ní ọjọ́ kan tí gbogbo wọn péjọ, wọ́n bi í pé, “Oluwa, ṣé àkókò tó nisinsinyii tí ìwọ yóo gba ìjọba pada fún Israẹli?
Naomi bá dá wọn lóhùn, ó ní, “Ẹ má pè mí ní Naomi mọ́, Mara ni kí ẹ máa pè mí nítorí pé Olodumare ti jẹ́ kí ayé korò fún mi.
 Opo ise iwadii ninu imo ero yoo ran wa lowo lati fopin si isoro yii.
Fani-kayode sọrọ naa loju opo Twitter rẹ nigba ti o n ki Atiku Abubakar ku oriire lẹyin ti o jawe olubori gẹgẹ oludije fun ipo Aarẹ labẹ asia ẹgbẹ oselu PDP lọjọ Aiku.
Àwọn osisẹ yabo iléesé MTN ní Nàìjíríà Naijiria yoo sewadi ile ifowopamọ CBN ‘Buhari kìí fá orí apákan, dá apakan sí’ Ile ifowopamọsi agba naa fi ikede naa sita loju opo Twitter re lojo aje.
Yusufu Buratai, ti wa gbosuba fun iko omo ogun naa fun aseyori ti won se,
Lẹyin o rẹyin ni wọn kede pe wọn ti yọ orukọ Festus Adedayọ kuro, ti wọn si yan ẹlomiran rọpo rẹ.
Pàápàá jùlọ, yóo jẹ àwọn tí wọn ń tẹ́ ìfẹ́kúfẹ̀ẹ́ ara wọn lọ́rùn níyà.
"Ẹgbẹ wa kii ṣe ẹgbẹ oni jagidijagan, bo ba ṣe pe a fẹ ra ibọ ni, owo wa bẹẹ si ni a ju gbogbo ọmọ ogun Naijiria lọ ṣugbọn kii ṣe ologun tabi ọlọpaa lo ti olori wa mọle bi ko ṣe aarẹ Buhari gangan""."
Àwọn Filistini sì pada lọ sí agbègbè wọn.
Àwọn ologun dóòlà akẹ́kọ̀ọ́ mẹ́fà lọ́wọ́ àwọn ajínigbé ní Kaduna Ta ni Sadiya Umar Farouq tí ìròyìn ẹlẹ́jẹ̀ ń gbé pé òun ló fẹ́ dí ìyàwó tuntun Buhari?
Ẹ̀ ń ṣe ibojì fún àwọn wolii, ẹ sì ń ṣe ibojì àwọn eniyan rere lọ́ṣọ̀ọ́.
Koda awọn ẹran agbo rẹ lo n ba ṣere nile ti o si fi fidio rẹ sori oju opo Instagram rẹ.
yoruba/Facebook Yoruba ni ori ti yoo de adé, kò ní ṣalai dade, ọrun tí yóò sì wọ ejigbara ilẹkẹ, kò ní ṣe aláì wọ ọ, bẹ́ẹ̀ ni ibadi tí yóò lo mọsaaji, aṣọ ọba tó jinna koro koro, kò kúkú ní ṣe aláì lo o.
Bákan náà ni ó gbé ife fún wọn lẹ́yìn oúnjẹ, ó ní, “Ife yìí ni majẹmu titun tí Ọlọrun ba yín dá pẹlu ẹ̀jẹ̀ mi tí a ta sílẹ̀ fun yín.
Bakan naa ni Kenya, ọpọ oloṣelu a maa lọ ṣọọṣi lati ba awọn alatilẹyin wọn sọrọ.
Bakan naa ni wọn yoo tun san ẹkunrẹrẹ owo oṣu kẹjọ fawọn oṣiṣẹ pẹlu.
Ilé Aṣòfin Eko: A fẹ́ mọ̀ bí Ambode ṣé nà ₦45b tó fi ra BRT
Ọna pataki kan ti ijọba n gba fi ọrọ sita lori arun naa ni nipasẹ ẹrọ mohunmaworan, rẹdio ati lori itakun ayelujara.
Nítorí ó yẹ kí ẹni tí ń roko kí ó máa roko pẹlu ìrètí láti pín ninu ìkórè oko, bẹ́ẹ̀ ni kí ẹni tí ó ń pa ọkà ní ìrètí láti pín ninu ọkà náà.
Oluwo: Èmi ni adarí àti aláṣẹ lórí gbogbo òrìṣà ilẹ̀ Yoruba àti káàkiri àgbàyé
Wo àwọn ọmọ Naijiria mẹ́ta tó jáwé olúborí nínú ìdìbò sílé aṣòfin ilẹ̀ Amẹrika Wo díẹ̀ lára àwọn gbajúmọ̀ òṣèré Yorùbá tó bẹ̀rẹ̀ eré ṣíṣe ní èwe.
Lẹ́yìn ti wọ́n fi Olumide kalẹ̀ ní àgọ́ ọlọ́pàá ni ó bẹ̀rẹ̀ si ni kọ irírí rẹ̀ sórí twitter.
" Ẹgbẹ CAN n sọ ọrọ yii nigba to n fesi lori bi ijọ aguda se pada darapọ mọ ẹgbẹ naa lẹyin to ti fii silẹ fun bi ọdun marun.
Solomoni ti ṣe pẹpẹ bàbà kan, ó gbé e sí àgbàlá ilé náà.
Àwọn ọmọ Jonadabu, ọmọ Rekabu mú àṣẹ baba ńlá wọn tí ó pa fún wọn ṣẹ, ṣugbọn àwọn eniyan wọnyi kò gbọ́ràn sí mi lẹ́nu.
Oríṣun àwòrán, Ministry of Foreign Affairs Àkọlé àwòrán, Zainab ati awọn oṣiṣẹ ileeṣẹ orilẹede Naijiria niluu Jeddah lẹyin ti wọn tu u silẹ l'ọgba ẹwọn.
Ìlú tí ó wà ní òkè àfonífojì dáradára,ohun àmúyangàn fún àwọn tí ó mutí yó.
Aare Buhari ti gbosuba fun lilo imo ero fun eto idibo odun 2015, ni eyi to ran an lowo lati jawe olubori ninu eto idibo to gbe e wole gege bi aare, bakan naa, lo tun dekun awon iwa mago-mago to maa n waye lasiko eto idibo.
Kyari ninu ọrọ rẹ nibẹ, rọ awọn ara adugbo lati maa ta awọn agbofinro lolobo, bi wọn ba ti ko firi awọn to n bẹ ọpa epo.
 babaláwo nígbà tì àwọn olùbọfá lóbìnrin jẹ ́ Ìyá onifá .
Bẹ́ẹ̀ ni mi bẹ̀rẹ̀ sí pé oríkì ọkùnrin náà òun sí ń mi orí ó ń dá mi lójùn lẹ́ẹ̀kọ̀ọ̀kan.
Onígun mẹrin ni wọ́n ṣe férémù tí wọ́n fi ṣe àwọn ẹnu ọ̀nà ati fèrèsé ilé náà, wọ́n to àwọn fèrèsé ní ìlà mẹta mẹta ninu ògiri, ni àgbékà àgbékà, lẹ́gbẹ̀ẹ́ kinni keji ilé náà; wọ́n dojú kọ ara wọn.
Kollington, Bàbá Suwe, Ogun Majek wà lára àwọn gbajúmọ̀ tí ayé ti parọ́ ikú mọ́ sẹ́yìn Èèyàn 627 ló lùgbàdì àrùn Coronavirus ní Naijiria ní Ọjọ́ Ẹtì Irọ́ ni pé Gómìnà Edo Obaseki ti darapọ̀ mọ́ ẹgbẹ́ PDP Amugbalẹgbẹ yii la gbọ pe o fi ibinu pe olori awọn alaabo iyẹn CSO ti o si ni ko fi awọn ẹsọ iyawo aarẹ to da lọna si ahamọ.
Gbajugbaja olorin taka-sufe omo Naijiria, Davido ti gba ami eye onkorin to mose ju ti ‘Best International Act’ nibi idije ami eye BET ni Los Angeles.
O gba ladura pe ki awọn maa ṣe ja ireti awọn to yan wọn sipo kulẹ.
Nipase itọju yi, wọn a ma lo ẹdọ foro atọwọda lati se iranwọ mimi fun ẹni naa eleyi ti yoo ma gbe atẹgun wọ ẹdọ foro rẹ ti yoo si tun ma gbe jade pada.
Bí ọ̀sẹ̀ àkọ́kọ́ yóó ṣe rí rèé Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Láìsí àní àní, ìre náà yóo mọ́ ọn.
Adesokan jẹ́ ọ̀kan nínú àwọn eléré ìdárayá wa tí Nàìjíríà rán lọ́ ibi ìdíje Paralymics tó nlọ lọ́wọ́ lọ́wọ́ báyìí ní ìlú London.
 “Ipenija kan naa ni won ni, won n
Ile ise nla iwakusa gbede ti awon ara Indonesia n sakoso re naa farahe ninu isele naa ni ekun Paupua.
Aarẹ orilẹede Naijiria nigbakan ri, Oluṣẹgun Ọbasanjọ lo pariwo sita ninu lẹta ibanikẹdun to kọ ranṣẹ si aṣiwaju ẹgbẹ afẹnifẹre, alagba Rueben Faṣọranti lori ajalu iku ọmọ rẹ obinrin, Funkẹ Ọlakunrin.
Gbé ọ̀pá rẹ sókè kí o na ọwọ́ sórí Òkun Pupa, kí ó sì pín in sí meji, kí àwọn eniyan Israẹli lè kọjá láàrin rẹ̀ lórí ìyàngbẹ ilẹ̀.
 fífún àwọn ọmọdé ní àjẹsára lè dáàbò bo àwọn ẹlòmíràn tó wà ní àyíká wọn .
Ẹ kò gbọdọ̀ gbẹ̀san, tabi kí ẹ di ọmọ eniyan yín sinu, ṣugbọn ẹ níláti fẹ́ràn ọmọnikeji yín gẹ́gẹ́ bí ara yín.
Àwọn alátakò ti sọ pé ó ṣe pàtàkì láti rántí wípé ìwé ẹ̀rí ọmọ-ìlú-fún-ìrìnnà dúró fún ìdánimọ̀ ọmọ ìlú ní òkè òkun, torí ìdí èyí, kò ṣe é yẹ̀ sílẹ̀ fún wọn.
 Ali ati oga agba ile ise NNPC Maikanti Baru.
Mo ti gbé inú ayé fún ìgbà díẹ̀, àwọn tí mo bá láyé sì ti sọ fún mi pé, bí ẹni tí ó ń soore tilẹ̀ fi ẹsẹ̀ kọ̀, kò le ṣubú láéláé.
Atamatase, akoni iko agbaboolu Chelsea ati orile-ede Code Voire teleri, Didier Drogba ti setan lati feyin ti ninu ere boolu afesegba.
Mose fún àwọn ẹ̀yà Reubẹni ní ilẹ̀, gẹ́gẹ́ bí iye ìdílé wọn.
Ẹ má máa fi burúkú san burúkú.
Ó pàṣẹ fún un pé kí ó lọ bá Modekai kí ó bèèrè ohun tí ó ṣẹlẹ̀, ati ohun tí ó fà á.
Àwọn Farisi ati àwọn amòfin tí wọ́n wà ninu ẹgbẹ́ wọn wá ń kùn sí Jesu.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Yusuf Magaji Bichi di Olùdarí àgbà tuntun 14 Owewe 2018 Oríṣun àwòrán, @BysShuwaki Àkọlé àwòrán, Yusuf Bichi Àjọ Ọ̀tẹlẹ̀múyẹ́ DSS ti ní Olùdarí àgbà tuntun.
Bakan naa lo parọwa fun gbogbo awọn to kopa nibi ipade itagbangba naa pe ki wọn dẹkun ṣiṣe eyi lati ẹyin ipade naa lọ.
ewúrẹ́, àgbọ̀nrín ati èsúó ati ìgalà, ati oríṣìí ẹranko igbó kan tí ó dàbí ewúrẹ́, ati ẹranko kan tí wọn ń pè ní Pigarigi, ati ẹfọ̀n, ati ẹtu.
Gbogbo ayé ni yóo ranti OLUWAwọn yóo sì pada sọ́dọ̀ rẹ̀;gbogbo ẹ̀yà àwọn orílẹ̀-èdèni yóo sì júbà níwájú rẹ̀.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Nigeria Customs Service: Kò sí ǹkan tó jọ tòmátò tó ní májèlé ní Nàìjíríà' 15 Agẹmo 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Igbakeji Oludari Ajọ Aṣọbode Naijiria, Anthony Ayalogu ti sọ pe ajọ naa ko mọ nipa tomato alagolo oni majele ti awọn eniyan kan sọ pe wọn ko wọ orilẹede Naijiria lati Iran.
Ṣugbọn bí àwa fúnra wa tabi angẹli láti ọ̀run bá waasu ìyìn rere mìíràn yàtọ̀ sí èyí tí a ti waasu fun yín, kí olúwarẹ̀ di ẹni ègbé.
Gbà mí, Ọlọrun,nítorí omi ti mù mí dé ọrùn.
Oyo àti Sokoto ni 5, Plateau ni 4 tí Taraba si ni 3 Àjọ tọ n gbógun ti ìtànkálẹ̀ àjàkálẹ̀ ààrùn ni Nàìjíríà (NCDC) ti kéde pé ènìyàn ọ̀ọ̀dúnrun àti mẹ́w['a ló tun ṣẹ̀sẹ̀ lùgbàdì ààrùn coronavirus lórílẹ̀-èdè Nàìjíríà Nínú àtẹ̀jáde ojoojúmọ́ ilé iṣẹ́ náà lójú òpó Twitter rẹ̀ ló lo ti salaye pé, ìpínlẹ̀ méjìlá ni ọwọ́jà ààrùn náà dé dúró ní Nàìjíríà fún tí ọjọ́ kẹrin osù kejìlá ọdún 2020.
Oríṣun àwòrán, OTHERS Asiko to si wa ninu ọgba ẹwọn naa lo ṣe alabapade oloogbe Wolii T.
Ilé ti wọ́n kọ́ fún oníbodè náà jẹ́ ilé òkúta, wọ́n sì kọ ọ̀rọ̀ nípa bàbá mi sí ara rẹ̀ lẹ́hìn òde.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ondo politics: Ọ̀gá àgbà iléeṣẹ́ ọlọ́pàá pàṣẹ kí wọn dá àwọn ẹ̀ṣọ́ aláàbò igbákejì gómìnà ìpínlẹ̀ Ondo padà 21 Òkùdu 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 29 Òkùdu 2020 Oríṣun àwòrán, others Ọga agba ileeṣẹ ọlọpaa Naijiria, Mohammed Adamu ti paṣẹ pe ki kọmiṣọna ọlọpaa ipinlẹ Ondo, Bolaji Salami da ẹṣọ alabo igbakeji gomina ipinlẹ naa pada fun un.
Àwọn ọmọ àwọn iranṣẹ Solomoni nìwọ̀nyí: àwọn ọmọ Sotai, àwọn ọmọ Sofereti, ati àwọn ọmọ Perida, 
Ṣugbọn ta ni ọkunrin yii to n pe ara rẹ ni Jesu gan an, ati pe kinni o n ṣe kaakiri ilẹ adulawọ?
Àwa la mọ báa ṣe mú Sunday Shodipe táa fà a lé ọlọ́pàá lọ́wọ́ - Ọlọ́dẹ Soludero Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Ìgbà tí mo máa fi lajú sáyé padà, ọ̀fọ̀ ikú mi ní wọ́n ń kígbe' Ohun to ṣẹlẹ̀ tẹlẹ Ṣaaju, ọga Agba ileewe fasiti ipinlẹ Eko ti wọn yọ nipo, Oluwatoyin Ogundipe ti gba ileẹjọ lọ lẹyin ti Ajọ amuṣẹya fasiti naa yọ ọkuro nipo.
Wọ́n dá a lóhùn pé, “Ìwọ yìí tí wọ́n bí ninu ẹ̀ṣẹ̀, tí wọ́n tọ́ dàgbà ninu ẹ̀ṣẹ̀, o wá ń kọ́ wa lẹ́kọ̀ọ́!
Karoline bẹrẹ isẹ pada lori redio, to si kọ iwe nipa igbe aye rẹ laarin ọdun meji to de si orilẹede South Afrika.
Agbẹ́nusọ fún àjọ ọlọ́pàá ìpínlẹ̀ Ekó ní ọwọ́ àwọn agbófinró bàá ní òsẹ̀ tó kọjá ní Ìdí Ìrókò lásìkò tó ń gbìyànjú láti sá kúrò lórílẹ̀-èdè Nàìjíríà lọ sí orílẹ̀-èdè Benin Republic Oti sàlaàyé pé àwọn ó ni pẹ́ gbé lọ sí ilé ẹjọ́.
Toyin Abraham: Ìgbéyàwó la kọ́ gbọ́, ọmọ ló tẹ̀le lọ́jọ́bọ
Ábíára: Ọmọ tí oyún rẹ̀ kò tí i hàn dáadá tí baba rẹ fi kú.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Oba Samuel Adeniran Asusumasa Atewogboye II: Alaaye ti Efon Alaaye tí wọ́n yẹgi fún lọ́dún 1949 30 Agẹmo 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 8 Ògún 2020 Oríṣun àwòrán, Others Yoruba ni ẹni ti a ni ko ki ni lẹyin, ko yẹ ko fi ẹgun sọwọ, bẹẹ ni ẹni ti a ni ko fẹ ni loju, ko gbọdọ fi ata sẹnu.
 Orilẹede ti a kọ sori okuta iyebiye Dayamọndi Orilẹede Botswana ni ọpọ maa n pe ni itan aṣeyọri ilẹ Afirika - o gba ominira rẹ lai ta ẹjẹ silẹ gẹgẹ bi ọpọ awọn orilẹede to mule tii ṣe ṣe, ko fi igba kan ri ni wahala ogun abẹle bẹẹni eto idibo rẹ kii ni rogbodiyan ninu rara."
Akwasi Frimpong Ọjọ ori: Mokanlelogbon Orilẹẹde: Ghana Ere idaraya: Skeleton  Akwasi Frimpong ni oludasile ajo ere idaraya ere ori yinyin ilẹ Ghana,ti a mo si Bobsled and Skeleton Federation(BSF-Ghana) lodun 2016.
Wo àwọn tó ń jí owó Covid-19 tí Ìjọba ní wọ́n yóò kàwọ́ pọ̀nyìn rojọ́ Kò sí ìsinmi ìdajì táàmù fáwọn akẹ́kọ̀ọ́ ìjọba l‘Ọyọ - Seyi Makinde Ìjọba ìpínlẹ̀ Eko ti bẹ̀rẹ̀ àtúnkọ́ ilé tí ẹlikọ́pútà tó jábọ́ bàjẹ́ ní ìlú Eko Boss Mustapha to jẹ akọwe ijọba apapọ to tun jẹ alaga igbimọ amuṣẹya aarẹ lori ọrọ COVID-19 fi ikilọ yii lede lọjọ Aje ni ilu Abuja nibi ipade ikejilelọgọta igbimọ naa.
Ṣugbọn ọgbẹni Doku ni fifi ofin de ẹrọ ibanisọrọ kọ ni ọna abayọ loju toun si iṣoro yii.
Kọmiṣọnna fun ọrọ oye jijẹ ati ijọba ibilẹ Arabinrin Aisha Patigi ni oludari tuntun fun ile iṣẹ ijọba to n ri si ọrọ oye jijẹ ati ọrọ ijọba ibilẹ ni ipinlẹ Kwara bayii.
Awọn oṣiṣẹ maa n yan bi ologun, awọn alaṣẹ maa n fi ọjọ yii saaba ṣe ikede ohun tuntun ti wọn ba ni fawọn eniyan Naijiria lasiko naa.
Liverpool 19:45ifigagbaga ti yoo waye lojoRU(Wednesday)Bayern Munich ?
Awọn ọmọogun jẹwọ idi ti wọn ko fi lee pa ina Boko haram
Oríṣun àwòrán, @BokoHaramWatch Awọn ọmọ ikọ Boko Haram yii wa gbagbo sori nigba ti asaaju wọn, Mohammed ku si ahamọ awọn agbofinro, ti wọn si bẹrẹ si ni soro bii agbọn.
OLUWA jọba, kí ayé ó yọ̀;jẹ́ kí inú ogunlọ́gọ̀ erékùṣù ó dùn.
Ó ní, “Ọmọ mi, mo ní i lọ́kàn láti kọ́ tẹmpili kan fún orúkọ OLUWA Ọlọrun mi, 
O ni ti ere rẹ ko ba pọju ni, o ṣeeṣe ki ijamba ọhun ma ṣẹlẹ.
Àwọn náà ṣe bí àwọn angẹli tí wọ́n kọjá ààyè wọn, wọ́n ṣe àgbèrè ati oríṣìíríṣìí ohun ìbàjẹ́ tí kò bá ìwà eniyan mu.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Akure Death: Ọmọ ọdún mẹ́wàá ṣàlàyé ìdí tó ṣe ti àbúrò rẹ̀ tó jẹ́ ọmọ ọdun kan àbọ̀ sínú kàǹga 20 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Oríṣun àwòrán, @NtaAdo Ileeṣẹ ọlọpaa ipinlẹ Ondo ti fi ṣinkun ofin mu ọmọdebinrin ẹni ọdun mẹwaa kan ti wọn fẹsun ipaniyan kan lagbegbe Owode, ni ijọba ibilẹ Ariwa Akure.
“Nítorí náà, mo kó wọn kúrò ní ilẹ̀ Ijipti, wá sinu aṣálẹ̀.
Lara awọn ohun to n ṣe ni ẹṣọ ile, ṣiṣe iṣẹ ọna sara aṣọ atawọn nnkan miran to jọ mọ ṣiṣe ara lọṣọ.
jai, ki ero kalekaako kan gbe iroyin eleje, eleyi ti ko fidi mule jade pelu
Wọn ni ireti pe wnyoo pari idanwolilo abẹrẹ yi lọdun 2023.
A bere lọwọ awọn to ti la iru nnkan bẹ kọja lati sọ iriri wọn ati awọn ohun ti eeyan lee ṣẹ to ba n ni idojukọ ninu igbeyawo rẹ, pẹlu ọkọ oniwa ipa.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Tiwa Savage tọwọ́ bọ'wé àdéhùn pẹ̀lú UMG fún òkìkí orin rẹ̀ 2 Èbibi 2019 Oríṣun àwòrán, Universal Music Group Àkọlé àwòrán, Tiwa pẹlu awọn onigbọwọ Lónìí, ajọ awọn onigbọwọ orin to ga ju lagbaye (Universal Music Group) ti kede ajọṣepọ nla laarin wọn ati gbajugbaja olorin, Tiwa Savage.
Ṣaaju asiko yii, gbogbo orilẹ-ede kaakiri agbaye ni awọn ẹlẹsin Islam ti maa n lọ si Mecca ati Medina lati ṣe Hajj lọdọọdun.
Facebook ni ile isẹ kan ni orilẹede Isreal lo n pin awọn iroyin ẹlẹjẹ to nii se pẹlu eto oselu ati eto idibo ni awọn orilẹede si awọn oju opo ayederu yii lati da rogbodiyan silẹ.
maa n ri  ipa pataki ti ijoba ti n ko
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù CAN: Ipenija aabo ni Naijiria n fẹ ẹjẹ tuntun lawọn ileeṣẹ alaabo 23 Èrèlè 2018 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ẹgbẹ CAN kọminu lori kikuna ileesẹ alaabo lati pẹka awọn apanijaye gbogbo to n da omi alaafia orilẹede Naijiria ru Ẹgbẹ ọmọlẹyin Kristi lorilẹede Naijiria, CAN ti pe fun atunto ileeṣẹ aabo gbogbo lorilẹede Naijiria eleyi ti ko se lẹyin wahala to n de ba eto ọrọ abo paapaajulọ gulegule ipaniyan nihin-lọhun to n waye.
OLUWA Ọlọrun, Ọlọrun àwọn ọmọ ogun ní: “Ẹ gbọ́, kí ẹ sì kìlọ̀ fún ìdílé Jakọbu.
Ẹwẹ, awọn iwa ti awọn ọkunrin to ma n ṣe iku pa iyawo wọn lati ri ki wọn ma jowu,tabi ki ẹru ma ba wọn wi pe awọn iyawo wọn yoo fi wọn silẹ.
Ìwọ ni ò ń gba aláìlágbáralọ́wọ́ ẹni tí ó lágbáratí o sì ń gba aláìlágbára ati aláìnílọ́wọ́ ẹni tí ó fẹ́ fi wọ́n ṣe ìjẹ.
O ni gbogbo ibi ti awọn ba de ni ọpọlọpọ eeyan ti maa n beere alaye lori igbesẹ ti awọn gomina n gbe lati dẹkun ipenija eto aabo.
Awọn ileeṣẹ agbofinro bii DSS ni o maa n saba ṣe eleyii.
Wọn ni nítori pé ọ̀pọ̀ ọmọ Naijiria ló ti n gbin ìrẹsì lẹyin ti aarẹ Buhari ti ẹnu ibode pa.
Ó fún àwọn ọmọ Merari ní ọkọ̀ ẹrù mẹrin ati akọ mààlúù mẹjọ, gẹ́gẹ́ bí iṣẹ́ ìsìn wọn, lábẹ́ àkóso Itamari ọmọ Aaroni alufaa.
Ọ̀gá ọlọ́pàá tó wà ní 'Check Point' kàgbákò ikú òjijì lọ́wọ́ awakọ̀ l'Eko Olanrewaju Bamidele fi 'Screw driver' gún ìyáwo rẹ̀ pa Inú ìbànújẹ́ ni mo wà lórí ikú alága CAN tí àwọn Boko Haram pa- Buhari Nipa eto idibo gbogboogbo to kọja, Ọga Ajọ EFCC naa fikun pe, awọn ri daju wi pe awọn gbogun ti iwa rira ibo ati tita ibo lorilẹede Naijiria.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Buhari, o ṣẹ ilẹ̀ Yorùbá púpọ̀, ló àyájọ́ ìbí rẹ̀ láti tọrọ àforíjìn - PDP Wo ìdí tí ààrẹ Buhari kìí fi ṣe ẹ̀dà Jubril láti Sudan Ẹ dín agbára ìjọba àpapọ̀ kù, kẹ ṣì ṣe àgbékalẹ̀ ọlọ́pàá ìpínlẹ̀ - Tinubu bẹ̀bẹ̀ Wo eyi to súnmọ́ ọ nínú àwọn ibùdó 203 fún ìforúkọsílẹ̀ fún NIN rẹ Adigunjalè méjì ko ìjàmbá ọ̀kadà lẹ́yìn ìṣẹ́ ibi n‘Ibadan, ọ̀kan kú lójijì, aráàlú dáná sun èkejì Àwọn ohun kàyéèfì tó le mú kí ọmọbìnrin ní oyún ìju Ṣugbọn, onimọ kan nipa ọrọ aje, Gbadamosi Olusola, to jẹ Igbakeji Aarẹ Ẹgbẹ awọn onimọ ọrọ aje ati iṣiro ni Naijiria, sọ fun BBC pe, idẹrun ọlọjọ diẹ ni yoo mu wa fun araalu.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ọọni: Ilẹ̀ ifẹ̀ ní ìran Ìgbò tí ṣẹ wá kìí ṣe ilẹ̀ juu 23 Ìgbé 2019 Oríṣun àwòrán, Yera Moses Olafare Onimọ kan nipa igbe aye ati ihuwasi awọn eeyan aye atijọ to fi fasiti UNN Nsukka ṣe ibujoko sọ pe o ṣeeṣe ki iran Igbo ṣẹ wa lati Ile Ifẹ ni ilẹ Yoruba.
Minisita tesiwaju pe “iye oko to n bo lati ilu Eko lo si Shagamu po pupo, idi niyi ti oju opo meta-meta yoo wa loju opopona Eko si Shagamu, ti Shagamu si Ilu Ibadan yoo je opo meji-meji loju popo.
Gomina Bala Mohammed ni awọn ti ṣaaju buwọlu ofin to n daabo bo awọn eeyan lọwọ iwa ipa to si ni awọn yoo fi atunto ofin naa sọwọ sile aṣofin ipinlẹ.
Àtúntẹ̀ ti 1876, tí a pèsè lati ọwọ́ Àlàgbà Orson Pratt ní abẹ́ ìdarí Brigham Young, ṣe ètò àwọn ìfihàn náà ní ìbámu sí àkójọ àwọn ìṣẹ̀lẹ̀ lẹ́sẹẹsẹ ó sì mú àwọn àkọlé titun wá pẹ̀lú àwọn ọ̀rọ̀ ìṣaájú onítàn.
Bakan naa lawọn kan sọ pe nitori pe o jẹ agbẹjọro fun ijọba ipinlẹ Oyo ni.
- UN21 Bélú 2017 Burundi don give unmarried couples till end of 2017 to marry6 Bélú 2017 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Ìhà wo gan-an ni ìjọba Nàìjíríà kọ sí ọ̀rọ̀ ẹ̀sùn tí wọ́n fi kan Ibarahim Magu?
OLUWA wí fún Mose pé, “Gun orí òkè tọ̀ mí wá, kí o dúró sibẹ, n óo sì kó wàláà tí wọ́n fi òkúta ṣe fún ọ, tí mo kọ àwọn òfin ati ìlànà sí, fún ìtọ́ni àwọn eniyan yìí.
Nígbà tí Paulu bẹ̀rẹ̀ sí sọ ti ẹnu rẹ̀, ó ní, “N kò ṣe ohunkohun tí ó lòdì sí òfin àwọn Juu tabi sí Tẹmpili; n kò sì ṣẹ Kesari.
Àná yìí náà ló dé ọ̀dọ̀ mí, láti ìgbà tí ó sì tí dé ọ̀dọ̀ mi yìí ńkọ́, òun ní mo ti ń ṣe àkíyèsí wí pé gbajúmọ̀ ènìyàn ni, bí a bá tilẹ̀ wí pé kí á sọ̀rọ̀ nípa ọkùnrin náà tó bí ó ti níláárí ni, a kò bá tí wí pé igba ojú ni ó mọ̀ ọ́n mọ́, bẹ́ẹ̀ ni a kò bá pé ẹgbẹ̀ta ojú ni pẹ̀lú.
Agbẹnusọ Ile Igbimọ Aṣofin Ipinlẹ Eko sọrọ iṣiti yii ninu ọrọ ikini-ku ọdun Ileya rẹ si awọn ara ilu, eyi ti alukoro agba rẹ, Ọgbẹni Musibau Rasak buwọ luAṣofin Ọbasa rọ awọn ọmọ orilẹ-ede Naijiria lati ni iwa aforiti ati suuru eleyii ti Anabi Ibrahim, iyawo rẹ, Hajarat ati ọmọ wọn, Ismaila  wu, ti gbogbo wọn fi pinnu lati fi ọmọ wọn kan ṣoṣo naa, Ismaila rubọ si Ọlọrun gẹgẹ bi majẹmu wọn nigba ti wọn n wa ọmọ naa.
Yóo máa wá ojurere rẹ,pẹlu oríṣìíríṣìí ọrọ̀.
musulumi yọ bi wọn se n pari osu mimọ Ramadan ọdun 2019 yii.
Àwọn ọmọ Israẹli ń tẹ̀lé gbogbo ìwà ẹ̀ṣẹ̀ Jeroboamu, wọn kò sì yipada kúrò ninu wọn, 
Ojoojumọ ni wọ́n ń kìlọ̀ fún un, ṣugbọn kò gbọ́.
Láìṣe bẹ́ẹ̀ kò sí ẹni tí yóo rí Oluwa.
Wọn ti gbe awọn ti wọn ti ri lọ sile iwosan bi wọn ṣe yọ wọn.
ofin to faramo pe ki obinrin di ipo adari iko omo-ogun  mu lorile ede Naijiria sugbon  oga agba patapata fun ile-ise ologun orilede
"Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Nigeria's Under-19:Ẹ wo bí Ikọ̀ Cricket Naijiria ṣe mi àgbáyé titi Ọpọlọpọ awọn ololufẹ Ighalo lo ya lẹnu pe ""Red Devils"" buwọlu igbesẹ Ighalo yii pẹlu bi Man U ṣe jẹ ọkan lara awọn ẹgbẹ agbabọọlu to gbajumọ gan lorilẹede Naijiria."
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Kemi Lala: mo ń gbìyànjú láti mú inú òbí mi dùn Kini awọn eeyan n wi?
Ọlọrun wò wọ́n, ó sì rí i pé wọ́n dára.
Eyín akọ̀ròyìn fò yọ lásìkò tó n ka ìròyìn lọ́wọ́ lórí tẹlifísàn Wo àwọn olorì àgbà mẹ́rin tí Aláàfin ń wárí fún Ẹ dá àwọn ẹ̀ṣọ́ aláàbò igbákejì gómìnà ìpínlẹ̀ Ondo padà ní kíá - ọ̀gá àgbà iléeṣẹ́ ọlọ́pàá Ati pe atunṣe to dara ni kikuro ti Ajayi kuro l'ẹgbẹ APC jẹ fun ẹgbẹ naa.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù PDP: A fẹ́ gba odindin Imo padà ni lọdún tó n bọ 27 Ìgbé 2018 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, PDP kò gbàgbọ́ nínú ètò ìdìbò ìjọba ìbílẹ̀ típínlẹ̀ Imo fẹ́ ṣe lóṣù keje ọdún yìí Égbẹ́ òṣèlú People's Democratic Party (PDP) nipínlẹ̀ Imo ti ni ó ṣeéṣe kí ó má kópa nínú ètò ìdìbò tó m bọ̀ Ọjọ́ kẹrìnlá, oṣù keje ọdún yìí ni wọ́n ń pinnu kí ìdìbò fún yíyan alága ìjọba ìbílẹ̀ nípínlẹ̀ Imo wáyé.
Oríṣun àwòrán, MMM Àkọlé àwòrán, MMM sọ pe oun n pese iranlọwọ fun awọn eniyan ni, ati pe awọn olojukokoro lo n ba iṣẹ jẹ fun wọn.
Èyí jẹ́ àpẹẹrẹ ohun tí ń bọ̀ wá ṣẹlẹ̀ sí àwọn tí kò bẹ̀rù Ọlọrun.
"Mí o le lọ nítori mo gbàgbọ́ pé àwọn tó wà ni ibẹ̀ le pa mí lára, nítori náà mo sá pamọ́, bi wọ́n ṣe n ja sọ́ọ̀bù, àwá kan náà sá pamọ́ nínú ọgbà náà, sùgbọ́n àwọn tọ́ ń já sọ́ọ̀bù ń lọ láti inú sọ́ọ̀bù kan si èkejì wọ́n si n ji ǹkan.
Ogbeni Kolade Segun-Okeowo, to je gbaju gbaja osere omo leyin Jesu atawon onimo ninu esin Kristieni ti parowa fawon eniyan Naijiria lori Pataki nini kaadi idibo won lowo saaju idibo odun 2019 to m bo.
O ni ki awọn araalu fojusọna fun abajade iwadii ti awọn alaṣẹ yoo gbe jade laipẹ.
Nítorí náà mo sọ àwọn olórí ibi mímọ́ mi di aláìmọ́,mo fi Jakọbu sílẹ̀ fún ìparun;mo sì sọ Israẹli di ẹni ẹ̀sín.
ọmọ Etini, ọmọ Sera, ọmọ Adaya; 
Báwo wá ni afọ́jú ti nrí ìwé kà?
Wọn ni iwa rẹ le da ija ẹlẹyamẹya silẹ, to si tun le ru igbesunmọmi soke.
Abẹ́ ìrọ̀rí rẹ̀ ni ó wà nígbà tí ó ń ṣàìsàn.
Nibayii, igbokegbodo ọkọ ti bẹrẹ pada ni opopona naa, lẹhin ti wọn bomi pa ina ọhun, ti awọn ẹṣọ abo oju popo si n se akoso awọn ọkọ to n lọ to n bọ lagbegbe naa.
Nígbà tí ìròyìn dé ilé ọba Dafidi pé àwọn ará Siria ati Efuraimu ń gbógun bọ̀, ọkàn òun ati àwọn eniyan rẹ̀ mì tìtì bí afẹ́fẹ́ tíí mi igi ninu igbó.
lasiko ayeye ajodun ojo asa Berom Cultural Festival ti o waye niluu Jos, nipinle
Òòró ìloro náà jẹ́ ogún igbọnwọ (mita 9), ìbú rẹ̀ sì jẹ́ igbọnwọ mejila (mita 5½), àtẹ̀gùn rẹ̀ ní ìgbésẹ̀ mẹ́wàá, òpó sì wà ní ẹ̀gbẹ́ kinni keji àtẹ́rígbà rẹ̀.
Dafidi fi àwọn òbí rẹ̀ sílẹ̀ lọ́dọ̀ ọba Moabu, wọ́n sì wà níbẹ̀ ní gbogbo ìgbà tí Dafidi wà ní ìpamọ́.
N óo yọ ọkàn tí ó le bí òkúta kúrò, n óo sì fun yín ní ọkàn tí ó rọ̀ bí ẹran ara.
Oríṣun àwòrán, EPA Àkọlé àwòrán, Eto aṣekagba isinku yoo waye ni Ọjọ kẹrinla oṣu kẹrin ọdun yii.
Àwọn tí ó ń gbé Jerusalẹmu ati àwọn olóyè wọn, wọn kò mọ ẹni tí Jesu jẹ́, bẹ́ẹ̀ ni ohun tí àwọn wolii ń sọ kò yé wọn bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé lọ́sọ̀ọ̀sẹ̀ ni wọ́n ń kà á.
Salah ni ọmọ ilẹ Afirika keji ti yoo gba ami ẹyẹ yii, lẹyin ti Riyad Mahrez ti gba a, ni saa bọọlu 2015 si 2016, pẹlu ẹgbẹ agbabọọlu Leicester city.
Wo àwọn tó ń jí owó Covid-19 tí Ìjọba ní wọ́n yóò káwọ́ pọ̀nyìn rojọ́ Kọmisọnna fun eto ẹkọ naa fikun wi pe idi ti ijọba ipinlẹ Kogi ṣe ni ki awọn akẹkọọ pada si ileẹkọ ni pe awọn ko kabamọ pẹlu awọn akẹkọọ Primary 6, JSS3 ati SS3 ti wọn ti kọkọ wọle.
Ó le láti jẹ́ atọ̀hùn-rìnwá, ṣùgbọ́n ìjàjàǹgbara yìí ní ó sọ mí di bí mo ṣe wà.
Tọọ ba ti ri ọba fin, o ti padanu gbogbo ohun too ni ati to n ri lọdọ ọba; a o si wa wa ọta rẹ a o gbe gbogbo ohun toun ri gba lọwọ ọba fun ọta rẹ""."
Ìdí táwọn apòògùn Nàìjíríà fi tako oògùn Coronavirus láti Madagascar Mo kábàámọ̀ pé n kò kàwé, kí n tó bẹ̀rẹ̀ iṣẹ́ tíátà - Sanyeri Ìtàn ìgbésí ayé Oshodi, ọmọ Tápà léǹpe tó di akọni ní ìlú Eko El-Rufai bá Yemi Osinbajo ṣàwàdà!
Egbe awon osise lorile-ede Naijiria ti kora jo bayii lati lo sepade po pelu ijoba apapo nile ise akowe agba ijoba lati jo jiroro ona abayo lori iduna-dura ekunwo owo osu awon osise.
Onka awọn to to ti ri iwosan gba ti ara wọn ti ya lẹyin itọju bayi jẹ 19,565.
Wọn rọ awọn eniyan ti wọn ba ni ikọ tabi inira lati mi, ki wọn lọ si ile iwosan fun iwosan to peye.
'Obinrin lo maa n pọ ju ninu awọn to maa n ṣiṣẹ nile aarẹ, wọn si maa n gba ọpọ wọn lati tẹ ifẹkufẹ aarẹ l'ọrun ni.
Eyi ni iye owo ti ijọba apapo kede laipe yi pe awọn ri gba pada lọdun 2017 lati ọdọ ijọba orileede Switzerland ninu owo ti Aarẹ orileede Naijiria nigba kan ri ọgagun Sani Abacha ji pamọ.
Ó tún ké sí ẹ̀ṣọ́ tí ó wà ní ẹnu ọ̀nà, ó ní, “Wò ó, ẹnìkan ni ó tún ń sáré bọ̀ yìí.
igbakeji Akojanu  fun igbimo asofin naa.
Oríṣun àwòrán, others Oríṣun àwòrán, others Oríṣun àwòrán, others Oríṣun àwòrán, others Oríṣun àwòrán, others Oríṣun àwòrán, others Lori ẹsun ti Naijiria fi kan Ghana pe o gba ileesẹ aṣoju oun, Nkrumah sọ pe, ọdun mẹrindinlaadọta sẹyin ni adehun ti orilẹ-ede mejeeji fọwọ́ si pẹlu ẹni to ni ile naa, Thomas D.
Fifa, nínú àtẹ̀jáde rẹ̀ sọ wí pé ìdúnàádúrà fún Ife Àgbáyé ti ọdún 2026 náà lọ ní ìrọwọ́rọsẹ̀ àti wí pé, Orílẹ̀èdè Morroco àti Amẹrika pẹ̀lú àjọsèpọ̀ orílẹ̀ède Mexico àti Canada ni ó kù sẹ́nu ìdúnàádúrà fún Ife Àgbáyé náà.
Sex party: Ìjọba gbé ilé ijó oníhòhò tì pa lórí ẹ̀sùn títàpá sí ìlànà àti dẹ́kun coronavirus
Nítorí gbogbo nǹkan wọnyi ni àwọn abọ̀rìṣà ń lépa.
ọgbọ̀n abo ràkúnmí, tàwọn tọmọ wọn, ogoji abo mààlúù ati akọ mààlúù mẹ́wàá, ogún abo kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ ati akọ mẹ́wàá.
Ọ̀rọ̀ OLUWA nìyí; tí a kọ sinu ìwé ìran tí Nahumu ará Elikoṣi rí nípa ìlú Ninefe.
Àbò mi rèé lórí èyí, kÓlódùmarè ó fún mi lókun láti se àwon isé tí ó tún wà níwájú mi.
- Obasanjo gbarata Ìbẹ̀rù bá olùgbé Eko torí àwọn ọ̀dọ́ Òkè Ọya tó dìhámọ́ra Olùkọ́ mi ń bá mi lòpọ̀ kí ń le yege ìdánwò WAEC - Akẹ́kọ̀ọ́ l‘Ogun Olólùfẹ PDP 18 kú nínú ìjàmbá ọkọ̀ lásìkò tí wọn ń lọ pàdé gómìnà Iyabo Ojo ṣílé, Toyin Abraham fẹ́ ṣílé iṣẹ́ f'ọmọ, àtàwọn nǹkan míràn lágbo òṣéré Dokita Ezenwankwo lo fi ilanilọyẹ yii silẹ ninu ifọrọwanilẹnuwo kan to ṣe lori ohun to lee fa wahala yii.
Oríṣun àwòrán, @AmnestyNigeria O ni awọn ẹri yii fihan pe awọn sọja yinbọn mọ awọn oluwọde lootọ ni Lekki laarin aago meje ku isẹju mẹẹdogun si mẹsan alẹ.
4 67968 Orilẹede Afganistan 1900 5.
Ṣé Òfin wá di òtúbáńtẹ́ nítorí igbagbọ ni?
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Fulani Kidnapping: Owó púpọ̀ la san kí wọ́n tó fi mi sílẹ̀ Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Ọgbẹni Bloomberg ti kọwọ bọwe lati kopa ninu idibo abẹle ẹgbẹ oṣelu Democrat ti yoo waye nipinlẹ Alabama.
Ẹyin Ẹyin jẹ ọkan lara awọn eroja to ṣe koko ni ara eniyan.
Ọọniriṣa, Adeyẹye Ogunwusi ko da gbalejo aṣoju ijọba ilẹ Gẹẹsi naa, oun pẹlu Olori rẹ, Yeyelua Naomi Ogunwusi atawọn agbagba Ile Ifẹ ni wọn ki arabinrin Catriona Laing kaabọ si ile Oodua nileefẹ.
park jung-yang ( 박중양 朴重陽 , 3 may 1872 - 23 april 1959 ) ninu ilominira and Ìṣèlú , liberalism Àwọn amòye gba kòréà gúúsù .
 dírẹ ́ bà wọn ń sáré gan-an ni .
Dafidi bá pe Solomoni, ọmọ rẹ̀, ó pàṣẹ fún un pé kí ó kọ́ ilé kan fún OLUWA Ọlọrun Israẹli.
Ní ọjọ́ náà ọba yóo pa ọ̀dọ́ akọ mààlúù kan fún ẹbọ ìmúkúrò ẹ̀ṣẹ̀ fún ara rẹ̀ ati fún gbogbo àwọn ará ìlú.
Pópóọlá gbé Akin, Ilésanmí àti Kọ́lá.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ajimobi: Orúkọ èmi, Akala, Ladoja, Adebayo Faleti àtàwọn míì 15 Èbibi 2019 Oríṣun àwòrán, Abiola Adeyemi Ajimobi/Facebook Àkọlé àwòrán, Gomina Ajimobi Ijọba ipinlẹ Oyo ti fun awọn adugbo pataki kan ni ilu Ibadan atawọn ilu mii nipinlẹ Oyo lorukọ mii.
Wéréwéré ló bá a wá ewé igi ti bàbá rẹ̀ béèrè yìí.
Èdè Gẹ̀ẹ́sì tí pọju nínú tíátà Yorùbá tá n gbé jáde lóde òní - Afeez Ọwọ Oṣere tiata Yoruba ti awọn eeyan mọbi ẹni mowo nni, Afeez Ọwọ ti bẹnu atẹ lu bi awọn oṣere tiata Yoruba ṣe n faye gba ede oyinbo pupọ ninu ere sinima wọn.
Awon alakata-kiti elesin Islam ohun ti seku pa ogoro awon omo-ogun ijoba, awon olopaa, ati awon ara-ilu ti won kii se ologun, ni paapaa ni apa ariwa Sinai, ati awon agbegbe miiran lorile-ede Egypy.
, o tun lo si Fafiti Eko ni ilu Eko.
 wọn máa ń lo ìrùkẹ ̀ rẹ ̀ láti jó ijó àpíìrì .
Ibẹru lọsan atoru ni iru obinrion bẹ ma n wa.
Ẹkẹrinlelogun mú Romamiti Eseri, òun ati àwọn ọmọ rẹ̀ ọkunrin, ati àwọn arakunrin rẹ̀ jẹ́ mejila.
- Sowore 'Ọjà tí wọ́n ti ń ká owó ni ìlú Eko jẹ́ fáwọn onílé báyìí' Yinka Ayefele ṣe ìkọ́mọ ìbẹta rẹ̀, ọ̀nà ò gbẹsẹ̀ Àṣírí ilé ìmúni nígbèkùn míràn tú síta ní Ibadan 'Màálù tó bá tàsẹ̀ àgẹ̀rẹ̀ níwájú ilé mi, ó dẹran àsun!
Ọwọ́ sìnkún ọlọ́pàá ba èniyàn mẹ́fà nínú wọ́n, to fi mọ eégún ọ̀ún fúnra rẹ̀.
'Iroyin ẹlẹjẹ nipa ikọlu awọn ọmọ ẹgbẹ okunkun' Àkọlé àwòrán, Awọn ti awọn ọmọ ẹgbk okùnkun ti pa nile ekọ Wọn ti fẹsun kan awọn ọmọ ẹgbẹ okunkun pe awọn ni wọn wa nidi ikọlu lawọn fasiti kaakiri Naijiria ti wọn a si tun ma dunkoko mọ awọn olukọ lati fun wọn ni maaki.
O gba awọn neiyan ni imọran lati ni itẹlọrun pẹlu irufẹ aawọ ti Olọrun fun wọn laye.
"Awọn ọmọ orilẹede Naijiria naa, Seun Adigun, Ngozi Onwumere ati Akuoma Omeoga ngbaradi gẹgẹbi ikọ akọkọ lati ilẹ Afirika ti yoo kopa ninu idije olimpiiki ori yinyin (Winter Olympics) nigba ti wọn yoo maa kopa ninu idije kẹkẹ ori yinyin ti wọn npe ni ""Bobsledding"" Oríṣun àwòrán, Reuters Àkọlé àwòrán, Olimpiiki ori yinyin, (Winter Olympics) n waye ni ilu PyeongChang lorilẹede South Korea Ninu ọrọ iyanju to fi ransẹ si awọn oludije mẹta naa lori ikanni ayelujara twita rẹ , Sẹnatọ Bukọla Saraki kan sara si awọn ọmọbinrin mẹta naa fun akitiyan wọn lati rii wipe wọn kogoja ninu idije naa."
Bakan naa, ni eka Radio, osuwon owo ti o wole nipase ipolowo oja orile-ede ni odun 2016 je milionu mokanlelogorin owo dollars, eyi ti o je iko marundinlogorin ninu ida ogorun tun ja kule si ti awon akegbe re lorile-ede South Africa ati orile-ede Kenya, eyi ti apapo  owo won din die nirinwo milionu owo dollars.
Oríṣun àwòrán, AFRICAN DRUM FESTIVAL Àkọlé àwòrán, Ijọba ipinlẹ Ogun lo n ṣe agbatẹru ajọdun ilu ilẹ Afirika Minisita feto iroyin ati aṣa gboriyin fun awọn to gbe ayẹyẹ naa kalẹ pẹlu ileri atilẹyin ijọba apapọ fun ijọba ipinlẹ Ogun lori ajọdun naa.
OLUWA ní: “Ẹ ti fèrè bọnu, nítorí ẹyẹ igún wà lórí ilé mi, nítorí pé wọ́n ti yẹ àdéhùn tí mo bá wọn ṣe, wọ́n sì ti rú òfin mi.
Afara naa ti wọn ṣi lọdun 1996 lo nasẹ ju ninu awọn afara mẹta to so agbegbe Lagos Island ati mainland pọ ni ipinlẹ Eko.
"O ṣàpèjúwe awọn ẹgbẹ okunkun ode oni gẹgẹ bi ""ẹgbẹ kebbe,ẹgbẹ alaburu"" ""Mi o fi igba kankan ro pe ẹgbẹ kankan ninu ile iwe fasiti yoo ma ṣamulo awọn iwa buruku bi ijinigbe,ipaniyan,fifi ipa bani lopọ,ajigunjale ati awọn iwa miran bayi"" "" Mi o lero pe yoo pada da bo ti se ri yi,ki lo si mu di bayi?"
Àkókò tí mo fi ń múra Igbó Olódùmarè ni òun náà fi ‘’n ṣe òkú bàbá rẹ̀, orúkọ ẹni tí ń jjẹ́ Ìwàtútù tí ó jẹ́ ènìyàn pàtàkì ní ìlú wa.
O ni lara igbesẹ ti ijọba apapọ fẹ gbe naa ni lati ko awọn ologun si oju popo marosẹ kaakiri.
ng Àkọlé àwòrán, Minisita foro ilera ni Naijiria yọ Usman Yusuf Aarẹ Muhammadu Buhari ti da akọwe ajọ to n risi eto adoju-tofo lẹka eto ilera Naijiria (National Health Insurance Scheme), Usman Yusuf pada sẹnu iṣẹ lẹyin ti Minista fọrọ ilera yọ ọ kuro nipo lori ẹṣun jẹgudujẹra.
Iko Super Eagles pari sipo keta pelu ami keta lori tabili, ti Argentina si pari sipo keji pelu ami merin lori tabili.
Lodun 2014 ni Ebola koko wo Naijiria lati ara Patrick Sawyer ara Liberia ni eyi to fi tan kale ti o si gba emi awon eniyan kan.
Nibayii, ileeṣẹ ọlọpaa ṣi n wa awọn akẹẹgbẹ rẹ maarun to ti salọ.
Nígbà tí àwọn ọmọ aráyé sọ̀rọ̀ ẹnu wọn tán ẹ̀dá náà dìde ó wí fún wọn kí wọn máa lọ si ilé àti wí pé nígbà tí ó bá di òwúrọ̀ ọjọ́ kejì olúkúlùkù yóó rí i pé ohun gbogbo tí òun béèrè ni òun ti rí gbà.
Lẹ́yìn ìgbà náà ni àwọ̀n òṣìṣẹ́ yan ìṣẹ́ lódì fún ìgbà díè.
Bí ẹnikẹ́ni bá pe ara rẹ̀ ní wolii, baba ati ìyá rẹ̀ tí ó bí i yóo wí fún un pé yóo kú, nítorí ó ń purọ́ ní orúkọ OLUWA.
gba lọwọ awon onisowo ati onibara to ba fẹ ya owo ele lati ọdọ wọn , idi niyi
Eniyan a máa rí anfaani níwọ̀nba tí ó bá ń ṣe eré ìdárayá ti ara, ṣugbọn anfaani ti ẹ̀mí kò lópin; nítorí ó ní anfaani ní ayé yìí, ó tún fún eniyan ní anfaani ti ayé tí ń bọ̀.
Ṣùgbọ́n òmíràn a máa jẹ́ gberefu.
BI Ipo ate ajo FIFA se lo ni kikun nilee Afrika.
’Nítorí èmi ni n óo máa gbọ́ adura rẹ̀,tí n óo sì máa tọ́jú rẹ̀.
nítorí ó ń kọ́ wọn bí ẹni tí ó ní àṣẹ, kì í ṣe bí àwọn amòfin wọn.
El Rufai ni ki awọn ti ọrọ naa kan fi ọkan balẹ nitori pe ijọba yoo ri i daju pe idajọ ododo fẹsẹ mulẹ, ati pe awọn ọdaran to ṣe iṣẹ naa ko ni lọ lai jiya to tọ labẹ ofin.
Ìwọ sá máa tẹ̀lé mi ní tìrẹ.
Ṣebí Ọlọrun mọ ọ̀nà mi,ó sì mọ ìrìn mi.
Gomina Akeredolu ṣalaye loju opo Twitter rẹ pe Oluṣẹgun Abraham to jẹ okan lara awọn oludije mẹwaa to n ba a ta kangọn ti gba lati ti oun lẹyin.
Gbajumọ oṣere tiata naa tun salaye pe lootọ ni wọn maa n kọ ẹnu ifẹ si obìnrin ninu iṣẹ tiata bi awọn akẹẹgbẹ oun kan ti n sọ amọ kii ṣe tipatipa.
O menuba idanilekoo ona eto ogbin onigbalode tijoba n se fawon agbe ekun yii ti ko ni pe bi eso rere lataari ere oko ti won maa ri ta laipe.
Wọn ni Obìnrin kàn láran awọn tí boko-haram ji gbé to ribi sá mọ wọn lọwọ l'agbegbe ibẹ ló jẹri sí wí pé lootọ ní àwọn ọmọ obinrin náà wà lahamọ níbẹ.
Àkúntúnkú, ìgbà márùn ún rè é tí Shekau kú tí wọ́n ní kò kú mọ Jesu orí ayélujára kan rèé tó wa fun isoji ni Afirika Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí kan sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
“Idije boolu agbaye odun 2026: gbigbimopo lati sagbateru idije boolu agbaye ko je itewogba fun ajo FIFA, leyin eyi ti o waye lodun 2002.
Ohun kan ti ọpọ awọn onimọ n sọ bayii ni pe ẹya kokoro arun COVID-19 to tun gbaye kan bayii gẹgẹ bi a ti ṣe rii ni awọn ilu agbaye bii ilẹ Gẹẹsi fẹ tun yatọ si eyi to gbilẹ tẹlẹ ni ibẹrẹ ọdun 2020.
Bí ẹnikẹ́ni ninu yín bá wà ninu ìyọnu, kí olúwarẹ̀ gbadura.
Kìnìún mẹ́rìnlá bọ́ sígboro Jesu Oyingbo rèé, pásítọ̀ tó láṣẹ ìbálòpọ̀ lóri ọmọ ìjọ obìnrin Igbó mímu lè ṣe kóríyá, kò lé fi kún orín ẹnu òṣèré - 9ice Ìtàn tó wà nídi òwe ‘Sebótimọ Ẹlẹ́wà Sàpọ́n’ Ọba Adesoji Aderemi, Ọọ̀ni Ifẹ̀ tó gba ipò ọba mọ́ tòṣèlú Bẹẹ si ni awọn asọgbo to wa ni ọgba ẹranko Kruger, ti n sọ irinsi awọn kiniun naa, ki wọn ma baa seara abule ti wọn sa si lese.
"Kete ti ọba ba ti gori oye nilẹ Yoruba, ati ọ́pọ́ aṣẹ, ade ọba, irukẹrẹ lo ti di awọn nkan ami aṣẹ fun ọba alade naa eyi ti awọn eeyam si fi maa n pe wọn ni ""alaṣẹ ikeji oriṣa""."
Oun naa ṣalaye fun BBC Yorùbá pé ọwọ́ Oluwa ni gbogbo ẹ̀yà ara ẹ̀dá wà ati pe kò sí ohun ti Ọlọrun kò le ṣe.
Sugbọn mi o mọ pe igba ikẹhin ti ma a ri niyẹn.
Ó bá ọba dé odò Jọdani láti sìn ín kọjá odò náà.
Nígbà tí ẹgbẹrun ọdún bá parí a óo tú Satani sílẹ̀ ninu ẹ̀wọ̀n tí ó ti wà.
Òun kò bá wọn lóhùn sí ète tí wọ́n pa, ati ohun tí wọ́n ṣe sí Jesu.
Ó kó gbogbo ìṣúra tí ó wà ninu ilé OLUWA ati ti ààfin ọba pátá; gbogbo apata wúrà tí Solomoni ṣe ni ó kó lọ pẹlu.
Ẹni tí ó bá kórìíra eniyan,lè máa fi ọ̀rọ̀ ẹnu bo ara rẹ̀ láṣìírí,ṣugbọn ẹ̀tàn wà ninu rẹ̀,
pé lónìí ni n óo mú ìbúra tí mo búra fún ọ ní orúkọ OLUWA Ọlọrun Israẹli ṣẹ, pé, Solomoni, ọmọ rẹ ni yóo jọba lẹ́yìn mi.
Alaga ẹgbẹ TAMPAN, to jẹ agbarijọpọ awọn oṣere tiata, Alagba Bolaji Amusan, Mr Latin lo fi ikede naa sita lori ayelujara Instagram rẹ.
Koda wọn tun gbe iwọde wọn lọ si iwaju ile igbimọ aṣofin agba niluu Abuja.
O wá jẹ́ pé níwá lẹ́yín ni a rí àwọn tí wọ́n gbé àáké yìí.
Isẹ iwadiiGomina  Ambode ni ijoba yoo se
Ta ló jẹ́ máa tọ́jú aguntan láìmu ninu wàrà aguntan tí ó ń tọ́jú?
Orile ede Ghana ti ni eto isuna odun 2019 yoo din ni ida merin ninu ogorun un si idamerin aabo ti odun 2018.
Gẹgẹ bi awọn iroyin to gba oju opo ikansiraẹni Twitter ti wi, awọn ọmọ ologun oju omi, Nigerian Navy lo n le awọn eeyan naa kuro ni agbegbe ọhun to wa ni erekusu ipinlẹ Eko.
 wọn ní àkókò yẹn ni ìgbà tí àwọn hausa bẹ ̀ rẹ ̀ sí kó ara wọn jọ sí abẹ ́ àkóso ìlú síṣe .
Nibi idije ere ije agbaye to waye ni Japan loṣu to kọja, wọn ti sọ fun Naijiria pe wọn ti bẹgi dina wọn, wọn o ni ri owo kankan gba mọ, wọn yoo si dena Naijiria lati ma le kopa ninu awọn ere ije IAAF mọ lagbaye.
ohun alumọọni ohun lona ti awon eniyan yoo se jẹ anfaani ọhun.
Lẹ́yìn odi ìlú ni ìfúntí náà wà.
Bẹẹ si ni asise ni yoo jẹ fun mi ti n ko ba sọ ẹri oore ti Ọlọrun se fun mi yii fun araye, ki awọn eeyan to ni ọkan rere lee ba mi gbe orukọ Allah ga.
Orúkọ Heburoni tẹ́lẹ̀ ni Kiriati Ariba; Ariba yìí ni ẹni tí ó jẹ́ alágbára jùlọ ninu àwọn òmìrán tí à ń pè ní Anakimu.
Bákan náà ni ẹni tí ń búra ati ẹni tí ó takété sì ìbúra.
Alaga igbims awọn gomina ipinlẹ lorilẹede Naijiria to tun jẹ gomina ipinlẹ Ekiti, Ọmọwe Kayọde Fayẹmi lo sọ eyi di mimọ lẹyin ipade ori ayelujara tawọn gomina naa ṣe lọjọru.
Olugbo ni awọn eeyan ti oye ko ye lo n ro pe aawọ wa laarin oun ati Ọọni ile Ifẹ.
seyin labe asia egbe oselu Action Democratic Party, ADP sugbon ti o fidi rẹmi,
"Ó ní ""lásìkò tí òun bá ń kírun, kò ni sí ǹkankan lára òun bí ààbò, pé sùgbọ́n tí òun bá ti kírun tán, tí òun wọ agbáda òun padà, bí wọ́n bá kòjú òun kò sí ǹkan ti wọ́n le ṣe si, ǹkan kan ko le ràn òun."
OLUWA bá sọ fún Elija wolii ará Tiṣibe pé, 
 Ó gba oríyìn mímú ẹ ̀ yà orin yìí gbajúmọ ̀ padà èyí tí ó ti ń di ti àwọn mùsùlùmí ẹ ̀ yà yorùbà ayé àtijọ ́ .
Oríṣun àwòrán, Seyi Makinde Bakan naa, Alẹsinlọyẹ ni awọn tun n fẹ ki Buhari gba gomina Makinde nimọran, lati bọwọ fun ifẹ awọn ara ilu, ko si gba awọn gomina naa ni aaye lati sisẹ bii alaga ijọba ibilẹ tawọn eeyan dibo yan.
Èmi ni OLUWA Ọlọrun yín, tí ó ko yín jáde wá láti ilẹ̀ Ijipti, kí ẹ má baà ṣe ẹrú wọn mọ́.
Awon obinrin ohun tun ro  gbogbo ipele ijoba, lati se aleku isuna owo lori eto ogbin, ni iyanju ati mu igberu ba ipese ounje lorile-ede Naijiria.
 ( there is a reasonable prospect that his debts will be paid .
Ṣé ẹ óo yege bí ó bá dán yín wò?
Àkọlé àwòrán, Àgbálùmọ̀ Lawọn igberiko ni wọn ti maa n saba gbin agbalumọ laarin oṣu kejila ọdun si inu oṣu kẹrin ọdun tuntun lo maa n jade.
O wa ro awon omo orile-ede Naijiria lati lo anfaani akoko yii lati safihan ati amulo awon eko ti Jesu ko wa.
Idahun si ibeere yii pin si ọna meji.
Wọ́n gbé òkú rẹ̀ sórí ẹṣin wá sí Jerusalẹmu, wọ́n sì sin ín sinu ibojì àwọn ọba, ní ìlú Dafidi.
Níbi tí àwọn ará Filistia ti ń sá lọ, wọ́n gbàgbé àwọn oriṣa wọn sílẹ̀, Dafidi ati àwọn eniyan rẹ̀ sì kó wọn lọ.
 látìgbà yí ni ìwà ẹlẹ ́ yinjú-àánú ti bẹrẹ sí fi ara hàn nínú rẹ ̀ ní àkókò tí ọjọ ́ orí rẹ ̀ kò tíì tó ǹkan nítorí tí ó ń ran àwọn aláiní lọ ́ wọ ́ ní ìlú Ìpoti nípa bíbá wọn ṣe iṣé ọmọ-ilé láì gba owo ọ ̀ yà !
3 Nítorínáà, bí ẹ̀yin bá ní ìfẹ́ láti sin Ọlọ́run, a pè yìn sí iṣẹ́ náà;
O parowa sijoba atawon osise to yan iselodi lati jo fojusunnukun wo oro naa wo pe: “Asiko ti to ki iko mejeeji dide kidagbasoke to ye ko de ba eto ogbin lodun tuntun yii ki ebi ma pa ara ilu”.
”Aare wa gbosuba fun gomina ipinle Jigawa, Mohammed Badaru Abubakar fun igbese to n gbe lati tele ipa ti aare la sile nipa mimu idagbasoke ba ohun amayederun ati awon ora ajile to n pese fun  aon agbe lori ise oko won ,bo tile je pe owo to n wole sapo ipinle naa kere jojo.
"Ìgbéyawó yìí lárinrin Amọṣa, Pasuma ni ko si iye owo to lee mu oun lọ si Saudi Arabia lọ kọrin nitori 'ile adura ni' ""A maa n wa gba adura ni Saudi Arabia ni."
'' Ni ilu to lofin, to si ni Aarẹ to jọju, wọn yoo ti ba awọn eniyan sọrọ lati le tu wọn ninu lasiko rogbodiyan yii, amọ aarẹ ati igbakeji dakẹ, ti wọn si n woran.
O ni oun n wa awọn ile iwosan ti oun le fi ounjẹ ati iranwọ ranṣẹ si, titi ti oun yoo fi le ṣe nkan miran.
30 Agẹmo 2018 Oríṣun àwòrán, Fagoriola/facebook Àkọlé àwòrán, Ìròyìn tó tẹ BBC lọ́wọ́ sọ pé Fagoriola jẹ́ alága ní Akure North láàrín 2004/2007 lábẹ́ Gómiànà Olusẹ́gun Agagu Alága ijọba ìbílẹ̀ Aríwá Akure nígbà kan rí, ní ìpínlẹ̀ Ondo, Dele Fagoriola, tí di ẹni àwáti léyìn tí wọn tí jíi gbé nínú oko rẹ̀.
Ìwọ gan-an ni kí o ṣáájú wọn lọ sí ogun náà.
E̩nì kò̩ò̩kan tí a bá fi è̩sùn kàn ló ní è̩tó̩ tó dó̩gba, tó sì kún, láti s̩àlàyé ara rè̩ ní gban̄gba, níwájú ilé‐e̩jó̩ tí kò s̩ègbè, kí wo̩n lè s̩e ìpinnu lórí è̩tó̩ àti ojús̩e rè̩ nípa irú è̩sùn ò̩ràn dídá tí a fi kàn án.
Ofin igbeyawo ni Naijiria fun awọn ololufẹ ni anfani meji - yala igbeyawo ni ile ẹjọ tabi ni ile ijọsin.
EFCC: A fẹ́ mọ bí Saraki ṣe gb'owó osù gómìnà, ààrẹ ilẹ́ asòfin
Oríṣun àwòrán, @presidency Àkọlé àwòrán, Buhari gba lati san naira mẹtadinlọgbọn ní owó ọ̀yà òṣìṣẹ́ Naijiria.
Mc Oluọmọ wa pari ọrọ rẹ pẹlu nipa jijẹjẹ lati satilẹhin fun aarẹ ẹgbẹ awakọ ero lorilẹede yii, ọjọgbọn Tajudeen Ibikunle Baruwa.
Ipade yii tun mẹnu ba bi awọn eeyan ko ṣe tẹle awọn ofin ti ijọba la kalẹ lati dena arun yii.
Awọn agbofinro fẹsun kan awọn afurasi yii pe wọn lọwọ ninu ipaniyan to waye lagbegbe Akinyele ni ilu Ibadan.
Ni ọjọ kẹtadinlọgbọn oṣu kẹrin ni aarẹ Muhammadu Buhari paṣẹ konile o gbele eleyii to de igbokegbodo ọkọ laarin agogo mẹjọ alẹ si agogo mẹfa owurọ gẹgẹ bi ara ọna lati dena itankalẹ ajakalẹ orun COVID-19.
Laakotan, alekun ba iye oja ti awon onibara ra, ati eyi ti awon oludokowo ra ti won sit a je 384.
Ẹ fun fèrè ní Sioni,ẹ kéde ìdágìrì lórí òkè mímọ́ mi.
Àti àwọn ìbéèrè míràn Àwọn nǹkan tí obìnrin lè ṣe pẹ̀lú olólùfẹ́ oníwà ipá lásìkò ìgbélé Coronavirus yìí Owó ìtanràn N40,000 ni mo san nítorí pé mí ò wọ ìbòmú- Vincent Ǹjẹ́ òògùn vitamin C lè pa coronavirus?
2 Sẹ́rẹ́ 2021 Oríṣun àwòrán, PSG Lẹyin ọ rẹyin, Mauricio Pochettino di akọnimọọgba tuntun fẹgbẹ agbabọọlu Paris St-Germain(PSG).
“Ṣugbọn gbogbo ẹran tí ó bá ti jẹ́ àkọ́bí, ti OLUWA ni, ẹnikẹ́ni kò ṣẹ̀ṣẹ̀ tún ní yà á sọ́tọ̀ mọ́; kì báà jẹ́ mààlúù tabi aguntan, ti OLUWA ni.
Bi Cyril Ramaphosa ti di aarẹ South Africa Olootu ijọba Ethiopia kọwe fipo silẹ Assaju rẹ ni ipo aarẹ, Jacob Zuma, fi ipo silẹ ni ọjọru lẹyin igba ti ẹgbẹ ANC ton s'akoso orilẹede naa ko ni papa mọra.
"Oríṣun àwòrán, queenola2 Instagram ""Ti mo ba sọ itan igbesi aye mi fun yin, o seese kẹ ba mi sọkun, o si ti wa ye mi bayii pe gbogbo ohun to n dan kọ ni wura, sugbọn Alihamdulilahi, mo ti ri iwosan ọkan."
Ex Boko Haram: Àwa ọmọ ẹgbẹ́ Boko Haram kan kìí kírun, à ń mu ìmukúmu, a sì ń ṣe ṣìná
"Ẹ̀yin tí ẹ kò gbọ́ Yorùbá, ẹ ṣúnmọ́ bí láti kọ́ lítíréṣọ̀ èdè Yorùbá lórí BBC Ẹ wá dánrawò níbí pẹ̀lú Àpólà Ọ̀rọ̀ Orúkọ, ""Noun Phrase"" Ọdún mẹ́ta lẹ́yìn Adebayo Faleti, ìran Yorùbá ń ṣe ilédè rẹ!"
O ni laipe yi ni Naijiria ati China buwọlu iwe adehun lati fikun ise lori ọkọ oju irin ti wọn sẹsẹ se ati lori ètò ìbáraẹnisọ̀rọ̀ àti ìmọ̀ ẹ̀rọ.
Ìwífúnni fún àwọn àkọlé ìpín ni a ti mú láti inú Àfọwọ́kọ Ìwé Ìtàn Ìjọ àti History of the Church (Ìwé Ìtàn Ìjọ́) títẹ̀jáde (lápapọ̀ tí a ntọ́ka sí nínú àwọn àkọlé bíi ìtàn ti Joseph Smith) àti Joseph Smith Papers (Àwọn awẹ́ ìwé Joseph Smith).
O rọ̀ àwọn ọlọpàá láti gbé ọmọ oun lọ si ilé ọmọ alaini iya titi àwọn ẹbi òun yóò fi wá gbé e àti pé òun kò fẹ́ kí ọmọ náà wà lọ́dọ̀ ẹbi Arinze nítori wọn o fi ìya jẹ ẹ́.
Ilé Iṣẹ́ BBC ti kan si Busy Bee fun ọ̀rọ̀ lẹnu wọ́n Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí DR Congo: Military plane crash don kill 12 people30 Owewe 2017 Ivory Coast: Plane wey carry load crash enter sea, kill 414 Ọ̀wàrà 2017 Mexico plane crash: How 103 passengers take survive1 Ògún 2018 Iran: Plane crash don kill 66 people18 Èrèlè 2018 Cuba plane crash kill pass 10019 Èbibi 2018 Algeria military plane crash: 257 pipo don die near Algiers11 Ìgbé 2018 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Ẹ̀ṣọ́ NSCDC ṣèèṣì yìnbọ̀n pa ọlọ́pàá ọ̀tẹlẹ̀múyẹ́ DSS l'Osun MC Murphy ko sọ òótọ́ ọ̀rọ̀ to wà níbẹ̀, tó ba wùú kó sọ òótọ- Adebayọ Bakan naa ni ọga ọlọpaa tun paṣẹ pe ọlọpaa kankan ko gbọdọ mu ẹnikẹni nigba ti o ba wọ aṣọ ile.
 won gba pe awon oludaniloro na fe fi lo kolu boya kapitol ( ile to je ti igbimo asofin orile-ede amerika ) tabi white house .
Gbọ́ ọ̀rọ̀ OLUWA nisinsinyii, ṣé o ní kí n má sọ àsọtẹ́lẹ̀ fún àwọn ọmọ Israẹli mọ́, kí n má sì waasu fún àwọn ọmọ Isaaki mọ́?
idibo naa se lọ ni irọwọ ati irọsẹ laijẹ pe o mu itajẹsilẹ dani, bo tilẹ je pe,
Akowe agba tun tesiwaju pe , “Laifi
By Peter Mwai and Christopher Giles BBC Reality Check 9 Agẹmo 2020 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Báwo ló ṣe n tànkálẹ̀ l'Afrika?
Ẹsẹ̀ rẹ̀ dàbí òpó alabasitatí a gbé ka orí ìtẹ́lẹ̀ wúrà.
Ẹ̀jẹ̀ tí ẹ bá fi kun àtẹ́rígbà ìlẹ̀kùn gbogbo ilé yín ni yóo jẹ́ àmì láti fi gbogbo ibi tí ẹ bá wà hàn.
Oòrùn ati òṣùpá ti ṣókùnkùn,àwọn ìràwọ̀ kò sì tan ìmọ́lẹ̀ mọ́.
Oríṣun àwòrán, leadership Àkọlé àwòrán, Ọjọ keje oṣu kẹwa ọdun 2018 ni alagba Moses Adejumọ ti ọpọ eeyan mọ si baba sala jade laye Ko si eeyan to lee kọ iyan Baba sala kere lagbo orin, itan kikọ, ere itage ati sinima paapaa julọ ka pani lẹrin.
Aare ro awon omo orile ede Naijiria lati je oju –lalakan-fi-n-sori, ki won si ri I pe won yan awon to ni ife orile ede yii lokan , lasiko idibo 2019 to n bo.
“Mo tún sọ fun yín pé bí ẹni meji ninu yín bá fi ohùn ṣọ̀kan ní ayé nípa ohunkohun tí wọn bá bèèrè, bẹ́ẹ̀ ni yóo rí fún wọn láti ọ̀dọ̀ Baba mi tí ń bẹ lọ́run.
Morocco: Aṣa, Oju Ọjọ ati awọn ohun amuyẹ ilu yii jẹ ko jẹ ibi aayo fun awọn ololufẹ.
Lẹsẹkẹsẹ bí ó ti dé ọ̀dọ̀ Jesu, ó ní, “Ẹ pẹ̀lẹ́ o, Olùkọ́ni.
Abenugan ile igbimo asofin tele ri, asofin Ken Nnamani ti bu enu ate lu awon oloselu ti won so ipo di tipa-tikuu-ku, O wa ro won lati wa ise miiran se.
Buhari gbe igbimọ kalẹ lori okoowo Afrika Èrè ńlá ńbẹ fáwọn obìnrin nínú okoòwò ọ̀fẹ́ ní Áfíríkà Aarẹ Muhammadu Buhari ati Aarẹ Patrice Talon ti Benin, ni wọn fi ọwọ si iwe adehun naa loju awọn olori orilẹ-ede to ku ni olu ilu Niger, Niamey nibi ti wọn yoo kọ ibudo ọrọ aje naa si.
Ngige ni iṣẹ́ n lọ lọ́wọ́ lórí ǹkan ti ASUU n bèèrè 'Kò sí ǹkan tí o kò lè ṣe tóo bá ní àfojúsùn' O gba awọn eniyan nimọran lati dide ṣe ohunkohun to ba wu wọn lati ṣe lai naani ìdíwọ́ to ba yọju.
Wọ́n gbọdọ̀ pa àwọn òfin ati ìlànà mi mọ́ lákòókò gbogbo àṣàyàn àjọ̀dún wọn, wọ́n sì gbọdọ̀ ya ọjọ́ ìsinmi mi sí mímọ́.
Ni ọjọru ni ile ẹjọ naa sun igbẹjọ rẹ si lati sọrọ lori boya ki wọn fun un laye lati gba oniduro tabi ki wọn ṣi fi si ahamọ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Osun Supreme: Àwọn èèyàn Ọṣun rọ Oyetọla láti jẹ́ kí àsìkò rẹ̀ tú aráàlú lára Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
ǹ bá sọ gbogbo ìgbésẹ̀ mi fún Ọlọrun,ǹ bá bá a sọ̀rọ̀ bí ìjòyè.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Oyo: Bisi Ilaka ní ìdìbò àwọn alága ìjọba ìbílẹ̀ lòdì sófin 31 Èbibi 2019 Oríṣun àwòrán, Oyo State Government Ijọba Ipinlẹ Oyo ti salaye idi abajọ ti Gomina Ṣeyi Makinde fi paṣe wi pe, ki gbogbo awọn alaga ijọba ibilẹ nipinlẹ naa fi ipo wọn silẹ ni kiakia.
 O tun je ohun iwuri fun mi, lati ri pe awa alawo dudu mu lohun okunkundun lati gba ohun otun igbalode ni ona lati mu idagbasoke ba boolu afesegba.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Baby abandoned on dunmpsite: Mo ti bímọ mẹ́rin tẹ́lẹ̀ fún bàbá méjì nínú òṣí- Dupe Ogbomos Itan yii ko tii tan sibẹ, a gbọ pe wọn gbe ori ọba Olajide Olayode atawọn ẹya ara rẹ yoku sọwọ, wọn n jo yika ilu pẹlu ẹjẹ bala-bala ati orin eebu, ti gbogbo ilu Ogbomoso si daru lọjọ naa.
OLUWA sì fi ibinu ńlá ati ìrúnú lé wọn kúrò lórí ilẹ̀ wọn, ó sì fọ́n wọn dà sórí ilẹ̀ mìíràn gẹ́gẹ́ bí ó ti rí lónìí.
Coronavirus in Kenya: Ojú òpó Facebook Live ni mo ti wo ìsìnkú ìbátan mi Ọjọ́ Satide ni ìgbà àkọ́kọ́ tí ènìyan 553 yóò kó àrùn Coronavirus léékan naa ní Naijiria A n ti n reti rẹ ko pada sile lọjọ naa nitori pe o ti n to bi aago mẹfa irọlẹ.
''Lọwọlọwọ bayi, ajọ Waec to n seto idanwo fawọn to fẹ jade ileewe girama kan sun ọjọ idanwo siwaju ni,wọn ko wọgile.
Ilé ẹrù míì tó jábọ́ l‘Eko tún mú ẹ̀mí obìnrin méjì lọ Àwọn ọmọ orílẹ̀èdè Mali ń fò fáyọ̀ pé ológun gba ìjọba mọ́ alágbádá lọ́wọ́ Ìròyìn ayọ̀!
Irọ́ ni ọ́lọ́pàá npa nípa Dino
tun ni, Gomina ile ifowopamo agba(Central Bank of Nigeria), oludari agba fun
Oríṣun àwòrán, @anaedoonline A gbọ pe aye nira fun wọn nibẹ to bẹẹ ti wọn fi n ra lita epo pẹtirolu kan ni ẹgbẹta naira.
Minisita fun eto iroyin at aṣa, Lai Mohammed lo kede bẹẹ nibi ipade awọn akọroyin kan to waye ni ilu Abuja.
alafia mule, ki won si pese eto aabo to peye lasiko idibo, bee si ni o sekilo
Bi o tilẹ jẹ pe arun Coronavirus bẹ jiga saarin agbaye ninu ọdun 2020, amọ ko daju pe ojisẹ Ọlọrun kankan sọ asọtẹlẹ nipa rẹ, lati mu kawọn eeyan gbaradi fun.
Lẹ́yìn náà, ó mú mi lọ sí ìloro tẹmpili, ó sì wọn àtẹ́rígbà rẹ̀.
Idi ni pe awọn oluwọde yika orilẹede yii, to n beere fun opin ọlọpaa SARS, ni wọn gbe igi dana lawọn opopona ati papakọ ofurufu.
Ilé ẹjọ́ dájọ́ ikú fún èèyàn mẹ́ta nítorí ikú akẹ́kọ̀ọ́ fásitì UNIOSUN Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí kan sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ilé aṣòfin Ekiti ní kí àwọn alága ìjọba ìbílẹ̀ dá N3.
Boko Haram: Ọwọ́ iléeṣẹ́ ológun tẹ afurasí tó pa akẹẹgbẹ́ rẹ̀
Oyun to ni ṣẹṣẹ pe oṣu mẹrin nigba ti iṣẹlẹ naa waye ni.
O ṣalaye nipa obinrin kan ti ọkọ rẹ ti di awati lati nnkan bi ọdun mẹsan an sẹyin, ṣugbọn lẹyin ti ajọ to gbe kalẹ ṣabẹwo si obinrin ọhun, ti wọn kọ ọ niṣẹ ọwọ, igbe aye rẹ ti yipada, Oríṣun àwòrán, NIGERIAN ARMY Adeeko ni iru awọn iriri bayii lo maa n dun oun ninu, to si maa n ru oun soke lati tẹsiwaju nipa ṣiṣe iranlọwọ fun awọn eeyan naa.
Bi idibo ba ti tan, o ni ibudo kan ṣoṣo ti wọn yoo ko gbogbo ẹ lọ.
Lẹyin eyi ni Mọ̀mí-n-mọ̀ọ́ laarin ẹbi mejeeji kó tó kan ìdána.
"O ni ""a ti mu afurasi ọgọrin a si ti bẹrẹ iwadi lori wọn, a fun gbogbo awọn to ji ẹru ẹlẹru ko labẹ asia iwọde EndSARS ni wakati mẹrinlelogun lati da awọn ẹru naa pada tabi ki wọn foju wina ofin."
OLUWA dáhùn pé, “Ǹjẹ́ abiyamọ le gbàgbé ọmọ tí ń fún lọ́mú?
Ipinlẹ Eko lo ni eniyan to poju pẹlu eniyan 188 ni Ojo Aiku nikan soso.
INEC: Èsì ìdìbò Ekiti lẹ́kùnrẹ́rẹ́ NURTW Ekiti fẹgba yọ àwọn adarí kúrò ní gáréèjì!
Kọmiṣọnna oko-owoỌgbẹni Agbaje wahab lo jẹ kọmiṣọnna fun ile iṣẹ ijọba to n ri si ọrọ oko owo.
Ẹ̀wẹ̀, ìgbìmọ̀ tí ẹgbẹ́ kó jọ yìí sọ pé yéké yéké ni àwọn párí iṣẹ́ àwọn, gbogbo ìgbìmọ̀ fọ́wọ́ sí i láì sí àtakò kànkàn.
Agbekoya: Bí a bá na oògùn abẹnugọ̀ngọ̀ s'ókè, ìjínigbé á d'ópin!
Ọjọgbọn Balarabe Maikaba Ọjọgbọn Maikaba jade laye ni ọjọ Aiku, ọjọ kẹrindinlọgbọn oṣu kẹrin ọdun 2020 lẹyin ti aisan iba daa wolẹ fun ọjọ diẹ, gẹgẹ bi iroyin ti a gbọ ṣe sọ ṣugbọn ni o ni aisan itọ ṣuga tẹlẹ.
Alaga igbimọ naa, Boss Mustapha sọ eyi o si tun pe akiyesi si ọrọ awọn ara orilẹede meji kan ti wọn gbamu to yọ wọ Naijiria o si gboriyin fun ileeṣẹ to n ri si iwọle wode ni Naijiria fun iṣẹ takun takun.
" Bakan naa ni Gomina ipinlẹ Eko tun kan saara si ẹka idajọ fun idasilẹ asayan ileẹjọ to n gbọ ẹsun to rọ mọ iwa ibanilo lọna ti ko tọ.
” Ni Peteru bá sọ̀kalẹ̀ ninu ọkọ̀, ó rìn lójú omi lọ sọ́dọ̀ Jesu.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Minimum Wage: Ẹgbẹ́ àwọn òṣìṣẹ́ TUC fárígá sí ìjọba Naijiria lórí owó oṣù tuntun 17 Agẹmo 2019 Oríṣun àwòrán, others Àkọlé àwòrán, ẹgbẹ oṣiṣe yari fun ijọba Naijiria Laarin oṣu karun un ọdun 2019 ni ijọba Naijiria gbe igbimọ kan kalẹ lati mojuto ọrọ afikun owo oṣu awọn oṣiṣẹ.
Kóòdì USSD yìí wà fún àwọ oníbàárà MTN, Glo, Airtel ati 9mobile.
O ni, 'ko si aṣa tabi ẹsin to faye gba gbigba ẹmi.
O lọ si ileewe Birch Freeman High school Lagos ati Igbobi College ni ilu Eko ki o to gba fasiti Benin lọ lati kawe gba imọ ijinlẹ ninu ẹkọ ofin lọdun 1987.
Gbogbo igi igbó Lẹbanoni kò tó fún iná ẹbọ,bẹ́ẹ̀ ni ẹranko ibẹ̀ kò tó fún ẹbọ sísun.
Àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ wá sọ́dọ̀ rẹ̀, wọ́n sọ pé, “Ṣe àlàyé òwe èpò inú oko fún wa.
Arabirin kan, Esther ṣalaye fun akọroyin wa pe Ti eeyan ba wa ninu igbeyawo oni jagidijagan, awọn iwa ipa naa ma n wa lemọ lemọ ni, bii eebu ati ilu bara."
Ajọ LASTMA ti ri i, a si ti bẹrẹ iwadii.
Ranti ẹlẹ́dàá rẹ ní ìgbà èwe rẹ, kí ọjọ́ ibi tó dé, kí ọjọ́ ogbó rẹ tó súnmọ́ etílé, nígbà tí o óo wí pé, “N kò ní inú dídùn ninu wọn.
ní àkọ ́ kọ ́ , a bí gama ní àsìkò tí àwọn àyípadà kan bẹ ̀ rẹ ̀ sí í dé sí brazil léyìn tí brazil yọ kúrò ní oko ẹrú ( 1840-1889 ) .
Bi awọn kan ṣe n fi sita pe sisa to salọ ko ṣẹyin ọga ọlọpaa kan, lawọn mii n ni ile iya iya/baba rẹ ni wọn ti pada ri i mu ṣugbọn a o tii le fidi eleyii mulẹ.
Kò sí ẹni ti wọ́n fi dandan mú láti ṣe ohunkóhun, sùgbọ́n gbogbo ọmọ ti Peller fi sílẹ̀ ló ṣe dáadáa.
Ọ̀pọ̀ àwọn ọlólùfẹ́ Teni lórí àtẹjiṣẹ́ twitter lo ti n yin Tẹ́ni pàápàá jùlọ lóri ìmúra rẹ lásikò to ba n ṣe àyẹyẹ orin àti ní gbogbo ìgbà.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Sugbọn laipẹ yii ni ọkunrin akọrin kan, August Alsina, tii se ẹni ọdun mẹtadinlọgbọn, sọ loju opo Facebook rẹ pe, oun ati osere tiata lobinrin naa, Jada Pinkett Smith jọ ni ajọsepọ ri .
#StopRobbingUs ni wọn n lo lati fi fi ẹhọnu wọn han lori ẹrọ ayelujara lori bi awọn ọlọpaa se n na wọn, ti wọn si n gba owo ni ọwọ wọn lọna aitọ.
Kí ìran rẹ̀ run,kí orúkọ rẹ̀ parẹ́ lórí àwọn ọmọ rẹ̀.
O sọ pe oun kuro ninu ẹgbẹ naa lati faaye gba alaafia ni.
N kò lẹ́bi pé ejò kó ₦36m owó àjọ JAMB mì -Philomina NURTW l‘Abuja yóò kàn sí Makinde láìpẹ́ lórí bó ṣe fòfin dè wá l‘Ọyọ - Ejiogbe Kíni N11trn owó ìrànwọ́ epo tí ìjọba àpapọ̀ san fún àwọn agbépo lè rà?
Nítorí náà, ọba ranṣẹ pe Jehoiada tí ó jẹ́ olórí wọn, ó bèèrè lọ́wọ́ rẹ̀ pé: “Kí ló dé tí ẹ kò fi jẹ́ kí àwọn ọmọ Lefi lọ máa gba owó fún àgọ́ ẹ̀rí lọ́wọ́ àwọn eniyan Juda ati Jerusalẹmu bí Mose, iranṣẹ OLUWA, ti pa á láṣẹ?
Igbakeji Aare orile-ede Ghanaso pe, ijoba yoo se odiwon goolu ti won n ko lo sile-okeere, gege bi akitiyan lati gbe igbese ti o nipon lori eka naa, ati lati ri daju pe, orile-ede ohun n gba eto re loore-kooreAkosile ile-ifowopamo agba lorile-ede Ghana safihan pe, orile-ede naa, ti o je orile-ede keji ti o tobi ju nipa ohun alumoni iwakusa goolu nile-Africa, leyin orile-ede South Africa, n ri owo ti iye re to billion 5.
Wọn yóo rọ́ kún gbogbo ààfin rẹ ati ilé gbogbo àwọn ẹmẹ̀wà rẹ ati ilé gbogbo àwọn ará Ijipti, àwọn eṣú náà yóo burú ju ohunkohun tí àwọn baba ati àwọn baba ńlá yín ti rí rí lọ, láti ọjọ́ tí wọ́n ti dáyé títí di òní olónìí.
Ọdun 2005 ni Boko Haram dara pọ mọ IS nigba ti Abu Musab jẹ agbẹnusọ.
Awọn ìlà àyẹwò míiràn: Editorial Guidelines - Mandatory referrals Editorial Guidelines - Gathering material Editorial Guidelines on user contributions in news output Àwọn àbọ̀ tó ṣe siṣẹ́ lé lórí: A ṣe àgbékalẹ̀ ìlànà tí BBC ńgba láti moju to aríwisi awọn alábàra wọ́n BBC Complaints Framework.
Adájọ́ pàṣẹ kí wọ́n fi ọlọ́pàá tó lọ́wọ́ nínú ikú Kolade Johnson sí àhámọ́ Kini ọ̀nà àbáyọ sí ooru tó mú lásìkò yìí ní Nàìjíríà?
ijamba ile riri je ohun ti o maa n sele lopolopo lorile-ede Indonesia, eleyi ti
Iná Èkó: Kò sí ẹni to le dá okú rẹ mọ̀
O ni oun ko tii mọ ẹgbẹ agbabọọlu tuntun ti oun yoo maa tẹ le bayii, ṣugbọn o ti tan laarin oun ati Arsenal.
Bí wọ́n ti ń lọ ninu ìrìn àjò wọn, Jesu wọ inú abúlé kan.
Ninu ifọrọwerọ kan ti Kabiyesi Alaafin ṣe pẹlu iwe iroyin abẹle kan ni ọdun diẹ sẹyin, Ọba Layiwọla ṣalaye pe 'Emi kọ ni mo dẹnu ifẹ kọ eyikeyi ninu awọn olori mi.
'Ìṣòro àìrílégbé ló burú jùlọ nínú ìṣòro ẹ̀dá láyé' Kí ló dé táwọn ọ̀dọ́ dìbò 140m fún BBNaija àmọ́ tí ìbò ààrẹ Nàíjíríà jẹ́ 28m?
Nígbà tí wọ́n bá wọlé dé, ilẹ̀ á ti mọ́n tóní-tóní.
aserbaijan ní ètò ìkànìyàn 1995 , àwọn tí ó ń sọ èdè yìí jẹ ́ mílíọ ̀ nù méjè àbọ ̀ .
Kì í ṣe fún àwọn tí ó gba ètò ti Òfin nìkan, bíkòṣe fún ẹni tí ó bá ní irú igbagbọ tí Abrahamu ẹni tí ó jẹ́ baba fún gbogbo wa ní.
Ilú rò wi pé Ìjọba Alágbádá yio ni àánú ilú ju Ìjọba Ológun lọ.
Kí ni ẹ rò tí ẹ fi ń tẹ àwọn eniyan mi ní àtẹ̀rẹ́,tí ẹ̀ ń fi ojú àwọn talaka gbolẹ̀?
Ẹni ti kò hùwà èké wọn a wi pe olúwaarẹ̀ ń hùwà èké títí onítọhun á fi pinnu lọ́kàn rẹ̀ pé, níwọ̀n ìgbà tí ọmọ aráyé ti wí pé òun ṣe ǹkan tí òun kò ṣe, ó yẹ kí òuun kúkú ṣe bẹ́ẹ̀ dandan – eléyìí jẹ́ ọ̀kan pàtàkì nínú ìpilẹ̀ṣẹ̀ ìṣubú fún àwọn ọmọ tí Olódùmarè dá sí orí ilẹ̀ ayé.
Iko agbaboolu Super Eagles bere igbaradi ni kikun saaju ifigagbaga keyin pelu iko agbaboolu orile-ede Argentina, eleyi ti o safihan bi iko ohun yoo ba tesiwaju fun ipele ti o kan ninu idije agbaye to n lol owo ohun lorle-ede Russia.
Ogbeni Ayariga soro yii, nigba to  n dahun awon ibeere kan to jade lasiko ijiroro nile igbimo asofin  ajo ECOWAS to wa niluu Abuja.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ronke Oṣodi: òótọ́ ọ̀rọ̀ máa ń korò gan ni f'áwa èèyàn Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Sàká: Oun ti orí bá yàn fún ẹ̀dá ni kó ṣe Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Nigba ti awọn eeyan kọkọ ri oku ọrẹbinyin ọmọ ologun ọhun, wọn ṣebi ọkunrin naa lo ṣekupa ni lai mọ pe ọmọ ọdọ ọhun ti pa jagunjagun naa ṣaaju.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Australia: Igbe ayekòótọ́ sàànfàní, ó kó olówó rẹ̀ yọ lọ́wọ́ ikú gbígbóná 3 Bélú 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 4 Bélú 2020 Oríṣun àwòrán, NATIONAL GEOGRAPHIC SOCIETY Arakunrin ọmọ Australia kan ti f'orin ọpẹ bẹnu lẹyin ti ayekootọ rẹ ko yọ lọwọ ina to sadede ṣeyọ nile rẹ laarin oru.
Àkọlé àwòrán, Ẹru to n ba wọn nisinyi ni ikọlu tuntun to ṣẹlẹ lọjọ Aiku, ọjọ ajinde to kọja.
Awọn ajafẹtọ ni idajọ otitọ gbọdọ leke lori iku Richard Gbadebo lẹnu iṣẹ, ki awọn ijọba ati awọn ileeṣẹ kaakiri Naijiria ba le kọ ẹkọ wi pe ẹmi awọn oṣiṣẹ ṣe iyebiye.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Segalink:ìkùnsínú pọ̀ láàrin àwọn agbófinró bẹ́ẹ̀ wọn kò ni agbẹnusọ Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Atamatase ohun fi otoo oro naa mule nirole ojoRu(Wednesday, leyin ti o fi aworan omo kekere re sori ero ayelujra pelu oro idagbere si boolu afesegba.
    Ìgbà tí a dé ọ̀hùn, a bá ara wa nínú ààfin ńlá kan tí ó dára tó bẹ́ẹ̀ tí kò sí ọ̀rọ̀ láti fi sàpèjúwe ibẹ̀, àṣé ilé rẹ̀ ni èyí nì.
Nígbà tí ọba rọ̀gbọ̀kú lórí ìjókòó rẹ̀,turari mi ń tú òórùn dídùn jáde.
June 12: Buhari yóò la ọ̀na 2,000 kìlómítà, èèyàn 100 yóò yọ nínú òṣì
Kò sí ohun tí ó ṣòro lọ́wọ́ Ìwọ Ọlọ́run Ọba, kò sí ìbànújẹ́ tí ó dé bá ọmọ ènìyàn tí ìwọ kò lè kó ènìyyàn yọ.
Ṣebí kìí ṣ'owó ìjọba O ni ''eelo ni gbogbo owo naa (41.
Àwọn Olúkọ ìpínlẹ̀ Oyo fakọyọ lórí ètò Akọ́mọlédè àti Àṣà púpọ̀ Wo bí ilé ìwòsàn LUTH ṣe ń gba owó ibùsùn lọ́wọ́ àwọn aláìsàn, tí àwọn míràn sì ń sun ìta 'Àwọn agbébọn tó pá Olufon ti Ifon ti ṣe ohun èèwọ̀ ní ilẹ̀ Yoruba' Látilẹ̀ ni mo ti fẹ́ràn orin ìjọ Kérúbù àmọ́ ẹlẹ́sìn mùsùlùmí àti krìstẹ́nì ni mí- Qdot Rògbòdìyàn bẹ́ sílẹ̀ láàrin àwọn ọlọ́kadà àti àwọn òṣìṣẹ́ ọgbà ẹ̀wọ̀n ní Ibadan - Ẹnu ọna iloro fun awọn to n fi ẹsẹ rin loju popo.
Ó kọ́kọ́ lo agbára yìí láàrin àwọn Juu, lẹ́yìn náà ó lò ó láàrin àwọn Giriki.
 Bashir Magashi (rtd) – Kano, Minisita fun eto aabo (Defence) márùndínlọ́gbọ̀n ) Hadi Sirika – Katsina,  Minisita fun eto irinna oju ofurufu(Aviation) mẹ́rìndínlọ́gbọ̀n ) Abubakar Malami – Kebbi, Agbẹjọro agba ati minisita fun eto idajọ (HAGF and Minister of Justice) mẹ́tàdínlọ́gbọ̀n) Ramatu Tijani Aliyu – Kogi, Minisita abẹle fun olu ilu orilẹede Naijiria, FCT, State méjídínlọ́gbọ̀n) Lai Mohammed – Kwara, Minisita feto iroyin ati aṣa(Information and Culture) mọ́kàndínlọ́gbọ̀n) Gbemisola Saraki – Kwara, Minisita abẹle fun igbokegbodo ọkọ(Transportation), State  ọgbọ̀n ) Babatunde Raji Fashola – Lagos, Minisita fun iṣẹ ode ati ile gbigbe(Works and Housing) mọ́kànlélọ́gbọ̀n ) Adeleke Mamora – Lagos, Minisita abẹle fun eto ilera(Health), State méjílélọ́gbọ̀n ) Mohammed A.
Lai Mohammed: A ti gba 800 bílíọ̀nù padà lọ́wọ́ àwọn tó jíi kó, àwọn 1,400 ti dèrò ẹ̀wọ̀n
Federal Cabinet: Onímọ̀ ní ewu ń bẹ lórí bí ìsàkóso ìjọba ṣe dúró rigidi
Wọ́n fi idà pa gbogbo wọn patapata bí wọ́n ti ṣe pa àwọn ará Libina.
 níbẹ ̀ ni odùduwà ti rí omi tí ó tẹ ́ jú lọ , ó sọ adìye yìí sí orí omi yìí , adìyẹ yìí sì bẹ ̀ rẹ ̀ sí tan yanrìn náà títí .
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Eid-il Kabir: Iléẹjọ́ f'òfin de Oluwo pé kò gbọdọ̀ darí ìrun ní 'EID' lọ́dún Iléyá 10 Ògún 2019 Oríṣun àwòrán, Facebook/Emperor Abdulrasheed Adewale Akanbi Àkọlé àwòrán, Ọrọ aṣẹ ileẹjọ Ileẹjọ giga ipinlẹ Oṣun ti paṣẹ pe Ọba Oluwo ti ilẹ Iwo, Oba AbdulRasheed Adewale Akanbi ko gbọdọ irun Jimọh tabi ayẹyẹ ọdun Sallah ati ayẹyẹ ọdun musulumi kankan niluu Iwo.
Ọmọge Campus: Arẹwà obìnrin àti àwọn àwòrán rẹ̀ Àdó olóró parí ọdún ìtúnu àwẹ̀ Ramadan Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Lórí ìgbéyàwó mi, ẹ̀ ṣáà jẹ́ kó wà báyìí' Òsèré Yorùbá, Ẹniọla Badmus ti fara hàn nínú ọ̀pọ̀lọpọ̀ sinimá àgbéléwò Yorùbà tó fi mọ́ àwọn fíìmù tí wọn se lédè gẹ̀ẹ́sì.
Saaju eyi ni, minisita ti kan si gomina ipinle Kwara Abdulfatah Ahmed ati komisona awon agbofinro, Lawan Ado  lati ba won kedun ni ipinle naa.
Òun ni OLUWA Ọlọrun wa,ìdájọ́ rẹ̀ ká gbogbo ayé.
Awọn ipinlẹ kan nilẹ kaarọ o jiire ti wọgile ìsìn yi patapata lọdọ wọn.
Ọ̀tọ̀ ni ẹran-ara eniyan, ọ̀tọ̀ ni ti ẹranko, ọ̀tọ̀ ni ti ẹyẹ, ọ̀tọ̀ ni ti ẹja.
Koda, awọn iroyin, aworan ati fidio to jinna sootọ nipa isẹlẹ Lekki lo lu ori ayelujara kan, eyi to mu ko fẹ lọwọ iwa ẹlẹyamẹya ninu bayii.
Ṣugbọn bí ibi tí ó wú náà bá bẹ̀rẹ̀ sí tàn káàkiri ní ara rẹ̀, lẹ́yìn tí ó fi ara rẹ̀ han alufaa fún ìwẹ̀nùmọ́, kí ó tún pada lọ fi ara han alufaa.
ni  Abakaliki lonii yii to jẹ ọjọ Abamẹta.
Oríṣun àwòrán, AFP Ṣáájú áti lẹ́yìn ìforúkọsílẹ̀ N-Power, ohun tó yẹ kóo mọ̀ rèé o!
Abajade iwadii wa re e: Gẹgẹ bi Cynthia Fogoe, onimọ nipa ibalopọ ṣe sọ, fifun ara ẹni ni adun tabi itẹlọrun ibalopọ, ni iwulo to n ṣe fun ara.
Ẹ óo fi òbúkọ kan rú ẹbọ ìmúkúrò ẹ̀ṣẹ̀, ẹ óo sì fi àgbò meji ọlọ́dún kọ̀ọ̀kan rú ẹbọ alaafia.
7 418 Orilẹede Tanzania 21 0.
Ṣugbọn ẹ kò gbọdọ̀ dúró níbẹ̀, ẹ máa lé àwọn ọ̀tá yín lọ, kí ẹ máa pa wọ́n láti ẹ̀yìn.
“Nítorí náà, bí mo bá pada dé ọ̀dọ̀ baba mi tí n kò sì mú ọmọdekunrin náà lọ́wọ́, níwọ̀n ìgbà tí ó jẹ́ pé ọmọdekunrin yìí gan-an ni ó fi ẹ̀mí tẹ̀, 
Ṣùgbọ́n ọpọ ṣi gbagbọ pe ẹlẹsẹ ayo Cristiano Ronaldo ni ami ẹyẹ Ballon D'or 2018 tọ si lẹyin to gba ife ẹyẹ UEFA Champions League pẹlu Real Madrid ko to darapọ mọ ikọ Juventus.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Biafra at 50: Ó tó mílíọ̀nù mẹ́ta èèyàn tó bá ogun náà lọ 15 Sẹ́rẹ́ 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 6 Agẹmo 2020 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ọgagun Odumegwu Ojukwu n sọrọ nibi ipade alaafia laarin Biafra ati Naijiria.
Iṣẹlẹ naa lo waye lọjọ keji oṣu kini nile oloogbe to wa ni adugbo Kinkinau nipinlẹ Kaduna.
Ìlú kan náà ni ó ti lọ ilé ìwé girama.
Anna le sọ ede Ilẹ Geesi ati Faranse daradara.
N ó parí ìwé ti eléyìí nísisì yìí, kí Ọlọ́run dá ẹ̀rú sí, a o tún máa gbúròó ara wa ní ọjọ́ mìíràn.
Koda, nigba ti iroyin awọn ọmọ Nigeria to ha sorilẹede Libya gbode, ileesẹ ti wọn gbe isẹ kiko awọn ọmọ Nigeria wale lati orilẹede Libya le lọwọ, mọọmọ kan si wa lati fun wa ni ẹkunrẹrẹ iroyin nipa iriri awọn ọmọ Nigeria, bẹrẹ lati akoko ti wọn n gbera lati orilẹede yi lọ si Libya, titi de igba ti wọn pada de.
Saulu pàṣẹ fún àwọn iranṣẹ rẹ̀ pé, “Ẹ lọ bá Dafidi sọ̀rọ̀ ní ìkọ̀kọ̀ pé, inú ọba dùn sí i lọpọlọpọ, ati pé gbogbo àwọn iranṣẹ ọba fẹ́ràn rẹ̀, nítorí náà ó yẹ kí ó fẹ́ ọmọ ọba.
Olufẹmi, lasiko to n ba BBC sọrọ ni, o ṣoro fun ọdọ lati ṣe iṣẹ agbẹ ni Naijiria nitori ko si iranwọ fun wọn.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù BBNaija 2019: Ta làwọn ọmọ Yorùbá tó ń kópa nínú ètò BB Naija 1 Agẹmo 2019 Oríṣun àwòrán, @seyiawolowo Lori ayelujara orukọ Awolowo tun ti di ohun ti awọn eeyan n jẹ lẹnu.
Ó gbà bẹ́ẹ̀; ó bá bẹ̀rẹ̀ sí wá àkókò tí ó wọ̀ láti fi Jesu lé wọn lọ́wọ́ lọ́nà tí ọ̀pọ̀ eniyan kò fi ní mọ̀.
Ahabu bi àwọn òṣìṣẹ́ rẹ̀ pé, “Ǹjẹ́ ẹ mọ̀ pé àwa ni a ni ìlú Ramoti Gileadi?
Ọjọ́ meje ni o níláti fi ṣe ètùtù fún pẹpẹ, kí o sì yà á sí mímọ́, nígbà náà ni pẹpẹ náà yóo di mímọ́, ohunkohun tí ó bá sì kan pẹpẹ náà yóo di mímọ́ pẹlu.
Ohun ti iroyin naa sọ ni pe Olori Damilola, to jẹ iyawo kekere, lo tapa si ọkan lara awọn ofin to de ihuwasi wọn ni aafin, eyi to mu ki wọn o ti i mọ yara ibawi to wa ninu aafin Oyo.
Ẹ fi ojú yín rí àwọn ìdààmú ńláńlá tí ó bá wọn, ati àwọn iṣẹ́ ìyanu ńlá tí OLUWA ṣe.
Ajọ Amnesty ṣafihan ninu aworan kan ti wọn fi lede loju opo Twitter wọn awujọ kan ti ko si ile igbọnsẹ, omi mimu to dara ati ọna gidi.
Ní ìgbà kan, bí wọ́n ti fẹ́ máa sìnkú ọkunrin kan, wọ́n rí i tí àwọn ọmọ ogun Moabu ń bọ̀, wọ́n bá ju òkú náà sinu ibojì Eliṣa.
ilé orímóògùnjẹ ́ kò ju ilé kẹ ́ rin lọ sí ilé Àlàó .
O ṣalaye pe ''ọkọ baalu ti wọn fẹ ba lọ ti gba aṣẹ lati ko awọn dokita mejilelogoji lọ si ilẹ Gẹẹsi fun eto idanilẹkọ kan ṣugbọn meji pere ninu awọn mejidinlọgbọn to n lọ lo ni iwe aṣẹ irinna.
Bakan naa ni awọn kan sọ pe ọkunrin naa ti ko fẹ ẹ si aṣọ ni ara arẹ dide, o si pada si ibi ariya naa.
Ẹ gbọ́ ọ̀rọ̀ OLUWA, ẹ̀yin ilé Jakọbu, ati gbogbo ìdílé Israẹli.
Kò sí ààbò fún àwọn ọmọ rẹ̀,wọ́n di àtẹ̀mọ́lẹ̀ ni ẹnubodè,kò sì sí ẹni tí ó lè gbà wọ́n là.
Joṣua Dá Àwọn Ẹ̀yà Ìhà Ìlà Oòrùn Pada Sílé.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Lẹyin iṣẹ abẹ yii ni ko pada ji mọ.
"Oríṣun àwòrán, Seyi Makinde Atẹjade ọhun fikun pe ""Mo fẹ tun tẹnumọ fun yin pe gbigba owo lawọn ile iwe labẹ etekete kankan jakejado ipinlẹ Ọyọ lodi sofin, ẹnikẹni to ba si tapa si asẹ yii laa ri bii abẹyinbẹbọjẹ, ijiya to jopin si n duro de onitọun."
ẹkọ won lorile  ede Naijiria ni
'Ẹ má ṣi Fayemi túmọ̀ lórí àṣẹ tó pa nípa sísọ èdè Yorùbá' Kòsí àṣà tó faramọ́ fífi èmí ènìyàn ṣe ìrúbọ - Olúwó Ajínigbé ń bèèrè fún epo, iṣu àti ọ̀tí Schinap gẹ́gẹ́ bí owó ìtanràn Kòsí àṣà tó faramọ́ fífi èmí ènìyàn ṣe ìrúbọ - Olúwó Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Aisha Buhari: Aya Ààrẹ Buhari ké sí àwọn aya gómìnà pé kí wọ́n lọ paná ìdàrúdàpọ̀ ágbègbè kóówá 7 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Oríṣun àwòrán, @Aishat Aisha Buhari rọ àwọn aya gómìnà láti gbárùkù ti ètò àláafíà láwùjọ wọń.
Oluwo ni Olori to n bọ lọna ''lẹtikẹ, nla ni eleyi, o ja gbogbo 'scale' patapata.
 enití ó kókó dé agbo-ilé yìí ni ìwádìí fi yé mi pé ó ńjé búoyè .
Kò sí àníàní, Coronavirus ló mú ẹ̀mí Ajimobi lọ - Ìjọba Eko Wo bí o ṣe lè di aṣojú tó ṣe pàtàkì nínú àjọ ìṣọ̀kan àgbáyé 'UN Goodwill Ambassador' A kò ní fara mọ́ fífi àkókò ṣòfò lórí ẹjọ́ Sotitobire - Ìjọba Ondo Ìpínlẹ̀ Oyo sọ àsìá Nàìjíríà kalẹ̀ láti dárò Abiola Ajimobi Lilọ Hajj jẹ ọkan pataki ninu opo to di ẹsin Musulumi mu, wọn si mu u ni ibaada fun gbogbo musulumi lati rii wi pe wọn lọ si Mecca, o kere tan lẹẹkan ki wọn to dagbere faye.
Bí èrò ọkàn ẹni bá ṣẹ, a máa fúnni láyọ̀,ṣugbọn àwọn òmùgọ̀ kórìíra ati kọ ibi sílẹ̀.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Irun tita jẹ owo olowo n la Iwadii kan pẹlu ẹgbẹrun mẹfa obinrin adulawọ ni fasiti Boston ni ọdun mẹta sẹyin fi han wi pe, obinrin mejidinlaadọta ni iwaju tabi aarin ori wọn ti pa.
Amọ ijọba maa n faye gba kiko ọunjẹ kaakiri lasiko naa ki awọn eeyan le ri ohun ti wọn maa jẹ nigba ti wọn ba ninu ile.
Fọnran fidio taa n wi yi, o le ni eeyan miliọnu kan ti wo.
Oríṣun àwòrán, Others Àkọlé àwòrán, Bode Thomas ní ọpọlọ pípé, ó jẹ́ aṣaájú àmọ́ ó ní inú fùfù Gẹgẹ baa ti ri ka loju opo ikansiraẹni lori ayelujara, Wikipedia, awọn ohun to yẹ ka mọ nipa Olabode Thomas ree, tori bi onirese rẹ ko ba fingba mọ, awọn eyi to ti fin silẹ ko lee parun.
Yan àwọn tí o fẹ̀ fún ẹgbẹ agbábọ́ọ́lù ààyò rẹ Wo àwọn ẹranko tí wọ́n máa figagbaga ni Egypt nínú AFCON 2019 Àwọn orílẹ̀èdè àjọ ECOWAS yóò máa ná owó kan nàá l'ọ́dún 2020 Ta ni awàdà rẹ̀ wú u yín lórí jù ní Yollywood?
Mose bá pada wá, ó pe àwọn àgbààgbà Israẹli jọ, ó sì sọ gbogbo ohun tí OLUWA pa láṣẹ fún un fún wọn.
Angẹli OLUWA náà dá Manoa lóhùn, ó ní, “Gbogbo ohun tí mo sọ fún obinrin yìí ni kí o kíyèsí.
Lasiko ajọdun Dubar ilu Ilọrin ti ọdun yii, Emir ti ilu Ilọrin, Alhaji Ibrahim Sulu-Gambari lo lewaju awọn ẹlẹṣin ti ko din ni ẹẹdẹgbẹta pẹlu ṣin ti wọn ṣe lọṣọ ati lọjọ loriṣiriṣi lati ṣe ajọyọ ajọdun naa.
oun yii kan naa si tun ni agbabọọlu to gba goolu mẹta wọle ninu ifẹsẹwọnsẹ kan naa julọ lagbaye.
ijamba bii ibọn, ati awon kẹkẹ  alupupu
"Olùkọ́ Seyi Makinde gba èrè tiẹ̀ láyé, gómìnà yàn án sípò òṣèlú Ilé ẹjọ́ dá Ààfá dúró láti gbé ọmọ ọdun 16 sílé gẹ̀gẹ́ bí ìyàwó rẹ̀ kẹ́sàn án Wo ohun tí a mọ̀ nípa iléeṣẹ́ ""ISON Xperiences"" tí òṣìṣẹ́ 78 ti kó àrùn coronavirus ní Ìbàdàn Arákùnrin tó jí Ese Oruru gbé ti rí ẹ̀wọ̀n ọdún 26 he Mo wọ bàtà àti fìlà wọ pẹpẹ Cele láti ṣe wáàsí, kò sí ṣọ́ọ̀ṣì tí n kò le wọ̀ - Sheik Buhari ọmọ Musa Ki awọn eeyan ba le ribi jọsin, sọọsi Martha Lutheran ni Kreuzberg nawọ iranwọ pe ki awọn olujọsin to kuwa si ọdọ awọn lati le kirun jimọ to kẹyin ninu osu awẹ Ramadan."
Ọfọ nla ṣe ni adugbo Oke-Odo to n bẹ ni agbegbe Igisogba Omo-Adio ilu Ibadan nibi ti agbara ojo ti gbe alaga adugbo naa ati awọn eeyan meji mii lọ lọjọ Aje.
Tí mo bá ti wo oòrùn nígbà tí ó ń ràn,tabi tí mo wo òṣùpá ninu ẹwà rẹ̀:
Naijria yoo bere si maa jegbadun opo ounje janturu, ise , eto alaafia ati
Àkọlé àwòrán, Awọn eekan ninu ẹgbẹ oselu APC ni wọn ki Fayemi ku orire.
Àwòrán ìwọ́de NLC, TUC, ULC lónìí NLC, TUC: Àwa ò gba owó lọ́wọ́ Fayose ooo Lẹ́tà Obasanjo: Àjálù ń bọ̀ bíi ti Rwanda, tí Buhari kò bá ṣàtúnṣe ètò ààbò NLC, TUC, ULC yóò ṣe ìwọ́de l'ónìí Loṣu kọkanla ọdun 2018 ni aarẹ Buhari ni oun a gbe abadofin naa siwaju ile ni eyi ti awọn aṣojuṣofin sọ di ẹgbẹrun mẹtadinlọgbọn ninu ijokoo wọn.
 Ó jẹ ́ kíkọ ́ sókè látọwọ ́ cern láti ọdún 1998 dé 2008 , pẹ ̀ lú èrò láti gba àwọn aṣefísíksì láyè láti ṣe àdánwò ìsọtẹ ́ lẹ ̀ àwọn orísi àròjinlẹ ̀ físíksì eruku àti físíksì olókun-gíga , àti àgàgà láti wá bọ ́ yá bósónì higgs wà lóòótọ ́ àti orísirísi àwọn eruku tuntun tí àjọbáramu adárajùlọ ṣe àsọtẹ ́ lẹ ̀ .
Bi a ba ka a ni meni meji, igba ikẹjọ ree ti ik Super Eagles yoo gba ami ẹyẹ baba kan naa, Bronze.
Mo na ọwọ́ sí ọ fún ìrànlọ́wọ́;bí òùngbẹ omi í tií gbẹ ilẹ̀ gbígbẹ,bẹ́ẹ̀ ni òùngbẹ rẹ ń gbẹ ọkàn mi.
Bákan náà ni yóo fi ẹ̀jẹ̀ wọ́n ara àgọ́ náà ati gbogbo ohun èèlò ti ìsìn.
Egbe osise lorile ede Naijiria ti faake kori lori ẹgbẹrun
Ìwọ Beteṣasari, sọ ìtumọ̀ rẹ̀, nítorí gbogbo àwọn ọlọ́gbọ́n ìjọba mi kò lè túmọ̀ rẹ̀ fún mi.
Bi o ba wa kẹẹfin pe o ni eyikeyi ninu ifarahan wọnyii, maa jayo pa o, to ba jẹ wi pe iwọ nikan lo n gbe ile, yara duro sile fun ọjọ meje lọ.
" O fikun pe ẹsẹ ti Buhari sẹ awọn eeyan ẹkun iwọ guusu Naijiria julọ ni bo se wọgile oju ọna ọkọ ayarabiasa ti wọn pe ni Metroline, tijọba Lateef Jakande gbe kalẹ.
Ṣugbọn ní tiyín, bí ẹ tilẹ̀ ṣe jù bẹ́ẹ̀ lọ,n kò ní ka ẹnikẹ́ni kún ọlọ́gbọ́n láàrin yín.
Ileeṣẹ ọlọpaa ipinlẹ Ọyọ ti ni oṣiṣẹ ọlọpaa ti Sunday fi ẹsun kan wi pe o ṣi awọn silẹ ti n foju wina ibawi.
Oríṣun àwòrán, OLUWO ILU IWO Àkọlé àwòrán, Olúwó ní àlááfíà wa láàárín àwọn ọba alaye ní ilẹ̀ Yorùbá Ohun ti a gbọ ni wí pé awọn ọba alaye kan lo lọ pẹ̀tù si Olúwó ti ìlú Iwò Oba Abdulrasheed Akanbi lẹyin ipade ti wọn ṣe gbẹ̀yìn ni oṣu keje ọdun 2017.
Ní ọjọ́ náà, olukuluku yóo pe aládùúgbò rẹ̀ láti wá bá a ṣe fàájì lábẹ́ àjàrà ati igi ọ̀pọ̀tọ́ rẹ̀.
Dafidi fúnrarẹ̀ wí nípa ìmísí Ẹ̀mí Mímọ́ pé, ‘Oluwa wí fún Oluwa mi pé:Jókòó ní ọwọ́ ọ̀tún mitítí n óo fi fi àwọn ọ̀tá rẹ sí abẹ́ ẹsẹ̀ rẹ.
”MTN gbagbo pe sise atileyin fun sisami ayeye awon odun ibile yii gege bi won ti n se kaakiri agbaye maa n mu irepo wa sii ni ati idagbasoke agbegbe kookan.
Àgbájọ àwọn ènìyànkéènìà kan dìgbò lù ú, wọ́n sì pa ọkọ àti ọmọ rẹ̀ ọkùnrin.
Lẹ́yìn ọdún díẹ̀, ọba Ijipti yóo ní àjọṣepọ̀ pẹlu ọba Siria, ní ìhà àríwá, ọmọbinrin ọba Ijipti yóo wá sí ọ̀dọ̀ ọba Siria láti bá a dá majẹmu alaafia; ṣugbọn agbára ọmọbinrin náà yóo dínkù, ọba pàápàá ati ọmọ rẹ̀ kò sì ní tọ́jọ́.
Iroyin ayẹwo Gomina Makinde yii n waye lẹyin ti wọn da ẹni akọkọ ti wọn kede pe o larun naa ni ipinlẹ Ọyọ silẹ.
Mi o mọọmọ'' Ọmọ atapata dide lemi naa, mo si tun jẹ Kristẹni."
00), ti Naijiria Security ati Civil defence Corps (NSCDC) yoo gba  “bilionu meta le die ni ẹ̀ẹ́dẹ́gbẹ̀ta owo naira (=N=3,573,534,500.
Ẹ̀yin gan-an lè jẹ́rìí, Ọlọrun náà sì tó ẹlẹ́rìí wa pé, pẹlu ìwà mímọ́ ati òdodo ati àìlẹ́gàn ni a fi wà láàrin ẹ̀yin tí ẹ gbàgbọ́; 
Ẹ̀yin gómìnà Yorùbá, ẹ wá ṣàlàyé ìdí tẹ fi ṣèfilọ́lẹ̀ ètò Àmọ̀tẹ́kùn - Iléeṣẹ́ ààrẹ Ikú òjijì kò jìnnà àmọ́ ọ̀nà méje rèé láti dènà rẹ̀ Kodjovi Obilale, to jẹ aṣọle nigba naa kan ṣadeedee ri pe oun ti fara gbọta, loju ẹsẹ lo rii pe ẹjẹ bẹrẹ si ni da lati ikun ati ẹsẹ oun mejeeji.
 A ko si ni maa beere fun iru atilẹyin, ifọwọsowọpọ ati adura bayii siwaju, gẹgẹ bi ẹni to dupẹ oore ana ti yoo gba omiran si, nitori awọn wọnyi gangan ni eroja aṣeyọri ẹda.
 kò sí álfábẹ ́ tì oníbiṣẹ ́ kankan fún un títí ọdún 1992 , sùgbọ ́ n ọnà-ìkọ ́ lárùbáwá àti latin únjẹ ́ lílò fun .
A kò máa dà á kiri láti inú ìgò kan sí òmíràn.
Tọkọ taya kú lọ́jọ́ kan náà l'Abeokuta lẹ́yìn ìgbéyàwó ọdún méjìléláàdọ́rin 72 Èmi kọ́ ló pàṣẹ fún àwọn sọ́jà láti má a pa èèyàn ní Oyigbo - Nyesom Wike 'Ṣọ́ọ́ṣì ni mọ ti ń bọ̀ kí n tó pàdé àwọn sójà tó fi abẹ gẹ irun fún mi' Ǹkan tí a mọ̀ nípa kọ́lẹ̀jì olùdìbò tó ń fìdì ẹni ti yóò jẹ ààrẹ ilẹ̀ Amérika múlẹ̀ Agbenusọ fun ajọ WAEC, Demianus Ojieogu sọ fun BBC Pidgin pe awọn akẹkọọ ti ọrọ kan ko ti i le ṣe nkankan, nitori pe awọn ṣi n ṣe iwadii lati mọ boya lootọ ni wọn ṣe mago-mago lasiko idanwo.
Yoruba ni ẹni to ba fẹ parọ laa ni ẹlẹri oun wa lọrun.
Oju opo rẹ 'his real account' to ni ami idamọ alawọ buluu.
Bi Ọlọ́run bá kọ ọ́ pé èèyàn ba wọn gba awẹ níbẹ̀, wákàtí méjìlelogun gbáko ní èèyàn o fí mẹnu mọ fún jíjẹ àti mímú.
Agbẹjọ́rò fún Sotitobire yọ ọwọ́ nínú ìgbẹ́jọ́ rẹ̀ lónìí!
Igba keji ree ti Chelsea yoo fidi rẹmi laarin ọjọ mẹrin lẹyin ti Manchester United na wọn lọjọ Aiku ninuidije Premier League Chelsea láǹfààní láti t'ọ́mọlúábí wọn ṣe pẹ̀lú Liverpool lálẹ́ òní Iduro ko si ibẹrẹ ko si fun ẹni to gb'odo mi lọrọ ẹgbẹ agbabọọlu Chelsea bayii, lẹyin ti wọn kabuku olorombo lọwọ Manchester United lọjọ Aiku to lọ ninu idije Premier League.
Oruko ti won fi ranse naa ni : Ummu Jalingo (Ila-oorun), Justina Nnabuko (Ila oorun- Gusu ), Mike Obadan (Ila Gusu), Abdu Abubakar (Ila -Ariwa) and Adeola Adetunji (Iwo oorun ).
Sibẹ Ẹni Mímọ́ ni ọ́,o gúnwà, Israẹli sì ń yìn ọ́.
wọ́n lo ọgbọ́n, wọ́n tọ́jú oúnjẹ, wọ́n mú àwọn àpò ìdọ̀họ tí wọ́n ti gbó, wọ́n dì wọ́n lé orí kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ wọn.
Ọjọ kẹrinla oṣu kẹfa ọdun 2020 ni obinrin naa dagbere faye.
Mariam Azwer to n ṣiṣẹ pẹlu BBC ko awọn abajade iwaadi na jọ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Wo àwọn ìbejì tó lẹ́ pọ̀ lẹ́yìn àṣeyọrí ìṣẹ́ abẹ dókìtà 70 Awọn ọtọkulu bi Ọjọgbọn Wole Soyinka, eekan ẹgbẹ Afenifere, Oloye Ayo Debanjo; agbẹjọro agba ati ajafẹtọ, Femi Falana, Oloye Olu Falae, ati Aarẹ Ọnakakanfo, Iba Gani Adams atawọn mii ni wọn ti sọrọ lati gbaruku ti eto Amọtẹkun.
“Tani yoo rokan lati fi iru iko yii sile?
Ẹ̀yin ọ̀tá mi, ẹ lọ dì mọ́ òpò ina lọ́dún 2020- Ayodele Fayose Ẹni mẹ́ta wọ gbaga ọlọpàá nítori ajílẹ̀ tí wọ́n kó tà ní ọja Daleko ní Mushin Ileeṣẹ ologun ati alaabo ilu lo kede iku akinkanju Aduku naa lori ayelujara lọjọ kinni, oṣu kinni, ọdun 2020.
Ẹwẹ, agbẹnusọ fun ileeṣẹ ọlọpaa ipinlẹ Eko, Muyiwa Adejobi ti ṣalaye pe iwadii si n lọ lọwọ lati mu awọn mẹta yoku ti gbimọ pọ pẹlu Yusuf lati pa Kembi.
” Ó bá bẹ̀rẹ̀ pẹlu gbogbo agbára rẹ̀.
Ẹ̀yin tí ẹ kù lára àwọn ọmọ Anakimu, ẹ óo ti fi ìbànújẹ́ ṣá ara yín lọ́gbẹ́ pẹ́ tó?
Ẹni ìyìn ni OLUWA, Ọlọrun Israẹli,lae ati laelae!
Lati igbà ti Ijọba Ológun ti lé àwọn àjòjì ti ó dá ilé ọjà nla silẹ fún ọ̀pọ̀lọpọ̀ ọdún, àwọn Olówó ilú kò ronú lati ṣe irú ilé ọjà bẹ́ ẹ̀ si gbogbo agbègbè Èkó fún irọ̀rùn ará ilú ju bi gbogbo ọjà nla ti kó ori jọ si Erékùṣù Èkó.
Ṣugbọn iranṣẹ rẹ̀ wí pé, “Báwo ni n óo ṣe wá gbé èyí kalẹ̀ níwájú ọgọrun-un eniyan láti jẹ?
Ẹwu tí àwọn ẹnìkejì mi yàtọ̀ sí tèmi, aṣọ ti ẹ̀wù wọn kìí ṣe góòlù ṣùgbọ́n wọ́n fi góòlù ṣe ọnà síi lára.
Efuroni dá Abrahamu lóhùn, ó ní, 
Ẹ̀yin ará, à ń pàṣẹ fun yín ní orúkọ Oluwa wa Jesu Kristi pé kí ẹ yẹra fún àwọn onigbagbọ tí wọn bá ń rìn ségesège, tí wọn kò tẹ̀lé ẹ̀kọ́ tí ẹ ti kọ́ lọ́dọ̀ wa.
Ofin yii si lo wa lati ri daju pe ayika wa ni mimọ toni toni, ẹnikẹni ko gbọdọ sọ idọti kaakiri ayika, ọkọ ero kọọkan si lo gbọdọ ni ike idalẹsi.
Ní ilẹ̀ Oòduà, gẹ́gẹ́ bí wọ́n ti ń ṣe káàkiri àwọn ilẹ̀ adúláwọ̀ gbogbo, pàtàkì ni igi ọ̀pẹ jẹ́.
Bianca júwe ilé fún Serena Williams nínú ìdíje l'America Naomi Osaka: Obìnrin adúláwọ̀ Japan tó na Serena Serena kò gbọdọ̀ wọ aṣọ Black Panther mọ́ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Kí lo tíì rí nípa Amotekun?
Babangida ati Abacha ki se ọre gidi Ère Gani Fawẹ̀hìnmí Gani Fawehinmi lọ àmọ́ kò kú lẹ́yìn ọdún mẹ́wàá tó dará ilẹ̀ June 12: Kíni o mọ nípa M.
Wọn ni eyi ṣẹlẹ lasiko ti wọn sọ ado oloro lati oju ofurufu lọjọ kọkansinlogun, oṣu kẹsan an ọdun 2016.
 Ọ ̀ wọ ́ kẹfà ni koyolu àti Ẹlẹ ́ pẹ ̀ ẹ ́ àkọ ́ kọ ́ tí wọ ́ n wá láti ilé-ifẹ ̀ láti ṣe àwárí ọ ̀ wọ ́ ti Ọbanta .
Kò dára kí orísun rẹ máa ṣàn káàkiri,bí omi àgbàrá ní gbogbo òpópónà.
Lẹyin eyi lo tẹkọ ofurufu leti lọ sile ẹkọ fasiti Kennsaw ni Atlanta Georgia, lorilẹ-ede Amẹrika.
Bí ẹ bá fẹ́ gbà á, Johanu ni Elija, tí ó níláti kọ́ wá.
"Owo ajẹmọnu ti wọn n san ni Naijiria ko difa rara tori iye ti wọn n san fawn dokita ni UK koda bi ko ba si owo ajẹmọnu ohun toju n ri nibẹ ṣi pọ ju iye ti Naijiria n san lọ""."
Ibẹrubojo to wa ni Harare lọwọlọwọ tun ti le kenka sii pẹlu ọwọ ti awọn oṣiṣẹ alaabo tilẹ n gbe lati ja olu ileeṣẹ ẹgbẹ alatako gba to fi mọ bi awọn ikọ amuṣẹya ṣe n tu si igboro lati mu ibọwọ fofin isede ni dandan fawọn araalu.
Àwọn ìdílé Kohati kò gbọdọ̀ wọ inú ibi mímọ́ láti yọjú wo àwọn ohun mímọ́, ẹnikẹ́ni tí ó bá yọjú wò wọ́n yóo kú.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù AfCFTA: Awọn onimọ sọrọ lori ohun ti jijawọ Naijiria lee fa 19 Ẹrẹ̀nà 2018 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Buhari jawọ kuro ninu adehun idokoowo ilẹ Afirika Awọn alẹnulọrọ lẹka ọrọ ilẹ okeere ati idokoowo ti sọ wi pe igbesẹ ti aarẹ orilẹede Naijiria gbe lati jawọ kuro ninu adehun idokoowo ilẹ Afirika ku diẹ kaato.
''Awon omo Naijiria n fe ri abajade ise ti ijoba n se, pelu awon eniyan to wa ninu minisita.
50) si naira mẹtalelogóje le ni ọgọrin kọ́bọ̀(N 143.
Olori ẹgbẹ alatako, Democratic Alliance, Mmusi Maimane sọ pe ko ti i si aridaju pe alafo to wa laarin awọn olowo ati talaka yoo di pa.
Ìwé ìròyìn Premium Times jábọ̀ pé ''Magu fi ìdí rẹ̀ múlẹ̀ pé olú iléeṣẹ́ tuntun nàá kò le gba gbogbo àwọn òṣìṣẹ́ àjọ nàá tó wà ní ìlú Abuja.
Ṣugbọn nǹkankan ni, èmi a máa gbàgbé ohun gbogbo tí ó ti kọjá, èmi a sì máa nàgà láti mú ohun tí ó wà níwájú.
Bakan naa ni wọn yoo jiroro lori ọrọ ile ìṣẹ Huawei ti China ti Amerika yọwọ ẹ lawo lataari eto aabo.
Amẹrika: Ipa ti idẹnukọlẹ isejọba ni lori araalu ‘Trump kò yẹ láti jẹ́ ààrẹ’ Trump bu ẹnu atẹ lu FBI Ileeṣẹ orileede Amerika ni Naijiria sọ wi pe awọn yoo bẹrẹ iṣẹ pada ni kete ti wọn ba ti ribi yanju aawọ naa.
30 Ìgbé 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 17 Agẹmo 2020 Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Zainab Aliyu: Orílẹ̀-èdè Saudi túu sílẹ̀ lẹ́yìn oṣù mẹ́rin tó it wà ni ahámọ́ balẹ̀ Zainab Habib Aliyu ti ijọba orilẹede Saudi Arabia fi ẹsun kan pe o gbe oogun oloro ni ọjọ kini ana ti pari agunbanirọ rẹ.
Naijiria ti rọ ajo to n mojuto rto irinna oko ofurufu lorile  ede yii ( Federal Airports Authority of
Igba ti aburo to jade lọ yoo fi pada sile ni o dede kan ẹgbọn rẹ ninu agbara ẹjẹ ni itosi baluwẹ wọn to n bẹ ni ẹyinkunle.
Ṣugbọn iṣẹ́ ibi wọn kò ní ààlà.
Amọ eleegun ti wọn fẹsun kan naa wi pe o pa ọmọkunrin naa, Olu Olowokere sọ wi pe oun ko lo pa arakunrin naa.
N óo wá kọlu àwọn ọ̀tá yín,n óo gba àwọn arọ là,n óo sì kó àwọn tí a ti fọ́nká jọ.
Fayose si Buhari: Kí ló fa ìdíwọ́ àfihàn ìwé ẹ̀rí rẹ di àsìkò yí?
Araale: Ṣe ẹ n gburo Aunty Tacha?
Xenophobia: Kò sí wàhálà fún àwọn okòwò South Africa ni Eko
Nísàlẹ̀ àwọn yàrá ìhà gúsù, ọ̀nà kan wà ní apá ìlà oòrùn.
Tiwa Savage tọwọ́ bọ'wé àdéhùn pẹ̀lú UMG fún òkìkí orin rẹ̀
Fún ìgbà díẹ̀, ilé mímọ́ rẹ jẹ́ ti àwa eniyan mímọ́ rẹ;ṣugbọn àwọn ọ̀tá wa ti wó o lulẹ̀.
Ta ni Ken Saro-Wiwa tí ìjọba ológun sekúpa?
N óo gbé wọn ró, n kò ní fà wọ́n tu, 
e awọn akoroyin to niṣe pẹlu ọdaran (CRAN) lo n selede lẹyin akẹgb.
Iriri awọn dokita kan ni Capetown ti fihan pe awọn irinṣẹ kan wa to jẹ olowo pọọku ti yoo si ṣiṣẹ daradara ju awọn fẹntiletọ jaanran ti awọn alaṣẹ ni ki wọn maa rọ owo ra.
ni ti idagbasoke ba de ba awon ohun amayederun ni aarin ilu ati igberiko , o ni
Ọ̀pọ̀ ènìyàn l'ó fi ẹ̀dùn ọkàn-an wọn hàn nígbà tí wọ́n gbọ́ nípa àmúdipẹ̀tẹ́lẹ̀ ilé náà.
Osun Governorship Elect: Dele àbúrò Adeleke ní PDP yóò borí nílé ẹjọ́ tó gajù lọ
Ogbeni Miguna so lojo-Isegun pe, won fi oun sihamo nile igbonse, ni eyi ti won ko je ki awon molebi oun wa ri oun.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Osinbajo fárígá: Mò ṣetán láti wàákò pẹ́lù àwọn tó ń bàmí lórúkọ jẹ́!
Oríṣun àwòrán, @sowore Àkọlé àwòrán, Omoyele Sowore, okan lara awọn ọdọ to dije dupo aarẹ Naijiria ninu eto idibo to kọja ti wa lati mọle ijọba.
Iwadi fihan pe awọn obinrin ti n se gudugudu meje ati ya ya ya mẹfa lagbo oselu lati ba awọn ọkunrin fi ẹgbẹkẹgbẹ ninu eto oselu ati idibo, ti wọn si ti n ri ọwọ yọ, paapa lati igba ti orilẹede wa ti gba ominira.
 Lara awọn aṣofin to tun bu ẹnu atẹ lu iwa ikọlu yii ni Aṣofin Ṣẹgun Olulade, Aṣofin Bisi Yusuf, abbl.
Mo bá bi í pé, “Kí ni ìtumọ̀ àwọn igi olifi meji tí wọ́n wà lẹ́gbẹ̀ẹ́ fìtílà náà?
Lasiko ti awọn ayaba ba n ti igba, wọn yoo fi igba nla abi kekere siwaju ara wọn, igba nla kan lee wa niwaju ayaba kan abi meji, ayaba kan si le mu igba kan siwaju ara rẹ.
Oun tun ni ẹlẹsẹ ayo Liverpool ati agbabọọlu to tii pẹ ju lagbaye (4,465).
Joshak ni aheso ni pe awọn  yoo ti enu ona ile ijọba pa:”Awa  ko wa lati wa tapa si ase  Gomina Ayo Fayose .
O sì ti fi ìfẹ́ ńlá tí kì í yẹ̀ yìí hàn sí i, o fún un ní ọmọ tí ó jọba lẹ́yìn rẹ̀ lónìí.
Lasiko abẹwo ọhun ni gomina Makinde gbe miliọnu lna ẹẹdẹgbẹta naira kalẹ lati lee fopin si iyansẹlodi awọn olukọ ile ẹkọ̀ fasiti naa, to si tun se ipade pọ pẹlu awọn eeyan ti ọrọ ileẹkọ naa gberu lọna ati wa ojutu si wahala to n koju ileeẹkọ naa.
Jija si agba: Ni ọpọ igba tun ni ẹnu kun oloogbe Abiola Ajimobi pe o kundun ko maa ja si agba.
Ojo ola Victor Moses ninu iko agbaboolu Chelsea ti n fara han pe, o seese ki o kuro ninu iko ohun lọdun to n bo.
Damilọla wa rọ awọn obi lati maa se iwuri fun awọn ohun ara ọtọ, ti awọn ọmọ wọn ba n se, ki wọn ma si lero pe nkan naa ko seese.
Ọ̀pọ̀ agbófinró gbàródan sí pápákọ̀ òfurufú Abuja fún ìpadàbọ̀ Zakzaky Papakọ ofurufu Nnamdi Azikwe nilu Abuja ti kun fọfọ bayii fun awọn agbofinro ti oju wọn ko rẹrin, ti wọn gbarodan sibẹ fun igbaradi ipadabọ asaaju ẹsin Shiite, Sheik Ibrahim El-Zakzaky lati orilẹede India.
Amẹrika ń gbẹ̀san lára Nàíjíríà, owó ‘Visa’ di ọ̀nà méjì láti wọ Amẹrika Ìrẹsì jọ̀lọ́ọ̀fù Ghana la jọ̀lọ́ọ̀fù Nàìjíríà mọ́lẹ̀ nínú ìdíje Bíodun Fatoyinbo ti fojú hàn ní àgọ ọlọpàá Ìyá tó lu ọmọ ọdún mẹ́rin pa l‘Akurẹ bọ́ sọ́wọ́ ọlọ́pàá Ko ṣai gbe ọrọ rẹ lẹsẹ pẹlu ipa ti ajọ United Nations ti o wa fun idagbasoke ilu ti ko lori lpinlẹ naa.
Tí o fún un ní oúnjẹ ati idà, tí o sì tún bá a ṣe ìwádìí lọ́dọ̀ Ọlọrun.
Nígbà tí wọ́n dé ibi ìpakà Atadi, níwájú Jọdani, wọ́n pohùnréré ẹkún, Josẹfu sì ṣọ̀fọ̀ baba rẹ̀ fún ọjọ́ meje.
Lawal sọ wipe ile-igbimọ yoo polongo ọjọ tuntun ti wọn ba mu fun ipade ijiroro lori eto aabo naa.
Ẹgbé agbabóòlù Arsenal ṣe Frankurt báṣubaṣu pèlu ayò mẹta si odo.
4 2126 Orilẹede Guinea 79 0.
Lẹ́yìn ìgbà díẹ̀, Joaṣi pinnu láti tún ilé OLUWA ṣe.
Àáfà tó yàn, tó yan jú
Laipẹ́ yi ni awọn igun ẹgbẹ asaaju Yoruba kan n sọ pe ọjọgbọn Akintoye ti kọ ipo ti wn yan si.
Oríṣun àwòrán, Reuters Àkọlé àwòrán, Niṣe ni ẹkun gba ẹnu awọn afgbabọọlu Cameroonlẹyin ti VAR fagile goolu ti wọn jẹ Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Egypt ṣíná fún Zimbabwe, ẹ̀kọ́ mẹ́rin tó yẹ ní kíkọ́ Super Falcons gòkè odò bọ́ sípele ìkẹrìndínlógún ní France Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Wọn kere si Number, Ori wa a dara, Saworo, Eko Akete, Baba Wa, Toba fe mo Dollar, Aduke, Feso Jaiye, Iyawo Ma pa mi.
Bí wọn sì tún ra ilé náà, wọn yóò máa gbe wa sórí afẹ́fẹ́, Kín ló dé ?
Oríṣun àwòrán, Facebook/Seyi Makinde Lara awọn eeyan mii to peju sibi ipade naa ni awọn gomina lati awọn ipinlẹ to wa nilẹ Yoruba, awọn ileesẹ agbofinro lorisirisi, awọn ọba alaye nilẹ Yoruba ninu eyi ta ti ri Olubadan ati Ọọni tilu Ile Ifẹ, awọn ẹlẹgbẹjẹgbẹ lawujọ, awọn asaaju ẹsin ati awọn asaaju awujọ.
Oríṣun àwòrán, @IAM_DAVIDO, @ISIAKAADELEKE1 Àkọlé àwòrán, Adeleke ni aburo baba gbajugbaja olorin Davido O seese ko jẹ wi pe ibi ti inagijẹ rẹ ‘Dancing Sẹnẹtọ’ ti wa ye ree.
N óo gbẹ̀san gbogbo ẹ̀ṣẹ̀ wọn lára wọn,ati ti àwọn baba wọn.
Primate Ayodele ti ijọ INRI evangelical sọrọ yii lasiko eto ti ijọ naa fi n pese iranlọwọ ohun ini fawọn opo ati alaini ni awujọ nile ijọsin wọn ni Eko.
Naira Marley koju ija si Ruggedman Kii ṣe Simi nikan ni Naira Marley ba wọ iya ija lori ọrọ boya jibiti ori ayelujara, yahoo-yahoo tọna paapaa julọ lẹyin orin 'Am I a yahoo boy?
August 15, 2019 Ibrahim El-Zakzaky yóò padà sí orílẹ̀èdè Nàíjíríà láti orílẹ̀èdè India níbi tí ó ti lọ ṣàyẹ̀wò ara láì gba ìtọ́jú August 16, 2019 El-Zakzaky de Naijiria fí àwọn ǹkan míràn han Awọn to ṣe àkójọ yìí, Azeezat Olaoluwa, Princess Abumere, Olawale Malomo Awọn to ya aworan yii: Getty Images.
Wọn ni nọmba ọkọ agbepo to yi danu naa ni: LSROIXX.
Oríṣun àwòrán, @chukwudi52 Gẹgẹ bi alaye ti o ṣe fun akọroyin wa, o ni lati ọdun 2014 lawọn ti n dunadura pẹlu ijọba lori ọrọ yii, ṣugbọn pabo ni gbogbo rẹ ja si.
Ẹ sọ fún àwọn ọmọ yín nípa rẹ̀,kí àwọn náà sọ fún àwọn ọmọ wọn,kí àwọn ọmọ wọn sì sọ fún àwọn ọmọ tiwọn náà.
"Ẹ gba mi, isẹ ti fẹ bọ lọwọ mi, ọmọ Naijiria lo ni ibudo itaja ti mo ti n sisẹ, kii se ọmọ South Africa, ija yii ti wa dojukọ alaisẹ, ki lo maa n se awọn eeyan dudu gan?
Ṣe ni awọn ara adugbo naa n fi aworan awọn oku naa sori atagba Twitter ti gbogbo ero si n lọ pe wo awọn oku ati ori naa ki awọn ọlọpaa to gbee lọ.
''Loni, ida ọgọta ninu ọgọrun awọn eeyan ilẹ Afirika lo jẹ ọdọ.
a bí kọ ́ lá akínlàdé ní ọdún 1924 , ní ìlú ayétòrò ní ìpínlẹ ̀ Ògùn ní ilẹ ̀ nàìjíríà .
Ojo nla to ro  fun opolopo ojo lo je ki oke naa ya lule.
Nígbà tí ó sọ gbogbo ohun tí OLUWA pa láṣẹ fún un pé kí ó sọ fún gbogbo àwọn eniyan náà tán, gbogbo wọn rá a mú, wọ́n ní, “Kíkú ni o óo kú!
O ti bi ọmọ kan to si tun jẹ ọmọ gbẹ alatako Peoples National Party ni Jamaica.
Ní ọ̀nà, ní ibi tí alágbẹ̀dẹ́ ti fi Kọ́lá sí ọkọ̀ ní ìjelòó, wọ́n rí àwọn méjì tí wọ́n ń jà Ògúndélé ni orúkọ alágbẹ̀dẹ yìi.
O le ni ọgọrun eeyan ti wọn ti mu si ahamọ.
Ọ̀rọ̀ òtítọ́ yóo máa wà títí ayéṣugbọn irọ́, fún ìgbà díẹ̀ ni.
Ní ọjọ́ kan, Josẹfu lá àlá kan, ó bá rọ́ àlá náà fún àwọn arakunrin rẹ̀, àlá yìí sì jẹ́ kí wọ́n túbọ̀ kórìíra rẹ̀ sí i.
Bakan naa ni, olugbeleke re  Eddie Hearn tun se ipade pelu Dillian Whyte
Ìdí rè é tí mo ṣe lọ sí South Africa fún àpérò ọrọ̀ ajé - Ezekwesili ṣàlàyé Ìkọlù sáwọn àjèjì kò tíì tán ní South Africa, ètò ń lọ láti kó ọmọ Nàíjíríà wálé Ọlọ́pàá fi afẹ́fẹ́ tajú-tajú àti omi tú àwọn tó fẹ́ ṣun ilé ìtajà ShopRite l‘Abuja ká Xenophobic Attack: Àwọn ọmọ Nàìjírìá bínú kọlu Shoprite l'Eko Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Amb.
Wọn ni oju El-Zakzaky kan fọ nitori ijiya tawọn ologunh fi jẹẹ, ati pe ekeji naa tun le fọ ti ko ba ri itọju gidi lasiko.
George Akume ni awon eniyan ti n ri gudugudu meje yaya mefa ti aare n se lati mu ise ati osi kuro ati lati daabobo emi ati dukia awon eniyan.
Ọ̀rọ̀ Aisha Buhari sí Ramaphosa wú ọ̀rọ̀ síta lẹ́nu àwọn ọmọ Nàìjíríà Àwọn Olukọ paapaa fẹsẹ rajo ninu idije ti onikaluku rẹrin pẹlu idunnu ti awọn kan si gbegba oroke ninu idije naa.
Dafidi dáhùn, ó ní, “Kò burú.
 Èbúmàwé àti Òsémàwé ni ó wà ní ìpín karùn ún .
Kọla Balogun ti o ti fi igba kan ri jẹ kọmiṣọna fun karakata ati amojuto awọn ẹgbẹ alajẹṣẹku ni ipinlẹ Ọyọ ni wọn kede gẹgẹ bi ẹni ti o jawe olubori ninu eto idibo si ipo Ṣẹnetọ ẹkun idibo guusu ipinlẹ Ọyọ naa.
Ọkunrin kan ń lọ sí ìdálẹ̀.
Deji naa si gbadura ki Olorun fi ọrun kẹ mama to doloogbe.
Nítorí Ọlọrun kò pè wá sinu ibinu, ṣugbọn sí inú ìgbàlà nípasẹ̀ Oluwa wa Jesu Kristi, 
Ikọ́ lásán ló pa Orisabunmi"" Àwọn nkan tó yẹ kí o mọ̀ nípa App tí NIMC ṣẹ̀ṣẹ̀ ṣe Èèyàn kan kú, ẹni mẹ́ta farapa nínú àkàsọ̀ ìgbàlódé(lift) tó já ní Cocoa House n'Ibadan Ìpínlẹ̀ Eko yí ohùn padà, Ó kéde ọjọ́ tuntun fún ìwọlé àwọn akẹ́kọ̀ọ́ Gẹgẹ bi awọn onwoye ṣe n woo, eyi ko fẹẹ ṣẹyin ọwọja ọwọ keji ajakalẹ aarun COVID-19, eyi to ti gbagboro kan bayii."
Ọmọde náà kò kú; ó sùn ni.
Gedoni salaye siwaju pe, oun ko ni ifẹ si Venita rara, sugbọn khafi nikan ni ọkan oun fa si.
Kí ló dé tí ìyá mi gbé mi lẹ́sẹ̀?
Badenosh yii lo jẹ ọmọ ẹgbẹ oselu Conservative ati ọmọ ile asofin apapọ nilẹ Gẹẹsi, eyi to n soju ẹkun idibo Saffron Walden.
Nítorí náà, mo rò ó ninu ara mi pé, kí n kọ́ sọ fún ọ pé kí o rà á, níwájú àwọn tí wọ́n jókòó níhìn-ín, ati níwájú àwọn àgbààgbà, àwọn eniyan wa; bí o bá gbà láti rà á pada, rà á.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Widows Day 2019: Mo máa ń sá kiri wá owó ilé ni -Opó Lọpọ igba,awọn eeyan a maa to fún ọpọlọpọ wakati ki wọn to le ri iwe irinna pasipọọti wọn gba.
Kááábíèsí Ọba tó ju gbogbo ọba lọ.
 Ìpín kẹjì ni àwọn akọnidòòṣà .
Ajogunba ni ere itage ṣiṣe fun Ọgbẹni Fẹmi Adebayọ.
Bí wọn ti rìn díẹ̀ ni wọ́n rí iwin kan tí o ń sáré bọ̀ tí ó ń ké, ‘Ikú!
Nítorí pé, OLUWA ti fún ọ ní ìṣẹ́gun lónìí lórí gbogbo àwọn tí wọ́n fẹ́ pa ọ́.
Labala ika titẹ, oun ti wọn sọ ni pe ki oludibo fi ika wọn kan ọda itẹwe ki wọn si fi ika ti wọn fi ọda si yii tẹ oju aye ẹgbẹ ti wọn fẹ lori iwe idibo.
Ọ̀pọ̀ ìgbà ló jẹ́ wí pé ìyàwó pẹ̀lú ọmọ kì í mọ ibi tí owó yìí fara sin sí.
Shittu ni bẹẹ si ni awọn ọmọ ẹgbẹ PDP naa ko ni jakan ninu ifẹ ti wọn ni si Saraki nitori ile ti wọn wo yi.
Afẹ́nifẹ́re kìí ṣe asọju ọmọ Yorùba, ẹgbẹ́ lásàn ní wọn
- Afẹnifẹre Adajọ naa ni o wa gun le igbẹjọ ile ẹjọ ti o ri si esi ibo pe idajọ ododo ni wọn ti kọkọ da.
Ṣugbọn fún ìgbà díẹ̀ ní àkókò yìí, OLUWA Ọlọrun wa, o ṣàánú wa, o dá díẹ̀ sí ninu wa, à ń gbé ní àìléwu ní ibi mímọ́ rẹ.
Ọkan lara awọn ti wọn ran lọ ẹwọn pẹlu rẹ jẹ ọmọ Naijiria ti orukọ rẹ n jẹ Jonathan Okigbo.
 kò tíì ju ọmọ ọdún méjìdínlógún lọ lásìkò yìí káńsà ( cancer ) ni ó pa ìyá rẹ ̀ .
Nítorí ìwọ OLUWA, ni ìrètí mi,OLUWA, Ọlọrun mi, ìwọ ni mo gbẹ́kẹ̀lé láti ìgbà èwe mi.
Lalekan Ayokunnu Are: Ọmọwe Olalekan Ayokunnu Are jẹ onimọ ati olukọni pataki nilẹ Naijiria.
Bakan naa ni ile isẹ apanilẹrin ‘Ola’ naa ni awọn ti ni ile igbọnsẹ ni gbogbo ibi.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Florence Ajimobi: Àwọn Káfíńtà ti kó igi dé láti tún òrùlé ilé ìtajà tó jóná ṣe 6 Bélú 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 9 Bélú 2020 Awọn agba ni ọjọ taa ba ri ibi, ni ibi n wọ ilẹ, ohun to ba si ti ya kan, kii tun pẹ ms.
Nígbà tí ó bá baba ati ìyá rẹ̀, ó fún wọn lá ninu rẹ̀; ṣugbọn kò sọ fún wọn pé ara òkú kinniun ni òun ti rẹ́ afárá oyin náà.
Oríṣun àwòrán, Nigeria Police Àkọlé àwòrán, Ọga Agba ọlọpaa Naijiria, Mohammed Adamu n ṣe ayẹwo awọn nkan ija oloro ti ọwọ tẹ Nibayii, awọn ọtẹlẹmuyẹ nileeṣẹ ọlọpaa ti bẹrẹ iwadii lati mọ orisun ti awọn afurasi naa ti n ri awọn nkan ija oloro ti wọn n lo.
Iko agbaboolu Ajax taraji ninu ifesewonse ikolu keji
 Awon alafowosopo pelu awon agbateru eto naa ni Akereke ti Style house files Creative Agency ni Heineken Nigeria, FETS Wallet, ti won seleri milionu marun un fun iko to ba gbegba oroke julo ati Nigerian Export Promotion Council (NEPC).
Ohun ti onitọhun ti ko fẹ ki a darukọ oun ṣe lalaye ni pe ko si ootọ kan ninu iroyin naa ati pe ṣaka lara baba le.
Eyi ni igba akọkọ ti Liverpool yoo gba ife ẹyẹ naa laarin ọgbọn ọdun bayii.
Bakan naa lo ke ke gbajare sita pe oun ko ṣetan ati gbalejo kankan lasiko yii nitori pe ilana ati daabo bo ara ẹni kan oun naa gẹgẹ bi Ọba.
Ó jẹ́ àfihàn ìgbàgbọ́ àti ìgboyà tí wọ́n ní nínu ipá tí wọ́n ríi pé Kayode Fayemi ni láti ṣe gẹ́gẹ́ bí ó ṣe ṣèlérí nínú ìpolongo rẹ̀ àti bí ó ṣe kọ irú òṣèlú tí PDP ń ṣe.
Eyi ni igba kọkanla ni ṣisẹ-n-tẹle ti Arsenal yoo maa ṣina iya fun Burnley lati oṣu kẹta ọdun 2009.
“Nítorí pé orílẹ̀-èdè kan láti ìhà àríwá ti gbógun tì í,yóo sọ ilẹ̀ rẹ̀ di ahoro,kò sì ní sí ẹni tí yóo gbé inú rẹ̀ mọ́,ati eniyan ati ẹranko, wọn óo sá kúrò níbẹ̀.
Bakan naa, niwaju awọn lọba lọba ipinlẹ Ondo nikalẹ, atawọn lọga lọga ikọ alaabo, gomina Akeredolu fi da awọn eeyan loju pe idibo to n bọ lọna yoo waye ni irọwọrọsẹ ati pe ipinlẹ naa ko ni faaye gba lilo janduku tabi iwa ọdaran lasiko idibo.
Àṣé ìtunmọ̀ nbẹ nínú ọ̀rọ̀ yìí  ju bí a ṣe rò lọ.
Lẹ́yìn tí Jehu kí i tán, ó bèèrè lọ́wọ́ rẹ̀ pé, “Ṣé ọkàn rẹ mọ́ sí mi bí ọkàn mi ti mọ́ sí ọ?
"Inu n bi wọn pe Trump n ti Kristẹni lẹyin ni, kẹẹ yaa tete mọ.
Eyi ni igba keji ti Arsenal fi iya panu lọwọ awọn ẹgbẹ agbabọọlu miran ninu idije Premiership laarin ọsẹ kan.
pẹpẹ tí a fi igi ṣe wà níwájú ibi mímọ́.
Orisun akọsilẹ yii wa lati itakun agbaye ijọ Satani Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
 Ẹ sọ ìlò afẹ́fẹ́ aláta àti ìbọn ònírọ́bà di òfin fáwọn obìnrin - Oluwo Èèyàn 389 ló tún lùgbàdì àrùn Coronavirus ní ọjọ́ Àbámẹ́ta ní Naijiria Ìlú yóò le, ọmọ le kú, àìsàn yóò pọ̀ bí eégún kò bá jáde nílùú Ibadan - Olóòlù ₦35,000 ni mò ń gbà bíi Adelé ọba, kò sí ọkọ̀ ayọ́kẹ́lẹ́ - Adelé Olúbọ̀rọ̀paAjikanle wa bẹ awọn ẹlẹyinju aanu lati bun owo lowo fi tọju apa kan, ẹsẹ kan to rọ naa nitori ko si iranwọ lati ibikíbi mọ."
Lara awọn eto pataki to waye lasiko ajọdun aadọta ẹgbẹ naa ni gige akara oyinbo, ọdun Ogun bibọ, abẹwo si awọn ibudo manigbagbe ati fifun awọ̀n eeyan jankan jankan lami ẹyẹ.
Ṣugbọn ileẹjọ to julọ ni Naijiria tu idajọ ti ileẹjọ kotẹmilọrun da fun un ka.
Ninu oro ti adele akowe agba eka iforotonileti egbe oselu APC, ogbeni Yekini Nabena, gbe jade.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Awọn eeyan ti n pe fun ọna to daju lati koju aarun iba Dokita Schellenberg ni ''Ko si ẹni to sọ pe ajẹbi idan ni abẹrẹ yi ṣugbọn yoo ni ipa ti yoo ko lati kojuaarun iba'' Ẹmẹrin ni wọn yoo fun eeyan labẹr yi,ẹmẹta laarin oṣu ti ẹni naa yoo si gba ikẹrin loṣu mẹjidinlogun lyin igba naa.
Ọ̀kan lọ sí oko rẹ̀, òmíràn lọ sí ìdí òwò rẹ̀.
Ọwọ́ tẹ babaláwo àti adigunjalè márùń ni Imo - Olọpàá Naijiria gbọdọ̀ jáwọ́ nínú ìwà rádaràda kí ‘Change’ lè wáyé -Buhari Ninu ọrọ oludari ajọ NEMA nipinlẹ Eko, Idris Muhammed, lo ti ni ajọṣepo laarin NEMA, ajọ awọn arinrinajo lagbaye IOM ati ajọ EU lo mu ki ipadawasile awọ́n atipo yii rọrun.
Laycon sọ pe awọn eeyan ma n ṣi oun tumọ lọpọ igba, ṣugbọn ou kii ni ẹnikẹni ninu nitori oninu ire ni oun jẹ.
ede Britain ni ojo keje,  osu kẹ́fà
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ondo marijuana: Naijiria kò fẹsẹ̀rinlẹ̀ tó láti gba igbó láàyè fún ìtọ́jú àìsàn- Onímọ̀ ìlera 16 Èbibi 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Gomina Ipinlẹ Ondo Rotimi Akeredolu ni ipinlẹ naa dara fun ọgbin igbo Dokita to n ṣe itọju ọpọlọ Raliat Akerele ti ṣe ikilọ wi pe wahala yoo bẹ silẹ ni Naijiria ti Ipinlẹ Ondo ba bẹrẹ si ni gbin igbo ti igbo naa si di oun ti ofin gba laaye ni orilẹee yii.
kí wọ́n sì ṣe ibùgbé fún mi, kí n lè máa gbé ààrin wọn.
Ninu atẹjade ti alukoro ajọ naa, Nosa Okunbor fọwọ si, o ni awọn ko si akitiyan lati yọ ọmọ ọdun mẹta ọhun ni lati nkan bii agogo mẹjọ ku iṣẹju mejidinlogun alẹ ọjọ abamẹta ni number 1 Gemini Bus Stop, Baruwa Ipaja.
Òun pàápàá dìde ó lọ sí Rama.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ọgá Ọlọ́pàá: Ẹ̀yin ọmọ Naijiria ẹ má bẹ̀rù, ọkọ̀ òfúrufú ọlọ́pàá yóò bẹ̀rẹ̀ sí ní káàkiri ìpínlẹ̀ 30 Ògún 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ilé-iṣẹ́ ọlọ́pàá lórílẹ̀èdè Naijiria ni àwọn gbé ìgbéṣẹ̀ yíì látì kójú ètò ààbò tó dẹnukọlẹ̀ ní Naijiria.
Olori ekun naa, Helen Zille, ni ogbele yii buru jojo nitori ida omi to wa ni agbami won bayii ko to ida ogun rara, bee, o seese ko ma si ojo pupo laarin awon ose to m bo.
Dandan ni pé kí òun túbọ̀ jẹ́ pataki sí i, ṣugbọn kí jíjẹ́ pataki tèmi máa dínkù.
Àwọn kan ninu àwọn ará Jerusalẹmu bẹ̀rẹ̀ sí sọ pé, “Ẹni tí wọ́n fẹ́ pa kọ́ yìí?
1 billion-oun nikan lobirin to wa ninu wọn.
Wọn á dùbúlẹ̀, wọn á máa lá àlá.
kuro lori pipese ipe, o tun ni”lopo odun ni ile-ise naa ti n koju isoro
" Fífọ idọti ara (Day 16-30) Ni kété ti ààwẹ ba ti dá si meji, gbogbo agọ ara ni yóò ti duro deede ni igbaradi fun ààwẹ náà.
”Ninu oro minisita to n mojuto eto idajo, Abubakar Malami (SAN), so pe, aare teleri ohun ko ni eridaju ti o fese mule pe isakoso ijoba re gbiyanju lati koju iwa ibajẹ lorile-ede Naijiria.
Nígbà náà ni àwọn eniyan náà gbéra ninu àgọ́ wọn láti la odò Jọdani kọjá pẹlu àwọn alufaa tí wọn ń gbé Àpótí Majẹmu lọ níwájú wọn, 
Wọn ni ọga ni kanwun lawujọ okuta ni orilẹede Afghanistan ati Irag.
Oríṣun àwòrán, Rotimi Akeredolu Facebook O ṣalaye pe oun ti pe Gomina Akeredolu lori ago ti o si ni pe oun ti kọja tan ki iṣẹlẹ naa to waye ati pe oun ko mọ pe iru nkan bẹ waye.
Aare fi ipinnu re han nibi ipade alatilẹkun-mọri ti igbimo akanse egbe APC se ni olu-ilu ile -egbe ohun ti o wa niluu Abuja.
Ẹgbẹ oṣelu All Progresives Congress (APC), ẹka ti Ipinlẹ Eko ti dibo yan Ọgbẹni Tunde Balogun gẹgẹ bi Alaga tuntun fun ẹgbẹ oṣelu naa ni Ipinlẹ Eko.
08 ni iseju kan - eyi to jẹ intanẹti to yara sikeji nilẹ Afirika lẹyin Cape Verde.
 Ileesẹ FBI ti gba wipe o kuna lati gbẹ igbẹsẹ kankan lori olobo ti wọn taa nipa afurasi Nikolas Cruz to yibọn pa awọn eniyan."
"Ọkọ̀ rélùwéè 16 yóò ná Eko sí Ibadan láti oṣù tó ń bọ̀ lọ - Iléeṣẹ́ Rélùwéè kéde Ọba Ilorin ló pàṣẹ pé kí ń padà sọ́dọ̀ ọkọ mi - Risikat olójú búlúù Ọkọ̀ tírélà epo forí sọ ọkọ̀ tírélà tó kó ẹja l‘Osun, ẹ̀mí èèyàn méjì sọnù Deji Akure pàṣẹ kí wọ́n ti gbogbo ọjà pa fún ọjọ́ méjì, ohun tó fàá nìyí Ọkan lara wọn, Andre Naidoo sọ fun ileeṣẹ iroyin AFP pe ""Ọsẹ meji ṣeyin, baba wa ṣi n la igi, ṣaka lara rẹ da, ko si si nkan kan to ṣelẹ si i."
“Bí ẹnìkan bá jẹ́ kí ẹran ọ̀sìn rẹ̀ jẹ oko olóko, tabi ọgbà àjàrà ẹlòmíràn, tabi tí ó bá da ẹran wọ inú oko olóko tí wọ́n sì jẹ nǹkan ọ̀gbìn inú rẹ̀, ibi tí ó dára jùlọ ninu oko tabi ọgbà àjàrà tirẹ̀ ni yóo fi dí i fún ẹni tí ó ni oko tabi ọgbà àjàrà tí ẹran rẹ̀ jẹ.
Ẹgbẹ́ òṣèlú PDP, ẹ̀ka ìpínlẹ̀ Eko fún Fayose lọ́jọ́ méje láti bẹ àwọn adarí ẹgbẹ́ A ti ń bimọ ju ǹkan tí apá orílẹ̀èdè lè ká lọ, ẹ má bí ju méjì, mẹ́ta lọ mọ́ o!
Nitori naa ni wọn parọwa si ijọba lati pese abẹrẹ ajẹsara fun awọn ọmọde kaakiri orilẹede Naijiria, ki wọn si mu imọtoto ati omi mimọ ni ọkunkundun.
O seese ki Adajọ tun nse agbende ẹsun naa Awọn onile itura ati awakọ naa lo pe awọn ọlọpa, ko to di wipe o gba ọkọ rẹ ni nnkan bi aago mẹjọ aarọ.
Alukoro fun egbe naa ogbeni Bolaji Abdullahi lo soro yii , lasiko to n ba awon akoroyin soro leyin ipade ti gbogbo awon alakoso egbe naa se  ni gbogan egbe naa, to wa niluu Abuja.
Sibẹ ó pàṣẹ fún ìkùukùu lókè,ó sì ṣí ìlẹ̀kùn ọ̀run sílẹ̀.
majẹmu tí ó bá Abrahamu dá,ìlérí tí ó ti ṣe fún Isaaki,
Kí ni ayé jẹ́ fún mi láìsí olùfẹ̀ mi!
Ki Adewọle o to yọ akọwe Yusuf nipo, igbimọ t'o ṣewadi lori aṣemaṣe nile isẹ eto ilera, sọ wipe ọgbẹni Yusuf lu owo ilu ni ponpo, to si ji owo awọn ar'ilu.
Fi ojurere wò wá, kí á lè là!
Awọn agbẹnusọ fun ile ẹjọ ti o gbẹjọ iwa ọdanran lagbaye naa sọ wipe wọn gbẹkẹle awọn ikanni alaye rẹpẹtẹ, pẹlu awọn ipinnu abajade ọrọ ti ijọba ti Kaduna ti ṣeto rẹ.
“Nígbà tí Mose di ẹni ogoji ọdún, ó pinnu pé òun yóo lọ bẹ àwọn ará òun, àwọn ọmọ Israẹli, wò.
 Esther pari ọrọ rẹ pe A ko tii le sọ pe ọna ababyọ kan gboogi ni eyi o, ṣugbọn ti ẹmi ba wa, ireti n bẹ.
Koda MC Oluọmọ kọ nọmba Mike gadagba sori opo Instagram rẹ fawọn ololufẹ rẹ pe ki wọn dibo fun Mike.
O ni iṣẹ atunṣe naa ti bẹrẹ bayii.
Tí à ń fìyà jẹ ara wa, ṣugbọn tí kò náání wa?
Ọkan gboogi lara ọmọ ẹgbẹ, Ọpẹyẹmi Bamidele atawọn mi i fara gba ọta ibọn.
Gbogbo àwọn eniyan sì ń bọlá fún wọn.
Lassa Fever: Dokíta mẹrin àti àwọn mẹ́tàdinlólogun ti kú ni Kano àti Ondo.
Ọgbẹni Sam Olumekun, Alakoso fun Ajọ Eleto Idibo, ẹka ti Ipinlẹ Eko ni o sọrọ yii di mimọ nibi Ipade Awọn Alẹnulọrọ ti ajọ INEC ṣe agbatẹru rẹ ni ifọwọsowọpọ pẹlu Eto Idaabobo Ara Ilu lorilẹ-ede Naijiria (Nigeria Policing Programme (NPP) ti Ipinlẹ Eko.
O ni lati ojo kinni osu kinni odun 2018 si ojo kerin osu keta, isele mokanlelogun le nigba ni won ti ri bayii.
Ọ̀nà láti sọ fásitì Lautech di ti Ọyọ nìkan ni Makinde ń sán - Ìjọba Ọṣun Akeredolu ò ṣe ǹkan àrítọ́kasi ni Ondo- Komísọnà ọ̀rọ̀ to n lọ tẹ́lẹ̀rí Ẹ máṣe gba ààwẹ̀ dójú ikú, ẹ gba iye tí agbára yín gbé - Dókítà Ọlabisi Ajala rèé, ó gun ọ̀kadà yíká àgbáyé, tó sì dé orílẹ̀èdè 87 Senatọ yii ni ijọba Naijiria ṣi ni iṣẹ lati ṣe lati gba owo itanran fawọn ti ọrọ kan.
Ta ló bẹ̀rù OLUWA ninu yín,tí ń gbọ́ràn sí iranṣẹ rẹ̀ lẹ́nu,tí ń rìn ninu òkùnkùn,tí kò ní ìmọ́lẹ̀,ṣugbọn sibẹ, tí ó gbẹ́kẹ̀lé OLUWA,tí ó fẹ̀yìn ti Ọlọrun rẹ̀.
 Ó sì fi ìlú Ọ ̀ yọ ́ sílẹ ̀ nígbẹ ̀ yìn-gbẹ ́ yín .
, Duration 8,0016 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 10:52 Fídíò, Kayode Williams ọmọ lẹyin Oyenusi, ògbóǹtarìgì adigunjalè tó ń fi àyípadà rẹ̀ ran àwọn ẹlẹ́wọ̀n lọ́wọ́, Duration 10,521 Owewe 2020 6:56 Fídíò, Wòlíì Kasali sọ̀rọ̀ nípa awuyewuye pé ó lé ìyàwó rẹ̀ jáde nílé, Duration 6,5628 Ọ̀pẹ̀̀ 2018 BBC News, Yorùbá Ìdí tí ẹ fi le è nígbàagbọ́ nínú ìròyìn BBC Ìlànà Lílò Nípa BBC Òfin Àṣírí Cookies Kàn sí.
Ọjọ keji ti wọn tu awọn ọmọ naa silẹ ni ọwọ tẹ wọn.
Ewe, iwadii safihan pe, awako oju-omi ohun gbase lodo eni ti o ni oko oju-omi naa, lati lo si ilu Misurata lorile-ede Libya, eyi ti o n lo bi igba kilomita o le, si apa ila-orun ilu Tripoli ti n se olu-ilu orile-ede Turkey lati lo ja eru naa sibe.
Swearing in 2019: Seyi Makinde ní òun kò yan igun ẹgbẹ NURTW kankan nípọ̀sìn
Kí ọkùnrin náà tóó mú ẹja tí ọba rán an dé, ọba ti ránńṣẹ́ sí àwọn ìjòy[r rẹ̀ wí pé kí wọ́n wá sí aafin òun.
Nígbà tí àwọn ará Amoni rí i pé àwọn ti di ọ̀tá Dafidi, wọ́n ranṣẹ lọ fi owó gba ọ̀kẹ́ kan (20,000) jagunjagun ninu àwọn ará Siria tí wọ́n ń gbé Betirehobu ati Soba.
Eyi ko ṣẹyin aṣẹ aarẹ Buhari pe ki awọn ile ijọsin pada bẹrẹ si ni si fun awọn eniyan lọna ati jẹ ki ofin konile-o-gbele rọle si ni Naijiria.
Lilo lo sọ bẹẹ ninu ifọrọwerọ kan pẹlu atukọ eto ọhun, Ebuka, lẹyin ti wọn fi ọwọ osi juwe ile fun un lori eto naa.
Aisha Buhari: Ìjọba kò le è ṣe àmúṣẹ ìlérí rẹ̀ tó bá yan alátakò sípò
324 èèyàn bá ẹ̀kún omi lọ Bóò ṣe lè yẹra fún ikú nígbà òjò - Onímọ̀ Ehi Iden Wo àwọn ìlérí tàwọn Gómìnà tuntun ṣe nínú ìbúra wọn Láìpẹ́, ará ìlú rẹ ni ọlọ́pàá tí yóò máa ṣọ́ ìlú rẹ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Omiyale Ile Ife: Dukia sọfọ, awọn eniyan si tun farapa Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Agbara omiyale pọ, ko si ibi ti ko le wo.
Ó bá lọ, ó kó àwọn ẹ̀mí meje mìíràn lẹ́yìn tí wọ́n burú ju òun alára lọ, wọ́n bá wọlé, wọ́n ń gbé ibẹ̀.
Abikẹyin naa ni sinima nikan ni ẹgbọn oun Michelle maa n wo lọpọ igba to ba wa nile, o si kundun ko maa jade lọ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, FUTA: Àwọn mẹ́jọ ló ṣíná ìyà fún Bolu ní FUTA Iṣẹ iwadii lagbaye ti gbọrẹjẹgijẹ de ibi ti burọọṣi ifọyin, foonu, ati ọpọ nkan idana naa ti n lo batiri bayii.
Ọpọlọpọ àwọn ọ̀dọ́ lo ti lùgbàdì aṣilo oogun nipa ẹgbẹ́kẹ́gbẹ́ àti àìní àbójútó àwọn òbí ati alagbatọ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Wole Soyinka: Buhari kọ́ ló ń darí wa ni ipo òṣèlú ṣe fì sí apá kan 6 Òkùdu 2020 Oríṣun àwòrán, Instagram/wolesoyinka Gbajugbaja onkọwe nni, ọjọgbọn Wole Soyinka ti koro oju si bi wọn ṣe pin ipo oselu ni Naijiria, to fi fi si apa kan ju ọkan lọ.
Bí àparò tíí pa ẹyin ẹlẹ́yinbẹ́ẹ̀ ni ẹni tí ó fi èrú kó ọrọ̀ jọ.
Wo àwọn ọmọ Naijiria mẹ́ta tó jáwé olúborí nínú ìdìbò sílé aṣòfin ilẹ̀ Amẹrika US election 2020: Bi kò tilẹ̀ wọlé, ẹ wo ayípadà tí Ààrẹ Trump mú bá awọn orilẹede ní àgbáyé Ajakalẹ aarun naa, ati ipa to ni lara ọrọ aje, gbe Trump ṣubu lori ileri idagbasoke ati ọrọ to fi n polongo ibo.
Ooni Crown Prince: Èyí ni bí wọ́n ṣe bí Àrẹ̀mọ tuntun Ọọ̀ni Adeyeye ti Ile Ife àti orúkọ tí ó kọ́kọ́ jẹ́
Sanitaisa to n fọ owo mọ: Ọkunrin kan to n ṣiṣẹ ifoworanṣẹ ni Kenya, Danson Wanjohi lo ṣe ẹrọ onigi to maa n fọ owo mọ lati ṣadinkun arun Covid-19.
Asamoah Gyan: O ṣeéṣe kí èyí jẹ́ ìdíje AFCON ìkẹyìn mi ''Òsìsẹ́ Custom tó déédé sọ ara rẹ̀ di Ọ̀gá Àgbà CG ní ìdàmú ọpọlọ'' Ẹ yé irọ́ pa, mí o fún Super Eagles ní ẹbùn owó kánkan -Sanwo Olu Ilé ẹjọ́ sún ẹjọ́ Sẹ́nétọ̀ Abbo síwájú pẹ̀lú béèlì mílíọ̀nù márùn-ún O ni ohun gbogbo ni oun n fi agbọn Badagry da ni ara bii kikọ ilé, ilẹkẹ, ṣiṣẹ ohun ọ̀ṣọ́ ara ati tinu ile, ṣiṣẹ apamọwọ loriṣiirisi ati bẹẹ bẹẹ lọ.
Uganda: Á lo owọ́ orí náà láti san gbèsè táa jẹ
Agbẹnusọ fun Sẹ́nẹ́tọ̀ DIno Mélayé, Gideon Ayọ̀délé lo lede oro yi fún BBC Yorùbá ninu iforowanilenuwo kan lori ẹro ibanisọrọ.
“Bí ọ̀run tuntun ati ayé tuntun tí n óo dá, yóo ṣe máa wà níwájú mi, bẹ́ẹ̀ ni arọmọdọmọ ati orúkọ rẹ̀ yóo máa wà.
aleefa lọdun 1979, aare ana ki i je ki awon adari to wa lori aleefa leyin re,  fi ẹdọ lori oronro, koda ko yo egbe oselu to
 bí ó tilẹ ̀ jẹ ́ pé a pilẹ ̀ àjẹsára náà nínú sẹ ́ ẹ ̀ lì adìẹ , a lè lòó fún àwọn tó ní ìfèsì ara lọ ́ nà òdì sí ẹyin .
Buhari ti kú: Ní Oṣù kẹsan an, ọdún 2017 ni Iròyìn gbòdé pé ààrẹ Nàìjíríà Muhammedu Buhari kú.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Òṣìṣẹ́ reluwé tó bá gbé owó gun tíkẹ́ẹ́tì, yóò gé ìka jẹ - Amaechi Àwọn adigunjalè pa èèyàn mẹ́fà ní báńkì kan nìpínlẹ̀ Ondo “Kò sí àgbègbè Nàìjíríà kánkan tó wà lábẹ́ àkóso Boko haram” Wo bí o ṣe lè kọ́ ọmọ rẹ lẹ́kọ̀ọ́ ìbálòpọ̀ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Parental Guidance: Ọdún méjì ni kí ẹ ti bẹ̀rẹ̀ kíkọ́ ọmọ nípa ìbálòpọ̀ Iroyin naa ni Ọjọ Keji, osu Kẹjọ ni eto ipolongo ibo yoo bẹrẹ ni ipinlẹ mejeeji, ti yoo si wa sopin ni ọjọ Kọkanlelọgbọn, osu Kẹwa, ọdun 2019 naa.
ASP Nansel sọ pe bi awọn ṣe jọ doju ibọn kọ ara awọn fihan pe awọn agbebọn naa pọ gan-an.
Harry and Meghan: Olóòtú Canada ní ọ̀rọ̀ gbọ́dọ̀ wáyé nípa ìgbésẹ̀ wọ̀n
Dabiri fesi si ọrọ yi ni idahun si ibeere akọroyin ile iṣẹ iroyin Vanguard lasiko idibo atundi to waye nipinlẹ Eko lọjọ Abamẹta.
Àkọlé àwòrán, Dokita mẹjọ lo ti ba arun lassa lọ ni Naijiria O ni akẹkọ fasiti ipinlẹ Ebonyi ni arakunrin ti wọn mu pẹlu arun iba Lassa ati pe, ibudo ikẹkọ agba nipa ofin, to wa ni ilu Eko lo wa lati gba imọ kun imọ nipa ẹkọ imọ ofin, ko to di pe aarẹ muu.
Jesu Mú Wèrè, Ará Geraseni, Lára dá.
11 Àti pé bí ìwọ bá béèrè, ìwọ yíò mọ àwọn ohun ìjìnlẹ̀ títóbi àti yíyanilẹ́nu; nítorínáà ìwọ yíò lo ẹ̀bùn rẹ, kí ìwọ lè wá àwọn ohun ìjìnlẹ̀ rí, kí ìwọ lè mú ọ̀pọ̀lọpọ̀ wá sí ìmọ̀ ti òtítọ́ náà, bẹ́ẹ̀ni, ní yí wọn lọ́kàn padà nínú àṣìṣe àwọn ọ̀nà wọn.
Nígbà náà ni Pilatu sọ fún un pé, “Èmi ni ìwọ kò dá lóhùn?
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Tope Alabi: Ìlúmọ̀ọ́ká akọrin ẹ̀mi náà ní ìdílé kòlà-kòṣagbe l'òun ti wá 6 Ògún 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 27 Ọ̀wàrà 2019 Oríṣun àwòrán, Instagram/Tope Alabi Gbajugbaja akọrin ẹmi nni, Tọpẹ Alabi to pe ẹni ọdun mọkandinlaadọta lọjọ Aiku, ọjọ kẹtadinlọgbọn oṣu kẹwaa ọdun 2019 sọ fun BBC Yoruba pe, idile kola-kosagbe ni oun ti wa.
Farao bá sọ fún Josẹfu pé, “Níwọ̀n ìgbà tí ó jẹ́ pé ìwọ ni Ọlọrun fi gbogbo nǹkan yìí hàn, kò sí ẹni tí ó gbọ́n, tí ó sì lóye bíi rẹ.
Ojú alágbe ni wọ́n fi ń wo alága ìdúró- Ayo Oladokun Ìpanu ‘Cheese ball’ ni wọ́n fi jí Ikimot gbé, àmọ́ ó padà sílé lẹ́yìn ọdún márùn-ún ìfipábánilòpọ̀: Má dákẹ́ - Oluwaseun Wọ́n ta ère Ọ̀ṣun Osogbo sí Togo - Bàbá Ọṣun figbe ta Baṣọ̀run Gáà, tó yan ọba mẹ́rin, pa ọba mẹ́rin àmọ́ ọba karùn-ún ló pa á Ọbasanjọ sọ àsírí sàgbàdèwe rẹ̀ Jesu Oyingbo rèé, pásítọ̀ tó láṣẹ ìbálòpọ̀ lóri ọmọ ìjọ obìnrin Igbó mímu lè ṣe kóríyá, kò lé fi kún orín ẹnu òṣèré - 9ice Ìtàn tó wà nídi òwe ‘Sebótimọ Ẹlẹ́wà Sàpọ́n’ Ọba Adesoji Aderemi, Ọọ̀ni Ifẹ̀ tó gba ipò ọba mọ́ tòṣèlú MKO Abiola, iṣẹ́ aṣẹ́gità ló fi bẹ̀rẹ̀ okoòwò Iṣọla Oyenusi rèé, ẹnití ìfẹ́ obìnrin ṣun dé ìwà ìdigunjalè Taiwo Akinkunmi, ọmọ Ibadan tó ya àsìá Naijiria Ayinla Ọmọwura, orin èébú àti oríyìn lo fi di ọ̀rẹ́ àwọ̀n obìnrin O ni oun lee ka bii ejo ati ẹja, eyi si lo gba ẹmi oun lọwọ ewu nigba ti oun ja bọ lati ori oke bọ wa silẹ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù JAMB post UTME screening: UNN, MAPOLY, Auchi poly, AKSU àtàwọn míì ti bẹ̀rẹ̀ ìgbésẹ̀ àtiwọlé ní Naijiria 26 Èbibi 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 12 Ògún 2020 Oríṣun àwòrán, Others Awọn ileewe giga kọọkan lorilẹ-ede Naijiria ti bẹrẹ si ni ta fọọmu idanwo Post UTME fun awọn akẹkọọ ṣẹṣẹ fẹ wọ ileewe giga.
32) ti Obinrin si jẹ 396, 361 ( ida 52.
Buhari ni oun yoo ya agbado haa si awọn to n pe oun ni ''baba go slow'' lẹnu ni saa keji yii.
Oriṣiiriṣii ni awọn eeyan n ka lasiko yii nipa awọn iṣẹ maleegbagbe ti Ibrahim Magu ṣe lasiko to fi tukọ ajọ EFCC to n gbogun ti iwa jẹgudujẹra ni Naijiria.
Lanlẹhin ni lori eto abo ni ohun to n fa wahala ni ilu yoo gba amojuto nipa ipese iṣẹ.
UK ṣetán láti dá Adìyẹ 'Àkùkọ' Nàíjìrìa ti wọ́n gbé padà Gbèsè Nàìjíríà yóò di $50b tí wọ́n bá tún yáwó- Shehu Sani Aàrẹ Trump kọ̀ láti jẹ Tòlótòló ìsìn ìdúpẹ́ 2019 nílé, ó gba Afghanista lọ!
Àwọn ọmọ Israẹli bá dá OLUWA lóhùn pé, “A ti dẹ́ṣẹ̀, fi wá ṣe ohun tí ó bá wù ọ́.
Eyi kò jẹ ki o ṣeeṣe fawọn agbofinro lati kọlu wọn.
OLUWA, ìfẹ́ rẹ tí kì í yẹ̀ ga kan ọ̀run;òtítọ́ rẹ sì kan ojú ọ̀run.
Ó yá ẹ pa òwe kan tí Ọ̀RỌ̀ jẹ jáde nínú è.
Wọ́n ti da ẹ̀jẹ̀ wọn sílẹ̀ bí omi, káàkiri Jerusalẹmu;kò sì sí ẹni tí yóo gbé wọn sin.
Ẹkunrẹrẹ fidio yii ṣe afihan bi omi ti wọn n mu ṣe pupa, ti ko si yẹ fun mimu tabi lilo.
Nigbati wọn gba Ìjọba lọ́wọ́ àwọn Òṣèlú ti ó ba ilú jẹ́ pẹ̀lú iwà ìbàjẹ́ ti wọn fi kó ilú si igbèsè lábẹ́ Olóri Òṣèlú Shehu Shagari, wọn fi ìkánjú ṣe idájọ́ fún àwọn tó hu iwà ibàjẹ́, eleyi jẹ ki ilú ké pé Ìjọba wọn ti le jù.
MA - BBC News Yorùbá BBC News, YorùbáFò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Owó làwọn olóṣèlú mọ̀ ni wọ́n ṣe fẹ́ kí dókítà lọ sókè òkun - NMA 24 Ìgbé 2019 Oríṣun àwòrán, @Gebrekiros Ẹgbẹ awọn dokita lorilẹede Naijiria, NMA ti bu ẹnu atẹ lu ọrọ ti minisita fọrọ isẹ, Chris Ngige sọ wi pe, awọn dokita pọ yanturu lorilẹede Naijrria, nitorina aaye si silẹ fun awọn dokita to ba fẹ kuro nilẹ yii lọ si oke okun.
A kò ní fárí apá kan, dá apá kàn sí nínú ìjọba wà - Buhari PDP fáríga lórí èsì Idibò PDP pè fún ìwọ́gilé èsì ìdìbò ààrẹ ní ìpínlẹ̀ mẹ́rin .
Oríṣun àwòrán, EPA Ajakalẹ arun ''adenovirus'' ti o maa n sokunfa ikọ hihu ati otutu ni wọn lo lati fi ṣe oogun naa ti yoo mu ki eroja 'immune' ara ko gbokun sii.
Ninu oṣu karun ọdun 2018, lasiko ti igbẹjọ n lọ lọwọ, ṣaa dede ni agbẹnusọ fun ẹgbẹ oṣelu PDP tẹlẹ ri, Olisa Metuh ṣubu yakata silẹ nigba ti wọn pe e to fẹ maa rin lọ sinu koto ijẹjọ to si fa ariwo hee nile ẹjọ.
Apapọ awọn ero to fara gbọgbẹ ninu ijamba naa ni mọkandinlọgọta, ti eeyan kan si gbẹ mi.
Ijọba Naijiria figbe ta lọjọ Ẹti pe El-Zakzaky n gbero lati lọ ṣe atipo nilẹ okere, bakan naa ni ijọba sọ pe iwuwasi El-Zakzaky lorilẹede India doju ti ijọba orilẹede naa ati ti Naijiria.
Ọlawale fi ẹsun kan pe awọn oloṣelu nla, ati awọn Ọba alaye maa n ṣaaba bẹbẹ pe ki ijọba fi awọn afipabanilopọ ti ọwọ ba tẹ silẹ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Malabu Deal: Ìgbẹ́jọ́ bẹ̀rẹ̀ lóri rìbá tí Eni, Mobil san fún Nàíjíríà 26 Bélú 2018 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ọrọ lori owo epo rọbi Ile ẹjọ kan ni ilu Milan lorilẹede Italy ti bẹrẹ si gbọ ẹsun iwa ajẹbanu ti wọn fi kan ile iṣẹ epo rọbi meji, Eni ati Shell lori owo epo to jẹ ki Naijiria padanu biliọnu mẹfa naira.
Ní tèmi, mò ń gbìyànjú láti ṣe ohun tí ó wu gbogbo eniyan ní gbogbo ọ̀nà.
wa laarin ijọba ipinlẹ yii, awọn ijọba ibilẹ ati Iko LSNC.
 Ó máa ń kọ ìtàn-àròsọ àti ewì .
Mo parí iṣẹ́ àṣepatì 239, iṣẹ́ 236 míì ń lọ lọ́wọ́ - Seyi Makinde Nǹkan oṣù obìnrin le jáde ní imú tàbí ìdodo yàtọ̀ sí ojú ara - Dókítà Ni Ọjọ Eti, ni ile Aarẹ ni Amerika, White House wa ni tit pa lẹyin ti awọn eniyan fariga ni iwaju ile aarẹ ohun.
Ó ṣe ohun tí ó burú lójú OLUWA.
Àwọn mìíràn ń sọ pé, “Òun ni Mesaya.
O rọ awọn ọdọ lati ri ifẹhọnuhan EndSars gẹgẹ bi ọna ati beere fun ọjọ ọla to dara lọwọ ijọba, eleyii ti wọn wa n lo lati ba ohun ini ijọba jẹ.
"Idunnu mi ni wi pe a n gba awọn eniyan la, ki wọn ma ba a ku sinu omi.
Ẹ kọ orin sí Ọlọrun ẹ̀yin ìjọba ayé;ẹ kọ orin ìyìn sí OLUWA.
Ajo eleto idibo n fi da awon ara-ilu loju pe, ohun yoo seto idibo ti ko ni kolofin ninu.
Amọ fun Abdullahi Olatoyan, ẹni to n fi isẹ fifọ gilaasi ọkọ loju popo se isẹ jẹun, isẹ naa n tii loju pupọ, to si nira fun lati kọ̀nu ifẹ́ si obinrin.
gba lati ile-ise ifowopamo  ijoba apapo  to wa ni ipinle Calabar  si  awon
 Nitori pe, Israel ni eto lati le daabobo ara won.
Sẹ́nétọ̀ Dino Melaye kéde láti dupò gómìnà Kogi Bàálù to gbe Yẹmi Oṣinbajo já lulẹ̀ ní Kabba nípìnlẹ̀ Kogi Àwọn agbébọn jí alága ẹgbẹ́ òsèlú PDP gbé ní Kogi Ilé ẹjọ́ fagilé ìpè Dino láti wá kó Ọlọ́pàá kúrò nílé rẹ̀ Wòlíì Kasali ní Dolapo Awosika kò lé ìyàwó òun jáde Mẹtadinlogun ninu aṣofin mọkandinlogun to wa ni ile naa ni wọn fi ọwọ si igbesẹ naa; ti wọn si fun adajọ agba ni gbedeke ọjọ meje lati gbe igbesẹ agbekalẹ igbimọ naa.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Amọṣa, ọga ọlọpaa naa ti ni nibi ti ọrọ de duro bayii, ilu Akurẹ gan an ni ki wọn ko gbogbo wọn wa si fun ayẹwo.
Tánńganran kúnlé gbári, ohun ọ̀sọ́ kò sì lóhùnkà.
55 Ati lati ríi pé ìjọ nní ìpàde papọ̀ nígbàkúùgbà, àti bákannáà lati ríi pé gbogbo ọmọ ìjọ nṣe ojúṣe wọn.
Heṣiboni ni olú ìlú Sihoni, ọba àwọn ará Amori.
Ẹ yàgò fún ìwà adìẹ dàmí lóògùn nù, màá fọ lẹ́yin lásìkò ìjà - Buhari Iṣẹ́ bọ́ lọ́wọ́ ọ̀gá ilé iṣẹ́ ológun lórí ikú Fulani 134 Ọmọ ìjọ Èṣù ni Linda Fairstein -Femi Fani Kayode Olùdíje mẹ́rin ti Gbajabiamila lẹ́yìn ṣáájú ìbò ilé aṣojú ṣòfin Bakan naa ni wọn fẹsun kan awọn agbebọn kan ni Dongon ti wọn n pè ni Dan Na Ambassagou'."
aare tun so pe ,”owo to n bo sinu apo ipamo ile okeere wa, tun ti le si laarin osu karun un odun 2018 ti a wa yii.
Ó mọ ohun tí ọ̀nà igbagbọ jẹ́ dáradára.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Àwọn oúnjẹ tó n gbayì níbi ayẹyẹ báyìí ‘Olùkọ́ fipá bá akẹ́ẹ̀kọ́ girama lòpò nítorí máàkì’ Tinubu kìlọ̀ fún Buhari lórí ohun tó leè ṣàkóbá fún sáà kejì rẹ̀ Mìmì kan kò mì wá, Ẹlẹka yóò jíǹde bí i Lasaru inú Bíbélì -PDP Ekiti Ogbeh gbe ọrọ yii kalẹ lati fi pariwo ọwọja bi awọn eeyan ṣe n ko nnkan wọle sorilẹede Naijiria sita ni.
Johanu sọ fún gbogbo eniyan pé, “Omi ni èmi fi ń ṣe ìwẹ̀mọ́ fun yín, ṣugbọn ẹni tí ó jù mí lọ ń bọ̀.
Àwọn èròngbà kòòsí ìlò èdè Yorùbá yíì ni pé mo fẹ́ kí àwọn akẹ́kọ̀ọ́ mọ èdè Yorùbá lo dáradára nítorí náà a wo ìjúba ni awùjọ Yorùbá, a wo ààtò, Ìtúmọ̀, ìlò, àti àgbéyẹ̀wò àwọn òwe, àkànlò èdè àti ọ̀rọ̀ àmúlò mííràn.
Lẹyin naa ni ijọba gbe asaaju ẹgbẹ Revolution Now ọhun lọ sile ẹjọ lori ẹsun pe o gbimọ lati da omi alaafia Naijiria ru to fi mọ lilu jibiti ati tita abuku aarẹ Muhammadu Buhari.
Ọrọ yii jẹ jade nigba tawọn agbẹjọro Adeyinka Olumide-Fusika (SAN) ati Adesina Ogunlana fi ọrọ wa ọgagun naa lẹnu wo.
Àwọn ọmọ Nàìjíríà ní bí ẹni pé ènìyàn n fọṣọ ìdọ̀tí rẹ̀ níta gbangba lọ̀rọ̀ náà rí to sì tini lójú gẹ́gẹ́ bí orílẹ̀-èdè.
"Oríṣun àwòrán, mrwoodberry/TWITTER Àkọlé àwòrán, Olalekan Jacob Ponle ti awọn eeyan mọ si Woodberry ati Hushpuppi lọwọ awọn ọlọpaa Dubai tẹ Oludari ileesẹ ọtẹlẹmuye FBI Christopher Wray wa kan sara si awọn ọlọpaa ilẹ Dubai, fun iṣẹ ribiribi ti wọn ṣe lati mu Raymond Igbalode Abbas, ti awọn eeyan mọ si ""Hushpuppi"" ati Olalekan Jacob Ponle, ti inagijẹ rẹ n jẹ ""Woodberry""."
Bakan naa ni amugbalẹgbẹ fun gomina, Muhammad Funtua sọ fun BBC pe eto ti wa nilẹ pe Aarẹ Muhammadu Buhari yoo yọju si awọn ọmọ naa lọjọ Ẹti.
21 Ọ̀pẹ̀̀ 2019 Ọjọ kejidinlogun, oṣu Kejila ni ile aṣoju-ṣofin ilẹ̀ Amẹrika dibo yọ Aarẹ orilẹede naa, Donald Trump nipo.
Bakan naa lo ni laarin ọdun 1984 si ọdun 1989 ko si igba kankan ti ọlọpaa ikọ naa kankan lori laya lati yinbọn pa araalu.
Òun ni ó dá ẹ̀mí wa sí ní gbogbo ọ̀nà tí a tọ̀ láàrin gbogbo àwọn orílẹ̀-èdè tí a là kọjá.
Ohun ti ẹni to ba n tọ sile ko gbọdọ ṣe; Ma sọ wi pe o ko ni mu omi nitori ati mase tọ sile, amọ ki ẹni naa ma a mu omi ni owurọ ati ọsan yatọ si aṣalẹ.
Orúkọ ọmọ ni Yorùbá gbà pé ó máa ń ro ọmọ nílẹ̀ Oodua
Ṣebí o mọ̀ pé mo ti kọ̀ ọ́ lọ́ba lórí Israẹli.
ÒMÙGỌ́DIMẸ́TA GORÍ OYÈ SỌ̀PỌ̀NNÁ GBÉ ÒMÙGỌ́DIMÉJÌ LỌ
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Lagos Kidnap: Wo ohun tí ọlọ́pàá ti ṣe nípa àwọn méje tí wọ́n jí gbé l'Eko 8 Ìgbé 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Awọn ọlọpaa Naijiria Ile iṣẹ Ọlọpaa ipinlẹ Eko ti sọrọ lori ibi ti wọn ba iṣẹ de lori ọrọ adari kan nile iṣẹ pana-pana, Rashidi Musbau atawọn mẹfa mii ti wọn ji gbe.
 O ni  nipa nini ẹmi ifẹ ati alaafia lati fi bara wa lo ni aami ti oṣu Ramadan duro fun.
9 151066 Orilẹede Luxembourg 549 90.
Hesekaya sì ń ní ìlọsíwájú ninu gbogbo iṣẹ́ rẹ̀.
Ninu iwe ẹhonu ti agbẹnusọ igbimọ naa, Festus Keyamo, kọ, wọn ni awọn eeyan kan lati gbPDP fi ọna ojoro wọ oju opo Inec ki wọn ba le gbe esi ibo ayederu wọ ibẹ.
Nítorí nígbà tí eniyan Ọlọrun sọ fún ọba pé, “Ní ìwòyí ọ̀la, lẹ́nu bodè Samaria, àwọn eniyan yóo máa ra òṣùnwọ̀n ìyẹ̀fun kíkúnná kan tabi òṣùnwọ̀n ọkà baali meji ní ìwọ̀n ṣekeli kọ̀ọ̀kan,” 
Ojú ọba yipada, ẹ̀rù bà á, ara rẹ̀ ń gbọ̀n, orúnkún rẹ̀ sì ń lu ara wọn.
nipa  ina mona-mona, ipese isẹ, eto aabo,
 ohun ni eni pataki ju nigba iyipada larin igba orin klasika ati romantik ninu orin klasika europe , be sini o je alakopo orin togbajulo ati tonipajulo .
Amọ, ẹpa ko boro mọ nitori nigba ti yoo fi de ileewosan ijọba ni Owo, Oba ti tẹri gbasọ.
Ọ̀fọ̀ ṣẹ̀ lágbo eré bọ́ọ̀lù, Reyes to gbá bọ̀ọ́lù fún Arsenal rí jáde láyé Wọ́n ti ni kí àwọn alága ìjọba ìbílẹ̀ Ogun lọ rọọ́kún nílé Àràmọ̀ǹdà àwòràn láti ilẹ̀ àdúláwọ̀ lọ́sẹ̀ yìí Ajimobi tako àṣẹ iléẹjọ́ pẹ̀lu ìbò ìjọba ìbílẹ̀ tó ṣe - Ìjọba Ọyọ Harry Kane ni ẹlẹsẹ ayo fun Tottenham nigba ti Mohamed Salah si jẹ ẹlẹsẹ ayo fun Liverpool.
Àárẹ̀ mú ọ nítorí ìrìn àjò rẹ jìnnà,sibẹsibẹ o kò sọ fún ara rẹ pé, “Asán ni ìrìn àjò yìí.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Nigba ti o di Ọjọ Keji, Dangote ni ohun da owo naa pada si banki.
AFCON: Cameroun kò ní leè gbàlejò ìdíje nítorí àwọn kùdìẹ̀-kudiẹ kan
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Ẹlẹha naa to ni wọn lo iṣuju fun oun ni sọ pe lẹyin ti oun kuro ni ọja naa ni oju oun to la lati rii pe gudẹ ni awọn obinrin naa gbe le oun lọwọ dipo bata ti o lọ ra.
Èyí tí ó kọ́ yà mí lẹ́nu ni èyí pé, ojú ọ̀nà ilé Ikú kún fún ẹ̀jẹ̀ gbogbo, àwọn ewéko tí ó sì wà lójú ọ̀nà kún fún ẹ̀jẹ̀ pẹ̀lú, síbẹ̀síbẹ̀ Bab-onírùngbọ̀n ń tẹ orí ẹ̀jẹ̀ náà lọ láìbìkítà, ‘rùngbọ̀n rẹ̀ sì bẹ̀rẹ̀ sí pa mí lẹ́rìn-ín bí ó tí ń wọ́lẹ̀ guruguru, tí ó ń la inú ẹ̀jẹ̀ lọ.
A ti fi ohun tí ó dára hàn ọ́, ìwọ eniyan.
Wo àwọn Adelé-Ọba aládé méje tó jẹ́ obìnrin nílẹ̀ Yorùbá Èyí ni àwọn aṣíwájú ìjọba tí ajé ìwà ìjẹkújẹ ti ṣí mọ́ lórí láàrin ọdún 1960 sí àsìkò yí Mi ò le tòṣì láéláé!
"Àtúnṣe àwọn àjápọ̀ èdè míràn"" Àtunṣe ojúewé yi gbẹ̀yìn wáyé ni ọjọ́ 18 Oṣù Kẹ̀sán 2016, ni ago 08:08."
kí ó má ka ẹ̀yà Lefi mọ́ àwọn ọmọ Israẹli nígbà tí ó bá ń kà wọ́n.
Mose rán oníṣẹ́ láti Kadeṣi sí ọba Edomu pé, “Arakunrin rẹ ni àwa ọmọ Israẹli jẹ́, o sì mọ gbogbo àwọn ìṣòro tí ó ti dé bá wa.
OLUWA bá tún sọ fún Elija pé, 
Ẹ̀wẹ̀, wọ́n ti pe àwọn ìwé ẹ̀rí tó sọ pé òun ní níjà.
Ewe, eyi je igba kesan an bayii ti arun Ebola yoo be sita lorile-ede DR Congo lati odun melo kan seyin ti won ti sawari arun ohun letido abule kan.
Sogbogbe ni o asiko ti Adam Oshiomole yọ gbogbo awọn adari nipo ni ileẹjọ wa gbe ọpa aṣẹ le Giadom lọwọ lati tukọ ẹgbẹ naa.
Àwọn ọmọ wọn lọ sí ilẹ̀ náà, wọ́n sì gbà á, o ṣẹgun àwọn ará Kenaani tí wọn ń gbé orí ilẹ̀ náà tẹ́lẹ̀, o sì fi wọ́n lé àwọn ọmọ Israẹli lọ́wọ́, àtàwọn, àtọba wọn, àtilẹ̀ wọn, kí àwọn ọmọ Israẹli lè ṣe wọ́n bí wọ́n bá ti fẹ́.
Nisinsinyii ó jẹ́ ohun ìjọjú fún àwọn ẹlẹgbẹ́ yín àtijọ́, nígbà tí ẹ kò bá wọn lọ́wọ́ sí ayé ìjẹkújẹ mọ́, wọn óo wá máa fi yín ṣe ẹlẹ́yà.
Antonella Roccuzzo lati Argentina to je iyawo Lionel Messi ti awọn kan gba pe oun lo mọ bọọlu gba ju lagbaye lasiko yii.
Nítorí pé iṣẹ́ kan náà ni wọ́n ń ṣe, Paulu lọ wọ̀ lọ́dọ̀ wọn, ó sì ń ṣiṣẹ́.
Ni bi a ṣe n sọrọ yii, gba-gba-gba lawọn agbofinro wa nikalẹ lati mojuto eto abo ni ile ẹjọ naa.
 Ìlú kọ ̀ ọ ̀ kan ló ní àwọn ẹgbẹ ́ yìí fún ra rẹ ̀ .
"Dokita Black tẹsiwaju pe ""Gbogbo nnkan ti bẹrẹ si n dojuru,"" lẹyin naa lo fidi rẹ mulẹ fun BBC pe awọn alaisan ma n ja si ẹrọ to n ran eemi lọwọ nile iwosan Livingstone to wa ni Port Elizabeth."
maa jẹ ohun elo fun awon oloselu.
Gẹ́lẹ́ ti Gomina tuntun ti ipinlẹ Eko Babajide Sanwoolu gun ori pepele lati burawọle niwaju adajo lojo bẹrẹ si ni bọ́ to bẹẹ̀ ti wọn sare ga agboojo le gomina tuntun lori.
Taraba Ni ọjọ Satide, ọjọ kẹrinlelogun, oṣu Kẹwaa ọdun 2020 ni awọn kan bori awọn ẹṣọ alabo, ti wọn si kọlu ile ti ijọba ipinlẹ naa ko ounjẹ Covid-19 si.
Ni ó bá kúnlẹ̀, ó kígbe, ó ní, “Oluwa, má ṣe ka ẹ̀ṣẹ̀ yìí sí wọn lọ́rùn.
Àwọn ìpínlẹ̀ mẹ́fà bi Ondo, Oyo, Rivers, Zamfara, Borno, àti Bauchi ní èèyàn kọ̀ọ̀kan Àjọ NCDC kéde èèyàn 248 míràn tó ni ààrùn Covid-19 lórílẹ̀-èdè Naijíríà Àkọlé àwòrán, Àjọ NCDC kéde èèyàn 248 míràn tó ni ààrùn Covid-19 lórílẹ̀-èdè Naijíríà Àjọ tó ń gbógun ti àjàkálẹ̀ ààrùn lórílẹ̀-èdè Nàìjíríà NCDC lọ́jọ́ àìkù ti kéde pé ènìyàn ìgbàléméjìdíláàdọ́ta ni àyẹ̀wò tún fi hàn pé o ti ní ààrùn Coronavirus lórílè-èdè yìí ti àpapọ̀ àwọn to ni ààrùn náà ni Nàìjíríà sì ti di ẹgbẹ̀rún mẹ́rin àti mọ́kàndínnírinwó.
Ọlọrun yìí ni ààbò mi tí ó lágbára,ó mú gbogbo ewu kúrò ní ọ̀nà mi.
Ìgba tí a bá ń padà bọ̀ a ní ìrètí pé ojú àwọn Èdìdàrẹ́ yóó ti là.
Ṣugbọn ileeṣẹ aarẹ sọ wi pe irọ ni iroyin igbeyawo naa.
Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Lagos, Delta Curfew: Sanwo Olu ní kí àwọn òṣìṣẹ́ ìjọba padà sẹ́nu iṣẹ́ ní Eko, Delta sọ tirẹ̀ dí aago mẹ́jọ alẹ́ sí mẹ́fà ìdájí1 Bélú 2020 5:55 Fídíò, Soyinka Cancer: Àṣe ara mi ni iso ti n run gbogbo bí mo ṣe n ṣèrànwọ́ lórí jẹjẹrẹ, Duration 5,5527 Bélú 2019 Èyí tí a wò jùlọ 5:03 Fídíò, Omolola Arohunmolase Welder: Mo ti fí iṣẹ́ 'Welder' gbayì láwùjọ, tó mo fi tọ́ ọmọ yanjú, Duration 5,039 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 5:39 Fídíò, Akomolede ati Asa lori BBC: Olùkọ́ Kikelomo Ogunboye tan ìmọ́lẹ̀ sí ìwà olè ọ̀gá ọlọ́pàá Audu gẹ́gẹ́ bí àwòkọ́ṣe àsìkò yìí, Duration 5,398 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 4:11 Fídíò, Oba Adeyeye Ogunwusi: Ojú mi ti rí lọ́pọ̀ lọpọ̀, ọ̀pọ̀ èèyàn ni kò tilẹ̀ gbàgbọ́ pé mo lè jọba- Ooni, Duration 4,117 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 4:43 Fídíò, Promise Akinlade: ọmọ ọdún mọ́kànlá tó ń fi ìlù dárà bíi àgbàlagbà sọ̀rọ̀ nípa tálẹ́ǹtì rẹ̀, Duration 4,437 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 0:59 Gbọ́, Ìsẹ̀lẹ̀ jákèjádò orílẹ̀èdè àgbáyé láàárín ìṣẹ́jú kan, Duration 0,59wákàtí 6 sẹ́yìn 4:45 Fídíò, Yoruba Films: Ẹ̀ẹ́ bẹ̀ mi kúrò láyé ni, mi ò lè kú - Fadeyi Oloro, Duration 4,4526 Èrèlè 2020 7:03 Fídíò, Olumuyiwa Bolade Adedeji Military Bruitality: Bí arákùnrin onípèníjà ara tí sọ́jà lù ṣe dé, Duration 7,035 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 2:48 Fídíò, Esther Ajayi: Èmi náà ti borí ìṣòro rí ló ń mu mi ṣojú àánú, Duration 2,481 Ògún 2019 6:08 Fídíò, Adebola Ademilua: Àìrísẹ́ ṣè lẹ́yìn ìwé kíkà ló sọ mi dí ìyá onírú, mo dúpẹ́ tèmi, Duration 6,0827 Bélú 2020 5:55 Fídíò, Soyinka Cancer: Àṣe ara mi ni iso ti n run gbogbo bí mo ṣe n ṣèrànwọ́ lórí jẹjẹrẹ, Duration 5,5527 Bélú 2019 BBC News, Yorùbá Ìdí tí ẹ fi le è nígbàagbọ́ nínú ìròyìn BBC Ìlànà Lílò Nípa BBC Òfin Àṣírí Cookies Kàn sí.
Kenyan Woman: Aláboyún fi bílédìì gbé ọmọ jádé nínú ara a rẹ̀ ní Tanzania
''Ọpọlọpọ awọ̀n ara abule to n sa a lọ lo si farapa, ti awọn kan tilẹ kan ni ẹsẹ.
Mose bá sọ fún Kora pé, “Ní ọ̀la kí ìwọ ati àwọn ẹlẹgbẹ́ rẹ wá siwaju Àgọ́ Àjọ.
Wọ́n yan àwọn akọrin, Hemani, Asafu ati Etani láti máa lu aro tí wọ́n fi idẹ ṣe 
Aarẹ Buhari ni aarẹ ti Rex Tillerson ṣe ipade pọ pẹlu gẹgẹ bi aṣoju ati akọwe ijọba orilede America.
N óo fún àwọn ará ìlà oòrùn ní òun ati ilẹ̀ Amoni, wọn óo di ìkógun, kí á má baà ranti rẹ̀ mọ́ láàrin àwọn orílẹ̀-èdè.
Loju opo Twitter niṣe lawọn ọdọ n fi ọrọ iwuri ranṣẹ si awọn aṣoju wọnyi.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Kidnap cases in Nigeria: Iléeṣẹ́ ọ̀lọ́pàá ní ọwọ́ tẹ afurasí méjì, méjì míì sálọ 29 Ìgbé 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 21 Ògún 2020 Oríṣun àwòrán, Others Ọwọ sinkun ọlọpa nipinlẹ Oyo ti ba ọkunrin meji lori ẹsun pe wọn ji obinrin onisowo nla kan gbe pamọ.
À ń kọ àwọn nǹkan wọnyi si yín kí ayọ̀ wa lè kún.
Ẹgbẹ oṣelu PDP loju opo Twitter ni ẹgbẹ oṣelu APC n lọ awọn ọlọpaa naa lati da ẹru ati ipaya silẹ ni ilu naa nitori Gomina Obaseki n gbajumọ si nipinlẹ naa.
Ẹ̀mí kan a máa gbé e.
Wọ́n yí orúkọ Leṣemu pada sí Dani, tíí ṣe orúkọ baba ńlá wọn, wọ́n sì ń gbé ibẹ̀.
Mother's day: Ka àwọn ìròyìn tí BBC News Yorùbá tí ṣe fún ìdàgbàsókè àwọn obìnrin
N óo ya àgọ́ àjọ ati pẹpẹ náà sí mímọ́, ati Aaroni ati àwọn ọmọ rẹ̀ pẹlu, kí wọ́n lè máa sìn mí gẹ́gẹ́ bí alufaa.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Àkójọ́pọ̀ àwòrán rèé lórí bí ìwọlé akẹ́kọ̀ọ́ ṣe lọ sí ní Oyo Bí Hushpuppi ṣe tiraka rèé l‘Eko, kí ọlà ‘òjijì’ tó dé Akẹ́kọ̀ọ́ wọlé padà, ìjọba Oyo kò pèsè ìbòmú lòdì sí ìlérí rẹ̀ Ẹ wo bí ọ̀rọ̀ òṣèlú, ẹ̀sìn àti ẹ̀yà ṣe fa ogun abẹ́lé Biafra Kàkà k‘éwé àgbọn dẹ̀ lágbo òṣèlú l‘Ondo, akọ̀wé ìjọba tún kọ̀wé fipò sílẹ̀ Ẹ wo bí ọ̀rọ̀ òṣèlú, ẹ̀sìn àti ẹ̀yà ṣe fa ogun abẹ́lé Biafra O sọ ọ di mimọ pe, ṣiṣe ofin konile ogbele tuntun miran le waye lati dẹkun itankalẹ arun yii to n peleke sii.
Ó kù díẹ̀ kí UNN rán akẹ́kọ̀ọ́ kan sọ́run àrèmabọ̀ Ìwádìí BBC: Àwọn ará Èkìtì ń sáré gba N4,000 sáájú ìbò Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Ni eerro awọn kan, wọn le sọ pe anfaani pupọ ni bi ijọba ṣe gbẹsẹ kuro lori ofin konile o gbele nitori pe awsn eeyan raaye jade lọ si ẹnu'ṣẹ wọn lati pawo.
" lẹ ́ yìn tí ó ti ṣiṣẹ ́ tí ó sì kówó jọ fún ọdún kan pẹ ̀ lú ìwé ẹ ̀ rí "" modern school "" , ó tún tíraka láti tẹ ̀ síwájú lẹ ́ nu ìwé rẹ ̀ ."
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Sola Sobowale: Iṣẹ́ tí Ọlọ́run kọ mọ́ mi ni mò ń ṣe Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Sola Sobowale: Iṣẹ́ tí Ọlọ́run kọ mọ́ mi ni mò ń ṣe 3 Ọ̀wàrà 2018 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 27 Ọ̀pẹ̀̀ 2019 Gbajúgbajà tó tún jẹ́ àgbà ọ̀jẹ̀ òṣèré Yollywood, Sola Sobowale sọ nípa ìrìn àjò rẹ̀ dé inú iṣẹ́ Tíátà, àwọn ìpèníjà, àṣeyọrí tó fi mọ́ kùdìẹ kudiẹ tó ṣeéṣe kí òṣèrè bá pàdé nínú iṣẹ́ tí wọ́n yàn láàyò.
Bí ẹlẹ́mìí kó bá gbà á,
Ní àkọ́kọ́, ìtumọ̀ orúkọ rẹ̀ ni “ọba òdodo.
'Àṣà ìgbéyàwó Yorùbá gbàràdá ní Kenya' Èrò àwọn ọmọ Nàìjíríà ṣọ̀tọ̀ọ̀tọ̀ lórí ọ̀rọ̀ Obi àti Ọṣinbajo Ilé iṣẹ́ ológun Nàìjíríà gbẹ́sẹ̀ kúrò lórí òfin tó de UNICEF Olorin régè Ras Kimono naa re iwalẹ aṣa lọjọ kẹwaa, oṣu kẹfa, ọdun 2018.
Ẹlikọpita naa, Bell 206, to ni nọmba idanimọ 5N BQW, jẹ ti ileeṣẹ Quorum Aviation lo ja lulẹ lati inu ofurufu wọ inu ogiri to la ile meji ni nọmba 16A Salvation Road, Opebi Ikeja ni Eko ni nkan bii agogo mejila abọ ọsan ọjọ ẹti.
A bẹ wọn, ki wọn o ba wa mu adinku ba.
Ṣugbọn ó dá wọn lóhùn pé, “Mo ní oúnjẹ láti jẹ tí ẹ̀yin kò mọ̀ nípa rẹ̀.
O rọ Gomina Akeredolu lati pese eto aabo fun awọn lọbalọba lati ri wi pe iru iṣẹlẹ yii ko waye mọ.
Awọn ẹsun naa ni i ṣe pẹlu ipaniyan, ifiyajẹni to waye lasiko ijọba ọlọdun mejilelogun to ṣe.
Angẹli mìíràn tún dé, ó dúró lẹ́bàá pẹpẹ ìrúbọ.
Saudi Arabia: Jí foonu ọkọ rẹ̀ wò, kóo fi ẹ̀wọ̀n jura
Àwọn ọ̀tá yóo fi idà pa wọ́n níṣojú rẹ, n óo fi gbogbo ilẹ̀ Juda lé ọba Babiloni lọ́wọ́.
N ò ṣe ojúṣàájú fún àwọn ará Tibet láti ní àwọn ẹ̀tọ́ wọn yìí nìkan, ó wù mí kí àwọn tí wọ́n wá láti Hong Kong àti Taiwan, ìwọ̀-oòrùn Turkey, àwọn ẹgbẹẹgbẹ̀rún lọ́nà ẹgbẹ̀rún ní ìlọ́po méjì 60 ẹni ogúnléndé tí ó wà ní kárí ayé àti fún gbogbo àwọn ènìyàn láti jàǹfààní ẹ̀tọ̀ wọ̀nyí.
Ọlọrun tún ní, “Ti ọwọ́ rẹ bọ abíyá pada.
Amotekun Recruitment: Ìròyìn ayọ̀ fún gbogbo àwọn tó forúkọ sílẹ̀ fún ikọ̀ Amotekun ní ìpínlẹ̀ Oyo
Iroyin to gbode ni pe ile ẹjọ paṣẹ kan eleyi to ṣegbe fun ẹgbẹ oṣelu African Action Congress,eyi to ni ki Inec da ọwọ kika ati akojọ awọn esi idibo to waye nipinlẹ Rivers.
" Wo bi ina naa ṣe bẹrẹ: Orilẹ-ede Cameroun bẹrẹ idije Biggy 237 lọjọ Kejilelogun oṣu Kẹjọ ọdun 2020.
 nígbà tí a bá gba ọ ̀ nà yìí , lẹ ́ hìn tí a dé Ìlúpéjú-Èkìtì ni a óò wá yà kúrò ní títí ọlọ ́ dà sí apá ọ ̀ tún .
” Láti ìgbà náà ni wọn kò wá ní ọjọ́ ìsinmi mọ́.
Àwọn ọba Filistini maraarun tẹ̀lé wọn títí dé odi Beti Ṣemeṣi.
Fayemi ni oun ko ni ja igbekele ti awon omo ipinle Ekiti ni fun oun lati dibo yan an gege bi gomina fun ipinle naa kalẹ.
Gege bi aare egbe ASUU, ojogbon  Abiodun Ogunyemi, “Ipadeyii waye gege bi a se lero, inu wa si dun pelu awon igbese ti ijoba n gbe latiri wipe opin de ba iyanselodi to n lo lowo yii.
Èrò mi ni pé kí ènìyàn tó kú ó ní láti ti gbéyàwó, kí ó sì ti bímọ!
Mo dúpẹ́ lọ́wọ́ rẹ, nítorí pé o gbọ́ ohùn mi,o sì ti di olùgbàlà mi.
Adari eto Biggy 237, Cyril Akonteh sọ fun BBC pe ina ọhun bẹrẹ lati inu apoti amu-ounjẹ gbona makirowefu ti wọn lo ni ilokulo.
Àwọn aṣojú ẹgbẹ́ PDP àti APC gúnlẹ̀ sí ilé ẹjọ́ fún ìdájọ́ Oyetola àti Adeleke Ilé ẹjọ́ yọ ìbò 2,029 nínú ìbò APC, 1,246 nínú ibò PDP l'Ọṣun Dino Melaye: Mò ṣetán láti gbà àwọn èèyàn Kogi lọ́wọ́ ìjọba Nebuchadnezzari Kete ti iroyin idajọ yi kan awọn ololufẹ Gomina Oyetola nilu Oṣogbo ni wọn tuyaya sita lati da ọwọ idunu Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ìtàn tó wà nídi òwe ‘Sebótimọ Ẹlẹ́wà Sàpọ́n’ Taiwo Akinkunmi, ọmọ Ibadan tó ya àsìá Nàíjíríà Ogedengbe Agbógun Gbórò, Akọni tó ń dẹ́rù ba ikú.
Wọ́n jọ àwọn ọmọde tí wọ́n jókòó ní ọjà.
Obasanjọ pàrọọwà sí Makinde: yàgò fún òṣèlú sọ ọ́ sápò
Ẹwẹ, banki apapọ Naijiria, CBN, ni owo dollar kan ko to irinwo naira, gẹgẹ bi iṣiro to wa loju opo wọn lori ayelujara.
 Ẹni tí kò kọ ́ ìlù eré àpíìrì tàbí orin rẹ ̀ kò lè mọ ̀ ọ ́ n .
Ẹ óo wá mọ̀ pé èmi ni OLUWA àwọn ọmọ ogun.
Àwọn ọmọ Ìjèbú -jẹ ̀ ṣà jẹ ́ aláfẹ ́ púpọ ̀ pàápàá nígbà tí ọwọ ́ wọn bá dilẹ ̀ .
Tabi kí ó ka idamẹrin àwọn ọmọ Israẹli?
Ó jẹ́ òmìrán ẹ̀fúùfù tó ní ìsúpọ̀ tó fi díẹ̀ dín ju ìkan-nínú-ìdálẹ́gbẹ́rùún ìsúpọ̀ Òrùn lọ sùgbọ́n ìsúpọ̀ lọ́nà méjì àti àbọ̀ ti ìsúpò gbogbo àwọn plánẹ̀tì yìókù nínú Sítẹ̀mù Òrùn lápapọ̀.
Igbakeji Aarẹ Yemi Osinbajo lo dele fun Aarẹ Buhari nigba ti o wa nilu London.
omo orile-ede Naijriia lati bere si ni n sise lojuna ati fopin si gbogbo
”Ó ní, “Gbà pé kí àwọn ọmọ mi mejeeji yìí jókòó pẹlu rẹ ní ìjọba rẹ, ọ̀kan ní ọwọ́ ọ̀tún ekeji ní ọwọ́ òsì.
Ní ọdún mẹ́wàá sẹ́yìn tàbí nnkan bẹ́ẹ̀ ni wọ́n sọ pé ìdíje náà ní màgòmágó nínú  pẹ̀lu ìlọ́wọ́sí àwọn alẹ́nulọ́rọ̀ tí ó ni ilé iṣẹ́ ìgbóhùnsáfẹ́fẹ́, afiorin-tí-a-ti-ká-sílẹ̀ dá àwọn ènìyàn lára dá àti àwọn aláṣẹ ilé iṣẹ́ orin kíkọ tí a mọ̀ sí “jàndùkú soca”  kò ì yọ́ ìgbàgbọ́ wípé Ìwọ́de Ojúnà jẹ́ ohun àwọn ènìyàn.
Nítorí náà, ní ọjọ́ ogun yìí kò sí ẹnikẹ́ni ninu àwọn ọmọ ogun Israẹli tí ó ní idà tabi ọ̀kọ̀ lọ́wọ́, àfi Saulu ati Jonatani ọmọ rẹ̀.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Iṣọla Oyenusi rèé, ẹnití ìfẹ́ obìnrin ṣun dé ìwà ìdigunjalè Agbekoya: Bí a bá na oògùn abẹnugọ̀ngọ̀ s'ókè, ìjínigbé á d'ópin!
OLUWA ti fún yín ní ọjọ́ ìsinmi, nítorí náà ni ó fi jẹ́ pé, ní ọjọ́ kẹfa ó fún yín ní oúnjẹ fún ọjọ́ meji, kí olukuluku lè dúró sí ààyè rẹ̀, kí ẹnikẹ́ni má ṣe jáde ní ilé rẹ̀ ní ọjọ́ keje.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Woli Kasali: Angẹli mi ni orékelẹ́wà Dọlapo Awoṣika Aṣoju orilẹede India ni Naijiria, Abhay Thakur sọ pe bi India ba le fọwọ si ẹyawo naa, wọn yoo bẹrẹ ipele ikinni riri awọn opo itakun agbaye naa mọlẹ lakọkọ ni ipinlẹ Oyo ki wọn to gbe e lọ si awọn ipinlẹ to ku.
O yá ère, o sì dá oniruuru oriṣa láti máa sìn, o mú mi bínú, o sì ti pada lẹ́yìn mi.
 Issa sọ pe mọlẹbi oun ti fi ara mọ pe ki oun fẹ Janine, ati wi pe igbeyawo yoo waye ti yoo ba fi di oṣu Kẹta ọdun."
Ẹ̀gbọ́n mi ti rí ti ẹ̀ síwájú; ìyá mi sì ti ṣe àlàyé díẹ̀ fún mi nípa rẹ̀.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Police Brutality: Ojú mi rí tó lọ́wọ́ ọlapàá nítorí Múrí màrùn ún- Adebayo Olaide Ipa ti ijọ ko Ninu iwe itan, awọn ile ijọsin naa kopa ninu ṣiṣagbekale ọjọ 'Boxing Day'to wa fun pinpin ẹbun fi mọ riri ara ẹni.
Ṣugbọn, o ku diẹ ki eto idibo bẹrẹ ni Akintọla naa sọ pe oun yọnda fun Adelabu.
Mavrodi Mundial Money-box (MMM) Eto sogun-dogoji MMM jẹ agbekalẹ ileeṣẹ orilẹede Russia kan to de si orilẹede Naijiria l'ọdun 2015, botilẹjẹ pe o ti wa lati ọdun 1989.
Ẹ́ gba fóónù, ẹ pe ẹbí yín pé a fẹ́ dáná ṣun yín - Aráàlú sọ fún adigunjalè méji Àbọ̀ ìpàdé bòńkẹ́lẹ́ láàrin Tinubu àti Buhari rèé Ilẹ̀ UAE ti n fún àwọn arìnrìnàjò ní ìwé ìrìnnà ọlọ́dún márùn ún Wo àwọn mẹ́ta tí Buhari ti dá padà rí lẹ́yìn tí wọ́n yọ wọ́n lóyè Yatọ si pe ajọ FIFA fofin de Siasia, ajọ naa tun ni ko san owo itanran bi miliọnu mejidinlogun naira.
'Obinrin jẹ amuludun' 'Obinrin lo mu mi fẹran orin kikọ' Ta ni Daura DSS tó ń bi oriṣii awuyewuye yìí?
Minisita naa darukọ awọn orilẹ-ede mii lagbaye to n ṣakoso bi awọn eeyan wọn ṣe n lo ẹrọ ayelujara, bi Singapore, China, South Korea, ati bẹẹ bẹẹ lọ.
Ọdun kannaa ni wọn bi EmirAminu Ado Bayero ati Lamido Sanusi Ọdun 1961 ni wọn bi ọba Aminu Ado Bayero eleyi to se rẹgi pẹlu ti Sanusi Lamido Sanusi ti o gba ipo lọwọ rẹ yi.
Yóo máa bọ́ wọn, yóo sì máa ṣe olùṣọ́ wọn.
Ewe, awon agbebon ji Pa Michael Obi gbe lojo kọ́kàndínlọ́gbọ̀n osu kefa odun ti a wayii, wakati di e ki ifesewonse Naijiria ati Argentina ko to bere ti idije boolu agbaye.
ki ounje lee po janturu  lorile ede yii
Àlejò àpàndodo ni Fayoṣe, a kò fìwé pèé - Afuye Wọ́n mú ọjọ́ ìgbẹ́jọ́ agbésúnmọ́mí 9/11 tó ṣẹlẹ̀ l'Amẹrika Kí ni ó gbé ọlọ́pàá dé ibi àjọ̀dún ọjọ́ ìbí i Bobrisky?
Moghalu so pe “o da mi loju pe , iru iwa bayii ni yoo waye nigba eto idibo ti  ipinle”.
Ṣugbọn ta ni lè mọ àṣìṣe ara rẹ̀?
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù FG Survival Fund: Ènìyàn 174,574 ló ti forúkọ sílẹ̀ fún ètò ìrànwọ́ ìjọba fáwọ̀n olókoòwò kéékèé 21 Owewe 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 25 Owewe 2020 Ìjọba ti kéde àwọn tó kàn láti gba owó ìrànwọ́ ìjọba MSME láti 25/09/2020 lọ Mínísítà fún ilé iṣẹ́, káràkátà àti ìdókoòwò Mariam Katagum ní láàrín ọjọ́ méjì péré ènìyàn ẹgbẹrún lanà àádọ́sàn o lé díẹ̀ ló ti fi orúkọ sílẹ̀ fún ètò náà.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Yemen Water Child: Ọmọdé 44 ni Sọ́jà pa, tí 100 míì sì kú látọwọ́ ohun ìjà olóró Osa wa fọwọ gbaya pe ori ohun tawọn sọ si lawọn wa o pe, lilọ ni Oluwo yoo lọ nitori pe o si n tẹsiwaju lati maa ba awọn ni orukọ jẹ, bẹẹ ni ko setan lati yanju aawọ naa nitunbi n nubi.
Wọn ni o tun di ile aṣofin lọwọ iṣẹ nipa kikuna lati fọwọsowọpọ pẹlu ile naa nigba ti wọn ṣewaadi ọrọ naa.
Ninu ọrọ tirẹ, gbajugbaja oṣere Yoruba, Foluke Daramọla Salako ṣe apejuwe Baba Lẹgba gẹgẹ bi ẹni to ni imọ ati oye nipa oṣere, to si kun fun ọgbọn.
Nítorí náà, ó ní kí n mú un lọ́kàn le, nítorí òun ni yóo jẹ́ kí Israẹli gba ilẹ̀ náà, kí wọ́n sì jogún rẹ̀.
Lasiko ti wọn n ba BBC Yoruba sọrọ, ọpọ osere tiata lọkunrin lobinrin si lo n kọrin rere ki agba osere naa pe iya daada ni.
Ọgá Ọlọ́pàá: Ẹ̀yin ọmọ Naijiria ẹ má bẹ̀rù, ọkọ̀ òfúrufú ọlọ́pàá yóò bẹ̀rẹ̀ sí ní káàkiri ìpínlẹ̀
Nítorí náà, Ọlọrun ta Pulu ọba Asiria ati Tigilati Pileseri ọba Asiria, nídìí láti gbógun ti ilẹ̀ náà; wọ́n bá kó àwọn ẹ̀yà Reubẹni, ati ti Gadi ati ìdajì ẹ̀yà Manase tí wọn ń gbé ìhà ìlà oòrùn lẹ́rú lọ sí ilẹ̀ Hala, Habori, Hara, ati ẹ̀bá odò Gosani títí di òní olónìí.
O lé àwọn opó jáde lọ́wọ́ òfo,o sì ṣẹ́ aláìní baba lápá.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Stella Obasanjo Motherless: A ti rí àwọn ọmọ tó sọnù ní ilé àwọn ọmọ òrukàn ní Abeokuta 2 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Oríṣun àwòrán, Abimbola Oyeyemi/Facebook Nigba ti BBC Yoruba kọkọ kan si ọlọpaa ipinlẹ Ogun, agbẹnusọ ọlọpaa, Abimbola Oyeyemi sọ fun wa pe iwadii ṣi n lọ lọwọ lori ọrọ awọn ọmọ naa to si kọ lati pese ẹkunrẹrẹ.
O ni awọn olorin agbagba wọnyii lo n wu oun nigbakugba.
"Edwared Boye ni tirẹ sọ pe ""Aarẹ, o dami loju pe ẹ ko tii ri awọn fidio to n tan ka lori ayelujara nibi ti wọn ti pa awọn oluwọde ni Lekki."
Ṣugbọn Oluwa dá a lóhùn pé, “Ẹ̀yin alágàbàgebè!
‘Amọ, Tolulope rora lati dide, ni mo ṣe pinnu lati gbe e lọ si ibẹ.
Aare Muhammadu  Buhari ti ni o je iyanilenu fun oun nipa iku awon omo Ologun ti iko olote Boko Haram pa ni  ileto Metele to wa ni ipinle Borno.
’ ” Ọdọmọkunrin yìí bá gún un ní idà, ó sì kú.
Ọ̀rọ̀ ẹnu nìkan kò tó láti fi bá ẹrú wí, ó lè fi etí gbọ́ ṣugbọn kí ó má ṣe ohunkohun.
Oríṣun àwòrán, @PDP Àkọlé àwòrán, PDP: Gbogbo ènìyàn mọ̀ pé ipá àti agídí ni APC fi gbà káàdì àwọn oludibo Ekiti Ẹlẹka ninu atẹjade to fi lede so pe oun ti fi ọwọ osi da esi idibo naa nu nitori pe oun gbagbọ pe oun lo jawe olubori gẹgẹ bi gomina ni ipinlẹ Ekiti.
5 Ẹ wo ọba kan nílẹ̀ Yorùbá, tí kò ṣe ètùtù tàbí náwó ànájù, kó tó jọba 6 Covid-19 pa Ọlọ́lá Akin Olugbade, ẹ wo dúkìá jaburata tó fisílẹ̀ 7 Ǹjẹ́ ó ṣeéṣe kí ìyáwò rẹ gbé ọmọ àlè wá sílé láì mọ̀?
Bẹẹ si ni gomina ipinlẹ Oyo lo asiko naa, lati fi ki awọn eniyan ipinlẹ Ondo, fun atilẹyin ti wọn ṣe fun ẹgbẹ oṣelu PDP, lasiko idibo sipo gomina to waye ni Osu Kẹwaa, ọdun 2020.
Obinrin náà sọ fún Elija pé, “Mo mọ̀ nisinsinyii pé eniyan Ọlọrun ni ọ́, ati pé òtítọ́ ni ọ̀rọ̀ OLUWA tí ń ti ẹnu rẹ jáde.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Iniesta yóò kúró ní Barcelona 27 Ìgbé 2018 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Àwọn olólùfẹ́ ikọ̀ Barcelona fẹ́ràn Andres Iniesta kárí ayé Àgbàọ̀jẹ̀ agbábọ́ọ̀lù ikọ̀ Barcelona, Andres Iniesta, ti kéde wí pé òun yóò fi ẹgbẹ́ agbábọ́ọ̀lù náà sílẹ̀ l'ópin sáà yìí Iniesta yóò kúrò ní Barcelona lẹ̀yìn ìgbà t'óti gbábọ́ọ̀lù fún ikọ̀ náà fún ọdún méjìlélógún.
Ẹ̀ báà tilẹ̀ gbadura, gbaduran kò ní gbọ́;nítorí ọwọ́ yín kún fún ẹ̀jẹ̀,
Amosa, aare Buhari wa gbosuba fun awon osise ile-ise to n mojuto isẹlẹ  pajawiri lorile ede yii, lori igbese ti won
Child Health) to wa ni ile Ayinke , atunse si ile iwosan ode-oni fun eto ọmọ
 awọn ọbẹ ti a le fi iru si ni ọbẹ ila , ọbẹ ewedu , ọbẹ ẹfọ , ọbẹ ata , ọbẹ egusi , ọbẹ ọgbọnọ ati bẹẹ bẹẹ lọ .
Ó rọrùn láti lò púpọ̀ ju àwọn ìyókù lọ, tí ó bá ti móni lára tán.
OLUWA kí ló dé tí o fi jẹ́ kí á ṣìnà, kúrò lọ́dọ̀ rẹ;tí o sé ọkàn wa lé, tí a kò fi bẹ̀rù rẹ?
Ọpọlọpọ eniyan ń bá a wí pé kí ó panu mọ́.
Amòfin Ojo ní ọ̀pọ̀ ǹkan lo fá idí ti èyí bi pọ̀, sùgbọ́n èyí to ga jùlọ níbẹ̀ ni pé, àwọn ọlọ́pàá kò ṣiṣẹ́ lásìkò kónílé-ó-gbéle nínú oṣù kẹrin ki wọ́n tó dẹwọ́ rẹ̀ silẹ̀.
Bi o ti se n se eleyi, ko ye wa si '' Oríṣun àwòrán, Spl Ti o ba seese ki a rin gba ọna ọfun wa si ibi iho kekere to wa ninu ẹdọ foro, o yẹ ki a le ri awọn aaye atẹgun kekeeke meji kan.
ún  odun seyin  lọ ti awon adari ile-ise ijoba ti kan si
A kò mọ ẹni tó pa ọlọ́pàá Ondo àti ìyàwó rẹ̀, òun kọ́ ló pa ara rẹ̀- ọlọ́pàá Saaju la ti sọ fun yin pe irọ ni iroyin kan to sọ pe ọlọpaa kan ti wọn pe orukọ ni Tolulọpe pa iyawọ ati ara rẹ lori ẹsun pe iyawo naa n ṣe agbere.
0 13308 Orilẹede Andorra 88 114.
Farao bá sọ fún Josẹfu pé, “Wò ó!
”<blockquote class=”twitter-tweet” data-lang=”en-gb”><p lang=”en” dir=”ltr”> <a hrẹf=”https://twitter.
" Ọ ̀ pẹ ̀ lẹ ̀ jẹ ́ ohun èlò àyẹ ̀ wo kékeré tí àwọn babaláwo ń lò ; wọ ́ n gbàgbọ ́ pé "" olùrànlọ ́ wọ ́ "" tàbí "" ẹrú "" Ọ ̀ rúnmìlà ni , ẹni tí ń ṣe alágbàsọ ìfẹ ́ Ọ ̀ rúnmílà fún babaláwo tí ó sì tún ń mú láti ọ ̀ dọ ̀ babaláwo padà fún Ọ ̀ rúnmìlà ."
Nibi ijoko ile ẹjọ naa to waye lọjọ Aje to kọja, iya-iya ọmọ naa ati mọlẹbi rẹ kan wa lara awọn ti wọn pe gẹgẹ bi ẹlẹri nibi igbẹjọ ọjọ naa.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Osinbajo: Ikẹnnẹ yẹ kó jẹ́ Mẹ́kà òṣèlú ni Oríṣun àwòrán, AsoRockVilla Àkọlé àwòrán, Ààrẹ Buhari àti Adájọ́ Walter Onnoghen Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Lara awọn alejo to wa nibi ipade naa sọ pe ifori ade tẹlẹ ni ki olori ẹsọ Ọọni layalaya lati ti Ọba onipo kini bii ti Oluwo kuro lọna.
Ṣé ẹyin mọ awọn eroja ẹlẹmi meje to n sọ ila alasepọ di ajẹpọnnula?
OLUWA tún bá mi sọ̀rọ̀, ó ní, 
Eyẹ idi Super Eagles fi Algeria gba ipo kẹta ninu idije AFCON ti orilẹ-ede Angola gbalejo ẹ lọdun kẹjọ to tẹlẹ ikọlu wọn miran.
Iroyin ni wọn ni ki awọn akọroyin yẹba fun ile ki wọn to jiroro lẹkunrẹrẹ lori abadofin ti banki Naijiria gbe wa siwaju ile naa.
awọn ara ilẹ Egypt ko le wọ Hijaz.
95bn sórí reluwé làti Kano sí Niger Republic- PDP Bẹẹ ni Oluwo naa ti salaye pe iwa ajẹbanu lo n da awọn afọbajẹ to fẹ rọ oun loye laamu nitori pe awọn eeyan kan lo gbe owo fun wọn lati se bẹẹ.
4 445828 Orilẹede Romania 12948 66.
Ṣugbọn, òun náà fẹ́ tún nǹkan ṣe, ni ó fi ṣe ohun tí ó ṣe.
0 1103 Erekusu Cayman Island 2 3.
''Emi o dawon lẹ̀bi nitori ati se eré ìdárayá ko rọrùn nile Afrika.
”Awon egbe oselu to n koju egbe
nikale lati  owurọ  lati dibo fun awon ti yoo soju fun won nile
Ẹ̀mí Mímọ́ ti fihàn án pé kò ní tíì kú tí yóo fi rí Mesaya tí Oluwa ti ṣe ìlérí.
Ilúmọ̀ọ́ká oníròyín, Ayinde Soaga ti jàjàbọ́ lọ́wọ́ àrun Covid-19 Ilumọọka oniroyin orileede Naijiria, Ayinde Soaga ti moribọ lọwọ arun Covid-19.
ng Arabinrin kan ti wọn fi ẹsun kan pe oun ati ọkọ rẹ lu ọmọ wọn pa, ti wa ni ahamọ awọn ọlọpaa bayii.
Awọn ẹgbẹ oṣelu mejeeji yii lo ṣeto idibo abẹnu ti wọn si fa oludije fun ipo aarẹ kalẹ lati gbe asia ẹgbẹ oṣelu koowa wọn.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Èyí ni ìdí tí àwọn obìnrin kan to n ṣe nkan oṣù fi n yọ ilé ọmọ wọn kúrò ní India 7 Agẹmo 2019 Oríṣun àwòrán, AFP Àkọlé àwòrán, Oju buruku ni wọn fi maa n wo awọn obinrin to ba n ṣe nkan oṣu ni India Abọ iwadii kan lori ọrọ awọn obinrin to n ṣiṣẹ, to si n ṣe nkan oṣu ti jade lati India.
Iṣẹ́ náà a wá dàbí ti ikán tọ́n parapọ̀ tọ́n mọ'lé.
Sugbọn ti ọkan wọn ko balẹ nitori pe wọn n wo o pe bi wọn ba fi ọrọ naa silẹ fun tikere tikere ilu, wọn lee yan ẹni ti ko kun oju oṣuwọn fun ipo naa; Eyi lo mu wọn gbe igbimọ agbaọjẹ oludibo yii kalẹ.
2 bílíọnù fi tún wáyà iná àti inú ilé Aso Rock ṣe- Buhari Bakan naa lo fikun un wi pe ijọba gbọdọ ṣe ohun ti o tọ, ki awọn araalu ba lẹ ni igbẹkẹle ninu wọn, nitori awọn eniyan ko ni igbagbọ ninu ijọba Buhari mọ.
Àdéhùn wọn kò wúlò fún wa mọ́.
OLUWA ra ẹ̀mí àwọn iranṣẹ rẹ̀ pada;ẹnikẹ́ni tí ó bá sá di í kò ní jẹ̀bi.
Losu kejo odun 2017 ni Henrik kede pe ki won salai sin oun si egeb iboji iyawo oun ni eyi to se lodi si asa to bere ni o din die ni eedegbeun odun nile Faranse.
Èrò ibi wo ni ẹ̀ ń gbà sí OLUWA?
Ojú àwọn tọ́wọ́ ti tẹ̀ lára àwọn tó jí 'tíá rọ̀bà ọ̀kadà', fíriìjì, ẹ̀rọ ata kó nílée Sẹ́nétọ̀ Teslim Folarin rèé Ẹ wo ojú àwọn jàndùkú tí ọwọ́ ọlọ́pàá tẹ nígbà tí wọ́n lọ kó ọjà ọlọ́jà ní Shoprite Ilorin Wo àwọn ayédèrú ìròyìn tó gbà'gboro kan lásìkò ìwọ́de #EndSARS Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí End SARS Protest: Babangida ní ejò lọ́wọ́ nínú lórí ìsẹ̀lẹ̀ rògbòdìyàn tó ń wáyé káàkiri Nàìjíríà22 Ọ̀wàrà 2020 Fídíò, Ogbomosho shooting, End Sars, End SWAT: Isiaka Jimoh fi ọmọbìnrin kan àti ìyàwó tó lóyún sínú sílẹ̀ ló- Òbí Isiaka17 Ọ̀wàrà 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Ta ni kò ní bẹ̀rù rẹ, ìwọ ọba àwọn orílẹ̀-èdè?
Bí mo ti bọ́ sí orí ibùsùn ní alẹ́ ọjọ́ tí a ń sọ̀rọ̀ rẹ̀ yìí tán ni ìyàwó mi pa iná tí ń bẹ nínú iyàrá mi, ó dìde ó jẹ ataare kan lẹ́nu ó sì tu ú sí mmi lára, ó ní, ‘Bí igi àjà bá sùn kì í dìde, alákọrí rẹ kò gbọdọ̀ dìde títí n ó fi dé.
ikolu ibon lotun losi, eleyi ti agbenuso ile-ise olopaa, Frank Mba so pe, awon
 Ó lo sí ilé-ìwé alákóbèrè ti àwon Ìjo Àgùdà tì ó wà ní ni agbègbè maryland ní Ìpínlẹ ̀ Èkó .
Nnkan o rọgbọ fun Ideye ni Tianjin nibi ti wọn ti rọ nipo pada si akasọ kẹji ẹgbẹ agbabọọlu rẹ pẹlu bi wọn ti se ra agbabọọlu ọmọ Ghana, Frank Acheampong.
Bi ìyàwọ mi ṣe n jábọ́ sí gọ́tà ló jẹ́ kí n kọ́kọ́ fura pé kò ríran mọ́- ọkọ Dorcas
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Tunde Kelani k'ẹdun iku Akinwunmi Ishola Bakan naa, ifọrọjomitoro ọ̀rọ̀ naa sawari nipa iru eniyan ti Oladejo jẹ, itan igbesi aye rẹ to fi mọ irufẹ ọna ti oun gẹgẹ bi akọṣẹmọṣẹ onkọwe ọmọ il adulawọ n gba kọ awọn itan rẹ.
Nígbà tí gbogbo àwọn eniyan rí i, wọ́n kígbe sókè, wọ́n sì dojúbolẹ̀.
Buhari at 76: Àwọn àwòrán tó làmì-laaka nípa Buhari
Wo itan awọn nkan to ti ṣẹlẹ nibẹ: Ninu ile ijọsin Notre ni wọn ti de ade fun Oba Henry kẹfa ti England ni France.
Ẹwẹ, o ni yoo dara ti ilu Bakana ba ṣe nkan iranti kan si ibi ti ọkọ oun ku si, nitori ti awọn ọmọ rẹ ba n beere ibi ti wọn sin baba wọn si l'ọjọ iwaju.
Aṣaaju ni Adebayo ará Ijilejee, Akande Oloyemọyin ninu awọn nkan àrà to pọ to gbe ṣe nigba aye rẹ.
Gbogbo awọn n kopa ninu jijẹ aṣuwọn orilẹ-ede Naijiria lajẹrun pẹlu awọn ti wọn n ṣe baba rere, baba kẹ fawọn to n ko owo ilu jẹ nitori pe wọn jẹ ọmọ ẹya kan naa tabi ẹsin kan naa.
Iroyin naa ni, obirin kan, ẹni ogun ọdun , lo bi awọn ibeji to lẹpọ naa, sugbọn ọkan ninu wọn ko mi rara eyi to nilo ki wọn sisẹ abẹ ni kiakia lati doola ẹmi ikeji rẹ to n mu, ki wọn si ya wọn si ọtọọtọ.
Estimated Billing Owo ina ọba ti ara ilu n san jẹ ọrọ kan pataki ti ile asofin eẹlẹẹkẹjọ lorile-ede Naijiria ko tii ribi yanju.
Apànìyàn ni ẹnikẹ́ni tí ó bá kórìíra arakunrin rẹ̀.
Lẹyin to pari ẹkọ rẹ nibẹ, gbogbo ohun to sẹlẹ yii ni Onyeama kọ sinu itan iriri aye rẹ to kọ.
Wúrà níláti kọjá ninu iná, bẹ́ẹ̀ sì ni ó pẹ́ ni, ó yá ni, yóo ṣègbé.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù BBNaija: Laycon, Nengi, Dorathy, Neo àti Vee ti jẹ ẹ̀bùn rẹpẹtẹ lórí ètò Big Brother Season 5 26 Owewe 2020 Oríṣun àwòrán, BIG BROTHER NAIJA Àkọlé àwòrán, Awọn olukopa marun-un to kẹhin sori eto BBNaija season 5, Laycon, Nengi, Dorathy, Neo àti Vee Awọn ololufẹ ato ori amohunmaworan, BBNaija 2020, ti n foju sọna fun ẹni ti yoo gba miliọnu marunlelọgọrin, to jẹ ẹbun ati owo, laarin awọn olukopa marun to kẹhin sori eto naa.
Orobosan Adun: Kí wọ́n to lọ fún ìfẹsẹwọ́nsẹ pẹlú Enugu Ranger, àwọn ọmọta kan ti wọ́n fúra si pe o jẹ oloufẹ àwọn ẹgbẹ́ agbábọọlu ti wọ́n fẹ́ lọ bá gbá ti kọkọ ṣe ìkọlu si asọle ẹgbẹ́ agbábọọlu Warri Wolves (Adun).
Alakoso ajo NEMA to wa ni
Lasiko idajọ to yọ Eleruwa nipo, Adájọ ni gbogbo igbesẹ, láti ori yíyan ọmọ oye to fi mọ bi ìjọba ṣe gbe ọ̀pá àṣẹ fún un ko tọ̀na rara.
Ẹsẹ ti adajọ tori rẹ ni ki wọn yẹgi fun wọn ni pe wọn fipa ba ọmọdebinrin ọdun mẹrinla kan lo pọ ti wọn si tun ṣeku pa a.
Àwọn obìnrin tí kò lọ́kọ ń kojú ìsòro ilé gbígbà Ìjì líle pa arẹ̀wà fasiti tó ń ya fọ́tò létí òkun Májèlé ni àdí-àgbọn, ẹ yàgò fun - Dókítà APC àti PDP takora wọn lórí Olùsirò owó àgba Ọsun tó fisẹ́ sílẹ̀ Nigba to n fesi lori alaye arabinrin Christiana naa, Kọmisana feto ilera nipinlẹ Eko, Ọgbẹni Jide Idris ni Christiana lẹtọ lati mọ̀ohun to n sẹlẹ sii.
" Oni oun rọ awọn ọmọ Naijiria, lati ma a gbọ ọrọ ijọgbọn, ati aṣinilọna ti Arabinrin Maimuna Abubakar, sọ ni gbangba.
 kò pẹ ́ tí àwọn fascist bẹ ̀ rẹ ̀ síí darí ilẹ ̀ italy .
nítorí ọjọ́ tí ń bọ̀, tí yóo jẹ́ ọjọ́ ìparun gbogbo àwọn ará Filistia,ọjọ́ tí a óo run gbogbo àwọn olùrànlọ́wọ́ tí ó kù fún Tire ati Sidoni.
Ni ọdun 2002 lo da ẹgbẹ Ahlu Sunna Waljama Wal-Jihad silẹ nilu Maiduguri ti o ti n ṣe iwaasu eleyi to pada wa kale kako ni ipinlẹ naa.
Orilẹ̀ede mejeeji ti wa ninu aigbọraẹni ye lori ọjọ iwaju apa Ila Oorun Sahara.
Wọ́n ń kú bí iná, wọ́n sì ń ṣàìsàn láì-rò-tẹ́lẹ̀, síbẹ̀ wọn kò jẹ́ ronú, ki wọ́n máa ṣe àkíyèsí ọ̀rọ̀ ẹ̀yin àgbàlagbà wọ̀nyí, kí wọ́n máa fi ọgbọ́n kún ọgbọ́n kí wọ́n máa ffi ìmọ̀ kún ìmọ̀, kí wọ́n mo ìtàkùn tí ó kọ́ àwọn ará ìṣáájú lẹ́sẹ̀ kí àwọn náà má baà ṣubú sínú ọ̀gbun.
Lọjọ Abamẹta, ọjọ kẹrinlọgbọn, oṣu Kẹsan, ọdun 2020 ni Olori fi oriṣiriṣii fọto rẹ ati ti Alaafin pẹlu pẹlu ọmọ ti Eleduwa fi jinki wọn si oju opo Instagram rẹ.
Donald Trump ní Joe Biden wọlé ìbò ààrẹ Amẹrika ṣùgbọ́n.
O tun le jẹ pe nitori pe iru obinrin bẹ n ro bi ọjọ iwaju rẹ yoo ṣe ri, paapa ni ibamu pẹlu ọrọ Yoruba pe a kii ti kootu de, ka ṣe ọrẹ"" Bakan naa lo sọ pe aṣa ati iṣe ẹya ti iru obinrin bẹ ẹ ti wa tun le ni ipa lori igbesẹ rẹ."
Oríṣun àwòrán, PAstor Adeboye/twitter Pasitọ Odesola sọ pe o ṣe pataki fun ileeṣẹ ọlọpaa lati ma a ṣe atunto ojuṣe rẹ ni gbogbo igba ni ibamu pẹlu nkan ti ara ilu nilo.
Ìjòyè kan wà ní Kapanaumu tí ọmọ rẹ̀ ń ṣàìsàn.
Jẹ́ kí n sọ ohun tí OLUWA wí fún mi ní alẹ́ àná fún ọ.
 “A fe ki awon oloja olokoowo keekeeke , ri owo lati fi bere eto okoowo won; a ti se ti awon olokooowo nla-nla nipa eto ironi lagbara ti ijoba apapo (Government Enterprise and Empowerment Programme,GEEP), da sile ,egberun lona ogorun un si egberun lona ọgọfa ni a fun won.
Ṣebí Ẹ̀mí kan náà ni ó ń darí wa?
Nigba wo lawọn akẹkọ yoo pada si ileewe?
Biṣọọbu ni tori naa lawọn ṣe ni awọn yoo ṣe ọjọ eeru wọn lati gba adura fun awọn to fara gba ninu ikọlu ati adura fun ẹmi awọn to ti papoda.
”Eto idibo naa lọ ni irọwọ ati
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Mikel Arteta: Wọ́n ti kéde Mikel Arteta gẹ́gẹ́ bí akọ́nimọ̀ọ́gbá ikọ̀ Arsenal tuntun 20 Ọ̀pẹ̀̀ 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Arteta ti sẹṣẹ gẹgẹ bi adari labẹ Pep Guardiola ni Manchester City Ẹgbẹ agbabọọlu Arsenal ti kede Mikel Arteta gẹgẹ bi akọnimọgba rẹ tuntun.
Ìwọ ọmọ mi, n kò ní í lè sọ ju èyí lọ, àwọn ọmọ ènìyàn a máa lo àkókò bí ẹni pé kò lè tán láéláé, ṣùgbọ́n ìṣẹ́jú kan ní ìlò tirẹ̀ ni òde ọ̀run.
ile-eko  nipa Alaafia ati Ise (Society
Òtítọ ní Obasanjo sọ, Buhari n fí agbára fún ẹlẹ́yàmẹ̀yà ní Nàìjíríà-Soyinka
Ti ipinlẹ Oyo naa gberu sii nibi ti eeyan mọkanlelaadọta to ko arun naa.
Ṣugbọn kí ó lè hàn dájú pé gbogbo wọn kì í ṣe ara wa ni wọ́n ṣe kúrò lọ́dọ̀ wa.
Loju opo Twitter awọn kan ko tilẹ pẹ ọrọ sọ pe orin naa gboriyin fun pipa eeyan lati fi ṣe ogun owo tabi wiwa ọna ẹburu lati ni owo eleyi ti awọn eeyan mọ si ''yahoo plus'' Ọrọ naa le ma bi awọn kan ninu ṣugbọn Olamide fun ara rẹ ti jade soju opo Twitter rẹ lati slaye pe oun ko ri nnkan to buru ninu orin naa.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Dúkìá àti ọjà jóná ráúráú lásìkò tí iná sọ ní ọjà Mushin ní ìpínlẹ̀ Eko 2 Ògún 2020 Oríṣun àwòrán, lasema Ina sọ lapakan ọja awọn to n ta ibusun ni agbegbe Ladipo ni Mushin ni ilu Eko lọjọ Abamẹta.
Kò sí eegun, kò sí èérún, ọmọ èèyàn pòórá mọ́lẹ̀
OLUWA Ọlọrun ní, “Ìwọ ọmọ eniyan, ké pe oniruuru ẹyẹ ati gbogbo ẹranko igbó, kí o sọ fún wọn pé, ‘Ẹ gbá ara yín jọ, kí ẹ máa bọ̀ láti gbogbo àyíká tí ẹ wà.
"Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Àkíyèsí nípa àìsàn ‘Coronavirus’ tó ń ṣàkóbá fún ba ṣe ń mí Ìbẹ̀rù nípa Amotekun ló ń mú káwọn èèyàn kan máa wí ìwíkùwí - Soyinka Wo àwọn àdúgbò tí ìpínlẹ̀ Eko ti fòfin de ọ̀kadà àti Marwa Àwa ò ri lẹ́ta kankan gbà láti ọ̀dọ̀ Malami lóri ọ̀rọ̀ àwọn alága Kansu - Makinde Àwọn nkan tó yẹ kí o mọ̀ nípa ìgbẹ́jọ Trump tí yóò blrẹ̀ l'ọ́dọ̀ àwọn Sẹ́nétọ̀ Mí ò le nífẹ̀ẹ́ obìnrin Nàìjíríà kankan mọ lẹ́yìn ti mo ti tọ́ obìnrin òyìnbó wò- Issa Otuji ni ""Afojusun wa ni lati daabo bo awọn irinsẹ to jẹ ti ajọ elepo rọbi nilẹ wa lọwọ awọn eeyan to n fọ ọpa epo kiri."
Josẹfu náà gbéra láti Nasarẹti ìlú kan ní ilẹ̀ Galili, ó lọ sí ìlú Dafidi tí ó ń jẹ́ Bẹtilẹhẹmu, ní ilẹ̀ Judia, nítorí ẹbí Dafidi ni.
Ó fẹ́rẹ̀ má ì tí ì parí ọ̀rọ̀ rẹ̀ yií nígbà tí èmi náà ti fún un lésì, mo ní, N kò ní í mú ìlérí eléyìí ṣẹ.
"Alkurani nìyí…nígbà tí mo wòó, mo ríi pé Ọlọ́run fi òfin de ṣìná àti ìmukúmu, mo si ríi pé wọ́n ń mu ìmukúmu, wọ́n ń ṣe ṣìná ọ̀hún.
Lábẹ́ rẹ̀ ni gbogbo ẹranko inú igbó ń bímọ sí.
Koda, wọn a maa figba gbogbo ranti pe ko si ibi to dabi ile.
Mc Oluomo lo fi ọrọ naa lede loju opo Instagram rẹ nigba toun mọriri Ọlọrun fun yiyan ti wọn yan oun sipo naa.
Angẹli OLUWA náà bá na ọ̀pá tí ó wà ní ọwọ́ rẹ̀, ó sì fi ṣóńṣó orí rẹ̀ kan ẹran ati burẹdi tí kò ní ìwúkàrà ninu náà; iná bá ṣẹ́ lára àpáta, ó sì jó ẹran ati burẹdi tí kò ní ìwúkàrà ninu náà.
Awọn ileesẹ ipọnpo meji yii njẹjọ lori ẹsun pe wọn lọwọ ninu iwa kotọ ninu idokoowo wọn lori ibudo ipọnpo kan lorilẹede Naijiria.
BBC Yorùbá jade kaakiri lọ wadii boya awọn obinrin funra wọn ti ṣetan lati gbe obinrin ẹgbẹ wọn sori aleefa iṣejọba alagbada.
Ileepo NNPC to wa ni agbegbe naa ni ina naa ti sọ eyi ti o jo ọpọlọpọ dukia olowo iyebiye.
Ìjọba Buhari ní kí Ológun pa mí láàrin ọjọ́ kan péré - Omoyele Sowore 'Cartoon' nípa Anọbi Muhammed kó Ọ̀jọ̀gbọ́n kan sí ìyọnu ní Egypt Orilẹ-ede China ni wọn tun ti ni yoo ti fẹẹ jade.
Ní ọdọọdún, ni àkókò Àjọ̀dún Ìrékọjá, Pilatu a máa dá ẹlẹ́wọ̀n kan tí wọ́n bá bẹ̀bẹ̀ fún sílẹ̀.
Rírà ni n óo ra oúnjẹ tí n óo jẹ lọ́wọ́ rẹ, n óo sì ra omi tí n óo mu pẹlu.
Ìpínlẹ̀ Ekiti ló bàjẹ́ jùlọ ní Naijiria- Afe Babalola Khadijah, obìnrin àkọ́kọ́ tó dẹnu ìfẹ́ kọ àyànfẹ́ rẹ̀ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Nigeria Independence Day: Wo ìlérí tí àwọn ènìyàn ṣe Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
29 Ògún 2019 Oríṣun àwòrán, AFP Àkọlé àwòrán, Brexit nibo ni ọrọ yii maa ja si fun UK Laarọ ọjọru ni alakoso Britain tuntun, Boris Johnson gbe igbesẹ lati so ijokoo ile rọ.
Diepreye Alamueyesigha: Gomina ipinlẹ Bayelsa tẹlẹ ni, ni ọdun 2007 ni wọn ran an lọ si ẹwọn ọdun meji lloriikowojẹ.
 A ti ri owo to le ni  ẹ̀ẹ́dẹ́gbẹ̀ta bilionu naira nipa eto ilana itanillolobo.
Káàdì ìdánimọ̀ ]ijọba apapọ̀, káàdì ìfọ́rukọsilẹ̀ fún ìdìbò tàbi káàdì ìrìnajò lọ ilẹ̀ òkèrè Onídúró kan Ilé iṣẹ́ ti o ti fi orúkọ rẹ̀ silẹ̀ Nọmba ìdánimọ ti Banki (BVN) Àwọn ilé iṣk ti ọ̀rọ̀ náà kan ṣì n foríkori lati rii dáju pé ètò náà kò nira bi ìgbà ti ènìyàn bá fẹ ṣe ẹyáwo ni banki Nàìjíríà.
Lootọ ni ko ṣeeṣe ko maa waye, ṣugbọn gbigbe igbeaye ilera to peye le dinku.
Ẹ yọ̀, ẹ̀yin eniyan Ọlọrun, ẹ̀yin aposteli, ati ẹ̀yin wolii, nítorí Ọlọrun ti ṣe ìdájọ́ fún un bí òun náà ti ṣe fún yín!
Ṣugbọn àwọn ọmọ Kohati ni Mose kò fún ní nǹkankan, nítorí pé àwọn ohun mímọ́ tí wọ́n máa ń fi èjìká rù ni iṣẹ́ ìsìn wọn jẹ mọ́.
Ni Enugu, ọdọbinrin kan tilẹ so asia naa mọ ori, o joko sori ere kan to ga to si n wa ẹkun mu nitori ohun ti awọn oṣiṣẹ SARS ti fi oju mọlẹbi rẹ ri.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Dino Melaye: Mí ò sí lára àwọn aṣòfin tó bú Buhari 6 Sẹ́rẹ́ 2019 Àkọlé àwòrán, Dino Melaye jọ̀wọ́ ara a rẹ fun awọn ọlọpa lẹyin ọṣẹ kan ti wọn ti gẹ̀gùn de e Sẹnetọ to n ṣoju ẹkùn idibo nipinlẹ Kogi, Dino Melaye ti sọ pe oun ko si lara awọn aṣofin to pariwo le Aarẹ Muhammadu Buhari lori lasiko to n ka aba eto iṣuna ọdun 2019 niwaju awọn aṣofin Naijiria lọjọ kọkandinlogun, oṣu Kejila, ọdun 2019.
Ero ara ilu lori owo awọn sẹnatọ Naijiria Òpópónà àti afárá 19 níjọba fẹ́ ṣe nínú àbá ìṣúná ọdún 2020 Àwọn sẹ́nétọ̀ Nàìjíríà fa ìbínú yọ 'torí N2Miliọ̀nù owó àjẹmọ́nú Kérésì tí wọ́n fún wọn Latari iṣẹlẹ eyi ti o mu iye owo epo rọbi walẹ di bi ọgbọn dọla lati ọgọta dọla Ọmọwe Chijioke sọ pe ijakulẹ ọrọ aje eleyi ti a mọ si Recession lede oyinbo di dandan Iduro ko si mọ fawọn to n ṣe ijọba bayi Ẹlẹẹkeji ipa to ni adinku iye owo epo yi yoo ni lara awọn eeyan Naijiria ni pe iye owo gbogbo nkan lọja yoo gbowo lori.
Ti eeyan ba jẹ ori ahun, to ba ba de ibi isinku Ibidunni, omi gbọdọ bọ loju rẹ.
Awọn iṣan ti wọn fi da itọ duro ni ti pelvis, ti yoo si fun wọn ni òye aaye to wa.
DSS ti gbé Pasitọ ìjọ tí wọ́n fẹ̀sùn kan pé ó mọ̀ sí Gold Kolawole tó sọnù ni Akurẹ Kí a tó dá ẹjọ́ Pásítọ̀ ìjọ Sọ titobi rẹ, ó di 2020- Adájọ́ ní Akurẹ Ọlọ́pàá fìbọn fọ́mi lójú nítorí #100; ó ní eṣù ló ṣe òun- Akẹ́kọ̀ọ́ Adebayo Wo àwòràn ohun tó ṣẹlẹ̀ nílé ìjọsìn Sotitobire tí wọ́n sun ní àná Missing Child: Òbí àti asọ́nà ṣọ́ọ̀ṣì 14, lọ́ búra nì'dí imọlẹ̀ l'Akure Wọn pa ọlọ́pàá kan níbi tí wọ́n ti dáná sun ìjọ Sotitobire l'Akurẹ - Police PRO Ọmọ ọdún kan póòrá!
senior registrar for di Federal Neuro-Psychiatric Hospital for Lagos.
Gbogbo ojú títì a tanná niniini.
Ṣe tí onírèsé ò bá fíngbá mọ́,
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ẹ̀yin ọ̀dọ́ ti rí èrè ìwọ̀de yín lórí EndSARS àmọ́ ẹ ṣọ́ra, kẹ má baà sọ èrè náá nù - Tinubu Owó ìrànwọ́ Covid-19 dé, ìjọba fẹ́ san ₦75bn fún 54,000 olókoòwò Ìjọba ìpínlẹ̀ Eko ti iléèwé pa nítorí ìwọ́de #EndSARS Ìrẹ̀wẹ̀sì ń bá wa torí ìdánwò NECO tẹ ń ṣún síwájú lọ́pọ̀ ìgbà - Akẹ́kọ̀ọ́, ọ̀gá iléèwé Agbára ìgbìmọ̀ ìdájọ tí mo gbé kàlẹ̀ yóò dé ọ̀dọ̀ àwón ólọ́pàá tó ti kúrò lẹ́nu iṣẹ́ tẹ́lẹ̀- Sanwo Olu Wo àwọn orílẹ̀èdè míràn tó ń fojú winá ìwọ́de bíi ti ENDSARS Mo fura pé ẹ fẹ́ da Nàíjíríà rú, ń kò ṣe ìwọ́de mọ́ - Segalink, agbátẹrù ìwọ́de yọwọ́ Aliyu sọ pe A ti n fimu finlẹ lori ipa ti iwọde to n lọ lọwọ le ni lori iburẹkẹ ajakalẹ arun Covid-19, a si ti n woye bi a ṣe maa ṣe ayẹwo."
Shiite: Àwa kọ́ la yìnbọn pa ọ̀gá ọlọ́pàá àti akọ̀ròyìn
Ẹ má gbàgbé láti máa ṣe rere, kí ẹ sì máa fún àwọn ẹlòmíràn ninu àwọn ohun ìní yín.
Ṣugbọn bawo lawọn oludibo yoo ṣe mọ boya otitọ lawọn oludije n sọ?
Bí èmi ti máa ń kọ̀wé nìyí.
Lọjọ Aje yoo ṣelẹ gan loju aye, o si le ma yatọ si bi o ti ṣe waye ninu ere amounmaworan naa, a o le sọ.
Ṣugbọn wọ́n ń fi tipátipá kó àwọn ará ìlú Beti Ṣemeṣi ati ti Betanati ṣiṣẹ́.
Wọ́n pa Kudirat sínú ọkọ rẹ̀ pẹ̀lú ìbọn, bẹ́ẹ̀ ni awakọ̀ rẹ̀ náà bá ìṣèlẹ̀ yìí lọ pẹ̀lú, ṣùgbọ́n olùrànlọ́wọ́ pàtàkì rẹ̀ tí wọn fẹ̀sùn kàn pé ó lọ́wọ́ nínú iku rẹ̀, to wà nínú ọkọ pẹ̀lú rẹ̀, kò fi ara pa rárá.
Láti àárọ̀ tí ó ti dé, ni ó ti ń ṣiṣẹ́ títí di àkókò yìí láìsinmi, bí ó ti wù kí ó mọ.
'Fashọla, o ò dẹ̀ bẹ̀rù Ọlọ́run!
Oríṣun àwòrán, @ProfOsinbajo ACF fikun pe, ọrọ Osinbajo tun dakun wahala to wa nlẹ ni nitori awọn ọrọ to sọ lẹnu le fa ẹtanu ati ija.
Giwa ile-ise ologun, ogagun agba yan-yan Tukur Buratai so oro yii nibi eto ona ibasepo ara eni nile Afrika fun ti odun 2018, eyi ti o wa sopin lojo-Abameta ni ilu Apapa nipinle Eko.
Jehoiakimu kú, Jehoiakini ọmọ rẹ̀ sì jọba lẹ́yìn rẹ̀.
Wíwọ̀n ni wọn yóo máa wọn oúnjẹ le yín lọ́wọ́; ẹ óo jẹ, ṣugbọn ẹ kò ní yó.
Àwọn tí mo fọwọ́ mi dá fún ara mi,kí wọ́n lè kéde ògo mi.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ash Wednesday: Àyájọ́ ọjọ́ eérú t'ọdún yìí bẹ̀rẹ̀ pẹ̀lú aṣọ ọ̀fọ̀ 26 Èrèlè 2020 Ọjọ mimọ ni ayajọ ọjọ eeru jẹ lagbaye fun awọn Kristẹni gẹgẹ bi ọjọ ti wọn n pe ni akoko Lẹnti eyi tii ṣe akoko awẹ ati adura.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Vitiligo: Síkẹ̀ẹ̀tì tó gùn ni mo máa ń wọ̀ bíi eégún tórí yẹ̀yẹ́ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Vitiligo: Síkẹ̀ẹ̀tì tó gùn ni mo máa ń wọ̀ bíi eégún tórí yẹ̀yẹ́ 4 Agẹmo 2019 Wọ́n fi itiju karun, wọn jade sita nigba ti wọn ri ẹlẹgbẹ wọn loke okun t'oun naa ni iru abawọn yii lara to si di di gbajugbaja arinrin oge.
Ènìyàn 27 lo ti bá iṣẹ̀lẹ̀ ọkọ̀ ofúrufú tó já rìnrìn ajò Oúnjẹ márùn-ún tó lè ṣekú pa'ni kíákíá Pasuma kìí ṣe ọkọ mi o!
Aare Muhammadu Buhari yoo farahan niwaju ile igbimo asofin ki ile oni to su lati wa salaye lori igbese to n gbe lati dekun bi won se n pa awon  eniyan alailese ni awon ipinle Benue, Taraba, Zamfara ati  awon ipinle miiran  lorile ede Naijiria.
Bakan naa ni awọn miran n bu ẹnu ẹ̀tẹ́ lu àwọn ọmọbinrin naa pe kini wọn n wa kiri lasiko yii ati pe o yẹ ki tile oge wọn maa to wọn lati jẹ.
Ati ibẹ ni ọga mi ti gbe mi lọ si ile ijọba, a debẹ, ni wọn ba n ya fọto fun wa, ohun ta ri naa nuu.
Nibi akanṣe eto naa to waye ni Alliance Francaise de Lagos/The Mike Adenuga Center, Ikoyi, Kollington sọ pe orin Fuji ti kọja bẹẹ lasiko yii.
Bukọla Saraki lo jẹ iyalẹnu pe ajọ EFCC n tako aṣẹ ile ẹjọ giga l'Abuja eleyi to dena ajọ naa lati gba dukia rẹ.
"Ìṣesí Kunle Ọlasọpe ni mo ṣe yan iṣẹ́ akọ̀ròyìn láàyò - Lekan Alabi Fasiti Eko ti ""Cold Room"" ni Staff Club wọn pa látàri ìwádìí BBC lórí àwọn olùkọ́ kan Àṣírí tú!"
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Kollington ṣàlàyé bí orin Fuji ṣe bẹ̀rẹ̀ gan an ní Nàiìjíríà Olorin ọmọ orilẹede Uganda, Bebe Cool fi aworan iwe ile ẹjọ ti wọn fi paṣẹ pe ki wọn tu awọn mẹtẹẹta silẹ sita loju opo Twitter.
Ijoba ipinle Kwara n satileyin bii ipese oko atawon nkan miran ki ise yin le tubo rorun sii.
Ipinlẹ Oyo Gomina ipinlẹ Oyo, Seyi Makinde kede wi pe ijinasiraẹni gbọdọ tẹsiwaju ni ipinlẹ naa nitori iye awọn to n ni arun naa n peleke si ni ipinlẹ naa.
1 40786 Orilẹede montenegro 566 90.
Oríṣun àwòrán, others Àkọlé àwòrán, Ibidun Ituah Ighodalo fayé silẹ̀ ìlúmọ̀ọ́ká arẹwà tí fáyésilẹ̀ Iroyin ni awọn eeyan kereje atawọn eeyan diẹ to sun mọ oloogbe naa ni wọn fiwe pe sibi isinkun naa.
Bí a bá wà láàyè nípa Ẹ̀mí, ẹ jẹ́ kí á máa gbé ìgbé-ayé ti Ẹ̀mí.
Amasaya sọ fún Amosi pé, “Ó tó gẹ́ẹ́, ìwọ aríran, pada lọ sí ilẹ̀ Juda, máa lọ sọ àsọtẹ́lẹ̀ níbẹ̀, kí wọ́n sì máa fún ọ ní oúnjẹ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Damilọla Ajayi: Ọ̀dá owó ló ṣún mi dé ìdí lílo ìyarun bíi fèrè Aṣẹ alaafin lo ṣokunfa kiko awọn katakata nlanla ls si ilẹ naa lati fa awọn igbo naa kuro.
Èdè Yorùbá dùn lẹ́nu àwọn ọmọ òyìnbó yìí ní Michigan!
Awọn iroyin ti ẹ lee nifẹ si: Ọmọ to n ko ọmọ alainile kuro lori titi Tinubu ti bẹrẹ isẹ ti Buhari gbe le lọwọ Kini 'pen' lede Yoruba?
Wayi o, ikọlu meji miran lo tun waye laarọ Ọjọbọ nilẹ Faranse ati Saudi Arabia.
sc ) ati másíta síáyẹ ́ nsì ( b.
Orilẹede wo lo ni awọn obinrin to pọ julọ nile asofin rẹ?
"Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Camel sọ nigba kan wipe oun ni iru taba ti awọn dokita fẹran ju Lẹyin ti wọn ri i pe taba ni oogun kan ti wọn n pe ni ""nicotine"" ni ọdun 1828, ni awọn onimọ ilera bẹrẹ si ni yẹra fun lilo taba diẹdiẹ."
Lọ́jọ́ Iṣẹ́gun ọsẹ̀ yìí ni àwọn ọmọ ilé ìgbìmọ̀ aṣòfin dìbò láti gba àbá náà wọle kí ó le di òfin tí ará ìlú yóò tẹ̀lé (Free Provison Scotland) Èyí túmọ̀ sí pé, ojúṣe ìjọba ìbílẹ̀ ni láti máa pèsè àwọn páàdì yiìí fún gbogbo ẹni to ba nílò rẹ̀.
”Baba rẹ̀ dáhùn pé, “Láti kékeré ni.
29, lo jade lati inu apo asuwọn ijọba ipinlẹ Eko, to si wọ apo asuwọn miran nile ifowopamọ FCMB kan ti wọn ṣi ni ọjọ kẹtadinlogun, oṣu Kẹsan, ọdun 2017 lasiko iṣakoso gomina ipinlẹ Eko tẹlẹ, Akinwumi Ambode.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Oduduwa Alphabet: Òmìnira èdè ti dé fún Port Novo báyìí Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Oduduwa Alphabet: Òmìnira èdè ti dé fún Port Novo báyìí 15 Sẹ́rẹ́ 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 15 Èbibi 2020 Ìdalu ni ìṣèlú, ibi gbogbo la ti n kadiyẹ alẹ́ ni ọrọ ede jẹ́.
 Oun kii fẹ farahan ni gbangba.
Kí èpè di aṣọ ìbora fún un,ati ọ̀já ìgbànú.
Nígbà tí ọpọlọpọ ninu àwọn Juu mọ̀ pé Jesu wà ní Bẹtani, wọ́n lọ sibẹ, kì í ṣe nítorí ti Jesu nìkan, ṣugbọn nítorí kí wọ́n lè rí Lasaru tí Jesu jí dìde kúrò ninu òkú.
Inú àwọn orílẹ̀-èdè ń ru,àwọn ìjọba ayé ń gbọ̀n;OLUWA fọhùn, ayé sì yọ́.
Oríṣun àwòrán, @AkinwunmiAmbode Àkọlé àwòrán, Gomina Ambode, Jide Sanwọnolu ati Ọbafẹmi Hamzat lo ti gbamu bayii laaring o#selu APC leko Jide Sanyaolu Sanwonolu jẹ kọmiṣọna labẹ iṣejọba gomina ana nipinlẹ Eko Babatunde Faṣọla, ti Ambọde pẹlu si tun yan an gẹgẹ bii ọga agba ileeṣẹ to n mojuto ọrọ dukia nipinlẹ Eko, Lagos State Property Development Corporation (LSPDC) lọwọ yii.
Sanwo-Olu, Jimi Agbaje yọ kúrò nínú ìfọ̀rọ̀wérọ̀ ìtagbangba BBC ní Eko Àwọn àwòrán ẹ̀yìn ìtàgé níbi ìpàdé ìfọ̀rọ̀wérọ̀ BBC Yorùbá l'Eko 'Obìnrin tórí ẹ̀ pé lè tọ́ ọmọ láì nílò ọkọ rẹ̀' Ṣé INEC yóò tún ìwé ìdìbò tẹ̀ nítorí Banky W?
Gomina Babajide Sanwo Olu ti buwọlu iwe ofin meji eleyi to faṣẹ si itusilẹ awọn ẹlẹwọn mẹfa ati iyipada idajọ iku si ẹwọn gbere fawọn mẹta miran.
Wọ́n bẹ̀rẹ̀ sí jó yípo pẹpẹ tí wọ́n kọ́.
Samo Baba: Eléréepá ní mi láti kékere, ẹjọ́ sí pọ̀
Ọmọbinrin náà dá baba rẹ̀ lóhùn pé, “Baba mi, bí o bá ti jẹ́jẹ̀ẹ́ kan níwájú OLUWA, ṣe sí mi gẹ́gẹ́ bí ẹ̀jẹ́ rẹ níwọ̀n ìgbà tí OLUWA ti ràn ọ́ lọ́wọ́ láti gbẹ̀san lára àwọn ará Amoni, tí í ṣe ọ̀tá rẹ.
Oríṣun àwòrán, Facebook/SEyi Makinde Kọmisọnna fun eto idajọ ati olootu naa sọ wi pe o da awọn loju pe awọn asofin yoo ri daju pe abadofin naa kẹsẹjari, ki gomina naa le fowosi laipẹ.
Bakan naa lo sọ nibi apero ọhun pe ọrọ eto aabo to mẹhẹ ni Naijiria nii ṣe pẹlu awọn ọta ile ti wọn ṣi ilẹkun fun ti ita.
Owó tí Àbáchà jí: Wo ohun tí ó lè ṣe fún ará ìlú
Ó tí wáye ní ìpínlẹ̀ Ọyọ, Ogun ati Eko nàá.
Ninu ọrọ kan to kọ si ori ayelujara Twitter rẹ lo tun ti paṣẹ pe ki ajọ to n ri si ina mọna-mọna pin ẹrọ to n ṣe onka ina, meter, kaakiri Naijiria.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Aliko Dangote: Mo gbà $10m ní bánkì kí o lè dami loju pé lòótọ́ ní mò lowo 7 Ìgbé 2019 Oríṣun àwòrán, BBC/GETTY Olokoowo to lowo ju lọ ni Afrika Aliko Dangote ti ṣọ bi ohun ti ṣe gba miliọnu dọla mẹwa ni banki tori pe ohun fẹ mọ daju pe lootọ ni ohun lowo to to bẹ.
Ọ̀dọ́ Aguntan náà dàbí ẹni pé wọ́n ti pa á.
"Ẹ́yin ọdọ ti ri ere nipa awọn tẹ n beere fun lati ipasẹ iwọde tẹ n se, amọ, ẹ gbọdọ sọra se, kẹ ma ba padanu awọn ere naa nitori bi iwọde ọhun se n di ọlọjọ gbọọrọ.
Àwọn kan bá mú ọkunrin tí ojú rẹ̀ ti fọ́ rí yìí lọ sọ́dọ̀ àwọn Farisi.
Ẹ gbọ́, gbogbo ẹ̀yin orílẹ̀-èdè,fetí sílẹ̀, ìwọ ayé, ati gbogbo ohun tí ó wà ninu rẹ̀.
Báyìí ni ojú wọn rí: olukuluku wọn ní ojú eniyan níwájú, àwọn mẹrẹẹrin ní ojú kinniun lápá ọ̀tún, wọ́n ní ojú akọ mààlúù lápá òsì, wọ́n sì ní ojú ẹyẹ idì lẹ́yìn.
Ẹ̀yin ẹkùn yókù, ẹ fi ikọ̀ àbò Amotekun ṣe àwòkọ́ṣe rere - APC Ọmọọba ilẹ̀ Gẹ̀ẹ́sì, Harry àti ìyàwó rẹ̀ kọ ipò wọn sílẹ̀ ní ìran ọba Ta ló ń fi ògùn Paracetamol, Hypo dín Gààrí lọ́dọ̀ yín níbẹ̀ yẹn?"
N kò ní èrò wí pé mo tún lè sí nínú ayé yìí mọ́.
Ṣugbọn kò pa àwọn pẹpẹ ìrúbọ run, àwọn eniyan ṣì ń rú ẹbọ, wọ́n sì ń sun turari níbẹ̀.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: ‘A ti mọ̀ tẹ́lẹ̀ pé Kayọde Fayemi ni yóò jáwé olúborí ní Tribunal’ Ṣé o fẹ́ mọ gbogbo kókó pàtàkì ti wọn gbé yẹ̀wò nipinlẹ Eko- #BBCGoveDebate Day 19: Wo ohun àràmàndà tí àwọn olósèlú máa ń ṣe lásìkò ìbò #BBCNigeria2019 Iwọ́de ṣẹlẹ̀, ọlọ́pàá ti ọ́fíísì Onnoghen pa Ìbòòsí!
Arabinrin naa, Osinibibra Warmate, pẹlu iranlọwọ awọn agbẹjọro rẹ, pe ẹjọ miran si ile ẹjọ giga ilu abuja, ti wọn si fi ẹsun kan Sẹnetọ Abbo pe o tẹ ẹtọ rẹ mọlẹ.
Eyi ko ṣẹyin bi Gomina ana Abdulaziz Yari ṣe kọwe beere owo ifẹyinti rẹ oṣu meji ti wọn ko ti san fun.
O ṣiṣẹ olukọni ni Fasiti olódòdó Ifẹ, to ti di Obafemi Awolowo University, Ile Ifẹ nibi to ti gba oye ọjọgbọn to tun ti ṣe adari ẹka ẹkọ nipa ilẹ Adulawọ (Institute of African Studies) lati ọdun 1974 si 1977.
O tẹsiwaju pe ''o mu ki ara mi ko ṣiọ ti mi o si mọ oun ti ma ṣe pe ọgbẹni Pulev lẹ wuwa si mi lọna aitọ.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Boko Haram pa èèyàn 25 ní Màìdúgùri Oluwo Ìwo ṣ'àlàye lori oye Emir Àwọn akínkanjú obìnrín tó ń se isẹ́ ọkùnrin Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
ayẹyẹ ọdun Sallah to koja yii ni won so pe o poora bi iso.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Coronavirus tips: Kìí ṣe gbogbo ìbòmù ló ń dá coronavirus dúró O ni erongba oun ni ibẹrẹ iwadii naa ni pe kamẹra oni milimita mẹjọ a le maa lo batiri naa fun ọpọ wakati.
Òkìkí kan nígboro lẹ́yìn tí Davido fí fotò síta pé oun bẹ̀rẹ̀ ètò agúnbánirọ lẹ́yìn ọdun mẹ́ta tó parei ẹkọ rẹ̀ ní fasiti.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Àwọn akọ̀rọ̀yìn fárígá l'órílẹ̀-èdè Ghana Àwọn akọ̀rọ̀yìn fárígá l'órílẹ̀-èdè Ghana Ọọni, Ọlọta pe fun ipamọ aṣa Yoruba Ilé aṣòfin àgbà takò ìdájọ lori Omo-Agege Àwọn ará Makoko so pé, ìyàlẹ́nu lọ je lati ri awon ọmọ onílẹ̀ pẹ̀lú àwọn ọlọ́pàá, Ó ní, wọn kọ́kọ́ lọ ìjọ Àpọ́sítélì kan ládùúgbò òhún, tí wọn lọ bá nkan je nibẹ, leyin náà, ni wọn bere sini bá ilé jẹ aarin ládùúgbò, tí wọn sì ń pa ènìyàn lọ́sàn-án gangan.
Nigba to n ba BBC Yoruba sọrọ, awọn osisẹ ibudo itaja naa salaye pe ọna lati mase jẹ ki itakun kan soso da awọn lepo nu lẹẹkeji lo mu ki awọn alasẹ ileesẹ Shoprite gbe igbesẹ naa, tori owo gọbọi ni wọn padanu lọjọ Isẹgun lasiko ikọlu awọn eeyan to n fẹhonu naa, ti wọn ko ọpọ ọja wọn.
Nǹkan yan, àwọn aṣẹ́wó fẹ́ daṣẹ́ sílẹ̀ nítorí ẹ̀kúnwó epo ní Nàìjíríà Àwọn tó fẹ́ kí ọba máa ta ilẹ̀ ilú ló fẹ́ yọ Oluwo lóyè- Ẹgbẹ̀ Baálẹ̀ Iwo.
Ẹkunrẹrẹ ajọsọ ọrs pẹlu BBC News Yoruba lori ẹrọ ayelujara lo wa loke iroyin yii.
Wẹrẹ ti isẹlẹ naa sẹlẹ ni awakọ tirela naa ti fẹsẹ fẹ, amọ ti ọlọpaa ni wọn n wa a lọwọ.
Ẹsun ti wọn fi kan an ni pe ko fi ọwọ mimọ ṣe eto isuna awọn owo ti ajọ naa ri gba pada lọwọ awọn eeyan.
Orile ede Naijiria ti ni owo nibi ipamo ju ti ateyinwa lo, o tun fesun kan ijoba ana nipa ,bi won se ba orile ede yii je,bo tile je pe owo goboi ni won ri lori epo robi lasiko ijoba aare ana”.
"Ẹ̀tanu ni àwọn ìmáàmù Yoruba fi yan Waziri míì, ojúṣe ọba ni - Oluwo Gani Fawehinmi lọ àmọ́ kò kú lẹ́yìn ọdún mẹ́wàá tó dará ilẹ̀ Ìdájọ́ ọmọ mi tó gbé àdó ìkú wọ bàálù le púpọ̀, ẹ bá mi wòó ṣe - Bàbá Mutallab Àtúnse gbọdọ̀ bá bí EFCC ṣe ń gbógun tí ìwà ọ̀daràn - Ọọ̀ni ""Bàbá mi kú, kò sówó ni mo ṣe kúrò ní fásitì Ilorin láti fọ gíláàsì ọkọ̀ lójú pópó"" Ọkọ̀ agbépo gbiná lọ́nà maròsẹ̀ Eko sí Ibadan Bakan naa lo ṣalaye pe ijọba apapọ ti gbe atunto eto igbayegbadun jade fun awọn ọlọpaa paapaa lori itọju ilera wọn ati lati lee ni ilera ara wọn."
O ni lẹyin abajade gbogbo iwadii ti awọn igbimọ ti Buhari yan lati ṣe iwadii ẹsun ikowojẹ naa ni Aarẹ gbe igbesẹ yii.
Eyi ṣe bi ẹni rini lára díẹ̀ sùgbọ́n àwọn ara Sardinia ni Italy nifẹ òun náà gidigidi.
OLUWA Yan Isikiẹli Gẹ́gẹ́ Bí Olùṣọ́.
eto iranwo ti won se fun orile ede Naijria, pe iru eto bayii yoo tun je ki igbe
Awọn ileesẹ agbohunsafẹfẹ yi ni wọn ti pinnu tẹlẹ lati gbe eto ibura olori awọn ọmọ ẹgbẹ alatako lorilẹede naa, Raila Odinga safẹfẹ lọjọ isẹgun.
Aare Russia, Vladimir Putin, ba gomina ipinle Kemerovo soro lori ero ibanisoro ati ile-ise panapana lagbegbe naa lati sofintoto ohun ti o sokunfa ijamba ina naaAare Vladimir Putin kedun pelu awon ore ati ebi awon oloogbe ohun, o si gbadura pe olorun yoo tewon si afefe rere.
"Fun apẹrẹ bo ṣe tu awọn oluwọde ""Black Lives Matter"" ka eyi to June bii igbesẹ ikorira."
Ṣugbọn Dafidi túbọ̀ ní igbẹkẹle ninu OLUWA Ọlọrun rẹ̀.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ọmọ Nàìjíríà tó fẹ́ pa adájọ́ lọ ẹ̀wọ̀n gbére ní Amẹ́ríkà 3 Ọ̀wàrà 2018 Oríṣun àwòrán, Olopaa Texas Àkọlé àwòrán, Ile ẹjọ ni Onyeri yoo lo iyoku aye rẹ ni ẹwọn Ọmọ Naijiria ẹni ọdun mọkanlelogun kan Chimene Onyeri ti rẹwọn he ni orilẹede Amerika lẹyin fun ẹsun jibiti, if'ọgbọn gbowo eru ati pe o gbiyanju lati yinbọn pa adajọ kan ti orukọ rẹ n jẹ Julie Kocurek ni ọdun 2015.
Oríṣun àwòrán, STEFAN HEUNIS STEFAN HEUNIS/AFP/Getty Images Àkọlé àwòrán, Ọmọ tó dín díẹ̀ ni Mílíọ̀nù méjì ni ó wà nínú ewu àìrí oúnjẹ jẹ Ó kéré tán ènìyàn tó lé ní Mílíọ̀nù Márùn-ún ni yóò nílò oúnjẹ àti iranlọwọ láti gbé ìgbé ayé wọn lásìkò tó ṣeé ṣe kí nkan burú sii.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Eyi kii ṣe igba akọkọ ti Aarẹ Buhari yoo ko iyan awọn ara ilu rẹ kere lẹyin odi #LazyNigerianYouths - Muhammadu Buhari / oṣu kẹrin, 2018 Yoruba bọ,wọn ni bi a ba ta ara ile ẹni lọpọ, a ko le ri ra l'ọwọn.
Èèyàn mẹ́tàdínláàdọ́fà ló móríbọ́ lọ́wọ́ Covid-19, 443 míì tún lùgbàdì rẹ̀ lọ́jọ́ Ẹtì Èèyàn 16 kú lẹ́yìn tí bàálù Air India já lulẹ̀ , tó sì kán sí méjì ní Kerala Ilé ẹjọ́ ti dájọ́ Naira Marley, wọ́n ní kó san owó ìtànràn, kó tún tọrọ àforíjì O ni awọn ileeṣẹ igbohunsafẹfẹ kan yoo mọọmọ gbe ọrọ kobakungbe sita lori afẹfẹ, ti wọn yoo si gba lati san owo itaran ọhun.
Ninu ọrọ to ba ikọ BBC Yoruba sọ l'Ọjọbọ, nibi ti ayẹwo ti n lọ lọwọ fun awọn to fẹ darapọ mọ ikọ Amọtẹkun ni papa iṣere Lekan Salami nilu Ibadan, ni Toogun ti sisọ loju ọrọ yii.
Fani Kayode ninu lẹta naa ni, bi oun ṣe fẹran Tinubu to amọ iwa rẹ lo mu ki oun sa fun un, nitori imọtara ẹni nikan n ba ja.
Nítorí àwọn tí à ń yàn bí olórí alufaa lábẹ́ òfin Mose jẹ́ eniyan, wọ́n sì ní àìlera.
Wọ́n tún un kọ́, wọ́n sì ń gbé ibẹ̀.
Ṣùgbọ́n ìyá mi kọ̀, ó ni òun kò fẹ́ ẹnikẹ́ni mọ́ lóde ayé, òun ó jókòó nínú ilé bàbá mi kí òun máa tọ́jú wa.
Nisinsinyii, gbà wá lọ́wọ́ àwọn ọ̀tá wa, a óo sì máa sìn ọ́.
Fun ọpọlọpọ ọjọ, awọn ọdọ wọn yii, kekere ati agba pẹlu ọkunrin ko sun lalẹ Ada ati ọkọ ni wọn mu dani ti wọn n kaakiri opopona adugbo wọn lati duro de awọn ole ti ko wa si agbeegbe wọn.
Ìgbà tí obbìnrin yìí dakẹ́ ọ̀rọ̀ – ísọ ó ki ọwọ bọ àpò yẹ̀rì rẹ̀ óo sì mú èèso igi dídán kan jáde, lẹ́hìn ìgbà tí ó yẹ̀ ẹ́ wò díẹ̀ ó sọ ọ́ sí ẹnu.
Bẹẹ tun ni Taiwan mu alekun ba iye asọ idaabobo ara ẹni tawọn osisẹ ilera n wọ to fi mọ ibomu .
Josaya bá pàṣẹ pé kí wọ́n fi sílẹ̀ bí ó ti wà, kí wọ́n má ṣe kó egungun rẹ̀.
Bí ó bá ní orin kan tí ń fi gbogbo ọ̀nà wá oyè Ìwọ́de Ojúnà ti ọdún yìí, ni orin yìí tí ó ní àyè láti jáwé olúborí: ìlù “soca tí ó tani jí”, ọ̀rọ̀ orin tí ó sọ nípa ìṣọ̀kan tí àjọ̀dún náà máa ń mú wá, àti ègbé ọlọ́pọlọ tí ó kó gbogbo ẹ̀yà tí ó ń kópa nínú Ijó ìta-gbangba náà pọ̀  tí ó ń bá òṣìṣẹ́ akọrin kiri, tàbí bí àwọn ọmọ ìbílẹ̀ Trinbago ṣe máa ń sọ, “famalay” rẹ (kí a máà ṣèṣì fi wé “ẹbí”) :
"Akọle to fun un ni ""Survival of Jelili"" Laarin ọsẹ yii naa lo ṣe afihan rẹ ni itagbangba fun igba akọkọ."
 Òun náà gba ònà ilé-ifè , ó sì yà kí odùduwà .
 iye ikú tí èyí ń fà kò tíì yé ni dáradára .
Kinni ibeere ti won lo fun iwadii naa?
San Louis Keita to jẹ olórí ọ̀tẹlẹ̀múyẹ́ ní Mali ló fẹ̀sùn náà kàn lọ́jọ́ Jimọ, ọjọ́ keje, oṣù kẹ̀jọ, ọdún 2020 níbi ìpàdé àwọn oníròyìn kan tó pè ni Abidjan tí i ṣe olúùlú Ivory Coast.
O si lọ fi ìlú Eko ṣe ibugbe, nibi to ti gbé pẹlu Alhaji N.
To óò bá lọ roba idaboobo nítorí pé ìwọ àti enikeji rẹ tí ṣe ayẹwo pé eko ni a aarun tí ń tí ara ìbálòpọ̀ wáyé, tàbí ẹ ń lọ oogun tí kì je ki eniyan ni oyún tí ènìyàn kò fẹ́, ìyẹn dára, sugbon tó bá jẹ́ pé ó kii lọ roba idaabobo ni torí ó fi ọkàn sí pé ẹ ó máa faa yọ tàbí ẹ ń fọkàn sí pé ẹ ó lè ní aarun tó ń tí ara ìbálòpọ̀ mú ènìyàn, ó ṣe pàtàkì kí ẹ bere si lọ roba idaboobo ni asiko yii.
Nítorí èyí, wọ́n di eniyan ńlá,wọ́n di olówó,
Coronavirus in Nigeria: Wọ́n ti fi ọmọ orílẹ̀-èdè Italy tó kó coronavirus sílẹ̀ nílèéwòsàn
Nítorí pé, gbogbo àwọn ọba Amori, tí wọn ń gbé agbègbè olókè, ti kó ara wọn jọ sí wa.
Odumosu ni awakọ ni ẹgbẹrun kan aabọ naira ni oun yoo gba, nigba ti ero ọkọ yari si ẹgbẹfa naira, eyi si lo mu ki awakọ pana ọkọ lagbegbe lori omi nitori iyatọ ọọdunrun naira.
Ọ̀rọ̀ yi ṣe rán ẹni ti ó bá nfi àárọ̀ ṣeré leti pé bi igbà bá ti lọ, kò ṣe rà padà.
Deng, tí a tún mọ̀ sí Huang Huang, tí ó jẹ́ ayàwòrán aládàádúró tí ó ti bá òǹyàwòrán Beijing, Ai Weiwei ṣiṣẹ́ papọ̀.
Afénifẹ́re: Oníkálukú ni yóò tẹ̀ka síbi tó wù ú tó bá yá
Idibo ti yoo waye naa yoo ni awọn oludije mejidinlaadọta pẹlu orukọ ẹgbẹ oselu wọn ni ori patako Ajọ INEC to wa ni ilu Osogbo ni ipinlẹ Osun.
Àwọn ọmọ Sebuluni kò lé àwọn tí wọ́n ń gbé ìlú Kitironi jáde, ati àwọn tí ó ń gbé Nahalali, ṣugbọn àwọn ará Kenaani ń bá wọn gbé, àwọn ọmọ Sebuluni sì ń fi tipátipá kó wọn ṣiṣẹ́.
Loṣu kẹjọ ọdun to kọja ni awọn alaṣẹ ṣeto idanilọla nipinlẹ Eko fun awọn oṣiṣẹ eleto aabo meji ti wọn da owo gọbọi ti wọn ri he pada ati awọn ohun eelo olowo iyebiye mii.
Kohati bí ọmọkunrin mẹrin: Amramu, Iṣari, Heburoni ati Usieli.
"Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Toríi ""Coro"", ẹ wo bí ètò ìsìn ìgbéyàwó orí ayélujára Zoom ṣe lọ Wo àwọn iléeṣẹ́ ilẹ̀ òkèrè tó ti kógbáwọlé rí ní Nàìjíríà àti ìdí Oríṣun àwòrán, Facebook Ọjọ kẹta, oṣu Kẹjọ, ọdun 2020 ni iroyin kan gbode pe gbajugbaja ile itaja Shoprite fẹ kogbawọle ni Naijiria nitori airi ere jẹ latari ajakalẹ arun Covid-19 to mi gbogbo agbaye titi."
Ọ̀gágun tí ó ti jagun fẹ̀yìntì kì í sinmi ní orílẹ̀-èdè Nàìjíríà
3 2441 Orilẹede Lesotho 44 2.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Amọṣa, Ọgbẹni Saleshando ko gba eyi gbọ.
Ìyàwó rẹ̀ pàápàá kú bẹ́ẹ̀ ni àwọn ara ìlkú náà kò fẹ́ràn rẹ̀, ojoojúmọ́ ni wọ́n ń di rìkíṣí mọ́ ọn.
Ṣebí tí kò bá nídìí, obìnrin kìí jẹ́ Kúmólú.
yatọ si Oloye Gani Adams, Baba Yẹmi Ẹlẹbibọn ati awọn eekan mii, a ṣi n reti awọn alejo pataki mii gẹgẹ bi eto naa ṣe gbinaya.
Ibi ààbò ni yóo máa gbé, àpáta ńlá ni yóo jẹ́ ibi ààbò rẹ̀.
Iroyin naa fikun pe, awọn mẹjọ ni wọn wa ni inu ọkọ Sharon Volkswagen ti eniyan marun pẹlu awakọ ku, amọ wọn ko mọ ibi ti eniyan yoku wa.
Ki aṣa yii ma ba a parun, awọn ọmọ Kaaro o jiire, yala nijọba tabi aladani, maa n ṣe agbekalẹ ibudo ise nkan isembaye lọjọ si, lati fi gbe awọn atọka aṣa Yoruba larugẹ.
Ìròyìn bi Ọlọpa funfun ti yin ibọn si ọkùnrin Aláwọ̀-dúdú ni ojú ọmọ àti aya nlọ lọ́wọ́ nigbati ìròyìn bi Ọlọpa funfun ti pa okunrin Aláwọ̀-dúdú miran bi ẹni pa ẹran ti tún jáde.
ti o dibo rẹ tan, pẹlu iyawo rẹ arabinrin,Toyin Saraki, ni agboole  Ode Opobiyi  ni woodu 005 ,Ajikobi ni ijoba ibile  Ilorin ni ipinle Kwara.
"Anfani ayajọ awọn obinrin yii ni lati woye awọn isẹ takuntakun ti awọn obinrin n se lagbaye.
OLUWA, Ọlọrun àwọn ọmọ ogun, gbọ́ adura mi;tẹ́tí sílẹ̀, Ọlọrun Jakọbu!
Àwọn ìjòyè ilẹ̀ Hori, gẹ́gẹ́ bí olórí ìdílé ìdílé wọn ní ilẹ̀ Seiri.
Raila Odinga fidiremi ninu idibo ọdun to kọja eleyi ti Uhuru Kenyatta jawe olu bori sugbọn o kọ lati gba abajade ẹsi ibo naa.
ìjọba Nàìjíríà ti kéde ìsinmi lọ́jọ́ Ìṣẹ́gun àti Ọjọ́rú Bakan naa lo dupẹ lọwọ awọn ọmọ Naijiria fun fifi ile, ọna ati okoowo wọn silẹ lati jade dibo lasiko idibo apapọ to waye ṣaaju lọdun yii, lai naani ohun to pe ni ọrọ alufansa to ni awọn eeyan kan ṣaaju ọdun yii lori ohun ti yoo ti ẹyin idibo naa jade pe ko ni rọgbọ.
Ṣugbọn nítorí pe òtítọ́ ni mò ń sọ, ẹ kò gbà mí gbọ́.
Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Risikat Azeez: Aya gómìnà tún fẹ́ gba sọ́ọ́bù, ra ọjà fún obìnrin olójú búlúù8 Owewe 2020 5:58 Fídíò, Akomolede ati asa Yoruba: Ẹ wá kọ́ nípa àpòtí ìṣura èdè wa lórí BBC Yorùbá, Duration 5,5820 Ògún 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Ààrin ìgbà méjéèjì wọ̀nyí ni ìgbà ìrúwé tí  ìgbà òtútù nparadà di ìgbà ooru, àti ìgbà ìwọ́wé tí  ìgbà ooru nparadà di ìgbà òtútù.
Bí a bá gbáa yín mú tí ẹ́ ju Ààdọ́ta olùjọ́sìn lọ pẹ́rẹ́ ní ṣọ́ọ̀ṣì.
Nibayii, eeyan 956 lo ti ba ajakalẹ arun naa lọ ni Naijiria.
Wọn gba ipe lori ẹrọ alagbeka rẹ wọn si ṣalaye ọna de aafin fun awọn kan."
Ẹ̀rù kò bà mí láti padà sí Bolivia- Evo Morales Ọlọpàá gba owó ilé ìwé #150,000 lọ́wọ́ akẹ́kọ̀ọ́ DELSU kan Olùdíje 24 ni yóò kópa ní ìdìbò Kogí Kò sí aàyè fún ìbò rírà àti títà ni Kogi àti Bayelsa- IGP Irọ́ ni pé wọ́n sèkọlù sí Gómìnà Seyi Makinde - Ọlọ́pàá Kogi Kàyéfì rèé!
Ta ló tó dúró níwájú rẹtí ibinu rẹ bá dé?
Christina Brazzale, ni sise isẹ lati ile ko ni awọn nkan ti yoo ma dari ọkan kaakiri pupọ bi ki eeyan wa ni ibisẹ.
com Iran ko ti tan ni ifẹsẹwọnsẹ naa nitori lẹyin iṣẹju mẹsan si asiko goolu yii ni Calvert-Lewin daa pada bi owo baba ijẹbu fun Everton.
Wọn a maa pe e ni akọrin f'ọba, fun aarẹ atawọn adari orilẹede.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Supreme Court: Atiku ní ìdájọ́ ilé ẹjọ́ tó dá Buhari láre kò b'òun nínú jẹ́ 30 Ọ̀wàrà 2019 Oríṣun àwòrán, Twitter/Muhammadu Buhari 'Bi ile ẹjọ ba da idajọ ododo tabi ti wọn ba idajọ ododo nidakeji bakan naa, awọn ọmọ Naijiria lo le sọ.
awon omo ogun olote naa, nikete la fi awon omo ogun ranse sibe lati lo se won
Ogun Flood: Ọ̀pọ́ Dúkìá ló sọnù ní 2019 lásìkò tí ìjọba ṣí dáàmù Ọyan
Ìdí rèé tí Aisha Buhari kò tíì padà sí Nàìjíríà- Iléeṣẹ́ ààrẹ Lọjọ kẹẹdogun oṣu keje ọdun 2019 lawọn ajinigbe gbe iya Siasia niluu Odoni to wa nijọba ibilẹ Sagbama nipinlẹ Bayelsa.
Yoruba Films: Bó ṣe ń lọ́ lágbo Yollywood lópin ọ̀sẹ̀ yìí
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ilé ẹjọ́ tú ìgbéyàwó ọdún mọ́kànlá ká nítórí pé ìyàwó fí ìbálòpọ̀ dun ọkọ rẹ̀ Ó kéré tán ọmọdé 142,000 sí 160,000 ní àìsàn otútú àyà ń pa lọ́dọọdún ní Nàìjíríà Èèyàn 1,076 ni ìjàmbá mọ́tò ti sọ di olóògbé láti oṣù mẹ́ta sẹ́yìn ní Nàìjíríà- FRSC Ìdí tó fi yẹ kí o máa mú ẹmu ògidì Wọn ni awọn kii ko ejo ti awọn n ta ninu igbo, awọn maa n sin ejo fun tita ni.
O ni awọn kan lo ran oun niṣẹ ibi naa.
Amọ ko dara ki eniyan jẹ ẹ ni ajẹju nitori o le mu ki suga ara pọsi, to si le e fa ijamba si ara.
Sugbọn aṣọ ko ba Omọyẹ mọ.
Alaga ẹgbẹ oselu PDP ni ipinlẹ Kwara, Kola Shittu, lasiko to n ba BBC Yoruba sọrọ ni, ẹgbẹ PDP ti setan lati kọ esi idibo naa, amọ awọn si n duro ki INEC fi akọọlẹ akojọpọ esi ibo naa ransẹ si awọn.
Ṣugbọn nígbà tí ó di ọjọ́ keje, Samsoni sọ fún un, nítorí pé ó fún un lọ́rùn gidigidi.
Wọn fi ẹsun ijinigbe ati ifiyajẹni kan an nipa ọmọ ọdun mẹrinla kan, Stompie' Seipei.
Nígbà tí ẹ bá ń kọjá lọ ní oko ọkà ẹlòmíràn, tí wọn kò tíì kórè, ẹ lè fi ọwọ́ ya ìwọ̀nba tí ẹ lè jẹ, ṣugbọn ẹ kò gbọdọ̀ fi dòjé gé ọkà ọlọ́kà.
Oríṣun àwòrán, Wikipedia Sugbọn sibẹ, ilu ko tuba tusẹ, titi ti Sani Abacha fi ku sori aleefa, MKO Abiola naa jade laye, ti ijọba ologun Abubakar Salami si gba akoso orilẹede yii lọdun 1998.
Jesu bá sọ fún un pé, “Dìde, máa lọ.
 ebun sveriges riksbank ninu ìmọ ̀ ìjìnlẹ ̀ okòwò ní Ìrántí alfred nobel jẹ ́ dídìmúlẹ ́ látọwọ ́ sveriges riksbank ní ọdún 1968 ó sí kọ ́ kọ ́ jẹ ́ bíbùn ní ọdún 1969 .
Ninu ọrọ kan eleyi ti alukoro fun ileesẹ ọmọogun lorilẹede Naijiria, Ọgagun John Agim ba BBC sọ, o ni aisi iroyin to to lati ọdọ awọn olugbe awọn agbegbe ti ina wahala naa ti n jo fun awọn ọmọogun n pagidina wiwa egbo dẹkun si gulegule awọn ikọ Boko Haram.
Agbébọn Fulani Darandaran dá ọmọ olókùú lọ́nà-Samson Ayokunle Ọmọ Yoruba to fẹ Fulani Ilorin Odumakin sọrọ lori Fulani darandaran Ọmọ Yoruba niyawo mi - Arakunrin Fulani Omowe Tunde Hamzat ni oun ri aridaju pe àwọn Fulani yii ko ṣiṣẹ wọn lasan.
Ọjọ Ẹti, ọjọ kejilelogun oṣu Kẹta 2019 ni meji ninu ọmọ igbimọ to gbọ ẹsun to jẹyọ latara idibo naa dajọ pe oludije PDP lo wọle.
Toun ti akitiyan awọn onimọ sayẹnsi jakejado agbaye,diẹ lohun ta mọ nipa arun yi ti gbogbo aye si ti wa n ṣakitiyan lati wa idahun si ibeere to mu wa.
Nítorí náà, orúkọ ṣe pàtàkì ni Ọlọ́run ṣe fún ẹ̀dá alààyè kìn- ín- ní ní orúkọ tí Ó sì fú un láṣẹ láti fún àwọn ẹ̀dá ìyókù ní orúkọ tí wọn yóò máa jẹ́.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Aisan Cancer pa ọkunrin kan lẹ̀yin ọjọ̀ díẹ̀ to jẹ milionu kan dọ́là 3 Èrèlè 2018 Oríṣun àwòrán, Science Photo Library Àkọlé àwòrán, Àìsàn jẹjẹrẹ ti seku pa ọpọ eniyan Arakunrin kan ti wọn pe orikọrẹ ni Donald Savastano ni ìbànújẹ́ ti pade ayọ̀ rẹ̀, nigba ti a gbọ pe o gbẹ́mìí mì lẹ́yìn ọjọ mẹ̀tadinlogun gééré to jẹ miliọnu kan owo dọ́là ninu ìyíkoto.
lagbara lati yan awọn igbimọ abẹnugọ ti yoo maa ba wọn ṣe awọn ojuṣe wọn
A wá fún un ní idà kan tí ó tóbi.
Ìwọ̀n àwọn àwo kòtò tí wọ́n fi wúrà ṣe jẹ́ ọgọfa (120) ṣekeli.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ìgò ọtí méje àti sìgá ṣokùnfà ẹjọ́ ikú 'Owó ìbò ni bílíọ̀nù kan tí Buhari bu'wọ́ lù' 'Àwọn Dókítà fẹ́ kẹ́yin s'awọ̀n alárùn lassa' Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Biba ara eni ni ibalopọ lori afẹfẹ kii ṣe aṣa ilẹ wa rara.
Ó máa ń jẹ́ kòsee-mámu, táa bá sì muú jù, ó leè ní ipa tí kò dára lórí ọpọlọ àti ara.
Abẹwo yii n waye lẹyin ikọlu sawọn ajeji to ṣẹlẹ ni Soth Africa laipẹ yii ni eyi ti ọpọ awọn ọmọ Naijiria ti ni lati pada wa sile.
Àwọn kan ninu àwọn ọkunrin mi rọ̀ mí pé kí n pa ọ́, ṣugbọn mo kọ̀ láti ṣe bẹ́ẹ̀.
Ijamba ọkọ ofurufu miran to waye lai pe yi Gbogbo eeyan mokanlẹladorin to wa ninu baalu Russia kan to jabọ ni ọjọ aiku ni wọn ku.
Ọọni ni pé wọ́n o mú wọ́n si ilé Orisà Oodua láti lọ wádìí ibi ti ọmọ náà wa.
Ikú tí yóò pa ọmọ Ádámọ̀
Ṣùgbọ́n ìwà rẹ̀ burú tó bẹ́ẹ̀ ó sì dá rìkiṣí sílẹ̀ ní òde ọ̀run.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Nigeria SWAT team, EndSars, End SWAT: Àfiwé owó oṣù ọlọ́oàá Nàìjíríà pẹ̀lú akẹgbẹ́ wọn lókè òkun 17 Ọ̀wàrà 2020 Oríṣun àwòrán, @NPolice Se ileeṣẹ Ọlọpaa Naijira dabii gbogbo ileeṣẹ to ku ni?
Fi ohun ìní rẹ bọ̀wọ̀ fún OLUWApẹlu gbogbo àkọ́so oko rẹ.
Olubadamoran ijoba ile Geesi tí gba ìjọba nimoran pé àwọn kò tíì tlri àrídájú bóyá aarun tó ń bá ìgbà rìn ni, tó bá jẹ́ àsìkò lọ ń bá ṣe ó túmọ̀ sí pé nkan tó kéré sì kata àti ofinkin ni.
n mojuto eto ilera ,lo n mojuto ile itoju naa.
Ẹ̀kọ́ kẹta ti ogun Ìjàyè kọ wa ni pe ti àlàáfíà bá wà nílẹ Yoruba, àwọn ará ìta kò ni ráyè dá sí ọ̀rọ̀ wa lati mú iyapa wa.
Ṣé o lè gbẹ́kẹ̀lé e nítorí pé agbára rẹ̀ pọ̀,tabi kí o fi iṣẹ́ rẹ sílẹ̀ fún un láti ṣe?
‘Ọlọ́run ní kẹ ra bàálù tuntun fún mi’ Wọn fi ẹsun kan awọn ọkunrin mẹtẹẹta ọhun pe wọn fun awọn ọmọ orilẹ-ede Uganda kan ni kẹmika ti wọn ṣe latara 'Chlorine Dioxide'.
Ẹnikẹ́ni kò fún wa ní koríko, sibẹ wọ́n ní dandan, a gbọdọ̀ mọ iye bíríkì tí à ń mọ tẹ́lẹ̀.
A ti gbé kọ́kọ́rọ́ sẹ́nu ibodè Nàìjíríà kí ọrọ̀ ajé wa leè gbé pẹ́lí- ìjọba àpapọ̀ Ipinlẹ Kogi yoo wọ inu agbami eto idibo gomina ni oṣu kọkanla pẹlu oniruuru iroyin nipa gbese ti wọn ni ijọba jẹ oṣiṣẹ nibẹ.
Nítorí ìkọlù àjòjì ní South Africa, èèyàn 5000 ló padánù iṣẹ́ wọn ní Nàìjíríà Gbogbo igbiyanju BBC lati ba awọn agbofinro ipinlẹ Kaduna sọrọ lori ẹseun yii ko tii bi eso rere bayii.
Ní ọgbọ̀n ọjọ́ nínú oṣù kẹfà ọdún 2012, wọ́n dá ẹjọ́ ikú fún Hamza Al-Mustapha àti Alhaji Lateef Shofolahan lóri pípa Kudirat Abiola.
Matriculation Board, JAMB) ti se idanwo fun awon omo orile ede yii to  wa niluu okeere ati awon to n gbe lorile ede
Ọmọbinrin naa ku sileewosan aladani kan nilu Kaduna, lẹyin ọjọ meji to bimọ, nitori aisan aromọleegun 'Sickle cell Anaemia.
Ẹni tí ó kọ etí dídi sí òfin Ọlọrun,adura rẹ̀ pàápàá yóo di ìríra sí Ọlọ́run.
Ẹwẹ, awọn eeyan mejilelogoje miran lo ti ri iwosan ti wọn si ti ni ki wọn maa lọ ile wọn layọ ati alaafia.
Minisita agba fun Kerala ni omiyale yii lo tii buruju lati bi ọgọrun ọdun ni orilẹede India.
Obìnrin àti ọmọdé tó há sábẹ́ ilé tó wó ní Ebute Meta ti ń gba ìtọ́jú, LASEMA ń ṣàyẹ̀wò ilé náà lọ́wọ́ Wo ohun tí Adájọ́ sọ nípa ìgbẹ́jọ́ Wòlíì Sotitobire l'Ondo 'Kìí ṣe pé ìjánu Ọkọ̀ tó pa Tolulope Arotile já tàbí kò já, ìwádìí wà lọ́wọ́ ọlọ́pàá' Wo ǹkan tí ojú àwọn èèyàn rí lẹ́yìn tí wọ́n ti afárá 'Third Mainland' Èèyàn 591 míràn tún kó COVID-19 ní Nàìjíríà l'Ọ́jọ́ Ẹtì Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Itan Ilu gangan Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Bi o ti le je pe, abenugan ile igbimo asofin, dokita Bukola Saraki ati akegbe re nile igbimo asoju-sofin Yakubu Dogara ko kopa ninu ayeye ohun, awon osise, awon asofin kookan ati awon afenifere miiran ko gbeyin ninu ayeye naa.
Ní àkọ́kọ́, kí ẹ mọ èyí pé ní ọjọ́ ìkẹyìn, àwọn tí wọn óo máa fi ẹ̀sìn ṣe ẹlẹ́yà yóo wá, tí wọn óo máa ṣe ìfẹ́kúfẹ̀ẹ́ ara wọn.
Ati pe ohun yoo ṣe agbekalẹ ilera ọfẹ.
Nígbà tí nǹkan burúkú bá ṣẹlẹ̀,tí ó já sí ikú òjijì,a máa fi aláìṣẹ̀ ṣe ẹlẹ́yà ninu ìdààmú wọn.
ṣugbọn Ṣama dúró gbọningbọnin ní ojú ogun.
Amọ kii ṣe igba akọkọ ni yii ti Ọga ọlọpaa yoo tu ikọ SARS ka, ati wi pe igba kẹrin leleyii.
Hubert Ogunde rèé, baba àwọn òsèré tíátà Duro Ladipọ, ìlúmọ̀ọ́ká òṣèré tíátà àti ọmọ àlúfà tí kò gbàgbé àṣà ìbílẹ̀ Kíni ẹ mọ̀ nípa Mama Rainbow tó jẹ́ àgbà òṣẹ̀ré tíátà Yoruba?
Lara awọn asaaju ẹgbẹ Agbekoya nigba naa ni, Tafa Adeoye, Folarin Idowu, Mustafa Okikirungbo, Tafa Popoola, Adeniyi Eda, Adeagbo Kobiowu, Rafiu Isola, Adegoke Akekuejo ati Mudasiru Adeniran.
Ẹgbẹ agbabọọlu naa gbe idibo ori ayelujara kan jade lori Twitter lati fun awọn eniyan lanfani lati dibo fun orilẹ-ede ti wọn ro pe jọlọfu rẹ dara ju.
N kò fẹ́ gbà yín ní àkókò títí, mo bẹ̀ yín kí ẹ fi pẹ̀lẹ́pẹ̀lẹ́ gbọ́ ohun tí a níláti sọ ní ṣókí.
Female Driver: Sokunbi ni obìnrin àwakọ̀ Dáńfó l‘Eko, tó ń lọ̀ láti ìpínlẹ̀ kan sí òmíì
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Àyájọ́ òṣìṣẹ́: NURTW gba ẹ̀jẹ̀ lára àwọn òsìsẹ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àyájọ́ òṣìṣẹ́: NURTW gba ẹ̀jẹ̀ lára àwọn òsìsẹ 1 Èbibi 2018 NURTW fárígá níbi àyájọ́ ọjọ́ òṣìṣẹ́ nipinlẹ̀ Eko Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Òògùn ikọ́ olómi Codeine dùn àmọ́ ewu ni Òǹyẹ̀ kò leè yẹ èlé owó osù - Ẹgbẹ́ òsìsẹ́ Davido fi mọ́tò #45 milionu dá Chioma lọ́lá Ipò àgbà ló yẹ́ kí a ti bá olórí - Fani-Kayode Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí kan sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
Haruna ni awọn ti ṣe ayẹwọ fun awọn eniyan to wa lati ijọba ibilẹ ogoji ninu mẹrinlelogoji to wa ni ipinlẹ naa.
Kardiata Malick Diallo, tí ó jẹ́ igbákejì, sọ ọrọ àròjinlẹ̀ ní ilé Ìgbìmọ̀ aṣòfin Mauritania láti máà jẹ́ kí àwọn ènìyàn gbàgbé, tí ó sì fi ẹ̀sùn kàn ààrẹ tí ó wà lórí oyè pé ó ń dáàbò bo àwọn oníṣẹ́-ibi náà, tí wọ́n ṣì ń dipò gíga mú nínú ìjọba nígbà tí wọn kò tí ì wá nǹkan ṣe sí ẹ̀tọ́ àwọn olùfarapa:
"O jẹ enikan ti mo nifẹ si pupọ, ti mo si fẹ dabi tirẹ"" ọrọ Rubadiri ree."
Báyìí ni Àrẹ̀mọ Ooni Adeyeye Ogunwusi ṣe wọ ṣọ́ọ̀ṣì fún ìgbà àkọ́kọ́ láti bá bàbá rẹ̀ ṣe ìdúpẹ́ ìwúyè Irú iṣẹ́ wo ní Funke Akindele rán sí Bukunmi Oluwasina, tó fa ariwo lórí ayélujára?
Ó wá pàṣẹ fún wa láti waasu fún àwọn eniyan, kí á fi yé wọn pé Jesu yìí ni ẹni tí Ọlọrun ti yàn láti jẹ́ onídàájọ́ àwọn tí ó ti kú ati àwọn tí ó wà láàyè.
Nígbà tí Dafidi dàgbà, tí ó di arúgbó, ó fi Solomoni, ọmọ rẹ̀ jọba lórí Israẹli.
Da ẹran jẹ̀ nígboro, ko fẹ̀wọ̀n oṣù méje jura tàbí san ₦200,000 - Ilé aṣòfin Ọyọ dábàá Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Iya Adura Esther Ajayi sọ àṣírí owó rẹ̀ tó fi ń ṣàánú Ìyàwó Kanu, @amarakanu wà lára àwọn to kí Kanu lóri òpó instagram rẹ̀, ó ní Kí Ọlórun dáhùn si gbogbo èrò ọkan rẹ̀.
Oríṣun àwòrán, NASSofficial Àkọlé àwòrán, Ki ẹgbẹ oselu APC lọ ki owo ọmọ wọn bọsọ oo, ko si éni to le fa ààrẹ kalẹ Awọn sẹnatọ ọ̀hún fẹ̀sùn kan pé, APC ń fún ara ilú ni òyé bi ẹni pé Saraki ni ipa tó ń ko láti yan olori ile igbimọ asofin agba fun sáà tó ń bọ.
Jehu sọ fún Bidikari, ẹni tí ń ru ihamọra rẹ̀, ó ní, “Gbé òkú rẹ̀ kí o jù ú sinu oko Naboti.
Gbogbo adajọ mejeeje to joko lori igbẹjọ naa ni wọn fohun ṣọkan pe ile ẹjs giga apapọ ilu Eko to gbe idajọ kalẹ pe Kalu, ileeṣẹ rẹ Slok Nigeria Limited ati oludari eto iṣuna tẹlẹ nipinlẹ Abia, Jones Udeogu jẹbi ẹsun kiko ipinlẹ Abia owo to le ni biliọnu meje naira jẹ.
" Czech Republic: Takọ-tabo Kìnìún ni ọkùnrin náà ń sìn nínú àgò kanṣoṣo Oríṣun àwòrán, ZDENEK NEMEC/MAFRA/PROFIMEDIA Àkọlé àwòrán, Czech Republic: Kìnìùn ṣe ikú pa olówó rẹ̀ Atẹjade naa ni lati ojule de ojule ni wọn yoo pin 'voucher' naa, eyi ti yoo ni sitampu, ọjọ ati akoko ti gbigba ounjẹ yoo kan ile kọọkan, ti wọn yoo si loo lati gba ounjẹ ni ibudo ti wọn ti n pin ounjẹ naa.
 lákòókó tí ó fi dúró yẹn , ó rò wí pé òun ti rìn jìnnà díẹ ̀ sí àbúrò òun kò mọ ̀ wí pé nǹkan ibùsọ ̀ mẹ ́ fà péré ni òun tí ì rín .
 Eleyii yoo le mu igberu ba ọrọ-aje ipinlẹ yii, yoo si jẹ ki ipinlẹ yii ṣe aṣeyori lati fi ẹsẹ ẹka irinajo-afẹ mulẹ”.
Lara awọn gbajumọ oṣere to wa nibi akọja ewe ipade idanilẹkọ naa ni Mr Latin, ọga Bello, Jide Kosoko, Yinka Quadri.
Àfi àwọn àgbàlagbà ẹbọra ni wọn kò lè rí àyè wá nítorí ìdíwọ́ ilé wọn.
gbogbo awon to n lowo ninu jagidijagan lati ti owo omo won bo asọ.
Àwọn òṣìṣẹ́ aláàbò kọlu àwọn tó n ṣe ìwọ́de ní Sudan Obìnrin pa olólùfẹ́ rẹ̀, ó fi se ìrẹsì John Ogu bá BBC Yorúbá sọ̀rọ̀ lórí ìgbáradì Nigeria vs Madagascar COZA: Mi ò fípá bá obìrin lò pọ̀ rí láyé mi - Pásítọ̀ Fatoyinbo Kọmputa ni wọn fi ṣe iṣẹ iwadii naa kakiri orilẹ-ede mẹwaa.
Ìfihàn sí Wòlíì Joseph Smith, Oliver Cowdery, àti David Whitmer, tí a fi fúnni ní Fayette, New York, Oṣú Kẹfà 1829.
Iroyin naa sọ pe ipinlẹ Edo ti gba to arinrinajo to din diẹ ni ẹgbẹrun mẹrin wọle laarin oṣu ikọkanla ọdun 2017 si ikeje ọdun 2018.
Ninu atẹjade naa si lo ti n dupẹ lọwọ gbogbo awọn alatilẹyin rẹ, to dibo fun, to si tun n jẹjẹ pe oun setan lati sisẹ fun ilọsiwaju ipinlẹ Ọsun ni ipokipo ti oun ba ba ara oun.
Ijọba to n sejoba lọwọ lorile ede Naijiria, iyen All Progressives Congress (APC) ti pe awọn ọmọ ẹgbẹ wọn to wa nile igbimo asofin lati mu suuru, bi awọn ọmọ ẹgbẹ wọn se n ro lo si inu ẹgbẹ  miiran.
Àìsàn tí yóò já sí ikú nìkan ni irú òfin yìí wà fún, ó sì yàtọ̀ si ìrànwọ́ láti gbẹ̀mí ara ẹni.
Wọn a ma lo ọrọ ti o se pe awo lo le ye, ọgbẹri ko le mọ koda wọn a tun ma lo ami idanimọ to ṣafihan irinṣẹ ijayi wọn fẹran julọ pẹlu awọ ti wọn ṣa lesa.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: N kò fẹ́ ṣiṣẹ́ aṣẹ́wó ló mú mi máa wa ọkọ̀ taxi - Obìnrin tó ń wa Uber Wo àwọn àkókò tó yẹ ko sàìsàn, tí ara rẹ yóò fì tètè dá Davido fi orúkọ bàbá rẹ̀, Adedeji, sọ ọmọ tuntun tó bí Oníbàárà tó bá fi owó ránṣẹ lórí ẹrọ ibaraẹnisọrọ yóò sanwo orí Ọdún mẹ́rin kò tó láti parí ẹ̀kọ́ ọ̀fẹ́ ní Ọ̀yọ́ - Seyi Makinde Atẹjade kan ti ileesẹ ologun fisita ni ọwọ tẹ ọkan lara awọn adunkooko mọni yii , ẹni to jẹ pe isẹ to yan laayo n tiẹ ni lati maa gbe ẹja gbigbẹ wa sorilẹede yii lati orilẹede Lake Chad to mule ti wa.
 A ni lati sa gbogbo ipa wa lati ri daju pe, a ko fayegbe irewesi bi o ti le wu ko mo.
Èyí wáyé lẹ́yin ọ̀pọ̀ ọ̀sẹ̀ díẹ̀ tó Fatoyinbo ti kọ̀ láti fóju han ní àgọ́ ọlọpaàá lẹ́yìn ti wan ránṣẹ́ pèé fún ìfọ̀rọ̀wánilẹ́nuwò.
“Pàṣẹ fún àwọn ọmọ Israẹli kí wọ́n ṣe oko jọnwọnjọnwọn sí etí aṣọ wọn ní ìrandíran wọn; kí wọ́n sì ta okùn aláwọ̀ aró mọ oko jọnwọnjọnwọn kọ̀ọ̀kan.
Mo ti buwọ́lu àdínkù owó orí nítorí ìrọ̀rùn àwọn èèyàn ìpínlẹ̀ Ogun lásìkò Covid 19- Dapo Abiodun Wasiu Dada tun sọ pe irọ nla ni pe awọn obi oun sọ pe ki oun pinya pẹlu Risikat nitori pe awọn ọmọ ti o n bi ni oju buluu.
Election 2019 Updates: Atiku n ṣé iranran lórí ìbò 1.
nibikibi ti a ba wa niluu okeere.
Aarẹ Ghani naa gboriyin fun wọn o si ni awọn ọmọ ogun Afghan naa ti n ji giri siṣẹ ogun lẹyin iranlọwọ America.
Oúnjẹ alẹ́ ni wọ́n ń fi Ọ̀ọ̀nì ṣe níbí Èyí tí a wò jùlọ 5:03 Fídíò, Omolola Arohunmolase Welder: Mo ti fí iṣẹ́ 'Welder' gbayì láwùjọ, tó mo fi tọ́ ọmọ yanjú, Duration 5,039 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 5:39 Fídíò, Akomolede ati Asa lori BBC: Olùkọ́ Kikelomo Ogunboye tan ìmọ́lẹ̀ sí ìwà olè ọ̀gá ọlọ́pàá Audu gẹ́gẹ́ bí àwòkọ́ṣe àsìkò yìí, Duration 5,398 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 4:11 Fídíò, Oba Adeyeye Ogunwusi: Ojú mi ti rí lọ́pọ̀ lọpọ̀, ọ̀pọ̀ èèyàn ni kò tilẹ̀ gbàgbọ́ pé mo lè jọba- Ooni, Duration 4,117 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 4:43 Fídíò, Promise Akinlade: ọmọ ọdún mọ́kànlá tó ń fi ìlù dárà bíi àgbàlagbà sọ̀rọ̀ nípa tálẹ́ǹtì rẹ̀, Duration 4,437 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 0:59 Gbọ́, Ìsẹ̀lẹ̀ jákèjádò orílẹ̀èdè àgbáyé láàárín ìṣẹ́jú kan, Duration 0,59wákàtí 5 sẹ́yìn 7:03 Fídíò, Olumuyiwa Bolade Adedeji Military Bruitality: Bí arákùnrin onípèníjà ara tí sọ́jà lù ṣe dé, Duration 7,035 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 4:45 Fídíò, Yoruba Films: Ẹ̀ẹ́ bẹ̀ mi kúrò láyé ni, mi ò lè kú - Fadeyi Oloro, Duration 4,4526 Èrèlè 2020 2:48 Fídíò, Esther Ajayi: Èmi náà ti borí ìṣòro rí ló ń mu mi ṣojú àánú, Duration 2,481 Ògún 2019 6:08 Fídíò, Adebola Ademilua: Àìrísẹ́ ṣè lẹ́yìn ìwé kíkà ló sọ mi dí ìyá onírú, mo dúpẹ́ tèmi, Duration 6,0827 Bélú 2020 2:36 Fídíò, Sotitobire: Ìdájọ́ òdòdò ló fẹsẹ̀ múlẹ̀ lórí ọ̀rọ̀ Pásítọ̀ Sotitobire - Agbẹjọ́rò fún ìjọba, Duration 2,367 Ọ̀wàrà 2020 BBC News, Yorùbá Ìdí tí ẹ fi le è nígbàagbọ́ nínú ìròyìn BBC Ìlànà Lílò Nípa BBC Òfin Àṣírí Cookies Kàn sí.
Bi a ba ka'wọ gbera, ọrọ yii ko le lójútùú.
ti ipinle naa se sọ pe, Minisita fun eto inawo 
Ìṣẹ̀lẹ̀ kan tó ṣẹlẹ̀ láyé-àtijọ́ tún fún àwọn èèyàn ìgbà náà ní ìdánilójú pé agbára Sulis ń bẹ nínú omi náà.
Iko Boko Haram ti ran ẹgbẹgbẹrun awọn eniyan lọ si ọrun, lati bi ọdun mewa, ti wọn ti bẹrẹ si n sọse lagbegbe ila oorun ariwa Ile-Naijira, ti wọn si fi tipa ko awọn akẹkọbinrin Chibok lọdun 2014.
Ni ọdun 2016, aarẹ Muhammadu Buhari ṣe ẹkun ti o ga julọ si owo epo ti wọn bẹr sii ta epo ni 145 naira.
Omiṣore bá APC lọ, ó gbà'lejò akọ̀wé ìjọba àpapọ̀ ‘A ó ran àwọn tó lùgbàdì omíyalé ìpínlẹ̀ Kogi lọ́wọ́’ Osun rerun election: A kò ní gba èsì àtúndì ìbò tó wáyé-PDP Ọọni kọ́lé fàwọn ọmọ òrukàn ní Ibadan Ọọnirisa pa àwọn aṣàtìpó lẹ́rin ayọ̀ ni Ibùdó Wasa Eyi tumọ si pe Alhaji Gboyega Oyetọla ti APC lo maa tukọ ipinlẹ Ọṣun gẹgẹ bii gomina tuntun fun ọdun mẹrin to m bọ.
' Ọjọ kẹwaa, oṣu karun ni ajọ EFCC mu u laipẹ.
 díẹ ̀ lára àwọn ilé tí ó yà ni harewood house , york ; osterley park , kedleston hall , derbyslire ; luton hoo , bedfordshire àti kenwood .
 O fikun pe oun ti fi ọrọ naa to ijọba atawọn agbofinro leti nipa awọn ikslu ojoojumọ yii, oun si n fẹ ki wọn gba oun ati ẹbi oun ki oun ma baa ku lojiji."
O fikun pe aawọ laarin awọn ọmọ Naijiria ati awọn ọmọ South Africa ko le to bi wọn ṣe n pariwo rẹ nitori ko fi bẹẹ tan kaakiri, koda, o ni laasigbo naa ko de ibiti oun wa ri.
Oríṣun àwòrán, Others Amofin agba Dayo Akinlaja ni, labẹ ofin gbogbo ọmọ Naijira ni ẹtọ lati sọrọ bo ṣe wuu, nitori naa, ti eeyan ba ni idi pataki lati ni ju siimu mẹta, ko yẹ ki ijọba sọ pe eeyan ko gbọdọ lo siimu mẹta lọ.
Muhammadu Buhari so pe ijoba orile-ede Naijriia ti o wa lori aleefa lowo
 orísirísi ènìyàn ló parapọ ̀ di àwùjọ-bàbá , ìyá , ará , ọ ̀ rẹ ́ , olùbátan ati bẹ ́ ẹ ̀ bẹ ́ ẹ ̀ lọ .
Ẹni tí mo kọ́ ṣe àkíyèsí ni ọkùnrin kan báyìí tí orúkọ rẹ̀ ń jẹ́ Ìjàǹbàforítì tí ó jẹ́ ọdẹ aperin.
Ó ṣe ohun tí ó burú lójú OLUWA bí Manase, baba rẹ̀ ti ṣe.
Ẹ pa awọn eku to ba wa ni inu ile ati agbegbe yin.
Ọlọrun bá gòkè lọ kúrò lọ́dọ̀ rẹ̀ níbi tí ó ti bá a sọ̀rọ̀.
Ní àkókò yìí ni a bí Mose.
Coronavirus symptoms in Nigeria: Pẹ̀lú èròjà olùgbèjà ara 'Antibodies' ṣé ó ṣeéṣe kí ènìyàn tó ní àrùn coronavirus rí lè níi lẹ́ẹ̀kejì
Ninu wọn la ti ri iyawo Aarẹ Amerika ana Michelle Obama.
Awọn ipinlẹ miran tawọn Gomina ati igbakeji wọn ti n jẹ iru anfaani yii Loju opo Twitter wọn, BudgIT Nigeria fi orukọ awọn ipinlẹ ti ofin ṣe agbekalẹ owo ifẹhinti to yatọ si eleyi ti ajọ to n mojuto sisan owo fawọn oṣiṣẹ lorileede Naijiria gbe kalẹ.
Risikat Azeez: Kaosarat àti Hassanat gba ẹ̀bùn ẹ̀kọ́ ọ̀fẹ́ ₦1.
Kí OLUWA Ọlọrun àwọn baba ńlá yín jẹ́ kí ẹ tún pọ̀ jù báyìí lọ lọ́nà ẹgbẹrun.
Peller gbé 'gbá ìbò fún 2019 Ọwọ́ tẹ ayédèrú agbẹjọ́rò ní Eko Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Àwòrán díẹ̀ lára àwọn ǹkan ti ASUU ń jà fún nì yíi Ọpọlọpọ ni kò mọ pe atunṣe sawọn ọgba ile iwe giga ni koko nkan ti ẹgbẹ awọn olukọ fasiti ni àwọn n jà fun lasiko yii.
Nítorí mo mọ̀ pé, tí ó bá kúkú ṣubú lulẹ̀, yóo kú náà ni.
Fun apẹẹrẹ, ni orilẹede wa Naijiria, bi o tilẹ jẹ pe awọn obinrin n gberi diẹ diẹ nilẹ Naijiria nidi oselu yii, sibẹ aba ofin to wa fun ipese anfaani ibaradọgba laarin akọ ati abo lo ti fori sanpọn lọpọ igba nile asofin apapọ.
Makamba sọ pé àwọn tó jí Mo gbé pa á tì sórí pápá kan lẹ́bàá ilé ijó Gymkana ni Dar es Salam èyí tíí ṣe olú ìlú kátàkárà Tanzania.
Nígbà tí a kúrò nínú àfonífojì yìí, a pàdé ẹbọra kan tí ó ń ti ọ̀dọ̀ Baba-onírùngbọ̀n-yẹ́úkẹ́ bọ̀, ojú kan ṣoṣo ni ẹbọra náà ní, a sì jọ kí ara wa dáadáa nígbà tí a pàdé ara wa: nítorí ní àkókò wọn-ọnnì, ẹ̀rù àwọn ẹbọra kò bà wá jú bẹ́ẹ̀ lọ mọ́, ṣe ni a jọ ń pàdé, tí a jọ ń pínyà, tí a jọ ń sọ̀rọ̀, tí a jọ ń ṣe àwàdà, tí a sì jọ ń ṣe àṣàrò fún ara wa, díẹ̀ ló kù kí àwa pàápàá di ẹbọra.
oludari ni ekun Ariwa- Senator Bashir NaladoOludari eto
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fọ́nrán ohùn, Fásitì OAU ní ohùn ọ̀jọ̀gbọ́n Richard Akindele ni wọ́n ká sílẹ̀ Awọn miran ni ki ileeṣẹ BBC wa si ile iwe awọn kaakiri Naijiria nitori o ti di ankoo fawẹli to n ba ni ninujẹ: Ohun to jọ ọpọ eeyan loju, to si n bi wọn ninu julọ, ni ọjọ ori ẹni ọdun metadinlogun ti ọrọ naa kan, eyi buru jai.
Nígbà tí a yọ sí ìlú wọn gan-an nǹkan kan ṣeẹlẹ̀ sí wa.
Ogun eniyan lo wa ninu baluu naa, ilu Dakar ni wọn si morile lati sinku kan nilu Ziguinchor (guusu) lasiko ti ijamba naa sẹlẹ.
Kí wá ni ẹ jáde lọ wò?
Òun kan náà ni ó tún fún wa ní iṣẹ́ ìlàjà ṣe.
"Olagbe sọ pe ""Ko rọrun fun wa lati maa ṣiṣẹ ninu ebi lai si owo oṣu."
Àwọn eniyan náà dá Joṣua lóhùn pé, “Rárá o, OLUWA ni a óo máa sìn.
Ko ni si ele idiyele to yẹ ni sisan lori aitete san owo ori ẹni tabi ti ileeṣẹ fun oṣu mẹjọ sẹyin.
Wọn ni akẹkọọ tabi olukọ ti ko ba lo ibomu ko ni lanfani lati wọle si inu ọgba ile ẹkọ.
Lẹsẹkẹsẹ Jesu sọ fún wọn pé, “Ẹ ṣe ara gírí.
Ṣugbọn tí ó bá jẹ́ dandan ni mo fi ń ṣe é, iṣẹ́ ìríjú tí a fi sí ìtọ́jú mi ni.
 ní ilé ẹ ̀ kọ ́ gíga akẹ ́ kọ ̀ ní àǹfààní lati se ohun tówùú nígbà ti ó bá fẹ ́ tí kòsì olùkọ ́ tí yóò yẹ ̀ ẹ ́ lọ ́ wọ ́ wò .
Gomina Gboyega Oyetola ni Ọjọbọ ni awọn yoo da ọlọpaa sita lati ma a wọ ojule si ojule lati fi panpẹ ọba mu awọn to ba ni ohun ini ti wọn ko fi owo ra si ile.
Omo Ibadan coaching center bá iléeṣẹ BBC lálejò, ẹrín ń pé èrín rán níṣẹ
dilma vana rousseff ( , ojoibi december 14 , 1947 ) je oloselu ati aare orile-ede brasil tele , lati 1 january 2011 de 31 august 2016 .
Lórí ibasepọ to wá laarin Oluwo àti Ọọni tilu ilé Ilé-Ifẹ̀, Oluwo ni ibasepọ àwọn gùn régé pupọ, to sì tun tọ ipàṣẹ orírun àwọn ìdílé to ń jọba n'ilu Iwo lọ sí Ilé-Ifè nítorí Ooni obìnrin Luwoo Gbagida to wá láti agboolé Lafogido n'ilu Ilé-Ifè.
Ko din ni miliọnu meji awọn eniyan ti ogun abẹle ti le kuro ni ile wọn lorilẹede South Sudan, bẹẹni ọpọ miran lo tun ti sa fi orilẹede naa silẹ patapata lọ sorilẹede miran.
O mú ìtàkùn àjàrà kan jáde láti Ijipti;o lé àwọn orílẹ̀-èdè jáde, o sì gbìn ín.
Nígbà tí ẹ bá jẹun, tí ẹ yó, ẹ óo dúpẹ́ lọ́wọ́ OLUWA Ọlọrun yín fún ilẹ̀ dáradára tí ó fun yín.
Ta ni ó lẹ́wà bi ọmọ náà láàrin ọmọ ènìyàn!
Ẹ lọ sọ fún ọba pé, báyìí ni OLUWA wí, ‘O kò ní sàn ninu àìsàn náà, kíkú ni o óo kú.
 Lodun 1983 ni awon egbon ati aburo marun un parapo da ile ise yii sile ti won si ti ni eka ni Texas ati Panama.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ifa Priest: ọdún mọ́kànlá ni mo fi ṣe iṣẹ́ agbejọ́rọ̀ kí n tó gbọ́ràn si Ifá lẹ́nu Ayajọ ọjọ ominira Naijiria: ọjọ kinni, oṣu kẹwaa Gbogbo orilẹ-ede agbaye lo ni ọjọ ti wọn ya sọtọ ti wọn fi n sami ayẹyẹ ominira wọn kuro lọwọ ijọba amunisin.
Àwọn tí wọn ń dá ẹni tí ó jẹ̀bi sílẹ̀nígbà tí wọ́n bá ti gba àbẹ̀tẹ́lẹ̀ tán;tí wọn kì í jẹ́ kí aláìṣẹ̀ rí ẹ̀tọ́ gbà.
Bẹẹ lo ṣalaye si pe awọn mẹrin mii farapa ti awọn mẹjọ ribi sa asala fun ẹmi wọn ṣugbọn awọn ajinigbepawo naa gbe awọn mẹwa salọ ninu wọn.
Wọ́n ń ro èrò ìkà,wọ́n ń ṣe iṣẹ́ ibi,wọ́n sì ń pète ẹ̀tàn lọ́kàn.
 “O je ohun ikominu lori bi awon osise ijoba se n sise ni awon enu-ibode, eyi ti won sakoba fun sise okowo tako ojuse won.
yoo ma dije ninu egbe won, ni eyi ti o je ki ile-ejo naa fagile eto idibo to
Awọn mejeeji fi ifigagbagba yi han nigba ti Naijiria ati South Afrika pade ninu idije AFCON 2019 Ọmọ Nàìjíríà ń retí ifẹ ẹ̀yẹ AFCON lọ́dọ̀ yín - Aarẹ́ Buhari Bí ìdíje láàrin Nàíjíríà àti South Afrika ṣe lọ sí Ìjọba South Africa pèpàdé lórí ìkórìíra àlejò Iṣẹ́ bọ́ lọ́wọ́ ọ̀gá ilé iṣẹ́ tó bẹ́nu àtẹ̀ lu Obinrin Èèmọ̀ wọ̀lú!
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Yollywood: Àwọn èèyàn fèsì pé Kemi ń díbọ́n ni, tórí ọ̀rọ̀ ọkùnrin ni 16 Ọ̀wàrà 2019 Oríṣun àwòrán, @KemiAfolabi Gbajugbaja oṣere fiimu yoruba, Kemi Afolabi ti ke gbajare pe arabinrin kan n lepa ẹmi oun lati pa.
Lẹ́yìn tí ọba ti fi ìwé náà jóná, ati gbogbo ohun tí Jeremaya ní kí Baruku kọ sinu rẹ̀, OLUWA sọ fún Jeremaya pé, 
Oríṣun àwòrán, Nimc Oríṣun àwòrán, Nimc Oríṣun àwòrán, Nimc Oríṣun àwòrán, Nimc Oríṣun àwòrán, Nimc Oríṣun àwòrán, Nimc Bakan naa, ileeẹ ibaraẹnisọrọ ni ijọba apapọ pẹlu ti gbe ilana bi o ṣe lee yanju fọọmu iforukọsilẹ fun kaadi idanimọ apapọ naa lati gba nọmab idanimọ NIN rẹ.
O kò gbọdọ̀ bá aya ọmọ rẹ lòpọ̀, nítorí pé, aya ọmọ rẹ ni.
ni apa guusuilaorun naijiria , ilu-oba nri ti awon igbo gbooro larin odunrun 10wa titi de 1911 .
K1 to tun jẹ Mayegun ilẹ Yoruba ṣalaye pe ile agbaọjẹ olorin Juju, Ajihinrere Ebenezer Obey Fabiyi ni Ikeja ni idile mejeeji ti pade.
Ọgbọ́n ń kígbe ní òpópónà,ó ń pariwo láàrin ọjà,
Wolii náà bá sọ fún wọn pé, “OLUWA, Ọlọrun Israẹli ní, ‘Mo ko yín wá láti ilẹ̀ Ijipti, mo ko yín kúrò ní oko ẹrú.
A ti gba iwe asẹ  lati ọdọ ajọ to n mojuto eto idagbasoke ICRC lọsẹ meji sẹyin, nipa bayii a le bẹrẹ lati maa wa  awọn  onisowo.
"Ẹkunrẹrẹ ilana, ofin ati ikilọ wa ni oriko ""download pdf"" eyi ti ajọ JAMB ti fi sori itakun agbaye wọn."
“Ẹ gba ẹnu ọ̀nà tí ó fún wọlé.
irinna ofurufu ti pese isẹ to le ni milionu meje  , ni eyi ti o si  ti pese owo to le ni bilionu meje sapo asunwon
 Yoo jẹ fun awọn ikọ mokanlelogorun un lati UNWTO pelu minista fun irinajo afẹ lati orile ede mẹjọ ati aṣoju orile ede merinlelogoji nilẹ Adulawọ ni eyi ti yoo tobi julọ ninu awọn eyi ti wọn ti ṣe seyin.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù FIBA World Cup: D'Tigress tún fakọyọ lẹ́yìn tí wọ́n na Argentina 24 Owewe 2018 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 25 Owewe 2018 Oríṣun àwòrán, @DTigressNG Àkọlé àwòrán, Ikọ̀ D'Tigress fàgbà han Argentina Ikọ agbabọọlu afọwọgba ti obirin Niajiria ti orukọ wọn njẹ D'Tigress tun ti fakọyọ ninu ife ẹyẹ agbaye to n lọ lọwọ lorilẹede Spain lẹyin ti wọn fagba han ikọ Argentina ayo marundinlọgọrin si aadọrin(75-70) ninu ifẹṣẹwọnsẹ keji wọn ninu idije naa.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Irokotọla: Báwo ló ṣe rọrùn láti fi àmì sí ọ̀rọ̀ yìí, ‘Irokotọla’?
Igbimo amusese ijoba ohun fenuko pe, Aare obinrin akoko lorile-ede Mauritius gbodo fori alefa sile, leyin ti won fesun ti o lagbara kan-an.
Bakan naa lo fi kun un pe Eeyan marundinlaadọrin ninu wọn ti wọn ti rinrinajo kuro nilu Eko lọ sawọn ilu miran pẹlu wa labẹ itanna ajọ WHO lati mọ ibi ti ọkọọkan wọn wa.
”Egbe naa wa pe awon ajo eleto aabo lati maa kaare nipa mimu awon to lowo nibi isele buruku yii, ki won si fi won jofin lona ati dekun iru isele yii.
ASP, Sunday ni gẹ́gẹ́ bi ibi ti ìwádìí dé, kò sí ìja tàbi rgbòdìyàn tó le mú kí ọlọ́pàá náà yìnbọ̀n sùgbọ́n ìwádìí ṣi n lọ lọ́wọ́ láti mọ pàtó ìdí ti ọlọ́pàá náà fi yìnbọ̀n.
Aisha ni ìwà àìtọ ló n hù nínú ẹgbẹ́ pàápàá julọ lóri ètò ẹgbẹ́.
Sunday Dare sọ pe ''pẹlu aṣẹ aarẹ, gbogbo ọjọ kini oṣu kọkanla ọdun ni wọn yo maa fi ṣe ayajọ ọjọ awọn ọdọ Naijiria.
O ni bi awọn eeyan nbere ki lode ti awọn fi bẹru.
Awọn alaṣẹ naa ni awọn ajinigbe naa ko ṣiṣẹ fun ẹgbẹ agbesunmọmi kankan, amọn awọn agbebọn ti wọn n wa owo ni.
Dìde Ọlọrun, gbèjà ara rẹ;ranti bí àwọn òmùgọ̀ eniyan tí ń fi ọ́ ṣe yẹ̀yẹ́ tọ̀sán-tòru.
Ẹ̀ṣẹ̀ ń gbin lọ́kàn eniyan burúkú,kò sí ìbẹ̀rù Ọlọrun ninu èrò tirẹ̀.
ní ayé àtijọ ́ , bí aláwo bá kú , àwọn àwọn olúwo ní ń sìnkú irú ẹni bẹ ́ ẹ ̀ .
Igbake aare orile ede Naijiria, Yemi Osinbajo ti ro awon omo  orile ede Naijiria lati ni ogbon atinuda, ki won si  je akinkanju lona ti won yoo fi gbe orile ede Naijiria de ibi aseyori.
Ẹgbẹrun lọna ọọdunrun ati ọgọrin eeyan lo ti ko arun coronavirus lorilẹede Amẹrika, awọn to si ti ran lọ si ọrun din diẹ ni ẹgbẹrun mọkanla.
Ìfihàn tí a fi fúnni nípasẹ̀ Wòlíì Joseph Smith sí Oliver Cowdery, ní Harmony, Pennsylvania, ní Oṣù Kẹ́rin 1829.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù 2019 Budget: Á ò fọwọsi àbádafofin ìṣúna láìpẹ- Bukola Saraki 3 Ìgbé 2019 Oríṣun àwòrán, @bukolasarakiofficial Àkọlé àwòrán, Bukola Saraki ti jẹ ààrẹ ilé igbimọ aṣofin lọdun 2015 Ilé ìgbìmọ asọfin àgbà Nàìjíríà ti ṣe ìléri láti búwọlu àbádofin ètò ìṣúná ọdun 2019 lọjọ kẹrìndínlogun oṣù yìí.
 wọ ́ n máa ń gba abẹ ́ rẹ ́ àjẹsára yí sára gba inú iṣan tàbí abẹ ́ ẹran ara .
Lẹ́sẹ̀ kan náà gbogbo wa sì ti fi aṣọ di etí wa a ń lọ.
ni Ipinle Oyo, Omowe Bashir Olanrewaju n soro lori ewu to ro mo dida idoti sibi
Angẹli náà bá ké sí mi, ó ní, “Àwọn ẹṣin tí wọn ń lọ sí ìhà àríwá ti jẹ́ kí ọkàn mi balẹ̀ nípa ibẹ̀.
Wọ́n rán UK létí pé òkò tí a sọ sí igi ọ̀pẹ ni í sọ padà sí ẹni.
Àkọlé àwòrán, Igbakeji Gomina ipinlẹ Ọyọ, Moses Adeyẹmọ naa n bẹ nibẹ.
Aare  Muhammadu Buhari oludije fun egbe to n sejoba
Lẹyin to jawe olubori ninu eto naa, o lọ si ipinlẹ Jos lati ipinlẹ Eko lati lọ bẹrẹ iṣẹ orin gẹgẹ bi iṣẹ to yan laayo.
Saulu sọ fún ọmọ rẹ̀ Jonatani ati gbogbo àwọn iranṣẹ rẹ̀ pé kí wọ́n pa Dafidi.
Ṣé ibinu rẹ yóo máa tẹ̀síwájú láti ìran dé ìran ni?
ṣíbí wúrà kan tí ìwọ̀n rẹ̀ jẹ́ ṣekeli mẹ́wàá tí ó sì kún fún turari.
"Pupọ owo yii ni kii se ileefowopamọsi lo gbaa sugbọn ọfiisi wọn ni a san an si.
Bí ẹ bá ti yà á sí mímọ́ tán, ẹ óo mú akọ mààlúù tí kò ní àbààwọ́n ati àgbò tí kò ní àbààwọ́n láti inú agbo ẹran, ẹ óo fi rú ẹbọ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Dòdò Ìkirè: Ó dúdú lára sùgbọ́n oyin ni lẹ́nu O ni kete ti oun yọ ẹsẹ alakọkọ ni oun ri awọn kokoro oyin to ku ninu oju arabinrin naa.
“Ẹ má bẹ̀rù, ẹ̀yin eniyan Jakọbu, iranṣẹ mi,ẹ má sì jẹ́ kí àyà fò yín, ẹ̀yin ọmọ Israẹli.
 Ṣùgbọ ́ n wọn ò sọ nǹkan náà tí jìjì fẹ ́ ràn jù tó fẹ ́ kí a fit a òun lọ ́ rẹ fún kábíèsí .
Mallam Bukar so pe, awon ti o gbe awon akekoo ohun ja won sile, ti o si sina-moko lai so ohun-kohun, amo o dupo pupo lowo Olorun oba ti o so awon omode-binrin naa de layo atalaafia.
Jospeh Yobo ti di igbákejì akọ́nimọ̀ọ́gbá Super Eagles tuntun Ìpínlẹ̀ Oyo, Ogun, Ondo buwọ́lu àbádòfin Àmọ̀tẹ́kùn Ẹ wo àwọn ìlérí tí Buhari ṣe láti ọdún 2015 àmọ́ tí kò tíì mú ṣẹ Wọn fi kun pe awọn saba maa n pà ipenija tawọn ba n koju mọra lasiko ti awsn ba wa lori afẹfẹ ni, lọna ati mu ayọ ati idunnu ba awọn eeyan to n gbọ awọn.
Ọ̀pọ̀ èèyàn tí kò yin Ajimobi lojú ayé, tó ń yìn-ín lẹ́yìn ikú, yóò jẹ ìyà - Oníwáàsí Ìgbà mẹ́jọ tí awuyewuye wáyé lórí ìṣèjọba Ajimobi!
Lẹyin naa ni wọn gbee lọ ẹwọn.
Èyí ni bí Hushpuppi ṣe gbìyànjú láti jí $124m lọ́wọ́ ẹgbẹ́ agbábọ́ọ́lù Premier League kan Àjọ NCDC kéde ènìyàn 454 tó tún ṣẹ̀ṣẹ̀ ní Coronavirus ní Nàìjíríà Báwo ní 'Aṣọ ẹbí' ṣe bẹ̀rẹ̀ ní ilẹ̀ Yorùbá?
awon eniyan lo tu jade lati wa dibo ni ipinle Kwara fun idibo aare ati ti ile
Ta ni Olabode Thomas, iru igbe aye wo lo gbe?
O nilo itakun iwadii ti igbalode (pẹlu atilẹyin JavaScript) lati wo ibi yii Ṣe awọn eniyan orilẹ-ede rẹ nigbagbọ ninu abẹrẹ-ajẹsara?
Dagunro ní ìtẹríba, tó sì ń gbé àṣà lárugẹ - Ọ̀gá Bello Kókó ọ̀rọ̀ tí Buhari sọ ní àyájọ́ June 12 FRSC: Èèyàn mẹ́jọ ló kù nínú ìjàmbá ọkọ̀ nípìnlẹ̀ Ògùn Akẹ́kọ̀ọ́ LAUTECH 15 wọ gàù l‘Ọyọ torí ẹ̀ṣùn olè àti ṣíṣe ẹgbẹ́ òkùnkùn Wo odiwọn ẹjẹ ara re: Pupọ ninu eeyan adarihurun maa n saaba ni ẹjẹ jálá lita marun un ni agọ ara wọn.
Àwọn ọmọ ń kó igi jọ, àwọn baba wọn ń dá iná, àwọn obinrin ń po ìyẹ̀fun láti fi ṣe àkàrà fún Ayaba Ọ̀run.
Wenger sa ipa ribiribi ni ẹgbẹ agbabọọlu naa.
Ambode sọ pe ibaṣepọ oun ati Ajimobi nigba aye rẹ ju ti ọmọ iya tabi akẹẹgbẹ lọ.
Àwọn ẹni ibi wọnyi, tí wọ́n kọ̀, tí wọn kò gbọ́ tèmi, tí wọn ń fi oríkunkun tẹ̀lé ìfẹ́ ọkàn wọn, tí wọ́n sì ti sá tọ àwọn oriṣa lọ, tí wọn ń sìn wọ́n, tí wọn sì ń bọ wọ́n.
When I think of the last 20 years of my professional career, looking at this picture can’t make me more proud of what I’ve achieved as a player but most importantly how this journey as shaped me as a man.
 Ó gba ìjoba lọ ́ wọ ́ kakuei tanaka gẹgẹ bíi alákoso .
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Shiite: Bí Buhari kò bá tú ZakZaky silẹ̀, apa APC kò níí káa mọ́ 9 Èbibi 2018 Àkọlé àwòrán, Ìgbà àkọ́kọ́ kọ́ nìyí tí àwọn ọmọ ẹgbẹ́ Shiite yóò fẹ̀hónú hàn fún ìtúsílẹ̀ olori wọn Ẹgbẹ́ ẹlẹ́sìn Islamic Movement kan ni Nàìjíríà, Shiite, ti ṣe ìfẹ̀hónú han lọ sí ilé ọ̀kan ninu aṣíwájú ẹgbẹ́ òṣèlù All Progressives Congress, APC, Aṣíwájú Bola Tinubu, tó wà ní ìlú Èkó.
N óo bá wọn dá majẹmu alaafia; n óo lé àwọn ẹranko burúkú kúrò ní ilẹ̀ náà, wọn yóo máa gbé inú aṣálẹ̀ ati inú igbó láìléwu.
Ta ló leè rò pé ọmọ mẹ̀kúnnù bí èmi leè dé ipò alága NURTW?
'ọ̀pọ̀lọpọ̀ òbí ló máa ń sunkún ti wọn bá wa wo awọn ọmọ wọn níbí'.
Wo tuntun tó ṣẹlẹ̀ lágbo àwọn òṣèré Yollywood bíi Femi Adebayo, Odunlade Adekola, Toyin Abraham, Funke Akindele lọ́sè̩ yìí
Kí ni Oluwo lọ ṣe ní Aso Rock lẹ́yìn lẹ́tà rẹ̀ sí ààrẹ Buhari?
83 Àti bákannáà, bí a bá ti lé ẹnikẹ́ni kúrò nínú ìjọ, kí á lè pa orúkọ wọn rẹ́ nínú ìwé àkọsílẹ̀ awọn orúkọ gbogbogbòò ti ìjọ.
Kí o tó jẹ mí níyà, mo yapa kúrò ninu òfin rẹ;ṣugbọn nisinsinyii, mò ń mú àṣẹ rẹ ṣẹ.
Ninu ọrọ ti oun pẹlu ba BBC News Yoruba sọ, awọn aṣofin ti ọrọ kan fẹ yọ oun ati gomina ipinlẹ naa nipo ni.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: OAU lé ọ̀jọ̀gbọ́n tó bèèrè ìbálòpọ̀ fún máàkì ‘Lóòótọ́ ni ọ̀jọ̀gbọ́n fẹ́ bá mi lòpọ̀’ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fọ́nrán ohùn, Fásitì OAU ní ohùn ọ̀jọ̀gbọ́n Richard Akindele ni wọ́n ká sílẹ̀ Bakan náà ní ìgbìmọ̀ alásẹ ọ̀hún tún ríi àwọn ni ẹ̀rí tó dájú pé, ọ̀jọ̀gbọ́n Akindele fẹ́ yí èsì ìdánwò ọmọ náà pada sí páàsì, kí ọmọ náà lè bá òún ní àjọṣepọ̀, èyí tó fi ìdí ọ̀rọ̀ náà múlẹ̀ nínú fọ́nran ohùn ti wọn ka silẹ̀, tí òun pẹ̀lú sì fi ìdí rẹ̀ múlẹ̀.
Ebuka Obi- Uchendu naa ni yoo ṣagbatẹru eto naa ṣugbọn lọtẹ yii, Ebuka ati ọkan ninu awọn olukopa miran ni wón yoo jọ dari ẹ.
Ǹjẹ́ bí ọjọ́ ti eniyan ni ọjọ́ rẹ rí?
Godfatherism: Ṣé ọ̀rọ̀ bàbá ìsàlẹ̀ nínú òṣèlú lè dópìn bí El-Rufai ṣe sọ?
Loju awọn ileeṣẹ iroyin ayederu ni Biden ti wọle ibo aarẹ Amẹrika.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Kwara: Dókítà 66 ló síṣẹ́ abẹ fún àwọn ìbejì tó lẹ̀pọ̀ ní ilé ìwòsàn fasiti Ilorin 15 Sẹ́rẹ́ 2021 Oríṣun àwòrán, UITH Fásitì ìkọni nílùú Ilorin (UITH) ti kede fún gbogbo àye ni Ọjọ́bọ bi wọ́n ṣe ṣe aṣeyọri iṣẹ́ abẹ fún àwọn ibejì tí wọ́n lẹpọ wá sáyé.
“Ẹ kò gbọdọ̀ máa sin OLUWA Ọlọrun yín káàkiri bí wọ́n ti ń ṣe.
Ẹgbẹ́ àwa dókíta ló ra ìbòmú fúnra wa- Alága NMA Ogun Owó wọgbó!
”Jesu sọ fún un pé, “Máa bọ́ àwọn aguntan mi.
Josẹfu pèsè ohun jíjẹ fún baba ati àwọn arakunrin rẹ̀, ati gbogbo àwọn ìdílé baba rẹ̀ gẹ́gẹ́ bí iye eniyan tí olukuluku wọn ń bọ́.
Iya Angel sọ fun BBC pe omi ọyan ohun ti gbẹ lẹyin ti wọn pin oun niya pẹlu ọmọ naa fun oṣu maarun akọkọ aye rẹ.
Ẹẹmeji ni mò ń gbààwẹ̀ lọ́sọ̀ọ̀sẹ̀.
Ijọba ipinlẹ Cross River fi ofin de ipejọpọ nile ijọsin.
Ijegun pipeline fire: Ẹ̀mi méjì, ọkọ̀ tó lé ni 30 ṣòfò níbi ọ̀pá epo tó gbaná
Sugbọn ni ọdun 2018 ni ijọba orilẹ-ede ọhun yi ofin pada to si kan nipa fun awọn ileeṣẹ lati ma san iye owo kan fun takọtabo.
O ni iru ọgbọn bayi ni wọn da ti wọn fi satunto awọn ọga ọlọpaa nipinlẹ saaju idibo Kini APC sọ?
Ṣùgbọ́n ti ènìyàn bá jẹ ẹ jù ó ma ń ṣokunfa ǹkan to pọ̀: o maa n gbéni léèbì, kìí jẹ kí ènìyàn le mi dáada, o tun máa n jẹ ki ènìyàn ní janin-janin.
Bí mo ṣe ń dàgbà ni ǹkan ọmọkùnrin mi ń tóbi síi àmọ́ obìnrin ni mi' Ìdájọ́ ẹ̀wòn gbére kò ní kí Wòlíì Sotitobire má lọ sí ilèẹjọ́ kòtẹ́milọ́rùn - Agbẹjọ́rò Pásítọ̀ Alfa Babatunde Oníṣẹ́ ọwọ́, oníṣẹ́ àdáni, awakọ̀, ẹ wo ọ̀nà láti gba lára owó ìrànwọ́ Covid-19 tí ìjọba gbékalẹ̀ Wo ọ̀nà àbáyọ sí bo ṣe ń han‘run Ìdí ọlà mí mọ́, bí mo sì ta gbogbo dúkìá mi, kò ní kí òṣì tán ní Nàíjíríà - Dino Melaye Dapo Abiodun yan Laycon ní aṣojú pẹ̀lú ẹ̀bún ₦5m àti ilé oníyàrá mẹ́ta Ọkọ̀ agbépo subú lọ́nà Badagry, súnkẹrẹ-fàkẹrẹ ọkọ gbòde - LASEMA Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ondo Elections 2020: Ọgọ́rùn-ún ọdún tí a máa lò lórí oyè l'Ondo, ẹ ó rí àrà - Ojon YPP Wòlíì Alfa Babatunde, ìjọ Sotitobire Alfa Babatunde ti ìjọ Sotitobire yìí ni ó kẹyin lasiko ti a n kọ iroyin yii nínú àwọn tí irú ìṣẹ̀lẹ̀ yìí ti ṣẹlẹ̀ sí lara àwọn ìránṣẹ́ Ọlọ́run ti aaje ìwàbàjẹ́ pada ṣímọ́ lórí pé wọ́n jẹ bi ẹsùn ọ̀daran tí wọ́n fi kàn wọ́n.
Jeremy Hunt ni òun gbà pé Boris Johnson á ṣiṣẹ́ dáadáa Ibo ẹgbẹrun lọna mejilelaadọrun ati mẹtalelaadọjọ ni Johnson ni ninu apapọ ibo ti wọn di nigba ti alatako rẹ, Jeremy Hunt ni ibo ẹgbẹrun lọna mẹrindinlaadọta, ẹgbẹta ati mẹrindinlọgọta.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Okada Ban: ọjọ kini oṣù keji ni òfin tuńtun yóò bẹ̀rẹ̀ Ẹ wo bí Amotekun ṣe gba ilẹ̀ Yoruba silẹ̀ lọ́wọ́ agbéṣùnmọ̀ní ní igba ọdún sẹ́yìn Tí ìjọbá bá kọ̀ láti san owó oṣù wa, a o da iṣẹ́ sílẹ̀ - ASUU Maryam Sanda, ìyàwó tó pa ọkọ rẹ, ri ìdájọ ikú he Wo ìgbésẹ̀ tó yẹ ko gbé tí kokoro bá ba irè oko rẹ jẹ́ Ẹ wo fidio yii lati mọ iye eeyan ti arun yii ti pa, awsn ohun to n sokunfa rẹ, ami ta fi mọ pe iba Lassa wa lara eeyan kan ati ọna ta lee gba dena rẹ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Eld Kabir in Nigeria: Mùṣùlùmí àti Kristiẹni sọ̀rọ̀ nípa àdun oúnjẹ́ àti ẹran ọdún Ileya Fifi ọ́wọ si adinku owo ori yii wa ye lẹyin osu kan ti Sanwo-Olu ti wọ́n ti n gbe ee yẹ́wo.
Ní báyìí o ti ku àwọn akópa mẹ́rìndílógún nínú ilé ẹlẹ́gbọ̀n-ọ́n àgbà.
Eléyìí mú kí òun àti Ayédèrú-ẹ̀dà máa rí àyé bá ìfẹ́ ara wọn lọ.
Obìnrin tó bá fẹ́ wọn, igbó Sambisa ló lọ - Lizzy Anjorin Mo le búra pé kò sí ìbáṣepọ̀ láárin Olorì Badrat àti Wasiu Ayinde - Olori Folashade Nàíjíríà ti pín yẹlẹyẹlẹ láyé Buhari, ìjákulẹ̀ dé!
N óo sì pa gbogbo àwọn ará àfonífojì Afeni run.
Ninu ogun yìí ni Elihanani ọmọ Jaareoregimu, ará Bẹtilẹhẹmu, ti pa Goliati, ará Giti, ẹni tí ọ̀pá ọ̀kọ̀ rẹ̀ nípọn tó igi òfì tí àwọn obinrin fi máa ń hun aṣọ.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Obasanjọ sabẹ̀wò sí Akurẹ́ lórí ìbo 2019 Kíni ilé iṣẹ́ Akọ̀wé ìjọ̀ba Naijiria fẹ fí ojú òpó 64,000000 ṣé?
Wọ́n gbé e lọ sí ilé Dagoni, oriṣa wọn; wọ́n sì gbé e kalẹ̀ lẹ́gbẹ̀ẹ́ ère oriṣa náà.
idibo ekun keta, ni agbegbe Kofar Baru III, Gidan Niyam ward, Daura, ipinle
Awon to kopa nibe gbadun eto na adaadaa bi awon akekoo atawon odo.
Awọn nkan mi i tawọn ologun tun ri ni kaadi pelebe ajọ INEC mẹẹrin, ati awọn apo iwe to jẹ ti ile ijọba ipinlẹ Rivers.
Ni ilu Ilorin ati kaakiri ipinlẹ Kwara, ọrọ yi ti n mu iriwisi ọtọọtọ wa ti awọn kan si ni ki wọn fi ẹlẹ yanju ọrọ naa ki o ba ma da wahala silẹ nilu.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ẹni mẹ́ta wọ gbaga ọlọpàá nítori ajílẹ̀ tí wọ́n kó tà ní ọja Daleko ní Mushin 2 Sẹ́rẹ́ 2020 Oríṣun àwòrán, Punch Àkọlé àwòrán, Ènìyàn mẹ́ta wọ gbaga ọlọpàá nítori ajílẹ̀ Ọlọpàá ìpínlẹ̀ Eko ti mú àwọn ọkùnrin mẹta kan Banjo Adeleke, James Dalex, àti Haladu Junaid ti wọ́n fẹ̀sun kan pé wọ́n ji ajílẹ̀ ọ̀ọ́dunrun àpò nígba ti wọ́n ja ilé ikẹru si ilé iṣẹ́ Iganmu Flour Mill.
Batiṣeba bá wọlé tọ ọba lọ ninu yàrá rẹ̀.
Rutu bá tún bẹ̀rẹ̀ sí ṣa ọkà.
Igbesẹ naa gẹgẹ bi minisita fun eto ilera, Ọjọgbọn Isaac Adewọle ṣe sọ, jẹ ọna lati ti tubọ fi ipinnu ijọba apapọ lati f'opin si aṣilo oogun ikọ olomi to ni codeine ninu, ati awọn oogun mi i l'orilẹede Naijiria han.
Ko pẹ si igba naa ni Ighalo gba bọọlu gba abẹ agbabọọlu Cameroon kan ti Alex Iwobi si gba bọọlu wọ awọn Cameroon.
Ilẹkun Baalu Dana fo yọ nilu Abuja Awọn asofin agba yoo sewadi ilẹkun baalu Dana to fo yọ Awọn aworan lati ibiti baalu naa bo si se afihan ageku ọkọ-ofurufu naa lori papa ti o kun fun yinyin.
 ipinle Benue, ti ekun aarin gbungbun
Wọn dẹ jọ gba ọmi ookan si ookan ni Constantine ki FIFA to fun Algeria.
pupo lati so fun yin wipe, afikun un ti de ba awon ile-ise ijoba apapo lojuna
Balogun Ikọ naa lasiko to n ba BBC sọrọ ni idunnu ati ayọ lọ jẹ fun awọn pe awọn ṣe aṣeyọri latyi kopa ninu idije naa bi o tilẹ je pe awọn eniyan ko fi taratara gba ti ere idaraya ọhun.
 Bakan naa lo ni ti eeyan ba de ipo naa, ti wọn n pe ni ‘Tarbiyatul Askaru’, wọn yoo ya wọn sọtọ lati mase da ẹsẹ, ti wọn si leehu iwa to ba wu wọn lai ro pe ẹsẹ ni wọn n da."
Election Update 2019: Sowore dẹ́bi aijáde dibo àwọn èèyàn rú ìhàlẹ̀ Buhari
Oríṣun àwòrán, BIG BROTHER NAIJA Ẹni ọdun mẹtalologun ni Victoria Adeyeye, to jẹ akọrin.
Àwọn ọmọ Isakari ní ìdílé-ìdílé nìwọ̀nyí: ìdílé Tola, ìdílé Pua; 
Sibẹ Baba yín tí ń bẹ ní ọ̀run ń bọ́ wọn.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìtàn Mánigbàgbé: Òwe ‘aṣọ kò bá Ọ́mọ́yẹ mọ́.
O wa ro awon ile-ise aladaani lati maa kaare nipa iranwo won lati tubo gbogun ti aarun kogboogun lorile ede Najiria.
- Ilé ẹjọ́ ìpínlẹ̀ Ondo Ilé ìwòsàn kan rèé tó ń fi àtùpà gbẹ̀bí aláboyún Ijakadi pẹlu Ọlọrun O di oloṣelu lẹyin ọdun mẹrinlelogun to ti jẹ oludari ijọ Assemblies of God.
Obinrin kan wà tí ó ní irú ẹ̀mí èṣù kan tí ó sọ ọ́ di aláìlera fún ọdún mejidinlogun.
Chidozie to jẹ akẹkọọ imọ ede Gẹẹsi sọ fun BBC pe, iba diẹ lo mu oun toun fi lọ si ileewosan fasiti naa lọjọ karun, oṣu Keje 2018.
Ọ̀dọ́ 30 ń gba ìtọ́jú lọ́wọ́ nílé ìwòsàn torí ọ̀gbẹ́ ìbọn ní Lekki - Sanwo-Olu ṣàlàyé Oríṣun àwòrán, @jidesanwoolu Gomina ipinlẹ Eko, Babajide Sanwo-Olu ti sọ ko pe din ni eeyan ọgbọn to to wa nile iwosan bayii, lẹyin ti ọta ibọn ba wọn nibi iwọde End SARS to waye ni Lekki Toll Gate lọjọ Iṣẹgun.
Wo ọkùnrin tó fipá bá ìyá ọdún 60 lò nítorí 'ìkébè rẹ̀ tó ń mì Wo ọkùnrin tó fipá bá ìyá ọdún 60 lò nítorí 'ìkébè rẹ̀ tó ń mì Gbogbo awọn majẹobajẹ lorilẹede Naijiria ni wọn n ke gbajare lori ọwọja iwa ipa si awọn obinrin, paapaa julọ ifipabanilopọ.
Ó ní, ta ni Hesekaya gbẹ́kẹ̀lé tí ó fi ń dìtẹ̀ mọ́ òun?
"Koda, ìrírí tó dára julọ fún ẹ̀dá ni ìgbéyàwó jẹ nítorí ó tí yí idamọ mi padà.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Liverpool yóò wàákò pẹ̀lú Bayern ní Champions League Salah gba àmì ẹ̀yẹ̀ agbábọ́ọ̀lù Afirika BBC lẹ́ẹ̀kejì Kíni yóò sẹlẹ̀ sí àwọn òsìsẹ́ Diamond Bank?
Ki lo yẹ ki ololufẹ meji to ha sinu ara wọn se lati jajabọ?
Wọn tun dana sun awọn ile itaja kan ni adugbo naa.
Elédùmarè ló rán mi sí gbogbo Ọba Yorùbá - Oluwo Ọ̀ọ̀ni kò láṣẹ láti yọ mí nípò, mi ò sì ní ááwọ̀ mọ́ pẹ́lú Aláàfin-Oluwo Ìjọba Ọ́ṣun, Oluwo kò yẹ lẹ́ni tó leè darí ìlú, ẹ bá wa le kúrò lórí ìtẹ́ - Olú ti Ilé-Ogbó Dele, ọmọdé tó ń fi iná ẹ̀rọ ATM ṣe iṣẹ́ àmurelé sọ ìdí tó fi kára mọ́ ẹ̀kọ́ rẹ̀ fún BBC Yorùbá Ọba Oyedọtun ni, Ọọni tilu Ile Ifẹ lo pe ipade pajawiri awọn lọbalọba pe kawọn wa jiroro, lori ohun to lee faa aawọ laarin Oluwo ati Agbowu, gẹgẹ bo se waye lọsẹ kan sẹyin, bẹẹ si ni ọjọ naa kii se ọjọ ipade awọn.
ṣé ẹ ẹ̀ mọ̀ pé OLUWA Ọlọrun Israẹli ti fi iyọ̀ bá Dafidi dá majẹmu ayérayé pé àtìrandíran rẹ̀ ni yóo máa jọba lórí Israẹli títí lae?
 akin olúṣínà àti ilésanmí lọ sí ilé Ọ ̀ sanyìnnínbí .
Gbajúmọ̀ pátápátá gbáàni Ènìyàn-ṣe-pẹ̀lẹ́ ó sì jẹ́ arẹwà ọkùnrin.
Ṣugbọn ṣá, ninu Oluwa, bí obinrin ti nílò ọkunrin, bẹ́ẹ̀ ni ọkunrin nílò obinrin.
Ninu ọrọ to tun ba BBC sọ, Shehu sọ pe iroyin to tẹ awọn lọwọ ni pe olóyè kan ni agbegbe naa lo ṣagbatẹru bi wọn ṣe wo ile naa."
Ileeṣẹ BBC news Yoruba tun tẹ siwaju lati kan si ẹgbẹ OPC lati mọ boya wọn mọ si igbesẹ ajọsepọ yii ati ipa ti wọn n ko ninu rẹ.
Iwo oorun Ibarapa ni Ipinle Oyo ,nigba ti asofin Mohammed Fadeyi di igbakeji
Ó wá sọ fún àwọn olórí alufaa, ati àwọn ẹ̀ṣọ́ Tẹmpili ati àwọn àgbà tí wọ́n wá mú un pé, “Ọlọ́ṣà ni ẹ pè mí ni, tí ẹ fi kó idà ati kùmọ̀ wá?
Agbẹjọrọ fun arabinrin naa ti ni o ṣeeṣe o ko jẹ pe awọn alagbara ti fẹ maa fi agbara wọn lo ipo lori ọrọ naa eyi to ni o ṣeeṣe ko fa bi arabinrin naa ṣe wa n ṣe bi ẹni ni iyipada ọkan lori ọrọ naa lẹnu lọwọlọwọ yii.
Ijipti wí pé, ‘N óo kún, n óo sì bo ayé mọ́lẹ̀,n óo pa àwọn ìlú ati àwọn tí wọn ń gbé inú wọn run.
Aaroni yà wọ́n sọ́tọ̀ gẹ́gẹ́ bí ọrẹ fífì fún OLUWA, ó sì ṣe ètùtù fún wọn láti wẹ̀ wọ́n mọ́.
Bakan naa lo ni oun ko ni tori rẹ bara jẹ.
Ori lo mọ ọlọrọ, ori lo mọ ọba.
ṣugbọn OLUWA, jọ̀wọ́, dárí ẹ̀ṣẹ̀ wọn jì wọ́n, bí bẹ́ẹ̀ kọ́, pa orúkọ mi rẹ́ patapata kúrò ninu ìwé tí o kọ orúkọ àwọn eniyan rẹ sí.
Ile igbimo asoju  niluu Abuja ti yan asofin Femi Gbajabiamila gege
Ó yá aṣọ ìyàwó, ó sì lọ síbi tí ayẹyẹ ìgbéyàwó nàá yóò ti wáyé.
Iya rẹ binu gidigidi si i, to si gba ọmọ naa lọwọ Ọmọyẹ, pe ki oun lọ fi ẹrọ wọ ni gbogbo ara ninu ile, ki ara ma baa ro ọmọ naa, paapa ori to fi gbalẹ.
Gbogbo ohun tó bá gbà lá máa fún un láti wa àwọn agbébọn náà- Ọlọ́pàá Ó gbẹnután!
Ṣugbọn ẹ ranti pé ẹ̀yin náà ti jẹ́ ẹrú rí ní ilẹ̀ Ijipti, ati pé OLUWA Ọlọrun yín ni ó rà yín pada níbẹ̀, nítorí náà ni mo fi ń pàṣẹ fun yín láti ṣe èyí.
Alakoso awọn oṣiṣẹ aṣọbode l'Apapa, Muhammed Abba Kura ṣalaye pe, awọn oogun Tramadol ọhun to ọgọta miliọnu Naira.
Eyi ni ero awọn agbejọro kan ni Naijiria kan ti wọn fesi si ipe kan ti agba amofin, Afe Babalola pe, eyi to ni ki aarẹ Buhari pe ipade apero apapo, taa mọ si 'Constitutional Conference.
Ọpọlọpọ igba ni awọn eeyan ti pariwo Dokita Anu, ati ileeṣẹ rẹ lori ayelujara lati bi ọdun meji sẹyin.
” Àwọn ọmọkunrin tí Siba ní nígbà náà jẹ́ mẹẹdogun, àwọn iranṣẹ rẹ̀ sì jẹ́ ogún.
Ọ̀dọ́ aguntan kan fún ẹbọ àárọ̀ ati ọ̀dọ́ aguntan kan fún ẹbọ àṣáálẹ́, 
Ọ̀pọ̀lọpọ̀ akéwì ni ó máà ń lo èdè Yorùbá ti a ó sì gbédìí fún ẹwà akéwì náà.
)Òun ni ó dá ilẹ̀, tí ó fi ìdí rẹ̀ múlẹ̀,kò dá a ninu rúdurùdu,ṣugbọn ó dá a kí eniyan lè máa gbé inú rẹ̀Ó ní, “Èmi ni OLUWA, kò sí Ọlọrun mìíràn.
E tò‐è̩kó̩ sì gbo̩dò̩ kún àwo̩n akitiyan Àjo̩‐ìsò̩kan orílè̩‐èdè àgbáyé ló̩wó̩ láti rí i pé àlàáfíà fìdí múlè̩.
Ìre tí ó sú fún ẹ̀yà Gadi ni pé:“Ibukun ni fún ẹni tí ó bukun ilẹ̀ Gadi,Gadi dàbí kinniun tí ó ba láti fani lápá ya, ati láti géni lórí.
Àti pé ayé ìrora ni wọ́n ń gbé, wọ́n sì ń tiraka láti gbé.
Ko si ọrọ oṣelu to buru to yii lati ọdun 1945.
 Ògborogondá tí a mọ ̀ sí Ọ ̀ bánta tí o ń wá olú-Ìwà baba baba rẹ tí ó ti kú kí ó tó dé ni ó jẹ ́ ìpín kẹta .
Ko le ma a jo skelewu' O tẹsiwaju wipe idi ti aare Muhammadu Buhari fi ba wọn peju-pesẹ sibi eto naa kii se fun itẹsiwaju isakoso ẹgbẹ oselu APC nikan, sugbọn lati fi da gbogbo eeyan ipinlẹ Ọṣun loju wipe ise rere ti egbe naa ti bẹrẹ yoo yọri.
O ni kewu ti toun ka ko ta ninu iṣẹ tiata.
Dafidi sọ fún gbogbo ìjọ eniyan pé, “Ẹ yin OLUWA Ọlọrun yín.
ti o ba fẹ eto alaafia  ati aseyori orile
Àwọn tí ó mọ̀ pé asán ni púpọ̀ nínú àwọn ọmọ ènìyàn, bí ẹni tí ń ṣe oore bá sì ní ìrètí wí pé kí àwọn tí òun ń ṣe oore fún mmọ oore nì, olúwaarẹ̀ ń fi ẹ̀hìnti òfuurufú.
bi ofin orile ede  Naijiria  se laa sile ninu eto ofin Section 230(2)
Bakan naa ni ijọba n gbero lati pe awọn ileeṣẹ ti owo ori to gọbọi ati awọn ilana ijọba ti ko fararọ, ti le kuro l'Ekiti, pada, to fi mọ ṣiṣe iṣẹ agbẹ aladanla.
Mo láyọ̀ pupọ ninu Oluwa nítorí ọ̀rọ̀ mi tún ti bẹ̀rẹ̀ sí sọjí ninu èrò yín.
Charles sọ pe lẹyin ti ariwo pọ loju opo ayelujara awọn olootu iwe iroyin naa ṣẹṣẹ wa kọ iroyin nipa iṣẹlẹ naa ṣugbọn wọn ko ni i ki Fani Kayode tọrọ aforinjin lọdọ akọroyin wọn.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Sickle Cell In Nigeria: Makinde ní ìgbàgbọ́ ninú ìdílé òun ṣèdíwọ́ láti ṣàyẹ̀wò ẹ̀jẹ̀ ''Ọkọ mi ti ko arun ibalopọ nitori alagbere ni, bi o ṣe n gbe dudu lo n gbe pupa.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìtàn Mánigbàgbé: Duro Ladipọ fi òjò àti àrá ńlá sàmì ìpapòdà rẹ̀ 16 Ìgbé 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 11 Ọ̀wàrà 2020 Oríṣun àwòrán, Yomi Duro Ogunmola Ni awujọ awọn osere tiata, odu ni oloogbe Duro Ladipọ, kii si se aimọ fun oloko.
Oríṣun àwòrán, others Eyi ni diẹ lara awọn awọn dukia ilu ti wọn ti fi sọ ori awọn eekan kan lawujọ.
Eyi ko tun yọ awọn ọmọ ogun bi ọgọrun un ẹgbẹrun silẹ.
Oríṣun àwòrán, EPA Àkọlé àwòrán, Obirin kan n da omi ẹrọ sinu garawa ni Abidjan, l'Ọjọru (Wednesday) nigba ti ọjọ ayẹyẹ omi agbaye ku ọla.
 Aare Buhari wa ro awon ololufe, ebi ati ojulomo re lati to ipase oloogbe naa, eyi ti o mu ife ati oye joba laarin eni kookan, eleyi ti o je okan gbogi fun idagbasoke orile-ede.
yoo gbe seranwo fun awon eniyan ti iko omo gun 
 Tottenham HotspurFebruary 14 20:45 FC Porto ?
Mo lérò pé wọ́n wá gbàdúrà kí ara bàbá wa kékeré yìí yá kíákíá ni, à ṣé wọ́n wá tú ọ̀fọ̀ ikú rẹ̀ ni.
Bí wọn bá ṣe inúnibíni yín ní ìlú kan, ẹ sálọ sí ìlú mìíràn.
Bí ó ti jé̩ pé ó s̩e pàtàkì kí ìdàgbàsókè ìbás̩epò̩ ti ò̩ré̩‐sí‐ò̩ré̩ wà láàrin àwo̩n orílè̩‐èdè,
Gege bi Klopp se so,”Inu mi o dun rara fun bi a se kopa ni saa kinni ifesewonse ohun.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Alaafin: Olori Aanu Adeyemi ṣàlàyé ìdí tó ṣe gẹ́ Oba Lamidi Adeyemi ti ìlú Oyo Ondo Election: Akeredolu f'ògún ikọ̀ Amotekun Ondo gbárí fún ìdìbò tó ń bọ̀.
ifowopamo naa fun atileyin ti won n se fun orile ede Naijiria paapaa julọ lori
àjẹ ̀ sára lodì sí àrùn náà kòsí .
’ Bẹ́ẹ̀ ni wọ́n ṣe ń fojú tẹmbẹlu àwọn eniyan mi, títí tí wọn kò fi dàbí orílẹ̀-èdè lójú wọn mọ́.
Kí ló dé tí o óo fi dàbí àlejò ní ilẹ̀ náà?
Kílódé tí ìjọba Nàíjíríà kò fòpin sí lílo ike rọ́bà lẹ́ẹ̀kan?
"Nígbà ti a ri mó fẹ́ lọ bá awọn boys mi, agbègbè ibi ti o maa n wà ni, ni a ri pẹlú ọmọ kekere kan, mo wa dúro si bi móto mi ti tayà rẹ̀ fọ́, mó dọ́gbọ́n bi pe mò n gba ìpè, sùgbọ́n àwọn ọ̀rẹ mi ti n tẹ̀le bọ̀.
Koda gbigbe irun to jọ ti were sori naa kọwọrin pẹlu awọn eleyii labẹ ofin ileewe.
Gómìnà Amosun f'ohùn sílẹ̀ láti kúrò ní APC Akinlade ni yóò di gómìnà tuntun ní ìpínlẹ̀ Ogun- Amosun PDP fà Buruji Kashamu kalẹ̀ bíi olùdíje Gómìnà l‘Ogun Lẹyin wa igba naa ni o ri tikẹti gba lati du ipo asofin labẹ asia ẹgbẹ APC ṣugbọn ti aayo rẹ fun ipo Gomina Adekunle Akinlade ko ri tikẹti ẹgbẹ gba.
 Àwọn ìtọ ́ jú mìíràn tún lè jẹ ́ gígé kúrò ọgbẹ ́ -inú náà .
Kò tọ̀nà láti gbé adájọ́ Onnogben lọ síwájú CCT - Adájọ́ fẹ̀yìntì 2019 elections: Ìgbésẹ̀ méje fún ìdìbò 2019 tí ó yẹ kí o mọ̀ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Claudiah: ìrẹ̀wẹ̀sì ọkàn bá mi fínra fún ọpọlọpọ ọdún Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Alao Akala:Èmi àti Ajimọbi kò ṣe ìlérí kankan fún ara wa Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Abìjà: Bàbá mi fi iṣẹ́ ọdẹ ti ń pa lémi lọ́wọ́ ni nítorí babaláwo ni Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Nígbà tí Dafidi mọ̀ pé Saulu ń wá òun kiri, 
Gbogbo ẹyẹ ojú ọ̀run yóo kọ́lé sórí ìtì igi rẹ̀ tí ó wó lulẹ̀.
Àwọn ìròyìn mìíràn tí ẹ lè nífẹ̀ẹ́ sí: Akeredolu, Ọgá NDLEA lọ kọ nípa gbíngbin igbó ní Thailand Sọ́ra, òògùn ikọ́ codeine lee yi ọ lórí Àwọn mọ̀lẹ́bí ajínigbé tó pàdánù ẹ̀mí l'Ondo kò tí ì yọjú Èyí ni díẹ̀ lára ìgbà tí Buhari àti àwọn aṣòfin gbéná wojú ara wọn Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Eyi waye lẹyin ti Igbakeji Aarẹ, Yẹmi Ọṣinbajo ati awọn gomina ṣe ipade bonkẹlẹ ni ilu Abuja lati jiroro lori erongba ijọba apapọ.
El-Zakzaky pé ìpàdé pẹ̀lú àwọn àgbẹ́joro India àti àwọn àjọ ti kìí ṣe ti ìjọba
Wọn kò sin wọ́n bí àwọn alágbára tí wọ́n wà ní àtijọ́ tí wọ́n sin sí ibojì pẹlu ohun ìjà ogun wọn lára wọn: àwọn tí a gbé orí wọn lé idà wọn, wọ́n sì fi asà wọn bo egungun wọn mọ́lẹ̀; nítorí àwọn alágbára wọnyi dẹ́rù bani nígbà tí wọ́n wà láàyè.
Lẹ́yìn ọjọ́ kẹwaa, ojú wọn rẹwà, wọ́n sì sanra ju gbogbo àwọn ẹlẹgbẹ́ wọn tí ń jẹ oúnjẹ àdídùn tí ọba ń jẹ lọ.
N óo jẹ́ kí èso igi ati èrè oko pọ̀, tóbẹ́ẹ̀ tí ìtìjú kò ní ba yín láàrin àwọn orílẹ̀-èdè mọ́ nítorí ìyàn.
Àkọlé àwòrán, Ijọba fofin de awọn ileeṣẹ elepo to n gbe epo ti ko dara wọ Najiria.
Ní òwúrọ̀ kutukutu ọjọ́ keji, Labani fi ẹnu ko àwọn ọmọbinrin rẹ̀ ati àwọn ọmọ ọmọ rẹ̀ lẹ́nu láti dágbére fún wọn, ó súre fún wọn, ó sì pada sílé.
Lassa: Ẹnikan ku,ogoji mii wa labẹ ayẹwo l'Ọsun Ewe aloe vera wọpọ nitori lilo rẹ fun isegun Nibi igegeru ni awọn ibeji ọhun ti lẹpọ, eyi tawọn onisegun oyinbo ni, o maa n waye lẹẹkan ninu ibi miliọnu marun Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Wọ́n sì sin òkú rẹ̀ sí ilé rẹ̀ ní Rama.
Ó ràn mí lọ́wọ́,ó kó mi yọ ninu ewu,ó sì gbà mí là,nítorí pé inú rẹ̀ dùn sí mi.
Adeoye ṣalaye pe awọn oṣiṣẹ OYRTMA ni ki awọn awakọ ọhun kuro ni ibi ti wọn wa tẹlẹ lọ si ibomiran, ki ọna lee ja gaara, ṣugbọn wọn kọ'ti ikun si aṣẹ ọhun.
Oríṣun àwòrán, Getty Images 'Ọ̀pọ̀lọpọ̀ ni inú wọn kò dùn sí bí Hajj kò ṣe ní wáyé lọ́dún yii' Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Saudi Arabia Hajj 2020: Alaga Hajj ni Naijiria ni inú wọn kò dùn sí bí Hajj kò ṣe ní wáyé.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ṣé lóòótọ́ ni Amcon gba ilé Toke Makinwa ti wọn ní bàbá olówó rà á fun?
ogbin lorile-ede Naijiria lati dekun ebi lawujo.
Ikẹtalelogun iru rẹ - BBC News Yorùbá BBC News, YorùbáFò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Winter Olympics 2018 - Ikẹtalelogun iru rẹ 9 Èrèlè 2018 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Winter Olympics ti bere ni south korea Idije ere idaraya ti Winter Olympics 2018 ti ẹlẹẹketalelogun yoo bẹrẹ ni Olu-Ilu South-Korea, Pyeongchang lọjọ kẹsan si ọjọ karundinlogbon osu keji, ọdun 2018 pelu otutu to lamilaaka julọ ni itan orilẹede naa.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Belly Mujinga: Bí iléeṣẹ́ ọlọ́pàá ní UK ṣe parí ẹ̀ṣùn rẹ̀ mú kí àwọn adúláwọ̀ fa ìbínú yọ O fikun pe Bi gomina ba wa kọ lati fa akoso le emi igbakeji rẹ lọwọ lasiko to wa ni iyasọtọ yii, a jẹ pe o tapa si ofin ilẹ wa ni, to si foju tẹnbẹlu awọn eeyan ati ofin ilẹ wa to jẹjẹ lati tẹle."
Kí ojú ti àwọn alátakò mi,kí inú èmi, iranṣẹ rẹ, sì máa dùn.
Amọ nigba to n fun Ahmed lesi ọrọ rẹ, Sunday Igboho se apejuwe ọrọ yii bii iwa anikanjọpọn ati eyi ti ko boju mu.
Ò ti gba ibùsùn lọ́wọ́ aboyún rí nítorí ẹ̀kọ sísì; ό sì ti lu ọmọ òkú ọ̀run ní kùmọ̀ lόrí rí nítorí-i kúlíkúlí-i ṣílè kan.
"Awọn oloṣelu lo ni àṣẹ bayii, kii ṣe ọba mọ.
Orile-ede ọtọọtọ gbe igbesẹ ọtọọtọ lati koju arun Covid-19 latara pe ọtọọtọ ni alumọni ti wọn ni ati pe nkan ko ri bakan naa lọdọ wọn.
Àwọn Olúkọ ìpínlẹ̀ Oyo fakọyọ lórí ètò Akọ́mọlédè àti Àṣà púpọ̀ Wo bí ilé ìwòsàn LUTH ṣe ń gba owó ibùsùn lọ́wọ́ àwọn aláìsàn, tí àwọn míràn sì ń sun ìta 'Àwọn agbébọn tó pá Olufon ti Ifon ti ṣe ohun èèwọ̀ ní ilẹ̀ Yoruba' Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ìgbátí ìgbámú àná látọwọ́ sọ́jà obìnrin ti bá arákùnrin náà dé iléèwòsàn Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
” Àwọn eniyan Israẹli sì ṣe bí OLUWA ti wí.
3 3212 Orilẹede Togo 65 0.
Ní ọjọ́ keji, lẹ́yìn tí wọ́n sọ̀kalẹ̀ láti orí òkè, ọ̀pọ̀ eniyan wá pàdé rẹ̀.
Ẹ fura, làásìgbò le wáyé ní ìjọba ìbílẹ̀ mẹ́fà yìí lásìkò ìbò gómìnà Ondo - YIAGA Oríṣun àwòrán, Nguher Gabrielle Zaki Awọn ajọ ajafẹtọ ọmọniyan ti ke gbajare si awọn alaṣẹ lati dena jagidijagan ati awọn iwa kotọ mii, to le waye lasiko idibo Gomina to n bọ nipinlẹ Ondo.
Dayọ tẹsiwaju pe, asọye to muna doko ti wa laarin ajọ NFF ti ilẹ Naijiria ati alaṣẹ ileeṣẹ ọkọ ofurufu naa lati tete ko awọn ohun eelo naa pada de saaju ọjọ lsẹgun.
Bàbá fìdí ọmọ ọdún márùn ún jó sítóòfù gbígbònà, ó di aláàbọ̀ara nítorí ó jí ẹja Ileeṣẹ ọlọpaa ni ipinlẹ Ogun ti fi panpẹ ọba mu arakunrin kan, Idowu Sikiru fun ẹsun pe o fi iya jẹ ọmọ rẹ, ọdun marun un, Segun Sikiru.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Mathematics Education: Fasiti Ibadan f'orin tàkasúfèé wá ojúùtú si ìṣòro ẹ̀kọ́ ìṣirò 24 Èrèlè 2020 Oríṣun àwòrán, UI Àkọlé àwòrán, Fasiti UI forin tàkasúfèé wá ojúùtú si ìṣòro ẹ̀kọ́ iṣirò Lójúnà ati wá ojúútú si bi àwọn ènìyàn ṣe maa n fìdírẹmi nínú ẹkọ ìsirò yála nilé ìwé alákọbẹ́rẹ̀ tàbi ni girama lásìkò ìdánwò, olùkọ́ni kan láti ẹka ẹkọ àwọn ọmọde ni Fasiti Ibadan, Omowe Ishola Salami ti ṣe àgbekalẹ̀ orin tàkasúfèé láti mu ẹkọ náà rọrùn.
 Ṣugbọn Adeniyi ṣalaye siwaju sii pe, ohun to fa ede aiyede ko ṣẹyin bi awọn kan ṣe n fi aadọrin ẹgbẹ ọmọ Yoruba ti ko kọja ilu Ketu, ni Benin Republic ṣafiwe ẹgbẹ ọmọ Yoruba kakiri agbaye, eyi ti Akintoye jẹ adari fun ki wọn to fi ọwọ osi juwe ile fun un."
Eyi ko ṣẹyin bi wọn yoo ṣe si papakọ ofufuru fun igbokegbodo ọkọ ofurufu ni Naijiria lati Ọjọ Kẹjọ, Osu Keje yii.
Gbogbo ara Lasaru jẹ́ kìkì egbò.
Bakan naa lo bu ẹnu atẹ lu iwadii kan to ni awọn osisẹ ijọba yọ ẹrọ ayaworan to n ka isẹlẹ silẹ, CCTV to wa ni bode Lekki nibi tawọn oluwọde naa wa lati ọsẹ meji sẹyin.
Chelsea kọ́wọ̀ọ́ rìn pẹ̀lú Arsenal lọ àṣekágbá Europa Àkọ́dá oró.
Nígbà gbogbo ni àwọn talaka wà lọ́dọ̀ yín, ṣugbọn èmi kò ní sí lọ́dọ̀ yín nígbà gbogbo.
Wọ́n ń lù wá, a kò sì ní ibùgbé kan tààrà.
O ni adura oun fun olootu ijọba tuntun naa lorukọ awọn alalẹ ilẹ Yoruba ni pe yoo ṣe rere ni ipo rẹ tuntun naa.
Sugbọn olori ẹgbẹ kan to jẹ tawọn darandaran Fulani (Gan Allah Fulani Development Association), Alhaji Saleh Bayeri, sọ wipe ko yẹ ki ipinlẹ Edo se agbekalẹ ofin to l'odi si ẹran dida lalẹ nitori awọn Fulani kii daranjẹ lalẹ O s'afikun wipe didaranjẹ lalẹ ni ewu fun awọn maalu ati darandaran nitori ikọlu eranko bi ikoko ati ejo.
bi eto  ofin orile ede yii se laa sile.
Ninu atẹjade to fi sita lẹyin ibo abẹle naa, Agboọla ni awọn alagbara ti ko lẹgbẹ loun dojukọ lo jẹ ki oun fidirẹmi.
ẹrú tí ó jọba,òmùgọ̀ tí ó jẹun yó,
Awon arinrinajo ohun so fun awon alase ile-ise orile-ede Mozambique naa pe, won bere irinajo won lati orile-ede Ethiopia lo si orile-ede Kenya ati Tanzania, ni iyanju ati wa ibi tile gbe tutu ni awon orile-ede ti o mule gbe orile-ede South Africa.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Manchester United: Paul Pogba sọ pé òun ti ṣe tán láti padà sórí pápá 16 Ìgbé 2020 Oríṣun àwòrán, Getty Images Agbabọọlu fun Manchester United, Paul Pogba sọ pe ebi àṣeyọrí lo n pa oun ju bayii lẹyin ti oun padanu ọpọlọpọ ọjọ ninu idije saa yii nitori ifarapa.
Ìròyìn Yàjóyàjó - 'Ganduje ti rọ Ẹ́míà ìlúu Kánò lóyè Buhari, ìjọba rẹ ń jọ bí ègún f'órílẹ̀èdè Nàìjíríà-Oyedepo Nínú ọkùnrin àt'obìnrin, ta ni Coronavirus yóò tètè ṣe lọ́ṣẹ́?
Ìlú tuntun tó kún fún ohun àdáyébá láìsí ọkọ̀ tàbí òpópónà ń bọ̀ ní Saudi Arabia Lẹ́yìn ọgọ́rùn ún ọjọ́ tí wọn ti Lekki Toll Gate pa, ẹ wo owó gọbọi tíjọba Eko ń pàdánù Àwọn olorì Aláàfin fi oríkì awúnilórí yẹ́ ọkọ wọn sí fún àádọ́ta ọdún tó gorí ìtẹ́ Agbẹjọ́rò àgbà ní Nàìjíríà ti pàsẹ kí wọ́n dáwọ́ ètò ìgbanisíṣẹ́ NDLEA dúró Mamora to jẹ ọkan lara ọmọ igbimọ amuṣẹya PTF to n ri si ati dẹkun coronavirus ni Naijiria ṣalaye pe ojuṣe ijọba ni lati daabo bo ọmọ Naijiria ni gbogbo igba.
Egbe osise lorile ede Naijiria (NLC) ti  tako iwa ipaniyan to waye ni awon apa ibikan lorile ede Naijiria.
Fadeyi ni Kọmiṣọ́nna ọlọpaa ti wa pasẹ pe wọn gbọdọ se awari awọn olubi ẹda to huwa laabi yii kiamọsa.
Ọwọ́ àwọn alásẹ ọgbà ẹ̀wọn ní ọ̀daràn to ni Corornavirus wà báyìí-Kọmísọ́nà ìlera Ondo Kí ló fà ogun Ìjàyè àti ìṣubú Kurunmi, ìfẹ́ ìlú ni àbí orí kunkun?
Ninu ilẹ̀ ẹ̀yà Isakari, wọ́n fún wọn ní: Kiṣioni, Daberati, 
Lara awọn ohun manigbagbe ti wọn fi n ṣe iranti Nnamdi Azikwe ni awọn ibi ti wọn fi sọ orukọ rẹ bi; papakọ ofurufu to wa ni Abuja, Nnamdi Azikwe International Airport.
Ṣugbọn bí obinrin náà bá kọ̀ tí kò tẹ̀lé ọ, nígbà náà ọrùn rẹ yóo mọ́ ninu ìbúra tí o búra fún mi, ṣá má ti mú ọmọ mi pada sibẹ.
Àṣà kan wà ní'lẹ̀ yìí tó jọ mí lójú.
Ọga agba ajọ to n ri si ọrọ pajawiri (LASEMA), Olufemi Oke-Osanyintolu, ṣalaye pe eeyan mẹtadinlogun lo padanu ẹmi wọn ninu iṣẹlẹ naa.
 O tẹsiwaju pe  Mo jẹ oloriire pe mo jẹ ọrẹ rẹ, mo si nireti pe ọjọ ibi rẹ yii yoo jẹ pataki fun ọ, mo gbadura pe ki gbogbo ala rẹ wa si imusẹ.
 Àwọn krómósómù le wà bóyá bí i áṣẹ ́ po tàbí aláìṣẹ ́ po .
Ní ìdílé Aláàfin, ọjọ́ kẹfà ni à ń sọ ọmọ lórúkọ.
Ibi tí àwọn odò ti ń ṣàn wá, ibẹ̀ ni wọ́n tún ṣàn pada lọ.
"EndSARS, EndSWAT Protests: Òbí agbábọ́ọ̀lù Kazim Tiamiyu Kaka àtàwọn míì tí ọlọ́pàá pa sọ̀rọ̀, omijé bọ́ lójú ''Àjọ NERC ti fún Disco láṣẹ láti padà sí owó tàríìfù tuntun iná mọ̀nàmọ́ná'' Ẹ dẹ̀kun lílo Sniper àti Dichlorvos fún ìtọ́jú oúnjẹ- NAFDAC kìlọ̀ Ajọ WAEC gbé èsì ìdánwò ọdun 2020 jáde Ninu ọrọ ti o ba BBC Yoruba sọ, o ni ile ijọsin ni oun ti n bọ l'ọjọ aiku ti oun si pada ikọ ologun ""Operation Burst"" ni agbegbe Bẹẹrẹ nilu Ibadan."
" Oríṣun àwòrán, @others Àkọlé àwòrán, Awọn oju to fẹ gba N60 miliọnu Gloria Shoda nitirẹ wi pe oun ko lodi si eto BBNaija, sugbọn biba ara ẹni lopọ lori afẹfẹ je ohun ti ko dara rara.
Ṣugbọn a óo pa àwọn ọlọ̀tẹ̀ ati àwọn ẹlẹ́ṣẹ̀ run,àwọn tí ó kọ OLUWA sílẹ̀ yóo sì ṣègbé.
Ó súre fún ọjọ́ keje yìí, ó sì yà á sí mímọ́, nítorí pé ọjọ́ náà ni ó sinmi ninu gbogbo iṣẹ́ ìṣẹ̀dá tí ó ti ń ṣe bọ̀.
ṣugbọn ó pàṣẹ kí wọ́n lọ so olórí alásè kọ́ igi, gẹ́gẹ́ bí Josẹfu ti túmọ̀ àlá wọn fún wọn.
O ṣalaye fun akọroyin BBC pé nigba ti ọrọ oju yii fẹ maa gba ẹbọ lọwọ oun ni oun ba morile ile iwosan ni Guusu Taiwan.
Ọ̀gbẹ́ni Comey ṣàlàyé ọ̀rọ̀ yìí nínú ètò ìfọ̀rọ̀wánilẹ́nuwò àkọ́kọ́ kan tó se lórí tẹlifísàn lẹ́yìn tí Trump yọọ́ nípò, tí Trump sì tún nàka àléébù síi pé òpùrọ́ ni Comey nínú ètò ìfọ̀rọ̀wérọ̀ kan.
Idije AFCON ti ilẹ Adulawọ ṣi n lọ lọwọ ni orilẹ-ede Egypt to n gbalejo ẹ.
A tako esi ibo to eyi ti wọn ti kede Abdullahi Umar Ganduje gẹgẹ bi ẹni to wole ipo Gomina nitori aisedede to waye saaju, lasiko ati lẹyin idibo atundi to gbe wọlẹ'' Alaga ẹgbẹ alatako PDP nilu Kano,ọgbẹni Rabiu Bichi sọ fun Inec pe ki wọn wọgile idibo atundi naa nitori iwa janduku ati ailedibo awọn oludibo lọpọ agọ idibo."
Ó mú Agagi, ọba àwọn ará Amaleki láàyè, ó sì fi idà pa gbogbo àwọn eniyan rẹ̀.
lati  tun ri i pe iji omi lile  naa ko waye.
Joe Biden náà ti gba abẹ́rẹ́ àjẹsara Covid-19 Ìjọba àpapọ̀ ti kéde ìsúnsíwájú ọjọ́ ìforúkọsílẹ̀ nọ́mbà NIN Yatọ si eyi, o ni asiko yi ni '' a gbọdọ ṣa gbogbo ipa ti mo si rọ awọn lọba lọba ati olori sin lati polongo si etigbọ awọn eeyan wa'' Ni ọjọ Aje ni aarẹ Buhari gbẹnu igbimọ naa kede pe ki awọn oṣiṣẹ ijọba apapọ wa joko sile fun ọṣẹ marun un lati le koju itankalẹ arun yi .
Tàbí pé, irọ́ ni ilé-iṣẹ́ náà ń pa fún wa.
Ohun tí ó mú mi dúró nílé ẹjọ́ nisinsinyii ni pé mo ní ìrètí pé ìlérí tí Ọlọrun ṣe fún àwọn baba wa yóo ṣẹ.
Awọn atipo naa wa ninu adọfa eeyan ti wọn gba sile lati inu ọkọ ojuomi kekere kan ti wọn fe lo lati wọ Yuroopu lọna aitọ.
Aarẹ orilẹede Ghana, Nana Akufo-Addo lo kede bẹẹ lasiko to n bawọn ọmọ orilẹede naa sọrọ pẹlu afikun pe, ko gbọdọ si ipade apero kankan mọ, to fi mọ isin laarin awọn ẹlẹsin, idije ere idaraye ati iwọde awọn oloselu, fun ọsẹ mẹrin gbako.
Ko si owo ninu iṣẹ tiata mọ, Koda, o tun nira lati ni orukọ pẹlu.
“Ǹjẹ́ òfin wa dá eniyan lẹ́bi láìjẹ́ pé a kọ́ gbọ́ ti ẹnu rẹ̀, kí á mọ ohun tí ó ṣe?
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Brazil vs Nigeria: Ọ̀mì aláyò kọ̀ọ̀kan lakitiyan Super Eagles pẹ̀lú Brazil jásí 13 Ọ̀wàrà 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Ifẹsẹwọnsẹ ọlọọrẹsọọrẹ to waye laarin ikọ agbabọọlu Naijiria ati Brazil lo pari si ọmi.
Paulu bá bẹ̀rẹ̀ sí sọ̀rọ̀, ó ní, 
Gbọ́ ẹ̀bẹ̀ wa láti ibùgbé rẹ ní ọ̀run, kí o sì dáríjì wá.
" Kabiyesi Alaafin ko fẹ kawọn Olori o fa sẹyin lori ọrọ eto ẹkọ Oríṣun àwòrán, olori memunat adeyemi Pupọ ninu awọn olori laafin Ọba Lamidi Ọlayiwọla Adeyẹmi kẹta, lo jẹ wi pe alaafin funrarẹ lo ran wọn lọ si fasiti.
Ẹ fi ìgbàlà ṣe fìlà onírin tí ẹ óo máa dé, kí ẹ sì mú idà Ẹ̀mí Mímọ́, tíí ṣe ọ̀rọ̀ Ọlọrun.
Mo lero wi pe awa funra wa ni iṣẹ lati ṣe lati mọ bi a ṣe nilo nkan wọnyi si.
Ẹ jẹ́ kí àwọn aṣiwaju yín bá mi kálọ kí wọ́n wá sọ bí wọ́n bá ní ẹ̀sùn kan sí i.
bẹrẹ ninu oṣu kinni ọdun to n bọ.
Ninu ọrọ rẹ, o ni ida ogoji yoo jẹ fun awọn ọdọ, nigbati ida ọgbọn yoo lọ si ọdọ awọn obinrin ati wi pe awọn agbalagba ni yoo wa ni ida ọgbọn to ku.
Ní àkókò náà, ọ̀pọ̀ eniyan yóo dìde sí ọba Ijipti; àwọn oníjàgídíjàgan láàrin àwọn eniyan rẹ̀ yóo dìde kí ìran yìí lè ṣẹ; ṣugbọn wọn kò ní borí.
Wéré tí ó sọ ọ́ sílẹ̀, logan ni ó rí ọ̀nà ní iwájúu rẹ̀.
Amugbalẹgbẹ fun gomina Rotimi Akeredolu lori akanṣe iṣẹ, Ọmọwe Doyin Ọdẹbọwale ṣalaye fun BBC News Yoruba ninu ifọrọwanilẹnuwo kan pe awọn ọlọpaa ti wọn ko sẹnu ibọde ipinlẹ naa lati maṣe jẹ ki ọkọ kọọkan wọle lati awọn ipinlẹ miran n gbabọde fun ijọba ni.
Mo bùn ọ́ ní gbogbo rẹ̀.
Majekodunmi Temitope Oluwaseun Arakunrin yi ni ẹnikeji ti wọn yan lati ṣoju awọn ọdọ ninu igbimọ iwadii nipinlẹ Eko.
Okota (Cele)/Ijesha Link Bridge Ijọba ibilẹ Mushin / Oshodi-Isolo 15.
”Alaga ile-ise LADOL, oloye Oladipo Jadesimi, so pe oun ati awon osise re wa lati dupe lowo aare Buhari fun pipese ayika ti o rorun ati idasile isakoso to n gbogun ti iwa ibaje, eleyi ti o sanfaani pupo fun okoowo won lati gberu si lawujo laarin awon akegbe re.
Awọn ọdọ to n se iwọde, awọn ẹlẹgbẹjẹgbẹ ajafẹtọ ọmọniyan atawọn agbẹjọro ti wọn tako igbesẹ naa ni awọn fura pe o seese ki ejo lọwọ ninu lori igbesẹ ologun yii.
Gbogbo ìjọ eniyan bá mú un lọ sẹ́yìn ibùdó, wọ́n sì sọ ọ́ lókùúta pa gẹ́gẹ́ bí OLUWA ti pàṣẹ fún Mose.
Tó bá di ìgbà náà, kò ní sí òtútù tabi òjò dídì mọ́, 
Adekeye Adebajo Àkọlé àwòrán, Gbajumọ to gbalafẹ ni Israel Adebajo Bi a ba ka awọn gbajumọ ni meni meji lasiko ti o logba, yoo ṣoro ki a ma mẹnu ba ilumọọka oniṣowo ọmọ bibi ilu Ẹpẹ nni, Israel Adebayo Ogunyeade Adebajo.
O wa fewe ọmọ mọ awon èèyàn tó ń sọ ahesọ ọ̀rọ̀ kiri láti má ṣe yí orúkọ Sunday Igboho wọnú rògbòdìyàn náà nítorí ẹni àlàáfíà nii ṣe.
Àwọn ọmọ Kohati jẹ́ mẹrin: Amramu, Iṣari, Heburoni, ati Usieli, 
Gbé ẹrù rẹ lé èjìká níṣojú wọn, kí o sì jáde ní òru.
”A óo dárí ẹ̀ṣẹ̀ àwọn tí ń gbé ibẹ̀ jì wọ́n.
mélòó-mélòó ni ẹ̀jẹ̀ Kristi, tí ó fi ara rẹ̀ rú ẹbọ tí kò lábùkù sí Ọlọrun nípa Ẹ̀mí ayérayé, yóo wẹ ẹ̀rí-ọkàn wa mọ́ kúrò ninu iṣẹ́ tíí yọrí sí ikú, tí yóo sì fi ṣe wá yẹ fún ìsìn Ọlọrun alààyè.
Kí ló dé tí Igbákejì Gomina Ondo ní kí wọ́n yọ Abẹnugan Ilé Aṣòfin?
Baba arúgbó tí ó ni ilé yìí bá jáde sí wọn, ó bẹ̀rẹ̀ sí bẹ̀ wọ́n, ó ní, “Ẹ̀yin arakunrin mi, ẹ má hu irú ìwà burúkú báyìí, ṣé ẹ rí i pé ọkunrin yìí wá wọ̀ sinu ilé mi ni, ẹ má hu irú ìwà burúkú yìí sí i.
asofin lati ri daju pe idagbasoke de ba eka ile-ise epo robi lorile-ede
Ìlú mejila ni wọ́n pín fún àwọn ọmọ Merari ní ìdílé ìdílé, lára àwọn ìlú ẹ̀yà Reubẹni, Gadi ati ti Sebuluni.
Àwọn ọmọ ogun Amoni, ati Moabu gbógun ti àwọn ará Òkè Seiri wọ́n sì pa wọ́n run patapata.
Zoe ni Fun apẹẹrẹ, ti ẹ ba n wa ọrọ yii 'Penis' tii se ẹya ara ọkunrin, orisirisi imọ lẹ ri nipa rẹ amọ eyi ko ni ri bẹẹ, tẹ ba beere fun 'Vagina', tii se ẹya ara obinrin."
Zeid Ra'ad Al Hussein, tí ó jẹ́ aṣàkóso fún ẹ̀ka ìjàfẹ́tọ̀ọ́ ènìyàn lábẹ́ United Nations gbé àkọsílẹ̀ kan jáde ní 29, oṣù Òkúdù 2016:
    Ẹ̀yin ọ̀rẹ́ mi, ibi tí mo bá ìròyìn náà dé lánà ni ikú Òmùgọ̀diméjì.
Minisita tun tesiwaju pe ko si
Adura pẹlu igbagbọ yóo mú kí ara aláìsàn náà yá.
” Ogbeni Nuhu ni orile ede
Ọmọ mi ti ṣèlérí pé oun máa mú mi lọ sí òkè òkun k'àwọn SARS tó pá á - Iya Kazeem Tiamiyu Ọ̀jọ́ eérú t'ọdún yìí bẹ̀rẹ̀ pẹ̀lú aṣọ ọ̀fọ̀ Ilé ẹjọ́ gíga jùlọ dúró gbọingbọin lórí ìdájọ́ ìdìbò gómìnà Bayelsa Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Mi ò kí ń ṣèèyàn burúkú tàbí Babalawo bí ẹ ṣe mọ̀ mí nínú eré - Fadeyi Oloro Oríṣun àwòrán, Goldmyne Àkọlé àwòrán, Lagos -Ibadan Express: Súnkẹ́rẹ fakẹrẹ ọkọ òpópónà marosẹ̀ tòní tún kọ sísọ Ìròyìn to tẹ BBC lọ́wọ́ ni pe, mọto to gbé ẹpo kan ló gbaná ni dédé ààgo méje alẹ ana ọjọ Isẹgun lópòpóna Lagos-Ibadan Express, èyí sì ló ṣe okùnfà súnkẹrẹ fàkẹrẹ ọkọ̀.
Titi di isin yii wọn ko ti fi idi ọrọ mulẹ nipa ibi ti awọn akẹkọbirin naa wa ati ounka wọn.
Anambra Rape: Ìdí ti mo fi bá ọmọ ọdún méje lòpọ̀- Ejike Kanu
Ọrọ yi ko ṣẹyin igbesẹ to n gbe lati koju Covid-19 ati bi ọwọja arun naa ṣe n peleke si.
Kekere kọ Ipinlẹ́ Ogun: Gbogbo eto lo ti to bayii ni papa isere idaraya MKO Abiola nilu Abẹokuta fun ayẹyẹ ibura gomina ti ilu dibo yan ni ipinlẹ Ogun, Ọmọọba Dapọ Abiọdun.
Fidio kan to fi sita loju opo instagram rẹ lọjọ kini, oṣu karun un ni Sẹnetọ Abiọla Ajimọbi ṣi ti n ki ijọba apapọ atawọn oṣiṣẹ eto ilera ati aabo fun iṣẹ takuntakun ti wọn n gbe ṣe lori igbesẹ ati dẹkun itankalẹ ajakalẹ arun coronavirus lorilẹ-ede Naijiria.
Eyi lo mu ki ọpọ awọn ọmọ orilẹede Naijiria o maa beere ohun ti o ba eyi wa nitori kii ṣe ohun ikọkọ pe ki eeyan to de ipo ilu giga bẹẹ yoo la ọpọlọpọ iwadi ati ifọrọwanilẹnuwo kọja.
Ko sọ ohun ti ipade naa dale lori.
Bẹ́ẹ̀ ni ilẹ̀ Efuroni ní Makipela, tí ó wà ní apá ìhà ìlà oòrùn Mamure ṣe di ti Abrahamu, ati ihò tí ó wà ninu ilẹ̀ náà, ati gbogbo igi tí ó wà ninu rẹ̀ jákèjádò.
Ó kó wọn tọ ọkunrin náà wá, láti mọ orúkọ tí yóo sọ olukuluku wọn.
2 151721 Orilẹede Myanmar 2201 4.
Nígbà náà ni OLUWA sọ fún Jakọbu pé, “Pada lọ sí ilẹ̀ baba rẹ ati ti àwọn ìbátan rẹ, n óo sì wà pẹlu rẹ.
, Duration 1,0927 Ẹrẹ̀nà 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Ó sọ yìnyín sílẹ̀ bí òkò,ta ni ó lè fara da òtútù rẹ̀?
fáwẹ ̀ lì ni ìró tí a pè tí kò sí ìdiwọ ́ fún afẹ ́ fẹ ́ tàbí èémí ton ti inu edo foro bo wa si ona enu .
ara ilu ki eto aabo ba lee kẹsẹjari.
" Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Obateru Akinruntan: Wíwá ohun tá jẹ títí láé ló gbé wa kúrò nílé Ife Igboho tẹsiwaju pe, wọn se agbekalẹ ikọ alaabo ọhun lati daabo bo ẹmi ati dukia nilẹ Yoruba ni lai naani ẹya, ẹsin ti ẹni kọọkan n se.
Ìbọn ọlọ́pàá ló pa èèyàn, ẹgbẹ́ wa kìí lo ìbọn - Shiite fárígá Ipa tí ìyànsípò Olóòtú ìjọba Gẹ̀ẹ́sì tuntun yóò mú bá ‘Brexit’ Ninu ọrọ rẹ, Ọsọba kede pe ohun meji lo n dun ohun nipa Jakande, akọkọ ni pe baba naa ko kọ itan kankan nipa igbesi aye rẹ silẹ, tori ko ba yaayi pupọ lati gbọ latẹnu rẹ bo se lo akoko rẹ lẹnu isẹ iroyin ati eto iselu.
Nigba to n sọrọ lori iṣẹlẹ naa, Ọga Agba ileeṣẹ ọlọpaa Naijiria, Muhammed Adamu dupẹ lọwọ awọn araalu fun bi wọn ṣe fun ileeṣẹ ọlọpaa ni awọn iroyin to ran an lọwọ lẹnu iṣẹ naa.
Ní àkókò náà gan-an, àwọn kan sọ fún un nípa àwọn ará Galili kan tí Pilatu pa bí wọ́n ti ń rúbọ lọ́wọ́.
Agbaboolu omo odun mejilelogbon ohun ni olokan-o-jokan ifarapa ti n koju re lati bi odun mewa ti o ti wa ninu iko naa.
Eyi ni awọn igba mẹrin kan tawọn eekan ilu ti wọnu ipo idubulẹ aisan lasiko ti wọn n koju igbẹjọ tabi iwadii lori ọkan o jọkan iwa aṣẹmaṣẹ to niiṣe pẹlu iwa jẹgudujẹra.
Ó ti di ọ̀gá àwọn ọ̀mọ̀wé wọn-ọnnì ṣe ni wọ́n ń ká ọwọ́ sí ẹ̀hìn bí wọ́n bá ń bá a sọ̀rọ̀, wọn a máa sáré nígbà tí ó bá pè wọ́n, wọn a sì máa yẹ́ ẹ sí nígbà tí ó bá dé ọ̀dọ̀ wọn.
O jẹ akoko ironupiwada fun ọsẹ mẹfa ṣaaju ọdun ajinde.
Nigba ti Minisita fun oro awon osise ati ise lorile ede Naijiria, Chris Ngige  n ba awon akoroyin soro leyin ipade igbimo ijoba apapo so pe  awon igbimo to n jiroro lori ekunwo awon osise ko i ti fenuko lori  iye ti awon osise yoo maa gba.
 Ẹnì tí wọn tí tí mọ ́ lẹ ̀ fún ẹ pànìyàn lè méjì dín là aadota ọ ̀ tọ ̀ ọ ̀ tọ ̀ .
Inú bí i sí Eleasari ati Itamari, àwọn ọmọ Aaroni tí wọ́n ṣẹ́kù, ó ní, 
IKEDC - BBC News Yorùbá BBC News, YorùbáFò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Electricity Tarrif: A kò tíì gbé àwọn oníbàrà wa sórí tàríìfù tuntun - IKEDC 31 Ọ̀wàrà 2020 Oríṣun àwòrán, @EKEDP Ileeṣẹ apinaka ni ipinlẹ Eko, Ikeja Electric Distribution Company, IKEDC, ti sọ pe awọn ko tii bẹrẹ si ni gba idiyele owo ina tuntun lọwọ awọn onibara wọn.
Nígbà tí Tẹra di ẹni igba ọdún ó lé marun-un (205), ó kú ní ilẹ̀ Harani.
Oruko awon elere idaraya lokunrin ati lobinrin ti won ko lo sipago ni: Bashir Abdulazeez, Nafisat Adebayo Lawal  (Karate), Sasere Taiwo, Nwokemkwu Favour, Badmus Shukrat (Athletics), Aishat Bello (Volleyball), Idowu Abdulrazaq, Muinat Sodiq (Handball), Okeke Victory, Mustapha Suliyat ati Ashaolu Michael Omotayo (Badminton).
Ọjọ pe, ọjọ si ti ko, ti eto idanwo asejade nile ẹkọ girama, WAEC, yoo bẹrẹ, gẹgẹ bi wọn se kede rẹ.
Àkọlé àwòrán, Awọn eniyan ipinlẹ Ekiti nreti esi idibo 'INEC, APC yi ibo' 05:34am Ẹwẹ, awọn alatilẹyin ati aṣoju ẹgbẹ oṣelu PDP to wa ni ile iṣẹ INEC nibi ti wọn ti n ka ibo sọ pe ajọ eleto idibo ti yi ibo da fun ẹgb oṣelu APC.
Loju opo Twitter awọn eeyan ti n sọ tẹnu wọn nipa aṣẹ tawọn ijọba gbe kalẹ.
Ọ̀rọ̀ ẹnu ni ó fi lé àwọn ẹ̀mí náà jáde, ó sì tún wo gbogbo àwọn tí ara wọn kò dá sàn.
Kí wọn máa rú ẹbọ ọpẹ́,kí wọn sì máa fi orin ayọ̀ ròyìn iṣẹ́ rẹ̀.
Ṣugbọn bí a bá ń gbé inú ìmọ́lẹ̀, bí òun náà ti wà ninu ìmọ́lẹ̀, a ní ìrẹ́pọ̀ pẹlu ara wa, ẹ̀jẹ̀ Jesu Ọmọ rẹ̀ sì ti wẹ gbogbo ẹ̀ṣẹ̀ wa nù kúrò lára wa.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Military Bruitality: Sójà obìnrin lù mí lálù bami nílùú Ibadan 4 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Oríṣun àwòrán, Bolade Adedeji/Facebook Ọkùnrin kan nílùú Ibadan ló ti ke gbajarè bi obinrin sójà kan ṣe lu òun lálùbami lẹ́yìn tí òun ba ọmọ rẹ̀ wí pé ó fẹ́ jánà mọ́ mótò òun lẹ́nú.
e ni idakọnkọ ati lai si iranwọ
Aifi ara mọ aba ati awọn ilana ti awọn ọmọ ẹgbẹ fi ẹnu ko le lori.
Nígbà tí wọ́n súnmọ́ abúlé tí wọn ń lọ, Jesu ṣe bí ẹni pé ó fẹ́ máa bá ìrìn àjò rẹ̀ lọ.
Lọdun 2019, awọn agbegbe bii Mile 12, Ketu, Owode, Oworoshoki ati Bariga ni ipinlẹ Eko lo kun fun ẹkun omi, ti ọpọ dukia si ṣofo lẹyin ti wọn ṣi daamu ọhun.
Mi o mọ ohun to lee fa aṣigbọ ati aṣitumọ yii."
Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí In pictures: Muslims around the world celebrate Eid The three-day festival marks the final day of Ramadan, a holy month of fasting in Islam.
Ìbánújẹ́ gbọkàn àwọn èèyàn nílé abílékọ ọlọ́mọ mẹ́ta tí wọ́n ṣẹ̀ṣẹ̀ pa ní Ibadan Bakan naa lo kede pe ile iwosan First Cardiologist Consultant, to jẹ ileewosan aladani tijọba fọwọsi lati maa tọju arun Covid-19, ni Ajimobi dakẹ si nibi to ti n gba itọju.
'Irọ́ ni o, àò pinnu láti kógbá Shoprite wọlé ní Nàìjíríà' Afẹ́fẹ́ Gáàsì tó rọra ń yọ́ọ́ jò pa Ajibola lẹ́nu iṣẹ́ jórin-jórin Coronavirus já wá sílẹ̀ ju ti àt'ẹ̀yìn wá lọ, kò ju èèyàn 288 tó kó o lọ́jọ́ Ajé Toun ti pe ẹka ofurufu ti bẹrẹ iṣẹ pada ni Naijiria ko yi nkan pada nitori pe ipalara ti ba ẹka naa eyi ti ko ni atunṣe.
Lọdun 2014 ti mo gbegba ibo gomina l'Ekiti lẹẹkeji ni mo ni iriri iwa ifiyajẹni awọn ọlọpaa,'' Fayemi lo sọ bẹẹ.
Ó ní, “N óo kó wọn kúrò lórí ilẹ̀ wọn; n óo sì kó àwọn ọmọ Juda kúrò láàrin wọn.
Dafidi bá rán àwọn oníṣẹ́ kan sí Iṣiboṣẹti, ọmọ Saulu, pé kí ó dá Mikali, aya òun, tí òun san ọgọrun-un awọ orí adọ̀dọ́ àwọn ará Filistia lé lórí pada fún òun.
Wọn pa Kudirat lasiko ti ijọba orilẹ-ede Naijiria labẹ iṣejọba ologun to fi ọkọ rẹ sẹwọn.
Bi ti ọkunrin lo wa n sọ ni tabi ti ara obinrin, awa o le pin in si isọri.
Ibadan Sallah Killing: Àwọn tó ṣojú wọn kòró bá BBC Yorùbá sọ̀rọ̀, Ọlọ́pàá fèsì
’’Minisita so pe nigba ti  awọn  n wa oruko ti wọn  yoo maa pe baalu orilẹ ede  yii,  awọn  gbe ipinnu wọn  sita lori ero ayelujara nipase ajo to n mojuto eto irinna , ni eyi ti opolopo  awọn  odo, omo ile-iwe ati omo orilẹ ede  yii bere si n fi erongba wọn  han sita.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, CUPP: JJ Ọmọjuwa sọ ohun tí ìdàpọ̀ àwọn ẹgbẹ́ yìí yóò jẹ́ Ajọ náà ní ẹni tó ba ti pe ọmọ ọgbọn ọdun kò lè ni ànfààní láti sìnrú ìlú bàbá rẹ̀.
Nítorí náà, bí a bá ti ji yín dìde pẹlu Kristi, ẹ máa lépa àwọn ohun tí ó wà lọ́run níbi tí Kristi wà, tí ó jókòó ní ọwọ́ ọ̀tún Ọlọrun.
Gomina ipinlẹ Yobe di ẹbi iṣẹlẹ Dapchi ru ileeṣẹ ologun
"A ti fẹẹ to laarin ọgbọn si ogoji obi ti a ti kan si bayii.
Ẹgbẹ oselu Peoples Democratic Party, PDP, ti tọrọ aforiji lọwọ aarẹ ana, Oloye Oluṣẹgun Ọbasanjọ lori iwa 'buruku ti wọn hu si.
“Ọlọrun, ranti pé afẹ́fẹ́ lásán ni mo jẹ́,ati pé ojú mi kò ní rí ohun rere mọ́.
Eyi waye lẹyin ti wọn gbọ pe ọkan lara awọn oniṣowo ọhun ti gun ẹnikan to n tẹle eegun lọbẹ.
Lẹyin naa lo rọ awọn ara ilu lati ma foya lori iroyin itankalẹ arun Coronavirus nitor ale bori arun naa ti a ba fọwọ sowọpọ.
Bakan naa ni wọn ke si ẹgbẹ oselu APC wi pe ki o ba adari rẹ sọrọ ko ye tẹnubọlẹ kiri mọ gẹgẹ bi agba.
Ó sì ṣe nígbà tí àwọn eniyan náà kó ara wọn jọ láti dojú kọ Mose ati Aaroni, wọn bojúwo ìhà Àgọ́ Àjọ, wọ́n sì rí i tí ìkùukùu bò ó, ògo OLUWA sì farahàn.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù APC: A kò ní takò ìdájọ ilé ẹjọ lórí àṣẹ lọ rọọ́kún nílé Oshiomole 4 Ẹrẹ̀nà 2020 Oríṣun àwòrán, Google Ọrọ aṣẹ lọrọọkun nile ti ile ẹjọ pa fun alaga ẹgbẹ oṣelu APC ma tun ti gba ọna mi yọ pẹlu bi Adams Oshiomole ti ṣe sọ pe ohun ṣi ni alaga ẹgbẹ naa.
– mo lọ fún yín o!
Saraki sọrọ di mimọ ninu atẹjade ti oluranwọ rẹ lori ọrọ iroyin, Yusuph Olaniyonu fi sita.
Bí mo ti jáde ni mò rí àwọn ẹranko méjì kan tí wọn jọ irúfẹ́ ẹṣin kan.
Igbaye-gbadunEmuekpere ni awon osise iko omo oju omi ni ile ti won n  gbe , ti awon si tun ti se atunse si awon ibugbe miiran  ni gbogbo agbegbe naa.
Àwọn atòràwọ̀ ayéijọ́un mọ Júpítérì, bẹ́ ẹ̀ sìni ó jẹ́ gbígbà nínú ẹ̀sìn àti àṣà àwọn ènìyàn ìgbà náà.
Ni bayii, ikọ naa ti pada wale pẹlu akọnimọọgba wọn, Gernort Rohr.
Nítorí nígbà tì mo bá jẹ́ aláìlera, nígbà náà ni mo di alágbára.
Nínú àlàyé Isaac Bamidele to jẹyọ lórí ayélujára, Isaac ni òun fi ilú Akurẹ silẹ̀ láti wa gba òtẹ́lìì sí agbègbè Mọniya ni ilú Ibadan pẹlú àwọn ọ̀rẹ́ òun kọọkan tí àlàyé sì ti wà lórí ǹkan ti ó fẹ́ wá ṣe.
Olumide Fusika ló bèrè lọ́wa Brig.
Ìjọba ìpinlẹ̀ Ondo ni ènìyàn mẹrindínlógun lo ti di olóógbé nípasẹ̀ àìsàn Ibà Lassa nígbà ti ènìyàn mẹ́rìnlélọ́gọ́rin tí ni ifarahàn àìsàn náà.
Gomina, eni to soro yii nibi ipade kan ni ijoba ibinle gusu ila-orun Esan pe, lara erongba ogbon atinuda ijoba lori eto ogbin ohun ni a ti ri: irinwo eeka ile fun gbingbin agbado ati ise-akanse eto osin-elede ni agbegbe ile-eko giga fafiti Ambrose Alli, ti o wa ni Ekpoma.
 Ókú ní osù kewá , ọjọ kẹr ̀ inlá , 1988 .
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù AMVCA7 2020: Funke Akindele, Toyin Abraham áti Yewande Famakin gba àmí ẹ̀yẹ 14 Ẹrẹ̀nà 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 15 Ẹrẹ̀nà 2020 Ayẹyẹ fifun awọn osere tiata lami ẹyẹ lati fi se koriya fun isẹ ti wọn n se lati ọdun kan sẹyin, eyiti African Magic se agbatẹru rẹ, lo si n ja rainrain nilẹ bayii.
Ibinu ọba dàbí bíbú kinniun,ẹni tí ó bá mú ọba bínú fi ẹ̀mí rẹ̀ wéwu.
Eyi waye lasiko ijiroro laarin oga agba ile –ise eso enu ibode lorile ede Naijiria Hameed I.
Àwọn baba wa jẹ mana ní aṣálẹ̀, sibẹ wọ́n kú.
Ai ni igbagbọ ninu ijọba Ṣe kii ṣe ọna lati gba ilẹ fawọn Fulani ni ijọba n wa pẹlu Ruga?
Awọn to ni ileesẹ to nii se pẹlu ohun ọgbin, isẹ́ agbẹ, ọ̀sìn ẹja, eto irinna, iwakusa ati bẹẹ bẹẹ lọ.
Wọn mu ẹjọ yi wa ni itako iyansipo Gomina Babajide Sanwo Olu ti ẹgbẹ APC.
Ṣugbọn Ọlọrun mú kí wọ́n gba ọ̀nà aṣálẹ̀, ní agbègbè Òkun Pupa, àwọn eniyan Israẹli sì jáde láti ilẹ̀ Ijipti pẹlu ìmúrasílẹ̀ ogun.
Ó ní, “Mo wá mọ̀ nítòótọ́ pé Oluwa ni ó rán angẹli rẹ̀ láti gbà mí lọ́wọ́ Hẹrọdu, ati láti yọ mí kúrò ninu ohun gbogbo tí àwọn Juu ti ń retí.
O ni, Mo fẹran bi a ṣe maa n fi iga gbaga, ṣugbọn mo buyi kun pupọ."
Ni bayii, Manchester City bo si oke tente tabili idije EPL latari esi ifesewonse yii pelu ami mọ́kàndínláàdọ́rùn ún(89point), ti iko agbaboolu Liverpool si tele won leyin pelu ami méjídínláàdọ́rùn ún(88point).
Kò sí ìyàtọ̀ lójú rẹ̀,nítorí náà ni mo fi wí pé,ati ẹlẹ́bi ati aláìlẹ́bi ni ó ti parun.
igbakeji oludari eto – Ogagun Gambo and Mr.
Wọn ko awọn oṣiṣẹ alaabo kuro lọdọ awọn aṣofin Ninu oṣu Kẹfa, 2018, ariyanjiyan kan tun waye lori bi wọn ṣe n pin awọn oṣiṣẹ alaabo fun awọn to di ipo oṣelu mu, eyi to mu ki ajọ DSS ko ida marundinlọgọta awọn oṣiṣẹ alaabo kuro lọdọ awọn awọn olori ile aṣofin.
Bẹ́ẹ̀ náà ni òṣere náà ti kọ́kọ́ ṣe iṣẹ́ ní iléeṣẹ́ amóhùnmáwòran NTA láì gba owó.
Snake Market: Àwọn òńtàjà ní àwọn ń sin ejò fún títà ni, wọn kìí ko nínú igbó
Gbogbo àwọn ọ̀rẹ́ rẹ̀ ti dà á,wọ́n dìtẹ̀ mọ́ ọn,wọ́n sì di ọ̀tá rẹ̀.
“A ni lara awon agbaboolu ti o ni ibasepo ti o da yato pelu orile-ede Russia.
“Oluwa Ọlọrun wa, ìwọ ni ó tọ́ sí láti gba ògo, ati ọlá ati agbára.
Loju awọn kan bii Chijoke, o n beere irufẹ ọla ati ọna ibanikẹdun wo ni Buhari n ṣe lẹyin to jẹ pe oun lo gba ijọba lọwọ Shagari pe: Oríṣun àwòrán, @Shagariofficial Àkọlé àwòrán, Okú Sheu Shagari ti wọn káà ill sùn ní ìlú Shagari Sokoto Loju àwọn ọmọ Naijiria mii, ni ṣe lo yẹ ki Buhari kọkọ tọrọ aforijin lọwọ Shagari ati Ekwueme to fagidi gba ijọba lọwọ wọn ni 1984.
“Sọ fún àwọn eniyan náà kí wọ́n kúrò ní agbègbè àgọ́ àwọn Kora ati Datani ati Abiramu.
"Kakanfo tumọ sii 'ka-ka-ka-nii-fo' Awọn ọrọ wọnyii ni awọn onimọ nipa itan ni a so pọ lati mu orukọ oye nla yii, ""Aarẹ ọna kakanfo"" Asiko alaafin Ajagbo si ni itan sọ wipe a ti kọkọ loo."
Sally Pearson omo bibi orile-ede Australia, ti o tun je olukopa ti o darajulo lagbaye ninu ere sisa hurdles, ni koni tesiwaju ninu idije Commonwealth Games to n lo lowo latari ifarapa ti o ni lese, leyi ti o si mu yeba kikopa ninu ere-idaraya ohun fun odun kan.
Dafidi ati àwọn eniyan ń fi tagbára-tagbára jó níwájú Ọlọrun, pẹlu orin ati àwọn ohun èlò orin: dùùrù, hapu, ìlù, Kimbali ati fèrè.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Buhari gbọ Faari 4 Ẹrẹ̀nà 2018 Oríṣun àwòrán, @MBuhari Àkọlé àwòrán, Buhari gbọ faari Fun ọpọ to n fi oju arugbo ti ko gbọ faari wo Aarẹ Muhammadu Buhari, Aarẹ Buhari niyi ni oko rẹ nilu Daura nibi to ti wọ bata ọsọ igbalode trainers lọ si oko rẹ.
WBC title: Deontay Wilder lu Dominic Breazeale bí ẹni lu bàrà láti di ìgbánú ẹ̀yẹ WBC mú
Bí ó bá pa mí, a óo di ẹrú yín.
"Oríṣun àwòrán, @APC ""Ẹgbẹ tiwa kii ya owo sọtọ fun awọn janduku."
Pasitọ kan naa ba BBC Yoruba sọrọ lori iha ti ẹsin Kristẹni kọ si ọrs akudaaya.
Ọrọ yii jẹyọ ninu faki-n-fa to n waye bayii laarin ileesẹ awakọ baluu, Executive Jet ati ijsba apapọ lori bi gbajugbaja akọrin takasufe ni Naira Marley ṣe farahan ni ilu Abuja nibi to ti lọ kọ orin ni ile ijo kan, to si jẹ pe ijọba apapọ ati ijọba akoso ilu Abuja paapaa ko tii fi aye silẹ fun ipejọpọ ọlọpọ ero eleyi to si ti da spọlọpọ awuyewuye silẹ kakiri orilẹede Naijiria.
Èyí ni kò jẹ́ kí ìmọ́lẹ̀ ìyìn rere Kristi, tí ó lógo, kí ó tàn sí wọn lára; àní, Kristi tíí ṣe àwòrán Ọlọrun.
Àwọn wọnyi ni ìdílé Aaroni ati ti Mose, nígbà tí OLUWA bá Mose sọ̀rọ̀ ní orí òkè Sinai.
Ní gbogbo ọdún mẹẹdọgbọn náà, ọba Olagbegi jà fitafita láti padà sórí ìtẹ́, ó lọ sílè ẹjọ́, ó kọ̀wé ẹ̀sùn lorisirisi, tó sì yọjú síwájú igbimọ oluwadii ni àìmọye ìgbà, àmọ́ síbẹ̀-síbẹ̀, pàbó ni gbogbo aayan rẹ ọhun jásí.
Ogbeni James Akinjobi to je adari ile ise ijoba apapo to n mojuto isele pajawiri ni Naijiria, NEMA, to saaju iko to lo sabewo naa nipinle Kaduna lo so eyi di mimo ni Kafancha lasiko ti won n se abewo naa.
Wọn gba pe orukọ ọmọ lo máa n ro ọmọ.
Iyalẹnu lo jẹ fun awọn ololufẹ wọn, nitori pe ko si adehun ifẹ laarin awọn mejeeji.
Àwọn òńkọ̀wé ń dárò Okediji tí kò bá pé ẹni ọdún 90 lókè eèpẹ̀ lónìí 1) O le ku lati ọwọ Oloogbe Ọjọgbọn Akinwumi Orojide Iṣola.
Àwọn Gómínà ẹgbẹ́ òṣèlú Peoples Democratic Party, PDP náà ti bẹ̀rẹ̀ sí kí olùdíje ẹgbẹ́ alátakò, Kayode Fayemi kú àṣeyọrí àbájáde ìdìbò ìpínlẹ̀ Ekiti gẹ́gẹ́ bíi gómìnà.
Lẹhin ti Ọbabinrin Elizabeth keji gun ori oyè ni ọdún mẹtalelọgọta sẹhin, ó bẹ ilú Èkó wò ni ọgọta ọdún sẹhin, nigbati Ilú Èkó jẹ́ Olú-Ilú orilẹ̀ èdè Nigeria ki a tó gba Òminira lábẹ́ Ilú-Ọba ni odun Ẹdẹgbaalelọgọta.
Eyi to tun ṣẹṣẹ jẹ tuntun laarin wọn ni igba ti gomina Makinde n fesi si abajade ẹsun ti ajọ to n ri si iwa jẹgudujẹra, EFCC fi kan Ayo Fayose ti Makinde ni ko si ohunkohun ti Fayose i baa ṣe lori ẹjọ yii, ẹwọn ni yoo lọ gbẹyin.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Aarẹ sọ pe Saraki ati Dogara ko ni ifẹ Naijiria lọkan, ni wọn ṣe mu idiwọ ba aba iṣuna fun oṣu meje.
Orúkọ Heburoni tẹ́lẹ̀ ni Kiriati Ariba, (tí a tún ń pè ní ìlú Ariba), Ariba yìí ni baba Anaki.
Wọ́n ń pẹ̀gàn eniyan, wọ́n ń sọ̀rọ̀ pẹlu ìlara;wọ́n sì ń fi ìgbéraga halẹ̀.
Leyin ti Jonathan dibo tan, o fi idunnu re han bi eto idibo naa
Ènìyàn 653 míràn tún kún iye àwọn tó ní COVID-19 ní Nàìjíríà Aàrẹ Buhari buwọlu yíyí orùkó àwọn ibùdókọ ọkọ ojú ìrìn bíi ti Apapa padà fi sọrí àwọn èèkàn ìlú 'kò sí ẹ̀rí àrídájú níńu ọ̀rọ̀ Akpabio' Nibayii eeyan 860 lo ti ṣe alaisi nipasẹ ajakalẹ arun naa lorilẹede Naijiria.
"Àkọlé àwòrán, Aarẹ Muhammadu Buhari ṣe ileri atilẹyin fun idagbasoke aṣa Àkọlé àwòrán, Ọna abawọle si ori oke olumọ Oríṣun àwòrán, AfricanDrumFestival Àkọlé àwòrán, ""Kani a mọ pataki idagbasoke aṣa si idagbasoke eto ọrọ aje wa, a o tẹpa mọ"" Oríṣun àwòrán, AfricanDrumFestival Àkọlé àwòrán, Ó lé ní ogún ìpínlẹ̀ tí yóò kópa níbi ayẹyẹ àjọ̀dùn ìlù nílẹ̀ Áfíríkà náà Oríṣun àwòrán, AFRICAN DRUM FESTIVAL Àkọlé àwòrán, Ijọba ipinlẹ Ogun lo n ṣe agbatẹru ajọdun ilu ilẹ Afirika Oríṣun àwòrán, AfricanDrumFestival Àkọlé àwòrán, Awọn ọbalaye kan sara si awọn agbaṣaga Oríṣun àwòrán, AfricanDrumFestival Àkọlé àwòrán, Àgba awọn to wa nipo aṣẹ lẹka iṣejọba gbogbo niyanju lati rii wei pe wọn n ṣe koriya fun igbedide aṣa ilẹ Yoruba."
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Champions League: Ẹ ò ní dúró!
 Ronaldo, omo odun mẹ́rìnlélọ́gbọ̀n ohun kopa ribi-ribi ninu ifesewonse naa, leyin ti o ran iko re lowo lati fagbahan Atletico Madrid pelu ami-ayo meta sodo(3-0)   Ni bayii, Ronaldo yoo kopa ninu ifesewonse ese akoko ti iko re Juventus yoo gba pelu iko agbaboolu Ajax lojo kewa osu kerin odun ti a wayii.
Ta ni olóògbé Jerry Rawlings, tó darí Ghana fún ogún ọdún?
Fun awọn ti ilera wọn ba ti dẹnukọlẹ pupọ, wọn yoo lo fẹntilatọ lati fi gbe eemi wọ inu ẹdọfooro wọn ni taara lati ẹnu, imu tabi iho kekere ti wọn ba lu ni ọfun ẹni naa.
12 Nítorí, njẹ́ ìwọ kò kíyèsíi pé mo ti fun ìránṣẹ mi Joseph ní ànító okun, nípa èyí tí àlàfo náà dí?
Oríṣun àwòrán, @NhisNg Àkọlé àwòrán, Kí ló dé tí Ààrẹ Buhari tún ń dá àwọn tó fúnrarẹ̀ yọ nípò pàdà Usman Yusuf, oludari agba ileeṣẹ adojutofo ilera, NHIS Lẹyin ọpọlọpọ iwadii si awọn ẹsun iwa aṣemaṣe ti wọn fi kan an ni minisita feto ilera nigba naa, Ọjọgbọn Isaac Adewọle yọ Usman Yusuf nipo gẹgẹ bii akọwe agba ileeṣẹ adojutofo ilera, NHIS.
O fi oro naa mule pe, lara awon omo ogun olote naa, ti oruko re n je Ibrahim  Lawal ni won gba ibon AK 47 ati iwe iroyin meji ti aworan opolopo ohun ija ogun wa lara re.
Ìwọ kò kó ohun ti Ọlọrun lékàn àfi ti ayé.
Kàkà kí ó jẹ, òwe ló tún pa.
O ni lootọ ni ikọ SARS ti arabinrin naa mọle lawọn akoko kan ni ọdun 2018 ṣugbọn ko si eyikeyi arakunrin rẹ kankan ti ikọ naa pa.
Bakan naa, ninu ọrọ tirẹ, Afọlabi Ọlalekan to ni oun jẹ ọkan lara awọn akẹkọ to lọ si ileewe kan naa pẹlu oloogbe naa ṣalaye pe, eeyan ti o fẹran lati maa saapọn fun igbayegbadun awọn eeyan to ba wa ni ayika r ni Djxgee jẹ.
Igbimo amusese ijoba ti fenuko lojo-Ru ojo kerinla osu kerin odun 2018 ninu ipade pe, ki Aare fowosi adehun ifenuko naa.
"Ko si nnkankan to ṣe iya yii nibẹ.
Ọba sì ti sọ pé ẹni tí ó bá lè pa á yóo gba ẹ̀bùn lọpọlọpọ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù EFCC: Ibrahim Magu ní ìwá ìbàjẹ́ ló fa Coronavirus 19 Èrèlè 2020 Oríṣun àwòrán, Efcc/Facebook Àkọlé àwòrán, Àrùn Coronavirus bẹ́ sílẹ̀ lórílẹ̀èdè China níbi tí ó ti pa ènìyàn tó lé ní 2,000 ní ilẹ̀ náà.
Sibẹsibẹ àwọn ọmọ Israẹli kò pada sí ọ̀dọ̀ ẹni tí ó jẹ wọ́n níyà,bẹ́ẹ̀ ni wọn kò wá OLUWA àwọn ọmọ-ogun.
 Ninu ifọrọwanilẹnuwo kan ti iwe iroyin The Nation ṣe fun, Olori Folashade sọ pe, lasiko ti oun wa nileewe olukọni Emmanuel Alayande College of Education, ni oun bẹrẹ irinajo ifẹ pẹlu iku baba yeye, alaṣẹ ekeji orisa."
 Barau Jibril-Maliya, Asofin Kabir Gaya ati oluranlowo agba fun Aare Muhammadu Buhari lori oro awon omo ile igbimo asofin, Alhaji Abdurrahman Kawu Sumaila atawon miran.
Gegẹ bi ohun ti ikọ Save-A-Soul sọ, orileede Naijiria laaye ti gba tita oogun ayederu ju lọ.
Taa ni Ọọni àná tí Ọba Ogunwusi forúkọ ọmọ rẹ̀ sọ?
awon omo orile-ede Naijiria lati fiyin fun Olorun fun ebun emi gigun ti o fi
Àwọn ọmọ Iyabọ Ojo rí Bàbá lẹ́yìn ọdún mẹ́fà Mo ti fọ́ bàbá mi, Ọ̀gá Bello létí rí - Fẹmi Adebayọ̀ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Wòlíì Àrólé sọ àsọtẹ́lẹ̀ s'áyé BBC ní London Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
“Ẹ̀yin aláìmọ̀kan, ẹ óo ti pẹ́ tó ninu àìmọ̀kan yín?
Ṣugbọn ori gbe Dapọ de ibi giga, eyi to ju ipo kọja ero rẹ, nigba to dije wọle bii gomina lọdun 2019, to si jawe olubori gẹgẹ bii gomina tuntun fun ipinlẹ Ogun labẹ asia ẹgbẹ oṣelu APC.
Ninu atẹjade kan ti akọwe ẹgbẹ naa, Yinka Odumakin fi sita, ẹgbẹ Afenifere ni awọn gbawọn aṣofin lamọran yii lẹyin ti wọn ranṣẹ si awọn lati kopa ninu eto atunṣe iwe ofin Naijiria ti ọdun 1999 ti a n lo lọwọ.
Òwe Nípa Àwọn Ẹyẹ Idì ati Àjàrà.
Ààrẹ Trump ti bura wọlé fún adajọ náà ni White House, to wa ni ilu Washington DC.
Maalu ko jẹ ki baalu balẹ l'Akurẹ Ọrẹ Tiffani, Deanna Noel-Dale lo fi sita pe, ori ko ọrẹ oun yọ.
Ogbeni Mohammed tun kan si ogba ile-iwosan ijoba apapo ati ile-iwosan fafiti to wa ni Ilorin ,nibi ti awon eniyan to farapa nibi ikolu naa ti n gba itoju.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Tomomewo Favour: olóṣèlú kìí ṣe ọ̀daràn tàbí alágbèrè O ni ti ile ẹjọ ba fi aaye gba ẹgbẹ PDP, eyi tumọ si pe 'wọn ti gba pe oju opo ayelujara apapọ kan wa ti gbogbo esi idibo ọjọ kẹtalelogun, oṣu Keji wa.
Ewe, ninu oro ti agbenusoro ajo naa Ademola  Olajire so,”Mgbolu sise gege bi agbenusoro ajo (NFA) fun saa 1993 si 2001.
N óo rú ẹbọ ọpẹ́ sí ọ,n óo sì pe orúkọ rẹ OLUWA.
Ewe, ki Oloogbe Worlu o to di asoju sorile-ede Sao Tome, o ti fi igba kan je komisona agba si orile-ede India.
''Buhari, fi kùráànì búra lórí èsì WAEC rẹ'' Èrò àwọn ọmọ Nàìjíríà ṣọ̀tọ̀ọ̀tọ̀ lóri oúnjẹ #3.
Ní bayìí èèyàn ẹgbẹ̀run mẹ́rin din díẹ̀ (3912) lo ti lùgbàdì à[rùn Coronavirus ní Nàìjíríà.
Ṣugbọn Ẹsita kò sọ fún ẹnikẹ́ni nípa ẹ̀yà rẹ̀ ati àwọn eniyan rẹ̀, gẹ́gẹ́ bí Modekai ti pàṣẹ fún un, nítorí ó gbọ́ràn sí Modekai lẹ́nu, gẹ́gẹ́ bí ó ti ń ṣe nígbà tí ó wà lábẹ́ ìtọ́jú rẹ̀.
Jesu dá wọn lóhùn pé, “Ẹ ti ṣìnà patapata!
Àwọn ará Siria sì ṣá Joramu lọ́gbẹ́ lójú ogun náà, 
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ọkọ̀ Awólọ́wọ̀ yìí ti lọ yíká Nàíjíríà Ninu ọrọ ti o ba awọn oniroyin sọ lẹyin ipade ti o waye ninu ọgba fasiti ilẹ Ibadan, ọkan lara awọn oluranlọwọ fun gomina ipinlẹ Ọyọ, Ẹniọwọ Idowu Ogedengbe ṣe alaye pe lara awọn oniṣegun ibilẹ naa ti ni itọwo awọn ogun ti wọn popọ.
Kí ó sọ̀kalẹ̀ nisinsinyii láti orí agbelebu, a óo gbà á gbọ́.
Eyi ri bẹẹ nitori pe bayii, orilẹede Amẹrika ti ni lara awọn ohun amuyẹ ti oun yoo maa beere lọwọ awọn to ba fẹ gba iwe aṣẹ irinna silẹ okeere ni iroyin nipa oju opo wọn lori ikanni ayelujara Facebook, twitter atawọn miran.
Ọpọ ni yoo si ro pe, bi ile ẹjọ ṣe kede idajọ yii, ṣe ni Adeleke yoo ko ẹru ti yoo si kọri si ile ijọba ni Oṣogbo lati lọ gba ipo rẹ lọwọ Gboyega Oyetọla ti ẹgbẹ oṣelu APC ti ajọ eleto idibo INEC ti kọkọ kede gẹgẹ bii gomina.
 Wọn ni ede Yoruba ti kuro ni ede kekere, ti ẹnikan le fọwọ rọ sẹyin lagbaaye, pe bi ede yii ṣe gbajumọ ni orilẹ-ede Cuba, Brazil, bẹẹ ni wọn n sọ ọ ni ọpọ orilẹ-ede ni ilẹ Europe.
Adele aare orile ede Naijiria lo pase fun oga olopaa lati ri I pe ki eka tuntun naa maa ri si gbigbogun ti iwa odaran,igbesunmomi ati awon esun miiran.
Ṣé Elieseri ará Damasku yìí ni yóo jẹ́ àrólé mi ni?
Gẹgẹ bi ohun ti a ri ka ninu atẹjade kan tioludari eto ifọrọto ara ilu leti ati idanilẹkọ awọn oludibo Festus Okoye buwọlu,Inec ni awọn fi idi ọrọ mulẹ pe idibo waye ni pupọ ninu awọn agọ idibo ti awọn si kede esi wọn.
 wọ ́ n yẹ ọkọ ̀ yìí wò ní oṣù keje ọdún 1989 , wọ ́ n sì tún máa yẹ ̀ ẹ ́ wò ní oṣù keje .
Nítorí náà ẹ fi ìfẹ́ yín hàn sí wọn.
Gbogbo ìdájọ dá lórí irú ẹ̀ṣẹ tí ènìyàn bá ṣẹ̀.
O salaye pe, erongba ati so atagba aarun HIV latara iya si omo lorile-ede Naijiria yoo yorisi rere.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ẹni to ni ile iwe sare lati doola awọn akẹkọ ni ile wolu Ko pẹ si igba naa, ni ile miran tun dawo ni adugbo Egerton Square, Oke Arin ni Isale Eko kannna.
Mo lóbìnrin tó bímọ fún mi, ṣùgbọ́n ọ̀rọ̀ ìyàwó kò tíì yọ fún mi báyìí-Pasuma Ìjọba àríwá Italy fẹ́ dé èèyàn 16 mílíọ̀nù mọ́lé lórí àrùn Coronavirus Odunlade fẹ́ j'ọba, Bolanle Ninalowo fun ìyàwó rẹ̀ ni ẹ̀bun kanka, Pá Kasumu rebi àgbà ree 4.
Odunlade Adekola, Femi Adebayo, Jenifa ṣi aṣọ lójú àwọn fíìmù tuntun tẹ́ẹ ti ń retí Awọn ẹgbẹ osisẹ naa ni awọn yoo gun le iwọde lati tako ele owo ori epo naa, bẹẹ ni awọn ti n se koriya ati itaniji fawọn osisẹ lati kopa ninu iwọde naa.
Obinrin miran sọ pe 'ooyi lo maa n kọ oun nigba gbogbo, ti oun ko si le rin daadaa'.
Ó bẹ̀rẹ̀ sí pa wọ́n láti Aroeri títí dé agbègbè Miniti tí ó fi wọ Abeli Keramimu.
 Osinbajo ni, o da oun loju pé APC lo maa wọle ti oun ati
Aare ati iyawo re ni eni akọkọ
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Mr Macaroni sọ nípa eré tí Fraky freaky, Sugar Daddy, You are doing well, freaky spicy fẹ́ Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Ibadan Divorce: Abílékọ Idowu faraya ní kóòtù kọkọ-kọkọ n'Ibadan, Ó ní òun ò leè pín ọkọ òun pẹ̀lú ẹnikẹ́ni18 Ògún 2020 Olusegun Obasanjo sọ̀rọ̀ síta pé ọpẹ́lọpẹ́ Walter Carrington láyé òun nígbà tí Sani Abacha ń lé òun kíri18 Ògún 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Oyo fun odun 2000, (Section 22 (2) of the chief’s law, cap 28 of Oyo State
Ninu lẹta rẹ, o pari rẹ pe ki wọn sin ohun ni kete ti wọn ba ti rii pe oun ku.
Wumi Toriola gbeyawo lọdun 2018 pẹlu ọkọ rẹ to n gbe nilẹ okeere wọn si ti ni ọmọ ọkunrin ninu oṣu kẹwaa, ọdun 2019.
''Nigba myi yoo ba ọkan jẹ, nigba mii ara rẹ yoo ya si wa ti a ba fun un ni iroyin bi ẹjọ rẹ ṣe n lọ si'' Deji Adenuga tó jó èèyàn mẹ́sàn-án mọ́lé bọ́ sọ́wọ́ Ọlọ́pàá Nítorí Sẹ́nétọ̀ Adeleke, ìyá àti ọmọ gbé iléeṣẹ́ ọlọ́pàá lọ sílé ẹjọ́ Game of Thrones tàbí Ìrèké Oníbùdó, èwo lẹ dìbò fún?
Ta ni ọba náà láyó yìí tí ó lè fi ọwọ sọ àyà pé ìlú òun dárá bí ìlú mi?
Ilé ẹjọ́ kéde Ademọla Adeleke gẹ́gẹ́ bíi gómìnà ìpínlẹ̀ Ọṣun Ademọla Adeleke, Fayoṣe, Atiku sọ̀rọ̀ lórí ìdájọ́ ilé ẹjọ́ Ijọba ipinlẹ Ọṣun wa rọ awọn eeyan ipinlẹ naa lati maa ba iṣẹ oojọ wọn lọ lai da omi alaafia ilu laamu.
Ilé ẹjọ́ kòtẹ́mílọ́rùn yọ alága ẹgbẹ́ òṣèlú APC Adams Oshiomhole nípò Alága méjì láàrín ọjọ́ kan, sinimá oríta láàrín àwọn adarí APC Ǹkan mẹ́jọ tó máa kọ́kọ́ ṣẹlẹ̀ kí olólùfẹ́ méjì tó pa ara wọn Ìdílé márùn-ún tó gbajúmọ̀ fún òwò ẹrú nílẹ̀ Yorùbá Nnkan ti a mọ nipa Dan Foster Daniel Foster ti wọn maa n pe ni Dan Foster jẹ sọrọ-sọrọ lori redio to jẹ ọmọ orilẹedẹ Amerika to n gbe ni Nijiria.
Kódà, Ojerinde tún pàdánù àwọn ìpín idokowo àti ọ̀pọ̀ owó goboi tó ní làwọn ilé ifowopamo sí ọwọ àjọ ICPC.
Ayọ̀ ń bẹ fun ẹni tí apó rẹ̀ kún fún wọn.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Daniel Lewis Lee, ẹni àkọ́kọ́ tí wọ́n yóò yẹgi fún ní US lẹ́yìn ìdádúró ọdún 17 13 Agẹmo 2020 Oríṣun àwòrán, AFP Fun igba akọkọ lati ọdun mẹtadinlogun, orilẹ-ede America yoo yẹgi fun awọn ọ̀daràn kan ni Indiana lọjọ Aje.
Ṣugbọn nínà ni wọ́n nà án, wọ́n bá lé e pada ní ọwọ́ òfo.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Donald Trump ti gúnlẹ̀ sí UK fún àbẹ̀wò ọlọ́jọ́ mẹ́ta 3 Òkùdu 2019 Àkọlé àwòrán, Trump ti gbé òdòdó ìrántí sójú oórì akọni lójú ìjà Lojo Iṣẹgun ni ipade aarẹ Trump ati Theresa May yoo bẹrẹ.
Ogbeh ní tí Naijiria kò bá jáfara, irẹsì náà yóò wọnú orílẹ̀ède yí láti ẹnu ibodè.
com/9zdZ9MP8TQOgagun Daramola sapejuwe ise akanse naa gege bi irure akoko ti yoo gunle si eka ila oorun orile-ede Naijiria, eleyi ti o si waye lati ri daju pe awon omo ogun ohunati molebi won yoo lanfaani si ile-iwosan ti o peye.
Bí o bá ń dẹ́ṣẹ̀, má dẹ́ṣẹ̀ mọ́,má sì ṣe jẹ́ kí ìwà burúkú, wà ní ọwọ́ rẹ.
Pataki laarin awọn eeyan ti arun yii ti da bira ninu igbe aye wọn ati ọna ajọṣepọ wọn ni awọn eeyan orilẹede Italy.
Iye awọn eniyan to ku ninu ijamba ọkọ ofurufu Ukraine Ọmọ Ilẹ Iran mejilelọgọrin(82) Ọmọ Ilẹ Canada mẹtalelọgọrin (63) Ọmọ ilẹ Ukraine mọkanla ati gbogbo awọn oṣiṣẹ ọkọ (11) Ọmọ Ilẹ Sweden mẹwaa (10) Ọmọ Ilẹ Afganistan mẹrin (4) Ọmọ Ilẹ Germany mẹta (3) Ọmọ Ilẹ Gẹẹsi mẹta (3) Njẹ́ ẹ mọ̀ pé 'orílẹ̀èdè Nàìjíríà n wo 'Blue film' jù?
Báyìí ni àwọn ọmọ Israẹli ṣe da ara wọn pọ̀ mọ́ oriṣa Baali tí ó wà ní Peori, ibinu OLUWA sì ru sí wọn.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ijọba ti da awọn olori ileesẹ́ alaabo atawọn osisẹ wọn sipinlẹ Yobe lati se awari awọn akẹkọ Dapchi Wakil, ẹni to maa nkan si ikọ Boko haram atawọn asaaju rẹ kede pe oun setan lati fi ẹmi ara oun lelẹ lati doola ẹmi awọn ọmọ Dapchi naa.
Ọọni Ile ifẹ́, Ọba Adeyẹye Ẹnitan Ogunwusi, Ọjaja keji ni, ko yẹ ka maa foju tẹ́mbẹ́lu awọn obinrin lawujọ̀, toripe wọ̀n n se bẹbẹ lati to ẹbi ati ilu wa.
Ọlọpàá mú ọ̀rẹ́kùnrin Matilda akékọ̀ọ́ fasiti ìpínlẹ̀ Rivers ti wọ́n gún pa Makinde kò gbé àjọ ìwà ìbàjẹ́ kalẹ̀ torí ìfẹ́ aráàlú, ó ń fẹjú mọ́ alátakò ni - Ọmọ ẹgbẹ́ APC Ìdí tí Oluwo fi kọ Olorì rẹ̀ sílẹ̀ rèé China o, Nàìjíríà o, kò s'áyè òwò mọ́ ní Ghana!
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Yoruba World Congress: Mi o fi gbogbo ẹnu sọ pé ẹ̀yà Yorùbá yóò tún èrò rẹ̀ pa ní October 1- Akintoye 1 Owewe 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 28 Owewe 2020 Oríṣun àwòrán, @thesignalng Aarẹ ẹgbẹ ọmọ Yoruba l'agbaye, Ọjọgbọn Banji Akintoye ti sọ pe oun ko lọwọ si lilo ipá tabi agidi fi ya kuro lorilẹ-ede Naijiria gẹgẹ bi ẹya Yoruba.
Ẹ̀bùn OLUWA ni ọmọ;òun ní fi oyún inú ṣìkẹ́ eniyan.
CAN: Samson ni ọrọ awọn ajinigbe ti gba àpérò ní Naijiria
Biola Alabi lolootu ere naa nigba ti Tosin Coker dari ẹ.
“Bí ẹnìkan bá dáná, tí iná náà bá ràn mọ́ koríko, tí ó bá jó oko olóko, tí ó sì jó ọkà tí wọ́n ti kórè jọ tabi tí ó wà lóòró, olúwarẹ̀ gbọdọ̀ san òmíràn pada fún olóko.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Orileede Cameroon lo gba ami ẹyẹ Afcon 2017 ṣugbọn wọn kuna lati gbalejo idije 2019 Orileede Ivory Coast to yẹ ki wọn gbalejo idije 2021 ko faramọ igbesẹ yi ti wọn si ti gbe ọrọ naa lọ si iwaju ile ẹjọ to n pẹtu saawọ to niṣe pẹlu ere idaraya.
Wo àwọn olorì àgbà mẹ́rin tí Aláàfin ń wárí fún Koda, awọn iroyin kan ti a ko le lee fidi rẹ mulẹ ni Alaafin ti le olori ọhun jade kuro ninu aafin rẹ.
Ààrẹ Buhari: Irọ́ ni pé Leah Sharibu ti kú sí àhámọ́ Boko Haram
Oríṣun àwòrán, Seyi makinde Ninu ọrọ to fi si oju opo Twitter rẹ, Gomina Ṣeyi Makinde ni oun mọ riri adura atilẹyin ati adura awọn eeyan ipinlẹ Ọyọ lasiko ti oun fi wa ni igbele iyasọtọ fun itọju arun naa.
Ó bá sọ fún àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ pé kí wọn tọ́jú ọkọ̀ ojú omi kan sí ìtòsí nítorí àwọn eniyan, kí wọn má baà fún un pa.
“Bọ̀wọ̀ fún baba ati ìyá rẹ, kí ẹ̀mí rẹ lè gùn lórí ilẹ̀ tí èmi OLUWA Ọlọrun rẹ fi fún ọ.
"‘Ẹ maa kọ ọmọ yin l'ede Yoruba’ ""Mo fẹ́ pa ara mi torí ojú àbùkù tí wọn ń fi wò mí pé mo fi iṣẹ́ abẹ bímọ"" Èyí ni ojú ọ̀nà àrèmabọ̀ fáwọn ẹrú ní Badagry Awọn obi ati alagbatọ agbegbe yii mẹnuba bi ẹru ṣe maa n ba wọn nigba gbogbo ti awọn ọmọ wọn ba n lọ sile iwe."
A óo kó agbo ẹran wọn lọ tọmọtọmọ, ibùjẹ àwọn ẹran wọn yóo parun nítorí tiwọn.
nítorí bí ẹlẹ́ran-ara ni ẹ̀ ń hùwà sibẹ.
“Àpẹrẹ Ẹrú ati Owó Àna fún Ìtọrọ Iyàwó ni Idilé Arinmájàgbẹ̀” 
Máa gbọ́ ẹ̀bẹ̀ iranṣẹ rẹ ati adura àwọn ọmọ Israẹli, eniyan rẹ, nígbà tí wọ́n bá kọjú sí ilé yìí, tí wọ́n sì gbadura, máa gbọ́ tiwa láti ibùgbé rẹ lọ́run, kí o sì máa dáríjì wá.
Àwọn ọmọ Manase kò lé àwọn ará ìlú Beti Ṣeani ati àwọn ará Taanaki jáde, ati àwọn ará Dori, àwọn ará Ibileamu, àwọn ará Megido ati àwọn tí wọn ń gbé gbogbo àwọn ìletò tí ó wà ní àyíká àwọn ìlú náà; ṣugbọn àwọn ará Kenaani ṣì ń gbé ilẹ̀ náà.
Kí ẹ̀san pípa tí Abimeleki pa àwọn aadọrin ọmọ baba rẹ̀ ati ẹ̀jẹ̀ wọn lè wá sórí Abimeleki, ati àwọn ará ìlú Ṣekemu tí wọ́n kì í láyà láti pa wọ́n.
O ni ijọba ti ṣeto to mọyan lori lati gbe Sanusi lọ si ibugbe rẹ tuntun lai si ifoya.
Wajir Women Rep Fatuma Gedi allegedly assaulted inside parliament buildings by Rashid Kassim Mp Wajir East.
Ìwà Eri burú tóbẹ́ẹ̀ tí Ọlọrun fi pa á.
Lẹyin to pada de, ni Odumosu n lọ sawọn ijọ ajihinrere igbalode kaakiri, to si ti ipa ibẹ di aríran ati alálàá, o ni oun ni Olugbala ran wa gba aye la, to si bẹrẹ isẹ iransẹ rẹ nipa sise isin irọlẹ ninu sọọbu rẹ Ni igba ti Odumosu bẹrẹ isẹ iransẹ rẹ lọdun 1952, iwaasu kiko ara ẹni nijanu, iwa ọmọluabi ati irẹlẹ lo fi bẹrẹ, ti ijọ rẹ si n gbooro lagbegbe erekusu Eko, Lagos Island, to si ni ki awọn eeyan kọ ọti ati siga mimu pẹlu obinrin kiko silẹ, ti ọmọ ijọ rẹ si to ọgbọn lọdun 1954 Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Èmi gan máa ń béèrè lọ́wọ́ ara mi pé ta ni Wole Soyinka gangan' Lasiko yii, Odumosu maa n fi fun awọn alaini, to si tun maa n se koriya fawọn ọmọ ijọ lati maa fi ohun ini wọn silẹ fun itankalẹ ihinrere, ko si pẹ ti ọmọ ijọ tuntun kan fi fi ile rẹ kan silẹ, eyi to wa ni adugbo Ebute Meta nibi ti Odumosu lọ tẹdo si Odumosu rọ awọn ọmọ ijọ rẹ lati lọ gba ile si ẹba ijọ naa, ki wọn si fi ile ara wọn ti wọn n gbe silẹ, ki wọn si kede ọrọ ti wọn ni fun ijọ ninu eyi to ti n yọ idamẹwa, bẹẹ lo tun n gba owo ile lọwọ wọn.
Nítorí náà, nígbà tí mo bá parí ètò yìí, tí mo ti fi ọwọ́ ara mi fún wọn ní ohun tí a rí kójọ, n óo gba ọ̀dọ̀ yín kọjá sí Spania.
Nítorí náà, lọ sí ibi tí o farapamọ́ sí ní ìjelòó, kí o sì farapamọ́ sẹ́yìn àwọn òkúta ọ̀hún nnì.
Àwọn wọnyi ń jẹ àpọ̀jẹ lóòótọ́, ṣugbọn pátákò ẹsẹ̀ wọn kò là, nítorí náà, wọ́n jẹ́ aláìmọ́ fun yín.
Ẹ ti fi àwọn ohun ìríra yín ba majẹmu mi jẹ́.
Ijoba ipinle Enugu ti bere igbese gbigbe awon akosemose onisegun oyinbo merin merin lo si ile iwosan igberiko meje to wa nipinle naa ki eto ilera awon eniyan ipinle Enugu le gbe soke sii.
OLUWA Ọlọrun ní, “Ní ọjọ́ kinni oṣù kinni, ẹ pa ọ̀dọ́ akọ mààlúù kan tí kò ní àbààwọ́n, kí ẹ fi ṣe ìwẹ̀nùmọ́ ibi mímọ́.
O rọ ijọba apapọ lati gbiyanju lati ba wọn da si ọrọ naa ni kiakia nitori o ti n da ọrọ ojoojumọ.
Aare tun so pe “mo n yọ yin lẹnu nitori mo mọ ipo yin lawujo, ẹ si wa lati ekun to ni ipa pataki lawujo, ohun ti ẹ ba si sọ ni ipa pataki to n ko ni ẹkun yin”.
Moses wa lara ikọ to ba Naijiria gba ife ẹyẹ ti Afrika ni 2013, to dẹ tun kopa ni ife ẹyẹ Afrika to waye ni 2014 ati 2018.
Bí ẹ kò bá lé gbogbo wọn jáde, ohun tí mo ti pinnu láti ṣe sí wọn, ẹ̀yin ni n óo ṣe é sí.
Ọmọ-ìbílẹ̀ ìlú yìí ba rán an lọ sí oko rẹ̀ láti máa ṣe ìtọ́jú ẹlẹ́dẹ̀.
OLUWA, ṣebí láti ayérayé ni o ti wà?
Bákan náà ni Sanwo-Olu tún ni gbogbo ẹbí wọ́n ni yóò gba owó ìrànwọ́.
” Ará Kuṣi náà bá tẹríba fún Joabu, ó sì sáré lọ.
Atẹjade kan ti alukoro ajọ naa, Azeez Sani fi sita lọjọ Aiku ṣalaye pe niwọn igba ti lilọ bibọ ọkọ ti n fara gba ninu iwọde to n lọ kaakiri naa o ti ṣe idiwọ pẹlu fun awọn igbesẹ lati ko awọn ohun elo idanwo kaakiri lọ si ibi gbogbo to yẹ.
” O fikun oro re pe, o tun se pataki lati tun se atunse si ofin ati ilana iwe abadofin ti won fi sedasile ajo GIABA lojuna lati tun lanfaani le gbogun ti awon iwa-ibaje ti o ba kan ajo ECOWAS nile okere.
 onímọ ̀ ìṣirò ( mathematics ) ni .
AMAA 2018 Ami eye sinima ti won ya dara julo
Bi ọrọ naa ṣe kan ọmọde lo kan agba, bo ṣe kan irinajo okeere naa lo kan ile iwe atawọn ile ijọsin.
 Idanileko naa yoo waye ki odun yii ko to pari, nitori pe, a tun fe ki i awon akonimoogba wa tun  ni imo ijinle di e ninu ere idaraya naa,”Ewe, orile-ede Naijiria ko ni kopa ninu idije ere idaraya ohun ti yoo waye loril-ede Congo (African Women’s Handball Championship), lataari ofin ti  ajo to n mojuto boolu afowogba nile Afrika fi de Naijiria.
Oríṣun àwòrán, Instagram Àkọlé àwòrán, Ibrahim Yekini ti awọn eniyan ma n pe ni Itẹlẹ ni wọn bi ni ọjọ Kini, Osu Kini ọdun 1980 ni agbeegbe Bariga, ni ilu Eko.
Ero ayelujara ajo naa lojo-Bo nilu Abuja safihan pe, ina ti won pese lojoojumo ti le ni egberun lona ogorun megawasi ni ojo-kejo osu kejila odun 2017.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù INEC: Òpómúléró ni ASUU jẹ́ fún àṣeyọrí ìbò 2019 5 Sẹ́rẹ́ 2019 Oríṣun àwòrán, INEC Àkọlé àwòrán, ìfọ́wọ́sowọ́pọ̀ ASUU ló le jẹ́ kí ìdìbò wa ó kẹ́sẹjári Àwọn ọmọ ẹgbẹ́ ASUU ti gba láti kópa nínú ètò ìdìbò ọdún 2019.
”Aṣofi Ọbasa wa ṣe ileri pe Ile Igbimọ Aṣofin
O ni aye n wo iṣe aarẹ ti ọrọ naa si le fa wahala.
Chief Kanran ni kii ṣe pe mama Ẹfunṣetan Aniwura ko le e kopa ninu ere mọ, amọ awọn eniyan ni ko pe wọn si iṣẹ.
Ninu ija yii ni wọn ti sọ ọrọ kobakungbe sira wọn, ti inu si bi Bayewu debi pe o gbe gilaasi to fi n mu bia, to si la a mọ Ayinla Ọmọwura lori.
Elija dáhùn pé, “Ohun tí o bèèrè yìí ṣòro, ṣugbọn bí o bá rí mi nígbà tí wọ́n bá ń gbé mi lọ, o óo rí ohun tí o bèèrè gbà.
Oríṣun àwòrán, @Mainframe 2) Ogboju Ọdẹ Ninu Igbo Irunmọle lati ọwọ oloogbe Daniel Olorunfẹmi Fagunwa Oloogbe Daniel Olorunfrmi Fagunwa lati Oke Igbo ni ipinlẹ̀ Ondo lo kọ iwe yii Lọ́dun 1938 ni Fagunwa kọ iwe itan aroso yii to jẹ́ akọ́kọ́ iru rẹ̀ nilẹ̀ Adulawọ ni eyi ti wọ́n gbe jade lọ́dun 1950 saaju ominira Naijiria.
Adams soro yii nibi ipade igbimọ adari  ẹgbẹ APC to
Xenophobic Attack: Awọn ọmọ Nàìjíria tí yarí pé àwọn náà yóò gbẹ̀san
Alukoro ileeṣẹ agbofin ọtẹlẹmuyẹ DSS, Ọmọwe Peter Afunaya ṣalaye ninu atẹjade kan pe lootọ oṣiṣẹ ileeṣẹ agbofinro DSS ni arakunrin ti wọn funrasi pe o yin ibọn naa, ati pe ara awọn ẹṣọ alaabo ti wọn yan ti olori ileegbimọ aṣoju-ṣofin orilẹede Naijiria, Họnọrebu Fẹmi Gbajabiamila ni.
Ẹkọ kejì ni pe ka ma gbe ara wa ga kọja ofin orilẹ ede wa nitori ọwọ palaba le segi ni ọjọ kan.
“Nítorí náà, ẹ máa ṣọ́nà, nítorí ẹ kò mọ ọjọ́ tabi àkókò.
Dafidi Di Ọba Israẹli ati ti Juda.
Awọn minisita lorilẹ ede Naijiria ti salaye nibi ipade agbaye awọn oniroyin ati akọrọyin to n lọwọ  niluu Abuja, pe  ijọba ti se gudugudu-meje , yaya mefa lati mu igbe aye idẹrun ba awọn omo orilẹ ede yii.
Awọn iroyin ti ẹ lee nifẹ si: Ijọba kede iye ọmọ to sọnu ni Dapchi Naijiria k'ọmọogun lati wa'wọn ọmọ Dapchi Asoju ijọba Naijiria mi titun de Dapchi Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
OLUWA Ọlọrun sọ fún ìlú Tire pé, “Ǹjẹ́ gbogbo ilẹ̀ tí ó wà létí òkun kò ní mì tìtì nítorí ìṣubú rẹ, nígbà tí àwọn tí wọ́n farapa bá ń kérora, tí a sì pa ọpọlọpọ ní ìpakúpa ninu rẹ?
Adéláyò dúpé, ó sì fi ìbànújé kúrò lódò àwon àgbà náà, nígbà tí Àyìnlá n béyin kee nítirè fún ayò pé òun ni òun yóò ni gbogbo dúkìá Oba nígbà tí Adéláyò bá ti mú òkan péré.
Ìgbà wo ni yóo ṣe èyí dà, tí yóo máa gba ìdógò lọ́wọ́ àwọn onígbèsè rẹ̀ kiri?
Nítorí náà, lílọ ni a ó lọ.
Ibeere yii lawọn eeyan n beere loju opo Twitter EFCC, lati fesi si ikede iroyin ti wọn fi sita naa.
Gẹ́gẹ́ bí aṣọ, a óo pààrọ̀ wọn.
Bígbà tí a pàdé rẹ̀ ó kí Baba-onírùngbọ̀n ṣùgbọ́n kò kí mi.
O ni wọn tun dunkooko mọ oun lati yọ fidio naa kuro.
"Ẹ wá dánrawò níbí pẹ̀lú Àpólà Ọ̀rọ̀ Orúkọ, ""Noun Phrase"" Ẹ̀yin tí ẹ kò gbọ́ Yorùbá, ẹ ṣúnmọ́ bí láti kọ́ lítíréṣọ̀ èdè Yorùbá lórí BBC Àṣà Oge Ṣíṣe ní Akọ́mọlédè BBC Yorùbá ń gbé yẹ̀wò lónìí, Ó yá, iṣẹ́ ti bẹ̀rẹ̀."
Nítorí èyí, àwọn ọlọ́pàá a máà gbáradì fún oṣù mélòó kan kí ayẹyẹ náà tó wáyé.
Ó bá fi ohun gbogbo sílẹ̀, ó dìde, ó ń tẹ̀lé e.
olugbe ilu  Itighidi lati fowosowopo pelu
Ta ló kéde rẹ̀ láti ìgbà àtijọ́?
Idi ree ti Lisabi ati awọn ẹmẹwaa rẹ pa orukọ ẹgbẹ wọn pada si Ẹgbẹ Ologun, ti wọn si n gbe awọn ohun ija oloro lorisirisi rin, bẹẹ ni wọn n gbaradi bii ologun lati kọ iya fun awọn ọmọ Ẹgba.
nítorí pé níbẹ̀ ni àwọn tí ó kó wa ní ìgbèkùnti ní kí á kọrin fún àwọn.
pẹlu àwọn àmì ati iṣẹ́ ìyanu tí Ẹ̀mí fún mi lágbára láti ṣe.
A óo máa pè é ní Ìyanu, Olùdámọ̀ràn,Ọlọrun alágbára, Baba ayérayé,Ọmọ-Aládé alaafia.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìjọba Zamfara wọ́gilé owó ìfẹ̀yìntì tàbùà tabua fawọ̀n Gómìnà 27 Bélú 2019 Ile aṣofin ni ipinlẹ Zamfara ti wọgile owo ifẹyinti ti ijọba ana nipinlẹ naa ṣagbekalẹ rẹ fun Gomina ati igbakeji rẹ.
”Àwọnmìíràn ní, “Wolii ni, bí ọ̀kan ninu àwọn wolii àtijọ́.
" Ṣé lóòtọ́ ni Lateef Adedimeji àti Adebimpe Oyebade ṣe ìgbéyàwó?
Moses gba ami ayo kan wole, ti o si se iranwo ami-ayo kan lati ran iko agbaboolu Chelsea lowo lati jawe olubori ninu ifesewonse pelu iko agbaboolu Burnley ni papa isere Turf Moor.
Àní bí ó ti rí ní àkókò Noa, bẹ́ẹ̀ ni yóo rí nígbà tí Ọmọ-Eniyan bá dé.
Iroyin naa ni ọpẹlọpẹ asaaju Yoruba kan, Oloye Sunday Adeyẹmọ, ti gbogbo eeyan mọ si Sunday Igbohoati ẹnikeji rẹ, Bako, to gba wọn silẹ lọwọ wahala naa.
6 3,337 French Guiana 74 26.
Ibùsùn náà dára ό wu ni jọjọ.
Àwọn Farisi ati àwọn amòfin wá bi í pé, “Kí ló dé tí àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ kò fi tẹ̀lé àṣà ìbílẹ̀, tí wọn ń fi ọwọ́ àìmọ́ jẹun?
OLUWA wí fún Mose pé, “Ẹ gòkè tọ èmi OLUWA wá, ìwọ ati Aaroni, ati Nadabu, ati Abihu, ati aadọrin ninu àwọn àgbààgbà Israẹli, kí ẹ sì sin èmi OLUWA ní òkèèrè.
Kí OLUWA Ọlọrun wa kí ó wà pẹlu wa, bí ó ti wà pẹlu àwọn baba ńlá wa; kí ó má fi wá sílẹ̀, kí ó má sì kọ̀ wá sílẹ̀, 
Ìpínlẹ̀ Oyo, Ogun, Ondo buwọ́lu àbádòfin Àmọ̀tẹ́kùn Ẹ wo àwọn ìlérí tí Buhari ṣe láti ọdún 2015 àmọ́ tí kò tíì mú ṣẹ Ìsinmi oṣù mẹ́fà lẹ́yìn ìbímọ yóò túbọ̀ mú àdínkù bá ikú mọ wẹ́wẹ́ - Àwọn Obìnrin Ekiti Yobo ni ọpọ iriri gẹgẹ agbabọọlu latari bo ṣe ti gba bọọlu ni oriṣiriṣi ẹgbẹ agbabọọlu kaakiri agbaye.
O wa rọ awọn ileewe lati ṣeto aye to tọ fun awọn akẹkọọ tabi olukọ ti ara wọn ko ba ya lati maa kọ ẹkọ tabi ṣiṣẹ wọn lati ile nipasẹ ayelujara iyẹn, Virtual learning"" tabi ""Virtual work"" Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 3 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 5 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!"
Olori agba naa, to ti le ni ẹni ọgọrin ọdun kii se iyawo mọ fun ọba alade naa, a si lee pe ni iya rẹ nitori aajo ati itọju to ti n se fun lati ọpọ ọdun wa.
Ṣùgbọ́n gẹ́gẹ́ bí ìwà Ìjàpátìrókò ọkọ yánníbo ọ̀dàlẹ̀ pátápátá ni.
Ó mú ife wúrà lọ́wọ́, ife yìí kún fún ẹ̀gbin ati ohun ìbàjẹ́ àgbèrè rẹ̀.
A san owo fun kaadi idanimọ ati lẹta atẹransẹ SMS pẹlu.
Nígbà náà ni Farao pe Mose ati Aaroni, ó ní, “Ẹ bẹ OLUWA kí ó kó ọ̀pọ̀lọ́ kúrò lọ́dọ̀ èmi ati àwọn eniyan mi, n óo sì jẹ́ kí àwọn ará Israẹli lọ rúbọ sí OLUWA.
Àwọn ọmọ ogun Filistini ati àwọn ẹgbẹ́ ogun tí wọ́n ń digun-jalè wárìrì, ilẹ̀ mì tìtì, jìnnìjìnnì sì dà bo gbogbo wọn.
Òye kò ì tíì ye yín sibẹ?
Ọba yìí paa á láṣẹ pé kí wọ́n pa ọkùnrin náà.
Láti ìgbà tí Nàìjíríà ti padà sí ìlànà Democracy, ni Abdulrahman àti ọmọ ìya rẹ̀, Alimi Abdulrahman, ti ń gbìyànjú láti gba agbára ìṣèjọba kúrò lọ́wọ́ ìdílé Saraki.
Bakan naa lo tun ni ṣe ni ajọ to n gbogun ti itankalẹ ajakalẹ arun ni Naijiria, NCDC n fi ọrọ arun naa ja orilẹ-ede yii lole ni.
" Ọjọgbọn Banji Akintoye ti fi igba kan jẹ senetọ lasiko iṣejọba awaarawa ẹlẹkeji.
Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Nigerian Youth Investment Fund: FG cash transfer NYIF loan of 75 Billion to credit microfinance bizness of young pipo don ready - See how you fit apply25 Agẹmo 2020 Flying Officer Tolulope Arotile: Nigerian Air Force hand over suspects in accident wey cause her death to police25 Agẹmo 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Ẹ wo àwọn ẹyẹ lójú ọ̀run.
Ègún wà lórí gbogbo yín nítorí pé gbogbo orílẹ̀-èdè yín ní ń jà mí lólè.
O wa ni manigbagbe ni Promise yoo jẹ fun gbogbo eniyan.
Irianajo rẹ gẹgẹ bi olorin Fuji Lọdun 1966, Sikiri ayinde Barrister gbe rẹkọọdu orin rẹ akọkọ jade.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Akomolede àti Aṣa: Ọ̀rọ̀ Ẹ̀yán ni Bunmi Femi Amao ń kọ́ wa lórí ètò Akọ́mọlédè àti Àṣà lóri BBC Yoruba Awọn olukọ to kọ wa ni ipinlẹ Oyo lọtẹ yii ni: 1) Arabinrin Olubunmi aya Femi Amao to kọ wa ni ọrọ ẹyan asapejuwe.
Aare Buhari so fun awon igbimo naa pe: ‘‘Mo fi dayin loju pe, labe isakoso mi, ko si eya kankan ti ma foju re koja bi o se le wu ko mo.
Lowurọ ọjọ Aje ni ọpọlọpọ awọn oniṣowo to ni ṣọọbu si agbegbe naa ṣẹṣẹ n mọ ina to jo dukia wọn ti wọn si n gbiyanju ati ṣaa nnkan ti wọn lee ri ko jọ.
Idí nìyí tí wọ́n fi máa ń sọ pé;
Ọ̀pọ̀ kò ní ibití wọ́n máa sùn bí ìjọba ìpínlẹ̀ Èkó se bẹ̀rẹ̀ ilé wíwó LASEMA so ètò ìdóòlà ẹ̀mí rọ̀ ní ibùdó tí ilé ti wó nílùú Eko Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Àlàyé rèé lórí ilé kẹ̀ta tó wó l'Eko Lasiko to n ṣe ifilọlẹ igbimọ naa, kọmisana fun ile kikọ ati idagbasoke ilu, Prince Rotimi Ogunleye sọ pe awọn nkan pataki ti igbimọ naa yoo mojuto ni wiwa ọna ti opin fi le de ba iṣẹlẹ ile wiwo lọjọ iwaju, to fi mọ iwa aibikita awọn abanikọle tabi ẹni to nile, ati ipa ti ijọba ipinlẹ naa n ko ninu iru iṣẹlẹ bẹ.
Ẹ gba talaka ati aláìní sílẹ̀,ẹ gbà wọ́n lọ́wọ́ àwọn eniyan burúkú.
Bí ẹ bá dáríjì ẹnikẹ́ni, èmi náà dáríjì í.
Àwọn ohun tí ojú yín yóo máa rí yóo kó ìpayà ati ẹ̀rù ba yín, tóbẹ́ẹ̀ tí yóo fi jẹ́ pé, bí ilẹ̀ bá ti ṣú, yóo dàbí kí ilẹ̀ ti mọ́; bí ilẹ̀ bá sì ti tún mọ́, yóo dàbí kí ilẹ̀ ti ṣú.
Walter Carrington was the initiator of many wide-ranging diplomatic operations, particularly during his tenures as the US Ambassador to Senegal from 1980-1981and Nigeria from 1993 to 1997.
Aṣofin Rotimi Olowo ni o dabaa gbigba abadofin iṣuna
aare Muhammadu Buhari  ti o je alaga
O ni isọro kan gboogi ti ijọba ipinlẹ Ondo n dojukọ ni bi awọn awọn eeyan ipinlẹ Ondo ko ṣe kọbi ara si gbogbo alakalẹ ijọba lori arun arun Covid-19.
Ewe, gege bi ero ayelujara ile Faranse, ti ogbeni Ziad Takieddine te jade, O ni, won fi esun kan-n lodun 2013 pe, Gaddafi fi owo ti o to milionu marun-un euro 5 million euros ($6 million)  ranse si lati inu apo ifowopamo oloye Abdullah Senussi ti o je agbofinro tele ri sinu apo ifowopamo alakoso eto idibo Sarkozy Tobi Sangotola.
Duro Ladipọ, ìlúmọ̀ọ́ká òṣèré tíátà àti ọmọ àlúfà tí kò gbàgbé àṣà ìbílẹ̀ Àwọn ará Ọwọ gé igi Ọjà láti ṣe ìdárò Ọba Folagbade Ọlateru!
 Ajagunfẹyinti kan, Ousmane Diallo lo sọ bẹẹ, to si lo agekuru aarẹ ana naa pẹlu afikun pe ""Awọn araalu ti ja ajasẹgun."
Lalong  ti egbe  All Progressives Congress (APC) ti jawe
Taiwo Aromokun: Ibeji di iran lo yẹ ka maa pe gbajumọ oṣere tiata, Taiwo Aromokun nitori ibeji ni, to si tun bi ibeji ni igba meji ọtọọtọ.
Ẹwẹ ni New Zealand, olootu ijọba Jacinda Ardern, gbe ọkan lara awọn igbesẹ to lagbara ju lọ lagbaye nipa arun Coronavirus to n damu aye yi.
Day 23: Àwọn nkan márùn ún tó gbajúmọ̀ nípa Daura #BBCNigeria2019 Ọrọ miran to tun tọka si ni gbolohun Igbo eleyi ti Ọọni sọ pe o ṣẹ wa lati igba ti awọn Igbowa ni Ile Ifẹ.
ọkàn àgbàlá tẹmpili OLUWA ń fà mí,àárò rẹ̀ ń sọ mí;tọkàn-tara ni mo fi ń kọrin ayọ̀sí Ọlọrun alààyè.
Khadijah, obìnrin àkọ́kọ́ tó dẹnu ìfẹ́ kọ àyànfẹ́ rẹ̀ Ilé ẹjọ́ rán àwọn mérìndínlógún lẹ́wọ̀n gbére fún dídáná-sun Nusrat Ọwọ ṣìkún òfin ti tẹ Maina, alága àná fún ọrọ owó ìfèyìntì - DSS Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
N kò lóyún, bẹ́ẹ̀ ni ń kò ní ọkọ, ẹ fi mí lọ́rùn sílẹ̀ - Dayo Amusa Ifẹ afẹju lo maa n mu iwọ lo n se mi wa, ti ifẹ ba si ju bo se yẹ lọ, o lee fa ija.
Mutharika to jẹ ẹni ọdun mejidinlọgọrin ọhun lo wa ni ipo gẹgẹ bi aarẹ, ti awọn eniyan si tako idibo to waye ni Ọjọ kọkandinlogun, Osu karun un, ọdun yii pẹlu igbakeji rẹ.
Ẹkunrẹrẹ lori iroyin yii wa ni: Yinka Ayefele di bàbá ìbẹta Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Yinka Ayefele: Oṣù àwọn ìbẹ́ta mi kò pé ní kò jẹ́ kí n kọ́kọ́ kéde ìbí wọn Ṣé kí àwọn Fulani Darandaran padà sílé tàbí dúró síbi tí wọ́n wà?
BBCCopyright: BBC LawanImage caption: Lawan Article share tools Facebook Twitter ṢàpínlòView more share options Share this post Copy this linkKà síwájú síi nípa àwọn ìtọ́kasí wọ̀nyí.
Wo ìdí márùn-ún tí Biden fi bórí nínú ìdìbò ààrẹ America Àwọn àkọ́lé ìròyìn mẹ́ta tó leè tẹ̀lẹ́ ìdìbò Ààrẹ ilẹ̀ Amẹrika Agbára wa kò ká àrùn Covid-19 mọ́ - Ìjọba ilẹ̀ Amẹrika Báwo ni Donald Trump ṣè ń rí ọwọ́ mú sí nínú àkójọ èrò àwọn olùdìbò?
Ẹ máa hùwà bí ọmọ ìmọ́lẹ̀.
Ní ọdún kẹtadinlogun tí Peka, ọmọ Remalaya, jọba ní Israẹli, ni Ahasi, ọmọ Jotamu, jọba ní Juda.
Ninu iwadi naa, wọn ni owo to wa lọwọ awọn ọkunrin mẹta to lowo julọ ni ilẹ Afrika, kọja ti awọn ẹgbẹta le ni aadọta miliọnu alaini to wa nilẹ naa.
 tó bá dé ibẹ ̀ , yóò ṣe ìdárò fálábiamọ .
5 million) to ti tẹ eroja ififẹ han (Likes) to wa ni isalẹ oju opo naa.
Mahmood wa ni, ohun ti o je ki awon sun eto idibonaa siwaju ni lati le
Ẹ̀wẹ̀ nínú ọ̀rọ̀ tirẹ̀, kọmísọna ìròyìn ní ìpínlẹ̀ Eko Gbenga Omotsho ní ìgbésẹ̀ yìí kìí ṣé ǹkan tó burú tàbi ti etí kò gbọ́ rí.
Ile isẹ arabinrin naa ni wipe lati ibẹrẹ Osu kini, Ọdun yii, ọdọ to jẹ alawọdudu aadota, 50 ni wọn ti gun lobe tabi ti won yin ibon pa ni ilu london.
OLUWA Ọlọrun ní, “Èyí ni yóo jẹ́ ààlà tí ẹ óo fi pín ilẹ̀ láàrin àwọn ẹ̀yà Israẹli mejeejila.
Oríṣun àwòrán, Olubayode Alebiosu Àkọlé àwòrán, Ajọ agbaye UNESCO ti kede Ọdun naa gẹgẹ bii ara awọn ọdun aṣa manigbagbe lagbaye Ọdọọdun ninu oṣu kẹjọ ni ọdun Ọṣun Oṣogbo maa n waye ni ilu Osogbo.
 lónìí ati rí àgbẹ ̀ aládà-ńlá , alápapò se , àti bẹ ́ ẹ ̀ bẹ ́ ẹ ̀ lọ.
koju aarun naa pelu awon irinse tuntun , paapaa julo, nipa lilo awon oogun
Èèyàn 403 ló lùgbàdì àrùn Coronavirus ní Naijiria ní Ọjọ́ Isinmi Iná sọ nílùú Akure, dúkìá ẹgbẹ̀lẹ́gbẹ̀ tún báa lọ!
O salaye pe, ajo UNICEF n fowosowopo pelu ijoba apapo, ijoba ipinle ati ijoba ibile , lati pese omi to mo nipase ise-akanse ajo WASH, lati bi odun marun-un seyin fun awon eniyan ti iye won to milionu mejo ti won wa ni igberiko.
O ni: Igbimo Amusese ti fowo si ise akanse tuntun fun kikooju ona oko oju irin Ibadan si Kaduna , Kaduna si Kano ni eyi to fi je pe ise yoo maa lo loju ona Ibadan si si kano taarata.
Angẹli Oluwa sọ fún Filipi pé, “Dìde kí o lọ sí apá gúsù, ní ọ̀nà tí ó lọ láti Jerusalẹmu sí Gasa.
Ṣugbọn mo nifẹ si ki n mọ iwe kọ ati ki n mọ iwe ka.
Àkọlé àwòrán, Ile ti mọ, ta lo jawe olubori ni ibeere awọn eniyan ni owurọ kuto ọjọ keji idibo.
''Kani awọn ile asofin ni ko buwọlu owo ti wọn fẹ fi ṣeto idibo ni, a o mọ wi pe idi pataki niyẹn ṣugbọn ki wọn kan sun idibo siwaju lai nidi to gba ọgbọn, eyi ku diẹ kaato''.
Kìnìhún joko jẹ ẹran ara afurásí ọdẹ tí kò gbààyè kó tó ṣọdẹ Ìpànìyàn Zamfara: Kò gbọdọ̀ sí ìwakùsà ní Zamfara Ìdíje bọ́ọ̀lù fa ìtàjẹ̀ sílẹ̀ ní Poly Ibadan Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ayekofẹnifọrọ: Ó yá, ẹ fi àmì sórí ọ̀rọ̀ náà.
Iwadii Partnership for Evidence-based Response to Covid-19 (PERC), to ṣe atojọ ni aladani ati ti ijọba fihan pe ọṣẹ́ ti Covid 19 ṣe nilẹ Adulawọ kere niye pẹlu afiwe nọmba iye eeyan to wa nibẹ.
Nigba ti agbẹnusọ naa n sọrọ lori iwa aibikita awọn ara ilu kan si ipe awọn Ile Igbimọ Aṣofin lorilẹ-ede yii ati bi awọn janduku kan ṣe ji ọpa-aṣẹ ni Ile Igbimọ Aṣofin-agba ati Ile Igbimọ Aṣofin Ipinlẹ Gombe, o tẹnu mọ ọ pe Ile Igbimọ Aṣofin jẹ gbongbo fun ijọba oṣelu tiwantiwa,Nigba ti o n mẹnu ba awọn aṣeyọri ti Ile naa ti ṣe laarin ọdun mẹta sẹyin, agbenusọ Ile naa sọ pe, “a ti ṣe ọpọlọpọ ofin fun ilọsiwaju Ipinlẹ Eko.
Nígbà tí àwọn eniyan náà kọ ilà abẹ́ tán, olukuluku wà ní ààyè rẹ̀ ninu àgọ́ títí egbò wọn fi jinná.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Inú mi máa ń dùn láti kọrin fún àbúrò mi - Josh Posh Obìnrin awakọ̀ Bàálù àkọ́kọ́ láti Ọffa rèé 'Èmi ò kí ń ṣe ọkọ torí mi ò kí ń ṣe ojúṣe mi' 'Ìjákulẹ̀ ọkùnrin ló sọ mí di alárinà' Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí 2 sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
Ayọ̀ ń bẹ fún ẹrú náà tí ọ̀gá rẹ̀ bá bá a lẹ́nu iṣẹ́ rẹ̀.
 odùduwà kò àwọn ẹmẹ ̀ wa rẹ ̀ yóòkù dé ilé-ifẹ ̀ ní ìgbẹ ̀ yíngbéyín .
Jonatani kó àwọn ohun ìjà rẹ̀ fún ọmọ náà pé kí ó kó wọn lọ sílé.
Òun ni ó ranti wa ní ipò ìrẹ̀lẹ̀ wa,nítorí pé ìfẹ́ rẹ̀ tí kì í yẹ̀ wà títí lae;
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Iná Ibadan: Gbogbo dúkìá tó wà lókè ilé alájà kan náà ló jóná tán Iṣẹlẹ ijinigbe laipẹ yii lorilẹede Naijiria paapaa iha Guusu Iwọ-Oorun ti di ohun to n kọ ọpọlọpọ lomiinu ti ko si yọ olowo tabi talaka silẹ.
O sọ eniyan di erùpẹ̀ pada,o sì wí pé, “Ẹ yipada, ẹ̀yin ọmọ eniyan.
Ọrọ ko wọ laarin Fayose ati Fayemi naa Laipẹ yi ni Ijọba ipinlẹ Ekiti labẹ akoso Gomina Ayodele Fayose fẹsi si ẹsun ti Gomina ti wọn sẹsẹ dibo yan ni ipinlẹ Ekiti, Kayọde Fayẹmi fi kan lori jijẹ gbese ₦117bn kalẹ de Fayemi.
" Òbítíbitì ẹ̀gbin ti sọ ìlú Ibadan di ààtàn - Aráàlú figbe bọnu $2,600 àǹtí mi ni mo jí láti lọ sókè òkun àmọ́ àbámọ̀ ló gbẹ̀yìn ọ̀rọ̀ mi"" Àìsàn ìtọ̀ súgà kò túmọ̀ sí pé èèyàn ti gba ọjọ́ ikú- Dókítà Wilson A ti gba aṣẹ ilé ẹjọ míì to tako àṣẹ́ ilé ẹjọ to wọ́gile olùdije APC ni Bayelsa O ni kii ṣe Naijiria ni orilẹ-ede akọkọ ti yoo ṣofin iṣakoso opo ikansiraẹni lori itakun agbaye."
O gba awọn obi niyanju lati maa kọ awọn ọmọ wọn lẹkọ ibalopọ lati igba ti wọn be ti wa ni kekeke.
Sùgbọ́n àwọn ayàwòrán ni wọ́n ya gómínà náà nígba tó ṣe bẹ́ẹ̀, tí wọ́n sí gbẹ́e síta tí ó fi dà bí ẹni pé ó ń ṣe bí wòlíì.
Akitiyan awọn ileeṣẹ iroyin: Lati igba ti iroyin ti kede pe ọmọ orilẹ-ede Italy kan ko arun naa wọ Naijiria, ni awọn ileeṣẹ iroyin to ṣe e fọkan tan, bii ileeṣẹ BBC atawọn ileeṣẹ iroyin miran ti n ṣe ifitonileti iroyin nipa arun ọhun.
Joṣua to òkúta mejila mìíràn jọ láàrin odò Jọdani lọ́gangan ibi tí àwọn alufaa tí wọ́n gbé Àpótí Majẹmu dúró sí; àwọn òkúta náà wà níbẹ̀ títí di òní olónìí.
 Aṣofin Victor Akande naa ki Ọba Akiolu ku oriire, bẹẹ lo gbe oṣuba o-kare fun Ọba, paapaa fun iṣẹ atilẹyin wọn fun ilu.
Bi Ọba bá wàjà, Ọba titun yio ṣu gbogbo iyàwó ti ó bá láàfin lópó.
Ẹ wo ìyá ẹni ọdún 81 tó sẹ̀sẹ̀ parì ilé iwé alákọ̀bẹ̀rẹ̀!
"Ọwọ mi di lati lọ bẹ ẹ wo gẹgẹ bi mo se maa n se nitori o sọ fun mi pe oju ọjọ taa wa yii tutu fun oun.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Visa Application: Amẹ́ríkà ń béèrè ìròyìn ojú òpó arìnrìnàjò 2 Òkùdu 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Oṣù kẹta ọdún 2019 ni àṣẹ yìí kọ́kọ́ jáde Gbogbo awọn eeyan to ba fẹ rinrin ajo lọ sorilẹede Amẹrika bayii gbọdọ ṣetan ati ko gbogbo iroyin to ba jọ mọ iṣe wọn lori ayelujara kalẹ.
Arugba Osun Osogbo jade ni deede aago mẹwa ku ogun isẹju aarọ, ti ọgọọrọ awọn eniyan siwaju rẹ pẹlu ijo ati ayọ, ti wọn si n se adura ti wọn kigbe Ore yeye ooooooo."
"Oríṣun àwòrán, Instagram/opeyemi_ayeola1 ""Ọdun mẹta ni ọkọ mi fi n wa ọna lati ba mi sọrọ, ko to o ri nọmba aago ipe mi."
ó gbọdọ̀ san ẹ̀jẹ́ rẹ̀, àfi bí ọkọ rẹ̀ bá lòdì sí i nígbà tí ó gbọ́.
Datani ati Abiramu yìí ni wọ́n jẹ́ olókìkí eniyan láàrin àwọn ọmọ Israẹli.
Amina Zakari: INEC ní Amina Zakari kọ́ ni yóò wà ní ìdí ìbò kíkà lásìkò ìdìbò 2019
Ikọ BBC News Yoruba kan si olu ileeṣẹ ajọ ọlọpaa nipinlẹ Ọyọ lori ọrọ naa, wọn ṣe alaye wi pe ahesọ ọrọ lasan ni wi pe iro ibọn ati awọn ohun ijagun oloro ni awọn ẹgbẹ awakọ fi le awọn olugbe Ẹgbẹda lopin ọsẹ.
Emi o raye awọn nnkan bẹyẹn.
“Kí ló dé tí àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ kò fi tẹ̀lé àṣà tí àwọn baba wa fi lé wa lọ́wọ́?
"Ṣe ni gbogbo oju opo ayelujara rẹ kun fun awọn fọto oriṣiriṣi to fi ""dẹmọ"" to tun fi ""dupẹ"" lọwọ Ọlọrun."
Fọnran fidio ibi ti oniwaasu Oluwole Ilesanmi ti n bẹ awọn ọlọpaa ki wọn ma ṣe gba bibeli rẹ lawọn eeyan ti wo ni igba miliọnu mẹta le loju opo ayelujara.
''Mi o le nifẹ obinrin meji pọ lẹẹkan naa, nitori naa, o maa nira fun mi lati ni olori meji laafin,'' Oba Uba lo woye bẹẹ.
Ahasi gé àwọn ẹsẹ̀ idẹ ti agbada ńlá, ó gbé agbada náà kúrò.
Bi o tilẹ jẹ wi pe ariwo awọn ajinigbe pawo ni ileeṣẹ ọlọpaa npa lori iṣẹlẹ ọhun ṣugbọn agbẹnusọ fun ẹgbẹ Afẹnifẹre, Yinka Odumakin ni rara o, ọwọ awọn darandaran la ba nibẹ.
Jó ìdámẹ́ta rẹ̀ ninu iná láàrin ìlú, ní ìgbà tí ọjọ́ tí a fi dóti ìlú náà bá parí.
Ìjọba àpapọ̀ - BBC News Yorùbá BBC News, YorùbáFò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Sowore ń gbìmọ̀dìtẹ̀ láti gba ìjọba lọ́wọ́ Ààrẹ Buhari - Ìjọba àpapọ̀ 21 Owewe 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 22 Owewe 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Tayọtayọ ni mo fi n ki Soworẹ kaabọ sagbo awa ti wọn ti fẹsun kan Ọjọgbọn Wole Soyinka bu ẹnu ẹ̀tẹ́ lu ijọba Naijiria lori ẹsun ti wọn fi kan Soworẹ.
"Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Bolaji Faleke ni Olùkọ́ tó ń kọ́ wa ní àṣà oge ṣiṣe lórí BBC Yorùbá Akor ni: ""Nigba miran mo le ta apo igbo kan ni egberun lọna ogun Naira, o wa lọwọ ibi ti mo fẹ taa si, mo tun le taa ju bẹẹ lọ."
O ni ijọba ilẹ Naijiria ati Ireland si ti tọwọ bọ iwe adehun lori ọna ti wọn fi da owo naa pada silẹ wa.
Oríṣun àwòrán, @jidesanwoolu Sanwo-Olu ni meji ninu awọn eeyan to fara gba ọgbẹ ni Lekki ni wọn sisẹ abẹ fun loru mọju, ti ara wọn si ti n balẹ.
Ninu atẹjade kan to fi sita lẹyin ti awọn oṣiṣẹ EFCC naa gbọn ile rẹ to wa nilu Ẹpẹ ati Parkview ni Ikoyi yẹbẹyẹbẹ, Akinwunmi Ambọde ni wọn ko ba ẹbọ ni ile oun lẹyin ti wọn ṣe ayẹwo wọn tan.
Nítorí a gbọ́ nígbà tí ó sọ pé Jesu ti Nasarẹti yóo wó ilé yìí, yóo yí àwọn àṣà tí Mose fún wa pada.
"Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Àwọn opó 150 gba irinṣẹ́ ọrọ̀ ajé nílú Ìwó 5 Ògún 2018 Àkọlé àwòrán, Awọn ohun elo iṣẹ alabọde bii ẹrọ ilọta, ẹrọ guguru, ẹrọ iṣerun, ẹrọ iranṣọ, ati owo lati fi bẹrẹ iṣẹ kereje-kereje ni awọn opo naa tẹwọ gba ""Ohun ti awa opo n dojukọ lawujọ kii ṣe kekere rara."
 awon apako ati orisii kemikaa maa n sakoba fawon eweko oju omi atawon eja ni eyi ti awon eniyan n je leyin o reyin to wa n di majele fun awon eniyan”.
Ileesẹ BBC gbiyanju ni ọpọlọpọ igba lati ba ileesẹ ijọba Naijiria to wa fun ọrọ abẹle, ati ileesẹ aṣoju Naijiria nilu London sọrọ, wọn ko fi esi kankan ránsẹ.
Yára wá ràn mí lọ́wọ́, OLUWA, ìgbàlà mi.
ya wo agbegbe Lilo , ni eyi ti won pa awon eniyan mejo , ti awon eniyan
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Fr Mbaka, ọmọ ìjọ rẹ̀ kọ̀lu akọ̀ròyìn BBC, wọ́n lù wọ́n ní àlùdojúbolẹ̀ Amotekun yóò gba owó oṣù kẹtàlá ní ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́ - Seyi Makinde Maina dákú fún ọ̀pọ̀ ìṣẹ́jú, iléejọ́ sáré so ìjókòó rọ̀ Ọlọ́pàá tún yìnbọn pa awakọ̀ Márúwá, ìwọ́de gba Portharcourt kan Wo ìròyìn tó pọ̀ jùlọ táwọn èèyàn ń wá ní Google lọ́dún 2020 Obasanjo àti Gani Adams tẹ́ mi pẹ̀lú bí wọn ṣe tahùn síra wọn - Adebanjo Buhari le sọ ipò ààrẹ́ nù tí kò bá yọjú sáwọn aṣòfin - Amòfin Ẹgbẹ́ òṣèlú alátakò takú láti gba èsì ìbò ààrẹ ní Ghana Ọ̀pọ̀ nkan tó n ṣẹlẹ̀ kò jẹ́ kí n gbàgbọ́ pé Naijiria wà ní abẹ́ ìdarí ẹnikẹ́ni - Wole Soyinka Ọmọ ẹgbẹ́ òkùnkùn ṣoro ní Ijebu Ode, ọ̀pọ̀ ẹ̀mí sọnù Gẹgẹ bo ṣe sọ, oun n lo agbo ọhun koun ma baa sanra ju, ṣugbọn o dabi pe oṣere naa ko fẹran bo ṣe ri mọ.
Nígbà tí Ọlọrun mú kí n máa káàkiri kúrò ní ilé baba mi, mo wí fún un pé, ‘Oore kan tí o lè ṣe fún mi nìyí: níbi gbogbo tí a bá dé, wí fún wọn pé, arakunrin rẹ ni mí.
Agẹṣin Adimula ni nitori pe kii ṣe ori gbogbo ọmọ lo maa n tete gbo ti wọn yo fi lee tete fa.
Idi ni pe Aarẹ Trump ko ye tẹnu mọ pe oogun hydroxychloroquine jẹ oogun kan gbogi to ma n koju arun Covid 19.
Ìpele ikọ̀ mẹrindinlogun Congo DR vs Senegal.
Ipinlẹ Eko lo wa ni ipo kinni pẹlu 93, FCT si wa ni ipo keji pẹlu 21.
àwọn ọmọ Ṣefataya ati àwọn ọmọ Hatili, àwọn ọmọ Pokereti Hasebaimu ati àwọn ọmọ Ami.
"Taiwo Adisa sọ pe ""ọrọ ilẹ naa wa nile ẹjọ, oun ko si le tapa si àṣẹ ile ẹjọ."
O ni eyi yoo tun pese iṣẹ fun awọn eeyan ti o to miliọnu kan abọ ni iye.
Ẹrọ kọmputa Bill Gates ti eeyan ko le foju ri Iroyin ofege ti a o tun mẹnuba ni ti ẹrọ kọmuter to kere jọjọ, ti eeyan ko le foju ri ti wọn sọ pe baba olowo Bill Gates wa nidii rẹ.
ati àwọn arakunrin rẹ̀, àwọn baálé baálé lápapọ̀ jẹ́ ojilerugba ó lé meji (242).
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Iya Woli: Ẹ̀mí ìjókíjó, Wòó, Ṣọ̀kí, Wojú, Ṣàkùṣákù, One Corner.
N óo dájọ́ fun yín, n óo fọ́n gbogbo àwọn tí ó kù ninu yín káàkiri igun mẹrẹẹrin ayé.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Inec: Èsì ìbò ko tó làti yọ Dino Mélayé 29 Ìgbé 2018 Oríṣun àwòrán, @inecnigeria Àkọlé àwòrán, Kò sí ọ̀nà míràn lábẹ́ òfin fún àwọn ará ìlú látí ṣe ìpàdé ìta gbangba láti dìbò yọ Dino Melaye.
Oríṣun àwòrán, Twitter/Nigeria Presidency Àkọlé àwòrán, M.
7 240981 Orilẹede Georgia 1540 38.
Ó kúnlẹ̀, ó bá bẹ̀rẹ̀ sí gbadura.
Àgbẹ̀ kì í fi òkúta ńlá ṣẹ́ ẹ̀gúsí,bẹ́ẹ̀ ni kò ní fi kùmọ̀, lu kumini.
Sibẹ a mọ̀ pé ọgbọ́n Ọlọrun tọ̀nà nípa ìṣesí gbogbo àwọn ọmọ rẹ̀.
gbogbo ati pataki fifọwọ ọkunkundun mu ọrọ aabo fun awon ara ilu    O
Buhari ni iyipada orilẹ-ede Naijiria ko le e waye, ti awọn ọmọ Naijiria ko ba fi ọwọsọwọpọ pẹlu ijọba lati mu Naijiria de ilẹ ileri.
Adajọ Agim ni awọn olupẹjọ ko tẹle ohun ti ofin ilẹ wa naa la kalẹ nidi pipe ẹjọ, ti adajọ to gbọ ẹjọ naa nile ẹjọ giga pẹlu tun kuna lati gbe idajọ rẹ kalẹ laarin ọgọrin ọjọ Adajọ naa wa kede pe kawọn olupẹjọ lọ san milliọnu mẹta naira fun Adeleke fun bi wọn ṣe da a laamu.
“Ṣugbọn kò sí ẹnìkan tí ó lè wọ ilé alágbára kan lọ, kí ó kó dúkìá rẹ̀ láìjẹ́ pé ó kọ́ de alágbára náà mọ́lẹ̀, nígbà náà ni yóo tó lè kó ilé rẹ̀.
Lẹyin na lo ki Neo nilọ lori iṣẹlẹ naa.
Iko agbaboolu Super Eagles padanu ifesewonse keyin tipele kerin(group D) ohun sowo Argentina pelu ami-ayo kan sodo, ninu ifesewonse ti o waye ni papa isere Saint Petersburg lale ojo isegun.
Ẹ ṣọ́ra fún ìròyìn ẹlẹ́jẹ̀ lórí ètò ààbò - Ọlọ́pàá Iléeṣẹ́ ọmọ ogun dá Bashir tó ri owó he lọ́lá Ọmọ Yorùbá tó bá ti rú òfin, ẹ gbé e jàntò - Oluwo Mo ṣe tán láti kú tọmọ taya bí wọn kò bá fi El-Zakzaky sílẹ̀ - ọmọ ẹgbẹ́ Shiite Iwọde awọn Shiite yii bẹrẹ ti wọn fi n beere pe ki ijọba fi olori wọn El Zakzakky to ti wa latimọle lati ọdun 2015 silẹ.
Wọn tun gba pe adehun yii yoo jẹ ki ibaṣepọ awọn olokowo lati orilẹ-ede ilẹ̀ Adulawọ dan mọran sii.
Ṣugbọn awọn aisan miran bii igbona (Measles) ti n pada yọju saye, ti awọn onimọ si n fọnrere rẹ pe, awọn eeyan n yẹra fun abẹrẹ ajẹsara to lee dena irufẹ awọn arun yii, nitori ibẹru ati aṣigbọ.
Ìtàn Àrọ̀gìdìgbà jẹ́ kí ń rò pé bàbá mi yan Yemọ̀ja ní àlè - Ọmọ Fagunwa Oní gègé àrà Oladejo Okediji d'ẹni ilẹ!
Ganduje: Mi Ò gba rìbá lọ́wọ́ ẹnikẹ́ni rí láyé mi Ikú Bademosi- Ọwọ́ ọlọ́pàá tẹ afurasí alásè Koda iroyin to tẹ wa lọwọ tiẹ sọ pe alakoso ajọ WAEC lo fi iwe ẹri ọhun le Aarẹ Buhari lọwọ.
Dexamethsone tablets: Báwó ni òògùn yìí ṣe ń ṣiṣẹ́ lára
’’O ni eto ijoba tiwa-n-tiwa kọ
Lo ba dahun pe, oun ṣẹmi, ki n dariji oun.
Ile –ise aare ti benu ate lu aheso oro ti awon oloselu kan
ede South Africa lasiko yii lo fa ijamba omiyale ni eyi ti ọpọlọpọ eniyan ti
òun OLUWA óo fìyà jẹ Ṣemaaya ará Nehelamu náà ati ìran rẹ̀; kò ní sí ẹnikẹ́ni tí yóo wà láàyè láàrin àwọn eniyan rẹ̀ láti fojú rí nǹkan rere tí n óo ṣe fún àwọn eniyan mi, nítorí ó ti sọ̀rọ̀ ọ̀tẹ̀ sí OLUWA.
’ Bí ẹ bá fẹ́ràn mi ni, yíyọ̀ ni ẹ̀ bá máa yọ̀ pé, mò ń lọ sọ́dọ̀ Baba, nítorí Baba jù mí lọ.
Atiku: Kò pọn dandan kí ń díje fún ipò àarẹ́ Nàíjirìa Igbákejì àarẹ́ Nàíjirìa tẹ́lẹ̀rí Atiku Abubakar, ti ní, òun kò sọpé ó pọn dandan fún òun láti jẹ àaré orílẹ́èdè Nàíjirìa ní ọdún 2019.
Ó mú ìwé kékeré kan lọ́wọ́ tí ó wà ní ṣíṣí.
O si wa iṣẹ aje wa si ilu Eko.
Nítorí pé wọ́n ti dẹ́ṣẹ̀ sí OLUWA.
A gbọ́ pé ẹnìkan ń bá iyawo baba rẹ̀ lòpọ̀!
Nitori naa nigbati iroyin itusilẹ wọn bọ ode, ọpọ lo tu sori ayelujara lati dupẹ lọwọ gbogbo awọn to kẹnu bọ ọrọ naa ati bi ijọba Naijiria ko ṣe fa sẹyin rara lori ọrọ naa.
Okan lara erongba todun 2030 ti ao je afojusun idagbasoke fun ajo isokan agbaye ati awon orile ede kookan labe re ni ki opin ti de si abe dida fomobinrin patapata lagbaye ati fifipa fomode binrin loko laito ojo ori.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù US Presidential Election: Ṣé ìrànwọ̀ ni Kamala, ìgbákejì tí Biden yàn yóò jẹ́ fún un tàbí ìpalára?
Ẹ̀bẹ̀ ni yóo sì máa bẹ̀, pé kí ó fi òun sí ipò alufaa kí òun baà lè máa rí oúnjẹ jẹ.
Ẹni tí ó bá ń ṣe burúkú kò mọ Ọlọrun.
Amọ sa, ajọsepọ rẹ lkka aabo n fẹju si lati ọdun 2014, to si fọwọsi iwe adehun ibasepọ ologun pẹlu awọn orilẹede mọkandinlogun nilẹ Afrika.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Mayowa Omoniyi: Kò sí orin Obey, Sunny Ade abí tàkasúfèé tí ń kò le ta gìtá sí Agbẹnusọ fun ẹgbẹ Afẹnifẹre naa sapejuwe bi Aarẹ orilẹede Naijiria nigbakan ri, Oluṣegun Ọbasanjọ ṣe dọbalẹ lati ki Ọọni lọdun 2016 bii bibu ọwọ nla fun ori ade naa.
Ọjọ́rú,ọjọ́ kẹrìnlá osù kẹrin ọdún 2018 sì ló wọ káà ilẹ̀ sùn.
Bí mo ti ń sọ fun yín tẹ́lẹ̀ nígbàkúùgbà, bẹ́ẹ̀ ni mo tún ń fi omijé sọ nisinsinyii.
Bi wọn ṣe fi ẹjọ sun yii, mu ki Olodumare ni oun yoo ran ikọ kan lati wo nkan to n ṣẹlẹ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, The Polytechnic Ibadan: Ẹ̀rọ abẹ́lé tó ń fọ ọwọ́ àti ‘Ventilator’ ló ṣẹ̀ṣẹ̀ gbé jáde O ni inu awọn ọkọ oju irin naa mọ lolo, o dun wo loju, o si ba igba mu gẹgẹ ni iru rẹ to wa lawọn orilẹ-ede miran to ti goke agba kaakiri agbaye.
 Gege bi orin ti awon eniyan n kọ
Niṣe ni wọn raga bo ere Churchill lati rii wi pe awọn olufẹhonuhan mii ko woo lulẹ.
rẹ pe; “ A ṣakiyesi awọn kudiẹkudiẹ kan ninu iṣuna-owo ọdun to koja,
Ara rẹ pada balẹ lẹyin ti wọn fun un ni omi mu.
Awọn ere adayaba naa fara gba ninu ibinu awọn araalu lasiko iwọde gbogbo.
ẹni tí ó gbẹ́ kòtò yìí gbọdọ̀ san owó mààlúù tabi kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ náà fún ẹni tí ó ni ín, òkú ẹran yìí yóo sì di ti ẹni tí ó gbẹ́ kòtò.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Bolaji Faleke ni Olùkọ́ tó ń kọ́ wa ní àṣà oge ṣiṣe lórí BBC Yorùbá Joshua ti fẹṣẹ yanju awọn ilumọọka akanṣẹ bi Wladimir Klitschko, Charles Martin, Joseph Parker, Alexander Povetkin ati Andy Ruiz Jr.
    Nígbà tí obìnrin náà rí mi, ó wá sí ọ̀dọ̀ mi, ó rẹ́rìn-ín o sì bẹ̀rẹ̀ síí wádìí bí mo ti n rìn tí òun fi rí mi o wá sí ọ̀dọ̀ mi nini tí mo wà, mo sàlàyé fún un dáadáa, ṣùgbọ́n bí o ti ń sọ̀rọ̀ ni o ń rẹrìn-ín músẹ́ sí mi, ọ̀rọ̀ rẹ̀ wọ̀nọnnì sì ṣe mi lóòre lọ́pọ̀lọpọ̀ nítorí ayé ti ṣu mi ni àkókò tí a ń wí yìí, ọkàn mi sì tilẹ̀ ti ń kábàámọ̀ pé kí ni ṣe tí n kò jẹ́ kí Ẹlẹ́gbára kúkú pa mi jẹ.
Awọn ileesẹ alaabo ni yoo maa se idanilẹkọ fun awọn ẹsọ ta ba gba, igbanisisẹ ati idanilẹkọ yoo si maa lọ ni rọgba-rọgba ni.
’ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Relive the tense moments as Neil Armstrong manually pilots the lunar module towards the surface of the Moon.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ija, ìyà ati nina lojoojumọ lo maa n ṣaaju iku ninu iru ajọṣepọ bawọn yii 3) Eni kini ni yoo maa dari ẹnikeji lai ki n fẹ gba imọran ẹlomiran mo tirẹ rara, o maa maa kó ololufẹ rẹ ni papa mọra.
Irinajo ti Oscar Martinez Ramirez kọ ko tẹle adura yii o.
Ọjọgbọn Usman Yusuf ni awọn eeyan ti wọn n lo owo ara ilu lati lu jibiti lẹka naa ni wọn n fin ina mọ oun nidi.
Sibẹsibẹ, àwọn tí wọn ń tu ọkọ̀ náà gbìyànjú láti tu ọkọ̀ wọn pada sórí ilẹ̀, ṣugbọn kò ṣeéṣe, nítorí pé, afẹ́fẹ́ líle dojú kọ wọ́n, ìjì náà sì ń pọ̀ sí i.
Nígbà tí wọ́n wà níbẹ̀, Kaini dìde sí Abeli àbúrò rẹ̀, ó sì lù ú pa.
31 Lafikun, awon ise akanse to ni i se pelu awon ohun alumoni ati adayeba  ti o to metalelaadorin, lati se ikawo awon afara ti o ti ya ,ti o so le a omiyale  ,ni awon ilu kaakiri .
ọ̀rọ̀ tí mo ń sọ yìí kúrò ní kékeré, nítorí mo fẹ́rẹ̀ kú níbi tí wọ́n ti ń túmọ̀ àlá náà fún mi n kò sì jẹun títí ilẹ̀ ọjọ́ kejì fi sú nítorí àlá náà.
OLUWA tún bi í pé, “Ǹjẹ́ o ṣàkíyèsí Jobu, iranṣẹ mi, pé kò sí ẹni tí ó jẹ́ olóòótọ́ ati eniyan rere bíi rẹ̀ ní gbogbo ayé, ati pé ó bẹ̀rù èmi OLUWA, ó sì kórìíra ìwà burúkú?
Video content Video caption: Coronavirus: Báwo ní gbogbo àgbáyé ṣe lè gba abẹ́rẹ́ ajẹ́sara àrún Coronavirus?
A bii ni ọjọ kejilelogun oṣù kẹta, ọdún 1979, nibi ọdun mẹta lẹyin ti wọn da ipinlẹ naa silẹ.
lowo si ile kikọ, eto ẹkọ ,eto okoowo ati eto ilera.
Ninu atẹjade kan ti akowe iroyin Gomina Taiwo Adisa fowosi, ni gomina ti rọ ara ilu lati ni ifọwọsowọpọ pẹlu oun lati mu ilọsiwaju ba ipinlẹ Oyo.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Akomolede ati asa Yoruba: Ẹ wá kọ́ nípa àpòtí ìṣura èdè wa lórí BBC Yorùbá Nigba ti wọn ni ko wa wi tẹnu rẹ, afurasi ọhun ni oun gba pe oun jẹbi ẹsun ti wọn fi kan oun.
Ọmọ Eleme ni ipinlẹ Rivers ni Lawrence Oyor, wọn bi i lọjọ kẹrindinlogun oṣu kẹfa ọdun 1992.
Oríṣun àwòrán, Twitter Àkọlé àwòrán, Taló ya fídíò ibi tí Aisha Buhari ti ń jà?
Olódùmarè lolùkọ́ àkọ́kọ́, Ọba tó fìmọ̀ mọ gègé lọ́jọ́ ọjọ́ un.
A ko ridi eyikeyi awọn alaye yi fi mulẹ ṣugbọn ohun ti ko ruju ni pe ado oloro ni wọn fi pa Dele Giwa eleyi ti wọn gbe sinu apo ifiweranṣẹ si ni.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Domestic Violence: Ìjà láàrin lọkọlaya sọ aya dèrò ọ̀run Jamilu ni: Zaharadeen ko lo ohun ija kankan, ọwọ lasan ni awọn mejeeji fi jọ n ja lasiko yii ati pe lojiji ni o fun Farawa ni iṣẹ nikun ti iyẹn dẹ ṣubu lulẹ ti gbogbo awọn si sare sibẹ lati gbee dide ki wọn fopin si ija naa.
Nítorí èpè tí wọ́n ṣẹ́ ati irọ́ tí wọ́n pa,
Ó jẹun, ó mu omi, ó sì tún dùbúlẹ̀.
"Ẹ má gbìyànjú láti bo àṣírí ìpànìyàn tó wáyé ní Lekki, á ní ẹ̀rí tó dájú - Amnesty International Wo ojú àwọn òṣèré yìí láì lo ""Make-up"" orí ìtàgé bó ṣe rí gẹ́lẹ́ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Kété tí wọ́n bá ti báa yín sùn tàn torí pé ẹ tóbi, ẹ gbà pé ìfẹ́ yẹn ti parí - Auntie Remi Ọlọ́yàn ńlá Oríṣun àwòrán, Archive Ki lo fa ifẹhonuhan akẹkọọ Ali Must Go?"
Ìyàn ń bọ̀ ní Nàìjíríà lẹ́yìn coronavirus àyàfi.
Mẹ̀kúnnù 80,000 l'Ọṣun ti j'ànfàaní ètò ìlera láìsan kọ́bọ̀ - Oyetola Ẹ wo ìpínlẹ̀ táwọn gómìnà tẹ́lẹ̀ àti igbákejì wọn ń gba dúkìá ìfẹ̀yìntì tabua Ẹ̀tọ́ wa ni!
Ahmẹd Benchemsi, oludari ajọ to n ja fẹtọ ọmọniyan lagbegbe naa ṣapejuwe idajọ yi gẹgẹ bi ''ọjọ buruku'' forile-ede Morocco.
Lakotan, Amẹrika ni o ṣe dandan ki ijọba ri wipe awọn to lọwọ ninu iṣẹlẹ ijinigbe naa foju wina ofin debi to lapẹrẹ.
aafin Enyi I tilu Aba lati sepade pelu awon agbaagba ilu naa.
Wọn ni idi niyi ti iwe kika ninu ẹwọn ṣe pataki fun awọn ẹlewọn.
Ẹgbẹ naa ni dokita Stella ko sọrọ lorukọ apapọ awọn oṣiṣẹ eto ilera, bikoṣe lorukọ ara rẹ.
Wo àwọn míniístà mẹ́fà tí ẹnu ń kùn jùlọ Ọlọ́pàá Adamawa ni #30,000 ni wọ́n fi bọ́ igún látìmọ́lé Mà á ṣiṣẹ́ bí i gómìnà tó ní èrò aráàlú lọ́kàn - Seyi Makinde Irọ́ ni o!
Idí abájọ ni pé ètò tó péye wà fún awakẹ̀kẹ́ lójú títì.
Nítorí náà ni mo fi pàṣẹ fun yín pé, ẹ níláti ya ìlú mẹta sọ́tọ̀.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Shiite protest: Ọ̀gà ọlọ́pàá pàṣẹ́ kí ètò ààbò le si kárakára 26 Agẹmo 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ọ̀pọ ẹ̀mí ló sọnù sí ìkọlù láàrín àwọn ọlọ́pàá àti àwọn ẹlẹ́sìn Shia tí wọ́n ń pè fún ìtúsílẹ̀ adarí wọn, EL-Zakzaky.
Lẹyin rẹ ni igbimọ to n ṣe akoso ajọ NHIS tun ni ki Yusuf lọ rọkun nilẹ.
Ó wípé bí ọjọ́ ṣe ń yí lé ọjọ́, tí oṣù ń yí l’óṣù, tí ọdún yí l’ọ́dún, kí ọpọlọ wá náà máa gbòòrò síi.
ASP Ikoro ṣalaye pe awakọ kan wa ninu awọn eeyan mẹrin to gbẹmi mi ninu iṣẹlẹ naa, nigba ti awakọ keji sa lọ nitori ẹru ba a pe awọn eeyan le lu u pa.
Bakan naa ni awọn oṣiṣẹ ijọba yoo ni anfaani si ida mẹwaa ninu ile igbe ti ijọba apapọ n kọ kaakiri.
Ta ló máa gba iṣẹ́ lọ́wọ́ Theresa May?
Elija kọjá lẹ́gbẹ̀ẹ́ rẹ̀, ó bọ́ ẹ̀wù rẹ̀, ó gbé e wọ Eliṣa.
Ṣugbọn wọn maa saa ba gbawọn eeyan naa ni imọran lati jina si ara wọn ti wọn ba n kẹru si ọkọ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Buhari fi orukọ awọn Minisita tuntun ranṣẹ sile aṣofin 23 Agẹmo 2019 Àkọlé àwòrán, Awọn wọnyii ko ba awọn orukọ tuntun jade Bi àwọn eeyan kan ṣe n pariwo pe awọn ko ri orukọ awọn ti wọn n fẹ ni a rii pe orukọ awọn miran ko si nibẹ.
Ó ń gbé ìlú tí ó ti di ahoro,ninu àwọn ilé tí eniyan kò gbọdọ̀ gbé,àwọn ilé tí yóo pada di òkítì àlàpà.
Aawọ bẹrẹ laarin awọn awọn mejeeji lẹyin ti Ajayi naa fi erongba rẹ lati dije fun ipo gomina, han.
Ikede adinku yi n waye lasiko igba ti ijọba ipinlẹ Eko naa n sọ pe iye awọn to gba itọju nile t'ara wọn si ti ya ti di 10,946 bayi.
ati Quissanga, Gege bi osise ajo isokan agbaye, Deborah Nguyen se so,”Eru n ba wa lopolopo nitori pe, gege bi awon onwoye oju ojo, won ni o tun seese ki ojo a roro da tun waye fun ojo merin miiran gbako,” Wayii, okere tan apapo eniyan ti o le lẹ̀ẹ́dẹ́gbàárun ni o ti ba isele omiyale agbara ya soobu lo bayii jake-jado orile-ede meta ninu osu keta odun ti a wayii.
Ninu atejade kan ti  o waye lojo Aiku, aare Buhari sapejuwe
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Peters Ijagbemi dá àrá lórí ètò 'Ṣé o láyà' ti BBC Yorùbá lọ̀sẹ̀ yìí Awọn ọlọpaa ti n wa awọn to ṣe ọṣẹ naa Awọn ọlọpaa ti gbe oku iya agbalagba naa lọ si ile igboku pamọ si kan, ni ile iwosan nla Tamale Teaching Hospital fun ayẹwo.
A ó ṣèrànwọ́ fáwọn ẹbí ọlọ́pàá tó bá rògbòdìyàn EndSARS lọ láti inú N500m tí a yà sọ́tọ̀- Makinde Nítorí pọpọ́ọ̀fù #200 ní Alaba ilé Sàlámàlékù ṣe da òróró gbígbóná sórí mi- Qudus Kàyééfì!
Eyi jẹ lasiko to n lo ọfa to maa n yọ ina lati fi ja ogun, idi si niyi ti wọn ṣe n pe e ni Timi Agbale Ọlọfa ina.
Oríṣun àwòrán, @IbeKachikwu Àkọlé àwòrán, Kachukwu kawe gboye orisirisi sugbọn iroyin to jade nipa rẹ yi fẹ tapo si aṣọ ala rẹ ''L'ọ́dún ta n wí yí, àmì ẹyẹ márùn ni mo gbà nínú méje tí ilé ẹ̀kọ́ náà fún àwọn akẹ́kọ̀ọ́.
Ní ọdún kẹta tí Asa gorí oyè ní ilẹ̀ Juda, ni Baaṣa pa Nadabu.
Wọ́n Gbé Àpótí Ẹ̀rí Wá sí Jerusalẹmu.
Ni papa isere Ikot Ekpene ni wọn ti n ṣe ayẹyẹ ikini kaabo sinu ẹgbẹ fun un ni ipinle Akwa Ibom.
” Báyìí ni Ọlọrun ti ń ṣe ìpinnu rẹ̀ láti ayébáyé, nígbà tí ó bá yan àwọn kan.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Johesu sẹ́wé lé ìyanṣẹ́lódì Buhari buwọ́ lu òfin ọ̀dọ́ leè dupò Dino Melaye bẹnu àtẹ lù Buhari Dangote mẹnu le ọrọ lasiko to fi kọwọrin pẹlu awọn oniṣowo jankanjankan lorilẹ-ede Naijiria lọ sibi apejẹ iṣinu awẹ eleyi ti aarẹ Buhari ṣeto ni lu Abuja.
Oríṣun àwòrán, Erica Leycon Instagram Erica, tii se olori ile lọwọ lọwọ ni ihuwasi rẹ yii ya awọn akẹẹgbẹ rẹ to wa ninu ile naa lẹnu, paapaa lori ojo eebu ati abuku to n rọ sori Laycon.
Pochettino ni oun ''ṣetan lati ṣiṣẹ pọ pẹlu awọn agbaọjẹ agbabọọlu to wa ni PSG.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Àwọn fíìmì òde òní ń kọ́mọ lólè àti ọ̀pọ̀ ìwà burúkú Ọmọde kan wà ní ẹsẹ̀ kan aye ẹsẹ kan ọ̀run lẹ́yìn ìṣẹ̀lẹ̀ ilẹ̀ rírì ní Croatia Wo àwọn irọ́ ti ọ̀pọ̀ ń pa nípa Coronavirus!
Awọn ibudo idibo ti atundi ti waye loni ni Ifẹ North wọọdu 10; Ifẹ South Olode wọọdu 7; Ifẹ South Osi wọọdu 8; Orolu wọọdu 8 ibudo 001; Orolu wọọdu 8 ibudo 004, àti Osogbo Ataoja wọọdu 5.
Ẹ wo àwòrán tó làmìlaaka níbi Àjọ̀dún Ìlù Ọdún 2019!
Ṣowore ni ifẹhonu han yii, ti yoo bẹrẹ laago meje aarọ ko ni gbedeke ọjọ ti yoo pari, o ni o digba ti ijọba ba gbe igbesẹ ti yoo mu irọrun ba awọn ọmọ Naijiria kawọn to dẹkun ifẹhonu han.
Ohun kan to tun da yatọ ninu fọran fidio orin naa ni bi wọn ṣe lo awọn eto ayẹyẹ igbeyawo wọn ninu rẹ.
 aadogun , aadogbọn , ọwọ ́ èmí ni gbogbo rẹ wa .
O fikun pe o wa wa lọwọ ileesẹ aarẹ lati sawari awọn ikọ alatunto yii, eyi to pe ni ‘Team Restructuring’.
Oluomo sọ eyi ni igba diẹ ṣaaju ki gomina ipinlẹ Ogun, Dapo Abiodun to gbe aba eto isuna ọdun 2021 siwaju ile ni ile igbimọ aṣofin wọn to wa ni Oke-Mosan, Abeokuta.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Goitre Patients: Àwọn èèyàn tó ní àrùn gẹ̀gẹ̀ ní ọ̀pọ̀ ìkórira àti ìdẹ́yẹsí ní àwọn ń kojú O ni oun ti se iwọn ti oun le se, amọ ti wọn ba setan fun irẹpọ Yoruba, ki wọn ke si oun, to si n beere pe se o dara bi awọn ajeji se n fi oju Yoruba gbolẹ nilẹ baba wọn.
Ọba Asiria ni ó kọ́kọ́ fi ṣe ẹran ìjẹ, ọba Babiloni sì ń wó àwọn egungun rẹ̀ tí ó kù.
Wọ́n pa ọpọlọpọ ninu wa, wọ́n pa Hofini ati Finehasi, àwọn ọmọ rẹ mejeeji pẹlu.
Ẹ̀rù yín yóo máa bà wọ́n, nítorí náà, ẹ ṣọ́ra gidigidi; 
Bíi aṣiwèrè tí ó ju igi iná tabi ọfà olóró,
Bí orín bá tètè jáde, tí kò sí dúró pẹ́ títí ní ìgboro, orin mìíràn tí ó ń bá a figagbága lè rọ́ ọ sí ẹ̀gbẹ́.
Losu to koja ni won bẹrẹ lati maa  fọrọ wa aare ana Al- Bashir lẹnuwo lori sise owo ilu kumọ-kumọ ati
Haiti lo dagba si sugbn nigba ti yoo fi lọ si ile ẹkọ giga,Amerika lo ti kawe ni Yunifasiti New York.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Osun Osogbo: Ọdọọdún ni Àtáója ń gbàlejò gbogbo Arugbá lásìkò ọdún Ọ̀ṣun Òṣogbo Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Osun Osogbo: Ọdọọdún ni Àtáója ń gbàlejò gbogbo Arugbá lásìkò ọdún Ọ̀ṣun Òṣogbo 15 Ògún 2019 Ọdọọdun laa ri orogbo, ọdọọdun laa ri awusa, ọdọọdun si laa ri ọmọ obi lori atẹ, amọdun ko si jinna, kẹni ma ri eebu sun jẹ.
Igba wo la maa n saba ri esi idibo Amẹrika?
Ọlọrun pè mí, ó fi mí ṣe òjíṣẹ́, ó sì yà mí sọ́tọ̀ láti máa waasu ìyìn rere rẹ̀.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ọdún kan lẹ́yìn ogun musulumi Rohingya, ìbànújẹ̀ dorí àgbà kodò Olootu agba fun ile ise Iroyin Reuters, Stephen Adler, ni ''ọjọ buruku loni jẹ fun Myanmar,awọn akoroyin mejeeji ati idabo bo awọn akoroyin lagbaye'' Ọpọ eeyan ti se apejuwe ẹjọ naa gẹgẹ bi oun to fọwọkan idaabo bo awọn akoroyin nidi isẹ wọn.
Awọn ti ọrọ naa ṣoju wọn ni dirẹba naa tiraka lati ko awọn nkankan to ku lara ọkọ naa ti o ti le wulọ, lẹyin to ti jọna tan.
Awọn Iroyin mii ti ẹ le nifẹ si Barrister ló sọ mí di èèyàn ńlá - Ayinla Kollington Ìtàn tó wà nídi òwe ‘Sebótimọ Ẹlẹ́wà Sàpọ́n’ Ìtàn tó rọ̀ mọ́ òwe ‘aṣọ kò bá Ọ́mọ́yẹ mọ́.
Ṣùgbọ́n Ijẹ̀bú - Ẹrẹ̀ ni wọ́n kọ́kọ́ máa ń pe ìlú yìí rí nítorí ẹrẹ̀ tí ó ṣe ìdènà fún awọn Ọ̀yọ́.
Oladejo Okediji àti ìgbé ayé ìtàn kíkọ rẹ̀ Nàìjíríà wà ní ìsọ̀rí kejì pẹ̀lú Burundi, Madagascar àti Guinea Kíni ìdí tí àwọn ẹbí àwọn ọmọ Chibok fi ń tọ woli lọ?
"Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, John Amanam: Ìfẹ́ tí mo ní sí àbúrò mi ló sọ mi dí ẹni tó ń ṣe 'Prosthetic' báyìí Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Electricity new tariff: ''Àjọ NERC ti fún Disco láṣẹ láti padà sí owó tàríìfù tuntun iná mọ̀nàmọ́ná''2 Bélú 2020 Fídíò, Oluwaremilekun Fatolu: Mo máa ń wọ kọ́mú “size 50H"", ẹyọkan leè tó N15,000, Okrika N9,0002 Bélú 2020 Olapade Agoro: Olùdíje dùpo aàrẹ Nàìjíríà rí, Owatapa ti Itapa Ijesha, Wolii Olapade Agoro jáde láyé2 Bélú 2020 Fídíò, Soyinka Cancer: Àṣe ara mi ni iso ti n run gbogbo bí mo ṣe n ṣèrànwọ́ lórí jẹjẹrẹ27 Bélú 2019 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 3 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 5 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!"
<Story> Awọn iroyin to suyọ lori ayelujara n sọ pe Iku baba yeye ti da ẹru ọkan lara awọn olori rẹ, Badirat Ajọkẹ, sita.
yoo gbe ise akanse lan  jide .
Lẹyin eyi wọn ni ki awọn oloṣelu ti ọrọ kankan o kan ṣugbọn to wa sile ẹjọ jade kuro ninu ile ẹjọ ti awọn ọlọpaa si lo aja lati ran wọ́n lọwọ ki ero le din ku.
wọ́n ti paá , wọ́n ti paá ẹ lọ jùú si ibẹ̀ yẹn Abesan o fara rọ, bí ẹní to ká fọ́ran náà ṣe n pariwo rèé nígbà ti wọ́n ń gbé okú ẹni náà lọ ibi ti wọ́n ni wọ́n ti pàa.
“Awon ile-ise ohun; Nigeria Communication Satellite, Nigcomsat, National Information Technology Development Agency, NITDA ati Nigeria Postal Service, Nipost.
Lẹ́yìn tí ó bí Enọṣi, ó tún gbé ẹgbẹrin ọdún ó lé meje (807) láyé, ó sì bí àwọn ọmọ mìíràn lọkunrin ati lobinrin.
Agbẹnusọ ajọ NYSC ṣalaye fun BBC Yoruba pe lootọ ni iṣẹlẹ ọhun ṣẹlẹ ati pe awọn ti kan si obi agunbanirọ naa.
O ni daju daju, ijọba mọ si ohun gbogbo to n ṣẹlẹ nipa ijinigbe lorilẹ-ede yii.
al-Mukarramah”Ifowosowopo fun ojo ọla” lati le mu idagbasoke ba isokan awon
NLC, ẹ máa retí ìdádúró lẹ́nu iṣẹ́ 'tórí N30,000 Oríṣun àwòrán, Others Àkọlé àwòrán, Ngige àti àwọ́n òṣìṣẹ́ Awọn gomina l'orilẹede Naijiria ti sọ pe awọn ko ni le san ọgbọn ẹgbẹrun Naira ti ẹgbẹ oṣiṣẹ n beere fun bi bẹẹẹ kọ, ki wọn maa reti idaduro awọn oṣiṣẹ kan lẹnu iṣẹ.
O ni ti wọn ba ni aanu mẹkunu lọkan ni, wọn ko ni fi kun owo epo rara.
Tani DCP Kayọde Ẹgbẹdokun, ọ̀gá ọlọ́pàá tuntun ní ìpínlẹ̀ Eko?
Nibayii, Coronavirus ti ran kọja aala ohun tawọn oṣiṣẹ ilera lee kapa ni South Africa.
Nítorí pé ìpín OLUWA ni àwọn eniyan rẹ̀,ó yan àwọn ọmọ Jakọbu ní ohun ìní fún ara rẹ̀.
CNN fidi iku rẹ mulẹ pe Chef Eric Ripert to jẹ ọrẹ rẹ lo kọkọ rii.
Igbiyanju wa lati ba awọn tile iṣẹ aarẹ sọrọ lori ohun to n ṣẹlẹ yii ko tii bi eso rere di asiko yii.
Aare seleri pe“A ti pinnu lati sowopo da igbe aye alafia ti o joba nile Chad pada si bose wa tele,”Aare fikun un oro re pe: “A ko gbodo feyin ti gba awon oniise ibi laaye lati saseyori lori erongba ibi won gbogbo.
Ni waransesa ni ileeṣẹ ọlọpaa ipinlẹ Kano ti sọ pe ọọ awọn ti ba ti wọn fi ẹsun kan pe wọn ta ibo, wọn si sọ pe wọn n sa agbara wọn lati ri pe lati gbegidina iru iwa yii.
Kí ni kí á wá wí wàyí ò?
"Kíkọ́ ẹ̀kọ́ gboyè nínú iṣẹ́ ìṣègùn ìbílẹ̀ yóò pèsè ìtọ́jú tó péye fọ́mọ Nàìjíríà- Ẹgbẹ́ àwọn dókítà Àtúnṣe òpópónà Lagos-Ibadan àwọn ọ̀ná míràn ti e lè gba EFCC gba ọkọ ayọ́kẹ́lẹ́ 30, òògùn ìbilẹ̀ àti ọ̀pọ̀ fóònù lọ́wọ́ àwọn gbájúẹ̀ Gómínà Bauchi kí olùdíje PDP tó fẹ̀yìn rẹ̀ janlẹ̀ Iwa nabi tu igbeyawo ọgbọn ọdun ka "" Kiìí ṣe gomina lo ni kí a wá dúro de ìyàwó olun , à wá fun ra wa lá gbàá léro láti ṣe bẹ́ẹ̀ pàápaá julọ láti pàde rẹ̀ ni pápákọ ofurufu"" Iyawo gomina ni, ẹni ọwọ sì ni, àsà wa ni lati bu ọlá fun gẹgẹ bi òṣìṣẹ́ gomina."
Ni ọjọ aje ni igbimọ naa gbe igbesẹ ati kọwe naa nibi ipade pajawiri to ṣe nilu Abuja.
aare ni yoo tun maa sọrọ lasiko ti won ba fẹ side ipade apero naa.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Hubert Ogunde ló m'órí mi yá láti di òṣèré Lori idajọ ti ile ẹjọ kọtẹmilọrun ti da ẹjọ ti Onnoghen pe nu, adajọ fẹyinti naa ni ile ẹjọ kotẹmilọrun ni asẹ lati da ẹjọ rẹ nu nitori wi pe Ajọ CCT naa ni asẹ lati gbọ ẹjọ rẹ.
Bawo ni irinajo aarẹ Buhari si ilẹ okere fun igba akọkọ lasiko COVID-19 yoo ṣe ri?
Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí 5:58 Fídíò, Akomolede ati asa Yoruba: Ẹ wá kọ́ nípa àpòtí ìṣura èdè wa lórí BBC Yorùbá, Duration 5,5820 Ògún 2020 International flights resumption: Bàálù ilẹ̀ òkèèrè bà l'Abuja léyìn ìṣéde oṣù márùn ún coronavirus8 Owewe 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
” Ó sọ bẹ́ẹ̀ nítorí ó rò pé alaafia ati ìfọ̀kànbalẹ̀ yóo wà ní àkókò tòun.
Yóo parẹ́ bí àlá,yóo sì di àwátì,yóo pòórá bí ìran tí a rí lóru.
"Nígbà tó ń sọ̀rọ̀ nípa ohun tí àwọn ẹbí fẹ́ máa fi ṣe irántí Gbenga Adeboye, Oluwadamilola ni ""èmi àti màmá pẹ̀lú àwọn àbúrò mi ti pinnu láti máa ṣe atilẹyin fún àwọn osere tó ṣẹ̀ṣẹ̀ ń dìde nilẹ láti ìpilẹ̀ṣẹ̀, ní kété tí ajakalẹ àrùn Coronavirus bá ti tan."
Akeredolu ni, eto aabo gbọdọ fi ẹsẹ mulẹ lati ẹnu iloro ipinlẹ kan si ikeji ni ẹkun iwọ-oorun guusu.
Gege bi adajọ agba nile ejo giga, Abdu Kafarati tun se alaye idi pataki lati tun yan awon adajọ miiran lojuna ati mu adinku ba ise won gbogbo.
“Bí ẹnìkan bá fẹ́ rú ẹbọ alaafia, tí ó sì mú ẹran láti inú agbo ẹran rẹ̀ fún ẹbọ náà, kì báà jẹ́ akọ tabi abo, ó níláti jẹ́ èyí tí kò ní àbààwọ́n níwájú OLUWA.
Ìyá mi ti fi àkísà nu ojú rẹ̀, ṣùgbọ́n omijé kò í tì í bọ́ ní ojú rẹ̀.
lẹ́yìn rẹ̀ Hilikaya, Tebalaya ati Sakaraya.
Bí ogun tilẹ̀ dó tì míàyà mi kò ní já.
Mikaya dáhùn pé, “Ojú rẹ yóo já a ní ọjọ́ náà, nígbà tí o bá lọ sá pamọ́ sí kọ̀rọ̀ yàrá.
Ileeṣẹ ọlọpaa ni awọn ko tii lee sọ ni pato boya igbenipa ni iku rẹ ni abi nnkan miran.
Gege bi balogun iko ohun, Gary Cahill se so,“A sise takun-takun lati gba ife eye yii,  lati ye saa wa todun yii si, lataari aise deede wa ninu olokan-o-jokan idije yooku ti a kopa ninu re.
Ẹgbẹ́ òṣèlú PDP ní ìpínlẹ̀ Bayelsa jáwé olúbori nínú ìdìbò ìjọba ìbílẹ̀ Àṣìta ìbọn ló pa obìnrin nílùú Eko lọ́jọ́ Satide- Ọlọ́pàá Òṣùká kékeré kò rẹrùn àgbà, orílẹ́èdè Nàìjíríà ṣòro púpọ̀ láti darí - Ibrahim Babangida Sowore ṣèpàdé pẹ̀lú Nnamdi Kanu láti dojú ìjọba Nàíjíríà bolẹ̀ - Àjọ DSS Ilééjọ́!
Iléeṣẹ́ aṣọ́bodè gba àgbá ọjà tó kún fún ẹrù ogun
Ti a ko ba gbagbe, ọdun 2016 ni Facebook ti bẹrẹ iwadii lori awọn iroyin ẹlẹjẹ to jade lasiko idibo sipo aarẹ ni ilẹ Amẹrika to waye ni ọdun naa, ti o si gbe aarẹ Donald Trump.
Bí o bá ń gbọ́ tèmi, tí o sì ń pa gbogbo àwọn òfin, ati àwọn ìlànà mi mọ́, gẹ́gẹ́ bí Dafidi, baba rẹ ti ṣe, n óo fún ọ ní ẹ̀mí gígùn pẹlu.
 Àwọn aládùgbóò tàbí tí wọ ́ n jọ sún mọ ́ ara wọn ni : ibibo , igbo , mama àti mumuye .
O ti ko ipa ribiribi ni agbọn kan abi omiran, ko to de ipo gomina.
Eyi jẹ asalẹ maleegbagbe fun akọnimọọgba fun ẹgbẹ agbabọọlu Watford, Javi Gracia ati akọnimọọgba fun ẹgbẹ agbabọọlu Chelsea, Antoni Conte.
Gẹgẹ bi iwe iroyin Nigerian Tribune se gbe sita, Tokyo lo kọkọ pe Auxillary lori aago lẹyin ọdun mẹwa ti igbakeji rẹ naa, ti yẹ aga mọ nidi, ti Lateef Salakọ Eleweọmọ si di alaga.
Àbí ẹ kò mọ̀ pé ẹni tí ó bá alágbèrè lòpọ̀ ti di ara kan pẹlu rẹ̀?
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Yahoo Yahoo: Ọ̀pọ̀ olórin ti kọ́rin ìwúrí fún àgbéga rẹ̀ 14 Èbibi 2018 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 15 Èbibi 2018 Àkọlé àwòrán, 'Yahoo-yahoo' tàbí 419, kìí ṣe tuntun ní Nàìjíríà, bí ó tilẹ̀ jẹ́ wí pé ìwà ọ̀daràn ni.
 babiesessence nikan ni ile-iṣe rẹ ti o wa ni naijiria .
Ọjọ́ ìṣòro ni ọjọ́ náà yóo jẹ́ fún àwọn aboyún ati àwọn tí ó ń fún ọmọ lọ́mú ní àkókò náà.
‘Alágàbàgebè yóò máa tí orí ìtìjú dé ìtìjú, òun kì í ṣe ẹni òkè, yóó maa wà láàrin àwọn èrò ẹ̀hìn láéláé.
Orile-ede America ti pase ifofin de ogagun-agba kan lorile-ede Congo, latari pe, oun ni igi woroko ti n dana ru to wa leyin laasigbo ti o n waye lorile-ede naa.
Awosanya ni Ile Igbimọ Aṣofin Agba ati minisita fun ọrọ abẹle Abdulrahman Dambazau ti gbọ si ọrọ naa.
Bakanna ni wọn n gbeero lati fi awọn idije kan han lori amohunmaworan lọfẹ.
67 year old mother: Ìdílé Otubusin yọ ayọ̀ ọmọ lẹ́yìn ìgbéyàwó ogójì ọdún
"Wọn yin eniyan meji nibọn, lara wọn ni ọmọ ọdun mẹtala ọkunrin kan to ti n gba itọju nile iwosan bayii""."
Osadebe to jẹ awako nigba kan ni nigba ti aisan oun bere ni oun lọ ilu awọn fun itoju ti iyawo oun si kọ lati tẹle oun lọ.
Kunle Fela Anikulapo-Kuti: Olótìítọ́ ni Fẹla
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Toma Unu: Ọmọbìnrin tó ń fi ẹsẹ̀ rẹ̀ ya àwọran nítori pe ó ni ìpènija ọpọlọ O wa kesi gomina tuntun fun ipinlẹ Ọyọ, Onimọ Erọ Seyi Makinde, pe ko ma ṣe yi ohùn pada lori awọn ileri to ṣe lasiko to n polongo ibo.
Iṣẹ́ ti òní tó máa retí mi ní kùtù hàì òwúrọ̀ ọ̀la.
Bakan naa, ni o ro awon adari lati mu eto-ilera lokunkun-dun, toripe, oke aimoye awon eniyan ni ko ni anfaani si eto-ilera rara.
Nibayii ti gomina ipinlẹ Edo, Godwin Obaseki ti wọlẹ pada, awọn oniroyin bere ẹ lọwọ boya yoo gba ki awọn aṣofin mẹrinla ti ẹgbẹ oṣelu APC pada si Ile Igbimọ Asofin?
Peppiat ni loorekore ni awọn eeyan maa n ni ki ohun wa wo irufẹ iṣẹ ọna naa ti o si jẹ wi pe ọpọ ninu wọn ni kii ṣe ojulowo.
Kí ló dé tí inú rẹ fi ń ru sí àwa aguntan pápá rẹ?
Serena Williams ti yọwọ ninu idije Italian Open ti yoo waye ninu osu yii ni ilu Rome.
Gbogbo ewé wọnyi wúlò fún àyiká ju ọ̀rá ti wọn ńlò lati pọ́n oúnjẹ láyé òde òni.
Ẹ má tan ara yín jẹ: eniyan kò lè mú Ọlọrun lọ́bọ.
Èmi nìkan ni mo dá wà níbẹ̀.
Sugbọn ọpọ wa la n gbe ni ayika ti imọlẹ ti yi wa ka, sugbọ o le seranwọ fun ara rẹ nipa mimu adinku ba imọlẹ to wa ni ayika rẹ, nigba to ba ku wakati kan to fẹ sun.
Laipẹ ni ẹgbẹ yii figbe ta ti wọn si fi ọrọ ranṣẹ pe ki aarẹ Muhammadu Buhari fopin si eto agbelewo naa ni kiakia tori pe iwa ibajẹ pọ nibẹ.
Yóo lọ sibẹ ní alẹ́, ní òwúrọ̀ yóo pada wá sí ilé keji tí àwọn ayaba ń lò, tí ó wà ní abẹ́ ìtọ́jú Ṣaaṣigasi, ìwẹ̀fà tí ó ń tọ́jú àwọn obinrin ọba.
Ati fi ara balẹ̀ yẹ ìfọ̀rọ̀wánilẹ́nuwò nínú ètò náà wò dáadáa, ní ìbámu pẹ̀lú kókó tó ń kọ wọn lóminu.
Oríṣun àwòrán, others Nínú ọ̀rọ̀ rẹ̀, agbẹnusọ ọlọ́pàá ìpińlẹ̀ Ekiti, ASP Abutu Sunday sàlàyé pé, ọlọ́pàá to ṣe iṣẹ́ aburu náà ti wa lagọ̀ọ́ ọlọ́pàá báyìí.
tun so pe “Won gbodo le e lo awon ajo eleto idibo lona ti won ko fi ni
Ijọba apapọ ni awọn ko ni aadọta miliọnu naira ti awọn fẹ san bayii, amọ aarẹ ẹgbẹ ASUU ni awọn yoo lọ ba awọn eniyan awọn sọrọ ṣaaju ọjọ ti wọn sun ipade si.
Iru awọn eeyan wo ni awọn oluwọde to wa nibẹ.
Awọn orilẹede mẹwa, t'oun ti orilẹede ti ọrọaje rẹ gbooro ju l'Afrika, Naijiria, wọn kọ jalẹ lati f'ọwọ si eto naa nitori ibẹru pe ole la iṣẹ lọ.
Èyí ló mú kí àwọn ọmọ Naijiria máa kọ ha pe, kí lo fi sorí tí ẹlòmiran o ṣe, kí ní ìdí ti Dikko kò fi ní ṣẹ̀wọ̀n.
"Odumakin sọ fun BBC Yoruba wi pe: ""Afenifẹre ko ṣe ipade kankan pẹlu Buhari."
gba gómìnà walter egerton ní ìyànjú lórí ètò ẹ ̀ kọ ́ ní Ìpínlẹ ̀ Èkó .
“Nígbà tí ẹ bá dé ilẹ̀ tí OLUWA Ọlọrun yín fun yín, ẹ kò gbọdọ̀ tẹ̀lé ìwà ìríra tí àwọn orílẹ̀-èdè náà ń hù.
Gege bi iroyin se so, O ni, awon miran farapa yanayana ninu isele ohun ti o waye lasiko ayajo odun Nawruz.
Olóore ọ̀fẹ́ ati olódodo ni OLUWA,aláàánú ni Ọlọrun wa.
Ó sọ ìmọ́lẹ̀ ní ọ̀sán, ó sì sọ òkùnkùn ní òru.
Wọn kì í tan fìtílà tán kí wọ́n fi igbá bò ó; lórí ọ̀pá fìtílà ni wọ́n ń gbé e kà.
Nígbà tí omi tán ninu ìgò aláwọ náà, Hagari fi ọmọ náà sílẹ̀ lábẹ́ igbó ṣúúrú kan tí ó wà níbẹ̀.
“gbagede isale, yoo wa fun awon ololufe iko agbaboolu orile-ede kookan fun atileyin, ipa, ife ati ifarajin won lati je ki idije agbaye naa wa yorisayo.
Wọ́n wá run ilẹ̀ náà,ati gbogbo ohun tí ó wà ninu rẹ̀,ati ìlú ati àwọn tí wọn ń gbé inú rẹ̀.
Nítorí ọmọde ni wá,a kò mọ nǹkankan,ọjọ́ ayé wa sì dàbí òjìji.
Òun ni baba ńlá àwọn ìdílé Ahaheli, ọmọ Harumu.
Ninu ìnira, o ké pè mí, mo sì gbà ọ́;mo dá ọ lóhùn ninu ìjì ààrá, níbi tí mo fara pamọ́ sí;mo sì dán ọ wò ninu omi odò Meriba.
OLUWA dójúlé wọn nítòótọ́ títí gbogbo wọn fi parun patapata ninu ibùdó àwọn ọmọ Israẹli.
Rọ òróró kún inú ìwo rẹ kí o lọ sọ́dọ̀ Jese ará Bẹtilẹhẹmu, mo ti yan ọba kan fún ara mi ninu àwọn ọmọ rẹ̀.
9 42805 Orilẹede Lebanon 1099 16.
Urine Colour: Fídíò Lahanmi yìí ló ń ṣàlàyé nípa ọ̀pọ̀ àìsàǹ tó rọ̀ mọ́ bí ìtọ̀ wa ṣe rí
Bakan naa ni minista fun àṣà ati iṣẹṣe, Lina Mendoni naa fi atẹjade sita pe igbesẹ naa ku diẹ kaa to.
Àjọ JAMB kéde ìlànà ìgbà ni wọlé tuntun fún àwọn ilé ẹ̀kọ́ gíga Ọwọ́ ikọ̀ aláàbò STF tẹ afurasí mẹ́jọ tó lọ́wọ́ nínú ìpànìyàn lemọ́-lemọ́ọ Gúúsù Kaduna Èèyàn 290 míràn ló ṣẹ̀ṣẹ̀ fara káásá àrùn Covid-19 ní Nàìjíríà, 160 gbàwòsàn Ọwọ́ ikọ̀ aláàbò STF tẹ afurasí mẹ́jọ tó lọ́wọ́ nínú ìpànìyàn lemọ́-lemọ́ọ Gúúsù Kaduna Amọ o ni ipolongo ẹlẹkundẹkun ni yoo fihan bi awọn eniyan ṣe fẹran awọn oludije naa si.
 eni ti o se awari naa ni shoemaker ati e.
Bakan naa ni ọkan lara awọn ẹlẹrii tọka si Ọba Asusumasa Atewogboye pe, oun lo ran wọn nisẹ ipaniyan naa, ti wọn si lọ mu Ọba si atimọle lọgan.
Bayelsa Election: Ẹgbẹ́ òṣèlú APC kọ̀ láti kópa nínú ìdìbò, PDP jáwé olúborí
Ṣugbọn tiyín kò ní rí bẹ́ẹ̀.
Mercy, Cindy ati Jackye ja fitafita lati moke ninu abala to kẹyin, ṣugbọn Khafi la gbogbo wọn mọ lẹ.
" Bẹẹ ba si gbagbe, BBC Yoruba ti se ifọrọwanilẹnuwo ri fun Olori Anu, ẹni to yonbo Ọba Adeyemi pupọ, to si ni o n kẹ oun loju-nimu, eyi ti ọdọkunrin miran ko le se.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Downsyndrome: Dayo ń wa mótò, ó fẹyawọ, o tún lọ ilú òyìnbó Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Downsyndrome: Dayo ń wa mótò, ó fẹyawọ, o tún lọ ilú òyìnbó 6 Ọ̀pẹ̀̀ 2019 Baba Dayo ni ǹkan tí òun ti rí nípa ọmọ rẹ̀ tó ni Downsyndrome fi han pé kò sí ọmọ ti ko wúlò .
Lẹ́ẹ̀kọ̀ọ̀kan nínú ìwé mi mo máa ń sọ̀rọ̀ kan ibẹ̀ ṣùgbọ́n kò ni fèsì apa ibi tí moti sọ̀rọ̀ náà nígbà tí o bá máa fún mi ni èsì.
Ikú, bo je t'ọmọdé tàbí àgbà jẹ nnkan tí ó máa ń ba ni nínú jẹ.
Nígbà náà ni àwọn ọba Amori maraarun, ọba Jerusalẹmu, ti Heburoni, ti Jarimutu, ti Lakiṣi, ati ti Egiloni parapọ̀, wọ́n kó gbogbo àwọn ọmọ ogun wọn jọ.
Ẹ jìnnà sí alágbèrè obinrin,kí ẹ má tilẹ̀ súnmọ́ ẹnu ọ̀nà rẹ̀,
Fidio ti BBC Yoruba se nipa ile Adebisi to wa ni Idikan ree nisalẹ yii: Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Adebisi Idikan: Òun ló gba Ìbàdàn sílẹ̀ lọ́wọ́ ìyà owó orí sísan A wa n gbadura pe Ọba oke yoo dẹ ilẹ fun Asiwaju Sanusi Adebisi Giwa Idikan, gẹgẹ bi a se n ranti iwa rere to gbe ile aye se lasiko yii, nitori bi onirese rẹ ko tilẹ fin igba mọ, awọn eyi to ti fin silẹ, ko parun rara.
Ní àkókò ẹbọ àṣáálẹ́, mo dìde kúrò níbi tí mo ti ń gbààwẹ̀ pẹlu aṣọ ati agbádá mi tí ó ya, mo kúnlẹ̀, mo sì tẹ́wọ́ sí OLUWA Ọlọrun mi, mo gbadura pé:
Ẹsẹ̀ rẹ̀ dàbí idẹ tí ń dán, tí alágbẹ̀dẹ ń dà ninu iná.
“Kí n tó dá ọ sinu ìyá rẹ ni mo ti mọ̀ ọ́,kí wọ́n sì tó bí ọ ni mo ti yà ọ́ sọ́tọ̀,mo yàn ọ́ ní wolii fún àwọn orílẹ̀-èdè.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Kí ló le è mú kí agbábọ́ọ̀lù subú, kó sì kú lásìkò ìfẹsẹ̀wọ̀nsẹ̀?
’’Aare tun wa seleri pe eni to ba je olootọ,
nígbà tí wọ́n bá ṣe akiyesi ìwà mímọ́ ati ìwà ọmọlúwàbí yín.
Ọpọlọpọ ọdún ni o fi mú sùúrù pẹlu wọ́n, tí o sì ń kìlọ̀ fún wọn nípasẹ̀ Ẹ̀mí rẹ, láti ẹnu àwọn wolii rẹ, sibẹ wọn kò fetí sílẹ̀.
”Eto Ilana TuntunGege bi aarẹ se sọ, o ni ajo ECOWAS ko ni pe gbe eto ilana kan jade ni eyi ti yoo tun je ki awon omo egbe ECOWAS tun wa ona miiran nipa eto oro aje ati lati maa se okoowo pelu orile ede China.
Ṣaaju ni ọjọ Aje, ọjọ kẹrinlelogun, oṣu kẹjọ, ọdun 2020 ni wọn ti fi Alhaji Aderẹmi Jimoh jẹ oye babalọja gẹneral kan naa ni gbọngan awọn lọbalọba ipinlẹ Ọyọ.
Bẹẹ ni iye awọn to ti ri iwosan gba ti da mẹfadinlẹgbẹjọ, ti eniyan mejilelọgọsan si ti ri iwosan gba.
Nítorí n óo rú ọpọlọpọ orílẹ̀-èdè sókè, láti ìhà àríwá, n óo sì kó wọn wá, wọn óo wá dóti Babiloni, wọn yóo gbógun tì í.
Laarin isẹju mẹrinlelogun,awọn ikọ mejeeji ti gba ayo meji meji wọ ile ara wọn.
Coronavirus: Ètò Làá hàn mí yìí ló ń kìlọ̀ fún wa láti mú ìmọ́tótó ní pàtàkì, ká le è dènà Coronavirus
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Omar Al-Bashir ti wọ́n gbajọba lọ́wọ́ ẹ ló di wàhálà Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Mársì áà le mọ́lẹ̀ bíi Júpítérì fún ìgbà díẹ̀ tó bá wà ní ààyè kan pàtó lórí ojúọ̀nàìyípo rẹ̀.
mú ọrẹ ẹbọ wá siwaju OLUWA.
A ó san án fún un lẹ́kùn-únrẹ́rẹ́ lọ́jọ́ àìpé,gbogbo ẹ̀ka rẹ̀ ni yóo sì gbẹ.
Lẹyin naa lo dupẹ lọwọ awọn alatilẹyin rẹ fun ifẹ wọn lori idile rẹ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Seyi Makinde: Àwọn ọba yoo ko ipa pataki lati gbogun ti aabo to mẹhẹ 20 Òkùdu 2019 Oríṣun àwòrán, Google Àkọlé àwòrán, Gomina ipinlẹ Ọyọ naa ni awọn ọba yoo ko ipa pataki lati gbogun ti eto aabo to mẹhẹ ni ipinlẹ naa.
ẹ wo àwọn eniyan burúkú bí wọ́n ti kẹ́ ọfà;wọ́n fa ọrun;wọ́n sì fi òkùnkùn bojú láti ta olódodo lọ́fà.
Ṣugbọn nigba ti o ba BBC Yoruba sọrọ, Ọgbẹni Jide Onigbogi to jẹ oludari idasoke okowo ileewe Chrisland ṣalaye pe ọpọ ninu awọn obi awọn akẹkọọ ileewe naa lo fọwọ sii pe ki saa igbẹkọọ tuntun bẹrẹ lori ayelujara.
O ni koda, awọn ara ilu ṣi le maa yọju sibẹ nigba to ba wu wọn.
Diṣani ni baba Usi ati Arani.
Ẹka alaṣẹ ko wule gbiyanju lati ni ki Magu yọju nigba kẹta .
Àwọn nǹkan tí obìnrin lè ṣe pẹ̀lú olólùfẹ́ oníwà ipá lásìkò ìgbélé Coronavirus yìí Ilé ẹjọ́ tú ìgbéyàwó ọdún mọ́kànlá ká nítórí pé ìyàwó fí ìbálòpọ̀ dun ọkọ rẹ̀ A kọ òfin gígé nǹkan ọkùnrin tó bá fipá bá obìnrin lòpọ̀ - Àwọn Alfa yarí Iwa nabi tu igbeyawo ọgbọn ọdun ka Tẹgbọn-taburo se igbeyawo ni Anambra Wo bí ìgbéyàwó ọmọ bàbá olówó, Adama Indimi àti Prince Malik Ado ọmọ Ọba Ohinoyi ilẹ̀ Ebira ṣe lárinrin tó Oríṣun àwòrán, Gistreel.
Báwo lẹ ṣe wọnú ọdún titun?
O si jẹwọ pe ilẹ isinku to wa ni Oke-Eri nilu Ijebu-Igbo, ni oun ati ẹnikan ti ge awọn ẹya ara naa."
Gambia, Ivory Coast, ati Rwanda ti fi ofin de awọn eroja ibora to ni hydroquinone ninu.
14 Àti pé ẹlòmíràn ni èmi kì yíò fún ní agbára yìí, láti gba ẹ̀rí yìí kannáà láàrin ìran yìí, nínú ìbẹ̀rẹ̀ ti ìgbédìde yìí àti ìjádewá ìjọ mi láti inú aginjù—kedere bíi òṣùpá, tí ó sì mọ́lẹ̀ bíi oòrùn, tí ó sì ní ẹ̀rù bíi ẹgbẹ́ ọmọ ogun pẹ̀lú àwọn àsìá.
Eyi tun mọ si wi pe nigba ti awọn ọmọkunrin ba n lọ si ile iwe ti wọn si n ṣe oun ti yoo mu ọjọ iwaju wọn dara, obinrin lo lẹtọ lati ṣe iṣẹ ile tabi ki wọn fi fun ọkọ, ki wọn ba le ri owo fi seun to tọ ni ile.
Labẹ ofin orilẹede Naijiria, ẹsun kan ti Ile Igbimọ Aṣofin Ipinlẹ le fi kan Igbakeji Gomina lati yọ ni ipo, ni ti tapa si ofin orilẹede Naijiria.
Àwòrán-an Emma Lewis, a lò ó pẹ̀lú àṣẹ.
Eyi ti won ti se amulo ero naa ninu orisirisi idije lagbaye.
Gba àwọn eniyan rẹ là, OLUWA,kí o sì bukun ilẹ̀ ìní rẹ.
Ọmọ Naijirià di ààrẹ fún ìpéjọpọ̀ àjọ UN Iṣẹ́ Kudirat Abiọla ṣì ń fọhùn síbẹ̀, lẹ́yìn ọdún 23 tó papòdà Àwòran bó ṣe ń lọ káàkiri àwọn Yídì rèé NURTW yóò fikùlukù pẹ̀lú Gómìnà Makinde láìpẹ́ Aarẹ ni ki Osinbajo tọju ara rẹ o ki aarẹ ma daa lulẹ tori ailokun rẹ lee mu ailokiki ba ijọba to wa lori alefa ti awọn eniyan ko si ni mọ riri iṣẹ takun takun ti awọn n ṣe.
O ní ọ̀nà ti àwọn ọmọlẹ́yìn Kristi yóò fi ri ìtójú gbà lọ́dọ̀ ìjọba lo jẹ ajọ CAN lógun jùlọ, èyí si ni àwón maa n múgbọ.
Ọdun kan ati oṣu mẹrin pere ni mo fi ṣe igbeyawo o si da bii ọrun apaadi ni.
Ìtàn ìgbé ayé Isola Ogunsola 'I-sho Pepper', ògbóǹtagí òṣèré tíátà tó s'eré Yorùbá yíká Nàìjíríà Kí ló wà ní ìdí igbá tí àwọn olorì Aláàfin máa ń tí lóde Ọ̀yọ̀ Ìjà Awolowo, Akintola àti ogun 'Wẹtiẹ', ẹ̀kọ́ wo ló kọ́ wa?
 rosia ni bode mo awon orile-ede wonyi ( latiariwaiwoorun de guusuilaorun ) : norway , finland , estonia , latvia , lithuania ati poland ( lati egbe kaliningrad oblast ) , belarus , ukraine , georgia , azerbaijan , kazakhstan , saina , mongolia , ati north korea .
Ẹ rán ọ̀kan ninu yín kí ó lọ mú àbíkẹ́yìn yín wá, ẹ̀yin yòókù ẹ óo wà ninu ẹ̀wọ̀n títí a óo fi mọ̀ bóyá òtítọ́ ni ọ̀rọ̀ yín, bí bẹ́ẹ̀ kọ́, mo tún fi orúkọ Farao búra, amí ni yín.
Ọpọ ọmọ Naijiria ninu ọrọ yii lo si fi oju han pe wọn ti sọ ireti nu nipa orílẹede Naijiria.
Naijiria fun ti odun 2018, eleyii to waye ni ile-ise omo ogun to wa ni Maimalari
Ẹ óo dá wọn lóhùn pé, ‘A ti jẹ́ ẹrú Farao ní ilẹ̀ Ijipti rí, ṣugbọn agbára ni OLUWA fi kó wa jáde kúrò ní ilẹ̀ Ijipti.
Ayé kí wọ́n máa jowú ara wọn!
Melaye ni, òkun ọrun ko ye adiẹ, nítorí náà kò tọ́ bi Aare Buhari ṣé sọ iru ọrọ bẹẹ sì àwọn aṣòfin.
Nígbà náà ni Jesu ṣe akiyesi pé ó fi òye sọ̀rọ̀, ó wí fún un pé, “Ìwọ kò jìnnà sí ìjọba Ọlọrun.
Tàpá sí ìlànà ìdáàbò bò Coronavirus, ko rí ìdánilẹ́kọ̀ọ́ òjijì he - Ìjọba Osun Àjọ NCDC kéde ènìyàn 561 tó tún ṣẹ̀ṣẹ̀ ní Coronavirus ní Nàìjíríà Oríṣun àwòrán, @NPOWER_NG TWITTER Iye eeyan meloo ni N-Power fẹ gba siṣẹ lọdun 2020?
Nígbà tí ọdọmọkunrin náà gbọ́ ọ̀rọ̀ yìí, ó kúrò níbẹ̀ pẹlu ìbànújẹ́ nítorí ó ní ọrọ̀ pupọ.
Ọlọ́run yóò ṣe ìdájọ́ nkan tó wà láàrin èmi àti Ireti Ajanaku - Tope Alabi A kò mọ̀ọ́mọ̀ pa ọlọ́pàá mẹ́ta, aráàlú kan, ó ṣèèsì ni, ajínigbé la pè wọ́n - Iléeṣẹ́ ológun Sowore àti àwọn ọmọ ẹgbẹ Revolution Now kò ṣẹ̀ ṣófin lórí ìwọ́de, ẹ tú wọn sílẹ̀ - NLC Òṣùká kékeré kò rẹrùn àgbà, orílẹ́èdè Nàìjíríà ṣòro púpọ̀ láti darí - Ibrahim Babangida Adajọ Taiwo ti wa sun igbẹjọ naa di ọjọ Kọkanlelogun osu Kẹsan ọdun 2019.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù University of Transportation Daura: Nǹkan mẹ́wàá tó yẹ ní mímọ̀ nípa fásitì ẹ̀kọ́ ìrìnnà 2 Ọ̀pẹ̀̀ 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 3 Ọ̀pẹ̀̀ 2019 Oríṣun àwòrán, Buharisallau1 Àkọlé àwòrán, Nǹkan mẹ́wàá tó yẹ ní mímọ̀ nípa fásitì ẹ̀kọ́ ìrìnnà Aarẹ Muhammadu Buhari ti lọ ṣe ifilọlẹ fasiti onimọ nipa irinna akọkọ iru rẹ ni Naijiria.
Ọpọlọ àwọn miran nínú aláìsàn yìí kò sì ní pe mọ kí wọn tó kú nítorí ìrora ńlá tí wọn ń jẹ.
”“Nitori naa, gege bi o se wa labe ofin ile igbimo asofin pe ki won maa
Nǹkan mẹ́sàn án tí Mùsùlùmí gbọdọ̀ ṣe nínú oṣù Dhual- Hijjah Ilé ẹjọ́ wọ́gilé ìgbẹ́jọ́ Olalekan 'Woodberry' Pọnle Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Kogi vs Bayelsa: Primate Ayodele sọ àsọtẹ́lẹ̀ Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
"Àwọn gómìnà kìí ṣábà buwọ́ lu àṣẹ láti pa ẹlẹ́wọ̀n, bákan nàá ni wọ́n kìí fún wọn ní òmìnira, ló fàá tí àwọn ẹlẹ́wọ̀n tó n retí ikù pọ̀.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ẹ̀yin obìnrin, ẹ lọ kọ́ iṣẹ́ káfíńtà torí ó lówó lórí ju iṣẹ́ aránṣọ lọ"" Àwọn ọmọbíbí ìpínlẹ̀ Ọyọ nìkan ni yóò rí iṣẹ́ àgbàṣe gbà lábẹ́ ìjọba mi - Seyi Makinde Àwọn obìnrin yarí, wọ́n kò fẹ́ àwọn ọkùnrin ní òde ijó wọn Asọ́ ń pe aṣọ ránsẹ́ níbi ayẹyẹ ojúde Ọba ní'lùú Ijẹbu Ninu atẹjade kan ti Giwa ajọ LASWA, Emmanuel Oluwadamilọla fi sita, eeyan mẹtala ni wọn yọ laaye ninu ijamba naa to waye alẹ ọjọ iṣẹgun."
Awọn oúnjẹ to sara loore ni wọn maa n fáwọn akẹkọọ yii jẹ, ninu eyi ti odidi abi idaji ẹran adìẹ wa.
Kírìtì Oti Méjì Ìgò ògógóró 501 kan Obì ẹyọ mérin Ẹgbẹ̀rún kan Náírà láti la obì Kándu, àṣọ funfun àti pupa Lẹ́yìn ìpèsè gbogbo ǹkan wọnyìí Godwin rọ ojò lẹyìn wákatí méjì, ti ojò náà rọ fun ìṣẹ́jú márùn kó to dá.
’ rèé Ìgbín ní èmi àti ìyá mi máa ń he kiri, ká tó lee jẹun - Lizzy Anjọrin Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí 2 sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 2:23 Fídíò, Water Generator: Ó leè ṣiṣẹ fún wákàtí mẹfà, kó tó sinmi, Duration 2,2310 Òkùdu 2020 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
Bukola Saraki: Àìbọ̀wọ̀ f'áṣẹ ilé-ẹjọ́ n'ìgbẹ́sẹ̀ EFCC láti gba ilé mi ní Ilorin
Jesu yìí ti kú, ṣugbọn Paulu ní ó wà láàyè.
A máa ṣíjú àánú wo àwọn aláìní ati talaka,a sì máa gba àwọn talaka sílẹ̀.
Oyetola fikùn pé àṣẹ ọhun, tí yóò bẹ̀rẹ̀ lọ́jọ́ Ajé ọjọ́ kẹrin oṣù karùn-ún, ní yóò tún mú kó rọrùn fún ìjọba láti darí Ìpínlẹ̀ náà bọ ṣe yẹ.
Wo bóo ṣe lè mọ̀ ayédèrú Gbọ́ ọ̀rọ̀ lẹ́nu afurasí tí Ọlọ́pàá ní ó pa Barakat Bello, Grace Oshiagwu àtàwọn míì l'Akinyele Ibadan Pasuma kìí ṣe ọkọ mi o!
Ajọ oṣiṣẹ pajawiri ni ipinlẹ Eko, LASEMA fi iroyin ijamba ọkọ to waye ni alẹ Ọjọ Iṣẹgun naa lede ni oju opo ikansiraẹni Facebook wọn.
Ọ̀kanòjọ̀kan ọnà ni ó wà ní ara ilé náà  àwọn àràbarà ọnà abẹ́ àjà àti bẹ́ẹ̀ bẹ́ẹ̀ lọ.
Lara awọn ayeye ti yoo ma waye ni ile igbafe naa ni, awọn olorin takasufe ti yoo ma lu ilu si awọn eniyan ni ibadi ati awọn alasọ alarabara ti yoo ma fi ẹwa wọn han nibi ayẹyẹ naa.
Iwe Iroyin kan sọ pé Baba Wande fẹsun kan Tunde Kelani wi pe owo to tọ si oun, kọ ni wọn fun oun lori fillmu naa ti o si jẹ wipe oun lo kọ itan naa.
Meji ni wọ́n pín àwọn ẹ̀yà Josẹfu sí, àwọn ìpín mejeeji náà ni ẹ̀yà Manase ati ti Efuraimu.
Ṣimei, ọmọ Ela, ni alákòóso agbègbè Bẹnjamini.
Wọn ni eyi ṣẹlẹ lẹyin ti awọn janduku jo ile ijọsin naa nina lalẹ ọjọ ti wọn n fẹhonu han.
Fun ọpọlọpọ ọdun, siga mimu mu awuyewuye wa ni eyi to fi di ọrọ arugbo ṣoge ri, akisa lo ìgbà rí.
Reubẹni bá dá wọn lóhùn, ó ní, “Mo sọ fun yín àbí n kò sọ, pé kí ẹ má fi ohunkohun ṣe ọmọ náà?
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Èèyàn mi mẹ́ta ló wà nínú ọkọ̀ ojú omi tó dà nù!
Femi naa wa gba awọn tọkọtaya nimọran pe, ti igbeyawo wọn ko ba mu adun lọwọ, yoo dara ki wọn pin gaari, ki olukaluku si ba tirẹ lọ.
Nataniẹli bi í pé, “Níbo ni o ti mọ̀ mí?
Nígbà tí Josẹfu rí Bẹnjamini pẹlu wọn, ó sọ fún alabojuto ilé rẹ̀, ó ní, “Mú àwọn ọkunrin wọnyi wọlé, pa ẹran kan kí o sì sè é, nítorí wọn yóo bá mi jẹun lọ́sàn-án yìí.
mo fun ojo pipe, lati asiko re gege bi akonimoogba iko Chelsea ati igba ti o wa
#BBCNigeria2019 Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ẹ wo ọ̀nà àbáyọ tí àwọn olùdíje gómìnà pèsè sí ìṣòro Eko Oríṣun àwòrán, FACEBOOK Àkọlé àwòrán, Gomina Rauf Arẹgbesọla ni ọdun 2014 wọ asọ ile iwe awọn alakọbẹrẹ lati polongo idibo fun saa keji gẹgẹ bi gomina Ọṣun.
Mo ṣe àṣàrò lórí ohun tí mo ṣàkíyèsí,mo sì kọ́ ẹ̀kọ́ lára ohun tí mo rí.
Wọ́n sì mú èso pomegiranate ati èso ọ̀pọ̀tọ́ wá pẹlu.
”Mose dá wọn lóhùn pé, “Kí ló dé tí ẹ fi ka ẹ̀sùn sí mi lẹ́sẹ̀?
Sọra fun ọmọkunrin to ba wa lati ile ti wọn ti ri iwa ipa gẹgẹ bi igbesi aye to dara.
Ọ̀pọ̀ àwọn agbowó-odè ati àwọn ẹlẹ́ṣẹ̀ ni wọ́n wá, tí wọn ń bá Jesu ati àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ jẹun.
Wo àwọn ìlérí tàwọn Gómìnà tuntun ṣe nínú ìbúra wọn Dapọ Abiọdun ree, ẹni tó dépò gómìnà ní àyájọ́ ọjọ́ ìbí rẹ̀ Rochas Okorocha, káàbọ̀ sí àwùjọ àwọn gómìnà tí EFCC ń wá - Fayose Ohun tó wù kí ileẹjọ́ kòtẹ́milọ́rùn sọ, Adeleke kò lè di gómínà Ọ́ṣun - APC Lẹyin ariwisi loriṣiiriṣii ni awọn ọmọ ilé fẹnuko pe awọn wọgile gbogbo ilana eto iṣuna tabi iṣẹ akanṣe ti Gomina Amosun ṣe tẹlẹ lai gba aṣẹ awọn ọmọ ile patapata.
Wọ́n ń wí pé, ‘OLUWA ti kọ ilẹ̀ yìí sílẹ̀, kò sì rí ohun tí ń ṣẹlẹ̀ ninu rẹ̀.
Àwọ̀ àwọn ewéko a máa jọ́ni lójú púpọ̀.
Pẹlu imọran pe ki onikaluku tete ja itanna rẹ to n tan nitori a ko mọ igba ti ọlọjọ maa de.
” Abrahamu dáhùn pé, “Èmi nìyí.
Ijoba apapo Naijiria ti seleri lati tun gbogbo ile ti o baje ko ni guusu Kaduna lataari ija to sele laarin awon agbe ati awon darandaran ekun naa ko laipe ojo.
Awọn eeyan naa lo sọ ọrọ ọhun lẹyin ti awọn ọmọ ẹgbẹ agbesumọmi Boko Haram ṣekupa eeyan mẹtaleogoji ninu oko irẹsi kan lọjọ Abamẹta ni ipinlẹ Borno.
Awọn obi agbabọọlu ikọ Remọ Stars, Tiamiyu ti bere fun iwadii otitọ lori iku to pa ọmọ wọn nipasẹ awọn ọlọpaa.
Ìyá Siasia kúrò lákàtà àwọn ajínigbé lẹ́yìn oṣù méjì ààbọ̀ Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Ẹ̀yin olùwọ́de, ẹ lọ kọwọ́ ọmọ yín bọṣọ, bí bẹ́ẹ̀ kọ́.
Ẹni ọgọta ọdun ni Akinwumi Adesina.
Akinyele murder: Àwọn aṣekúpani tún ti pa ọmọ ọdún 16 ní Akinyele nípìnlẹ̀ Oyo
O sọ wipe ara n ni awọn eniyan.
Atẹjade kan eyi ti alukoro ileeṣẹ ọlọpaa ni ipinlẹ Ogun, Abimbola Oyeyẹmi ni ọmọdekunrin naa daku lagọ ọlọpaa lasiko ti wọn fi gbe ẹjọ rẹ wa sibẹ.
T́ ò gbin ẹ̀gẹ́ l’ó jẹ̀bi ebi t’ó n pa ni.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Ohun ta gbọ ni pe iye owo apapọ to wa ninu akoto owo ifẹyinti awọn oṣiṣẹ Naijira to triliọnu mọkanla Naira le diẹ bayi.
Agbẹjọro naa sọ pe afurasi yii ko kẹkọ imọ ofin debi ti yoo kawe gboye lati maa sisẹ agbẹjọro.
Wọ́n mú ẹbọ wọn wá siwaju pẹpẹ.
Eto idibo ti yoo waye ni ojo keje osu keta je ona kan gboogi lati mu idagbasoke ba eto ijoba tiwa-n-tiwa lorile-ede naa ti o wa ni ekun iwo-oorun ile-Africa, eto idibo ohun yoo fitan bale, yala egbe oselu to wa lori alefa tabi egbe oselu alatako ni yoo jawe olubori ninu eto idibo si ipo Aare naa.
Yoruba Films: Adewale Elesho ní àìkàwé ló ṣàkóbá fún òun nínú iṣẹ́ tíátà
a níláti tọ ́ ka sí i pé Ìjẹ ̀ bú ti Ìjẹ ̀ ṣà yí lè ní nǹkan kan í ṣe pẹ ̀ lú Ìjẹ ̀ bú ti Ìjẹ ̀ bù - Òde .
Minisita fún eto ìdẹ̀rùn aráàlú, Sadiya Umar-Farouq lo sísọ lójú ọ̀rọ̀ yìí lásìkò tó ń bá àwọn akọroyin sọ̀rọ̀ n'ilu Abuja.
Dino ní ìyàwó ni Adeyemi jẹ́ f'óun lágbo òṣèlú, Adeyemi l'ọ́mọ ọ̀dọ̀ ni Dino jẹ́ Kò sí súnkẹrẹ-fàkẹrẹ mọ lópópóna márosẹ̀ Eko si Ibadan Nǹkan mẹ́wàá tó yẹ ní mímọ̀ nípa fásitì ẹ̀kọ́ ìrìnnà òní $50m ní Nàìjíríà Èso Apple tuntun tí ẹ lè fi pamọ́ fún ọdún kan ti wọ ọjà Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, World Aids Day: Wo bí kòkòrò ààrùn HIV se bẹ̀rẹ̀ lágbàyé!
Mo bá yan ọkùnrin kan báyìí ti orúkọ rẹ̀ ń jẹ́ kùkùté, tí ó jẹ́ alágbára tí ó sì mọ ọwọ́ ìjàkadì púpọ̀.
" Agbẹnusọ fun ileesẹ Ọlọpa nipinlẹ Eko, Arabinrin Bọla Ajao, fidi isẹlẹ naa mulẹ pẹ́lu afikun pe ọpọ ohun to jona ni wn fi awọn ohun eelo ti kii se ọrẹ ina kọ.
Salah, ẹni ọdun mẹrindinlọgbọn fi ẹyin akẹgbẹ rẹ ninu ẹgbẹ agbabọọlu Liverpool, Sadio Mane ati ọmọ ẹgbẹ agbabọọlu Arsenal to wa lati Gabon, Pierre-Emerick Aubameyang, janlẹ ninu ifigagbaga fun ami ẹyẹ naa.
oko oju irin ti se ise lorile ede yii.
Aarẹ Muhammadu Buhari ati ẹgbẹ osẹlu APC ti wọn fẹsun kan ko si nibi igbẹjọ ọhun.
Ẹ farabalẹ̀, kí ẹ gbọ́ ọ̀rọ̀ mi,lẹ́yìn náà, ẹ lè máa fi mí ṣẹ̀sín ǹṣó.
 agígírí rìn díẹ ̀ síwájú kí ó tó dúró .
9% ninu idibo sipo aarẹ naa.
OLUWA bá tún gbé mi lọ sí ẹnu ọ̀nà gbọ̀ngàn, nígbà tí mo wò yíká, mo rí ihò kan lára ògiri.
Election 2019 Updates: Makinde ní Ajimọbi fẹ́ ná owó Ọyọ tán, láti dá ìjọba òun lóró
Ààrẹ Buhari buwọ́lu ẹ̀dínwó ìdánwò NECO àti JAMB Saraki: Ọ̀gá ọlọ̀pàá Idris ń lépa ẹ̀mí mi Ọlọ́pàá f'aṣọ bójú gbé Dino kúrò nílé ìwòsàn Bi fọọmu naa ṣe ti wa jade kaakiri Naijiria fun ẹni to ba fẹ gba, awọn nkankan wa ti ajọ JAMB fẹ ki awọn aṣedanwo mọ eyi ti yoo jẹ ki ilana iforukọ silẹ wọn rọrun.
Olùbùkún ni ẹni tí ń bọ̀ ní orúkọ Oluwa.
Oríṣun àwòrán, Rasheed Adeleke Àkọlé àwòrán, Awọn ọmọ ẹgbẹ ati awọn olori ẹgbẹ lo korajọ pọ silu Ẹdẹ, ti i ṣe ilu abinibi Ademọla Adeleke fun eto adura naa.
data in detail Scroll table to see more data *Deaths per 100,000 people Filter: The world Africa North America Latin America & Caribbean Asia Europe Middle East Oceania Country Deaths Death rate* Total Cases New Cases 0 10 100 1k 10k ** US 387,741 118.
O ni ounjẹ ni awọn onisunmọmi naa n wa ati wipe wọn ko fẹ ji ẹniyan gbe.
Ọkùnrin kan sálọ lẹ́yìn tó gbẹ̀mi ènìyàn mẹ́ta Bianca júwe ilé fún Serena Williams nínú ìdíje l'America Ààbò tó péye wà fún àwọn okòwò ará South Africa ni Eko -Sanwo Olu Níńu oṣù keje ijọba Naijiria ati Siemens to jẹ ilé iṣẹ̀ Germany jọ kọwọ́ bọ̀wé adehun fún ina mọ̀námọnà.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Peters Ijagbemi dá àrá lórí ètò 'Ṣé o láyà' ti BBC Yorùbá lọ̀sẹ̀ yìí Ọmọ Faleti a maa dari ere, a tun maa kó ere oniṣe, o n kọ ewi, o n ka ewi, o tun n kọ itan arosọ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Kayeefi: 'Ọkọ mi ṣẹ̀ṣẹ̀ ní kí n lọ se mọ́í-mọ́í, tó ṣẹ̀ bá mi ṣeré tán ni mo gbọ́ pé Mopol"" yìnbọn pa á' Agbẹnusọ náà sàlàyé pé, ọ̀rọ̀ Covid-19 ni ìjọba Nàìjíríà gbájú mọ́, tí wọ́n ko si ṣe àyẹwò fún àwọn ènìyàn lórí ààrùn ibàpójú."
Ọjọ kẹtalelogun, osu kọkanla ọdun 1859 si ni iwe iroyin akọkọ naa jade .
Oṣere naa pari ọrọ rẹ pe bi awọn eeyan ṣe maa n bu ẹni to ba sanra lo n mu ki ọpọ ninu wọn ronu pa ara rẹ.
Oluwa mi ni ó rán mi sí ọ pé, ‘Nisinsinyii ni meji ninu àwọn ọmọ àwọn wolii tí wọn ń gbé òkè Efuraimu wá sọ́dọ̀ mi.
Ní ọjọ́ keje, wọ́n gbéra ní òwúrọ̀ kutukutu, wọ́n yípo ìlú náà bí wọ́n ti máa ń ṣe, nígbà meje.
"Orlẹede Isreal Benjamin Netanyahu ti orlẹede Isreal ní tirẹ̀ sọ pe, lati ọdún to kọjá ni oun ti sọọ́ pe, oun faramọ́ ki aarẹ Amerika Donald Trump ""gbé ìgbésẹ̀ to tọ́ lori lílo Kẹ́míkà olóró"" láàárín awn orilẹede lagbaaye."
O ni ẹni ti eeyan n fi igbe aye rẹ tọrọ ni Alaafin, to si jẹ ẹni ti eeyan gbọdọ kọ ọgbọn lọdọ rẹ.
Kò ní ní ọrọ̀,ohun tí ó bá ní, kò ní pẹ́ lọ́wọ́ rẹ̀,òun alára kò sì ní fìdí múlẹ̀.
Aajọ to n risi ọrọ irinajo lorilẹede Naijiria,(NIS) pẹlu ajo to n gbogun ti iwa ifini sowo ẹru lorilẹede Naijiria ati Ajọ papakọ to n sakoso papakọ ofurufu lorilẹede Naijiria ni wọn ki awọn arinriajo naa kabọ sorilẹede yi.
O ṣalaye pe ofin lo gbe awọn de ori oye fun iparapọ ati ilọsiwaju llu lbadan.
ṣugbọn a óo pa ẹni ibi run lórí ilẹ̀ náà,a óo sì fa alárèékérekè tu kúrò níbẹ̀.
Nọọsi Olabode naa wa parọwa si awọn akẹgbẹ rẹ lati mọ daju pe awọn naa le wa ni ipo ti awọn obinrin naa wa lọla, nitori naa ki wọn huwa si wọn gẹgẹ bi eniyan bi ti ara wọn.
Musulumi ati Kristẹni ati ẹlẹsin ibilẹ, lo wo ere Mount Zion, bo o lẹ ṣe ṣe e?
Iwadii BBC fihan pe, kaakiri agbaye ni wọn ti n ko adiẹ alẹ nipa oorun akọkọ laarin lọkọlaya lalẹ ọjọ igbeyawo.
nigba ti Muhammadu Buhari ni iye ibo milionu mẹ́rìndínlógún.
Ikọkanlelogun mú Hotiri, òun ati àwọn ọmọ rẹ̀ ọkunrin, ati àwọn arakunrin rẹ̀ jẹ́ mejila.
Ẹ wo ojú owó ìrẹ̀sì báyìí lẹ́yìn tí ìjọba ti ibodè pa Ìgbẹ́jọ́ Naira Marley sún síwájú bí àwọn agbẹjọ́rò ṣe ń jà sí àga ìjókòó Ohun mẹ́wàá tó yẹ kóo mọ̀ nípa Kunle Afod Kí làwọn ọmọ Nàìjíríà rí sí iléeṣẹ́ tí ààrẹ yí padà sí Ministry of Communication and Digital Economy?
Nígbà tí Asaraya, olórí alufaa ati àwọn alufaa rí i tí ẹ̀tẹ̀ yọ níwájú rẹ̀, wọ́n yára tì í jáde.
Wọn ni awọn ri oku rẹ pẹlu ti iya agbalagba kan ẹni ọdun marundinlọgọrin lẹgbẹ Wahnish Way and Orange Avenue, Tallahassee.
Eweko Artemisia ni eroja gboogi to wa ninu agbo naa, pẹlu afikun awọn eweko miran to wa orilẹ-ede Madagascar.
lowo Bernado Silva ati Leroy Sane fun ami ayo mejeeji ti o ran iko Man City
Akaroyin tẹlẹ ri Julie Gichuru fi iroyin kan lede lori opo Twitter rẹ lọjọ karundinlọgbọn oṣu kẹwa ki awọn eeyan jiroro lori bi Ọgbẹni Quest ṣe n gbadun ara rẹ ni Kenya.
Coronavirus ki o to kuro lorileede rẹ.
 O wa rọ wọn pe ki wọn ma fa sẹyin, ki wọn le jere ijoba tiwantiwa ti ẹgbẹ oṣelu All Progressives Congress siwaju.
Ó ń ro bí yóo ṣe hùwà ẹni tí kò mọ Ọlọrun,tí yóo sọ̀rọ̀ ìsọkúsọ sí OLUWA;tí yóo fi ẹni tí ebi ń pa sílẹ̀, láì fún un ní oúnjẹ,tí yóo sì fi omi du ẹni òùngbẹ ń gbẹ.
Igbesẹ yii n waye lẹyin ti o jẹyọ sita wi pe ninu ẹẹdẹgbẹta o din mẹsan awọn ileeṣẹ ati lajọlajọ to jẹ ti ijọba apapọ lorilẹede Naijiria, mẹtadinlaadọta pere lo tii tẹle ofin yii.
OLUWA bá wí fún Mose pé, 
“Wọn óo pada sí ilẹ̀ Ijipti, Asiria óo sì jọba lé wọn lórí, nítorí pé wọ́n kọ̀, wọn kò pada sọ́dọ̀ mi.
Nígbà tí mo bá pọ́n idà mi,tí ó ń kọ yànrànyànràn,n óo fà á yọ láti fi ṣe ẹ̀tọ́.
"Toyin Abraham ni ọjọ kẹtalelogun, oṣu keje ti aṣita ọta ibọn ọlọpaa ti wọn n pe ni ""Stray bullet"" ba Adenike ni agbegbe Apata niluu Ibadan, wọn gbe lọ ileewosan."
mọ eyi gẹgẹ bi ojuṣe rẹ”.
Lẹyin to pari ile ewe girama rẹ, Olutoye gba ọgba fasiti Ọbafẹmi Awolọwọ lọ lati kọṣẹ imọ iṣegun oyinbo nibẹ.
Ilé ìjọba Amẹrika sàlàyé pé, èyi yóò fún àwọn ojúlówó ọmọ ilẹ̀ Amẹrika tí ó n kójú ìṣòrò nítori ìtànkálẹ̀ àrùn Coronavirus ní ààfàní láti rí iṣé ṣe.
"A ko fi ipa mu awọn eeyan wọnyii lati san ẹgbẹrun lọna ogoji naira yii.
N óo gbèjà ìlú yìí, n óo sì dáàbò bò ọ́ nítorí ògo mi ati ìlérí tí mo ti ṣe fún Dafidi iranṣẹ mi.
Nítorí pé mo dàbí àlejò tó wọ̀ ní Meṣeki,tí ń gbé ààrin àwọn àgọ́ Kedari.
O ni ọpọlọpọ awọn ohun ini ti awọn eniyan ti da pada ti le ni miliọnu meji naira.
Àwọn ọmọ Elipaali ni: Sebadaya, Meṣulamu, Hiṣiki, ati Heberi, 
ẹ má ṣe orí kunkun bí ẹ ti ṣe ní Meriba,ati bí ẹ ti ṣe ní ijọ́un ní Masa, ninu aṣálẹ̀ 
Olorin Naijiria, Wale lo gbogbo agbara ọkunrin to ni lati kọ ọrọ inu naa pe mo le jẹ akewi fun ọ nile rẹ, mo le ba ọ ṣiṣẹ ọpa omi ẹrọ rẹ to ba bẹ."
Bi nnkan ba ti ṣe n lọ si ni BBC Yoruba yoo ma fi too yin leti.
”Eto ibasepo Gomina so pe ijoba ohun yoo gbiyanju lati se ohun to wa nikawọ rẹ lati tubo fese ibasepo to wa laarin ilu Eko ati Britain mule  si i.
Ṣugbọn gbogbo ati ranmu gangan ipadawasile wọn ko ṣẹyin gangan oludari ati alaga ileeṣẹ ọkọ ofurufu Peace Airline,Allen Onyeama.
Baba rẹ, gomina tẹlẹri ti wọn pa lọdun 1972 jẹ ọmọ ijọ Katoliki ti iya rẹ si jẹ ọmọ ijọ Angilika.
Ọsẹ kan laa fi kọṣe yi.
" Lai tẹsiwaju lati sọ pe ọrọ Kyari dabi olootọ ti kii lẹni.
 Ẹgbẹ naa tun la awọn eniyan lọyẹ nipa Erongba Ifẹsẹmulẹ Idagbasoke Agbaye (Sustainable Development Goals (SDGs) onipele metadinlogun, pe ẹni kọọkan lo ni ipa lati ko fun aṣeỵọri erongba yii, ti atubọtan rẹ yoo tubọ mu idagbasoke ba awujọ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Yoruba Films: Òṣèrè tíátà Muideen Oladapo gbàràdá lórí ètò 'Ṣé o láyà?
Nígbà tí wọ́n tún ilé OLUWA náà ṣe tán, wọ́n kó owó tí ó kù pada sọ́dọ̀ ọba ati Jehoiada.
ohun, ni eyi ti o ti pe arabinrin ohun lati gbọ ọrọ lẹnu rẹ.
Yatọ si àwọn ọmọ wọnyìí ninu ọkọ àwọn oṣiṣẹ eto ilera náà wa nínú ọkọ ti wọn si bomilọ Oríṣun àwòrán, BBC Àkọlé àwòrán, Oku ọmọ meji pere ni wọn Wọn ni ogoji ọmọ lo wa ninu ọkọ oju omi to rì náà sugbọn ti ori ko àwọn to ku yọ lágbegbe odo Nile.
O di olori awọn agbesunmọmi Boko Haram lẹyin iku ọga rẹ lati ọwọ awọn agbofinro lọdun 2009.
Ta ni Aminat Abiọdun, Ìyálóde ilẹ̀ Ìbàdàn tó d'olóògbé 'Ọdún 35 ni ọmọbìnrin gbọdọ̀ ti bímọ tán' Obìnrin mẹ́jọ nínú mẹ́wàá tó n lo wíìgì ló pá lórí"" Ni ti awọn obinrin ti ko ba si nile ọkọ gan ni anfani lati sọ eyi ti o ba fẹ."
Mo fi Tirofimọsi sílẹ̀ ní Miletu pẹlu àìlera.
Amọ Dolapo, tii se ẹni ọdun mẹtalelogun ko lee sọrọ rara nitori oro ọgbẹ ada ti wọn sa a, eyi to jin wọnu.
Bẹ́ẹ̀ náà ni àwọn ohun èlò onígi tí ó bá fọwọ́ kàn, wọ́n gbọdọ̀ fọ̀ wọn.
Ninu oṣu Karun, ọdun 2018, ile ẹjọ giga ti Onidajọ Adebukola Banjoko to dajọ naa sọ pe gomina nigba kan ri naa jẹbi ẹsun mọkandinlọgbọn.
Àkọlé àwòrán, Àjọ NCDC kéde èèyàn 386 míràn tó ni ààrùn Covid-19 lórílẹ̀-èdè Naijíríà Àjọ NCDC kéde ènìyàn 381 míràn tó ní ààrùn Covid-19 l'órílẹ̀-èdè Nàìjíríà NCDC update on coronavirus: Àjọ NCDC tún ti kéde ènìyàn 381 tó ní Covid-19 l'órílẹ̀-èdè Nàìjíríà Àkọlé àwòrán, Èèyàn 5 mííràn tún ti lùgbàdì ààrùn Coronavirus ní Naijiria Esi ayẹwo aarun Covid-19 tun ti fihan pe eeyan ọrinlelọọdunrun o le ẹyọkan lo tun ti ni aarun naa l'orilẹ-ede Naijiria.
Toun ti bi Gbajabiamila ti ṣe jẹ ilumọka oloṣelu, o ni awọn iṣẹlẹ kan to ṣe bi ẹni tapo saṣọ ala rẹ.
Ọkan lara awọn eeyan ti ile itaja rẹ faragba ninu ijamba ina naa, Ọgbẹni Oluwadare Ọlawale to ba BBC News Yoruba sọrs lori ẹrọ ibanisọrọ ṣalaye pe gbogbo ẹru ati ile oun lo jona raurau.
Kò sí ẹni tí yóo wo ọgbẹ́ rẹ sàn nítorí egbò rẹ pọ̀.
Ó ní, “Ẹ sún sẹ́yìn, nítorí ọmọde náà kò kú, ó ń sùn ni.
Àwọn ọmọ Israẹli ati ti Juda tí wọn ń gbé àwọn ìlú Juda náà san ìdámẹ́wàá mààlúù ati aguntan, ati ti àwọn ohun mímọ́ tí wọ́n ti yà sọ́tọ̀ fún OLUWA Ọlọrun wọn, wọ́n kó wọn jọ bí òkítì.
"Ko si eyikeyi ninu awọn Oludije mẹtẹẹta to tẹ fun ọkan.
N óo sọ eniyan ati ẹran ọ̀sìn di pupọ lórí yín, wọn óo máa bímọlémọ, wọn ó sì di ọ̀kẹ́ àìmọye.
Àkókò márùún ninu ayé Winnie Mandela Bi Ramaphosa ṣe di aarẹ South Africa Bí ọkọ rẹ̀, Winnie nàá lo ìgbà l'ọ́gbà ẹ̀wọ́n, nítorí pé ó n ṣ'òṣèlú.
Nisinsinyii, Baba, jẹ́ kí ògo rẹ hàn lára mi; àní kí irú ògo tí mo ti ní pẹlu rẹ kí a tó dá ayé tún hàn lára mi.
Ri i daju pe awọn numba naa jẹ ogun lori ẹyọ kan; eyi to fihan pe ogun lọna mẹta ọtọọtọ lawọn nọmba naa jẹ.
Ọmọ ilu Ọtun Ekiti ni ipinlẹ Ekiti ni, ṣugbọn Abẹokuta lo gbe dagba, eyi ti o si maa n fi han ninu ede ẹgbọ ti o maa n saba lo ninu ere rẹ nigba miran.
    Ó pẹ́ kí ó tó ti òde náà dé, mo jókòó lórí àga kan ìgbà tí mo jókòó títí tí kò dé, mo sùn lọ.
Ṣé gbogbo nǹkan ti tẹ yín lọ́rùn!
Àwọn ni wọ́n tí ń tẹ̀lé Jesu láti Galili, tí wọn ń ṣe iranṣẹ fún un.
Bí eléyìí bá wọ bàtà góòlù, tọ̀hún a wọ ti idẹ, tìhín a wọ ìlẹ̀kẹ̀, àfi àwọn tí kò ní ẹsẹ̀ rárá ni wọn kò wọ nǹkan kan tí wọn ń tọ bí ọ̀pọ̀lọ́ kiri.
Garba ní àjọ ọ̀tẹlẹ̀múyẹ́ tí àwọn jọ ń ṣiṣẹ́ pọ̀, ló ta àjọ òun lólobó nípà òògùn Tramadol tó fẹ́ wọlé pèlú ọkọ̀ òfurufú United Arab Emirate.
Funmi Adewara: Tele Medicine' ní a fi ń ṣàyẹ̀wò èèyàn ìdá ọgọtá láti dènà ìtànkálẹ̀ Covid 19
Alaga ajọ LSESSOT ṣalaye siwaju si i pe awọn o ba ohun to le ṣakoba fun ẹnikẹni lara wọn ṣugbọn o ni iwadii si n tẹsiwaju lori awọn naa.
Ta ba ni ka ka wọn mi meni, meji, awọn ayaba naa le ni mẹẹdogun , ti awọn to ti dagba laarin wọn si ti ni ọmọ-ọmọ ati arọmọdọmọ pẹlu.
Wọ́n tún fìdí rẹ̀ múlẹ̀ pé ẹ̀yà Kwa yìí ló wọ́pọ̀ jùlọ ní sísọ, ní ìwọ̀ oòrùn aláwọ̀ dúdú fún ẹgbẹ̣ẹgbẹ̀rún ọdún.
Nígbà tí wọ́n dé ọ̀dọ̀ Jesu, wọ́n rí ọkunrin náà tí ó ti jẹ́ wèrè rí, tí ó ti ní ẹgbaagbeje ẹ̀mí èṣù, ó jókòó, ó wọ aṣọ, iyè rẹ̀ sì ti bọ̀ sípò.
ile-ise ọlọpaa lorile ede Niajiria Mohammed
Ọmọ yìí nìkan náà ni ìyá rẹ̀ bí.
Ó bá wá sọ́dọ̀ àwọn ọkunrin Sukotu, ó ní, “Ẹ wo Seba ati Salimuna, àwọn ẹni tí ẹ tìtorí wọn pẹ̀gàn mi pé ọwọ́ mi kò tíì tẹ̀ wọ́n, tí ẹ kò sì fún àwọn ọmọ ogun mi tí àárẹ̀ mú ní oúnjẹ.
Labani dáhùn, ó ní, “Ní ilẹ̀ tiwa níhìn-ín, àwa kì í fi àbúrò fọ́kọ ṣáájú ẹ̀gbọ́n.
Àwọn ọ̀dọ́ kan ń ṣèwọ́de láti pè fún lílé àwọn àjòjì kúrò ní South Africa Nítorí ìkọlù àjòjì ní South Africa, èèyàn 5000 ló padánù iṣẹ́ wọn ní Nàìjíríà Iye epo rọ̀bì tí wọ́n ń kó níbùdó ìpọnpo ti dínkù, ṣé ẹ fẹ́ mọ ìdí i rẹ̀?
Ọgbẹni Agba ni lootọọ ni awọn eto iṣede ti ijọba ṣe lori ati dẹkun ajakalẹ aarun covid-19 dara, amọ o ti ṣakoba nla fun ọrọ aje Naijiria.
lori  ipa Pataki ti o ko nipa eto ijọba
Awọn onimọ nipa eto ilera si ti sọ pe awọn to ba ni iru awọn aisan bẹ ẹ lara tẹlẹ ni coronavirus yara lati pa.
 iṣẹ ́ ẹ ̀ ka yìí láti ṣèjìròrò pẹ ̀ lú àwọn ọmọ orílẹ ̀ èdè nàìjíríà àti láti jábọ ̀ fún armed forces ruling council , lórí ọ ̀ nà tí ìjọba lè gbà láti mú ìgbà ọtun bá ọmọ orílẹ ̀ èdè nàìjíríà .
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ sí: Bukola Saraki di adarí gbogboògbò PDP Irú ẹ̀dá wo gaan ni Fẹla Jẹ́?
 A ti fi ye aare pe ise akanse gbodo kari ekun kookan ni.
Bakan naa lo farahan nibi eto idanilẹkọ ori afẹfẹ kan eleyi ti ileeṣẹ redio kan ṣe lasiko awẹ Ramadan to waye loṣu karun nibi ti o ti ko ipa gẹgẹ bi alaga eto idanilẹkọ awẹ naa Pẹlu iroyin to n ja ranyinranyin nilẹ yii ati ohun ti ẹni to sun mọ Sẹnetọ Ajimọbi sọ yii, ibeere to wa gbode lẹnu awọn ololufẹ agba oṣelu yii atawọn onwoye ni pe: 'Nibo gan an ni Sẹnetọ Abiọla Ajimọbi wa lọwọ yii'?
Ọwọ ọlọpa tẹ adigunjale ajọkọgbe nipinlẹ Ọsun Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Offa Robbery: Àwọn aráàlú ṣi n gbé nínú ìpaya lẹ́yìn ọdún kan Ṣugbọn gbogbo igbiyanju wọn lati ri owo ko jade nibi ti ileefowopamọ naa n ko owo si lo ja si ofo.
oko oju omi niluu Ibadan (Ibadan inland Dry Port) sile, lati mu adinku de ba
 Henry Offia scored Flying Eagles’ only goal.
Kìí ṣe gbogbo ohun tí dókìtà ni kí n má jẹ torí àìsàn jẹjẹrẹ ni mo tẹ̀lé- Soyinka Itan omi gbigbona ati tutu ni Ikọgosi Ekiti Ìyálé àti ìyàwó bínú di omi gbígbóná àti tútù O ṣójú mí kóró bí wọ́n ṣé fí àdó olóró pa Dele Giwa lọdún 1986- Soyinka Seun Egbegbe lo ọdún méjì àti oṣù méje lẹ́wọ̀n láì tìí san béèlì rẹ̀ Ọpọlọpọ eewọ ati iṣẹse lo rọ mọ gbigbe eegun naa jade ni Ogbomọṣọ.
 Awọn iroyin ti ẹ lee nifẹẹ si: Eko: Ambọde nfẹ ki wọn fi Yooba kọrin orilẹede wa Ibo Italy: Ọmọ Naijiria di asofin agba ni Italy O fikun pe pẹlu agbekalẹ awọn ilana ofin yii, o da oun loju pe taa ba tun ni asaaju to tọ, ilẹ Afrika yoo tiraka lati le osi wọ igbẹ, ti eto isejọba alagbada yoo si maa rẹsẹ walẹ."
Nítorí ẹ̀ ń ṣe ìdámẹ́wàá lórí ẹ̀fọ́ tẹ̀tẹ̀, gbúre ati oríṣìíríṣìí ewébẹ̀, nígbà tí ẹ kò ka ìdájọ́ òdodo ati ìfẹ́ Ọlọrun sí.
Idije naa to waye ni ilu Alexandria lorilẹ ede Egypt jẹ idije
Yorùbá fẹ́ràn lati má a bọ̀wọ̀ fún àgbà nitori eyi, ẹni ti ó bá ju Bàbá àti Ìyá ẹni lọ Bàbá tàbi Ìyá la n pè é, wọn ki pe àgbà ni orúko nitori eyi, wọn lè fi orúkọ ọmọ pe àgbà tàbi ki wọn lo orúkọ apejuwe (bi Bàbá Èkó, Iyá Ìbàdàn).
Diana já kúrò nínú ìdíje BBnaija 4.
n rin, ile igbafẹ,ile -ijọsin ati awon ibi ti awon odaran lee gba se ise ọwọ
" Minisita feto irinna ni bi ijọba apapọ ko ba gba owqoya ilẹ okeere nitori bawọn eeyan kan se n bu ẹnu atẹ lu, a jẹ pe opin yoo de ba awọn isẹ idagbasoke tijsba apapọ dawọle ni.
Ọmọ Yorùbá míràn tún dé ipò gíga l‘Amẹrika Ìjọba South Africa pèpàdé lórí ìkórìíra àlejò Wo aarẹ orilẹede South Africa tuntun Tani Winnie Mandela tó d'olóògbé?
Àwòrán ìgbeyàwó ọmọ Fayose dùn, ó lárinrin Fayemi, Fayose ń tahùn sí ara wọn nítorí gbèsè owó oṣù òṣìṣẹ́ Rẹ́díò Fayose di títìpa l'Ekiti Fayoṣe tí lahùn, ó dá APC lóhùn pé.
'NLC, ẹ máa retí ìdádúró lẹ́nu iṣẹ́ 'tórí N30,000' Kwara - Àwọn agbébọn kọlu olùdíje APC O ni 'fun anfani ẹgbẹ oṣelu Zenith Labour Party ni mo ṣe gbe igbesẹ yii.
Èèyàn lè sọ ọjọ́ ọ̀sẹ̀ wo ni kó gbálẹ̀, ati ní wákàtí wo.
Owó làwọn olóṣèlú mọ̀ ni wọ́n ṣe fẹ́ kí dókítà lọ sókè òkun
''BBC Yoruba ti dé fún ògo Yorùbá àti igbe lárugẹ èdè àti àṣà Yoruba pelu awon eto mii tí a ní lọ́jọ́ iwájú bíi idije, ààyè àti ojúlówó ìròyìn ti o je òótọ́''.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Africa Free Trade Zone: Kò sí ìdènà láti kó ọjà láti orílẹ̀èdè kan sí òmíràn 30 Èbibi 2019 Àkọlé àwòrán, Agbekalẹ adehun yii ni wọn gba pé o maa jẹ ki ọja tita tubọ rọrun fawọn olokowo keekeeke Naijiria jẹ orilẹ-ede ti eto ọrọ aje ẹ tobi julọ nilẹ Adulawọ.
 wọ ́ n ti ṣàpèjúwe àwọn àmì tí ó jọ bv nínú ìtàn , àkọsílẹ ̀ àkọ ́ kọ ́ wáyé ní ọdún 1894 .
Bukola Saraki pe fun ajọṣepọ laarin Ghana ati Naijiria
Èéṣe tí o fi dúró níta gbangba?
Ọdun mọkanla sẹyin ni Wasiu Ayinde ti n dafun tolo si oye Mayegun ilẹ Yoruba, ki Alaafin to o jawe oye le lori l'ọdun 2020.
Oju ati ohun rẹ lori amohunmaworan ati loju opo ayelujara lawọn eeyan fẹrẹ damọ julọ lasiko iṣẹlẹ yii.
 Bakan naa lo fi asiko ohun  ro gbogbo omo orile ede Naijiria , paapaa julo
Mo ki ẹnikẹni ti wọn ba gbe oye naa fun ku orire.
Ẹ dẹ̀kun lílo Sniper àti Dichlorvos fún ìtọ́jú oúnjẹ- NAFDAC kìlọ̀ Oríṣun àwòrán, @Omojuwa Ajọ WAEC gbé èsì ìdánwò ọdun 2020 jáde Ajọ WAEC to n ṣe akoso idanwo ile iwe girama ni apa iwọ oorun ilẹ Afirika ti gbe esi idanwo awọn akẹkọọ oniwe mẹwaa ọdun 2020 yii jade.
Jesu gbọ́ pé wọ́n ti ti ọkunrin náà jáde kúrò ninu ilé ìpàdé.
Oludije to ba si moke ninu awọn oludije PDP yii ni yoo koju gomina ipinlẹ Kogi, Yahaya Bello lati ẹgbẹ oselu APC, ninu idibo gomina ti yoo waye ni Ọjọ Kẹrindinlogun, Osu Kọkanla, ọdun 2019.
Ó mọ bí a tií ṣe iṣẹ́ ọnà sí ara aṣọ elése àlùkò, aṣọ aláwọ̀ aró, àlàárì, ati aṣọ ọ̀gbọ̀ onílà tẹ́ẹ́rẹ́tẹ́ẹ́rẹ́.
N kò le rí àwọn ènìyàn tí wọ́n ń rìn nílẹ̀ mọ́n nítori mo ti jìnnà sókè jù.
Ǹjẹ́ àwọn onígbèsè rẹ kò ní dìde sí ọ lójijì, kí àwọn tí wọn yóo dẹ́rùbà ọ́ sì jí dìde, kí o wá di ìkógun fún wọn?
Sotitobire àti àwọn wòlíì ọmọ Nàìjíríà míràn tó ti lọ sẹ́wọ̀n nítorí ẹ̀sùn ìwà ọ̀daràn
''Baba mi kọ mi ni oriṣiiriṣii nkan nipa Ifa nigba ti mo wa ni ọmọ kekere, koda o tun gba onifa mii, Agbongbon Awo ilu Osogbo, Oloye Faniyi Ajani lati maa kọ mi ni Ifa,'' Oloye Elebuibon ṣalaye.
Àwọn eniyan náà súre fún àwọn tí wọ́n fa ara wọn kalẹ̀ láti lọ máa gbé Jerusalẹmu.
won yọ kuro nipo losu keji ,odun 2018 leyin odun merin ti o ti lo gege bi
Ki eeyan to le foju ri oṣu yi nigba ti o ba jade,awọn ọmọ igbimọ a ma lo irinṣẹ igbalode lati mọ ni pato pe oṣu naa jade.
Wọ́n tún ṣe bẹ́ẹ̀, wọ́n mú okùn ìkòkò ìse-ìrẹsì.
ni yóo ti fi ọwọ́ ara rẹ̀ mú ẹbọ sísun wá fún OLUWA.
Kí ó sì wáá jẹ́ pé òkú rẹ̀ ni mo máa rí!
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Idibo ko ni waye ti wọn ko ba mu ọkọ mi jade 'Nnamdi Kanu gbọdọ foju han ki Igbo to d'ibo ni 2019' ‘A ko mọ ibi ti Nnamdi Kanu wa’ Kanu ni wọn ko ti gburo rẹ lati igba ti awọn ọmọ ogun orilẹede Naijiria yabo ile rẹ nibi osu mẹfa sehin, lọna a ti kapa awọn ajijagbara naa.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Tsunami: Lẹ́yìn ọ̀sẹ̀ kan ti Jumasil ti sọnù ni wọ́n rii padà O ni ki awọn ọdọ o ṣọra fun ilepa owo ojiji lai ṣiṣẹ nitoripe bopẹ boya igbẹyin rẹ kii san fun awọn to ba ṣee.
OLUWA Ọlọrun fi ìran kan hàn mí!
Ọmọ orilẹede Kenya, David Barmasai lo gba ami ẹyẹ ipo kinni ninu ere eje-gigun ti ilu Eko ti ọdun 2020.
Kembi to n gbe pẹlu awọn obi rẹ lagbegbe Tabon Tabon l'Agege pade iku ojiji lọjọ kejilọgbọn oṣu keje ọdun 2020 yii nigba to lọ sun nile Yusuf.
Wọn ni Tinubu wa lara awọn to mu ki ọpọ dibo fun aarẹ Buhari ni ọdun 2015 ati ni ọdun 2019.
Kò tó ẹni tí í wò ó.
6 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 7 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Oríṣun àwòrán, @FRSC Bayii ti ọdun keresimesi ti n kan ilẹkun ti ọpọ si ti n rinrirn ajo kaakiri.
Ìmọ̀ràn yìí dára lójú wa, a dúpẹ́ lọ́wọ́ Ènìyàn-ṣe-pẹ̀lẹ́ a sì pinnu àti tẹ̀lé ìmọ̀ràn náà.
Èmi ni OLUWA Ọlọrun yín, tí ó yà yín sọ́tọ̀ kúrò lára gbogbo eniyan.
Iyawo akọkọ rẹ ṣafihan aṣiri pe o n mu oogun oloro, ọti to si n lọ ile ti awọn aṣẹwo ti ma n jo nihoho ati pe wọn le e danu kuro nileeṣẹ awọn ọmọ ogun ilẹ Amẹrika tori pe o n mu oogun oloro sinu iwe ikọsilẹ wọn Lọdun to kọja o fẹ iyawo ẹlẹẹkeji lẹyin ọsẹ kan ti o pade rẹ.
kan ti o te jade lojo Aje(Monday).
Adari ikọ naa pari ọrọ rẹ pe ki awọn ti orukọ wọn ko jade má ṣe iyọnu lati yọju si ọgba ileewe ti idanilẹkọọ ati igabradi naa yoo ti waye.
Ọba wọn ni yóo ṣáájú wọn, OLUWA ni yóo sì ṣiwaju gbogbo wọn.
Ni apá kan, inú ọmọ ẹni ti ó hu iwà rere ni àwùjọ á dùn lati ránti ọmọ ẹni ti ó nṣe, ṣùgbọ́n inú ọmọ “Olè”, apànìyàn, àjẹ́, àti oniwà burúkú yoku, kò lè dùn lati ránti ọmọ ẹni ti wọn nṣe.
Gomina Makinde kede ọrọ naa latẹnu olori oṣiṣẹ rẹ, Bisi Ilaka, pẹlu afikun pe ki awọn alaga naa gbe iṣakoso silẹ fun awọn olori awọn oṣiṣẹ tabi oludari agba lawọn ijọba ibilẹ wọn.
 Ni ọrọ iyanju ti aarẹ fun awọn ọmọ igbimọ rẹ tuntun naa."
Nígbà tí ó ṣe, pàṣán yìí gbó, mo sì tún rí ọwọ́ yìí tí ó di àáké mú tí ó tún ń lé ọkùnrin náà kiri nínú àwọn ó ń ṣá àáké mọ́ ọn lára, ẹ̀rù bà mí nígbà tí mo ń rí ojú ọgbẹ́ tí mo ń rí àgbàrá ẹ̀jẹ̀ tí mo sì ń fi ojú mi rí egungun ara.
 Àtúnbọ ̀ tán wọ ́ pọ ̀ púpọ ̀ lára àwọn ènìyàn tí agbára àti kojú àìsàn wọn kò bá múnádóko , a sì má a lágbára púpọ ̀ .
olúbákin gbé ẹgbẹ ́ ọmọ ogun ọlọ ̀ tẹ ̀ dìde sí àbúrò rẹ ̀ pẹ ̀ lú èrò àti gba ìjọba padà sọ ́ wọ ́ araarẹ ̀ gẹ ́ gẹ ́ bí ẹni ti oyè náà tọ ́ sí .
Pogba: Ikọ̀ Real Madrid ń gbáradì láti kó £70m lé Paul Pogba lórí
"Tori eyi, ""ọmọ Nàiìjíríà náà ni Fulani, mu wọn bi arakunrin yin""."
Ṣugbọn n kò ka ẹ̀mí mi sí ohunkohun tí ó ní iye lórí fún ara mi.
Idásilẹ̀ Amotekun ko ba òfin ọdún 1999 mu- Malami Aláàfin Ọyọ: Ọba tó bá n mú ọtí ní ìta kò yẹ ní ẹni tàá bọ̀wọ̀ fún Idásilẹ̀ Amotekun ko ba òfin ọdún 1999 mu- Malami Ìjọba orilẹ̀-èdè Naijiria ti ṣe àfiwe ẹgbẹ́ ààbò tuntun ti àwọn gómìnà ẹkun ìwọ̀ òòrun Naijiria dá sílẹ̀ Àmọ̀tẹ́kùn bíi èyí ti wọ́n dá sílẹ̀ lọ́nà ti kò bá òfin mú.
Won ni o le ni tolotolo aadọta miliọnu ti wọn n pa lọdọọdun ni amrica fun idupẹ ọdọọdun naa.
Gbogbo ìlú wọn jẹ́ ọgọta, gbogbo agbègbè Arigobu ati ìjọba Ogu ní Baṣani ni a gbà.
N-Power 2020 recruitment: Ṣé lóòtọ́ ní pé àwọn alákòso tí kéde àwọn tó ṣe àṣeyọrí nínú ètò ìgbanisíṣẹ́ ọdún 2020?
Àwọn ìjòyè sì wà lẹ́yìn gbogbo àwọn eniyan Juda, 
Wọ́n dá ọba lóhùn lẹẹkeji pé, “Kí kabiyesi rọ́ àlá rẹ̀ fún wa, a óo sì sọ ìtumọ̀ rẹ̀.
Messi ṣekú pa Man United pẹ̀lu 3-0
Koda, o ja nibi ogun Biafra.
“OLUWA Ọlọrun ọ̀run, Ọlọrun tí ó tóbi tí ó sì lẹ́rù, Ọlọrun tíí máa pa majẹmu ati ìfẹ́ tí kì í yẹ̀ mọ́ pẹlu àwọn tí wọ́n bá nífẹ̀ẹ́ rẹ̀ tí wọ́n sì ń pa òfin rẹ̀ mọ́, 
LASEMA naa wa rọ awọn eniyan lati ṣe suru fun awọn, ki ijamba miran ma ba tun waye ni agbegbe naa.
Ọ̀pọ̀ olólùfẹ́ eré bọ́ọ̀lù bẹnu ẹ̀tẹ̀ lu bí Iwobi àti Lukaku ṣe lọ Liverpool kun Arsenal wẹ́lẹ́wẹ́lẹ́ bí ẹran àsun 'lójúbọ' Anfield Ìjà orogún méjì ní London, Arsenal àti Tottenham ta ọ̀mì ''Mo fẹ darapọ mọ wọn lati gbogbo ife.
Àṣírí fàyàwọ́ ọmọnìyàn tú nílé ẹ̀kọ́ kan nípìlẹ́ Edo
Jakọbu pàápàá kíyèsí i pé Labani kò fi ojurere wo òun mọ́ bíi ti àtẹ̀yìnwá.
Wọ́n pé ọdún méjìlá báyìí Fatai Rolling Dollar, Ọmọ ìdílé oyè tó gbé igbá orin tí Ebenezer Obey ń ṣiṣẹ́ lábẹ́ rẹ̀!
Oríṣun àwòrán, Facebook Àkọlé àwòrán, Jide Sanwoolu jẹ oluranlọwọ pataki fun Bola Tinubu nigba kan ri Ki o to di pe Sanwoolu wọ agbo awọn oloṣelu, o ba awọn ile ifowopamọ oriṣiriṣi ṣiṣẹ.
Kí ni eniyan jẹ́, tí o fi n náání rẹ̀?
Ẹ máa fi ọ̀rọ̀ wọnyi tu ara yín ninu.
Mo wo àwọn òkè ńlá, wọ́n ń mì tìtì,gbogbo òkè kéékèèké ń sún lọ síhìn-ín sọ́hùn-ún.
Ṣe akiyesi àwọn eniyan tí a lè gbà láàyè kí wọ́n wọ inú tẹmpili ati àwọn tí kò gbọdọ̀ wọlé.
Ile ijọsin Four Square Gospel Church Nigeria ti paṣẹ ki Pasito Boniface Igbenoghu lo fidi mọle titi ti awọn yoo fi pari iwadii lori rẹ.
Nítorí náà Ọlọrun wa, jọ̀wọ́ gbọ́ adura ati ẹ̀bẹ̀ iranṣẹ rẹ.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Hema n lewaju ninu esi idibo ẹkun ariwa ti wọn ti ka Hema Malini lo ti kọko bori lọdun 2014 ni eyi to fi wọle ṣoju awọn eniyan ẹkun rẹ bi o ti wuu.
Hmmm ọrọ naa buso si ni lẹnu to tun bu yọ si.
Angẹli OLUWA bá lọ sí ibùdó àwọn ọmọ ogun Asiria, ó sì pa ọ̀kẹ́ mẹsan-an ó lé ẹgbẹẹdọgbọn (185,000) ninu wọn.
Ṣugbọn fi kùkùté, ati gbòǹgbò rẹ̀ sílẹ̀ ninu ìdè irin ati ti idẹ ninu pápá.
Iṣimaeli bá kó gbogbo àwọn tí wọ́n kù ní Misipa lẹ́rú, àwọn ọmọ ọba lobinrin ati gbogbo àwọn tí wọ́n kù ní Misipa, àwọn tí Nebusaradani olórí àwọn tí wọn ń ṣọ́ ọba fi sí abẹ́ ìṣọ́ Gedalaya.
Ajo naa ninu ofin re  so fun awon oniroyin lori ero alatagba lati san  owo itanran ati lati foruko sile pelu iye owo ti o to  oodunrun owo dola.
Coronavirus: Àwọn ìpèníjà nípa ṣíṣe iṣẹ láti ilé lásìkò COVID 19 yìí
Ọjọgbọn Ngozi Okonjo-Iweala Oríṣun àwòrán, @NOIweala Àkọlé àwòrán, Ọkan lara awọn eekan to lagbara labẹ iṣejọba aarẹ Ọbasanjọ laarin ọdun 2003 si 2006 ni Okonjo-Iweala Ọjọgbọn Ngozi Okonjo-Iweala jẹ minisita ijọba meji lorilẹede Naijiria-2003 si 2006 labẹ aarẹ Oluṣẹgun Ọbasanjọ, 2011 si 2015 labẹ iṣejọba aarẹ Goddluck Jonathan.
Ẹ sì ti mọ̀ pé kò sí apànìyàn kan tí ìyè ainipẹkun ń gbé inú rẹ̀.
Wo àwọn nkan tí o le ṣe gẹ́gẹ́ bi aláboyún lásìkò àjàkálẹ̀ ààrùn Covid-19 Àkọlé àwòrán, Ni kete ti ijọba apapẹ dẹwọ igbele, ile ifowopamọ lawọn eeyanb kan kọkọ fori le Ayẹwo ti awọn agbofinro naa n ṣe ti fa sunkẹrẹ fakẹrẹ ọkọ, ti ko si dun mọ awọn eeyan naa ninu nitori wọn ni awọn mii ma n lo wakati mẹrin lojukan.
" Ko tan sibẹ o, Makinde tun sisọ loju rẹ pe, ọga agba ọlọpa ti fọwọ si idasilẹ akanse igbimọ amusẹya kan ti kọmisana ọlọpa kan yoo ko sodi, eyi ti yoo tete pa ina eto aabo to mẹhẹ, eyi to n jo yika ilẹ Yoruba.
A bi Ayo Fasanmi lọjọ kẹtadinlọgbọn, osu kẹsan an, ọdun 1925.
Energy Drink: Ìjọba fi òfin de èyí tó ń mú ǹkan ọmọkùnrin le Kín ló kan ṣọ́ọ́sì pẹ̀lú ọkọ tí kò leè ta pútú?
Gbogbo nǹkan ẹ̀gbin tí àwọn orílẹ̀-èdè tí OLUWA lé jáde fún àwọn ọmọ Israẹli máa ń ṣe ni òun náà ṣe.
O ni gbogbo awọn ti ọrọ kan ni iwadii lori ẹsun naa ti bẹrẹ fun ati pe ijiya wa fun awọn ti ade ọrọ naa ba ṣimọ lori.
ati awon omo ile-igbimo asofin ipinle ti won nife si.
Ṣé àwọn alámọ̀dájú tuntun yìí á mọ̀ dájú dánu?
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Fani Kayode: Bùhárí ló lẹ̀bi Emir tí Olúwòó ń pe ara rẹ̀ 2 Ìgbé 2018 Oríṣun àwòrán, FFK/OLUWO Àkọlé àwòrán, Ẹnu kìí sin lara Femi Fani Kayode ati Oluwo Ẹni ba se ohun tẹnikan ko se ri, o di dandan ko gbọ ariwisi ti enikan o gbọ ri.
Mo sọ fún wọn pé, “A yà yín ati gbogbo nǹkan wọnyi sí mímọ́ fún OLUWA.
Bi awọn eeyan ko ba di ẹbi aisan naa ru wiwẹ ninu ojo,wọn a ni jijẹ agbado sisun a ma mu iba wa.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: A kò fẹ́ 23% tẹ fẹ́ yà sọ́tọ̀ bíí owónàá fáwọn ìjọba ìbílẹ̀ - ALGON Ọlọ́wọ̀ tìlú Ọ̀wọ̀ tuntun gorí ìtẹ́, idà àlááfìà ló mú ní Ìpèbí Ojú wa rí tó ní Egypt, bí wọ́n ṣe ń tẹ̀ wá lọ́mú, ni wọ́n ń gbá wa ní ìdí"" Ẹ wo adúrú ẹnu tí mó n bọ́ - Jaiye Kuti Wo orílẹ́èdè tí wọ́n tí ń dáwó ìsìnkú ara wọn pámọ́ Ayédèrú Ọ̀ṣun ni wọ́n ń bọ lónìí, kìí ṣe ojúlówó - Bàbá Ọlọ́ṣun tún figbe ta Lẹyin eyi ni Lizzy, ẹni to sẹsẹ ti Mecca de fun isẹ Hajj, wa fi epe silẹ fun awọn to ba n tabuku oun per oun ko ba Toyin Abraham yọ lori ọmọ to bi."
ti awọn ẹṣọ ẹlẹwọn, awọn ẹṣọ abẹle ijọba apapọ (civil defence),
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Akomolede àti Aṣa: Ọ̀rọ̀ Ẹ̀yán ni Bunmi Femi Amao ń kọ́ wa lórí ètò Akọ́mọlédè àti Àṣà lóri BBC Yoruba Wọn fi kun ọrọ wọn pe Oluwo tun da awuyewuye silẹ lasiko to kede ninu oṣu Keje ọdun naa, pe gbogbo ọkunrin ilẹ Yoruba, ni itẹ Ooni Ile-Ife tọ si.
Ti a ba wa padanu ẹbi tabi ọrẹ bawo ni o ti ṣe yẹ ki a fun iru eeyan bẹẹ ni iro iṣẹlẹ laabi yi ti ko fi ni mu ipalara ba a?
nítorí pé iṣẹ́ ìyanu ti burẹdi kò yé wọn, nítorí òpè ni wọ́n.
Iroyin kan tilẹ sọ wi pe wọn gbe awọn akọṣẹmọṣẹ kan to wa ba Nkurunziza ṣepade lọ si igberiko lati igboro ti wọn si ba aarẹ t n kọ ebe pẹlu awọn agbẹ ilu Bujumbura.
Ọkunrin kinni tí a fi erùpẹ̀ dá jẹ́ erùpẹ̀, láti ọ̀run ni ọkunrin keji ti wá.
ninu idibo to n lo lowo-lowo paapaa julo ni awon olu-ilu.
Ogun náà gbóná gidigidi ṣugbọn àwọn ará Bẹnjamini kò mọ̀ pé ewu ńlá súnmọ́ tòsí wọn.
Ẹ̀yin tí mò ń kọ ìwé yìí sí náà wà lára àwọn tí Jesu Kristi pè.
Ope Aiyeọla: Nkan to pa emi ati Baba Suwe pọ
Ọjọ keji ọdun Keresi ni IS gbe fidio naa jade, leyi to mu awọn onwoye ohun to n lọ sọ pe wọn fẹ mọọmọ jẹ ko ṣe dede ọdun Keresimesi ni.
Ile ẹkọ alakọbẹrẹ Peteru Mimọ ni ilu Ile Oluji ati Luku Mimọ nilu Oke Igbo lo ti ka eto ẹkọ alakọbẹrẹ rẹ.
Ó máa ń ba ìgbẹ́kẹ̀lé jẹ́ Ó máa ń mú ipínyà gbèèrú si Ó máa ń tàbùkù bá òtítọ́ Àwọn ojúlówó ilé ìròyìn ló ń jíyà rẹ̀ Ó máá ń jẹ́ kí ó nira fún àwọn ará ìlú láti ṣe ìpinnu lóri ìgbésẹ̀ Kò dára fún ìrọ̀rọ̀wérọ̀ Kò tilẹ̀ dára fún àlàáfíà ará ìlú Ó máa ń fa ọ̀rọ̀ ìkóríra, ìwà ìpá àti ikú Ó máa ń ba íjọọba tiwantiwa jẹ́ Ó sì máa ń sọ ìròyìn di irinṣẹ́ ogun Àwọn ìròyìn míràn ti ẹ lè nifẹ si: Ọdún mẹ́tàlélógún lẹ́yìn ikú Ken Saro-Wiwa Idi ti ọgba ẹwọn fi nkun akunfaya ni Naijiria 'Wọ́n ní a kò lówó tó láti díje dupò ní Nàìjíríà' Mahassin Quadri ló gbà ìrànwọ $5,000 Tony Elumelu Kílódé tí awọn ènìyan maa ń gba ìròyìn òfégè gbọ́?
Ibẹ̀ ni wọn yóò maá dàná fún un yá.
o ṣalaye pe lootọ mọ marun ni oun bi, ṣugbọn Uwa da yatọ laarin gbogbo wọn.
Gbogbo àwọn tí wọ́n rí i sì ń wí pé, “A kò rí irú èyí rí láti ọjọ́ tí àwọn ọmọ Israẹli ti jáde láti ilẹ̀ Ijipti títí di àkókò yìí, ọ̀rọ̀ náà tó àpérò, ẹ gbìmọ̀ ohun tí a ó ṣe, kí ẹ sì sọ̀rọ̀.
Owo yii ju iye ti ofin la kalẹ fun ẹnikẹni lati gba lorilede Naijiria.
Ìtùmò : nígbà tì kò tíì sí ònà móto bí àwon ti a ní lònìí yìí àwon ènìyàn ti wón jè yálà ode tàbí àgbè a máa fi adúgbò Ìdí Àbà se ìpàdé won .
Oríṣun àwòrán, @LuqmanTI_2 Igba mẹrin ọtọtọ ni wọn dibo yan oloogbe Osinnowo sile igbimọ aṣofin ipinlẹ Eko nigba aye rẹ.
Lamẹki fẹ́ iyawo meji, ọ̀kan ń jẹ́ Ada, ekeji ń jẹ́ Sila.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Kemi Lala: mo ń gbìyànjú láti mú inú òbí mi dùn Bassey ni eto aabo yoo mẹhẹ si lọdun 2020 nitori owo to wa ninu aba eto iṣuna fọdun to n bọ ti kere ju.
Ogun ló ń wáyé ní Kogi, kìí ṣe ìbò dídì - Olùdíje gómìnà Lai Mohammed: A kò ní bojú wẹ̀yìn lórí àbádòfin ìṣàkóso ẹ̀rọ ayélujára Ẹ̀yin ẹ̀ṣọ́, ẹ kò gbọdọ̀ fààyè gba jíjí àpótí ìdìbò ní Kogi àti Bayelsa- Buhari Ọlọ́pàá kan jáde láyé, èèyàn méjì fara gbọta lásìkò ìdigunjalè ní Falomo l‘Eko O tẹ siwaju pe, Aarẹ Buhari ko parọ fun ajọ INEC nipa ipele iwe to ka.
Pẹ̀lẹ́ sùúrù l’àgbà fì ń lò
àwọn ọmọ Usa, àwọn ọmọ Pasea, ati àwọn ọmọ Besai;
egbe Al-Habibbiyya seto rẹ, ni eyi ti o kere tan egberun eniyan ni won n fun ni
Oríṣun àwòrán, Instagram/Olori Anu/Bobrisky Adarí àjọ NDDC, Pondei ṣetán láti sọ ohun tó mọ̀ nípa ìwàdíì tó bá ti gbádùn- NDDC Ọkùnrin kan pa ara rẹ̀ sínú ọgbà àjọ TRACE tó n mójútọ ìrìnnà ọkọ̀ nípìnlẹ̀ Ogun A yìnbọn lu Precious láti dáa dúró ni, akò mọ̀ pé o máa kú- Ọlọ́pàá Wo bí ètò ìsìnkú Isa Funtua ṣe wáyé ní ìlú Abuja Oríṣun àwòrán, Instagram/queen anu Àkọlé àwòrán, Alaafin Oyo kò dàgbà jù fún mi, ohun tó wù mí ní mo ṣe pẹ̀lú ayé mi- Olori Aanu Alaafin Oyo kò dàgbà jù fún mi, ohun tó wù mí ní mo ṣe pẹ̀lú ayé mi- Olori Aanu Ọkan lara awọn olori Iku Baba Yeye, Alaafin ti ilu Ọyọ, Ọba Lamidi Ọlayiwọla III, Olori Anuoluwapọ Adeyẹmi ti kan lu oju opo ayelujara lati fun awọn to n sọrọ nipa igbeyawo oun ati Ọbalaye naa lesi.
Nítorí náà, ẹ pàṣẹ pé kí wọ́n dáwọ́ iṣẹ́ náà dúró títí wọn yóo fi gbọ́ àṣẹ mìíràn láti ọ̀dọ̀ mi.
Gawat Àkọlé àwòrán, Ọpọ onwoye gbagbọ pe omi n bẹ lamu fun Oshiomole lori iṣọkan ẹgbẹ oṣelu naa Alaga tuntun fun ẹgbẹ oṣelu APC, Adams Oshiomhole, ti kede pe aisi ifẹnuko to kuna laarin awọn adari ẹgbẹ ati awọn ọmọ ẹgbẹ lo n da wahala silẹ lẹgbẹ oṣelu naa.
Èmi fúnra mi kì í tilẹ̀ dá ara mi lẹ́jọ́.
Adesina to ti fi igba kan ri jẹ Minisita fun iṣẹ agbẹ n f'ojusọna lati tun jẹ olori banki naa ninu eto idibo ti yoo waye l'oṣu Kẹjọ.
Abẹ́rẹ́ àjẹsára tio ṣe ànfàni fún ọ̀kẹ́ àìmọye àwọn ènìyàn ní àwọ́n ọ̀ọ̀rùndúnrún to ti pẹ́ sẹ́yìn, síbẹ̀ ọ̀pọ̀ àwọ́n eléto ìlera ni àwọn orílẹ̀-èdè àgbáye lo n sọ pé awọ́n ṣe àkiyési pé kii ṣe gbogbo ènìyàn lo fi ara mọ ọrọ̀ abẹ́rẹ́ ajẹsára, ti àwọ́n miràn si n kọ jálẹ̀ pé àwọn ko fẹ́ ẹ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Victor Moses, Oshoala gba ami ẹyẹ NFF 20 Èrèlè 2018 Oríṣun àwòrán, @nff Àkọlé àwòrán, NFF fun awọn agbabọọlu ni ami ẹyẹ Awọn agbabọọlu orilẹede Naijiria meji, Victor Moses ati Asisat Oshoala ti gba amiẹyẹ kare nibi eto ami ẹyẹ Aiteo NFF fun awọn agbabọọlu lọkunrin ati lobinrin lorilẹede Naijria ti wọn pegede fi gbọọrọ jẹka.
Gege bi ero ayelujara iko ohun Globo se so, O fihan pe, ise akonimoogba ohun te awon lorun, eleyi ti o sokunfa sisun ibasepo pelu re siwaju.
Ẹ kí gbogbo àwọn eniyan Ọlọrun tí ó jẹ́ ti Kristi Jesu.
Olukoyode to n soju fun adele alaga ajo EFCC,ogbeni  Ibrahim Magu,naa n soro nibi ayẹyẹ naa, o so
Mi o faramọ bi Pulev ti ṣe fẹnuko mi lẹnu tabi bi o ti ṣe fi ọwọ kan idi mi'' O fi kun pe ko yẹ ki wọn wu iru wa bẹ si obinrin kankan.
Eka ajo agbaye to n mojuto ọrọ ounje lo tẹwọgba ẹbun yii
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù EndSARS, EndSWAT Protests: Òbí agbábọ́ọ̀lù Kazim Tiamiyu Kaka àtàwọn míì tí ọlọ́pàá pa sọ̀rọ̀, omijé bọ́ lójú Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ EndSARS, EndSWAT Protests: Òbí agbábọ́ọ̀lù Kazim Tiamiyu Kaka àtàwọn míì tí ọlọ́pàá pa sọ̀rọ̀, omijé bọ́ lójú 2 Bélú 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 3 Bélú 2020 Kàyééfì tuntun rèé lórí #EndSARS, ọ̀rọ̀ pọ̀ nínú ìwádìí BBC Mi ò gbọdọ̀ fojú rí ẹni tó wọ aṣọ SARS; òkú méjì a bá Olorun nílé ni- Iya Kaka Tiamiyu Aseyori ikọ SARS akọkọ ni Eko ni wọn fi tan wọn kalẹ Naijiria Iwa ibajẹ, idunkooko mọ ni ati bẹẹ bẹẹ lọ lo sọ awọn oṣiṣẹ SARS di ari ma dun nu si fun ọpọ ọmọ orilẹ-ede Naijiria.
Ìyàlẹ́nu ni ó jẹ́ nígbà tí a dé ìsàlẹ̀ tán tí a rí i pé àwọn àlejjò náà kì í ṣe méjì tàbí mẹ́ta àti pé wọ́n pọ̀ díẹ̀.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Èèyàn kan tún jáláìsí nínú ìjàǹbá ọkọ̀ lọ́nà márosẹ̀ Ibadan sí Eko Èèyàn mẹ́tàlá dèrò ọ̀run nínú ìjàmbá ọkọ̀ lópòpónà Ìbàdàn s'ÈKó Rògbòdìyàn tó bẹ́ sílẹ̀ lórí afárá London jọ ìgbésùnmọ̀mí Gbogbo ètò ti tò fún àtúndì ìdìbò Kogi lónì - INEC Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ogun Cholera: Ọdọọdún ni àrùn onígbá-méjì máa n ṣọṣẹ́ ní Nàìjíríà-NCDC Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 3 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 5 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Oríṣun àwòrán, ALLSPORT/Getty Images Àkọlé àwòrán, Eyi ni igba kẹta laarin ọjọ mẹjọ ti ikọ agbabọọlu Arsenal fidirẹmi Eyi ni yoo si jẹ igba kẹta laarin ọjọ mẹjọ ti ikọ agbabọọlu Arsenal fidirẹmi.
”Lẹ́yìn tí wọ́n wádìí, wọ́n ní “Burẹdi marun-un ni ati ẹja meji.
Arẹ́májà kò sí, Olubadan fi tìlù-tìfọn kí àwọn ìjòyè káàbọ̀ lẹ́yìn ọdún méjì Iléẹjọ́ fún Seyi Makinde láṣẹ láti yan adelé alága ìbílẹ̀ ní ìpínlẹ̀ Oyo Jesu orí ayélujára kan rèé tó ń ṣèlérí iṣẹ́ ìyanu l‘Afirika Olóòtú ìjọba Gẹ̀ẹ́sì yan ọmọ Yorùbá ní Mínísítà Bakan naa lo sọ pe, eeyan mejidinlaadọfa ni wọn gbe lọ si awọn ileewosan orilẹ-ede Saudi fun itọju to l'agbara nitori pe, aisan wọn le pupọ.
Wo ìtàn ayé gbajúmọ̀ adigunjalè méje nílẹ̀ Yorùbá E wo ọmọ Yorùbá àkọ́kọ́ tó jà fún ẹ̀tọ́ àwọn aláwọ̀dúdú ní America!
" ní àsìkò yìí , ohun ọ ̀ ṣọ ́ ọwọ ́ rẹ ̀ tí á ń pè ní "" Àkún ' gé ."
Akosile iko ohun ni won tenumo nibi ipade apero gbogbogbo elekerinleladota egbe oselu ANC ti o waye ninu osu kejila odun 2017, eyi ti won fenu ko le lori lati gba awon ile naa lai san owo gba mabuni.
Dokita naa mọ pe, aarun naa lo pa iya rẹ - o si fẹ ẹ ṣe ayẹwo fun lati mọ boya oun naa ni.
"Onkọwe kan, Nellie Thompson, sọ ninu àyọkà kan to kọ nipa Marie pe ""Bonaparte sọ pe oun dẹkun lati ma a fi ọwọ pa idọ oun fun adun ibalopọ l'ọmọ ọdun mẹjọ, nitori ibẹru pe ki o ma kú gẹgẹ bi wọn ṣe kilọ fun""."
Ọ̀rẹ́ mi, èmi ni mo wí fún ọ, kò sí bí olùfẹ́ méjì ti lè wà kí wọ́n máà ní ìṣòro kan láàárin wọn.
It is right that people from around the world at this point in time have been generously pouring encomiums on your late husband.
Nítorí náà, ẹ ṣọ́ra yín, kí á má ṣe rí ẹnikẹ́ni ninu yín, kì báà ṣe ọkunrin tabi obinrin, tabi ìdílé kan, tabi ẹ̀yà kan, tí ọkàn rẹ̀ yóo yipada kúrò lọ́dọ̀ OLUWA Ọlọrun yín lónìí, tí yóo sì lọ máa bọ àwọn oriṣa tí àwọn orílẹ̀-èdè náà ń bọ.
Peju àti Yomi Ogunmola: Oríṣun àwòrán, Peju ogunmola Àwọn gbajumọ òṣèré tíátà yìí, tí wọn jẹ obinrin àti ọkunrin, ló jogún isẹ tíátà lọ́dọ̀ bàbá àti iya wọn, olóògbé Kola Ogunmola àti ìyàwó rẹ.
" Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Oba Adedokun Abolarin ti Oke Ila: Ó ya ọ̀pọ̀ tó súnmọ́ mi lẹ́nu bí mo ṣe ń kọ́ Eyi ni ọrọ ti ileeṣẹ aṣoju ijọba orilẹede Amẹrika fi sita loju opo Twitter rẹ lọjọ Aje, ọjọ kẹtalelogun, oṣu kọkanla.
A kọ orúkọ àwọn ọmọ Israẹli sílẹ̀ gẹ́gẹ́ bí ìran wọn; a kọ wọ́n sinu ìwé Àwọn Ọba Israẹli.
Ọwọ́ mi ni mo fi fi ìpìlẹ̀ ayé sọlẹ̀,ọwọ́ ọ̀tún mi ni mo fi ta awọsanma sójú ọ̀run.
Ìrìnkèrindò, bí mo ti ṣe tó, síbẹ̀ o kò gbẹ́kẹ̀lé mi!
Ìmọ́lẹ̀ yóo tàn fún olódodo ninu òkùnkùn,olóore ọ̀fẹ́ ni OLUWA, aláàánú ni, a sì máa ṣòdodo.
Má bá wọn lọ́wọ́ sí ọ̀rọ̀ òmùgọ̀ ati ọ̀rọ̀ òpè.
C Igwe n dari ni olupẹjọ, Mao Ohuabunwa ti fi idi ẹjọ to pe mulẹ.
 a mọ ̀ wọ ́ n mọ ́ ìlẹ ̀ kẹ ̀ alárànbàrà àti agbọ ̀ n pẹ ̀ lú àwọn ñǹkan gbígbẹ ́ .
Ṣaaju ni iroyin ẹlẹjẹ ti gba ori ayelujara pe eto igbeyawo naa yoo waye laarin minista tuntun fun Abojuto lori ọrọ Ijamba ati Igbayegbadun ọmọniyan lorilẹ-ede ati aarẹ Naijiria.
2019 Elections: Iléeṣé ológun ṣèlérí láti mú àṣẹ Buhari ṣẹ
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Bakare Mubarak: ọ̀pọ̀ èèyàn ló máa ń fẹ́ dúró sí ẹgbẹ́ mí tójú si máa n tì mí Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, BIAFRA at 50: Ìhàlẹ̀ ológun ni Gowon ni ká kọ́kọ́ fi bẹ̀rẹ̀- Aladejẹbi Èyí ni bí ogun abẹ́lé Biafra ṣe bẹ̀rẹ̀ ní Nàìjíríà Ọ̀pọ̀ àwòrán tó ń ṣeni láàánú rèè nípa ogun abẹ́lé Nàíjíríà Àwọn ohun tó yẹ kí o mọ̀ nípa Gómìnà Imo tuntun Hope Uzodinma Irọ̀ ni ìjọba ń pa, Ikọ Amọtẹkun ba ofin Naijiria mu- Ìgbìmọ̀ Yoruba Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, O leè má mọ̀ bóyá o ní àrùn HIV/AIDS o!
Àlàyé rèé lórí ááwọ̀ Femi Fani-Kayode àti Tunde Bakare Ikú Adewole Oniluola, tó ní ẹ̀bùn ìlù lílù jùlọ lágbàyéé, yóò nípa lórí Yorùbá - Tunde Kelani Ayinla Ọmọwura, orin èébú àti oríyìn lo fi di ọ̀rẹ́ àwọ̀n obìnrin Ẹ wo ojú àwọn afurasí tí yóò rojọ́ ẹ̀ṣùn àjẹbánu lọ́dún 2021 Bí Nàíjíríà bá fẹ́ kí ọdún 2021 dára, ohun tí yóò ṣe rèé - Obasanjo Ẹgbẹ́ ọ̀dọ́ méjì fìjà pẹẹ́ta, ẹ̀mí kan bọ́, ọ̀pọ̀ farapa Àhámọ́ ajínigbé ni ń bá wà lónìí, ọ̀pẹ́ awakọ̀ mi"" Ẹ wo nkan tí Deeper Life High School tún sọ lórí Don Davis, akọ́kọ̀ọ́ JS1 tí wọ́n fi ipá bálòpọ̀ Wo ọ̀pọ̀ mílíọ̀nù fóónù tí Whatsapp kò ní bá ṣiṣẹ́ mọ́ lọ́dún 2021 Ọpọlọpọ eniyan to fi mọ aarẹ Buhari lo n ṣe idaro ẹni nla to re ibi agba n re naa, ni ẹni ọdun mẹtadinlọgọrin."
Gẹgẹ bi akọsilẹ iwadi iwa ajẹbanu lọdun 2018 se safihan rẹ, Nambia lo se ipo karun nilẹ Afirika, orilẹede Seychelles si lo n lewaju.
- Ilé ẹjọ́ ìpínlẹ̀ Ondo Ilé ìwòsàn kan rèé tó ń fi àtùpà gbẹ̀bí aláboyún Adajọ naa ni igbẹjọ ẹsun ijọmọgbe naa gbọdọ wa si òpin kí oṣù keje tó ń bọ̀ ó to parí.
O sọ loju opo Instagram rẹ pe ara ọjọ Ẹti ọsẹ yii ni imura oun duro fun eyi to pe ni ''Friday swag.
Koda, Biṣọọpu Abioye tun kede rẹ gẹgẹ bi ara awọn pasitọ to wa fun isin naa.
O tun sọ pe oun ko ni bojuwẹyin mọ bi banki ọhun ba tilẹ yi ipinu rẹ pada lori awọn apo to tipa.
 schmadel ni o se awari planeti kekere yi .
Wọ́n péjọ ní Jerusalẹmu ní oṣù kẹta ọdún kẹẹdogun ìjọba Asa.
Sugbọn nibẹ naa ni wọn ti n tako ẹni to pin aworan naa lori ayelujara pe irọ ni.
Ìròyìn sọ pé àjọ náà mú Sani ni ọjọ iṣẹ́gun nílùú Abuja pé ò n lò orúkọ adelé ajọ EFCC ọgbẹ́ni Ibrahim Magu láti gba owó tabua lọ́wa àwọn aará ìlú.
#BBCNigeria2019 HIV ni èrè tó rí lẹ́yìn tí wọ́n tàn án sisẹ́ aṣẹ́wó Day 25: Àwọn àkànlò èdè lásìkò ìdìbò #BBCNigeria2019 Exclusive: Atiku dára ju Buhari ní ìlọ́po méjì - Obasanjo #BBCNigeria2019 Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí kan sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
Kí oore-ọ̀fẹ́, àánú ati alaafia láti ọ̀dọ̀ Ọlọrun Baba, ati Kristi Jesu Oluwa wa, kí ó máa wà pẹlu rẹ.
Ta ni agbábọ́ọ̀lù obìnrin tí o fẹ́ràn jù?
Ò bá jẹ́ fa awọsanma ya kí o sì sọ̀kalẹ̀,kí àwọn òkè ńlá máa mì tìtì níwájú rẹ;
Wọ́n ń sọ pé, “Ta ni yóo kọ́ lọ́gbọ́n?
Won sin oloogbe Mustapha Akanbi, lojo Aiku nile re to wa ni Ilorin,ni ipinle Kwara.
Ohun tó yẹ kóo mọ̀ nípa Fásitì Babcock rèé Fún ìgbà kẹ́ta láàrín oṣù mẹ́ta, àrá tún sán pa àwọn màlúù Fúlàní.
Ọ̀gágun Adékúnlé Fájuyi fi ara rẹ ji pé ti wọn ba ma a gbee,  ki wọn gbé òhun pẹ̀lú.
Kin ni awọn onímọ̀ sọ lórí ki ọkunrin maa mu ọyan iyalọmọ?
"Kà nípa ohun tí Alaafin Oyo sọ nípa ""ìkòkò ọbẹ̀"" àwọn ọmọ Nàìjíríà lọ́jọ́ Kérésìmesì Ìjọba àpapọ̀ ti kéde ìsúnsíwájú ọjọ́ ìforúkọsílẹ̀ nọ́mbà NIN Ojúlówó ọmọ Oluyole gan ni Adedibu, ìpasẹ̀ akọni náà ló tọ̀ nígbà ayé rẹ̀ Wo eyi to súnmọ́ ọ nínú àwọn ibùdó 203 fún ìforúkọsílẹ̀ fún NIN rẹ Bauchi ni 33 nígbà tí Plateau ni 22, Ogun ni 18, Akwa-Ibom si ni 16, Delta ni 13, sùgbọ́n Kaduna àti Osun jọ ni 12."
Ileeṣẹ ọlọpàá ilu Reedsburg ni ọkọ to jẹ ẹni ọdun mọkandinlaadọta ati iyawo ẹni ọdun mejidinlaadọta naa ni awọn fi ẹsun aitọju ọmọ ati aikọbi ara si ọmọ ara ẹni to fa iku kan.
Lẹ́yìn náà, ó lọ bá ọmọbinrin náà sọ̀rọ̀.
Lọdun 1844 si 1864 ni wọn tun ile ijọsin yii kọ.
 Àwọn pápá àti iyanrìn ni ohun kan tó pọ ̀ jù níbẹ ̀ .
Ẹnu igbà tó joyè yìí náà ni, ọba Muṣin
Ẹ má ṣe jẹ́ kí àkókò kan kọjá láìjẹ́ pé ẹ lò ó bí ó ti yẹ.
Wo iléeṣẹ́ ìjọba tí Kọmísánà tuntun kọ̀ọ̀kan ní Ọyọ yóò dìmú Buhari o, pèsè ohun tó yẹ sí ọgbà ẹ̀wọ̀n, kí àyípadà orúkọ wọn léè pegedé Awọn ohun ti El-Zakzaky mẹnuba ninu fidio naa niyi: Ijọba orilẹede India, ni ifọwọsowọpọ pẹlu ijọba Naijiria n fi aṣẹ lelẹ pe anfani meji loun ni, yala ki oun faramọ ilana itọju ti wọn ba fi silẹ fun un tabi ki wọn daa pada si Naijiria Ijọba apapọ pinnu ni nnkan bii agogo mẹwa ku diẹ lalẹ ọjọbọ, lati gbe oun ati iyawo rẹ pada si ilu Abuja El-Zakzaky ni irọ pọ ninu atẹjade ti ijọba Naijiria fi sita ati pe, o ku sọwọ awọn eeyan lati mọ ibi ti wọn duro si, yala pẹlu oun ni tabi pẹlu ijọba O ni nigba ti awọn de orilẹede India ni awọn rii pe wọn ti yi ileewosan ti awọn ni lọkan pada kuro ni ileewosan ti awọn fẹ lo tẹlẹ O ni ohun ti ijọba n sọ fun araalu ni pe oun loun funra oun yan ileewosan, ti o si jẹ pe nnkan ti wọn n sọ fun awọn alaṣẹ ileewosan India ni pe ijọba Naijiria lo yan ileewosan ti wọn fẹ lo funra wọn O ni ajọmọ wa laarin ijọba Naijiria ati India pe, awọn n gbe awọn eeyan kan ti wọn n fi ẹsun iditẹgbajọba kan wa sibẹ, ti wọn si fẹ ki ijọba orilẹede India pese abo to peye fun O ni awọn dokita kan wa to fun awọn ni oogun kan ni nnkan bii ọdun mẹrin sẹyin lasiko ti wọn ṣi wa ninu ahamọ El-Zakzaky ni oun ko ni igbagbọ ninu ileewosan ti wọn gbe oun lọ nitori awọn iṣẹlẹ to waye lasiko ti wọn de orilẹede India Nitorina, o san ki awọn pada si orilẹede Naijiria dipo ki wọn ṣe itọju awọn ni ileewosan, latọwọ awọn dokita ti oun ko ni igbẹkẹle ninu wọn.
Oríṣun àwòrán, Olarewaju Onigegewura Àkọlé àwòrán, Ayipada diẹ ti de ba oye aarẹ ọna kakanfo nitori ko si ogun mọ ni ilẹ Yoruba Gani Adams Ọmọ ilu Arigidi-Akoko ni ipinlẹ Ondo lẹkun iwọoorun gusu orilẹede Naijiria ni Gani Adams.
Ó yẹ ki Òṣèlú Nigeria ṣe àyẹ̀wò òfin ti aṣojú Ilú Ọba – Lugard fi da Guusu àti Àríwá pọ fún irọ̀rùn ìṣàkóso orilẹ̀ èdè Nigeria ni ọgọrunlemeji ọdún sẹhin.
Nígbà tí àwọn ará ìlú wa rii pé mo ń ṣe bi iré bi iré mo ń di ènìyàn pàtàkì ni wọ́n ti bẹ̀rẹ̀ síí wọ́ wá sí ilé mi, ti wọn ń ṣe ọ̀rẹ́ mi, àwọn ìbátan wa gbogbo ti a sì ti sọnù rí ni ọ̀ràn yìí wú jáde tí wọ́n fi ara wọn hàn bí ará ilé mi bí àwọn ẹ̀gbọ́n mi ti ń bbí sii, ni àwọn àbúrò mi ń lé  síi, àkókò náà ni mo sì mọ̀ bí bàbá ńlá baba mi ti ṣe ba ìyá ńlá ìyá ẹelòmíràn tan.
 “Ireti wa pe, atunse si ilana ti awon egbe miiran yoo fi seto eyawo ohun fun awon agbe, yoo waye ni sise-n-tele”.
- Trump Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Kí lo tíì rí nípa Amotekun?
Ẹ jẹ́ kí ọkàn yín bàjẹ́, ẹ ṣọ̀fọ̀, ẹ sọkún; ẹ má rẹ́rìn-ín mọ́, ńṣe ni kí ẹ fajúro.
Ẹni ọdún 21 di ọ̀dọ́mọ́dé tó lówó jùlọ lágbàáyé Boko Haram ṣíná fún àwọn tó lọ ìsìnkú, èèyàn 23 pàdánù ẹ̀mí wọn Kò lè ṣééṣe kí Ruga wà lápá gúúsù Nàìjíríà fáwọn Fulani- Ganduje Ẹni ba sọrọ ikorira yoo wọ gbaga ofin Awọn miran to n gba owo gọbọi ni Ariana Grande to n gba $966,000, nigba ti Cristiano Ronaldo n gba $975,000 fun igba kigba ti wọn ba ko nkan si oju opo Instagram wọn lẹẹkanṣoṣo.
Gbogbo èdè kọ̀ọ̀kan ló ní àwọn ìró èdè tirẹ̀ tí a ń pè ní Fóníìmù.
 Sagbekale re fun ara-ilu akoko lorile-ede yii.
Justice for Uwa: Ọ̀gá Ọlọ́pàá Naijiria sèlérí láti wá àwọn tó ṣekúpa Omozuwa láwàrí Ọga Agba Ọlọpaa lorilẹede Niajiria, Mohammaed Adamu ti seleri wi pe awọn yoo se awari awọn to sekupa arabinrin Vera Omosuwa ni ipinlẹ Edo.
Iya agba, ẹni ọdun mọkandinlọgọrin, Mojisọla Odegbami ti ṣoju orilẹ-ede Naijiria ati ilẹ Afrika ninu awo orin tuntun ti olorin takasufe ilẹ Amerika, Beyonce ṣẹṣẹ gbe jade, to pe orukọ rẹ ni ‘Black is King’.
Lẹyin naa, tẹle awọn igbesẹ ti o ba yẹ Yatọ si 'Cardless Withdrawal, awọn ọrọ ti awọn ileefowopamọ tun maa n lo ni Cash-on-The-Go, Dial4Cash, Magic Cash, ati bẹẹbẹ lọ.
Ìwé àṣẹ náà wà fún aṣàlàyé atòlànà kọ ̀ mpútà àti bákanáà fún àwọn ìjésì míràn àti fún àwọn ìwé ìlànà .
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Helen Paul: Bí o kò bá fẹ́ kí wọ́n mọ ìrírí rẹ, òun pa ẹlòmíì lára Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Helen Paul: Bí o kò bá fẹ́ kí wọ́n mọ ìrírí rẹ, òun pa ẹlòmíì lára Oríṣun àwòrán, itshelenpaul Àkọlé àwòrán, Helen Paul 19 Ìgbé 2019 Apanilẹrin, olorin ati oṣere ni Helen Paul.
Tiemoko Sangare, leni ti o yan gege bi minisita tuntun ti yoo maa mojuto eto aabo, ti fi igba kan tele je minisita to n mojuto oro iwakusa ati ipese irin.
com/APC Àkọlé àwòrán, Orisirisi a[rà ni Sun n da lori ìkànì Twitter ẹgbẹ́ oselu APC Egbẹ APC ko tii fọhùn rárá lori ọ̀rọ̀ naa.
"Awan obinrin ti ko ni arun BV tẹlẹ ni kokoro iru eyi to dara fun agọ ara ti wọn n pe ni ""lactobacilli"" eyi to maa n mu ki oje oju ara obinrin duro deede ṣugbọn iduro deede yii naa le yẹ."
kun  oro won pe oniruuru ona ati igbese
Ọba Oluwole waja nigba to ya amọ dipo ki wọn fi Kosoko ti oye naa tọ si jọba, Akitoye, tii ṣe aburo baba rẹ lo gori itẹ nitori aisi nilu Kosoko, eyi to mu ki wahala miran bẹ silẹ nilu Eko nigba ti Kosoko pada wọ ilu.
Pẹlu ìrànlọ́wọ́ Ọlọrun, wọ́n fi Ṣerebaya, ọlọ́gbọ́n eniyan kan ranṣẹ sí wa.
Ki wọn fi eti si ohun ti ará ilú lati Guusu dé Àriwá sọ, pé ki wọn joko sọ̀rọ̀ bi wọn yio ti ma bára gbé.
Gaali ọmọ Ebedi ati àwọn arakunrin rẹ̀ kó lọ sí Ṣekemu, àwọn ará ìlú Ṣekemu sì gbẹ́kẹ̀lé e.
wọ́n gbẹ́ igi ọ̀pẹ, ati òdòdó, ati kerubu sí ara àwọn ìlẹ̀kùn náà; wọ́n sì yọ́ wúrà bò wọ́n patapata: ati igi ọ̀pẹ, ati òdòdó, ati àwọn Kerubu náà.
Ṣugbọn ẹni tí ó gba àpò kan lọ wa ilẹ̀, ó bá bo owó oluwa rẹ̀ mọ́lẹ̀.
Bakan naa ni o ṣe iranwọ fun Manchester City lati gba Premier League.
Ni ọjọ kẹrinla oṣu kẹfa ọdun 2019, ni ajọ EFCC kọkọ fi oju Afaa Jamiu ba ile ẹjọ lori ẹsun mẹrin ọtọọtọ to nii se pẹlu iwa gbajuẹ ati jibiti lilu.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ajá kìí rorò kó ṣọ́ ojú'lé méjì, kò tọ́ ọ́ sí Alaafin láti dásí ọ̀rọ̀ ọba l‘Ekiti - Peter Fatomilọla Coronavirus dá wàhálà sílẹ̀ ní Ghana, ìjọba gbé ìlẹ̀kùn gbogbo iléẹ̀kọ́ tìpa Iṣẹ́ akin ni ọ̀gá iléẹ̀kọ́ tó kú nínú ìbúgbàmù Eko ṣe, ẹ fàmì ẹ̀yẹ da lọ́lá - PDP késí ìjọba Rẹ́rẹ́ rún níbi ìbúgbàmù l'Eko, ọ̀pọ̀ àwòrán rèé Gbogbo ẹ̀yin tẹ fẹ́ yọ Oshiomole nípò, ẹ kò moore, ìwà yín ń kóbá APC - Tinubu Iwaadi ileeṣẹ iroyin BBC fi han pe, wọn ti gbe oku sista Henrietta Alokha, to jẹ alakoso ileewe Bethlehem Girls College ati awọn oṣiṣe ile iwe ọhun meji miran, ti jade laye lẹyin iṣẹlẹ yii, lọ si ile iwosan awọn omọ ogun ori omi nilu Eko.
Òsèré Tíátà ọmọ Nàìjíríà, olóòtú àti olùdarí eré.
Oríṣun àwòrán, Reuters Àkọlé àwòrán, Ọmọkunrin kan ni orilẹede olu ilu orilẹede Senegal, Dakar, da bi ẹni to n ṣọra fun awọn eye kan ti wọn kọja lọ l'Ọjọru (Wednesday).
Edo: Ẹran dida ati ibọn gbigbe deewọ
Nígbà tí Jakọbu ati ìdílé rẹ̀ lọ sí ilẹ̀ Ijipti, tí àwọn ará Ijipti ń ni wọ́n lára, àwọn baba ńlá yín kígbe pe OLUWA fún ìrànlọ́wọ́, OLUWA sì rán Mose ati Aaroni, wọ́n kó wọn jáde kúrò ní Ijipti.
Ẹ̀bùn a máa ṣí ọ̀nà sílẹ̀ fún ẹni tí ń fúnni lẹ́bùn,a sì mú un dé iwájú ẹni gíga.
Iwe abadofin tuntun ohun lo fi han pe, ki won fi kun iye eniyan ti yoo bowolu ipo ondije dupo aare lorile-ede ohun.
Koda, wọn n ji awọn eeyan gbe lagbegbe naa, wọn n fi tipa ba awọn obinrin lopọ, ti wọn si tun n gba oko lọwọ awọn agbẹ.
ti lọ bura Akọroyin BBC to wa ni ibi ti wọn ti bura sọ wi pe owurọ kutukutu Ọjọ Aje ni awọn eniyan lọ si ile Óba Deji lati lọ bura ti wọn ba mọ nipa bi ọmọ naa ṣe sọnu.
Gbogbo orin egúngún bìkiafù tí wọ́n kọ sí mi l'étí nípa Ajayi tí mi o gbọ̀ ló bu mí lọ́wọ́- Akeredolu 'Ẹ gbà wá o, á ti há sí Oman, ẹ dákun ẹ wá kó wa jáde o' Ǹjẹ o yẹ kí èèyàn máa sùn lẹ́nu iṣẹ́?
Loṣu kẹfa ni awọn agbofinro mu Ramoni Olorunwa Abbas lori ẹsun lilu jibiti lori ayelujara.
Koda o ṣalaye pe, gbedeke ọlọjọ meje tawọn fun ijọba yii kii ṣe akọkọ iru rẹ.
"Wiro sọ pe ""a maa n gba awọm ọdọbirin nimọran pe ki wọn maa lo oogun to le dena oyun."
Naijiria yoo koju ẹgbẹ agbabọọlu South Korea ninu ifẹsẹwọnsẹ keji wọn lẹyin ti wọn jẹ ajẹtun iya ami ayo mẹta sodo lọwọ Norway ninu ifẹsẹwọnsẹ akọkọ ti wọn gba.
Orílẹ̀-èdè Chad pé ọgọ́ta ọdún, àwọn ara ìlú ń pariwo lábẹ́ Aàrẹ Deby tó gba 'Field Marshal' Ọwọ́ ikọ̀ aláàbò STF tẹ afurasí mẹ́jọ tó lọ́wọ́ nínú ìpànìyàn lemọ́-lemọ́ọ Gúúsù Kaduna Diezani gan an ní Hushmummy tó ń bú àwọn Yahoo boys- Àwọn Ọmọ Naijiria lórí Twitter Olùrànlọ́wọ́ pàtàkì fún ọ̀rọ̀ ibojì òkú, àti àwọn ipò òṣèlú mìíràn tó jẹ́ kàyééfì ní Nàìjíríà Asojú ìjọba orílẹ̀-èdè Lebanon ti kọ̀wé fipò silẹ̀ nítorí ìbágbàmù tó gbẹ̀mi ènìyàn 200 Kini o ti ṣẹlẹ sẹyin?
naa wa ro awon oloselu ati awon  ti ọrọ
Ti wọn ba si fi silẹ ko tẹsiwaju, yoo dojuti ilu Kano.
SERAP: Àwọn èèyàn Oyo gbọdọ̀ dásí àbá àjọ tó ń gbógun tìwà ìbàjẹ́
OLUWA ní, “Ẹ la ọ̀nà, ẹ la ọ̀nà, ẹ tún ọ̀nà ṣe,ẹ mú gbogbo ohun ìkọsẹ̀ kúrò lọ́nà àwọn eniyan mi.
Mo bèèrè lọ́wọ́ wọn pé,“Ǹjẹ́ ẹ rí ẹni tí ọkàn mi fẹ́?
Oríṣun àwòrán, EPA 2) Boya wọn n jẹ ounjẹ aṣaraloore?
"Ọkọ Funke Akindele kó eléré àti òṣìṣẹ́ jọ fi ṣe ""Surprise Pato"" fún un lọ́jọ́ ìbí rẹ̀ Irú ẹ̀dá wo ni Ọjọgbọn Folasade Ogunsola jẹ́?"
Lẹyin ọpọ ọdun ti wọn ti n ṣiṣẹ lori rẹ o ti tobi biliọnu dọla kan ti wọn ti na lori rẹ bayi.
Ní ọjọ́ tí n óo bá jẹ Israẹli níyà nítorí ẹ̀ṣẹ̀ rẹ̀, n óo jẹ pẹpẹ Bẹtẹli níyà, n óo kán àwọn ìwo tí ó wà lára pẹpẹ, wọn yóo sì bọ́ sílẹ̀.
”Ṣugbọn alufaa wí pé, “Ẹ jẹ́ kí á kọ́kọ́ bèèrè lọ́wọ́ Ọlọrun ná.
Ilẹ̀ yín ní ìhà gúsù yóo bẹ̀rẹ̀ láti aṣálẹ̀ Sini lẹ́bàá ààlà Edomu.
ni ipinle Kaduna lati ran awon eniyan leti pe gbigba eto alaafia laaye se Pataki
DJ Switch ni awọn ọmọ ogun to dihamọra atawọn ọlọpaa, lo ṣina ibọn bolẹ fun awọn oluwọde EndSARS lalẹ ọjọ Iṣẹgun.
”Ogbeni Namdas fikun un oro re pe, awon asofin ohun ti sagbekale igbimo eleni mejo tuntun ti yoo mojuto bi iwe isuna naa yoo se de ile-ise aare lati fase si.
 omu ka ko ise ribiribi lokunkundun .
O da a silẹ lati maa ran awọn alaini lọwọ nitori bi idile rẹ ṣe talaka nigba to wa ni kekere.
“Ọpọlọpọ igba ti wọn ba ni ẹ wo baba kukuru yii, emi naa a ni ẹ wo baba giga yii, a kan ma sọ ọ di awada tori naa mi o jẹ ki gbogbo iyẹn mu irẹwẹsi de ba mi” Koda, oluṣọ aguntan ni pẹlu ni ijọ Redeem Church.
Erongba mi ni pe, awọn eniyan yoo wo o pe mi o ki n ṣe obinrin rere lo mu ki ọkọ mi gbe igbesẹ bẹ ẹ.
Nítorí bí pàkúté bá lọ bá ọ ní ibiburúkú kò ní í dára, bí ó bábá orí, orí lè fọ́, bí ó bá bá ẹsẹ̀, ẹsẹ̀ lè gé dànù, òuun sìlè sọ olúwaarẹ̀ di ẹni tí ń rìn yẹ́ńkúyẹ́ńkú kiri.
8 akẹkọọ to forukọ silẹ lọdun yii eleyii tumọ si pe o fi diẹ ju iye miliọnu 1.
Kano Woman who killed son: Obìnrin kan dèrò ilé ẹjọ́ lórí ẹ̀sùn pé ó fi ọ̀bẹ rẹ́ ọmọ rẹ̀ lọ́rùn
Kò kúkú lè lọ sí ilé- ẹ̀kó, ńṣe ni àwọn ẹgbẹ rẹ̀ tí wọ́n gbọ́, wá ń kí I nílé.
Solomoni ni wọ́n ń gbé bọ̀, lórí ìtẹ́ rẹ̀,ọgọta akọni ọkunrin, lára àwọn akọni Israẹli,ni ó yí ìtẹ́ rẹ̀ ká.
Ọ̀gá tíṣà rí ẹ̀wọ̀n ọdún mẹ́wàá he nílùú Eko fún ẹ̀sùn lílú jìbìtì Ọwọ́ tẹ àwọn ọlọ́pàá tó fìyà jẹ obìnrin kan lọ́nà àìtọ́ n'Ibadan Wo ǹkan tí ojú àwọn èèyàn rí lẹ́yìn tí wọ́n ti afárá 'Third Mainland' Ọlọ́pàá kan sọ pé òun ní láti ṣàyẹ̀wò ìlédíìí ǹkan oṣù Arabìnrin kan kó tó lè kọjá Ò kéré tán N1million là ń ná lórí alárùn Coronavirus kọ̀ọ̀kan; àlàyé rèé- Ìjọba Eko Ìgbésẹ̀ wo ní aláboyún lé gbé láti dẹ́kun ìjẹkújẹ nínú oyún?
Ọmọ ọdọ̀ Ọpẹ Bademosi kò kú 31 Ọ̀wàrà 2018 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 29 Bélú 2018 Oríṣun àwòrán, Ope bademosi/facebook.
Ọ̀pọ̀ omi kò lè pa iná ìfẹ́,ìgbì omi kò sì lè tẹ̀ ẹ́ rì.
Iwọde #ENDSARS ni Lekki Ni ṣe ni àwọn oluwọde naa di oju ọna marosẹ Lekki si Epe, pẹlu oriṣiriṣi akọle ti wọn gbe dani.
Nígbà náà ni ẹ̀mí gbé mi dìde, ó sì gbé mi lọ.
Super Tuesday: Kí ni ìtumọ̀ àti pàtàkì rẹ̀?
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù NEC fi òfin de dída ẹran ọ̀sìn kiri nìpínlẹ̀ márùn uń 27 Ìgbé 2018 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Darandaran Nàìjíríà gbọ́dọ̀ kọ́ ọgbà fún ẹran ọ̀sìn wọn báyìí NEC bẹ̀rẹ̀ ìgbésẹ̀ wíwá ojútùú sí ìṣòro àwọn àgbẹ̀ àti àwọn darandaran pẹ̀lú òfin Àwọn ìgbìmọ̀ alásẹ ìjọba àpapọ̀ orílẹ̀èdè Nàìjíríà, NEC, fọwọ́ sí àbádòfin àwọn ìgbìmọ̀ tí ìjọba yàn láti wá ojútùú sí ìjà ojoojúmọ́ láárín àwọn àgbẹ̀ àti àwọn darandaran gbé wá.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ibikunle Amosun: Ǹ ó fi ẹgbẹ́ òsṣèlú APC sílẹ̀' 11 Ọ̀wàrà 2018 Oríṣun àwòrán, Senator Ibikunle Amosun Facebook Àkọlé àwòrán, Gómìnà Ibikunle Amosun Gómìnà Ibikunle Amosun ti ìpínlẹ̀ Ogun, Sẹ́nétọ̀ Ibikunle Amosun ti dẹ́rù bolẹ̀ lọ́jọ́rú ọjọ́ kẹwàá oṣù kẹwàá pé oun yóò fi ẹgbẹ́ òṣèlú APC sílẹ̀.
Bí àwọn baba ńlá wa ṣe lọ sí ilẹ̀ Ijipti, tí wọ́n sì gbé ibẹ̀ fún ìgbà pípẹ́.
Awon agbebon sekupa asofin Sugar ni agbegbe
Aṣọ rẹ̀ mọ́ gbòò bí ọjọ́.
Eyi si mu ki gbogbo awọn to tẹle e wa sibẹ o ma a fẹ ẹ l'oju, fẹ ẹ nimu, rọ omi si i l'ori ko ma baa gba bẹ lọ.
"Koda, ẹni to ba ju Abiola Ajimobi, yoo tun sọ fun pe ""ọjọ melo gan lẹ fi ju mi lọ""."
"Oríṣun àwòrán, funkejennifaakindele Lẹyin eleyi lo tun ṣe afikun pẹlu agbejade ""Return of Jennifer""."
Isẹlẹ naa la gbọ pe o waye ni owurọ Ọjọru, ti wọn si jo ile naa kanlẹ.
Àwọn alátìlẹ́yìn-in rẹ̀ ń pè fún ìtúsílẹ̀ẹ rẹ̀ lóríi ẹ̀tọ́ ọmọnìyàn, látàrí wípé a ti yọ àbọ̀ ẹ̀dọ rẹ̀ nítorí àrùn jẹjẹrẹ àti àrùn ọkàn àti ìṣòro kíndìnrín.
Sikiri ni baálé ní ìdílé Abija,Pilitai ni baálé ní ìdílé Miniamini ati Moadaya,
Yatọ si Joshua, Odion Ighalo to jẹ agbabọọlu Naijiria naa da si ọrọ yii.
Ajọ EFCC to ni, igbesẹ awọn ko ni nkankan ṣe pẹlu Atiku Abubakar tabi awọn ọmọ rẹ, wa tako awọn iroyin to wa nita.
O salaye pe asiko yii ni Seyi wa wo oun loju, to si ni oun ni olukọ oun nile ẹkọ St Michael, ti awọn si di mọ ara awọn.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Shiite: Tinúbú, bá Buhari sọ̀rọ̀ kó tú ZakZaky sílẹ̀ kó tó pẹ́ jù O ni oun ko mọ ofin ni kikun ṣugbọn nkan kan ti o da oun loju ninu ifọrọwerọ naa ni pe ijọba ti gbe ẹjọ kotẹmilọrun lọ sile ẹjọ agba ni ipinlẹ Kaduna.
N óo sọ ọ́ di ahoro títí lae, ẹnikẹ́ni kò sì ní gbé inú àwọn ìlú rẹ mọ́.
Oluwo gba Aláàfin nímọ̀ràn pé kí olorì máa dé adé Só lè jẹ búrẹ́dì tí wọ́n fi Aáyán se?
Awọn alaṣẹ Barcelona ni Messi ko le lọ bayii nitori oṣu karun ti kọja, amọ Messi ni ajakalẹ arun coronavirus ni ko jẹki oun sọrọ lati igba yii wa.
Ki lo n bi awọn eeyan ninu nipa abadofin yii?
Ní gbogbo ìgbésí ayé rẹ tí ó bá sì kù, tọ́jú ìwà rẹ, máṣe bá ojú kòkòrò ṣe àjọpín, nítorí ojúkòkòrò ti lu òfin kẹẹ̀wá Olódùmarà, òun dàbí ọ̀mùtí ènìyàn tí ó ṣẹ̀ṣẹ̀ fẹ́ lọ mọ ìlú Èkó, tí o wọ reluwé, nígbà tí ó dé ibi tí à ń pè ní Ìdó, ó sọ̀kalẹ̀, ó kọjú sí Èkó, nígbà tí o sì dé o ń afá tí ó wà lórí omi ọ̀sà, o ń wo ìhín wo ọ̀hún, kò fi ojú sí ibi tí ó ń lọ, nígbẹ̀yìn, ó dúró, ó yọjú lórí afá, o tún ṣe, ó gun orí irin gíga tí wọ́n fi mú afá dúró, ó ń rẹ́rìn-ín lẹ́yìn náà, ó doríikodò, o ń fì dùgbẹ̀, ibi tí o ti ń fì dùgbẹ̀, ọwọ́ já, ó tàkìtì, ó di inú odò ẹja ríi, ẹja gbée mi ẹranko ńlá tún rí ẹjà, ẹranko ńlá ggbé ẹja mi, ejò ńlá mìíràn tún rí ẹranko, ejò ńlá tún gbé ẹranko mi, ẹja inú òkun wá bá ẹja inú ọ̀sà seré, ó rí ejò, ó tún gbé ejò mi, nígbà tí ó padà dé inú òkun, ó ti sanra, ẹja mìíràn tún rìí, ó tún gbé e mì, àsẹ̀yìnwá àsẹ̀yìnbọ̀ àwọn apẹja rí ẹja ńlá yìn, wọn pa á, wọ́n wọ́ ọ sí òkè, wọn mú ọ̀bẹ wọ́n la inú ẹja.
 wọn a maa yọ díè nínú ìdejú tí ó pa lara , tí wọ ́ n sì maa rán pàpọ ̀ padà .
Nígbà náà ni ẹ̀tanú gba ọkàn Olórí Alufaa ati gbogbo àwọn ọmọ ẹgbẹ́ Sadusi tí ó wà pẹlu rẹ̀.
“Ní ọjọ́ keje, ẹ óo máa fi ẹgbọ̀rọ̀ akọ mààlúù meje, àgbò meji ati ọ̀dọ́ àgbò mẹrinla ọlọ́dún kọ̀ọ̀kan tí kò ní àbààwọ́n rúbọ.
Ogagun Salvador Cienfuegos, to je minista fun eto aabo ile Mexico ti lo sibe lojo Abameta lo baa won eniyan daro pelu ebe pe ki won ma binu lori isele naa ti oun yoo sa ipa oun lati je ko rorun.
Àwọn ilé iṣẹ́ tó jẹ́ pe abẹ́lé ni wọn tí ń ṣe iṣẹ́ tiwọ̀n, yóò maa san mílíọ̀nù mẹ́wàá Náírà láti gba ìwé àṣẹ, tí wọ́n yóò sì máa san mílíọ̀nù mẹ́rin náírà láti sọ ìwé àṣẹ wọn dọtun lọ́dọọdún.
"Oríṣun àwòrán, Instagram/officialwaleelesho ""Fiimu meji ti mo ṣe pẹlu awọn akẹgbẹ mi, ko si ẹni to gba lọwọ wa, nigba to ya ni gbogbo awọn ọmọ ẹgbẹ oṣere mi tuka, ti o si ku emi nikan."
Ilana ohun tun wa fun mimu igberu ba oja ati ounje ti awon ara-ilu n ra lorile-ede Nigeria.
Mo fẹ́ kí ó yé ọ kedere pé bí ọkùnrin bá wu obìnrin bí obìnrin náà bá si fi ifẹ́ yìí han si ọkùnrin eléyìínì kò lòdì si òfin.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ǹjẹ́ o mọ pàtàkì igi tó wà ní àyíká rẹ bí?
Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí What are opioids and what are the risks?
Ọọ̀ni obìnrin, Lúwòó Gbàgídà rèé, akọni tó ń gun ọkùnrin ní ẹṣin rìn LASEMA ni arabinrin naa wa ni Kilasi SS3 ni ile iwe girama New Era, ni Surulere ni wọn si oku rẹ lẹyin ọjọ kan ni Canal Onilegogoro ni agbegbe Suurulere.
Ọpọ igba ni eeyan maa n gba awọn alejo to wu ni lati gba pẹlu ayọ ati idunnu.
Igbimọ ajọ adojutebi naa ni ibanujẹ ni iku awọn oṣiṣẹ wọn yii jẹ fun wọn pe o si dun wọn pẹlu gbogbo akitiyan wọn lati bere fun itusilẹ wọn.
" Adesina ni awọn mejeeji ku silẹ fun ẹrin, tawọn ayaworan si ya awọn, eyi ti wọn lo lori mohunmaworan, ti ọpọ eeyan si n bi ohun leere pe ki lo mu ki awọn mejeeji rẹrin arintakiti bẹẹ.
Ibanujẹ ibẹ ni pe iroyin naa ni lẹyin ọrọ pẹlu baba ọmọdebinrin wón jọ ṣe adehun lati maa san ẹgbẹrun lọna ọọdunrun ati addọrin naira loṣooṣu titi di oṣu keji ọdun 2020.
Ìdí nìyí tí ìlérí náà fi jẹ́ ti igbagbọ, kí ó lè jẹ́ ọ̀fẹ́, kí ó sì lè fẹsẹ̀ múlẹ̀ fún gbogbo ọmọ Abrahamu.
Tí ènìà bá rìn díẹ̀ kọjá orí òkè kékeré yìí dé ibi èbá odi tí ó yí pápá onígbẹ̀ẹ ́yìi po, ènìà ní láti fo odi ọ̀hún kọ̀ já sí òdì kejì kí ènìà tó lè tẹ̀ síwájú.
Ìtàn tó wà nídi òwe ‘Sebótimọ Ẹlẹ́wà Sàpọ́n’ Saraki pín owó ìyọ̀nda rẹ̀ fún ẹbí Leah Sharibu àtàwọn míì Dangote, Fayemi pari ìjà láàrin Ganduje àti Emir Sanusi Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Iba Gani Adams: Bẹ́ẹ gbé màláíkà kan lọ sí Aso Rock, kò lè ṣàṣeyọrí Ni oṣu kẹrin, ile ẹjọ dajọ pe Walter Onnoghen jẹbi awọn ẹsun ti wọn fi kan an ti wọn si ni ko lọ rọọkun nile.
Ninu ìran náà, mo rí i tí ìjì kan ń jà bọ̀ láti ìhà àríwá, pẹlu ìkùukùu ńlá tí ìmọ́lẹ̀ ńlá ati iná tí ń kọ mànàmànà yí ìjì náà ká, ààrin iná náà sì dàbí idẹ dídán tí ń kọ mànà.
Ṣugbọn Hobabu dá a lóhùn pé: “Rárá o, n óo pada sí ilẹ̀ mi ati sọ́dọ̀ àwọn eniyan mi.
Amọṣa, Ndidi tun ọmọluwabi rẹ ṣe nigba to fi ori gbe bọọlu sinu awọn Chelsea ni iṣẹju kẹtadinlaadọrin ifẹsẹwọnsẹ naa.
Ni wọn igba ti aarun naa si ti tan kaakiri agbaye diẹ diẹ - nipa irinajo kiri agbaye - ti oju ọjọ si ti n yi pada, o ṣòro lati tọka si ipa oju ọjọ.
9 132 Erekusu Virgin Island tilẹ Gẹẹsi 1 3.
Ọ̀gá àgbà ilé-ìwé Ọbafẹ́mi Awolọ́wọ́ tún fi kún ọ̀rọ̀ rẹ̀ pé, àwọn ń sapá láti fopin sí gbogbo ìwà ìdúkòò mọ́ni fún ìbálòpọ̀ nílẹ̀ ẹ̀kọ́ náà   Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Fasiti ile iwe giga Toronto ni Boyle Komolafe kọkọ lọ lati kọ ẹkọ to ni i se pẹlu ihuwasi ati awujọ ni ọdun 2005 si ọdun 2008 Fasiti ile iwe giga Liverpool lo ti kọ ẹkọ eto isuna owo ni ọdun 2009 si ọdun 2012.
bí mo bá fi ìyà jẹ aláìníbaba,nítorí pé mo mọ eniyan ní ilé ẹjọ́,
Ko si si idi ti ẹnikẹni fi gbọdọ fi ipa ba eeyan lopọ."
Oríṣun àwòrán, Abiola Ajimobi Akala, ẹni ti ohun rẹ rẹwẹsi lasiko to n ba wa sọrọ ni ohun ko tii le sọ ohunkohun nipa oloogbe naa.
Bí ó bá jẹ́ ọkunrin, tí ó jẹ́ ẹni ọdún marun-un sí ogun ọdún, yóo san ogun ìwọ̀n ṣekeli; bí ó bá jẹ́ obinrin, yóo san ṣekeli mẹ́wàá.
INEC: Yinka Ayefẹlẹ jẹ adari tootọ ni eto iroyin
0 348 Orilẹede Seychelles 0 0.
Òkè Ìdànrè rèé níbi tí ilé ayé ti tẹ́jú pẹrẹsẹ Fídíò rèé nípa bí Aláké tuntun ṣe ń gba ìwúre lábẹ́ Olúmọ kó tó gba adé Géńdé agbébọn jí adájọ́ gbé lọ ní ìpínlẹ̀ Ondo Wúndía àti Ọba nìkan ló lè dé Orí Òkè Ọwá ní Ìjàrẹ Ondo- Àgbà Oloye Afi bii igba teeyan n goke re ọrun ni, boo ba ti sọnu tabi ha sinu igi lọna, o pari; koda, oke naa kii ṣe eyi teeyan le ni oun fẹ naro lati maa pọn ọn gun.
Aare ajo NFF, Amaju pinnick dupe
Ikede yi ta ri ka loju opo awọn ileesẹ iroyin sọ pe o faye silẹ laipẹ ọjọ ti o ṣe isẹ abẹ ọpọlọ.
Báyìí ni èkúté sọ fún mi mo sì dúpẹ́ lọ́wọ́ rẹ gidigidi, mo ní, Mo dúpẹ́ lọ́wọ́ rẹ o, ìwọ èkúté, ki Ọlọ́run bò ọ́ ni àṣírí, kí Olódùmarè dà ọmọ sí fún ọ; èdè rẹ yé mi dáradará, mo gbọ́, n ó máa retí agogo náà, n ó si múra sílẹ̀ de èfúùfù, n kò sì ní í jẹ́ kí igi dé ibi ìpàkọ́ mi.
 O wa fikun ọrọ rẹ pe oun yoo nilo lati ko
Apá ìhà gúsù tí ó jẹ́ ẹgbaa meji ó lé ẹẹdẹgbẹta (4,500) igbọnwọ (mita 2,250), yóo ní ẹnu ọ̀nà mẹta.
) 1 – 029’Bersant Celina  2 – 0 45′69’2 – 1     Bernardo Silva78’2 – 2 (o.
egbe ULC ni awon ko ni faramo ẹgbẹrun mẹ́tàdínlọ́gbọ̀n ekunwo owo osu ti igbimo ipinle
Bí àwọn ẹyẹ tií da ìyẹ́ bo ìtẹ́ wọn,bẹ́ẹ̀ ni OLUWA àwọn ọmọ ogunyóo dáàbò bo Jerusalẹmu,yóo dáàbò bò ó, yóo sì gbà á sílẹ̀yóo dá a sí, yóo sì yọ ọ́ kúrò ninu ewu.
Ìjọba Saudi Arabia ti kéde òfin tuntun tó fààyè gba obìnrin láti rìnrìn ajò lọ orílẹ̀-èdè tó ba wù wọ́n láì gba ìwé àṣẹ tàbi kí wọ́n de ẹ̀rọ ayawòrán mọ́ wọn lára Ìgbésẹ̀ yìí ní àwọn ènìyàn rí bi àyípàdà túntun ti ọmọ ọba Saudi Mohammad Salman ń ṣe ni orílẹ̀-èdè náà.
Dafidi ati Samuẹli aríran, ni wọ́n fi wọ́n sí ipò pataki náà.
Ori ẹrọ ibaraẹni sọrọ alagbeka ni wọn ti n pe ara wọn lati wa gba owo, ni ibamu pẹlu wọọdu ti ẹni kọọkan wọn ti wa.
A lè fi ibàjẹ́ ohun amáyé-dẹrùn ti àwọn Òṣèlú àkọ́kọ́ pèsè fún ara ilú wọnyi wé ọbẹ̀ tó dànu,̀ ti igbẹhin rẹ já si òfò fún onilé àti àlejò.
Ẹran Jijẹ ẹran dara ni ara bakan naa lo si ni awọn abawọn.
Wayi o, ninu ilakaka wọn lati ri pe ofin naa dohun ni ọpọ orilẹede to wa nilẹ Afirika, awọn obinrin ajafẹtọ ẹni to to marundinlaadọta lati orilẹede mẹẹdogun, gbimọ pọ kọ iwe kan sawọn asaaju orilẹede lagbaye, losu Kẹta ọdun 2019.
Nitori bi nkan ṣe ri pẹlu awọn aarun miran, to fi mọ aisan otutu, o jọ pe o ni asiko to ma n waye ni iha àríwá.
Ṣugbọn mò ń lọ sí Jerusalẹmu báyìí láti fi ẹ̀bùn tí wọ́n fi ranṣẹ sí àwọn onigbagbọ tí ó wà níbẹ̀ jíṣẹ́.
Bi ọrọ ba rii bẹ,Trump o ni ribi pada sipo koda ti Pence ba yan ni igbakeji.
Ninu fidio naa o gba awọn pasitọ ọdọ ni imọran nipa nnkan mẹta to ni o wa ninu Bibeli O ni ko si nnkan to pamọ ti ko ni lu sita.
Iroyin taa gbọ ni wipe o ṣeeṣe ki oloogbe Ọgagun yii ti ko arun Covid-19 ran awọn ti wọn jọ n kopa nibi ipade naa.
Ojo kinni, oṣu kẹwaa, ọdun 1949 ni Mao-Zedong ti ọpọ mọ si Chairman Mao kede ominira orilẹ-ede China tuntun.
Mẹta lo karun coronavirus ni Kano, meji wa lati Rivers, eeyan kan lo larun naa lati Bauchi.
Àwọn ìrí mìíràn tí àtúntẹ̀ titunjùlọ yìí ní nínú ni àwọn àwòrán tí a ti ṣe àgbéyẹ̀wò tí wọ́n nṣe àfihàn àwọn ibi aláwòrán pàtàkì nínú èyítí a ti gba àwọn ìfihàn, pẹ̀lú àwọn fọ́tò tí a ti mú dára síi ti àwọn ibi onítàn ti Ìjọ, àwọn atọ́ka sọ́tũn-sósì, àwọn àkọlé ìpín, ati àwọn àkékúrú àkòrí-ọ̀rọ̀, gbogbo èyítí ó jẹ́ pípèrò láti ran àwọn ònkàwé lọ́wọ́ láti ní òye àti láti yọ̀ nínú ọ̀rọ̀ ìfiránṣẹ́ ti Olúwa bí a ṣe fi fúnni nínú Ẹ̀kọ́ ati àwọn Májẹ̀mú.
Tolori tẹlẹmu lawọn to lugbadi ipaniyan yi ti ọpọ ile alayọ si bọ sinu ibanujẹ.
Ọlọrun fẹ́ràn àwọn eniyan rẹ̀,gbogbo àwọn tí a yà sọ́tọ̀ fún un wà lọ́wọ́ rẹ̀,nítorí náà ni wọ́n ṣe ń tẹ̀lé ọ̀nà rẹ̀,tí wọ́n sì ń gba àṣẹ lọ́dọ̀ rẹ̀,
Igba akọkọ niyi ti ẹgbẹ agbabọọlu Madagascar n kopa ninu idije Afcon.
Ọjọ́ ń bọ̀ tí a óò tún fi ojú gán-ánní ara wa,
Ọga agba ajọ LASEMA,Tiamiyu ṣalaye pe ko si ẹni tii le sọ ni pato iye awọn ọmọ ileewe to fara kaaṣa ninu iṣẹlẹ naa nitori pe titi di asiko yii, ẹni to ni ileewe naa ṣi wa lẹsẹ kan aye, ẹsẹ kan ọrun nileewosan bayii, ko si si ẹni ti o lee ṣalaye ni pato iye awọn ọmọ ileewe to wa si ileewe ni ọjọru ti iṣẹlẹ buruku naa ṣẹlẹ.
Gómìnà ìpínlẹ̀ Kebbi náà bá Kayode Fayemi yọ̀ lórí àbájáde èsì ìdìbò ìpínlẹ̀ Ekiti.
Oríṣun àwòrán, @T_Bakare O fikun pe, orilẹede ti eto ẹkọ rẹ́ ti dẹnu kọlẹ, ti awọ̀n akẹkọ ati olukọ si joko sile fun ọjọ pipẹ, ko yẹ ni eyi ti eeyan ku fun.
'Ẹnikẹ́ni ò lè tì mí gbọ̀ngbọ̀n láti gbé orúkọ mínísítà jáde' EFCC ń wádìí iléeṣẹ́ Bola Tinubu,' Alpha Beta Consulting Ltd' Lizzy Anjọrin wa kede pe ile nla ti oun sẹsẹ kọ naa lo wa ni ijọba ibilẹ Eti-ọsa nipinlẹ Eko.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ondo APC: Irọ̀ ni Ayiloge ń pa mọ gómìnà Akredolu, kìí ṣe ọmọ ẹgbẹ́ wa 8 Owewe 2019 Oríṣun àwòrán, Akiti@official Àkọlé àwòrán, Ondo APC: Irọ̀ ni Ayiloge ń pa mọ gómìnà Akredolu, kìí ṣe ọmọ ẹgbẹ́ wa Awọn ohun amayedẹrun ko yatọ nipinlẹ Ondo labẹ Akeredolu - Ayiloge Ẹgbẹ́ òṣèlú All Progressives Congress (APC) níjọba ìbílẹ̀ Ifedore nípínlẹ̀ Ondo tí ni àwọn kọ olùdijé ẹgbẹ́ wọ́n, ọgbẹ́ni Banji Ayiloge.
Nígbà tí Angẹli OLUWA sọ ọ̀rọ̀ yìí fún gbogbo àwọn ọmọ Israẹli, wọ́n bẹ̀rẹ̀ sí sọkún tẹ̀dùntẹ̀dùn.
Bẹẹ naa lo ṣe jẹ pe obinrin mẹfa pere naa lo ṣe minista pẹlu aarẹ Buhari ni saa iṣejọba rẹ akọkọ ninu awọn minista mẹrindinlogoji to yan nigba naa.
Williams to pada si ni gbabọọlu ẹlẹyin lẹyin ti o bi ọmọbinrin rẹ, fi idi rẹmi nigba to n figagbaga pẹlu Briton Johanna Konta pẹlu ami ayo 6-1 6-0.
Nítorí pé OLUWA àwọn ọmọ ogun, Ọlọrun Israẹli ati Juda kò kọ̀ wọ́n sílẹ̀;ṣugbọn ilẹ̀ Kalidea kún fún ẹ̀bi ẹ̀ṣẹ̀,tí wọ́n dá sí Ẹni Mímọ́ Israẹli.
Awon omo orile-ede Zimbabwe fi edun okan won han lori iku oloogbe naa to waye ni ojo Ru Wednesday latari aisan jejere ,ti o si so egbe oselu alatako naa  si ipo ko ye mi mo leyin osu keta ti awon oloogun si gun le Aare Robert Mugabe kuro lori aleefa.
Awọn iroyin ti ẹ lee nifẹẹ si: Tunji Oluwatimilehin sọrọ nipa iriri rẹ gẹgẹ bi adẹtẹ Ope Aiyeọla: Nkan pa emi ati Baba Suwe pọ Alukoro fun ileesẹ ọlọpa nilu owerri, Andrew Enwerem, nigba to n safihan awọn tọkọtaya naa sọ wipe, awọn ri ọmọ ti wọn ta naa gba pada lọjọ kẹtadinlogun osu yi, ati wipe awọn yoo gbe ọrọ naa lọ sileẹjọ lẹyin tawọn ba ti pari gbogbo ọfintoto to niise pẹlu isẹle naa.
" O salaye pe oun ri ipo naa gẹgẹ ipe lati sisẹ sin awọn olugbe ilu Eko, to si rọ awọn ọmọ igbimọ fidihẹ to ko sodi, lati ṣatileyin fun ki wọn lee mu ayipada to ye kooro ba ẹgbẹ awakọ nilu Eko ati lorilẹede Naijiria lapapọ.
Wọn óo wá mọ̀ nígbà náà pé èmi ni OLUWA.
Obìnrin míì tún ti kú lórí ìṣẹ́ abẹ ìdí ńlá Alukoro ẹgbẹ́ nàá, Kọla Ologbondiyan, sọ pé àwọn yóò gbé ìwé ẹ̀sùn nàá lọ sí ọ̀dọ̀ àjọ INEC àti iléèṣẹ́ ọlọ́pàá.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Yaa Asantewaa: Ti ẹyin ọkunrin Ashanti kò bá tẹsiwaju, awa obinrin yóò lọ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Yaa Asantewaa: Ti ẹyin ọkunrin Ashanti kò bá tẹsiwaju, awa obinrin yóò lọ 11 Agẹmo 2018 Itan akinkanju obinrin Yaa Asantewaa, to wa ninu itan orilẹede Ghana, ẹni to léwájú àwọn obìnrin tó koju ogun Gẹẹsi to fẹ gba ilẹ Ashanti, tawọn obinrin naa si bori.
O fikun un pe ile iṣẹ awọn to wa ni Abuja ni yoo ṣiṣẹ naa fun opopona Abuja si Kaduna ati awọn agbegbe to wa ni Ariwa orilẹ-ede Naijiria.
Bi awọn boko haram, ati aji ẹran ọsin gbe ati ikọlu awọn agbẹ ati darandaran Fulani ṣe n ṣelẹ ni oke ọya.
Irú àwọn wọnyi fihàn pé a ti kọ iṣẹ́ ti Òfin sinu ọkàn wọn.
 Ọdún ń tẹ ̀ síwájú pẹ ̀ lú àìsùn Ìlagùn , asorò tàbí àìsùn Ògún tí ó máa ń wáyé ní ọjọ ́ Ògún ku ọ ̀ tunla .
Ó bá wọn dá majẹmu, ó sì mú kí wọ́n búra láti fọwọsowọpọ pẹlu òun ninu ohun tí ó fẹ́ ṣe.
Ògo tuntun yóò sọ ní ọdún 2020!
Wole Soyinka: A ti f'aaye gba ipaniyan darandaran fun igba pipẹ
Oríṣun àwòrán, Facebook/Femi Falana ''Ẹjọ ti mo pe ijọba wa ni ileẹjọ kotẹmilọrun bayii ninu eyi ti mo ti sọ pe ki ijọba ṣe eto iwosan to peye fun gbogbo eeyan nitori ori ko ju ori,'' Falana lo sọ bẹẹ.
Ó bá gbé ọwọ́ lé wọn; ó sì kúrò níbẹ̀.
Lábẹ́ ètò yìí ẹgbẹ̀rún kan ọmọ Nàìjíríà ti yóò gba ẹgbẹ̀run lọ́nà ogún Naira lósoosù fun oṣù mẹ́ta àwọn ènìyàn yìí yóò wá láti ìjọba ìbílẹ̀ kọ̀ọ̀kan ní orílẹ̀-èdè Nàìjíríà.
Assistant Commissioner of Police: Àwọn afurasí ṣá ìgbákejì kọmísọ́nà ọ̀gá ọlọ́pàá láàké dójú ikú
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ìṣẹ̀lẹ̀ Bakana: àwọn tórí kó yọ fẹ́ bẹ̀rẹ̀ ètò ìrànlọ́wọ́ Okòwò wo ni ẹ̀gbẹ̀rún mẹ́wàá tó ó ṣe?
Lójú kan náà Jesu mọ̀ ninu ara rẹ̀ pé agbára ìwòsàn jáde lára òun.
Bayi ti wọn ti ti awọn ile itaja pa ni Herat, ipenija tawọn ọmọbinrin yi ni ni wi pe wọn ko le jade lati lọ ra awọn eroja ti wọn yoo lo lati fi se fẹntilatọ wọn.
ede Naijiria ,Dr Francis Faduyile, lo so fun awon akoroyin niluu Abuja pe, bi
Lẹyin ọpọlọpọ ọdun ifẹhonuhan, ni oṣu keje, ọdun 1948, ni awọn Oloye Ẹ̀gbá atawọn agbaagba ninu iṣelu gbe ofin sita, to fẹsun kan Alake pe o n huwa aitọ, to tun n ṣi agbara Ọba lò.
Ọmọ ọdún márùn-ún wọ gàú ajínigbé ní Warri, ọlọ́pàá ri he ní Lafia Ajimọbi tún gbé iṣẹ́ àgbàṣe ₦30bn jáde lọ́jọ́bọ - Seyi Makinde Iná ṣe ọṣẹ́ ní Mile 12 l‘Eko, ọ̀pọ̀ ilé àti ìsọ̀ jóná Ikọlu naa waye nigba ti awọn aṣoju ajọ isọkan agbaye n jiroro lati dẹkun iwa janduku.
Ẹni ọdun mẹrinlelogun ni Prince, igbagbọ rẹ si ni pe orukọ rere san ju wura ati fadaka lọ.
“Pelu mi nibi ni oludari agba fun ajo to n mojuto isele pajawiri National Emegency Management Agency (NEMA), lati pese awon ohun elo iranwo ti o ye fun lilo nibi.
Yoruba Movie: Wumi Toriọla ṣàlàyé òun tó mú tírélà gbà àárín òun àti ọ̀rẹ́ rẹ̀
O fi kun oro re pe, asiko ipolongo idibo ti de tan, mo n ro awon oloselu ati awon ti oro kan gbogbo lati yera ninu awon ohun ti o le tabuku ba igbese eto idibo naa.
 Sugbon, ni bayii oro ohun ti wa lowo awon olopaa Australia.
Nígbà tí olódodo bá kígbe fún ìrànlọ́wọ́, OLUWA a máa gbọ́,a sì máa gbà wọ́n kúrò ninu gbogbo ìyọnu wọn.
Kí ẹnikẹ́ni tí ó bá fara kan ibùsùn rẹ̀ fọ aṣọ rẹ̀, kí ó sì wẹ̀, yóo jẹ́ aláìmọ́ títí di ìrọ̀lẹ́.
Ẹ̀yin baba, ẹ má ṣe rorò mọ́ àwọn ọmọ yín, kí ìrẹ̀wẹ̀sì ọkàn má baà bá wọn.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Aworan abẹwo Aarẹ Buhari si ipinlẹ Plateau 9 Ẹrẹ̀nà 2018 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 17 Ọ̀pẹ̀̀ 2018 Aarẹ Muhammadu Buhari n ṣe abẹwo ọlọjọ meji si ipinlẹ Plateau.
Bí wọ́n ṣe nkí aráàlú ni wọ́n nkí àjèjì.
Gbogbo ọmọ ẹgbẹ́ ilẹ̀ káàrọ́ọ̀-òò jíire jakéjádò àgbáyé (Assembly of All Yoruba Groups, Worldwide) ló péjọpọ̀ ní ìlú Ibadan tíí ṣe olú ìlú Ipinlẹ̀ Oyo láti yan Aṣíwáju tuntun fún ìran Yorùbá.
O kilọ wipe fifa iru iru eefin bẹ naa jẹ ohun ti o buru fun ilera eniyan.
Mo yẹ gbogbo rẹ̀ wò, bí ó ti jẹ́ pé ọwọ́ Ọlọrun ni àwọn olódodo, àwọn ọlọ́gbọ́n, ati gbogbo iṣẹ́ ọwọ́ wọn wà.
Ìlú yìí yóo bọ́ sọ́wọ́ ọba Babiloni, yóo sì dá iná sun ún, èmi OLUWA ni mo sọ bẹ́ẹ̀.
Nítorí ohun tí ara ń fẹ́ lòdì sí àwọn nǹkan ti Ẹ̀mí; bẹ́ẹ̀ sì ni ohun tí Ẹ̀mí ń fẹ́ lòdì sí àwọn nǹkan ti ara.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù NBC kilọ fun awọn ileeṣẹ igbohunsafẹfẹ lori isọrọ odi 9 Èrèlè 2018 Oríṣun àwòrán, @nbcgovng Àkọlé àwòrán, Ọdun 2019 ni idibo gbogboogbo yoo waye ni Naijiria Ajọ ti o n risi iṣakoso igbohunsafẹfẹ lorilẹede Naijiria, (NBC) ti ka awọn ofin ati aigbọdọmaṣe to wa fun awọn ile iṣẹ igbohunsafẹfẹ lori ipolongo awọn ẹgbẹ oselu ati isọrọ odi lori afẹfẹ.
Mose pe gbogbo àwọn ọmọ Israẹli jọ, ó wí fún wọn pé, “Àwọn nǹkan tí OLUWA pa láṣẹ pé kí ẹ máa ṣe nìwọ̀nyí: 
Shoprite ni ileeṣẹ awọn ọmọ orilẹ-ede South Africa kẹta ti 'yoo fi Naijiria silẹ.
Báyìí ní ìwé mi náà ṣe lọ:
Oríṣun àwòrán, @followlasema Ọjọ Kẹtadinlọgbọn Osu Kẹrin, Iṣẹlẹ ibugbamu ile epo NNPC Adugbo Yaya Abatan ni Ogba nilu Eko ti oun naa wa labẹ ijọba ibilẹ Ifako Ijaiye ni ibugbamu taa n sọ yi ti waye.
Bẹẹ si ni igbe ẹkun ti sọ kikan kikan ni ile Ajimobi to n bẹ ni agbegbe 6th Avenue, Yemoja street, Oluyole Estate nilu Ibadan.
O si jẹ orukọ kan to lọ fun ọpọ ọdun.
Eyín ọkùnrin náà kò jọ ti ènìyàn rárá, o tẹ̀ kọ̀ọ̀lọ̀ kọ̀ọ̀lọ̀ o sì ba ni lẹ́rù bí ó bá ti ń sọ̀rọ̀ jáde lẹ́nu, eyín náà pàápàá pupa o sì ba ni lẹ́rù.
Nibayi ti Atiku ti de lati Amẹrika, yoo joko bayi lati koju isejọba, ki ni lilọ Amẹrika nii se pẹlu atiku."
ti yoo se ri lawujọ, naa ni ki a ri pe a ni.
Igbimọ awọn Ulamas naa ni awọn yoo ṣe abẹwo si ile igbimọ Aṣofin ipinlẹ naa lati ba awọn aṣofin jiroro lori ọna abayọ si ofin tuntun naa, ni ọna ti yoo tẹlẹ ẹsin Islam.
àwọn ọgọrin eniyan kan wá láti Ṣekemu, Ṣilo ati láti Samaria pẹlu irùngbọ̀n wọn ní fífá, wọ́n fa agbádá wọn ya, wọ́n sì ṣá ara wọn lọ́gbẹ́.
Ó fún Jeroboamu ni mẹ́wàá ninu rẹ̀, ó ní, “Gba mẹ́wàá yìí sọ́wọ́, nítorí OLUWA Ọlọrun Israẹli ní kí n wí fún ọ pé, òun óo gba ìjọba kúrò lọ́wọ́ Solomoni òun óo sì fi ẹ̀yà mẹ́wàá fún ọ.
A Kú Àmójúbà Oṣù Ramadana O!
Ẹ̀yin tí ń gbé Sioni,ẹ hó, ẹ kọrin ayọ̀, ẹ̀yin olùgbé Sioni,nítorí Ẹni ńlá ni Ẹni Mímọ́ Israẹlití ó wà láàrin yín.
' O darukọ Ọmọwe Ishola Oyenusi, Babatunde Folorunsho, Baba Koshewọn to jẹ pe ọwọ ọlọpaa ko ki n tẹ ẹ.
Awon omo egbe tuntun ohun ni: Ogbeni Jude Anyadibe (Alaga), Ojielo Pascal (igbakeji Alaga), Ebubeagu Felix Okafor (Akowe), Mabel Owoh (Adari awon obinrin) ati Sylvester Onyia (Akapo).
Oríṣun àwòrán, Twitter/NCDC Lapaapọ, eeyan mọkanla laarun covid-19 pa lọjọ Satide kaakiri Naijiria gẹgẹ bi akọsilẹ.
Ẹ wo ọpọ eré ìdárayá nílẹ̀ Yorùbá tó ti ń di ohun ìgbàgbé Coronavirus tún ti ṣe ọṣẹ́ lórí iṣẹ́ líla ojú ọ̀nà relùwe láti Eko sí Ibadan - Ìjọba àpapọ̀ A n ṣé àyẹwò ẹni tá fúnra sí pé o ní Coronavirus l'Eko-Kọmísánà ìlera Wakati kan ni ijọba fún wa lati kúro ni ibi ti a ngbé O ṣalaye pe ọkan ninu awọn meji to ku wọle lati England nigba ti ẹni kẹta wọn de lati China nibi ti arun Coronavirus yii pọ si.
Olùbùkún ni ẹni tí ń bọ̀ ní orúkọ Oluwa ati ọba Israẹli.
“A bẹrẹ eto idibo naa ni
Bi o tilẹ jẹ pe awọn alasẹ ko ti se akojọpọ iye eeyan to faye silẹ, sibẹ awọn akojọps awọn isẹlẹ to waye lawọn ipinlẹ kọọkan fihan pe, nnkan ko fara rọ.
" Sẹ́ láyà lètò, ètò ni sẹ́ láyà.
Wọ́n fi aṣọ aláwọ̀ aró, ati ti elése àlùkò, ati aṣọ pupa, ati aṣọ funfun onílà tẹ́ẹ́rẹ́tẹ́ẹ́rẹ́ ṣe aṣọ títa fún ẹnu ọ̀nà, wọ́n sì ṣe iṣẹ́ ọnà aláràbarà sí i lára.
90 ninu kokoo maaki 4 eyi to ga ju ni arabinrin Akintola gbe jade nile ẹkọ naa.
O le ṣe àmúlò Google láti fi wò ó bóyá ìṣẹ̀lẹ̀ nàá kò tilẹ̀ wáyé.
Ǹjẹ́ ipa wọn mú ìlọsíwájú wá fún ìran Yorùbá?
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, The swearing-in"" ceremony follows two disputed elections Ti a ko ba gbagbe, wọn se ibura fun aarẹ Uhuru Kenyeta fun saa keji, losu kọkanla ọdun ti o kọja."
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Akukọ ti wọn so abẹ mọ lẹsẹ tawọn eeyan fi n ja Ọga ọlọpaa lagbegbe ti iṣẹlẹ yi ti waye,Arnel Apud sọ fun ileeṣẹ iroyin AFP pe iṣẹlẹ naa fọwọkanilẹmi to si ni ''o kọja ohun ti eeyan le ṣalaye'' ''O jẹ iyalẹnu fun mi nigba ti wọn kọkọ fi to mi leti.
Oríṣun àwòrán, @others Àkọlé àwòrán, Oriṣirisi ounjẹ aladun naa ni wọn maa n se ti onikaluku fi maa n gbadun isinmi naa.
Hosa, láti inú ìran Merari bí ọmọkunrin mẹrin: Ṣimiri (ni baba rẹ̀ fi ṣe olórí, bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé kì í ṣe òun ni àkọ́bí); 
Ẹni ọdún mejilelọgbọn ni nígbà tí ó gorí oyè, ó sì wà lórí oyè ní Jerusalẹmu fún ọdún mẹjọ.
O ni o ma a n ṣẹlẹ, paapa ti wọn ba fẹ ẹ sọ agbara iru ọba bẹ ẹ di yẹpẹrẹ, nitori pe o kọ lati ṣe awọn nkan to yẹ ko ṣe, boya ìrúbọ tabi nkan míì, tabi to ba n ṣe aigbọran.
Ọba Akiolu wipe, igba ati akoko Aarẹ Buhari dara ju ti igba Aarẹ tẹlẹri, Olusẹgun Ọbasanjọ lọ, to si fikun wipe, Aarẹ tẹlẹri, Goodluck Jonathan ko ba se daradara ti ko ba si awọn asebajẹ ti wọn jọ kọwọrin.
" Oríṣun àwòrán, AFP/Getty Images Àkọlé àwòrán, Awọn araalu nke si aarẹ orilẹede Ghana lati tete gbe igbesẹ lori ọrọ ẹkunwo epo.
Ibukun ni fun yín bí ẹ bá tẹ̀lé òfin OLUWA Ọlọrun yín, tí mo fun yín lónìí yìí.
O kọwe si Oba rẹ pe oun kẹfin pe awọnMaya ti wọn n mu koko a maa ni okun ati agbara ti kii fi rẹ wọn pupọ.
Ìròyìn ayọ ló jẹ́ nígbà ti Lizzy Anjonrin kéde pé òun ti di ìyàwó lọ́ọ̀dẹ̀ ọkọ.
Kabiyesi Ataọja no oun ko ta oriṣa Ọṣun ṣẹngẹṣẹ, lile ti igbimọ Atasja le Alagba Ọlayiwla Adigun kuro nipo Baba Ọṣun lo mu ki o gbarata sọ ọrọ odi naa jade.
Lọwọlọwọ, pipa ti wọn pa ọgagun kan lorilẹede Iran, Ọgagun Qasem Soleimani ti olu ileeṣẹ ologun America, Pentagon, sọ pe AArẹ Trump lo paṣẹ fun awọn lati pa, ni iroyin to gbaju-gbaja ju l'agbaye.
Bi awọn ipinlẹ naa ṣe lọ ree: Eko-308 FCT-207 Kaduna-179 Plateau-46 Niger-43 Adamawa-26 Sokoto-18 Rivers-16 Yobe-15 Enugu-13 Kano-13 Ogun-12 Delta-10 Edo-5 Osun-3 Oyo-3 Anambra-2 Ekiti-1 Èèyàn 806 míràn tún lùgbàdì àrùn Covid-19 ní Naijiria Oríṣun àwòrán, @NCDCgov Eeyan ẹgbẹrin lẹ mẹfa lo tun ṣẹṣẹ lugbadi aarun Covid-19 ni Naijiria.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Sunday Igboho: Kò bójúmu bí wọn ṣe ní ká wá fi orúkọ́ sílẹ̀ bíi ọmọ ẹgbẹ́ Àmọ̀tekún lórí ayélujára Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Sunday Igboho: Kò bójúmu bí wọn ṣe ní ká wá fi orúkọ́ sílẹ̀ bíi ọmọ ẹgbẹ́ Àmọ̀tekún lórí ayélujára 19 Ògún 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 20 Ògún 2020 Ilumọọka awujọ kan to tun jẹ ajafẹtọlu, Oloye Sunday Adeyemọ, ti ọpọ eeyan mọ si Sunday Igboho ti gbarata lori ilana agbekalẹ ẹgbẹ Amotekun.
Ṣugbọn, mo tọrọ aforiji pe mi o ni le fun l'ọyan nitori wipe omi ọyan mi ti gbẹ lẹyin oṣu maarun.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ọjọ́ Àbámẹ́ta la ó mọ ẹni tí yóò lékè láàrín bàbá ìsàlẹ̀ àti àwọn mẹ̀kúnnù nipinlẹ̀ Ọyọ.
Aláfojúdi ati olóríkunkun ẹ̀dá ni wọ́n.
Ẹ ní ẹ̀rí ọkàn tí ó mọ́, tí ó fi jẹ́ pé nígbà tí wọ́n bá ń sọ ọ̀rọ̀ yín ní àìdára, ojú yóo ti àwọn tí wọn ń sọ̀rọ̀ àbùkù nípa yín, nígbà tí wọn bá rí ìgbé-ayé yín gẹ́gẹ́ bí onigbagbọ.
Ọjọ kẹrindinlogun ni idibo Aarẹ ati ti awọn asoju ile aṣofin yoo waye jakejado orileede Naijiria.
Àwọn tí wọ́n kù jẹ́ ẹgbaarun (10,000).
Mọ sii nipa awọn sitaili to wa nita ninu ẹkọ yii.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ọjọ́ Ìsẹ́gun di ọjọ́ ìbànújẹ́ fún ọ̀pọ̀ ìdílé ní Nàíjíríà torí òkú tó ṣùn Ọ̀dọ́ 30 ń gba ìtọ́jú lọ́wọ́ nílé ìwòsàn torí ọ̀gbẹ́ ìbọn ní Lekki - Sanwo-Olu ṣàlàyé Àwọn ṣọ́jà ṣíná ìbọn bolẹ̀ ni Lekki Tollgate Àwọn ọlọ́dẹ darapọ̀ mọ́ ìwọ́de #EndSARS l'Osogbo, wọ́n ní kò sáyè fún jàǹdùkú mọ́ Kíní ìtumọ̀ ''Sọ̀rọ̀ Sókè'' tí àwọn afẹ̀họ́núhàn EndSars ń lò káàkiri Ìpínlẹ̀ Ogun náà ti ilé ìwé títí dí ọjọ́ Ajé tó m bọ̀, kò ní sí lílọ bíbọ̀ ọ̀kádà fún wákàtí 24 Buhari, jáde bá ọmọ Nàíjíríà sọ̀rọ̀, orí àgbá ẹ̀tù la dúró lé - NUJ pariwo O ni ipaniyan to n waye yii pakasọ, to si ṣe eemọ pe gbogbo nnkan yii n waye nitori awon eeyan fẹ gbe ni alaafia?"
3 Bélú 2020 Fídíò, Soyinka Cancer: Àṣe ara mi ni iso ti n run gbogbo bí mo ṣe n ṣèrànwọ́ lórí jẹjẹrẹ27 Bélú 2019 Yoruba Movie Actors On Set vs Off Stage: Bí àwọn òṣèré fíìmù ṣe rí láì mura gegege1 Bélú 2020 Fídíò, End bad government: Wọn rò pé a maa jà tàbí ba ǹkan jẹ́ ni ṣùgban ọmọlúwàbí ni wa-Afẹ̀hónúhàn17 Ọ̀wàrà 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
jegbadun ina mọna-mọna deede , ni eyi ti orile ede Naijiria naa yoo tun maa ta
Koda, awọn miran n gba a ni imọran lati rọra na owo naa, ko ba ma na owo ori to yẹ ki o san pọ mọ.
Oríṣun àwòrán, Facebook/Asiwaju Bola Tinubu ''Igbimọ fidihẹ to ajọ NEC ṣe agbekalẹ rẹ ko si ninu ofin ẹgbẹ oṣelu APC, ṣugbọn ọmọ ojulowo ọmọ ẹgbẹ ni mi, n ko ni fẹ tako ẹgbẹ,'' Balogun lo sọ bẹẹ.
 ( biobaku 1955 : 88 ) .
"Buhari sọ pe ""A ni awọn ilana eto ilera ti a n tẹlẹ lorilẹede yii, nitori naa, a ko ni sọ agbo naa di lilo fun awọn ọmọ Naijiria ayafi ti awọn oṣiṣẹ eto ilera wa ba ṣayẹwo rẹ, ti wọn si fọwọsi pe o dara ni ."
Arúgbó atọrọjẹ òyìnbó bọ̀ ó pòwe
Ẹ ṣe àyẹ̀wò àpẹrẹ oríkì ti ìyá Olùkọ̀wé yi sọ fún ni ibi ayẹyẹ ọjọ́ ìbí rẹ̀ ni ojú ìwé yi.
Lásìkò ti Trump ń ba àwọn oníroyin sọ̀rọ̀ pẹ̀lú Kim lẹ́ẹ̀gbẹ́ rẹ̀, o ní Malegbagbé ni ìpàdé àwọn inú òun si dùn láti dá ilà ààrin North Korea àti South Korea koja> Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, John Ogu bá BBC Yorúbá sọ̀rọ̀ lórí ìgbáradì Nigeria vs Madagascar Ní ti Kim niti rẹ ó ni ipade pọ àwọn jẹ́ ohun àmi fún ńkan ti o tayọ.
Bi a ba ri erin, ki a gbà pẹ a ri erin.
Nítorí ẹ̀ ń fi ààyè gba àwọn ẹlòmíràn tí wọn ń wá waasu Jesu yàtọ̀ sí bí a ti waasu rẹ̀, ẹ sì ń gba ìyìn rere mìíràn yàtọ̀ sí èyí tí ẹ ti kọ́ gbà.
Bí mo ti ń ṣe ẹja wọn-ọnnì, ǹjẹ́ kí n ro obẹ lórí iná, kábíyèsí, ṣe ni ògiri ilé tí mo ti ń wá oúnjẹ là sí méjì tí mo rí ọmọbìnrin kan pẹ́lú idpa lọ́wọ́ tí ó da ẹja mi nù lórí iná.
Mahmood Yakubu,soro yii lasiko ti o n ba awon ti oro kan soro, awon egbe oloselu
Atẹjade ileesẹ ọlọpaa naa ni, ni kete ti iroyin naa kan ọga ọlọpaa to wa ni agọ ọlọpaa Agodi lara lo morile ibi isẹlẹ naa amọ ko to de ibẹ, ẹpa ko boro mọ.
Ó wá ṣe, ni àwọn ara ilé Wọ̀bìáparapọ̀ wí fún àwọn ọ̀rẹ́ wọn tí àwọn ìyàwó wọn kò bímọ yìí pé kí wọ́n jẹ́ kí àwọn ìyàwó wọn wọ̀n-ọnnì wá gbé ilé àwọn ni odidi ọdún kan kí àwọn bá wọn wá egbòogi tí ó dájú fún àìbímọ wọn wọ̀nyí, nítorí, ṣe kí a sọ òótọ́ kọ?
Ọ̀rọ̀ coronavirus to je ajakale arun yii ni awọn oirlẹ-ede kan ti n bọ lọ́wọ́ re ti awọn mii si n ba jagun bayii Oríṣun àwòrán, others Link Báwó ni òògùn dexamethasone ṣe ń ṣiṣẹ́ lára Òògùn ìtura dé fún Coronavirus!
Bi ọdún bá sún mọ́ etílé, oúnjẹ àti ohun èlò gbogbo maa nwọn nitori àwọn ọlọ́jà yio ti fi owó kún ọjà nitori èrò ti ó fẹ́ ra ọjà maa n pọ̀ si ni àsikò yi.
Iroyin naa ni ẹsẹ kan aye, ẹsẹ kan ọrun ni Eniola wa, ti wọn si du ẹmi rẹ lọwọ nile iwosan.
O ni ilẹ naa ko ni irinṣẹ ayẹwo to to lati ṣayẹwo Coronavirus, nitori naa, ki ile iwe ṣi wa ni titi pa lọwọ yii.
Ebi a pa á, àárẹ̀ a sì mú un; kò ní mu omi, a sì máa rẹ̀ ẹ́.
O maa n la o si maa n sipẹpẹ ni gbogbo igba.
Ọmọ atàpátadìde ni mí, télọ̀ ni bàbá mi- Abiola Ajimobi Seyi Makinde, bàtà tí Ajimobi bọ́ sílẹ̀ ni ko tẹsẹ̀ bọ̀ fún àṣeyọrí Ọyọ - APC Arisekola ló fún mi ní ilẹ̀ tí ìjọba Ọyọ gbẹ́sẹ̀ lé, ń kò ní gbà - Ajimobi Ayefele fi orin ẹ ṣeun sẹ́nu kí Ajimobi Seyi Makinde, yé é sọ̀rọ̀ mi láìdà - Gomina Ajimobi Bakan naa ni Fatima tun dupẹ lọwọ awọn eeyan to n pe lati beere nipa Baba wọn Ajimọbi, o pari ọrọ rẹ pe ko si ẹni ti ko ni ku lọjọ kan ṣugbọn ẹbi Ajimobi n dupe pe o ṣi wa laaye.
Ileeṣẹ ikanni ayelujara, google ti gbe awọn ibudo lilo ayelujara lọfẹ wa si agbegbe marun nipinlẹ Eko.
Àwọn ẹni-tórí-kó-yọ àti ajàfẹ́tọ̀ọ́-ènìyàn rò wípé àwọn ènìyàn gbogbo kò ti ìfòpin sí ìṣọdẹ-àjẹ́ lẹ́yìn.
29 Àti pé àwọn ni àwọn náà tí a ti yàn láti ọwọ́ mi láti rìbọmi ní orúkọ mi, gẹ́gẹ́bí èyítí a ti kọ;
Awọn ounjẹ ile Yoruba ni koko ti a n gbe yẹwo lonii lori eto akomolede ati Asa lori BC Yoruba.
com Ilẹ apati yii ni wọn lo ti wa di ẹrujẹjẹ to lee pagidina abo awọn olugbe agbegbe naa ti wọn n ni awọn iwa ọdaran bii ifipabanilopọ, idigunjale ati ile fifọ lo n waye lati ibẹ wa.
Ilé ẹjọ́ ní kí wọ́n lọ yẹgi f'ọmọ Ọba ìlú Eko tẹ́lẹ̀ Olórin obìnrin tí kìí ṣi ìhòhò rẹ silẹ̀- Olólúfẹ Teni Aàrẹ Trump kọ̀ láti jẹ Tòlótòló ìsìn ìdúpẹ́ 2019 nílé, ó gba Afghanista lọ!
Nigba to wa ni fasiti, o ṣiṣẹ gẹgẹ bi amugbalẹgbẹ fun Ọga Agba ileeọẹ kan nilu Eko.
Àwọn ni a ti rà pada láti inú ayé, wọ́n dàbí èso àkọ́so fún Ọlọrun ati fún Ọ̀dọ́ Aguntan.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Oronpoto Animation: Akin Alabi ní kò dára bí eré aláwòrán fáwọn ọmọdé ṣe jẹ́ aláwọ̀ funfun Bakan naa lo fi kun pe Fasanmi jẹ ọkan gboogi lara awọn to tẹlẹ Baba Obafemi Awolowo nigba aye rẹ ni, to si ja fun idagbasoke ilẹ Yoruba 'Wọn gbaruku ti Awolowo, to fi mọ igba ti o wa ni atimọle' Akẹ́kọ̀ọ́ Babcock tí wọn bá lòpọ̀ nínú fídíò rí ẹ̀kọ́ ọ̀fẹ́ ní fásitì òkè òkun Wo ìyàtọ̀ tó wà láàrin Bíbélì Yorùbá tí Kumuyi kọ sí èyí tó wà ńlẹ̀ Ìkúnlẹ̀ abiyamọ, ìkókó mẹ́jọ kú nílé ìwòsàn lálẹ́ ọjọ́ kàn Dayo Amusa gbarata lórí bí agbófinró ṣe ń pa ọ̀dọ́ láì nídìí Wọn tun jẹ Sẹnetọ ni ipinlẹ Ondo ninu ẹgbẹ oṣelu UPN ni saa ijọba alagba ti ekeji ni Naijiria (2nd Republic), ti wọn si ko ipa ribiribi ninu ẹgbẹ naa.
"Ẹ kò nílò nọ́mbà ìdánimọ̀ NIN fún ìdánwò àṣewọlé ọdún 2020 - JAMB African Parents: Òbí ayé àtijọ́ ló tọ́ ọ dàgbà tí o bá ṣe àwọn ǹkan wọ̀nyii Ilé iṣẹ́ ọmọogun kò sọ fún mi pé ọkọ mi kú fún ọdún kan- Iyawo soja Iran ní àwọn kò mọ̀ọ́mọ̀ ju irínṣẹ́ ìbúgbàmù ""missile"" lu bàálù Ukrain tó já Amotekun kò ní gbé ìbọn o!"
Iwadii ti a ṣe fi yewa pe, Joseph yi ti jẹ anfani owo jibiti, ti oye rẹ to ọgọta milliọnu naira, ti wón fi ranṣẹ lati ori ẹrọ ifoworanṣẹ Western Union.
Awọn obinrin Canada mejeeji ti wa ni alaafia ni Accra laifarapa rara.
É e ṣojú un ríro, ìṣẹ̀dálẹ̀ rin ni
Wọ́n dáhùn, wọ́n ní, “Rárá o, a óo bá ọ pada lọ sọ́dọ̀ àwọn eniyan rẹ.
Yóo fi àwọn olódodo sí ọwọ́ ọ̀tún, yóo fi àwọn ìyókù sí ọwọ́ òsì.
Oríṣun àwòrán, @AkinwunmiAmbode Ambọde ni, n ṣe lawọn aṣofin ipinlẹ Eko mọọmọ n yi iwe ati akọsilẹ lori rira okoolelẹgbẹrin ọkọ bọọsi bọgini akero naa, gẹgẹ bi o ṣe wa ninu iwe ofin iṣuna ipinlẹ Eko ti ọdun 2018 eleyi tawọn aṣofin ile naa fọwọ si funrawọn.
Ègbé ni fún àwọn tí wọ́n wà ninu ìdẹ̀ra ní Sioni, ati àwọn tí wọn ń gbé orí òkè Samaria láìléwu, àwọn eniyan ńláńlá ní Israẹli, tí ó jẹ́ àkọ́kọ́ láàrin àwọn orílẹ̀-èdè, àwọn tí àwọn eniyan gbójúlé.
Iye awọn to ti lugbadi arun naa nipinlẹ Oyo lọwọ yii jẹ mọkandinlogoji, ti mejidinlọgbọn ninu wọn si n gba itọju lọwọ.
Idi ree ti aarẹ tẹlẹ ni Naijiria, Olusegun Obasanjo fi n figbe bọnu pe Naijiria ma ti n kuna lọ laye isejọba Buhari, eyi to yẹ ka tete doola rẹ.
“A fẹ ki ijọba ro awọn obinrin wa ni agbara ki wọn le maa ṣiṣẹ fun idagbasoke ilu, bo ti lẹ ṣe pe ijọba n ṣiṣe idagbasoke ilu kaakiri, o yẹ ki wọn ṣe eyi ti atijẹ atimu yoo fi rọrun, paapaa fun awọn obinrin wa”.
” Nítorí pé, wọn kò mọ ohun tíí ṣe.
Ṣáájú ni ọjọ Ẹtì kàn náà ni Ààrẹ àná orílè-èdè Nàìjíríà, Olusegun Obasanjo, ti figbe ta pé ìjọba Buhari n pète láti ka ẹsùn sí òun lọrùn.
Bí ó ti ń rìn kiri lójú pópó,bẹ́ẹ̀ ni yóo máa lọ, tí yóo máa bọ̀ láàrin ọjà,yóo máa dọdẹ kiri ní gbogbo kọ̀rọ̀.
Nígbà tí Nahori di ẹni ọdún mọkandinlọgbọn ni ó bí Tẹra.
Mose bá bá OLUWA sọ̀rọ̀ nípa wọn, 
Apata ni awọn ọlọpaa kogberegbe naa kii bọwọ fun ofin ibọwọ fun aabo awọn ara ilu.
o wa lati ekun aarin gbungbun ipinle Delta , o wa si ile igbimo asofin agba ni  ọjọ kéjídínlọ́gbọ̀n, osu kẹ́ta, odun 2015.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù 9th Assembly: Femi Gbajabiamila ni ẹgbẹ́ APC fọwọ́sí sùgbọ́n.
Fasiti orilẹ-ede Naijiria, Nsukka naa ti kesi awọn akẹkọọ ti o mu ileewe wọn gẹgẹ bi ileewe giga akọkọ ti wọn fẹran lati lọ, ti wọn si gba maaki to to 180 tabi ju bẹẹ lọ ni asiko idanwo JAMB ni anfaani lati lo ṣe iforukọsilẹ fun idanwo Post UTME.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Oyin lé àwọn ènìyàn kúrò l'ábúlé kan ní Plateau 13 Sẹ́rẹ́ 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Oyin ti le awọn ara abule Gunsun, to wa ni ijọ̀ba ibilẹ Kanam nipinlẹ Plateau kuro niluu.
Ìwọ ni ibi ìpamọ́ mi ati asà mi,mo ní ìrètí ninu ọ̀rọ̀ rẹ.
Igbesẹ tuntun yii ti mu ki iye awọn to n ba gomina Akeredolu figa-gbaga ninu idibo abẹle naa, ṣugbọn ti wọn jawọ di mẹrin.
Ojú tí Rebeka náà gbé sókè, ó rí Isaaki, ó sọ̀kalẹ̀ lórí ràkúnmí.
Seyi Makinde kò leè gba adé lórí àwa ọba 21, iléẹjọ́ ni yóò là wá níjà - Lekan Balogun Goodluck Jonathan jẹ́ olùfọkànsìn àti ìwúrí fún ìrandíran ní Nàìjíríà - Buhari Ìtọ́jú ara di ìrọ̀rùn!
Láti aṣálẹ̀ Sinai wọ́n lọ sí Kiburotu Hataafa.
Ṣugbọn o sọ pe awọn gomina lorilẹede Naijiria ko ti ni iriri lati dari ọlọpaa ipinlẹ.
Labẹ asia ẹgbẹ oṣelu PDP, Goodluck Jonathan figagbaga pẹlu igbakeji aarẹ tẹlẹ ri, Atiku Abubakar t'oun naa n du ipo aarẹ.
Nígbà tí ìròyìn kàn mí pé àwọn kan láàrin àwọn Juu ti dìtẹ̀ sí ọkunrin yìí, mo bá fi í ranṣẹ si yín.
Ní àkókò náà Jesu láyọ̀ ninu Ẹ̀mí Mímọ́.
Will: Àwọn olùgbé Eko ni ẹni tó ní owó, ló ń ṣe àkọsílẹ̀ ìlànà ogún pínpín
Orilẹede Libya jẹ oriẹede ti awọn atipo ma n gba kọja lati de ilu afojusun wọn ni ilẹ Yuroopu.
Ohun tí a mọ̀ nìyí nípa àwọn tí yóò láǹfàní àti lọ sí Hajj lọ́dún yìí Àwọn agbénipa tún ti pa ọmọ ọdún márùn ún kan ní Ibadan Ọwọ́ ọlọ́pàá tún tẹ afurasí tó fipá bá odi àti adití lòpọ̀ nílùú Ibadan Wákàtí márùn ún márùn ún ní wọ́n ń fipá bá obìnrin kàn lò pọ̀ ní Nàìjíríà- Ọga Ọlọpaa O ní àwọn ti kan sí àwọn lọ́balọ́ba, àwọn ọ̀dọ́ àdúgbò, àwọn ọlọ́dẹ, àti àwọn àjọ elétò ààbò míràn láti maa fi ìṣẹlẹ to bá n wáye láyìká wọ́n tó ọlọ́pàá létí .
" Ṣe wahala wá ti ọkọ bá kọ̀ láti fún aya tó ti kọ̀ silẹ lára ogún rẹ?
Source: Johns Hopkins University, national public health agencies and UN population data Figures last updated: 15 January 2021, 17:44 GMT Àjọ WHO sọ pé, ìdí èyí kò ju nítori pé, ọ̀pọ àwọn ènìyàn ilẹ Aduláwọ Afrika kò fi bẹ́ẹ̀ ni àrúgbó púpọ̀.
Oríṣun àwòrán, dorathy bachor Ta ni Dorathy Bachor?
Wiwọ ibomu(face mask) ti di ọranyan bayii ni ita gbangba, ko si gbọdọ si ipejọpọ ọlọpọ ero nibikibi.
Ladugbo Aba Tuntun, Ijebu Igbo ni ijọba ibilẹ Ijebu North ni ipinlẹ Ogun niṣẹlẹ yi ti waye.
Bakan naa ni Gomina Abubakar Bagudu kede pe ijọba òun ti gbakoso itọju ọmọ naa, eto ilera ati ẹ̀kọ́ rẹ.
 Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'A rí wàhálà táwọn èèyàn ń kojú nilẹ̀ẹ̀ Yorùbá la ṣe fi ""Amotekun"" fi ọkàn wọn balẹ̀' Sunday Igboho wa kesi awọn ọmọ ẹgbẹ OPC, Fijilante atawọn eeyan miran to ni nkan se ninu ipese eto aabo labẹ Amotekun lati fi ọpọlọ se e, ki wọn si ri daju pe wọn ko tẹ ẹtọ awọn araalu mọlẹ."
" Oríṣun àwòrán, @ScooperNG Irọ́ ni o, kò sí ẹ̀rí pé Hydroxychloroquine leè kojú àrùn Coronavirus- Ẹgbẹ́ àwọn adarí ilé ìwòsàn ní Naijiria Òtítọ́ lékè!
O ni ijoba ti pinnu lati fi igba eeka saare ile sile fun ogbin koko igbalode ni Ijugbere nijoba ibile Owo.
Nítorí náà, mo rí i pé ó di dandan pé kí n bẹ àwọn arakunrin láti ṣiwaju mi wá sọ́dọ̀ yín, kí wọ́n ṣe ètò sílẹ̀ nípa ẹ̀bùn tí ẹ ti ṣe ìlérí, kí ó jẹ́ pé yóo ti wà nílẹ̀ kí n tó dé.
“Bi ẹ bá fetí sí òfin wọnyi, tí ẹ sì pa wọ́n mọ́, OLUWA Ọlọrun yín yóo mú majẹmu tí ó bá àwọn baba yín dá ṣẹ lórí yín, yóo sì fi ìfẹ́ ńlá rẹ̀ hàn yín gẹ́gẹ́ bí ó ti ṣèlérí fún wọn.
Ìbejì ọmọ ọdún méjì Mínísítà fún ọ̀rọ̀ omi bá odò lọ Leah Sharibu pé ọmọ ọdún 16 ní àhámọ́ Boko Haram Àgbedọ̀!
Wẹrẹ ti eniyan ba ti kọja ala iye eniyan to le ni wọn yoo gbegile oju ọpọ rẹ.
Ẹgbẹ́ òṣìṣẹ́ NLC, PDP, MAN fọnmú lórí epo bẹntiró tó dí N162 Ijọba apapọ n kede afikun owo epo bẹntiro lẹyin ọjọ kan ti wọn kede ẹkunwo owo ina mọnamọna jakejado orilẹede Naijiria.
Awọn igba ti Olisa Metuh ti foju ba ile ẹjọ ri Yọju sile ẹjọ tabi ko lọ sewọn Metuh yọju sileẹjọ lori ibusun alaisan Metuh dákú ní ilé ẹjọ́ Oríṣun àwòrán, @FocusOgun Wọn fi ẹsun kan agbẹnusọ ẹgbẹ oṣelu PDP tẹlẹri yii lórí iye owo to to irinwo miliọnu naira (N400,000,000).
''A ni lati sọ ododo fun ara wa.
56 dola, ni eyi to je pe o tun gbe peli ju iye ti won ti n ta agba epo robi won lati osu kejila odun 2014  lo.
Ọkàn Daniẹli, tí wọn ń pè ní Beteṣasari, pòrúúruù fún ìgbà díẹ̀, ẹ̀rù sì bà á.
Èrè wo ló wà ninu pé kí n wọ inú kòtò?
 bí a bá sì ń sọ nípa ọ ̀ rọ ̀ àgbẹ ̀ , kìí ṣe iṣẹ ́ oko nìkan là ń sọ .
Ìfẹ́ ọkàn olódodo a máa yọrí sí rere,ṣugbọn ìrètí eniyan burúkú a máa já sí ibinu.
Ọlọrun sì mú kí gbogbo ìwà ibi àwọn ará Ṣekemu pada sórí wọn.
Òun ni ó ń mú ìparun wá sórí àwọn alágbára,kí ìparun lè bá ibi ààbò wọn.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Fashola EndSARS Protest: Fashola rí kámẹ́rà he ní ibùdó ìṣẹ̀lẹ̀ Lekki Tollgate, àwọn ọmọ Nàìjíríà bá figbe ta 20 Ọ̀wàrà 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 26 Ọ̀wàrà 2020 Oríṣun àwòrán, @alrhemist Ni ọjọ Aiku ni awọn minisita atawọn gomina kan ṣabẹwo si ilu Eko lati wo bi ọrọ ṣe lọ lasiko iwọde to di gbodonroṣọ nibẹ.
O ni bi epo naa ṣe yi danu sinu awọn koto ati loju titi ni awọn eeyan lọ n gbọn ọn ko to lana to si di akoba fun awọn ọkọ miran lori titi naa.
Ọpọ lo san ọpọlọpọ miliọnu Naira lati fi ri ẹbi wọn gba pada ṣugbọn to tun ja si pabo.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Mayowa Omoniyi: Kò sí orin Obey, Sunny Ade abí tàkasúfèé tí ń kò le ta gìtá sí O fikun wi pe yiyọ ti ijọba yọ owo iranwọ epo naa, yoo mu ibugbooro ba ọrọ aje ni Naijiria.
9 Kí làwọn nǹkan tó lè rán ọkùnrin sí ọ̀run alákeji lásìkò ìbálòpọ̀ pẹ̀lú obìnrin?
Pa Olabode Olajide: Pé Osinbajo wá kí mi ló mú inú mi dùn jù nílé ayé mi
Àwọn tí ẹ bèèrè fún, tí ẹ ní, ‘Ẹ fún wa ní ọba ati àwọn ìjòyè.
OLUWA yóo da oówo burúkú bò yín lẹ́sẹ̀ ati lórúnkún, yóo burú tóbẹ́ẹ̀ tí ẹnikẹ́ni kò ní lè wò yín sàn.
Manchester United ni ti wọn jawe olubori ninu mẹfa ninu ifẹsẹwọnsẹ meje ninu idije EFL ti wọn gba pẹlu awọn ẹgbẹ agbabọọlu to n kopa ninu idije Premier League.
Ni òtitọ́, ará ilú nké pé kò si owó àti ọ̀wọ́n ọjà, nitori eyi ayé àjẹ jù le ma si, ṣùgbọ́n bi ẹlòmíràn kò ni owó, á gba àwin ọti pé àwọn fẹ́ fi pa irònú rẹ́.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Alaafin: Olori Aanu Adeyemi ṣàlàyé ìdí tó ṣe gẹ́ Oba Lamidi Adeyemi ti ìlú Oyo Kinni ofin sọ lori eyi?
Nítorí alábàáṣiṣẹ́pọ̀ ni wá lọ́dọ̀ Ọlọrun.
Nígbà kan rí ẹ jẹ́ òkú ninu ìwàkiwà ati ẹ̀ṣẹ̀ yín.
” IFOJUSUNNigba ti akowe ijoba apapo Boss Mustapha naa n soro , o ni o daju pe aare Muhammadu Buhari naa ni yoo tun  jawe olubori ninu eto idibo odun to n bo,nitori awon aseyori ti o ti se .
Nítorí náà ènìyàn pàtàkì ni Olówó-ayé ẹbọra pàtàkì sì ni ìwọ náà pẹ̀lú, ẹ kò sínínú ọ̀rẹ́ tí ènìyàn lè náání, kí Olódùmarè máṣe náání ẹnikẹ́ni nínú wa; o kú àtijọ́ o, ó pẹ́ díẹ̀ tía ti rí ara wa mọ, mo rò pé o ń rí nǹkan ṣe nǹkan, èmi náà ń bá ìgbésí-ayé mi lọ, gẹ́gẹ́ bí àṣẹ Ẹlẹ́dàá mi, èmi náà, ọ̀rẹ́ rẹ àtàtà, Baba-onírùngbọ̀n-yẹ́úkẹ́, ẹni tí ń gbé ibi gegele òkúta.
Owo sile d‘imi eegun ni Nigeria Owo ifẹyinti tan fawọn gomina ana ni Kwara Weah ge owo osu rẹ fun idagbasoke Liberia Oga agba Sadique Abubakar to jẹ agbẹnusọ fun ileeṣẹ ologun ofurufu ti Naijiria ti paṣẹ eto idanilọla fun olootọ ọmọ ogun yii.
Wọ́n bẹ̀rẹ̀ sí ya ara wọn sí mímọ́ ní ọjọ́ kinni oṣù kinni.
Lara awọn to tako àṣẹ rẹ yi la ti ri Aisha Yesufu, awọn agbẹjọro to fi mọ awọn ajafeto-omoniyan.
Oríṣun àwòrán, Ogun State Governor's office Àkọlé àwòrán, Nibi ọdun ilu ti ọdun 2019 naa ni wọn ti se afihan awọn asa ati awọn aso ibilẹ bii adire ti o wọpọ ni ilẹ Yoruba.
awọn ohun miiran to rọ mọ Abadofin oloju iwe
Kí á má dàbí Kaini tí ó wá láti ọ̀dọ̀ Èṣù, tí ó pa arakunrin rẹ̀.
Lọwọlọwọ bi a ti ṣe nkọroyin yi, agbo pe wọn ti da awọn oṣiṣẹ ile iroyin naa sita kuro ni ọfisi wọn to wa ni adugbo Jabi nilu Abuja.
Ṣugbọn níbi tí kò bá sí òfin, kò sí ẹ̀ṣẹ̀.
 Ó jẹ ́ ìkẹfà ọkọ ̀ ojú omi ẹ ̀ lẹ ́ rù , tí àwọn ajalèlókun tí wọ ́ n ṣẹ ̀ sẹ ̀ gba owó ìdásílẹ ̀ rọgùrọ ́ gù mílíọnù dọ ́ là máa dojú kọ .
O ni: Lati ile ni ẹlomii ninu wọn ti ni lọkan pe nkan ti awọn fẹ ẹ lọ ṣe niyẹn."
Ilẹ ẹjọ fagilé ìbò ọmọ ẹgbẹ́ APC nípinlẹ̀ Ogun pè kí àtúndì ìbò wà Ajímọ̀bí lè pe Ọlọ́run lẹ́jọ́ bí ìdájó kò bá tẹ́ ẹ lọ́rùn -Kọla Balogun Ọlọ́pàá Nàìjíríà àti Ẹgbẹ́ IMN n ṣé fakinfa lórí ikú àwọn olùwọ́de ìdárò Ashura Inú APC ń dùn nígbà tí ayọ̀ PDP kò kún lórí ìdájọ́ náà Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí kan sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
Díẹ̀ lára àwọn nkan tí àwọn aṣòfin fi síta lójú òpó Twitter nìyíì: Ọkan nínú àwọn sẹ́natọ Rafiu Ibrahim ní 'wọn dí òun l'ọ́nà láti wọ ilé ìgbìmọ̀.
Oríṣun àwòrán, Family handout Àkọlé àwòrán, Ọkọ Judith lo seku pa sinu oko Judith Chesang, ọmọ ọdun mejilelogun, lati orileede Kenya Lọjọ kini Oṣu kẹwa,Judith Chesang ati ọmọ iya rẹ Nancy n ṣiṣẹ ninu oko wọn.
" Ankara Gucci ni iṣẹ Agbẹjọro lo wu baba oun ki oun ṣe amọ ayanmọ oun ni awada ṣíṣe jẹ, eyi toun bẹrẹ lati ile ẹkọ girama, ti o si fun oun ni okiki lori ayelujara.
@YoungOtutu, o ni lẹyin gbogbo atotonu yii, ẹ jẹ ka se agbẹyẹwo ọrọ awọn mejeeji, ta si lee sọ pe aarẹ Buhari ti kuna ni gbogbo ọna.
Ara ọtọ ni ọjọ ibi rẹ nitori pe wọn bii ni ọjọ kẹsan osu kẹsan (09/09) Olulufẹ ere bọọlu ni Odumejeje bákan náà lo ni pe erongba oun ni lati di ọmọ agbabọọlu nigba to wa ni kekere.
Bi ọpọ ti mọọ si ogbontagi oloṣelu, lawọn miran mọọ si aṣiwaju ẹgbẹ oṣelu APC.
fayegba iwa ibaje tabi awon iwa ti ko se feti gbo lowo awon ti oun yan sipo
Mose fún ẹ̀yà Gadi ní ìpín tiwọn, gẹ́gẹ́ bí iye ìdílé wọn.
N óo tú u sí ìhòòhò lójú àwọn olólùfẹ́ rẹ̀, kò sì ní sí ẹni tí yóo lè gbà á sílẹ̀ lọ́wọ́ mi.
Wọn ni lati mọ nnkan ti ofin ẹgbẹ sọ ki wọn to gbe iru igbesẹ bẹẹ'' Oríṣun àwòrán, Getty Images O wa ṣalaye pe, awọn igbesẹ kan wa labẹ ofin ẹgbẹ ti eeyan gbọdọ ṣe, ki o to le ni oun fẹ yọ alaga ẹgbẹ lapapọ ''Ni ipele nipele ni ohun gbogbo wa ninu eto.
 ""Mo si n fi gbogbo ẹnu ati asẹ mi sọ pe Alaafin se asise pẹlu bo se ni lati igba iwasẹ ni awọn asaaju ọba ni Ekiti ti jẹ mẹrindinlogun, eyiun awọn ọba ti ko lee darukọ wọn, amọ okan n dibọn pe oun ko mọ pe iye ọba to wa labẹ pẹlupẹlu koo duro si oju kan."
Aliyu ni iyawo Aisha Buhari mọ pe arun Covid-19 ṣi wa lawujọ, nitori naa lo ṣe ri daju pe gbogbo awọn to peju sibi igbeyawo ọmọ rẹ tẹle ilana ijinasiraẹni ti awọn eleto ilera gbe kalẹ.
ninu ifọ̀rọ̀wánilẹnuwò ti Anthony Joshua ṣe pẹlu ilé iṣẹ iroyin Punch lo ti salaye pe gbogbo asiko ohun ni Naijiria oun ko ti ni nkan kan ṣe pẹlu ọrọ SARS bákan náà ni oun ko gbọ ẹka ọlọpaa SARS ri.
Ati aarẹ ile asofin ati igbakeji rẹ ni wọn yoo yan lọjọ iṣẹgun.
Awọn ọdọ sewọde nilu Abuja Buhari wa ẹnu si àwọn ọdọ Nàìjíríà Sowore: olùdíje Ààrẹ tó fẹ gbà Nàìjíríà padà fún àwọn ọdọ Minisita ọrọ awọn ọdọ ni eyi tun fihan pe aarẹ Buhari ni ifarajin ati atilẹyin fun awọn aato to ba wa fawọn ọdọ Naijiria.
Danjuma, tí ó jẹ olórí àwọn ológun, tí o si tún jẹ́ mínísítà fún ètò abo ní ìgbà kan rí, bu ẹnu àtẹ́ lu ẹgbẹ́ ológun bí wọ́n ṣe ń gbé lẹ́yìn apá kan dá apá kan sí nínú aáwọ̀ tí ó wáyé láàárín àwọn darandaran àti àgbẹ̀, pàápàá jù lọ èyí tí ó wáyé ní ilée rẹ̀ tí í ṣe ìpínlẹ̀ Taraba.
Wọ́n fi ìlẹ̀kùn ẹnubodè sílẹ̀ ní ṣíṣí, wọ́n ń lé àwọn ọmọ Israẹli lọ.
#U20WC-Nàìjíríà,Senegal àti S/Africa ti pegedé fún Poland 2019
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ekiti decides: Oshiomole fẹ̀sùn kan Fayose 10 Agẹmo 2018 Àkọlé àwòrán, Ààrẹ Muhammadu Buhari, Bola Tinubu àti àwọn adarí ẹgbẹ́ òsèlú APC wà ní àsekágbá ìpolongo ìdìbò gómìnà lábẹ́ òsèlú APC ní ìpínlẹ̀ Ekiti.
" Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Tantra: Ìlànà yìí ló ń kọ́ wa láti fi èémí àti ìṣẹ́po ara gbádùn ìbálòpọ̀ Bakan naa ni Dojumo fikun pe awọn n sọrase lati mase se asise lori isọwọ sisẹ ikọ alaabo naa pẹlu afikun pe, o seese ki wọn ma pese asọ isẹ pataki fun ikọ naa bayii, tori ipinnu kankan ko tii waye lori eyi.
Ó kí mi dáadáa ó sì wí fún mi pé ọ̀gá òun ń fẹ́ẹ́ rí mi, nígbà tí mo sì béèrè orúkọ ọ̀gá rẹ̀ náà ó ní ìgbà tí mo bá dé ọ̀dọ̀ rẹ̀ yóó sọ orúkọ ara rẹ̀ fún mi, mo bá tẹ̀lé e.
Kia ni mo bẹrẹ si ni yẹ awọn atẹranṣẹ rẹ wo, mo si ri aridaju pe, wọn ti n fẹ ara wọn ṣaaju asiko to sọ fun mi pe awọn bẹrẹ, Wọn ti lọ si ile itura laimọye igba, wọn si ti jọ rinrinajo afẹ lọpọlọpọ igba pẹlu.
A kò lòdì sí kí àwọn mùsùlùmí ṣé ìwọ́de àyájọ́ Ashura-Ọlọ́pàá Nàìjíríà Ni ileewosan nla Aminu Kano teaching Hospital, AKTH to wa nilu Kano ni o dakẹ si ni ọjọ Aje.
Àwọn tí ẹsẹ̀ wọn yá nílẹ̀ kò lè sálọ, bẹ́ẹ̀ ni àwọn ọmọ ogun kò lè sá àsálà.
Anfaani nla ni ẹjẹ owo biliọnu meji poun naa jẹ́ ti awọn olori orilẹede fun Naijiria, ọkan lara awọn orilẹede ti o n koju ipenija aarun iba.
Bẹ́ẹ̀ ni kò sí ẹni ti yóò wù mi mọ́ nínú àwọn ọkùnrin, rékọjá Ìrìnkèrìndó yìí, ẹni ti ń gbé ilé Alárìnkiri.
Irú iṣẹ́ wo ní Funke Akindele rán sí Bukunmi Oluwasina, tó fa ariwo lórí ayélujára?
Ṣugbọn bí ẹrú náà bá fúnra rẹ̀ wí ní gbangba pé òun fẹ́ràn olówó òun, ati aya òun, ati àwọn ọmọ òun, nítorí náà òun kò ní gba ìdásílẹ̀, kí òun má baà fi wọ́n sílẹ̀, 
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Fredie Blom: Ọkùnrin tó dàgbà jù lágbàyé jáde láyé lẹ́ni ọdún 116 ní South Africa 23 Ògún 2020 Oríṣun àwòrán, AFP Ọkunrin ọmọ orilẹ-ede South Africa kan ti wọn ni o dagba julọ lagbaye ti dagbere faye lẹni ọdun mẹrindinlọgọfa.
Gẹgẹ bi alaye ti Araba ti ilu Oṣogbo, oloye Ifayẹmi Ẹlẹbuibọn ṣe fun BBC News Yoruba, ko si ọba to n jẹ ọkan ki o to de ori itẹ.
Mo rí àwọn ọ̀dọ́ tí wọn kò ní ìrírí,mo ṣe akiyesi pé láàrin wọn,ọmọkunrin kan wà tí kò gbọ́n.
Mo rí ìwé tí wọ́n kọ orúkọ àwọn ìdílé tí wọ́n kọ́kọ́ wá sí, mo sì rí ohun tí wọ́n kọ sinu wọn pé:
Igbagbọ ni àwọn àgbà àtijọ́ ní, tí wọ́n fi ní ẹ̀rí rere.
A ti ń sin òkú méjì sínú ibójì kan náà nítorí ọ̀wọ́ngógó ibojì ìsìnkú"" Ẹ̀gbọ́n àti àbúrò wà ní ilé ẹ̀jọ́ lórí ikú Tolulope Arotile 'Àwa ọmọ Nàìjíríà tó farapa fẹ́ wálé láti Lebanon, ìjọba kó wa pamọ́' Ọlọ́run nìkan ló mọ bí ìrìnàjò ìfẹ́ ẹ̀dá á ṣe rí láyé, ọ̀dọ́ Aláàfin ní orí gbémí yà sí, ó sì tẹ́milọ́rùn- Olorì Aanu Kini o ṣeeṣe lati ṣẹlẹ?"
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Yinka Ayefẹlẹ: Àdúrà lẹ ṣe pé mo bí ìbẹta, yóò sì rí bẹ́ẹ̀ 6 Òkùdu 2019 Oríṣun àwòrán, yinkaayefele Àkọlé àwòrán, Yinka Ayefẹlẹ: Àdúrà lẹ ṣe pé mo bí ìbẹta, yóò sì rí bẹ́ẹ̀ Gbajugbaja akọrin Tungba nni, Yinka Ayefẹlẹ ti kigbe sita faraye pe oun ko bi ibẹta gẹgẹ bi awọn eeyan kan ti n tan iroyin naa kalẹ lawọn oju opo ikansiraẹni lori ayelujara.
O ni ko jọ ohun loju nitori pe tẹlẹ naa ko si ipa ti awọn ileeṣẹ aṣoju orileede Naijiria n ṣe fawọn to wa nilẹ okere.
Ẹgbẹ́ òṣèlú ZLP gbàmí tọwọ́tẹsẹ̀ láti díbò gómínà ní Ondo- Agboola Ajayi Ifẹ̀họ̀núhàn ń lọ lọ́wọ́ ní Belarus lẹ́yìn tí ìdìbò tùn gbé Ààrẹ̀ Lukashenko tó ti wà nípò fún ọdún 26 wọlé Dẹ́rẹ́bà kẹ̀kẹ́ Maruwa rí ẹ̀wọ̀n gbére he lẹ̀yìn tó fi ipá bá ọmọ ọdún mẹ́rìnlá lòpọ̀ Wo ohun tó yẹ kí o mọ̀ nípa Yahaya Sharif-Aminu tó gba ìdájọ́ ikú ní Kano lórí ẹ̀sùn ọ̀rọ̀ òdì sí Ànọ́bì Coronavirus: Ewu wo làwọn òṣìṣẹ́ elétò ìlèra ń kojú ní Nàìjíríà?
Fun igba akọkọ ni ọpọlọpọ ọdun, gbogbo agbaye fi ohun ṣọkan lori iwa ibajẹ awujọ eleyi to mu Iwọde waye kaakiri gbogbo agbaye lati minneapolis ti iṣẹlẹ iku Floyd ti waye titi lọ kan Mexico, Canada, Brazil, Australia, New Zealand titi kan awọn orilẹ€de kan lorilẹede Afirika.
O ti le lọsẹ kan ti awọn ọdọ jakejado ipinlẹ Eko ti awọn ọdọ ti n darapọ mọ awọn akẹgbẹ wọn kaakiri gbogbo ipinlẹ orilẹede Naijiria lati ja fun iwa ika latọdọ awọn ọlọpaa Naijiria ati fifopin si iṣekupani lọna aitọ to n ti ọwọ awọn ikọ agbofinro SARS wa.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ritual killer: Ọwọ́ ọlọ́pàá tẹ ọkùnrin tó gé akẹ́kọ̀ọ́ ọ̀rẹ́bìnrin rẹ̀ wẹ́lẹ́ wẹ́lẹ́ fún òògùn owó ní Ikorodu 20 Owewe 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 21 Owewe 2020 Oríṣun àwòrán, Twitter/@Codedwizzy Ọwọ awọn ọlọpaa ti tẹ afurasi ọkunrin kan, Owolabi Yusuf ti wọn fẹsun kan pe o ṣekupa akẹkọọ ile iwe giga gbogbonṣe kan, Toluwalase Kembi lati fi ṣe oogun owo.
Nígbà tí ọtí dá lójú Noa, tí ó gbọ́ ohun tí àbíkẹ́yìn rẹ̀ ṣe sí i, 
O ni eyi yoo jẹ ki wọn mọ ewolewo laarin awọn gomina ati awọn eekan ti ọbẹ ofin ti ba ni idi fun iwa ijẹkujẹ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìkọlù Benue: Adaran pa àlùfáà méjì, ọmọ ìjọ 13 nílé ìjọsìn 24 Ìgbé 2018 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Bíi ẹgbẹ̀rún kan àbọ̀ ènìyàn ni ó ti kú ní Benue láti 2013 Ìròyìn kàn ní àwọn afurasí darandaran agbébọn ti pa àlùfáà méjì àti ọmọ ìjọ mẹ́tàlá ní ilé ìjọsìn kátólíìkì kan tí ó wà ní Ayar Mbalom ní ìjọba ìbílẹ̀ ìlà oòrùn Gwer ní ìpínlẹ̀ Benue.
Liverpool ṣé Barcelona ríṣarìṣa pẹ̀lú àtòrì ẹlẹ́nu mẹ́rin 7 Èbibi 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 8 Èbibi 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Messi dori kodo Ẹgbẹ agbabọọlu Liverpool ti jajabọ tẹsiwaju lati kopa ninu aṣekagba idije Champions League pẹlu bi wọn ṣe doju Barcelona bole ni Anfield.
Awon oludije mefeefa ni won ti fi oruko won sile, eyi ti awon oniroyin ile-ise iroyin BBC, ati awon miiran yoo bere ibeere lowo won.
Àwọn adigunjalè yabo ṣọ́ọ̀ṣì, fipá bá obìnrin kan lòpọ̀, yìnbọn fún òmííràn Ìkébé mi tóbí ju ohun tí mo lè dọwọ́ bò lọ, n kìí fí ṣakọ- Nkechi Blessing Ọ̀rọ̀ Soyinka àti Obasanjo papọ̀ lórí pé Buhari n ṣe ìpínyà Nàìjíríà A fẹ́ kí a máa tẹ àwọn afipábánilòpọ̀ lọ́dàá ni báyìí - Ìjọba Ekiti Dokita àti Nọ́ọ̀sì fìyà jẹ mí lásìkò tí mò ń rọbí- Alaboyún Olori awọn oṣisẹ ni Naijiria ṣalaye pe ijọba apapọ ṣi n jiroro lọwọ pẹlu ẹgbẹ awọn oṣiṣẹ lori ohun ti wọn fẹ ki ijọba ṣe gan an.
''Ati ẹni to n ta ata lọja ati awọn ti ko ni nkan ṣe pẹlu dọla,gbogbo wọn ni yoo gbe owo ọja lọ soke.
Titi di asiko yii, ileeṣẹ ọlọpaa ko tii sọ ohunkohun lori ọrọ naa.
 Atunse to monyan lori ti de ba yara igbalejo to wa ni papa
osise omo ogun Naijiria lo sekolu naa.
“Wọ́n tilẹ̀ tún ranṣẹ lọ pe àwọn ọkunrin wá láti òkèèrè, oníṣẹ́ ni wọ́n gbé dìde kí ó lọ pè wọ́n wá; àwọn náà sì wá.
Ẹ ró aṣọ ọ̀fọ̀,ẹ máa sọkún, kí ẹ sì máa sá sókè sódò láàrin ọgbà!
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Adam Johnson: Agbábọ́ọ́lù Sunderland nígbà kan rí jáde lẹ́wọ̀n lẹ́yin ọdún mẹ́ta 23 Ẹrẹ̀nà 2019 Oríṣun àwòrán, PA Àkọlé àwòrán, Adam Johnson lọ ẹ̀wọn ọdun mẹ́fa ni 2016 Baba agbabọọlu Sunderland ati Ilẹ Gẹẹsi nigba kan ri, Adam Johnson ni inu oun dun pe ọmọ oun ti jade lẹwọn Johnson gba bọọlu fun Middlesbrough, Manchester City ati Sunderland ki wọn to ju u si ẹwọn ọdun mẹfa ni 2016 nitori wipe o ba ọmọ ọdun mẹẹdogun kan ṣere ifẹ.
Oríṣun àwòrán, @Zainab Àkọlé àwòrán, Zainab ni o jẹ minista abẹle fun eto iṣuna ati ilana aatẹle fun ijọba apapọ lọdun 2015.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Lateef Adedimeji: Adebimpe Oyebade kọ́ ni àfẹ́sọ́nà mi, ọ̀rẹ́ lásán la jẹ́ 15 Sẹ́rẹ́ 2021 Oríṣun àwòrán, Instagram/adedimeji lateef Gbajugbaja oṣerekunrin, Lateef Adedimeji ti papa sọrọ nipa ajọṣepọ to wa laarin oun ati akẹẹgbẹ rẹ obinrin ninu isẹ tiata, Adebimpe Oyebade.
Laarin ọdun 1965 si 1967, Buhari ṣiṣẹ gẹgẹ bii ọgagun Second Infantry Battalion wọn si fi jẹ oye brigade major ti Second Sector, First Infantry Division ni osu kẹrin si ikeje ọdun 1967.
jẹ́ kí wọn mu ún, kí wọn gbàgbé òṣì wọn,kí wọn má sì ranti ìnira wọn mọ́.
Nollywood: Bàbá Sàlá, Ọmọgé Campus, Ajimajasan àtàwọn òṣèré mí ì jáde láyé ní 2018
Ààrẹ orilẹede Burundi, Pierre Nkurunziza ti jáde láyé lẹ̀ni ọdún 55 Iṣẹ́ ọpọlọ ló yẹ ká ṣe nínú tíátà, kìí ṣe àfihàn ara bíbó àbí ìhòòhò wa - Binta Mọgaji Iwọde tako iwa ẹlẹyamẹya gbinaya lagbaye lẹyin iku arakunrin adulawọ kan, George Floyd latọwọ awọn ọlọpaa Minneapolis lorilẹede Amẹrika .
Ẹni tí ó rán mi níṣẹ́ wà pẹlu mi, kò fi mí sílẹ̀ ní èmi nìkan, nítorí mò ń ṣe ohun tí ó wù ú nígbà gbogbo.
Gbogbo owó tí o ti ń ná láti àná tí mo ti dá yìí jọ mi lójú gidigidi, ṣùgbọ́n nǹkan tí ò ń gbìn sílẹ̀ yìí, o ko ní sàà ka èso rẹ lọ́jọ́ kan.
Alaye awọn osisẹ Sars naa, gẹgẹ bi a se gbọ ni wipe, ko ni lee rọrun fun awọn lati maa fi asọ ọlọpaa le awọn adigunjale tabi awọn ajinigbe.
Oríṣun àwòrán, Getty Images O ni bi o tilẹ jẹ pe Ibrahim fẹ kọ oun silẹ, amọ oun yari pe oun ko lọ sibi kankan, to si daba pe kawọn lọ se ayẹwo nile iwosan lati mọ oun to sẹlẹ si ibale oun.
Alaga naa tun seleri lati pari ona Ogbia-Nembe to maa na to bilionu merinlelogun owo naira fun ki odun 2017 yii to pari.
Ẹ̀yin ọ̀tá mi, ẹ lọ dì mọ́ òpò ina lọ́dún 2020- Ayodele Fayose Ó ti tán fún mí lọ́dún 2023- Ààrẹ Muhammadu Buhari Wo àwọn èèyàn jáńkán tí yóò ṣe ọdún tuntun ní ọgbà ẹ̀wọ̀n Àwọn fóònù wọ̀nyìí kò ní lè ṣe WhatsApp láti ọdún 2020 Àfàìmọ̀ kí Naira Marley má fi ẹ̀wọ̀n bẹ̀rẹ̀ ọdún 2020 Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ọbẹ Ẹgusi sise ati jijẹ Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Nilu ti iji ti sọṣẹ niṣe ni awọn ọmọkunrin wọn yi n ṣere lori igi agbọn ti iji wo lọjọru Oríṣun àwòrán, AFP Àkọlé àwòrán, Lorile-ede Kenya, awọn akẹkọọ da muso fun olukọ wọn ni papakọ ofurufu Kenya nigba to dari lati ibi ti o ti gba ẹbun $1m (miliọnu dọla kan) gẹgẹ bi olukọ to pegede julọ lagbaye Oríṣun àwòrán, @ProfOsinbajo Àkọlé àwòrán, Igbakeji aarẹ Naijiria ati iyawo rẹ, Dolapo Osinbajo nibi ayẹyẹ isin idupe lẹyin ti wọn wọle gẹgẹ bi igbakeji aarẹ nidibo Naijiria tó kója nilu Ikenne, ipinlẹ Ogun Oríṣun àwòrán, AFP Àkọlé àwòrán, Lọjọ Aiku, alatilẹyin ẹgbẹ agbabọọlu Zimbabwe yi n dawọ idunnu bi ikọ rẹ ti ṣe fi ami ayo 2-0 sagba Congo-Brazzaville ninu ifẹsẹwọnsẹ lati kopa ninu idije Africa Cup of Nations Oríṣun àwòrán, Reuters Àkọlé àwòrán, Lọjọ Abamẹta, ajagunfẹyinti orile-ede Ethiopia yi n fẹsẹ rajo nibi ayẹyẹ kan ti wọn ṣe lati fi gba alejo irun ori Emperor Tewodros II ti ile iṣẹmbaye ilẹ Gẹẹsi, National Army Museum da pada si Ethiopia Oríṣun àwòrán, AFP Àkọlé àwòrán, Lọjọ keji, oludibo yi n yẹ orukọ rẹ wo loju patako lati le kopa ninu idibo aarẹ Comoros Islands Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Fọfọ ni igboro Algiers kun nibi iwọde to waye lọjọ Eti.
26 milliom, eyi ti o je N5.
"Nipasẹ bẹẹ, a ti le Leonard Ezenwa kuro ẹgbẹ oṣelu yii, gbogbo awọn kọlọransi ọmọ ẹgbẹ to kopa ninu ipade to waye nilu Abuja naa ni a ti paṣẹ lọ rọọkun nile titi di igba ti iwadi ba pari lori ipa ti koowa wọn ko.
Nàìjíríà wà ní ìsọ̀rí kejì pẹ̀lú Burundi, Madagascar àti Guinea Ìfipá-bọmọdélòpọ̀ jẹ́ ohun tí òbí gbudọ̀ sàkíyèsí Wo bí o ṣe lè kọ́ ọmọ rẹ lẹ́kọ̀ọ́ ìbálòpọ̀ Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí kan sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
Ṣugbọn pẹlu alaye awọn to wa ninu ọgba ẹwọn, ko fibẹẹ tii si ohun ti wọn ṣe gẹgẹ bi atunṣe si El Helicoide.
Ẹ kórìíra ibi, kí ẹ sì fẹ́ ire, ẹ jẹ́ kí ìdájọ́ òdodo gbilẹ̀ lẹ́nu ibodè yín; bóyá OLUWA Ọlọrun àwọn ọmọ ogun yóo ṣàánú fún àwọn ọmọ ilé Josẹfu yòókù.
Baba Sala wa lara awọn to kọkọ mu ẹrẹ sinima wa si orileede Naijiria pẹlu awọn akẹgbẹ rẹ bi Hubert Ogunde,Kola Ogunmola Oyin Adejobi ati Duro Ladipo.
Igbeṣẹ iwaadi irufẹ eleyi ti wọn n fẹ ṣe naa a ma mu ki wọn pe aarẹ ko wa wi tẹnu rẹ, ti o si ṣeeṣe ki wọn yọ nipo latari rẹ.
“Gbogbo ẹ̀yin tí ẹ yí i ká, ẹ dárò rẹ̀,kí gbogbo ẹ̀yin tí ẹ mọ orúkọ rẹ̀ sì wí pé,‘Ọ̀pá àṣẹ tí ó lágbára ti kán,ọ̀pá àṣẹ tí ó lógo ti ṣẹ́.
Ohun to wu olukuluku ni lati san an Oríṣun àwòrán, @PeaceCorpsNG Àkọlé àwòrán, 'Ki o to lee darapọ mọ ajọ yii, eniyan bẹẹ yoo ti wo fọọmu igbaniwọle ninu eyi ti a ti se alaye ohun ti owo ti wọn san wa fun' Kini yoo sẹlẹ si owo ti wọn san bayii?"
ti mo dije fun ipo aarẹ .
Lẹ́yìn náà ó mú mi lọ sí ibi mímọ́, ó wọn àtẹ́rígbà rẹ̀, ìbú rẹ̀ ní ẹ̀gbẹ́ kinni keji jẹ́ igbọnwọ mẹfa (mita 3).
Gẹ́gẹ́ bí o ti jẹ́rìí iṣẹ́ mi ní Jerusalẹmu, bẹ́ẹ̀ ni o níláti jẹ́rìí nípa mi ní Romu náà.
Lẹyin naa ẹnikan ninu wọn yoo ma a bere pe ‘talo wa ninu ọgba naa’, awọn iyoku yoo ma dahun pe, ‘ọmọ kekere kan ni, ṣe ki n wa wo o’ ?
Satani fẹ́ ta jamba fún àwọn ọmọ Israẹli, nítorí náà ó gbó Dafidi láyà láti kà wọ́n.
Ẹ fọn fèrè ní ọjọ́ oṣù titun, ati níọjọ́ oṣù tí a yà sọ́tọ̀, ati ní ọjọ́ àsè.
Amọ iwadii fihan pe kii ṣe gbogbo wọn lo maa n ṣiṣẹ ni oko ireke.
Kí ó wá sórí Josẹfu,àní, sórí ẹni tó jẹ́ aṣiwaju fún àwọn arakunrin rẹ̀.
Segun Afolayan so pe, ninu awon arinrin-ajo ohun,“ obinrin meje pere lowa laarin won, ti awon okunrin si je mẹ́tàléláàdọ́jọ.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ikú ọkọ mi ṣì n dàbí àlá l'ójú mi àtawọn ọmọ DBanj gbé àwo tuntun jáde lẹ́yìn ikú ọmọ rẹ̀ Ikọ̀ ẹlẹ́sìn Hàkíkà rèé, níbití wọn ti ń pààrọ̀ ìyàwó láàrín ara wọn Irú ẹ̀dá wo ni aṣòfin Bukola Saraki jẹ́?
Amọṣa ọrọ yi pada ni ọjọru nigba ti ile ẹjọ naa tẹti si ẹbẹ awọn igun mejeeji lati yanju aawọ naa ni tubiinubi laarin ara wọnIle ẹjọ giga apapọ ilẹẹwa to wa ni ilu Portharcourt ti fa iwe ẹjọ ti wọn pe tako iduro gomina Godwin Obaseki gẹgẹ bi oludije ni idibo abẹle fun ipo gomina lẹgbẹ oṣelu PDP ni ipinlẹ Edo.
Má pa àwọn ọ̀rẹ́ rẹ tì ati àwọn ọ̀rẹ́ baba rẹ;má sì lọ sí ilé arakunrin rẹ ní ọjọ́ ìṣòro rẹ.
 ajíbogun dúró níbi tí a ń pè ní iléṣa lónìí yìí , òun sì ni Ọwá iléṣà kìíní .
Àwọn ni òfin tí ó jẹmọ́ àrùn ẹ̀tẹ̀.
Bí a bá lè rí ìwọ̀n Homeri baali kan ká ninu rẹ̀ lẹ́ẹ̀kan, iye rẹ̀ yóo jẹ́ aadọta ìwọ̀n ṣekeli fadaka.
Adajọ tí wá ṣàlàyé pé, kí wọn gbìyànjú láti jẹ ki awon Ẹlẹ́rìí náà pọ ni iye bíi bẹẹ kọ, ilé ẹjọ́ yóò pé àwọn ẹni a fẹ̀sùn kan, ní pàtàkì Alfa Babatunde láti jẹ ẹlẹ́rìí ara rẹ nítorí wọn fẹ ki igbejo náà tètè parí.
Ẹja Puffer Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Eyií jẹ ẹja ti wan maa ń lo bi ìpanu ní ilẹ̀ Japan Ẹja Puffer yiìí dàbí Májèlé, ó sì le pànìyàn.
Ẹni tí ó bá lọ sun wọ́n, yóo fọ aṣọ rẹ̀, yóo sì wẹ̀, lẹ́yìn náà, ó lè wọ ibùdó wá.
Nígbà tí ó di ọjọ́ keji, àwọn ìjòyè ati àwọn àgbààgbà ati àwọn amòfin péjọ ní Jerusalẹmu.
(Nítorí ohun tí Ìwé Mímọ́ wí kò tíì yé wọn pé dandan ni kí ó jí dìde ninu òkú.
Òru òní, ọjọ́rú ni àdéhùn níní ibùdó olókoòwò ọ̀fẹ́ nílẹ̀ Adúláwọ̀ bẹ̀rẹ̀ ni èyí tí Aarẹ Buhari ti Naijiria kòì tíì fọwọ́síi.
Ẹlẹni/ibusun alagbeka Nitoriipe ọpọlọpọ awọn mii lo maa n lọ alọsun.
Eyi tumọ si pe Obaseki to jẹ oludije ẹgbẹ oṣelu PDP fẹyin oludije APC Osagie Ize-Iyamu gbalẹ ninu idibo ọhun.
O ti pẹ ti ijọba Afghan ti n pe fun alaafia ṣugbọn awọn alakatakiti Taliba to ti gba awọn agbegbe to pọ bayii ni rara.
Adigunjalè pa oníbàárà báńki tó ṣẹ̀ṣẹ̀ gba owó n'Ibadan Wo ojú àwọn tó na ìka máa lọ ilé sí Praise nilé ẹlẹ́gbọ́n àgbà BBNaija Àwa la mọ báa ṣe mú Sunday Shodipe táa fà a lé ọlọ́pàá lọ́wọ́ - Ọlọ́dẹ Soludero Amọ, ko si ẹni to mọ ohun to da awọn ọlọpaa ati Ọgbẹni Blake pọ.
Ètò ìgbógunti ìwà àjẹbánu rẹ̀ fì sí ẹ̀gbẹ́ kan.
Mo fẹ́ ìdájọ́ òdodo lórí ikú tó pa ọmọ mi- Baba ọmọ ti SARS pa Ẹfunsetan Aniwura, ọmọ Ẹ̀gbá tó di akíkanjú obìnrin nílẹ̀ Ibadan Iṣẹ́ Oníbúrẹ́dì ní mo kọ́, ìfẹ́ àṣà Yorùbá ló sún mi dé ìdí ẹ̀ṣà pípé tí mo fi là- Ajobiewe Ìya Emma oní POS ṣẹ̀ṣẹ̀ rékọjá lọ síbí ilé yẹn ni àtọmọdé, ó sì wó pa wọ́n - Láńlọọ̀dù Obalende Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí End SARS, End SWAT: MC Oluomo ní òun kọ́ ló rán àwọn jàǹdùkú sáwọn olùwọ́de l'Eko15 Ọ̀wàrà 2020 10:43 Fídíò, Wole Soyinka sọ ìdí tó fi ni òun a fi màálù Fulani ṣe súyà fáwọn èèyàn abúlé, Duration 10,4323 Owewe 2020 Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí kan sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
yii ki i ṣe pe awọn n lepa gomina paapaa nigba ti wọn ṣakiyesi awọn kudiẹkudiẹ
Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí 1:16 Fídíò, Kogi àti Bayelsa: Primate Ayodele sọ àsọtẹ́lẹ̀, Duration 1,1618 Bélú 2019 Prophecy 2020: Primate Ayodele, Baba Adeboye àti Father Mbaka sọ àsọtẹ́lẹ̀ nípa 2020!
Ṣé ẹ kò ní ilé tí ẹ ti lè máa jẹ, kí ẹ máa mu ni?
Makinde vs Adelabu: Olùdíje APC ní àkọsílẹ̀ àyànmọ́ òun nínú ìtàn Oyo kò gbọdọ̀ yẹ̀
Ikọ ọmọ ogun Al Shabab ti o wa nidi igbesunmọmi lagbegbe yii ti ni isẹ ọwọ awọn ni.
 Mo lọ́ra láti kàwé, bóyá nítorí pé mo jẹ́ ajagun-fẹ̀yìntì ni.
Nítorí tọ̀sán-tòru ni o fi ń jẹ mí níyà;gbogbo agbára mi ló lọ háú,bí omi tíí gbẹ lákòókò ẹ̀ẹ̀rùn.
Ẹ gbọdọ̀ ṣọ́ra, kí ẹ sì ṣe gbogbo ohun tí wọ́n bá ní kí ẹ ṣe.
" onírúiyepúpọ ̀ nínú àpẹrẹ òkè yìí jẹ ́ kíkọ ní bí àwọn agbára "" x "" ṣe ún kéré sí ."
O to idamẹwa owo osu awọn osisẹ ijọba ti wọn yoo maa yọ losọọsu.
- Ọmọ Mamman Daura 14 Ọ̀wàrà 2019 Oríṣun àwòrán, TWITTER Àkọlé àwòrán, Ní ìpin ọ̀sẹ̀ ni fídíò ibi tí ìyàwó Ààrẹ Buhari, Aisha Buhari ti ń pariwo pé kí wọ́n sí ilẹ̀kùn ilé fún òun.
Bakan naa ni agbẹnusọ awọn asofin nipinlẹ Ondo naa ni oun ko ya ara oun sọtọ nitori pe oun ko ni arun Coronavirus.
Nígbà tí Daniẹli gbọ́ pé wọ́n ti fi ọwọ́ sí òfin náà, ó lọ sí ilé rẹ̀, ó wọ yàrá òkè lọ, ó ṣí fèrèsé ilé rẹ̀ sílẹ̀, sí apá Jerusalẹmu.
Ẹnu ọlọ́gbọ́n a máa tan ìmọ̀ kálẹ̀,ṣugbọn ti òmùgọ̀ kò rí bẹ́ẹ̀.
“Fi idẹ ṣe agbada omi kan, kí ìdí rẹ̀ náà jẹ́ idẹ, gbé e sí ààrin àgọ́ àjọ ati pẹpẹ, kí o sì bu omi sinu rẹ̀.
Sọ fún un kí ó wá ràn mí lọ́wọ́.
''Aláàfin kìí ṣe ọkùnrin tí wàá jẹ lásán, tó sì wá sálọ - Aráàlú fèsì fún Olorì Anu Ọ̀dọ́mọdé olówó, ẹni ọdún 36 sọ̀rọ̀ sílẹ̀ pé aṣọ funfun ni kí wọn fi sìnkú òun Òkò gbọnin lórí ìjọba àpápọ̀ tórí pé ó pe àwọn olùwọ́de EndSARS ní agbésùnmọ̀mí Wo iye owó tí ìjọba Amẹrika ń na sí ìdìbò Ààrẹ àti ibi tí owó náà ti ń wá Wọn ni ohun to n fa ni aisi eto abẹrẹ ajẹsara fun awọn ọmọde, paapaa ni fun awọn ọmọde ti wọn bi si igberiko.
Nígbà tí mo wo inú ihò mi báyìí, ṣe ni àgbàrá òjò kún inú rẹ̀ bámúbámú, gbangba báyìí ni mo sì ń wao àwọn ìkarawun ìgbín tí mo fi ń pọ̀n omi àti igbá ẹ̀hìn ìjàpá tí mo ń lò bí àwo óunjẹ, gbogbo wọ́n dà bí ọkọ̀ lójú omi.
Abuja yoo naa ijoba lowo ti o to bilionu merin din milionu kan owo dola($3.
Ẹwẹ, iroyin to wa n ja kalẹ ni wi pe ile iṣẹ rẹdio yii kan wa fun ẹgbẹ kan ni.
Ó dúró tì mí, ó ní, ‘Saulu arakunrin, lajú!
"Baraakat Bello ni ọmọbinrin ẹni ọdun mejidinlogun, ti awọn olubi ẹda kan ṣekupa, lẹyin ti wọn fi ipa baa lopọ tan l'oṣu kẹfa ọdun yii, ni agbegbe Akinyẹle, Ninu ọrọ ti o ba ikọ BBC Yoruba sọ l'Ọjọ Aje, iya Baraka ni, ""A dupẹ lọwọ ọmọ Naijiria nilẹ yii ati ni oke okun."
Child marriage: $3,500 la gbà láti fa ọmọ ọdún márùn-ún f'ọ́kọ
Ko pẹ ko jinna ni ọrọ ifẹ wọn wọ̀ daadaa ti Gauri ni oun fẹran Roshan ju bi iya rẹ ṣe fẹran rẹ lọ.
Àní sẹ́, gbogbo irun orí yín ni ó níye.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Tantra: Ìlànà yìí ló ń kọ́ wa láti fi èémí àti ìṣẹ́po ara gbádùn ìbálòpọ̀ Kabiyesi Alawe ni ọgbọn ati imọ ni Kabiyesi Ọọni fi n to ilẹ Yoruba, Ọọni ko le kọ iru iwe ti Alaafin kọ to fi n bu gomina atawọn ọba alaye l'Ekiti.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Benue clashes: Àwọn agbébọn yìnbọn pa èèyàn mẹ́sàn án ni Benue 18 Ògún 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Aṣe ododo ọrọ pọnbele ni ọrọ awọn agba to ni oku n sunkun oku akaṣọleri n sunkun ara wọn.
APCSugbon igbakeji aare orile ede Naijria ojogbon Yemi
“Àwọn ọmọ Israẹli ti gbàgbé Ẹlẹ́dàá wọn, wọ́n sì ti kọ́ ààfin fún ara wọn.
Buhari pàṣẹ lórí àdínkù owó bẹntiró, alágbàtà ń ṣe tiwọn Lẹyin naa lo rọ awọn ile ijọsin lati gunle isin olojule ti awọn eeyan ti yoo wa nibẹ ko ni pọ ju boṣeyẹ lọ, tabi ki wọn maa ṣe isin lati ori itakun agbaye ti awọn ọmọ ijọ le darapọ mọ lati ile wọn.
ni nkan bi aago mọkanla aabọ owurọ l’Ọjọru, ile-eṣẹ ọlọpaa ni Guernsey sọ pe,
Àwọn tí ń ṣe àkóso àwọn ohun ìní ọba nìwọ̀nyí: Asimafeti, ọmọ Adieli, ni alabojuto àwọn ilé ìṣúra tí ó wà ní ààfin ọba.
Bí a ti ń gba ọlá, bẹ́ẹ̀ ni à ń gba ìtìjú.
Ẹni tí ó ní ọgbọ́n fẹ́ràn ara rẹ̀,ẹni tí ó bá sì ní òye, yóo ṣe rere.
Oríṣun àwòrán, Olubunmi Labiyi Àkọlé àwòrán, Ọba Adeyẹmi ti le ni ọgọrin ọdun ko to bi ibeji ni ẹẹmeji laarin ọsẹ kansoso Ọpọ eeyan si lo nya lẹnu pe Ọba Adeyẹmi to ti le ni ọgọrin ọdun si tun ni agbara lati bi ibeji ati ibẹta lọpọ igba, ti wọn si fẹ mọ asiri agbara Alaafin.
 o bẹrẹ ni ọdun 2018 , gẹgẹbi iṣaju fiimu ajọyọ ni akọkọ ni orilẹ-ede .
Ó sun wọ́n níná níbẹ̀, ó lọ̀ wọ́n lúbúlúbú, ó sì fọ́n eérú wọn ká sórí ibojì àwọn eniyan.
Hasori Hadata, Kerioti Hesironi (tí a tún ń pè ní Hasori); 
ewuro si awon alatako rẹ lati inu egbe oselu miiran bi i , ogbeni Alfred Bello to
- Olùkọ́ Eyi mu ki ọpọ awọn ololufẹ Laycon o gbohun soke pe ṣile kan ko gbọdọ re jẹ ninu owo aarẹ ẹgbẹ ICON naa.
Awọn àdájọ eré ìdáraya métà ní Switzerland lo odidi oṣù meji láti gbé ìdájọ wọn jáde èyí to ṣe afihan bi ìdájọ náà se se pàtàkì tó.
Ojú rẹ yóo fọ́, o kò ní lè rí oòrùn fún ìgbà kan!
Nilẹ Afirika paapaa ju lọ ni Naijiria, bi wọn ba sọ ọ sita, awọn eeyan a ni wọn o nigbagbọ.
Ó ń ṣá ni lọ́gbẹ́,ṣugbọn ó tún ń dí ọgbẹ́ ẹni.
Jẹ́ kí pápá oko ati gbogbo ohun tí ó wà ninu rẹ̀ yọ̀.
''Ikọ Super Eagles ti fi ẹnu ko lati gboju kuro lara ọ̀rọ̀ ajẹmọnu lasiko yii, bi ko ṣe ko gbaju mọ ọna lati gba ife ẹyẹ Afcon 2019.
Àkọlé àwòrán, Adajọ agba Durosinlohun Kawu Ni ilu Ibadan, ijo ibilẹ ni wọn fi n ki awọn eniyan kuabọ si gbọngan ti iburawọle yoo ti waye ni ilu Ibadan.
Akọwe ẹgbẹ naa ni Ipinlẹ Osun, Kunle Oyatomi sọ fun BBC Yoruba wipe, igbẹjọ naa ko yẹ ireti ẹgbẹ APC wipe, Adeleke ko le de ipo gomina ipinlẹ naa lailai.
oríṣìírìṣìí fíìmù ni ó wá .
Nígbà tí ẹ bá péjọ pọ̀, bí ẹnìkan bá ní orin, tí ẹnìkan ní ẹ̀kọ́, tí ẹnìkan ní ìfihàn, tí ẹnìkan ní èdè àjèjì, tí ẹnìkan ní ìtumọ̀ fún èdè àjèjì, ẹ gbọdọ̀ máa ṣe ohun gbogbo fún ìdàgbà ìjọ.
''Mo ti wa ọmọ naa titi.
Àwọn ọmọ Israẹli sì yọ wọ́n kúrò láàrin wọn gẹ́gẹ́ bí àṣẹ OLUWA.
9 Èbibi 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Ni ọjọ kini oṣu kẹfa, ikọ Ilẹ Gẹẹsi meji Liverpool ati Totenham yoo figa gbaga ni aṣekagba Champions League ti yoo waye ni papa iṣere Wanda Metropolitano to wa ni Madrid ni orilẹede Spain.
 Gege bi ile-ise alabo lorile-ede naa, won ni ikolu ohun waye lojo aje (Monday), sugbon nigbeyin omi pada teyin wogbin won lenu.
Mọ̀ nípa adelé adájọ́ àgbà tuntun, Ibrahim Tanko Muhammed
O wa laarin ikùn ati itan.
Ọ̀pá epo NNPC bú gbàmú ní Benin, òṣìṣẹ́ méje kàgbákò ikú òjijì Ọ̀fọ̀ ńlá ṣẹ̀ ní Ivory Coast, Olóòtú ìjọba, Amadou Gon Coulibaly jáde láye Tó o bá fẹ́ wọ bàálù lásìkò yìí, wo òfin tuntun tó tẹ̀lé Adurogboye fikun pe, awọn ko tii da ọjọ ti wọn yoo si papakọ ofurufu naa, nitori ọpọlọpọ nnkan lo rọ mọ igbesẹ naa.
Àwọn ọ̀tá wọn ti bàjẹ́ bíi Sodomu ati Gomora,wọ́n dàbí àjàrà tí ń so èso tí ó korò tí ó sì lóró.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Amaju Pinnick: Ìjọba Naijiria bèrè bó ṣe ná $8,400, N4bn 8 Èbibi 2019 Oríṣun àwòrán, Google Àkọlé àwòrán, Ààrẹ erébọ́ọ̀lù Naijiria, Amaju Pinnick ti bu ẹnu àtẹ́ lu ẹ̀sùn wí pé òun se màgòmágó pẹ̀lú owó NFF.
 ilu idogo , ní ẹnu bodè ti o pa ààlà orílẹ ̀ -èdè nàìjíríà àti ni a ti bi ebenezer obey .
Èyí ni àwọn mìíràn ń lépa tí wọ́n fi ṣìnà kúrò ninu igbagbọ, tí wọ́n sì fi ọwọ́ ara wọn fa ọpọlọpọ ìbànújẹ́ fún ara wọn.
Mo ti gbọ́ pé ẹ̀mí Ọlọrun Mímọ́ ń bẹ ninu rẹ; ati pé o ní ìmọ̀, òye, ati ọgbọ́n tí kò lẹ́gbẹ́.
Bakan naa ni aṣoju ẹkun idibo Oshodi/Isolo, Jude Idimogu to kọwọrin pẹlu Alaga naa ni awọn yoo wo ilana ti yoo mojuto bi wọn ko ṣe ni maa ta afẹfẹ gaasi ni itosi ile ibugbe jakejado ipinlẹ Eko.
Bakan naa lo tun fa bẹmbẹ ọrọ ya o nigba to wi pe awọn eeyan to n jẹ ajẹbanu lorilẹede Naijiria tun fẹ ṣe bi ẹni n pọ sii lọwọ yii pẹlupẹlu ipolongo igbogun tiwa ijẹkujẹ ti Aarẹ Buhari n lọgun rẹ tan-tan-tan.
"Tinubu sọ eleyii ninu atẹjisẹ kan to kọ si Ọsinbajo lati fi to baa dunnu wipe o pe ẹni ọdun mọkanlelọgọta, to si jẹ ""ẹni to fara rẹ́ ji fun idajọ ododo, otitọ ati sisẹ deede laarin gbogbo eniyan lawujọ."
Ayaba to n na igba kekere ọhun ni yoo jẹ onilu fun awọn ayaba to n tigba yoku, oun naa tun ni yoo lewaju orin ti wọn n kọ, nigba ti awọn ayaba yoku yoo maa gbe e.
Aṣọ rẹ kún fún òórùn oríṣìíríṣìí turari,láti inú ààfin tí a fi eyín erin ṣe lọ́ṣọ̀ọ́ni wọ́n tí ń fi ohun èlò ìkọrin olókùn dá ọ lára yá.
Ọpọlọpọ ninu wọn lo tun fi ara gbọgbẹ ọta ibọn.
Oṣu kan gbakako lawọn papakọ ofurufu mejeeji naa yoo fi wa ni titi pa.
Igba kẹta ree ti ile aṣofin n funpe si aarẹ Buhari lati yọ awọn ọga awọn ologun.
gomina ipinlẹ  Eko, Gomina Babajide Sanwo-Olu eleyii ti
Èmi ni ẹni kinni ati ẹni ìkẹyìn.
 Ohun to ku ni ki a tubo ko ara wa lona idokowo lenu ise onikaluku ki a le jo maa fowosopo se afihan awon aso igbalode bi won se n se nile okeere lodoodun.
Ohun ti wọn fi ṣe bẹẹ ree.
Nítorí pé a óo yọ ẹnikẹ́ni tí ó bá jẹ ọ̀rá ẹran tí a fi rú ẹbọ sísun sí OLUWA, kúrò lára àwọn eniyan Ọlọrun.
O jẹ agbegbe ti ọpọ eeyan n gbe, opa epo gba ibẹ kọja, ibẹ naa si ni ile iwe Bethlehem College wa, bakan naa ni ile epo NIPCO wa ladugbo ọhun pẹlu.
Asaretete ko ni kọja ile bẹẹ ni aringbere ko ni sun sọna ni imọran pe ki onikaluku ṣe iṣẹ niwọnb ko si maa dide.
Ọgbọ́n, ati ọrọ̀ rẹ pọ̀ rékọjá ohun tí mo gbọ́ lọ.
N kò ní ṣàánú wọn, n kò ní dá ẹnikẹ́ni sí, n kò sì ní yọ́nú sí wọn débi pé kí n má fẹ́ pa wọ́n run.
Bí ó ti ń lọ bu omi náà, Elija tún pè é pada, ó ní, “Jọ̀wọ́ bá mi mú oúnjẹ díẹ̀ lọ́wọ́ sí i.
Èèyàn 250 míràn lárùn náà Ìdí tí mo fi gbàdúrà ìyàwó bíi Chanel Chin fáwọn tó d'ẹ̀bi ìkọ̀sílẹ̀ rẹ̀ rù mí rèé - Oluwo Loju opo Twitter rẹ si ni wọn ti tufọ iku rẹ laṣalẹ ọjọ Ẹti.
Oluwa wa fúnrarẹ̀ ati Ọlọrun Baba wa, tí ó fẹ́ wa, tí ó fún wa ní ìtùnú ayérayé ati ìrètí rere nípa oore-ọ̀fẹ́, 
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù BBNaija: Mercy ló gbadé BBNaija ọdún 2019 6 Ọ̀wàrà 2019 Oríṣun àwòrán, Instagram Ko si ohun to ba ni ibẹrẹ, ti kii lopin, bẹẹ lọrọ ri pẹlu eto Big Brother Nigeria to ti n waye lati bi osu mẹta sẹyin.
Mo sì ti súre fún un.
Ogbeni Onyema Nwodo, to je adari eto nile ise ijoba ipinle Enugu to n mojuto idagbaoske eto ogbin, ENADEP ti gba awon agbe nimoran lati maa lo apakoriko dipo ki won maa sun papa.
Ẹbi ọmọdebinrin ọhun sọ fun awọn akọroyin pe ileeṣe ọlọpaa ẹkun Elere l'Agege ko ti gbe oku akẹkọọ naa fawọn.
Jonatani bá dáhùn pé, “Ó dára, a óo rékọjá sọ́hùn-ún, a óo sì fi ara wa han àwọn ará Filistia.
Igbakeji gomina ipinlẹ Ondo, Agboọla Ajayi ṣalaye pe awọn araalu ni ipinlẹ Ondo ni wọn fẹ ki oun wa oko miran ṣan ki ala rẹ lati di gomina ipinlẹ naa lee ṣẹ.
tí mo sì pa ààlà fún un,tí mo sé ìlẹ̀kùn mọ́ ọn,
Allison Becker Awọn balogun adilemu to pegede julọ: 1.
19 Ẹrẹ̀nà 2020 Oríṣun àwòrán, Aisha Àkọlé àwòrán, Coronavirus:Ọmọ mi to ṣẹ̀sẹ̀ dé láti UK ko fi àmi Coronavirus han, sùgbọ́n.
Àwọn ti wọ́n kò lọ ilé iwé gbọdọ́ ni ǹkan ti a fi n dáni mọ Olùforúkọ silẹ̀ gbọdọ ti kọ iwé ti yóò sàlàyé, bí okoòwò náà yóò ṣe ri, iye èrè ti yóò wà nibẹ̀, owó ti yóò to láti bẹ̀rẹ̀, àti èrèdi ti o fi fẹ́ ṣe iṣẹ́ náà.
Bi a ko ba ni gbagbe, ni orilẹ-ede Naijiria naa lo ti ṣẹlẹ ri ti ọkan lara awọn osisẹ ajọ to n se idanwo si ile ẹkọ giga fasiti nibẹ, JAMB ti kede faye gbọ pe ejo mi miliọnu mẹrindinlogoji Naira owo ajọ JAMB to wa ni ipamọ ọfiisi naa ni ipinlẹ Benue lorilẹ-ede Naijiria.
Loju opo Twitter kaakiri, ero ọkan awọn alatilẹyin ẹgbẹ mẹtẹta, Man U, Liverpool ati Man City a ma farapera ti wọn a si tun ma yapa si ara wọn Laago mẹjọ alẹ oni ni gbangba yoo dẹkun ti kedere yoo bẹẹ wo.
Àwọn wolii ati àwọn olùkọ́ wà ninu ìjọ tí ó wà ní Antioku.
Dino vs Adeyemi: Ìyàwó ni Adeyemi lágbo òṣèlú lọ́jọ́kọ́jọ́
Ayẹwo iwe ẹri: o ni ohun ti o tun ṣe pataki ni lati mọ boya lootọ ni awọn eeyan yii ni iwe ẹri ti o fi ṣọwọ si wọn.
A jẹ́ pé mo kí gbogbo yín ẹkú ọjọ́dọ́gba àná o!
Ìninilára ń gorí ìninilára,ẹ̀tàn ń gorí ẹ̀tàn,OLUWA ní, “Wọ́n kọ̀ wọn kò mọ̀ mí.
Mo mọ wí pé àwọn ọmọ orílèèdè yii n kẹ ìrora ṣugbọn ariwo won ko ti lagbara dé ibi kí wọn mu iyipada wa.
Nigba ti orilẹede Naijiria gbe eto PEWASH rẹ kalẹ lọdun 2016, ida mẹtadinlọgọta ninu ọgọrun, 57% awọn olugbe igberiko lo lanfani si omi to mọ, ti ida mọkandinlọgbọn ninu ọgọrun si ni anfani si ohun elo igbsnsẹ eyi si kere si agbajọpọ apapọ orilẹede Naijiria ni ọdun to ṣaaju rẹ.
Lasiko to n ba BBC Yoruba sọrọ, Ikimot ní kẹ́kẹ́ Marwa ni obinrin kan fi ji oun gbe salọ, nigba ti oun n pada bọ lati ile ẹkọ ni Ebute Mẹta.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Oyo NURTW: Tokyo ló kọ́kọ́ bá Auxillary sọ̀rọ̀ lẹ́yìn ọdún gbọọrọ 18 Ẹrẹ̀nà 2019 Oríṣun àwòrán, Tirbune Arẹmaja kan ko si, ajamarẹ ni ko sunwọn.
Dino ṣalaye pe lọpọ igba ni igbe aye oun ko dan mọran laarin ọdun marun to kọja yii debi pe oun fẹẹ le gbẹmi ara oun.
Gba ẹ̀mí mi lọ́wọ́ idà,gbà mí lọ́wọ́ àwọn ajá!
Ritual killer: Ọwọ́ ọlọ́pàá tẹ ọkùnrin tó gé akẹ́kọ̀ọ́ ọ̀rẹ́bìnrin rẹ̀ wẹ́lẹ́ wẹ́lẹ́ fún òògùn owó ní Ikorodu
''Iwa aibikita aarẹ yii kọja bo ṣe yẹ lọ'' ''Ki aarẹ sọrọ lori awọn iṣoro ti awọn araalu n la kọja ti ogun tabi oun ti awọn eniyan yoo ma bẹbẹ fun.
Ajimobi coronavirus: Àwọn èèyaǹ jàǹkàn mérin tó ti jẹ́ Ọlọrun nípè nítorí àrùn Coronavirus ní Naijiria
 Awon agbaboolu tuntun bi: Kalu, Simon Chukwueze, Victor Osimhen n se dara pupo, eleyi ti o si n ron iko yii lowo,”Bi o ti le je pe, olukoni ohun si n wa agbaboolu owo iwaju miiran ti o tun danto si, sugbon inu re si dun pupo fun awon agbaboolu ti o wa nile fun lati lo.
Bákan náà ni Ogun Majek nílò iranlọwọ owó láti fi tọju ara rẹ, ko le bọ lọwọ àìsàn náà.
"Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ọgbà ẹ̀wọ̀n ni wọ́n ti já àbálé Esra lábẹ́ àwáwí àyẹ̀wò wúndíá Ganduje ni: ""Nitori naa mo gbe igbesẹ oogun ti Jonathan gbe lati doola ilana ati eto Ọba jijẹ ni Kano, mo si lo o daadaa."
Minisita fun eto iroyin ni orilẹ-ede Ghana, Kojo Oppong Nkrumah sọ pe Aarẹ Nana Akufo-Addo yoo jiroro pẹlu Aarẹ Muhammadu Buhari, lati yanju ọrọ naa ni tubi-inubi.
Ó pàṣẹ, ìjì líle sì bẹ̀rẹ̀ sí jà,tóbẹ́ẹ̀ tí ìgbì omi fi ru sókè.
Koda, awọn aladugbo wọn gan mọ nipa isẹlẹ naa, ti wọn si dide lati ran ọkunrin naa lọwọ.
Yóo mú kí koríko dàgbà ninu pápá fún àwọn ẹran ọ̀sìn yín, ẹ óo jẹ, ẹ óo sì yó.
Oríṣun àwòrán, Others Ọba Oluwadare Adepoju Adesina, Deji tilu Akurẹ: Isẹlẹ irọloye Ọba Oluwadare Adepoju Adesina ko tiẹ jinna rara.
Nígbà tí wọ́n bà á jẹ́ tán, ó kúrò lọ́dọ̀ wọn pẹlu ìríra.
Ẹ̀ ń hùwà wọ̀bìà, ìfẹ́kúfẹ̀ẹ́, ìmutípara, ayé ìjẹkújẹ, ìmukúmu ati ìbọ̀rìṣà tí ó jẹ́ èèwọ̀.
Asoju Olukunle Bamgbose n feyinti leyin odun márùndínlógójì ti o lo, lenu  ise ijoba, ni ajo naa.
Ní ọdun 1992 lásìkò tó wà Fasiti, o sááju àwọn akẹ́ẹ̀kọ́ ẹgbẹ́run mẹ́jì nínú ìwọde ìfẹ́honuhan lodi si ìjọba Naijiria àti àwọn asíwájú tí wọ́n ń wuwa ajẹbanu.
Oholiabu yìí mọ iṣẹ́ ọnà gan-an.
Abileko Taiwo Gabriel ti ni awọn dokita, nọọsi ati awọn onisẹ abẹ lo fi iya jẹ oun lasiko ibimọ ni ipinlẹ Eko.
Oríṣun àwòrán, Adebayo Adelabu/Facebook Àkọlé àwòrán, Adelabu ti figba kan jẹ igbakeji gomina banki apapọ Nigeria, CBN.
Àwọn eniyan yóo ṣẹ́kù tí yóo wá láti Jerusalẹmu àwọn tí wọn yóo sá àsálà yóo wá láti orí òkè Sioni.
Obirin naa to jẹ iya ọmọ kan sọ pe yoo pẹ diẹ ki wọn to pin ya pata-pata nitori pe wọn jọ bimọ pọ.
Ere ni, awada ni, wọn wa ọmọ naa titi, ti ilẹ fi su, amọ wọn ko ri eegun tii jẹ Ajikẹ, iya Adediwura sunkun titi, oju ni oun ko ran-an nisẹ.
Ó bá pe àwọn ọmọ-ọ̀dọ̀ rẹ̀ mẹ́wàá, ó fún ẹnìkọ̀ọ̀kan wọn ní owó wúrà kọ̀ọ̀kan.
 ami-isoju fun nomba ni an pe ni aminomba ( numeral ) .
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Obateru Akinruntan: Wíwá ohun tá jẹ títí láé ló gbé wa kúrò nílé Ife O gba ẹbun to le ni ọgọta miliọnu Naira, ọgbọn naira lo jẹ ẹbun owo, ẹgbẹ marundinlọgbọn naira ni moto bọginni Innoson ti wọn gbe fun, bakan naa lo rinrin ajo lọ Dubai pẹlu awọn miran.
"Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ẹ wo ọba kan nílẹ̀ Yorùbá, tí kò ṣe ètùtù tàbí náwó ànájù, kó tó jọba ""Olórí àwùjọ tó ń fi eékà ilẹ̀ pààrọ̀ fún màálù torí ìnáwó ló jẹ́ ki darandaran rọ̀wọ́ mú"" Mo ti ní ìyàwó àfẹ́sọ́nà, ayẹyẹ ìgbeyàwó mi ń bọ̀ láìpẹ́ - Lateef Adedimeji Dókítà 66 síṣẹ́ abẹ fún ìbejì tó lẹ̀pọ̀ nílé ìwòsàn fasiti Ilorin Awọn igbesẹ to le mu ki ọmọ ale wọnu idile lai jẹ pe iyawo yan ale: Ayẹwo fun mọlẹbi ti DNA wọn bara mu: DNA tẹgbọn-taburo tabi ti baba ati ọmọ lee sunmọ ara wọn tabi ko jẹ nkankan naa."
Gẹgẹ bi iwe iroyin Vision Newspaper ṣe jabọ, Roman Kato ati Raiding Wasswa n ṣere ninu ọgba ile wọn ni lasiko ti iṣẹlẹ aburu yii waye.
Ṣé a óo ṣẹ̀ṣẹ̀ tún bẹ̀rẹ̀ láti máa ṣe àpèjúwe ara wa ni; àbí a nílò láti mú ìwé ẹ̀rí tọ̀ yín wá tí yóo sọ irú ẹni tí a jẹ́ fun yín, tabi kí á gbà lọ láti ọ̀dọ̀ yín?
Agbẹnusọ fun aarẹ Muhammadu Buhari, Garba Shehu ninu atẹjade kan sọ pe, ki awọn eeyan dẹkun ati maa so iṣẹlẹ naa mọ aarẹ lọrun, nitori ko mọ ohunkohun nipa bi ọrọ naa ṣe ṣẹ.
Lataari ipa ribiribi ti iko Super Eagles ko ninu olokan-o-jokan ifesewonse ipegede fun idije agbaye naa, ti  o fi mo awon ifigagbaga olorejore won pelu Argentina ati Poland eleyi ti iko ohun jawe olubori, Balogun wa so pe, ki okun awon agbaboolu pe yoo ran iko naa lowo pupo lati saseyori ninu idije agbaye ohun.
Wọ́n ń sá fún idà,wọ́n sá fún idà lójú ogun.
Nigba ti ijọba Fatimid da wo lọdun 1168,, A.
ajọ naa ni eka ti ajo ohun pe ni (UNAMID),
Ọlọrun ti yan àwọn mẹ̀kúnnù ayé yìí láti jẹ́ ọlọ́rọ̀ ninu igbagbọ ati láti jogún ìjọba tí ó ti ṣe ìlérí fún àwọn tí ó fẹ́ràn rẹ̀.
Oríṣun àwòrán, Nigeria police Àkọlé àwòrán, Ǹjẹ o yẹ kí èèyàn máa sùn lẹ́nu iṣẹ́?
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ọmọ Yoruba ni mi Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Ipinlẹ Ondo Gomina ipinlẹ Ondo, Oluwarotimi Akeredolu ti fi da awọn asaaju ile ijọsin loju wi pe oun yoo ṣe ipade pẹlu wọn lati jiroro lori bi awọn ile ijọsin naa yoo ṣe bẹrẹ pada.
Kí eniyan burúkú fi ọ̀nà ibi rẹ̀ sílẹ̀,kí alaiṣododo kọ èrò burúkú rẹ̀ sílẹ̀,kí ó yipada sí OLUWA,kí OLUWA lè ṣàánú rẹ̀.
Ó ti wọ inú yàrá tí ó wà ninu, lẹ́yìn aṣọ ìkélé, 
09 % gẹ ́ gẹ ́ bí ìkúnnú ojúọ ̀ run ayé .
Ìdúnàdúrà ṣì n lọ láti dóòlà ọmọ Ọffa mẹ́fà lọ́wọ́ ajínigbé- ODU Shittu tun sọrọ lori ọna iṣejọba aarẹ Buhari lasiko yii ati awọn igbesẹ aarẹ lori ikọlu awọn ọmọ Naijiria ni orilẹ-ede South AfricaÀwọn ọ̀dọ́ kan ń ṣèwọ́de láti pè fún lílé àwọn àjòjì kúrò ní South Africa.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Justice for Richard: Òbí àkẹ́kọ̀ọ́ tó kú síléeṣẹ́ ọṣẹ ń bèèrè fún ìdájọ́ lórí ikú ọmọ wọn Fidio oke yii ni ọrọ baba ati iya Richard Gbadebo pẹlu BBC yoruba.
Kí alaafia ati àánú Ọlọrun kí ó wà pẹlu gbogbo àwọn tí ó bá ń gbé ìgbé-ayé wọn nípa ìlànà yìí, ati pẹlu àwọn eniyan Ọlọrun.
O jẹ ko di mimọ pe oun wọ iṣẹ ninu iṣẹlẹ ibanujẹ ati eyi to da yatọ.
Oludari agba ohun, Dokita Edu wa lo anfaani naa lati ro ijoba apapo ati ijoba ipinle lati dojuko awon isoro pe-pee-pe ti o n koju awon agbegbe abele lolokan-o-jokan lati pese awon ohun amayederun fun awon agbegbe ohun nipase sise amulo awon eka ke-kee-ke ile-ise to n pese eto ilera ofe fun awon ara ilu (Primary Healthcare Centres, PHCs)E faaye gba igbe-aye alafia
  Awon olukopa lati orile ede Afirika
 aso jé kí o dà bí obìnrin dáadáa.
Amọ Gomina ipinlẹ Katsina sọ pe ẹgbẹ Miyetti Allah ko ipa ribiribi ninu idunadura ti wọn fi doola ẹmi awọn akẹkọọ naa.
Àwọn ati àwọn ìjòyè wọn, ati àwọn ará Juda ati ará ìlú Jerusalẹmu yóo máa gun ẹṣin ati kẹ̀kẹ́ ogun wọlé.
Ṣugbọn oore-ọ̀fẹ́ Oluwa wa pàpọ̀jù lórí mi, ati igbagbọ ati ìfẹ́ tí a ní ninu Kristi Jesu.
Tinubu ni igbesẹ yii n ṣakoba fun ẹgbẹ oṣelu APC, bakan naa lo n ṣe ipalara fun iṣejọba Aarẹ Muhammadu Buhari.
''Aláàfin kìí ṣe ọkùnrin tí wàá jẹ lásán, tó sì wá sálọ - Aráàlú fèsì fún Olorì Anu Olorì Aláàfín tẹ́lẹ̀, Anuoluwapo Adeyemi gba àmì ẹ̀yẹ lórí ipa tó kó nínú oge ṣíṣe Ṣé lóòtọ́ ni olorì méjì míì tún ti kúrò láàfin Oyo?
É ó rantí pé Obasanjo ti kó àwọn ẹgbẹ atúnlùúṣe kan sọ̀dí pẹ̀lú èròǹgbà láti ríi pé ìjọba míràn wọlé ní 2019.
Ayederu iroyin maa n tankalẹ nitori pe wọn maa n ni ipa lori bi ihuwasi wa yoo ṣe ri.
N kò rin ọ̀nà ibi kankan,kí n lè pa òfin rẹ mọ́.
Modekai mú un sọ́dọ̀ bí ọmọ ara rẹ̀, lẹ́yìn tí baba ati ìyá rẹ̀ ti kú.
Liverpool ṣubú dàánù ní Napoli Tani yóò gba ife ẹ̀yẹ UEFA Champions League ti saa yi?
Awọn ẹrọ amuna wa naa yoo wa dipo awọn daku daji tokunbọ tabi aloku to n da ẹmi awọn eeyan legbodo bii ni akoko ti wọn ba n ṣe iṣẹ abẹ 'Ohun tó ṣẹlẹ̀ sí Ezekwesili kò le ṣẹlẹ̀ sí mi' #BBCNigeria2019 Tani Ọjọgbọn Mahmood Yakubu ti yóò ṣètò ìdìbò 2019?
Tone marks: Ṣé ẹ̀yin lè ṣe jú àwọn tó f'àmì sí Awọlumatẹẹ?
Ìjọba ti buwọ́lu lílo hijab láwọn iléèwé ní ìpínlẹ̀ Osun Ọwọ́ ọlọ́pàá ti tẹ afurasí mẹ́ta tó lọ́wọ́ nínú ìjínigbé alága Iganna l'Oyo Wo ọ̀nà àbáyọ fún àwọn akẹ́kọ̀ọ́ tí àjọ WAEC gbẹ́sẹ̀ lé èsì ìdánwò wọn A ó ṣèrànwọ́ fáwọn ẹbí ọlọ́pàá tó bá rògbòdìyàn EndSARS lọ láti inú N500m tí a yà sọ́tọ̀- Makinde Ṣugbọn Adajọ ọhun fi kun un pe o lee san owo itanra ti iye rẹ to N150,000 dipo ko lọ fi aṣọ penpe roko Ọba.
Gẹgẹ bi eto idibo ọdun 2019 ṣe
Ọrọ yii jẹ yọ lẹyin ti ẹlẹsẹ ayo Pierre-Emerick Aubameyang koro oju nigba ti wọn parọ rẹ ninu ifẹsẹwọnsẹ Arsenal pẹlu ẹgbẹ agbabọọlu Newcsatle lẹyin ti Aubameyang kuna lati fakọyọ ninu ere bọọlu naa.
Bo tilẹ jẹ pe awọn mẹsan an ti ri iwosan, awọn kan ti jẹ Ọlọrun nipe nipe nitori arun naa.
Ṣugbọn kò rí bẹ́ẹ̀, arakunrin mi ló jọba, nítorí pé bẹ́ẹ̀ ni ó wu OLUWA.
Davido àti Chioma aya rẹ̀ ti d'ọ̀rẹ́ padà ní Instagram Produced by: Joshua Akinyemi Èyí tí a wò jùlọ 5:03 Fídíò, Omolola Arohunmolase Welder: Mo ti fí iṣẹ́ 'Welder' gbayì láwùjọ, tó mo fi tọ́ ọmọ yanjú, Duration 5,039 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 5:39 Fídíò, Akomolede ati Asa lori BBC: Olùkọ́ Kikelomo Ogunboye tan ìmọ́lẹ̀ sí ìwà olè ọ̀gá ọlọ́pàá Audu gẹ́gẹ́ bí àwòkọ́ṣe àsìkò yìí, Duration 5,398 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 4:11 Fídíò, Oba Adeyeye Ogunwusi: Ojú mi ti rí lọ́pọ̀ lọpọ̀, ọ̀pọ̀ èèyàn ni kò tilẹ̀ gbàgbọ́ pé mo lè jọba- Ooni, Duration 4,117 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 4:43 Fídíò, Promise Akinlade: ọmọ ọdún mọ́kànlá tó ń fi ìlù dárà bíi àgbàlagbà sọ̀rọ̀ nípa tálẹ́ǹtì rẹ̀, Duration 4,437 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 0:59 Gbọ́, Ìsẹ̀lẹ̀ jákèjádò orílẹ̀èdè àgbáyé láàárín ìṣẹ́jú kan, Duration 0,59wákàtí 5 sẹ́yìn 7:03 Fídíò, Olumuyiwa Bolade Adedeji Military Bruitality: Bí arákùnrin onípèníjà ara tí sọ́jà lù ṣe dé, Duration 7,035 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 4:45 Fídíò, Yoruba Films: Ẹ̀ẹ́ bẹ̀ mi kúrò láyé ni, mi ò lè kú - Fadeyi Oloro, Duration 4,4526 Èrèlè 2020 2:48 Fídíò, Esther Ajayi: Èmi náà ti borí ìṣòro rí ló ń mu mi ṣojú àánú, Duration 2,481 Ògún 2019 6:08 Fídíò, Adebola Ademilua: Àìrísẹ́ ṣè lẹ́yìn ìwé kíkà ló sọ mi dí ìyá onírú, mo dúpẹ́ tèmi, Duration 6,0827 Bélú 2020 2:36 Fídíò, Sotitobire: Ìdájọ́ òdòdò ló fẹsẹ̀ múlẹ̀ lórí ọ̀rọ̀ Pásítọ̀ Sotitobire - Agbẹjọ́rò fún ìjọba, Duration 2,367 Ọ̀wàrà 2020 BBC News, Yorùbá Ìdí tí ẹ fi le è nígbàagbọ́ nínú ìròyìn BBC Ìlànà Lílò Nípa BBC Òfin Àṣírí Cookies Kàn sí.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Aminat Abọdun: Ọ̀pọ̀ èèyàn se ẹ̀yẹ ìkẹyìn fún akọni obìnrin tó lọ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Aminat Abọdun: Ọ̀pọ̀ èèyàn se ẹ̀yẹ ìkẹyìn fún akọni obìnrin tó lọ 10 Ọ̀pẹ̀̀ 2018 Ọjọ manigbagbe ni ọjọ Aiku nilẹ Ibadan nigba ti wọn fi tiyi-tẹyẹ ki Iyalode ilẹ Ibadan, Oloye Aminat Abiọdun pe o digbose.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Cerebral Palsy: àrùn tó n gba omijé lójú ẹni láìnídìí Kinni iwadii na sọ?
Dokita àti Nọ́ọ̀sì fìyà jẹ mí lásìkò tí mò ń rọbí- Alaboyún Ilé-isẹ́ ìpòogùn Johnson & Johnson san biliọnu 8 dọ́là fún ẹni tóògùn gbòdì lára rẹ̀!
Dokita ọhun fi kun pe ti ijọba apapọ ba fẹ kapa arun Coronavirus patapata, niṣẹ lo yẹ ko kede ofin konileogbele kaakiri gbogbo Naijiria.
Ramaphosa so fun egbe oselu nibi iwode kan ti o waye ni ilu Cape Town lojo-Aiku pe, “ mo mo pe, e fe fi enu ko, tori pe, awon eniyan wa n fe ki oro naa niyanju, eyi ti igbimo egbe oselu naa n sise le lori”.
Lẹyin to dupẹ lo ba awọn eniyan sọrọ pe otitọ ni pe aarun coronavirus wa lode.
Loni ọpọ awọn ọmọ orilẹede Naijiria lọpọ awọn ipinlẹ lo lanfani si omi to mọ gaara, ṣugbọn kii ṣe omi ẹrọ ijọba.
Awọn oṣiṣẹ panapana ti wa ni agbeegbe Aguda, Ogba ni ipinlẹ Eko nibi ti ina ti sọ ni irolẹ Ọjọ Eti.
 O wa salaye pe, o se pataki fun omo orilede yii lati ma wadii ohun
Àlàfo àárín yìí sí jẹ ohun tó suniloju di asiko yii èyí sì lè ṣokùnfà aarun miran.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ìtàn rèé nípa bí Ogbomoso ṣe pa ọba, yọ nǹkan ọkùnrin rẹ jó kiri ìlú Háà ilẹ̀ wẹ!
Wọn yóo jẹ́ ìlú ààbò fún àwọn ọmọ Israẹli tabi àwọn àlejò tí ó wà láàrin wọn.
Adari Ajọ LASEMA, Damilola Oke-Osanyintolu lo fi atẹjade naa lede fun awọn eniyan.
Ó wí fún àwọn ẹmẹ̀wà rẹ̀ pé, “Johanu Onítẹ̀bọmi ni èyí.
Ohunkohun tí ó bá ti wà, ó ti ní orúkọ tẹ́lẹ̀, a sì ti mọ ẹ̀dá eniyan, pé eniyan kò lè bá ẹni tí ó lágbára jù ú lọ jà.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Yoruba Staff of Office: Àwọn ọbá aláye ilẹ̀ Yorùbá márùn-ún rèé pẹ̀lú ọ̀pá àṣẹ wọn 26 Ọ̀wàrà 2020 Oríṣun àwòrán, Screenshot Ni ilẹ kaarọ ojiire, ọpa aṣẹ jẹ ohun kan pataki to ni itumọ tir ninu aṣa iran Yoruba to bẹẹ ti pataki rẹ ṣe dede pẹlu ade ori ọba gan funrarẹ tori o wa lara aṣẹ ti ọba ni.
Oríṣun àwòrán, @others Ayajọ iṣejọba Tiwantiwa- ọjọ kejila, oṣu kẹfa Lọdun 2019 ni Naijiria paarọ ọjọ sisami ayajọ awa ara wa to maa n waye lọjọ kọkandinlọgbọn, oṣu karun un ọdun.
Jesu sọ fún un pé, “Bí o bá fẹ́ ṣe àṣepé, lọ ta dúkìá rẹ, kí o pín owó rẹ̀ fún àwọn talaka; o óo sì ní ìṣúra ní ọ̀run.
World Food Day: Wo àwọn oúnjẹ ìṣẹ̀mbáyé Yorùbá tó ti ń di àpatì Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fọ́nrán ohùn, Sajẹ: Mo n rọ awọn akẹẹgbẹ mi lati se suuru de asiko Ọlọrun Òṣèré tíátà, Kemi Afolabi fi ohùn ìdúpẹ́ ránṣẹ́ láti Meccah fún àdúrà ọmọ Nàíjíríà Ẹ lọ́ jáwé gbé jẹ́ẹ́ sọ́wọ́ bí bẹ́ẹ̀ kọ́.
Èmi kò tó ẹni tíí tú okùn bàtà rẹ̀.
Olowo marun un lorilẹ-ede Naijiria ni owo to to san owo isunna lorilẹ-ede Naijiria.
"Tí ẹ bá wo orílẹ̀ èdè Ghana, ó ní ọ̀nà tí ìjọba ń gba láti dènà ifarakinra.
Ehudu bá tọ̀ ọ́ lọ, níbi tí òun nìkan jókòó sí ninu yàrá tútù kan, lórí òrùlé ilé rẹ̀, ó wí fún un pé, “Ọlọ́run rán mi ní iṣẹ́ kan sí ọ,” ọba bá dìde níbi tí ó jókòó sí.
‘Kí ni o fẹ́ máa ṣe níhìn-ín?
Alákọ̀wé ti gba òmìnira kúro ní   Ẹ súré tete lọ sí 
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Facebook love: Ọla àti Folashade ṣègbéyàwó lẹ́yìn ọjọ́ mọ́kànlá tí wọ́n ríra ni Facebook 2.
Eyi ko ṣẹyin idajọ ile ẹjọ to fagilẹ iyansipo awọn Emir tuntun mẹrin miran, ati wi pe ijọba ipinlẹ naa ko tẹle ọfin ipinlẹ naa ki wọn to yan Emir tuntun.
Ènìyàn 216 ló ní àrùn Coronavirus ní Ọjọ Ajé Orilẹede Naijiria ti ni eniyan mẹrindinlogunlenigba lo tun ṣẹṣẹ ni arun Coronavirus ni Naijiria.
Mo ti kopa ninu awọn ọpọ sinima, ti mo si tun n ṣiṣẹ takuntakun bayii ninu isẹ tiata, ti mo si ti n po sinima kan pọ, ti ko ni pe jade sita bayii."
Kùrù-kẹrẹ Coronavirus ṣeéṣe kó dópin láàrín ọdún méjì - WHO Oríṣun àwòrán, Police Ó ni ǹkan tó ṣe pàtàkì jùlọ ní pé ojú méjéjì ni ọlọ́pàá fí n wá ọmọkunrin náà ki àṣírí gbogbo àwọn to wu ìwà ìbàjẹ́ náà láàrín àwọn ọlọ́pàá baà le tú.
Eyi lo mu ki awọn kan ma sọ pe, o ṣeeṣe ki o ti ko arun Covid-19 ṣugbọn a ko ti fidi ọrọ yi mulẹ.
Fún ìdajì ọdún meje náà, yóo fi òpin sí ẹbọ rírú ati ọrẹ.
Bẹ́ẹ̀ ni ó tún sọ níbòmíràn pé, ‘O kò ní jẹ́ kí Ẹni ọ̀wọ̀ rẹ mọ ìdíbàjẹ́.
Oríṣun àwòrán, AFP Àkọlé àwòrán, Iṣẹlẹ yi waye nipinlẹ Borno lọsẹ ti o pe ọdun mẹwaa ti Boko Haram bẹrẹ si ni ṣoro ni Naijiria.
ati àwọn ẹran ọ̀sìn yín, ati àwọn ẹranko ìgbẹ́ tí wọ́n wà ní ilẹ̀ yín, gbogbo èso ilẹ̀ náà yóo sì wà fún jíjẹ.
Lateef Adedimeji: Nkan tí a mọ̀ nìyíì nípa ìgbéyàwó tí Lateef àti Adebimpe Oyebade
Oríṣun àwòrán, NIGERIAN GOVERNMENT L'ọjọ naa ni Aarẹ Buhari pada sile ijọba nibi ti wọn ti bẹrẹ ayẹyẹ igbeyawo Damilọla Ọsinbajo, to jẹ ọmọ igbakeji Aarẹ, Yẹmi Ọsinbajo.
Àfẹ́sọ́nà Davido, Chioma nàá ti ní ààrùn Coronavirus Fíímù ṣíṣe dáwọ́ dúró, Joke Muyiwa di 'grandma', Lizzy Anjorin sọ pé coronavirus ko gbọdọ̀ díwọ́ ọjà títà Ìjọba ìpínlẹ̀ Eko bẹ̀rẹ̀ pínpín oúnjẹ fún àwọn èèyàn lásìkò ìgbélé Coronavirus Arabinrin Nnenna ni bi o tilẹ jẹ wi pe omi ti awọn n mu ko dara fun mimu, awọn ko i ti ni aisan nipa mimu omi naa ri.
 Asofin Enyinnaya Abaribe,okan ninu awon omo ile lo side oro lori koko yii ninu ipade won.
Oríṣun àwòrán, @MBuhari O wa rawọ ẹbẹ sawọn ọdọ to n sewọde lati fi orukọ eeyan meji silẹ, ti yoo soju wọn ninu igbimọ oluwadii ti ijọba gbe kalẹ lori ẹhonu wọn.
Àwọn onigbeeraga ń kẹ́gàn mi gidigidi,ṣugbọn n ò kọ òfin rẹ sílẹ̀.
Ademola Adeleke to dupo  gomina  labe asia egbe oselu Peoples Democratic Party
Àwọn yìí ni ó gbọ́ ọ̀rọ̀ náà, tí wọ́n gbà á, tí wọ́n sì so èso, òmíràn ọgbọọgbọn, òmíràn ọgọọgọta, òmíran ọgọọgọrun-un.
Khadijat Oluboyo n mura lati jade fasiti ni ile iwe giga fasiti Adekunle Ajasin ni Akungba Akoko ni ipinlẹ Ondo, ki o to jade laye.
Lai Mohammed: Kò sí ohun tó burú nínú kí ìjọba yá owọ láti fi ṣe àwọn ohun amáyédẹrùn
Àkọlé àwòrán, ICPC: Ìwádìí ti pari lóri iwe ẹ̀ri ayéderun Kemi Adeosun Agbẹnusọ fún ICPC, Rasheedat Okoduwa sọ̀rọ̀ sàlàyé pé àwọn dáwọ́ ìwádìí náà dúro kó máa dí ọ̀nà méjì.
Ẹ le tẹ ibi yii lati dibo.
Gbogbo àwọn aṣẹ́wó ọkunrin tí ó kù ní ilé àwọn oriṣa láti àkókò Asa, baba rẹ̀, ni ó parun ní ilẹ̀ náà.
Eyi waye lẹyin ti rogbodiyan waye laarin awọn akẹkọọ kan nileewe naa.
Samuel Eto o fi búùtù bọ́ọ̀lù rẹ̀ kọ́, Ó ní òun kò gbá bọ́ọ̀lù mọ́ Egbé agbábọọlù Super Eagles gbàgbé ohun eèlò wọn - Ọlajiire Alexis Sanchez: Mí o kabamọ ìgbà tí mo ló ní Man United Sanusi wọ gau torí pé o kọrin bù Gómìnà Ganduje Báyìí ni ayẹyẹ wíwé láwàní Mike Zhang ọmọ China ṣe lọ Koda, o dara pọ mọ ikọ Super Stars lasiko tawọn akẹgbẹ rẹ n sinmi, ti o si mu ki wọn mọ wi pe ẹlẹsẹ ayo ni Salisu.
    Ẹ̀yin ọ̀rẹ́ mi, ọba náà kòì tíì sọ jù báyìí lọ àfi ìgbà tí ẹnìkan déedée kígbe, ‘ó dé, ó dé, obìnrin náà tún dé o!
Eyi ni bi iko naa se sajoyo jijawe olubori ohun.
Amọ, ipinlẹ mọkanla ni iha ariwa orilẹede Niajiria ni ko i tii sọ di ofin.
Idajọ naa si lo kọ amọ Naijiria lominu, paapaa nitori fidio kan to lu ayelujara pa lori bi Sẹnatọ Abbo se fiya jẹ obinrin ontaja kan, OsimibibraWarmate.
Ẹwẹ, lọna miran, gomina tun ti fọwọ si ṣiṣe pasiparọ awọn kọmiṣọna meji mii ni ipinlẹ Oyo pe ki wọn parọ iṣẹ ara wọn.
7 15272 Orilẹede Mozambique 211 0.
Wo nkan tó yẹ́ kí o mọ̀ nípa Adeyinka Godson tó fún ẹ̀yà Igbo ní wákàtí 48 láti kúrò nílẹ̀ Yorùbá Ẹni tó jí ọ̀pá aṣẹ ń bọ̀ wá túbá fúnrarẹ̀, mo fi dáa yín lójú gẹ́gẹ́ bí ìyá - Erelu Kuti Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Egbò tó ti fẹ́ẹ̀ jiná ni ìtàn bí wọ́n ṣe pa Soun Ogbomoso, Ọba Olayode tẹ ń bèrè' Ọ̀nà láti sọ ọ̀rọ̀ ajé ilẹ̀ Yorùbá di akúrẹtẹ̀ ni àwọn ìkọlù tó wáyé ní Eko - Àwọn gómìnà Oríṣun àwòrán, twitter/Gboyega Akosile Awọn gomina kan ni ẹkun Iwọ-oorun Gusu Naijiria ti ṣe abẹwo ibanikẹdun si gomina ipinlẹ Eko, Bababjide Sanwo-Olu.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Art Exhibition: Ṣé ẹ láwọn ọ̀dọ́ kò mọ Àṣà ni, ẹ wo itú t'ọ́mọ ọdún mẹ́rìndílógún kan ń pa Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Art Exhibition: Ṣé ẹ láwọn ọ̀dọ́ kò mọ Àṣà ni, ẹ wo itú t'ọ́mọ ọdún mẹ́rìndílógún kan ń pa 6 Bélú 2019 Gbigbe aṣa Yoruba larugẹ ti di ohun to n jẹ awọn ọmọ kaarọ o jiire logun bayii to bẹẹ tawọn ọdọ ko gbẹyin.
Àwọn ọmọ ati àwọn ọmọ ọmọ wọn sì ń ṣe bẹ́ẹ̀ títí di òní olónìí.
Arẹbẹsọla wa sapejuwe iwa alaafia gẹgẹ bii ipilẹ rere fun ọrọ aje ati idagbasoke oselu nitori ko si idagbasoke kankan to lee waye lasiko ogun.
 Ìtọ ́ jú ( iṣẹ ́ abẹ ) ni kí a lò tí ipin yìí bá lágbára tàbí tí ẹyin ojú bá fẹ ́ bàjẹ ́ .
"Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Kò sáyè iwọ́de mọ́ l'Eko ẹ lọ tọwọ́ yín bọṣọ - Ọlọ́pàá Ìwọ́de #EndSARS rán èèyàn méjì sọ́run n‘Ibadan, Seyi Makinde da ikọ̀ Operation Burst sígboro N kò ní buwọ́ lu ìṣúná tí kò pèsè owó fún ẹ̀bí àwọn tó kú nínú ìwọ́de EndSARS - Gbajabiamila ""Ẹ ràn wá lọ́wọ́ láti rí àwọn ẹlẹ́wọ̀n tó sálọ ní Oko àti Benin padà"" Ìwọ́de EndSARS ló ń sọ pé inú ń bí àwọn ọ̀dọ́, ìjọba, ẹ náání wọn - Obasanjo Ẹni iyì àti akíkanjú tó ṣe gbẹ́kẹ̀lé làwọn èèyàn Akure, ilú ìyá mi - Seyi Makinde Ẹ̀yin ọ̀dọ́ ti rí èrè ìwọ̀de yín lórí EndSARS àmọ́ ẹ ṣọ́ra, kẹ má baà sọ èrè náá nù - Tinubu Owó ìrànwọ́ Covid-19 dé, ìjọba fẹ́ san ₦75bn fún 54,000 olókoòwò Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Kété tí wọ́n bá ti báa yín sùn tàn torí pé ẹ tóbi, ẹ gbà pé ìfẹ́ yẹn ti parí - Auntie Remi Ọlọ́yàn ńlá Bakan naa ni NUJ tun kesi ọga agba ọlọpaa pata loriẹede yii lati fopin sawọn iwa ifiyajẹni ti wọn n se sawọn akọroyin."
Bí onigbagbọ obinrin kan bá ní àwọn opó ninu ẹbí rẹ̀, òun ni ó níláti ṣe ìtọ́jú wọn.
Bagudu ni owo iranwo ti won koko bowolu lati fi ranse si awon
gbogbo eniyan ni yóo ṣègbé,tí wọn yóo sì pada di erùpẹ̀.
Solomoni ọba bá pàṣẹ fún Bẹnaya, ọmọ Jehoiada, pé kí ó lọ pa Ṣimei; Bẹnaya bá jáde lọ, ó sì pa á.
O kudiẹ ki ipele akọkọ ere bọọlu naa pari ni Willian gba pẹnariti wọle fun Chelsea eyi to mu wọn ṣiwaju ninu ifẹsẹwọnsẹ naa.
Àwọn ọmọ Jafẹti ni Gomeri, Magogu, Madai, Jafani, Tubali, Meṣeki ati Tirasi.
Oríṣun àwòrán, Getty Images ''Ilẹ Afrika n lewaju laarin awọn ilẹ agbaye gẹgẹ bi ibi ti oṣi oun iṣẹ ti n peleke.
baba re jagun pelu ile-ise adigun ile fransi nigba ogun agbaye keji , awon nazi si timole .
N óo fún ọ ní ohun tí o kò tilẹ̀ bèèrè.
marun-un fún àwọn ti ẹ̀gbẹ́ àríwá, marun-un fún àwọn tí wọ́n wà lẹ́yìn, lápá ìwọ̀ oòrùn àgọ́ náà.
O salaye pe, a ti n wo akoko ojo bayii, pupo awon agbe ni won si wa nipago awon asafogun, pelu iberu bojo ikolu latodo awon daran-daran.
Ṣugbọn ọpọ lo ṣeyawo lai ti to awọn ọdun yii.
Ọmọ ọdún mẹjọ ni Josaya nígbà tí ó jọba, ó sì wà lórí oyè ní Jerusalẹmu fún ọdún mọkanlelọgbọn.
Bi awọn ṣe n sọ pe o yẹ tabi ko yẹ ki Olamilekan san owo ori, lawọn miran n jiyan lori iye owo ori ti Laycon jẹ gangan.
Lóòótọ́ àwọn ara ayé ni òye púpọ̀, ṣùgbọ́n kò sí ẹ̀dá náà ní òde ayé tàbí ni òde ọ̀run tí ó mọ ibi tí kọ́kọ́rọ́ ìfẹ́ ìyá sí ọmọ rẹ̀ wà àfi Ọlọ́run Ọba nìkan ṣoṣo.
kíni wọn yóò máa ṣe ní ìpínlẹ̀ - DAWN Commission Àwọn ọmọ Iran yarí mọ́ ìjọba lọ́wọ́ lẹ́yìn tó jẹ́wọ́ pé òun ló já bàálù Ukrain lulẹ̀ Wo Sultan Qaboos bin Said, ẹni tó gbàkóso ìgbé ayé òṣèlú Oman fún àádọta ọdún Ẹ kò nílò nọ́mbà ìdánimọ̀ NIN fún ìdánwò àṣewọlé ọdún 2020 - JAMB Amọ, ijọba lasiko ti wọn n fesi si igbeṣẹ naa ni ọmọbinrin naa ni Hanan ni aṣẹ labẹ ofin lati lo ọkọ ofurufu naa gẹgẹ bi ọmọ Aarẹ orilẹ-ede Naijiria.
"A kó dúnkoòkò mọ́ Ambode, isẹ́ wa là ń ṣe - Ilé Aṣòfin Eko ""Bi mo tilẹ̀ jẹ́ apárí síbẹ̀ kò tìmí lójú"", Liliya Kukushkina Awọn ibi ti o ti ṣiṣẹ Ọjọgbọn Omọtayọ ṣiṣẹ olukọ laarin ọdun 1957 si ọdun 1963."
Wọn kò gbọdọ̀ sọ pé àwọn n pèsè ètò ẹ̀kọ́ ọ̀fẹ́, kì wan sì má pèsè ohun èlò ìkẹ́kọ̀ọ́.
Alápatà lu ìyàwó rẹ̀ pa ní Ogun Ọmọ ẹgbẹ okunkun f'oju ba'le ẹjọ Afunrasi afipajinigbe k'agbako ni Ogun Tọkọ-taya wọ gàù nítorí orúkọ tí wọ́n sọ ọmọ wọn O ni nigba ti wọn si fi ọrọ wa lẹnu wo, o jẹwọ wipe awọn akẹgbẹ oun wa ni Ifo.
Oríṣun àwòrán, OTHER Nkan to fà iṣẹlẹ buruku to sọ awọn idile kan sinu ibanujẹ ko ṣe e sọ ni pato.
Nígbà tí àwọn eniyan rí iṣẹ́ ìyanu tí ó ṣe, wọ́n ní, “Dájúdájú, eléyìí ni wolii Ọlọrun náà tí ó ń bọ̀ wá sí ayé.
Kí gbogbo àwọn tí wọn ń gbé ilẹ̀ náà wárìrì,nítorí ọjọ́ OLUWA ń bọ̀, ó sì ti dé tán.
Mo ra itan àti igbá-àyà adìẹ, pẹ̀lú àwọn amúgbálẹ́gbẹ̀ẹ́ oújẹ kọ̀ọ̀kan, pẹ̀lú ife Pepsi tútù kan.
Lẹ́yìn tí wọ́n ti wa ọkọ̀ bí ibùsọ̀ mẹta tabi mẹrin wọ́n rí Jesu, ó ń rìn lórí òkun, ó ti súnmọ́ etí ọkọ̀ wọn.
Awọn wo ni yoo kopa ni Hajj ọdun yii?
Mo fọwọ́ sọ̀yà pé irúkírú oúnjẹ alátá tí wọ́n bá sè fún mi níbẹ̀, èmi Alákọ̀wé á jẹ ẹ́ láì mu omi kankan sí i.
Bakan naa ni o gboriyin fun ogoro owo ti o n wole latodo awon oludokowo ati awon alagbata oja owo ile-okere, eyi ti o so pe, o ti sokunfa owo ti o le ni bilionu metalelogbon $33 billion lati inu osu kerin odun 2017, nigba ti won se idasile re.
 bí a bá ti se àlàkalẹ ̀ bí a óò se náwo wa yóò dín ìnákùùná kù láwùjọ wa .
Bakanaa ni a maa gbe iwe orukọ ti a tẹ jade le wọn lọwọ pẹlu.
Òun ni mo fi ń yangàn fún àwọn ọ̀rẹ mi kan nílẹ̀ yìí o.
Bukola Saraki kò kọjá òfin - EFCC Saraki gbé N16.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Coronavirus: Ètò Làá hàn mí yìí ló ń kìlọ̀ fún wa láti mú ìmọ́tótó ní pàtàkì, ká le è dènà Coronavirus Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Coronavirus: Ètò Làá hàn mí yìí ló ń kìlọ̀ fún wa láti mú ìmọ́tótó ní pàtàkì, ká le è dènà Coronavirus 3 Ẹrẹ̀nà 2020 Yoruba ni igi gogoro ma gun mi loju, ati okeere laa ti lọ̀, bẹ́ẹ́ si ni ati okeere ni oloju jinjin ti n mu ẹ́kun sun.
“Ohun ti o wa lokan wa ni lati ri I pe idagbasoke ba eto ofin.
Ọpọlọpọ ọmọ Naijiria lo ti fọn si oju opo Twitter lati sọ ero wọn nipa irinajo ti a gbọ pe iyawo aarẹ lọ yii.
abatunde Gbadamosi - BBC News Yorùbá BBC News, YorùbáFò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Joe Igbokwe kò yẹ́ fún ipò ti wọ́n fún un nípìnlẹ̀ Eko - Babatunde Gbadamosi Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Joe Igbokwe kò yẹ́ fún ipò ti wọ́n fún un nípìnlẹ̀ Eko - Babatunde Gbadamosi 21 Ògún 2019 Awuyewuye kò ti i pari lórí àwọn Kọmísọnà àti olubadámọràn pàtàkì tí gómìnà ìpínlẹ̀ Eko, ti Babatunde Sanwo-Olu yàn ní ọjọ Ajé.
A Silva jẹ agbẹjọrò, oun naa si ni Bọbajiro tilu Eko.
Ìkọlù agbébọn tó ṣékú pá ọmọ ogún Niger 89, iṣẹ́ bọ lọ́wọ́ Ọgágun àgbà Kano Governorship: Ilé ẹjọ sún ìgbẹ́jọ Ganduje sí ogunjọ oṣù kíní Abdularahaman, Ọmọ ọdún 17 kó sí páńpẹ́ EFCC lórí ẹ̀sùn yahoo-yahoo ní Ibadan Gomina ologun ni agbegbe Gusu-Ila oorun, Ọgagun Odumegwu Ojukwu, ati ile aṣofin agbegbe naa kede pe agbegbe Guusu-Ila oorun ti yapa kuro lara orilẹ-ede Naijiria, nitori bi wọn ṣe pa awọn eniyan ẹya Igbo ni ipakupa ni agbegbe Ariwa, ati mago-mago eto idibo.
Ṣugbọn awọn oun ti ẹ lẹ má mọ̀ rèé: 1.
Ẹ̀yin eniyan mi tí a ti tẹ̀ mọ́lẹ̀,bí ẹni tẹ ọkà ní ibi ìpakà,ohun tí mo gbọ́ láti ọ̀dọ̀ OLUWA àwọn ọmọ ogun,Ọlọrun Israẹli, ní mò ń kéde fun yín yìí.
Wọ́n pe Lọti, wọ́n ní, “Níbo ni àwọn ọkunrin tí wọ́n dé sọ́dọ̀ rẹ ní alẹ́ yìí wà?
Kí oore-ọ̀fẹ́ Oluwa Jesu Kristi, ati ìfẹ́ Ọlọrun ati ìdàpọ̀ Ẹ̀mí Mímọ́ wà pẹlu gbogbo yín.
Wọ́n jó ibi mímọ́ rẹ kanlẹ̀;wọ́n sì ba ilé tí a ti ń pe orúkọ rẹ jẹ́.
Bí àwọn ẹ̀gbọ́n rẹ̀ ṣe ń kìlọ̀ fún un tó, ṣe ni ó máa ń wa ọrùn kì, tí ó ń kọ etí ikún sí ohun tí wọ́n ń sọ fún un.
Ọkùnrin marun un àti obìnrin mọkanla ni àjọ arannilọwọ ti kìí ṣe tijọba, Bus De Femme, ti gbe lọ sile ẹjọ ni France.
"Ẹ̀yin olólùfẹ́ mi àti ẹbí ni mo bẹ̀ Kemi Olunloyo dá sí ìjà Toyin Abraham àti Lizzy Anjorin Kò sí ọkùnrin tí yóò fún obìnrin tó halẹ̀ bíi tèmi lówó - Lizzy Anjorin Lizzy Anjorin gbàgbé ọ̀rọ̀ àná, ó kí Iyabo Ojo kú ọjọ́ ìbí, Femi Adebayo kọ ọmọ l'áṣà Toyin Abraham kìí bá èmi náà yọ̀, ni kò jẹ́ kí ń gbé e lárugẹ fún ayọ̀ ọmọ - Lizzy Anjorin ""Mo nifẹ igbe aye mi bo se n lọ yii, ti emi ati ẹnikan ba si tahun sira wa, amọ ti ipenija ba de ba a, maa pe onitọun, ti maa si tun se iranwọ fun to ba nilo rẹ."
Mo gbàgbọ́ pé n óo rí oore OLUWA gbàní ilẹ̀ alààyè.
Ó bá wọ inú ọkọ̀ tọ̀ wọ́n lọ, afẹ́fẹ́ bá rọlẹ̀.
ja fun  ẹkunwo ọgbọ̀n ẹ̀gbẹ̀rún fun  awon osise won.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Èyí ni àwọn ìdí tí INEC fi sún ìdìbò aarẹ síwájú Ẹnikẹ́ni tó bá ṣáájú láti jì àpótí ìbò, ẹ̀mí rẹ̀ ló fi ń ṣeré - Buhari Ihalẹ Buhari: PDP na ìká àbuku sí Buhari lẹyìn ìpàdé wọn O ṣeéṣe ki iṣẹ́ bọ́ lọ́wọ́ ọlọ́pàá inú àwòrán 4+4 APC, PDP, CUPP kọ etí ikún sí òfin INEC Àwọn ìgbà tí ẹ̀ṣọ́ aṣọ́bodè ti pànìyàn lọ́nà àìtọ́ Àjọ aṣọ́bodè gba Codeine N200m Iléeṣẹ́ aṣọ́bodè gba nǹkan ìjagun àìtọ́ Ní ọdun 2015, nigba ti gbogbo Naijiria n mura kirakita fun idibo gbogbogbo ninu eyi ti aarẹ igba naa, Goodluck Jonathan ati Muhammadu Buhari jẹ oludije fun ẹgbẹ oṣelu PDP ati APC, Jonathan sọ ọrọ kan to mu iwuri ba ọpọlọpọ: Sugbọn Buhari lo jawe olu bori ninu idibo naa.
mọ ohun ti wọn n ṣeAṣofin
Dokita Faduyile sọ pe eyi gan an le mu ki coronavirus tun bẹ silẹ fun igba keji.
pátá ni yóo gbé jáde kúrò ninu àgọ́, lọ síbìkan tí ó bá mọ́, níbi tí wọn ń da eérú sí, yóo sì kó igi jọ, yóo dáná sun ún níbẹ̀.
 Eleyi ti o tun mo si pe, awon osise jake-jado orile-ede Naijiria yala nile-ise ijoba tabi ti aladani gbodo leto si ogbon ẹ̀gbẹ̀rún(N30,0000) nipari osu.
O óo di àwọn ẹ̀ṣẹ̀ mi sinu àpò,o óo sì bo àwọn àìdára mi mọ́lẹ̀.
Ilé iṣẹ́ ológun Nàìjíríà gbẹ́sẹ̀ kúrò lórí òfin tó de UNICEF Èrò àwọn ọmọ Nàìjíríà ṣọ̀tọ̀ọ̀tọ̀ lórí ọ̀rọ̀ Obi àti Ọṣinbajo 'Àṣà ìgbéyàwó Yorùbá gbàràdá ní Kenya' Ìsèjọba ìgbìmọ̀ asòfin dára ju ìsèjọba ààrẹ lọ -Femi Okunronmu Gold gba awọn ọdọmọbinrin niyanju pé ki wọn tẹramọ ere idaraya eyikeyi to ba wu wọn lati maa ṣe nitori orí lo mọ iṣẹ aṣela ẹda laye.
Ṣugbọn nígbà tí o bá di arúgbó, ìwọ yóo na ọwọ́ rẹ, ẹlòmíràn yóo wọ aṣọ fún ọ, yóo fà ọ́ lọ sí ibi tí o kò fẹ́ lọ.
" Àwọn iléesẹ́ abáni fi ẹrù ránṣẹ bẹ̀rẹ̀ ìyaṣẹ́lódì tako àfikún owó Nipost Agbarijọpọ ẹgbẹ awọn ileesẹ to n báni fi nkan ránṣẹ 'logistics', ti bẹrẹ iyansẹlodi lọjọ Aje.
”Ó sọ fún wọn pé, “Ó tó!
Ní tèmi, mo ti dàgbà, ogbó sì ti dé sí mi.
 Ìwádìí tún fi yé mi pé óní ojú igbá tí òmùtí yìí fi máańmu otí .
Ní ọdún 2001, ó kẹ́kọ̀ọ́ gboyè nínú ìmọ̀ ẹ̀kọ́ Tíátà ní ilé ìwé gíga fásitì ti Eko ó sì dara pọ̀ mọ́ iṣẹ́ Tíàtà lẹ́kùnrẹ́rẹ́ ní ọdún 2006.
Ọjọ́ ìkíní rèé o, a ṣẹ̀ṣẹ̀ bẹ̀rẹ̀.
Orilẹẹde 44 t'ọwọ bọ'we lori AfCFTA AfCFTA: Kini yoo jẹ atubọtan fun Naijiria?
Tí a bá yọwọ́ àwọn ọba alayé kúrò, kò ní sí Nàìjíríà mọ́- Alaafin Oyo Ìlú ò rẹ́rìn ín rárá, Alaafin Adeyemi III fárígá fún Buhari nínú lẹ́tà tuntun Ipa tí mo kó lágbègbè mí lásìkò ìwọ́de EndSARS ló dènà làásìgbò - Alaafin Ọmọ ti lọ kí baba, Fayemi bẹ Aláàfin wo l‘Ọyọ, wọ́n jírórò lórí lẹ́tà O tun kọ lẹta mii to pe ni Ominira awọn obinrin: Nkan ti ko wọpọ nilẹ Yoruba.
Èmi OLUWA Ọlọrun, ni mo sọ bẹ́ẹ̀.
 Ère ajá ni wọṅ ń sí ojúbọ òrìsà wọṅ .
egbe awon odo, awon olorin ati awon osere ni jake jado orile ede Naijiria.
òkú méjìlá jóná mọ inú mọ́ṣúárì Fásítì OAU 'Ọ̀la la máa mọ̀ bóyá Jonathan tako òfin PDP pé ó gbàlejò APC ní Bayelsa' Kìnìhún tí wọ́n mú l'Eko kìí ṣe ti orílẹ́èdè Nàíjíríà Àwọn jàndùkú dáná sun Aṣáájú obìnrìn ẹgbẹ́ òṣèlú PDP mọlé ní Kogi Àwọn fasiti to ku ni Fasiti Jos ọgọrin mẹrin mílíọnu lé mẹrindinlọgọrun (896) miliọnu), ilé ìwòsàn University College Ibadan (701 mílíọnu) Fasiti Usnman Dan Fodiyo (636 mílíọnù) àti Fasiti Ibadan (558 mílíọnù).
Fasiti Ibadan ti sanmọnti gbe dunlẹ lo ti kawe gboye lọdun 1987 Oríṣun àwòrán, Reuters Àkọlé àwòrán, Aworan to jọju yii lo ṣafihan agba eranko abiwo gaaraga yii to n rẹ oungbẹ ni papa Richmond ni iwọ oorun guusu London.
 Ó bẹ ̀ rẹ ̀ iṣẹ ́ orin wákà kikọ nígbà tí ó ṣe orin tó sọọ ́ di ìlú-mọ ̀ ọ ́ ka tí ó pè àkọ ́ lé rẹ ̀ ní  ' late general murtala ramat mohammed "" , ní ọdún 1976 , lábẹ ́ ilé iṣẹ ́ ( leader records ) ."
 làlà kokofẹ ̀ fẹ ̀ yìí ní ó jẹ ́ kí Ọba ademola ẹ ̀ ẹ ̀ kejì fi orí ìtẹ ́ sílẹ ̀ ní ọdún 1949 .
Ni asiko yii, ọba Adeyemi ko tii gori itẹ awọn baba nla rẹ, ti ko si ti ye rara pe ori ade ni oun bi o tilẹ jẹ pe ọmọ Alaafin ana ni.
Ogbeni Oginga fidi remi ninu eto idibo ti o waye ninu osu kejo odun to koja, eyi ti won fagile latari “kudie-kudie to wa ninu re”.
Ó yẹ kí èyí fihàn ọ́ pé n kò ní ìfẹ́ láti ṣọ̀tẹ̀ sí ọ, tabi láti pa ọ́.
Mo ti pinnu láti kó àwọn orílẹ̀-èdè ati àwọn ìjọba jọ, láti jẹ́ kí wọn rí ibinu mi, àní ibinu gbígbóná mi; gbogbo ayé ni yóo sì parun nítorí ìrúnú gbígbóná mi.
Awọn aba to jọ mọ gbesẹ lati da awọn ileesẹ ti isẹ wọn jọra papọ.
Agbẹnusọ Ile Igbimọ Aṣofin Ipinlẹ Eko, Aṣofin Mudashiru Ọbasa ni o sọrọ yii di mimọ nibi ipade itangbangba lori Abadofin fun ofin lati ṣe idasilẹ Ilana Akọsilẹ awọn oṣiṣẹ Olutọju ni Ile kọọkan ni Ipinlẹ Eko ati awọn ọrọ miiran to nii ṣe pẹlu rẹ.
"Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Mistura Oseni Akintunde: Ara múmú kìí ṣe oríṣun ìfipábánilòpọ̀, ìran àwòjù ló ń fà á ""Ojo n rọ lakọlakọ lọjọ naa, to si nira fun awakọ lati ri ọkankan, koda, a ko lee ri ọkọ to n bọ niwaju, lojiji ni tirela kan sadede rọ lu ọkan lara awọn mọto wa."
Bakan naa ni awọn dokita naa ni ọpọlọpọ awọn nkan ti o lemu iṣẹ wọn dẹrun ni ko si nile iwosan naa.
Gbogbo ayé yóo sì mọ̀ pé Ọlọrun wà fún Israẹli.
 “Awon omo egbe to ba wa ni ipinlẹ ti won yoo
ati àwọn arakunrin wọn tí wọ́n jọ ṣe iṣẹ́ ilé náà, wọ́n jẹ́ ẹgbẹrin lé mejilelogun (822).
Oúnjẹ náà wà ní ọlọ́kanòjọ̀kan, bótilẹ̀jẹ́pé ìjẹkújẹ oní ṣúgà la rí jẹ lọ́jọ́ náà.
nítorí Hẹrọdu bẹ̀rù Johanu, nítorí ó mọ̀ pé olóòótọ́ eniyan ni ati pé kò ní àléébù.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Iraq, Palestine wà nínú orílẹ̀-èdè mẹ́wàá tí ìwádìí BBC ti wáyé Aarẹ Trump ni oun ati aarẹ Moon ti fẹnuko lori adehun okowo tuntun ti yoo bi eso rere fawọn orilẹ-ede mejeeji.
Ó bá fi àwo pẹrẹsẹ gbé orí rẹ̀ wá, ó fi í fún ọmọbinrin náà.
Ọmọde pàápàá a máa fi irú eniyan tí òun jẹ́ hàn nípa ìṣe rẹ̀,bí ohun tí ó ṣe dára, tí ó sì tọ̀nà.
N kò mú alaafia wá; idà ni mo mú wá.
"Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: ""Àwọn ọ̀tá Nàíjíríà tó fẹ́ dojú ìjọba bolẹ̀ ló wà lẹ́yìn ìwọ́de EndSARS"" Ó parí ni ohùn tó gbẹnu ọ̀pọ̀ ọmọ Nàíjíríà lẹ́yìn ọ̀rọ̀ Buhari Ìwọ́de EndSARS kìí ṣe ọ̀rọ̀ ẹlẹ́yàmẹ̀yà, ara ti kan àwọn èèyàn ni - Afenifere Buhari kọ́ ni ìṣòro wa, bó ṣe wà láti láéláé rèé - Fr Mbaka Àwọn ọ̀dọ́ fi ọ̀nà àrífín pe Tinubu lórí aago àmọ́ ó ní òun kò mọwọ́-mẹsẹ̀ nípa ìpànìyàn Lekki Á ràgà bo CCTV Lekki bí i ẹ̀rí tó dájú fún ìwádìí ìpànìyàn - Sanwo-Olu SERAP gbé ìjọba àpapọ̀ lọ ilé ẹjọ́ àgbáyé ICC lọrí ẹ̀sùn ìpànìyàn Akọwe ẹgbẹ naa, Amofin Yinka Oguntimehin, to fi atẹjade sita lorukọ ẹgbẹ sọ pe ""iwa ẹranko gba a ni iṣẹlẹ to waye ni Lekki""."
Ọlọ́run ló ní kí Abacha kú, àwọn àgbà Yorùbá púpò kò bá ṣòfò- Dele Momodu Ṣé lóòtọ́ ni àdó olóró bú níléeṣẹ́ ìjọba South Africa tó wà nílùú Abuja?
Bakan naa ni Minisita fun eto ẹkọ naa fikun pe lilo eto ẹkọ lori ẹrọ ayelujara naa yoo ṣeranwọ fun awọn eniyan lati koju ipenija itankalẹ arun Coronavirus.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ìgbésí ayé àwọn ọmọdébìnrin wọ̀nyìí di ọ̀tun láti 2008 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Ibà-ẹ̀fọn ti ọdún yìí jẹ́ tuntun, ó sì yára pa ènìyàn.
O jẹ ọkan lara awọn oludije meje ṣugbọn ṣe lawọn mẹfa to ku ni awọn o dupo aarẹ mọ ti wọn si fi ẹhonu han pe wọn ti da ibo ru fun anfani Bouteflika.
Ko si ẹni ti ọwọ́jà igbogunti iwa ajẹbanu mi ko ni kan ti aṣiri wọn ba ti tu.
Asoju orile-ede Amerika lorile-ede Naijiria Ogbeni Stuart Symington, ti ro awon omo orile-ede Naijiria lati mu igbeeru deba eto –oro aje lorile-ede Naijiria.
Lẹ́yìn tí mo bá ti sọ̀rọ̀ tán,ẹnikẹ́ni kì í tún sọ̀rọ̀ mọ́,ọ̀rọ̀ mi a máa wọ̀ wọ́n lára.
A gbọdọ ri i pe a se
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Kini itumọ ‘International passport’ l'ede Yoruba?
" ní ọdún 1977 , òun àti Ṣínà peters dá ègbẹ ́ orin tiwọn sílẹ ̀ tí wọ ́ n pè ní "" shina adéwálé and the superstars international "" ."
Bí mo ti fẹ́ràn obìnrin náà ni òun náà ń fẹ́ràn mi.
ile-ise ti won n  soju fi lu awon ara ilu
FaceApp: Ǹjẹ́ ẹwu wà nínú lílò ẹ̀rọ yìí?
Mo ti kó kúrò nílé Olu Jacobs rí lẹ́ẹ̀mejì- Joke Silva Àkúntúnkú, ìgbà márùn ún rè é tí Shekahu kú tí wọ́n ní kò kú mọ Kò sí ìfòyà lásìkò ọdún iléyá ní òpópónà Marosẹ Eko si Ibadan Ibadan NURTW: Àwọn ti Auxilliary àtàwọn tí Ajanaku gangan ló ń dàgboro rú Bo tilẹ jẹ pe ijọba Ajimọbi ni oun ti ṣe ipade ati ijiroro pẹlu igbimọ lọbalọba ki oun to gbe igbesẹ naa, amọ Olubadan ati Osi Olubadan, Oloye Rashidi Ladoja tako igbesẹ naa, ti ọrọ si di ti ile ẹjọ, laarin aafin Olubadan ati ijọba ipinlẹ Oyo.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Iná Edo: Àwọn ọmọ ni àdájọ́ lọ wò ní fásitì, tí ina fi mú wọn 29 Òkùdu 2018 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 11 Ògún 2018 Oríṣun àwòrán, @wololo_co_ke Bi eeyan ba jẹ ori ahun, yoo sunkun ni ọjọ ẹti nigba ti ijamba ina kan waye ni ilu Ekpoma ni ipinlẹ Edo lasiko ti ọkọ adajọ kan se agbako tanka epo to fọn epo silẹ, to si gbinna.
Latari eleyi,o jẹ ohun iyalẹnu fawọn ololufẹ ere boolu nigba ti afihan ati ọrọ alaye ta mọ si 'commentary' lede oyinbo ko lọ geere nigba ti Super Eagles Naijiria koju akẹ́gbẹ wọn lati Benin Republic.
Ajọ naa ni ileese ologun ko sapa to lati daa aabo bo awọn eeyan ti wọn si kọ lati ṣe iwadi tabi mu awọn ti wọn fura si wi pe wọn n ṣe iku paniyan.
O ka Usman Jafaru ati Terdoo Moses naa mọ wọn sugbọn ko si ẹni to mọ ibi ti wọn wa.
Maria yìí jókòó lẹ́bàá ẹsẹ̀ Jesu, ó ń gbọ́ ọ̀rọ̀ rẹ̀.
 Awọn onwoye idibo meji lo wa.
"Nítori àwọn àtúgbẹ́yẹ̀wò, o níra láti ṣe àkójọpọ fún àwọn ọkọ́ naa Orisun: Johns Hopkins University atawọn ajọ eto ilera ilu Iye akọsilẹ to waye gbẹyin 7 Oṣù Ọ̀pẹ̀ 2020 14:22 WAT+3 Nigba ti wọn fi ibeere sọwọ si nipa bi awọn akẹkọ yoo se bọ si ipele mi,o ni ''idanwo ti yoo gbe wọn lọ kilasi mii yoo waye lẹyin tawọn ba ti ri aridaju pe wọn ti kẹkọ to yẹ'' ""Fawọn to wa ni kilasi ti wọn yoo ti bọ si abala miran o fi kun pe awọn n se igbaradi fun wọn."
Oniruuru ipa ni Yoruba gbagbọ pe igbesẹ naa yoo ni lori ẹni to ba se ati awujọ wa.
Shiite: Ojú Zakzaky kan ti fọ́, májèlé sì wà nínú ara rẹ̀, ìyàwó rẹ̀ kò sì le è rìn mọ́
Lati asiko naa si ni Pasitọ Alfa Babatunde ati awọn ọmọ ijọ rẹ ti wọn mu ti wa ni ọgba ẹwọn Olokuta nilu Akurẹ, nibi ti wọn n gba lọ sile ẹjọ fun igbẹjọ.
Amọ, ikọ Boko Haram naa ṣi n ṣọṣẹ ti wọn si n pa awọn araalu ati awọn ọmọgun Naijiria.
"Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ sí: Chelsea àti Man U gbéná wojú ara wọn Wọ́n ti rí ọ̀dọ́mọkùnrin olówó Afrika tí wọ́n jí gbé Lẹ́yìn ọdún kan, wọ́n rí Nnamdi Kanu ni Israel ""Ó bà mí lọ́kàn jẹ́ púpọ̀."
Dokita Ọladiji to jẹ alaga igbimọ igbaninimọran lori arun naa sọ pe o ṣeeṣe ki wọn ran gbe awọn ọdọ naa lọ sile ẹjọ fun titapa si ofin to wa nilẹ pe ẹnikẹni ko gbọdọ ṣi tabi lọ si ile ijo lasiko yii.
Ali, tun ro awon akoroyin pe
Gbogbo àwọn nǹkan wọnyi yóo ṣègbé bí ẹ bá ti lò wọ́n tán.
Lori akete aisan, o doju kọ ẹsun to ni ṣe pẹlu iwa ibajẹ ati ipaniyan.
Ní àfikún, ìjọba ti pín iye owó irúfẹ́ ìrìnàjò tí ó wà sí ọ̀tọ̀ọ̀tọ̀, ó tò ó ní ẹsẹẹsẹ.
Felix Ofulue ko sọ pato iye kan pato ti awọn onibara wọn pataki yii n san, amọ o ni awọn fi owo le iye owo ti wọn n san lori lilo ina, ti eleyi si wa ni ibamu pẹlu ofin lilo ina ni Naijiria.
Ṣiṣe ere idaraya loorekoore maa n ran awọn to n ṣiṣẹ nile lọwọ.
Bakan naa ni wọn ni idanwo BECE fun awọn akẹkọọ ni ipele kẹta akọkọ nile iwe girama yoo waye laarin ọjọ kẹrinlelogun, oṣu kẹjọ si ọjọ Keje, oṣu kẹsan an.
Nígbà tí wolii àgbàlagbà náà gbọ́, ó ní, “Wolii tí ó ṣàìgbọràn sí ọ̀rọ̀ OLUWA ni.
Aarun Ebola naa bẹrẹ si ni maa
Wo bí àwọn ọmọ yìí ti ń ṣe é Amọṣa, O ni ni iwoye ọlọpaa, kii ṣe awọn fulani darandaran lo ṣe ọṣẹ naa bikoṣe awọn janduku.
Ọrọ aabo ilẹ Yoruba ati ijinigbe to n gbilẹ ni agbegbe naa ti di ọrọ nla lọwọlọwọ bi awọn ọdaran darandaran ṣe bẹrẹ si ni ṣọsẹ.
Yemi Osinbanjọ ti ya ara rẹ̀ sọ́tọ̀ fún àyẹ̀wò àrùn Coronvirus ''Tí a bá ní káwọn èèyàn jókòó sílé nítorí coronavirus, ebi àti olè jíjà ma pọ̀'' Mò ti ya ara mi sọ́tọ̀ bí mo ṣe dé láti America nítorí coronavirus- Soyinka Ìjọba ìpínlẹ̀ Eko ti ni ki gbogbo ọjà wà ni títì pa, sùgbọ́n.
-Ọlọ́pàá Igba ti BBC Yoruba kan si kọmiṣọna fun ọlọpaa ni Ipinlẹ Ondo Undie Adie, o ni oun ko tii gbo nipa ọrọ naa.
OLUWA ti gbé ìtẹ́ rẹ̀ kalẹ̀ lọ́run,ó sì jọba lórí ohun gbogbo.
Ọwọ́ ẹni tí a bá ti bá a ni yóo di ẹrú mi, kò sí ohun tí ó kan ẹ̀yin yòókù rárá.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ibadan NURTW: Àwọn ti Auxilliary àtàwọn tí Ajanaku gangan ló ń dàgboro rú 29 Agẹmo 2019 Oríṣun àwòrán, @Oyoaffairs Awọn olugbe agbegbe Ẹgbẹda nilu Ibadan ti ṣe alaye wi pe igbiyanju awọn alakoso ẹgbẹ awakọ NURTW ipinlẹ Ọyọ lati wa ojutu si ofin ti ijọba fi de wọn lo ṣokunfa rogbodiyan ti o waye ni agbede naa lopin ọsẹ.
N óo sọ nípa òdodo rẹ ati iṣẹ́ ọwọ́ rẹ,ṣugbọn wọn kò ní lè ràn ọ́ lọ́wọ́.
Ìwúrí ńlá ni eléyìí jẹ́ fún gbogbo ọmọ Yorùbá pátápátá
Tinubu kìlọ̀ fún Buhari lórí ohun tó leè ṣàkóbá fún sáà kejì rẹ̀ Tinubu: Emi ko mọ nipa iyansipo mi Iléeṣé MTN ti san bíliọnù N55 owó ìtanràn wọn tó kù -MTN Áfíríkà yóò gba ife ẹ̀yẹ UEFA Champions league lónìí Ajọ SEC ni ki awọn ẹni kọọkan ati ileeṣe OANDO san owo itanran bẹrẹ lati ọdọ awọn oludari ileeṣẹ ọhun .
Dokita mii sọ fun pe, iṣẹlẹ yii kii ṣe nkan tuntun, ko ṣẹṣẹ ma waye.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Làá hàn mí: Ètò yìí ló ń kìlọ̀ fún wa láti mú ìmọ́tótó ní pàtàkì láti dènà Coronavirus Amọṣa bi o ko ba ni ohun elo tamomita ti wọn fi n wọn bi nnkan ṣe gbona si, oo ṣakiyesi pe ara rẹ n gbona,bi eeyan ba si fi ọwọ kan ẹ, aya rẹ ati ẹyin rẹ yoo gbona wa.
Amọ awọn eniyan kan fẹsi wi pe awn afẹhọnuhan lo ṣe eyi, bikoṣe awọn janduku nitori awọn afẹhọnuhan ko le e lọ si ọgba ẹwọn lati lọ ṣọṣẹ.
Ninu oṣù kẹsan-an ni ọ̀rọ̀ yìí ṣẹlẹ̀, ọba sì wà ní ilé tíí máa gbé ní àkókò òtútù, iná kan sì wà níwájú rẹ̀ tí ń jó ninu agbada.
Wọn fi iya Aminu fun ọkọ iyẹn Emir Ado Bayero ilu Kano ti o si bi ọpọ ọmọ fun un.
O ni ''bayi ti mo wa nile, mi o ki n fi asiko ti maa rin jade lati gba oorun tabi atẹgun sara ṣere.
Gbajugbaja oṣere ni Desmond Eliot ko to di wi pe wọn dibo yan an gẹgẹ bi aṣofin to soju ẹkun Surulere ni Ile Igbimọ Aṣofin ipinlẹ Eko.
Ọ̀gá ni ninu ẹgbẹ́ àwọn Nasarene.
Bi awọn ipinlẹ to ni Coronavirus ti ṣe lọ ni : FCT-93 Lagos-78 Plateau-64 Kaduna-54 Oyo-47 Ondo-32 Adamawa-23 Bauchi-19 Rivers-9 Ogun-9 Delta-9 Edo-7 Kano-6 Enugu-6 Nasarawa-5 Osun-1 Eeyan 481 ni wọn kede pe ayẹwo tun fihan pe o laarun COVID-19 lorilẹede Naijiria bayii.
"O ni: "" Ewe, tii ṣe iṣẹ idọti lo sọ mi di ọlọla, ogun lo si le mi de idi ewe tita, ki Ọlọrun tete fi ọna han ẹda."
#Mothersday2019: Àwọn ìpèníjà obìnrin láwùjọ Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Ilééṣẹ́ Facebook leè mọ ìgbà tí àwọn tó wà lójú òpó wọn ń ní ìbálòpọ̀ Awakọ̀-èrò, ọlọ́kadà farakásá àṣẹ ìjọba Ekiti láti dẹ́kun Coronavirus Ẹ wo ǹkan to sẹlẹ̀ sí ọmọ àti ìyàwó ọmọ Atikú tó lùgbàdì ààrun Coronavirus Àrùn Coronavirus ti gba ẹ̀mí ẹni àkọ̀kọ̀ ní Zimbabwe Eni mẹ́rin míì kó coronavirus ní Nàìjíríà, àfàìmọ̀ kó má dàbi ti China, Italy- Mínísítà kìlọ̀ Ajọ NCDC ṣalaye pe mẹta ninu awọn eeyan wa lati ipinlẹ Eko nigba ti ẹyọkan to ku wa lati olu ilu orilẹede Naijiria, Abuja.
O tun so pe “awọn  ile wonyi ni won yoo lo lati yanju awọn  isoro lori oro ile ati awọn  wahala ti won maa n koju nigba ti won ba fe fun awọn eniyan  naa nile.
"Ìjọba gbé ilé ijó oníhòhò tì pa lórí ẹ̀sùn títàpá sí ìlànà àti dẹ́kun coronavirus Ogun abẹ́lé tó ń ja Akeredolu l'Ondo, òní la ó mọ̀ bóyá yó borí rẹ̀ Ẹ̀yà kòkòrò Covid-19 míràn jáde ní ọgọ́ta agbègbè nílẹ̀ Gẹẹsi, àjọ eletò ìlera ni k'ára ìlú má fòyà Wọ́n ní kí ọ̀gá àgbà ""Ede Poly"" lọ rọ́kún nílé lórí ẹ̀sùn pé ó kan bẹ́ẹ̀dì sí ọ́fíìsì 3) Igbesẹ 3Gba nọmba NIN rẹ Bi ọjọ meji sí mẹta ni wọn yóò lo ki o to le gba iwe ẹri nọmba yi lẹyin ti wọn gba oju ika rẹ àti àwòrán oju rẹ silẹ O ṣeeṣe ki o pe ki o to ri nọmba yi gba nigba miran nitori NIMC yoo ni lati ṣe ayẹwo to peye."
Nípa báyìí, ìpàdé àpapọ̀ kan ti Ijọ́ pe Joseph Smith ní 1831 láti “ṣe àtúnṣe àwọn àṣìṣe tàbí àìdára èyítí òun le ti ṣe àwárí nípa Ẹ̀mí Mímọ́.
láti dènà bíburújù àrùn náà , a nílò láti ṣe àyẹ ̀ wò gbogbo àwọn ènìyàn tó wà lábẹ ́ ewu níní àrùn náà nípasẹ ̀ àyẹ ̀ wò ẹ ̀ jẹ ̀ fún kòkòrò àrùn ajọ ̀ fẹ ́ t.
A ṣì ń ṣèwádìí lọ́wọ́ lórí àwọn t'ọ́ta ìbọn pa lọ́jọ́ ọdún Eid n'Ibadan - Ọlọ́pàá Kí ló dé tí Shoprite fẹ́ kógbá kúrò ní Nàìjíríà?
Ọpọlọpọ awọn obinrin orilẹ-ede naa lo jade lati foju gan an ni idije ọhun nigba ti o waye ni Iran.
A si ṣe akojọpọ diẹ lara awọn nkan ti wọn sọ.
''Gẹgẹ bi ijọba, a ṣetan lati gbe igbesẹ ti yoo mu ki awọn ara ilu tẹle ofin to de ayika wa, inu wa dun pe ko si ẹmi kankan to ba iṣẹlẹ yi lọ.
Àwọn ológun fi ẹ̀sùn kan ẹgbẹ́ pro-Iranian pé wan ń gbìyànjú láti pa Ọ̀gágun Tukur Buratai èyí tí wọ́n ní irọ́ ni.
Nitori naa, ti a ba lo akọsilẹ Gini, awọn to n bu ẹnu ẹ̀tẹ́ lu iṣejọba ẹgbẹ ANC ko parọ́ pe aidọgba pọ ni South Africa Ṣugbọn irọ ni wọn pa pe o n buru u si, paapa lati bi ọdun mẹwaa sẹyin ti akọsilẹ wa fun.
Gbogbo oúnjẹ tí wọ́n bá rí kójọ ní agbègbè ìlú ńlá kọ̀ọ̀kan, Josẹfu a kó o pamọ́ sinu ìlú ńlá náà.
75, ati amojuẹrọ ni ileeṣẹ Continental Broadcasting Service (TVC/RC) Arabinrin Mojisola Alli-Macaulay gẹgẹ bi oloṣelu, o ti jẹ Counsillor ward Bini ọdun 2010- 2013), O jẹ Igbakeji Adari Ile Igbimọ Aṣofin ijọba ibilẹ Amuwo ̣Ọdọfin, Ọmọ Ile Igbimọ Asofin lọwọlọwọ lati ọdun 2019 titi di isinyi NI Arabinrin Mojisola Alli-Macaulay Mojisola Alli-Macaulay fẹran lati ma kawe, rinrinajo ati gbigbọ orin amoriwu.
Bí àríyànjiyàn bá bẹ́ sílẹ̀, àwọn ni wọ́n gbọdọ̀ jẹ́ onídàájọ́, wọ́n sì gbọdọ̀ ṣe ìdájọ́ gẹ́gẹ́ bí èmi gan-an yóo ti ṣe é.
Ibanujẹ bẹrẹ wayii O sare lọ si ibudokọ omi Abonnema, ṣugbọn wọn ko jẹ ko ri oku rẹ nitori pe o n t'ọmọ lọwọ.
Làá hàn mí dé, ètò tó ń ṣàlàyé ohun tó yẹ ká ṣe láti dènà àrùn Coronavirus Kí lẹ tíì rí nípa Amotekun?
Buhari ti fòfin de àwọn mínísítà láti rìnrìn àjò lọ sí ilẹ̀ òkèrè Nàìjíríà kò nílò sénétọ̀ kankan- Fayemi Ọpẹ́ o!
Ogun mìíràn tún bẹ́ sílẹ̀ pẹlu àwọn ará Filistia kan náà, ní Gobu.
" Ọrọ Darlington ya ọpọ awọn eniyan lẹnu l'ori Twitter, ti wọn si n ba dupẹ pe ori koo yọ.
Lẹ́yìn náà, Elija sọ fún Ahabu ọba pé, “Lọ, jẹun, kí o wá nǹkan mu, nítorí mo gbọ́ kíkù òjò.
Ìrìnàjò láti Addis Ababa sí Nairobi
Mo dàbí àwọn tí ó ń wọ ibojì lọ;mo dà bí ẹni tí kò lágbára mọ.
Amọṣa, dẹrẹba to wa ọkọ arabinrin naa lọjọ buruku eṣu gbomimu yii ba BBC News Yoruba sọrọ lori bi ọrọ ṣe ṣẹlẹ gan an.
omowe  Ogbonaya Onu lo soro yii lasiko ti
Gbogbo nǹkan yòókù tí Jotamu ṣe ni a kọ sinu Ìwé Ìtàn Àwọn Ọba Juda.
Àwọn kan wà tí wọn ń gbé baba wọn ṣépè,tí wọn kò sì súre fún ìyá wọn.
lati fi pa kokoro ni papa ofurufu  ijoba
Oríṣun àwòrán, AFP Àkọlé àwòrán, Sugbọn awọn ọmọde wọn yii saasala kuro nibi ojo naa.
O ni igba gbogbo ni inu oun maa n dùn ti oun ba ti n kọrin.
Buhari, o kò ṣe bẹbẹ kankan láì jẹ́ pé o gba Leah Sharibu náà sílẹ̀"" Wo àwọn nǹkan to tún nílò NIN fún yàtọ̀ fún ìforúkọsílẹ̀ síìmù Ilé aṣòfin àgbà yọ gómìnà nípò, ẹni tó fi owó ìlú rán ọmọ lọ sí Amẹ́ríkà Amẹ́ríkà yarí pé àwọn agbégbọn tó jí akẹ́kọ̀ọ́ 344 gbọ́dọ̀ fojú winá òfin Sé lóòtọ́ ni pé Dino fẹ́ ṣe ìgbeyàwó?"
Tọkọ-taya Aràrá: Àwọn èèyàn máa ń wò wá, ta bá fa ọwọ́ ara wa ní títì
Iléeṣẹ́ náà bẹ̀rẹ̀ iṣẹ́ ní agbègbè yìí ní ọdún-un 1991 nígbà tí àwọn aládùúgbò fi ẹ̀sùn kan obìnrin kan pé ó lọ́wọ́ nínú ikú ọmọdékùnrin kan.
Ṣaaju, iyawo funrarẹ ti sọ idi ti igbeyawo yii ṣe waye lasiko yii pe 'Coronavirus ló mú mi fẹ́ ọkọ mi tí a sì ṣèyàwó lóríi ‘Zoom’ Tẹgbọn-taburo se igbeyawo ni Anambra Àwọn nǹkan tí obìnrin lè ṣe pẹ̀lú olólùfẹ́ oníwà ipá lásìkò ìgbélé Coronavirus yìí Ọkọ'yàwó jẹ àjẹranjú ìyà lẹ́yìn tí ìyàwò rẹ̀ yọjú síbi ìgbéyàwó òun àti obìnrin mìràn Iléẹjọ́ wọ́gilé ìgbeyàwó nílànà ẹ̀sìn Islam pé kò bófin mu Ile iṣẹ BBC ba Pasitọ to so ọkọ ati iyawo pọ sọrọ to jẹ Pasitọ ijọ HICC.
"Albert Askonnemenjr nfẹ ki ""aarẹ Weah ranti wipe irapada lati ọdọ Ọlọrun ni eto isakoso rẹ jẹ fun Liberia."
 Congo DR wa ni ipo mẹ́rìndínláàdọ́ta (46th), ti Morocco si wa ni ipo mẹ́tàdínláàdọ́ta(47th).
Inú rẹ̀ bàjẹ́ gidigidi fún Dafidi, nítorí pé baba rẹ̀ dójú tì í.
Ṣugbọn lode oni, isẹ yii ti n parun lọ diẹdiẹ, idi si ree ti BBC Yoruba fi tọ awọn to n mọ amọ lati mọ ọna ti wọn n gba ki isẹ amọ ma baa parun.
Oríṣun àwòrán, Instagram/miketyson Ọdun 2018 ni alatako rẹ, Jones kẹyin, oun lo si bori alatako rẹ, Scott Sigmon lọdun naa.
1 13198 Orilẹede Aruba 45 42.
Kolade Johnson: Adájọ́ pàṣẹ kí wọ́n fi ọlọ́pàá tó lọ́wọ́ nínú ikú Kolade Johnson sí àhámọ́
Ṣebí nítorí ẹ̀ṣẹ̀ náà ni àjàkálẹ̀ àrùn fi bẹ́ sílẹ̀ ní ààrin ìjọ eniyan OLUWA?
Aisha Raheem gbe imọ ẹrọ kalẹ ti yoo ma a ran awọn agbẹ lọwọ ati ẹbi wọn lati ri wi pe wọn ko ko ounjẹ danu lọna aitọ.
Akọwe ijọba ipinlẹ Kano, Alhaji Usman Alhaji lo kede Emir tuntun lẹyin wakati diẹ ti ijọba Abdulahi Ganduje rọ Lamido Sanusi loye.
Àwọn òpó ní àwòṣe ọnà ilée ionic àti Corinthian.
15 Ṣùgbọ́n àwọn tí wọ́n bá sé ọkàn wọn le nínú àìgbàgbọ́, tí wọ́n sì kọ̀ ọ́ sílẹ̀, yíò yípadà sí ìdálẹbi tiwọn—
Wakati mẹrin lẹyin ti awọn eeyan wọnyii gunlẹ ni ko si ẹnikẹni ti yoo yọju si wọn.
Kí oòrùn ati ìmọ́lẹ̀ ati òṣùpá ati ìràwọ̀ tó ṣókùnkùn, kí ìkùukùu tó pada lẹ́yìn òjò; 
ipinle  ni ile iwosan abẹle wa nikawo
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Bode George: Emi ati Ọbanikoro kii ṣe ẹgbẹ Arinrinajo ara Portugal kan, Pedro Alvares Cabral lọ si Brazil ni ọdun 1500, nibi to ti rii pe wọn n lo taba lati fi tọju egbo wọn.
Alaga ijọba ibilẹ Isolo, Shamsudeen Abiodun Olaleye lo fidi ọrọ yi mulẹ fun BBC lasiko to ṣe abẹwo si ibi ti ijamba naa ti waye.
Ihò òkúta yìí wà ninu pápá ní Makipela, ní ìhà ìlà oòrùn Mamure ní ilẹ̀ Kenaani.
Wo ọ̀nà ìsanwó tuntun fún àwọn oníbárà iná mọ̀nàmọ́ná ní Eko (EKDC) Àwọn dókítà yóò bẹ̀rẹ̀ ìyanṣẹ́lódí lọ́jọ́ Ajé Níbo lọ̀rọ̀ dé dúró nípa iṣẹ́ àwọn tó n wa iṣẹ́ N-Power?
Awọn to ni aarun coronavirus ni Naijiria tun ti le si bayii, lẹyin ti ajọ NCDC kede esi aadọrun eeyan to tun ṣẹṣẹ ni Ninu esi ayẹwo ti ajọ naa fi sita lori Twitter, ipinlẹ mẹtadinlogun, ati ilu Abuja ni esi ayẹwo naa ti wa.
Bakan naa ni wọn yọ oku obinrin kan, Charity Ohaka, ti awọn to pa a ju sinu kanga kan ni Rumuosi.
mo igbese to ye ki won gbe ti won ba ri ifarahan eyikeyi ninu aarun to le fa
"Oríṣun àwòrán, Ayodele Fayose ""Bí wọn ṣe yọ fila lori Bola Ige bi yẹn ni Ile Ife."
Wọn ni eniyan mẹẹdogun miiran tun ti lugbadi aarun naa ni ipinlẹ Eko, mẹrin ní Abuja, meji ni Bauchi, ẹyọkan ni ipinlẹ Edo.
Aarẹ Biya jẹ ọkan lara awọn aarẹ to dagba ju ni Afrika Oríṣun àwòrán, Lintao Zhang Àkọlé àwòrán, Biya yoo pe ẹni ọdun mejidinlaarun nigba ti yoo ba fi pari saa keje rẹ Aarẹ Biya bọ si ori aga iṣakoso l'ọjọ kẹfa, oṣu Kọkanla, ọdun 1982, lasiko ti Aarẹ Amadou Ahidjo gbe agbara iṣakoso le e lọwọ.
O sọ pe nkan miran to tun wa nibẹ ni pe ko si ilana tabi ofin ijọba kankan nilẹ lati ri i pe DisCos tẹle ilana tuntun naa.
Awọn kokoro aifojuri a ma sọsẹ nipa wiwọ awọn sẹẹli inu ara ti wọn si ma gba akoso wọn.
Amọ, ero awọn kan ṣọtọọtọ lori ọrọ naa, fun apẹrẹ, @funshi ni oniyẹyẹ ni pasitọ Omashola, o ni pasitọ naa ko riran pe Fashola Azeez lẹmi Eṣu.
Fun apẹẹrẹ, ile ẹjọ to ga julọ ni orilẹede India ti n gbẹjọ ẹsun ifipabanilopọ to ni ṣe pẹlu dokita kan ni ilu Chhattisgarh nitori pe o ni ibalopọ pẹlu ọmọbinrin kan lẹyin to ṣeleri fun pe oun yoo fi ṣ'aya, ṣugbọn to pada lọ ọ fẹ ẹlomii.
Gbogbo awon omo orile ede Naijiria ni yoo maa fọwọsowọpọ lati maa lo
ó ní, “Ẹ̀yin ará, mo wòye pé ewu wà ninu ìrìn àjò yìí.
Kọmiṣọna ọlọpaa ni ipinlẹ Ọṣun, ni a gbọ pe o ṣẹṣẹ wa pẹtu si ọkan awọn akẹkọ naa ki wọn to bu omi suuru mu.
Igbesẹ Ipinlẹ OyoNi ti ipinlẹ Oyo, o fi ofin de ipejọpọ ọpọ eniyan, o ti gbogbo ileewe pa, o ti awọn ọjà nla pa.
" O ni ayederu iroyin ni awọn iroyin to sọ pe oun salọ, tabi pe awọn kan ji ọmọ rẹ ọkunrin, Seyi Tinubu gbe nitori iṣẹlẹ naa.
Amọṣa o ni lootọ lawọn wu oku naa ati pe iwadii n lọ lati mọ bi iku arakunrin naa ṣe ri.
Ìrìn ọjọ́ mọkanla ni láti Horebu dé Kadeṣi Banea, tí eniyan bá gba ọ̀nà òkè Seiri.
Oríṣun àwòrán, Others Dare rọ ijọba ipinlẹ Kwara lati tẹsiwaju ninu igbiyanju wọn, lati mu idagbasoke ba awọn ọdọ ni agbegbe wọn.
Sugbọn awón akẹgbẹ won mii bii Maya, MIA ati My Period Tracker maa n pin iwadii wọn pelu Facebook.
Àjọ Lasema rí òkú èèyàn nínú èèrù iná àwọn ọkọ̀ agbépo tó jóná ní afárá Kara Ẹ wo òtítọ́ ọ̀rọ̀ nípa bí àwọn agbébọn ṣe wó ile ní iléèṣẹ́ aṣojú Nàìjíríà ní Ghana Wo àwọn oníròyìn méje tó kú láàrin ọjọ́ méje ní Nàìjíríà Lẹ́yìn tí mo gbé ayé mi yẹ̀wò, mo ríi pé asán layé - Toyin Abraham Elesho ni ''ọmọ obinrin mi nikan ni mi o ja si ihoho ri.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Risikat Moromoke Azeez: Inú èmí àti Òbí mi dùn nígbà ti Risi bí ọmọ olójú búlù- Wasiu Ẹ má bínú pé mo kọ́kọ́ ní akẹ́kọ̀ọ́ mẹ́wàá péré ni wọn kó nílé ìwé Kankara - Garba Shehu Oríṣun àwòrán, @NGRPresident Agbẹnusọ fun aarẹ Muhammadu Buhari, Garba Shehu ti tọrọ aforiji lọwọ awọn ọmọ Naijiria, fun aṣiṣe rẹ lẹyin to kọkọ kede pe awọn akẹkọọ mẹwaa pere ni awọn agbebọn ji gbe ni Kankara.
Oyetola lo fi ọrọ naa lede ninu igbohunsafẹfẹ to ṣe laarọ ọjọ Isinmi to tẹlẹ iwọde ọhun.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Hepatitis: A kò leè kóo nípa dídìmọ́ ara ẹni O ni  a n gbe ẹsẹ meji siwaju, mẹwaa sẹyin."
Nítorí náà ẹni tí ó bá rẹ ara rẹ̀ sílẹ̀ bí ọmọde yìí, òun ni ó jẹ́ eniyan pataki jùlọ ní ìjọba ọ̀run.
Ẹ̀ ń jókòó sọ̀rọ̀ arakunrin yín níbi:ẹ̀ ń sọ̀rọ̀ ìbàjẹ́ nípa ọmọ ìyá yín.
Nítorí àwọn tí Ọlọrun ti yàn tẹ́lẹ̀, àwọn ni ó yà sọ́tọ̀ kí wọ́n lè dàbí Ọmọ rẹ̀, kí Ọmọ rẹ̀ yìí lè jẹ́ àkọ́bí láàrin ọpọlọpọ mọ̀lẹ́bí.
Iroyin to tẹ BBC News lọwọ jẹ ko di mimọ pe, ẹgbọn aarẹ Buhari obinrin lo fẹ baba Amina Zakari, iyẹn Emir ti Kazaure.
Mugabe fi ìgboyà dáábò bo ilẹ̀ Áfíríkà lọ́wọ́ ìmúnisìn Àwọn ọ̀rọ̀ apanílẹ̀rín tí Mugabe sọ tó jẹ́ mánigbàgbé Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 3 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 5 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Ẹ̀wẹ̀, àwọn òṣìṣẹ́ aláàbò ti gbégi dínà gbogbo ọ̀nà tó wọ ìlú Abuja látu agbègbè ọ̀hún.
Aṣeri yóo máa rí oúnjẹ dáradára mú jáde ninu oko rẹ̀,oúnjẹ ọlọ́lá ni yóo máa ti inú oko rẹ̀ jáde.
Asọ alawọ eweko, tii se asọ ọgba ẹwọn si ni Babatunde wọ wa sile ẹjọ, ti wsn si fi ọkọ ọgba ẹwọn bọọsi kan gbe wa sibẹ.
Amọ awọn eeyan naa pasẹ fun ayaba lati gbe ọmọ naa kalẹ nitori awọn ko ri gbọ pe ayaba kankan bimọ laafin lasiko igba naa.
5 144369 Orilẹede Denmark 885 15.
“Mo ranti awon nkan ti o sele seyin, ti a fi padanu ipo gomina nipinle Ekiti lodun 2014.
Ko tẹsiwaju ẹkọ rẹ mọ lẹyin to kuro nile iwe girama, ṣugbọn o bẹrẹ si n ṣiṣe sobata.
tìtorí rẹ̀, n óo sọ yín sókè, n óo sì gbe yín sọnù kúrò níwájú mi, àtẹ̀yin, àtìlú tí mo fi fún ẹ̀yin, ati àwọn baba ńlá yín.
Iko agbaboolu Argentina lo n samulo papa isere odo iko Manchester City fun ifesewonse ohun ti yoo waye lojo Eti(Friday).
O sọ ninu ẹsun rẹ ti fidio Y!
Òun ló jẹ́ kí gbajúgbajọ̀ òsèré tíátà, Mosun Filani gba àwọn obìnrin ní ìmòràn, pe kí wọ́n máà fi abẹ gé àwọ̀tẹ́lẹ̀ tí wọn kò bá nílò mọ́ wẹlẹwẹlẹ, dípò pe kí wọ́n máa sọ́ si ibi tí àwọn tó lè fi ṣe oogun owó yóò ti ri i.
Ninefe, ìwọ pàápàá yóo mu ọtí yó, o óo máa ta gbọ̀n- ọ́ngbọ̀n-ọ́n; o óo sì máa wá ààbò nítorí àwọn ọ̀tá rẹ.
Kiiṣe ohun tuntun pe awọn oloṣelu maa n lo awọn janduku ti eto idibo ba n bọ lọna, lasiko eto idibo ati ti idibo ba waye tan.
OLUWA wí fún un pé, “Ilẹ̀ tí mo búra fún Abrahamu, ati fún Isaaki, ati fún Jakọbu pé, n óo fi fún àwọn arọmọdọmọ wọn nìyí, mo jẹ́ kí o rí i, ṣugbọn o kò ní dé ibẹ̀.
Ni ipinlẹ Eko ati ipinlẹ Ogun awọn akẹkọọ ti yoo kọ idanwo aṣekagba SSCE ti wọn n wa lati ile ati awọn eyi to n gbe ni ileewe ni wọn ti ni ki wọn pada sẹnu Eko.
Coronavirus in Nigeria: Wo àwọn ìrìnàjò tí gómìnà Makinde rìn kí èsì àyẹ̀wò rẹ̀ tó jáde Oríṣun àwòrán, SEYI MAKINDE Gomina ipinlẹ Ọyọ, Onimọẹrọ Ṣeyi Makinde kede ni aṣalẹ ọjọ Aje pe oun ti ko arun Coronavirus ti o n ja kale-ka'ko bayii.
Nítorí èyí, ẹ óo gba ìdálẹ́bi pupọ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ẹwa Agọnyin jẹ aayo ounjẹ Badagry 'Koda, ẹrọ amunawa t'oun lo lahamọ ti wọn fi si, awa la ra a.
Igboho ni awọn kan to wa nipo agbara n lo ipo ti wọn wa lai bikita fun abo ẹmi ati dukia awọn araalu.
Muhammadu Buhari ti so pe laipẹ yii ni won yoo fiwe abadofin ekunwo ranse sile
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìṣẹ̀lẹ̀ ìpànìyàn: Iléeṣẹ́ aṣọ́bodè ní àṣìta ìbọn ló fa sábàbí 19 Èrèlè 2019 Oríṣun àwòrán, Nigeria Customs Service Àkọlé àwòrán, Ajọ aṣọbode gba pe lootọ ni oṣiṣẹ wọn to yinbọn pa ọkunrin naa ko tẹ ohun to le dena ki ibọn naa o maa yin ara rẹ.
Ẹni tí ó fa ewúrẹ́ náà tọ Asaseli lọ ninu aṣálẹ̀ yóo fọ aṣọ rẹ̀, yóo sì wẹ̀, lẹ́yìn náà, ó lè wọ ibùdó.
Ti eeyan ba ti sun mọ ẹrọ naa, yoo yọ omi ati ọṣẹ jade ti eeyan yoo fi fọwọ rẹ fun iṣẹju marundinlọgbọn gẹgẹ bi ilana ti ajọ WHO gbe kalẹ.
Bakan naa nigba ti BBC News Yoruba gbe ọrọ naa tọ awọn to yẹ ko mọ nipa rẹ laafin, eeyan kan laafin Kabiyesi Alaafin ilu Ọyọ to sun mọ kabiyesi Iku baba yeye ṣalaye pe ko si nnkan to jọ bẹẹ rara.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Yollywood: Kò sí ẹni ti òbí mi kò lè sọ̀rọ̀ sí -Sisi Quadri Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Kegel: Eré ìdárayá tí àwọn onímọ̀ sọ pé ó n fikún adùn ìbálòpọ̀ fún obìnrin, tó tún n fún ọkùnrin ní agbára
Èyí àbúrò sọ fún baba rẹ̀ pé, ‘Baba, fún mi ní ogún tèmi tí ó tọ́ sí mi.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Ni ilẹ adulawọ nikan, o le ni aadoje miliọnu eeyan to n lo oju opo ikanni Facebook.
Nipasẹ oṣuwọn yii, ati lilo akọsilẹ ti Banki Agbaye fi sita, South Africa lo ni ipele aidọgba ju ni agbaye.
’’O tun tẹsiwaju pe ohun to le tan isọrọ yii ni ki awọn eniyan fi aaye gba ara wọn, o wa rọ awọn eniyan lati gba imọ ẹrọ tuntun laaye paapaa julọ nipa pipese ọgba ijẹran.
Ẹ̀rù ba àwọn tí wọn ń tu ọkọ̀, olukuluku bá bẹ̀rẹ̀ sí ké pe oriṣa rẹ̀, wọ́n ń da ẹrù wọn tí ó wà ninu ọkọ̀ sinu òkun kí ọkọ̀ lè fúyẹ́.
Adájọ́ Raliat Adebiyi tí ó gbọ́ ẹjọ́ Nwobike, so pé àjọ tí ó ń kojú ìwà jẹgúdújẹrá tí a mọ̀ sí EFCC ti fi hàn dájúdájú pé agbẹjọ́rò àgbà náà bá àwọn òṣìṣẹ́ ilé ẹjọ́ kan sọrọ̀ láti jẹ́ kí wọ́n máa gbé àwọn ẹjọ́ rẹ̀ lọ sí iwájú àwọn adájọ́ ti ó fẹ́.
Akọwe ẹgbẹ ọmọ bibi ilẹ Yoruba, Afenifere, Yinka Odumakin, sọ pe ẹ̀tanú lo mu ki ijọba Buhari yọ orukọ Obasanjo sọ ibudokọ oju'rin kankan.
Ta ni Ebuka Obi-Uchendu tó ń gbàlejò BBNaija 2020?
Ìrìnàjò kan tí mo rìn dé Andalusia ní orílẹ̀èdè Spain níjọ́sí, oríṣìí nǹkan l’ojú rí níbẹ̀.
Àwọn iranṣẹ wọn pàápàá a máa ni àwọn eniyan lára.
Oríṣun àwòrán, Nigeria Air Force Àwọn kókó tó ṣe pàtàkì Ìfórúkọsilẹ̀ orí ayélujára bẹ̀rẹ̀ lọ́jọ́ kẹrinlélógun yóò si kágbá nílẹ̀ kọkànlélógún oṣù kẹjọ ọdún 2020.
Púpọ̀ nínú àwọn àrùn wọ̀nyí, àwọn kòkòrò tí a kò lè fi ojú lásán rí ni wọ́n nfà wọ́n.
Sanwo-olu gbé ìwé ẹ̀dùn ọkàn olùwọ́de ENDSARS lé Buhari lọ́wọ́ Ẹ lo ìfẹ̀họ̀núhàn #EndSARS lati fí tún gbogbo ohun tó bàjẹ́ ṣe ní Naijiria- Pásítọ̀ Sam Adeyemi Bisola Alfa ni irọ oriṣiriṣi ni wọn pa mọ ọkọ ohun ati pe wolii kii ṣe oloselu.
Akẹkọọ ipele keji ni ẹka imọ nipa ilẹ Yuroopu (Department of European Studies, Faculty of Arts, University of Ibadan) ni Richard ti n kẹkọọ ki ọlọjọ to de.
" Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí BBC: Iroyin yoruba yoo bẹrẹ ni pẹrẹwu Akanṣe iroyin ni ede Yoruba yoo wa ni ori opo ayelujara bbc.
'Mo máa tó dìde lórí àìsàn', Muyiwa Ademola sọ̀rọ̀ látorí àkéte àìsàn rẹ̀ Àwọn Tíṣà Oyo kó owó tó wà fún àkóso iléèwé jẹ, ni wọ́n fi ń fọwọ́ kọ ìdánwò pẹ̀lú ṣọ́ọ̀kì - Seyi Makinde Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Mo kàn máa ń lọ́ ayẹyẹ kiri torí ijó láì ṣe pé wọ́n pe mí ló sọ mí di DJ olórin Fuji nìkan' Ìrẹsì ọ̀fadà, ikọ́kọre, àti àwọn oúnjẹ míì tóo lè fí gbádùn ẹ̀mí rẹ lásìkò Kérésì Àìbìkítà yíì gbọ́dọ̀ dópin, ìjọba gbọdọ̀ mú ẹ̀dùn ọkàn àwọn aráàlú lọ́kùnkúndùn- Agbẹjọ́rò Àgbà Wo àwọn kọ̀ndísàn tuntun tí àwọn olùwọ́de #ENDSARS gbé jáde lẹ́yìn tí wọ́n tú SARS ká Wo ìgbà mẹ́rin tí ìjọba ti tú ikọ̀ ọlọ́pàá SARS ká sẹ̀yín ṣùgbọ́n.
Agbenusoro iko olote Taliban, Qari Yousuf Ahmadi so pe, olopaa marundinlogbon ti o fi mo awon oga agba olopaa ni won seku-pa, ti won si dana sun oko olopaa merin.
Bi ẹ ba fẹ ṣeto wẹjẹ-wẹmu tabi igbafẹ kankan, ẹ gbọdọ gba aṣẹ lọwọ awọn oṣiṣẹ ajọ agunbanirọ, yala lẹkun ijọba ibilẹ tabi oludari nipinlẹ; aṣẹ mi niyẹn."
Wọ́n bá yọ Daniẹli jáde kúrò ninu ihò kinniun, àwọn kinniun kò sì pa á lára rárá, nítorí pé ó gbẹ́kẹ̀lé Ọlọrun rẹ̀.
Èmi ni ìyá mi rán lọ da májèlé sínú ọbe orogun rẹ̀ tí orogun fi kú, èmi ni ìyá mi fi obí oogun rán sí àbúrò rẹ̀ tí àbúrò rẹ̀ fi jáde láyé, èmi ni mo dá ìja sílẹ̀ láàrin àwọn ìjòyè ìlú wa tí gbogbo wọn fi da ẹ̀yìn kọ ara wọn.
Atẹjade kan ti ẹgbẹ Shiite fisita sisọ loju rẹ pe, oun gbe igbesẹ naa lọna ati faaye gba iwadi nipa isoro to n koju wọn, paapa ẹjọ tawọn agbẹjọro awọn gbe ls sile ẹjọ eyi to da lori bijọba apapọ se kede pe oun ti fi ofin de ẹgbẹ ẹlẹsin musulumi naa.
irú oúnjẹ tí ó wà lórí tabili rẹ̀, ìjókòó àwọn ìjòyè rẹ̀, ìṣesí àwọn iranṣẹ rẹ̀ ati ìwọṣọ wọn, àwọn tí wọ́n ń gbé ọtí rẹ̀ ati ẹbọ sísun tí ó ń rú ninu ilé OLUWA, ẹnu yà á lọpọlọpọ.
Ǹjẹ́ Ọ̀gá Ògo tilẹ̀ ní ìmọ̀?
Ni ọjọ́ keje, ẹbí àti ará tún péjọ lati pari ọ̀rọ̀ ogún pin-pin, wọn pe ọmọ Bàbá jade pé ki ó wá mú ohun kan ṣoṣo ti ó fẹ́ ninú ẹrù Baba rẹ.
nítorí o ṣàìgbọràn sí àṣẹ mi ninu aṣálẹ̀ Sini.
Yatọ si pe wọn padanu ọpọ dukia, pupọ lara awọn eeyan naa lo n lo ọkọ oju omi lati de ile wọn nitori omi pe gba gbogbo opopona ti wọn lee gba kọja.
Omodan Abdel Wahab banu je, lori oro ti o sele ninu osu kejila odun ti o koja, nigba ti aworan fidio re jade lori ero ayelujara, eyi ti won fi bere pe, ki o korin lori Mashrebtesh Men Nilha, eyi ti adako re dale, n je o ti mu ninu omi odo Nile.
Saaju ni Aarẹ Buhari ti kede pe ki wọn tu ikọ olọpaa kogberegbe SARS ka ni Naijiria lẹyin ti iwọde naa ti n de awọn orilẹ-ede miran.
Ẹ̀gà tún bá iṣẹ́ rẹ̀ lọ.
18 Ìgbé 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 19 Ìgbé 2020 Oṣere tiata Yoruba, Muideen Oladapo fihan lori eto BBC Yoruba, ''Ṣe o Laya'' pe oun laya gbangba.
Ẹ fi ọlọ́pàá wa sáàrin ọlọ́pàá yín ní South Africa fún ààbò àjèjì - ìjọba Nàíjíríà bèèrè Oríṣun àwòrán, @Julisco_ Ijọba ilẹ Naijiria ti kesi ijọba ilẹ South Africa pe ko yara tete setan lati san owo gba ma binu fun awọn ọmọ Naijiria to fara kaasa ọpọ ikọlu lati ọwọ awọn ọmọ orilẹede rẹ.
Àwo ati abọ́ náà kún fún ìyẹ̀fun kíkúnná tí a fi òróró pò, fún ẹbọ ohun jíjẹ.
Ekiti 2018 Election:Irọ́ lásán ni ìgbẹ́jọ́ Fayemi tó jáwé olúborí
Agbára tí ó ń gbéraga sí yóo dópin.
Ọkọ Risikat oloju buluu naa ko sai tun se sadankata si aya gomina ipinlẹ Kwara, fun iranwọ to n se lati ri pe idile oun pada toro pẹlu itọju to n se fun wọn.
A pa àṣẹ ti àkọ́kọ́ tì nítorí kò lágbára, kò sì wúlò.
Saaju la ti sọ fun yin pe awọn janduku naa ya bo aafin ọba Akiolu lasiko isede tijọba ipinlẹ Eko kede rẹ tori iwọde EndSARS to di rogbodiyan.
Àkọsílẹ̀ orúkọ àwọn baálé baálé ninu àwọn ọmọ Lefi títí di ìgbà ayé Johanani ọmọ Eliaṣibu wà ninu ìwé Kronika.
bẹ́ẹ̀ sì ni ìlú Baalati ati gbogbo ìlú tí wọn ń kó ìṣúra pamọ́ sí, ati àwọn ìlú tí àwọn kẹ̀kẹ́ ogun rẹ̀ wà, ati ìlú fún àwọn ẹlẹ́ṣin, ati gbogbo ohun tí ó pinnu lọ́kàn rẹ̀ láti kọ́ ní Jerusalẹmu, ati ní Lẹbanoni, ati ní gbogbo ibi tí ìjọba rẹ̀ dé.
Odion Ighalo: Ẹlẹ́sẹ̀ ayò Ighalo ń ronú láti padà sí Super Eagles láìpẹ́
net Àkọlé àwòrán, Abu Musab Al-Barnawi ni akọbi ọmọ Mohammed Yusuf, iyẹn oludasile Boko Haram ti wọn pa ni ọdun 2009.
Kí ni ẹ óo ṣe lọ́jọ́ ìjìyà yíntí ìparun bá dé láti òkèèrè?
Iroyin sọ pe Tanko n fẹ ẹkunwo owo oṣu lọwọ ọga rẹ ni, ko to o gun-un pa.
 pópóọlá gbé akin , ilésanmí àti kọ ́ lá .
N kò ní ṣe ọ́ ní ibi mọ́, nítorí pé ẹ̀mí mi níye lórí lójú rẹ lónìí.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Èyí ni àwọn arẹwà ‘ẹ̀lẹ̀ Daddy’, àfẹ́fẹ́ tí Aláàfin fi ń mí APC kò ní olórí tí yòó tọwọ́ bọ̀wé, INEC yarí fún ìbò abẹ́nú l‘Ondo Ìhòhò ọmọlúàbí ni mo má a ń bá àwọn ọmọkùnrin mi wí - Elesho Ọ̀dàlẹ̀ ni Igbákejì Gómìnà, kìí ṣe pé a dẹ́yẹ si - ìjọba Ondo Onyeama, jọ̀ọ́ má bínú ìdẹ́yẹsí tá a ṣe torí pé o jẹ́ adúláwọ̀ - Ilé ẹ̀kọ́ Eton Gbadero tun gba ile ẹjọ to ga julọ ni Naijiria lọ lọdun 1977, ti wọn si fa ẹjọ ọhun wọ ọjọ kẹrindinlọgbọn oṣu Kẹwa ọdun 1978, nigba ti idajọ waye pe lootọ ni Eji Gbadero jẹbi ẹsun ipaniyan.
Oludije fun ipo gomina nipinlẹ́ Ekiti labẹ asia ẹgbẹ oselu APC, Ọmọwe Kayọde Fayẹmi, lo gbegba oroke ninu idibo naa, to si fi ẹyin oludije latinu ẹgbẹ oselu alatako, to sun mọ pẹki-pẹki, Ọjọgbọn Olusọla Ẹlẹka janlẹ̀, ẹni to n soju fun ẹgbẹ́ oselu to n sejọba lọwọ ni ipinlẹ naa, PDP.
Wọ́n dá a lóhùn, wọ́n ní, “Baba wa, iranṣẹ rẹ ń bẹ láàyè, ó sì wà ní alaafia.
O le ni miliọnu meji eeya to wo fidio naa laarin ọjọ meji ti wọn gbee si ẹrọ ayelujara You tube.
Ó bá dúró níbẹ̀ fún ọjọ́ meji.
Yorùbá ni “Alágbàtà tó nsọ ọjà di ọ̀wọn”, bi ilé bá ti wọn tó ni owó ti Abániwále má a ri gbà ti pọ̀ tó.
"Oríṣun àwòrán, john boyega/instagram John Boyega John Boyega, osẹre to jẹ ọmọ Naijiria ati Britain sọ pe ""awọn ọdọ ni Naijiria lẹtọ si iṣakoso rere, ati itọni."
Àìsan N30,000 owó oṣu f'óṣìṣẹ́ kò ní rọgbọ o- NLC Iléèṣẹ́ ológun ti ri òkú Ọ̀gágun Alkali tí wọ́n n wá nínú kànga Ọ̀rẹ́kùnrin mi fún mi ní àárùn HIV, mo sì gbẹ̀san NMA: Buhari ni iṣẹ ṣe lori ilera alabọde Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Aarẹ Donald Trump to n tukọ ilẹ America labẹ asia ẹgbẹ Republican ti lọ si orilé-ede Afhanista ni igba akọkọ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Yorùbá tone mark: Fífi àmì ohùn sí orí ọ̀rọ̀ Yorùbá ṣe pàtàkì Iya ọmọ ti wọn ji lọ naa sọ fun BBC pe wọn ko ti i ri ọmọ naa titi di bi wọn ṣe n sọrọ, ati wi pe ọmọ ti wọn ri ni Akure pe o sọnu kii ṣe ọmọ oun.
Bí Jesu ti ń rìn lọ lẹ́bàá òkun Galili, ó rí àwọn tẹ̀gbọ́n-tàbúrò meji kan, Simoni tí ó tún ń jẹ́ Peteru ati Anderu arakunrin rẹ̀.
"Lodi si ero mi, "" inu rẹ dun ọkan rẹ si balẹ nigba to ri mi mi o si le pa omije oju mi mọra bi mo se di mọọ Mukankuranga wa n wo ọjọ iwaju pẹlu ironu ọtun pe o ṣeeṣe\\ki oun le ri atunse si ibasepọ pẹlu ẹbi rẹ."
Àṣìṣe ló ṣẹlẹ̀ níbi ètò ìsìnkú Abba Kyari- FCTA Awa naa gba pe aṣiṣe lo waye nibi eto isinku ati lẹyin isinku olori oṣiṣẹ fun Aarẹ Buhari, Abba Kyari- FCTA Ileesẹ ijọba apapọ to n mojuto ọrọ Abujato jẹ olu ilu Naijiria ti sọrọ lori ohun to ṣẹlẹ nibi eto isinku Abba Kyari ni iboji Gudu nilu Abuja ni ana.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Nigeria Police: Àwòrán àwọn afurasí tí a fi léde kìí ṣe ayédèrú, a kàn dọọ́gbọ́n síi ni 3 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Oríṣun àwòrán, @PoliceNG Ileeṣẹ ọlọpaa orileede Naijiria ti sọ pe fọto awọn ọdaran to wa loju opo Twitter rẹ kii ṣe ayederu.
Ìtàn Manigbagbe: Àwọn àjakalẹ-àrun to ti wáyé rí ṣáájú Coronavirus Yewande bí'mọ tuntun jòjòló, Mercy Aigbe pàdánù èèyàn rẹ̀, Toyin Abraham fèsì lórí aṣoju NCDC Bí àwọn sọ̀rọ̀sọ̀rọ̀ lórí rédíò ní Rwanda ṣe ń dánilẹ́kọ̀ọ́ nípa àrùn Coronavirus rèé Ìjọba yóò lo BVN àtàwọn ọ̀nà méjì míràn láti pín owó ìrànwọ̀ fún aráàlú Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí kan sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
' Ipa ti Idiagbon ko lati fi iwa ọmọluabi mulẹ ni Naijiria Lẹyin ti ijọba ologun Olusegun Obasanjo gbe ijọba silẹ fun oloselu lọdun 1979, ti Shehu Shagari di aarẹ oniruuru iwa ibajẹ lo ti fidi mulẹ ni Naijiria.
Àwọn ìròyìn míì tí ẹ lè nífẹ sí Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Tọkọ-taya Aràrá: Àwọn èèyàn máa ń wò wá, ta bá fa ọwọ́ ara wa ní títì Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Awọn aṣeyọri rẹ ninu jija ẹṣẹ fihan pe idile rẹ gbajumọ tayọ ilu wọn nikan de gbogbo orilẹede Naijiria.
Nitori eyi, ki èniyàn hu iwà rere.
Gbogbo àwọn tí a ti yàn láti ní ìyè ainipẹkun bá gbàgbọ́.
Adajọ naa tun tesiwaju pe awon ẹri ti asofin Ademola Adeleke pe
Àìsàn Ibà Lassa ti gbẹ̀mi àwọn dókìtà méji àti àwọn ènìyàn mẹ́tàdinlógun mírànn ni ìpínlẹ̀ Kano àti Ondo.
Riyad Mahrez bowolu iwe adehun olodun marun ninu iko ohun pelu owo ti o to ọgọ́ta millionu owo euro (£60 million).
Awọn oloṣelu Naijiria ati Awada Kẹrikẹri Kete ti fọnran fidio Kọmisana yi lu oju ayelujara lawọn eeyan ti bẹrẹ si ni bu ẹnu atẹ lu u pe ẹkun eke lo n sun.
4m ''Lẹyin ti mo ṣalaye ipenija mi lagbo oṣelu tan, pasitọ Adeboye sọ pe ''ọmọ mi, ma foya, iwọ ni yoo bori, wa si wọle ibo gomina lẹẹkeji,'' Obaseki lo sọ bẹẹ.
“A o ko iko omo ogun ẹgbẹ̀wàá lo si ipinle Zamfara.
Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Ondo Election 2020: Ẹ wo àwọn olùdíje sípò gómìnà nípínlẹ̀ Ondo tó takò bàbá ìsàlẹ̀26 Owewe 2020 Fídíò, Wole Soyinka sọ ìdí tó fi ni òun a fi màálù Fulani ṣe súyà fáwọn èèyàn abúlé23 Owewe 2020 Fídíò, Akomolede àti Aṣa: Ọ̀rọ̀ Ẹ̀yán ni Bunmi Femi Amao ń kọ́ wa lórí ètò Akọ́mọlédè àti Àṣà lórí BBC Yorùbá24 Owewe 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Ìyàwó mi ló ṣì ń dáná, bu oúnjẹ mi, gé èékáná fún mi - Pásítọ̀ Adeboye Ǹjẹ́ o mọ iye ẹ̀bùn owó tí olúborí BBNaija yóò gbà lọ́dún yìí?
Ọwọ́ tẹ àwọn pásítọ̀ oniíṣẹ́ ìyanu èké méji nílùú Eko Saheed Balogun sìnkú ìyá rẹ̀, Ogogo ní ẹgbẹ́ agbábọ́ọ̀lù!
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Yollywood: Wo àwọn òṣèré Yoruba tí wọ́n bí ní ọjọ kan náà 20 Ẹrẹ̀nà 2020 Njẹ ẹyin mọ wi pe ọjọ kan naa ni wọn bi Mustapha Solagbade,Mercy Aigbe, Moyo Lawal ati Ibrahim Yekini?
Bawo ni ipalẹ̀mọ́ ọdún Kérésìmesì àti ọdún titun?
salaye pe lara idi pataki ti oun fi se abewo lo si ofiisi egbe akoroyin
Akeredolu lo fi ọrọ naa ledeloju opo Twitter rẹ lẹyin ti ileeṣẹ iroyin abẹlẹ kan kede rẹ.
Orji ni ẹni to jẹ gomina ana nipinle ọhun.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Dambe fight: ìdíje ìjà láàrin àwọn akóni tó n ja ẹ̀ṣẹ̀ Magu tun fi da awọn ọmọ Naijiria loju pe laipẹ laijina ni wọn maa tun ri iṣẹ ajọ EFCC sii lori awọn igbẹjọ to ti bẹrẹ tẹlẹ Ó ṣeésẹ kí ọkùnrin tó n mu àmujù ọtí ó maa lo ìwà ipá pẹ̀lú ìyàwó rẹ̀ Irú kí lèyì!
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Akomolede ati Aṣa lori BBC: Mọ̀ si nípa oríṣìí ẹ̀ka ìsọ̀rí ọ̀rọ̀ àti ìwúlò wọn Aya Peters sọ ohun ti apola orukọ jẹ lati ile iwe Ogba Junior Grammar school.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Wàhálà bẹ́ sílẹ̀ níbi ìpolongo Buhari ní Abẹokuta UNO bẹnu àtẹ́ lu ìdàdúró Onnoghen Inec: Kò sí ìká tí o kò lè fí dìbò, ṣáà tí tẹ̀ ẹ́ sójú ẹ dáadáa Igbimọ naa tun pinnu lati gbe igbimọ alabẹṣekele kan kalẹ lati wo awọn ẹsun ti wọn fi kan Onnoghen ati adele adajọ agba, Tanko Muhammad.
OLUWA ní,“A gbọ́ ohùn kan ní Rama,ariwo ẹkún ẹ̀dùn ati arò ni.
akin olúṣínà : Òun ni wọ ́ n máa ń pè ní akin Ọlófìn-íntótó , ọmọ olúṣínà .
Ọ̀dọ̀ fásitì jànkàn Oxford ló ti jáde Ẹ wo ohun tó yẹ kí ẹ mọ̀ nípa oògùn 'Sputnik V' Russia tó ń wo àrùn Coronavirus Titi di asiko yii ni ajọ eleto ilera agbaye WHO ni ko tii si oogu ati abẹrẹ ajẹsara kan ni pato ti iṣẹ ti pari lori é to le wo ajakale arun Covid 19 san bayii Mo fẹ́ kí Ọlọ́run fún wa ní ọmọ olójú búlúù si lẹ́yìn yìgì - Ọkọ olójú búlúù Afurasí lórí ikú Tolulope Arotile ti dé ilé ẹjọ́, èyí ni ẹ̀sùn tí wọ́n fi kàn án Ẹ̀yin gómìnà, Ifá nìkan ló le tọ yín sọ́nà láì kùnà lórí Amotekun - Babaláwo Kí ló ń ṣẹlẹ̀ lọ́wọ́ sí Mamman Daura àti ìlera rẹ̀?
Bakan naa ni awọn kan rọ awọn eniyan lati maṣe kẹgan ohun ti Sẹgun sọ, nitori o ṣeeṣe ki ijọba ti dunkoko mọ nitori pe o ṣe agbatẹru fun EndSars.
774,000 Jobs: Ọmọ Tinubu náà wà lára àwọn tí yóò agbani síṣẹ́ Oríṣun àwòrán, Lawma Lagos Ijọba apapọ ti yan Alaafin tilu Oyo, ọba Lamidi Olayiwola Adeyemi kẹta ati alaga ẹgbẹ awakọ ero nipinlẹ Eko, Musiliu Akinsanya, MC Oluomo, sinu igbimọ ti yoo mojuto eto igbani sisẹ nipinlẹ Oyo ati Eko.
Fun awọn miran, olowo lasan, to mọ eeyan ni.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Buhari: Iléeṣẹ́ ọlọ́pàá àti ológun ti kùnà lórí ètò ààbò Nàìjíríà 28 Èbibi 2019 Oríṣun àwòrán, Presidency Àkọlé àwòrán, Ifọrọwerọ pẹlu aarẹ Muhammadu Buhari Aarẹ orilẹede Naijiria Muhammadu Buhari sọ gbankọgbi ọrọ ninu ifọrọwerọ to ṣe lalẹ ọjọ Aje lori ẹrọ amohunmaworan ijọba apapọ, NTA.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Gbenga Adeboye:Àwọn olúlufẹ rẹ̀ sọ̀rọ̀ lóri ǹkan ti wọn pàdánù 30 Ìgbé 2019 Oríṣun àwòrán, Itu baba ita Àkọlé àwòrán, Gbenga Adeboye: Akọni nínú àwọn sọ̀rọ̀sọ̀rọ̀ pé ọdún mẹ́rìndílógún ní káà ilẹ̀ lónìí Elijah Oluwagbemiga Adeboye ti gbogbo ènìyàn mọ si Fúnwọntán, Alhaji pastor Olúwo, Abẹfẹ, Jengbetiele, Itu baba ita, Alaye mi Gbengulo pé ọdún mẹ́rìdínlógún lónìí to di olóògbé.
"RUGA, Ruga tí wọ́n ń pariwo kò lè tó awọn 500,000 Fulani tó wà nínú igbó""."
 Èyí ló sì tún fà á tí olùpilèsè náà fi féran láti máa je èkuru .
Ọpọ àwọn olugbé ìpínlẹ Eko pàápàá jùlọ àwọn ènìyàn àgbègbè ọgba, Agege, Abesan, Ipaja, Ayobo lo ti gba ori twitter kan pe awọn o loju oorun mọ nitori iwa ìdigun jale to kún àdúgbò náà Oníruuru fọnran ló lu orí àtẹjisẹ twitter pa láti fi han bi olúkúlùkù ṣe n se ààbò lóri àdúgbò wọ́n.
Nígbà tí Farisi tí ó pe Jesu wá jẹun rí i, ó rò ninu ara rẹ̀ pé, “Ìbá jẹ́ pé wolii ni ọkunrin yìí, ìbá ti mọ irú ẹni tí obinrin yìí tí ó ń fọwọ́ kàn án jẹ́, nítorí ẹlẹ́ṣẹ̀ ni.
Ọgbẹni Bukọla Ọlọpade, ọkan lara awọn ẹgbẹ Igbimọ to n ṣamojuto Idije ere Idaraya ori Papa ile Afirika, ti wọn pe ni “African Athlethcs Championship, ti ọdun 2018” to waye ni ilu Asaba, ni Ipinlẹ Delta ni o sọrọ iṣiti yii, nigba ti o n ba awọn oniroyin sọrọ ni ilu Asaba, Ọgbẹni Ọlọpade wa fi iṣẹ akinkanju ile-iṣẹ Rite  Foods Limited ṣe apẹẹrẹ ti wọn ṣe agbatẹru inawo ohun jijẹ ati mimu fun awọn elere idaraya nibi idije naa.
Ẹnikẹ́ni tó bá fẹ́ wọnú ilé Ọlọrun, pípa ni kí ẹ pa á.
Àwa ati àwọn ẹran ọ̀sìn wa kò ní yà kúrò ní ojú ọ̀nà wọ inú oko yín, tabi ọgbà àjàrà yín.
Jesu bá bá a wí, ó ní, “Pa ẹnu mọ́, kí o jáde kúrò ninu ọkunrin yìí.
Omotola Jalade ní Nàìjíríà dàbí ọ̀run àpáàdì lábẹ́ ìjọba Buhari Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Helen Paul sọ idi tó fi gba orúkọ ní kékere Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Hakeem: Mo lè sọ arúgbó dí ọmọge nígbà tó bá wù mí Atiku ti sọ tẹlẹ pe oun ṣetan lati kọwọ rin pẹlu awọn akọṣẹmọṣẹ onimọ ẹrọ Kọmputa lọ sibi igbẹjọ lori idibo aarẹ to kọja lọ ti o pe.
O fikun ọrọ rẹ pe ẹran adiẹ ati tolotolo naa wulo nitori wọn maa n dena arun ninu ara.
Lasiko yii lọdun ti a wa yii, awọn ọmọ ijọ Katoliki ni Naijiria n lo ọjọ eeru lati fi ṣ'ọfọ awọn to fara gba ninu gbogbo iwa ipa to damu orilẹede yii.
Àwọn ẹ̀yà Josẹfu bá dáhùn pé, “Ilẹ̀ olókè yìí kò tó fún wa, bẹ́ẹ̀ ni àwọn ará Kenaani tí ń gbé pẹ̀tẹ́lẹ̀ ní kẹ̀kẹ́ ogun tí wọ́n fi irin ṣe, bẹ́ẹ̀ náà sì ni àwọn tí wọn ń gbé Beti Ṣani, ati àwọn ìletò tí ó wà ní agbègbè rẹ̀, ati àwọn tí ń gbé àfonífojì Jesireeli.
Iro ni ile Amerika pa mo mi lori esun jibiti- Allen Onyema Uganda kó rọ́bà ìdáàbòbò mílíọ̀nù kan kúrò ní ìlú N'Golo Kante lo kọkọ gba bọọlu wọle fun Chelsea, ki o to di wi pe De Bruyne ti ikọ Man City da imọ mọ ru, ti o si gba bọọlu wọ inu awọn.
Nigba to di ọdun 1968 ti wahala naa yoo bẹrẹ, ogun abẹle ti n waye lọwọ ni Naijiria, ohun gbogbo ko ṣe deede mọ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Alaafin: Olori Aanu Adeyemi ṣàlàyé ìdí tó ṣe gẹ́ Oba Lamidi Adeyemi ti ìlú Oyo Koda, ọpọ osisẹ to n soju ijọba lo ti n gba riba, ti wọn si n mu ara ní araalu, paapaa awọn agbẹ.
Ó ṣe àwọn abọ́ ńlá ati ìjókòó wọn.
a nlù agẹrẹ lọjọ ọdun awọn ọdẹ .
Ọga ọlọpaa patapata to wa ni ẹkun olu ilu orilẹede naa Accra, DCOP Afful Boakye-Yiadom ṣalaye pe eyi ṣe pataki gan ni tori pe iṣọwọ ti eeyan fi n ni ibalopọ maa n ṣakoba fun agbara awọn ọlọpaa tori naa wọn nilọ okun ati agbara fun iṣẹ lasiko idibo.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Sotitobire: Ọkọ mi kò mọ̀ Jegede PDP rí, kódà kò fa ẹnikẹ́ni kalẹ̀ dípò Akeredolu- Bisola Apata ni NBA ṣetan lati ṣiṣẹ papọ fun idagbasoke Naijiria ati pe ki awọn eeyan le bọwọ fun ofin ati ẹtọ awọn ọmọ Naijiria.
Nígbà tí Rakẹli rí i, ó bẹ Lea pé kí ó fún òun ninu èso mandiraki ọmọ rẹ̀.
Barcelona vs Osasuna: Real Madrid gbadé ògo La Liga, Messi ní Barcelona ò lè ta pútú mọ́
Ọmọ-ọ̀dọ̀ náà ṣe oríire tí oluwa rẹ̀ bá bá a tí ó ń ṣe bí wọ́n ti rán an nígbà tí ó bá dé.
“Obi kopa fun iko agbaboolu ti o lamilaaka lati ojo kekere aye re, besini o ti gba orisirisi ife-eye gege bi agbaboolu, o si tun je akinkanju eni to n farajin fun ise re.
"Lásìkò tó ń ba àwọn akọròyin sọ̀rọ̀ lọ̀rí ọ̀rọ̀ to ṣẹ̀lẹ̀ nínú oṣù kọkànlá òsu 2018, ọgá àgbà pátápáta fawọn aṣọbodè sọ pé "" kíkọ ààdọ́jọ mílíọ̀nù náírà owó àbẹ̀tẹ̀lẹ̀, sàfihan àwọran òṣìṣẹ́ aṣọ́bode tó ti gbà àtúnṣe, ti wọn sì ń fi ọ̀rọ̀ àrá ìlú sáájú ju imọ̀ tara ẹni nikan lọ."
Idahun ranpẹ: Wọn ti ka a fun igba akọkọ nile igbimọ aṣofin.
Bẹẹ ba gbagbe, lọdun 2019 ni ijọba ipinlẹ Ọyọ fa awọn alaga kansu latinu ẹgbẹ oselu APC, labẹ saa ijọba ana lọ sile ẹjọ pe, ki ile ẹjọ ka wọn lapa ko, ki wọn si maa pada si ipo alaga mọ.
Tí a fiṣọwọ́ ní 17:43 14 Sẹ́rẹ́ 202117:43 14 Sẹ́rẹ́ 2021 Ìjọba àpapọ̀ pàṣẹ kí ilé-ẹ̀kọ́ wọlé ní ọjọ́ 18, oṣù kíní ọdún.
"Mo fẹ́ kí Ighalo gba ife pẹ̀lú Manchester United kó tó kúrò lọ́dún 2021- Solskjaer Ronaldo Brazil làgbà gbogbo agbábọ́ọ̀lù, kì í ṣẹgbẹ́ ẹ Messi àti Ronaldo- Roberto Carlos Arsenal rántí ""Invincibles,"" ó pé ọdún mẹ́rìndínlógún tí Arsenal gba ife Premier League Àràmọ̀ndà agbábọ́ọ̀lù tó ń jẹ Messi, ó ju Ronaldo lọ lórí pápá- Jurgen Klopp Ẹlẹsẹ ayo Ighalo ni oun kede ifẹyinti tẹlẹ nitori Naijiria jina si China nibi ti oun ti n gbabọọlu fun ikọ Shanghai Shenshua."
Ìbànújẹ́ ni ohùn ọmọ wa tí a gbọ́ jẹ́ fún wa - Nathan Sharibu Oríṣun àwòrán, ISAAC LINUS ABRAK Àkọlé àwòrán, Awọn kan ninu awọn obi awọn akẹkọbirin Dapchi n sukun ayọ Ìbánújẹ, ìpòrúuru, ìrètí àti ìmọkanle ní àwọn ìmọlára tí ènìyàn yóò ni bí ènìyàn bá dé ilé àwọn Baba Leah, lẹ́yìn ti fọnran ohùn Leah jáde fún ìjọba oríilẹ̀-èdè Nàìjíríà.
Ṣugbọn Mose wí fún OLUWA pé, “OLUWA mi, n kò lè sọ̀rọ̀ dáradára kí o tó bá mi sọ̀rọ̀, bẹ́ẹ̀ náà sì ni lẹ́yìn tí o bá èmi iranṣẹ rẹ sọ̀rọ̀ tán, nítorí pé akólòlò ni mí.
“Ti a ba wo iye awon omo egbe  ti a ni bayii, a o ri I pe , a si wa leyin pupo.
Lónìí, mo yà KFC lọ nítorí ebi ni.
Kì wọn tó kùrò ni Ifẹ̀, wọn mú àádọta ènìyàn pẹ̀lú wọn, ṣùgbọ́n ìgbà tí wọ́n dé Iléṣà ti Ajíbógun dúró, ẹ̀gbọ́n rẹ̀ fún un ní ọgbọn nínú àádọ́tà ènìyàn náà.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Orangun: Èdè àti àṣà Yorùba ní láti jọ wá lójú Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Àṣìkà ìṣirò èsì ìbò ààrẹ nípìnlẹ́ẹ̀ 11, ló fa ìjákulẹ̀ mi - Atiku Buhari o, pèsè ohun tó yẹ sí ọgbà ẹ̀wọ̀n, kí àyípadà orúkọ wọn léè pegedé Ọdẹ ìbílẹ̀, OPC àti agbófinró ń pèèlò tí yóò se ọbẹ̀ ààbò jinná nílẹ̀ Yorùbá Gẹgẹ bii ileeṣẹ ọlọpaa ni ipinlẹ Benue ṣe fi to araalu leti, awọn marun to ku yii kagbako iku wọn lasiko ti awọn kan fi lọ gbẹsan ikọlu wọn laarin ileto Amaafu, Sati Agirigiri ati Ikurav Tiev ni ijọba ibilẹ Katsina-Ala.
Ó ti àwọn ọ̀pá náà bọ inú àwọn òrùka tí wọ́n wà lẹ́gbẹ̀ẹ́ àpótí ẹ̀rí náà láti máa fi gbé e.
Energy Drink: Ìjọba fi òfin de èyí tó ń mú ǹkan ọmọkùnrin le
O tun kilọ fun Gomina Wike ninu atẹjade naa pe ki o maa gbe oṣelu bo ba a o pa a, boo ba o bu lẹsẹ wa si ibi idibo gomina ipinlẹ Ondo.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Sextuplet: Àdúrà Ìbùkún ló kú lẹ́yìn ọmọ mẹ́fà yìí- Ifeoma Thelma àti Onyemaechi Chiaka Nigba to di ọjọ kinni, osu keje, awọn ọlọpaa ya bo awọn agbẹ ni Olorunda, lẹba Akanran nilu Ibadan, ti wọn si n kọrin pe awọn yoo fi oju awọn agbẹ naa ri mabo.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ondo disability: Kò sí ẹni tí àkàndá kò lè ya ilé rẹ̀- Ayọdele Wọn ṣe eyi ni iranti olori ijọba ologun lorilẹ-ede Naijiria nigbakan ri, Ọgagun agba Murtala Muhammed to ku ni ọdun 1976.
Iléeṣẹ́ ọlọ́pàá ní ọwọ́ ko ti tẹ àwọn afurasí to jí olórí ìlú Buhari gbé
"Ko si ẹni kankan to n soju Arewa, Guusu tabi Ila oorun, nnkan ti mo nsọ ni pe, wọn ni awọn n soju ibẹ sugbọn irọ ni.
Olówó-ayé fi orí lé ọ̀nà igbó Olódùmarè ojú rẹ̀ sì le koko bí ojú ẹni ebi ń pa.
Ẹfunroye Tinubu - Ògbóǹtagí oníṣòwò, olówò ẹrú àti afọbajẹ Samuel Ajayi Crowther, òjíṣẹ́ Ọlọ́run tó gbé èdè Yoruba lárugẹ Mọrèmi Àjàṣorò, akọni obìnrin tó gba Ilé Ifẹ̀ sílẹ̀ lóko ẹrú Ọ̀rọ̀ǹpọ̀tọ̀niyùn, Aláàfin obìnrin àkọ́kọ́ rèé, tó ní nǹkan ọkùnrin Ireti awọn ọmọ Naijiria ni pe ko yẹ ko si ohunkohun ti yoo maa da aarẹ lọwọkọ mọ lati yan awọn ọmọ igbimọ alasẹ rẹ, ki eto isejọba lee tẹsiwaju laisi idaduro rara.
A mọ ìfẹ́ tí Ọlọrun ní sí wa, a sì ní igbagbọ ninu ìfẹ́ yìí.
“Ẹ fi ọpẹ́ fún Ọlọrun ninu àwùjọ eniyan,ẹ̀yin ìran Israẹli, ẹ fi ọpẹ́ fún OLUWA.
Èyí wáyé lẹ́yìn ti ọ̀pọ̀ àwọn ọmọ ẹgbẹ́ alátakò ń ṣe ìwọ́de lórilẹ̀-èdè náà, òfín tuntun yìí jẹ ọ̀nà láti dẹ́kun ìwọ́de wọn.
Bí bẹ́ẹ̀ kọ́, wọn yóo fi ẹsẹ̀ tẹ̀ wọ́n mọ́lẹ̀, wọn yóo sì pada bù yín jẹ!
Ọba bá rán ọ̀gágun kan ati àwọn aadọta ọmọ ogun rẹ̀ kí wọ́n lọ mú Elija.
Àkọsílẹ̀ yìí di òfin fún gbogbo àwọn tí wọ́n wà ní ìgbèríko, kí àwọn Juu baà lè múra láti gbẹ̀san lára àwọn ọ̀tá wọn ní ọjọ́ náà.
Ǹ jẹ́ o mọ iye ìgbà tí Super eagles àti Argentina ti pàdé?
Ọpọ lo koro oju si ijọba pe awọn lo ni ki ole wa ja, awọn naa lo tun ni ki oloko waa mu un.
Awọn abuda rere Da Rocha lo yẹ ki awa naa fi se awokọse rere, ka si tun jẹ ọmọ ti yoo sọ ọla di pupọ, dipo ka jẹ agboju logun ati akotileta.
Mo bá dìde, mo jáde lọ sí àfonífojì.
Awon meji miiran ti won tun daruko ni won fi sile tori pe, won ko ni eri kan gboogi tako won.
Lẹ́yìn náà, Joṣua fi idà pa wọ́n, ó so wọ́n kọ́ orí igi marun-un, wọ́n sì wà lórí àwọn igi náà títí di ìrọ̀lẹ́.
Mílíọ́nù mẹ́wàá Náírà ni ilé ẹjọ́ ni kí Kábíyèsí san gẹ́gẹ́ bí owó ìtaran ilẹ̀ tí ó gbà lọ́nà àìtọ́ SERAP ké sí ìjọ̀ba láti mú àdínkù bá owó ìná ìṣèjoba Ẹran ara ọlọ́pàá di èkìrí ẹran súyà, wo àwọn tó jẹ́ níbẹ́.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Disability: Àwọn òbí mi gbìyànjú títí ní kékeré mi ṣùgbọ́n .
Olori ajọ to n ri si ọrọ ilẹ nipinlẹ Kwara idi niyii ti ijọba ṣe wo ile naa lẹyin ti Gomina AbdulRahman AbdulRazaq ti gbaṣẹ lati gba ilẹ naa pada.
Ìgbéyàwo Irìnkerindo pẹ̀lú àbúrò olókun iwin inu omi
Saulu mọ̀ pé Dafidi ni ó ń sọ̀rọ̀, ó bá bèèrè pé, “Dafidi ọmọ mi, ṣé ìwọ ni ò ń sọ̀rọ̀?
”Ojogbon Yemi Osinbajo wa seleri wipe ijoba apapo yoo ri daju pe gbogbo eto wa ni sepe lojuna ati laseyori leyin idije naa.
Ní òru ọjọ́ náà gan an, ó dìde ó kó àwọn aya rẹ̀ mejeeji, àwọn iranṣẹbinrin mejeeji ati àwọn ọmọ rẹ̀ mọkọọkanla, ó kọjá sí ìhà keji odò Jaboku.
Ọba dá wọn lóhùn pé, “Mo mọ̀ dájú pé ẹ kàn fẹ́ máa fi ọgbọ́n fi àkókò ṣòfò ni, nítorí ẹ ti mọ̀ pé bí mo ti wí ni n óo ṣe.
Lagos-153 Ondo-76 Edo-54 FCT-41 Enugu-37 Rivers-30 Benue-24 Osun-20 Kaduna-15 Kwara-13 Abia-9 Borno-8 Plateau-6 Taraba-5 Ogun-3 Kano-3 Kebbi-2 Nasarawa-2 Bayelsa-1 Gombe-1 Ènìyàn 575 ló tún ti ní ààrùn Covid-19 ní Nàìjíríà 06/07/2020 Esi ayẹwo ajakalẹ aarun Coronavirus ti ajọ NCDC fi sita lọ̀jọ̀ Aje fihan pe, ọrinlelẹẹdẹgbta ati maarun (575) eeyan lo tun ti ni aarun naa ni Naijiria.
Eto idibo n lo ni  Irowo -IroseAwon oludibo , koda ko yo awon arugbo sile, ti won jade lati wa dibo won ni ile idibo to wa ni Orolu ward .
10 Rántí, àwọn ọkàn ṣe iyebíye púpọ̀ níwájú Ọlọ́run;
Lasiko ti oloogbe naa ṣi n ṣe saa lori alefa gẹgẹ bii gomina nipinlẹ Ọyọ, oniruuru awuyewuye lo waye lasiko naa nipa awọn igbesẹ kan ti ijọba rẹ gbe.
Gẹgẹ bi ohun ti wọn sọ, ọja Komputa ati ohun to jọ mọ imọ ẹrọ kii ṣe ibi ti wọn ti n yan iyalọja.
Kàkà bẹ́ẹ̀, ńṣe ni kí ẹ para dà, kí ọkàn yín di titun, kí ẹ lè mòye ohun tí ó jẹ́ ìfẹ́ Ọlọrun, tí ó dára, tí ó yẹ, tí ó sì pé.
Bi o ti le je pe, Nadal fowo seese nipele keta idije ohun, ki o to fakoyo lati gbo ewuro si  Thiem loju ninu asekagba idije naa lara oto.
igbimo naa tun menu ba bi ajo eleto idibo INEC, se sun ojo eto idibo siwaju si
A máa lépa wọn, a sì máa kọjá wọn láìléwu,ní ọ̀nà tí ẹsẹ̀ rẹ̀ kò tẹ̀ rí.
Bakan naa ni agba amofin to wa lara ikọ agbẹjọro Atiku, eyiun amofin Mike Ozekhome naa fidi rẹ mulẹ pe ẹjọ ti Atiku ati PDP pe kii se ofuutu fẹẹtẹ, aasa ti ko ni kaun rara, nitori pe ẹjọ naa lẹsẹ nilẹ, to si tun lowura pẹlu.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Fadá méji, ọmọ ìjọ 13 kú nínú ìkọlù darandaran Gani Adams kilọ f'awọn darandaran Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Lara awọn oju ọna ti wọn gbe jade pe awọn fẹ tun se ninu owo na to kan ilẹ Yoruba lati ri: N5,666,666,666.
Bakanna lo ni gbogbo ẹka SARS teleri ri to wa labẹ ti bọ si abe FSARS pẹlu iyipada tuntun yi.
Ọ̀rọ̀ ẹnu ọlọ́gbọ́n a máa bu iyì kún un,ṣugbọn ẹnu òmùgọ̀ ni yóo pa á.
“Ẹ máa yìn ín ẹ̀yin eniyan OLUWA, gbogbo ẹ̀yin orílẹ̀-èdè,nítorí pé yóo gbẹ̀san lára àwọn tí wọ́n bá pa àwọn iranṣẹ rẹ̀.
Lẹyin ti ko gba pe wọn ko jẹbi lo ni ki wọn ko gbogbo wọn lọ si ọgba ẹwọn ọlọpaa SARS, ti o si sun igbẹjọ naa si ọjọ kejila, oṣu kẹwaa, ọdun yii.
lorle-ede Venezuela laarin omo-ogun ijoba orile-ede naa ati awon ololufe egbe
Ki gan an ni pataki ileeṣẹ agbegbe (constituency office) fun aṣofin?
Mali yoo waako pẹlu ẹgbẹ agbabọọlu Italy nipele komẹsẹoyọ ẹleni mẹjọ bayii lọjọ Ẹti.
Irú èrò yìí lè wa si yín lọ́kàn sugbon o tini lójú láti béèrè.
Nígbà náà ni talaka opó kan wá, ó dá eépìnnì meji tí ó jẹ́ kọbọ kan sinu àpótí.
Chike nigba to n rojọ nile ẹjọ sọ pe awọn ọmọ oun sọ fun oun pe iya awọn maa n gbe ọkunrin wa sile, ti awọn mejeeji si jọ maa n tilẹkun yaara ibusun pa mọra wọn.
Gbogbo ẹ̀yin orílẹ̀-èdè láti òkèèrè, ẹ máa bọ̀,gbogbo yín ẹ máa bọ̀ bí ẹranko inú ìgbẹ́, ẹ wá jẹ àjẹrun.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Wo ẹ̀bùn àti owó tí àwọn olùkópa ti jẹ lórí ètò BBNaija season 5 Kíni 'Ẹ̀lẹ̀ daddy' Olorì Abbey Adeyemi ṣe tí ojú òpó ayélujára Instagram rẹ̀ fi ń yeruku lálá?
Lilo oyun inu fun abẹrẹ ajẹsara Covid-19 A tun ti ri awọn iroyin kan to sọ pe ẹdọforo oyun ti wọn ṣẹ yoo jẹ ọkan lara awọn eroja ti wọn yoo fi po abẹrẹ ajẹsara Covid-19 ọhun.
Bakan naa lo fi kun un pe eeyan ogun ni aarun naa tun ti pa.
Nigbẹyin gbẹyin, awọn mejeeji ni ile iwosan Virtua Our Lady of Lourdes ni Camden parọ kindirin wọn, koda ile iwosan ni ara awọn mejeeji ti bọ wa s'ipo bayii.
 Aare ko ni  da si liana eto idibo tabi se ojusaaju lona ti
gomina naa loju wipe awon yoo sa ipa won lati satileyin ni kikun fun won lojuna
O mẹnuba ohun tó ni lọkan lati ṣe fun itẹsiwaju LAUTECH ki eto ẹkọ le dara sii ni Ọṣun.
Wọ́n kó gbogbo ti’lé tà tán, gbogbo orílẹ̀ tí í ṣe ti adúláwọ̀ wá kó si gbèsè rẹpẹtẹ.
Oludari ileeṣẹ naa, Abayomi Omomuwasan toun naa farahan niwaju igbimọ aṣedajọ ipinlẹ Eko lori awọn iṣẹlẹ pataki to waye lọjọ Aje fi apoti kan han igbimọ naa eyi to ni ẹrọ ayaworan CCTV wa ninu rẹ to ya fidio gbogbo nkan to ṣẹlẹ ni Lekki Tollgate lọjọ ti wọn yinbọn.
Coronavirus and sport: Paul Onuachu ni agbábọ́ọ̀lù Super Eagles Nàìjíríà àkọ́kọ́ tó lùgbàdì Covid 19
O ni ajọ NBC ti fawọn leti lọpọ igba paapaa lasiko eto idibo Naijiria to kọja ki wọn le so ewe agbejẹ mọwọ.
“Ẹ ṣọ́ra lọ́dọ̀ àwọn amòfin tí wọ́n fẹ́ máa wọ agbádá ńlá.
 Asiko ti to ki ipinle Eko wa ona miran lati mu owo wole ki ilana ofin ti yoo gbe e kale le lo bi o ti ye”.
Ọpọ awọn ọmọ Naijiria si lo n koro oju si ijọba apapọ pe o gba Ileesẹ South Africa laaye, lati maa yan wọn jẹ nilẹ baba awọn.
O óo jọba láàrin àwọn ọ̀tá rẹ.
Abẹnugan ile asofin naa wa dupẹ lọwọ awọn aṣofin naa fun bi wọn ṣe parapọ lati tete buwọlu abadofin naa.
Ni ọsan ọjọ Abamẹta ni awọn aṣofin naa abẹwo si ile Ajimọbi to n bẹ ni agbegbe Oluyọle niluu Ibadan.
Ẹsun kẹta ni pe Obasa lo miliọnu lọna ọtalenigba o din meji naira (N258m) lati fi tẹ iwe ipe sibi ayẹyẹ ifilọlẹ ijoko ile asofin kẹsan-an nipinlẹ Eko, eyi to jẹ olori ile fun.
Ariwo rẹ ni ọkọ rẹ gbọ ti o si sare si ibi ti aya rẹ ti n fọ abọ sugbọn epa ko ba oro mọ.
Ó wa jẹ́ gẹ́gẹ́ bí ọba orílẹ̀èdè UK àti gbogbo àwọn ilú káàkiri àgbáyé tí wọ́n wà lábẹ́ UK nítorí àwọn Gẹ̀ẹ́sì ló mú wọn sìn.
Ni ipari o gboriyin fun ijoba ipinle Borno fun sisatileyin fawon agbe lasiko inira igbedide leyin ogun boko haram yii paapaa labe ise akanse anchor borrower yii ki opolopo le je anfaani e.
Nitori eyi, bi wọn kò ti ẹ̀ lọ si ilé Aláró, Olósùn àti Ẹlẹ́fun, àwọ̀ wọn á si wa bẹ̃, síbẹ-síbẹ, àwọn ẹiyẹ wọnyi gbiyànjú lati lọ si ibi ti wọn ti lè ri ohun ti yio tú ara wọn ṣe ki ó ma ba ṣa.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Olùdije ipò gómínà ní Ìpínlẹ̀ Ekiti, Kole Ajayi, jáde láyé 19 Èbibi 2018 Oríṣun àwòrán, FACEBOOK/BANKOLE AJAYI Àkọlé àwòrán, Wọn gbe olóògbé Bankole Ajayi lọ ilé ìwòsan níbi tí ó ti gbẹ́mìí mì Ọkan lára àwọn olùdíje tí ó kọkọ jáde fun ipò gomina lábẹ́ ẹgbẹ́ òṣèlu APC ní Ipínlẹ̀ Ekiti fun ibò tí ó ń bọ lọna yìí, Kole Ajayi, ti jáde laye.
Àwọn obinrin wọnyi ń kẹ́kọ̀ọ́ nígbà gbogbo, sibẹ wọn kò lè ní ìmọ̀ òtítọ́.
Ẹ múra gírí, kí ẹ sì mú ọkàn gidigidi.
Lẹnu ọjọ mẹta yi, Adesina ti n tako ọrọ si awọn to n bẹnu atẹ lu iṣejọba aarẹ Buhari to fi mọ awọn to ṣe iwọde RevolutionNow to ṣe apejuwe wọn gẹgẹ bi awọn ọmọdekunrin ati obinrin ati pe eremọde lasan lasan ni iwọde wọn jẹ.
Coronavirus ti di ara wa, kò le è kúrò mọ láéláé - WHO Ìdí rèé tí ilẹ̀ Afirika fi gbọdọ̀ kópa nínú dídán abẹ́rẹ́ coronavirus wò Adajọ yì ìgbẹ́jọ rẹ̀ padà lóri àtúndi ìbò Adamawa Olóṣèlú wọ gau torí pé o ní orí ààrẹ dàrú 'kò sí ààyẹ fún ẹkún' ''Kinaya ni orukọ ẹni ti a fi ọrọ wa lẹnuwo ṣugbọn kii ṣe orukọ rẹ nitootọ bi ko ṣe pe a pààrọ orúkọ rẹ̀ jẹ ẹni to n gbe ni ilẹ Gẹ̀ẹ́sì Awọn ebí rẹ̀ wá láti ìwọ -oòrun ilẹ Afríkà ní ibi ti àṣà ọmú lílọ tí ṣẹ̀ wá, ò sí jẹ ọkan nínú àwọn ti ó la irú ìṣẹ̀lẹ̀ yìí kọjá nígbà ti ó wà ní ọmọ ọdun mẹwàá."
Trump sọ fawọn ololufẹ rẹ pe eru wa ninu ibo aarẹ Amẹrika ninu eyi to ti fidi rẹmi.
Aare so pe  “A yoo sin orile ede Naijiria pelu  otitọ,ati pẹlu gbogbo  ọkàn ati agbara wa.
Ninu iwe naa to fi ṣọwọ si awọn oniroyin, Tinubu ni 'Niṣe ni ijakulẹ ọkan bami nigba ti mo ri wi pe o gbe igbesẹ to tako ọrọ ajọsọ wa.
Ni ọjọ Aje, ọjọ kẹrinla, oṣu kejila, ọdun 2020 lawọn ọmọ igbimọ oludibo alaṣẹ, Electoral College parapọ lati fi ontẹ lu ibo to gbe Joe Biden gẹgẹ bi aarẹ tuntun fun orilẹ-ede Amẹrika.
Oríṣun àwòrán, @cbngov_akin1 Ileesẹ ilẹ Amẹrika naa ni, ijọba orilẹede Naijiria lo n dina gbogbo igbiyanju wọn lati ri owo Abacha gba pada, eyi ti wọn tọpasẹ rẹ de ọdọ alaga ẹgbẹ awọn gomina fẹgbẹ oselu APC, tii tun se gomina ipinlẹ Bauchi ọhun.
Èèyàn 78 kú ó lé ní 4000 tó farapa níbi ìbúgbàmù tó wáyé ní Beirut, Lebanon Eniyan to to mejidinlọgọrin ni ijọba Lebanon ti kede pe wọn padanu ẹmi wọn ti awọn to le ni ẹgbẹrun mẹrin si farapa ninu ibugbamu to waye ni Beirut lọjọ Iṣegun.
Ṣe wọn ni inu ẹni kii dun ka paa mọra, Ọga wọda ni ipinlẹ Ẹnugu, Ọgbẹni Mustapha Attah ti ko lee pa idunnu rẹ mọra kan sara sawọn ẹlẹwọn to n lo asiko wọn ni ile ọgbọn naa lati fi tun igbesi aye wọn ṣe.
Ó ní òun jẹ́ eniyan ńlá kan.
Bí ó ti jé̩ pé s̩ís̩e àkíyèsí iyì tó jé̩ àbímó̩ fún è̩dá àti ìdó̩gba è̩tó̩ t̩í kò s̩eé mú kúrò tí è̩dá kò̩ò̩kan ní, ni òkúta ìpìlè̩ fún òmìnira, ìdájó̩ òdodo àti àlàáfíà lágbàáyé,
 Ti ijoba ba tun awon ona lati oko si oja se daadaa, ire oko yoo tete maa de arowoto awon oloja ati ki a tun eko ninu ona fif ire oko pamo se daadaa bii ti awon ile okeere”.
Ojú mi náà báyíí ni akọ̀wé sì fi fún un ní ìwe.
Wọn yóo máa wí pé, ‘Ọba ṣá ti ranṣẹ sí ayaba pé kí ó wá siwaju òun rí, tí ó kọ̀, tí kò lọ.
AMAA 2018 Ami eye ipese aso to dara julo
Kí n tó sọ̀rọ̀ tán ni ó ní, ‘ Tàbí ìwọ náà ti di obìnrin?
"O ni ""yala ẹnikẹni ro iku tabi iye ro o, gbogbo eeyan lo jẹ gbese iku ti wọn si gbudọ san, tori naa, ki lo de taa fẹ kanju tufọ rẹ nigba ti akoko rẹ ko tii to."
Ìgbà tí wọ́n wá dé òdì kejì náà wàyí ò, ni ìráńṣẹ́ Olódùmarè yí ara padà tí ó funfun báláú tí ó ga fíofío, ó dáhùn osì wí pé, ‘Nítorí ìwọ ṣe mi lóore yìí, láti òní lọ n o máa ránṣẹ́ wa láti òde ọ̀run ní ọdọọdún kí kí àwọn ìrańṣẹ́ mi máa sín yín ni gbẹ́rẹ́, kí kí Ilẹ̀ẹ́gbóná ma ba à bá yín jà mọ́, yóò sì ṣe, ẹni tí ó bá fi ara rẹ̀ sílẹ̀ fún gbẹ́rẹ́ sín sín yìí, kì yóò rí ìjà ṣọ̀pọ̀nnà bí gbogbo ènìyàn tilẹ̀ ń kú bẹẹrẹ.
Idajọ naa n waye lẹyin ọsẹ kan ti ileẹjọ dajọ pe awọn ọmọ ogun marun un ninu meje lo jẹbi ẹsun ipaniyan naa, nigba ti awọn meji gba ominira ni Ọjọ Kẹtadinlogun, Oṣu Kẹjọ, ọdun 2020.
Hesekaya ati ìjọ eniyan yọ̀ nítorí ohun tí Ọlọrun ṣe fún wọn, nítorí láìròtẹ́lẹ̀ ni gbogbo rẹ̀ bẹ̀rẹ̀.
Were naa n rin lọ loju titi nigba to sọ fun mi pe n o gbọdọ gba, ọdun 2007 lọrọ yii ṣẹlẹ,'' Obesere lo sọ bẹẹ.
Lẹ́yìn náà ó wá lọ sọ́dọ̀ àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀, ó sọ fún wọn pé, “Ẹ tún wà níbi tí ẹ̀ ń sùn, tí ẹ̀ ń sinmi!
Ibadan: awon araalu figbe bonu pe ilu doti Ọ̀pọ̀ àwòrán rèé tó ń sàfihàn bí Ibadan se kún fún ẹ̀gbin àti òórùn Cancer: Àṣe ara mi ni iso ti n run gbogbo bí mo ṣe n ṣèrànwọ́ lórí jẹjẹrẹ Oríṣun àwòrán, FACEBOOK Makinde ko fi ọ̀rọ̀ naa se ti ipo asaaju, funra ara rẹ loun naa bọ si ita gbangba lati mojuto eto naa lẹyin aṣẹ to pa fun awọn oṣisẹ ijọba ati oloselu naa, ti awọn osisẹ fun ile isẹ to n risi imọtoto ayika naa si kọwọrin tẹle Gomina Makinde lati ṣe eto gbalumọ ọhun.
Bẹ́ẹ̀ sì ni àwọn akọ̀wé, tí ń kọ̀wé láti ni eniyan lára;
Ti wsn o si da orilẹ-ede ti wọn, Oduduwa Republic silẹ.
Nigba ti alaga awon obinrin oniroyin ni Ipinle Oyo (Oyo
“Aaroni yóo fa akọ mààlúù kan kalẹ̀ tí yóo fi rú ẹbọ ìmúkúrò ẹ̀ṣẹ̀ fún ara rẹ̀, yóo sì ṣe ètùtù fún ara rẹ̀ ati ilé rẹ̀; yóo pa akọ mààlúù náà fún ẹbọ ìmúkúrò ẹ̀ṣẹ̀ fún ara rẹ̀.
Ninu ọrọ rẹ, Emmanuel Igbasan fikun wi pe epo bẹntiroolu ti ijọba gbe ọkan le lo mu ki wọn fi ọwọ yẹpẹrẹ mu awọn ohun alumọni ti Ọlọrun ti fi fun ipinle naa.
Òun ni ó kọ ìwé sí Akin Olúṣínà pé kí ó wá bá òun wádìí owó bàbá òun tí wọn kò rí mọ́.
Lagos Senatorial Elections: Abiru ṣ'àbẹ̀wò sí Tinubu lẹ́yìn tó wọlé àtúndi ìbò Sẹnẹtọ ìlà oòrùn ìpínlẹ̀ Eko
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: ‘Ọ̀rọ Baba Ọbasanjọ kò jọ wá lójú mọ́’ Mo lọ ilé ìwòsàn Gbagada láti ṣe ìrànwọ́ ni- Sanwo-Olu Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Mo ti gba kádàrá lórí bí Ọlọrun ṣe dá mi' Ọgbẹni Ogundamisi fikun ọrọ rẹ pe ọpọ eeyan to wa lati ilẹ Afirika ni ireti pe iṣẹ yoo sìn wọn bọ̀ ti Olootu ijọba May ba ṣe aṣeyọri pẹlu eto Brexit, nitori awọn eeyan miran ti wọn wa ṣiṣẹ nilẹ Gẹeṣi yoo pada sorilẹ-ede abinibi wọn.
Aṣọ òfì ni Yéwándé wọ̀ nígbà tó wọ́n ń ṣe ìwádìí yìí torí òtútù.
kí ó tó já Pizza: Èló ni yóò ná ọ láti ra ìpápánu Pizza wá láti London?
ti osise SARS hu yii, nitori naa ijoba fi n da awon eniyan loju pe awon ti  gbe igbesẹ lati rii pe awon afurasi ọdaran
Nítorí pé ẹnikẹ́ni tí ó bá fẹ́ gba ẹ̀mí rẹ̀ là, yóo pàdánù rẹ̀, ṣugbọn ẹni tí ó bá pàdánù ẹ̀mí rẹ̀ nítorí mi, òun ni yóo gba ẹ̀mí rẹ̀ là.
''Ọkunrin naa da bi ọrẹ si mi, o lu mi, o si fi ika atanpako rẹ meji bọ mi loju, lẹyin naa lo fipa bami lopọ ti ẹjẹ si bo mi.
Fr Mbaka, ọmọ ìjọ rẹ̀ kọ̀lu akọ̀ròyìn BBC, wọ́n lù wọ́n ní àlùdojúbolẹ̀ Àwọn jàndùkú ṣọṣẹ́ nílé aṣòfin ìpínlẹ̀ Ogun, wọ́n jí ọ̀pá àṣẹ gbé!
tẹlẹ ba gbọ eyi, o ṣeeṣe ko fẹsẹ fẹẹ ki ifẹ naa ka kuro loju rẹ Eyi ko ṣẹyin lilọ họsibitu lonii, họsibitu lọla, daku lonii, ji lọla, wọn ko ki n le sọ fun ẹnikẹni ju ki wọn bo o mọra wọn lọkan lọ.
Oyo Police: Àwọn àkẹ́kọ̀ọ́ náà jẹ́wọ́ pé ọmọ ẹgbẹ́ òkùnkùn Ẹyẹ ni àwọn
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Iná Èkó: Kò sí ẹni to le dá okú rẹ mọ̀ 29 Òkùdu 2018 Àkọlé àwòrán, ọ̀pọ̀ àwọn ebí ló bo ilé ìwòsàn Mainland bibà, lati wá àwọn olólùfẹ́ wọn.
"O ni ""Mo nifẹ awọn ololufẹ mi ni Naijiria pupọ, o si jẹ ibanujẹ lati gbọ nipa nkan to n ṣẹlẹ""."
Aarẹ Muhammadu Buhari ti ilẹ wa Naijiria ni ajọ to n se asepọ ni idi okoowo lẹkun iwọ oorun Afrika, ECOWAS, dibo yan gẹgẹ bii alaga rẹ nibi ipade ajọ naa to waye ni ilu Lome, tii se olu ilu orilẹ-ede Togo ni ọjọ isẹgun.
Ojisẹ Ọlọrun naa fikun pe, awọn elesinjesin gan ti kuna ninu gbigbe ogun tiwa ajẹbanu.
Àwọn olórí alufaa bá pinnu láti pa Lasaru, 
atunse lori awon kudie-kudie to ba ku , nitori eto  isejoba ko gbọdọ duro soju kan , nipa sise  eyi, yoo tun je ki eto idagbasoke tun ba wa ni
5 Àti pé ìgbàgbọ́, ìrètí, ìfẹ́ àìlẹ́gbẹ́ àti ìfẹ́, pẹ̀lú fífi ojú sí ògo Ọlọ́run nìkan, mú un yẹ fún iṣẹ́ náà.
 oníṣòwò ẹrú , williams ní ó ràá lọ ́ wọ ́ abass , tí ó sì múu lọ sí orílẹ ̀ èdè brazil .
    Àti ọjọ́ yìí wa ni Ẹlẹ́dàá ti ohun gbogbo tẹ́ mi lọ́rùn ní ilé mi, ṣùgbọ́n ìwọ ọmọ ènìyàn bí mo ti ri ọ lónìí inú mi dùn jọjọ, mo sì fẹ́ kí o wí fún àwọn ènìyàn rẹ kí ẹ tẹ̀lé mi kí ẹ wa lọ̀ mọ ilé mi.
Pelu iranwo orile ede China awon ibi igbafe yoo tun ni idagbasoke si i , ni eyi ti yoo se maa pese ise lopo janturu ati  eyi ti yoo tun jr ki osi di ohun afiseyin ti eegun n fi aso.
Awọn ẹlẹsin Kristieni ni wọn fi n sami ayẹyẹ ọjọ ibi Jesu Kristi.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Organisation of Islamic Cooperation: Àǹfààní wo ló wà nínú ẹgbẹ́ OIC?
Aàrẹ àná NMA, Francis Faduyile ní ìwọ́de 'End SARS' lè ṣe okùnfà àjàkálẹ̀ arùn covid 19 lẹ́ẹ̀kejì ní Nàìjíríà Ọlọ́pàá méjì dèrò ọ̀run nínú ìjàmbá ọkọ̀ l'Akure lẹ́yìn tí wọ́n kúrò níbi tí Akeredolu ti gba ìwé-ẹ̀ri moyege Ẹ wo èrò bìbà níbi ìwọ́de #EndSARS ní ìlú Ibadan Mo fẹ́ ìdájọ́ òdodo lórí ikú tó pa ọmọ mi- Baba ọmọ ti SARS pa Àwọn aṣòfín ní ìpínlẹ̀ Edo ti yọ Abẹnugan Ilé, Francis Okiye bí jìgá Ọjọgbọn Faduyile ṣalaye pe ti ajakalẹ arun ba bẹ silẹ lẹẹkeji, ọwọja rẹ maa n ṣaa ba le ju ti igba akọkọ lọ.
Ni ipinlẹ Rivers bakan naa, ko din ni eeyan mẹẹdogun taa gbọ pe o gbẹmi mi lasiko rogbodiyan to waye lawn ọpọ agọ idibo to wa yika ipinlẹ ọhun.
 Ijọba ologun yọ Bashir kuro lori aleefa ni ọjọ kọ̀kànlá, osu kẹrin leyin ti awon eniyan bere si n fi ifehonuhan lati lee  kuro lori aleefa leyin ọgbọ̀n ọdun ti o ti wa lori aleefa.
Bákan náà ni wọ́n gbọdọ̀ tọ̀rọ̀ àforijì lórí ọ̀rọ̀ náà.
ninu eto idibo gomina ati ile igbimo asofin to n bọ ni awon ipinle lorile ede
Ẹyọ oyún kan kò ní bàjẹ́ lára àwọn obinrin yín, bẹ́ẹ̀ ni ẹyọ obinrin kan kò ní yàgàn ninu gbogbo ilẹ̀ yín.
Ọba Ijipti ni ó lé e kúrò lórí oyè ní Jerusalẹmu, ó sì mú àwọn ọmọ Juda ní ipá láti máa san ọgọrun-un (100) ìwọ̀n talẹnti fadaka, ati ìwọ̀n talẹnti wúrà kan, gẹ́gẹ́ bí ìṣákọ́lẹ̀.
"Ogbontarigi agbabọọlu naa tẹsiwaju pe: ""Wọn ba mi fi nkan we e nileewosan."
 O je ohun itiju gbaa fun egbe oselu ti a kasi pe, omo egbe re poju lo  nile Afrika, ki o tun wa maa bebe fun ibasepo pelu egbe oselu keekeeke nitori ati gori aleefa ni papandodo.
Ní ọjọ́ kan, àwọn ọba Filistini kó ara wọn jọ láti rú ẹbọ ńlá kan sí Dagoni, oriṣa wọn, ati láti ṣe àríyá pé oriṣa wọn ni ó fi Samsoni ọ̀tá wọn lé wọn lọ́wọ́.
A ṣe bí wọ́n tí dá wa lẹ́bi ikú ni.
A gba gbogbo àwọn ìlú ńláńlá rẹ̀ nígbà náà, kò sí ìlú kan tí a kò gbà lọ́wọ́ wọn ninu gbogbo àwọn ìlú wọn.
Ṣé bí a bá dàgbà tán, à yéé ṣorò bí èwe!
CBN: Ẹ lè kò owó yín tó dọ̀tí lọ bánkì fún pàsípàrọ̀ ''Ọrẹbinrin mi jẹ́ mí ní ₦20,000 ní mò fí dáná sún àwọn ẹbí rẹ'' Àwọn ọmọge wọ gàù l'Abuja nítorí asọ péńpé Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
yóo ti ọ̀pá irin náà bọ inú ìkòkò ẹran, gbogbo ẹran tí ó bá yọ jáde á jẹ́ ti alufaa.
Awọn adajọ to n fi ipo iṣedajọ yan alailagbara jẹ tabi ti wọn sọ iṣedajọ di owo ree idajọ ree.
Ìjọba Nàìjíríà kìlọ̀ ìṣọ́ra ní ìlú London
Nitori eyi, ko mọ ibi ti wọn sin ọkọ rẹ si.
Eniyan meje lo padanu ẹmi wọn ti awọn mẹẹdogun miran si tun fara gb'ọgbẹ nigba ti ija kan bẹ silẹ lagbegbe Kasuwan Magani ni ijọba ibilẹ Kajuru ni ipinlẹ Kaduna.
Lẹyin eyi ni wọn ba din dundun iya fun iya agbalagba naa.
Àsọtẹ́lẹ̀ nípa Tire nìyí:Ẹ sọkún tẹ̀dùntẹ̀dùn, ẹ̀yin ọlọ́kọ̀ ojú omi ìlú Taṣiṣi;nítorí pé Tire ti di ahoro,láìsí ilé tabi èbúté!
 Ójẹ ́ òṣèré jẹ oṣere orí ìtàgé ọmọ ilẹ ̀ nàìjíríà .
Abalọ ababọ ọrọ naa, Chukwunonsọ jẹwọ pe oun ra awọn ọmọ naa ni lọdọ arabinrin kan nile awọn ọmọ alainiya kan nilu Jos toun si ko wọn wa si Eko.
Ó ti rán àwọn iranṣẹbinrin rẹ̀kí wọn lọ máa kígbe lórí àwọn òkè láàrin ìlú pé:
"Èsì ìdánwò òhun tí a ṣé síwájú là n bá fínra báyìí ní Nàìjíríà- Yemi Shodimu Dupe ni ""bi mo ṣe bi i tan, mi o tiẹ wo boya ọkunrin ni tabi obinrin."
Jakọbu rán àwọn oníṣẹ́ ṣáájú lọ sọ́dọ̀ Esau, ẹ̀gbọ́n rẹ̀, tí ó wà ní ilẹ̀ Seiri, ní agbègbè Edomu.
Ohun to ṣẹlẹ ni wi pe awọn eroja ara n tiraka lati gbogun ti arun Coronavirus naa, eleyii le fa ki awọn eroja ara bẹrẹ si ni ṣiṣẹ aṣeju, eleyii to ba ago ara jẹ.
o je ki won ti ile itoju Medecins Sans Frontieres (MSF) naa pa.
Títí di ọjọ́ mìíràn ọjọ́ ire, Emi ni tiyín ní tòótọ́, Ọmọba Onanusi Olusegun.
A ra kẹkẹ mii ni ẹgbẹrun lọna ẹgbẹrin naira tabi ko din diẹ, koda omiran, a n sanwo rẹ diẹdiẹ ni.
Ozo-Esan ni ko si ohun to kan ẹgbẹ oṣiṣẹ pẹlu igbimọ amuṣẹya ti aarẹ tun ni oun yoo gbe kalẹ lori ọrọ ẹkunwo oṣu tuntun naa.
O jẹ ohun to maye dẹrun fun ọgọọrọ eeyan to n gbe ni ilu Eko paapaa lasiko ọrọ aje to dẹnu kọlẹ.
Ẹ̀yin ọ̀gá, ohun tí ó dára ati ohun tí ó yẹ ni kí ẹ máa ṣe sí àwọn ẹrú yín.
Babalade to kopa ninu idije Africa Cup of Nations ni ọdun 1992, lo ku lojiji lẹyin ti o ni aisan ọkan.
Ó ti pe àwọn ẹbí ati àwọn tí ó jẹ́ ọ̀rẹ́ rẹ̀ tímọ́tímọ́ jọ.
INEC: Èsì ìdìbò Ekiti lẹ́kùnrẹ́rẹ́ Ẹlẹka: Ìdá àádọ́rin nínú ọgọ́rùn ni mo ní nínú ìbò Ekiti Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, #EkitiDecides: 'Ìjà ẹgbẹ́ òkùnkùn ló ń ṣẹlẹ̀ kìí ṣe ti òṣèlú' Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Kayode Fayemi : Awọn osisẹ ni Ekiti ko i tii gba owo osu ni ọdun yii Bákan náà ní wọn ti yàn abẹnugan mìíràn, Adeniran Alagbada nígbà ti wọn tún igbákejì abẹnugan tí wọn ti gbọ̀n yọ tele Segun Adewunmi pada sípò gẹ́gẹ́ bíi igbákejì abẹnugan ilé.
iṣẹ olukọ ko yẹ ko mu iwa ibajẹ bayii dani Ki lawọn eeyan n sọ nipa iṣẹlẹ yi?
Ẹgbẹ ile ijọsin kan, Freedom of Religion South Africa ni gidigba ni awọn wa lẹyin ile igbafẹ Beloftebos to kọ jalẹ fun awọn ololufẹ naa lati lo ile igbafẹ wọn.
Gbajugbaja onkọwe lede Yoruba Oladejo Okediji ti papoda lẹni ọdun mọkandinlaadọrun un.
" bi o tile je pe o ni : "" afojusun apileko oun yoo da le wujo yoruba ."
Ẹfunsetan Aniwura, obìnrin tó ju ọkùnrin lọ Ọ̀rọ̀ǹpọ̀tọ̀niyùn, Aláàfin obìnrin àkọ́kọ́ rèé, tó ní nǹkan ọkùnrin Lọwọ lọwọ, awọn ọlọpaa, oṣiṣẹ alaabo atawọn ọlọdẹ ibilẹ ti kan lu agbami iṣẹ wiwa Dayo.
Àwọn tí wọn kò dẹ́ṣẹ̀,ṣugbọn tí wọn ń rìn ní ọ̀nà rẹ̀.
Ṣé Fulani daran-daran ni àwọn tó n jí ènìyàn gbé ní ìpínlẹ̀ Ondo?
A máa mójútó ọjà tí ó ń tà,fìtílà rẹ̀ kì í sì í kú lóru.
Eyi ni igba akọkọ ti orilẹede France yoo de ipele aṣekagba idije ife ẹyẹ FIFA lati ọdun 2006 ti wọn ti fidirẹmi nigba ti wọn koju ikọ orilẹede Italy.
Akọroyin wa kàn si agbẹnusọ ileeṣẹ ọlọpaa ni Ipinlẹ Eko, Bala Elkanah lori ọrọ naa.
Ààrẹ Buhari ni orilẹ̀-èdè Nàìjíríà ń woye lọ́nà to gbòòrò, láti ba àwọn ọmọ ajọ ìsọkan àgbáye tó kù ṣiṣẹ́,eyi ti yoo mu ìtẹ̀síwáju ba ètò àlááfíà lágbàyé, ètò ààbò, dídènà wàhálà àti lati mú ki ìbáṣepọ̀ túbọ̀ gbópọ̀n si ni àgbáyé, riro àwọn ọ̀dọ́ àti àwọn obinrin lagbara, pẹ́lú fífàyè gba ẹ̀tọ́ ara ilú.
wa lara awon ajagunfeyinti nile-ise agbofinro lasiko ogun abẹle tun so pe lasiko
Iha wo wa ni Boris Johnson kọ si ilana kikuro ninu ajọ isọkan ilẹ Yuroopu laini adehun ninu?
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Àwọn àwòrán mánigbàgbé nípa ìdìbò abẹnu nipinlẹ Osun Ademọla Adeleke ni yóò sojú PDP nínú ìbò gómìnà Ọ̀sun Olùdíje méta yẹ̀bá nínú ìbò abẹ́lé APC l‘Ọ́sun Pade Okunọla di olùdíje fún ipò gómìnà fẹ́gbẹ́ Accord l‘Ọ́sun Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Bọlanle Aliyu: N kò nílò bàbá ìsàlẹ̀ láti di gómìnà O ni nigba ti wọn tun ibo naa ka ni ẹẹkeji, sebi ibo oun tun lowura ju ti akọkọ lọ, eyi to fihan pe eto idibo naa lọwọ magomago ninu, ti ko si tẹ oun ati awọn alatilẹyin oun lọrun.
Ó bèèrè alaafia wọn, ó ní, “Ṣé alaafia ni baba yín wà, arúgbó tí ẹ sọ̀rọ̀ rẹ̀ fún mi?
Ìṣòro pupọ ni yóo bá àwọn tí wọ́n bá bá a ṣe àgbèrè, àfi bí wọ́n bá rí i pé iṣẹ́ burúkú ni ó ń ṣe, tí wọn kò sì bá a lọ́wọ́ ninu rẹ̀ mọ́.
Nafa so pe, ijoba gbodo se ojuse re ni awon igberiko, nipa pipese awon ohun amayederun  bi: omi-ero, ina-mona-mona, ohun elo igbalode ni awon ile-iwosan,  lati le je ki awon ara igberiko le gbe igbe aye irorun.
Lẹyin igba naa, Aarẹ, Buhari ati awọn gomina mejilelogun (22) ni wọn pe sibi igbeyawo ọmọ gomina ipinlẹ Ọyọ ati tipinlẹ Kano ninu osu kẹta.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Ìgbé ayé rere Bàbá Sala ló jẹ́ kí ikú rọ̀ ọ́ lọ́rùn' Lowuro ọjọ aje ni ìròyìn tẹ̀ wa lọ́wọ́ pé gbajúgbajà òṣèré tíátà Yoruba ọkunrin nì, Alagba Moses Adejumọ gbekuru jẹ lọwọ ẹbọra.
Harry ní òun kò tíì mọ orúkọ tí wọn yóò sọ ọmọ rẹ̀ tuntun Ajimobi figbe ta, ó ní 'èmi kọ́ ló pa Ṣugar o!
“Ohun tí èmi OLUWA Ọlọrun Israẹli sọ nípa àwọn ará Juda tí wọ́n wà ní ìgbèkùn, àwọn tí mo ti mú kí á kó lẹ́rú láti ibí yìí lọ sí ilẹ̀ àwọn ará Kalidea, ni pé, n óo kà wọ́n sí rere gẹ́gẹ́ bí àwọn èso ọ̀pọ̀tọ́ dáradára wọnyi.
Èyí tí ó wí pé ìyàwó òun jẹ́ ọmọ tálákà ti lọ fẹ́ ọmọ olówó kan ṣùgbọ́n nígbà tí ọkùnrin náà fi máa yọ sí Aṣojú-Olódùmarè, kò ju pàṣán lọ nítorí ọkàn rẹ̀ kò bálẹ̀.
Oríṣun àwòrán, Twitter/@elrufai Àkọlé àwòrán, Gómǹà Elrufai sọ wípé ìgbésẹ̀ náà lótọ́ fún ìpínlẹ̀ náà Gómínà ìpínlẹ̀ Kaduna, Nasir El-Rufai, ti kéde kónílé ó gbélé ní ìgboro Kaduna àti àwọn agbègbè rẹ̀ nítorí ìjà tó bẹ́ sílẹ̀ ní ìlú náà.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Belarus Idibo ni Belarus nibi ti olori ilẹ naa, Alexander Lukashenko to ti wa nipo fun ọpọlọpọ ọdun tun bori lo fa wahala iwọde ni Belarus pẹlu bi ọpọlọpọ awọn eeyan ṣe n ni makaruru wa ninu idibo naa lati gbe Lukashenko O le lẹgbẹrun lọna ọgọrun un awọn eeyan to peju si Central Minsk, to jẹ olu ilu orilẹede naa fun ọjọ Aiku mẹrin ọtọtọ ni ṣiṣẹ n tẹle, bẹẹni o le ni ẹgbẹta eeyan tawọn agbofinro ti de mọ kulu ahamọ .
Ẹwẹ, ajọ to n ri si ere bọọlu ni Naijiria sọrọ loju opo Twitter rẹ pe ikọ Flying Eagles yoo gbiyanju lati fiya jẹ Ukraine ninu ifẹsẹwọnsẹ Ọjọbọ.
Ẹfunsetan Aniwura, obìnrin tó ju ọkùnrin lọ Ọ̀rọ̀ǹpọ̀tọ̀niyùn, Aláàfin obìnrin àkọ́kọ́ rèé, tó ní nǹkan ọkùnrin Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Tomomewo Favour: olóṣèlú kìí ṣe ọ̀daràn tàbí alágbèrè Èyí ẹ ṣe tó, England àti VAR júwe ilé fún Cameroon Ọ̀rọ̀ ti yanjú dé ibì kan lórí owó àjẹmọ́nú àwọn Super Falcons Iṣẹ́ ẹ̀mí ẹ̀tàn ló bàlemi lasiko tí mo sọ àṣọtẹ́lẹ̀-Simeon Ononogbu Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Nítorí náà gbogbo àwọn tí wọ́n bẹ̀rù ọ̀rọ̀ OLUWA ninu àwọn iranṣẹ Farao pe àwọn ẹrú wọn wálé, wọ́n sì kó àwọn ẹran ọ̀sìn wọn wálé pẹlu.
Netaneli ọmọ Suari ni olórí ẹ̀yà Isakari.
eyi gbọdọ dopin, ki atunto si wa, gbogbo awọn osisẹ ti ko ba ri isẹ se ni kijọba gbe lọ sawọn agbọn ti isẹ pọ si.
O ni koda, omi ọyan obinrin dara ju ti ẹranko lọ.
Funmilayo OgunsolaIjewuru ni adape orukọ Funmilayo Ogunsola ninu iṣẹ tiata, to si ti silẹ bora lọdun 2019 lati ipasẹ aisan ẹjẹ ruru to ba fínra.
Nígbà tí ó ṣe, ilẹ̀ ṣú, gbogbo àwọn ènìyàn wọn-ọnnì si ṣe ibùsùn sí etí adágún odò yìí, wọ́n sùnlọ.
Nǹkan mẹ́sàn án tí Mùsùlùmí gbọdọ̀ ṣe nínú oṣù Dhual- Hijjah O ti lé ní ènìyàn mẹ́wàá tí ina jó gúrúgúrú nínú ìjàmbá tó wáyé ní Delta Ilé Aṣòfin yóò pe Godswill Akpabio l'ẹ́jọ́ fún ìbanilórúkọ jẹ́ Ta ni Yusuf Satia ti iku mu lọ?
Ibinu ìwọ OLUWA mú kí inú mi máa ru,ara mi kò sì gbà á mọ́.
Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Alaafin of Oyo: Kí ni àjọṣepọ̀ tó wà láàrín Aláàfin, àwọn olorì àti àṣà igbá títí lóde Ọ̀yọ̀?
ni Ipinle kọọkan lati fowosowopo pelu won ki won ba le se aseyẹ talakan n sepo.
AfricanDrumFestival: Àwọn àwòrán tó làmìlaaka níbi ayẹyẹ
Oríṣun àwòrán, @ClemsonTigerNet Idi niyi ti orilẹede Amẹrika naa se f gba ẹsan lara Naijria, to si jẹ pe ileesẹ asoju ilẹ Amẹrika nikan ni wọn yoo maa san owo afikun owo ti wọ̀n fi n gbẹsan ọhun, ti wọ̀n pe ni ‘reciprocity fee’ naa si, kii se ile ifowopamọ kankan.
EndSARS Protest Update: Ọ̀gá àgbà ọlọ́pàá àti ọ̀gá àjọ ọlọ́pàá ń késí àwọn òṣìṣẹ́ wọn
Lẹ́yìn náà, OLUWA dìde bí ẹni tají lójú oorun,bí ọkunrin alágbára tí ó mu ọtí yó tí ó ń kígbe.
Saheed Oṣupa: Ọlọ́pọlọ pípé kò leè ṣe òṣèlú Nàìjíríà
Paulu bá jáde kúrò láàrin wọn.
Àwọn ohun tó yẹ kí o mọ̀ nípa Shehu Shagari tó d'olóògbé Dandan ní kí a mú Dino sí àhámọ wa- Ọlọ́pàá Àwọn ìmúra tó lààmìlaka ní Nàìjíríà lọdún 2018 Loju awọn mii, iku to n pa ojugba ẹni, owe nla lo n pa fun ni.
Derin Ẹlẹran ni àpèjá ti ọpọ awọn onibara rẹ maa n pèé.
Yatọ si pe o jẹ aṣofin, o tun di ipo Minisita fọr ọdọ ati aṣa ilẹ naa laarin ọdun 2012 si 2016 Ki lawọn eeyan n sọ loju ayelujara?
Dokita Evan Boyar ti ile ajọ awọn ile iwe Broward Health sọ fun awọn akọroyin l'ọjọru wipe wọn ti gbe awọn eeyan mẹtadinlogun lo si awọn ile iwosan l'agbegbe naa.
Mínísítà fún ìbáraẹni sọ̀rọ̀ àti ètò ọ̀rọ̀ ajé, Isa Pantami, ló sọ èyí di mímọ̀ nínú ọ̀rọ̀ to kọ sórí àtẹjíṣẹ́ twitter rẹ̀ lówùrọ̀ sátide.
Kí ni ẹní bá ga tó sì ní ẹsẹ̀ nlá ó wa ṣe?
"Lo ba tun kọ esi latẹ́nu akọwe ile pe ""Haha Ọga, ẹ ma ṣeyọnu, mo ti di i mu daadaa""."
Àdúrà mi ni pé kí Olódùmarè sọ agbára wọ́n di ọ̀tun.
Idije ti won gba pelu Poland naa ko wuni lori to nitori agidi ni won fi gba 1-0 ti Serbia si na won pelu 2-0 ni London.
e Ajọ INEC ati Ajọ SIEC ni ipinlẹ kọọkan
Nígbà tí ọkàn mí bàjẹ́,tí ọ̀rọ̀ náà gbóná lára mi,
Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold Covid-19: Ilé aṣojú-ṣòfin l'Abuja dábàá kí ìjọba sún ìwọlé àwọn akẹ́kọ̀ọ́ síwájú pẹ̀lú oṣù mẹ́ta Àwọn ìṣẹ̀lẹ̀ ńlà lọ́sẹ̀ tó kọjá tó fi mọ́ bí Covid-19 ṣe gbẹ̀mí èèyàn 23 lọ́jọ́ kan ṣoṣo Ọjọ́ orí wo ló yẹ kí ikùn ẹ̀dá bẹ̀rẹ̀ sí tóbi?
O ni ninu aadọjọ awọn oloogun oloro naa, mejila ninu wọn lo jẹ obinrin.
 o tun jẹ ede osise ni india .
Arabinrin mi dàbí ọgbà tí a ti ti ìlẹ̀kùn rẹ̀.
Ẹ kú ọ̀rọ̀ ìmùlẹ̀ yín tó di olóògbé
Lagos Tanker Accident: Ìjàmbá ọkọ̀ agbépo mú ẹ̀mí èèyàn kàn lọ ní Èkó, awakọ̀ tírélà f'ẹsẹ fẹ́ẹ
Ṣugbọn Jesu dá wọn lóhùn pé, “Ẹ kò kà nípa ohun tí Dafidi ṣe nígbà tí ebi ń pa òun ati àwọn tí ó wà pẹlu rẹ̀?
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Bí o ṣe lè fí òǹkà, ọ̀mọ̀ ìka tàbí ìkúùkù wọn oúnjẹ́ Bakan naa ni Aarẹ Buhari fi kun wi pe ijiroro naa n lọ lori Leah Sharibu ti ikọ Boko Haram naa jigbe ni ile iwe rẹ ni Dapchi ni ipinlẹ Yobe ni Ọjọ Kọkandinlogun, Osu Keji, ọdun 2018.
Oríṣun àwòrán, Pulse Àkọlé àwòrán, Ijọba gbọdọ gbé igbimọ alaabo kalẹ laarin awọn olugbe awọn adugbo ti agbara ojo ti maa n ṣọsẹ.
Pa èmi iranṣẹ rẹ mọ́ kúrò ninu ẹ̀ṣẹ̀ àmọ̀-ọ́n-mọ̀-dá;má jẹ́ kí wọ́n jọba lórí mi.
 Ìbò náà wáyé ní oṣù kẹ ́ wàá ọdún 2007 .
Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Ahmadu Ali Must Go Protest: Àfikún owó oúnjẹ akẹ́kọ̀ọ́ ní Fáṣítì fa ẹ̀hónú tó mú ọ̀pọ̀ ẹ̀mí lọ Kii se ìwọ́de ENDSARS ni igba akọkọ tawọn ọdọ yoo Sọrọ Soke tabi fi ẹhonu han, ti ologun yoo si koju wọn, o ti waye ri.
Ajọ INEC  tun fi to awon akoroyin leti pe gbogbo awon to
Muhammad Bande ni ọmọ orílẹ̀-èdè Nàìjíríà kejì tí yóò dé orí ipò náà, lẹ́yìn Joseph Garba tó jẹ ajagunfẹ̀yìntì, tó si tún jẹ asojú orílẹ̀-èdè Nàìjíríà lókè òkun.
Oríṣun àwòrán, Facebook/Seyi Makinde Nigba to n sọrọ lorukọ awọn onisẹse naa, Akọda Awo tilẹ Ibadan, Oloye Ifalere Ọdẹgbọla ni o ti le ni ọdun meji ti awọn ti gbe ibeere naa siwaju ijọba to kogba wọle.
recruitment process must be thorough and pick the best hands 2.
Adajọ naa tun fi han wipe ẹlomiiran yoo rọpo oun ninu igbimọ naa.
Ó ti tán fún mí lọ́dún 2023- Ààrẹ Muhammadu Buhari Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Ẹwẹ, ajọ ọlọpaa ipinlẹ Ogun ti sọ pe, ikọ SARS ipinlẹ naa ko mọwọ mẹsẹ ninu iṣẹlẹ ọhun.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Olori Badra sọ̀rọ̀ nípa ayé rẹ̀, ó ní ẹ́ bá òun sọkún Bàyíì ni mo ṣe kílọ̀ fún Donald Trump, àmọ́ kò gbọ́rọ̀ - Primate Ayodele Akọ tó fẹ́ akọ ṣayẹyẹ ìgbéyàwó ọdún kẹrin, wọ́n ra ilé kejì Jàndùkú ṣọṣẹ́ lọ́jà Agbeni, àwọn àti agbófinró kọjú ìbọn síra wọn Díẹ̀ ló kú kí owó tán l‘ápò mi torí ìrànwọ́ Coronavirus - Pasuma Mo ṣèlérí láti rí sí ìrẹ́pọ̀ àti ìwòsàn Amẹ́ríkà - Joe Biden Ìjọba Oyo gbé ilé ẹ̀kọ́ gíga kan tìpa torí àrùn Coronavirus Ayangburen tilu Ikorodu, Ọba Kabiru Sotobi tii se igbakeji alaga igbimọ lọbalọba naa, si lo sọrọ lorukọ awọn ọba alaye yoku to ko sodi, lọ si aafin Iga Iduganran lagbegbe Lagos Island.
Ọjọ́ orí mi kò tíì dé ibìkan lẹ́gbẹ̀ẹ́ ti àwọn baba mi.
Oníjàgídíjàgan ẹ̀dá ni yóo jẹ́, bíi kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ inú igbó, yóo máa bá gbogbo eniyan jà, gbogbo eniyan yóo sì máa bá a jà, títa ni yóo sì takété sí àwọn ìbátan rẹ̀.
Ìgbà yí ni àwọn òdòdó aláràbarà ń so lórí àwọn ewéko ab'òdòdó gbogbo.
Nọmba ara ọkọ ayọkẹlẹ wọn lasi fi wadi orukọ ati ibi ti wọn n gbe.
”Wọ́n dá a lóhùn pé, “A lè mu ún.
Àwọn ọmọ wọn ati arọmọdọmọ wọndi eniyan pataki pataki lójú ayé wọn.
Aya Trump naa, Ivanka gbadura wi pe ki Eleduwa tẹ Ọgbẹni Robert si afẹfẹ rere.
" Fun gbogbo awọn to n sọ pe Ooni ti bi Ọba lọla, Elebuibon sọ pe ti wọn ni wọn n sọ yẹn nitori gbogbo igi kọ lo maa n so olu.
Ọmọ Nàìjíríà tó ń gbálẹ̀ ní Italy láì gba àṣẹ bọ́ nínú páńpẹ́ òfin Ẹ̀yin baálé ilé, ẹ yé sá tẹ̀lé mi kiri mọ́!
Lákòótán, ẹ̀kọ́ nípa àwùjọ-ẹ̀dá jẹ́ ẹ̀kọ́ tó lárinrin.
Agbejoro Abol Fotouh, Abdelrahman Haridy so fun awon oniroyin pe, oun koi ti gbo ipinnu ile-ejo ati pe, koi ti han kedere boya gbigbe ese le dukia wa lara ofin ifiya jeni naa.
Ninu eeyan miliọnu mẹrinlelogun, eeyan mẹfa pere lo ti padanu ẹmi wọn lọwọ arun yi.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Lagos Explosion: Ohun tí a mọ̀ tó fa ìgbúgbàmù Eko rèé, ọ̀rọ̀ rèé lẹ́nu ó ṣojú mi kòró 18 Ẹrẹ̀nà 2020 Oríṣun àwòrán, others Ọpọ awuyewuye lo ti n waye lori ohun to fa Ibugbamu to ṣelẹ lọjọ Isinmi, ọjọ karundinlogun, Oṣu Kẹta ọdun 2020 lagbegbe Abule-Ado, nipinlẹ Eko.
Sugbọn wọn ko ni faaye silẹ fun ohun to lee fa ipinya laarin awọn Fulani ati Yoruba nibẹ.
OLUWA ní ń kọ́ ìlú Jerusalẹmu;òun ni yóo kó àwọn ọmọ Israẹli tí a fọ́n ká jọ.
Keyamo sọ̀rọ̀ yìí ní ìdáhùn sí ẹ́sùn kan pé, ìjọba Buhari fárí apá kan, dá apá kan si, àti pé, àwọn òsìsẹ́ ń gba ọ̀nà ẹ̀yìn wọ Bánkì orilẹ̀-èdè Nàìjíríà (CBN).
Oríṣun àwòrán, @KBStGovt Dipo ka gbajumọ ọna ti APC yoo fi bori ninu awọn eto idibo to wa nilẹ, n se la n foju tẹnbẹlu ara wa."
ran ojogbon Dayo Amokaye si igbakeji aare.
” Bẹ́ẹ̀ ni Farao ṣe fi Josẹfu ṣe olórí, ní ilẹ̀ Ijipti.
Farah  omo odun merinlelogbon ohun ti n gbaradi lorile-ede Ethiopia, ki o to bale silu London lojo-Bo(Thursday) saaju ifigagbaga ere ije naa.
Ṣugbọn ẹ̀yin wí pé, ‘Bí eniyan bá wí fún baba tabi ìyá rẹ̀ pé ohunkohun tí n bá fun yín, Kobani ni,’ (èyí ni pé ẹ̀bùn fún Ọlọrun ni), 
Irinajo MKO Abiọla ninu oṣelu: Ọmọ ti yoo ba jẹ aṣamu, kekere ni yoo ti maa jẹ ẹnu samusamu ni ọrọ MKO Abiọla ninu oselu nitori ẹni ọdun mọkandinlogun lo wa, to fi darapọ mọ oselu sise, ẹgbẹ oselu NCNC si lo darapọ mọ nigba naa, ko to lọ pari ẹkọ rẹ.
O fikun ọrọ rẹ pe, awọn akẹkọọ ati olukọ to le lẹgbẹrin ni wọn n jẹ anfaani awọn yara ikawe ọhun.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ebenezer Obey fi ìkéde síta pé òun n gbèèrò láti gbé ìyàwó tuntun, 1 Ògún 2020 Oríṣun àwòrán, Instagram/ebenezer obey Eekan olorin ti gbogbo agbaye mọ ni Oloye Ebenezer Obey jẹ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Muhammed Alkali; Iléèṣẹ́ ológun ti ri òkú rẹ̀ nínú kànga 13 Ẹrẹ̀nà 2018 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 31 Ọ̀wàrà 2018 Oríṣun àwòrán, Ikechukwu Oha Àkọlé àwòrán, Ṣaaju ni ilé-iṣẹ́ ọmọogun orílẹ̀-èdè Nàìjíríà sọ pe àwọn rí sàárè tí wọn sin Alkali tó ó sọnù sí lẹ́yìn tí wọ́n paá tán.
Wọn yóo gbé Àpótí Majẹmu OLUWA gbogbo ayé kọjá níwájú yín sinu odò Jọdani.
Amọ bi irọ ba lọ titi fun ogun ọdun, ọjọ kan ṣoṣo ni otitọ yoo ba a.
“OLUWA a máa fi ìrora jẹ eniyan níyà lórí ibùsùn rẹ̀;a sì máa kó ìnira bá egungun rẹ̀.
Iroyin sọ pe ọlọpaa aṣọna kan ti o n ṣiṣẹ rẹ lagbegbe Oshodi ni ilu Eko ni Small Doctor yọ ibọn si.
Ajọ WAEC ni awọn ọfiisi ohun kan naa faragba ninu iṣẹlẹ lasiko rogbodiyan #EndSARS to ṣẹlẹ lorilẹede Naijiria.
Democratic Party ) pe won jawe olubori ninu eto idibo gomina ni ipinle Bauchi.
Wande Ajayi ni tiẹ sọ pe Dangote ti wọn yan gẹgẹ bi ọmọ igbimọ ipolongo idibo Aarẹ Buhari ko le dun'nu si bi owo rẹ ṣe n dinku labẹ ijọba Buhari.
Nítòótọ́, n kò ní agbára mọ́,bẹ́ẹ̀ ni n kò sì ní olùrànlọ́wọ́.
Ìwọ yóo wá wí pé, “Gígé ni a gé àwọn ẹ̀ka kúrò kí á lè fi mí rọ́pò wọn.
Mo ti jẹ́ ọmọde rí; mo sì ti dàgbà:n kò tíì ri kí á kọ olódodo sílẹ̀,tabi kí ọmọ rẹ̀ máa tọrọ jẹ.
Leyi ti BBC ri fidi rẹ mulẹ, Dokita Stella kẹkọ gboye ti o ṣi n ṣe itọju awọn ọmọde nile iwosan Rehoboth Medical Centre to ti n ṣiṣẹ.
Ko ji owo ilu lati pese fun ọjọ ọla arọmọdọmọ rẹ, ti ko si ja ile onile bo tiẹ lẹyin, bi ọpọ adari wa ti n ṣe.
Ẹwọn oṣu ẹta ni adajọ fun baba ọmọde naa fun ẹsun pe o kuna ni iṣẹ rẹ gẹgẹ bii obi.
Ẹ̀yin jẹ́ ọlọ́lá, àwa jẹ́ aláìlọ́lá!
lati gbe igbese kiakia lori abadofin atunto oro ina mona-mona, paapaa julo
Pataki ọdun yii ni lati fi gba adura si oriṣa Ọṣun ti itan gba pe o jẹ ọkan lara awọn aya Ṣango.
Ó lè ṣe pàtàkì níhà ibìkan
Ọrọ yi ṣe bi ẹni ba ẹka aṣofin orile-ede Naijiria mu pẹlu awọn nnkan ti wọn dawọlẹ ti o jọ bi ẹni pe wọn ko ni le pari ki saa iṣejọba kẹjọ ti wọn n lo lọwọ yi yoo fi wa si opin.
Adut Akech to jẹ arinrinoge South Sudan pade Naomi Cambell ikeji rẹ lati England.
Èmi ni OLUWA, kò tún sí ẹlòmíràn.
Ko pẹ ti fidio naa jade to fa oju ayelujara ya, ọpọ eeyan lo ti pin fidio naa kaakiri ni Naijiria ati loke okun.
Ẹ má mú ẹ̀wù àwọ̀tẹ́lẹ̀ meji.
 Ìwọ ̀ n egbògi àkọ ́ kọ ́ ni a gba ni nímọ ̀ ràn láti gbà bí ènìyàn bá ti ń pé ọmọ ọ ̀ sẹ ̀ mẹ ́ ẹ ́ fà , èkejì sì gbọdọ ̀ wáyé ní ọ ̀ sẹ ̀ kẹẹ ̀ rin sí àsìkò yìí .
Nínú márùn-un yìí, méjì nínú wọn yìí jẹ́ láti ipinlẹ Eko, meji ni ìpínlẹ̀ Kwara, ẹyọkan ni ipinlẹ Katsina Ajọ to n gbogun ti ajakalẹ arun lorilẹede Naijiria, NCDC lo kede eyi loju opo twitter rẹ lalẹ ọjọ Aikú.
Ọlọ́pàá ti mú afurasí ajínigbé Hamisu Wadume Abayọmi ni ikọ ẹṣọ FRSC ri ẹgbẹrun lọna irinwo le ni ọgọjọ naira nibi ijamba ọkọ to ṣẹlẹ ni ọjọ kẹtadinlogun, oṣu kẹjọ ọdun yii ni opopona marosẹ Argungun si Birnin Kebbi.
 Aare wa salaye pe orile ede
Àsìkò tó láti fi ìwọ́de gba ara wa sílẹ̀ lọ́wọ́ ebi àti oko ẹrú - Sowore Ìjọba Buhari ń wùwà bíi ìjọba Abacha lórí ọ̀rọ̀ Ṣoworẹ- Ṣoyinka Ọlọ́pàá àti àwọn olùfẹ̀hónúhàn gbéná wojú ara wọn níbi ìwọ́de Revolution Now Koda, aago meje ko tii lu, ti wọn fi gunwa si ibẹ ni aarọ ọjọ Aje, bẹẹ ni eegun awọn oluwọde kankan ko sẹ titi di ọwọ iyalẹta ti akọroyin wa fi iwaju fasiti Ibadan naa silẹ.
Ọjọ́ òní ló di ọdún méjìléláàádọ́ta báyìí tí Orílẹ̀ Nàìjíríà gba òmìnira lọ́wọ́ ìjọba amúnisìn ti ọba àwọn Gẹ̀ẹ́sì.
Ṣiṣe atilẹyin fun awọn onile iṣẹ nlanla.
Ni igba ti a n sọrọ rẹ yii, awọn ile iṣẹ nla bi Leventis, UAC, Nigerian Railway Corporation, ati Electricity Corporation of Nigeria (ECN) ni wọn ni ikimi lati da ẹgbẹ agbabọọlu silẹ ni orukọ wọn.
Leyin ọrẹyin ni wọn sinku ọmọ naa si ẹba ọdọ ti wọn ti ri oku rẹ.
Aisi ounjẹ ati imọtoto naa wa lara ohun to mu ki aisan yii wọpọ laarin awọn ọmọde.
Oríṣun àwòrán, COPYRIGHT LUCIPOST Àkọlé àwòrán, Ibeere ti awọn ọmọ Naijiria n bere ni pe, ki ni iyawo aarẹ Buhari n se, ti o fi wọ asọ to fẹrẹ to miliọnu meji Naira?
Ọ̀pọ̀ èèyàn tí kò yin Ajimobi lojú ayé, tó ń yìn-ín lẹ́yìn ikú, yóò jẹ ìyà - Oníwáàsí Eto akanse adura Fidau ọjọ kẹjọ fun gomina ana nipinlẹ Ọyọ, Isiaka Abiola Ajimobi ti waye lọjọ Aiku.
Jeremaya ní nígbà tí Seraaya bá ka ìwé yìí tán, kí ó di òkúta kan mọ́ ọn kí ó jù ú sí ààrin odò Yufurate, 
Hannan Gazi náà se àgbéjáde tirẹ̀:
Àwọn àgbà Oyè tú ọ̀fọ̀ ni iwá́jú Gómìnà Rauf Arégbẹ́ṣọlá ti ipinlẹ̀ Ọ̀ṣun, ni Ọjọ́rú, ọjọ́ kejila oṣù kẹjọ ọdún Ẹgbãlemẹ͂dógún.
Ogun Jija Ogedengbe: Lẹyin eyi, o ko ọpọlọpọ ọmọ ogun to pọ jọ ti wọn si doju ija kọ ilu Ibadan lọpọlọpọ igba.
Oríṣun àwòrán, facebook/Rt Hon Michael Adeyemo Àkọlé àwòrán, Iléèwòsàn ńlá UCH nílùú Ìbàdàn ni àyẹ̀wò yii yoo sì ti waye Kí ó tó kú, ẹkùn ìdìbò ìlà oòrùn Ìbàràpá ni aṣòfin Adeyẹmọ ṣojú fún.
 a kò gbọdọ ̀ fún àwọn tó ní oyún tàbí tí agbára àti kojú àkóràn àìsàn wọn ti dínkù pátápátá ní àjẹsára náà .
Eastern Cape, Western Cape, Kwa-Zulu Natal, North West ati Mpumalanga .
Meji meji lo ko covid-19 l'Ọjọbọ ni Bauchi, Kaduna ati Niger nigba ti ẹni kọọkan lugbadi arun ọhun lati ipinlẹ Kano, Ondo, Osun ati ipinlẹ Rivers.
 okan nínú won ni jean-jacques rousseau .
Nígbà tí aboyún bá ń rọbí, ó gbọdọ̀ jẹ ìrora, nítorí àkókò ìkúnlẹ̀ rẹ̀ tó.
Ọkọ rẹ̀ bèèrè lọ́wọ́ rẹ̀ pé, “Kí ló dé tí o fi fẹ́ lọ rí i lónìí?
Josaya sì digun lọ bá a jà.
Nítorí pé ihà ilé-aiyé kan ló kojú sóòrùn lẹ́ẹ̀kannáà, tí ìdàkejì á sì kọjú sí òkùnkùn òfurufú, ìmọ́lẹ̀ òòrùn yìí ni a npè ní ojúmọ, tí òkùnkùn  ṣì njẹ́ àsìkò alẹ́ àti òru.
Àfihàn àwọn afurasi ọmọ ẹgbẹ Boko Haram náà wáyé ni Maiduguri ní ìpínlẹ̀ Borno.
Ṣugbọn ńṣe ni Saulu túbọ̀ ń lágbára sí i.
Atiku fọrọ yii lede lọjọ Aiku lẹyin ti minisita fun ọkọ ofurufu tẹlẹ ri, Femi Fani-Kayode sọ pe ata akara ti ko ran ikọ lọrọ ti ijọba apapọ sọ pe idasilẹ Amọtẹkun ko ba ofin mu.
Jesu rí ọmọ kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ kan, ó bá gùn un, gẹ́gẹ́ bí a ti kọ ọ́ pé,
Báwo ni mo ṣe lè ní ololufe ni asiko yii, mi ò fe je apon lásìkò yìí.
Wọn ni awọn ti gbe ajoku awọn ọkọ mejeeji kuro nibẹ.
Igbagbọ yii si ni awọn onimọ ijinlẹ sayẹnsi tako pe ko lee rí bẹẹ laelae.
Oríṣun àwòrán, OTHERS Àkọlé àwòrán, Ọga ọlọpaa lọrilẹede Naijiria, Mohammed Adamu ti kesi ẹnikẹni to ba fẹ fa ijọngbọn lati ti ọwọ ọmọ wọn bọ asọ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Makurdi Church theft: Àga oníke mẹ́wàá ní wọ́n kọ́kọ́ ni Joseph jí tó fi di èrò ẹ̀wọ̀n ní NASME Barracks ní Benue 9 Owewe 2020 Oríṣun àwòrán, others Ọkùnrin ẹni ọdun marunlelogun kan, Joseph Ada ti NASME Barracks ni Makurdi ti foju bale ẹjọ majisireeti fun ẹsun ole jija, igbimọ iwa ọdaran.
Ẹ ranti bí a ti ja ìjà líle, tí ẹ farada ìrora, látijọ́, nígbà tí ẹ kọ́kọ́ rí ìmọ́lẹ̀ igbagbọ.
Irinajo baalu naa jẹ ọkan lara eyi ti ijọba n ṣe lati ko awọn ọmọ orilẹ-ede India ti coronaviru se mọ ita pada sile.
Ọkunrin kan, Gbeminiyi Adeyinka, tii se ẹni ọdun mejidinlaadọrun (88), lo wọ iyawo rẹ, Sẹkinat, ẹni ọdun marundinlaadọta (55), wa sile ẹjọ pe o to gẹẹ, ibagbepọ oun ati aya oun ko wọ mọ lẹyin ti wọn ti se tọkọ-taya fun odidi ọgbọn ọdun.
Ọpọ ọmọ Naijiria ko lee pa ẹnu mọ lori ọrọ̀ yii o.
Ijamba baluu naa ṣẹlẹ nilu Missirah, lẹgbẹ ẹnu alaa orilẹede naa pẹlu ariwa orilẹede Gambia.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Baby abandoned on dunmpsite: Mo ti bímọ mẹ́rin tẹ́lẹ̀ fún bàbá méjì nínú òṣí- Dupe Ogbomos O wa fi kun pe abaabọ fifi awọn ti ko yẹ sipo ni Naijiria n ba finra bayi.
Alukoro ileeṣẹ naa, Olugbenga Fadeyi sọ pe wọn ti gbe ọdaran naa lọ sile ẹjọ ko to fẹsẹ fẹ.
kii idije agbaye ohun o to bere.
Israel Adesanya: Romero yóò jìyà bí mo bá gbá a mú
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Alápinni: Kò sí ẹni to fẹ́ kọ́kọ́ kọ́ iṣẹ́ òṣèré bíi ti àtẹ̀yìnwá Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Nígbà tí mò ń wà Awolowo, Gowon, Babangida, mo fi ara mi sípo ọ̀wọ̀ tóri .
Ẹ máa sọkún, kí ẹ sì máa ké gidi nítorí ìṣẹ́ tí ó ń bọ̀ wá ṣẹ́ yín.
Wò ó ọ̀nà láti mú ara rẹ dé ibi tó ga jùlọ nínú ìbálòpọ̀ pẹ̀lú ìlànà Tantra Àwọn àmì tó fi mọ̀ pé wọn ń fipá bá ọmọdébìnrin rẹ lòpọ̀ Njẹ́ ẹ mọ̀ pé orílẹ̀-èdè Nàìjíríà ló n wo 'Blue film' jù Fásitì Ghana lé olùkọ́ méjì tí àṣírí wọ́n tú lórí ẹ̀sùn ìbálòpọ̀ lọlé Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ohun tẹ́ẹ gbúdọ mọ nípa kókó orí ọyàn yín lásìkò fífọ́mọlọ́yàn Ọkunrin keji ni tiẹ sọ pe, kọndọọmu ti oun naa ja, ti oun si ko aarun gonorrhoea.
Ẹ gbọdọ̀ lawọ́ sí i, kí ẹ sì yá a ní ohun tí ó tó láti tán gbogbo àìní rẹ̀, ohunkohun tí ó wù kí ó lè jẹ́.
Èèyàn 59 míràn ló lùgbàdì coronavirus ní Nàìjíríà lánàá Fun igba akọkọ lati ọjọ pipẹ, ipinlẹ Eko ko si lori atẹ esi ayẹwo awọn eeyan to ṣẹṣẹ ni Covid-19 ni Naijiriai.
Kollington, ẹni to gbosuba fun Barrister to wa wọ kuro lẹnu isẹ sọja, wa kan saara si oloogbe naa pe, ti kii ba se ti Barrister ni, isẹ asọna ni oun ko ba maa se.
Ìyá rẹ̀ bá bi í pé, “Ọmọ, kí ló dé tí o fi ṣe wá báyìí?
Méjìléláàdọ́fà ninu ọ̀rìnlénígba din mẹrin awọn ọmọbinrin naa ti wọn jigbe ni wọn ko mọ ibi ti wọn wa bayi.
Òwe Nípa Aguntan tí Ó Sọnù.
Yaara kan loun gbe pẹlu iya rẹ.
Ọga ologun naa tẹnumọ pe, awọn ọmọ ogun ko yinbọn lu oluwọde tabi pa ẹni kankan, ati pe iroyin to ni awọn pa awọn eeyan nipakupa lalẹ ogunjọ oṣu Kẹwa ọdun yii, kii ṣe ootọ.
Ilé wó lu ọ̀gọ̀ọ̀rọ̀ èèyàn ní Abraka Fulani DaranDaran di fà kí n fà láàrin Gómìnà Ganduje àtàwọn Gómìnà ilẹ̀ Yorùbá Ẹ wo ìpínlẹ̀ 15 tó faramọ́ ìdásílẹ̀ àbúlé Ruga Àwọn kan fẹ́ da Naijiria rú torí ààbò tó mẹ́hẹ - Osinbajo gbarata Ọjọ́ kìí pẹ́, àlàyé àti fídíò rèé lóríi bí èèyàn ṣe rìn lórí Òsùpá ní ààdọ́ta ọdún sẹ́yìn O ni bi awọn eeyan ṣe n sọ Fulani ni suna ti kii ṣe ti wọn nipa pipe wọn ni darandaran to mu iṣẹ ọdaran mọ iṣẹ ko bojumu to.
Lára ìdajì tí ó jẹ́ ti àwọn ọmọ Israẹli, mú ẹyọ kan ninu araadọta ninu eniyan ati mààlúù ati kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ ati ẹran ọ̀sìn; kí o sì kó wọn fún àwọn ọmọ Lefi tí ń ṣe ìtọ́jú ibi mímọ́ OLUWA.
Laipẹ́, ọmọ tí kò bá pé ọdún méjìdínlógún kò ní leè jáde girama l’Ọṣun Wọ́n ti pa ẹni to yìnbọn pa ará Texas márùn ún -ọlọ́pàá Adeboye sọ̀rọ̀ lórí ètò pápá ìjẹko RUGA Leah Sharibu ṣì wà láàyè - Iléeṣẹ́ Aarẹ Buhari Loju awọn miran igbesẹ yii ko ni rọrun fun awọn mẹkunnu rara ni Naijiria.
Nipasẹ abala ofin irinna ọkọ Section 12 subsection 2 iwe ofin Naijiria.
 O ni ki ijọba Ipinlẹ Eko ṣiṣẹ lojuna ati jẹ ki awọn ara ilu san owo-ori tẹlẹ naa deedee, dipo ti wọn fi gbe owo le e.
Ìdí kan náà nìyí tí ẹ fi ń san owó-orí.
Bakan naa ni awọn miran naa tun sọ ẹri wọn, to farajọ ti ọdọmọbinrin naa.
Bákan náà ni àwọn ibi tó jẹ́ pé kò fi bẹ́ẹ̀ sí atẹ́gùn, ti àwọn ènìyàn si maa n gba èémí fúnra ẹni ni, yóò nira díẹ̀ láti máà ni ààrùn náà, àwọn ilé ìtajà ìgbàlódé kò fi bẹ́ẹ̀ léwu, nítorí pé àsìkò péréte ni wọn lò ní àyíká kan.
Bakan naa, Moses tun gba ife-eye idije EPL fun iko agbaboolu Chelsea ni saa 2016/2017, ti o si kopa ninu ifesewonse ogoji fun iko naa.
Ó sì wọ ọmọ eniyan lọ́rùn pupọ.
Àkọlé àwòrán, Miliọnu mẹta din diẹ ni wọn naa owo itusilẹ ti wọn gba ki wọn o to yọnda awọn ibeji naa ku Yatọ si pe ọwọ tẹ wọn, miliọnu mẹta din ẹgbẹrun lọna igba Naira (2.
Ondo APC Primary: Mo ti bẹ̀rẹ̀ sí ń bá àwọn akẹgbé mi nínú ẹgbẹ́ sọ̀rọ̀ kí àláàfíà léè jọba
Yóo di ibi tí wọn óo máa sá àwọ̀n sí láàrin òkun, nítorí èmi OLUWA Ọlọrun ni mo sọ bẹ́ẹ̀; yóo sì di ìkógun fún àwọn orílẹ̀-èdè mìíràn.
Nígbà wo ni ìwọ óo dájọ́ fún àwọn tí ń ṣe inúnibíni mi?
Ara ọtọ ni Abubakar fi sọ pe oun ṣi wa laye lọtẹ yii nipa lilo fonaran olohun fi sọrọ pe oun ni oun ṣi n dari Boko Haram o.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Widows Day 2019: Mo máa ń sá kiri wá owó ilé ni -Opó Kini èrò ajọ CAN ọmọlẹyin Kristi lori asọtẹlẹ ẹ̀tàn: Ẹ̀wẹ̀, BBC Yoruba kan si ẹgbẹ́ adarí awọn ọmọ lẹ́yìn Kristi (CAN), Ẹni ọ̀wọ̀ Bayo Oladeji lóri èrò wan lóri isọtẹ́lẹ̀ ti kó wá si ìmúṣẹ ỌHUN.
Minisita fọrọ ilera ni Naijiria fikun un wipe lẹta naa rọ oun lati sisẹ pẹlu ifọwọsowọpọ pẹlu ọgbẹni Yusuf ti o ba ti pada s'ẹnu iṣẹ.
Àkọlé àwòrán, Àjọ òsìsẹ́ lórílẹ̀èdè Nàíjírìà pè fún ìfẹ̀họ́nú hàn nítorí iléesẹ́ ìbáraẹnisọ̀rọ̀ MTN kò fún àwọn òsìsẹ́ wọn láàyè láti darapọ̀ mọ́ Àjọ òsìsẹ́.
wọn ni ilẹ ̀ níbẹ ̀ , sùgbọ ́ n wọn a máa lọ sí ẹ ̀ yìn odi ìlú láti lọ múlẹ ̀ oko .
" Ẹlomiran tilẹ ni, aarun naa ti kuro ni 'China virus ' o ti di 'Trump Virus' Rhoma McGuire ni tirẹ ni, oun ko ni igbagbọ pe lootọ ni Trump ni aarun naa nitori opurọ ni.
 agbara opolo yi , lapapo mo inaro ara to jagbekun awon owo lati fowo se awon ohun , gba awoniyan laaye lati lo awon ohun isise daada ju awon iru miran lo .
Eni mẹ́rin míì kó coronavirus ní Nàìjíríà, àfàìmọ̀ kó má dàbi ti China, Italy- Mínísítà kìlọ̀ Ilééṣẹ́ Facebook leè mọ ìgbà tí àwọn tó wà lójú òpó wọn ń ní ìbálòpọ̀ Ìpínlẹ̀ Ogun fẹ́ fi òfin wọ́gilé ìsìnkú ọba lọ́nà ìṣẹ̀mbáyé Awakọ̀-èrò, ọlọ́kadà farakásá àṣẹ ìjọba Ekiti láti dẹ́kun Coronavirus Ẹṣa egungun jẹ ewi abalaye to jẹ atẹnudẹnu ti wọn maa n fi ki egungun ko ma baa rẹ wọn ninu ẹ̀kú.
Àwọn ará Kalidea bá dá ọba lóhùn pé, “Kí ọba pẹ́!
Otinieli náà bí Hatati ati Meonotai.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Barack Obama sọ pe aworan yii dara pupọ Iyalẹnu nla lo jẹ fun Michelle Obama, iyawo aarẹ nigbati wọn ṣi'ṣọ loju aworan rẹ, eyi ti Amy Sherald, ayaworan miiran to jẹ alawọ dudu ya.
Ọjọ́ náà ń bọ̀,ọjọ́ OLUWA dé tán!
Iroyin ni ọpọ ọdọ to n se iwọde lo jade laye, ti akọsilẹ ko si tii salaye iye wọn ni pato, nigba ti ọpọ eeyan wa nile iwosan, ti wọn n gba itọju lati ipasẹ ọgbẹ ti wọn ni.
Cira Fernandes so pe, dida awon arinrinajo lona aibofin mu pada si awon orile-ede won je inawo nla-nla fun ijoba, lodun to koja, ijoba nawo ti iye re to egberun lona igba owo dollars lati da awon arinrinajo lona aibofin-mu  ti won ko ni akosile, eyi ti iye won to egberun merin  pada si orile-ede won.
Chichi Igbo: Ọ̀pọ̀ máa ń rò pé mo ní nǹkan ọkùnrin lábẹ́ torí ìrísí mi jọ ti ọkùnrin
Ojo ikinni ti n rọ sori awọn akẹkọ-binrin naa Yooba ni bi eegun ẹni ba jo ree, ori a maa ya atọkun rẹ.
Àpapọ̀ àwọn ohun èlò wúrà ati fadaka yìí jẹ́ ẹẹdẹgbaata ó lé irinwo (5,400).
A ti já gbogbo ojú òpó ìjọba Nàìjíríà gbà lórí Twitter láti ṣàtìlẹyìn ìwọ́de End SARS"" - Anonymous Mo kọ̀ láti kópa nínú ìpàdé orí ayélujára Nàìjíríà yìí- Falz Wo ìsọ̀rí àwọn tó jẹ́ kí ìwọ́de End SARS / end SWAT lárinrin àti ìtumọ̀ Ìjọba ìpínlẹ̀ Eko ti kéde orúkọ àwọn ọlọ́pàá tó fi ìyà jẹ àwọn olùwọ́de #EndSARS Oyemade lo fi ọrọ naa lede loju opo Twitter rẹ, nibi to ti rọ ileeṣẹ ọlọpaa lati fi imu awọn agbofinro ti aje iwa ibajẹ ba ṣi mọ lori fọn feere."
" Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ilé ẹjọ́ pàṣẹ kí wọ́n fi àwọn tó pa àkẹ́kọ̀ọ́ LASU sí ẹ̀wọ̀n Bí àwọn ọ̀tá mi bá jẹ ilá àti ẹ̀bà tán, itẹ́ òkú ní wọn yóò ti fọwọ́ - Bobrisky Èyí ni fídíò bí wọ́n ṣe ní Iran ló kọlu bàálù Ukraine tó já ní Tehran Ilé Asòfin US dìbò láti dín agbára Ààrẹ Trump kù lórí Iran Ọlọpàá f'ọ̀bẹ la ará ilú nífun nílùú Eko.
 Bakannaa ni Amofin Akeem Fadun tun mu aba wa pe, bi araalu ko ba ni igbagbọ ninu ilana idajọ lorilẹede yii, boya ki wọn maa gbe igbimọ kan kalẹ, lati maa tọpinpin bi awọn agbofinro ṣe n yanju awọn afurasi ti wọn ba gbe wa si ọdọ wọn."
Ẹlẹ́rù níyìn tíí ṣe ohun ìyanu.
Awọn ogboju ọdẹ nikan lo le mu wọn looyẹ afi ti àwọn omode ba tun ni oore ọfẹ lati lọ wo wọn ni ọgba ẹranko.
Ẹ̀jẹ̀ rẹ̀ nìkan ni ẹ kò gbọdọ̀ jẹ; dídà ni kí ẹ dà á sílẹ̀ bí omi.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Coronavirus treatments: Lẹ́yìn ìgbélé Coronavirus, ọ̀nà wo ni mo lè gbà láti bọ́ l'ọ́wọ́ níní Covid-19.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ìya Emma oní POS ṣẹ̀ṣẹ̀ rékọjá lọ síbí ilé yẹn ni àtọmọdé, ó sì wó pa wọ́n - Láńlọọ̀dù Obalende Awọn ọmọ Alaafin kan ti di ipo oselu mu sẹyin, ti awọn miran si tun wa nipo oselu.
NURTW l‘Abuja yóò kàn sí Makinde láìpẹ́ lórí bó ṣe fòfin dè wá l‘Ọyọ - Ejiogbe Ìpínlẹ̀ Oṣun kò nílò Gómìnà oníjó - Oshiomole ‘Fayose ń lo owó osù òsìsẹ́ fún ara rẹ̀’ Ọmọ ẹgbẹ́ òsèlú APC tako Oshiomole Bi eniyan ba tun wa wo awọn ẹsun ti Sẹnetọ Shu'aibu ka silẹ fun Oshiomhle ninu lẹta to kọ si i pe ko fi ipo silẹ gẹgẹ bii alaga ẹgbẹ oṣelu naa, aigbọ ọrọ lẹnu awọn ọmọ ẹgbẹ jẹ awọn ẹsun ti wọn fi kan an.
Nítorí anfaani ni èyí fun yín, kì í ṣe pé kí ẹ gba Kristi gbọ́ nìkan ni, ṣugbọn pé ẹ̀ ń jìyà fún Kristi.
Tafa jẹ́ ọdaran pọnbele to mọ ọgbọn ayinike ati ayinipada awọn onisẹ ibi lorisiirisi ki o to di pe o salabapade Lapade ti o si yipada si olootọ ni awujọ.
Saheed Balogun, ta mọ si Walata, ti oun naa ko gbẹyin nibi ayẹyẹ naa, se apejuwe ọlọjọ ibi naa gẹgẹ bii iya rere to wulo pupọ lagbo isẹ tiata, kii wa isubu awọn ọdọ, to si maa n fun awọn ni imọran loore koore nipa bi a se n gbe ile aye se rere.
Lati igba naa ni wọn ti ṣe alaye lọpọlọpọ lori ọna ti wọn yoo gbe e gba, ṣugbọn awọn eniyan ṣi n wo bi yoo ṣe ri.
'Ootọ ní fídíò ọmọogun Nàìjíríà tí kò fẹ́ kojú Boko Haram ṣùgbọ́n.
Bi a o ba si ranti daadaa, wọn kii tilẹkun ileeṣẹ ọlọpaa nitoripe awọn ọlọpaa kii ṣiwọ iṣẹ ọlọjọyipo.
 Kete leyin ikede yii ni awon eekan ninu adari ijoba South Korea lati Seol ti won yoo koko lo sabewo si Ogbeni Kim lati igba to ti de ori aleefa lo sabewo si Pyongyang ti won si wa fun apeje lodo re.
Wọ́n ń ṣe ìdájọ́ àwọn eniyan náà nígbà gbogbo; àwọn ọ̀rọ̀ tí ó bá fẹ́ díjú nìkan ni wọ́n ń kó tọ Mose lọ, wọ́n ń yanjú àwọn ọ̀rọ̀ kéékèèké láàrin ara wọn.
 Mo mo daju pe, won yoo gbadun ara won lopolopo.
O ni ko see se ki oun ri Ọba to ni iyi fin gẹgẹ bi ọmọ Yoruba gidi sugbọn oun si ni ojuse lati da abo bo ọga rẹ.
Bakan naa ni Yinka Ayefẹlẹ, tii se akọrin ẹmi ati sọrọsọrọ lori redio salaye pe iwa igbẹsan tawọn ọmọ Naijiria n se gbọdọ wa sopin nitori ohun ti ko dara, ko dara.
Eto ipolongo idibo rẹ lọdun 2019 yii lo ni kọhun kọọ to pọ ninu nitori pe awọn eniyan bu ẹnu ẹ̀tẹ́ lu bo ṣe n ya fọto bii pe oun n ṣọgbin lori ẹrọ ayelujara.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Osisẹ Fidelity Bank: Lati Osu Kẹwa, ọdun to kọja lati gba owo osu kẹhin.
Awọn merin naa ti rojọ niwaju adajọ Magistrate to wa ni ilu Akure.
'Iye awọn Fulani darandaran to n wọle si ilẹ Yoruba ko lonka, paapaa ni ilu Ọyọ ati Ogun' Oríṣun àwòrán, Oyo amotekun 'Nitori naa awọn ikọ Amọtẹkun to mọ iṣẹ wọn ati awọn ogboju ọde ni yoo koju awọn Fulani darandaran yii, ki wọn ma ba a ṣe awọn eniyan ni ijamba.
 Bakan naa lo salaye pe ijoba ti sanwo lori ilera fawon osise won fun adojutofo won ti won si ti san owo to ye ti won je awon osise feyinti tele.
Awọn AGBA IFE ti Ile Ife lo tẹwọ gba a lati ki i kaabọ eyi ti Obalufẹ ti Ifẹ, Oba Idowu Adediwura, dari wọn.
Segubu, àbíkẹ́yìn rẹ̀ ọkunrin sì tún kú bákan náà, nígbà tí ó gbé ìlẹ̀kùn sí ẹnubodè rẹ̀; gẹ́gẹ́ bí OLUWA ti sọ tẹ́lẹ̀, láti ẹnu Joṣua, ọmọ Nuni.
Ijamba ọkọ naa la gbọ wi pe akọkọ rẹ ṣẹlẹ ni nnkan bi ago meje ọjọru ti awọn miran si tun ṣelẹ lowurọ ọjọbọ.
Ninu fidio naa, ọmọkunrin naa sọ pe awọn alaṣẹ mu oun kuro ni ilegbe awọn akẹkọọ to wa ni kilaasi kekere, nitori pe oun n tọ sile, ti wọn si ni ki oun lọ ma a sun si ọdọ awọn akẹkọọ to wa ni SS 1 ati SS 2.
lítíréṣọ ̀ aláfohùnpè ni eré àpíìrì .
Lose to koja naa nile ise LVMH’s Louis Vuitton brand, to je eyi to ta julo nile Faranse lasiko yii kede pe oun ti gba Virgil Abloh to je omo Ghana ati Amerika sise lati mojuto ipese awon awotele okunrin won tuntun.
Wakati meji, o le isẹju mẹtadinlogun ni ẹni to gbe igba oroke naa lo lati fi sare lati papa isere ti Surulere de Eko Atlantic City.
Afara Third Mainland lo gun ju lọ ninu awọn afara mẹta to lọ si erkusu ilu Eko, awọn meji to ku ni Eko Bridge ati Carter Bridge.
Sẹẹli ko ni ji pepe mọ Ti sẹẹli ba ti bajẹ ju boṣeyẹ lọ, ko ni ṣiṣẹ mọ, ko maa ba pese awọn sẹẹli mi i ti ko dara.
"Nitori pe a ko fẹ ki ede Yoruba parun la ṣe n ṣeto "" Bawo ni iwọ ṣe gbọ Yoruba to?"
Máa kọ orin dídùn ní oríṣìíríṣìí,kí á lè ranti rẹ.
mo gbádùn láti máa ṣe ìfẹ́ rẹ, Ọlọrun mi;mo sì ń pa òfin rẹ mọ́ ninu ọkàn mi.
" Àkọlé àwòrán, Minimum Wage: Ilé ìgbìmọ asofin dájọ ti sísan yóó bẹ̀rẹ̀ Ọsẹ to kọja ni Saraki yàn ìgbákeji ọmọ ilé tó pọ̀jù lọ, Sẹnatọ Francis Alimikhena, gẹ́gẹ́ bii adelé olórí ìgbìmọ náà, lẹ̀yìn ti alága ti wọn yan Sẹnatọ Olusola Adeyeye yọ aara rẹ kurò, pelú àlàyé pé òun ni àìlera.
Iyatọ nla wa laarin ilana eroja ajẹsara amuwaye (immune system) ọmọde ati ti agbalagba.
Àwọn ọmọ Jẹriko jẹ́ ojilelọọdunrun ó lé marun-un (345)
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Yoruba Culture: ọjọ́ méje ni wọ́n fí n rẹ ẹ̀kú Danafojura kó tó jáde Ẹni ti o jẹ adari ẹka naa, Arabinrin Yemisi Adeniyi ati ojugba rẹ Ogbẹni Ojo Anthony sọ wi pe, awọn ti wọn mu yii ti wa ni ahamọ ofin.
Bakan naa lati rii daju pe igbesẹ wa fun idamọ, bibojuto ati didaabo bo eeyan lori awọn iwa tabi ọrọ irọ lawọn oju opo ayelujara.
 Ìtọ ́ jú pẹ ̀ lú egbòògi tí ó ń pa àkóràn kòkòrò tí wọ ́ n maa ń gbà sí ẹnu bíi cephalexin , amoxicillin , tàbí cloxacillin , ní wọ ́ n maa ń sábà lò .
Ọmọ Ibadan, Peace Busari tí wọ́n fẹ́ tà lórí Facebook ti dé sí Naijiria láti Lebanon Iná jó àwọn ènìyàn 10 tó ń gbà ìwòsàn arùn Coronavirus níbùdó ìtọ́jú Àwọn omidan Naijiria ni wọ́n fi ń ṣerú ní Lebanon- Ọmọlọla Ìjọba Nàìjíríà ti rí obìnrin tó wà l'óko ẹrú ní Lebanon gbà Àkọlé àwòrán, Asojú ìjọba orílẹ̀-èdè Lebanon ti kọ̀wé fipò silẹ̀ nítorí ìbágbàmù tó gbẹ̀mi ènìyàn 200 Asojú ìjọba orílẹ̀-èdè Lebanon ti kọ̀wé fipò silẹ̀ nítorí ìbágbàmù tó gbẹ̀mi ènìyàn 200 Awọn alaṣẹ ijọba orilẹede Lebanon ti kọwe fipo silẹ laarin ọpọlọpọ irunu ati ibinu awọn araalu nitori bugbamu nla to waye lọjọ iṣẹgun ọsẹ to kọja eyi to ba nkan jẹ kọja afẹnusọ ni ilẹ Beirut to si tun mu ẹmi eniyan to le nigba lọ.
Adamawa election result: Olùdíje PDP já ipò gómìnà gbà mọ́ gómínà Bindow lọ́wọ́
Ọgbẹni Adeniji ṣalaye pe afikun owo ina ọba dabi jija awọn ọmọ Naijiria lole.
Lati nkan bi aago mẹfa idaji ni awọn ara ilu ati orisirisi awọn onilu ti korajọ siwaju aafin Ataọja tilu Oṣogbo, lati se ajọyọ ọdun Ọṣun Oṣogbo ti ọdun yii.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Orisirisi ni bo se maa n ri lẹnu Ikeji ni pé ó sòro láti rí, àjọ EU ko si fi ààye gbàá nítori náà kó ṣe tà si orilẹ̀-èdè míràn Ikẹta ni pe wọ́n ti sàpejuwe rẹ bíi ọkàn lára àwọn ounjẹ to léwu jùlọ lágbàyé nítori pé o lé ni ààbọ lori iléra ẹni to ba n jẹ ẹ.
Ẹni tí ń rìn déédéé, tí ń ṣe òdodo;tí sì ń fi tọkàntọkàn sọ òtítọ́.
 Nigba ti ọgbọ̀n ninu won je awon ti
Ó sọ fún àwọn eniyan náà pé, “Ẹ máa tẹ̀síwájú, ẹ rìn yípo ìlú náà kí àwọn ọmọ ogun ṣáájú Àpótí Majẹmu OLUWA.
awon akẹgbẹ rẹ lati inu ẹgbẹ  oselu (All
Wo àwọn òṣìṣẹ́ kólẹ̀-kódọ̀tí tó ń fi ẹ̀mí wọn wéwu kí Abuja leè mọ́ tónítóní Ethiopia ni ireti pe odo naa yoo le pese ina fun miliọnu mẹwaa eeyan to n gbe lai ni anfani ina lorilẹ-ede wọn.
Eyi jẹ ibẹrẹ ṣaa, mo si mu u mọra fun igba pipẹ; mo n lọ fun igbaradi, mo si tun n gbiyanju lati fi gba bọọlu.
“ iye ipin idokoowo ti ida ogorun un 13.
A fun fèèrè kò dáhùn, a kígbe títí a kò rrí i títí di òní olónìí.
Ọmọ Nàíjíríà faraya lórí àìkópa Buhari àti Atiku nínú ìjíròrò Irú kan náà ni Atiku àti Buhari, kò s'íyàtọ̀ nínú wọn - Tunde Bakare Ọbasanjọ: Ó yẹ kí Amina Zakari kọ̀wé fipò sílẹ̀ Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí kan sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
Ọ̀rọ̀ tí Jeremaya gbọ́ lẹ́nu OLUWA nìyí nígbà tí ọba Sedekaya rán Paṣuri, ọmọ Malikaya, ati alufaa Sefanaya, ọmọ Maaseaya, sí i; 
Idi ni pe oniruuru igbesẹ to n waye lẹnu ọjọ mẹta yii ati gbọyi sọun laarin awọn eekan ẹgbẹ ko ye wa si.
Fún kátàkárà, yóò kan iye owó ti yoo ma wọlé, owó tí àwọn ènìyàn yóò fi maa dọókoowo yóò gọbọi, yóò si níra láti ri ọjà tà.
Lara awọn nkan ti o wa ninu idọti naa ni awọtẹlẹ ọkunrin, rọba, ọra iyẹfun kọfi ati okun wa lara ohun ti wọn ba ninu rẹ.
Bi o ba ti wqa lati iran ẹru ni ilẹ Igbo(Igboland), ko sọna fun ọ rara niyẹn o lati lọkọ tàbí ni aya.
Omowe Onu so pe iru igbiyanju bayii yoo tun je ki idagbasoke
Ninu isiro ati asotele naa, won ni o seese ki ipinle Benue koju ikolu omiyale lataari ekun omi odo naa.
Ohun tí o kò mọ̀ nípa Ebila One Million Boys"" àti Ekugbemi, olórí ẹgbẹ́ òkùnkùn méjì tó da ìlú Ibadan rú Ó yẹ kí ìjọba gbé ilé ìwé tì pa títí di ọdún 2021- ASUU Akanbi mi, má fọ̀ ọ́, mo wà pẹ̀lú ẹ; ẹni tó ṣe ìgbéyàwó olórùka ló l'ọkọ- Lizzy Anjorin Afurasí tí Ọlọ́pàá ní ó pa Barakat, Grace àtàwọn míì l'Akinyele ti sọ̀rọ̀ pé."
Ebola ti o ti wa ni titipa fun igba pipẹ leyin ikolu to waye, lọsẹ to  koja ni orile ede Congo, ni won ti si pada
Ẹnìkan kì í kẹ́gàn olè tí ó bá jí oúnjẹ jẹ nítorí ebi.
"Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, EndSars, EndSwat: Ọlọ́pàá ti fi ìbọn lù mí láyà rí torí mó ní 'extra tyre' méjì- afẹ́hònúh Ṣugbọn fun igba akọkọ, wọn ko ni ko ohun amugbagbara ""charger"" ati ẹrọ igbohun ""earpiece"" sinu pali rẹ."
Àwọn olórin Naijiria pọ̀ tó fakọyọ nilẹ̀ Adulawọ ni 2018
Giwa fasiti ilẹ Ibadan, Ọjọgbọn Olayinka Idowu sọ wi pe ajọṣepọ laarin awọn to n bẹ lẹka eto ẹkọ, awọn oṣiṣẹ ijọba, Awọn oniṣẹ adani ati awọn oniṣegun ibilẹ je ọna kan gboogi lati wa ojutu si aarun to n ba gbogbo aye finra.
OLUWA Ọlọrun ń bá àwọn òkè ńláńlá ati àwọn òkè kéékèèké wí!
Ṣugbọn Maria dúró lóde lẹ́bàá ibojì, ó ń sunkún.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: France wọ ìpele àṣekágbá Russia 2018 'Ìdánwò ńlá ni Croatia jẹ́ fún England' Ta ni yóò gba ''golden boot'' ní Russia?
 ní ilé-ìwé yìí , òun ni ó kéré jùlọ lọ ́ jó orí nínú àwọn tí ó ń gbá bọ ́ ọ ̀ lù aláfẹsẹ ̀ gbá .
Wọ́n bi í pé, “Níbo ni baba rẹ wà?
O ni nkan bii aago mejila ọsan oni ni alumuntu wọle de were to mu ẹgbọn oun lọ.
Ó wá dé Nasarẹti, ìlú tí wọ́n ti tọ́ ọ dàgbà.
N kò sọ fún ìyá mi kí ń tó lọ sílé BB Naija - Laycon Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, ''Ẹ gbudọ̀ ṣe àwọn ǹkan wọ̀nyí lọ́jọ́ ìdìbò gómìnà l'Ondo bí bẹ́ẹ̀ kọ́ .
Bí omi ṣe é yìnrìn òkúta,tí àgbàrá sì í wọ́ erùpẹ̀ ilẹ̀ lọ,bẹ́ẹ̀ ni o óo ṣe sọ ìrètí eniyan di òfo.
Awọn onimọ iṣegun maa n pe iru iṣẹ naa ni Cosmetic Surgery.
Ajo to n mojuto eto idibo lorile-ede Naijiria, INEC  ti tenumo oro re lati pese eto idibo ni irowo-irose saaju eto idibo ipinle Ekiti to n bo lona, lojo kerinla osu keje odun ti a wayii, nipinle ti o kogun si eka gusuu iwo oorun orile-ede Naijiria.
Oyo Algon: Agbẹjọ́rò ìjọba Ọyọ ní Makinde kò tí ì rí ìwé ìpẹ̀jọ́
Ekunwo tun ti de ba sise pasipaaro owo Dola si owo Naira torile-ede Naijiria loju oja nipinle Eko, eka gusuu iwo oorun orile-ede Naijiria.
Iganmu / Funsho Williams Bridge Ijọba ibilẹ Surulere 10.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ó di dandan kí ará India yìí sọ ìdí tó fi ń sìn kìnìhún- Egbeyemi Bó tilẹ̀ jẹ́ pé bi ìjọba ṣe dẹkun ki òṣìṣẹ́ máa sùn lẹ́nu iṣẹ́ lé mu ọkàn pòruuru, síbẹ̀ ìfọ̀rọ̀wérọ̀ o dúró lóri rẹ̀.
Àkọsílẹ̀ ìran Adamu nìyí: Nígbà tí Ọlọrun dá eniyan, ó dá wọn ní àwòrán ara rẹ̀.
Amọ, bi ọrọ ti ṣe jẹ bayii, awọn ọna wo ni o lee fi daabo bo ara rẹ lọwọ arun yii.
- Amẹ́ríkà fọnmú Èmi àti Kolington kò fẹ́ra padà o, ọba Wákà kò fẹ́ ọba Fuji mọ́ - Salawa Abeni Èmi sì ní Oluwo tilẹ̀ Iwo, kò sí ìgbìmọ̀ ọba kankan tó lè ní kí ń rọ́ọ́kún nílé - Oluwo Toyin Abraham ọkọ rẹ̀ àti Ire ní London, Odunlade 'kòlábò' pẹ̀lú Mercy Aigbe Èlé owó iná ọba kọ́ ló kàn, ẹ kọ́ ṣàtúnṣe sí ìlànà àdánú tẹ́ ń ṣe fún wa - Iléeṣẹ́ apínná sọ fún ìjọba Bẹẹ ba si gbagbe, ẹgbẹ Miyetti Allah yi lo ti n tako agbekalẹ eto alaabo Amotekun latẹyinwa, ti wọn si ni afojusun eto naa ni lati le ẹya Fulani jinna rere si ẹkun iwọ oorun guusu Naijiria.
Awon gomina naa soro ohun di mimo lasiko abewo gomina ipinle Kano si gomina Ikpeazu nile ipinle ohun niluu Umuahia.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Òṣèrè tíátà Muideen Oladapo gbàràdá lórí ètò 'Ṣé o láyà?
Ruga settlement: YCE ní ìjọba àpapọ̀ kò tó bẹ̀ẹ́ láti kọ́ àgọ́ Fulani sílẹ̀ Yoruba
Kí wọn yọ́nú sí mí o 
Balaamu bá bẹ̀rẹ̀ sí fi òwe sọ̀rọ̀, ó ní:“Láti Aramu, Balaki mú mi wá,ọba Moabu mú mi wá láti àwọn òkè ìlà oòrùn.
O ni: “ọfọ nla ni eleyii jẹ fun Naijiria lapapo paapaa fawa elere idanilaraya.
Ninu fidio naa, Olaniyan sọ pe gbogbo ipe ti oun pe si ori ẹ̀rọ ibanisọrọ Florence Ajimobi, ni kò gbé.
Lẹ́yìn ọjọ́ marun-un, Anania olórí Alufaa dé pẹlu àwọn àgbààgbà ati agbẹjọ́rò kan tí ń jẹ́ Tatulu.
#HowGodMademechallenge: Ṣe lóòtọ́ bí àwọn olólùfẹ́ BBC Yoruba ṣe rí rè é?
Bí ìrìnàjó ààrẹ ọlọ́dún méje nílẹ̀ Mali, Keita, ṣe lọ rèé Oríṣun àwòrán, Others Brahim Boubacar Keita ti gbogbo eniyan mọ si IBK ni ọjọ kọkandinlọgbọn, oṣu kini ọdun 1945.
Agba kan ninu mọlẹbi awọn mẹta ti wọn ji gbe naa ṣalaye pe kete ti awọn ajinigbe ti kan si mọlẹbi ni wọn ti kede nkan ti wọn fẹ gba.
Ọkan lara awọn ọmọ bibi ilẹ Ibadan to jẹ akọni ti ko see gbagbe ni Asiwaju Sanusi Adebisi Giwa Idikan.
Ejo ma a n mi ounjẹ wọn ni nitori wọn ko ni eyin ti wọn ma fi jẹ ounjẹ wọn.
jẹ ̀ dọ ̀ jẹ ̀ dọ ̀ b jẹ ́ àkóràn kòkòrò àìlèfojúrí afàìsàn hepatitis b virus ( hbv ) tí ó maa ń dójú kọ ẹ ̀ dọ ̀ .
Àkọlé àwòrán, Aworan afikun iroyin nipa ajakalẹ arun coronavirus ni Naijiria Ni bi a ṣe n sọrọ iye awọn ti ayẹwo ti fihan pe on laarun coronavirus lorilẹede Naijiria ti ẹgbẹrun mẹta o dun aadọta eeyan bayii.
Fayoṣe gunlẹ si ile ẹjọ naa ni nkan bi aago mẹjọ owurọ Ọjọru, ni awọn alatilẹyin rẹ duro wamu-wamu lati ṣe koriya fun.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, CAN: Samson ni ọrọ awọn ajinigbe ti gba àpérò ní Naijiria Koda, ajọ ajafẹtọ ọmọniyan l'agbaye, Amnesty International ti dasi ọrọ naa, to si ti kesi ileeṣẹ ọlọpaa Naijiria lati wadii rẹ.
Ninu iwe ateranse ipese owo ise akanse eyi ti aare ko sile igbimo ohun, aare so di mimo pe, ninu apapo òjìlénígba lé meji bilionu Naira(N242 billion) ti n se owo isuna eto idibo ohun, pe ki ile-igbimo asofin pese bilionu mẹ́rìnlélọ́gọ́jọ le mẹ́rìnlélọ́gọ́rùn ún Naira(N164.
Mò ń dúpẹ́ lọ́wọ́ Ọlọrun mi nígbà gbogbo nítorí yín, nítorí oore-ọ̀fẹ́ tí Ọlọrun fun yín ninu Kristi Jesu.
Ohun tí mò ń sọ ni pé mo fẹ́ wà láàrin yín kí n baà lè ní ìwúrí nípa igbagbọ yín, kí ẹ̀yin náà ní ìwúrí nípa igbagbọ mi.
“Ṣugbọn lẹ́yìn náà, n óo dá ire àwọn ará Amoni pada.
Jonatani ti ṣubú lulẹ̀,wọ́n ti pa á lórí òkè.
Bakan naa ni ipenija wa lori bi wọn yoo ṣe fun eniyan miliọnu lọna ọgọrin ni abẹrẹ ajẹsara, ti o si ṣe wi pe wọn gbọdọ gbe oogun naa ṣi ibi to ba tutu bii inu yinyin (minus 80C).
Gege bi akosile ajo naa pe, idagbasoke ti o ba eka ti ki I sepo-robi wa lati eka eto ogbin, kata-kara, irina oko ati kiko nnkan pamo.
Adájọ́ Ibrahim Sarki Yola ni bàbá náà jẹ̀bi ẹ̀sùn fífi ipá bá ọmọ ọdún mẹ́wàá kan lò pọ̀.
Lara awon to fenuko ohun ni gomina ipinle Gombe teleri , ti otun je okan lara awon to n dije dupo ohun, Danjum Goje , ni o so pe oun kodije mọ, ti o si darapo mo awon to n satileyin fun Ahmad gege bi abenigan ile igbimo asofin agba.
Ẹ bu ọlá fún Ọlọrun,ẹni tí ògo rẹ̀ wà lórí Israẹli;tí agbára rẹ̀ sì hàn lójú ọ̀run.
Ọjọ kẹfa oṣu Keje ọdun 2016 ni agba ọjẹ oṣere tiata naa jade laye.
Láti túnbọ̀ fi pàtàkì ìlú Ìjẹ̀bú -Jẹ̀ṣà hàn, gẹ́gẹ́ bí ó ti wà nínú ìtàn ìwásẹ̀, ti Ọwá bá fẹ́ ṣe ìdájọ́ fún ọ̀daràn apànìyàn kan, Ọba Ìjẹ̀bú - Jẹ̀ṣà gbódọ̀ wà níjòkó, bí èyí kò bà rí bẹ́ẹ̀, Ọwá gbódọ̀ sùn irú igbẹ́jọ́ tábi ìdájọ́ bẹ́ẹ̀ sí ọjọ́ iwájú.
Àgbo tí mò ń lò láti jò kó bá mi, ìdí mi ti yọ́ tán - Nkechi Blessing figbe ta Ọlọ́pàá tún yìnbọn pa awakọ̀ Márúwá, ìwọ́de gba Portharcourt kan Olisa Metuh Ni ọdun 2018 kan naa ni wọn gbe Olisah Metuh to jẹ alukoro tẹlẹ fun gbẹ oṣelu PDP.
Ibo naa ti n lọ lọwọ bayii.
Ṣugbọn nigba ti wọn wa gbe sita ni ede Swahili to jẹ ede apapọ Tanzania lori opo ayelujara nipasheonline.
“ leyin ifehonuhan ati isele  to waye lorile ede naa ni ijoba fi gbe igbese lati parowa fun awon ti oro kan pe ki won ma aba ise won lo.
Jẹfuta tún ranṣẹ pada sí ọba Amoni pé, 
Pierre-Emerick Aubameyang Gabon ati Sadio Mane Senegal ni wọn n ba du ipo naa.
Ẹ wa nkan fidi le ki ẹ wa kọ ẹkọ.
Wọn royin pe pasitọ ọhun rinrinajo lọ si Dubai pẹlu Ibrahim Magu ti wọn si lo orukọ rẹ lati fi ra ilẹ fun Magu ni Dubai.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Myanmar: kékeré ni wọ́n ti n kọ́ àwọn ọmọ nípa ọ̀nà oge ṣiṣe A gbọ pe wọn ti kọkọ gbe obinrin naa lọ sileewosan ilu Kirando fun itọju ko to o bimọ.
Eleyii ni iwadii fihan pe o ran awọn oniṣẹ ilera to n fun awọn to ni aisan naa ni itọju Coronavirus jẹ ẹka aisan ti o ma n fa aisan Pneumonia ati awọn aisan ibalopọ miran Lara awọn aisan to n wa lati ara arun Coronavirus ni Sars, lati ara Sars (lati ara Bamboo) ati Mers (lati ara ẹsin), amọ iwadii si n lọ lọwọ lori ibi ti aisan eleyii ti san wa.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Oyè Mọ́gàjí àti Báálẹ̀ ti di owó rèé, ọjà rèé ní Ibadan - Lekan Balogun Ọ̀pọ̀ òṣèré tíátà tó ń sàìsàn ni kò ṣe dáadáa f'ẹ́gbẹ́ - Jide Kosọkọ Seyi Makinde, yé é sọ̀rọ̀ mi láìdà - Gomina Ajimobi Awọn ọmọ igbimọ yoku ni Wale Adepọju, Debọ Ogundoyin, Oyedijọ Bọsẹde Ayọ Famọla, Ọlọlade Ajibọla, B.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Òògùn ikọ́ olómi Codeine dùn àmọ́ ewu ni A ò gba ìbálòpọ̀ akọ ṣákọ tàbí abo sábo ‘ Ẹ fún Buhari ní ọdún mẹ́rin míràn ’ Adari ile isẹ ọlọpaa lẹkun Khost, Abudul Hanan sọ fun BBC Afghan wipe, ni se ni awọn agbebọn ti wọn ko mọ yinbọn pa Shah lori kẹkẹ rẹ, ko to di wipe wọn gbe lo si ile iwosan amọ ẹpa ko boro mọ.
F Odunjo kọ awọn iwe akagbadun, arosọ, ere onise, ewi, ati iwe kika ni ede Yoruba pọnbele, ti awọn iwe yii si di ohun iwuri ati itọni fun ọpọ onkọwe ode oni Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Wo itan omi gbigbona ati tutu ni Ikọgosi Ekiti Bakan naa ni akọni onkọwe yii wa lara awọn ọmọ igbimọ to n risi akọtọ ede Yoruba (Yoruba Orthography Committees) laarin ọdun 1966 si 1969 Lara awọn iwe ti J.
Ni Peteru bá tẹ̀lé e jáde.
Iko agbabioolu Spain padanu ifigagbaga ipele keta si asekagba idije agbaye naa sowo Russia pelu boolu agbesile gba.
Ejò bu abóyún jẹ nílé ìyàgbẹ́, ó kú pẹ̀lú oyún oṣù mẹ́jọ ní Kaduna Ẹ̀yin ọmọ Kwara, ẹ seun fún àtilẹ́yìn yin lórí ilé Arugbo - Bukola Saraki Ojú ẹni t'ọlọ́pàá ló wà lẹ́yìn ìdigunjalẹ̀ Báńkì Abuja rèé Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Inu mi bàjẹ́ nígbà tí mo bí i, odidi oṣù mẹ́ta, mi ò lè gbàdúrà s'Ọ́lọ́run' Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Ọgọ́ta òṣìṣẹ́ reluwé Eko sí Ibadan kó àrùn Covid-19 ASUU ní fásitì kò le jẹ́ ṣíṣí padà láì sí ìpèsè èèlò ìdènà Covid-19 tó yẹ Ọ̀wọ́n afẹ́fẹ́ ‘oxygen’ àti ibùṣùn dá wàláhà nídìí ìtọ́jú àrùn Coronavirus Jíjábọ̀ ohun tí ń lọ lọ́wọ́ Nípasẹ̀ Yetunde Olugbenga, Olumide Owaduge àti Ahmed Ambali Gbogbo àkókò tí a kọ jẹ́ ti UK Tí a fiṣọwọ́ ní 16:4316:43 Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTC Video content Video caption: Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanAkójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kan Article share tools Facebook Twitter ṢàpínlòView more share options Share this post Copy this linkKà síwájú síi nípa àwọn ìtọ́kasí wọ̀nyí.
Gẹgẹ bo se n gbona lọwọ loju opo Twitter, awọn eeyan kan ti n pin iwe idanwo WAEC to wa fun isiro kiri, ti wọn tẹ ọdun 2020 sinu rẹ.
Ki aṣa maa parun ni ojuṣe gbogbo wa.
O ni o ti n ṣaisan ki idanwo to bẹrẹ.
Igba keji ree ti Liverpool yoo fidi rẹmi nibi ifẹsẹwọnsẹ pẹnariti lọdun 2020 yii lẹyin ti Manchester City ti kọkọ lu wọn pẹlu pẹnariti.
Sẹnetọ Akpabio ni iṣẹ minisita to n ri si ọrọ ẹkun Niger Delta ni lati maa ṣe abojuto kii ṣe lati dari gbogbo nkan.
 nígbà tí ó ọjà àwòran , ó dá ẹgbẹ ̀ rún lọ ́ nà mẹ ́ wá dọ ́ là lée lórí tí ó sì ní ìgbàgbọ ́ wípé kò sí ẹni tí ó maa ràá .
O ni owó ọhun ni ọga oun si paṣẹ foun lori ẹrọ ibanisọrọ lati gbe fun Musiliu Obanikoro.
Ẹgbẹ agbabọọlu Pharaoh ti Egypt si lo ti gba ife ẹyẹ idije naa ju lọ.
Fayemi sọrọ akin yii nilu Ishan Ekiti laisko to n ba awon oniroyin sọrọ lẹyin ti ajọ eleto idibo Naijiria INEC kede pe o jawe olubori ninu idibo to ti na Ojogbon Oluṣọla Eleka to dije labe ẹgbé oṣelu PDP.
Gbogbo wọn ń kùn sí Mose ati Aaroni pé, “Ó sàn fún wa kí á kúkú kú sí Ijipti tabi ní aṣálẹ̀ yìí.
Gomina naa ti o ti figba kan je minisita to n mojuto oro iwakusa ati ohun alumoni kede iyansipo naa lasiko ifinijoye re ti o waye lojo isegun(Tuesday).
Iwadii fihan wi pe, oogun naa ko ni aleebu kankan fun ẹni to ba lo o, amọ a ko le sọ wipe otitọ ni lai wẹyin, nitori oogun paracetamol ti ko ni abawọn, naa ni ipenija tirẹ.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Victor Moses, Oshoala gba ami ẹyẹ Argentina lé Nàìjírìa lọ 'lé láti Russia Ilé yá!
Nítorí nípa ṣíṣe báyìí, ìwọ yóo wa ẹ̀yinná ìtìjú lé e lórí.
Awọn kan lara wọn wọ agọ ọlọpaa to wa nitosi, ti wọn si pa ọlọpaa mẹsan, to fi mọ ọlọpaa obinrin kan to loyun sinu.
Chadia Nishimwe, akẹkọọbinrin ọmọ ọdun mẹrinla ni baba rẹ sọ fun BBC pe o jẹ Ọlọrun ni pe lẹyin ti olukọ kan lu u lalubolẹ.
Nítori àwọn àtúgbẹ́yẹ̀wò, o níra láti ṣe àkójọpọ fún àwọn ọkọ́ naa Orisun: Johns Hopkins University atawọn ajọ eto ilera ilu Iye akọsilẹ to waye gbẹyin 7 Oṣù Ọ̀pẹ̀ 2020 14:22 WAT+3 Ṣe ó tọ̀nà láti máa lọ fún àyẹ̀wò ìgbàdédéìgbà àwọn aláboyún?
"Àmọ́ Apiwe Nxusani-Mawela, tí ṣe obinrin àkọ́kọ́ tí yóò dá ileesẹ ipọnti silẹ, to tún jé alaga ẹgbẹ́ àwọn oloko owó ọtí títa ni South Africa ṣàlàyé pé ""èyí kò dára rárá"", to sì fi ibẹru hàn pé, ó ṣeé ṣe kí oko-owo òun dojú de, tí òfin tó dé kata-kara ọtí líle náà bá tẹsiwaju."
Ìdààmú bá gbogbo àwọn eniyan, ó pá wọn láyà.
Ẹ kọrin sí OLUWA, gbogbo ayé!
''Ijọba ni lati ronu jinlẹ lati koju awọn ipenija to n mu ki awọn ọmọ Naijiria maa sa kuro nilu.
Oríṣun àwòrán, Other Dokita Abubakar ni, awọn dokita onimọ nipa itọju ẹranko mẹfa lo jọ ṣiṣẹ abẹ naa, o ni ohun to jẹ idunnu oun ni pe, ijapa naa ti gbadun bayii, o si ti n ṣere nile olowo rẹ.
Amadou Toumani Toure: Ọdún 72 ló lò lókè èèpẹ̀, kó tó jáde láyé
Àgọ́ ti àwọn ará Midiani wà ní apá ìhà àríwá wọn ní àfonífojì lẹ́bàá òkè More.
Nígbà tí OLUWA bá fún wọn láṣẹ ni wọ́n máa ń pàgọ́, nígbà tí ó bá sì tó fún wọn láṣẹ ni wọ́n tó máa ń gbéra.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ti o bá dá ara ẹ lójú, ki ẹni tó n ṣe irun kí n gbọ́?
Arauna kó gbogbo rẹ̀ fún ọba, ó ní, “Kí OLUWA Ọlọrun rẹ gba ẹbọ náà.
Wọn yóo wó ọ lulẹ̀, wọn yóo sì pa àwọn eniyan tí ó wà ninu rẹ.
Ó ranṣẹ sí Abimeleki ní Aruma, ó ní, “Gaali, ọmọ Ebedi, ati àwọn arakunrin rẹ̀ ti dé sí Ṣekemu, wọn kò sì ní gbà fún ọ kí o wọ ibí mọ́.
Ọlọ́pàá fìyà jẹ mí lọ́dún 2014, mò wà lẹ́yìn àwọn ọ̀dọ́ lórí ìwọde EndSARS- Fayemi Fatai Rolling Dollar, Ọmọ ìdílé oyè tó gbé igbá orin tí Ebenezer Obey ń ṣiṣẹ́ lábẹ́ rẹ̀!
Nadabu, arakunrin Abiṣuri náà bí ọmọ meji: Seledi ati Apaimu; ṣugbọn Seledi kò bímọ títí tí ó fi kú.
amosa, won yoo fi ogbeni Bashir  pamọ si
Ẹ ṣọ́ra kí ẹnikẹ́ni má ṣe dàbí igi kíkorò, tí yóo dàgbà tán tí yóo wá fi ìkorò tirẹ̀ kó ìdààmú bá ọpọlọpọ ninu yín.
Sugbọn, tako nkan ti Gomina Masari sọ, agbenusọ fun Aarẹ Muhammadu Buhari, Garba Shehu, sọ fun BBC pe awọn ọmọkùnrin to raaye sa mọ agbebọn naa lọwọ sọ pe ọmọ mẹwaa lo si wa ni ọdọ awọn agbebọn.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ekiti Election: Alailójúti ní Buhari- Fayose 16 Agẹmo 2018 Oríṣun àwòrán, Ayodele Fayose/Facebook Àkọlé àwòrán, Ayọdele Fayoṣe ti máa ń tako ìjọba Ààrẹ Muhammadu Buhari Irọ́ ni Buhari ń pa, kò féran ìdàgbàsókè ìṣèjọba alágbádá rárá Láti ọjọ ti wọn ti ká èsì ìdìbò ní ìpínlẹ̀ Ekìtì ní gbogbo ọmọ Nàìjíríà tí ń retí kí Gomina Ekìtì, Ayodele Fayose fèsì lórí àbájáde èsì ìdìbò gomina ipinlẹ Ekiti.
Ìrìnàjò Toyin Abraham, láti orí gbèsè jíjẹ, ó di onílé, onimọto àti aya lọ́ọ̀dẹ̀ ọkọ Baba Latin ṣe bẹbẹ lori èto Se o láya, sùgbọ́n.
Ẹ̀yin àyànfẹ́ mi, gbogbo nǹkan tí à ń ṣe, fún ìdàgbàsókè yín ni.
Igbeṣẹ yii lo n waye lẹyin ti fidio kan gbode lori ayelujara, eyi to ṣafihan igo ọti ọhun ti wọn kọ orukọ ipinlẹ ipinlẹ Ondo si lara pẹlu orukọ ti ọpọ eeyan mọ gomina ọhun si, iyẹn Aketi.
Bí wọn tí ń mu ọtí, ọba tún bi Ẹsita léèrè pé, “Kí ni ìbéèrè rẹ Ẹsita, a óo ṣe é fún ọ, kí ni ẹ̀bẹ̀ rẹ, gbogbo rẹ̀ ni a óo jẹ́ kí ó tẹ̀ ọ́ lọ́wọ́ títí dé ìdajì ìjọba mi.
Ati pe, Ileeṣẹ Amcon ti gbẹsẹ le awọn ohun ini Pan Ocean kọọkan nitori gbese naa to to oji le ni igba biliọnu owo naira.
Lasiko Goodluck Jonathan to sejọba saaju aarẹ Buhari, o na ọpọlọpọ biliọnu owo naira lati kọ awọn ile ẹkọ almajiri Amọ, Aarẹ Buhari to wa lori oye yi ti sọ pe oun fẹ ki wọn wọgile iru ẹkọ yi ki wọn si ko awọn ọmọ almajiri lọ si awọn ile ẹkọ ti wọn kọ labẹ ijọba Jonathan sabẹ akoso ijọba ati awọn onimọ ẹsin.
Ohun tí wọ́n fi ń ṣe báàgì, bàtà ni wọ́n ń tà bíi ‘pọ̀ǹmọ́’— NAFDAC Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Nigeria Pensioners: Wàhálà àyẹ̀wò iwé ìfẹyinti yì ti pọ̀jù Amọ awọn eniyan miran ti bu ẹnu ẹ̀tẹ́ lu owo gọbọi ti awọn ilumọọka yii n gba.
Àwọn agbébọn ṣekúpa akẹ́kọ̀ọ́ tó wà nípele àṣekágbá ní fásítì Kogi Má ṣe fi ọkọ̀ rẹ gbé àgùnbánirọ̀ lẹ́yìn aago mẹ́fà ìrọ̀lẹ́- FRSC Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Akure Kidnap: Àwọn abiyamọ fẹ̀hónúhàn lórí ọmọ tí wan jígbé nílé ìjọsìn Akurẹ Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Liverpool pègúnrẹ́, wọ́n gbé ife ẹ̀yẹ̀ Premier league lẹ́yìn ọgbọ̀n ọdún Wo àwọn Gómìnà Naijiria tí àrùn Covid-19 ti bá fínra Pissetzky, to jẹ agbẹjọro nilu Chicago, sọ fun awọn oniroyin pe, wọn ko ti i yọnda rẹ, ati pe oun ṣi ni agbẹjọro rẹ, tako iroyin kan to sọ pe Hushpuppi ti kọ ọ ni agbẹjọro.
    Ní ọjọ́ keje tí Òmùgọ́diméjì kú ni wọn fi àkọ́b;i ọmọ rẹ̀ joyè, ẹni tí orúkọ rẹ̀ ń jẹ́ Òmùgọ́dimẹ́ta.
Ta ba ni ọkunrin, ati obinrin, awọn isẹda kẹta ti yoo wa ni awọn to ni oju ara meji.
ṣugbọn tí ó bá jẹ́ àríyànjiyàn nípa àwọn ọ̀rọ̀ tabi orúkọ, tabi òfin yín, ẹ lọ rí sí i fúnra yín.
Auxiliary, ẹni tó bá BBC Yorùbá sọ̀rọ̀ tún mẹnuba bí ìṣẹ̀lẹ̀ náà ṣe kan èèkàn àwùjọ kan, Oloye Sunday Adeyemo, tí àwọn èèyàn tún mọ sì Sunday Igboho.
Seyi Makinde wa leri leka pe gbogbo isẹ agbase ti Ajimọbi ba gbe jade lẹyin idibo gomina to kja ni oun yoo tu isu de isalẹ ikoko wọn ni kete ti oun ba gba ọpa asẹ tan losu karun ọdun yiii.
Ijọba fikun un pe esi idanwo saa eto kini ati ti saaeto ẹkọ keji fun ọdun 2020/21 yoo bere ni Ọjọ Kọkanlelogun, Oṣu Kẹsan an ati Ọjọ Kejidinlogun, Oṣu Kejila, ọdun 2020.
Ọrọ laarin agboole oduduwa ni, a si ti yanju rẹ Bakan naa ni Ewi ti ilu Ado Ekiti, Ọba Rufus Adeyẹmọ Adejugbe pẹlu Ajero ti Ijero Ekiti, Ọba Adewọle Adebayọ ti wọn sọrs loruks awọn ọba pelu-pelu mọkanla yooku ni awọn ti panupọ lati fagile gbogbo ẹjọ to wa niwaju ile ẹjọ lori ọrọ naa.
Owoṣeni ni o digba ti ọwọ oun ba tẹ eeku ida aṣẹ gẹgẹ bii oludamọran ki oun to le ṣalaye awọn ipinnu to ni lori eto aabo lasiko yii.
Ṣema bí Rahamu, Rahamu bí Jokeamu, Rekemu sì bí Ṣamai.
Àwọn apẹja ti kúrò ninu àwọn ọkọ̀ yìí, wọ́n ń fọ àwọ̀n wọn.
Mo di àkòtagìrì fún àwọn ojúlùmọ̀ mi,àwọn tí ó rí mi lóde sì ń sá fún mi.
Ireti wa pe aare Buhari yoo
O sọ eyi nibi ipade igbimọ alaṣẹ ipinlẹ Oyo pe N900.
Oríṣun àwòrán, Baba Oloye Àkọlé àwòrán, Ileesẹ ọlọpa ni gbogbo awọn ọbayejẹ lọwọ yoo ba nipinlẹ ọsun laipẹ Kọmisọna ọlọpa Adeoye ni, awọn ọlọpa yoo se iwadi to jinlẹ lori ọrọ wọn, yoo si rii daju pe wọn ko bọ lọwọ ofin.
Obinrin ṣagbako iku nibi ti o ti sa fun ọwọn ọmọ onilẹ ti wọn n fẹhonu han.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Talàwọn ọmọlẹ́yìn Saraki tó ń du ipò Gómìnà ní Kwara?
ati òwìwí ńlá, ati òwìwí kéékèèké, ati ògbúgbú, 
Yíyípo ni afẹ́fẹ́ ń yípo, a sì tún pada sí ibi tí ó ti wá.
Bí Jesu ti jókòó lọ́kàn-ánkán àpótí owó, ó ń wò bí ọpọlọpọ eniyan ti ń dá owó sinu àpótí.
Ipò ètò ààbò ń já àwa gómìnà láyà, ó ń kọ wá lóminú - Àwọn gómìnà Aarẹ Buhari ni ko dun mọ oun ninu lati yọ Onnoghen ṣugbọn nigba ti iwadii fihan pe owo gọbọi ni wọn ba ninu asuwọn rẹ.
Ọjọ́ ìdààmú wọn kù sí dẹ̀dẹ̀,ọjọ́ ìparun wọn sì ń bọ̀ kíákíá.
Fuel Reduction: Awọn ọmọ Naijiria ni muri kan ti kéré ju láti yọ nínú jálá epo
Ó ní bí wọ́n tilẹ̀ ké pe òun, òun kò ní fetí sí tiwọn.
Ọdọ rẹ si ni gbogbo arun ati gbogbo nkan wa.
Tunde Bakare: Ọlọrun kìí yan ọ̀lẹ sí iṣẹ́ ìránṣẹ́ rárá Eyi ni ifọrọwanilẹnuwo pẹlu gbajugbaja pasitọ Tunde Bakare lasiko ti ọrọ idamẹwa sisan n fa ariyanjiyan lorilẹede Naijiria.
oselu APC fun ipinle  Ebonyi, asofin Sonni
1 Ẹ fetísílẹ̀, Áà ẹ̀yin ènìyàn ìjọ mi, ni ohùn ẹnití ngbé ní ibi gíga, àti ẹnití ojú rẹ̀ wà lára gbogbo ènìyàn ńwí; Bẹ́ẹ̀ni, lõtọ́ ni mo wí: Ẹ fetísílẹ̀ ẹ̀yin ènìyàn lati ọ̀nà jíjìn; àti ẹ̀yin tí ẹ wà lórí àwọn erékùsù òkun, ẹ jùmọ̀ tẹ́tísílẹ̀.
Awọn mọlẹbi naa lasiko ti wọn kede isinku rẹ sọ pe nitori pe o fẹ kọ ọkọ rẹ silẹ ni Pasitọ Sylvester fi yinbọn lu lẹẹmeeje ti eyi si ṣokunfa iku rẹ.
Ọkọ̀ kan tàkìtì nínú ìjàmbá tó wáyé lẹ́bá afárá Third Mainland l'Èkó Emir Bornu lé àwọn aṣẹ́wó léré, ó ní kò sáyè fúnwọn nípìnlẹ̀ òun Ẹ wo àwọn ààrẹ tí ikọ̀ ọmọ ogun ti gba ìjọba lọ̀wọ̀ wọn Makinde vs Adelabu: Ilé ẹjọ́ tó ga jùlọ ní Nàìjíríà ní yóò yanjú ọ́rọ́ ìdìbò Gómìnà Oyo Aàrẹ, igbákejì aàrẹ àti aàrẹ ilé ìgbìmọ̀ aṣòfin kọ̀wé fipò sílẹ̀ lọ́jọ́ kan náà Wọn tun kilọ pe kawọn olugbe ipinle Eko sa fun omi mimu ati ohun jijẹ koda eso ti ko ba mọ nitori pe ilera ni ọrọ.
Pinra-pinra si ni wọn nya fọto pẹ́lu baba.
Oríṣun àwòrán, Twitter Wọn pa a laṣẹ fun gbogbo awọn olukọ ni fasiti jakejado orilẹede Naijiria, lati ṣiwọ iṣẹ loju ẹsẹ ti aṣẹ naa jade.
Ọgbẹni Tony Okoroji to jẹ alaga awọn ẹgbẹ to n ri si ohun ini ninu idanilaraya ni oun lọ wo oloogbe naa nigba ti o ṣi wa nile iwosan ko too ku.
Alfa Babatunde atawọn ọmọ ijọ rẹ mẹfa ti wọn jẹ oṣiṣẹ nile ijọsin naa ni wọn jọ foju ba ileẹjọ lori ẹsun to da lori koko mẹta ti wọn fi kan wọn.
Ninu iwadii naa, Oxfam ni ida kan awọn ọlọla ni Iwọ Oorun Afirika ni owo ju gbogbo ida mọkandinlọgọrun to jẹ mẹkunnu.
Facebook fi kọ́kọ́rọ́ ti àwọn ojú òpó ayédèrú ìròyìn léde Yorùbá àti Igbo Ayọ̀ abara bíńtín!
Page 1 nínú 50 rewind previous Navigate to the next page nextNavigate to the last page forward Padà sí òkè ÀkọléÀkọlé abala Àkọlé abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Rìn káàkiri BBC News Sport Weather Radio Arts Ìlànà Lílò Nípa BBC Òfin Àṣírí Cookies Ìrànlọ́wọ́ Ìwọlé Ìtọ́ni Òbí Kàn sí BBC Get Personalised NewslettersCopyright  2021 BBC.
Gomina Amosun, eni ti igbakeji re Yetunde Onanuga  soju fun, ro awon onile-ise nipinle naa lati fowosowopo pelu ijoba lati mu igberu ba awon ohun amayederun, igberu ba eto eko, ati sisan owo ori won lore-koore.
N óo fìdí majẹmu mi múlẹ̀ pẹlu rẹ̀, gẹ́gẹ́ bíi majẹmu ayérayé fún atọmọdọmọ rẹ̀.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Olaitan Olamide: mò lè má nílò ìwé ẹ̀rí mi tí mo bá parí ní LASU Eyi ni awọn ọta ti orilẹ-ede Naijiria ni gẹgẹ bi Pasitọ Bakare ṣe sọ ọ.
Mú ìwà èké jìnnà sí mi,kí o sì fi oore ọ̀fẹ́ kọ́ mi ní òfin rẹ.
Kí ẹ wá àwọn eniyankeniyan meji kan tí wọ́n ya aṣa, kí wọ́n jókòó níwájú rẹ̀, kí wọ́n sì fi ẹ̀sùn kàn án pé, ó bú Ọlọrun ati ọba.
 lẹ ́ hìn ti ààfin sísun fún yìí , wọn a tún máa sún tẹ ̀ lé ọba yìí bí ó bá ńlọ sí ìdálẹ ̀ kan .
Èmi, ọgbọ́n, òye ni mò ń bá gbélé,mo ṣe àwárí ìmọ̀ ati làákàyè.
Wọ́n dìde ní òwúrọ̀ kutukutu ọjọ́ keji, wọ́n rú ẹbọ sísun, wọ́n sì mú ẹbọ alaafia wá, wọ́n bá jókòó, wọ́n bẹ̀rẹ̀ sí jẹ, wọ́n ń mu, wọ́n sì ń ṣe àríyá tóbẹ́ẹ̀ tí wọ́n bẹ̀rẹ̀ sí bá ara wọn lòpọ̀.
Bi o tilẹ jẹpe aarẹ Buhari ti ba ọga ọlọpaa sọrọ, Yakassai nipe o yẹ ki aarẹ ba awọn araalu sọrọ loju koroju ni.
Ẹni to bori: Egypt Ìpele to ṣaaju eyi to kangun si aṣekagba Senegal vs Morocco.
Èèyàn méjì kú, méjìdínlógóje míì ṣẹ̀ṣẹ̀ kó COVID-19 lọ́jọ́ Àìkú Wo nkan tó yẹ kí o mọ̀ nípa Tolanibaj, Wathoni àti Brighto ni wọ́n lé kúrò ni BbNaija l'ọ́sẹ̀ yìí Irọ́ ni, kò sí olóyún nínú àwọn tí Tírélà pa ní Ondo ṣùgbọ́n awakọ̀ ti sá lọ- Ọlọ́pàá Ondo Ààrùn coronavirus tó ràn mí jẹ́ kí n mọ̀ pé àlààfo díẹ̀ ló wà láàrin ikú àti ìyè - Lola Alao Boseman jade laye lẹyin ọdun mẹrin ti aisan jẹjẹrẹ ti n ba a finra, iyawo rẹ naa si wa pẹlu rẹ ni ile rẹ to wa ni Los Angeles nigba to mi eemi ikẹyin.
Igba akọkọ si kọ ree ti aawọ n waye laarin Daddy freeze ati David Oyedepo, paapaa lori ọrọ kawọn ọmọlẹyin Kristi maa san idamẹwa.
" Èdè ni ariwo tí ń ti ẹnu ènìyàn jáde tó ní ìlànà .
Lọdun 2018 kan naa, o le ni ẹgbẹrun meji ti wọn fun awọn ara Sudan, ọdunrun o din mẹwaa ni wọn fun awọn ara Tanzania ti wọn si fun awọn ara Eritrea ni mọkanlelọgbọn.
‘Bí ẹ bá dúró ní ilẹ̀ yìí, n óo kọ yín bí ilé, n kò sì ní wo yín lulẹ̀.
So etí kinni keji àwọn ẹ̀wọ̀n mejeeji mọ́ ojú ìdè mejeeji, kí o so ó mọ́ èjìká efodu náà níwájú.
8 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Ohun tó yẹ kí o mọ̀ nípa ìgbésẹ̀ tí Amẹ́ríkà fẹ́ gbé lórí Nàìjíríà nítorí ọ̀rọ̀ ẹ̀sìn Ijọba orilẹede Amẹrika ti fi orukọ Naijiria si inu iwe mákàn"" lori ọrọ ominira ati ṣe ẹsin tk ba wuni."
Ọdọmọbinrin kan ree, Adedamọla Adebukọla, ti ko ni oluranlọwọ lẹyin eto ẹkọ girama, amọ ti ko setan lati gbe igba nabi abi tọrọ agbe, sugbọn to wa ohun ti yoo se jẹun dọjọ alẹ Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: 'Ọjọ́ lọjọ́ tí mo mọ̀ pé wọ́n bí mi láà ní ojú ara obìnrin àti ilé ọmọ' Ọmọ ti lọ kí baba, Fayemi bẹ Aláàfin wo l‘Ọyọ, wọ́n jírórò lórí lẹ́tà Coronavirus dá rúkè-rúdò sílẹ̀ ní pápákọ̀ òfurufú l‘Amẹrika, ọ̀pọ̀ ń forí gbárí Òṣèré tíátà Yorùbá mẹ́ta gbàmì ẹ̀yẹ pé wọ́n pegedé Òkú ṣùn nínú ìbúgbàmú tó wáyé l‘Eko Àwọn kókó ohun tó wà nínú lẹ́tà tí Aláàfin kọ sí Fayemi rèé Nigba to n ba BBC Yoruba sọrọ, Adebukọla ni osu marun pere ni oun fi kọ isẹ aworan yiya, eroja ohun mimu kọfi, Zobo ati tii elewe Lipton si ni oun fi maa n ya aworan.
 O ni, ipinnu awon agba-boolu oun ni lati gba idije naa.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Ara awọn ohun manigbagbe ti ajakalẹ arun Coronavirus lagbaye mu ba aye ree.
”Mo ní, “Èso ọ̀pọ̀tọ́ ni, àwọn tí ó dára, dára gan-an, àwọn tí kò sì dára bàjẹ́ tóbẹ́ẹ̀ tí wọn kò ṣe é jẹ.
Gẹgẹ bi ileesẹ iroyin AFP ti kede rẹ, asoju naa yọju si ileesẹ ajọ isọkan agbaye lọjọ Aje, to si ba igbimọ kan sisẹ eyi to nii se pẹlu ọrọ ofin.
Alfa Babatunde wa nile ẹjọ Oke Eda, to wa nilu Akure lọwọ bi a ṣe n kọ iroyin yii.
" Arteta sọ pe oun lọ ṣayẹwo lẹyin ara oun rẹwẹsi, leyi to fi han pe Coronavirus lo n ba finra.
Alukoro ẹgbẹ agbabọọlu naa, Dimeji Oshode sọ ninu atẹjade kan pe, iṣẹlẹ naa waye lopopona Sagamu nigba ti ologbe ọhun ati akẹgbẹ rẹ, Sanni Abubakar n rinrin ajo.
Gomina tuntun ti won sese dibo yan nipinle Ekiti, ilu ti o kogun ni eka iwo oorun orile-ede Naijiria, dokita Kayode Fayemi ti kede awon alabasise po labe isakoso re akoko.
 ní april 2000 , ilé ìṣura metropolitan ṣí àjọ a.
Gbajugbaja ni oloogbe onkọ̀we Oladejo Okediji jẹ larin awọn onkọ́we Yoruba ọmọ orilẹ-ede Naijiria.
Kí ìjọ mi ní Sagamu le gbòòrò ni mo fi ń ṣiṣẹ́ ajínigbé pawó - Pásítọ̀ Àwa àti fijilanté pẹ̀lú ọdẹ́ ìbílẹ̀ ló dojú kọ adigunjalè ní First Bank Okeho - Iléeṣẹ́ ọlọ́pàá Ìtàn ọba Yorùbá tí wọn yẹgi fún torí ó jí ọmọ gbé ṣe ètùtù Ẹ káàbọ̀ sọ́jọ́ Arafat, tí Ọlọ́run yóò fi ààwẹ̀ Mùsùlùmí pa ẹ̀ṣẹ̀ wọn rẹ́ Ọmọ mi kò tíì mọ̀ pé òun ti di ìlúmọ̀ọ́ká, ó ń wádìí bó ṣe ń rí ara rẹ̀ lórí ayélujára"" Boko Haram da ìbọn bo ọkọ̀ gómìnà Borno, ẹ̀ṣọ́ àláàbò rẹ̀ farapa O ni aarẹ Buhari ti fọwọ sọya fawọn ileesẹ alaabo pe oun yoo pese awọn ohun eelo to yẹ fun wọn lati lee koju aifararọ eto aabo nibikibi lorilẹede Naijiria."
"Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Àwọn kókó ohun tó wà nínú lẹ́tà tí Aláàfin kọ sí Fayemi rèé Ronke Oshodi Oke ṣe àwo orin jáde fún MC Oluomo fún ọjọ́ ìbí rẹ̀ Ẹ wo ìdí tí El Rufai kò fi leè fi Sanusi sílẹ̀ ""N kò kọ̀ kí ń kú, ìfẹ́ tí mo ní sí Buhari ni mo ṣe sáré dì mọ"" Pẹ̀lú gbogbo ìròyìn ajanilaya to n waye lati Italy nipa ọsẹ arun Coronavirus naa, lo mu ki BBC Yoruba kàn si àwọn ọmọ Naijiria to wà lorilẹede naa, láti mọ irú ipò ti wọ́n wà pẹ̀lú ajakálẹ̀ ààrun yìí."
Adajọ Anthony Apkovi ti o ṣoju igbimọ ẹlẹni mẹta ti o risi igbẹjọ naa lo kede abajade iṣẹ iwadii wọn lọjọ Iṣẹgun.
 orile ede Najiria ti la awon ipenija kọja
Ó ní ogúnlọ́gọ̀ àwọn ọmọ ni wọ́n ti pa ni àwọn ilé iwé tí ẹnikẹni ko si mọ́ ìdí ikú to pa wọ́n àti pé, kò si ìwádìí kan to kẹ́sẹ jári nínú àwọn tó ti kú.
    Ìtàn sísọ ni iṣẹ́ wọn nínú ilé Òpìtánparapọ̀ ibẹ̀ sì ni ọkùnrin kan báyìí ń gbé tí ó lè sọ ìtàn dé góngó, orúkọ ẹni ti ń jẹ́ Ìtándìran.
" Bayii, ajọ eleto idibo INEC ti kede esi idbo naa ni eyi ti Kayode Fayemi ti egbe oselu APC ti jawe olubori.
Àwọn olùfẹ̀hònúhàn kọ etí ikún s'íkìlọ̀ ọlọ́pàá ṣe ìwóde ní London Oríṣun àwòrán, Reuters Ẹgbẹẹgbẹrun un awọn olufẹhonuhan lo tu jade laarin gbungbun ilu London lọjọ Satide, bo tilẹ jẹ pe awọn ọlọpaa ti kilọ fun wọn lori iwọde naa.
“Èmi kò lè dá nǹkankan ṣe.
Ti ọpọlọpọ aworan apanilẹrin nipa 'igbeyawo naa' si kun ori ayelujara.
 bakanna , o tun gba ipo kinni ni emerin fun awon idije inuule , ohun si tun ni adijekinni marathon idaji agbaye 2001 .
”Gege bi akowe agba ajo NFF, Mohammed Sanusi, said, “Ikinni wa lati odo awon oludari ajo NFF si ijoba apapo fun atileyin won, eyi ti o ron iko yii lowo lati saseyori ninu idije AWCON.
Ó rẹ ara rẹ̀ sílẹ̀, ó gbọ́ràn sí Ọlọrun lẹ́nu títí dé ojú ikú, àní ikú lórí agbelebu.
Ọjọ kọkandinlọgbọn, oṣu karun un, ọdun 2019 ni awọn to wa nipo bayii a kogba wọle ti awọn ojú tuntun a gori aleefa ni awọn ipinlẹ Naijiria.
Nítorí pé wọ́n ti jẹ́ iranṣẹ fún wọn níwájú àwọn oriṣa, wọ́n sì di ohun ìkọsẹ̀ tí ó mú ilé Israẹli dẹ́ṣẹ̀, nítorí náà, mo ti búra nítorí wọn pé wọ́n gbọdọ̀ jìyà.
Adajọ ni o gbọdọ wa lati ṣalaye idi ti awọn ko fi ni gba owo ọgọta miliọnu Naira to fi ṣ'oniduro fun Faisal.
Ṣe eto igbani sisẹ ti bẹrẹ?
Aṣoju ẹgbẹ awọn Onile-iwe Aladani ni Ipinlẹ Eko, Ọgbẹni Joseph Idornigie naa rọ ijọba lati yọ iru owo-ori ilẹ yii kuro ninu nnkan ini awọn ile-iwe nitori iṣe ilu ni awọn n ṣe.
Nígbà tí Aṣojú-Olódùmarè fi máa dé púpọ̀ nínú àwọn aláìsàn ti kú, ara wọn kò lágbára láti gbé àìsàn tí wọ́n béèrè nígbà tí òun kọ́ wá.
Oríṣun àwòrán, Others Ibẹrẹ isubu alagbara Eji Gbadero: Ni ọjọ kan lọdun 1975, Eji Gbadero ati awọn ọmọ ẹyin rẹ lọ san ilẹ nla kan to gbooro ni agbegbe Alumoso, ibẹ ko si tii laju nigba naa, inu abule ni.
Ẹfunsetan Aniwura, obìnrin tó ju ọkùnrin lọ Ọ̀rọ̀ǹpọ̀tọ̀niyùn, Aláàfin obìnrin àkọ́kọ́ rèé, tó ní nǹkan ọkùnrin Loju opo Instagram ni Dino ti fi aworan ati ọrọ to pe akọle rẹ ni nigba to ba n ba ole aji ọpa aṣẹ ṣiṣẹ""."
Ko si ẹni to le sọ bi awọn ọmọ yi ti se ko arun yi sugbọn ko lee sẹyin bi wọn ti se n gba bara kiri lati ojule kan si ekeji.
‘Buhari gbà wá o, Seyi Makinde n fi jàǹdùkú halẹ̀ mọ́ wa láti kúrò lọ́ọ́fìsì’ Buhari, fí mí jẹ olùrànlọ́wọ́ pàtàkì fépo rọ̀bì- Guru Maharaji Ẹ dákẹ́ àhesọ ọ̀rọ̀, n kò bí ìbẹta - Yinka Ayefẹlẹ Ọba Adesoji Aderemi, Ọọ̀ni Ifẹ̀ tó gba ipò ọba mọ́ tòṣèlú Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ladoja: Àwọn èèyàn Oyo fì ìbò sọ̀rọ̀ pé ìjọba Ajimobi kò dára Gomina ipinlẹ Bayelsa ni asiko mti to lati ṣe ẹkunwo gidi fawọn oṣiṣẹ nitori ọjọ ti pẹ ti wọn n ti n gba owo kekere.
Bẹ́ẹ̀ ni ó ṣe ń ṣàkóso àwọn orílẹ̀-èdè;ó sì ń fún wọn ní oúnjẹ lọpọlọpọ.
Olówó yalumọ àkọ́kọ́ nílẹ̀ Yorùbá Ọ̀wọ́ngógó oúnjẹ, epò, iná ọ̀ba ti sọ owó oṣù N30,000 da N9 nitórí náà kò ní sí ọjà, epo, iléèwòsàn láti Ọjọ́ Ajé - NLC Iléẹjọ́ ní kí Yakubu lọ gé oko àgọ́ ọlọ́pàá fọ́jọ́ méjì lẹ́yìn tó jí fóònù N8,700 Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Toyin Atoyebi mechanic: Ẹ wo Toyin, ọmọbinrin ọdún 16 tó ń tún skadà àti gẹnẹrátọ̀ ṣe ní Nigba to tun di inu oṣu keje ọdun 2020, ijọba tun un gbe wa siwaju ile igbimọ aṣofin kẹsan eyi si ti n mu ọpọ ọmọ Naijiria yari fohun silẹ.
 “Orukọ  awọn  olori adigunjale naa ni: Ayoade Akinnibosun, Ibukunle Ogunleye, Adeola Abraham, Salawudeen Azeez, Niyi Ogundiran ati  awọn  afurasi  mẹ́tàdínlógún to lọwọ nibi idigunjale nile-ifowopamọ  to waye niluu Offa, ati bi  wọn  se pa  awọn  eniyan mẹ́tàdínlọ́gbọ̀n , lara  wọn  ni  awọn  alaboyun ati ọlọpaa  mẹsan an, ti  wọn  si tun  jewọ pe  awọn  n sisẹ gẹgẹ bi janduku oloselu fun Abẹnugan ile igbimọ asọfin Bukola Saraki ati gomina ipinlẹ Kwara , Alhaji Abdulfatah Ahmed.
Kọmísọ́na sàlàyé pé, gbogbo ọ̀nà ni ìjọba ìpínlẹ̀ Eko maa n gbà láti bá ará ilú sọ̀rọ̀, àwọn lọ́balọ́ba, àwọn asojú àgbègbè kọ̀ọ̀kàn ló wá ti ìjọba sì n bá wọ́n sọ̀rọ̀ tí wọ́n bá nílò láti fi ọ̀rọ̀ ránṣẹ́ si àwọn ti kò láàfáni láti wà lórí àwọn ojú òpó ìkànsíraẹni.
Ko mu idajọ wa sori gbogbo awọn aṣebi ko si jẹ ki alafia wa niluu.
Wo bí wọ́n ṣe sìnkú àwọn àgbẹ̀ 43 tí Boko haram dúmbú ní Borno Bí mo bá leè rí ọmọ alágbe t'áyé fẹnu sí pé mo fi ẹlẹ́rìndòdò lá lójú, máa kúnlẹ bẹ ẹ - Motara Bakan naa ni Araba ti ilu Osogbo, Oloye Fayẹmi Ẹlẹbuibọn pẹlu kin ọrọ yii lẹyin ti wọn ni ọba ti ko ba ṣe oro ibilẹ ki o to de ori oye kii ṣe Ọba.
"Oríṣun àwòrán, BBC Sport ""Eyi lo mu ka bẹrẹ iwadi wa, ta si gbe ọkunrin naa, Chibuzor nilu Portharcourt to wa, amọ nigba to bọ si gbaga wa, lo yi ohun pada pe ọgbọn atijẹ ni oun n da, oun ko mọ ẹnikẹni tabi ohunkohun nipa isẹlẹ naa."
Lẹyin naa ni wọn ko awọn iwe kika àti iwe ẹri jade ni ibi ti wọn ko wọn si, wọn si dana sun wọn.
OLUWA, gẹ́gẹ́ bí iṣẹ́ òdodo rẹ, dáwọ́ ibinu ati ìrúnú rẹ dúró lórí Jerusalẹmu, ìlú rẹ, òkè mímọ́ rẹ; nítorí pé ẹ̀ṣẹ̀ ati àìdára àwọn baba wa, ti sọ Jerusalẹmu ati àwọn eniyan rẹ, di àmúpòwe láàrin àwọn tí ó yí wa ká.
Iroyin naa ni se ni awọn ẹbi Sanwo-Olu to n gbe ninu ile naa, to wa ni opopona Omididun lagbegbe Lagos Island sa asala fun kmi wọn.
Gomina ohun wa gboriyin fun Tinubu fun bi o se je asiwaju rere, ni eyi ti o so pe, o ti ko ipa ribi-ribi lori eto ijoba tiwa-n-tiwa ati isakoso ijoba rere lorile-ede Naijiria.
Ibà ti agbara oogun apakokoro ati egboogi ko ka Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ayẹwo ẹjẹ gbọdọ maa waye l'oore-koore lati tọpinpin ibà ti agbara egboogi ko ka Ajọ WHO ti fi ikil sita pe abo ẹ̀fọn ti n fi agbara han lera-lera pe agbara egboogi ati oogun apakokoro ko ka oun - to si n mu idiwọ ba iṣẹgun lori iba.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ṣé ẹ fẹ́ mọ ìgbà tí ẹ̀fọn meji bá ń kọ orin ifẹ́ léti yín?
lasiko to n fi ami ayeye ikẹyin da oloogbe ,
Baali bí Beera, tí Tigilati Pileseri ọba Asiria mú lẹ́rú lọ; Beera yìí jẹ́ olórí ninu ẹ̀yà Reubẹni.
Raymond Dokpesi to ni DAAR Communications ti ṣalaye pé awọn ko tete san owo idiyele igbohunsafẹfẹ ti saa yi nitootọ.
Ṣugbọn àwọn eniyan mi ti di ìkà,bí ògòǹgò inú aṣálẹ̀.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Ki lo ṣẹlẹ lọjọ Satide ọjọ kejindinlọgbọn?
Ati pe gbogbo igba ti oun ba lọ si irinajo l'oun maa n lọ si awọn ile igbafẹ ti awọn eniyan ti maa n jo ni ihoho tabi ṣe afihan fiimu onihoho.
Gege bi ẹ se mọ pe ilu Eko  ni ibi ti awon onisowo gunlẹ si lorile ede Naijiria.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù World Sickle Cell Day: Àwọn ǹkan ti alárùn SS kò gbọdọ̀ ṣe fún alááfíà ara- Dókítà Igbekele 19 Òkùdu 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 20 Òkùdu 2020 Oríṣun àwòrán, others Àkọlé àwòrán, Ohun méje tí o kò gbọ́ rí nípa aláìsàn fòníkú fọ̀ladìde Ni igba akọkọ ti wọn yoo ṣe ayajọ ọjọ aisan arunmọleegun, ajọ isọkan agbaye lo kọkọ ṣe agbekalẹ rẹ lọdun 2008.
"Awọn saraki-saraki eeyan lonibara mi nigba naa, awo orin igbalode CD ko si tii wọpọ nigba naa.
Báwo ni àrùn coronavirus ṣe ń wọ Nàìjíríà Ìjọba ti pápákọ̀ òfúrufú Eko àti Abuja pa nítorí coronavirus Aawakọ̀èrò, ọlọ́kadà farakásá àṣẹ ìjọba Ekiti láti dẹ́kun Coronavirus Wọ́n ti fi ọmọ orílẹ̀-èdè Italy tó kó coronavirus sílẹ̀ nílèéwòsàn Ogun ebi ni Nàìjíríà ń bá fínra lọ́wọ́, ogun coronavirus kò gbọdọ̀ kún un-Oluwo O ti di eeyan mẹrin to ti lugbadi arun coronavirus bayii, nigba ti ipinlẹ Eko ko mọkandinlogun ninu rẹ, eeyan meji lo karun naa nipinlẹ Ogun, eeyan kọọkan larun naa nipinlẹ Oyo ati Ekiti.
Eyí mú kí ọ̀pọ̀ ènìyàn maa fi omí iyọ wẹ ti ọ̀pọ́ si di èrò ilé ìwòsàn fún àlòjù iyọ̀ nígbà ti àwọn ènìyàn mejí ku.
o, eyi wa ni ibamu pẹlu aba ti igbimọ ti Aarẹ Muhammadu Buhari gbe kalẹ lati
Ile igbimọ Aṣofin naa buwọlu abadofin to faaye gba ki wọn ge nnkan ọmọkunrin, lẹyin ti aṣofin Nuraddeen Alhassan gbe abadofin naa kalẹ ni Ọjọ kẹẹdogun, Oṣu Keje, ọdun 2020.
Oríṣun àwòrán, AFP Awọn to ṣagbatẹru iwọde ti ọjọ Satide ti rọ awọn eeyan lati maa darapọ mawọn ti wọn fẹ ṣe ifẹhonuhan lati tako iwa ẹlẹyamẹya.
Iroyin sọ pe ṣe ni Egbegbe a tan wọn pẹlu ko sọ fun wọn pe oun ni owo Naira ti oun fẹ parọ si ti ilẹ okeere tabi ti ile okeere si Naira ni yoo ba lọ wọn lọwọ gba.
Aṣojú Seyí Makinde lásan ní mo jẹ, òṣìṣẹ́ gbọdọ̀ bọ̀wọ̀ fún mi - Ọ̀dọ́mọdé Kọmísánà Nínú gbèsè Nàíjíríà, ₦121,000 ló kàn ẹnìkọ̀ọ̀kan, ṣó o ṣetán láti san tìẹ?
kí àwọn eniyan tí ó gbé orí òkè ńlá lè rí alaafia,kí nǹkan sì dára fún àwọn tí ń gbé orí òkè kéékèèké.
Dino Melaye Dino jẹ ọkan gboogi lara awọn oloṣelu to ni idan lọwọ ni Naijiria nitori ko ṣeni to le sọ iru aṣa ti o le ti ọwọ rẹ jade.
Ta ni lè gbà wá lọ́wọ́ àwọn oriṣa tí ó lágbára wọnyi?
Oúnjẹ  ṣe pàtàkì nínú iṣẹ́ mi, n ó máa wá a lákòókò, n ó máa ṣè é dáadáa pẹ̀lú, n o ṣe ìtọ́jú baálé mi tó bí ó ti yẹ bí ara rẹ̀ kò bá le, nítorí mo mọ̀ pé, ègún ni fún obìnrin náà, tí ara baálé rẹ̀ kò dá, tí ó mú aṣọ tí baálé rẹ̀ rà fún un, tí o ṣiré bá òde lọ; ègún ni fún obìnrin náà, tí ó ti torí pé ìjà dé tí o ń sọ̀rọ̀ tí òun àti ọkọ rẹ̀ ti fi ṣe ìpamọ́ sí ìta.
Loni ọjọ Aiku si ni gbogbo eeyan yoo mọ ẹni ti yoo jaye olubori lati gba ọgọta miliọnu naira laarin awọn oludije marun to sẹkun nile BB Naija.
Bio ti le je pe, opo lo n bu enu ate lu Messi pe, koi kopa daradara to fun orile-ede re bi o se maa n gba boolu fun iko keji ti n se Barcelona, sugbon ni bayii, Costa ro awon ololufe iko agbaboolu Argentina lati dupe pe won ni Messi laarin won, ti o si fikun-un oro re pe, ipa Messi ninu iko naa ko se ye sile rara.
Ẹfunsetan Aniwura, obìnrin tó ju ọkùnrin lọ Ọ̀rọ̀ǹpọ̀tọ̀niyùn, Aláàfin obìnrin àkọ́kọ́ rèé, tó ní nǹkan ọkùnrin Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Àánú ṣe é, ó wí pé, “Ọ̀kan ninu àwọn ọmọ Heberu nìyí.
Alaga tuntun fun Ajo Isokan Ile Afriika, A.
Lẹ́hìn tí ẹsẹ̀ yìí san tán kòkòrò jókòó sí inú ara lọ́hùn-un ó fi ibẹ̀ ṣe ilé, ní ìgbẹ̀hìn, oríṣiríṣi àìsàn bẹ̀rẹ̀ sí ṣe ọkùnrin yìí, àìsàn kan sì bẹ̀rẹ̀ sí fa òmíràn jáde ṣùgbọ́n kòkòrò ìjọ́sí ni ó bẹ̀rẹ̀ nǹkan wọ̀nyí.
Gbogbo àwọn olólùfẹ́ yín ti gbàgbé yín;wọn kò bìkítà nípa yín mọ́,nítorí mo ti nà yín bí ọ̀tá mi,mo sì fi ìyà jẹ yín bí ọ̀tá tí kò láàánú,nítorí àṣìṣe yín pọ̀,nítorí ẹ̀ṣẹ̀ yín pọ̀ rékọjá ààlà.
ni eyi to fihan pe owo nina yatọ si mimọ iṣẹ bọọlu gbigba de ibi to yẹ pẹlu ipinnu.
Ikọ ọmọogun orilẹede Naijiria ti bẹrẹ 'operation positive identification’ lati koju ikọ Boko Haram to ti ṣe ikọlu si ọpọlọpọ eniyan ni ẹkun ariwa orilẹede Naijiria.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù NLC Kwara-Iṣẹ́ tí èèyàn kò bá tí ṣé, kò yẹ kó gba owó rẹ̀ 2 Èbibi 2019 Oríṣun àwòrán, Facebook/NLC Ohun to kọju si ẹni kan,ẹyin lo kọ si ẹlomiran lọri ki ijọba yara san owo oṣu oṣiṣẹ.
Ṣugbọn ní ti Jesu, ó wà títí.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Yoruba World Congress: Banji Akintoye ní àwọn ọlọ́pàá fẹ́ sọ àwọn ọmọ ẹgbẹ́ òun sá àhámọ́ 1 Ògún 2020 Oríṣun àwòrán, others Ọjọgbọn Banji Akintoye to jẹ aṣiwaju igbimọ Yoruba lagbaye, Yoruba World Congress, ti salaye pe Naijiria ko fararọ fun ẹya Yoruba.
Nigba to de, o ya ara a rẹ sọtọ, lasiko to bẹrẹ si ni ri awọn apẹẹrẹ arun naa.
Ile-ejo Giza ohun tun so pe, ki onile naa ti o je elesin kriteni tun sanwo itanran, eyi ti o je ojidinnirinwo pounds owo orile-ede Egypt fun siso ile gbigbe re di ile-ijosin lai gba iwe ase.
A o tẹra mọ iṣẹ fun idagbasoke ara ilu.
Link O ni aimọwe ohun daadaa nile ìwé lo jẹ ki oun ronu ọna miran ti oun fi le wulo lawujọ Yoruba gẹgẹ bii ọmọ Oodua gidi to fẹ gbe aṣa ga ‘Ọ̀rẹ́ mi ní kí n fi ‘acid’ sí oúnjẹ ọmọ mi’ Àwọn àṣà àti ìse tó yọ obìnrin sílẹ̀ nílẹ̀ Yorùbá Lekan kingkong lọmọ Yorùbá tó ń fi òwe dárà lẹ́yìn odi Níbo làwọn òṣèré apanilẹ́rìn ín wọ̀nyí tó pilẹ̀ sínima àgbéléwò Yorùbá wà?
Bi eniyan ba wa lori yinyin ti o’n ba ere lo ni wara wara.
Nígbà tí aadọrin ọdún bá pé, OLUWA yóo ranti Tire.
Dokita Sule fikun pe  Awakọ mọto naa salaye pe, ọkan ninu awọn agbebọn naa sọrọ ni ede oyinbo, nigba tawọn yoku sọrọ ni ede Hausa ati Fulani, wọn ko si ti pe wa lati sọ iru eeyan ti wọn jẹ ati erongba wọn."
" Amọ o, eyi ni ohun ti awọn ọmọ Naijiria kan n sọ lori twitter nipa ija ọhun.
 Sotayo salaye pe oun wo bi igbẹjọ Maryam Sanda, ti wọn dajọ iku fun tori pe o pa ọkọ rẹ lọdun 2017, se ti lọ nile ẹjọ, ti oun si rinrin ajo lai kuro loju kan soso."
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Aisha Buhari: Ọ̀pọ̀ aráàlú ní Aisha ti pariwo ṣáájú pé Buhari kọ ló ń darí ìjọba 15 Ọ̀wàrà 2019 Oríṣun àwòrán, @aishambuhari Ọpọ ọmọ Naijiria lo ti n sọ ero ọkan wọn lori aawọ to n waye nile ijọba nilu Abuja laarin aya aarẹ, Aisha Buhari ati Mamman Daura.
"Oríṣun àwòrán, Who ""O ṣe pataki ka ṣe agbeyẹwo eleyi: Coronavirus yii tun le e di ara awọn ajakalẹ arun miran to wa nilẹ ni awujọ wa, ti ko si ni lọ mọ laelae."
“Ìrètí ẹni tí ó bá fẹ́ bá a jà yóo di òfo,nítorí ojora yóo mú un nígbà tí ó bá rí i.
Alásè Buhari kú, Buhari ń ṣọ̀fọ̀ Agbejọ́rò Dakolo:Mílíọ́nù mẹ́wàá náírà tí a béèrè kì í ṣe owó gbà má-bínú Ajọ EFCC ni o da awọn loju wi pe nipa ọna ẹburu ati magomago, pẹlu lilu owo ilu ni ponpo ni Madueke fi ko ọrọ naa jọ.
₦30,000 owó oṣù yòó bẹ̀rẹ̀ ní September - Alága ẹgbẹ́ òṣìṣẹ́ l‘Ekiti Láti January lọ, gbogbo ẹni tó bá ra ọjà lórí ayélujára yóò máa sanwó orí - FIRS Aṣojú Seyí Makinde lásan ní mo jẹ, òṣìṣẹ́ gbọdọ̀ bọ̀wọ̀ fún mi - Ọ̀dọ́mọdé Kọmísánà Nigba ti oun gbe osuba kare fun awọn asaaju lpinlẹ naa, ni pataki, awọn gomina ana ninu eyi ti o ka ijọba ana kun ti o pe ni'' ifẹsẹ mulẹ to muna doko''ninu eyi ti awọn to ku n gunle.
Ṣaaju ni tọkọ-taya naa ti gbiyanju lati pada si orilẹ-ede Naijiria lati bi awọn ọmọ naa, ṣuigbọn wọn ha si Dubai nitori isede ti ijọba Dubai kede lẹyin ti ajakalẹ arun Coronavirus burẹkẹ kaakiri agbaye.
kí ìgbéraga má gba ọkàn yín, kí ẹ sì gbàgbé OLUWA Ọlọrun yín, tí ó mu yín jáde láti ilẹ̀ Ijipti, níbi tí ẹ ti ń ṣe ẹrú.
Lọjọ ẹti ni okiki kan pe Kẹmi Adeọṣun kọwe fipo minisita feto iṣuna silẹ lori ẹsun ayederu iwe ẹri ti wọn fi kan an.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Daddy Freeze: 'Kátàkárà ni owó orí gbígbà lórí ọmọbìnrin jẹ́' 31 Ògún 2019 Oríṣun àwòrán, Instagram/daddyfreeze Sisọ omo soko ẹru ni gbigba owo ori ìdána nibi igbeyawo -Daddy Freeze Yoruba bọ, wọn ni dandan lowo ori, tulasi laṣọ ibora.
Nítorí igbe ìrora mi,mo rù kan eegun.
 Ọ ́ n lè fi iṣẹ ́ abẹ tọ ́ jú àrùn yìí .
Bí ó bá lè kú fún wa nígbà tí a sì jẹ́ ẹlẹ́ṣẹ̀, nisinsinyii tí Ọlọrun ti dá wa láre nítorí ẹ̀jẹ̀ rẹ̀, yóo fi ìfẹ́ rẹ̀ hàn ju ti àtẹ̀yìnwá lọ, a óo sì torí rẹ̀ gbà wá kúrò ninu ibinu tí ń bọ̀.
Kí ni pàtàkì nọ́mbà 615 láàrín àwọn èèyàn ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ̀ Ọpa epo rọọbi orilẹede Naijiria: Bakan naa ni ijọba n pese eto aabọ fun awọn ọpa epo lorilẹede Naijiria lati le e mu imugbooro ba eto epo rọọbi orilẹede Naijiria, eleyii ti Aarẹ Buhari sọ wi pe oun mu owo wọle fun orilẹede naa.
Ibrahim Magu lo ti kọkọ yọju siwaju igbimọ oluwadii kan ti ileesẹ aarẹ gbe kalẹ lọjọ Aje lati tanna wadi awọn ẹsun aidaa ti wọn fi kan-an.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Kò sí ọ̀nà ti èèyàn kò lè fi pèsè ìrànlọ́wọ́ fún ará ìlú ẹ Adan yanana bi oun ṣe n rọ awọn akẹkọọ ti oun n kọ ni awọn ile iwe giga lati doola ẹmi awọn eniyan nipa fifi dọla kan ṣe iranwọ oṣooṣu fun ipese ọkọ gbigbe alaisan ti Aamin.
Ojú ara yín yóo sì tì yín nígbà tí ẹ bá ranti gbogbo nǹkan burúkú tí ẹ ti ṣe.
Djokovic yoo tun gba ami-eye olukopa ti o dara julo lagbaye fun igba karun un bayii.
Ile Igbimọ Aṣofin Ipinlẹ Eko ti sọ fun Gomina
Eyi tumọ si pe ile ẹjọ gbọdọ pari igbẹjọ laarin oṣu mẹrin.
Nígbà tí Saulu dé Jerusalẹmu, ó fẹ́ darapọ̀ mọ́ àwọn ọmọ-ẹ̀yìn Jesu.
26 Kìí ṣe àwọn nìkan tí wọ́n gbàgbọ́ lẹ́hìn tí ó wá ní ààrin gbùngbùn àkókò, nínú ẹran ara, ṣùgbọ́n gbogbo àwọn wọ̃nnì tí wọ́n gbàgbọ́ láti ìbẹ̀rẹ̀, àní gbogbo ọ̀pọ̀lọpọ̀ àwọn tí wọ́n wà kí òun tó wá, tí wọ́n gbàgbọ́ nínú àwọn ọ̀rọ̀ àwọn wòlíì mímọ́, tí wọ́n sọ̀rọ̀ bí wọ́n ti ní ìmísí nípasẹ̀ ẹ̀bùn Ẹ̀mí Mímọ́, ẹnití ó jẹ́rìí tòótọ́ nípa rẹ̀ nínú ohun gbogbo, nilati ní ìyè ayérayé,
Ní ọjọ́ kan, lẹ́yìn tí ọmọ náà dàgbà, ó lọ bá baba rẹ̀ ninu oko níbi tí wọ́n ti ń kórè.
Election Observers (Onwoye lasiko idibo) : Awọn wọn yii ni ajọ tabi ẹgbẹ to n se onwoye lasiko idibo, wọn maa n lọ si agbegbe ti idibo ti n waye lati mojuto eto idibo lati ibẹrẹ titi de opin.
Isẹ ọpọlọ rẹ maa n da wa lọrun gan, o maa n ṣe ọkan wa pẹlẹ.
Ó bá sọ pé, “Ọdọmọkunrin, mo sọ fún ọ, dìde.
Gomina Wike wa rọ awọn obi lati ri wi pe ọmọ wọn ko bọ sita lati tapa si aṣẹ oun.
A ba awọn olokoowo sọrọ lori awọn ipenija to niṣẹ pẹluu owo ori sisan.
#BabanrigaMobileBanking Ọrọ yi ti mu iriwisi ọtọọtọ wa ti o si ti bi hastag kan to n ja rain rain loju opo Twitter-#BabanrigaMobileBanking .
Onimọ owo ori nnkan ini kan (estate valuer), Ọgbẹni Oladipupo Onabanjo, ṣe kilọkilọ pe ko yẹ ki ofin naa ti wọn fọwọ si ninu oṣu keji bẹrẹ ojuṣe ni oṣu kinni.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Awọn janduku yii lọpọ igba maa n da eto ipolongo ibo tabi iwọde oṣelu ẹgbẹ tabi ẹni to jẹ alatako fun ẹni to bẹ wọn niṣẹ ru.
Ìbàlẹ̀ ọkàn a máa mú kí ara dá ṣáṣá,ṣugbọn ìlara a máa dá egbò sinu eegun.
Ibom, ogbeni Monday Uko, so pe ijoba ti fi aaye sile fun aare lati lo papa isere
Idije to pa awọn mejeeji pọ laipẹ yii ni nigba ti Naijiria koju Algeria ninu idije kikopa ninu ife ẹyẹ agbaye Russia 2018 to kọja.
Tẹ́lẹ̀ rí, ó ṣiṣẹ́ ní Belgrade Atelje 212.
Mohammed Salah gba àmì ẹ̀yẹ̀ CAF fún ìgbà kejì Wàhálà bẹ́ sílẹ̀ níbi ìpolongo ìbò APC l'Eko Lara awọn ti ọta ibọn ba ni oniroyin kan lati ileeṣẹ iwe iroyin the Nation, Emmanuel Oladesu, Temitọpẹ Ogunbanke lati iwe iroyin NewsTelegraph pẹlu ayaworan ileeṣẹ mohunmaworan Ibilẹ Television, Abiọdun Yusuf atawọn eeyan miran.
Obinrin to n ṣe nnkan oṣu ko le jọsin fun Ọlọrun: Igbagbọ kẹta ti ko fi idi mulẹ nipa nnkan oṣu obinrin ni pe obinrin ko ba n ṣe nnkan oṣu ko le jọsin niwaju Oluwa, ko jẹ itẹwọgba.
"Góòlù pọ̀ ní ìlú Madaka ṣùgbọ́n wọn kò ní ọ̀nà fún ọgọ́rùn ún ọdún ""$2,600 àǹtí mi ni mo jí láti lọ sókè òkun àmọ́ àbámọ̀ ló gbẹ̀yìn ọ̀rọ̀ mi"" Òbítíbitì ẹ̀gbin ti sọ ìlú Ibadan di ààtàn - Aráàlú figbe bọnu A ti gba aṣẹ ilé ẹjọ míì to tako àṣẹ́ ilé ẹjọ to wọ́gile olùdije APC ni Bayelsa Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, World Diabetes Day: Ọdún kọkandinlogun ti mo ti wà lẹ́nu itọ ṣúgà nìyí Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?"
Ọlọpaa gbé àpótí adènà ẹ̀rọ ìbánisọ̀rọ̀ sílé Dino Amọṣa, DJ Sosogee ni oun ko lee sọ boya 'nitori iyawo rẹ fi ile silẹ tabi nitori awọn ẹbi rẹ toju bọ ọrọ wọn' lo ṣokunfa bi o ṣe gbẹmi arar rẹ.
Bí Jesu ti jókòó ní ilé Lefi, ọpọlọpọ àwọn agbowó-odè ati àwọn ẹlẹ́ṣẹ̀ ń bá Jesu ati àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ jẹun, nítorí wọ́n pọ̀ tí wọn ń tẹ̀lé e.
Bayelsa Attack: Ọ̀gá ọlápàá fọnmú pé kí wọn ṣàwárí àwọn ọ̀daràn tó pa ọlọ́pàá
Awọn akopa ko figba kan bọkan ninu idahun wọn si BBC Yoruba nitori wọn nifẹ lati mọ ẹni to ni alakalẹ gidi fun awọn araalu.
Àkọlé àwòrán, Awọn akọni Burundi naa gba pe wọn to gabngba sun lọyẹ Kọju si mi ki n gbaa sile ni Guinea fi na Burundi lọdun 1994.
Nítorí a rí ẹ̀rí níbìkan pé,“Ìwọ yóo jẹ́ alufaa títí lae,gẹ́gẹ́ bíi ti Mẹlikisẹdẹki.
Nítorí náà, mo farada ohun gbogbo nítorí àwọn àyànfẹ́, kí àwọn náà lè rí ìgbàlà tí ó wà ninu Kristi Jesu pẹlu ògo tí ó wà títí lae.
”Ajo eleto idibo ati ile-ise agbofinro ti se ikilo fun awon oludibo lati maa se ta tabi ra ibo won .
Ẹ̀rù nǹkan kaan kò tilẹ̀ wáá bà mi lákòókò náà mọ́ nítorí ẹni tí ó ti kúrò láàrin àwọn ọmọ ènìyàn tí ó fi orí lé ọ̀nà Igbó Olódùmarè tí ó dé ọ̀hún tán tí ó tún ń wá ilé Ikú kiri, eléyìínì ti fi ṣẹ́kẹ́ṣẹekẹ̀ bọ ara rẹ̀ lẹ́sẹ̀, ó so ẹ̀wọ̀n mọ́ ara rẹ̀ ní ìbàdí, ó fún omi ata sí ojú, ó sì ń wá ìjàǹbá káàkiri òde – bẹ́ẹ̀ ni Baba-onírùngbọ̀n ń lọ tí èmi tí kò ní ‘rùngbọ̀n náà ń tẹ̀lé e.
Baba ni lootọ ni Yoruba n ṣe aajo owo, awure, oṣo o ni bi wọn ṣe n ṣe e o si ni awọn ti wọn n ṣee fun.
O Oke, SAN; Dr Paul Ananaba, SAN; Emeka Etiaba, SAN; Emeka Okpoko, SAN; and Kehinde Ogunwuminju, SAN.
“Ǹjẹ́ o lè pàṣẹ fún ìkùukùu pé,kí ó rọ òjò lé ọ lórí?
" Àrùn yí gba orúkọ rẹ láti látínì ọ ̀ rọ ̀ "" lepra "" , tí ó túnmọ ̀ sí "" scaly "" , nígbà tí ọ ̀ rọ ̀ "" Àrùn hansen "" wá láti orúkọ oníṣègùn gerhard armauer hansen ."
Awọn adari ẹgbẹ Afẹnifẹre to fi ero wọn han ni Oloye Ayọ Adebanjọ ati Yinka Odumakin, to jẹ akọwe ẹgbẹ naa.
Èmi sọ fún un pé kò tọ́pẹ́ rárá.
Oun naa ni aburo aarẹ ile igbimọ aṣofin agba to kogba wọle laipẹ yii, iyẹn Bukọla Saraki.
 “Awo omo egbe ECOWAS ni opolopo ohun nnkan igbafe.
" Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Òǹtàjà aṣọ ni mí tẹ́lẹ̀, ọ̀dá owó ló sọ mi di alábárù Nígbà tó ń sọ̀rọ̀ lórí akojọpọ esi tí ileesẹ tó ń gbógun ti àrùn nilẹ yìí, Momoodu ni Naijiria kò ní àkọsílẹ̀ tó dára lórí iye èèyàn tó ní Coronavirus ni Naijiria, bẹ́ẹ̀ sì ni ọpọ àwọn èèyàn tó wà nibẹ lo ń fẹ́ jẹun láti ara àìsàn náà.
zamenhof ni apejo kariaye akoko esperanto , o si je didasile pelu oruko lingva komitato , eyun igbimo ede .
Idi ree ti oun fi ra oogun to n pa eku lati gbe majele jẹ, ki oun kuku ku danu.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù PasitoTunde Bakare: Aago Nàìjíríà ti kún àkúnwọ́sílẹ̀ 15 Agẹmo 2019 Oríṣun àwòrán, @T_Bakare Gbajugbaja Agbẹjọro ati Pasito Ijọ Latter Rain Assembly, Tunde Bakare ni awọn adari orilẹ-ede Naijiria n se oselu pẹlu ẹmi awọn araalu ni Naijiria.
Aisha Raheem to jẹ ọmọ orilẹ-ede Naijiria bẹrẹ ile iṣẹ rẹ Farmz2U lati lọ imọ ẹrọ fun ipese ounjẹ to n ṣe ara loore Ọdun mẹsan an ni Raheem wa ti o ti n kọle fun awọn ẹran ọsin O ni imọ ninu iṣakoso ati idanilẹkọọ fun isẹ aladani fun awọn eniyan Ọdun 2017 ni Raheem bẹrẹ iṣẹ ara rẹ to n lo imọ ẹrọ lati ran awọn oṣiṣẹ ọgbin lati pese ounjẹ fun awọn eniyan.
10 Sẹ́rẹ́ 2021 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Idaji kutu hai owurọ ọjọ Isẹgun ni irawọ osere kan, Jumoke Odetola lo tufọ oloogbe naa, ti ọpọ akẹẹgbẹ rẹ lagbo tiata si n tara poro lori iku aitọjọ naa.
Wo ọ̀nà tí àwọn ‘ẹ̀lẹ̀ Daddy’ gbà dé ààfin Ọyọ Mo le búra pé kò sí ìbáṣepọ̀ láárin Olorì Badrat àti Wasiu Ayinde - Olori Folashade Kí ló pa Bobrisky àti Olorì Aláàfin Oyo pọ̀?
Farao bá bi í léèrè pé, “Kí lo fẹ́ tí o kò rí lọ́dọ̀ mi, tí o fi fẹ́ máa lọ sí ìlú rẹ?
Ijọba apapọ lorilẹ-ede Naijiria ti pasẹ ki wọn dawọ duro lori gbogbo iṣẹ iwakusa lagbegbe ilu Zamfara lẹsẹkẹsẹ.
Wọn si maa n paṣẹ fun awọn cardinal naa lati kọ orukọ ẹni naa ni ọna ti ẹnikẹni ko le mọ wi pe awọn ni wọn kọ ọ, ki wọn o si ka iwe pelebe naa lẹẹmeji.
Ko ti i fojuhan ibi ti ọrọ ọja eporọbi l'agbaye yoo ja ọrọ aje Naijriia si, paapa bi arun coronavirus ṣe n tan kiri.
Ìgbẹ́tì ni ìlú tí a gbà tì, tí a kò rí gbà lásìkò ogun, èyítí í se ìlú Àgbàtì àmọ́ tó wá di Ìgbẹ́tì báyìí.
Kí lo kàn ìlànà iyansipo àti ìwé ẹrí NYSC lorílè-èdè Nàìjíríà?
Èrò tèmi ni pé, bíótilẹ̀jẹ́pé ilé-iṣẹ́ KFC fi dá wa lójú pé àwọn ò tíì pààrọ̀ àwọn èròjà tí wọ́n ń fi s’óúnjẹ láti ọdún 1930, kiní ọ̀hún ò dùn lẹ́nu tèmi mọ́n o.
Bakan naa ni wọn wa nile iwosan ti wọn ko awọn eeyan to farapa lọ.
Amọ dipo ki Lisabi mu awọn ọrẹ rẹ lọ si oko rẹ fun aaro, ohun to sọ fun wọn ni pe ọna ti awọn yoo gba gba ilu Ẹgba silẹ lo kan oun, aaro ti wọn yoo si ba oun gba ni kikọju ogun si awọn ilari Ọlọyọ.
Ile iṣẹ Ọlọpaa ipinlẹ Enugu bu ẹnu atẹ lu ọpọlọpọ ẹsun to n tan kalẹ ati eyi to sọ pe iṣẹ ọwọ awọn to n ji ẹranko pa lọna aitọ lo fa iku awọn ẹranko abiyẹ naa.
Idije naa ṣi silẹ fun gbogbo awọn akẹkọọ ile ẹkọ giga ni Afirika.
marun-un (17,665) esi ibo, nigba ti akẹgbẹ rẹ lati ẹgbẹ oṣelu PDP,
Ikilọ yi waye lẹyin iṣẹlẹ ijamba ọkọ oju omi to danu ni Egbin, lagbegbe Ikorodu lalẹ ọjọ Abamẹta.
Ìdí nìyí ti a fi ń pe ilẹ̀ náà ní, “Ilẹ̀ ẹ̀jẹ̀” títí di òní olónìí.
Mú kí ọkàn mi fà sí òfin rẹ,kí ó má fà sí ọrọ̀ ayé.
Ọkùnrin tí ìwọ ń wò yìí ti fi ìyà jẹ àwọn ènìyàn tí Ọlọ́run fẹ́ràn, tó bẹ́ẹ̀ tí ìfẹ́ náà kò ṣeé fi ẹnu sọ!
CBN gbé òfin tuntun jáde fún àwọn Báǹkì Níbo ni Kemi Adeosun wà?
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'A máa ń bẹ́ orí ẹni tó bá gbé imọlẹ̀ ọdún ìjẹṣu tó bá ṣubú ni' Ogagun Azinta to jẹ olori ikọ ọmọ ogun ni ẹkun yii ni wọn ti paṣẹ fun pe ko rii pe gbogbo ọmọ ogun sá ipa wọn fun alaafia awọn eniyan Ekiti ati Ondo ti wọn n gbe ninu ipaya bayii.
Bakannaa lo tun pe fun eto ilanilọyẹ fun araalu lori ipenija ati ewu to wa lori idajọ ọwọ.
 Won gba pe won yoo jo jiroro lori oro Syria, Iraq atawon asatipo ekun naa.
Nàìjíríà ló wà nípò kẹfà nínú ewu ikú àìtọ́jọ́ l'ágbàáyé nítorí nkan mímú tó ní ṣúgà Ìdíje bọ́ọ̀lù fa ìtàjẹ̀ sílẹ̀ ní Poly Ibadan Dangote: Mo ti gbà $10m ri ní bánkì kí n lè mọ bí o tí ṣé rí lójú Oyè Mọ́gàjí àti Báálẹ̀ ti di owó rèé, ọjà rèé ní Ibadan - Lekan Balogun Idiyele owo ti wọn n ta ìwo Túùkú fawọn orilẹ ede Asia ni \\awọn kan gba pé o ṣokunfa ki ọpọ maa fi ẹmi wọn sinu ewu lati wa ìwo èranko ti wọn maa tà.
Pilatu tún bá wọn sọ̀rọ̀, ó fẹ́ dá Jesu sílẹ̀.
Èèyàn 125 ní àrùn Coronavirus tún ṣẹ̀ṣẹ̀ ràn ní Nàìjíríà ní Ọjọ́bọ̀ Ajọ to n gbogun ti ajakalẹ aarun lorilẹ-ede Naijiria, NCDC ti kede pe eeyan 125 miran ti kun iye awọn to ti ni aarun COVID-19 ni Naijiria.
Ní ọjọ́ náà,OLUWA Ọlọrun àwọn ọmọ ogun fi ìpè sóde pé,kí ẹ máa sọkún, kí ẹ máa ṣọ̀fọ̀,kí ẹ fá orí yín, kí ẹ sì fi aṣọ ọ̀fọ̀ bora.
Ṣugbọn Peteru sẹ́, ó ní, “N kò tilẹ̀ mọ ọkunrin yìí!
Nítorí ìgbà gbogbo ni ẹ ní àwọn talaka láàrin yín, nígbàkúùgbà tí ẹ bá fẹ́, ẹ lè ṣe nǹkan fún wọn; ṣugbọn kì í ṣe ìgbà gbogbo ni èmi yóo máa wà láàrin yín.
O ni kẹkẹ mẹ́wàá to je ti iko omo oogun Boko Haram ni won ri gba.
Àbí ọ̀rọ̀ mi kì í ṣe àwọn tí wọ́n bá ń rin ọ̀nà ẹ̀tọ́ ní rere?
'Àwọn Dókítà fẹ́ kẹ́yin s'awọ̀n alárùn lassa' 'Naijiria n koju itankalẹ arun iba' Iba ọrẹrẹ pa eeyan kan l'Ọsun O jọ bi ẹni pe itankalẹ aarun iba tun ti fẹ ma gbori lyin bi ọdun mẹwa ti awọn oṣiṣẹ ilera bori aarun yi.
Ṣé lóòtọ́ ni òjòjò dá Abiola Ajimobi wólẹ̀?
Ewe, ni apere nipinle Kano, ketekete ti oye re je ẹ̀gbẹ̀rún màrúndínlógún ati ẹ̀gbẹ̀rún méjìdínlógún(15,000 naira and 18,000), ni won ta ni ẹ̀gbẹ̀rún lona àádọ́rin,  ẹ̀gbẹ̀rún lona márùndínlọ́gọ́rin bayii.
Àkọlé àwòrán, Iku babayeye Alaafin of Oyo Kábíyèsí ni ede Yorùbá dára púpọ̀, ''Pọ́ńbélé Yorùbá ni mí, n ò sì ní tijú rẹ níbikíbi''.
O ni eyi lo maa fun wọn ni agbara lati yan eni ti wọn fẹ sipo to ba wu wọn.
Makinde tun salaye pe gbogbo isẹ akanse ti ijọ to kogba wọle nipinlẹ Ọyọ se ni asepati ni oun yoo pari, to si tun kede pe oun ti gbe olu ileesẹ to n ri si idagbasoke eto ọgbin OYSADEP pada si ilu Saki ti wọn ti gbe kuro.
O kọ, o si tun ko awọn ẹbun ti amugbalẹgbẹ naa fẹ ẹ fun, ko le gba lati fẹ aarẹ.
Oríṣun àwòrán, Reuters Àkọlé àwòrán, Awon obi kan tii nwa omo won ninu awọn ibi ti won koruko si Dapchi to wa ni iha ariwa ilu Chibok fi oju wina ikọlu Boko Haram ni ọjọ aje ọsẹ to kọja ti o mu ki awọn akẹkọ ati awọn olukọni ileewe girama naa sa lọ farasinko sinu igbo lagbegbe naa.
 O seni laanu pe awon odo ti so agbgeb naa di eyi ti ko ni eto aabo to peye fun awon ile ise nlanla.
“Òṣùnwọ̀n eefa ati òṣùnwọ̀n bati náà gbọdọ̀ jẹ́ ìwọ̀n kan náà, eefa ati bati yín gbọdọ̀ jẹ́ ìdámẹ́wàá òṣùnwọ̀n homeri kan.
si n gbe lawon ipago awon alainile lori ni ekun naa.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Àrà kengé!
Olukuluku ń ran ẹnìkejì rẹ̀ lọ́wọ́,ó ń sọ fún arakunrin rẹ̀ pé, ‘Ṣara gírí.
Owó kékeré kọ́ ni àwọn èèyàn wa ń ná dà sí ìlú yìí o.
Ife re isakoso ijoba rere, ifara jin, akitiyan re lati ro awon odo lagbara mu ki o je awokose laarin awon akegbe re kaakiri agbaye.
ati awon iwa odaran gbogbo” .
Nígbà náà ni Jesu bẹ̀rẹ̀ sí bá àwọn ìlú wọ̀n-ọn-nì wí níbi tí ó ti ṣe àwọn iṣẹ́ ìyanu pupọ jùlọ, nítorí wọn kò ronupiwada.
Abẹwo yii ti bi awọn ifẹhonuhan lawọn ẹkun bii London, Manchester, Belfast, Birmingham.
Botilẹ jẹ pe idibo ko tii waye ni Edo ati Ondo, akowe agba orile-ede Amẹrika Mike Pompeo fofin fisa Amẹrika de awọn ẹniyan kan nitori ipa ti wọn ko bi eto idibo awọn ipinlẹ mejeeji yii se n bọ lọna.
Mose bá búra ní ọjọ́ náà pé, ‘Dájúdájú, gbogbo ibi tí ẹsẹ̀ rẹ ti tẹ̀ ni yóo jẹ́ ìpín fún ọ ati fún àwọn ọmọ rẹ títí lae, nítorí pé o ti fi tọkàntọkàn tẹ̀lé OLUWA Ọlọrun mi.
Pẹlu iru nkan bayi, anfaani wa bẹẹ si ni ipenija wa ṣugbọn gbogbo rẹ ku si ọwọ awọn to n ṣe ijọba.
Ọjọ́ kọkànlélógún, oṣù Kárùn, ni àwọn òṣìṣẹ́ ètò ìlera bẹ̀rẹ̀ sí ní fún àwọn ará ìlú ní abẹ́rẹ́ àjẹsára, láti dá ìtànkálẹ̀ àìsàn náà dúró.
Exxon Mobil ni oun ti ti ibudo fife afefe gaasi re pa bayii lataari wiwo ti apa kan ile ise naa ati ile gbigbe awon osisse to baje se ri lasiko yii.
Bí ẹran mẹ́wàá bá kọjá lábẹ́ ọ̀pá darandaran, ikẹwaa gbọdọ̀ jẹ́ mímọ́ fún OLUWA.
”Ó ní òun kò mọ̀wé kà.
Nígbà tí ẹ bá wọ inú ilé kan lọ, ẹ kí wọn pé, ‘Alaafia fún ilé yìí.
 orúkọ tí wọ ́ n ń pé ilé-iṣẹ ́ náà , tí ó kó àwọn òṣèré mọ ́ àwọn tí ń ṣe fíìmù jọ ni wọ ́ n ń pè ní nollywood .
Ooni ile-ife alayeluwa Ooni Adeyeye Enitan Babatunde Ogunwusi Ojaja II, ti safihan omidan Shilekunola Moronke Oluwaseyi Naomi gege bi olori tuntun laafin re.
Eliṣa bá sọ fún Gehasi pé, “Ṣe gírí, kí o mú ọ̀pá mi lọ́wọ́, kí o sì máa lọ.
155 Trn) fọdun 2021 kalẹ, niwaju ile aṣofin ipinlẹ Eko.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ibadan Murder: Oyún oṣù méje ló ń bẹ nínú Azeezat, kí wọ́n tó f'òkúta fọ́ ọ lórí Ọgbẹni Nkurunziza mori bọ lọwọ igbiyanju awọn kan lati pa a ninu oṣu karun eyi ti ologun kan fẹ fi gba ijọba lọwọ rẹ.
Alaga igbimọ tẹẹkoto lori ọrọ abẹle nile asofin agba orilẹede Naijiria, Sẹnatọ Andy Uba tẹnumọ bi o se se pataki fun awọn lajọlajọ ijọba lati maa jihin abajade iroyin gbogbo nipa ileesẹ ati ajọ wọn fun ayẹwo ati igbesẹ to tọ.
Wolves bu Arsenal jẹ bí ajá Fun apẹẹrẹ, a o maa ṣalaye ranpẹ lori wọn labẹ akori ọrọ kọọkan.
Lẹ́yìn náà, ó ní, “Ẹni ìyìn ni OLUWA Ọlọrun Israẹli, tí ó mú ohun gbogbo tí ó wí fún Dafidi, baba mi, ṣẹ fúnrarẹ̀, nítorí ó wí pé, 
Ṣùgbọ́n bí a bá ti mú ti irun orí mi àti ’rùngbọ̀n mi yìí kúrò nígbà tí mo ti gbé inú igbó náà pẹ́ ni inú mi kò ti bàjẹ́ mọ́: nítorí mo ti mọ ọgbọ́n àwọn àgbàlagbà wọn-ọnnì tí ó wí pé bí ó wù tí ipò ọmọ ènìyàn re ẹ̀hìn tó lórí ilẹ̀ ayé, ó yẹ kí olúwaarẹ̀ lo àǹfààní ipò náà bi ó ti yẹ, aṣiwèrè ni ẹni tí ó wí pé ti òun tán nínú ayé, bí ẹ̀mí bá ń bẹ ìrètí ń bẹ, èrò tèmi lákòókò náà ni èyí wí pé, bí ótilẹ̀ jẹ pé mo wà ní èmi nìkan ṣoṣo síbẹ̀ ẹ̀mí mi ń bẹ, ọgbọ́n orí mi yàtọ̀ sí ti ẹranko, bẹ́ẹ̀ ni Olódùmarè tí Ó dá ẹnu fún mi kò ní ṣàì mọ ọ̀nà tí òun Ó gbà ti Òun ó fi jẹ́ kí n máa rí nǹkan fi sí i.
6 5,956 Saint Martin 27 72.
Idaamu Boko Haram: Igbẹjọ awọn afunrasi bẹrẹ ni gbangba loni
Alufaa yóo fi òróró tí ó kù ní ọwọ́ rẹ̀ ra orí ẹni tí wọ́n fẹ́ sọ di mímọ́.
Ó dùbúlẹ̀ lórí ibùsùn rẹ̀, ó kọjú sí ògiri, kò sì jẹun.
Ọọni, Aláàfin, Ojisẹ Ọlọ́run àti oniṣẹ ìwádìí fi Ògún gbari pé òògùn ìbílẹ̀ le wo Covid-19 Aláàfin gbé àṣẹ kalẹ̀ láti dènà àtúnṣẹ̀ ìṣẹ̀lẹ̀ 'Soka'nílùú Ọ̀yọ̀ 'Ìnira ńlá ni coronavirus mú bá èmi àtàwọn ọmọ mi gẹ́gẹ́bí opó tó fọ́jú' Mo kábàámọ̀ pé n kò kàwé, kí n tó bẹ̀rẹ̀ iṣẹ́ tíátà - Sanyeri Ìdí táwọn apòògùn Nàìjíríà fi tako oògùn Coronavirus láti Madagascar O ni ohun ti wọn fi n pe ni olode ni pe aarun naa maa n gba ode lọwọ olode ni, ko ni jẹ ki oloko lọ soko, ko si ni jẹ ki olodo lọ sodo mọ.
Mose kó àwọn ọ̀pá náà jáde kúrò níwájú OLUWA, ó kó wọn wá siwaju àwọn ọmọ Israẹli.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Online VAT: Sísan owó orí ọjà lórí ayélujára yóò mú kí ọrọ̀ ajé rú gọ́gọ́ si 27 Ògún 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Ajọ to n pawo wọle labẹle labẹ ijọba apapọ (FIRS) ti kede pe, oun yoo bẹrẹ si ni gba owo ori VAT, lori awọn ọja ti awọn ọmọ Naijiria ba ra lati ori ayelujara.
Ọpọ to ri nkan mu ṣe ọrọ lawujọ ni kii ranti awa opo.
Ọkan lara wọn sọ fun mi wipe, awọn ko tilẹ ri ibudo ọkọ ọlọpaa (checkpoint).
Wọ́n fẹ̀sùn kàn pé irú àwọn gómìnà yìí ń ṣiṣẹ́ láti da àdéhùn ẹgbẹ́ NLC àti ìjọba àpapọ̀ rú ni lórí 30,000 owó oṣù òṣìṣẹ́ tó kéré jù.
 Sharan tun n ba ajo ICPC, EFCC
Lily Loveth@Love 96047280 ke gbajare pe awọn araalu ati awọn alaisẹ ni awọn eeyan to n fẹhonu han naa n dojukọ bayii, papaa bi wọn se wa kọlu ibudo itaja ti oun ti n sisẹ.
Lásìkò to ń kopa lórí eto kan ni ìkànnì BBC Yoruba, to ń jẹ 'Sọ tiẹ̀', Akorede ni oun ti gbé eto kan kalẹ lórí YouTube láti dá àwọn èèyàn laraya, kọ wọn ní ẹ̀kọ́ àti gba wọn nímọ̀ràn, èyí tí to pé àkòrí rẹ ni 'Ààbọ̀ ọ̀rọ̀'.
Ògo OLUWA yóo bò wọ́n bí àtíbàbà ati ìbòrí.
Awọn nkan to ma n fa ati ajẹ fi ma n yọ eeyan lẹnu Ni ibẹrẹ pẹpẹ, ọmọ eniyan lo dalẹ, eyi to mu ki awọn ajẹ binu.
Inu wa dun lati gba Victoria gẹgẹ bi ọkan lara wa lati gbe ifaraji rẹ wọ ile iṣẹ BBC gẹgẹ bi Jamie Angus to jẹ adari BBC World Group ṣe sọ.
Oríṣun àwòrán, @LASEMA Ọkọ agbepo naa ni wọn ni o jẹ toni iwọn ogun ẹsẹ bata.
Eyi jẹ nigba ti ẹgbẹ Shiite musulumi gan an ti wọn pe ara wọn ni Qarmatians yabo ilu Mecca nitori wọn gbagbọ pe awọn keferi lo n ṣiṣẹ Hajj.
Awọn nkan Mẹjọ to n fa ijamba ina ninu ile Titan abẹla lori ike tabi pako le fa ijamba ina ninu ile Ti agbara ina ọba ba pọ ju, ti a ko si pa ina ọba to wọ inu ile Titan ina ọba silẹ ti a ba n jade kuro ninu ile Gbigbe epo bẹntiroolu sinu ile Dida epo bẹntiroolu sinu ẹrọ amunawa lasiko ti o ba si n sisẹ lọwọ Gbigbe agba afẹfẹ gaasi si inu ile tabi ni abẹ tabili ninu yara ti wọn ti n se ounjẹ Sisun igbo ati oko ni ayika ile le fa ijamba Mimu siga ninu ile tabi lasiko ti oorun ba n kun eniyan.
sylvia plath ( october 27 , 1932 - february 11 , 1963 ) a bí plath ní ọdún 1933 .
Ni ida kinni, o ni igesẹ ti ajọ yẹn gbe dara fun ẹni ti ko ba fẹran iwa jẹgudujẹra ṣugbọn ko si bi igbesẹ naa ṣe fẹ dara to, ti ko ba ti ba ofin mu, ko dara naa niyẹn."
Jehonatani ni baálé ní ìdílé Ṣemaaya,Matenai ni baálé ní ìdílé Joiaribu,
(Ní àkókò yìí Joramu ati àwọn ọmọ ogun Israẹli ń ṣọ́ Hasaeli ọba Siria ní Ramoti Gileadi; 
Eyi lo mu wa jade lọ beere irufẹ ọmọ ti Yoruba n pe ni olugbodi.
Èdùmàrè a sọ ìpàdé wa ju ọ̀la lọ.
Idehen ni o le ni miliọnulọna marundinlọgọjọ awọn ọmọ Naijiria to ti bẹrẹ iforukọsilẹ wọn, amọ ti idamẹta awọn nọmba wọnyii jẹ ẹbu nitori wọn ko pari iforukosilẹ naa tabi awọn ọrọ akọsilẹ wọn ko barajọ, eleyii to jẹ ko lufin ajọ NCC.
Sọ àsọtẹ́lẹ̀ orílẹ̀èdè tí yóò borí ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ t'òní Ò ti pé ọdún 27 tí Shah Rukh Khan ti ń se fíìmù India US-North Korea: Trump ati Kim John-un bẹ̀rẹ̀ ìpàdé Ẹ má ba ẹnikẹ́ni jà nítorí ọ̀rọ̀ ìfípábánilòpọ̀ mi -Fatoyinbo Awọn agbabọọlu Madagascar ti ni ki Naijiria ma foju rena awọn nitori pe awọn ko wa ta guguru ninu idije AFCON to n lọ lọwọ ni Egypt.
Lẹyin naa ni adajọ kede wi pe olujẹjọ, Saheed arogundade jẹbi ẹsun gbigbimọ ipaniyan ati ipaniyan.
Àwà gómìnà PDP ṣetán láti san #30,000 owó oṣù fáwọn òṣìṣẹ́- Dickson Ilé ẹjọ́ ní kí NBC yí àṣẹ padà lórí DAAR Communications Ọjọ́ tí inú mi bàjẹ́ jùlọ gẹ́gẹ́ bíi ààrẹ ilé aṣòfin àgbà-Saraki Lẹ́yìn-ọ̀-rẹyìn, bàbá ọgọ́rùn-ún ọdún gba ìdáǹdè l‘ẹ́wọ̀n Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Ẹ̀yin ará, à ń bẹ̀ yín pé kí ẹ máa bu ọlá fún àwọn tí ń ṣe làálàá láàrin yín, tí wọn ń darí yín nípa ti Oluwa, tí wọn ń gbà yín níyànjú.
Ṣùgbọ́n dípò kí òun bínú ó tún fún mi lésì, ‘Mo ṣe bí ìwọ ń fi ọwọ́ tẹ ìbàdí nígbà náà ni?
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Barcelona Vs Liverpool: Barca sọ ara rẹ̀ di ìbákà, orin góòlù.
gbogun ti ipenija to n koju eto aabo ni ekun naa.
Nibi ijoko ile naa to waye ni owurọ Ọjọru ni awọn aṣofin naa ti fẹnuko lati wadi ọrọ ọhun nigba ti Sẹnetọ Uba Sani mu wa si etigbọ ile naa lati tete wa nnkan ṣe sii nitori 'iṣẹlẹ naa ti ta ẹrẹ ba aṣọ ala ọpọ awọn aṣofin agba.
Facebook yóò bẹ̀rẹ̀ ìnáwó orí ayélujára Theresa May fẹ́ kọ̀wé fipò rẹ̀ sílẹ̀ ní UK Ọwọ́ ọlọ́pàá tẹ ọmọ Britain tó ń ta kẹ́míkà gẹ́gẹ́ bi omi ìyanu Ipinlẹ Ọ́yọ̀: Ile-iwe wa ni titi pa nitori iyansẹ̀lodi Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Niyi Akano,Alaga NUT Oyo lori iyanselodi Ati pe iyanṣẹlodi naa yoo wa titi ti aṣẹ mi i yoo fi jade.
Àwọn ọ̀tá mi ń parọ́ mọ́ mi,àwọn nǹkan tí n kò jíni wọ́n ní kí n fi dandan dá pada.
O ni pataki dida duro lẹnu iṣẹ ara oun lo jẹ ki oun fiṣẹ silẹ lati gbajumọ iṣẹ ẹran tita.
co/dZhsQJmyj8 #URURUS #WorldCup #URU #RUS pic.
 “bio tile je pe, Naijiria je okan gbogi lara orile-ede ti o bowolu abadofin ajo AU, nipa pipese ida marundinlogun ninu ida ogorun lodoodun sinu eto ilera, sugbon o seni laanu pe orile-ede yii koi ti gbenu le ida mefa ninu ida ogorun 6%yii lati odun 2001 ti won se ifilole ilana naa.
Ó yẹ kí a sẹ àkíyèsí obìnrin yìí dáadáa nítorí pé òun nì a wá fi hàn gẹ́gẹ́ bí ẹni tí ó jí owó Àkàngbé Orímóògùnjẹ́ jí ní iwájú.
Ilé ẹjọ́ tó ga jù ní kí gómìnà tẹ́lẹ̀, Jolly Nyame lọ fẹ̀wọ̀n ọdún 12 ṣara rindin Àwọ̀n àkàndá ẹ̀dá fọnmú l‘Eko, wọ́n fẹ́ kíjọba dá ọ̀kadà àti kẹ̀kẹ́ padà ṣójú pópó Ìsọkúsọ ni Olúbàdàn ń sọ, àwa la lè yọ́ lóyè.
Josẹfu bá yára jáde kúrò lọ́dọ̀ wọn nítorí pé ọkàn rẹ̀ fà sí àbúrò rẹ̀, orí rẹ̀ sì wú, ó wá ibìkan láti lọ sọkún.
O óo wọ̀ wọ́n bí ìgbà tí iyawo kó ohun ọ̀ṣọ́ wọ̀.
Onigbagbọ Ń Pe Ara Wọn Lẹ́jọ́ Níwájú Àwọn Alaigbagbọ.
Aare Muhammadu Buhari pada siluu Abuja, ti n se olu-ilu orile-ede Naijiria, lojoRu(Wednesday), leyin ti o lo fun ipade apero alaafia, eyi ti o je akoko iru re ti o waye niluu Paris, lorile-ede France.
"O halẹ pe ẹnikẹni ko gbọdọ sun mọ òun.
Omiyalé Àkútè: N50 si N100 làwọn èèyàn fi ń kọjá lórí ẹ̀kún omi 'À kò ní f'ìlú sílẹ̀ fún jégúdújérá' Èrò àwọn oníbàárà Skye Bank tó porúkọ dà Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Adeleke fọhùn, 'èmi ni gómìnà tí wọ́n dìbò yàn' Eniyan ọgọrun o le mẹjọ lo ba isẹlẹ naa lọ, ti ijọba ibilẹ aadọta si parẹ sinu ekun omi naa ni ipinlẹ Kogi.
O si jẹ ọkan gboogi lara awọn aṣaaju akọkọ ni orilẹ-ede Naijiria, bẹẹ si ni o tun jẹ adari ẹgbẹ Northern People's Congress.
Èkó: Àwọn akínkánjú obìnrín tó ń wa Márúwá
Bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé òun ni ó kéré jùlọ ninu gbogbo irúgbìn, 
Hesekaya bèèrè lọ́wọ́ àwọn alufaa ati àwọn ọmọ Lefi nípa àwọn òkítì náà.
Ati pe ile naa n fa ijamba.
Ọpọlọpọ ninu àwọn eniyan gbà á gbọ́, wọ́n ń sọ pé, “Bí Mesaya náà bá dé, ǹjẹ́ yóo ṣe iṣẹ́ ìyanu ju èyí tí ọkunrin yìí ń ṣe lọ?
 Ó jẹ ́ olóòtú ìjọba slovenia ní 1992 sí 2002 .
Lẹyin eyi ni ọkunrin naa ba gba ile-isẹ awọn SARS ni Abeokuta lọ, lati lọ sọ gbogbo bi isẹlẹ naa se ri.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ronald Koeman gbami ẹyẹ Yuropu pẹlu Barca lọdun 1992 Ipo keji ni Barcelona gba ni saa bọọlu to ṣẹṣẹ pari ninu eyi ti wọn ko si ri ife kankan gba fun igba akọkọ lati ọdun 2008.
Nígbà tí Jesu sọ báyìí tán, ọkàn rẹ̀ dàrú.
 bí ó tilẹ ̀ jẹ ́ pé a kò kaá sí àrùn ìbálòpọ ̀ .
ati Arsenal) tun padanu ifesewonse miiran laarin ọsẹ kan, eleyi ti o mu
Gomina ipinlẹ Ekiti naa, ẹni to ti fi ọpọlọpọ igba lewaju awọn ipe to tako ijọba to wa lode bayii lorilẹede Naijiria ni lọdun to kọja ni ajọ to n tọpinpin iwa ibajẹ lagbaye, Transparency International kede wipe iwa ibajẹ ati ijẹkujẹ laarin ileesẹ ọmọogun orilẹede Naijiria n se ọpọlọpọ akoba fun akitiyan lati dẹkun gulegule ẹgbẹ agbesunmọmi Boko haram.
Àjọ Commomwealth gbọ̀dọ pé ìpáde pàjáwìrì lori ọ̀rọ̀ Brexit- Wole Soyinka O ṣójú mí kóró bí wọ́n ṣé fí àdó olóró pa Dele Giwa lọdún 1986- Soyinka Ọ̀rọ̀ ẹnu lásán ló fi pàṣẹ̀ àti ìkìlọ̀ fún màálù àtàwọn tó ń dà wọ̀n tó bá tasẹ̀ àgẹ̀rẹ̀ wọn ò sì bí baba màálù kankan dáa.
Ẹ̀mí yìí náà ni ó jẹ́ kí á lè máa ké pe Ọlọrun pé, “Baba!
Efuraimu dàbí ẹyẹ àdàbà, ó jẹ́ òmùgọ̀ ati aláìlóye, ó ń pe Ijipti fún ìrànlọ́wọ́, o ń sá tọ Asiria lọ.
Ọgbẹni Ogunwuyi sọ pe awọn eeyan ti bẹrẹ si ni forukọ silẹ diẹdiẹ bayii lẹyin ipenija ti wọn ti kọkọ doju kọ.
Ó bá dá àwọn yòókù pada sí ilé wọn.
 lẹ ́ yìn tí àwọn oriṣa dá ayé tan , ti wọ ́ n sì ti ń gbé ibẹ ̀ ni odùduwà tó wá sí ile-ifẹ ̀ láti ìlú mẹka .
Ìkánjú tí mo fi kúrò nílé kò jẹ́ kí n ranti mú idà tabi ohun ìjà kankan lọ́wọ́.
owo ni won fi be gbogbo awon eniyan to wa si ibi ipolongo ti a se.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Edo election 2020: Ọlọ́pàá méjì kú nínú ìjàmbá ọkọ̀ tó ṣẹlẹ̀ sí Adams Oshiomole, APC ní kìí ṣe ojú lásán 2 Owewe 2020 Oríṣun àwòrán, others Ori ko alaga ana lẹgbẹ oṣelu APC, Adams Oshiomhole yọ lọjọ Iṣẹgun, ṣugbọn ọrọ ko ri bẹẹ fun awọn ọẹọpaa meji ti wọn jẹ ẹṣọ rẹ.
 a fẹ ́ jẹ kí àwon akẹ ́ kọ ̀ ọ ́ mọ ̀ pé àwon nnkan wònyí jẹ ́ àìkọ ́ , lára àwon akówọ ̀ ó rìn ug nínú àká - ọ ̀ rò náà ( atúmò èdè tí iyè náà ) .
Ẹlòmíràn sá gun  orí igi, ọmọde kò lè rí ẹ̀rù kí ẹ̀rù má bà á - Ẹlẹ́gbára kúrò ni nǹkan yẹpẹrẹ.
Orí ìpàǹtí ni wọn gbé gbogbo ọjà títà lé.
Kii ṣe ọrọ owo lo tiẹ kọkọ fa ironu, bi koṣe pe nkan ti mi o ro tẹlẹ, ṣẹlẹ."
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Coronavirus: Wale Akintade ní ìjọba ń sanwó oṣù fáwọn àmọ́ nǹkan kò rọgbọ 14 Ẹrẹ̀nà 2020 Oríṣun àwòrán, Others Àìsàn Coronavirus to n jagún káàkiri agbáye ko ti sinmi ìjà rẹ, se lo si n ja rain lọ gẹgẹ bii ajakalẹ arun ti wọn pe e.
Ile igbimọ aṣoju-ṣofin Naijiria lo kan an nipa fawọn obinrin atawọn ọkunrin to ba fẹ fẹ ara wọn ni Naijiria ninu apero wọn l'Ọjọbọ.
Ki ijọba pese awọn ọkọ ti ado oloro alagbinsinu ilẹ, (Mines) ko lee ran fawọn ologun 5.
Oríṣun àwòrán, @kayode Kayode ni kii ṣe pe iwa awọn pasitọ wu oun lorii loun fi faye oun fun Jesu bi ko ṣe pe Ọlọrun diidi gba ẹnu adajọ to paṣẹ ẹwọn ọdun mẹwaa fun un sọrọ sinu aye oun.
“Lasiko ti a ba n se
Dokita ni awọn ọmọ naa ni ipenija oju ati imu.
Ó ní àdúrà lo ṣe pàtàki ti ìràn Yorùbá nílò láti kẹ́sẹ jári.
“Awa la n sagbeteru ife ẹyẹ agbaye , mo si ni ireti pe gbogbo yin ti ni anfaani lati ri ewa orile ede Russia.
Lẹyin naa lo lọ si ile iwe girama ni Zaria.
22 Sátánì rú wọn sókè, kí ó lè sìn ọkàn wọn lọ sí ìparun.
Ìdẹ̀ra dé, Gẹnẹrátọ̀ tó ń lo omi dé, a bọ́ lọ́wọ́ òkùnkùn Khafi jẹ̀bùn ọkọ̀ ₦7.
Ogbó ti mú kí ojú Israẹli di bàìbàì ní àkókò yìí, kò sì ríran dáradára mọ́.
Ọ̀pọ̀ ninu wọn jẹ́ Giriki, wọ́n ń sin Ọlọrun; pupọ ninu àwọn obinrin sì jẹ́ eniyan pataki-pataki.
Àwọn ọmọ Geriṣoni yóo pàgọ́ tiwọn sẹ́yìn Àgọ́ Àjọ ní ìhà ìwọ̀ oòrùn.
OLUWA Yóo Jẹ Ilẹ̀ Ayé Níyà.
“Nítorí ìwà ìkà tí ẹ hù sí àwọn ọmọ Israẹli, arakunrin yín,ojú yóo tì yína óo sì pa yín run títí lae.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ọwọ́ ọlọ́pàá kò tíì tẹ àwọn jàńdùkú tó ṣiṣẹ́ náà Iroyin ni, ọmọde meji ni o ti sọnu ni agbegbe naa laarin oṣu kan sẹyin.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Yorùbá tone mark: Fífi àmì ohùn sí orí ọ̀rọ̀ Yorùbá ṣe pàtàkì Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
“Ta ló dàbí rẹ OLUWA ninu àwọn oriṣa?
Awọn alako Tinubu ati awọn ọmọ oṣelu PDP kan ṣalaye pe saa karun un ni yoo jẹ fun Tinubu ti ẹgbẹ APC ba tun wọle ninu ibo gomina to n bọ nipinlẹ Eko.
Bí àwọn olè bá wọlé lóru,ṣebí ìba ohun tí ó bá wù wọ́n ni wọn yóo kó?
o si tun tẹsiwaju lati maa ba ara wa se pọ.
ṣe ẹ ko gbagbe pe bi ọdun meji sẹyin ni Ajimọbi ko ẹbi ara ati ọrẹ lọ ṣe idana nilu Kano ni ile gomina Ganduje nibiti o ti mu Fatima ọmọ Ganduje fi ṣe aya fun ọmọ rẹ.
setoju ara rẹ, afaimọ ni ki o maa di eni ti ko ni lee rin mọ.
'Ambode ṣì gbọdọ̀ yọjú sí wa - Ilé aṣòfin Eko' Só mọ àwọn gómìnà tó ti jẹ́jọ́ lórí àjẹbánu ní Nàìjíríà?
Amọ idẹyẹsi naa ko tun jẹ ko fi iwe ẹri fasiti rẹ sisẹ lawọn ileesẹ nlanla nitori ọpọ wọn lo taku pe awọn ko le gba oloju kan sẹnu isẹ.
Koda, oun naa tun ti kede loju opo Instagram rẹ pe Oluwa ti sọ oun layọ.
Ó sì pàṣẹ fun yín pé kí ẹ fi ilẹ̀-ìní arakunrin wa Selofehadi fún àwọn ọmọbinrin rẹ̀.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ìjọba kò ní ti afẹ́fẹ́ ìbánisọ̀rọ̀ Nàìjíríà pa - NCC Àwọn nọmbà yìí ló le fi bá iléèṣẹ́ ológun sọ̀rọ̀ lásìkò ètò ìdìbò #NigeriaDecides Ṣé àdúrà aṣaájú ẹ̀sin lórí olùdíje kan leè nípa lórí èsì ìbò?
Igbakeji aare orile ede Naijiria, ojogbon Yemi Osinbajo yoo ba awon toro kan soro nibi ipade keta lori oro Niger Delta ti yoo waye niluu Umuahia, ni ipinle Abia, lati ojo kéjìlélógún  titi di ojo kẹ́tàdínlọ́gbọ̀n, osu keje.
"Ọga agba ni ẹka ibanisọrọ ninu ajọ eleto ilera lagbaye WHO, sọ fun BBC pe: ""laarin ọjọ kinni, oṣu Kinni si ọjọ kẹrinlelogun, oṣu Keje, ọdun 2019, ikọlu igba din meji ti ajọ eto ilera l'agbaye, WHO, ṣe akọsilẹ rẹ, fa iku oṣiṣẹ eto ilera meje, ti awọn mejidinlọgọta si fi ara pa ni orilẹede DRC."
O sọ pe ko si ijọba kan to nifẹ ara ilu lọkan ti yoo laju rẹ silẹ ki eeyan kan wa da oju ijọba rẹ bolẹ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Àwọn ọ̀dọ́ Nàìjíríà fohùn ránṣẹ́ sí ìjọ̀ba tí yóò wọlé Awọn alaga ajọ eleto idibo ti n ṣalaye kaakiri ibi ti awọn oniroyin ti kan si wọn wi pe ajọ eleto idibo laṣẹ lati ṣe awọn ofin fun eto idibo ṣugbọ́n awọn ẹgbẹ oṣelu ni laa, awọn yoo tẹsiwaju pẹlu ipolongo.
Aarẹ Muhammadu Buhari ti fi iwe ikẹdun ransẹ si awọn  ẹbi ati ọrẹ adajọ agba tẹlẹri lorilẹ ede Naijiria, Aloysius Iyorgyer Katsina-Alu to ku LọjọRu.
ile-ise iroyin , ni ile-ise akowe agba fun ijoba apapo  ogbeni Willie Bassey,gbe jade pe ki awon
"Ìjọba kéde ọjọ́ ìwọlé àwọn àgùnbánirọ̀ sí ìpàgọ́ lẹ́yìn Covid 19- Sunday Dare Gbọ́ ìtàn bí ikọ̀ SARS ṣe dà bó ṣe dà láti ẹnu Ọ̀gá ọlọ́pàá tó dá SARS sílẹ̀ Ìyá gómìnà Seyi Makinde dágbére fáyé lẹ́ni ọdún 81 Àjọ elétò ìdìbò kéde ọjọ́ tí ìdìbò aàrẹ Nàìjíríà 2023 yóò wáyé 'Garri ṣíṣe kò rọrùn fún àwa obìnrin' Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí End SARS protest: Lára àwọn ìlú tí ìwọ́de ti wáyé ní Ibadan, Ado Ekiti, Osogbo, Ado Ekiti ati Eko19 Ọ̀wàrà 2020 EndSARS Protest Update: Aisha Yesufu ní Buhari jẹ́wọ́ pé òun kò láànú aráàlú nínú ọ̀rọ̀ rẹ̀23 Ọ̀wàrà 2020 5:55 Fídíò, Soyinka Cancer: Àṣe ara mi ni iso ti n run gbogbo bí mo ṣe n ṣèrànwọ́ lórí jẹjẹrẹ, Duration 5,5527 Bélú 2019 Apple iPhone 12 pro Max:Mọ̀ nípa iPhone 12, fóònù ológo 5G tí kìí lo ""Charger” tó ṣẹ̀ṣẹ̀ jáde15 Ọ̀wàrà 2020 Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí 2 sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn."
Bẹẹ ni ọrọ ri pẹlu ọkunrin ati obinrin kan ti wọn sẹsẹ se igbeyawo amọ ti wọn ti jẹ ọrẹ ati kekere.
Lẹyin ifikunluku ati idibo lori ayelujara, agbarijọpọ ẹgbẹ ajafẹtọ ti forukọ ọdọ meji ranṣẹ ni Eko lati jẹ ọmọ igbimọ iwadii to n tọ pipin iṣẹlẹ ikọlu to waye ni Lekki.
Ìyà tí Ọlọrun yóo fi Jẹ Àwọn Ọlọ̀tẹ̀.
Ti a ko ba gbagbe, Minisita tẹlẹri naa lo pe ẹjọ mọ Ajọ EFCC wi pe wọn wọle oun lọna aitọ, ti wọn si ko awọn ohun ẹṣọ ara rẹ.
Asoju orile ede Naijiria si orile ede Russia ojogbon Steve Ugba lo sọrọ yii lori ero fidio ayelujara , ni eyi ti o fi ranse si agbenusọrọ ajo to n ri si ọrọ ile okeere, Tope Elias-Fatile lojo Aiku, niluu Abuja.
Ṣugbọn Jesu mọ èrò wọn, ó sọ fún wọn pé, “Gbogbo ìjọba tí ó bá gbé ogun ti ara rẹ̀ yóo parun, ilé tí ó bá dìde sí ara rẹ̀ yóo tú ká.
(Gbogbo àwọn ará Atẹni ní tiwọn, ati àwọn àlejò tí ó ń gbé ibẹ̀, kí wọn ṣá máa ròyìn nǹkan titun tó bá ṣẹ̀ṣẹ̀ wọ̀lú ni iṣẹ́ tiwọn.
Ọba bá pe Siba, iranṣẹ Saulu, ó wí fún un pé, “Gbogbo ohun tí ó jẹ́ ti Saulu, ọ̀gá rẹ tẹ́lẹ̀, ati ti gbogbo ìdílé rẹ̀, ni n óo dá pada fún Mẹfiboṣẹti ọmọ ọmọ rẹ̀.
Ọjọ́ pẹ́ tí mo ti dé ìhín, ó ju ẹgbẹ̀ẹ́dógún ọdún lọ.
ti won n san fun awon osise ko tọ rara.
Nítorí náà, ẹ gbọdọ̀ máa tẹ̀lé ìlànà mi kí ẹ sì máa pa àwọn òfin mi mọ́.
Nígbà tí àwọn ará Asiria bá wá gbógun tì wá, tí wọ́n bá sì wọ inú ilẹ̀ wa, a óo rán àwọn olórí wa ati àwọn akikanju láàrin wa láti bá wọn jà.
Coronavirus tún ti ṣe ọṣẹ́ lórí iṣẹ́ líla ojú ọ̀nà relùwe láti Eko sí Ibadan - Ìjọba àpapọ̀ Àrùn Coronavirus fa'lẹ̀ya láwọn ìletò aláwọ̀dúdú ní Amẹ́ríkà Èèyàn mẹ́wàá tún ti ṣẹ́gun Coronavirus l'Eko àkéte Gomina ipinlẹ Eko, babajide Sanwo-Olu ti kede iroyin ays eleyi to ni eeyan mẹwaa miran ti ruula lọwọ arun Coronavirus l'Eko akete.
Agbenusoro  awon olopaa, ko lati towobo iwe esun naa lojo-Ru(Wednesday), leyin ti o ni afi ti oun ba ri iwe lati odo awon agbejoro re.
O tẹ siwaju pe: Lọwọlọwọ yi, awọn eniyan buburu wa ni ibi ti wọn ti n pa eniyan nitori owo ati ipo.
Nígbà tí ọlọ́gbọ́n bá pe òmùgọ̀ lẹ́jọ́,ẹ̀rín ni òmùgọ̀ yóo máa fi rín,yóo máa pariwo, kò sì ní dákẹ́.
Ọkan lara awọn oluranlọwọ Aisha Buhari ti BBC ba sọrọ naa ṣalaye pe fidio naa ti pẹ.
Gba ẹ̀wù ẹni tí ó bá ṣe onídùúró fún àlejò,gba aṣọ ẹni tí ó ṣe onígbọ̀wọ́ ẹni tí kò mọ̀ rí.
Ní ìtẹríba, n óo kọjú sí ìhà tẹmpili mímọ́ rẹ,n óo sì máa yin orúkọ rẹ,nítorí ìfẹ́ rẹ tí kì í yẹ̀ ati òtítọ́ rẹ,nítorí pé o gbé ọ̀rọ̀ rẹ ati orúkọ rẹ ga ju ohunkohun lọ.
Mamman Daura: Ọmọ Nàíjíríà ní ọgbọ́n àti gbé ààrẹ fún ẹ̀kùn àríwá ni
Gbàrà, ṣe ni iku Alhaja Kudirat Abiola ṣe agbende akinkanju obinrin mii ni idile Abiola, iyẹn Hafsat Costello ọmọbinrin ti wọn bi lọdun 1974 ẹni to pinnu lati tẹsiwaju lati maa gbe opo ijangbara ti iya rẹ ja ro Alhaja Kudirat Abiola ku ṣugbọn iṣẹ akinkanju rẹ ṣi n gbe aye lọkan awọn ọmọ Naijiria.
̣ Iṣẹlẹ naa waye ni ilu Sapele, ni ipinlẹ Delta ninu ile kan ti wọn ri ẹrọ CCTV ọhun si.
” Láti ìgbà náà ni ọmọ-ẹ̀yìn náà ti mú ìyá Jesu lọ sílé ara rẹ̀.
30 Ọ̀wàrà 2019 Oríṣun àwòrán, EFCC Babalawo kan, Fatai Olalere Alli, ti inagijẹ rẹ n jẹ baba Osun to tasẹ agẹrẹ sofin, tọwọ sinkun ajọ EFCC si baa, ni adajọ kan nile ẹjọ giga nilu Ibadan ti ni ki wọn lọ fi si ahamọ.
, leyin oloogbe  Alhaji Umaru Yar’Adua
" O tẹsiwaju pe oun ni ẹri ati akọsilẹ to fi han pe lootọ ni awọn awọn aṣoju-ṣofin n gba iṣẹ lọwọ ajọ NDDC.
Osinbajo ni ọrọ yi ti wa n fẹ di lemọlemọ ti awọn to n ba ohun lorukọ jẹ naa ko si fẹ jawọ ninu iwa yi.
Ìṣe èèyàn ni ìṣe ẹranko, ẹ wo àwọn ìnàkí tí wọn fẹ́ràn fọ́tò yíyà bíi èèyàn Asiri ibudo igbafẹ ẹranko ni Naijiria Lẹyin ti ọwọ ọlọpaa tẹ ẹyẹ naa, wọn fi pamọ si ahamọ wọn lati fi ọrọ wa a l'ẹnu wo lori ohun to mọ nipa awọn oniṣowo oogun oloro ọhun.
Awon aworan ayederu wo nileese ologun nsọ?
Kò tọ̀nà láti fi ipá mú aláìṣẹ̀ san owó ìtanràn,nǹkan burúkú ni kí á na gbajúmọ̀ tí kò rú òfin.
Oba Abd-Ganiy sọ eyi lasiko to n ke gbajare wi pe awọn ajinigbe ti poju lagbegbe naa, lẹyin ti wọn kede orisirisi iṣẹ ijinigbe to ti waye lagbegbe Ibarapa ati Oke-Ogun ni ipinlẹ Oyo.
Nítorí náà, àtèmi ati àwọn arakunrin mi, ati àwọn iranṣẹ mi, ati àwọn olùṣọ́ tí wọ́n tẹ̀lé mi, a kò bọ́ aṣọ lọ́rùn tọ̀sán-tòru, gbogbo wa ni a di ihamọra wa, tí a sì mú nǹkan ìjà lọ́wọ́.
Ẹẹmarun-un ni àwọn Juu nà mí ní ẹgba mọkandinlogoji.
Ó fẹ́rẹ̀ má tíì dákẹ́ ọ̀rọ̀ tí ó ń sọ, tí àwọn ọmọ Dafidi fi wọlé, tí wọ́n sì bẹ̀rẹ̀ sí sọkún, Dafidi ati àwọn iranṣẹ rẹ̀ náà sì sọkún tẹ̀dùntẹ̀dùn.
Tabi orílẹ̀-èdè ńlá wo ni ó tún wà, tí ó ní ìlànà ati òfin òdodo gẹ́gẹ́ bí àwọn tí mo gbé ka iwájú yín lónìí?
yii ko ju ti ọrọ iṣuna owo ilu ti ọdun 2019.
Awon eniyan diẹ lo si wa
Alukoro ileeṣẹ ọlọpaa ipinlẹ Kano, Haruna Kiwaya fi aridaju ọrọ naa han fun BBC lowurọ ọjọ ẹti.
Eto adura ko tun waye lasiko itunu awẹ ọdun 2020, nitori itankalẹ coronavirus.
Ogboju Ọdẹ ninu Igbo Irunmọlẹ da lori itan igbesi aye Akara Oogun, akani ọ́dẹ́ to n pa erin, pa ẹfọ̀n to jẹ olu ẹda itan iwe naa.
Màá fún àwọn èèyàn tó forí ṣọta ìbúgbàmù l'Eko ní ₦2bn Gomina ipinlẹ Eko, Babajide Sanwo-Olu ati igbakeji rẹ Obafemi Hamzat ti ṣabẹwo si ibi ti ọpa epo gaasi ti bu gbamu lagbegbe Abule Ado naa.
Awọn onimọ sàlàyé pé ó ṣe pàtàkì kí ìnú ènìyàn máà dún ni gbogbo ìgba, kí ẹmi baa lè gùn.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Awọn ipinlẹ yoku to si ti tun kede atilẹyin wsn fun agbekalẹ abule Ruga ni iwọnyii: Gombe Taraba Adamawa Kaduna Sokoto Nassarawa Kaduna Zamfara Kebbi Katsina ati Kogi.
kí ọ̀rọ̀ tí wolii Aisaya sọ lè ṣẹ pé,
Issa so pe, “a gba ilana ofin iforiji kan ati ofin ti o de awon oloselu wole, ni bayii, omo orile-ede Libya ti ko lejo labe ofin, ni eto lati dije dupo aare, eto idibo yoo fihan boya Saif ni okiki laarin egbe re”.
Idibò na a lọ wẹ́rẹ́ lai si ìjà, kò gbà ju ìṣéjú kan si meji lọ lati wọlé dibò ti ó  bẹ̀rẹ̀ ni agogo meje àárọ̀ titi di aago mẹwa alẹ́.
Ni àsìkò ti wọ́n ba ti ba wa sọ̀rọ̀ ìgbéyàwó wọn a fún wa ni àsìkò láti ronu sii sùgbọ́n wọn kìí fẹ́ ẹni ti kò ba gba Islam.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Lockdown in Africa: Nínú Ọlọ́pàá àti Coronavirus, èwo gan an laráàlú ń bẹ̀rù jùlọ?
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù June 12: Ilé Aṣòfin rọ INEC ko kéde èsì ìbo àarẹ 1993 7 Òkùdu 2018 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, 'Ẹ kede esi ibo' Ilé Ìgbìmọ Aṣòfin Àgbà ti ké pe àjọ elétò ìdìbo Naijiria (INEC) láti kéde èsì ìbo ti àarẹ 1993 ti gbogbo eniyan gba pe olóògbé MKO Abiola ti jáwé olú borì.
“Mo ni ifarapa lasiko igbaradi mi, ti mo si nilo lati setoju papaapa lai fi fale rara.
 Òṣìṣẹ́ ológun Navy ni mí àmọ́ àwàdà ayélujára ló sọ mí di olókìkí - Cute Abiola Wo orin l'édè Yoruba àti Zulu tí Burna Boy fi fa ayélujára ya Kí ló dé tí Aàrẹ Buhari kìí fí í dá sí aáwò àwọn ọmọ ẹgbé APC?"
Enọṣi bí Kenaani, Kenaani bí Mahalaleli, Mahalaleli bí Jaredi; 
O ni eyin DRovans ni agbegbe Ringroad ni Ibadan ni iyaloja yoo ti wo kaa ile lo,.
Liigi orilẹede Italy: ajọ to n dari ere bọọlu lorilẹede Italy n gbero ati bẹrẹ ayẹwo awọn agbabọọẹu fun mims ẹni to ba ni arun coronavirus ninu wọn ni oṣu karun un ni igbaradi fun bibẹẹrẹ saa ligi wọn pada.
Oríṣun àwòrán, LASEMA Ninu atẹjade kan ti ọga agba ileesẹ pajawiri nilu Eko LASEMA, Olufemi Osanyintolu fi sọwọ si BBC, awọn eleto aabo ati panapana ni wọn jijọ pa ina to jo ọkọ naa.
Iṣẹ to saba maa n se ni lati fọ idọti to le fa idiwọ kuro ninu ara, ti o ba n lo ipara olowo nla lati mu ki awọ rẹ jọlọ to si dabi ẹni pe ko ṣiṣẹ, gbiyanju omi Mimu deede.
Iléẹjọ́, ẹ sọ fùn ọ̀gá DSS kó fún wa ní ₦1bn torí àhámọ́ lọ́nà àìtọ́ - Sowore àti Bakare Gbogbo ohun tó bá gbà lá máa fún un láti wa àwọn agbébọn náà- Ọlọ́pàá Ọ̀nà kan ò wọjà fáwọn òṣèré tíátà, bí wọn ṣe ń ta ìpara ìbóra ni wọ́n ń ta aṣọ ẹbí Ìtọ́jú ara di ìrọ̀rùn!
Ọkùnrin kọ́ ló ra jeep fún Iyabo Ojo, òógùn ojú mi ni mo fi rà á fun Tí wọ́n bá kó owó wá fun yín lásìkò ìdìbò, owó tí wọ́n jí ni o, ẹ gbà á àmọ́.
 Ọmọ ilẹ ̀ gẹ ̀ ẹ ́ sì ni .
FRSC dá N443,180 padà fún ẹbí ẹni to ní ìjàmbá mọ́tò PFN: Fatoyinbo kọ̀ láti yọjú ni ìwádìí wa kò ṣe parí Ọlọ́pàá Germany ń wádìí àfurasí mẹ́rin nínú àwọn tó kọlu Ekweremadu ni Germany Ọwọ́ ti tẹ ọlọpàá mẹ́rìn to pa afurasí Garba Sheu, sàlàyé pé ọ̀rọ̀ náà dà bí ìgbà tí tọ́kọ́taya ba túka ni, ó fí kún-un pé gbogbo àwọn ipin yìí ló ti wà tẹ́lẹ̀ tí wọ́n sì ni àwọn àkọ̀wé ilé iṣẹ́, sùgbọn ni ọdún 2015 ní ìjọba dà wọ́n pọ̀ tó sì tún pín wọ́n bàyíì Agbẹnúsọ ìjọba fi kún un pé ní bayìí gbogbo wọ́n yóò pada si ibi tí wọ́n ti wá.
Jẹ́ kí wọ́n máa gbé ilẹ̀ Goṣeni, bí o bá sì mọ èyíkéyìí ninu wọn tí ó lè bojútó àwọn ẹran ọ̀sìn dáradára, fi ṣe alabojuto àwọn ẹran ọ̀sìn mi.
Ẹ wí fún mi pé, ‘Yan ẹnìkan, tí yóo jọba lórí wa.
Ẹ óo máa fọn wọ́n nígbà tí ẹ bá mú ọrẹ ẹbọ sísun ati ọrẹ ẹbọ alaafia yín wá fún Ọlọrun.
Oṣinbajo parọwa fun iran Yoruba lati dibo gbe Buhari wọle lẹẹkan sii ni 2019 ki iṣejọba le kan wọn pada ni 2023.
Ikẹnnẹ jẹ ọkan lára àwọn ijọba ibilẹ to wa ni ẹkun Rẹmọ ní ipinlẹ Ogun ni ẹkun Guusu-iwọ oorun Naijiria.
Atejade ohun tun fenuko pe, orile-ede mejeeji yoo tesiwaju lati maa wa anfaani ajosepo ni awon agbegbe bi: irina oko oju-omi, oko oju-ofurufu, irinajo afe, idanilekoo ati ipese ise, ni ibamu pelu ifenuko won.
"APC Ekiti pàṣẹ lọ rọ́ọ́kún nílẹ̀ fún àna Tinubu àti Babafemi Ojudu Ọgbọ̀n ọdún ni mo fi ṣe iṣẹ́ púlọ́mbà kí n tó dí Gomina ìpínlẹ̀ Eko - Babajide Sanwo-Olu OPC láwọn mú afurasí agbébọn ajínigbé mẹ́rin l'Oyo, ọlọ́pàá ní àpapọ̀ òṣìṣẹ́ elétò aàbò ló ṣiṣẹ́ náa Wo bí ìwọ náà ṣe lè rí gbà nínú owó ìrànwọ́ tí ìjọba Nàìjíríà fẹ́ pín Wọ́n kọọ́ sórí rẹ pé Àmìẹ̀yẹ wura PDSA "" Fún ẹranko to ní ìgbpoya àti ìtẹramọ́ṣẹ́ lẹ́nu iṣẹ́"" láàrín àwọn ẹranko ọgbọ̀n to ti gba irú ami ẹyẹ yìí rí, Magawa ni ẹranko àkọ́kọ́ to jẹ́ Èkúté."
Awọn kan sọ pe ìgbésẹ̀ ọ̀ún jẹ́ eyi tó tọ́ tó sì yẹ, nigba ti awọn mìíran ríi gẹgẹ bii oun tí kò tọ̀nà rárá.
Nígbà tó yá mo sọ padà sílẹ̀ mo bẹ̀rẹ̀ sí í lọ.
Ẹni naa to fẹ ki mi, ki o to ṣeṣi fi ọkọ gba mi wa pada fun mi ẹgbẹrun mẹwa naira to fisi apo iwe'' Oríṣun àwòrán, Grace oyin Adejobi Lọdun 1953 ni Iya Oṣogbo ni oun bẹrẹ si ni ṣere.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ayédèrú Afenifere ló bá Buhari ṣépàdé - Odumakin gbanájẹ Dapo Abiodun wà lára àwọn tó ta ohun ìjà olóró fún mi - Amoṣun Kí ló mú bàbá àti ọmọ rẹ̀ méjì rẹ́wọ̀n oṣù mẹ́fà he ?
Wọ́n pé ọdún méjìlá báyìí Ìbálòpọ̀ ọ̀lọ́jọ́ méje mú kí ilé ẹjọ́ tú ìgbéyàwó ọdún mẹ́wàá ká ní Ibadan Ninu ọrọ tiẹ, Abiru ni oun ṣetan lati ṣoju ẹkun ila oorun ipinlẹ daadaa, bẹẹ ni oun ko si ni jawọn oludibo kulẹ.
Orí àkìtàn ni wọ́n ti rí ọkùnrin tó ń fi ìgbẹ́ jẹ Búrẹ́dì -Iléeṣẹ́ ọlọ́pàá Oyo Ọba Ilorin ló pàṣẹ pé kí ń padà sọ́dọ̀ ọkọ mi - Risikat olójú búlúù 'Ẹ̀pa ò bóró mọ́!
Ǹjẹ́ o mọ ipa tí ẹja Panla kó lásìkò ogun abẹ́lé Biafra?
Ìròyìn nípa ìyàwó túntún fún ọkọ mi kò mì mí lọ́kàn rárá-Aisha Buhari Ta ló leè rò pé ọmọ mẹ̀kúnnù bí èmi leè dé ipò alága NURTW?
Óti pé bíi ọgọ́rùún mẹ́sàán ọdún ti àwọn ènìà ti ngbé abúlé yìí.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Vaginismus: Nígbà tí ara rẹ bá kọ ìbálòpọ̀, kí ló ṣẹlẹ̀?
3bílíọ́nù owó ìjọba Ondo fọ́dún mẹ́wàá?
O rọ gbogbo awọn ọmọ ijọ CCC Genesis Global wi pe ki wọn kun fun ayọ, ki wọn si maa ṣe bi ẹni ti ibanujẹ ba nitori ohun to ṣẹlẹ si alufaa Oladele.
Ṣugbọn OLUWA yóo bukun mi, yóo sì fi ẹsẹ̀ ìjọba Dafidi múlẹ̀ títí lae.
'Mi ò fẹ́ gbé àrùn Coronavirus lọ sí Áfíríkà' Oríṣun àwòrán, Other Àkọlé àwòrán, Ejiogbe NURTW ati Auxilliary Ki lo ti kọkọ ṣẹlẹ laarin NURTW ati Auxilliary funra rẹ ni Ibadan?
Ìwọ ilẹ̀;n óo fa ibi lé àwọn eniyan wọnyi lórí,wọn óo jèrè èso ìwà burúkú wọn;nítorí pé wọn kò fetí sí ọ̀rọ̀ mi,wọ́n sì ti tàpá sí òfin mi.
UNICEF: Nàìjíríà ti bí ìkókó 26, 039 lónìí ọjọ́ kíní, oṣù kínií, ọdún 2020
12 Ìgbé 2018 Ǹjẹ́ ìwọ mọ kọ́mú tí wọn ń pè ní foamless, spacer, plunge, strapless, backless àti clap in front?
Awọn onimọ nipa ẹranko igbẹ ti n se iwadii ninu igbo ọhun lori iye awọn ẹranko to n gbe ibẹ̀ ni pàtó, nitori ko si iwadii lori iye awọn ẹranko ọhun lati bi ogun ọdún.
Tọ́mọ bá dára ó yẹ ká wí, ẹ wo Odunlade ọmọ Adekola Ọkọ̀ báàlù mi yóò ṣi padà lọ́ kó ọmọ Nàíjíríà tó kù sí South Africa - Alákoso Airpeace Lọdun 2005, wọn tun sun orin wọn Danfo Driver siwaju sii nipa ṣiṣe agbejade awo Danfo Travel: Success Story lati sọ nipa bi wọn ṣe bọ ninu iṣẹ si aṣeyọri.
" Báwo ni mo ṣe fẹ́ fi ìyàwó àfẹ́sọ́nà mi akáta hàn fáwọn òbí mi?
O fikun pe, awọn alaga ijọba ibilẹ naa ti pinnu pe ikoko ko ni gba omi, ko gba ẹyin, ko tun gba sọsọ, ti gomina Makinde ba fi tẹsiwaju lati fẹ fi tipa gba akoso awọn ijọba ibilẹ naa, nitori eyi yoo pagidina eto alaafia nipinlẹ Ọyọ.
O ti fi agbára rẹ gba àwọn eniyan rẹ là;àní, àwọn ọmọ Jakọbu ati Josẹfu.
Inú mi ru sí mẹta ninu àwọn darandaran tí wọ́n kórìíra mi, mo sì mú wọn kúrò láàrin oṣù kan.
O ṣẹgun rẹ̀ títí lae, ó sì kọjá lọ,o yí àwọ̀ rẹ̀ pada, o sì mú kí ó lọ.
Ṣugbọn ní àkókò ìkẹyìn yìí ni ó tó fi ara hàn nítorí tiyín.
Ẹgbẹ ọmọ bibi ẹya kọọkan bii Arewa, Afenifere, Ohaneze, Pandef ati bẹẹ bẹẹ lọ ni orin isọkan Naijiria ko si lẹnu wọn mọ, orin bo le di ogun , ko di ogun ni wọn n kọ.
Amọ o sọ pe Atiku lanfani lati gbegba oroke ninu idibo Aarẹ ọdun 2019 ju Aarẹ Muhammadu Buhari lọ.
Yatọ si Kọburu ti wọn pa, Sajẹnti kan naa, Patrick Okuone, naa tun fi ara pa yanna-yanna nibi iṣẹlẹ ọhun, nitori ibọn ti awọn oluwọde yin.
 Àwọn ọmọ ogun ilẹ ̀ faransé pọ ̀ gan-an ni .
Jakọbu bá sùn lọ́dọ̀ rẹ̀ di ọjọ́ keji.
Abadofin yii ni wọn gbe kalẹ labẹ ilana ''Doctrine of Necessity'' Femi Gabjabiamila ni wọn yan gẹgẹ bi olori ọmọ ẹgbẹ to pọju lọ, ni ile aṣofin kẹjọ ni Naijiria.
Eyi tumọ si pe ọmọ ọmọ Samuel Ajayi Crowther ni Herbert Macaulay, tii se ajijangbara laye eebo amunisin, jẹ Ajayi di ojisẹ Ọlọrun, ti wọn si yan an bii Bisọọbu ilu London.
Bakan naa lo tun paṣẹ fun awọn agbofinro lati pana iwọde to n da rogbodiyan silẹ ni Naijria.
Wọ́n bá bẹ̀ ẹ́ kí ó dúró lọ́dọ̀ wọn fún ọjọ́ díẹ̀.
won ko ja si asan,yoo tun je ohun iwuri fun wa lati tun tesiwaju nipa ojuse wa
Nígbà tí Jesu sọ ọ̀rọ̀ báyìí, ọpọlọpọ eniyan gbà á gbọ́.
Ondo: 'Kò sẹlẹ̀rí ní ìtàn Ondo ká fagilé ọdún Ekimogun' Ajọ to n risi idagbasoke ilu Ondo ni ipinlẹ Ondo, ODC ti kede wi pe ọdun Ekimogun ko ni waye ni ọdun yii.
Orukọ abisọ DJ Switch ni Obianuju Catherine Udeh, o jẹ olorin to gbegba oroke ninu idije X Factor akọkọ iru rẹ, ti ileeṣẹ ibaraẹnisọrọ Glo ṣagbatẹru rẹ lọdun 2013.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Coronavirus: Ǹjẹ́ fífi omi àti iyọ̀ yọnu leè dènà àrùn Coronavirus?
Aare orile-ede Naijiria, Muhammadu Buhari so pe, awon ota orile-ede yii ni o wa nidi gbogbo ikolu ipaniyan ti o n sele kaakiri.
Àṣẹ rẹ̀ nìyí: pé kí á gba orúkọ Ọmọ rẹ̀, Jesu Kristi, gbọ́, kí á sì fẹ́ràn ẹnìkejì wa, gẹ́gẹ́ bí Jesu ti fi àṣẹ fún wa.
Láti ìgbà náà, ó ti yírapadà di ajìjàǹgbara olùtako ìfìyàjẹ àwọn obìnrin pẹ̀lú àtìléyìn Ilé-iṣẹ́-tí-kìí-ṣe-tìjọba.
Eto ẹkọ Ninu ọrọ rẹ, ọjọgbọn naa ni owo ti orilẹede Naijiria n na si eto ẹkọ to le ro awọn ọmọ Naijiria lagbara ti kere ju.
2 bílíọnù fi tún wáyà iná àti inú ilé Aso Rock ṣe- Buhari Lẹyin iṣẹju diẹ Oloruntoba duro ti Okikiola ri wọn si n reti ki wọn ta Sharwama ti wọn fun wọn ni afurasi naa ba pada de, o fa ibọn yọ lo ba yin in lu ibi ti awọn mejeeji suro si.
Nǹkan kò ṣẹnuure fáwọn obìnrin nínú ìgbìmọ̀ ìṣèjọba Buhari Iṣẹ́ bọ́ lọ́wọ́ ọlọpàá mẹ́rìn to pa afurasí, wọ́n tún dèrò ẹ̀wọ̀n Wo ipò tí Buhari fún Faṣọla, Lai Mohammed, Saraki àti bẹ́ẹ̀ bẹ́ẹ̀ lọ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fọ́nrán ohùn, Joe Igbokwe kò yẹ́ fún ipò ti wọ́n fún nípìnlẹ̀ Eko - Babatunde Gbadamosi Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Nítorí náà, OLUWA rán Mose pé kí ó sọ fún àwọn ọmọ Israẹli pé olóríkunkun ni wọ́n, ati pé bí òun bá sọ̀kalẹ̀ sí ààrin wọn ní ìṣẹ́jú kan, òun yóo pa wọ́n run; nítorí náà, kí wọ́n kó gbogbo ohun ọ̀ṣọ́ wọn kúrò, kí òun lè mọ ohun tí òun yóo fi wọ́n ṣe.
Èmi nìkan kọ́ ni mo dúpẹ́ lọ́wọ́ wọn, gbogbo ìjọ láàrin àwọn tí kì í ṣe Juu náà dúpẹ́ pẹlu.
IG Police: Ààrẹ Buhari yan Adamu Mohammed ladelé ọ̀gá ọlọ́pàá Nàìjírìa
Nítorí èwo ni ẹ fi fẹ́ sọ mí ní òkúta ninu wọn?
 eésinkin ajagun-má-rùkú ló wa yàrà yí gbogbo ìlú Ọ ̀ ra po .
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Kunle Afolayan: èmi kò fẹ́ fi ogún sílẹ̀ fún ọmọ mi Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Kunle Afolayan: èmi kò fẹ́ fi ogún sílẹ̀ fún ọmọ mi 2 Agẹmo 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 30 Owewe 2019 Ìdí ti mo ṣe kọ̀ láti lo ẹbí mi nínú àwọn fíìmù mi -Kunle Afolayan Mo kọ̀ láti kọ́ ilé méjì láyé - Kunle Afolayan Gbajugbaja oṣere ati oludari ere ni Kunle Afolayan to jẹ ọmọ agba ọjẹ oṣere 'Ade Love' to ti doloogbe nsiyi.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ministerial List: Buhari tí dájọ tí yóò búra wọle fún àwọn mínísítà rẹ̀ 6 Ògún 2019 Oríṣun àwòrán, TWITTER/@BASHIRAHMAAD Ààrẹ Muhammadu Buhari yóò búra fún àwọn mínísítà rẹ̀ ní ọjọ kọkànlélógún oṣù kẹjọ ọdún 2019.
Wabba wa rọ awon osise lati maa se kaarẹ ninu igbiyanju yii , lona ti won yoo fi ri  ekunwo won  gba .
Abala akọkọ idije naa ko ti i de ibi kan to ti da bi i pe ode ko ni dara fun Carlo Ancelotti.
Sunday Igboho dá sí ọ̀rọ̀ ìbejì Akeugbagold tí wọ́n jí gbé Kí ló fà ogun Ìjàyè àti ìṣubú Kurunmi, ìfẹ́ ìlú ni àbí orí kunkun?
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ibadan clash: Rògbòdìyàn bẹ́ sílẹ̀ láàrin àwọn ọlọ́kadà àti àwọn òṣìṣẹ́ ọgbà ẹ̀wọ̀n ní Ibadan 24 Bélú 2020 Rogbodiyan bẹ sile laarin awọn ọlọkada ati awọn oṣiṣẹ ọgba ẹwọn n'Ibadan.
Hassan  lo so eleyii di mimọ, lọjọ Aiku
    Ìgbà tí wọ́n tú u sílẹ̀ tán, ó bẹ̀rẹ̀ sí í wá mi kiri, ó ránṣẹ́ lọ sílé ayé, ó rán lọ sí àjùlé ọ̀run ó wá  mi dé ọ̀run àpáàdì pàápàá, ṣùgbọ́n kò rí mi mo fi ara pamọ́ pátápátá nítorí mo tí mọ̀ pé mo dá ọ̀ràn tí ó kọjá ọ̀ràn, mo wo kìnìún lójú, mo ṣe ‘síọ̀’sí ìjàpá, mo tẹ ọká ní ìrù mọ́lẹ̀, mo mú obìnrin jáde lọ́jọ́ tí orò gba ojúde.
Ṣé nítorí pé ẹ̀ ń ṣe iṣẹ́ òfin ni ẹni tí ó fi ẹ̀bùn Ẹ̀mí fun yín ṣe fun yín lẹ́kùn-únrẹ́rẹ́, tí ó tún ṣiṣẹ́ ìyanu láàrin yín, tabi nítorí pé ẹ gbọ́ ìyìn rere, ẹ sì gbà á?
Oríṣun àwòrán, @Oddy4real Àkọlé àwòrán, Ọba Olateru-Olagbegi kejì àti Oloye Obafemi Awolowo lọ́dún 1952 Kò tán síbẹ̀, ọba James Titus Olateru-Olagbegi kejì tún lakaka láti mú ayé dẹrun fáwọn èèyàn rẹ, tó sì rí dájú pé, ìlú Ọwọ ni omi ẹ̀rọ, iná ọba, ọ̀pọ̀ ilé ifowopamọ, ibùdó ìgbafẹ́, ilé ìwòsàn, gbọ̀ngàn ìlú, ilé ẹ̀kọ́ alakọbẹrẹ àti gírámà lorisirisi.
Dokita Hong Chi Ting ni wọn ti yọ oyin naa loju arabinrin He; wọn de ti fii silẹ ki o maa lọ sile rẹ ni alaafia.
Ọpọlọpọ awọn eniyan lo ti bẹrẹ si ni fesi si igbeṣẹ Segun Awosanya to bu ẹnu atẹ lu ifẹhọnuhan EndSARS to n lọ lọwọ.
BBC's Grace Ekpu lo ya awọn aworan yii Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí The horsemen making a living on Lagos beach Nigeria The young people who make a living from taking people for horse rides on Nigeria's beaches.
Ṣe iyẹn ko ni fa wahala ṣa.
Saaju ni May ti se abẹwo si orile-ede South Africa nibi ti o ti so pe orile-ede Naijiria ni awọn to tosi julo lagbaye.
Nígbà náà ni ọmọ-ẹ̀yìn náà túbọ̀ súnmọ́ Jesu sí i, ó bi í pé, “Oluwa, ta ni rí?
Ó dùn mi pe n kò rí àyè ròyìn ìjà Ẹyin-ológbà fún yin, nítorí àkókò ń lọ.
Onimọ nipa eto ọrọ aje, Dokita Garrick Hileman sọ pe ìdá ọgọ́rin si àádọ́rùn-ún àwọn eeyan naa lo kan fi n dokowo.
N óo máa fi ẹnu mi yin OLUWA gidigidi,àní, n óo máa yìn ín ní àwùjọ ọ̀pọ̀ eniyan.
Ààrẹ Buhari buwọ́lu ẹ̀dínwó ìdánwò NECO àti JAMB Nínú ọ̀rọ̀ rẹ̀ àgbénusọ fún àjọ Jamb Ọmọ̀wé Fabian Benjamin tó bá BBC sọ̀rọ̀ sàlaàyé pé àfojúsún tí ìjọbá fún àwọn láti siṣẹ́ ló ń tukọ̀ ìṣesí àjọ JAMB pàápàá jùlọ láti ìgbà ti ọjọ̀gbọn Isa'aq Oloyede ti dí adarí àjọ náà.
Àwọn tó wà nínú ìjàmbá ọkọ̀ órí afára Otedola ń lọ ìpínlẹ̀ míì láti Eko ni - LASTMA 'Ìbọn dún láàfin Ọ̀ọ̀ni ilé ifẹ̀ lóòtọ́, ṣùgbọ́n kò séwù' Àwọn ìbejì Akeugbagold kò le rìn dáadáa mọ́ lẹ́yìn tí wọ́n dáwọn padà Ẹ wo àwọn gbajúmọ̀ òṣèré tíátà tó jogún eré ṣíṣe lọ́dọ̀ òbí wọn Wo báwọn mùsùlùmí ti ṣe ọdun ìtúnu ààwẹ̀ káàkiri ilẹ̀ Afirika lásìkò covid-19 yìí Èsì àyẹ̀wò tí àjọ NCDC gbé síta fihàn pé ènìyàn 265 ló tún ti ní ààrùn Covid-19 ní Nàìjíríà O ni iyanu nla ni yoo jẹ ti aarun naa ba kuro lori ilẹ aye patapata.
Àwọn ẹlẹ́bọlóògùn sì ń foríbalẹ̀ níwájú bàbá mi.
Ṣugbọn Jesu sọ fún wọn pé, “Kò yẹ kí wọ́n lọ; ẹ fún wọn ní oúnjẹ jẹ.
Wọ́n ti ṣí ilé oúńjẹ ọgbọ̀n náírà (N30) lẹ́yìn tí mínísítà Nanono sọ pé oúńjẹ N30 le yó èèyàn
Ìjọba àpapọ̀, ẹ gbà lọ́wọ́ ìrẹ́jẹ iléeṣẹ́ DSTV àti èlé owó rẹ̀ - ọmọ Nàìjíríà faraya 'Orísúnmibáre ni àìsàn 'Polio' tó kọlù mí ní kékeré' Wo àwọn ọmọ ilé ìgbìmọ̀ aṣòfin l'Abuja tó sùn fọnfọn lásìkò ìjókòó ilé 'Ó tẹ́mi lọ́rùn kí n pàdánù ẹsẹ̀ mi, ju kí ǹkan ṣe oyún inú mi' Atẹjade naa ni Eyii to kan wa lominu julọ nibẹ ni pe awọn ọmọ ẹgbẹ ISIS ti kora wọn wa si agbegbe Okeogun ni ipinlẹ Oyo."
Isa fi kun un pe, ilu Baga ni gomina naa n lọ nigba ti ikọlu naa waye.
Ẹ kò gbọdọ̀ ṣe ojuṣaaju ninu ìdájọ́ yín; kì báà jẹ́ àwọn eniyan ńláńlá, kì báà jẹ́ àwọn mẹ̀kúnnù, bákan náà ni kí ẹ máa gbọ́ ẹjọ́ wọn.
“Boya won lo awon Ologun tabi won ko lo iko omo oogun, emi ko lee jiyan eleyii,lati odun 1999,2003 ni won ti n lo iko omo oogun .
Ojú rẹ̀ yóo pọ́n fún àmutẹ́rùn ọtí waini,eyín rẹ̀ yóo sì funfun fún àmutẹ́rùn omi wàrà.
Nítorí nǹkan wọnyi ni ibinu Ọlọrun ṣe ń bọ̀.
Akinwumi Adesina jáwé olúborí gẹ́gẹ́ bí adarí Báńkì AFDB Tarrant tó yìnbọn pa èèyàn 51 ní mọ́ṣálááṣí méjì gbà'dájọ́ ẹ̀wọ̀n gbére Wo ojú àwọn afurasí tó fipá bá Uwaila, akẹ́kọ̀ọ́ Uniben sùn tí wọ́n tún pa á sínúu ṣọ́ọ̀ṣì Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Oyenusi ló mú mi wọ ẹgbẹ́ adigunjalè kó tó di pé mo b'Ólúwa pàdé' Segun Akinremi Oríṣun àwòrán, Other Gbajugbaja osere tiata, Segun Remi, ti ọpọ eeyan mọ si Chief Kanran kesi araye pe nnkan n ṣe oun.
Iroyin naa ni awọn obinrin miran ti ko rọmọ bi, n gba ọna ẹburu lati bimọ, eleyi to n mu wọn lọsi ọdọ Babalawo ti yoo pese ọmọ fun wọn.
Wọ́n dúró níbẹ̀ lọ́dọ̀ àwọn onigbagbọ fún ìgbà pípẹ́.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ayédèrú Afenifere ló bá Buhari ṣépàdé - Odumakin gbanájẹ Dapo Abiodun wà lára àwọn tó ta ohun ìjà olóró fún mi - Amoṣun 'A máa ń fí oògùn olóró 'ginger'ká tó ka ẹsẹ bíbélì ni ṣọ́ọ̀ṣì' Orin kíkọ kò dí ìwé mi lọ́wọ́ rárá -Hameen School Boy Àwòrán apanilẹ́rìn-ín fún ọ̀sẹ̀ yìí, ìtọ́wò rèé Atẹjade naa ni iyansipo arabinrin Adeọsun lo wa nibamu pẹlu igbagbọ Gomina Seyi Makinde ninu awọn obinrin ati ikopa wọn ninu eto isejọba.
Oríṣun àwòrán, Alaafin Oyo Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Òun nìkan bá pada ní ibi òkúta tí wọ́n gbẹ́, tí ó wà lẹ́bàá Giligali, ó tọ ọba lọ, ó ní, “Kabiyesi, mo ní iṣẹ́ àṣírí kan tí mo fẹ́ jẹ́ fún ọ.
Makinde ni ijọba ti setan lati se ohun gbogbo to yẹ lati ri wi pe eto aabo gbooro si ni ipinlẹ Ọyọ.
Ni bayii, ogbeni Lourenco yoo koju orisirisi idojuko lataari eto oro aje orile-ede Angola to mehe, bee si ni oro epo robi won ti ohun si n rakoro lati odun 2014.
Ọ̀pọ̀ àwọn NCE ọ̀hún ni kò sì yàtọ̀ sí iléèwé girama.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìjọba ìpínlẹ̀ Oyo: Oṣú mẹ́fà ni òṣìṣẹ́ ìjọba tó bá bímọ yóò máa lò nílé kó tó wọṣẹ́ padà- Seyi Makinde 4 Bélú 2020 Oríṣun àwòrán, @Makinde Oṣu mẹfa ni oṣiṣẹ ijọba to ba bimọ yoo maa lo nile ki o to wọṣẹ pada-Kọmisọnna Oyo Ijọba ipinlẹ Oyi ti buwọlu fifun awọn aboyun lẹnu iṣẹ ijọba laaye oṣu mẹfa lati duro nile tọju ọmọ lẹyin ti wọn ba bimọ tan.
N óo mú ìjọba rẹ̀ gbòòrò dé òkun;agbára rẹ̀ yóo sì tàn dé odò Yufurate
Oríṣun àwòrán, AFP Àkọlé àwòrán, Ipaniyan yi ti se okunfa ogunlọgọ awọn ọlọpa nibudo ọkọ ti i wa ni Idumọta Diẹ ninu awọn oniṣowo ti o sọrọ pẹlu BBC ni agbegbe naa n parọwa si Gomina Akinwumi Ambode lati dẹkun wahala ati iṣoro to nwaye ninu ẹgbẹ NURTW, Lagos Island ki alaafia le jọba.
1 Iṣẹ́ títóbi ati yíyanilẹ́nu kan ti fẹ́ jáde wá ní ààrin àwọn ọmọ ènìyàn.
Àwọn ìròyìn mìíràn tí ẹ lè nífẹ̀ẹ́ sí: Lagos Building Collapse: Ìjọba ìpínlẹ̀ Eko gbé ìgbìmọ̀ olùwádìí kalẹ̀ A gba ìwé ìpẹ̀jọ́ ₦200m lọdọ mọlẹbi Sugar - UCH Ilé ẹjọ kò pàṣẹ dá kíkà èsì ìbò ìpínlẹ̀ Rivers dúró-INEC Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Kloe: Èmi kìí mu òògùn olóró, àmọ́ mo fẹ́ràn láti máa wà lẹ́bà omi Igba ti awọn aladugbo maa de ibẹ, oku awọn mẹta naa ni wọn ba nilẹ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Àwọn òbí mi rò pé ẹ̀jẹ́ ti ta sí ọpọlọ mi nígbà tí mo bẹ̀rẹ̀ sí ba ẹranko igbó ṣọ̀rẹ́ Bakan naa lo mẹnuba awọn ẹgbẹlẹgbẹ awọn ololufẹ rẹ lori ẹrọ ayelujara, ti wọn lodi si ayederu idi nla ti oun ṣe naa.
Ohun ìríra ni èyí lójú OLUWA.
Nítorí ẹnikẹ́ni tí ó bá tijú mi ati àwọn ọ̀rọ̀ mi, òun ni Ọmọ-Eniyan yóo tijú nígbà tí ó bá dé ninu ògo rẹ̀ ati ògo Baba rẹ̀, pẹlu àwọn angẹli mímọ́.
Ní ọjọ́ náà, àwọn eniyan yóo wá sọ́dọ̀ yín láti ilẹ̀ Asiria títí dé ilẹ̀ Ijipti, láti ilẹ̀ Ijipti títí dé bèbè odò Yufurate, láti òkun dé òkun, ati láti òkè ńlá dé òkè ńlá.
Ìfọwọ́ọ ṣìnkún òfin múni nítorí àtúnpín túwíìtì 
Àwọn ọmọ Israẹli bá yipada sí àwọn ará Bẹnjamini, wọ́n sì bẹ̀rẹ̀ sí pa gbogbo àwọn tí wọ́n bá fojú kàn, ati eniyan ati ẹranko.
Ṣugbọn wọ́n ti na ìyẹ́ wọn bí eṣú, wọ́n sì fò lọ.
Ọrọ naa tun le sii nigba ti wọn ni wọn ba ẹgbẹrun lọna igba ati aadọta naira lara rẹ.
Ṣugbọn òtítọ́ ọ̀rọ̀ yìí ni pé a ti jí Kristi dìde kúrò ninu òkú, òun sì ni àkọ́bí ninu àwọn tí wọ́n kú.
BBCCopyright: BBC Onimọẹrọ Rauf ỌlaniyanImage caption: Onimọẹrọ Rauf Ọlaniyan BBCCopyright: BBC Onimọẹrọ Rauf ỌlaniyanImage caption: Onimọẹrọ Rauf Ọlaniyan Article share tools Facebook Twitter ṢàpínlòView more share options Share this post Copy this linkKà síwájú síi nípa àwọn ìtọ́kasí wọ̀nyí.
Lekki Toll Gate - Kí ló wà ninú lẹ́tà tí ìjọba Naijiria kọ sí CNN - BBC News Yorùbá BBC News, YorùbáFò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Nigeria government - Lekki Toll Gate - Kí ló wà ninú lẹ́tà tí ìjọba Naijiria kọ sí CNN 24 Bélú 2020 Oríṣun àwòrán, Twitter/cnn/bashirahmad Ijọba orilẹ-ede Naijiria ti kọ lẹta si ileeṣẹ iroyin CNN, lati tun iwadii ṣe lori iṣẹlẹ ipaniyan to waye ni Lekki toll gate, nipinlẹ Eko.
Nítorí náà, àwọn náà óo ṣubú nígbà tí àwọn yòókù bá ṣubú,a ó bì wọ́n ṣubú nígbà tí mo bá ń jẹ wọ́n níyà,Èmi OLUWA ni mo sọ bẹ́ẹ̀.
Bí ẹjọ́ kan bá le jù fun yín láti dá, ẹ kó o tọ̀ mí wá, n óo sì dá a.
Nítorí ó ṣe fun mi bí bàbá tí í ṣe fún ọmọ, èmi náà sì sa ipá mi dé góńgó kí òun ba le mọ̀ pé mo mọ ohun tí òun ṣe fún mi, bẹ́ẹ̀ ni onírúurú ǹkan ńlá gbogbo ni mo ń rrò nínú ara mi pé bí bàbá mi kò bá tètè kú, n ó fi wọ́n ṣe bàbá mi lóore.
NAFDAC ṣèkìlọ̀ lórí ẹja aṣekúpani tó wà nígboro Kí ló fà á tí àwọn ọmọ Obasanjo ń ta kò ó ní gbangba?
Ìtàn kẹta gùn ju ìtan kejì ti ìṣáájú lọ.
Ǹkan tí a mọ̀ nípa kọ́lẹ̀jì olùdìbò tó ń fìdì ẹni ti yóò jẹ ààrẹ ilẹ̀ Amérika múlẹ̀ Banki Nàìjíríà, CBN ṣàlàyé nípa àwọn tó máa rí gbà nínú owó ìrànwọ́ N75b tíjọba gbé kalẹ̀ Wo iye owó tí ìjọba Amẹrika ń na sí ìdìbò Ààrẹ àti ibi tí owó náà ti ń wá Ǹkan tí a mọ̀ nípa kọ́lẹ̀jì olùdìbò tó ń fìdì ẹni ti yóò jẹ ààrẹ ilẹ̀ Amérika múlẹ̀ Wo iye owó tí ìjọba Amẹrika ń na sí ìdìbò Ààrẹ àti ibi tí owó náà ti ń wá Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí 6:30 Fídíò, Akomolede ati Aṣa lori BBC: Mọ̀ si nípa oríṣìí ẹ̀ka ìsọ̀rí ọ̀rọ̀ àti ìwúlò wọn, Duration 6,308 Owewe 2020 5:55 Fídíò, Soyinka Cancer: Àṣe ara mi ni iso ti n run gbogbo bí mo ṣe n ṣèrànwọ́ lórí jẹjẹrẹ, Duration 5,5527 Bélú 2019 2:08 Fídíò, John Amanam: Ìfẹ́ tí mo ní sí àbúrò mi ló sọ mi dí ẹni tó ń ṣe 'Prosthetic' báyìí, Duration 2,081 Bélú 2020 5:52 Fídíò, Akomolede àti Aṣa: Ọ̀rọ̀ Ẹ̀yán ni Bunmi Femi Amao ń kọ́ wa lórí ètò Akọ́mọlédè àti Àṣà lórí BBC Yorùbá, Duration 5,5224 Owewe 2020 Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí 2 sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
Èyí sì tù wọ́n ninu lọpọlọpọ.
Adeyanju sọ eyi lasiko to n ba BBC Yoruba sọrọ lori ipo ti Sowore wa, ẹni to jẹ adari fun awọn afẹhọnu han to n pe fun atunse eto ijọba lorilẹede Naijiria, eyii to fa a idi ti wọn fi ti i mọle.
Kí ó sì tún mú ìdámẹ́wàá ìwọ̀n efa ìyẹ̀fun kan tí ó kúnná dáradára, tí wọ́n fi òróró pò fún ẹbọ ohun jíjẹ, pẹlu ìwọ̀n ìgò òróró kan, 
sugbon a ni isoro awon eniyan ti won ni iwa ọmọluabi , ti won si lee lo awon
Ti Ghana ba dibo fun NDC o tumọ si pe ohun amayedẹrun ni wọn yan ṣugbọn ti wọn ba dibo fun Nana akufo-Addo lẹẹkan sii, o tumọ si pe eto ọrọ aje ni wọn fẹ ko fi ẹsẹ mulẹ sii.
Ìtàn ìkọlù ẹgbẹ́ Shiite ní Nàìjíríà àti àwọn ìfarahàn adarí wọn, Ibraheem Zakzaky níle ẹjọ́.
Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Trump news: Biden tun fẹyin Trump gbolẹ ninu atunka ibo to waye ni Georgia20 Bélú 2020 US Elections 2020: Primate Ayodele ní òun ti sọ àsọtẹ́lẹ̀ pé Trump yóò fìdírẹmi, tí kò bá ṣọ́ra ṣe8 Bélú 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Awn ijọba ibilẹ mẹfa yoku ti wọn ko tii kede ni Ondo West, Odigbo, Okitipupa, Ilaje, Ese Odo ati Ondo West.
Aabọ iwadi kan ti wọn gbe jade ni ibẹrẹ ọdun yii fihan pe, ileeṣẹ ẹgbẹrun mẹjọ le igba (8200) ọmọ ogun ni awọn ileeṣẹ ologun naa nilo.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ìjọba Ọ̀yọ́: Kò sí ilé kan tí wọn kò tíì bí ìbejì ní Igbó Ọrà Ọ̀pọ̀ ọmọ Nàìjíríà si ló tí ń gbarata lórí ọ̀rọ̀ náà pé, owó àbẹ̀tẹ́lẹ̀ ní Ganduje ń gbà lọ́wọ́ àwọn kọngila.
O ni: O dun wa pe wọn ti ta ibo wọn ni Ondo nitori pe igboro ko rẹrin.
Naijiria pegede sinu asekagba idije CHAN ti o waye lorile-ede Morocco, sugbon won padanu ife-eye ohun sowo Morocco.
Super Eagles fi iyọ̀ sójú Seychelles pẹ̀lú àmì ayò 3-1 Iṣẹ́ bọ́ lọ́wọ́ ọ̀gá ilé iṣẹ́ ológun lórí ikú Fulani 134 Ilé kẹta da wó l'Eko láàrin ọsẹ méjì Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Èré Ọṣun: Àtáója ní wọn kò jí ère Ọṣun, ó sì wà níbi tó wà Ikọ agbabọọlu Amuneke lo ṣepo keji ni isọri 'L' ti ẹgbẹ agbabọọlu Cranes of Uganda si ṣe ipo kinni.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Myanmar: kékeré ni wọ́n ti n kọ́ àwọn ọmọ nípa ọ̀nà oge ṣiṣe Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Myanmar: kékeré ni wọ́n ti n kọ́ àwọn ọmọ nípa ọ̀nà oge ṣiṣe 1 Òkùdu 2019 Irun wa maa n ṣafihan boya sisí ni wa tabi bẹẹkọ.
Ajọ agbaye ti ni aarun kogboogun HIV/AIDS ni i se pelu ilera awon eniyan, nitori naa, ajọ agbaye ti setan lati se awon eto ti yoo maa satileyin fun orile ede Naijiria, ni eyi ti yoo fi dekun itankale aarun kogboogun lorile ede Naijiria.
Bẹ́ẹ̀ sì ni àwọn òkè kéékèèké rẹ, ati gbogbo àwọn àfonífojì rẹ, ati gbogbo ipa odò rẹ.
Amọ, ṣe lo sa kuro nileewosan, to si pada sile.
INEC kéde pé àwọn ẹgbẹ́ òṣèlú lé tẹ̀síwájú pẹ̀lú ìpolongo ìbò Èyí ni àwọn ìdí tí INEC fi sún ìdìbò aarẹ síwájú 'Ọrọ Nàìjíríà fẹ itusilẹ' àti àwọn èsì míràn tó tẹlé bí INEC ṣé dajọ sí ìdìbò INEC: Kò sí ìká tí o kò lè fí dìbò, ṣáà tí tẹ̀ ẹ́ sójú ẹ dáadáa Nitori naa, ootọ ni Aarẹ Buhari sọ pe, ipaniyan awọn agbebọn naa ti ls silẹ gidigidi lati igba ti o ti de ipo ni ọdun 2015, amọṣa o tun ti peleke sii ni ọdun 2019.
Ẹwẹ, ọgọọrọ awọn ololufẹ Ekeinde ni wọn gbadura fun ilera to peye fun un, wọn ni laipẹ lai jina, Eleduwa yoo mu un lara da.
 “Mo fi tokan tara lodi si ikolu ti o waye nilu Ouagadougou lojo oni, mo fi asiko yii kedun pelu awon ara-ilu ati ijoba orile-ede Burkina Faso”.
Isoro lasiko ibalopọ Irora lasiko ibalopọ nitori awọn eroja ara ti ko si mọ.
DR Congo Park: Olùdarí ìbùdó náà ní wọ́n ń fi fọ́tò yíyà sín olùtọ́jú wọn jẹ ni
Bakan naa lo tun kede eeyan 1,270 tuntun to tun ṣẹṣẹ lugbadi arun naa ni Naijiria.
Farao sọ fún un pé, “Mo lá àlá kan, kò sì tíì sí ẹni tí ó lè túmọ̀ rẹ̀.
Ìná ẹgbẹ́ òṣìṣẹ́ NLC ati ìjọba kò wọ̀ níbi ìpadé Ọmọ Nàìjíríà, ẹ forijìn mí!
Otunba Moses Alake-Adeyemo salaye ọrọ yii lasiko to fi n sọrọ lori eto ileesẹ redio kan ni ilu Ibadan.
Eto idibo ile-igbimo asofin ye ko waye loko kerinlelogun osu keta, nigba ti eto idibo ijoba ibile ati ti elekun-jekun yoo waye bakan naa ninu odun ti a wa yii, amo ipinnu won ni eto idibo Aare ti yoo waye ni odun 2020.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ekiti Election: Joe Odumakin ni ko si ìdí fun 30, 000 ọlọpaa 9 Agẹmo 2018 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 14 Agẹmo 2018 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ajá ọlọpàá, àwọn ọlọpàá to ń yanju àdó olóro àti àwọn ẹ̀ka míiràn ni yóò péjú síbi ètò ìdìbò náà Ajafeto araalu kan nilẹ Naijiria, Dokita Joe okei-Odumakin ti koro ojú lori ọgọro ọlọpaa ti wọn ko ṣọwọ si ipinlẹ Ekiti.
Yan eniyan burúkú tì í,jẹ́ kí ẹlẹ́sùn èké kó o sẹ́jọ́.
Bí inú OLUWA bá dùn sí wa, yóo mú wa dé ilẹ̀ náà, yóo sì fún wa; àní ilẹ̀ tí ó kún fún wàrà ati fún oyin, ilẹ̀ ọlọ́ràá tí ó lẹ́tù lójú.
Buhari fi ọ̀kadà, ọkọ̀ àti $500,000 ta orílẹ̀èdè Guinea Bissau l'ọ́rẹ fún ètò ìdìbò wọ̀n
Amọran Michelle Obama fun Meghan Markle Oríṣun àwòrán, Getty Images Ninu ọrọ tirẹ, aya aarẹ ana lorilẹede Amẹrika, Michelle Obama ki Ọmọọba Harry ati Meghan ku oriire na.
“Ìwọ ọmọ eniyan, ṣe àpèjúwe Tẹmpili yìí, sọ bí ó ti rí ati àwòrán kíkọ́ rẹ̀ fún àwọn ọmọ Israẹli, kí ojú ẹ̀ṣẹ̀ wọn lè tì wọ́n.
Irinajo ti gbérasọ padà ní pápákọ̀ òfurufú ìpínlẹ̀ Imo lẹ́yìn ìjàmbá iná Àwọn ológun dojú ìjà kọ ara wọn ní Khartoum Rélùwéè tẹ alágbe kan pa ní Eko Beckham, àgbábọ́ọ́lù tẹ́lẹ̀ rèé tó ń sọ èdè Yorùbá Opọ arugbo ni Hakeem ti sọ di ọmọge bẹẹ lo ti sọ ẹya ara awọn eeyan di nkan mii laarin ọdun mejila ti oun ti n ṣe.
Awọn ọmọ Nàìjíríà bá aarẹ Buhari sọ̀rọ̀ lójú òpó BBC lórí ètò ààbò ìlú
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Manfe-Dove: Àgbà ìlú kan ní ohùn kan ló fọ̀ sáwọn baba ńlá àwọn láti ṣe bẹ́ẹ̀ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Manfe-Dove: Àgbà ìlú kan ní ohùn kan ló fọ̀ sáwọn baba ńlá àwọn láti ṣe bẹ́ẹ̀ 19 Ẹrẹ̀nà 2019 Iwadi BBC fihan pe, eewọ ni fun alaboyun ni ilu Manfe Dove, lorilẹede Ghana lati bimọ tuntun sinu ilu naa.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Manchester City gba ife ẹ̀yẹ EPL Arsenal ja bi ẹlẹṣẹ - Wenger Manchester City gba ife ẹyẹ Carabao Manchester United yóò gbálejò Leicester Cit, tí Liverpool yóò si ṣe bẹẹ gẹ́gẹ́ fún West Ham.
"Oríṣun àwòrán, @NIMC Àkọlé àwòrán, Ajọ NIMC ti wa ni Amẹrika ati Canada, ki awọn ọmọ Naijiria to wa lọhun lee forukọ silẹ lai si idiwọ O ni ""Ko si otitọ ninu iroyin yẹn."
Oríṣun àwòrán, Others Wayi o, gomina ipinlẹ Eko, Babajide Sanwo-Olu ti se abẹwo si ibudo ti ọpa gaasi naa ti bu gbamu, to si ni ki wọn setọju awọn eeyan to faragba ni kiakia.
Ó fi kun pé, òún sọ fún alága NIPOST àti àdari ilé iṣẹ́ náà lọ́jọ́ Ẹtì pé, kí wọ́n ṣì dá ìfilọ́lẹ̀ rẹ̀ dúró náà kí wọ́n sí fí abájáde wọ́n ránṣẹ́ si ilé iṣẹ́ tọ n dari wọ́n lọ́jọ́ Ajé.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Coronavirus in Nigeria: Ìpínlẹ̀ Eko bẹ̀rẹ̀ fínfín àyíká nítorí Coronavirus Ọọni Ile Ifẹ ṣalaye ninu atẹjade naa pe, lara awọn ibi ti oro naa yoo gba kọja ni iwara ilode, oke atan, iloro, aganhun, arubidi, moremi, ondo road, olurin, omi okun, iyekere, oroto, itaagbon, oke ayetoro, oke soda, otutu, ajamopo, ita sun, lokore, odoiwara, olumogbe, ijio, ojafe, edena, igbo agbo, obaloogun, onpetu, oduduwa college road, akiile, ilare, saabo, iremo, okerewe, obalejugbe, garage isale, mokuro road, ojaja, ogbingbin, okejan, iredumi, lagere, fajuyi, gbodo, ita olopo, isale agbara, ogbon agbara, ogbon oya, akui, obalufon, itakogun, oriyangi, ehindi, omisore,olurin, pediro, okemorisa, atawon ibo mii Coronavirus updates: Èyí ni bí àwọn ọmọ Nàìjíríà ṣe lo ìgbélé wọn Oríṣun àwòrán, Getty Images Ọpọlọpọ ènìyàn ló ti ń sọ iriri wọn bí wọn ṣe ló ojo kini wọn nínú ilé leyin ti ijoba apapo kéde konileogbele ni ipinle Eko, Ògún àti Ábuja.
Irú àbùdá yìí ni onímọ̀ ẹ̀dá-èdè ń pè ní “Structure dependence”.
“Nígbà tí o kò bá jẹ́ kí òjò rọ̀, nítorí pé wọ́n ṣẹ̀ ọ́, tí wọ́n bá ronupiwada tí wọ́n sì kọjú sí ilé ìsìn yìí, tí wọ́n gbadura sí ọ, nígbà tí o bá jẹ wọ́n níyà, 
O ku ọsẹ meji ti wọn yoo dibo Gomina ni o sọ ọrọ yi ni oṣu Kini ọdun 2019 Ki lo mu Gomina ma ṣẹ lori ileri Opopona Apapa jẹ ọkan ti o ṣe pataki fun lilọ bibọ ọkọ ati awọn ero nilu Eko.
wọ́n kó gbogbo ìkógun: eniyan ati ẹranko.
 Lara ohun ti aare yoo tun maa mojuto ni eto ẹkọ ati ilera.
Oríṣun àwòrán, @jidesanwoolu Ẹ ṣọ́ra ní òpópónà AIT, ọkọ̀ agbépo kan ti yí dánù lọ́nà agbègbè Alagbado Àjẹ́ àti Aṣẹ́wó ní ìyá Rainbow - Òjòpagogo Mi ò mọ̀ nípa àwọn tọ́ọ̀gì tó da ìwọ́de EndSARS Alausa rú, mo ṣì wà lẹ́yìn yín digbí!
A kò rí nǹkan abàmì kan tí ó ṣe pàtàkì fún ọjọ́ díẹ̀, ó tó bí ojọ́ mẹ́ta tí a tì sin Gọ̀ǹgọ̀ṣútàkìtì  kí ó tó di pé nǹkan mìíràn tún dé bá ni, báyìí ni: 
Wo ìdí tí Osun fi kede ìsinmi fún ọdún ìṣẹ̀ṣe, tàwọn ìpínlẹ̀ yókù kò dáhùn, Ọdún Hijri mùsùlùmí tuntun wọlé dé, ẹ wo kókó pàtàkì nípa rẹ̀ Mo fẹ́ kí Ọlọ́run fún wa ní ọmọ olójú búlúù si lẹ́yìn yìgì - Ọkọ olójú búlúù Wo amuyẹ ti o gbọ́dọ̀ ni ki o to le gba fọ́ọ́mù: O ni lati jẹ ọmọ ọdun mẹtalelogun si mẹtadinlọgbọn nigba to ba maa fi di oṣu kinni ọdun 2021.
Lọpọ ibi ti iru nkan ayọ bayi ba ti waye ni awọn ara ilu ti ma n peju si aafin ọba lati ba ọba yọ ku orire.
O ranṣẹ lọ kó àwọn ohun èlò ilé Ọlọrun wá siwaju rẹ.
Nítorí pé wọn kò fetí sí ọ̀rọ̀ tí mo rán àwọn iranṣẹ mi, àwọn wolii, láti sọ fún wọn nígbà gbogbo.
26 Àti lẹ́ẹ̀kansíi, èmi pàṣẹ fún ọ pé ìwọ kò gbọdọ̀ ṣe ojúkòkòrò sí ohun ìní rẹ, ṣùgbọ́n kí ìwọ ó fi òmìnira jọ̀wọ́ rẹ̀ fún iṣẹ́ títẹ̀ Ìwé ti Mọ́mọ́nì, èyí tí ó ní òtítọ́ àti ọ̀rọ̀ Ọlọ́run nínú—
Láti 1999 títí di 2019, wo àwọn ààrẹ tó jẹ ní Nàìjíríà Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí 2 sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 2:23 Fídíò, Water Generator: Ó leè ṣiṣẹ fún wákàtí mẹfà, kó tó sinmi, Duration 2,2310 Òkùdu 2020 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
A óo sì sọ wọ́n sinu òkùnkùn biribiri.
Ó bá tún wí pé, “OLUWA, jọ̀wọ́ má bínú sí mi, bí a bá rí ọgbọ̀n eniyan ńkọ́?
Nse lo dabi ala titi taa fi bẹrẹ isẹ.
idagbasoke ba eto oro aje ipinle naa.
Ṣugbọn wọn kò wọ inú ilẹ̀ àwọn ará Moabu, nítorí pé, ààlà ilẹ̀ Moabu ni Anoni wà.
Duro Ladipọ, ìlúmọ̀ọ́ká òṣèré tíátà àti ọmọ àlúfà tí kò gbàgbé àṣà ìbílẹ̀ Ọ̀rọ̀ǹpọ̀tọ̀niyùn, Aláàfin obìnrin àkọ́kọ́ rèé, tó ní nǹkan ọkùnrin Eto abo Nkan bii ọkọ ogun mẹwaa ni gomina Ambode ra lẹyin oṣu melo kan to de ipo gẹgẹ bii gomina.
Kí ayé wà ní ìkáwọ́ yín, kí ẹ ní àṣẹ lórí àwọn ẹja inú omi, lórí ẹyẹ ojú ọ̀run, ati lórí gbogbo ẹ̀dá alààyè tí ń rìn káàkiri lórí ilẹ̀ ayé.
Won tun pinnu lati tele gbogbo eto ilana ati ofin ti o ro mo eto idibo lorile ede Najiria.
Jide Kosọkọ wa tun rọ awọn ọmọ ẹgbẹ osere tiata lede Yoruba lati maa tọju ara wọn, ki wọn ma si lo gbogbo owo ti wọn n ri lati fi jẹnu tan, amọ ki wọn pọn omi silẹ de oungbẹ fun ọjọ alẹ.
Olóyè Tajudeen Agboọlá ni ó wa lóri alèéfà Elétu Òdìbò nígbà tí Olóyè M.
Gbogbo nǹkan wọnyi ni ẹ ní, tí ẹ sì ní lọpọlọpọ: igbagbọ, ọ̀rọ̀ sísọ, ìmọ̀, ati ìtara ní ọ̀nà gbogbo, bẹ́ẹ̀ náà ni ìfẹ́ tí ẹ ní sí wa.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù 'Ogún ọdún lẹ́yìn ikú Abiọla; ipa rẹ̀ ń yọ sílẹ̀ káàkiri' Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ 'Ogún ọdún lẹ́yìn ikú Abiọla; ipa rẹ̀ ń yọ sílẹ̀ káàkiri' 12 Òkùdu 2018 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 7 Agẹmo 2018 Ilé Ààrẹ tí Abiọla ń kọ́ lọ l'Abẹokuta ti di ọgbà wèrè báyìí.
“Mo ti fi orúkọ rẹ han àwọn eniyan tí o fún mi ninu ayé.
O salaye fun TIME pe: “Fun gbogbo ona abayo ti onkawe ba mu lo latu inu iwe to ka je nkan rere fun awujo nitori yoo bi eso alaafia sii ni ni eyi ti mo n gbiyanju ki o maa jade ninu ise mi gege bii alawomo litireso ni awujo wa”.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Shittu: Máà ṣiṣẹ́ tako olùdíje fún ipò gómìnà l'ábẹ́ APC ní ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ̀ 13 Ọ̀pẹ̀̀ 2018 Oríṣun àwòrán, @HMAdebayoShittu Àkọlé àwòrán, Ṣaaju eto idibo abẹle ẹgbẹ naa ni aṣiri tu pe Shittu ko kopa ninu eto isinru ilu (NYSC).
Eyi to jẹ pe ti ìgbésẹ̀ tó tọ kò bá tètè wáyé láti fi òpin si ònà ti kò bá òfin mú nípa ṣíṣe ètò àfojusun owo ori tó n wọle le fi bi wahala.
Wọ́n tú àṣírí ìfiyàjẹni àwọn Ológun àti SARS káàkiri Nàìjíríà Èèyàn mẹ́wàá tó m bọ̀ láti ìpàgọ́ àdúrà kú nínú ìjàmbá ọkọ̀ ojú pópó l'Osun Àrá sán pa aboyún ìnàkí àtàwọn mẹ́ta míì tó jẹ́ àrà ọ̀tọ̀ láyé Àrá sán pa aboyún ìnàkí àtàwọn mẹ́ta míì tó jẹ́ àrà ọ̀tọ̀ láyé Ajọ naa ni ibanujẹ ọkan lo jẹ fun awọn pẹlu bi aarẹ Buhari ko ṣe naani awọn araalu lori eto aabo.
“Dìde, lọ sí Ninefe, ìlú ńlá nì, kéde, kí o sì kìlọ̀ fún wọn pé mo rí gbogbo ìwà burúkú wọn!
Tí a fiṣọwọ́ ní 11:59 29 Èbibi 201911:59 29 Èbibi 2019 Òjò ń pa Sanwoolu!
Iṣimaya, ará Gibeoni, akikanju jagunjagun ati ọ̀kan ninu “àwọn ọgbọ̀n” jagunjagun olókìkí ni, òun sì ni olórí wọn; Jeremaya, Jahasieli, Johanani ati Josabadi ará Gedera.
WAEC Result: Olùdíje kò nílò ìwé ẹ̀rí WAEC fún ìpò ààrẹ tàbí gómìnà
orile ede Naijiria ti yan igbimo ti yoo maa sakoso eto irinna ọkọ oju irin(Nigerian
Ṣé Yorùbá ti kúkú ní “a kìí lẹ́ni ní mọsàn ká mun kíkan’.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Irọ́ ni o!
Pa Kasumu: Òṣèré tíátà Yorùbá ní àìsàn tó ń bá òun fínra kìí ṣojú lásán
Ó ní, “Dandan ni kí Ọmọ-Eniyan jìyà pupọ, kí àwọn àgbà ati àwọn olórí alufaa ati àwọn amòfin kọ̀ ọ́, kí wọ́n sì pa á, ṣugbọn a óo jí i dìde ní ọjọ́ kẹta.
Orilẹ-ede Russia lo n gbalejo idije ife ẹyẹ agbaye ninu ere bọọlu alafẹsẹgba lọdun 2018.
5 46061 Orilẹede Venezuela 938 3.
Ninu oro re, o fi idunnu re han nipa agbende ipade apero  iko laarin orile-ede mejeeji, eyi ti ogoro awon asoju ni olokan-o-jokan eka ati awon onisowo jankan-jankan ti kopa.
Agbẹjọro David Lyon, Afe Babalola ro ẹjọ pe ki ile ẹjọ da ẹjọ ti wọn kọkọ da nu eyi to fa idaduroo onibara rẹ Lyon to si fagile anfani rẹ lati di gomina.
Betipeori, gẹ̀rẹ́gẹ̀rẹ́ òkè Pisiga, ati Beti Jeṣimotu; 
Ẹni tí Ọlọrun fún ní ọrọ̀, ohun ìní ati iyì, tí ó ní ohun gbogbo tí ó fẹ́; sibẹsibẹ Ọlọrun kò jẹ́ kí ó gbádùn rẹ̀, ṣugbọn àjèjì ni ó ń gbádùn rẹ̀.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Richard Akinjide: Ìtàn igbe ayé Richard Akinjide, agbẹjọro àti olóṣèlú tó moye 21 Ìgbé 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 22 Ìgbé 2020 Yoruba ni awaye ku kò sì, kò sì ẹni tí kò ní kú, kò si ẹni ti oko baba rẹ kò ní di igboro.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Gómìnà Seyi Makinde bá ẹbí Isiaq Jimoh tó kàgbákò ikú òjijì dárò Àwọn Ọba Yorùbá kan rèé tí wọ́n rọ̀ lóyè, tí ọba míràn jẹ lójú ayé wọn Ààrẹ Buhari ṣèpàdé pẹ̀lú Ọ̀gá Àgba iléèṣẹ́ ọlọ́pàá lórí #ENDSARS, ẹ wo àbájáde ìpàdé wọ́n Wo bí ìwọ́de #ENDSARS tí Toyin Abraham ṣe nípínlẹ̀ Oyo ṣe lọ Wo àwọn àwòrán tó jẹ́ ojú ní gbèsè níbi ìdána ọmọbìnrin Mike Bamiloye Ìdúnnú ṣubú layọ̀ fún Funke Akindele àti ọkọ rẹ, ìjọba Eko fún wọn ní ìdáríjì Ninu awọn esi ibo ti wọn kede naa, ijọba ibilẹ mẹta pere ni ẹgbẹ oselu PDP ti moke, nigba ti ẹgbẹ oselu APC jawe olubori nijọba ibilẹ mẹsan.
Ogun abẹle naa waye fun ọdun mẹta gbako, eyi to mu ẹmi eeyan bii miliọnu meji lọ, ti iyan ati ebi si pa ọpọ obinrin atawọn ọmọ wẹwẹ lẹkun ila oorun Naijiria.
sekolu si ipago awon omo ogun olote boko haram ti won fi agbegbe Arboko, nipinle
Wọ́n f'ẹ̀sùn ọkọ̀ jíjí kan Naira Marley; Ó ní òun ni Buhari yóò gbé ìjọba fún Òkété bórù mọ àwọn ọjọgbọ́n méji lọ́wọ́, UNIABUJA jù wọ́n síta Yàtọ̀ sí Olúwó, wo àwọn Ọba alayé tó ti kọ ìyàwó rí láìpẹ́ nílẹ̀ Oodua Adájọ́ ẹ tú wa ká, ìyàwó mi n gbé ààlè wá sórí ibùsùn wa- Ọkọ ìyàwó Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Oluwo Divorce: ko si ẹni ti kò mọ pé ọmọ ilẹ̀ òkèrè ni mó fi ṣe aya Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Ọpọ ọrọ lawọn eeyan ti n sọ lori ayelujara, ṣugbọn ewo lootọ, ewo ni irọ nibẹ?
Zulaihat ni ọmọbinrin akọkọ ti aarẹ bi, aarẹ si fẹran rẹ pupọ, eyi to mu ki aarẹ fi orukọ iya rẹ sọ ọ.
Àwọn alága ìbílẹ̀ tún wọ́ Seyi Makinde relé ẹjọ́ ‘Buhari gbà wá o, Seyi Makinde n fi jàǹdùkú halẹ̀ mọ́ wa láti kúrò lọ́ọ́fìsì’ Sanusi wọ gau torí pé o kọrin bù Gómìnà Ganduje Ẹgbẹ náà wà rọ gbogbo àwọn èèyàn Kwara láti má ṣé kọbi ará sí ìgbésẹ yìí nítorí pé àwọn alága náà ṣì ní aṣojú ará ìlú tí wọn dibo yan.
Bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé ó jẹ́ ànfàní fún ẹ̀kọ́ àti ìtọ́sọ́nà, àwọn ìdánilẹ́kọ̃ wọ̀nyí ni a ti yọ kúrò nínú Ẹ̀kọ́ àti àwọn Májẹ̀mú láti àtẹ̀jáde 1921 nítorí ti a kò fi wọ́n fúnni tàbí gbé wọn kalẹ̀ bíi àwọn ìfihàn sí gbogbo Ìjọ.
Gbogbo wọ́n bá péjọ siwaju rẹ̀ ní àkókò àjọ̀dún, ní oṣù Etanimu, tíí ṣe oṣù keje ọdún.
Ni àwọn eniyan bá bẹ̀rẹ̀ sí lu Paulu ati Sila.
Wọn le e wukọ tabi ni iba, ara riro, ọfun dundun ati ori fifọ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ògidì ọmọ Yorùbá gbọ́dọ̀ kọ́ ọmọ rẹ̀ ni àṣà àti ìṣe Yorùbá Ẹ̀kún omi gbé ọmọ oṣù mẹ́ta lọ 'Eyi ni bi àgbàrá omíyalé sẹ ru ìyàwó mi lọ' Iṣẹ́ abẹ ìdí ńlá sọ obìnrin kan d'èrò ọ̀run Mercy ni 'oun ko ti i fi tara-tara gbagbọ pe ọkọ oun ti ku , nitori nigba mi i, o maa n ṣe oun bi pe yoo rin wọle wa ba oun.
Òun ni Ọlọrun fi ṣe aṣiwaju ati olùgbàlà, tí ó gbé sí ọwọ́ ọ̀tún rẹ̀, kí ó lè fi anfaani ìrònúpìwàdà ati ìdáríjì ẹ̀ṣẹ̀ fún Israẹli.
OLUWA bá rán Jerubaali ati Baraki, ati Jẹfuta ati èmi, Samuẹli, láti gbà yín lọ́wọ́ àwọn ọ̀tá yín káàkiri, ó sì jẹ́ kí ẹ wà ní alaafia.
Abdulrahman ti du ipò gómìnà Kwara rí ní ọdún 2011 l'ábẹ́ àsìyá ẹgbẹ́ CPC àná, ṣùgbọ́n Abdulfatah Ahmed ti ẹgbẹ́ PDP lo di gómìná ìpínlẹ̀ náà l'ọ́dún náà.
" Ni ti awọn onibara wọn ti iye ina ti wọn n ri gba kò tó ti iye owo ti wọn san, o ni o ṣeṣe ki irufẹ awọn eeyan bẹẹ ti jẹ gbese ina tẹlẹ ki wọn to gba mita ti wọn n lo.
Ranti pé mo ti pàṣẹ fún ọ pé kí o múra, kí o sì ṣe ọkàn gírí.
Níbẹ̀ ni n óo ti fún Dafidi ní agbára;mo ti gbé àtùpà kalẹ̀ fún ẹni tí mo fi òróró yàn.
Amọṣa ori ko eeyan kan miran yọ nigba ti awọn oṣiṣẹ ikọ Amọtẹkun gba a silẹ lọwọ awọn ero to n binu naa.
Sept 11 bomb: Wọ́n mú ọjọ́ ìgbẹ́jọ́ agbésúnmọ́mí 9/11 tó ṣẹlẹ̀ l'Amẹrika
Àìbìkítà yíì gbọ́dọ̀ dópin, ìjọba gbọdọ̀ mú ẹ̀dùn ọkàn àwọn aráàlú lọ́kùnkúndùn- Agbẹjọ́rò Àgbà Buhari ni: ''Igbesẹ akọkọ ni pe a tu SARS ka lara ipinu wa lati mu atunto to gbooro ki awọn ọlọpaa baa le ṣe Iṣẹ wọn to jẹ didaabo bo ẹmi ati ọna ijẹ ara ilu'' Bẹẹ naa ni aarẹ ni gbogbo awọn to taṣẹ agẹrẹ sofin ni yoo foju wina ofin.
Ìkùukùu ati òkùnkùn biribiri ni ó yí i ká;òdodo ati ẹ̀tọ́ ni ìpìlẹ̀ ìtẹ́ rẹ̀.
 Àkíyèsí nípa ìwà ọba tàbí ìrísí ọba .
 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!"
Ó ń rìn lórí omi, ó fẹ́ kọjá lára wọn.
Amotekun: Ìjọba Eko kéde pé òun ní ẹ̀ṣọ́ aláàbò tẹ́lẹ̀, òun kò sí ní yí orúkọ rẹ̀ padá sí Amotekun
Ọ̀pọ̀ eniyan ni yóo kọsẹ̀ níbẹ̀; wọn yóo ṣubú, wọn yóo sì fọ́ wẹ́wẹ́.
Oríṣun àwòrán, others Ìgbẹ́sẹ̀ láti máse gba àwọn fóònù tó ti pẹ́ láàyè láti lo WhatsApp mọ́ kìí ṣe ǹkan túntun, nítorí èyí máa n ràn wọ́n lọ́wọ́ láti lé jẹ́ kí àwọn ǹkan èlò wọ́n ni àlò pẹ́ ni.
Oríṣun àwòrán, @YemiOsinbajo Awọn iwe iroyin kan lo gbe iroyin naa jade pe, wọn fi ẹsun kan Ibrahim Magu pe, o ko owo to to biliọnu mọkandinlogoji naira jọ, to si fun Osinbajo ni biliọnu mẹrin naira ninu rẹ.
Adari egbe yii ,to tun je oludari ajo asobode lorile ede Naijiria, Hammed Ali, so pe opolopo omo orile ede Naijiria lo fe ki aare Muhammadu Buhari pada wa se aare lorile ede yii leekeji nitori, iwa otito, ife ati emi ifokansin to ni.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Bi ọkọ tó ń sáré ṣe bá ara rẹ lórí àjà ilé onílé kàn rèé Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Bi ọkọ tó ń sáré ṣe bá ara rẹ lórí àjà ilé onílé kàn rèé 22 Sẹ́rẹ́ 2018 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 12 Èbibi 2020 O daju pe awakọ naa ko bikita nipa awọn awakọ mii to wa loju ọna to fi n wa naa lọna ti ko boju mu.
Ìfọwọ́sowọ́pọ̀ nìkan ni ọ̀nà abáyọ sí ìṣòro Nàìjíríà- Olusegun Obasanjo Ìtura ìgbà díẹ̀ ni bọ́dà tí ìjọba ṣí padà, kò lóòre nínú - Onímọ̀ ọrọ̀ ajé Wo ìdí tí ààrẹ Buhari kìí fi ṣe ẹ̀dà Jubril láti Sudan O ṣalaye pe lati bi ọdun mẹwaa ni oun ti n pin igi Keresimesi fun adari ẹsin Kristiẹni, pẹlu iwoye pe ọrọ ẹsin ati oṣelu ti ba ọpọlọpọ nkan jẹ ni Naijiria, to si tun n mu ifasẹyin ba alaafia.
Àjọ NCDC kéde pé ènìyàn ojìlélọ́ọ̀dúnrún àti méjì ló ṣẹ̀ṣẹ̀ lùgbàdi ààrùn Corornavirus, èyí jẹ́ ìdajì iye ènìyàn ti wọ́n kédé lọ́jọ́ Satide.
#BBCNigeria2019:Àkójọpọ̀ àwòrán láti ìpàdé ìtagbangba pẹ̀lú àwọn olùdije ní Ọyọ
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Orlando Owoh: Ayé ti sú mi, àdúrà ikú ìrọ̀rùn ló wù mí- Christiana, Ìyá Orlando Owoh tó ti pé ọdún 110 Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Orlando Owoh: Ayé ti sú mi, àdúrà ikú ìrọ̀rùn ló wù mí- Christiana, Ìyá Orlando Owoh tó ti pé ọdún 110 4 Bélú 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 5 Bélú 2020 Wo itan igbe aye Orlando Owoh nibi A bi Stephen Oladipupo Owomoyela ni ilu Osogbo ni ipinlẹ Osun ni guusu Iwo oorun Naijiria ni ọjọ kẹrinla, oṣu kejì, ọdun 1932 ṣugbọn ọmọ ipinlẹ Ondo ni.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Kí ló wà láàrin Olorì Badra àti Bobrisky, tí ọ̀rọ̀ wọn fi wọ̀?
Bẹ́ẹ̀ iṣẹ́ ori ránni làá ṣe.
"Ọjọbọ ti ijọba Ekiti kede faye naa ni wọn sọ fun wa.
N óo ya ìbòjú yín kúrò, n óo gba àwọn eniyan mi lọ́wọ́ yín.
 Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, SS3 ní mo wà báyìí, mo sì ti gba àmì ẹ̀yẹ̀ púpò nílé-lóko gẹ́gẹ́ bí onílù - Ayansike Kọmisọna Ọlọpaa Ipinlẹ Eko Hakeem Odumosu ti awọn ọlọpaa lati ṣe awari afurasi to ṣiṣẹ ibi naa."
 Ó jẹ ́ ọkan nínú wọn .
Awọn mẹsan an ninu awọn mẹwaa to wa nibi ijoko ile naa lo buwọlu lẹta iyọnipo rẹ.
Ó mí èémí ìyè sí ihò imú rẹ̀, eniyan sì di ẹ̀dá alààyè.
Ibrahim-Boyi salaye pe, awon agbe oniresi ti won foruko sile labe ipele akoko eto yii lasiko ogbele n lo be edegberin 295, ni eyi ti iko bi ogoji 40% ninu ida ogorun ti gba eyawo naa.
Bakan naa ni Oloye Tinubu tun jẹ ko di mimọ peawọn oluwọde to wa ni agbegbe Lekki Tollgate lasiko ti iṣẹlẹ naa waye pẹlu ni ibeere lati dahun leyi to ni yoo ran ijọba lọwọ lati lee ṣi aṣọ loju ohun gbogbo to ṣokunkun sraye nipa ikọlu naa.
Àwọn ará Gileadi gba àwọn ipadò odò Jọdani lọ́wọ́ àwọn ará Efuraimu.
Mercy ni awọn ti ri awọn apẹẹrẹ ki iṣẹlẹ buruku naa to waye.
Ile ejo agba Supreme Court ti bu enu ate lu esun ti won fi kan abenugan ile igbimo asofin, Bukola Saraki.
O ni oun ro pe Babatunde Fasola to jẹ minista ni Naijiria ni wọn fẹ fi baalu naa gbe ni, oun ko mọ pe Naira Marley ni ti orukọ rẹ n jẹ Azeez Fashola.
 Àwọn àyípadà tí ó bẹ ̀ rẹ ̀ sí ní dé bá ilẹ ̀ europe fúnra rẹ ̀ ń ṣe àkóbá fún brazil ní àsìkò yìí .
Ó ní, “Nígbà tí ọ̀gágun Lisia bá dé, n óo sọ bí ọ̀rọ̀ yín ti rí lójú mi.
Ṣugbọn bí ẹ kò bá lè túmọ̀ àlọ́ náà, ẹnìkọ̀ọ̀kan yín yóo fún mi ní ẹ̀wù funfun kọ̀ọ̀kan ati aṣọ àríyá kọ̀ọ̀kan.
Lasiko naa ni ado oloro dynamite miran tun bu gbamu nibẹ, to si fa ipalara fun ọlọpaa kan ati ọkan lara awọn afẹhonu han naa.
Nigba to wa ni ọmọde, o maa n yọ yẹlẹkẹlẹ kuro ni ile alufa to wa ninu ọgba sọọsi, lati lọ wo iran egungun ati awọn ajọdun orisa miran ti wọn n se nigba naa Wo àwọn nkan tí o le ṣe gẹ́gẹ́ bi aláboyún lásìkò àjàkálẹ̀ ààrùn Covid-19 Coronavirus: Kíni àwọn àmì tuntun tó n fihàn?
N ò kọ̀ kí ẹni rere bá mi wí,n ò kọ̀ kí ó nà mí;kí ó ṣá ti fi ìfẹ́ bá mi wí.
Rárá o, ẹ kò gbọdọ̀ sìnkú akẹ́kọ̀ọ́ LASU tí wọn fi ṣe òògun owó - Ìjọba Eko yarí Ọlọ́pàá hú òkú akẹ́kọ̀ọ́ fásítì LASU tí ọ̀rẹ́kùnrin rẹ̀ àti pásítọ̀ ṣekúpa Pasitọ Omoshola fikun ọrọ rẹ pe Naira Marley ni lati ronu piwada ni kiakia ko too pẹ fun un.
Wọ́n bá sọ fún ọba pé, “Daniẹli, ọ̀kan ninu àwọn ìgbèkùn Juda kò kà ọ́ sí, kò sì pa òfin rẹ mọ́.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù BBC Yorùbá: Ọ̀pọ̀ òjò ti rọ̀, ilẹ̀ ti fimu láàrin ọdún kan BBC Yorùbá 19 Èrèlè 2019 Àkọlé àwòrán, Ní ọjọ́ kọkàndínlógún ọdún 2018 ni wọ́n ṣe ìfilọ́lẹ̀ BBC News Yorùbá ní ìlú Eko gẹ́gẹ́ bíi ara àwọn ìkànnì tuntun méjìlá BBC lágbáyé Ni aarin ọdun kan ti BBC News Yoruba ti bọ sori afẹfẹ, oniruuru iroyin manigbagbe ni o ti gbe sita eleyi ti o ti rinlẹ kọja orilẹede Naijiria.
nítorí ẹ ti kó fadaka ati wúrà ati àwọn ìṣúra mi olówó iyebíye lọ sí ilé oriṣa yín.
Awọn alatilẹyin ara Hindu BJP yii lo ti n fidunnu wọn han kaakiri pe awọn ni yoo gbegba oroke.
Nínu àlàyé rẹ̀, o ni iṣẹ́ ti ìran oun ni oun ń ṣe láti ìgbà ìwáṣẹ̀ ṣùgbọn láti mú òjò rọ̀ àwọn nílò.
Nígbà tí ọmọ yìí wà láàyè, ò ń gbààwẹ̀, ò ń sọkún nítorí rẹ̀.
Nebukadinesari, ọba Babiloni, kó ninu àwọn ohun èlò ilé OLUWA lọ sí Babiloni, ó kó wọn sinu ààfin rẹ̀ ní Babiloni.
"Wo bí ìgbéyàwó ọmọ bàbá olówó, Adama Indimi àti Prince Malik Ado ọmọ Ọba Ohinoyi ilẹ̀ Ebira ṣe lárinrin tó Buruji Kashamu jẹ́ ènìyàn tó nífẹ̀ aráàlú- Gómínà Dapo Abiodun Awuyewuye ń wáyé lórí bí ìjọba Ìpínlẹ̀ Kaduna ṣe kó àwọn oníbárà sí àhám ""Pẹlu igbesẹ tuntun to wa loke yii, ọrọ jade, aṣẹ tẹle e pe ki o ko gbogbo ohun ini ijọba to ba wa ni ikawọ rẹ silẹ fun akọwe ijọba""."
N óo wẹ̀ yín mọ́ kúrò ninu gbogbo ìbọ̀rìṣà yín.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Mí ò ya wèrè, mí ò burú, ọ̀nà àtijẹ là ń wá' Hawkins ni o ṣeeṣe ki a dena iku awọn ọdọ wẹẹrẹ wọnyii paapaa ninu ọdun mẹwaa miran ti a bẹrẹ yii ti gbogob ijọba ba gbe igbesẹ to yẹ.
"Mo ti lọ sí ilé aarẹ Nàìjíríà, Aso Rock ni ẹẹmeji, ìyàwó Buhari gan tí fun mi ni àmì ẹyẹ rí, mo sì máa ń lọ silu oyinbo loore koore, láti ipasẹ awada yìí náà ni.
ipinle Oyo n lo lowo ni ijoba ibile Lagelu.
Iṣẹ abẹ idi ati ọyàn ni Dokita naa ma n ṣe.
ati pé Sedekaya ọba Juda kò ní bọ́ lọ́wọ́ àwọn ará Kalidea.
Ní àkókò ìyàn,yóo gbà ọ́ lọ́wọ́ ikú.
Ajọ to n gbogun ti jẹgudujẹra lorileede Naijiria, EFCC kede pe ni kete to ba pari saa ijọba rẹ lawọn yoo wọ lọ si ile ẹjọ.
Òun ni Ọlọrun àwọn baba ńlá mi;n óo máa gbé e ga.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Xenophobia: Allen Onyeama ní 300 mílíọ̀nù náírà ní òun fí gbé àwọn ọmọ Nàìjíríà wálé Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Xenophobia: Allen Onyeama ní 300 mílíọ̀nù náírà ní òun fí gbé àwọn ọmọ Nàìjíríà wálé 12 Owewe 2019 Yin ni yin ni,ki ẹ ni baa le ṣe mi,bẹẹ lọrọ ri ti a ba yẹ ọrọ ọmọ Naijiria to ṣagbatẹru dida awọn eeyan pada wale lati orileede South Africa.
Èmi, àní èmi pàápàá ni mo sọ̀rọ̀, tí mo pè é,èmi ni mo mú un wá,yóo sì ṣe àṣeyege ninu àdáwọ́lé rẹ̀.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Sunday Igboho gba àwọn èèyàn Soka n‘Ibadan sílẹ̀ lọ́wọ́ àwọn ọmọ onílẹ̀ tó wá ṣọṣẹ́ Ẹ̀yin ọba alayé, ẹ mà ń dákẹ́ pọ̀ lórí ààbò tó mẹ́hẹ ní Nàíjíríà - Sultan figbe ta Àgbà olórin, Victor Olaiya jáde láyé.
Kí àṣàrò ọkàn mi kí ó dùn mọ́ ọn ninunítorí mo láyọ̀ ninu OLUWA.
Àwọn ajìjàngbara sọ wípé ìgbàgbọ́-asán tí ó rinlẹ̀ ní ìgbèríko ni ó ń fa ìwà pálapalà náà.
Bi wọn ṣe n ṣe burẹdi.
Awọn ara ile rẹ to ku ti BBC ba sọrọ ni irọ ni pe ori rẹ daru ati pe awọn ko mọ pe Idris ni ibọn ninu ile rara.
Ọkọ mi ni, oun si ni baba ọmọ ti mo mu dani yii."
O ti fún mi ní asà ìgbàlà rẹ,ọwọ́ ọ̀tún rẹ ni ó gbé mi ró,ìrànlọ́wọ́ rẹ sì ni ó sọ mí di ẹni ńlá.
Agbẹnusọ ti gbogbo eeyan gba pe kii figba gbogbo sọrọ lori oṣelu naa ni ohun to wu ki Boris wi; igbesẹ isinmi lasiko yii jẹ ọna lati dina ijiroro lori Brexit nile igbimọ aṣofin ni.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Russia Covid 19 Vaccine: Ẹ wo ohun tó yẹ kí ẹ mọ̀ nípa oògùn 'Sputnik V' Russia tó ń wo àrùn Coronavirus 12 Ògún 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 15 Ògún 2020 Oríṣun àwòrán, Reuters Aarẹ orilẹ-ede Russia, Vladimir Putin ti kede oogun 'Sputnik V' gẹgẹ bi oogun tuntun to n sawotan arun Coronavirus.
Igboho ṣàlàyé pe, kò si ìgbà kankan tí awọn kọlu àwọn ọmọlẹ́yìn Auxiliary nítorí pé òun máa ń figba gbogbo wa ọ̀nà bí omi àlàáfíà ìlú yóò fi toro ni, tí idagbasoke yóò sì bá àwùjọ wa.
Gómìnà Godwin Obaseki yóò d'ọmọ ẹgbẹ́ òṣèlú PDP lọ́sẹ̀ yìí O daju pe ẹgbẹ oṣelu Peoples Democratic Party, PDP ni Gomina Godwin Obaseki nlọ, Yoo si darapọ mọ ẹgbẹ naa ki eto idibo abẹle lati yan oludije ipo gomina ipinlẹ Edo lọjọ kọkandinlogun ati ogunjọ oṣu yii.
Ọkan lara awọn ọgaagba ajọ to n ṣe iwadi nipa ọrọ omi lorilẹede Naijiria, Clem Eze ṣalaye wi pe bi ati n sọrọ yii, kikun omi odo ọya, iyẹn River Niger ti le ni mita mẹwa eleyii to pọ ju mita mẹwa o din diẹ to wa lasiko iṣẹlẹ ẹkun omi ọdun 2012 to si n pọ sii ni wakati, wakati.
Awọn kan ni ọkan awọn ti balẹ bayii, ẹnikan ti igbeyawo rẹ pẹlu Lanre Kuti naa sọ tẹnu rẹ bẹ́ẹ̀ si ni Bakan naa ni awọn mii ni ṣe ni ko pa ọrọ awọn eeyan ti pe bi kii ba ṣe ẹni to wa lati ile ire to si gba ẹkọ lo fi n ṣalaye ọrọ tori naa ko pa wọn ti pe ko jẹ wọn ni alaye kankan.
”Ò ń wá agbára kún agbára,nítorí náà àárẹ̀ kò mú ọ.
Jẹ́ kí oyún máa bàjẹ́ lára obinrin wọn, kí ọmú wọn sì gbẹ.
Eyi tumọ si pe ni owo naira, iye rẹ yoo jẹ laaarin ẹgbẹrun mẹrin o le diẹ naira (4,224.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: A ṣe ọdún Ọ̀ṣun lásìkò yìí láti kó Coronavirus lọ ni - Ooni ṣàlàyé Wo àwọn nǹkan tí o kò mọ̀ nípa 'Church of Satan' Àwọn afurasí ajínigbé tó tan oníṣòwò jáde ní ṣọ́ọ́sì wọ gàù Ọlọpaa Eré ìtàgé lórí ayélujára, àbíkẹ́yìn faraya pé iṣẹ́ ilé ń pá òun lórí, ó gbé òfin kalẹ̀ fún ẹbí Boko Haram 601 parí iléẹ̀kọ́, ìjọba yóò san ₦20,000 lóṣù fún ẹnì ìkọ̀ọ̀kan Aráàlú faraya torí èèyàn 63 tó dèrò ọ̀run ní Gúúṣù Kàdúná láàrin ọ̀sẹ̀ kan Lasiko abẹwo BBC Yoruba si awọn adugbo bii Stadium, Ipọnrin, Shitta, titi wa si adugbo Oworonsoki, a sakiyesi pe lati aago mẹrin owurọ ni awọn ọkọ ti gbemu-lemu.
kọ́ wa láti máa ní ṣùúrù 11 Agẹmo 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Awọn baba nla wa nilẹ Yoruba jẹ ọlọpọlọ pipe, ti ori wọn kun fun ọgbọn ati oye.
Ènìyàn 653 míràn tún kún iye àwọn tó ní COVID-19 ní Nàìjíríà Wo ohun tó yẹ kí o mọ̀ nípa Laycon, akẹ́kọ̀ọ́jáde UNILAG tó ń kópa nínú BBNaija 2020 Àwọn àádọ́ta ọ̀dọ́ wọ gàù nítorí ilé ijó ní Ilorin Ondo APC primaries: Olùdíje míràn, Olusegun Abraham tún ti gbé àgá fún Akeredolu níbi ètò ìdìbò abẹ́lé APC ìpínlẹ̀ Ondo Bi awọn aṣoju oludibo lẹgbẹ oṣelu APC ṣe n gbaradi lati yan oludije ẹgbẹ oṣelu naa fun ibo gomina to n bọ lọna, oludije miran tun ti dide lori aga fun gomina Rotimi Akeredolu.
Bákan náà ni gígùn iwájú tẹmpili tí ó kọjú sí ìlà oòrùn ati àgbàlá, òun náà jẹ́ ọgọrun-un (100) igbọnwọ (mita 45).
Lẹ́yìn náà, ó pàṣẹ pé kí wọ́n ṣe ìrìbọmi ní orúkọ Jesu Kristi.
le ni bilionu naira sọtọ lati fi se awon akanse isẹ lati fi seto idagbasoke ohun
Eeyan ti dero ọrun ninu awọn to larun naa ni Naijiria, ọjọ Aje ni ọkunrin naa ẹni ọdun mẹtadinlaadọrin ku.
Nítorí àwọn Juu ń bèèrè àmì: àwọn Giriki ń lépa ọgbọ́n; 
Awọn agbabọọlu Tottenham gan an ti mọ pe igba ọtun ti de, agbabọọlu bi Dele Alli ti ina ere bọọlu rẹ ti n jo ajo rẹyin tẹlẹ ti sọji bayii.
 wọ ́ n tún ń sọ èdè yìí ní apá kan ilẹ ̀ tọ ́ kì ( turkey ) .
Inú bí bàbá mi nítorí ọ̀ràn yí ó si bẹ̀rẹ̀ sí ti ẹwbọra náà lọ títí ó fi dé ìdí igi ẹlẹ́gùn-ún tí o fi agbára ti Èṣù-kékeré mọ́ igi ẹlẹ́gùn-ún èyí tí ó mú kí ẹbọra burúkú yìí kígbé ńlá tí ó sì mú kí ó bẹ́ sílẹ̀ láti èjìká bàbá mi.
Ọdún mẹta ló fi jọba ní Jerusalẹmu.
Mose ati Eleasari alufaa sì pe àwọn eniyan náà jọ ní pẹ̀tẹ́lẹ̀ Moabu, lẹ́bàá odò Jọdani, létí Jẹriko, 
Dapo Ojora: Ẹ̀gbọ́n ìyàwó Bukola Saraki kú l'Eko, èdè aìyedè wà lórí bó ṣe kú
Ohun ti wọ́n kọ sí ibẹ̀ ni ìwọ̀nyí:
NFF ni titi lai loun yoo maa ṣe iranti akọni agbabọọlu to re iwalẹ asa.
Àwọn ọba tí yóo jẹ lẹ́yìn rẹ̀ kò ní jẹ́ láti inú ìran rẹ̀, kò sì ní sí èyí tí yóo ní agbára tó o ninu wọn; nítorí a óo gba ìjọba rẹ̀, a óo sì fún àwọn ẹlòmíràn.
Síbẹ̀ ọ̀pọ̀ àwọn ebí ló bo ilé ìwòsàn Mainland bibà, lati wá àwọn olólùfẹ́ wọn.
UK Parliament on Nigeria: Geoffrey Onyeama ni aṣofin UK kò lágbára láti sọ̀rọ̀ lórúkọ ìjọba UK
Biṣọọbu Agba ni Ile Ijọsin Eleto ‘Methodist’, ti Ipinlẹ Eko, Ẹni-ọwọ Julọ Luke Odubanjọ ti pe awọn ọmọ orilẹ-ede Naijiria lati tubọ sunmọ Ọlọrun paapaa ninu isin ati iyin wọn ninu gbogbo ipo ti wọn ba wa, wi pe pelu eleyii yoo jẹ ki inu Ọlọrun o maa dun si wa, ki o si maa da si gbogbo ọrọ wa, ti iyipada rere yoo fi ba orlẹ-ede yii.
 O gba pe egbogi oloro ti oun n mu lọdọ ni ko je ki o pari ẹkọ rẹ ni Vassar College.
Gabriel Jesus ti ko ri bọọlu kankan gbá sáwọ̀n lati ọṣu mẹrin sẹyin dẹni to n jẹ goolu meji laarin iṣẹju mejidinlọgbọn ninu idije kan ṣoṣo!
Oríṣun àwòrán, Twitter/femi aladejuyigbe Ẹgbẹ́ akẹ́kọ̀ọ́ gíga n'Ibadan ṣèwọ́de lọ iléeṣẹ́ ọlọ́pàá lórí afurasí tó dàwátì Iwọde ti n waye baye ni ilu Ibadan lati fi ẹhonu han lori bi afurasi ti wọn mu fun iku awọn eeyan marun kan ni agbegbe Akinyẹle ni ilu Ibadan ṣe salọ ni ahamọ ọlọpaa.
Ogun state lockdown update: 'Èèyàn 104 tó kó covid-19 ní ílééṣẹ́ kan ní Sagamu fihàn pé ààrùn náà ti wà láwùjọ'
Ifipagbajọba nilẹ Afirika Igba mẹfalelugba ni ifapagbajọba ti ṣẹlẹ nilẹ Afirika lati ọdun 1950, iwadii awọn onimọ eto oṣelu meji to jẹ ọmọ ilẹ Amẹrika, Jonathan Powell ati Clayton Thyne lo fidi ọrọ naa mu lẹ.
Lẹ́yìn náà, ó wí fún Gehasi pé kí ó pe obinrin ará Ṣunemu náà wá, Gehasi bá pè é.
Ajo naa so ninu atejade kan ti komisona , to tun wa lara igbimo to n ri si ilaniloye ati ipolongo eto idibo ,Mohammed Haruna gbe jade niluu Abuja lojo Isegun, pe nibi ipade ni igbimo ti fori-kori lati mu ipinnu yii sẹ.
Gbogbo wọn bá kún fún Ẹ̀mí Mímọ́, wọ́n wá bẹ̀rẹ̀ sí sọ oríṣìíríṣìí èdè mìíràn gẹ́gẹ́ bí Ẹ̀mí ti fi fún wọn láti máa sọ.
Jesu wí fún igi náà pé, “Kí ẹnikẹ́ni má rí èso jẹ lórí rẹ mọ́ lae!
Ile ise iwadii ti a mo si: The International Food Policy Research Institute” (IFPRI) ti bere idanilekoo olojo meji fawon akoroyin atawon osise nile igbimo asofin Naijiria lojo Eti nilu Abuja.
 idagbasoke eso-ise dasarin 5 % ni bi odun meje seyin , sugbon iposi iyearabudo ko je ki iposi yi o ni ipa kankan .
Lojoojumọ, kí oòrùn tó wọ̀, ni kí ẹ máa san owó iṣẹ́ òòjọ́ rẹ̀ fún un, nítorí pé ó nílò owó yìí, kò sì sí ohun mìíràn tí ó gbẹ́kẹ̀lé.
Alufaa yóo sì ti ìka bọ inú ẹ̀jẹ̀ rẹ̀, yóo fi sí ara ìwo pẹpẹ ẹbọ sísun, yóo sì da ẹ̀jẹ̀ yòókù sí ìdí pẹpẹ.
O ni bi o ti n sa fun oun ni oun tun waa lọ.
Fa ọ̀kọ̀ yọ kí o sì dojú kọ àwọn tí ń lépa mi!
Belgium); Moses Simon (Levante FC, Spain); Henry Onyekuru (Galatasaray SK,
Ẹ ò wá wo ọmọ inú ọgbà bí wọ́n ti ń ṣe
Akẹkọgboye jade ni Poly Ibadan ọhun ni ''Mo ri awọn alagbe to ku ti wọn si bẹnu atẹ lu mi.
Oríṣun àwòrán, cable Àkọlé àwòrán, YabaLeft: #7000 si #10000 ni owó àbẹ̀tẹ́lẹ̀ fún bẹẹdi ní ilé àwọn aláìsàn ọpọlọ Ní ti Ekúté ńkọ?
"O ko owo naa fun Ronke lati ṣe ayẹyẹ ọjọ ibi ọmọ naa, amọ Ronke ko pada ṣe ayẹyẹ kankan.
Ẹ yé gba owó orí níbi ìdána ìyàwó mọ́, sísọmọbìnrin s'óko ẹrú ni- Daddy Freeze A kò fòfin de owó naira tó ti pẹ́ ní Naijiria -CBN Ẹmi marun sọnu ninu ija Kaduna Akẹkọ kan ku,ileẹkọ jona ninu ija akẹkọ fasiti Modibbo Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
“E maa se beru, ki e ma si foya, aabo ti o peye wa fun yin lakooko
Wọ́n dá a lóhùn pé, “Pípa ni yóo pa àwọn olubi náà, yóo fi ọgbà àjàrà rẹ̀ lé àwọn alágbàro mìíràn lọ́wọ́, tí yóo fún un ní èso ní àkókò tí ó wọ̀.
Ó tún wípe rárá, ìrèké náà kù díẹ̀ káàtó.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ sí: Ẹlẹka: Ìdá àádọ́rin nínú ọgọ́rùn ni mo ní nínú ìbò Ekiti Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Fayẹmi bá BBC sọ̀rọ̀ ní kété tó di gómìnà Ekiti Ẹwẹ̀, akọ̀ròyìn wa tó wà ní ìpínlẹ̀ Ekiti ti ń wá ọ̀nà láti bá a sọ̀rọ̀ lọ́pọ̀lọpọ̀ ìgbà àti agbẹnusọ rẹ̀ sùgbọ́n pàbò ló já sí.
Bakanaa ni ikọ Boko Haram fidi rẹ mulẹ pe oun lee tun gba ilẹ kan si lọdun 2017 pẹlu bo se tun kọlu ẹknu ariwa orilẹede Cameroon, agbegbe Niger Diffa ati Lake Chad, ti gbogbo wọn wa leti aala ilẹ ila oorun ariwa Naijiria.
Asofin Suleiman so pe, igbimo naa yoo bowolu iwe isuna eto idibo gbogbogbo to n bo lọdun 2019, eyi ti isuna re yoo jeyo ninu eto isuna odun 2018 gege bi aare se so fun ile igbimo asofin.
N kò bẹ̀bẹ̀ pé kí o rán ibi sí wọn,bẹ́ẹ̀ ni n kò fẹ́ ọjọ́ ibi fún wọn.
Àwọn afurasí ṣá ìgbákejì kọmísọ́nà ọ̀gá ọlọ́pàá láàké dójú ikú 'Àwọn ọmọ 5 kọ́ ló sọnù, ọmọ 28 ló sálọ síléeṣẹ́ foyúngbowó nípinlẹ̀ Ogun' Soun ilẹ̀ Ogbomoṣo pàdánù ọmọkùnrin rẹ̀ Ṣé lóòtọ́ ni ìjà ti parí láàrin ìdílé Ayinde Barrister àti Kwam 1?
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Coronavirus pandemic numbers:Ṣé ìrètí wà pé coronavirus yóò dínkù lásìkò ooru?
Aubameyang, to jẹ agbabọọlu Arsenal lo wa fi ọba lee ni aadọrun iṣẹju iufẹsẹwọnsẹ naa.
Ṣugbọn kí wọn tó tẹ́ ìfẹ́ ọkàn wọn lọ́rùn,àní, nígbà tí wọn ṣì ń jẹun lọ́wọ́.
Ìwọ ti fi ayọ̀ kún ọkàn miju ayọ̀ àwọn tí ó rí ọpọlọpọ ọkà ati ọtí waini nígbà ìkórè.
Jesu dá a lóhùn pé, “O kò mọ ohun tí mò ń ṣe nisinsinyii; ṣugbọn yóo yé ọ tí ó bá yá.
8 1 Sẹ́rẹ́ 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ẹgbẹ́ òṣìṣẹ́ NLC, TUC àti ULC ní èyí ni ẹ̀bùn ọ̀dún tuntun fún Nàìjíríà àyàfi tí ìjọba bá gbé ìgbésẹ̀ tó tọ́ lórí ẹ̀kúnwó oṣù tuntun Ẹgbẹ oṣiṣẹ lorilẹede Naijiria ti ni awọn ni ẹbun nla fun orilẹ-ede Naijiria bi ijọba apapọ atawọn ijọba ipinlẹ ba kuna lati fi ẹnu ọrọ ẹkunwo oṣu tuntun jo ibikan ṣaaju gbendeke ọjọ kọkanlelọgbọn, oṣu kejila, ọdun 2018.
Àwọn ìtàn mánigbàgbé tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ìtàn Àrọ̀gìdìgbà jẹ́ kí ń rò pé bàbá mi yan Yemọ̀ja ní àlè - Ọmọ Fagunwa Ó pé ọdún mẹ́rìnlélàádọ̀ta tí Akintola kú, ìdí abájọ ìja rẹ̀ pẹ̀lú Awolowo rè é Ìtàn Gbọnka àti Timi, akọni méjì tó borí Aláàfin Ṣango Wo ìṣẹ̀lẹ̀ márùn-ún tí kò bá pín Nàíjíríà sí yẹ́lẹ-yẹ̀lẹ Eji Gbadero, ọmọ Ibadan àti jayé-jayé ọmọ ónílẹ̀ ti wọn yẹgi fun l'Eko Lisabi Agbongbo Akala rèé, ẹni tó fi ìfẹ́, ìṣọ̀kan àti ìrẹ́pọ̀ gba ilẹ̀ Ẹ̀gbá lọ́wọ́ ìmúnisìn Wọn wa n rọ awọn eeyan awujọ lati ye maa ro pe ko yẹ ki iru awọn eeyan to ba ni ipenija bayii jade laye tabi pe o ti tan fun wọn.
yoo se di afisẹyin ti eegun n fi asọ.
A níló ìràpadà fún àwọn olùkọ́ wa.
Kí òkùnkùn ṣú bo alẹ́ ọjọ́ náà biribiri,kí á yọ ọ́ kúrò ninu àwọn ọjọ́tí ó wà ninu ọdún,kí á má sì ṣe kà á kúnàwọn ọjọ́ tí wọ́n wà ninu oṣù.
Nítorí pé, ọjọ́ mẹfa ni èmi OLUWA fi dá ọ̀run ati ayé, ati òkun, ati gbogbo ohun tí ó wà ninu wọn; mo sì sinmi ní ọjọ́ keje.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Eto atunto ati atungbeyẹwo ofin ati ilana iṣẹ ọlọpaa n waye kaakiri orilẹede Amẹrika.
O tun so pe “Mi o ni nnkankan ti mo fe so Nipa Nnamdi Kanu.
OLUWA ní, “Ọtí waini ati waini tuntun ti ra àwọn eniyan mi níyè.
Nigba ti yoo fi wa si igbẹjọ nileẹjọ, gbalaja bayii ni Metuh sun sori bẹẹdi alaarẹ, Stretcher wa si ile ẹjọ.
Fún mi ní òye ati ìmọ̀ pípé,nítorí mo ní igbagbọ ninu àṣẹ rẹ.
Bakan naa ni adajọ sọ pe o gbọdọ mu awọn meji ti yoo ṣe oniduro rẹ wa.
 oluilu re , belgrade , je ikan ninu awon titobijulo ni apaguusuilaorun europe .
WAEC gbé èsì ìdánwò WASSCE jáde Ooni Ife fohùn ránṣẹ́ sí Boris Johnson, ó ní, bóo bá joun gbé, má johùn gbé"" Bíbéèrè fún ìbálòpọ̀ gbogbo ìgbà sọ ìyàwó ilé dèrò ilé ìwòsàn Etí ìjọba Buhari di sí ìmọ̀ràn àwọn ará ìlú -Jiti Ogunye Ẹ jẹ́ kí n sọ ọgbọ́n tí ẹ lè fi mú Fulani Ẹ mu àwọn Fulani lọ ilu oyinbo ki wọn lọ kọ bi wọn ṣe n ṣe eto ẹran igbalode ""Apẹrẹ gidi ni mi lori ọrọ Fulani, Ọba temi wa Fulani lọle ninu igbo rere, mo wọ inu Gaa Fulani lọ""."
Corona ma kọkọ se akoba fun tọna ọfun yi,ẹdo foro ti a si sọ wọn di ile isẹ to n gbe awọn kokoro aifojuri aimọye ti wọn yoo ma se akoba fun awọn sẹẹli ara mi.
Ile-ise PZ Industries naa jere N1.
O si le jẹ nipasẹ isẹ abẹ ile itọ tabi aisan ninu ile itọ.
Ọlọpa Spain mu awọn onigbowo nabi Owo sile d‘imi eegun ni Nigeria Ọjọ̀gbọ́n Fatunde: Báyìí ni bàbá ìsàlẹ̀ nínú òṣèlú ṣe lè dópìn bí El-Rufai ṣe sọ Iye awọn to n lepa irinajo yii ti n dinku lati ẹbẹrun lọna ogoji to gba ori okun gunlẹ si orilẹede Italy lọdun 2016 si ẹgbẹrun kan o le igba ati aadọta ni ọdun to kọja, eleyii ti ko yẹ lori igbesẹ mawoju ẹ eleyi ti ajọ orilẹede Yuroopu gbe lati kọ oju oro sawọn to n ṣowo fifi eeyan ṣọwọ soke okun lọna ti ko bofinmu.
Owú jíjẹ burú, àfi bí isà òkú.
Síbẹ̀síbẹ̀, àwọn tí ó fara kááṣá ò tilẹ̀ ní àǹfààní sí ilé-ẹjọ́ òfin kí àgbájọ-àwọn-ènìyànkéènìà ó tó kojúu wọn.
Oríṣun àwòrán, EPA Àkọlé àwòrán, Ajọ to n ri si akoso awọn orilẹede nilẹ Yuroopu yoo ni Kọmisana tuntun, Ursula von der Leyen, lati ọjọ kinni, osu Kọkanla O ni oun yoo se atilẹyin fun afikun ọjọ ti ilẹ Gẹẹsi yoo kuro ninu ajọ isọkan ilẹ Yuroopu, amọ o ni awọn ko ni tun se idunadura mọ lori ilana adehun ti ilẹ Gẹẹsi yoo gba kuro ninu ajọ naa.
Agogo marun-un irọlẹ ọjọ Aiku ni afara naa di ṣiṣi pada fun lilo.
Fiimu naa lo gab ipo keji ninu iṣide fiimu lọdun 2018.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Victor Agunbiade ni ojú àlá ni Ọlọrun ti yan iṣẹ́ ọmọ ogun ojú omi fún òun ní America Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Fídíò, Natalia Mufutau ìyá Yakub, Kamil àti Adam sọ̀rọ̀ lórí bí wọ́n ń sọ èdè mẹ́rin pàpọ31 Ògún 2020 Fídíò, Yoruba Language: Akomolede ati Asa Yoruba tọ̀sẹ̀ yí rèé lẹ́nu olùkọ́ wa30 Ògún 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Bí ojú rẹ bá ríran kedere, gbogbo ara rẹ yóo ní ìmọ́lẹ̀.
Zelensky ti ṣe ileri lati koju iwa ajẹbanu ati pe oun yoo mu opin ba ogun to n waye laarin orileede naa ati awọn ọmọ ogun ọlọtẹ lariwa orileede ọhun ti Russia n gbe lẹyin wọn.
Ní gbogbo ọ̀nà ẹ ti fihàn pé ọwọ́ yín mọ́ ninu ọ̀ràn náà.
L'ọkọ̀ bàlúù tí o wọ̀ já pàù nínú afẹ́fẹ́ lókè lọ́hùn-ún
Lágbede méjì ojú ọ̀nà ni ìròyìn sọ pe ọ̀kan lára àwọn awakọ̀ to wa ọkọ̀ oun lọ forísọ ọkọ̀ àjàgbé kan ti wọ́n fi ń sisẹ́ ojú ọ̀nà.
Agbẹnusọ fun awọn ọlọpaa nipinlẹ naa, ASP Rahman Nansel sọ pe wọn ti gbe oku rẹ lọ si ileewosan, nitori iwadii ṣi n tẹsiwaju.
OLUWA yóo jọba títí lae,Sioni, Ọlọrun rẹ yóo jọba láti ìran dé ìran.
Buhari si fi igbimọ ẹlẹni mẹtala rọpo wọn, to si jẹ pe gomina ipinlẹ Yobe, Mai Mala Buni ni alaga wọn.
Akintọla tẹsiwaju ẹkọ rẹ nile iwe Baptist College lọdun 1925.
yin lọyẹ nipa ijamba to wa nibi pe eniyan n ba nnkan jẹ ati akoba to n se fun
Àyẹ ̀ wò lóri ìbágbépọ ̀ àti ìlera ti ọdún 2003 fihàn pé méjìlá nínú ọgọ ́ rún ọdọ ́ mọbìrin tí ọjọ ́ orí wọn wà láàrín 15-19 ni wọ ́ n ti dábẹ ́ fún tí bíi mẹ ́ tàdínlógojì nínú ọgọ ́ rún ni wọ ́ n gé idọ rẹ ̀ .
Aawọ to n waye lopo ipinlẹ ti ẹgbẹ APC ti'n ṣe ijọba lo mu ki Aarẹ Muhammadu Buhari kede ifilọlẹ igbimọ kan ti Asiwaju Bọla Tinubu ko sodi lati doola aawọ laarin awọn ọmọ ẹgbẹ oṣelu APC jakejado Naijiria.
Koda, ile ẹjọ yoo gbẹsẹ le dukia ti o ba fi sẹ oniduro fun ẹni to salọ.
Kurt Van de Wouwer ti ẹbi rẹ wo ẹyẹle New Kim dagba ni iyalẹnu nla ni iye ti wọn ra ẹyẹle naa jẹ fawọn.
Gomina ipinlẹ Ogun, Ibikunle Amosun, ati akẹẹgbẹ rẹ ni ipinlẹ Imo, Rochas Okorocha, naa ti sọ bẹ ẹ nitori pe tikẹẹti ẹgbẹ ko ja mọ awọn oludije wọn lọwọ lati dije fun ipo gomina.
 Àwọn ohun-èlò ìgbàlódé tí a mú wọ ́ nú eré jùjú ní gìtá , ọ ̀ pọ ̀ ìlú alásopọ ̀ tí ẹnìkanṣoṣo máa ń lù , bóńgò , kóńgà , ẹ ̀ rọ gbohùngbohùn , míkísà , búsítà , àkọ ́ díọ ̀ nù àti dùùrù àfẹnufọn , nígbà kan rí .
Gbogbo awọn to n lo irinṣẹ ilu lati fi tipatipa gba awọn to ba tako wọn wọlẹ.
AlakeAlakoso fun awon Ekun kọọkanIla- Iwo
Sebi wọ́n ni ti òògun ẹni ba dáni loju, a maa fi n gbári ni, ọmọ yoruba míràn tún rèé nínú ere idara abẹsẹ kù bi ojo.
” ó sì dá a lóhùn pé, “Èmi, iranṣẹ rẹ nìyí.
Ogbeni Bashir to je omo odun merinlelaadorin lo dite gbajoba lodun 1989.
 Ìdí èyí ni pé ìmọ ̀ ẹ ̀ rọ to ti ọ ̀ dọ ̀ àwọn òyìnbó aláwọ ̀ funfun wá ti gbalégboko .
Ọpọlọpọ ninu orin naa ni o bi èso oriṣiiriṣi lawujọ.
ÌLÀNÀ:Ó gbọdọ̀ dáhùn ìbéèrè yìí láti àkókò yìí títí di agogo méje alẹ́ òní 
    “Èmi ni Ìrìnkèrindò ti ń gbé Ilé Alárìnkiri Ìbátan ni èmi àti Àkàrà-Oògùn tí ó wá ní ijọ́ssí jẹ́, ẹgbẹ́ la si jọ jẹ́ pẹ̀lú.
Ju gbogbo rẹ lọ, maa ranti pe ọrọ aarun coronavirus yii kii ṣe tẹnikan.
Josh Posh sàlàyé pé kékeré ni òun ti máa ń gbé àbúrò òun sí ẹsẹ̀ láti kọrin fún-un.
O gba ọtẹlẹmuyẹ aladani kan lati ba se awari baba to bi lọmọ lai se aseyọri.
 Fun idi eyi, awon ti a ba gba ami-eye yii, ni a o maa seranti won, ki awon omo kekeke leyinwa ola o le maa wo awokese won.
Ile-ise ti o n ri si eto isuna naa so pe, orile-ede Egypt se akojo bilionu merin owo dollars fun eto tita eya-wo ile Euro, fun ipele olodun marun-un, mewaa ati ologbon odun, eyi ti o pari lale ojo-Isegun.
Dipo ọgọta ọjọ, o ni oun yoo dẹkun ipenija yi laarin ọgọrun ọdun ti oun ba de ori alefa.
Níbẹ̀ ni Debora, olùtọ́jú Rebeka kú sí, wọ́n sì sin ín sí abẹ́ igi oaku kan ní ìhà gúsù Bẹtẹli, Jakọbu bá sọ ibẹ̀ ní Aloni-bakuti.
Àkọlé àwòrán, Atúndì ibo bere ni láwọn ìjọba ìbílẹ̀ Kwara Oludije fẹgbẹ oselu APC ninu atundi ibo naa, Raheem Ọlawuyi ninu atẹjade kan ti amugbalẹgbẹ rẹ fisita fawọn akọroyin nilu Omu Aran ni PDP da awọn janduku sita lati maa dun mahuru mahuru mọ awọn oludibo keto idibo naa to waye ni.
” Nígbà tí ó gbọ́ bẹ́ẹ̀, orí rẹ̀ fò lọ fee, kò kọ́ gbà wọ́n gbọ́.
Fífọ́ ni wọ́n sì gbọdọ̀ fọ́ ìkòkò amọ̀ tí wọ́n bá fi sè é, ṣugbọn tí ó bá jẹ́ pé ìkòkò idẹ ni wọ́n fi sè é, wọ́n gbọdọ̀ fi omi fọ̀ ọ́, kí wọ́n sì ṣàn án nù dáradára.
Ẹ kọ orin sókè sí Ọlọrun, agbára wa;ẹ hó ìhó ayọ̀ sí Ọlọrun Jakọbu.
Kí ni òkè ńlá jámọ́ níwájú Serubabeli?
Nígbà tí Rakẹli rí i pé òun kò bímọ fún Jakọbu rárá, ó bẹ̀rẹ̀ sí jowú ẹ̀gbọ́n rẹ̀, ó wí fún Jakọbu pé, “Tí o kò bá fẹ́ kí n kú sí ọ lọ́rùn, fún mi lọ́mọ.
Ẹ wo àbájáde ìwádìí wa Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Working religious women: Ẹ̀lẹ́hàá kìí ṣe ọ̀lẹ- Aminat Adegoke Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Mose rán wọn láti lọ ṣe amí ilẹ̀ náà.
Mo tún wí pé gbogbo ẹni tí a bá kọ nílà di ajigbèsè; ó níláti pa gbogbo òfin mọ́.
Ọrọ yii ni oludije fun ipo aarẹ fẹgbẹ osẹlu PDP, Alhaji Atiku Abubakar sọ lẹyin ti ile ẹjọ to ga julọ da a lẹbi lori ẹjọ to pe aarẹ Muhammadu Buhari lori ibo aarẹ to lọ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Drug Trafficking: Obìnrin méjìlá ló wà lára àwn olóògùn olóró náà 26 Òkùdu 2020 Oríṣun àwòrán, NDLEA Ọwọ palaba awọn eeyan to le ni aadọjọ to n gbe oogun oloro ti segi bayii, ti wọn si ti wa ni ahamọ ajọ to n dena ilokulo oogun oloro.
Èyí mú inú mi dùn nítorí yín.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Eégun àti orò, bí wọ́n ṣe jọ bí Ẹ̀ṣà Egúngún nílẹ̀ Yorùba rèé Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Oluwo: Èmi ni adarí àti aláṣẹ lórí gbogbo òrìṣà ilẹ̀ Yoruba àti káàkiri àgbàyé16 Bélú 2020 Christian Obodo, agbábọ́ọ̀lù Super Eagles tẹ́lẹ̀ bọ́ lọ́wọ́ àwọn ajínigbé lẹ́ẹ̀kan síi16 Bélú 2020 Fídíò, Kenya Baby Stealer: Àwọn ajọ́mọgbé náà kò mọ̀ pé BBC ní wọ́n bá dòwò pọ̀17 Bélú 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Nigba ti o n da ẹjọ naa, Justice Haruna Tsammani ni o da ipẹjọ naa nu ti o ni ko lẹsẹ n lẹ rara.
owo dola RTGS fun idunna –dura.
Oríṣun àwòrán, @YemieFash Bi awon kan ṣe n pariwo pe wọn ri oku ọmọ naa nile ijọsin yii ni awọn miran ni pe irọ ni.
Saaju, Ikọ BBC Yoruba kan si agbegbe ibi ti ile alaja mẹta naa ti da wo nilu Ibadan.
ti iko Wolves yoo si bo si ipo keje pelu ami mọ́kànléláàdọ́ta(51point) ni itele n
O ni ọmọ ọdun mẹjọ ni oun wa bakan naa ti oun fi darapọ mọ ẹgbẹ osere Adẹrupọkọ nilu Ibadan lati maa se ere tiata, ki oun to tun lọ sọdọ oloogbe Isọla Ogunsọla Àjẹ́ àti Aṣẹ́wó ní ìyá Rainbow - Òjòpagogo Mama Rainbow pe 77 lónìí, àwọn òṣèré tíátà kọrin re kìí Kèǹgbè lílù ní Ilọrin rèé, orin ìgbéyàwó, àwàdà àti ẹ̀ẹ̀kẹ́ èébú Ṣé ẹ̀kú Danafojura gan ni otútù ń mú ni tàbí ẹni tó gbé Eégún yìí gan?
Ìpolongo ìbò Obaseki mú làásìgbò lọ́wọ́ láàfin Ọba Benin, èèyàn mẹ́wàá farapa O kere tan eniyan mẹwaa ni wọn wa ni ile iwosan lẹ̀yin ti ija bẹ silẹ, laarin awọn onijagidijagan to n ṣe atilẹyin fun gomina ipinlẹ Edo, Godwin Obaseki ati Pasitọ Osagie Ize-Iyamu to n dije labẹ ẹgbẹ oṣelu PDP.
Àwọn ọmọ Israẹli bá gbéra ní ọjọ́ kẹta, wọ́n sì bẹ̀rẹ̀ sí ka àwọn ìlú wọn.
1 200379 Orilẹede Canada 13130 35.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Ajọ WHO ni lai tii ri oogun coronavirus, abẹrẹ yoo ṣe iranwọ fun adinku itankalẹ aarun naa.
 lóòótọ ́ , ìlú kọ ̀ ọ ̀ kan ló ní òrìsà tirẹ ̀ tó se pàtàkì , fún àpẹẹrẹ , àwọn Òwu ló ni Òtòǹpòrò àti Ẹlúkú .
Ó ní, “Ẹ kó wọn wá fún mi níhìn-ín.
Cavani ti o wa nibe, eleyi ti o n dena re lati ri anfaani pupo.
 Akonimoogba iko ohun, Solskjaer naa fi idunnu re leyin ti Martial
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Gbajugbaja akọrin Angelique kidjo pe fun anfani f'awọn obinrin Angelique Kidjo, to jẹ asoju fun ajọ to n se amojuto idagbasoke awọn ọmọde labẹ ajọ isọkan agbaye sapejuwe awọn ọkunrin gẹgẹbii kiigbọ-kiigba ati pe nibi ti awọn ọkunrin ba ti fi aake kọri pe awọn ko ni gba, afi ki awọn obinrin naa yara gun le iyansẹlodi.
Ọmọ-ẹ̀yìn keji yìí jẹ́ ẹni tí Olórí Alufaa mọ̀.
Ijọba ti ni awọn ọmọ Naijiria yoo pada bẹrẹ si ni san owo oju popo ni gbogbo opopona ijọba apapọ.
Bi abala Ikini ti ṣe lọ Nkan kọkọ fẹ jọbi pe ko ṣẹnu re fun ẹgbẹ agbabọọlu Manchester City ninu ifẹsẹwọnṣẹ to n lọ lọwọ ninu idije Premiership.
Ibi a wí ni a dé yìí o!
2020: Ọdun 2020 yii ko nìí nira fún àwọn tó bá bẹ̀rù Olorun
Iná ṣẹ́yọ nílé ìtajà aya Ajimobi lẹ́yìn ọjọ́ mẹ́ta tó jáde opó Oríṣun àwòrán, oyoinsight.
Nigba to n sọrọ lori ẹrọ amohunmaworan, Aarẹ Keita tun kede pe, oun ti tu ijọba oun ati ile igbimọ aṣofin ka.
50) si ọgọrun un nairia le ni naira mókanlelogun aabọ(N121.
Mustapha sọ pe igbesẹ yii waye lati le fi idi aṣeyọri ti Naijiria ti n ṣe lori igbogbun ti aarun coronavirus mulẹ.
Ati pe oun n lọ fi ọkọ gbe awọn iyoku oun fun iṣẹ naa ni ọwọtẹ.
Ṣugbọn gẹgẹ bii oludari agba fajọ NACA, Dokita Sani Aliyu, to gbe abajade iwadii naa kalẹ niwaju Aarẹ Muhammadu Buhari ṣe sọ, iwadii ọhun ti jẹ ki okodoro iroyin nipa kokoro arun naa lorilẹede Naijiria fi oju han bayii.
Nisinsinyii n óo pada lọ bá aláṣẹ ìjọba Pasia jà, tí mo bá bá a jà tán, aláṣẹ ìjọba Giriki yóo wá.
lori ekunwo owo osu awon osise ni igbimo ipinle sẹsẹ wa jokoo lati jiroro lori
daju pe, won ni eri to daju lati gbe iroyin won lese, ki won si yago fun iwa ‘fifari
Lẹ́yìn táwọn agbébọn ja Aborode lólè tán ní wọ́n tún gbébọn fún un- Iléeṣẹ́ Ọlọ́pàá Lóòtọ́ ni mo yìnbọn níbi yánpọnyánrin tó wáyé ládúgbò mi-Seun Kuti Àṣeyọrí Anthony Joshua fi hàn pé owó tí à ń ná lórí eré ìdarayá kò lọ lásán - Dapo Abiodun Mi ò le tòṣì láéláé!
Wọn ni eniyan mẹta ni ilu Bauchi ati eniyan meji ni olu ilu Naijiria, Abuja.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Baby abandoned on dunmpsite: Mo ti bímọ mẹ́rin tẹ́lẹ̀ fún bàbá méjì nínú òṣí- Dupe Ogbomos Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Fídíò, Àṣìṣe ọlọ́pàá àti Adájọ́ sọ mí di ẹni tí wọ́n dájọ́ ikú fún, ọpẹ́lọpẹ́ Fayoṣe tí ko buwọ́lù ú5 Owewe 2020 Fídíò, Akomolede: Bolaji Faleke ni Olùkọ́ tó ń kọ́ wa ní àṣà oge ṣiṣe lórí BBC Yorùbá1 Owewe 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
ní ọjọ́ tí yóo bá ṣe ètò bí àwọn ọmọ rẹ̀ yóo ṣe pín ogún rẹ̀, kò gbọdọ̀ ṣe ojuṣaaju, kí ó pín ogún fún ọmọ ẹni tí ó fẹ́ràn gẹ́gẹ́ bí àkọ́bí, kí ó sì ṣe ọmọ ẹni tí kò fẹ́ràn bí ẹni pé kì í ṣe òun ni àkọ́bí rẹ̀.
Á máa jẹ wọ́n níyà ní gbangba,nítorí ìwà ibi wọn.
"O Fagunwa si wa laye ni, to si ba ọkunrin naa du afẹsọna rẹ ọhun, yoo dara ki onitọun tete fi ada le danu, ko to da isoro nla silẹ nitori ko si obinrin ti Orowọle ko lee fi gege rẹ sọ nipa ẹwa rẹ, ti onitọun yoo si maa ba lọ""."
Aare ni ijoba oun ko ni kuna lati maa mojuto igbaye -gbadun awon omo Ologun orile ede yii ati awon ara ilu.
Makinde sọ pe ninu ẹẹdẹgbẹta miliọnu naria ti ijọba Oyo ya sọtọ fawọn to fara kaasa ninu rogbodiyan ifẹhonuhan EndSARS ni ijọba yoo ti mu ṣe iranwọ fawọn ẹbi awọn ọlọpaa naa.
Ọlọrun mú kí ọba Kalidea gbógun tì wọ́n.
Yin ara rẹ fun aṣeyori ti o n se lọwọlọwọ ati bi o ṣe n dahun ibeere idanwo naa.
Àwọn ìpìlẹ ̀ núkléù pín sí irú méjì : àwọn purínì , a àti g , tí wọ ́ n jẹ ́ ọlọ ́ mọ ẹgbẹ ́ márùún àti mẹ ́ fà àwọn àdàpọ ̀ aláàyípoọ ̀ tọ ̀ ọ ̀ tọ ̀ , àti àwọn pirimidínì , ọlọ ́ mọ ẹgbẹ ́ mẹ ́ fà c àti t.
Àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ bẹ̀rẹ̀ sí bèèrè láàrin ara wọn pé, “Àbí ẹnìkan ti gbé oúnjẹ wá fún un ni?
Ẹsira bí Jeteri, Meredi, Eferi, ati Jaloni.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Working religious women: Ẹ̀lẹ́hàá kìí ṣe ọ̀lẹ- Aminat Adegoke Awọn iwe iwadii kan to tẹ BBC lọwọ naa fidi rẹ mulẹ pe Adajọ Robert W.
Oko baluu aare bale si papako ofurufu Nnamdi Azikiwe niluu Abuja, laago marun un abo irole ojo Isegun(Tuesday).
Agbẹnusọ fun aarẹ Buhari naa ti ni irọ ni pe awọn ọmọogun Naijiria ko ni oun ija ti wọn nilo lati koju ikọ Boko Haram.
Tó bá jẹ́ pé isẹ́ tìrẹ gba kí o maa bâ àwọn oníbàrá rẹ sọ̀rọ̀ lójú kojú ni tàbí èyí tó n mú ariwo dání, o léwu fún ọ Tó bá jẹ́ pe kí o lọ rajà lásán láwọn ilé ìtajà ni, níwọ̀ba àsìkò tí o n lò níbẹ̀, ewu rẹ̀ kéré jọjọ, ṣùgbọ́n fún àwọn òṣìṣẹ́ ilé ìtajà náà Ó ṣe pàtàkì ki a maa rántí pe kìí ṣe ṣínsín síni nìkan ni o yẹ ki a máa ṣọ́ra fún, e rántí pé àwọn kòkòrò yìí maa n bàlé àwọn irinsẹ́ tí à ń lò nítorí naa, o se pàtàkì láti máa fọ owọ́ rẹ déédéé kí o si ṣọ́ra láti máa fi owọ́ kan ojú.
Ṣé títí ayé ni ọ̀tá yóo máa gan orúkọ rẹ ni?
Joṣua mú gbogbo àwọn ọba wọnyi, ó sì gba gbogbo ilẹ̀ wọn lẹ́ẹ̀kan ṣoṣo, nítorí pé OLUWA Ọlọrun jà fún Israẹli.
Ta ló ti fi aṣọ rẹ̀ di omi?
Iroyin ayọ ti ko ba jẹ fun Liverpool ni ipari ifẹsẹwọnsẹ naa nigba ti Henderson gba goolu kan wọle ṣugbọn ayẹwo igbalode VAR dawọn lẹkun idunnu naa.
Ohun kan ti wọn tun ri ni wipe ọna kan wa to n yọ to si lọ taara latoju gọta lọ sinuu kanaari kan, ibi yii ni wọn ni o nira lati wọ.
Tí ó ń ṣẹgun ní ibikíbi tí ó bá fẹsẹ̀ tẹ̀?
Ọjọ mẹta pere lawọn oṣiṣẹ naa ṣi fi n ṣiṣẹ laarin ọsẹ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Festac Explosion: Àwọn àwòràn tó ṣeni ní àánú níbi ìbúgbàmù Eko 16 Ẹrẹ̀nà 2020 Ibugbamu to waye ni adugbo Festac nilu Eko lọjọ Aiku ba ọpọlọpọ dukia jẹ, to si mu ẹmi eeyan lọ, Oríṣun àwòrán, others Àkọlé àwòrán, Ọkọ yii jona, o tun run kọja aala nibi ibugbamu agbegbe Festac Oríṣun àwòrán, others Àkọlé àwòrán, Bi awọn dukia kan ṣe wo kanlẹ, ni wọn tun jona Oríṣun àwòrán, others Àkọlé àwòrán, Awọn ara adugbo naa tu jade, ti wọn si n duro ni mẹta-mẹẹrin lati jiroro lori iṣẹlẹ aburu naa Oríṣun àwòrán, others Àkọlé àwòrán, Ọkọ ayọkẹlẹ miran tun re e, ohun naa fara gba lara ibugbamu naa Oríṣun àwòrán, others Àkọlé àwòrán, Iṣẹlẹ naa ko yọ awọn ọkọ ti wọn paaki silẹ, ibugbamu naa lo fọ gbogbo gilaasi ọkọ yii Oríṣun àwòrán, others Àkọlé àwòrán, Ọpọlọpọ ile alarambara lo wo, jona lasiko ibugbamu naa Oríṣun àwòrán, others Àkọlé àwòrán, Ile alaja kan re e to wo lati oke de ipilẹ nibi ti agbara ibugbamu naa to Oríṣun àwòrán, others Àkọlé àwòrán, Ọkan tun re e lara awọn ọkọ ayọkẹlẹ ti ibugbamu fi ọwọ ba, a ko le sọ boya ina tabi ile to wo lo sọ ọkọ yii di rirun jege-jege Oríṣun àwòrán, others Àkọlé àwòrán, Ọkan lara awọn ile to wa ninu ọgba ileewe Bethlehem ti ibugbamu naa fọwọ ba niyii, awọn akẹkọọ to n gbe ninu ọgba ileewe naa farapa Oríṣun àwòrán, others Àkọlé àwòrán, Ọpọlọpọ ile lo wo kanlẹ patapata lẹyin iṣẹlẹ ibugbamu naa BBC News, Yorùbá Ìdí tí ẹ fi le è nígbàagbọ́ nínú ìròyìn BBC Ìlànà Lílò Nípa BBC Òfin Àṣírí Cookies Kàn sí.
Iná ni a óo fi dán iṣẹ́ olukuluku wò.
"Ileesẹ ilẹ Gẹẹsi to wa fun ọrọ okowo, amusagbara ati dida ileesẹ silẹ, sọ pe ""ọmọ orilẹ-ede miran ti wọn fi ẹsun kan ni ilẹ okeere si lanfaani lati da ileesẹ silẹ nilẹ Gẹẹsi, ni wọn igba ti ko ba ti i si iwe lati fi ofin gbe e."
Ma sẹ fi ọwọ rẹ nikan kan eku, boya o ti ku tabi wa laaye.
Nígbà tí Boasi bá a lòpọ̀, ó lóyún, ó bí ọmọkunrin kan.
Ó gbé e pamọ́ fún Atalaya, Atalaya kò sì rí i pa.
Ààrẹ Buhari buwọ́lu ẹ̀dínwó ìdánwò NECO àti JAMB Ojọgbọn Ishiaq ni bi awọn ile iwe giga kọọkan ṣe n sunkun ọ̀dá akẹkọọ ni awọn mii n ni akẹkọọ to n mu ile iwe awọn ti pọ ju, ṣe eyi wu mi ko wu ọ ni kii kuku jẹ ki ọmọ baba meji fẹ iyawo kan naa.
” Balaamu sì bá wọn lọ.
Ní ayé ìgbàànì àwọn obìnrin gbọ́ ju ti ayé ìwòyí lọ, nítorí wọn kì í fẹ́ ọkùnrin nítorí fáàrí ọkùnrin, wọn kì í fẹ́ ẹ nítorí ẹwà rẹ̀ nìkan, ṣùgbọ́n wọn a máa fẹ́ ẹ bí ó bá jẹ́ alágbára ọkùnrin, bí ó bá ní ìfẹ́ ìjìnlẹ̀ tí ko lè ṣá, bí ó bá sí mọ nǹkan títọ́ ní àti nǹkan yíyẹ ní yiyẹ.
Ẹbi àti ará ti bẹ̀rẹ̀ si palẹ̀mọ́ fún ọjọ́ ibi ọgọrun fún Olóògbé, Olóyè Hannah Ìdòwú Dideolú nigbati iròyin ikú rẹ jade pé iyá sùn ni ọjọ kọkàndinlógún, oṣú kẹsan ọdún Ẹgbàálemẹ̃dógún.
"O ni ""kọmisọna ọlọpaa ti ṣe ibẹwo sibẹ, nibi ti wọn ti ri awọn ọkọ pẹlu awọn ohun kọọkan to le wulo fun wa fun iroyin""."
Àwọn tí wọ́n wá láti Teli Mela, ati láti Teli Hariṣa, Kerubu, Adoni, ati Imeri, ṣugbọn tí wọn kò mọ ilé baba wọn tabi ibi tí wọ́n ti ṣẹ̀, tí kò sì sí ẹ̀rí tí ó dájú, bóyá ọmọ Israẹli ni wọ́n tabi wọn kì í ṣe ọmọ Israẹli nìwọ̀nyí: 
ni ojo kejila, osu kefa, dipo ojo kọ́kàndínlọ́gbọ̀n , osu karun un.
si iwe -ẹri ti olukọ agba  ile-iwe Ede
 ) ìparí ; òpin iró ni ìtan náà láti ìbèrè dé òpin .
Ṣaaju eto idibo naa ni iroyin gbe e pe awọn janduku oloṣelu yabo iwọde oṣelu ẹgbẹ APC ninu oṣu Kẹfa.
Obìnrin kò gbọdọ̀ jáde alẹ́ mọ́ ní Kano Game of Thrones tàbí Ìrèké Oníbùdó, èwo lẹ dìbò fún?
Olódodo ni Ọlọrun, ẹni tí kì í ṣe àṣìṣe,ẹ̀tọ́ ní í máa ń ṣe nígbà gbogbo.
Ayọ̀ ni òòrùn fi ń yọ
Àwọn ọmọ Lefi tí wọn ń ṣàkóso wọn ni: Jahati ati Ọbadaya, láti inú ìran Merari, ati Sakaraya ati Meṣulamu, láti inú ìran Kohati.
Ó wí pé, “Ẹ̀yin oluwa mi, bí inú yín bá dùn sí mi, ẹ jọ̀wọ́, ẹ má kọjá lọ bẹ́ẹ̀ láìdúró díẹ̀ lọ́dọ̀ èmi iranṣẹ yín!
Igbakeji alukoro fun ile iṣẹ ọlọpaa Naijiria, Ọgbẹni Adeniran Aremu to ba BBC Yoruba sọrọ ṣalaye pe ile iṣẹ ọlọpaa yoo gbe igbesẹ to ba yẹ lẹyin to pari iṣẹ iwadi lori fọnran ọhun.
Awọn kan tiẹ sọ pe ẹbun ayẹyẹ ọjọ ibi ni awọn agbabọọlu Chelsea fi ijaweolubori ninu ere bọọlu naa ṣe fun akọnimọọgba wọn Frank lampard to pe ọdun mejilelogoji lọjọ Abaméta.
lati yan awon adari ile igbimo asofin ti ikẹ́sán án yii,lọna ẹburu, ko ni lọ laijẹya .
Sihoni ọba àwọn Amori,nítorí pé ìfẹ́ rẹ̀ tí kì í yẹ̀ wà títí lae; 
Oríṣun àwòrán, EMIHD KANO EMIRATE Àkọlé àwòrán, Ọjọ́ Ajé, ọ̀sẹ̀ tó kọjá ní ìjọba ìpínlẹ̀ Kano yọ Sanusi Lamido ní orí oyè gẹ́gẹ́ bí Emir ìpínlẹ̀ Kano.
Man U f'aṣọ iyì ya mọ́ Man City lára pẹ̀lú àmì ayò 2-0 Ọpọ igba ni Sanusi ma n sọrọ tako ijọba Kano pe o fi ẹtẹ silẹ lati mojuto lapalapa leyi to bi iwaadi iwa ibajẹ kan ninu ijọba naa.
Ni kiakia ni awọn ara abule sare gbe ọmọ naa lọ sileewosan, nibiti awọn dokita ti tọju rẹ, ti wọn si fidirẹmulẹ pe ilera rẹ ṣi wa ni pipe.
Awọn ologun ṣipaya pe ati agbara ohun ija oloro ati eyi tii kii ṣe ti ohun ija lawọn papọ fi ri i pe wọn doola gbogbo awọn ọmọ ọkunrin naa lai farapa.
Mo sọ ọ daadaa pe, Joe Biden yoo bori, ti ẹgbẹ oṣelu Democrats ba fi yan-an ni aṣoju wọn.
Ọpọ okun ni awọn eeyan fi sofo lati dabaru eto yii dipo ki wọn wa ọna abayọ si Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
" Mo kọ̀ láti yí ọ̀rọ̀ mi padà lórí ètò ẹ̀kọ́ ọ̀fẹ́ - Gómìnà Dapo Abiọdun Ọjọgbọn Okedayo tó jẹ onímọ ìṣirò tí wọn jigbé ti di olóògbé -JAC Chairman Ọlọ́pàá Nàìjíríà àti Ẹgbẹ́ IMN n ṣé fakinfa lórí ikú àwọn olùwọ́de ìdárò Ashura Ṣaaju ni alaga ileeṣẹ ọkọ ofurufu Air Peace, Allen Onyema, ti yọnda lati ko awon ọmọ ilẹ yi to ba nifẹ lati kuro ni South Africa walẹ lofẹ.
twó different kinds of negation should be distinguishes .
Olorì Aláàfin, Memunat Adeyemi, fohùn ránṣẹ́ sí ikú bàbá yèyé Atẹ́gùn òjò rán ọ̀pọ̀ lóko àdánù nílùú Ìbàdàn, aráàlú gbarata Wo àwọn ǹkan tí a mọ̀ nípa àgbo tí orílẹ̀-èdè Madagascar ṣe fún Covid-19 Ẹ yé tako ìjọba lórí iléèjọ́sìn títì pa, ẹ jọ̀wọ́ ṣọ́ọ̀ṣì yín fún ìtọ́jú àwọn tó lárùn coronavirus- Tunde Bakare Ọkan lara awọn ọmọ ọkunrin Emir tẹlẹ fun ilu Kano naa, Ashraf to fi idi ibi naa mulẹ ṣalaye pe ọmọbinrin ni Mallam Sanusi Lamido Sanusi bi.
Ṣaaju asiko naa ni Ọjọgbọn Yusuf sọ pe awọn ti o fẹ maa ṣe owo araalu to wa labẹ eto adojutofo ilera baṣubaṣu ni wọn n ko ina wahala mọ oun ni idi, ṣugbọn awọn ọmọ igbimọ naa sọ pe o di igba ti abọ iwadi ba jade ki awọn eeyan to ri idi okodoro ọrọ naa.
Ẹ̀yin ọmọ mi, ọ̀rọ̀ burúkú ni àwọn eniyan OLUWA ń sọ káàkiri nípa yín.
Muazu wa fọkan awọn olugbe ipinlẹ Eko balẹ pe ileesẹ ọlọpa mu aabo ẹmi ati dukia wọn lọkunkundun, to si tun fewe ọmọ mọ awọn ọdaran leti lati tun ero wọn pa, bibẹẹkọ ikoko ko ni gba omi, ko gba ẹyin, ko tun gba ṣọṣọ.
Ìjọba ìpínlẹ̀ Zamfara ti gbé iléèwé mẹ́wàá tìpa lẹ́yìn tí wọ́n jí àwọn akẹ́kọ̀ọ́ iléèwé Kankara gbé Bo tilẹ jẹ pe ijọba ko sọ idi to fi pa aṣẹ naa, awọn kan sọ pe o ṣe e ṣe ko jẹ nitori bi awọn agbebọn ṣe ko awọn akẹkọọ nileewe Government Science Secondary School, Kankara nipinlẹ Katsina.
Mo ti rán Huramu sí ọ; ó mọṣẹ́, ó sì ní làákàyè.
Kí lo lè mú ọmọ ọdún mẹrin yìnbon pá ọmọ ọdún méjì?
O ni iṣẹ dẹrẹba lo n ṣe tẹlẹ ati pe aisan naa de si i lẹyin ti wọn ji ọkọ bọọsi to n wa lọ.
Ori ijinle lémi ati awọn akẹgbẹ mí wa, è gbà alaafia láàyè n'ilẹ wa.
 Àrùn tí í sìí ṣe Àbọ ́ yadé , gbogbo Ọya níí ṣe .
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Kíni Gómìnà Sanwo-Olu sọ nípa ìṣẹ̀lẹ̀ ìpànìyàn Lekki tó ń mú awuyewuye wà lórí ayélujára?
Bawo ni o ṣe ti bẹrẹ lati aarọ Ohun gbogbo ti ṣetan ni ilu Pọta ni ipinlẹ Rivers ni eyi ti ajọ INEC yoo ti kede esi idibo gomina to ku.
Lilo orisi ọna lati koju arun yi naa ni ipa to ko Bawọn olori ta n sọ yi ti se n se eto oselu wọn naa ni ipa to kọ gẹgẹ bi awọn onwoye ti se sọ.
nipa isoro to wa nipa ina mona-mona fun mi.
Nítorí náà, ẹ óo fún àwọn ará Moreṣeti Gati ní ẹ̀bùn ìdágbére; ilé Akisibu yóo sì jẹ́ ohun ìtànjẹ fún àwọn ọba Israẹli.
Kò sí ìyìn rere mìíràn ju pé àwọn kan wà tí wọn ń yọ yín lẹ́nu, tí wọ́n fẹ́ yí ìyìn rere Kristi pada.
Ẹniọla Badmus: Bí mo ṣe fẹ́ wà nìyìí
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ohun ti Seyi Makinde sọ lẹyin ipade awọn ẹgbẹ alatako Fatai Owoseni ṣàlàyé fun BBC pe ó di ìgbà tí Oun bá dé orí àga nibise kí oun to le gbe igbesẹ kankan lati dẹkùn iṣoro awọn Fulani ati awọn ajinigbe ọhun.
Nítorí náà ó di ọlọ́rọ̀ ati ọlọ́lá.
Minisita fun iroyin, ifitonileti ati aṣa, Lai Mohammed lo sọ ọrọ naa fun awọn akọroyin.
Boko Haram ti pa to eeyan ẹgbẹrun lọna ọgun ti wọn si ti ṣidi awọn aimọye eeyan kuro nile wọn laarin ọdun mẹjọ ti wọn ti n koju awọn ọmọogun orileede Naijiria.
mu idagbasoke bae to ohun amayederun ni ipinle naa.
Olori ọmọẹgbẹ oṣelu to pọ julọ nile aṣofin ipinlẹ Kogi, Abdullahi Bello-Balogun lo lewaju aba kan ti wọn gbe ka iwaju ile naa lori ẹsun pe igbakeji gomina ọhun gbiyanju ati da yẹyẹ gomina Yahaya Bello ati ijsba ipinlẹ naa sita gbangba ati pe gbangba bayii lo ṣe atilẹyin fun ẹgbẹ alatako lasiko idibo aarẹ to kọja.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Sotitobire: Ọkọ mi kò mọ̀ Jegede PDP rí, kódà kò fa ẹnikẹ́ni kalẹ̀ dípò Akeredolu- Bisola Ẹwẹ, ọkan lara awọn olugbe ilu Akure, Oluwatosin Oladapo sọ fun BBC Yoruba pe Gbogbo ibi ni awọn oluwọde naa ti di bayii, koda wọn n jo taya lagbegbe Old Garage, awọn eeyan ko si ri ọna kọja."
Àkọlé àwòrán, Ikọlu Boko Haram lọdun 2016 Gẹ́gẹ́ bí ìròyìn tó tẹ̀ wá lọ́wọ́ láti ọ̀dọ̀ AFP, alẹ́ Ọjọ́bọ̀ ni àwọn ọmọ ogun Boko Haram ya bo ibùdó àwọn ọmọ ogun Nàìjíríà ní abúlé Sari, ìpílẹ̀ Borno, tí wọ́n sì gba ìṣàkóso agbègbè nàá fún ìgbà díẹ̀.
” Oluwa Ọlọrun ló sọ bẹ́ẹ̀, ẹni tí ó ti wà, tí ń bẹ, tí ó sì tún ń bọ̀ wá, Olodumare.
Baba Suwe, ẹni to ranti iku aya rẹ, Mọladun Kẹnkẹlẹwu, to jẹ gbajumọ oṣere tiata miran nigba aye rẹ, lasiko ifọrọwerọ naa wa fajuro pe, oun mọ iku iyawo oun naa lara, ti oun si n ṣe aaro rẹ ni ojoojumọ.
Awon minisita ogbon , ti won yan ti je ki wahala dinku lorile ede naa, bo tile je pe eto idibo ti yoo waye lorile ede naa, ni yoo je ki won mo ibi ti orile ede naa yoo dojuko.
Ó lé ní ọdún mẹ́wàá tí wọ́n fi ṣe ẹjọ́ Rev King, kí, ilé ẹjọ́ gíga ìlú Eko tó dájọ ikú fún lẹ́yìn ti wọ́n ni ó jẹ̀bi ẹsùn ìpànìyàn.
Osinbanjo wi pe  “A o ti pari eto idibo .
O sọ wipe baalu na jabọ lẹgbẹ abule Argunovo.
Won fi esun kan an lodun 2013 , nigba ti o je aare.
Nṣe ni ilé náà dúró gbain-gbain bí igi osè ni.
Oríṣun àwòrán, others Ọ̀gá LASEPA náà ṣe àlàyé pé àjàkálẹ̀ ààrùn ti sọ ará ìlú di ọ̀kan tí ó sì gbà wọ́n ní ìyànjú àti máà ìròyìntó àwọn aláṣẹ létí.
Bí ó ti sọ báyìí tán, ó bojú wẹ̀yìn, ó bá rí Jesu tí ó dúró, ṣugbọn kò mọ̀ pé òun ni.
Àwọn akọni ọmọ ogun mẹta yìí bá fi tipátipá la àgọ́ àwọn ará Filistia kọjá, wọ́n pọn omi láti inú kànga náà, wọ́n sì gbé e wá fún Dafidi.
Leah Sharibu pé ọmọ ọdún 16 ní àhámọ́ Boko Haram Lasiko ti ijinigbe naa waye, ọpọ ọmọ Naijiria ni ẹnu ya pe pupọ ninu awọn akẹkọ mẹtadinlọgọta to raaye salọ ko le sọ ede Gẹẹsi botilẹjẹ wi pe ipele to kẹhin ni wọn wa nileewe girama.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Amugbalẹgbẹ fun Gomina Akeredolu, Ọmọwe Doyin Ọdẹbọwale koro oju si Amọṣa awọn mejeeji yii ni awọn onwoye n foju si lara gẹgẹ bii irin meji ti ikan ko ni fẹ tẹ fun ọkan bọrọ.
Fi orukọ silẹ ni oju opo igbanisiṣẹ ọlọpaa Eyi lo mu ki a ṣe akojọpọ idahun ranpẹ si awọn ibeere náà.
” Ó sì da ẹnu dé e ní ẹ̀rẹ̀kẹ́.
Àkọlé àwòrán, Igba kẹfa ree ti orilẹede Naijiria yoo maa kopa ninu idije ife ẹyẹ agbaye Ọga agba fun eto iroyin ni ileeṣẹ BBC lorilẹede Naijiria, Peter Okwoche fi idunnu rẹ han si awọn alaṣẹ ere bọọlu lagbaye fun ipade yii.
Ilẹ̀ Ìjẹ̀ṣà wà ní ìpínlẹ̀ Ọ̀yị́ ní Nàìjéríà.
Ilẹ̀ náà jẹ́ ìpín ti ẹ̀yà Bẹnjamini, gẹ́gẹ́ bí iye ìdílé wọn.
naa ni fafiti orile ede Naijiria Nsuka, Fafiti Uyo ati  Fafiti Usman Dan Fodio ti won gbe ipo kinni
Àwọn ará Bẹnjamini jáde sí wọn, àwọn ọmọ Israẹli bẹ̀rẹ̀ sí fi ọgbọ́n tàn wọ́n kúrò ní ìlú; àwọn ará Bẹnjamini tún bẹ̀rẹ̀ sí pa ninu àwọn ọmọ Israẹli bíi ti iṣaaju.
“Nisinsinyii, ẹ̀yin ọmọ mi, ẹ fetí sí mi, ayọ̀ ń bẹ fún àwọn tí ń rìn ní ọ̀nà mi.
Bákan náà ni ìyàwó gómìnà ìpínlẹ̀ Kwara Olufolake Abdulrahaman ti fẹ̀bun owó ránṣẹ́ sí obìnrin náà pẹ̀lú.
Gbogbo agbara ọrun to wa ninu ohun Waje lo lo sinu orin yii.
 Ó fún àwon alágbádá ni méjìlá nínú ipò méèdógbòn ti amojútó ìgbìmò isé ìjoba .
Naijiria, iyen ijoba apapo ati awon gomina ti gbe igbesẹ lati din wahala tabi
Kò ju ọjọ́ mejila lọ nisinsinyii tí mo lọ ṣọdún ní Jerusalẹmu.
ohun ti awon eniyan yoo maa jiroro lori eto idibo naa ni ọrọ ilẹ,ile,
Akeugbagold fi ikede naa sita lori ayelujara Facebook rẹ lowurọ oni pe ẹgbẹ igbo nla kan ni wọn ti ri awọn ọmọ naa lẹyin ọjọ kẹjọ ti wọn ti ji wọn gbe nile rẹ to wa ni adugbo Ọjọ nilu Ibadan.
Kòkú sẹ́ni tó lè bèère ibi tí ẹnikẹ́ni ti ṣàn wá ní ìlú Èkó.
Kínní ero àwọn Nàìjíríà lori ọrọ yii loju opo Twitter: Ó dàbí ẹni pé gbogbo èèbú yìí ló fà idí abajọ ti Ọkẹowo fí sọ pé òun ò ṣe mọ ooo Atiku Abubakar ní sáà kan ní òun tọrọ lọ́wọ́ ọmọ Nàìjíríà Oríṣun àwòrán, AFP Àkọlé àwòrán, Atiku Abubakar ní kò sí tipá nínú kí òun di àarẹ́ Nàíjirìa Igbákejì ààrẹ àná lórílẹ̀-èdè Nàìjíríà, Atiku Abubakar tí rọ awọn ọmọ orilẹ̀-èdè Nàìjíríà láti gbà òun láàyè, lati lo sáà kan soso gẹ́gẹ́ bíi ààrẹ orílẹ̀-èdè Nàìjíríà.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fọ́nrán ohùn, Gómìnà Zamfara kò lágbára ní tòtọ́ọ́ lórí ọ̀rọ̀ ààbò- amòfin O ni awọn gomina dabi aja ti ko leyin lẹnu ti ko si tun lee gbo debi pe yoo bu eeyan jẹ, nitori gbogbo awọn oṣiṣẹ eleto aabo pata wa labẹ aarẹ orilẹede Naijiria.
Oríṣun àwòrán, Instagram/iambangalee Àkọlé àwòrán, Oṣù tó kọjá ní Daniel pé ọmọ ọdún kàn A gbọ́ pé inú adágún omi ti won se lọ́jò sínú ilé wọn ni ọmọ náà já sí ti ó sí kù sí inú rẹ̀.
Joabu bá fọn fèrè ogun, gbogbo àwọn ọmọ ogun rẹ̀ sì fi ìlú náà sílẹ̀, wọ́n pada sí ilé.
Oríṣun àwòrán, Abdullahi Ganduje Gomina Ganduje ni nṣe ni ikọ amuṣẹya ti ijọba apapọ gbe kalẹ lori gbigbogun ti arun Coronavirus lorilẹ-ede Naijiria, the presidential task force on covid-19 ,dẹyẹsi ipinlẹ Kano lasiko ti arun naa burẹkẹ si bayii.
"Bẹẹ ọrọ ọja ti ọmọ ba ti wọ ti di òkùtà ni bayii""."
Nígbà tí Baaṣa gbọ́ ohun tí ń ṣẹlẹ̀, ó dáwọ́ odi Rama tí ó ń mọ dúró.
“obinrin ninu awon olote naa fe pa okunrin ati iyawo re, nibi ti won sun si nita ile won,bi o se ni ki oun tu ado oloro ni o ba gbemi ara rẹ’’.
Ilẹkun Baalu fo yọ nilu Abuja Davido ra baalu lẹyin ọkọ̀ ‘Assurance’ Oṣiṣẹbirin ọkọ ofurufu jabọ latinu baalu Nigba ti o n sọrọ níbi ayẹyẹ igboruko tuntun ọkọ òfurufú náà jáde níbi ayẹyẹ àfihàn ọkọ òfurufú to n wáyé ni Farnborough, Hadi sọ pé ìṣẹlẹ manigbagbe ni igboruko jade náà jẹ.
Ati pe a maa ra ounjẹ fun oun yoo si tun fun oun ni ẹẹdẹgbẹta naira pẹlu.
Àwọn olóṣèlú, àti àwọn Ọba n gbàbọ̀dè fún ìpínlẹ̀ Ekiti lórí ọ̀rọ̀ àwọn tó n fi ipá bánilòpọ̀- Kọmísọ́nnà ètò ìdájọ́ Ọmọbìnrin tó tayọ nínú ìdànwó WAEC ọdún 2019 pẹ̀lú A1 méje ti kú Ohun mẹ́wàá pàtàkì nípa Maradona àti ìbáṣepọ̀ rẹ̀ pẹ̀lú ẹlẹ́sẹ̀ ayò Diego Costa rèé Ganiyat tó fi irin gbígbóná àti àdá ya ara ọmọ àbúrò ọkọ rẹ ti dèrò àgọ́ ọlọ́pàá l' Ogun Wo dókítà ọmọ Nàìjíríà tí àgbáyé ń wárí fún nítorí abẹ́rẹ́ àjẹsára COVID-19 Ilé aṣòfin orílẹ̀-èdè UK n gbèrò fífí ìyà jẹ àwọn adarí Naijiria tó lọ́wọ́ nínú rògbòdìyàn ENDSARS Àwọn aṣòfin UK ṣetán láti fìyà jẹ àwọn adarí Naijiria tó lọ́wọ́ nínú rògbòdìyàn ENDSARS Ile aṣofin ilẹ Gẹẹsi, ti n jiroro lori iwe ipẹjọ kan ti wọn si n gbero lati fiya jẹ awọn alaṣẹ Naijiria to ba lọwọ ninu ipaniyan ENDSARS.
Ọjọ́ keji tí wọ́n pa Gedalaya tán, kí ẹnikẹ́ni tó gbọ́ nípa rẹ̀, 
Aare sapujwe iku adari ana naagege bi “ohun to bururu jai ati iwa
Ise ijoba yii ni lati gbe igbese akin lori awon abadofin to daabo boa won ewe Naijiria kaakiri agbaye pelu awon erongba rere ti a maa muse laipe.
Ṣugbọn o ti le ni miliọnu kan eeyan to ti forukọ silẹ fun eto ọhun lọdun yii.
''Nigba ti a gbọ ọrọ yii, a ko ara wa jọ lati lọ ba awọn alaṣẹ ileeṣẹ naa.
Dafidi bá ń lọ gbé orí òkè kan tí ó ṣe é farapamọ́ sí ní aṣálẹ̀ Sifi.
O ni itiju lo jẹ fun Naijiria, bi ijọba ṣe lọ sẹ ikojade ileeṣẹ tuntun naa ni orilẹede England.
Orúkọ àwọn aṣọ́nà tí wọ́n fẹ́ obinrin àjèjì nìwọ̀nyí:Ṣalumu, Telemu, ati Uri.
Nígbà tí Gaali rí wọn, ó sọ fún Sebulu pé, “Wò ó, àwọn eniyan kan ń sọ̀kalẹ̀ bọ̀ láti orí òkè.
Coronavirus: Ìjọba Osun ní àìlo ìbòmú aráàlú ló mú kí Corovirus peléke si
Ẹwẹ, igbimọ to n risi ọrọ iboji ni Kano sọ pe oun mọ nipa ipo ti awọn iboji ipinlẹ naa wa, oun si ti fi ọrọ naa to ijọba leti.
Bẹ̀rẹ̀ láti ọmọ oṣù kan lọ sókè.
Ni lọwọlọwọ yii, ẹgbẹrun mẹta ati ọta-le-lẹgbẹta-le-meji (3,662) awọn ibudo idibo kekere yii lo wa ni Ipinlẹ Eko lati fi ṣadinkun awọn ipenija to nii ṣe pẹlu eto ayẹwo orukọ awọn ondibo lọjọ idibo.
Lasiko to fi n ba awọn eeyan orilẹede Ghana sọrọ ni Aarẹ Akufo Addo ti sọ eyi di mimọ.
Ibrahim El-Zakzaky: 'Ó ṣeésẹ kí El-Zakzaky máa lọ òkè òkun fún ìtọ́jú mọ́'
Gbogbo ile iṣẹ to jẹ ti ijọba yoo fi aaye ida marun un iṣẹ silẹ fun awọn akanda.
Àwọn ọmọ rẹ ìbá pọ̀ bí iyanrìn,arọmọdọmọ rẹ ìbá pọ̀ bí erùpẹ̀ ilẹ̀ tí kò lóǹkà.
Mo sá kúrò nílé tí mo yá mílíọ̀nù 17 kọ́ ní Àkútè- Bayo Okeowo Ṣé ẹ̀kú Danafojura gan ni otútù ń mú ni tàbí ẹni tó gbé Eégún yìí gan?
Ni bi a ṣe n sọrọ yii, ileeṣẹ ọmọogun ko tii sọ ohunkohun lorii rẹ bẹẹ ni ko tii si ẹnikẹni to lee sọ ni pato ohun gan to le ṣokunfa eyii.
Ìgbì líle kan sì dé lójú omi òkun; ó pọ̀ tóbẹ́ẹ̀ tí ó jẹ́ pé omi fẹ́rẹ̀ bo ọkọ̀; ṣugbọn Jesu sùnlọ.
O ni eyi lodi si asa, ise ati ohun ajogunba wa lorilẹ-ede Naijiria, idi si ree ti iwa ipanle se n pọ si lorilẹ-ede yii.
Ìyá mi pèmí sí ìyàrá rẹ̀, ó ní, Ìyábọ̀, o di obìnrin lónǐ o.
 Àkótó rómáànù ni wón fi ń ko ó sílè .
Bẹ́ẹ̀ ni ó ṣe fún gbogbo àwọn iyawo àjèjì tí ó fẹ́, tí wọn ń sun turari, tí wọ́n sì ń rúbọ sí àwọn oriṣa wọn.
Ọkàn ọba Siria kò balẹ̀ nítorí ọ̀rọ̀ yìí, nítorí náà, ó pe gbogbo àwọn olórí ogun rẹ̀ jọ, ó sì bi wọ́n pé, “Ta ló ń tú àṣírí wa fún ọba Israẹli ninu yín?
O ni o yẹ ki awọn amofin ti ṣa ipa tiwọn lati inu oṣu kẹsan ọdun to kọja.
“ ‘O kò gbọdọ̀ pe orúkọ OLUWA Ọlọrun rẹ lásán; nítorí pé, èmi OLUWA yóo dá ẹnikẹ́ni tí ó bá pe orúkọ mi lásán lẹ́bi.
 roof jẹ ́ wọ ́ iṣẹ ́ ibi tó ṣe nírètí pé yíò fa ogun ẹlẹ ́ yàmẹ ̀ yà wá .
Ìpolongo fífòpin sí SARS ti lágbára si Ǹjẹ́ o rí ọlọ́pàá SARS tó ń hùwà àìtọ́ láwùjọ?
ba jawe olubori , ko ni si idagbasoke kankan lorile ede yii.
Nitori naa bi ẹ ba fẹ fi igo ọtí ẹlẹrindodo le ounjẹ ti e jẹ tan, e ranti pe suga pupọ lẹ fẹ dá sí inú yin ti eleyi sile ṣakoba fún ọpọlọ.
Àwọn Juu tí wọ́n wà ní àwọn agbègbè kó ara wọn jọ láti gba ara wọn sílẹ̀ lọ́wọ́ àwọn ọ̀tá wọn.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù ASUU strike: Ẹgbẹ́ olùkọ́ fásitì ń tẹ̀síwájú pẹ̀lú ìyanṣẹ́lódì 9 Ẹrẹ̀nà 2018 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 27 Bélú 2018 Àkọlé àwòrán, ko si si olukọ kankan ninu awọn yara ikẹkọ lati sisẹ ni ọgba fasiti Ibadan Ipade to waye laarin ijọba apapọ ati Ẹgbẹ Olukọ Fasiti, ASUU pari lai si ọna abayọ si iyansẹlodi ọlọsẹ mẹrin ti ẹgbẹ osisẹ ti gunle.
Oríṣun àwòrán, Toyin Abraham/instagram Ninu fidio iwọde ti Toyin fi si ori ayelujara Instagram rẹ ni owurọ ọjọ Satide, o fojuhan pe ipinẹ Oyo ni iwọde naa ti waye.
'A máa ń fí oògùn olóró 'ginger'ká tó ka ẹsẹ bíbélì ni ṣọ́ọ̀ṣì' Orin kíkọ kò dí ìwé mi lọ́wọ́ rárá -Hameen School Boy Opó ni mí, ṣùgbọ́n ọ̀pọ̀ ló ń rí opó bíi gbọkọgbọkọ Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí kan sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
ede Algeria tuntun  ti so pe aare Abdelaziz
 O yá ẹ pa òwe kan tí “ỌMỌ ” jẹ́ jáde nínú rẹ̀.
lorile ede Naijiria , Lai Mohammed ti ni aseyori ijoba apapo labe akoso aare
wọn kulẹ,maa sa ipa mi ”.
7 % inu won gbe loko ati 48.
Mo ranṣẹ pada sí i pé, “Ohun tí ó jọ bẹ́ẹ̀ kò ṣẹlẹ̀ rárá, o kàn sọ ohun tí o rò lọ́kàn ara rẹ ni.
Ni kekere nigba ti ko tii ni oye iru eeyan to lee da lọjọ iwaju lai wo ti ipo rẹ, o maa n bi Ọlọrun leere pe ki lo de to fi da oun ni arara.
àwọn olórí àwọn ẹ̀yà Israẹli, tí wọ́n jẹ́ olórí ní ìdílé wọn, tí wọ́n sì wà pẹlu Mose nígbà tí ó ka àwọn eniyan Israẹli, 
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Inu Iyalufa n dun si ọpọ aseyọri Ọmọlufa amọ ibanujẹ nla lo n dori agba rẹ kodo lori ọrọ Ọmọyẹ.
Pẹlu gbogbo ọ̀rọ̀ yìí, agbára-káká ni wọn kò fi jẹ́ kí àwọn eniyan bọ wọ́n.
Mi o jẹ ta ara mi lọpọ'' Olóyè Olu Falae kò tíì mú ẹjọ́ wá si àgọ́ ọlọ́pàá kankan- Agbenusọ ọlọ́pàá Rògbòdìyàn bẹ́ sílẹ̀ láàrin àwọn ọlọ́kadà àti àwọn òṣìṣẹ́ ọgbà ẹ̀wọ̀n ní Ibadan Omotara pàdánù isẹ́ olówó ńlá nítorí ó fi ọtí ẹlẹ́rìndòdò sódà lá ọmọ alágbe lójú Iṣu ata yáan yàan!
"Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ǹkan tí ẹ̀mí mímọ́ fi hàn mí kí n tó bẹ̀rẹ̀ orin ìfèdèfọ̀ rèé- Testimony Jaga ""Gbogbo oṣiṣẹ pata ni yoo ṣe ayẹwo naa bẹrẹ latori emi"", lohun ti Babandede sọ."
Ẹrú náà ṣe ọ̀wọ́n fún un.
Iwadii naa tun fihan pe arun naa tankalẹ lasiko otutu ni orilẹ-ede South Africa pupọ ju igba ti ooru ti n bẹrẹ lọ nibẹ.
Ó ku kí ó máa tẹ ilẹ̀ tútù.
Àwọn Farisi bá jáde wá, wọ́n ń bi í bí ó bá tọ́ kí ọkunrin kọ iyawo rẹ̀ sílẹ̀.
” Ṣugbọn Gedalaya kò gbà wọ́n gbọ́.
9bn lo wa fun igbaradi idibo 2019N2bn ni wọn yoo fi san owo ajẹmọnu lọjọ ibo N1.
Ṣaaju asiko yi Oluwo ti fariga pe awọn lọbalọba ko laṣẹ lati ni ki oun lọ rọọkun nile.
Onnoghen: PDP so ìpolongo ìbò rọ̀ ‘Ìjọba kò tẹ̀lẹ́ ìlànà òfin lòrí ọ̀rọ̀ Onnoghen’ Onnoghen ní 'mi ò jẹ̀bi olúwa mi' nílé ẹjọ́ CCT Ilé ìgbìmọ aṣofin ti dájọ tí wọn ó fọwọsi àbádofin ìsúna 2019 Ninu ọrọ rẹ, o fẹsun kan pe awọn kan ti pari ipade eyi ti wọn ti paṣẹ ki olori ile aṣofin ipinlẹ naa yọ adajọ agba nipo bi bẹ kọ wọn yoo yọ ohun gaan alara.
Ọọni, ẹni to koro oju si iwa ipaniyan to n gogo lasiko yii, iwa jiji maalu ko, atawọn iwa to nii se pẹlu iwa ọdaran lorilẹede yii, paapa nilẹ Yoruba, tun salaye pe, awọn janduku apanijaye ẹda yii lo ni afojusun lati ta abawọn si orukọ rere orilẹede Naijiria.
Àwọn ọmọ Sebuluni ní ìdílé-ìdílé nìwọ̀nyí: ìdílé Seredi, ìdílé Eloni ati ìdílé Jaleeli.
Minisita fun ilaniloye ati asa lorile ede Naijiria, Lai Mohammed lo soro yii ni Istanbul, lorile ede Turkey nibi ayeye asa ati igbafe ti ajo agbaye(UNWTO/UNESCO World Conference on Tourism and Culture) se,eleyii lo je iketa iru re ti ajo agbaye yoo se .
Mo láyọ̀ ninu ayé tí àwọn ẹ̀dá alààyè ń gbé, inú mi sì ń dùn sí àwọn ọmọ eniyan.
Aráyé ẹ gbà mí, nǹkan ń ṣe mí, èyí tó ju àìsàn lọ - Kanran Ààrùn coronavirus tó ràn mí jẹ́ kí n mọ̀ pé àlààfo díẹ̀ ló wà láàrin ikú àti ìyè - Lola Alao Àwọn òṣèré Nollywood tí wọn ò sí lóri amóhùmáwòrán mọ́ Èèmọ̀!
"Ṣe aṣoju Iran si Naijiria naa ti di onsunmọmi?
Atẹjade kan, ti ẹgbẹ naa fi ṣọwọ si BBC Yoruba, tun fi kun pe oloogbe naa silẹ bora lẹyin aisan ranpẹ.
Edward Onaja naa gba iwe ẹri o pegede lati gba ipo igbakeji gomina ipinlẹ Kogi Adájọ́ àgbà ní Kogi búra fún igbákejì gómìnà tuntun.
Àwọn Ẹ̀gbá darapọ mọ ogun ìjàyè, tí wọn sì gbé sẹ́yìn Kurunmi láti tako Ibadan, kò máa bàa di aṣáájú miran fún ẹ̀yà Yoruba.
Gbajugbaja agbohunsafẹfẹ ni baba rẹ, Olurọpo.
Ọrọ yi ni balogun ẹgbẹ agbabọọlu ọkunrin Naijiria, John Mikel Obi sọ l'Ọjọbọ.
Usaya ọba fún gbogbo àwọn ọmọ ogun rẹ̀ ní apata, ọ̀kọ̀, àṣíborí, ẹ̀wù ihamọra, ọfà, ati òkúta fún kànnàkànnà wọn.
Òwò mẹ́wàá tí yóò pàdánù àìsí ìpéjọpọ̀ ńlá RCCG lọ́dún yìí Wo iye àwọn ilé ìjọsin ìlú Eko ti wọ ko ni ṣí ìlẹ̀kùn ilé ìjọisin wọ́n lẹ́yìn ti ìjọba ti ni wọ́n le máa jọ́sìn Wo àwọn àìsàn ti ìwọ́ ọmọ tuntun le wòsàn Ipa tí Fathia Balogun kó nínú bí mo ṣe dèèyàn lágbo òṣèré fíìmù Yorùba rèé - Baba Ijesha Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Oronpoto Animation: Akin Alabi ní kò dára bí eré aláwòrán fáwọn ọmọdé ṣe jẹ́ aláwọ̀ funfun Kọmisọnna naa tun fi kun ọrọ rẹ pe ijọba gomina Seyi Makinde ti fọwọ si adinku ida marindinlọgọ́rin ninu ọgọ̀run un fun awọn osisẹ to kuna lati san owo ori tẹ́lẹ̀ nitori wahala Covid 19 ti ko jẹ́ ki agbaye ri isẹ́ se yii.
Ìyíde ọ̀hún fa awuyewuye lórí ẹ̀rọ-alátagbà níbi tí àwọn ènìyàn gbé oríyìn fún ìyíde kiri náà nígbà tí àwọn ènìyàn kan fẹ́ mọ ìdí tí ilé iṣẹ́ oníròyìn kò ṣe rò nípa rẹ̀.
Èèyàn mẹ́jọ jónà ráúráú nínú ìjàmbá ọkọ̀ akérò tó ṣẹlẹ̀ ní mọ́rosẹ̀ Eko sí Ibadan Ọ̀wọ́ngógó búrẹ́dì gbòde kàn lẹ́yìn tí àwọn oníbúrẹ́dì da iṣẹ́ sílẹ̀ Ẹwọ́n ọdún méjìlá ni wọ́n fún àwọn Ṣója mẹ́rin tó pa ìyá àti ọmọ méjì ní Cameroon Àbájáde ìwádìí ẹlikọ́pítà to já ni Opebi nílùú Eko laipẹ yii ti jáde Wo boo ṣe lee kopa.
Bukunmi, ẹni ti inu rẹ dun dẹyin lori oore naa, ti ko si le e pa a mọra, lo bọ soju opo Instagram rẹ lati kede nipa ifa to wọle tọ ọ fun araye.
Kì í ṣe gbogbo yín ni ẹ ní ẹ̀bùn kí á ṣe ìwòsàn.
Wò ó, wá kí n rán ọ sí wọn.
Ẹ kò gbọdọ̀ máa ṣe òfófó káàkiri láàrin àwọn eniyan yín, bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò gbọdọ̀ kọ̀ láti jẹ́rìí aládùúgbò yín, bí ẹ̀rí yín bá lè gba ẹ̀mí rẹ̀ là.
Ọ̀nà tí àṣà ìbálé lálẹ́ ìgbeyàwó ń gbà dọdẹ àwọn obìnrin òde òní BBC ba ọmọde kan ti o sọrọ lori iriri rẹ bi oun ṣe n tọrọ owo.
Wọ́n ń bá àwọn arakunrin wọn gbé, àdúgbò wọn kọjú sí ara wọn ní Jerusalẹmu.
Ní ìlú tí ìgbín àti Ìjàpá ń gbé, ìṣẹ̀lẹ̀ kan ṣẹlẹ̀ ní ọjọ́ kan.
Moabu, ṣebí ò ń fi Israẹli ṣe yẹ̀yẹ́?
Serubabeli, O óo kọ́ ilé náà parí, bí o bá sì ti ń parí rẹ̀ ni àwọn eniyan yóo máa kígbe pé, “Áà!
Mohammed Adoke: EFCC dájọ́ wíwà láhàmọ́ ọjọ́ mẹ́rìnlá fún Mínísítà ètò ìdájọ tẹ́lẹ̀
Ewé rẹ̀ lẹ́wà, ó so jìnwìnnì, oúnjẹ wà lórí rẹ̀ fún gbogbo eniyan, abẹ́ rẹ̀ ni àwọn ẹranko ń gbé, orí àwọn ẹ̀ka rẹ̀ sì ni àwọn ẹyẹ ń sùn.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Asamoah Gyan lè má kópa nínú ìdíje AFCON mọ lẹyìn tí Tunisia júwe ilé fún Ghana 9 Agẹmo 2019 Oríṣun àwòrán, @SaddickAdams Àkọlé àwòrán, Gyan ni ko daju pe oun yoo kopa ninu idije Afcon mi mọ Niṣe ni ibanuje dori agba kodo lẹyin ifidirẹmi Ghana lọwọ Tunisia fawọn agbabọọlu ati alatilẹyin ikọ Black Stars.
ìdámẹ́wàá òṣùnwọ̀n efa fún ọ̀dọ́ aguntan kọ̀ọ̀kan; 
Ẹnìkan ninu wọn kò dá ọ lẹ́bi?
Ọpọlọpọ lo ti ki Seyi Makinde fun iwa akin to hu nipa mimu ileri rẹ ṣe.
Ṣugbọn Adonija ti fi ara rẹ̀ jọba, bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé kabiyesi kò mọ nǹkankan nípa rẹ̀.
 Bello so pe, “iye ojo ti o ye ki won se pasi-paaro oja ni awon enu-ibode  tabi ni awon ori omi wa lorile-ede Naijiria koja iye ojo ti awon iko osise oju omi n lo ni awon orile-ede yoku”.
Aare Buhari yoo pada  wa si ilu Abuja ki ile oni to su .
’ ” Josẹfu bá tún lépa wọn lọ sí Dotani, ó sì bá wọn níbẹ̀.
Lẹyin ipade ti wọn ṣe pẹlu awọn Ọga Agba Fasiti, Ọga Agba ile ẹ̀kọ́ gbogbo ni ṣe (polytechnic), ati awọn Ọga Agba awọn ile ẹ̀kọ́ gíga to kù.
Lẹ́nu òní sí àná ni a gbọ́ pé iná jó àwọn agbègbè kan ní ìlú Èkó.
Ṣugbọn o ni awọn eeyan miran to sọ pe, ki awọn eeyan foju aanu wo Aanu nitori o ṣeeṣe ki o ma jẹ oju lasan lo mu kuro ni aafin.
Bẹ́ẹ̀ náà ni Hileni, ati Debiri, 
Lizzy Anjọnrin fẹ̀si fáwọn agbọ́yì-sọ̀yí lórí ìgbéyàwó rẹ̀, Madam Sajẹ dasójú ilé iṣẹ́, àti àwọn ǹkan míràn tó ṣẹlẹ̀ lágbo tíátà lọ́sẹ̀ yìí Jatau sọ pe, ajọ to n risi idagbasoke ẹkun ariwa Naijiria, (North East Development Commission) ati Ajọ to n risi akoso lilọ-bibọ ero lati agbegbe kan si omiran, (International Organisation for Migration) lo fi iranwọ naa ṣọwọ si awọn ikọ Boko Haram to ronupiwada naa.
Nítòótọ́,ìwọ ni Ọlọrun tí ó ń fi ara pamọ́,Ọlọrun Israẹli, Olùgbàlà.
O slaye pe, “arabinrin naa daku sugbon o si wa laaye, nigba ti o de ile-iwosan naa lale ojo-Ru, amo o gbemi ni kete leyin naa.
Ìlú yìí ni yóo máa gbé títí tí àwọn ìgbìmọ̀ yóo fi ṣe ìdájọ́ rẹ̀, yóo máa gbé ibẹ̀ títí tí ẹni tí ó jẹ́ olórí alufaa ní àkókò náà yóo fi kú, lẹ́yìn náà ẹni tí ó ṣèèṣì pa eniyan yìí lè pada lọ sí ilé rẹ̀ ati sí ìlú rẹ̀ níbi tí ó ti sá wá.
N óo gbìn yín bí igi, n kò sì ní fà yín tu, nítorí mo ti yí ọkàn mi pada nípa ibi tí mo ṣe sí yín.
Serena Williams jẹ ọkan lara awọn odu elere idaraya Lawn Tennis ti itan agbaye ko lee gbagbe laye lẹyin awọn bẹbẹ loriṣiriṣi to ti gbe ṣe lere idaraya naa.
''Baba go slow'' Aarẹ Buhari sọ ninu ọrọ rẹ tun fesi pada fun awọn to n pe ni ''baba slow'' pe, yoo rii gbangba ni saa keji oun, boya lootọ tabi irọ ni oun lọra ninu iṣejọba oun.
Nígbà tí Banaba aposteli ati Paulu aposteli gbọ́, wọ́n fa ẹ̀wù wọn ya, wọ́n bá pa kuuru mọ́ àwọn èrò, wọ́n ń kígbe pé, 
Iwa to hu lo mu ki awọn eeyan mọrọ rẹ bẹnu loju opo ayelujara.
Kanye West ti bẹ̀rẹ̀ ìpolongo àti díje dupò aàrẹ ilẹ̀ Amẹrika Ètò ìdìbò abẹ́lé sípò gómìnà APC ni ipinlẹ Ondo ti bẹ̀rẹ̀ ní pẹrẹwu Adelé Ọ̀gá Àgbà àjọ NDDC dákú rangbọndan lásìkò tí ìwádìí n lọ lórí ẹ̀sùn ìnákúnàá Wo bí Dorathy Bachor ṣe di gbajúmọ̀ lóríi Instagram lẹ́yìn tí ètò àgbéléwò BBNaija bẹ̀rẹ̀ Ayẹwo rẹ ti wọn ṣe lara eeyan ẹgbẹrun kan o le mẹtadinlọgọrin fi han pe abẹrẹ naa gbe awọn ajagun inu ara dide toloyinbo n pe ni 'antibodies' ati eroja ara mii fun ijagun (white blood cell) eyi to lee doju ija kọ arun Coronavirus.
Secondus, to ba awọn akọroyin sọrọ lẹyin ipade naa fidi rẹ mul pe 'lootọ lawọn oloye ẹgbẹ PDP lọ si Abẹokuta lati ni ijiroro pẹlu ọbasanjọ lori eto idibo ọdun 2019.
 Oríṣun àwòrán, @OfficialPDPNig PDP fikun pe ni bayii tawọn ti ri pe Buhari ati ẹgbẹ APC ko ni awijare kankan ti wọn fẹ sọ nile ẹjọ, awọn n rọ wọn lati yọ awọn ọmọ Naijiria nipa fifi tinutinu gbe ọpa asẹ le Atiku lọwọ, eyi tawọn ọmọ Naijiria gbe fun latipasẹ ibo wọn Ìgbìmọ̀ ìpolongo Buhari kọ̀wé sí IGP, DSS pé PDP gbà ọ̀nà ẹ̀bùrú wọ ojú òpó INEC Igbimọ ipolongo ibo aarẹ orileede Naijiria Muhammadu Buhari ti kesi ileeṣẹ ọlọpaa ati ile iṣẹ ọtẹlẹmuye,DSS lati ṣe iwadi ẹgbẹ oṣelu PDP lori ẹsun pe wọn fi ọna ẹburu wọ oju opo Inec."
“Bi elomiran ba so fun o pe, afojusun re tobi pupo, iwo sa so pe, o se, ki o si tepa mose re lojuna ati mu wa si imuse.
 Àṣeyọrí àwo orin ' sóyòyò ' túmọ ̀ pé ọ ̀ dọ ́ ( lọ ́ pọ ̀ ìgbà onígbàgbọ ́ tàbí abọgibọ ̀ pẹ ̀ ) òde òní ti yorùbá ti wá ń ṣàfihán ìfẹ ́ wọn nínú orin àpàlà .
Ìyìn ni fún OLUWA, Ọlọrun ìgbàlà wa,tí ń bá wa gbé ẹrù wa lojoojumọ.
O ya, ẹni ba laya ko wa wọọ.
Lati igba ti Liz ti wa nile iwe girama lo ti nifẹ si kikopa ninu awọn ere ori itage to si ti n ba wọn kopa nigba naa.
    Lẹ́yìn èyí, a bẹ̀rẹ̀ sii wa àwọn lébìrà kiri, àwọn ará ọ̀run gan-an, Adéforítì ni òun rò pé afi àwọn ará ọ̀run gan-an ni yóò lè bá òun ṣiṣẹ́ náà.
Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí NÍ YÀJÓYÀJÓ Covid 19: Ìjọba ìpínlẹ̀ Ogun pàṣẹ kí wọ́n ṣí gbogbo ilé ìjọsìn, ilé ìgbafẹ́ padà lẹ́kúnrẹ́rẹ́ Fídíò, Wole Soyinka sọ ìdí tó fi ni òun a fi màálù Fulani ṣe súyà fáwọn èèyàn abúlé23 Owewe 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Ṣugbọn nigba ti yoo fi di ọjọ kẹtala, kokoro aifojuri yi di ajakalẹ ti awọn orilẹede bi Thailand, Japan, South Korea ati Amẹrika naa si bẹrẹ si ni kede awọn to kọkọ nii lọdọ wọn.
Ajọ NCDC naa fi lede loju opo ikansiraẹni Twitter wọn ni alẹ Ọjọ Aje.
Agbẹjọro fun awọn ọlọkada naa, Abdullahi Yakubu sọ wi pe, ijọba ipinlẹ Eko gbọdọ san owo gba ma binu fun wọn, nitori wọn ti wọn mọle lọna aitọ, lai se pe wọn jẹ ọdaran.
Adedamọla Kasumu gbegba oroke pẹlu esi ibo ẹgbẹrun mẹrindinlogun-le-ẹẹdẹgbẹrun
Wéré, ó dọ̀bálẹ̀ ó bu erùpẹ̀ lé orí, ó ké kábíyèsí ó sì yẹ́ ẹ sí bí ọba.
Rògbòdìyàn tó bẹ́ sílẹ̀ lórí afárá London jọ ìgbésùnmọ̀mí Wòólì Alfred kú lọ́dún 1964, ó tún padà wà sí ìlú Agelu f'ọ́jọ́ mẹ́rìnlá!
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù NHIS: Aarẹ Buhari da Usman Yusuf pada s'ipo gẹgẹ bi akowe eto ilera 7 Èrèlè 2018 Oríṣun àwòrán, nhis.
14trn) ni ijọba n na lati san ele lori awọn gbese naa lọwọ-lọwọ.
Lójiji ni erin náà bẹ́rẹ̀ sí ni sìwàwù tó si ń lé ara ìlú lásìkò yìí tẹ ọmọkunrin kekere kan, Fa'izu Chiroma Musa pa, tó sì kú lójú ẹsẹ̀, síbẹ̀ àwọn ènìyàn náà kò dẹ̀yìn lẹ́yìn erin náà.
Ṣugbọn Oyetola la Adeleke mọ lẹ lẹyin ti afikun idibo waye lawọn ibudo idibo kan ti wọn wọgile ibo.
A tún lè ṣe àpẹrẹ pé wọn mbẹ Adájọ́ ki ó ṣe àánú fún ọ̀daràn lai jẹ ki ó ronú ohun burúkú ti ó ṣe, ki ó lé yi padà.
Nítorí OLUWA ń bínú sí gbogbo orílẹ̀-èdè,inú rẹ̀ sì ń ru sí àwọn eniyan ibẹ̀.
Ní ọjọ́ kẹta, ọwọ́ ara wọn ni wọ́n fi da àwọn ohun èèlò inú ọkọ̀ náà sinu òkun.
Àwọn ọmọ Israẹli bẹ̀rẹ̀ sí káàánú àwọn ẹ̀yà Bẹnjamini arakunrin wọn, wọ́n ní, “Ẹ̀yà Israẹli dín kan lónìí.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Alaafin: Olori Aanu Adeyemi ṣàlàyé ìdí tó ṣe gẹ́ Oba Lamidi Adeyemi ti ìlú Oyo Ẹnikan lára àwọn to n tọ pinpin iṣẹlẹ naa, Amofin Hamza Attahiru, lati ajọ ajafẹtọ ọmọniyan Human Rights Network, sọ pe ẹnikan lára àwọn to doola ẹmi Jubril jẹri pe bi oun ṣe maa n ri ọmọ naa ti wọn so o pọ mọ àwọn ewurẹ jẹ iyalẹnu.
Idi ti wọn fi n gba aawẹ yii ni lati bu ẹwa kun aye igbagbọ wọn ati ihuwa bi Ọlọrun, eleyii ti yoo mu wọn sun mọ Ọlọrun ati gbigbe igbe aye to wuyi, ti o si bu ọla fun Ọlọrun.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù 2019 elections; INEC gba ìwé ẹ̀rí lọ́wọ́ olùdíje APC, PDP lẹ́yìn ìdìbò àpapọ̀ 2019 20 Èbibi 2019 Oríṣun àwòrán, Inec Àkọlé àwòrán, INEC ni aṣẹ ile ẹjọ lo fa igbesẹ ti awọn gbe naa Ajọ eleto idibo orilẹede Naijiria, INEC ti gba iwe ẹri idiboyansipo pada lọwọ awọn oloṣelu marundinlọgbọn kan ti wọn bori lasiko idibo apapọ to waye lọdun 2019.
Ṣebí ẹ mọ̀ pé gbogbo àwọn tí ń sáré ìje ni ó ń sáré, ṣugbọn ẹnìkan ṣoṣo níí gba ẹ̀bùn.
Ṣugbọn igba ti igbesẹ keji yii naa ko pa baba wọn, wọn ti akisa aṣọ bọọ lẹnu ti wọn si fi ọwọ bo imu ati ẹnu rẹ ki o to wa ku.
Ikọ̀ ìwádìí BBC ṣí àwọn tó ń jí ìkókó gbé sí gbangba Yàtọ̀ sí ìpè gómìnà sí àwọn ọmọ ológun láti ràn òun lọ́wọ́.
Ajọ to n ri si imọtoto ayika atawọn iwa ọdaran mii nipinlẹ Eko (Lagos State Environment Sanitation and Special Offenses Taskforce) ti mu awọn ọdọmọkunrin mẹtalelọgọfa ti wọn n bọ wa siluu Eko lati ipinlẹ Jigawa pẹlu alupupu wọn ti ọpọ mọ si okada lọjọ Ẹti.
Àkókò márùún ninu ayé Winnie Mandela 'Aarẹ Zuma gbọdọ lọ' Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Kefariamoni, Ofini, ati Geba; gbogbo ìlú ati ìletò wọn jẹ́ mejila.
Àgbálùmọ̀, ohun mẹ́fà tó ń ṣe lára tí o kò mọ̀ Àwọn àwòrán ẹ̀yìn ìtàgé níbi ìpàdé ìfọ̀rọ̀wérọ̀ BBC Yorùbá l'Eko Day 19: Wo ohun àràmàndà tí àwọn olósèlú máa ń ṣe lásìkò ìbò #BBCNigeria2019 Sowore: olùdíje Ààrẹ tó fẹ gbà Nàìjíríà padà fún àwọn ọdọ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ademọla Ogunbanjo: A nílò bàbá ìsàlẹ̀ nínú òsèlú Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ìwẹ̀ wíwẹ́ má n dín agbára ìrẹ̀wẹ̀sì ọkàn kù Ileeṣẹ ọlọpa sọ pe awọn ba àdá meji, ọfà, to fi mọ ọpọlọpọ àsìá ati awọn nkan mi i to jẹ ami idanimọ asiko ti ikọ Nazi n dari, ati ti National Action ti wọn fi ofin de, ni yaara ibusun Thomas ati Patatas.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Àpapọ̀ owó táwọn amúgbálẹ́gbẹ̀ẹ́ aṣòfin ń gbà rèé ‘A ti yọ ọwọ́ lọ́rọ̀ Ààrẹ Buhari fún sáà kejì’ Ìyàtọ̀ wà nínú ìlépa àwọn òṣèré tíátà ayé àtijọ́ àti ìsisìnyí-Papalolo Tẹ̀gbọ́n-tàbúrò gé orí ọmọ aládùúgbò torí ₦200,000 owó ìkómọ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Igun OPC: OPC ti sọnù, àwọn èèyàn ń sá fún wa láì fẹ́ darapọ̀ mọ́ wa Sugbọn EFCC, ninu atẹkade kan loju opo ikansiraẹni Twitter rẹ ṣalaye pe, ahesọ ọrọ ati irọ to jina sootọ ni ẹsun naa.
Ogbeni  Bobboi Kaigama, aare egbe TUC
Ó dára láti lọ sí ilé àwọn tí ń ṣọ̀fọ̀ju ati lọ sí ibi àsè lọ,nítorí pé àwọn alààyè gbọdọ̀ máa rán ara wọn létí péikú ni òpin gbogbo eniyan.
Ni bayii, iye awọn to ti lugbadi arun Coronavirus ni Naijiria ti da 26,484, ti eniyan 603 si ti ku.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, ‘Tunde Kelani yan mi jẹ lori fiimu ‘Toluwanilẹ’ Lopin ọsẹ ni Iwe Iroyin kan sọ pé Baba Wande fẹsun kan Tunde Kelani wi pe owo to tọ si oun, kọ ni wọn fun oun lori fillmu naa ti o si jẹ wipe oun lo kọ itan naa.
Abiodun wa ro awon eniyan naa lati dibo fun aare Buhari ati ojogbon  Osinbajo ati fun gbogbo awon to n dije ninu
 pópóọlá tí ó jẹ ́ ọlọ ́ pàá ni ó pàṣẹ pé kí wọn dá ọwọ ́ ìjà dúró tí wọ ́ n sì ṣe bẹ ́ ẹ ̀ .
wòn bí Ìṣọ ̀ lá ní ìgboro ìlú Ìbàdàn ní ọdún 1939 , ó sì lọ sí ilé ìwé alákọ ̀ ọ ́ -bẹ ̀ ̀ rẹ ̀ lábọ ̀ dé methodist school àti ilé ìwé gíga ti wesley college .
" Àwọn àjẹsára fún àwọn ẹranko kan wà fún àwọn oríṣi "" leptospira "" kan , èyí tó lè dín ewu àtànká àrùn náà sára àwọn ènìyàn kù ."
Ọba tí ó wà nínú ihò náà sì tún fèsí, ó ní, Iṣẹ́ kan péré lo kù fún ọ láti ṣe.
    A dúró, a simi díẹ̀, olúkúlùklù ròyìn ohun tí òun bá pàdé ni ibi tí òun ti ń sá kiri, a dúpẹ́ lọ́wọ́ iwin inú Fìlàsayépọ̀ kí ó tó tún di pé o padà wọ inú fìlà ọ̀rẹ́ wa lọ.
Oríṣun àwòrán, AFP Àkọlé àwòrán, Aarẹ Trump ninu ọrọ rẹ fidiẹ mulẹ pe awọn Taliban ti ṣetan lati bawọn sọrọ bayii.
Ipinlẹ Plateau lo tun lewaju iye awọn to laarun naa lọjọru pẹlu eeyan mọkandinlọgọta (59), ipinlẹ Rivers eeyan mẹtadinlọgbọn (27), ipinlẹ Abia eeyan mejilelogun (22), ipinlẹ Eko eeyan ogun (20), ipinlẹ Ọyọ, (18), ipinlẹ Enugu eeyan mẹtadinlogun (17), ipinlẹ Kaduna eeyan mọkanla (11), olu ilu ilẹẹwa Abuja eeyan mọkanla (11), ipinlẹ Ogun eeyan mẹwaa (10), ipinlẹ Ebonyi eeyan mẹrin (4) Ipinlẹ Ekiti mẹrin (4), ipinlẹ Ọṣun eeyan mẹrin (4), Delta eeyan mẹta (3), ipinlẹ Edo eeyan mẹta (3), ipinlẹ Akwa Ibom eeyan meji (2), ipinlẹ Bauchi eeyan kan ṣoṣo (1).
Biya ko kuna ri ninu eto idibo aarẹ Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ọjọ keje, oṣu Kẹwaa ni wọn ṣe eto idibo to gbe Biya wọle fun igba keje Aarẹ Biya kọkọ fi ẹyin Amadou Ahidjo janlẹ l'ọdun 1982.
Gbogbo ọ̀rọ̀ tí ó ba yín sọ láti ààrin iná, ní ọjọ́ tí ẹ péjọ sí ẹsẹ̀ òkè náà ni ó wà lára àwọn tabili náà.
 Totti so eyi di mimo lasiko to dipo oludari mu,“Mi o ni anfaani lati so ero okan mi bi o se le wu ko kere mo, yala bi iko Roma se n gba awon akonimoogba tabi ra awon agbaboolu sinu iko yii.
Lootọ ni pe ilu Ibadan ti Toyin gbe dagba ṣe iranwọ fun lati gbọ ijinlẹ ede Yoruba amọ ọmọ bibi ilu Auchi nipinlẹ Edo nii ṣe.
Awọn iroyin ti ẹ lee nifẹẹ si: Àìsan ọkàn pa olùdásílẹ̀ sogúndogójì MMM 'Iléeṣẹ́ ológun kò mọ̀ nípa ìkọlù Dapchi' Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí 2 sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
Abenugan  ile igbimo asoju niluu Abuja, ogbeni Femi
Kì í ṣe ẹni tí ó yin ara rẹ̀ ni ó yege, bíkòṣe ẹni tí Oluwa bá yìn.
O fẹsun kan pe kọmisana naa ran awọn kan wa a gbe oun lati ilu Okenne lọ si Lokoja, nibẹ lo si ti lu oun ati aburo rẹ to jẹ ọrẹ oun ni ilukulu.
Ó mú kí Israẹli dẹ́ṣẹ̀ lọpọlọpọ gẹ́gẹ́ bíi Jeroboamu, tí ó ti jọba ṣáájú kò sì ronupiwada.
Ṣebí ìwọ, Ọlọrun wa, ni o lé gbogbo àwọn tí wọ́n ń gbé ilẹ̀ yìí tẹ́lẹ̀ kúrò fún àwa ọmọ Israẹli, eniyan rẹ, tí o sì fi ilẹ̀ náà fún arọmọdọmọ Abrahamu, ọ̀rẹ́ rẹ, títí lae?
O óo gbọ́ ohun tí wọ́n ń sọ, lẹ́yìn náà, o óo ní agbára láti lè gbógun ti àgọ́ náà.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Masazo Nonaka láti ilẹ̀ Japan ni ẹni tuntun tó dàgbà jù lọ lágbàyé Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Masazo Nonaka láti ilẹ̀ Japan ni ẹni tuntun tó dàgbà jù lọ lágbàyé 11 Ìgbé 2018 Ọmọ ilẹ Japan, Masazo Nonaka ni ẹni to dagbaju lagbaye Ati ri ẹni tuntun to dagba ju lọ lagbaye, lẹni ọdun 112 Masazo Nonaka lati Ashoro ni Japan ni wọn bi lọdun 1905 O fẹran lati ma lọ si ibi isaraloge ati ki o ma jẹ akara oyinbo ẹlẹrindodo Orilẹede Japan ni awon arugbo to to 68,000 ti ọjọ ori wọn ju ọgorun lọ.
 “Lara awon ti o gba aami ẹyẹ
Isreal Adesanya fàgbàhàn Kelvin Gastelum ni Atlanta Ọlọ́pàá gbé àwọn tó yìnbọn lu olólùfẹ́ ní Ajegunle Sega link mẹnuba awọn igbesẹ to yẹ ki ijọba gbe lati di àlàfo to wa laarin awọn agbofinro ati ara ìlú.
 Ìdí tí mo fi sọ̀rọ̀ bẹẹ ni pé, a kì í ṣiṣẹ́ pọ pẹ̀lú àwọn osere tíátà lédè Yorùbá, ẹnìkan ṣoṣo tó kanka nínú wọn, èyí un Funke Akindele, nikan la ń bá ṣiṣẹ.
Àwọn olórí ìdílé àwọn ọmọ Gileadi, ọmọ Makiri ati ẹ̀yà Manase ọmọ Josẹfu, wá sọ́dọ̀ Mose ati àwọn olórí ẹ̀yà Israẹli, 
O salaye pe, “inu wa dun, bi ile-ise naa se n sise won, pelu iyanju ati se adinku laala tabi wahala lorun ijoba, amo sa, won ko gbodo ni awon ara-ilu lara.
Okunnu ni wọn le sọ pe ki oun ṣe ọmuti tabi ki oun gba obinrin lọ sile itura, eleyi to tako wiwọ eyin Mecca.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Mauricio Pochettino: Ṣé Pochettino lè gba ife ẹ̀yẹ UEFA Champions League tí PSG ń wá fún wọn?
Randy tọrọ garafara lọwọ awọn ololufẹ Majek Fashek ti wọn fẹ ki gbajugbaja olorin to lọ wọ kaa ilẹ lọ niluu abinibi rẹ ni Naijiria.
Èèyàn méjì kú, méjìdínlógóje míì ṣẹ̀ṣẹ̀ kó COVID-19 lọ́jọ́ Àìkú Ni ọsẹ to kọja ni ijọba ipinlẹ Eko kede ni tirẹ pe awọn akẹkọọ ileewe giga gbogbo ni ipinlẹ naa yoo wọle pada sẹnu eto ẹkọ ni ọjọ kẹrinla oṣu kẹsan an nigba ti awọn ileewe alakọbẹrẹ ati girama yoo tẹlee ni ọjọ kọkanlelogun, oṣu kẹsan kan naa.
D) lori imọ kikun ninu itan lọdun 1966 ni Fasiti Ibadan.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Nigba ti awọn mẹta tó kù si wa lati ipinlẹ Sokoto, Nassarawa ati Kan Kana fi kun ọrọ rẹ pe, arinrinajo to le ni ẹgbẹrun mẹwaa lati Naijiria lo ti gba iwosan ni awọn ileewosan orilẹ-ede Naijiria to wa ni Makkah ati Madinah.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Awon oludibo Mahmood salaye pe, igbese yii yoo fun awọn ara ilu laanfani lati tọpinpin awọn to fẹ soju wọn saaju ọjọ idibo.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Buhari yoo lọ sibi ayẹyẹ ọdun kọkanlelọgọta ni Ghana 4 Ẹrẹ̀nà 2018 Oríṣun àwòrán, SIMON MAINA Àkọlé àwòrán, Papa isere Igbamominira orilẹede Ghana ni ayẹyẹ ọun o ti waye Aarẹ Buhari yoo gbera sọ lọjọ aje lati lọ si orilẹede Ghana fun ayẹyẹ igbominira ọdun kọkanlelọgọta ti yoo waye ni ọjọ isẹgun to n bọ.
ife ilẹ Afrika, Afcon 2019 to n lọ lọwọ ni orilẹede Egypt.
Lawal ni idanwo aṣekagba ti wọn ṣẹṣẹ ṣetan yii ni awọn fi wo boya yoo ṣeese ki awọn akẹkọọ pada si ileewe lai lugbadi arun Coronavirus.
nítorí pé Joabu ati àwọn ọmọ ogun rẹ̀ wà ní ilẹ̀ Edomu fún oṣù mẹfa, títí tí ó fi pa gbogbo àwọn ọkunrin tí wọ́n wà ní ilẹ̀ Edomu run.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Àgbà ni Obasanjo, oun tó ń sọ yé e, ìjọba ni kó tají - Wale oke Mo wọgile gbogbo iṣẹ́ akanṣe tijọba to kọja lọ ti gbe sita tẹlẹ- Yahaya ipinlẹ Gombe Gomina Inuwa Yahaya ti ẹgbẹ oṣelu APC lo wọle bayii ni ipinlẹ Gombe.
Ẹnu n kun Rabiu Musa Kwankwanso pupọ lori boya yoo du ipo Aarẹ lọdun 2019 .
 fìlà rẹ ̀ sí bọ ́ sílẹ ̀ nínú mọ ́ tò tí ó wọ ̀ .
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Akomolede ati Aṣa lori BBC:Wo ìrúfẹ́ ìgbeyàwó méje tó wà nílẹ̀ Yorùbá àti ojúṣe Alárinà Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Ǹjẹ́ o rí ọlọ́pàá SARS tó ń hùwà àìtọ́ láwùjọ?
Kashimaawo Abiola lo n jawe olubori ninu idibo to waye ni Naijiria nigba naa lọhun lọdun 1993.
Owo ọkọ wa laaarin ọọdunrun pọun si ẹẹdẹgbẹrun o din aadọta pọun.
 alè ṣàwarí àrùn yíi lẹ ́ hìn tí àwọn àmì rẹ ̀ bá farahàn .
Oluwo Ìwo ṣ'àlàye lori oyé oba oni lawàni
Sri Devi to jẹ gbajugbaja oṣere Bollywood to ṣe fiimu to le lọọdunrun naa lọ lọmọ ọdun mẹrinlelaadọta.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Yinka Ajia: ìbẹ̀rù Ọlọrun ni mo fẹ́ fi tukọ̀ Kwara ti mo ba wọlé Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Yinka Ajia: ìbẹ̀rù Ọlọrun ni mo fẹ́ fi tukọ̀ Kwara ti mo ba wọlé 2 Ẹrẹ̀nà 2019 Ohun to n ṣelẹ ni Kwara lo n ba mi ninujẹ ni mo fi jade dupo gomina lasiko yii.
Asẹyin ni: ''A ti fun awọn ajinigbe ni epe lati ma ṣe rojuraye ni agbegbe wa mọ, nitori o ti pọju ni agbegbe Ibarapa ati Oke-Ogun.
Nítorí náà, OLUWA Ọlọrun ní: “Ègbé ni fún ìlú apànìyàn, ìkòkò tí inú rẹ̀ dípẹtà, tí ìdọ̀tí rẹ̀ kò ṣí kúrò ninu rẹ̀!
Ile-ẹjọ giga ni Igbosẹrẹ ni ipinlẹ Eko ti ran Sunday Anani to pa Oloye Ope Badamosi lọ si ẹwọn gbere.
Olaju ati iṣe ode toni lo mu ki ọpọ ma mọ ipa pataki ti Iyalọja n ko lawujọ.
EndSARS protest in Nigeria: Mr Macaroni, Falz, Wizkid, Tiwa Savage àtàwọn míì ṣe ìwọde
Emefiele fi kun pe, nibamu pẹllu ofin, awọn onibara banki Skye tẹlẹ ti di onibara banki Polaris bayii lẹyẹ o sọka.
Àwọn Òwe Mìíràn tí Solomoni Pa.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ẹsa ninu aworan Afrika: 9-15, ose kẹta ọdun 2018 17 Ẹrẹ̀nà 2018 Ẹsa ninu awọn aworan to rẹwa ju l'Afrika ati aworan awọn ara Afrika nibomiran lagbaye ninu ọse yii.
 Ìdàpapọ ̀ ṣiṣẹ ́ yìí kìí ṣẹlẹ ̀ ní ìgbésẹ ̀ kan ṣùgbọn ó maa ń kọ ́ kọ ́ jásí dihydropentacene tí wọ ́ n maa ń yọ hydrogen kúrò nínú rẹ ̀ ní ìgbésẹ ̀ kejì pẹ ̀ lú copper gẹ ́ gẹ ́ bí amúlọsíwájú bá ìdàpapọ ̀ ṣiṣẹ ́ .
Ninu oro tire, alaga apejopo ohun, Ooni Ile-ife, Oba
Ẹwẹ, gbajugbaja agbabọọlu tẹniisi ọmọ ilẹ Gẹẹsi, Andy Murray ni ẹkọ nla ni awọn agbabọọlu tẹniisi to lugbadi coronavirus jẹ fawọn yoku.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Aja Pitbulls Aja Bully Kutta tabi Mastiff: Irufẹ aja yii jẹ aja to le lati kọ lẹkọ, ti o si ma n wuwa ipa, nitori naa wọn ma n lo lọpọ igba fun aja ti wọn ma fi n ja ni.
“Ṣugbọn lẹ́yìn tí a bá ti jí mi dìde, n óo ṣiwaju yín lọ sí Galili.
O ni awọn eeyan maa nwa lati origun mẹrẹẹrin agbaye ni ojoojumọ lati bu omi Ikọgọsi fun iwosan.
O ni ko si abajade pe ijọba South Africa fiya jẹ awọn oniṣẹ ibi yii ri lati ẹyin wa ni eyi to gbọdọ dopin lasiko yii.
Nitorinaa, ka iroyin nipa alakalẹ ibi ti oun lo lori arun Coronavirus.
Awọn to fi ẹsun kan wọn sọ pe ihuwasi wọn tako ẹsin Islam.
Ìlédè Agígírì kọjá sí láti lọ múlẹ̀ tuntun tí ó sì kọ̀lé sí Ilédè náà ní ibi tí Aàfin Ọba Ijẹ̀bú-jẹ̀ṣà wà títí di òní yìí.
Isẹlẹ naa to waye lopopona Adebimpe lo sọ ọpọ ile ati ibudo itaja ti wọn fi paanu ati pako kọ di eeru.
obinrin tí ayé kórìíra tí ó wá rí ọkọ fẹ́,ati iranṣẹbinrin tí ó gba ọkọ mọ́ ọ̀gá rẹ̀ lọ́wọ́.
” Mo sọ fún ara mi pé, asán ni eléyìí pẹlu.
Ìjọba Kano fi páńpẹ́ òfin mú Ọba àwọn Oṣó lórí ẹ̀sùn jìbìtì Aisha Buhari, ohun mẹ́fà tò fi yàtọ̀ sí àwọn aya ààrẹ tó ti jẹ kọjá!
Ohun díẹ̀ nípa Thomas John Ọmọ ipinlẹ Cross River ni Thomas M.
Bíbọ̀ ni kí ẹ bọ̀ ọ́, kí ẹ jẹ ẹ́ ní ibi tí OLUWA Ọlọrun yín bá yàn pé kí ẹ ti máa jọ́sìn, nígbà tí ó bá sì di òwúrọ̀ ẹ óo pada lọ sinu àgọ́ yín.
Wọn kò ranti agbára rẹ̀,bẹ́ẹ̀ ni wọn kò ranti ọjọ́ tí ó rà wọ́n pada lọ́wọ́ ọ̀tá;
Ikọ Senegal yoo koju ẹni to ba jawe olubori ninu ẹgbẹ agbabọọlu Japan tabi South Korea ni ipele kọmẹsẹọyọ ẹlẹni mẹjọ.
igba akoko(French Player of the Year).
Ọọ̀ni: Àwọn ọ̀daràn Fulani fẹ́ ba orúkọ rere Nàíjíríà jẹ́ ni
Onisegun oyinbo Zsuzsanna Jakab lati ajo WHO ni: “Gbogbo awon eniyan tuntun ti won kagbako igbona nile Euroopu ni ati ri pe won ko gba abere ajesara nigba to ye ki won gbaa ni eyi to fihan pe ifaseyin ti wa ninu odiwon awon ti won n gba abere ajesara bi o se ye ki won gba a”.
Adajọ Dimgba lo kede bẹẹ lori ẹjọ kan to waye laarin olokoowo kan, Rupert Irikefe ati banki apapọ ilẹ wa, CBN pẹlu banki olokoowo Zenith ati agbẹjọro agba ni Naijiria.
Gomina fi ọ̀rọ́ yìí léde lorí atẹjísẹ́ twitter rẹ̀ lasàn òní pe inú oun dùn fún igbésẹ ọ̀gbẹ́ni Femi Adeoye pẹlu bi o ṣe ṣe pẹlu ọmọ bíbí rẹ̀ nítori pé o ni igboya, o si nifẹ ìpińll Ekiti lọ́kan.
Gbajabiamila sọ èyí lásìkò tó lọ ṣe ẹkú ọrọ èèyàn si àwọn ẹbi olóògbé lágbègbè Kwata ní Madalla-Suleja.
Òṣèré tíátà míì ń ṣàìsàn láti bí ọdún mẹ́ta, ọkan rèé tó ń bẹ̀bẹ̀ f'ówó Onírù tuntun Oba Abdulwasiu Gbolahan Lawal gba ọ̀pá àṣẹ Ẹ má san ìdámeẹ́wàá tàbí owó ọrẹ lásìkò àrùn coronavirus - Pásítọ̀ Adewale Giwa ₦80m la fi rán ogún ìyàwó asòfin lọ Dubai - Obasa Eeyan 3959 lo ti ri iwosan gba, nigba ti awọn 354 ti dero ọrun nitori arun ọhun.
awon omo orile ede Naijiria lati satunse si awon asise ati aseyege ti orile ede
Ṣugbọn, ẹ̀yin arakunrin mi,ẹlẹ́tàn ni yín, bíi odò àgbàrátí ó yára kún,tí ó sì tún yára gbẹ,
ọrun ma kanju ni awọn agba Yoruba maa n wi!
Ọdún Ọlọ́jọ́ dùn nílé Ifẹ̀, ó lárinrin Obafẹmi Hamzat Kadiri ni oun kò díje mọ sipo gomina ipinlẹ Eko Dokita Kadri Ọbafemi Hamza, to kede igbesẹ rẹ yii fawọn Akọroyin ni pe oun ko ni dije mọ lati dupo gomina ipinlẹ Eko.
Obí rẹ̀ gbìyànjú láti fí èdè àti àṣà kọ́ ọ tó si dí ohun àmúyangan láàrin àwọn òyìnbó lókè òkún.
A kò mọ ẹni tí ó dá owó wa pada sinu àpò wa.
Kìí ṣe Gbogbo ọmọ Yoruba ni Oodua bí Kìí ṣe gbogbo ọmọ Yoruba ni Oodua bí o, ṣùgbọ́n òun lo kọ́kọ́ mu Ade wa, ìjọba tuntun ni Oodua mu wa, ti o si ti yan awon ti wọ́n yoo jọ se ìjọba, ìgba náà ni ọba bẹ̀rẹ̀ si ni yan, Balogun , ọtun Oba, àti oníruuru ìjọye to n ba ọba jiroro.
Nítorí náà, ẹ̀yin àyànfẹ́ mi, nígbà tí ẹ̀ ń retí nǹkan wọnyi, ẹ máa ní ìtara láti wà láì lábùkù ati láì lábàwọ́n, kí ẹ wà ní alaafia pẹlu Ọlọrun.
Awon adari ajo ECOWAS ti ro orile-ede Naijiria ati Senegal lati ri daju pe eto idibo orile-ede won kookan to n bo lona lodun 2019 zwaye nirowo-rose, bee si ni lai fi igba kan bo kan ninu bi o se le wu ko mo.
Ti OLUWA ni ogun yìí, yóo sì gbé mi borí rẹ̀.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Oyo 2021 Appropriation Bill: Makinde takú mọ́ àwọn aṣòfin lọ̀wọ̀ pé òun kò fẹ́ ìṣúná gbèsè 19 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Oríṣun àwòrán, Facebook/Seyi Makinde Yoruba ni ohun ti yoo ba dara nigbẹyin, o lee kọkọ wọ nibẹrẹ.
Bakan naa ni wọn tun ni ẹtọ lati sọ pe awọn fẹ ẹ ya kuro lara Naijiria.
Ohun tí ojú wa ń rí níbi ètò ìdìbò abẹ́lé APC ìpínlẹ̀ Ondo nílùú Akure rèé Èèyàn 789 gbèkuru jẹ lọ́wọ́ ẹbọra nítorí COVID-19 ní Nàìjíríà Ó yẹ kí ìjọba gbé ilé ìwé tì pa títí di ọdún 2021- ASUU Ǹjẹ o yẹ kí èèyàn máa sùn lẹ́nu iṣẹ́?
Ọrọ ipari rẹ ninu lẹta naa ni wi pe o ti tan fun Tinubu ninu oṣelu orilẹede Naijiria, oun ti o ku ni ki o lọ rọkun nile, ki o si ma a sinmi.
Ṣugbọn ilẹ̀ tí ẹ̀ ń lọ gbà yìí jẹ́ ilẹ̀ tí ó kún fún òkè ati àfonífojì.
Ni oṣu kejila ọdun 2018 ni Saraki ṣeleri ati san owo oṣu awọn oṣiṣẹ bẹrẹ pẹlu ijọba ibilẹ kọọkan kaakiri ẹkun idibo apapọ mẹtẹẹta to wa ni ipinlẹ Kwara.
Iwuri yii si jẹ mu aabo ba ọpọlọpọ awọn akọroyin ti wọn ko ku iru iku to pa iya mi.
ki o to di pe aare Buhari yan an gege bi oluranlowo aare lori ọrọ to jẹ mọ ilẹ okeere  Nigba ti alaga igbimo asofin
Kìnìún mẹ́rìnlá bọ́ sígboro Ilé ẹjọ́ ní kí NBC yí àṣẹ padà lórí DAAR Communications Wo àwọn agbábọ̀ọ́lù obìnrin ti wọ́n jọ máa figagbága ni France 2019 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Osun Kidnap: Òṣìṣẹ́ àjọ FRSC méjì bọ́ sọ́wọ́ àwọn ajínigbé l'Ọsun
Lẹ́hìn èyí èmi àti ọ̀rẹ́ mi lọ sí ibi tébùrù a sì jẹun.
Àwọn jàndùkú kọlu Ọba Eko àti Gomina ìpínlẹ̀ Edo lọ́nà ilé Oshiomole Kí ni àwọn ẹ̀ṣẹ̀ àti ẹ̀sùn tó ń da Oshiomole láàmú?
“Mò ń sọ fun yín, ẹ̀yin ọ̀rẹ́ mi, pé kí ẹ má bẹ̀rù àwọn tí wọ́n lè pa ara, tí kò tún sí ohun tí wọ́n le ṣe mọ́ lẹ́yìn rẹ̀!
Àkọlé àwòrán, Awọn afurasi ti ọlọpaa mu fun didana sun agọ ọlọpaa niluu Isẹyin Lara awọn afurasi naa ni; Taoreed Hamsat ẹni ọdun mẹrindinlọgbọn, Tajudeen Ibrahim ẹni ogoji ọdun, Moshood Fatai ẹni ọdun mọkandinlogoji, Musibau Abubakar ẹni ọdun mọkanlelogun.
Alhaji Lai Mohammed ni 'mi o lero wipe mo fẹ sọ ohunkohun lori ọrọ ti CAN sọ.
"Osai Ojigho sọ wipe ""iru ipa ti wọn lo fi se idẹrubalẹ yii buru jai, o nseku pani ko si ba ofin mu."
Boya owo oṣu naa de ọdọ awọn oṣiṣẹ naa tun jẹ ọrọ miiran to yẹ lati gbe yẹwo.
    Báyìí ni ìtan apá tí wọn n bù ṣe lọ
Ọba Ìjẹ̀bú-Jẹ̀ṣà ni ẹ̀gbọ́n tí Ọwá sì jẹ́ àbúrò.
Ọjọ̀ Isinmi ni asekagba Ife Ẹyẹ Agbaye ti Russia 2018 naa yoo waye nigba ti ikọ ilẹ Faransẹ yoo ma a waako pẹlu ikọ orilẹede Croatia.
Mo fẹ́ lọ fi ojú ara mi rí i, kí n fi mọ̀, bóyá gbogbo bí mo ti ń gbọ́ nípa wọn ni wọ́n ń ṣe nítòótọ́.
Ní ilẹ̀ Isakari, ati ti Aṣeri, àwọn ọmọ Manase ni wọ́n ni ìlú Beti Ṣeani ati àwọn ìletò tí wọ́n wà ní agbègbè rẹ̀, Ibileamu ati àwọn ìletò tí wọ́n wà ní agbègbè rẹ̀, ati Dori, Endori, Taanaki ati Megido ati gbogbo àwọn ìletò tí wọ́n wà ní agbègbè wọn.
25 Nítorínáà, bí wọn kò bá mọ orúkọ èyí tí a fi pè wọ́n, wọn kì yíò lè ní ààyè nínú ìjọba Bàbá mi.
Lasiko ti Kabiesi n gbalejo awọn ọmọ wọnyii lo fara balẹ ṣalaye itan Oodua àti ìtẹ́ ni aafin fawọn ogo wẹẹrẹ wọnyii.
Ìgbà tó bá fẹ́ yàgbẹ́, ìgbà tó bá fẹ́ tọ̀ tàbí ìgbà tí ó bá fẹ́ mọ́ra ni yóò maá jáde sí gbangba.
" O ni tori ọrọ ijọba kii ya nigba miiran bi o tilẹ jẹ pe awọn jọ ṣepade.
Agbabọọlu Chelsea, Giroud lo kọkọ si san bantẹ iya fun Arsenal to jẹ ikọ rẹ tẹlẹri, ki Pedro ati Hazard to pari iya naa fun Arsenal.
Atẹjade kan lati ọwọ agbẹnusọ ile-iṣẹ ọlọpaa Ipinlẹ Eko Chike Oti ni Ọjọru ṣalaye wipe ibudo Force Squadron 22 ni Ikeja ni Useni ti n ṣiṣẹ.
Sagamu: Ìkọlù ń wáyé bí ará ìlú ṣe gbéná wòjú ọlọ́pàá torí ikú agbábọ́ọ̀lù Iléeṣẹ́ ọlọ́pàá bẹ̀rẹ̀ ìwáàdí lórí ikú Tiamiyu Kazeem tí wọ́n ní SARS pa ní Sagamu Oluwo yí ìpinnu padà,Telu lóun yóò tẹlé àṣẹ lọ rọọ́kún nílé ṣùgbọ́n.
Nigba aye rẹ, oun ni Alaga ileesẹ CreditSwitch Technology, to wa nilu Eko.
''Níṣe ni wọn kún gbogbo àárin ojú ọ̀nà, tí ẹnikẹ́ni kò si le kọjá.
Ile iṣẹ Aamin ti ṣiṣẹ takuntakun lati pese iranlọwọ to yẹ fawọn eniyan lai naani ẹya tabi boya ọmọde tabi agba ni o nilo wọn.
EFCC ń wádìí iléeṣẹ́ 'Bola Tinubu,' Alpha Beta Consulting Ltd' Àṣìta ìbọn pa èèyàn kan lásìkò tí SARS ń kojú adigunjalè l'Eko Lẹ́tà Obasanjo: Àjálù ń bọ̀ bíi ti Rwanda, tí Buhari kò bá ṣàtúnṣe ètò ààbò Fulani nìkan kọ́ ló ń pa ènìyàn ní Naijiria -Tinubu Bakan naa, Makinde ni ẹgbẹrun un lọna ọgbọn owo dọla titi di ọjọ kejidinlọgbọn, oṣu karun un nile ifowopamọ si.
Ìjọba ìpínlẹ̀ Ondo kéde òfin konile-o-gbele ní Ode ati Ishinigbo lẹ̀yìn rògbòdìyàn tó wáyé níbẹ̀ Wọ́n ti rí Ọ̀pá Àṣẹ ilé aṣòfin ìpínlẹ̀ Ogun tí àwọn jàndùkú jí gbé nípinlẹ̀ Eko o!
NCDC ni apapọ awọn to ti ni arun naa kaaakiri orilẹ-ede Naijiria ti wa di 19,147bayii.
Nítorí Baba yín tí ń bẹ ní ọ̀run mọ̀ pé ẹ nílò gbogbo wọn.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Gómìnà Dapo Abiodun fún Modupe Akintola n'íṣẹ́ ọ̀fẹ́ 16 Ọ̀wàrà 2019 Gomina ipinlẹ Ogun, Ọmọọba Dapo Abiodun ti fi iṣẹ ọfẹ ta arabinrin Akintola Esther Modupe to jawe olubori gẹgẹ bi akẹkọọ to pegede ju ni ile ẹkọ akọṣẹmọṣẹ ti Ilaro lọrẹ.
iriri agbeyẹwo ẹka iṣuna owo ilu gḅọdọ yatọ si ti ẹka iṣẹ adani ati
Òjìji rẹ̀ bo àwọn òkè mọ́lẹ̀,ẹ̀ka rẹ sì bo àwọn igi kedari ńláńlá;
Bakan naa ni aya gomina Kwara fi awọn ọmọdebinrin mejeeji naa sile iwe to jẹ ọkan lara awọn ile ẹkọ to dara julẹ ni ipinlẹ Kwara.
  Nígbànáà ni ènìà yó rí ọ̀nà kékeré tó lọ́ tààrà sí ẹsẹ̀ òkúta nlá yìí.
Èmi OLUWA Ọlọrun ní mo sọ bẹ́ẹ̀.
Wọ́n kó ibùsùn lọ́wọ́ wá fún wọn, ati àwo, ìkòkò ati ọkà baali, ọkà tí wọ́n ti lọ̀, ati èyí tí wọ́n ti yan, erèé ati ẹ̀fọ́; 
Amọ kokoro awọn ologun ko jẹ ki awọn eeyan ipinlẹ Ondo gbadun obi Olumilua to gbo kaka, nitori oṣu Kọkanla ọdun 1993 ni awọn ologun gba ijọba lọwọ awọn oloselu alagbada, eyi ti oloogbe Sani Abacha ṣe agbatẹru rẹ, ti wọn si yẹ aga akoso mọ Olumilua nidii.
Ninu iroyin naa, ''Ọgbẹni Abubakar'' sọ pe ohun akọkọ ti oun yoo ṣe nigba t'oun ba di aarẹ ni pe oun yoo wọgi le ofin ti ko gba ki ọkunrin ati ọkunrin ẹgbẹ rẹ fẹ ara wọn eyi ti aarẹ ana, Goodluck Jonathan bọwọ lu lọdun 2014.
Nítorí pé o ti gba ẹ̀mí mi lọ́wọ́ ikú,o gbà mí, o kò jẹ́ kí n kọsẹ̀,kí n lè máa rìn níwájú Ọlọrunninu ìmọ́lẹ̀ ìyè.
Ní ìgbẹ̀yìn gbogbo wọn, obinrin náà kú.
Wọ́n bá dúró níbẹ̀ láti máa tọ́jú ogbà náà, wọ́n sì dúró pẹ́ dìẹ̀.
Minisita fun eto ẹkọ ni Niajiria, Mallam Adamu Adamu ṣalye ninu iwe atẹjade kan to sita pe awọn ipinlẹ lominira lati ṣe ohun to ba wu wọn lori ọrọ naa.
O fi kun pe kii ṣe ohun to bojumu ki awọn eeyan maa dana sun ọkọ nigba ti ijamba ọkọ ba ṣẹlẹ nitori wọn ko mọ ẹni to jẹbi iṣẹlẹ naa ki wọn to ṣe idajọ ọwọ ara wọn.
Bakan naa fun ibaṣepọ to danmọran ti yoo fọ gbogbo ohun idiwọ ẹtọ irina laarin awọn ọmọ Afirika mii.
Ni abala keji ifẹsẹwọnsẹ naa lo tun ti fa aṣọ Riyadh Mahrez to jẹ agbabọọlu Mancity ti rẹfiri si fọn fere fun pẹnariti ti o si tun fun un ni kaadi pupa pe ko jade kuro lori papa.
Samuẹli dá wọn lóhùn pé, “Ẹ má bẹ̀rù, bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé ohun tí ẹ ṣe burú, sibẹsibẹ ẹ má ṣe yipada kúrò lọ́dọ̀ OLUWA, ṣugbọn ẹ máa sìn ín pẹlu gbogbo ọkàn yín.
“Wọn yóo gbọ́rọ̀ sí ọ lẹ́nu, ìwọ ati àwọn àgbààgbà Israẹli yóo tọ ọba Ijipti lọ, ẹ óo sì wí fún un pé, ‘OLUWA Ọlọrun àwọn Heberu ti wá bá wa, jọ̀wọ́, jẹ́ kí á lọ sinu aṣálẹ̀, ní ìwọ̀n ìrìn ọjọ́ mẹta, kí á lè rúbọ sí OLUWA, Ọlọrun wa.
O tun jẹ alawọdudu ọmọ ilẹ Afrika akọkọ ti wọn fi oye ọmọwe ninu imọ sayẹnsi Doctor of Science da lọla nile ẹkọ Imperial College of Science and Technology,London ni 1974 Bakanna ni akọsilẹ wa wi pe o leri lati pari ẹkọ ọlọdun mẹrin nipa imọ ẹrọ Bsc Mechanical Engineering laarin ọdun mẹta pere ti o si ṣe bẹ nile Eko fasiti Nigerian College of Arts Science and Technology lọdun 1962.
Ìjọ kò ní tilẹ̀kùn ilé ìjọsìn nítorí àrùn Coronavirus - Ondo PFN Ṣé Makinde kò wá rugi oyin báyìí lórí ìpàdé ìtagbangba PDP tó ṣe níbàdàn Láì náání àjàkálẹ̀ àrùn coronavirus?
 Pupọ ninu awọn ololufẹ awọn oṣere memeji lo ti n fi erongba wọn lede lori ọrọ naa."
3 125669 Orilẹede Sudan 1319 3.
- Sanwo-Olu Ìjọba Oyo fẹ́ mọ ikú tó pa akẹ́kọ̀ọ́ UI níléeṣẹ́ tó ń ṣe ọṣẹ Ijọba ipinlẹ Oyo ti paṣẹ ki ileeṣẹ ti akẹkọọ fasiti Ibadan kan ti pade iku ojiji, fi atẹjade sita nipa ohun to ṣẹlẹ si akẹkọọ yii.
Alukoro FRSC, Florence Okpe sọ fun awọn akọroyin pe, ijamba naa ṣẹlẹ ni nkan bi aago meje irọlẹ, ni agbegbe ti ileeṣẹ to n tun opopona ṣe ti pin ọna si meji.
"O sọ pe ""Ọpọlọpọ awọn ogun apakokoro ti wọn n ta ni ọja kọ lo yẹ ki a maa lo ninu ile."
1 11407 Orilẹede Burkina Faso 68 0.
Lọjọ Ẹti, Minisita agba Amarinder Singh pe fun iwadii lori ohun to n ṣeku pa awọn eeyan.
Boris Johnson ni ibo 157, Micheal Gove ni 61, nigba ti Jeremy Hunt si ni ibo 59.
Gbogbo èyí yóo ṣẹlẹ̀ kí igi mìíràn tí ó bá wà lẹ́bàá omi náà má baà ga fíofío mọ́, tabi kí orí rẹ̀ wọ inú ìkùukùu ní ojú ọ̀run.
fun won ni igboya pe won ti pegede si asekagba idije ohun, nitori awon
2) Davido - Assurance Orin yii di orin ti tọmọde tagba n jo si ni kete to jade.
"Ẹnikeji yoo si dahun pe, ""Onitẹsiwaju""."
"Awa ti a n pe ara wa lọ́ba lórilẹ̀ aye kọ́ lọ́ba, Ọlọrun gan lọba, a kan n róle fun Ọba ni""."
Bamiloye ni eyi lodi si ofin Ọlọrun.
Fasola gbà pé ìdàgbàsókè iná mọ̀nàmọ̀nà jẹ ìjọba lógún fún ilọsíwájú ètò ọrọ̀ ajé Nàìjíríà pàápàá lásìkò yìí.
Wọn si fẹnuko pe ipade igbimọ alaṣẹ ti ẹgbẹ ṣe lọjọ ẹti ko ba ofin mu.
Oríṣun àwòrán, @AporkoDoctor Ninu awọn ti ko ti i ṣe bẹẹ ni ipinlẹ̀ Oyo ati Osun wa ti BBC Yoruba si gbiyanju lati mọ ohun to n dawọn duro ati bi wọn ti ṣe fẹ gbe gba.
 Ẹni tó bá gbé ìyá igbá lé ọmọrí igbá tit ò ó lódì .
Gege bi awon ti isele ohun soju won, won fi mule pe, inu lo bi Katz lataari pe ko jawe olubori ninu idije boolu Amerika ohun (American football eSports event), ni eyi ti O mu wu iwa lona aito.
Oti ni kete ti ọga ọlọpaa ni Ipinlẹ Eko, Edgal Imohimi gbọ nipa iṣẹlẹ naa, lo paṣẹ fun ọga ọlọpaa agbegbe Area 'J' Elemoro, lati gbe awọn to lọwọ ninu ọrọ naa ti mọle.
Esabod: Esther Aboderin tí ọ̀pọ̀ mọ̀ sí Esabod ní ẹ̀sín pọ̀ fún òun lọ́jọ́ tí wọn parọ́ pé mo mu sìgá lórí Facebook
 fífòmó murtala kan gbogbo isé ìjoba pátápátá , bí àwon olópàá , amòfin , ìgbìmò tó n mójútó ètò ìléra , ológun , àti unifásitì .
 O tẹsiwaju pe Opin ọsẹ lo ma n lekenka ju nitori ko ki n si ẹnikẹni ninu ile.
Oludari ajọ NDLEA nipinlẹ naa, Haruna Gagara ni wọn se ipade akọroyin ọhun lati fi sami ayajọ gbigbogun ti ilokulo oogun ati gbigbe oogun oloro fun tọdun yii ni.
Oda ikunle(Paint) Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Bi eeyan ba wọ inu iyara ti wọn ṣẹṣẹ kun lọda lewu Igbiyanju eeyan lati fi ọda pa oju ile naa a maa ṣokunfa ijamba ninu ille gẹgẹ bi alaye Dokita Anthony.
'Ẹ̀yin tẹ́ẹ fẹ́ pa ara yín torí olóṣèlú, ẹ wò Fayemi àti Fayose' FUTA pàṣẹ lọ rọọ́kún nílé f'ákẹ́ẹ̀kọ́ méje tó lu akẹgbẹ́ wọ́n Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Bẹ́ẹ̀ gan-an ni, nígbà tí ẹ bá rí gbogbo nǹkan wọnyi, kí ẹ̀yin náà mọ̀ pé àkókò súnmọ́ tòsí, ó ti dé ẹnu ọ̀nà.
Wọ́n ń ṣọ́ apá ẹnu ọ̀nà ìlà oòrùn ilé ọba.
Saa marun ni Angel di Maria lo ni Madrid ki o to gbe igba bọọlu agbajẹun rẹ lọ si PSG lorilẹede France.
" Ṣé ìnàkí tún gbé owó tó lé ní mílíọ̀nu mẹ̀fà Náírà mì ni?
Gbogbo ibi gíga Isaaki yóo di ahoro, ilé mímọ́ Israẹli yóo parun, n óo yọ idà sí ìdílé ọba Jeroboamu.
Àkọsílẹ̀ àwọn tí a yàn ati iṣẹ́ wọn nìyí:
Gẹgẹ bẹẹ se mọ pe awọn ọmọde ati agba maa n foju sọna fun ọdun alarinrin yii nitori awọn adun kan to wa ninu rẹ.
“O kò gbọdọ̀ yá èrekére fún ara rẹ, kì báà ṣe àwòrán ohun tí ó wà ní òkè ọ̀run, tabi ti ohun tí ó wà ní orí ilẹ̀, tabi ti ohun tí ó wà ninu omi ní abẹ́ ilẹ̀.
’’Adari ajo naa wa ro awon omo ipinle Anambra ti ko ti lo gba kaadi ibo won, lati tete lo gbaa , ki o to di  ojo kẹ́tàdínlógún, osu kejo yii, ti opin yoo de ba gbigba kaadi naa.
Damola Olatunji: Damola Olatunji ati iyawo rẹ Bukola Adeyemi, ti ọpọ eeyan mọ si Bukola Arugba, jẹ oṣere tiata to gbajugbaja, ti aye si n fẹ wọn.
O ni Osinbajo lasẹ labẹ ofin lati pe eniyan lẹjọ, amọ ẹnikẹni ko laṣẹ labẹ ofin la ti pe e lẹjọ tabi se iwadii rẹ lasiko to ba ṣi wa ni ipo isejọba.
Wọ́n tún fún wọn ní àwọn ìlú wọnyi, pẹlu àwọn pápá ìdaran tí ó wà ní àyíká wọn: Geseri, 
Àwọn ọmọ Aaroni ni yóo máa rúbọ náà níwájú pẹpẹ, níwájú OLUWA.
Kemi Olunloyo dá sí ìjà Toyin Abraham àti Lizzy Anjorin Ìjà Toyin àti Lizzy kìí ṣe àkọ́kọ́, àwọn òṣèré t'ọ́rọ̀ ìjà kàn rí rèé Lizzy Anjorin: Mi ò bẹ Toyin o!
Oríṣun àwòrán, Getty Images Akẹgbẹ Oshoala, Francisca Ordega to n gba bọọlu fun ikọ Shanghai Shengli tiẹ sọ pe Naijiria niṣẹ to pọ lati ṣe lori ero awọn eeyan nipa ere bọọlu obinrin.
 lóòtọ ́ , ọba ló nilẹ ̀ , òun ló sì ń gbọ ́ ẹjọ ́ tó bá tóbi jù .
Lockdown school feeding programme: To bá ní ọmọ ni kíláàsì Kínní dé ìkẹta nílé ẹ̀kọ́ alákọ̀ọ́bẹ̀rẹ̀ tìjọba, lọ gba oúnjẹ fún ọmọ rẹ
Istanbul to jẹ olu ilu Turkey ni ibudo iṣẹmbaye yii wa ti wọn ko awọn nakn iṣura ati ohun itan orilẹ-ede Turkey si Ile ọhun ti wọn kọ gẹgẹ bii Katidira ni nnkan bi ẹgbẹrun ọdun kan abọ ṣeyin ni wọn kọkọ yipada si Mọṣalaṣi lọdun 1453 lasiko ogun Ottoman.
Ojú kò tì mí láti waasu ìyìn rere Jesu, nítorí ìyìn rere yìí ni agbára Ọlọrun, tí a fi ń gba gbogbo àwọn tí ó bá gbà á gbọ́ là.
Ẹni tí ó gbé ìdánwò ńlá ka ọ̀rẹ́ ìmùlẹ̀ láyà ni ó wí pékí onítọ̀ún ṣe àbòsí òun.
ati Jarimutu, Enganimu pẹlu àwọn pápá ìdaran tí ó wà ní àyíká wọn, gbogbo wọn jẹ́ ìlú mẹrin.
Pọgba sọ fun ikọ̀ agbohunsafẹfẹ Manchester United pe oun ko ti i la iru nkan bẹẹ kọja ri lati igba ti oun ti n gba bọọlu jẹun, sugbọn oun gba kadara.
Ìwọ a-rí-tẹni-mọ̀-ọ́n-wí, kọ́kọ́ yọ ìtì igi kúrò lójú ara rẹ, nígbà náà, ìwọ óo ríran kedere láti lè yọ ẹ̀ẹ́rún igi tí ó wà lójú arakunrin rẹ.
Oríṣun àwòrán, TWITTER/AYO FAYOSE Àkọlé àwòrán, Ninu alatako ijọba Buhari, Gomina Ayo Fayose lo je gbajugbaja ju lọ Atiku ko gbeyin Oríṣun àwòrán, TWITTER/ATIKU ABUBAKAR Àkọlé àwòrán, Atiku Abubakar n na owo ife si awọn olori kakiri orilẹẹde Naijiria.
Oríṣun àwòrán, Oniadimula Kà nípa ibi tí wọ́n bí Àrẹ̀mọ tuntun Ọọ̀ni Ife sí, àti orúkọ tó ń jẹ́ Ǹjẹ́ o mọ Olorì Moremi tó jà fún òmìnira àwọn ẹrú nílẹ̀ Ifẹ̀?
Ẹgbẹ naa ti gbiyanju lati pada si Libya, sugbọn agbara rẹ ko fẹsẹ mulẹ daada mọ.
Alaye ti agbejoro naa se fi han ni ṣoki pe ''bí èèyàn bá sì fẹ ṣiṣẹ́ fún ìjọba yálà gẹgẹ bí Mínísítà ní tàbí ní ipò míràn, bi o bá ti sọ wí pé òun parí ilé ẹkọ gíga yunifásítì, o di dandan kí o fí ìwé ẹrí pé o parí ètò àgùnbánirọ̀ han.
Ìbá ti dára tó kí ìgbàlà Israẹli ti Sioni wá!
Idi ni pe ọrọ di boolọ, ko ya fun mi nigba ti awọn agbofinro ya bo ibudo ti wọn kede pe eto iwọde alaafia naa yoo ti gberesọ.
Losu kọkanla ọdun yi, adele oludari ẹka iroyin ileeṣẹ́ ologun Naijiria,ọgagun John Agim so wi pe ajọ Amnesty International n gbe iroyin ayederu jade nipa lNaijiria lati le bẹnu atẹ lu.
Wo iye ọ̀tá tí èmi nìkan ní,ati irú ìkórìíra ìkà tí wọ́n kórìíra mi.
Wọn ko si gbọdọ si oúnjẹ jíjẹ tabi iwẹ ni ibudo naa.
Ọba Ogunwusi ni laipẹ ni wọn yoo pada si ohun to n waye ni atijọ nidi dida awọn ọja tuntun silẹ si ni ilu Ile Ifẹ.
O wa fi kun un pe kọkọrọ kan to n bẹnu aja jẹ lori ọrọ yii ni pe awọn orilẹede Afirika ko ni owo lati fi awọn nnkan wọnyii lọwọ; idi niyi ti wọn si fi nilo ati tọ awọn ileeṣẹ nlanla lagbaye lọ lati yawo ni ele ti ko ga ju ara lọ.
 bakanna ni leba awon ebute ni gusu a le ri awon omo-omo awon eru ti won kopada wa lati brasil .
Igbimọ NJC ti kọkọ kọwe ranṣẹ si awọn adajọ agba mejeeji yii nibi ijoko rẹ lọjọ kọkandinlọgbọn oṣu kinni ti wọn si fun wọn ni gbedeke ọjọ meje lati dahun si ẹsun ti wọn fi kan wọn.
Mo si ti pasẹ pe ki wọn so gbogbo isẹ ijọba rọ na fun ọjọ mẹta, ayafi awọn osisẹ alaabo nikan."
Oríṣun àwòrán, BBnaija Iyalẹnu si ni eyi jẹ, nitori pe awọn alakoso eto BBNaija ko kede tẹlẹ pe awọn gbajugbaja olorin mejeeji yoo kọrin ni aṣekagba.
onínú burúkú; akọ̀mágbẹ̀bẹ̀, abanijẹ́; àwọn tí kò lè kó ara wọn níjàánu, òǹrorò; àwọn tí kò fẹ́ ohun rere; 
Ẹ ranti àwọn aṣiwaju yín, àwọn tí wọ́n mú ọ̀rọ̀ Ọlọrun wá fun yín.
Dúró de OLUWA,ṣe bí akin, kí o sì mú ọkàn gírí,àní, dúró de OLUWA.
O óo lọ sí ibi ìsinmi, ṣugbọn lọ́jọ́ ìkẹyìn, o óo dìde nílẹ̀ o óo sì gba ìpín tìrẹ tí a ti fi sílẹ̀ fún ọ.
‘Emi kọ o,awọn ọmọ yahoo yahoo ti gbakoso oju opo mi’ Amọ sa akọroyin naa ti fi ikilọ sita pe ki awọn ara ilu sọra fawọn alaburu ori ẹrọ ayelujara ti wọn ti gbakoso ikanni ibaraẹnisọrọ rẹ ni Facebook.
Lati igba to si tun ti wa ni ipo naa, ni awọn ẹsun iwa ibajẹ ti n jẹyọ lori boṣe n dari ajọ EFCC.
Lati ọdun 2005 ni Pierre Nkurunziza ti di aarẹ orilẹede Burundi, o si n mura lati fa aṣẹ ipo aarẹ le ẹni ti wọn ṣẹṣẹ dibo yan sipo aarẹ nibẹ, Evariste Ndayinshimiye ni ogunjọ oṣu kẹjọ ọdun 2020.
"Aya Fayemi lẹ́jọ́ jẹ́ lórí ikú àwọn akẹ́kọ̀ọ́ Fuoye - Segalink ""Mo fa Fayoṣe lé Ọlọrun lọ́wọ́"" Àwọn ará South-Africa yarí 'torí gbọ̀ngàn kọ̀ ìgbéyàwó abo-sábo Ẹ má mu gaarí mọ́ nítorí ìbà Lassa- Dókítà Boniface Ẹwẹ, Fayemi ni awọn gomina kan yii naa wulo fun bi Oshiomole ṣe di alaga, wọn kan n fẹ ibọwọ tiwọn ni gẹgẹ bi adari ẹgbẹ ki wọn si maa gba ọrọ wọn yẹwo."
Wọ́n lé wọn títí dé Gati ati dé ẹnu ibodè Ekironi.
Bí ìwọ bá búra èké, kìnnìún á pa ọ́ jẹ; bì ìwọ kò bá sì búra, ìyà à jẹ ọ́ gidigidi: ọ̀go lẹ́hìn aṣiwèrè, ìgbà tí mo bá sì nà ọ́ ní igi lẹ́hìn ọrùn, ìwọ á mọ nǹkan tí ń bẹ.
Bẹẹ ba gbagbe, laipẹ yii ni ọmọbinrin naa ṣe idana, to si lọ sile ọkọ.
Ìwádìí ti fihàn pé Ajá n gbọ́ òórùn àìsàn ibà 'Inú wa dùn pé wọ́n mú àwọn oniṣẹ́ ibi náà' Ọdún mẹ́tàlélógún lẹ́yìn ikú Ken Saro-Wiwa Wo díẹ̀ nínú ipa tí ẹnu bodè ti Nàìjíríà tì pa kó nínú ọjà ọdún Kérésì Ni ipari, akọṣẹmọṣẹ yii rọ àwọn obi lati maa farabalẹ gbọ ọrọ ẹnu ọmọ wọn ki wọn si maa ṣe iwadii to yẹ lori ohun ti ọmọ ba sọ fun wọn nitori ẹ̀ṣẹ́ kìí deede ṣẹ́.
"'Irọ́ ni o, Ọlọ́pàá 167 tó fẹ́ koju Boko Haram kò sá lọ' Àwọn sinimá tó pegedé ni 2018 lágbàyé ‘Awakọ̀ Ọ̀gágun Alex Badeh tí wọ́n pa kò kú’ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ijó Bàtá ti Yorùbá gb'oríyìn ní Calabar Festival 2018 ""A ti ṣe àṣeyọri lóri ọ̀rọ̀ yìí nítori àti mú àwọn afunra sí méjì tí à ó fojú wọn han lónìí ọjọbọ̀"" Ẹ ní tó bá akọròyìn Punch sọ̀rọ̀ sàlàyé pé àwọn kan tí na papa bora sùgbọ́n ọwọ́ yóò tẹ̀ wọn láìpẹ́ Gẹ́gẹ́ bí wọn ṣe sọ àwọn tó wà nínú àhámọ ọlọpàá jẹ́ àwọn adigunjalè lórí títì márosẹ̀ tí won tí ń pa èèyàn tàbí jí èèyàn gbé látẹ̀yìn wá ní sùgbọ́n ẹjọ́ wọn ò dé ìwájú àwọn ọlọ́pàá nítorí wọn ò kà wọn kún ọdaràn tó léwu."
 ilu na ni idiye olugbe 1,711,000 ( idiye 2009 ) .
"Nígbà tí wọ́n tàn wá wọ inú ẹgbẹ́ yìí, ẹ̀sìn Islam ni wọ́n fi tàn wá.
 Ìrí-àwòn- he ; gbígbà bóòlu wonu àwòn .
Pe nigba to ba ya, gbogbo ọrọ naa a yé onikaluku.
Oore wo lo n bẹ ninu ilana naa fun ọmọ Naijiria?
- Madam Saje Ẹ lọ́ jáwé gbé jẹ́ẹ́ sọ́wọ́ bí bẹ́ẹ̀ kọ́.
Ṣugbọn wahala bẹ silẹ lẹyin ti India ṣe opopona si agbegbe Ladakh, lẹba ilẹ kan naa to pin awọn mejeji ti wọn n ja si.
Timi sọ fun onisẹ Alaafin pe oun ti faake kọri lati san isakọlẹ fun Alaafin, to si ran wọn pada silu Ọyọ lọwọ ofo, ti isẹlẹ naa si bọ si apo ibinu Ọba Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Wo itan omi gbigbona ati tutu ni Ikọgosi Ekiti Alaafin Sango wa ran ikọ ọmọogun kekere kan lọ kọlu Timi ni Ede, ko lee mọ pe Ọba ba lori ohun gbogbo amọ ajẹkun iya ni awọn onisẹ Alaafin jẹ, ti Timi si lu wọn bi ẹni lu bara.
Ẹran aja je ounjẹ pataki ni South Korea lati ọjọ pipẹ, ti wọn si maa n jẹ to aja milionu kan lọdọọdun.
Awọn eniyan mejeeji ti wọn bọ si ipo keji ati ipo kẹta naa wa lati orilẹede Kenya.
Ẹgbẹ agbabọọlu mẹrindinlogun lo maa n kopa tẹlẹ.
igbimo, ti igbakeji aare Yemi Osinbajo dari rẹ.
 Ìgbà mìíràn màà pòṣé sààràsà ; ìgbà mìíràn màá tú yẹ ̀ rì ètè ; màá tújú ká .
Ta ni Sikiru Ayinde Agbéjélọlá Barrister?
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Wo itan omi gbigbona ati tutu ni Ikọgosi Ekiti Bode Thomas jẹ oninu fufu ti kii pẹ binu, kii pa ọrọ mọra, o maa n sọ tinu rẹ jade lai fẹ mọ ẹniti ọrọ naa yoo bi ninu, eyi to maa n mu ko di ọta ọpọ eeyan Nibi ipade igbimọ lọbalọba to waye lọdun 1953 eyi ti Bode Thomas jẹ alaga fun, la gbọ pe o ti yaju si ọba Adeniran Adeyẹmi, tii se baba Alaafin Lamidi Ọlayiwọla Adeyẹmi kẹta to wa lori oye bayii, to si n sọrọ si ori ade naa pe ko dide duro lati yẹ oun si nigba ti oun wọle, gẹgẹ bi awọn Ọba alaye yoku to wa nikalẹ ti se Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Sogidi Lake: Kòṣẹja-kòṣèèyàn lá bá nínú adágún odò náà -Ojedele Iroyin kan ti ko fidi mulẹ, to n lọ lati atẹnudẹnu tun sọ pe ọrọ yii bi Ọba Adeyẹmi ninu to bẹẹ, to si ni ki Bode Thomas maa gbo lọ pẹlu bo se n bu oun yii, lọjọ kejilelogun, osu Kọkanla lẹyin ipade ti Bode dele rẹ ni Yaba nilu Eko lati Ọyọ, lootọ lo ba n gbo bii aja.
Nítorí náà, wọ́n sá lọ ní àṣáálẹ́ ọjọ́ náà, wọ́n fi ibùdó ogun wọn ati àwọn ẹṣin wọn ati àwọn kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ wọn sílẹ̀, wọ́n sì sá àsálà fún ẹ̀mí wọn.
O ni awọn le awọn eeyan lẹnu iṣẹ ki awọn baa le ribi gbọ awọn bukata miran ti o wọ awọn lọrun lasiko Covid-19 yi.
 A o ri daju pe wọn ka ibo olukuluku, pẹlu eto idibo to poju owo ni ọdun 2019.
Kò si ǹkan ti a le jọ maa jòkó sọ lábẹ ]akóso boti wu kó ri, àyàfi ki ààrẹ orilẹ̀-èdè ó dá sii, láì jẹ bẹ́ẹ̀ àwọn osiṣẹ́ yóò daṣẹ́ sílẹ̀ Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!"
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Saraki vs Abdulrazaq: Àwọn arúgbó ní kí ìjọba máà ṣe wó ilé arúgbó m'áwọn lórí 31 Ọ̀pẹ̀̀ 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 1 Sẹ́rẹ́ 2020 Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Àwọn arúgbó ní kí ìjọba máà ṣe wó ilé arúgbó m'áwọn lórí Ọrọ lori ile arugbo ti Ijọba ipinlẹ Kwara lawọn fẹ gba ilẹ naa pada lọwọ aarẹ ile aṣofin agba tẹlẹ Bukola Saraki ti gba ọna mi yọ.
Àwọn ará Amoni náà wá kó àwọn ọmọ ogun wọn jọ láti gbogbo ìlú wọn.
com Ọwọ awọn oṣiẹ alaabo DSS tun ti tẹ ajafẹtọ ọmọniyan kan to jẹ alakoso ẹgbẹ Revolution now ni ipinlẹ Osun, Ọlawale Bakare.
Gbogbo Israẹli ti rú òfin rẹ, wọ́n ti pada lẹ́yìn rẹ, wọ́n kọ̀, wọn kò gbọ́ tìrẹ.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Badagry: Ojú ọ̀nà àrèmabọ̀ fáwọn ẹrú tó ń lọ sókè òkun Ọbásanjọ́: Ẹ má dìbò fún ìjọba aláròyé Òsèlù Èkìtì: Ọ̀pọ̀ ọmọ PDP ń rọ́ lọ sẹ́gbẹ́ òsèlú SDP Bẹ́ẹ̀ sì ni fóónù ni orísun ẹ̀rì tó fẹsẹ̀múlẹ̀ fún ẹ̀sùn àgbèrè.
Awon alatako re benu –atelu  Maada Bio wi pe o tabuku ba eto awon omo eniyan lakoko to wa lori aleefa  eyi ti o ri gege-bi ipinnu gbogbogbo.
Constitution Review: Afenifere rọ àwọn aṣòfin láti lo àbá 2014 CONFAB fún àtúnṣe ìwé òfin Nàìjíríà
Obok n jẹun lọwọ ni a gbọ pe Ọjemba ba fi ada ge ori ẹgbọn rẹ bọ silẹ.
O ni ọpọ awọn ẹlẹwọn lo ti dide ti wọn si ti n kọri si ile ẹjọ koowa wọn fun igbẹjọ gbogbo to kan wọn lasiko to fi waye.
Ní ọjọ́ náà, n óo fi ìwọ Serubabeli, ọmọ Ṣealitieli, ṣe aṣojú ninu ìjọba mi nítorí pé mo ti yàn ọ́.
Meje ninu awọn minisita naa ni wọn yan lati ẹkun iwọ oorun gusi orilẹede Naijiria.
NAiraMarley ki lohun to n ti ẹ gbọngbọn gan?
Ó jẹ́ kí àwọn tí ebi ń pa máa gbé ibẹ̀,wọ́n sì tẹ ìlú dó, láti máa gbé.
Kọmiṣọnna ọrọ to n lọ ni ipinlẹ ọhun, Kingsley Fanwo lo sọ ọrọ naa ninu iforowerọ pẹlu ileeṣẹ amohunmaworan abẹle Channels.
Lateef Adedimeji Gbajugbaja oṣere, Lateef Adedimeji gbarada lẹyin to ro dẹdẹ to kan dudu bi awẹlẹwa obinrin.
OLUWA ti dá ẹ̀mí mi sí, gẹ́gẹ́ bí ó ti wí, láti nǹkan bí ọdún marunlelogoji tí OLUWA ti sọ ọ̀rọ̀ yìí fún Mose nígbà tí àwọn ọmọ Israẹli ń rìn ninu aṣálẹ̀.
Afọ́jú ni ẹni tí kò bá ní àwọn nǹkan wọnyi, olúwarẹ̀ kò ríran jìnnà, kò sì lè ronú ẹ̀yìn-ọ̀la.
Ó bá sọ fún ẹlòmíràn pé, “Máa tẹ̀lé mi.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Wo ikọ̀ ọlọ́pàá tí àwọn ọ̀daràn ń sá fún PDP: A fẹ́ dara pọ̀ mọ́ àwọ́n ẹgbẹ́ míì Mugabe yóò d'élé asòfin lórí ọ̀rọ̀ tó sọ Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Olùṣọ́-aguntan wo ló lè dúró dè mí?
Femi Adebayo Oríṣun àwòrán, femiadebayosalami Femi Adebayo to jẹ gbajugbaja oṣere ti ọpọlọpọ eeyan fẹran fi ọrọ igbeyawo rẹ ṣe apẹrẹ lori eto ileeṣẹ Amohunmaworan TVC kan ti awọn atọkun obinrin ti da ibeere bo o.
yoo tun tan imole si bi a tun se maa tuko ijoba nile-igbimo asofin.
Ṣugbọn lara awọn ọrẹ rẹ ti fi si oju opo Twitter pe, ara Segun ti n balẹ bayii.
nígbà tí ó jọba lórí Israẹli.
Ajeogungunniso 1; Aare Ona Kakanfo ile Yoruba, Otunba Gani Adams; Ambs
Fìdíhẹẹ́ ní Banji Akintoye nínú YWC, lílọ ni yóò lọ - Tola Adeniyi A kò sí lára àwọn tó ń ṣèwọ́de tako èlé owó epo àti iná ọba - NLC Jàńdùkú olóṣèlú gbàkóso ilé aṣòfin l‘Ondo Gbogbo ẹni tó bá tàbùkù David Oyedepo ni màá ya pẹ́rẹpẹ̀rẹ - Pásítọ̀ Ibiyeomie Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Temitope Akinnusi: Ọ̀pọ̀ iléeṣẹ́ ló takú láti gbà mí síṣẹ́ torí mo ní ojú kan Ki lo ti ṣẹlẹ sẹyin?
Ṣugbọn mo tun gbagbọ pe, nkan ko lọ deede pẹlu ọkọ mi.
EPL: Chelsea ati Manchester United f'idi rẹ'mi
Lati ọdun alalumọle ni kẹkẹ wiwa ti wa ni ilẹ Yoruba koda ṣaaju ki mọto gigun to di kari aye yii.
Páànù ọkà baali mẹta fún owó fadaka kan.
” Àwọn ọba Filistini maraarun bá wá sọ́dọ̀ rẹ̀, wọ́n mú owó náà lọ́wọ́.
 láàti ibi-ìdèra ni wón ti so ibè di òkè-ìdèra .
Àwọn mìíràn tí ó ní ìrètí sí ipò ààrẹ Nàìjíríà ni:
Ẹni ọmọ ọdun mẹtadinlọgọta nii ṣe.
Ojú rẹ̀ mọ́lẹ̀ bí oòrùn ọ̀sán gangan.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àmúwá Ọlọ́run lásán ní ìṣẹ̀lẹ̀ tó wáyé ní Iba-Eburu Iba Oba Okunoye Wúndía àti Ọba nìkan ló lè dé Orí Òkè Ọwá ní Ìjàrẹ Ondo- Àgbà Oloye Àgbáríjọpọ ẹgbẹ OPC, fijiláńté VGC, Agbẹkọyà ti bẹrẹ ètò aàbò ní ilẹ Yorùbá Wọ àwòrán àwọn ẹbí òṣèré Nollywood yii!
Awọn ikọ agbabọọlu orilẹ-ede bii Argentina, Portugal, Spain, Denmark, Mexico, Japan.
“Kí ni ó pa tàwa-tìrẹ pọ̀, Jesu ará Nasarẹti?
Ọpọ eeyan lo si ti bẹrẹ si n woye bi ọrọ iku naa ṣe jẹ lẹyin ti akẹgbẹ rẹ nigba kan nileewe girama fi ọkọ gba a, to si gbabẹ dero ọrun.
Ó dára bí Aisha ṣe ń gbarata lórí ètò áábó tó mẹ́hẹ - BBC News Yorùbá BBC News, YorùbáFò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Obasanjo - Ó dára bí Aisha ṣe ń gbarata lórí ètò áábó tó mẹ́hẹ 4 Òkùdu 2019 Oríṣun àwòrán, @AsoRock Aarẹ ana ni Naijiria, Oloye Olusẹgun Ọbasanjọ ti kesi aya aarẹ Muhammadu Buhari, Aisha, lati pe ọkọ rẹ wọ yara, ko si ba sọ ootọ ọrọ nipa eto aabo to mẹhẹ lorilẹede Naijiria, pẹlu awọn ipenija miran lọkanojọkan ti a n fara gba.
Bí àìsàn bàbà mi ṣe ń lọ, ló tún ń padà, kódà kò yé mi mọ- Ọmọ Bàbá Sùwé Èmi àti Sanyeri ti tọrọ oúnjẹ jẹ rí nílé oninawo torí ebi, ká tó di gbajumọ oṣere Iriri aye yii si lo da lori bi awọn aṣọbode nilẹ wa se mu ni papakọ ofurufu pe o pe oogun oloro Cocaine.
Ẹwẹ, wọn gbe ọkunrin naa lọ siwaju ileejọ Magisireeti l'Ọjọru nibi to ti sọ pe oun ko jẹbi ẹsun naa.
Aago mẹjọ abọ lalẹ ọ jọ Bọ ni aarẹ Trump de si Afghan ko to lọ pada laidagbere nitori eto aabo rẹ.
Ọpọlọ ọmọ mi kò pé, ó ní àìsàn ọ̀nà ọ̀fun, wárápá, tí kò sì rìn lọ́mọ́ ọdún méje àmọ́ pẹ̀lú ìgbàgbọ́, ayọ̀ ló já sí ₦400 péré ni àfẹ́sọ́nà mi nílò, ìfẹ́ obìnrin yìí sì ló sọ mi di adigunjalè - Iṣọla Oyenusi Ẹ̀ṣẹ́ ju ẹ̀ṣẹ́ lọ!
Akomolede ati Aṣa lori BBC: Mọ̀ si nípa oríṣìí ẹ̀ka ìsọ̀rí ọ̀rọ̀ àti ìwúlò wọn
Kí ló dé tí o kò dáàbò bo ọba, oluwa rẹ?
Oríṣun àwòrán, Others Ọba Ọlatẹru Ọlagbẹgi, Ọlọwọ tilu Ọwọ: Ọdun 1941 ni ọba Ọlatẹru Ọlagbẹgi gori itẹ awọn baba nla rẹ, to si jẹ ọba fun ọdun mẹẹdọgbọn ko to di pe wọn le kuro lori itẹ, eyi ti ko sẹyin wahala to n waye laarin Awolowo ati Akintola nitori ọrọ oselu ati ẹgbẹ oselu Ọlọpẹ A gbọ pe Ọlatẹru Ọlagbẹgi se atilẹyin fun Samuel Ladoke Akintola lati tako Obafemi Awolowo nigba naa, nigba tawọn ologun si gba ijọba lọdun 1966, awọn ara ilu Ọwọ fi ẹhonu han tako ọba wọn, eyi to mu kijọba Adekunle Fajuyi le kuro lori itẹ losu kẹfa ọdun 1966 Wo ìtàn ọgọ́ta ọdún Nàíjíríà nínú àwòrán mẹ́fà péré Ọba Lamidi Adeyẹmi, òṣìṣẹ́ adójútòfò àti Abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò kó tó jọba Duro Ladipọ, ìlúmọ̀ọ́ká òṣèré tíátà àti ọmọ àlúfà tí kò gbàgbé àṣà ìbílẹ̀ Wo ìmọràn tó lè jẹ kóo gbádùn ṣíṣe iṣẹ láti ilé lásìkò kónílé-ó-gbélé COVID 19 yìí O gbiyanju lati pada sori itẹ lọdun 1968 amọ eyi se okunfa iporogan nla nilu Ọwọ, wọn sun ọpọ ile nina, ti ọpọ ẹmi si lọ si bakan naa, eyi to mu ki ijọba Adeyinka Adebayọ kuku le kuro lori itẹ patapata, ti wọn si le silu Okiti pupa lati maa gbe, ti ọba Adekola Ọlagunoye si gun ori itẹ laarin osu kan Ọba Ogunoye waja lọjọ kejilelogun osu kẹrin ọdun 1993, ti ijọba Bamidelu Olumilua si yan Ọlatẹru Ọlagbẹgi pada gẹgẹ bii Ọlọwọ tilu Ọwọ lọdun 1993, to si waja lọdun 1998, ti ọmọ rẹ, Folagbade Ọlatẹru Ọlagbẹgi si jọba lẹyin rẹ.
"Igba ipọnju la maa n ronu jinlẹ ju, ara ohun ti yoo si jẹyọ lara arun Covid-19 yoo mu idagbasoke ba wa, bi ilẹkun kan ko ba si ti, omiran kii si.
Minisita tẹlẹ ri, Obi Ezekwesili ntiẹ́ rọ Omotola pe ko maa da awọn ti wọn n buu lohun.
”O fikun oro re pe, ipade apero naa lo maa n waye lodoodun lati jo jiroro po koju awon idojuko to ba koju awon adajọ nile ejo, ati awon ohun miiran.
Ninu atẹjade kan ti ẹgbẹ na fi lede, ti agbẹnusọ rẹ, ọmọwe Hakeem Baba-Ahmed buwọlu, wọn ni ẹmi eeyan ko niyi mọ labẹ iṣejọba Buhari.
Wọ́n ní, “Kò yẹ kí ọba Asiria wá, kí ó bá omi tí ó tó báyìí.
Idanileko olose kan ohun, eyi ti olu ile-ise iko omo ogun naa yoo se agbateru re, pe akori re ni: ‘Kikun iko omo-ogun lowo lati koju idojuko to n koju eto aabo.
Ó bá yọ́ ninu afárá oyin náà sí ọwọ́, ó bẹ̀rẹ̀ sí lá a bí ó ti ń lọ.
Ọ̀nà tí arúgbó náà júwèé tọ orí òkè kékeré kan lọ.
O ni oun kii ṣe Mayegun olorin, ṣugbọn ojuṣe oun gẹgẹ bii Mayegun ni lati ṣe iṣẹ olupẹtusaawọ ati olulaja nilẹ Yoruba.
Sùgbọ́n báwo ní ìwọ yóò ṣe mọ̀ bí agogo yìí ṣe ń ṣiṣẹ́?
Nítorí náà, bí ó bá jẹ́ pé pẹlu òtítọ́ inú, ati ọ̀nà ẹ̀tọ́ ni ẹ fi ṣe ohun tí ẹ ṣe sí Gideoni ati ìdílé rẹ̀ lónìí, ẹ máa yọ̀ lórí Abimeleki kí òun náà sì máa yọ̀ lórí yín.
 O soro yii ninu iforowanilenuwo to se pelu awon akoroyin ni Abuja lati fi sami ayajo ose Glaucoma lagbaye fun odun 2018 eyi to bere lojo kokanla si ojo ketadinlogun osu keta odun yii ti won pe akori re ni “GREEN: lo se ayewo to ye fun oju re ki o bo lowo Glaucoma”.
Nkurunziza, ẹni ọdun mẹrinlelaadọta la gbọ pe o maa n kopa ninu idije ere bọọlu lẹẹmẹta lọsẹ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ebola Virus: ìdí tí Ebola fi ń tàn kálẹ̀ Awọn agbabọọlu mẹfa lo ku ninu awọn mejidinlọgbọn ti wọn ṣoju orilẹ-ede wọn nigba naa.
Hadiiti sọ pe aawẹ lọjọ Arafa maa n pa gbogbo ẹsẹ ọdun to kọja ati eyi to n bọ rẹ Ilé Aṣòfin yóò pe Godswill Akpabio l'ẹ́jọ́ fún ìbanilórúkọ jẹ́ Ta ni Yusuf Satia ti iku mu lọ?
Àwọn ènìyàn ń f’ẹ̀sùn kan àwọn ẹlẹyẹ fún iṣẹ́-ibi ọwọ́ọ wọn: ikú ènìyàn tàbí ẹranko, ọ̀dá òjò, àìso jìngbìnnì irúgbìn, àti bẹ́èbẹ́è lọ.
Nítorí wọ́n kọ òfin OLUWA àwọn ọmọ ogun sílẹ̀,wọ́n sì kẹ́gàn ọ̀rọ̀ Ẹni Mímọ́ Israẹli.
Bí Paulu ti ń sọ̀rọ̀ báyìí, Fẹstu ké mọ́ ọn pé, “Paulu, orí rẹ dàrú!
bi awọn kan ṣe n di mọ 'ra wọn gbagi lawọn kan n fẹ aisa wọn soke.
Irufẹ iṣẹlẹ ina bayi ko jẹ tuntun ni Naijiria paapa julọ ti ọrọ ba ti niiṣe pẹlu ki awọn eeyan wa ṣe iṣiro owo tabi ti iwadii kan ba n lọ lọwọ.
Alaafin funrarẹ farahan pẹlu ibomu nibi ayẹyẹ naa toun tawọn olori rẹ.
Eyi lo mu ki ilumọọka osere tiata nni, Idowu Phillips, ti gbogbo eeyan mọ si Iya Rainbow fi n ke tantan si gbogbo agbaye.
 o je abatan elebun nobel omo india sir c.
O ni Ere bọọlu ti da idakuda laye ode oni, idi niyii ti a fi wa ni ihoho."
Àwọn ọ̀tá OLUWA yóo parun;OLUWA yóo sán ààrá pa wọ́n láti ojú ọ̀run wá.
Ẹranko náà ní orí meje ati ìwo mẹ́wàá.
Ẹ tètè yára wá gbà wá kalẹ̀, ẹ wá ràn wá lọ́wọ́.
Ìgbàgbọ́ wà pé, ìkọ̀lù awọn ọmọ ogun ilẹ̀ Naijiria ló sekú pa ọ̀pọ̀ ninu awọn ọmọ náà.
Akọwe agba fún ilé iṣẹ́ eto Eko ni Naijria lo fi idi ọrọ naa mulẹ Amọ, ijọba ni gbogbo awọn akẹkọọ ati olukọ lo gbọdọ tẹle awọn ofin to rọmọ didẹkun itankalẹ arun Coronavirus lorilẹede Naijiria.
Ìwọ tóò bá ti fẹ́ yí ǹkan padà, ṣì lọ máa bulù sójú.
Kí obinrin náà mu ún, omi náà yóo sì mú kí ó ní ìrora.
A óo dójú ti àwọn ará Ijipti,a óo fà wọ́n lé àwọn ará ìhà àríwá lọ́wọ́.
aare orile ede Amerika ogbeni,  Mike
Lẹyin ti Nengi kuro ni Big Brother kede asiko ti to fun Dorathy ati Laycon lati fi ile naa silẹ, lẹyin aadọrin ọjọ.
Igba keji ti a jọ jade ni mo ti sọ fun, o si jẹ ko ye mi pe, aarun HIV lo pa aburo oun kan.
Nígbà tí ó rí iṣẹ́ abàmì ati iṣẹ́ ìyanu ńlá tí ó ń ṣe, ẹnu yà á.
Ilé yìí ga ti n kò rí irú rẹ̀ rí, ó lẹ́wà rékọjá ààlà kò sì sí ẹni tí ó lè ka iye iyààrá inú rẹ̀ tán.
Ẹ̀yin ẹ̀ṣọ́, ẹ kò gbọdọ̀ fààyè gba jíjí àpótí ìdìbò ní Kogi àti Bayelsa- Buhari A gbé ìgbìmọ̀ kan kalẹ̀ láti ṣiṣẹ́ lórí gbígba àkóso fásitì LAUTECH - Seyi Makinde ‘Ilé ẹjọ́ kò gbé ẹ̀sùn ìfipánílòpọ̀ yẹ̀wò, à ń lọ sí ilé ẹjọ́ - Busola Dakolo Èèyàn méjì farapa nínú ilé tó jóná ní Tejuoso l‘Eko Ile paa laṣẹ fun igbimọ to n ri si eto ilera, iroyin, ọrọ ilanilọyẹ ati ọrọ lati rii pe igbesẹ yii di imuṣẹ.
Ó rí Juu kan níbẹ̀, tí orúkọ rẹ̀ ń jẹ́ Akuila, ará Pọntu.
Olori yii tutu niwa, ti awọn eeyan ko si fẹẹ mọ ohun pupọ nipa rẹ lori ayelujara.
Wo àwọn nkan tó yẹ kí o mọ̀ nípa Abdulganiyu Abdulrasaq, bàbá gómìnà Kwara tó kú Ọ̀gá tíṣà rí ẹ̀wọ̀n ọdún mẹ́wàá he nílùú Eko fún ẹ̀sùn lílú jìbìtì Ò kéré tán N1million là ń ná lórí alárùn Coronavirus kọ̀ọ̀kan; àlàyé rèé- Ìjọba Eko Gẹgẹ bi o ṣe sọ, awọn mejeeji ti wọn ji gbe naa Aremọ Abiodun, ẹni aadọọta ọdun, ati abilekọ Agnes Afogun aadọta ọdun n rinrin ajo lọ si ilu Ugbe lọ Simerin fun okoowo nigba ti wọn ji wọn gbe.
Lati fihan pe ibasepo to monyan lori wa laarin orile ede Naijiria ati Gambia,ni  aya aare orile ede Gambia  arabinrin Fatoumatta Bah Barrow se se ayeye ojo ibi re  niluu Abuja, lorile ede Niajiria, ni eyi ti o tun lo si ile- ẹkọ  ati ile- iwosan ni opin ose yii.
Olukopa obinrin ti o darajulo lagbaye teleri, Karolina Pliskova fi agbara re fagbahan omo odun merindinlogun Amanda Anisimova.
Wọ́n ya ẹnu wọn sí mi bí kinniun,bí kinniun tí ń dọdẹ kiri tí ń bú ramúramù.
"o le ni ogun orisiri "" lẹṣmania "" ti o nse okùnfa àkóràn arun yi lara eniyan ."
Ballon D'or 2018: Modric jáwé olú borí, Ronaldo, Messi fìdí r'ẹmi
ti yoo sẹlẹ sii leyin ti o ti wa ni ipamọ bayii.
Ewe, ni saa ti o koja Messi gba
Ó dín in kù sí ihò mẹ́fà-mẹ́fà, ó sì ṣé e to fi bá álúfábẹ́ẹ̀tì Faransé mu.
Farao tún sọ fún un pé, “Èmi ni Farao, ẹnikẹ́ni kò gbọdọ̀ ṣe ohunkohun ní ilẹ̀ Ijipti láìjẹ́ pé o fọwọ́ sí i.
 Ẹ ̀ sín ọ ̀ ún ti ń ku lọ díẹ ̀ díẹ ̀ .
 gbogbo ìgbìyànjú àwọn wọ ̀ nyí ni ó mú àyípadà rere wáyé ní séńtúúrì kọkàndínlógún .
“Ṣé ọlọ́gbọ́n a máa fọ èsì tí kò mọ́gbọ́n lọ́wọ́?
Lojuopo Twitter,orisisisi iriwisi lo ti tẹle fọnran fidio yi to ṣe afihan awọn obinrin to n jo ni ihoho ninu ọkọ kan.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù BBNaija: Kiki Osinbajo gbóṣùbà fún Seyi Awolowo, MC Oluomo gbárùkù ti Mike 5 Ọ̀wàrà 2019 Oríṣun àwòrán, Instagram/Seyi Awolowo Ti eegun ni ba mọọ jo, ori a ya atọkun.
O tun jẹ́ agba ẹgbẹ́ oloye ti APC.
Eyi jasi pe, awon eniyan yoo maa nawo ti ko to lori aisan, owo ti o ye ki won toju, won a yawo setoju ara won, opo a ta awon ohun ini won, ni eyi ti o n sakoba fun ojo ola won ati ti awon omo won pelu”.
Fadaka ati wúrà jẹ́ ọrẹ àtinúwá fún OLUWA Ọlọrun àwọn baba yín.
O ni ọrọ 'ọgagun' Buhari wipe ki awọn agbofinro fi ọwọ lile mu ẹnikẹni to ba ji apoti idibo, jẹ ọrọ to bani ninu jẹ, ti ko si yẹ ki adari ilu kankan sọ jade lẹnu.
O ni iṣejọba oun yoo kọ ibudo ilera ti ijọba si awọn apa ibi ti ko tii si ile iwosan ni ipinlẹ Eko bẹẹ si ni wọn yoo kọ ile iwosan si awọn ijọba ibilẹ ti ko tii ni ile iwosan.
Gbogbo ilé rẹ̀ patapata ni Jakọbu kó lọ́wọ́ lọ sí Ijipti, ati àwọn ọmọ rẹ̀, ati àwọn ọmọ ọmọ rẹ̀, lọkunrin ati lobinrin, gbogbo wọn ni ó kó lọ sí Ijipti patapata.
Awọn ajafẹtọ ti fi igbe ta pe idẹyẹsi ni lati ma ṣe ofin kan naa to rọmọ igbeyawo fun ọkunrin ati ọbinrin kan naa.
Ninu ọrọ kan to fi sita loju opo twitter rẹ @toyin_abraham1 kede pe ogoji ọdun ohun pe oun o si yọnu.
''Lati igba ti mo wa ni kekere ni mo ti nifẹ si baalu wiwa.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Eld Kabir in Nigeria: Mùṣùlùmí àti Kristiẹni sọ̀rọ̀ nípa àdun oúnjẹ́ àti ẹran ọdún Ileya Amaechi tun lo anfaani eto naa lati ja ahesọ ọrọ kan to n lọ kiri pe Naijiria ti ta ominira rẹ fun China nitori abala ofin kan to wa ninu iwe adehun ti wọn tọwọbọ lori gbigba owoya naa.
James ni igba mii ogun tabi ọta lo maa n ti eeyan de ọdọ oloore eeyan.
Oríṣun àwòrán, others Aisha ni ṣaaju aworan naa, ẹyin loun maa n duro si ki awon oluwode to jẹ ọdọ le e wa niwaju ki oun to wa ṣakiyesi pe awọn ọlọpaa kan fẹ maa dun mọhurumọhuru mọ wọn.
ti ajo eleto idibo ti sun ibo aare ati awon asoju-sofin to ye ko waye ni ojo kẹ́rìndínlógún,
"Iyawo kan ṣoṣo ni Islam ni ka fẹ amọ kọndisan lo gbe iyoku wa sugbọn ọkùnrin ti ko ba fẹ ki awọn obinrin fi igbọnsẹ ati itọ ṣe òògùn ifẹ fun oun, o dara ko ṣe deede laarin awọn iyawo to ba fẹ sile.
Iwe ti wọn fi ransẹ si wọn naa fihan wipe Pow Technologies Limited"" to kalẹ si ilu Abuja kọ lati ko irinsẹ ti wọn fi n se ayẹwo ina ninu ile ati kaakiri ile isẹ NAPTIN ti wọn san miliọnu mọkandinlogoji fun ninu miliọnu mẹtadinlaadọrun, amọ ti wọn kọ lati ko irinsẹ naa wa."
 ní 1872 ó tún jẹ ́ dídìbòyàn lẹ ́ kàansíi bíi ààrẹ làìbéríà keje .
Ninu ọrọ to ba BBC News Yoruba sọ, lori ẹrọ ibanisọrọ, alagba Ogun Majek ṣe e lalaye pe ajakalẹ arun Coronavirus to de lo gbe oun kuro ni ileewosan naa.
Àti pé dídárasí ati wíwuyìsí EarPod olówó pọ́ọ́kú yìí, bíi ti olówó iyebíye ni.
“Ǹjẹ́, orílẹ̀-èdè ńlá wo ni ó tún wà, tí ó ní oriṣa tí ó súnmọ́ ọn gẹ́gẹ́ bí OLUWA Ọlọrun tií súnmọ́ wa nígbàkúùgbà tí a bá pè é?
Titi di asiko naa, ko ti i ri iṣẹ kankan ṣe.
Ẹ̀yin ọlọ́pàá, ẹ di ìhàmọ́ra kẹ́ẹ já àlàfíà ìlú gbà padà - Ọ̀gá àgbà ọlọ́pàá Oríṣun àwòrán, NPF Ọga agba awọn ọlọpaa ni Naijiria, Muhammed Adamu ti fohun silẹ pe ẹni to ba tasẹ agẹrẹ yoo lori aṣẹ tuntun to ṣẹṣẹ jade fun araalu yoo foju wina ofin.
Bẹ́ẹ̀ sì ni OLUWA kò tíì sọ pé òun óo pa gbogbo Israẹli run, nítorí náà, ó ṣẹgun fún wọn láti ọwọ́ Jeroboamu ọmọ Jehoaṣi.
Alaafia, alaafia ni fún ọ,alaafia sì ni fún àwọn olùrànlọ́wọ́ rẹ!
Oyeyemi ni awọn yoo fi ọrọ sita lẹkunrẹrẹ nigba ti wọn ba t ri ọpa aṣẹ naa pada lodindi.
“Oníyẹ̀yẹ́” ni orúkọ ẹni tí ń gbéraga,tí ó sì ń ṣe mo tó báyìí-dà báyìí.
Nitori abajade ipade alaafia to waye lọdun 2003 eyi to mu ki igun ọlọtẹ pin agbara pẹlu ijọba, Ọgagun Ndayishimiye de ile de olori ọmọ ogun ilẹ Burundi nigba naa.
Wọ́n ti yan adarí tuntun míì fún fásitì Unilag Oríṣun àwòrán, Others Iroyin to n tẹ wa lọwọ ni pe awọn alaṣẹ ile iwe giga fasiti Eko, Unilag ti yan giwa tuntun mii lati maa tukọ ile iwe naa.
Ile-ẹkọ naa sọwipe lootọ ni awọn jẹ ijọba orilẹede Naijiria ni ẹgbẹrun lona mejilerugba owo okeere, $202,000, lẹyin ti wọn san gbogbo owo tan, sugbọ awọn ti fi owo naa si apo iṣuna kan ni ile ifowopamọsi.
A óò bẹ̀rẹ̀ sí san 30,000 owó oṣù òṣìṣẹ́ tó kéré jù lóṣù yìí- Fayemi Kiki Osinbajo gbóṣùbà fún Seyi Awolowo, MC Oluomo tọrọ ìbò fún Mike ní BBNaija Idahun di alẹ oni, ẹ sa maa ba wa bọ lati gbọ abọ iroyin lori ẹni to moke nile Big Brother Nigeria fun tọdun yii.
Bí ẹnìkan bá fi ẹ̀sùn kan àgbàlagbà, má ṣe kà á sí àfi tí ẹlẹ́rìí meji tabi mẹta bá wà.
Àkọsílẹ̀ fi yẹ wa pé títí di ọdún 2018, èèyàn mílíọ̀nù mejidinlogoji ni kòkòrò àrùn HIV àti AIDS ti sekupa jákèjádò agbaye.
Ọlọrun bá dá a lóhùn pé, “N óo wà pẹlu rẹ, ohun tí yóo sì jẹ́ àmì fún ọ, pé èmi ni mo rán ọ ni pé, nígbà tí o bá ti kó àwọn eniyan náà kúrò ní Ijipti, ẹ óo sin Ọlọrun ní orí òkè yìí.
Kí iná orí pẹpẹ náà sì máa jó, kò gbọdọ̀ kú nígbà kan.
Orile-ede Qatar ni yoo gbalejo ife ẹye agbaye lodun 2022.
Oriṣiriṣi fidio ibalopọ naa lo kun ori ayelujara Twitter ọmọkunrin ọhun, to ti ni ololufẹ to le ni ẹgbẹrun mẹrindinlọgbọn to n tẹle e lori ayelujara.
25bn Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Ohun tí ẹ̀ bá máa wí ni pé “Bí Oluwa bá dá ẹ̀mí sí, a óo ṣe báyìí báyìí.
Saaju asiko yii, ẹgbẹ oselu APC lo n dari akoso ipinlẹ naa ti gbogbo awọn asoju to fi mọ awọn to di ipo mu wa lati inu ẹgbẹ APC.
Bi a ba wo akọsilẹ to wa lati.
“Wàyí ò, èmi gan-an mọ̀ pé gbogbo ẹ̀yin tí mo ti ń waasu ìjọba Ọlọrun láàrin yín kò tún ní fi ojú kàn mí mọ́.
Àwọn ọmọ Besai jẹ́ ọọdunrun ó lé mẹtalelogun (323)
Bí abàmì ẹ̀dá náà ti jáde láti inú ilé rẹ̀, Baba-onírùngbọ̀n kọjú sí mi, ó wí pé; ‘Wò ó, ẹ̀dá pàtàkì náà ní ń bọ̀ lọ́hùn-ún nì, Ikú, ẹni tí ilé rẹ̀ ń bẹ lágbedeméjì ayé òun ọ̀run.
"Nigba to fi iriri ara rẹ ninu oṣelu yangan lọdun 2012, o sọ fun awọn ero ti o da bii pe ọrọ ko ye pe ""ẹyin eeyan mi, mo le sọ fun yin pe mo ti mọ aarẹ mẹjọ, mo si mọ mẹta ninu wọn denu denu"", ohun to si n sọ nibi ni pe o ti ba wọn lopọ ri dipo pe wọn kan jọ jẹ ọrẹ."
 Femi, ti oju rẹ kọrẹ lọwọ lori isẹlẹ bi wọn se dajọ iku fun Maryam Sanda wa rawọ ẹbẹ sawọn eeyan pe Ẹ jọwọ, ẹ dakun, mo rọ yin, ẹ jẹ ka maa sọra fun inufufu ati igbonara, ẹni apọnle ni abuku n wa kiri, adura mi si ni pe Ọlọrun oba yoo maa dari isisẹ wa.
Baba náà ni ó yẹ kí òun fi ọ̀rọ̀ obìnrin oloyun tó wà sì Èkìtì láti ìlú Èkó ṣe arikọgbọn, ẹni tó ko àrùn Coronavirus wá Ekiti láti Eko.
Eto naa, ta pe ni Akọmọlede ati Aṣa Yoruba, lo n waye fun igba akọkọ lonii loju opo ikanni BBC Yoruba, ti yoo si maa kọ wa ni ede ati asa wa, ko maa ba parun.
Nollywood: Àwọn ǹkan pàtàkì tó yẹ kí o mọ̀ nípa Clarion Chukwura
Ẹ gbọ ohun to sọ nipa kòkòrò náà.
Oríṣun àwòrán, gospelfilmsng Oríṣun àwòrán, gospelfilmsng Àkọlé àwòrán, Ayẹyẹ idagbere 'Bridal shower' ti awọn ọrẹ iyawo ṣe fun ṣaaju ọjọ igbeyawo re e.
Lucian Kendel Hippolyte’s pẹ̀lú orin-in ti wọn láti ṣe àrídájú wípé iṣẹ́ náà dé ibi tí ó yẹ kí ó dé.
Victor Agunbiade ni ojú àlá ni Ọlọrun ti yan iṣẹ́ ọmọ ogun ojú omi fún òun ní America Ilé ayé mi ti d'ojú bolẹ̀ pẹ̀lú ikú àfẹ́sọ́nà mi- àfẹ́sọ́nà Immaculate Okochu Àgbo Covid-19 Madagascar kò ṣiṣẹ́, àwọn ènìyàn tí bẹ̀rẹ̀ sí ní kú níbẹ̀ Ilé ẹjọ́ ju ọmọ ìjọ tó fi ìpá bá ọmọ pásítọ̀ rẹ̀ sùn ní ìpínlẹ̀ Ondo sí ẹ̀wọ̀n gbére Ọ̀nà márùn ún lati gbà dáàbòbò ara ẹni lọ́wọ́ ìjàmbá!
Ọlọ́pàá fìbọn fọ́mi lójú nítorí #100; ó ní eṣù ló ṣe òun- Akẹ́kọ̀ọ́ Adebayo Bi àwọn kan ṣé n jẹ àsun ní àwọn míì n ṣeré lórí omí láti gbádùn Kérésì àná Èyí ni ìdí tí a kò fi yọ̀nda El-Zakzaky pẹ̀lúù Sowore àti Dasuki- Malami Larisa ọmọ ọdún 66 bẹ̀rẹ̀ iṣẹ́ arìnrìn oge!
Bí àwọn ọlọ́ṣà tií ba de eniyan, bẹ́ẹ̀ ni àwọn alufaa kó ara wọn jọ, láti paniyan ní ọ̀nà Ṣekemu, wọ́n ń ṣe nǹkan ìtìjú láìbìkítà.
Bobrisky:'Mo bá ẹni tó kọlu mọ́tò mi jà bí pé mo mu ǹkan ní'
bẹ́ẹ̀ ni eniyan ṣe é sùn,tí kì í sìí jí mọ́,títí tí ọ̀run yóo fi kọjá lọ, kò ní jí,tabi kí ó tilẹ̀ rúnra láti ojú oorun.
Iyawo baba Amina Zakari ni ẹgbọn Buhari, ṣugbọn kii ṣe iya rẹ.
Láti agogo mejila ọ̀sán ni òkùnkùn ti bo gbogbo ilẹ̀, títí di agogo mẹta ọ̀sán.
Ninu ipo ate keyin ti o jade, Naijiria wa ni ipo méjílélógójì  lagbaye pelu ami  ẹgbẹ̀ta o le mesan lori tabili.
Oríṣun àwòrán, Bashir Ahmad Àkọlé àwòrán, Awọn janduku kọlu Buahri atawọn adari ẹgbẹ oṣelu APC Nṣe lawọn eeyan naa n sare gun ori odi ti wọn mọ yii papa iṣire naa ka lati sa asala fun ẹmi wọn.
Iwadii fihan pe ọna ti ọpọlọpọ ileeṣẹ ofurufu ni Naijiria n pa fi pa owo wọle ni gbigbe epo rọọbi ati afẹfẹ gaasi lọ si oke okun.
Ẹnikẹ́ni kò gbọdọ̀ ṣe iṣẹ́ kankan ní ọjọ́ náà; olukuluku yín ati ọmọ rẹ̀ lọkunrin ati lobinrin, ati ẹrú rẹ̀ lọkunrin ati lobinrin, ati ẹran ọ̀sìn rẹ̀, ati àlejò tí ó wà ninu ilé rẹ̀.
Ṣowore ati Bakare gbe awọn mejeeji lọ si ile ẹjọ giga l'Abuja, bakan naa ni wọn beere fun ẹẹdẹgbẹta miliọnu naira fun ẹni kọọkan wọn fun inira ti ajọ DSS fun wọn lati igba ti wọn ti wa latimọle.
New Kim gba oriṣiiriṣii ami ẹyẹ lẹyin to kopa ninu awọn idije ereeje kan.
Mọ ilana bi a ṣe n kọ arokọ ni kikun.
Ní ọ̀pọ̀ ìgbà tí o bá rí ẹnìkan to n lọ lójú pópó, ó maa ròó pé sáká ni àra rẹ̀ dá, pàápàá jùlọ, tó bá ń ṣàwàdà tàbí rẹ́rìn-ín, sùgbọ́n òótọ́ ibẹ̀ ni pé, wọ́n kan ń fí ẹẹrin náà bò ìṣoro wọn mọ́lẹ̀ ni.
' Onimọ nipa ofin jẹ ko di mimọ pe bakan meji ni ọ̀rọ̀ naa.
Buhari fi orukọ awọn Minisita tuntun ranṣẹ sile aṣofin
pe awọn mejeeji ni wọn gbọdọ ni iriri iṣẹ ẹka mejeeji.
Balogun ikọ Arsenal, Pierre-Emerick Aubameyang lo ra ọmi fun Arsenal nigba to gba goolu wọle ni iṣẹju kẹtalelọgọta ifẹsẹwọnsẹ naa.
Ó rúbọ sí àwọn oriṣa àwọn ará Damasku tí wọ́n ṣẹgun rẹ̀, nítorí ó rò ninu ara rẹ̀ pé, “Àwọn oriṣa àwọn ọba Siria ràn wọ́n lọ́wọ́, n óo rúbọ sí wọn kí wọ́n lè ran èmi náà lọ́wọ́.
 Gomina ipinle Katsina, Aminu Masari naa so pe : 
ati pe igbimo Olubadan yi kan naa lo lowo sii, bi o se de ipo naa.
Kó àwọn burẹdi ati àkàrà náà sinu agbọ̀n kan, gbé wọn wá pẹlu akọ mààlúù ati àgbò mejeeji náà.
Ẹnìkan bá sáré, ó ti kinní kan bíi kànìnkànìn bọ inú ọtí kíkan, ó fi sí orí ọ̀pá láti fún un mu, ó ń wí pé, “Ẹ jẹ́ kí á máa wò ó bí Elija yóo wá gbé e sọ̀kalẹ̀!
Ọṣu Kẹjọ, ọdun 2018 ni wọn da ikọ FSARS silẹ Ni ọdun 2018 ti wọn da ikọ SARS silẹ, ohun ti wọn sọ ni wi pe awọn wọnyii ko ni ma a da awọn eniyan duro lọna, lati ma wo ohun ti wọn gbe sinu ọkọ.
Nígbà tí ọba gbọ́ ọ̀rọ̀ yìí, ó fa aṣọ rẹ̀ ya láti fi ìbànújẹ́ rẹ̀ hàn.
Ẹ maa gbagbe pe itakun ayelujara 5G n lo afẹfẹ lati mu igbayegbadun awọn eeuan to ba n lo ẹrọ ibanisọrọ.
Ìpayà ati ìrora yóo mú wọn,wọn yóo wà ninu ìrora bí obinrin tí ó ń rọbí;wọn óo wo ara wọn tìyanu-tìyanu,ojú yóo sì tì wọ́n.
Kí ìwà rere ó gbèrú ní ìgbà tirẹ̀;kí alaafia ó gbilẹ̀ títítí òṣùpá kò fi ní yọ mọ́.
"O ní ìgbarata àjọ ọlọ́pàá ju ti àrá ilú lọ nítorí ọ̀rọ̀ náà ti fẹ́ mu ìtìjú dání fún ilé iṣẹ́ ọlọ́pàá, ""ṣùgbọ́n ti o ba ku pé ki a fi owó kún owó ẹbùn móríyá fún ẹni to bá bá ọlọ́pàá kẹ́fin Sunday ti yóò si sọ fun ọlọ́pàá, ilé iṣẹ́ ọlọ́pàá ṣetán láti ṣe bẹ́ẹ̀""."
N óo sì ba yín ṣẹ́ gègé níhìn-ín níwájú OLUWA ní Ṣilo.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ọmọyẹni lo jẹ aburo fun Ọmọlufa, agba naa kii si se agba kan to pẹ lọ titi, tori ọdun meji pere ni wọn gba lọwọ ara wọn.
Coronavirus Fake News: Ṣe lóòtọ́ bí àwọn olólùfẹ́ BBC Yoruba ṣe rí rè é?
Nígbà tí ó bá rí àwọn ẹlẹ́ṣintí wọn ń bọ̀ ní meji-meji, bí ó bá rí ití àwọn kan gun kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́,tí àwọn kan gun ràkúnmí,kí ó fara balẹ̀ dáradára,kí ó dẹtísílẹ̀ dáradára.
Nítorí náà, ẹ kò gbọdọ̀ bẹ̀rù wọn.
O gboriyin ayipada rẹ yi fun eniyan meji: ibatan rẹ kan, ati ọmọ ọdun mẹtala alakisa kan to pade nibi idije ere bọọlu alafẹsẹgba kan llyin to pari ileewe girama.
Nígbà tí Paulu ati àwọn ẹlẹgbẹ́ rẹ̀ kúrò ní Pafọsi, wọ́n wọ ọkọ̀ ojú omi lọ sí ìlú Pega ní ilẹ̀ Pamfilia.
iji yi to ri bi oval unyipo lonaodiago , pelu akoko bi ojo mefa .
Isho Pepper pẹ̀lú àfihàn àwọn ìyàwó tó jẹ́ igi lẹ́yìn ọgbà fun un níní iṣẹ́ tíátà
Òwúrọ̀ kùtù-kùtù kan ni èmi àti àwọn ọ̀rẹ́ mi wọ̀nyí gbéra, tí a kórí sí inú igbó kan.
Ogbeni  Bouteflika,ti o ti wa ni ori aleefa lati odun
Ẹ̀yin amòfin ati ẹ̀yin Farisi, ẹ̀yin aláṣehàn, nítorí ẹ̀ ń la òkun ati oríṣìíríṣìí ìlú kọjá láti mú ẹyọ ẹnìkan láti orílẹ̀-èdè mìíràn wọ ẹ̀sìn yín.
N óo sọ àwọn ọmọ rẹ di pupọ bí ìràwọ̀ ojú ọ̀run, n óo sì fún wọn ní ilẹ̀ wọnyi.
    “Báyìí ni mo wí ní tèmi tí mo kúrò ní ibojì bàbá mi tí mo wá sí ilé.
Ọlọrun rán wolii Jehu, ọmọ Hanani, pé kí ó sọ fún Baaṣa ọba pé, 
OLUWA, à ń bẹ̀ ọ́, gbà wá,OLUWA, à ń bẹ̀ ọ́, jẹ́ kí á ṣe àṣeyege.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ibidun Ighodalo: Ǹkan ti amọ̀ nípa ilúmọ̀ọ́ká arẹwà obìnrin nígbà kan rí tó d'olóògbé 5 Òkùdu 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 16 Òkùdu 2020 Oríṣun àwòrán, Others Awọn ebi oloogbe Ighodalo ti gbe oku rẹ lọ si ileewosan kan ni agbegbe Lagos Island ni ilu Eko.
ara ilu maa sa fun owo-ori sisan; ati awon isoro miiran le mu akude ba idagbasoke
“Inu mi dun pe iko agbaboolu yin se daradara, gege bi ijoba ojuse wa ni lati ran iko kookan lowo lati tun bo maa se daradara si.
OLUWA ní, “Láti ìgbà àtijọ́ ni mo ti kéde,àwọn nǹkan tí yóo ṣẹlẹ̀,èmi ni mo sọ wọ́n jáde,tí mo sì fi wọ́n hàn.
Ebi níí mú kí òṣìṣẹ́ múra síṣẹ́,ohun tí a óo jẹ ní ń lé ni kiri.
Jẹ́ kí á mú baba wa mu ọtí àmupara, kí á sì sùn lọ́dọ̀ rẹ̀, kí ó lè bá wa lòpọ̀, kí á le tipasẹ̀ rẹ̀ bímọ.
    Báyìí ni mo sọ fún ọkùnrin náà, níwọ̀n ìgbà tí ó sì ti jẹ́ pé gbogbo ilé ti sùn tán bámúbámú, tí o jẹ́ pé èmi nìkan ló kù tí kò sùn nínú ilé wa, èmi ni mo lọ fi ọbẹ̀ ra iná tí mo wá oúnjẹ fún un.
O sọ pe ko si iṣẹ kankan lọwọ oun bayii, toun si n beere iranwọ lọdọ awọn araalu lati se atọna bi oun yoo se ri isẹ.
Òfin ṣì gbẹ́sẹ̀lé Ẹgbẹ́ awakọ̀ èrò NURTW ní ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́ Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Sanusi ní òun ti gba kádàrá ṣùgbọ́n agbẹjọ́rò rẹ̀ ní àwọn ṣì lè gba ilé ẹjọ́ lọ Emir ana ilu Kano Sanusi Lamido Sanusi ni oun ti gba kadara iyọnipo to ṣẹlẹ si oun gẹgẹ bi amuwa lati ọdọ Ọlọrun.
Ẹgbẹ́ aláwọ̀ Dudu ni a ti rí Neo Dorathy Ozo Nígbà ti ẹgbẹ́ aláwọ̀ funfun ni Trikytee Vee Laycon Àwọn ẹgbẹ́ méjèèjì yìí yàn Laycon àti Trikyhtee bákan náà wọn mú Dorathy àti Ozo Nínú àwọn mẹ́rin yìí a kò tíì kò tii mọ eniyan meji tí yóò lọlé lònìí Tani ẹyi rò pé yóò lọ ilé nínú àwọn mẹ́rin yìí lálẹ́ òní Oríṣun àwòrán, Instagram/Nengi Nengi di olórí tuntun nílé ẹlẹ́gbọ̀n-ọ́n àgbà BBNaija Nengi ti di olori ile ẹlẹgbọn ọn agba Big Brother Naijia ọjọ Aje ọjọ kẹrinla oṣu kẹsan an.
Gómìnà ìpínlẹ Kwara yan Kọmíṣónnà tí ó kéré julọ!
 Anfani po nipa lilo apako dipo papa sunsun nitori pe awon ohun ajile atawon amohun ogbin dagba yoo si wa ninu ile ti eso yoo nilo fun idagbasoke.
Sleeping at work: Ǹjẹ o yẹ kí èèyàn máa sùn lẹ́nu iṣẹ́?
Mose bá kọjú sí Kora, ó ní: “Ẹ gbọ́ ẹ̀yin ọmọ Lefi!
Àmọ́ o, igun kan tó fi kanlẹ̀  kò dín ìyanu náà kù rárá.
Jẹ́ kí ìpayà bá wọn,ṣugbọn má jẹ́ kí èmi páyà.
Ó mọ odi yí mi ká,ó sì fi ẹ̀wọ̀n wúwo dè mí,kí n má baà lè sálọ.
oríṣìíríṣìí ìtàn ìwàṣẹ ̀ ló wà tó jẹ mọ ́ ìṣẹ ̀ dá ilé-ifẹ ̀ .
padanu ẹmi won, ni awon apa ibikan lorile ede yii nitori iwa buruku ti won fe
Ẹnìkan tí ó jẹ́ mímọ́ yóo kó eérú mààlúù náà jọ sí ibìkan tí ó mọ́ lẹ́yìn ibùdó.
ṣugbọn itan ilẹ ọlọraa ti gbogbo wọn yii n le yatọ nitori ọpọ lo n pada de ilẹ Amẹrika tabi awọn orilẹ-ede miran bẹẹ tan ti wọn wa di isansa, ati alarinkiri nitori iṣẹ ti wọn foju si ko waye.
Tí o bá ń ṣe bẹ́ẹ̀, ìwọ yóo gba ara rẹ là ati àwọn tí ó ń gbọ́ ọ̀rọ̀ rẹ.
Nibi ijoko itagbangba ti wọn se naa, lara ohun ti awọn yọ sita gẹgẹbi ohun to n fa ifasẹyin ba ipo ti awọn ọgba ẹwọn wa naa ni aisi ifọkansin to loorin lati ọdọ ijọba gbogbo, aisi isuna to kun oju iwọn.
Ko ti daju ibi ti Zlatan yoo lọ bayi ṣugbọn o ti n ta awọn eeyan lolobo pe awọn ẹgbẹ agbabọọlu kan ti n fifẹ han si pe ki oun darapọ mọ wọn.
Awọn ijọ nla nla lo kun iha Guusu Naijiria tii ṣe orilẹede to pọ ju ni Afirika.
Ìrònú ohun tí ọ̀lẹ fẹ́ ni yóo pa á,nítorí ọwọ́ rẹ̀ kọ̀ láti ṣiṣẹ́.
Kogi àti Bayelsa: Gomina Yahaya Bello ti Kogi àti David Lyon ti Bayelsa gba ìwé ẹ̀rí INEC
Iroyin fi mule pe, awon olopaa se amulo ohun ija tajutaju inu afefe ti  a mo si (Teargas) lati fi dina igbimo naa ti o n gbero lati wo ile igbimo asofin.
Wọn óo pa àgọ́ sí ààrin yín; wọn óo tẹ̀dó sí ààrin yín; wọn óo máa jẹ èso oko yín, wọn óo sì máa mu wàrà yín.
Àwọn ọmọ Efuraimu múra ogun, wọ́n ré odò Jọdani kọjá lọ sí Safoni.
to n sise pelu ajo United Nations.
Iroyin si ti fi idi ẹ mulẹ wi pe iya wọn ṣii n pọn abigbẹyin ni.
Wọ́n á ní ọmo àti aya nílé
Nítorí ẹni tí ó bá jìyà nípa ti ara ti bọ́ lọ́wọ́ agbára ẹ̀ṣẹ̀.
Ọrọ naa lo sọ Gassama di olokiki jakejado agbaye bi fidio kan ṣe jade nibi to ti n fo ile alaja mẹrin lati lọ doola ẹmi ọmọ naa tó fẹ́ ré jábọ́.
Láti Ijipti ati Kue ni àwọn oníṣòwò Solomoni tií máa bá a ra àwọn ẹṣin wá.
"Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Àwọn kànga ìṣẹ̀ǹbáyé rèé ní Badagry tó ń pa ẹrú níyè Ìyàwò lárìnlọọ̀dù mi pè mí ní akálòlò ni mo ṣe paa - Afurasí ""Ambode, wá jẹ́jọ́ lórí ọkọ̀ BRT 5000 to ló fi ₦45b rà, àmọ́ 820 péré ló kó wá"" Buhari, pe ìpàdé àpérò ọmọ Nàíjíríà fún àgbékalẹ̀ òfin tuntun - Afe Babalola ‘Kò sí ohun tó lè yẹ ìfèhọnú ọjọ karun un Oṣu Kẹsan lórí àtìmọ́lé Omoyele Sowore’ Iwadi si fi han pe owo to to triliọnu meji ati biliọnu lọna ogoje naira (₦2."
" Lẹyin naa lo gba ijọba apapọ niyanju lati ṣe ohun ti yoo rọ awọn ara ilu lọrun ni gbogbo igbesẹ to ba n gbe lati kapa arun naa nitori igbele akọkọ ko rọrun fun awọn eeyan.
Hydroxychloroquine, Zinc ati Zithromax : Ààrẹ Trump tí sọ̀rọ̀ nípa Dókítà Stella Immanuel,ẹ gbọ́ ohùn tó sọ
Àwọn ọmọ orílẹ̀èdè Mali ń fò fáyọ̀ pé ológun gba ìjọba mọ́ alágbádá lọ́wọ́ Ìròyìn ayọ̀!
“N óo pada sí ibùgbé mi títí wọn yóo fi mọ ẹ̀bi wọn, tí wọn yóo sì máa wá mi nígbà tí ojú bá pọ́n wọn.
Terver Akase ti ó jẹ́ agbẹnusọ fún Gomina Samuel Ortom sọ fún BBC Yorùbá pé, awon fadá ti o padanu ẹ̀mi wọn ninu ikolu naa ni Fadá Joseph Gor ati Fadá Felix Tyolaha.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Akomolede àti Aṣa: Ọ̀rọ̀ Ẹ̀yán ni Bunmi Femi Amao ń kọ́ wa lórí ètò Akọ́mọlédè àti Àṣà lóri BBC Yoruba Ifẹhonuhan lori afikun owo epo ọdun 2012 Ọjọ kinni oṣu kinni ọdun 2012 ni ijọba Good luck Jonathan kede pe ohun ti mu owo iranwọ ori epo(subsidy) kuro.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Lassa: Ẹnikan ku,ogoji mii wa labẹ ayẹwo l'Ọsun 12 Èrèlè 2018 Àkọlé àwòrán, Ọpọ ẹmi lo n sọnu sọwọ arun iba ọrẹrẹ lorilẹede Naijiria Eeyan kan ti ku bẹẹni awọn ogoji miran wa ni abẹ isọ kaakiri awọn ibudo ifinipamọsi fun ayẹwo to wa fawọn eeyan ti wọn ba kẹẹfin pe o seese ko ni arun iba ọrẹrẹ nipinlẹ Ọsun.
Ọjọ kẹrindinlọgbọn, oṣu Kẹwaa ọdun 2015 ni Ooni Adeyeye Enitan Babatunde Ogunwusi gori itẹ gẹgẹ bi Arole Oduduwa Olofin Adimula Ile Ife.
Nigba ti a beere bo ya ijọba apapọ mọ si bi wọn ṣe bẹrẹ si gba tariifu tuntun, oṣiṣẹ Disco naa sọ pe ajọ NERC nikan lo le dahun ibeere yii.
Ẹ gbọdọ̀ fi wọ́n sílẹ̀ fún àwọn talaka ati àwọn àlejò.
Ìgbà mi ń bẹ ní ọwọ́ rẹ;gbà mí lọ́wọ́ àwọn ọ̀tá mi,ati lọ́wọ́ àwọn tí ń lépa mi.
Igbagbọ rẹ ti mú ọ lára dá.
O tẹsiwaju pe lẹyin 200 biliọnu ti wọn san ni 2013 ati 20 biliọnu nipari 2018,ijọba ko ṣika adehun tawọn jijọ ṣe pọ.
Bishop Oyedepo: Ifedayo Olarinde tó ń jẹ́ Daddy Freeze tọrọ àforíjì pé o sọ ọ̀rọ̀ ẹ̀gbin sí David Oyedepo
Ni ọjọ Aje ni gomina Ambode sọ ọrọ yii nigba to n lewaju ayẹyẹ irin ipolongo kan ti wọn ṣe lati tako iwa ipa ninu ile ati iwa ifipabanilo lawujọ.
Ó ra ilẹ̀ ibi tí ó pàgọ́ rẹ̀ sí ní ọgọrun-un (100) gẹsita lọ́wọ́ àwọn ọmọ Hamori, baba Ṣekemu.
omo ile-igbimo asofin lo ti wa leba ona bayii.
Bákan náà, àwọn alufaa tí wọ́n jẹ́ aṣaaju ati àwọn eniyan yòókù pàápàá ṣe aiṣootọ sí OLUWA, wọ́n tẹ̀lé ìwà ìríra àwọn orílẹ̀-èdè tí ó yí wọn ká, wọ́n sì sọ ilé tí OLUWA ti yà sí mímọ́ ní Jerusalẹmu di aláìmọ́.
Alaga ẹgbẹ Arewa naa, Audu Ogbeh ni ọrọ agọ ni Obasanjo sọ, eleyii ti ko mu ọpọlọ dani rara, ti o si le e da wahala silẹ lorilẹede Naijiria.
Ojú mi ti ń bá ọ kiri nínú ìrìnkiri rẹ.
 Busari wa fi asiko ohun ,ke si ijoba to wa lode
“Eyi ti o niloo igbese ni kiakia lati so ise ohun osi di afiseyin teegun n fiso, eyi ti o n sokunfa laasigbo ni ekun naa”.
Àbí ohun tí ó wu eniyan ni mo fẹ́ máa ṣe?
Àwọn Olúkọ ìpínlẹ̀ Oyo fakọyọ lórí ètò Akọ́mọlédè àti Àṣà púpọ̀ Bawo igbeyawo Opeyemi Ayeola?
Ogun kidnap: Àwọn ajínigbé gbé ọkọ̀ ojú omi ọlọ́pàá lọ lẹ́yìn tí wọ́n dóòlà ẹ̀mí ọmọ Ìmáàmù
6m lórí ètò BBNaija torí pó sọ̀rọ̀ ìwúrí nípa Nàíjíríà Bí mo ṣe dúró ti Toyin nílé ìgbẹ̀bí jẹ́ kí ń mọ̀ pé ó yẹ kí ọkùnrin máa bọ aya wọn - ọkọ Toyin Abraham Ìjíròrò forí ṣánpọ́n lóri sísan owó oṣù tuntunÌdí rèé tí mi ò fi yọjú sí ìgbìmọ̀ àjọ PFN- Fatoyinbo Bakanna la ri minisita obinrin meje, ninu awọn mejidinlogun to jẹ minisita tẹlẹri kuna lati ri ipo bi ti Shittu.
awon ajo  to ni nnkan se pelu asa ati
Gen Ahmed Taiwo sọ lọ́jọ́ sátidé, pé àwọn olùfẹ̀hónú hàn #EndSars fẹ sọ ìpínlẹ̀ Eko di aláìlólórí.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Aṣọle fun Tottenham Hugo lloris mu pẹnariti ti ẹlẹsẹ ayo Man City Sergio Aguero gba.
Ọgbẹni Enwonwu, ti ọpọ eeyan ri gẹgẹ bi oludasilẹ iṣẹ ọna igbalode lorilẹede Naijiria ya oriṣi mẹta ẹẹda aworan Tutu.
Ile naa ni a gbo pe , awon ile
Wo bí mo ti fẹ́ ẹ̀kọ́ rẹ tó!
Atọmọdọmọ rẹ kẹrin ni yóo pada wá síhìn-ín, nítorí ẹ̀ṣẹ̀ àwọn ará Amori kò tíì kún ojú òṣùnwọ̀n.
Lati igba naa si ni awuyewuye ti n waye lori rẹ.
Ileẹjọ f'ofin de ọdun oro nipinlẹ Ogun Ẹ múra fún ogun ijọba àpapọ̀ - Ọbásanjọ́ 'Ekute jẹ ogun oloro lagọ ọlọpa' Obasanjo, Osinbajo, Shonekan àtàwọn èèkàn ọmọ Ogun nínú ìṣèjọba Nàìjíríà.
Solomoni ọba kó gbogbo apata wọnyi sinu Ilé Igbó Lẹbanoni.
din owo ọkọ ti awọn eniyan yoo maa wọ oko ku ni gbogbo ibudo ọkọ won to wa
Dá mi láre, OLUWA,nítorí ninu ìwà pípé ni mò ń rìn,mo sì gbẹ́kẹ̀lé OLUWA láìṣiyèméjì.
Ǹjẹ́ o mọ̀ pé ètò ìdìbò kan wà tí erin àti òkúta Dáyámọ́ǹdì leè yí èsì rẹ̀ padà Wo bí ètò ìsìnkú Tolulope Arotile ṣe n lọ nílùú Abuja Ìjọba ìpínlẹ̀ Kano tí wọ́gilé ayẹyẹ lẹ́yìn ìrun ọdún Iléyá!
Ṣugbọn bí alufaa bá yẹ̀ ẹ́ wò, tí irun ọ̀gangan ibẹ̀ kò funfun, tí kò sì jìn ju awọ ara rẹ̀ lọ, ṣugbọn tí ó wòdú, kí alufaa ti ẹni náà mọ́lé fún ọjọ́ meje.
Wọ́n bá tún bẹ̀rẹ̀ sí sọkún.
    Nínú gbogbo wa, kò sí ẹni tí kò fi ara pa àfi Ìbẹ̀ǹbẹ́-Olókùnrùn.
Oríṣun àwòrán, Office of the Governor Àkọlé àwòrán, Gomina Okezie Ikpeazu, Nasir El Rufai , Bala Muhammed ati Seyi Makinde Esi ti gomina Ikpeazu kọkọ fi han pe ko ni arun naa nigba to lọ ṣe ayẹwo lọgbọn ọjọ oṣu karun ṣugbọn nigba to pada lọ ni ọjọ kẹrin oṣu kẹfa, o pada wale pẹlu esi pe o ni arun naa.
Ẹgbẹ OIC tun pinnu pe awọn yoo ṣe imugbooro aṣa ati imọ sayẹnsi lawọn orilẹede to jẹ ọmọ ọhun.
Ramadan, wakati ṣọ̀tọ̀ọ̀tọ̀, kini ẹ mọ̀ nipa àwọn Yollywood?
Ile iwe ọhuun, Government Science Secondary School, to jẹ ti awọn akẹkọọ ọkunrin nikan ní akẹkọọ to le ni ẹgbẹrin.
Eto idibo 2019 ni yoo je eyi to le ju ti awon alatako ANC lagbara julo lati odun 1994 nigba ti won fopin si ikonileru ara eni.
Nígbà tí ó ti dágbére fún wọn, ó lọ sí orí òkè, ó lọ gbadura.
Kini ijọba ti ṣe fun awọn eniyan abule yii?
Ọlọ́gbọ́n ọmọ ni ọmọ tí ó pa òfin mọ́,ṣugbọn ẹni tí ń bá àwọn wọ̀bìà rìn, ń dójúti baba rẹ̀.
Ọdun kẹrin lo wa nileewe nigba ti ọwọ tẹ ẹ pe o joko ṣe idanwo fun akẹkọọ mi.
Ijoba naa ni eto naa wa lati
'Ọọ̀nì ńlá méjì ní wọ́n jọ ń gbé nínú iyàrá' Simí, Davido gba àmì ẹ̀yẹ 'Headies' Davido fi mọ́tò #45 milionu dá Chioma lọ́lá Davido, Falz, Tiwa Savage tàn bí oòrùn ní AFRIMA Hamen ṣalaye fun BBC pe orin kikọ dabi iwe, ẹbi ati aburo fun oun.
Ààrẹ fi nǹkan ọkùnrin rẹ̀ pa mí lójú, kó tó fipá bámi lòpọ̀ - Ọmọge Arẹwà Thomas John: Kí ló yẹ kóo mọ̀ nípa adelé alága NNPC tuntun?
Oríṣun àwòrán, @followlasema Ó fi kún un pe wọn ti ti ile naa pa, lati dena ijamba miran.
“Ọkunrin tí wọ́n bá tẹ̀ lọ́dàá, tabi tí wọ́n bá gé nǹkan ọkunrin rẹ̀, kò gbọdọ̀ bá ìjọ eniyan OLUWA péjọ.
O óo sọ gbogbo ẹ̀ṣẹ̀ wa sí ìsàlẹ̀ òkun.
 ajèbú àti olóde jé lára àwon àtèlé alárè .
Oríṣiiriṣii àpẹẹrẹ irufẹ awọn ọkunrin bẹẹ lawọn eeyan n fi lede loju opo Twitter.
Diẹ lara awọn eeyan to baa ileeṣẹ BBC News sọrọ nipa awọn mọlẹbi wọn to ku ṣalaye pe itọ ṣuga tabi aisan ọkan lo ja okun ẹmi wọn.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Cameroon first daughter: Ọmọ ààrẹ lọ ṣí sọ́ọ́bù irun ṣí Amerika 13 Agẹmo 2020 Oríṣun àwòrán, Brenda Biya/Facebook Oriṣiriṣi awuyewuye àti ariwisi lo ti n waye lori bi Brenda Biya, ọmọ aarẹ orilẹ-ede Cameroon, Paul Biya ṣe ṣi sọọbu irun tita silẹ Amerika.
Yóo fi àáké gé àwọn igi igbó tí ó dí, Lẹbanoni pẹlu gbogbo igi ńláńlá rẹ̀ yóo sì wó.
Ọsun Decides: Charlie Boy ni ọ̀pọ̀ àìda ló wáyé lásìkò ìbò Ọ̀sun
O tun wa ro awon omo leyim Kristi lati lowo ninu eto oselu, yala ki won je oludije labi oludibo.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Port Harcourt: Afurasi tó fa ìpayà nílé ìwé ti bọ́ sọ́wọ́ ọlọ́pàá 26 Èbibi 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 27 Èbibi 2019 Oríṣun àwòrán, Google Àkọlé àwòrán, Fidio to jade safihan awọn akẹẹkọ girama ti wọn n sa asala fun ẹmi wọn lẹyin ti ọkan ninu won da ipaya sile.
Ninu ọrọ to kọ soju opo Instagram rẹ, o ni ọmọ Naijiria to jẹ akọrin, Burna Boy, lo pe oun lati fi nkan to n ṣẹlẹ ni Naijiria to o l'eti.
O sọ pe oju ẹsẹ lo ku.
Akọwe ẹgbẹ oṣelu PDP, Kola Ologbondiyan lo sọ ọrọ yii ninu atẹjade ti ẹgbẹ oṣelu naa fi lede.
 gbogbo wọn ń tàkurọ ̀ sọ , wọ ́ n ń retí ọmọ wọn tí wọ ́ n pè sí ìpàdé .
Àwọn ọmọ Israẹli ṣẹgun àwọn ará Midiani, wọn kò sì lè gbérí mọ́; àwọn ọmọ Israẹli sì sinmi ogun jíjà fún ogoji ọdún, nígbà ayé Gideoni.
Ẹwẹ, ẹka to n risi ọrọ Iroyin nipa ẹgbẹ APC loju opo Facebook wọn ti fi ikede sita wi pe, ko si ootọ ninu iroyin kan to ni pe awọn ọdọ koju oro si Yahaya Seriki.
 Mo si dupe lopolopo fun awon omo Naijiria fun orisirisi adura atejise ti won ma n fi n ranse si mi lori ero ibanisoro mi.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ọlọ́pàá gba àna ADC Buhari silẹ̀ lọ́wọ́ ajínigbé Ìròyìn Yàjóyàjó - Ẹ wá gbà wá ní Ijegun o, Ọ̀pá epo ń jóná lọ́wọ́lọ́wọ́!
Ọga Bello tun tako ọrọ kan ti akẹẹgbẹ rẹ ninu isẹ tiata, Yẹmi Solade sọ pe, alagbe ni ọpọ osere tiata.
Galadima,(The Alliance for New Nigeria ,ANN)  Khadijah Abdullahi-Iya, All Progressive Congress
Delila tún wí fún Samsoni pé, “Sibẹsibẹ o ṣì tún ń fi mí ṣe ẹlẹ́yà, o tún ń purọ́ fún mi.
 Arinrinajo kan lati ile Amerika to pe oruko ara re ni Laurie ni: “Ibi yii je okan pataki lara awon ibudo ti arinrin ajo maa n fe wa yewo ki o si fi gbadura.
Àwọn ni a gbọ́ pé ó dóòla ẹ̀mí ọmọ náà.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ìbejì Oníbẹ̀mbẹ́ Òru tí kò yara wọn lẹ́yìn ọgọ́ta ọdún Ohùn ìjálá lásán ni mo fi ń pa ẹran nínú igbó - Ọdẹ Oníjàálá Mo fẹ́ ọkọ mi torí bó se ń kọrin, kìí se torí owó - Ìyàwó Aràrá Mo fẹ́ kí àyẹyẹ ìgbeyàwó mi dùn ni mo se bú sẹ́kún - Ọkọ ìyàwó ẹlẹ́kún Samuel Ladoke Akintọla jẹ́ Agbẹjọ́rò àti Akọ̀ròyìn tí ọ̀rọ̀ dá lẹ́nu rẹ̀ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ìfipálówó: Bàbá ọmọ tí wọn gé lórí ní òun rán an láti l gbowó lẹ́nu ATM ni O ni pe 'botilẹ jẹ wi pe oun ko ni gbe oludije kan le wọn lori, imọran ti oun yoo gba awọn ọmọ Naijiria ni pe, ẹni ti yoo mu idagbasoke ati ayipada ba igbe aye wọn ju boṣe wa bayii lọ, ni ki wọn dibo fun.
“Mo ri i bi awon adari ile Amerika se n tuko ijoba won, bee si ni, mo ri pe a nilo adari ti o mo bi yoo se seto ilu, bi awon omo wa yoo se ri ise, bi idagbasoke yoo se de ba ina mona-mona , bi ounje yoo se po lopo yanturu, ti iyan ati osi yoo se di afiseyin ti eegun n fiso, lorile ede Naijiria.
Ninu iwóde yii ni ogunlọgọ awọn ọdọ ti ya bo igboro lati pe fun wiwagbo dẹkun si iwa aitọ awọn ọlọpaa.
N óo pa ìró ayọ̀ ati ẹ̀rín rẹ́ láàrin wọn, ẹnìkan kò sì ní gbọ́ ohùn ọkọ iyawo ati ohùn iyawo tuntun mọ́.
Ìfẹ̀hònú hàn nàá tó wáyé lọ́jọ́ kẹsàn án, oṣù Karùn ún, ni wọ́n ṣe, láti fi rawọ́ ẹ̀bẹ̀ sí Tinubu, kó le bá Ààrẹ Muhammadu Buhari sọ̀rọ̀, láti tú olórí wọn, Ibrahim Zakzaky, sílẹ̀.
Iroyin fidi rẹ mulẹ pe awọn oluwọde naa ṣi peju babi sibi iwọde ni iloro Lekki Tollgate naa lai naani aṣẹ konile o gbele ti ijọba pa bẹrẹ lati agogo mẹrin irọlẹ ọjọ Iṣẹgun kan naa.
Ati pe oun ko ti ẹ le fi ori ṣiro ibanujẹ ti iku rẹ jẹ fun ẹbí rẹ.
Àwọn eniyan náà jẹ, wọ́n sì yó;nítorí pé Ọlọrun fún wọn ní ohun tí ọkàn wọn fẹ́.
Don Messerschmidt kọ nípa  àkọsílẹ̀ tí onímọ̀-nípa-ẹyẹ S.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Buhari, tètè gba isẹ́ lọ́wọ́ àwọn ọ̀gá ológun - Afẹnifẹre Buhari buwọ́lu owó oṣù tuntun fáwọn ọlọ́pàá Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Goodluck Jonathan ní òun nìkan kọ́ ló l'ẹ̀bi ìjínigbé akẹ́kọ̀ọ́ Chibok àti Boko Haram Ẹgbẹ́ alákatakítí agbébọ̀n tuntun wọ Nàìjíríà!
Ẹ̀yin tẹ́ẹ tako àgbékalẹ̀ àgọ́ Fulani, ìkórira ló ń yọ yín lẹ́nu - Ìjọba àpapọ̀ Òṣìṣẹ́ OSCOTECH gb'òmìnira lọ́wọ́ ajínigbé darandaran Fulani Ọmọogun pa darandaran mẹwa ni Adamawa Fulani darandaran lo iwa ipa ni guusu Akurẹ Sanwo Olu yan kọ̀míṣọ́nnà 25 àtàwọn olùbádámọ́ràn Àwọn olówó Naijiria 5 tí owó wọn ju owó ìsúnná Naijiria lọ!
Lẹnu ọjọ mẹta yi, aisan iba ọrẹrẹ gbale kaakiri orilẹede yi.
Aarẹ Buhari tun fi ero rẹ han lori awọn ọrọ mii bi ọrọ awọn atipo abẹle, iwa ajẹbanu ati igbogun ti iwa ibajẹ kaakiri nilẹ Afrika, ati awọn ọrọ mii to se pataki.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Stolen phone: Fóònù mi ni mo lọ́ tún ṣe lọlọ́pàá bá he mí pé mo jí fóònù Ifẹhonuhan si waye nigba naa.
 O ni: “Ero wa ni ki ile iṣẹ fiimu ti Togo naa di orisun iṣẹ oojọ fun awọn eeyan.
Nígbà tí àwọn ọmọ Israẹli rí i pé Abimeleki ti kú, olukuluku gba ilé rẹ̀ lọ.
Patí oṣù mẹ́ta tí mo ṣe ló jẹ́ kí Anthony Joshua fọ́ mi lẹ́nu-Andy Ruiz Oríṣun àwòrán, Getty Images Anthony Joshua ti gba igbanu ẹyẹ abẹṣẹkubiojo to gbayii julọ lagba fun ipele WBO, WBA, ati IBF pada lọwọ ẹni to doju rẹ kọ orun alẹ ni nnkan bii oṣu mẹfa sẹyin, iyẹn Andy Ruiz.
“Ìwọ ọmọ eniyan, Nebukadinesari ọba Babiloni mú àwọn ọmọ ogun rẹ̀ gbógun ti ìlú Tire kíkankíkan.
Naira Marley: Ilé ẹjọ́ sún ìgbẹ́jọ́ Naira Marley lórí ẹ̀sún jìbìtì
Nítorí mo fẹ́ kí ẹ mọ̀ dájúdájú pé, ọ̀pọ̀ àwọn wolii ati àwọn olódodo dàníyàn láti rí àwọn nǹkan tí ẹ̀ ń rí, ṣugbọn wọn kò rí wọn; wọ́n fẹ́ gbọ́ àwọn ohun tí ẹ̀ ń gbọ́ ṣugbọn wọn kò gbọ́.
Ruga ati Fulani, nibo ni wọn ti papọ?
O fẹrẹẹ dabii fa ki n fa laarin oun ati adajọ.
loju pe won yoo se atileyin fun won , ijoba ko tun ni dakẹ adura fun awon
O sọ fun BBC wipe ti wọn ba bẹrẹ si ni gbin igbo ni Ipinlẹ Ondo ti ijọba si gba a laye labẹ ofin, alaisan yoo le wọ ile itaja oogun lati ra igbo gẹgẹ bi oogun lai ni iwe dokita lọwọ nitori abojuto oogun lilo ko fẹṣerinlẹ to.
Ṣugbọn olódodo ni Oluwa, òun ni yóo fi ẹsẹ̀ yín múlẹ̀, tí yóo sì pa yín mọ́ kúrò ninu ibi gbogbo.
Bíótiwùkíórí, láì jọ ti àwọn alágbádá – Yar'Adua àti Jónátánì – tí ó gbé ní arugẹ, tí ó sì tún yẹpẹrẹ wọn, ti Buhari dá yàtọ̀ gedegbe.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Bayii ni ẹgbẹ kan ṣe fi ijo ibilẹ da awọn eeyan lọla nibi ayẹyẹ ominira Naijiria lọdun 1960.
Ilẹ̀ náà yóo bẹ̀rẹ̀ láti ibi tí ilẹ̀ mímọ́ pin sí, lọ sí ààlà tí ó wà ní apá ìlà oòrùn, ati ibi tí ilẹ̀ mímọ́ náà pin sí, lọ sí ààlà tí ó wà ní apá ìwọ̀ oòrùn.
Kedere ni ohùn ń jáde láti inú ilé àpérò ìlú-mọ̀ńká United Nations Conference ní Paris (COP21) lọ́dún-un 2015.
N óo fi ẹ̀mí mi sinu yín, ẹ óo sì tún wà láàyè; n óo sì mu yín wá sí ilẹ̀ yín.
“Àwọn ará Taṣiṣi ń bá ọ rajà nítorí ọpọlọpọ ọrọ̀ rẹ: fadaka, irin, páànù ati òjé ni wọ́n fi ń ṣe pàṣípààrọ̀ ọjà lọ́dọ̀ rẹ.
Minisita fun  eto iroyin  ati asa lorile ede Niajiria Alhaji Lai Mohammed,ti ro ile akede orile ede Amerika(VOA) lati fọwọsowọpọ pelu ijọba orile ede Najiria lati gbokun ti awọn iroyin eke , ni eyi ti iyipada yoo se de ba oju ti wọn fi n wo orile ede yii.
Lẹ́hìn ṣíṣe ìpínfúnni oúnjẹ alẹ́ Olúwa, Joseph àti Oliver gbé ọwọ́ lé àwọn olùkópa lórí ní ẹnìkọ̀ọ̀kan fún ìfifúnni Ẹ̀mí Mímọ́ àti fún fifi ìdí ẹnìkọ̀ọ̀kan múlẹ̀ gẹ́gẹ́bí ọmọ ìjọ.
Ó dá agbọ́tí pada sí ipò rẹ̀ láti máa gbé ọtí fún un, 
Lẹhìn eléyìínì bàbá mi kọjú sí ọ̀nà tirẹ̀ àwọn náà sí kọkú si ọ̀snà tiwọn.
Deji Akure pàṣẹ kí wọ́n ti gbogbo ọjà pa fún ọjọ́ méjì, ohun tó fàá nìyí Wo ohun tó ṣẹlẹ̀ sí Saka, Sunkanmi Omobolanle àtàwọn òṣèré sinimá míràn lọ́sẹ̀ yìí Làásìgbò òṣèlú wáyé nílùú Ondo, ọ̀pọ̀ èèyàn fara pa Kí ni ọkùnrin yìí ṣe tí bàbá rẹ̀ fi só mọ́lẹ̀ fún ọgbọ̀n ọdún?
Ṣé irú ẹni bẹ́ẹ̀ ni o dojú kọ,tí ò ń bá ṣe ẹjọ́?
 Bi mo si ṣe maa n ṣe iru awọn eto ironilagbara yii lọdọdọọdun ree, o kan ṣe pe mo fi ti ọtẹ yii sọri awọn agbalagba nikan ni”.
Olùfẹ́, má tẹ̀lé àpẹẹrẹ burúkú, ṣugbọn tẹ̀lé àpẹẹrẹ rere.
Ẹkunrẹrẹ lori iroyin yii wa ni: Ẹyẹ j’ẹyẹ lọ!
Akonimoogba agba iko agbaboolu orile-ede DR Congo, Florent Ikwange Ibenge ti kede iko ti o kun fun agbaboolu méjídínlọ́gbọ̀n  ti yoo koju iko agbaboolu Super Eagles ninu ifesewonse olorejore saaju ifesewonse idije boolu agbaye to n bo lona.
Eyi ko sẹyin ofin tuntun ti ileesẹ ìjọba Naijiria to wa fun fifi nkan ránṣẹ, NIPOST, fi sita pe awọn ileesẹ naa yoo ma san awọn owo kan bayii.
ọrọ tirẹ, Alaga Ikọ Ẹṣọ Alaabo ilu labẹle ni Ipinlẹ Eko (LNSC) yii,
Leon van Biljon dí èrò ọrun nípasẹ̀ Kìnìún rẹ̀ Sugbọn bi mo ṣe wa niwaju yin bayi, mo lee sọ kedere pe, ẹni ire lee darapọ mọ eto oṣelu.
jẹ́ ọ̀kẹ́ meji le ẹẹdẹgbẹjọ (41,500).
Ààrẹ Buhari wọ́gilé kí àwọn òṣìṣẹ́ ìjọba máa wọ ọkọ̀ bàálù olówó gọbọi Aarẹ Buhari kẹ́dùn ọ̀pọ̀ ẹ̀mí àti dúkìá tó jóná ni ọjà Onitsha A ti fẹnu kò lórí ọ̀rọ̀ Brexit- Boris Johnson Bàbá ìsàlè ilé ìwé fásitì Nàìjíríà ni Ọba Enitan Ogunwusi!
Ọmọ Downsydrome ti mo bí ló fún mí láǹfàní láti de ilú Oyinbo O fi kun ọrọ rẹ pe awọn obi oun ranṣẹ pe ẹbi ọkọ oun lati yanju ọrọ, ṣugbọn ẹnikẹni ninu wọn ko yọju.
Wọn sin gbiyanju ati da awọn ẹniti ajalu naa ba l'ọwọ.
Kamilu Compo - BBC News Yorùbá BBC News, YorùbáFò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ń ko dúró ṣe ìdánwò WAEC nílé ẹ̀kọ́ gírámà, kí n tó bẹ̀rẹ̀ tíátà - Kamilu Compo 13 Èrèlè 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 7 Èbibi 2020 Oríṣun àwòrán, kamilu kompo Ilumọọka osere tíátà kan, Tijani Adekola, tí ọ̀pọ̀ èèyàn mọ si Kamilu Compo àbí Gọlugọ, tí kesi àwọn olólùfẹ́ rẹ láti má ṣe bá ẹnikẹ́ni dá àṣà pé ko si ohun tó ń jẹ àrùn Coronavirus.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Inú mi máa ń dùn láti kọrin fún àbúrò mi - Josh Posh Obìnrin awakọ̀ Bàálù àkọ́kọ́ láti Ọffa rèé Wo ilé Adebisi Idikan n‘Ìbàdàn, àwòdamiẹnu ni '₦30,000 ní mo fí bẹrẹ iṣé perfume tita' 'Èmi ò kí ń ṣe ọkọ torí mi ò kí ń ṣe ojúṣe mi' Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí kan sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
Bẹẹ naa lo fi ọrọ ibanikẹdun ransẹ si awọn mọlẹbi arabinrin Salau to padanu ẹmi rẹ lasiko to n ja fẹtọmọniyan lọwọ ifiyajẹni ati aisedeede.
daabo bo ile naa, ki o maa baa dawo lulẹ.
Ajọ to n risi iṣẹlẹ pajawiri nipinlẹ Eko, LASEMA, ti parọwa sara ilu lati sọra fun wiwọ ọkọ oju omi lalẹ.
” Kò sì sí oró májèlé ninu oúnjẹ náà mọ́.
O le ni àádọ́jọ (150) ololufe ere boolu ti wọn  je  omo orile ede Naijiria  ti  awọn  onibara  ọkọ  ofurufu kuna lati ko pada wa si orile ede Naijiria , ni eyi ti  awọn  eniyan naa lo si ile-ise to n soju orile ede Naijiria ni Moscow lojo kejila osu keje , lati beere fun iranwo lati odo ajo naa leyin ti ere boolu idaraya  to waye lọdun yii pari .
O ṣalaye ni kikun lori bi ijamba ọkọ naa ṣe waye nigba ti o n fa abajade wọn le Ogagaun Hadi Ahmed to jẹ Commander 453 Base Services Grioup (453 BSG) ni Kaduna.
 Àrùn náà a tún má a wáyé lára àwọn ẹranko melo kan yàtọ ̀ sí lára ọmọ ènìyàn .
Àwọn kan ń lo ayùn, àwọn mìíràn ń lo ọkọ́ onírin, ati àáké onírin, àwọn mìíràn sì ń gé bulọọku, wọ́n ń sun ún.
Àfàìmọ̀ kí Naira Marley má fi ẹ̀wọ̀n bẹ̀rẹ̀ ọdún 2020 Àwọn orílẹ̀èdè tó ti ṣáájú Nàìjíríà wọ ọdún 2020 Nàìjíríà bí ìkókó 26, 039 lónìí ọjọ́ kíní, oṣù kínií, ọdún 2020- UNICEF Idi ti EFCC ṣe mu Sheu Sani S'ahamọ.
Ọgbẹni Adekunle ni ta lo mọ boya oogun Flagyl gan le ṣe itọju aarun HIV lẹyin tawọn onimọ iṣegun ti sọ pe, Chloroquine dara lati koju corona virus.
Diẹ lara awọn to ṣajọyọ yii pẹlu Alayeluwa ni alaga awọn onimọ ẹrọ ẹka ti ipinlẹ Oyo / Osun / Ondo / Ekiti, Ogbẹni Kola Akosile atawọn mii.
Eliudi bí Eleasari, Eleasari bí Matani, Matani bí Jakọbu.
Àwọn ni olórí tí a yàn ninu àwọn ọmọ Israẹli, olukuluku wọn jẹ́ olórí ninu ẹ̀yà wọn, ati ní ìdílé wọn.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù O burú jai!
Igbimọ naa rọ awọn ọmọ Naijiria pẹlu lati maa rinrin ajo lọ si lọ si oke okun lasiko yii yala fun iṣowo tabi isinmin papaajulọ si awọn orilẹede ti arun coronavirus ti n ṣọṣẹ lọwọlọwọ.
Osise ajo INEC nipinle Osun, ojogbon  Olusegun Agbaje kede abajade  esi idibo aare niluu Abuja.
Orúkọ awọn ibeji akọkọ naa ni Jade ati Jamine nigba ti Taiwo tun bi ibeji miran lọdun 2017, ọkùnrin kan ati obinrin kan si ni awọn ọmọ naa.
Kèǹgbè lílù ní Ilọrin rèé, orin ìgbéyàwó, àwàdà àti ẹ̀ẹ̀kẹ́ èébú Russia tun n pese iranwọ nidi imọ ẹrọ igbalode nidi ohun ijagun oloro fun ọpọ awọn orilẹede ni ilẹ Afirika, to fi mọ sise agbekalẹ ibudo ipese ohun eelo ijagun oloro lorilẹede Egypt lọdun to n bọ, eyi ti yoo na wọn to owoya biliọnu mẹẹdọgbọn dọla.
Abala ofin mẹrẹẹrin si jẹ ti ọdun 2004.
 Osaka se so, “Inu mi dun ti mo se kopa si, bee si
Àdó olóró Iran: Trump ati Macron fẹ́ s’àdéhùn tuntun
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Mọ̀ síi nípa Shina Rambo tó pàdé Jesu lọ́gbà ẹ̀wọn lẹ́yìn tó ti jalè Ogun Àgbẹ́kọ̀yà, ìjà òmìnira fáwọn àgbẹ̀ ni àbí ìfẹ̀míṣòfò?
Akọsilẹ wọn fihan pe ikọlu tọdun 2008 ati ti 2015 lo lagbara julọ.
Ni ọjọ kọkanlelogun, oṣu Kọkanla, ajọ DSS da awọn oṣiṣẹ ajọ EFFC duro lati maa fi ofin gbe Ita Ekpeyong, to jẹ Ọga agba ajọ DSS tẹlẹ, lai fi ti pe wọn ni aṣẹ lati mu u ṣe.
Awọn fẹndọ fẹ se iwọde ifẹhonu han Ẹwẹ awọn fẹ́ndọ to n ta iwe iroyin lAbuja sọ pe awọn yoo bọ si igboro lati se iwọde lori iku ọkan lara wọn yi.
Gbogbo àwọn tí wọ́n wà pẹlu Saulu sì wà ninu ìbẹ̀rù ńlá.
Ìtan ilu Daura ko pe rara lai sọ nipa kanga Kusugu.
Ninu aworan to fi sita loju opo Instagram rẹ, babasuwe_official, ibẹ lo ti kede pe oun ti wa ni ẹnu isẹ ere tiata pada.
Ó ń sọkún tẹ̀dùntẹ̀dùn lóru,omijé ń dà lójú rẹ̀,kò sì sí ẹni tí yóo tù ú ninu, láàrin àwọn alajọṣepọ rẹ̀.
Ọlọ́pàa dóòlà ẹ̀mí fadá mẹ́rin lọwọ àwọn ajínigbé
Amọ o fikun pe àwọn ni ọ̀gá tí wọn n fún wọn ní ẹgbẹrun lọna ẹẹdẹgbẹta naira, ₦500,000 tàbí ẹgbẹrun lọna ẹgbẹta naira, ₦600,000 náírà ńbẹ.
Ṣé ó lè fún wa ní òkèlè pẹlu,àbí ó lè pèsè ẹran fún àwọn eniyan rẹ̀?
Bakan naa, nigba ti Wunmi Toriola ṣe ọjọ ibi ni ọjọ kọkanla osu keje ọdun 2020, Seyi Edun kan ki i ranpẹ ni, eyi to mu ki awọn eeyan kan bẹrẹ ẹjọ lori ayelujara.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Antoine Griezmann lo gbá bọọlu kọju-simi-n-gbaa sile fun àwọn Les Bleus.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àwọn ọmọ Yorùbá àtàtà: Báwo lẹ se gbọ́ òwe sí ?
Ni ọjọ mẹta ṣẹyin, ni osu kẹrin, ọdun 2020, ni Abiola Ebila pa orogun rẹ ninu ẹgbẹ okunkun miran, Ekugbemi, lati igba naa si ni awọn agbofinro ti n wa Abiola Abila, ko le e koju igbejọ ẹṣun naa.
Ọpọ ijiroro waye nibi ipade naa.
Ó ṣa igba (200) ewúrẹ́ ati ogún òbúkọ, igba (200) aguntan, ati ogún àgbò, 
O sọ nipa asiko ti ere naa yoo di wiwo ni kaakiri Dino Melaye fìdí rẹmi, Smart borí nílé ẹjọ́ kòtẹ́milọ́rùn Ta ni Sadiya Umar Farouq tí ìròyìn ẹlẹ́jẹ̀ ń gbé pé òun ló fẹ́ dí ìyàwó tuntun Buhari?
 Ronkẹ Oshodi-Oke wá ń bèèrè pé kín ni wọ́n ń se èyí fún?"
Oloogbe Worlu ti n sise ninu ajo to n ri si oro ile-okere lati ogbon odun seyin, aare wa sapejuwe iku oloogbe naa gege bi ohun ti o bani n nu je lopolopo.
Ẹ wo iye t'óúnjẹ dà báyìí lọ́jà lẹ́yìn tí ìjọba ti ibodè Ilé ìwòsàn New Jersey ṣ'àṣìṣe ṣiṣẹ́ abẹ kìndìrín fún aláìṣàn l'Amẹrika Eku gba ìjọba ní Estonia, ìjọba pàdánù owó gọbọi EFCC fẹ́ gbẹ́sẹ̀ lé ilé tí mo fi owó ìfẹ̀yìntì kọ́ nílùú Ilorin- Saraki Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ọmọ Yahoo tú àṣírí ara rẹ̀ fún, bí wọ́n ṣe ń ṣe é BBC Yorùbá Watchiranot Thongtep ati Smitanan Yongstar ni wọn ṣafikun iroyin yii ka to gbe e wa si eti igbọ yin.
O fi kun un wi pe koda, owo ajẹmọnu ti ijọba Naijiria n sọ yii, ọdọ awọn dokita ijọba apapọ nikan lo n de, bi yoo ba kan awọn oṣiṣẹ ipinlẹ lọwọ rara, o ku sọwọ gomina wọn.
Musiliu Dasofunjo wa sapejuwe Ogun Majek gẹgẹ bi ẹni to ni suuru, ti kii si fa wahala.
Ìdámẹ́wàá gbogbo agbo mààlúù, ati ti agbo aguntan jẹ́ ti OLUWA.
Iroyin naa ni awakọ ọhun ni wọn lo gbe ọkunrin alawọ funfun kan to ni arun Coronavirus, ti wọn si ti yaa sọtọ tori pe o ni arun ọhun.
Ẹgbẹrun marun lo ti ni Coronavirus ni Germany: Ninu iroyin miran, eto agbelewo kan to n lọ lori amohunmawoaran ni Germany lati ọjọ kẹfa, oṣu Keji, nibi ti awọn to olukopa ti wa ni ilu ile kan naa, ti wọn ko ti ẹ ti i gbọ nipa aarun COVID-19.
 “Stephan yoo ra iko yii lowo pupo, yala lori papa tabi nibo miiran,”Gege bi Lichtsteiner se so lori ero ayelujara twitter re,”Inu mi dun pupo lati darapo mo iko agbaboolu yii.
BBCCopyright: BBC Article share tools Facebook Twitter ṢàpínlòView more share options Share this post Copy this linkKà síwájú síi nípa àwọn ìtọ́kasí wọ̀nyí.
Bi o tilẹ́ jẹ́ pe a tiraka lati mọ ẹgbẹ oselu to n pin owo naa fawọn oludibo, sugbọn idahun ikọọkan wọn yatọ sira.
william edward burghardt du bois ( ; osu keji 23 , 1868 - osu kejo 27 , 1963 ) je ara amerika to je alakitiyan awon eto araalu , pan-afrikanisti , onimo oro-awujo , olukowe itan , oludako , ati olootu .
Ìfihàn tí a fúnni nípasẹ̀ Wòlíì Joseph Smith sí Peter Whitmer Kékeré, ní Fayette, New York, Oṣu Kẹfà 1829.
Awosanya ni 'awọn ni awọn ti gba beeli wọn, titi di igba ti ileeṣẹ ọlọpaa yoo mọ ẹsun ti wọn fẹ ẹ fi kan wọn.
Ibẹru lo si mu ki a gba pe a jẹbi ẹsun ti wọn fi kan wa.
Ninu ilana electoral College taa n wi yi, idibo a maa waye labẹ akori ipinlẹ kọọkan dipo ki wọn ka iye eeyan to dibo ni gbogboogbo.
Kí ẹ̀dà àwọn òfin yìí máa wà pẹlu rẹ̀, kí ó sì máa kà á ní gbogbo ọjọ́ ayé rẹ̀; kí ó lè kọ́ láti bẹ̀rù OLUWA Ọlọrun rẹ̀, nípa pípa gbogbo òfin ati ìlànà wọnyi mọ́, kí ó sì máa tẹ̀lé wọn; 
Presidency: Akinkanju ológun ni Buhari, kìí ṣùn lójú ogun
Eyii lo si mu ọmọ naa di ero ile ẹgbọn baba rẹ.
Mo na àwọn ọmọ yín lásán ni,wọn kò gba ẹ̀kọ́.
Ipa to si ko ninu idagbasoke Naijiria lo mu ki Aarẹ ologun, Murtala Muhammed yan oun nikan gẹgẹ bi ọba lati ilẹ Yoruba, lati kọwọrin pẹlu rẹ lọ si ilu Mecca fun Hajj.
Gẹ́gẹ́ bi ile iṣẹ́ ọlọpàá ṣe fi idi rẹ̀ múlẹ̀, ọlọpàá mú Oguche pẹ̀lú ìrànlọ́wọ́ àwọn ará ìlú lẹ́yìn ti àwọn ọmọ ológun tún fẹ gba akẹgbẹ́ wọ́n kúrò ni àhámọ ọlọpàá.
Oríṣun àwòrán, Lagos state Government Nínú oṣù kẹwàá ọdún 2020 ni àwọn ọ̀dọ́ yabo títì láti fẹ̀hónú hàn lórí bi àwọn ọlọ́p['a ṣe n hùwà ìkà sí àwọn ará ìlú tí wọ́n sì ń pè fún àtúnṣe.
Ọ̀pọ̀ àwọn alaye míran ti wọn tun ṣe ni pé ó ṣe pataki lati yin ohun rẹdio kalẹ ti o ba ti de ọdọ̀ ọlọpàá.
Iye awon oludibo ni ipinle Nasarawa
'Mo ti gba kádàrá lórí bí Ọlọrun ṣe dá mi'
Nígbà tí ọdún jubili bá kò, tí a óo dá gbogbo ilẹ̀-ìní pada fún àwọn tí wọ́n ni wọ́n, ilẹ̀-ìní àwọn ọmọbinrin Selofehadi yóo jẹ́ ti ẹ̀yà àwọn ọkọ wọn, èyí yóo sì mú kí ilẹ̀ tiwa dínkù.
Awọn olori Naijiria ti n jaran nkan ti wọn le se si eto ẹkọ yi lọjọ to ti pẹ.
Ọkunrin kan wà, ará Bẹtilẹhẹmu, ní ilẹ̀ Juda, òun ati aya rẹ̀, ati àwọn ọmọ rẹ̀ ọkunrin mejeeji; wọ́n lọ ń gbé ilẹ̀ Moabu.
ni awon odaran daran-darane ni ekun Ariwa , amọ bayii o ti yipada si ohun
Ṣugbọn lẹyin ọjọ kan to fi ọrọ naa lede lo tun sọ loju Instagram kan naa pe, agbo ọhun ti n jẹ ki adinku de ba ibadi oun.
Ẹ óo fúnrúgbìn, ṣugbọn ẹ kò ní kórè rẹ̀; ẹ óo ṣe òróró olifi, ṣugbọn ẹ kò ní rí i fi para; ẹ óo ṣe ọtí waini, ṣugbọn ẹ kò ní rí i mu.
Ọkunrin ọhun, Fọlọrunsọ Olawale, ni iroyin naa sọ pe 'aisan rẹ le si’ nigba to de ileewosan naa, to si bẹrẹ si ni ba awọn irinṣẹ ileewosan jẹ.
Nàìjíríà ló wà nípò kẹfà nínú ewu ikú àìtọ́jọ́ l'ágbàáyé nítorí nkan mímú tó ní ṣúgà Ìdíje bọ́ọ̀lù fa ìtàjẹ̀ sílẹ̀ ní Poly Ibadan Oyè Mọ́gàjí àti Báálẹ̀ ti di owó rèé, ọjà rèé ní Ibadan - Lekan Balogun Ọkọ̀ ojú omi ''fẹri'' kọlu afárá, ọkọ̀ méjì já sódò Aarẹ Buhari ninu ọrọ rẹ tubọ salaye pe aisi anfaani eto igbayegbadun ati aikari mudunmudun eto ọrọ aje lo mu ki ipenija aabo ma peleke si lagbaye .
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Cyclone Idai: Ààrẹ Mozambique ní òun rí ọ̀pọ̀ òkú tó lé téńté lórí odò 19 Ẹrẹ̀nà 2019 Oríṣun àwòrán, AFP O kere tan o le ni eeyan ẹgbẹrun kan ti ẹmi wọn ti bọ ninu ọwọja afẹfẹ iji lile, ti wọn pe ni ‘Cylone Idai’, to bẹ silẹ ni orilẹede Mozambique.
Nilu London ni o ti fi ọrọ yi sita ninu ifọrọwerọ pẹlu ile iṣẹ iroyin Reuters.
Ogbeni Kehinde sọrọ lori ikini akọni ti Obasanjọ fun oloogbe Kashamu ati pe, Obasanjọ fi ibanujẹ rẹ han lori iku naa pẹlu adura pe ki Olorun tẹ oloogbe si afẹfẹ rere ninu atẹjade kan naa.
Kini ọna abayọ si aisan lukuluku: Dokita nipa ohun ọsin adie naa, John Jesuwale ni, ki eniyan kọkọ fun awọn adiyẹ ni abẹrẹ ti yoo dẹna aisan lara wọn ati eleyii ti yoo mu wọn ji pepe.
Eucharia Anunobi naa kopa ninu eré naa.
’ Bí àwọn kan tí ń sọ nǹkankan, ni àwọn mìíràn ń sọ nǹkan mìíràn.
Japan visit: Iléeṣẹ́ ààrẹ ní ẹgbẹ́ IPOB kò tako Buhari ní Japan
Abdullahi Zubair Dada Paulen Talen Maigarai Dingyadi Sale Mamman Abubakar D.
Bukky Ajayi: Oríṣun àwòrán, others Ọmọwe ati ọlaju ni Zainab Bukola Ajayi nigba aye rẹ, o kawe nilẹ Gẹẹsi, to si tun ṣiṣẹ nileesẹ tẹlifisan NTA bii Olootu eto, ko to dara pọ mọ awọn oṣere tiata.
Ohun tó tún dá kún ìsòro yìí pàápàá ní orílẹ̀-èdè Nàìjíríà ni pé wọn ti dá ààrẹ Buhari lóhùn nígbà kan ri lórí àtẹ̀jíṣẹ́ twitter rẹ lẹ́yìn tó dárukọ Sàtánì.
Ọ̀nà ìdílé Ahabu ọba ni Ahasaya tẹ̀ sí, ó sì ṣe burúkú níwájú OLUWA, bí ìdílé Ahabu ti ṣe; nítorí pé àna ló jẹ́ fún Ahabu.
Ní òru, Jehoramu ati ogun rẹ̀ dìde, wọ́n fọ́ ogun Edomu tí ó yí wọn ká tàwọn ti kẹ̀kẹ́ ogun wọn, ati àwọn tí ń wà wọ́n.
Obinrin náà dàbí ọkọ̀ ojú omi oníṣòwò,tí ó ń mú oúnjẹ wálé láti ọ̀nà jíjìn réré.
pe, ijoba aare Buhari yoo tesiwaju lati faye ijiroro sile lojuna ati petu si
O ni oun ti bẹrẹ ile to n kọ fun iyawo rẹ yii lati ọdun 1999.
Saulu sì fi ọmọbinrin rẹ̀, Mikali, fún Dafidi.
Police Brutality: Bí ọlọ́pàá ṣe bọ́ aṣọ mi tí wọ́n lù mi, wọ́n tún gba #260, 000 lọ́wọ́ mi- Olumide
Awon ara-ilu ni won n gbiyanju ati fara pamo sinu awon oko, ti won si fi ibe se ipago.
Amo, Alex Iwobi ti Arsenal naa ko jẹ ki iya naa ko jẹ awọn gbe, bẹẹ lo da ẹyọkan pada fun Chelsea, ti ayo naa si pari si 4-1.
Àwọn kan fẹ́ da Naijiria rú torí ààbò tó mẹ́hẹ - Osinbajo gbarata Ọ̀rọ̀ ti ń gba ibòmíràn yọ lórí ẹ̀ṣùn ìfipábánilòpọ̀ - Timi Dakolo Pariwo Ìjọba Nàìjíríà gbọdọ̀ ṣàlàyé ìdí tí 13.
Ijọba Naijiria yẹ ẹ si nipa fifi aworan rẹ si owo Naira marun un ati bi wọn ti yi orukọ Fasiti Bauchi pada si oruke rẹ.
Ṣugbọn ajọ EFCC tako iroyin to kọkọ jade sori ayelujara pe, Ibrahim Ibrahim Magu ti wa ni gbaga ajọ ọtẹlẹmuyẹ DSS.
Gomina ipinlẹ Ondo ni, ko si ohunkohun to pọju lati ṣe fun aabo ẹmi ati dukia awọn eeyan ilu.
Bí ó ti ń bá wọn sọ̀rọ̀ lọ́wọ́ ni Rakẹli dé pẹlu agbo aguntan baba rẹ̀, nítorí pé òun ni ó ń tọ́jú wọn.
Èyí ni ìdí tí Bàbá Kérésì fi máa n wọ aṣọ pupa àti funfun nígbà gbogbo Ẹ ronúpìwàdà lásíkò ọdún, àti àwọn ìkíni mìrán tó jẹ yọ fún Kérésì Ọkọ̀ agbépo tó da epo nù fa súnkẹrẹ-fàkẹrẹ lòpópónà márosẹ̀ Eko sí Ibadan Mo mọ àwọn mẹ́rin tó já fún ìtúsílẹ̀ Dasuki àti Sowore- Fani Kayode Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ǹjẹ́ o mọ pàtàkì igi tó wà ní àyíká rẹ bí?
Nígbà tí Pilatu rí i pé òun kò lè yí wọn lọ́kàn pada, ati pé rògbòdìyàn fẹ́ bẹ́ sílẹ̀, ó mú omi, ó fọ ọwọ́ rẹ̀ níwájú wọn.
”Ó dáhùn pé, “N óo mú ọ lọ, bí o bá ṣèlérí ní orúkọ Ọlọrun pé o kò ní pa mí, tabi kí o fi mí lé oluwa mi lọ́wọ́.
’ Bí ó ti wí báyìí ni n kò rí ẹrù náà mọ́ bẹ́ẹ̀ ni n kò rí ẹni tí o sọ̀rọ̀ sí.
Lara awon ipinle lorile-ede Mozambique, bi Pemba ti n se
  “Eyi yoo waye ni gbogbo ipinle jake-jado orile ede Naijiria , pelu Abuja lojo Isegun, Ogbonjo, osu kewaa, odun yii.
Luca Traini yinbọn si eniyan marun lọjọ yẹn.
Fi àwọn eniyan wọnyi sílẹ̀ kí wọ́n lè lọ ra oúnjẹ fún ara wọn ninu àwọn ìletò.
Oral Sex: Bóo bá ń gba ẹnu ní ìbálòpọ̀, wo àìsàn tóo lè kó lójú ara rẹ Wo bí o ṣe le fi ẹjọ́ sun àjọ FCCPC tí o bá ra ọjà tó ti 'expire' Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Tíátà ọ́mọdé tí wọ́n ń kọ́ wa ní Bariga ti mú mi lọ Germany, Switzerland, Amsterdam.
Ṣugbọn Mikaaya dáhùn pé, “OLUWA alààyè, ń gbọ́!
Bi iye awọn eeyan to n ko aarun yii ṣe n fojojumọ goke sii, paapaajulọ ni awọn ipinlẹ bii Eko, Kano ati Abuja, Aarẹ Buhari kede ofin konile-o-gbele ọlọjọ mẹrinla lawọn ipinlẹ bii Eko, Ogun ati Abuja.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Kemi Dairo: Iṣẹ́ abẹ nínú ọpọlọ àti ẹ̀rọ ni mo fi ń gbọ́ ọ̀rọ̀ báyìí Kini awọn ẹsun to kọkọ ṣaaju ni ipinlẹ Ondo: Akeredolu, aya àti ẹbí rẹ̀ ló ń ṣèjọba ni mo ṣe fipò sílẹ̀ - Akọ̀wé ìjọba tẹ́lẹ̀ l'Ondo Akọ̀wé ìjọba tẹ́lẹ̀ ní irọ́ ni, òun kò sọ pé èrú ìbò ló gbé Akeredolu wọlé Ọjọ Aje ni awọn ileesẹ iroyin kan gbe iroyin sita pe, akọwe ijọba nipinlẹ Ondo to kọwe fipo silẹ naa, Ifedayo Abegunde, ti kede pe, gomina ipinlẹ Ondo, Rotimi Akeredolu kọ lo wọle ibo gomina to gbe depo.
Nitori naa, iyẹn jẹ apẹẹrẹ pe o le ma jẹ otitọ.
Nígbà tí mo bá fi idà mi lé ọba Babiloni lọ́wọ́, yóo fa idà náà yọ yóo gbógun ti ilẹ̀ Ijipti.
Ó bá kígbe sí ẹni tí ó ru ihamọra rẹ̀ pé, “Mo ti fara gbọgbẹ́, yipada kí o gbé mi kúrò lójú ogun.
Abineri bá bojúwo ẹ̀yìn, ó bèèrè pé, “Asaheli, ṣé ìwọ ni ò ń lé mi?
Kọ́ sí i nípa àwọn oúnjẹ aṣaralóore tó yẹ kí Aláboyún máa jẹ Afurasí Boko Haram pa ológun àti ọlọ́pàá mẹ́rìnlá ní Borno Ẹ wá ná, kí ló ń ṣẹlẹ̀ pẹ̀lú APC àti Kayode Fayemi ní Ekiti gan an?
Iroyin tun fi mule pe, opo awon ara ilu Kashmir lo n satileyin fun awon omo ogun olote ti won ja fun ominira tabi lati darapo mo Pakistan.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Tinubu kìlọ̀ fún Buhari, Osinbajọ lórí àfikún owó orí ọjà VAT Ta ni ipò ààrẹ ilé aṣòfin àpapọ̀ tọ́ sí?
Parí-parí ẹ̀, ènìà tún lè fi ọtí ẹlẹ́ridòdò kan lé e.
Mo ti rán gbogbo àwọn iranṣẹ mi, àwọn wolii, si yín, ní ọpọlọpọ ìgbà pé kí olukuluku yín yipada kúrò ní ọ̀nà burúkú tí ó ń tọ̀, kí ẹ tún ìwà yín ṣe, kí ẹ má sá tẹ̀lé àwọn oriṣa kiri, kí ẹ yé máa sìn wọ́n; kí ẹ lè máa gbé ilẹ̀ tí mo fún ẹ̀yin ati àwọn baba ńlá yín.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Òsìsẹ́ Custom tó wọ asọ Ọ̀gá Àgbà CG ti wà ní ile iwosan!
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Yinka Ayefele: Aláàánú kan fi kẹ̀kẹ́ tuntun ta akọrin Tungba lọ́rẹ 28 Ògún 2020 Oríṣun àwòrán, Screenshot/instagram/yinka ayefele Gbajugbaja olorin juju nni, Yinka Ayefele ti le e naro bayii lori ẹsẹ rẹ to ba wu u.
Ìwà àwọn ará àdúgbò yìí kò dènà kí Bádérù ní àwọn ọ̀rẹ́.
"Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ondo Elections 2020: Ọgọ́rùn-ún ọdún tí a máa lò lórí oyè l'Ondo, ẹ ó rí àrà - Ojon YPP ""Àwọn ajínigbé yìí dájú o, wọ́n fipá bá obìnrin mẹ́rin ló pọ̀ níwájú mi"" Oríṣun àwòrán, Hamisu Mallamawa Àkọlé àwòrán, Musa Adamu ti ori ko yọ lọwọ awọn ajinigbe Ó ṣojú mi kòró làwọn agbébọn ṣe fipá bá ọmọ ọdún mẹ́wàá lòpọ̀!"
Wọn ni Muritala Babatunde, to jẹ ẹni ọdún mọ́kàndínlọ́gbọ̀n ni olórí ẹgbẹ́ òkùnkùn tí a mọ̀ sí Black Axe Confraternity ló ṣe ikú pa wọ́n.
Election Monitors (Olutọpinpin idibo) : Awọn wọn yii jẹ
Wo àwọn tó dipò ìlú mú tí wọ́n jẹ́jọ́ lórí dúkìa Ilé ẹjọ́ fagilé ìpè Dino láti wá kó Ọlọ́pàá kúrò nílé rẹ̀ Ọ̀gá ọlọ̀pàá tún ránsẹ́ pe Saraki lóri ìdigunjalè Ọ̀ffà Oríṣun àwòrán, @Bashir Ahmad Àkọlé àwòrán, Idris Adamu ati Aarẹ Buhari nile ijọba Naijiria Adamu sọ pe gbogbo eto ti ẹni to fi ipo silẹ saaju ohun mulo ni ohun naa yoo tele lati ri wi pe ọhun gbogbo nkan lọ ni irọwọrọsẹ ni Naijiria.
Èyi fihàn pé, “Ibi ti àgbà bá wà lọmọdé mba”, ṣùgbọ́n àgbà ti ṣe ọmọdé ri.
Ọkunrin kan, ará Juda láti inú ẹ̀yà Bẹnjamini wà ní ààfin Susa, orúkọ rẹ̀ ń jẹ́ Modekai, ọmọ Jairi, ọmọ Ṣimei, ọmọ Kiṣi.
Nigeria Police Recruitment 2020: Iléeṣẹ́ ọlọ́pàá ní Kano tí ṣe àyẹ̀wò àwọn 13, 048 tó fẹ́ darapọ̀ mọ́ wọn
Makinde ṣe abẹwo si ibudo itọju awọn alaarun to n bẹ ni agbegbe Olodo niluu Ibadan lọsan ọjọ Aje.
Ẹ máa kó àwọn agbo mààlúù yín lọ, ati agbo aguntan yín, gẹ́gẹ́ bí ẹ ti wí.
Bí àpẹẹrẹ adìyẹ ní ìró èdè bí ogún, ti mààlúù jẹ́ mẹ́wàá ṣùgbọ́n kọ̀lọ̀kọ̀lọ̀ ní ọgbọ̀n
Nítorí pé ó ti ṣe àwọn ohun ìríra wọnyi, yóo kú ni dájúdájú; lórí ara rẹ̀ sì ni ẹ̀jẹ̀ rẹ̀ yóo wà.
Adé náà yóo wà ní ilé OLUWA gẹ́gẹ́ bí ohun ìrántí fún Helidai ati Tobija ati Jedaaya ati Josaya, ọmọ Sefanaya.
Tí a bá ti ṣe, ti àìsàn yìí bá ti lọ pátápátá, à ó pada si bí a ṣe ń ṣe tẹ́lẹ̀.
”“A  ni gbogbo asiri ti egbe APC lo lọwọ nipa bi wọn se lo awọn agbofinro ati ajo INEC lati yí esi ibo fun egbe oselu APC  nibi ti wọn ti n ka esi ibo.
je omobibi orile-ede Naijiria, ni apapo ile-igbimo ohun dibo yan gege bi
Ọgbẹni Imana fi ẹsun kan iyawo rẹ, Nkem pe o fi oun silẹ, ko si tun foun laye lati ri ọmọ oun.
Jẹ́ kí wọn máa yin OLUWA nítorí ìfẹ́ rẹ̀ tí kì í yẹ̀,àní, nítorí àwọn iṣẹ́ ìyanu tí ó ṣe fún eniyan.
ati ajo to n mojuto ise otẹlẹmuyẹ(State security services) pe ki won mu adajọ Walter
Ibeere ti ọpọ eeyan wa n beere ni pe ki ni yoo jẹ ireti awọn ọmọ ẹgbẹ APC lẹkun guusu Naijiria ni bayii ti alaga afunsọ ẹgbẹ APC tun ti lọ si ẹkun ariwa Naijiria?
Àwọn angẹli yóo wá, wọn óo yanjú àwọn eniyan burúkú kúrò láàrin àwọn olódodo, 
COZA: Àdúrà kò le pa ìfipábánilòpọ̀ rẹ́, àtàwọn àkọlé mìí tó jẹyọ lórí ọrọ Fatoyinbo
ó bá pada lọ sí ìlú Jesireeli láti wo ọgbẹ́ tí wọ́n ṣá a lójú ogun ní Rama nígbà tí ó ń bá Hasaeli ọba Siria jagun.
Bí kò bá ní arakunrin, kí ẹ fi ilẹ̀ ìní rẹ̀ fún àwọn arakunrin baba rẹ̀.
O ni ohun mo oju ti  awon
Ṣé jíjẹ ata le mu adun balopọ rẹ pọ sii?
Ronaldo ní Tottenham yóò jẹ moyó ìyà lọ́wọ́ Liverpool Ọjọbọ, ọgbọnjọ, oṣu Karun un, ọdun 2019, ni iṣẹlẹ yii waye ni ilu Kirando, to wa ni ẹkùn Rukwa l'orilẹ-ede Tanzania.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ṣíṣe-ṣíṣe bá Arsenal,Wolves dá bàǹtẹ́ ìyà fún wọn 24 Ìgbé 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 25 Ìgbé 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Aṣọ ti bọ lara ọmọyẹ, Arsenal rin hoho wọ ọja pẹlu bi wọn ti ṣe fidirẹmi goolu mẹta si ookan lọwọ Wolves.
 awon eniyan da ifidimule awujo tosoro to ni opo awon eniyan ti won fowosowopo ati ti won takorawon , lati inu awon ebi de inu awon orile-ede .
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ghana Floods: Omiyalé ní Ghana, èèyàn 28 dolóògbé!
Ó bèèrè pé, Ìran Ìgbò nìkan ní ojú wà lára rẹ̀ láti ìgbà tí olùkọni kan láti fásitì Bayero ni àríwá Nàìjíríà ti fẹ̀sùn kan àwọn olókowò Igbò pé àwọn ni wọn ń pín Codeine.
Àwọn ṣiiri ọkà tínínrín meje náà gbé àwọn meje tí wọ́n yọmọ mì.
Ọjọgbọn John Fafunwa to jẹ oludari agba ile iwosan ipinlẹ Eko.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ko sẹni to le koju Trump ninu awọn to tii jade Bloomberg to jẹ ẹni ọdun mẹtadinlọgọrin atawọn mẹrindinlogun miiran ni wọn yoo jọ waako ninu idibo abẹle Democrat bayii.
Olówó-ayé ni orúkọ mi, bàbá mi sì ni ẹni tí orúkọ rẹ̀ ń jẹ́ Akọ̀wédìran.
eyi ti o tọna, bo tile je pe egbe APC je egbe to n sejọba lọwọ.
Eeyan bi ẹgbẹrun lọna aadọrin lo ti ni coronavirus ni Belarus, ninu miliọnu mẹsan aabọ to n gbe nibẹ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Obìnrin ló ni ilé àti àdúgbò fún ìdí èyí wọ́n lè ṣe ìlú dáadáa' Oludije naa ni oun ko ni ibẹru pe ti oun ko ba parapọ pẹlu awọn oludije to ku, oun ko ni wọle.
”Yoo mu adinku ba owo epo 
Ẹlẹ́dàá kò ya àwọn ọmọ aráyé ní ipá, ó ṣe wọ́n ní ọ̀kan ṣoṣo, àgbájọ̀ ọwọ́ ni a fi ń sọ àyà.
Ó sọ̀rọ̀, ó sì mú wọn lára dá,ó tún kó wọn yọ ninu ìparun.
"Àsìkò tó láti fi ìwọ́de gba ara wa sílẹ̀ lọ́wọ́ ebi àti oko ẹrú - Sowore Aáwọ̀ ọ̀dọ́ Yorùbá àti Hausa ló dá wàhálà sílẹ̀ ní Ṣásá - Ṣeriki Hausa Èmi kò gbé pọ̀ pẹ̀lú Kollington Ayinla àmọ́ ọjà t'ọ́mọ ti wọ̀ lọ̀rọ̀ àwa méjééjì - Salawa Abẹni Òṣèré tíátà, Kemi Afolabi fi ohùn ìdúpẹ́ ránṣẹ́ láti Meccah fún àdúrà ọmọ Nàíjíríà Osere tiata naa, ti oju rẹ ti gun rege pada ni ""Mo fẹ lo akoko yii lati dupẹ pupọ lọwọ awọ Ko tan sibẹ, ọga agba ọlọpa naa tun ni wọn gbọdọ se awari awọn olubi ẹda to seku pa Fada kan fun ijọ Aguda, Ẹni ọwọ Paul Offu ni ipinlẹ Enugu."
Joṣua gbéra ní Makeda, ó kọjá lọ sí Libina pẹlu gbogbo Israẹli láti gbógun ti Libina.
Ọgbẹni Ayọrinde sọ pe bi iru ajọ yii ba wa yoo jẹ ki idokoowo ẹka irinajo-afẹ gbooro si, yoo si pese ọpọ anfani fun awọn ọdọ lati ṣiṣẹ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìkọlù New Zealand: Jacinda, Alabi ati àwọn mii gboriyin 18 Ẹrẹ̀nà 2019 Àkọlé àwòrán, Diẹ lara awọn to wu iwa akin lasiko ati lẹyin iṣẹlẹ naa re Ati oore ati ika, ko si ikan ninu rẹ ti yoo gbe ni Yoruba a ma wi.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ṣé irúfẹ́ oúnjẹ tí ò ń jẹ́ lè jẹ́ kí o gbádùn ìbálòpọ̀ rẹ síi?
Gẹgẹ bi oun to sọ, awọn nkankan ṣẹku tawọn yoo jiroro le lori ki wọn to le so iyanṣẹlodi naa to bẹrẹ lọjọ kẹrin ọdun 2018 rọ.
Àṣẹ náà yóò dàmú àwọn oní físà J-1 èyí túmọ̀ sí ètò pàsípàrọ̀ ti wọ́n máa n ṣe fún àwọn akẹ́kọ̀ọ́ fásitì pẹ̀lú àwọn akẹ́kọ̀ọ́ ọmọ orílẹ̀-èdè AU.
O fikun pe asiko to fun wọn lati dẹkun iwọde naa, ki wọn le fun ijọba lanfani ati aaye lati mojuto awọn ẹhonu ti wọn gbe kalẹ.
ati ohun ti awọn ara ilu nilo nipa abadofin naa ki igbesẹ ṣisẹ agbekalẹ
Hesekaya ati wolii Aisaya, ọmọ Amosi bá fi ìtara gbadura sí Ọlọrun nípa ọ̀rọ̀ yìí.
Apá ìhà àríwá tí ó jẹ́ ẹgbaa meji ó lé ẹẹdẹgbẹta (4,500) igbọnwọ (mita 2,250), yóo ní ẹnubodè mẹta.
lati wa ojutuu si wahala ati isoro to maa n waye nipa lilo imo ero igbalode.
Mò ń wo OLUWA ní iwájú mi nígbà gbogbo,nítorí pé Ọlọrun dúró tì mí, ẹsẹ̀ mi kò ní yẹ̀.
Kí ni Ọjọgbọn Wole Soyinka sọ ni tirẹ?
Latin lórí àìsàn Ogun Majek Wo bí ìgbé ayé Richard Akinjide ṣe lọ gẹ́gẹ́ bí agbẹjọ́rò àti olóṣèlú tó mòye Ìyàn ń bọ̀ ní Nàìjíríà lẹ́yìn coronavirus àyàfi.
Ẹ Jọ̀wọ́ Darapọ̀ Mọ́ Wa lati kọ nipa Àṣà àti Ìtàn Àdáyébá ni Agbègbè Yin 
Ninu iṣuna naa ni aarẹ ti kede owo ori tuntun to jẹ ida meje abọ, gẹgẹ bi ọrọ ti ofiisi aarẹ sọ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù MC Oluomo: Agbálẹ̀ títì ni ìyá mi, ọmọ ọdún 13 ni mo sì ti sá nílé lọ bẹ̀rẹ̀ iṣẹ́ kọ̀ǹdọ́ 9 Òkùdu 2020 Oríṣun àwòrán, InSTAGRAM/MCOLUOMO Alaga ẹgbẹ onimọto NURTW nipinlẹ Eko, Alhaji Musiliu Ayinde Akinsanya, ti ọpọ eeyan mọ si MC Oluomo, ti salaye bo ṣe bẹrẹ igbe aye rẹ ati bo ṣe di gbajumọ lọjọ oni.
Wọ́n ní,“A fi ìyìn fún ọ, Oluwa, Ọlọrun Olodumare,ẹni tí ó wà, tí ó ti wà,nítorí o ti gba agbára ńlá rẹ, o sì ń jọba.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: MKO Abiọla gba oyè GCFR tó ga jùlọ ní Nàìjíríà Àwọn ọ̀rọ̀ àyọlò MKO Abiọla 'Ẹ kéde èsì ìdìbo àarẹ 1993' Gomina Ambọde ní oun ri pe, ó yẹ kí ìjọba ṣe ère to ga ju ti tẹ́lẹ̀ lọ láti yẹ́ẹ̀ Abiola sí.
Ìyanṣẹ́lódì òṣìṣẹ́ ilé aṣòfin bẹ̀rẹ̀ ní pẹrẹwu nílé aṣòfin Nàìjíríà Ọ̀tọ̀ọ̀tọ̀ lèrò àwọn èèyàn lórí ìyanṣẹ́lódì SSANU Alápinni: Àwọn tí kò kọ́ṣẹ́ tíátà n ṣàkóbá fún iṣẹ́ náà Àwọn àwòrán mánigbàgbé nípa Ààrẹ Muhammadu Buhari Sugbọn afojusun oun lọjọ iwaju ni pe ki Hridoy le da ṣe nkan fun ra rẹ lẹyin to ba kawe jade nile ẹkọ giga naa tan.
Ko si idi meji fun awọn eewọ wọnyii ju wi pe oriṣa, ẹni ori ṣa da lawọn Ọba alaye jẹ gege bi igbagbọ ilẹ Yoruba.
O fi kun un pe gbogbo awọn eeyan naa ni wọn n gba itọju to peye lọwọ bayii.
Tinubu ni k'Ọ̀basanjọ, IBB lọ rọ ọ kun ni'le Ipaniyan Benue: Buhari sepade pẹlu awọn t'ọrọ kan Ninu awọn ọmọ ẹgbẹ APC ti wọn lede aiyede laarin wọn ni agbegbe naa ni gomina Kano, Abdullahi Ganduje pẹlu sinetọ Rabiu Kwankwaso, ati gomina Kaduna, Nasir El-Rufai ati sinetọ Shehu Sani.
1 Èbibi 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 2 Èbibi 2019 Oríṣun àwòrán, @ogundamisi Àkọlé àwòrán, Fọnran fidio naa ti n mu iriwisi ọtọọtọ wa lori Twitter Fọnran fidio kan to jẹyọ lori ẹrọ ayelujara Twitter ti n da igboru ru lori bi ọlọpaa kan ti ṣe sọ ninu rẹ pe ''Ọlọrun ko lodi si ole jija.
Oyebamiji ni ofin isẹde naa ti kuro ni ọlọjọyipo si aago mẹfa aarọ si aago mẹjọ alẹ kaakiri gbogbo ipinlẹ naa.
Bakan naa gomina Babajide Sanwoolu fi si oju opo instgram pe oun ni imọlara ohun tawọn ọdọ n ja fun torinaa ko ṣeeṣe ki oun tun ran awọn janduku lati wa da iwọde wọn ru.
Àgàgà tí a bá fi àmì sọ́rọ̀, a máa fa ìrújú fún púpọ̀ nínú wọn.
Nigba ti o n ba BBC Yoruba sọrọ, Olajide ni ''ko si ẹnikankan to di ipo mu ninu ẹgbẹ to ṣe ipade kankan loni depo pe wọn yoo wa yọ oun lẹgbẹ.
Ní sáàa Mughal àti ìjọba amúnisìn British, ọ̀pọ̀lọpọ̀ ilé tí a kọ́ ni ó ní ìtàn-ìṣẹ̀lẹ̀-àtẹ̀yìnwá àti àjogúnbá ìlú náà kan tí ó rọ̀ mọ́ ọn.
Jesu Pe Àwọn Ọmọ-Ẹ̀yìn Rẹ̀ Àkọ́kọ́.
 níbi tí wọ ́ n ti únṣe ẹ ̀ ṣọ ́ alumíníọ ́ mù ni wọ ́ n ti únsábà ṣe é àti lò ó , sùgbọ ́ n ó tún wúlò ní àwọn ilẹ ́ -iṣẹ ́ kẹ ́ míkà míràn .
N óo dúpẹ́ lọ́wọ́ OLUWA tọkàntọkàn,láàrin àwọn olódodo,ati ní àwùjọ àwọn eniyan.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Báyìí ni ẹgbẹ́ ajàfẹ́tọmọnìyàn ṣe pè fún ìdájọ́ ikú fún àwọn afipábánilòpọ̀ Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 3 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 5 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Gbogbo ìjọ eniyan bá bẹ̀rẹ̀ sí i kùn sí àwọn àgbààgbà.
 Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Wo àwọn ọ̀nà tí o lè gbà láti di ọjọ́ ogbó pẹ̀lú olólùfẹ́ rẹ Nigba ti iku ẹni keji waye ni nnkan bii kilomita marun un si agbegbe iwọde ọhun.
Awọn olori orilẹede Naijiria naa ṣalaye, ninu atẹjade kan ti Fẹmi Adeṣina to jẹ agbẹnusọ fun aarẹ Buhari, pe ko tọna bi awọn eeyan kan ṣe lo anfani rukerudo naa lati maa tan ina ipinya lorilẹede Naijiria.
O ṣalaye pe oun gbagbọ pe iru ijiya bẹẹ le dẹkun iwa ifipabanilopọ lorilẹ-ede yii.
eru fayawo ti iye owo ori won din die ni Milioni merindinlogbon naira gba lọwọ wọn
Wọ́n yá owó lọ́wọ́ ẹnìkan tí í máa ń yá eniyan lówó pẹlu èlé.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Human Trafficking: Iṣẹ́ tíṣà ni wọ́n sọ pé màá ma ṣe ní Dubai, oko ọmọ ọ̀dọ̀ ni mo ba ara mi ní Oman 6 Èrèlè 2020 Àkọlé àwòrán, Temitope kawe jade ni fasiti ni orilẹ-ede Naijiria, to si ti n ṣe iṣẹ aje diẹdiẹ ko to o di pe o gbiyanju lati lọ si ilẹ okeere.
Fún ọ̀pọ̀lọpọ̀ obìrin nínú iṣẹ́ gbogbo.
N kò lè sọ̀rọ̀ nípa àwọn nǹkan yìí fínnífínní ní àkókò yìí.
Ó wo Èṣù-kekeré-òde bí ìgbà bí ìgbà ti jàndùkú obìnrin bá ffi ojú ìbàjẹ́ wo ọkọ rẹ̀, ó wí pé: Ẹni tí ó fi asẹ́ gbe òjò o tan ara rẹ̀ jẹ; ẹni tí ó dúró dé rélùwéè yóó bá ara rẹ̀ ni ọ̀run alákeji; àgbà tí ó rí ejò tíkò sá ara ikú ló ń yá a; ẹranko tí ó bá ń fi ojú di ọdẹ ẹ̀hìn ààrò ni yóò sùn, ẹni tí ó gbójú lé ogún fi ara rẹ̀ fún òṣì ta; ẹbọra ti ó bá fi ojú di mí yóó máa ti ọ̀run dé ọ̀run ni, èmi ọkùnrin ni mo wí bẹ́ẹ̀, òní ni n ó sọ fún ẹ̀yin ẹbọra Igbó-Olódùmarè pé, nígbà tí Ẹlẹ́dàá dá ohun gbogbo tí ń bẹ nínú ayé tán, ó fi ènìyàn ṣe olórí gbogbo wọn.
O tẹsiwaju pe, oun fẹran lati maa wa nibi ti omi ba wa, tori omi maa n mu oun roun jinlẹ daada.
Gbogbo nkan ta n ri ninu awuyewuye oselu ipinlẹ Edo n jẹki ọrọ yi rinlẹ si lọkan gbogbo ẹni to ba n fi ọgbọn ati oye ba bọ wi pe awọn oloselu kii ba ara wọn se ọrẹ timọ timọ.
Bí kò bá sí olè tí ó jà á nígbà tí òun kúrò nínú Igbó Olódùmarè tí ó wá si ilé ni, owó náà ìbá pọ̀ tó bẹ́l tí irú àwa wọ̀n yí kò bá tí ṣiṣẹ́ kí á tóó máa jẹun.
Ṣáájú, wọn ti fẹsun kan wọn wi pe wọn n lo awọn fọto ti awọn eniyan ba fi sori erọ FaceApp lati fi da oju awọn eniyan mọ, tabi se iwadii wọn.
O sọ fun iwe iroyin The Punch pé, Lawal nìkan ni ọkùnrin tí ìyá òun fí ọwọ́ sí kó tó ò kú.
Lojo-Aje (Monday) gomina Ifeanyi Ugwuanyi ti ipinle Enugu fowo si isuna owo odun 2018, ti iye re le logorun bilionu.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Sunday Igboho: Ẹ fi Ògún búra fún wa láti jà fún ilẹ̀ Yorùbá láì gbé Amotekun sábẹ́ ìjọba O le ni miliọnu meji eeyan ni ila oorun ariwa Naijira ti wọn ti di aṣatipo lataari ikọlu Boko haram ni ẹkun yii Ajọ iṣọkan agbaye, United Nations ti kilọ [pe iṣẹ nla lo ṣi wa niwaju Naijiria nitori pe ohun eelo iranwọ kotii de ọwọ idaji awọn to nilo rẹ gẹgẹ bii aṣatipo.
Solomoni ya gbọ̀ngàn ààrin tí ó wà níwájú ilé OLUWA sí mímọ́, nítorí pé ibẹ̀ ni ó ti rú ẹbọ sísun tí ó sì sun ọ̀rá ẹran fún ẹbọ alaafia, nítorí pé pẹpẹ bàbà tí ó ṣe kò lè gba gbogbo ẹbọ sísun, ẹbọ ohun jíjẹ ati ẹbọ ọ̀rá.
Ìdí rè é tí a fí wó ìlè arúgbó ní ìdàjí -ìjọba ìpínlẹ̀ Kwara Ọlọ́pàá hú òkú akẹ́kọ̀ọ́ fásítì LASU tí ọ̀rẹ́kùnrin rẹ̀ àti pásítọ̀ ṣekúpa Èèyàn méjì gbẹ́mìí mì nínú ìjàmbá ọ̀kọ̀ tó ṣẹlẹ̀ lórí afárá Otedola Ọ̀sẹ̀ àkọ́kọ́ ọdún 2020: Àwọn ìròyìn tó mí ìgboro tìtì Èyí tí a wò jùlọ 5:03 Fídíò, Omolola Arohunmolase Welder: Mo ti fí iṣẹ́ 'Welder' gbayì láwùjọ, tó mo fi tọ́ ọmọ yanjú, Duration 5,039 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 5:39 Fídíò, Akomolede ati Asa lori BBC: Olùkọ́ Kikelomo Ogunboye tan ìmọ́lẹ̀ sí ìwà olè ọ̀gá ọlọ́pàá Audu gẹ́gẹ́ bí àwòkọ́ṣe àsìkò yìí, Duration 5,398 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 4:11 Fídíò, Oba Adeyeye Ogunwusi: Ojú mi ti rí lọ́pọ̀ lọpọ̀, ọ̀pọ̀ èèyàn ni kò tilẹ̀ gbàgbọ́ pé mo lè jọba- Ooni, Duration 4,117 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 4:43 Fídíò, Promise Akinlade: ọmọ ọdún mọ́kànlá tó ń fi ìlù dárà bíi àgbàlagbà sọ̀rọ̀ nípa tálẹ́ǹtì rẹ̀, Duration 4,437 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 0:59 Gbọ́, Ìsẹ̀lẹ̀ jákèjádò orílẹ̀èdè àgbáyé láàárín ìṣẹ́jú kan, Duration 0,59wákàtí 5 sẹ́yìn 7:03 Fídíò, Olumuyiwa Bolade Adedeji Military Bruitality: Bí arákùnrin onípèníjà ara tí sọ́jà lù ṣe dé, Duration 7,035 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 4:45 Fídíò, Yoruba Films: Ẹ̀ẹ́ bẹ̀ mi kúrò láyé ni, mi ò lè kú - Fadeyi Oloro, Duration 4,4526 Èrèlè 2020 2:48 Fídíò, Esther Ajayi: Èmi náà ti borí ìṣòro rí ló ń mu mi ṣojú àánú, Duration 2,481 Ògún 2019 6:08 Fídíò, Adebola Ademilua: Àìrísẹ́ ṣè lẹ́yìn ìwé kíkà ló sọ mi dí ìyá onírú, mo dúpẹ́ tèmi, Duration 6,0827 Bélú 2020 5:55 Fídíò, Soyinka Cancer: Àṣe ara mi ni iso ti n run gbogbo bí mo ṣe n ṣèrànwọ́ lórí jẹjẹrẹ, Duration 5,5527 Bélú 2019 BBC News, Yorùbá Ìdí tí ẹ fi le è nígbàagbọ́ nínú ìròyìn BBC Ìlànà Lílò Nípa BBC Òfin Àṣírí Cookies Kàn sí.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Teni entertainer: Idi ti mi ò kì ń ṣí ìhòhò mi bi àwọn olórin obìnrin míran Yemisi Oyedepo Broadcast Journalist 18 Ọ̀pẹ̀̀ 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 23 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Tẹniọla: Pè mí láago tí o bá mọ iyán gún pẹ̀lú ọbẹ̀ ilá tó dùn Yoruba bọ wọ́n ni bí fingbáfingbá kò bá fingbá mọ, èyi to tí fin silẹ̀ kò ni parún.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ekiti Election: Ará Èkìtì ń fẹ́ gómìnà tí yòò tù wọ́n lára Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, #EkitiDecides: 'Ìjà ẹgbẹ́ òkùnkùn ló ń ṣẹlẹ̀ kìí ṣe ti òṣèlú' Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ekiti Election: Pọpọ sinsin idibo n lọ lori lawọn wọọdi Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Àwọn Alákòso gárèjì ló kó ìbọn àti àdá tọ ọlọ́kadà wá ní Soka-Alága ẹgbẹ́ ọlọ́kadà Ọyọ Folaranmi ni àwọn fi ìṣẹ̀lẹ̀ náà tó ileesẹ ọlọ́pàá tó wà ládùúgbò Sanyo létí, tí wọn sì pe igun méjèèjì sí ìpàdé àlàáfíà ni iléesẹ ọlọ́pàá tó wà ní Iyaganku.
Oríṣun àwòrán, PHOTOPQR/LE PROGRES/Photo Jean-Pierre BALFIN Àkọlé àwòrán, Iwọde waye ni iranti Marie-Amélie Vaillat Kini a le ṣe lati fi iṣẹlẹ pipa obinrin to awọn ijọba leti?
Latin wa lara awọn agbaagba ẹgbẹ to lọ ṣe aayan idibo naa.
Oríṣun àwòrán, others O fi kun un pe igbesẹ ni ti Olubadan to jawe oye le e lori ati pe yoo ṣi tọ awọn Ọbalaye yoku ni ipinlẹ Ọyọ lọ fun igbọwọle tiwọn naa.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Ọ̀lọ́pàà ìlú ọba ti fi páńpẹ́ ọba mú olùdásílẹ̀ Wikileaks, Julian Assange ní ìlú London.
Oríṣun àwòrán, Press Association Àkọlé àwòrán, Awọn ọjọ ori ti aarun naa n damu julọ ni ni ọdun mọkandinlogun si ogoji ọdun Iwadi ajọ naa fihan pe eeyan to le ni ẹgbẹrun mẹta lo ti lugbadi aarun iba lassa ni ipinlẹ mejilelogun lati oṣun kinni titi di oṣu kọkanla ọdun yii.
Ṣugbọn nigba ti ina sọ, awọn ara ilu lo fara kaasa ọrọ naa.
Kekere si lo yẹ ka ti pẹkan iroko awọn ọmọ wa, nipa sisọ ede abinibi si wọn ninu ile nitori ọpọ adanu lo wa lọjọ iwaju, ti ọmọ ko ba mọ ede Yoruba sọ.
ni igbiyanju si  n lọ lọwọ lati ro awon
Lẹ́sẹ̀ kan náà, àwọn ẹgbẹ́ rẹ̀ tẹ́ aṣọ wọn sílẹ̀ fún un kí ó dúró lé, wọ́n sì fun fèrè pé, “Kabiyesi, Jehu ọba!
Wọ́n yí ilé náà po, wọ́n sì ba dè é níbi ẹnu ọ̀nà bodè ìlú ní gbogbo òru ọjọ́ náà.
ko kere nitori opo eniyan to wa nibẹ.
Wọn si ti fi oye Ọmọwe da lọla ni fasiti NSUKA àti Egbinedon.
" Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Táyà ọkọ̀ agbépo tó fọ́ fa ìjàmbá ọ̀kọ̀ l'Ékò, èèyàn kan farapa Boris Johnson àti ẹgbẹ́ rẹ̀ wọlé ìbò, Trump àtàwọn ààrẹ míì kíi kú oríire Ọdun ń lọ sópin, ariwo 'ń sọ̀ ní ilé ńlá l'Abuja Ẹjọ́ Sowore bọ́ sọnù lọ́wọ́ àjọ DSS Ẹ́ wo ojú àwọn òṣèré tíátà tó péjú sí Ibadan fún ìpàdé ọlọ́dọọdún Ìtàn Àrọ̀gìdìgbà jẹ́ kí ń rò pé bàbá mi yan Yemọ̀ja ní àlè - Ọmọ Fagunwa Bakan naa ni Lizzy fikun pe oun nifẹ goolu pupọ, ti oun si maa n de orilẹede meje lati wa goolu to yatọ, eyi to si dara ni oun maa n wa lọ lati ra.
Arabinrin to jẹ ọmọwe ati gbajumọ lawujọ, Arlène Agneroh sọ iriri rẹ lori bi awọn eniyan se ma n fi agbara mu awọn ọmọbinrin to ti to oju bọ, lati lọ fẹ ọkọ, nitori abamọ nla ni loju wọn ti obinrin to ba balaga, ko ba fẹ ọkọ lasiko.
Lẹ́yìn tí àwọn amòye ti pada lọ, angẹli Oluwa kan fara han Josẹfu ní ojú àlá, ó sọ fún un pé, “Dìde, gbé ọmọ náà ati ìyá rẹ̀, kí o sálọ sí Ijipti, kí o sì wà níbẹ̀ títí di ìgbà tí mo bá sọ fún ọ, nítorí Hẹrọdu yóo máa wá ọmọ náà láti pa á.
Ọlọ́lá jù lọ Terry Waya ni Bàbá Terseer Kiddwaya tó ń kópa nínú BBNaija 2020 Gẹgẹ bi iwe iroyin abẹle Premium Times ṣe sọ, ile ẹjọ ilẹ Amẹrika ni awọn ko ni ẹsun kankan lodi si Woodberry Ọlọpaa mu Ponle ati Ramon Abbas ti gbogbo eniyan mọ si Hushpuppi ni Dubai ni ọjọ kẹwaa, oṣu keje, ọdun 2020.
2019 Elections: Ìpínlẹ Akwa Ibom ti gbà kí Buhari lo pápá ìṣeré fún ìpolongo
 Ile ise idibo fun Trump kede Brad Parscale gege bi alagbara to too mojuto ipolongo Trump ju bi o ti se lo lodun 2011.
Lẹyin naa lo parọwa si awọn ọmọ bibi ilẹ Ijebu lati ṣe ọdun ọhun laaye ara wọn lai si ariwo.
Ìpínlẹ̀ Kaduna ní èèyàn 74 nínú àwọn 169 tí Covid-19 ṣẹ̀ṣẹ̀ ràn ní Naijiria Esi ayẹwo coronavirus lati ipinlẹ mejila ti ajọ NCDC fi sita ni Ọjọbọ.
Nigba ti o n soro lori ojuse re gege bi olugbani nimoran lori oro ile-okere, Omishore so pe, ojuse oun ni lati satileyin fun Aare ile-igbimo asofin agba lati mu ajosepo to muna-doko  wa laarin awon orile-ede lagbaaye.
Elusai, Jerimotu, ati Bealaya; Ṣemaraya, Ṣefataya ará Harifi; 
Iyabo Ojo tẹsiwaju pe laarọ ọjọ Aje oni ni oun wọle silẹ Naijiria pẹlu esi ayẹwo coronavirus naa, ti wọn ko tiẹ yẹ iwe naa wo lai naani wahala ti oun se lorilẹede Turkey.
Ko si ohun to kan an pẹlu ibo kika nitori ojuṣe alaga ajọ INEC niyẹn.
O salaye wi pe,  “kikowe fipo naa sile pon dandan ni iyanju ati se atuse eyi ti yoo faye gba alaafia ati igberu ba eto tiwa-n-tiwa”Hailemariam, eni ti o ti n tuko orile-ede naa lati odun 2012, ni o tun fipo alaga apapo egbe to n sejoba sile.
Ó sọ orúkọ wọn ní Hafoti Jairi.
Kete ti Abdirahman Adan de lati orilẹ-ede Pakistan to ti lọ kọ ẹkọ iṣegun nipa itọju eyín lo ni oun ti woye pé ko si ọkọ igbe-alaisan lọ sile iwosan ni Mogadishu.
Oríṣun àwòrán, KTN Àkọlé àwòrán, Ajọ awọn oniroyin nilẹ Kenya, sọ pe igbese ijọba Kenya naa kọjumọ, ti kosi lẹtọ labẹ ofin to faaye gba ominira awọn oniroyin Nitori naa, ni wọn se gbe NTV, KTN ati Citizen TV kuro lori afẹfẹ lagoogo mẹsan kọja isẹju mẹwa, (niye aago Kenya), lọjọ ibura naa.
Alufaa Babatunde atawọn ọmọ ijọ marrun un mii ni adajọ Odusola dajọ ẹwọn gbere fun un lọjọ Iṣẹgun ọjọ kẹfa oṣu kẹwaa ọdun 2020.
Koda, banki apapọ Naijiria, ati ajọ to n dáabo bo awọn oludokowo ni Naijiria ti kilọ fun awọn ọmọ Naijiria, lati sọra ṣe fún awọn okoowo ti èrè ibẹ ba farajọ majiiki.
Ṣugbọn OLUWA kò sí ninu iná náà.
Ìyàwó Ọ̀ọ̀ni Ogunwusi kò bímọ tuntun Donald Trump àti ìyàwó rẹ́ ti lùgbàdì àrùn CoronaVirus Fídíò rèé lórí bí Sunday Igboho ṣe korò ojú sí ìwà ọ̀dàlẹ̀ nílẹ̀ Yorùbá Ìfẹ́ Yorùbá ló mú mi fi ẹ̀mí wéwu láti kojú ajínigbé ní Kishi - Sunday Igboho Buhari, ayẹyẹ kí là ń ṣe gan, ṣé ti ìpànìyàn àbí ìjínigbé?
 Ọjà Àgbáláta ní Badagry rèé, níbití ẹran ejò ti dùn ju ẹran adìẹ lọ Lórí ìmọ̀ràn Sunday Igboho, Ẹlẹbubọn ní yóò dára kí Yorùbá padà sí àmúlò èròjà ìbílẹ̀ fún ààbò A kò mọ̀ọ́mọ̀ pa ọlọ́pàá mẹ́ta, aráàlú kan, ó ṣèèsì ni, ajínigbé la pè wọ́n - Iléeṣẹ́ ológun Sowore àti àwọn ọmọ ẹgbẹ Revolution Now kò ṣẹ̀ ṣófin lórí ìwọ́de, ẹ tú wọn sílẹ̀ - NLC Òṣùká kékeré kò rẹrùn àgbà, orílẹ́èdè Nàìjíríà ṣòro púpọ̀ láti darí - Ibrahim Babangida Sowore ṣèpàdé pẹ̀lú Nnamdi Kanu láti dojú ìjọba Nàíjíríà bolẹ̀ - Àjọ DSS Soyinka ni iwa isekupani ni aimọye ọna ti gba akoso ni gbogbo ọna lẹkun iwọ oorun guusu Naijiria, ti iwa ijinigbe naa ko si gbẹyin, wọn si ni ma fi oko mi sọna, ọjọ kan bayii ni eeyan maa n kọ ọ."
" Lara awọn ọdọ to ṣabẹwo si Alayeluwa ni, Mr Macaroni, Seyi Awolowo, atawọn eeyan miran.
Gómìnà Ambode ti ọrọ náà kan ko tí fèsì sí ọrọ yí.
Amofin agba naa sọ pe itan ati afarawe iye ti wọn n ta epo ni Saudi Arabia ati Egypt ko kan awọn ara ilu lasiko yii, bikoṣe pe ki aijọba sọ fun wọn bi igbe aye wọn yoo ṣe gbe pẹẹli ju ti atẹyinwa lọ.
Yorùbá dùn lédè, ẹ máa sọọ́ Ẹfunroye Tinubu - Ògbóǹtagí oníṣòwò, olówò ẹrú àti afọbajẹ Samuel Ajayi Crowther, òjíṣẹ́ Ọlọ́run tó gbé èdè Yoruba lárugẹ Mọrèmi Àjàṣorò, akọni obìnrin tó gba Ilé Ifẹ̀ sílẹ̀ lóko ẹrú O ni ijọba Naijiria kò ba àwọn oṣere ja ija naa bi o ti yẹ pe ohun lo faa ti onikaluku fi n dọmu iya rẹ gbe.
Àkọlé àwòrán, Aafin yii ni wọn kọkọ gbe Sanusi Lamido Sanusi lọ lẹyin ti wọn rọ ọ l'oye Hamed sọ pe wọn gbe e kuro ni Loko nitori pe agbegbe naa ko tọ si i ni ipo ọlọla to wa.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìjọba ìpínlẹ̀ Èkó -Àbẹ̀wò Buhari kò mú ìdìwọ́ bá lílọ bíbọ̀ ará ìlú 8 Èrèlè 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 9 Èrèlè 2019 Oríṣun àwòrán, @followlasg Àkọlé àwòrán, Ikede naa waye lati fi ọkan ara ilu balẹ pẹ ko ni si ọna ti wọn yoo ti pa Ijọba ipinlẹ Eko ti kede pe awọn ko ni ti ọna kankan pa lasiko abẹwo Aarẹ Muhammadu Buhari si ipinlẹ naa.
Ebenezer Obey ni lọjọ ti oun yoo kọkọ yọju si ileeṣẹ rẹkọdi Decca, pe ko gbe awo orin oun jade, oun rin lati adugbo Mushin de Akọka nilu Eko ni, nibi ti ileeṣẹ rẹkọọdi naa wa.
Bẹ́ẹ̀ ni àwọn méjì wọn-ọnnì pinnu àti sá kúrò ní ilé kí wọ́n lọ sí ìlú mìíràn ki wọ́n baà jọ máa gbé gẹ́gẹ́ bí ìfẹ́ ọkàn wọn.
Fun awọn onwoye ohun to n lọ lawujọ, alaafin kii fi ọrọ asa sere, ta si le ni o kogiri mọ ojuse rẹ bi ọba alaye lati ri daju pe awọn asa, ise ati ede wa ko lọ sokun igbagbe.
 Aare ki awon gomina ipinle kookan ti won yan labe asia egbe oselu APC ku ise ile nipinle koowa won.
Ẹ dìde, ẹ̀yin obinrin tí ara rọ̀,ẹ gbóhùn mi; ẹ̀yin ọmọbinrin tí ẹ wà ninu ìdẹ̀ra,ẹ tẹ́tí sí ọ̀rọ̀ mi.
Omole ni awọn asofin ogun to tẹlẹ Gomina Akeredolu naa ni yoo lọ ṣe ayẹwo fun aarun Coronavirus ni Ọjọ Keji, Osu Keje, ọdun 2020.
Mo jẹ alabukun fun lati jẹ ara mọlẹbi BBC to gbooro.
A gbìn ín ní ara tíí díbàjẹ́; a jí i dìde ní ara tí kì í díbàjẹ́.
Enyeama wa pẹlu ikọ agbabọọlu ilẹ Faranse, Dijon nibi ti o ti n gbaradi fun ati pada sori papa.
Agbegbe Ṣapade ni ilu Ogere ni ipinlẹ Ogun ni iṣẹlẹ naa ti ṣẹlẹ.
Ajimọbi, ti o tun jẹ oludije dupo nile igbimo asofin ni aarin gbungbun ijọba
Iṣẹlẹ aburu yi lo fa ibinu awọn ọdọ adugbo, eyi to mu ki wọn lọ si ile Simeon Abuh, eni to jẹ ẹgbọn fun Gowon, to ṣe ijamba naa.
awon agbegbe to jẹ pe eto idibo ko tete bẹrẹ, won ti fi kun wakati to yẹ ki eto
Bauchi Police: Ẹ wá wó arákùnrin tó pa ọmọ-ọmọ rẹ̀ tuntun jòjòló nítorí nípa ibálòpọ̀ ni wọ́n fi lóyún rẹ̀!
Aarẹ ileegbimọ orilẹede Naijiria ṣalaye ọrọ yii lasiko to fi n gbe idanilẹkọ kan kalẹ lorilẹede Ghana lati sami ayẹyẹ ọdun mẹwa ọtọọtọ laisi idaduro ti ileegbimọ aṣofin orilẹede Ghana ti nṣiṣẹ.
Iroyin ni nibi ti wọn ti n yinbọn lai nidi kan pato ni ọta ibọn ba Kolade lori ijoko rẹ.
ipinlẹ Eko, Idris Muhammed ni o soju abẹ nikoo lọjọ Ẹti, lasiko to n ba awon akoroyin
Ó dájú pé ẹ̀bẹ̀ ni màá fi ìyókù ọdún yìí bẹ ọ̀pọ̀ èèyàn nítorí ìgbéyàwó mi - Bukunmi Oluwasina Gbàjarè!
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ẹ̀mí sùn níbi ìkọlù Shiite àti ọlọ́pàá Agbẹjọro ati onimọ nipa eto ofin naa ni gbogbo ọmọ Naijiria lo ni aṣẹ ni abẹ ofin lati jọsin bi o ṣe wu wọn.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Esther Ajayi: Èmi náà ti borí ìṣòro rí ló ń mu mi ṣojú àánú Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Esther Ajayi: Èmi náà ti borí ìṣòro rí ló ń mu mi ṣojú àánú 1 Ògún 2019 Ọlọ́run ló fún èmi ní oreọ̀fẹ́ àti máa f'owó ṣàánú""."
Ekiti Bishop: Ìjọ Anglican pàṣẹ lọ rọọ́kún nílé fún Bíṣọ́ọ̀bù tó ń bá ìyàwó àlùfáà abẹ́ rẹ̀ sùn l'Ekiti
Minisita naa gbe ogorun apoti ero igbalode fun ijoba ipinle Enugu lati pin fun awon eniyan lofe.
Awọn eto ati ilana yooku niwọnyii: Aṣẹ konile-o-gbele lati irslẹ si kutukutu owurọ ni ibamu pẹlu ohun ti aarẹ Muhammadu Buhari pa laṣẹ ninu ọrs rẹ.
Bayii, o di ojo karun un ti awon oko ofurufu ogun ti bale ni ila oorun Ghouta leba olu ilu Syria.
Ibudo ilera Maternal &Peadiatric Centre, Olodo Ibadanni wọn ti pe lorukọ Abiola Ajimobi Maternal &Paediaitric Centre.
Ogbeni Israel Ibeleme, ti o je amugbalegbe minisita naa lo so oro ohun di mimo lojoBo(Thursday), niluu Abuja.
 ní Áfíríkà a ti wò lápapọ ̀ pé ó fa ìpàdánù $ 12 bílíọ ́ nù owó amẹ ́ ríkà ní ọdún kan èyí tí ó wáyé lára ìgbówó lórí ìtọjú-ìlera , àínífẹ ̀ sí iṣẹ ́ ṣíṣe àti ìpalára arìn-ajò .
Ìdí tí a fi ṣe òfin tuntun fún àwọn akọ̀ròyìn tí yóò ṣiṣẹ́ nílé aṣòfin - NASS Báwo ni Joel ṣe ṣe iku pa ọga rẹ?
Oríṣun àwòrán, Getty Images Aisan lukuluku ti awọn oloyinbo n pe ni Bird flu, ti wọn n pẹ ni avian influenza, ma n pa adiyẹ, awon eranko miran ati eniyan pelu.
4m O yannana rẹ siwaju pe, ninu owo naa, miliọnu mẹrinla abọ naira ni wọn na lori bairo ikọwe nikan, miliọnu mẹrindinlaadọta naira ni wọn fi tẹ iwe alakọle Letterhead ileeṣẹ naa, ti wọn si fi miliọnu mẹrindinlọgọta naira ra awọn ohun elo fun ẹrọ itẹwe (Photocopy) ileeṣẹ naa.
 Eto ayeye naa n waye ni
Ìsọkúsọ ni àwọn ère ń sọ, àwọn aríran ń ríran èké; àwọn tí ń lá àlá ń rọ́ àlá irọ́, wọ́n sì ń tu àwọn eniyan ninu lórí òfo.
Yóo gbọ́ adura àwọn aláìní,kò sì ní kẹ́gàn ẹ̀bẹ̀ wọn.
Àkọlé àwòrán, Gbajugbaja osere Yoruba Fadeyi Oloro Àkọlé àwòrán, Awọn eniyan ipinlẹ Ọṣun sọ ohun ti wọn n reti lọwọ gomina tuntun Àkọlé àwòrán, Ara ipinlẹ̀ Ọṣun BBC News, Yorùbá Ìdí tí ẹ fi le è nígbàagbọ́ nínú ìròyìn BBC Ìlànà Lílò Nípa BBC Òfin Àṣírí Cookies Kàn sí.
Èèyàn 125 ní àrùn Coronavirus tún ṣẹ̀ṣẹ̀ ràn ní Nàìjíríà ní Ọjọ́bọ̀ Oluwo kọ̀ láti sọ̀rọ̀ lórí àwọn afọbajẹ tó fẹ́ yọ ọ́ nípò, aráàlú fọ́n síta láti fẹ̀hónú hàn APC Ekiti pàṣẹ lọ rọ́ọ́kún nílẹ̀ fún àna Tinubu àti Babafemi Ojudu APC Ekiti pàṣẹ lọ rọ́ọ́kún nílẹ̀ fún àna Tinubu àti Babafemi Ojudu O ti n sebi ẹni rugbo bọ ninu ẹgbẹ oselu All Progressives Congress ni Ipinlẹ Ekiti nibi ti wọn ti ni kawọn eekan ẹgbẹ kan lọ rọọkun nile.
Oyun naa ti pe oṣu marun un bayii.
Àbálọ àbábọ̀, ó kúrò ní ilé-ìwé, ó sì di ẹni-àpẹẹrẹ àwòrán láti so ẹ̀mí àti ara ró.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ilé iṣẹ́ ológun Nàìjíríà korò ojú lórí fídíò ayédèrú 24 Bélú 2018 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 25 Bélú 2018 Oríṣun àwòrán, Getty Images Ileesẹ ologun lorileede Naijiria ti faraya lori bi awọn eeyan ṣe n pin fidio ati aworan ti wọn pe ni ayederu kaakiri lori iku awọn ọmọogun ti Boko Haram pa ni Borno.
ati àwòrán gbogbo ohun tí ó ní lọ́kàn láti ṣe sinu àgbàlá ilé OLUWA, ati ti àwọn yàrá káàkiri, àwọn ilé ìṣúra tí yóo wà ninu ilé Ọlọrun, ati ti àwọn ilé ìṣúra tí wọ́n o máa kó ohun tí a yà sọ́tọ̀ fún OLUWA pamọ́ sí.
Ìhó ayọ̀ ni a óo hó nígbà tí o bá ṣẹgun,ní orúkọ Ọlọrun wa ni a óo sì fi ọ̀págun wa sọlẹ̀;OLUWA yóo dáhùn gbogbo ìbéèrè rẹ.
Awọn oṣiṣẹ alakasọ igbega kini de ikejila yoo tẹsiwaju lati maa ṣe iṣẹ wọn lati ile ayafi ti ọga tabi adari ẹka ileeṣẹ ijọba ti wọn n ba ṣiṣẹ ba ni ki wọn wa ṣe ohunkohun nileeṣẹ ijọba.
Isola Ogunsola, I Show Pepper: Oríṣun àwòrán, others Agba ọjẹ oṣere tiata ni Olusola Isola Ogunsola, ti ọpọ eeyan mọ si I Show Pepper nigba aye rẹ, o si jẹ ọmọ bibi ilu Abeokuta.
Eyi ariwo ti Ọbabirin orin Waka, Salawa Abẹni fi bọnu.
Ẹni to ba ti bọ sọna lati bii ọwọ ọsan ti ko tete ji kuro nile yala latinu ilu Eko ni tabi lati bii Ibada ati ipinlẹ Ogun, ko si ani ani yoo ko sinu sunkẹrẹ fakẹrẹ lawọn oju popo to ba dari si Redemption Camp.
 Bush, ti o gbe igbe aye re lati fi sin ilu ati awon eniyan.
Gomina Benue, Samuel Ortom ni gbogbo ohun to wa ninu abadofin naa ko ba eyi to wa ninu iwe ofin lilo ilẹ mu torinaa o ni ijọba ni nkan mii ti wọn fẹ ṣe labẹlẹ.
Bí ẹnikẹ́ni bá gbọ́ ohùn mi, tí ó ṣílẹ̀kùn, n óo wọlé tọ̀ ọ́ lọ, n óo bá a jẹun, òun náà yóo sì bá mi jẹun.
Oríṣun àwòrán, @Toosaino Awọn abanikẹdun ti yabo ile Tunde Braimoh, aṣofin ipinlẹ Eko to jade laye lowurọ ọjọ Ẹti.
 nínú ìrìnàjò wọn , olúkúlùkù bẹ ̀ rẹ ̀ sí níí tẹ ̀ dó sí ojú ọ ̀ nà , nínú èyí tí kòkòbírí ní Òkè Ọya wà .
ìgbà tí mo sì wo ẹ̀hìn mo rí i pé ojú rẹ̀ kò dára sí ìpákọ́ mi, mo ni, O jẹ́ lọ jókòó, ìpàkọ́ onípàkọ́  ni ènìyàn ń wò, wọn kì í wo ìpàkọ́ ara wọn.
Ṣugbọn wọ́n dáhùn pé, “Àwa kò lè gbà kí ó ṣe arabinrin wa bí aṣẹ́wó.
Ẹni to bori: Nigeria Guinea-Bissau vs Angola.
Ẹsẹ ti Jubrin sẹ awọn asofin nigba naa ni pe o fẹsun kan gbogbo ijoko ile pe wọn se magomago ninu eto isuna, to si gbe iwe naa le awọn asofin lọwọ eyi tawọn akẹẹgbẹ rẹ fi oju wo nigba naa gẹgẹ bii iwa ibanilorukọ jẹ.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ọbasanjọ sọ àsírí sàgbàdèwe rẹ̀ Jesu Oyingbo rèé, pásítọ̀ tó láṣẹ ìbálòpọ̀ lóri ọmọ ìjọ obìnrin Igbó mímu lè ṣe kóríyá, kò lé fi kún orín ẹnu òṣèré - 9ice Ìtàn tó wà nídi òwe ‘Sebótimọ Ẹlẹ́wà Sàpọ́n’ Eléyìí le jẹ́ ọnà àtìlẹyìn fún un tàbí kó jẹ́ ìdàkejì rẹ̀ .
Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Pigeon: Wo ìdí tí wọ́n fi ta ẹyẹlé kan ṣoṣo ní ₦893,000,00016 Bélú 2020 3:21 Fídíò, Joke Silva: Olu, ó tó gẹ́ pẹ̀lú obìnrin yìí níkan tó ń ba ẹ ṣeré ìfẹ́ nínú sinimá!
“Tabi bí ẹnikẹ́ni bá fi ẹnu ara rẹ̀ búra láìronú, kì báà jẹ́ láti ṣe ibi ni, tabi láti ṣe rere, irú ìbúra kíbùúra tí eniyan lè ṣe láìmọ̀, nígbà tí ó bá mọ̀, ó di ẹlẹ́bi.
E̩nì kò̩ò̩kan ló ní è̩tó̩ sí ààbò àn fàní ìmo̩yì àti ohun ìní tí ó je̩ yo̩ láti inú is̩é̩ yòówù tí ó bá s̩e ìbáà s̩e ìmò̩ sáyé̩n sì, ìwé kíko̩ tàbí is̩é̩ o̩nà.
Ipade UNWTO                       Minista fun ifitonileti, irin ajo afẹ ati ọrọ aṣa ni Naijiria, Oloye Lai Mohammed dupẹ lọwọ gomina Ambbode tipinle Eko fun atileyin to ṣe fun gbigbalejo 61-UNWTO/CAF ni Naijiria.
Gbogbo ohun tí ọbabinrin Ṣeba fẹ́, tí ó tọrọ lọ́wọ́ Solomoni pátá ni Solomoni fún un, láìka ọpọlọpọ ẹ̀bùn tí wọ́n ti kọ́ fi ṣe é lálejò.
Genotype test: Ilé aṣòfin kàn án nípá fáwọn tó fẹ́ ṣèyàwó láti ṣàyẹ̀wò ẹ̀jẹ̀
Lagos Budget: Onímọ̀ nípa ìsúná ṣàlàyé ìgbésẹ̀ Ambode
Lẹ́yìn náà ni àwọn tí wọ́n wà lábẹ́ ọ̀págun ẹ̀yà Efuraimu ṣí, wọ́n tò ní ìsọ̀rí-ìsọ̀rí.
Obinrin náà yóo wà ninu ẹ̀jẹ̀ ìwẹ̀nùmọ́ rẹ̀ fún ọjọ́ mẹtalelọgbọn; kò gbọdọ̀ fi ọwọ́ kan ohun mímọ́ kan, bẹ́ẹ̀ ni kò sì gbọdọ̀ wá sinu ibi mímọ́, títí tí ọjọ́ ìwẹ̀nùmọ́ rẹ̀ yóo fi pé.
N óo ta kẹ̀kẹ́ ogun ati àwọn tí wọn ń gùn wọ́n lókìtì.
 Gege bi Mikel se so lori ero ayelujara ajo NFF,”England je orile-ede ti mo nife si pupo, leyin opolopo odun ti mo lo ni be,’’O fikun un pe, gbogbo agbaboolu Super Eagles patapata ni won ti n fikun-lukun, ti won si ti n fojusona si ifigagbaga naa.
"Awọn alaṣẹ orilẹede India ti wa pinnu lati daa pada si Naijiria nitori ""wọn ko fẹ ki o lo orilẹede wọn lati fa oju agbaye si ẹgbẹ rẹ'."
Ó ní o yẹ ká ṣe àtúnṣe sì àwọn ohun tó jẹ́ kúdíẹ̀-kúdíẹ̀ láti ẹyin wá.
Ayò wà ní 4-0 nígba tí wọ́n fi lọ ìsinmi abala ikinni ifẹsẹwọnsẹ naa.
Ó sì mú ọ̀gágun tí ń ṣe àkóso àwọn ọmọ ogun ní ìlú ati àwọn aṣojú ọba marun-un tí ó rí ninu ìlú ati akọ̀wé olórí ogun, tí ń kọ orúkọ àwọn eniyan ilẹ̀ náà sílẹ̀ fún ogun jíjà, ati ọgọta ọkunrin tí ó rí ninu ìlú náà.
Ibi tí mo ti ń wo òkè ni mo déédéé rí háhá àgbàdo kan tí ẹ̀fúùfù ń gbé kiri mo sì ń ṣe àkíyèsí ibi tí háhá àgbàdo náà yóó balẹ̀ si.
 teletele o ti je alakoso agba ile turki lati 2002 de 2003 , o si tun je alakoso oro okere ile turki lati 2003 de 2007 .
Ṣé Irọ́ ni pé àwọn adigunjalè ń ṣọṣẹ́ ní ìpínlẹ̀ Eko àti Ogun?
Tí àtúntò kò bá wáyé ní Naijiria, ó ṣeéṣe kó túká- Pásítọ̀ Adeboye Orí yọ dírẹ́bà ọkọ̀ tó jóná ráúráú ní Delta Kò yẹ mi ìdí tí Wasiu Ayinde fi hu ìwà àbùkù tó hù sí mí- MC Murphy Àdigunjalè báńkì ní Iyin-Ekiti fẹsẹ̀ fẹ, bí wọ́n ṣe rí wa - Iléeṣẹ́ ọlọ́pàá Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 3 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 5 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Pẹlu awọn fidio to n ṣe aridaju awọn iṣẹlẹ yii ti wọn fi han, aṣiri tu sita pe ifiyajẹni ti di aṣa ti ọpọlọpọ ẹka ileeṣẹ Ọlọpaa Naijira atawọn ologun n lo.
Nípa ti ìtọrẹ tí ẹ̀ ń ṣe fún àwọn eniyan Ọlọrun, bí mo ti ṣe ètò pẹlu àwọn ìjọ Galatia, bẹ́ẹ̀ gan-an ni kí ẹ̀yin náà máa ṣe.
Kini Fani-Kayode sọ ṣaaju ko to o pada bẹbẹ?
"Olori ilu naa, Mayor Lori Lightfoot ni arun coronavirus ""n ṣe ọṣẹ to lagbara laarin awọn alawọ dudu ilu Chicago""."
Ere ni, awada ni, ko jẹ ri bẹẹ, a ko ni gba, ẹ daa pada ni ọpọ idahun táwọn akẹkọọ fi n fesi si ikede ele owo oúnjẹ naa.
Idunnu ṣubu lù ayo fún gbogbo ilẹ náà tí kò sì sí ìyàtọ̀ kánkan láàrin àwọn tó n dojú ìjà kọ ara wọn mọ ;asiko ajọyọ ọhun.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Murphy Elégungun Rọba: Mo fẹ́ di ẹnití egungun rẹ rọ jùlọ ní àgbáyé Oríṣun àwòrán, NAiraland Àkọlé àwòrán, Lọdun 2015, a ri awọn aworan to jẹyọ pẹlu gaari, ẹpa ati ṣuga pẹlu asia ẹgbẹ oṣelu PDP ti wọn pin fun awọn eniyan.
Nítori náà dexamethasone ń mu àdínkù bá àwọn ìjàmba ti àwọn òògùn míràn le ṣe fún ara.
 Ati wi pe, awọn ẹsun adigunjale ati awọn ajinigbe nikan ni awọn oṣiṣẹ FSARS yoo maa mojuto.
“Ta ló lànà fún ọ̀wààrà òjò,ati fún ààrá,
Papakọ ofurufu ilu Eko ni orukọ rẹ tẹlẹ ki wọn to yi orukọ rẹ pada si papakọ ofurufu Murtala Muhammed.
Asamọ yii ni ijọba ipinlẹ Oyo n pa lowe lowe fun asaaju igbimọ to n ṣe akoso gareeji ọkọ ni ipinlẹ Oyo, Alhaji Mukaila Lamidi, ti ọpọ eeyan mọ si Auxiliary.
Ẹni to n wa awọn ekeji rẹ yoo ma kọrin wi pe,‘ boju boju o, oloro nbọ, ẹ para mọ, ṣe ki n ṣi.
Ni bayii, Mancini yoo kuro ninu iko ohun lai gba owo gba mabinu kankan.
Orúkọ náà ni wọ́n ń jẹ́ títí di òní olónìí.
Se awọn ẹru yii ni akọkọ ti yoo gunlẹ si orilẹede Amẹrika bi?
A di pàǹtí fún gbogbo eniyan títí di bí a ti ń sọ̀rọ̀ yìí.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Audu Ogbeh: Mínísítà fẹ́tò ọ̀gbìn ní pápánu Pizza ìlú London làwọn kan ń jẹ ní Nàìjíríà 30 Ẹrẹ̀nà 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ijọba apapọ orilẹede NAijiria lọpọ igba ti pariwo pe bi awọn eeyan ṣe n ko ọja wọ orileede naa lati oke okun yoo ṣe akoba fun ọrọ aje rẹ Laipẹ yii ni minisita fun eto ọgbin lorilẹede Naijiria fọ igba yangan lori pe awọn eeyan kan wa lorilẹede Naijiria to jẹ wi pe ipapanu ti wọn njẹ, lati ilẹ okeere lo ti n wa.
Lati igbà ti iroyin ti jade, àwọn ‘Ẹgbẹ́ Agbẹjọ́rò’ lérí pé àwọn yio da iṣẹ́ silẹ̀ ti Olóri Òṣèlú Muhammadu Buhari kò bá pàṣẹ ki wọn tú àwọn Adájọ́ naa silẹ̀ ni wéréwéré.
Fẹmi Fani-Kayode ni, aarẹ Buhari lo ni ẹbi bi oluwoo se npe ara rẹ ni Emir.
ọkọ̀ ojú omi tuntun bẹ̀rẹ̀ iṣẹ́ Abiy Ahmed gba àmì ẹ̀yẹ̀ ti àláfíà lágbàáyé gẹ́gẹ́ bí ọmọ Africa Ìgbẹ̀yìn ọkùnrin tó pa obìnrin 93 ni America Òjò àrọ̀rọ̀ọ̀dá òní ṣọṣẹ́ tó pọ̀ ni Lekki nipinlẹ Eko Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, EkitiRapeCastration: ìgbésẹ̀ míì lè dẹ́kun ìwà ìfipábánilòpọ̀ Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Gẹgẹ bi eto idibo sipo gomina ni ipinlẹ Ondo ati ipinlẹ Edo ṣe ti n sunmọle bayii, awọn Baba Isalẹ yii ni wọn n sọ bi o ṣe maa ri.
Awọn kan tilẹ sọ pe, o sẹeṣe ko jẹ pe ileeṣẹ to n da awọn aṣọ igbeyawo naa ni wọn n ba polowo ọja.
Bakanna ni ajọ naa tun ṣalaye wipe oun ti fi ikọ awọn akọṣẹmọṣẹ ranṣẹ si awọn ipinlẹ lo mu ile ti orilẹede Benin Repubublic, iyẹn awọn ipinlẹ bii Kebbi, Kwara, Niger ati Ọyọ lati tubọ ṣeto amojuto to yẹ fun awọn agbegbe naa.
Bẹẹ ba ri iroyin naa ka, ọjọ ọdun Keresimesi ni alawada naa, Abdulgafar Ahmad Oluwatoyin, ti ọpọ tun mọ si Ankara Gucci, gbe soju opo Instagram rẹ pe oun ti ni iyawo afẹsọna, ti orukọ rẹ n jẹ Adedamola Adewale @Adeherself.
Ṣé ẹni tí ó kọlà nìkan ni ó ṣoríire ni, tabi ati ẹni tí kò kọlà náà?
Ni gbogbo ilẹ Yuroopu eeyan mejilelọgọta 62 lo ba ikọlu igbesunmọmi lọ eyi si dinku si igba 200, to jẹ lọdun 2018.
Solomoni gun orí pẹpẹ yìí, níbi tí gbogbo eniyan ti lè rí i.
Lẹyin naa ni Aarẹ Buhari fi oṣu mẹta mi i kun ọjọ rẹ ni ipo naa.
niluu Butembo lo je ọkan lara meji ile itoju naa ti awon ọlọtẹ kọlu, ni eyi ti
'Buhari ló lè sọ ìgbà tó máa yan minisita míì' Dalung, Audu Ogbe, Shittu Adebayo àti Isaac Adewole kò wọlé Inú mi dùn pé ẹni tó gbà ìjọba lọ́wọ́ mi ń san gbèsè tí mo fi kalẹ - Aregbesola Gẹ́gẹ́ bí àkọwé ìjọba àpapọ̀ ṣe sọ Boss Mustapha sàlàyé pé ayẹyẹ ìbúrawole náà yóò wáye níu ilé ìjọba lásìkò ìpàdé ìgbìmọ aláṣẹ́ Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Àwọn ará ilú kò ro ìnáwó ti ó kó wọn si, ariwo, àti èéfín burúkú ti ẹ̀rọ yi nfẹ sinú afẹ́fẹ́.
Ogbeni Olukolu lo fidi oro yii mule lasiko ti o se abewo
Àwọn ọmọ Haṣumu jẹ́ igba ó lé mẹtalelogun (223)
Òrò Yorùbá dé, kí eku ilé gbó, kó so fún t'oko, kí àdán gbo, kó rò fún òòbè.
Oun lo tun kọkọ gba Akọkọ ṣe Slam lẹyin ọmọ Russia to gbaa lọdun 2004 ni Wimbledon Bianca jẹ ọdọmọde to ni igbooya ati ọkan akin ninu gbogbo idawọle rẹ, eyi to han ninu idije naa.
Ní kété tí èròjà ara tó bá àìsàn ja bá ti rí èyí yóò fi ààyè gba àwọn èròjà tó kú láti kó ọmọ ogun wọlé láti dáàbò bo ara.
Dafidi ati àwọn eniyan rẹ̀ bẹ̀rẹ̀ sí rékọjá sí òdìkejì odò Jọdani.
Láìpẹ́ ìyàwó ọba náà wáá sọ fún ọba kẹ́lẹ́kẹ́lẹ́ pé ọkùnrin apẹja náà ti mú ẹja dé ọba sì pàṣẹ kí wọn mú un wá sí iwájú òun, ó ní Ọmọkùnrin, ọ̀rọ̀ èmi àti ìwọ kúrò ní ọ̀rọ̀ ìkọ̀kọ̀, mú ẹja wá kí á máa se ẹja.
Ọdun 2018 ni Wumi ṣe igbeyawo pẹlu ọkọ rẹ to n gbe nilẹ okeere.
a óo rí àwọn nǹkan olówó iyebíye kó,ilé wa yóo sì kún fún ìkógun.
dola owo ile okeere ran awon eniyan ti iye won din ni ẹ̀ẹ́dẹ́gbéje ẹ̀gbẹ̀rún
Ọkunrin náà ríran bàìbàì, ó ní, “Mo rí àwọn eniyan tí ń rìn, ṣugbọn bí igi ni wọ́n rí lójú mi.
Wo òtítọ́ nípa oúnjẹ Nódùùlù táwọn ọmọde ma ń jẹ Iya Rainbow jẹ́ gbajúmọ̀, àmọ́ kí lo mọ̀ nípa rẹ̀?
Teslim Folarin: Ọwọ́ tẹ àwọn tó kó nkan tówó rẹ̀ tó N200m nílée Sẹ́nétọ̀ tó n ṣojú Oyo Cental
Nítorí bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé òmìnira ni mo wà, tí n kò sì sí lábẹ́ ẹnìkan, sibẹ mo sọ ara mi di ẹrú gbogbo eniyan kí n lè mú ọpọlọpọ wọn wá sọ́dọ̀ Jesu.
Dafidi náà sọ̀rọ̀ nípa oríire ẹni tí Ọlọrun kà sí ẹni rere, láìwo iṣẹ́ tí ó ṣe.
Agbona kẹkọọ nipa imọ Microbiology, ni fasiti Achievers, to wa ni ilu Owo, iyẹn ni ipinle Ondo.
Bakan naa ni ileẹjọ miran paṣẹ ki Ile Igbimọ Aṣofin apapọ ma ṣe lo agbara lori Ile Igbimọ Aṣofin ipinlẹ Edo.
Iru aaye tẹriba ko maa lọ yi naa ni awọn aṣofin fi gba Gbemi Saraki to jẹ minisisita lati ipinlẹ Kwara.
Iwadii ti Ileeṣẹ iwe iroyin atigba-de-igba lori ayelujara sọ pe ida aadọta lo n ṣe igbọnsẹ loojọ, nigba ti ida mejidinlọgbọn eeyan ninu ogorun un n lọ lẹẹmeji ati ida marun abọ ni ẹẹkan lọsẹ.
Awon ti o gba ami eye Mo Ibrahim yoo gba milionu marun-un owo dollas fun odun mewaa, nigba ti yoo tun maa egberun lona igba owo dollas titi ojo aye re.
"Ti wọn ba wọgile sinima kan nitori pe ko dara to, olukuluku yoo mu iṣẹ naa ni òkunkundun.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ẹbí Melaye: Ẹ̀rù ń bá wá lóri ilera Dino, ìgbésẹ̀ ọlọ́páà sì jẹ́ ìpálara fún 3 Sẹ́rẹ́ 2019 Oríṣun àwòrán, @Dino Melaye Àkọlé àwòrán, Dino Melaye ni ikọ́ sẹ́mìí-sẹmìí- Ebi Dino Ile ẹjọ giga kan labuja ti fagile ẹbẹ agbejoro Sẹnetọ Dino Melaye pe ki awọn ọlọpaa kuro niwaju ile rẹ.
 Ko tii si ẹni lee sọ ohun to fa ijamba ile to wo naa titi di igba ti a fi ko iroyin yii jọ."
awakọ ofurufu kan lo jọ wa ninu ọkọ baalu naa to deede poora ni eka erekusu
Wọn ko bi iwa bẹẹ mọ wọn; amọ, awọn ni wọn yan lati maa hu iwa bẹẹ'' O ni awọn obinrin kii saba hu iwa bẹẹ.
Nítorí ẹnìkan sọ níbìkan pé:‘Ninu rẹ̀ ni à ń gbé,tí à ń rìn kiri,tí a wà láàyè.
Loju ẹsẹ ni Elisha gbẹmi mi nigba ti iyawo rẹ ku nile iwosan.
Ọmọwe Jonathan fun aarẹ Buhari ni imọran yii lasiko to fi ṣe abẹwo si ile alagba Rueben Faṣọranti lori iku ọmọ rẹ ti wọn ni awọn agbebọn pa ni ọjọ Ẹti to kọja.
Ni irole ojo Aiku ni aare orile ede Naijiria Muhammadu Buhari de si orile ede Netherlands saaju irinajo rẹ lo si ile-ejo agbaye fun iwa odaran, ICC niluu Hague.
FIJI Guusu Ibi Omi Pacific Afrika ni ilu yii naa wa.
26 Bélú 2020 10:17 Fídíò, Oba Adedokun Abolarin ti Oke Ila: Ó ya ọ̀pọ̀ tó súnmọ́ mi lẹ́nu bí mo ṣe ń kọ́ àwọn akẹ́kọ̀ọ́ pẹ̀lú ipò Ọba, Duration 10,1723 Bélú 2020 Amos Dauda, Iphone: Ilé ẹjọ́ dájọ́ ẹgba mẹ́ẹ̀dóògún fún ọ̀daràn tó jí Iphone ní Kaduna25 Bélú 2020 4:48 Fídíò, Akọ́mọlédè àti Àṣà lórí BBC Yorùbá: Kọ́ síi nípa iṣẹ́ tí oúnjẹ ń ṣe lára níbí, Duration 4,4824 Bélú 2020 Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí 2 sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 2:23 Fídíò, Water Generator: Ó leè ṣiṣẹ fún wákàtí mẹfà, kó tó sinmi, Duration 2,2310 Òkùdu 2020 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
Eniyan márùndínláàdọ́ta lo padanu emi won nipinle Uttar Pradesh, ti awon mẹ́rìndínlógójì miiran si padanu emi won ni agbegbe Agra ti n se ile awon Taj Mahal.
Ọlọrun ni ó fi àṣírí yìí hàn mí lójú ìran, gẹ́gẹ́ bí mo ti kọ ọ́ sinu ìwé ní ṣókí tẹ́lẹ̀.
" O ṣalaye pe, bi iya ni K-1 ṣe mu gbogbo olori Alaafin, to si ma n pọn wọn le.
Ìlànà tí Dafidi Fi Lélẹ̀ fún Kíkọ́ Tẹmpili.
Adamu lo sọ ọrọ naa ninu atẹjade kan ti agbẹnusọ ileeṣẹ ọlọpaa, Frank Mba fi ṣọwọ si awọn akọroyin.
Ìyìn rere tí mò ń waasu nìyí.
Ó ní, “Ṣé ọ̀rọ̀ yìí kò kàn yín ni,gbogbo ẹ̀yin tí ẹ̀ ń kọjá lọ?
 mozambique sì bẹ ̀ rẹ ̀ síí ṣe pàtàkì fún òwò ẹrú .
Ọdun 2012, 2016 àti 2020 ni John Mahama àti Nana Akufo-Addo ti jọ ń figagbága dupò aàrẹ Ghana Gbọ́yì-sọ̀yí àti ìròyìn èké láti ọ̀dọ̀ àwọn olólùfẹ́ wa ló ṣáábà ma ń da ìgbéyàwó àwọn òṣèré rú- Ọpẹ Ayeola Ọlọ́jọ́ padà dé!
” Wọ́n dákẹ́, wọn kò sì lè fọhùn.
Ni ipari o gba gbogbo omo egbe niyanju pe ise awa akoroyin ni lati gba alaafia laaye nipa yiyago fun ohunkohun ti ko ba faaye gba alaafia tabi ki won sa fun ohunkohun to n fon rere oro ikorira laarin iran kan tabi elesin kan si ikeji nitori pe Naijiria je orile ede ti o kun fun iran ati eya pupo.
A fún àwọn eniyan wọnyi láṣẹ láti ṣe ìdájọ́.
e maa se gbagbe pe , nigba ti mo je gomina fun ipinle Edo, mo so fun awon eniyan pe mo nilo iko omo oogun fun eto idibo.
Bi ọlọpaa Naijiria tabi ọtẹlẹmuyẹ ba jẹ ọmọ ẹgbẹ Shiite, ṣe ẹ o pe wn ni Sunmọmi."
Idì yìí bá hú u níbi tí wọ́n gbìn ín sí, ó lọ gbìn ín sí ilẹ̀ kan tí ó lọ́ràá lẹ́bàá odò, kí ó lè yọ ẹ̀ka, kí ó so èso, kí ó sì di àjàrà ńlá tí ó níyì.
O tun gbe oṣuba fun ijọba ara rẹ pe awọn ti ṣe daadaa lori ọrọ aabo, ọrọ aje ati gbigbe ogun ti iwa jẹgudujẹra.
Àwọn ọmọ Israẹli yòókù yóo wà láàrin ọpọlọpọ orílẹ̀-èdè, bí ìrì láti ọ̀dọ̀ OLUWA wá, ati bí ọ̀wààrà òjò lára koríko, tí kò ti ọwọ́ eniyan wá.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Florence, Italy, nibi ti awọn Poopu kan ti sọ pe aye yoo parẹ si 4.
Sábàbí ire ní ikú Barakat padà já sí - Ẹ̀bí fẹ̀mí ìmoore hàn sọ́mọ Nàíjíríà Sunday Igboho yarí, ó fohùn ránsẹ́ sáwọn èèyàn tó ń pẹ̀gàn rẹ̀ Magu gba ₦9.
Kí ẹ tún máa gbadura pé kí Ọlọrun gbà wá lọ́wọ́ àwọn eniyan burúkú ati àwọn ìkà, nítorí kì í ṣe gbogbo eniyan ni ó gbàgbọ́.
Gbogbo nǹkan yòókù tí Manase ṣe ati àwọn ẹ̀ṣẹ̀ tí ó dá ni a kọ sinu Ìwé Ìtàn Àwọn Ọba Juda.
Nígbà tí àìbàlẹ̀ ọkàn mi pọ̀ pupọ,ìwọ ni o tù mí ninu, tí o dá mi lọ́kàn le.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Gọngọ a sọ bí Belgium ti kojú France Sé o lè kópa nínú ìdíje ata jíjẹ nítorí owó?
Crystal Palace pàkúta sí gaàrí Manchester United ní Old Trafford A padà san owó ìtanràn fáwọn ajínigbé kí wọ́n to fi àwọn mẹ́tẹ̀ẹ̀ta sílẹ̀- Ẹbí N650,000 péré ni mò ń gbà gẹ́gẹ́ bíi owó oṣù -Gomina Ọyọ Àjẹ́ àti Aṣẹ́wó ní ìyá Rainbow - Òjòpagogo Amẹ́rika dá akẹ́kọ̀ọ́ padá nítori Facebook Agbabọọlu Van Dijk to jẹ ọmọ orilẹde Netherlands lo ti n fakọyọ lati to ti darapọ ikọ Liverpool lati Southampton loṣu kinni ọdun 2018 fun pọun marunlelaadọrin(£75m).
Àkọlé àwòrán, Ijọba fesi pe laipẹ laijina ohun gbogbo yoo yipada lorii imọtoto ilu Ibadan ati ipinlẹ Ọyọ lapapọ.
Àwọn ọmọ Israẹli ń fẹ́mọ lọ́wọ́ àwọn eniyan orílẹ̀-èdè náà, àwọn náà ń fi ọmọ fún wọn; àwọn ọmọ Israẹli sì ń bọ àwọn oriṣa wọn.
Òkúta gbígbẹ́ ni a óo fi tún wọn kọ́.
O wá ń fi gbogbo ọjọ́ ayé bẹ̀rù ibinu àwọn aninilára,nítorí wọ́n múra tán láti pa ọ́ run?
Pupọ ninu awọn tofarakasa ninu iṣẹlẹ naa jẹ ara ilu.
Ileeṣẹ ọlọpaa nipinlẹ Kaduna ti kede itusilẹ awọn akẹkọọ Fasiti Ahmadu Bello ni Zaria mẹta ti awọn ajinigbe jigbe lọjọ Iṣẹgun loju ọna marose Kaduna si Abuja.
Tọpẹ Alabi gbé owó gọbọi kalẹ̀ fáwọn aláìní lásìkò Coronavirus Coronavirus: Àwọn èèyàn ìpínlẹ̀ Eko ń sunkún ebi lásìkò ìgbéléWo bí wọ́n ṣe ń fín àyíká láti dènà Coronavirus Àwòrán ìhòhò: Salawa Abeni ti sọ̀rọ̀, ẹgbọ́ ohun tó wí Nítorí 'ẹbọra Coronavirus,' Ọọ̀ni Ogunwusi gbé orò jáde ní ilé Ifẹ̀ Commissioner feto ilera, Ọjọgbọn Akin Abayọmi lo kede iroyin ays yii nibi apero pẹlawọn akọroyin to ṣe lọjọ Ẹti.
 Leyin abewo naa, aare yoo tun lo sefilole ipade apero awon ogagun nile ise omo ogun naa.
BBC News Yoruba kuku waa lọ lati gboṣuba fun awọn iya lori ipenija itọju ọmọ.
Ni aago merin osan ojo Aje ni Golden Eaglet yoo maa koju Burkina Faso.
"Iru awọn eeyan ti o ba n ba rin ni yoo sọ iru eyi ti waa ṣe.
O gbe ẹrọ naa kalẹ latari bi owo ṣe n ti ọwọ ẹnikan bọ sọwọ ẹlomiran.
A máa gbé ìwé ńlá kan sí ọwọ́ rẹ̀ nínú èyí tí orúkọ ẹ̀ṣẹ̀ tí gbogbo ọmọ aráyé ń ṣẹ̀ wà; wọ́n to orúkọ àwọn ẹ̀ṣẹ̀ wọ̀n-nnì lẹ́sẹẹsẹ lọ: ẹ̀ṣẹ̀ ìpànìyàn, èkè, ẹ̀gàn, orúkọ-bíbàjẹ́, àìnítìjú, ìlara, ìgbéraga, ojúkòkòrò àti onírúúrú àwọn ẹ̀ṣẹ̀ ńlá mìíràn gbogbo, lẹ́hìn èyí, àwọn ẹ̀ṣẹ̀ míràn tí ó da bi ẹni pé wọ́n kéré ni wọ́n tobi níwájú àǹjànnú-ìbẹ̀rù tí i ṣe oníbodè igbó Olódùmarè.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Sunday Igboho: Sé èmi nìkan ló wà ní Nàíjíríà ni, ó lé ní 1m ọlọ́pàá tó yí ilé mi po 1 Ọ̀wàrà 2020 Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Yoruba Independence rally: Sunday Igboho ní àwọn àgbàgbà Yoruba dalẹ̀ Ẹ̀yin tẹ dà wá, tẹ sálọ fún ìwọ́de, ilẹ̀ Yorùbá yóò bi yín - Sunday Igboho bínú Ilumọọka ajafẹtọ ẹni kan nilu Ibadan Oloye Sunday Adeyemo, ti ọpọ eeyan mọ si Sunday Igboho se amusẹ ileri rẹ lati se iwọde lọjọ ominira.
” Samuẹli dáhùn pé, “Èmi nìyí.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù April Fool's Day: Wo àwọn ẹ̀tàn tí àwọn ènìyàn ti ṣe 1 Ìgbé 2019 Oríṣun àwòrán, WIKIPEDIA Àkọlé àwòrán, Ọjọ́ Kíní, Osù Kẹ́rin, ọdọọdún ni àyájọ́ Ọjọ́ April Fool tí àwọn ènìyàn tí ma ń tan àwọn ẹlòmíràn.
To ba ri bẹẹ, àsìkò yìí gan an ni òó mọ pé ọ̀rọ̀ dátà níní lóri fóònu jẹ ìpènijà gidi fún àwọn eniyan láwùjọ.
Ó ní òun yóò ṣe àgbékalẹ̀ ọ̀nà tí àwọn ará ìlú kò ní fi máà pẹ́ lójú ọ̀nà Oríṣun àwòrán, PIUS UTOMI EKPEI Sanwo-Olu ṣe ilérí láti parí ọ̀na ojú irin tí gómínà àná, Babatunde Fasola bẹ̀rẹ̀ ní pópónà Eko si Badagry, èyi tí ìjọba ti pa ti láti ọdún mélòó kan sẹ́yìn Oríṣun àwòrán, Lago State Government Ó ní òun yóò fún àwọn obinrin láàyé nínú ìjọba òun Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Olùdíje fún ipò gómìnà 24 ló pegedé ní APC Gómìnà Ambode gbà pé òun fìdí rẹmi nínú ìdìbò abẹ́nú APC l'Eko Jimi Agbaje yan igbákejì Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Femi Hamzat yẹ̀bá fún Sanwo-Olu ní ìdìbò abẹ̀lẹ̀ APC Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Lẹyìn ikú ẹ̀gbọ́n Orisabunmi, àbúrò rẹ̀ tún jáde láyé10 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Elebuibon: Lẹ́yìn ọ̀pọ̀lọ́pọ̀ oṣù tí òjò kò rọ̀ ní orílẹ̀èdè Cuba, Ọba ilẹ̀ Yorùbá ló pàṣẹ kí ó rọ̀ tó sì rọ̀1 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Yoruba Taboo: Èèwọ̀ ni fún ọba láti gbé Bibeli tabi Kurani dání dípò ifá- Elebuibon, Agẹṣin Àdìmúlà29 Bélú 2020 Yemi Elebuibon: Babaláwo èké kò le è kii ẹsẹ mẹ́rin nínú odù ifá10 Agẹmo 2019 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
21 Máṣe lépa láti kéde ọ̀rọ̀ mi, ṣùgbọ́n lépa lati gba ọ̀rọ̀ mi, àti nígbànáà ni okùn ahọ́n rẹ yíò tú; nígbànáà, bí ìwọ bá fẹ́, ìwọ yíò ní Ẹ̀mí mi àti ọ̀rọ̀ mi, bẹ́ẹ̀ni, agbára Ọlọ́run sí àìṣiyèméjì àwọn ènìyàn.
Lasiko yii ni wọn gbe owo ẹyọ Bet9ja wọọ, gẹgẹ bi owo ti wọn o maa na ninu ile ẹlẹgbọn ọn agba.
OLUWA ní, “Èmi ni OLUWA Ọlọrun yín, láti ìgbà tí ẹ ti wà ní ilẹ̀ Ijipti: ẹ kò ní Ọlọrun mìíràn lẹ́yìn mi, bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò sì ní olùgbàlà mìíràn lẹ́yìn mi.
nítorí èmi fúnra mi ni n óo fi ọ̀rọ̀ si yín lẹ́nu, n óo sì fun yín ní ọgbọ́n tí ó fi jẹ́ pé ẹnikẹ́ni ninu gbogbo àwọn tí ó lòdì si yín kò ní lè kò yín lójú, tabi kí wọ́n rí ohun wí si yín.
O kò gbọdọ̀ tẹríba fún wọn, bẹ́ẹ̀ ni o kò gbọdọ̀ sìn wọ́n, nítorí pé Ọlọrun tíí máa ń jowú ni èmi OLUWA Ọlọrun rẹ.
Irun Jimọ ko waye nibẹ lonii.
Ni bayii ọpọ awọn gbajumọ lo ti darapọ mó awọn oluwọde pe o to gẹ.
Wọn ni awọn ọlọpaa gbe oku oku mẹrin kuro ṣugbọn mọlẹbi ọkan to ku ko yọnda rẹ nitori wọn ko gba wọn laye lati gbe e lọ."
Àwọn àṣà àti ìse tó yọ obìnrin sílẹ̀ nílẹ̀ Yorùbá Lẹ́yìn ọlọ́pàá, VIO nìkan ló láṣẹ láti dá ọkọ dúró láìṣẹ̀ - Ọ̀gá VIO Eko Kò dùn mí pé mo sọ̀rọ̀ tako Buhari -Adedayo Festus Ìgbà Marún-un ti Aisha Buhari ti tako ìjọba Buhari Eyi kii ṣe igba akọkọ ti awọn agbabọọlu Naijiria maa fariga lori aisan owo ajẹmọnu wọn gẹgẹ bi ajọ NFF ṣe ṣeleri fun wọn.
Ọrọ ti o gba ẹnu ọpọ ọmọ Naijiria ree lẹyin ti ajọ eleto idibo orile-ede Naijiria da ọjọ si idibo Aarẹ ati ti awọn aṣoju ile aṣofin ti o yẹ ki o waye lọjọ Abamẹta.
Ní ọdún kọkandinlogoji ìjọba Asa, àrùn burúkú kan mú un lẹ́sẹ̀, àrùn náà pọ̀ pupọ.
N óo gbẹ̀san,n kò sì ní dá ẹnìkan kan sí.
Ọmọ rẹ̀ ọkùnrin mẹ́ta wà lára àwọn tí wọ́n pa.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ọga akọrin RCCG : Fẹla lo ṣe iwuri fun mi Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Ọga akọrin RCCG : Fẹla lo ṣe iwuri fun mi 2 Ẹrẹ̀nà 2018 Oluṣọ aguntan ati ọga akọrin ijọ irapada (RCCG) sọ wipe oloogbe Fẹla Kuti jẹ ẹni ti o mu feere fifọn wu oun.
O ka iwe gboye nile eko giga fafiti ilu Eko, bee si ni O tun tesiwaju ninu eko re ti o si gba iwe eri Post Graduate Diploma (PGD) Diplomacy & International Relations ni Foreign Service Academy nipinle Eko, iwe eri PGD miiran ninu Theology nile eko giga fafiti Redeemers, O tun gba iwe eri Protocol Service Duties nilu Rome lorile-ede Italy, bakan naa, iwe eri MBA ninu Human Resources ni nile eko giga fafiti Shobhit nilu Meerut, lorile-ede India.
Ǹjẹ́ àrùn Coronavirus leè wà lára èèyàn títí lái?
ko ni kaarẹ lati daabo bo awon eniyan lasiko ati lẹyin  eto idibo.
O ni lasiko to n dahun ibeere lori itakurọsọ BBC Yoruba ni ko si ijọba to ti kọja lọ nipinlẹ naa, to gbe eto lárugẹ to ijọba toun.
"Fun awọn ipinlẹ, Ọgbẹni Rewane sọ pe ""ilana ti igbimọ naa gbe igbesẹ naa gba yoo mu ko rọrun fun wọ̀n lati sanwo naa ju ijọba apapọ lọ, ti wọn ba le naa owo wọn pẹlu eto to yẹ."
Adari nile igbimo asofin kekere Femi
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Kí ló fà á tí àwọn ọmọ Obasanjo ń ta kò ó ní gbangba?
 awọn awọn kokoro atan arun ni okunfa gan ti akoran igbe gbuuru ati aisan aran inu .
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Pa Olabode Olajide: Pé Osinbajo wá kí mi ló mú inú mi dùn jù nílé ayé mi Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Pa Olabode Olajide: Pé Osinbajo wá kí mi ló mú inú mi dùn jù nílé ayé mi 20 Èbibi 2019 Baba Olabode Olajide ni awakọ to wa ọpọlọpọ awọn aṣaaju orilẹede Naijiria.
O tẹnu mọ pe awọn agbesunmọmi yii ko ni aato kankan to mọyan lori ayafi iṣẹ ibi ṣiṣe nipa ki wọn kan maa pa awọn alaiṣẹ lodi si itọni ẹsin Islam eyi to lodi si ipaniyan.
O ni oun yoo rii pe atunto ba ipo aarẹ ile asofin agba ti oun yoo si ṣapa lati koju iwa jẹgudujẹra.
Nibayii, ile aṣoju-ṣofin ti dibo pe ki igbakeji aarẹ, Mike Pence yọTrump nipo, bi ko ba si se bẹẹ, awọn asofin funra wọn ti setan lati yọ nipo.
fẹnuko lori adehun pe awon omo orile ede mejeeji lee wa si orile ede won laini
Equality; Ẹ wo ọ̀nà márùn ùn tí ọ̀kùnrin ṣì ń jẹ gàba lé obìnrìn lórí
Dafidi wí fún un pé, “Bí o bá bá mi lọ, ìdíwọ́ ni o óo jẹ́ fún mi.
Ẹ wá, ẹ jẹ́ kí á pa á, kí á wọ́ ọ sinu kòtò kan, kí á sọ pé ẹranko burúkú kan ni ó pa á jẹ, kí á wá wò ó bí àlá rẹ̀ yóo ṣe ṣẹ.
Ni bi ọdún marun-dinlọgọta sẹhin, nigbati Aláwọ-funfun ṣe òfin lati ya Aláwọ̀-dúdú si ọ̀tọ̀, pé wọn kò lè lo ohun amáyédẹrùn (bi ọkọ̀ wi wọ̀ pọ̀, ilé oúnjẹ, ilé ìgbọ̀nsẹ̀ àti bẹ́ ẹ̀ b ẹ́ ẹ̀  lọ)  ti wọn pèsè fún ará ilú pẹ̀lú Aláwọ-funfun, Muhammad Ali kò pa ẹnu mọ lati dẹbi fún irú òfin àti iwà burúkú yi.
Eden Hazard ti Chelsea ni Maurizio Sarri gbà pé o tó gbangba sun lọyẹ pẹlu awọn akẹgbẹ rẹ ni kete to ti sun siwaju yii.
Ọba Adesoji Aderemi wàjà ni ọjọ́ Kẹta, oṣù Keje, ọdún 1980.
Àwọn ọrẹ náà ni: wúrà, fadaka ati idẹ, 
FRSC: Èèyàn mẹ́jọ ló kù nínú ìjàmbá ọkọ̀ nípìnlẹ̀ Ògùn Wo àwòrán pápá ìṣeré MKO Abiola National Stadium Ghana ti mu àwọn afurasí ajínigbé ọmọ Naijiria mẹ́ta Buhari kò tíì ṣe to lóri June 12- NADECO Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Africa Eye: Ìjìjàgbara fún àwọn ọmọdébìnrin tó wà lọ́wọ́ ewu
Brazil ni William Abass ti mọọkọ-mọọka ninu ede Dutch tilẹ Netherlands, bakan naa lo gbọ ede oyinbo, Spanish ati pọtugi.
 O ni owo ya tijoba n beere fun lati fi sise naa ko wa fun ekun iwo oorun nikan.
Ó kó wọn wá sí ilẹ̀ mímọ́ rẹ̀,sí orí òkè tí ó ti fi agbára rẹ̀ gbà.
O ni o le ni ẹgbẹrun marun un eniyan to le padanu iṣẹ wọn lori iṣẹlẹ yii to jẹ ọmọ Naijiria.
Ó wí fún mi pẹ̀lú bí ó ti jẹ́ pé gbogbo ọgbọ́n imì òun, òun kò fi ọ̀kan pamọ́ fún ọ, ó sì tún wí fún mi pẹ̀lú bí ó ti ṣe jẹ́ ohun ẹ̀dùn ọkan rẹ, ìwọ Ìrìnkèrindò pé o kò lè bá àwọn Àkàrà-oògùn lọ sí Òkè Láńgbòdó tí wọ́n lọ láòpẹ́ yìí, nítorí ibib ti òun rán ọ, àti pé nígbà tí o bá ti ibẹ̀ dé, ọkàn rẹ yóò túbọ̀ gbó láti ṣe bí àwọn ẹgbẹ́ rẹ ti ń ṣe.
Ẹ máa gbìjà aláìníbaba, kí ẹ sì máa gba ẹjọ́ opó rò.
Nígbà náà ni ọba yóo sọ fún àwọn ti ọwọ́ ọ̀tún pé, ‘Ẹ wá, ẹ̀yin tí Baba mi ti bukun.
Lẹhin ọjọ diẹ ti wọn bura wọle fun Ṣeyi Makinde gẹgẹ bii gomina ipinẹ Ọyọ ni o fi ofin de awọn ẹgbẹ awakọ, ti o si paṣẹ wi pe ki wọn kuro ni gbogbo ibudokọ ati awọn ikorita ti wọn ti n gba owo.
OLUWA kò faramọ́ pé kí á máa ni àwọn ẹlẹ́wọ̀n lára lórí ilẹ̀ ayé,
Fadeyi ni ọwọ ti tẹ awọn afurasi kan lori awọn iwa isekupani ati ikọlu to n waye lagbegbe Akinyele naa.
A kò fòfin de owó naira tó ti pẹ́ ní Naijiria -CBN Ẹ yé gba owó orí níbi ìdána ìyàwó mọ́, sísọmọbìnrin s'óko ẹrú ni- Daddy Freeze Iṣẹ́ ṣẹ̀ṣẹ̀ bọ́ lọ́wọ́ Seth Ator tó yìnbọn pa ọ̀pọ̀ èèyàn ní Texas ni- ọlọ́pàá Wọn rọ Olootu ijọba ilẹ Gẹẹsi, Boris Johnson pe ko gbaruku ti Aarẹ Muhammadu Buhari lati gbogun ti iwa ajẹbanu.
ṣé ẹ óo dúró títí wọn óo fi dàgbà ni, àbí ẹ óo sọ pé ẹ kò ní ní ọkọ mọ́?
bayii, Osaka yoo lo koju olukopa lati orile-ede Croatia, Donna Vekic ti
ti o nife ere idaraya lopolopo, eleyi ti o sokunfa idi ti won fi fi Gomina
”Baba rẹ̀ sì sọ fún iranṣẹ kan kí ó gbé ọmọ náà lọ sọ́dọ̀ ìyá rẹ̀.
92 ) Ọga agba ajọ WAEC naa wa fi kun wi pe iwe ẹri esi idanwo WAEC naa yoo wa fun awọn eniyan lati gba ni Osu mẹta si asiko yi.
Ìdààmú ati ìrora dẹ́rùbà á,wọ́n ṣẹgun rẹ̀, bí ọba tí ó múra ogun.
N ko dara pọ mọ ẹgbẹ oṣere tiata kankan, bẹẹ ni n ko ni ọga kankan pato to kọ mi niṣẹ, amọ mo ni ọpọlọpọ ọga to n tọ mi sọna ni ẹnu isẹ tiata naa.
Bakan naa, aare Buhari ti ro
Ṣùgbọ́n ìjọba mi kì í ṣe ti ìhín.
Ondo Police: À ń wá Deji Adenuga tó dáná sun ènìyàn mẹ́jọ
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù World Cup 2018: Salah yóò kópa nínu ìdíje Russia vs Egypt lọjọ Iṣẹgun 18 Òkùdu 2018 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 19 Òkùdu 2018 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Salah ló gba àmì ẹ̀yẹ̀ ẹlẹ́sẹ̀-ayò tó gbá bọ́ọ̀lù sáwọ̀n jù nínú ìdíje Premier League ní sáà tó kọjá Ìrètí wà pé Salah yóò gbógo fun Egypt nínú ìdíje Russia 2018.
Ta ni kò ní bẹ̀rù rẹ, Oluwa?
Àwọn tí wọ́n wá ni Iṣimaeli, ọmọ Netanaya, Johanani, ọmọ Karea, Seraya, ọmọ Tanhumeti, ará Netofa, ati Jaasanaya, ọmọ ará Maakati.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Isẹ́ Tíátà tí mò ń se ti tó mi jẹun' Koko iroyin: Ọwọ tẹ awọn ọlọ́ṣà Ọfa, Ọmọ Naijiria ń ta ara wọn nilu òyìnbó 'EFCC mo dé' àti àwọn àṣà míì táwọn olóṣèlú fi dagbo rú ní 2018 Àrà ọ̀tọ̀ inú orin tó jáde lọ́dún 2018 ní Nàìjíríà Buhari àti Atiku kí àwọn Krìsìtẹ́nì kú ọdún kérésìmesì Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Asisat Oshoala: ìbẹ̀rẹ̀ mi kò rọrùn rárá nínú eré bọ́ọ̀lù Sylvia Fiimu yii ni ọpọ gba pe o jẹ ọkan lara àwọn fiimu Naijiria to dara julọ lọdun 2018.
Pípọ́n ìwé ẹ̀rí lé ju ìmọ̀ lọ n kó bá ètò ẹ̀kọ́ l'órílẹ̀èdè Nàìjíríà.
Eyi waye ni iwaju ita gbọngan kan ni ilu Konduga nibi ti awọn ololufẹ ere bọọlu ti maa n woran lori ẹrọ amohumaworan.
Gege bi oro lati enu amugbalegbe re pataki si eto iroyin ati igbodegba, ogbeni Yusuph Olaniyonu.
“Wọlé lọ sí ọ̀dọ̀ Farao, ọba ilẹ̀ Ijipti, kí o wí fún un pé kí ó jẹ́ kí àwọn eniyan Israẹli jáde kúrò ní ilẹ̀ rẹ̀.
Iyekíye tí ó bá wù yín ni kí ẹ bèèrè fún owó orí iyawo, n óo san án, ẹ ṣá ti fi omidan náà fún mi.
Oríṣun àwòrán, @hadd1nzarewa Bakan naa ni awọn eeyan kan n bu ẹnu atẹ lu iru igbesẹ bayii, ti wọn si fẹ mọ idi ti aabo to peye ko se wa fun awọn iwe idanwo to se koko bayii.
Ẹni tí a bí ní aláìkọlà tí ó ń pa Òfin mọ́, ó mú ìtìjú bá ìwọ tí a kọ Òfin sílẹ̀ fún, tí o kọlà, ṣugbọn sibẹ tí o jẹ́ arúfin.
Ninu eleyi to ṣe laipẹ yi, ko tiẹ sọrọ rara.
BBC Yoruba gbe awọn oju oge oju to n gbe ogo Oodua ga nilẹ America ati Europe yii ki awọn ọdọ ọmọ Yoruba to pinnu lati lọ silẹ okeere le ri awokọṣe rere lati ṣoju iran Yoruba daadaa nibi kibi ti wọn ba wa iṣẹ aje lọ.
 Ènìyàn ò gbọdọ ̀ máa to nǹkan lódìlódì .
Ri i daju pe nọmba atẹsanwo gba ina ọba mẹta lo gba 3.
Arsenal ṣẹ́ṣó ìyà, búlálà ẹlẹ́nu mẹ́ta ni Leicester City fi lù wọ́n lálù bami Man Utd Vs Man City: Ọ̀rẹ́ dì ọtá, ọtá dì ọ̀rẹ́ torí ife ẹ̀yẹ Ìjọ̀ba Saudi ti tú Zainab tí wọ́n fẹ̀sùn òògùn olóró kàn sílẹ̀ ''Ọrẹbinrin mi jẹ́ mí ní ₦20,000 ní mò fí dáná sún àwọn ẹbí rẹ'' Nigba ti abala keji ifẹsẹwọnsẹ naa bẹrẹ ni pẹrẹu, o dabi wi pe awọn ọmọ agbabọọlu Tottenham ti n jawe sobi, sugbọn gbogbo laalaa wọn ko yọri si rere.
Kí ẹ lè mọ ọ̀nà tí ẹ óo gbà, nítorí pé ẹ kò rin ọ̀nà yìí rí.
Ọmọ atàpátadìde ni mí, télọ̀ ni bàbá mi- Abiola Ajimobi Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Nítorí Dafidi kò gòkè lọ sí ọ̀run.
Louise Braille ló wá ṣe àtúnṣe sí ètò ihò-títò náà.
APC ni eto idibo lawọn fẹ ṣe kii ṣe ogun lawọn n gbaradi fun un.
 Ọbẹ yọjẹ ọbẹ to wọpọ ni apa ariwa iwọ irun ati apa ariwa busu orun ni ilẹ naijiria .
Ọ̀pọ̀ eniyan ni ó ń gba ibẹ̀.
Nítorí ẹni tí ó fún Peteru ní agbára láti ṣiṣẹ́ láàrin àwọn tí wọ́n kọlà ni ó fún mi ní agbára láti ṣiṣẹ́ láàrin àwọn tí kì í ṣe Juu.
Ọlọrun wí pé, “Èmi ni Ọlọrun baba rẹ, má fòyà rárá láti lọ sí Ijipti, nítorí pé n óo sọ ọ́ di orílẹ̀-èdè ńlá níbẹ̀.
Ni ọlọpaa agbegbe Mestre lẹba Venice ba wọn ọn ni faini to fẹrẹẹ to $400 (iyẹn nkan bii N144,000).
"Ẹ kò gbọdọ̀ jẹ ajá mọ́' ''Olóde'' ni Yorùbá ń pe coronavirus, iléeṣẹ́ Yemkem ti rí òògùn rẹ̀ báyìí- Olùdásílẹ̀ Yemkem Coronavirus ti di ara wa, kò le è kúrò mọ láéláé - WHO ""Emi gan an ti ni ọmọ to n ṣe awada lagbo iṣẹ tiata, orukọ rẹ si ni Olusola Omidina."
Ni bayii, Belgium dipo kinni mu pelu ami mesan an lori tabili nipele keji(Group 2), saaju orile-ede Switzerland ti o dipo keji mu.
Nígbà tí bàbá mi parí eléyìí obìnrin náà wwáá béèrè lọ́wọ́ rẹ̀, ó ní, Kí ni ìdí rẹ̀ tí ìwọ fi fẹ́ràn mi?
OLUWA n ṣe àwọn ará Filistia níbi ní gbogbo ọjọ́ ayé Samuẹli.
Timi Agbale ati Gbọnka Ebiri jẹ akọni ọdẹ aperin ati jagunjagun ni Ọyọ atijọ, ti wọn ko si lee kọ iyan wọn, ki wọn ma fi ewe boo, ti itan si sọ fun wa pe Timi lo da ilu Ẹdẹ, to wa nipinlẹ Ọṣun silẹ.
Oríṣun àwòrán, NCDC Èèyàn 1,041 tuntun míràn ló ṣẹ̀ṣẹ̀ fara kásá Coronavirus ní Naijiria Oríṣun àwòrán, @NCDCgov Esi ayẹwo Coronavirus lati ipinlẹ mejilelogun at Abuja ti ajọ NCDC ṣẹṣẹ fi sita ti fi han pe, eeyan 1,041 tun ti ni aarun naa ni Naijiria.
Ó dáhùn ó sì wí pé: Ọ̀rọ̀ tí o sọ rọ̀ bí ọ̀gẹ̀dẹ̀ pupa kò fẹ́ èsì tí ó le bí òkúta dídán inú omi.
Onkọrin Naijiria, Davido lo fi orin naa fọn rere Chioma to pe ni assurance ololufẹ oun.
Oludari agba ileeṣẹ naa, Mohammad Babandede ati gbogbo oṣiṣẹ ileeṣẹ naa ni yoo ṣe ayẹwo naa.
Nigba naa, wọn ni Oluwo nsọrọ pẹlu Minisita abẹle, ọgagun Abdulrahman Dambazzau ti wọn jọ wa lori tabili kan naa pẹlu Ọọni ati gomina ipinlẹ Rivers, Nyesome Wike.
Ní Parani yìí ni àwọn ọkunrin mìíràn ti para pọ̀ mọ́ wọn, tí gbogbo wọ́n sì jọ lọ sí Ijipti.
Nibayii, oru Ọjọbọ, ọjọ kọkanlelogun, oṣu Keji ni ipolongo ibo aarẹ ati tile aṣofin apapọ yoo wa sopin.
Ní òwúrọ̀ ọjọ́ keji, Jonatani mú ọmọde kan lọ́wọ́, ó lọ sí orí pápá gẹ́gẹ́ bí àdéhùn òun ati Dafidi.
Iwọn rẹ ko gbọdọ din ni aadọta kilo bẹẹ ko gbọdọ ju ọgọjọ kilo lọ.
Nnamdi Kanu: Ìdí tí mo fi sá ní Nàìjíríà EFCC gbé Fayoṣe wà jẹjọ ní Èkó Ǹjẹ́ ara rẹ ń kọ ìbálòpọ̀ bí?
8 ènìyàn ni ágbáyé, ọ̀pọ̀ nínú wọn ọmọdé 5 Òkùdu 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 6 Òkùdu 2019 Oríṣun àwòrán, AFP Àkọlé àwòrán, Eefin Port Harcourt ti di oun to n ba gbogbo eniyan to ba de ilu naa lẹru Ajọ ilera agbaye WHO ni Naijiria wa lara orilẹede ti atẹgun oró ti n pa awọn eniyan ju.
Ní ti Ọlọrun yìí, pípé ni ọ̀nà rẹ̀,òtítọ́ ni ìlérí OLUWA,ó sì jẹ́ apata fun gbogbo àwọn tí wọ́n bá sápamọ́ sábẹ́ ààbò rẹ̀.
"Iya Awero, ọnku Larry àti Baba Feyikọgbọn kò fìgbà kankan tọrọ oúnjẹ àbí iranwọ lọ́nà kọna lọ́wọ́ mi rí, mo kan béèrè iranwọ fún wọn gẹ́gẹ́ bíi ara aáyán mi láti ṣe atilẹyin fún wọn.
Kò tíì sẹ́ni tó fojú hàn gẹ́gẹ́ bí ẹni tó sokùnfà rẹ̀ sùgbọ́n òjú ni kìí se àìmọ̀ f'ólóko pé ikọ̀ Boko Haram máa ń ṣ'ọṣẹ́ ní agbègbè náà.
Gẹgẹ bi ohun ti akọwe ẹgbẹ awọn dokita oniṣegun oyinbo nipinlẹ Ondo, Dokita Olasakinju Tunde ṣe fidi rẹ mulẹ fun BBC, mọjumọ Ọjọbọ ni onimọ iṣegun yii dagbere faye.
Bí Hana ti ń gbadura sí OLUWA, Eli ń wo ẹnu rẹ̀.
“Àlejò ni mo jẹ́ láàrin yín, ẹ bá mi wá ilẹ̀ ní ìwọ̀nba ninu ilẹ̀ yín tí mo lè máa lò bí itẹ́ òkú, kí n lè sin òkú aya mi yìí, kí ó kúrò nílẹ̀.
 odùduwà ni a gbó pé ó kókó sí kúrò ní agbègbè náà wá sí ilé-ifẹ ̀ .
 gbígbé papọ ̀ yìí máa ń mú ìdádúró láì sí ìbẹ ̀ rù dání nítorí bí òṣùṣù ọwọ ̀ ṣe le láti ṣẹ ́ , bẹ ́ ẹ ̀ ni àwùjọ tó fohùn ṣọ ̀ kan .
Inú rẹ̀ bàjẹ́, ó ní, “Nítorí kí ni àwọn eniyan ṣe ń wá àmì lóde òní?
Ọbafẹmi Hamzat ti fi ẹgbẹrun lọna mọkan-dinlojileẹẹdẹgbẹrin ati
Torinaa, ki la le ṣe lati ni inu didun lasiko ṣiṣe iṣẹ lati ile?
Nígbà tí mo bá pa á rẹ́, n óo bo ojú ọ̀run; n óo jẹ́ kí ìràwọ̀ ṣóòkùn n óo fi ìkùukùu bo oòrùn lójú, òṣùpá kò sì ní tan ìmọ́lẹ̀.
Àwọn ojú oge Yollywood t'ọ́jà wọ́n ṣì ń tà wàràwàrà Àgbo ló ṣiṣẹ́ fún mi l''asìkò tí mò ń wojú Olúwa fún ọmọ - Toyin Abraham Ẹ gbà mi o!
Kọ́ wa ní ohun tí a lè bá Ọlọrun sọ,a kò lè kó àròyé wa jọ siwaju rẹ̀,nítorí àìmọ̀kan wa.
Ọ̀gbẹ́ni Túndé Atọ̀pinpin: Òun ló ní kí Dúró fi ọ̀rọ̀ owó tí ó sọnù lo Olófìn-íntótó.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Coronavirus in Nigeria: Ọmọ Nàìjíríà kan ṣàlàyé pé nǹkan ò dẹ̀rùn láyé coronavirus yí ní orílẹ̀èdè Italy Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Coronavirus in Nigeria: Ọmọ Nàìjíríà kan ṣàlàyé pé nǹkan ò dẹ̀rùn láyé coronavirus yí ní orílẹ̀èdè Italy 22 Ẹrẹ̀nà 2020 Lati igba ti arun Coronavirus ti bs sigboro agbaye, ko si eniyan ti arun naa ko tii mu ayipada ba igbe aye rẹ.
Babáyẹjú: Ọmọbìnrin tí a bí lẹ́yìn ikú baba rẹ
Olori Memunat Omowunmi Adeyemi: Oríṣun àwòrán, olori_omoh_one Olori Memunat yii wa lara awọn ayaba ọba Adeyemi to gbafẹ, o lọyaya, to si ko ni mọra.
Gregory‘s College, Ọbalende Imọ nipa isẹ Amofin lo wu Lamidi lati kọ nile ẹkọ fasiti kan nilu oyinbo, o ku ọjọ meji ti yoo tẹ ọkọ leti ni wọn rọ baba rẹ loye, ti ko si lee lọ mọ N kò mọ bí wọ́n ṣe n bá obìnrin sọ̀rọ̀ ìfẹ́ - Aláàfin Yàtọ̀ sí Ọ̀ṣun Òṣogbo, Ṣàǹgó pẹ̀lú a máa ní arugbá lóde Ọ̀yọ̀ Àwọn alálẹ̀ kò ní forí jìn mí tí ń kò bá ṣe ọdún Ṣàngó - Alaafin Ìlú ò rẹ́rìn ín rárá, Alaafin Adeyemi III fárígá fún Buhari nínú lẹ́tà tuntun Bàbá ọlọ́mọ méjì fi ipá bá ọmọ ọdún mẹ́rin lò pọ̀; Adájọ́ rán an ní ẹ̀wọ̀n gbére Isẹ aayan laayo ti Lamidi kọkọ mu se nigba ewe rẹ ni isẹ adojutofo (Insurance), to si tun jẹ akọsẹ-mọsẹ abẹsẹkubiojo, bẹẹ si lo tun maa n se ere idaraya titi di akoko yii lai naani ọjọ ori rẹ Ki Ọlayiwọla to gun ori itẹ awọn baba nla rẹ, iyawo meji lo ni, eyiun Olori Abibat Adeyẹmi, ti wọn n pe ni iya Dodo ati Olori Rahmat Adedayọ Adeyẹmi, ti wọn mọ si iya Ile koto Orukọ Akọbi ọmọ Ọba Adeyẹmi ni Kudirat Akọfade Erediuwa, ẹni to ti jade laye bayii Eeyan mẹwaa lo du itẹ Alaafin pẹlu Lamidi Ọlayiwọla lẹyin iku Alaafin Bello Gbadegẹsin Ladigbolu keji.
Nítorí náà, ranṣẹ lọ sí Jọpa, kí o lọ pe Simoni tí àdàpè rẹ̀ ń jẹ́ Peteru wá.
Nkan bi ọsẹ kan ni abala aisan yi ma fi n waye- ti ọpọ a si ma re kọja nitori awọn ọmọ ogun ara wọn ti ba kokoro naa ja.
 À ń lo kòkòrò àìlèfojúrí afàìsàn rọpárọsẹ ̀ tí a ti pa láti fi ṣe oríṣi kan , a sì má a ń fún ni ní èyí bíi abẹ ́ rẹ ́ ( ipv ) , a sì tún ń lo kòkòrò àìlèfojúrí afàìsàn rọpárọsẹ ̀ tí kò lágbára mọ ́ láti fi ṣe oríṣi kejì , a sì ń gba ẹnu lo èyí ( opv ) .
Ìpínlẹ̀ Sokoto Ní ti Sokoto, ètò ẹ̀kọ́ sì n lọ, kò sí ọ̀rọ̀ lórí bóya wọ́n yóò ti ilé ẹ̀kọ́ tàbi wọn o ni tì í.
 ilé ọkọ lobìnrin í gbé , ilé ọkọ ni àdépẹ ̀ kun obìnrin .
Nítorí náà, n óo pa yín dà sí àìdára, ẹ óo sì di yẹpẹrẹ lójú àwọn eniyan; nítorí pé ẹ kò tẹ̀lé ìlànà mi, ẹ̀ ń fi ojuṣaaju bá àwọn eniyan lò nígbà tí ẹ bá ń kọ́ wọn.
Ọjọbọ ni wọn gbẹmi awọn eeyan ti wọn fẹ sin papọ naa, ti aarẹ Muhammadu Buhari si sẹsẹ se abẹwo ibanikẹdun sipinlẹ naa lọjọ aiku.
Ifẹsẹwọnsẹ naa to waye ni gbagede ibuba Everton to wa ni Merseyside pari pẹlu awọn oniruuru arisọ to kan ikọ mejeeji.
Na pẹ̀gànpẹ̀gàn eniyan, òpè yóo sì kọ́gbọ́n.
Ó tún gba àwọn ìpè kan, èyí tí ó ń kọ “orin pupa” (orin ọ̀tẹ̀ tí ó ń yín Ẹgbẹ́ Òṣèlú Chinese Communist Party).
Làásìgbò ọ̀tun súyọ nínú ẹgbẹ́ òṣèlú APC Asamọ ọrọ kan lo ni ile to ba gbogun ti ara rẹ, ko ni duro, bẹẹ si ni adiẹ kii jẹ ifun ara wọn.
Aago Naijiria ti kún àkúnwọ́sílẹ̀ - Tunde Bakare Fulani nìkan kọ́ ló ń pa ènìyàn ní Naijiria -Tinubu Ǹjẹ́ ẹ mọ ohun tí igbákejì ààrẹ Yemi Osinbajo sọ nílé bàbá Fasoranti Kí ló mú àwọn adarí Nàìjíríà tako ra wọn lórí ikú ọmọ alága ẹgbẹ́ Afenifere?
Ẹ̀jẹ̀ sì wà níbi gbogbo jákèjádò ilẹ̀ Ijipti.
Japheth Omojuwa wa lara awọn to ki ku ori ire.
Divorce in Ibadan: Iléẹjọ́ tú ìgbéyàwó ọdún méjé ká nítorí àìnáání ara ẹni
O ni ṣaaju asiko naa, oun ko ti ni anfaani lati rinrin ajo kuro ni Naijiria lọ si orilẹede miiran lati Naijiria.
Eyi jẹ ọjọ diẹ saaju ki ijọba o to kede aṣẹ konile-o-gbele ni Ipinleẹ Eko, Ogun, ati olu-ilu Naijiria, Abuja.
Àwọn ìlú bíi Diboni, Bamoti Baali, ati Beti Baalimeoni; 
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Lẹyin gbogbo ifagagbaga, Argentina fagba han Super Eagles pẹlu ami ayo meji si ẹyọ kan ni 1994 Argentina v Nigeria, 02 June 2002 (1-0) Nigba to di idije ife ẹyẹ agbaye FIFA ni ọdun 2002, ikọ mejeeji tun pade.
Mo rò ó lọ́kàn mi, mo sì dá àwọn ọlọ́lá ati àwọn ìjòyè lẹ́bi.
Messis vs Ronaldo: Jurgen Klopp ní àràmọ̀ndà agbábọ́ọ̀lù tó ń jẹ Messi, ó ju Ronaldo lọ lórí pápá
Ṣé ìwọ leè wa kẹ̀kẹ́ lórí ìgò?
 fọláṣadé ni ó yí orúkọ padà tí ó di fìlísíà .
O fí kun un pé áwọn agbébọn Boko haram náà yìnbọn s'ókè kíkankíkan pẹ̀lú àdó olóró lásìkò ìkọlù wọn náà, eléyìí tó ṣokùnfà ìfarapa ọgọ́ta àwọn èèyàn tí wọ́n ti gbé lọ sí ilé ìwòsàn fún ìtọ́jú báyìí.
Abiy ṣẹṣẹ ba awọn ero sọrọ tan nibi iwọde naa, ni ado oloro ọhun dun.
Nítorí pé Mose ti fún àwọn ẹ̀yà meji ati ààbọ̀ ní ìpín tiwọn ní òdìkejì odò Jọdani, ṣugbọn kò pín ilẹ̀ fún àwọn ẹ̀yà Lefi.
Bí a kò bá rẹ́ni gbẹ́kẹ̀lé, à á tẹra mọ iṣẹ́ ẹni
Tó bá sì ṣe tán á padà sí ibi tí ó nsùn sí.
Aaroni ni a yà sọ́tọ̀ fún iṣẹ́ ibi mímọ́, pé kí òun ati àwọn ìran rẹ̀ títí lae máa sun turari níwájú OLUWA, kí wọ́n máa darí ìsìn OLUWA, kí wọ́n sì máa súre fún àwọn eniyan ní orúkọ rẹ̀ títí lae.
Ìbànújẹ́ ni kí eniyan bí ọmọ tí kò gbọ́n,kò sí ayọ̀ fún baba òmùgọ̀.
Owo sinkun olopaa ti te awon
Iroyin sọ pe Abba Kyari ni aisan otutu aya, Pneumonia, ati awọn aisan miran ninu agọ ara rẹ, ko to di pe o ko aarun coronavirus.
“Ẹ kò gbọdọ̀ pọ́n aládùúgbò yín lójú tabi kí ẹ jà á lólè; owó iṣẹ́ tí alágbàṣe bá ba yín ṣe kò gbọdọ̀ di ọjọ́ keji lọ́wọ́ yín.
Oluwo sọ f'Aláàfin pé k'Olorì máa dádé Aarẹ ọna kakanfo Yoruba Àwọn méjì kan ti bi ìbejì l'ọ́dún 2018.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Wo ìròyìn tó pọ̀ jùlọ táwọn èèyàn ń wá ní Google lọ́dún 2020 Obasanjo àti Gani Adams tẹ́ mi pẹ̀lú bí wọn ṣe tahùn síra wọn - Adebanjo Buhari le sọ ipò ààrẹ́ nù tí kò bá yọjú sáwọn aṣòfin - Amòfin Ẹgbẹ́ òṣèlú alátakò takú láti gba èsì ìbò ààrẹ ní Ghana Ọ̀pọ̀ nkan tó n ṣẹlẹ̀ kò jẹ́ kí n gbàgbọ́ pé Naijiria wà ní abẹ́ ìdarí ẹnikẹ́ni - Wole Soyinka Ọmọ ẹgbẹ́ òkùnkùn ṣoro ní Ijebu Ode, ọ̀pọ̀ ẹ̀mí sọnù Fidio kan to gba ori ayelujara kan, to se alaye bi wọn se n ji Maina nile ẹjọ lo fidi ọrọ yii mulẹ.
 Ó jẹ ́ ọmọ gbórówó tí í ṣe ọmọbìnrin alárẹ ̀ tí ó fún odùduwà fẹ ́ ní ilé-ifẹ ̀ , ipasẹ ̀ àwọn ẹbí ìyáa rẹ ̀ ni Ògbòrògánńdà tọ ̀ wá , lẹ ́ hìn ikú bàbá rẹ ̀ .
Orukọ wọn ree, Uzoho ni aṣọle akọkọ, Shehu, Emeruo, Ekong, jamilu, Ndidi, Etebo, Musa, Onyekuru, Iwobi ati Ighalo ni yoo bẹrẹ ninu ifẹsẹwọnsẹ naa.
Aare orile ede Naijiria Muhammadu Buhari ti seleri pe oun ko ni ja orile
Abadofin naa yannana ẹwọn ọdun marun un gbako fun olukọ ti ọwọ ofin ba tẹ pe o n fi ilọkulọ ibalopọ lọ akẹkọbinrin tabi ọkunrin.
Ati pe fifi ofin de IMN waye lẹyin ti ile ẹjọ gba iwe ipe fun aṣẹ lati ọdọ ijọba apapọ ki alaafia le jóba lasiko yii.
Dájú-dájú ìran jata-jata ni àwa ń ṣe.
Bakan naa, won tun dibo yan awon omo egbe tuntun toro kan gbongbon fun ijoba ibile Udi.
Jafaru to sọrọ niwaju ijoko itagbangba ti ile asofin agba n se lori igbesẹ lati dẹkun akunfọ ati akunfaya ọgba ẹwọn lorilẹede Naijiria.
Àwọn tí wọ́n kọ́ ọ fi ẹwà jíǹkí rẹ.
Apẹ̀rẹ̀ ni wọ́n fi sọ̀ mí kalẹ̀ láti ojú fèrèsé lára odi ìlú, ni mo fi bọ́ lọ́wọ́ rẹ̀.
 O ni “ọpọ anfani ni a le ri ninu ẹka irinajo-afẹ, ti ijọba ipinlẹ Eko le ṣamulo.
Ẹ fi ìfẹnukonu ti alaafia kí ara yín.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Yahaya Bello ni oun ko tu igbimọ iṣejọba ipinlẹ Kogi ka 12 Ẹrẹ̀nà 2018 Oríṣun àwòrán, @FanwoKings Àkọlé àwòrán, Digbi n'ijọba Kogi wa - Yahaya Bello Gomina ipinlẹ Kogi, Yahaya Bello wipe oun ko f'igba kan kan yọ awọn kọmiṣọna ati awọn alaga ibilẹ nipo nipinlẹ naa.
ni maa yan awon igbimo , ẹ o ri awon ti yoo wa ninu igbimo wonyi ati bi a se fi
bi igbimo ojuse yii ni lati seto ilana nipa eto okoowo ati eto ọrọ aje ti
Ó ṣe ibi ìrúbọ káàkiri àwọn ìlú Juda níbi tí yóo ti máa sun turari sí àwọn oriṣa.
Ikọ̀ ìwádìí BBC ṣí àwọn tó ń jí ìkókó gbé sí gbangba Ọkunrin naa ni mi o lo Access Bank mọ nitori Access bank ti ja ara rẹ kulẹ gẹgẹ ile ifowopamọ, o si tun ja ara rẹ kulẹ niwasju awọn ọmọ Naijiria lapapọ."
Ìbálòpọ̀ fún máàkì: Monica fojú hàn níwájú ìgbìmọ̀ OAU
Tani Mojisola Alli-Macaulay, aṣòfin tó ní àwọn ọ̀dọ́ Nàìjíríà fa igbó yó ni orí wọ́n ṣe máa n gbona?
"Oríṣun àwòrán, Ayaba folashade/instagram Ninu ọrọ to kọ si ori ayelujara ibaraẹnidọrẹ Instagram rẹ, Olori Folashade ṣapejuwe ibẹta ọmọ naa, gẹgẹ bi ""akanṣe iyanu Ọlọrun; ibẹta kan ṣoṣo to ti i jẹ ti Adeyemi Kẹta""."
Awon koko to je yo nibe naa ni ona ibaraenisoro ati ona gbigba esi pada lenu ise onikaluku pelu mimi=ojuto igbe aye alaafia awon osise.
Oríṣun àwòrán, @ATIKULATE_2019 Àkọlé àwòrán, Ọbabìnrin Elizabeth Kejì ń bọ̀ Ọba Olateru-Olagbegi kejì lọ́wọ́ lọ́dún 1960 Oṣù kan lẹ́yìn ìṣẹ̀lẹ̀ náà, ní igun ológun míràn ditẹ gba ìjọba ni Naijiria, tí wọn si rán Adekunle Fajuyi sajule ọrun ni ọjọ́ kọkandínlọgbọn, oṣù keje ọdún 1966 yìí kan náà, tí ìjọba ológun Yakubu Gowon sì gba àkóso.
Amọ Olubadamọran fun aarẹ Muhammadu Buhari lori ọrọ iroyin, Femi Adesina fi lede wi pe, eto aabo ko dẹnukọlẹ to bi awọn eniyan ṣe n sọ to.
Gbé mi ró, kí n lè wà láìléwu,kí n lè máa ka ìlànà rẹ sí nígbà gbogbo.
O ni ijọba ọun yoo ma ṣatunyẹwo igbesẹ naa ni igba de igba titi ti ọrọ ajakalẹ arun ọhun yoo fi niyanju.
Onidajo Agba, Josephine Oyefeso lasiko to n se idajọ naa ni Ọjọ Ẹti sọ wi pe o jẹbi ẹsun ẹyọkan ti ijọba ipinlẹ Eko fi kan an.
" Nigba ta bi pe ki lo fẹ se nipa isẹlẹ yii, MC Murphy ni isẹlẹ naa ti kọja agbara oun, ti olu ile ẹgbẹ awọn agbohunsafẹfẹ ni Naijiria, FIBAN, si ti tẹsẹ bọ ọrọ naa.
Oríṣun àwòrán, others Àkọlé àwòrán, Akeredolu fún Malami lésì lẹ́yìn tó ní ìdásílẹ̀ Amotekun kò bá òfin mu Akeredolu wa sọ pe awọn gomina ilẹ Yoruba yoo ṣe ipade laipẹ, ti wọn yoo si gbe igbesẹ to tọ lori ọrọ ti Malami sọ, pe ikọ Amotekun ko ba ofin ilẹ Naijiria mu."
    Ọba Ọlagbegi II tí ó jẹ́ Ọlọ́wọ̀ ní ọ̀wọ̀ lónìí jẹ́ ẹni àkíyèsí pàtàkì kan.
Koda o lee tọka si eniyan gẹgẹ bii onijagidijagan ẹda tabi ki o fun ọlọpaa ni ero pe onitọhun n gbimọran ati sa mọ ọlọpaa lọwọ ni.
Ọ tèsíwájú pé, inú ará ìlú kò dùn sí bí àwọn tó di ipò mu ti ṣe n gba owo tabua, ti àwọn ará ìlú mi kò sí ri oúnjẹ jẹ.
fun awon eniyan agbegbe Kishi lori ewu to ro mo aifaaye gba awon osise ile ise
Nígbà tí ọkà dàgbà, tí ó yọ ọmọ, èpò náà dàgbà.
To ba ṣe ọmọbinrin tirẹ n kọ?
"Gbogbo wọn lo ti fẹrẹ lọ soke okun tan ti wọn si lowo lati lọ sawọn ajọdun orin ati ijo kaakiri agbaye.
Awon asofin naa tun ro igbimo re lati ri daju pe awon omo ogun ti o ku buyi ti o to fun awon ti o padanu emi won.
Ẹ̀yin ni ẹ sì sọ mí dà bẹ́ẹ̀.
daabo bo ẹmi ati dukia awon eniyan.
Ile-ejo to n ri si iwa odaran nilu Cairo  fi awon eniyan metadinlogun si ewon gbere, nigba ti won fun awon merindinlogun miiran si ewon odun die, ewon gbere lorile-ede Egypt je odun medogbon.
Iru ewi wo ni ẹkun iyawo?
- Ìwádìí BBC Kìí ṣe sinimá ni mò ń ṣe, ìṣẹ̀lẹ̀ ojú ayé gangan ní sùgbọ́n.
Arakunrin baba rẹ̀ rí òun ati iranṣẹ rẹ̀, ó bi wọ́n pé, “Níbo ni ẹ ti lọ?
Bẹ́ẹ̀ sì ni àwọn ẹ̀wù tí a ṣe oríṣìíríṣìí iṣẹ́ ọnà sí fún iṣẹ́ ìsìn àwọn alufaa ninu ibi mímọ́, ẹ̀wù mímọ́ fún Aaroni alufaa ati ẹ̀wù fún àwọn ọmọ rẹ̀ náà, tí wọn yóo fi máa ṣe iṣẹ́ wọn bí alufaa.
Kàkà bẹ́ẹ̀, orí aṣọ òtútù rẹ̀ ni ó sùn, pẹlu àwọn ẹ̀ṣọ́ ninu ilé ìṣọ́ ọba, ní ààfin.
Lero ti Bọlanle Austen-Peters, to se Mọremi ninu ere naa, o gba pe itan Yoruba dun, ohun si lawọn eeyan nile ati loke okun fẹ gbọ, eyi ti yoo se afihan idamọ wa si iran miran.
Ṣugbọn akoroyin BBC, Andrew Gift to ṣabẹwo si gbọngan naa sọ pe wamuwamu lawọn oṣiṣẹ DSS, ọlọpaa atawọn ologun duro siwaju bẹ ti wọn ko si jẹ ki ẹni kankan wọ bẹ.
Ènìyàn méje kú lásìkò tí àwọn Fulani àti ikọ̀ Àmọ̀tẹ́kùn kojú ara wọn ni Oyo Oríṣun àwòrán, Amotekun Àwọn ọmọ ikọ̀ Àmọtẹ́kùn àti àwọn Fulani kan ni ìròyìn sọ pé wọ́n wọ ìyá ìjà ní àgbègbè Aiyete ní ìjọba ìbílẹ̀ Ibarapa North nípínlẹ̀ Oyo .
 A ti faramọ ogbon egberun naira lati  je ki ijoba mo  pe egbe osise naa setan lati farada awon ohun ti o n sele lorile ede yii.
Àjẹ́ àti Aṣẹ́wó ní ìyá Rainbow - Òjòpagogo Iya Rainbow, Jide Kosoko, Ọga Bello, yóò polongo Buhari fún 2019 Wo ọ̀nà tí orin gbígbọ́ fi ń ṣèrànwọ́ f'ọpọlọ ọmọ ìkókó ‘Mo ta oyún osù mẹ́fà nítori kò sí oúnjẹ O mẹnuba ẹkọ lẹnu iṣẹ ere ṣiṣe to ṣe koko laye igba naa ati ohun ti awọn oṣere n ṣe laye ode oni pe o yatọ si ara wọnẸ wo adúrú ẹnu tí mó n bọ́ - Jaiye Kuti.
Wọnyi ni awọn ipejọpọ nla mẹta to yẹ ko waye ni opin ọsẹ yii ni ipinlẹ Oyo, Ogun ati Eko, ṣugbọn ti awọn alamojuto wọn ti wọgile nitori arun Coronavirus.
Awọn akẹẹkọ gbọdọ lọ si ile iwe alakọbẹrẹ ati ọdun mẹta to saaju ni girama, amọ ti ijọba ipinlẹ ko nii san owo yii.
yii se je pataki  fun orile ede yii ni pe,
Ẹbọ tí a fi iná sun ni, tí ó ní òórùn dídùn tí inú OLUWA sì dùn sí.
Gẹ́gẹ́ bí ó ti jẹ́ dídùn inú OLUWA láti ṣe yín ní rere ati láti sọ yín di pupọ, bákan náà ni yóo jẹ́ dídùn inú rẹ̀ láti ba yín kanlẹ̀ kí ó sì pa yín run.
Awọn olori ijọ ti ba awọn eeyan agbegbe naa kẹdun iṣẹlẹ laabi ọhun.
Wọ́n ti ṣí ilé oúńjẹ oní ọgbọ̀n náírà (N30) ní Kano Ìdí tí mo ṣe fẹ́ yọ ayédèrú ìdí ńlá tí mo ní- Sophie Ìlú kò mọ ohunkóhun nípa iṣẹlẹ màálù tó kú nilu Ikarẹ- Oba Olukarẹ Ìgbà tí òògùn ẹ̀jẹ̀ ríru lè ṣiṣẹ́ jù rèé- Onímọ̀ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ofada Rice: kíni ẹ̀yin gbádùn nínú ìrẹsì ọ̀fadà?
Kalebu ọmọ Jefune ati Joṣua ọmọ Nuni nìkan ni ó kù lára wọn.
Nahaṣi dá wọn lóhùn pé, “Ohun tí mo fi lè ba yín dá majẹmu ni pé, kí n yọ ojú ọ̀tún ẹnìkọ̀ọ̀kan yín, kí ó lè jẹ́ ìtìjú fún gbogbo Israẹli.
Mo nigbagbo pe ise ijoba yoo mu ere dani.
Ẹ dákẹ́ àhesọ ọ̀rọ̀, n kò bí ìbẹta - Yinka Ayefẹlẹ Lẹ́yìn ọ̀sẹ̀ kan, CAF ní kí Esperance dá ife ẹ̀yẹ CAF Champions League padà ‘Buhari gbà wá o, Seyi Makinde n fi jàǹdùkú halẹ̀ mọ́ wa láti kúrò lọ́ọ́fìsì’ Irú ọmọ wo ni Yorùbá ń pè ní Àjàyí?
Nítorí pé OLUWA sọ nípa Joahasi, ọba Juda, ọmọ Josaya, tí ó jọba dípò Josaya baba rẹ̀, tí ó sì jáde kúrò ní ibí yìí pé, “Kò ní pada sibẹ mọ́.
Ó súwọ̀n kí àwọn eranko àti ẹiyẹ wọ̀nyí máa bí síi kí wọ́n sì máa rẹ̀ síi dípò kí wọ́n wà ní àtìmọ́lé ọmọ ènìà.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Taiwo Akinkunmi, ọmọ Ibadan tó ya àsìá Nàíjíríà Ẹ̀yin tẹ tako àgbékalẹ̀ àgọ́ Fulani, ìkórira ló ń yọ yín lẹ́nu - Ìjọba àpapọ̀ Ọlọ́pàá ìpínlẹ̀ kọ́ ní ojútùú ìṣòro ìjínigbé ilẹ̀ Yoruba - Onímọ̀ ọ̀rọ̀ ààbò Iṣọla Oyenusi rèé, ẹnití ìfẹ́ obìnrin ṣun dé ìwà ìdigunjalè Bakannaa lo ni, ko si nkankan to n jẹ baba agba, eyiun ''senior elder'' ninu igbimọ agbagba Yoruba.
O ni nkan to mu ki orukọ Obafemi Awolowo wà nibẹ, naa lo yẹ ko mu ki ti Obasanjo naa pẹlu wọn.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Wo fidio 'ẹwọn idẹra' O yẹ ko ni ọkọ baalu tirẹ lọtọ, ile igbalejo si, akasọ onina ati oke tente ti yoo wa pataki jul fun ile naa.
Ṣugbọn awọn ara ilu Kenosha ti bẹrẹ ifẹhonuhan lẹyin iṣẹlẹ ọhun, koda wọn dana sun ọpọ ọkọ ti wọn si n pariwo pe o to gẹ.
Ìṣẹ̀lẹ̀ tó fara jọ èyí ṣẹlẹ̀ ní 2016, lẹ́yìnin rògbòdìyàn sáà kẹ́ta Ààrẹ náà, nígbà tí àwọn akẹ́kọ̀ọ́ nílé ẹ̀kọ́ kọ ìkọkúkọ sórí àwòrán (Ààrẹ) Nkurunziza nínú ìwé ìkọ́ni.
Ko din ni miliọnu mẹrinla awọn arinrinajo lọdun to fi mọ awọn atipo to le ni ẹgbẹrun lọna ẹẹdẹgbẹrin ti aṣẹ yii lee kan.
Ọlọrun ti rí ẹ̀bi àwa iranṣẹ rẹ.
Wọn óo di etí wọn sí òtítọ́; ìtàn àhesọ ti ara wọn ni wọn yóo máa gbọ́.
Salman wa lara eniyan mejilelogun to gbemi mi ninu ikolu naa.
Awọn ti wọn ba ni arun naa ni UK le pe ago NHS lori nọmba 111 fun igbani niyanju.
Òkè Idanre rèé tí odidi ìlú kan ló ń gbé lórí ẹ̀ Eji Gbadero, ọmọ Ibadan àti jayé-jayé ọmọ ónílẹ̀ ti wọn yẹgi fun l'Eko Lisabi Agbongbo Akala rèé, ẹni tó fi ìfẹ́, ìṣọ̀kan àti ìrẹ́pọ̀ gba ilẹ̀ Ẹ̀gbá lọ́wọ́ ìmúnisìn A jọ ṣe ìyàwó pọ̀, a jọ bímọ ní ọjọ́ kan náà, a tún jọ máa ń ṣàìsàn pọ̀ ni Ìyàwó mi fẹ́ràn ìrìnàjò òfurufú ni mo ṣe kọ́ ilé Bàálù yìí fún un Omi ìṣẹ̀ńbáyé tó ń dà ní Ówù rèé, èyí tó ga jùlọ ní Afirika Ile ẹkọ Poly Ibadan ni oun ti gbe ẹrọ Ventilator fun ayẹwo nile ẹkọ Poly Ibadan, ti wsn si ni o n sisẹ bo se yẹ.
Akẹkọọ kọọkan mọ iye mita to maa wọn ti ko fi le sunmọ akẹkọọ miran Germany Ni ipelenipele ni Germany si awọn ile ẹkọ pada lẹyin ti wọn jajabọ lọwọ arun Covid-19.
Bí ẹ bá ń wá àwọn tí ó wọ aṣọ olówó iyebíye, ẹ lọ sí ààfin ọba!
”“Ni orile ede ti iwa ibaje ti gbile bi ewu , Akanbi ya ara re soto gege bi eni to feran  ooto ati  ifarasin dipo ife owo lenu ise re”.
Buhari: Naijiria ko kabamọ lilewaju fun ijijagbara South Africa
”Atamatase omo odun mọ́kànlélọ́gbọ̀n ohun fikun un oro re lasiko iforowanilenuwo pelu awon akoroyin pe, “iko wo lo seese ki o gba ife-eye agbaye ohun?
Bí ó ti lẹ̀ jẹ́ pé ìṣẹ̀lẹ̀ náà kò ju wákàtí díẹ̀ lọ, ó mú ìjáyà ńlá bá àwọn ajàfẹ́tọ̀ọ́ ní agbègbè náà, tí ọ̀ràn ìwà àìtọ́ tí orílẹ̀-èdèe Tanzania ń wù sí àwọn ajìjàgbara àti oníṣẹ́-ìròyìn ń peléke sí i.
Ohun tí wọ́n fi ń ṣe báàgì, bàtà ni wọ́n ń tà bíi ‘pọ̀ǹmọ́’— NAFDAC 'Nàìjíríà, ṣọ́ra, ogun ń sọ ilé ọlá di ahoro!
South Africa: Awọn adoola ẹmi ti muse se ni ibudo iwakusa
Ipinu awọn Gomina orileede Naijria labẹ aṣia ẹgbẹ Nigeria Governors Forum lati ya triliọnu mẹtadinlogun owo ifẹyinti awọn oṣiṣẹ ti n mu awuyewuye wa.
ijoba ohun ko ni kunna lati tun tesiwaju ninu isẹ akanse ti yoo ni ipa pataki
“Sibẹsibẹ n óo dá ire Moabu pada lẹ́yìn ọ̀la, èmi OLUWA ni mo sọ bẹ́ẹ̀.
Iṣẹlẹ to ṣẹlẹ pato to fi tun wu eyi jade ko ṣẹyin iroyin kan to sọ pe ikọ SARS yinbọn pa ọkunrin kan lọjọ Abamẹta.
 Bakan naa, ẹ gbọdọ lee gbokun ti iwa ibajẹ.
Àkọlé àwòrán, Awọn obi tẹle awọn ọmọ wọn de ẹnu ọna ileewe lọjọ kini iwọle pada yi Soyombo sọ pe ijọba yoo ṣe ẹdinwo fawọn akẹkọọ ileewe aladani lori owo ayẹwo yi sugbọn ẹni to ba fẹ ṣe ayẹwo lọwọ ara rẹ ni lati ṣe lawọn aaye ti ajọ to n gbogun ti arun ni Naijiria NCDC buwọlu.
Mo gbàgbọ́ pé ọmọ mi kò kú, mo ṣì ń wá a - Bàbá Akẹ́ẹ̀kọ́ fásitì Akungba 'Ẹ̀yin tẹ́ẹ fẹ́ pa ara yín torí olóṣèlú, ẹ wò Fayemi àti Fayose' Ọwọ tẹ akẹkọ to fowo ileewe rẹ ta MMM Fayemi ránṣẹ́ ìbánikẹ́dùn sí ẹbí akẹ́kọ̀ọ́ FUOYE méjì t'ọ́lọ́pàá pa Ninu fọnran fidio naa, a ri ọkunrin kan ati awọn obinrin ti wọn n lu obinrin kan.
Gomina ipinlẹ Ọyọ fikun pe akanṣe eto yii si jẹ imuṣẹ ileri ti awọn gomina ṣe lasiko iburawọle, pẹlu alaye pe inu oun dun lati jẹ olukopa ninu agbekalẹ eto ti yoo fẹ oju eto aabo ati igbayegbadun awọn eeyan ilu.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù PDP: APC ń kéde pé Saraki ni ipa tó ń ko láti yan olori ile asofin agba 27 Ẹrẹ̀nà 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ààrẹ ilé ìgbìms aṣofin ko lọ́wọ́ nini bi àó ṣe yan ààrẹ ilé ìgbìmọ̀ túntún Ẹgbẹ́ òṣèlú People's Demoractic party (PDP) àti awọn sẹnatọ rẹ̀ ti bu ẹnu àtẹ lu ààrẹ Muhammadu Buhari, ẹgbẹ́ òṣèlú APC àti alága ẹgbẹ́ náà, Adams Oshiomole lóri ibi ti wọn fi si nípa ẹni ti yoo adari ilé igbimọ aṣofin apapọ to ń bọ.
Gẹgẹ bi ohun ti gomina naa sọ, o ni ẹbun nla ni aṣeyọri naa jẹ, ati pe yoo tun jẹ ohun iwuri fun awọn elomiran lati tẹpa mọ ohunkohun ti wọn ba yan laayo.
Oun lo le igba oṣelu PDP wọle ni Kwara pẹlu 'O tó gẹ'.
tí ó sì ti fìdí rẹ̀ múlẹ̀ pẹlu Jakọbu,gẹ́gẹ́ bíi majẹmu ohun tí yóo wà títí lae,
Aare egbe NLC, ogbeni Ayuba Wabba, lo soro ohun di mimo fun awon akoroyin lojo Aje(Monday), niluu Abuja.
O ni ere idaraya , yiyago fun ọti lile, siga tabi awọn nkan oloro miran, naa ṣe koko fun oyun ti ko ni i mu wahala kankan dani.
Ọpọlọpọ igba lo jẹ pe ọkada ati marwa ni awọn oṣiṣẹ, ontaja ati ẹni toju ba n kan maa n saaba fi ọkada ati marwa rirnirnajo wọn nitori sunkẹrẹ-fakẹrẹ Eko.
Ó pé ọdún kẹrin tí àwọn ọmọbìnrìn Chibok nù Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Iya Adura Esther Ajayi sọ àṣírí owó rẹ̀ tó fi ń ṣàánú BBC ṣe ìfọ̀rọ̀wánilẹ̀núwò fún Naomi Adamu tó jẹ́ ọkan nínú àwọn ọmọ Chibok tí Boko Haram jígbé ní ọdún 2014 tó si lo ọdún mẹ́ta gbáko ni àhámọ wọn.
19 Nítorínáà a ó paárun, àti iṣẹ́ náà bákannáà; àti pé a ó ṣe èyí kí ojú má baà tì wá ní ìkẹhìn, àti kí á ba lè gba ògo ti ayé.
Tí a fiṣọwọ́ ní 12:47 12 Sẹ́rẹ́ 202112:47 12 Sẹ́rẹ́ 2021 Àmúlò ẹ̀rọ POS fun òwò ṣíṣe, ṣé ó tọ̀nà nínú Islam àbí bẹ́ẹ̀ kọ́?
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ẹ má bínú, mo kábàmọ́ pé mo na obìnrin -Elisha Abbo Ẹ̀tàn lásán ni ìkéde ìjọba àpapọ̀ lórí RUGA - Afenifere Gbẹgẹdẹ fẹ́ gbiná l‘Ọṣun, àwọn olùkọ́ iléẹ̀kọ́ gíga fẹ́ gba àjẹẹ́lẹ̀ owó oṣù ìdajì Grandpa àti Uncle mi, ń fipá bá mi lòpọ̀ láti ọmọ ọdún mẹ́rin"" Ileẹkọ fasiti yii lo mọ iriri ẹmi ifaraẹnijin, ipamọra ati ipa ribiribi ti Sotonye n ko si iwadi lori isẹda, ibalopọ ati ẹtọ ọmọniyan, paapa bo se foju sun ẹtọ awọn obinrin ati ẹtọ si eto ẹkọ fawọn ọdọbinrin ọmọ Naijiria."
O fi kun un pe bi awọn ileewe ba lee di ṣiṣi pada, aaya bẹẹ lẹ o bẹ s'are ni fun awọn nitori awọn ṣetan lati ṣe idanwo naa ni kete ti wọn ba ti ri ilana gba lati ọdọ ijọba lori ọna ti eto ipada si ileewe yoo gba bayii.
Oríṣun àwòrán, @aayola81 Àkọlé àwòrán, Àwọn alátìlẹyìn Zakzaky kò fi ijọba àpapọ̀ lọ́rùn sílẹ̀ lórí bó se fi asaájú wọn sí àhámọ́ ọlọ́jọ́ gbọọrọ Nígbà tó ń bá àwọn akọ̀ròyìn sọ̀rọ̀ lẹ́yìn ìgbẹ́jọ́ náà, ọ̀kan lára agbẹjọ́rò rẹ̀, Amòfin Maxwell Kyom ni lára àwọn ẹ̀sùn tí wọn fi kan Zakzaky ni pé ó ń kó àwọn èèyàn jọ, lọ́nà tó lòdì sófin, ìdìtẹ̀ hùwà ọ̀daràn àti ìwà pípa ọ̀pọ̀ èèyàn, èyí tí ikú jẹ́ èrè ẹ̀sẹ̀ rẹ̀.
Orí rẹ̀ bí òkúta, kò mọ ìwé olóókan, àfi bí ó ń ya àwòrán kiri.
Lọdun 2016 ni haruna Andrew di ọga agba patapata fun fasiti ijọba apapọ to wa ni Gashua nipinlẹ Yobe.
Serena Williams ti fi idunnu re han pupo leyin jijawe olubori ninu ifigagbaga WTA, leni ti o sese pada sini dije latari isinmi osu merinla omo ti o sese bi.
Ọja, ile ẹkọ, ibudo itaja tabi Ileesẹ ti ayika rẹ ba kun fun ẹgbin ru igi oyin, ti iya nla si n duro de ẹni to ba tako ofin imọtoto ayika.
Àwọn fóònù wọ̀nyìí kò ní lè ṣe WhatsApp láti ọdún 2020 'Ẹ̀ ń fi ẹ̀wọ̀n run imú o' Ẹ̀yin Olóyè Ibadan mọ́kànlélógún tẹ ń pe ara yin lọ́ba Bàbá akẹ́kọ̀ọ́bìnrin LASU tí ọ̀rẹ́kùnrin rẹ̀ àti pásítọ̀ fi ṣ'òògùn owó ń bèèrè fún ìdájọ́ òdodo Àwọn ìròyìn mẹ́wàá tó mí ilẹ̀ titi láàrin ọdún 2010-2019 Wo àwọn èèkàn tí ikú mú lọ lọ́dún 2019 2.
Ìjàpá tó wà ni ààfin Ṣọ̀ún Ogbomọṣọ ti jáde láyé lẹ́yìn to ti lo 344 ọdún láyé
Sugbọn Iyabọ ko ba wọn ya ninu fọto ti awọn mọ naa ba baba wọn ya.
Idunkoko awọn ọmọ South Afrika mọ awọn ọmọ orileede Afrika miran lẹnu ọjọ mẹta yii jẹ ohun to n fọwọ kan ọpọ eeyan lẹmi.
Àhesọ ni pé Ìjọba àpapọ̀ ní kí wọ́n yọ Onnoghen - Femi Adeshina Kò tọ̀nà láti gbé adájọ́ Onnoghen lọ síwájú CCT - Adájọ́ fẹ̀yìntì Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Obìnrin ló ni ilé àti àdúgbò fún ìdí èyí wọ́n lè ṣe ìlú dáadáa' Wọnyii ni awọn ipo ti adajọ tanko ti di mu ri lorilẹede Naijiria ati awọn koko ọ̀rọ̀ miiran ti o le mọ nipa rẹ̀.
 Aare je eni akoko ti yoo fi iru itan bayii le le.
Baali Hanani, ará Gederi, ni ó wà fún àwọn ọgbà olifi ati ti igi sikamore.
''Awọn ẹbi ati iyawo Chris Sodje bẹ awọn agbebọn naa lati jọwọ gba miliọnu kan Naira, ti awọn ni agbara lati san.
Ṣugbọn àwọn agbowó-odè ati àwọn aṣẹ́wó gbà á gbọ́.
Lẹ́yìn tí ó kúrò ní Nasarẹti, ó ń lọ gbè Kapanaumu tí ó wà lẹ́bàá òkun ní agbègbè Sebuluni ati Nafutali.
Ọpọlọpọ ni wọ́n ti pa sílẹ̀,òkítì òkú kúnlẹ̀ lọ kítikìti;òkú sùn lọ bẹẹrẹ láìníye,àwọn eniyan sì ń kọlu àwọn òkúbí wọn tí ń lọ!
Ajọ EFCC ni awọn mejeji yoo foju ba ileẹjọ lẹyin ti iṣẹ iwadii ba ti pari.
àwọn ọmọ Beraya ni: Ahio, Ṣaṣaki, ati Jeremotu, 
Ajíbógun mú irin-àjò rẹ̀ pọ̀n, níkẹhìn ó bá àwọn ẹ̀gbọ́n rẹ̀ ó sì gba ọ̀pọ̀lọpọ̀ ohun ìní padà lọ́wọ́ wọn.
Ẹni tó jí ọ̀pá aṣẹ ń bọ̀ wá túbá fúnrarẹ̀, mo fi dáa yín lójú gẹ́gẹ́ bí ìyá - Erelu Kuti Ó tó gẹ́ẹ́!
Ọjọgbọn naa fi kun un wipe, wọn ti n ṣeto lati ṣe ipinya awọn ọmọ naa tipẹ ṣugbọn wọn ni lati dawọ duro di ọjọ kẹwaa, oṣu kẹjọ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Broadcasting Service of Ekiti State di ṣíṣí padà lẹ́yìn oṣù máàrùn 25 Ọ̀pẹ̀̀ 2018 Oríṣun àwòrán, @nbcgovng Àkọlé àwòrán, NBC ni ileesẹ igbohun-safẹfẹ Ekiti n hu awọn iwa to tako ofin isẹ igbohunsafẹfẹ.
Àgbáríjọpọ ẹgbẹ OPC, fijiláńté VGC, Agbẹkọyà ti bẹrẹ ètò aàbò ní ilẹ Yorùbá.
Ọ̀rọ̀ èmi àti Olorì Chanel Chin kò yé ara wa mọ́ nínú ilé- Oluwo Ija eerin meji: Oluwo ati Ọọni Oluwo gba Aláàfin nímọ̀ràn pé kí olorì máa dé adé Naira Marley ti tèṣù mọ́lẹ̀ nílé ẹjọ́ májísíréètì lórí ẹ̀sùn ìjọ́kọ̀gbé Bẹẹ naa ni Alaafin sọ pe Wasiu Ayinde ti beere fun oye Mayegun yii lati nkan bi ọdun mọkanla sẹyin ṣugbọn awọn Oyo Mesi ko faṣẹ si i nigba naa.
Adajọ to n gbọ ẹjọ naa, Nicholas Oweibo pinnu lati sun ẹjọ ọhun siwaju lẹyin ti agbẹjọro fun olujẹjọ, Olalekan Ojo, rọ ile ẹjọ naa lati kan an nipa fun EFCC lati pese afikun iwe ẹri lori afurasi naa.
Ẹwẹ, o gboriyin fawọnipinlẹ to n jabọ deedee nipa iye awọn to ti lugbadi arun naa.
Won ni ofin Sharia wa fun awon musulumi nikan ni eyi ti wọn si gbọdọ tẹle asẹ idajo re gẹgẹ bi o se tọ Sunah ẹ̀sin Islam.
Ó jẹ́ ẹnì kan tí kò mọ̀ ju pé kí ó máa rẹ́rìn-ín ṣáá lọ.
Lori bi awọn eeyan kan ṣe n beere pe ki ijọba o da ofin konile-o-gbele pada, Dokita Duyile sọ pe kii ṣe ofin konile-o-gbele nikan lo le dẹkun itankalẹ aarun yii.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Nkwocha Ernest: Ìdọ́tí ni wọ́n ń pè é ṣùgbọ́n èmi pè é ni ohun èlò Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Nkwocha Ernest: Ìdọ́tí ni wọ́n ń pè é ṣùgbọ́n èmi pè é ni ohun èlò 20 Ìgbé 2019 Nkwocha Ernest jẹ agbẹ́ ère lọna ara ọtọ.
Ọjọ pẹ ti ọrọ bi ọmọ ọdun kan to sọnu ni ie ijọsin kan nipinlẹ Ondo eyi ti Wolii Alfa Babatunde Sotitobire n dari ẹ ti n waye.
Lẹyin ọdun marundinlogun ti Macron wa sisẹ ni ile isẹ to n soju ilẹ Faranse ni orilẹede Naijiria, o tun pada wa se ipade pẹlu Aarẹ Buhari ko to di wi pe yoo wa si ilu Eko.
Alukoro ileeṣẹ ọlọpaa ni ipinlẹ Edo, SP Chidi Chibuzor salaye fun BBC pe ọmọ ọdun mọkanla naa wa lara awọn janduku to fọ ile ikonkan pamọ si kan, aṣọ ọlọpaa lo si wa lọruun rẹ nigba ti ọwọ agbofinro tẹ ẹ.
''Ipade apero gbọdọ ri pe wọn fi sinu iwe ofin Naijiria pe, ẹkun kọọkan to wa ni Naijiria (Geo political Zone) yoo ma ṣe ijọba lati igbadegba.
ṣugbọn wọ́n lè máa ran àwọn arakunrin wọn lọ́wọ́ nípa bíbojú tó wọn; ṣugbọn àwọn gan-an kò gbọdọ̀ ṣiṣẹ́ níbẹ̀ mọ́.
"Lara ohun ti paali ti wọn gbe lọwọ yi ""ọọdunrun akẹkọ ni ko tii forukọ silẹ fun idanwo UTME"", ""Awa ko tii setan fun idanwo"" ati wipe ""Idanwo tọdun yii yoo jasi pabo""."
Mààlúù ati ẹranko beari yóo jọ máa jẹun pọ̀,àwọn ọmọ wọn yóo jọ máa sùn pọ̀,kinniun yóo sì máa jẹ koríko bí akọ mààlúù.
Eyi ko sẹyin bo ṣe ni o gbe atẹjade ori ayelujara kan ti arabinrin kan fi soju opo rẹ jade si gbangba.
O ni laarin oṣu diẹ sẹyin awọn eekan ipinlẹ Ọyọ ati agbegbe Ibarapa ti awọn ajinigbe ti wọn fura si pe wọn jẹ Fulani darandaran ji gbe.
Ó bá tẹ́ pẹpẹ kan níbẹ̀, ó sì sin OLUWA.
Gẹgẹ bi atẹjade kan ti ajọ naa fi soju opo twitter rẹ lowurọ ọjọ Aiku, eeyan kan naa sọ iye awọn ti wọn kede pe wọn ni arun naa ni ọjọ Aiku nikan di mẹrun bayii.
Akọmọna Ó to gẹẹ gaan ni akawe kan gbogi to ṣe apejuwe bi ọrọ akọmọna ti ṣe lagbara lati ṣe iwuri fun awọn oludibo.
ijeoma balogun je onise iroyin nipa igbesi aye .
to je olu-ilu ipinle  Borno  fun ifilọlẹ awon ise akanse lori eto ẹkọ ,
Ko si nkan to tako igbesẹ yi ninu iwe ofin Amẹrika, fun idi eyi, o ṣeeṣe bẹ.
Ati pe lẹni ọdun marunlelaadọta, ko fibẹẹ kere bi a ba wo o si Joe Biden ẹni ọdun mẹtadinlọgọrin, oun ṣi kere jọjọ.
Ọjọ Kẹtala, Oṣu Kẹsan an, ọdun 2020 ni awọn oṣiṣẹ ilera naa gunle iyanṣẹlodi, ki wọn to ṣẹṣẹ pada si ẹnu iṣẹ bayii.
Jẹ́ kí ọ̀rọ̀ ẹnu mi, ati àṣàrò ọkàn mijẹ́ ìtẹ́wọ́gbà ní ojú rẹ,OLUWA ibi ààbò mi ati olùràpadà mi.
Minisita, ẹni to kede bẹẹ nibi ipade akọroyin kan to waye lọjọ Ẹti ni ọjọ kejila osu Kẹwa ọdun 2020 ni ilẹkun awọn ile ẹkọ naa yoo di sisi.
Àkọsílẹ̀ àwọn ọmọ Lefi nìyí, gẹ́gẹ́ bí ìdílé wọn.
Opopona Ibadan si Eko: Aarẹ Buhari ni awọn yoo pari gbogbo atunse ti awọn n se ni oju ọna marosẹ Ibadan si Eko ati ọkọ oju irin ni ọdun 2022, pẹlu awọn ọna miran ti wọn n se kaakiri Naijiria.
Ìwọ yóò máa gbọ́ ìtàn eléyìínì níwájú.
Eyi si tumọ si pe, oju titi to wọ inu papakọ ni awọn arinrinajo duro si.
Wọn fi ẹsun kan Sunday pe ogun ọga rẹ, Ọpẹ Bademọsi pa lasiko to fẹ ja oloogbe l'ole nile rẹ to wa ni Ikoyi nipinlẹ Eko.
Ṣugbọn kì í ṣe ẹ̀dá ayé nìkan ló ń jẹ̀rora.
"Ninu ọrọ to ba BBC News Yoruba sọ, agbẹnusọ fun Ọbalaye naa, Moses Ọlafare ni ninu ko jẹ wi pe awọn onijibiti lo ti kan arabinrin naa lara abi ko jẹ pe awọn eeyan kan ti iṣe Ọbalaye naa ko dun mọ ninu lo n lo ohun olohun tabi oju oloju lati fi ba kabiyesi lorukọ jẹ, ""Nigba ti a wo aworan ti arabinrin naa fi si ori itakun facebook rẹ, oju naa ko jọ eyi to wa si ayika kabiyesi tabi aafin ri."
Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Lagos, Delta Curfew: Sanwo Olu ní kí àwọn òṣìṣẹ́ ìjọba padà sẹ́nu iṣẹ́ ní Eko, Delta sọ tirẹ̀ dí aago mẹ́jọ alẹ́ sí mẹ́fà ìdájí1 Bélú 2020 5:55 Fídíò, Soyinka Cancer: Àṣe ara mi ni iso ti n run gbogbo bí mo ṣe n ṣèrànwọ́ lórí jẹjẹrẹ, Duration 5,5527 Bélú 2019 Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí 2 sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
Tiwa jẹ ọkan lara awọn obinrin ilẹ Afirika to ni ọpọlọpọ ololufẹ orin rẹ to fẹrẹẹ́ to miliọnu meje lori itakun ayelujara.
Koda, ijọba ni ile ounjẹ, ile ero, ibudo ere idaraya ati awọn ṣọọbu itaja ti ko ta nkan ko ṣe e malo yoo wa ni titi pa.
Ni ọjọ kẹrindinlọgbọn, oṣu kẹfa, ọdun 2017 ni awọn agbenipaṣowo kan pa akẹkọ onipele kẹrin fasiti UNIOSUN ni agbegbe Oke Baalẹ ni ilu Oṣogbo.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Wọ́n jí òsìsẹ́ ẹgbẹ́ alágbèlébù pupa gbé ní ìlú Mogadishu 3 Èbibi 2018 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Wọ́n jí òsìsẹ́ ẹgbẹ́ alágbèlébù pupa gbé ní ìlú Mogadishu Ẹgbẹ́ alágbèlébù pupa lágbayé, ICRC ní wọ́n ti jí ọ̀kan lára àwọn òsìsẹ́ rẹ̀ gbé ní Mogadishu tíí se olú ìlú Somalia.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ọkan lara awọn eto ipolongo ibo ti shagari ṣe nigba to fẹ du ipo aarẹ Naijiria Ninu eto idibo naa, o jawe olubori, o si di aarẹ Naijiria.
Lasiko to n fi idi bi wọn se ri wọn gba silẹ, igba keji adari ibaṣepo ara ilu fun ile ișẹ ọmọ ogun ni ipinlẹ Ondo, Ayorinde Omojokun, salaye fun awọn akọroyin pe awon ọmọ ogun se awari ibi ti awọn eniyan naa wa pẹlu iranlọwọ awọn ikọ IGP - IRT nínu igbo kan ni Iboropa.
BBC: Iroyin yoruba yoo bẹrẹ ni pẹrẹwu
Awọn nkan naa to maa n ran, to lee kere pada to si lee le ri bii aran inu omi eyi ti awn onim sayẹnsi n pe ni Urechis caupo.
Titi di asiko ti iroyin yii n jade, epo inu rẹ ko tii maa danu si oju titi ṣugbọn LASEMA n kilọ fawọn eniyan agbegbe opopona AIT ni alagbado pe ki wọn ṣọra ṣe nibẹ.
Oun sọ pe iwa to buru ju ni ki ọkọ tabi iyawo gbiyanju lati fi ẹnikeji ṣe ogun owo.
Federal High CourtCopyright: Federal High Court Ere ile ẹjọ gigaImage caption: Ere ile ẹjọ giga Article share tools Facebook Twitter ṢàpínlòView more share options Share this post Copy this linkKà síwájú síi nípa àwọn ìtọ́kasí wọ̀nyí.
Ó ní kí ti òun má bàa jẹ́ òfo nílé Orímóògùnjẹ́ ni ó jẹ́ kí òun jí owó rẹ̀ gbé.
Steph Hermmerman jẹ obinrin akna da ẹda kan to kọ lati jẹ ki arun de oun mọlẹ.
Àwọn ilana tuntun ti ijọba Eko la kalẹ fun awọn ara ilu lori Covid-19 Gẹgẹ bi gomina ipinlẹ Eko, Babajide Sanwo-Olu ṣe sọ ọ lọjọ abamẹta, O ni ki awọn ara ipinlẹ Eko fi sọkan pe aridaju akọsilẹ n wa pe bi eeyan pupọ ba korajọ, o lee dakun aranka arun Covid-19.
Odinga ko lati kopa ninu atundi eto idibo naa, ni eyi ti o so pe, won yoo seru si ibo ohun ti o le je anfaani fun Aare Uhuru Kenyatta.
Aworan kan lori ero amuhun-maworan orile-ede naa safihan awon oku nile, eyi ti ko lapa tabi ori, oko ayokele eyi ti o ni awon iho lara.
Lati ibẹrẹ ọdun 2019 ni ooru to n mu ni awọn apa ibikan ni Naijiria ti n to odiwọn ìdá '35-38 degree Celsius.
Bí alufaa bá yẹ àrùn ẹ̀yi yìí wò, tí kò bá jìn ju awọ ara lọ, tí irun dúdú kò sì hù jáde ninu rẹ̀, kí alufaa ti ẹni náà mọ́lé fún ọjọ́ meje.
Nítorí a fi irun gígùn fún obinrin láti bò ó lórí.
Irúfẹ́ kòkòrò aṣekúpani kan wà tí wọ́n npè ní HIV.
Ẹlẹ́wọ̀n 200 sálọ lọ́gbà ẹ̀wọ̀n Benin lásìkò ìwọ́de EndSars Oríṣun àwòrán, https://twitter.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ondo Elections 2020: Ọgọ́rùn-ún ọdún tí a máa lò lórí oyè l'Ondo, ẹ ó rí àrà - Ojon YPP Nigba ta bi Laycon nipa obinrin to n pariwo lori ayelujara pe oun ti loyun fun, Olamilekan ni laelae, ọrọ ko ri bẹẹ, irọ si lo wa nidi rẹ nitori obinrin kankan ko ni oyun fun oun.
Lọdun 1995, Ọgagun Sani Abacha yan an gẹgẹ bi alaga igbimọ to n risi ọrọ yiyi ijọba pada kuro ni ijọba ologun si ijọba alagbada.
olubori lataari oye ibo re ti o poju lo.
Diẹ lara awọn iroyin to jade lopin ọsẹ to kọja sọ pe 'apoti ikẹru 'container' mẹfa lo ko tomato alagolo ti ọjọ ti lọ lori rẹ, ti ko si tun pojuowo, ti orukọ rẹ n jẹ 'Shirin Asal my tomato paste'' wọ Naijiria lati Iran.
Adari apapọ NNPC tó ń k'ógbá wọlé lọ, Maikanti Baru, tó kéde ọ̀rọ̀ náà nílu Abuja sàlàyé pé alága tuntun yoo di ipo náà mú títí ti wọ́n yoo fi yan mínísíta abẹle tuntun.
Ojoojúmọ́ ni òjò ń rọ̀ báyìí.
Lati owurọ Ọjọbọ ti fidio igbeyawo rẹ ti jade si ori ayelujara, ni awọn ololufẹ rẹ ati awọn akẹẹgbẹ rẹ kan ti n sọ boṣe ya wọn lẹnu pe o ṣe igbeyawo ni ikọkọ.
Ọba pàápàá tí fún wa ní àṣẹ bẹ́ẹ̀ kí á tó kúrò ní ilé, o ti wí fún wa pé bbí a bá dé ibikíbi tí a rí i pé ohun tí a f ẹ́ ṣe yóò gbà wá tó oṣù mẹ́fà tàbí jù bẹ́ẹ̀ lọ, kí a máṣe kánjú, kí a ṣe é dáadáa.
Ọba bọ́ òrùka àṣẹ tí ó wà ní ọwọ́ rẹ̀, ó fún Hamani, ọmọ Hamedata, ará Agagi, ọ̀tá àwọn Juu.
Orilẹ ede naa sun mọ Naijiria daada ti o si ni ọpọlọpọ ojuko igbafẹ bii ibi afọwọsi ajọ UNESCO ti a mọ si Pendjari Park.
Ẹ̀bùn Ọlọ́run ni ọmọ bíbí ni mo ṣe bí ọmọ 17 Wole Soyinka rèé láti kékeré Ooni Ile ife, Ààrẹ Gani Adams fárígá lórí ikú ọmọ Fasoranti Awọn kokoro maa n pese eroja aṣaraloore fun igi ninu igbo bi ohun naa ṣe n pese ṣuga.
Ẹ wo ilẹ̀ àwọn ará Kalidea!
"Mo mọ arákùnrin mi gẹ́gẹ́ bíi Olúwó.
Lẹyin naa lo fontẹ le ẹjọ ti ile ẹjọ to n gbẹsun idibo da ṣaaju pe, Muhamadu Buhari ni ojulowo ẹni to bori ninu idi aarẹ lọdun 2019.
Kí ni òfin sọ nípa asòfin tó bá jẹ́ ọmọ orílẹ̀èdè méjì?
Ọkọ Sienna to ni nọmba AZ 478 MKA (Kaduna) ni Adejoh wa to si kọlu Tolulope lasiko to n rin ni opopona Air Marshal Ibrahim Alfa ní NAF Base ni Kaduna ko to di pe ẹlẹmii gbaa.
Inú Tẹmpili wá kún fún èéfín ògo Ọlọrun ati ti agbára rẹ̀.
Eleyi lodi sofin ile ọhun, ti ijiya rẹ si le ṣe okunfa ohun ti akẹkọọ yoo fi dero ile.
“Bi a se n gbosuba fun
Lẹyin ti Abiola ri ibi salọ si ilu London, iyawo ati ọmọ rẹ naa pada ri ọna salọ ba a lọhun nibi ti wọn ti jọ n yi i mọra wọn ninu ile kolobo kan pẹlu idile awọn Olunloyo.
America, UK, France kọlu Syria Ìkìlọ̀!
Mose kọ sílẹ̀ báyìí nípa ìdáláre tí Òfin lè fúnni pé, “Ẹnikẹ́ni tí ó bá pa wọ́n mọ́, yóo ti ipa wọn rí ìyè.
50 ní Nàìjíríà báyìí Ijọba ti kede ẹkunwo epo bẹntiro lati ọgọrun un nairia le ni naira mẹtalelogun aabọ(N123.
” Wọ́n bá kígbe, nítorí ẹ̀rù bà wọ́n.
Amotekun kò ní gbé ìbọn o!
Agbègbè yìí la ti lè rí ọ̀bìrìkìtì ńlá tí wọ́n ń pè ní ‘ojú Lọndọn’ – London Eye.
Kí àwọn onídàájọ́ fi pẹ̀lẹ́pẹ̀lẹ́ wádìí bí ọ̀rọ̀ ti rí, bí wọ́n bá rí i pé ẹ̀rí èké ni ọkunrin yìí ń jẹ́, tabi pé ẹ̀sùn èké ni ó fi kan arakunrin rẹ̀; 
Nígbà tí Oluwa rí obinrin náà, àánú rẹ̀ ṣe é.
Okan lara agba egbe PDP , ti o tun je minisita teleri fun ile-ise to n mojuto awon agbofinro lorile ede Naijria, Jelili Adesiyan ati okan lara agba egbe SDP (Social Democratic Party), Senator Olasunkanmi Akinlabi-Rasheed naa jade lati wa dibo tire ni  Ode-Omu.
Amọ sa, o ni oun si n dan isọwọ sisẹ ẹrọ naa wo lọwọ, lati mọ kudiẹ-kudiẹ to ku lara rẹ, ki oun to gbe sori atẹ, inu oun yoo si dun lati maa ri ẹrọ ọhun tawọn eeyan ba n lo ninu ile wọn.
Idi niyi ti BBC Yoruba fi kanlu agbami itọpinpin lori ohun gan ti awọn aṣofin maa n wo ki wọn to gba eniyan kan sipo ilu.
Ni ọjọ kẹrinla, Oṣu kẹsan an, ọdun 2018 ni minisita fun eto iṣuna, Kemi Adeosun ko iwe fipo rẹ silẹ lẹyin ti awuyewuye kan jẹyọ lori ẹsun wi pe ko ni iwe agunbanirọ ti awọn ọdọ fi n sin ijọba fun ọdun kan to pọn dandan ki eniyan to le se isẹ ijọba tabi ki o gba iwe ti o sọ pe o ti dagbaju lati se agunbanirọ.
Tunde Bakare: Ọmọ Nàíjíríà, ẹ gbáradì fún àgbékalẹ̀ Nàíjíríà tuntun
A tọpinpin awọn ti wọn fi ara pa lọ si ile Iwosan Al-Salam to n bẹ ni agbegbe Mọniya, lati ti fi ọrọ wa wọn lẹnu wo lori iṣẹlẹ naa, ṣugbọn awọn ọlọpaa to duro wamuwamu si ẹnu ọna ile iwosan naa ko jẹ ki ẹnikẹni wọle sibẹ.
Ọkunrin naa, Chimah Daniel Iweregbu, wa lara awọn afurasi onijibi ori ayelujara ti ajọ ọtẹlẹmuyẹ ilẹ Amẹrika, FBI, n wa lati oṣu diẹ sẹyin.
Ìdajì yòókù, tí ó jẹ́ ìpín àwọn ọmọ Israẹli tí kò lọ sójú ogun, 
Ìdí ti àwọn kọmísọna ṣe to láti kí ìyáwó gómìnà tuntun káàbọ̀ EFCC gba ọkọ ayọ́kẹ́lẹ́ 30, òògùn ìbilẹ̀ àti ọ̀pọ̀ fóònù lọ́wọ́ àwọn gbájúẹ̀ Àwọn ọmọ Naijiria kóju ija sí àwọn South Africa wọ́n ní Ó tó gẹ́"" Àtúnṣe òpópónà Lagos-Ibadan àwọn ọ̀ná míràn ti e lè gba Dino Melaye tó ń díje dupò gómínà Kogi ni irọ́ ni pé òun ti ju awà sílẹ̀ Lara awọn agba ijoye to kọwọrin pẹlu Olubadan ni Ọtun Olubadan, Agba oye Lekan Balogun, Agba oye Owolabi Ọlakulẹyin, Asipa Olubadan Eddy Oyewọle, Asipa Balogun Olubadan, agba oye Lateef Adebimpe, Ẹkarun Olubadan, agba oye Amidu Ajibade ati Ẹkarun Balogun Olubadan, agba oye Kọla Adegbọla."
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Akomolede ati Asa: Mọ̀ si nípa àwọn ọ̀nà tí Yorùbá ń gbà ran ara wọn lọ́wọ́ Ninu ọrọ tirẹ, Deji ti ilu Akure ni iya Gomina naa, Abigail Omojolagbe Makinde to wa lati idile Omoregie, jẹ idile ti awọn eniyan mọ fun iwa ọtọ ati awọn eniyan to ṣe e gbẹkẹle.
14 Àti pé èyí ni ìdí tí ìwọ fi pàdánù àwọn ànfaní rẹ fún ìgbà kan—
 Eleyii ni o maa n waye bayii ni ọjọ kinni oṣu karun-un ọdọọdun.
Ìtara OLUWA àwọn ọmọ ogun ni yóo ṣe èyí
Akojọpọ iroyin tati ọwọ Anthony Zurcher a Tara McKelvey Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
yoo se fun un ni iwe idibo miran, amo ti o ba ti dibo tan, asoju Ajọ INEC
Faruq Onikijipa ati Bukola Saraki Oniwaasu ẹlẹsin Islam yi ninu fọnran fidio kan ti o gbalẹ loju opo ayelujara ṣeleri pe ko si ẹni ti yoo yọ Aarẹ ile aṣofin agba Bukola Saraki kuro nipo rẹ.
Ni ọjọ karun oṣu kẹta ọdun 1937 ni a bi Oloye Ọbasanjọ ni ilu Abẹokuta.
Ohun ìtìjú patapata ni yóo sì jẹ́ fún ìwọ náà ní Israẹli.
Iyawo Finehasi, ọmọ Eli, wà ninu oyún ní àkókò náà, ọjọ́ ìkúnlẹ̀ rẹ̀ sì ti súnmọ́ etílé.
Minisita fun eto iroyin ati asa, Lai Mohamed ni o soro naa nibi ifilole lilo ero igbalode ti a mo si Digital Switch Over (DSO) to waye nipinle Enugu.
Àwọn ìròyìn mìíràn tí ẹ lè nífẹ̀ẹ́ sí: Àwọn òṣèré tíátà Yorùbá tó bá 2018 lọ Mi ò tan mọ́ ààrẹ Buhari rárá o!
Ti a o ba gbagbe pe a-pa-rapo egbe awon osise ti ni ninu  ipade ti awon se pelu ijoba  lori ekunwo owo osu awon osise, leyin ti awon osise aladaani ti rawo ebe si won lati fenuko  lori  ogbon egberun naira , pe iye yii ni awon lagbara lati san.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Sowore: olùdíje Ààrẹ tó loun fẹ gbà Nàìjíríà padà fún àwọn ọdọ 4 Èrèlè 2019 Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Sòwòrẹ́: Èmi kò leè bá jẹgúdújẹrá APC àti PDP se pọ̀ Ṣaṣa ni ọmọ Naijiria ti on fi ọkan tele awọn isẹlẹ lori ẹrọ ayelujara ti ko ti gbọ nipa Sahara Reporters.
Ẹ ní, èmi ọba ni mo ní kí ẹ sọ fún wọn pé, kí wọ́n jù ú sinu ẹ̀wọ̀n, kí wọn sì máa fún un ní àkàrà lásán ati omi, títí tí n óo fi pada dé ní alaafia.
ipinnu isejoba rẹ sẹ lori pipese eto ilera fun gbogbo eniyan.
Joramu ọba ní, “Ó mà ṣe o, OLUWA pe àwa ọba mẹtẹẹta jọ láti fi wá lé ọba Moabu lọ́wọ́.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Election Update 2019: Amúgbálẹgbẹ̀ẹ́ Saraki ní ọ̀gá òun kò kí olùdíje APC kú oríire 25 Èrèlè 2019 Oríṣun àwòrán, @bukolasaraki Àkọlé àwòrán, Ààrẹ ilé aṣòfin àgbà, Bukọla Saraki ní òun kò kí APC kú oríire gẹ́gẹ́ bí ìròyìn kan tó ń káàkiri ṣe ń sọ Aarẹ ile aṣofin, Bukọla Saraki ko ni si ni ile aṣofin naa fun saa iṣejọba to n bọ, eyii kii sii ṣe iroyin mọ; ṣugbọn iroyin to yọ nibẹ bayii ni pe lẹyin to padanu idibo ẹkun aṣofin apapọ ti aringbungbun Kwara, Saraki ko ki Oloriẹlgbẹ ti ẹgbẹ oṣelu APC to bori ku oriire o.
Awon ebi ti oro kan ni won ti seleri lati sanwo gbama-binu fun leyin ti ijoba seto isinku awon marundinlogoji to salaisi ninu isele naa.
Akọroyin BBC to kan si ile iwosan naa ni oun foju gan ni awọn iya ọlọmọ ati ẹbi wọn ti wọn n mura lati sun ni ita gbangba lati nnkan bi aago mẹjọ alẹ.
Igbakeji aare orile ede Naijiria ojogbon Yemi Osinbajo ati aare ana fun orile ede Naijiria ajagun feyinti Yakubu Gowon, ti soro lojo Isegun(Tuesday), niluu Abuja pe awon nigbagbo pe orile ede Naijiria yoo dara.
abule  Akilubu ti o ri ọpọ eniyan to duro nibẹ pẹlu ọkọ wọn , ni wọn sọ pe
Ẹni ọ̀ràn yìí dà bíi àwọn aláàárẹ̀ tí a máa ń bá pàdé nínú ìyára ìtọ́jú àwọn tí ó ní ìjàmbá àti ìtọ́júu pàjàwìrì – àwọn tí egbògi olóró tí sọ di ìdàkudà, àwọn tí ó ń sun títì, àwọn ogún-lé-mi-dé.
Ẹbọ ohun jíjẹ tí ẹ óo máa rú pẹlu wọn ni ìyẹ̀fun tí ó kúnná dáradára tí a fi òróró pò, ìdámẹ́wàá lọ́nà mẹta òṣùnwọ̀n efa, fún akọ mààlúù kọ̀ọ̀kan, ìdámárùn-ún òṣùnwọ̀n efa fún àgbò kọ̀ọ̀kan, 
’’Asoju Minisita fun oro ile okeere lorile ede Naijiria, ogbeni Geoffrey
'Kò sí ǹkan tó jọ tòmátò tó ní májèlé ní Nàìjíríà' NAFDAC: Ẹ ṣọ́ra fún ẹja aṣekúpani Puffer Fish Iṣẹ́ abẹ tí mo ṣe láti fi kún ìkébé mi ṣàkóbá fún mi- Omotola Taiwo Kọ́ńdọ̀mù tó bẹ́ gbé iléèṣẹ́ ìjọba àti aládáni kan dé ilé ẹjọ́ Wo igbesẹ to yẹ ki o gbe ṣaaju rira ọja kankan: Yẹ deeti ti wọn kọ si ara rẹ lati mọ ọjọ ti ko ni i ṣiṣẹ mọ Ti o ba wa ṣeeṣi ra iru ọja bẹ, o ni anfaani labẹ ofin lati da ọja naa pada si ile itaja ti o ti ra a pẹlu ẹri pe ibẹ lo ti ra Ofin sọ pe onile itaja naa gbọdọ gba a pada lọwọ rẹ, ko si fun ọ ni omira, tabi da owo rẹ pada.
Àwọn ọmọ tí a bí nípa ìlérí Ọlọrun ni a kà sí ìran Abrahamu.
À ń retí alaafia, ṣugbọn ire kankan kò dé.
 Ọ ̀ kànlélógójì nínú ọgọ ́ rún obìrin ní wọ ́ n ti dábẹ ́ fún .
Awon iko ti won jo n koworin ni Minista fun oro ile okeere, Geoffery Onyeama, olubadamoran lori oro eto aabo fun aare, Babagana Monguo ti won yoo si jo pada si Abuja lojo Isegun leyin ayeye naa.
Gege bi ile-ise ti o n ri si oro abele se so pe, o to egberun mejilelogoji 42,000 awon arinrinajo lona aibofinmu omo ile Africa lorile-ede Israel, ninu eyi ti idaji won je omo-wewe, awon obinrin tabi awon okunrin pelu awon molebi won, ti won ko ni koju idapada ni kiakia.
Oríṣun àwòrán, Others Àkọlé àwòrán, Coronavirus: Alaye rèé lóri pò ti ni àwọn ọmọ Naijiria wà ní Italy Akintade ni ìròyìn ti àwọn n gbọ ni pe, àwọn ènìyàn dudu ti Coronavirus mu kò ju bii mẹta lọ, sùgbọ́n yàtọ si ààrun náà, ǹkan ko rọ̀gbọ fun ẹnikẹni nitori wọ́n ti dènà mọ gbogbo ǹkan.
A gbé e lọ sí Paradise níbi tí ó gbé gbọ́ àwọn ọ̀rọ̀ tí kò ṣe é sọ, ọ̀rọ̀ àṣírí tí kò gbọdọ̀ jáde lẹ́nu eniyan.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ọrọ lori epo rọbi ni Naijiria Iwadi naa si gbe jade pe, mọkaruru wa ninu adehun ti wọn ṣe lati gbe lẹyin awọn ile isẹ epo mejeeji, ati pe orilẹede Naijiria le padanu owo to din diẹ ni biliọnu mẹfa($5.
E̩nì kò̩ò̩kan ló ní è̩tó̩ láti s̩is̩é̩, láti yan irú is̩é̩ tí ó wù ú, lábé̩ àdéhùn tí ó tó̩ tí ó sì tún ro̩rùn, kí ó sì ní ààbò kúrò ló̩wó̩ àìrís̩é̩ s̩e.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Osun Osogbo: Àṣọ ń pe àṣọ ránṣẹ́ lásìkò ọdún 16 Ògún 2019 Àkọlé àwòrán, Àngéré ń dá àwọn ènìyàn lára yá Àkọlé àwòrán, Awọn ẹyọ ti a mọ si ti ìlú Eko náà kò gbẹ́yìn lásìkò ọdún Osun Osogbo Àkọlé àwòrán, Awọn olùbọ Omi Osun Osogbo ń lọ ojúbọ Àkọlé àwòrán, Awọn ero ìwòràn ní ojúbọ Osun osogbo Àkọlé àwòrán, Arugba àti Awọn èrò nibi Osun Osogbo Àkọlé àwòrán, Aarẹ Ọna Kankanfo, Oloye Gani Adams ati adari ileeṣẹ aṣa, Nike Art gallery naa ti wa ni ikalẹ.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Inec: Kò sí ìká tí o kò lè fí dìbò, ṣáà tí tẹ̀ ẹ́ sójú ẹ dáadáa Ilé isẹ́ Àjọ INEC gbaná ní ìpínlẹ̀ Plateau Ààrẹ Muhammadu Buhari gbé ìpolongo ìbò dé ìlú Eko Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ọkọ àti ìyàwó sọ àsọtẹ́lẹ̀ tani yóò wọlé nínú PDP tàbí APC Bi awọn ero ti ṣe wa ni gbagede papa iṣire MKO Abiola nilu Abẹokuta lati pade aarẹ Buhari ni awọn eeyan kan ti ọpọ gbagbe pe wọn jẹ ọmọ ẹgbẹ oṣelu kan ṣa dede bẹrẹ si ni le awọn ololufẹ oludije ipo gomina lẹgbẹ oṣelu APC, Dapọ Abiọdun kuro ni ori ijoko wọn.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Wo ewu tó rọ̀ mọ́ tí o kò bá bẹ̀rẹ̀ sí ní jẹ oúnjẹ́ aṣaralóòre lẹ́yìn ti oyún ti dúró sí ọ lára 25 Owewe 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 26 Owewe 2020 Oríṣun àwòrán, SPL Oúnjẹ́ aṣaralóòre nìkan kò tó ò tí o bá n gbèèrò láti lóyún tàbí tí ó bá lóyún Ko jẹ tuntun lati gbọ ki awọn eeyan o ma a gba alaboyun ni imọran pe ki wọn o ma a jẹun daadaa nitori ki wọn o le bi ọmọ ti ilera ara rẹ pé.
 Ọ ̀ sán ( n ) afternoon : come again this afternoon .
Ó sọ lójú àwọn arakunrin rẹ̀ ati àwọn ọmọ ogun Samaria pé, “Kí ni àwọn Juu aláìlera wọnyi ń ṣé?
Orúkọ apàṣẹ wàá tó ń darí ìjọba Rome nígbà náà, Emperor Marcus Aurelius Antoninus Augustus si ni wọn fi sọrí àjakalẹ-àrun naa, èyí tó fẹẹ run gbogbo ilẹ̀ naa.
Gen ló ń bèrè ìbérè yiìí pé yàtọ̀ sí gómìnà ìpińlẹ̀ Eko ta tún lo bẹ Brig.
nítorí pé tí ibi bá dé bá wa, tabi ìdájọ́, tabi àjàkálẹ̀ àrùn, tabi ìyàn, a óo dúró níwájú ilé yìí ati níwájú rẹ, nítorí orúkọ rẹ wà ninu ilé yìí.
Àwọn yìí ni wọn yóo gba ìdálẹ́bi sí ìparun ayérayé, wọn yóo sì kúrò níwájú Oluwa ati ògo agbára rẹ̀; 
Ṣugbọn lati igba naa, o ti di ile ibẹru eyi ti wọn n ko ati ọdaran atawọn oloṣelu ẹlẹwọn si Ile iṣẹ BBC ti ba awọn to ti kuro lọgba ẹwọn yii, ẹbi wọn, awọn aṣoju onimọ ofin, ẹgbẹ ti ko rọgbọ ku le ijọba to fi mọ aṣọgba ẹwọn meji lati sọ itan gẹlẹ bi igba aye El Helicoide ṣe ri.
Aare wa seleri pe oun ko ni
Bẹ́ẹ ni àwọn òṣìṣẹ́ tí yóò lọ ṣiṣẹ́ nibẹ̀ yóò jẹ́ ẹgbẹ̀rún kan àti ọgọ́rin.
Ilẹ̀ kinni tí wọ́n kọ́kọ́ ṣẹ́ gègé lé lórí bọ́ sí ọwọ́ àwọn ọmọ Kohati.
Noa ni ẹni kinni tí ó kọ́kọ́ ṣe iṣẹ́ àgbẹ̀, tí ó gbin ọgbà àjàrà.
Ẹ wo fídíò bí eyín akọ̀ròyìn ṣe fò yọ lásìkò tó n ka ìròyìn lọ́wọ́ lórí tẹlifísàn
Dokita sọ pe ko si asiko ti eeyan ko le ṣe ere idaraya yii, boya ni owurọ, ọsan tabi alẹ.
Bakan naa lo tun ni awọn agbẹ ti di ọba bayii ti apo wọn gan ti wu soke ju ti awọn oṣiṣẹ ijọba gan an lọ.
Ẹ̀yin òkè olórí pupọ,kí ló dé tí ẹ̀ ń fi ìlara wo òkè tí Ọlọrun fẹ́ràn láti máa gbé,ibi tí OLUWA yóo máa gbé títí lae?
Ó sì leè de ẹyin, kó padà máa pè mí wí pé òun kọ ni òun hùwà ọhun.
Maa tun wa lẹ irun miiran mọ.
Bakan naa, ni ipade ohun tun mu ibasepo ti o donmonran jeyo larin awon torokan gbangban ninu oro abo nile Afrika.
Gomina Fayemi fi ọrọ ọhun lede ninu ọrọ ọdun tuntun to bawọn eeyan ipinlẹ Ekiti sọ l'Ọjọru, ọjọ kinni, oṣu kinni, ọdun 2020.
Lamidi Adedibu fi ipa mánigbàgbé lélẹ̀ ní agbami òṣèlú Oríṣun àwòrán, Obasanjo Foundation Lai si ti Adedibu ẹgbẹ oṣelu PDP ki ba maa ti ni Gomina lasiko isejọba mi.
Ṣé a lè sọ̀rọ̀ ìfẹ́ rẹ tí kì í yẹ̀ ninu ibojì?
OLUWA ti pa gbogbo ibùgbé Jakọbu run láìsí àánú.
Azeez ozi Sanni Iku kan ilẹkun de ile iṣẹ iroyin The Nation pẹlu nigba to wọbẹ lọ mu ayaworan wọn lọ Azeez Sanni Sanni ku lọjọ aje nilu Ibadan.
EndSARS School Resumption: Àwọn akẹ́kọ̀ọ́ lè padà sílé ìwé láti ọjọ́ Ajé
Ó sọ fún un bí Saulu ṣe pa àwọn alufaa OLUWA.
Bí ohun kan bá wà, a jẹ́ pé ní ọkàn tiyín ni.
Ajọ to n risi idena ati amojuto ajakalẹ aarun, NCDC lo fi ikede naa sita loju opo Twitter rẹ.
Abajade idibo ipinlẹ Zamfara Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Eyi ni atupalẹ diẹ nibẹ.
“Bí mo bá kọ̀ láti fetí sí ẹjọ́ àwọniranṣẹkunrin ati iranṣẹbinrin mi,nígbà tí wọ́n bá fẹ̀sùn kàn mí,
- Oshonaike Agbabọọlu ẹlẹyin Table Tennis to ti gbami ẹyẹ nilẹ Afirika ri, Olufunke Oshonaike ti bu ẹnu ate lu bi awọn ọkunrin to ni iyawo sile ṣe n bere fun ibasepọ pẹlu oun.
Minisita fun ọrọ igbanisiṣẹ, Chris Ngige to kede ọrọ yi fun awọn akọroyin sọ pe ijọba ti buwọlu sisan owo to le ni biliọnu mẹẹdogun fun atunṣe awọn ile ẹkọ fasiti ati wi pe Aarẹ Buhari ti ni ki wọn san ogun biliọnu naira fun sisan owo oṣu ti ijọba jẹ awọn olukọ naa lati ọdun 2009 si 2012.
Mò ń ráhùn tọ̀sán-tòru,mo sì ń kérora; OLUWA óo gbọ́ ohùn mi.
Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
" Oṣinbajo ni bi ijọba ṣe n tiraka lati rii pe iwa ọdaran dẹkun lawujọ, o tun yẹ ka ba awọn oṣiṣẹ SARS naa sọrọ lati mọ ẹtọ awọn araalu ninu iṣẹ yoowu ti wọn ba n ṣe.
Ijọba ipinlẹ Kogi ko tii fun un ni esi ọrọ.
‘Ǹjẹ́ ẹnikẹ́ni lè jẹ́ olódodo níwájú Ọlọrun?
Àwọn eniyan ń wá a kiri.
Ṣugbọn bí ẹrú náà bá gbé odidi ọjọ́ kan tabi meji kí ó tó kú, kí ẹnikẹ́ni má jẹ olówó ẹrú náà níyà, nítorí òun ni ó ni owó tí ó fi rà á.
Bẹẹni minisita feto ilera lorilẹede Naijiria, NCDC, Dokita Osagie Ehanire ṣalaye pe ọrọ ti kuro nibẹ, nitori pe iye awọn oṣiṣẹ eto ilera to ti ko arun coronavirus bayii ti kuro ni ogoji (40), o ti dieeyan mẹtalelaadọfa (113).
You need one to watch live TV on any channel or device, and BBC programmes on iPlayer.
 O ni akoonu idanilẹkọọ naa ni lati jẹ ki awọn oṣiṣẹ yii ni imọ sii ninu bi a ṣe n jabọ ohun to ṣẹlẹ gbogbo ninu Ile ati bi a ṣe n ko wọn silẹ lati le mu igberu ba iṣẹ Ile Igbimọ Aṣofi Ipinlẹ Eko.
Femi Odekunle: Àwọn ohun mánigbàgbé ti ọ̀jọ̀gbọ́n náà gbé ile ayé ṣe rèé
Ohun ti wọn n sọ nipe bi ero ti peju sibi isinku Abba Kyari lodi si ilana itakeke sirẹni ti ijọba la kalẹ lati le gbogun ti aarun coronavirus ni Naijiria.
 Bi a ba se n dagba ni eya ara maa n gbo ti awon aisan ojo ogbo maa n yoju.
Bakan naa o ni onibara oun ni iṣoro ilera nitorinaa ki wọn gba beeli rẹ paapaa toripe ko da ẹṣẹ kankan to fi yẹ ki wọn fiya jẹ ẹ.
Igbimọ yii wa lati se iwadii awọn ẹsun oniruuru ti wọn ti fi n kan Magu, lati igba to ti gori oye.
Sanusi tí kúrò ní ìlú Awe lọ sí Abuja- Gomina El-Rufai Músò!
Oríṣun àwòrán, Seyi Makinde Bakan naa ni Makinde fọwọ idaniloju sọya pe ijọba oun ko ni mẹẹri nidi ipese eto idẹrun to yanranti fun awọn osisẹ ipinlẹ Ọyọ, eyi ti yoo mu igbe aye wọn bẹsuẹ si.
Díẹ̀ lára àwọn òṣèré Nollywood ti wọ́n ti ṣe ìgbéyàwó lẹ́ẹ̀kejì Kàyééfì rèé!
Mo ké pe Ọlọrun Ọ̀gá Ògo,Ọlọrun tí ó mú èrò rẹ̀ ṣẹ fún mi.
àwọn ẹ̀ka rẹ̀ tàn kálẹ̀ títí kan òkun,àwọn èèhù rẹ̀ sì kan odò ńlá.
Ninu oro tire, Aare egbe awon alarun HIV/AIDS lorile-ede Naijiria, Victor Omoshehin dupe pupo lowo ijoba orile-ede Naijiria, fun akitiyan re lati je aarun HIV/AIDS di ohun igbagbe lorile-ede NaijiriaOmoshehin so pe, “Mo ro pe, pelu ifowosowopo, a le se aseyori erongba iran odun 9090, ki a si so aarun HIV di afiseyin teegun n fiso bi o ba fi maa di odun 2030, ti a ba wa ni isokan, ife ati irepo”.
Ṣé bí ìgbín bá sì fà ìkarahun rẹ̀ a sẹ̀ lé e ni a máa ń gbọ́.
Simbiat Atinukẹ Soaga ni iyale rẹ, ọdun 1960 si lo ba segbeyawo, ko to fẹ Kudirat Ọlayinka Adeyẹmi tẹle lọdun 1973, lẹyin naa lo fẹ Adebisi Ọlawunmi Ọshin lọdun 1974 ati Doyinsọla Abọaba lọdun 1981.
''Àwọn ìṣòrò tó n ba ètò ẹ̀kọ́ Nàìjíríà jẹ́'' Ọ̀pọ̀lọpọ̀ àwọn olùkọ́ wa ní òde òní ní àwọn fúnra wọn kò mọ̀ nkan tí wọ́n n kọ́.
Eleyii ti wọn ni o fun awọn lanfani lati tun bẹrẹ si nii da tabi gba garaaji atawọn ibudokọ gbogbo nipinlẹ Ọyọ ti wọn si fi n doju ija kọ awọn oṣiṣẹ ORTMA ati lati da omi alaafia ilu ru.
Alaga igbimo ajo  orile ede Naijiria , Independent National
ti yipada rara, o sekilo pe, “Enikeni ti owo ijoba ba te tabi ti won
Nisinsinyii èmi ni mò ń fi ọ̀rọ̀ mi dá wọn lẹ́jọ́.
Ijiroro Tẹ ẹ ki a le jọ fikuluku < Pada si akọsilẹ orukọ awọn oludije Ayẹwo<br>lati mọ otitọ.
Bí mo bá kúrò lọ́dọ̀ rẹ tán tí ẹ̀mí Ọlọrun bá gbé ọ lọ sí ibi tí n kò mọ̀ ńkọ́?
Bẹ́ẹ̀ ni ọ̀rọ̀ tó ń jáde lẹ́nu mi yóo rí,kò ní pada sí ọ̀dọ̀ mi lọ́wọ́ òfo,ṣugbọn yóo ṣe ohun tí mo fẹ́ kí ó ṣe,yóo sì ṣe é ní àṣeyọrí.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Toyin Ibietan: Àlòkù táyà ọkọ̀ ló mú mi rí nǹkan ṣe lásìkò ìgbélé COVID-19 Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Toyin Ibietan: Àlòkù táyà ọkọ̀ ló mú mi rí nǹkan ṣe lásìkò ìgbélé COVID-19 18 Òkùdu 2020 Ọpọ ni wahala COVID-19 sọ di alairikanṣekan lasiko igbele ti ijọba kede lati dena ajakalẹ arun naa, ṣugbọn bẹẹ kọ lọrọ ri fun arabinrin Toyin Ibietan.
àfi pé láti ìlú dé ìlú ni Ẹ̀mí Mímọ́ ń fi àmì hàn mí pé ẹ̀wọ̀n ati ìyà ń dúró dè mí níbẹ̀.
Iroyin ti a gbọ fihan pe idi ti wọn fi pa Oladipupo ni wi pe o fi aaye gba awọn onikẹkẹ alupupu ni agbegbe Aiyetoro eyi to si n mu ifasyin ba owo to n wọle fun ẹgbẹ NURTW to wa nibẹ.
Aare soro yii lasale ojoRu , nigba ti o n gba awon  ọdọ oloselu ti won jọ n se ijoba rẹ.
Iye awọn ti wọn fidirẹmulẹ nipasẹ ayẹwo lati bi osu meji si asiko yii pọ ju iye awọn ti akọsilẹ wa fun ni 2017.
Eric Lamela lo gba wọle nigba ti ifẹsẹwọnsẹ naa wọ iṣẹju kẹtalelogun.
ati ọgbọ̀n  odun ti aare Omar al-Bashir ti wa lori aleefa
Ṣe wọn ni iku ogun nii pa akinkanju, iku odo nii pa omuwẹ, oju ija, iyẹn lori papa ni Samuel Okwaraji ku si ninu ifẹsẹwọnsẹ fun ati kopa ninu idije ife ẹyẹ agbaye ti yoo waye ni ọdun 1990.
oluwa mi, gbọ́, mo fún ọ ní ilẹ̀ náà, ati ihò tí ó wà ninu rẹ̀, lójú gbogbo àwọn eniyan mi ni mo sì ti fún ọ, lọ sin aya rẹ sibẹ.
E̩nì kò̩ò̩kan ló ní è̩tó̩ sí òmìnira èrò, òmìnira è̩rí‐o̩kàn àti òmìnira e̩ sìn.
Aré ni àwọn eniyan náà sá gun òkè odò Jọdani.
Ìwé ìpíngún kò wúlò níwọ̀n ìgbà tí ẹni tí ó ṣe é bá wà láàyè.
Ni ọjọ ti wọn ji awọn ibeji mi gbe lọ, emi pẹlu rẹ la dijọ wa ninu mọto, bi wọn si ṣe pe mi lati ile pe wọn ti ji awọn ọmọ gbe lọ, a dijọ n le gbogbo mọto to jọ ti awọn ajinigbe naa ni, to si n ṣe eto lori redio, bẹẹ lo n bẹbẹ lori Facebook pe ki wọn tu awọn ọmọ naa silẹ."
 wọ ́ n dé pélú àwọn ọmọ àti àwọn ẹrú pérete kan .
N óo ko yín lọ sinu aṣálẹ̀ àwọn orílẹ̀-èdè mìíràn, níbẹ̀ ni n óo ti dájọ́ yín lojukooju.
Bí ó ti ṣe pẹpẹ ìrúbọ tí ó wà ní Bẹtẹli ni ó ṣe àwọn pẹpẹ ìrúbọ náà.
Ko pẹ si akoko yii ti iyawo rẹ, Kim ardashian fidi ọrọ naa mulẹ pe ootọ ni o wu Kanye West lati bi ọmọ meje.
 Ìwọ ̀ n agbára àwọn àjẹsára náà láti ṣiṣẹ ́ ju bíi 90 % lọ .
Ìdí rẹ̀ sì ni èyí pé, obìnrin kò lè ní ọkọp mẹ́ta pọ̀ lẹ́ẹ̀kan ṣoṣo.
Yóo ye wọn nígbà tí ọjọ́ ìkẹyìn bá dé.
O kò tíì kó wa dé ilẹ̀ tí ó lọ́ràá tí ó kún fún wàrà ati oyin, tabi kí o fún wa ní ọgbà àjàrà ati oko.
Ọ̀pọ̀lọpọ̀ àwọn tó kẹ́kọ̀ọ́ jáde ní fásitì ní Nàìjíríà lásìkò yìí ló n gba iṣẹ́ olùkọ́ nítorí àìríkan ṣèkan.
Homepage Accessibility links Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Ìrànlọ́wọ́ Ìwọlé News Sport Weather Radio Arts Ààtò BBC News Yorùbá BBC Yoruba ÀkọléÀkọlé abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Àkọlé bọ̀tìnnì síwájú síi Olùmúdọ́gba bọ́tìnnì síwájú síi Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Media player Close player Close player Close player Lọ́wọ́lọ́wọ́Lọ́wọ́lọ́wọ́ Ẹ ṣọ́ra, ọwọ́jà Corovirus ń peléke si ní Nàíjíríà, a ń wọ abala kejì àjàkálẹ̀ àrùn lọ - Ìjọba àpàpọ̀ I'll sign in later And we'll keep you signed in.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Nigeria 2019 Elections: INEC kéde pé àwọn ẹgbẹ́ òṣèlú lé tẹ̀síwájú pẹ̀lú ìpolongo 19 Èrèlè 2019 Oríṣun àwòrán, @inecnigeria Ajọ eleto idibo Naijiria, INEC ti fi aṣẹ si pe awọn ẹgbẹ oṣelu le tẹsiwaju pẹlu ipolongo ibo wọn, ni imurasilẹ fun eto idibo aarẹ ati tile aṣofin apapọ ti yoo waye lọjọ Abamẹta.
ile igbimo asoju ati ile-ise idajo yoo se da duro funra won lori eto isuna lati
"Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Oshiomọlẹ ń se bi adìẹ tí ojò pa, tó ń sunkún kiri- Saraki Tanka epo tó jóná gbẹ̀mí àdájọ́, ọmọkùnrin rẹ àtàwọn míì ""Ohun tí ojú opó ń rí láwùjọ kò kéré"" Ikọ̀ ẹlẹ́sìn Hàkíkà rèé, níbití wọn ti ń pààrọ̀ ìyàwó láàrín ara wọn Irú ẹ̀dá wo ni aṣòfin Bukola Saraki jẹ́?"
Ògiri ilé ìsìn náà ní àwọn fèrèsé tí wọ́n fẹ̀ ninu ju bí wọ́n ti fẹ̀ lóde lọ.
Awọn akẹkọọjade to wa ni ileewe alakọbẹrẹ (Primary 6), ti girama kekere (JSS3), ti girama agba (SSS3) yoo bẹrẹ isinmi lati Ọgbọnjọ, Oṣu Keje yii, ti wọn yoo si pada si ileewe nigba ti idanwo wọn ba bẹrẹ.
Ó ni, ‘láti kékeré ni ìyá mi ti maa ń rán mi lọ gbọ́ ọ̀rọ̀ ọlọ́rọ̀ ki n bà le wá máa ṣe ofófó fún òun.
Ẹ jẹ́ kí òye yìí yé wa: a ti kan ẹni àtijọ́ tí àwọn eniyan mọ̀ wá sí mọ́ agbelebu pẹlu Jesu, kí ẹran-ara tí eniyan fi ń dẹ́ṣẹ̀ lè di òkú, kí á lè bọ́ lóko ẹrú ẹ̀ṣẹ̀.
O sì ń ba ẹwà rẹ jẹ́ níbẹ̀, ò ń ta ara rẹ fún gbogbo ọkunrin tí wọn ń kọjá, o sì sọ àgbèrè rẹ di pupọ.
Ọga agba ajọ naa, Chikwe Ihekweazu lo fi eyi lede lọjọ aje lasiko ti wọn n ṣepade pẹlu igbimọ amuṣẹya ti aarẹ gbekalẹ lori arun yii ni ilu Abuja.
Nígbà náà ni Pilatu mú Jesu, ó ní kí wọ́n nà án.
Lẹ́yìn gbogbo nǹkan wọnyi, ẹ fi igbagbọ ṣe ààbò yín.
Enrimoni, Eteri, ati Aṣani, gbogbo ìlú ati ìletò wọn jẹ́ mẹrin, 
Ìkùukùu rẹ̀ yóo sì bo ìmọ́lẹ̀.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Arsene Wenger lọ láì gbà ife ẹ̀yẹ kankan Akànṣẹ́ Tony Bellew fàgbàhàn David Haye Wọ́n so ìdìbò APC rọ̀ l'Ekiti Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Ó ń wọ ojúlé kiri, ó ń fa tọkunrin tobinrin jáde, lọ sẹ́wọ̀n.
"Tẹ ba ri awọn fidio ti mo n se lati polowo ọja mi, ẹ ri pe ojoojumọ ni mo maa n jo lati polowo awọn ọja naa.
Ki ijọba ṣe atilẹyin gbogbo to ba yẹ fun kiko awọn ti ogun le lọ sorilẹede Niger ati Cameroun pada wa sile.
Ọmọdebinrin, ọmọ ọdun mẹwa kan to wa laarin wọn kan n sunkun ni bi wọn ṣe n fipa ba a lopọ'' Adamu ni wọn sọ fun adelebọ kan ti wọn fipa ba lopọ pe, awọn ko ni tusilẹ nitori pe awọn gbadun rẹ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ọ̀gá Ọlọ́pàá: Àwọn ọ̀gá ọlọ́pàá ìpínlẹ̀ ni yóò máa ṣàkósó FSARS báyìí 21 Sẹ́rẹ́ 2019 Oríṣun àwòrán, @NPF_NIGERIA Ọga agba ọlọpa tuntun lorilẹede Naijiria, Muhammed Adamu ti kede lọsan ọjọ Aje pe, oun ti se atunto ikọ ọlọpaa to n gbogun ti iwa idigunjale lorilẹede Naijiria.
Bí ọba ti pada wá láti inú àgbàlá sí ibi tí wọ́n ti ń mu ọtí, ó rí Hamani tí ó ṣubú sí ibi àga tí Ẹsita rọ̀gbọ̀kú sí.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Àwọn òṣèré tíátà Yorùbá tó bá 2018 lọ 'Mí ò sí lára awọ̀n aṣòfin tó bú Buhari'' BBC Yorùbá yóò se ìpàdé ìtagbangba ní Kwara Mi ò tan mọ́ ààrẹ Buhari rárá o!
Ṣugbọn kí ẹ dáhùn pẹlu ìrẹ̀lẹ̀ ati ìwà pẹ̀lẹ́.
Orukọ oloogbe naa ni Williams Anuoluwapọ, ti ọpọ mọ si Kumbalee.
Awọn mii ti ẹgbẹ ni ko lọ sinmi nile ni Chief Akin Akomolafe; Bamigboye Adegoroye; Olusoga Owoeye; Dele Afolabi; Toyin Oluwasola, Bunmi Ogunleye, Dr Wole Oluyede; Ayo Ajibade ati Femi Adeleye Saaju asiko yi, fakinfa ti n waye laarin Gomina Kayode Fayemi ati Sẹnẹtọ Babafemi Ojudu.
O ni milionu meta naira ni awon na lati se awon atunse ati ayewo naa, to si je pe ti won ba gbe awon oko ofurufu naa lọ si ile-ise ti won ti se oko ofurufu yii, yoo na won ni ọgbọ̀n milionu naira.
 lára àwọn orin aládùn rẹ ̀ ni  wọ ́ n kéré sí si number wa "" ."
 Ogbeni  Okoye wa rọ awon  oludibo lati jade sun atundi ibo ti yoo waye
’ Lẹsẹkẹsẹ ojú mi là, mo bá gbójú sókè wò ó.
Omowumi tun ni a i ki n riidajọ ododo gba lati ọdọ awọn agbofinro lo faa ti awọn eeyan ṣe maa n ṣe idajọ lati ọwọ ara wọn.
Ààyè sí sílẹ̀ fún ọmọ Nàíjíríà láti di ológun nílẹ̀ Gẹẹsì Agbébọn kọlu àwọn ènìyàn níbi ìdíje eré sísá ẹṣin Ènìyàn 721 fi ayédèrú ìwé ẹ̀rí gba iṣẹ́ ìjọba àpapọ̀ - ICPC Ọpọ lo n foju sọna lori ohun to maa yatọ lori ọrọ epo rọbi ni Naijiria lẹyin ti wọn ba gba iṣẹ tan.
Oríṣun àwòrán, Tade Oludayo Amofin Akeem Fadun ni ọpọ igba ni araalu maa mu ọdaran lọ si agọ ọlọpaa ṣugbọn to jẹ wi pe wọn yoo tun ri ọdaran bẹẹ nigboro lẹyin wakati tabi ọjọ diẹ.
Ọjọ kọkanlelogun oṣu Kẹrin ọdun 2020 ni alagba Richard Akindele dagbere faye pe o digba, lẹni ọdun mọkandinlaadọrun.
” Ọlọrun mi ló sọ bẹ́ẹ̀.
O tun salaye pe o yẹ ko waye lọ́jọ mii ọj ire nitori pe ki magomago kankan ma baa wa ye lataari awọn to maa fẹ dibo nipa ifiransẹ si awọn to n seto idibo naa.
Awon oye egbe ti won yoo dibo fun ni elekun-jekun niyi:Ekun Aarin gbungbun Ariwa– Igbakeji Aare (NC),Alukoro Agba,adari awon obinrin,igbakeji akapo egbe,igbakeji akowe to n mojuto igbaye-gbadun egbe.
Gbogbo ǹkan ti ìjọba n ṣe yìí fún ànfàní olúkúlùkù ni, nítórí náà gbogbo ǹkan ti a bá le ṣe, láti dẹ́kun àjàkálẹ̀ ààrùn Covid-19 ki ó fi kásẹ̀ nílẹ̀, ni à ó ṣe.
Polling Unit (Agọ idibo) : Agọ idibo ni agbegbe to wa
Ṣé yóo wá sùn ní ibùjẹ ẹran rẹ lálẹ́?
Bobrisky ni oun sun mọ Ọlọrun pupọ, ti oun si maa n gbadura si i, ko si yẹ ki awọn eeyan maa foju ẹlẹṣẹ wo oun nitori o jẹ afojusun oun lati lọ ṣe Hajj nilu Mecca.
Bi ọrọ se ri ree pẹlu ilumọọka osere tiata lobinrin kan, Dayọ Amusa, ẹni to figbe ta loju opo Instagram rẹ pe ki awọn ololufẹ oun jọwọ dakun fi oun lọrun silẹ, nitori itara wọn nipa igbesi aye oun ti pọju.
Ọgbẹni Oputa ni lati ọjọ to ti pẹ ni ajọṣepọ to dan mọran ti wa laarin oun ati Kenyamo, o ni pe oun ti maa n ba ṣiṣẹ tẹlẹ.
Ìṣẹ ̀ lẹ ̀ mìíràn ọ ̀ tọ ̀ ọ ̀ tọ ̀ tí ó níí ṣe pẹ ̀ lú bí gama ṣe dàgbà ni ó sẹlẹ ̀ ní ìgbà tí ó wà ní ọmọ ọdún méje .
Ni bi ọgbọ̀n ọdún sẹhin, nigbati àwọn ọmọ iṣẹ́ ri pé àwọn ọ̀gá ti ó nji owó, kò si ẹni ti ó mú wọn, àwọn na a brẹ̀rẹ̀ si lọ yọ nkan lára ẹ̀rọ ti ó gbé iná wọ àdúgbò lati lè gba àbẹ̀tẹ́lẹ̀ lọ́wọ́ ará àdúgbò.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ohun tó wù kí ileẹjọ́ kòtẹ́milọ́rùn sọ, Adeleke kò lè di gómínà Ọ́ṣun - APC Irú ọmọ wo ni Yorùbá máa ń pè ní Ìgè?
Inú àpáta nlá kan ni orísun odò náà wà.
Jesu sọ fún un pé, “Ìdí rẹ̀ tí o fi ń pè mí ní ẹni rere?
Gẹgẹ bi ohun ti Bloomberg sọ, ko pẹ ti wọn fi da awọn iru gilasi ti wọn kọkọ fi sọwọ si wọn pada pe niṣe ni wọn n fọ.
Ijẹbu lo ni Ìfọ́kọrẹ́/Ìkọ́kọrẹ́ gbogbo Yorùbá ló ni Ọ̀jọ̀jọ̀ 
Jesu wí fún un pé, “Arabinrin, gbà mí gbọ́!
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Aremu: Eré ìtàn nípa ìbí, àti jéèyàn pẹ̀lú ìpèníjà Olusegun Aremu Obasanjo Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Lẹyin ọjọ diẹ, Idiagbon pada si Naijiria, ti ijọba Babangida si fi sinu ahamọ ninu ile nilu Benin ati Bauchi fun ọpọlọpọ osu.
Ire ọdún titun á kárí gbogbo wa o.
Agbára wo ni June 12 fún MKO Abiola tó ṣì ń fọhùn lẹ́yìn ikú rẹ̀?
Araba ilu Osogbo ni iwe tawọn ọmọ oun ka ko ni ki wọn pa iṣẹ Ifa ṣiṣe ti.
Goolu mẹsan, fadaka mẹsan ati baaba mẹfa ni awọn oludije lati orilẹede Naijiria ti gba bayii.
Gomina lpinle Osun, Gboyega Oyetola ti ṣalaye wi pe ijọba ipinlẹ Osun ti ṣe tan lati ṣe atilẹyin fun ipenija to ba eto aabo ni ilẹ yii.
Lai beṣu bẹgba, ni igbimọ ile to wa fun igbogun tiwa ajẹbanu ati siṣe owo ilu kumọkumọ labẹ alaga Chukwuka Utazi ti sọ pe, ki ile ṣe apero lori iyansipo naa lati ọdọ aarẹ.
Jiti Ogunye fesun kan pe ijọba Buhari gan an ni o n huwa bii agbẹsunmọni nitori awọn ṣoja pa awọn ọmọ ẹgbẹ Shia to to 360 ni ọdun 2015 gege bi oun se gbo Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Joke Silva: Olu, ó tó gẹ́ pẹ̀lú obìnrin yìí níkan tó ń ba ẹ ṣeré ìfẹ́ nínú sinimá Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
 Ki won to se atunto yii ni eka FSARS to kọkọ wa labe eka to n mojuto iwa odaran ati ise iwadii, (Force Criminal Intelligence and Investigations Department (FCIID).
Mọ bi ọna adugbo rẹ ṣe ri daradara loju mọmọ: Iden ni ki o to le yago fun ijamba ti agbara ojo ba ka ọ mọ adugbo rẹ, o ni lati mọ bi ọna adugbo rẹ ṣe ri daju.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Màá fún àwọn èèyàn tó forí ṣọta ìbúgbàmù l‘Eko ní ₦2bn - Sanwo-Olu Iléẹjọ́ kún fọ́fọ́ fún èrò nítẹ̀síwájú ẹ̀ṣùn ìjọ́mọgbé tí wọn fi kan aṣaájú ìjọ Sotitobire Rẹ́rẹ́ rún níbi ìbúgbàmù l'Eko, ọ̀pọ̀ àwòrán rèé Ọmọ oṣù mẹ́rin ní Coronavirus ní Cambodia, Turkey ya 10,000 sọ́tọ̀ Gbogbo ẹ̀yin tẹ fẹ́ yọ Oshiomole nípò, ẹ kò moore, ìwà yín ń kóbá APC - Tinubu O ni ki Fayemi paapa ma danwo lati rọ awọn ọba loye tori awọn ọba naa lẹtọ lati yari fun gomina to ba gbe ọba ti ko tọna wa fun wọn, bẹẹ si ni kii ṣe gbogbo ọba Ekiti lo wọ igbimọ Pelupelu .
"Baa ṣe le sọrọ soke, baa ṣe le rin lori itage, ṣiṣẹju si eeyan, lilo ọwọ, iru aṣọ to yẹ ka mọ ni ọga kọ wa.
Ẹ̀yin ọmọ Bẹnjamini, ẹ sá àsálà!
 olówó rẹ ̀ , williams yìí ni ó ṣokùnfa bí ó ṣe padà sí ilẹ ̀ aláwọ ̀ dúdú , Áfíríkà .
Ó yàtọ̀ sí gbogbo àwọn ẹranko tí ó ti wà ṣáájú rẹ̀, ìwo mẹ́wàá ni ó ní.
NCDC kéde èèyàn 601 tó ṣẹ̀ṣẹ̀ lùgbàdì Covid-19 ní Nàìjíríà Ariwo ló ń mú owó wọlé fún mi, kò wù mí láti gbé ayé tó dákẹ́ rọ́rọ́ - Lizzy Anjorin Majek Fashek tí wọ káà ilẹ̀ lọ!
Atẹjade kan ti Kọmisana fajọ eleto idibo nipinlẹ Ekiti, Ọjọgbọn Abdulganiyu Raji fi sita nirọlẹ ọjọ Abamẹta, ni eyi ti jẹyọ.
Ọlọrun alágbára yóò tọ́ ọ sọ́nà gẹ́gẹ́ bí o ṣe ń múra láti bẹ̀rẹ̀ iṣẹ́, bẹ́ẹ̀ sì ni àkòkò rẹ yóò mú ìdàgbàsókè wá síi fún ìpínlẹ̀ náà àti àgbéga bá ìgbé ayé àwọn ènìyàn."
Bakan naa ni ileeṣẹ ọlọpaa ni Bauchi fikun wi pe baba arabinrin to wu iwa buruku naa ti jẹwọ wi pe lootọ ni oun pa ọmọ-ọmọ oun.
" Nigba to n sọrọ lori ipenija to koju lẹnu isẹ tiata, Sanyeri ni oun bu sẹkun nigba ti aburo oun sọrọ buruku si oun nigba ti oun ko ri ọwọ mọlẹbi da, ìyá awọn si lo pari ija naa lẹyin ọdun kan.
Gbajúgbajà òṣèré India, ọmọ, ìyàwó ọmọ àti ọmọ-ọmọ rẹ̀ lùgbàdì ààrùn Coronavirus Kí ló ṣẹlẹ̀ tí àwọn ọmọogun Nàìjíríà tó lé ní 350 fẹ́ kọ̀we fi iṣẹ́ sílẹ̀?
 Aare to n kogba wole yii naa ki minista atawon osise eleto ilera apapo fun fifowosopo pelu oun lati sise yanju.
Gbogbo àwọn tí a kà ninu ẹ̀yà Sebuluni jẹ́ ọ̀kẹ́ mẹta ó lé ẹẹdẹgbẹta (60,500).
“Bí ebi bá tilẹ̀ pa mí, ẹ̀yin kọ́ ni n óo sọ fún,nítorí èmi ni mo ni gbogbo ayé ati àwọn nǹkan tí ó wà ninu rẹ̀.
Ẹwẹ latari ati fi ọrọ ikini ku ara fẹraku ranṣẹ si alagba Fasoranti, oriṣiriṣi ẹda ọ̀rọ̀ lo n jẹyọ latẹnu awọn eekan Naijiria to ti fi ọrọ ranṣẹ si baba oloogbe naa.
Ta ba wa wo oniruuru isoro ati isẹlẹ to n mi ifẹsẹmulẹ Naijiria, ki ni ọna abayọ?
Àwọn Farisi bá bi wọ́n pé, “Àbí ẹ̀yin náà ti di ara àwọn tí ó ń tàn jẹ?
Àwọn ará Midiani tí wọ́n ra Josẹfu tà á fún Pọtifari, ará Ijipti, ọ̀kan ninu àwọn ìjòyè Farao.
Ẹni to bori: Tunisia Benin vs Egypt.
Oríṣun àwòrán, @NigeriaNewsWeb Àkọlé àwòrán, Amọṣa, Pasuma ni ko si iye owo to lee mu oun lọ si Saudi Arabia lọ kọrin nitori 'ile adura ni' Ọkan lara awọn ololufẹ Pasuma lo fi ibeere ṣọwọ si i lórí ètò Facebook Live pẹ̀lu Pasuma ni wi pe awọn n reti rẹ ni orilẹ-ede naa lati wa fi orin da awọn laraya nitori awọn n ri bira ti aṣiwaju elere fuji naa n da lara kaakiri awọn orilẹ-ede agbaye ati pe igba wo gan an lo n bọ wa kọrin ni Saudi.
Dafidi dáhùn pé, “Ta ni èmi ati ìdílé baba mi tí n óo fi di àna ọba?
 A ti sọ fun yin saaju pe ọsẹ to kọja ni Alaafin kọ lẹta kan si Gomina Fayẹmi, lẹyin ti Fayẹmi kede pe, oun yoo rọ awọn ọba kan l'oye l'Ekiti nitori pe wọn n fapajanu lori ẹni to fi jẹ alaga awọn ọba ipinlẹ naa."
Eyi tii se ikọlu Boko Haram ni ẹkun ariwa ati tawọn ajijagbara lẹkun aarin gbungbun guusu Naijiria.
Ọ̀fọ̀ ati ẹkún yóo pọ̀ ní ẹnu ibodè Jerusalẹmu.
Obìnrin kò gbọdọ̀ jáde alẹ́ mọ́ ní Kano Dangote, Fayemi pari ìjà láàrin Ganduje àti Emir Sanusi Àna gómínà Ọ̀yọ́, Ganduje yan Emir mẹ́rin ní Kano Iroyin ti a gbọ ni pe, arakunrin Idris ni oun ko fẹ ki wọn gbe ere ije ẹlẹṣin naa de adugbo oun ṣugbon awọn to n sare ko gbọ sii lẹnu.
Magu fi ẹsun kan awọn alabaṣiṣẹpọ wọn nilẹ okeere pe, wọn n daabo bo Diezani ni Ilẹ Gẹẹsi lati dena ati wa jẹjọ rẹ lorilẹede Naijiria.
"Lojiji ni awọn ero to ko ada ati ibọn dani yi wa ka.
Àwọn òṣèré tíátà Yorùbá tó bá 2018 lọ'Mo máa ń parọ́ díẹ̀díẹ̀ ṣùgbọ́n kò pọ̀' Eré Mọrèmi rèé, obìnrin tó gba Ilé-Ifẹ̀ là lọ́wọ́ ìparun Kwara yóò gbàlejò BBC Yoruba Mi ò tan mọ́ ààrẹ Buhari rárá o!
“Ẹni tí ó ní àrùn ẹ̀tẹ̀ yìí gbọdọ̀ wọ aṣọ tí ó ya, kí ó fi apá kan irun orí rẹ̀ sílẹ̀ játijàti, kí ó bo ètè rẹ̀ òkè, kí ó sì máa ké pé, ‘Aláìmọ́!
àwọn bíi: àwọn ará Edomu, àwọn ará Moabu, àwọn ará Amoni, àwọn ará Filistia, ati àwọn ará Amaleki; pẹlu ìkógun Hadadeseri, ọba Soba.
Jesu tún wí fún wọn pé, “Èmi ń lọ ní tèmi; ẹ óo máa wá mi kiri, ẹ óo sì kú sinu ẹ̀ṣẹ̀ yín.
Nítorí pé, ẹni mímọ́ ni ẹ jẹ́ fún OLUWA Ọlọrun yín, OLUWA Ọlọrun yín ti yàn yín, láàrin gbogbo àwọn eniyan tí wọ́n wà ní gbogbo ayé, pé kí ẹ jẹ́ ohun ìní fún òun.
Ni ọjọ́ kejì, mo tún lọ, ṣùgbọ́n bí ó ti fi ojú kàn mi ni ó yìnbọn, díẹ̀ ló sì kù kí ìbọn náà bá mi.
“Bi a se pegede fun idije agbaye yii ko rorun-un rara, beesini a ko le maa jawe olubori ninu gbogbo ifesewonse wa.
Ọjọ Kẹrinla, Oṣu Kẹjọ ni Tolulope Arotilẹ jade laye lẹyin ti awọn ọrẹ rẹ ti wọn jọ lọ sile iwe girama pẹlu wọn ni Air Force Secondary School ni Kaduna, wa ọkọ pa a.
Omije n bọ loju arabinrin Yetunde Morẹnikeji Raji ṣugbọn o ni omije ayọ ni.
Eeyan 9,746 lo ti ri iwosan gba, nigba ti awọn 590 ti dero ọrun nitori arun ọhun.
Igbakeji akọwe ẹgbẹ APC tẹlẹri naa ni ohun ti ko ba ofin mu ni bi wọn se fi panpẹ ọba mu Doyin Okupe, ti wọn si lọ se‘abẹwo ti ko tọ’ si ile ọmọ Atiku Abubakar to jẹ oludije si ipo aarẹ ni ẹgbẹ oselu APC.
Aarẹ Trump sọ lati ọọfisi rẹ pe ''Lọna ati mase jẹ ki iṣẹlẹ aisan tuntun wọ ilẹ wa, a ti so gbogbo irinajo eeyan lati Yuroopu si ilẹ wa rọ'' Oríṣun àwòrán, @dcexaminer ''Ago mejila ọjọ Ẹti ni awọn igbesẹ yii yoo gberasọ'' O fi kun pe aṣẹ ọhun ko kan awọn ọmọ orileede Amẹrika to n pada bọ wa sile lati Yuroopu.
Lara ohun ti eeyan le fi danrawo boya lootọ ni aayan mọ ijinlẹ ede Yoruba niyii, a ti ṣe akojọpọ diẹ lara awọn òwe ti BBC Yorùbá ti lò sẹyin fun yin.
Ọgọ́jọ(160) ọmọ Nàìjíríà tí coronavirus ṣé mọ́ Amẹrika ti gúnlẹ̀ s'Abuja Àwọn nǹkan tí obìnrin lè ṣe pẹ̀lú olólùfẹ́ oníwà ipá lásìkò ìgbélé Coronavirus yìí O fi kun un pe ko si ipinlẹ kọkan lara awọn ipinlẹ to wa lẹkun naa to pẹlyinda si afẹnuko lori idasilẹ ikọ ọhun.
iPhone mi ọ̀wọ́n yára máa bọ̀ wálé o!
Atẹjade naa ni ọjọ Isẹgun, ogunjọ oṣù kẹwaa ọdun 2020 ni eto naa yoo bẹrẹ, ti yoo si pari l'ọjọbọ, ọjọ kọkanlelọgbọn oṣù Kejila.
Awọ̀n ilu lo se inawo iwuye mi: Oba ilẹ Uba ni ''idile ọba ni wọn bi mi si, ati idile mama ati baba mi ni wọn n maa n jọba.
Siga fifa le mu ki eeyan ni arun to n mu ọpọlọ kuru bi Dementia ati Alzheimer.
 nínú ìtẹ ̀ sìwájú , Ìtàn mìíràn tó fara jọ ìtàn òkè yìí , a gbọ ́ pé àwọn ọmọọba méjì ló fẹ ́ lọ tẹ ìlú dó .
Fun eyi, aarẹ gbe igbimọ amusẹ ya kan silẹ lati ri mimu u ṣẹ ni kanmọ kanmọ.
Ounjẹ owurọ ko i tii pe ni Ilẹ Gẹẹsi ti ko ba si ẹjẹ ẹranko ti wọn ti se nibẹ.
Ninu ọ̀gbun ilẹ̀ ni a óo ti máa gbóhùn rẹ̀,láti inú erùpẹ̀ ni a óo ti máa gbọ́, tí yóo máa sọ̀rọ̀.
Ere ọlọsọọsẹ ni o mu ki Ajimajaṣan o di gbajugbaja.
ni eyi ti o si lee fa sunkẹrẹ gbakẹrẹ awon eniyan .
Àwọn tẹ̀gbọ́n-tàbúrò meje kan wà lọ́dọ̀ wa.
SARS ti bẹ̀rẹ̀ ìgbésẹ̀ láti yọ àwọn ọ̀bàyéjẹ́ kúro níṣẹ́
ṣùgbọ́n nígbà tí ó di ẹ̀ẹ̀kẹta wàyì tí bàbá mi sì tún máa bojúwo ẹ̀hìn náà ńkọ́, ṣe ni ojú òun àti obìnrin yìí tún ṣe dọ́gbadọ́gba – bẹ́ẹ̀ ni bàbá mi ko ì tí ì nì obìnrin, àpọ́n ni, síbẹ̀síbẹ̀ náà, ó tún rọ́jú, ó ń lọ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Trump picture: ọjọ́ tí Trump kí mi kú iṣẹ́ lórí 'twitter' ní inú mi dùn jù- Oyedele Awọn mejeeji a koju Asia Muhammed ati Taylor Townsend ninu idije naa lọjọ Aiku.
Victoria Rubadir ọmọ Kenya ló gba àmì ẹ̀yẹ Komla Dumor BBC World News.
Oníbodè yìí kò tilẹ̀ bìkítà fún bàbá mi.
Ọwọ́ ọlọ́pàá tẹ 'ọba alayé' àti ọmọ rẹ̀ tó fi ipá bá ọmọ ọdún mẹ́rìnlá lòpọ̀ l'Ọ́ṣun Ọwọ titẹ ọba alaye kan, Ọba David Ogungbemi ati ọmọ rẹ, Idowu, fun pe wọn fi ipa ba ọmọbinrin, ọmọ ọdun mẹrinla kan lopọ.
ni ajo  EFCC tun salaye pe awon afurasi
Awọn ọmọ baba rẹ ni Oyefi, Ajẹnju, Arohanran ati Oduniyi Timi Agbale bi ọmọkunrin meji amọ ti itan ko sọ ohunkohun fun wa nipa Gbọnka Ebiri.
O si daju pe awọn akẹkọ ileewe Girama nipinlẹ Osun ko ni gbagbe Gomina Aregbesola laelae lori ipese ọpọn imọ.
Bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé ẹ kò rí i, sibẹ ẹ fẹ́ràn rẹ̀.
Agbẹnusọ fún ilé aṣòfin àgbà - BBC News Yorùbá BBC News, YorùbáFò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Gbèsè tí Buhari ń jẹ bójúmu, isẹ ìdàgbàsókè ló fi ń ṣe - Agbẹnusọ fún ilé aṣòfin àgbà 18 Ìgbé 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 5 Èbibi 2020 Oríṣun àwòrán, Nigeria senate Ṣenatọ Surajudeen Ajibola Basiru, tí gbogbo ènìyàn mọ si SRJ, tíì se agbẹnusọ fun ilé igbimọ asofin àgbà ilẹ̀ wa ti ṣàlàyé pé, kò seese kí ilé asofin fi òfin de ẹnikẹ́ni, pàápàá àwọn aṣáájú wá, láti lọ gba itọju lókè òkun.
Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Elebuibon: Àwọn asòfin Ogun yóò ṣe àkóbá fún ilẹ̀ Yoruba pẹ̀lú òfín tó fágilé àsà6 Ẹrẹ̀nà 2020 Orisabunmi: Ìkúnlẹ̀ Abiyamọ ò!
Ó bá dìde, ó bá tọ́jú oúnjẹ fún un.
Oríṣun àwòrán, WAEC Nigba ti ìkọlu naa n waye, awọn akẹkọọ tun fọ ẹrọ ibanisọrọ awọn alakoso naa mọlẹ nitori fidio bi wọn ṣe n gbe iwe wọle to wa lori rẹ.
A ko tilẹ maa n sọrọ nipa rẹ ni, nitori wi pe ohun itiju lo jẹ.
Nínú ìfọ̀rọ̀wáni-lẹ́nuwo orí ẹ̀rọ ìbánisọ̀rọ̀ pẹ̀lú Stand News, Chemi Lhamo sọ pé òun nígbàgbọ́ pé ohun tí ó ṣẹlẹ̀ kò sẹ́yìn àwọn àjọ tí wọ́n ń bá Ìjọba China ṣe, ẹ̀sùn èyí tí àwọn òṣìṣẹ́ àgbà àjọ ọba China ti sẹ́ lé lórí.
ijoba to wa ni Agodi niluu Ibadan, ni ipinle Ọyọ to wa ni Gusu, orile ede
O ni ohun to ṣe pataki ni i awọn orileede mejeeji wa ọna labẹ ofin ti wọn yoo fi yanju aawọ to ba waye.
Nígbà tí ó ti sọ báyìí tán, ó tutọ́ sílẹ̀, ó fi po amọ̀, ó bá fi lẹ ojú ọkunrin náà.
Nígbà tí Juda ati àwọn arakunrin rẹ̀ pada dé ilé Josẹfu, ó ṣì wà nílé, wọ́n bá dọ̀bálẹ̀ gbalaja níwájú rẹ̀.
Ṣugbọn awọn onimọ nipa bi ọpọlọ ṣe n ṣiṣẹ ni awọn ọna kan wa ti eniyan fi le yago fun ijakulẹ ninu idanwo.
Nígbà tí wọ́n ti nà wọ́n dáradára, wọ́n bá sọ wọ́n sẹ́wọ̀n.
Ó kó ẹ̀yà Juda wá ní agbo-ilé kọ̀ọ̀kan, wọn sì mú agbo-ilé Sera.
Báyìí-báyìí ó ti wà ní ibiṣẹ́ àwọn onímọ̀ ẹ̀rọ náà.
Ó di ìgbà ti ọwọ́ ẹni ò bá tó o mọ́ kí olúwarẹ̀ tó mọ iyì rẹ̀ o.
Tanker Accident: Awakọ̀ dèrò ilé ìwòsàn lẹ́yìn tí ọkọ̀ agbépo dànù L’eko
Erongba NFVCB lojo iwajuThomas soro lori igbiyanju ajo fiimu Naijiria yii ati ipinnu won pe won n gbe igbese lati fowosopo pelu ajo akoroyin Naijiria, iyen National Broadcast Commission fun ipolongo awon ero ati ilana won.
Àwọn Juu wá sọ fún un pé, “A wá mọ̀ dájú pé o ní ẹ̀mí èṣù wàyí!
 Donald Trump kede ọrọ yi fun Piers Morgan lori eto redio kan ti wọn pe ni 'Good Morning Britain' nibi to ti n seto ifọrọwanilẹnuwo pẹlu rẹ nilu Davos lana ọjọbọ."
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, EndSars, EndSwat Protest: Òbí agbábọ̀ọ̀lù Gbenga Tiamiyu Kaka àtàwọn míì tí ọlapàá pa sọ̀r Ọdun 1972, lo kọkọ di sẹnetọ, o si ti jẹ ni igba mẹfa.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ikogosi-Ekiti: Ilu ti omi tutu ti dapọ mọ gbigbona Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Òkú wọn yóo máa rùn;n óo pa wọ́n run nítorí ibi ńlá tí wọ́n ṣe.
OLUWA bá ní:“Lọ, sọ fún àwọn eniyan wọnyi pé;wọn óo gbọ́ títí, ṣugbọn kò ní yé wọn;wọn óo wò títí, ṣugbọn wọn kò ní rí nǹkankan.
Adebola Ademilua ni akẹkọgboye imọ ijinlẹ sayẹnsi to sọ iru ṣiṣe di iṣẹ oojọ rẹ to fi n pa owo wọle.
Aarẹ ilẹ orilẹede Faranse, Emmanuel Macron se abẹwo si Fela Shrine ni Naijiria Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ààrẹ ilẹ̀ Faranse, Emmanuel Macron yóò dé sí Nàíjíríà ní Ọjọ́ Isẹgun, níbi tí yóò ti má a se ìpàdé pẹ̀lú Ààrẹ Muhammadu Buhari.
O tẹsiwaju pe lori awuyewuye to n lọ lode pe ọmọbinrin naa n gbo bi aja, oun ko le sọ boya ootọ ni tabi irọ.
O ni ko ba ofin mu, nitori pe oun ko fi aṣẹ sii.
 Bakan naa, ni  a mọ pe ,a nilo ibaraẹnisọrọ
Sugbọn, Woli Sotitobirẹ ni idi ti oun ko fi kọ ibi ara si ọrọ awọn obi ọmọ ti wọn jilọ naa ni wi pe, awọn obi ọmọ naa bu oun pe oun ko sin Olorun to ni ọmọ naa fi di awati ni ile ijọsin rẹ.
Nítorí tiyín ni gbogbo èyí, kí oore-ọ̀fẹ́ lè máa pọ̀ sí i fún ọpọlọpọ eniyan, kí ọpẹ́ yín lè máa pọ̀ sí i fún ògo Ọlọrun.
Ẹ fún eniyan burúkú ní ìgbà díẹ̀ sí i, yóo pòórá;ẹ̀ báà wá a títí ní ààyè rẹ̀, kò ní sí níbẹ̀.
Nínú Ifesewonse to waye ní Sudan, ni ikọ agbabọọlu Ivory Coast ti da bantẹ iya góòlù mẹta si ọkan fún wọn.
Iròyìn to ń tẹ̀ wá lọ́wọ́ lórí afárá London ni pé àwọn ọlọpàá ilẹ̀ Gẹ̀ẹ́sì ni àwọn ti pa ọkùnrin kan ọ́wọ́ ìgbésùmọ̀mi si ni àwọn fi mú ìṣẹ̀lẹ̀ náà.
Ọ̀dá yóo dá ní ilẹ̀ wọn,kí àwọn odò wọn lè gbẹ!
Kí ó má jẹ́ ẹni tí ó ṣẹ̀ṣẹ̀ di onigbagbọ, kí ó má baà gbéraga, kí ó wá bọ́ sọ́wọ́ Satani.
Ó yan ọ̀kẹ́ mẹta ó lé ẹgbaarun (70,000) ninu wọn láti máa ru nǹkan ìkọ́lé, ó ní kí ọ̀kẹ́ mẹrin (80,000) eniyan máa la òkúta, kí ẹẹdẹgbaaji ó lé ẹgbẹta (3,600) jẹ́ alákòóso tí yóo máa kó wọn ṣiṣẹ́.
Tí àtúntò kò bá wáyé ní Naijiria, ó ṣeéṣe kó túká- Pásítọ̀ Adeboye Adari ijọ Redeemed Christian Church of God, Pasitọ Enoch Adeboye ti kesi ijọba lati tete wa ọna abayọ si igbe awọn eniyan to n bere fun iyapa orilẹede Naijiria Oríṣun àwòrán, PastorEAAdeboye Àkọlé àwòrán, Pasitọ agba ijọ Redeemed Christian Church of God, Enoch Adeboye naa ti darapọ mọ awọn to n bere fun atunto Naijiria Adeboye sọ eleyii ni ibi ayẹyẹ ayajọ ọgọta ọdun ti orilẹede Naijiria gba ominira, eleyii ti ijọ Redeemed Christian Church of God ati Nehemiah Leadership Institute gbe kalẹ.
Bẹ́ẹ̀ ni Farao ọba Ijipti jẹ́ sí gbogbo àwọn tí ó bá gbára lé e.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Ọ̀lọ́pàá shátà mi láti Mowe dé Magboro dé Shagamu, wọ́n ní ṣé mi ò mọ̀ pé ìjọ́ba ni mo ṣiṣẹ́ fún' Atẹjade kan lati olu ileeṣẹ ọlọpaa ipinlẹ Oyo ṣalaye pe, kọmiṣọna ọlọpaa ni ipinlẹ naa ti jawe ikilọ ranṣẹ sawọn to kundun idajọ ọwọ nibẹ ati pe ẹnikẹni ti ọwọ ba tẹ yoo kabamọ ṣiṣe bẹẹ.
Àdó ikú tí Boko Haram fi sójú ọ̀nà pa méje lára wọn Ikọ ọmọogun Naijiria ti kede pe ikọ Boko Haram ti fun ra wọn ko si idẹkun ti wọn dẹ silẹ fun ikọ ọmọogun Lafia Dole.
Kò pẹ ní Ibadan, tíì ṣe ìlú tó tóbi julọ nilẹ Yoruba, pé ìpàdé pẹlu awon ilu miran nilẹ Oodua.
Bí eniyan tilẹ̀ fẹ́ bá a jiyàn,olúwarẹ̀ kò ní lè dáhùn ẹyọ kan ninu ẹgbẹrun ìbéèrè tí yóo bèèrè.
Nítorí ọjọ́ ayé wa ń kọjá lọ ninu ibinu rẹ;ayé wa sì ń dópin bí ẹni mí kanlẹ̀.
Ara awọn eto ti wọn fi n sami ọdun Ọṣun Ọṣogbo si ni ipejọpọ awọn arugba ni aafin Ataoja tilu Osogbo eyi to ti waye bayii.
Meredi tún ní iyawo mìíràn, òun jẹ́ ará Juda, ó bí ọmọkunrin mẹta fún un: Jeredi, baba Gedori, Heberi baba Soko, ati Jekutieli, baba Sanoa.
Bi o tilẹ jẹpe aarẹ Buhari ni eto ti oun ni lo fa sababi aiyọju oun, ti Atiku naa si sọ pe, aiwa Buhari lo jẹ k'oun naa kọ lati kopa ninu eto ọhun, ni ọpọ eeyan bu ẹnu atẹ lu.
Ọjọ Arafa ni ọjọ to kangun si ọjọ Eid-al-Adha, iyẹn Ọjọ Ileya, eleyii ti wọn ma n se ni aadọrin ọjọ lẹyin ọdun Ramadan.
O ni o se pataki lati mọ ipa ti ẹnikeji rẹ ko ninu iṣẹlẹ naa, nitori ẹni kan kii jẹ awa de.
 Ni bayii, wọn ti n dunkoko mọ mi pe awọn yoo gbẹmi mi tabi ki wọn ji mi gbe, ti kii si se oni ni awọn eeyan ti n jalaisi nitori oselu lorilẹede Naijiria sugbọn n ko ni jawọ nitori idunkoko wọn.
Bakan naa, ipade naa tun so eso rere, leyin ti igbimo naa bowolu iwe adehun pelu ajo E-Health Africa lati koju awon isoro to n dojuko eto ilera, bee si ni lati pese awon ohun elo ati ero igbalode ni gbogbo ipinle maraarun un.
Ọjọ́ tí inú mi bàjẹ́ jùlọ gẹ́gẹ́ bíi ààrẹ ilé aṣòfin àgbà-Saraki Àwà gómìnà PDP ṣetán láti san #30,000 owó oṣù fáwọn òṣìṣẹ́- Dickson Èèmọ̀ wọ̀lú!
Dafidi gbé ní ilẹ̀ àwọn ará Filistia fún ọdún kan ati oṣù mẹrin.
Iya di meji fawọn arinajo loju popo naa lẹyin ti ọna naa di, eleyi ti ọkọ ko le rin geere tẹlẹ nitori iṣẹ to n lọ lori titi naa.
Nàìjíríà làwọn ní ìfẹ́ sí ìpèsè abẹ́rẹ́ àjẹsára Covid-19 tí Russia ṣe Wo ọ̀nà ìsanwó tuntun fún àwọn oníbárà iná mọ̀nàmọ́ná ní Eko (EKDC) Àwọn dókítà yóò bẹ̀rẹ̀ ìyanṣẹ́lódí lọ́jọ́ Ajé Ninu aye Femi Adebayo, bẹbẹ jade lọsẹ yii: Odu ni Femi Adebayo ninu agbo awọn oṣere Yoruba toun naa si ti n ṣe itọwo awọn fiimu to fẹ gbe jade.
Nǹkankan ti bò wọ́n lójú kí wọn má baà lè ríran; ó sì ti sé wọn lọ́kàn kí òye má baà yé wọn.
Ìrísí rẹ̀ dàbí òkè Lẹbanoni, ó rí gbọ̀ngbọ̀nràn bí igi Kedari.
and Disaster Management and Police Affairs).
Ọjọ kọkandinlogun naa ti awọn akẹkọọ wọle ni ijọba ipinlẹ naa kede pe ki awọn akẹkọọ o gbe ile wọn naa titi di igba ti ọrs yoo fi tutu nigboro.
Olaboye to tun jẹ akọwe igbimọ alaabo ilu Offa fidi ọrọ naa mulẹ pe awọn ti gburo lati ọdọ awọn ajinigbe naa ti wọn si ti sọ pe awọn fẹ gba owo lori awọn ti wọn jigbe.
Bi o tilẹ jẹ pe ẹsẹ Bibeli ni majẹmu laelae ati Kurani tọkasi eyi, ti awọn Kristẹni alaṣọ funfun atawọn Musulumi si n tẹle, ti awọn ẹlẹṣin abalaye naa si fara mọ igbagbọ yii, sibẹ awọn ọlaju ati imọ sayẹnsi kan tako igbagbọ naa pe ko tọna, ti ọpọ obìnrin miran si maa n jọsin lasiko ti wọn n ṣe nnkan oṣu lọwọ.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ sí: A dájọ́ ọjọ́ pé, Ìpàdé ìtagbangba Ọṣun kò 'A gbọ́dọ̀ gbé ìgbésẹ̀ tí ìpínlẹ̀ Eko gbé nípa èdè Yoruba’ Omotara pàdánù isẹ́ olówó ńlá nítorí ó fi ọtí ẹlẹ́rìndòdò sódà lá ọmọ alágbe lójú Jemila dáná sún ilé ọ̀rẹ́kùnrin rẹ̀ àti ọ̀rẹ́bìnrin tó bá nílé Rògbòdìyàn bẹ́ sílẹ̀ láàrin àwọn ọlọ́kadà àti àwọn òṣìṣẹ́ ọgbà ẹ̀wọ̀n ní Ibadan Oluṣọagutan Joel Olugbenga, to jẹ APICP FCT 6 nilu Abuja gba awọn kristiẹni nimọran lori ọrọ ipa ninu idile.
Oríṣun àwòrán, ayaba_folashade Ṣe lootọ ni pe Olori Badirat Ajoke ni ajọṣepọ pẹlu KWAM 1?
Ìsìn ń lọ nínú ìjọ Sotitobire àmọ́ a kò le lu ìlù, gbogbo rẹ̀ ti jóná - Ọmọ ìjọ Wọ́n gbé òkú ọgá iléẹ̀kọ́ àti òṣìṣẹ́ méjì míì tó kú nínú ìbúgbàmù lọ sílé ìgbókùsí ológun ojú omi l‘Eko Ajá kìí rorò kó ṣọ́ ojú'lé méjì, kò tọ́ ọ́ sí Alaafin láti dásí ọ̀rọ̀ ọba l‘Ekiti - Peter Fatomilọla Coronavirus dá wàhálà sílẹ̀ ní Ghana, ìjọba gbé ìlẹ̀kùn gbogbo iléẹ̀kọ́ tìpa Mwalimu ti rọ awọn ọmọ orilẹede naa lati ma foya nitori ijọba yoo ṣe gbogbo to yẹ ni ṣiṣe lati dẹkun itankalẹ arun naa lorilẹede naa.
Ṣugbọn bí ọmọbinrin alufaa kan bá jẹ́ opó, tabi tí ó ti kọ ọkọ rẹ̀ sílẹ̀ láì bímọ fún un, tí ó bá pada sí ilé baba rẹ̀ gẹ́gẹ́ bí ìgbà tí ó wà ní ọdọmọbinrin, ó lè jẹ ninu oúnjẹ baba rẹ̀; sibẹsibẹ àjèjì kankan kò gbọdọ̀ jẹ ninu rẹ̀.
Gẹgẹ bii kọmiṣọnna ọlọpaa ni ipinlẹ Ọyọ, Nwachukwu Ewonwu ṣe sọ, awọn afurasi naa ni wọn gbẹmi Barakat Bello ni ọjọ kinni oṣu kẹfa.
se ipade po pelu awon adari orile ede Europe, lara won ni adari ijoba ti orile
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Àwọn olúlùfẹ́ fí ìbòjú fi ẹnu ko ara wọn ní Philippine O ṣalaye pe bi ijọba ṣe ti awọn ibode naa ti ṣe adikun si bi awọn kọlọransi kan ṣe n ko aṣọ wọle si Naijiria lọna ti ko ba ofin mu.
Vuyo Dabula – Five Fingers For Marseille
Esi rẹ̀ ni pe, awọn ọmọ orilẹede South Africa kúṣẹ̀ẹ́ lasiko yii.
OLUWA sọ̀kalẹ̀ láti òkè Sinai sí ibi mímọ́ rẹ̀pẹlu ẹgbẹẹgbẹrun lọ́nà ẹgbẹrun kẹ̀kẹ́ ogun,ẹgbẹẹgbẹrun lọ́nà ẹgbẹrun.
Ó yẹ ki wọn gbé eyi yẹ̀wò nitori ni ilú ti òfin bá wà, kò yẹ ki ẹnikẹni kọjá òfin.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Àsìsọ ọ̀rọ̀ kóba Olasunkanmi Okeowo láti díje fún ààrẹ Àwọn obìnrin tí kò lọ́kọ ń kojú ìsòro ilé gbígbà Òbí tó n fa sìgá n fi ọmọ rẹ̀ sínú ìdè àìsàn l'ọ́jọ́ iwájú Àìsàn kíndìnrín tó dasẹ́ sílẹ̀ ló pa Fẹ́lẹ́ - Ààrẹ NURTW Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Àwọn èèyàn àti awakọ̀ ké igbe ìrora bí àwọn ọkọ̀ ńlá ṣe dí ọ̀nà mọ́rosẹ̀ Apapa-Oshodi pa Bákan náà ni àwọn ẹgbẹ́ àwọn tó ń rí sí ìlera ọkan l'Amerika, rọ̀ àwọn ènìyàn láti yàgò fún àdín àgbọn nínú ìwé ìròyìn Business Insider ti Deutschland.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Chelsea vs Manchester United: Àwọn agbábọ́ọ̀lù Ole lé Chelsea kúrò ní ìdíje Carabao Cup 30 Ọ̀wàrà 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Ẹgbẹ agbabọọboolu Manchester United ya ọpọ lẹnu lẹyin ti wọn fiya jẹ Chelsea mọle ninu idije Carabao Cup.
    Kò sí ẹni tí ẹ̀rù kò bà nínú wa nígbà tí wọ́n yọ, àfi bí a bá máa púrọ́.
Chelsea tún ṣubú dàánù lẹ́ẹ̀kan si 14 Ògún 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Pàá lẹ́ẹ̀kínní, pàá lẹ́ẹ̀kejì!
" Ṣé lóòtọ́ ni aya ààrẹ, Aisha Buhari fò lọ sí Dubai fún ìtọ́jú?
Lara awọn to fi ipo silẹ fun Wada ni: AVM Salihu Atawodi, Muhammed Tetes, Emmanuel Omebije, Mrs Grace Iye Adejor, Dr.
Ṣugbọn ọpẹ́ ni fún Ọlọrun tí ó jẹ́ kí á lè wà ninu àjọyọ̀ ìṣẹ́gun tí Kristi ṣẹgun, nígbà gbogbo.
Amọ ti ẹ ba moju kuro lawọn iyatọ diẹ diẹ yi, ẹ o ri pe ile Ọlọrun naa nibi jẹ'' Oríṣun àwòrán, Reuters Koda pasitọ sọọsi naa, Monika Mathias , n kopa ninu ijọsin ọhun, to si ba wọn sọrọ.
Àwọn míràn tún fa ẹ̀rí fọ́nrán mìíràn síta pé ìpàdé ri àwọn òṣìṣẹ́ ṣe lẹ́yìn tí wọ́n lé wọn jáde lọ́fììsì lásìkò tí Abike Dabiri ò sí nílé.
Ni ọjọọru ni awọn alasẹ ere bọọlu lagbaye gbe ife ẹyẹ naa ka aarẹ Buhari mọ ile ijọba Aso rock nilu Abuja gẹgẹbi itaniji ati ipolongo ti o nlọ lọwọ lori idije ife ẹyẹ agbaye fun bọọlu afẹsẹgba ti yoo waye lorilẹede Russia ni osu kẹfa ọdun 2018.
Oríṣun àwòrán, toyin_abraham O wa n rawọ ẹbẹ si Oloye Bruce lati se atilẹyin fun isẹ oun nipa sise afihan sinima naa nitori isẹ asekara ni oun se ninu sinima ọhun, ti oun si n fẹ ki oogun oju oun naa ma ja si asan Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ọmọ ọdún méje ni mo bẹ̀rẹ̀ òwò nàbì nílé aṣẹ́wó tó tóbi jùlọ lágbàyéé"" Kí ni àyájọ́ ‘Má wọ kọ́mú’ wà fún?"
Ẹ̀yin ará mi, ohun tí mò ń wí yìí kò ṣe àjèjì si yín (nítorí ẹ̀yin náà mọ òfin), pé òfin de eniyan níwọ̀n ìgbà tí ó bá wà láàyè nìkan.
Awon yoruba ni, bi a ba da ojo ojo a pe, bi a ba si da osu, dandan ni kosu o ko.
Iroyin sọ pe wọn ba agbari eeyan mẹrin, ọwọ meji, ati àgbọn mẹta lọwọ ri.
Amọ lasiko ti a pe FestusAdedayọ, pe ko wa sọ bii ọrọ naa se ri, ko gbe ẹrọ ilewọ rẹ.
Ọdun 1981 lo kẹkọ gboye imọ dokita ni eto oselu ni imọ eto oselu lati ile-iwe giga fasiti Boston ati ile -iwe fasiti Toronto ni orilẹede Canada ni ọdun 1987.
#BBCOGUNDEBATE: O ṣe pataki láti yan àwọn akanda ẹda si ipò kọmisọna.
Ipinlẹ Borno gbé igbimọ amusẹya kalẹ lati sisẹ pẹlu awọn ileesẹ aladani, ile ijọsin ati awọn ajọ ti kii se ti jọba lati koju aarun naa, to ba fi le wọ ibẹ.
Ẹ̀fọn Arsenal já bàálù Liverpool lulẹ̀ ní Wembley ní ìrìn-àjò sí Community Shield Ronald Koeman di akọ́nimọ̀ọ́gbá Barcelona tuntun lẹ́yìn ìjàmbá Champions League Oral Sex: Bóo bá ń gba ẹnu ní ìbálòpọ̀, wo àìsàn tóo lè kó lójú ara rẹ Ọkùnrin kan di èrò ọ̀run nítorí pé o fi ẹ̀sùn kan alájọgbélé rẹ̀ pé o n yan ìyàwó ẹnìkan lálè Wọ́n ti sún ìdájọ́ àwọn sójà tó pa ìyá àti ọmọ ní ọdun 2018 sí oṣù tó m bọ̀ Oyenusi ló mú mi wọ ẹgbẹ́ adigunjalè kó tó di pé mo b'Ólúwa pàdé - Kayode Williams Ọba ni mí, mi ò le b'ọ̀rìṣà, Olorì tuntun tó ń bọ̀ já gbogbo ''scale''- Oluwo ti Iwo Bakan naa ni a gbọ pe baba Messi, Jorge yoo ṣe ipade pẹlu awọn alaṣẹ Barcelona lọsẹ yii lati sọrọ lori bi Messi yoo ti fi ẹgbẹ agbabọọlu silẹ.
" A kú ayẹyẹ gbogbo ọmọ orílè èdè Nàìjíríà.
Ọmọ ẹgbẹ Ile Igbimọ Aṣofin Ipinlẹ Eko kan, Aṣofin Nurudeen Solaja-Saka, ṣe eto ironilagbara fun ọpọ awọn eniyan ni ilu Imota ni ẹkun Ikorodu keji ni Ipinlẹ Eko lapa Iwọ-oorun Gusu orilẹ-ede Naijiria.
Joshua Beckford yìí ló kéré jùlọ to ti wọ ilé iwé Oxford ní England, ọmọde náà ni òun setan láti tún ayé ṣe láti di dọkíta oniṣẹ-abẹ ọpọlọ lojúnà ati ran aye lọ́wọ́ lọ́jọ́ kan.
Ó bá mú kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ rẹ̀ gùn, ó gbọ̀nà, ó sì rí òkú wolii náà nílẹ̀ lójú ọ̀nà, níbi tí kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ ati kinniun náà ti dúró tì í.
Inú ilé Farao ọba ni ayaba Tapenesi ti tọ́ ọmọ náà dàgbà, láàrin àwọn ọmọ ọba.
Ẹnìkan lè sọ pé, “Kò sí ohun tí kò tọ̀nà fún mi láti ṣe.
Ṣe bi owo ku lawọn oṣiṣẹ ijọba ọhun yoo gba Wọ́n léè ta mílíọ̀nù kan páálí láàrín ọ̀sẹ̀ kan ṣoṣo!
Mo fẹ́ kí ẹ mọ̀ pé yóo ṣe ẹ̀tọ́ fún wọn kíákíá.
Orúkọ yìí ló wú n tí ó sì sọ ìlú tí òun náà tẹ̀dó ní orúkọ náà.
Ranti pé angẹli mi yóo máa ṣáájú yín lọ, ṣugbọn ọjọ́ ń bọ̀, tí n óo jẹ àwọn eniyan náà níyà nítorí ẹ̀ṣẹ̀ wọn.
Ẹ óo ra oúnjẹ jẹ lọ́wọ́ wọn, ẹ óo sì ra omi mu lọ́wọ́ wọn.
Kí ẹ gbà á tọwọ́-tẹsẹ̀ ninu Oluwa, kí ẹ máa bu ọlá fún irú àwọn bẹ́ẹ̀.
Amọ atẹjade miran tileesẹ eto ẹkọ nipinlẹ Ọyọ fisita lọjọ Ẹti, ọjọ kẹẹdọgbọn osu Kẹsan ọdun yii fihan pe atunse tun ti ba eto ẹkọ lawọn ile ẹkọ tijọba ati taladani to wa nipinlẹ naa.
Sugbọn wọn tiraka lati doola owo Rupee to to milliọ̀nu kan ati ẹgbẹrun lọna ẹẹdẹgbẹrin to wa ninu ẹrọ apọwo naa, ko to pẹju.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Boko Haram yóò dá Leah sílé Ko si iye meji pe Yusuf tako ẹkọ igbalode eleyi to ni o jẹ ''haramu'' nitori pe awọn ilana rẹ ko ba ti ofin Ọlorun Sharia mu.
Ẹni tí ó bá ń ṣẹ́jú sí ni, ète ibi ló fẹ́ pa,ẹni tí ó bá ń fúnnu pọ̀ sọ̀rọ̀, ọ̀rọ̀ burúkú ni yóo sọ jáde.
Ṣùgbọ́n rírò ni tti ènìyàn, ṣíṣe ni ti Ọlọ́run; ènìyàn mọ òní, Olódùmarè mọ ọ̀la, ó mọ ọ̀túnla, ó sì mọ ọ̀kẹ́ aàimọye ọdún tí ń bẹ níwájú wa.
FIFA 2019: Ọdún 1991 làkọ́kọ́ irú rẹ̀ ní àgbáyé
Ewe, awon meji ninu awon omo-ogun olote naa gbemi ara won nipase ado-oloro, awon omo-ogun gbemi meji, won si fi owo sikun mu kan.
Koda, ofin naa tun ni awọn darandaran yoo lọ gba iwe idanimọ lọdọ ijọba eyi ti wọn yoo maa gbe kọrun ni gbogbo igba, eyikeyi wọn ti ko ba si se bẹẹ yoo san ẹgbẹrun lọna ọgọrun naira tabi ko fi ẹwọn ọdun meji jura, abi ko se mejeeji papọ.
Ẹ wò wá ẹ wo iṣẹ́ ọwọ́ wa Àwọn adigunjàlè pà òṣìṣẹ́ Aso Rock l’Abuja Anthony Joshua gba nọ́mbà ìdánimọ̀ NIN, àwọn ọmọ Nàìjíríà kan kérora lórí ètò náà Coronavirus: Ó dá mi lójú pé ìwá ìbàjẹ́ ló fa àrùn yìí - Ọ̀gá àgbá EFCC Àwọn ìgbà tí ìmọ̀ràn Pásítọ̀ Adeboye lóri igbéyàwó ti fa àríyànjiyàn Sokunbi ni isẹ asejere ni isẹ danfo wiwa, bi o tilẹ jẹ pe ko rọrun rara, sibẹ, oun fẹ di ọga nla.
Nítorí ọkàn àwọn eniyan yìí kò ṣí; wọ́n ti di alágbọ̀ọ́ya,wọ́n ti dijú.
Èmi, Olówó-ayé, ọmọ Akọ̀wédìran, arẹwà lọ́kùnrin, mo wá sí Igbó Olódùmarè láti ṣe ọdẹ, mo bá ìṣòro pàdé lójú ọ̀nà, ṣùgbọ́n Olódùmarè yọ mí nínú wọn, ní ìgbẹ̀hìn mo dé ọdọ ọba Igbó Olódùmarè, ọba náà ni ó ṣe ìnáwó ìgbéyàwó fún mi, ìgbéyàwó ìyàwó mi tí ó bí ọmọ mi, Àkàrà-oògùn.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù K1 De Ultimate: Bí Barrymade bá ní alágbàfọ̀ bàbá òun ni mí, oríire ni mo ṣe Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ K1 De Ultimate: Bí Barrymade bá ní alágbàfọ̀ bàbá òun ni mí, oríire ni mo ṣe 14 Èbibi 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 15 Èbibi 2019 Alhaji Wasiu Ayinde ti gbogbo ènìyàn mọ̀ si K1 de Ultimate tẹnu bọ ọrọ lori ọrọ ti Barrymaade, ọmọ abúrò Oloogbe Sikiru Ayinde Barrister sọ si i wi pe oun (Kwam1) ni alagbafọ baba òun, Sikiru Ayinde Barrister.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Àwọn obìnrin kan tilẹ̀ máà n ta omi ọyàn wọn fún àwọn ìyálọ́mọ́ tí kò le fún àwọn ọmọ wọn ní ọyàn O ni eyi yoo ṣe iranlọwọ fun idagbasoke ati ọjọ iwaju awọn ọmọ naa, ati pe fi fun ọmọ lọyan maa n mu ki ifẹ ati isopọ wa laarin iya ati ọmọ.
Bakan naa, o menu ba aba to safihan pe ki ayalegbe maa
nítorí jamba lè ti ọ̀dọ̀ wọn wá lójijì,ta ló mọ irú ìparun, tí ó lè ti ọ̀dọ̀ àwọn mejeeji wá?
Awọn oludije alatako mẹfa ni yoo figa gbaga pẹlu Faure ninu ibi gbogbogbo ọjọ Abamẹta.
Ní ọdún kẹẹdogun tí Amasaya ọmọ Joaṣi jọba ní Juda ni Jeroboamu, ọmọ Jehoaṣi, ọba Israẹli jọba ní Samaria, ó sì wà lórí oyè fún ọdún mọkanlelogoji.
Sarri ni akọnimọọgba akọkọ ti yoo lọ ni ọna to wuu gan lati igba ti Abramovich ti ra Chelsea.
Ẹni kọọkan lo ko aarun coronavirus lọjọ Iṣẹgun lati Bauchi, Gombe, Nasarawa, Niger ati Osun.
Ọlọ́pàá tó n gba rìbá sọ pé 'Ọlọ́run gan fara mọ́ olè jíjà' Wòlí ní Gbenga Adeboye jẹ nígbà ayé rẹ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, '500 level'' ni mo wà nígbà tí mo di adélé Ọba' Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Àìsàn Orímóògùnjẹ́ kò ju ọjọ́ mẹ́wàá lọ tí ó fi kú.
Ninu oju opo ikansira ẹni twitter ni Aare Donald Trump ti sọ pe lilo ọna ifi idibo ẹni ransẹ lapapọ le sakoba fun nini iye nọmba idibo to jẹ tototọ nitori o le mu kudiẹkudiẹ dani.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ẹ wo ìfọ̀rọ̀wẹ́rọ̀ pẹ̀lú Saheed Osupa 17 Èbibi 2019 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Oríṣun àwòrán, @others Àkọlé àwòrán, ọpọ ero lo fẹ mọ ohun ti a ṣẹlẹ lasiko Jimọh Koda, iroyin ni ero pọ pupọ ni mọṣalaṣi naa de ibi pe wọn gba pe awọn fẹ wa woran pe boya lootọ nigbeyawo yoo waye laarin Aarẹ ati minista fawọn aṣatipo rẹ tuntun.
Ọpọlọpọọ wọn si lo jẹ ọmọ orilẹede Sri Lanka.
Ati ọmọde ati agba lo mu u bi iṣẹ nilu naa Àkọlé àwòrán, Ilu Ọyọ ni ojulowo Ilu gangan nilẹ Yoruba.
 wọ ́ n á gbà wí pé , àsìkò rẹ ̀ kò tíì tó .
Ṣebí ọmọ ẹ̀ṣẹ̀ ni yínirú ọmọ ẹ̀tàn;
O ni ijọba Naijiria nbeere pe bawo ni ọbọ se se ori ti inaki o se niwọn bo se jẹ wipe orilẹede Amẹrika yii kan naa faaye gba awọn osisẹ orilẹede miran to ta awọn baluu yii fun lati wa kọ bi wọn se to awọn baluu naa jọ.
Ko da ọpọ wọn lo sọ pe ko ṣee gbọ seti.
ati ile igbimo asoju sofin , ni eyi ti o waye jake –jado orile ede Naijiria.
OLUWA, a mọ ìwà burúkú wa,ati ẹ̀ṣẹ̀ àwọn baba wa,nítorí a ti ṣẹ̀ ọ́.
Jesu wá ń kiri gbogbo Galili, ó ń kọ́ àwọn eniyan ninu ilé ìpàdé wọn, ó ń waasu ìyìn rere ìjọba Ọlọrun, ó tún ń wo oríṣìíríṣìí àrùn sàn lára àwọn eniyan.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù AFCON 2019: Ọmọ Nàijíríà rọ Super Eagles lati tubọ sápa wọn pẹlú Madagascar Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ AFCON 2019: Ọmọ Nàijíríà rọ Super Eagles lati tubọ sápa wọn pẹlú Madagascar 26 Òkùdu 2019 Ọ̀pọ̀ ọmọ Nàìjíríà ló tí ń ṣe sàdánkata káre sí ikọ Super Eagles lóri ìfẹsẹ̀wọnsẹ tó wáye lóni láàrin àwọn ati Guinea.
Amọ ṣa ko tori r ma ṣe iṣẹ rẹ gẹgẹ bi Minisita eto iroyin.
Buhari tún ti yan òkú sípò alàyè Wo àwọn tí yóò leè jáde l'Eko lọ́jọ́ ajé tó ń bọ̀ Wòlíì Arole ni ọpọ ni kò fẹ́ kọ́kọ́ tẹ́wọ́ gba mi nígbà tí mo bẹ̀rẹ̀, wọn ní èdè Yorùbá ni mo ń sọ àmọ́ nígbà tí kìí se àwọn ni Ọlọ́run, mo rí ọ̀nà àbáyọ."
A tun ri i kọ pe iku obi ọmọ ko ni ki ọmọ ma de ibi to fẹ de, eyi ko si yẹ ko jẹ awawi lati di ẹni pataki nile aye.
"- Ooni Ile Ife Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Kayeefi: 'Ọkọ mi ṣẹ̀ṣẹ̀ ní kí n lọ se mọ́í-mọ́í, tó ṣẹ̀ bá mi ṣeré tán ni mo gbọ́ pé ""Mopol"" yìnbọn pa á' N\\igbà tí a tún n pada bọ̀ ni ọ̀san, mó tun ri obìnrin yìí tó wọ asọ sója, ara fun mi pé wọ́n fẹ́ ṣe ǹkan, mo sọ fún ọmọ mi obinrin pe kó mú fóònù kó bẹ̀rẹ̀ sí ni ya àwòrán, Bẹ́ẹ̀ ni obìnrin yìí tún bẹ̀rẹ̀ sí ni lù mí gẹ́gẹ́ bi àwọran yìí ṣe fi han Lásìkò ti BBC Yoruba kan si ọkùnrin náà, ọgbẹ́ni Olumuyiwa Adedeji lówùrọ̀ òní, ó sàlàyé fún BBC pé ilé ìwòsàn ni òun wà lọ́wọ́lọ́wọ́ fún ìtọ́jú ara òun."
Nítorí Ọlọrun kò dáríjì àwọn angẹli tí ó ṣẹ̀ ẹ́, ṣugbọn ó jù wọ́n sinu ọ̀gbun tí ó ṣókùnkùn biribiri ní ọ̀run àpáàdì títí di ọjọ́ ìdájọ́.
Nítorí bí n kò bá lọ, Alátìlẹ́yìn tí mo wí kò ní wá sọ́dọ̀ yín.
Ọmọ Downsydrome ti mo bí ló fún mí láǹfàní láti de ilú Oyinbo Ìdí tí mi ò fi lègbà kí ẹnikẹ́ni fọwọ́ tẹ ara mi gẹ́gẹ́ bí olórin-Sola Allyson Ọlọ́pàá, adájọ́ àtàwọn aṣọ́bodè ló gba rìbá jùlọ ní Nàìjíríà-NBS Ìròyìn nípa ìyàwó túntún fún ọkọ mi kò mì mí lọ́kàn rárá-Aisha Buhari Ere bọọlu mọ Man City loju nigba ti Anthony Martial gba goolu keji sawọn Man City, lo ba ayo meji sodo ti wọn fi n siwaju wọn.
Ighodalo fẹ pasito ijọ Trinity House ni ọdun 2007, amọ ti ko si bimọ fun ọpọlọpọ ọdun ki o to di wi pe iroyin kan so wi pe , o gba awọn ọmọ meji tọ.
Àkókò dé láti pa àwọn tí ó ń ba ayé jẹ́ run.
Lara awọn dukia ijọba tawọn agbẹ naa bajẹ ni ọpọ ile ẹjọ ati ile ijọba, ti wọn si tun tu ọpọlọpọ ẹlẹwọn silẹ, to fi mọ awọn ọmọ ẹgbẹ wọn.
Àwọn ọmọ wọn á di alágbára,wọn á dàgbà ninu pápá,wọn á sì lọ, láìpadà wá sọ́dọ̀ àwọn òbí wọn mọ́.
"Bo tilẹ jẹ pe agbegbe kekeeke ni ikọ naa n dari bayii, amọ o si n ṣe ikọlu tako nkan ti Aarẹ Muhammadu Buhari n tẹnumọ pe, awọn ti ""sọ ikọ Boko Haram di alailagbara""."
"Wọn ti fi ọrọ na to ọga ileeṣẹ iṣiwa ati iṣilọ Naijiria leti, a si ti bẹrẹ iwadi lori rẹ.
Nigeria Debt: Gbèsè Nàíjíríà yóò pòórá, tí ìkọ̀ọ̀kan ọmọ Naijiria bá san ₦121,000
O ni awọn ati ẹgbẹ Miyetti Allah awọn fijilante ati ọlọde ni wọn gbarijọpọ koju awọn ọdaran nibẹ.
Gbogbo eeyan lo tẹwọgba iṣẹ Larisa tuntun, koda, ọmọ ọmọ rẹ ọkunrin lo n ṣe olootu Larisa ati aṣoju fun un.
Supplementary Elections: Ganduje ní ìbò 1,033,695, tí alátakò rẹ̀ sì ní 1,024,713.
4 901892 Orilẹede Hungary 11177 115.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Osteogenesis, aisan níní egungun tó rọ̀ ló ń ba Efia fínra Ọmọ ẹgbẹ oṣelu Democrat ni Bloomberg to fi di ọdun 2001, o darapọmọ ẹgbẹ Rupublican lọdun 2001.
O si wa lọwọ ileẹjọ lati sọ boya nini ibalopọ ninu ọkọnita gbangba jẹ iwa kotọ , paapa, taa ba wo wo ọkọ ti wọn lo jẹ dukia adani.
Abija ọmọ rẹ̀ sì jọba lẹ́yìn rẹ̀.
4 3055 Orilẹede Guinea Bissau 44 2.
ASUP so iṣẹ́ rọ̀ ni iléẹ̀kọ̀ gíga mẹ́ta l'Ọ́ṣun Àkọlé àwòrán, Iyanṣẹlodi awọn olukọ nileẹkọ giga yii n waye lẹyin bi ọsẹ kan lẹyin ti awọn olukọ nileẹkọṣẹ olukọni ni ilu Ileṣa naa ti gun le iyanṣẹlodi Ile ẹkọ giga mẹta nipinlẹ Ọṣun ni wọn ti gbe ti pa bayii nitori iyanṣẹlodi awọn olukọ nibẹ.
Ni ti ọrs Laycon ti apapọ owo ohun to jẹ gẹgẹ bi ẹbun jẹ miliọnu marundinlaadọrun naira, N85m o ṣeeṣe ki owo ori ti Laycon yoo san o maa fara pẹ miliọnu mẹjọ abọ naira.
Àwọn eniyan Israẹli sì ṣe bẹ́ẹ̀, àwọn mìíràn kó ju ohun tí ó yẹ kí wọ́n kó, àwọn mìíràn kò sì kó tó.
Nígbà tí àwọn eniyan bá ti mu ọtí yó tán, wọn á wá gbé ọtí èyí tí kò dára tóbẹ́ẹ̀ wá.
Gbogbo àwọn tí ń kọjá lọ ní ń kó o lẹ́rù;ó ti di ẹni ẹ̀gàn lọ́dọ̀ àwọn aládùúgbò rẹ̀.
Àwọn eniyan wá ń sọ ọ̀rọ̀ àfojúdi sí Ọlọrun nítorí ìparun tí yìnyín yìí ń fà, nítorí ó ń ṣe ọpọlọpọ ijamba.
Nígbà tí àwọn olódodo bá rí i, ẹ̀rù óo bà wọ́n,wọn óo fi rẹ́rìn-ín, wọn óo sì wí pé,
 Ipinle Kwara ati orile ede Naijiria yoo  maa se iranti re.
Awọn ileeṣẹ iroyin ati ajọ to jẹ tijọba ti n ṣe ọpọlọpọ ipolongo imọ toto.
Fi àwọn ọmọ Lefi fún Aaroni ati àwọn ọmọ rẹ̀.
Orukọ awọn marun un ti wọn jẹbi ẹsun ipaniyan naa ni Fabassou Etienne, Bitouala Ciriaque, Tchanga Chiengang Jean B, Donassou Gorvo Barnabas, Ntienche Feuroli Ghislain Landry.
Ajọ aṣeṣiro orilẹede Naijiria, NBS lo n pese awọn iroyin iwadi nipa ọrọ aje, ọrọ ilu ati abo kaakiri Naijiria, ṣugbọn agbẹnusọ wọn kan ṣalaye fun BBC pe, awọn ko ni iroyin to kuna lori iṣẹ Boko Haram.
Asiko yii lo to o mọ lọran, to si pe ọkọ rẹ, to si paṣẹ pe ki awakọ wọn o gbe e lọ sileewosan."
Tẹ iye owo ti o fẹ ẹ gba ( Eyi ko gbọdọ yatọ si iye ti o ti kọ tẹlẹ nigba ti o bẹrẹ igbesẹ naa lori ẹrọ ibanisọrọ rẹ).
Ìgbà tí ejò sì tún yí padà ó di èkúté, èkúté tún yi padà ó di òkété, òkété yípadà ó di ìgbín, ìgbín yípadà ó di ìjàpá,ìjàpá yípadà ó di òjòlá, òjòlá yípadà di kìnnìun, kìnnìún yí padà ó di àjànàkú, nígbà tí àjànàkú sì yí padà ó di obìnrin tí i ṣe ẹ̀gbọ́n ìyàwó bàbá mi.
Ṣugbọn ó ti tó ọgbọ̀n ọjọ́ sẹ́yìn tí ọba ti pè mí.
Lẹyin iku rẹ ni aya rẹ ọhun wọle opo ologoje ọjọ gẹgẹ bi ilana ẹsin Musulumiṣe gbe kalẹ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Collapsed Building: Ayálégbé ló dára bí ìjọba ṣe wólé àmọ́ wọ́n fẹ́ ìrànwọ́ ilé míràn Nigba to n salaye ohun ti oju awọn osisẹ ajọ amunawa ọhun ri lọwọ awọn ọdọ ọhun fawọn akọroyin, Osisẹ alarina fun ajọ IBEDC nipinlẹ Ọsun, Kikẹlọmọ Owoẹyẹ leri leka pe, inu okunkun lawọn ijọba ibilẹ naa yoo wa.
Aare egbe naa, Adams Oshiomhole lo soro yii ni asalẹ ọjọBọ nibi ipade awon adari egbe naa to waye ni ile-aarẹ, to wa niluu Abuja.
"Oyatomi ni, ""Ṣebi ki i kuku ṣe ẹgbẹ wa APC lo gbe ẹjọ yii lọ iwaju ile ẹjọ giga Abuja, eyi to ni Adeleke ko ni ẹtọ lati dije fun ipo gomina ni ibẹrẹ pẹpẹ."
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Buns ni ọmọ mi jẹ tán ní ṣọ́ọ̀ṣì, ló bá di àwátì' O ni awọn eeyan kan farapa ninu rogbodiyan naa, ti wọn si ti gbe wón lọ sile iwosan fun itọju ẹsẹ ti wọn ti gba ọgbẹ.
Rẹgi lọrọ yi ṣe losu kẹrin ọdun 2018 nigba ti awọn ọdọ Naijiria tutọ soke, foju gba lori bi wọn ti ṣe ni Ààrẹ Buhari sọ wípé àwọn ọ̀dọ́ Nàìjíríà kò fẹ ǹkan ṣe.
" Iya Tiamiyu Kazeem ti oṣiṣẹ ileeṣẹ SARS fa ṣababi iku rẹ nilu Sagamu ti sọ pe ogo ọjọ iwaju idile wọn ni ọmọ naa jẹ ko to di pe awọn ọlọpaa dẹmi rẹ legbodo.
Lẹ́yìn náà, Mose pa á, ó da ẹ̀jẹ̀ rẹ̀ sórí pẹpẹ yípo.
Àwọn kànga ìṣẹ̀ǹbáyé rèé ní Badagry tó ń pa ẹrú níyè Ambode, wá jẹ́jọ́ lórí ọkọ̀ BRT 5000 to ló fi ₦45b rà, àmọ́ 820 péré ló kó wá"" Buhari, pe ìpàdé àpérò ọmọ Nàíjíríà fún àgbékalẹ̀ òfin tuntun - Afe Babalola ‘Kò sí ohun tó lè yẹ ìfèhọnú ọjọ karun un Oṣu Kẹsan lórí àtìmọ́lé Omoyele Sowore’ Kọmiṣọna Ọlọpaa Asuquo Mba ni ilu Akurẹ ni Afurasi naa sa lọ lẹyin to ṣe iṣẹ laabi naa ti o si lọ fara sinko si inu ṣọọṣi kan."
Oríṣun àwòrán, Others Ki lo tun ti ṣẹlẹ lori idajọ Sharia ni Kano?
Fasiti Ọbafẹmi Awolowo University, Ọọni ile ifẹ takorawọn lórí ẹ̀sùn májèlé táwọn kan dà sómi iléèwé náà
Ọrẹ tirẹ̀ ni: àwo fadaka kan tí ìwọ̀n rẹ̀ jẹ́ aadoje (130) ṣekeli, abọ́ fadaka kan tí ìwọ̀n rẹ̀ jẹ́ aadọrin ṣekeli, ìwọ̀n tí wọn ń lò ní ibi mímọ́ ni wọ́n fi wọ̀n ọ́n.
Àwọn ọ̀rẹ́ olóògbèé, àwọn abánikẹ́dùn àti ọ̀pọ̀ àwọn olóṣèlú ló péjú síbi ìsìnkú náà.
 Bakan naa, ni a ti se ohun ti o to, lati fi oro naa to awon agbofinro leti.
Dokita sisẹ abẹ fun alaisan ti ko yẹ 'Ọkọ mi yọ kindinrin mi lati rọpo owo ori' Coronavirus ti di ara wa, kò le è kúrò mọ láéláé - WHO Àfi ìgbà tí mo bọ́ sọ́wọ́ ọ̀tá mí nínú ìrìnàjò ìfẹ́- Roshan Ile iṣẹ iroyin lorilẹ-ede naa pin aworan burọọsi naa lẹyin ti awọn dokita ṣe iṣẹ abẹ to yọ ohun ifọyin ọhun kuro ninu rẹ.
Isẹlẹ naa waye nigba ti awọn ọlọọpa n wa ọkọ kaakiri ni agbeegbe Anyibe titi to fi de ijọba ibilẹ Ayilamọ ni ipinlẹ Benue.
kora yin jọ,ẹ  o lee ran ọpọ eniyan ti
Wọn gbóríyìn fún mi, wọ́n wa ń wo èmi Alákọ̀wé gẹ́gẹ́ bí òrìṣà kan láàrin wọn.
Igba akọkọ ti idile wa pade rẹ ni ọdun mẹfa ṣeyin nigba to wa sile wa lati wa gbe ti mọle.
Àgbo tí mò ń lò láti jò kó bá mi, ìdí mi ti yọ́ tán - Nkechi Blessing figbe ta 7 Wo ìgbà tí Ààrẹ Buhari yóò ṣí 'bọ́dà' padà 8 Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Ẹ kúrò lọ́dọ̀ mi, ẹ̀yin oníṣẹ́ ibi wọnyi!
Lẹ́yìn ọdún mejilelọgọta lọ́nà meje yìí, wọn óo pa ẹni àmì òróró Ọlọrun kan láìṣẹ̀.
Ó sàn kí o má jẹ́ ẹ̀jẹ́ rárá ju pé kí o jẹ́ ẹ̀jẹ́ kí o má mú un ṣẹ lọ.
Isẹ Iroyin to ni Igbẹkẹle kikun Niwọn igba to jẹ pe akọmọna ileesẹ agbohunsafẹfẹ BBC ni otitọ, orukọ rere ati aisegbe sibikan, eyiti oju opo BBC Yoruba yoo jogun, se ọmọ kii ba ipele iya rẹ, ko si asọ da, ko si aniani pe eyi yoo fun awọn Yoruba to jẹ ololufẹ oju opo yii lanfaani lati tẹwọgba ilana isẹ iroyin to se ara ọtọ, to si da lori igbẹkẹle awọn araalu.
Atẹjade naa fikun pe osu Kẹsan to n bọ ni wọn yoo si eto irinna reluwe lati ilu Eko si Ibadan, ti ara yoo si tu awọn arinrinajo to fẹ lọ silu Ibadan lati Eko.
Òun ni akápò; a máa jí ninu owó tí wọn bá fi pamọ́.
Saaju ni iroyin kan ti ni awọn alakatakiti ẹsin ISWAP kọlu awọn ọmọ ogun ni Chad tẹlẹ.
Ẹ bẹ̀rẹ̀ sí bá a jagun, kí ẹ sì máa gba ilẹ̀ rẹ̀.
Mika sì mú un gẹ́gẹ́ bí ọmọ.
Gomina naa sọ pe ete naa ni lati rii daju pe awon eniyan  ri  ẹgbẹ APC bi ẹgbẹ  to tẹle eto iselu ijọba tiwantiwa ni awujọ nigba ti a ba fiwe awọn ẹgbẹ oselu
Ó bẹ̀rẹ̀ orin kíkọ ní ọdún 2014.
“Pàṣẹ fún àwọn ọmọ Israẹli kí wọ́n lé gbogbo àwọn adẹ́tẹ̀ kúrò ní ibùdó wọn, gbogbo àwọn tí ó ni ọyún lára ati ẹnikẹ́ni tí ó di aláìmọ́ nípa fífi ọwọ́ kan òkú.
Ṣugbọn oluranlọwọ fun Aarẹ Muhammadu Buhari lori ọrọ ile aṣofin, Ita Enang, sọ pe 'Aarẹ Buhari ko mọ nkankan nipa iṣẹlẹ naa.
Ẹni gbé epo lájà, bi kò bá ri ẹni gba a pamọ́, kò ni ya lára lati tún ji omiran.
Nítorí Ọlọrun kì í ṣe ojuṣaaju.
Ọkà oriṣiriṣi ló wà ṣùgbọ́n, Ọkà Àgbàdo àti Bàbà ni wọn mọ̀ jù lati fi ṣe Ògì funfun tàbi pupa.
Ṣugbọn nisinsinyii, ó ti kú, kí ni n óo tún máa gbààwẹ̀ sí?
Bí o bá ń bá ẹni tí ó pè ọ́ lẹ́jọ́ lọ sí kóòtù, gbìyànjú láti yanjú ọ̀rọ̀ náà pẹlu rẹ̀ bí ẹ ti ń lọ lọ́nà.
Lai dena pẹnu, awọn eeyan kan ni Magodo Estate ti n gbadun ina ọba fun bi ogun wakati lojumọ tori pe, wọn buwọlu adehun ti wọn pe orukọ rẹ ni Premium Power Deal, pẹlu ajọ amunawa yii.
Èèyàn 16 míràn tún ti ní àrùn Coronavirus ní Naijiria Ǹjẹ́ òògùn vitamin C lè pa coronavirus?
Erongba ofin yii ni lati ṣe iforukọsilẹ awọn oṣiṣẹ wọnyi ni ile kọkọkan ni Ipinlẹ Eko.
Bayii lọrọ ri abẹṣẹ ku bi ojo ọmọ Naijiria, Efe Ajagba to ni oun ṣetan lati fi ẹṣẹ din dodo iya fun ogbontarigi akẹṣẹ Anthony Joshua.
Bakan naa lo fi kun pe lọsan oni ni wọn yoo se afihan awsn afurasi to wa nidi isẹlẹ Akinyele naa ni olu ileesẹ ọlọpaa to wa ni Ẹlẹyẹle nilu Ibadan.
Ìdúró rẹ dàbí igi ọ̀pẹ,ọyàn rẹ ṣù bí ìdì èso àjàrà.
Yoruba ni bi a ba da ọjọ, ọjọ a pe, bi a ba da osu, osu a ko, bo pẹ titi, ogun ọdun n bọ wa ku ọla Bẹẹ ni ọrọ ri pẹlu igbẹjọ Wolii Alfa Babatunde, ti ijọ Sotitobire nilu Akure, ẹni to n koju ẹsun ijinigbe lati ọdun kan ati osu diẹ sẹyin.
Wọ́n ni ikú tí o yẹ ki ó pa Ojúayédùn ni ó pa a, Ojúayédùn tí ó jẹ́ pé òun lo le kí ènìyàn ju ẹnìkan lọ, tí ó ń dọ̀bálẹ̀ fún àti ọmọdé àti àgbà nínú àwọn tí kò sì sí nǹkan ti kìí fẹ́ ṣe láti fi wa ojú ènìyàn mọ́ra ko yẹ kí o hu irú ìwà tí o hù, ikú tí o yẹ Ojúayédùn ni Ojúayédùn kú.
Wole Soyinka rèé láti kékeré Ẹ̀bùn Ọlọ́run ni ọmọ bíbí ni mo ṣe bí ọmọ 17 Kíló burú nínú kí Sanwo-Olu fún Super Eagles lówó?
Ko si ẹni to fẹ ku Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Oríṣun àwòrán, Ojude Oba Facebook Idije ẹsin gigun, ibọn yinyin ati ijo jijo: Lara awọn ayẹyẹ to n mu ki ọdun Ojude Ọba jẹ manigbagbe nilẹ Ijẹbu ati nilẹ Yoruba lapapọ ni bi wọn trun se n se afihan ara asa wa lọna miran, eyi to nii se pẹlu ibọn yinyin, gigun ẹsin bii ọlọla ati sise idije ijo jijo laarin awọn ẹlẹgbẹjẹgbẹ lsna ti mọ ẹgbẹ to gbegba oroke.
Njẹ ajọsepọ awọn to kora jọ lati doju ija kọ ara wọn wọnyi, yoo jẹ ọlọjọ pipẹ tabi awọn naa yoo pada wa tutọ si ara wọn loju?
A nilo ifowosowopo  lati dekun iwa fayawọ yii ni.
O ni nigba ti wọn fipa ba a lopọ, nkan ri bakan bakan fun un titi tọmọ rẹ ko ṣe lọ ileewe mọ torii idẹyẹsi ladugbo.
Iko agbaboolu Russia sa gbogbo ipa won lati da ami-ayo ohun pada, sugbon omi poju oka lo.
" Irú àìsàn wo ló ń ṣe Aisha Buhari tó fi fò lọ sí Dubai fún ìtọ́jú?
Oríṣun àwòrán, Oyo State Government Eyi naa ni ofin eto idibo faramọ."
O fi eyi ṣalaye bo ṣe bẹrẹ ere Tiata.
Oyin lé àwọn ènìyàn kúrò l'ábúlé kan ní Plateau Tani DCP Kayọde Ẹgbẹdokun, ọ̀gá ọlọ́pàá tuntun ní ìpínlẹ̀ Eko?
“Kọ́ àgọ́ ìpàdé ní ọjọ́ kinni oṣù kinni.
Ní ọ̀jọ̀ keje oṣù keje ọdún 1998 tí ó yẹ ki Abiola jáde kúrò lẹ́wọn ni òkìkí ikú rẹ̀ kan, èyí tún fa ìfẹhonu hàn míràn.
Ti ẹ ba wo aworan yii lakọkọ, ẹ maa ro pe ọwọ nla kan fẹ ji arakunrin naa gbe ni.
Klopp ni ikanra ni Man United yoo gbe wa lẹyin ti Valencia fẹyin wọn gbolẹ ninu idije Champions League laarin ọṣẹ to kọja.
Elliot gboriyin fun Abẹnugan Ile Igbimọ Aṣofin to bu ẹnu atẹ lu ifiyajẹni to waye ni Lekki Toll gate.
Alaga ajo eleto idibo lorile-ede Sierra Leone Mohameed Conteh fi n da awon omo orile-ede Sierra Leone loju pe, gbogbo eto ti to lati daabobo ibo ti won di yan eni tokan won fe, bakan naa ni o so pe, awon esi ibo miiran lati awon agbegbe yoku yoo jade laipe.
Ṣugbọn Odunbaku sọ fun BBC pe ko si otitọ ninu iroyin naa.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, JAMB 2019: A ó fagi lé ìdànwò ẹni tó bá ṣe aṣemáṣe Lara awọn to lo si ilu Eko fun adura lọdọ pasitọ T.
Ẹmi marun sọnu ninu ija Kaduna O ni ohun to ba ijọba lọkan jẹ pupọ ninu wahala ọhun to waye ni pe ayederu iroyin kan to tan kaakiri gbogbo agbegbe ti iṣẹlẹ naa ti waye, ni awọn janduku lo anfaani rẹ lati ṣe iṣẹ ibi.
 Ṣùgbọ ́ n , tí ọ ̀ rọ ̀ -ìṣe bá ju ọ ̀ kan , tàbí tí àpólà-ìṣe bá ní fọ ́ nrán tí ó ju ọ ̀ kan lọ , a lè ṣe ìyísódì fọ ́ nrán ìhun tàbí ti odidi gbólóhùn .
 Àwọn ìgbésẹ ̀ ìdàpapọ ̀ ṣiṣẹ ́ míràn , ìdáàbòbò alcohol pẹ ̀ lú methyl orthoformate àti boron trifluoride ) àti ìmúkù ketone pẹ ̀ lú sodium borohydride ṣe ìmújáde èyí tí a lè ṣètò monosaccharides lati inú rẹ ̀ .
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Africa Eye: Olùkọ́ méjì ní fásitì Eko àti Ghana lùgbàdì ọ̀fíntótó BBC lórí ìwà ìbàjẹ́ 5.
Èrè yín ni ọkà ìlú Sihori,ìkórè etí odò Naili.
Nítorí ẹ mọ oore-ọ̀fẹ́ Oluwa wa Jesu Kristi, pé nítorí tiwa, òun tí ó jẹ́ ọlọ́rọ̀ di aláìní, kí ẹ lè di ọlọ́rọ̀ nípa àìní tirẹ̀.
06 yoo wa lati apo ijoba apapo, nigba ti bilionu ogbon N30 yoo wa wa lati owo ti ijoba n gba wole, eyi ti o je iko adota  50 ninu ida ogorun, bakan naa ni bilionu mejo N8 yoo wa lati owo Paris ati London clubs“The recurrent revenue for the 2018 fiscal year of N89 billion, is higher than that of 2017, which stood at N71.
 Òbítíbitì àwọn ènìyàn tí n ṣí lọ láti ibikan sí òmíràn tún mú àwọn agbègbè tí àrùn chagas náà ti n ṣe ọṣẹ ́ fẹ ̀ sì i , tí ilẹ ́ gẹẹ ̀ ́ sì àti ilẹ ̀ amẹrika sìn bẹ lára wọn pẹ ̀ lú .
Loṣu Kẹfa ọdun 2014 ni ọfisi Amerika ni Naijiria kede pe awọn ti bẹrẹ eto ilana fifi iwe irina ranṣẹ ninu apo iwe fawọn ti iwe irina wọn ko ba ti jọba fun igba to ju ọdun meji lọ.
Osusan Oluwatobi tricycle accident: 'Ìgbà tí mo máa fi lajú sáyé padà, ọ̀fọ̀ ikú mi ní wọ́n ń kígbe'
Iwoyi esi naa ni awọn oṣiṣẹ ajọ DSS mu Ọgbẹni Ọlawale Bakare ti wọn si gbe oun ati Ọmọyẹle Ṣoworẹ lọ sile ẹjọ nigba naa.
Oríṣun àwòrán, @NCDCgov Pẹlu bi aarẹ ti ṣe ni ki igbimọ yi tẹsiwaju iṣẹ wọn, o tun ni ki awọn ọmọ Naijiria maa ṣe jafira ki wọn si daabo bo ara wọn paapa lasiko ọdun to de yi.
Àwọn ará Rama ati Geba jẹ́ ẹgbẹta lé mọkanlelogun (621).
idibo ni ipinlẹ ni o wa ni isakoso idibo ni awọn ijọba ibilẹ.
” Wọ́n dá a lóhùn pé, “Harani ni.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Hungary lè di àlá làsàn fún Pẹlumi tí kò bá rì N1 mílíọ́nù láti kòpa nínú ìdíje Olympiad ní orílẹ̀èdè náà Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Hungary lè di àlá làsàn fún Pẹlumi tí kò bá rì N1 mílíọ́nù láti kòpa nínú ìdíje Olympiad ní orílẹ̀èdè náà 17 Èbibi 2019 Ṣe bi iṣu ma ta ninu ebe, ẹrin a pa ẹẹkẹ oloko ni.
Àkọlé àwòrán, Awọn eeyan Kogi ati Bayelsa ṣetan lati yan Gomina ti yoo tukọ wọn di 2023.
Adari iko omo ogun owo keji yii wa salaye pe, ni igba kan ri ni ko si
2 53 MS Zaandam cruise ship 2 9 Bhutan 1 0.
Akọwe ijọba sọ awọn idi to mu ki ijọba o gbe igbesẹ naa.
bámijì Òjó gẹ ́ gẹ ́ bí ẹnìkan tí ó ní ìtara ọkàn.
O ni oun pinnu lati gba iṣẹ naa lọwọ rẹ nitori ẹsun ati awuyewuye to n waye lori rẹ, lati ọdọ awọn ọmọ orilẹ-ede Naijiria, ati awujọ agbaye.
) Victor Adesimbo Kiladejo, Jilo III gba ọpa aṣẹ ni ọdun 2006.
Akọwe agba ati alukoro ẹgbẹ oṣelu PDP, Kola Ologbondiyan to ba BBC Yoruba sọrọ ṣalaye pe aimọ eyi to kan lo jẹ ki ijọba gbe igbesẹ naa.
Awọn kan ro pe fifi emi eniyan se irubọ je aṣa.
Adebisi ni ijọba ti ṣetan lati wa ojutuu si ija ojoojumọ lori ọrọ iaylọja ati babalọja ni Ibadan lasiko yii ati pe ẹnikẹni ko gbọdọ pe ara rẹ bẹẹ titi ijọba Seyi Makinde a fi gbe igbesẹ to yẹ.
Auxiliary gbé èèyàn mẹ́fà tó ń jáwèé ayédèrú fáwọn awakọ̀ lọ sí ilèẹjọ́ ní Ibadan Kí ló le è mú kí agbábọ́ọ̀lù subú, kó sì kú lásìkò ìfẹsẹ̀wọ̀nsẹ̀?
“Ẹ ranti àṣẹ tí Mose, iranṣẹ OLUWA, pa fun yín pé, ‘OLUWA Ọlọrun yín ń pèsè ibi ìsinmi fun yín, yóo sì fi ilẹ̀ yìí fun yín.
Ewe, Raheem Sterling gba ami-ayo meji wole, ami-ayo Sergio Aguero ni o so di agbaboolu kesan an ti yoo ni àádọ́jọ ami-ayo ninu idije EPL.
Ile iwe alakọbẹrẹ Saint Michael ni Epe ni Eniola ti bẹrẹ iwe kika.
A fi agbára fún ọ̀já mọ́nú,a sì tẹpá mọ́ṣẹ́.
E̩nì kò̩ò̩kan ló ní è̩tó̩ láti rìn káàkiri ní òmìnira kí ó sì fi ibi tó bá wù ú s̩e ìbùgbé láàrin orílè̩‐èdè rè̩.
Lẹ́yìn náà ni àwọn ọmọ Lefi wọnyi: Jeṣua, Kadimieli, Bani, Haṣabineya, Ṣerebaya, Hodaya, Ṣebanaya ati Petahaya, pè wọ́n pé, “Ẹ dìde dúró kí ẹ sì yin OLUWA Ọlọrun yín lae ati laelae.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Olórin, Small Doctor, gba ìtúsílẹ̀ nínú àhámọ́ 3 Ọ̀pẹ̀̀ 2018 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 4 Ọ̀pẹ̀̀ 2018 Oríṣun àwòrán, Small doctor Gbajugbaja olorin Adekunle Temitọpẹ ti gbogbo eniyan mọ si Small Doctor to tun jẹ aṣoju olorin fun ileeṣẹ ọlọpaa ti gba itusilẹ bayii.
5 Àti pé wọn yíò jade lọ, ẹnikẹ́ni kì yíò sì dá wọn dúró, nítorí èmi Olúwa ti pàṣẹ fún wọn.
Wọn ti n gbee kaakiri awọn ile iworan sinima ni Naijiria.
Adé orí ọ̀kín kò lè ṣe déédé orí ẹyẹkẹ́yẹ Àgbàdo inú ìgò, ó di àwòmọ́jú fún adìyẹ Pẹ́pẹ́yẹ ńlérí lásán ni, kò ní kọ A kì í dàgbà jù fún ohun tí a kò bá mọ̀ Kíkéré l'abẹ́rẹ́ kéré, kì í ṣe mímì fún adìyẹ Ó di ìgbà tí òjò bá dá kí alágborùn tó mọ̀ pé ẹrù lòún gbé Dídákẹ́ lerín dákẹ́ àjànàkú ló lẹgàn Adẹ́tẹ̀ ò lè fún wàrà ṣùgbọ́n ó lè da wàrà nù Àdánìkànrìn ejò ló ńjẹ ọmọ ejò níyà Tí ẹja bá sùn ẹja á fi ẹja jẹ.
Nígbà tí ọbabinrin ìlú Ṣeba gbọ́ nípa òkìkí Solomoni, ó wá sí Jerusalẹmu láti wá dán an wò pẹlu àwọn ìbéèrè tó le.
Kò pẹ́ tí wọ́n pa á tán tí àwọn ẹnìkan dé tí wọ́n mú wọn lọ.
Wọ́n pé ọdún méjìlá báyìí Nibẹ naa ni awọn obinrin kan ti wọn ṣẹṣẹ bi ọmọ naa n sun ita yii kan naa.
Oríṣun àwòrán, Others O ṣiṣẹ gẹgẹ bi olootu iroyin nileeṣẹ New Africa Holdings Limited nilu Kaduna.
"Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Coronavirus in Nigeria: Ẹ wo bí ẹ ṣe lè ṣe ""hand sanitizer"" nínú ilé yín 7."
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù UK students Phone ban: A fẹ́ bẹ̀rẹ̀ òfin má lo fóònù mọ́ fàwọn ọmọ wa -Òbí 2 Owewe 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ẹ dẹ́kun lílo èrò ibanisọrọ lasiko yii A fẹ ki ẹ fi ofin de ki awọn akẹkọọ maa lo ẹrọ ibanisọrọ - Obi ni UK Iṣẹ iwadii kan ti wọn ṣe ni United Kingdom lo fi erongba awọn obi ati alagbatọ hande lori ki awọn ọmọ maa lo ẹro ibanisọrọ nile iwe.
Yatọ si pali ti yoo lọ gba, o gbọdọ ni iwe aṣẹ lati le wọ inu ilẹ bẹẹ eleyi ti oloyinbo n pe ni Visa.
Oríṣun àwòrán, Instagram/Abiola Ajimobi Àkọlé àwòrán, Ọ̀pọ̀lọpọ̀ awuyewuye ló tí súyọ lẹ́yìn tí ẹgbẹ́ òṣèlú APC kéde Abiola Ajimobi gẹ́gẹ́bí igbákejì alága APC.
Ní ti òdodo nípa iṣẹ́ Òfin, n kò kùnà níbìkan.
“eyi wa lara atileyin ti ile ijosin n gba lati mu igberu ba ere-idaraya ni Naijiria.
O sọ pe ajọ naa ti kọkọ fun awọn aadọjọ ileeṣẹ aladani ati ti ijọba ni iwe aṣẹ lati ma a fi orukọ awọn eeyan silẹ.
Amọ, Ọga ọlọpaa ni ko si otitọ kankan ninu ẹsun ti wọn fi kan wọn naa.
Bakan naa ni ẹgbẹ YCE rọ Aarẹ Muhammadu Buhari pe ko ma ṣe gbọ ohun tawọn kan n sọ fun un lori ọrọ Osinbajo wi pe ko ranti bi Osinbajo ṣe duro ti i lati igba ti wọn ti jọ bẹrẹ.
Njẹ́ jíjẹ́ aláwọ̀ dúdú le gbà ọ́ sílẹ̀ lọ́wọ́ ààrùn Coronavirus?
Ipade ẹlẹẹkẹtadinlọgọta iru rẹ lo n lọ lọwọ.
86 ni osu kinni odun 2018Bakan naa ni iroyin ohun safihan awon ipinle ti won san owon gogo lori owo oko laarin ilu, bi: Abuja(N380) Cross River (N303.
Ìdí tí gbólóhùn yìí fi ṣe pàtàkì ni pé ó jẹ́ nkan tí àwọn onígẹ̀ẹ́sì npè ní “Pangram”.
Eostre ni òrìṣà nkan tuntun, ìgbà tuntun, bí ọmọ bíbí.
Wọ́n ṣolóòótọ́ ní kíkó àwọn ẹ̀bùn, ati ìdámẹ́wàá àwọn ohun ìyàsọ́tọ̀ náà pamọ́.
Wọ́n sì pada wá ròyìn fún ọba.
Ọ̀pọ̀ ń wá ojurere olórí,ṣugbọn OLUWA níí dáni ní ẹjọ́ òdodo.
N kò ní tíì lé wọn jáde fún ọdún kan, kí ilẹ̀ náà má baà di aṣálẹ̀, kí àwọn ẹranko sì pọ̀ tóbẹ́ẹ̀ tí wọn yóo gba gbogbo ilẹ̀ náà mọ́ yín lọ́wọ́.
Won fi esun kan an pe o  se agbodegba fun  ejo ti won fi kan “Cashgate”.
Lẹyin ikopa rẹ ninu ipaniyan yii Mukankuranga to jẹ ẹya Hutus pada sile lọdọ awọn ọmọ rẹ meje pẹlu irobinujẹ ọkan, tí ọkan rẹ ba tun lọ si bi iṣẹlẹ naa ṣe waye, oun jẹ lọkan gidi.
Àwọn ará Dani gbé ère dídà náà kalẹ̀ fún ara wọn.
MKO Abiola, iṣẹ́ aṣẹ́gità ló fi bẹ̀rẹ̀ okoòwò Iṣọla Oyenusi rèé, ẹnití ìfẹ́ obìnrin ṣun dé ìwà ìdigunjalè Taiwo Akinkunmi, ọmọ Ibadan tó ya àsìá Naijiria Ayinla Ọmọwura, orin èébú àti oríyìn lo fi di ọ̀rẹ́ àwọ̀n obìnrin Bakan naa ni BBC Yoruba, lasiko ọdun ibeji tọdun yii nilu Igboọra, tun ka bi ayẹyẹ manigbagbe naa se lọ, o ya, ẹ fun oju lounjẹ ninu fidio alarinrin yii.
’ Ibi tí a ti ń sọ èyí ni ẹnìkan ti ti òde wọlé tí ó ní òun ń bá ọba kẹ́dùn ó ni, ‘Kábíyèsí ẹ kò lọ túbọ̀ múra?
O si ṣeeṣe ko ṣoro fun obinrin to ba si ti ni ṣaaju igbeyawo lati ri ọkọ fẹ.
“Ẹ kò gbọdọ̀ pa baba dípò ọmọ rẹ̀, bẹ́ẹ̀ sì ni ẹ kò gbọdọ̀ pa ọmọ dípò baba, olukuluku ni yóo kú fún ẹ̀ṣẹ̀ tí ó bá dá.
Idi ti awọn onimọ maa fi n ṣe ato irinajo ẹni to ba ni arun yii ni lati mọ ibi ti wọn lee wa awọn to lee ti koo lati ara wọn si.
Idahun si ibeere naa wa lọwọ iwọ ati emi.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ni ọjọ kẹrindinlogun osu Kọkanla ọdun 2001 ni awọn ọmọge kan dije fun idije omidan to dara julọ lagbaye, eyi to waye lorilẹede South Africa, ti ọmọge kan lati Naijiria, Agbani Darego si moke.
Ẹgbẹ agbabọọlu rẹ Cardiff gba ifẹsẹwọnsẹ wọn akọkọ lati igba ti baalu Sala ti poora ni ọjọ Abamẹta.
lori ekunwo owo osu awon osise.
Fèrèsé yí inú ati ìloro rẹ̀ ká, bíi àwọn fèrèsé ti àwọn ẹnu ọ̀nà yòókù.
Ó gbẹ́ kòtò,ó sì jìn sinu kòtò tí ó gbẹ́.
Arsenal f'agba han Watford Cazorla dágbére fún Arsenal EPL: Swansea f'agba han Arsenal Ohun ẹ rí ẹ wí.
Oríṣun àwòrán, @officialEFCC Àkọlé àwòrán, Magu fi ìdí rẹ̀ múlẹ̀ pé olú iléeṣẹ́ tuntun nàá kò le gba gbogbo àwọn òṣìṣẹ́ àjọ nàá tó wà ní ìlú Abuja.
Alfa Babatunde Sotitobire lo mn jẹjọ pẹlu awọn mẹfa mii lori ẹsun igbimpọ lati ji ọmọ ọdun kan, Gold Kolawole gbe lọdun 2019.
Labiyi ni ipa gboogi ti Maiyegunyoo ko ni lati ri wi alaafia to niye gbinlẹ ni ilẹ Yoruba.
Inu wọn dun pẹ ala yi di mumuse.
Adura rẹ̀ sí Ọlọrun, ati bí Ọlọrun ṣe dá a lóhùn, àwọn ẹ̀ṣẹ̀ ati aiṣododo rẹ̀, wà ninu ìwé Ìtàn Àwọn Aríran.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Akomolede Yoruba: Kí ni ìdí tí aṣọ fi máa ń pọ̀ lára Egúngún ju Orò lọ́?
Ẹwẹ, Dogara ti ni oun yoo ba awọn oniroyin sọrọ laipẹ ọjọ.
Nítorí náà oró ejò kò tu irun kan lárá wa ṣùgbọ́n kì í ṣe gbogbo àwọn ènìyàn tí ó jáde ní ààfin ló mu oògùn yìí nítorí nígbà tí á ń mu ún a kò rí àwọn mẹ́fà kan báyìí, ígbà tí ìjà náà sì gbóná, márùn-ún kú nínú wọn.
Hesekaya pàṣẹ pé kí wọ́n rú ẹbọ sísun lórí pẹpẹ.
ẹnìkọ̀ọ̀kan wọn máa ń mú ẹ̀bùn wá fún un lọdọọdun, àwọn ẹ̀bùn bíi: ohun èlò fadaka, ati ti wúrà, aṣọ, ohun ìjà ogun, turari, ẹṣin, ati kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù #BBCOGUNDEBATE: O ṣe pataki láti yan àwọn akanda ẹda si ipò kọmisọna.
Àwọn amí tí ọba Benhadadi rán jáde lọ ròyìn fún un pé, àwọn eniyan kan ń jáde bọ̀ láti ìlú Samaria.
”Bakan naa, alakoso oludari awon ifsewonse ajo CAF, Eddy Maillet fi idunu re han fun ifilole sise amulo ero igabalode naa nile Afrika.
BBC Yoruba rin kaakiri ilu Ibadan olu ilu ipinlẹ Ọyọ lati ṣe amojuto awọn ayipada to rọ mọ alekun naa.
Ǹjẹ́ nisinsinyii, Oluwa, ṣe akiyesi bí wọ́n ti ń halẹ̀, kí o sì fún àwọn iranṣẹ rẹ ní ìgboyà ní gbogbo ọ̀nà láti lè sọ ọ̀rọ̀ rẹ.
''Bakan naa ni ida aadọrin awọn eniyan to ni arun Coronavirus ni Naijiria ni ko fi ami han lara wọn, ti ko si ṣe wọn ni ijamba.
Akojọpọ ero awọn oludibo lorileede Amẹrika jẹ ọna kan gbogi lati fi mọ bi awọn oludibo ba ti ṣe gba ti oludje kọọkan si.
Azeez Saka: Lọ́dun 2017, okiki irú èyi náà tún kan nígbà ti ọmọ akọnimọọgba bọọlu ori tabili Kasali Lasisi ku.
Ní àkókò ìjọba Atasasesi, ọba Pasia, ni àwọn wọnyi dìde: Biṣilamu, Mitiredati, Tabeeli ati àwọn ẹlẹgbẹ́ wọn yòókù.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Muhammadu Buhari: PDP ṣàlàyé àwọn ẹ̀ṣẹ̀ ààrẹ bó ṣe ń ṣàjọyọ̀ ọ̀jọ́ ìbí 17 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Oríṣun àwòrán, Facebook/Femi Adesina Ẹgbẹ oselu PDP ti fi ọrọ iyanju ransẹ si aarẹ Muhammadu Buhari ni ayajọ ọjọ ibi ọdun kejidinlọgọrin to ko l'Ọjọbọ.
Collins Akano jẹ́ onímọ̀ nípa oúnjẹ tó ṣara lóore, ó sì sàlàyé pé ẹmu ni àǹfàní fitamin A fitamin B ati C Ó sàlàyé pé àwọn èròjà yìí maa n ìgbòkè gbodò ara ka dáradára.
Ní àbáwọ ọ̀nà yìí atọ́ka míràn wà tí ó tún júwèé ilé oúnjẹ arúgbo ẹ̀ẹ̀kan.
Mosa bí Binea; Binea bí Rafa, Rafa bí Eleasa, Eleasa sì bí Aseli.
Ninu alaye ti alukoro awọn akẹkọọ fasiti ilu Ibadan, Oladeji Olawunmi Abiodun ṣe fun BBC, o ni onitiju akẹkọọ ti ko ni wahala ni Richard Gbadebo jẹ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù RUGA: Ààrẹ àná, Goodluck Jonathan ní kí Buhari máà fi ọ̀rọ̀ RUGA kọ́ òun lọ́rùn 3 Agẹmo 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Gomina Lalong tipinlẹ̀ Plateau lo ṣalaye fawọn oniroyin pe lasiko iṣejọba Jonathan ni ọrọ itẹdo darandaran, RUGA ti kọkọ bẹrẹ Emi ko mọ nipa Ruga o - Goodluck Jonathan Aarẹ ana, Goodluck Jonathan ti kọminu lori ọrọ kan ti gomina ipinlẹ Plateau sọ pe lasiko iṣejọba Jonathan ni wọn ti ṣeto itẹdo darandaran RUGA silẹ kaakiri orilẹ-ede Naijiria.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Herdmen-Farmers Clash: Fatai Owoseni ní àwọn ọlọ́lá ló jẹ́ baba ìsàlẹ̀ fáwọn agbégbọn darandaran 15 Sẹ́rẹ́ 2021 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 16 Sẹ́rẹ́ 2021 Oríṣun àwòrán, Getty Images Yoruba ni ẹyinkule ni ọta wa, inu ile lawọn aseni n gbe, bẹẹ si ni bi ko ba si ole ile, ti ita ko le wa ja.
Party of Nigeria,ti o yọ ara rẹ kuro lati satleyin fun aare Buhari.
Àwọn Òṣèlú Òkè-Òkun nfi owó Nigeria tọ́jú ará ilú wọn nitori eyi, gbogbo ọ̀dọ́ Nigeria ti kò ni iṣẹ́ fẹ́ lọ si Òkè-Òkun ni ọ̀nà kọnà.
OLUWA, Ọlọrun mi, mo ké pè ọ́,o sì wò mí sàn.
Marz so pe, igberu ti n ba ipate ita gbangba eto ogbin ti o n waye ni ipinle Eko naa, toripe, alekun ti n ba awon olukopa ninu ipate naa lati bi ipago merin si mewaa bayii.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù EFCC: A ó ri dájú pé Diezani padà wálé láti jẹ́jọ́ ìwa jẹgúdújẹrá 20 Sẹ́rẹ́ 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 22 Sẹ́rẹ́ 2020 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ajọ tó ń gbogun ti ìwà jẹgúdújẹrá, EFCC ti ní minisita fún epo bẹntirolu, Diezani Allison-Madueke ni ilè òkèèrè ń dá àbòbò.
ipolongo ohun, ni eyi ti won wa lati ijoba ibile metalelogun lati yẹ awon ti
Lórí ìfọ̀rọ̀wérọ to wáye níle iṣẹ́ BBC News Yoruba lonii pẹlú Abass Akande loti sàlaye oníruuru nipa àra rẹ àti iṣẹ́ orin to yàn láàyò.
Pẹlu gbogbo idunkooko mọ ọ yii, Kudirat Abiola tẹsiwaju pẹlu ipolongo lorukọ ọkọ rẹ.
Wọn ni ko bojumu ki ara ilu ma padanu iṣẹ lasiko yii ti ati ri iṣẹ jẹ ipenija nla.
Mo sì ti sọ fún àwọn iranṣẹ mi pé kí wọ́n pàdé mi ní ibìkan.
Ẹsun kẹrin lo nii ṣe pẹlu bi olori ile asofin nipinlẹ Eko naa ṣe buwọlu ọgọrin miliọnu naira fun awọn iyawo awọn asofin ogún lati lọ ṣe idanilẹkọọ nilu Dubai.
Mustapha ni, o ti de etigbọ ijọba pe awọn olori ileesẹ ijọba kan kọ lati mu asẹ yi sẹ.
Haram  ati awon ọdẹ to n pese eto aabo
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Onímọ̀ ọrọ̀ ajé: Àfíkún ìsúná táwọn asòfin se b‘ófin mu Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Isẹ́ bọ́ lọ́wọ́ Ọ̀jọ̀gbọ́n tó fẹ́ bá akẹ́kọ̀ọ́ lò pọ̀ Ọ̀mùtí ọmọ Nàìjíríà kábàmọ̀ ní Russia Ìpèsè ayélujára dúró nítorí ìdánwò akẹ́kọ̀ọ́ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Lórí ìgbéyàwó mi, ẹ̀ ṣáà jẹ́ kó wà báyìí' Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Dafidi gba àwọn apata wúrà tí àwọn ọ̀gágun Hadadeseri fi ń jagun, ó sì kó wọn wá sí Jerusalẹmu.
World Cup ti o waye lorile-ede Russia, lodun ti o koja.
Oríṣun àwòrán, Reuters Eyi ni awọn igba igba miiran tawọn musulumi ko lanfaani lati ṣiṣẹ Hajj: 1) Okuta dena iṣẹ Hajj ni eyi ti ko si Hajj fun odindin ogun ọdun Lara awọn igba tawọn musulumi ko le ṣiṣẹ Hajj lo ṣẹlẹ 930, A.
Igbakeji minisita eto ilera, Li Bin ṣalaye pe ijọba n ṣiṣẹ takuntakun lori idena aarun naa lati ma le ran sii mọ.
Kí alufaa pè é ní aláìmọ́; àrùn ẹ̀tẹ̀ ni.
Busola Dakolo: Ìdájọ́ ilé ẹjọ́ yàtò sí ǹkán tó sẹ̀lẹ̀ ní
Sọ pé, mo ní ninu gbogbo ibi tí mo ti ń bá àwọn ọmọ Israẹli lọ káàkiri, ǹjẹ́ mo tíì yanu bèèrè lọ́wọ́ onídàájọ́ kankan, lára àwọn tí mo pàṣẹ fún láti máa darí àwọn eniyan mi, pé kí wọ́n kọ́ ilé kedari fún mi?
Ninu ilẹ̀ gbígbẹ, ninu aṣálẹ̀ ni ó wà,ninu ilẹ̀ iyọ̀ tí ẹnikẹ́ni kò lè gbé.
Ewu ti àròkàn lè fà ni: ẹ̀fọ́rí igbà gbogbo, aisan wẹ́rẹ-wẹ̀rẹ, aisan ẹ̀jẹ̀ riru, òyi àti àárẹ̀.
Àwọn agbébọn jí ìyàwó bàbá Sẹ́nétọ̀ Abbo tó lu obìnrin nílùú Abuja gbé ní Adamawa
Nígbà tí ó ṣaláìsí, wọ́n sin ín sí Gileadi, ìlú rẹ̀.
oludari ohun wa ro ijoba orile-ede Togo lati fi ese Alafia mule sinsin laarin
Sugbọn ni ti Egypt to jẹ pe ọpọ omi amọlolo ti wọn n o, odo Nile ni wọn ti n ri i, wọn n poruru ọkan pe igbesẹ naa yoo mu wahala ba ipese omi fun orilẹ-ede ti wọn.
yii ni pe ko ni kuro loju  ilana aseyọri.
Nibi apejẹ naa ti o ṣe pẹlu awọn akẹgbẹ rẹ ti wọn jijọ kawe gboye ni ile iwe fasiti ilu Eko laarin ọdun 1998/2000,iroyin kan pe Sanwoolu ṣeleri pe oun yoo mu opin ba sunkẹrẹ fakẹrẹ Apapa laarin ọgọta ọjọ.
Awon oludari eka ajo naa ti won da duro lenu ise ni ,adari  eto inawo ati iwe isiro, , Akinbola Hakeem Gbolahan, adele fun adari eka  fun ise akanse, ogbeni Umesi Emenike;adari fun eka to n ri si isele pajawiri ,Mallam Alhassan Nuhu; adari awako isele pajawiri  ofurufu ,ogbeni Mamman Ali Ibrahim, oludari eka to n mojuto  irinse, ogbeni Ganiyu Yunusa Deji; ati oludari eka to mojuto eto iranwo , ogbeni Kanar Mohammed.
Wọn yóo fà yín lọ siwaju àwọn ọba ati àwọn gomina nítorí orúkọ mi.
Nítorí iṣẹ́ burúkú àwọn tí wọn ń gbé inú rẹ̀,àwọn ẹranko ati àwọn ẹyẹ ṣègbé,nítorí àwọn eniyan ń wí pé,“Kò ní rí ohun tí yóo ṣẹlẹ̀ sí wa.
Ẹẹkẹta nìyí tí n óo wá sọ́dọ̀ yín.
Ọ̀rọ̀ fún Àwọn Ọkọ ati Aya.
NEMA, NHISA ní ó ṣeéṣe kí ẹ̀kun omi wáyé ní ìpínlẹ̀ méjìlá
Ni Alhaji ọrẹ rẹ naa ba fẹ sare ran an lọwọ ni oun naa ba ko si kọnga.
Ẹ súnmọ́ ibí, kí ẹ wá gbọ́, ẹ̀yin orílẹ̀-èdè,ẹ tẹ́tí sílẹ̀, gbogbo ẹ̀yin eniyan.
Eko, ko si ẹni to jiyan eyi.
Pedaaya bí ọmọ meji: Serubabeli, ati Ṣimei.
Bashir, wa so pe awon ile okeere
OLUWA ní,“Nígbà tí Israẹli wà ní ọmọde, mo fẹ́ràn rẹ̀,láti ilẹ̀ Ijipti ni mo sì ti pe ọmọ mi jáde.
Mo kórìíra wọn dé òpin;ọ̀tá ni mo kà wọ́n kún.
O ṣalaye pe Anabi Mohammed (SAW) so pé: ki a fi ọrọ naa jiṣẹ lati ọdọ ẹnikan si ikeji ni.
 pàápàá ní ìlú ilésà gangan , bẹ ́ pẹ ̀ lú ní àwọn oyè míràn tún wà ní ààrín àdúgbò .
Chamisa so pe, ipade pata ki yoo waye lati wa ona abayo si ipo egbe oselu naa wa laipe.
Plateau-27 Kaduna-17 Ogun-6 FCT-4 Anambra-1 Ekiti-1 Nasarawa-1 Apapọ awọn to ti ni aarun naa jẹ 56,478 44,430 ti gba iwosan Awọn to ti ku si jẹ 1,088 Àjọ NCDC tún kéde èèyàn 132 tó ṣẹ̀ṣẹ̀ ní coronavirus lọjọ Aje ní Nàìjíríà Awọn to ni aarun coronavirus ni Naijiria tun ti le si bayii, lẹyin ti ajọ NCDC tun kede esi eeyan mejilelaadoje to tun ṣẹṣẹ ni, lọjọ Aje.
bí àwọn ọkunrin mẹta náà bá tilẹ̀ wà níbẹ̀, bí èmi OLUWA ti wà láàyè, wọn kò ní lè gba ọmọkunrin tabi ọmọbinrin wọn là.
Ó ní, bóyá ó fẹ́ kí òun sọ ẹ̀dùn ọkàn rẹ̀ fún ọba ni tabi fún balogun?
"Ko tii si iroyin kankan to tii jade nipa ohun to ṣokunfa iku rẹ, ṣugbọn iroyin sọ pe ilu rẹ, Agọ Iwoye lo mi eemi ikẹyin sii Ìyàwó mi fi mí sílẹ̀ kó lọ sílé ọkùnrin míì nínú báráàkì kan náà, àmọ́ mò sí tún fẹ́ràn rẹ̀- Sọ́jà Wo àwọn ìṣesí ojoojúmọ́ mẹ́wàá tó le ṣàkóbá fún ọpọlọ rẹ Gomina Sanwo-Olu sún ọjọ́ ""ṣiṣẹ́ láti ilé"" síwájú fún àwọn òṣìṣẹ́ ìjọba Opral Benson, ẹni ti oge ṣíṣe sọ di gbajúmọ̀ àti Yeye Oge ìlú Eko Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ado Ekiti Blind Couple: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!"
Iṣẹ́ ẹ̀mí ẹ̀tàn ló bàlemi lasiko tí mo sọ àṣọtẹ́lẹ̀-Simeon Ononogbu Mo gbàgbé sùnlọ sìnú ọkọ̀ òfurufú, ẹ̀rù ikú bà mí -Tiff Ìdí tí ilé fi wó lu ènìyàn méjì ní Oshodi -LASEMA Kini ero EFCC lori MMM ni Naijiria?
Àṣìta ìbọn pa èèyàn kan lásìkò tí SARS ń kojú adigunjalè l'Eko Ǹjẹ́ ẹ mọ ohun tí igbákejì ààrẹ Yemi Osinbajo sọ nílé bàbá Fasoranti Fulani nìkan kọ́ ló ń pa ènìyàn ní Naijiria -Tinubu Aago Naijiria ti kún àkúnwọ́sílẹ̀ - Tunde Bakare Lẹ́tà Obasanjo: Àjálù ń bọ̀ bíi ti Rwanda, tí Buhari kò bá ṣàtúnṣe ètò ààbò Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Olórí Ọ̀dọ́ l'Ondo ní oníkálùkù yóò bẹ̀rẹ̀ sí ní jà fúnra wọn Atẹjade naa ṣalaye pe ni nkan bi agogo meji oru ganjọ ọjọ kẹẹdọgbọn oṣu keje ọdun 2019 ni awọn agbegbọn ti ẹnikẹni ko mọ gba ọna oju omi River Nun wọ ile Arabinrin Beauty.
Ẹ̀gbọ́n ati ìyá Rebeka dáhùn pé, “Jẹ́ kí omidan náà ṣe bí ọjọ́ mélòó kan sí i lọ́dọ̀ wa, bí kò tilẹ̀ ju ọjọ́ mẹ́wàá lọ, kí ó tó máa bá yín lọ!
Nigeria 2019 Election: Ọjọ́ Sátidé tí wọ́n sún ìbò ààrẹ sí ni ìgbéyàwo àwọn ìbejì yìí
Awọn ọmọ Naijiria ko tilẹ jẹki ayẹyẹ naa pari ki wọn to bẹrẹ iriwisi loju opo Twitter.
Oluwo ilu Iwo Oba Abdulrasheed Adewale Akanbi ni oun kabamọ iṣlẹ to waye laarin oun ati Agbowu ilu Ogbaagbaa .
"Ti esi ayẹwo ba fi han pe wọn ni i, ohun lao fi ṣe ẹri nile ẹjọ.
Arabinrin kan ti a ba sọrọ ni agbegbe Orita ṣe alaye wi pe epo ẹgbẹrun kan naira ni oun maa n ra sinu ọkọ tẹlẹri ki ijọba to mu alekun ba owo epo.
Wọ́n ní, “Gbà fún wa pé, nígbà tí ó bá di ìgbà ìgúnwà rẹ, kí ọ̀kan ninu wa jókòó ní ẹ̀gbẹ́ ọ̀tún rẹ, kí ẹnìkejì jókòó ní ẹ̀gbẹ́ òsì rẹ.
Ọ̀kẹ́ mẹẹdogun (300,000) ni àwọn tí wọ́n wá láti ilẹ̀ Israẹli, àwọn tí wọ́n wá láti Juda sì jẹ́ ẹgbaa mẹẹdogun (30,000).
Eyi to mu ki ẹgbẹ oselu rẹ yan Cyril Ramphosa lati dipo rẹ gẹgẹ bi asaaju ninu ẹgbẹ oselu naa.
Bẹẹ lọpọ n beere ibeere nla pe awọn oniṣẹ ibi wo lo ṣe iṣẹ naa.
Oríṣun àwòrán, @BashirAhmaad Gbogbo igbiyanju Gomina Obaseki lọ si ile Aarẹ ni Aso Rock lọdọ Aarẹ Buhari nigba ti ẹgbẹ APC fẹ yọwọ rẹ lawo lati dupo Gomina lo ja si pabo.
Ayinla Kollington: ọ̀rẹ́ ni èmí àti Barrister kó tó jáde láyé
Ipa ti imọ ẹrọ lee ko lasiko Ramadan Oríṣun àwòrán, Getty Images Sheikh Othman sọ pe Ori ayelujara ni mo ti maa ṣe Tafsir lọjọ Ẹti lati inu iyẹwu mi."
" Ẹwẹ, oludamọran fun Gomina ipinlẹ Oyo lori ọrọ aabo, Ọgbẹni Odukoya Sunday to bawọn sọrọ ṣeleri lati jiṣẹ wọn fun Makinde.
Eyi ko ṣẹyin igba ti aawọ laarin Gomina Godwin Obaseki ati alaga ẹgbẹ oṣelu APC, iyẹn Adams Oshiomole bẹrẹ yi, A ti ri itu orisirisi lati ọwọ awọn to n kopa ninu ohun to fẹ jọ ere ori itage yii, sugbọn to se pe awọn oloselu ni oṣere to wa ninu rẹ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Olusegun Obasanjo: Ọmú ìyá mi ti mo fi ń mùkọ ni kekere ló jẹ ki ń lókun Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Richard Gbadebo: Ìjọba ìpínlẹ̀ Oyo yóò ṣe ìwádìí ikú tó pa akẹ́kọ̀ọ́ Fásitì Ibadan
Nígbà náà ni n óo gbà pé,agbára rẹ lè fún ọ ní ìṣẹ́gun.
Ìdí rèé tí mínísítà tẹlẹ fún ìrìnà ojú òfurufú, Femi-Fani Kayode se gbé àtẹ̀jáde kan síta, tó pé àkọlé rẹ̀ ni ta lo n fun Tunde Bakare l‘ẹpọ̀n pọ̀?
Ó yan ẹẹdẹgbaaji ó lé ọọdunrun (3,300) ọkunrin, láti máa bojútó iṣẹ́ àwọn òṣìṣẹ́.
Oríṣun àwòrán, SPNigeria Àkọlé àwòrán, Sẹnẹtọ Bukola Saraki ati Ike Ekweremadu ni won di ipo aarẹ ati igbakeji aarẹ ile asofin mu ni saa to kọja Bi a ko ba gbagbe, lasiko ti idibo ile asofin agba waye ni saa to kọja ẹnu ẹgbẹ ko ṣebi ẹni papọ soju kan eleyi to mu ki Sẹnẹtọ Bukola Saraki ati Sẹnẹtọ Ike Ekweremadu gbegba oroke.
Nígbà tí mo bá gba oúnjẹ lẹ́nu yín, obinrin mẹ́wàá ni yóo máa jókòó nídìí ẹyọ ààrò kan ṣoṣo láti ṣe burẹdi.
Egypt ṣíná fún Zimbabwe, ẹ̀kọ́ mẹ́rin tó yẹ ní kíkọ́ Ẹyẹ ju ẹyẹ lọ, Super Eagles fi àmì ayò kan gbé ẹyẹ Swallow ti Burundi mì Oko òkú rèé, níbití òkú ti ń jẹrà mọ́lẹ̀ fún àyẹ̀wò Ìgbà Marún-un ti Aisha Buhari ti tako ìjọba Buhari Abiy tun sọ pe ọpọlọpọ awọn ọmọ ogun ni wọn ti ṣekupa ninu ikọlu kan to waye ni olu ilu agbegbe Amhara, Bahir Dar.
won ko won lọ si ibudo ti omi ko pọ si .
Mo mú kí ìbẹ̀rù ati ìwárìrì já lù wọ́n láìròtẹ́lẹ̀.
Ohun tí OLUWA sọ fún kirusi, ẹni tí ó fi àmì òróró yàn nìyí:Ẹni tí OLUWA di ọwọ́ ọ̀tún rẹ̀ mú, tí ó lò,láti rẹ àwọn orílẹ̀-èdè sílẹ̀ níwájú rẹ̀,láti tú àmùrè àwọn ọba,láti ṣí àwọn ìlẹ̀kùn níwájú rẹ̀,kí ẹnubodè má lè tì.
Eleyi ko ni mu ki a kan maa daamu ara wa lasan.
Wọn o lọ ile iwe rara debi ti wọn yoo mọ ọ kọ tabi mọ ọ ka.
Ẹkun sisun Kọmisana yi si ti wa mu kawọn eeyan maa darukọ awọn to jẹ gbajumọ ẹlẹkun ori amohunmaworan mii laipẹ yi bi: Gomina Ben Ayade ipinlẹ Cross River Sẹnatọ Dino Melaye Kogi Gomina tẹlẹ ni ipinlẹ Ekiti Ayodele Fayose ati Iyawo aarẹ tẹlẹ Dame Patience Jonathan.
N óo gbà yín là n óo sì yọ yín lọ́wọ́ rẹ̀.
Ṣugbọn wọ́n rọ̀ ọ́ títí tí ojú fi ń tì í, ó sì wí fún wọn pé, “Ẹ rán wọn lọ.
Olutoyin Odusanya Agbẹjọro to dantọ ni iya afin Olutoyin Odusanya, o si tun jẹ ọkan lara ọmọ ẹgbẹ awọn agbẹjọro ni Naijiria, NBA.
nipa fifi ẹmi ara rẹ ji lori igi agbelebu loke Kafari, eyi ti o je ẹbọ nla
Èrò àwọn ọmọ Nàìjíríà yapa lóríi fídíò codeine Mairo Mandara, nínú ìkànnì twitter rẹ̀ @Drmairomandara, sọ̀rọ̀ pé, kí ìjọba fòfin de ṣíṣe oògùn ikọ́ olómi Codeine lọ́dọ̀ àwọn iléeṣẹ́ tọ́rọ̀ kàn, bíi Emzor Pharmaceuticals, Bioraj Pharmaceuticals àti Peace Standard Pharmaceuticals Nínú èrò ti Politbru ni ìkànnì twitter @Politbru, ní, ìsẹ̀lẹ̀ yìí ti ń ní ọwọ́ kan ẹlẹ́yàmẹ̀yà nínú.
“Ṣé ẹfọ̀n ṣetán láti sìn ọ́?
james adomian ( ọjọ ́ ọ ̀ kànlélọ ́ gbọ ̀ n oṣù kínín ọdún 1980 ) jẹ ́ aláwàdò àti òṣèré ará amẹ ́ ríkà .
Mo ṣèlérí pé n óo yọ wọ́n kúrò ninu ìpọ́njú Ijipti.
Awọn mọlẹbi rẹ ko foju han lẹyin ti ọwọ tẹ Wọn ni ọwọ epo lọmọ araye n ba ni la, wọn kii ba ni la ọwọ ẹjẹ.
“Ṣugbọn, ǹjẹ́ ìwọ Ọlọrun lè gbé inú ayé yìí?
Lọdun 1998 ni ijọba Naijiri a gbe igbesẹ yi lati fi han Amẹrika pe awọn naa ko gba gbẹrẹ.
Ninu irufe idije naa ti o waye lodun 2010 ati 2014, Falconets pari idije naa sipele keji si asekagba, besini lodun 2012 won pari sipo karun-un.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìgbà mélòó ní wọn fẹ kéde ikú ẹṣọ tó pá Ọ̀gágun Lorílè-èdè Ethiopia ?
agbekale naa tan, igbimo ohun si bowolu iyansipo mi gege bi oga agba ile-ise
A rékọjá Ẹnubodè Efuraimu, a gba Ẹnubodè Àtijọ́, ati Ẹnubodè Ẹja ati Ilé-ìṣọ́ Hananeli ati Ilé-ìṣọ́ Ọgọrun-un, lọ sí Ẹnubodè Aguntan, wọ́n sì dúró ní Ẹnubodè àwọn Olùṣọ́ Tẹmpili.
Ṣugbọn bí wọ́n bá lọ́kọ lára ẹ̀yà Israẹli mìíràn, a ó gba ilẹ̀-ìní wọn kuro ninu ilẹ̀-ìní awọn baba wa, ilẹ̀-ìní wọn yóo jẹ́ ti ẹ̀yà àwọn ọkọ wọn, èyí yóo sì mú kí ilẹ̀ wa dínkù.
Iṣẹ́ ìyanu rẹ̀ sì lágbára lọpọlọpọ!
Igbimọ to n gbẹjọ awuye-awuye lori eto idibo gomina to
Awo orin rẹ akọkọ to gbe jade, Iba, lọdun 1980, ko ta daada.
osu keji siwaju si ọjọ ketalelogun osu keji ati osu keta.
Mugabe omo odun merinleladorun, ni ile-ise ologun fipa yo kuro lori alefa ninu osu kokanla odun 2017, eyi ti enikan ti o sunmo Aare teleri naa so pe, o je ohun edun okan fun Mugabe, bi won se fipa le kuro lori alefa leyin odun metadinlogoji, ti o ti wa lori alefa, ni eyi ti o pinnu lati satileyin fun egbe oselu tuntun naa.
Ọ̀dọ Ìyàndá ọmọ Àdísátù la wàyìí
Ṣugbọn àwọn ọmọ Israẹli kò pa wọ́n, nítorí pé àwọn àgbààgbà wọn ti búra fún wọn ní orúkọ OLUWA Ọlọrun Israẹli.
Oríṣun àwòrán, Adejare Taofeek Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Amọṣa awọn eto wa ni ṣisẹ n tẹle ti yoo maa waye kaakiri ipinlẹ Eko ni ibamu pẹlu aṣẹ ti aarẹ Muhammadu pa ni ọjọ Aje lori awọn igbesẹ ọlọtọ ni toun ọtọ tawọn ipinlẹ lee maa gbe lawọn ipinlẹ kọọkan lati pinwọ ajakalẹ arun Coronavirus.
Ilé wó pa Jide, ọmọ ọdún mọ́kànlá, l'Oṣogbo Sultan pàṣẹ fún àwọn mùsùlùmí láti ṣ'ọdẹ òṣùpá lónìí Àwọn òṣìṣẹ́ aláàbò kọlu àwọn tó n ṣe ìwọ́de ní Sudan Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fọ́nrán ohùn, Àwọn ènìyàn sọ àwọn ewu tí wọn pàdé nínú lílo òògùn ẹ̀fọn Wọn yẹ ike eso olomi to mu wo, wọn si gboorun oogun apakokoro ninu rẹ.
“Nígbà tí obinrin bá ń ṣe nǹkan oṣù rẹ̀, kí ó wà ní ipò àìmọ́ fún ọjọ́ meje.
Bí ẹnìkan bá dojú ìjà kọ ọ́, kìí ṣe èmi ni mo rán an,ẹnikẹ́ni tó bá gbéjà kò ọ́, yóo ṣubú nítorí rẹ.
Alhaji Hamzat Abudulkarim, ti onisowo oja ata ni oja ti o wa nile-Epo so pe, adinku ti ba iye iwon oja ti won n gbe wa, toripe o je oja ti o ni asiko.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Seun Kuti: Fela ló n pọ́n gbogbo òǹkọrin Afrobeat lagbaye Lara ohun taa ma n ṣe ni yiyan gẹgẹ bi ologun, ọrọ ikẹyin leti iboji, adura ni aafaa Islam tabi alufa Kristẹni to fi mọ yiyin ibọn soke ati bẹẹ bẹẹ lọ lo wa ninu ọrọ ti wn fi sita."
Bí ìwọ ti ń ṣe ojú mi ni ìwọ ń ṣe ẹ̀hìn mi pẹ̀lú.
N kò mọ bí wọ́n ṣe n bá obìnrin sọ̀rọ̀ ìfẹ́ - Aláàfin Àwọn ajínigbé bèèrè N20m fún ìyàwó ọba ‘Ibi a gbé dàgbà níi se pẹ̀lú ìhùwàsì wa’ Ayẹyẹ igbeyawo melo ni Aarẹ Buhari lọ?
Olootu orin yii ni: “Lojo ti mo dibo gbeyin, gbogbo eniyan to wa nibe lo mo eni ti mo dibo fun.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Jàńdùkú olóṣèlú gbàkóso ilé aṣòfin l‘Ondo Temitope Akinnusi: Ọ̀pọ̀ iléeṣẹ́ ló takú láti gbà mí síṣẹ́ torí mo ní ojú kan Eruku ìjà sọ lálá lórí ayelujára láàrin Oyedepo àti Daddy Freeze Ọmọ Nàíjíríà kó N6m jọ lórí ayélujára fún Erica tí wọn lé ní BB Naija Mo fòpin sí àjẹbánu lórí owó ìrànwọ́ epo àti iná ọba, ní èlé ṣe wáyé - Buhari Comrade Joe ni awọn ko i tii fun ọmọ ẹgbẹ awọn ni aṣẹ kankan lati bẹrẹ ifẹhọnu han.
Lagos City Marathon: Ipò wo ni Gómìnà Sanwo-Olu gbà?
UN Plane Crash: Èèyàn méjì, tó fi mọ́ ọmọ ọdún márùn-ún ló kú nínú bàálù tó já ní Borno
Èyí túmọ̀ sí pé, ọ̀fẹ́ ni tí o bá ló kóòdú *346#.
Nigba ti wọn maa wo inu ọkọ ti wọn wa, ori ọmọdekunrin naa ti wọn pe ni ọmọ ọdun mẹwaa ni wọn ba ninu rẹ Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: ‘Irọ́ ni pé Ọmọ ọdọ̀ Ọpẹ Bademosi kú’ 'Óṣeéṣe kí ọ̀rẹ́kùnrin Khadijat fẹ́ fi ṣowó' Agbẹnusọ fun ileeṣẹ ọlọpaa Ipinlẹ Eko, Chike Oti ni awọn afunrasi naa ti wọn n gbe agbegbe Shapati ni Ibẹju-Lekki, ṣalaye fun awọn ọlọpaa pe ọgbẹni kan ti orukọ rẹ njẹ Sodiq Abẹfẹ ni o ni ki awọn lọ wa ori eniyan kan wa ti oun yoo si nfun wọn ni ẹgbẹrun lọna igba naira (N200,000).
Saaju ikede yii to waye lọjọ kẹrinla, oṣu Kẹrin , ijọba ti fofin de ipejọpọ ọpọ eniyan, ileewe wa ni titi pa, ko si lílọ ati bibọ ọkọ lati ipinlẹ miran.
Awọn mẹrin to wa ni Alhaji Fatai Akinbade, Alhaji Gboyega Oyetọla, Alhaji Moshood Adeoti àti Senetọ Iyiola Omiṣore nigba ti a kò ri Senetọ Ademọla Adeleke.
Ẹsun tàwọn ọdọ naa fi n kan ọba Falabi ni pe, o yi idajọ ile ẹjọ to ga julọ lorilẹ-ede yii po, eyi to wọgile ilana to yan ọba ọhun sipo lọdun 1993.
daju pe, awon osise alaabo fowowewo lati sise papo pelu awon osise alaabo
ile kan dawo lu awon eniyan.
Oríṣun àwòrán, @muhammed Ki lo mu kawọn ọmọ yi maa tọrọ bara fun owo kiri titi?
Bakan naa, fidio miran tun jade lẹyin eyi nibiti aya aarẹ, Aisha naa tun ti n ba awọn akọroyin sọrọ pe, lootọ oun lo wa ninu fidio ti Fatima Daura gbe sita naa.
Ó fi ìkùukùu ṣe atọ́nà wọn ní ọ̀sán,ó fi ìmọ́lẹ̀ iná tọ́ wọn sọ́nà ní gbogbo òru.
fagbahan orile-ede Egypt pelu ami ayo kan sodo(1-0).
Premier League: Southampton dáná sun Stamford Bridge pẹ̀lú àmì ayò 2-0
Ó gba ààrin títì ìlú náà.
BBC Yorùbá yóò se ìpàdé ìtagbangba ní Kwara 'Mí ò sí lára awọ̀n aṣòfin tó bú Buhari'' Kíni Amosun mú Adekunle lọ ṣé lọdọ Buhari?
Donald Trump ò ka gbogbo ilẹ̀ Aláwọ̀dúdú si nkankan tàbi dárúkọ Nigeria.
O fikun pe awọn ọlọpaa naa lọ ibomiran, amọ awọn afẹhọnu han naa tun tẹlẹ wọn.
Ẹyẹ àkọ̀ tí ń fò lójú ọ̀run pàápàá mọ àkókò rẹ̀.
Ilé ẹjọ́ ìbílẹ̀ kọ ìwé ẹ̀dùn tí Min Htin Ko Ko Gyi kọ fún béèlì.
OLUWA,ṣe akiyesi ohun tí ń ṣẹlẹ̀!
Awọn ilana ti ijọba Saudi gbe kalẹ lori ṣise Hajj 2020 ree: Ayẹwo yoo waye fawọn ti yoo ṣe Hajj lati mọ boya wọn ni arun Covid-19 lara, bi wọn ba si pari Hajj naa, wọn yoo ṣe ayẹwo wọn Awọn to n gbe Saudi ati ọmọ ilu ti ọjọ ori wọn ko to ọdun marundinlaadọrin ni yoo kopa.
Aya aarẹ fọrọ yii lede nigba tawọn iyawo gomina ipinlẹ mẹrẹẹrindinlọgbọn ṣabẹwo si i nile ijọba.
"Mo mọ pe n ko mọ baa se n gba ijakulẹ mọra, paapa nigba ti awọn ọmọ ikọ agbabọọlu mi saayan to pegede lati koju agba ọjẹ agbabọọlu meji lagbaye""."
Aare tun tenumo ipinnu ijoba lati pese eto idibo ti yoo waye
Olukuluku yín bá múra láti jagun, gbogbo èrò yín nígbà náà ni pé kò ní ṣòro rárá láti ṣẹgun àwọn tí wọn ń gbé agbègbè olókè náà.
Koda awọn eeyan kan tiẹ se alaye pe, niwọn igba ti a mọ iye eeyan to jẹ ọmọ orilẹede Naijiria, ti wọn jẹ miliọnu lọna igba eeyan, ti gbese wa si jẹ triliọnu mẹrinlelogun ati biliọnu lọna irinwo naira din diẹ ( ₦24.
“Fìyà jẹ àwọn ará Midiani fún ohun tí wọ́n ṣe sí àwọn ọmọ Israẹli.
"Oríṣun àwòrán, Olubayode Alebiosu Àkọlé àwòrán, Ẹbun ayika to wuyi jọjọ ni oriosun omi orioke ẹrin Ijẹṣa naa jẹ Nigbati wọn ri omi naa, o fa oju wọn mọra, wọn si ni oriṣa miran niyii, wọn pee ni 'olu miran'ni ede wọn, iyẹn ""olumirin"" Ipele meje ni omi orisun apata Olumirin yii ti n jabọ Oke meje ni eeyan yoo gun lati ri orisun rẹ gangan ni oke tente."
Ṣugbọn ní tiwa, ojúmọmọ ni iṣẹ́ tiwa, nítorí náà, ẹ jẹ́ kí á farabalẹ̀, kí á wọ aṣọ ìgbàyà igbagbọ ati ìfẹ́, kí á dé fìlà ìrètí ìgbàlà.
Ninu Òfin, ó wà ní àkọsílẹ̀ pé, Oluwa wí pé,“N óo bá àwọn eniyan yìí sọ̀rọ̀láti ẹnu àwọn eniyan tí ó ń sọ èdè àjèjì,ati láti ẹnu àwọn àlejò.
 olórí ló ní aṣẹ ilè ìran .
June 12: Sadik ní àwọn tó ṣiṣẹ́ pẹ̀lú Abacha ní kò kówó jẹ, ó fi pamọ́ fún ìdí kan ni
Awọn tọrọ ṣoju wọn ni ọmọkekere kan ati iya kan to wa ra nnkan ọbẹ lọja wa lara awọn to farakasa iṣẹlẹ naa.
Òye ìdájọ́ òdodo kò yé àwọn eniyan burúkú,ṣugbọn ó yé àwọn tí ń wá OLUWA yékéyéké.
Nígbà tí wọ́n súnmọ́ Misia, wọ́n gbìyànjú láti lọ sí Bitinia.
Ogunwusi, seleri pe won yoo ri daju lati se ojuse won lasiko eto idibo ohun nipase
Bí a bá ti dé ọ̀dọ̀ àwọn ọdẹ ti wọ́n wà lójú ọ̀nà wọ̀n-ọnnì, wọ́n á yìnbọn.
Nebukadinesari bá dáhùn pé “Ògo ni fún Ọlọrun Ṣadiraki, Meṣaki ati Abedinego tí ó rán angẹli rẹ̀ láti gba àwọn iranṣẹ rẹ̀, tí wọ́n gbẹ́kẹ̀lé e, tí wọn kò ka àṣẹ ọba sí, tí wọ́n fi ẹ̀mí wọn wéwu, dípò kí wọ́n sin ọlọrun mìíràn yàtọ̀ sí Ọlọrun wọn.
 Ipinle Eko feran afihan asa ati ise ati idanilaraya pupo laiso ti ere-onise ati fiiimu agbelewo ni eyi ti won fi n pe awon eniyan ipinle Eko ni awon alayo nile aye.
Bí Jesu ti ń bá àwọn eniyan sọ̀rọ̀ ni ìyá rẹ̀ ati àwọn arakunrin rẹ̀ bá dé, wọ́n dúró lóde, wọ́n fẹ́ bá a sọ̀rọ̀.
se n sunmọle  lorile ede Naijiria lati
 a yi kúrò ni ipò ìṣe lọ sí ìse aláyìísódì .
O ni bi nkankan ba ṣe awọn akẹkọọ ọhun ni, awọn ologun naa lawọn ọmọ Naijria yoo da ẹbi rẹ le lori.
Nígbà kúúgbà ti to ba yẹ, a máa n fi ìlà ti a o fi de ojú opó àwọn ti ni ìròyìn, tàbi tan imọlẹ̀ si ǹkan ti à ń sọ ínú ìròyìn wa.
ede Naijiria to wa ni ipinle Bayelsa ti mu awon janduku ati ọbayejẹ  màrúndínlógún lasiko eto idibo aarẹ ati ile
Pasitọ Bakare wa tọka si orilẹ ede ti eeyan lee ku fun bii: Orilẹede ti yoo lee pese awọn ohun eelo amayedẹrun to yẹ bii ipese irinna oju irin Orilẹede ti yoo lee pese eto ilera to se koko, ti awọn eeyan orilẹede naa ko si ni maa ku bii adiẹ, paapa lasiko ibimọ Orilẹede ti yoo lee daabo bo ara rẹ ati awọn eeyan inu rẹ, paapa awọn eeyan rẹ loke okun, ti wọn ko fi ni maa pa wọn nipakupa Orilẹede ti eto iselu rẹ duro re, ti iwa jagidijagan ko ni gba ilẹ kan, tawọn oloselu ko ni maa jija gidu lati jẹ ohun alumọọni rẹ ni ijẹkujẹ Bakare ni nitori pe orilẹede Naijria ko se ku fun, ni awọn ọmọ Naijiria se setan lati ta kaadi idibo wọn, tori ko si ohun iwuri kankan to lee mu ki wọn fi ẹmi wọn lelẹ fun ilẹ baba wọn.
''Emì ko ṣe ǹkan ti wọn ní mo ṣe.
abenugan ile igbimo asofin ti ile si yan asofin Sanjo Onaolapo gege bii
Àdó okoró búrẹ́kẹ' Oríṣun àwòrán, @Thenichenews Niṣe lawọn ọmọ ile igbimọ aṣoju-ṣofin l'Abuja ti ke si Aarẹ Muhammadu Buhari lati wa ṣalaye ibi ọrọ de duro nipa eto abo orilẹ-ede Naijiria.
wa ni Oke Mokola niluu Ibadan.
Faparusi kekọọ gboye ninu iṣẹ iṣegun oyinbo, ni Fasiti ilu Ibadan nibitri sanmọnti gbe dun ile ti wọn tun ni ọgba ẹlẹranko.
 Ọ ̀ wọ ́ ìlù mẹta la papọ ̀ se àgẹ ̀ rẹ ̀ ògún .
 lẹ ́ yìn èyí , ó tẹ ́ síwájú lọ sí ilé ẹ ̀ kọ ́ gbogboǹṣe polí Ìbàdàn ( the polytechnic Ìbàdàn ) ní ibi tí ó ti kọ ́ nípa ẹ ̀ kọ ́ ìbánisọ ̀ rọ ̀ gbogbogbòò tí ó sì jàde ní ọdún 1990 .
Igba akọkọ re e ti Liverpool yoo kopa ninu ifẹsẹwọnsẹ Community Shield lati ọdun 2006 nigba ti na Chelsea pẹlu ami ayo meji sẹyọkan.
Ònlo Weibo kan fi ẹ̀hónú hàn:
S Embassy Fayoṣe yọjú sílé ìgbìmọ̀ aṣòfin l'Ekiti lórí ọ̀rọ̀ owó Káńsù, óní kòséwu lòko Peter Ayodele Fayoṣe, ẹni ti o jẹ gomina ana ni ipinlẹ Ekiti ti yọju si Ile igbimọ aṣofin ipinlẹ naa lori ẹsun ti wọn fi kan an nipa ọrọ owo Kansu.
Kini ero awọn onwoye lori ikanni ayelujara?
“Coach of the Year (Men)’’,Kennedy Boboye, ti o je akonimoogba agba iko agbaboolu Plateau United FC tilu Jos.
"Oríṣun àwòrán, Premium times nigeria Okeowo ṣalaye pe ""Kii ṣe dandan ki igbakeji gomina yọju si ibi ipade awọn aṣejọba nitori wọn kii pe sibi ipade ọhun tẹlẹ gan lọpọ igba, nitori naa, to ba wu yoo lọ, to ba si wu, ko ni lọ."
Tẹlẹtẹlẹ, orilẹede Sudan lo ni ilẹ to fẹ julọ ni Afirika, ko to di pe wọn pin lọdun 2011.
Gbogbo àwọn nǹkan yòókù tí Rehoboamu ọba ṣe ni a kọ sílẹ̀ ninu Ìwé Ìtàn Àwọn Ọba Juda.
O ni awọn obi maa n ṣaa ba ni iru iṣọri ẹjẹ kan naa tawọn oloyinbo n pe ni ''genotype.
Ẹ banújẹ́, ẹ̀yin àgbẹ̀,ẹ sọkún tẹ̀dùntẹ̀dùn ẹ̀yin tí ẹ̀ ń tọ́jú ọgbà àjàrà,nítorí ọkà alikama ati ọkà baali,ati nítorí pé ohun ọ̀gbìn ti ṣègbé.
Banky W naa sọ pe iroyin ọ̀hún fọwọ ba oun lẹmi tohun ti iroyin isẹlẹ ipaniyan to waye ni ipinlẹ Plateau Olamide ati Davido ko gbẹyin Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ajé kò gbà, ẹ rìn síwájú Awọn ololufe Dbanj ti n bá a kẹ́dùn láwọn ojú òpó ayélujára tó ní.
iresi ile okeere to le ni egberun meta; garawa ororo 319; Beeli merindinlogoji ,aso
Sabidi, ará Ṣifimu, ni ó wà fún ibi tí wọ́n ti ń pọn ọtí.
Mo bẹ̀ yín, ẹ dúró bẹ́ẹ̀,kí ẹ má baà ṣẹ̀.
Ẹ lo gbogbo àkókò yín dáradára nítorí àkókò tí a wà yìí burú.
Osu Kesan, ọdun 2019 ni ileesẹ ọlọpaa ilu Eko mu u fun biba alaafia ilu jẹ.
"Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Policeman smoking shisha: Iléeṣẹ́ ọlọ́pàá ti bẹ̀rẹ̀ ìwádìí lórí fídíò ọkùnrin kan tó ń mu ""shisha"" 13 Owewe 2020 Oríṣun àwòrán, Facebook/Nigeria Police Force Ileeṣẹ ọlọpaa orilẹede Naijiria ti bẹrẹ iwadii lori fọnran kan to lu ori ayelujara pa ninu eyi ti ọkunrin to wọn aṣọ ọlọpaa ti mu ''shisha."
Nibẹ lo si ti n gba itọju lati bi ọdun kan, ko to o jade laye.
Ìjọba Kaduna: Gbogbo àwọn tó wà nídìí ìṣẹ̀lẹ̀ ìpànìyàn yóò gé ìka jẹ
O jọ bi ẹni pe, o ti sa lọ ki awọn ọlọpaa o to de.
Iléeṣẹ́ ọmọ ogun dá Bashir tó ri owó he lọ́lá Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Kí ló dé tí o ò fi kúkú rì mí bọmi?
N óo ṣe bẹ́ẹ̀ kí wọ́n lè ṣe aláìní oúnjẹ ati omi, kí wọ́n lè máa wo ara wọn pẹlu ìpayà, kí wọ́n sì parun nítorí ẹ̀ṣẹ̀ wọn.
Ìyìn sì ni fún Ọlọrun Ọ̀gá Ògo, ẹni tí ó bá ọ ṣẹgun àwọn ọ̀tá rẹ.
 Won ni ki awon to n sise naa tele ilana agbekale to wa ni eyi ti won koko ya nibi ti oko-oju-irin ti wa kaakiri Naijiria gege bii oko irinna.
Awọn afurasi naa, Emeka Madu to jẹ oludasilẹ ileeṣẹ naa, ati oṣiṣẹ mẹta; Eze Young, Chijoke Umunna ati Kingsley Obilo.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Intersex: Abiyamọ ní dókítà kò leè sọ bóyá akọ ni ọmọ òun àbí abo 18 Ìgbé 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 8 Èbibi 2020 Ni ile aye ta wa yii, akọ ati abo ni ẹda lee jẹ amọ ti iyalẹnu maa n wa, ta ba ri ẹnikan ti kii se akọ abi abo.
Ẹ ní ìpéjọpọ̀ mímọ́ ní ọjọ́ náà, kí ẹ gbààwẹ̀, kí ẹ sì rú ẹbọ sísun sí OLUWA.
com/0msXrYbeqBminisita fun oro to je mo abẹle  Abdulrahman Bello Dambazau naa ti wa nikale niluu Abuja.
Adí-àgbọn: Ọ̀jọ̀gbọ́n Fasiti Harvard ní kẹ má mu àdí-àgbọn mọ́
O lee beere pe ki o kọkọ yẹ ọlọpaa naa wo ki o to yẹ ọ wo Eyi wa lati rii pe wọn ko di ẹru ti kii ṣe tirẹ le ọ lori.
"Ti o bá ṣeeṣe kí àwọn ènìyàn máa rin irinajo lọ si àwọn orilẹ̀-èdè ti irú rẹ̀ ti n wáye, pàápàá jùlọ Yuroop nibi ti ọ̀pọ̀ àwọn orilẹ̀-èdè ti ba ààrun náà fíra, àyàfi ti ìrìnàjo náà ba ṣe pàtàkì jùlọ.
Nigba ti atọkun eto beere lọwọ rẹ pe, ki ni yoo ṣe, to ba jẹ oun lo wole gẹgẹ bi Buhari?
Nítorí ìfẹ́ rẹ tí kì í yẹ̀ ni mo tẹjúmọ́,mo sì ń fi òtítọ́ bá ọ rìn.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí Owó dé!
’ Bẹ́ẹ̀ ni kò jẹ́ kí n rí òkú náà wò bí wọ́n ṣe ń gbé e bọ̀.
Lẹ́yìn tí Jeremaya ti wà ní ọgbà ẹ̀wọ̀n fún ọpọlọpọ ọjọ́, 
Àsọtẹ́lẹ̀ Fada Mbaka, tó yẹ àga mọ́ gómìnà Imo nídìí rèè Ọ̀gá mi fẹ́ fi tipá bámi lòpọ̀ ní Lebanon àmọ́ ìjọba yọ mí l'óko ẹrú - Ọmọ Nàíjíríà míì Bí ìtàn ayé Toyosi Arigbabuwo ṣe lọ rèé láti ẹnu Musiliu Dasofunjo àti Ogun Majek Ọjọ kẹsan an, Oṣu Kinni ọdun yii ni awọn gomina ipinlẹ mẹfa lati ilẹ Yoruba ṣe ifilọlẹ ikọ Amọtẹkun nilu Ibadan.
Shuijin tun so pe, “ajo yii n gbe igbese ti o nipon lati satileyin fun eka eto oro-aje ni iyanju atimu idagbasoke ba orile-ede mejeeji ohun”.
Ileeṣẹ ato ilu nipinlẹ Ekiti gbe ileeṣẹ rẹdio naa ti pa ni owurọ ọjọbọ lori ẹsun pe ko gba iwe aṣẹ ikọle.
Lẹyin naa ni wọn ko wọn lọ si ilẹ Amẹrika fun igbẹjọ lori ẹsun iwa 419 ori ayelujara ti awọn Naijiria maa n pe ni Yahoo-Yahoo.
“Nigba ti mo gbe omo naa si apa mi, mo ba omo naa soro, o si so pe, kilo de ti mo fi se eyi?
Àwọn ọ̀nà tí obìnrin fi le gbádùn ìbálòpọ̀ Kí lo mọ̀ nípa Eniọla Badmus?
O sọ ninu fidio to fi soju opo instagram pe orukọ rẹ ni Gloria Johnson o n dẹru ba mi lọpọlọpọ igba""."
Trump: Ìpàdé èmi àti Trump so èso rere
O fi kun pe nigba ti esi awọn lpaa naa ba jade lawn yooku yoo tun l ṣe e.
Arun Covid 19 lo ṣekupa ogbontarigi oloselu yii lẹni aadọrin ọdun.
faa sile fun ipo aare lọdun 1999 sile.
Koda, ile aṣofin agba Naijiria kọ lati bu ọwọ lu iyansipo rẹ lẹẹmeji ọtọọtọ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Akinwumi Ambode: Awọn àgbà ọ̀jẹ̀ agbábọ̀ọ̀lù ní Afíríkà yẹ́ Gomina Ambode si 18 Èbibi 2019 Oríṣun àwòrán, Akinwumi Ambode Àkọlé àwòrán, Akinwumi Ambode: Awọn àgbà ọ̀jẹ̀ agbábọ̀ ọ̀lù lágbàyé yẹ́ Gomina Ambode si Ọ̀pọ̀ àwọn àgbà sjẹ̀ oníbọọ̀lù láti orilẹ̀-èdè Nàìjíríà àti Afíríkà ló péju sí pápá ìṣere Agege lọ́nìí láti yẹ gọmina ìpínll Eko Akinwumi Ambode bí ó ṣé ń fi ìpò sílẹ̀ gẹ́gẹ́ bii gómìnà.
Ẹ̀wọ̀n gbére leè jẹ́ ìjìyà fún afipábánilòpọ̀ bí àwọn gómìnà ṣe dìde si Alhaja Kudirat Abiola: Odindi géńdé ọkunrin mẹ́fà ni wọ́n gbé iṣẹ́ ikú rẹ̀ fún Wo àwọn òṣèré tíátà Yorùbá tó bí ìbejì Kí ló mú Aisha Buhari figbe bẹnu pé kí Ọ̀gá Ọlọ́pàá tú àwọn ẹ̀sọ́ rẹ̀ siíẹ̀?
Ẹ óo mú díẹ̀ ninu ẹ̀jẹ̀ rẹ̀, ẹ óo fi sí ara ìwo pẹpẹ ati igun mẹrẹẹrin pèpéle rẹ̀, ati ara etí rẹ̀ yíká, bẹ́ẹ̀ ni ẹ óo ṣe wẹ pẹpẹ náà mọ́; bẹ́ẹ̀ ni ètò ìwẹ̀nùmọ́ pẹpẹ lọ.
Lockdown: Àwọn jàǹdùkú ṣe ikú pa ẹnìkan ní Aboru l'ágbàgbè Iyana Ipaja Oríṣun àwòrán, PIUS UTOMI EKPEI Àkọlé àwòrán, Lockdown: Àwọn jàǹdùkú ṣe ikú pa ẹnìkan ní Aboru l'ágbàgbè Iyana Ipaja Ènìyàn kan ti pàdánù ẹ̀mí rẹ̀ níbi ìjà àwọn jàndùkú láti Aborun àti Mosan ní agbègbè Oke-Odo àti Ipaja nípìnlẹ̀ Eko.
Bakan naa ni ẹgbẹ agbabọọlu Chelsea ti jawe olubori fun igba mẹrin, ti meji jẹ ti CWC, Uefa Cup ati CL.
OLUWA ní, “Ṣugbọn bí orílẹ̀-èdè tabi ìjọba kan bá kọ̀, tí wọn kò sin Nebukadinesari, ọba Babiloni, tí wọn kò sì ti ọrùn wọn bọ àjàgà rẹ̀, ogun, ìyàn ati àjàkálẹ̀ àrùn ni n óo fi jẹ orílẹ̀-èdè náà níyà títí n óo fi fà á lé ọba Babiloni lọ́wọ́.
Lasiko ti wọn n ba BBC Yoruba fọrọwerọ, awọn ibeji onibẹmbẹ oru ni, ara adugbo gan mọ awọn papọ pe, to ba di aago mẹta ni oru, ọkan ninu awọn yoo ji lati lọ ri ekeji lati sọrọ.
 Kiev 0-5 (0-8)Chelsea 🏴󠁧󠁢󠁥󠁮󠁧󠁿🇷🇺 Krasnodar 1-1 (2-3) Valencia 🇪🇸🇦🇹 Salzburg 3-1 (3-4) Napoli 🇮🇹🏴󠁧󠁢󠁥󠁮󠁧󠁿 Arsenal 3-0 (4-3) Rennes 🇫🇷🇵🇹 Benifca 3-0 (3-1) D.
Wọn ni o jẹ ohun ti o kọ ni lominu bi awọn alakoso NCAA ti ṣe ma n gbe awọn eeyan wa lati ita lati wa jẹ olori le awọn ọmọ ẹgbẹ awọn ti o kun ọju oṣunwọn.
 Austria pelu ami ayo meji sookan (2-1).
Ọpọ orin to n fọ awujọ mọ loriṣiiriṣii ni Falz ti gbe sita ṣaaju asiko yii.
Dafidi lọ sí ọ̀dọ̀ àwọn igba (200) eniyan tí àárẹ̀ mú pupọ, tí wọn kò lè kọjá odò, ṣugbọn tí wọ́n dúró lẹ́yìn odò Besori; àwọn náà wá pàdé Dafidi ati àwọn tí wọ́n bá a lọ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Temitope Akinnusi: Ọ̀pọ̀ iléeṣẹ́ ló takú láti gbà mí síṣẹ́ torí mo ní ojú kan Akintoye ní àwọn mẹ́rin ti wọ́n kọ lati ba awọn ṣe ìpàdé ti àwọn ṣe kẹ́yin, ti wan kọ̀ láti darapọ̀ mọ́ àwọn kò lágbára láti sọ pé òun kìí ṣe ààrẹ YWC.
Nítorí pé, ó gbé mi jù sinu ibú, ní ààrin agbami òkun,omi òkun sì bò mí mọ́lẹ̀;ọwọ́ agbára rírú omi òkun rẹ̀ sì ń wọ́ kọjá lórí mi.
EFCC ni Olawale tun fi ọpọ ayederu fọto ile ati ọkọ ti wọn yoo fun Hayatou ranṣẹ si i.
Awọn Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 3 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 5 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Ṣugbọn Ìwé Mímọ́ ti sọ pé ohun gbogbo wà ninu ìgbèkùn ẹ̀ṣẹ̀ kí á lè fi ìlérí nípa igbagbọ ninu Jesu Kristi fún gbogbo àwọn tí ó gbàgbọ́.
Kò sí ẹni tíí yan ara rẹ̀ sí ipò yìí.
Ọ̀rẹ́ Orímóògùnjẹ́ ni Ajíṣefínní tí ó ń ta kòkó.
Jotamu ọmọ rẹ̀ sì ń ṣàkóso ìjọba nípò rẹ̀.
Ṣugbọn ikilọ ti Apple fi sita ni pe iyatọ le wa nitori adugbo ti eeyan ba wa ati bi itakun ayelujara ibẹ ba ṣe lagbara to.
 O ṣapejuwe ọdun yii gẹgẹ bi eyi
Njẹ o mọ̀ boya mimu ọti maa n fikun adun ibalopọ laarin ololufẹ meji?
Musa sọ pe, o ti to ọdun mẹta toun ti dara pọ mọ awọn ajinigbe yii, iṣẹ toun si ni lati maa gbẹmi awọn eeyan.
Eyi ni akojọpọ awọn adẹrinpoṣonu ti wọn ti logba ni agbo sinima ni ilẹ Yoruba, amọ ti oju wọn ko fi bẹẹ se deede mọ ninu awọn fiimu agbelewo.
ti di pe ara o rokun, ara ko tun ro adire 
Ẹṣọ alaabo nilẹ Yoruba, Amọtẹkun nipinle Osun ti Kede faye gbọ pe ohun ko ni faye gba aṣọ iwọkuwọ ati titabuku ede Yoruba nipinlẹ naa.
Ṣugbọn mò ń làkàkà pé nígbà tí mo bá lọ tán, kí ẹ ní ohun tí ẹ óo fi máa ṣe ìrántí nǹkan wọnyi nígbà gbogbo.
Nigba to wa n fi okodoro ọrọ mulẹ pe ayaba si ni oun laafin Oyo, olori Badirat bọ soju opo Instagram rẹ, @queenola2, to si ṣe afihan aworan oun ati ọkọ rẹ, Alaafin papọ.
gbomi ewuro si ẹni ti won jọ n dupo naa iyen Abubakar Giri,ti egbe oselu  Social Democratic Party (SDP) ti o ni iye ibo
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Toma Unu: Ọmọbìnrin tó ń fi ẹsẹ̀ rẹ̀ ya àwọran nítori pe ó ni ìpènija ọpọlọ Ọ̀pọ̀ àwọn ọmọ Nàìjíríà ló ti ń ṣelédè lẹ́yìn ọmọbìnrin náà lójú òpó Twitter Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Contortionist: Mo lè gbé ìfun mi pamọ́ ki n tún se èémí!
Ife ibukun tí à ń dúpẹ́ fún, ṣebí àjọpín ninu ẹ̀jẹ̀ Kristi ni.
Lẹyin naa lo sọ fun iyawo rẹ pe, ko ba oun mu nkan ninu yaara ti wọn, o si salọ kuro nile.
Awọn ẹbi rẹ kede pe aisan ti wọn ko lee sọ bo ṣe jẹ lo gba ẹmi lẹnu rẹni ọdun 1940 ni wọn bii ni ilu Kano to si kẹkọ gba imọ ọjọgbọn ninu imọ eto ọrọ aje.
"O ni ""mo tun un sọ pe ọrọ eebu gbaa ni eleyii, mi o si le gba iru ẹ latọdọ ẹda kankan taa bi ninu obinrin""."
Ẹlẹ́wọ̀n tẹ́lẹ̀ gboyè ìmọ̀ ìjìnlẹ̀ méjì lọ́gbà ẹ̀wọ̀n Kíni ìdí ti àwọn ọmọ ogun fi n ṣọ́ àwọn Imaam ni Mecca?
“Baba, mo fẹ́ kí àwọn tí o fi fún mi wà pẹlu mi níbi tí èmi gan-an bá wà, kí wọ́n lè máa wo ògo tí o ti fi fún mi, nítorí o ti fẹ́ràn mi kí á tó fi ìpìlẹ̀ ayé sọlẹ̀.
Wo ohun tó yẹ kí o mọ̀ nípa òfin NCDC tó ń dá rògbòdìyàn sílẹ̀ Obìnrin pa olólùfẹ́ rẹ̀, ó fi se ìrẹsì Àjọ tó n mójútó ìpèsè òògùn ní America ti fọ́wọ́ sí lílo òògùn Ebola fí tọ̀jú Coronavirus Àwọn ọlọ́pàá wú òkú akẹ́kọ̀ọ́ Fásitì Uniport mẹ́ta tí àwọn ajínigbé sin O pari ọrọ rẹ pe ile ifowopamọ ọhun yoo bẹrẹ si ni ṣi awọn ẹka rẹ pada, ṣugbọn ko ni ṣi gbogbo rẹ tan nigba kan naa nitori awọn ẹka mii yoo wa ni titi fun awọn oṣu diẹ si.
O ni: “Ipade naa yoo waye laarin awon minista to n soju fun orile ede mokanlelaadota atawon alase toro kan gbogbo.
”Joṣua bá dá wọn lóhùn pé, “Ta ni yín, níbo ni ẹ sì ti wá?
Ko to di akoko yii, ni iwadii abẹle ti kọkọ fi lede pe, Adesina ko wu iwa ibajẹ kankan, amọ orilẹede Amerika kọ iwadii naa, ti wọn si gbe omiran kalẹ.
Nígbàkúùgbà tí o bá gbọ́ ohunkohun lẹ́nu mi, o gbọdọ̀ kìlọ̀ fún wọn.
Ṣé o fẹ́ fi júújúú bo àwọn eniyan wọnyi lójú ni, a kò ní dá ọ lóhùn.
ó ni àfojúsùn, ó sì níwà.
Ǹkan to sọ rèé Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Nigerian Youth Investment Fund: Ijọba àpapọ̀ yóò kó bílíọnù 75 owó ẹyá fún àwọn ilé ìfowópamọ́ kéékèké fún ìṣòwò àwọn ọ̀dọ́25 Agẹmo 2020 Nigeria Air Force recruitment 2020: Ilé iṣẹ́ ọmọogun Nàìjíríà ti ṣí ojú opó rẹ̀ fún ìforúkọ silẹ̀ àti ọ̀nà ti ó le gbà ṣe ìfọ̀rọ̀wánilẹ̀nuwò orí ayélujára fún iṣẹ́ náà25 Agẹmo 2020 Nigeria Police recruitment 2020: Ṣé àbáwọle sójú òpó NPF policerecruitment.
Awọn oṣisẹ eleto pajawiri Lastma ti wa ni ibi iṣẹlẹ naa ti wọn si tin gbiyanju lati wọ awọn ọkọ naa kuro loju ọna.
Awọn ọmọbinrin naa yoo kọnu ifẹ si ọkunrin naa, ti ko si gbọdọ kọ.
Ìgbà tí o kọ ń buu wa mo ti rò pé bí ó bá parí bíbú rẹ̀, ni a ó bẹ̀rẹ̀ ìjà, ṣùgbọ́n nígbà ti ó fi máa parí ọ̀rọ̀ rẹ̀, èrì ọkàn mi ti padà nítorì gbogbo ọ̀rọ̀ tí o sọ wọ̀n-ọnnì, kò fi wọn purọ́ mọ àwọn ọmọ aráyé,  nítorí eyí, ìgbà tí ó parí ọ̀rọ̀ rẹ̀, mo sọ orí kọ́, èmi àti àwọn ọ̀rẹ́ mmi dórikodò, à ń rìn kọ́ńdú kọ́ńdú lọ.
Aarẹ Trump si ti fi ọrọ sita loju opo Twitter rẹ pe oun fọkan ba iṣẹlẹ naa lọ Isẹlẹ iyinbọn kii ṣe ohun ajoji lorileede Amerika Lai pe yi ni Aarẹ Donald Trump ilẹ Amẹrika sọ pe asiko ti to ki ile aṣofin fọwọ si ẹkunrẹrẹ ofin ti yoo dẹkun ilokulo ibọn lawujọ.
" Lásìkò yìí bákan náà, àwọn ọmọ onílẹ̀ kó àwọn ọlọ́pàá leyin ni ti wọ́n sì ṣe àwọn tó n ṣiṣẹ́ lóri oko náà léṣe' Ó rọ ìjọba àpapọ àti ijọba ìpińlẹ̀ Oyo láti dá si ọ̀rọ̀ náà nítori ìdájọ ilé ẹjọ to waye ni 13/07/2016 ti parí ọ̀rọ̀ sùgbọ́n ti àwọn ọmọ onílẹ̀ Iragbiji tún wá lọ ń kó ọlọ́pàá sodí láti wá gba ilẹ̀ náà.
Bakan naa ni Ọgbẹni Gbadamosi tọka si pe, o tun mu ki owo ọja lọ soke pẹlu ìdá tó le ni ọgọrun.
Lẹ́yìn wọn, Hatuṣi ọmọ Haṣabineya ṣe àtúnṣe tiwọn.
Abubakar, ti o jẹ gomina to wa lori aleefa ni iye ibo  5,117 .
alufaa yóo lọ yẹ ilé náà wò.
Bí ó ti dé ibi ọgbà àjàrà àwọn ará Timna kan báyìí, ni ọ̀dọ́ kinniun kan bá bú mọ́ ọn.
Ilé aṣòfin ìpínlẹ̀ Oyo jáwée lọ sinmi nílé fún alága ìgbìmọ̀ mẹ́tàlá káàkiri ìjọba ìpínlẹ̀ Ilé aṣòfin ìpínlẹ̀ Oyo jáwée lọ sinmi nílé fún alága ìgbìmọ̀ mẹ́tàlá káàkiri ìjọba ìpínlẹ̀ Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí US presidential election 2020: Ta a ni Joe Biden tó ń díje fún ipò aárẹ America4 Bélú 2020 Fídíò, Soyinka Cancer: Àṣe ara mi ni iso ti n run gbogbo bí mo ṣe n ṣèrànwọ́ lórí jẹjẹrẹ27 Bélú 2019 Ekiti rape: Ẹni ọdún 51 fipá bá ọmọ ọdún 12 lòpọ̀, ìjọba ìpínlẹ Ekiti lẹ awòrán rẹ̀ gbangba sí àárín ìlú4 Bélú 2020 A ó ò dasẹ́ sílẹ̀ fún ojọ́ gbọọrọ tí ìjọba bá kọ̀ láti san owó oṣù mẹ́rin tó jẹ wa- Àwọn dokita ìpínlẹ̀ Ondo4 Bélú 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 3 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 5 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Ki wọn ma a se ere idaraya lasiko to yẹ.
Àmọ́ ó ní kó ni sì lílọ bibọ ọkọ àti èrò láti ìpínlẹ̀ kan si òmíràn lásìkò yii, tí wọn yóò sì gbé àwọn ẹnu bode ìpínlẹ̀ Osun tí pá.
Àáyá bẹ sílẹ o bẹ sáré,wábiwọ́sí ìyá ni Flying Eagles fi bẹrẹ fún Qatar Orúkọ àwọn Super Falcons 23 tó ń lọ France ti jáde Àwọn bàbá ìsàlẹ̀ òṣèlú tó bá ìtìjú bọ̀ nínú ìbò Gómìnà rèé NBC fọwọ́ sí ìdásílẹ̀ ilé iṣẹ́ Fulani Radio Ko da ajọ IAAF tun sọ pe awọn yoo f'ofin de Naijiria bi o ba kọ lati dawo naa pada lai pẹ.
O tẹsiwaju pe, awọn to n gbe ahesọ ọrọ kiri fẹ si Gomina Makinde lọna ni.
Oluwa sọ fún wọn pé, “Bí ẹ bá ní igbagbọ tí ó kéré bíi wóró musitadi tí ó kéré jùlọ, bí ẹ bá wí fún igi sikamore yìí pé, ‘Hú kúrò níbí tigbòǹgbò- tigbòǹgbò, kí o lọ hù ninu òkun!
O ni ko si ipese ina lati ọdọ ìjọba, ko si nọmbà foonu ipe pajawiri, pẹlu afikun pe, o yẹ ki agbekalẹ ilana wa fun ẹni to ba nilo itọju pajawiri, lọna ti igbele Covid-19 ko fi ni ṣe akoba fun ilera rẹ.
Ni ọpọ igba ni ọba oke maa nda ara to ba wu, ti yoo si mu ki eeyan kan ni oju ara ti ọkunrin ati obinrin papọ eyi ti awọn oloyinbo n pe ni 'Hermaphrodites'.
Kò pẹ́ púpọ̀ tí a kúrò ní ìlú náà tí ilẹ̀ fi ṣú, ọ̀nà ni a sì sùn mọ́jú ọjọ́ náà.
Okwaraji ṣubu lori papa, o si gba ibẹ ku nigba to n kopa ninu ifẹsẹwọnsẹ ati yege fun idije ife ẹyẹ Italian '90 to waye laarin Naijiria ati Angola niluu Eko lọjọ kejila oṣu kẹjọ ọdun 1989.
Ó bá ń gbé ìlú kan tí à ń pé ní Nasarẹti.
O ni laarin oru ni ọkan lara awọn oṣiṣẹ alaabo naa wa ji oun ninu ọkọ ti oun sun si pe eefin n ru jade lati abẹ ọkọ.
Oríṣun àwòrán, AFP Àkọlé àwòrán, Nelson àti Winnie Mandela nígbà tí wọ́n da sílẹ̀ l'ọ́gbà ẹ̀wọ̀n l'óṣù Kejì ọdún 1990 Lóòtọ́ ni abílékọ Mandela kò ṣ'ẹ̀wọ̀n fún ipa tó kó, ìgbìmọ̀ olùwádìí tí Àlùfá Desmond Tutu léwájú, ''Truth and Reconciliation Commission fi ìdí rẹ̀ múlẹ̀ pé ó kó ipa pàtàkì nínú ìṣẹ̀lẹ̀ naa."
Goodluck: Ṣèbí ajagunfẹ̀yìntì ni Buhari, o yẹ kó mọ ohun tó yẹ láti kápá ìpèníjà ààbò
naa jẹ 1,509,481, nigba ti awon to yege lati dibo jẹ 613,720Alamojuto eto idibo ni ipinle
Bi o ba ma'n gbadun ere alabala ti orukọ rẹ njẹ ''How to Get away with Murder,'' Morenike wa lara awọn ti wọn ma'n kọ itan fun ere naa.
 Ọlọ ́ run kò ní jẹ ́ kí á ri ogun .
ni deede aago  10:00 GMT, nigba ti aare
Fidio naa ree: Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Africa Eye: Ìrírí àwọn ọ̀dọ́bìnrin tó dágbà sójú pópó àti ìrètí wọn fún ọjọ́ ọ̀la Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Lẹyin naa ni wọn fi tipatipa bọ oruka ọwọ ọkan lara wọn ti Adebayo si gbe e mi loju wọn.
Theresa Villers, okan ninu awọn aṣofin ni UK lo fi to awọn to ku rẹ leti pe awọn eeyan 220, 330 lo ti buwọlu iwe ẹsun naa ni eyi to fun wọn ni aṣẹ lati gbe e yẹwo.
Wo iye owó tí ìjọba Amẹrika ń na sí ìdìbò Ààrẹ àti ibi tí owó náà ti ń wá Àwọn àkọ́lé ìròyìn mẹ́ta tó leè tẹ̀lẹ́ ìdìbò Ààrẹ ilẹ̀ Amẹrika Wo ǹkan tó yẹ kí o mọ̀ nípa Joe Biden, tó ń kojú Trump nínú ìbò America 5.
Ṣùgbọ́n ọ̀rọ̀ tiyín ti yàtọ̀ pátápátá, tiyín yìí lo sì wá fi hàn mi pé, ìwà ènìyàn ń pè ni ìfẹ́, ìfẹ́ kò lórúkọ méjì.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Lagos doctors strike: Ẹgbẹ́ dókítà bẹ̀rẹ̀ ìyanṣẹ́lódì lórí owó oṣù àti ètò adójútòfò fún ìtọ́jú covid-19 13 Agẹmo 2020 Oríṣun àwòrán, Twitter/Prof Akin Abayomi Nibi a ti n ṣe laa tii jẹ.
O salaye pe, pelu ogoro milionu merinlelogun ile ti o n samulo ero amohunmaworan,  eyi ti a tun je orile-ede ti ko se yesile ninu eto idanilaraya, Naijiria yoo di olu awon orile-ede ero amohunmaworan nile Afrika laarin odun perete.
Nítorí náà, gẹ́gẹ́ bí Ẹ̀mí Mímọ́ ti wí,“Lónìí, bí ẹ bá gbọ́ ohùn rẹ̀, 
Ṣugbọn ìrìbọmi tí Johanu ṣe nìkan ni ó mọ̀.
George Floyd: Àwọn olùfẹ̀hónúhàn wó ère ówò ẹrú lulẹ̀ ní UK Ifẹhonuhan lati tako iwa ẹlẹyamẹya l'Amẹrika ati ilẹ Gẹẹsi bẹyẹn yọ, lẹyin tawọn olufẹhohan wo ere oniṣowo ẹru, Edward Colston ni Bristol.
Joṣua ọmọ Nuni ati Kalebu ọmọ Jefune tí wọ́n wà lára àwọn amí fa aṣọ wọn ya láti fi ìbànújẹ́ wọn hàn.
Wọ́n lọ sí Gileadi, ati sí Kadeṣi ní ilẹ̀ àwọn ará Hiti.
Ọrọ ko tan sibẹ́ Pẹlu gbogbo wahala wọn yi,igbesẹ Google yi pẹlu aṣẹ ti aarẹ Trump pa,Huawei kii ṣe ile iṣẹ ti a fi ọwọ rọ sẹyin lagbaye.
Ṣugbọn yóo fi òdodo ṣe ìdájọ́ àwọn talaka, yóo fi ẹ̀tọ́ gbèjà àwọn onírẹ̀lẹ̀,yóo fi ọ̀rọ̀ ẹnu rẹ̀ na ayé bíi pàṣán,yóo sì fi èémí ẹnu rẹ̀ pa àwọn oníṣẹ́ ibi.
 Ọ ̀ pọ ̀ lọpọ ̀ àwọn idoma ni wọ ́ n yan iṣẹ ́ àgbẹ ̀ láàyò .
Ohun akọkọ ti awọn ti nnkan yii ba ṣẹlẹ yoo se ni lati maṣe ko aya soke, ki wọn fi ọkan balẹ, i wọn si ke si awọn onimọ nipa rẹ fun iranwọ, iyẹn gẹgẹ bi dokita Ezenwankwo ṣe sọ.
Sotitobire: Ojú àwọn Wòlí tó tí lọ sẹ́wọ̀n lórí ẹ̀sùn ọdaràn tẹ́lẹ̀ rèé Ìdájọ́ òdòdò ló fẹsẹ̀ múlẹ̀ lórí ọ̀rọ̀ Pásítọ̀ Sotitobire - Agbẹjọ́rò fún ìjọba Bode George ní Fayose gọ̀, ó fẹnu họra, Fayose ní ''ẹ ò lè pa mí bí ẹ ṣe pa Bola Ige Tí àtúntò kò bá wáyé ní Naijiria, ó ṣeéṣe kó túká- Pásítọ̀ Adeboye 'N500 dé fún gbogbo ọmọ tuntun lóṣooṣù bí mo bá di gómìnà Ondo - Adeleye AAC Ọ̀rọ̀ Soyinka àti Obasanjo papọ̀ lórí pé Buhari n ṣe ìpínyà Nàìjíríà Ọjọ́ ìdájọ́ déé!
Lero tiyin, se ko yẹ ki ijọba fi ile atawọn dukia ti Fagunwa lo yii se ibudo irinajo afẹ fun iran Yoruba, ka si tun ibẹ se.
Nítorí ìdí èyí, kẹ̀kẹ́ gígùn kò wọ́pọ̀ ní ilẹ̀ Yoòbá.
Kin lo yẹ ko mọ nipa apọju oogun Tramadol ninu ara ?
Nítorí náà, ó fi àkọ́bí rẹ̀ ọkunrin, tí ó yẹ kí ó jọba lẹ́yìn rẹ̀ rú ẹbọ sísun sí oriṣa Moabu, ní orí odi ìlú náà.
Dino ni isẹ ọwọ awọn ọta oun ni ipolongo ọun ati wi pe iru iwa bẹẹ ko boju mu.
MKO Abiola, iṣẹ́ aṣẹ́gità ló fi bẹ̀rẹ̀ okoòwò Iṣọla Oyenusi rèé, ẹnití ìfẹ́ obìnrin ṣun dé ìwà ìdigunjalè Taiwo Akinkunmi, ọmọ Ibadan tó ya àsìá Naijiria Ayinla Ọmọwura, orin èébú àti oríyìn lo fi di ọ̀rẹ́ àwọ̀n obìnrin Wọn salaye pe eyi too mu ki sunkẹrẹ fakẹrẹ ọkọ dopin loju ọna yii, ti ara yoo si rọ awọn eeyan to n gbe ni Lekki-Ajah.
Pilatu bá bi í pé, “Ṣé ìwọ ni ọba àwọn Juu?
Oríṣun àwòrán, AFP Àkọlé àwòrán, Ni orilẹede Zimbabwe, awọn eniyan pejọ lati sedaro asaaju ẹgbẹ oselu Movement for Democratic Change (MDC), Morgan Tsvangirai to ku lọmọ ọdun marundinlaadọrin.
soro  tan, o ni oju ona to lo si  Kaduna-Abuja, ti o ti di ojo ibẹru , ti wa ni
O fihan pe ko fẹ si iyatọ laarin Atiku ati Buhari nitori awọn mejeeji dijọ n wa ohun ti ko sọ̀nu kiri ni.
Nítorí láti ọ̀dọ̀ Oluwa ni mo ti gba ohun tí mo fi kọ yín, pé ní alẹ́ ọjọ́ tí a fi Jesu Oluwa lé àwọn ọ̀tá lọ́wọ́, ó mú burẹdi, 
Bí ó bá ṣe pé ọ̀tá ní ń gàn mí,ǹ bá lè fara dà á.
Obinrin kan wà, tí nǹkan oṣù rẹ̀ kò tètè dá rí fún ọdún mejila, ó gba ẹ̀yìn wá, ó fi ọwọ́ kan ìṣẹ́tí aṣọ Jesu; 
Ọmọ ilu Bajuwen, ni ijọba ibilẹ Odẹda, ni ipinlẹ Ogun ni Lekan.
Ogagun Akili Mundos tuko awon omo-ogun orile-ede Congo fun odun meji fun ise-akanse tako awon omo ogun olote orile-ede Uganda ti a mo si Allied Democratic Forces (ADF)Ajo isokan orile-ede agbaye ri-I lasiko naa pe, ogagun-agba Mundos lowo ninu siseku pa awon eniyan ti won kii se ologun, ti iye won to irinwo.
Bẹ́ẹ̀ ni OLUWA ṣe gba Hesekaya ati àwọn ará Jerusalẹmu sílẹ̀ lọ́wọ́ Senakeribu, ọba Asiria, ati gbogbo àwọn ọ̀tá Hesekaya, ó sì fún un ní alaafia.
Dafidi bá tu Batiṣeba, aya rẹ̀ ninu, ó bá a lòpọ̀, ó sì bí ọmọkunrin kan fún un.
A máa lọ láti ààfin ọba Farao káàkiri gbogbo ilẹ̀ Ijipti.
Agolo gáásì kéeké tó ń jò bú gbàmù l‘Eko, ẹ̀mí kan bọ́, mẹ́ta fara pa Nàìjíríà ṣí àwọn ilé ìwé padà; Ìdánwò WAEC á bẹrẹ lẹyìn ọdún Iléyá!
Ẹ má ṣe rò pé èmi ni n óo fi yín sùn níwájú Baba, Mose tí ẹ gbẹ́kẹ̀lé gan-an ni yóo fi yín sùn.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Pasitọ ge ọmọ ijọ lori, sinku rẹ sinu ṣọọṣi nipinlẹ Ogun 4 Ìgbé 2018 Oríṣun àwòrán, The Punch Àkọlé àwòrán, Oluwatobiloba Ipense jẹ oluṣọ ni Holy Gathering Evangelical Church of God, Papalanto ni Ewekoro Ọwọ ṣikun awọn ọlọpa ipinlẹ Ogun ti tẹ arakunrin kan ti o jẹ oluṣọ agutan ni ile ijọsin kan ni agbegbe Ewekoro nipinlẹ Ogun, Oluwatobiloba Ipense wipe o bẹ ori arabinrin abilekọ kan ti o ge apa rẹ mejeeji pẹlu ki o too sin oku rẹ sinu ile ijọsin rẹ.
Nigba ti ikọ BBC news de ile oloogbe naa lagbagbe Bourdilourn ni ilu Eko lowurọ ọjọ Aje nibi ti awọn eeyan leni ejeeji ti n wọle ba wọn daro.
Awọn ayaba kii saba yọju sita ni ọjọ lasan, inu káà wọn ni wọn saba maa n wa.
Lẹ́yìn rẹ̀ ni Baruku, ọmọ Sabai, ṣe àtúnṣe láti apá ibi Igun odi títí dé ẹnu ọ̀nà ilé Eliaṣibu olórí alufaa.
Issac Promise' Death: Àdánù ń lá ni ikú agbábóòlù mẹta jẹ fún wa
Gbogbo ìlú bá jáde lọ pàdé Jesu.
Nigbati aawọ yi waye, Gowon Simeon fi ọbẹ gun Awolu Zekeri ni itan, eyi to fa iku Zekeri lona ile iwosan.
Lori eyi, Mompha to wa latimọle bayii.
O ni idi ti eyi fi ri bẹẹ ni pe gbogbo wọn gba pe ẹẹdẹgbẹta miliọnu naira ti ajọ NBC ni ki ileeṣẹ aladani san ti pọju ni.
O wa pari ọrọ rẹ pe oun ko tii le sọ ni pato akoko ti ASUU yoo fopin si iyanṣẹlodi naa.
Amọ a gbadura pe ki Ọba oke tẹ oloogbe naa si afẹfẹ rere.
Oríṣun àwòrán, Church of Satan archive Àkọlé àwòrán, Awọn ọmọ ìjọ sàtánì ń bínú sí Nàìjíríà Femi Fani-Kayode tó jẹ́ ọmọ ẹgbẹ alátakò People's Democratic Party (PDP), sọ pé Ọ̀jọ̀gbọ́n Osínbajo ò yẹ lẹ́ni to lè bẹnu àtẹ́ lu àwọn olùṣọ́ àgùntàn tó hùwà àjẹbánu ni orílẹ̀-èdè yìí nítorí òun gan-an tí dalẹ̀ àwọn àwọn ọmọlẹ́yìn Kírístì Ọ̀rọ̀ ti Fani Kayode so lórí òpó twitter rẹ̀ tó fa ìbínú tí ìjọ Sàtáni tó ti bẹ̀rẹ̀ láti ọdún 1966 nìyìí: Ó sọ̀rọ̀ náà nígbà tó ń fèsì sí ọ̀rọ̀ ti Osinbajo sọ láti tako àwọn olùsọ àgùntan tí wọn ni àwọn tako ìgbógun ti ìwà àjẹbanu ti ìjọba àpapọ̀ ń jà àti pé àwọn kìí wàásù lòdì síi.
“Ní ìrọ̀lẹ́ ọjọ́ kẹrinla oṣù kinni ni kí ẹ máa ṣe àjọ ìrékọjá OLUWA.
Awọn alaṣẹ Ka'bah ni ọpọ ero lo n wa si Mecca ati Medinah fun idi loriṣiiriṣii ni eyi to fi di dandan lati daabo bo awọn aafa Olorun yii lọwọ ikọlu awọn ero.
Tiger Brands Oríṣun àwòrán, Reuters Nigba ti ileeṣẹ Tiger Brands wọ Naijiria lọdun 2012, ida mẹtalelọgọta owo rẹ lo fi ṣowo nileeṣẹ Dangote, eyii to mu ko jẹ ọkan gboogi lara awọn to lẹnu nibẹ.
Ẹ foríjìn wá ọmọ Nàìjíríà, mó mọ̀ pé ẹ̀ ń bínú tórí a kò tètè gbé ìgbésẹ̀ lórí ọ̀rọ̀ EndSARS- Osinbajo Àwọn olùwọ́de ṣetán láti bá mínísítà FCT Abuja wọ̀ ṣòkòtò kan lórí àṣẹ má ṣe ìwọ̀de Tola Oyediran ọmọ Obafemi Awolowo ti jáde láyé Wo ìsọ̀rí àwọn tó jẹ́ kí ìwọ́de End SARS / end SWAT lárinrin àti ìtumọ̀ Ohun tí ojú ìyàwó mi rí lọ́wọ́ SARS kò ṣe é fẹnusọ- Poju Oyemade Wo nọ́mbà tí o le è pè láti gba owó gbà-má-bínú tí ọlọ́pàá bá fìyà jẹ ọ́ lọ́nà àìtọ́ l'Eko Ki lo fa ijamba ina naa?
Ẹni to bori: Namibia Aṣekagba South Africa Namibia South Africa vs Namibia.
₦30,000 owó oṣù yòó bẹ̀rẹ̀ ní September - Alága ẹgbẹ́ òṣìṣẹ́ l‘Ekiti Ọwọ́ EFCC tẹ ọ̀kan lára àwọn ti FBI fi èsún jìbìtì kàn!
Awọn oluwaadi ti kesei ẹnikẹni to ba ni iroyin to le mu ki awọn ri awọn to hu iwa yi lati kan si awọn lori ago 850-891-4200 tabi Crime Stoppers lori ago 850-574-TIPS.
Ọla Adedibu ní Ladoja jẹ̀ tó fi wọlé Gómìnà l‘Oyo labẹ ẹgbẹ́ PDP - Obasanjo Ẹ̀sìn kò fàjà!
ti mo lero pe o yẹ, ki a sisẹ fun ni bi a o se ni anfaani lati maa dibo
River ,ekun Gusu orile ede Naijiria.
Ibi tí wọn mú un ní ìgbèkùn lọ ni yóo kú sí; kò ní fi ojú rí ilẹ̀ yìí mọ́.
Davido, Simi,Omawumi gbégba orókè nínú ìdíje 2018
Nítorí náà, ó ń bá àwọn Juu ati àwọn olùfọkànsìn tí kì í ṣe Juu jiyàn ninu ilé ìpàdé ní ojoojumọ.
Ida meje ninu ọgọrun, (7%) ko fara mọọ Ida mẹrinla ninu ọgọrun (14%) ko tilẹ fi sibikan.
Oríṣun àwòrán, Reuters Àkọlé àwòrán, Wọn fi ẹsun kan an pe o n tẹ awọn alatako ri mọlẹ lati ṣi wa lori alefa Abdelaziz gbiyanju lati rii pe alafia jọba ni orilẹede Algeria bi o tilẹ jẹ pe awọn onija ẹsin Islam ṣi tẹsiwaju ti wọn si yan orukọ tuntun Al-Qaeda lọdun 2007, wọn n ṣe ikọlu kaakiri awọn orilẹede agbegbe.
Ajọ naa tun sọ pe ifẹhonuhan ti wọn n ṣe lori fopin si ọlọpaa SARS eyi ti ijọba ti fagile jẹ inilara fawọn ọmọ Naijiria mii.
" wọ ́ n pèé ní "" Ìkan lára àwọn márún tí ó gbayì jùlọ ní bíi ọdún mẹ ́ wá sẹ ́ yìn "" tí ó jẹ ́ pé ní ọdún 2009 , ó gba ẹ ̀ bùn geoffrey beene lifetime achievement award láti council of fashion designers of america ( cfda ) , tí ó darapọ ̀ mọ ́ àwọn yves saint laurent , giorgio armani , ralph lauren , àti diane von furstenberg ."
Aare soro ohun di mimo lasiko
Oríṣun àwòrán, AFP Àkọlé àwòrán, Ni Jerusalẹẹmu, alufaa onigbagbọọ orilẹede Ethiopia kan n gbadura lẹgbẹ ilẹkun ile-ijọsin Holy Sepulchre to wa ni titi.
    Ojú mi gbangba báyìí ni wọ́n ṣe ń kọjá,mo sì dúró mo n wo ìgbà tí Ẹlẹ́gbára pàápàá máa tẹ̀lé wọn.
Ìtàn kíkùn lórí Mọ́ṣáláṣí Anabi ní Medina tó bẹ̀rẹ̀ lọ́dún 1440 sẹyin Jesu orí ayélujára kan rèé tó ń ṣèlérí iṣẹ́ ìyanu l‘Afirika Àkọlé àwòrán, Inu ile ijọsin Sistine ti idibo ti maa n waye.
Oluwatoyin Olanipekun to jẹ akẹkọọ-jade fasiti Obafemi Awolowo ni Ile Ife Oodua nibi ti ojumọ ti n mọ waye lo ba BBC sọrọ ni kikun lonii.
Ọdún mẹtadinlaadoje (127) ni Sara gbé láyé.
Kayode ti owo rẹ̀ lọ́dún kò ju ẹgbẹ̀rún mẹ́tàdínlọ́gọ́ta pọ́ùn lọ lọ́dún ni wọ́n rán lọ sẹ́wọ̀n lórí ẹṣùn lílu ọwó ìjó Haberdasher' ilé ìwé ìpínlẹ̀ Aske ni jibiti.
EndSARS: Olórí ilé aṣofín-ṣòfin ní ìṣúnà 2020 gbọdọ̀ pèsè owó fún ASUU bí bẹ́ẹ́kọ̀.
Iyẹn awọn ipinlẹ meje to ni oun lọ'' Ibeere mi ko ju bayi lọ ti Minisita si gbanajẹ to bẹrẹ si ni mu mi bu.
Láti Bene Jaakani wọ́n lọ sí Hori Hagidigadi.
Ori ibusun Fagunwa ree bi o tilẹ jẹpe awọn eeyan kan tun ti lo ori ibusun yii lẹ yin iku rẹ Àkọlé àwòrán, Lara awọn eroja ta foju ri ni yara Fagunwa ree.
àwáàrí fún gbogbo àwọn tí ó fẹ́ mú wọ̀n dè.
Ẹlẹẹkẹjọ ni yii ti Fulham yoo ma fidi rẹmi ninu idije Premier League ti saa yii.
ISWAP jẹ ọkan lara awọn ẹya Boko Haram.
Bi wọn ṣe n ṣe aṣọ ibomu.
O wa rọ awọn ara ilu lati maa fi gbogbo igba dupẹ lọwọ Ọlọrun, paapaa fun ilera pipe ati alaafia ara, gẹgẹ bi ẹbun nla ti Ọlọrun fun awọn eniyan.
Mo mọ̀ pé agbára rẹ kéré, sibẹ o ti pa ọ̀rọ̀ mi mọ́.
ANC pahunpọ pe ki Zuma f'ipo s'ilẹ
Gomina Ipinlẹ Eko Babajide Sanwo Olu pẹlu awọn ti wọn jọ kọwọ rin lati wo idaniloju ọkọ naa ni Falọmọ, ilu Eko.
Gẹ́gẹ́ bi ìṣe ọkọ rẹ̀ tó ti di olóògbé, Lady Peller, gẹgẹ bi àwọn èniyàn ṣe máa n pé, náà gbówọ́ nínú ká pidán, pàápàá jùlọ láàrìn ọdún 1980 si 1990.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Coronavirus in Nigeria: Ǹjẹ àgbo lè ṣe òògùn coronavirus?
Ọdun mejilelaadọrin ni oloogbe naa lo loke eepẹ, ko to ki aye pe o digbose.
Ṣugbọn lọdun 1958 ni gbogbo ala ire Marcos Perez pe ki iṣẹ akanṣe yii di ẹṣin iwaju ja sofo to si di ẹsin inu iwe lasan lasan.
to je opakutele si idagbasoke ati ilosiwaju ekun Gusu yii .
Èyí yóo jẹ́ ìlànà ayérayé fun yín, kí wọ́n lè máa ṣe ètùtù fún àwọn ọmọ Israẹli ní ẹ̀ẹ̀kan lọ́dún, nítorí ẹ̀ṣẹ̀ wọn.
Chimamanda Adichie ninu oro rẹ ni iṣẹ Harold Pinter maa n fun oun ni iwuri nigba gbogbo ni.
Mo rí ìfarahàn ògo Ọlọrun Israẹli níbẹ̀ bí mo ti rí i lákọ̀ọ́kọ́ ní àfonífojì.
Sedekaya ṣọ̀tẹ̀ sí Nebukadinesari, bẹ́ẹ̀ sì ni Nebukadinesari ti fi ipá mú un búra ní orúkọ OLUWA pé kò ní ṣọ̀tẹ̀ sí òun.
'Óṣeéṣe kí ọ̀rẹ́kùnrin Khadijat fẹ́ fi ṣowó' Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Ohùn gooro ló gbé mi dé ọ̀dọ̀ ààrẹ̀ Bush, Obama, Obasanjo, Goodluck, Buhari' 'Afẹsunkan gba anfani igbeyawo, ọmọ bibi ati ẹmi gigun lọwọ ọga rẹ' Adajọ ni bi Joel ṣe pa alaanu rẹ, oo gba anfani igbeyawo, ọmọ bibi ati ẹmi gigun lọwọ Adeleke.
Ọlọrun baba rẹ yóo ràn ọ́ lọ́wọ́.
Oníṣègùn ninú òwe yi lè jẹ́, Òbi, Ọ̀gá ilé-iṣẹ́, Adájọ́, Ọlọpa, Ọ̀rẹ́, Ẹ̀gbọ́n, Àbúrò àti bẹ́ ẹ̀ bẹ́ ẹ̀ lọ, nigbati Aláìsàn jẹ ẹni ti ó ṣẹ̀.
N kò lẹ́tọ̀ọ́ sí èyí tí ó kéré jùlọ ninu ìfẹ́ ńlá rẹ tí kì í yẹ̀, ati òdodo tí o ti fihan èmi iranṣẹ rẹ, nítorí ọ̀pá lásán ni mo mú lọ́wọ́ nígbà tí mo gòkè odò Jọdani, ṣugbọn nisinsinyii, mo ti di ẹgbẹ́ ogun ńlá meji.
Ohun ta ba se laye lo ja ju, tori naa, ẹjẹ ka gbe ile aye se rere nitori bo pẹ, bo ya, bi onirese wa ko ba fin igba mọ, eyi to ti fin silẹ ko lee parun.
Bí ẹnikẹ́ni bá fẹ́ fi èdè àjèjì sọ̀rọ̀, kí wọ́n má ju meji lọ, tabi ó wá pọ̀jù patapata, kí wọ́n jẹ́ mẹta.
" Àpètán Ọọ ̀ ni ni "" ọni kọ ́ ni ilẹ ̀ "" ."
Nítorí ẹni tí ó bá ní nǹkan, òun ni a óo tún fún sí i, kí ó lè ní ànító ati àníṣẹ́kù.
" Ti wọn ba gbiyanju ati mu ẹ binu, wa nnkan mii ṣe, bii ki o kawe ti o ba fẹran tabi ohunkohun to le mu ọkan rẹ jina rere si sakani wọn.
(1,821)       Lara awọn ọmọ ẹgbẹ Ile Aṣofin naa ti wọn dibo
Láti Tapua, ààlà náà lọ sí apá ìwọ̀ oòrùn títí dé odò Kana, ó sì pin sí Òkun Mẹditarenia.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Akomolede ati Aṣa lori BBC: Mọ̀ si nípa oríṣìí ẹ̀ka ìsọ̀rí ọ̀rọ̀ àti ìwúlò wọn Iya agba ni, Ọba Layode naa kii se ọba yẹpẹrẹ ti wọn kan le pa tuẹ bii ẹni pa adiẹ nitori oun gan le pawọda nilana ti ibilẹ pẹlu oogun abẹnu gọngọ.
Ninu ilẹ̀ ẹ̀yà Aṣeri, wọ́n fún wọn ní Maṣali ati Abidoni; 
Kí ló dé tí ìjọba Ilẹ̀-Adúláwọ̀ ń f'òfin de ọ̀rọ̀ sísọ orí-ayélujára?
“Bẹ́ẹ̀ gan-an ni, àwọn èrò ẹ̀yìn yóo di ará iwájú, àwọn ará iwájú yóo di èrò ẹ̀yìn.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Se bia nikan lo n jẹ ki ikun yọ sita?
Wọn wá sí ilẹ̀ Ìjẹ̀ṣa láti dó sí kí wọn lè ni àyè ijọba tiwọn.
À-rí-gi-ṣẹ́-gi"" lọ̀rọ̀ ti a mu lonii, awọn itumọ to wọle kuku wa ṣugbọn ọpọ ọdọ Yoruba ṣi nilo akọmọlede."
Ikede yii lo waye lẹyin ti obinrin kan to ni arun naa sa kuro nile itọju awọn alarun Coronavirus.
”Dafidi bá ranṣẹ sí Abigaili pé òun fẹ́ fẹ́ ẹ.
wa laarin  awon onile ati ayalegbe  lọwọ lati wa ni irepo ati pe yoo tun ran awon
Ìyá ọmọ tó sọnú níléèjọ́sìn l'Akure bú sẹ́kún nílé ẹjọ Báwo ni o ṣe le mọ̀ pé o ní àrùn Coronavirus?
Mose wí fún wọn pé, “Ẹ jẹ èyí lónìí, nítorí pé òní ni ọjọ́ ìsinmi OLUWA, ẹ kò ní rí kó rárá ní òní.
Babalwa lasiko to n ba ololufẹ rẹ sọrọ ni eni to ba wu oun ninu ọkunrin ati obinrin ni oun le fẹ, nitori oun ko ni ile ọmọ bi awọn obinrin miran, sugbọn oun ni ara bii ti obinrin.
Day to ku ni ẹni ọdun mẹtadinlọgbọn dero ile iwosan lọjọ Satide to kọ ja, ko da ko le sọrọ mọ, bẹẹ ni ko mo ohun kankan mọ nitori.
” Nítorí náà, kò sí ẹnikẹ́ni lọ́dọ̀ Josẹfu nígbà tí ó fi ara rẹ̀ han àwọn arakunrin rẹ̀ pé òun ni Josẹfu.
Wíwó rẹ̀ yóo dàbí ìgbà tí eniyan la ìkòkò mọ́lẹ̀,tí ó fọ́ yángá-yángá,tóbẹ́ẹ̀ tí eniyan kò rí àpáàdì kan mú jáde ninu rẹ̀,tí a lè fi fọn iná ninu ààrò,tabi èkúfọ́, tí a lè fi bu omi ninu odò.
Josaya, ọmọ rẹ̀ sì jọba lẹ́yìn rẹ̀.
Boasi bí Obedi, Obedi sì bí Jese.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Buhari: Mo tara lori ijinigbe ju ijọba ana lọ 14 Ẹrẹ̀nà 2018 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Buhari ni oun yoo sa gbogbo agbara to ba wa nikawọ oun lati gba itusilẹ awsn akẹkọ Dapchi Aarẹ Muhammadu Buhari ti kede lọjọru pe ijọba oun tete gbe igbesẹ lọjọ kọkandinlogun osu keji ọdun yii ti ikọ Boko Haram ji aadọfa akẹkọ gbe lọ nileẹkọ girama to wa nilu Dapchi nipinlẹ Yobe.
Ẹgbẹ agbaagba nilẹ Yoruba, YCE lo rọ igbakekeji aarẹ wi pe ko ma kọwe fi ipo rẹ silẹ.
Níbẹ̀ ni ó ti rú ẹbọ sísun, ati ẹbọ ohun jíjẹ, ati ti ọ̀rá ẹran tí ó fi rú ẹbọ alaafia; nítorí pé pẹpẹ bàbà tí ó wà níwájú OLUWA kéré jù fún àpapọ̀ gbogbo àwọn ẹbọ wọnyi.
Iro ibọn naa ni wọn ni o dun fun iṣẹju diẹ ki o to dakẹ.
Lati igba ti eto naa bẹrẹ ti o si foju han ni awọn eeyan ti n ṣe eemo ohun to mu ki ọmọ ọmọ Awolowo lọ darapọ mọ eto naa.
"Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Segun mu òògùn apakòkòrò tórí máàkì 167 nínú JAMB Nàìjíríà yóò ní iná, kò ní ní, di ìtahùn síra láàrin TCN, TUC Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Àwọn onímọ̀ ọpọlọ ní to bá gbé ìgésẹ̀ yí, aṣeyege dájú ní ìdánwò ""Awọn ọmọ ẹgbẹ wọnyii, ti Leonard Ezenwa , akọwe apapọ ẹgbẹ yii tẹlẹ ti wọn paṣẹ lọ rọọ kun nile fun lori awọn ẹsun to rọ mọ ṣiṣe owo ẹgbẹ baṣubaṣu , ko sodi ti fihan pe awọn ko ni ipin ninu awọn ilana ati ohun ti ẹgbẹ oselu African Action Congress duro le."
Oríṣun àwòrán, @HMKemiAdeosun Àkọlé àwòrán, Kemi Adeosun Lórí ọ̀pọ̀lọpọ̀ ìwé ìròyìn abẹ́lé ní orílẹ̀èdè Nàìjíríà ni ó ti jáde wí pé mínísítà àná fún ètò ìsúná, Kemi Adeosun ti rìnrìnàjò jáde kúrò lórílẹ̀èdè Nàìjíríà.
Khalifa:Khalifa ni ọga Mukadam, arole Shehu loju ọna ibẹlọrun ati isunmọ Ọlọrun ọba to wa.
Ẹgbọ ọ̀rọ Madam Sajẹ siwaju- Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fọ́nrán ohùn, Sajẹ: Mo n rọ awọn akẹẹgbẹ mi lati se suuru de asiko Ọlọrun Lara awọn ere ti Madam Sajẹ ti se, eyi to fun ni okiki ninu isẹ tiata ni Nkan Okunkun, Ọmọ Ẹlẹmọsọ, Serekode, Moriyeba, Olowo laye mọ, Ọjọ Ikunlẹ ati bẹẹ bẹẹ lọ.
Won ni enikeni to ba jẹ́ musulumi ni Naijiria ni ilana ofin wa fi aaye gba ki wọ́n gbe lọ sile ẹjọ́ Sharia ki wọ́n si tẹle asẹ́ ti Adajọ Sahria ba pa bii ti Yahaya ti adajo Sharia da ẹjọ́ iku fun yii.
Àmọ́ lẹ́yìnọ̀rẹyìn o, kòsí ẹni tí kò ní kú, ti oko baba rẹ̀ ní di ìgbòòrò – gẹ́gẹ́ bí òwe Yoòbá kan – a dífá fún Rolihlahla tó w'àjà l'ọ́sẹ̀ tó kọjá, ti gbogbo aráyé ń ṣọ̀fọ̀ rẹ̀.
OLUWA bá rán angẹli kan lọ pa gbogbo akọni ọmọ ogun, ati àwọn ọ̀gágun ati àwọn olórí ogun Asiria ní ibùdó wọn.
Yóo ya ọjà tí ó ń tà ati èrè tí ó bá jẹ sọ́tọ̀ fún OLUWA, kò ní máa to èrè rẹ̀ jọ, tabi kí ó máa kó o pamọ́; ṣugbọn yóo máa lò wọ́n láti pèsè oúnjẹ ati aṣọ fún àwọn tí ó bá ń sin OLUWA.
Ni Ogunjọ, Osu Keje, ọdun 1969 ni ọkọ ofurufu Apollo 11 to gbe wọn lọ si inu Osupa sọkale si ile isẹ ofurufu, Tranquility Base.
Nígbà tí Jesu rí i tí ó dùbúlẹ̀ níbẹ̀, tí ó sì mọ̀ pé ó ti pẹ́ tí ó ti wà níbẹ̀, ó bi í pé, “Ṣé o fẹ́ ìmúláradá?
Gambia, Guinea, Mali, Mauritania, Niger ati orile-ede Senegal, erongba naa si
Kí OLUWA máa ranti ẹ̀ṣẹ̀ àwọn baba rẹ̀,kí ó má sì pa ẹ̀ṣẹ̀ ìyá rẹ̀ rẹ́.
Wo arẹwà tí àwọn ọmọ Nàìjíríà fẹ́ kó di àárẹ wọn
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Bí ìrẹsì tèmi Ayinde bá ń pàkùta, kò tọ́ sẹ́nu aláàrù Barrymaade' Gẹgẹ bi o ṣe wa ninu akọsilẹ iroyin to jade, awọn ọna naa ni: 1.
Ní ọdọọdún ni àwọn ọmọ ogun Moabu máa ń gbógun ti ilẹ̀ àwọn ọmọ Israẹli.
Ibi to lewu ju nileewosan ni yara ijẹun.
DSS ti fi igbákejì gómìnà CBN tó ní gómìnà kan ní Àríwá Naijiria ní Ọ̀gá Boko Haram sílẹ̀ Ogundipe gbé fásitì Unilag ló sí iléẹjọ́ nítórí wọn yọ́ ní ipò VC 'Inú mi dùn pé wọ́n dájọ́ sísọ̀kò pa bàbá arúgbó tó fipá b'ọ́mọ lòpọ̀' Ikú dóró!
Bí ẹnikẹ́ni tí kì í ṣe ọmọ Lefi bá súnmọ́ tòsí wọn, pípa ni kí wọ́n pa á.
”Aare tun salaye lofintoto ojuse igbimo tuntun ohun pe: “Igbimo yii yoo maa mojuto bi won yoo se maa samulo isuna ti ijoba yoo pese fun awon idagbasoke ati ise akanse naa , pipese awon ohun amayederun, bi opopona marose, ile-igbe, sise amojuto awon agbegbe awon to kudie kaato fun, kiko ile-iwosan ati awon ohun mere-mere miiran si awon ipinle mefa yii.
Coronavirus Pandemic: Babàbá Adeboye ní coronavirus kò lè tán lórí ilẹ̀ ayé pátápátá Oríṣun àwòrán, Facebook/Pastor E.
”Ni bayii, iko agbaboolu Crystal Palace, Wolverhampton Wanderers ati Shanghai SIPG ti o wa ninu idije China ti fi erongba won han lati ra Moses wa sinu iko won.
Oludamọran Aarẹ, Shehu ni yoo lọ fun eto Umrah niluu Mecca lẹyin apero ti yoo waye niluu Riyadh.
Aso Villa: Wàhàlà kankan kò rúgbó nílé Ààrẹ
Ile aṣofin kekere ti yọ ọ nipo, Aarẹ Trump si ni aarẹ kẹta ti orukọ rẹ wọ inu iwe itan awọn aarẹ America ti wọn yọ nipo.
 O ni: “ọna ti a fi le ṣe aṣeryọri eyi ni akọkun imọ fun awọn oṣiṣẹ.
Ó fẹ́ kí n wá bá òun ṣépè lé wọn, kí ó lè bá wọn jà, kí ó sì lè lé wọn kúrò lórí ilẹ̀ rẹ̀.
Kò gbọdọ̀ jẹ́ alásọ̀, tabi ẹni tí ó ní ọ̀kánjúwà owó.
Àkọlé àwòrán, Awọn agbẹjoro mejeeji to n soju ijọba ati awọn afunrasi naa wi tẹnu wọn ni iwaju adajọ Agbẹjọro ìjọba, Bola Gold naa fí ọrọ wa awọn afunrasi naa lẹnu wo.
pe Gomina ati awọn ikọ rẹ si lati ṣalaye”  Aṣofin Agunbiade sọ pe ọrọ
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Oba Adedokun Abolarin ti Oke Ila: Ó ya ọ̀pọ̀ tó súnmọ́ mi lẹ́nu bí mo ṣe ń kọ́ Àwọn ìpińlẹ̀ kan ni Amẹrika, naa ti sọọ di ofin pe ki wọ́n maa fun awọn akẹ́kọ̀ọ́ ni iléèdi nkan oṣù lọ́fẹ̀ẹ́.
Nítorí náà, bí Ìwé Mímọ́ ti wí,“Nítorí láìpẹ́ jọjọ,ẹni tí ń bọ̀ yóo dé,kò ní pẹ́ rárá.
Ọta le lugba o din mẹwaa ẹgbẹrun owo pọun(£250,000) ni Cavani yoo maa gba ni Manchester United.
O ni ko yẹ ki Ọbasanjọ gba ẹbẹ Buhari nigba to ń sunkun bi ìkókó pe Bẹẹ, Dada kò le ja ni ọrọ Buhari, o ni aburo to gboju nitori pe Festus Keyamo naa fun Femi Fani-kayode lesi pe, aṣiṣe Ọbasanjọ ni yiyan àwọn to n mu oogun oloro sipo olori bii Fani-kayode Àjọ tó n jà fún àkóyawọ́ lẹ́ka ètò ọrọ̀ Ajé ní Nàìjíríà, (SERAP), lọ́dún 2017 nínú àbọ̀ ìwádìí kan fi ẹ̀sùn kan ìṣèjọba Olusẹgun Ọbasanjọ, olóògbé Umar Yaradua, tó fi mọ́ Goodluck Jonathan, pé wọ́n ná bílíọ́nù mọ́kànlá Naira básu-bàṣù lórí ọrọ iná ọba.
Bakan naa, ni iko agbaboolu Sporting Gijon FC kedun iku atamatase oloogbe ohun, leni ti o kopa fun iko naa fun saa otooto meji.
''Igbelarugẹ ati iṣọkan orilẹede yii wa lọwọ awọn araalu to ba ṣiṣẹ papọ pẹlu awọn ọlọpaa,'' Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, John Amanam: Ìfẹ́ tí mo ní sí àbúrò mi ló sọ mi dí ẹni tó ń ṣe 'Prosthetic' báyìí ''Amọ, ti iwa ọmluwabi ba sọwọ lawujọ, ti awọn janduku si gbajọba, ko ni si alaafia lorilẹede Naijiria mọ.
- Obasanjo gbarata Ìbẹ̀rù bá olùgbé Eko torí àwọn ọ̀dọ́ Òkè Ọya tó dìhámọ́ra Olùkọ́ mi ń bá mi lòpọ̀ kí ń le yege ìdánwò WAEC - Akẹ́kọ̀ọ́ l‘Ogun Olólùfẹ PDP 18 kú nínú ìjàmbá ọkọ̀ lásìkò tí wọn ń lọ pàdé gómìnà Iyabo Ojo ṣílé, Toyin Abraham fẹ́ ṣílé iṣẹ́ f'ọmọ, àtàwọn nǹkan míràn lágbo òṣéré Wo fọ́tò àrà MC Oluomo, Pasuma àtàwọn òṣèré tíátà míì níbi ìṣílé Iyabo OjoWo ìyá ọlọ́mọ mẹ́ta tó ti pé ọdún 48 tó ń ṣe ìdánwò WAEC, kó le di nọ́ọ́sí Bakan naa, lo tun sọ nipa bo ṣe pada gbe ọmọ naa lọ si yara awọn ọmọ wẹwẹ, ati bo se wa di ohun to n kọ ni lẹnu lati sọ bi ọmọ ọdun kan ti ko tii le rin tabi sọrọ ṣe poora.
Nítorí àwọn ẹ̀ṣẹ̀ rẹ̀ ga dé ọ̀run,Ọlọrun kò gbàgbé àìṣedéédé rẹ̀.
Lẹ́yìn náà, wọ́n jẹ́wọ́ ẹ̀ṣẹ̀ wọn fún nǹkan bíi wakati mẹta, wọ́n sì sin OLUWA Ọlọrun wọn.
Akọnimọọgba Naijiria ni eyi tumọ si pe Ola Aina àti Chidozie Awaziem lo máa di ẹ̀yìn ilé mú nínú ìdíje òní.
"Gbogbo awọn nnkan kan wa ti a o kọkọ gbewo to jẹ bi ami ororo ti wọn o ti yan, ti wọn o si ti mọ iru eeyan ti ọmọ yii maa jẹ.
Ṣugbọn n óo tìtorí tiwọn ranti majẹmu tí mo bá àwọn baba ńlá wọn dá, àní àwọn tí mo kó jáde láti ilẹ̀ Ijipti lójú gbogbo àwọn orílẹ̀-èdè, kí n lè jẹ́ Ọlọrun wọn.
Ijọba si tun ni lati fi iya ti o tọ jẹ ẹnikẹni ti ọwọ ofin ba tẹ pe o hu iwa ibajẹ, lai ro iru ẹya ti iru ẹni bẹẹ ti wa ati ẹsin to n sìn.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ero awọn eeyan lori ẹka BBC Yoruba Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Ero awọn eeyan lori ẹka BBC Yoruba 19 Èrèlè 2018 Nkan ti awọn eeyan nsọ lori BBC Yoruba.
” Hesekaya dáhùn, ó ní, “Láti ilẹ̀ òkèèrè, ní Babiloni ni wọ́n ti wá.
Ile-ise olopaa ti fun eka to n gbokun ti iwa odaran, (Special Anti-Robbery Squad, SARS) l’oruko tuntun, eleyi ti won pe ni: ‘Federal Special Anti-Robbery Squad (FSARS).
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù COZA RAPE: Ilé ọlọpàá ìlú Abuja pé Fatoyinbo fún ìfọ̀rọ̀wánilẹ́nuwò 27 Ògún 2019 Àkọlé àwòrán, Busola Vs Fatoyin: Ilé ọlọpàá ìlú Abuja ti pé Fatoyinbo fún ìfọ̀rọ̀wánilẹ́nuwò Olùṣọ́-àgùntàn Biodun Fatoyinbo ti ìjọ Commonwealth of Zion Church tí fára rẹ̀ sílẹ̀ ní ilẹ̀ ọlọpàá fún ìfọ̀rọ̀wánilẹ́nuwò lóri èsùn ìfipábánilòpọ̀ Busola Dakolo fí kàn -àn.
Mustafi f'ori kan bọọlu sinu awọn nigba ti Mesut Ozil gba sile Watford.
Ikọ̀ bàlúù TM112/3, tí ó rin ìrìn àjò láti olú ìlú, Maputo, àti Manica  tí jíjìn sí ara wọn tó máìlì 442  ni a tí rí atukọ̀ Admira António, atukọ̀ kejì Elsa Balate,  olóyè ọkọ̀ Maria da Luz Aurélio, àti òṣìṣẹ́ inú ọkọ̀ Débora Madeleine.
AFCON 2019: Ṣé Super Eagles yóò rí agbábọ́ọ̀lù tí yóò mú ìyàtọ̀ wá bí Bright Omokaro ṣe ṣe ní Maroc '88?
Ó tẹ́ pẹpẹ kan sibẹ, ó sì sọ ibẹ̀ ní Eli-Bẹtẹli, nítorí pé níbẹ̀ ni Ọlọrun ti farahàn án nígbà tí ó ń sálọ fún arakunrin rẹ̀.
Ọnà tó gbà ṣe oríire bẹrẹ nígbà tí o n lọ jẹjẹ ládugbó kan níbi tó ti ri awọn èèyàn tó pejọ.
Jakọbu bá dáhùn pé, “Ìwọ náà mọ̀ bí mo ti sìn ọ́ ati bí àwọn ẹran ọ̀sìn rẹ ti ṣe dáradára lọ́wọ́ mi.
Josaya bá pe ìpàdé gbogbo àwọn olórí Juda ati Jerusalẹmu.
Sugbọn ṣa, bi Thailand ba lee ṣe bi ọkunrin ti wọn ko gba ki Chile gba ayo ju ẹyọ kan tabi meji si awọn wọn, gba ọmi tabi na Chile, taara ta ni Falcons yoo lọ si ipele to kan.
Ajọ NCDC ṣalaye loju opo Twitter rẹ pe ọkunrin naa ti ni awọn aisan kan lara tẹlẹ bi arun itọ ṣuga ati arun ti oloyinbo n pe ni Myeloma.
Àwọn ará Manase ń bá àwọn ará Efuraimu jà,bẹ́ẹ̀ ni àwọn ará Efuraimu náà ń bá àwọn ará Manase jà.
A ko le sọ ni pato, iru eeyan ti awọn ọmọ ẹgbẹ okunkun yii jẹ, ṣugbọn awọn akọsilẹ kan sọ pe awọn ọdọ ẹya Hausa lo pilẹ rẹ, ki awọn ẹya miran to o tun ma a darapọ mọ wọn.
‘Èmi ni Ọlọrun Abrahamu, Ọlọrun Isaaki ati Ọlọrun Jakọbu.
Ti wọn ba gba igbesẹ Boris yii wọle, o tumọ si pe ko ni si ijokoo ile fun ọjọ iṣẹ mẹtalelogun ni UK.
Nǹkán márùn ún tó yẹ ko mọ̀ nípa Elon Musk, bàbá olówó tó lówó jùlọ lágbàáyé Agbẹjọ́rò àgbà ní Nàìjíríà ti pàsẹ kí wọ́n dáwọ́ ètò ìgbanisíṣẹ́ NDLEA dúró Wó ọjọ́ ti àjọ NUC kéde pé àwọn akẹ́kọ̀ọ́ fásítì Nàìjíríà yóò wọlé Wo ẹ̀bùn owó gọbọi tí Sanwo-Olu fún akẹ́kọ̀ọ́ tó gba ipò kínní ní fásítì LASU l'Eko Kíló fa wàhálà náà?
Alabi ni iye eeyan ti ko ba ba isẹlẹ naa lọ ko ba pọ ju iye to ku lọ, bi kii ba se ọkunrin kan to pe orukọ rẹ ni Azeez, ẹni ọdun mejidinlaadọta, to gba gbara lọwọ agbebọn naa.
Folasade Ojebiyi ni lati ilẹ ni iṣẹ oyin sinsin ti wu ohun lati ṣe nigba ti o woo pe bawo ni oyin to lee ta eeyan pa ṣe lee di ohun ti eeyan fi n ṣe iṣẹ.
Ẹnikẹ́ni kò ní yè ninu àwọn tí wọ́n ṣẹ́kù ní Juda, tí wọ́n lọ fi ilẹ̀ Ijipti ṣe ilé; wọn kò ní sá àsálà, wọn kò sì ní yè, bẹ́ẹ̀ ni wọn kò ní pada sí ilẹ̀ Juda tí ọkàn wọn fẹ́ pada sí.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Cardi B ti pín yà pẹ̀lú ọkọ rẹ̀ Offset lẹ́yìn ọdún kan 5 Ọ̀pẹ̀̀ 2018 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Cardi B àti Offset ṣeré pọ̀ lọ́jọ́ Àìkú tó jẹ́ ọgbọ̀n ọjọ́ oṣù kọọ̀kànlá.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, ‘Naijiria gbọdọ̀ kọ ìrẹ́pọ̀ pẹ̀lú South Africa ’ O wa kesi ijọba Naijiria lati ri wi pe ijọba ilẹ South Africa da gbogbo ikolọ awọn ọmọ Naijiria ti wọn bajẹ pada, bakan naa ni ki wọn fi imu awọn aseka yii fọn fere.
 Aarẹ tẹsiwaju pe ki gbogbo ileeṣẹ ati ajọ to n ṣewadii ajọ NDDC jara mọṣẹ, ki wọn si bu oun gbọ lori ibi ti wọn ba baṣẹ de."
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Àwọn afurasí lórí ẹ̀ṣùn jíjí ìbejì Akeugbagold gbé yọnú sílé ẹjọ́ láì ní agbẹjọ́rò Mo kábàámọ̀ pé ń kò bẹ Baba Legba wò, nígbà tó pè mí - Foluke Daramola Aṣòfin méje yarí mọ́ Akeredolu lọ́wọ́ torí ọkọ̀ ayọ́kẹ́lẹ́ tí kò pín fún wọn Aya gómìnà Kwara gba ilé fún Risikat olójú búlúù àti ọkọ rẹ̀ Risikat, ìyá àwọn ọmọ olójú búlù tí bẹ̀rẹ̀ sí ní kọ́sẹ́ aṣojú lóge Àjọ ECOWAS yan Aàrẹ Ghana, Nana Akufo-Addo gẹgẹ bíi aàrẹ tuntun Sùgbọ́n ní lọjọ Isẹgun ni Daddy Freeze náà tún fún òjíṣẹ́ Ọlọrun náà ni èsi nípa ìdúkòkò ikú mọ́ni, ti pásítọ̀ náà gbé sórí ayelujára.
Egbe naa so pe awon to olukopa nibi idanilekoo naa wa lati gbogbo ipinle merindinlogoji to wa lorile ede Naijiria ati ilu Abuja.
 Afihan idawo idunu awon ololufe, ara ilu ati awon egbe oselu PDP nile Onimo ero Seyi Makinde pic.
Remilekun Fatolu bú sẹ́kún fún ohun tó ti pàdánù láyé torí ọyàn ńla rẹ̀.
Ní ọ̀nà òdodo ni ìyè wà,kò sí ikú ní ojú ọ̀nà rẹ̀.
" Ọpọ awọn eeyan loju opo Instagram naa si lo n gbarata lori iroyin ofege naa.
Ẹ̀yin òkè kéékèèké, kí ló ṣẹlẹ̀ tí ẹ fi fò bí ọmọ aguntan?
Ó lọ gbógun ti ìlú Hamati ati Soba, ó sì ṣẹgun wọn.
Ọbasa ninu ọrọ ikini rẹ fun ọdun Keresimesi tọdun 2018 ṣalaye pe iru
Eliud Kipchoge to gba ami ẹyẹ wura nibi idije ere idaraya Olympics to waye nilu Rio, naa lo jẹ ẹni to le e sare onibusọ gbọọrọ julọ̀ lagbaye, to si n lo wakati meji, isẹju kan ati winni-winni mọkandinlogoji.
4 Nítorí-èyí, tí ó túmọ̀ sí ìjọ, ẹ níláti ṣe àkíyèsíi gbogbo àwọn ọ̀rọ̀ àti àwọn àṣẹ èyítí òun yíò fi fún yín bí òun náà ṣe gbà wọ́n, rírìn ní gbogbo ìwà mímọ́ níwájú mi;
Àwọn ọmọ Gomeri ni: Aṣikenasi, Rifati, ati Togama.
Ọjọ Aje ni Atiku morile ile ẹjọ lati gbe atako rẹ kalẹ, nigba to ku wakati mẹrinlelogun pere ki iye ọjọ ti ofin la kalẹ fun oludije kan lati pe ẹjọ tako esi ibo pe.
Nígbà tí Peteru pada dé Jerusalẹmu, àwọn onigbagbọ tí ó jẹ́ Juu dá àríyànjiyàn sílẹ̀ lórí ọ̀rọ̀ náà.
Oludije naa sọ pe erongba oun ni lati fi ẹgbẹrun mọkanlelogun kun, ti yoo si jẹ ẹgbẹrun mẹrinlelogun laarin ọdun kan ti oun ba di aarẹ.
OLUWA, nítorí ti èmi iranṣẹ rẹ, ati gẹ́gẹ́ bí ìfẹ́ ọkàn rẹ, ni o fi ṣe àwọn nǹkan ńlá wọnyi, tí o sì fi wọ́n hàn.
Ọrẹ mi daadaa ni Lizzy, a jọ maa n ṣe tọkọtaya lori Instagram ni, awa si la jẹ ki awọn eeyan ro pe a n fẹ ara wa."
Ilééṣẹ́ Aṣọ́bodè Naijiria n pa bílíọ̀nù N5.
Oríṣun àwòrán, Others Kekere lo ti mọ ilu lu, amọ, ẹkọ ọfẹ ti ẹgbẹ Alaanu Rotary gbe kalẹ lo fun ni anfaani lati lọ silẹ Amẹrika lọdun 1950, níbi to ti kawe.
” Nítorí àwọn alufaa ní kí wọ́n má pa á ninu tẹmpili OLUWA.
Lati oṣu kejila ọdun 2019 ti arun naa bẹrẹ lorilẹede China, o ti ran kaakiri ọpọlọpọ orilẹede agbaye bayii.
Bí mo bá wọlé padà, mí ò lè yàn Ize Iyamu tàbí Osagiobare sípò olùbádámọ́ràn- Obaseki Olórin Kano tí wọ́n dájọ́ ikú fún pe ẹjọ́ kòtẹ́milọ́rùn Ìjọba ìpínlẹ̀ Kogi kéde ọjọ́ ìwọlé àwọn akẹ́kọ̀ọ́ padà sí iléèwé Tinubu, yé é sọ̀rọ̀ abẹ́lẹ̀, bọ́ sí gbangba láti bèèrè àtúntò Nàíjíríà lọ́dọ̀ Buhari - Afẹnifẹrẹ Afenifere tun bu ẹnu atẹ lu afikun owo ina ati epo bentiroolu ti ijọba kede laipẹ yìí.
won gba owo to le ni milionu kan naira.
Ọlọ́pàá kọ́ lo pa olórí àwọn ''One Million Boys'' Ebila n'Ibadan- Ọ̀gá ọlọ́pàá Oyo Ènìyàn 653 míràn tún kún iye àwọn tó ní COVID-19 ní Nàìjíríà Wo ohun tó yẹ kí o mọ̀ nípa Laycon, akẹ́kọ̀ọ́jáde UNILAG tó ń kópa nínú BBNaija 2020 Ṣe iku Abiola Ebila yoo fopin si ẹgbẹ one million boys bi?
Nítorí náà, ẹ níláti mọ ìyàtọ̀ láàrin àwọn ẹran tí ó mọ́ ati àwọn tí kò mọ́; ati láàrin àwọn ẹyẹ tí ó mọ́ ati àwọn tí kò mọ́.
Àṣà àwọn ọmọ ènìyàn yí ń fi ìyà jẹ apá kan nínú àwọn ọmọ ènìyàn bẹ́l ni bi ọkùnrin ri ejò bí obìnrin pa ejò, bí ejò kò bá ti lọ kò lòdì ssi òfin.
Ṣugbọn wọ́n bẹ̀rù rẹ̀, nítorí ìyàlẹ́nu ni ẹ̀kọ́ rẹ̀ jẹ́ fún gbogbo eniyan.
Ẹ gbọ́ ohùn akéde kan tí ń wí pé, “Ẹ tún ọ̀nà OLUWA ṣe ninu aginjù,ẹ la òpópónà títọ́ fún Ọlọrun wa ninu aṣálẹ̀.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù NFF: Ilé ẹjọ́ ní k'ọ́lọ́pàá ó wọ́ Amaju Pinnick wá síwájú òun lórí ẹ̀sùn ìkówójẹ 2 Agẹmo 2019 Oríṣun àwòrán, @thenff Àkọlé àwòrán, 'Kí ni alága NFF, Amaju Pinnick ń wá ní Egypt fún AFCON?
Mo kọ èyí si yín, ẹ̀yin tí ẹ gba orúkọ Ọmọ Ọlọrun gbọ́, kí ẹ lè mọ̀ pé ẹ ní ìyè ainipẹkun.
Awọn eniyan wa lati Zimbabwe, Mozambique, Lesotho to to ida aadọrin ninu ọgọrun un awọn ajoji.
 Àwọn ẹ ̀ yà ẹ ̀ ṣọ ́ tí ó maa ń ṣe ní ilà ẹ ̀ ṣọ ́ , bàtà ẹsẹ ̀ , ìpara , pàfúmù , ìgò ojú , àwọn ohun ẹ ̀ ṣọ ́ àti ẹ ̀ bùn .
Ọpọlọpọ eranko, bíi àgbọ̀rín, máa ń lo àsìkò yìí látí ṣe ìbálópọ̀ tá bí kí wọ́n fí ara pamí (hibernate).
Wàhálà to bẹ́ sílẹ̀ jọ ìgbésùnmọ̀mí, ọlọpàá yìnbọn pa ẹnikan.
Ọkọ mi kò fẹ́ràn oúnjẹ òyìnbó àfi ti ìbílẹ̀ - Lizzy Anjorin Mercy Aigbe ṣá ọmọ rẹ̀ sínúu fíìmù tuntun, wo itú tí ọmọ ọdún mẹ́wàá náà pa Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 3 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 5 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Ayé á fi pàṣán ṣe óúnjẹ
Ṣaaju eyi, Alaga Igbimọ Tẹẹkoto fun Ọrọ Irinajo-afẹ, Aṣa ati Iṣe ninu Ile Igbimọ Aṣofin Ipinlẹ Eko, Aṣofin Desmond Eliot sọ pe erongba ofin yii ni lati ṣe ipolowo ati ipolongo Ipinlẹ Eko ni orilẹ-ede Naijiria ati lagbaye lapapọ paapaa bi ẹka irinajo-afẹ lagbaaye ṣe di okoowo nla bayii.
Ọ̀kan ń jẹ́ Hana, ekeji sì ń jẹ́ Penina.
Lẹyin ọjọ mẹta pere ti ẹgbẹ awọn dokita da iyanṣẹlodi ti wọn gunle duro, ẹgbẹ gbogbo oṣiṣẹ eleto ilera ni Naijiria, Joint Health Sector Unions, JOHESU naa ti kede iyanṣẹlodi kaakiri orilẹede Naijiria.
Ó jẹ́ arakunrin mi, alábàáṣiṣẹ́ pẹlu mi, ati ọmọ-ogun pẹlu mi.
Oríṣun àwòrán, Tunde Fatunde Ni Ipinlẹ Eko, ọpọ ni o ti n fẹsun kan gomina Ipinlẹ naa nigba kan ri, Oloye Bola Tinubu wipe oun ni baba isalẹ gbogbo gomina to ti de ipo naa lati igba to ti kuro ni ijọba.
Jọ́họ̀jọ́/ Yérímisá: Ọmọbìnrin tí a bí tí ìyá rẹ̀ sì kú lọ́jọ́ náà tàbí kí á tó sọ ọ́ lórúkọ
Àwọn ọmọ Israẹli dẹ́ṣẹ̀ sí OLUWA nítorí pé ẹnìkan mú ninu àwọn ohun ìyàsọ́tọ̀.
Ìwọ tí o gba ìjọba mọ́ Saulu lọ́wọ́, OLUWA ń jẹ ọ́ níyà nisinsinyii, fún ọpọlọpọ eniyan tí o pa ninu ìdílé Saulu.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Buhari: Àwọn ọ̀dọ́ ní kò rọrùn láti ṣiṣẹ́ ọ̀gbìn láìsí ohun èèlò ìgbàlódé 11 Owewe 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 11 Owewe 2020 Aarẹ Muhammadu Buhari ti kesi awọn ọdọ lati mura giri, ki wọn si gba ọna oko lọ nitori eto ọgbin ni ọna abayọ si iṣoro Naijiria.
O jẹ ẹni tó ń ṣe àgbélẹ̀rọ èròjà ayélujára, ó si ti sàlàyé fún BBC pe ọ̀nà àbáyọ ti wà láti sàmúlò dátà kékere tó wà lóri ẹ̀rọ alágbéka rẹ Wo àwọn irinṣẹ tó ń siṣẹ́ lábẹlẹ̀ kí o si pa 'ààpù' wọ̀n ti wọ́n kò ba ṣe pàtàkì lóju ẹsẹ.
Ti mo ba je a-gbe-fokunrin, ni mi o ni fun obinrin ni ipo minisita fun eto inawo orile ede yii?
Nítorí náà, Ẹni Mímọ́ Israẹli ní:“Nítorí pé ẹ kẹ́gàn ọ̀rọ̀ yìí,ẹ gbẹ́kẹ̀lé ìninilára ati ẹ̀tàn,ẹ sì gbára lé wọn,
Agbẹjọro Anthony Bignall sọ fun ileẹjọ Bristol Crown pe iwa ti ọkunrin hu kudiẹ kaato.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Àwọn sinimá tó pegedé ni 2018 lágbàyé Ìtàn tó wà nídi òwe ‘Sebótimọ Ẹlẹ́wà Sàpọ́n’ Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Bakan naa, ajọ EFCC ṣafihan Ọgbẹni Uyiekpen Osagie-Giwa to wọn ọpọ gbagbọ pe oun ni agbaẹjọro Atiku lori ẹsun pe o gbe owo bi miliọnu meji dọla ṣaaju idibo gbogbogbo.
Ṣugbọn wọ́n bẹ̀ ẹ́ pupọ pé, “Dúró lọ́dọ̀ wa, ọjọ́ ti lọ, ilẹ̀ ti ṣú.
9m kalẹ̀ fún owó oṣù òṣìṣẹ́ ní Kwara O ṣalaye pe Bukola Saraki gan an ni ọrọ naa kan julọ, amọ ohun to ba ti ba oju, o ti ba imu.
O ti ṣẹlẹ lawọn igba kan sẹyin ti ogun tabi ọrọ oṣelu dena mọ awọn eeyan ti wọn fẹ ṣiṣẹ Hajj.
Mikaya dáhùn pé, “Tí o bá pada dé ní alaafia, a jẹ́ pé kì í ṣe OLUWA ni ó gba ẹnu mi sọ̀rọ̀.
Ominira lati lo tabi ta igbó - Ṣoworẹ ti sọ tẹlẹ pe ọpọlọpọ orilẹede l'agbaye ti mọ anfaani to wa ninu igbo lilo ninu eto iwosan ati ọrọ aje, nitopi pe o le p'awo wọle.
Super Falcons: 3-0 ni Norway fi ṣi'de ìyà fún Nàìjíríà
Má kọ̀wé fipò sílẹ̀, àwọn àgbààgbà Yorùbá sọ fún Osinbajo Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
"-Olugbo Obateru Akinruntan Bí mo bá leè rí ọmọ alágbe t'áyé fẹnu sí pé mo fi ẹlẹ́rìndòdò lá lójú, máa kúnlẹ bẹ ẹ - Motara Omo Ghetto: Funke Akindele ṣàlàyé bí àwọn agbébọn ṣe kọlù wọn làsíkò tí wọ́n ń ya fíìmù ""Ibanujẹ si lo ma n jẹ fun mi, ni gbogbo igba ti mo ba ri ibusun ati awọn ẹrù rẹ ninu yaara."
Níbo ni ìjà sì ti ń wá sáàrin yín?
Awon osise ati awon egbe osise meteeta ile-eko giga fafiti, ti a mo si NASU, SSANU, ati NAAT kede ida iyanselodi olosu meta ati ojo mewaa naa duro lojo-Ru.
Bádérù kò kúkú mọ̀ pé ẹnikẹ́ni ń wo òun.
Ìkamọ̀dù l’ó lọ s’ógun ibá ikán jà,
“Ẹ rán mi létí ọ̀rọ̀ yín kí á jọ ṣàríyànjiyàn;ẹ ro ẹjọ́ tiyín,kí á lè da yín láre.
Ní tìrẹ, àwọn ohun tí ó bá ẹ̀kọ́ tí ó yè kooro mu ni kí ó máa ti ẹnu rẹ jáde.
O tesiwaju pe , o ya oun lenu pelu ahesọ
Ẹwẹ, awọn aṣofin naa tun kọ lati fi ọwọ si yiyan Ibrahim Magu gẹgẹ bi alaga ajọ to n gbogun ti iwa ibajẹ, EFCC, ti wọn fi ẹsun kan pe 'oniwa ibajẹ ni.
Ojọgbọn Pail Howard-Jones to jẹ ogbontarigi ni Fasiti Bristol ni: O ṣe pataki ki ọmọ kọ nipa lilo ẹrọ ibanisọrọ lasiko to ba jẹ pe pataki iwe kika ni lati le gbe ninu aye pẹlu irọrun.
O ni ṣokoto ati aṣọ ni oun fẹ lọ ra, ki aburo oun obinrin to tẹle oun to mu oun lọ inu ṣọọbu ti wọn ti n ta ohun ibalopọ.
"Àjọ náà ni ""lẹ́yìn àgbéyẹ̀wò kíkún àti nǹkan ti ọjà epo bẹtiróò ń sọ lágbàyé nínú oṣù kẹfa, àwọn ṣe àmójútó ìyé tó to gbé epo jáde tí ẹnikẹni kò sì ni pàdánì owó"" ""Nítorí náà, a rọ àwọn ilé epo láti máa ta jálá epò bẹtiróò ní ogóje náìrà sí náírà mẹ́tàlélógóje ó lé ọgọ́rin kọ́bọ̀, fún oṣù keje ọdún 2020."
Moabu ń pohùnréré ẹkún nítorí Nebo ati Medeba.
Sẹnẹtọ to wa lara awọn ile igbimọ aṣofin kẹjọ, Shehu Sani lo fọrọ yii lede lọjọ Abamẹta.
Idi ni pe ode ko daa fun wọn nigba ti awọn ọdẹ ibilẹ to wa nilu naa bawọn fija pẹẹta pẹlu ibọn, lasiko ti wọn n digun jale.
Yóo sun gbogbo ọ̀rá òbúkọ náà lórí pẹpẹ, gẹ́gẹ́ bí ọ̀rá ẹran tí wọ́n bá fi rú ẹbọ alaafia.
Akọkọ ni ti Christensen to gba kaadi pupa lẹyin to fa Sane titi to fi ṣubu lasiko to n gbiyanju lati lọ jẹ ni ile Chelsea.
Lagos Rape: Ẹnikẹ́ni tó bá á ní ìbálòpọ̀ pẹ̀lú ọmọ kékeré jẹ́ alárùn ọpọlọ- Onímọ̀
Orile ede Naijiria fẹyin  orile ede Cameroon gbolẹ pẹle ami aayo mẹ́ta    si méjì 3:2  lati pegede fun ipele  kẹ́rin  (quarter finals) ninu idije ife
Ṣugbọn olùtọ́jú ọgbà dá a lóhùn pé, ‘Alàgbà, fi í sílẹ̀ ní ọdún yìí, kí n walẹ̀ yí i ká, kí n bu ilẹ̀dú sí i.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Tọkọ-tayà Osinbajo kò gbẹ́yìn níbi ayẹyẹ ọjọ́ ìbi Folu Adeboye 14 Agẹmo 2018 Oríṣun àwòrán, Rccg/twitter Àkọlé àwòrán, O ni àwọn ise ìrànwọ ti ó ń wọn se fawọn ọ̀dọ́ àti àwọn alaini kò lẹ́gbẹ́ Ìyá Adeboye jẹ́ àwòkọ̀ṣe rere fàwọn obínrin ìwòyí Igbakeji ààrẹ orílẹ̀-èdè Nàìjíríà, Ọjọgbọn Yemi Osinbajo, tí dáwọ̀ọ́ ìdùnnú pẹ̀lú ìyàwó adari ìjọ ìràpada (Redeemed Christian Church of God), Olusọaguntan Folu Adeboye.
NLC ni awọn igbesẹ ijọba naa gbọdọ fun awọn osisẹ ni igbe aye irọrun, ki wọn si da awọn ohun to wọn gogo pada si bi o ṣe wa tẹlẹ.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Eléègè-àrà ni àwọn olólùfẹ́ Barcelona mọ Andres Iniesta sí Agbábọ́ọ̀lù náà sọ pé òun yóò kéde ẹgbẹ́ agbábọ́ọ̀lù tuntun tí òun yóò darapọ̀ mọ́ n'íparí sáà yìí.
Àwọn kan ninu àwọn àgbààgbà ìlú dìde, wọ́n bá gbogbo ìjọ eniyan sọ̀rọ̀; wọ́n ní, 
ati àwọn ohun èlò mìíràn tí àwọn oníṣẹ́ ọnà yóo lò: wúrà fún àwọn ohun èlò wúrà, ati fadaka fún àwọn ohun èlò fadaka.
Nítorí ẹ̀yà ara Kristi ni a jẹ́.
N óo fi ohun ìyanu hàn wọ́n gẹ́gẹ́ bíi ti ìgbà tí ẹ jáde kúrò ní ilẹ̀ Ijipti.
Mo ní ìrètí ati rí ọ láìpẹ́, nígbà náà a óo lè jọ sọ̀rọ̀ lojukooju.
Àwọn ọmọ Reubẹni, àkọ́bí Jakọbu, ni: Hanoku, Palu, Hesironi ati Kami.
Bakannaa ni minisita Dan Ali tun sọ wi pe, lara awọn nkan mii ti ilẹ Amẹrika beere fun ni pe ko si aaye funfifi awọn osisẹ omọogun ilẹ Naijira sswọ si ilẹ Amẹrika lati kọ nipa bi wọn se se awọn baluu ogun naa.
pipese eto ilana fun lilo imo ero igbalode nikan lo le din wahala ati isoro to
Nítorí náà mo sọ fun yín lónìí yìí pé bí ẹnikẹ́ni bá ṣègbé ninu yín, ẹ̀bi mi kọ́.
@bdexibojo ni tiẹ sọ pe, ile iṣẹ ologun loun wa lẹyin wọn nitori awọn lo n gbogun ti awọn agbesunmọmi, ti wọn si n fi ẹmi wọn lelẹ fun orilẹede Naijiria.
Àkọlé àwòrán, Awọn ara ipinlẹ Oyo naa tu yaya tu yaya si gbagede ibi ti wọn ti se iburawọle fun gomina tuntun naa.
" Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ọ̀pọ̀lọpọ̀ló ń fara pamọ́ mu igbò O ṣalaye pe, lootọ ko si aisan kan pato ti a le sọ pe igbo n wosan, ṣugbọn wọn maa n lo igbo tin-n-tin ni, gẹgẹ bi ọkan lara awọn eroja ti wọn n lo fun ṣiṣe awọn oogun naa.
Kò ha yẹ kí ìwọ náà ṣàánú ẹrú, ẹlẹgbẹ́ rẹ, bí mo ti ṣàánú rẹ?
Kunle Afọlayan ṣalaye pe, lẹsẹkẹsẹ loun ti jẹ ko di mimọ fun arabinrin naa pe Ẹ gba mi o, ewo n temi"" Bakan naa lo fi kun un pe, oun ko korira ẹya igbo tabi dẹyẹsi wọn, bi o ti wulẹ o mọ."
omo orile ede Tanzania  ati alatako ijoba
Oríṣun àwòrán, Shuhaila El-Zakzaky Ilana ti ijọba Kaduna fi lelẹ ki El-Zakzaky tó lọ gba itọju: Ileesẹ to wa fun ọrọ ilẹ okeere tijọba apapọ ilẹ wa, gbọdọ lọ fidi rẹ mulẹ ni ile iwosan ti El Zakzaky ati iyawo rẹ fẹ lọ nilẹ India, pe lootọ ni ile iwosan naa n reti wọn fun itọju El Zakzaky ati iyawo rẹ ni ikọọkan wọn gbọdọ fi ọwọ siwe pe awọn yoo pada wa si orilẹede Naijiria lati tẹsiwaju pẹlu ẹjọ ti wọn n jẹ lọwọ nile ẹjọ ni kete ti wọn ba ti gba itọju tan ni India El Zakzaky ati iyawo rẹ ni yoo san gbogbo owo ti wọn yoo fi rin irinajo lọ si India, owo itọju ara wọn nile iwosan ati awọn owo ti wọn yoo na lasiko ti wọn ba lọ gba itọju naa Ikọọkan awọn olujẹjọ naa yoo fa oniduro meji-meji silẹ, ọkan ninu aọn oniduro naa yoo jẹ oloye abi Emir onipo kinni, n igba ti oniduro keji yoo jẹ eekan ilu kan ti yoo tọwọ bọ iwe pe oun yoo fa olujẹjọ ti oun duro fun kalẹ nigba kuugba ti ile ẹjọ ba fẹ rii.
Ṣùgbọ́n ó múmi ronú pé tí ayé bá máa parẹ́ kí Kérésì tó dé, njẹ́ èmi ti ṣetán láti pàdé Ẹlẹ́dàá báyìí?
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù YCE Crisis: Kunle Olajide ní áwọn tó déte yíyọ òun ní ákọ̀wé YCE kò lẹ́nu ńbẹ̀ 27 Òkùdu 2019 Oríṣun àwòrán, nkirukanistoran Àkọlé àwòrán, Ọmọwe Kunle Olajide Awuyewuye to n waye lori asaaju ẹgbẹ igbimọ agba Yoruba, YCE ti n gba ọna miran yọ pẹlu bi awọn kan ninu ẹgbẹ ti ṣe jawe lọ rọkun nile fun akọwe ẹgbẹ naa, Dokita Kunle Olajide.
Loju opo Twitter rẹ lọjọ Aiku,o ni oun yoo ṣe agbekalẹ ilana iṣejọba ohun ni ọjọ aje ti o si rọ awọn alatilẹyin rẹ lati pade oun lori ẹrọ ayelujara fun ẹkunrẹrẹ.
Àwọn tí wọ́n lóye yóo sọ fún mi,àwọn ọlọ́gbọ́n tí wọn ń gbọ́ mi yóo sọ pẹlu pé,
Adajọ Odusola wa fajuro lori bi agbẹjọro fun olujẹjọ, Alfa Babatunde, se tun beere pe ki wọn sun ẹjọ naa siwaju nitori ailera rẹ.
Coronavirus ti mú kí Rábí elépo pupa ó lówó ju Rábí elépo rọ̀bì lọ́ Ni bi a ṣe n to iroyin yii jọ, agbẹ olowo epo pupa labule kabule lorilẹede Naijiria ma ti di olowo ju baba olowo oniṣowo epo rọbi nibikibi lagbaye.
"Tori naa ilana ati wa na abayọ si eyi gbudọ jẹ eyi to gbe iwa obi soju""."
Lara awọn ohun tawọn ọba yii si maa n fi se ọla ni nini olori tabi ayaba puọ lọọdẹ wọn.
1 6296 Orilẹede Maldives 49 9.
Awọn APC ni wọn dá ogbe simi lara ti wọn sì tún ba mọto mi jẹ, APC ọhun ni wọn tun ni ki a ti lẹyin emi ọ ṣe ọ!
    Nígbà tí obìnrin yìí padà tán, gbogbo wa tọ ọba lọ sí ibi tí ó dún sí, a sì bẹ̀rẹ̀ sí í bá a gbọn ìpàǹtí orí rẹ̀, àwọn ìpàǹtí tí ó dì mọ́ ọ lórí gbogbo ní ibi tí obìnrin náà ti ń gbé e yílẹ̀.
Àwọn ọmọ Lefi kan wà fún orin kíkọ ninu tẹmpili, wọ́n jẹ́ baálé baálé ninu ẹ̀yà Lefi, ninu àwọn yàrá tí ó wà ninu tẹmpili ni àwọn ń gbé, wọn kì í bá àwọn yòókù ṣiṣẹ́ mìíràn ninu tẹmpili, nítorí pé iṣẹ́ tiwọn ni orin kíkọ tọ̀sán-tòru.
Awọn ti ọjọ ori wọn si ti le ni ọgọta ọdun lo ṣaba ma n ni aisan yii.
Oluwo wa gba mọmọ rẹ ni imọran lati lọ sọ ohun to ṣẹlẹ ni ẹka banki naa, mọmọ ko beṣu bẹgba, o lọ sibẹ, nibẹ gan an ni wọn ti sọ fun mama pe kaadi ATM ko ṣiṣẹ daadaa wi pe o nilo omiiran.
Awọn ọrọ miiran ti awọn aarẹ naa n sọ, si lo n faa bi awọn araalu se n bu ẹnu atẹ lu wọn, ti awọn miiran si n gba oriyin.
Oríṣun àwòrán, Seyitan/instagram Àkọlé àwòrán, Seyitan Babatayo to fi ẹsun kan D'banj Ọmọbinrin naa f'oju han si gbangba Lẹyin ti Ese fi alaye ọrọ naa sita ni ọmọbinrin kan, Seyitan Babatayo jade sita pe oun ni ẹni naa.
Losoosu, ogoro awon oniroyin ni won gbe iroyin bi oro oja se lo jake-jado orile-ede Nigeria, ati orisirisi oja ti awon onibara n ra, ti akosile wa fun lati mo igba tabi akoko ti alekun ba owo ori oja naa.
Ìbá sàn kí o fi mí pamọ́ sinu ibojì,kí o pa mí mọ́ títí inú rẹ yóo fi rọ̀,ò bá dá àkókò fún mi, kí o sì ranti mi.
Àwọn ìkìlọ̀ tí ọ̀gá àgbà ọlọ́pàá là kalẹ̀ lórí ìpànìyàn Eko Omíyalé gbẹ̀mí èèyàn méje, o tún ba dúkìá púpọ̀ jẹ́ Wo aláànú tó n wa ọkọ̀ tí wọ́n fi n gbé aláìsàn lọ́fẹ̀ẹ́ Kínni ife ẹ̀yẹ ti Tiger Woods gbà ní Augusta fi yàtọ́?
Awọn oṣiṣẹ ilera ti kilọ fun awọn eniyan lati ṣe awọn akiyesi wọnyii, titi ti ọna abayọ yoo fi yọju nipa aarun naa.
14 Agẹmo 2019 Oríṣun àwòrán, others Àkọlé àwòrán, Ṣé o rántí itú tí Bright Omokharo fi Algeria pa ní MAROC '88?
com/yoruba/afrika-47649104 Ìwà ipá nínú ìdílé máa ń bí ìgè àti àdùbí ni tó lè já sí ikú Àkọlé àwòrán, Ìwà ipá nínú ìdílé máa ń bí ìgè àti àdùbí ni tó lè já sí ikú Lode oni, ọpọ idile ni iwa ipa ti n ṣẹlẹ.
Ọmọọ̀dọ̀ tó pa Ope Bademosi ti rí ẹ̀wọ̀n gbére he!
Idi abajọ ni pe, awọn ọkunrin meji kan, gẹgẹ bi James Daniel ṣe sọ, ni wọn da oun duro gẹgẹ bi onibara loju popo lagbegbe Igbatoro nilu Akurẹ pe ki o gbe awọn lori ọkada rẹ de Ibafo ki o si tun gbe awọn pada.
Ti ẹ ko ba gbagbe pe ijọba pasẹ lọdun 2018 lati dawọ isẹ  ikọ agbofinro SARS duro lati se atunse to
Àríyànjiyàn Osinbajo àti PDP Buhari ba osinbajo sayẹyẹ igbeyawo ọmọ rẹ Yemi Osinbajo: Ìgbákejì Ààrẹ tó gbọ́ nípa ẹ̀!
Natani bá tọ Dafidi lọ, ó sì sọ fún un pé, “Àwọn ọkunrin meji wà ninu ìlú kan, ọ̀kan jẹ́ ọlọ́rọ̀, ekeji sì jẹ́ talaka.
Baba Obasanjọ kò ní àrùn Coronavirus- NCDC Àǹkóò àrùn coronavirus dé orílẹ̀èdè Togo Ṣé ìrètí wà pé coronavirus yóò dínkù lásìkò ooru?
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Boko Haram: Pásítọ̀ Adeboye ní Ikọ̀ Boko Haram àti gbogbò àwọn tó ń sàtìlẹyìn fún wọn kò ní rí ọdún tuntun 3 Ọ̀wàrà 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 4 Ọ̀wàrà 2020 Oríṣun àwòrán, Google Adari ijọ Redeemed Christian Church of God, Pasitọ Enoch Adeboye ti paṣẹ pe ikọ Boko Haram ko ni ri ọdun tuntun ti wọn ko ba jawọ iṣẹ ibi wọn.
Ṣíbbí fàdákà ni àwa tí a jẹ́ ènìyàn àti àwọn tí ó jẹ́ iwin lò, àwo fàdákà ni a fi jẹun, ife fàdákà ni a sì fi mu omi.
A ṣiré títí ilẹ̀ ọjọ́ náà fi ṣú, inú èmi náà pàápàá tilẹ̀ dùn púpọ̀ lákòókò náà nítorí, lọ́nà kínní, ọjọ́ pẹ́ tí mo ti rí ẹnikẹ́ni sọ̀rọ̀ sí kí á sì jọ máa wọlé kí á jọ máa jádde, lọ́nà kejì, ọjọ́ pẹ́ tí mo ti rí aṣọ dáadáa wọ̀ mọ bẹ́ẹ̀ ni ìgbà tí mo sì dé ọ̀dọ̀ Baba-onírùngbọ̀n ni mo ti wọ ṣòkòtò àti ẹ̀wù tuntun tí ìyà mi wáá mú fún mi, àwọn aṣọ náà sì ba mi mu púpọ̀ nítorí oníṣọ̀nà òde ọ̀run ni ó rán wọn: èmi náà bẹ̀rẹ̀ si ṣe fáàrì lọ́dọ̀ Baba-onírùngbọ̀n mo ń yan tẹ́nki-tẹ́nki kiri.
Àwọn ọmọ Bẹnjamini bá kó ara wọn jọ láti gbogbo ìlú ńláńlá, wọ́n wá sí Gibea láti gbógun ti àwọn ọmọ Israẹli.
Hanan kọ ẹkọ imọ gẹgẹ bi ayaworan ni fasiti Ravensbourne ni Ilẹ Gẹẹsi, nigba ti ọkọ rẹ jẹ oluranlọwọ pataki si minisita fun ọrọ iṣẹ ati ile gbigbe, Babatunde Fashola.
Ó ti sọ òlè jíjà di iṣẹ́ àṣejẹ.
Oríṣun àwòrán, omotala_jalade Awọn ololufẹ Omọtọla Ekeinde ti ọpọlọpọ mọ si Ọmọsexy gbadura fun un lẹyin to ko COVID-19 Lati igba ti o kede pe oun ti ko aarun COVID-19 laipẹ yii, awọn ololufẹ agba oṣere sinima naa ti n ki i pẹlu adura pe yoo ye arun naa ati pe piri lolongo rẹ yoo ji lẹyin o rẹyin arun naa.
Oríṣun àwòrán, AFP Àkọlé àwòrán, L'ọjọ kan naa , awọn ọmọ orilẹede Libya yii n s'afihan aṣọ aṣa wọn lọjọ ayajọ aṣọ ibilẹ Libya ni olu ilu wọn, Tripoli.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fọ́nrán ohùn, Joe Igbokwe kò yẹ́ fún ipò ti wọ́n fún nípìnlẹ̀ Eko - Babatunde Gbadamosi Kini ero awọn ọmọ Naijiria lori iṣẹlẹ Ike Ekweremadu yii?
Awọn oṣiṣẹ eleto aabo ti di ọna si ile alaja meji na pa ki o ma lọ wo tan lu awọn eniyan lẹyin ti wọn ko gbogbo ayalegbe kuro.
Alaye re e lori ipinlẹ ti awọn ẹni tuntun naa ti wa: Lagos-256 Katsina-23 Edo-22 Rivers-14 Kano-13 Adamawa-11 Akwa Ibom-11 Kaduna-7 Kwara-6 Nasarawa-6 Gombe-2 Plateau-2 Abia-2 Delta-2 Benue-2 Niger-2 Kogi-2 Oyo-2 Imo-1 Borno-1 Ogun-1 Anambra-1 Ṣugbọn, eeyan 2,501 ti ri iwosan, 254 si ti ku.
Nígbà tí gbogbo àwọn eniyan náà rékọjá sí òdìkejì odò Jọdani tán, OLUWA wí fún Joṣua pé, 
Èyí ni ó di ìgbà kẹta tí Jesu fara han àwọn ọmọ-ẹ̀yìn lẹ́yìn ajinde rẹ̀ ninu òkú.
 Ìtán sọ fún wa pé ibẹ ̀ náà ló ti mú un bọ ̀ .
Ẹ gbọ́ ìròyìn ayọ̀ lórí àrùn Coronavirus Gomina Oyetọla ṣalaye siwaju sii pe, awọn ọmọ ipinlẹ naa ti wọn n ti orilẹede Côte d'Ivoire bọ wa sile ni wọn ko arun naa dani to fi di pe o tubọ peleke sii nipinlẹ naa.
Burẹdi wa nìyí, ó gbóná nígbà tí a dì í nílé fún ìrìn àjò yìí ní ọjọ́ tí a bẹ̀rẹ̀ ìrìn àjò náà.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Ọgbẹni Enang sọ fun awọn oniroyin pe awọn ti ko ni ju oṣiṣẹ mẹẹdọgbọn lọ nikan ni owo oṣu tuntun naa yọ silẹ.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Bí Hushpuppi ṣe tiraka rèé l‘Eko, kí ọlà ‘òjijì’ tó dé Akẹ́kọ̀ọ́ wọlé padà, ìjọba Oyo kò pèsè ìbòmú lòdì sí ìlérí rẹ̀ Ẹ wo bí ọ̀rọ̀ òṣèlú, ẹ̀sìn àti ẹ̀yà ṣe fa ogun abẹ́lé Biafra Kàkà k‘éwé àgbọn dẹ̀ lágbo òṣèlú l‘Ondo, akọ̀wé ìjọba tún kọ̀wé fipò sílẹ̀ Ẹ wo bí ọ̀rọ̀ òṣèlú, ẹ̀sìn àti ẹ̀yà ṣe fa ogun abẹ́lé Biafra Oke-Osanyintolu ni eniyan mẹtalelogun lo wa ninu ọkọ oju omi naa, ko to yi danu.
Aranṣọ awọn poopu ti maa n ran awọn aṣọ naa silẹ fun ẹni to sanra tabi ti ko sanra - ṣugbọn wọn le ṣe atunṣe pajawiri si i.
Èkíní ni pé, ikú Kyari fìdí rẹ múlẹ̀ pé, lóòótọ́ ni àrùn Coronavirus wá, to sì ń pá èèyàn.
Ati ààyè tí ó wà lókè ẹnu ọ̀nà, títí kan yàrá inú pàápàá, ati ẹ̀yìn ìta.
Nítorí mo wí fun yín pé bí òdodo yín kò bá tayọ ti àwọn amòfin ati ti àwọn Farisi, ẹ kò ní wọ ìjọba ọ̀run.
Ninu ọrọ rẹ, Atiku ni idasilẹ ọlọpaa ipinlẹ tabi ọlọpaa ẹkunjẹkun yoo ṣe iranwọ lori eto aabo to mẹhẹ lorilẹede Naijiria.
”  O fikun oro re pe, aye ijoba tiwan-tiwa lawa yii, omo egbe ti o ba wa wu lati fe dije dupo aare labe asia egbe oselu APC, ofin ati ilana fi aye gba iru eni be, lai fa wahala rara.
Bí bẹ́ẹ̀ kọ́, n óo tú u sí ìhòòhò, n óo ṣe é bí ìgbà tí a ṣẹ̀ṣẹ̀ bí i.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Dapchi: Àwọn akẹgbẹ́ Leah Sharibu padà sí ilé ìwé, ṣùgbọ́n Leah kò bá wọn wọlé 16 Bélú 2018 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ni ọjọ kọkandinlogun oṣu keji ọdun 2018 lawọn Boko haram ji aadọfa akẹkọ gbe n'ile iwe kan ni ilu Dapchi, ipinlẹ Yobe Oṣu mẹsan lẹyin ti awọn agbebọn Boko haram ji aadọfa akẹkọbinrin gbe ni ile iwe kan ni ilu Dapchi ipinlẹ Yobe, ileewe naa ti pada bẹrẹ iṣẹ ẹkọ kikọ bayii.
Ninu ọrọ rẹ, O ni o yẹ ki Mama Oriṣabunmi, gẹgẹ bi awọn oṣere ṣe maa n pe e o wa ni ili Ilẹ Oluji fun iṣẹ sinima kan ti Lọla Adegoke ti ọpọ mọ si Mọremi agbaye fẹ ya nibẹ ni ti Mama Oriṣabunmi funra rẹ gan ti pe lati le tete mọ ọjọ ti yoo kan ipa ti o fẹ ko nibẹ.
Bi o tilẹ jẹpe ọpọ igba lawọn eeyan maa nfi ọrọ yii sere laarin ara wọn tẹlẹ, amọ o dabi ẹnipe awada lasan yii ti fẹ di ootọ ni kete ti ẹgbẹ agbabọọlu Brighton gbo ewuro soju Arsenal pẹlu ami ayo meji si ọkan lopin ọsẹ.
Ní ti àwọn tí kì í ṣe Juu tí wọ́n gba Jesu gbọ́, a ti kọ ìwé sí wọn pé kí wọ́n yẹra fún oúnjẹ tí a ti fi rúbọ sí oriṣa, ati ẹ̀jẹ̀, ati ẹran tí a lọ́ lọ́rùn pa; kí wọn sì ṣọ́ra fún àgbèrè.
Ọjọ ti obinrin naa fi n ṣe nkan oṣu yoo pọ, yoo si maa ni irora inu rirun lasiko nkan oṣu O ma n buru debi pe obinrin naa yoo nilo ki wọn fa ẹjẹ si lara Oyun yoo ma a bajẹ mọ obinrin naa lara.
O ni ninu fiimu ti oun kọkọ darapọ mọ ti akọle rẹ jẹ 'Oshodi Oke', ni awọn eniyan ti bẹrẹ si ni pe oun bẹẹ, amọ ko ni nkankan ṣe pẹlu ọmu aya oun.
Awọn ileeṣẹ iroyin abẹle gbogbo lorilẹede Naijiria ni wọn ti saaju gbe e sita lọsan ọjọ ẹti pe minisita Adeosun ti kowe fipo sile.
Joṣua bá pe àwọn ọmọ Israẹli jọ, ó wí fún wọn pé, “Ẹ gbọ́ ohun tí OLUWA Ọlọrun yín wí.
Ẹlikọ́pítà Quarom aviation já lulẹ̀ ní Ikeja, gbogbo èrò inú rẹ̀ ló ti tẹ́rí gbaṣọ!
"Ọjọgbọn Wallen sọ pe ""òfo ọjọ keji ọja ni iṣẹ abẹ naa ja si."
Sùgbọ́n Afẹnifẹre ni ẹgbẹ́ ẹnu méjèèjì ni Tinubu fi ń sọ̀rọ̀ àti pé ọ̀rọ̀ rẹ̀ ko ni arígbámu kankan nínú.
Mo dupẹ gan an fun ọkọ Toyota Prado 2020,'' ọrọ ti Taye Currency sọ niyii loju opo Instagram rẹ niyii.
Tí ètò ìdìbò bá ti n bọ̀ lọ́nà, ayédèrú ìròyìn ṣábà máà n wọ́pọ̀.
Joṣua Bá Àwọn Eniyan náà Sọ̀rọ̀ ní Ṣekemu.
Ó fi igi akasia ṣe ọ̀pá, ó sì yọ́ wúrà bò wọ́n.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Mo ba oloriire yọ ni ọrọ naa pada ja si Andreescu ni ti ẹnikẹni ba sọ fun oun pe oun a koju Serena Williams ninu idije oun maa sọ pe ẹni naa ti ya were ni.
"Ọkọ Funke Akindele kó eléré àti òṣìṣẹ́ jọ fi ṣe ""Surprise Pato"" fún un lọ́jọ́ ìbí rẹ̀ Adigunjalè pa oníbàárà báńki tó ṣẹ̀ṣẹ̀ gba owó n'Ibadan 'A ó ran ara wa lọ́wọ́ o bẹ́ẹ bá lẹ́ ò ní ṣiṣẹ́ẹ yín, àwọn àgbẹ̀ Ikoyi Ile síjọba ìpínlẹ̀ Oyo!"
Oyedepo ni ẹ̀rín ni toun lọ́jọ́ gbogbo ati pe ti oun ba waasu ti ko mu ayọ̀ ati ẹ̀rin da ni pe ki awọn eeyan ma gbọ́ oun.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù AFCON 2019: Níbo ni ọ̀rọ̀ owó ajẹmọnu ikọ Super Eagles dé dúró?
Ààlà àwọn ará Amori bẹ̀rẹ̀ láti ẹsẹ̀ òkè Akirabimu, láti Sela lọ sókè.
Gbogbo yín ti gbìmọ̀ pọ̀ láti máa parọ́, ati láti máa fi ọgbọ́n fi àkókò ṣòfò.
Kii ṣe gbogbo igba ti nkan ọmọkunrin ba dide lo tumọ si pe ọkunrin naa fẹ l ni ibalopọ.
Ekuko ni oun ko gbagbọ pe awọn ksn le ma a hu iwa buruku bẹ.
Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Ìkíni kú oríire ti ya bo Funke Akindele àti ọkọ rẹ̀ JJC Skillz23 Ọ̀pẹ̀̀ 2018 Fathia Balogun, Toyin Abraham bá Funke Akindele Kẹ́dùn ikú bàbá rẹ̀9 Ọ̀pẹ̀̀ 2019 Fídíò, Dálémoṣú ni mí ṣùgbọ́n ó ní ìdí - Adaku inú eré Jẹnifa11 Ìgbé 2020 Funke Akindele: Ajirebi ní Funke Akindele f'óun lówó t'óun fi gba ilé ni, kò ra ilé f'óun11 Agẹmo 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 3 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 5 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Ọ ̀ pọ ̀ ìtàn ìwáṣẹ ̀ tó rọ ̀ mọ ́ òrìṣà gẹ ̀ lẹ ̀ dẹ ́ ni a ti rí púpọ ̀ rẹ ̀ nínú odù ifá .
Wọ́n pé ọdún méjìlá báyìí Ọlọ́pàá fìyà jẹ mí lọ́dún 2014, mò wà lẹ́yìn àwọn ọ̀dọ́ lórí ìwọde EndSARS- Fayemi Amọ, ọgọọrọ eeyan lo lanfaani lati ṣe ẹyẹ ikẹyin fun un, ọpọ lo n sunkun, nigba ti awọn mii n ṣe sadakanta lẹgbẹ posi Maradona.
Oríṣun àwòrán, @queen_anu O wu emi naa lati lati gbe ile aye bo ṣe yẹ, ki n si jẹ iya rere to dara julọ fun awọn ọmọ mi.
Bakan naa ni Babangida bu ẹnu atẹ lu iṣekupani awọn afẹhọnuhan lorilẹ-ede Naijiria nigba ti awọn ikọ Ologun Naijiria da ibọn bo wọn ni agbegbe Lekki Tollgate ni ilu Eko ati kaakiri Naijiria pẹlu.
Ọjọ kẹsan an, oṣu kẹta, ọdun 2019 ni awọn eniyan ipinlẹ Rivers ti kopa ninu eto idibo gboogbo ti awọn eniyan Naijiria ti kopa nipinlẹ Mọkandinlọgbọn ti wọn ti n yan gomina.
awon afipagboko keji fi baalu ifoloke 77 american airlines kolu pentagonu ni ago 9 : 37 a.
Ewe, enikeji re omo bibi orile-ede New Zealander, Parker naa koi ti oadanu ifigagbaga Kankan ninu ifigagbaga merinlelogun ti o ti ja bayii, beesini yoo gbe beliti igbadi WBO ti o gba keyin wa fi dije ninu ifigagbaga naa.
Awọn Iroyin mii ti ẹ le nifẹ si Ẹ wo àwọn ìròyìn tó ṣì ń gbóná fẹli fẹli lọ́sẹ̀ yìí Ẹ wo ìpínlẹ̀ 15 tó faramọ́ ìdásílẹ̀ àbúlé Ruga Barrister ló sọ mí di èèyàn ńlá - Ayinla Kollington Ìtàn tó wà nídi òwe ‘Sebótimọ Ẹlẹ́wà Sàpọ́n’ Ìtàn tó rọ̀ mọ́ òwe ‘aṣọ kò bá Ọ́mọ́yẹ mọ́.
Ó ní àwọn ti ń gbìyànjú láti bẹ iléẹjọ́ pé kó fún ẹlẹ́wọ̀n yìí lááyè láti lọ sílé ẹ̀kọ́ gíga.
INEC-Àwọn jándùkú àti ọmọ ilé ìṣẹ́ ológun lo dá ètò ìdìbò Gómìnà Rivers rú 'Ọrọ Nàìjíríà fẹ itusilẹ' àti àwọn èsì míràn tó tẹlé bí INEC ṣé dajọ sí ìdìbò Wike ní àwọn ọmọogun fẹ́ 'dìtẹ̀ gbá'jọba' lọ́wọ́ òun Iroyin naa tun sọ pe ẹgbẹ oṣelu Labour ati Advance Peoples Democratic Alliance na kowe ẹsun tako Inec ni ile ẹjọ giga lAbuja lori ọrọ naa.
Sabadi bí Efiali, Efiali sì bí Obedi.
Bí ẹ kò bá ní gbọ́ràn, tí ẹ kò sì ní fi sọ́kàn láti fi ògo fún orúkọ mi, n óo mú ègún wá sórí yín, ati sórí àwọn ohun ìní yín.
OLUWA àwọn ọmọ ogun bá rán mi pé, 
Pẹlu ajọṣepọ ileeṣẹ panapana ati ileeṣẹ ọlọpaa agbegbe Alagolo ni wn jọ pawọpọ doola ọmọ naa latinu kanga.
O sọ pe lootọ ni ajọ naa ti fi ofin de lilo chloroquine fun itọju aisan iba ni Naijiria, ṣugbọn wọn ti n ṣe agbeyẹwo rẹ pada lati fi koju aarun tuntun, coronavirus.
Kí Olódùmarè tún jẹ́ kí á máa gbúròó ara wa o.
Nǹkan tí Omiri ṣe burú lójú OLUWA, ibi tí ó ṣe pọ̀ ju ti gbogbo àwọn tí wọ́n wà ṣáájú rẹ̀ lọ.
Oyo Ni ọan ọjọ Iṣẹgun ni gomina Makinde ba awọn eeyan ipinlẹ Ọyọ sọrọ lori rukerudo to n waye lori bi awọn janduku kan ṣe ti sa wọ aarin awọn oluwọde ni ipinlẹ Ọyọ ti wọn si ti n lo iwọde naa lati fi kọlu awọn dukia ijọba, ẹmi ati dukia araalu.
Coronavirus: Àsìkò ti tó láti tilẹ̀kun mọ àwọn alejo to ń wọ Naijiria- Ilé Asofin Ilé ìgbìmọ̀ aṣòfin àgbà, ti ké si ìjọba àpapọ pe ki wọ́n fi sínú ìrònú wọ́n láti fi ofin de àwọn arinrin ajò ti kìí ṣe ọmọ Naijíríà láti àwọn orilẹ̀-èdè ti ààrun (COVID-19) náà n bá fíra láti ma wọ orilẹ̀-èdè mọ́.
Àwọn ẹrú baálé náà bá wá sọ́dọ̀ rẹ̀, wọ́n bi í pé, ‘Alàgbà, ṣebí irúgbìn rere ni o gbìn sí oko, èpò ti ṣe débẹ̀?
Laarin iṣẹju diẹ ti ifẹsẹwọnsẹ naa yoo pari ni Roberto Torres tun ri ẹyin awọn Barcelona nigba kan sii, eyi to mu ki goolu Osasuna di meji.
E ka ekunrere re ni bii Awọn nkan miran ti ẹ ni lati mọ loni Yemi Osinbajo: Ìgbákejì Ààrẹ tó gbọ́ nípa ẹ̀!
N kò gba ₦4bn lọ́wọ́ Magu, ẹ má ró àjẹbánu mọ́ mi láṣọ - Osinbajo pariwo Igbakeji aarẹ Yemi Osinbajo ti sẹ lori ahesọ iroyin kan to ni Ibrahim Magu, alaga ajọ EFCC tẹlẹ, ti jẹwọ pe, oun tẹwọ gba miliọnu mẹrin naira lọwọ rẹ.
"Àwọn Jàǹdùkú yabo ilé ìkó-ǹkan-pamọ́ sí, wọ́n kò 'Covid 19 Palliative"" lọ ní Eko Awon janduku ti sekolu si ile ikohunpamọsi nilu Eko nibi ti wọn ko awọn ohun amayedẹrun Covid -19 si."
Kíni àwọn ọmọ Nàìjíríà n sọ lórí ọ̀rọ̀ yìí?
" Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Fayose to jẹ ọkan gboogi ninu awọn alatako aarẹ orilẹede Naijiria, Muhammadu Buhari Gomina ipinlẹ Ekiti wa gba ijọba apapọ orilẹede Naijiria lamọran lati gbe opo ayelujara kan kalẹ ti yoo wa fun kikede awọn dukia ti ajọ to n gbogun ti ṣiṣe owo ilu baṣubaṣu lorilẹede Naijiria, EFCC ti gba lọwọ awọn to lu owo ilu ni ponpo ati awọn eeyan ti wọn ta awọn dukia naa fun.
Ikede kan ti aarẹ ajọ alaanu naa, Oloye Dozie Kaidi Obiaku se loju opo Instagram rẹ, lo sisọ loju ọrọ naa, to si ni Oreoluwa ko ni se asoju ajọ naa lọfẹ, wọn yoo tun fi owo osu tii nidi fun-un.
O dara pe a jọ tọrọ aforiji lọwọ ara wa a si dari ji ara wa""."
”Ó bá sọ fún wọn pé, “Tí ó bá rí bẹ́ẹ̀, ẹ fi ohun tí ó jẹ́ ti Kesari fún Kesari, kí ẹ sì fi ohun tíí ṣe ti Ọlọrun fún Ọlọrun.
Nibayii, eniyan meje to wa nibi ayẹyẹ to waye ni White House ni ọsẹ to kọja lo ti lugbadi arun naa.
Ṣugbọn ní tiwa, kì í ṣe ẹ̀mí ti ayé ni a gbà.
Igbesẹ yii n waye nitori ayipada ti ajọ to n mojuto ohun gbogbo lẹka ipese ina ọba lorilẹede Naijiria, NERC gbe kalẹ.
O fi atẹjade naa sita pe ko dara bi ijọba ṣi ṣe fi Sowore Omoyele si ahamọ DSS ati pe ẹsun meje ti ijọba fi kan Soworẹ yii ko tọna.
Ẹ ro ti irú ẹni bẹ́ẹ̀ tí ó fọkàn rán àtakò àwọn ẹlẹ́ṣẹ̀, kí ọkàn yín má baà rẹ̀wẹ̀sì.
Olori osisẹ ajọ to nrisi eto irina lojupopo, (FRSC) nipinle Ondo, ọgbẹni Vincent Jack nigba ti o fi idi isẹlẹ naa mulẹ, sọ wi pe eniyan mẹrin lo padanu ẹmi wọn, ti eniyan meji si parapa.
Gbọ́ adura mi, OLUWA;kí o sì jẹ́ kí igbe mi dé ọ̀dọ̀ rẹ.
Pákó fẹ́lẹ́fẹ́lẹ́ ni wọ́n fi bo ara ògiri ibi mímọ́ jùlọ Tẹmpili náà ati yàrá inú ati 
FFK: Buhari ló ń fún àwọn Fulani láàyè láti máa pa ènìyàn'
Ko din ni eniyan marundinlogoji ti awọn eeyan kan ti wọn funrasi pe wọn jọ agbebọn ti ṣe ikupa ni ipinlẹ Zamfara ni apa iwọ oorun ariwa orilẹede Naijiria.
Ṣugbọn OLUWA tún mú kí ọkàn Farao le, kò sì jẹ́ kí àwọn ọmọ Israẹli lọ.
Ìfihàn yìí àti méjì tí yíò tẹ̀lé e (Ìpín Kẹ̃dogún àti ẹkẹrìndínlógún) ni a gbà ní ìdáhùn sí ìbéèrè kan nípa lílo Urimù àti Thummimù.
2 16766 Orilẹede Ghana 326 1.
Yorùbá á tún máa pa òwe kan pé, ‘orúkọ ọmọ ni ìjánu ọmọ’.
Wọ́n ń fi ẹnu jẹ́wọ́ pé àwọn mọ Ọlọrun, ṣugbọn wọ́n ń sẹ́ ẹ ninu ìwà wọn.
FIFA fi ofin ayeraye dee pe o gba riba ni eyi ti wọn fi yọọ nipo.
Ọ̀pọ̀lọpọ̀ òkú ẹyẹ igún ré bọ́ lọ́jà Eke-Ihe Àwa ò mọ ẹgbẹ́ kankan tó ń jẹ́ fijilanté fulani l'Ondo- Ìjọba ìpínẹ̀ Ondo Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
El-Zakzaky fi India sílẹ̀, níbo ni yóò dé sí ní Nàìjíríà?
Ile ẹjọ to ga julọ lorilẹede Naijiria woye pe aṣẹ ti aarẹ ile ẹjọ kotẹmilọrun fun un pe ko lọ gbs ẹjọ naa labẹ ofin iṣedajọ lorilẹede Naijiria ko ba ofin mu.
O ni ohun ti atẹjade ti oun fi sita sọ ni pe awọn kọlu awọn ajinigbe naa ni.
Minisita sọ pe awọn ti wa ni igbaradi lati doju ogun kọ aarun naa.
A múra a kọ́jú sí ọ̀nà wa, sí òkè Ìrònú ti ń bẹ nínú Igbó Elégbèjè.
Wo ohun tó 'sun Sẹ́nétọ̀ Dino Melaye dé ìdí tíátà Gómìnà Kwara kéde àgùnbánirọ̀ àtàwọn míì gẹ́gẹ́ bí kọmíṣọ́nnà tuntun Táyà ọkọ̀ agbépo tó fọ́ fa ìjàmbá ọ̀kọ̀ l'Ékò, èèyàn kan farapa Boris Johnson àti ẹgbẹ́ rẹ̀ wọlé ìbò, Trump àtàwọn ààrẹ míì kíi kú oríire Ọlọpaa sọ pe olorin ọhun ni oun ko lee da owo iṣẹ naa pada ayafi ti ijọba ipinlẹ Imo ba fagile adehun iṣẹ ọhun.
Kò sí ẹranko kankan pẹlu mi àfi kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ tí mo gùn.
Ó gbẹ́ ère Aṣera tí ó gbé sinu ilé OLUWA, ibi tí OLUWA ti sọ fún Dafidi ati Solomoni pé, “Ninu ilé yìí, àní, ní Jerusalẹmu, ni mo yàn láàrin àwọn ìlú àwọn ẹ̀yà mejeejila Israẹli, gẹ́gẹ́ bí ibi tí ẹ óo ti máa sìn mí títí lae.
Afárá kan wà ní ibi tí odò àti igbó ti pàdé.
mojuto pipese ina mọna-mọna lorile ede Naijiria (Transmission Company of
 Ọmọ tí a bá ṣẹ ̀ ṣè bí tí a kò kọ ́ ní èdè , àti àwùjọ jẹ ́ kòríkòsùn .
Nígbà tí Johanani, ọmọ Karea ati gbogbo àwọn olórí ogun tí wọ́n wà pẹlu rẹ̀ gbọ́ gbogbo iṣẹ́ ibi tí Iṣimaeli, ọmọ Netanaya ṣe, 
Oríṣun àwòrán, @AfricaFactsZone Awọn koko ohun to si yẹ kẹ mọ nipa Ajala, the Traveller ree: Orilẹ-ede Ghana ni wọn bi si, amọ to lọ sile ẹkọ Baptist Academy nilu Eko ati Ibadan Boys‘ High School, ni orilẹ-ede Naijiria Idile olobinrin pupọ lo ti wa, iyawo mẹrin ni baba rẹ ni, to si bi ọmọ mẹẹdọgbọn ọmọ O lọ soke okun lẹni ọdun mejidinlogun lati kọ isegun oyinbo ko lee yi awọn ọmọ Naijiria lọkan pada nipa lilo oogun abẹnu gọngọ Ọdun 1952 ni Ajala di ilu mọọka nigba to fi kẹkẹ lasan rin orilẹ-ede Amẹrika ja, eyi to toto ẹgbẹrun meji ati ọọdunrun maili nigba naa Asọ iran Yoruba, taa mọ si Agbada ati Sokoto ni Ajala wọ lori kẹkẹ to fi rin yika agbaye, eyi to fẹ fi yi ero ọkan awọn alawọ funfun pada pe ihoho ni awọn alawọ dudu maa n rin tabi so ewe mọ ara Irinajo agbaye ti Ajala se yii jẹ ko di gbaju-gbaja loke okun, ti wọn si n pe e sinu awọn ere Sinima bii White Witch Doctor, to si n jẹ orukọ Ọla nibẹ Orilẹ-ede mẹtadinlaadọrun (87) ni Ajala fi ọkada de jake-jado agbaye laarin ọdun mẹfa Awọn orilẹ-ede bii Israel, India, Australia, Iran, Russia, Ghana, Cyprus, Egypt ati bẹẹ bẹẹ lọ ni Ajala de, to si pade awọn eeyan nla-nla to fi mọ awọn olori orilẹ-ede naa Aya pupọ ni Ajala ni, bo se fẹ dudu, lo fẹ pupa, koda o kọ ọmọ si oyinbo kan lọrun, eyi to di ọrọ ileẹjọ Losu kẹta ọdun 1953 ni Ajala koju ẹsun iwe yiyi, ole jija ni ipinlẹ Califonia, eyi to ni oyinbo kan lo gba oun Ajala lọ sẹwọn ọdun kan, ti wọn si di lapanyaka kuro ni orilẹ-ede Amẹrika, paapa nitori pe ko lọ si ile ẹkọ to wa fun mọ nilẹ Amẹrika O gun ori opo ẹrọ alatagba to to ọgọrin ẹsẹ bata, to si n dunkoko pe oun yoo jabọ silẹ, eyi to fi n fi ẹhonu han tako bi wọn se le ni Amẹrika O tun bẹrẹ si ni yan ounjẹ lodi lati fi ẹhonu han, lẹyin o rẹyin wọn gbe lọ si ilu London, ti wọn ko si gbe wa silẹ Naijiria mọ Ajala pada si Amẹrika lọdun 1954 pẹlu aya rẹ alawọ funfun, Hermie Aileen amọ ti obinrin naa kọ silẹ lori ẹsun pe o n ko obinrin pupọ Ọdun 1955 lo tun fẹ iyawo miran, ti se osere ori tẹlifisan, ẹni ọdun mọkandinlogun Ajala pada si ilẹ Naijiria lẹyin ọpọ ọdun loke okun, o dagba, aisan rọlapa, rọlẹsẹ si mu, amọ ko si owo fun lati tọju ara rẹ Ọjọ keji osu keji ọdun 1999 ni Ọlabisi Ajala ki aye pe o digbose nile iwosan ijọba to wa ni Ikẹja.
Ọgbẹni Rex Tillerson ni owooya lati orilẹede China lewu pupọ fun awọn orilẹede Afirika ati wi pe ikilọ naa kii se ọgbọn ati di ọna mọ owo orilẹede China ti o n regun silẹ Afirika.
Ibudo igbafẹ kan to wa ni ilu Kaduna lawọn gende agbebọn kan ti yinbọn mọ lasiko to wa si orilẹede Naijiria lati lo isinmi rẹ.
O kere tan, ọgbọn eeyan lo fara gbọgbẹ ọta ibọn lẹyin ti awọn ologun sina bolẹ nibẹ.
Lara awọn foonu ti pipada lẹyin wọn eyi ti WhatsApp yoo ṣe yoo koba ni Nokia Lumia eyi to jẹ foonu to gbẹyin lati bẹrẹ si ni lo ilana iṣiṣẹ atijọ OS ti Microsoft Windows.
Wọ́n ti fa Ààrẹ Amẹrika, Donald Trump kalẹ̀ fún àmì ẹ̀yẹ Nobel Peace Prize Auxiliary gbé èèyàn mẹ́fà tó ń jáwèé ayédèrú fáwọn awakọ̀ lọ sí ilèẹjọ́ ní Ibadan Ibadan NURTW: Àwọn ti Auxilliary àtàwọn tí Ajanaku gangan ló ń dàgboro rú Kí ló le è mú kí agbábọ́ọ̀lù subú, kó sì kú lásìkò ìfẹsẹ̀wọ̀nsẹ̀?
Iru igbese bayii yoo tun jẹ ki owo
pe ajo INEC yoo seto idibo to n bo yii ni irọwọ ati irọsẹ.
Ṣugbọn nígbà tí òun fúnrarẹ̀ ní kí á gbé ẹjọ́ òun lọ sí ọ̀dọ̀ Kesari, mo pinnu láti fi í ranṣẹ.
Ọdun 2018 ni wọn kọkọ tii mọle, ki wọn to gba beeli rẹ, wọn tun ti i mọle pada ni ọdun 2019.
Toò, a tún ṣe t’òní o, ọpẹ́ ni fún Olódùmarè.
Oríṣun àwòrán, others Femi, to tí lo ọdún marundinlogoji lẹ́nu iṣẹ́ tíátà, tún pàrọwà sawon èèyàn láti ṣe ìwádìí kíkún kí wọn tó dárapọ mọ iléèwé tíátà kan.
Ẹ má máa fi ìyà jẹ àwọn opó, tabi àwọn aláìníbaba, tabi àwọn àlejò tí wọn ń gbé ààrin yín, tabi àwọn aláìní.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Childhood Games: Ewo nínú àwọn eré ìdárayá ilẹ̀ Yorùbá tẹ ṣe ní kékeré wo lẹ fẹ́ràn jù?
Ni afikun gbogbo omo ile ro awon ajo apese iranlowo bii ti isokan agbaye ati awon Medicine Sans Frontiers pelu awon onisegun oyinbo lati bere ise won pada ni ibudo asatipo Rann nipinle Borno ni ariwa ila oorun Naijiria pada.
Awọn aginjù ti wọ́n ti gbàgbé Awọn inaki wa ninu ewu lorilẹ̀ede Naijiria ati Cameroon.
Oríṣun àwòrán, Senate Bi wọn ṣe buwọ lu abadofin yii yá ju ti ọdun 2018 nigba ti awọn aṣofin buwọ lu abadofin ti ọdun naa ni oṣu karun un.
Ọkunrin ọgọrun le mẹta lo wa ni ahamọ yii ati obinrin marun un ti ọjọ ori wọn wa laarin ọdun mejila si ogoji ti wọn si de ọpọ wọn nigbekun.
Jẹ́ kí wọ́n rá, kí wọn ṣàn lọ bí omi;kí á tẹ̀ wọ́n mọ́lẹ̀ bíi koríko, kí wọn sì rọ.
F Odunjo ni Asiwaju ilẹ Ẹgba, ko to dagbere fun aye pe o digbose lọdun 1980.
Bi o tilẹ jẹ pe Hubert Adedeji Ogunde ti waye, o ti se iwọn to lee se, ti ipa to fi lelẹ ninu idagbasoke igbe aye ọmọniyan ko si lee parẹ; O yẹ ki awa ta jẹ abẹmi loke eepẹ loni fi eyi se awokọse rere, ka si se aye re.
Dafidi sọ fún un pé, “Ta ibi ìpakà yìí fún mi, kí n lè tẹ́ pẹpẹ kan níbẹ̀ fún OLUWA.
Lati owurọ ọjọ Aiku ni ọgọrọ eeyan ti yabo oju ayelujara nibi ti wọn ti n kepe ijọba lati wọgile ọlọpaa nitori ọṣẹ ti wọn n ṣe fun ọpọ araalu papaa julọ awọn ọdọ.
Jesu bà fà á lé ìyá rẹ̀ lọ́wọ́.
Onimọ ofin ti ni iwe ofin Naijiria gbe kalẹ wi pe yiyan Aarẹ Ile Asofin Agba ati Olori Ile Igbimọ Asofin kekere fi lele wi pe aarin ara wọn ni wọn ti n yan ẹni ti yoo jẹ olori wọn.
Ile ẹjọ ni o fipa ba oloogbe naa lopọ, ko to yin lọrun.
Aṣole fun Manchester City Ederson ati agbabọọlu aaringbungbun Fernandinho ko ni le kopa ninu ere bọọlu naa, nitori o pẹ diẹ ki wọn to pada de lẹyin ti wọn ṣoju Brazil ninu idije Copa America, Claudio Bravo Bravo ni yoo dile mu fun Man City ninu ifẹsẹwọnsẹ ọhun.
Ṣùgbọ́n Olódùmarè kò jẹ́ sọ báyìí, nítorí aláàánú ni Òun í ṣe.
Idi ree ti Sara se bẹrẹ si ni banujẹ, to si n roun.
" Ninu ọrọ tiẹ, Jamine sọ pe igba akọkọ niyi ti oun wa si ilẹ Africa, inu oun si dun si bi awọn eniyan ṣe n tọju rẹ.
Ni ọjọ iṣẹgun ni Aarẹ Buhari fi orilẹede Naijiria silẹ lọ si ilu Lọndọn, lẹnu irinajo ati tọju ara rẹ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Yorùbá tone mark: Fífi àmì ohùn sí orí ọ̀rọ̀ Yorùbá ṣe pàtàkì Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ebola Virus: ìdí tí Ebola fi ń tàn kálẹ̀ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Ebola Virus: ìdí tí Ebola fi ń tàn kálẹ̀ 22 Òkùdu 2019 O lé ni ènìyàn 28, 000 tó ti gbẹmi mi lori ọrọ Ebola.
Ekejidinlogun mú Hanani, òun ati àwọn ọmọ rẹ̀ ọkunrin, ati àwọn arakunrin rẹ̀ jẹ́ mejila.
Gege bi Pinnick se so,“Won yoo samulo ero igbalode VAR ninu ifesewonse olorejore wa pelu orile-ede England,.
Lasiko to n ba awọn akọroyin sọrọ Akintoye ni oun gba oye naa tọwọ tẹsẹ ti o si pe fun ifọwọsowọpọ awọn ọmọ Yoruba.
 Botilẹ jẹ pe mo doola ẹmi awọn ọmọ naa, mo kuna lori awọ ọkunrin meji akọkọ."
 O gboriyin fun Sisi to n tuko orile-ede naa lowo, oun naa ni aare ile Adulawo akoko ti o koko lo sabewo si Trump losu kerin odun yii.
''Ti Ambode ba wa bawa lóni ti a sì ṣẹ àgbéyẹ̀wò ti a ri wí pé tọ́kàn tókàn ló fi fẹ dárapọ mọ́ wà, a lè gbà wọlé.
Ṣugbọn nisinsinyii, OLUWA Ọlọrun mi ti fún mi ní alaafia ní gbogbo agbègbè tí ó yí mi ká.
Ọlọ́pàá mú èèyàn márùn ún lórí ìjà láàrin Hausa àti Yorùbá l'Eko Wàhálà bẹ́ sílẹ̀ láàrín àwọn ọ̀dọ́ ní Oke Odo ní ìpínlẹ̀ Eko Aṣírí ìdí ti El-Zakzaky fi padà Nàìjíríà láti India Fayemi fojú Alufa to fipa bá ọmọde lòpọ̀ síta l'Ekiti Laisi ani ani, ipade naa pada waye ni Ikeja, niluu Eko lọjọ Aje.
 Iriri re seyin yoo wulo pupo fun wa lati seto ipolongo alara oto ti a nilo lodun 2020”.
Òun ati gbogbo ìdílé rẹ̀ sì bẹ̀rù Ọlọrun.
" Oríṣun àwòrán, twitter/Seyi makinde Update on Coronavirus ní Nigeria: Bí a ṣe fi N2.
Yoo si tun ma a san owo ileewe wọn, ati bukaata to ku.
Asiko yii lawọn dokita ati eleto ilera fi le gbe igbesẹ ki arun naa ma baa tan kalẹ Ṣe coronavirus le tan kalẹ ju otutu igba ọginiti lọ Lati ọwọ Merry Fitzpatrick ni Sydney Michelle Roberts Adari iko eleto iroyin ilera ni BBC Aisan mejeeji jẹ ajakalẹ arun o kere tan, eeyan meji si mẹta le ko coronavirus lara ẹni to nii nigba ti ẹni kan le ko otutu igba ọginiti lara ẹni to nii Awọn igbesẹ to rọrun wa too le gbe lati dẹkun itankalẹ coronavirus Maa fọ ọwọ rẹ pẹlu ọṣẹ ati omi loorekoore Dẹkun fifi ọwọ kan oju ati imu rẹ ti ọwọ rẹ ko ba mọ Hukọ tabi ki o sín sinu tíṣu ki o si sọ ọ nu sile idọti Igba wo lo ti rẹ ẹ mọ?
a ba wo awon iwa ibaje ati rogbodiyan ti awon oniise ibi, ada alafia ilu laamu
Ọpọ eeyan ni ko mọ pe Alaafin bi ibẹta, nitori pe ibeji ati ẹyọ kan lo wọpọ ju ninu awọn ọmọ ti baba n bi.
Ẹni to bori: Egypt Ìpele to kangun si aṣakagba South Africa vs Nigeria.
Suberu Dada - Minisita abẹle fun ọrọ ilẹ okeere.
Oríṣun àwòrán, Instagram/muhammadubuhari Ipinlẹ Eko lo si n lewaju pẹlu awọn to larun naa julọ, ẹẹdẹgbẹrin eeyan le ni mẹtala(713) lo karun ọhun nipinlẹ Eko nikan lọjọ Ẹti.
Eyi ni ẹkọ taa kọ lati ọdọ Ade Love ati Hubert Ogunde'' O ni sọ nipa pataki orin kikọ ninu aṣa ati igbelarugẹ ede Yoruba Èèyàn méjì gbẹ́mìí mì nínú ìjàmbá ọ̀kọ̀ tó ṣẹlẹ̀ lórí afárá Otedola Ọ̀sẹ̀ àkọ́kọ́ ọdún 2020: Àwọn ìròyìn tó mí ìgboro tìtì 'Ipò àpọ́nlé ni mo fi Gómìnà Abdulrahman sí ṣugbọn kò hùwa àpọ́nlé' Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Ki ni ajọ WHO tun wi?
Ọjọ kọkandinlogun oṣu Keje ọdun 2020 ni idije BBNaija 2020 bẹrẹ, ọpọ awọn ololufẹ eto ọhun lo si ti n reti iru awọn sinimna orita ti yoo ṣelẹ ninu ile naa lọdun yii.
Linda tun ṣalaye bi oun ati Sholaye ti pade ara wọn, bakan naa lo ṣalaye bi ọrọ ti bẹyin yọ ti onikaluku ṣi fi ba tirẹ lọ.
Ó ń ba ìtàn náà lọ ó sì wí pé:
Abọ iwadii ile asofin Eko lori ẹsun mẹrin ti wọn fi kan olori wọn: Lori ẹsun akọkọ to sọ pe Obasa ni apo asunwọn owo mẹrinlelọgọta ni banki, igbimọ oluwadii naa ni irọ nla ni eyi nitori nọmba BVN ti wọn kọ kii ṣe ti Obasa, awọn Ileesẹ ti wọn si ni oun lo ni, kii ṣe tiẹ.
Irinajo ti gbérasọ padà ní pápákọ̀ òfurufú ìpínlẹ̀ Imo lẹ́yìn ìjàmbá iná Àwọn ológun dojú ìjà kọ ara wọn ní Khartoum Rélùwéè tẹ alágbe kan pa ní Eko Bakan naa ni Ilé iṣẹ́ ọlọ́páà tún dupẹ́ lọ́wọ́ ìjọba ìpínlẹ̀ Eko fún ìrànwọ àti gbogbo àrá ilú fún àwọn ìfitóniléti tí wọn ṣe to si ran àwọn lọ́wọ́ láti rí àwọn ènìyàn náà gba lọ́wọ́ àwọn ajínígbe.
 a kò tíì ṣe àkọsílẹ ̀ àtànká àrùn náà nípasẹ ̀ afẹ ́ fẹ ́ ní àyíká adánidá .
Ni bi a ṣe n sọrọ yii ẹgbẹ agbabọọlu Manchester United ti kede rẹ faye gbọ pe Diallo ti gunlẹ si gbagede Old Trafford lati ikọ Atalanta lorilẹede Italy .
Bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé ẹ pọ̀ bí ìràwọ̀ ojú ọ̀run, ẹ kò ni kù ju díẹ̀ lọ mọ́, nítorí pé ẹ kò gbọ́ ti OLUWA Ọlọrun yín.
“Oholiba, àbúrò rẹ̀ rí èyí, sibẹsibẹ, ojú ṣíṣẹ́ sí ọkunrin ati àgbèrè tirẹ̀ burú ju ti ẹ̀gbọ́n rẹ̀ lọ.
Lilo ati Ka3na ni wọn kọkọ le danu lori eto BBNaija 2020 lẹyin ti awọn ololufe eto naa atawọn akẹgbẹ wọn lori eto ọhun fawọn kalẹ gẹgẹ bi awọn ti asiko ti to fun lati pada sile.
Ni kete to gunlẹ si ilu Kishi ati awọn ikọ rẹ, aafin Iba tilu Kishi ni Igboho kọkọ morile, nibi to ti lọ se ago laafin si ori ade naa, ajeji kii sa wọ ilu, ki onilẹ ma mọ.
 Lara awon to tun wa ki aare
Ẹwẹ, fun awọn to wa ni ipinlẹ Osun, ayẹwo naa yo waye ni awọn ijọba ibilẹ kọọkan ni awọn ọjọ wọnyii: Ọjọ Aje, 24/08/2020 1.
 Ó darapọ ̀ mọ ́ ẹgbẹ ́ eré ìdárayá àwọn tí kò lẹ ́ sẹ ́ ní mila .
”“Ni akoko ti nkan ko ba lo deede, eyan ma n fi akoko naa ko eko ni.
Wọn ni ajọ eleto idibo ilẹ wa ati awọn ileesẹ agbofinro ti yẹsẹ kuro loju opo ofin isẹ wọn, to si ti foju han pe ijọba apapọ ilẹ wa fẹ́ se mago-mago ninu eto idibo naa.
Gbogbo nǹkan wọnyi ni ẹ ti ṣe tí mo sì dákẹ́;ẹ wá ń rò ninu yín pé, èmi yín rí bákan náà.
Ọlọrun Pàṣẹ fún Abrahamu pé Kí Ó fi Isaaki Rúbọ.
Tabi ọba rẹ̀ kò sí ninu rẹ̀ ni?
Ìkọlù àwọn ti Boko Haram pa níbi ìsìnkú Borno ti lé síi Odiwọn iye awọn to ba ikọlu Boko haram to ṣẹlẹ yii lọ ti di marun dinlaadọrin bayii.
Iye ọdún tí ó bá ti rékọjá lẹ́yìn ọdún jubili ni ẹ óo máa wò ra ilẹ̀ lọ́wọ́ aládùúgbò yín, iye ọdún tí ẹ bá fi lè gbin ohun ọ̀gbìn sórí ilẹ̀ kan kí ọdún jubili tó dé ni òun náà yóo máa wò láti tà á fun yín.
Kò sí ìwé ìrìnnà 'VISA' fáwọn ọmọ Naijiria tó hùwà àìtọ́ nígbà ìdìbò 'Ìdùnnù wa kọ́ ni kí á má fún ọmọ Nàìjíríà ní 'Visa' Ìbọn ọlọ́pàá ló pa èèyàn, ẹgbẹ́ wa kìí lo ìbọn - Shiite fárígá Ṣé irúfẹ́ oúnjẹ tí ò ń jẹ́ lè jẹ́ kí o gbádùn ìbálòpọ̀ rẹ síi?
Báyìí ni orin ìsìn ìkẹyin olóògbé Ibiduni Ighodalo ṣe lọ Àkọlé àwòrán, Báyìí ni orin ìsìn ìkẹyin olóògbé Ibiduni Ighodalo ṣe lọ Àkọlé àwòrán, Olórin ìgbàgbọ́ Tope Alabi náà péjú sibi ìsìn òrin to wáye Àkọlé àwòrán, Awọn ènìyàn to n sọ̀rọ̀ nípa olóògbé Àkọlé àwòrán, Olùsọagutan Ituah Ighodalo nínú ìṣìn orin ìkẹ́yìn Àkọlé àwòrán, Báyìí ni orin ìsìn ìkẹyin olóògbé Ibiduni Ighodalo ṣe lọ Ibidun Ighodalo death: Ilé Ighodalo dá páropáro, òkú Ibidunni Ighodalo ti wà nílé ìgbókúpamọ́sí l'Eko Awọn ebi oloogbe Ighodalo ti gbe oku rẹ lọ si ileewosan kan ni agbegbe Lagos Island ni ilu Eko.
Wò ó, a di ẹrú rẹ, oluwa mi, ati àwa ati ẹni tí wọ́n bá ife náà lọ́wọ́ rẹ̀.
Géńdé agbébọn mẹ́rin kọlu Toyosi Adesanya, awakọ̀ rẹ̀ dèrò ọ̀run Oríṣun àwòrán, Toyosi Adesanya Ileyemi Iroyin kan to gba ori ayelujara kan ti kede pe, ori lo ko osere tiata lobinrin kan yọ, Toyosi Adesanya Ileyemi, lọwọ iku ojiji.
Israẹli bá tún rán oníṣẹ́ sí Sihoni, ọba àwọn ará Amori, tí ó wà ní ìlú Heṣiboni, wọ́n ní, ‘Jọ̀wọ́ jẹ́ kí á gba ilẹ̀ rẹ kọjá lọ sí agbègbè ilẹ̀ tiwa.
Ìṣẹ̀lẹ̀ yìí sí lo mú kí àwọn ikọ Ogun Ìjẹ̀bú, Ẹ̀gbá àti Fulani to ń ṣe atilẹyin fun ìjàyè tètè fà sẹ́yìn lójú ogun, nígbà tí wọn rí pé olórí ogun ti awọn tẹle tí di ara ilẹ̀.
Àwọn ọba Filistini ń wò wọ́n bí wọ́n ti ń ṣe, lẹ́yìn náà, wọ́n yipada sí ìlú Ekironi ní ọjọ́ náà gan-an.
Ikede yi to fi soju opo rẹ ni Instagram lo sọ pe ara oun ko ti ya daada nitori bi oun ti ṣe fori gbalẹ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Stingy Men Association: Ojú òpó Twitter ń ṣọkutu wọ̀wọ̀ pẹ̀lú ọ̀rọ̀ àwọn ọkùnrin ahun 11 Sẹ́rẹ́ 2021 Oríṣun àwòrán, Twitter Njẹ ẹyin mọ ẹgbẹ tuntun tawọn eeyan n sọrọ rẹ bayii lori ayelujara ni Naijiria bayii?
mo rọ iranṣẹ Ọlọrun yii lati tete dahun si ẹsun nla wọnyii.
Ó tún wọn ìloro, ó jẹ́ ogún igbọnwọ (mita 9).
Tí a fiṣọwọ́ ní 11:15 11 Òkùdu 201911:15 11 Òkùdu 2019 Ìdìbò parí, kíkà bẹ̀rẹ̀!
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Aremu: Eré ìtàn nípa ìbí, àti jéèyàn pẹ̀lú ìpèníjà Olusegun Aremu Obasanjo Abdulsalam fi kun un pe, awon oniduro rẹ gbodọ jẹ olugbe adugbo ile ẹjọ ki o si ni iṣẹ gidi lọwọ pẹlu ẹri iwe owo oei to n san deede fun ijọba ipinlẹ Ogun.
Wọ́n ti dẹ tàkúté sílẹ̀ fún miní ọ̀nà tí mò ń rìn.
Yinka Ayefele fi orin ẹ ṣeun sẹ́nu lórí ilé orin tuntun rẹ̀
Bi o tilẹ jẹ wi pe ọpọ lo n sọ kiri pe, Dapọ ṣeku pa ara rẹ ni, sibẹ Sẹnetọ Saraki ti sọrọ sita pe awọn agbofinro ti bẹrẹ iwadii lori rẹ.
Èkó: Ọ̀bọ lé àwọn ènìyàn kúrò ní Gbàgádà
Mo bẹ̀ ọ́, gbà mí lọ́wọ́ Esau arakunrin mi, nítorí ẹ̀rù rẹ̀ ń bà mí, kí ó má baà wá pa gbogbo wa, àtàwọn ìyá, àtàwọn ọmọ wọn.
Wọ́n rí alààyè obìnrin tó ti kú tẹ́lẹ̀ nínú mọ́ṣúárì
”Amo sa,awon kan n so pe ohun to mu igbakeji gomina naa lati kowe fipo sile ni pe, mokanlelogbon awon omo ile igbimo asofin ipinle naa ,ni won ti fowo si iwe lati yọ igbakeji gomina naa nipo, ni eyi ti won yoo jiroro lori re lojo Aje.
Ilé aṣòfin kùnà láti ṣe ìpàdé pàjáwìrì tó pè 'Mímu ọyàn àyà ìyàwó rẹ̀ ní àǹfàní tó pọ̀' Èyí lágbára, Ajínigbé sùn lọ lẹ́nu iṣẹ́ Ọ̀fọ̀ ńlá ṣẹ̀, aya gún ọkọ pa torí owú jíjẹ!
”Lara awon ti won soro nile igbimo asofin ti ECOWAS naa ni orile ede Sierra Leone, Senegal ati Liberia.
Akọroyin BBC jabọ pe 'saaju ki awọn ọlọpaa o to yin afẹfẹ taju-taju si afẹfẹ ni wsn ti kọkọ kilọ fun awọn to n fi ẹhonu han pe ki wọn o tuka.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Crystal Palace vs Manchester United: Crystal Palace pàkúta sí gaàrí Manchester United ní Old Trafford 24 Ògún 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Ajẹtun iya ni Manchester United jẹ lọwọ ẹgbẹ agbabọọlu Crystal Palace lọjọ Abamẹta ninu idije Premier League.
Moshood ni ọjọ mẹfa lẹyin rẹ - ọjọ kẹtadinlọgbọn oṣu keje, ọdun 2017 ni awọn ọlọpaa mu ṣẹnetọ, ti wọn si mu Sikiru Adeleke ni ọjọ kẹjọ oṣu kẹjọ, ọdun 2017.
ede Naijiria,Ayuba Waba  wa ro gbogbo
Oríṣun àwòrán, @SPNigeria Amọṣa, aṣoju ileeṣẹ epo rọbi ni ijọba apapọ, Godwin Akubo, ni wọn gbe igbesẹ naa jade lati tete mojuto ohun to n jẹ awọn ipin kọọkan to wa labẹ ileeṣẹ naa ni.
Ogun aye lo ti mi de ori Facebook, ibẹ si ni mo ti ṣe oriire."
Gomina Makinde ni ọdun 2002 loun ati oloogbe Kẹhinde Ayọọla pade ti o si jẹ olootọ ati olufọkansin eeyan.
Ó sọ fún wọn pé, “Nígbà tí ẹ bá ń gbadura, ẹ máa wí pé,‘Baba, ọ̀wọ̀ ni orúkọ rẹ.
A kò jẹ́ ṣe oríkunkun sí OLUWA tabi kí á kọ̀ ọ́ sílẹ̀, kí a má sì sìn ín mọ́ kí á wá tẹ́ pẹpẹ mìíràn fún ẹbọ sísun tabi ẹbọ alaafia tabi ẹbọ mìíràn, yàtọ̀ sí pẹpẹ OLUWA Ọlọrun wa tí ó wà níwájú àgọ́ rẹ̀.
Ambode ní kò sí gìrì, eré ọwọ́ lásán ni EFCC ń ṣe 'Ẹ má ṣi Fayemi túmọ̀ lórí àṣẹ tó pa nípa sísọ èdè Yorùbá' Kòsí àṣà tó faramọ́ fífi èmí ènìyàn ṣe ìrúbọ - Olúwó Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Beṣasari bá pàṣẹ, pé kí wọ́n gbé ẹ̀wù elése àlùkò, ti àwọn olóyè, wọ Daniẹli, kí wọ́n sì fi ẹ̀gbà wúrà sí i lọ́rùn.
Mo ti kọkọ sọ fún Toyin Abraham pe mi o le ṣe amúgbálẹ́gbẹ rẹ̀- Sam Olatunji
fontẹ lu ipinnu re lati je ki adari ile-ifowopamo ti ijoba apapo, ogbeni Godwin
Lori iroyin pe ọlọpaa yinbọn pa ẹnikan nibi iṣẹlẹ naa, Ọgbẹni Joseph sọ pe oun ko le sọ pe nkan bẹ ẹ ṣẹlẹ.
Ilorin illegal Rehab: Bàbá ẹni ọdún 77 ni alákòóso ibùdó
Ṣé kí a wá sọ ẹ̀yà ara Kristi di ẹ̀yà ara àgbèrè ni?
Ọwọ́ ọlọ́pàá tẹ ọmọ Britain tó ń ta kẹ́míkà gẹ́gẹ́ bi omi ìyanu Wọ́n jí ọmọ yìí gbé láti máa fi tọrọ bárà l'Eko ‘Bi Gomina Ajimobi se yan adarí òsìsẹ́ tuntun ní Oyo kò dí wa lọ́wọ́’ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Abdulfatah Ahmed: Àwọn Kwara fẹ́ dán ilé ọkọ kejì wo ni lásìkò yí Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Footballers: ìkà láwọn aṣojú agbábọ̀ọ̀lù míì lágbàyé Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Ẹni tí ó tó pe ọba ní eniyan lásán,tí ó tó pe ìjòyè ní ẹni ibi;
O tun ṣeleri atilẹyin ijọba fun awọn ọmọ igbimọ naa.
Mo ti ṣalabapade ọpọ eniyan ni Kenya yii to ni iru aarun yii, a si n sọ iriri wa fun'ra wa.
Lẹ́hìn èyí ìyàwó mi padà dé òun náà sì gun orí ibùsùn ó sùn tì mí.
Omohtee ti fẹsun kan dokita to ṣe iṣẹ abẹ naa, dokia Anu fun iṣẹ ajabanku to ṣe si oun lara.
Ṣugbọn ejò náà dáhùn, ó ní, “Ẹ kò ní kú rárá, 
Ará Eko, ẹ pariwo ó tó gẹ́ẹ́ lórí làásìgbò tó gbòde torí ìwọ́de EndSARS - Sanwo-Olu Oríṣun àwòrán, LASG Gomina ipinlẹ Eko, Babajide Sanwo-Olu ti sọ pe ibanujẹ lo jẹ fun oun, bí àwọn janduku ṣe ja iwọde ipolongo #ENDSARS gba.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìjọba Ọyọ: Olówó nìkan kọ́ ni ìdájọ́ iléẹjọ́ yóò máa gbè ní Ọyọ 24 Ògún 2019 Oríṣun àwòrán, @Lagostalks913 Ijọba ipinlẹ Ọyọ ti fi ọwọ idaniloju sọya pe latri akoko yii lọ, oun yoo maa gbe igbesẹ lati mu adinku ba ajaga ẹru ẹjọ to wa lawọn ileeẹjọ, ti wọn yoo si maa yanju awọn ẹjọ pẹlu iyara kankan.
Bí ó sì tí ń sọ̀rọ̀ wọn-ọnnì pẹ̀lú, èmi náà ń mi orí mi bí àmì láti fi hàn wí pé mo ń gbádùn ọ̀rọ̀ ẹnu ọ̀rẹ́ mi: nítorí ẹni tí ó gbé ni gun orí ìtẹ́ ló tí wí pé kí á hùwà ènìyàn ńlá, ẹni tí ó gbé ẹ̀wù sányán bọ ni lọ́rùn ló ti wí pé kí a hùwà ènìyàn pàtàkì, bí ọ̀rẹ́ mi ti ń sọ̀rọ̀ mi dáradára wọn-ọnnì, èmi náà rọra ń fi ohùn ìsàlẹ̀ wí kẹ́lẹ́kẹ́lẹ́ sí i létí wí pé: ‘Baba-onírùngbọ̀n-yẹ́úkẹ́, ọọ kú ọmọ, Baba-onírùngbọ̀n-yẹ́úkẹ́, ọọ kú ọmọ, àti bẹ́ẹ̀ bẹ́ẹ̀ lọ.
Pé ó gbà kí ọkọ àfẹ́sọ́nà rẹ bá ọ ní àjọṣepọ̀ kò ní kó fẹ́ ọ - Ṣọla Allyson Ǹjẹ́ o mọ̀ pé Baba Sala ló kọ́ Sunny Ade nísẹ́?
Jesu Oyingbo rèé, pásítọ̀ tó láṣẹ ìbálòpọ̀ lóri ọmọ ìjọ obìnrin Yorùbá kìí ṣe egúngún oníhòhò, ìwà wèrè ni sinimá oníhòhò táwọn òṣèré kan ń ṣe- Lere Paimo Mo fẹ̀ lọ gba owó oúnjẹ lọ́wọ́ bàbá mí ni mo bá wọn tí wọ́n ti pokùnso- Ọmọ Oloogbe Eyín ọ̀ọ́kán mi ni Barakat tí wọ́n pa lẹ́yìn tí wọ́n fipá bá a lòpọ̀- Ìyá Barakat IGP ti jọ̀wọ́ Hamisu Wadume fún aádájọ́ àgbà Nàìjíríà Èmi ni Ààrẹ tó ṣe rere fún ilẹ̀ adúláwọ̀ jù - Donald Trump Ọmọdé yóò máa sọnù ládùúgbò, arúgbó leè kú láì tọ́jọ́, tí wọn bá jókòó sílé lásìkò ìjọsìn - CAN Kí ni ìdí tí ilé ẹjọ́ tún ti sún ìgbẹ́jọ́ Alfa Babatunde Sotitobire síwájú Ohun mẹ́fà tí àgbáyé kò mọ̀ nípa Majek Fashek tó d'olóògbé nìyí Ọwọ́ ọlọpàá tí tẹ ọ̀kan nínú àwọn ọ̀daràn tó ṣekú pa Uwaila Èyí tí a wò jùlọ 5:03 Fídíò, Omolola Arohunmolase Welder: Mo ti fí iṣẹ́ 'Welder' gbayì láwùjọ, tó mo fi tọ́ ọmọ yanjú, Duration 5,039 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 5:39 Fídíò, Akomolede ati Asa lori BBC: Olùkọ́ Kikelomo Ogunboye tan ìmọ́lẹ̀ sí ìwà olè ọ̀gá ọlọ́pàá Audu gẹ́gẹ́ bí àwòkọ́ṣe àsìkò yìí, Duration 5,398 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 4:11 Fídíò, Oba Adeyeye Ogunwusi: Ojú mi ti rí lọ́pọ̀ lọpọ̀, ọ̀pọ̀ èèyàn ni kò tilẹ̀ gbàgbọ́ pé mo lè jọba- Ooni, Duration 4,117 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 4:43 Fídíò, Promise Akinlade: ọmọ ọdún mọ́kànlá tó ń fi ìlù dárà bíi àgbàlagbà sọ̀rọ̀ nípa tálẹ́ǹtì rẹ̀, Duration 4,437 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 0:59 Gbọ́, Ìsẹ̀lẹ̀ jákèjádò orílẹ̀èdè àgbáyé láàárín ìṣẹ́jú kan, Duration 0,59wákàtí 6 sẹ́yìn 4:45 Fídíò, Yoruba Films: Ẹ̀ẹ́ bẹ̀ mi kúrò láyé ni, mi ò lè kú - Fadeyi Oloro, Duration 4,4526 Èrèlè 2020 7:03 Fídíò, Olumuyiwa Bolade Adedeji Military Bruitality: Bí arákùnrin onípèníjà ara tí sọ́jà lù ṣe dé, Duration 7,035 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 2:48 Fídíò, Esther Ajayi: Èmi náà ti borí ìṣòro rí ló ń mu mi ṣojú àánú, Duration 2,481 Ògún 2019 6:08 Fídíò, Adebola Ademilua: Àìrísẹ́ ṣè lẹ́yìn ìwé kíkà ló sọ mi dí ìyá onírú, mo dúpẹ́ tèmi, Duration 6,0827 Bélú 2020 5:55 Fídíò, Soyinka Cancer: Àṣe ara mi ni iso ti n run gbogbo bí mo ṣe n ṣèrànwọ́ lórí jẹjẹrẹ, Duration 5,5527 Bélú 2019 BBC News, Yorùbá Ìdí tí ẹ fi le è nígbàagbọ́ nínú ìròyìn BBC Ìlànà Lílò Nípa BBC Òfin Àṣírí Cookies Kàn sí.
Ati ṣe tan lati ran wọn lọwọ, ọwọ wọn lo ku si.
" Onimọ nipa ẹṣin Islam naa ni, inu oun maa n dun lati ṣun mọ ẹni to loye, ti oun si fa afurasi naa mọra debi pe, oun nikan lo maa n wọ yara ibusun oun, ti awọn si dijọ maa n jẹun ninu awo kan ṣoṣo lasiko isinu aawẹ.
Lai si ibuwọlu awọn aṣofin, ko si ọna ti owo yoo fi jade sita fun ajọ INEC lati bẹrẹ igbaradi fun eto idibo 2019.
Àwọn èèyàn kò fi bẹ́ ẹ̀ ní ìbálòpọ̀ lásìkò ìgbélé yìí - Iléèṣẹ́ kọ́ńdọ́ọ́mù Durex Ayẹwò kò dáwọ́ dúro botílẹ̀ jẹ́ pé èròjà ayẹwò (Reagents) kò si mọ́ Èmi àti Sanyeri ti tọrọ oúnjẹ jẹ rí nílé oninawo torí ebi, ká tó di gbajumọ oṣere Èrò ọmọ Nàìjíríà ṣ'ọ̀tọ̀ọ̀tọ̀ lórí ọ̀rọ̀ Bíṣọ́ọ́bù Oyedepo pé kò sí ìdí tí iléèjọ́sìn láti wà ní títì pa Adepoju ni òun bẹ̀rẹ̀ ère tíátà, tí òun sì ni ìlọsíwájú nínú eré itage, Atọ́ka, fídíò àgbéléwò àti sinima, kò tó di pé òun dá dúró, láti máa ṣe iṣẹ́ ti ara òun.
Wọn ni wakati kan pere ni wọn fun awsn eeyan to n gbe ni agbegbe ọhun lati ko ẹru wọn, eyi to mu ki ohun gbogbo dojuru.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Teach your children Yoruba: Wo àwọn òyìnbó tó ń kẹ́kọ̀ọ́ èdè Yorùbá ní Michigan, America Ko ni si owo ori ọlọsọọsẹ fawọn ileeṣẹ to n te tẹtẹ lati oṣu kẹrin ọdun si oṣu kẹfa.
Oríṣun àwòrán, Alaafin Oba Adeyemi III Awọn arugba Sango yii ni yoo gbe igba lati Ṣango Koso ls si ọdọ Iya Naso ni aafin Alaafin.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Commonwealth: Eléré ìdárayá Cameroon mẹ́jọ di àwátì 11 Ìgbé 2018 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Eléré ìdárayá mẹ́jọ láti Cameroon sálọ ní Australia Orílẹ̀èdè Cameroon ti kéde pé, mẹ́jọ nínú àwọn eléré ìdárayá orílẹ̀èdè náà, tó lọ sí ìdíje Commonwealth tó ń lọ lọ́wọ́ ni Gold coast, lórílẹ̀ede Australia, ni wọ́n ti di àwátì báyìí.
Oríṣun àwòrán, @femigbaja Olori ile asoju-sofin ni ile asofin naa yoo tun ri daju pe ijọba gbe igbesẹ lati se atunse ati atunto awọn ileeẹkọ giga gbogbo nilẹ wa, ti yoo fi ba ode oni mu.
TABILI ABAJADE ESI IDIBO AARẸ TI ỌDUN 2019Ademola Adepoju.
Ida kan ninu ida mẹta awọn eeyan Larubawa ati ariwa Afrika ni wọn fẹ ko kuro ni ilu wọn.
Owatapa ti Itapa Ijesha, Wolii Olapade Agoro jáde láyé Sanwo Olu àti Okowa dẹwọ́ ìséde ní Eko àti Delta pẹ̀lú àlàyé tuntun Aàbò tó péye yóò wà fún àwọn tí yóò kópa nínú ìfẹsẹwọ̀nsẹ̀ Naijiria àti Sierra Leone ní Benin - Obaseki Ǹkan tí a mọ̀ nípa kọ́lẹ̀jì olùdìbò tó ń fìdì ẹni ti yóò jẹ ààrẹ ilẹ̀ Amérika múlẹ̀ O ni  Wọn gba mi loju, wọn lu mi, wọn si fi aṣọ mi wọ mi sita."
Kí o máa sọ fún àwọn ẹlẹ́wọ̀n pé, ‘Ẹ jáde,’ati fún àwọn tí ó wà ninu òkùnkùn pé, ‘Ẹ farahàn.
Ọlọrun, ò bá jẹ́ pa àwọn eniyan burúkú,kí àwọn apànìyàn sì kúrò lọ́dọ̀ mi.
Ó dára kí o máa ṣe aṣojú àwọn eniyan náà níwájú Ọlọrun, kí o sì máa bá wọn kó ẹ̀dùn ọkàn wọn tọ Ọlọrun lọ; 
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Oyo physically challenged protest: Ìdí rèé táwọn àkàndá ẹ̀dá fi dí iwájú iléeṣẹ́ ìjọba ìpínlẹ̀ Oyo pa l'Agodi n'Ibadan 7 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Oríṣun àwòrán, Megaiconmagazine Sunkẹrẹ fakẹrẹ gbode kan l'Agodi niluu Ibadan lọjọ Aje ọjọ keje oṣu kejila ọdun 2020 yii lẹyin tawọn onipenija ara bọ soju popo lati fẹhonuhan.
Wọn ko si ti i ri awọn to ku yọ Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
lookan aya won sinsin lati wa ojutu si ipenija to n koju eto aabo lorile-ede
Lẹ́yìn náà ó tún lọ ní apá ìhà àríwá náà títí dé Kabulu, 
Ó ní: “Ìwọ ọ̀rẹ́ mi, nígbà tí ó di ọdún kẹẹẹ̀ẹ́dọ́gbọ̀n ti bàbá mi ti dé inú ayé ni ó múra ní òwúrọ̀ ọjọ́ kan báyìí tí ó bá igbó àbàmì kan lọ lẹ́bàá ìlú wa láti lọ ṣe ọdẹ,àwọn ara ìlú wa a máa pe ni igbó Olódùmarè, nítorí ibi tí ó ní ẹ̀rù gidigidi ni.
7m 4 Ọ̀wàrà 2020 Oríṣun àwòrán, Twitter/EFCC Nigeria Ajọ to n gbogun ti iwa ibajẹ ati iṣowo ilu kumọkumọ, EFCC ti mu ọdọkunrin kan, Adebayo Olawale ati pasitọ ijọ CAC Ile Ife, Gbenga Moses Adesoju lori ẹsun pe wọn lu Umar Hayatu ọmọ ipinlẹ Gombe ni jibiti owo to din diẹ ni miliọnu mẹtala naira(N12.
Bakanaa ni Aarẹ Buhari tun paroko ikilọ ransẹ sawọn eeyan to n se atọkun ikọlu ati ipaniyan gbogbo kaakiri orilẹede Naijiria, papajulọ awọn darandaran Fulani to wa nidi ikọlu ipaniyan to waye nipinlẹ Benue laipẹ yii.
 A Abbas Filling Station, Takad, Garaje, Ashim, Mifi and Zilan ni Takad ijoba ibile Kaura.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Borno Zabamari Massare: Àjọ NCC fẹ́ tú ìwé owó àwọn olúpèsè ìtàkùn ìbánisọ̀rọ̀ wo 8 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 10 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Oríṣun àwòrán, Getty Images Ajọ to n risi eto ibanisọrọ lorilẹede Naijiria, National Communications Commission, NCC ti ni ki gbogbo awọn ileeṣẹ to n pese itakun fun ibanisọrọ lori foonu, dawọ tita kaadi ibanisọrọ duro.
Eyi si ni wọn lo n mu isoro ba eto isejọba ati didaabo bo ilu lọna to yẹ lorilẹ-ede Naijiria.
Adele Baalẹ ilu naa, Alagba Moses Adewale rọ ijoba ninu ọrọ rẹ lati pese awọn ohun amayedẹrun idagbasoke paapaa omi fun ilu naa.
Ẹ̀ṣẹ̀ ni ohunkohun tí eniyan kò bá ṣe pẹlu igbagbọ.
Wọn rí ọpọlọpọ wàrà lára mààlúù wọn,ati ọ̀pọ̀ omi wàrà lára ewúrẹ́ wọn,ó fún wọn ní ọ̀rá ọ̀dọ́ aguntan ati ti àgbò,ó fún wọn ní mààlúù Baṣani, ati ewúrẹ́,ati ọkà tí ó dára jùlọ,ati ọpọlọpọ ọtí waini.
Bí o bá sì ti kọ aya rẹ, má ṣe wá ọ̀nà láti tún gbé iyawo.
 gẹ ́ gẹ ́ bí elbs ti ṣàfihàn rẹ ̀ ní ọdún 1884 wípé óṣeéṣe lati rí anthracene nínú dehydration.
Gbogbo ẹ̀ náà láti dáàbò bo nkan ìní àti dúkìá àwọn ará àdúgbò ibẹ̀ ni.
Ó sọ fún wọn pé, “Ẹ má ṣe mú nǹkankan lọ́wọ́ lọ ìrìn àjò yìí: ẹ má mú ọ̀pá lọ́wọ́, tabi àpò báárà tabi oúnjẹ tabi owó, tabi àwọ̀tẹ́lẹ̀ meji.
"O wọpọ fun awọn eeyan lati ma a lo oogun ara riro, ti inu ba n dun wọn.
Awọn ti ko ba to ọmọọdun maarun yoo gba itọju ọfẹ.
Ni ibẹrẹ ọdun yii lo yẹ ki Whittaker koju Kelvin Gastelum ṣugbọn eyi ko waye lataari iṣẹ abẹ ti o ṣe.
Nígbà tí Jesu rí i pé àwọn ìjọ eniyan ń sáré bọ̀, ó bá ẹ̀mí èṣù náà wí, ó ní, “Ìwọ ẹ̀mí tí o jẹ́ kí ọmọ yìí ya odi, tí o sì di í létí, mo pàṣẹ fún ọ, jáde kúrò ninu rẹ̀, kí o má tún wọ inú rẹ̀ mọ́.
Nígbà tí mo sùn sílẹ̀ ní ọjọ́ kan tí mo di ojú mi láìjẹ́ pé mo sùnlọ, nǹkankan ṣẹlẹ̀.
Oríṣun àwòrán, Bolu Akin-Olugbade Ta ni ọlọla Akin Olugbade ti arun Coronavirus gbẹmi rẹ?
Wọn yóo dà wọ́n fún àwọn èkúté ati àwọn àdán.
Wọ́n ti kó owó tí wọ́n rí ninu ilé OLUWA jọ, wọ́n sì ti kó o fún àwọn tí wọn ń ṣe àkóso iṣẹ́ náà ati àwọn òṣìṣẹ́;” 
Ṣùgbọ́n àwọn ọlọ́pàá wọn-ọnnì ti gba ohun ìjà wa gbogbo nígbà tí a ti dé ibẹ̀ wọ́n sì ti kó wọn sínú ilé ìṣúra náà.
Forceful Penetration: Bí ó bá ṣe obìnrin ló fi agídí mú ọ̀kùnrin bá a lò pọ̀ ńkọ́?
Muslim Marriage: Lẹ́yin ìsopọ̀ ogún ọdún, ìyàwò fẹ́ ṣèyàwó lábẹ́ òfin
“O wa n ro awon omo orile-ede Naijiria ti won n rin irinajo lo si orile-ede South Africa tabi awon orile-ede miiran lati maa se ko ounje wole, ki won si sora nipa ounje ti won yoo j, lati maa le ko aarun naa”“O salaye pe, “orile-ede Naijiria ko faye gba kiko eran wole ati awonnnkan miiran, ajo ohun ko fun enikeni niwe ase gbigbe eran wole, amo gbegbe awon nnkan wonyii wole lona aibofin mu ni ipenija nla ti a ni.
O wa gba awọn obìnrin ti wọn ba fi ipa ba lopọ nimọran lati tete fi iṣẹlẹ naa to awọn Ọlọpa ati awọn Ileesẹ ìjọba pẹlu ẹgbẹ to n ja fun ẹtọ awọn obinrin leti, ki wọn lee tete dide si ọrọ naa.
Yóo lòdì sí ohun gbogbo tí ó jẹ́ ti Ọlọrun tabi tí ó jẹ mọ́ ti ẹ̀sìn.
Awọn 46,867 lo to ti fara kasa arun naa, ti awọn 33,346 si ti ri iwosan gba lọwọ ajakalẹ arun ọhun.
si ojo karunun, osu keje, odun 2019 yii.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Alaafin: Olori Aanu Adeyemi ṣàlàyé ìdí tó ṣe gẹ́ Oba Lamidi Adeyemi ti ìlú Oyo Aṣẹ ti Ọlọrun fun wa ni ki a maa ṣe ikilọ fun awọn olori to n hu iwa buburu, ki ẹjẹ wọn maa ba si lori wa.
ibi isele ohun lati se ohun ti o ati eyi to ye.
Olórí Alufaa bi Jesu nípa àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ ati nípa ẹ̀kọ́ rẹ̀.
Nigeria, IPMAN)ti omo egbe won je àádọ́ta egberun, to si je pe awon lo n dari
To Awọn to duro lati ṣe iwadii ni Afrika ko ni oluranlọwọ ni eyi ti ko jẹ ki wọn le maa ṣe ayẹwo pupọ lori iwadii.
“Èmi náà ti gbọ́ irú nǹkan wọnyi rí,ọlọ́rọ̀ ìtùnú kòbákùngbé ni gbogbo yín.
Ẹni tí ń lépa òdodo ati àánúyóo rí ìyè, òdodo, ati iyì.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Big Brother Naija: O tó gẹ́; a kò fẹ́ ìwòkuwò mọ́ ní Nàijíríà 19 Ògún 2019 Oríṣun àwòrán, @others Àkọlé àwòrán, Iṣekuṣe ni eto yii n kọ awọn eeyan ni ero NCAC Ijọba apapọ orilẹ-ede Naijiria ti fi aidunnu rẹ han si ibalopọ ti o n waye lori eto Big Brother Naija (BBN), ti o n lọ lọwọ.
Bẹẹ ni wọn o le fun mi ni oogun ara riro to le din irora mi ku, nitori ọmọ to wa ninu mi."
Kwam 1: Ọmọṣẹ́ Wasiu ni MC Murphy, tó bá fẹ́ lọ sílé ẹjọ́ kó nìsó níbẹ̀- Alákòso orín K1 Ni owurọ ọjọ Abamẹta ni ariwo gba ilẹ kan pe, ilumọọka akọrin Fuji ati Mayegun ilẹ Yoruba, Wasiu Ayinde Mashall, ti ọpọ eeyan mọ si Kwam 1, gba gbajumọ agbohunsafẹfẹ kan leti loju agbo.
Oríṣun àwòrán, iyaboojofespris Àkọlé àwòrán, Iyabo Ojo ṣi ile tuntun laarin ọsẹ, nibi ti ọpọlọpọ awọn ẹbi, ọrẹ ati ojugba rẹ ninu iṣẹ tiata peju si.
Ẹnikẹ́ni tí ó bá ṣèèṣì pa eniyan lè sá lọ sí èyíkéyìí ninu wọn, yóo sì bọ́ lọ́wọ́ ẹni tí ń gbẹ̀san ẹ̀bi ẹ̀jẹ̀ títí tí àwọn ìgbìmọ̀ yóo fi ṣe ìdájọ́ rẹ̀.
Wọ́n ni ọkàn nínú àwọn olùrànlọwọ inu ọkọ ofurufu sọ̀rọ̀ nipa ẹsin ìgbà jew ti àwọn ń sìn.
Ile aṣofin ipinlẹ Ọyọ ko tii fi iroyin sita lori iku rẹ.
" Oríṣun àwòrán, The Cable NG Tijjani sọ pe oun ṣe ile alufa naa ni ọṣọ, lati bu ẹwa kun pẹlu igi, ina, aṣọ ati awọn nkan ẹṣọ mii.
Ni ti idije Olimpiiki to yẹ ko bẹrẹ loṣu keje ọdun 2020, awọn igbimọ to n risi eto na ti ni kaka ki wọn wọgile, niṣe ni wọn yoo jẹ ko waye laisi ero iworan, ṣugbọn ko ṣeni to mọ ohun ti le ṣelẹ.
Ó ṣe é ṣe kí o ti ní coronavirus kí ó má mọ̀ nítorí pé ó kò rí àpẹẹrẹ Ogun eeyan ni wọn ti gba iwosan lọwọ yii ti eeyan meji si ti jade laye.
Sibẹsibẹ àwọn nǹkankan wà tí o ṣe tí ó dára, o run àwọn ère oriṣa Aṣera ní ilẹ̀ yìí, o sì ti ṣe ọkàn rẹ gírí láti tẹ̀lé Ọlọ́run.
mẹ́tàdínlọ́gbọ̀n ti ijoba gbe wa siwaju ile igbimo asofin je , eyi ti yoo
Tẹkúntẹkún ni wọn yóo wá,tàánútàánú ni n óo sì fi darí wọn pada.
Iroyin ti awọn eeyan orilẹede naa n wu gbọ bayii ni pe aarẹ al-Bashir ko ni pẹ gbe ijọba silẹ ṣugbọn ko tii si ikede kan ni pato lati ọdọ awọn alaṣẹ ilẹ naa.
Fayemi naa bere si n ki awon eniyan ni mesan an-mewaa ti o si n bo won lowo.
Ilẹ̀ mú ọ̀pọ̀ ìkórè jáde;Ọlọrun, àní Ọlọrun wa, bukun wa.
Àánú wọn ṣe é, ó bá wo àwọn tí wọ́n ṣàìsàn ninu wọn sàn.
 wọ ́ n kọjá odò ọnà .
Ijoba apapo gbe  ipin idokoowo ida ogorun un 12.
Wo ìgbẹ́sẹ̀ méjọ tí ilé aṣòfin ìpínlẹ̀ gbọdọ̀ tẹ̀lé láti yọ igbákejì gómìnà Àlàyé rèé lórí ìdí tí Magu àti awọn alága EFCC míràn ṣe bá ìtìjú kúrò nípò Àwọn ẹlẹ́sìn ìbílẹ̀ ń bèèrè owó lọ́wọ́ àwọn Alfa lórí ìsìnkú ẹni tó pokùnso Hushpuppi di gbajúmọ̀ ẹlẹ́wọ̀n tó ní nọ́ńbà l‘Amẹrika, orúkọ̀ rẹ̀ wà lórí ayélujára Wọn ni akoko naa yoo fun awọn akẹkọo ọhun laaye lati gbaradi fun idanwo to n bọ lọna.
Kí òrùka kọ̀ọ̀kan súnmọ́ ìgbátí tabili náà, òrùka wọnyi ni wọn yóo máa ti ọ̀pá bọ̀ láti fi gbé tabili náà.
Àbí nítorí Dafidi yìí kọ́ ni àwọn ọmọbinrin Israẹli ṣe ń jó tí wọ́n sì ń kọrin pé, ‘Saulu pa ẹgbẹẹgbẹrun tirẹ̀,ṣugbọn Dafidi pa ẹgbẹẹgbaarun tirẹ̀?
Wọn ni o di igba ti ọkan ba balẹ lori abo ati alaafia awọn akẹkọọ ki awọn to gbe igbesẹ ati ṣi ileewe pada.
N óo sì dáàbò bo ìlú yìí nítorí tèmi fúnra mi ati nítorí ìlérí tí mo ṣe fún Dafidi, iranṣẹ mi.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Facebook love: Ọla àti Folashade ṣègbéyàwó lẹ́yìn ọjọ́ mọ́kànlá tí wọ́n ríra ni Facebook Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Kíá ni àti mùsùlùmí àti kìrìstẹ́nì ń da omígbóná ságbárí.
Bí ó ti fẹ́ wọlé ni ọmọ tí ń ṣàìsàn náà kú.
Aarẹ ni iku rẹ maa fi pupọ nitori pe o jẹ ẹnikan ti aarẹ gbarale pupọ fun imọran."
Dókítà Rosena Allin-khan sọ pé aarun náà kì ṣe fún àwọn àgbàlagbà nìkan, tàbí ẹni tí ó ti ní àìsàn lára tẹ́lẹ̀.
Nwobike ní òótọ́ ni òun fi ìfìwéránṣẹ́ náà ṣọwọ́ sí àwọn òṣìṣẹ́ náà ṣùgbón kìí ṣe láti fẹ́ yí dà ojú òfin bolẹ̀.
Awọn ọlọpaa ko tii sọrọ lori iṣẹlẹ ọhun.
Sikiru Ayinde Barrister: Kwam 1 ní Agbajelola ló ṣe olùlànà fún àwọn olórin Fuji òde òní
Botilẹjẹ wi pe ko si akọsilẹ tuntun, awọn onimọ ri i pe igbeaye awọn to toṣi ju ko fi bẹ ẹ dara ju ti tẹlẹ lọ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Toyin Atoyebi mechanic: Ẹ wo Toyin, ọmọbinrin ọdún 16 tó ń tún skadà àti gẹnẹrátọ̀ ṣe ní Orílẹ̀èdè Amẹrika ti bẹ̀rẹ̀ sí ní wo wọlé-wọ̀de Atiku, àwọn ìyàwo rẹ̀ lórí owó tí wọ́n kó lọ sí òkèèrè Iwadii tuntun ti FINCEN gbe jade pẹlu ajọsepọ awọn oniroyin lagbaye fihan bi igbakeji aarẹ lorilẹede Naijiria tẹlẹri, Atiku Abubakar ṣe n ko owo lọ si oke okun.
àwọn olórí aadọta ọmọ ogun, ati àwọn ọlọ́lá,àwọn adáhunṣe ati àwọn pidánpidán, ati àwọn olóògùn.
Lara awọn ohun ija oloro ti wọn ka mọ awọn darandaran naa lọwọ ni ibọn atamatase AK47 kan, ọta ibọn mọkanlelogoji, ibsn atọwọda kan pẹlu ọta rẹ marundinlọgbọn tofimọ ada kan.
Iyabo Ojo gé okùn àjọṣepọ̀ rẹ̀ pẹ̀lú olóṣèlú nínú ẹgbẹ́ APC ati PDP Àṣírí tó ń bẹ láàrín Oluwo àtàwọn ọ̀dọ́ Iwo tí wọ́n fi fi ẹ̀mí wọn lélẹ̀ dáàbò bo ààfin rẹ̀ Ẹni tó jí ọ̀pá aṣẹ ń bọ̀ wá túbá fúnrarẹ̀, mo fi dáa yín lójú gẹ́gẹ́ bí ìyá - Erelu Kuti Ilé ẹjọ́ yẹ àga mọ́ Ọba Ìkirè nìdí lẹ́yìn ọdún 27 lórí ìtẹ́ Àwọn ọbá aláye ilẹ̀ Yorùbá márùn-ún pẹ̀lú ọ̀pá àṣẹ wọn Opalola ni awọn ko tii ri ẹnikẹni mu lori iṣẹlẹ naa, amọ iwadii si n tẹsiwaju.
Bẹ́ẹ̀ ni kì í ṣe gbogbo yín ni ẹ lè sọ èdè àjèjì.
Ẹlẹsẹ ayo, Kevin De Bruyne lo gba goolu kẹta sawọn fun Man City, lọrọ ba di họ fun Chelsea.
 Airisese ti sakoba fun eto ilera, eto eko ati awon idagbasoke gbogbo.
Wọn ni yoo foju ba ile ẹjọ laipẹ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Cardi B leaked video: Cardi B ṣàlàyé ohun tó gbé fọ́tò ìhòhò rẹ̀ d'órí ayélujára Instagram 16 Ọ̀wàrà 2020 Oríṣun àwòrán, INSTAGRAM/IAMCARDIB Onkọrin, ọmọ ilẹ America, Cardi B ti fesi lẹyin to ṣe e ṣi fi fọto ihoho rẹ sori ayelujara Instagram rẹ.
Duro Ladipo: Oríṣun àwòrán, dawn commission Akọni oṣere tiata, Onkọrin ati onijo ni Durodola Ladipo, ti ọpọ eeyan tun n pe ni Sango.
Nítorí ẹ̀yin fúnra yín mọ bí ó ti yẹ kí ẹ ṣe àfarawé wa, nítorí a kò rìn ségesège nígbà tí a wà láàrin yín.
Lasiko to n fesi si ọrọ naa, kọmisana fun ọrọ ayika ni ipinlẹ Ọyọ, Asofin Kehinde Ayọọla ṣalaye wi pe lootọ ni igboro ilu Ibadan dọti ṣugbọn ọrọ ko dede ri bẹẹ, o ni bo se jẹ.
Àtẹ̀jáde ìkíni orí Facebook láti ọwọ́ ajàfúnẹ̀tọ́ obìrin Eliana Nzualo, ti ní ìsọsí tí ó tó 450, tí a ti pín tó ìgbà 460, àti pé ọ̀pọ̀ èsì tí ó tó 2,000 ni ó gbà:
"O ye ijọ wa daadaa, idi ti awọn eeyan fi yari, a si mọ riri ohun ti wọn n ṣe.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù 'Mi ò ní wo bọ́ọ̀lù mọ́ ti Nàìjíríà bá fìdírẹmi ni Russia 2018' Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ 'Mi ò ní wo bọ́ọ̀lù mọ́ ti Nàìjíríà bá fìdírẹmi ni Russia 2018' 15 Òkùdu 2018 Ìdíle Adeṣẹmọwọ ni kò si ìjà lórí rìmóòtù mọ́ titi ti Russia 2018 yóò fi parí.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ile iṣẹ BBC fẹ ki o kopa ninu ami ẹyẹ 2019 BBC World News Komla Dumor Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Fídíò, Natalia Mufutau ìyá Yakub, Kamil àti Adam sọ̀rọ̀ lórí bí wọ́n ń sọ èdè mẹ́rin pàpọ31 Ògún 2020 Fídíò, Akomolede: Bolaji Faleke ni Olùkọ́ tó ń kọ́ wa ní àṣà oge ṣiṣe lórí BBC Yorùbá1 Owewe 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Iyapa waye ninu ISWAP lẹyin ti IS fi awọn miran rọ́pò awọn adari rẹ, Abu Bakr bin Muhammad Shekau ati Abu Musab al-Barnawi.
Kò sí ẹ̀mí tó sínú níbi ilé náà.
Wọn bi Mama Rainbow ni ọjọ kẹrindinlogun, oṣu kọkanla, ọdun 1942, ni ilu Ijẹbu Ode, ipinle Ogun, to wa ni iwọ oorun orilẹede Naijiria.
2m ọmọdé kò ṣe lọ sílé ẹ̀kọ́ - SERAP ké tọ iléẹjọ́ àgbáyé Darandaran Fulani kìí lo ìbọn, 'pọ̀pá' la máa ń lò Ìlú ò rẹ́rìn ín rárá, Alaafin Adeyemi III fárígá fún Buhari nínú lẹ́tà tuntun Ọrọ̀ ajé Nàíjíríà tún leè dagun tí Buhari bá fi ìyànsípò àwọn mínísítà falẹ̀ si - Onímọ̀ Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Lamidi Adeyẹmi, Anthony Joshua: Ọmọọba mẹ́wàá ló du òyè pẹ̀lú Adeyẹmi, tó sì já mọ́ ọ lọ́wọ́
apapo fe san fun awon osise, ni eyi ti o yato si ọgbọ̀n egberun (30,000)
Yóo kó àwọn eniyan rẹ̀ lọ, yóo sì fi ọrọ̀ ilẹ̀ Ijipti ṣe ìkógun, èyí ni yóo jẹ́ èrè fún àwọn ọmọ ogun rẹ̀.
Ṣugbọn awọn dokita oniṣegun oyinbo sọ pe, ewu maa n wa ninu irufẹ igbeyawo bẹẹ nigba mii gẹgẹ bi iwadii tawọn onisayẹnsi ṣe.
Oríṣun àwòrán, Alamy Àkọlé àwòrán, Sowore nibi ti o ti n se ere idaraya Bo je ni ọdun 1992 ti wọn fi si ahamọ fun pe o kopa ninu iwọde ti awọn ọlọpa ti yinbọn pa eeyan meje tabi lodun 1993 to lewaju nigba iwode idibo June 12,Sowore kii ṣe ẹran rirọ ti awọn alaṣẹ le fọwọrọ sẹgbẹ.
” Ó bá kúrò ní Efesu.
apa ariwa cameroon ni ibùgbé àwọn ènìyàn wum .
Leyin igba naa, ni wọn yoo tun koju ẹgbẹ agbabọọlu orilẹede Senegal lọjo kẹtadinlogun ati akẹẹgbẹ wọn lati Togo lọjọ kọkandilogun osu keji ọdun2018.
I) wúlò gẹ́gẹ́ bí àmì ìdánimọ̀ ní àárín ìlú Angola.
Àwọn tí wọ́n kà ninu àwọn ọmọ Israẹli ni wọ́n dá wúrà ati fadaka ati idẹ yìí jọ.
Ala ti ko ni le sẹ ni'' Gẹgẹ bo ti se sọ́, isẹ yi Amọtẹkunse lawọn ijọba ibilẹ mẹrin to ja si iku eeyan mẹjẹ wọn ko da nikan se.
Wayi o, adajọ Odusola ti wa sun ẹjọ naa siwaju di ọjọ Aje, ọjọ kọkandinlọgbọn osu Kẹfa ọdun 2020, eyiun ọsẹ to n bọ.
kí wundia tí ó bá tẹ́ ọba lọ́rùn jù sì jẹ́ ayaba dípò Faṣiti.
Naijiria lo n lewaju isọri wọn pẹlu ami ayo mẹta bayii.
“Ẹ jẹ ka mọ pe laisi oye kikun ninu ede abinibi, yoo ṣorọ fun akẹẹkọ lati le ni agbọye kikọ awọn ẹkọ miiran.
Nítorí náà, nígbà tí ìbátan náà wí fún Boasi pé, “Rà á bí o bá fẹ́.
16 Dúró fún ìgbà díẹ̀ síi, títí tí ìwọ yíò fi ní ọ̀rọ̀ mi, àpáta mi, ìjọ mi, àti ìhìnrere mi, kí ìwọ lè mọ̀ pẹ̀lú ìdánilójú nípa ẹ̀kọ́ mi.
Níwọ̀n ìgbà tí àbùkù bá ti wà lára wọn, OLUWA kò ní tẹ́wọ́gba irú wọn lọ́wọ́ yín, nítorí àbùkù náà.
Sugbọn agbẹnusọ ileesẹ Dana sọ wi pe , Ko si bi wọn yoo ti sọ wipe ilẹkun baalu naa n'mi nitori wi pẹ atẹgun kankan ko wọ inu baalu naa."
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Akọ́mọlédè àti Àṣà lórí BBC Yorùbá: Kọ̀ síi nípa iṣẹ́ tí oúnjẹ ń ṣe lára níbí Sáájú ní ọlọ́pàá Chidi ni Stephen Fracis kan mu ẹjọ́ wá si aga ọlọ́pàá Gabasawa ní ọjọ́ kẹ́ẹ̀dógún, oṣù kọkànlá ọdún yìí.
Oludamọran pataki fun Sẹnetọ Folarin, Ọgbẹni YSO Olaniyi sọ fun BBC Yoruba pe ni owurọ kutukutu ọjọ Satide ni awọn janduku naa to to igba niye, kọlu ile naa to wa ni Oluyole Estate nilu Ibadan, ti wọn si ko awọn nkan ti Sẹnetọ ra fun idẹrun ara ilu salọ, Lara nkan ti wọn ko ni ọkada bi igba, ẹrọ to n lọ ata, firiji, ẹrọ ti wọn fi n pọ taya ọkọ, ati awọn nkan miran.
 Àwọn ni ó pè ní Ẹ ̀ gbá gbàgùrà .
” Nígbà tí wọ́n gbọ́ bí ó ṣe dá wọn lóhùn, inú wọ́n yọ́.
Iwadi ijinlẹ kan to waye lori iha tawọn eeyan lagbaye n kọ si abẹrẹ ajẹsara fihan pe, igbẹkẹle wọn ninu rẹ ti lọ silẹ pupọ.
Oludari ẹka ibaraẹnisọrọ nileeṣẹ FIRS, Abdullahi Ismaila Ahmad, to fi esi naa sita sọ pe rọ òpè ati alaini oye ni Arabinrin Abubakar sọ, ati pe awọn ko ba ma fun ni esi, ṣugbọn pataki ọrọ naa lo mu ki oun fun ni esi.
Ṣé ẹ rò pé n óo gba irú ẹbọ bẹ́ẹ̀ lọ́wọ́ yín?
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Desmond Elliot, Mojisola Alli-Macaulay fa ayélujára ya torí ọ̀rọ̀ wọn níle aṣòfin Eko 30 Ọ̀wàrà 2020 Oríṣun àwòrán, Desmond Elliot, Mojisola Macaulay Arabinrin Mojisola Alli-Macaulay to jẹ akẹgbẹ aṣofin nipinlẹ Eko sọ wi pe ko si igba ti awọn ọdọ lorilẹede Naijiria kii fa igbo nitori naa ni ori wọn ṣe n gbona ni igba gbogbo Iroyin ni ibi ijoko Ile Aṣofin nipinlẹ Eko ni Alli-Macaulay ti sọ ọrọ naa lẹyin rogbodiyan to waye lasiko ifẹhọnuhan EndSars, ti awọn onijagidijagan gba mọ wọn lọwọ.
Eyi n waye botilẹjẹ wi pe ọpọ ninu wọn ti dabẹ fun nigba ti wọn wa l'ọmọde - nigba ti wọn wa ni ọmọ ọdun mẹẹrin si mẹwa ni wọn maa n ṣe e.
Atẹjade naa ni ọjọ kọkanlelogun oṣu kẹsan-an si ọjọ kejidinlogun oṣu kẹwaa ọdun 2020 ni abala kinni saa eto ẹkọ ọdun 2020 si 2021 yoo bẹrẹ.
"Banki Nàìjíríà, CBN ṣàlàyé nípa àwọn tó máa rí gbà nínú owó ìrànwọ́ N75b tíjọba gbé kalẹ̀ Ìgbónára ló máa ń mú àwọn èèyàn ṣe ""Jungle justice"" tí ìjàmbá ọkọ̀ bá ṣẹlẹ̀- Dokita Oṣú mẹ́fà ni òṣìṣẹ́ ìjọba tó bá bímọ yóò máa lò nílé kó tó wọṣẹ́ padà- Seyi Makinde A kó ní sanwó oṣú ASUU láìjẹ́ pé wọ́n gba IPPIS- Ìjọba Àpapọ̀ Lẹnu lọọlọ yi, iwa ifipabanilopo iru eleyi ṣebi ẹni peleke kaakiri Somalia."
Ìjọba Eko bẹ̀rẹ̀ sísan N35,000 owó oṣù tuntun ní November Ibodè tí a tì ló fa ọ̀wọ́ngógó owó ọjà - Ìjọba Naijiria Mẹ̀kúnnù 80,000 l'Ọṣun ti j'ànfàaní ètò ìlera láìsan kọ́bọ̀ - Oyetola 'Ẹ gbà mí o lọ́wọ́ ṣọ́ọ̀ṣì wa, mi ò lènìyàn, ẹ bá mi wá ọmọ mi rí'!
Saulu bá pe gbogbo àwọn ọmọ ogun rẹ̀ jọ láti gbógun ti Keila kí wọ́n sì ká Dafidi ati àwọn ọmọ ogun rẹ̀ mọ́ ìlú náà.
Lara awọ́n nnkan ti ile ti yanju de ibi to lapẹrẹ lati ri: Bibuwọlu sisan ẹgbẹrun lọna ọgbọn naira gg bi owo osu to kere julọ f'oṣiṣẹ Gbigbe igbesẹ lati mu opin ba didẹyẹ si awọn akẹkọ jade ile ẹkọ giga gbogboniṣe nipaiwe eri wọn pẹlu ti awọn akẹkọjade fasiti.
Security Summit: Ìlànà òfin ní ó yẹ kí Naijiria tọ̀ kìí ṣe ipàdé àbòsí- Odumakin
Nígbà tí Dafidi gbọ́ ohun tí ó ṣẹlẹ̀ sí wọn, ó ranṣẹ sí wọn pé kí wọ́n dúró ní Jẹriko títí tí irùngbọ̀n wọn yóo fi hù, kí wọ́n tó máa pada bọ̀.
Ni idajọ ti ile ẹjọ naa gbe kalẹ ni ọjọ ẹti da ipẹjọ awọn mejeeji nu gẹgẹ bii aasa ti ko ni kaun ninu.
Mo ní n óo gun ọ̀pẹ ọ̀hún,kí n di odi rẹ̀ mú.
Amọ ko sai yan pe kii ṣe inu iṣẹ tiata nìkan ni wọn ti n kọ ẹnu ifẹ si obìnrin nitori o wa kaakiri, ti awọn obinrin miran si maa n pa irọ nigba mii.
Mo sọ fún wọn pé, “Ẹ̀ ń ni àwọn arakunrin yín lára.
Aṣọ àti bàtà tọ́ka sáwọn afurasí gbéwiri lábúlé Bugaje
Kete to wọ inu ọkọ ofurufu Air Canada lati Quebec lo ba gbagbe sun lọ.
Àdúrà mi ni kò jẹ́ kí ìyà Manchester United ó pọ̀ jù lọ́wọ́ Barcelona- Wòlíì Àrólé Funke Akindele ti di ìyábejì Àwọn ọmọ Naijiria bínú lẹ́yìn tí ọlọ́pàá pa obìnrin kan àti ọ̀rẹ́kùnrin rẹ̀ Kete ti Isreal jawe olubori yii ni o ti sun soke di 17-0 ninu akọsilẹ ija rẹ.
Iyẹn nipe, Kabiyesi Ọọni Ile Ife, Oba Adeyeye Ogunwusi ati aya rẹ, Olori Silẹkunọla Naomi Ogunwusi ti bi ọmọ tuntun.
Àwọn fíìmù Nollywood ń mú kí òògùn owó àti ìjínigbé gbilẹ̀ síi - Fashola Àwọn ológun ṣíná ìbọn pa Sọjà tó pa èèyàn 26 ní Thailand Lẹ́yìn tó fi ọ̀bẹ halẹ̀ mọ́ ọ, ọkọ Magarita fi àáké gé e lọ́wọ́, kí ló ṣe tó bẹ́ẹ̀?
Opayinka rọ ijọba ni ipari ọrọ rẹ pe, ko ma gbe agadagodo ṣenu ọna ile ijọsin latari arun Coronavirus nitori ijọ nikan ṣoṣo ni ọna abayọ si araun naa to n tan kaakiri agabaye.
OLUWA sọ̀kalẹ̀ sórí òkè Sinai, ó dúró ní ṣóńṣó òkè náà, ó pe Mose sọ́dọ̀, Mose sì gòkè tọ̀ ọ́ lọ.
Elòmíràn, kò ni ṣe iwadi ohun ti àwọn èniyàn fi ńsáré, ki ó tó bẹ̀rẹ̀ si sáré.
Nítorí náà bí ẹ kò bá ṣe é gbẹ́kẹ̀lé nípa nǹkan owó ti ayé yìí, ta ni yóo fi dúkìá tòótọ́ sí ìkáwọ́ yín?
Leyin ti Tafa yipada tan si ẹni rere, lo bẹrẹ si ni ran Lapade lọ́wọ lati mu awọn to n se ika ni awujọ sugbọn awọn jẹgudujẹra ọlọpaa bii Oga Audu ko jẹ ki isẹ wọn yọ rara.
Adeyeye tẹsiwaju ninu ọrọ rẹ pe awọn oluwadii ni orilẹ-ede France ati America ti gbiyanju ogun naa fun itọju coronavirus, ti wọn si sọ pe o ṣiṣẹ.
N óo da àwọ̀n mi bò ó mọ́lẹ̀, pańpẹ́ mi yóo mú un, n óo sì mú un lọ sí Babiloni.
Ṣugbọn ẹ kì í ṣe ti ayé nítorí mo ti yàn yín kúrò ninu ayé; ìdí rẹ̀ nìyí tí ayé fi kórìíra yín.
Elo ni owo oṣu ọlọpaa ni Naijiria?
Ijoba orile-ede naa na fiwe pe omo ile-igbimo asofin lorile-ede America  , Jeffrey Flake ati omo ile-igbimo asofin teleri Andrew Jackson Young Junior.
Wọ́n fi ìbéèrè yìí dán an wò ni.
Ìgbìmọ̀ ìgbẹ́jọ́ Kano: Ganduje ló pegedé nínú ìdìbò sípò Gómìnà Ìgbìmọ̀ ìgbẹ́jọ́ ṣetán láti dajọ Gómìnà Kano, Ganduje àti Tambuwal ti Sokoto Wole Soyinka rèé láti kékeré Awakọ̀ 700 kò sí páńpẹ́ òfin, 191 ṣẹ̀wọ̀n lórí ẹsùn wíwakọ̀ lẹ́yìn tí wọ́n mu ọtí 10.
Ọmọ-Eniyan dé, ó ń jẹ, ó ń mu, ẹ ní, ‘Ẹ kò rí ọkunrin yìí, oníjẹkújẹ ati ọ̀mùtí, ọ̀rẹ́ àwọn agbowó-odè ati àwọn ẹlẹ́ṣẹ̀.
Ahọ́n ni a fi ń yin Oluwa ati Baba.
Wọ́n ń bọ̀ wá dojú kọ ọ́, ìwọ Babiloni!
Nibayii, wọn ko tii mọ idi pato to fa ile wiwo naa.
Níwọ̀n ìgbà tí o ti mú ọkàn wọn yigbì sí ìmọ̀,nítorí náà, o kò ní jẹ́ kí wọ́n borí.
 Òun ló ń pèsè ewúrẹ ́ kọ ̀ ọ ̀ kan lódọọdún láti fí bọ òrìṣà náà èyí wà ní ìbámu pẹ ̀ lú àdéhùn rẹ ̀ ní ìgbà tó gba òrìṣà náà òun yóò máa fún un ní ewúrẹ ́ kọ ̀ ọ ̀ kan lọ ́ dọọdún títí dòní ló sì ń ṣe ìràntí ìlérí rẹ ̀ ọjọ ́ kìíní .
Nígbà tí gbogbo nǹkan bá ti wà ní ìkáwọ́ rẹ̀ tán, ni Ọmọ fúnrarẹ̀ yóo wá bọ́ sí ìkáwọ́ Ọlọrun tí ó fi gbogbo nǹkan sí ìkáwọ́ rẹ̀, kí Ọlọrun lè jẹ́ olórí ohun gbogbo ninu ohun gbogbo.
Ajimọbi ṣèpàdé àtilẹkùnmọ́rí pẹ̀lú Ayefẹlẹ ‘Ọdún Ojúde Ọba kìí se gbàgede olósèlú’ Ọwọ́ ba òsìsẹ́ SARS tó pà akẹ́ẹ̀kọ́ ní Iwo Olùdíje fún ipò aàrẹ (Republican) lọdun 2008 jáde láyé Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
    Bí wọn ti ń kọ ilé wọn kò dára rárá, nítorí kì í sí ẹyọ ferese kan ní ilé wọn, gbogbo ibẹ̀ á ṣókùnkùn dudu, atẹ́gùn kì í síí rí àyè dé ibẹ̀ jù bẹ́ẹ̀ lọ.
Daddy Freeze @DaddyFRZ lójú òpó tiẹ̀ ni, ẹkọ mẹta ni ikú Abba Kyari kọ àwa ọmọ Nàìjíríà àtàwọn oloselu.
a bẹ ̀ rẹ ̀ ìmúlò àjẹsára ibà pọ ́ njú-pọ ́ ntọ ̀ ní ọdún 1938 .
Àgbẹ́kọ̀yá yarí; Afẹnífẹ́re ní ilé ẹjọ́ ló kàn lórí ọ̀rọ̀ Àmọ̀tẹ́kùn Aláàfin Ọyọ: Ọba tó bá n mú ọtí ní ìta kò yẹ ní ẹni tàá bọ̀wọ̀ fún Bí ìtàn ayé Toyosi Arigbabuwo ṣe lọ rèé láti ẹnu Musiliu Dasofunjo àti Ogun Majek Imam tó fẹ́ ọkùnrin míì níyàwó forí kó ìjìyà òfin Eto ẹkọ Akintola Akintola bẹrẹ eto ẹkọ rẹ nile iwe Church Missionary Society school niluu Minna to jẹ olu-ilu ipinlẹ Niger lonii.
Wọ́n ń bi ara wọn pé, “Kí ni ìtumọ̀ èyí?
Ó gbé e kalẹ̀ níwájú wọn; Saulu ati àwọn iranṣẹ rẹ̀ jẹ ẹ́, wọ́n sì jáde lọ ní òru náà.
"Àwọn to péjọ náà ni: OGE OKOYE MUTIU ADEPOJU YEMI sOLADE ARALOLA OLAMUYIWA Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Jude Chukwuka: Wọ́n yóò fi ojú ọlọgbọ́n wo akúrí tó bá sọ ojúlówó èdè Yorùbá Awọn miran ni: SAHEED MUHAMMED (FUNKY MALLAM) YOMI FABIYI KEMI AFOLABI ADESIPE Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Natalia Mufuta ìyá Yakub, Kamil àti Adam sọ̀rọ̀ lórí bí wọ́n ń sọ èdè mẹ́rin pàpọ STEPHEN UGOCHUKWU (RUGGEDMAN) MURPHY AFOLABI FOLUKE DARAMOLA Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Bí ẹ ṣe mọ̀wé tó, ẹ wá dánrawò níbí pẹ̀lú ""Àpólà Ọ̀rọ̀ Orúkọ - Noun Phrase Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!"
epo ati afẹfẹ gaasi aladani tirẹ silẹ lọdun 1997, lẹyin to ti ṣiṣẹ fun ọdun
Èrò ọkàn eniyan dàbí omi jíjìn,ẹni tí ó bá ní ìmọ̀ ló lè fà á jáde.
Bẹ́ẹ̀ ni èmi nìyí, tí mo rí tẹ́ẹ́rẹ́ bí ejòi, tí n kò sanra bí ekòló, tí mo ń rìn táńpẹ́-táńpẹ́ kiri.
O ṣalaye pe ọjọ kinni oṣu kọkanla ọdun 2020 yii ni ajọ to n ṣakoso awọn ileeṣẹ mọnamọna, NERC ti fawọn laṣẹ lati pada si owo in a tuntun.
Bẹ́ẹ̀ rèé ènìyàn ò báà bẹ́ sínú àmù ọmígbóná oníyọ̀, kó jẹ́ orógbó agbọ̀n kan, kó sì jẹ obì tó kún apẹ̀rẹ̀.
N óo jogún Juda bí ohun ìní mi ninu ilẹ̀ mímọ́, n óo sì yan Jerusalẹmu.
OLUWA kò lè farada ìwà burúkú tí ẹ̀ ń hù, ati àwọn nǹkan ìríra tí ẹ̀ ń ṣe, nítorí náà, ni ilẹ̀ yín ṣe di ahoro ati aṣálẹ̀, ati ilẹ̀ tí a fi ń gégùn-ún, tí kò ní olùgbé, títí di òní.
Ọrọ naa n mu awọn oṣere tiata lọkan gan to bẹẹ ti wọn n tu aṣiri bi wọn ṣe ṣe ninu igbeyawo tiwọn ko to de ibi to buru jai ti ipa wọn ko ni le ka.
OLUWA yóo pa àlọ ati ààbọ̀ rẹ mọ́,láti ìsinsìnyìí lọ ati títí lae.
Bẹẹ si ni yoo rii daju pe bi o tilẹ ṣe ẹyọkan ti wọn yoo si maa sanwo fun, dokita yoo maa wa lawọn ibudo ilera alabọde.
Alhaji Atiku seleri lati pese igba aye irorun ati awon ohun amayederun fun awon eniyan ipinle Benue, ti o fi mo yiyan won mo isakoso isajoba re ti oun ba jawe olubori gege bi aare orile-ede Naijriia.
Má sọkún mọ́, nu ojú rẹ nù,nítorí o óo jẹ èrè iṣẹ́ ọwọ́ rẹ.
Chlesea ti wa ni ipo kẹrin lori afara liigi bayi pẹlu ami mẹ́tàdínláàdọ́rin Burnley si wa ni ipo kẹẹdogun pẹlu ami ogoji Ayé le, ìbòsí ò!
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Shiite: Tinúbú, bá Buhari sọ̀rọ̀ kó tú ZakZaky sílẹ̀ kó tó pẹ́ jù Garba shehu tẹpẹlẹ mọọ ninu ọrọ rẹ fun BBC pé aarẹ Buhari ni ọpọlọpọ ẹlẹsin Shiite lo wa ni orilẹ-ede Naijiria ti wọn n gbe ni alaafia ti wọn ko ba ijọba ja rara.
Bẹẹ naa si ni ọrọ tawọn eeyan n sọ pe lati ibẹrẹ ijọba Trump lawọn Democrats ti n pariwo ki wọn yẹ aga nidi rẹ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù SERAP: Owo ifẹyinti ko tọ si ẹni ti o sisẹ gẹgẹ bii gomina 25 Sẹ́rẹ́ 2018 Oríṣun àwòrán, APC/ Twitter handle Àkọlé àwòrán, Ọpọ awọn gomina nigbakanri lo tu n gba owo osu gẹgẹ bii minisita Ariwo nla lo sọ kaakiri orilẹede yii ni awọn asiko diẹ sẹyin nigba ti awọn ipinlẹ kan lorilẹede Naijiria gbe ofin owo ifẹyinti kalẹ fun awọn gomina ati igbakeji wọn.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ebola Virus: ìdí tí Ebola fi ń tàn kálẹ̀ Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
#BBCNigeria2019 Àwọn ohùn tó ṣé kókó tó yẹ ká mọ ṣáájú ìdìbò 2019 INEC: Kò sí ìká tí o kò lè fí dìbò, ṣáà tí tẹ̀ ẹ́ sójú ẹ dáadáa Atikulated Latara orukọ oludije ipo aarẹ fun ẹgbẹ oṣelu PDP ni wọn ti da aṣa ipolongo Atikulated kalẹ.
Kanye West, Ozil, Boyega, àti àwọn gbajúmọ̀ ilẹ̀ ilẹ̀ okèèrè tó ṣàtìlẹyìn fún ìpolongo #ENDSARS Ẹ̀yin olùwọ́de, ẹ lọ kọwọ́ ọmọ yín bọṣọ, bí bẹ́ẹ̀ kọ́.
Awọn olori ẹ̀sìn bi olùdásílẹ̀ ìjọ Living Faith Church, Bíṣọ́ọ̀pù David Oyedepo, tó fi mọ Bíṣọ́ọ́pù ijọ Aguda ni ipinlẹ Saokoto, Matthew Kukah, ati Oniwaasu ẹsin Islam, Ahmed Gumi.
N óo dìde, n óo tọ baba mi lọ.
Bí ó bá ṣe bẹ́ẹ̀, ńṣe ni ọtí titun yóo bẹ́ àpò, ọtí yóo tú dànù, àpò yóo sì tún bàjẹ́.
Ìwọ tí o gúnwà láàrin àwọn kerubu, yọ bí ọjọ́
Deji Akure pàṣẹ kí wọ́n ti gbogbo ọjà pa fún ọjọ́ méjì, ohun tó fàá nìyí Wo àmúyẹ kí o tó lè di ọmọ ogun ilẹ̀ Nàìjíríà pẹ̀lú fọ́ọ́mù tó jáde yìí Ìgbà mẹ́ta ọ̀tọ̀ọ̀tọ̀ tí ìjọba Nàìjíríà ti gbẹsan lára orilẹ-ède mí tó dẹ́yẹsí i Wo ohun tó ṣẹlẹ̀ sí Saka, Sunkanmi Omobolanle àtàwọn òṣèré sinimá míràn lọ́sẹ̀ yìí 7.
”Jesu dá a lóhùn pé, “Kí Filipi tó pè ọ́, nígbà tí o wà ní abẹ́ igi ọ̀pọ̀tọ́, mo ti rí ọ.
Iléeṣẹ́ ológun bẹ̀rẹ̀ 'Operation Crocodile Smile' yíká Naijiria fún oṣù méjì Davido sọ̀kò ọ̀rọ̀ sí Oyetola lẹ́yìn tí 'èèyàn méjì pádánù ẹ̀mí wọn' níbi ìwọ́de End SARS Osogbo Òkú tó jí lọ́jọ́ kejì ní mọ́ṣúárì padà kú síléèwòsàn Ṣé lóòtọ́ ni àjọ ọlọ́pàá dá Abayomi Shogunle àti Dolapo Badmus dúró?
iwadii lori awon iwa ibajẹ to waye lasiko ijoba Zuma .
Wo ohun tí ilé ẹjọ́ ní kí wọ́n ṣe fún Sunday Shodipe, afurasí ìṣekúpani l'Akinyele Níbo lọ̀rọ̀ dé dúró nípa iṣẹ́ àwọn tó n wa iṣẹ́ N-Power?
Ifarapẹra laarin aarẹ Naijiria ati aarẹ ilẹ Amerika Awọn mejeeji de ipo aarẹ nigba ogbo wọn Awọn mejeeji o ki n se oloselu tiwantiwa ki wọn to di aarẹ Igboya lai wo oju ẹnikẹni Ẹnu o ki n si lara awọn mejeeji nitori ọrọ enu wọn Buhari ti jagun ri, Trump o ki n se ologun Aarẹ Trump jẹ gbajugbaja onisowo, bẹẹkọ ni ti ti aarẹ Buhari ri.
Opopona Marosẹ Eko si Ibadan Lagos Ibadan Expressway2.
Tabi ìwọ nìkan ni o rò pé o gbọ́n?
Anthony Joshua vs Pulev highlights: Ẹ̀bùn ọdún Kérésìmesì ni àseyọrí Joshua lẹ́yìn tó na Pulev lálùbolẹ̀
"Ìtàn ayé Henry Fajemirokun, olówó tó fi owó mọ Olúwa àti ènìyàn N kò gba ₦4bn lọ́wọ́ Magu, ẹ má ró àjẹbánu mọ́ mi láṣọ - Osinbajo pariwo Ó ṣeéṣe kí àrùn Coronavirus tànkálẹ̀ gba inú afẹ́fẹ́- WHO Ọ̀pá epo NNPC bú gbàmú ní Benin, òṣìṣẹ́ méje kàgbákò ikú òjijì Adarí àgbà ilé iṣẹ́ náà, Chema Vera ní ""àrùn Covid-19 ni pabanbarì iṣẹ́ nitóri pé mílíọ́nù àwọn ènìyàn ti ń tiraka láti la àsìkò yìí já tẹ́lẹ̀""."
Ìgbà tí a ṣe eléyìínì tán a padà wọ ààfin lọ a kó oúnjẹ jáde a bẹ̀rẹ̀ sí jẹun.
Ilé ẹjọ́ kòtẹ́milọ́rùn da ẹjọ́ Walter Onnoghen nù!
Wọn yóo ṣẹgun rẹ̀, wọn yóo kó àwọn eniyan ibẹ̀ lẹ́rù lọ, wọn yóo sì fi tipátipá bá àwọn obinrin wọn lòpọ̀.
abenugan ile-igbimo asofin, asofin Ahmed Lawan, nile igbimo asofin niluu Abuja.
Pasitọ ge ọmọ ijọ lori, sinku rẹ sinu ṣọọṣi nipinlẹ Ogun
bayii, ti ọpọ eniyan ko fi jade dibo.
Malikzai fikun un oro re pe, iko omo ogun Taliban ti koko sekolu si ibudo awon omo ogun meji otooto ti o wa lagbegbe Balamerghab.
Lati bi ọjọ melo kan ti ijọba apapọ ti kede pe oun yoo da awọn agbegbe igberiko silẹ fun awọn agbẹ nkan ọsin, ni ẹnu ti n kun un, ti ọpọ eniyan, paapa lati awọn ipinlẹ to wa ni ẹkùn Gusu Naijiria si n sọ wi pe ọna lati sọ orilẹede Naijiria di ti ẹya Fulani nikan ni Aarẹ Buhari n wa pẹlu eto naa.
Odumejeje ni ọpọ awon eniyan maa n pe, wọn si tun npee ni akọrin, ti àwọn eniyan si maa n gbọ orin rẹ jakejado orilede Naijiria.
Ẹyẹ náà tí kò fi bẹ́ẹ̀ tóbi jẹ́ alárédè nínú ìṣẹ̀dáa rẹ̀ kò sì rọrùn láti rí, bíkòṣe ní ìbẹ̀rẹ̀ pẹ̀pẹ̀ àkókò ìtọ́jú ọmọ bíbí tí àwọn akọ máa ń kọrin kiri agbègbè.
ti àwọn ará Hiti, ti àwọn ará Perisi, ti àwọn ará Refaimu, 
Ó ń sọ òkúta lu Dafidi ati gbogbo àwọn iranṣẹ rẹ̀, bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé àwọn eniyan ńláńlá ati ọpọlọpọ eniyan mìíràn wà ní ẹ̀gbẹ́ kinni keji Dafidi ọba.
''Ẹyin omugọ ti ẹ n pariwo ẹnu pe ki n lọ ṣe igbeyawo, ti o ba ka yin lara, ẹ wa fi ipa mu mi ki ẹ si sin mi lọ si ile ọkọ,'' Blessing lo sọ bẹẹ.
73 PMF Squadron, Magumeri ni ipinlẹ Borno ACP Egbe Eko Edum ni kọmisọna to n ṣakoso No.
Aṣọ ìkélé tí ó wà ninu Tẹmpili ya sí meji láti òkè dé ilẹ̀.
Kí wọ́n máa pàgọ́ wọn yí Àgọ́ náà ká.
Wọ́n sì fi ewúrẹ́ kọ̀ọ̀kan rú ẹbọ ìmúkúrò ẹ̀ṣẹ̀ fún ọ̀kọ̀ọ̀kan ninu ẹ̀yà Israẹli mejeejila.
ninu adura wa ki alaafia ati ifẹ le fẹsẹ mulẹ ni orilẹ-ede Naijiria”.
Bakan naa, awon olugbe agbegbe Okinawa, ti bu enu ate lu ipago awon omo ogun ti o wa niluu ohun, lataari isele orisirisi ti o n waye nipase ipago awon omo ogun naa, ti won si fe ki won fi ilu ohun sileNi bayii, adari ijoba Shinzo Abe ti n gbero lati ko iko omo ogun naa kuro ni ipago ohun, losi ilu kekere ti o kogun si iwo oorun agbegbe ilu Nago,  lati dekun awon isele ibi tabi ajalu ti o n koju awon ara ilu naa.
 Òun ni ó jẹ ́ èdè ìjọba fún aserbaijani níbi tí àwọn ìdá mẹ ́ ta nínú mẹ ́ rin àwọn tí ó ń gbé ibẹ ̀ ti ń sọ ọ ́ .
Kí alufaa náà yẹ ọ̀gangan ibi tí àrùn náà wà lára ẹni náà wò.
Àwọn ìbọn náà sì gba ọgbọ̀n ọta lẹ́ẹ̀kannáà.
Ìkookò a gbé ninu àwọn aguntan lọ, a sì tú wọn ká, 
#BBCNigeria2019 Ìjọba pàṣán ni ìjọba Buhari yóò jẹ́ fún Nàìjíríà ní sáà kejì- Ṣoworẹ Gomina ipinlẹ Kano ọhun ni oun to ye oun ni pe Ọlọrun nii fi ọba jẹ oun naa si nii rọ ọba loye.
Iṣẹ́ Ọlọrun ni èyí láti ìbẹ̀rẹ̀ dé òpin.
Obinrin naa, to ti da eto kan silẹ to pe ni ‘Diary of CS Mum’ wa fi tayọtayọ sọ lẹyin o rẹyin pe, inu oun maa n dun lati wo oju apa isẹ abẹ naa, tori pe oun ri nkan ti oun se isẹ abẹ fun.
Àjọ eletò agùnbánirọ ̀ ilẹ ̀ nàìjíríà tí a mọ ̀ sí ( nysc ) the national youth service corps jẹ ́ ètò tí ìjọba ilẹ ̀ nàìjíríà gbé kàlẹ ̀ fún àwọn ọ ̀ dọ ́ langba tí wọ ́ n ti kẹ ́ kọ ̀ ọ ́ jáde ilé ẹ ̀ kọ ́ ńlá ńlá jáàkiri ilẹ ̀ nàìjíríà , léte àti lè jẹ ́ kí àwọn ọ ̀ dọ ́ wọ ̀ yí ó lè mú iṣẹ ́ ìdàgbà sókè ilẹ ̀ baba wọn ní ọ ̀ kúnkún dùn .
O fikun pe awọn yoo se ifẹhọnu han miran ni Ọjọ Satide, Ọjọ Kẹwa, Osu Kẹjọ, ọdun 2019, ti ijọba ba kọ lati fi silẹ ni Ọjọ Abamẹta.
N650,000 péré ni mò ń gbà gẹ́gẹ́ bíi owó oṣù -Gomina Ọyọ Ṣe ẹ ti gbọ́ ri?
niloo lati pawopo mu igbe-aye alaafia joba laarin eni kookan won lati koju
Lilo ami idanimọ kii ṣe nnkan tuntun ninu ibo orileede India nitori pe wọn a maa fun awọn oludibo lanfaani lati da ẹgbẹ to ba wu wọn mọ.
Isaaki gbadura sí OLUWA fún aya rẹ̀ tí ó yàgàn, OLUWA gbọ́ adura rẹ̀, Rebeka aya rẹ̀ sì lóyún.
" Nigba to n gb'osuba fun awọn osisẹ alaabo ati ileesẹ ọmọogun fun isẹ takuntakun ti wọn nse lai naani ọda owo awo olokun to wa nilẹ lorilẹede yii, Ọjọgbọn Ọsinbajo sekilọ wipe ati ijọba ati gbogbo lẹnilọrọ lo gbọdọ gbiyanju lati rii wipe aigbọraẹniye yii ko burẹkẹ di ija ẹlẹyamẹya tabi ẹlẹsinmẹsin.
“Ẹni tí ó bá fẹ́ràn baba tabi ìyá rẹ̀ jù mí lọ, kò yẹ ní tèmi.
Ó gbọn òǹgbẹ ni Azerbaijan, ilẹ̀ tí àwọn ará ìlú ti máa ń gbọ́ kí Aliyev sọ̀rọ̀ lórí afẹ́fẹ́, àmọ́ tí wọn kò sì rí i rí kó tàkùrọ̀sọ pẹ̀lú oníbèèrè.
Murphy ni Olu ti ilu Itori tawọn lọ ba se ayẹyẹ ti bẹ oun, nitori oloye ni oun nilu Itori, oun si ni Aarẹ Amuludun fun gbogbo ilu Itori.
”  Ajo naa tun so pe awon egbe oselu tuntun naa yoo gba iwe iforuko sile won ni olu-ilu ile ise naa,lọjọBọ.
Iya rẹ si sọ fun BBC pe yoo kuro nileewosan ni ọla.
Igbimọ naa ni Yusuf ru ofin to n ṣe akoso bi wọn ṣe n gbe iṣẹ jade labẹ ijọba ati ofin to n dari ileeṣẹ ijọba.
’ Nítorí náà, ẹ jẹ́ kí ẹ̀yà kọ̀ọ̀kan tò kọjá níwájú OLUWA ní ọ̀wọ̀ọ̀wọ́.
O ṣe ileri wipe, oun yoo ṣiṣẹ gẹgẹ bii gomina to ni eero awọn ara ilu lọkan.
Gbogbo ìlú àwọn orílẹ̀-èdè bá tú.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ẹnu kò sìn lára Olúwòó lórí oyè Emir Ìdílé Ọba tako ọmọ Aláàfin lórí isẹ́ àkànṣe Ìdílé Fálaè yóò gba 246m owó gbà má bìnúú Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí kan sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
Wọn a maa ki batiiri bọ ina lati fi maa gun wọn lara.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, World Diabetes Day: Ọdún kọkandinlogun ti mo ti wà lẹ́nu itọ ṣúgà nìyí Ni ọdun 2009 si ọdun 2012 ni o darapọ mọ ile iwe Liverpool International College, nibi ti o ti ṣiṣẹ gẹgẹ bi oluranlọwọ fun awọn akẹkọọ pẹlu akọnimọọgba ẹgbẹ agbabọọlu ile iwe naa.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ẹlẹ́tàn ni ọkùnrin, tó bá rí nkan tó n wa lára obìnrin, yóò yí ìwà padà - Bimpe Oyebade A kò le gbà kí ASUU gba ₦30bn nínú ₦40bn tíjọba gbé kalẹ̀ - NASU yarí Ẹ̀yin adarí Nàíjíríà, ẹ dẹ́kun àwáwí asán lórí ètò ààbò tó mẹ́hẹ - Ààrẹ àṣòfin àgbà Ẹ dákẹ́ àhesọ ọ̀rọ̀, ohun tó pa ẹ̀gbọ́n àti àbúrò Orisabunmi rèé - Mọ̀lẹ́bí gbarata Wo àdánù tó wà nínú gbígba ayédèrú áápù fún ìforúkọsílẹ̀ NIN lórí ayélujára Àmúlò ẹ̀rọ POS fun òwò ṣíṣe, ṣé ó tọ̀nà nínú Islam àbí bẹ́ẹ̀ kọ́?
Ó ń ṣe àṣeyọrí nítorí pé OLUWA wà pẹlu rẹ̀.
Eyi lo mu ki igbakeji aarẹ orilẹede Liberia, arainrin Jewel Howard Taylor fi ọrọ ibanikẹdun ranṣẹ ati adura fun idile to fi silẹ lọ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Asisat Oshoala: ìbẹ̀rẹ̀ mi kò rọrùn rárá nínú eré bọ́ọ̀lù Ikọ agbabọọlu mẹrinlelogun lo n ṣoju orilẹ-ede merinlelogun ti wọn yoo jọ dije gba ife ẹyẹ ti 2019 naa.
Wo bó se ń lọ nínú ìdíje Russia 2018 'Èmi ò kí ń lu ìyàwó mi' 'A fún Super Eagles, ni rìmóòtù wa, torí ife' Isẹ́ bọ́ lọ́wọ́ Ọ̀jọ̀gbọ́n tó fẹ́ bá akẹ́kọ̀ọ́ lò pọ̀ Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí kan sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
Alufaa yóo bù ninu ọkà pípa ati òróró náà, pẹlu gbogbo turari orí rẹ̀, yóo sun ún gẹ́gẹ́ bí ẹbọ fún ìrántí.
Eyi lo difa fun ajọ agunbanirọ lorilẹede Naijiria, NYSC ti wọn sọ agadangodo si iloro gbogbo ibudo ifinimọle fawọn agunbanirọ kaakiri orilẹede Naijiria; iyẹn lẹyin ti wọn ti ni ki awọn agunbanirọ naa o maa lọ sibi ti wọn yoo ti ṣe isinruulu lẹyẹ o ṣọka.
Ọjọ́ kínní osù kejì ló kọ́kọ́ sẹlẹ̀ lọ́dún yìí kó tó tún dákú padà báyìí.
 Ọ̀gá Omeje sàlàyé pé ọ̀pọ̀ ló ń wá si ilé iṣẹ́ àwọn láti wá fi orúkọ sílẹ̀ láti gba ìwé ìrìnà, sùgbọ́n ní kété ti wọn ba ti gba iwé ti yóò fi han pé wọn ti ń ṣe iwé ìrìnà wọn lọ́wọ́ ni wọn kìí pada wá mọ láti wá gba ojúlówó iwé ìrìnà wọn."
Wọ́n bí ọmọbinrin kan tí ń jẹ́ Miriamu ati ọmọkunrin meji: Ṣamai ati Iṣiba.
Ṣugbọn bí Ahija ti gbúròó rẹ̀ tí ó ń wọlé bọ̀ ní ẹnu ọ̀nà, ó ní, “Wọlé, ìwọ aya Jeroboamu.
àbọ́pa mààlúù mẹ́wàá, ogún mààlúù tí wọn ń dà ninu pápá, ati ọgọrun-un aguntan; láìka àgbọ̀nrín, egbin, ìgalà, ati oríṣìíríṣìí ẹyẹ àbọ́pa.
Idanilẹkọ gẹgẹ bi o ti se sọ wa ni ibamu pẹlu ilana ti ajọ to n gbogun ti aisan lorileede Naijiria, NCDC gbe kalẹ.
Ó rọrùn fún ràkúnmí láti gba ojú abẹ́rẹ́ kọjá, jù fún ọlọ́rọ̀ láti wọ ìjọba Ọlọrun!
Láti inú ẹ̀yà Simeoni: Ṣefataya, ọmọ Maaka.
Ṣùgbọ́n mo fẹ́ẹ́ sọ kin ní kan fún ọ - ibànújẹ́ ti pọ̀ jù láàárin àwọn ọmọ ènìyàn tó bẹ́ẹ̀ ti àwa tí a jẹ́ ẹbọra kì í fẹ́ẹ́ gbé ààrin wọn.
Nigba ti BBC kan si ijọba, wọn ni awọn ko ni ohunkohun lati sọ lori fidio ti ileeṣẹ iroyin CNN gbe jade, eyii to n ṣafihan pe ijọba pa irọ lori iṣẹlẹ to waye lẹnu iloro naa.
Oríṣun àwòrán, TWITTER Akeredolu ti ẹgbẹ oṣelu APC la Jedege mọlẹ pẹlu ibo 29,2830, ti Jegede ti ẹgbẹ oṣelu PDP si ni ibo 195,791.
Àarẹ ilẹ̀ Amẹrika Donald Trump, ti sọ pé ìṣekúpa àwọn ọmọlẹ́yìn Krístì nílẹ̀ Nàíjírià gbódọ̀ dópin.
Die lara awon to lo sile pelu ife eye ni to gba osere binrin to dara ju fun igab akoko ati Odunlade Adekola to gba osere kunrin apanilerin to dara julo.
Àwọn aṣọ wa ati àwọn bàtà wa ti gbó nítorí ìrìn àjò náà jìn.
Bakan naa ni wọn koro oju si ijọba ṣe gbẹsẹ le apo asunwọn awọn oluwọde naa.
Mo jẹ́ àlejò, ẹ kò gbà mí sílé.
Ṣugbọn mo ní ìtara fún orúkọ mímọ́ mi, tí àwọn ọmọ Israẹli sọ di nǹkan yẹ̀yẹ́ láàrin àwọn orílẹ̀-èdè tí wọ́n wà.
EFCC ń wádìí iléeṣẹ́ Bola Tinubu,' Alpha Beta Consulting Ltd' MAROC '88; eyi kọja bẹ́ẹ̀ Agbabọọlu ọmọ Naijiria nigba kan ri, Bright Omokharo ti ọpọ mọ si 'Ten-Ten' ni a fẹẹ lee tọka si gẹgẹ bii agbabọọlu ilẹ yii ti egungun rẹ le julọ ninu iwe itan.
Láti ìgbà yìí ni ọmọ èèyàn ti bẹ̀rẹ̀ sí ń tọ́ kiní funfun ọ̀hún sí gbogbo nkan jíjẹ àti mímu.
” Hesekaya dáhùn, ó ní, “Gbogbo ohun tó wà láàfin ni wọ́n rí.
Aṣalẹ oni ni Liverpool yoo rinrin ajo lọ si Napoli, lati lọ koju ikọ ọhun, ti Chelsea yoo si gba ikọ Valencia lalejo.
Ẹ̀kún omi India: Ìsẹ̀lẹ̀ náà ló tíì burú julọ́ làti ọgọ́rùn-ún ọdún sẹ́yìn
Ṣugbọn Jẹfuta dá wọn lóhùn pé, “Ṣebí ẹ̀yin ni ẹ kórìíra mi tóbẹ́ẹ̀ tí ẹ fi lé mi jáde kúrò ní ilé baba mi?
O ni eeyan mẹrindinlogun ni awọn ri yọ kuro ninu omi, nigba ti awọn meje to jẹ kiki obinrin padanu ẹmi wọn.
Oríṣun àwòrán, Fatima Muhammad Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Loju opo Twitter ọrọ yẹyẹ gbẹnu awọn ọmọ Naijiria kan lori bi Ghana ti ṣe kogba wọle ninu idije AFCON yi Orile-ede Ghana ti o ti gba ife ẹyẹ AFCON lẹmẹẹta ọtọọtọ wa lara awọn to ro pe wọn yoo gba ife eye naa ṣugbọn ti ijakulẹ ba wọn.
 Leta aare akoko ko soro lori ise ni ekun guusu ila oorun si ariwa ila oorun.
Ki ni itumọ Brexit ti ko ni adehun ninu?
ÌLÚ ÀWỌN ÈDÌDÀRẸ́ NÍ IBI TÍ ÒMÙGỌ́DIMÉJÌ Ti Ń ṢE ỌBA WỌN
Ṣugbọn, Ọlọrun sọ fún mi pé, kì í ṣe èmi ni n óo kọ́ ilé fún òun, nítorí pé jagunjagun ni mí, mo sì ti ta ẹ̀jẹ̀ pupọ sílẹ̀.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Awọn onwoye eto idibo labẹle ati lẹyin odi si lo ni ko si apade alude kankan ninu ibo naa, kedere lo han fun araye bo se lọ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Asset Declaration: Buhari, Osinbajo ti fi fọ́ọ̀mù ìkéde Dúkìá sọwọ́ 29 Èbibi 2019 Oríṣun àwòrán, @ProfOsinbajo, Getty Images‏ Àkọlé àwòrán, Aarẹ Buhari àti Igbakeji rẹ Osinbajo Aarẹ Muhammadu Buhari ti fi iwe ikede dukia ti o gba ṣọwọ pada si ajọ to n boju wo dukia awọn to di ipo nla mu niluu, Code of Conduct lọjọ aje ọjọ kejidinlọgbọn.
Apapọ ẹgbẹ awọn Alaga Ijọba ibilẹ lorilẹede Naijiria lo kọ ibudo ilera naa lọdun 2014.
O ṣoju mi koro to ba wa sọrọ ṣe alaye wi pe awọn janduku kan to n yọ awọn ontaja iṣu lẹnu ni agbegbe Bẹẹrẹ ni awọn ọlọpaa lati Mapo le wa si agbegbe Oke-Arẹ ti wọn si n yin ibọn soke.
Oríṣun àwòrán, Others Ṣé ìjọba àpapọ̀ tí ṣí àwọn ìléèwé àti ilé ìjọsìn padà bí?
Ọba Asiria rán àwọn ọ̀gágun rẹ̀: Tatani, Rabusarisi ati Rabuṣake pẹlu ọpọlọpọ ọmọ ogun láti Lakiṣi láti gbógun ti Hesekaya ní Jerusalẹmu.
tí o fi ọ̀bẹ dú àwọn ọmọ mi, o fi wọ́n rú ẹbọ sísun sí àwọn oriṣa?
26 Òkùdu 2018 Àwọn ọmọ Nàìjíríà f'ògún Jẹẹsí Super Eagles gbárí pé àwọn kò paá tì láíláí wọn kò sì ní fi ti ipò wọ́n níní idíje ife ẹ̀yẹ àgbáyé Russia 2018 ṣe.
Ni igba to n b a BBC sọrọ, agbẹnusọ gomina ọhun, Onyebuchi Ememanka sọ pe gomina naa ti wa ni igbele, ati pe awọn akọṣẹmọṣẹ dọkita ti n ṣe itọju rẹ.
Ọ̀fẹ́ ni ẹ rí agbára wọnyi gbà.
Èyí ni ẹnu ọ̀nà OLUWA;àwọn olódodo yóo gba ibẹ̀ wọlé.
Ṣugbọn, ibo awọn mẹtẹẹta lo kere julọ.
Àwọn ọ̀dọ́ Naijiria ti sọ̀rọ̀ síta lórí ohun ti wọ́n ń retí lọ́dọ̀ minista tuntun
Oríṣun àwòrán, Super Eagles Àkọlé àwòrán, Ọjọ ti àwọn onisowo to ń ta asọ super Eagle bẹ̀rẹ̀ títà.
Gba ìtọ́ni rẹ̀,kí o sì kó ọ̀rọ̀ rẹ̀ lékàn.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Èmi gan máa ń béèrè lọ́wọ́ ara mi pé ta ni Wole Soyinka gangan' 9) Aláàfin ìlú Ọyọ - Ọba Adeyemi Adediran Keji Ọ̀tẹ̀ oṣelu lo fa bi wọn ṣe rọ baba to bi Alaafin ìlú Ọyọ to wa nipo bayii, (Ọba Lamidi Adeyemi Kẹta) Ọba Adediran Adeyemi nipo.
“Mo bẹ̀ ọ́ OLUWA, ranti bí mo ti sìn ọ́ pẹlu òtítọ́ ati ọkàn pípé, ati bí mo ti ń ṣe ohun tí o fẹ́.
Wọn a ko ire oko awọn Ẹgba bo ṣe wu wọn, ti wọn si tun n fẹ wọn laya pẹlu laisi ẹni ti yoo yẹ awọn Ilari yii lọwọ wo, nitori aye Ọba ni wọn njẹ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ikogosi-Ekiti: Ilu ti omi tutu ti dapọ mọ gbigbona Awọn isẹlẹ yii ko dun mọ Lisabi ati awọn ọmọ ẹgbẹ aaro rẹ ninu, ti wọn si maa n jẹ awọn iya ti awọn Ilari fi n jẹ wọn lẹnu lojoojumọ.
Mo ti gba ife àmutagbọ̀n-ọ́n-gbọ̀n-ọ́n lọ́wọ́ rẹ,O kò ní rí ibinu mi mọ́.
"Isley ní: ""mo gbìyànjú láti lo owù fún dídá ìsun ljẹ̀ dúró nígbà tí mo wà láàrin ọdún kan sí mẹ́wàá, ó kan mí lára gaan bí ẹni pé kò sí ihò lójú ara mi tàbí ògiri dí i pa."
Olusẹgun Abraham, to baa du ipo asia gomina ninu ẹgbẹ oselu APC nipinlẹ Ondo, lo n pee lẹjọ.
8 ènìyàn ni ágbáyé, ọ̀pọ̀ nínú wọn ọmọdé
Iṣẹ ati oṣi n ba awọn eeyan Togo finra, akọsilẹ ajọ IMF tiẹ sọ pe orilẹede naa lo tosi ju sikẹjọ lagbaye.
" O ṣe awọn awo orin miran jade, o ṣi n tẹsiwaju lati maa kọ orin titi di asiko yii.
Abuja, Port Harcourt ati Kano .
olubori ninu abajade esi idibo ti ile igbimo asoin ati ti aarẹ.
Ni ọjọ́ kan, Ẹkùn gbéra lọ sinú igbó lati lọ wa oúnjẹ fún àwọn ọmọ rẹ, àwọn ọmọ ẹ kéré wọn kò lè yára bi iyá wọn.
O ni gbogbo isesi ọba Mufutau lo safihan rẹ gẹgẹ bi awokọse daada ati ẹgbọn fun oun laarin awọn ọba ilẹ Yoruba.
 Fadá Anselm Adodo Ojisẹ Ọlọ́run kan nínú ìjọ Kátólíìkì, tíì tún ṣe olùdarí fún ilé ìwòsàn ìbílẹ̀ nipinlẹ Edo, Fadá Anselm Adodo tí fi ìkéde kan síta lójú òpó Facebook rẹ, ní Ọjọ́bọ, ọjọ́ Kokandinlogbon oṣù kẹrin ọdún 2020 pé, ibùdó ayẹwo òun ti gbé òògùn ìbílẹ̀ kan jáde, tó le wo àrùn Covid-19."
Ẹ jẹ́ kí á máa rìn bí ó ti yẹ ní ọ̀sán, kí á má wà ninu àwùjọ aláriwo ati ọ̀mùtí, kí á má máa ṣe ìṣekúṣe, kí á má máa hu ìwà wọ̀bìà, kí á má máa ṣe aáwọ̀.
"N'ise ninu awọn eeyan maa n bajẹ ni Namibia bi wọn ba ṣe iranti igba amunisin yi Laarin ọdun 1904 si 1908 awọn ọmọ-ogun Germany pa to ọpọ eeyan ẹya Nama ati Herero bi ẹni pa ẹran ninu iṣẹlẹ t'awọn onkọtan a máa pe ni ""Forgotten Genocide"" Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Borno Zabarmani Rice Farmer Massacre: Àwọn àgbàgbà Òkè Ọya ní ẹ̀mí èèyàn kò níyì mọ́ lábẹ́ ìṣèjọba Buhari5 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Lagos Senatorial Elections: Abiru ṣ'àbẹ̀wò sí Tinubu lẹ́yìn tó wọlé àtúndi ìbò Sẹnẹtọ ìlà oòrùn ìpínlẹ̀ Eko7 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?"
Wọ́n bèèrè pé, “Níbo ni ọmọ tí a bí tí yóo jẹ ọba àwọn Juu wà?
Lagos-113 FCT-86 Abia-47 Kaduna-39 Rivers-27 Katsina-22 Benue-14 Oyo-13 Kano-12 Enugu-8 Edo-7 Imo-7 Bauchi-6 Ebonyi-6 Ogun-6 Ondo-4 Nasarawa-1 Ẹgbẹrun mẹtalelaadọrin o le marundinlọgọsan (73,175) eeyan lo ti ko aarun naa lorilẹede Naijiria lati igba ti wọn ti kẹẹfin ẹni akọkọ to laarun naa ni Naijiria ni oṣu keji ọdun 2020.
Òtútù yẹ kó ti máa dínkù.
Oríṣun àwòrán, @thenff Àkọlé àwòrán, Ẹgbẹ agbabọọlu Chelsea nilẹẹ Gẹẹsi ni Victor Moses ti n gba bọọlu jẹun Ẹgbẹ agbabọọlu Chelsea nilẹẹ Gẹẹsi ni Victor Moses ti n gba bọọlu jẹun ti Asisat Oshoala si wa pẹlu ẹgbẹ agbabọọlu Dalian Quanjian lorilẹede China.
Wọ́n bá dákẹ́ nítorí ní ọ̀nà, wọ́n ti ń bá ara wọn jiyàn lórí ta ni ó ṣe pataki jùlọ.
Amọ ti wọn fori ja igbo lati ri i pe wọn de ipo giga nile aye lai naani ọpọ ẹgun to wa ni ọna wọ̀n.
Seyi Makinde: Gbogbo ìgbà ni ìyá mi máa ń sọ fún mi pé díẹ̀ ló kù kí àwa méjèjì kú lọ́jọ́ tó bí mi
Musa gbá bọ́ọ̀lù sáwọ̀n fún ikọ̀ tuntun CAF kéde orúkọ àwọn olùdíje àmì ẹ̀yẹ agbábọ́ọ̀lù Áfíríkà Ǹjẹ o mọ bí 'April Fool's Day' se bẹ̀rẹ̀?
Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Cure for coronavirus: Nigerian researchers announce say dem develop Covid-19 vaccine?
Nígbà tí o bá ń la ibú omi kọjá,n óo wà pẹlu rẹ;nígbà tí o bá la odò ńlá kọjá,kò ní bò ọ́ mọ́lẹ̀,nígbà tí o bá ń kọjá ninu iná, kò ní jó ọ.
Ojú alábaṣiṣẹ́pọ̀ Mompha rèé, EFCC ṣí i síta Tí o bá rí àpẹrẹ mẹ́fà yìí, sá àsálà fún ẹ̀mí rẹ̀!
Oṣu marun un gbako ni ko fi si lilọ bibọ ọkọ ofurufu lati ilẹ okeere sí Naijiria ati lati Naijiria sí oke okun nitori iṣede coronavirus.
Pẹlu esi ifẹsẹwọnsẹ yii, Everton lo ṣi n lewaju loke tente tabili liigi ilẹ Gẹẹsi bayii ti liverpool si n tẹlee pẹly ami mẹwaa.
Saaju lọjọbọ ni ẹgbẹ oselu APC nipinlẹ Ọyọ ki kede loju opo Twitter rẹ pe ijọba Ọyọ ti yan Auxiliary gẹgẹ bii alaga ẹgbẹ ọlọkọ ero.
O ni awọn ẹrọ yii lo le fa ọwọ isẹ awọn ẹrọ kaadi idibo ṣeyin tabi ko sayipada bawọn ẹrọ naa ṣe n ṣiṣẹ pada.
Ẹ̀yin ará, kò nílò pé a tún ń kọ̀wé si yín mọ́ nípa ti àkókò ati ìgbà tí Oluwa yóo farahàn.
Igbeyawo ọmọde Ni orilẹede Afghan, ọdun ti ofin faaye gba ki ọmọ ṣe igbeyawo ni ọdun mẹrindinlogun fun ọmọbinrin ati mejidinlogun fun ọmọ ọkunrin.
Tí a fiṣọwọ́ ní 8:488:48 Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold ''O pa mi lẹrin nigba ti mo gbọ ọrọ awọn ọdọ ti wọn n pe ara wọn ni ẹgbẹ awọn ọkunrin to lahun,'' Akeugbagold lo sọ bẹẹ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Mo fẹ́ gbé ògo ìdílé ìyá àti bàbá mi ga pẹ̀lú iṣẹ́ Mọkálìíkì' Ẹkọ ti itan igbe aye Shina Rambo kọ wa: Ẹkọ akọkọ ni pe ki obi mase huwa ibajẹ loju awọn ọmọ wọn nítorí obi ni awokose fawọn ọmọ wọn.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Abacha Loot: Amẹ́ríkà ní gómìnà Kebbi ló bá Abacha kó ọ̀pọ̀ bílíọnù dọ́là wá, tó sì lo oṣù mẹ́fà ní àhámọ́ òun 22 Èrèlè 2020 Oríṣun àwòrán, @FRNcitizens Laipẹ yii ni iroyin kan awọn ọmọ Naijiria pe ijọba ilẹ Amẹrika tun ti sawari owo kan ti olori tẹlẹ fun ijọba ologun ni Naijiria, oloogbe ọgagun Sani Abacha ko pamọ sorilẹede naa, ti wọn si setan lati daa pada fun wa.
Dafidi dáhùn pé, “Ògo ni fún OLUWA Ọlọrun Israẹli tí ó rán ọ sí mi lónìí.
Ọmọ mi, bí o bá gba ọ̀rọ̀ mi,tí o sì pa òfin mi mọ́,
“Moabu ti parun; a gbọ́ igbe àwọn ọmọ rẹ̀.
Agbẹnusọ fun ileeṣẹ ọlọpaa ni, wọn gbe Salisu digbadigba lọ si ile iwosan nibi to ku si nitori ẹpa ko boro mọ.
Oríṣun àwòrán, @BashirAhmaad Àkọlé àwòrán, Ọdọmọkunrin kan duro si oju ọna niwaju ọkọ ayọkẹlẹ Aarẹ Buhari Oríṣun àwòrán, @BashirAhmaad Àkọlé àwòrán, Ọdọmọkunrin kan duro si oju ọna niwaju ọkọ ayọkẹlẹ Aarẹ Buhari nipinlẹ Plateau Oríṣun àwòrán, @BashirAhmaad Àkọlé àwòrán, Aarẹ Buhari ṣe ipade pẹlu awọn alẹnulọrọ nipinlẹ Plateau Oríṣun àwòrán, @BashirAhmaad Àkọlé àwòrán, Ipade Aare Buhari pelu awon loba-loba nilu Jos Oríṣun àwòrán, @BashirAhmaad Àkọlé àwòrán, Awọn eniyan ipinlẹ Plateau tu jade si oju popo fun igbalejo Aarẹ Buhari BBC News, Yorùbá Ìdí tí ẹ fi le è nígbàagbọ́ nínú ìròyìn BBC Ìlànà Lílò Nípa BBC Òfin Àṣírí Cookies Kàn sí.
Mo ti pèsè ẹgbẹẹdogun (3,000) ìwọ̀n talẹnti wúrà dáradára láti ilẹ̀ Ofiri, ati ẹẹdẹgbaarin (7,000) ìwọ̀n talẹnti fadaka tí a ti yọ́, láti fi bo gbogbo ògiri tẹmpili náà, 
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 2020 in Retrospect: Ìjàmbá iná, ilé tó dàwó, ìwọ́de àti àrùn Covid-19 wà lára ìṣẹ̀lẹ̀ 2020 Bákan náà ló gbọdọ sọ̀ nípa àwọn ohun ti mo ṣe nípa ilé ifówópamọ tí orúkọ ẹni tó ni yí pada láìpẹ́ yìí, tí ó sì níṣe pẹ̀lú mi.
Awọn iroyin miran ti ẹ le nifẹ si: Wọn ri oku ọmọ to sọnu ninu ọkọ orogun iya rẹ O see se ki ọti ati siga gbowoleri China ti f'ọwọ si 'aarẹ lailai' Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Wọn óo máa bi ara wọn léèrè pé, ‘Kí ló dé tí OLUWA fi ṣe báyìí sí ilẹ̀ yìí ati ilé yìí?
naa waye ni osu keje, odun 2018 lati igba naa ni awuye-wuye ti n waye lori eto
Awọn mẹrẹẹrin ni Mallam Nuhu Ribadu, Arabinrin Farida Waziri, Ọgbẹni Ibrahim Lamorde, ati Ibrahim Magu.
"ogun kọ ni gbogbo iyẹn, a ni ẹ o mọ asiko ti ẹ o mu abọ lọwọ ti ẹ o si ni ri ounjẹ jẹ""."
Wọ́n sì fi àwọn èkúté marun-un tí wọ́n fi wúrà ṣe ranṣẹ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Mo ti kọkọ sọ fún Toyin Abraham pe mi o le ṣe amúgbálẹ́gbẹ rẹ̀- Sam Olatunji 10 Ìgbé 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 13 Ìgbé 2020 Oríṣun àwòrán, Toyin/instagram Àkọlé àwòrán, Ọpẹ ni fún Ọlọ́run lórí ayé Toyin Abraham, láti orí gbèsè jíjẹ, ó di onílé, onimọto àti aya lọ́dọ̀ ọkọ Gbajúmò osere tíátà lobinrin, tó ń kopa ninu ère tíátà lédè Yorùbá àti oyinbo ní Toyin Abraham.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ìwà pípa àlejò gbòdekan ní orílẹ̀èdè South Africa Ó sàlàyé pé ọmọkùnrin náà tí ó jẹ́ ọmọbíbí ìlú Njikoka ní ìpínlẹ̀ Anambra lùgbàdì ikú òjijì ní ìlú Rustenburg.
 shogun ieyasu ní ìfẹ ́ sí i gidi ni , nítorí ìdí èyí , wọn fi ibi tí àwọn gẹ ̀ ẹ ́ sì àti dutch ti lè máa ṣòwò lélẹ ̀ ní japan .
Nígbà tí ẹ bá pọ̀ síi ní ilẹ̀ náà, ẹ kò ní sọ̀rọ̀ nípa Àpótí Majẹmu OLUWA mọ́, ọ̀rọ̀ rẹ̀ kò ní sọ si yín lọ́kàn, ẹ kò ní ranti rẹ̀ mọ́, bẹ́ẹ̀ ni ọkàn yín kò ní fà sí i mọ́, ẹ kò sì ní ṣe òmíràn mọ́.
Diẹ ree ninu aworan igbe aye rẹ: Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Lọdun 1982 ni Maradopna ti kọkọ kopa ninu idije ife ẹyẹ agbaye ni Spain ṣugbọn lọdun 1986 niiraw rẹ tan ni Mexico.
Lẹ́yìn ọjọ́ mẹfa, Jesu mú Peteru ati Jakọbu ati Johanu lọ sí orí òkè gíga kan, àwọn mẹta yìí nìkan ni ó mú lọ.
O ṣalaye pe lilo kẹmika bi oogun ẹfọn tabi 'sniper' maa n ba ẹya ara jẹ́ diẹdiẹ ni tabi ko pa eniyan l'oju ẹsẹ.
O ṣakawe iṣẹlẹ kan to nii ṣe pẹlu arabinrin kan ti aarẹ n daamu rẹ debi wi pe ko le bimo.
Síbẹ̀síbẹ̀, ìdájọ́ òfin yìí kò le tó, ìtìmọ́lé ọdún méjì sí mẹ́jọ.
 olúbákin àti àbúrò rẹ ̀ tí wọ ́ n jọ jẹ ́ ọmọ bàbá ni wọ ́ n jọ dunpò awùjalẹ ̀ ìkẹtàdínlógójì ti ilẹ ̀ Ìjẹ ̀ bú lẹ ́ yìn tí Ọba morógbèsọ ̀ , awùjalẹ ̀ ìkejìlélogojì .
Police Killing: Ọlọpàá mẹ́rìn to pa afurasí dèrò ẹ̀wọ̀n lẹ́yìn tíṣẹ́ bọ́ lọ́wọ́ wọn
7) Iwadi tuntun ti atọna awọn ọlọrọ lagbaye, Bloomberg Billionaires index, gbe jade n fidirẹ mulẹ pe biliọnu mejidinlaadoje biliọnu dọla ($128b) ni odinwọn ọrọ awọn mejeeji bayii.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: PDP: A ò fẹ́ ẹ̀jẹ̀ Buhari gẹ́gẹ́ bí alábojútó ìbò kíkà Iya Rainbow, Jide Kosoko, Ọga Bello, yóò polongo Buhari fún 2019 Àwọn òṣèré tíátà Yorùbá tó bá 2018 lọ Ọgbẹni Osaze-Uzzi to jẹ agbẹnusọ fun ajọ INEC ṣalaye pe ojuṣe igbimọ ti wọn fi Amina Zakari ṣe olori fun ni lati ṣaayan eto gbogbo fun lilọ wọọrọwọ eto ibo kika ati pe Alaga ajọ naa ni Ọga agba patapata lori eto ibo kika ti ko si si ohun kan ti o lee yii pada.
idagbasoke lee ba awujọ wa ,”  bakan naa ni aare Buhari
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù EFCC: Ìwádìí lórí ẹ̀sùn ìwà jẹgúdújẹrá tí wọ́n fi kan Babatunde Fowler tó jẹ́ àdàrí iléeṣẹ́ FIRS tẹ́lẹ̀ 2 Bélú 2020 Oríṣun àwòrán, Google Ileeṣẹ to n gbọ ẹsun iwa ibajẹ, EFCC ti bẹrẹ si ni fi ọrọ wa Ọga Ajọ to n risi owo ori labẹle lorilẹede Naijiria, Babatunde Fowler lẹnu wo.
A n fe ki won pese abere ajesara fawon eran osin ti wan aa saaju asiko ojo ki won ma lo ni otutu ati ofinkin.
Ipade naa n lọ lọwọ ni gbọngan nla Theophilus Ogunlesi to n bẹ ladojukọ UCH nilẹ Ibadan.
Awọn oludaabobo awọn ẹranko ti se awari akìka to tobi ju fun igba akọkọ lorilẹede Naijiria.
"Ọga ọlọpaa ni awọn ni ijọba gbẹkẹle ki awọn janduku ma baa gba akoso igboro ilu nitorinaa ""ko si bi eeyan ṣe fẹ́ bi wa ninu to tabi sọrọ abuku si wa ti a o ni ṣe iṣẹ wa bo ṣe yẹ."
Esi to tẹyin ayẹwo yi wa mu ki awọn eeyan faraya.
Ṣugbọn bí ẹ kò bá ní gbọ́,ọkàn mi yóo sọkún níkọ̀kọ̀ nítorí ìgbéraga yín.
Aare ni olooogbe naa ti fi ise rere sle fawon eniyan lati keko lara re paapaa lasiko to je omo goun ile ni Naijiria titi to fi dori ipo ogagaun agba ko to tun lo soju ekun guusu ipinle Plateau nie igbimo asofin lÁbuja.
Elieli, ati Obedi, ati Jaasieli, ará Mesoba.
Àwòrán bí ìlú Ìwó se rọ̀sọ̀mù f’ọ́dún eégún Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Ọ̀lọ́wọ́ òsì kọ́ndọ́rọ́' Bi awọn egungun kan ṣe n gbe odo lori, ni awọn mii n yọ atori, bakan naa sini awọn kan ninu wọn tun fa ọmọ lọwọ, lasiko ti wọn n ṣe afihan igbelaruge aṣa ilẹ Yoruba yii.
Ọ̀gbẹ́ni Loiuse Braille tí í ṣe ọmọ orílẹ̀èdè Faransé ló ṣètò álúfábẹ́ẹ̀tì yìí fún àwọn afọ́jú ní ọdún 1821.
’Ati pé,‘Kí á fi ipò rẹ̀ fún ẹlòmíràn.
Gbogbo awon ijoba ibilẹ yii ni awon ohun elo ati irinse eto idibo ti de si ni kutu owurọ yii , awon ni: Baruwa Ward 4, unit 19 ati 20, Ward 10 ,unit 13, Fagbesa ni ijoba ibilẹ Osogbo , ward 8 unit 3  ni ijoba ibilẹ Olorunda ati Ward 7, ijoba ibilẹ Eripa Boluwaduro ati ward 4, unit 10,Olobu road,ijoba ibilẹ  Irepodun.
Ohun tí ó yé kóò kọ́ nípa ìròyìn òfégè ṣáájú ìdìbò 2019
Ifẹsẹwọnsẹ mii to wa ninu idije UEFA Champions League lalẹ ọjọ Iṣẹgun yoo waye ni papa iṣere Anfield nibi ti Liverpool yoo ti gbalejo FC Porto.
Lara awọn ẹgbẹ agbabọọlu ti Yobo ti ṣeṣẹ tẹle ni ikọ Olympique Marseille, Everton, Norwich City ati Fenerbahçe.
Kò yẹ ki ẹnikẹni pa ẹnikeji nitori àwọ̀ ara tàbi nitori ẹni ti èniyàn bá ni ìfẹ́ si.
Nítorí náà, ẹ ṣọ́ra yín, kí ẹ máa tẹ̀lé majẹmu yìí, kí ohun gbogbo tí ẹ bá dáwọ́lé lè máa yọrí sí rere.
Ọlọrun pàṣẹ pé kí omi tí ó wà lábẹ́ ọ̀run wọ́jọ pọ̀ sí ojú kan, kí ìyàngbẹ ilẹ̀ lè farahàn, ó sì rí bẹ́ẹ̀.
Ohun tí ó ṣe burú lójú OLUWA Ọlọrun rẹ̀, kò rẹ ara rẹ̀ sílẹ̀ níwájú wolii Jeremaya ẹni tí Ọlọrun rán sí i láti bá a sọ̀rọ̀.
countries without coronavirus: Ọwọ́jà coronavirus yóò ṣì wà pẹ̀lú àgbáyé fún ìgbà pípẹ́- Ngozi Okonjo-Iweala
Coronavirus in Nigeria: Ǹjẹ́ ṣé òògùn apakòkòrò le pa ààrùn coronavirus?
Agbeyẹwo Iṣuna Owo Ilu ṣe pataki a si gbọdọ jẹ ki wọn ṣiṣẹ wọn laṣe
Ṣugbọn òun ṣe ìrúbọ lẹ́ẹ̀kan fún ẹ̀ṣẹ̀ tí ó tó fún gbogbo ìgbà, ó wá jókòó ní ọwọ́ ọ̀tún Ọlọrun.
 Ọ ̀ pọ ̀ àwọn àkóràn ń wáyé ní ìwọ ̀ gúùsù afíríkà , bí o tìlẹ ̀ jẹ ́ pé àti ṣàwarí àwọn ìṣẹlẹ ̀ kan ní yemen àti ní àwọn agbegbè ìyàsọtọ ̀ aarin àti gúúsù amẹríkà .
Awọn aṣofin naa ti iye owo ọhun ko ba lara mu ti ni ajọ naa gbọdọ ṣalaye bi yoo ṣe na owo naa.
Ilẹ ẹjọ fagilé ìbò ọmọ ẹgbẹ́ APC nípinlẹ̀ Ogun pè kí àtúndì ìbò wà Kò tíì sí ìrànlọwọ owó f'àwọn ọmọ Nàìjíríà tí ń bọ láti South Africa -Abike Dabiri Ileeṣẹ ọlọpaa ti paroko ikilọ ranṣẹ sawọn ọmọlẹyin Shiite naa pe ko si aye fun wọn lati ṣe irin aro naa nitori gẹgẹ bii aṣẹ ile ẹjọ, ẹgbẹ Shiite naa kii ṣe ẹgbẹ to ba ofin mu lorilẹede Naijiria.
Wọ́n kàn kéde rẹ̀ lójú òpó Twitter wọn ni pé ''àwọn ọmọ ogun dojú ìjà kọ Boko Haram ní Sari.
Oríṣun àwòrán, @NGRPresident Àkọlé àwòrán, Fayose to jẹ ọkan gboogi ninu awọn alatako aarẹ orilẹede Naijiria, Muhammadu Buhari Lara awọn to wa nibi ipade naa ni wipe yoo farahan nibi ipade yii ni Oloye Olusegun Obasanjo, gomina ipinlẹ Ekiti, Ayọdele Fayose atawọn gomina ipinlẹ lorilẹede Naijiria.
Ìfẹ́, ayọ̀ ìdùnnú àti ifọkanbalẹ kò ní jina sí bẹ,
Kíni yóò sẹlẹ̀ sí àwọn òsìsẹ́ Diamond Bank?
NLC: A ò ní dìbò wa fún àwọn gómìnà ọlọ̀tàá ICPC gbé ọ̀jọ̀gbọ́n tó bèérè fún ìbálòpọ̀ ní fásitì OAU lọ ilé ẹjọ́ Saraki àti Buhari fẹ́ wọ ìyá ìjà ní Kwara Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ìgbé ayé Instagram fún ọ́sẹ̀ kan Àwọn míì tó wà níbi ìpàdé ọ̀hún ni olùṣirò owó àgbà ti orílẹ̀èdè yìí àti akọ̀wé àgbà ilé iṣẹ́ tó ń rí sí ètò ẹ̀kọ́.
Ati pe iwadi fihan pe aisan jẹjẹrẹ yoo jina si obinrin to ba n fun ọmọ ati ọkọ rẹ l'ọyan.
Teni entertainer: Idi ti mi ò kì ń ṣí ìhòhò mi bi àwọn olórin obìnrin míran
Gege bi ile-ise olopaa se so, won ni, oruko afurasi ohun n je David Katz, omo odun merinlelogun ti o wa lati ilu Baltimore.
Alexandra Popp lo ku ninu awọn agbabọọlu naa to maa koju Naijiria.
Ẹ̀yin ni ìdájọ́ náà dé bá; nítorí ẹ dàbí tàkúté ní Misipa, ati bí àwọ̀n tí a ta sílẹ̀ lórí òkè Tabori.
Má wààsú fún-un: Má sọ Ara rẹ di pásítọ̀ fún wọn.
Yoruba Films: Àwọn òṣèré tíátà Yorùbá ọkùnrin tí ó rẹwà Oríṣun àwòrán, Gabriel Afolayan Àkọlé àwòrán, Gabriel Afọlayan, Gfresh Oniruuru ni awọn oṣere tiata ni ilẹ Yoruba.
Wọ́n kígbe pè ọ́, o sì gbà wọ́n;ìwọ ni wọ́n gbẹ́kẹ̀lé, ojú kò sì tì wọ́n.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Barrister lo bi gbogbo oníṣẹ́ fújì -Oṣupa Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Barrister lo bi gbogbo oníṣẹ́ fújì -Oṣupa 30 Èbibi 2019 Kollington Ayinla naa jẹ baba fun gbogbo ẹni to ba ṣoriire nidi Fuji- Osupa.
O sagbatẹru bi awọn ọba kan nilẹ Yoruba ṣe di ọba alade Oríṣun àwòrán, others Ṣaaju akitiyan Alaafin Adeyẹmi, awọn ọba kan nilẹ Yoruba kii de ade ilẹkẹ.
Ṣugbọn mo lero wi pe asiko ti to lati yẹba, ki n ba a le fọkan si ẹgbẹ agbabọọlu ti okeere ti mo n ṣiṣẹ fun ati idile mi.
Lọ́tọ̀ ni a óo fún wọn ní ilẹ̀ tiwọn.
Tiamiyu Kazeem: Ìjọba ìpínlẹ̀ Ogun ní dandan, àwọn yóò ṣewadii ikú Tiamiyu Kazeem Oríṣun àwòrán, @Official3SC Gomina ipinlẹ Ogun, Dapo Abiodun ti sọ pe gbogbo awọn to lọwọ ninu iku Tiamiyu Kazeem, to jẹ ọmọ ẹgbẹ agbabọọlu Remo Stars ti ipinlẹ Ogun ko ni lọ lai foju wina ofin.
Akande so pe “bi awon odaran ati abayeje se kolu ile-ijosin je ohun to buruju jai”.
Tó bá di ìgbà náà, àwọn eniyan yóo bọ̀wọ̀ fún Ẹlẹ́dàá wọn, wọn yóo sì máa wo ojú Ẹni Mímọ́ Israẹli.
Ṣaaju ko to darapọmọ Galaxy lo ti gba fun Manchester United, PSG, Barcelona,Inter Milan ati Ajax.
Iko agbaboolu Super Eagles pari sipo kerìnlélógójì ninu ipo
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Awọn alatako ni wọn a ma lo ofin Sharia nilokulo ''Otọọtọ ni iha ti ọrọ a máa kọ si onikaluku'' O tẹsiwaju pe ''a ko le sọ pe ofin Sharia gbe awọn ọkunrin ju awọn obinrin lọ .
Apapọ awọn to ti ni arun naa kaaakiri orilẹ-ede Naijiria ti wa di 26,484 bayii.
Tẹbi-tara tojulumọ lo maa pade lati ṣe ẹyẹ ikẹyin fun un ni Canada.
Nítorí náà, a gbàgbọ́ pé láti ọ̀dọ̀ Ọlọrun ni o ti wá.
Nínú fọ́nran fidio kan ti o fi ṣọwọ́ sí oju opo Facebook, a rí i ti awọn kàn n yẹ orúkọ tó wà lórí àkọsílẹ wò ti wọn sì ni eniyan kan lo bọwọ luwe ọ̀pọ̀ orúkọ.
Ni àárọ̀ ọjọ́ kan, Ìgbéraga ji ṣùgbọ́n kò lè di de nitori ó ti yarọ.
Agege nilu Eko ni orisun ẹgbẹ yii.
Kalebu tún ní obinrin kan tí ń jẹ́ Efa, ó bí ọmọ mẹta fún un: Harani, Mosa ati Gasesi.
Lọdun 2003 o di agbẹjọro agba akọkọ ilu San Fransisco lẹyin igba naa lo tun di agbẹjọro agba nilu California.
Lara kudiẹkudiẹ to mẹnu ba ni pe Gomina Akeredolu kọ ni ẹgbẹ rẹ dibo yan lati ṣoju wọn ninu idibo Gomina.
Irinajo Musa si Mecca Okiki ijọba Musa kan kari aye nigba to lọ si ilu Mecca fun iṣẹ isin, to si gba ọna aṣalẹ Sahara ati orilẹede Egypt lọ irinajo ọhun.
PVC :Party Agent (Asoju ẹgbẹ oselu) : Eyi ni ẹni ti o n
Ṣugbọn mo ti tú àwọn ọmọ Esau sí ìhòòhò,Mo ti sọ ibi tí wọn ń sápamọ́ sí di gbangba,wọn kò sì rí ibi sápamọ́ sí mọ́.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Abiola Ajimobi: Irọ́ ikú làá pa mọ́ àdá, kokoko lara baba wa le, ẹbí Sẹ́nétọ̀ Abiola Ajimobi pariwo síta láàrín ìròyìn ikú rẹ̀ 19 Òkùdu 2020 Oríṣun àwòrán, Instagram/abiola ajimobi Irọkẹkẹ iroyin nipa agba oṣelu, Sẹnetọ Abiọla Ajimọbi lo gba igboro kan lalẹ ọjọbọ nigba ti iroyin dede lu sita pe gomina ana ni ipinlẹ Ọyọ naa ti dagbere faye; bẹẹ lawọn to sun mọọ pẹlu n pariwo irọ iku laa pa mọ ada, kokoko lara ọta le.
Trump nílò láti káwọ́ pọ̀nyìn jẹ́jọ́ nítori ọgagun Soleimani tí Amẹ́ríkà pa-Iran Ìdí táwọn olùwọ́de EndSARS fi kọ oúnjẹ àti ọtí ẹlẹ́rìndòdò tí MC Oluomo gbé wá rèé E wo ọmọ Yorùbá àkọ́kọ́ tó jà fún ẹ̀tọ́ àwọn aláwọ̀dúdú ní America!
Ọmọ Otedola bú sẹ́kún lẹ́yìn tí Brighton tún d'ẹrù ìyà lé Arsenal lórí Chelsea dun DJ Cuppy nínú lẹ̀yìn tí Arsenal gba omijé lójú rẹ̀ Ọkúnrin kan gún àfẹ́sọ́nà rẹ̀ pa tán ló bá tún pa ara rẹ̀ náà Wo bí ìpinu Amẹ́ríkà lórí gbígba físà ṣe kan ọ́ Báwó ni òògùn dexamethasone ṣe ń ṣiṣẹ́ lára Coronavirus: Ewu wo làwọn òṣìṣẹ́ elétò ìlèra ń kojú ní Nàìjíríà?
Ẹnikẹni to ba fẹ kọ ile ti araalu yoo maa lo(ile ounjẹ, ileewosan, ile itaja ati bẹẹbẹ lọ), awọn ajọ to wa fun ile kikọ gbọdọ ṣayẹwo ilana ti wsn la kalẹ fun kikọ ile naa lati ri daju pe o pa ofin ọhun mọ.
”Opolopo ile-ise ati ajo ijoba ni a ti n ba soro lati wa da ile-ise sile lorile ede Naijiria .
Alukoro ileeṣẹ ọlọpaa ni awọn ko tii ri oku ọmọde naa ati wi pe, o ṣeeṣe ki awọn lọkọlaya naa ti sin oku rẹ.
    Nígbà tí a bìlà sẹ́yìn díẹ̀ báyìí tí a jókòó ní ibi kan tí a ṣe àsàrò lórí ọ̀ran náà, ogunlọ́gọ̀ nínú àwọn ọdẹ ni wọ́n fẹ́ pé kí a bá a lọ.
Boya ori ọkan ninu awọn aga yii gan lo ti kọ ọkan ninu iwe rẹ Àkọlé àwòrán, Ẹnu ọna abawọle yara D.
 Ìdáhun agbóguntàìsàn tí ó wáyé láàárìn 10 sí 100 miu / ml jẹ ́ ìdáhun tí kò péyé .
Dá ẹ̀mí mi sí nítorí olùfọkànsìn ni mí;gba èmi iranṣẹ rẹ tí ó gbẹ́kẹ̀lé ọ là;ìwọ ni Ọlọrun mi.
Bákan náà lo sísọ lójú rẹ pé ara, ara ìyá ìbejì kò dá rárá, ṣe ló ń dákú lọpọlọpọ ìgbà, tí òun sì ń gbe láti ilé ìwòsàn kan si òmíràn, tí ẹ̀jẹ̀ ruru òun sì ń ga sì lojoojumo.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ondo Crisis: Aṣòfin Iroju Ogundeji, Favour Tomowewo àti Williams Adewale ń lọ rọọkún nílé 6 Agẹmo 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 8 Agẹmo 2020 Oríṣun àwòrán, @Ondo Govt Àkọlé àwòrán, Ondo Sinima orita awoowotan ni ọrọ adari ile igbimọ aṣofin ati awọn ọmọ ile igbimọ n di lasiko yii ni ipinlẹ Ondo.
Lara awon eru ti ile ise asobode ohun ri gba fun saa keji yii ti apapo
Kò sí ẹnikẹ́ni tí ó ṣe aláìní ohun kan láàrin wọn.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Waste to Wealth: Ẹ̀gbin tìrẹ ni èròjà táwọn èèyàn míràn fi n ṣiṣẹ́ ajé, okoòwò ńlá ni Bakan naa ni olokoowo to gbajumọ julọ ni Afirika, Aliko Dangote, lasiko ipade apero ti banki apapọ ilẹ wa se laipẹ yii ti koro oju si bi orilẹede Naijiria ko see tii waọna miran fun ọrọ aje rẹ yatọ si epo rọbi, to ti di okuta lọja agbaye bayii.
Nígbà wo ni o fẹ́ dúró dà, kí o tó dá àwọn eniyan rẹ lẹ́kun pé kí wọ́n yé lépa àwọn arakunrin wọn?
Mo so pe idibo yii ni se pelu ojo iwaju orile ede yii.
Ẹẹdẹgbẹrin (700) akọni ọkunrin tí wọn ń lo ọwọ́ òsì wà láàrin àwọn ọmọ ogun wọnyi.
Isinku ọhun yoo waye lọjọ Abamẹta, ogunjọ oṣu kẹfa ọdun 2020.
N óo mú gbogbo ọ̀rọ̀ burúkú tí mo ti sọ nípa ilẹ̀ náà ṣẹ, ati gbogbo ohun tí a kọ sinu ìwé yìí, àní àwọn àsọtẹ́lẹ̀ tí Jeremaya sọ nípa gbogbo àwọn orílẹ̀-èdè.
Ajibade Babalade: Àwọn ọmọ Naijiria ṣèdárò gbajúgbajù agbábọ́ọ̀lù Super Eagles tó dolóògbè
Ẹlẹ́dẹ̀ nàá tó jẹ́ ọdun mẹ́jọ wà ní Derbyshire ní Ìlẹ̀ Gẹ̀ẹ́si.
kí o sì fi àsọtẹ́lẹ̀ bá a wí, pé OLUWA Ọlọrun ní, Mo lòdì sí ọ, ìwọ Gogu, olórí Meṣeki ati Tubali.
Tottenham ya aṣọ iyì mọ́ Manchester United lára nírọ̀lẹ́ ọ̀jọ́ ìsinmi Dákúdájí Chelsea bínú já òrùlé Stamford Bridge lé Crystal Palace lórí Agbẹjọ́rò fún Sotitobire yọ ọwọ́ nínú ìgbẹ́jọ́ rẹ̀ lónìí!
APC pe aarẹ Buhari ko ni da si eto idibo atundi, nipa didari ajo eleto idibo
Awọn oṣiṣẹ ajọ AIB sọ pe ni nkan bi aago mẹta ọsan ni wọn ri apoti naa.
Wọ́n bá ń bu ẹnu àtẹ́ lu ohun tí Paulu ń sọ; wọ́n ń sọ ìsọkúsọ sí wọn.
Nisinsinyii, kabiyesi, oluwa mi, jọ̀wọ́ fetí sí ẹ̀bẹ̀ mi, má dá mi pada sí ilé Jonatani akọ̀wé, kí n má baà kú sibẹ.
Ṣaaju nijọba Ipinlẹ Akwa sọ pe ohun ko ni yọnda papa iṣere ọhun nitori pe ile-iṣẹ to mojuto papa isẹre naa ti lọ fun isinmi opin ọdun.
O ni obi gbọdọ ma a mọ ohun ti ọmọ rẹ ba n ṣe ni gbogbo igba, nitori naa ni wọn gbọdọ pin ninu iya.
Bakan naa lọpọ eeyan loju opo Twitter n sọ pe o ti to asiko fun Emery lati fipo rẹ silẹ.
’ Mo dáhùn pé, ‘Èmi nìyí.
O wa fikun ọrọ rẹ pe, ijoba apapo n wa ona ti eto ọrọ aje orile ede yii
to n bọ, Bakan naa ni  eto idibo gomina,ile igbimo asoju-sofin ati ti ijoba ibile olu-ilu Abuja FCT  , yoo waye ni ọjọ keji osu kẹta di ọjọ kẹ́sán án    , osu kẹta.
Ni nnkan bii agogo meji abọ oru oni to jẹ agogo mẹjọ abọ alẹ lorilẹ-ede Amẹrika ni wọn bẹrẹ idibo naa.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Nollywood: Àwọn ǹkan pàtàkì tó yẹ kí o mọ̀ nípa Clarion Chukwura 5 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Oríṣun àwòrán, Clarion Chukwurah Àgbà ọ̀jẹ̀ òṣèré tíátà lọ́dún díẹ̀ sẹ́yìn Clarion Folasade Chuwkurah sọ̀rọ̀ nípa bi ó ṣe bẹ̀rẹ̀ eré tíáta ni ọmọ ọdún mẹ́ẹ̀dógún.
Ṣé àfọ́kù ìkòkò tí ẹnikẹ́ni kò kà kún ni Jehoiakini?
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Obalende Building Collapse: Gbogbo àwọn to há sọ́bẹ́ ilé tó wó la mọ̀ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Obalende Building Collapse: Gbogbo àwọn to há sọ́bẹ́ ilé tó wó la mọ̀ 13 Ọ̀wàrà 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 14 Ọ̀wàrà 2020 Igbakeji alaga ẹgbẹ awọn Lanlọọdu ni agbegbe Odo nibi ti ile alaja mẹta ti wo ni Obalende, Eko sọ fun BBC Yoruba pe bi mọlẹbi ni gbogbo awọn to n gbe ni Obalende.
Awọn ajinigbe ti gbe oṣiṣẹ ajọ ẹṣọ oju popo meji gbe ni ipinlẹ Oṣun.
Ọdún 1905 ni wọ́n tó ṣe irúfẹ́ rẹ̀ lédè Gẹ̀ẹ́sì.
Eeyan bi ẹgbẹrun un mẹtalelaadọfa ni ile iwosan naa fẹ ṣiṣẹ abẹ pipaarọ kindirin fun gẹgẹ bi iroyin ti wọn fi sita lori oju opo itakun agbaye wọn.
Awọn awo orin ti Wasiu Alabi Pasuma ti gbe jade Ọga Nla Ọmọ Butty Iyale Ọkan Mushini Ọtunba Fuji Ahọn Lẹgbon Ẹyin Olorukọ topọ Abẹgi Anu Ability Sabaka Night Bus Stop to Bus Stop So Far So Good Àìrí nǹkan ṣe ló ń fa ìjà èmi àti Sàheed Oṣupa- Pasuma Gbajugbaja olorin Fuji, Alhaji Wasiu Alabi ti ọpọ eeyan mọ si Pasuma ti ni ko si ohunkohun ti o lee mu ki oun gbe ode ere orin lọ si orilẹ-ede Saudi Arabia.
Gẹgẹ bi ohun ti ileeṣẹ ologun ofurufu sọ, igba ti Adejoh n wa ọkọ naa pada sẹyin lati ki Tolulope lo kọlu u, eyi to yọri si iku rẹ.
ti n kanlẹkun bayii, oriṣiiriṣii ọrọ, awon akanlo ede  ni awon eniyan yoo maa so jade lenu, lasiko
Mọ̀ síi nípa ìtàn ojúbọ̀ nàá Wàhálà bẹ́ sílẹ̀ l'Osogbo lẹ́yìn tí ọlọ́pàá lé afurasí Yahoo dé ojú ikú Lanlehin kéde ìparí gbogbo ètò láti darapọ̀ mọ́ ẹgbẹ́ òṣèlú APC Oyo Àwọn ọmọ Nàìíjíà gbarata lóríi fọ́nrán tí Tinubu fi síta lóríi dídìbò f'ún Obaseki ti Edo Ọmọkunrin kan, Tobiloba Jolaosho, ni awọn ọlọpaa ti mu nitori pe o ya fidio ibalopọ ninu igbo Osun Osogbo, to si tun fi fidio naa sori ayelujara.
Christmas 2018: Àkójọpọ̀ àwòrán ọdún Kérésìmesì lágbáyé
Joseph àti akọ̀wé rẹ̀, Oliver Cowdery ti kọ́ ẹ̀kọ́ lati inú ìtumọ̀ àwọn àwo Ìwé Ti Mọ́mọ́nì pé àwọn Ẹlérìí pàtàkì mẹ́ta ni a ó yàn (wo Ìwé Étérì 5:2–4; Ìwé Néfì 11:3; 27:12).
Eyi gbọdọ waye, paapa ni ipinlẹ Edo, nibi ti wahala ti waye lori idibo abẹnu wọn.
Eliṣa gbé ọwọ́ lé ọwọ́ ọba, 
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Oluwo woju Ọọni niwaju awọn lọba-lọba 3 Èrèlè 2018 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Itahunsira waye laarin Oluwo ti ilu Iwo, ati Ọọni ti Ile Ifẹ nibi ipade awọn lọba-lọba Ipade awọn ori ade lorilẹede Naijiria waye ni ilu Port-Harcourt lọjọ isẹgun ọsẹ to kọja fẹrẹẹ ri idiwọ pẹlu idojukọra to waye laarin oluwo ti Iwo, Ọba Abdulrasheed Adewale Akanbi ati olori ẹsọ Ọọni ti ile Ifẹ, Ọba Adeyẹye Ẹnitan Ogunwusi, Ọjaja keji.
Fayose ke s'ijọba lati kede dukia ti EFCC gba Iná sọ ni ọfísì Aregbesọla l'Osun Nàìjíríà gba orúkọ burúkú lórí ìgbẹ́ yiyá síta gbángba Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ina jo ọja binukonu lọjọta Iwadii kan n lọ lọwọ nigbana naa lori ẹsun jẹgudujẹrati wọn fi kan awọn alaṣẹ ajọ naa.
Ni bayi, iko ohun ti wa ni ipo mejileladota pelu ami egbeta-lemefaBakan naa, Naijiria sepo keji ninu idije CHAN  ti o waye lorile-ede Morocco.
Fún àpẹrẹ, wọn a ni Ìjẹ̀bú fẹ́ràn owó ju ẹmi lọ, Ondó njẹ Ajá, Ọ̀yọ́ ‘ayọ́mọọ́lẹ̀’’, Èkìtì ni agidi, Ìjẹ̀shà – Òṣómàáló’ àti bẹ́ ẹ̀ bẹ́ ẹ̀ lọ.
Kí ẹsẹ̀ kẹta jẹ́ òkúta jasiniti, ati òkúta agate, ati òkúta ametisti.
Ṣugbọn oun naa si ti fesi pada pe, ki gan-an ni wọn fẹ ki oun ṣe?
Ni Hẹrọdu bá kúrò ní Judia, ó lọ sí Kesaria, ó lọ gbé ibẹ̀ fún ìgbà díẹ̀.
Yoruba Films: Ẹ̀ẹ́ bẹ̀ mi kúrò láyé ni, mi ò lè kú
Ti eeyan ba gbọ itan igbe aye Isọla Oyenusi, yoo gba lootọ pe bi eeyan ba ni aya, ko sika, amọ to ba ri iku Gaa, yoo sọ ootọ nitori bo se gbajumọ bii isana ẹlẹẹta to lasiko aye rẹ fun iwa idigunjale, sibẹ iku ẹsin ati itiju lo ku.
Lẹyin ti ile ẹjọ kotẹmilọrun ti fi idi Gboyega Oyetọla mulẹ gẹgẹ bii gomina ipinlẹ Ọṣun, oludije fun ẹgbẹ oṣelu PDP, Sẹnetọ Ademọla Adeleke ti gba ile ẹjọ to ga julọ lorilẹede Naijiria lọ lati lee yi idajọ naa pada.
Iwa Ibajẹ Ileri: Lati ṣiṣẹ pẹlu ile aṣofin apapọ lati ṣe ofin eto 'olofofo' whistle blower Eto naa wa fun ṣiṣe koriya fun ẹnikẹni to ba mọ ohunkohun nipa iwa ti ko tọ lawujọ lati fito awọn alaṣẹ leti.
OLUWA o ti gbé ọwọ́ rẹ sókè láti jẹ àwọn ọ̀tá níyà, ṣugbọn wọn kò rí i.
Eto ẹkọ Gomina ipinlẹ Oṣun ni ijọba oun ti kọ yara ikawe mẹtadinlaadọsan an ni ijọba ibilẹ mejilelọgbọn kaakiri ipinlẹ naa.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ilé Ìgbìmọ̀ Aṣòfin gba àbá owó ìṣuná 2019 wọlé pẹ̀lú àfikún N10bn 30 Ìgbé 2019 Oríṣun àwòrán, Pulse Ilé Ìgbìmọ̀ Aṣofin Àgbà Naijiria ti gba àbá òfin ìṣuna owo ọdun 2019 wọlé, pẹlu afikun biliọnu mẹrindinlaadọrin ju iye ti Aarẹ Muhammadu Buhari gbe siwaju ile.
Nígbà tí àwọn ará Sidoni, àwọn ará Amaleki, ati àwọn ará Maoni ń pọn yín lójú; ẹ kígbe pè mí, mo sì gbà yín lọ́wọ́ wọn.
“Lẹ́yìn náà, mú Aaroni ati àwọn ọmọ rẹ̀ wá sí ẹnu ọ̀nà àgọ́ àjọ, kí o sì fi omi wẹ̀ wọ́n.
O wa kọju ọrọ rẹ si ijọba Naijiria pe, wọn ko lojuti pẹlu bi wọn ti ṣe doju ibọn kọ awọn oluwọde to n fehonu han.
January 13, 2018 April 16, 2018 Ìkọlù wáyé láàrín àwọn ọlọ́pàá àti àwọn ọmọ lẹyìn El-Zakzaky ti a mọ̀ sí IMN láti pè fún ìtúsílẹ̀ ọ̀gá wọ́n ní Unity Fountain Abuja, ẹni kan kú tí ọ̀pọ́ sì fara pa.
 O tẹ siwaju pe Aṣofin Rikiji, Agbẹnusọ Ile Igbimọ Aṣofin Ipinlẹ Zamfara ni wọn yan lati ṣoju ẹkun Iwọ-oorun Ariwa, nigba ti Aṣofin Kawuwa Damina, Agbẹnusọ Ile Igbimọ Aṣofin Ipinlẹ Bauchi ṣoju ẹkun Ila-oorun AriwaAṣofin Guni sọ pe wọn tun fẹnu ko ninu ipade apero naa lati rọ gbogbo awọn ẹka ijọba to yẹ lati tete ṣamulo ofin to fun awọn aṣofin ati ẹka eto idajọ ipinlẹ lanfani ominira ati ṣakoso iṣuna-owo wọn taarata.
Wọn ti sun igbẹjọ naa di ọjọ kọkandinlọgbọn, oṣu keje ọdun.
Daurama A ko le sọrọ nipa ilu Daura, lai mẹnuba Ayaba Daurama - oun ni Ọbabinrin to jẹ kẹyin ni Daura.
Bí ó bá kọ ọkọ rẹ̀, ó níláti dá wà ni, bí bẹ́ẹ̀ kọ́, kí ó bá ọkọ rẹ̀ rẹ́, kí ó pada sọ́dọ̀ rẹ̀.
Láti ìgbà tí ọdún eégú ti bẹ̀rẹ̀ ní ọjọ́kọkanlélọ́gbọ̀n, oṣù karùn-ún ọdún yìí ní gbogbo elégún ti ń ṣe ọdún wọ́n ni ààrín agbo ilé wọ́n.
Mò ń sọ èyí kí ojú kí ó lè tì yín ni.
Ní ojúmọ́ ọjọ́ ẹti yìí, iye ènìyàn to wà lọ́rí àkéte ààrùn Covid-19 jẹ́ ẹgbẹ̀rún mẹ́ta àti ẹgbẹ̀rin lé mẹ́ẹ̀dógún ènìyàn nígbà ti èèyan ẹgbẹ́run kanlélọ́gọ́san ti wà láàlàfíà.
Wọ́n jáde, wọ́n gbọ̀nà ilẹ̀ Kenaani.
 a kò le mọ èrò ọ ̀ kọrin yìí tí a bá gbọ ́ ìlà kìíní orin yìí láìgbọ ́ ìlà kejì .
èmi ninu wọn ati ìwọ ninu mi, kí wọ́n lè jẹ́ ọ̀kan ṣoṣo, kí ayé lè mọ̀ pé ìwọ ni ó rán mi níṣẹ́, ati pé o fẹ́ràn wọn gẹ́gẹ́ bí o ti fẹ́ràn mi.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Sri Lanka: Gauria ti di ololufẹ Roshan bẹ́ẹ̀ ọ̀tá ni wọ́n nígbà ogun abẹ́lẹ́ Sri Lanka By Suneth Perera BBC News 15 Òkùdu 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 21 Èbibi 2020 Àkọlé àwòrán, Roshan ti n ṣiṣẹ ni abule yii ki iṣẹ tó gbe Gauri lọ si abule yii.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Toma Unu: Ọmọbìnrin tó ń fi ẹsẹ̀ rẹ̀ ya àwọran nítori pe ó ni ìpènija ọpọlọ O ni aṣe igbẹyin nii dun oloku ada lọrọ oun yoo pada ja si nitori lẹyin o rẹyin ni oun to kọgbọn ninu ọrọ ti igbakeji aarẹ sọ.
Àwọn tí ó bá bẹ̀rù OLUWA ni OLUWA ń mú ní ọ̀rẹ́,a sì máa fi majẹmu rẹ̀ hàn wọ́n.
Ibẹ̀ ni àwọn ará Jẹriko ti bẹ̀rẹ̀ iṣẹ́.
ise pupo fun awon omo orile ede Naijiria.
Wayi o, Ijọba ipinlẹ Ọyọ ti ṣe alaye wipe, eti ikun ti gbaju-gbaja akọrin juju, Yinka Ayefẹlẹ kọ si aṣe ajọ to n risi aato ati idagbasoke ilu, lo mu ki ijọba wo apa kan ile iṣẹ redio rẹ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù PENGASSAN Strike: Bí ìjọba bá dá wà lohùn lórí IPPIS láàrin wákàtí mẹ́rìnlélógún, a o so ìyanṣẹ́lódì rọ̀ 9 Bélú 2020 Oríṣun àwòrán, Getty Images Iyanṣẹlodi ti awọn oṣiṣẹ agba to n ṣiṣẹ lẹka epo rọbi ni Naijiria, PENGASSAN, seleri lati gunle lọjọ Aje.
"Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Fulani Ilorin l'ọkọ mi' Oga àgbà àwọn agbófinró ní Naijiria, Mohammed Adamu ti pàṣẹ iṣẹ́ àkànṣe ""Operation Puff Adder"" ní Guusu Naijiria."
Sonko ni ọpọ eeyan mọ bii ẹni to n gbe igbe aye olowo nla nipa wiwọ asọ ati goolu olowo iyebiye amọ gomina tẹlẹ naa ti sẹ lori awọn ẹsun ti wọn fi kan.
Nigba toun naa n sọ ero rẹ lori ofin yii, ajọ to n dena iwa kotọ ni Naijiria, SERAP ni abala ogoji ninu ofin naa lo n tako ẹtọ ọmọniyan nipa ominira ibakẹgbẹpọ.
Ọjọgbọn Fiwapẹ to ṣe ikede naa ni eto idibo ọhun ri bi oun ṣe kaa fun ẹgbẹ osẹlu kọọkan àti oludije wọn.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Adeleke fọhùn, 'èmi ni gómìnà tí wọ́n dìbò yàn' Ṣugbọn ile ẹjọ kotẹmilọrun yii ẹjọ naa danu, ki Adeleke to gbori le ile ẹjọ agba patapata ni Naijiria.
Alaalẹ ọjọ Aiku lọsọọsẹ ni wọn yoo si maa yọ ẹni kan kuro ninu ile ẹlẹgbọn agba naa.
Ọ̀rẹ́ Akin Olófìn-íntótó, ọmọ Olúṣínà ni.
AfCFTA: Awọn onimọ sọrọ lori ohun ti jijawọ Naijiria lee fa
53712017Ìwà Bashorun Gaa ni Obaseki hù ní ipínlẹ̀ Edo -Tinubu Wo ohun tí Adájọ́ ṣe sí àṣùwọ̀n ìfowópamọ́sí Wòlíì Sotitobire Ìtàn ayé Shina Rambo, adigunjale tó fi oyún 27 gún ọṣẹ Wo àwọn àìsàn ti ìwọ́ ọmọ tuntun le wòsàn Afárá Third mainland gba ẹ̀gbọ́n Àwọn olè ń ṣọṣẹ nínú súnkẹrẹ-fàkẹrẹ ọkọ̀ tó ń wáyé nítorí afárá 3rd Mainland tí ìjọba tì Oluwatoyin gba awọn Obi ati alagbatọ nimọran lati kọ awọn ọmọ wọn ni ede ati aṣa Yoruba lẹyin to ṣafihan awọn oyinbo to n sọ Yoruba lẹnu nibẹ.
Ìpínlẹ̀ Ogun, Eko ti gbáradì fún ẹ̀kún omi yalé O ni ki ile ẹjọ fagile ibo naa, ni eyi ti ajọ eleto idibo nilẹ yii INEC ti kede ọmọ ẹgbẹ oselu APC gẹgẹ bi olubori.
Mo ti gbà wọ́n dípò gbogbo àkọ́bí àwọn ọmọ Israẹli, wọ́n sì di tèmi patapata.
Tesiwaju si, Iran wa ni ipo mẹ́rìndínlógójì lagbaye, bee si ni, pipegede fun idije agbaye todun yii, ni yoo di igba karun un bayii ti won yoo kopa ninu idije boolu agbaye.
4 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Nkechi Blessing: Gbajúgbajà òṣèré ní ó sàn fún òun láì tíì lọ́kọ báyìí ju kí òun lọ́kọ láì láyọ lọ11 Ọ̀wàrà 2020 Nkechi Blessing: Ọ̀rọ̀ ìfẹ́ wa dàbí ti Romeo àti Juliet9 Sẹ́rẹ́ 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 3 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 5 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
re  fi ibinu jade kuro nile igbimo
Oríṣun àwòrán, Olawale Abolade Alaga ajọ naa ni ipinlẹ Ondo, Rufus Akeju ni iwadii ti bẹrẹ lati mọ ohun to ṣokunfa ina ọhun ni eyi ti wọn yoo si gbe si ojutaye bi o ṣe yẹ.
O ṣalaye pe, ọpọ igba ni isẹ Oluwa ma n gba gbogbo akoko oun, debi i pe oun kii ri aaye wa pẹlu rẹ.
Bi eeyan ba mu Ethanol, koda ko jẹ diẹ lo mu, o le ṣokunfa ki oju onitọun fọ, ki ẹdọ rẹ bajẹ tabi ki ẹni naa ku.
 wọ ́ n fi ojú èdá èdè pín wọn sí swuthern azerbaijani ) àti northern azerbaijani tí mílíọ ̀ nù méje ènìyàn ń sọ .
Eyi kiiṣe iyalẹnu, nitori anfaani wa fun ọpọlọpọ eniyan lati fi erongba wọn han bẹ ẹ ninu ẹgbẹ oṣelu.
O tun mẹnu ba bi ibaṣepọ kikun to wa laarin awọn ẹka mẹtẹẹta ni ipinlẹ Eko lati ori saa ijọba Aṣiwaju Bọla Ahmed Tinubu gẹgẹ bi gomina titi de asiko Gomina to wa lori aleefa bayii ṣe so eso rere.
Nnkan bii ọsẹ kan sẹyin ni awọn janduku agbebọn kan dede ya bo ileewe GSS to wa ni Kankara, ni ipinlẹ Katsina, ti wọn si ji awọn ọmọ naa gbe ki wọn to tu wọn silẹ lọjọbọ.
Lẹ́yìn náà, Samuẹli wí fún àwọn ọmọ Israẹli pé, “Mo ti ṣe ohun tí ẹ ní kí n ṣe.
Jawahir Roble: Hijab tí mò n lò kọ́kọ́ jẹ́ ìyàlẹ́nu fún àwọn agbábọ́ọ̀lù mi
Àyípadà tó dé bá ìpínlẹ̀ yìí ò ṣe é fọwọ́ rọ́ sẹ́yìn rárá.
Nítorí pé àwọn agbéraga dìde sí mi,àwọn ìkà, aláìláàánú sì ń lépa ẹ̀mí mi;wọn kò bìkítà fún Ọlọrun.
Èyí tí ó yà mi lẹ́nu jùlọ ni pé ṣe ni gbogbo ìlẹ̀kùn tí ó wà ní ojú ọ̀nà bẹ̀rẹ̀ sí ṣí lọ bí ó ti ń kọjá láìjẹ́ pé ó fi kọ́kọ́rọ́ sí wọn, ṣùgbọ́n bí òun tí ń lọ bẹ́ẹ̀ náà ni èmi náà ń tẹ̀lé e lọ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù #JusticeFor Chima: Àgbáríjọ àwọn ajàfẹ́tọ̀ọ́ pè fún ìdádujro Kọmisọna ọlọpàá 17 Èrèlè 2020 Àkọlé àwòrán, Iku Mọkaliki: Agbarijọ awọn aja fẹtọ pe fún ìdádujro Kọmisọna ọlọpàá Agbárijọ ẹgbẹ́ awọn ajafẹtọ ọmọniyan ti ke si ọgà àgbà ajọ ọlọpàá, Muhammed Adamu láti dá kọmisọna ọlọpàá nipinlẹ Rivers, Mustapha Dandaura nítori ikú mọkaliiki, Ikwunado Chima to kú si atimọle ọlọpàá lẹ́yin ti wọ́n mu òun ati àwọn ọ̀rẹ́ rẹ̀ mẹ́rin.
Ẹ kí àwọn ará ilé Arisitobulu.
Abubakar ti ki oludije fun ipo gomina ni ipinle Bauchi labe asia egbe oselu Peoples
Nígbà tí ó di ọjọ́ keje wọ́n bẹ̀rẹ̀ sí jagun.
Bẹẹ ni oun si gba esi ayẹwo naa laarin wakati mẹfa pereninu papakọ ofurufu ti oun ti se ayẹwo ọhun.
Ọba Adeyemi ni awọn dukia ẹya Yoruba nikan ni wọn bajẹ lasiko ifẹhọnuhan to waye ni ipinlẹ Eko, eleyii ti o le jasi ija ẹlẹyamẹya.
Oríṣun àwòrán, Sanjana Rishi Ọkan ninu awọn alamojuto iwe iroyin igbeyawo ni ile India, Nupur Metha Puri salaye pe oun ko ti i ri iru imura bẹẹ ri lati igba ti oun ti n se iru iṣẹ naa, O ni aṣọ India ati awọn ẹsọ ibilẹ India ti wọn gba lọwọ iya wọn tabi iya-iya/ Iya baba wọn ni wọn maa n lo.
Lẹyin naa ni awọn ọdọ ilu dana sun ile ijọsin naa.
wa dun bi won se wa sibi ipade apero naa.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù NCAA: A fún àwọn adarí ní ọ̀sẹ̀ méjì si láti dá wọn lóhùn 31 Ọ̀pẹ̀̀ 2018 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 2 Sẹ́rẹ́ 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Murtala Muhammed international Airport 2 Àpapọ̀ àwọn òṣìṣẹ́ ẹka irina ofurufu iyẹn NUATE ati ATSSSAN ti fagile iyansẹlodi ti wọn sọ wi pe awọn yoo gunle ni Ọjọ Keji, Osu Kini, ọdun 2019.
Mo parí iṣẹ́ àṣepatì 239, iṣẹ́ 236 míì ń lọ lọ́wọ́- Seyi Makinde Kàyééfì BBC News Yorùbá gbé òtítọ́ òògun owó yẹ̀wò Nǹkan oṣù obìnrin le jáde ní imú tàbí ìdodo yàtọ̀ sí ojú ara - Dókítà Kòkòrò coronavirus sì wà lára mi títí mo fi kúrò ní ibùdó ìtójú àwọn alárùn covid-19 l'Eko- Motosinoluwa Afolaranmi Ìjà Awolowo, Akintola àti ogun 'Wẹtiẹ', ẹ̀kọ́ wo ló kọ́ wa?
Ní ọjọ́ náà, ọkàn àwọn ọmọ ogun Moabu yóo dàbí ọkàn obinrin tí ó ń rọbí,
Gege bi atejade kan lati ile-ise ti o n ri si oro ile-okere lorile-ede America, erongba yii ni lati dena lati maa se je ki omo orile-ede America ni ohunkohun n se pelu awon omo-ogun olote naa.
"ṣugbọn Latin o le da a ṣe o, awa ni igi lẹyin ọgba rẹ""."
O ni ọrọ to sọ fun oun ni ọjọ kini ọdun 2021 ni pe ki awọn maa gba adura.
"Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Eegunjobi Omotanbaje Ajobiewe- Èébú ní wọ́n kọ́kọ́ ń bù mí nígbà tí mo bẹ̀rẹ̀ ẹ̀ṣà pípé ní O ni ""o se koko lati jẹ ki ijọba o mọ pe ileesẹ ologun Naijiria ti rọpo ọlọpaa SARS, ti awọn eeyan n polongo tako""."
Awọn ololufẹ Baba Suwe si lo n ki ku oriire loju opo rẹ naa, bẹẹ ni wọn n gbadura pe ogun to sẹ fun-un, ko ni gberi mọ laelae.
Sudan: Ilu yii jẹ ibi ti o ni agbegbe awọn eranko ti o si ni ojuko ibi igbafẹ ṣugbọn ti iwe irinna gbigba rẹ jẹ lati ẹnu ọna abawọle.
Nigba ti o n ṣalaye fun ikọ akọroyin Radio 1 Newbeat, ni tootọ owo naa kere si bi o ti yẹ, pe o yẹ ki o wọn ju bẹẹ lọ.
Mo kan saara si pe o jade lati du ipo aarẹ, mo si mọ pe pẹlu jijade rẹ ati awọn oluidije yoku to jẹ ọdọ, ko si ẹni ti yoo sọ mọ lẹyin idibo pe, ko si oludije to pegede lasiko ibo naa.
A Ajayi fọ́wọsi fi kún un pé, ìbáṣepọ̀ tí kò tọ́ tó wà láàrín àwọn olórí òṣìṣẹ́ àti gómìnà àná ní kò jẹ́ kí àwọn lè rí ẹ̀tọ́ àwọn òṣìṣẹ́ gbà nínú ìṣèjọba.
Lati igba naa si ni ara ko rọ okun, ti ko si rọ adiẹ ninu ẹgbẹ oselu APC.
#BBCNigeria2019 Ni kete ti wọn pari idibo abẹle ni wọn ko fun un ni tikẹẹti 'a yan ọ gẹgẹ bi oludije ẹgbẹ', sugbọn o bọ lọwọ rẹ si ọwọ oludije miran.
Àkọlé àwòrán, ASUU: A ó kópa nínú ètò ìdìbò 2019 A ti ní ìpinu pé ètò ìdìbò náà kò gbọdọ̀ ní kọ́nu-n-kọhọ nítori ìyanṣẹ́lodì àwọn oṣìṣẹ́ Fasiti.
8 8805 Orilẹede Malta 164 37.
Lóòótọ́, “Ohun tí a bá fẹ́ ni a lè ṣe,” bí àwọn kan ti ń wí.
Adunni Oluwole, akọni obìnrin tó tako òmìnira Nàìjíríà, ó ní òyìnbó kò gbọ́dọ̀ lọ Ìròyìn ayọ̀!
èyí tí ó dàgbà jù nínú àwọn méjèéjì ni ọmọkùnrin, èyí èkejì jẹ́ ọmọbìnrin.
Eleyii jade ninu atejade kan ti akowe egbe naa, Emma Ibediro gbe sita.
Àwọn oriṣa tí ẹ yọ́ fadaka bò, ati àwọn ère tí ẹ yọ́ wúrà bò yóo di nǹkan èérí lójú yín.
O kò gbọdọ̀ ṣe ojuṣaaju sí talaka lórí ẹjọ́ rẹ̀.
Asa Ọba Ṣẹgun Àwọn Ará Sudani.
Jokebedi sì bí Aaroni ati Mose fún un.
Bakan naa ni aarẹ fi kun pe ìjọba yoo fi alaalẹ sita lori igbesẹ ti awon ile iṣẹ yoo gbe ni asiko yii.
" Eyi ni atẹjade agbẹnusọ igbakeji aarẹ Osinbajo iyẹn Ọgbẹni Laolu Akande loju opo Twitter rẹ.
”Ọba bá sọ fún gbogbo àwọn iranṣẹ rẹ̀ tí ó wà lọ́dọ̀ rẹ̀ pé kí wọ́n jáde, gbogbo wọn sì jáde.
Balogun Buratai  fi mule pe,“Awon omo ogun Naijiria n se igbaradi lorisirisi lati mu igberu ba oni kaluku ni gbogbo ona, ni ona lati wa ni ibamu pelu ofin ati ilana pataki ile-ise naa lati daabo boa won ara ilu ati ohun ini won, gbigbogun ti awon omo ogun olote, rukerudo laarin eya abbl.
Lọwọ lọwọ, awọn eniyan ti wa nikalẹ ti awọn onilu si n fi ilu ki awọn eeyan kuabọ bi wọn ṣe n wọle si gbagede.
O kere tan eniyan mẹ́tàlélógójì  ti padanu emi won sinu ijamba ina nile itaja kan ti o fi agbegbe Siberian ni Kemerovo, Russia se ibugbe.
Ẹnikẹ́ni kò gbọdọ̀ sọkún láìjẹ́ pé ó tó àkókò ẹkún ní ìlú àwọn Aláṣejù.
fọ́n owó ká fáwọn èrò lẹ́yìn tó pariwo 'Merry Christmas' Poopu tuntun yoo wọ aṣọ oye rẹ.
Ilé Aṣòfin yóò pe Godswill Akpabio l'ẹ́jọ́ fún ìbanilórúkọ jẹ́ Kí ló pa Bobrisky àti Olorì Aláàfin Oyo pọ̀?
Àṣírí náà ni pé, Kristi tí ó ń gbé inú yín ni ìrètí ògo.
Aarẹ Muhammadu Buhari si tun tu igbimọ oludari ẹgbẹ naa ka, nibi ipade pajawiri naa to waye nile Aarẹ.
Lasiko ajọdun ti ọdun yii to n lọ lọwọ ni ilu Ọyọ bayii, Ọtunẹfa ati Iya Naso lo gba awọn arugba mejeeji lalejo laafin Iku baba yeye.
Ni ọdun 1972 ni Baba Suwe di osere tiata sugbọn sinima Ọbalende lo gbe orukọ rẹ jade.
Nigba ti BBC Yoruba bi iya Kaosara leere pe se lootọ lo ti n lọ sun sile ọkọ rẹ gẹgẹ bi ọkọ rẹ ti sọ fun wa, o dahun pe: Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Risikat Azeez: Ìyá àti bàbá ọmọ olójú búlù tí parí ìjà- wọ́n fẹ́ tún yìgì so Mo fi Ọlọrun Ọba bura, ko si ohun to jọọ, ile wa ni mo wa, n ko si lọ sile ọdọ rẹ"" Lori ipalẹmọ lati tun yigi so, Risikat ni ọba Ilọrin ti ran awọn eeyan wa lati ba awọn pari ija, to si ni wọn ti n pari rẹ lọwọ."
Jẹ́ kí wọn máa yin OLUWA nítorí ìfẹ́ rẹ̀ tí kì í yẹ̀,àní nítorí àwọn iṣẹ́ ìyanu tí ó ṣe fún eniyan.
Àmọ́ ẹ ríi pé ẹ dáàbò bo ẹ̀mí yín - Ọ̀gá àgbà ọlọ́pàá Wumi Toriọla ti sọ̀rọ̀ sóke láti fi idí rẹ̀ múlẹ̀ pé òun àti ọ̀rẹ́ òun níjà Ojúmọ́ kan, ìdàmú kan ni mo fi lo ogún ọdún àkọ́kọ́ lórí oyè - Alaafin O fi kun pe igbaradi ati idanilẹkọọ fun awọn eeyan na yoo waye fun ọsẹ meji gbako.
Wo àlàyé bí Inec yóò se náwó nínú ìbò 2019 Yoruba ni ti a ba ta, aa tọ ni, nitori ti a ba pa, ti a ko tọ, o lee di ẹran onidin.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù EFCC: Ẹlẹ́rìí ṣàlàyé bí wọ́n ti ṣé gbé N1.
Bí wọ́n bá ti ń sọkún,wọn óo máa kọ orin arò nípa rẹ báyìí pé:‘Ìlú wo ló tíì parun bíi Tire, láàrin òkun?
Awọn kan tilẹ n ṣe atupalẹ iru ounjẹ ti ẹnikan le jẹ loṣu.
 serbia ni bode pelu orile-ede 8 , hungary ni ariwa ; romania , bulgaria ni ilaorun ; orile-ede makedonia ni guusu ; ati kroatia , bosnia ati herzegovina , montenegro ni iwoorun ; bode re pelu albania je jijiyansi .
Jeremaya bá ń gbé gbọ̀ngàn àwọn tí wọn ń ṣọ́ ààfin títí di ọjọ́ tí ogun kó Jerusalẹmu.
5 Nítorínáà, bí ìwọ bá béèrè ní ọwọ́ mi, ìwọ yíò rí gbà; bí ìwọ bá kan ìlẹ̀kùn, a ó ṣí i fún ọ.
alufaa yóo ṣírò iye tí ilẹ̀ náà bá tó títí di ọdún Jubili, ẹni náà yóo sì san iye rẹ̀ ní ọjọ́ náà bí ohun ìyàsọ́tọ̀ fún OLUWA.
Ọpọlọpọ ọmọ lo n sagbe, ti wọn si n sa ilẹ jẹ lati le fi tọ ara wọn nitori ọrọ aje wọn to dẹnu kọlẹ loriẹede Venezuela naa.
Ní aiyé àtijọ́ ọkùnrin kan wà tí orúkọ rè njẹ́ Robin Hood.
Alaga ajo to n ri si ọrọ ilẹ
Gbogbo orílẹ̀-èdè yóo sì parapọ̀ láti bá a jà.
Ìdí rẹ̀ nìyí tí Ọlọrun fi ka igbagbọ rẹ̀ sí iṣẹ́ rere fún un.
Lọ, yí adágùn omi nì padà sí ilú, yí ẹeja ibẹ̀ padà sí ènìyàn, lẹ́hìn èyí n óò jáde wá gẹ́gẹ́ bí ọba lórí ìlú náà, ìwọ ni yóò jẹ́ olóró àwọn ayaba, ìwọ yóó máa dé adé owó ìwọ yóó sì máa wọ ẹ̀wù ìlẹ̀kẹ̀ bẹ́ẹ̀ ni ìránṣẹ́ kùnrin àti ìráńṣẹ́bìnrin yóó maa wọlé tí wọn ó sì máa jáde níwájú rẹ.
Ẹ mú àwọn wọ̀nyí, ẹ̀yin ọlọ́pàá mi, ẹ kó wọnnlọ sí àgbàlá mi.
Ajọ NCDC naa fi ikede naa si oju opo ikansiraẹni Twitter wọn, ti apapọ awọn eniyan to ni arun naa ti wa da 10162.
"Tí a fiṣọwọ́ ní 4:434:43 Gomina Sanwo-Olu sún ọjọ́ ""ṣiṣẹ́ láti ilé"" síwájú fún àwọn òṣìṣẹ́ ìjọba Ọpọlọpọ ọkọ ero nipinlẹ Eko lo n kun akunfaya, lai bọ̀wọ̀ fun ilana idaabobo lọwọ Coronavirus."
Ajọ Bill ati Melinda Gates ti sọ fun BBC pe awọn ko ṣe ẹrọ kankan lati fi sinu agọ ara eeyan lati le mọ ibikibi ti wọn ba wa ni gbogbo igba.
Ni bayii, aare Buhari yoo teko leti lo si gbagede Monguno ibi ti ayeye ohun ti n waye.
Iroyin to n tẹ wa lọwọ lati ilẹ Gẹẹsi lo n sọ pe akọnimọọgba Chelsea ati Manchester United nifẹ si ko gba iṣẹ akọnimọọgba ẹgbẹ agbabọọlu Arsenal.
 Ọ ̀ pọ ̀ lọpọ ̀ àwon ìyá ìlù ló ma ń sọ ̀ rọ ̀ bí ènìyàn .
Ẹfunsetan Aniwura, obìnrin tó ju ọkùnrin lọ Ọ̀rọ̀ǹpọ̀tọ̀niyùn, Aláàfin obìnrin àkọ́kọ́ rèé, tó ní nǹkan ọkùnrin Taiwo Akinkunmi, ọmọ Ibadan tó ya àsìá Nàíjíríà Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Kayefi BBC Yorùba: Bàbá ọmọ, Mọ́ṣúárì, Ọlọ́pàá kẹ́jọ́ rò nípa òkú ọmọ tó pòórá Musa fi aidunnu rẹ han si aṣa jíjẹ awọn agbabọọlu ni ajẹmọnu, eyi to wọ pọ laarin awọn ẹgbẹ agbabọọlu ilẹ Afrika, to si rọ awọn alaṣẹ ajọ to n mojuto bọọlu gbigba lati jawọ ninu iwa naa.
"Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Omolola Arohunmolase Welder: Mo ti fí iṣẹ́ 'Welder' gbayì láwùjọ, tó mo fi tọ́ ọmọ yanjú ""Iyẹn ti wọn ko ba ṣe ojusaaju oṣelu nitori o ṣe ni laanu pe ọpọ nkan ni a n fi ọrọ oṣelu yanju ni Naijiria."
Ọlọkan-ojọkan alejọ pataki ni wọn kalẹ si ipinlẹ Kano nitori igbeyawo naa.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù EFCC ti ri mílíọ̀nù 65.
A kò le ṣe kí a má kí ara wa ní orísirísi ọ̀nà bóyá ọ̀rẹ́ sí ọ̀rẹ́, pẹ̀lú orísirísi ẹwà èdè.
Femi Hamzat wa parọwa si awọn ọmọ ẹgbẹ APC lati fọwọsowọpọ, ki itẹsiwaju le ba ẹgbẹ naa.
Oríṣun àwòrán, Others Nigba to fẹ Lamidi Olayiwola Adeyemi lo di Abibat Nihinlola Adeyemi.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Nigeria kidnap: Àwọn jàndùkú jí agbábọ́ọ̀lù Nàìjíríà méjì gbé lópòpónà Owo sí Benin 23 Ẹrẹ̀nà 2020 Oríṣun àwòrán, Eniymba FC Awọn janduku ti ji agbabọọlu ọmọ Naijiria meji, Dayo Ojo ati Benjamin Iluyomade gbe.
"Báyìí ni 50kobo ṣe dá ìfẹ̀hónú ""Ali Must go"" sílẹ̀ tó mú ọ̀pọ̀ ẹ̀mí akẹ́kọ̀ọ́ lọ Ẹ̀kọ́ ọ̀fẹ́ déé fáwọn ọmọ Ọlọ́pàá tó kú lásìkò EndSARS, Gómìnà ìpìnlẹ̀ Eko kéde Ṣé o mọ̀ pé o leè forúkọ̀ iléeṣẹ́ rẹ̀ sílẹ̀ lọ́fẹ̀ẹ́?"
Ọdun mẹta lo fi lọ si ẹwọn lẹyin to jẹwọ pe lootọ ni oun gbe oogun oloro naa.
19 Àti pé nítorí ìdí èyí gãn ni a ṣe pa àwọn àwo wọ̀nyí mọ́, èyí tí ó ní àwọn àkọsílẹ̀ wọ̀nyí nínú—kí àwọn ìlérí Olúwa baà lè wá sí ìmúṣẹ, èyí tí ó ṣe fún àwọn ènìyàn rẹ̀.
Hassan Stan Labo (Reitired Colonel) POINTS: No better time to start than now.
Mekoh so pe, bi ijoba ba le fowosowopo pelu awon agbe, eyi ti yoo tun mu ayipada baa won agbe alada kekeke, eleyi yoo mu baa won agbe naa.
" Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Sextuplet: Àdúrà Ìbùkún ló kú lẹ́yìn ọmọ mẹ́fà yìí- Ifeoma Thelma àti Onyemaechi Chiaka Ṣaaju ni Ọọni Ifẹ ti kọkọ sọrọ pé.
Bi atupalẹ afikun awọn to kun iye arun coronavirus ni Naijiria se lọ niyi Eko-Ọgọsan, Abuja_mẹrindinlaadọrun, Kaduna mẹrindinlọgọta, Ondo-mẹtadinlogoji- Kwara- marundinlogoji, Ogun-19, Rivers-19, Kano-17, Ebonyi-16, Enugu-16, Delta-7, Bayelsa-4, Bauchi-3, Abia- 1 Ènìyàn 653 míràn tún kún iye àwọn tó ní COVID-19 ní Nàìjíríà Eyitayọ Jegede (PDP) ló máa gbéná wojú Rotimi Akeredolu (APC) nínú ètò ìdìbò Ondo tó ń bọ̀!
Gege bi o se jabo o ni isele aburu naa bere lojoBo(Thursday) ti
Ọjọ karundinlọgbọn oṣu kọkanla ọdun ni wọn maa n bẹrẹ awẹ yii titi di ọjọ kẹfa oṣu kini ti o jẹ ọjọ aisun keresimesi tiwọn.
O salaye pe, iwe mimo, ti o je iwe itonisona,  gbogbo oro Olorun  ti a ba se amulo re je ayo ati alaafia, o fi kun oro re pe, ko si ona abayo si igboran.
Farida Waziri (2008 - 2011): Wọn ni o yọnda awọn gomina tẹlẹ ti ajọ naa fi ẹsun ibajẹ kan.
Akẹgbẹ rẹ to jẹ olorin takasufe Korede Bello naa wa lara awọn ti ileeṣẹ ọlọpaa yan gẹgẹ bii awokọṣẹ ati aṣoju laarin awọn ọdọ.
Àwọn tí ń rìn ní ọ̀nà òtítọ́, wọn óo wà ní alaafia,wọn óo máa sinmi lórí ibùsùn wọn.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Dele Momodu : Lẹ́yìn Buhari àti Atiku, èrò ọjà làwọn olùdíje yóòkù ní ìdìbò 2019 Iroyin to n tẹ wa lọwọ ni wi pe awọn ọmọ ẹgbẹ ẹlẹsin musulumi Shiite ti wọn n pe ni Islamic Movement of Nigeria atawọn ọmọ ọlọpaa Naijiria wọya ija ni olu ilu orilẹ-ede yii, Abuja.
Fatoyinbo ni, irọ pọnbele ni ẹsun Busola Dakolo, ati wi pe yatọ si iṣẹ oun gẹgẹ bii pasitọ, oun ko ba arabinrin naa ni nkankan pọ ni ikọkọ oun ko si fi ipa ba obinrin kankan lo pọ ri.
Ṣugbọn awọn akọṣẹmọṣẹ ni ko ṣeeṣe ki Apple kọkọ ṣe itakun agbaye sita afi ki wọn duro ki itakun naa kọkọ farahan ki wọn to fi lọọlẹ.
Olókìkí ènìyàn ni ọkùunrin náà, nítorí ìgbà tí ó kọ́ bẹ̀rẹ̀ ọdẹ-ṣíṣe ni ó ti ṣe nǹkan kan tí ó ya gbogbo ènìyàn lẹ́nu ní ìlú wa.
hu lasiko eto idibo, , o wa dupe lowo awon agbofinro fun iwa akin ti won fihan
Isaac Haastrup ni ẹsẹ ko duro lati igba ti iroyin iku Baba ti lu jade.
Toyin Abraham: Ó dára ká ní àròjinlẹ̀ pé ayé ni Ọlọ́run fi ju ẹ̀dá lọ
Wo ohun tó yẹ kóo mọ̀ nípa Notre-Dame tó jóná ‘Ọgbọ́n tí mo dá rèé kí àwọn bàbá lè pọn ọmọ sẹ́yìn’ Ǹjẹ́ o mọ̀ pé o le gba owó lára 'ATM' láì lo káàdì?
agba fun ile –ise eto idajo lorile ede Naijiria,Dayo Akpata lo soro yii niluu Abuja,
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ààyè sí sílẹ̀ fún ọmọ Nàíjíríà láti di ológun nílẹ̀ Gẹẹsì Ìyanṣẹ́lódì ẹgbẹ́ òṣìṣẹ́ kò le fa ọ̀wọ́n epo - NNPC Kí lo fẹ́ mọ̀ nípa ‘Ajala Travels’?
Gẹ́gẹ́ bí ọ̀mọ̀lé tí ó mòye, mo fi ìpìlẹ̀ lélẹ̀ nípa oore-ọ̀fẹ́ tí Ọlọrun fi fún mi, ẹlòmíràn wá ń kọ́lé lé e lórí.
Àyè kò sí fún mi láti sọ nípa Gideoni, Baraki, Samsoni, Jẹfuta, Dafidi, Samuẹli ati àwọn wolii.
Ọdun 2005 ni Tyson ja kẹyin nigba ti Kevin McBride lu u lalubami.
A ti gbiyanju lati pe wọn titi lori ẹrọ alagbeka ṣugbọn pabo lo n ja si""."
Àwọn ọmọ Asigadi jẹ́ ẹgbaa ó lé ọọdunrun ati mejilelogun (2,322).
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Buhari buwọ́lu owó oṣù tuntun fáwọn ọlọ́pàá Wo ìdí tí Boko Haram fi ń pa ọmọogun Nàìjíríà Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Osun 2018: Àwọn olùdíje ADC, ADP, APC, SDP bá aráàlú sọ̀rọ̀ lórí èròǹgbà wọn Ohun mẹwaa nipa Alhaji Isiaka Adegboyega Oyetola to dije dupo labẹ ẹgbẹ oselu APC Isiaka Adegboyega ti wọn bi ni ilu Iragbiji, ni ijọba ibilẹ Boripe ni ipinlẹ Ọsun lo si ile iwe girama ti Ifeoluwa Grammar School ni ilu Osogbo ni ọdun 1972.
Lọjọ ti ọmọ mi obinrin n ṣegbeyawo l'ọdun 2006, ni Philippe deede pe mi pe ara oun ko ya, oun ko si ni le wa fun apejẹ lẹyin ayẹyẹ igbeyawo naa.
Kò séwu nínú ìdìbò tó ń bọ̀ l'Ondo àfi gìrì àparò- Akeredolu Àwọn ǹkan tí ó yẹ kí o mọ̀ nípa 'Sharia Law' ní Nàìjíríà Ohun gbogbo tí mò ń rí ní ààfin tẹ́ mi lọ́rùn, èmí ní mo ní ayé mi- Olori Aanu O ni gidigba loun duro ati wi pe mimi kan lo le mi oun.
Oyo 2019 Budget: Ìjọba Ọyọ gé ₦282bn owó ìsúná 2019 sí ₦181bn
Àwọn ọmọ Israẹli ti búra nígbà tí wọ́n wà ní Misipa pé, “Ẹnikẹ́ni ninu wa kò ní fi ọmọ rẹ̀ fún ará Bẹnjamini.
Ohun tí ó ṣe kókó ni igbagbọ tí ó ń ṣiṣẹ́ nípa ìfẹ́.
Nearaya bí ọmọ mẹta: Elioenai, Hisikaya ati Asirikamu.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìrìnàjò China: Nnkan márùn ún tó ṣẹlẹ nigba tí Buhari ko sì nílé 8 Owewe 2018 Oríṣun àwòrán, @Bashir Ahmad Àkọlé àwòrán, Lẹyin ti wọn gba fọọmu fun Aarẹ Buhari ni fọọmu gbigba fun awọn to n du ipo ba di asa Lati igba iwasẹ ni Baale ile ti maa n dari gbogbo eto ile.
Baba wo ninu yín ni ó jẹ́ fún ọmọ rẹ̀ ní ejò, nígbà tí ọmọ bá bèèrè ẹja?
 wọ ́ n tún ń sọ ọ ́ ní turkish armenia .
ẹ̀yin ẹranko ìgbẹ́ ati ẹran ọ̀sìn,ẹ̀yin ẹ̀dá tí ń fàyà fà ati ẹyẹ tí ń fò.
''O ṣeni laanu wi pe Wike to jẹ agbẹjọro naa lo tun wa tako ofin to fun awọn eniyan laaye lati fi ẹhọnu wọn han ni Naijiria.
Ó ṣe ìwọ̀nyí fún ọ̀pọ̀lọpọ̀ ìgbà láìjẹ́ pé mo mọ nǹkankan.
Gege bi iwe isuna eto idibo gbo-gbo-gbo o naa, ile-ise to n gba awon ajo alaabo nimoran National Security Adviser (NSA), yoo gba “bilionu mesan an le nirinwo naira (=N=9,481,500,000.
”Akowe agba fun  egbe osise lorile
Ó sọ gbogbo ohun tí ó ṣẹlẹ̀ sí i fún Sereṣi, iyawo rẹ̀, ati gbogbo àwọn ọ̀rẹ́ rẹ̀.
Bẹ́ẹ̀náàni onírúirú ẹ̀rọ ìgbàlódé ti njáde fún àwọn afọ́jú.
Oríṣun àwòrán, Others Gẹgẹ bi awọn kan ti se sọ, wọn tun ni Ramoni ti ta aṣọ bọsikọrọ nigba to wa l'Eko, koda wọn tun sọ wi pe o kọ isẹ foonu ati kọmputa tita ni Computer Village nilu Eko kan naa.
OLUWA, Ọlọrun Israẹli sọ nípa àwọn ilé tí wọ́n wà ní ìlú yìí, ati ilé ọba Juda, àwọn tí wọn dótì wá, tí wọn ń gbógun tì wá yóo wó wọn lulẹ̀ 
Bi a ba ran ni nise eru, a fi to mo je ni, Chelsea fi iko agbaboolu Frankurt ranse sorile-ede Germany pelu eru iya lori.
Kò tíì sí àrùn Coronavirus ní ìpínlẹ̀ Oyo, a ṣi ń retí èsì àyẹ̀wò - Ijọba Oyo Ìjọ kò ní tilẹ̀kùn ilé ìjọsìn nítorí àrùn Coronavirus - Ondo PFN Wo àwọn irọ́ tí wọ́n ń pa fún ọ nípa àrùn Coronavirus Nílé ijó Fẹla Anikulapo, àrùn Coronavirus dá fàájì dúró Gomina ọhun pari ọrọ rẹ nipa fifi nọmba wọyin lede 08038210122, 08023229267, 08073431342.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Lizzy Anjorin: Ẹ má bú mi, ọ̀pọ̀ òṣèré tíátà ni kìí bá mi yọ̀ fún ire mi 24 Ògún 2019 Oríṣun àwòrán, Instagram/lizzyanjorin Oju opo Instagram tun ti n gbona jain-jain bayii nitori awọn ololufẹ awọn osere tiata obinrin meji, Toyin Abraham ati Lizzy Anjọrin, ti wsn n tahun si ara wọn.
Nǹkan púpọ̀ ni mó fẹ́ bèèrè lọ́jọ́ náà lọ́hǔn, ṣùgbọ́n n kò rí ẹni bi.
Àwọn ìfihàn náà jẹ kíkọsílẹ̀ ní ojúlówó láti ọwọ́ àwọn akọ̀wé Joseph Smith, àwọn ọmọ Ìjọ sì fi tọkàntọkàn pín àwọn ẹ̀dà àfọwọ́kọ pẹ̀lú ara wọn.
Fún ọ̀pọ̀lọpọ̀ ẹbi Yorùbá, ogoji ni oye àwọn ẹrù bi Obi, Orógbó, Ataare, Ẹja-gbígbẹ àti Iṣu ti idile ma ngba.
Oga agba ohun fi kun oro re pe, “agbodo wa ni imura sile, lati ri daju pe, a gbodo wa ona ati de gbogbo awon ijoba ibile wonyii, a gbodo fun awon omode wonyii ni abere ajesara, a ti fere de ibe tan, lati le ni aseyori nipa fifun awon omode wonyii ni abere ajesara”.
Ọjọ kinni oṣu kejila ọdun 2020 yii ni mama Oyediran to jẹ ọkan ninu awọn ọmọ olootu ijọ iwọ oorun guusu Naijiria nigba kan ri, Oloye Obafemi Awolowo ko ba ṣe ayẹyẹ ọjọ ibi ọgọrin ọdun laye.
O ni awọn to lagbara lati dari eto idibo ati awọn ọmọ ogun bo ti ṣe wu wọn lo le máa foya pe ijiya Amẹrika yi yoo kan awọn.
Shehu ni eto naa yoo bẹrẹ lọjọ Iṣẹgun, ọjọ kọkandinlọgbọn, oṣu kẹwaa, yoo si wa sopin lọjọ kọkanlelọgbọn, oṣu kẹwaa.
N óo dùbúlẹ̀, n óo sì sùn ní alaafia,nítorí ìwọ OLUWA nìkan ni o mú mi wà láìléwu.
" Ero Arabinrin Esther Ojo, toun naa jẹ onileesẹ abani fi ẹru ransẹ, nipa igbesẹ ijọba naa, ko yatọ si ti akẹẹgbẹ rẹ.
Eyi ri bẹẹ nitori kii ṣe awọn ilu mẹrin taa ti darukọ yii nikan ti Ogedengbe ti jẹ gbajugbaja.
2 bílíọnù fi tún wáyà iná àti inú ilé Aso Rock ṣe- Buhari Oríṣun àwòrán, Teni Àkọlé àwòrán, Teni: Idi ti mí kìí fi ṣí ìhòhò mi bi àwọn olórin obinrin míran.
Awọ ara wa gbóná bí iná ààrò,nítorí ìyàn tí ó mú lọpọlọpọ.
 Ti Joshua ati iko re ba to gbangba sun loye.
Wọ́n ń bá ara wọn sọ pé, “Bí ó bá rí bẹ́ẹ̀, ta ni yóo là?
Ṣugbọn ọkà alikama ati ọkà ria kò bàjẹ́, nítorí pé wọn kò tètè hù.
Ológun mú àwọn sọ́jà tó kọ́wọ̀ọ́ fipá bá akẹ́kọ̀ọ́ fásitì AAUA lò pọ̀ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Imperial Majesty ni Olubadadan, Royal Majesty làwa, òfin sì tẹ̀lé e - Ọtun Olubadan Wọn tun ti lọ nọmba idanimọ orilẹede yii, NIN pọ mọ nọmba apapọ ile ifowopamọ BVN nitori naa ko ni si nkan to jọ pe ẹni ọtọ ni wọn n sanwo fun.
Síbẹ̀ irú àwọn wọ̀n-ọn nì pọ̀ nínnú ayé suu.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ondo: Dejí sun ọmọ méje àtagbalagba meji mọ́lé nítorí pé ó ń bínú O ni ọna ti awọn eniyan le gba ṣe atilẹyin fun gbogbo ilakalẹ ijọba apapọ ni lati ri wi pe aarun naa dinku lawujọ, ki ohun gbogbo le pada si ipo.
pese lati fi ran won lowo ni ajilẹ,eso ohun ọgbin,ogun kẹmika, ohun abiyẹ ati ẹranko
Ẹ jẹ́ ká kí bàbá kú ayẹyẹ ọjọ́ ìbí èmi yín a gùn.
Orukọ gomina tuntun naa ni Agboọla Ajayi.
 Adeyinka Oluwaseun Moraanugba ni wọn sọ ọmọ tuntun naa."
À lágbára láti san gbogbo gbèsè tá jẹ Ipade ti aarẹ Buhari n lọ ṣe la gbo pe o ni ohun ṣe pẹlu awọn orileede to wa ni aarin ila oorun agbaye ati awọn ti ariwa ilẹ Afrika.
Àkàrà tú sépo, Trump ló kọ èsì ìlera ara rẹ̀ Àwọn Gómìnà Gúúsù-Ìwọ̀ Oòrùn kéde June 12 Yemi Osinbajo: Ìgbákejì Ààrẹ tó gbọ́ nípa ẹ̀!
Ẹ̀gà tún rẹ́rìn-ín ó ní, ‘Ẹ jókòó yín jẹ́ ẹ́, wọn kò níí wá, àwọn àna mìíràn dára ṣùgbọ́n púpọ̀ buru ju gbèsè ìdílé lọ.
Kunle Afolayan, òṣìṣẹ́ báńkì tẹ́lẹ̀ kó tó di gbajúgbajà òṣèré.
Kọmisana fun eto ilera nipinlẹ Eko, Ọjọgbọn Akin Abayomi lo sisọ loju ọrọ naa ninu atẹjade kan to fi sita.
Mo tún bèèrè: Àbí Israẹli kò mọ̀ ni?
Àjọ NCDC kéde ènìyàn 490 tó tún ṣẹ̀ṣẹ̀ ní Coronavirus ní Nàìjíríà Ilé ìfowópámọ́ Access ti gbà láti dá owó àwọn oníbàráà wọ́n padà Ẹ wo àwòrán bí ìsìnkú Abiola Ajimobi ṣe lọ!
Má fi ohunkohun sílẹ̀ láì ṣe ninu iṣẹ́ iranṣẹ rẹ.
Oluwo ni ile isẹnbaye ni o yẹ ki awọn oriṣa wa nitori nnkan ti yatọ si ti aye ọjọun nigba ti wọn bẹrẹ si ni bọ awọn oriṣa naa.
Kò mọ̀ bóyá ilé òun yóò dí àtúnkọ́ tàbí wọn yóò dà á wó pátápátá kọ́ òmíràn.
Adwa je ilu ibi itaja, ti o ya kuro ni apa ariwa orile-ede Ethiopia ni paapaa julo ekun Tigray, eyi ti won mo si ilu ti o sunmo agbegbe ti ogun Adwa ti waye ni odun 1896 pelu awon omo-ogun orile-ede Italy.
Ó díje fún ipò gómìnà ìpínlẹ̀ Ọṣun l'ọ́dún 2014 l'ábẹ́ àsìá ẹgbẹ́ òṣèlú Peoples Democratic Party, PDP, sùgbọ́n Rauf Aregbẹsọla fi ẹ̀yìn rẹ̀ janlẹ̀ nínú ètò ìdìbò nàá tó wáyé ní ọjọ́ kẹsàn án, oṣù Kẹjọ 2014.
Ṣugbọn ẹni tí ó bá sẹ́ mi níwájú eniyan ni a óo sẹ́ níwájú àwọn angẹli Ọlọrun.
Ajọ naa ni, o le ni miliọnu mẹfa awọn eeyan orilẹede South Sudan ti ọwọngogo ounjẹ n ba finra atipe miliọnu kan eeyan miran lee kun wọn laarin osu mẹta si asiko yii.
Mo ṣetán láti kú nítorí àwọn aguntan.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ohun tẹ́ẹ gbúdọ mọ nípa kókó orí ọyàn yín lásìkò fífọ́mọlọ́yàn Ki lo ti ṣẹlẹ sẹyin?
Oríṣun àwòrán, Getty Images Ṣugbọn o fidi rẹmi, eyi to jẹ ko di aarẹ Amẹrika ẹlẹẹkẹrin to kuna lati wọle saa keji.
Baluu yii lee da fo funrarẹ lai jẹ wipe awakọ baluu wọ inu rẹ.
Eyi ni esi ifesewonse idije Nigeria Professional Football League (NPFL), ti o waye lojo Aiku (Sunday):Abia Warriors 2-1 Rivers UnitedEl-Kanemi Warriors 2-0 Nasarawa UnitedPlateau United 1-0 Katsina UnitedKano Pillars 2-0 Heartland FCSunshine Stars 1-1 Lobi StarsEnyimba International 0-0 Akwa UnitedRangers International 3-0 Wikki TouristsGo Round FC 0-0 FC IfeanyiUbahYobe Desert Stars 0-0 Kwara UnitedNiger Tornadoes 1-0 MFM FC.
Ó máa ńmú inú mi dùn tí mo bá ńrántí ẹ̀.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: ‘Wọn ti ji Dino Melaye gbe’ Ìpinu Gómìnà Ortom ya ni lẹ́nu - APC Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ìwádìí Anas: $1000 ni rìbá tí akọ́ni-mọ̀ọ́gbá Super Eagles gba Igba meji ni orilẹede naijiria ti de ipele aṣekagba; orilẹede Germany lo si na wọn ni igba mejeeji ni ọdun 2010 ati 2014.
Ìlẹ̀kùn wà ní títì bẹ́ẹ̀ ni Jesu bá tún dé, ó dúró láàrin wọn, ó ní, “Alaafia fun yín!
NCDC kéde èyí lọ́jọ́ sátidé pé ìpínlẹ̀ Eko to jẹ́ orísun ààrun náà lo gbégba orókè jùlọ pẹ́lù irínwo ènìyàn, nígbà ti Abuja ṣe ipò keji pẹlú ènìyàn mẹ́tàdinlógójì.
wọ́n yóo jẹ́ ìyè fún ẹ̀mí rẹ,ati ohun ọ̀ṣọ́ ní ọrùn rẹ.
akin àti ilésanmí wá filísíà yìí lọ sí pètéèsì aláwò pupa rúsúsúsú .
Ìwọ Ọlọ́run Ọba tó ó dá m,i ìwọ Olódùmarè tí o dá Igbó Olódùmarè, Ìwọ Ẹni ìyanu tí o dá ǹkan iyanu gbogbo, Ìwọ Ẹlẹ́dàátí ó dá gboggbo àwọn ọdẹ tí ń bẹ nínú ayé; àkókò náà dé wàyí tí mo fẹ kí o ṣe alátìlẹ́hìn mi.
Koko awọn ọrọ ti Aarẹ Buhari sọ ni October 1: Eto aabo: Ijọba n ra awọn ohun ija fun ileesẹ ọmọ ogun Naijiria lati le sisẹ takuntakun ti yoo fi opin si Boko Haram ati eto aabo to dẹnukọlẹ lorilẹ-ede Naijiria.
Oríṣun àwòrán, TWITTER@GOOGLEAFRICA Àkọlé àwòrán, Ramesh Nagarajan ''Bi eeyan ba fẹ jẹ anfaani lilo ohun Naijiria yii lori ẹrọ, yoo kan lọ yii kuro lede Gẹẹsi si ede Gẹẹsi ti Naijiria ni.
Bí àrùn bá ti tàn káàkiri lára ògiri ilé náà, 
Nítorí ẹ mọ àwọn ìlànà tí a fun yín, nípa àṣẹ Oluwa Jesu.
Ó pàṣẹ lórí ilẹ̀ ayé,àṣẹ rẹ̀ sì múlẹ̀ kíá.
Ọmọ mi fetí sí ọgbọ́n tí mò ń kọ́ ọ,tẹ́tí rẹ sí òye mi,
Inú ìyá mi, Ẹni-ayé, kò dùn sí ọ̀ràn náà nítorí ó fẹ́ ki n bá àwọn èrò òkè láńgbòdó lọ, èmi náà pàápàá sì fẹ́ bẹ́ẹ̀ pẹ̀lú.
Awọn iwe mii to ti kọ to gbajumọ ni Atoto Arere (1981), Rẹrẹ Run (1973).
2bn Naira tó fẹ́ ẹ yá lọ́wọ́ Brazil Ẹ wo ẹyẹ ayékòótọ́ tó kó olówó rẹ̀ yọ lọ́wọ́ ikú gbígbóná Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Fídíò, Akomolede àti Asa lórí BBC Yorùbá: Mọ̀ síi nípa ẹ̀kún ìyàwó níbí3 Bélú 2020 Fídíò, Soyinka Cancer: Àṣe ara mi ni iso ti n run gbogbo bí mo ṣe n ṣèrànwọ́ lórí jẹjẹrẹ27 Bélú 2019 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 3 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 5 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Jide Kosoko forin sẹ́nu sọ pé òun ni igi lẹ́yìn ọgbà Mr Latin lórí ipò ààrẹ TAMPAN tó wà Igbo Olodumare rèé, níbi tí Ìgbín ti tóbi ju Ìjàpá lọ Wo àwọn Adelé-Ọba aládé méje tó jẹ́ obìnrin nílẹ̀ Yorùbá Kí ló fà ogun Ìjàyè àti ìṣubú Kurunmi, ìfẹ́ ìlú ni àbí orí kunkun?
Atẹjade ti ileesẹ ọlọpaa fisita sọ pe wọn gbe Marley lọ sile ẹjọ lori bi oun ati Awonuga ṣe gbe baalu adani lọ silu Abuja lọjọ Kẹtala oṣu kẹfa ọdun 2020 ni deede aago meji ọsan.
Òmùgọ̀ ni gbogbo eniyan, wọn kò sì ní ìmọ̀,gbogbo alágbẹ̀dẹ wúrà sì gba ìtìjú lórí oriṣa tí wọn dà;nítorí pé irọ́ ni ère tí wọ́n rọ,wọn kò ní èémí.
Ẹni tí wọ́n ti ń pè ní àgàn rí sì ti di aboyún oṣù mẹfa.
O’Hara, Wendie Renard; Julie Ertz, Amandine Henry, Rose Lavelle; Marta, Alex
4 560382 Orilẹede Turkey 14900 18.
Bí England se jà fitafita tó síbẹ̀ wọn ri ipò kẹ́ta mú.
Ile igbinmo asofin ipinle Eko ti rọ  ile igbinmo asofin agba lorile ede Naijiria
 Awọn ajinigbe naa sọ fun wa pe awọn yoo san owo ibọn AK47 ti awọn ya, owo ọga wọn lara miliọnu mẹwaa Naira ti a ba san.
Ẹ̀sìn ìṣẹ̀ṣe ṣún síwájú, wo orin aládùn lẹ́nu ẹgbẹ́ akọrin àti ìjèrè ọkàn tí wọn ń ṣe Ojúlówó Shina Rambo yọjú sígboro lọ́jọ́ Àìkú, ó fi ìka hánu lórí ìpànìyàn tó ti ṣe Àwọn ọ̀dọ́ Benue pa pásítọ̀ ti wọ́n fẹ̀sùn kan pé ó ń mú ǹkan ọmọkunrin Iléẹjọ́ mú ọjọ́ kejìdínlógún, oṣù kọkànlá fún ìgbẹ́jọ́ àwọn tó jí ìbejì Àáfà Akeugbagold ní Ibadan Ọjọ diẹ ẹyin ni aarẹ ana lorilẹede Mali naa gunlẹ silẹ Turkey pẹlu baalu olokoowo kan to ja si olu ilu Turkey, Istanbul.
Osanyintolu ni agbegbe Cappa Avenue, Palmgrove nilu Eko ni ibugbamu naa ti waye.
Ẹ̀yin tẹ́ẹ tako àgbékalẹ̀ àgọ́ Fulani, ìkórira ló ń yọ yín lẹ́nu - Ìjọba àpapọ̀ Òṣìṣẹ́ OSCOTECH gb'òmìnira lọ́wọ́ ajínigbé darandaran Fulani Fulani darandaran lo iwa ipa ni guusu Akurẹ Ọmọogun pa darandaran mẹwa ni Adamawa Ijọba ni wọn n ṣeto lori igbesẹ yii lati wa ojutu si iṣoro ija laarin awọn darandaran ati awọn agbẹ to n gba ọpọlọpọ ẹmi ati dukia.
Kò sí ẹnì kan tí ènìyàn lè bẹ̀rù àfi Ọlọ́run Ọba.
Onitsha Building Collapse: Ilé alájà mẹ́ta wó lúlẹ̀, ènìyàn kan ti kú
Ninu atẹjade rẹ, ẹgbẹ oṣelu PDP ni nigba ti ẹru ajaga ijakulẹ ni gbogbo igba ti n wọ ẹgbẹ APC lọrun ati pe iwa ọbayejẹ to wọ wọn lẹwu ati iṣoro ifasẹyin ọrọ aje to gogo, iṣekupani ohun bi ilu ṣe le koko ti wọn ko ba awọn araalu lo mu wọn fi tipa tikuuku gba ara wọn da sita kuro ninu oṣelu nipa titu gbogbo awọn adari wọn ni gbogbo ipele lapapọ ka.
’’O ni enikeni to ba jawe olubori nibi eto idibo ti yoo waye
Koda kii se Miyetti Allah lasan, awọn Fulani bawọn lọwọ ninu ibasepọ yii, ti wọn si fi ọrọ to Seriki awọn Fulani leti'' Wo àwọn ohun tí Amotekun kò ní le è ṣe mọ́ ní ìpínlẹ̀ Oyo.
Liverpool fí ògùn ẹ̀yìn ja Barcelona ''Mi ò ṣe àrífín Sultan àmọ́ mi ò lè bẹ̀rẹ̀ àwẹ̀ láì fojú r'óṣù' Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Owó tí mo ń rí lórí Garri ni mo fi ń ran ọkọ lọ́wọ́' Amọ ni ọpọ igba ni Amaju Pinnick ti sọ wi pe ẹẹbu ni ẹsun lilu owo ilu ni ponpo ti wọn fi kan oun.
Party (PDP),ninu eto idibo gomina to waye ni Osu kesan an, odun 2018 ni  ipinle Osun.
Ní ọjọ́ náà àwọn ẹgbẹẹdogun (3,000) eniyan ni a kà kún ọmọ ìjọ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Sogidi Lake: Kòṣẹja-kòṣèèyàn lá bá nínú adágún odò náà -Ojedele Iru iku wo lo pa Ayinla Ọmọwura?
Nígbà tí wọ́n dákẹ́, ó bẹ̀rẹ̀ sí sọ̀rọ̀ ní èdè àwọn Heberu.
OLUWA Ọlọrun wa, o dá wọn lóhùn;Ọlọrun tíí dáríjì ni ni o jẹ́ fún wọn;ṣugbọn ó gbẹ̀san ìwàkiwà wọn.
Nkechi Blessing: Gbajúgbajà òṣèré ní ó sàn fún òun láì tíì lọ́kọ báyìí ju kí òun lọ́kọ láì láyọ lọ
Bí gbogbo wa ti ṣubú lulẹ̀, mo gbọ́ ohùn kan tí ó ń bá mi sọ̀rọ̀ ní èdè Heberu.
Ẹkunrẹrẹ iroyin yii ati fidio bi ọrọ naa se waye n bọ lọla, ẹ maa ba wa bọ.
Awọn ti iṣẹlẹ naa ṣoju wọn sọ pe ina naa ṣadede ṣẹyọ lọsan ọjọ Aiku lati ọwọ ẹyin ile itaja naa ti ko si pẹ to fi ran kaakiri.
" A ti ṣe àbẹ̀wò sí ibi ìṣẹ̀lẹ̀ náà, à sì ti gbé ọmọ ọ̀hún lọ sí ilé ìwòsàn fún àyẹ̀wò àti ìtọ́jú, tí àwọn dókìtà sì fi ìdí rẹ̀ múlẹ̀ pé lóòtọ́ ni wọ́n fi ipá bá ọmọ náà lòpọ̀.
Wọ́n bá gbà pé kí Rebeka arabinrin wọn máa lọ, pẹlu olùtọ́jú rẹ̀ láti ìgbà èwe rẹ̀, ati iranṣẹ Abrahamu, pẹlu àwọn ọkunrin tí wọ́n bá a wá.
Ni ọjọ aje ọjọ kẹjọ, oṣu kẹwa ni ọmọ rẹ tufọ rẹ faye.
Wakil, jẹ ọmọ igbimọ to nrisi eto ifikunlukun ati yiyanju ipenija eto aabo nitunbi nnubi ( Dialogue and peaceful resolution of security challenges committee), ti ijọba Jonathan da silẹ.
 debehogne ' s aphelion je 2.
Eyi ni agbẹnusọ rẹ Willy Nyamitwe sọ.
Ènìyàn 653 míràn tún kún iye àwọn tó ní COVID-19 ní Nàìjíríà Bí ẹgbẹ́ One Million Boys ṣe bẹ̀rẹ̀ rèé àti ọṣẹ́ tó ṣe n'Ibadan Nínúu kẹ́ẹ kọ̀wé fipò sílẹ̀ tàbí kí ẹ gba ìdádúró, ẹ mú ọ̀kan - Ilé aṣòfin sí àwọn ọ̀gá àgbà ológun Wo bí ètò ìsìnkú Isa Funtua ṣe wáyé ní ìlú Abuja Bakan naa ni ajọ NCDC tun fi kun un pe eeyan mẹrin miran ti padanu ẹmi wọn nipasẹ awọn aisan to peleke tori arun yii lagọ ara wọn.
Tsietsi to jẹ ẹni ọdun marundinlọgọta ṣalaye pe nkan bi ọdun meji sẹyin lawọn bẹrẹ ile ijọsin awọn.
Ọmọbinrin náà bá sáré lọ sọ gbogbo ohun tí ó ṣẹlẹ̀ fún àwọn ará ilé ìyá rẹ̀.
Agbẹnusọ ọlọpaa nipinlẹ Katsina, Gambo Isah fidi iṣẹlẹ yii mulẹ fun BBC, to si ni awọn n ṣapa lati doola awọn ti wọn jigbe.
“Ẹ pe àwọn tafàtafà jọ, kí wọn dojú kọ Babiloni; kí gbogbo àwọn tí wọn ń tafà pàgọ́ yí i ká, kí wọn má jẹ́ kí ẹnikẹ́ni sá àsálà.
Gomina ni ijọba oun pese awọn ohun eelo fun eto aabo ati ọkọ ayẹta pẹlu awọn ohun elo mii fawọn oṣiṣẹ eleto aabo nipinlẹ Oṣun.
'Mi ò mọ̀ pé mo lóyún àfìgbà t'ọ́mọ ń rún'ra' 'Mo gba kádàrá lórí àìlera mi láìnáání yẹ̀yẹ́' 'Kò sí ǹkan tí o kò lè ṣe tóo bá ní àfojúsùn' Kíni itumọ àṣẹ wàá tí àwọn Ààrẹ orílèèdè má n pá?
Gba ohun tí ó tọ́ sí ọ kí o máa bá tìrẹ lọ; nítorí ó wù mí láti fún àwọn yìí tí wọ́n dé kẹ́yìn yìí ní ohun tí mo fún ọ.
Awon ajo agbaye naa ti mo pe,o ye ki  orile ede Guinea Bissau dibo ni ojo kokandinlogun osu kokanla sugbon ti eleyii ko lee waye mo.
Lara Awọn ara ilu Mamu-Ijẹbu ni Ipinle Ogun lapa Iwọ-Oorun Gusu ni orilẹede Naijiria ti rọ ijọba ati awọn tọrọ kan gbogbo lati gba wọn lọwọ iya owọngogo omi laarin ilu.
 Ajọ naa sọ siwaju si pe, ikọlu ti ijọba ṣe si awọn oluwọde ni Lekki, Alausa ati kaakiri Naijiria n ṣafihan pe, ijọba Buhari ko bọwọ fun ẹtọ ọmọniyan, bakan naa ni ko naani ẹmi eeyan ati aye lati sọrọ bo ṣe wu wọn."
Gomina Ipinle Ọyọ, Abiola Ajimobi ti seleri lati satileyin
Ohun elo aṣeranwọ eemi ti ko nilo ati ti bọ inu ara Gẹ́gẹ́ bí àjọ elétọ̀ àbò àgbáyé (WHO) ṣe sọ ìdá ọgọ́rin àwọn ènìyàn tó ní ààrùn Coronavirus ni kò nílò láti dé ilé ìwòsàn kí ara rẹ̀ tó dá.
asofin ba ti wọle , ki a gbiyanju lati lo sibẹ, ki a bẹbẹ fun  ofin ti yoo gba awon omo orile ede yii laaye
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ethiopia Airlines ET302: Obìnrin yìí ṣì ń ṣèdárò àwọn tó kú nínú ìjàmbá bàálù Ethiopia Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Ethiopia Airlines ET302: Obìnrin yìí ṣì ń ṣèdárò àwọn tó kú nínú ìjàmbá bàálù Ethiopia 16 Ìgbé 2019 Obinrin ọmọ orilẹede Ethiopia yii, Mulunesh Bejiga gbọ ariwo ki baalu ET302 to ja si ẹgbẹ ile rẹ.
” Ṣafani sì kà á níwájú ọba.
Dúró ni àkọ́bí ọmọ Àkàngbé Orímóògùnjẹ́.
Iko omo ogun 16 Brigade orile
Láti inú ẹ̀yà Juda ẹgbaafa (12,000) ni a fi èdìdì sí níwájú, láti inú ẹ̀yà Reubẹni, ẹgbaafa (12,000), láti inú ẹ̀yà Gadi, ẹgbaafa (12,000); láti inú ẹ̀yà Aṣeri, ẹgbaafa (12,000), láti inú ẹ̀yà Nafutali, ẹgbaafa (12,000) láti inú ẹ̀yà Manase, ẹgbaafa (12,000), láti inú ẹ̀yà Simeoni, ẹgbaafa (12,000), láti inú ẹ̀yà Lefi, ẹgbaafa (12,000), láti inú ẹ̀yà Isakari, ẹgbaafa (12,000), láti inú ẹ̀yà Sebuluni ẹgbaafa (12,000), láti inú ẹ̀yà Josẹfu, ẹgbaafa (12,000), láti inú ẹ̀yà Bẹnjamini, ẹgbaafa (12,000).
Igbimọ adajọ ẹlẹni mẹta to gbe idajọ kalẹ lori ọrọ yii ni, ọga ọlọpaa Mohammed Adamu ko laṣẹ tati ṣeto igbanisiṣẹ.
Wọn yóo máa kọrin ìyìn sí OLUWA ní àràárọ̀, bẹ́ẹ̀ náà sì ni ní ìrọ̀lẹ́ ìrọ̀lẹ́, 
Goolu mẹta ni Naijiria fi ṣagba Cameroon ninu ifẹsẹwọnsẹ naa to waye ni Alexandria.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Sunday Igboho yarí, ó fohùn ránsẹ́ sáwọn èèyàn tó ń pẹ̀gàn rẹ̀ Magu gba ₦9.
Wọ́n wá láti Galili ati Judia ati Jerusalẹmu; 
Olùṣọ́ náà pàṣẹ pé kí á fi gbòǹgbò igi náà sílẹ̀ ninu ilẹ̀; ìtumọ̀ rẹ̀ ni pé, dájúdájú, o óo tún pada wá jọba, nígbà tí o bá gbà pé Ọlọrun ni ọba gbogbo ayé.
Idije AFCON to n lọ lọwọ ni orilẹ-ede Egypt ni Naijiria ti koju Madagascar ninu ipele ẹgbẹ ti wọn yoo fi bọ si ti ẹni mẹrindinlogun.
N kò ní fojú fo ọ̀rọ̀ yín, n kò sì ní ṣàánú yín.
Àbí ní orúkọ Paulu ni wọ́n ṣe ìrìbọmi fun yín?
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù 500 Teeth: Àgbọ̀n ọmọ náà tó wú làwọn obi rẹ̀ gbe lọ sí ilé ìwòsàn 1 Ògún 2019 Ara meeriri, mo ri ori ologbo lori atẹ ni itan ọmọdekunrin kan ti awọn dokita yọ eyin to le ni ẹẹdẹgbẹta ni agbọn rẹ.
    Eléyìí mú kí ẹ̀gbọ́n àgbàlagbà wọ inú igbó.
Ó bá yipada sí àwọn eniyan, ó bèèrè pé, “Ta ni fọwọ́ kàn mí láṣọ?
Nítorí nígbà tí ẹnìkan ń sọ pé ẹ̀yìn Paulu ni òun wà, tí ẹlòmíràn ń sọ pé ẹ̀yìn Apolo ni òun wà ní tòun, ó fihàn pé bí eniyan kan lásán ni ẹ̀ ń hùwà.
Iru rẹ naa waye nipinlẹ Edo.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ 9ice: Ǹjẹ́ olórin tàkasúfèé yìí ń mu igbó bí àwọn òṣèré mìíràn?
N kò rí i títí ìsìn fi dé òpin.
” Samuẹli bá gé Agagi wẹ́lẹwẹ̀lẹ níwájú pẹpẹ ní Giligali.
N kò gbàgbé ọ̀ràn yìí títí ọjọ́ ayé mi nítorí bíkò bá si eléyìí náà ńkọ́, èmi ìbá ti rí ọkùnrin tí ó máa fẹ́ mi.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Kidnapping in Nigeria: Arìnrìnàjò kan ṣàlàyé bí orí ṣe ko yọ lọ́wọ́ ajínigbé 29 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Oríṣun àwòrán, Facebook/Remi Oladoye Ọkunrin kan ti ori ko yọ ti salaye ohun toju rẹ ri nidi isẹlẹ ijinigbe to n waye lemọlemọ, paapaa loju ọna Ilesa si Ekiti.
Ami ayo ti Henry Onyekuru ati Simeon Nwankwo gba wole lo ran iko Super Eagles lowo siwaju, ki o to di pe Kpah Sherman da ami ayo kan pada pelu boolu agbesile gba(penalty kick).
Kí ni mo fi ṣe ọ́!
Ọgbẹni Onigbogi fikun ọrọ rẹ pe awọn ti ko tii sanwo ileewe fun saa keji igbẹkọ to lọ nikan ni ko ni lanfaani lati kopa ninu igbẹkọ ori ayelujara.
Aeroplane House: Látọdún 1999 ni mo ti bẹ̀rẹ̀ kíkọ́ ilé yìí fún ìyàwó mi ọ̀wọ́n
Ọwọ́ ọlọpàá tí tẹ ọ̀kan nínú àwọn ọ̀daràn tó ṣekú pa Uwaila ₦35,000 ni mò ń gbà bíi Adelé ọba, kò sí ọkọ̀ ayọ́kẹ́lẹ́ - Adelé Olúbọ̀rọ̀pa Ìlú yóò le, ọmọ le kú, àìsàn yóò pọ̀ bí eégún kò bá jáde nílùú Ibadan - Olóòlù Ọwọ́ bàtá Auxiliary tó ń ró ní àrójù, leè ya láìpẹ́ - Ìjọba Oyo dúnkookò Barakat, ẹni taa gbọ pe wọn ti sin, ni ọpọ eeyan lori ayelujara wa n beere pe ki awọn agbofinro ṣe awari awọn to fi tipa ba lopọ, ti ẹmi rẹ fi bọ.
Èèyàn 196 míràn tún ti ní àrùn Coronavirus ní Nàíjírìa Eeyan mẹrindinlọgọfa miran ni ayẹwo tun ti fihan pe o laarun Coronavirus lorilẹede Naijiria bayii.
Toyin Abraham bí ọmọkùnrin jòjòló Awọn to ṣe iwọde naa ni idi abajọ ni wi pe Fakorede jẹ ọmọ ẹgbẹ oṣelu alatako APC.
Awọn Dokita to ni ki ikọ BBC fi orukọ bo awọn laṣiri sọ pe, mọriwo ni iṣẹlẹ naa jẹ, egungun ṣi n bọ lẹyin nitori pe ko si ipese ohun eelo to yẹ fawọn oṣiṣẹ ilera lati ṣe iṣẹ wọn.
Ajo to n ri si lila awon eniyan loye nipa owo –ori , ti fun awon to je owo-ori ni anfaani lati forijin won nipa ijiya to ye ki won je.
BBC kan si alaga ẹgbẹ APC ni Ondo lati gbọ alaye lẹnu rẹ.
Bákan náà ni WhatsApp kò ni le bá iOS 9 ti ilé iṣẹ́ Apple ṣe lọ́dún 2015.
Lọwọ-lọwọ bayii, oriire ti gbe alawo re ko Adetutu, ti gbaju-gbaja olorin kan ni ilẹ Amẹrika, Rihanna si ti n fesi pada fun Adetutu lori ibeere rẹ lati ba Rihanna sisẹ pọ.
Àwọn ẹlẹ́ṣẹ̀ ni mo wá pè sí ìrònúpìwàdà.
Ẹ̀gbọ́n mi sọ pé òun tì wá àwọn méjéèjì lọ sí ilé àbúrò rẹ̀, ṣùgbọ́n òun kò bá ẹnìkan ní ilé.
’ Mo fẹ́ kí o ṣe ètò kí n lè fi ojú kan ọba, bí ó bá sì jẹ́ pé mo jẹ̀bi, kí ó pa mí.
Àti àwọn ìbéèrè míràn Àwọn nǹkan tí obìnrin lè ṣe pẹ̀lú olólùfẹ́ oníwà ipá lásìkò ìgbélé Coronavirus yìí Aláàfin Ọyọ: Ọba tó bá n mú ọtí ní ìta kò yẹ ní ẹni tàá bọ̀wọ̀ fún Coronavirus: Kíni àwọn àmì tuntun tó n fihàn?
 Ikọ yii ṣabẹwo sipinlẹ Eko ti wọn si kan si Gomina Ambode Akinwunmi lori eto ti wón la kale nibi ipade 61-UNWTO/CAF ti wọn ṣẹṣẹ pari ni Abuja.
Abramu gba gbogbo ìkógun tí wọ́n kó pada, ó gba Lọti, ìbátan rẹ̀ pẹlu ati gbogbo ohun ìní rẹ̀, ati àwọn obinrin ati ọ̀pọ̀ àwọn eniyan mìíràn.
Lara and The Beat Seyi Shay jẹoṣere Nollywood tuntun nibi to ti kopa olu ẹda itan ninu fiimu onijo-lorin yii.
Awon Asole(Goalkeepers): Ikechukwu Ezenwa (Enyimba FC); Francis Uzoho (Deportivo La Coruna, Spain); Daniel Akpeyi (Chippa United, South Africa); Dele Ajiboye (Plateau United)Awon agbaboolu owo eyin(Defenders): Abdullahi Shehu (Bursaspor FC, Turkey); Tyronne Ebuehi (Ado Den Haag, The Netherlands); Olaoluwa Aina (Hull City, England); Elderson Echiejile (Cercle Brugge KSV, Belgium); Brian Idowu (Amkar Perm, Russia); Chidozie Awaziem (Nantes FC, France); William Ekong (Bursaspor FC, Turkey); Leon Balogun (FSV Mainz 05, Germany); Kenneth Omeruo (Kasimpasa FC, Turkey); Stephen Eze (Lokomotiv Plovdiv, Bulgaria)Awon agbaboolu aarin(Midfielders): Mikel John Obi (Tianjin Teda, China); Ogenyi Onazi (Trabzonspor FC, Turkey); Wilfred Ndidi (Leicester City, England); Oghenekaro Etebo (UD Las Palmas, Spain); John Ogu (Hapoel Be’er Sheva, Israel); Uche Agbo (Standard Liege, Belgium); Joel Obi (Torino FC, Italy); Mikel Agu (Bursaspor FC, Turkey)Awon agbaboolu owo iwaju(Forwards): Ahmed Musa (CSKA Moscow, Russia); Kelechi Iheanacho (Leicester City, England); Moses Simon (KAA Gent, Belgium); Victor Moses (Chelsea FC, England); Odion Ighalo (Changchun Yatai, China); Alex Iwobi (Arsenal FC, England); Nwankwo Simeon (Crotone FC, Italy); Junior Lokosa (Kano Pillars).
orile-ede Naijiria miiran, Ibrahim Abubakar laago mewaa owuro pelu oko ofurufu Saudi
Baba Iyabọ ṣalaye pé òun kò kabamọ igbesẹ ti oun gbé lori ọrọ Ode.
Oríṣun àwòrán, @tottenham Àkọlé àwòrán, Adura ara lile laip#e ni op#o n gb[a fun Eric 6) Ko sẹni ti ìgbà rẹ ko le de nitori bi teeyan kan ko bajẹ, tẹlomii ko le daa nigbagbọ awọn Yoruba.
Ọmọ naa ti orukọ rẹ n jẹ Seyi Jebose la gbọ pe nigba to n ṣere ninu ọgba ti oun atawọn obi rẹ n gbe ni o ṣubu latorii ideri onipaanu ti wọn fi bo kanga naa.
Ọ̀dọ̀ fásitì jànkàn Oxford ló ti jáde 20 Agẹmo 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 30 Ògún 2020 Oríṣun àwòrán, Oxford University Oogun arun Coronvirus kan ti wọn fiaridaju han pe o n ṣiṣẹ ti jade lati ile iwe giga fasiti Oxford eyi to si fi han pe ko mu ewu dani rara.
Èyí fi hàn pé ó ń wá ìjà ni.
Lẹ́yìn tí ó ti ṣètò ilé rẹ̀, ó pokùnso, ó bá kú; wọ́n sì sin ín sí ibojì ìdílé rẹ̀.
Ṣugbọn Oloye Falae ni anfaani to pọ wa ninu ifilọlẹ ẹṣọ eleto aabo Amọtẹkun nitori eto aabo to mẹhẹ kaakiri orilẹede Naijiria.
ẹ̀yin tí ẹ kún fún ìṣekúṣe lábẹ́ igi Oaku,ati lábẹ́ gbogbo igi eléwé tútù.
3 - Kíni àfojúsùn iléèṣẹ́ ìròyìn nàá?
Wọ́n dá wọn lóhùn pé, “Bí ẹ óo bá dá àpótí Ọlọrun Israẹli pada, ẹ gbọdọ̀ dá a pada pẹlu ẹbọ ìmúkúrò ẹ̀bi, àpótí ẹ̀rí náà kò gbọdọ̀ pada lọ lásán, láìsí nǹkan ètùtù.
Nasiri náà yóo fá irun orí rẹ̀ ní ẹnu ọ̀nà Àgọ́ Àjọ, yóo sì fi irun náà sinu iná tí ó wà lábẹ́ ẹbọ alaafia.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Tinubu Colloquium: Ìṣẹ́gun APC ní ìdìbò 2019 ni ẹ̀bùn pàtàkì tí mo rí gbà fún ọjọ́ ìbí mi 28 Ẹrẹ̀nà 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 29 Ẹrẹ̀nà 2019 Oríṣun àwòrán, Ileowo Kikiowo Àkọlé àwòrán, Ọdọọdun ni apero yii maa n waye fun ijiroro lori awọn koko ohun to n lọ lawujọ Aṣiwaju ẹgbẹ oṣelu APC, Bọla Ahmed Tinubu ti sọ pe iṣẹgun ti ẹgbẹ oṣelu APC ni ni idibo aarẹ to waye lorilẹede Naijiria ati ibo ile aṣofin apapọ ti ẹgbẹ naa ti moke jẹ ẹbun pataki ti oun ri gba fun ayẹyẹ ọjọ ibi oun fun ọdun 2019.
”Dafidi bá tún bèèrè pé, “Kí ni ẹ wá fẹ́ kí n ṣe fun yín?
Ṣugbọn oṣu kinni, ọdun 2019 ni wọn to tun daa pada sipo naa.
Ìyanu ni ayé pàápàá jẹ́: ayé kún fún ènìyàn ẹlẹ́sẹ̀ méjì àti ẹranko ẹlẹ́sẹ̀ mẹ́rin, ejò afayàfà àti alágẹmọ tí Olódùmarè wọ̀ ní onírúurú aṣọ.
Kí ló mú kí àyájọ́ June 12 ṣe pàtàkì ní Nàìjíríà Ta ni Femi Gbajabiamila tó di Olórí tuntun nílé Asojú-sòfin Nàìjíríà?
@solomon__c bu ẹnu atẹ lu u pe gbogbo ọrọ naa loju toun da bi ẹni to n keree gbogbo ipo ati iyi nla ti wọn ti gba ni.
Wọn bi i ni ọjọ karundinlọgbọn, oṣu kẹwaa, ọdun 1900.
Laipẹ yii ni Abba Kyari to jẹ olori awọn oṣiṣẹ nile iṣẹ aarẹ tẹlẹ di oloogbe lẹyin to lugbadi aarun coronavirus.
Gege bi alaga igbimo tuntun ohun, Idris Haroon se so“a ni awon egbon ati aburo, ti won fe lo sile-mimo, sugbon ti won ko ni owo lowo lati lo.
23 Sẹ́rẹ́ 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ẹgbẹ́ òsìsẹ́ NLC ti ní N33,000 ni gbèdéke owó osù òsìsẹ́, lẹ́yìn tí ìgbìmọ̀ májẹ̀kóbàjẹ́ fi ọwọ́ sí N27,000.
Lẹhin eyi ó fi àgbà ara ka ìwé ni ilé-ìwé ẹ̀kọ́ giga.
Ṣé ẹ rí adìẹ KFC yíì, wọn ò kàn kí ń dín in lásán o.
Àwọn agbowó-odè náà wá láti ṣe ìrìbọmi.
- Sanwoolu Ìyá gómìnà Seyi Makinde dágbére fáyé lẹ́ni ọdún 81 DIG Taiwo Lakanu Wọn bi Taiwo Lakanu ni ọjọ kejila, oṣu Kẹwaa, ọdun 1959 ni Lagos Island, ni ipinlẹ Eko.
Bakan naa ni wọn maa n sisẹ ilu nipa titọju awọn oni warapa ni itẹ ti wọn maa n gbe oku si ati ile iwosan wọn.
Nibayii, eeyan 878 lo ti ṣe alaisi nipasẹ ajakalẹ arun naa lorilẹede Naijiria.
OLUWA jẹ́ agbára fún àwọn tí ọ̀nà wọn tọ́,ṣugbọn ìparun ni fún àwọn oníṣẹ́ ibi.
Coronavirus in Nigeria: BBC ṣe àbẹ̀wò sí Mọ́ṣáláṣí Alhaja níbití àwọn aládùúgbò ti kọlu àwọn ọlọ́ọpàá ní ìpínlẹ̀ Èkó
O ni ko sí aye fun awọn iléeṣẹ́ kan lati bẹrẹ sí ni ko ero ni saa yii.
Wọ́n ṣe ẹnu ọ̀nà, wọ́n ṣe àwọn ìlẹ̀kùn, wọ́n sì ṣe ọ̀pá ìdábùú sí wọn.
Ati pe inu awon si maa dun lati jọ́ dowopọ sii lodun to m bo Ayuba Sarafa, Olọ́kadà kan tó jẹ́ eni ọdún 22 pokùnso ní Ibadan N kò mọ ẹni tó fẹ́ gba ìyàwó mi, àmọ́ wọn máa ń sọ pé ó rẹwà - Mike Bamiloye Wo bí ìtàkurọ̀sọ láàrin Donald Trump àti Joe Biden yóò ṣe wáyé Ilé ẹjọ́ gíga ní kí òsìsẹ́ First Bank tẹ́lẹ̀ lọ sí ẹ̀wọ̀n ọdún 98 lórí ẹ̀sùn pé o jí mílíọnù 49 àti $368, 000 níbẹ̀ Ki lo ti kọ́kọ́ sẹlẹ̀?
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Atiku ṣetán láti pèsè isẹ́ mílíọ́nù mẹ́ta lọ́dọọdún PDP fà Buruji Kashamu kalẹ̀ bíi olùdíje Gómìnà l‘Ogun Ará Kwara soríre bí mo se jáwé olúborí - Ọlawuyi Aregbesola: mí ò gba owó oṣù gómìnà rí Ninu iwe naa, o se alakalẹ awọn eto to fẹ ṣe labẹ isọri bi mejila ti a si ri ninu wọn: Ipese iṣẹ, Ipese awọn nnkan amayederun, Mimu agbega ba pipese ina ọba, Iranwọ owo, Ile ifowopamọ ti yoo ma pese owo fun awọn oniṣẹ ọwọ, Eto ilera ati mimu alẹkun ba iyẹ awọn ti o n kopa ninu isejọba.
Ṣugbọn ẹgbẹ agbabọọlu Naijiria fakọyọ ni papa iṣere Stephen Keshi lọjọ Aje lẹyin ti wọn gbayo mẹrin sawọn ti Libya kosi le da ẹyọkan pada.
Ọmọ Wasiu ni MC Murphy now, ko si yẹ ko gbe ọrọ naa lọ sọdọ awọn akọroyin, oun n gan mọ pe oun ko sọ ootọ bi ọrọ naa se ri.
Oríṣun àwòrán, AFP Àkọlé àwòrán, Losu to koja ni Volodymyr Zelensky jawe olubori ninu idibo aarẹ O yẹ aga nidi aarẹ Petro Poroshenko to ti wa lori aleefa lati ọdun 2014.
“Máa ṣe akiyesi gbogbo ohun tí mo ti sọ fún ọ, má sì ṣe bọ oriṣa kankan, má tilẹ̀ jẹ́ kí n gbọ́ orúkọ wọn lẹ́nu rẹ.
'Sùgbọ́n bí ìrísí rẹ̀ ṣe wá rí bíi èkúte, ó fa ni mọ́ra ju àwọn ìṣeré ti ìṣájú lọ.
Àìmọye ènìyàn káàkiri àgbáyé ni a ti fún ní àjẹsára náà , a sì mọ ̀ pé èyí a má a dáàbò bo iye àwọn ènìyàn tó ju 250,000 lọ lọ ́ dún .
Aare ajo FIFA teleri, Sepp Blatter  ti gbe si orile-ede Morocco leyin lati sagbateru idije boolu  agbaye lodun 2026, leyin ti o fowosoya pe orile-ede ohun ti o kogun si ariwa gusu ile Afrika to gbangba sun loye.
Olupẹjọ James Scutt ṣalaye fun ileẹjọ pe awakọ Uber ọhun Bonchev sọ fun Mallet pe ko kuro ninu ọkọ oun.
OLUWA ti pàṣẹ nípa Asiria, pé: “A kò ní ranti orúkọ rẹ mọ́, ìwọ ilẹ̀ Asiria, n óo run àwọn ère tí ẹ̀yin ará Asiria gbẹ́, ati àwọn tí ẹ dà, tí wọ́n wà ní ilé oriṣa rẹ, n óo gbẹ́ ibojì rẹ, nítorí ẹlẹ́gbin ni ọ́.
Nígbà tí ó di ọrinlenirinwo (480) ọdún tí àwọn ọmọ Israẹli kúrò ní ilẹ̀ Ijipti, ní ọdún kẹrin tí Solomoni gun orí oyè ní Israẹli, ní oṣù Sifi, tíí ṣe oṣù keji ọdún náà, ni ó bẹ̀rẹ̀ kíkọ́ ilé OLUWA.
Lẹ́yìn náà, ó gbé e sórí iná títí tí ó fi jinná, 
Gbajúgbajà òṣèré Black Panther jáde láyé!
Pẹlu, bí àwọn nǹkan rere tí o fún wọn ti pọ̀ tó, lórí ilẹ̀ tí ó tóbi tí ó sì dára tí o fún wọn.
Chelsea fún Man United lóúnjẹ ẹ̀tẹ́ jẹ, Cuppy bínú yí jọ̀lọ́ọ̀fù dànù Ọwọ́ tẹ àwọn ọlọ́pàá tó fìyà jẹ obìnrin kan lọ́nà àìtọ́ n'Ibadan Wo bí ètò ìsìnkú Isa Funtua ṣe wáyé ní ìlú Abuja Ikú Barakat Bello ní Akinyele gbé aláàánú pàdé ẹ́bí rẹ̀ Àwon wọnyi ni ẹni àkọ́kọ́ ti yóò maa fi ìfẹ́ han si ara wọ́n láàrin ọjọ́ mẹ́fà ti wọ́n bẹ̀rẹ̀ ètò ọlọ́sẹ̀ mẹ́wàá ni a ti rí Kiddwaya, ọmọ baba olówó Terry Waya àti ìgbákeji olórí ilé Wathoni ti orúkọ rẹ̀ gan n jẹ́ Florence Wathoni Anyansi.
Ṣugbọn ni nnkan bi oṣu diẹ sẹyin ni iroyin gbode pe Olori naa ti ko kuro ni aafin Iku Baba Yeye.
Oríṣun àwòrán, Oluwo/instagram Oluwo ni àwọn òwe Yorùbá kan wà tó yẹ kí a yí padà lédè Yorùbá B'ọ̀mọdé bá láṣọ bí àgbà kò lè lákìísà bí àgbà Erin kìí fọn kí ọmọ rẹ̀ fọn - ṣé a ò yí ilé koríko padà máá wá kọ́ ilé bíríkì báyìí?
Igba akọkọ si re e ti wọn yoo fi ado oloro pa eeyan ni Naijiria.
Ó sun ilé OLUWA níná ati ilé ọba ati gbogbo ilé tí ó wà ní Jerusalẹmu; gbogbo àwọn ilé ńláńlá ní ó dáná sun.
Ó sọ fún wọn pé, “Ẹ lọ sí ìletò tí ó wà ní ọ̀kánkán yín yìí.
Ṣé ẹ̀ṣẹ̀ tí a dá ní Peori, tí a kò tíì wẹ ara wa mọ́ kúrò ninu rẹ̀ kò tíì tó?
"N ṣe lawọn eeyan n ṣi mi gbọ ninu gbogbo ilakaka mi lati gbe ipinlẹ Imo goke agba.
Nítorí mo mọ̀ dájú pé gẹ́rẹ́ tí mo bá kú tán, ìṣekúṣe ni ẹ óo máa ṣe, ẹ óo sì yipada kúrò ní ọ̀nà tí mo ti pa láṣẹ fun yín, ibi ni yóo sì ba yín ní ọjọ́ iwájú, nítorí pé ẹ óo ṣe ohun tí ó burú lójú OLUWA.
Nipa eto ilera ni ipinlẹ Eko, gbogbo awọn oludije lo ṣalaye ilana eto ti wọn ni fun ilera.
Kìnìún mẹ́rìnlá bọ́ sígboro Lẹ́yìn-ọ̀-rẹyìn, bàbá ọgọ́rùn-ún ọdún gba ìdáǹdè l‘ẹ́wọ̀n O ba awọn akọroyin sọrọ lẹyin ipade kan to ṣe pẹlu Igbakeji Aarẹ Yemi Osinbajo, saaju ipade naa si ni gbogbo awọn gomina nilẹ wa ti ṣe ipade pọ pẹlu aarẹ Muhammadu Buhari ni Abuja.
Àwọn òǹtàjà kọjú ìjà sáwọn òṣìṣẹ́ tó ń wó ìsọ̀ wọn ní Ketu, ọta ìbọn ba éèyàn kan A ó pe àjọ DSS lẹjọ́ tí wọ́n bá kọ̀ láti tú Sowore sílẹ̀ - Falana Àbá ìṣúná ₦1.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Chad prisoners death: Ẹlẹ́wọ̀n 44 kú lagbà ẹ̀wọ̀n ní Chad látàárí ooru tó mú púpọ̀ 3 Agẹmo 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 12 Ògún 2020 Oríṣun àwòrán, AFP Àkọlé àwòrán, Eeyan mẹrinlelogoji Iwadii lori awọn ẹlẹwọn mẹrinlelogoji to ku si ọgba ẹwọn orilẹ-ede Chad ti pari.
Rape: Norma Ka Mbele ní ayé òun kò rí bákàn náà mọ́ lẹ́yìn ìfipábálòpọ̀
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Super touch: Roller Blader ni mí láti ọdún mẹ́jọ sẹ́yìn Eyi lo si fi mọ pe olododo eniyan ni mo jẹ.
6 miliọnu sagba Muhammadu Buhari ninu ibo aarẹ.
Wọnyii ni atupalẹ iye awọn to lugbadi arun covid-19 ni Naijiria lọjọ Abamẹta: Lagos-461 FCT-206 Plateau-197 Rivers-168 Kaduna-116 Anambra-53 Ogun-49 Ebonyi-47 Edo-42 Sokoto-32 Imo-31 Katsina-31 Oyo-30 Akwa Ibom-27 Delta-16 Kano-16 Abia-15 Niger-15 Ondo-11 Bayelsa-10 Borno-9 Kebbi-8 Ekiti-7 Jigawa-1 Lapapọ, eeyan 108,943 ni akọsilẹ fihan pe wọn ti larun covid-19 ni Naijiria nigba ti 85,367 ti ri iwosan.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Ni ẹka ẹnawo, iwadi naa sisọ loju rẹ pe awọn ijọba to wa lẹkun iwọ oorun Afrika lo n se iwuri fun aibaradọgba laarin awọn eeyan wọn nitori pe wọn ko pese owo sita fun ẹka igbe aye ọmọ niyan bii eto ẹkọ ati ilera.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Fathia Balogun: Kò sí ẹni tó bá mi lò pọ̀, kó tó fún mi ní isẹ́ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Fathia Balogun: Kò sí ẹni tó bá mi lò pọ̀, kó tó fún mi ní isẹ́ 19 Èrèlè 2018 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 22 Agẹmo 2018 Gbajú-gbajà òsèré tíátà, Fatia Williams, tí gbogbo èèyàn mọ̀ sí Fathia Balogun, lásìkò tó ń bá BBC Yorùbá sọ̀rọ̀ ní, orúkọ̀ tó bá wu òun ni òun leè jẹ́, àmọ́ ọ̀kan náà ni Fathia Balogun àti Fathia Williams, ìlò wọn sì wà lọ́wọ́ isẹ́ tí òun bá ń se.
náà si n reti lati mọ iru ọmọ ti idibo yii yoo bi.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Lagos Rape: Ẹnikẹ́ni tó bá á ní ìbálòpọ̀ pẹ̀lú ọmọ kékeré jẹ́ alárùn ọpọlọ- Onímọ̀ 25 Ọ̀wàrà 2019 Oríṣun àwòrán, Facebook/women of rubies Àkọlé àwòrán, Iwaadi fi han pe okunrin naab jẹbi ẹsun fifi ipa ba ọmọ ọdun meji lopọ Ẹnikẹni to ba n ni ibalopọ pẹlu ọmọ kekere jẹ alarun ọpọlọ to nilo ayẹwo.
Àwọn ni ará Keni tí wọ́n ṣẹ̀ láti ọ̀dọ̀ Hamati baba ńlá wọn ní ilé Rekabu.
Bẹẹ lo tun sọrọ alufaṣa si awọn Musulumi, to si pe awọn awọn kan lara wọn ni alakakiti ẹsin.
Ọmọ yìí bá sọ fún un pé, ‘Àbúrò rẹ dé, baba rẹ sì pa mààlúù tí ó sanra, ó se àsè nítorí tí àbúrò rẹ pada dé ní alaafia.
Ogun ń bẹ lóde; àjàkálẹ̀-àrùn ati ìyàn wà ninu ilé.
Odion Ighalo darapọ mọ́ ikọ̀ Manchester United, òjijì ló bá àwọn olólùfẹ́ rẹ̀ Ohun tó ti yá kan kìí pẹ́ mọ́, fọ́ọ̀mù ìgbaniṣíṣẹ́ fún Àmọ̀tẹ́kùn dé!
Minisista abẹle feto ẹkọ ni Naijiria, Emeka Nwajiuba, lo sọ ọrọ yi lasiko to n bawọn akọroyin sọrọ nibi ti igbimọ aarẹ to n dari eto gbogbo nipa Covid-19 n jabọ farailu.
Ninu ọrọ to ba BBC News Yoruba sọ, Alhaji Aderẹmi Jimọh ṣalaye pe ko si igba kan ninu itan oye Babalọja general ni ipinlẹ Ọyọ jijẹ ti oye naa wa lati ọdọ balaye kankan ni ipinlẹ Ọyọ, bẹẹni ko si eyikeyi ti wọn jẹ ni aafin ọba.
O si tun n kilo fun aare Buhari lati maa se dije fun ipo aare leekeji.
Wọ́n yí òtítọ́ Ọlọrun pada sí irọ́.
Ẹja yìí jẹ́ ìyàlẹ́nu fún ọba ó sì pàṣẹ fún ìyàwó rẹ̀ kí lọ sè é fún òun, obìnrin náà sì lọ.
Ìtùmò : akínkanjú obinrin kan wa ni Ègbá ni ayé ojóun .
Lori iṣẹlẹ naa, alukoro ileeṣẹ ọlọpaa ipinlẹ Ogun, Abimbọla Oyeyẹmi sọ fun BBC Yoruba pe kọmisana ọlọpaa ipinlẹ naa, Bashir Makama ti ko awọn oṣiṣẹ alaabo lọ si ibi ti iṣẹlẹ naa ti waye lati doola awọn ti wọn jigbe ọhun.
Nítorí mo gbọ́ igbe kan, tí ó dàbí igbe obinrin tí ó ń rọbí,ó ń kérora bí aboyún tí ó ń rọbí alákọ̀ọ́bí.
“As a citizen of this country, we have responsibility to prevent such products from coming in and as a nation; we ought to discourage citizens from patronising such products.
 Nigba ti agbenusoro fun awon  oludije naa, Morondiya Aiye to je omo egbe Unity
Kò sá tún lè pada wọ inú ìyá rẹ̀ lẹẹkeji kí á wá tún un bí!
Ekun Oromia je agbegbe ti ifehonu-han tako ijoba ti maa n waye lati odun 2015 si odun 2016, titi ti ijoba fi kede ilu-o-fara ro ninu osu kokanla odun  naa, eyi ti ijoba gbese kuro lori ikede naa ninu osu kejo odun 2017, amo ijoba tun ti kede olosu mefa miiran latari oro eto-aabo.
Gẹ́gẹ́ bí àṣà wa ní ilẹ̀ Yorùbá, a máa nkírawa gẹ́gẹ́ bí ojú ọjọ́ ti rí ni.
N óo nawọ́ ibinu sí ọ,n óo sọ ọ́ di ahoro ati aṣálẹ̀.
Ẹ máa fi orúkọ rẹ̀ ṣògo,kí ọkàn àwọn tí wọn ń sin OLUWA kún fún ayọ̀.
Mikel John Obi (Middlesbrough FC, England); Wilfred Ndidi (Leicester City,
Joramu bá kígbe pé, “Ọ̀tẹ̀ nìyí, Ahasaya!
Yatọ si awọn afurasi yi ti wọn ṣafihan wọn, wọn tun fi arakunrin ogboju ọlọṣa kan Fatai Ismail han.
Los Ageles gbe ilẹkun ile ounjẹ, ile ijo ti pa Olootu ijọba Los Angeles l'orilẹ-ede America, Eric Garcetti ti paṣẹ pe, ki gbogbo awọn ile ọti, ile ounjẹ, ati ile ijo to wa nilu naa gbe ilẹkun wọn ti.
 O ni “bi ẹmi ba wa ireti si n bẹ fun ọjọ iwaju rere.
Ó sọ lọ́kàn ara rẹ̀ pé, “Ọlọrun ti gbàgbé,OLUWA ti gbé ojú kúrò, kò sì ní rí i laelae.
Yahaya da ẹgbẹ kan silẹ lori ikanni WhatsApp fun awọn eeyan to ni ifẹ Anọbi Muhammed, o pe orukọ ẹgbẹ naa ni Umma Abiha."
Iṣẹlẹ ohun jẹ iyalẹnu fun awọn eniyan l'orileede naa, iranlọwọ si dide fun un lati ọdọ awọn ara ilu.
2019 Election: INEC ya ọ̀sẹ̀ kan sílẹ̀ fún àyẹ̀wò orúkọ oludibo
Igba to lọ sile iya ọkọ rẹ, o ri ọpọ eniyan to ko rajọ, ti wọn si n sunkun.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Super Falcons: Thomas Dennerby di olukọni mọọgba 25 Sẹ́rẹ́ 2018 Oríṣun àwòrán, AFP Àkọlé àwòrán, Thomas Dennerby yoo dari ikọ ọmọ ẹgbẹ Super Falcons di ọdun 2020 Ile Isẹ igbimọ alakoso fun ere bọọlu orilẹede Naijiria (NFF) ti t'ọwọ b'ọwe pẹlu ogbontarigi akọni mọọgba kan Thomas Dennerby ti o jẹ olukọni agba fun ọmọ ẹgbẹ agbabọọlu obinrin ti orile-ede Naijiria, Super Falcons.
se jiroro lori ẹjọ to ba ti wa nile- ẹjọ.
ọmọ Etani, ọmọ Sima, ọmọ Ṣimei, 
Ìdí nìyí tí mo fi ń fi àkọ́bí ẹran ọ̀sìn mi, tí ó bá jẹ́ akọ rúbọ sí OLUWA, tí mo sì fi ń ra àwọn àkọ́bí mi ọkunrin pada.
SayNotoRape: Àlùfá tọ ba ọmọ ọdún méje sùn, wẹ̀wọ́n ọdún Márùn-un ni ìpínlẹ̀ Ekiti
Bi awuyewuye yii ṣe n lọ lọwọ ni olugbani nimọran Aarẹ Muhammadu Buhari, Lauretta Onochie fi tikẹẹti ọkọ ofurufu kan to ni orukọ gomina Fayose sita.
O ni oun ti fẹ sọ pe iru adari ti a fẹ leleyii ṣugbọn oun tun ranti pe ẹgbẹ oṣelu APC naa maa n sọ ọrọ ọlọgbọn tẹlẹ ki wọn to ko wọ inu Aso Rock ti ohun gbogbo si yi biri.
8% ninu ida ọgọrun owo isuna ọdọọdun ni ijọba apapọ n na sẹka ilera.
'Irọ ni Amnesty International pa mọ wa' Ọwọ ologun tẹ darandaran mẹwa ni Benue Ìgbà mélòó ni darandaran ti kọlu wàá?
Òfin ati ìlànà kan náà ni yóo wà fún ẹ̀yin ati àjèjì tí ń gbé pẹlu yín.
Gbogbo wọn dé inú igbó, wọ́n rí oyin nílẹ̀.
Ipade ọhun, to gba wọn to wakati meje gbako, ni wọn tun sun siwaju di ọjọ Aje, ọjọ Keje osu Kinni ọdun 2019.
Olumo Rock: Òrìṣà Igùn lọba ọ̀pọ̀ òrìṣà tó wà lábẹ́ Olúmọ tó ń dáhùn àdúrà
O soro yii nigba ti o n baa won oniroyin soro nile-ise Aare, leyin ipade bonkele kan pelu Aare Buhari.
Níbẹ̀ ni n óo ti ṣe ìdájọ́ rẹ̀ nítorí ìwà ọ̀tẹ̀ tí ó hù sí mi.
Mose bá pàṣẹ, wọ́n sì kéde yí gbogbo àgọ́ ká, pé kí ẹnikẹ́ni, kì báà ṣe ọkunrin, tabi obinrin, má wulẹ̀ ṣòpò láti mú ọrẹ wá fún kíkọ́ ibi mímọ́ náà mọ́.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: ‘Daily Trust fi àsírí ìgbógun tí Boko Haram jáde la se tì í’ Kíni Amosun mú Adekunle lọ ṣé lọdọ Buhari?
Oríṣun àwòrán, Twitter Kọmisọnna fun eto ilẹra nipìnlẹ Eko, Ọjọgbọn Akin Abayomi lo sọ bẹẹ loju opo ikansiraẹni Twitter rẹ.
Ajọ to n mojuto ọrọ awọn ọmọ Naijria nilẹ okeere ti ko awọn ọmọ Naijiria to ha si ilu Dubai pada sile.
 Ó jẹ ́ ibìkan ní ìlú èkó tí ó ti wà tipẹ ́ , ọ ̀ pọ ̀ lọpọ ̀ àwọn ilé tí ó wà níbẹ ̀ ni wọ ́ n ti kọ ́ ní ìgbà ìletò àkọ ́ kọ ́ , tí wọ ́ n sì kọ ́ àwọn ilé tí ó wà níbẹ ̀ bi èyí tí ó wà ní orílẹ ̀ èdè brazil .
Oríṣun àwòrán, Other Olubadamọran pataki fun Aarẹ Buhari, Garba Shehu lọ sọ bẹẹ pe nitori o gba aṣẹ lọwọ Baba rẹ ni o fi lo ọkọ ofurufu naa.
Ẹ gbọ́, ẹ̀yin olórí ilé Jakọbu, ati ẹ̀yin alákòóso ilé Israẹli!
"Àwọn ẹgbẹ́ agbábọ́ọ̀lù ìlẹ̀ Gẹ̀ẹ́sì fẹnukò láti parí líìgì ọdún yìí Àwọn jẹsí tó gbajúmọ̀ nínú ìtàn ìdíje bọ́ọ́lù Bí ilumọọka agbabọọlu Drogba ṣe dáwọ ogun dúró ní Ivory Coast Ebi àṣeyọrí ló n pa mí báyìí lẹ́yìn àkókò mi tó ti ṣòfò - Paul Pogba ""Ẹgbẹ wà fí ìbínú ṣàfihàn ifehonuhan wà sí agbabọọlu yi"" Wọn fi kun ninu atẹjade pé àwọn tí sáájú tẹpẹlẹmọ pàtàkì titẹle alakalẹ ìjọba tó fi mọ dideju mọlé lásìkò ta wa yí nípa atẹjade orisirisi fawọn oṣiṣẹ wà"" Wọn wà tun so pe awọn ""gbosuba káre fawọn oṣiṣẹ ilera fún ifaraji wọn."
Iwájú tí ó dàbí ti eniyan kọjú sí igi ọ̀pẹ ní ẹ̀gbẹ́ kinni, ekeji tí ó dàbí ti ọ̀dọ́ kinniun kọjú sí igi ọ̀pẹ ní ẹ̀gbẹ́ keji.
O sàlàyé ilé iṣẹ́ ọmọ ogun ko ní sàì yọ ẹnikẹ́ni ti ìgbà ọ̀rọ̀ náà ba si mọ lóri níṣẹ́ pẹ̀lú ìjìyà tó tọ́ sí irú ẹní bẹ́ẹ̀ àti gbogbo àwọn ti wọ́n jọ sowọ́ pọ̀.
30 Èbibi 2019 BBC Yorùbá jáde bèèrè irúfẹ́ ọmọ ti Yorùbá n pè ni Ìgè.
À ń gba ẹ̀rí eniyan, ṣugbọn ẹ̀rí Ọlọrun tóbi ju ti eniyan lọ; nítorí ẹ̀rí Ọlọrun ni, tí ó jẹ́ nípa Ọmọ rẹ̀.
Lẹ́yìn tí Jesu ti gba ọtí náà tán, ó wí pé, “Ó ti parí!
Ẹ̀sìn ìṣẹ̀ṣe ṣún síwájú, wo orin aládùn lẹ́nu ẹgbẹ́ akọrin àti ìjèrè ọkàn tí wọn ń ṣe Ojúlówó Shina Rambo yọjú sígboro lọ́jọ́ Àìkú, ó fi ìka hánu lórí ìpànìyàn tó ti ṣe Àwọn ọ̀dọ́ Benue pa pásítọ̀ ti wọ́n fẹ̀sùn kan pé ó ń mú ǹkan ọmọkunrin Iléẹjọ́ mú ọjọ́ kejìdínlógún, oṣù kọkànlá fún ìgbẹ́jọ́ àwọn tó jí ìbejì Àáfà Akeugbagold ní Ibadan Àgọ́ ọlọ́pàá Sanyo ni wọ́n darí ọkọ̀ akérò tó kó àwọn Fulani wọ ìlú Ibadan lọ - Oyo OPC Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí 2 sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 2:23 Fídíò, Water Generator: Ó leè ṣiṣẹ fún wákàtí mẹfà, kó tó sinmi, Duration 2,2310 Òkùdu 2020 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
“Ní àkókò náà, ọ̀rọ̀ ìjọba ọ̀run yóo dàbí ohun tí ó ṣẹlẹ̀ sí àwọn wundia mẹ́wàá, tí wọn gbé àtùpà wọn láti jáde lọ pàdé ọkọ iyawo.
Ní báyìí, ilú Bikoro ni orílẹ̀èdè DR Congo ni a gbọ́ pé àìsàn náà tún ti bẹ́ jáde.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù WrestleMania 35: Kingston fẹnu ọmọ Amẹrika gbo lẹ̀ láti gbàmì ẹ̀yẹ 8 Ìgbé 2019 Oríṣun àwòrán, Twitter/WWE Àkọlé àwòrán, Kofi di ilumọọka ajijankadi Aileja lojude baba mi ko de bi ni Yoruba maa n wi.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Igba wo ni abẹrẹ ajẹsara yii yoo bẹrẹ si ni wa fun awọn eniyan lati gba si ara wọn?
Samuẹli bá mú Saulu ati iranṣẹ rẹ̀ wọ inú gbọ̀ngàn ńlá lọ, ó fi wọ́n jókòó sí ààyè tí ó ṣe pataki jùlọ níbi tabili oúnjẹ tí wọ́n fi àwọn àlejò bí ọgbọ̀n jókòó sí.
Imọtoto ni Yoruba gba pe o le ṣẹgun arun gbogbo paapaa laisko ajakalẹ arun Coronavirus to n ba agbaye finra yii.
Oríṣun àwòrán, @officialasanlu Àkọlé àwòrán, Ni kete ti Afọnja pada de lati Apomu lo gba aafin Ọyọ lọ, to si ni ki Alaafin Aolẹ funra ara rẹ fi ori apere silẹ Ki lo sokunfa aawọ nla laarin Afọnja ati Alaafin Aolẹ?
Àwọn Juu sọ fún ọkunrin tí ara rẹ̀ ti dá yìí pé, “Ọjọ́ Ìsinmi ni òní!
Ó sàn fún mi kí n má tíì lọ́kọ báyìí ju kí n lọ́kọ ṣùgbọ́n.
Ó bi wọ́n léèrè pé, “Ṣé nítòótọ́ ni ẹ kò fi orí balẹ̀, kí ẹ sì sin ère wúrà tí mo gbé kalẹ̀?
Tẹjuoṣo ni gbogbo ode alujo orin ti wọn gbe kalẹ wa lati ta awọn orin naa.
ní àṣáálẹ́, nígbà tí ọjọ́ ń pofírí,tí ilẹ̀ ti ń ṣú, tí òkùnkùn ti ń kùn.
Sibẹsibẹ, D'banj ko ti i sọ nkankan lori rẹ, yatọ si fidio kan to fi n jo si orin rẹ kan 'Ọlọrun ma jẹ'.
 A fẹ ki won ran wa lowo
Ninu ẹ̀yà Aṣeri, àwọn tí wọ́n tó ẹni ogún ọdún, tí wọ́n tó lọ sójú ogun, gẹ́gẹ́ bí àkọsílẹ̀ wọn ní ìdílé-ìdílé 
Ẹgbẹ oṣelu Peoples Democratic party ti kesi ijọba Naijiria labẹ Aarẹ Muhammadu Buhari lati da owo jala bẹntiroo ati ina mọnamọna ti wọn lekun pada walẹ ni kiakia.
Kí wọ́n tó lọ, ó sọ fún wọn pé, “Ẹ gba ọ̀nà ìhà àríwá, kí ẹ tọ̀ ọ́ lọ sí ìhà gúsù ilẹ̀ Kenaani, kí ẹ wá lọ sí àwọn orí òkè.
 oríṣi tó níí ṣe pẹ ̀ lú ihò nínú ara a má a sábà nílò iṣẹ ́ abẹ , òògùn lílò a sì tẹ ̀ lé e .
Wọ́n bá mú àwọn aposteli, wọ́n tì wọ́n mọ́lé ninu ilé ẹ̀wọ̀n ìgboro ìlú.
Olόwό-Ìbínú kì-í ṣe ohunkόhun láì ronú owó.
Olanipekun ni iye awọn to pegede ninu esi idanwo naa ni Ọkunrin jẹ 389, 655 (ida 47.
Agbẹnusọ fun ileeṣẹ ọlọpaa ni awọn yoo gbe awọn afurasi marun un tọwọ ọlọpaa tẹ lọ si ileẹjọ.
Àwọn kan gbé àwọn ọmọ kéékèèké wá sọ́dọ̀ rẹ̀ kí ó lè fi ọwọ́ kàn wọ́n.
Mo ti rí ìwà ìbàjẹ́ yín,gbogbo ìwà àgbèrè yín, bí ẹ tí ń yan ká bí akọ ẹṣin,ati ìwà ìṣekúṣe yín ní orí àwọn òkè ninu pápá.
Conjoined Twins: Wọ́n fi mí ṣe yẹ̀yẹ́ ládùúgbò, ojú tì mì
Ọlọ́pàá kọlu àwọn ọmọ onílẹ̀, ní ìbọn àṣìyìn pa ènìyàn méjì 'Ti o ba jẹ iriri lọba lootọ o yẹ ki ipinlẹ Ondo ti dagba ju bayi lọ' Oludije ẹgbẹ YPP ti sọ idi ti o se yẹ ki wọn fun awọn ọdọ lanfaani lati se ijọba.
Oríṣun àwòrán, AcupofKhafi Àkọlé àwòrán, Kíní ǹkan tí Kafayat Kareem ó pàdánu tí iṣẹ́ ba bọ́ lọ́wọ́ rẹ̀ O ni bi Khafi se ni ibalopọ pẹlu akẹẹgbẹ rẹ lori eto BB Naija tako asa ati ise ọmọ Yoruba to maa n bọwọ fun ara wọn, ti asa ilẹ Kaarọ oojire si lodi si iru iwa bayi lojutaye.
Eleyi lo njẹ ki àwọn iṣẹ́ ti ìjọba bá gbé sita lati tú ọ̀nà ṣe, lati pèsè iná mọ̀nàmọ́ná, omi àti ohun amáyédẹrùn miran wọn ju ti gbogbo àgbáyé lọ.
Ẹ ronú nípa iṣẹ́ wọn ati bí wọ́n ṣe kú.
Adájọ́ pàṣẹ kí wọ́n fi ọlọ́pàá tó lọ́wọ́ nínú ikú Kolade Johnson sí àhámọ́ Tani Deji Adenuga to dáná sun ènìyàn mẹ́jọ?
ologun gbodo maa ranti ofin ati ilana orile ede nigba ti won ba n se ojuse won,
Agba Inaki, lasiko to n kopa lori eto kan lori ikanni BBC Yoruba tun sisọ loju rẹ pe, ọmọ bibi ilu Ogbomoso ni oun, ti ẹru kankan kii si ba oun.
Òkúta tí mo sì gbé nàró bí ọ̀wọ̀n yìí yóo di ilé Ọlọrun, n óo sì fún ìwọ Ọlọrun ní ìdámẹ́wàá ohun gbogbo tí o bá fún mi.
Awọn alaga naa ni, ijọba Seyi Makinde setan lati san gbogbo owo oṣu ati ajẹmọnu awọn fun iye ọdun to ku, to yẹ kawọn fi pari saa awọn gẹgẹ bii alaga kansu, eyi tii se ara ilana ati pana aawọ naa, ṣugbọn awọn ko fẹ bẹẹ.
Awọn ajafẹtọ naa wa kesi ijọba ipinlẹ Oyo lati ri wi pe wọn fi ileeṣẹ naa jofin, ki iru iṣẹlẹ bẹẹ ma baa tun waye mọ.
 Bo tile je pe  ile naa ti wa
Kí gbogbo àwọn ọmọ ogun súnmọ́ tòsí,ogun yá!
Ìrísí wọn dàbí ìrísí ẹṣin,wọ́n sì ń sáré bí ẹṣin tí ń lọ ojú ogun.
Ijọba ipinlẹ Eko ti gbe igbimọ kan dide lati wa okodoro ohun to fa igbugbamu naa, gomina ipinlẹ Eko, Babajide Sanwo-Olu si ti ṣeleri pe oun yoo fi esi iwaadi naa lede.
Lootọ iroyin sọ pe idasilẹ ọlọpaa agbegbe (State and LG police) wa lara awọn ohun ti igbimọ yii da laba fun Aarẹ Buhari ninu abajade iwadii rẹ ṣugbọn gẹgẹ bii amugbalẹgbẹ fun aarẹ lori ọrọ iroyin ati ipolongo, Garba Shehu ṣe sọ, eyi ko tumọ si pe aarẹ ti buwọlu u.
Ọkunrin náà bá sọ fún mi pé, “Ìwọ ọmọ eniyan, ṣé o rí nǹkan?
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ọ̀kan lára àwọn akẹ́kọ̀bìnrin Chibok kàwé gboyè l'Amẹrika Àìgbọ́ran sí igbákejì ààrẹ Yemi Osinbajo lẹ́nu ló fa ìdàmú mi-Okorocha Ajá dóòlà ọmọ tuntun tí ìyá rẹ̀ bò mọ́lẹ̀ láàyè Adeleke ninu atẹjade kan ni oun ko reti ohun miran ni ile ẹjọ to ga julọ lorilẹede Naijiria bi ko ṣe ikede pe oun ni gomina ti ilu dibo yan.
Dafidi ranti ilé, ó ní, “Kì bá ti dùn tó kí n rí ẹni fún mi ní omi mu láti inú kànga tí ó wà lẹ́nu ibodè Bẹtilẹhẹmu!
Wọ́n di àwọn mẹtẹẹta pẹlu agbádá, ati aṣọ àwọ̀tẹ́lẹ̀, ati fìlà wọn, ati àwọn aṣọ wọn mìíràn, wọ́n sì sọ wọ́n sí ààrin adágún iná tí ń jó.
 ”Mo n  fojusona fun ifesewonse naa tori pe, mo ti kopa ri ninu idije ile geesi EPL, ti ma si feran lati ri awon oju ti a jo wa tele.
Egbe oselu National Grand Coalition (NGC) ti o ya kuro lara egbe oselu alatako Kandeh Yumkella, ti o je omo egbe ajo isokan UN teleri, , ti o tun je onisowo pata ki Musa Tarawally tun dari re.
 A se daradara rara, sugbon Mo ba awon agbaboolu mi soro lati pa okan po soju kan, inu mi si dun pe a jawe olubori ni keyin!
''Mo ti n gbadun bọ diẹ diẹ, ohun kan ti mo n ro lasiko yii ni lati gbadun pada,'' Wilder lo sọ bẹẹ.
24 Bélú 2017 Friday the 13th: Why pipo for overseas see di day as bad-luck day13 Ọ̀pẹ̀̀ 2019 Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Ninu ìdílé Heburoni, Haṣabaya ati ẹẹdẹgbẹsan (1,700) àwọn arakunrin rẹ̀, tí wọ́n jẹ́ alágbára ni wọ́n ń bojútó àwọn ọmọ Israẹli tí wọ́n wà ní apá ìwọ̀ oòrùn odò Jọdani, tí wọn ń ṣe iṣẹ́ OLUWA ati iṣẹ́ ọba, 
10 Owewe 2019 Oríṣun àwòrán, Inec Àkọlé àwòrán, Ogun Election: Ilé ẹjọ gbé àga lọ rèé jókòó jẹ sílé fún Ọsunsanya.
Orukọ mii fun igbẹ ni imi, eyi to tumọ si awọn nkan ti ko daa lara to fi mọ ounjẹ, kokoro atawọn nkan mii ti ko sẹrẹ lara ti ko si wulo fun ara eyi ti o n gba idi igbẹ jade sita.
Sugbọn ta ba n sọrọ awọn obinrin takuntakun nilẹ Ibadan ati nilẹ Yoruba, itan ko lee gbagbe Ẹfunsetan Aniwura, tori o se iwọn to lee se lasiko tiẹ.
BBC gbiyanju lati ba Jolaosho sọrọ lori foonu nipasẹ numba kan to fi si ori ayelujara Twitter rẹ, ṣugbọn igbiyanju wa ko so eso rere.
Kò yẹ kí eniyan máa waasu nípa irú nǹkan báwọ̀nyí, Ọlọrun kò ní dójútì wá.
Adepoju sàlàyé pé, níwọ̀n ìgbà ti àwọn mùsùlùmí àti onígbàgbọ́ kò lọ sí ilé ìjọsìn lásìkò ọdún wọ́n, kò sí bí ọ̀bọ ṣe sorí ti ìnàkí kò ṣe nítori náà àṣẹ ìjọba ni yóò múlẹ̀.
Oríṣun àwòrán, Ogun State Governor's office Àkọlé àwòrán, Ọdun 2016 ni gomina ipinlẹ naa, Ibikunle Amosun fi ajọdun naa le lẹ.
Ẹ ṣọ́ra kí ẹ má baà sọ ọrẹ mímọ́ àwọn ọmọ Israẹli di àìmọ́ nípa jíjẹ wọ́n láìsan ìdámẹ́wàá wọn.
foláṣádé : Òun ni ó jí owó orímóògùnjẹ ́ kó .
O wi pe iwadi ti o peye yoo waye lori isẹlẹ naa, nigbati o tẹnumọ iwulo fun awọn onile-epo ati afẹfẹ gaasi lati rii daju wipe eto wa fun awọn ohun eelo idojukọ isẹlẹ pajawiri lẹnu isẹ ati ni ibudo ikepopamọsi gbogbo.
Nítorí náà, Ahabu pe gbogbo àwọn Wolii jọ, gbogbo wọn jẹ́ irinwo (400).
Títí ilẹ̀ ọjọ́ fi ṣú, ariwo ẹkún ni ó gba ilé kan.
Wọ́n sọ fún un pé, “Ìran Abrahamu ni wá, a kò fi ìgbà kan jẹ́ ẹrú ẹnikẹ́ni.
Ninú èyí taa tí rí ara àwọn oludasilẹ ìjọ onitẹbọmi Baptist, Ẹni-ọwọ Thomas Bowen, to da ilé ẹ̀kọ́ silẹ ni ilu naa ati ìjọ onitẹbọmi àkọ́kọ́ ni Naijiria.
"Akeugbagold ni awọn eeyan to lọwọ ninu bi wọn ṣe ji ibeji oun gbe ni awọn nilo owo ni awọn ṣe huwa naa, ti awọn si gbọ pe oun lowo lọwọ, oun kan n fi ara pamọ ni.
- Primate Ayodele sọ àsọtẹ́lẹ̀ N kò tíì pa ọ̀rọ̀ ìfẹ́ tì, bí mo tilẹ̀ ti kúrò nílé ọkọ - Mercy Aigbe Aarẹ orilẹede Naijiria tẹlẹri, Ọgagun Oluṣẹgun Obasanjọ wa sapejuwe Bajọwa gẹgẹ bi ẹni to ni irẹlẹ ọkan, to si n bọwọ fun agba.
Gideoni tún dáhùn, ó ní, “Bí inú rẹ bá yọ́ sí mi, fi àmì kan hàn mí pé ìwọ OLUWA ni ò ń bá mi sọ̀rọ̀.
Ẹni ti ó nta ọjà á sọ̀rọ̀ si onibárà pẹ̀lú ẹ̀gàn, ojúkòkòrò, ìfẹ́ owó ki kó jọ ni ọ̀nà ẹ̀rú àti à ṣe hàn ló nfa iwà ibàjẹ́ àti olè jijà laarin àwọn Òṣèlú, olóri ẹ̀sìn, òṣiṣẹ́ Ìjọba, ọlọ́jà ti ó nkó ọjà pamọ́ lati fa ọ̀wọ́n, Olùkọ́ ilé iwé, ọmọ ilé-iwé kò ni itẹriba fún Olùko mọ́, àti bẹ́ ẹ̀ bẹ́ ẹ̀  lọ.
Ko gbọdọ si ọlọkada kankan to gbọdọ rinna yatọ si awọn to n ṣe iṣẹ alaaro(courier) Gbogbo awọn ileeṣẹ to fẹ bẹrẹ iṣẹ pada lọjọ kẹrin gbọdọ yoo maa ṣiṣẹ laarin agogo mẹsan owurọ si mẹta ọsan.
Èsì ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ ọjọ́ Àìkú fi hàn pé Nàìjíríà àti South Africa yóò tẹ̀síwajú ló sí ìpele tó kágun sí àṣekágbá (Semi-final) nínú ìdíje bọ́ọ̀lù àwọn obìnrin l'Afrika (AWCON).
Ṣùgbọ́n, iwọ Ajẹdiran, o kò si ni ipò àwọn aláìgbọ́n; ẹ̀gbọ́n rẹ jẹ pàtàkì fún ọ, bẹ́ẹ̀ ni àbúrò tí ó ba gbé ẹ̀gbọ́n ga lónìí kò ni ṣàì ri ìgbéga ẹhin ọ̀la, nítorí ojú àwọn ọmọ ẹ̀hìn kò fọ́, ó là silẹ kedere.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Yemi Osinbajo: Igbákejì ààrẹ ní ìṣẹ́ àti òsí tí Covid-19 kó bá wa, kò ṣe dúró wò 21 Èrèlè 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 9 Owewe 2020 Oríṣun àwòrán, Others Yoruba ni oye ni agba n wo, bẹẹ si ni agba ti ko ba kẹhun sọrọ, afaimọ ko ma kẹtan sare.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù NYSC: àgùnbánirọ̀ márùn ún gb'òmìnira lọ́wọ́ ajínigbé 21 Ọ̀wàrà 2018 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 26 Ọ̀wàrà 2018 Oríṣun àwòrán, NYSC Àkọlé àwòrán, NYSC Ile iṣẹ ọlọpaa ti gba awọn agunbanirọ marun ati awọn eeyan meji miran silẹ lọwọ awọn ajinigbe ninu igbo kan nipinlẹ Imo.
Bí kò bá gba ti ìjọ, kà á kún alaigbagbọ tabi agbowó-odè.
Aaroni sì ṣe gẹ́gẹ́ bí àṣẹ Mose.
Ileeṣẹ ọlọpaa fidi rẹ mulẹ pe awọn eeyan naa ti gbogbo wọn jẹ ọkunrin wa lati orilẹede Burkina Faso, Mali atawọn orilẹede ile Afirika miiran.
Awọn igbimọ yi ni yoo wa jabọ fawọn olri nipa ibi ti wọn ba ti ri oṣu tuntun.
Abewo Obama akoko si Egypt losu kefa odun 2009Irin-ajo Obama je elekewaa re ni eyi to ti lo si Cairo lojo kerin osu kefa odun 2009.
Àwọn òṣèré tíátà Yorùbá kọjú ìjà síra wọn lórí ìdárò akẹẹgbẹ́ wọn tó kú Aarẹ Mali sọ pe, oun ko lagbara kan mọ lẹyin tawọn kan ni ileeṣẹ ologun pinnu lati yẹ aga mọ oun nidi.
Ìgbà tí Àrùn bẹ̀rẹ̀ sí ro ẹjọ́ níwájú Ẹni tí Ó dá a, ó sọ̀rọ̀ àìyẹ jáde lẹ́nu, eléyìínì náà lo sì mú kí Olódùmarè lé e jáde ni òde ọ̀run.
Ilé-iṣẹ́ tí ó ni ilé ìtajà-ìgbàlóde Maxi, Delez Srbija, ṣe àgbéjáde àkọsílẹ̀ ìtúúbá lọ́jọ́ kan náà, ó sọ pé àwọn “gbàgbọ́ pé èyí á wà bí ìṣẹ̀lẹ̀ ìyàsọ́tọ̀ tí ó mú ìfura ẹni tí kò yẹ dání pé irú ìṣẹ̀lẹ̀ bẹ́ẹ̀ ò ní wáyé mọ́ lọ́jọ́ iwájú.
Sugbọn ṣa, iwọde ipolongo #ENDSARS ko ti i dawọ duro.
Majek Fashek: Àlàyé rèé lórí ikú tó pa gbajúgbajà olórin reggae Majek Fashek lẹ́ni ọdún 57 Erin wo, ajanaku sun bi oke.
Cancer: Ọjọ́ ‘Má wọ kọ́mú ló wà fún ìtanijí àrùn jẹjẹrẹ ọyàn
Oludamọran fun gomina feto igbokegbodo ọkọ naa tun salaye pe lọgan ni ofin ọhun ti bẹrẹ si ni fidi mulẹ, ti wọn ko si ni fi adi pa ẹnikẹni to ba sẹ sofin naa lori, amọ iru ẹni bẹẹ yoo foju bale ẹjọ.
Nítorí a mọ ẹni tí ó sọ pé, “Tèmi ni ẹ̀san, Èmi yóo sì gbẹ̀san.
 “Alaga ohun so pe, awon nnkan miiran ti o tun le mu igberu ba eto agbin ni lilo awon ohun elo igbalode fun ise agbe, pipese omi lasiko ogbele, mimu ajosepo to muna doko wa laarin awon agbe alada nla ati awon agbe kekeke, pelu iyanju ati mu igberu ba awon agbe alaroje naa”.
Deeper Life: Deeper Life High School ti sọ̀rọ̀ lórí ibi tí nkan dé nípa ọ̀rọ̀ tí wọ́n fi ipá bá lòpọ̀
Ile rẹ ko to wa ni Molete ko si jina si Kudeti, ti one million boys fi ṣe ibujoko.
Gbogbo òru ọjọ́ náà ni wọ́n fi rìn; ní òwúrọ̀ kutukutu ọjọ́ keji, ni wọ́n pada dé Heburoni.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Wo àgbáríjọpọ̀ àwọn Arugbá Ọ̀ṣun Òṣogbo látìgbà tó ti bẹ̀rẹ̀ Buhari júwe ọ̀nà ilé fún Obono-Obla lórí ẹ̀ṣùn ayédèrú ìwé ẹ̀rí Kí ní Khafi BB Naija yóò pàdánu tí iṣẹ́ ba bọ́ lọ́wọ́ rẹ̀?
Ogunlọ́gọ̀ eniyan péjọ pọ̀ sí ọ̀dọ̀ rẹ̀ tóbẹ́ẹ̀ tí ó fi níláti bọ́ sin ọkọ̀ ojú omi kan, ó bá jókòó níbẹ̀ lójú omi.
O si pe orúkọ ẹka naa ni ISWAP (West African Islamic League).
Ọkọ gbọdọ̀ máa ṣe ẹ̀tọ́ pẹlu iyawo rẹ̀, bẹ́ẹ̀ sì ni iyawo náà gbọdọ̀ máa ṣe ẹ̀tọ́ pẹlu ọkọ rẹ̀.
Bakan naa ni awon arugbo ti ọjọ ori wọn ko din ni odun marundinlaadota yoo maa janfani eto ilera ọfẹ bi oun ba wọlé.
Ijọba ni lati fi ipinnu han lori ipese abo ki wọn si yọ gbogbo awọn ti wọn ba rii wi pe wọn ko lee ṣiṣẹ ipese abo sita bi ẹni yọ jiga."
Jesu fún Àwọn Ọmọ-ẹ̀yìn Mejila Láṣẹ.
Arsenal náà jẹ́wọ́ ọmọ ọkọ bi wọn ṣe fi ojú Newcastle gbolẹ̀ nínú ìdíje àkọkọ ti wọ́n gba nínú òjò wẹ́liwẹ́li ní pápá St James lónìí Bótilẹ̀ jẹ́ pé gbogbo rẹ̀ fẹ́ lọ jáí níbẹ̀rẹ̀ nítori gbogbo àwọn ọmọ agbabọọlu tuntun ti wọ́n kowo rà ló wà lóri ìjọko Mesut Ozil àti Sead Kolasinac, Unai Emery gan o fara lálẹ̀ ní gbogbo sáà àkọ́kọ́.
Bi wọn se ko mi lẹru: Ọjọ nla, tii se ọjọ manigbagbe ni ọjọ Kejilelogun osu Keji ọdun 1837, eyi ti n ko lee gbagbe lailai, se ọjọ ti ẹda yoo ba sọnu, gaga ni ara ya ni.
N óo sọ fún Ọlọrun pékí ó má dá mi lẹ́bi;kí ó sì jẹ́ kí n mọ ìdítí ó fi ń bá mi jà.
"Oluwo ni fun apẹrẹ, ""Boo ba kowo jẹ ni China, pipa ni!"
E wo ọmọ Yorùbá àkọ́kọ́ tó jà fún ẹ̀tọ́ àwọn aláwọ̀dúdú ní America!
Adajọ Okon Abang sọ pe Metuh jẹbi ẹsun onikoko meje ikowo lọ ilu lọ si ilẹ okeere kan Metuh.
Gomina sọ wi pe ijoba buwọlu yiyọ owo ori ọdun mẹta kuro bẹ́rẹ́ lati ọdun 2017, 2018, ati 2019.
O tesiwaju pe idojuti nla ni ki ọga ọlọpa wa si ori ẹro amohunmaworan apapọ lati tan ara ilu jẹ lori iroyin ti ko daa loju.
Nígbà tí Jesu rí igbagbọ wọn, ó sọ fún arọ náà pé, “Ṣe ara gírí, ọmọ, a dárí ẹ̀ṣẹ̀ rẹ jì ọ́.
A gbọ pe omi tó ní kòkòrò aifojuri lọ ń fà àrùn onigbameji náà, tó fi mọ igbọnsẹ tí a kò pamọ dáadáa.
Àwọn arakunrin wọn ní ìdílé wọn ni: Mikaeli, Meṣulamu, ati Ṣeba; Jorai, Jakani, Sia, ati Eberi, gbogbo wọn jẹ́ meje.
Bí orúkọ ọmọ bá ti rí ni yóò ṣe máa huwà; nítorí náà ni wọ́ ṣe máa ń fara balẹ wo orúkọ tí wọn yóò sọ ọmọ.
Ọjọ́ kẹta tí mo bí ọmọ tèmi ni obinrin yìí náà bí ọmọkunrin kan.
Nígbà tó ń ṣàlàyé lórí imisi to ni nípa kíkọ ère Ti Olúwa Nile, bàbà Wande ni ilu Eko ni imisi náà tí wá, nígbà tí wọ́n ń ṣe ipilẹ ile ni oru, tí wọn sì ń kọ ilé náà ni oru, ó wá gbosuba fún Tunde Kelani tó fi owó tí sinima náà nìdí, tó fi di fíìmù àgbéléwò.
ipa ẹyẹ idì ní ojú ọ̀run, ipa ejò lórí àpáta,ọ̀nà tí ọkọ̀ ń tọ̀ lójú òkun,ati nǹkan tí ń bẹ láàrin ọkunrin ati obinrin.
Nítorí gbogbo ọjọ́ ayé rẹ̀ kún fún ìrora, iṣẹ́ rẹ̀ sì jẹ́ ìbànújẹ́ fún un.
O ni asiko ti to ki ijọba pese iranlọwọ fawọn oniṣe burẹdi ki ara le rọ tẹru tọmọ.
2bn fún Obanikoro Sọ àsọtẹ́lẹ̀ orílẹ̀èdè tí yóò borí ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ t'òní Gbigba iwe irina Naijiria yala nile ni tabi lẹyin odi a ma mu inira waye fun awọn ara ilu.
Bí ibi tí ó wú yìí bá wà bí ó ṣe wà, tí kò sì tàn káàkiri, ṣugbọn tí ó wòdú; àpá iná lásán ni, kí alufaa pè é ní mímọ́.
Iwe iroyin atigbadegba Forbes lo gbe orukọ awọn to lowo julọ lagbaye sita fun ọdun 2018 ti wọn si ni ipo kini ni Dangote wa pẹlu biliọnu mẹwa dọla o le die.
57 Ati pé àwọn diakónì yíò máa ràn án lọ́wọ́ nígbà gbogbo, nínú gbogbo iṣẹ rẹ̀ nínú ìjọ bí ó bá yẹ láti ṣe bẹ́ẹ̀.
”Ara ọmọ-ọ̀dọ̀ rẹ̀ sì dá ní àkókò náà gan-an.
Dembo,tun so pe ile ise naa ko ni
Orukọ awọn eeyan ti wọn kede ọhun ree: Adeniyi Adebayo Zikri, Tunde Ibrahim, Jimoh Ishola Lawal, Lolo Babatunde, Sulaiman Tunde, Idris Adewumi Adepoju, Abdul Raimi Awela Ajibola ati Yusuf Makeen Ajiboye.
Bakan naa ni gbongan ibi iko nkan iṣẹnbaye si wa ni Yaounde ati Mvog-Betsi ti o jẹ ibi ti ẹranko n la wa.
Ìpínll Eko náà si ni ìpínlẹ̀ to o ni ènìyàn to pọ̀ jù nítórí ibẹ̀ ni a ti rí ẹni àkọ́kọ́, ènìyàn to lé ní ẹgbẹ̀run kan abọ ló ti ni ààrùn náà ni ìpínlẹ̀ Eko, Ipinlẹ Kano lo tèlé, pẹ̀lú ènìyàn ọgọ́rùn márùn lé mẹ́rìndinlọ́gọ́rin, lẹ́yìn náà ni Abuja to ti ni ènìyàn ọ̀ọ̀dúnrún lé mẹ́tàlélógójì.
- Ilé ẹjọ́ ìpínlẹ̀ Ondo Ilé ìwòsàn kan rèé tó ń fi àtùpà gbẹ̀bí aláboyún Àwọn ìjọba ìbílẹ̀ méjìdínlógún yìí kò tíì lè bọ́ lọ́wọ́ ìséde - Ìjọba àpapọ̀ Idi si ree ti BBC Yoruba fi tọ onimọ kan nipa ofin lọ lati beere pe, se gomina Makinde rufin lootọ abi bẹẹ kọ lori gbigba ki wọn sin Ajimobi si GRA.
" Ìjọba Amẹrika yọ orúkọ Sudan kúrò nínú ìwé orílẹ̀-èdè tó ń ṣagbátẹrù ẹgbẹ́ agbésùnmọ̀mí Wo àwọn Adelé-Ọba aládé méje tó jẹ́ obìnrin nílẹ̀ Yorùbá Akẹ́kọ̀ọ́ 333 ni a kò tíì le sọ nípa wọn nílé ẹ̀kọ́ Kankara Katsina- Ìjọba Nàìjíríà Atẹjade naa tẹsiwaju pe ẹsun ti awọn eeyan naa n jẹjọ le lori ni titapa si ofin to rọ mọ ilana ajakalẹ arun Covid-19.
Kò ní gba owó ìtanràn,ọpọlọpọ ẹ̀bùn kò sì ní lè tù ú lójú.
” Nígbà náà ni ó mú mi gba etí odò náà pada.
ti won n soju awon eniyan lati se ohun ti o tọ’’.
Sergio Aguero: Ẹ̀rù n ba àwọn agbabọọlu láti padà sí ìdíje Premier League tó fẹ́ bẹ̀rẹ̀ padà
Ìròyìn sọ pé, awọn ènìyàn n fóri gbárí lásìkò tí eégún náà jáde nílu Ede, tí ọkùnrin kan, Mukaila Ismaila sì fàrapa yánayàna, ti wọn si ti gbe lọ sílé ìwòsàn.
Sọ pé, ‘Ẹ̀yin òkè Israẹli, ẹ gbọ́ ohun tí OLUWA wí: 
Ó ti pé oṣù mẹ́tàlá lẹ́yìn tí àwọ́n alátìlẹ́yìn rẹ̀ ní ìkọlù pẹ̀lú àwọn ológun ní ìlú Abia, ìhà Gúúsù-Ìlà Oòrùn orílẹ̀èdè Nàìjíríà.
Ṣaaju ni ẹgbẹ to n risi idagbasoke ilẹ Yoruba, Yoruba Council of Elders ti bu ẹnu ẹtẹ lu ohun ti agbejọro ijọba naa sọ lori idasilẹ ikọ Amọtẹkun to wa fun eto aabo ilẹ Yoruba.
Osun Accident: Èèyàn méjì pàdánù ẹ̀mí wọn nínú ìjàmbá ọkọ̀ tó wáyé ni Osun
Awọn orilẹ-ede to le ni ọgọrin lo maa n sami ọjọ yii ni ayajọ ọjọ iṣẹ ni agbaye.
Ọtun Olubadan, Olóyè Leka Balogun ni ohun ti sẹnetọ Ajimobi ṣe yii gan lo ṣẹ̀ṣẹ̀ ń jẹ́ titẹle aṣa ilẹ Yoruba."
Aṣọ ọ̀gbọ̀ ni kí o fi ṣe aṣọ títa apá gúsù àgbàlá náà, kí gígùn rẹ̀ jẹ́ ọgọrun-un igbọnwọ, 
Coronavirus: Mọ ọ̀nà láti tóju fóònu rẹ kí o ma ba ko àrùn
ilẹ̀ Nẹgẹbu ni apá gúsù ati gbogbo pẹ̀tẹ́lẹ̀ tí ó wà ní àfonífojì Jẹriko, ìlú tí ó kún fún ọ̀pẹ, títí dé ilẹ̀ Soari.
Lẹ́yìn náà, Jonatani sọ fún Dafidi pé, “Ọ̀la ni ọjọ́ àjọ̀dún oṣù tuntun, àwọn eniyan yóo sì mọ̀ bí o kò bá wá síbi oúnjẹ nítorí ààyè rẹ yóo ṣófo.
Orúkọ ìyá rẹ̀ ni Mikaya, ọmọ Urieli ará Gibea.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Sunday Igboho: Ẹ fi Ògún búra fún wa láti jà fún ilẹ̀ Yorùbá láì gbé Amotekun sábẹ́ ìjọba Lẹyin ti ajakalẹ arun to n ba gbogbo agbaye finra yii ti di ohun ti ajọ WHO ni ao kọ lati maa baa gbe titi abẹrẹ ajẹsara yoo fi jade ti yoo si gbọ wiwo ni.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù AfricanDrumFestival: Abẹ́òkúta gbàlejò èrò fún àjọ̀dùn ìlù 20 Ìgbé 2018 Oríṣun àwòrán, AfricanDrumFestival Àkọlé àwòrán, Ayẹyẹ àjọ̀dùn ìlù nílẹ̀ Áfíríkà ti bẹ̀rẹ̀ nílú Abẹ́òkúta Ayẹyẹ àjọ̀dùn ìlù nílẹ̀ Áfíríkà ti bẹ̀rẹ̀ nílú Abẹ́òkúta.
Nítorí tí mo ti pa ọ̀nà OLUWA mọ́,n kò ṣe ibi nípa yíyà kúrò lọ́dọ̀ Ọlọrun mi.
Gbogbo àwọn tí a kà ninu ẹ̀yà Dani jẹ́ ẹgbaa mejilelọgbọn ó lé irinwo (64,400).
Hesekaya gbà wọ́n lálejò, ó sì fi àwọn nǹkan tí ó wà ninu ilé ìṣúra rẹ̀ hàn wọ́n, fadaka ati wúrà, àwọn nǹkan olóòórùn dídùn ati òróró olówó iyebíye, ilé ìkó nǹkan ìjà ogun sí, ati gbogbo nǹkan tí ó wà ninu ilé ìṣúra.
Kunle Orlando Owoh, ọkan lara awọn ọmọ rẹ to n kọrin bayii sọrọ nipa imọran ti baba rẹ n fun un nigba aye rẹ.
Àwọn tí ń sùn sórí ibùsùn tí wọ́n fi eyín erin ṣe gbé!
Ko pẹ ti o rẹ Yusuf ti wọn si gbe e lọ si Germany fun itọju lẹyin ijamba to ni lori alupupu rẹ.
Àwa tí a bí ní Juu, tí a kì í ṣe ti àwọn orílẹ̀-èdè yòókù tí ó jẹ́ ẹlẹ́ṣẹ̀, 
Ẹ̀mí OLUWA bá bà lé e tagbára tagbára, ó lọ sí Aṣikeloni, ó sì pa ọgbọ̀n ninu àwọn ọkunrin ìlú náà, ó kó ìkógun wọn, ó sì fún àwọn tí wọ́n túmọ̀ àlọ́ rẹ̀ ní aṣọ àríyá wọn; ó bá pada lọ sí ilé baba rẹ̀ pẹlu ibinu.
tíátà jẹ ́ ọ ̀ rọ ̀ tí ó wáyé lati inú èdè gíríìkì tí o túmọ ̀ sí ibì ìwòran ó sì tún ní ẹ ̀ ka bí eré ìtàgé tí ó túnmọ ̀ sí pé , nígbàtí ènìyàn kan tàbí jù bẹ ́ ẹ ̀ bá kó ara wọn jọ ní àkókò kan tábì sí ìbìkan láti dá àwọn ènìyàn lárayá .
Mr Macaroni sọ nípa eré tí Freaky Freaky, Sugar Daddy, You are doing well, Freaky Spicy fẹ́
 láti 17 century , ọ ̀ pọ ̀ gbòógì àjàkálẹ ̀ ti àrùn náà wáyé ní àwọn amẹ ́ ríkà , Áfíríkà , àti yúrópù .
Yusuf niiwe adehun yi yoo papa mu ki eto ọrọ aje Naijiria di eleyi ti yoo darapọ mọ tawọn orile-ede miran.
Ahimeleki sì jáde pẹlu ìbẹ̀rù láti pàdé rẹ̀, ó sì bi í pé, “Ṣé kò sí nǹkan tí ìwọ nìkan fi dá wá, tí kò sí ẹnikẹ́ni pẹlu rẹ?
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Eld Kabir in Nigeria: Mùṣùlùmí àti Kristiẹni sọ̀rọ̀ nípa àdun oúnjẹ́ àti ẹran ọdún Ileya O fikun pe idi ree ti oun fi n ta awọn eroja obinrin, ti oun si maa n mura bii wọn, lati fa oju wsn mọra si eroja ti oun nta, ati bo se dara si lara oun.
Agbenusọ fun olootu Ijọba Ile Gẹẹsi, Theresa May, sọ wipe ọrọ naa kan oun lominu nigba to gbọ nipa isẹlẹ yii.
Ó kọlu àjàrà ati igi ọ̀pọ̀tọ́ wọn,ó sì wó àwọn igi ilẹ̀ wọn.
Wo iye ìgbà mẹ́rin tí ìtàkùn ìpínná ní Nàìjíríà ti dákú lọ́dún 2020 nìkan Olorì Aláàfín tẹ́lẹ̀, Anuoluwapo Adeyemi gba àmì ẹ̀yẹ lórí ipa tó kó nínú oge ṣíṣe Gbajugbaja òṣèré ''Toromagbe'' nínú fíìmù ''Arelu'' ti jáde láyé Mi ò ṣe ẹ̀tánú Ọọ̀ni ilé Ifẹ̀, ọmọ ìyá mi ni ṣùgbọ́n.
Ẹni to bori: Kenya South Africa vs Mauritania.
ikabo  to wa jake-jado orile ede Naijiria
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Face app: Àwọn òṣèré tíátà kan ṣàfihàn fọ́tò ọjọ́ ogbó wọn 17 Agẹmo 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 18 Agẹmo 2019 Oríṣun àwòrán, Woli Agba Àkọlé àwòrán, Ayọ Ajewọle asfihan bi yoo se ri tọjọ ogbo ba de Oríṣun àwòrán, Alamy Àkọlé àwòrán, Haa, arugbo soge ri ree o, Ọpẹyẹmi Aiyeọla lo ti yaa di iya agba yii Oríṣun àwòrán, Aremu Afolayan Àkọlé àwòrán, Hun, owe nla ni awọn aworan yii n pa fun ni pe ọjọ alẹ n bọ Oríṣun àwòrán, Laide Bakare Àkọlé àwòrán, Arugbo sogeri, ekisa logba ri ni aworan ọjọ ogbo Laide Bakare yii Oríṣun àwòrán, Mosunmola Filani Àkọlé àwòrán, Gbogbo ẹyin ewe, ẹmaa ranti pe agba n bọ wa kan wa Oríṣun àwòrán, Mike Bamiloye Àkọlé àwòrán, Ẹru si n yọ mi ba, ti mo ba ranti ọjọ ogbo, bawo ni iwọ yoo ti ri?
Iroyin ni eto isuna ti ọdun yii kere ju ti ọdun to kọja lọ pẹlu triliọnu Naira kan (N1.
O so pe“Awon obinrin lo maa n dibo ju lasiko eto idibo , nitori pe,awon ni o maa sọ bi eto idibo yoo se ri.
Nítorí pé ẹ óo dàbí igi oaku tí ó wọ́wé,ati bí ọgbà tí kò lómi.
Ileeṣẹ ọlọpa ti ṣe awari ayederu ileeṣẹ kan nibi ti awọn kan ti n ṣe ayederu oogun oyinbo ni ilu Eko.
Ọ̀kẹ́ meji (40,000) ni ilé tí Solomoni kọ́ fún àwọn ẹṣin tí ń fa àwọn kẹ̀kẹ́ ogun rẹ̀, ó sì ní ẹgbaafa (12,000) eniyan tí ń gun ẹṣin.
Àwọn aṣọ́nà Tẹmpili nìwọ̀nyí: Ṣalumu, Akubu, Talimoni, Ahimani, ati àwọn eniyan wọn; (Ṣalumu ni olórí wọn).
Boasi bá kìlọ̀ fún un pé, “Ẹnikẹ́ni kò gbọdọ̀ mọ̀ pé o wá sí ibi ìpakà.
Ayé ti já ẹ kulẹ̀ sẹ́yìn sẹ́yìn
Fatai Rolling Dollar, Ọmọ ìdílé oyè tó gbé igbá ori Fatai Rolling Dollar: Baba 70 kú nígbà tó ku ọdún kan kó pé 70.
Lara awon ti o wa nibi ipade ohun ni: aare ile igbimo asofin, dokita Bukola Saraki, oludari agba awon asofin, Ahmad Lawan, ti eni owo Ado Doguwa.
"ni ijọba maa n ranti wa bi idibo ba si ti tan, wọn a gbagbe wa""."
Gege bi aare ti so pe , awon se eleyii lati fi bu ola fun oloogbe Moshood Kashimawo Abiola , ti o jawe olubori ninu ibo aare sugbon ti won fagile ibo naa, ni eyi ti o dena re lati je  aare orile ede Naijiria.
kede  lo kede pe egbe oselu PDP  lo jawe olubori nigba ti won fi ibo to le die
Mohammed sọ fawọn akọroyin pe ọkunrin kan to wa nile itura ọhun, Ogbonna Nwankwo lo ta ileeṣẹ ọlọpaa lolobo iṣẹlẹ naa.
Iroyin sọ pe Ọgbẹni Bloomberg pinnu lati dije fun ipo aarẹ lẹyin to sọ pe ko si ẹni to le ba aarẹ Trump figagbaga ninu awọn to fẹ kopa ninu ibo abẹle ẹgbẹ oṣelu Democrat.
Gomina ipinlẹ Ọyọ, Onimọẹrọ Ṣeyi Makinde tẹwọ gba ajọṣepọ naa pẹlu alaye wi pe isọdọtun papakọ ofurufu ilẹ Ibadan yoo mu ki eto ọrọ aje gun oke agba.
Eyi fihan pe ni bi a ṣe n sọrọ yii ọga agba ileeṣẹTesla ati SpaceX naa ti di eeyan to lowojulọ lagbaye pẹlu Bill gate bayii pẹlu bi guruji rẹ ṣe tun rugọgọ sii lọjọ Aje.
Ṣùgbọ́n bàbá rẹ̀ tán wí fún un pé kí ó lọ bá òun wá ewé igi kan ti ń bẹ ní orísun omi òkun.
Oman Slave: Ó pe mi kí n máa mu Gari ní Nàìjíríà ju ìlú yẹn lọ o
Ileesẹ ọlọpaa nipinlẹ Kebbi, ti mu ọkunrin kan ati iyawo rẹ meji, fun pe wọn so ọmọ orogún wọn, Jubril Aliyu, ọmọ ọdún mẹwaa, pọ mọ ewurẹ fun ọdun meji.
O sọ pe irọ ni ẹsun ti Busola fi kan oun.
Nebusaradani olórí àwọn ẹ̀ṣọ́ bá kó àwọn eniyan tí wọn ṣẹ́kù ní Jerusalẹmu ní ìgbèkùn, lọ sí Babiloni pẹlu àwọn tí wọn kọ́ sá lọ bá a tẹ́lẹ̀.
O ni ọmọbinrin nilo aabo gbogbo wa torinaa ki gbogbo eeyan dide fun ootọ tori pe iṣẹlẹ yii ti su gbogbo obinrin.
Mo bá mú ọ̀pá mi tí ń jẹ́ “Oore-ọ̀fẹ́,” mo dá a, mo fi fi òpin sí majẹmu tí mo bá àwọn orílẹ̀-èdè dá.
OLUWA ní, “Gègé irin ni a fi kọ ẹ̀ṣẹ̀ Juda sílẹ̀ gègé òkúta dayamọndi ni a sì fi kọ ọ́ sí ọkàn yín, ati sí ara ìwo ara pẹpẹ wọn, 
OLUWA ní nǹkan kékeré ni kí n jẹ́ iranṣẹ òun, láti gbé àwọn ẹ̀yà Jakọbu dìde, ati láti kó àwọn ọmọ Israẹli tí ó kù jọ.
Harcourt-Aba  lọ si ile-isẹ INEC, bakan
O mọ ilé oriṣa sí òpin gbogbo òpópó, o sì ń kọ́ ibi ìrúbọ sí gbogbo gbàgede.
Èyí yóo jẹ́ kí majẹmu mi wà lára yín, yóo sì jẹ́ majẹmu ayérayé.
Ṣàkátápàrá làá síntọ́, ojú àfọ́ọ̀fọ́tán, ìjà lón dá sílẹ̀  
ati Ọbadaya ọmọ Ṣemaaya, ọmọ Galali, ọmọ Jẹdutumu, ati Berekaya ọmọ Asa, ọmọ Elikana, tí ń gbé agbègbè tí àwọn ọmọ Netofa wà.
Joseph Smith àti àwọn Ènìyàn Mímọ́ ìbẹ́rẹ̀ wo àwọn ìfihàn náà bí wọ́n ṣe wo Ìjọ: ní jíjẹ́ alààyè, níní ipá, tí ó sì le jẹ́ títúnṣe pẹ̀lú àfikún ìfihàn.
" Àwọn ìròyìn mìíràn tí ẹ lè nífẹ̀ẹ́ sí Ọlọ́pàá tó n gba rìbá sọ pé 'Ọlọ́run gan fara mọ́ olè jíjà' Ta ni Olatoye Temitope 'Sugar' tó di olóògbé?
Ìpinnu yìí dára lójú ọba ati gbogbo ìjọ eniyan.
Ọjọ kẹẹdọgbọn oṣu kẹrin to lọ ni Aarẹ Buhari rinrin ajo lọ si ilẹ Gẹẹsi lẹyin to ṣabẹwo si ilu Maiduguri tii ṣe olu ilu ipinlẹ Bornu.
oselu naa , Yusuf Dantalle lo soro yii lasiko ipolongo to waye ni Abeokuta, to
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìjàmbá Eko: Ṣúnkẹrẹ fàkẹrẹ gba òpópónà Berger kan torí ìjàmbá ọkọ̀ 23 Ọ̀wàrà 2019 Iye eeyan to padanu ẹmi wọn ninu ijamba ọkọ to waye lori afara Otedola lopopona Eko si Ibadan ko tii hande.
 Makinde si ti paṣẹ pe ki wọn o sọ asia orilẹ-ede Naijiria kalẹ loni ọjọ Ẹti, lati le ṣe idaro ""arakunrin, ọrẹ, ati eekan ọmọ bibi ipinlẹ Oyo""."
Ọkàn àwọn eniyan ati àwọn aláṣẹ ìlú dààmú nígbà tí wọ́n gbọ́ báyìí.
ati yẹtí wọn, ẹ̀gbà ọwọ́ wọn ati ìbòrí wọn.
Kii ṣe ọwọ kekere ni wọn fi maa n mu ẹsun ọrọ odi sisọ ni Pakistan.
O jẹ ọkan lara awọn to kọ aabọ iwadi kan - Awọn apẹrẹ pe o ti n darugbo - ninu eyi ti awọn oniwadii ti ṣe akọsilẹ awọn nkan gboogi to n waye ninu ara wa ni ojoojumọ.
Lateef Adedimeji and Adebimpe Oyebade: Ohun tí BBC mọ̀ nìyí nípa àjọṣepọ̀ òṣèré tíátà méjéèjì
Nitori ọpọlọ pipe ti Idiagbon ni, iwa ọlaju rẹ ati ikorira iwa ibajẹ ni oniruru ọna, Idiagbon lo ipo rẹ bii igbakeji adari ìjọba ologun lati ri pe iwa ọmọluabi gbilẹ ni Naijiria.
Eeyan kan to ba Gomina rin, ti ọrọ naa ṣoju rẹ ni, ikọ ọhun dẹ pakute kẹtẹkẹtẹ ti wọn so ado oloro mọ ara rẹ, si oju ọna ti Gomina gba.
Imọ ẹrọ tuntun naa wulo lasiko ti o ba gbagbe tabi ti o ko ba mu kaadi ATM rẹ dani, ti o si nilo owo pajawiri.
iṣẹ ́ yìí ṣe àyẹwò sí bí isẹlẹ inú àwùjo se jé òpákùtèlè ìwà òdaràn nínú ìsòwó àwọn fíìmù àgbéléwò yorùbá kan , b.
Eeku náà tí kò tíì ju ọdún méje ló, lọ fún ètò ẹ̀kọ́ rẹ̀ ni Belgium Charity Apopo to wà ni Tanzania níbi ti wọ́n ti ń tọ́ọ- Wọ́n máa n irú wọ́n ni HeroRATs- bí wọ́n ṣe ń ṣe àwárí imọ̀-ilẹ̀ àti ikọ́fée láti ọdún 1990.
Ó fún Nàìjíríà l'èsì àwọn ẹ̀sùn tó fi kàn-án Iyatọ wo lo wa laarin oge ṣiṣe laye atijọ ati ni isinyi?
Ọpọlọpọ eniyan lo n sọ orisirisi nipa bi ọjọ naa ṣe bẹrẹ, awọn miran ni Hilaria to jẹ ọjọ ọdun kan ni ilẹ Rome ti wọn ma n ṣe ni ọjọ kẹẹdọgbọn, osu kẹta.
NEXT level kii ṣe akọmọna ọrọ ẹnu lasan Oríṣun àwòrán, @MBuhari Àkọlé àwòrán, Ko si ẹni to lee sọ boya ijọba Buhari yoo tẹle awọn amọran ko tii di mimọ fun araalu Lasiko ipolongo idibo ni ọrọ akọmọna yii jade latọdọ ikọ ipolongo aarẹ Buhari gẹgẹ bii iwe akọsilẹ opo afojusun ijọba Buhari fun saa keji.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Africa Eye: Olùkọ́ méjì ní fásitì Eko àti Ghana lùgbàdì ọ̀fíntótó BBC lórí ìwà ìbàjẹ́ Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: N kò nílò ìwé ẹ̀rí Waec ní fásitì Amẹrika - Adeleke Àwọn mọ̀lẹ́bí ajínigbé tó pàdánù ẹ̀mí l'Ondo kò tí ì yọjú Ọọni kọ́lé fàwọn ọmọ òrukàn ní Ibadan Ọlọ́pàá gbé Samuel Ogundipe lọ ilé ẹjọ́ Ìṣẹlẹ ọ̀hún ló waye ní ìhà ariwa Sudan lasiko ti awọn ọmọ náà ń lọ si ile ẹkọ wọn, wọn ni ojiji ni ẹnjini bajẹ ti ọkọ oju omi náà si bẹ̀rẹ̀ si ni ri.
Lọdun 2017 nikan, nkan bii ẹgbẹrun mẹwaa ni ọmọ ti awọn ajoji bi si Amẹrika bẹẹ si ni bi ajọ ilẹ Amẹrika to n ri si idena aisan ni lati ẹgbẹrun mẹjọ din nigba ti ọdun 2007 lo ti goke si ẹgbẹrun mẹwaa.
Omiran tun ni iṣẹ alagbafọ aṣọ fifọ ni eyi to dabi apọnmita ti ko le kuna loju awọn kan.
Má jẹ́ kí abanijẹ́ fi ẹsẹ̀ múlẹ̀ lórí ilẹ̀ náà;jẹ́ kí oníwà ipá ko àgbákò kíákíá.
O pari ọrọ rẹ pe ki ọga ọlọpaa tu awọn ẹsọ oun ti wọn mu sọdọ silẹ ki wọn ma ba ko Covid-19.
Ẹni to bori: Burundi Egypt vs Tanzania.
Ẹ̀ẹ̀mejì péré ni ọjọ́ ndọ́ga báyìí lọ́dún.
Èrò ẹ̀ṣẹ̀ ni èrò ọkàn yín.
 Àjẹsára náà a má a dènà ìwọ ̀ n 15 sí 34 % ìṣẹ ̀ lẹ ̀ ìgbẹ ́ gbuuru tó lágbára púpọ ̀ náà ní àwọn orílẹ ̀ -èdè tó ṣì ń tẹ ̀ síwájú , àti ìwọ ̀ n 37 sí 96 % ìṣẹ ̀ lẹ ̀ ìgbẹ ́ gbuuru tó lágbára púpọ ̀ náà ní àwọn orílẹ ̀ -èdè tó ti ní ìtẹ ̀ síwájú .
Alakoso fun ajo eto idagbasoke nile Afirika,(New  Partnership For Africa, NEPAD)lorile ede Naijiria omooba-binrin, Gloria Akobundu ti ni iwa janduku ati iwa jagidi-jagan to maa n waye lasiko eto idibo lo maa n faa ti eto oro aje orile ede Afirika ko se ni idagbasoke to monyan lori.
com Àkọlé àwòrán, Kìí ṣe ìgbà àkọ́kọ́ nìyí tí Super Eagles àti Argentina yoo máa pàdé ní ìdíje ife àgbáyé FIFA Ni ọjọ kẹwa oṣu kini, ọdun 1995 Super Eagles tun pade Argentina ninu idije FIFA Confederations Cup to waye ni ọdun naa, ọmi olodo-odo ni wọn gba nigba naa.
Máa ṣe àpáta ààbò fún mi,jẹ́ odi alágbára fún mi kí o sì gbà mí,nítorí ìwọ ni ààbò ati odi mi.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Inu mi bàjẹ́ nígbà tí mo bí i, odidi oṣù mẹ́ta, mi ò lè gbàdúrà s'Ọ́lọ́run' Magu sọrọ lori bi awọn ile ẹjọ to n gbọ ẹsun iwa ibajẹ ṣe n fa bi igbin ki wọn to ṣe igbẹjọ lọpọ igba, eleyii ti Magu sọ wi pe ohun fa ifasẹyin fun iṣẹ awọn ni awujọ.
Nítorí pé, ninu ẹ̀jẹ̀ ni ẹ̀mí ohun alààyè gbogbo wà; mo sì ti fun yín, pé kí ẹ máa ta á sórí pẹpẹ, kí ẹ máa fi ṣe ètùtù fún ẹ̀mí yín; nítorí pé ẹ̀jẹ̀ níí ṣe ètùtù, nítorí ẹ̀mí tí ó wà ninu rẹ̀.
Aare Muhammadu Buhari soro yii nibi ipade ati ipate oja nipa imo ero lorile ede Naijiria to waye lojo Aje  ni gbongan  International Conference  to wa niluu Abuja.
Trump yọ Tillerson kuro nipo Àkàrà tú sépo, Trump ló kọ èsì ìlera ara rẹ̀ Trump bu ẹnu atẹ lu FBI Àwọn obìnrin ilé ìgbìmọ̀ aṣòfin Amẹrika fọnmú sí ọ̀rọ̀ Trump Ohun ti wọn n ṣe iwaadi le lori ni pe, Trump halẹ mọ orileede Ukrain pe ohun ko ni ṣe iranwọ nnkan ogun fun wọn ti wọn ko ba bẹrẹ iwaadi alatako rẹ kan to n ba du ipo.
''Asiko ti to fun wa lati gbe igbesẹ, a ko kan nii kawọ gbera maa wo ki wọn maa fi ẹjẹ awọn eniyan wa daabo bo iṣọkan Naijiria.
Olabiwonninu ni, gbogbo ofin to ba ti tọka si pe iwa yii ko lẹtọ, naa lo ma n sọ iru ijiya to tọ si ẹni to ba rufin naa ni agbegbe ọhun.
O tẹsiwaju pe ijọba ipinlẹ Ondo ki n fun igbakeji gomina naa lawọn ẹtọ kan to tọ si gẹgẹ ipo rẹ.
wákàtí 3 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBCwákàtí 5 sẹ́yìn Ìjọba ìpínlẹ̀ Ondo kéde òfin konile-o-gbele ní Ode ati Ishinigbo lẹ̀yìn rògbòdìyàn tó wáyé níbẹ̀wákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Tottenham sọ ọjọ́ ìsinmi olóyin di ''Black Sunday'' mọ́ Arsenal lọ́wọ́ pẹ̀lú ìgbájú-ìgbámú6 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Báyìí ni àgbàọ̀jẹ̀ agbábọ́ọ̀lù Diego Maradona ṣe wọ káà ilẹ̀ lọ lólú ìlú Argentina27 Bélú 2020 Ohun mẹ́wàá pàtàkì nípa Maradona àti ìbáṣepọ̀ rẹ̀ pẹ̀lú ẹlẹ́sẹ̀ ayò Diego Costa rèé26 Bélú 2020 Àwòrán rèé nípa bí 'Hand of God' ṣé dí inagijẹ Diego Maradona25 Bélú 2020 Àrẹ̀mọ Ooni Adeyeye Ogunwusi ti wọ Ààfin Ile Ife fún ìgbà àkọ́kọ́9 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Ṣé ẹ rántí àkọ́lé àwọn ìwé àkàgbádùn yìí?
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ọkùnrin tó fẹ́ fipábámilòpọ̀ fín ǹkan sí mi lójú ló ṣe rọ́nà wọlé sí mi lára Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Gomina ipinlẹ Eko, Akinwunmi Ambode Gomina ipinlẹ Bauchi, Mohammed Abdullahi Abubakar Gomina ipinle Jigawa, Mohammed Badaru Abubakar Gomina ipinle Imo, Rochas Anayo Okorocha Sẹnetọ to n soju ipinlẹ Nasarawa, Abdullahi Adamu Sẹnetọ to n soju ipinlẹ Benue, George Akume Sẹnetọ to n soju ipinlẹ Sokoto, Aliyu Wamakko Minisita fun ọrọ okeere, Geoffrey Onyeama, Minisita fun eto irina ọkọ, Rotimi Amaechi, Minisita fun ọrọ ile ati ẹrọ mọnamọna, Babatunde Fashola, Minisita olu ilu Naijiria, Muhammed Bello, Minisita fun ọrọ aje, Okechukwu Enelemah, Minisita fun ọrọ eto isuna, Udoma Udo Udoma Minisita fun ipese omi ati alumọni, Suleiman Adamu Minisita ipinlẹ fun ọrọ epo rọọbi, Ibe Kachikwu Minisita ipinlẹ fun ọrọ irinajo ofurufu, Hadi Sirika Oludamọran fun eto aabo lorilẹede Naijiria, Babagana Monguno Oludari fun eto iwadii lorilẹede Naijiria, Ahmed Abubakar Adari fun Ajọ NNPC, Maikanti Baru.
Aguero jade lasiko ti ifẹsẹwọnsẹ naa n lọ lọwọ lẹyin ti o fi ara pa.
Bill, Melinda Gates: Ebi, ikú ìyálọ́mọ àti ọmọ wẹ́wẹ́ nìsòro Nàíjíríà
A kò ní í sáré wá pè wá o.
Nítorí bí ẹni tí ó kọ́ ilé ti ní ọlá ju ilé tí ó kọ́ lọ, bẹ́ẹ̀ ni Jesu yìí ní ọlá ju Mose lọ.
Gẹgẹ bi ohun ti Kazeem sọ, ọkan lara awọn oṣiṣẹ ajọ naa ku ninu ikọlu yi ti omiran si gbẹmi mi ni ile iwosan.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Coronavirus: Ṣẹ́ lóòtọ́ ní ginger àti garlic lè pa àrun Coronavirus?
Oríṣun àwòrán, @YeleSowore Ẹgbẹ naa tun n beere fun ẹkọ ọfẹẹ, ati eto ilera fun gbogbo eniyan, ati eto ọrọ aje to dara.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Kanye West fẹ́ ẹ̀ díje fún ìdìbò ààrẹ ilẹ̀ America fún ọdún 2020 Gbajugbaja akọrin takasufe nilẹ Amẹrika, Kanye West ti kede pe oun naa yoo du ipo aarẹ ilẹ Amẹrika ninu eto idibo ti yoo waye lọdun 2020.
Gómìnà mẹ́rin yóò jẹ́jọ́ lẹ́yìn sáà wọn - EFCC 'Fashọla, o ò dẹ̀ bẹ̀rù Ọlọ́run!
Amọ igbakeji aarẹ ti wa ni ofuutu fẹẹtẹ, aasa ti ko ni kaun ni awọn ẹsun naa, to si se apejuwe wọn bii ara ọna lati ta epo si asọ aala oun loju araye ni.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Buhari: Ẹ mu awọn darandaran to ba n gbe'bọn 6 Èrèlè 2018 Oríṣun àwòrán, @NGRPresident Àkọlé àwòrán, Aarẹ Buhari ni ko saaye ipaniyan fawọn darandaran mọ Aarẹ Muhammadu Buhari ti orilẹede Naijiria pasẹ fun awọn agbofinro lati maa fi panpẹ ofin gbe ẹnikẹni ti wọn ba ba ibọn lọwọ rẹ lai gba asẹ lati lo ibọn.
Ó wá lébìrà títí kò rí, ó bá lọ sọ fún ìyá rẹ̀, ó ni, ‘Ìwọ ìyá mi tòótọ́, mo ti gbìyànjú bí ó ti yẹ ki ń gbìyànjú tó ṣùgbọ́n síbẹ̀ síbẹ̀ n kò lè ṣán oko tí ó wà nibi tí n o kọ́ ilé Ìgbéga-ọ̀run sí, ẹ ma bínú pé mo gbàgbé ki n sọ fún yin ki ń tó bẹ̀rẹ̀ iṣẹ́ náà, ṣùgbọ́n ẹ jọ̀wọ́ ìyá mi ọ̀nà wo ni mo lè gbà rí lébìrà tí yóò bá mi ṣiṣẹ́ náà ti n o fi lè kọ́ ilé ‘Ìgbéga-ọ̀run’?
Bakan naa, ni igbakeji gomina Ipinle Oyo, Onimo ero Rauf
, Duration 5,4413 Ògún 2020 Chad prisoners death: Ẹlẹ́wọ̀n 44 kú lagbà ẹ̀wọ̀n ní Chad látàárí ooru tó mú púpọ̀12 Ògún 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Mekong Watch gbàgbọ́ wípé  àwọn ìtàn wọ̀nyí “ti kó ipa ribiribi ní ti ìdáàbò ìṣẹ̀dá nípa dídẹ́kun ìwà àìbìkítà fún ọrọ̀ ìṣẹ̀dá.
Wọ́n ṣe wá ní àlejò gẹ́gẹ́ bí wọ́n ti gbọ́n mọ, nítorí awẹ́ obì kan ni Ìlábùrù fi fún gbogbo wa.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Nigeria swearing-in: Ọjọ́ kò!
Serena n gbero lati ṣe idije tennis f'awọn obinrin ni Afirika
Ìmọ̀ràn náà dára lójú Absalomu ati gbogbo àgbààgbà Israẹli.
odaran mejeeji yii ni oniruuru ero ibanisoro bi – iPhone xmax, Apple, iPhone 5,
Amọṣa ọpọ eeyan lo foju fo amọran rẹ lori ṣiṣe imọtoto ara ẹni ati ayika ẹni, fido ọhun nikan wọn gbajumọ.
"Sẹnetọ Adeleke to sọrọ ni oju opo twitter rẹ ni 'Ogo ni fun Oluwa"" Yatọ si Adeleke, Ọpọlọpọ awọn ọtọkulu lo ti sọrọ lori ọrọ yii."
Ogbeni Dipo yatọ si pe o gba adura fun itusilẹ Naijira faraya pe awọn ọmọ orile-ede kan rin irinajo wakati marun un lati le lọ dibo eleyi ti ko waye mọ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, #NigeriaDecides: BBC ti wa ni gbogbo ìpínlẹ̀ Naijiria láti firoyin gbogbo tóo yin létí Iha miran lọrọ yi kọ si ẹlomiran bi Naturalguy4eva ti o n kaanu awọn ti wọn ti dajọ igbeyawo si ọjọ kẹtalelogun Osu keji ti Inec sun idibo naa si Onnoghen ní 'mi ò jẹ̀bi olúwa mi' nílé ẹjọ́ CCT Àwọn ohùn tó ṣé kókó tó yẹ ká mọ ṣáájú ìdìbò 2019 Njẹ́ ìwọ mọ Àwọn tí ìdìbò kò dí lọ́wọ́ iṣẹ́ wọn?
O tẹsiwaju pe, wọn gbe kọkọrọ ṣenu ọna ni titẹle ilana ijinasiraẹnu gẹgẹ bi ajọ NCDC ṣe gbe kalẹ lọna ati dẹkun itankalẹ arun Coronavirus.
Ó ti pẹ́ ti mo ti mọ̀ wí pé mi ò lé gbádùn ìbálòpọ̀ tí mi ò bá lo ǹkan ìṣeré ìbálòpọ̀ tó tọ́, kí n sì sun ìhà tí mo ti kọ́kọ́ wà.
Pópóọlá bèèrè Túndé Atọ̀pinpin lọ́wọ́ Akin.
Awọn ọlọpaa kọọkan ni wọn n se agbodegba fun awọn ole ati awọn onisẹ ibi ninu iwe naa.
Nítorí náà, o kò ní pa eniyan mọ́, o kò sì ní pa àwọn eniyan rẹ lọ́mọ mọ́, Èmi OLUWA Ọlọrun ni ó sọ bẹ́ẹ̀.
Ọọni ni isẹ ku diẹ ko pari ni ibudo igbafẹ naa, to ba si buse tan, ẹnu yoo ya awọn ọmọ Naijiria lori awọn ohun meremere to wa nibẹ eyi ti yoo maa ta orilẹ́ede wa fawọn ilẹ okeere lagbaye.
Aarẹ tumọ si olori patapata to ba lori ohun gbogbo.
Àwòrán ìwọ́de NLC, TUC, ULC lónìí
Wọn ni lọwọ-lọwọ, Oluwo ba Oloye Abiola Ogundokun, Imran Adio (olori ẹṣin Isilaamu) to yọ nipo Otun Ajanasi, ja.
O ni nkan meji loun mọ pe ọmọ oun nifẹ si gan, ọrọ oun ti awọn obinrin n la kọ́ja atawọn ọdọ ti wọn n fipa ba lopọ.
"Ki igbeyawo to le dan mọran tabi ki o pẹ, ọkọ ati iyawo gbọdọ bọwọ fun ara wọn.
•Ọpọ awọn osisẹ lorilẹede naa ni ko ni lee lọ sẹnu isẹ nitori ko si owo ti wọn yoo gba, ti wọn si gba ile wsn joko, sugbọn awọn osisẹ kan ti isẹ wọn nii se pẹlu ẹmi ọmọniyan, to tun jẹ kosemase nikan ni wọn yoo maa se lọ sẹnu isẹ titi ti awọn asofin agba to jẹ ọmọ ẹgbẹ oselu Democrat ati Republican yoo fi fi ẹnu ọrọ jona , ti wọn yoo si dijọ fọwọsi aba naa.
ti igbakeji aare ojogbon Yemi Osinbajo tuko re, iroyin fi mule pe awon minisita
Bí ẹnikẹ́ni ninu yín bá ń ṣàìsàn, kí ó pe àwọn àgbà ìjọ jọ, kí wọ́n gbadura fún un, kí wọ́n fi òróró pa á lára ní orúkọ Oluwa.
Ṣé o fẹ́ dá mi lọ́kàn le lásán ni; bí ẹlẹ́tàn odò tíí gbẹ nígbà ẹ̀ẹ̀rùn?
Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Fuel Price Hike: Onímọ̀ ní oṣooṣù ni owó lítà epò kan yóò máa yàtọ̀, ó le léwó tàbí dínwó16 Owewe 2020 6:30 Fídíò, Akomolede ati Aṣa lori BBC: Mọ̀ si nípa oríṣìí ẹ̀ka ìsọ̀rí ọ̀rọ̀ àti ìwúlò wọn, Duration 6,308 Owewe 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Ṣùgbọ́n o, ìdìde Umar Mohammed Bago láti ìpínlẹ̀ Niger àti John Dyegh láti ìpinlẹ̀ Benue.
6 571253 Orilẹede Netherlands 9905 58.
Ta ni Aaroni tí ẹ̀yin ń fi ẹ̀sùn kàn?
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ibọn ba Ọpẹyẹmi Bamidele ní Ekiti 'Wọ́n ti yọ ọlọ́pàá tó yìnbọn l'Ékìtì níṣẹ́ Ikọ̀ ẹlẹ́sìn Hàkíkà rèé, níbití wọn ti ń pààrọ̀ ìyàwó láàrín ara wọn Àsùn-máparadà lọ̀rọ̀ ajínigbé tó lo Tramadol l‘Ondo Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Sunday Adelaja: Tẹ́tẹ́ làwọn pásítọ̀ tó ń gba owó ‘ìserere’ ń ta Adekunle Omega, to je olugbe ilu Ado sọ pe ẹni mimọ si oun ni Bunmi Ojo, ti iroyin iku rẹ si jẹ ohun ti o ba ni lọkan jẹ.
yóo jẹ́ kí òṣì dé bá ọ, bí ọlọ́ṣà dé bá eniyan.
Mo wa bi ara a mi leere pe, ṣe emi nikan ni?
Ó gba ìmọ̀ kúrò lọ́wọ́ àwọn ìjòyè ní gbogbo ayé,ó sì sọ wọ́n di alárìnká ninu aṣálẹ̀,níbi tí ọ̀nà kò sí.
Iṣẹ ọpọlọ yii da yatọ gedegbe, a lee ni lagbegbe ti arakunrin yii wa, ko tii si ẹni to ṣe iru eleyii ri.
Ṣugbọn mo mọ̀ ọ́n, mo sì ń pa ọ̀rọ̀ rẹ̀ mọ́.
Bolanle Ninalowo fi ile ta iyawo rẹ lọrẹ Loju opo Instagram Bolanle Ninalowo ni ofi ikede ẹbun ile to fi ta iyawo rẹ lọrẹ si.
Wọ́n se àsè kan fún un níbẹ̀.
O ni gbogbo rẹ lawọn ko silẹ fun ayẹwo iwe isuna ajọ naa.
àwọn ará Ijipti, àwọn ọmọ Juda, àwọn ará Edomu, ati àwọn ọmọ Amoni àwọn ará Moabu, ati gbogbo àwọn tí ń gbé inú aṣálẹ̀; tí wọn ń fá apá kan irun orí wọn; nítorí pé bí gbogbo àwọn orílẹ̀-èdè wọnyi kò ṣe kọlà abẹ́, bẹ́ẹ̀ ni àwọn ọmọ ilẹ̀ Israẹli kò kọlà ọkàn.
Wọn óo jẹ́ alufaa Ọlọrun ati ti Kristi, wọn óo sì jọba pẹlu rẹ̀ fún ẹgbẹrun ọdún.
O si ṣiṣẹ nọọsi fun ogún ọdun.
Agbaṣẹṣe kan pẹlu ijọba ipinlẹ Oyo, Olufemi Oniyide ti n fi apa janu lori ilana akoso tuntun lawọn gareeji ọkọ, ti ijọba ipinlẹ Oyo mu lo laipẹ yii.
A di igi, tí àwọn ẹyẹ ojú ọ̀run óo wá ṣe ìtẹ́ wọn lára ẹ̀ka rẹ̀.
wọ ́ n sì tẹ ̀ dó sí Òkè-igbó .
A gbọ pe Gomina Akeredolu sọ pe inu oun dun si bi Ajayi ṣe fi iru eniyan to jẹ han.
Iyabo Ojo Ọjọ kọkandinlogun, oṣu Kọkanla, ọdun 2020 yii ni Iyabo Ojo padanu iya rẹ, o si sin oku iya naa lọjọ kẹtadinlọgbọn, oṣu Kọnanla kan naa.
Àjọ tí ó ń tako àìjìyà ẹlẹ́ṣẹ̀ àti àìṣòdodo ní orílẹ̀-èdè Mauritania Forum Against Impunity and Injustice fi ìbànújẹ́ hàn lórí ìjàm̀bá àwọn tẹ̀gbọ́n-tàbúrò kan tí a yẹgi fún lálẹ́ ọjọ́ burúkú Èṣù gb'omi mu yìí.
 O ṣalaye pe awọn agbagba, awọn lọbalọba atawọn oloṣelu to lamilaaka nilẹ Yoruba to yẹ ko ja fun ominira naa ni wọn n ṣe bi pe ọrọ ọhun ko kan wọn."
Nígbà tí ó jẹ́ pé Judasi ni akápò, àwọn mìíràn ń rò pé ohun tí Jesu sọ fún un ni pé, “Lọ ra àwọn ohun tí a óo lò fún Àjọ̀dún Ìrékọjá, tabi ohun tí a óo fún àwọn talaka.
Dana d'awọn ero lẹbi ilẹkun to fo yọ Oṣiṣẹbirin ọkọ ofurufu jabọ latinu baalu Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Wiwa ọkọ Baalu da bi ki ẹ lọ da duro sori apata' Ojikutu mẹnu ba ọpọlọpọ idi ti iru papakọ ofurufu yii ko fi mọgbọn wa.
 O wa pe fun didaabo bo awọn ẹtọ to nii ṣe pẹlu awọn ẹka igbimọ aṣofin fun idagbasoke orilẹ-ede yii lapapọ.
N óo sì kó gbogbo àwọn eniyan rẹ̀ wá sọ́dọ̀ rẹ, gẹ́gẹ́ bí iyawo tí ó lọ bá ọkọ rẹ̀ nílé.
Saaju ni Aare Buhari ti buwọlu ofin tuntun lọjọ keje, osu yii nipa abadofin Companines and Allied Matters 2020 ni eyi ti ijọba fi paarọ 1990 CAMA.
mo yan arakunrin mi, Hanani, ati Hananaya, gomina ilé ìṣọ́, láti máa ṣe àkóso Jerusalẹmu, nítorí pé Hananaya jẹ́ olóòótọ́ ó sì bẹ̀rù Ọlọrun ju ọpọlọpọ àwọn yòókù lọ.
Ninu atẹjade kan to fi sita eleyi to tẹ BBC Yoruba lọwọ, ẹgbẹ CAN ni pẹlu bi nkan se ri bayii lori ọrọ abo lorilẹede Naijiria ti fihan wipe awọn ileesẹ alaabo rẹ nilo awọn ẹjẹ tutu to ni iran tuntun ti o lee da alaafia pada si agbami ọrọ abo orilẹede Naijiria ti ko duro deede ni lọwọlọwọ.
Ìwọ ni o dá àríwá ati gúsù,òkè Tabori ati òkè Herimoni ń fi ayọ̀yin orúkọ rẹ.
Isẹlẹ Iran: Ijamba baalu pa eeyan 66
Ọjọ́ náà ni mo kọ́ mọ ìyá rẹ̀ ẹni tí orúkọ rẹ̀ ń jẹ́ Ìlábùrù.
Awon olujosin bi egberun meta ni won wa nibi eto adura naa.
N óo fi ẹran àbọ́pa rú ẹbọ sísun sí ọ,èéfín ẹbọ àgbò yóo rú sókè ọ̀run,n óo fi akọ mààlúù ati òbúkọ rúbọ.
Nítorí náà, jọ̀wọ́ má ṣàìràn mi lọ́wọ́ nítorí ọ̀ràn yìí kí o sì gbà mí ní ìyànjú ọ̀nà tí n ó gbà tí n ó fi sọ̀klẹ̀ kúrò tí mo dúró sí téńté.
Mo bá fi mú àwọn olórí olórí ninu àwọn ẹ̀yà yín, àwọn tí wọ́n gbọ́n tí wọ́n sì ní ìrírí, mo yàn wọ́n gẹ́gẹ́ bí olórí fun yín.
A gbọ pe Savastano ati ọrẹbirin rẹ ọjọ pipẹ Julie Wheeler ni wọn jọ n gbe titi o fi di ọjọ iku rẹ.
Ki n máa siré lọ́hùn-ún, kí ó sì dàbí ẹni pé n kò bìkótà fún ìyàwó mi, nítorí aláìmọ̀kan ni ènìyàn náà, tí ara ìyàwó rẹ̀ kò dá nílé, tí ó bá òde ẹmu lọ, tí o ń rẹ́rìn-ín lọ́hùn-ún bí ẹni pé kò sí nnkan kan.
Kí ló dé tí o fi wó ògiri ọgbà rẹ̀,tí gbogbo àwọn tí ń kọjá lọsì fi ń ká èso rẹ̀?
Ninu itan Naijiria, ko ti si ijọba ti ko ni asoju lati gbogbo ẹya Naijiria.
Orúkọ Amuneke wọ ìwé ìtàn pẹ̀lú ikọ̀ agbábọ́ọ̀lù Tanzania Óya gbé bọ́dì ẹ!
Shina jẹ ẹda to ga, o to iwọn ẹsẹ bata mẹfa ati aabọ, to si tun ni omi lara, o si dudu lawọ.
Díẹ̀ nínú àwọn ọmọ ènìyàn ni ó moore, aláìmoore ni púpọ̀ nínú wọn, ẹni tí ń ṣe oore mú inú Olódùmarè dùn, ìdí rẹ̀ sì ni èyí tí àwọn ẹlòmíràn kò fi bínú lọ́jọ́ kan kí wọ́n fi oore-ṣíṣe sílẹ̀, àti pàápàá ènìyàn kò lè mọ ẹni tí yóó san oore, ẹni tí ìwọ rò pé yóó moore kò ní í mọ̀ ọ́n, ẹni tí ìwọ kò sì nírètí irú nǹkan bẹ́ẹ̀ sí ni yóó mọ oore tí ìwọ bá ṣe fún un tí yóó sì máa ròhìn rẹ káà kiri.
pelu ibi ti ise naa de duro bayii, o seese ki won pari re ki akoko ti ijoba da
Ó ta ọfà rẹ̀ jáde, ó sì fọ́n wọn ká,ó jẹ́ kí mànàmáná kọ, ó sì tú wọn ká.
Ojú yín yóo rí ọba ninu ọlá ńlá rẹ̀;ẹ óo fojú yín rí ilẹ̀ tí ó lọ salalu.
Nígbà míràn àwọn ògùn tí a nlò dà bí irinṣẹ́ àti nkan ìlò ogun fún àwọn ọmọ-ogun ara wa.
Ní kutukutu òwúrọ̀ ọjọ́ keji, ó jáde, ó lọ rí Saulu.
Nígbà ti Ọlọ́fìn-íntótó gbọ́ pé wọ́n mú Ọ̀sanyìnnínbí sí àgọ́ ọlọ́pàá Morèmi, òun àti Ilésanmí lọ́ sí ibẹ̀.
” Àwọn ará Keni bá jáde kúrò láàrin àwọn ará Amaleki.
ọjọ to n bọ ni egbe osise yoo sepade lati jiroro pelu awon egbe miiran lori
dana sun lati odun 2014,  o le ni ẹgbẹ̀fà iye awon oluko ati akẹẹkọ ti won ti farapa nibi
ni eyi ti yoo lee fopin si iwa odaran, ipaniyan ati agbesunmọmi to n sẹlẹ ni
Rọbọọti to n ṣọ igboro: Orile¬̣-ede Tunisia kan naa ni wọn ti ṣe rọbọọti to n ṣọ igboro loṣu Kẹrin, ọdun 2020.
Ki si ni gbajugbaja elere sinima to wa di oloṣelu yi sọ?
Koda nigba to ku diẹ kaato fawọn obi rẹ, ko jẹ ki eyi di i lọwọ lati ma lọ sinu ọgba ile iwe laini kọbọ lapo.
Awọn alakoso ile ẹkọ naa koro oju si awọn akẹkọ ti o hu iru iwa yii, ti wọn si tẹnumọ pe, ofin ile ẹkọ naa ko fi aye gba iru rẹ.
" Awọn miran ni sebi Trump yii kan naa lo maa n fi Joe Bidden ṣe yẹyẹ nitori pe o n lo ibomu, ọrọ naa ti kan oun naa bayii.
Spain ati Portugal: Orilẹede mejeeji ṣi ibode wọn lẹyin ọpọlọpọ oṣu nitori arun Coronavirus.
Ekweremadu so pe, “ni akoko ayeye odun ajinde yii, mo pe fun emi ironu-jinle lori ipo ti orile-ede yii wa.
Ǹjẹ́ ewé dongoyaro lè wo aàrùn coronavirus?
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù 'Penis Fish,', ẹ̀ja tuntun lúwẹ̀ẹ́ jáde nínú òkun ní Carlifornia 14 Ọ̀pẹ̀̀ 2019 Oríṣun àwòrán, KATE MONTANA Ẹgbẹgbẹrun awọn nkan abẹmi inu omi to fara jọ nkan ọmọkunrin ti wẹ jade sita lori omi okun kan ni ilu Carlifornia.
Beere fun iwe aṣẹ ofin lati mu ọ.
OLUWA ní, “N óo lọ ṣáájú rẹ,n óo sọ àwọn òkè ńlá di pẹ̀tẹ́lẹ̀;n óo fọ́ ìlẹ̀kùn idẹ,n óo sì gé ọ̀pá ìlẹ̀kùn irin.
Amọ ṣaa, ipo wo ni iṣẹlẹ buruku naa fi ilu Ọffa si?
Sibẹsibẹ, lẹ́yìn gbogbo èyí, Juda arabinrin rẹ̀, ọ̀dàlẹ̀, kò fi tọkàntọkàn pada tọ̀ mí wá.
Ẹ gbógun tì í ní gbogbo ọ̀nà,ẹ ṣí àká rẹ̀ sílẹ̀,ẹ kó o jọ bí òkítì ọkà,kí ẹ sì pa á run patapata,ẹ má dá ohunkohun sí ninu rẹ̀.
Àwọn ìyekan mi ati àwọn ọ̀rẹ́ mi tímọ́tímọ́ ti já mi kulẹ̀.
Ìgbájú àti ìgbámú ló sọ mí di olókìkí- Taaooma Káre Ẹfunroye Tinubu, Ògbóǹtagí oníṣòwò, olówò ẹrú àti afọbajẹ Coronavirus: Ọmọ márùn ún ni mo ní, ṣùgbọ́n kò sí oúnjẹ fún wa lásìkò ìgbélé yìí -Olùgbé ìlú Eko Ninu ọrọ kan to fi sita loju opo twitter rẹ Davido lọgun pe iṣẹ l'abiyamọ n ṣe.
Dabiri ni ẹsun toun ko mọwọ mẹsẹ ni wọn fi n kan oun.
US Elections 2020: Primate Ayodele ní òun ti sọ àsọtẹ́lẹ̀ pé Trump yóò fìdírẹmi, tí kò bá ṣọ́ra ṣe
Yóo jó ayé ati ohun gbogbo tí ń bẹ ninu rẹ̀ ní àjórun,tó fi mọ́ ìpìlẹ̀ àwọn òkè ńlá.
Oríṣun àwòrán, Facebook/Ooni Adeyeye Enitan Babatunde Ogunwusi II O ni asiko to bayi lati rii daju pe awọn alaṣẹ n tẹti si awọn ọdọ naa, ki wọn si ṣiṣẹ pọ pẹlu wọn lati rii daju pe orilẹede Naijiria goke de ibi ti mutumuwa n fẹ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ido-Ani Robbery: Àhámọ́ làwọn afurasí náà yóò wà di ọjọ́ Kejì oṣù Karùn-ún 24 Ìgbé 2019 Àkọlé àwòrán, Awọn maarun lo foju ba ile ẹjọ ti ẹnikẹfa wọn to ku ti na papa bora Ile ẹjọ magistireti to wa nilu Akure ti paṣẹ ki wọn ti awọn adijunjale mẹfa, ti wọn funra si pe wọn kopa ninu ikọlu ile ifowopamọ kan ni Idoani si ahamọ.
Bí o tilẹ̀ jẹ́ pe ẹgbẹ́ APC ni ikanni ìbáraẹni sọ̀rọ̀ lori Twitter tẹ́lẹ̀, ẹgbẹ́ ọun sọ pe ikanni ọun kii se tàwọn, ati pe, awọn o ni ounkóhun se pẹlu ikanni ọ̀un ti o ni àdírẹ́ẹ̀sì @APCNigeria.
Njẹ awọn obinrin ma n ṣe bẹ ẹ?
13 Àti pé báwo ni ayọ̀ rẹ̀ ti pọ̀ tó lórí ọkàn tí ó ronúpìwàdà!
Ni ipari, ile ifowopamo agba CBN ti bere igbenija re ni erongba lati wa ojutu si pasipaaro owo Naira loju oja ti ile okere.
O ti fún un ní ohun tí ọkàn rẹ̀ ń fẹ́,o kò sì fi ohun tí ó ń tọrọ dù ú.
A máa la ojú àwọn afọ́jú,a máa gbé àwọn tí a tẹrí wọn ba dúró;ó fẹ́ràn àwọn olódodo.
Ẹ óo wá mi,ṣugbọn n kò ní sí mọ́.
 Ṣadé padà sídìí iṣẹ ́ rẹ ̀ ( eyewitness news on december 13 , 2004 ) .
Ẹ̀rù kò bà mí púpọ̀, ṣùgbọ́n ó sì jẹ́ ohun ìyàlẹnu fún mi, ó sì ṣe àjèjì lára mi fún ìwọ̀n ọdún mélǒ kan.
ọdun 1967 sinu idile oloogbe Pa Olatunbosun Makinde ati iyaafin Abigael Makinde
Firmino lo tun sọ ọ sawọn fun wọn niṣẹju marundinlaadọrin pẹlu kọju-simi-o gbaa sile.
ijamba ina to sẹlẹ ni Ijegun ,ni ipinle Eko lojoBo kẹdun .
Awọn gomina ẹgbẹ to n sakoso lowo 
Ní àkókò náà, àwọn ará Kenaani ati àwọn ará Perisi ń gbé ilẹ̀ náà.
ẹran, ẹja, móinmọin, dodo, igbin, adiyẹ ati bẹẹ bẹẹ lọ lo maa n tẹlẹ jọọọfu rin lode ariya.
Ní àkótán olùdìbò 538 ló wà ni ilẹ̀ Amẹrika Olùdìbò kọ̀ọ̀kan ló dúró fún ìbò kan tí olùdíje ààrẹ kọ̀ọ̀kàn sì gbọdọ̀ ní ìbò 270 tàbi jù bẹ́ẹ̀ lọ láti di ààrẹ fún ọdún mẹ́rin.
Bí Hushpuppi ṣe tiraka rèé l‘Eko, kí ọlà ‘òjijì’ tó dé Àjọ NCDC kéde èsì àyẹ̀wò ènìyàn 575 tó tún ti ní ààrùn Coronavirus ní Nàìjíríà Magu lọ farahàn níwájú ìgbìmọ̀ tó ń ṣ'àyẹ̀wò EFCC, DSS kò mú un- EFCC Ọjọ́ Kẹrin oṣu Kẹ́jọ ni ìdánwò WAEC yóò bẹ̀rẹ̀ - Ìjọba àpapọ̀ Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Amọ aiṣetan ijọba lati ṣe gbogbo nnkan yii lo mu wọn pada gunle iyanṣẹlodi lọjọ Aiku.
Ẹwẹ, Trump fidirẹmi ninu ẹjọ to pe lori kika ibo lawọn ipinlẹ kan.
Oríṣun àwòrán, TWITTER/AGBOOLA AJAYI Àkọ̀tun ìṣòro tún ti súyọ fún gómìnà Akeredolu l'Ondo Kaka ki ewe agbọn dẹ ni ọrọ ọpọ wahala oselu ati ti isejọba to n doju kọ gomina Rotimi Akeredolu lọwọlọwọ bayii, ko ko ko lo n le si.
Igbákejì adarí alukoro fún àjọ ọmọogun ilẹ̀ 'Operation Lafiya Dole', Onyema Nwachukwu, ló fi ìdí ọ̀rọ̀ náà múlẹ̀ nínú àtẹjade kan pé, àwọn ọmọogun wọde ìfẹ̀honú hàn, sí bí ileesẹ ologun ṣe pín wọn fun iṣẹ́ ní Maoduguri, èyí dàbí ohun ti kò tẹ́ wọn lọ́rùn tó tó sì fa awuyewuye.
Àríyànjiyàn náà le tóbẹ́ẹ̀ tí wọ́n fi pínyà, tí olukuluku fi bá ọ̀nà rẹ̀ lọ.
Awọn esi to wa nita fihan pe ọlọpaa mejilelogun padanu ẹmi wọn ti awọn mii si farapa lasiko ifẹhonuhan naa""."
Ìdààmú bá ọkàn mi, mo rọ bíi koríko,tóbẹ́ẹ̀ tí mo gbàgbé láti jẹun.
Ǹjẹ́ jíjẹ́ olódodo rẹ̀ ṣe ohun rere kan fún Olodumare,tabi kí ni èrè rẹ̀ bí ó bá jẹ́ ẹni pípé?
MC Oluọmọ gbé ara rẹ̀ ṣépè nítorí ìwọ́de #ENDSARS Ìyá gómìnà Seyi Makinde dágbére fáyé lẹ́ni ọdún 81 Àjọ elétò ìdìbò kéde ọjọ́ tí ìdìbò aàrẹ Nàìjíríà 2023 yóò wáyé Àbádòfin ìṣúná 2021 ré kọjá ìpele ìkejì nílé aṣòfin àgbà Gẹlẹ bi Toyin ṣe kọ ọrọ tan si abẹ fọto Adenike to fi soju opo instagram rẹ pe ki oun to le sọ ọrọ yii sita, oun ni lati gba aṣẹ lọwọ ọlọrọ ni Adenikẹ to jẹ ọlọrọ gan an ni.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù UEFA Champions League: Kí ló ṣẹlẹ̀ nígbà tí ikọ̀ Ilẹ̀ Gẹ̀ẹ́sì méjì wọ àṣekágbá?
Ṣe kii ṣe ẹni ti yoo joko si ipo eku maa huwa ẹyẹ.
"Iya naa sọ pe gbogbo dukia rẹ lo ti ta tan.
Àwọn alufaa tí wọn ń gbé Jerusalẹmu nìwọ̀nyí: Jedaaya, Jehoiaribu, Jakini, 
Ẹ mú ọmọ náà wá síhìn-ín.
O gba imoran pe ti ija ba ti de ki onikaluku pari e ni alaafia fi le joba ni ile aye.
Ìgbà mẹ́jọ tí awuyewuye wáyé lórí ìṣèjọba Ajimobi!
Adajọ wa gbe idajọ kalẹ pe, awọn olujẹjọ kinni de ikẹfa ninu ẹjọ naa, jẹbi ẹsun iditẹ lati ji ọmọ gbe ti wọn fi kan wọn.
Mọ̀ pé ọkàn irú ẹni bẹ́ẹ̀ ti wọ́, ó ń dá ẹ̀ṣẹ̀, ó sì ń dá ara rẹ̀ lẹ́bi.
Ọmọ Ibadan wa gba awọn ololufe rẹ nimọran lati maa bọwọ fun ofin to rọ mọ idena itankalẹ arun Coronavirus nitori ewu to wa ninu ajakalẹ arun naa."
Josẹfu dá baba rẹ̀ lóhùn, ó ní, “Àwọn ọmọ mi, tí Ọlọrun pèsè fún mi níhìn-ín ni wọ́n.
Fásitì Ibadan: Kò sí àkẹ́kọ̀ọ́ obìnrin tí wọ́n fipá bá lòpọ̀
 Gege bi Kosuke Kiyohara omo odun méjídínlógójì se so, “Mo ti so fun awon ebi mi lati fara mo ohun kohun ti o ba sele, leni o si n wa aburo re ati awon omo okunrin re meji.
Stella Adadevoh ni dokita to tọju ọmọ orilẹede Liberia, Patrick Sawyer, to gbe aisan Ebola wọ Naijiria lasiko naa, ti ko si gba ko fi ileewosan silẹ.
Bakan náà ni wọ́n rọ àwọn alárina fún ilé iṣẹ́ lori ayélujara láti ṣọ́rọ́ nitori kò yọ ẹnikẹni kalẹ̀.
Iru awọn iroyin ti ẹ le nifẹ si: Ishaq Oloyede: Jamb ko nii fi esi idanwo silẹ ni kiakia Saraki pe fun ajọṣepọ Ghana ati Naijiria Jamb padanu owo s'ikun ejo Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
“N óo fìdí majẹmu mi múlẹ̀ láàrin èmi pẹlu rẹ, ati atọmọdọmọ rẹ.
“Opolopo awon ti o ba isele naa lo ni eefin ina sekupa, beesini a tun ri awon miran ti o padanu emi won latari fifo oju ferese ile naa,”“Awon ti o farapa ni itoju lo lowo lori won bayii, beesini a tun si n wa awon miran ti o ku sinu ile naa.
 Àwọn aládùgbóò rẹ ̀ ni ibibo , igbo , mama àti mumuye .
sese dibo yan sile igbimo asoju-sofin ilu Abuja se n dupo adari nile igbimo
Lẹyin iroyin naa ni ọpọ eeyan bẹrẹ si n beere pataki ọpa aṣẹ ninu ile igbimọ aṣofin, ati pe ki lo n tumọ si ti ko ba si ọpa aṣẹ ninu ile igbimọ aṣofin.
Wo ọ̀nà àbáyọ sí bo ṣe ń han‘run Ọ̀làjú sọ àṣà nù, wò ó báwọn obìnrin ṣe ń wà ọkọ kiri lórí ayélujára Nínú akànṣẹ́ mẹ́ta ọmọ Nàìjíríà tó dáńtọ́ lágbàáyé, Yorùbá méjì wà nínu wọn Bẹẹ ni mo n beere pe ki lo sẹlẹ si ayẹwo Coronavirus ti mo se lana, se ẹbu ni?
nígbàtí ó padá sí nàìjíríà ní bíi 1960 , ṣisẹ ́ olùkọ ́ ni yunifàsíti ifẹ ̀ ti wọ ́ n ń pè ní Ọbáfẹ ́ mi awólòwọ ̀ yunifásit ̀ ì nísìn , níbi tí ó tí dà ilé iṣẹ ́ olokun acting company àti port harcourt sílẹ ̀ .
Bakan naa, alaga ana fun ajo to n mojuto eto idibo lorile ede Naijiria ojogbon Attahiru Jega, ni yoo je alejo patake ti yoo maa ba awon eniyan soro lojo Aje(Monday), ni deede agogo mewaa aaro lojo kéjídínlọ́gbọ̀n, ni gbongan igbalejo International Conference Centre, niluu Abuja.
O wa ro awon omo orile ede
Lẹ́yìn náà, a óo dá a sílẹ̀ fún ìgbà díẹ̀.
"Aarẹ ni ""ko si ile tuntun, ko si afikun apo isuna ni banki nile ati lẹyin odi mi o si ni ipin idokoowo kankan to kun awọn ohun ti mo ni tẹlẹ""."
a lati lọ se ojuse wa, sugbon o jẹ iyalẹnu fun w ape , won sun eto idibo naa
 Ó wà ní ilé ìjọba Ìlú Èkó ní alausa , ikeja.
“Ẹ kò gbọdọ̀ yipada kí ẹ lọ bọ oriṣa tabi kí ẹ yá ère kankan fún ara yín.
Nítorí náà, tí ó bá di òru, kí ìwọ ati àwọn ọkunrin tí wọ́n wà pẹlu rẹ lọ ba níbùba.
Jesu dá a lóhùn pé, “Arakunrin, ta ni ó yàn mí ní onídàájọ́ tabi ẹni tí ń pín ogún kiri?
"Ẹ wo ohun tí wọn yóò máa ṣe ní ìpínlẹ̀ - DAWN Commission Ilé iṣẹ́ ọmọogun kò sọ fún mi pé ọkọ mi kú fún ọdún kan- Iyawo soja Iran ní àwọn kò mọ̀ọ́mọ̀ ju irínṣẹ́ ìbúgbàmù ""missile"" lu bàálù Ukrain tó já Wo Sultan Qaboos bin Said, ẹni tó gbàkóso ìgbé ayé òṣèlú Oman fún àádọta ọdún ""Awọn obi ilẹ̀ Afrika kii tọ̀rọ̀ aforiji ti wọ́n ba ṣẹ ọmọ."
Ewe, igbimo awon gomina naa tun kedun pelu gomina ipinle Plateau ati awon eniyan re fun ikolu awon daran-daran eleyi ti o gbemi opo eniyan lo nipinle ohun.
O ni lọwọlọwọ ẹka to n risi gbigbẹ ogun ti iṣẹ n samojuto awọn ati pe ifasẹyin ni yiyan Iyalọja yoo jẹ.
Akosile ejo ti Chigumba se ninu osu kokanla fihan bi o se fi ajafeto-omo eniyan alufa Evan Mawarire sile, eni ti o n koju igbejo lori awon esun iyanju lati doju ijoba Mugabe bole.
Omo odun mẹ́rìndínlógójì ohun nireti ti wa tele pe yoo darapo mo iko naa laipe.
O ni ọlọpaa to ṣeṣe naa n gba itọju lọwọ bayii nile iwosan.
Sugbon ko si awọn ẹbi Khadijat kankan nibi igbẹjọ naa.
Awọn Musulumi maa ri ọjọ mẹwaa akọkọ oṣu Dhul al- Hijjah gẹgẹ bi eyi to se pataki julọ niwaju Ọlọrun.
Àwọn òṣèré tíátà Yorùbá ọkùnrin táyé ni wọ́n rẹwà Àwọn òsèré Nollywood se ìdárò BURGER to jáde láyé Ni kete ti iroyin naa si tan kalẹ, ni ọpọ awọn eeyan ti n ki ku oriire aruye yii.
Mo wa n rọ awọn eeyan ipinlẹ yii lati fara da pẹlu mi nibayii ti mo n lakaka lati wa ojutu si isoro naa, ki wọn si fọwọsowọpọ pẹlu wa lati ri pe ayika wa mọ tonitoni, ti ko si lewu fun gbogbo wa lati gbe.
OLUWA Ọlọrun, má ṣe kọ ẹni tí a fi òróró yàn, ranti ìfẹ́ rẹ tí kìí yẹ̀ sí Dafidi, iranṣẹ rẹ.
Baba Awo Idowu Olukunle ni orisirisi magun pọ pupọ, ko si lopin, ohun ti wọn ba fi se, si ni yoo sọ nipa eewọ rẹ, amọ diẹ lara orisi Magunto mẹnuba ree: Njẹ o mọ pe oriṣiriṣi Magun lo wa?
Tọwọ́ tẹsẹ̀ laá fi gba ìrànwọ́ owó ẹ̀kọ́ Almajiri ní ìpinlẹ̀ Oyo- Alága Subeb Fọ́tò ló ṣàfihàn ibi tí ọmọ ti Nọọsi jígbé lódún 1997 wà Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Ajọ WHO ti ilera agbaye ni ẹnikẹni to ba wa ni alaafia lo le fi ẹjẹ silẹ̀.
Senegal Aarẹ Macky Sall sun ṣiṣi ile iwe siwaju ni Senegal lẹyin ti awọn olukọ kan lugbadi arun Covid-19.
“Nisinsinyii mo ti di orin lẹ́nu wọn,mo ti di àmúpòwe.
Link O ya, ẹni ba laya ko wa wọọ.
Gbogbo àwọn ẹ̀yà ayé yóo figbe ta, wọn yóo rí Ọmọ-Eniyan tí ó ń bọ̀ lórí ìkùukùu ní ọ̀run pẹlu agbára ògo ńlá.
Ṣé o rí nǹkan ìríra ńlá tí àwọn ọmọ Israẹli ń ṣe níhìn-ín láti lé mi jìnnà sí ilé mímọ́ mi?
Nígbà tí ọkunrin náà rí i pé òun kò lè dá Jakọbu, ó fi ọwọ́ kan kòtò itan rẹ̀, eegun itan Jakọbu bá yẹ̀ níbi tí ó ti ń bá a jìjàkadì.
Fashola: Omi ń bẹ lámù nídìí ìpèsè ina ọba
Wọ́n parí kíkọ́ Tẹmpili náà ní ọjọ́ kẹta oṣù Adari, ní ọdún kẹfa ìjọba Dariusi.
"O dun mi pupọ, debi pe mo ni lati lọ duro si ọdọ ọrẹ mi kan fun ọpọlọpọ ọjọ titi ti ara mi fi ya nitori pe mi o fẹ ki iya mi o mọ pe mo ṣe e.
Àwọn ọmọ Simeoni ní ìdílé-ìdílé nìwọ̀nyí: ìdílé Nemueli, ìdílé Jamini, ati ìdílé Jakini; 
Ẹ má ṣe gbèrò ohun gíga-gíga, ṣugbọn ẹ máa darapọ̀ mọ́ àwọn onírẹ̀lẹ̀.
Ojọbọ ni wọn n reti Ogbẹni Modi ni olu ile ipolongo ẹgbẹ ni Delhi nibi ti wọn yoo fi adagba eto rọ si ti wọn ba ti jawe olubori tan.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Ọga ọlọpaa lorilẹ-ede Naijiria wa ke si kọmiṣọna ọlọpaa lati ṣe iwadii si iṣẹlẹ naa lati lee gbe igbesẹ to ba ts ni ibamu pẹlu ofin.
Kọmisana feto idajọ ati agbẹjọro agba nipinlẹ Ondo, Adekola Olawoye lo fidi ọrọ yii mulẹ fawọn akọroyin pẹlu afikun pe lọla ọde yii ni Adajọ Olusegun Odusola, to n gbọ jọ Sotitobire yoo gbe idajọ rẹ kalẹ.
Ninu ilẹ̀ ẹ̀yà Dani, wọ́n fún wọn ní àwọn ìlú wọnyi pẹlu àwọn pápá ìdaran tí ó wà ní àyíká wọn: Eliteke, Gibetoni.
Akeugbagold wá ń béèrè pé kí ló dé tí àwọn ọlọ́pàá kò fi dá àwọn agbebọn náà dúró lójú ọ̀nà tí wọn di lásìkò isede Coronavirus, tí àwọn agbebọn ọ̀hún jí ọmọ òun gbé.
Ilé ẹjọ́ kòtẹmilọ́rùn yóò dajọ́ ìdìbò gómìnà Oṣun ọdún 2018 Ẹ fójú lóúnjẹ níbi ìbúra wọlé Oyetọla l'Ọṣun Kò sí ilé ẹjọ́ kankan tó yọ mí - Gboyega Oyetọla Ilé ẹjọ́ gba béèlì Sẹ́nétọ̀ Adeleke Lana, ile ẹjọ kotẹmilọrun to n gbejọ lori ọrọ ẹni tó lẹtọ lati jẹ Gomina nipinlẹ Osun laarin Gboyega Isiaka Oyetola ati Ademola Adeleke fi ikede pe awọn yoo dajọ naa lọjọbọ.
Ọlọ́pàá ń wa Iṣẹ́ àkànṣe tí kò parí ni Buhari ń bọ̀ wá ṣí l‘Eko - Aráàlú figbe ta Ọwọ́ ọlọ́páá tẹ ẹyẹ ayékòótọ́ tó maa n ṣ'òfófó!
Odun 1983 ni ija Sri Lanka bẹrẹ nigba ti awọn ẹka Tamil binu ti wọn si ṣafikun owo tawọn ẹkun Sinhalese n san lapapọ.
Afojusun awọn olori ẹya Yoruba ati Igbo lati gba ominira, mu ki wọn o faramọ ibeere awọn eniyan Ariwa.
Agbejoro kan so lojo-Isegun pe, “won ti fi owo sinkun mu awon mejo, eyi ti won w ni kolo olopaa bayii, o le ni awon eniyan ogota ti won foro wa lenu wo yala awon ti won kagbako isele naa tabi ti won jeri”.
Roy to keko gboye giga keji ninu ise ona ni: “Mo feran ise ona awon eniyan Naijiria pupo, nitori o maa n safihan opolo pipe won.
Kí ilẹ̀ gbọ́ ati gbogbo ohun tí ó wà lórí rẹ̀,kí ayé tẹ́tí sílẹ̀ pẹlu gbogbo nǹkan tí ń ti inú rẹ̀ jáde.
si ipo awon minisita ipinlẹ meji.
“ipade naa yoo fayesile fun ibasepo ti o donmonran lati lati jeyo larin awon adari ile-Afrika, ijiroro po lati wa ojutu si idojuko to n koju eto abo nile Afrika abbl,”O fikun-un pe, o se koko lati mu enu ba, pataki ile-ise omo ogun orile-ede Amerika ti eka ile Afrika (AFRICOM) fun ise akanse ti won gbese lati maa sagbateru ipade apero awon omo ogun ile Afrika pelu ifowosowopo pelu awon orile-ede miran lodoodun, o je ohun ti o dara pupo.
 Àwọn múùdù wọ ̀ nyí ni à ń dá pè ni ojúṣe wọ ̀ fún , àníyàn àti kànńpá lédè yorùbá .
Osise ile-ise pana-pana so pe, awon osise ile-ise naa ti gunle sibi isele ohun lati wa omode-kunrin naa ti won ti gba la.
Ajọ ẹlẹyinju anu ilẹ Gẹẹsi ni Oxfam Charity lo fi abajade yii sita lọjọ Iṣẹgun.
Adajọ oloyede nigba to n ba BBC sọrọ, wi pe Ajọ to n bojuto eto idajọ lorilẹede Naijiria (National Judicial Council) nikan lo lasẹ lati parọwa si Aarẹ orilẹede Naijiria lati kowe lọ gbe ile rẹ abi ki o lọ rọkun nile fun Adajo Agba lẹyin ti wọn ba ti se iwadii to fihan pe, o jẹbi ẹsun iwa ibajẹ.
Báwo ni ọkùnrin tí ọlọ́pàá bá òkú rẹ̀ nínú àgbá ní Oyingbo ṣe kú?
Ó ní ìwé kan níwájú rẹ̀ ninu èyí tí àkọsílẹ̀ àwọn tí wọ́n bẹ̀rù OLUWA, tí wọ́n sì ń bọ̀wọ̀ fún orúkọ rẹ̀ wà.
Ǹjẹ́ ó tọ́ sí mi láti ṣe irú ohun burúkú yìí kí n sì dẹ́ṣẹ̀ sí Ọlọrun?
 Aadọtalelẹgbẹta milionu dola ni owo ti a ya soto lati fi pese awon idagbasoke ohun amayederun , ina mona-mona, eto ilera,oju-ona Abuja si Kano, Eko si Ibadan, iwo oorun ati pipese ero amunawa ti Mambilla ati atunse si  oju-afara ti Niger.
Ẹ ṣe akiyesi àwọn ẹyẹ; wọn kì í fúnrúgbìn, bẹ́ẹ̀ ni wọn kì í kórè.
O ti gbọ́ ìròyìn ohun tí ọba Asiria ti ṣe sí àwọn tí ó ti bá jagun, pé ó pa wọ́n run patapata ni.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Àwọn òṣèré tíátà Yorùbá tó bá 2018 lọ 'Mí ò sí lára awọ̀n aṣòfin tó bú Buhari'' Iya Rainbow, Jide Kosoko, Ọga Bello, yóò polongo Buhari fún 2019 Àwọn àṣà àti ìse tó yọ obìnrin sílẹ̀ nílẹ̀ Yorùbá Ko si ani-ani pe, Yoruba lo pilẹ ere sinima agbelewo lorilẹede Naijiria, ti awọn agba oṣere Yoruba bii, Hubert Ogunde, Iṣọla Ogunṣọla, Ogunmọla, Ade Afọlayan, Adelove, Baba sala ati bẹẹbẹẹ si gbe ere itage de ibi to ga.
FLAC ti ń ṣe àtọ́nàa ìṣòfin tí ó tako ìṣọdẹ-àjẹ́ ní Jharkhand.
 bì a bá wà rí ení ti o bá fe lo sí ojúde yìí onítòhùn yòó sò pé òun lo si Ìtà-eko .
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Àwọn jàndùkú ṣe yabò àwọn olùwọ́de #ENDSARS ní Alausa l'Eko Bẹẹ naa lawọn ẹgbẹ ajafeto-omoniyan kan ati awọn agbẹjọro bẹnu àtẹ lu igbesẹ yi, pe minista fun FCT ni Abuja to jẹ olu ilu Naijiria ko ni agbara aṣẹ lati sọ pe ki iwọde ma wa nitori pe ẹtọ ọmọ Naijiria ni.
Amọ orilẹede Democratic Republic of Congo, Gabon, SUDAN ati Burkina Faso ti darapọ awọn orilẹede ni ilẹ Afirika ti awọn to lugbadi arun Coronavirus ti gbẹ ẹmi mi.
Ẹgbẹ́ náà ṣe gudugudu méje yàyà mẹ́fà kí ó tó kó oríṣiríṣi ìtàn 102 jọ ní Cambodia, Laos, àti Thailand.
 nítorí ìdí èyí yó ṣe pàtàkì fún wa láti lo bíbélì ìwé mímọ ́ àwon onígbgàgbọ ́ làti ṣe atọ ̀ nà wa nínú àlàyé yìí .
O fikun un pe, iko omo ogun sawari ipago awon omo ogun olote ohun lasiko ise akanse Lafiya Dole naa.
Lasiko to n sọrọ niwaju awọn aṣofin, Sanwo-Olu ni igbesẹ yii wa ni ibamu pẹlu ipinnu lati mu adinku ba owona ijọba.
Wọn si maa n fi idi rẹ mulẹ pe John Mark to kọ iwe ihinrere Maaku ninu Bibeli ni oludasilẹ wọn, to si tun jẹ Biṣọọbu akọkọ.
Gbogbo eniyan ni yóo rí ìgbàlà Ọlọrun.
Lara ojuṣẹ igbimọ naa ni lati ṣe iwadii iwa ifiyajẹni lọna aitọ ti awọn oṣiṣẹ SARS naa wu, ati bi awọn ti ọrọ kan yoo ṣe ri idajọ ododo gba.
Lasiko to n kopa lori akanse eto BBC Yoruba, Temitope ni oun ti n ta ounjẹ ni Naijiria lẹyin ti oun pari ileewe giga, ki wọn to sọ fun oun pe, awọn eniyan kan wa to lee gbe oun lọ silu oyinbo, lati le ri owo kojọ.
8 millionu owo dolla ni Naomi gba eyi to je iye owo to ti poju ti oludije yoo gba ninu idije naa.
Danbaba ni Nigba miran ti a ba fẹ sin oku, ni ṣe ni a maa n sin oku tuntun le eyii to ti wa nibẹ tẹlẹ."
Ẹni tí ó kọ ọkọ àárọ̀ rẹ̀ sílẹ̀,tí ó sì gbàgbé majẹmu Ọlọrun rẹ̀.
Báyìí ni iwin náà sọ si bàbá mi, bàbá mi náà fèsì bí ó ti yẹ ki alágbára fèsì fún alágbára.
Ọja Binukonu jamba ina ni ọdun 2015 ati ni oṣu kọkanla ni ọdun 2017.
Idagbasoke eto  IseluAkowe agba fun ajo agbaye tun salaye lori igbaradi eto idibo odun 2019 lorile ede.
Aare orile ede Naijiria Muhammadu Buhari ni won ti dibo yan gege bi alaga tuntun fun ajo  Ecowas , oun naa ni yoo maa sakoso awon igbimo adari orile ede ati ijọba ECOWAS.
Ni a bá dágbére fún ara wa, a wọ inú ọkọ̀, àwọn sì pada lọ sí ilé wọn.
NAFDAC ti parí ìwádìí lórí codeineNAFDAC: Ẹ yàgò fún ẹwà ti wọn fi òògùn apakòkòrò sinu rẹ NAFDAC: Ẹ ṣọ́ra fún ẹja aṣekúpani Puffer Fish O gba awọn eeyan niyanju lati ri wi pe wọn fi omi ṣan ẹwa wọn daada ki wọn to daa si ori ina Irufẹ iṣẹlẹ aṣilo oogun apakokoro o jẹ tuntun Ọmọ mẹ́ta láti inú ìyá kan náà kan gbẹ́mì mì nítorí òògùn apakòkòrò tí wọn fà símú.
Ninu ọrọ wọn, wọn kan sara si agbabọọlu Naijiria Chukwueze to fakọyọ ninu ifẹsẹwọnsẹ naa.
UNILAG VC: Ọ̀jọ̀gbọ́n Ogundipe ní òun sì ni gíwá UNILAG Giwa fasiti ijọba apapọ to wa niluu Eko, UNILAG, Ọjọgbọn Olawatoyin Ogundipe ti sọ pe iroyin ofege ni iroyin to tan kalẹ kaakiri pe wọn ti yọ oun nipo.
Ninu ọrọ tirẹ, Aṣofin Ṣolaja-Saka fi idunnnu han si aṣeyori eto naa.
Lati jọru ti iroyin afikun yii si ti jade lawọn eeyan lẹkajẹka gbogbo lawujọ si ti n fi ero wọn han lori rẹ.
 nínú ìmọ ́ èdè faranse ( french ) .
Fraud Allegations: Àjọ FBI mú ọ̀pọ̀ ọmọ Nàìjíríà lórí ẹ̀sùn jìbìtì l'Amẹrika
Èrò lórí Ọgbọ́n ati Ìwà Òmùgọ̀.
lati egberun márùndínlọ́gbọ̀n sqkm lọdun 1963 .
Jakọbu bá Rakẹli náà lòpọ̀, ó sì fẹ́ràn rẹ̀ ju Lea lọ, ó sì sin Labani fún ọdún meje sí i.
Nígbà tí àwọn ẹ̀ṣọ́ Tẹmpili tí wọ́n rán lọ mú Jesu pada dé ọ̀dọ̀ àwọn olórí alufaa ati àwọn Farisi, wọ́n bi wọ́n pé, “Kí ló dé tí ẹ kò fi mú un wá?
Afeez ga ni iwọn ẹsẹ bata to din diẹ ni mẹjọ bẹẹ ko sanra pupọ.
 ) ni a maa ń lò láti tọ ́ ni sí àwọn ààmì .
ENDSARS Tribunal: ọlọ́pàá àti olùjẹ́rìí tó gbá létí lẹ́ẹ̀mẹrin pàdé níwájú ìgbìmọ̀, ariwo sọ!
Igbákejì ni Jehosabadi; òun náà ní ọ̀kẹ́ mẹsan-an (180,000) ọmọ ogun tí wọ́n ti dira ogun, lábẹ́ rẹ̀.
Kò sí bóyá mọ́, ìgbà tí Arsenal yóò lè Unai Emery láwọn èèyàn n retí Ọrọ boya iṣẹ yoo bọ lọwọ akọnimọọgba ẹgbẹ agbabọọlu Arsenal Unai Emery tun fidi rinlẹ si lọkan awọn onwoye pẹlu bi ikọ rẹ ṣe fidirẹmi lọwọ Frankfurt ninu idije Europa League.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Rochas Okorocha, káàbọ̀ sí àwùjọ àwọn gómìnà tí EFCC ń wá - Fayose Sìgá mímu ń di èèwọ̀ oògùn ìlera pípé lagbaye Ṣeyi Makinde fòfin de ẹgbẹ́ NURTW Ọyọ, ó gbàkóso gáréjì ọkọ̀ Iyalẹnu lo jẹ fawọn eeyan nigba ti obinrin yii gbọrọ naa kalẹ niluu Makurdi, nipinlẹ Benue lọdun 2018.
Ẹ̀ṣùn méje gbòógì tí ìjọba àpapọ̀ fi kan Ibrahim Magu rèé Ibrahim Magu: Lára ẹ̀ṣùn rẹ̀ ni pé ìjọba àpapọ̀ kò mọ ohun tó ń lọ nípa àjọ EFCC Ana ode yii ni okiki kan lori ayelujara pe awon osisẹ ile ișẹ ọtẹlẹmuyẹ DSS, ti gbe ọga agba ajọ to n gbogun ti iwa ajẹbanu ati lilu owo ilu ni ponpo, EFCC, Ibrahim Magu fun ifọrọwanilẹnuwò.
Àwọn ọmọ ti Simeoni ni: Jemueli, Jamini, Ohadi, Jakini, Sohari, ati Ṣaulu, tí obinrin ará Kenaani bí fún un.
Ọ̀kan nínú àwọn òṣìṣẹ́ ilé ìwòsàn náà fí ìdí rẹ̀ múlẹ̀ pé gbogb àwọn òṣìṣẹ̀ ilé ìwòsàn náà ti lọ silé bótill jẹ́ pé àwọn aláìsàn pọ̀ lórí àkéte àìsàn tó lágbára.
"Oríṣun àwòrán, kemiafolabiadesipe ""A ti sekilọ fawọn arinrinajo Hajj lati orilẹ-ede Naijiria pe ki wọn lo awọn oogun to n dena iba sugbọn o se ni laanu pe nitori ọkan rẹ to foo, Kẹmi Afọlabi ko lo oogun kankan."
A ò ní gbà kẹ́ẹ buwọ́lu ofin tí yó máa dí wa lẹ́nu lórí ayélujára Iná mọ̀nàmọ́ná lọ fún wákàtí 24 ní Ghana, lariwo bá sọ!
Nígbà tí àwọn ará Filistia gbọ́ pé wọ́n ti fi òróró yan Dafidi lọ́ba lórí Israẹli, gbogbo wọn wá gbógun ti Dafidi.
Àwọn ọmọ-ogun ọ̀run ń tẹ̀lé e, wọ́n gun ẹṣin funfun.
Eyi waye lẹyin ija ajakuakata to waye ni ẹkùn Amhara, to wa ni apa Ariwa orilẹ-ede ọhun.
Bí owó àwọn ènìyàn yìí bá ga sí, ó túmọ̀ si pé, owó ọja yóò wọ́n sii.
Agbẹnusọ fun ilé iṣẹ́ ọlọ́pàá ní Ipinlẹ̀ Eko, Chike Oti, ni ọpẹ́lọpẹ́ ikọ̀ RRS tí ó wà ní itosi ibẹ̀.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Àlàyé rèé lórí ikú tó pa Ogun Majek Oyè adelé alága APC kúrò ní gúúṣù Nàíjíríà, ó bọ́ sẹ́kùn àríwá Abisola, aya wòlíì Babatunde ti ń jẹrìí nípa bí ọmọ ọdún kan ṣe sọnù Eji Gbadero, ọmọ Ibadan àti jayé-jayé ọmọ ónílẹ̀ ti wọn yẹgi fun l'Eko Èyí ni àwọn arẹwà ‘ẹ̀lẹ̀ Daddy’, àfẹ́fẹ́ tí Aláàfin fi ń mí Kalejaiye ni abajade ipade awọn igbimọ alaṣẹ, NWC lori yiyan alaga ẹgbẹ oṣelu APC tuntun ni yio sọ ibi ti ẹgbẹ oṣelu APC ni ipinlẹ Ondo n lọ.
Àwọn fúnra wọn kò wọ inú ààfin, kí wọn má baà di aláìmọ́, kí wọn baà lè jẹ àsè Ìrékọjá.
Obinrin kan wà láàrin wọn tí nǹkan oṣù rẹ̀ kọ̀ tí kò dá fún ọdún mejila.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Yiyago fun aṣiṣe Eleyi fẹ fa iṣoro dani ṣugbọn atẹyin wa lo ti ṣẹlẹ, awọn alatilẹyin Biden n gbero pe iṣọwọ ṣe si rẹ bayii yoo ran an lọwọ lati ma jabọ sinu panpẹ kan naa to ti awọn aarẹ labẹ ijọba awaarawa ko si lọpọ igba.
Ọkùnrin kan sálọ lẹ́yìn tó gbẹ̀mi ènìyàn mẹ́ta Ọmọ ọdún méjìlá ni mo ti ń ṣe bàálù, ọkọ̀, ilé àti ọkọ̀ ojú omi - Ọdọ́mọdé ‘Engineer’ Bọọli jẹ ọgẹdẹ agbagba sisun ti awọn eniyan maa n jẹ pẹlu ata dindin tabi ẹpa yiyan.
Ajafẹtọ naa wa fikun wi pe ifẹhọnu awọn ko nii se lati gba ijọba pẹlu ipa, amọ awọn n bere fun ijọba to bun iyi kun awọn ọmọ Naijiria, ki eto aabo orilẹede Naijiria gbooro si, ati wi pe ki alaafia ki o jọba ni Naijiria.
Gẹgẹ bi eto ajọ naa ṣe ri, ipo Umar to wa ni ipo adari ẹka iṣẹ ninu ajọ ọhun lo tẹle alaga.
sẹlẹ sii lọjọ Ẹti to kọja yii lasiko to n dana ounjẹ fun okan lara awon onibara
Kí àwọn tí OLUWA ti rà pada kí ó wí bẹ́ẹ̀,àní, àwọn tí ó yọ kúrò ninu ìpọ́njú,
 oluilu re ati ilu totobijulo re ni reykjavík , pelu ayika re to ni ida meji-inu meta olugbe orile-ede na .
Lẹ́yìn náà, ẹ ti kẹ̀kẹ́ ẹrù yìí sójú ọ̀nà, kí ẹ sì jẹ́ kí ó máa lọ fúnrarẹ̀.
Wolii Ajani wa rọ awọn ojisẹ Ọlọrun lati maa waasu tako iwa ibajẹ naa, ko le di ohun itan ni Naijiria Ọ̀pọ̀ nkan tó n ṣẹlẹ̀ kò jẹ́ kí n gbàgbọ́ pé Naijiria wà ní abẹ́ ìdarí ẹnikẹ́ni - Wole Soyinka Agba onkọwe, Ọjọgbọn Wole Soyinka ti sọ pe, oun ko gbagbọ pe Naijiria wa ni abẹ idari ẹnikẹni.
Ojú ẹsẹ̀ ni Adebayo kú gẹ́gẹ́ bí àwọn tí ọ̀rọ̀ náà sojú wọ́n ṣe sọ, sùgbọ́n àwọn ọlọ́pàá tó kù sáré gbé Adebayo lọ sí ilé ìwòsàn, bẹ́ẹ̀ ni ọlọ́pàá tó yìnbọn na pápá bora.
17 Bélú 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
OLUWA, fi ọ̀pá rẹ tọ́ àwọn eniyan rẹ, àní agbo aguntan ìní rẹ, tí wọn ń dá gbé ninu igbó, láàrin ilẹ̀ ọgbà; jẹ́ kí wọ́n máa jẹko ní Baṣani ati ní Gileadi bí ìgbà àtijọ́.
Owo tijọba apapọ fẹ ẹ ya latilẹ okeere ko ni i ṣe e ya.
Awọn Gomina APC fẹ Buhari Ṣaaju ki Buhari to kede pe ohun yoo du ipo Aarẹ lẹkan si, awọn Gomina labe ẹgbẹ APC ti ni ki Buhari so ero ọkan re lori ipo aarẹ lọdun 2019.
"Nítori àwọn àtúgbẹ́yẹ̀wò, o níra láti ṣe àkójọpọ fún àwọn ọkọ́ naa Orisun: Johns Hopkins University atawọn ajọ eto ilera ilu Iye akọsilẹ to waye gbẹyin 15 Oṣù Ṣẹ́rẹ́ 2021 20:44 WAT+3 Nigba ti wọn fi ibeere sọwọ si nipa bi awọn akẹkọ yoo se bọ si ipele mi,o ni ''idanwo ti yoo gbe wọn lọ kilasi mii yoo waye lẹyin tawọn ba ti ri aridaju pe wọn ti kẹkọ to yẹ'' ""Fawọn to wa ni kilasi ti wọn yoo ti bọ si abala miran o fi kun pe awọn n se igbaradi fun wọn."
Gbajumọ osere náà, tó ni òun kò leè sọ iye sinima tí òun ti kopa ninu rẹ, wá fi to àwọn olólùfẹ́ rẹ létí pé, òun sì ń kopa gidi nínú eré lásìkò yìí, àmọ́ ni àwọn ojú òpó ayélujára ni kí wọn tí máa pàdé òun.
N ò ní kú, yíyè ni n óo yè,n óo sì máa fọnrere nǹkan tí OLUWA ṣe.
Nigba to n gbarata lori isẹlẹ naa loju opo Twitter rẹ, Toyin wa n fi ohun ransẹ si Sẹnetọ Ben Bruce pe ki lo de ti gbogbo ile sinims n se afihan sinima oun ayafi ibudo sinima Murray Bruce to kọ lati se bẹẹ.
Àwọn ìlú wọn tí wọ́n wà ní ẹsẹ̀ òkè nìwọ̀nyí: Eṣitaolu, Sora, Aṣinai.
Gómìnà Oyetọla tú àṣírí àwọn tó ń kò àrùn Coronavirus wọ Ọ̀ṣun Àwakọ̀ tó wa ọ̀kọ̀ tó búgbàmù l'Akurẹ sọ bí ìṣẹ̀lẹ̀ nàá ṣe wáyé Wọ àwòrán àwọn ẹbí òṣèré Nollywood yii!
” Èyí rí bẹ́ẹ̀ kí Ìwé Mímọ́ lè ṣẹ tí ó wí pé,“Wọ́n pín aṣọ mi láàrin ara wọn,wọ́n ṣẹ́ gègé lórí ẹ̀wù mi.
Kọmíṣọ́nà àgbà fún ètò ìpolongo àti ìdánilẹ́kọ̀ọ́ lábẹ́ ájọ INEC, Ọ̀gbẹ́ni Dèjì Ṣóyèbí, ló fi ọ̀rọ̀ yìí tó BBC létí pé, àjọ náà fẹ́ lo àǹfàní nọ́ḿbà ìbánisọ̀rọ̀ tí wọ́n fi sílẹ̀ lásìkò ìforúkọsílẹ wọn, láti kàn sí àwọn olùdìbò lórí ibi tí wọn yóò ti lọ gba káádì ìdìbò wọn.
 wọ ́ n ń sọ wọ ́ n láti madagascar dé eastern island : wọ ́ n tún ń sọ wọ ́ n láti taiwan dé hawal títí dé new zealand .
Amọ, ni gbogbo igba ni Adesina ma n sọ wi pe, oun ko jẹbi ẹsun ti wọn fi kan oun.
Igbele naa ti wọn ni yoo bẹrẹ lẹsẹkẹsẹ ni ijọba ipinlẹ Ondo kede lẹyin rogbodiyan to bẹ silẹ laarin ilu memeji lati nnka bi ọsẹ kan sẹyin.
Ǹ báà lè sọ oríṣìíríṣìí èdè tí eniyan ń fọ̀, kódà kí n tún lè sọ ti àwọn angẹli, bí n kò bá ní ìfẹ́, bí idẹ tí ń dún lásán ni mo rí; mo dàbí páànù tí wọn ń lù, tí ń hanni létí bí agogo.
Ní ọjọ́ tí Elikana bá rú ẹbọ rẹ̀, a máa fún Penina ní ìdá kan ninu nǹkan tí ó bá fi rúbọ, a sì máa fún àwọn ọmọ rẹ̀ lọkunrin ati lobinrin ní ìdá kọ̀ọ̀kan.
' Ki ni abajade iwadii tuntun to jade yii?
nípa títẹ̀lé ìwà ẹ̀ṣẹ̀ àwọn ọba Israẹli.
“Ẹ gbọ́ ẹ̀yin tí ẹ̀ ń sáré ìdáǹdè,ẹ̀yin tí ẹ̀ ń wá OLUWA,ẹ wo àpáta tí a mú lára rẹ̀, tí a fi gbẹ yín,ati kòtò ibi tí a ti wà yín jáde.
NEC fi òfin de dída ẹran ọ̀sìn kiri nìpínlẹ̀ márùn uń
Àwọn kan ninu wọn di òmùgọ̀nítorí ẹ̀ṣẹ̀ wọn,ojú sì pọ́n wọn nítorí àìdára wọn.
Malema so pe, “ niwon igba ti won ba ti yo Zuma kuro nipo, ohun ti o kan ni titu ile-igbimo asofin ka, tori pe, ile-ejo ti dajo pe,ile-igbimo ti kuna lati se ojuse won bi o ti to ati bi o se ye, niwon igba ti won ko ti le daabobo  awon ara-ilu”.
Itsey Sagay: Irọ́ ni Ahmed Lawan pa pe ₦750,000 ni Sẹ́nétọ̀ kan nń gbà lóṣù
Ṣaaju ninu oṣu yii, ni ileeṣẹ ọlọpaa ipinlẹ Kano sọ pe, ọwọ tẹ ọkunrin kan ti wọn fura pe o ba ogoji obinrin lo pọ.
 sáájú ogun àgbéyé kìíní , àwọn orílẹ ̀ -èdè ló máa ń jẹ gàba lórí àwọ ́ n orílẹ ̀ -èdè mìíràn nígbà máà , kò pẹ ́ kò jìnnà tí àwọn orílẹ ̀ -èdè tí wọ ́ n ní mú sìn yìí bẹ ̀ rẹ ̀ ń jà fún òmìnira .
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Díẹ̀ ló kú kí owó tán l‘ápò mi torí ìrànwọ́ Coronavirus - Pasuma Mo ṣèlérí láti rí sí ìrẹ́pọ̀ àti ìwòsàn Amẹ́ríkà - Joe Biden Bí ọwọ́jà ìjọba mi kò bá tíì dọ́dọ̀ yín, ẹ ṣe sùúrù pẹ̀lú wa- Ààré Buhari bẹ̀bẹ̀ Agbẹjọ́ro ọ̀dọ́ sọ́rọ́ ilẹ̀ kún nìjókòó ìgbìmọ̀ tó ń ṣe ìwádìí Ọlọ́pàá dóòlà ẹ̀mí èèyàn 10 nínú àwọn 16 tí ajínigbépawó jí gbé l'Óǹdó Ijọba Oyo ni awọn ibudo gbogbo gbọdọ maa tẹle ofin to dena sisun mọ ara ẹni pẹki pẹki, lilo ibomu ati ọsẹ ifọwọ, to si tun n rọ awọn araalu lati maa fi oju sọri.
Atamatase agbaboolu orile-ede Argentina, Lionel Messi ti jawe olubori ninu idupo agbaboolu ti o dara julo lagbaaye saaju awon akegbe re, Virgil van Dijk ati Cristiano Ronaldo lati gba ami-eye FIFA ti o darajulo fun igba kefa bayii.
ICC pari iwadi lori iparun awọn Shiites, IPOB Fayose: Awọn darandaran to pa Tunde ko ni lọ lai jẹjọ O tun salaye wipe iwọde itaniji naa wa lati lee mu ki araalu mọ nipa aarun yii ki wọn si mọ igbesẹ to tọ lati gbe bi wọn ba kẹẹfin ẹnikẹni to nii layika wọn.
Nígbà tí ó ṣe, ẹbọra yí padà ó di òjòlá, Olówó-ayé náà yí padà ó di òjòla, òjòlá sì bẹ̀rẹ̀ sí bá òjòlá jà, gbogbo igbó ń ké bí ẹran, ìjàngbọ̀n sì gba Igbó Olódùmarè kan-kan.
Ninu ọrọ̀ Adesina, o ṣe alakalẹ awọn anfani ati ayipada ti ijọba to wa lori alefa lọwọlọwọ ti ṣe lati ọdun 2015 ti wọn ti gba ijọba.
Lẹ́yìn èyí ni ìjọba kẹta, tí ó jẹ́ ti idẹ, yóo jọba lórí gbogbo ayé.
” Èyí ni pé ó mú ti àkọ́kọ́ kúrò kí ó lè fi ekeji lélẹ̀.
Ẹ óo rú ẹbọ yìí pẹlu ẹbọ ohun jíjẹ ati ẹbọ ohun mímu rẹ̀, gẹ́gẹ́ bí ìlànà ti ọjọ́ kinni; 
Nígbà náà, o óo máa tọ́ ìṣísẹ̀ mi,o kò sì ní ṣọ́ àwọn àṣìṣe mi.
”Ṣugbọn èyí ekeji dáhùn pé, “Rárá!
Ohun kan ni mo ti tọrọ lọ́dọ̀ OLUWA,òun ni n óo sì máa lépa:Kí n lè máa gbé inú ilé OLUWAní gbogbo ọjọ́ ayé mi,kí n lè máa wo ẹwà OLUWA,kí n sì máa fi tọkàntọkàn sìn ín ninu tẹmpili rẹ̀.
Bi ayeye ayajo odun ominira orile-ede Naijiria se lo ni papa isere Eagle Square, niluu Abuja.
Ajọ to n risi ọrọ idibo nipinlẹ Wisconsin ti ni awọn ikọ ipolongo aarẹ Trump yoo san iye owo to to miliọnu mẹjọ dọla ilẹ okeere lati tun ibo ka nipinlẹ naa.
"Gẹgẹbii Klopp se sọ, "" Ko si iyatọ laarin awọn agbabọọlu ilẹ Afirika ati awọn agbabọọlu yooku lagbaye"" bi awọn anfani to wa fun awọn yooku ba si silẹ fun awọn naa."
Ọrọ yii lo da bii pe o fa sababi ọrọ gan ti iyawo aarẹ fi soju opo Twitter rẹ pe o yẹ ki ọwọ ofin tẹ ẹni to ba rufin ma rin lasiko isede yii.
Agbẹjọro ijọba lori ọrọ Woli Sotitobire ti ni ọwọ adajọ lo ku si lati sọ bọya Sotitobirẹ jẹbi ẹsun ti wọn fi kan an.
Finehasi ọmọ Eleasari, alufaa dá wọn lóhùn, ó ní, “Lónìí a mọ̀ pé OLUWA ń bẹ ní ààrin wa, nítorí pé ẹ kò hu ìwà ọ̀dàlẹ̀ sí OLUWA, ẹ sì ti gba eniyan Israẹli lọ́wọ́ ìjìyà OLUWA.
Àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ bi í pé, “Olùkọ́ni, ta ni ó dẹ́ṣẹ̀, ọkunrin yìí ni, tabi àwọn òbí rẹ̀, tí wọ́n fi bí i ní afọ́jú?
Iwadi wọn fi han pe awọn obirin ni wọn maa n fi ọrọ tita kaadi idibo lọ lọpọ igba.
Naijiria ,ojogbon Yemi Osinbajo ti fokan awon omo orile ede Naijiria balẹ pe ọjọ iwaju orile ede Naijiria si dara.
"Mo n pe awọn darandaran lati gbogbo awọn ilu Naijiria lati wa si Kano nitori a ni awọn ohun eelo to pọ lati gba wọn.
Igba ogun ni Adesanya ti fija pẹẹta pẹlu oriṣiiriṣii awọn alatako, ṣugbọn gbogbo wọn lo la lalubolẹ bi ilu bẹmbẹ.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Barca dín dòdò ìyà fún Man United nílé wọn Beckham, àgbábọ́ọ́lù tẹ́lẹ̀ rèé tó ń sọ èdè Yorùbá Kingston lọmọ Áfíríkà tó gba ohun tí Hulk Hogan kò rí gbà Ọkan lara awọn ololufẹ Manchester United to jẹ ilumọọka lorilẹede Naijiria ni Oluwatoyin Bayegun ti ọpọ mọ si 'Wolii Arole' Ninu ọrọ to ba BBC news Yoruba sọ lẹyin ifẹsẹwọnsẹ naa, wolii arole ni ọpẹlọpẹ adura oun gẹgẹ bii wolii ni ko jẹ ki iye paṣan ti Manchester United jẹ lọwọ Barcelona o pọ pupọ ju ẹyọ kan lọ.
O menuba Pataki apero naa lati safihan awon eko ati imo pelu ninu ajosepo to danmonran sii pelu idanileko to le ni igba ti yoo waye fun idagbasoke ilera Naijiria ati tile Adulawo lapapo.
Àwọn kan lérò wípé ìjọba ò mú kiní ibà-ẹ̀fọn ọ̀hún ní kanpá, àwọn ọmọìlú ń lo ẹ̀rọ-alátagbà mú kí àwọn ènìyàn ó mọ̀ nípa kòkòrò náà.
Kí lo mọ̀ nípa Kashamu tó fẹ́ jẹ gómìnà l'Ogun?
Israẹli ti ṣe ohun tó burú gan-an.
 báyìí gan-an nit i ìṣẹ ̀ dá ìlú Ọ ̀ ra-Ìgbómìnà rí .
Àwọn òṣìṣẹ́ ẹká ọtẹ̀lẹ̀múyẹ́ ni ilé iṣk ọlọpàá lọ fún iṣẹ́ ìdákọ́nkọ́ kan ti ASP Felix Adolije sááju wọ́n, ni [wan ti ni ìdóju kọ pẹ̀lú àwọn ọmọogun Nàìjíríà ní òpópónà Ibi-Jalingo lásìkò ti wọ́n gbé ogbóntarigi ajínígbé Hamisu Wadume lọ si olú ilé iṣe ọlọpaa kan ni Jalingo.
Wọ́n bá bẹ̀rẹ̀ sí dìtẹ̀ láti wá gbógun ti Jerusalẹmu kí wọ́n lè dá rúkèrúdò sílẹ̀.
-Shittu Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Èmí àti Ajimobi ni a ko jọ sin Naijiria ilẹ̀ bàbá wa ṣugbọn.
Diẹ lara wọn wa ni Ìwọ̀ Òòrùn Afrika.
nítorí pé àwọn aláìláàánú yóo di asán,àwọn apẹ̀gàn yóo di òfo;àwọn tí ń wá ọ̀nà láti ṣe ibi yóo parun;
sa lati fi ip[o rere Ipinlẹ Eko mulẹ lojuna ayi ni gbogbo ọna.
Bákan náà ni ọkùnrin ọhun jẹ́wọ́ pé lóòtọ́ ni òun fi ipá bá ọmọ náà lòpọ̀, sùgbọ́n iṣẹ́ esù ni.
Ẹni to bori: Guinea Uganda vs Algeria.
Mínísítà àti iléèṣẹ́ Nipost ń jiyàn lórí àfikún owó ìfìwéránṣẹ́ tuntun Ijọba apapọ ni òun kò lọ́wọ́ sí àfikún owó tí ilé iṣẹ́ NIPOST ń gberò láti fi lé owó àwọn ilé iṣẹ́ tó ń ba ènìyàn fí ẹrù jíṣẹ́, tí ilé iṣẹ́ Nigerian Postal Service kédé láìpẹ́ yìí.
'Ẹ wo àwokọṣe Ambode' Atẹjade aarẹ ni,Ninu idije, eniyan kan a bori, ẹlomiran a ja kulẹ."
Àwọn oníjàgídíjàgan kọlu aàfin Oba ìlú Eko àti iléesẹ́ ìròyìn LTV Oríṣun àwòrán, LAGOS STATE GOVERNMENT Àwọn oníjàgídìjágan kọlu aafin Oba ìlú Eko àti iléesẹ́ ìròyìn LTV Ileeṣẹ iroyin ipinlẹ Eko ti wa ni titi pa bayii lẹyin ti awọn onijagidijagan yabo ileeṣẹ naa.
Eyi lo mu ki wọn o gbe ẹjọ lọ siwaju ile ẹjọ to gaju pe ko fagile idajọ ile ẹjọ kotẹmilọrun, ko si gbọ ẹjọ naa lọtun.
Ile iṣẹ ọlọpa ti parọwa si awọn ara ilu lati ma ṣe alabapin fọnran fidio naa Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Awọn kan tiẹ nifẹ Iwobi ṣugbọn awọn ko fẹ wa lara awọn agbabọọlu Arsenal mọ.
 O tẹsiwaju pe Awa gangan ni wọn n pe ni Barcelona, o si yẹ ki a maa bori ninu gbogbo ifẹsẹwọnsẹ wa ni, ṣugbọn bẹẹ kọ lọrọ ri bayii.
Mose Rán Amí lọ sí Ilẹ̀ Kenaani.
" Ìpínlẹ̀ Ondo tú ìgbìmọ̀ eré ìdárayá ká Èrò márùn-ún kú, méjì farapa, tí awakọ̀ sì fẹsẹ̀ fẹ nínú ìjàǹbá ọkọ̀ l‘Ondo Ta ló da 'ewé' bo N4.
Dokita kan ti ko fẹ da orukọ toripe o n ba ijọba ibilẹ ṣiṣẹ ni Naijiria s fun BBC Yoruba pe idi ti ọpọlọpọ dokita Naijiria ma fi n lọ soke okun ni wipe nkan ti ijba n ṣe ku diẹ kaato.
Mose bá sọ fún àwọn eniyan náà pé, “Ẹ múra ogun kí á lè gbógun ti àwọn ará Midiani, kí á sì fìyà jẹ wọ́n fún ohun tí wọ́n ṣe sí OLUWA.
Ohunkohun to ba wu yin ni kẹẹ pe mi.
sii paapaa julo ni awon eka bi i eto ọrọ- aje, isejọba ati eto iranwọ.
27 Sẹ́rẹ́ 2018 Dino Melaye pa àga dà, ó jókòó ságbo PDP31 Èbibi 2018 Awọn oluwọde ya wọ ile-ẹjọ nitori aṣofin Dino Melaye1 Ẹrẹ̀nà 2018 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 3 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 5 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Eyi waye lakoko ti o fi oko re pa arabirin Phumzile Dube ninu odun 2014, eyi ti won ti fagile eto igbejo naa teleri.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ìsẹ́yìn: Ilé aṣọ òkè alárà ǹ barà Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Nítorí náà, ẹ̀yin ará, kí ó hàn si yín pé nítorí ẹni yìí ni a ṣe ń waasu ìdáríjì ẹ̀ṣẹ̀ fun yín.
Dafidi dáhùn pé, “Ọ̀kọ̀ rẹ nìyí, oluwa mi, jẹ́ kí ọ̀kan ninu àwọn ọmọ ogun rẹ wá gbà á.
 ní ilẹ ̀ amẹ ́ ríkà iye owó rẹ ̀ jẹ ́ 50 sí 100 usd .
Ọjọbọ ni iṣẹlẹ naa waye nilu Ughelli, lasiko ti awọn ọdọ ṣe iwọde lati polongo fun pipa ẹka ileeṣẹ ọlọpaa to n risi iwa idigunjale, SARS, rẹ.
Lójijì, a ó ké eniyan burúkú lulẹ̀;ìjì ibinu Ọlọrun yóo sì gbá wọn lọ.
Abẹsẹ ku bi ojo ọmọ Naijiria ṣalaye pe lootọọ ni pe Joshua lagbara, amọ ọgban inu loun maa fi ṣẹ AJ leegun ẹyin tawọn koju ara awọn.
Sise afihan ife-eye naa, yoo waye ni gbagede Hyundai Motorstudio lagbegbe New Arbat nilu Moscow.
Ènìyàn 241 tuntun ló ti lùgbàdì àrùn Coronavirus ní Ọjọ́ Ìṣẹ́gun ní Naijiria Alfa Babatunde Sotitobire tún fojú balé ẹjọ́ lọ́nìí, bàbá ọmọ jẹri níwájú adájọ́ Ohun mẹ́fà tí àgbáyé kò mọ̀ nípa Majek Fashek tó d'olóògbé nìyíí Bakan naa ni ileeṣẹ eto ilẹra ni ijọba ipinlẹ Rivers ti kọ iwe si Ajọ NDDC lati si ajọ loju eegun iku to Etang.
Eeyan mẹtalelọgbọn lo padanu ẹmi wọn ninu iṣẹlẹ idigunjale ilu Offa, gẹgẹ bii awọn ọlọpaa si ti ṣe sọ, awọn oṣiṣẹ ijọba kan lọwọ ninu rẹ."
Awọn ti ori ko yọ ninu iṣẹlẹ naa, ninu eyi tawọn kan ti di ero ọrun, ṣe iranti bi iṣẹlẹ ọhun ti ṣẹlẹ lapa ẹkun Cabinda lorilẹede Angola.
Ọmọbinrin tó kú àti èyí tí ó dàwátì ní wọn pè ni ọmọ Fasiti Ghana ẹ̀ka Mampong.
Kollington, Bàbá Suwe, Ogun Majek wà lára àwọn gbajúmọ̀ tí ayé ti parọ́ ikú mọ́ sẹ́yìn Èèyàn 627 ló lùgbàdì àrùn Coronavirus ní Naijiria ní Ọjọ́ Ẹtì Irọ́ ni pé Gómìnà Edo Obaseki ti darapọ̀ mọ́ ẹgbẹ́ PDP Alhaja Kudirat Abiola: Odindi géńdé ọkunrin mẹ́fà ni wọ́n gbé iṣẹ́ ikú rẹ̀ fún Eeyan 4,891 lo ti ri iwosan gba, nigba ti awọn 399 ti dero ọrun nitori arun ọhun.
Oríṣun àwòrán, Facebook/Abiola Ajimobi Àkọlé àwòrán, Idibo Ipinlẹ Oyo Ọgbẹni Kola Balogun ti ẹgbẹ PDP lo wọ le dipo Ajimobi fun Ẹkun Gusu Ipinlẹ Oyo.
Ṣugbọn ipinlẹ Zamfara lo buruju nipa gbi gba awọn ọmọbinrin si ile-iwe.
Ohun tí Onani ń ṣe yìí kò dùn mọ́ Ọlọrun ninu, Ọlọrun bá pa òun náà.
Ofin naa din ọjọ ori awọn oludije fun ipo aarẹ ku lati ogoji ọdun si ọdun marundinlogoji, ati tawọn gomina ku lati ọdun marundinlogoji si ọgbọn ọdun.
Àkiyèsí àti ìwádìí yìí ni àwọn eléde gẹ̀ẹ́sì ń gọ́ka sí nígbà tí àwọ́n ba sọ pé.
"Oríṣun àwòrán, Small doctor Àkọlé àwòrán, Kọmíṣọ́nà ọlọ́pàá ní ìpínlẹ̀ Eko ní èyí kìí ṣe ìgbà àkọ́kọ́ tí wọn yóò mú Small Doctor fún ẹ̀sùn tó níí ṣe pẹ̀lú ìbọn "" Wọn ni awọn ọkunrin mẹrin kan ninu ọkọ ti wọn ko gba nọmba idanimọ si fa ibọn kan yọ ti wọn si leri ati yiiin in ms ọlọpaa naa bi ko ba kuro ni oju ọna fun wọn."
Muhammad-Bande ni o ti jawe olubori gege bi aare kẹ́rìnléláàdọ́rin fun ajo agbaye , united Nations.
Lẹ́yìn náà Joṣua ka gbogbo òfin náà sókè ati ibukun tí ó wà ninu rẹ̀, ati ègún, gẹ́gẹ́ bí wọ́n ti kọ ọ́ sinu ìwé òfin.
 ilẹ ̀ Ìjẹ ̀ ṣà wà ní ìpínlẹ ̀ Ọ ̀ yị ́ ní nàìjéríà .
Arowolo fi kun ọrọ rẹ wi pe nigba ti ariwo sọ ni awọn to mọ pe ninu odo kan to n bẹ ni adugbo naa ni wọn sọ oku ọmọ naa si.
Arsenal vs Liverpool: Arsenal fìyà bẹ̀rẹ̀ sáà bọ́ọ̀lù tuntun fún Liverpool pẹ̀lú Community Shield
"But even in defeat, ""Chaos"" established himself as one of the greatest fighters on the planet with an excellent display that will surely still see his stock rise."
Eyi ri bẹ ẹ lẹyin ti ajọ to n mojuto aarun ni Naijiria, NCDC, tun kede ọrinlerugba din mẹẹrin (276) eeyan to tun ṣẹṣẹ ni lọjọ Iṣẹgun.
Gbogbo ẹran ọ̀sìn Kedari ni wọ́n óo kó wá fún ọ,wọn óo kó àgbò Nebaiotu wá ta ọ́ lọ́rẹ.
Olùkọ́ fásitì méjì ń bèèrè ìbálòpọ̀ lọ́wọ́ akẹ́kọ̀ọ́ fún máákì Nigba to n ba BBC Yoruba sọrọ, Ọba Solomon Oyewọle Asinbiorin Keji kaanu pe bi o tilẹ jẹ pe ibudo irin ajo afẹ to lagbara ni ibudo naa jẹ, sibẹ ko si ijọba oloselu kankan nipinlẹ naa, to satunse ibudo ọhun.
sipinle Abia laago mesan ti n se(9:15 GMT), lojo isegun(Tuesday).
Ilẹ Amẹrika ni arun naa tri ṣọṣẹ julọ, lẹyin rẹ ni Brazil ati India.
Bí ẹ bá ti kú pẹlu Kristi sí àwọn ìlànà ti ẹ̀mí tí a kò rí, kí ló dé tí ẹ fi tún ń pa oríṣìíríṣìí èèwọ̀ mọ́?
Amọ ṣa agbẹnusọ ajọ eleto idibo Inec Rotimi Oyekanmi sọ fun BBC pe ayederu iroyin lasan ni.
 kò sẹ ́ ni tỌ ́ lọ ́ run ó ṣe fún ; ó ṣe fájá ; ó ṣe fẹ ́ ran ; Ó ṣe fún kùkùté ẹ ̀ bá ọ ̀ nà ; ó ṣe fún akúwárápá ó ń janra rẹ ̀ mọ ́ lẹ ̀ .
“Lára àwọn tí wọ́n ṣẹ̀ṣẹ̀ ti oko ẹrú Babiloni dé, mú Helidai, Tobija ati Jedaaya lẹsẹkẹsẹ, kí o lọ sí ilé Josaya ọmọ Sefanaya.
Ni aago kan kọja ni oru ni Sowore fi si oju opo Twitter rẹ pe awọn ọlọpaa ti de si ile oun, ti wọn si gba ẹrọ ilewo rẹ.
Ìyàwó mi fi mí sílẹ̀ kó lọ sílé ọkùnrin míì nínú báráàkì kan náà, àmọ́ mò sí tún fẹ́ràn rẹ̀- Sọ́jà Wo àwọn ìṣesí ojoojúmọ́ mẹ́wàá tó le ṣàkóbá fún ọpọlọ rẹ Coronavirus: ''Ìjọba kò tíì pàṣẹ ìlànà ìtakété-síra-ẹni padà nínú BRT la ò ṣe máa tẹ̀le'' Ìjọba gbé ilé ijó oníhòhò tì pa lórí ẹ̀sùn títàpá sí ìlànà àti dẹ́kun coronavirus Wo àwọn Adelé-Ọba aládé méje tó jẹ́ obìnrin nílẹ̀ Yorùbá Pẹlu omije kikoro ati si ọpẹ Florence sọ nipa irinajo aye rẹ ati igbiyanju gbogbo to ṣe lati ri ọmọ gbejo gẹgẹ bii alaaye.
Nítorí náà, OLUWA Ọlọrun Israẹli sọ fún mi pé, “Ìlú tí àwọn eniyan ń sọ pé ọwọ́ ọba Babiloni ti tẹ̀, nítorí ogun, ìyàn ati àjàkálẹ̀ àrùn, 
Ti nnkan meje yii ba n ṣẹlẹ lagbegbe rẹ, ki o tete mọ pe ijọba ti kede ofin konile o gbele niyẹn.
Bakan naa, ko din ni aadọta ilegbe, ile ijọsin ati ileẹkọ to bajẹ kọja aala lasiko ti ọrinrin ibugbamu naa waye lagbegbe Abule Ado yii, ti ọwọja rẹ si tan de awọn agbegbe miran pẹlu.
Mú inú wa dùn fún iye ọjọ́ tí oti fi pọ́n wa lójú,ati fún iye ọdún tí ojú wa ti fi rí ibi.
 a máa ń gbé fíìmù jáde nígbà tí a bá gbá àwòrán àwọn ènìyàn àti àwọn nǹkan sílẹ ̀ pẹ ̀ lú kámẹ ́ rà , tàbí tí a bá ṣẹ ̀ dá àwòràn nǹkan nípa lílo àwọn irinṣẹ ́ kòmpútà .
1 11450 Orilẹede Gabon 66 3.
O kò bìkítà fún àwọn ohun mímọ́ mi, o sì ti ba ọjọ́ ìsinmi mi jẹ́.
Nítorí pé, n óo gba orúkọ Baali kúrò lẹ́nu rẹ̀, kò sì ní dárúkọ rẹ̀ mọ́.
Ipinle Oyo ni nile –ise  ijoba to wa ni agbegbe
Ahira ọmọ Enani ni yóo jẹ́ olórí láti inú ẹ̀yà Nafutali.
"Oríṣun àwòrán, Getty Images Lampard àtàwọn agbábọ́ọ̀lù Chelsea dọ́wọ́jọ di ẹrù wíwo lé Mourinho àti Tottenham lórí Oluwo kò gbọdọ̀ kọrin òwe tàbí bá àkọ̀ròyìn sọ̀rọ̀, kó má baà ba ẹjọ́ ara rẹ̀ jẹ́ - Ọ̀ràngún ṣàlàyé Ààrẹ Gnassingbe díje fún sáà kẹ́rin, òun àti bàbá rẹ̀ ti ṣèjọba Togo fún àádọ́ta ọdún lé mẹ́ta Jospeh Yobo ti di igbákejì akọ́nimọ̀ọ́gbá Super Eagles tuntun Ibanujẹ ni Wilder fi kuro ni gbọgan MGM ti ija naa ti waye nigba to sọ pe ""Ẹni to lee ja ju lo bori, jagunjagun ni mi, ṣugbọn ko si awawi."
Elédùmarè ló rán mi sí gbogbo Ọba Yorùbá - Oluwo Kabiyesi Oluwo ilẹ̀ iwo, Ọba AbdulRaheed Adewale Akanbi ti ke gbajare pé gbogbo ìṣòro Ilẹ́ Yorùbá ko ṣe lẹ́yìn ìwà àwọn lọ́balọ́ba ilẹ̀ Yoruba.
Àìṣojúṣe wọn ni ó fà á tí àwọn olóṣèlú olójúkòkòrò ṣe ń gba àwọn ilé àtijọ́ tí wọ́n sì ń dà wọ́n wó lulẹ̀.
Pondei padà dáku, lásíkò ti an fọ̀rọ̀ wa lẹ́nu wo lórí amohunmaworan lori gbogbo ìwà mágòmágó to ṣẹ̀lẹ̀ ni àjọ náà Godswill Akpabio NDDC vs Gbajabiamila: Ilé Aṣòfin yóò pe Godswill Akpabio l'ẹ́jọ́ fún ìbanilórúkọ jẹ́ Oríṣun àwòrán, @National Assembly Ile aṣofin Naijiria kekere sọ pe oun yoo pe Minisita fun idagbasoke ẹkun Niger Delta, Godswill Akpabio, l'ẹjọ fun ẹsun ibanilorukọ jẹ.
Omowe Onu wi pe ami eye naa yoo
Sikiru Adeleke, Alhaji Aregbesola Muftau to jẹ Ọga agba ile ẹkọ girama Ojo-aro Community grammar school, Gbadamosi Ojo to jẹ akọwe agba ileewe naa, pẹlu Dare Samuel Olutọpẹ to jẹ olukọ nibẹ ni wọn pe lẹjọ pe wọn lọwọ ninu iwa aṣemaṣe lasiko idanwo fun aṣekagba ileewe girama NECO June/July 2017.
'Èmi àti Toyin Abraham ṣẹ̀ sọ̀rọ̀ fún ìgbà àkọ́kọ́ láti ọdún méjì torí ìjà òun àti Lizzy' Funke Akindele, oníròyìn, agbẹjọrò àti òṣèré; ohun tí ẹ kò lérò nípa rẹ̀ Kàyééfì rèé!
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Baby abandoned on dunmpsite: Mo ti bímọ mẹ́rin tẹ́lẹ̀ fún bàbá méjì nínú òṣí- Dupe Ogbomos Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 3 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 5 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
"Mo ni lati ba Ọlọrun jiyàn lori ọna ti mo gba pe o yatọ pupọ.
 giga rẹ ni egypt so mọ ìdádúró ìpolongo ìtọjú gbogbogbòò fun schistosomiasis , lilo abẹrẹ onídígí ti a ko fọ mọ daradara .
Ó sọ fún Solomoni ọba pé, “Òtítọ́ ni ìròyìn tí mo gbọ́ ní ìlú mi nípa ìjọba rẹ ati ọgbọ́n rẹ.
teleri, Francesco Totti ti o tun je okan gbogi lara igbimo to n sakoso iko
O ni ileeṣẹ ọlọpaa ko ni la oju rẹ silẹ mọ, ki awsn ara ilu ma a kọlu awọn oṣiṣẹ rẹ, tabi awọn oṣiṣẹ eleto aabo miran."
Ṣugbọn bí ìwọ bá lè ṣe ohunkohun, ṣàánú wa kí o ràn wá lọ́wọ́.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Èyí ni àwọn arẹwà ‘ẹ̀lẹ̀ Daddy’, àfẹ́fẹ́ tí Aláàfin fi ń mí Ọkùnrin kan bá ọmọ oṣù mẹ́ta lòpọ̀, ìfun ọmọ tú jáde!
Bí wọ́n bá tilẹ̀ bímọ, n óo pa wọ́n tí kò ní ku ẹyọ kan.
Amọ o tun sọ pe ipa ti ko dara ni igbesẹ yii yoo ni lara akitiyan ati owo ti ijọba ti na sori eto ọgbin lasiko ti ẹnu ibode wa ni titi pa.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Mo ti gba kádàrá lórí bí Ọlọrun ṣe dá mi' APC yọ orúkọ Shittu kúrò láti kópa nínú ìdìbò abẹ́lé ‘Aawọ abẹnu lee koba APC ni 2019’ Ọkẹ ṣalaye pe Shittu nikan kọ lo wa ninu ẹgbẹ ki wọn to o fa a kalẹ fun ipo minisita.
com/theladyjokelet/ Koda, ilumọọka osere tiata lobinrin, Jumọkẹ Odetola gan bara jẹ pupọ lori iku asaraloge naa, ẹni to salaye pe o papoda lẹyin wakati diẹ ti wọn sọrọ lori aago.
Nígbà náà ni ẹ óo tó pada sí orí ilẹ̀ yín, tí Mose, iranṣẹ OLUWA, fun yín ní ìhà ìlà oòrùn odò Jọdani, ẹ óo sì máa gbé ibẹ̀.
Ó rọrùn fún ẹni ti ó kàwé àti oníṣẹ́ ọwọ́ lati ri iṣẹ́ nitori oriṣiriṣi iṣẹ́ pọ ni ilú nlá, ju ilú kékeré lọ.
Àwọn ọmọ Elamu jẹ́ ẹgbẹfa ó lé mẹrinlelaadọta (1,254).
Ní tèmi Alákọ̀wé, fàájì ni mo wà o jàre.
Nígbà tí ó jáde ní agogo marun-un ìrọ̀lẹ́, ó rí àwọn mìíràn tí wọn dúró, ó bi wọ́n pé, ‘Kí ló dé tí ẹ fi dúró láti àárọ̀ láìṣe nǹkankan?
Ìjọba pẹ̀lú yóò ṣe atúngbéyẹ̀wò àwọn iṣẹ́ òde ti wọ́n ń ṣe lọ́wọ́, tàbi ki wọ́n dá àwọn iṣẹ́ náà dúró, èyí túmọ̀ sí pé, iṣẹ́ yóò bọ́ lọ́wọ́ àwọn kan.
 O ti le ni oṣu mejila to ti jẹ ki n ba oun ni ajọṣepọ gbẹyin, ṣugbọn ọfẹ lo n fun aale rẹ.
O fi kun un pe oun yoo si pada si ẹnu iṣẹ ni ọjọ Aje.
Ìlú ò rẹ́rìn ín rárá, Alaafin Adeyemi III fárígá fún Buhari nínú lẹ́tà tuntun Dangote: Mo ti gbà $10m ri ní bánkì kí n lè mọ bí o tí ṣé rí lójú Ṣé lóòótọ́ ni pé Buhari ló fa àdínkù owó Dangote?
Oorun díẹ̀, òògbé díẹ̀,ìkáwọ́ gbera díẹ̀ láti sinmi,
Eto igbaniwọle ọhun ni iroyin ni pe o waye ni aago kan oru ọjọ Aiku, ni ile itura kan l'agbegbe Ẹgbẹda nipinlẹ Eko.
Ẹnìkan ń ṣe bí ọlọ́rọ̀,bẹ́ẹ̀ kò ní nǹkankan,níbẹ̀ ni ẹlòmíràn ń ṣe bíi talaka,ṣugbọn tí ó ní ọpọlọpọ ọrọ̀.
Ó fún wọn ní ohun tí wọ́n ṣe aláìní.
Ko si idi meji ju wi pe wahala to n bẹ silẹ laaarin awọn janduku oloṣelu pẹlu bi awsn oṣiṣẹ ajọ eleto idibo ṣe tun pẹ de pupọ awọn ibudo idibo naa.
Yanpọnyanrin bẹ silẹ nibi ipade ipolongo ibo ti ẹgbẹ oṣelu APC ṣe ni ipinlẹ Ogun nibi ti aarẹ Muhammadu Buhari ati ikọ ipolongo rẹ ti n polongo ibo aarẹ ti yoo waye ni ọjọ abamẹta ọsẹ yii.
Ṣugbọn, kọọrọ ni wọn ti maa n ṣe iṣẹ abẹ 'oju ara tuntun yii', nitori pe ẹgbẹ awọn onimọ iṣegun oyinbo ni Sudan tako o.
Eto idibo America: Oriṣiriṣi iṣẹlẹ lo ti ṣẹlẹ ni orilẹede America lati igba ti wọn ti d'ibo yan Donald Trump sipo aarẹ l'ọdun 2016.
Bẹ́ẹ̀ sì ni àwọn ọkunrin náà tọ́jú wa, wọn kò sì ṣe ibi kankan sí wa, nǹkankan tí ó jẹ́ tiwa kò sì sọnù nígbà tí a wà pẹlu wọn ní oko.
Bundesliga ni Liigi akọkọ nilẹ Yuroopu ti yoo bẹrẹ idije bọọlu lẹyin ti ajakalẹ arun Covid-19 mu ki ere idaraya kogba wọle kaakiri agbaye ni ibẹrẹ ọdun 2020.
Yorùbá fẹ́ràn àlejò, nitori eyi, bi Oniṣòwò bá lọ si Ọjà Oko ni ilú miran, ti kò lè délé ni ọjọ́ ti ó gbéra, yio ri ilé sùn ni abúlé ti ó bá dé ti ilẹ̀ fi ṣú lai sanwó.
"Soun ilẹ̀ Ogbomoṣo pàdánù ọmọkùnrin rẹ̀ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Ọkọ mi wa ọkọ̀ tẹ ""Poly Bag"" lásán, àfi gbùùàà!"
0 29572 Orilẹede Malaysia 396 1.
Wọ́n ti ṣí ilé oúńjẹ oní ọgbọ̀n náírà (N30) ní Kano Ìjọba, ẹ yé fi ẹ̀tọ́ ọmọnìyàn dun ọmọ Nàìjíríà mọ́- SERAP Ìlú kò mọ ohunkóhun nípa iṣẹlẹ màálù tó kú nilu Ikarẹ- Oba Olukarẹ EFCC gbé ọ̀gá owó ìfẹ̀yìntì tẹ́lẹ̀ lọ sÍ ilé ẹjọ́ fún ìwà ìbàjẹ́!
Bẹ́ẹ̀ ni ó ṣe sí àwọn ará ìlú Amoni yòókù.
Àwọn èrò tí ń lọ níwájú, ati àwọn tí wọn ń bọ̀ lẹ́yìn wá ń kígbe pé,“Hosana fún Ọmọ Dafidi,olùbùkún ni ẹni tí ó wá lórúkọ Oluwa.
Lẹyin ti ọkọ ati aya ba ti rira tan ni alarinna ti bẹrẹ iṣẹ.
Aare Muhammadu Buhari ti ro awon toro kan gbongbon ninu egbe oselu All Progressives Congress APC lati sise takuntakun lojuna lati jawe olubori ninu eto idibo gomina ipinle Ekiti ti yoo waye lojo kerinla osu keje odun ti a wa yii.
Wo àwọn oúnjẹ márùn ún tó ń mú kí àtọ̀ ọkùnrin dára síi Tí a bá yọwọ́ àwọn ọba alayé kúrò, kò ní sí Nàìjíríà mọ́- Alaafin Oyo Wo dókítà ọmọ Nàìjíríà tí àgbáyé ń wárí fún nítorí abẹ́rẹ́ àjẹsára COVID-19 Nkechi Blessing vs Toyin Abraham: Nkechi tí tọrọ ìdáríjí ẹ̀ṣẹ̀ lọ́wọ́ akẹgbẹ́ rẹ̀, Toyin Abraham Kí lo mọ̀ nípa ìbẹta kan ṣoṣo tí Alaafin Oyo bí?
Iko omo-ogun ofurufu orile-ede Naijiria, Nigerian Air Force (NAF) tun ti se aseyori ninu ise akanse eyi ti won n gbese lati doju ija ko awon agbesunmomi omo-ogun olote to n dojuko eka ila oorun orile-ede Naijiria.
Iyabo Ojo fi siga dara: Oríṣun àwòrán, others Ẹrin arintakiti ni loju opo Instagram pẹlu fidio kan ti Iyabo Ojo ṣe, to fi n sin awọn janduku jẹ.
" Ẹwẹ, biṣọbu Micheal Curry to waasu nibi igbeyawo Harry ati Meghan ni ọdun 2018 ni ibi ọmọkunrin naa fihan pe 'ireti n bẹ'Bẹẹni o ṣe adura ibukun fun ẹbi naaati ọmọ wọn tuntun.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Kollington ṣàlàyé bí orin Fuji ṣe bẹ̀rẹ̀ gan an ní Nàiìjíríà Ọjọ Iṣẹgun, ọjọ kẹẹdogun, oṣu Kejila,ọdun 2020, ni ajọ NCC kede fun gbogbo araalu lati ri daju pe nọmba NIN wọn wa lara iforukọsilẹ siimu wọn.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Wo bí o ṣe leè ṣe ìjìnàsíraẹni ní ibiṣẹ́ lásìkò Coronavirus yìí Wo ohun tó yẹ kí o mọ̀ nípa àbádòfin NCDC tó ń fa fà kí n fà lórí ìtàkùn àgbáyé Oríṣun àwòrán, @dabiodunmfr Lẹnu ọjọ diẹ sẹyin lawọn ọmọ Naijiria ti bẹrẹ si n fi erongba wọn lede lori abadofin to rọ mọ ajakalẹ arun ti ile igbimọ aṣojuṣofin dawọle.
 ‘Mo n foju sona lati bere ise ni kiakia.
Òní lọjọ́ pé ti àwọn ọmọ orílẹ̀èdè Amẹrika  nyan ààrẹ orílẹ̀èdè sípò nínú ìdìbò gbogbo gbòò.
Oríṣun àwòrán, @abdulrashid_mai Àkọlé àwòrán, Kí ló dé tí Ààrẹ Buhari tún ń dá àwọn tó fúnrarẹ̀ yọ nípò pàdà Abdulrasheed Maina, ileeṣẹ owo ifẹyinti awọn ọlọpaa Ni ọdun 2013 ni ajọ iṣẹ ijọba apapọ le Maina kuro nipo lẹyin aṣẹ ofiisi olori ẹka oṣiṣẹ ijọba lorilẹ-ede Naijiria.
Ó dúró ní ààyè rẹ̀, ó sì bá OLUWA dá majẹmu pé òun óo máa fi tọkàntọkàn rìn ní ọ̀nà OLUWA, òun óo máa pa òfin rẹ̀ mọ́, òun óo máa mú àṣẹ rẹ̀ ṣẹ, òun ó sì máa tẹ̀lé ìlànà rẹ̀.
“Bẹ́ẹ̀ ni Ọba tí ó ga jùlọ kì í gbé ilé tí a fi ọwọ́ kọ́.
”Ó dá wọn lóhùn pé, “Oró tí wọ́n dá mi ni mo dá wọn.
Oloye Lai  Mohammed to je Minista fun ifitonileti , asa ati irinajo afe fun Naijiria lo so eyi di mimo fawon akoroyin ile joba lAbuja lasiko to m ba won soro leyin ipade apapo igbimo amusese ijoba apapo eyi ti Aare dari.
Jẹ́ kí ìdajì awẹ́ tí ó kù ṣẹ́ bo ẹ̀yìn àgọ́ náà.
Afi bí o bá lọ sí ọ̀run àpáàdì nìkan ni ó tó lè rí wọn.
Bẹ́ẹ̀ ni ó bẹ̀rẹ̀ sí ffọ́ àwọn akèǹgbè orí ọ̀pẹ wọn-ọnnì bí ó ti ń lọ láti ọ̀kan dé ọ̀kan.
Ẹni to bori: Algeria Guinea vs Cameroon.
Oríṣun àwòrán, Others Ajọ NCDC naa fi ikede naa si oju opo ikansiraẹni Twitter wọn, ti apapọ awọn eniyan to ni arun naa ti wa da 9855.
Ṣugbọn omi kan a máa ru jáde láti inú ilẹ̀ láti mú kí gbogbo ilẹ̀ rin.
Eniyan ń ṣègbé lọ bí ohun tí ó ń jẹrà,bí aṣọ tí ikán ti mu.
 a ó ṣe àgbéyẹ ̀ wò wọn ní ọ ̀ kọ ̀ ọ ̀ kan .
Coronavirus ti di ara wa, kò le è kúrò mọ láéláé - WHO Ìdí rèé tí ilẹ̀ Afirika fi gbọdọ̀ kópa nínú dídán abẹ́rẹ́ coronavirus wò Jesu Oyingbo rèé, pásítọ̀ tó láṣẹ ìbálòpọ̀ lóri ọmọ ìjọ obìnrin Lẹyin eyi lo lo ọbẹ kan naa lati fi gun ikun ara rẹ, bi awọn ọmọ ijọ ṣe tun fẹ sare si wọn lori pẹpẹ lo fi ọbẹ naa ge ara rẹ rẹ ní ọ̀fun.
Kikanju ṣe ayẹwo - tabi aiṣe e rara lẹyin ileri lati ṣe e.
#justiceforstephen: Ọlọ́pàá ìpínlẹ̀ Èkó láwọn ti mú afunrasí méjì tó mọ̀ nípa ikú Dókítà Stephen Urueye
Kajwang ti o jẹ ọkan poogi lara awọn alẹnulọrọ ninu ẹgbẹ alatako naa, lo wọ asọ adajọ agba to bura wọ'le fun Odinga nibi ayẹyẹ naa, ti ọpọ alatilẹyin ẹgbẹ alatako na si ba Odinga yọ lori ibura to waye ni Uhuru park ni olu-ilu Kenya, Nairobi.
Ìdájọ tó wáyé lónìí ṣẹlẹ láì sí Dino ní ilé ẹjọ́.
Oniruuru iọọrọ odi si ni Naira Marley dojukọ fun ṣiṣe atilẹyin fun iwa jibiti ori ayelujara ti ọpọ mọ si yahoo-yahoo.
Ṣé o mọ̀ pé ilẹ̀ aṣálẹ̀ ni o fún mi; nítorí náà, fún mi ní orísun omi pẹlu rẹ̀.
Fún ọ̀pọ̀lọpọ̀ ìgbà, fẹ́lẹ́ fẹ́lẹ́ ni àwọn ǹkan ìseré ìbálòpọ̀ ma ń rí tojú ò sì leè rí i dáadáa"" Stuart Nugent tó jẹ́ alámojútó àgbáyé ilé iṣẹ́ tó ń ṣe ǹkan ìṣeré ìbálòpọ̀ ní orílẹ̀èdè Sweden, LELO sọ pé, ""Kò jẹ́ kí ọ̀pọ̀lọpọ̀ máa ra ǹkan ìṣeré yìí."
Ó bí Aaroni ati Mose ati Miriamu, arabinrin wọn fún Amramu.
Àlàó ń mu ẹmu lẹ́yìn tí ó jẹun tán Ilésanmú sì ń mu ògógóró.
Ọ̀rọ̀ bẹ́ẹ̀ ko mu'na doko l'ọdọ awọn eeyan rara.
Nítorí náà, ẹ̀yin ọba, ẹ kọ́gbọ́n;ẹ̀yin onídàájọ́ ayé, ẹ gba ìkìlọ̀.
Eyi waye lẹyin tawọn ologun kọju oro si Boko Haram ni ọdun 2015, pẹlu atilẹyin awọn orilẹede agbaye ti wọn si gba awọn ilu ti o wa labẹ iṣakoso iks agbebọn naa pada.
Àwọn ará Efuraimu bèèrè lọ́wọ́ Gideoni pé, “Irú kí ni o ṣe yìí, tí o kò pè wá, nígbà tí o lọ gbógun ti àwọn ara Midiani?
Ìgbà náà ló mọ̀ wí pé òun kò nílò láti ní ìrírí ìbálòpọ̀ bíi gbogbo ènìyàn.
 Àrùn yíì bẹ ̀ rẹ ̀ ní Áfíríkà , níbi tí o ti tàn dé gúúsù amẹ ́ ríkà nípasẹ ̀ òwò ẹrú ní 17 century .
Ìrí-bá-kan-náà, Danjuma fi ariwo ta nípa ète bí àwọn “ọlọ́pàá àti ológun” ṣe ń gbìmọ̀pọ̀ láti ṣe ẹ̀rú nínú ìbò ọdún 2019.
 O tun seto ona irorun nipa lilo ero
Peteru sọ fún un pé, “Bí mo bá tilẹ̀ níláti bá ọ kú, n kò ní sẹ́ ọ.
23 Bélú 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Nígbà tí wọ́n gúnlẹ̀, wọ́n rí ẹja lórí iná eléèédú, wọ́n tún rí burẹdi.
Ayo meji si odo ni ẹgbẹ agbabọọlu naa fi gbewuro soju ikọ Unai Emery.
Tabi ẹ kò kà ninu ìwé Òfin pé iṣẹ́ àwọn alufaa ninu Tẹmpili ní Ọjọ́ Ìsinmi a máa mú wọn ba Ọjọ́ Ìsinmi jẹ́?
Gègé mú Ṣupimu ati Hosa fún ẹnu ọ̀nà apá ìwọ̀ oòrùn ati ẹnu ọ̀nà Ṣaleketi, ní ojú ọ̀nà tí ó lọ sí òkè.
’ Ṣugbọn kẹ́kẹ́ pamọ́ ọkunrin náà lẹ́nu.
Awon miiran ni: Oghenekaro Etebo, John Ogu, Mikel Agu, Kelechi Iheanacho, Moses Simon, Victor Osimhen, Henry Onyekuru, Alex Iwobi, Isaac Success ati Samuel Chukwueze.
Báwo ni ẹ ṣe wá yipada patapata,tí ẹ di àjàrà igbó tí kò wúlò?
Ṣugbọn ó fẹ́rẹ̀ tó àkókò, tí yóo gòkè wá láti inú ọ̀gbun jíjìn, tí yóo wá lọ sí ibi ègbé.
O ki awọn onigbagbọ atawọn musulumi ninu fidio ọhun ku ọdun Ajinde, bakan naa lo ki wọn ku ọjọ Jimọ.
Lati gba ife eye idije yii ni igba mokanla otooto, o je ohun ti mi o ronun kan rara.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Eid el Kabir: Ọjọ́ márùn-ún ló ṣe kókó nínú iṣẹ́ Hajj 9 Ògún 2019 Oríṣun àwòrán, @tabir Nibayii ti ọdun ileya n kan ilẹkun, ti awọn musulumi to wa ni orilẹede Saudi Arabia si n gbaradi lati gun oke Arafat, o yẹ ka la ara wa lọyẹ lori ohun ti isẹ Hajj wa fun, ati bi wọn se n se e ki wọn to pe eeyan ni Alhaji abi Alhaja.
“OLUWA yóo kọ́kọ́ fún àwọn ogun Juda ní ìṣẹ́gun, kí ògo ilé Dafidi ati ògo àwọn ará Jerusalẹmu má baà ju ti Juda lọ.
Omowe Ali salaye pe, “orile-ede Naijira ko le gbeyin rara, erongba mi ni lati ri pe, ipade igbimo yii yoo je anfaani lati jiroro awon ilana ati eto ti yoo mu igberu ba sise atileyin owo fun aarun kogbogun naa, o je ohun idunnu lati bi odun kan seyin, a ti ni aseyori to po, ijoba apapo tun safihan ipinnu re lori atileyin fun aarun HIV, kii se atileyin  fun itoju nikan, bikose fifowo sowopo pelu ile-igbimo asofin lati salekun owo-na, ti a niloo fun aarun kogbogun HIV/AIDS.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù N-Power 2020 recruitment: Ṣé lóòtọ́ ní pé àwọn alákòso tí kéde àwọn tó ṣe àṣeyọrí nínú ètò ìgbanisíṣẹ́ ọdún 2020?
Yóo ru òkúta, ati igi, ati erùpẹ̀ tí ó wà ninu ìlú rẹ dà sinu òkun.
Nígbà tí gbogbo ètò ti parí, àwọn alufaa ati àwọn ọmọ Lefi dúró ní ààyè wọn gẹ́gẹ́ bí àṣẹ tí ọba pa.
lenu ise won,Gomina Ajimobi soro yii lasiko  ayajọ ayẹyẹ awon osise ti odun 2019, ti won pe
ṣugbọn ko ri ile gba bo tilẹ jẹ pe, o ni owo rẹ dani, gbogbo da lori wipe ko si nile ọkọ.
28 Agẹmo 2019 Oríṣun àwòrán, Google Àkọlé àwòrán, Gomina Makinde:Osù tó ń bọ̀ la ó gbé ètò ààbò ilẹ̀ Yoruba jáde!
Ẹ jáde lọ, ẹ̀yin ọmọbinrin Sioni,ẹ lọ wo Solomoni ọba,pẹlu adé tí ìyá rẹ̀ fi dé e lórí,ní ọjọ́ igbeyawo,ní ọjọ́ ìdùnnú ati ọjọ́ ayọ̀ rẹ̀.
Daniel, lasiko to n salaye bi isẹlẹ naa se waye ni lẹyin tawọn janduku yege lati jo agọ ọlọpa Makinde naa nina, ni wọn ya wa si baraki ilegbe awọn ọlọpaa, ti oun ati iya oun n gbe.
Nígbà tí balogun ọ̀rún gbọ́, ó lọ sọ́dọ̀ ọ̀gágun, ó bi í pé, “Kí lẹ fẹ́ ṣe?
eto idibo to n bo ni ipinle naa.
Nigba ti àwọn àgbà ọ̀jẹ̀ bii Germany to gba ife ẹyẹ gbẹyin paapaa ti kuro ni Russia pada sile.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Christmas:Ṣé ẹ ti ra fìlà ọdún?
Die ree lara ohun to yẹ ko mọ nipa alaga ajọ eleto idibo Ghana [Jean Adukwei Mensa].
9 66,635 South Korea 1,217 2.
BBC Yoruba beere itumọ 'Staircase' ni Yoruba
Ahimeleki sì dáhùn pé, “Idà Goliati ará Filistia tí o pa ní àfonífojì Ela nìkan ni ó wà ní ibí.
Kò dára kí á ṣe ojuṣaaju sí eniyan burúkú,tabi kí á dá olódodo ní ẹjọ́ ẹ̀bi.
Agbenusoro nile-igbimo asoju-sofin, Yukubu Dogara jawe olubori ninu abajade  esi idibo ile-igbimo fun ekun Bogoro, Dass Tafawa Balewa, nipinle Bauchi to n soju fun.
Ipade ohun ni Lavron se agbekale re.
Kì í fi ìgbà kan kúrò ninu Tẹmpili.
Martins ati Ayo Makun si gba boolu sagbon fun iko Nigerian stars ki ifesewonse
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Damilọla pàdánù ọ̀rẹ́kùnrin rẹ̀ nítorí ilà kíkọ Bawo lo ṣe ṣe e ti mi o mọ?
Akowe egbe  fun igbimo eto idibo egbe naa  to n sese kuro ninu ipo  asofin  Benjamin Uwajumogu lo soro yii  lasiko  to n fipo sile fun akowe tuntun,asofin Victor Ndoma-Egba  ni gbongan ile egbe to wa niluu Abuja.
Lasiko ti aarẹ Yaradua di oloogbe, ti igbakeji rẹ, Goodluck Jonathan si rọpo rẹ, yii gan an ni Dora Akunyili gbe akanṣe eto kan kalẹ to pe ni 'Re-branding Nigeria Project' fun atunṣe orukọ ati iyi orilẹede Naijiria.
Pápá oko tútù tí ìbẹ̀rù kò sí níbẹ̀ tẹ́lẹ̀ ti di ahoronítorí ibinu gbígbóná OLUWA.
Mo rọ yin lati yago fun iru ọrọ bẹ'' Ìlúmọọká akọròyìn NTA Nàìjíríà, Ayinde Soaga lùgbàdì Covid 19 Egbẹ akọroyin orile-ede Naijiria ẹka ipinlẹ Katsina tibanujẹ lori bi ọkan lara wọn, gbajugbaja akọroyin ni, Ayinde Soaga, ti se lugbadi arun Coronavirus.
Ọmọwe Kurami la alatko rẹ lati ẹgbẹ oṣelu PDP, Alhaji Aminu Magaji mọlẹ lati jawe olubori ninu eto idibo ọhun.
Lẹ́yìn tí Dafidi ti ṣẹgun ìlú olódi náà, ó ń gbé inú rẹ̀, ó sì yí orúkọ ibẹ̀ pada sí “Ìlú Dafidi”.
Ẹ̀yin ará, èmi gan-an kò ka ara mi sí ẹni tí ó ti dé ibi tí mò ń lọ.
Má ṣe bá ẹnikẹ́ni jà láìnídìí,nígbà tí kò ṣe ọ́ níbi.
Bakan naa, awọn ileewe alalọde to wa lara wọn ni G.
Ninu awọn mẹsan an to ku naa, awọn mẹrin ti wọn dibo pe wọn le ja kuro ninu BBNaija ni Dorathy Prince, Kiddwaya ati Ozo.
O ti sọ wá di ẹni ẹ̀gàn lọ́wọ́ àwọn aládùúgbò wa;a di ẹni ẹ̀sín ati ẹni yẹ̀yẹ́ lọ́dọ̀ àwọn tí ó yí wa ká.
pẹlu ìrànlọ́wọ́ àwọn ọkunrin mejila náà, wọ́n kọ orúkọ gbogbo àwọn ọmọ Israẹli sílẹ̀, láti ẹni ogún ọdún sókè, ní agbo-ilé agbo-ilé, ati ní ìdílé-ìdílé.
Kò pẹ́ púpọ̀ lẹ́hìn èyí tí àkúté kan ń rékọjá, ìrọ́jú ni mo sì fi mọ̀ pé èkúté ni, nítorí ibi tí mo wà jìnnà si ìsàlẹ̀, ohun gbogbo sì kéré gidigidi.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Odebiyi: ìgbà gbogbo ni Bàbá mi ń polówó iṣẹ́ mi fáráyé Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Odebiyi: ìgbà gbogbo ni Bàbá mi ń polówó iṣẹ́ mi fáráyé 7 Òkùdu 2019 Ẹ̀bùn mi ni ìlú lílù fógo Ọlọrun- Top sticks Odebiyi Temitope ti gbogbo eniyan mọ si Top sticks Onilu ṣalaye kikun lori bi oun ṣe bẹrẹ iṣẹ ilu lilu fún BBC.
Bí ó ti ń bọ̀ tí ó ń súnmọ́ etílé, ó gbọ́ ìlù ati ijó.
APC: Wọn kò fún wa láàyè láti dibo nígbà ti ẹ̀ri wà pe ẹgbẹ́ PDP ń díbo ní àìmọye ìgbà
Nítorí náà ohun tí Ọlọrun bá ti so pọ̀, kí ẹnikẹ́ni má ṣe yà á.
" Awọn iroyin ti ẹ lee nifẹẹ si: Nigba wo ni isuna 2018 yoo dohun?
Ilééṣẹ́ Facebook leè mọ ìgbà tí àwọn tó wà lójú òpó wọn ń ní ìbálòpọ̀ Ìpínlẹ̀ Ogun fẹ́ fi òfin wọ́gilé ìsìnkú ọba lọ́nà ìṣẹ̀mbáyé Awakọ̀-èrò, ọlọ́kadà farakásá àṣẹ ìjọba Ekiti láti dẹ́kun Coronavirus Ẹ wo ǹkan to sẹlẹ̀ sí ọmọ àti ìyàwó ọmọ Atikú tó lùgbàdì ààrun Coronavirus Ẹwẹ, minisita fun eto ilera, Dokita Osagie Ehanire ti sọ pe afaimọ ki ọrọ Naijiria naa ko ma dabi ti orilẹede China ati Italy lori bi ọrọ coronavirus ṣe n lọ yii.
team of the Nigeria Railway corporation), awon onimo ijinle nipa oko ojurin,
Igbesẹ yi waye lọjọ kan lẹyin ikọlu to waye lagbegbe Mopti nibi ti awọn ọlọdẹ kan ti yabo abule awọn Fulani.
meta  to di ado oloro mọra, lojo Aiku ọgbọnjọ
Ẹ wo ìdí tí ẹ gbọdọ̀ fi gba abẹ́rẹ́ àjẹsára fún ọmọ yín!
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Orlando Owoh: Èmí àti Oladipupo Owomoyela jọ lọ ẹ̀wọ̀n Alágbọn- Caroline Owoh, aya Orlando Adeniyi ni DPO Gwazarzah dunkoko mọ oun nigba ti oun lọ gbe aṣọ rẹ fun un lori ẹsun pe oun ko ran aṣọ naa daadaa.
“Maa gbiyanju lati mu ipinnu awon omo orile ede Naijiria sẹ.
Oríṣun àwòrán, lizzyanjorin_original Eyi jẹ ọkan lara awọn asiri aseyori mi, nitori ọkan mi mọ si gbogbo eeyan, bẹẹ ni ariwo ọja kii se idiwọ fun ontaja ati onraja, sugbọn bi ariwo ba se pọ si ninu sja ni ọja yoo se maa ya si.
nítorí alágbàṣe lásán ni, kò bìkítà fún àwọn aguntan.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Nkechi Blessing: Gbajúgbajà òṣèré ní ó sàn fún òun láì tíì lọ́kọ báyìí ju kí òun lọ́kọ láì láyọ lọ 11 Ọ̀wàrà 2020 Oríṣun àwòrán, Instagram/nkechiblessingsunday Gbajugbaja oṣere tiata Yoruba, Nkechi Blessing tun ti ja gudugbẹ ọrọ mii lẹyin to sọ pe o san fun oun lai tii lọkọ bayii ju ki oun ti ṣe igbeyawo lọ.
Ilé ẹjọ́ dájọ́ ẹgba mẹ́ẹ̀dóògún fún ọ̀daràn tó jí Iphone ní Kaduna Wo dókítà ọmọ Nàìjíríà tí àgbáyé ń wárí fún nítorí abẹ́rẹ́ àjẹsára COVID-19 Wo ọkùnrin ẹni ọdún 55 tí wọ́n ká agbárí èèyàn mẹ́rin, àti àwọn ẹ̀yà ara mìí mọ́ lọ́wọ́ ní Ogun Ìdí rèé tí ìjọba fi ń gbèrò pé kí àwọn tó ń gba 'minimum wage' má san owó orí mọ́ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Akọ́mọlédè àti Àṣà lórí BBC Yorùbá: Kọ̀ síi nípa iṣẹ́ tí oúnjẹ ń ṣe lára níbí Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Ilé ẹjọ́ tú ìgbéyàwó ọdún mẹ́wàá ká nítorí ẹ̀sùn ìbálòpọ̀ ọlọ́jọ́ gbọọrọ àti òògùn owó26 Bélú 2020 Grammy awards 2021 - Burna Boy, Beyoncé, àti Dua Lipa, wà lára àwọn ti wọ́n fi orúkọ wọn sílẹ̀25 Bélú 2020 Adeyeye Ile Ife: Kílódé tí Ọọni Ife, Oba Ogunwusi kò fi gbọdọ̀ rí ọmọ rẹ̀ tuntun títí di ẹ̀yìn oṣù mẹ́fà?
  Etí odò yìí ni enìà ní láti tọ̀ títí dé inú igbó kan.
Ọmọogun orí ilẹ̀ sọ fun gbogbo ayé pé òtu bántẹ́ ní ìròyìn náà, òtítọ́ kan kò sí níbẹ̀, nítorí náà kí gbogbo èniyàn lọ fi ọkan balẹ̀ pàápàá júlọ àwọn to wà ní ìhà ìlà-oorùn - àríwá láti ketí ọ̀gbọin sí àhesọ ọ̀rọ̀ náà nítori pe ètò ààbò tó wà nílẹ̀ kò ni kọ́nukọ́họ nínú.
Àwọn tó jí ọmọ mi gbé nílé ìjọsìn ní ń kò gbọdọ̀ wa tàbí kí ẹ̀mí mi lọ si"" Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?"
Àwọn ọmọ Nàìjíríà la ohùn Olùdásílẹ̀ Twitter bá wọn jó 'Soapy' ní Nàìjíríà , ó fi òǹtẹ̀ jan Tacha Akande ní, o ṣe ni láànú pé àwọn kan n fíra wọn silẹ̀ láti jẹ oun èlò àyálo, ti yóò da omi àláfíà to wà láàrin ààrẹ Buhari ati Igbákeji rẹ̀ Yemi Osinbajo ru.
2 Agẹmo 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Ko fẹ si ibi ti eeyan yoo kọju si lorileede Naijiria, ti ko ti ni ma gbọ ọrọ nipa Ruga settlement.
gbe Umar Bago ti won jo n dupo papo subu, nigba ti
Ni kete ti fidio ti ọmọ naa ti n bẹ iya rẹ pe ko calm down n ja rainrain lori ayelujara, ni ajọ naa ti fi ikede sita pe, wọn n wa ọmọde naa, lati wa se asoju ajọ ọhun.
Ohun to sọ pe o jẹ koko ni wi pe Ambode ti bẹrẹ si ni na owo lati inu isuna ọdun 2019 eyi ti wọn ko tii gbe siwaju ile to si lodi si alakalẹ ofin.
Ó dámi lójú pé èyí kò ní ṣe àṣemọn wọn o.
Nítorí náà, àgọ́ yín níláti jẹ́ mímọ́, kí OLUWA má baà rí ohunkohun tí ó jẹ́ àìmọ́ láàrin yín, kí ó sì yipada kúrò lọ́dọ̀ yín.
Ṣugbọn nígbà tí Reubẹni gbọ́, ó gbà á kalẹ̀ lọ́wọ́ wọn, ó ní, “Ẹ má jẹ́ kí á pa á.
 Ìdí nìyí tí ó fi jẹ ́ wípé àwọn obìnrin ló ma ń gbé gẹ ̀ lẹ ̀ dẹ ́ .
Jẹ́ kí wọ́n fi ojú ara wọn rí ìparun ara wọn,kí wọ́n sì rí ibinu Olodumare.
Sọ́ra fún gbájúẹ̀, BBC kò ṣètò owó ẹ̀kọ́ ọ̀fẹ́ Akẹ́kọ̀ọ́gboyè ní mí ṣùgbọ́n aṣọ òké ló ń pawó wọlé' Ǹjẹ́ o mọ̀ pé Baba Sala ló kọ́ Sunny Ade nísẹ́?
1 19468 Orilẹede Libya 1243 18.
Àgbàlagbà obìrin yìí kìí rí ẹlòmíràn bá sọ̀rọ̀ nítorípé ọkọ rẹ̀ ti ṣaláìsí.
Bí mo ti ń ṣe ni n óo tún máa ṣe, kí n má baà fi ààyè sílẹ̀ fún àwọn tí wọ́n fẹ́ ṣe ìgbéraga pé iṣẹ́ wọn dàbí tiwa.
Ní ọjọ́ kẹrin oṣù Èrèlé, Global Voices bá Fernando Gomes, ajìjàǹgbara ọmọ orílẹ̀ èdè Angola tí ó jẹ́ ọ̀kan lára àwọn alátìlẹ́yìn ìfẹ̀hónúhàn náà tàkùrọ̀sọ, láti mọ ohun gbogbo tí ó rọ̀ mọ́ ìṣẹ̀lẹ̀ náà.
Ẹ̀yin ará, ẹ jẹ́ kí á lo àkàwé kan ninu ìrírí eniyan.
Get help Worldwide Get Help Worldwide ṣeleri ajẹpọnnula èrè ìdá ọgbọn si aadọta (30%-50%) fun olukopa loṣooṣu.
19 Nítorí, pàsán ìsọdahoro yíò jade lọ sí ààrín àwọn olùgbé ilé ayé, yíò sì tẹ̀síwájú lati máa tú jade láti àkókò dé àkókò, bí wọn kò bá ronúpìwàdà, títí ilé ayé yíò fi di òfìfo, àti àwọn olùgbé rẹ̀ yíò fi jóná tán tí wọn yíò sì parun pátápátá nípa mímọ́lẹ̀ ti bíbọ̀ mi.
Ọba bá pàṣẹ pé, “Ẹ lọ wádìí ibi tí ó ń gbé, kí n lè ranṣẹ lọ mú un.
Sugbọn nigba to n fesi lori asẹ ti Makinde pa pe, kawọn alaga ijọba ibilẹ gbogbo to wa nipinlẹ Ọyọ ko aasa wọn kuro ni ọọfisi, agbẹnusọ fawọn alaga ijọba ibilẹ naa, Ọmọọba Ayọdeji Abass Alẹsinlọyẹ fajuro lori ipinnu Makinde naa, to si ni gomina tuntun ọhun tẹ ofin loju laarin wakati meji pere to seleri lati gbe ofin Naijiria ro.
Ó di agbábóòlù mẹta tí a ti pàdánù láàárín ọjọ meji - NFF Manchester United kò lèe ta pútú ní AZ Alkmaar Kiki Osinbajo gbóṣùbà fún Seyi Awolowo, MC Oluomo gbárùkù ti Mike ní BBNaija Àbọ̀ mi rèé láti orílẹ́èdè South Africa- Ààrẹ Muhammadu Buhari Tacha tọrọ àforíjí, ó da gbogbo ẹ̀bi lé ara rẹ̀ lórí Ọ̀pọ̀ èèyàn bẹnu ẹ̀tẹ́ lu Mercy Aigbe lórí bó ṣe ki Adeniyi Johnson Balogun ati aṣọle ikọ Tottenham, Hugo Lloris lo kọkọ tasẹ agẹrẹ bi Tacha lo ba mu bọọlu bọ sinu awọn ara rẹ.
" Shina Rambo fikùn pe, oun le e gbe orisirisi àwọ̀ eeyan wọ nigba kuugba to ba wu oun, eyi to mu ko nira fawọn ọlọpaa ri oun mu.
Afunra sí ọ̀hún Tunde Okunola ní wọn mú ní láyípo Marwa ní ìlú Lekki pẹ̀lú agbódegbà rẹ̀ Segun Adigun lásìkò tí wọn ń gbìyànjú ja Gift Omini lólè ní dédé ààgo márùn ku ìṣẹ̀jú méèdóógún ààrọ̀ lójọ́rú.
Ìgbákejì ààrẹ, tètè yọ Trump nípò, bí bẹ́ẹ̀ kọ́.
O ṣalaye siwaju síi pe Ọlọrun gan an lo fi awọn alaṣẹ ijọba sori oye, eyi to tumọ si pe a gbọdọ gbọran sí wọn lẹnu."
Orukọ ọkunrin eke Jesu yii ni Michael Job, o jẹ ọmọ orilẹede Amẹrika.
 nigba ti iyawo re je didakupa ni osu kejila 2007 , o di olori egbe ppp .
Ogbeni Likar wa so fun aare pe, orile ede Serbia yoo se atileyin fun orile ede Najiria nipa eto aabo, eto eko ,ere idaraya ati oro aje.
tabi kí á du eniyan ní ìdájọ́ òdodo.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Wo itan omi gbigbona ati tutu ni Ikọgosi Ekiti Gẹgẹ ba ṣe ka a loju opo itakun agbaye Wikipedia atawọn oju opo miran, iṣẹ takuntakun ni Oyinkan Abayomi ṣe lati ro awọn obinrin lagbara, to si jijagbara fun ominira wọn pẹlu.
Aṣẹ naa yoo bẹrẹ iṣẹ ni ọjọ Ẹti, ọjọ kẹtadinlọgbọn, oṣu Kẹta, ọdun 2020.
    Àkókò yìí ni a rí abàmì ẹ̀dá kan báyìí mú bọ̀ orúkọ ẹni ti ń jẹ́ Ìbẹ̀ǹbẹ́-Olókùnrùn tí ilé rẹ̀ n bẹ ní ipàlàpálá òkúta.
Arulogun fi kun ọrọ rẹ wipe akanṣe eto naa duro gẹgẹ bi ipilẹ fun ilepa lati ṣe akojọpọ awọn ibẹji l'agbaye, pẹlu afojusun akọsilẹ ninu iwe to n ṣe onka awọn iṣẹlẹ ayanilẹnu l'agbaye, 'Guiness Book of Record'.
Eyi lo ṣokunfa ipade Oba Ooni ti Ile Ifẹ, Ooni Adeyeye Eniitan Ogunwusi, Ojaja II pẹlu agba ọjẹ onkọwe agbaye ni, Ojọgbọn Wole Soyinka.
Wọn ni wọn ya aworan naa ninu ere sinima kan, kii si se otitọ ni ọrọ naa.
Ejò lé àwọn aṣòfin ìpínlẹ̀ Ondo kúrò nípàdé Oga agba ọlọpaa fi awọn eniyan Naijiria lọkan balẹ pe awọn agbofinro n ṣiṣẹ bi o ti yẹ lati ri si aabo ẹmi ati dukia awọn ara ilu.
Ẹ̀yin náà kò ri i pé ó dára bẹ́ẹ̀ dan?
Iyalọmọ kan ree to n salaye iru ipo to wa nigba to n fun ọmọ lọyan.
Saaju lawọn iwe iroyin kaakiri Naijria ti gbe iroyin pe ile ejọ giga nilu Abuja ti ni ki pasitọ Biodun Fatoyinbo ati Arabinrin Busola Dakolo foju ba ile ẹjọ laarin ọjọ mẹrinla.
Òun ati Pirisila iyawo rẹ̀ ṣẹ̀ṣẹ̀ ti ilẹ̀ Itali dé ni, nítorí ọba Kilaudiu pàṣẹ pé kí gbogbo àwọn Juu kúrò ní ìlú Romu.
ese mejeeji si je ami-ayo merin sodo(4-0) lati pegede sipele ti o kan ninu
A fí kí ọlọrun fún wà ní òkun àti agbára láti gbà níí'' Àwọn orílèèdè míràn tí wọ́n n gbà àwẹ̀ fún wákàtí to pé ni Russia àti Iceland wákàtí ogún Canada wákàtí metadinlogun Amerika wákàtí mẹẹdogun sí metadinlogun Nàìjíríà àti àwọn orílè-èdè bi Kenya n gbádùn lafiwe pẹlú àwọn tá ká ṣáájú.
Nígbà tí mo rí Ìbànújẹ́-ìsàlẹ̀ ojú kékeré ni mo fi wò ó, nígbà tí mo sì máa kí i, mo kí i bí ènìyàn yẹpẹrẹ.
Speed Limit: Ẹ̀wọ̀n oṣù mẹ́ta àti #3000 ni ìtanràn fun awakọ̀ to bá jẹ̀bi
Gbogbo ara wọn àtẹ̀yìn wọn, àtọwọ́, àtìyẹ́ ati gbogbo ẹ̀gbẹ́ kẹ̀kẹ́ wọn kún fún ojú.
Awọn mii ni ki Buhari kẹkọ lara bi aarẹ Ramaphosa ṣe dahun si imọran Malema.
Ọdun 1979 ni ogun abẹle ṣẹlẹ to fopin si gbigbe ni irẹpọ awọn eeyan Chad.
"Ohun ti Fayose sọ si Buhari ""Nkan buruku gbaa ni pipa ti wọn pa awọn fulani meje ni ilu Gboko nipinlẹ Benue."
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: 'Eyi ni bi àgbàrá omíyalé sẹ ru ìyàwó mi lọ' Iṣẹ́ abẹ ìdí ńlá sọ obìnrin kan d'èrò ọ̀run Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Baba Khadijat Oluboyo jẹ́rìí ọmọ rẹ̀ Baba ọmọ naa, to ba BBC sọrọ salaye pe, idunnu ṣubu lu ayọ fun oun nigba ti iyawo oun bimọ yii, nitori pe oun ni akọbi wọn, ṣugbọn o jẹ nkan ibanujẹ pe omi gbe e lọ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Risikat Moromoke Azeez: Mínísítà tí fi ẹ̀bùn owó ránṣẹ́ si ìyá Kausara, ó tún jẹ́jẹ̀ẹ́ ẹ̀kọ́ ọ̀fẹ́ f'áwọn ọmọ rẹ̀ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Risikat Moromoke Azeez: Mínísítà tí fi ẹ̀bùn owó ránṣẹ́ si ìyá Kausara, ó tún jẹ́jẹ̀ẹ́ ẹ̀kọ́ ọ̀fẹ́ f'áwọn ọmọ rẹ̀ 7 Ògún 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 10 Ògún 2020 Mínísíta fún ọ̀rọ̀ àwọn ọ̀dọ́ àti eré ìdáraya ní Naijiria Sunday Dare ti kéde pé àwọn ṣetán láti rán àwọn ọmọ olójú búlúù ti bàbá wọ́n lé àwọn àti ìyá wọ́n síta lọ si ilé iwé.
Ogoji ọdún ni ó fi jọba Israẹli.
Ọba Asiria kó àwọn eniyan láti Babiloni, Kuta, Afa, Hamati ati Sefafaimu, ó kó wọn dà sinu àwọn ìlú Samaria dípò àwọn ọmọ Israẹli tí ó kó lọ.
Ó wà pẹlu àwọn ọmọ-ẹ̀yìn Jesu tí ó wà ní Damasku fún ọjọ́ díẹ̀.
Ẹ̀yìn tí mo wò, mo rí àgádágodo
"O ṣe pataki ki gbogbo eeyan fi ọkan woye ẹyà kokoro tuntun yi nitori kokoro a máa yira pada lóòrèkóòrè ti o sí ṣeeṣe ki kokoro yi máa lọ ki sí maa bọ to ba ya"" Wo àwọn Adelé-Ọba aládé méje tó jẹ́ obìnrin nílẹ̀ Yorùbá Mi ò le tòṣì láéláé!"
Bi awọn akẹgbẹ arakunrin naa ṣe n tọju arakunrin to gun alupupu to gba erin naa ni oun pẹlu n tọju erin ọhun funrarẹ.
Àwọn Juu Dìtẹ̀ láti Pa Paulu.
Ẹgbẹ ASUU ni a fi dandan ki awọn tun adehun se lori ifẹnuko wọn ti se lọdun 2009 laarin ijọba ati ASUU, bi wọn se n ṣe owo oṣiṣẹ mọwọ ati awọn owo miran to tọ si wọn, yiyan awọn igbimọ abẹwo si fasiti O rọ ara ilu ati awọn tọrọkan ni Naijiria lati ba ijọba Naijiria sọrọ nibi ti wọn ti n gbọ ki wọn le di opin si ọrọ iyanṣẹlodi yii.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Àṣìlò òògùn: Ará ìlú sọ oun tó ń sún wọn dé'dí ìwà yí Awọn oniṣegun oyinbo ti n bẹnu atẹ lu aṣilo oogun lati ọjọ to ti pẹ, ṣugbon awọn ara ilu to ba ikọ BBC sọrọ ni wahala ti oju awọn n ri ti wọn ba lọ ile iwosan lo faa ti awọn fi di ẹni to n ṣi oogun lo.
Láti òní lọ, n óo mú kí ẹ̀rù yín máa ba gbogbo àwọn eniyan tí wọ́n wà láyé yìí, tí wọ́n bá gbúròó yín, wọn yóo máa gbọ̀n, ojora yóo sì mú wọn nítorí yín.
Mo fi òrùka sí ọ nímú, mo fi yẹtí sí ọ létí, mo sì fi adé tí ó lẹ́wà dé ọ lórí.
Iwadii fihan pe wọn tun maa n fẹ la omi ẹkún ojú eniyan nitori eroja aṣaraloore to wa ninu omi ẹkun.
Ó ní àti yíyọ àti kíkéde ẹlòmíràn kò bá ìlànà tó tọ́ mu.
Mo nifẹ si ọrọ akọkọ ti olootu ijọba ilẹ Gẹẹsi sọ ninu eyi to ti wi pe ọwọ araalu lagbara wa.
Ní Jesireeli ni ọgbà yìí wà, lẹ́bàá ààfin Ahabu, ọba Samaria.
Oríṣun àwòrán, Maigaskiya Photography Ọjọ Ẹti ni Sanusi n gbe ẹjọ naa lọ siwaju ile ẹjọ giga to wa nilu Abuja, to si n beere pe ki wọn tu oun silẹ ni ahamọ to wa, lẹyin ti Gomina ipinlẹ Kano le e kuro lori oye.
Ẹni tí ó ń fi èdè àjèjì sọ̀rọ̀, ara rẹ̀ nìkan ni ó ń mú dàgbà.
Gba fadaka ati wúrà lọ́wọ́ wọn, kí o fi ṣe adé, kí o sì fi adé náà dé Joṣua olórí alufaa, ọmọ Jehosadaki lórí.
” Èyí ni ọ̀rọ̀ igbagbọ tí à ń waasu, pé: 
OLUWA yóo le yín kúrò lórí ilẹ̀ tí ẹ̀ ń wọ̀ lọ láti gbà.
Awọn eniyan n pe oludije naa ni olufẹ ara ilu nitori awọn eto igbayegbadun to ti ṣe fun awọn ara ilu.
Faduyile salaye ọrọ naa lasiko to n ba BBC Yoruba sọrọ pẹlu afikun pe oun ko ti mọ ibi ti awọn ileesẹ iroyin kan ti n se akojọpọ akọsilẹ wọn, to si ni akoko to ti koowa yẹ ko joko si adugbo rẹ lati dena kiko arun Coronavirus.
''Aláàfin kìí ṣe ọkùnrin tí wàá jẹ lásán, tó sì wá sálọ - Aráàlú fèsì fún Olorì Anu Ọ̀dọ́mọdé olówó, ẹni ọdún 36 sọ̀rọ̀ sílẹ̀ pé aṣọ funfun ni kí wọn fi sìnkú òun Ta ni olóògbé Jerry Rawlings, tí wọ́n fún ní àlàjẹ́ 'Junior Jesus' Ileejọ si gba ki Zainab gbe ọmọ ẹyọkan ṣoṣo ti wọn jọ nipo si ọdọ rẹ.
Oríṣun àwòrán, Instagram/funkejenifaakindele Ọpọ awọn eeyan to ba Bukunmi yọ si lo tun n ke si Jenifa lati ran isẹ ayọ si awọn naa, paapaa lasiko ọdun Keresimesi yii, kawọn pẹlu le maa jo kiri ka inu ile.
Gomina Ipinlẹ Plateau, Simon Lalong ti ni ẹnikẹni to ba fẹ ipo oṣelu labẹ ijọba oun gbọdọ lọ si ọgba ẹranko to wa ni ipinlẹ naa lati yan ẹranko kan laayo, eyi ti yoo maa tọju.
Bí ó tilẹ̀ jẹ́ wí pé, púpọ̀ nínú àwọn olórin yìí ló maa n sọ pé àwọn kò ṣe ìgbé lárugẹ fún 'yahoo' ṣíṣe, ohun tó dájí ni pé, àwọn orin tí à n gbọ́, tàbi ere tí à n wò, ní ipa tó n kó lórí ìrònú àti ìgbé ayé wa.
Gbogbo igi inú igbó yóo mọ̀ péèmi, OLUWA, ni èmi í sọ igi ńlá di kékeré,mà sì máa sọ igi kékeré di ńlá.
Oun lo di ipo adari oṣiṣẹ aarẹ Buhari mu, ki o to di wi pe o doloogbe lẹni ọdun mẹtadinlaadọrin.
Aare Buhari panupo pelu gomina ipinle Eko, ogbeni Akinwunmi Ambode, ipinle Ogun, ogbeni Ibikunle Amosun, ara, ebi ati awon ojulumo re bi won se n yo pelu gbajugbaja naa, leni ti o ko awon omo orile-ede yii ni igbe aye alai-labawon nipa sise amojuto owo ati isakoso isuna.
OLUWA ní, “Ṣugbọn, ìwọ Bẹtilẹhẹmu ní Efurata, bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé o kéré láàrin gbogbo ẹ̀yà Juda, sibẹ láti inú rẹ ni ẹni tí yóo jẹ́ aláṣẹ Israẹli yóo ti jáde wá fún mi, ẹni tí ìran tí ó ti ṣẹ̀ jẹ́ ti ayérayé, tí ó ti wà láti ìgbà laelae.
''A gbọ́dọ̀ ri wí pé a se àwọn afojusun kan fún àwọn eléré ìdárayá wa ki won ba le mu ọkan kúrò nínú sisa lọ.
Jesu bá sọ fún wọn pé, “Èmi náà kò ní sọ irú àṣẹ tí mo fi ń ṣe nǹkan wọnyi fún yín.
Tọ Farao lọ ní òwúrọ̀, bí ó bá ti ń jáde lọ sí etídò, kí o dúró dè é ní etí bèbè odò, kí o sì mú ọ̀pá tí ó di ejò lọ́wọ́.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìwọ́de Shiite: Ọwọ́ ọlọ́pàá tẹ ogójì ọmọ ẹgbẹ́ Shiite lẹ́yìn ìwọ́de 9 Agẹmo 2019 Oríṣun àwòrán, @Deadlinechic Ọwọ sinku awọn ọlọpa ti tẹ ọgọọrọ awọn ọmọ ẹgbẹ ẹlẹsin Shiite ti wọn n fẹhonu han nile asofin apapọ ilẹ wa nilu Abuja.
Ile ejọ giga ni ilu New York ni adajọ ti ni Harvey Weinstein jẹbi ẹsun ti wọn fi kan an, eleyii to jẹ ki idojutini rẹ peleke si.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Kollington ṣàlàyé bí orin Fuji ṣe bẹ̀rẹ̀ gan an ní Nàiìjíríà Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Sex party: Ìjọba gbé ilé ijó oníhòhò tì pa lórí ẹ̀sùn títàpá sí ìlànà àti dẹ́kun coronavirus15 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Death During Sex: Àwọn nǹkan mẹ́ta tó le ṣekú pa ọkùnrin lásìkò ìbálòpọ̀ rèé9 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Male Fertility: Wo àwọn oúnjẹ márùn ún tó ń mú kí àtọ̀ ọkùnrin dára sí i7 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Covid-19 second wave: ''Ìjọba kò tíì pàṣẹ ìlànà ìtakété-síra-ẹni padà nínú BRT la ò ṣe tíì ma tẹ̀le''15 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Gege bi atejade kan lati ile-ise ti o n ri si oro awon arinrinajo lorile-ede naa, ti a mo si Mozambican Immigration Service (SENAMI) pe, won ri awon omo orile-ede Ethiopia bi ogoji ninu  igbo kan ti o wa ni agbegbe Gorongosa, bakan naa ni won tun  fi owo sinkun ofin mu awon yoku kaakiri orile-ede naa.
Ṣugbọn nígbà tí Mose bá wọlé lọ, láti bá OLUWA sọ̀rọ̀, a máa mú aṣọ ìbòjú náà kúrò ní ojú títí yóo fi jáde, nígbà tí ó bá sì jáde, yóo sọ ohun tí OLUWA bá pa láṣẹ fún àwọn ọmọ Israẹli.
Awọn abanijagun ilẹ okere ko ni aaye kankan ninu ofin ilẹ Naijiria ayafi bi wọn ba fẹ tun un ṣe nitori ki wọn lee gba wọn siṣẹ.
Nítorí náà èmi OLUWA ni mo sọ pé, n óo fi ìlú yìí lé àwọn ará Kalidea ati Nebukadinesari, ọba Babiloni lọ́wọ́, yóo sì gbà á.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Bisi Alimi: Ìyà mi rò pé n kò leè ṣe ni àmọ́ n kò ní ìfẹ́ abo ni mo ṣe fẹ́ akọ Lori ọrọ eto idibo gbogboogbo to kọja, Soyinka sọ pe eto idibo ọdun 2019 jẹ ọkan lara awọn idibo to ti i bani lọkan jẹ julọ ni Naijiria.
    Ṣùgbọ́n òun kọjú sí wa ó ni, ẹ̀yin ọmọ ènìyàn ènù ni ìránṣẹ́ Olódùmarè, àwọn ẹni ti ń ra ọja mi wọ̀nyyí ni à ń pè ni alátùn-únṣe.
1 56981 Orilẹede Swaziland 335 29.
Adele oludari agba ileeṣẹ naa, Kemebradikumo Pondei ni awọn aṣojuṣofin n fi ọrọ wa lẹnuwo lori bi wọn ṣe n na ẹgbẹlẹgbẹ owo ajọ naa, amọṣa ṣadede ni Ọjọgbọn Pondei ba ṣubululẹ to si daku.
Àwọn akọni Nàìjíríà padà sílé pẹ̀lú àmì ẹ̀yẹ 121 láti Morocco Òní nilé ẹjọ́ tó ga jùlọ yóò gbẹ́jọ́ ẹ̀sùn ayédèrú sabuké tí wọ́n fi kan Buhari A fẹ́ bẹ̀rẹ̀ òfin má lo fóònù mọ́ fàwọn ọmọ wa -Òbí Iṣẹ́ ṣẹ̀ṣẹ̀ bọ́ lọ́wọ́ Seth Ator tó yìnbọn pa ọ̀pọ̀ èèyàn ní Texas ni- ọlọ́pàá Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Àjọ̀dún àṣà nípínlẹ̀ Ekiti, EKIFEST pinminrin!
Ó wá sọ fún wọn pé, “Mo ní ìbànújẹ́ ọkàn tóbẹ́ẹ̀ tí mo fẹ́rẹ̀ kú.
Oríṣun àwòrán, NPF Kọmiṣọna ọlọpaa ṣalaye pe awọn afurasi naa ri aye sa asala nitori awọn fa ṣẹyin lati ṣina ibọn fun wọn, ki awọn ara ilu to wa lagbegbe ọhun ma ba a fara gbọta ibọn.
Gomina Seyi Makinde tun tesiwaju pe  isejoba oun yoo gbe awon igbese akin eleyii to
Wọ́n ń bẹ̀ ẹ́ pé kí wọn sá lè fi ọwọ́ kan etí ẹ̀wù rẹ̀.
akọ mààlúù kékeré kan, ati àgbò kan, ọ̀dọ́ àgbò kan, ọlọ́dún kan, fún ẹbọ sísun, 
 Agbanah wa jewo pe oun maa n lo aworan  Chris Dan yii lati parọ fun awon omobinrin
N óo fún ọ ní ọgbà àjàrà tí ó dára ju èyí lọ dípò rẹ̀, tabi tí ó bá sì wù ọ́, n óo san owó rẹ̀ fún ọ.
Kí àjèjì má baà jèrè iṣẹ́ yín,kí làálàá rẹ má sì bọ́ sápò àlejò.
Ẹ̀rù ba àwọn tí ó rí wọn gan-an.
Ó kó àwọn oriṣa ati àwọn ère kúrò ninu ilé OLUWA, ati gbogbo ojúbọ oriṣa tí ó kọ́ sórí òkè níbi tí ilé OLUWA wà, ati àwọn tí wọ́n kọ́ káàkiri gbogbo ìlú Jerusalẹmu.
Ìdí tí mo fi ń kọ gbogbo nǹkan wọnyi nígbà tí n kò sí lọ́dọ̀ yín ni pé nígbà tí mo bá dé, kí n má baà fi ìkanra lo àṣẹ tí Oluwa ti fi fún mi láti fi mú ìdàgbà wá, kì í ṣe láti fi wo yín lulẹ̀.
- Sanwo-Olu Ó ṣeéṣe kí ènìyàn 12,000 máa kú lójoojúmọ́ lẹ́yìn Covid-19 Wo iye owó tó wọlé fún ìjọba lórí COVID-19 àti bí wọ́n ṣe ná an Sanwo-Olu ni awọn ile ijọsin yoo di ṣiṣi pada fun awọn Musulumi ati Kristẹni ṣugbọn ida aadọta ninu ọgọrun pere ni wọn faaye gba.
Ṣugbọn bí ẹ̀yi yìí bá ti dáwọ́ dúró, tí irun dúdú ti bẹ̀rẹ̀ sí hù ní ọ̀gangan ibẹ̀, ẹ̀yi náà ti san, ẹni náà sì ti di mímọ́.
"A ti gbé ìwádìí dìde lórí ìpànìyàn tó wáyé lásìkò ìwọ́de EndSARS- Ilé ẹjọ́ àgbáyé, ICC A kó ní sanwó oṣú ASUU láìjẹ́ pé wọ́n gba IPPIS- Ìjọba Àpapọ̀ Oṣú mẹ́fà ni òṣìṣẹ́ ìjọba tó bá bímọ yóò máa lò nílé kó tó wọṣẹ́ padà- Seyi Makinde DPO ọlọ́pàá ju télọ̀ sátìmọ́lé, gbé e lọ sílé ẹjọ́ n'Ibadan torí ''ó ba aṣọ rẹ̀ jẹ́'' Oríṣun àwòrán, Instagram/oye4dc Ninu atẹjade to fi soju opo Instagram rẹ, Owolewa sọ pe ""mo fẹ fi akoko yii dupẹ lọwọ gbogbo awọn ẹbi ati ọre mi lagbegbe Colombia."
Ni ọpọlọpọ Igba ni aarẹ Trump ti ma n kede pe orilẹede Amerika lo lagbara julọ lagbaye, Amọ iwadii ti fihan wi pe ọrọ ko ri bẹẹ mọ labẹ akoso aarẹ Donald Trump.
Minisita ayika ti sọ loṣu Kẹsan an pe awọn ontaja nilẹ Thailand yoo dẹkun lilo ọra lati maa fi ta nkan bẹrẹ lati oṣu Kini, ọdun 2020.
Ẹni tí yóo fi mí fún àwọn ọ̀tá súnmọ́ tòsí.
Ni ọpọ igba, arumajẹ ati itanjẹ ni ọpọ gbajumọ oṣere n fi ẹwa ti wọn n gbe saye ṣe lori ayelujara wọn ati ninu awọn ere wọn.
Bukky Wright Ọjọ Iṣẹgun ọsẹ yii ni gbajugbaja oṣere, Bukky Wright ṣe ayẹyẹ ọ̀jọ ibi rẹ.
Ó ní wọ́n gbìyànjú làti dojúkọ ìlú Maiduguri gangan ṣùgbọ́n àwọ̀n ọmọ ogun kò gbà wọ́n láàyè.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìjọba Nàìjíríà ti ṣẹ́gun Boko Haram- Ààrẹ Muhammadu Buhari 11 Ògún 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 13 Ògún 2019 Àkọlé àwòrán, Jẹjẹrẹ ní ìwà àlákakiti ẹ̀sìn, ẹ yago fún ẹ̀kọ́ òdì -Ààrẹ Buhari Ààrẹ Muhammadu Buhari ti ke sí àwọn ọmọ Nàìjíríà pé ọ̀rọ̀ Boko Haram lórílẹ̀-èdè Nàìjíríà tí di àfìẹ́yìn tí éégún ń fisọ pàápàá jùlọ gbogbo ǹkan ìjà òògun wọn ti tán tí àwọn ọmọogun si ti tú wan ka pátápátá.
Nítorí náà, àwọn àgbààgbà Israẹli wá sọ́dọ̀ Dafidi ọba, ní Heburoni.
Ṣugbọn Jesu yipada sí àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀, ó bá Peteru wí.
Bakan naa, Sultan ti ilu Sokoto naa rọ gbogbo awọn Musulumi lagbaye lati tẹlẹ ofin titakete sirani lasiko ọdun Ramadan yii, ki wọn si gbadura nile wọn.
Ajo eleto idibo ti pase ki won se atunka ibo ti won di ni awon ekun mefa ti o wa ni apa ariwa orile-ede naa, latari esku kan pe, kudie-kudie jeyo ninu ibo naa.
N óo sì fi yín ṣe ẹrú fún gbogbo orílẹ̀-èdè ayé.
Ọgbọ́n àtiṣe ibi kún inú wọn:ṣugbọn wọn kò mọ rere ṣe.
Nadia ti gbiyanju lati gba ẹmi ara arẹ ni ọpọlọpọ igba ko to padé alaanu kan.
Lọ́dọọdún, bí àwọn tí wọ́n dipò mú ṣe ń ṣe ìrántí ìgùnkè wọn sí ipò gíga pẹ̀lú ìdùnnú, ẹbí àwọn olùfarapa máa ń sunkún, tí wọ́n sì máa ń fi ẹhónú hàn pẹ̀lú ìbànújẹ́ fún àtúnṣe àti ìdájọ́ òdodo.
"O ko mọ irora mi, o ko mọ boya a n jẹrora lọwọ aisan kan abi a ni isoro ninu ẹbi wa abi pe wahala jijẹ gbajumọ n pa wa ku lọ, ta kan n tiraka lati bo isoro wa mọlẹ fun araye.
Láti Eẹ̀sún ló ti wá sí Agóró: Agóró yìí ló dúró sí tí ó fi rán Lúmọ̀ogun akíkanju kan patàki nínú àwọn tí ó tẹ̀ lé e pé kí ó lọ sì iwájú díẹ̀ kí ó lọ wo ibi tí ilẹ̀ bá ti dára tí àwọn lè dó sí.
Nígbà tí ọdọmọkunrin náà rí i pé Saulu kú, òun náà ṣubú lé idà rẹ̀, ó sì kú.
 nítorí náà , títí di òní olónìí , onírè ti Ìlù Ìre-Èkìtì jẹ ́ ògbóǹtagi kan nínú àwọn ọba aládé tí ó wà ní Èkìtì .
Ọpọlọpọ wọn ni wn maa n lo gẹgẹ bi ọmọ ọdọ, olutaja tabi ki wọn maa kiri ọja loju popo ati laarin igboro.
Joṣua pe gbogbo ẹ̀yà Israẹli jọ sí Ṣekemu, ó pe gbogbo àwọn àgbààgbà, àwọn olórí, àwọn onídàájọ́, ati àwọn alákòóso ilẹ̀ Israẹli; gbogbo wọn sì kó ara wọn jọ níwájú OLUWA.
Aṣọ òkè: Alákọ̀wé ní ọ̀nà láti wá oúnjẹ fáwọn tó ń ṣe aṣọ òkè ló ṣún òun débẹ̀
Oríṣun àwòrán, TIZIANA FABI Àkọlé àwòrán, Aworann ọjọ idajọ ni Piazza del Popolo, ni Rome 10.
Siwaju si, o salaye pe, Ipinle Jigawa to ye ki aare lo, sugbon ti won sun siwaju nitori idibo abele ti egbe oselu All Progressives Congress (APC), ni aare yoo papa lo  ni ojo Aje, ojo kerinla titi di ojo karundinlogun, osun karun-un odun ti a wa yii.
Egbẹ́ agbábọ́ọ̀lù Nàìjíríà sàn N5,000 láti rà agbábọ́ọ̀lù tó n gbowó julọ
Orile-ede Amerika, Canada ati Mexico ni yoo sagbateru idije agbaye lodun 2026, leyin ti won jawe olubori pelu ibo mọ́kàndínláàdọ́rin saaju orile-ede Morocco ti oun naa n gbero lati sagbateru idije ohun.
Àwọn oníṣòwò wọnyi, tí wọ́n ti di olówó ninu rẹ̀ yóo dúró ní òkèèrè nígbà tí ẹ̀rù bá ń bà wọ́n nítorí ìrora rẹ̀, wọn óo máa sunkún, wọn óo máa ṣọ̀fọ̀.
“OLUWA Ọlọrun rẹ pàṣẹ fún ọ lónìí, pé kí o máa pa gbogbo ìlànà ati òfin wọnyi mọ́.
to ga julo lorile ede yii ti adele  adajo
ng Oríṣun àwòrán, Nigerian Air Force Àkọlé àwòrán, Àwọn ọmọogun ojú òfurufu dúró siwaju ọkọ̀ ofurufu ti wọ́n fi n jágun Kini BTMC?
Akẹ́kọ̀ọ́ wọlé padà, ìjọba Oyo kò pèsè ìbòmú lòdì sí ìlérí rẹ̀ Ẹ wo bí ọ̀rọ̀ òṣèlú, ẹ̀sìn àti ẹ̀yà ṣe fa ogun abẹ́lé Biafra Kàkà k‘éwé àgbọn dẹ̀ lágbo òṣèlú l‘Ondo, akọ̀wé ìjọba tún kọ̀wé fipò sílẹ̀ Ìjọba Akeredolu kò ní omi àánú lójú, a kò tọ́jú alárùn Coronavirus mọ́ - Dókítá Ondo Alẹ ọjọ Aje si ni ileeṣẹ ọgba ẹwọn fi orukọ Hushpuppi si ori itakun agbaye wọn.
Ayo mẹrin si odo ni ikọ Borussia Dortmund fi gbo ewuro soju ẹgbẹ agbagbọọlu Schalke 04 bi idije Bundesliga ṣe pada gberasọ lọjọ Abamẹte, ọjọ kẹrindinlogun oṣu karun un ọdun 2020.
Kò sẹ́ni tó wù láti jẹ́ àkàndá, ẹ má dẹ́yẹ sí wọn mọ́- Fola Owo ori ilẹ nipinlẹ Ondo fa ariyanjiyan 'Èèwọ̀' gààrí fún àwọn èèyàn ipínlẹ̀ Ondo ‘Ẹyin ará Ondo, Eko, Ogun, Osun, Ọyo, ẹ gbàdúrà ò!
Rẹfiiri ọmọ ilẹ Kenya, Marwa, to yẹ ko ṣiṣẹ ni Russia 2018 naa ti kọwe fipo rẹ silẹ.
Oríṣun àwòrán, @NOIweala Àkọlé àwòrán, Pupọ ọmọ orilede Naijiria ni ko ni gbagbe minisita 'alaṣọ ankara' yii pẹlu gele 'ipakọ o gbọ ṣuti' rẹ Ọkan lara awọn eekan to lagbara labẹ iṣejọba aarẹ Ọbasanjọ laarin ọdun 2003 si 2006 ni Okonjo-Iweala, o si ko ipa ribiribi ninu bi awọn igbimọ orilẹede agba kan lagbaye ṣe wọgile gbese biliọnu mejidinlogun dọla, $18bn ti orilẹede Naijiria jẹ ṣaaju igba naa.
Ẹ̀rù ba Peteru ati Johanu ati Jakọbu nígbà tí Mose ati Elija wọ inú ìkùukùu náà.
“Ṣugbọn, wọ́n ṣe àìgbọràn, wọ́n sì ṣọ̀tẹ̀ sí ọ.
Mose sọ fún Hobabu ọmọ Reueli, baba iyawo rẹ̀, ará Midiani, pé: “Àwa ń lọ sí ilẹ̀ tí OLUWA ti ṣe ìlérí láti fún wa, máa bá wa kálọ, a óo sì ṣe ọ́ dáradára, nítorí OLUWA ti ṣe ìlérí ibukun fún Israẹli.
Kí á má baà gbẹ́kẹ̀lé ara wa, bíkòṣe Ọlọrun, ni ọ̀rọ̀ fi rí bẹ́ẹ̀.
Àwọn ìgbà tí àwọn ọmọ Ọbasanjọ ti takò ó ní gbangba
Isalẹ ni aaye wa lati kọ orukọ ẹni ti wọn ba yan si.
EFCC fẹ́ gbẹ́sẹ̀ lé ilé tí mo fi owó ìfẹ̀yìntì kọ́ nílùú Ilorin- Saraki Ilé aṣòfin Amẹrika gbọnmú lórí ìtìmọ́lé Sowore, ó ní ìjọba Nàíjíríà tako òmìnira aráàlú Ẹ wo ìpínlẹ̀ táwọn gómìnà tẹ́lẹ̀ àti igbákejì wọn ń gba dúkìá ìfẹ̀yìntì tabua Iná mọ̀nàmọ́ná lọ fún wákàtí 24 ní Ghana, lariwo bá sọ!
Kí ó sọ pé, “OLUWA, o ti sọ pé o óo pa ibí yìí run, tóbẹ́ẹ̀ tí kò fi ní sí nǹkankan tí yóo máa gbé inú rẹ̀ mọ́, ìbáà ṣe eniyan tabi ẹranko.
Iya olooṣa naa pe awọn ayajọ kan, lo ba kede fun gbogbo awọn to wa nibẹ pe ajẹ ni iya arugbo naa.
Bí wọ́n ti ń lọ, Jehoṣafati dúró, ó sọ fún wọn pé, “Ẹ gbọ́ ẹ̀yin ará Juda ati ẹ̀yin ará Jerusalẹmu, ẹ gba OLUWA Ọlọrun yín gbọ́, yóo fi ẹsẹ̀ yín múlẹ̀, ẹ gba ohun tí àwọn wolii rẹ̀ wí gbọ́ pẹlu, ẹ óo sì ní ìṣẹ́gun.
O tó ìdá méjì àwọn ènìyàn àgbáyé to wà nínú ewu àìsàn ibà
Amọṣa wọn ni aaye wa fun igbokegbodo ọkọ ati awọn eeyan lasiko ti ọdun naa ba fi waye.
Akọnimọọgba D'Tigress Otis Hughley ree nibi to ti n ṣe aṣepari iṣẹ lori igbaradi awọn ikọ obinrin naa fun idije naa.
ti kilọ fun wọn pe,  omo egbe to ba tapa
Ati pe ko si ẹri to fidiẹ mulẹ pe awọn Castali ti Maya n fi ṣokoleeti mu nkan ọmọ ọkunrin wọn le sii lasiko naa.
O koju awọn musulumi agbesunmọmi to n gbogun ti awọn eniyan rẹ.
Gbogbo nǹkan yòókù tí Ahasi ọba ṣe ni a kọ sinu Ìwé Ìtàn Àwọn Ọba Juda.
Òmùgọ̀diméjì kò náání ẹlòmíràn àfi àwọn ìjàyè nìkan láàrin ìlù titi kan àwọn olówó àti àwọn ẹlòmíran gbogbo tí ẹnu wọn tó ilẹ̀ láàrin ìlú, kò fi tiwọn ṣe nígbà tí wọn kò ti sí ní ìgbìmọ̀ kí wọ́n máa tìí lẹ́yìn nínú ẹjẹ́ tí o ba ń dá.
Afrika ni awọn ọlopolọ pipe ọmọ to ti lami laaka ninu iwadii sayensi ṣugbọn orilẹ imiran ni wọn ti lọ n ṣiṣẹ sin nitori ko si owo fun iṣẹ iwadii nilẹ Afirka.
Funke Oshonaike: Uwa Omozua tí wọ́n fipá bá lòpọ̀ kú ní Benin ló mú mi sọ ìrírí tèmi náà
Lẹ́yìn náà mo kọ́ gbèrò ati fi ibinu pa wọ́n run patapata, kí n tẹ́ ibinu mi lọ́rùn lórí wọn ninu aṣálẹ̀.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Àsírí ajọ́mọgbé méjì tú ní Kwara Sé kí Nàíjíríà máa lo igbó fún ìwòsàn?
E ò lè pami lẹ́nu mọ.
Okina ni ,Lootọ lo wa ninu akisa, sugbọn ẹnu ya mi pẹlu bi o ṣe gbọn fefe."
Laarin igba naa titi di ọdun 2003 ti o kọkọ di aṣoju fun ẹkun Surulere nilu Eko nile aṣoju-ṣofin Naijiria, Femi Gbajabiamila da ile iṣẹ agbẹjọro tirẹ silẹ, ti o si tun bẹrẹ si ni kopa diẹ diẹ ninu oṣelu.
Eleyii ni yoo je igba keta ti omooba naa yoo wa se ibewo ni orile ede Naijiria, o koko wa si orile ede Naijiria lọdun 1990,1999,ati odun 2006, sugbon igba akoko niyi fun omooba Duchess ti ilu Cornwall lati wa si orile ede Naijiria.
Ṣugbọn lẹ́hin ìwádìí oríṣiríṣi tí ẹka iléeṣẹ́ ọlọ́pàá tí a mọ̀ sí IRT ṣe, wọ́n rí òkú àwọn méjéèji nínú igbó kan ni Oru-Ijẹ̀bu.
Ikolu iji lile ohun ti o waye lojoRu(Wednesday), ni iroyin fi mule pe, o ba orisirisi ohun amayederun je, o wo ile lorisirisi ti o si pa awon ohun osin lopolopo.
"Ohun ti mo ka bani ninu jẹ pupọ.
Bakan naa, orukọ Wilfred Ndidi to n gba bọọlu jẹun ni iks Leicester city ni ilẹ gẹẹsi pẹlu wa ni orukọ awọn agbabọọẹu ti wọn la kalẹ fun ami ẹyẹ agbabọọlu ọdọ ti o pegede.
O ni ki onikaluku di ile mu bi o ti ye nitori eto idibo ko ni pe e de mo ni eyi ti awon eniyan yoo ti gbe ise egbe wo fun osuwon.
Ǹjẹ́ bí aláìkọlà bá ń pa àwọn ìlànà òdodo tí ó wà ninu Òfin mọ́, a kò ha ní ka àìkọlà rẹ̀ sí ìkọlà?
Kí ní 'Economy' ní èdè Yorùbá?
 Obinrin miran ti ọmọ rẹ sọnu sọ fun BBC pe, ọmọ kan ṣoṣo ti oun bi ni wọn ji gbe lọ."
Wẹ́rẹ́, olorì finú ṣoyún, ó sọ̀ láyọ̀.
Ó tà á, ó sì mú owó rẹ̀ wá fún àwọn aposteli.
Àwọn ọmọ Nàìjíríà 320 yóò padà wálé láti South Africa lọ́jọ́rú - Adama Àgbáríjọpọ ẹgbẹ OPC, fijiláńté VGC, Agbẹkọyà ti bẹrẹ ètò aàbò ní ilẹ Yorùbá Ọlọ́pàá kò rí ǹkankan lábẹ́ pẹpẹ ilé ìjọsìn mi - Olùṣọ́àgùntàn Akure Oríṣun àwòrán, CLUB PORTAL Àkọlé àwòrán, Frankurt FC Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Mama Rainbow ti kopa ninu ọpọlọpọ ere agbelewo ati ere ori itage.
31 Àti pé àyàfi bí ìwọ bá ṣe èyí, kíyèsíi, ìwọ kì yíò ní ẹ̀bùn kankan mọ́, èmi yíò sì gba àwọn ohun tí mo ti fi pamọ́ pẹ̀lú rẹ lọ.
To ba ṣe eso, yoo jẹ ki ounjẹ wu eniyan jẹ kìí ṣe ti ka sare kọ ounjẹgelete siwaju ki a wa pa taarọ, ọsan ati talẹ pọ lẹẹkan.
"O ni ""oun ti a fẹ ṣe ni lati ṣe faaji ati wẹjẹ-wẹmu pẹlu awọn eeyan, kii ṣe pe a n reti ero pupọ."
Ènìyàn kọ̀ọ̀kan ló lùgbàdì àààrùn náà ní Ebonyi, Edo, Enugu Anambra Plateau àti Niger Àjọ NCDC kéde èèyàn 146 míràn tó ni ààrùn Covid-19 lórílẹ̀-èdè Naijíríà Àkọlé àwòrán, Àjọ NCDC kéde èèyàn 146 míràn tó ni ààrùn Covid-19 lórílẹ̀-èdè Naijíríà Àjọ tó ń gbógun ti àjàkálẹ̀ ààrùn lórílẹ̀-èdè Nàìjíríà NCDC ti kéde pé ènìyàn mẹ́rìndínláàdọ́jọ ni àyẹ̀wò tuntun fi hàn pé ó ní ààrùn Covid-19 lórílè-èdè Nàìjíríà ti àpapọ̀ àwọn tó ní ààrùn náà sì tì di ẹgbẹ̀rúnmẹ́rinlé ọ̀rìlélélẹ́ẹ̀gbẹ̀rin àti méje (4787) Gẹ́gẹ́ bi àjọ náà ṣe sọ lójú òpó twitter rẹ̀ lálẹ́ ọjọ́ ìṣẹ́gun ènìyàn mẹ́jìdílọ́gọ́jọ ló ti kú nígbà ti ọ̀tàdilẹ́ẹ̀dẹ́gbẹ̀rún-ó-dín-kan (959) ti ri ìwòsàn gbà.
“Nígbà tí ọkunrin alágbára bá wà ní ihamọra, tí ó ń ṣọ́ ilé rẹ̀, kò sí ohun tí ó lè ṣe dúkìá rẹ̀.
Bakan naa lo ni ki wọn tun dẹkun eto iforukọsilẹ fawọn olubara to n ra kaadi pelebe inu foonu lati fi sọrọ duro ni kiakia.
Mo nigbagbọ pe iwa akinkanju yin, yoo ran yin lọwọ lati tun  pada si ipo ti ẹ  wa tẹlẹ.
Ati pe laipẹ oun naa a di ẹni to niṣẹ lọ́wọ́ gẹgẹ bii obinrin rere.
Oloṣelu haunhaun ni Akintọla, ọmọ ilu Ogbomọsọ si ni.
1977 Wọn le abilekọ Madikizela-Mandela lọ si Brandfort, ilu kereje kan lẹkun Free State, fun bi ọdun mẹwa.
A ti ń sin òkú méjì sínú ibójì kan náà nítorí ọ̀wọ́ngógó ibojì ìsìnkú Ẹ̀gbọ́n àti àbúrò wà ní ilé ẹ̀jọ́ lórí ikú Tolulope Arotile 'Àwa ọmọ Nàìjíríà tó farapa fẹ́ wálé láti Lebanon, ìjọba kó wa pamọ́' Ọlọ́run nìkan ló mọ bí ìrìnàjò ìfẹ́ ẹ̀dá á ṣe rí láyé, ọ̀dọ́ Aláàfin ní orí gbémí yà sí, ó sì tẹ́milọ́rùn- Olorì Aanu Gomina Ortum naa fi eleyii lede ni ibi to ti n sọrọ ni ipade awọn gomina lorilẹ-ede Naijiria ti wọn ṣe lori ẹrọ ayelujara.
O ti kó sí mi lẹ́mìí, arabinrin mi, iyawo mi,ẹ̀ẹ̀kan náà tí o ti ṣíjú wò mí,pẹlu nǹkan ọ̀ṣọ́ tí ó wà lọ́rùn rẹ,ni o ti kó sí mi lórí.
Atejade kan latodo oga agba awon omo-ogun orile-ede America nile Afrika pe, ikolu ohun ti o waye ni ilu Ubani, ni eyi ti won se ni ibamu pelu ijoba ti ajo-agbaye n satileyin fun nilu Tripoli.
"Kabiyesi ba tun fi owe pari ọrọ awn to ni oun maa n ṣakọ pe ""Olówó máa ń jẹun jẹ́jẹ́ ni, òtòsì nìí yọkùn gàkìa-gàkià"" EFCC kó akẹ́kọ̀ọ́ fásitì UNIOSUN Wo àwọn tí gómìnà ìpínlẹ̀ Oyo fi orúkọ wọn sílẹ̀ fún ipò kọmísánnà Ẹ wo ọmọ ọdún méje tó di Gómìnà l'Ekiti Ẹni orí yọ, ó dilé!"
Gomina Obaseki ti o jẹ Gomina labẹ ẹgb oṣelu APC la ti ri pe o pada si ẹgbẹ oselu PDP, eyi to ti bẹnu atẹ lu tẹlẹ ri.
Awọn ọmọ naa si lo ma n sọ bi wọn ṣe fẹ ẹ rin irinajo aye wọn.
Orisun atijẹ atimu wsn ko ṣẹyin ṣiṣe janduku.
Àwọn ewéko a máa pa àwọ̀ dà, ewé wọn a máa pọ́n kuku, wọ́n a rí kàlákìnní.
Ninu fidio kan to wa lori ayelujara, Pasitọ Enenche ni ko tọ si Freeze lati ma a sọ iru ọrọ bẹ ẹ, nigba ti oun fun'ra rẹ ko ni igbeyawo to duro, tabi iṣẹ lọwọ.
Ilé iṣẹ́ ọlọ́pàá ìpínlẹ̀ Eko ti dá òṣìṣẹ́ SARS kan, Inspecor Charles Oluṣọla Ọmọtọshọ dúró lẹ́nu iṣẹ́ látàrí pé ó ńgba ẹgbẹ̀rún márùn-ún Náírà lójú pópó ní agbègbè Ikorodu.
Ọ̀gọ̀ọ̀rọ̀ agbébọn lo wà nílúù Kishi, National Park - Gani Adams figbe ta O ni wahala to bẹ silẹ naa tako adehun to wa laarin awọn ẹgbẹ oṣelu mejeeji ati ọlọpaa pe ko gbọdọ si ẹgbẹ oṣelu meji to gbọdọ maa ṣe ipolongo lagbegbe kan naa lasiko kan naa.
“Èèmọ̀ ni ki ọkùnrin fẹ́ ọkùnrin tàbi ki obinrin fẹ́ obinrin ni Àṣà Yorùbá ”
Ṣùgbọ́n oun tó dẹ́rù Ọlọ́run bani lọ́jọ́ náà ni pé bí òjò ṣe ń rọ̀ lemọ́-lemọ́ lé wa lórí, bẹ́ẹ̀ oòrùn ń ràn kalẹ̀ níhà ibòmíràn, tí a sì ń wò ó lọ́ọ̀ọ́kán.
Awọn to ku niwọn pe ni ajẹ, ti awọn mọlẹbi wọn si ti pa wọn ti - eyi jẹ ohun to wọpọ ni ipinlẹ Akwa Ibom.
Àwọn yòókù sì wà lẹ́yìn Omiri.
Nígbà tí mo gbọ́ ọ̀rọ̀ yìí inú mi bàjẹ́, nígbà tí mo tún rò ọ̀rọ̀ náà wò, inú mi sì dún.
Ere Idaraya: Aáwọ̀ ààrin Wenger àti Mourinho ti parí
"Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: ""Apena fẹ́gbẹ́ Oṣugbo, Opa, Akala àtẹ̀yin awo, ẹ wa ọ̀pá àṣẹ Ọ́ba Akiolu jáde"" Àwọn jàńkùkú tún padà lọ fọ́ ShopRite Ilorin lónìí lásìkò ìṣéde Ikú Aráàlú 51, ọlọ́pàá 11, Sọ́jà 7 tó kú lásìkò ìwọ́de EndSARS dùn mí - Buhari Ẹ wo ọ̀rọ̀ àwọn Wòlíì tó ti sọ àsọtẹ́lẹ̀ saájú nípa làásìgbò EndSARS Májèlé olóró lẹ jí l‘Ekiti dípò èròjà oúnjẹ Covid-19 - Ariwo sọ lórí ayélujára Ẹ sọ́ra fún ìwà olè àti jàgídíjàgan nílẹ̀ Yorùbá-Sunday Igboho ₦147m la rí kójọ fún ìwọ́de, a kò fẹ́ owó mọ́, ìwọ́de ti parí - Feminist Coalition Sanwo-Olu kéde ìlànà ìséde tuntun l'Eko Ìjọba ìpínlẹ̀ Kwara sọ̀rọ̀ lórí bí àwọn kan se lọ pín ""CaCovid 19 Palliative"" ní Ilorin pé."
Abbo ni awọn to wa ninu ṣọọbu naa kọkọ lu aburo oun bolẹ, ti wọn si gba ẹjẹ lẹnu rẹ ni oun ṣe lu awọn naa bolẹ.
1994 Wọn yan an gẹgẹ bi igbakeji minisita fun iṣẹ Ọna, Aṣa, Sayẹnsi ati imọ Ẹrọ.
Ninu ki wọn o maa ranju mọ eeyan nkankan, tabi ki wọn o ni erongba ti ko dara.
Ìdí tí mo ṣe rán Timoti si yín nìyí, ẹni tí ó jẹ́ àyànfẹ́ ọmọ fún mi, ati olóòótọ́ ninu nǹkan ti Oluwa.
Akeredolu, Oyetola, àtàwọn míì sọ̀rọ̀ lẹ́yìn tí ìjọba àpapọ ní Amotekun kò bá òfin mu Gomina ipinlẹ Ondo, Rotimi Akeredolu ti fesi si ọrọ agbẹjọro ijọba apapọ, Abubakar Malami.
Wo àwọn báńkì tó wà lẹ́yìn àwọn olówó èlé bí MMM Ẹ̀yin òṣìṣẹ́ elétò ìlera, ẹ padà sẹ́nu iṣẹ́- JOHESU Bí PDP ṣe na APC lálùbami ní Edo, bẹ́ẹ̀ ni yóò ṣẹlẹ̀ ní Ondo- PDP Wo ìdí tí ètò ìdìbò gómìnà ìpínlẹ̀ Edo ṣe lọ ní ìrọwọ́-rọsẹ̀ Wo àwọn ìlúmọ̀ọ́ká tó ṣe ìgbéyàwó ní ọdún 2020 yìí Ẹwọ́n ọdún méjìlá ni wọ́n fún àwọn Ṣója mẹ́rin tó pa ìyá àti ọmọ méjì ní Cameroon Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí 6:25 Fídíò, Akomolede Yoruba: Ìtàn ọ̀rẹ́ tó fi ògùn gba ọkọ ọ̀rẹ́ rẹ̀ nílùú òyìnbó rèé, Duration 6,2515 Owewe 2020 6:18 Fídíò, Akomolede: Bolaji Faleke ni Olùkọ́ tó ń kọ́ wa ní àṣà oge ṣiṣe lórí BBC Yorùbá, Duration 6,181 Owewe 2020 Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí 2 sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
“Bí ẹnìkan bá jẹ ohun mímọ́ kan ní ìjẹkújẹ yóo san án pada fún alufaa pẹlu ìdámárùn-ún rẹ̀.
Gómìnà ìpínlẹ̀ Kaduna fún Sanusi ní ipò tuntun Wo àwọn àwòrán Sanusi nígbà tó ṣì wà lórí oyè gẹ́gẹ́ bíi Emir Mo lóbìnrin tó bímọ fún mi, ṣùgbọ́n ọ̀rọ̀ ìyàwó kò tíì yọ fún mi báyìí-Pasuma Ìjọba ń ṣe afárá Eko Bridge l'Eko, àwọn ọ̀nà àbùdá tí ẹ lèè gbà nìyí Oludamọran Gomina lori ọrọ iroyin, Ọgbẹni Muyiwa Adekeye ṣalaye pe Sanusi ti di alakoso igbimọ alaṣẹ fasiti ipinlẹ Kaduna.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù CBN Policy: Buhari pàṣẹ fún báńkì àpapọ́ láti dẹ́kun owó ìrànwọ́ fáwọn tó ń gbé oúnjẹ wọ Nàìjíríà 14 Ògún 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Aarẹ ni aṣẹ naa yoo ran eto ọgbin labẹle lọwọ Ni ọjọ iṣẹgun ni aarẹ orilẹede Naijiria, Muhammadu Buhari kede si eti awọn gomina to jẹ ọmọ ẹgbẹ oṣelu APC pe, oun ti paṣẹ fun banki apapọ ilẹ wa, lati yee se akanse pasi paarọ owo Naira ilẹ wa si tilẹ okeere fun awọn to ba fẹ ko ounjẹ wọ orilẹede Naijiria.
Lucinda lo sedasilẹ eto kan to pe ni ẹ wo awọn obinrin wa san, eyi tii se ẹgbẹ ti ko wa lati ko ere jọ, , amọ to n gba awọn obinrin ni imọran, maa se idanilẹkọ fun wọn, to si tun maa n lọ yika igberiko lati se awari awọn obinrin ti wọn ba ji gbe pẹlu ipese ilegbe fun awọn obinrin to ba sa asala fun iwa ipa ninu ile.
keji ifesewonse ohun bere, aipe re ni, agbabọọlu arin iko naa, Gylfi Sigurdsson
Kò yẹ kí wọ́n di èrò ẹ̀wọ̀n ní ìbẹ̀rẹ̀, nítorí wọn kò jẹ̀bi ẹ̀sùn tí wọ́n fi kàn wọ́n.
 Ó pín wọn sí oríṣìí mẹ ́ ta nípa wíwo ọ ̀ nà tí wọ ́ n ń gbà jẹ yọ : Ó pe àkọ ́ kọ ́ ni èyí tó ń fi ṣiṣe é ṣe hàn ( possibility ) ; ó pe èkejì ní èyí tó ń fi gbígbààyè hàn ( permission ) ; ó pe ẹ ̀ kẹta ni èyí tó pọn dandan .
"Kíni ẹ̀yin rántí nínú ǹkan ti o ti ṣẹlẹ lọ́dun díẹ̀ sẹ́yìn àti nísìnyìí Lara awọn ọmọ ẹgbẹgun IS miran ti wọn mọ si ""The Beatles"" ni Mohammed Emwazi, ti apẹle rẹ n jẹ Jihadi John, ti wọn pa lọdun 2015 ati Aine Davis, to n faṣo penpe roko ọba lọwọ ni orilẹ-ede Turkey."
Fún ọpọlọpọ ọjọ́ ni oòrùn kò ràn tí ìràwọ̀ kò sì yọ.
Atejade naa tun so pe “ibasepo to wa laarin orile ede Naijiria ati Amerika jinle ,ti o si tun gun rege ati pe idagbasoke lori eto oro aje, eto aabo to monyan lori  ati iwa adari nile Afirika yoo tun je ki ibasepo orile ede mejeeji naa tun tesiwaju si i”.
Àwọn ọmọ yóo gbógun ti àwọn òbí wọn, wọn yóo fi wọ́n fún ikú pa.
aare waye lati ri daju pe isokan ati ibasepo to gboro jeyo laarin awon omo ile
"Vee: Oríṣun àwòrán, Instagram/vee Victoria ""Vee"" Adeyele lo kan bayii."
Ilẹ China ń sàmì àádọrin ọdun tí wọn gbòmìnira pẹ̀lú ìfẹ̀hònúhàn Wole Soyinka rèé láti kékeré Wo ohun tó ń ṣẹlẹ̀ níbi ayẹyẹ àyájọ́ ọdún òmìnira ní ìpínlẹ̀ Oyo Ẹ wo ìyá ẹni ọdún 81 tó sẹ̀sẹ̀ parì ilé iwé alákọ̀bẹ̀rẹ̀!
Yakubu Dogara,naa tun wa gbosuba fun aare  Buhari fun bi o se bowolu ofin naa lati
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìlú Eko: Ààrẹ Buhari yóò sàbẹ̀wò , àwọn òsìsẹ́ gba ìsinmi l’Ọ́jọ́bọ̀ 27 Ẹrẹ̀nà 2018 Oríṣun àwòrán, @NGRPresident Àkọlé àwòrán, Ipade laarin Tinubu, Akande ati Buhari ti fa oniruuru awuyewuye lẹsẹ Ìjọba ìpínlẹ̀ Eko ti kéde ọjọ́ kọkàndínlọ́gbọ̀n, Osù Kẹẹ̀ta gẹ́gẹ́bí ọjọ́ Ìsinmi fún àwọn òsísẹ́ ní ìpínlẹ̀ náà.
Wọn kò sọ ohunkohun fún ẹnikẹ́ni, nítorí ẹ̀rù ń bà wọ́n.
O wa gba awọn onitiata akẹẹgbẹ rẹ nimọran lati tẹra mọ ohun tí wọn n ṣe, ti aye fi n nifẹ wọn.
ti yoo se jẹ ki ise wa rọrun fun wa lati pese eto aabo lorile ede Naijiria
Nibi ipade ijoko ile igbimọ aṣofin fasiti naa to waye lọjọ Aje ni wọn ti yan Folashade.
OLUWA sì wí fún un pé, “Sọ̀kalẹ̀ lọ, kí o mú Aaroni gòkè wá, ṣugbọn má ṣe jẹ́ kí àwọn alufaa ati àwọn eniyan náà rọ́ wá sórí òkè níbi tí mo wà, kí n má baà jẹ wọ́n níyà.
Akọroyin wa to n jabọ lati ibẹ fi awọn aworan ranṣẹ si wa ti o si ni laipẹ yii ni adajọ ati Pasitọ naa yoo kalẹ si ile ẹjọ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Akomolede ati asa Yoruba: Ẹ wá kọ́ nípa àpòtí ìṣura èdè wa lórí BBC Yorùbá Ẹgbẹ́ MULAN wa parọwa fun awọn Aafa Islam pe ki wọ́n maa kọ́ awọn eeyan wọ́n sii nipa ofin, ilana ati ikọni ẹsin Islam gẹ́gẹ́ bi o se tọ suna lasiko yii ki iru idajọ Sharia bayii ma baa maa sẹlẹ̀.
Ajo isoka ile okere(EU) ati ajo ECOWAS ti gboriyin fun ilosiwaju orile-ede Naijiria ninu gbigbogun ti iko omo ogun olote boko haram.
Ọwọ́ wọn tẹ Lọti, ọmọ arakunrin Abramu tí ń gbé ní Sodomu, wọ́n mú un lẹ́rú, wọ́n sì kó gbogbo ẹran ọ̀sìn ati gbogbo ohun ìní rẹ̀ lọ.
Saaju ni adajo ile ejo giga kan labuja ti dajo ewọn ọdun meji tabi owo itanran ọtalelẹẹdẹgbẹrin o din mẹwa nair (N750,000) fun-un, lori ẹsun pe o lu biliọnu mẹrinlelogun naira owo ifẹyinti ọlọpaa ni ponpo.
Audu Ogbeh to jẹ minista fun eto ọgbin ati awọn miran naa ko si ninu orukọ ti wọn fi ranṣẹ.
Bẹ́ẹ̀ ni igi burúkú kò lé so èso rere.
Gẹgẹ bi iroyin ti a gbọ, opin ọsẹ yii naa ni Alaaja Ọṣuntoun jade laye lẹni ọdun mẹtadinlaadọrin.
Ni kete ti awọn ọmọ ile igbimọ aṣofin ti pari ayẹwo awọn ti aarẹ Buhari forukọ wọn ranṣẹ sile ni wọn ti n poungbẹ.
Apapọ gbogbo eeyan to ni aarun covid 19 ni Naijiria bayii jẹ mejidinlaadọrunlenigba.
Iwadii naa fihan pe ọdun 2015 ni ipaniyan naa waye.
"Oríṣun àwòrán, @nmanigeria Àkọlé àwòrán, Owo ti ijọba apapọ n la kalẹ labẹ eto isuna ko to iye ti ajọ isọkan agbaye la kalẹ ""Ti a ba n sọrọ eto ilera alabọde lorilẹede Naijiria, gbogbo awọn araalu ti wọn n lo eto ilera alabọde ni wọn n na owo gbẹmigbẹmi lati lanfani itọju, eleyi ti kii kuna to lẹyin-o-rẹyin."
Ọ̀gbẹ́ni Ṣóyèbí ní, ìdádúró yóò wà lórí gbígba káàdì ìdìbò láwọn ìpínlẹ̀ tí ìdìbò yóò ti wáyé lọ́dún yìí ní oṣù kan sí àkókò ìdìbò níbẹ̀.
Oríṣun àwòrán, PA Media Ija naa ti wọn ja lati aṣalẹ ọjọ Satide wọ kuutkutu owurọ ọjọ Aiku ni igba kejilelogun ti Joshua yoo fi ẹṣẹ ja akanṣẹjẹun miran bọ ni apo irẹsi, iyẹn Knockout lati igba to ti bẹrẹ si ni kan ẹṣẹ jẹun, eyi si ni igba keji ti Pulev yoo kuna lati igba to ti n ja ẹṣẹ jẹun.
Mo fún un ní àkókò kí ó ronupiwada, ṣugbọn kò fẹ́ ronupiwada kúrò ninu ìwà àgbèrè rẹ̀.
Ọ̀rọ̀ kànkà yí wáíyé ní ìrọ̀lẹ́ ọjọ́ kan tí èmi àti ọ̀rẹ́ mi kan fẹ́ pàdé láàrin ìlú.
Àwọn arakunrin rẹ̀ náà sì wá, wọ́n wólẹ̀ níwájú rẹ̀, wọ́n ní, “Wò ó, a di ẹrú rẹ.
Bí àpeere, eni ti wón rán ní ojà egbèfa náírà àmó tí ó ra elégbèrún náìrà fi owó rá igba náírà ni.
Niṣe ni Chelsea fi ọ̀bẹ̀ goolu ge Everton wẹlẹwẹlẹ.
A fẹ́ ìdájọ́ òdodo lórí ìsẹkúpani- àwọn akẹ́kọ̀ọ́ FUOYE Alásè Buhari kú, Buhari ń ṣọ̀fọ̀ Gbàgbé ẹ̀sọ́ ara $40m rẹ pátápátá - Ilé ẹjọ́ sí Dienzani Kí a tó sanwó ajínigbé ní àwọn agbófinró dóòlà ọmọ Ọffa mẹ́fà -ODU Gomina ipinlẹ osun tẹlẹ, Olagunsoye Oyinlola naa sọrọ nipa Obasanjo, o ni baba rere ti eeyan le ṣawokọṣe rẹ gẹgẹ bi aṣaju rere ni Obasanjọ.
Aṣafa Salamot ti gbogbo aye n pe ni Iya Wolii, Small Mummy lo fi talẹnti rẹ dara ki awọn eeyan le rẹrin gbagbe iṣoro wọn.
Àtúnṣe òpópónà Lagos-Ibadan àwọn ọ̀ná míràn ti e lè gba Bianca fo fun ayọ, o ni: Odun yii ni àlá mi wa sí imuṣẹ.
Nígbà tí mo jẹun òórọ̀ tán lọ́dọ̀ Baba-onírùngbọ̀n lọ́jọ́ kejì yìí mo wí fún un kí ó jẹ́ kí á lọ sí ilé Ikú kí á tóó dáwọ lé ohunkóhun ní ṣíṣe òun náà sì gbà sí mi lẹ́nu.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Olowo marun un lorilẹ-ede Naijiria ni owo to to san owo isunna lorilẹ-ede Naijiria.
Àwọn ọmọ Bangladeshi lo ẹ̀rọ-alátagbà fi gbógun ti àjàkálẹ̀ àìsàn ibà-ẹ̀fọn
Ni bayii, Ighalo ti sọ goolu mẹta sinu awọn ninu ifẹsẹwọnsẹ meji to ti kopa ninu rẹ lati igba to ti darapọ mọ ikọ ọhun ni Oṣu Kini, ọdun 2020.
Akẹgbẹ Ojo ti wọn jọ n gba bọọlu fun Enyimba, Emmanuel James naa wa ninu ọkọ naa ṣugbọn oun mori bọ ni tiẹ.
A ni lati kọ , bi a se lee maa ba ara  wa gbe ni irẹpọ”Garba shehu tun tesiwaju pe  “Aare  Buhari ti pinnu pe ohun yoo ri i pe eto aabo fẹsẹ
Abdelaziz Bouteflika ti o tun fẹ dije fun ipo aare .
Igba meji ọtọọtọ ni arakunrin yii ju bata lu aarẹ ilẹ Amẹrika ti oun pẹlu si yẹẹ nigba mejeeji ọhun.
 wọ ́ n sì ṣe iṣẹ ́ tí olódùmarè rán wọn ní àṣepé .
Awon miiran tun ni:Abenugan ile igbimo asofin ana, David Mark, gomina ana fun ipinle  Kaduna, Ahmad Makarfi, gomina ana fun ipinle Adamawa , Boni Haruna  ati awon eniyan pataki to wa ninu egbe PDP, ati awon gomina to n dije ninu egbe PDP.
Wọn sọ ninu atẹjade yi pe Minisita, Isa Pantami ati awọn alẹnulọrọ lẹka ibaraẹnisọrọ lo fẹnu ko lori igbes yi lasiko ipade kan.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Manfe-Dove: Àgbà ìlú kan ní ohùn kan ló fọ̀ sáwọn baba ńlá àwọn láti ṣe bẹ́ẹ̀ Wọn fi iwe ipẹjọ naa ṣọwọ si minisita fun eto ilera ati ẹgbẹ awọn dokita ẹka tilu Ibadan.
Àwọn ọmọ Israẹli gba gbogbo àwọn ìlú olódi ati ilẹ̀ tí ó lẹ́tù lójú, wọ́n sì gba ilé tí ó kún fún ọpọlọpọ àwọn nǹkan dáradára, ati kànga, ọgbà àjàrà, igi olifi ati ọpọlọpọ igi eléso, nítorí náà wọ́n jẹ wọ́n yó, wọ́n sanra, wọ́n sì ń gbádùn ara wọn ninu oore ńlá rẹ.
Ní òru ọjọ́ náà, ọba kò lè sùn.
Ati pé a sin ín, a sì jí i dìde ní ọjọ́ kẹta, gẹ́gẹ́ bí Ìwé Mímọ́ ti wí.
Giadom ti jẹ kọmiṣọnna fun akanṣe iṣẹ ni ipinlẹ Rivers, lasiko ti Minisita fun eto irinna ni Naijiria, Rotimi Amaechi fi jẹ gomina ipinlẹ naa.
Àwọn ọmọ ogun rẹ̀ tí a kà jẹ́ ọ̀kẹ́ meji ó lé ẹẹdẹgbẹta (40,500).
Mourinho to jẹ ọmọ ọdun marunlelaadọta ami ẹyẹ League Cup ati Europa nigba to fi tukọ Manchester United.
O fikun-un oro re pe, awon ondije olugbe irin miran, ti a mo si (weightlifters), Aka Angeline Filji ati Mikoumba Petit David, ni won ko ri ni Gold Coast.
Àbúrò mi ń yí kẹ̀kẹ́, ó fi ń pariwo.
Big Sean Ninu ọrọ tiẹ, Big Sean, to n na a jẹ afi orin sọrọ 'Rapper', nilẹ America, o ni oun fi ifẹ oun ranṣẹ si Naijiria, to jẹ orisun oun.
eleto idibo yoo lee kawọ awon oludibo to wa ni ayika yii.
O ti ṣiṣẹ pẹlu àwọn ile iṣẹ bii Africa Research and information Bureau ni London laarin 1991 si 1993; Deptford City Challeng, ni London lọdun 1993 si 1995; minista fun ìwakùsà ati irin tutu lọdun 2016 si 2018 nigba to kọwe fipo rẹ silẹ ko le dije fun ipo gomina Ekiti.
Iléesẹ́ ọlọ́pàá: Ihò tí wọ́n gbẹ́ fún wáyà, ni eku gbà wọlé
Ṣugbọn, n jẹ ẹ mọ pe, ajọdun Sango ni ilu Ọyọ pẹlu maa n gbe arugba sita.
Bakan naa, ninu idije Commonwealth Games ti o waye ni Glasgow, lorile-ede Scotland lodun 2014,  Naijiria gba ami-eye mẹ́rìndínlógójì, ti n se (11 Gold, 11 silver ati 14 bronze).
Awọn ọmọde a ma tan arun yi kaakiri nitori pe wọn a ma ba awọn ọmọ miran ṣere ṣugbọn a ko ti le sọ boya wọn ṣalabapin kokoro arun yi fẹlomiran.
Iwe iroyin UK Guardian jabọ pe Dakolo ṣalaye pe ọlọpaa kan gbe ibọn dani, ti ikeji si ni ki oun tọwọ bọ iwe ti wọn lo wa lati ọdọ ọga agba ọlọpaa.
Ohun ti iyawo ṣe pẹlu ọmọ wọn Oyeladun, o ṣi ni lẹnu silẹ koda iroyin rẹ ko ṣee foju ba ni ninu fidio to wa loke yii.
Èyí túmọ̀ sí pé láàrín ààgo mẹ́fà ààrọ̀ sí ààgo márùn-ún ìrọ̀lẹ́ dípò wákàti mẹ́rìnlélógun tí wọn gbé lée tẹ́lẹ̀ ni kóníléógbélé yoo fi wa kí àwọn ènìyàn lè ní àànfàní láti lọ sẹ́nu iṣẹ́ wọn.
Apá kan wọn yóo máa ṣàn lọ sinu òkun tí ó wà ní ìwọ̀ oòrùn, apá keji yóo máa ṣàn lọ sí òkun tí ó wà ní ìlà oòrùn, yóo sì máa rí bẹ́ẹ̀ tòjò-tẹ̀ẹ̀rùn.
 Èyí kò sí yi padà láti ọjọ ́ pípẹ ́ wá .
Juda bá sọ fún Tamari opó ọmọ rẹ̀ pé, “Wá pada sí ilé baba rẹ kí o lọ máa ṣe opó níbẹ̀ títí tí Ṣela, ọmọ mi yóo fi dàgbà.
Àwọn ìròyìn mìíràn tí ẹ lè nífẹ̀ẹ́ sí: Ọwọ ọlọpa tẹ adigunjale ajọkọgbe nipinlẹ Ọsun Ìdààmú Dino Melaye kò tíì tán, àwọn ọlọ́pàá tún ya bo ilé rẹ̀ SARS já wọ ilé àwọn akẹ́ẹ̀kọ́ fásitì Akungba Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Nítorí náà, ẹ kò ní ríran èké mọ́, ẹ kò sì ní woṣẹ́ mọ́.
lade -lade ati loye -loye, pelu gbogbo egbe omo ilẹ kaarọ- o-jire, lọlọkan-o-jọkan
”Ọba dáhùn pé, “Ìròyìn ayọ̀ ni òun náà ń mú bọ̀.
Oríṣun àwòrán, @policeng Igbesẹ yii lo n waye lẹyin ti rogbodiyan to bẹ silẹ nilu Sagamu lẹyin iku arakunrin naa to jẹ ọmọ ẹgbẹ agbabọọlu Remo Stars.
1 Kíyèsíi, àkọsílẹ̀ kan ni a ó pamọ́ ní ààrin yín; àti nínú rẹ̀ a ó pè ọ́ ní aríran, olùtúmọ̀, wòlíì, àpóstélì ti Jésù Krístì, alàgbà ti ìjọ nipa ìfẹ́ inú ti Ọlọ́run Bàbá, àti oore ọ̀fẹ́ Olúwa rẹ Jésù Krístì,
Nítorí ẹ̀yin ni ẹ tan ìyìn rere ọ̀rọ̀ Oluwa káàkiri, kì í ṣe ní Masedonia ati Akaya nìkan, ṣugbọn níbi gbogbo ni ìròyìn igbagbọ yín sí Ọlọrun ti tàn dé.
Pete Edoche: Elebuibon ní tá bá ṣọ́ra, àṣà àjèjì yóò sọ wá dẹrú òyìnbó
Ṣugbọn bí mo ti wòye, àwọn ẹ̀yà ara mi ń tọ ọ̀nà mìíràn, tí ó lòdì sí ọ̀nà tí ọkàn mi fẹ́, ọ̀nà òdì yìí ni ó gbé mi sinu ìgbèkùn ẹ̀ṣẹ̀ tí ń bẹ ninu àwọn ẹ̀yà ara mi.
Irọlẹ ọjọ yii naa lo ni ọkunrin naa ni otutu n mu oun, tawọn si ni ko bọ asọ, ti wọn si mu sinu ahamọ ninu yara kan, oun nikan si lo wa ninu yara naa.
Ìsọkúsọ ni Olúbàdàn ń sọ, àwa la lè yọ́ lóyè.
Oloye Lai Muhammed ran awon akoroyin leti lori ase ijoba apapo fun ajo to n mojuto ise awon oniroyin ni Naijiria, iyen, National Broadcasting Commission (NBC) pe ki won maa fofin de ile ise iroyin Kankan to ba gbe eto ki eto to n satileyin oro ikorira sita.
Nítorí pé Ọlọrun fún un ní ẹ̀kúnrẹ́rẹ́ Ẹ̀mí rẹ̀.
Kí ló dé tí ẹ̀ ń sunkún,nítorí ìnira yín tí kò lóògùn?
Wọ́n sì ti pín in ní ìdílé-ìdílé.
N óo wá bá ọ sọ̀rọ̀ níbẹ̀.
"Amofin ọhun pari ọrọ rẹ pe ""Ti eeyan ba ni simu meji tabi mẹta, emi o mọ bi iyẹn ṣe lee din iwa ọdaran ku."
Ogun ti oo le gboju le agbara rẹ ati ohun ija ni eyi bikoṣe ipa too ni lati ṣe e yanju.
To òkúta olówó iyebíye sí ara rẹ̀ ní ẹsẹ̀ mẹrin, kí ẹsẹ̀ àkọ́kọ́ jẹ́ òkúta sadiu, ati òkúta topasi, ati òkúta kabọnku.
Ijọba orilẹede Naijiria ti buwọlu ayipada si owo ti awọn ọmọ orilẹede Amerika to ba fẹ wa si Naijiria yoo ma san gẹgẹ bi owo Iwe Irinna(Visa).
Aare Buhari je okan lara awon aare , ti o ba soro ti yoo si mu ọrọ  rẹ sẹ, ti aare ba se ileri, ki eniyan fi okan
"Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Láàrín ìṣẹ́jú díẹ̀, ẹ ka ìwé Akinwumi Ishola, ""Nítorí Owó"" lórí Akomolede Yoruba 5) Agbeyẹwo iwe litireṣọ "" Nitori Owo"" ni a gbe yẹwo ni kilaasi yii ti Alagba Olanrewaju Akano lati ile ẹkọ Community Grammar School, Oke Ayo, Odo Ona Apata kọ wa."
Onyeama ninu iwe rẹ to kọ, sọ pe ''Wọn bi mi pe, se kii se pe o se magomago ninu idanwo?
Ẹ kéde ògo rẹ̀ láàrin àwọn orílẹ̀-èdè;ẹ sọ̀rọ̀ iṣẹ́ ìyanu rẹ̀ láàrin àwọn eniyan.
Mo bá pe Alufaa Uraya ati Sakaraya, ọmọ Jebẹrẹkaya, kí wọn wá ṣe ẹlẹ́rìí mi nítorí wọ́n jẹ́ olóòótọ́.
Nígbà tí o bá kúrò níbẹ̀, tí o sì ń lọ, o óo dé ibi igi oaku tí ó wà ní Tabori.
tabi pẹlu àwọn ọmọ aládé tí wọ́n ní wúrà,tí fadaka sì kún ilé wọn.
Ṣugbọn angẹli náà wí fún wọn pé, “Ẹ má bẹ̀rù mọ́, nítorí mo mú ìròyìn ayọ̀ ńlá fun yín wá, ayọ̀ tí yóo jẹ́ ti gbogbo eniyan.
Opolopo emi lo tun ti sonu leyin iselel yiiIjoba ipinle Benue ni Aare Buhari yoo lo se abewo si Tiv, ati ile Ojogbon James Ayatse ni Makurdi.
OLUWA ọmọ ogun ti búra lójú mi, ó ní,“Láìsí àní-àní, ọpọlọpọ ilé ni yóo di ahoro,ọ̀pọ̀ ilé ńláńlá, ati ilé dáradára yóo sì wà láìsí olùgbé.
Àwọn ará Beti Togama a máa kó ẹṣin, ati ẹṣin ogun, ati kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ wá ṣe pàṣípààrọ̀ àwọn nǹkan tí ò ń tà.
Oba Adedokun Omoniyi ni ọja ọla Naijiria lo jẹ oun logun ati mimu ayipada BBC Yoruba ba ninu awọn akẹkọọ ile iwe ọfẹ Kabiesi sọrọ nipa iriri wọn.
Ogbeni Richard Egbule to jẹ alaga igbimo naa lo kede aṣẹ tuntun ti Aarẹ Muhammadu Buhari pa yii fawọn oniroyin.
Ọ̀dọ̀ OLUWA ni ìrànlọ́wọ́ wa ti wá,ẹni tí ó dá ọ̀run ati ayé.
wọ́n ní, “Aadọta ọkunrin alágbára wà pẹlu àwa iranṣẹ rẹ, jọ́wọ́ jẹ́ kí wọ́n lọ wá ọ̀gá rẹ, bóyá Ẹ̀mí OLUWA tí ó gbé e lọ ti jù ú sílẹ̀ ní orí ọ̀kan ninu àwọn òkè agbègbè yìí, tabi ninu àfonífojì kan.
Awọn ara ilu sọrọ nipa Kabiesi to waja naa pe o gbiyanju ipa rẹ fun idagbasoke Ikare Akoko.
How to make bread Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ìpàdé NLC àti ìjọ̀ba àpapọ̀ lórí owó osù tuntun forí ṣánpọ́n ‘Daily Trust fi àsírí ìgbógun tí Boko Haram jáde la se tì í’ INEC: Àìmọ̀kan-mọ̀kàn ló ń ṣe àwọn tó ń sọ̀rọ̀ tako ìyànsípò Amina Zakari Atẹjade kan ti akọwe agba fun ẹgbẹ oṣiṣẹ NLC lorilẹede Naijiria fi sita ni ''lẹyin ipade ti agbarijọpọ ẹgbẹ oṣiṣẹ gbogbo lorilẹede fi sita ni ọjọ kẹtadinlogun oṣu Kejila ọdun 2018, ni ipinnu lati gunle iwọde dipo iyanṣẹlodi ti waye.
Ṣugbọn ni ẹnu lọwọlọwọ yii, ohun to n gbe Bọla Tinubu si oju aje ayelujara naa ni ariyanjiyan lori bi awọn kan ṣe ṣalaye pe, o n gbero lati du ipo aarẹ orilẹede Naijiria ni ọdun 2023.
Bakan naa lo ni ọgba ileewe wa lara awọn ibudo to dara lati wa julọ lasiko ajakalẹ arun bayii ṣugbọn ijọba ninu ọgbsn wọn le awọn akẹkọ kuro niblẹ wa sile nibi ti arun yi ti n gbilẹ.
Àwọn alufaa ni wọ́n tún Òkè Ẹnubodè Ẹṣin ṣe, olukuluku tún ibi tí ó kọjú sí ilé rẹ̀ ṣe.
Sùgbọ́n agbẹnusọ ilé iṣẹ́ ọlọ́pàá ìpińlẹ̀ Ondo Tee-Leo Ikoro sàlàyé pé, ènìyàn mẹ́jọ ni awọn le fi ìdí rẹ̀ múlẹ̀ pé ó kú nínú ìṣẹ̀lẹ̀ náà.
ni iroyin so pe o bere pelu mimu atunse ba awon ona ti won yoo gba lati mu eto
Pasitọ EA Adeboye jẹ ọkan pataki lara awọn iranṣẹ Ọlọrun to lokimi nilẹ Naijiria ti okiki rẹ si kan de oke okun.
Wọn bi Aarẹ Muhammadu Buhari ni idile ẹya Fulani kan ni ọjọ kẹtadinlogun oṣu kejila ọdun 1942 ni ilu Daura ipinlẹ Katsina.
Wọ́n a máa gbadura gígùn nítorí àṣehàn.
Òfin náà fún àwọn Juu ní àṣẹ láti kó ara wọn jọ, láti gba ara wọn sílẹ̀, ati láti run orílẹ̀-èdè tabi ìgbèríko tí ó bá dojú ìjà kọ wọ́n, ati àwọn ọmọ wọn, ati àwọn obinrin wọn.
Ṣọ́ra nípa kíkọ orúkọ àwọn opó tí wọ́n jẹ́ ọ̀dọ́ sílẹ̀, nítorí nígbà tí ara wọn bá gbóná, wọn yóo kọ ètò ti Kristi sílẹ̀, wọn yóo fẹ́ tún lọ́kọ.
Bí ẹni tí ó ya ilé yìí sọ́tọ̀ fún OLUWA bá fẹ́ rà á pada, yóo san iye tí ilé náà bá tó, yóo sì tún fi ìdámárùn-ún iye owó rẹ̀ lé e.
Tinubu ko awọn ọmọ ẹgbẹ APC rẹ lọ bẹ aarẹ wo ni.
Ó fọ́ ìgò náà, ó bá tú òróró inú rẹ̀ sí Jesu lórí.
Bakan naa ni ẹpa naa dara ni ara lati mu ki atọ ọkunrin dara si ni ara.
Progressives Congress, APC) ni ibo rẹ tun tẹlẹ 
Bakan naa ni iba ti agbara eegbogi ko ka naa n waye ni gbogbo igba.
O fẹ́ràn òdodo, o kórìíra ẹ̀ṣẹ̀.
Jesu bá kó wọn jáde lọ sí Bẹtani.
Iho dudu yii jina si wọn lọna ọgọrun marun miliọnu triliọnu kilomita si ibi ti wọn ti ya aworan naa pẹlu ohun awojuọrun mejo kaakiri agbaye.
Òtítọ́ ni ohun tí mò ń sọ yìí; n kò purọ́, nítorí Kristi ni ó ni mí.
Yemi Adenuga: Olùdìbò Ireland kìí gba ìrẹsì, àmọ́ wàá dé ilé kọ̀ọ̀kan láti bèèrè ìbò
Kilo tun ku ti o sọ?
Sibẹ òun ati àwọn ọmọ ogun rẹ̀ kò rí èrè kankan gbà ninu gbogbo wahala tí wọ́n ṣe ní Tire.
 nígbà tí yóò fi tó ọdún 2010 , ilé-ẹ ̀ kọ ́ náà ti ní àwọn akẹ ́ kọ ̀ ọ ́ tí ó tó ẹgbẹ ̀ rún mẹ ́ rin ( 4,000 ) .
A gbọ pe bi ọpa afẹfẹ gaasi naa ṣe bẹ wa latọwọ awọn oṣiṣẹ ileeṣẹ Julius Berger to n ṣiṣẹ ni opopona naa.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ẹgbẹ́ agbésùnmọ̀mí IS yọ Al-Barnawi ọmọ olùdásílẹ̀ Boko Haram nípò gẹ́gẹ́ bíi adarí ISWAP 5 Ẹrẹ̀nà 2019 Oríṣun àwòrán, LeBabi.
"Nítorí ìdí èyí, BBC ń ṣiṣẹ́ takuntakun láti sàlàyé ìrú àwọn ìmọ̀ ti ẹ ń kà tàbí wò lóri ẹ̀rọ ayélujára, níbo àti ọ̀dọ̀ tààni ìrú ẹni tó ń gbé ìròyìn náà jáde, àti pé báwo ní wọ́n ṣe kọ ìròyìn náà, nípasẹ̀ èyí, ẹyin gan ó le jẹ́rìí sí ọ̀nà ti ẹ fi lè ní ìgbẹkẹ̀lé nínú ìròyìn BBC À ń ṣe atọ́ka tó ṣàlàyé ìṣẹ́ ìròyìn tó ṣe gbẹ́kẹ̀lé ""ẹ̀rọ ìkàwé"", èyí túnmọ sí pé à lè ṣe àwári rẹ̀ nípa lílo èròjà tí a fí ń ṣe àwári ǹkan lórí àwọn èròjà àtẹjíṣẹ́ orí ẹ̀rọ ayélujára, èyí yóò ma ràn wọ́n lọ́wọ́ láti dá ìròyìn òótọ́ọ́ mọ̀ àti orísun rẹ̀ náà."
Ileeṣẹ ọlọpaa Naijiria si ti ri ọlọpaa mẹta, wọn ti mu meji to ṣe obinrin kan bo ṣe wu wọn ninu fọnran ọhun to gba ori ayelujara kan lẹnu ọjọ melo kan sẹyin.
O fikun pe ti iwadi naa ba fihan pe wọn kan fẹ fi iya jẹ awọn akọroyin naa lọna aitọ ni, ẹgbẹ NUJ yoo faraya si isẹlẹ yi.
A o maa mu esi wọn wa fun yin ni kete ti wọn ba ti fesi.
Oríṣun àwòrán, @SenGbengaAshafa Àkọlé àwòrán, Awọn Sẹnẹtọ ọmọ ẹgbẹ APC kọwọ rin pẹlu Akpabio Kíni awọn ọmọ Naijiria n sọ?
Ogbeni Olukolu tun lo asiko naa lati so fun ara ilu pe, ki
Oríṣun àwòrán, Instagram/olori_omoh_one Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Oríṣun àwòrán, Olubadan Amọ, Elebuibọn faramọ ki wọn mase kọla fun awọn obinrin ni oju ara, amọ ila oju wa fun ẹwa obinrin ati ọkunrin ati lati mọ ibi ti eniyan ti ṣẹ wa.
awon ẹsọ eleto aabo, awon ọba alaye ati awon ti ọrọ kan  ,pe ki won maa ta awon ẹsọ eleto aabo lolobo
Kí alufaa wọ ẹ̀wù àwọ̀kanlẹ̀ funfun rẹ̀, ati ṣòkòtò aṣọ funfun, kí ó kó eérú ẹbọ tí ó ti fi iná sun kúrò lórí pẹpẹ, kí ó sì dà á sí ibìkan.
Àwọn akọni ọkunrin bíi mélòó kan tí Ọlọrun ti fi sí ní ọkàn bá Saulu lọ.
Ipade adura ijọ Irapada Kristi (RCCG) Oríṣun àwòrán, Twitter/rccghq Alufaa agba ijọ Irapada Kristi l'agbaye, Pasitọ E.
Jesu bi àwọn amòfin ati àwọn Farisi tí ó wà níbẹ̀ pé, “Ṣé ó dára láti ṣe ìwòsàn ní Ọjọ́ Ìsinmi, tabi kò dára?
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Hon Buraimoh:Wọ́n fí ikú rẹ dáwà loro ní-abanikẹdun Ó ṣeéṣe kí ènìyàn 12,000 máa kú lójoojúmọ́ lẹ́yìn Covid-19 Orílẹ̀-èdè mẹ́wàá tí ẹgbẹ́ alákatakítí Islamic State n fínna mọ́ ní àgbáyé N kò gba ₦4bn lọ́wọ́ Magu, ẹ má ró àjẹbánu mọ́ mi láṣọ - Osinbajo pariwo Mi ò tíì gba ìwé ìfitónilétí pé wọ́n fẹ́ yọ mí nípò igbákejì gómìnà ìpínlẹ̀ Ondo- Agboola Ajayi Bo tilẹ jẹ pe a ko le fidi iru iku to pa oloogbe ọhun mulẹ, amọ o ta si akọroyin BBC Yoruba l'eti pe, ibudo itọju alarun Coronavirus to wa ni adugbo Yaba, ni Braimoh ku si.
Zaharadeen ni nigba ti oun lọ sin gbese ogoji naira ti ọrẹ oun Farawa ya ni ija bẹ silẹ laarin awọn mejeeji.
Wolíì náà béèrè lọ́wọ́ Olúwa nípasẹ̀ Urimù àti Tumimu òun sì gbà ìdáhùn yìí.
Nítorí náà, ẹ jẹ́ kí á lọ sí ibùdó ogun àwọn ará Siria.
"Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Toríi ""Coro"", ẹ wo bí ètò ìsìn ìgbéyàwó orí ayélujára Zoom ṣe lọ Bakan naa ni ijọba ipinlẹ Ogun ni gbogbo awọn ileewe aladani ni lati rii daju pe awọn akẹkọọ wọn ni iwe ẹri yii."
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Sunday Igboho: Fulani kò leè dúró, táa bá lo ohun ta jogún lọ́dọ̀ àwọ̀n bàbá wa Awọn iwa ibi yii lo ta Sunday Igboho nidi kan nirọlẹ ọjọ Isẹgun, ọjọ kejilelogun osu Kẹsan ọdun 2020, ti oun ati ọmọlẹyin rẹ fi gba ilu Kishi lọ lati bawọn afurasi afẹjẹwẹ naa fija pẹẹta ninu igbo Old Oyo National Park.
Alaafin Oyo: Ọmọ Yorùbá sọ fún olorì Anu pé kò yẹ kó tú àṣírí ìkọ̀kọ̀ ìgbéyàwó rẹ̀ sí gbangba
Ó wó àwọn pẹpẹ ìrúbọ tí àwọn ọba Juda kọ́ sórí ilé Ahasi ninu ààfin lulẹ̀, pẹlu àwọn pẹpẹ ìrúbọ tí Manase kọ́ sinu àwọn àgbàlá meji tí ó wà ninu ilé OLUWA.
Ati,“Òkúta tí yóo mú eniyan kọsẹ̀,ati àpáta tí yóo gbé eniyan ṣubú.
Ó lọ sí ọ̀dọ̀ Dafidi ọba, ó wí fún un pé, “Kabiyesi, iranṣẹ rẹ ń rẹ́ irun aguntan rẹ̀, mo sì fẹ́ kí kabiyesi ati gbogbo àwọn oníṣẹ́ rẹ̀ wá síbi àjọ̀dún náà.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Goodluck: Ṣèbí ajagunfẹ̀yìntì ni Buhari, o yẹ kó mọ ohun tó yẹ láti kápá ìpèníjà ààbò 16 Agẹmo 2019 Àkọlé àwòrán, Ààrẹ àná, Goodluck Jonathan naa kún ara awọn lookọ-lookọ to ti bẹ alagba Rueben Faṣọranti wo lori iku ọmọ rẹ ti awọn agbebọn pa Aarẹ ana lorilẹ-ede Naijiria, Goodluck Jonathan ti gba aarẹ Buhari ni imọran pe ko yi eto ati ilana ti o n lo lati gbogun ti ipenija aabo to mẹhẹ ni Naijiria.
Ibasepo orile-ede Naijriia pelu awon orile-ede lolokan-o-jokan yoo
Lati aago mẹrin irọle titi di oru ọjọbọ yii ni awọn aṣoju ẹgbẹ oṣiṣẹ ati awọn minista fun ọrọ oṣiṣẹ fi jọ ṣe ipade papọ ni eyi to tun fori ṣọnpọn.
Bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé Josẹfu mọ̀ dájú pé àwọn arakunrin òun ni wọ́n, wọn kò mọ̀ ọ́n.
- Ọọ̀ni Ife Wọn pa ọlọ́pàá kan níbi tí wọ́n ti dáná sun ìjọ Sotitobire l'Akurẹ - Police PRO Wo àwòràn ohun tó ṣẹlẹ̀ nílé ìjọsìn Sotitobire tí wọ́n sun ní àná Ọjọ kẹwaa, oṣu Kọkanla, ọdun 2019, ni iroyin jade pe, ọmọ naa deede poora ninu ṣọọṣi naa ni ẹka awọn ọmọde ti iya rẹ gbe e lọ, lọjọ isinmi naa.
Kí alufaa pàṣẹ pé kí wọn kó gbogbo ohun tí ó wà ninu ilé náà jáde, kí ó tó lọ yẹ àrùn náà wò; kí ó má baà pe gbogbo ohun tí ó wà ninu ilé náà ní aláìmọ́; lẹ́yìn náà, kí alufaa lọ wo ilé náà.
A tún ń gbadura pé kí ìgbé-ayé yín lè jẹ́ èyí tí ó wu Oluwa lọ́nà gbogbo, kí iṣẹ́ rere yín máa pọ̀ sí i, kí ẹ máa tẹ̀síwájú ninu ìmọ̀ Ọlọrun.
Minisita fun iroyin ati asa lorile ede Naijiria ,Lai Mohammed  ti so pe aheso oro lasan ni iroyin to so pe orile ede Naijiria n dun ikooko mo  orile ede Isreal lati da Kanu pada si orile ede Naijiria tabi ki orile ede Naijiria gbe igbese to le nitori re.
Nitori naa, aare wa beere fun”Iwadii
Fún àlàyé sii lọ sí ojú òpó Nigeria Airforce tabi kí o pe àwọn nọmbá yìí láàrin aago mẹ́sàn àbọ̀ òwúrọ̀ sí aago márùn àbọ̀ ìrọ̀lẹ́ láti ọjọ́ ajé sí ọjọ́ jímọ̀ 08043440802 and 09055840142 tabi ki o kọ̀wé ránṣẹ́ si ibi yìí e-mail: careers@airforce.
60 Olukúlùkù alàgbà, àlùfáà, olùkọ́ni, tàbí díakonì ni a ó yàn ní ìbámu pẹ̀lú awọn ẹ̀bùn àti awọn ìpè Ọlọ́run sí i; àti pé a ó yàn an pẹ̀lú agbára Ẹ̀mí Mímọ́, èyí tí ó wà nínú ẹnití ó yàn án.
Wo o daadaa boya sanitaisa hun ni nọmba aj NAFDAC.
Ìlú Igbo-Ọra: Ijọba ipinlẹ Ọyọ ṣe ayẹyẹ ọdun ibeji fún ìgbà àkọ́kọ́
1 671 Orilẹede Comoros 7 0.
Olujẹjọ gboogi ninu ẹjọ naa, Alfa Babatunde ko si yọju sile ẹjọ lọjọbọ nitori pe wọn ti sun igbẹjọ naa siwaju amọ awọn agbẹjọro rẹ fọwọ gbaya pe yoo yọju sile ẹjọ loni.
“Ìwọ ọmọ eniyan, sọ fún ọba Tire pé OLUWA ní, ‘Nítorí pé ìgbéraga kún ọkàn rẹ, o sì ti sọ ara rẹ di oriṣa, o sọ pé o jókòó ní ibùjókòó àwọn oriṣa láàrin òkun; bẹ́ẹ̀ sì ni eniyan ni ọ́, o kì í ṣe oriṣa.
Inu gbogbo ọmọ Ivory n dun ṣugbọn ki won to lè mọ bóyá wọn yóò tẹsiwaju tabi bẹẹkọ; wọn nilati kópa nínú ìdíje ife ẹyẹ agbaye ní ọdún 2006, Cameroon ti awọn náà n gba bọọlu lọwọ pẹlu Egypt ni lati gba ọmi.
Adebimbola Silva to jẹ onisegun oyinbo ní iya rẹ, nígbà ti baba rẹ, E.
Jíjìn rẹ̀ jẹ́ igbọnwọ marun-un ààbọ̀, fífẹ̀ rẹ̀ sì jẹ́ igbọnwọ mẹ́wàá.
29 Àti pé àwa mọ̀ pé gbogbo ènìyàn gbọ́dọ̀ ronúpìwàdà kí wọ́n ó sì gbàgbọ́ nínú orúkọ Jésù Krístì, àti kí wọ́n ó bu ọlá fún Bàbá ní orúkọ rẹ̀, àti kí wọn ó fi orí tìí nínú ìgbàgbọ́ ní orúkọ rẹ̀ títí dé òpin, bíbẹ́ẹ̀kọ́ wọn kò ní di ẹni ìgbàlà ní ìjọba Ọlọ́run.
Bala ní wọ́n ti fi ẹjọ náà ṣọwọ́ sí ẹka ìwádìí ìwà ọ̀daràn ni Panti Yaba fún ìwádìí tó yẹ àti pé àwọn ọlọ́pàá ti gbé oku náà si ìpamọ́ láti tẹ̀síwájú nínú ìwádìí Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
 yangí yìí dúró fún àmì Ẹ ̀ sù .
Egbe to n sakoso lowo lorile ede Naijiria ,All Progressives Congress, APC ti benu ate lu iwa apaniyan to waye ni ijọba ibile Barkin-Ladi ati Riyom, to wa ni ipinle Plateau gege bi iwa ika , alailaaanu ati iwa odaju.
Ati wipe o tilẹ ni awọn alarinna lati idile Osu ti orukọ wọn n jẹ Nneji, wọn ṣiṣẹ lati fopin si idẹyẹsi naa nipa mimu ololufẹ meji mọ ara wọn, awọn mejeeji yoo wa lati idile ẹru, ki wọn baa le fẹ ara wọn lai si ipọnju lati ọdọ awọn obi.
Agbẹnusọ Ile Igbimọ Aṣofin Ipinlẹ Eko, Aṣofin Mudashiru Ọbasa ti di Alaga Igbimọ awọn Agbẹnusọ Ile Igbimọ Asofin Ipinlẹ Lorilẹ-ede Naijiria.
 awon musulumi onisowo mu esin islam wa sibe , beesini awon alagbara lati europe ba ara won ja lati se adase owo ni awon erekusu spice maluku lasiko igba iwari .
" Ṣugbọn, awọn onimọ kan bi i Muhammad Tahar Adama (Baba Impossible) ati Ọjọgbọn Uba Adamu sọ pe ìtàn naa kii ṣe otitọ.
Opin iyọnipo nilẹ America Yatọ s'eto idibo, ile aṣofin America wa laarin gbungbun igbesẹ lati yọ Aarẹ Trump nipo, nitori ipe kan to pe aarẹ Ukraine.
Mo tún rán Onisimu, ọ̀kan ninu yín, tí òun náà jẹ́ àyànfẹ́ ati arakunrin tí ó sì ṣe é gbẹ́kẹ̀lé.
Angẹli náà bá dáhùn pé, “Àwọn wọnyi ni wọ́n ń lọ sí igun mẹrẹẹrin ayé lẹ́yìn tí wọ́n ti fi ara wọn han Ọlọrun ẹlẹ́dàá gbogbo ayé.
Gẹgẹ bi ọga Ọlọpaa ilu Nice, Christian Estrosi ti wi, ikọlu awọn adunkookomọni ni iṣẹlẹ naa, to waye ninu ijọ aguda kan.
Ile ise ijoba embasi ti France ati Belgium ni won seto ohun ni Naijiria nibi ti awon osere ti korin awon onkorin bii Fela Anikulapo Kuti ti won ti dagbere faye pe o digbose seyin.
Bi o tilẹ pe awọn kan ni aarin wọn dagba, wọn dogbo, amọ iku awọn miran ninu wọn jẹ agbọ-sọ-gbanu.
70, ti o je senti mokanlelogun 21cents ti o pajude lateyin wa.
(láti ìgbà èwe rẹ̀ ni mo ti ń ṣe bíi baba fún un,tí mo sì ń tọ́jú rẹ̀ láti inú ìyá rẹ̀); 
Ile ẹjọ to n gbọ ẹjọ ẹsun to ni i se pẹlu idibo si Ile Igbimọ Asofin ni ipinlẹ Eko ti fagile idibo to gbe Alaga Ile Igbimọ Asofin lori ọrọ Iroyin ati Awujọ, Sẹnatọ Dayo Adeyeyẹ.
Aarẹ àná, Barack Obama, ti wọn jọ dije dupo aarẹ ni ọdun 2008 sọ wi pe akinkanju eniyan ati ajafẹtọ ọmọniyan saaju ifẹaraẹni ni McCain to papoda naa.
Lẹyin iṣẹju marun un ti ipele keji ifẹsẹwọnsẹ naa bẹrẹ ni Christian Pulisic fọba lee fun Chelsea ti ifẹsẹwọnsẹ si di ami ayo meji sẹyọkan fun Chelsea.
Wọ́n fi òògùn yìí tọ́jú òkú Jakọbu.
Ayédèrú Afenifere ló bá Buhari ṣépàdé - Odumakin gbanájẹ Tinubu kọ lẹta si Odigie Ohun mẹ́fà tí kò yẹ́ kí o gbàgbé nípa Gómìnà Ambode Fulani nìkan kọ́ ló ń pa ènìyàn ní Naijiria -Tinubu Gẹ́gẹ́ bí olùgbékalẹ̀ ètò náà Victor Taiwo se sọ, ó ni Akintoye ní àwọn àmúyẹ mẹ́rìnlá ti yóò jẹ́ ki ìràn Yorùbá tẹ̀síwájú ní ọgbọ́n, ìmọ to pọ̀, ati oye.
 Èyiini tí a bá gba ọ ̀ nà adó-Èkìtì .
Ileejọ tako iyansipo Magu Magu ati Keyamo ri‘binu ijọba Àlàyé rèé lórí ìdí tí Magu àti awọn alága EFCC míràn ṣe bá ìtìjú kúrò nípò Wọ̀nyí ni àwọn ẹjọ́ tó làmìlaaka ti EFCC ṣe lásìkò Ibrahim Magu Coronavirus: Ó dá mi lójú pé ìwá ìbàjẹ́ ló fa àrùn yìí - Ọ̀gá àgbá EFCC Ẹsun miran ti wọn tun fi kan igbakeji aarẹ ninu awọn iroyin naa ni pe, o pasẹ fun ajọ EFCC lati wọgile awọn ipinnu rẹ kan lai tẹle ofin to yẹ.
Sì mú akọ mààlúù kan ati àgbò kan fún ẹbọ alaafia, kí ẹ fi wọ́n rúbọ níwájú OLUWA pẹlu ẹbọ ohun jíjẹ tí a fi òróró pò, nítorí pé OLUWA yóo fi ara hàn yín lónìí.
9 4165 Orilẹ́ẹede Boswana 71 3.
Ẹni mẹ́sàn án dòkú; mẹ́ta farapa nínú ìkọlù aàlà Borno àti Cameroon Ìwà ọ̀dàlẹ̀ ni bí ẹ kò bá gbé iléèwé ìkọ́ṣẹ́ olùkọ́ni kalẹ̀ sí ìlú Ìwó- Oluwo Irú kí lèyì!
O Fagunwa kú, dúkìá rẹ̀ sì ń fọhùn síbẹ̀, ilé rẹ̀ rèé Kí lo fẹ́ mọ̀ nípa D.
awon ile-ise miiran sile ti ofin ati ilana won ko si ni ibamu pelu ilana ofin
O sọ fun sẹnetọ Pilip Aduda pe ẹkun idibo tirẹ gan(Phillip) ko dibo fun oun(Buhari).
Àwọn kan wà tí ẹ̀ṣẹ̀ wọn hàn sí gbogbo eniyan, àwọn adájọ́ ti mọ̀ wọ́n kí wọ́n tó mú wọn dé kọ́ọ̀tù.
Ọmọ meji ni Elikana bí: Amasai ati Ahimotu.
Oríṣun àwòrán, Others Lọdun to kọja, oun lo lọ ṣoju Magu nibi ti ajọ EFCC ati ileeṣẹ ọtẹlẹmuyẹ FBI ti n ba awọn akọroyin sọrọ nilu Ekonibi ti wọn ti jabọ iye owo ti wọn ri gba pada lọwọ awọn gbajuẹ.
Ataoja wa rọ awọn eeyan lati wa silu Osogbo loni wa bọ Ọsun, ki wọn si kẹyin si ọrọ ti baba Ọlọsun n sọ.
Bakan naa ni o tun jẹ Olukọ ni ile iwe ẹkọ imọ nipa ọrọ okoowo ni ilu London, ki o to tun ṣiṣẹ pelu ajọ agbaye ti o gbe e de ilẹ Benin ati Italy.
O ni ọkan awọn obinrin yoo balẹ sii nidi okowo wọn lati ẹkun kan si ikeji ni eyi ti yoo mu ibugbooro ba okowo wọn sii.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Amọ kaka ki ewe agbọn dẹ ni ọrọ laasigbo oselu naa, ko ko ko lo tun n le si, ti iyapa ẹlẹyamẹya si gba ilu kan, paapaa laarin awọn ọmọ ogun ilẹ wa.
Ambode sanwo ènìyàn 50 tó há sí Russia Èsì PDP lórí bíborí Fayẹmi l'Ekiti Nàìjíríà bá RCCG, ìyá Folu Adeboye yọ ayọ̀ 70 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Ko i tii pe ọjọ melo ti awọn eeyan gba ominira pada wa si agbegbe Kukawa yii nipinlẹ Borno lẹyin ti wọn ti kọkọ sa asala fun ẹmi wọn kuro nibẹ ri.
Wọn ni igbesẹ yii da rugudu silẹ lojuko ti eto idibo abẹle naa ti n waye, ṣugbon awon ti pana aawọ naa.
Lagos Lockdown: Wo ìlànà tuntun ṣáájú ṣíṣí ilé ìtura, sinimá, gbọ̀ngàn ayẹyẹ ní Eko
Ọlọrun tí ó gbà mí lọ́wọ́ àwọn ọ̀tá mi;tí ó sì gbé mi ga ju àwọn abínú-ẹni lọ;ìwọ ni o gbà mí lọ́wọ́ àwọn ẹni ipá tí ó dìde sí mi.
 Àwọn ẹranko mìíràn gẹ ́ gẹ ́ bíi maalu , lè kó àrùn náà , kí wọ ́ n sì ní àkóràn àìsàn náà .
Mnisita ohun fikun oro re pe.
Àwọn ọmọ-ẹ̀yìn bá tún pada lọ sí ilé wọn.
COZA: A ti wọ́gilé ìwọ́de lórí COZA tí a fẹ́ ṣe tẹ́lẹ́ nítorí.
 Adura na la si maa maa gba si Olorun.
Tomasi wí fún un pé, “Oluwa, a kò mọ ibi tí ò ń lọ, báwo ni a ti ṣe lè mọ ọ̀nà ibẹ̀?
9 Ìgbé 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 11 Ìgbé 2020 Oríṣun àwòrán, Getty Images Iwadii ti awọn onímọ̀ ṣe ko ti i fihan boya itura tabi ayipada yoo de ba itankalẹ aarun coronavirus lasiko ooru.
Bakan naa lori ọrọ abo lorilẹede Naijiria, Kabiyesi naa pe fun idasilẹ Ọlọpaa agbegbe.
Ọga ọlọpaaAdamu sọ ọrọ yii ninu esi rẹ lori arabinrin kan to kọlu ọga ọlọpaa kan ni ilu Eruwa ni ipinlẹ Ọyọ.
Eré bọ́ọ̀lù, ìpàdé ìta gbangba àtàwọn nǹkan míì tó di àpatì torí Coronavirus Awọn agbẹjọro Weinstein ti tọrọ aforiji fun, to bẹ ti wọn fi sọ wi pe ẹwọn ọdun marun un fun un dabi ẹwọn gbere ni.
Anas tí ó jẹ́ akọ̀ròyin ọ̀tẹlẹ̀múyẹ́ tó máa ń da agọ̀ bojú kí wọn má bàá lé rí ojú rẹ̀, sọ pé, màgòmágó àti rìba ti ba ere bọ́ọ̀lù jẹ́ ní Ghana.
Ohun iyalẹnu ni wi pe gbogbo awọn oṣiṣẹ ti ko si ni ipele ikẹtala soke ni ko lanfani lati wọle ni ẹnu iloro.
Awọn ọmọ ìgbìmọ Eburu ti sọ fún ẹni to ni màálù náà láti lọ sún àwọn màálù náà ko ma ba fa àjàkálẹ̀ ààrùn."
''Ki wọn ma fi oju opo ayelujara maa fi doju ija kọ ara wọn'' Abdularahaman, Ọmọ ọdún 17 kó sí páńpẹ́ EFCC lórí ẹ̀sùn yahoo-yahoo ní Ibadan Bala Mohammed, Gòmínà Bauchi tó n jé ẹjọ́ lọ́wọ́ dèrò ilé ìwòsàn ní London Ìkọlù agbébọn tó ṣékú pá ọmọ ogún Niger 89, iṣẹ́ bọ lọ́wọ́ Ọgágun àgbà Ǹjẹ́ o mọ ipa tí ẹja Panla kó lásìkò ogun abẹ́lé Biafra?
Ibudo to n mojuto itankale arun ni Naijiria ti a mo si The Nigeria Centre for Disease Control (NCDC) ni ohun gbogbo ti setan fun apero olodoodun re fun todun 2018.
Usieli bí ọmọ meji: Mika, tí ó jẹ́ olórí, ati Iṣaya.
Alukoro ileeṣẹ ọlọpaa ni iyawo naa to di oloogbe, ẹni ọdun metadinlogun ko fẹ fẹ ọkunrin naa lọkọ, ṣugbọn wọn mu ni tipa tipa lati fẹ ẹ.
Ko tii si ẹni to lee sọ ni pato ohun gan ti ọkunrin naa fẹ ṣe to fi gbe ori ọmọde wa si ile aṣofin naa, bakan naa ni ko tii si ẹni to mọ ibi to ti ri ori ọhun.
''Ọpọlọpọ awọn oloṣelu n tan awọn araalu jẹ ni wọn ṣe n kuro ni ẹgbẹ oṣelu kan lọ si omiran.
O wa kesi awọn oludije fun ipo aasrẹ lati fọwọ sowọpọ sugba ẹni to ba wọle alti gbe Naijiria goke agba lati se agbekalẹ Naijiria tuntun.
Oríṣun àwòrán, Twitter Eyi n waye lai tii pe oṣu kan ti iru iṣẹlẹ naa waye, ti o si mu ẹmi eniyan mẹta lọ.
yoo foruko awon minisita rẹ ransẹ  ki ọsẹ
Ní ọjọ́ keji àjọ̀dún oṣù tuntun, ìjókòó Dafidi tún ṣófo.
" Atẹjade naa wa kesi gomina ipinlẹ Ọyọ lati lọ ka awọn akọsilẹ to tọ nipa bi wọn se n san owo osu awọn osisẹ fasiti Lautech, bi o tilẹ jẹ pe o han si awọn pe Makinde ti seleri lasiko ipolongo ibo rẹ pe oun yoo sọ fasiti naa di ti ipinlẹ Ọyọ nikan.
Iléeṣẹ́ Ọlọ́pàá ṣetán láti bẹ̀rẹ̀ ètò ìgbanisíṣẹ́ lákọ̀tun Ileeṣẹ Ọlọpaa Naijiria ti kede eto igbanisiṣẹ lakọtun bayii.
Lida kò jìnnà sí Jọpa, nítorí náà àwọn ọmọ-ẹ̀yìn Jesu ní Jọpa ti gbọ́ pé Peteru wà ní Lida.
Davido fi orúkọ bàbá rẹ̀, Adedeji, sọ ọmọ tuntun tó bí Oníbàárà tó bá fi owó ránṣẹ lórí ẹrọ ibaraẹnisọrọ yóò sanwo orí Ọdún mẹ́rin kò tó láti parí ẹ̀kọ́ ọ̀fẹ́ ní Ọ̀yọ́ - Seyi Makinde Atẹjade naa ni Mínísítà fún ìbáraẹnisọ̀rọ̀, ọmọwé Isa Ali Ibrahim Pantami kò mọ̀ nípa ìgbésẹ̀ yìí, ó sì ti pàsẹ fún àwọn to n moju to ijagaara eto ibanisọrọ ni Naijiria (NCC), láti ríi dáju pé ilé iṣẹ́ ìbánisọ̀rọ̀ MTN ṣẹ́wélé ìpinu rẹ̀, títí ti wọ́n yóò fi wá wi tẹnu wọn fún Minisità"" Àkọlé àwòrán, USSD: A ti pàssẹ fún ilké iṣẹ́ MTN láti ma gùnlé ìpinnu wọ̀n USSD Tax: Ọ̀pọ̀ ọmọ Nàíjíríà ń fapá jánú pé owó orí ti pọ̀ jù Oríṣun àwòrán, Others Ọrọ owo ori gbigba ti gba ọna miran yọ bayii nitori owo ori tun ti gun igbesẹ fifi owo ransẹ lati ori ẹrọ ibaraẹnisọrọ."
Ní ọjọ́ kejila oṣù kinni ni a kúrò ní odò Ahafa à ń bọ̀ wá sí Jerusalẹmu.
Èyí kò yọ ẹlẹsìn mùsùlùmí, onígbàgba àti àwọn ẹlẹ́sìn àbáláyé silẹ̀ pẹ̀lú.
ò ń sọ pé, o gbé, nítorí pé OLUWA ti fi ìbànújẹ́ kún ìrora rẹ; àárẹ̀ mú ọ nítorí ìkérora rẹ, o kò sì ní ìsinmi.
Ojelade ba pe ẹsa eegun titi to si ki ara rẹ dele baba rẹ Ojelarinaka ni baba naa ba tu u silẹ nigba to rii pe ọmọ oun ni.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Serena n gbero lati ṣe idije tennis f'awọn obinrin ni Afirika 6 Ẹrẹ̀nà 2018 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Serena Williams ni naa ni yoo dun mọ oun ninu ni lati kopa ninu idije tennis kan lori ilẹ Afirika Gbajugbaja elere bọọlu tennis ni, Serena Williams ti sọ wipe bopẹ boya, oun yoo ṣe eto idije WTA tennis kan ni ilẹ Afirika.
@voiceofnigeria The delectable Abiodun Koya rendering ‘Lift up Nigeria’.
Death During Sex: Àwọn nǹkan mẹ́ta tó le ṣekú pa ọkùnrin lásìkò ìbálòpọ̀ rèé
Ọkan lara awọn alakoso eto naa ni ipinlẹ Oyo, Segun Ogunwuyi lo fidi ọrọ yii mulẹ fun BBC Yoruba.
Fun awọn oludokowo Bitcoin ni Naijiria, owó Dọla nikan ni wọn le fi ṣe e.
5m péré wá, ko kópa nínú ìbò abẹ́nú fún ipò gómìnà ní Ondo àti Edo - APC kéde Àgbéyẹ̀wò àṣà: Ìdí tí Yorùbá kìí fí tufọ ikú òjìji fún èèyàn Ni bayi, wọn fi gbogbo ara sisẹ la ti le pari fẹntilatọ olowo pọọku yi ki osu karun un to kasẹ nilẹ Lorile-ede Afghanistan ti ogun ti se akoba fọpọ ọdun, wọn ko ni ju irinwo fẹntilatọ fawọn eeyan to to miliọnu mejidinlogoji le diẹ Eeyan ẹgbẹrun meje le lo ti ko arun naa ti eeyan mejidinlọgọsan si ti tọwọ rẹ dero ọrun.
Reubẹni, ìwọ ni àkọ́bí mi,agbára mi, ati àkọ́so èso agbára mi,ìwọ tí o ní ìgbéraga jùlọ,tí o sì lágbára jùlọ ninu àwọn ọmọ mi.
Ní tòótọ́, ó jí dé ibi tí wọ́n sin ọ̀rẹ́ rẹ̀ sí ó gbọ́n gbogbo yẹ̀pẹ̀ inú ibojì jáde, ó sì ṣa owó kúrò nínú ibojì.
"Bakan naa ni awujọ awọn ọmọ Naijiria to n gbe loke okun tun sọ si ọrọ naa pe: ""Ti wọn ba fi ẹsun kan eniyan, ko tumọ si pe o ti jẹbi."
Ti iru eleyii ba ṣẹlẹ, wọn le fi iru awọn obi bẹẹ jofin nitori wọn kọ lati sa ipa wọn fun awọn ọmọ wọn.
Irun orí rẹ̀ gun, ó dúdú, ó sì kun fún ípàǹtí, òṣù kan tí ó wà láàrin orí náà gùn, o sì ń kàn án ní ìdí bí o ti ń rìn lọ.
N óo sọ ọ́ di iyawo mi, lótìítọ́, o óo sì mọ̀ mí ní OLUWA.
0 31 Ilu Vatican 0 0.
Coronavirus Updates: Àì gba ìwé àṣẹ ìjọba ṣàkóbá fún sinima orítá ọmọkùnrin yìí
 ) ( ojoibi august 17 , 1952 in montgomery , alabama ) je onimosayensi ati arinlofurufu tele fun nasa ara amerika to ti lo wakati 975 ni ofurufu .
Seyi Makinde ni ohun ti n hu gbọ pe awọn eeyan kan ti n leri leka lati da rogbodiyan silẹ lọjọru , to si n rọ an igun ẹgbẹ NURTW to n se asọ, lati so ewe gbejẹ mọwọ.
Kí ló dé tí Adonija fi di ọba?
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù #StopRobbingUs: Ilé-isẹ́ ọlọ́pàá Naijiria gbọdọ̀ jáwọ́ nínú ìfìyajẹni 1 Ọ̀wàrà 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ọjọ́ 29, ní Osu Kẹ̀sán ni àwọn òsìsẹ́ onimọ̀ ẹ̀rọ parapọ̀ sọ wí pè òtógé pẹ̀lú bíí àwọn ọlọ́pàá se ń fìyàjẹwọ́n ní ọ̀na àìtọ́.
mefa naira ti won sọ pe inaki gbemi, ni ọgba awọn ẹranko ipinle naa.
igbakeji rẹ si ipo aleefa ni osu kárùn ún , ojo kọ́kàndínlọ́gbọ̀n, odun
Fadeyi ni ileesẹ ọlọpa tun ti n saayan lati se awari awọn afurasi meji mii to mọ nipa isẹlẹ naa, amọ ti wọn ti juba ehoro.
Ó fi Matanaya, arakunrin Jehoiakini jọba dípò rẹ̀, ó sì yí orúkọ rẹ̀ pada sí Sedekaya.
Eyi to sunmọ ootọ ninu ọrọ aye rẹ ni pe nilu Eko lo dagba si, ki o to kuro lorilẹede Naijiria.
Femi Fani Kayode bu ẹnu ẹ̀tẹ́ lu iwa ti agbofinro New York lorilẹ-ede America tẹlẹ, Lindsay Fairstein hu.
Ilé-iṣẹ́ agbóhùnsáfẹ́fẹ́ náà pè wọ́n láti fi ọ̀rọ̀ wá wọn lẹ́nu wò nípa ìfẹ̀hónúhàn àti ìrírí wọn fún jíjáde sí gbangba gẹ́gẹ́ bíi aṣe-ìbálòpọ̀-akọ-àti-akọ ní ẹ̀ka-ìlúu Russia.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ni Jigawa, àwọn obìnrin dáwó ra ọkọ̀ N1m láti máa fi gbé aláboyún ní iletò kan 10 Owewe 2020 Awọn obinrin kan ni ileto Bordo ni ipinlẹ Jigawa, ti da owo jọ fi ra ọkọ ti wọn fẹ maa fi gbe awọn alaboyun lọ sileewosan lasiko isẹlẹ pajawiri.
Púpọ̀ àwọn tí ó wà lórí ẹ̀rọ ayélujára gbogbo sọ̀rọ̀ lórí aìkọbì-ara sí bí ààrẹ ṣe gbé ara rẹ̀, bí ó ṣe múra àti àwọn kókó tí ilé ìṣe ìgbóhùn sáfẹ́fẹ́ ìjọba sọ̀rọ̀ lé lórí.
Mẹlikisẹdẹki ọba Salẹmu náà mú oúnjẹ ati ọtí waini wá pàdé rẹ̀.
Ayederu agbẹjọro yii ti orukọ rẹ n jẹ Elijah Ayodeji Ojo, lawọn ọlọpaa sọ pe o ti lo gbajuẹ fawọn eeyan pupọ, to si ti gba owo lọwọ wọn.
Ifẹsẹwọnsẹ to kan niwaju jẹ eleyi ti yoo pakasọ yala ti wọn ba koju Egypt tabi South Africa.
Nítorí pé wọ́n gbọ́ ọ̀rọ̀ rẹ,wọ́n sì ń pa majẹmu rẹ mọ́.
Iléeṣé MTN ti san bíliọnù N55 owó ìtanràn wọn tó kù -MTN Sẹ́nétọ̀ Dino Melaye kéde láti dupò gómìnà Kogi Akẹ́kọ̀ọ́ Poly Iree jáde láyé lẹ́yìn tó ṣubú ní gbọ̀ngàn iṣèdánwò Ni oṣu kẹta ọdun 2019 ni ileeṣẹ ọrọ ilẹ okeere ni ilẹ Amẹrika kọkọ kede igbesẹ tuntun yii lẹyin aṣẹ aarẹ orilẹede naa, Donald Trump pe ki wọn tubọ san okun ayẹwo fawọn arinrinajo si orilẹede naa ko gbopọn sii.
Ó kúrò níbẹ̀, ó sì lọ ń gbé inú ihò àpáta kan tí ó wà ní Etamu.
Iroyin so pe, ogunlogo awon omo-orile-ede Ethiopia lo kora jo lati sajoyo ijagbara ogun Adwa lowo awon amunisin Italy.
odù náà jẹ ọken nínú àwọn ìyàwó ọ ̀ rúnmìlà tí o ko orire ràn án .
Adeleke: APC ní ìdájọ́ ileẹjọ́ kòtẹ́milọ́rùn kò fún Adeleke ní ìrètí kankan
com/cSa1icAaeb— 🇳🇬 Super Eagles (@NGSuperEagles) June 5, 2018Super Eagles yoo kuro ni Essentuki, ti n se ipago iko ohun leni laago meta aabo lo si Kaliningrad ti ifesewonse naa yoo ti waye.
Ìdìde yín ń mu kí ọmọ ẹlòmíràn fẹ́ kí òun dìde, ìsọ̀rọ̀ yín ń mú kí ọmọ ẹlòmíràn fẹ́ sọ̀rọ̀, ijókòó yín mu kí ọmọ ẹlòmíràn fẹ́ jkókòó, ìrìn ẹsẹ̀ yín sì dàbí ẹni pé kí ènìyàn máa fi ẹsẹ̀ rìn láéláé ni.
8 24963 Orilẹede Finland 442 8.
Britain: Ọmọ-ogun 8200 la fẹ́ gbà láti orílẹ̀-èdè Commonwealth
Bayii coronavirus ti de orilẹ-ede mẹwaa din ni igba ni gbogbo agbaye.
Bonaparte gbagbọ pe ti obinrin ba ṣe iṣẹ abẹ lati sun idọ rẹ mọ oju ara, itura ibalopọ 'orgasm' yoo wa.
Sugbọn sa, Ọga Agba nileesẹ ologun to wa ni ipo Colonel tabi eyi to jọ ọ, to si jẹ ọmọ ipinlẹ rẹ naa le ba ọ buwọlu dipo Alaga ijọba ibilẹ.
Wọ́n jí àwọn ọmọbìnrin náà ní ìlú Toumour tó wà ní ẹnu ààlà orílẹ̀èdè náà àti Nàìjíríà ní ọjọ́ Àbámẹ́ta, gẹ́gẹ́ bí alákóso ilú Toumour náà ṣe fìdí ọ̀rọ̀ ọ̀hún múlẹ̀ fún iléeṣẹ́ ìròyìn Reuters.
Lẹ́yìn náà ó sọ Josẹfu ní orúkọ Ijipti kan, orúkọ náà ni Safenati Panea, ó sì fi Asenati, ọmọ Pọtifera, fún un láti fi ṣe aya.
Bẹ́ẹ̀ ni ọkunrin náà bọ́ aṣọ rẹ̀ sọ sí apá kan, ó fò sókè, ó bá lọ sí ọ̀dọ̀ Jesu.
Bakan naa, minisita to n ri si eto iroyin, Mathok Wal so pe
Amọ Ọsanyintolu ko tii lee sọ boya ẹmi kankan ba isẹlẹ naa rin abi iye dukia to ti sofo.
Òògùn ikọ́ olómi tó ní èròjà codeine - ibití wàhálà rẹ̀ dé Bí Codeine je oògùn ara ríro náà ni wọn ń lòó gẹ́gẹ́ bí i egbògi olóró ní èyí tí àpọ̀jù rẹ lè fa àrùn ọpọlọ àti ki ẹ̀yà ara kọ iṣẹ́.
N óo pa àwọn ìlú tí wọ́n wà lórí ilẹ̀ yín run, n óo sì wó ibi ààbò yín lulẹ̀.
Ijoba apapo Naijiria ti gba pe aadofa akekoobinrin lo ti di awati kuro nile iwe Government Science and Technical College to wa ni Dapchi, nipinle Yobe leyin ti awon onise ibi boko haram lo sile iwe naa lojo Aje, ojo Kokandinlogun osu keji odun yii lo ji won ko.
Èmi ni mo dúró láàrin ẹ̀yin ati OLUWA nígbà náà, tí mo sì sọ ohun tí OLUWA wí fun yín; nítorí ẹ̀rù iná náà ń bà yín, ẹ kò sì gun òkè náà lọ.
com Salah gba goolu kan wọle eyi to jẹ ọgọrun goolu rẹ ni idije Premiership ṣugbọn alayo meji meji ni Liverpool at Everton ta.
Ilé ìpàdé àwọn Juu kan wà níbẹ̀.
Violence against women: Ìjọba pàṣẹ lọ rọọ́kún nílé fún òṣìṣẹ́ káńsù tó lú obìnrin kan ní ìpínlẹ̀ Ogun nítorí ìséde
Wo ọ̀nà àbáyọ sí bo ṣe ń han‘run Bi Oluwo se n salaye tirẹ, naa ni awọn ijoye, afọbajẹ ati araalu lapapọ ko sinmi lori awijare tiwọn naa, ti laasigbo naa si n fọnna soju lojoojumọ.
Ikede iku ọba naa ko ti waye nitori pe awọn to yẹ ko ṣe ni o ni awọn etutu kan to yẹ ni ṣiṣe k'awọn to kede iku rẹ faraye.
Aare no o seni laanu pe
Oríṣun àwòrán, @D_Aruwajoye Àkọlé àwòrán, Ọba Adesoji Aderemi pelu Ọba Olateru-Olagbegi kejì n'ilu London lọ́dún 1953 Ọba alaye yìí, akanda Olódùmarè padà lo ọdún márùn-ún lórí ìtẹ́ lẹ́yìn tó padà dé orí òye lẹẹkeji, Kò tó dara pọ mọ àwọn baba ńlá rẹ ni ọdún 1998, tí kò sì jẹ ki àsọtẹ́lẹ̀ ifa kẹta sẹ, àmọ́ ọmọ rẹ, Victor Folagbade Olateru-Olagbegi Kẹta jọba lẹ́yìn rẹ.
'Ọmọ Naijiria 25,794 ló kú sí rògbòdìyàn láàrin ọdún mẹ́rin' Owó wọgbó!
Ẹ kọ orin tuntun sí OLUWA;ẹ kọ orin ìyìn rẹ̀ láti òpin ayé.
Jeremaya dá gbogbo àwọn eniyan náà lóhùn, pataki jùlọ àwọn obinrin, ó ní, “Ẹ gbọ́ nǹkan tí OLUWA sọ, gbogbo ẹ̀yin ará Juda tí ẹ̀ ń gbé ilẹ̀ Ijipti, 
Ìwé ìfowópamọ́ rẹ̀ tí Akin Olúṣínà rí lọ́wọ́ Kọ́lá náà tún wà lára ohun tí ó ran Akin Olúṣínà lọ́wọ́.
Akitiyan ṣi n lọ lọwọ lati kan si awọn agbofinro lori ibi ti iṣẹ iwadii de duro lori iṣẹlẹ ọhun.
O ni ìbí ko gbọdọ ju ibi nitori aṣa to fawọn ọkunrin lagbara lati dẹnu ifẹ kọ obinrin nigba ti o wu wọn naa lo yẹ ki obinrin ni lati dẹnu ifẹ kọ ọkunrin to wuu.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Ṣùgbọ́n wọn ní pe o jẹ owo ori, ejò yìí ni wón ṣe leyin rẹ tí wọn sì ju sì ẹwọn ọdún méje ni inu osu Kẹ̀wá ọdún tó kọjá.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Bode George: òòtọ́ ni ìkìlọ̀ Obasanjọ ati Soyinka Òun ní ẹni tó kéré jù lọ tó sì gba àmì ẹ̀yẹ ní òrílẹ̀-èdè Ghana Children's Day: Àwọn ọmọde tó ti bẹ́bẹ́ láwùjọ Afíríkà Kò sí àyè fún fíìmù eré ìfẹ ṣíṣe ni Kannywood mọ́ Kí ló yẹ kí Àyájọ́ ọjọ́ àwọn èwe Nàìjíríà lọ́dún yìí dá lé lórí?
Àwọn kan dúró lẹ́bàá òkun dígí náà, àwọn tí wọ́n ti ṣẹgun ẹranko náà ati ère rẹ̀, ati iye orúkọ rẹ̀.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Micheal Jackson Vs Beyonce: Àwọn èèyàn sọ ẹní tó jẹ ọgá láàrín olórin méjèèjì 22 Ìgbé 2019 Ki a ma ṣebi ẹni pe a ko ri ohun tawọn eeyan n sọ lori ayelujara lori ọrọ to n ja rain rain pe, taa lọga laarin oloogbe Micheal Jackson ati Beyonce, lo mu wa fi ibeere sita.
Gbogbo aṣọ ati awọ tí nǹkan ọkunrin náà bá dà sí gbọdọ̀ jẹ́ fífọ̀, kí ó sì jẹ́ aláìmọ́ títí di ìrọ̀lẹ́.
Ọrun àwọn alágbára dá,ṣugbọn àwọn aláìlágbára di alágbára.
Àwọn fíìmù tí ó kọ ́ kọ ́ jádé máa ń fi àṣà yorùbá hàn sí gbogbo àgbáyé nítorí wí pé àwọn tí wọ ́ n ń ṣe fíìmù nígbà náà gbà wí pé ọ ̀ nà kan tí àwọn lè gbà láti jẹ ́ kí àwọn ará ìlú òkèèrè ó gba fíìmù yorùbá gẹ ́ gẹ ́ bí iṣẹ ́ tí ó kúnjú òṣùwọ ̀ n ni láti fi ạ ̀ ṣà àti ìṣe wa hàn nínú eré náà .
Àjẹ́ àti Aṣẹ́wó ní ìyá Rainbow - Òjòpagogo Mo kọ̀ láti kópa nínú ìpàdé orí ayélujára Nàìjíríà yìí- Falz Irọ́ ni pé wọ́n hú òkú Kolawole Gold lórí pẹpẹ ìjọ ọkọ mi- Bisola aya Sotitobire Cardi B ṣàlàyé ohun tó gbé fọ́tò ìhòhò rẹ̀ d'órí ayélujára Instagram Ẹ ṣọ́ra ní òpópónà AIT, ọkọ̀ agbépo kan ti yí dánù lọ́nà agbègbè Alagbado Ajínigbé tú ìyá àti ọmọ ọdún mẹ́ta sílẹ̀ lẹ́yìn tí wọ́n gba ₦1.
Azeezat Shomuyiwa : Oyún oṣù méje ló wà nínú Azeezat, kí wọ́n tó f'òkúta fọ́ ọ lórí pa
ojo kẹ́sán án , osu  kárùn ún,odun
Èèyàn 20 ni coronavirus pa l'Ọ́jọ́bọ nìkan Oríṣun àwòrán, Bigbrother Naija/Africa Magic Wo ohun tó yẹ kí o mọ̀ nípa Laycon, akẹ́kọ̀ọ́jáde UNILAG tó ń kópa nínú BBNaija 2020 Laycon BBNaija 2020: Olamilekan ló pegedé jùlọ ni ẹ̀ka ìmọ̀ Phyilosophy ní fásitì UNILAG lọ́dún 2016 Ọkan lara awọn olukopa ninu idije BBNaija 2020, Olamilekan Agbeleshe ti inagijẹ rẹ n jẹ Laycon ni ẹni to pegede julọ ni ẹka imọ Phyilosophy ni fasiti ijọba apapọ to wa ni ipinlẹ Eko, UNILAG, lọdun 2016.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: A jọ ṣe ìyàwó pọ̀, a jọ bímọ ní ọjọ́ kan náà, a tún jọ máa ń ṣàìsàn pọ̀ ni Òkè Idanre rèé tí odidi ìlú kan ló ń gbé lórí ẹ̀ Ìyàwó mi fẹ́ràn ìrìnàjò òfurufú ni mo ṣe kọ́ ilé Bàálù yìí fún un Omi ìṣẹ̀ńbáyé tó ń dà ní Ówù rèé, èyí tó ga jùlọ ní Afirika 'Ǹkan tó jẹ́ kí iṣẹ́ ọ̀nà tèmi yàtọ̀ lágbàáyé ni ǹkan tí mò ń lò' Mo ti sọ ìran nípa ọkọ aképo tó gbiná ní Onitsha kó tó ṣẹlẹ̀ - Primate Ayodele Àlá àwọn òjíṣẹ́ Olúwa tó fẹ́ jẹ ààrẹ Nàíjíríà leè má ṣẹ lógún ọdún - Abiara Etu ni ọmọ mẹfa ni fasiti, ti ọkan yoku si wa nile ẹkọ girama, idi isẹ gbogbo elere, taa mọ si DJ yii si lo ti n ri owo gbọ bukata wọn.
Ninu ọrọ ti Olafare sọ, o ni ki awọn to ba n ṣiṣẹ akọroyin ri pe, wọn tẹle ilana iwadii ọfintoto, ki wọn to gbe iroyin jade.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, LASTMA: Ẹ̀rí la nílò láti fi òsìsẹ́ tó ń gba rìbá jófin Àyẹ̀wò DNA bẹ̀rẹ̀ lẹ́yìn ìjàmbá iná Eko Àwọn ọmọ tó há sínú ilẹ̀ ti jáde!
Lara awon to wa nibe naa ni awon alamojuto  ajo INEC fun ekun Oyo, Osun ati Ekiti, Omo’ba
Ọwó pálábá tọkọtaya tó ra ọmọ méjì ní ₦140,000 ségi Oríṣun àwòrán, Nigeria Police Ki lo le mu ki eeyan kan ra ọmọ lọmọ pẹlu erongba lati tun wọn ta?
Ninu atẹjade kan ti Minisita fun alumọọni eporọọbi, fi sita, o sọ pe owo eporọọbi ti ja walẹ kọja nkan to yẹ ko jẹ fun tita epo bẹtiro ti wọn gbe wọle.
Arakunrin ọkọ rẹ̀ ni ó gbọdọ̀ ṣú u lópó, kí ó sì máa ṣe gbogbo ẹ̀tọ́ tí ó bá yẹ fún obinrin náà.
Iwadi ti BBC News,Yoruba se loni, tifi idi re mulẹ wipe, ni ijọba ibilẹ̀ Lagelu ati ijọba ibilẹ̀ Ariwa-Ibadan, awọn akẹ́ẹ̀kọ́ ko lọ sile iwe, bẹ́ẹ̀ si ni awọn olukọ́ ko kuro nile wọn.
Ajá naa ti orukọ rẹ n jẹ Ping Pong lo n gbẹ ilẹ, to si n gbo ni ori papa kan nitosi abule Ban Nong Kham, nigba to ṣakiyesi ẹsẹ ọmọ naa to yọ sita.
" kọmísọ́nà lo sọ bẹ́ẹ̀ O ní bi kò ṣe si èròjà àyẹwò yìí, eyi ko dá àyẹwò dúró, sùgbọ́n ka ni a wà lọ́pọ̀ ni ayẹwò ko ba jù bẹ́ẹ̀ lọ.
Apapo ibo ti won di ohun ni; ẹgbẹ̀ta le méjílélọ́gọ́rin o le die lẹ̀ẹ́dẹ̀gbẹ̀rin(Total vote cast 714,682).
Bíṣọ́ọ̀bù ń lá ata ìyàwó àlùfáà abẹ́ rẹ̀ l'Ekiti Ṣé lóòtọ́ ni pé Aisha Buhari ti kó lọ sí Dubai?
Afurasi naa, Shagbada Erigga, jẹwọ pe lootọ ni oun hu iwa ọdanran yii nigba ti wọn fi oju rẹ atawọn afurasi mejilelọgbọn miran han.
abenugan nile igbimo asofin ti ajo ECOWAS laarin odun merin.
Ó sábà maa ń ràn nípa jíjẹ tàbí mímu oúnjẹ tàbí omi ẹlẹ ́ gbin tí ó ní ìgbẹ ́ àkóràn .
Jakọbu yẹ̀ ẹ́ wò, ó sì wí pé, “Ẹ̀wù ọmọ mi ni, ẹranko burúkú kan ti pa á, dájúdájú, ẹranko náà ti fa Josẹfu ya pẹ́rẹpẹ̀rẹ.
Wọn pe ọlọpaa si ibi ti iṣẹlẹ naa ti waye nigba ti awọn aladugbo ri wipe ija bẹ silẹ ni Welbeck Road ni agbegbe Barnet ni alẹ ọjọ Iṣẹgun.
Joṣua bá dá majẹmu pẹlu àwọn eniyan náà ní ọjọ́ náà, ó sì ṣe òfin ati ìlànà fún wọn ní Ṣekemu.
Ṣé lójú tiyín, ilé yìí, tí à ń fi orúkọ mi pè, ó ti wá di ibi ìsápamọ́ sí fún àwọn olè?
Adeola Adedipe lo n ṣoju ọkan lara awọn ti wn pe lẹjọ iyẹn ileeṣẹ Maina Common Input Property and Investment Ltd lori ẹsun ikowojẹ ti wọn fi kan Maina.
Muhammadu Buhari gege bi oludije fun ipo aare  egbe naa fun eto idibo to n bo lọdun 2019,
- Lori afara ati ni awọn opopona abẹ titi abẹlẹ.
Ọgbẹni Ikoro fikun ọrọ rẹ pe obinrin ati ọmọ rẹ naa wa lara awọn to ku ninu ijamba ọkọ naa.
Gbogbo igbiyanju wọn lati fi ọrọ wa afurasi naa lẹnu wo lo ja si pabo, nitori n se lo bẹrẹ si ni se bii ẹni to ni arun ọpọlọ.
Gbajugbaja onkorin omo bibi orile-ede Senegal– Amerika, Akon ti darapo mo ogunlogo awon omo orile-ede Ethiopia lati sayeye odun méjìlélọ́gọ́fà ijagbara ogun Adwa ti o waye lodun 1896.
Àwọn tí ń gbé aṣálẹ̀ yóo máa foríbalẹ̀ fún un;àwọn ọ̀tá rẹ̀ yóo sì máa fi ẹnu gbo ilẹ̀ níwájú rẹ̀.
Wọ́n ti fòfin ọdún márùn ún de Aàrẹ̀ CAF, Ahmad Ahmad Oríṣun àwòrán, Twitter screenshot Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí 10:17 Fídíò, Oba Adedokun Abolarin ti Oke Ila: Ó ya ọ̀pọ̀ tó súnmọ́ mi lẹ́nu bí mo ṣe ń kọ́ àwọn akẹ́kọ̀ọ́ pẹ̀lú ipò Ọba, Duration 10,1723 Bélú 2020 Fídíò, The New Pandemic: Kíni àwọn onímọ̀ sáyẹ́ńsì ń sọ nípa rẹ̀?
Mò ń kọ orin ọpẹ́ sókè,mo sì ń ròyìn iṣẹ́ ìyanu rẹ.
Kò dájú gẹ́gẹ́ bi ọ̀jọ̀gbọ́n náà ṣe sọ.
Ni ọkunrin tí ẹ̀mí burúkú wà ninu rẹ̀ bá fò mọ́ wọn; ó gbé ìjà ńlá kò wọ́n, ó sì ṣẹgun gbogbo wọn, ó ṣe wọ́n léṣe tóbẹ́ẹ̀ tí wọ́n fi sá jáde ninu ilé náà ní ìhòòhò, tàwọn ti ọgbẹ́ lára.
Ta ni kò mọ̀ ninu gbogbo wọnpé OLUWA ló ṣe èyí?
Àwọn obinrin wọnyi a sì máa pè wọ́n lọ síbi àsè ìbọ̀rìṣà.
Àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ bẹ̀rẹ̀ sí wo ara wọn lójú; nítorí ohun tí Jesu sọ rú wọn lójú.
Wa ọna orisi lati fi ṣe iṣẹ rẹ: Fun ọpọ eeyan nise ni ọjọ yoo dabi ẹni pe ko fẹ tan.
Obasanjo, Fayose ṣe'pade pẹlu aare Buhari l'Abuja
kinni osu keta lati lee soro lori ibasepo laarin ila oorun ati iwo oorun
Lawan  omowe Yahaya Abdullahi, lati ila
Ninu ifọrọwerọ rẹ pẹlu BBC, Munira, ẹni ọdun mejilelogun ati Khadija, ẹni ọdun mẹẹdọgbọn, ti wọn jẹ mususlumi salaye pe ode ijo naa ba ilana ẹsin Islam mu, eyi to faramọ ki awọn ọkunrin maa da wa loju kan.
toju bọ gbogbo ibi ti awọn ọdanran ba wa ṣaaju idibo naa.
Abuja Protest: À ń ṣe ìwádìí lórí àwọn obìnrin tí wọn mú nítorí aso péńpé
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Tola Oyediran: Buhari, Makinde, Sanwo-Olu ń ṣèdárò Tola Oyediran ọmọ Obafemi Awolowo tó papòdà 16 Ọ̀wàrà 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 17 Ọ̀wàrà 2020 Oríṣun àwòrán, Tribuneonline Ọpẹ eekan lagbo oṣelu lo ti n ranṣẹ ibanikẹdun si ẹbi mama Tola Oyediran tii ṣe akọbi obinrin Oloye Obafemi Awolowo to jade laye lọjọ Ẹti.
Amotekun: Akeredolu ní àwọn iléeṣẹ́ aláàbò ni yóò ṣèdánilẹ́kọ̀ọ́ fáwọn ẹ̀sọ́ náà
Nígbà tí àwọn wundia péjọ ní ẹẹkeji, Modekai jókòó ní ẹnu ọ̀nà ààfin.
Oun lo kọkọ gba bọọlu sáwọ̀n Netherland ninu idije aṣekagba naa ni papa iṣere Lyons eleyii to sọ USA di olu ọmọ ninu idije naa.
“Sọ fún àwọn ọmọ Israẹli pé, nígbà tí ọ̀kan ninu yín tabi àwọn ọmọ yín bá di aláìmọ́ nítorí pé ó fi ọwọ́ kan òkú; tabi ó wà ní ìrìn àjò, ṣugbọn tí ọkàn rẹ̀ sì fẹ́ ṣe Àjọ̀dún ìrékọjá.
daran-daran ati agbẹ lorile ede Naijiria.
Sc Ẹngineering Analysis) iwe ẹri PGD ninu imọ ọrọ aje nipa epo rọbi, Petroleum Economics ati imọ ijinlẹ akoso okoowo, MBA.
16 Nítorí kíyèsíi, èmi, Ọlọ́run, ti jìya àwọn ohun wọ̀nyí fún gbogbo èniyàn, pé kí àwọn má baà jìyà bí wọ́n bá lè ronúpìwàdà;
Àwọn alẹ́nulọ́rọ̀ tó bá BBC Yoruba sọ̀rọ̀ sọ pé irúfẹ́ èyí kò leè ṣàì wáyé bí ìdìbò 2019 ṣe ń súnmọ́ etílé.
Hema Malini, òṣèré Bollywood n léwájú nínú ìbò India ‘Bi Gomina Ajimobi se yan adarí òsìsẹ́ tuntun ní Oyo kò dí wa lọ́wọ́’ Wọ́n jí ọmọ yìí gbé láti máa fi tọrọ bárà l'Eko Lẹ́yìn igbe Atiku, Ààrẹ Ilé Ẹjọ́ kòtẹ́milọ́rùn yọra rẹ̀ nínú ìgbẹ́jọ́ èsì ìdìbò ààrẹ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Contortionist: Mo lè gbé ìfun mi pamọ́ ki n tún se èémí!
Nípa ti Òfin Mose, Farisi ni mí.
  Ara igi yìí la ti ń rí ẹmu funfun tí ṣe ògùrò tí àwọn àgbà ò jẹ́ fi ṣàwàdà.
Coronavirus in Nigeria: Ọmọ Nàìjíríà kan ṣàlàyé pé nǹkan ò dẹ̀rùn láyé coronavirus yí ní orílẹ̀èdè Italy
Oke ni ki ọdaran ọhun lọ fi ẹwọn jura fun ọdun mẹrin gbako lẹyin to jẹwọ pe oun jẹbi ẹsun naa ti wọn kan an.
Nígbà tí o lọ síwájú díẹ̀ ó tún padà sẹ́yìn nígbà tí o sì ń bọ̀ lẹ́ẹ̀kejì nì, tí ó tún gbé ojú sókè, A!
 Bee si ni awon miran so pe, awon eniyan ti o n fi ehonu won han ni o wa ni idi ikolu naa.
- Ẹ lọ ṣe àkíyèsí àwọn ewé orí igi, kí ẹ wo ìlà kéékèèkéé tí Ọlọ́run Ọba fi sí ara wọn, ẹ lọ wo àwọn ẹranko inú igbó, bí wọ́n ti pọ̀ tí wọ́n lágbára tí wọ́n ń bá ọ̀nà tí Ẹlẹ́dàá wọn fi ẹsẹ̀ wọn lé lọ, ẹ kíyè sí ogunlọ́gọ̀ ejò tí ń bẹ ní inú ayé, ẹ wo àwọn kòkòrò bí wọ́n ti pọ̀ tó, ẹ wo onírúurú ẹja, ẹ wo ọ̀pọ̀lọ́ tí ń gbé orí ilẹ̀ tí ó tún ń gbé inú omi.
Gẹgẹ bi igbakeji Supretendenti to tun jẹ agbẹnusọ ọlọpaa, Anjuguri Manzah ṣe fi aridaju rẹ han fun akọroyin BBC to ba a ni gbolohun lori ẹrọ ibanisọrọ, wọn ti gbe e lọ si ile ẹjọ.
Kọmisọnna to n moju to eto idasilẹ ati ikọni ọjọgbọn Daud Sangodoyin, lo sọ eyi di mimọ nilu Ibadan lasiko to n ba awọn akọroyin sọrọ lori abajade ipade igbimọ alasẹ ijọba ipinlẹ Oyo.
 ( born april 14 , 1969 ) jẹ ́ olùdarí ètò ní orí wabc ìkànì kéje ( channel 7 ) .
Oríṣun àwòrán, AFP/Getty Images Àkọlé àwòrán, Ẹgbẹ awọn ajafẹtọ ti pinnu lati tubọ se iwọde lowurọ ọjọọru kani ijọba o tu akọroyin naa silẹ Lati ọdun 2015 ti ijọba Muhammadu Buhari to wa lode bayii lorilẹede Naijiria ti gori oye, ko din ni oniroyin marundinlogun ti wọn ti fi si ahamọ.
 Coach Gernot Rohr treated the topic of Mikel’s playing position on the pitch.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù VAT: Kò sí àǹfàní kankan tí ìjọba ti ṣe fún mi sẹ́yìn Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ VAT: Kò sí àǹfàní kankan tí ìjọba ti ṣe fún mi sẹ́yìn 1 Owewe 2019 O yẹ ki ijọba ṣaanu awọn eniyan lasiko yii ni ero awọn kan.
Tí ilẹ bá sì ti mọ,ní wọn yóò padà sí inu atibaba wọn tó wà ní ilu Mina, níbí ti wọn yóò ti lọ sọ oko mọ Asetani ní Jamrah ti a ṣàlàyé ṣaaju.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù NSCDC/Police Clash: Ìwádìí nípa ikú òṣìṣẹ́ NSCDC tí ọlọ́pàá lù níwájú ìyàwó àti ọmọ ti jáde 15 Ìgbé 2019 Lẹyin ọ̀sẹ mẹ́rin ti iròyìn kan bi awọn ọlọ́pàá Nyanya nilu Abuja ṣe mu oṣiṣẹ NSCDC kan, Ochigbo Ogah, fun riru ofin oju popo, ti wọn si lu u titi ti wọn fi wọ ọ lọ agọ wọn nibi to ti gbẹmi mi, iwadii ti fi han wi pe, ṣe ni ẹjẹ da si i ni ọpọlọ lẹyin ti wọn fi nkankan lu u lori.
Jesebẹli, aya rẹ̀ dá a lóhùn pé, “Họ́wù!
Jọ̀wọ́, ṣá ti gbà wá kalẹ̀ lónìí ná.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ The New Pandemic: Kíni àwọn onímọ̀ sáyẹ́ńsì ń sọ nípa rẹ̀?
Nibayii awọn ọmọ orilẹede Naijiria kan ti n ta ohun si ara wọn lori ikanni ayelujara Twitter, lori boya o tọna ki Tinubu du ipo aarẹ ni ọdun 2023 tabi ko tọna.
Ìjọba ló ń ṣe kóríyá fún àlàfo ńlá láàrin ọlọ́rọ̀ àti mẹ̀kúnnù - Oxfam Dúkìá àti ọkọ̀ jóná, ọlọ́pàá mẹ́sàn-án fara gbọta lásìkò ìwọ́de Shiite Iṣu ló wà nínú mọ́tò mi, kìí ṣe èèyàn ni mo sọ di iṣu - Afurasí Ajínigbé figbe ta Ìlú tí ọ̀daràn bá tí dẹ́ṣẹ̀ ló yẹ kí wọn tí gbẹjọ́ rẹ̀ -Agbẹjọ́rò Igba mẹrinla ni Naijiria ati South Africa ti pade ara wọn.
Ni ilu Port Harcourt, eefin ileeṣẹ epo rọbi ti di ohun ti awọn ara ilu fi n ke gbajare si ijọba, ṣugbọn ọrọ naa ko ti i ni iyanju.
Nígbà tí ẹ bá gbin ohun ọ̀gbìn ní ọdún kẹjọ, ẹ óo tún máa rí àwọn èso tí ó ti wà ní ìpamọ́ jẹ títí tí yóo fi di ọdún kẹsan-an, tí ilẹ̀ yóo tún mú èso rẹ̀ jáde wá, àwọn èso ti àtẹ̀yìnwá ni ẹ óo máa jẹ.
A bí Kọ́lá Akínlàdé ní ọdún 1924, ní ìlú Ayétòrò ní ìpínlẹ̀ Ògùn ní ilẹ̀ Nàìjíríà.
 asiwaju pataki ati adoroso , churchill tun je ogagun ni ise adogun britani , onitankiko , olukowe ati asona .
Kola Olagbegi ni tirẹ di ẹbi ipenija aabo ru awn alaṣẹ ti ko munadoko.
“Ó ṣe àlàyé rẹ̀ fún mi báyìí pé: ‘Ẹranko kẹrin ni ìjọba kẹrin tí yóo wà láyé, tí yóo sì yàtọ̀ sí gbogbo àwọn ìyókù.
Ọmọkùnrin mi ti kó coronavirus, ẹ bá mi fi sínú àdúrà yín- Atiku Ẹ fi adura ranmi lọwọ nitori ọmọkunrin mi ti lugbadi arun coronavirus to n tan kalẹ kaakiri agbaaye bi ina inu ọyẹ.
Atẹjade kan tí ilé ìwòsàn UCH wá fi síta lẹ́yìn abẹwo naa ni lóòótọ́ nile ìwòsàn náà ń tọju afurasi alárùn Covid-19 kan lọ́wọ́ àmọ́ wọn ṣẹ̀ṣẹ̀ fi ayẹwo rẹ ransẹ sì ikọ ìjọba tó ń ṣe ayẹwo àrùn Coronavirus ni.
” Joṣua bá na ọ̀kọ̀ ọwọ́ rẹ̀ sí ọ̀kánkán ìlú náà.
Igbakeji adari eka igbohunsafefe fun ise akanse Operation Lafiya Dole, balogun Onyema Nwachukwu, lo so oro naa di mimo lasiko to  n ba awon akoroyin nilu Maiduguri.
Kí ló ń fa ìjàmbá omíyale ní Naijiria?
Ọba yìí sì tún fún un lésì, ó ní, Jọ̀wọ́ má ṣàìjẹ́ kí n mọ nǹkan tí ń ṣe ó, nítorí a kì í mọ̀, Ọlọ́run lè ní kí n tó ẹni tí ń ṣe ìrànlọ́wọ́ fún ọ.
” Minisita to n mojuto oro abele ogagun Abdulrahaman Danbazzau lo lo soju aare Buhari ninu ipade ohun.
O si maa n ko to ogoji eniyan dani lọ fun irinajo kọọkan to ba n lọ, wọn si le na to ẹgbẹrun mejidinlaadọta le ni ẹẹdẹgbẹta Dọla l'ọjọ kan.
Fayemi: Gbèsè tí mo bá nílẹ̀ ni kò jẹ́ kí n ti yan kọmíṣọ́nà Agbébọn pa ènìyàn 14, ọmọọ̀gun Naijiria sígun ni Kaduna Kíni yóò sẹlẹ̀ sí àwọn òsìsẹ́ Diamond Bank?
Iwadii si fi han pe oludije kan ti orukọ rẹ n jẹ Kanye Deez Nutz West"" fi orukọ silẹ lati dije labẹ asia ẹgbẹ oṣẹlu ""Green Party"" lọdun 2015."
Amọ, bo ṣe n kọ eyi naa lo tun n kọ imọ nipa aṣa ati ẹsin Yoruba lọdọ baba baba rẹ.
" O ni aṣa lasan ni ọpa aṣẹ naa, ko si da iṣẹ ijọba duro nitori ile igbimọ naa le lọ wa ọpa aṣẹ miran.
Oríṣun àwòrán, Comfort Fajemirokun Ẹni ọdun mọkanlelaadọta pere ni Henry Oloyede Fajemirokun nigba to lọ sọrun ọsan gangan.
Lẹsẹkẹsẹ, Anderu rí Simoni arakunrin rẹ̀, ó sọ fún un pé, “Àwa ti rí Mesaya!
Ìgbé ayé Abiola Ajimobi nínú àwòràn pẹ̀lú àwọn ǹkan tó ṣẹlẹ̀ Ìgbà mẹ́jọ tí awuyewuye wáyé lórí ìṣèjọba Ajimobi Yàtọ̀ sí coronavirus, wo ìgbà mẹ́wàá míì táwọn mùsùlùmí kò lè ṣiṣẹ́ Hajj Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Mobile Wash: iṣẹ́ fífọ́ mọ́tò tà ni mó yàn láààyò- Slay Mama Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 3 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 5 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Níbo ni mo lè sá lọ, tí ẹ̀mí rẹ kò ní sí níbẹ̀?
Ṣé ẹ fẹ́ máa jalè, kí ẹ máa pa eniyan, kí ẹ máa ṣe àgbèrè, kí ẹ máa búra èké, kí ẹ máa sun turari sí oriṣa Baali, kí ẹ máa bọ àwọn oriṣa tí ẹ kò mọ̀ káàkiri; 
Oríṣun àwòrán, Instagram/queen__aanu Mo kọ lati maa gbe ninu igbekun, maa si sa gbogbo ipa mi gẹgẹ bo se wa labẹ ẹtọ ti mo ni lati wa ni ominira."
Ọjọ́bọ̀ la ó mọ̀ bóyá a ní Coronavirus - Aṣòfin Ondo Aisan iba ni gomina Akeredolu kọkọ sọ pe oun ni to si n tọju ni nkan bii ọjọ diẹ sẹyin.
Oun lo jẹ akọbi ọmọ Mohammed Yusuf, iyẹn oludasile Boko Haram ti wọn pa ni ọdun 2009.
Àbẹ̀wò Buhari sí Eko: Àwọn ọ̀nà láti yàgò fún àyàfi tí ẹ ba gbé ibùsùn dání
Ẹwẹ, Ileeṣẹ ipolowo ọja loju opo Twitter wọn lawọn ti wọgile iwe aṣẹ ileeṣẹ Provision Media System to ni ọkọ naa.
Nítorí náà, mo bínú sí ìran wọn.
“Iye awon ti yoo je anfaani
Bí OLUWA bá na ọwọ́, tí ó bá gbá wọn mú,ẹni tí ń ranni lọ́wọ́ yóo fẹsẹ̀ kọ,ẹni tí à ń ràn lọ́wọ́ yóo ṣubú;gbogbo wọn yóo sì jọ ṣègbé pọ̀.
Amọ nigba to n fesi si awuyewuye araalu lori igbesẹ ijọba naa, agbẹnusọ fun aarẹ Muhammadu Buhari , Bashir Ahmad ni ko si ohun to jẹ pataki lori eyi.
8 Áà, ìran aláìgbàgbọ́ àti ọlọ́rùn líle yìí—ìbínú mi ru sókè sí wọn.
Gẹgẹ bi awọn onwoye oselu Naijiria ti se sọ, Aarẹ Buhari kii da si ọrọ aawọ to ba n waye laarin awọn ọmọ ẹgbẹ APC.
Bí ó ti ń sọ̀rọ̀ lọ́wọ́, ìkùukùu kan tí ń tàn bò wọ́n mọ́lẹ̀.
Ó ṣe abọ́ bàbà ńlá mẹ́wàá, ọ̀kọ̀ọ̀kan gba igba galọọnu, ó sì jẹ́ igbọnwọ mẹrin.
Fayemi sọ eyi gẹgẹ bi esi si iroyin kan to n tan ka pe awọn ọmọ ẹgbẹ kan fẹ yọ Adams Oshiomole loye gẹgẹ bii alaga APC.
Aare gboriyin fun igbese ipinle Kaduna, fun lilo awon orisirisi irinse igbalode lati tun fi dojuko ipenija to n koju eto aabo wa.
Coronavirus ti di ara wa, kò le è kúrò mọ láéláé - WHO Coronavirus cases in Africa- Atọ́nà bí nkàn ṣe ń lọ ní Afirika Ènìyàn 339 ló ní àrùn Coronavirus ní Ọjọ́ọ́bọ̀ ní Nàíjíríà Loṣu kẹta to lọ ni Ọgbẹni Tedros Adhanom Ghebreyesus to jẹ oludari ajọ eleto ilera lagbaaye, WHO sọ pe gbogbo agbaye gbọdọ fọwọsowọpọ lori ati wa oogun covid-19.
ìjọba Tanzania ko 30 Mílíọ̀nù rẹ̀ wọ̀lú Ileeṣẹ arannilọwọ Marie Stopes maa n pese ọna idaabobo ara ẹni, ati ifetosọmọbibi fun awọn orilẹ-ede to le ni marundinlogoji ni agbaye ni.
Àwọn eniyan tí wọ́n wà pẹlu Jesu nígbà tí ó fi pe Lasaru jáde kúrò ninu ibojì, tí ó jí i dìde kúrò ninu òkú, ń ròyìn ohun tí wọ́n rí.
Ni deedee aago kan aabọ kọja iṣẹju marun un ni baalu naa ba l'Abuja lọjọ Aje.
Muhammadu Buhari yoo fọwọsowọpọ pẹlu awon ipinlẹ lati
Awọn ọmọ ẹgbẹ oṣelu PDP meji kan, rasheed Ọlabayọ ati Idowu Oluwaseun, ni wọn gba ile ẹjọ lọ pẹlu ẹbẹ pe ki ileẹjọ paṣẹ lati da Adeleke lọwọkọ gẹgẹ bii oludije PDP ninu idibo sipo gomina nipinlẹ Ọṣun eleyi ti yoo waye lọjọ kejilelogun oṣu kẹsan, ọdun 2018.
Ẹ̀mí Mímọ́ fò wálẹ̀ bí àdàbà ó bà lé e lórí.
Bàbá tó pokùnso: Ọmọ ọdún mẹ́jọ ni ọmọdébìnrin tí baba rẹ̀ bá seré oge
Ìwo àgbáǹréré rẹ kò ṣẹ́yìn mi, ẹní àràmàńdà ẹ̀gbọ́n rẹ, mo mọ̀ nípa rẹ̀, èso igi ìmúláradá àbúrò rẹ kò jẹ́ ìpamọ́ fún mi, ìyà ìfẹ́ tí ìwọ jẹ́, kò ṣókùnkùn lójú mi, ṣùgbọ́n ìwọ ni iye lórí ju ohun tí ìwọ ń lépa, ìwọ sàn ju ẹni tí ìbá fẹ́ Ẹwàdapọ̀ lọ.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ọmọ onílẹ̀ wọ gàù, ó kó sí gbaga ọlọ́pàá Ayinla Ọmọwura, orin èébú àti oríyìn lo fi di ọ̀rẹ́ àwọ̀n obìnrin Olúbàdàn, ẹ bá wa bẹ́ Seyi Makinde kó tú wa sílẹ̀ - Oyo NURTW Ipò ètò ààbò ń já àwa gómìnà láyà, ó ń kọ wá lóminú - Àwọn gómìnà Nibayii, ajọ to n risi ere bọọlu ni Naijiria, NFF, ti n gba gbogbo ọna lati wa owo, ki awọn agbabọọlu naa ma ba a da iṣẹ silẹ.
Dino, Wada àti àwọn olùdíje 11 míràn n dù àsíá PDP fún gómìnà ìpínlẹ̀ Kogi Wike kìí ṣe dọ́là tí Ganduje leè kó sápò- Agbẹ́nuso ìjọba ìpínlẹ Rivers APC ní yóò jáwe olúbori ni Bayelsa ati Kogi- Tinubu Fábàdà!
Bi a ko ba gbagbe, ọmọ bibi ipinlẹ Oyo naa kuna lati ri tikẹẹti gba, eyi ti yoo fun laanfaani lati ṣoju ẹgbẹ APC ninu idibo Gomina to kọja nipinlẹ Oyo.
Wọn sọ pe o fi ikorira ati atako rẹ fun Ganduje han ni gbangba, to si tun fi owo rẹ ran oludije ẹgbẹ PDP lọwọ.
E tò è̩kó̩ gbo̩dò̩ lè rí i pé è̩mí; ìgbó̩ra‐e̩ni‐yé, ìbágbépò̩ àlàáfíà, àti ìfé̩ ò̩ré̩‐sí‐ò̩ré̩ wà láàrin orílè̩‐èdè, láàrin è̩yà kan sí òmíràn àti láàrin e̩lé̩sìn kan sí òmíràn.
Iroyin sọ pe wọn fi ọkunrin ṣẹ sin ati ẹlẹya ki wọn o to lu u, pe awọn furasi pe o ni ajakalẹ arun coronvirus lara.
Ṣé ogun kò ní pa wọ́n ní Gibea?
Bakan naa ni wọn tun sọọ ko awọn ọlọpaa naa loju pe ọtọ ni iye owo ti wọn n ta egboogi oloro naa nigboro, ọtọ ni iye ti awọn ọlọpaa yii kọ silẹ sinu iwe ofin ni agọ wọn.
Mo ti gba pé ológun ni ọkọ mí- Aisha Buhari Sex for Grade: Òkété boru mọ àwọn ọjọgbọ́n méji lọ́wọ́ UNIABUJA jùwọ́n síta Mo ṣẹ̀ṣẹ̀ já ọjà 10 mílíọ̀nù ní iná jó, ẹ dákún é gbà wá-Ọlọ́jà Sùgbọ́n lọ́jọ́ Aiku ọ̀ṣẹ̀ yìí ìyàlẹ́nu lọ́ jẹ nígbà ti Ọba Akanbi fi lédé lórí àtẹjisẹ́ instagram rẹ̀ pe Oun ti fi ìyàwo oun sílẹ̀.
Loṣu Kẹrin ọdun yi, awọn ara ipinlẹ Eko ati Ogun ko ara wọn jọ lati ma ṣe fijilante ladugbo kọọkan nitori iroyin to gbode pe awọn ọmọ ẹgbẹ janduku One Million Boys ati Awawa Boys n doju ija kọ awọn eeyan ladugbo wọn.
Agbenusoro fun ile-ise omo ogun naa, ogagun Texas Chukwu so ninu oro re ti o te jade lojoBo(Thursday) pe, awon omo ogun o figba kankan tura le, ti won si koju ogun siko omo ogun olote naa lai fi ikolu ohun fale rara.
"O ni, ""Àwọn kan ní bí wọ́n ṣe daadaa, bi wọn kò ṣe dáadáa, àwọn yoo máa ṣèjọba lọ, wọ́n yóó sì tún lo gbogbo agbára tí wọn ní lati dúró sórí àlèéfà."
A dúpl lọ́wọ́ Ọlọhun fún anfàni ti a ri gbà à sí dúpẹ̀ lọ́wọ́ gbogbo yín.
Ẹgbẹ́ òṣiṣẹ́ Nàìjíríà so ìyanṣẹ́lódì rọ̀ Ẹgbẹ oṣiṣẹ ti so iyanṣẹlodi to fẹ ẹ gun le l'ọjọ Iṣẹgun lati beere fun afikun owo oṣu rọ bayii.
 Ìtàn sopé òkan lára àwon ìyàwó Ààre kúrunmí ni tí ó jé agbèyìn bebo jé ni ó yó kélé lo tú basòrun Ògunmólá sílè láàrín òru .
Àwọn ohun tí ẹ kò kà sí wọnyi ni ó yẹ kí ẹ ṣe, láì gbàgbé àwọn nǹkan yòókù náà.
Ṣùgbọ́n máṣe jẹ́ kí ọ̀rọ̀ yìí bà ọ́ lọ́kàn jẹ́, nítorí àwọn ẹlòmíràn ń bọ̀ lẹ́hìn mi, bẹ́ẹ̀ ni bí ìwọ kò bá fi ọ̀rọ̀ rẹ jáfara tí ìwọ ń wí fún àwọn ẹni tí ń kọjá, nǹkan náà kò ní pẹ́ bọ́ sí i.
seto to waye niluu Abuja  to je olu –ilu orile
Igbeṣe yii lo n waye lẹyin ti Akpabio sọ niwaju igbimọ to n ṣewadii bi ajọ NDDC ṣe nawo laarin oṣu Kinni si oṣu Kẹfa, ọdun 2020, pe ọwọ awọn aṣojuṣofin ni pupọ ninu agbaṣẹ iṣẹ NDDC n bọ si.
Ní ọjọ́ náà gbogbo ẹni tí óbá ké pe orúkọ Oluwa ni a óo gbà là.
35 Nítorí èmi kìí ṣe ojúṣaájú ẹnikẹ́ni, àti kí gbogbo ènìyàn lè mọ̀ pé ọjọ́ náà dé kánkán; wákàtí náà kò tíì dé, ṣugbọ́n ó súnmọ́, nígbàtí a ó mú àlàáfíà kúrò lórí ilẹ̀ ayé, àti tí eṣù yíò ní agbára lórí ìjọba tirẹ̀.
Banki apapọ Naijiria, CBN, lo kọkọ kede idagbere wọn lọdun 2017.
Ọjọ diẹ lyin igba naa ni o pa ara rẹ lẹwọn.
'A ó san N30,000 owó osù òsìsẹ́ l’Ọyọ' - Alao-Akala, Adelabu, Sarumi, Lanlẹhin Àwọn ohun tí ó yẹ kí ẹ mọ̀ nípa Omobolanle Sarumi ‘Bi Gomina Ajimobi se yan adarí òsìsẹ́ tuntun ní Oyo kò dí wa lọ́wọ́’ Afurasi tó fa ìpayà nílé ìwé Port Harcourt ti wọ gàù Bi ẹ ba ranti lasiko ipade itagbangba BBC Yoruba pẹlu awọn oludije gomina ni ipinlẹ Oyo, Bolanle Sarumi ni gbogbo awon ọmọ wẹwẹ ti ọjọ ori wọn ko ju marun un lọ yoo gba eto ilera ofe.
O ku ni ọjọ kejila osu kejila ọdub 2010 NFF, LMC Kwara United bá Nasarawa United kẹ́dùn ikú Martins Oríṣun àwòrán, others Àkọlé àwòrán, NFF, LMC Kwara United bá Nasarawa United kẹdun ikú Martins Àjọ NFF àti LMC ṣì n sọ̀fá ìkú adilé mú ọmọ ẹgbẹ́ agbabọolu Nasarawa United Chineme Martins.
"Iha kokanmi ti Aarẹ Buhari n kọ si gbigbe igbesẹ to tọ lati dẹkun awọn isẹlẹ ipaniyan to n waye ni ipinlẹ Benue ati awọn ipinlẹ miran latọwọ awọn darandaran Fulani lewu pupọ fun ibagbepọ alaafia awọn ọmọ orilẹede Naijria.
Wọ́n pa Matani, alufaa Baali, níwájú àwọn pẹpẹ náà.
yoo san owo itoju awon eniyan naaGege bi o sesọ: “Igbakeji mi ti wa ni ile iwosan naa lati
''Ọpọlọpọ eniyan ni ẹmi wọn ti ba iṣẹlẹ iwa ipa ti ikọ SARS n lo pẹlu awọn eniyan''.
Iye owo ayọkẹlẹ Lexus naa ni miliọ̀nu mẹ́ta ati ẹgbẹrun lọna irinwo naira (N3.
Ẹ̀mí sùn níbi ìkọlù Shiite àti ọlọ́pàá
Àìríṣẹ́ṣe kọ́kọ́ sọ mi di olè ṣùgbọ́n mo di alásè ńlá lẹ́yìn ti mo ti ẹ̀wọ̀n dé- Eduardo Ọbabinrin Ilẹ̀ Gẹ̀ẹ́sì àti Ọmọọba Harry yóò sèpàdé ní Ọjọ́ Ajé Ṣé àsọtẹ́lẹ̀ ìjàmbá iná kò tíì máa ṣe báyìí?
nínu ìtàn ìwáṣẹ ̀ mìíràn , a gbọ ́ pé Ọbàlùfọ ̀ n aláyémore ni ọba àkọ ́ kọ ́ ti o tẹ ìlú Ẹ ̀ fọ ̀ n-aláayè dó .
Ọ̀rẹ́ mi ni Kẹ́hìndé Ayọ̀ọlá tó kú, olùfọkànsìn ńlá ni-Ṣeyi Makinde Ènìyàn 5,162 ló ti ní ààrùn Coronavirus ní Nàìjíríà, tí èèyàn 167 sì ti bá ààrùn náà rìn.
Gomina bi í pé, “Ìwọ ni ọba àwọn Juu bí?
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Obìnrin tí kò bá rẹwà ló ń ṣí ara sílẹ̀ - Ṣọla Allyson ‘Alẹ́ làwọn ọkùnrin fẹ́ bá mi jáde, torí mo kọ ilà’ Ohun tó burú ni ‘Dìbò kó o sebẹ̀’, ìyà ló bá dé - Olùdíje ANRP Ọbasanjọ kọ́ ni yóò sọ ibi tí Yorùbá yóò dìbò sí ní 2019 - Falọmọ Oluwo gba Aláàfin nímọ̀ràn pé kí olorì máa dé adé Iya Rainbow jẹ́ gbajúmọ̀, àmọ́ kí lo mọ̀ nípa rẹ̀?
Ẹmiọla kọkọ fẹ ṣe agidi ṣugbọn ibọn ti awọn ikọ naa gbe lọwọ ko ṣee yaju si.
Bẹ́ẹ̀ ni Jeremaya ṣe bẹ̀rẹ̀ sí gbé gbọ̀ngàn àwọn tí ń ṣọ́ ààfin.
Alaga egbe naa, Mai Mala Buni lo fi lede lẹyin ti ohun ati Dogara kọwọ rin lọ si ile Aarẹ ni Aso Rock ni Abuja.
Ajọ EFCC kọ loju opo twitter rẹ pe ajọ naa ko kawọ gbera lori iwe ifisun kan to jade pe ọwọ ileeṣẹ Alpha Beta Consulting Limited ko mọ lori ọrọ owo kan ti iye rẹ to ọgọrun un biliọnu Naira (N100bn).
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Trump picture: ọjọ́ tí Trump kí mi kú iṣẹ́ lórí 'twitter' ní inú mi dùn jù- Oyedele Ofin ati ilana ti ẹni to ba fẹ ẹ gba iwe irinna tuntun yii ko yatọ si eyi to ti wa nilẹ tẹlẹ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Bí ẹ ṣe mọ̀wé tó, ẹ wá dánrawò níbí pẹ̀lú Àpólà Ọ̀rọ̀ Orúkọ - Noun Phrase Bakan naa ni wọn ti gbe oku Stanley lọ si mọsuari."
Ẹgbẹ naa n fẹhonu han nitori olori wọn to wa latimọle, Ibrahim Zakzaky, ohun ti wọn n beere fun ni pe ki ijọba fun un lominira.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Arsene Wenger njọ̀wọ́ ìdarí Arsenal 20 Ìgbé 2018 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Wenger ti lo ọdún mọ́kànlélógún gẹ́gẹ́bíi adarí Arsenal Arsene Wenger tí ó jẹ́ akọ́nimọ̀ọ́gbá ẹgbé agbábọ́ọ̀lú Arsenal yóò fi àlèéfà sílẹ̀ lẹ́hìn sáà yí.
Àṣàkẹ́ máa ń kanra mọ́ ọmọdé.
"Ìjọba Eko bẹ̀rẹ̀ sísan N35,000 owó oṣù tuntun ní November Ẹlomiran naa sọ pe ""Nkan ti o yẹ ki wọn maa kọ awọn eeyan lati kekere ni."
Gomina Ibikunle Amosun ati iyawo rẹ ree ti wọn to sori ila lati dibo ni wọọdu
 iye owó rẹ ̀ lójú pálí jẹ ́ bíi 6.
" Awọn ẹgbẹrun lọna aadọta ẹja to wa ni oko Obasanjo naa lo jẹ ẹja alaran ati ọbọkun ti wọn tu da sinu odo ẹja lati dagba.
Àwọn onímọ̀ ṣàlàyé àǹfàní tó wà nínú gbígba ajaguntà láti kojú Boko Haram Oríṣun àwòrán, Facebook / Samuel Aruwan Orilẹede Naijiria tun ke irora iku ọwọọwọ ni ọjọ Ababmẹta, ọjọ kejidinlọgbọn oṣu kọkanla ọdun 2020 nigba ti awsn agbebọn Boko Haram tun kọlu ileto Koshebe nitosi Maiduguri ti wọn gbẹmi awsn agbẹ onirẹsi to le ni ogoji.
Bí ìjọ ti ń bọ̀wọ̀ fún Kristi, bẹ́ẹ̀ ni kí àwọn aya máa ṣe sí àwọn ọkọ wọn ninu ohun gbogbo.
awon omo orile ede Naijiria lọwọ lati lee pese isẹ fun wọn.
Ibi ọ̀rọ̀ dé dúró lórí ṣíṣí àwọn ilé ìwé padà ní Naijira rèé àti nílẹ̀ Afrika Ẹ pèsè ẹlẹ́rìí púpọ̀ bí bẹ́ẹ̀ kọ́, Sotitobire yóò jẹ́rìí fúnrarẹ̀ o!
Nígbà tí gbogbo nǹkan wọnyi bá ṣẹlẹ̀ sí ọ, ṣe ohunkohun tí ó bá wá sọ́kàn rẹ, nítorí Ọlọrun wà pẹlu rẹ.
Àjẹ́ àti Aṣẹ́wó ní ìyá Rainbow - Òjòpagogo Kí ní Khafi BB Naija yóò pàdánu tí iṣẹ́ ba bọ́ lọ́wọ́ rẹ̀?
2019 Hajj: NAHCON ní Nàìjíríà pàdánù èèyàn 5 láti ipàsẹ̀ àìsàn
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Àwọn ǹkan tí ẹ kò mọ̀ nípa Ìjàpá Ogbomoso kó tó kú 4 Ọ̀wàrà 2019 Àkọlé àwòrán, Akọwe Toyin Ajamu pẹlu Ijapa Ogbomoso Lẹ́yìn tí Ijapa to dagba ju nilẹ Afirika yii dagbere faye lẹni ọdun mejilelọọdunrun, ile iṣẹ BBC ṣewadii awọn nkan to laami laaka nipa rẹ.
Ìdí rèé tí mo fi ṣẹ̀ṣẹ̀ sọ̀rọ̀ lẹ́yìn tí wọ́n fipá bámi lopọ̀ lọ́mọ ọdún méje lọ́gọ́ta ọdún sẹ́yìn-Eli O ni eyi si n mu ifasẹyin ba igbogun ti iru iwa bẹ ẹ nipinlẹ Ekiti.
Láti òwúrọ̀ di alẹ́, mo na ọwọ́ mi sí àwọn ọlọ̀tẹ̀ eniyan; àwọn tí wọn ń rìn ní ọ̀nà tí kò dára,tí wọn ń tẹ̀lé èrò ọkàn wọn,
Ninu ọrọ rẹ, oni nigba tawọn ọmọ Chibok, bi ijọba se dakẹ lori ọrọ naa niyẹn, koto di wipe wọn sọ wipe awọn ọmọ orinlẹlugbadinmẹrin(276), lawọn ọmọ Chibok to sọnu.
Aisha Buhari: Afenifere, PDP, ajàfẹ́tọ̀ọ́ ẹni ni àgbà Buhari kò tolé
Nítorí iṣẹ́ yìí jẹ́ ẹ̀rí tí àwọn eniyan yóo fi máa yin Ọlọrun fún rírẹ̀ tí ẹ rẹ ara yín sílẹ̀ ní ìgbọràn gẹ́gẹ́ bí ìjẹ́wọ́ igbagbọ yín ninu ìyìn rere ti Kristi, ati nítorí ìlawọ́ yín ninu iṣẹ́ yìí fún wọn ati fún gbogbo onigbagbọ.
Yóo di ẹ̀bìtì ati tàkúté fún àwọn ará Jerusalẹmu.
Díẹ̀ nínú ǹkan to yatọ ninu orílẹ̀ èdè mẹ́wàá ti inú wọn dùn jùlọ lọ́dún yìí, ni Austria tó gba ipò Australia Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ghana elections 2020: NDC ní òun yóò kéde ìgbésẹ̀ tó kàn láìpẹ́ 10 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Oríṣun àwòrán, facebook Ẹgbẹ oselu alatako gboogi lorilẹede Ghana ti fọnmu lori abajade esi ibo aarẹ ti wọn kede rẹ nirọlẹ ọjọru.
    Nígbà tí ó di òwúrọ̀ ọjọ́ kan báyìí, bí mo ti jí, Ewe-ẹ̀yẹ ni mo kọ́ rí, ó wọ ṣòkòtò tí kò pupa tí kò sì funfun tí àwọ̀ rẹ̀ jẹ́ búlù èyí ni pé o fi ara jọ aṣọ aláró.
Ṣugbọn igi Olifi dá wọn lóhùn pé, ‘Ṣé kí n pa òróró ṣíṣe tì, tí àwọn oriṣa ati àwọn eniyan fi ń dá ara wọn lọ́lá tì, kí n má ṣe é mọ́, kí n wá jọba lórí ẹ̀yin igi?
Tuntun ti a rigbọ ni pe awọn alaṣẹ ileeṣẹ ọhun ni wọn kan fẹ ṣe atunṣe abẹle nikan ni, lodi si ọrọ to n lọ kaakiri pe wọn fẹ gbe ileeṣẹ ọhun ti patapata.
O rọ awọn eeyan lati maa ṣe ere idaraya ninu ile wọn lasiko ti ofin konle-o-gbele wa lode nitori ewu to wa ninu ṣiṣe ere idaraya loju popo tabi ni gbọngan ere idaraya lasiko yii.
ipade pelu awon oga ile ise alaabo nile-ise aare niluu Abuja.
Eeyan mẹta-mẹta lo nii lati Bauchi ati Edo ti eeyan meji si ko aarun naa ni Kano Eeyan kan ṣoṣo layẹwo fihan pe o ni aarun naa ni ipinlẹ Ọṣun.
O tun ṣeeṣe ki o rii pe awọ nkan to n jade ati kiki r ti yipada si bii awọ eeru ti ko funfun mọ bẹẹ si ni o maa ṣan.
Adajo agba ile-ejo agba lorile-ede Kenya, adajo George Odunga so pe, minisita oro abele lorile-ede naa, giwa ile-ise olopaa ati oga agba eso enu-ibode yoo foju wina ofin ti won ba kuna lati fi okunrin naa sile.
Ẹ bá mi dúpẹ́ lọ́wọ́ Sunday Igboho, Ajimobi, Seyi Makinde àti àwọn ọlọ́pàá fún iranwọ wọn láti rí ìbejì gbà padà Àwọn èèyàn kò fi bẹ́ ẹ̀ ní ìbálòpọ̀ lásìkò ìgbélé yìí - Iléèṣẹ́ kọ́ńdọ́ọ́mù Durex Obìnrin pa olólùfẹ́ rẹ̀, ó fi se ìrẹsì Coronavirus ti gbẹ̀mí èèyàn mìí ní ìpínlẹ̀ Osun O ni ko si iye owo yowu ti Man United ba fi lọ oun, oun ko ni duro.
O ni bi wọn ba file ri Iyalọja fi lọlẹ ni Komputa Village l'Eko,iru rẹ yoo waye ni Abuja ati awọn ibo miran.
Àwọn òkú kò lè yin OLUWA,àní àwọn tí wọ́n ti dákẹ́ ninu ibojì.
Taiwo Ogunjobi d'olóògbé Ìyá Leah Sharibu ké gbàjarè sí ìjọba Buhari Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ọkọ àti ìyàwó sọ àsọtẹ́lẹ̀ tani yóò wọlé nínú PDP tàbí APC Ẹwẹ, Aarẹ Muhammadu Buhari sọ pe o gbe igbesẹ lati rọpo adajọ Onnoghen lẹyin ti ile ẹjọ to n ri si igbẹjọ iwa ibajẹ awọn oṣiṣẹ ọba paṣẹ bẹẹ.
Ẹ ma jẹ ki a sọrọ nipa owo ti a o padanu."
Kí ló wá dé tí o fi fẹ́ ṣe bẹ́ẹ̀?
Ẹni tí ń gbé ibi gegele òkúta,
Wo ipò tí Buhari fún Faṣọla, Lai Mohammed, Saraki àti bẹ́ẹ̀ bẹ́ẹ̀ lọ Èrò àwọn ọmọ Naijiria ṣọ̀tọ̀ọ̀tọ̀ lórí àwọn ti Sanwo Olu yàn sípò Àwọn ọmọ Yorùbá wo ni mínísítà ní ìjọba Buhari?
ati òróró ìyàsímímọ́, ati turari olóòórùn dídùn fún ibi mímọ́.
Ìwọ́de Shiite: Ọrọ̀ ajé dẹnu kọlẹ̀ ní Kaduna
Ẹ kò rí i sójú nisinsinyii, sibẹ ẹ gbà á gbọ́, ẹ sì ń yọ ayọ̀ tí ẹnu kò lè sọ, ayọ̀ tí ó lógo, 
atileyin ti ijoba maa n se lati mu idagbasoke ba eto ẹkọ.
 Minisita ọhun tẹ siwaju pe Ijọba yii ni akọsilẹ awọn egbeje eeyan to wa ni ahamọ, bẹẹ ni a si ti gba owo to le ni ẹgbẹrin bilọnu naira pada, yatọ si awọn ohun ini ti agbẹsẹle.
Lojo karun un seyin ni igbakeji gomina ana naa n  so pe aheso oro ni iroyin ti won n gbe, pe oun ti kuro ninu egbe APC lo sinu egbe PDP.
Daura Kidnap: Àna ààrẹ Buhari, Musa dàwátì ní ìlú Daura
Gbogbo àwọn eniyan ń lọ sọ́dọ̀ rẹ̀.
Àwọn ọlọ́pàá tó mú Evans 'ajọ́mọgbé' gbá igbega
"Fadeyi Oloro - BBC News Yorùbá BBC News, YorùbáFò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Yoruba Films: Ẹ̀ẹ́ bẹ̀ mi kúrò láyé ni, mi ò lè kú - Fadeyi Oloro Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Yoruba Films: Ẹ̀ẹ́ bẹ̀ mi kúrò láyé ni, mi ò lè kú - Fadeyi Oloro 26 Èrèlè 2020 ""Emi Fadeyi Oloro, emi arisa ina ako tagiri ede werepe ti o nibi aa gbamu gbogbo ara ló fi ń jó 'ni."
Electricity tariff hike: SERAP ní aráàlú kò lè máa jìyà, káwọn tó dipò òṣèlú mú máa gbádùn
Ẹsun to si wọpọ ti wọn fi ma n kan wọn ni aṣilo ipo, ati iwa ibajẹ.
    “Kìí ṣe Ìbẹ̀nbẹ́-Olókùnrùn nìkan ni a rí mú bọ̀.
Bakan naa ni awọn eeyan ọhun kọti ikun si ofin to rọ mọ apejọjọpọ ọpọ ero ti ijọba gbe kalẹ nibi ayẹyẹ ọdun naa.
Níbo ni olùfẹ́ rẹ yà sí,kí á lè bá ọ wá a?
Ọba Lamidi Adeyemi sọ pé kò sí bí ènìyàn ṣe leè gbọ́ ede Gẹ̀ẹ́sì dáadáa tó, tí kò bá peregede nínú ede abínibí rẹ, kò já mọ́ ǹkankan.
Má gbé ara rẹ lọ́kàn gbóná nítorí ẹni tí nǹkan ń dára fún;tabi nítorí ẹni tí ń gbèrò ibi, tí ó sì ń ṣe é.
Tí ó bá wá jẹ́ pé àwọn nǹkan tí n kò fẹ́ ni mò ń ṣe, a jẹ́ pé kì í ṣe èmi ni mò ń ṣe é, bíkòṣe ẹ̀ṣẹ̀ tí ń gbé inú mi.
 Ipa ti awọn akinkanju onisowo yii n ko lori ọrọ aje orile ede Naijiria ko kere.
Ẹgbẹ awọn oniṣẹ irinajo ofurufu lagbaye ti ṣaaju fi ikilọ sita pe awọn eeyan yoo padanu iṣẹ nitori pe pẹlu bi ọjọ ṣe n gori ọjọ ti awọn ileeṣẹ ofurufu ko fi ṣiṣẹ ni Naijiria n padanu miliọnu mẹtadinlọgọrun Naira loṣooṣu.
Àwọn iranṣẹ ọba Asiria kígbe sókè nígbà tí wọ́n sọ ọ̀rọ̀ ní èdè Heberu, sí àwọn ará Jerusalẹmu tí wọ́n wà lórí odi, wọn fi dẹ́rùbà wọ́n kí wọ́n lè gba ìlú náà.
47 Kíyèsíi, èmi, Jésù Krístì, Olúwa rẹ àti Ọlọ́run rẹ, àti Olùràpadà rẹ, nípa agbára Ẹ̀mí mi ni mo fi sọ ọ́.
Pa mí mọ́, kí o sì gbà mí;má jẹ́ kí ojú kí ó tì mí,nítorí ìwọ ni mo sá di.
"Toyin Abraham bí ọmọkùnrin jòjòló Òṣèré tíátà Toyin Abraham daya Kolawole Ajeyemi Wo àgbáríjọpọ̀ àwọn Arugbá Ọ̀ṣun Òṣogbo látìgbà tó ti bẹ̀rẹ̀ Buhari júwe ọ̀nà ilé fún Obono-Obla lórí ẹ̀ṣùn ayédèrú ìwé ẹ̀rí Àjẹ́ àti Aṣẹ́wó ní ìyá Rainbow - Òjòpagogo Yagboyaju sọ wipe ""igbesẹ yi jẹ igbesẹ ti o wa ni ibamu pẹlu bi awọn orilẹede ti o ti goke agba ni agbaye se n se."
nitori pe ile –ejo tẹẹkotọ ko ni agbara labe ofin lati da ejo naa.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ọbasanjo kọ́ ni yóò fi ààrẹ jẹ nínú ìdìbò 2019 - Oshiomole SERAP ní kí Buhari gbé Dasuki, Jonathan lọ síwaju kóòtù àgbáyé Pín fídíò 'ayédèrú' kó o ríjà ológun Nàìjíríà Ẹ máse sá gaàrí síta mọ́ torí ibà Lassa - ìjọba Ondo figbe bọnu Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Adedoyin: Tí mo bá rí Buhari, màá sọ fun kó rántí pé Ọlọ́run wà Ede-aiyede naa lo fa bi wọn ṣe gbe ilẹkun ilẹ ẹkọ naa ti lati le dena ija ẹsin ti o ṣeeṣe ko waye, bi eefin ọrọ ọhun ba ru ju bo tiyẹ lọ.
21 Ìgbé 2019 Ajọ iṣọkan agbaye ni eeyan bi ẹgbẹrun mẹwaa ni yoo maa gbe ile to wa lori omi laipẹ laijina.
Kí gbolohun ẹnu rẹ jẹ́ ti ọmọlúwàbí, tí ẹnìkan kò ní lè fi bá ọ wí.
Lati igba ti isẹlẹ naa ti sẹlẹ ni orọ naa ti gbalẹ ni ori ẹrọ ayelujara Twitter nibi ti awọn eniyan ti n sọ wipe aibikita lo sokunfa iṣẹlẹ naa.
Awọn oṣiṣẹ pajawiri ni awọn ti ko awọn ọkọ to wa loju ọna kuro bayii.
Nígbà tí Kenani di ẹni aadọrin ọdún, ó bí Mahalaleli.
Burundi: Kọ Ìkọkúkọ sórí àwòrán Ààrẹ  kí o wẹ̀wọ̀n
Lẹ́yìn olóògbé Barrister àti Kollington, èmi làgbà kàn nínú iṣẹ́ orin Fuji- Obesere yarí Building Collapse: Iléèwé míràn tún dàwó ní ìpínlẹ̀ Eko Yatọ̀ sí pé ó ṣe sọ́jà, tó tún jẹ́ ọkọ Oriṣabunmi, wo àwọn nkan tí o kò mọ̀ nípa Jimoh Aliu Facebook mú àyípadà bá àtẹ̀jíṣẹ́ síra ẹni lórí òpó Instagram, wo àwọn ǹkan tó kàn ọ níbẹ̀ Kembi to ṣẹṣẹ kẹkọọ gboye ''ND'' nile ẹkọ giga gbogbonṣe n mura lati lọ fun ẹkọṣẹ ohun to lọ ṣe nile ẹkọ giga fun ọdun kan ki o tun ṣagbako iku ojiji.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Baba Khadijat Oluboyo jẹ́rìí ọmọ rẹ̀ Gẹgẹ bi ọrọ awọn ọlọpaa, akẹkọbinrin naa gba aafa gbọ, o si tẹle e lọ si Ilu Ikorodu nibi ti o ti fi ipa ba a lo pọ.
Àwọn ọmọ Asafu tí wọ́n jẹ́ akọrin ní tẹmpili jẹ́ mejidinlaadoje (128)
Diẹ lara wọn niyii: Zulaihat Adamu Hardo Aimọye igba ni Aarẹ Buhari ti sọrọ nipa iku iya rẹ to waye l'oṣu Kejila, ọdun 1988.
Minisita Lai Mohammed to n laa ye awọn akọroyin pe ijọba ko ṣa deede fi Ibrahim El-Zakzaky si ahamọ bikoṣe nitori pe ile ẹjọ ti o n gbọ ẹjọ rẹ ni ki wọn fi si ahamọ eyi to mu ki ileeṣẹ ọtẹlẹmuyẹ orilẹ-ede Naijiria o fi pamọ sinu ile kan ni ilu Abuja nibiti o ni ijọba ti n na owo to to miliọnu mẹta abọ ni ijọba apapọ lati fi gbọ bukata rẹ.
Ó jókòó; àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ bá lọ sọ́dọ̀ rẹ̀.
Mo je okan lara awon eniyan to n ro aare pe ki won bu ola fun Kudirat ati Nwosu  gege bi akinkanju eniyan, ki won si fun Okechukwu ni oye GCON gege bi eni to dari eto idibo JUNE 12”.
Kabiyesi ni oun n wọ ibomu lati jẹ awokọṣe rere fawọn ọmọ Naijiria nitori ifẹ ti oun ni si wọn.
Bẹẹ naa ni awọn miran ni laipe yii ni awọn iyawo oju ọna to ku yoo maa wo bi awokọse, wọn yoo si pa iṣẹẹṣẹ ati aṣa ibilẹ wọn ti.
Díẹ̀ ninú àwọn Òṣèlú ti Ilé Iṣẹ́ Agbógun ti Ìwà Ìbàjẹ́ fi ẹ̀sùn kàn
wọn yóo jù wọ́n sinu iná ìléru.
#BBCNigeria2019 Lọjọ Iṣẹgun ni ile igbimọ aṣofin agba Naijiria naa fi ọjọ ipade pajawiri si lati jiroro lori ọrọ yi kan naa.
awọn ọmọ ẹgbẹ igbimọ naa ati bi awọn tọrọ naa kan ṣe n dahun si awọn
Bee si ni , O so Tiena Coulibaly, ti o n mojuto eto aabo tele lati lo mojuto eto igbejo.
Nitori naa,awon omo egbe ECOWAS n fe ki orile ede China fun won ni anfaani lati maa ra tabi ta oja si orile ede China.
O fikun ọrọ rẹ pe awọn yoo tẹsiwaju lati ṣe atilẹyin fun ọmọ naa, bi awọn obi rẹ ba ṣe faaye gba wọn si.
Gbogbo ohun tí OLUWA Ọlọrun wa ti gbà fún wa ni a óo fọwọ́ mú.
Balogun tí ó wà fún oṣù kẹfa ni Ira, ọmọ Ikeṣi ará Tekoa; iye àwọn tí wọ́n wà ninu ìpín rẹ̀ jẹ́ ọ̀kẹ́ kan ó lé ẹgbaaji (24,000).
Ju gbogbo rẹ lọ, ajọ INEC ni eto iforukọsilẹ n tẹsiwaju ṣugbọn gbigba awọn kaadi to wa nilẹ lo n fa nílẹ̀ bii igbin.
Má ṣe lo agbára rẹ lórí obinrin,má fi ọ̀nà rẹ lé àwọn tí wọn ń pa ọba run lọ́wọ́.
"Ṣaaju ni aarẹ Trump ti fi sita loju opo twitter rẹ pe awọn obinrin mẹrẹerin ""le maa lọ""."
Wo ìdí tí àwọn obìnrin kan fi n yọ ilé ọmọ wọn kúrò Ṣé o ti gbọ́ ohun ti Ọọni Ifẹ́ àti Soyinka parí ọ̀rọ̀ Yorùbá sí?
O tun gboriyin fun awon erongba iko oluwaadi ile-ise IITA, Pataki julo idagbasoke eto ogbin ati ise agbe lorile-ede Naijiria ati ni ile Afirika lapaapo.
Gẹgẹ bi minisita eto iroyin ati aṣa, Lai Mohammed ṣe sọ, wọn ṣe alakalẹ abadofin ọhun lati pese abojuto nipa ikọṣẹmọṣẹ ti yoo si wulo fun gbogbo ọmọ Naijiria.
Ó dáhùn pé, “Ilẹ̀ Ṣinari ni wọ́n ń gbé e lọ, láti lọ kọ́lé fún un níbẹ̀.
Ẹ̀bẹ̀ mi ni pé kí o pa wọ́n mọ́ kúrò lọ́wọ́ Èṣù.
Egbe awon agbe olohun osin eran aguntan ati ewure, ti a mo si SHEGOFAN ti ro ijoba orile-ede Naijiria lati gba awon agbe to je omo egbe SHEGOFAN lati kopa ninu eto FADAM ki ere oko won le po sii.
Ko fẹẹ wọpọ ninu awọn ọmọ orilẹede Naijiria ti ko maa ṣe haahin lori bi iku naa ṣe n waye.
“Ní ọjọ́ kẹrin, ẹ óo máa fi ẹgbọ̀rọ̀ akọ mààlúù mẹ́wàá, àgbò meji ati ọ̀dọ́ àgbò mẹrinla ọlọ́dún kọ̀ọ̀kan, tí kò ní àbààwọ́n rúbọ.
Sùgbọ́n ayọ to wà nibẹ ni pé tí ènìyàn bá ṣee ko pẹ́ lóri iná ó máa n mú àdínkù ba ewu to wà nibẹ̀.
Ó rí mi, alákọrí ri mi, ìjàngbọ̀n tún bẹ̀rẹ̀, ó bẹ̀rẹ̀ si mi igi mọ́ mi ní ìdí ki n bà já tilẹ̀, mo tilẹ̀ kọ́ rò pé kò rí mi ni àti pé ó kàn n mi igi lásán ni, ìgbà tí mo sì rọra dákẹ́ ti n kò sọ̀rọ̀ ó dáhùn ó ni, wo ilẹ̀ kí o wo ọ̀run, mo ti rí ọ, ọwọ́ ba ìwọ ní tìrẹ ná.
Lọdun 2011 ìròyìn tàn ká pe Baba Suwe gbé òògun oloro sùgbọ́n ti o ni kò si òòtọ kankan nínú ọ̀rọ̀ náà to si pada gbé ajọ to n gbogun ti òògun oloro lọ́rilẹ̀-èdè Naijiria NDLEA lọ si ilé Ejọ Ilé Ẹjọ pada dájọ pe ki wọ́n san mílíọnu marundinlọ́gbọ̀n gẹ́gẹ́ bi owo ìtànran , sùgbọ́n ti Baba Suwe salaye pe àjọ NDLEA kọ lati ṣe ǹkan ti ilé ẹjọ sọ Baba Suwe ti kopa nínú ere ọlọsọọsẹ ni LTV 8 ati Erin Keke ni NTA Channel 7 nípinlẹ̀ Eko Orúkọ ọrẹ́binrin Baba Suwe ni wọ́n fi n pèé ni Baba Suwe Bab Suwe ni oun ti ṣe fiimu to lé ni ogojibayii.
Sam Adeyemi rọ aarẹ Muhammadu Buhari, awọn ajọ amuṣẹya, awọn aṣofin Ile Igbimọ Aṣofin, awọn gomina ati gbogbo awọn obi lati lo ifẹhọnuhan yii fun ohun rere.
Gbogbo nǹkan yòókù tí Jehoahasi ṣe ati agbára rẹ̀ ni a kọ sinu Ìwé Ìtàn Àwọn Ọba Israẹli.
" Oríṣun àwòrán, Ooni Àkọlé àwòrán, Ọdún 38 ni ìyá mí fi ṣiṣẹ́ ní UCH, màá kọ́ ibùdó ìtọ́jú àrùn jẹjẹrẹ ní ìrántí rẹ - Ọọ̀ni Arole Oodua tun woye pe gẹgẹ bii ojulowo ọmọ Yoruba ọpọ egboogi ibilẹ lo wa fun iwosan arun Coronavirus atawọn aisan asekupani miran eyi to yẹ ka tẹwọ gba fun itọju awọn alaisan naa pẹlu oogun oyinbo.
Asoju ijọba ati ẹgbẹ ASUU to ba awọn oniroyin sọrọ lẹyin ipade naa sọ wi pe wọn ti sun ipade si waju di Ọjọ Keje, Osu Keji, ọdun 2019.
 Bakan naa ni ẹni ti BBC ba sọrọ nile iṣẹ aarẹ to ni ki a ma darukọ oun ṣalaye pe irọ to jina si ootọ ni pe wọn dé aya aarẹ Buhari, Aisha mọ́lé ninu Aso Rock."
Bakan naa si la gbọdọ ri daju pe a n se odiwọn awọn aseyọri wa lojoojumọ, ta si n se gbogbo ohun to yẹ ni sise.
O ni oun ti rọ awọn ọmọ igbimọ pata lati kọwe fipo won silẹ bakan naa.
Wakili fi kun pe kawọn ọmọ Naijiria mase mikan rara nipa ipo tawọn ọmọ Dapchi naa wa nitori eera kankan ko rin won pẹlu ọmọ oun ati awọn ọrẹ rẹ.
 ní bẹ ́ ẹ ̀ a ní :.
"Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: ""Kí ló ṣe jẹ́ pé èmi ni yóò ní àrùn jẹjẹrẹ lẹ́ni ọdún mẹ́rìnlá?"
Ó ṣe ohun tí ó tọ́ lójú OLUWA, gẹ́gẹ́ bí Dafidi baba ńlá rẹ̀ ti ṣe.
 Minista fun igbokegbodo oko fun Russia, Maxim Sokolov ni ko si eni to wa laye ninu gbogbo awon to wa ninu oko ofurufu naa ati pe won maa se ayewo eya ara lati fi da oku kookan mo ni.
Fathia Balogun: Kò sí ẹni tó bá mi lò pọ̀, kó tó fún mi ní isẹ́
Oríṣun àwòrán, @kalvarez02 Adari ètò ilé ẹkọ náà ajagun fẹyìnti Baah Bentum sọ pé, àwoọn ọmọbinrin náà ń kópa nínú ìdíje ọmọbinrin to rẹwà jù ní Fasiti Ghana Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Jose Mourinho ẹgbẹTottenham, Serge Aurier ati Musa Sissoko náà tapa sí òfin lọnà kan tabi omiran.
Igbesẹ yi jẹ eleyi ti awọn eeyan ti n kan sara si ṣugbọn ibeere to gba ẹnu ara ilu bayi ni pe ṣe ẹmi ile aṣofin le gbe ṣise iwaadi to peye lati le mọ wulẹwulẹ ọrọ yi?
Àwọn alufaa, àwọn ọmọ Lefi ati àwọn kan ninu àwọn eniyan náà ń gbé Jerusalẹmu ati agbègbè rẹ̀.
Mikel Arteta: Wọ́n ti kéde Mikel Arteta gẹ́gẹ́ bí akọ́nimọ̀ọ́gbá ikọ̀ Arsenal tuntun
Jacksonville ni Alabama lorileede Amerika lo ti kẹkọ nipa imọ eto ẹkọ nipa idajọ, iwadi iwa ọdaran ati eto oselu.
Ó fi afẹ́fẹ́ ṣe ojú ọ̀run lọ́ṣọ̀ọ́;ọwọ́ ló fi pa ejò tí ń fò.
“Àánú àwọn eniyan wọnyi ń ṣe mí, nítorí ó di ọjọ́ mẹta tí wọ́n ti wà pẹlu mi, wọn kò ní ohun tí wọn yóo jẹ mọ́.
Ọjọ Iṣẹgun ni olori ile aṣofin naa, Femi Gbajabiamila, kede pe oun fun Akpabio ni wakati mejidinlaadọta lati fi orukọ awọn aṣofin naa sita.
Lori iṣẹlẹ Corona Virus yii naa ni ibeere gbankọgbi ti n jade ni orilẹ-ede Ghana.
 Ojogbon Yemi Osinbajo ti de si papa isere Eagles Square niluu Abujaigtbakeji gomina ti ipinle Bauchi, Abdu Sule Katagum,naa n gbe ijoba sile fun gomina tuntun fun ipinle naa Bala AbdulQadir Muhammad nile -ise gomina to wa ni ipinle, Bauchi,ni  asale ojo Isegunhttps://twitter.
Awuyewuye tẹle nigba naa, ti ko si si eyikeyi laarin awọn mejeeji to sọ boya lootọ ni wọn ṣe igbeyawo tabi rara.
Ó kéré parí , ènìyàn méjì tàbí jù bẹ ́ ẹ ̀ lọ ni wọ ́ n máa ń kọ irú orin yìí .
 yí ní atọ ́ ka awẹ ́ -gbólóhùn-asàpèjúwe nínu Ẹi .
ng Tẹ bọtinni Federal Scholarship Board, to wa ni oju ewe akọkọ Ka awọn ilana to wa nibẹ, ki o si fi orukọ silẹ lori fọọmu naa Tẹ fọọmu ti o fi ọwọ si jade Ranti pe , ọfẹ ni.
Amọ ko pẹ lẹyin naa, to fi pada silu Osogbo, to si da ẹgbẹ osere tiẹ silẹ lọdun 1961 Duro Ladipọ ni ẹbun orin kikọ ati ilu lilu, eyi to maa n se afihan wọn ninu ere rẹ, to fi mọ amulo owe pipa.
Mo láyọ̀ ninu pípa òfin rẹ mọ́,bí ẹni tí ó ní ọpọlọpọ ọrọ̀.
Gègé ni wọ́n ṣẹ́ lórí ìlú mẹ́wàá ara ilẹ̀ ìdajì ẹ̀yà Manase tí ó wà ní ìhà ìwọ̀ oòrùn, tí wọn sì pín wọn fún àwọn ìdílé Kohati tí ó kù.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ope Aiyeọla: Nkan to pa emi ati Baba Suwe pọ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Ope Aiyeọla: Nkan to pa emi ati Baba Suwe pọ 20 Èrèlè 2018 Opẹyẹmi Aiyẹọla sọ iriri rẹ nidi isẹ tiata ati pe nkan wa to pa oun ati Baba Suwe papọ.
Ó ń jáde tagbára tagbára láti inú odò, ó ń fẹsẹ̀ da omi rú, ó sì ń dọ̀tí àwọn odò.
Ahira, ọmọ Enani, kó akọ mààlúù meji ati àgbò marun-un, òbúkọ marun-un, ọ̀dọ́ àgbò marun-un, ọlọ́dún kọ̀ọ̀kan wá fún ẹbọ alaafia.
Wolverhampton Wanderers to jáwé olúborí ní Champions League to koja, yóò gbálejò Everton ní Molineux.
Alásè Buhari kú, Buhari ń ṣọ̀fọ̀ Oríṣun àwòrán, @GarShehu Ẹyin eeyan wa, aṣe awọn alagbara naa a maa mọ iyi ounjẹ to gbamuṣe.
Iroyin to tẹ BBC News Yoruba lọwọ ṣalaye pe nnkan bii aago kan oru ni ikọlu naa waye ni agbegbe ijọba ibilẹ Oke Ero nipinlẹ Kwara.
Bẹnaya ọmọ Jehoiada bá lọ sinu Àgọ́ OLUWA, ó pa Joabu, wọn sì sin ín sinu ilé rẹ̀ ninu aṣálẹ̀.
Ofin naa faaye gba won lati lo eniyan ile okeere atile ise ile okeere ti won ba setan lati wa ko awon eniyan Naijiria fun idagbasoke lati ni oore ofe lati wa sise naa nibi ti a ko ti ri akosemose Naijiria to le se ise naa.
Nítorí náà, bí Baba ti sọ fún mi pé kí n wí, bẹ́ẹ̀ gan-an ni mò ń sọ.
Bí eniyan ti wáyé níhòòhò láìmú nǹkankan lọ́wọ́ wá bẹ́ẹ̀ ni yóo pada, láìmú nǹkankan lọ́wọ́ lọ, bí èrè làálàá tí a ṣe láyé.
Onidajọ Oluṣẹgun Oduṣọla wa ṣalaye fun awọn agbẹjọro naa pe idajọ oun lo kan.
Emi ti mo n baa yin sọrọ yii, mo le jẹ eku mẹwa lojumọ, ti o dẹ ni ṣe mi ni nkankan.
 Aare Muhammadu Buhari ti kedun iku Ojogbon Akinwunmi Isola, ogbontarigi oluko asa ati ede Yoruba, onkowe ati osere to n gbe asa Yoruba laruge nile yii ati loke okun.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Uganda n fi ati waini lo tata ti wọn ti yi lata.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ẹ gbà mí, Nàíjíríà gbá mi lórí àyẹ̀wò Covid-19 - Iyabo Ojo figbe ta Àlàyé rèé lórí ìdí tí ẹgbẹ́ òṣìṣẹ́ kò fi ní bẹ̀rẹ̀ ìyanṣẹ́lódì mọ́ lónìí Ẹgbẹ́ òkùnkùn yìnbọn lu ọmọ kan ní ikùn lásìkò ìdárò akẹẹgbẹ́ wọn Laycon ni ọmọ ológo tó jáwé olúborí ní ètò BBNaija season 5 'Lockdown' Kí ló wà láàrin Olorì Badra àti Bobrisky, tí ọ̀rọ̀ wọn fi wọ̀?
Arakunrin naa, Ajayi Peter ẹni ọdun mọkanlelaadọta to jẹ ọmọ ilu Itapa Ekiti ti gba idajọ ẹwọn gbere ni ile ẹjọ giga ilu Ado Ekiti fun pe o fipa ba ọmọbinrin ọmọ ọdun mejila lo pọ.
Mo n fi adura jagun'' Ọrọ ti Dokita Stella fi ṣe apejuwe ara rẹ ree ninu fọnran fidio kan to fi si oju opo ile iwosan rẹ Rehoboth Medical Centre to wa ni ilu Houston Texas lorileede Amẹrika.
Isa Funtua, Abba Kyari àti Zulaihat Buhari jẹ́ àwọn tó súnmọ́ Aàrẹ tó papòdà láìpẹ́ Ọkùnrin kan pa ara rẹ̀ sínú ọgbà àjọ TRACE tó n mójútọ ìrìnnà ọkọ̀ nípìnlẹ̀ Ogun Wo àwọn òṣìṣẹ́ kólẹ̀-kódọ̀tí tó ń fi ẹ̀mí wọn wéwu kí Abuja leè mọ́ tónítóní Èèyàn 562 tuntun ló tún ti lùgbàdì COVID-19 ní Nàìjíríà ní àná Eyi lo mu ki awọn aṣofin lọjọ kọkanlelogun oṣu keje ni ki awọn mii rọpo awọn ọga ologun to wa nibẹ lọwọlọwọ.
Mikel soro ohun di mimo lasiko to n ba awon akoroyin soro ni ipago iko naa, Essentuki lorile-ede Russia, ki iko ohun o to teko leti lo silu Kaliningrad nibi ti won yoo ti lo koju iko agbaboolu Croatia fun ifesewonse akoko won lojo abameta(Saturday).
Mkhitaryan gba ami-ayo akoko wole fun Arsenal, ti Aaron Ramsey.
Ẹ sọ fún gbogbo ìjọ eniyan Israẹli pé, ní ọjọ́ kẹwaa oṣù yìí, ọkunrin kọ̀ọ̀kan ninu ìdílé kọ̀ọ̀kan yóo mú ọ̀dọ́ aguntan kọ̀ọ̀kan tabi àwọ́nsìn kọ̀ọ̀kan; ọ̀dọ́ aguntan kan fún ilé kan.
Ìjọba Eko bẹ̀rẹ̀ sísan N35,000 owó oṣù tuntun ní November Mẹ̀kúnnù 80,000 l'Ọṣun ti j'ànfàaní ètò ìlera láìsan kọ́bọ̀ - Oyetola Ẹ wo ìpínlẹ̀ táwọn gómìnà tẹ́lẹ̀ àti igbákejì wọn ń gba dúkìá ìfẹ̀yìntì tabua Tomato Tomato naa ko gbẹyin ninu awọn ounjẹ ati ohun elo to ti gbowo lori lẹyin ti ijọba ti ibode pa.
O ṣe akoso Ile-iṣẹ awọn agbabọọlu ọmọbinrin Sweden laarin ọdun 2005 ati 2012.
O ni nigba ti oun gbọ pe o fẹ se igbeyawo miran, oun nifẹ rẹ sugbọn oun ko le younda rẹ lai jẹ pe o fi ọmọ oun kalẹ ki o si da owo ori ti oun san pada.
 Ó jáde nílé ẹ ̀ kọ ́ j.
Aṣọ aláró ati aṣọ àlàárì láti etíkun Eliṣani wọ́n fi ṣe ìbòrí rẹ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Àwọn òbí mi rò pé ẹ̀jẹ́ ti ta sí ọpọlọ mi nígbà tí mo bẹ̀rẹ̀ sí ba ẹranko igbó ṣọ̀rẹ́ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àwọn òbí mi rò pé ẹ̀jẹ́ ti ta sí ọpọlọ mi nígbà tí mo bẹ̀rẹ̀ sí ba ẹranko igbó ṣọ̀rẹ́ 28 Ìgbé 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 29 Ìgbé 2019 Itọ́jú ati ídáábò bo ẹranko igbo ni ọpọlọpọ awọn eniyan ti mu ni ọkunkun dun kakakiri agbaye, nitori wipe ọpọlọpọ awọn ẹranko naa ni wọn ti fẹ pa tan fun oniruuru idi.
Ogagun  Otiki ni ,iko omo ogun naa ri awon irinse
Bayii ni bi esi awon ifesewonse ohun se lo ni kikun:🇺🇦 D.
"Ọba ti ko ba si ti ṣe kii ṣe ọba niyẹn""."
New date for School resumption: Ìjọbá àpapọ̀ tún yíhùn padà lórí ọjọ ìwọlé àwọn akẹ́kọ̀ọ́
Àwọn wọnyii jẹ́ ọmọ Ada, aya Esau.
Ṣugbọn a óo jí olukuluku dìde létòlétò: Kristi ni ẹni àkọ́kọ́, lẹ́yìn náà, nígbà tí ó bá farahàn, a óo jí àwọn tíí ṣe tirẹ̀ dìde.
Ìyà yìí pọ̀jù Suleiman Akingbolu tó jẹ́ oṣiṣẹ ìjọba ìpínlẹ̀ ní ìlú Ekiti ni kò bá dá ti Fáyẹmí ba le mú ìlérí yí ṣé nítorí ará n ní àwọn oṣiṣẹ.
N óo dá àwọn arọ sí, kí wọ́n lè wà lára àwọn eniyan Israẹli tí wọ́n ṣẹ́kù, àwọn tí a túká yóo sì di orílẹ̀-èdè ńlá; OLUWA yóo sì jọba lórí wọn ní òkè Sioni láti ìsinsìnyìí lọ ati títí laelae.
S Embassy Ò ń lọ s'Amẹrika bí?
Àwòrán Amosun, Adekunle àti Buhari tó n dá awuyewuye sílẹ̀
Níbẹ̀ ni wọn yóo máa kó àwọn ẹbọ mímọ́ jùlọ sí; ati àwọn ẹbọ ohun jíjẹ, ẹbọ ìmúkúrò ẹ̀ṣẹ̀ ati ẹbọ ìmúkúrò ẹ̀bi, nítorí ibẹ̀ jẹ́ ibi mímọ́.
pẹlu ẹbi ati ọrẹ arabinrin Mooney ati ogbeni  Oguche, a si tun fi n da awon eniyan loju pe
Aisaya tún sọ pé, “Gbòǹgbò kan yóo ti ìdílé Jese yọ,yóo yọ láti pàṣẹ fún àwọn orílẹ̀-èdè,nítorí lọ́dọ̀ rẹ̀ ni ìrètí àwọn orílẹ̀-èdè wà.
Orile-ede Ethiopia salalaye pe, erongba ikede ilu-o-fara ro lose to koja ni lati fi dekun laasigbo jake-jade orile-ede naa, leyin ti won tun ogoro awon oloselu to wa logba ewon sile, pelu iyanju ati je ki alaafia ati isokan joba lorile-ede naa.
Gbogbo aráyé a sì máa fẹ́ wá sọ́dọ̀ rẹ̀, láti tẹ́tí sí ọgbọ́n tí Ọlọrun fún un.
Etisalat UAE Oríṣun àwòrán, ETISALAT UAE/FACEBOOK Ọkan gboogi lara awọn ileeṣẹ to jere ju lagbaye ni Etisalat, eyii to mu ki wọn lamilaaka ni orilẹ-ede marundinlogun.
Mọ̀ sí i nípa àwọn ọmọ Nàìjíríà mẹ́sàn-án tó ń díje nínú ìdìbò ilẹ America lọ́jọ́ Ìṣẹ́gun Wo ǹkan tó yẹ kí o mọ̀ nípa Joe Biden, tó ń kojú Trump nínú ìbò America Ǹkan tí a mọ̀ nípa kọ́lẹ̀jì olùdìbò tó ń fìdì ẹni ti yóò jẹ ààrẹ ilẹ̀ Amérika múlẹ̀ Wo iye owó tí ìjọba Amẹrika ń na sí ìdìbò Ààrẹ àti ibi tí owó náà ti ń wá Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí US presidential election 2020: Ta a ni Joe Biden tó ń díje fún ipò aárẹ America4 Bélú 2020 US presidential election 2020: Iye owó tí ìjọba Amẹrika ń ná sí ìdìbò Ààrẹ rèé2 Bélú 2020 US presidential election 2020: Esther Agbaje, Oye Owolewa àti Nnamdi Chukwuocha jáwé olúborí nínú ìdìbò Amẹrika6 Bélú 2020 US presidential election 2020: Bí ààrẹ Trump kò ṣe gbé ipò sílẹ̀ yóò ṣe àkóbá fún ọ̀pọ̀ ènìyàn17 Bélú 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fọ́nrán ohùn, Ẹ̀rù ń bá wá lóri ilera sẹnatọ Dino Melaye Igbẹjọ yii waye ni Lọkoja to jẹ olu ilu ipinlẹ Kogi nibi ti oludije ipo sẹnetọ fun ẹgbẹ APC, Senetọ Smart Adeyẹmi ti pe ẹjọ kotemilorun.
”O tenumo pe, ikolu ohun tun tesiwaju si agbegbe ilu Hawsh al-Dawahiri, ti awon omo-ogun olote naa tun n farapamo si.
aare ana fun ile-ẹjọ kotẹmilọrun, adajọ agba Mamman Nasir.
Àwọn ọmọ tí o bá tún bí lẹ́yìn wọn, ìwọ ni o ni wọ́n, ninu ogún tí ó bá kan Manase ati Efuraimu ni wọn yóo ti pín.
Awọn ileesẹ bii ileesẹ ẹrọ ayarabiasa Microsoft, ileesẹ abaniseto irinajo Expedia, ati awọn ileesẹ kéékèèké kan bi ile itaja oúnjẹ lo ti n gba owó Bitcoin.
ìdí ẹ̀ ni pé gbogbo ìgbà ni àwọn òdòdó aláràbarà máa ń wà nínú ọgbà náà.
Má lérí nípa ọ̀la, nítorí o kò mọ ohun tí ó lè ṣẹlẹ̀ ní ọjọ́ kọ̀ọ̀kan.
Àwọn amí náà rí ọkunrin kan tí ń jáde bọ̀ láti inú ìlú náà, wọ́n wí fún un pé, “Jọ̀wọ́, fi ọ̀nà tí a óo gbà wọ ìlú yìí hàn wá, a óo sì ṣe ọ́ lóore.
Àwọn ọkunrin meji kan yọ lójijì, wọ́n ń bá a sọ̀rọ̀.
Nítorí àwọn ẹ̀mí burúkú ń lọgun bí wọ́n ti ń jáde kúrò ninu ọpọlọpọ eniyan.
Ishmael náà ní ìtẹríba fún Ọlọ́run àti fún bàbá rẹ̀.
Dabiri –Erewa fi da awon omo orile ede Naijiria loju pe ijoba apapo ko ni kawo gbera lati foju awon odaran wonyi bale ejo.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Akomolede ati Aṣa lori BBC: Mọ̀ si nípa oríṣìí ẹ̀ka ìsọ̀rí ọ̀rọ̀ àti ìwúlò wọn O fi kun pe ni ṣe lo yẹ ki Aarẹ Muhammadu Buhari kọwe fiposilẹ ti ko ba lee da owo epo bẹntiro pada si naira mẹtadinlọgọrun un.
Ó dáhùn, ó ní, “Arakunrin mi ni wọ́n, ìyá kan náà ni ó bí wa.
Nitori idi eyi, wọn gbọdọ tun ifẹsẹwọnsẹ naa gba ni papa iṣire miran ti ko ni jẹ ti orilẹede Tunisia; Igbimọ alaṣẹ ajọ CAF yoo gbe ọjọ ati ibi ti ifẹsẹwọnsẹ naa yoo ti waye sita laipẹ; Nitori idi eyi, ẹgbẹ agbabọọlu Espérance de Tunis gbọdọ da ife ẹyẹ ati awọn ami ẹyẹ gbogbo ti wọn fun wọn pada si olu ileeṣẹ ajọ CAF lẹyẹ o ṣọka; Gbogbo awọn ọrọ gbogbo to ku lori ibawi, ato ati bi awọn oludari ere bọọlu yoo ṣe ri yoo tẹ awọn igbimọ gbogbo to ba yẹ lọwọ fun igbesẹ ati ipinnu wọn.
Àwọn miran nlo egbò igi olóró ti á gbọ́ wi pé ó ti wọ́pọ̀ ni orilẹ̀ èdè Nigeria pàtàki laarin àwọn ọ̀dọ́.
ó bu omi sinu àwokòtò kan, ó bẹ̀rẹ̀ sí fọ ẹsẹ̀ àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀, ó ń fi aṣọ ìnura tí ó lọ́ mọ́ ìbàdí nù wọ́n lẹ́sẹ̀.
Ṣugbọn gbàrà tí egbò kan bá ti hàn lára rẹ̀, ó di aláìmọ́.
Àkọlé àwòrán, Lagbegbe kan ti wọn n pe ni Danko saaju ki a to de Sagamu ni o ti waye.
Ní ọjọ́ kẹẹdogun oṣù kan náà sì ni àjọ àìwúkàrà OLUWA.
Ninu atẹjade ti adari ileeṣẹ Lagos State Waterways Authority (LASWA), Oluwadamilola Emmanuel lo fi iroyin naa lede bẹẹ.
Pinnick gboriyin fun okan lara awon torokan gbangban ninu igbimo ohun, ogbeni Sunday Dele-Ajayi, fun ise takuntakun re ti o n gbese ni ona lati mu igberu ba ere-idaraya , besini O tun ki saaju ayeye ojobi re, ogota odun ti yoo waye lose to n bo.
Ijọba ni apapọ gbogbo owo awọn eroja ti wọn fẹ pin fun awọn obi akẹkọọ to lẹtọọ si ounjẹ naa, jẹ ẹgbẹrun mẹrin ati igba Naira, N4,200.
Gbajugbaja ni lagbo ere Yoruba pẹlu ọpọlọpọ awada rẹ ti ko ṣe e fọwọ rọ sẹyin.
Orile-ede Niger da ami-ayo kan pada niseju die ki ifesewonse ohun o to wa si ipari.
O tẹsiwaju wipe, awọn ijọba ipinlẹ yoo nilo ajọṣepo awọn eeyan ilu lati le tete wa ojutu si ipenija awọn ajinigbe, ọdaran ati Fulani darandaran.
eyi ti eto aabo to peye yoo tun wa nibẹ.
 bee si ni inu mi dun pe en se idanilekoo fun awon omo orile-ede Naijiria ati pipese ise fun won.
“Nígbà tí mo bá fẹ́ dá ire Israẹli eniyan mi pada, tí mo bá sì fẹ́ wò wọ́n sàn, kìkì ìwà ìbàjẹ́ Efuraimu ati ìwà ìkà Samaria ni mò ń rí; nítorí pé ìwà aiṣododo ni wọ́n ń hù.
Ìdílé àwọn ọmọ Noa ni wọ́n jẹ́, gẹ́gẹ́ bí ìran wọn ní orílẹ̀-èdè wọn.
Gẹ́gẹ́ bí ìlérí tí mo ṣe fun yín, nígbà tí ẹ jáde kúrò ní ilẹ̀ Ijipti, mo wà láàrin yín; nítorí náà, ẹ má ṣe bẹ̀rù.
OLUWA ní, “Ọjọ́ ń bọ̀ tí n óo kó àtènìyàn, àtẹranko kún ilẹ̀ Israẹli ati ilẹ̀ Juda.
Ti a o ba gbagbe pe .
Nínúu kẹ́ẹ kọ̀wé fipò sílẹ̀ tàbí kí ẹ gba ìdádúró, ẹ mú ọ̀kan - Ilé aṣòfin sí àwọn ọ̀gá àgbà ológun 'Adarí àjọ NDDC, Pondei ń ṣe àìsàn ló ṣe dákú lásìkó ìfọ̀rọ̀wánilẹ́nuwò' Alaafin Oyo kò dàgbà jù fún mi, ohun tó wù mí ní mo ṣe pẹ̀lú ayé mi- Olori Aanu Wo àwọn nkan tó yẹ́ kí o mọ̀ nípa 'Awawa Boys', ọ̀kan lára ẹgbẹ́ òkùnkùn tó n dá Eko rú Awọn eeyan jankan jankan ni Naijiria lo peju sibi ẹyẹ ikẹyin oloogbe naa, bẹẹ lawọn oloṣelu ko gbẹyin pẹlu.
Ìdí ni pé gbígbé papọ̀ pẹ̀lú ìsọ̀kan àti ìfọwọ́sowọ́pọ̀ ló lè mú ìtẹ̀síwájú àti ìdàgbà-sókè wá
UNHCR wa rọ ijọba orilẹede Naijiria lati siwọ ninu fifi ipa da awọn atipo ọmọ Cameroon pada si orilẹede kowa wọn.
To ba ya, àwọn asoju náà ni yóò wa lọ dibo fún olùkopa to ba wù wọ́n, eyi si ni yoo di asoju fun ẹgbẹ Democrat.
Saaju ni ọjọru ni akọroyin Ahmed Salkida ti kọkọ tu kẹkẹ ọrọ yi sita loju opo Twitter Salkida ṣalaye ninu ọrọ rẹ pe ISWAP lawọn pa oṣiṣẹ naa to jẹ ọkunrin nitori pe ijọba n mu awọn ṣere ni lẹyin ọpọ oṣu ti awọn ti jọ n ṣe idunadura.
Wọ́n wá orúkọ wọn ninu ìwé àkọsílẹ̀ tí a kọ ní ìdílé ìdílé, ṣugbọn wọn kò rí i.
Ìdí tí a fi ń ṣe “Amin” ní orúkọ rẹ̀ nìyí, nígbà tí a bá ń fi ògo fún Ọlọrun.
Ikú ni ọ̀tá ìkẹyìn tí yóo parun.
Iwadii yii bẹrẹ pẹlu owo to to $1,018,500 ti Atiku fi ranṣẹ si ile ifowopamọsi, Habib Bank Limited ni ilu New York, lorilẹede Amẹrika.
Iwọ-orun ariwa Naijiria lo ni awọn oludibo to pọ ju lọ l'orilẹede naa.
Nigbati ile iwe girama ọlọdun mẹta akọkọ ma n fi 43,000 po ju awọn obinrin lọ.
 Ó jé òkan nínú adarí omo ogun nàígíríà nígbà tí ogun náà dójú iná tán po .
Ni ọjọru, gomina tẹlẹ nipinlẹ Ọsun, Ọlagunsoye Oyinlọla se'filọlẹ agbarijọpọ ẹgbẹ awọn ọmọ Naijiria nilu Abuja pẹlu awọn eniyan jankan-jankan nibẹ, ti wọn si n pe fun ifọwọsowọpọ agbajọ awọn mọ Naijiria fun idagbasoke ti o peye.
Ìlú Ijẹ̀bú - Jẹ̀ṣà sì tó nnkan bí ibùsọ̀ mẹ́fà sí Iléṣà ní apá àríwá ilẹ̀ Ìjẹ̀ṣà.
Ṣugbọn nígbà tí òfin dé, ẹ̀ṣẹ̀ yọjú pẹlu, 
Ẹ tẹ́tí sílẹ̀, ẹ̀yin ọmọ Israẹli ati ẹ̀yin ìdílé ọba!
Gege bi gomina ana ati okan lara igbmo amuseya egbe, mo mọ daju pe o ti di asa pe, nigba ti  won ba yan igbimo lati yanju awon aawọ, to n sele ninu egbe , ti awon gbimo naa ba pari ise won, awon oloye egbe yoo gbe abajade naa sile lai se ise lori re rara.
Ẹwẹ, banki to ga ju lọ ti ni ọna ti wọn yoo gba da sẹria fun awọn banki ti ko ba gba lati parọ owo fun awọn eniyan.
 Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Afeez Agoro: O ṣòro fún mi láti wọ Danfo jáde Bakan naa ni a ba awọn agbẹ sọrọ ni awọn agbegbe bii Ipapo, Ilora, Eruwa, Ogbomosho, Iresaadu, Ijaiye, Akufo ati Lalupon.
Ambasadọ Goni to ni eyi kii ṣe igba akọkọ ti iru iṣẹlẹ ki Ọga Madaamu wọn wa maa fi ẹjọ sun.
Yatọ si ile iwosan ti wọn ti n tọju ajakalẹ arun IDH nilu Akure, awọn dokita ko tọju alaisan lawọn ile iwosan ijọba.
and Civil Defence Corps NSCDC), awon osise eleto aabo oju-ọna(Federal Road
"Olori ẹsin Musulumi ni Naijiria sọ pe ""alaye wo leeyan fẹ ṣe lori bi awọn eeyan yii ṣe n rinrinajo pẹlu ọpọlọpọ ọkọ, lai si ẹni to ri wọn?"
Olayanju, lasiko to n ba BBC Yoruba sọrọ lori isẹlẹ naa fikun pe awọ̀n ajeji agbegbọn naa maa n to ẹgbẹrun kan nigba mii.
N óo mú kí àwọn alabojuto yín wà ní alaafia,àwọn akóniṣiṣẹ́ yín yóo sì máa ṣe òdodo.
N óo dúró níwájú rẹ lórí àpáta ní òkè Horebu.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, CAN: Samson ni ọrọ awọn ajinigbe ti gba àpérò ní Naijiria Ohun ni wọn fi n gbogun ti iṣoro awọn darandaran ati gbewiri to n ṣọṣẹ nibẹ.
Kí á tó máa bá ọ̀rọ̀ wa lọ, mo dúpẹ́ lọ́wọ́ Ọlọrun mi nípasẹ̀ Jesu Kristi nítorí gbogbo yín; nítorí àwọn eniyan ń ròyìn igbagbọ yín ní gbogbo ayé.
Ọlọrun súre fún wọn, ó ní, “Ẹ máa bímọ lémọ, kí ẹ sì máa pọ̀ sí i, kí ẹ kún gbogbo inú omi òkun, kí àwọn ẹyẹ náà sì máa pọ̀ sí i lórí ilẹ̀.
Umar ni wọn pe ni oga patapata awọn ikọ adigunjale to n ṣọṣẹ ni ipinlẹ Edo ati Ondo nibi ti wọn ti ṣe ikọlu si awọn ile ifowopamọ.
Ṣùgbọ́n ohun ayọ̀ tí mo rí ni pé, nígbà tí mo wo inú háhá náà dáadáa mo rí ẹyọ àgbàdo gbígbẹ kan.
BBC Yoruba ń pè yín sí ìpàdé ìtagbangba #BBCGOVDEBATE Àwọn kan ni wọn n fẹ ipinlẹ Ijẹbu, ọpọ n fẹ atunṣe soju opopona gbogbo ti kò dara ṣugbọn ariwo kikọ ilé iṣẹ tuntun ni awọn iyalọja n pa ki ọja wọn le maa tà ti ero ba pọ lati fi dẹkun airiṣẹṣe awọn ọdọ.
Iṣẹ́ àwọn ọmọ Geriṣoni ninu Àgọ́ Àjọ nìyí, Itamari ọmọ Aaroni alufaa ni yóo jẹ́ alabojuto wọn.
Toyin, ti ọpọlọpọ eeyan tun n pe ni 'Mama Ire' tẹsiwaju pe aye yii kere ju ki eeyan maa fi ojoojumo ja lọ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Port harcourt Bole: Mi kò mọ́ pé bọ̀ọ̀lì títà lè gbé mi dé ipò yìí láyé mi!
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Oshisko twins: Ojú wa rí, ṣùgbọ́n ìgbọ́raẹniyé ló ń ràn wá lọ́wọ́ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Oshisko twins: Ojú wa rí, ṣùgbọ́n ìgbọ́raẹniyé ló ń ràn wá lọ́wọ́ 23 Ẹrẹ̀nà 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 23 Ìgbé 2020 Ibeji tootọ kọ ni Adigun Ọmọbọlanle Valentina pẹlu Oyedele Adebisi Yewande ṣugbọn wọn ti sọ ara wọn di ejirẹ ẹdunjọbi oyila lẹnu iṣẹ adẹrinpoṣonu lori ikanni agbaye Twitter, Instagram ati Facebook ni wọn.
"Haa, iya ma jẹ mi o.
Mose dáhùn pé, “Mo bẹ̀ ọ́, fi ògo rẹ hàn mí.
Ó kígbe sókè pé kí wọ́n tètè lọ pe àwọn aláfọ̀ṣẹ, àwọn ará Kalidea ati àwọn awòràwọ̀ wá.
Bẹ́ẹ̀ ni n óo ṣe tẹ́ ibinu mi lọ́rùn lára wọn patapata.
Ni ìdin bá jẹ ẹ́ pa.
Lara awọn ọna ti ijọba fi mu nkan dẹrun sii fawọn olugbe ipinlẹ Oyo to tun mẹnuba ni yiyọ́ kuro owo itanran to yẹ ki ẹni to ba lugbadi ofin aitete san owo ori yẹ ko san lasiko yii.
Idibo lori ẹsun meji yii ko ṣai ba ilana ẹgbẹ oṣelu lọ.
African Drum Festival: Ìbejì Àyànbìnrin tó ti ń di gbajúgbajà
Onírúurú ni ìbéèrè wọn, ó sì pọ̀ ju ohun kíkà lọ.
Naijiria gbe ile-ẹkọ giga okeere lọ ile-ẹjọ Siga tita d‘eewọ lẹba ile ẹkọ Ọlọ́pàá fi páńpẹ́ ọba mú ọmọ ogun ilẹ̀ Naijiria Ijọba Eko din owo-ori ilẹ ati ile ku Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ẹni to ni ile iwe sare lati doola awọn akẹkọ ni ile wolu Ibeji obinrin ati Idowu wọn ọkunrin lo wa ninu ilé alaja meji naa ati ọmọkunrin miran ni eyi ti wọn ti ko wọn lọ sile iwosan lẹyin ifarapa wọn.
Pupọ ninu awọn ọmọ orile-ede naa ni o ti n faraya lori ijakulẹ́ yi ti awọ́n miran si ni ki wọn gba iṣẹ́ lọwọ aknimọọgba ikọ naa, Akwasi Appiah O fẹ́ yọ́ wọ ààyè ibùsùn àwọn obìnrin lọwọ́ ọlọ́pàá bá tẹ̀ ẹ!
Ni alẹ patapata ni ikọlu yii waye ni ileto Birane ni agbegbe ijọba ibilẹ Zurmi.
Eto naa ti ileeṣẹ to n mojuto o sọ pe awọn gbe kalẹ lati ''máa pese iranlọwọ'' Àwọn olùdókòwò MMM ń fi apá jánú fun awọn eniyan.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, COZA: Ọpọ èrò ló jáde ṣe lòdì sí ẹ̀sùn ìfipábánilòpọ̀ Fatoyinbo Bakan naa ni Kwankur sọ pe awọn pasitọ to wa ninu fidio naa lọ sile ijọsin COZA latinu ifẹ ọkan wọn ni.
Kí àwọn eniyan Israẹli sì máa pa ìlànà náà mọ́ títí lae, láti ìrandíran.
Oríṣun àwòrán, @Agboola Ninu atẹjade kan ti oludamọran Ọgbẹni Agboola fi sita, igbakeji Gomina Ondo kọwe fipo rẹ silẹ gẹgẹ bi ọmọ ẹgbẹ PDP lọjọ Aje, ọjọ kẹwaa oṣu kẹjọ ọdun yii(2020).
Iwe ipẹjọ ọhun to jade lọjọ kejila oṣu Keji ọdun 2020 sọ pe, iwa ẹtanu ni bi wọn ṣe gbẹsẹ le ilẹ naa jẹ ati inunibini.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Orílẹ́èdè Russia gbìyànjú ṣùgbọ́n wan kùnà láti kọjá ìpele ''quarter finals'' nínú ife ẹ̀yẹ àgbáyé Antoine Griezmann to jẹ agbabọọlu iwaju fun orilẹede France naa ko gbẹyin ninu awọn ẹlẹsẹ ayo lẹyin ti o ti gb'ayo mẹta wọle.
Burundi: Wọ́n búra fún Evariste Ndayishimiye bii Ààrẹ Burundi
Ní òru ọjọ́ kẹ̀jọ ni àwọn mẹ́ta kọ́kọ́ sálọ kúrò ní ibùdó tí wọ́n fi àwọn eléré ìdárayá wọ̀ sí.
  ki Olorun alagbara julo, Allah (SWT)fi baba si aarin awon olododo eniyan.
Àwọn ọmọ Israẹli ati àwọn ọmọ Juda ti da majẹmu tí mo bá àwọn baba ńlá wọn dá.
Funke Akindele fún mi lówó tí mo fi gba ilé, kò ra ilé fún mi o - Ajirebi Mínísítà fún ọ̀dọ́ àti eré ìdárayá tí fi ẹ̀bùn owó ránṣẹ́ si ìyá Kausara, ó tún jẹ́jẹ̀ẹ́ ẹ̀kọ́ ọ̀fẹ́ f'áwọn ọmọ rẹ̀ Ènìyàn tó tó igba ló ti bá ìṣẹ̀lẹ̀ ìbúgbàmù tó wáyé ni Lebanon rin báyiìí Olùrànlọ́wọ́ pàtàkì fún ọ̀rọ̀ ibojì òkú, àti àwọn ipò òṣèlú mìíràn tó jẹ́ kàyééfì ní Nàìjíríà Ṣugbọn Jones sọ pe oun ṣetan lati na tan bi powo pelu Tyson nitori oun ko wo ija gẹgẹ bi eremọde rara.
Ìwọ, OLUWA Ọlọrun àwọn ọmọ ogun,Ọlọrun Israẹli,jí gìrì, kí o jẹ gbogbo orílẹ̀-èdè níyà;má da ẹnìkan kan sí ninu àwọn tí ń fi ìwà ọ̀dàlẹ̀ pète ibi.
O fi kun un wi pe ẹṣẹ si ilu ni awọn fi le yọ Olubadan ni ipo, ati wi pe tita oye ilu Ibadan ja si ẹṣẹ si ilu, amọ awọn ko ni i lọkan lati yọ Olubadan nipo.
Mú olórí kọ̀ọ̀kan ninu ẹ̀yà kọ̀ọ̀kan láti ràn wọ́n lọ́wọ́.
 Ọrọ yii ti wa di alatagba laarin awọn Ọmọ orilẹede Naijiria bayii."
Níbi ìjókòó ìta gbangba kan tí ìgbìmọ̀ tó wà fọ́rọ̀ òògùn olóró nílé asòfin àgbà ilẹ̀ wa gbé kalẹ̀ ni asojú kan fún àjọ ìsọ̀kan àgbáyé, Harsheth Kaur Virk, ti gbé ìmọ̀ràn yìí kalẹ̀.
Àwọn Juu sọ fún un pé, “Ìwọ yìí ti rí Abrahamu, nígbà tí o kò ì tíì tó ẹni aadọta ọdún?
Ìwọ ọ̀rẹ́ mi, irohin kò tó àfojúbà, ìwọ náà mọ onírúurú ìṣòro ti ń bẹ ní inu aginjù bẹ́ẹ̀ ni gbogbo ìyọnu wọ̀n-ọnnì ni bàbá mi fi ojú rí bí òun ti ń bá ọ̀nà Igbó Olódùmarè lọ; síbẹ̀síẹ̀, èmi ni mo wí fún ọ, nǹkan ti mo kà silẹ wọ̀n-ọnnì kò jámọ́ nkankan rárá bí a bá fi wọ́n wé ohun tí ojú rẹ̀ ri nígbà tí ó de ọ̀hún tán-
 Bakan naa ni ọmọ naa ni ẹmi ifarada debi pe o gba lati fi ara rẹ silẹ lati fi rubọ naa.
Alhaja Kudirat Abiola akọni obìnrin, tó gba ọkùnrin mẹ́fà kí wọ́n tó leè pa á Èèyàn 681 ló lùgbàdì àrùn Coronavirus ní Naijiria ní Ọjọ́bọ̀ Buhari yóò báwọn ọmọ Nàìjíríà sọ̀rọ̀ lọ́la 'June 12' tí ṣe àyájọ́ ìjọba àwarawa Irú èpè wo ni Aláàfin Aolẹ ṣẹ́ fún ìran Yorùbá?
O ni aarẹ agba lo pa Adewole, ọdun mẹta si lo ku ko pe ọgọrun amọ awọn dupẹ fun Ọlọrun pe o da ẹmi wọn si di akoko yii.
Ojikutu - BBC News Yorùbá BBC News, YorùbáFò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ekiti fẹ́ kówó s'ígbó fún papakọ tí àwọn ará ìlú kò le lò - Ojikutu 14 Èbibi 2019 Oríṣun àwòrán, Akure Airport Onimọ nipa irinna ofurufu kan ti tako igbesẹ ijọba Ipinlẹ Ekiti ti o n mura lati bẹrẹ iṣẹ lori papakọ ofurufu ni ipinlẹ naa.
Ranti pé ìjà ni wọ́n ń dá sílẹ̀.
Ewe, ifesewonse ohun yoo waye lojo keji osu kefa odun ti a wa yii, fun igbaradi ni kikun saaju idije boolu agbaye to n bo lona.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Election Update 2019: Iléeṣẹ́ ológunní Wike gbówó ńlá fáwọn láti da ìbò rú 26 Èrèlè 2019 Àkọlé àwòrán, Ileeṣẹ ologun Naijiria fẹsun kan gomina ipinlẹ Rivers, pe o gbiyanju lati fi owo ra awọn ọmọ ogun lasiko idibo to waye nipinlẹ Rivers.
Ìlú yìí dàbí ìkòkò, àwa sì dàbí ẹran.
"Igbẹ́jọ́ ilé ẹjọ́ Sharia náà sọ pé Yahaya Sharif-Aminu jẹ̀bi ẹ̀sùn pé orúkọ Anọ́bi Muhammed lọ́nà àìtọ́ nínú orin rẹ̀ tó ń jà rànyìn lóri ""Whatsapp"" nínú oṣù kẹta ọdún yii."
Awọn ọmọ akọroyin oluwadii bii ti iya mi, Ugur Mumcu, sọ fun mi wipe lẹyin ti ado oloro ti wọn fi pamọ sinu ọkọ pa baba wọn, ọga ọlọpaa ilu naa kọ lati ṣe iwadii lori iku naa.
Aarẹ Olusegun Obasanjo lo da ipo naa silẹ lasiko iṣejọba rẹ lọdun 1999.
Àgùntàn-ìnàkí ń kọrin kí àwọn ọlọ́pàá ejò baà jí kí wọ́n baà lè da gbogbo wa lójú rú ṣùgbọ́n bí ó ti ń ké ni àwa túbọ̀ ń tẹ ẹsẹ̀ mọ́ ìrìn, ìgbà tí àwọn ọlọ́pàá máa jí wọn kò rí àwa mọ́ ṣùgbọ́n wọ́n rí òun.
Bá wa kí gbogbo àwọn ọ̀rẹ́ wa lọ́kọ̀ọ̀kan.
 Awon iya loja ati babaloja Bodija ni a pile  seto ayewo yii fun  lati fi sami ayeye ayajo ojo kindinrin lagbaye ni ajosepo eka itoju kindinrin ati awon ile ise aladani kookan”.
Ọ̀gbẹ́ni Diran Odẹyẹmi, to jẹ́ oluranlọwọ alukoro ẹgbẹ́ òṣèlú PDP sàlàyé pé, ìgbésẹ́ Oyinlola yìí kò ya ẹgbẹ òṣèlú PDP lẹ́nu nitori pe kìí se ara wọn tẹ́lẹ̀-tẹ́lẹ̀.
Ìpínlẹ̀ Ogun, Eko ti gbáradì fún ẹ̀kún omi yalé ‘A ó ran àwọn tó lùgbàdì omíyalé ìpínlẹ̀ Kogi lọ́wọ́’ Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Opọ ero lawọn oṣiṣẹ eleto aabo ti doola ẹmi wọn kuro ninu agabra ojo yii Awọn oṣiṣẹ ileeṣe panapana ni orilẹ-ede Niger ti ko awọn eniayna kuro ni Niamey to jẹ olu ilu Niger.
2 Bélú 2020 5:55 Fídíò, Soyinka Cancer: Àṣe ara mi ni iso ti n run gbogbo bí mo ṣe n ṣèrànwọ́ lórí jẹjẹrẹ, Duration 5,5527 Bélú 2019 Èyí tí a wò jùlọ 5:03 Fídíò, Omolola Arohunmolase Welder: Mo ti fí iṣẹ́ 'Welder' gbayì láwùjọ, tó mo fi tọ́ ọmọ yanjú, Duration 5,039 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 5:39 Fídíò, Akomolede ati Asa lori BBC: Olùkọ́ Kikelomo Ogunboye tan ìmọ́lẹ̀ sí ìwà olè ọ̀gá ọlọ́pàá Audu gẹ́gẹ́ bí àwòkọ́ṣe àsìkò yìí, Duration 5,398 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 4:11 Fídíò, Oba Adeyeye Ogunwusi: Ojú mi ti rí lọ́pọ̀ lọpọ̀, ọ̀pọ̀ èèyàn ni kò tilẹ̀ gbàgbọ́ pé mo lè jọba- Ooni, Duration 4,117 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 4:43 Fídíò, Promise Akinlade: ọmọ ọdún mọ́kànlá tó ń fi ìlù dárà bíi àgbàlagbà sọ̀rọ̀ nípa tálẹ́ǹtì rẹ̀, Duration 4,437 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 0:59 Gbọ́, Ìsẹ̀lẹ̀ jákèjádò orílẹ̀èdè àgbáyé láàárín ìṣẹ́jú kan, Duration 0,59wákàtí 5 sẹ́yìn 7:03 Fídíò, Olumuyiwa Bolade Adedeji Military Bruitality: Bí arákùnrin onípèníjà ara tí sọ́jà lù ṣe dé, Duration 7,035 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 4:45 Fídíò, Yoruba Films: Ẹ̀ẹ́ bẹ̀ mi kúrò láyé ni, mi ò lè kú - Fadeyi Oloro, Duration 4,4526 Èrèlè 2020 2:48 Fídíò, Esther Ajayi: Èmi náà ti borí ìṣòro rí ló ń mu mi ṣojú àánú, Duration 2,481 Ògún 2019 6:08 Fídíò, Adebola Ademilua: Àìrísẹ́ ṣè lẹ́yìn ìwé kíkà ló sọ mi dí ìyá onírú, mo dúpẹ́ tèmi, Duration 6,0827 Bélú 2020 5:55 Fídíò, Soyinka Cancer: Àṣe ara mi ni iso ti n run gbogbo bí mo ṣe n ṣèrànwọ́ lórí jẹjẹrẹ, Duration 5,5527 Bélú 2019 BBC News, Yorùbá Ìdí tí ẹ fi le è nígbàagbọ́ nínú ìròyìn BBC Ìlànà Lílò Nípa BBC Òfin Àṣírí Cookies Kàn sí.
Perete lara ọrọ adari ẹgbẹ ajafẹtọọ musulumi ni iha Guusu-Iwọ Oorun iyẹn ilẹ Yoruba, Comrade Muftau Zakariyah ree nigba ti BBC Yoruba kan si i.
Nibi ìdána ni alága iduro fun ẹbi ọkọ ati alaga ijokoo fún ẹbi iyawo a ti ṣiṣẹ gẹgẹ bii aṣoju fun ẹbi mejeeji.
Nínú àwọn àtúntẹ̀ tẹ̀lé-n-tẹ̀lé lẹ́hìnwá ti Ẹ̀kọ́ àti àwọn Májẹ̀mú, àwọn àfikún ìfihàn tàbí àwọn ohun àkọsílẹ̀ míràn ni a ti fi kún un, bí a ṣe gbà wọ́n àti bí a ṣe tẹ́wọ́gbà wọ́n nipa àwọn ìpéjọpọ̀ tàbí àwọn ìpàdé àpéjọpọ̀ ti Ìjọ tí ó ní àṣẹ.
Ẹẹmẹta lọ́dún ni Solomoni máa ń rú ẹbọ sísun ati ẹbọ alaafia lórí pẹpẹ tí ó kọ́ fún OLUWA, a sì máa sun turari níwájú OLUWA.
Iná ọ̀hún ti wá ran’lé wàyí, ó ti bọ́ sára aṣọ.
Lẹsẹkẹsẹ ọmọdebinrin náà dìde, ó bá ń rìn, nítorí ọmọ ọdún mejila ni.
Premier League: FIFA f'òfin de Chelsea kí wọ́n má lè ra agbábọ́ọ̀lù
Wọ́n ti ni kí àwọn alága ìjọba ìbílẹ̀ Ogun lọ rọọ́kún nílé Sìgá mímu ń di èèwọ̀ oògùn ìlera pípé lagbaye SEC: Tinubu kò gbọdọ̀ ṣe olúdarí iléeṣẹ kankan fódùn márùn ún Ẹlẹri mẹjọ ati ọpọ akọsilẹ ninu iwe lawọn olupẹjọ lo gẹgẹ bi idaniloju nigba ti igbẹjọ naa n lọ lọwọ.
Àwọn ìlú rẹ̀ sì ti tú, wọ́n ti wó palẹ̀,láìsí eniyan tí ń gbé inú wọn.
Ẹran tí ẹ bá fi rúbọ kò gbọdọ̀ ṣẹ́kù ní ìrọ̀lẹ́ ọjọ́ kinni, títí di òwúrọ̀ ọjọ́ keji.
Ṣé yóo sì fi olukuluku yín ṣe olórí àwọn ọmọ ogun rẹ̀?
Lẹta Jeremaya sí Àwọn Tí Ogun Kó Lọ sí Babiloni.
Eyi ni ǹkan to tọna láti ṣe.
Ninu iwe Ireke Onibudo, Ireke to kọ ipa ribiribi ninu fiimu naa ba ọpọlọpọ abamiẹda ja bii Ewure iberù.
Èyí ni ẹ óo fi mọ̀ pé Ọlọrun alààyè wà láàrin yín, kò sì ní kùnà láti lé àwọn ará Kenaani, àwọn ará Hiti, àwọn ará Hifi, àwọn ará Perisi, àwọn ará Girigaṣi, àwọn ará Amori, ati àwọn ará Jebusi, jáde fun yín.
Ofulue fikun pe ''Lati nnkan bi ọjọ kẹẹdogun oṣu Kẹjọ ọdun 2019, lawọn eeyan Magodo ti n gbadun ina wakati mẹrinlelogun lojumọ.
ISIS àti Boko Haram fẹ́ ṣoro lásìkò ìbò 2019 - Amẹrika Ni ipari, gbogbo wọn ṣalaye fun BBC pé ibẹru Olorun lo ṣe pataki julọ lookan aya olori rere lainii fiṣe ọjọ ori rẹ.
Òdodo ati òtítọ́ ni àwọn iṣẹ́ ọnà rẹ,Ọba àwọn orílẹ̀-èdè.
Obìnrin bíi Ruth Bader ni yóò gba ipò rẹ́ ní iléẹjọ́ tó gajùlọ nílẹ̀ Amerika- Donald Trump 'Mo mọ̀ọ́mọ̀ sin ọmọ-ọmọ mi, ìkókó jòjòló láàyè ni, nítorí wọ́n fipá bá ọmọbìnrin mi lòpọ̀ ló fi lóyún rẹ̀'!
" Mi ò ṣe ẹ̀tánú Ọọ̀ni ilé Ifẹ̀, ọmọ ìyá mi ni ṣùgbọ́n.
Ati pe ni kiakia ni ki ẹni to ba ni iru irora yii lọ sileewosan.
Abilekọ Otubusin sọ eyi lasiko ti ó n ba BBC Yoruba sọrọ lasiko ti ìkómọjade ọmọ tuntun ti Oluwa fi jíǹkí rẹ̀ lẹyin igbeyawo fun ogoji ọdun lai bimọ n waye nilu Abẹokuta, nipinlẹ Ogun.
10 Kíyèsíi, ìwọ ní ẹ̀bùn, àti pé alábùkúnfún ni ìwọ nítorí ẹ̀bùn rẹ.
 Oríṣun àwòrán, Akewugbagold Àkọlé àwòrán, Ìlànà IVF là fi bí ìbejì tẹ gbé lẹ́yìn idaduro ọdún méjìlá, ẹ jọ̀ọ́, ẹ tú wọn ṣílẹ̀ - Akeugbagold, aya rẹ bẹ̀bẹ̀."
Ikeji ni pe o jẹ ipe fawa ijọba lati mọ ohun tawọn ọdọ fẹ kaṣe'' Loni ọjọ Kẹtadinlọgbọn oṣu Kẹwa ni igbimọ to n gbẹjọ ifiyajẹni lati ọdọ ikọ SARS yoo bẹrẹ ijoko wọn.
– Kí Olódùmarè má ṣe jẹ́ kí ẹyẹ àkàlàmàgbò yọ ojú àwọn ọmọ ilé-ìwé wa jẹ.
Àwọn tí ó pè ni ó dá láre.
Ilé asòfin àgbà ilẹ̀ wá se àpèjúwe ìsẹ̀lẹ̀ yìí gẹ́gẹ́ bíi ìwà ọ̀daràn sí ìjọba, nítorí ó jẹ́ ète láti já ẹ̀ka kan nínú ìjọba Nàíjíríà gbà pẹ̀lú ipá.
ẹ mú ìlutí kan, kí ẹ fi lu etí rẹ̀ mọ́ ara ìlẹ̀kùn.
yoo fi san owo ajemonu awon osise.
Mi ò m'àwọn ẹgbẹ́ tó ń gbé ''Tinubu 2023'' kiri- Bola Tinubu 'Bí a kò bá fẹ́ ìbínú Ọlọ́run, a gbọ́dọ̀ jẹ́ kí Tinubu du ipò ààrẹ̀ lábẹ́ àsìá ẹgbẹ́ APC ní 2023' Gbogbo ohun tí ènìyàn nílò láti dári ni Tinubu ní - APC Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Tinubu: Nítorí Tinubu, àwọn ọmọge Sanwo-Olu da ìlù bolẹ̀ Bakan naa lo sọ pe bi oun ṣe di obinrin akọkọ gẹgẹ bi iyawo gomina ipinlẹ Eko, mu ki oun mọ pe itọni Ọlọrun nikan lo le mu oun ṣe aṣeyọri lori ipo naa.
Ọkunrin naa to kẹkọjade nile ẹkọ fasiti ni ẹka imọ nipa eweko tun fikun pe oun ko ms isẹ ajorinmọrin tẹlẹ, amọ aniyan oun lo ti oun de idi rẹ.
Ki Olorun ṣawari Kolawole Gold to sọnu ni adura BBC.
Ìpéjọpọ̀ mímọ́ yóo wà ní ọjọ́ kinni, ẹ kò sì gbọdọ̀ ṣe iṣẹ́ líle kankan ní ọjọ́ náà.
 lára ipá ni lílo ogùn apẹ ̀ fọn , bíbo ọ ̀ pọ ̀ ara pẹ ̀ lú aṣọ , àwọ ̀ n apẹ ̀ fọn , àti rírí pé kòsí omi adágún nítorí ibí ni ẹ ̀ fọn ti ń bísi .
"Oríṣun àwòrán, Facebook/Lawrence Oyor Ẹ gbọ ohun ti mọlẹbi Mike Bamiloye sọ fun BBC: ""Lagbara Ọlọrun, imura igbeyawo naa ti n lọ rẹgi rẹgi."
" Oríṣun àwòrán, Olukemi Olufunto Badenosh Ọṣu Kinni ọdun 1980 ni wọn bi Olukemi Olufunto Badenosh.
Ọgbẹni Odumakin ni bi ẹmi eeyan ko ba jọ awọn oniṣẹ laabi aarin awọn darandaran Fulani naa loju ki wọn ara wọn naa ṣodiwọn.
Adajọ naa ni tori eleyi, Gomina Oyetola ni ile ẹjọ fi ontẹ jan gẹgẹ bii Gomina.
Amọ, o rọ awọn eniyan lati maṣe jẹ ki ifẹhọnuhan naa da rogbodiyan, eleyii ti yoo wa mu ki ijọba paṣẹ pe wọn n da ilu ru.
Ṣugbọn ẹ jẹ́ kí inú yín ó máa dùn,kí ẹ sì máa yọ títí lae, ninu ohun tí mo dá.
Nítorí náà, nígbà tí Joabu dóti ìlú Raba, ó rán Uraya lọ sí ibi tí ó mọ̀ pé àwọn ọ̀tá ti lágbára gidigidi.
Àwọn ọmọ Israẹli bá kó ogun jáde láti Misipa, wọ́n bẹ̀rẹ̀ sí lé àwọn ọmọ ogun Filistini lọ títí wọ́n fi fẹ́rẹ̀ dé ìsàlẹ̀ Betikari, wọ́n ń pa wọ́n bí wọ́n ti ń lé wọn lọ.
Owurọ ọjọ Ẹti ni igbẹjọ kọkọ waye lori awọn afurasi naa nile ẹjọ Majisireeti to wa nilu Akurẹ.
 wọ ́ n wà lórí Àkójọ Àwọn egbògi kòṣeémáàní ti Àjọ Ìlera Àgbáyé , àwọn òògùn tó ṣe pàtàkì jùlọ tí a nílò fún ètò ìlera ìbẹ ̀ rẹ ̀ pẹ ̀ pẹ ̀ yòówù .
O gba bọọlu s'inu awọn losu to kọja ninu ifẹsẹwọnsẹ to waye pẹlu Brighton.
Gẹgẹ bi akọsilẹ, nkan ti o n fẹ ni Jihad.
Iná sọ lóòtọ́ láàfin mi, ṣùgbọ́n kò sí gìrí- Ooni Ile Ife Risikat, ìyá àwọn ọmọ olójú búlù tí bẹ̀rẹ̀ sí ní kọ́sẹ́ aṣojú lóge Wo ibùdó arẹwà tí ọ̀pọ̀ èrò ń ya lọ ní Abuja Olólùfẹ́ mi ṣèèsì fi ọkọ́ gbá mi sí gọ́tà, mo rò pé ọlọ́jọ́ dé ni - Iya Osogbo Ẹgbẹ́ akẹ́kọ̀ọ́ gíga n‘Ibadan ṣèwọ́de lọ iléeṣẹ́ ọlọ́pàá lórí afurasí tó dàwátì Oríṣun àwòrán, others Ìpànìyàn tún wáyé ní Akinyele, àwọn ará àdúgbò ṣe ìwọ́de Àwọn afurasí elétùtù ọlà ṣá obìnrin kan yánna-yànna nítosí Olorunkole Rogbodiyan bẹ silẹ ni agbegbe Akinyele ni ọjọ Ẹti nitori iku arabinrin kan ti iroyin sọ pe awọn kan fi àdá ṣa yanna-yanna ni agbegbe naa nirọlẹ Ọjọbọ.
Tí ẹ bá lọ bọ àwọn oriṣa, tí ẹ sì foríbalẹ̀ fún wọn, inú yóo bí OLUWA si yín, ẹ óo sì parun kíákíá lórí ilẹ̀ dáradára tí ó ti fun yín.
” Ó bá dọ̀bálẹ̀ fún un.
Àwọn alágbẹ̀dẹ wúrà ati àwọn oníṣòwò sì ṣe àtúnṣe tí ó yẹ ní ààrin yàrá òkè orígun odi ati ti Ẹnu Ọ̀nà Aguntan.
Ó ṣe òróró ìyàsímímọ́ ati turari olóòórùn dídùn bí àwọn tí wọn ń ṣe turari ṣe máa ń ṣe é.
Ọjọ Iṣẹgun, ti i ṣe ọjọ kẹtalelogun, oṣu Kẹwaa ni igbimọ to n mojuto eto aabo ipinlẹ naa yo tun ṣe ipade lati lati jiroro lori ohun to kan lati ṣe si aṣẹ konile o gbele to wa nita.
Jẹ́ kí èmi iranṣẹ rẹ rí ojurere rẹ,gbà mí là, nítorí ìfẹ́ rẹ tí kì í yẹ̀.
Ó ṣe agbada omi kan ati ère mààlúù mejila sí abẹ́ rẹ̀.
ori  afẹfẹ  gbodo wa sibi ipade  ti won yoo tun se  lọjọ Aje.
Alaafin Aole: Ṣé òótọ́ ni 'èpè rẹ̀' ń ja Yorùbá?
Oríṣun àwòrán, Ogun State House of Assembly Adari ile igbimọ aṣoju-ṣofin ipinlẹ Ogun, Olakunle Oluomo ti sọ l'Ọjọbọ wipe aṣofin mẹrin lo wọdi mọ ile igbọnsẹ kan ṣoṣo nile igbimọ aṣofin.
Lyin iṣẹlẹ yii, iroyin sọ pe ohun gbogbo ti pada sipo bo ṣe yẹ ni agbegbe naa ni ilu Ibadan.
Aarẹ ileẹjọ, Henry Agbaje sọ wi pe ileẹjọ ti sa gbogbo ipa wọn lati jẹ ki igbeyawo naa duro, amọ igbeyawo naa ti daru patapata.
Ṣugbọn nigba ti yoo fi di ọdun 2015, afiwe naa ti lọ soke si ìdá ogoji.
Fun apẹrẹ, wọn sun ifẹsẹwọnsẹ laarin ikọ Arsenal ati Manchester City to yẹ ko waye lọjọ kọkanla Oṣu Kẹta ọdun yii siwaju.
Wọn ni ko kọwe si ileeṣẹ ọlọpaa, tabi ajọ to n gbogun ti iwa jẹgudujẹra atawọn ajọ miran to n gbogun ti iwa ibajẹ, to ba ni ẹsun kankan lati fi kan Olubunmi Tunji-Ojo.
Gbogbo àwọn wolii, láti ìgbà Samuẹli ati àwọn tí ó dé lẹ́yìn rẹ̀, fi ohùn ṣọ̀kan sí ọ̀rọ̀ yìí, wọ́n ń sọ nípa àkókò yìí.
Gbenga Adeyinka - Àwọn Adẹ́rinpòṣónú Nàìjíríà lè di ààrẹ Èèmọ̀ rèé o!
Sùgbọ́n ẹwà rẹ̀ yìí náà ló ṣ'àkóbá fún un o!
“Èmi, OLUWA Ọlọrun àwọn ọmọ ogun, Ọlọrun Israẹli wá ń bi yín léèrè pé, ‘Kí ló dé tí ẹ fi ń ṣe ara yín ní ibi tó báyìí?
Àwọn obìnrin ilé ìgbìmọ̀ aṣòfin Amẹrika fọnmú sí ọ̀rọ̀ Trump O ni lootọ ni iṣọkan Naijiria jẹ awọn logun ṣugbọn ko de ibi ati fi ẹmi ẹya kan ra a pada.
ìpàdé ní wọ́n ó ti pinnu àsìkò tí ilé ẹ̀kọ́ yóò wọlé padà àti ìlànà ti àwọn olùkọ́ àti àwọn akẹ́kọ̀ọ́ yóò tọ̀ ti wọ́n bá wọlé "" Ọ̀pọ̀ àwọn òbí ni Ìpínlẹ̀ Kano lo tí n káyà sókè pé àwọn ọmọ ti pẹ́ nílé láì lọ sí ilé ìwé àti pé àwọn ilé ìwé péréte lo ń ṣe ìkẹ́kọ̀ọ́ orí ayélujára fún àwọn akẹ́kọ̀ọ́ wọn."
Adura Gbigba lori ayelujaraFun awọn Kristẹni kan, paapa awọn to n lọ si awọn ile ijọsin bi i Anglican ati ijọ Aguda, wọn ni isẹ to pọ lati ṣe ki awọn pasitọ igbalode ma ba a gbá wọn.
Kí OLUWA Ọlọrun rẹ ṣá ti wà pẹlu rẹ gẹ́gẹ́ bí ó ti wà pẹlu Mose.
Russia Shooting: Ọmọ ogun mẹjọ ni ilẹ Russia ni wọn ti ríkú òjiji he tí méjì míràn si farapa.
Amugbalẹgbẹ rẹ, Laolu Akande lo fi ikede naa sita loju opo Twitter rẹ.
Giroud 100th cap: fi àràmọ̀ndà góòlù méjì ṣayẹyẹ ìfẹsẹ́wọnsẹ̀ ọgọ́rùn ún tó gbá fún France
Àwọn àràmọ̀ndà ìbomú-bẹnu tó gbòde lásìkò Coronavirus yìí Kò sí ibùdó ayẹwo àrùn Coronavirus ní UCH, ẹ má wá fún ayẹwo lọ́dọ̀ wa - Ọga àgbà UCH Nígbà tó ń gbé ìdájọ́ rẹ kalẹ, èyí tó gbà wákàtí mẹta gbáko, adájọ́ Olabisi Akinade pàṣẹ pé, nítorí ìpèsè ààbò tó péye, kí wọn tí gbogbo ọ̀nà tó wọ inú gbọ̀ngàn igbejọ náà, kí wọn sì kó àwọn kọ́kọ́rọ́ rẹ wá fún òun, lọ́nà àti dènà kí idaru-dapọ má bàa wáyé lásìkò tí igbejọ bá ń lọ lọ́wọ́.
Wọ́n tẹ̀ sí ìwà àwọn orílẹ̀-èdè tí ó yí wọn ká; wọ́n kọ òfin tí OLUWA ṣe fún wọn pé wọn kò gbọdọ̀ tẹ̀lé ọ̀nà wọn.
Nígbà tí ó rí eléyìí ó ṣe bí olúfẹ́ òun ti kú ni, ó bú sí ẹkùn kíkorò ó sì wí pé: 
ile igbimo asoju ti kọkọ bọwọlu iwe abadofin yii ,
- Kemi Afolabi Yatọ̀ fún orí ìtàgé, wo ohun tí o kò mọ̀ nípà Mr Latin Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Kayode Abiara: Ọmọ Nàíjíríà, ẹ má ba ọkàn jẹ́ lórí ààbò tó mẹ́hẹ, ewu ìgbà ìkẹyìn ló jẹ́ Ta gan ni Mamman Daura?
Progressives Congress,APC) yoo bere ipolonogo  ipo aare ninu eto idibo ti yoo waye lọdun 2019,
Èmi ni obinrin tí o rí níjelòó, tí mo dúró níhìn-ín níwájú rẹ, tí mò ń gbadura sí OLUWA.
N óo tú ọ sí ìhòòhò lójú wọn, kí wọ́n lè rí ìhòòhò rẹ.
Akosemose lori ounje jije ati itoju ara nile iwosan ijoba ni Garki ni Abuja, Grace Abasirim, ti kilo fawon eniyan Naijiria lati sora fun jije ounje lale nitori pe o maa n je ki eniyan sanra sii ki ora po sii lara bee naa lo maa n fa ki odiwon suga to wa lara po sii.
Coronavirus tún ti ṣe ọṣẹ́ lórí iṣẹ́ líla ojú ọ̀nà relùwe láti Eko sí Ibadan - Ìjọba àpapọ̀ Àrùn Coronavirus fa'lẹ̀ya láwọn ìletò aláwọ̀dúdú ní Amẹ́ríkà Ni ọjọ Abamẹta ati ọjọ Aiku, oniruuru iṣẹlẹ iku ojiji lo waye ni ipinlẹ naa ninu eyi ti awọn eekan ti a ka silẹ wọnyii pẹlu wa.
Ọba Adesoji Aderemi, Ọọ̀ni Ifẹ̀ tó gba ipò ọba mọ́ tòṣèlú Iṣẹ́ Kudirat Abiọla ṣì ń fọhùn síbẹ̀, lẹ́yìn ọdún 23 tó papòdà Oshisko twins, àwọn 'ìbejì' tó ń dẹ́rìn ín p'òṣónú Wọ́n ta ère Ọ̀ṣun Osogbo sí Togo - Bàbá Ọṣun figbe ta Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí 2 sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 2:23 Fídíò, Water Generator: Ó leè ṣiṣẹ fún wákàtí mẹfà, kó tó sinmi, Duration 2,2310 Òkùdu 2020 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
Wọn ni nitori pe awọn ọlọpaa fẹ bẹrẹ si ni ko awọn ọkunrin to n ba ọkunrin lo pọ atawọn obinrin to n ba obinrin lo pọ si inu koto ọlọpaa.
Ní báyìí, tí a bá wo èdè Yorùbá, àwọn onímọ̀ pín èdè náà sábẹ́ ẹ̀yà Kwa nínú ẹbí èdè Niger-Congo.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Ibanujẹ nla ni iku Floyd jẹ fun awọn mọlẹbi rẹ.
Mo ti gbé ẹnìkan dìde láti ìhà àríwá,ó sì ti dé.
 wọ ́ n di ajalèlókun yìí , second mate ken quinn sì tọ ́ jú egbò rẹ ̀ .
Ikọọkan awọn orilẹede yii ni wọn fẹsẹ wọnsẹ pẹlu ara wọn nibamu pẹlu agbekalẹ tabili idije ti awọn osisẹ to n se kokari idije AFCON gbe kalẹ ati ofin to de abala Komẹsẹ o yọ̀.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ayuba Wabba: Ẹ̀yin gómìnà kò lẹ́tọ̀ọ́ sí owó ìfẹ̀yìntì òṣìṣẹ́, ẹ rìn jìnnà si 4 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 11 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Oríṣun àwòrán, News Agency of Nigeria Ọrọ aje Naijiria to dagun ti ba ọna miran yọ, to si ti nira fun ọpọ ipinlẹ lati ri owo osu to kere ju san fawọn osisẹ wọn.
Ẹ má ṣe é nítorí ohun tí ẹ óo rí gbà níbẹ̀, ṣugbọn kí ẹ ṣe é pẹlu ìtara àtọkànwá.
Gomina Ambode lasiko to n gbe oko naa kale fun asoju igbimo  ajo arannilowo ti kii se tijoba, CECP to wa fun fifon-rere irogun-sini-lapa nile ijoba ni Alausa ni Ikeja ni oko alagbeka fun itoju arun jejere ohun to oni arundinlaadorin le loodunrun milionu naira.
Jesu kọ́ bá àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ sọ̀rọ̀ ná.
Ó gbá gbogbo orílẹ̀-èdè jọ fún ara rẹ̀, ó sì sọ gbogbo eniyan di ti ara rẹ̀.
Nítorí ẹ mọ̀ pé ohun rere tí ẹnìkọ̀ọ̀kan yín bá ṣe, olúwarẹ̀ ìbáà jẹ́ ẹrú tabi kí ó jẹ́ òmìnira, yóo rí èrè gbà lọ́dọ̀ Oluwa.
Agbẹnusọ fun Gomina ipinlẹ Kogi, Fanwo Kingsley bu ẹnu atẹ lu iroyin naa, o salaye pe irọ patapata ni.
Loju àwọn ọmọ inu ile Delesolu, 'Àṣà ni kìí ṣe ẹ̀sìn rara' tori wọn gba pe kò si awo kan láwo ẹ̀wà lori ọọni naa.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ọgbà ẹ̀wọ̀n ni wọ́n ti já àbálé Esra lábẹ́ àwáwí àyẹ̀wò wúndíá 7) Tejumade Falade Adeboye: Tejumade ni Baalẹ Odopetu, ni ilu Akure, ko pẹ ti wọn gbe niyawo tan to gori itẹ naa.
“Bí olè ni mò ń bọ̀.
Nígbà tí èdè-àìyedè bá wà láàrin àwọn aládùúgbò meji, èmi ni mo máa ń parí rẹ̀ fún wọn.
 Ó pokùnso sí ìdí igi àyàn kan lẹ ́ bà ọ ̀ nà nítòsí Ọ ̀ yọ ́ nígbàtí Ọya : Ìyàwó rẹ ̀ kan tókù náà sì di odò .
Ilé iṣẹ́ Ìkóròyìnjọ Orí-ayélujára Olómìnira Bulka ni ó kọ́kọ́ ro ìyìn ìṣẹ̀lẹ̀ náà ṣáájú àwọn ilé-iṣẹ́ ìròyìn Bulka mìíràn.
" Lasiko to n sọrọ nibi ajọyọ isile naa ni agbegbe Ọmí nilu Ibadan, Ọba Enitan, eni ti Agbolu ti Ilu Agbaje Ọba Adekunle Adebọwale soju fun fi idunnu rẹ han fun aṣeyọri akanṣe iṣẹ naa.
”Ṣugbọn o gbọ́ ẹ̀bẹ̀ minígbà tí mo ké pè ọ́ fún ìrànlọ́wọ́.
Nígbà tí Jakọbu tají ní ojú oorun rẹ̀, ó ní, “Dájúdájú OLUWA ń bẹ níhìn-ín, n kò sì mọ̀!
O mú kí àwọn ọ̀tá mi máa sá níwájú mi,mo sì pa àwọn tí ó kórìíra mi run.
Fun apẹrẹ, ko ni si ọfiisi ọkọ gomina ninu iṣejọba temi""."
Nígbà tí wọ́n pinnu láti fi wá ranṣẹ sí Itali, wọ́n fi Paulu ati àwọn ẹlẹ́wọ̀n mìíràn lé balogun ọ̀rún kan tí ó ń jẹ́ Juliọsi lọ́wọ́, ó jẹ́ ọ̀gágun ti ẹgbẹ́ kan tí wọn ń pè ní Ọmọ-ogun Augustu.
Buhari, Makinde, Sanwo-Olu kẹ́dùn pẹ̀lú ẹbí Tola Oyediran, àkọ́bí lóbìnrin tí Obafemi Awolowo bí tó papòdà Àwọn akẹ́kọ̀ọ́ 181 pẹ̀lú Olùkọ́ lùgbàdì Covid 19 níléèwé aláàdáni kan nípinlẹ̀ Eko Bakan naa lo ni oun ti fi oyin dipo ṣuga.
Wo àbọ̀ tí ọmọba kan, obìnrin àkọ́kọ́ tó ṣe ìwádìí nípa rẹ̀ gbé jáde Oríṣun àwòrán, GETTY IMAGES/LAURENE BOGLIO Ọmọ ọba ni Marie Bonaparte, o lowo, o lọrọ, o gbajumọ, o tun mọ eeyan.
Òun náà sì wá sọ ó ní, ‘Bí mo ti n gún iyán ni obìnrin náà bẹ̀rẹ̀ sí bú mi tí o wí pé ọwọ́ mi kò ran odó iyàn, èmi ń gún iyán tíẹ́típẹ́, àti pé ẹnu ni èmi lè máa fọ́n kiri, kò sí nǹkan kan tí mo lè ṣe ni mo bá ni kí ó yé bú mi, n kò wí jù bẹ́ẹ̀ lọ, àfi “gbàì” tí mo ggbọ́ létí mi tí ó gbá mi létí, ni mo bá bẹ̀rẹ̀ ǹjẹ́ ki n kó o lẹ́sẹ̀ kì n nà án mọlẹ̀ ní ògèdèǹgbé, bí mo ti bẹ̀rẹ̀ báyìí’, ṣe ló gbe mi ní ìpá tí mo fi orí na ọlọ ata.
Super Eagles gba iṣẹ́ lọ́wọ́ Seedorf olùkọ́ni Indomitable Lions Cameroun Yinka Ayefele di bàbá ìbẹta Buhari ti buwọ́lu ẹ̀kúnwó sísan owó oṣù tuntun fáwọn òṣìṣẹ́ àpapọ̀ A ti wọ́gilé ìwọ́de lórí COZA tí a fẹ́ ṣe tẹ́lẹ́ nítorí.
 wọn a sì máa fi orúkọ wọn búra pàápàá .
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Báwo ló ṣe mo àsìkò orun?
Esi awon ifesewonse to n waye ninu idije boolu agbaye to n lo lowo lorile-ede Russia je ohun to n ya awon eniyan lenu lopolopo, eyi waye lataari bi iko agbaboolu orile-ede Japan se gbo ewuro soju iko agbaboolu orile-ede Colombia pelu ami-ayo meji sookan(2-1) lojo isegun (Tuesday).
Ileeṣẹ MultiChoice Group bi ijọba apapọ ti ṣe afikun owo ori VAT, epo rọbi ati ina mọnamọna lo jẹ kawọn naa gbowo le DSTV.
Bakan naa ni dokita naa ni ti ayika ba tutu, o see se ki ẹfọn ma le e raye nibẹ ju igba ti ayika ba gbona, eleyii ti o ma n waye lọpọ igba ni ilẹ Afirika.
N kò tún ní ohun pupọ ba yín sọ mọ́, nítorí aláṣẹ ayé yìí ń bọ̀.
Àlàyé rèé lóríi àjọṣepọ̀ tó wà láàrin èmi àti MC Oluomo - Ronke Oshodi Oke N kò ri ipa ẹ̀jẹ̀ lára ọmọ mi tó kú sí iléeṣẹ́ ọṣẹ, èjò lọ́wọ́ nínú - Òbí àkẹ́kọ̀ọ́ UI Ọmọ Nàìjíríà di agbábọ́ọ̀lù Áfíríkà tí iye owó tí wọ́n rà à ga jù nínú ìtàn!
Bi awọn kan ti ṣe n kan sara si ijọba lawọn miran n sọ pe oṣu mẹrin ti pọju lati fi wọ reluwe lọfẹ Bakannaa lawọn miran n bere bi wọn ti ṣe fẹ ṣeto reluwe ọfẹ ti wọn ko ba ti pari eto to yẹ.
ji adari agbegbe Daura, Alhaji Musa Umar gbee, ti won
Gomina Sanwo Olu ni nitori inira ti isede naa yoo mu ba wọn lasiko isede akọkọ ni oun ṣe bẹrẹ.
Ọlọrun ló rán mi láti bá ọ sọ̀rọ̀, ati láti sọ nǹkan ayọ̀ yìí fún ọ.
"Àwọn adarí lágbàyé ṣèpàdé láti ṣèrànwọ́ fún Lebanon lẹ́yìn ìbúgbàmù tó pa ènìyàn 158 Mo ti buwọ́lu àdínkù owó orí nítorí ìrọ̀rùn àwọn èèyàn ìpínlẹ̀ Ogun lásìkò Covid 19- Dapo Abiodun Obasanjọ dúró lórí ọ̀rọ̀ tó sọ lẹ́yìn ikú Kashamu- Kehinde Akinyemi Àwọn akẹ́kọ̀ọ́ da ìdánwò WAEC rú, wọn gún infijilátọ̀ ní 'compass' O ni ""Ibẹrubojo kọkọ gba ọkan awọn olukopa to wa ninu ile naa, ṣugbọn wọn pa ina ọhun, ohun gbogbo si pada bọ sipo."
Ọmọdé méjì àtàgbà kan ló kú nílé alájà mẹ́ta tó wó l'Eko pátápátá - LASEMA Kí ló mú Obasanjo ti ilẹ̀kùn mọ́ ẹbí, òṣìṣẹ́, ojúlùmọ̀ ní ibi òkú àna rẹ̀?
Wọ́n ní, “Èyí ni pé Ọlọrun ti fún àwọn orílẹ̀-èdè yòókù náà ní anfaani láti ronupiwada kí wọ́n lè ní ìyè.
Alukoro fun ileeṣẹ ọlọpa nipinlẹ Ondo, Fẹmi Joseph sọ fun akọroyin BBC Yoruba, pe eniyan mẹta ni awọn ti wọn ji gbe lootọ, ṣugbọn ''ileeṣẹ ọlọpaa ko ti i le sọ boya Fulani lo ji wọn gbe nitori pe a ko ti i ri wọn'' tako iroyin to jade pe awọn fulani daran-daran lo ji wọn gbe.
Íjọ Jésù Krístì ti Àwọn Ènìyàn Mímọ́ Ọjọ́-Ìkẹhìn
Plaovits ni iṣẹ ṣi n lọ lati dabo to yẹ bo awọn waya yii lọwọ eku ki iru iṣẹlẹ yii ma le ṣẹlẹ mọ.
Awọn eeyan kan to n mu ẹkẹ ree loju ija nilu Khartoum.
Bí ẹni náà kò bá ní ẹbí tí ó lè ra ilẹ̀ náà pada, ṣugbọn ní ọjọ́ iwájú, tí nǹkan bá ń lọ déédé fún un, tí ó sì ní agbára láti ra ilẹ̀ náà pada, 
Eyi lo sọ asiko idibo ipinlẹ Kogi di adá tatọ sawọn ipinlẹ guusu ati aarin gbungubn to ku.
14 Sẹ́rẹ́ 2020 Oríṣun àwòrán, Facebook/alaafinoyo Àkọlé àwòrán, Mí o ní kí Wasiu Ayinde má bọ̀wọ̀ fàwọn ọba ilẹ̀ Yorùbá ayafi.
Oríṣun àwòrán, Reuters Àkọlé àwòrán, Ile ijọsin St Sebastian's to wa ni Negombo ba jẹ tori ado oloro naa Awọn ile igbafẹ ti wọn tun sọ ado oloro si ni Shangri-La, Kingsbury and Cinnamon to wa ni olu ilu orilẹee naa.
O tun wa seleri lati gbe eto kan jade ti yoo mu idagbasoke ba awon obinrin, ni eyi ti yoo mu won lowo ninu eto iselu.
Nígbà tí ó jáde, kò lè bá wọn sọ̀rọ̀.
O tun kọ wa pe ki gbogbo awọn oṣiṣẹ to jẹ agbofinro ni ootọ inu lai ṣegbe bii olo Olùkọ́ Bunmi Femi Amao ló ń kọ́ wa ní Ọ̀rọ̀ Ẹ̀yán lonìí Àwọn oúnjẹ ilẹ̀ Yorùbá ní à ń kọ nínú Akọ́mọlédè àti Àṣà lónìí Àṣà Oge Ṣíṣe ní Akọ́mọlédè BBC Yorùbá ń gbé yẹ̀wò lónìí, Ó yá, iṣẹ́ ti bẹ̀rẹ̀.
Ìyàwó mi ló ṣì ń dáná, bu oúnjẹ mi, gé èékáná fún mi - Pásítọ̀ Adeboye Ọkùnrin kan fipá bámi lòpọ̀ lọ́mọ ọdún mọ́kàndínlógún- Funke Oshonaike Ààrùn Coronavirus tún ti ran ènìyàn 595 l'órílẹ̀-èdè Nàìjíríà Ẹ wo ọ̀nà tí ìjọba Nàìjíríà fẹ́ gbà san owó àwọn olùkọ́ iléèwé aládàni tí kò rówó oṣù gbà Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Ẹlẹ́ẹ̀kẹjọ t'óyún máà bàjẹ́ lára mi ni mo tó rí àànú gbà' Ẹnikan ti iṣẹlẹ naa to waye l'oṣu Karun, lo ya fidio naa.
Tanzania ni orilẹ-ede akọkọ ti yoo ṣilẹkun ile iwe rẹ fun awọn ekẹkọ nilẹ Afrika lẹyin igbele Coronavirus.
Nítorí òun ni Ọlọrun wa,àwa ni eniyan rẹ̀, tí ó ń kó jẹ̀ káàkiri,àwa ni agbo aguntan rẹ̀.
Kò sí ohun tí ó dàbí ọmọ ìyá nítorí pé okùn ọmọ ìyà yi púpọ̀.
Àwọn tí wọn máa ń pẹ́ ní ìdí ọtí ni,àwọn tí wọn ń mu ọtí àdàlú.
Ìtàn ìgbé ayé ọba Dafidi láti ìbẹ̀rẹ̀ dé òpin ni a kọ sí inú ìwé ìtàn tí wolii Samuẹli kọ, èyí tí wolii Natani kọ, ati èyí tí wolii Gadi kọ.
Ẹ̀yin ará, ẹ máa gbadura fún wa.
"Disu ti fi ye wa wipe loru ọganjọ ni ajọ to n ri si iṣẹlẹ pajawiri ni ipinlẹ Eko, LASEMA ti gbe agolo naa Buhari pàṣẹ́ kí ojú ọ̀nà Apapa gba ìdáǹdè ní kíákíá ""Họ́wù!"
Wọn yóo mú un wọ inú ìlú lọ, wọn yóo fún un ní ibi tí yóo máa gbé, yóo sì wà ní ọ̀dọ̀ wọn.
wọn jọ lo igba lasiko kan naa ni.
Coronavirus in Nigeria: K1 de Ultimate ní káwọn ọmọ Nàìjíríà tí kò bá ńidìí láti jáde ó gbé inú ilé wọn
Small Doctor bẹ BBC Yoruba wo ni oṣu keje nibi to ti sọrọ nipa igbesi aye rẹ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Small Doctor: Mo kórira igbó, ọtí àti sìgá nítorí màmá mi lòdì si Oti ṣalaye pe wọn ba ibọn lọwọ gbajugbaja olorin naa ti iwadi si ti bẹrẹ lori ẹsun naa ati pe ni kete ti ọrọ ba yanju, wọn yoo gbe lọ si ile ẹjọ.
L'ọdun 2017, orilẹede maarun lo fẹ ẹ ko ilaji ninu awọn to ni ibà kaakiri agbaye: Nigeria (25%), Democratic Republic of the Congo (11%), Mozambique (5%), India (4%) ati Uganda (4%).
Àwọn alárùn Coronavirus l'Eko gbé fídíò síta Salawa sọ pe ọkunrin naa ba oun sọrọ lori ikanni WhatsApp, to si sọ pe ki oun fun un lowo, bi bẹ kọ, oun yoo fi aworan ihoho rẹ lede fun gbogbo aye lati ri.
Igba mẹrinlelọgọsan an ni Chelsea ati Manchester United ti jọ koju ara wọn, igba kẹfa si ree tawọn mejeeji yoo koju ara wọn ninu idije EFL.
“Bí ẹ̀yin alufaa ti ń pọ̀ sí i, ni ẹ̀ṣẹ̀ yín náà ń pọ̀ sí i, n óo yí ògo wọn pada sí ìtìjú.
Oríṣun àwòrán, Ojude Oba Facebook Bi ọdun Ojude Ọba si se n fẹju si, to si n di itẹwọgba, naa ni aayan n lọ lati jẹ ko di ilumọọka jakejado agbaye.
Àwọn ọmọ Lefi ati àwọn alufaa ń kọrin ìyìn sí OLUWA lojoojumọ pẹlu gbogbo agbára wọn.
Iléeṣẹ́ epo rọ̀bì ná ₦116m lórí báírò, ìwé ìkọ̀wé, àwọn aṣòfin fìka hánu Àádọ́ta Náírà tí báńkì ń yọ nínú owó ìpamọ́ oníbàárà kò tọ̀nà - Iléejọ́ Agbébọn tún gbẹ̀mí àgbẹ̀ míì lọ́nà oko lágbègbè Ibarapa Sanwo-Olu, El-Rufai fara pamọ́ torí COVID-19 lẹ́ẹ̀kejì Àwọn agbófinró Nàíjíríà yóò rojọ́ níwájú iléẹjọ́ àgbáyé ICC Wo ìgbéyàwó olówó iyebíye tí awakọ̀ Kabúkabú ti jẹ̀bùn ọkọ N3.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù AFCON 2019: Àwọn orílẹ̀èdè tó ń ṣe bẹbẹ nínú ìdíje tó ń lọ ni Egypt 28 Òkùdu 2019 Àkọlé àwòrán, Nínú àwọn olrílẹ̀-èdè yìí, orílẹ̀-èdè bíi Burundi ti Nàìjíríà kọ́kọ́ bá gbá, Mauritanian àti Madagascar ń kópà fún ninu ìdíje AFCON fún ìgbà àkọ́kọ́.
Buhari ń fowó aráàlú gbàtọ́jú nílùú òyìnbó nígbà táwọn ilé ìwòsàn wa ti di mọ́ṣúárì - Falana Èèyàn mẹ́wàá tó m bọ̀ láti ìpàgọ́ àdúrà kú nínú ìjàmbá ọkọ̀ ojú pópó l'Osun Àwọn adájọ́ àgbà ilẹ̀ Yoruba dá àba kí ìkọ̀ Amotẹkun máa lo ìbọn Àwọn fíìmù Nollywood ń mú kí òògùn owó àti ìjínigbé gbilẹ̀ síi - Fashola Àrá sán pa aboyún ìnàkí àtàwọn mẹ́ta míì tó jẹ́ àrà ọ̀tọ̀ láyé Awọn olugbe adugbo naa sọ fun BBC pe awọn n gbọ iro ibọn latọdọ awọn ologun to wa ni agbegbe naa ti wọn si ni ki gbogbo eeyan doju bo ilẹ.
 Àwọn tí ó ń sọ ọ ́ tọ ́ mílíọ ̀ nù márùn-ún .
 O ti wa di ayanmo aare Muhammadu Buhari bayii lati tun gbogbo ohun ti isakoso ijoba PDP ti baje seyin se.
Kódà, òun ni mò ń lò lọ́wọ́ báyìí.
Ọjọgbọn Odekunle ni iroyin sọ pe o dagbere faye ni ibudo iyasọtọ fun awọn alarun Coronavirus to wa ni Gwagwalada ni ilu Abuja.
O gba obinrin tí wọn ń pè ní Jesebẹli láàyè.
Àwọn ẹni òkùnkùn ló já ìṣẹ́gun mi gbà, mò ń lọ sílé ẹjọ́ tó ga jùlọ - Bayo Adelabu Àbádòfin ìdájọ́ yíyẹ igi fún 'ni tórí ọ̀rọ̀ ìkóríra!
Èyí wà fún anfaani ẹnikẹ́ni tí ó bá ṣèèṣì paniyan.
Amofin Oluṣọla Oke to jẹ ọkan lara awọn oludije nibi idibo naa lo sọ eyi fun BBC News Yoruba.
Ọkan o jọkan ile iṣẹ igbohun safẹfẹ ati awọn alabaṣiṣẹpọ pẹlu ile iṣẹ BBC lo peju pesẹ fun ilanilọyẹ lori awọn ayederu iroyin.
Iforuko sile fun eto idibo yoo wa sopin lonii, bi ajo eleto idibo orile-ede ohun se ro awon eniyan ki won dawo iforuko sile naa duro.
Mó fẹ́ wálé láti Italy ṣùgbọ́n ofin tó de ìrìnàjò wọ Nàìjíríà ni kò jẹ́-ọmọ orílẹ̀èdè Nàìjíríà ní Italy Èèyàn mẹ́wàá míràn kó àrùn Coronavirus ní Nàìjíríà Ìgbésẹ̀ ìjọba láti kojú àrùn coronavirus ń pani lẹ́rìn ín- Pásítọ̀ Adeboye Kò tíì sí àrùn Coronavirus ní ìpínlẹ̀ Oyo, a ṣi ń retí èsì àyẹ̀wò - Ijọba Oyo Àwọn ìbéèrè tó yẹ kí o bi ara a rẹ̀ kí ó tó gba ìròyìn kankan nípa coronavirus gbọ́ Ìjọba ti pápákọ̀ òfúrufú Eko àti Abuja pa nítorí coronavirus Ẹgbẹ agbabọọlu rẹ sọ pe Fellaini ko ṣe ojojo tabi iba, bẹẹ ni ko si apẹẹrẹ arun coronavirus kankan lara rẹ nigba to pada de.
Jairi láti inú ẹ̀yà Manase ni ó gba gbogbo agbègbè Arigobu tí à ń pè ní Baṣani, títí dé etí ààlà ilẹ̀ àwọn Geṣuri, ati ti àwọn Maakati.
Ipo naa lo wa di ọdun 1960 ti wọn tun sọ ọ di minisita fun ọrọ awọn oṣiṣẹ fẹhinti di ọdun 1962.
Gẹgẹbii ajọ to n mojuto ajakalẹ arun lorilẹede Naijiria naa se sọ, awọn ipinlẹ ti eeyan marundinlogoji naa ti ṣẹyọ ni ipinlẹ Edo pẹlu eeyan mọkandinlogun.
Yóo san ẹ̀san fún wọn gẹ́gẹ́ bí iṣẹ́ wọn,yóo bínú sí àwọn tí wọ́n lòdì sí i,yóo sì san ẹ̀san fún àwọn ọ̀tá rẹ̀,ati àwọn tí ń gbé erékùṣù.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù CS Mum: Omotolani Ekene ní ọ̀pọ̀ èèyàn gbà pé ọ̀lẹ, arugún, aláìlera ni ẹni tó fi abẹ bímọ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ CS Mum: Omotolani Ekene ní ọ̀pọ̀ èèyàn gbà pé ọ̀lẹ, arugún, aláìlera ni ẹni tó fi abẹ bímọ 7 Ògún 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 22 Ìgbé 2020 Oju abiyamọ n ri to, ko to fi inu soyun, paapa ni ọjọ ikunlẹ ati lẹyin ibimọ.
wọ ́ n gbẹ ́ gẹgẹ ́ bí dígí tí wọ ́ n fi ń ka wákàtí láyé àtijọ ́ , nígbà tí wọ ́ n fi awọ ewúrẹ ́ bòó níwájú àti lẹ ́ yìn , tí wọ ́ n sì fi àwọn awọ tẹ ́ ẹ ́ rẹ ́ ṣe okùn tí ó so àwọn awọ méjèèjì pọ ̀ mọ ́ ara wọn láàrín .
Awọn kan korajọ sẹyin Ayodele Fayose paapaa julọ awọn to wa ni Ekiti, Osun, Ogun ati Eko ti awọn ti Oyo ati Ondo gba sẹyin Seyi Makinde Kìí ṣe emí ni mó ràn amúgbálẹ́gbẹ̀ẹ́ mi tó sọ̀rọ̀ abùkù sí FIBAN níṣẹ́- Wasiu Ayinde Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'N500 dé fún gbogbo ọmọ tuntun lóṣooṣù bí mo bá di gómìnà Ondo - Adeleye AAC Àìgbọ́n àti àìmọ̀kanmọ̀kàn ló ń da Fayose láàmù, kò gba ẹnu rẹ̀ láti sọ̀rọ̀ sí mi - Bode George Oloye Olabode George, tii se asaaju kan ninu ẹgbẹ oselu PDP nipinlẹ Eko, ti fesi si oko ọrọ ti gomina ana nipinlẹ Ekiti, Ayodele Fayose sọ si.
N óo sọ ilẹ̀ náà di ahoro nítorí pé wọ́n ti hùwà aiṣootọ.
Lara awọn ileewe to fara gba aṣẹ tuntun yii ni ileewe meje tawọn akẹkọọ n gbe ninu ọgba rẹ atawọn ileewe alalọde mii.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Omolola Arohunmolase Welder: Mo ti fí iṣẹ́ 'Welder' gbayì láwùjọ, tó mo fi tọ́ ọmọ yanjú Latinwọ ni Ladoja lo fi oko kan pa ẹyẹ meji lasiko irinajo rẹ silu Eko naa, ẹni to fi ẹsẹ kan ya sile Tinubu lati ba kẹdun lasiko ti agba oselu naa lọ sibi ayẹyẹ isisnku kan nilu Eko.
Oríṣun àwòrán, The paper Àkọlé àwòrán, Fidio naa ni imọran to le ni ẹgbẹrun lọna ọgọta laarin wakati melo to fi sita.
Ẹ máa ṣọ́nà, kí ẹ máa gbadura, kí ẹ má baà bọ́ sinu ìdánwò.
Pípàsẹ fún ọ̀dọ́mọdé kó jí ní agogo 7 òwúrọ̀ dà bíi kí èèyàn jí ẹni àádọ́ta ọdún ní aago 5 òwúrọ̀.
Ṣugbọn bí wọ́n ti pọ̀ tó yìí, àwọ̀n náà kò ya.
Láti ìgbà náà lọ ni àwọn ọmọ Israẹli ti ń bá ilé Dafidi ṣọ̀tẹ̀ títí di òní olónìí.
Iwadii kan tun se agbeyẹwo ọgọrun ìlú ni China, nibi ti coronavirus ti kọlu eniyan to le ni ju ogoji, o si tọka si i pe ti oju ọjọ ba tutu gan-an, aarun naa ko ni i fi bẹ ẹ tankalẹ.
Awọn oṣiṣẹ naa ni wọn pe pada sẹnu iṣẹ lẹyin imọran igbimọ ti Fasiti naa gbe kalẹ lori ọrọ idaduro ọhun.
18 Irinajo Afẹ, Isẹ ọna ati asa - 6,012,710,830.
Ṣugbọn àwọn ọmọ ogun Kalidea lépa ọba Sedekaya, wọ́n sì bá a ní pẹ̀tẹ́lẹ̀ Jẹriko; gbogbo àwọn ọmọ ogun rẹ̀ bá fọ́nká lẹ́yìn rẹ̀.
Ọba, tí orúkọ rẹ̀ ń jẹ́ OLUWA àwọn ọmọ ogun,fi ara rẹ̀ búra pé, bí òkè Tabori ti rí láàrin àwọn òkè,ati bí òkè Kamẹli létí òkun,bẹ́ẹ̀ ni ẹnìkan tí yóo yọ si yín yóo rí.
Yóo fi òdodo ṣe ìdájọ́ ayé;yóo sì fi òtítọ́ ṣe ìdájọ́ àwọn eniyan.
"Ọkọ Funke Akindele kó eléré àti òṣìṣẹ́ jọ fi ṣe ""Surprise Pato"" fún un lọ́jọ́ ìbí rẹ̀ Lizzy Anjọnrin fẹ̀si fáwọn agbọ́yì-sọ̀yí lórí ìgbéyàwó rẹ̀, Madam Sajẹ dasójú ilé iṣẹ́, àti àwọn ǹkan míràn tó ṣẹlẹ̀ lágbo tíátà lọ́sẹ̀ yìí Oríṣun àwòrán, OTHERS Àkọlé àwòrán, Fótó ìgbéyàwó yii ni Funke kọ́ka gbésíta ni ìbẹ̀rẹ̀ ọ̀sẹ̀ yìí."
Lẹ́yìn ọdún kan tí ìṣẹ̀lẹ̀ yẹn wáyé, ọmọ-ọ̀dọ̀ ilẹ̀-òkèèrè mìíràn gba ìdádúró ní ẹnu iṣẹ́ fún oyún tí ó ní.
"Coronavirus ti di ara wa, kò le è kúrò mọ láéláé - WHO Àfi ìgbà tí mo bọ́ sọ́wọ́ ọ̀tá mí nínú ìrìnàjò ìfẹ́- Roshan Ọkùnrin kan gbé ‘búrọ́ọ̀ṣì ìfọyín’ mì O ni: ""A ṣe akọsilẹ ẹjọ naa labẹ ofin to ni i ṣe pẹlu ṣise paṣi-paarọ ẹya ara."
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Orílẹ̀-èdè Togo gbe òfin tuntun silẹ̀ lórí ìwọ́de ìfẹ̀hónu hàn 8 Ògún 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 9 Ògún 2019 Àkọlé àwòrán, Orílẹ̀-èdè Togo: Kò sí ààye ìwọ́de ìfẹ̀hónu han mọ́ lórílẹ̀-èdè yìí Ìlé ìgbìmọ̀ aṣòfin orílẹ̀-èdè Togo, tí jan òfin tuntun tó ni kò si ààyè fún ìwọ́de ìfẹ̀hónú han lọ́ntẹ.
Isọri A- Awọn ti yoo maa lo ina mọnamọna fun ogun wakati tabi ju bẹẹ lọ.
Nígbà náà ni Jesu wí fún wọn pé, “Ẹ fi nǹkan tí ó bá jẹ́ ti Kesari fún Kesari, ohun tí ó bá sì jẹ́ ti Ọlọrun, ẹ fi fún Ọlọrun.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Eniola Badmus kilọ fun awọn to n bu pe o ti sanra ju lati dẹyin lẹyin oun.
"Tí a fiṣọwọ́ ní 4:58 16 Sẹ́rẹ́ 20214:58 16 Sẹ́rẹ́ 2021 ""Olórí àwùjọ tó ń fi eékà ilẹ̀ pààrọ̀ fún màálù torí ìnáwó ló jẹ́ ki darandaran rọ̀wọ́ mú"" Owoseni wa gba awọn ọmọ Yoruba nimọran lati mase pe maalu ni buọda, tori pe wọn fẹ jẹran, tabi fi ohun ti wọn fẹ jẹ loni, ba ọjọ ọla wọn jẹ."
Àwọn òbí rẹ̀ fèsì báyìí nítorí wọ́n bẹ̀rù àwọn Juu; nítorí àwọn Juu ti pinnu láti yọ ẹnikẹ́ni tí ó bá jẹ́wọ́ pé Jesu ni Mesaya kúrò ninu àwùjọ.
Bakan naa ni wọn ni ori ko awọn oṣiṣẹ meji kan yọ lọwọ ijamba ina ọhun 'EFCC gbẹ́sẹ̀ lé owó Davido, Adeleke' Magu ati Keyamo ri‘binu ijọba Buhari gbọ́dọ̀ bẹ̀rẹ̀ ìwádìí Ganduje láàrín ọjọ́ mẹ́rìnlá-SERAP Ajẹ ké lana ọmọ ku loni O jọ gáté kò jọ gàté lọrọ to wa nilẹ yi pẹlu pe ko tii ju ọjọ mẹrin lọ ti Aarẹ Buhari paṣẹ pé kajọ EFCC ṣe iṣiro gbogbo owo ti o ti ri gba ti ina fi sọ ni ile ti wọn n ko ifitonileti si.
Loni ọjọ kẹrinla oṣu kejila ọdun 2020 ni onidajọ Okon Abang to n gbọ ẹjọ naa ya sọtọ fun idajọ rẹ.
Ni bayii, gbogbo eto lo ti to sile fun Aare Muhammadu Buhari, igbimo ajo NFF ati awon torokan gbangban lati gbalejo ife-eye boolu agbaye ni Naijiria, eyi ti o je ojuse ajo to n ri si boolu lagbaye FIFA lati lo safiahan ife-eye ohun lorile-ede kookan ti yoo maa kopa ninu idije agbaye naa Bakan naa, ni awon ololufe boolu afesegba nilu Abuja ati Eko yoo ni anfani lati yaworan pelu ife-eye agbaye ohun.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Agbófinró mú ọ̀dọ́mọkùnrin 57 níbi ètò ìgbaniwọlé fún ìbálòpọ̀ akọ-sí-akọ 28 Ògún 2018 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ofin Naijiria ko tako ibalopọ laarin ọkunrin s'ọkunrin Ẹgbọn ọkan lara awọn ọdọmọkunrin ti awọn ọlọpaa ko ni ọjọ Aiku nipinlẹ Eko, ti wọn fẹsun kan pe wọn n si ibalopọ akọ-si-akọ, ni irọ ni wọn pa mọ aburo oun.
Wọ́n ń wí pé,“Aláásìkí ni ẹni tí ó ń bọ̀ bí ọba ní orúkọ Oluwa.
"Mí ò gba kọngila gẹ́gẹ́ bi ọlọ́dani"" Anyanwu fi kun pé nítori pé òun jẹ́ ọmọ ẹgbẹ́ PDP ní oùn ni Akpabio ṣe n so irú nkan bẹ́ẹ̀ láti fi ba orúkọ oun jẹ́."
Nítorí ohun tí ó bá kún inú ọkàn ni ẹnu ń sọ jáde.
OLUWA yóo wá jáde, yóo bá àwọn orílẹ̀-èdè wọnyi jà, bí ìgbà tí ó ń jà lójú ogun.
Ṣugbọn nisinsinyii, mo ti kọ́ ilé kan tí ó lógo fún ọ,ibi tí o óo máa gbé títí lae.
Ati pe awọn ti di ọrẹ, eyi si lo mu ki oun gba yara nile itura, ki ọrẹ awọn le ba a gbooro si.
Mo rí ìfarahàn ògo OLUWA níbẹ̀, gẹ́gẹ́ bí mo ti rí i lẹ́bàá odò Kebari, mo bá dojúbolẹ̀.
Èèyàn 1,300 ni ìjọba Nàìjíríà ń wá báyìí nítorí àrùn Coronavirus Ìyá ọmọ tó sọnú níléèjọ́sìn l'Akure bú sẹ́kún nílé ẹjọ Báwo ni o ṣe le mọ̀ pé o ní àrùn Coronavirus?
Nitoripe alatako rẹ nigba naa, Donald Trump tawọn to pọ julọ ni igbimọ agba ọjẹ oludibo alaṣẹ, Electoral College dibo fun lo gbegba oroke.
Ireti ọpọ onwoye ni wipe, ọgbẹni Cyril Ramaphosa to jẹ alaga ẹgbẹ to n sejọba lorilẹede South Africa, ANC ni yoo bọ si ipo naa.
Gani Adams: OPC ti ṣe tán láti kojú ìpèníjà ààbò ilẹ̀ Yorùbá
"Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, ""Sex for grades"": Undercover in West African universities ''Ti awọn ẹbi ọmọde ti wọn ba lajọṣepọ bakẹjọ lọ sọdọ awọn ọlọpaa, ẹjọ naa ko ni lojutu nitori awọn ọlọpaa naa ni yoo gbawọn nimọran lati lọ yanju ọrọ naa ni itubi inunbi laarin ara wọn nile."
Awọn ọmọ Chibok- 'Mẹ́ẹ̀dógún lókù tó wà láàyè'
Fún àpẹẹrẹ, tí a bá ní agbẹjọ́rò gidi kan.
 E o ni anfaani lati dibo ni ibudo idibo ti
’ Mo ní láti jẹ́wọ́ fún un.
Ẹjọ́ Walter Onnoghen: NJC nìkan ló lásẹ láti yọ Adájọ́ Ágbá
Ní ìparí, ẹ̀yin ará, ẹ máa gbadura fún wa, pé kí ọ̀rọ̀ Oluwa lè máa gbilẹ̀, kí ògo rẹ̀ máa tàn sí i, àní gẹ́gẹ́ bí ó ti rí láàrin yín.
“Dájúdájú OLUWA Ọlọrun kì í ṣe ohunkohun láì kọ́kọ́ fi han àwọn wolii, iranṣẹ rẹ̀.
Kí ẹ dàbí àwọn tí ó ń retí oluwa wọn láti pada ti ibi igbeyawo dé.
Mo ṣe tán láti kú tọmọ taya bí wọn kò bá fi El-Zakzaky sílẹ̀ - ọmọ ẹgbẹ́ Shiite O fẹsun kan ijọba pe wọn pa ọmọ El Zakzakky mẹta ati awọn ọmọ Shiite to le ni ẹgbẹrun kan ni eyi to ṣokunfa iwọde kotẹmilọrun yii.
 O je eni ti o loye isakoso ere idaraya.
Bakan naa, laipẹ yii la tun kọ iroyin miran nipa awọn olo, ẹlẹjẹ tutu mẹjọ ti wọn n gbe ẹmi Alaafin tilu Ọyọ Èyí ni àwọn arẹwà ‘ẹ̀lẹ̀ Daddy’, àfẹ́fẹ́ tí Aláàfin fi ń mí .
babajide olusola sanwo-olu ( ti a bi ni june 25 , 1965 ) je oloselu lati ipinle eko ati idibo fun gomina ipinle eko ti odun 2019 fun egbe igbimọ [ .
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Port Harcourt dumped babies: Iléeṣẹ́ ọlọ́pàá rí òkú ọmọ ọjọ́ kan he lórí ààtàn ní Port Harcourt 26 Bélú 2020 Oríṣun àwòrán, Getty Images Iléeṣẹ́ ọlọ́pàá palẹ̀ òkú ọmọ ọjọ́ kan mọ́ lẹ́yìn t́i wọ́n jùú sórí ààtàn.
Àtúnbọ ̀ tán tó ní ipá kò fi bẹ ́ ẹ ̀ wọ ́ pọ ̀ .
Ó dá a lóhùn pé, “Bẹ́ẹ̀ ni, Oluwa, mo gbàgbọ́ pé ìwọ ni Mesaya Ọmọ Ọlọrun tí ó ń bọ̀ wá sí ayé.
National ID: Anthony Joshua gba nọ́mbà ìdánimọ̀ NIN, wo èsì àwọn ọmọ Nàìjíríà
a bí síkírù Àyìndé barrister nínú ẹb ́ i sàláwù balógun ní ìlú Ìb ̀ adàn , bàbá rẹ ̀ salawu balógun jẹ ́ alápatà Ẹran , nígbà tí ìyá rẹ ̀ jẹ ́ oníṣòwò pẹ ́ pẹ ̀ ẹ ̀ pẹ ́ .
Gbogbo wọn ni wọ́n ṣe ìrìbọmi ninu ìkùukùu ati ninu òkun, kí wọ́n lè di ọmọ ẹ̀yìn Mose.
Eyi wa lati mọ boya o mu ọti tabi ogun oloro.
Gege bi atejade to wa lati eka iroyin ajo  EFCC naa se sọ, Akeju eni odun mokanlelogbon
Iṣẹ́ bọ́ lọ́wọ́ ọ̀gá ilé iṣẹ́ ológun lórí ikú Fulani 134 A kò lè gba àwọn jandùkú Fulani láàyé nílẹ̀ Yoruba -Awọn gómínà Ẹ yàgò fún ìwà adìẹ dàmí lóògùn nù, màá fọ lẹ́yin lásìkò ìjà - Buhari Ṣé Fulani daran-daran ni àwọn tó n jí ènìyàn gbé ní ìpínlẹ̀ Ondo?
Bí ó bá jẹ́ pé ó wà ninu ayé, kì bá tí jẹ́ alufaa rárá, nítorí àwọn alufaa wà tí wọn ń mú ẹ̀bùn àwọn eniyan lọ siwaju Ọlọrun gẹ́gẹ́ bí ìlànà òfin.
Agbẹnusọ gomina Babajide Sanwo-Olu, Gboyega Akosile lo kede bẹ ninu atẹjade kan to fi lede loju opo Twitter rẹ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Nnamdi Kanu: Ilé ẹjọ́ wọ́gilé béèlì Nnamdi Kanu 28 Ẹrẹ̀nà 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Kò pẹ́ púpọ̀ lẹ́yìn tí wọ́n gba onídúró rẹ̀ tí Nnamdi Kanu sá kúrò ní orílẹ̀èdè Nàìjíríà Ile ẹjọ ti paṣẹ ki awọn agbofinro o pada lọ fi panpẹ ọba mu olori ẹgbẹ ajijagbara ẹya Biafra, Nnamdi Kanu.
Ọ̀dọ̀ fásitì jànkàn Oxford ló ti jáde Báwó ni òògùn dexamethasone ṣe ń ṣiṣẹ́ lára Coronavirus cases in Africa- Iye awọ̀n tó ní Coronavirus ní Áfíríkà Ẹwẹ, eeyan 19,270 lo ti ri iwosan gba ti wọn si ti ja ajabọ lọwọ ajakalẹ arun naa.
Aare Muhammadu Buhari yoo sepade po pelu aare orile-ede France, Emmanuel Macron nile aare nilu Abuja lojo isegun(Tuesday).
Iya Rainbow: Ó yẹ́ ká máa yẹ́ àwọn onítíátà sí ní ààyè, kìí ṣe òkú wọn
Amọ to ba ti wa di nkan to n ṣẹlẹ lemọlemọ, kini ka ti ṣe eyi si?
Ṣugbọn ẹni tí ó bá gbeyawo yóo máa páyà nípa nǹkan ti ayé yìí, yóo máa wá ọ̀nà láti tẹ́ iyawo rẹ̀ lọ́rùn; 
Àwọn ìràwọ̀ ojú ọ̀run já bọ́ sílẹ̀, bí ìgbà tí èso ọ̀pọ̀tọ́ bá já bọ́ lára igi rẹ̀ nígbà tí afẹ́fẹ́ líle bá fẹ́ lù ú.
Ko tan sibẹ o, ninu fidio naa lo ti han bi Erica paapa n ke ha, yu, bi ẹni n gbadun nkan to dun.
Weah ti kopa fun iko agbaboolu PSG
Peers of Heaven: Ààrẹ ẹgbẹ́ Emèrè ní àwọn ti wà tipẹ́, wọn kò pariwo síta ni
Awọn oṣiṣẹ inu baalu gbọdọ ri i daju pe awọn eero fi sanitaisa pa ọwọ wọn ti wọn ba fẹ ẹ sọkalẹ ninu baalu.
Oríṣun àwòrán, @Audu Àkọlé àwòrán, ikú to n pa ojugba ẹni ni ọrọ yii n di ni Naijiria Ọkan ninu awọn ọgagun ẹkun yii to ni ki BBC ma darukọ oun ṣalaye pe lojiji ni oun kọkọ gba ipe pajawiri lori iṣẹlẹ naa.
Ìpín ti Reubẹni yóo wà lẹ́gbẹ̀ẹ́ ti Efuraimu, láti ìlà oòrùn títí dé ìwọ̀ oòrùn.
aare tun fi aabo to peye da awon ara ilu loju lakooko ti won ba n se ojuse won,
Abajade ipinlẹ kọọkan ninu esi tuntun naa re e: Lagos-150 Rivers-49 Oyo-43 Delta-38 FCT-26 Anambra-20 Kano-20 Plateau-18 Edo-14 Ó ṣeéṣe kí àrùn Coronavirus tànkálẹ̀ gba inú afẹ́fẹ́- WHO 'Rọ́bọ́ọ̀tì ni yóò máa yẹ̀ yìn wò kẹ́ẹ tó rìnrìnàjò òfurufú ní Nàìjíríà' Hushpuppi di gbajúmọ̀ ẹlẹ́wọ̀n tó ní nọ́ńbà l‘Amẹrika, orúkọ̀ rẹ̀ wà lórí ayélujára Olórí òṣìṣẹ́ ìjọba ìpínlẹ̀ Kwara, Adisa Logun ti dágbére fáyé lẹ́yìn tó lùgbàdì àrùn Covid-19 Awọn ipinlẹ to ku ni: Bayelsa-13 Enugu-13 Osun-12 Kwara-10 Borno-8 Ogun-7 Kaduna-6 Imo-4 Bauchi-3 Gombe-3 Niger-2 Adamawa-1 Ènìyàn 575 ló tún ní ààrùn Covid-19 ní Nàìjíríà ní 05/07/2020 Awọn to ni aarun Covid-19 ni Naijiria ti pe 29,789, lẹyin ti ajọ NCDC tun kede eeyan 503 to tun ṣẹṣẹ ni i.
ilera, ina mọna-mọna ,eto idagbasoke lori ohun amayedẹrun ati gbigbogun ti isẹ
se so: “Asiko ti to bayii, nitori awon Yoruba bo, won ni: bi a ba da ojo,
Lara awọn ti aarẹ gba wọ ẹgbẹ rẹ ni gomina ipinlẹ naa meji nigba kan ri Adamu Mu'azu ati Isa Yuguda.
"Ìjọba Oyo fẹ́ mọ ikú tó pa akẹ́kọ̀ọ́ UI níléeṣẹ́ tó ń ṣe ọṣẹ Àwòkọ́ṣe ìwà ìrẹ̀lẹ̀, òtítọ́ àti olùfẹ́ mẹ̀kúnnù ni Ayo Fasanmi - Ìjọba Osun Àwa àti fijilanté pẹ̀lú ọdẹ́ ìbílẹ̀ ló dojú kọ adigunjalè ní First Bank Okeho - Iléeṣẹ́ ọlọ́pàá ""Ọmọ mi kò tíì mọ̀ pé òun ti di ìlúmọ̀ọ́ká, ó ń wádìí bó ṣe ń rí ara rẹ̀ lórí ayélujára"" Ìtàn ọba Yorùbá tí wọn yẹgi fún torí ó jí ọmọ gbé ṣe ètùtù Ẹ káàbọ̀ sọ́jọ́ Arafat, tí Ọlọ́run yóò fi ààwẹ̀ Mùsùlùmí pa ẹ̀ṣẹ̀ wọn rẹ́ Boko Haram da ìbọn bo ọkọ̀ gómìnà Borno, ẹ̀ṣọ́ àláàbò rẹ̀ farapa Oríṣun àwòrán, Facebook/Gov Zullum Ijọba ipinlẹ Borno ti fi idi rẹ mulẹ pe, lootọ l'awọn agbebọn Boko Haram kọlu awọn ọkọ to n kọwọrin pẹlu gomina ipinlẹ naa, Babagana Zullum ni Ọjọru."
Ó gbé ọkunrin náà ka orí kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ rẹ̀ tí ó gùn.
“Nítorí náà, gbọ́ nisinsinyii, ìwọ tí o fẹ́ràn afẹ́ ayé,tí o jókòó láìléwu,tí ò ń sọ lọ́kàn rẹ pé,‘Èmi nìkan ni mo wà,kò sí ẹlòmíràn lẹ́yìn mi.
Ìbànújẹ́ sọ ojú mi di bàìbàì,gbogbo ẹ̀yà ara mi dàbí òjìji.
O ni adajọ naa fẹ mọọmọ fi iya jẹ oun ni nitori ijiya yi ju ẹsẹ ti oun sẹ lọ.
Àkọlé àwòrán, Awọn ọmọ ilẹ okeere ko gbẹyin ni ọdun Ọlọjọ Àkọlé àwòrán, Oyinbp ree, to wọ asọ ibilẹ wa Àkọlé àwòrán, Ẹrin oyinbo yii nibi ọdun Ọlọjọ fa ni mọra Àkọlé àwòrán, Awọn Ajeji to wa sibi ọdun ọlọjọ kii se keremi Àkọlé àwòrán, Kabiyesi, Alayeluwa, Ọọni tilu Ifẹ ń ki àwọn araalu ku ọdun Àkọlé àwòrán, Awọn araalu n se Kabiesi si Ọọni BBC News, Yorùbá Ìdí tí ẹ fi le è nígbàagbọ́ nínú ìròyìn BBC Ìlànà Lílò Nípa BBC Òfin Àṣírí Cookies Kàn sí.
Oníṣẹ́ ìlú ni àwọn amọ̀nà, olùkọ́, oníṣègùn àti àwọn onímọ̀ mìíràn.
“Bí ẹnìkan bá ta ilé kan ninu ìlú olódi, ó lè rà á pada láàrin ọdún kan lẹ́yìn tí ó ti tà á.
naa jẹ ti iṣẹ ilu  ati pe eyikeyi ipade
Nigba ti o n ṣedajọ rẹ lọjọ Aje, igbimọ ẹlẹni mẹta ti adajọ I.
N óo kó àwọn ọmọ Israẹli jọ láti gbogbo orílẹ̀-èdè tí wọ́n wà, n óo kó wọn jọ láti ibi gbogbo wá sí ilẹ̀ wọn.
orile-ede Naijiria ti mehe lati bi odun melo kan seyin, eleyi ti o sokunfa
PDP: Lọgan ní a máa fún Ambode ni tíkẹ̀ẹ̀tì Gómìnà to ba dárapọmọ́ wà
Bakan naa ni awọn arinrinajo ọhun ni lati pese ẹri fun awọn ẹṣọ aṣọbode pe wọn ni alakalẹ bi wọn yóò ṣe wa ni igbele ọhun.
Àwọn alufaa ati àwọn ọmọ Lefi dìde, wọ́n súre fún àwọn eniyan; OLUWA gbọ́ ohùn wọn, adura wọn sì gòkè lọ sí ibùgbé mímọ́ rẹ̀ lọ́run.
O yanana oro lori akori ti o pe ni: “Awon odo Afrika ati idojuko irinrin-ajo” .
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, BBC Gov Debates: Ètò ẹ̀kọ́ ọ̀fẹ́ ni àwọn olùdíje yóò ṣe O ni ohun ti Fayoṣe beere fun ni oun fi fi owo naa ranṣẹ sii gẹgẹ bi o ṣe han ninu awọn ẹri ti awọn agbẹjọro Fayoṣe gbe kalẹ.
ENDSARS Protest Update: Iyabo Ojo ní ìpolongo tàbí ìbò dídì fáwọn olóṣèlú APC, PDP di eewọ f'óun
O ti kọ orin kaakiri agbaye fun awọn ọlọla, aarẹ, mọlumọọka o si ni afojusun fun ọjọ iwaju ẹya iru orin to n kọ.
Aarẹ ni, o yẹ ki awọn eeyan ni igbẹkẹle ninu oun, nitori pe ko si ẹnikan to le tọka si ọkankan ninu awọn minisita to ba oun ṣiṣẹ pe wọn wuwa ibajẹ kan tabi omiiran lati ọdun mẹrin sẹyin.
"Ìdí rè é tí mo ṣe lọ sí South Africa fún àpérò ọrọ̀ ajé - Ezekwesili ṣàlàyé Ààbò tó péye wà fún àwọn okòwò ará South Africa ni Eko -Sanwo Olu Ìkọlù sáwọn àjèjì kò tíì tán ní South Africa, ètò ń lọ láti kó ọmọ Nàíjíríà wálé ""A ti nílé, dúkìá àti ẹbí ní South Africa, àwa kò ṣetán láti padà sílé"" Senetọ to n dari igbimọ yii nile aṣofin agba ni Abuja ni iwa buruku gbaa ni awọn eniyan ilẹ South Africa hu yii ni eyi ti ko dara fun ilẹ Adulawọ rara."
Ta lo n lewaju lawọn ipinlẹ oju ina?
Awọn ontaja ati awakọ lọgba fasiti fi igbe ta Amọ lara awọn ontaja to ni sọọbu ninu ọgba ile ẹkọ giga naa gbarata lori ipa buburu ti iyanṣẹlodi naa yoo ko lori iṣẹ wọn.
Ọlọpa:Ọwọ palaba adigunjale mẹrin segi nipinlẹ Ọsun
"Onimọ nipa ihuwasi eeyan naa wa rọ awọn obi lati tọju awọn ọmọ wọn obinrin daradara, ki wọn ma baa ṣagbako awọn okunrin ti arun ""Pedophilia"" yii n ba finra."
ọgbọ́n inú yóo máa ṣọ́ ọ,òye yóo sì máa dáàbò bò ọ́,
Àwọn alákóso ikọ̀ Cameroon sí ibi ìdíje Commonwealth náà, ti fi ọ̀rọ̀ ọ̀hún tó àwọn agbófínró orílẹ̀èdè Australia létí.
ku isẹju mejila owurọ ( 10:48 am) (local time.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Lassa Fever:Ondo, Oyo, Kwara wà lára ìpínlẹ̀ tó kásáa ibà Lassa 22 Èrèlè 2019 Àkọlé àwòrán, Arun lassa ni Naijiria Ibùdó tó ń kojú àwọn àìsàn tó bá súyọ ní Nàìjíríà ní láàrin ọjọ́ kọkànlá sí ọjọ́ kẹẹ̀dọ́gbọ̀n oṣù kejì ọdun 2019, àkọsílẹ̀ mẹ́ẹ̀dọ́gbọ̀n ló ti wà nípa ibà Lassa lórílẹ̀èdè Nàìjíríà.
‘Ẹni mẹ́rin àti Àlága ADC nípìnlẹ̀ Ondo ni wọ́n jígbé lọ’ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ìnú mi kìí dùn nígbà trí mo ń ṣiṣẹ́ ni bánkì tó ìgbà ti mo bẹ̀rẹ̀ mẹkáníìkì Ọrọ yii ti wa di alatagba laarin awọn Ọmọ orilẹ-ede Naijiria bayii.
Ìwọ iyawo onípanṣágà tí ò ń kó àwọn ọkunrin ọlọkunrin wọlé dípò ọkọ rẹ.
Nígbà tí àwọn ọ̀gágun náà rí i pé kì í ṣe Ahabu, ọba Israẹli, wọ́n pada lẹ́yìn rẹ̀.
Ohun to n ko wa lominu ni kiko awon oja fayawo wole lati awon enu ibode, eyi ti ijoba apapo tako igbe naa gidi-gidi.
Ní ọdún 2011, ó lo oṣù méjì ní ẹ̀wọ̀n, àkókò yìí ni ìyàwóo rẹ̀ bí àkọ́bíi rẹ̀, Khaled.
Mo ti wẹ ara mi mọ́ nígbà náà.
Nigbàtí a dé  ìgbèríko náà ni a wá fi ọ̀rọ̀ wá àwọn ará ìlú lẹ́nu wò nípa ilé tó nléfò nínú igbó.
Kí ló mú olùdìbò ní India ge ìka rẹ̀ lẹ́yìn tó ṣèṣì dìbò fún ẹgbẹ́ mìíràn?
Ṣé ìwọ rò pé o lè là?
Tiamiyu Kazeem: Gbogbo egungun Tiamiyu ló kán lẹ́yìn tí wọ́n tì í jábọ́ nínú ọkọ̀ Boko Haram tẹ́ẹ ló ronúpìwàdà, ẹ ṣọ́ra o!
Sáájú àsìkò yìí, ẹsẹ tó bá niṣe pẹ̀lú ọ̀rọ̀ ara ẹni tí a sì gbé ẹjọ́ náà wá sọ́dọ̀ àwọn aláṣẹ Islam nìkan ní wọ́n ń lo Sharia fún.
Babaláwo yarí Wo ohun tó ṣẹlẹ̀ sí Saka, Sunkanmi Omobolanle àtàwọn òṣèré sinimá míràn lọ́sẹ̀ yìí Oríṣun àwòrán, Idris Ibrahim Kini o ti sẹlẹ̀ sẹ́yin?
Àlàó: Òun ni Olófin-íntótó àti Ilésanmí dé sí ọdọ rẹ̀.
Titi di asiko yi awọn ebi mi kan nbe tin nkọ mọ ibi ti wọn wa.
Aarẹ si fi adura le ibanikdun rẹ.
O ni bi orileede Naijiria ko ba fẹ fi awokọṣe buruku lori ibo rira, didun mọhuru mọ oludibo ati magomago lasiko idibo lelẹ, afi ki awọn alasẹ ti ọrọ kan o yara tete ṣe iwadii to kunna lori bi isu ṣe ku, ti ọbẹ sí bẹẹ lasiko idibo naa.
Akoda awo wa rọ awọn ọkunrin lati jinna si ṣina, ki wọn tọju obinrin wọn nitori ohun to ba wu ọkọ iyawo lo lee fi sọ iyawo rẹ.
Ìdí tí mo fi ń fi òwe bá wọn sọ̀rọ̀ nìyí, nítorí wọ́n lajú sílẹ̀ ni, ṣugbọn wọn kò ríran.
(Elifasi, ọmọ Esau ní obinrin kan tí orúkọ rẹ̀ ń jẹ́ Timna, òun ni ó bí Amaleki fún un.
Nítorí n óo mú kí ìwo rẹ lágbára bí irin, pátákò ẹsẹ̀ rẹ yóo sì dàbí idẹ; o óo fọ́ ọpọlọpọ orílẹ̀-èdè túútúú, o óo sì ya ọrọ̀ wọn sọ́tọ̀ fún OLUWA, nǹkan ìní wọn yóo jẹ́ ti OLUWA àgbáyé.
O ni ti awọn orilẹ-ede mẹrinlelaadọta ilẹ Adulawọ ba fọwọ si adehun yii, yoo rọrun fawọn olokowo paapaa obinrin lati rin laifoya lati orilẹ-ede kan si ikeji.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ado Ekiti Blind Couple: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú Elebuibon ni oun ko titori iya ti ọga oun fi jẹ oun ṣe, oun rii pe oun le kọwe, oun si le mọọ ka pẹlu.
Ṣugbọn Solomoni ni ó kọ́ ilé fún un.
Mo dúpẹ́ púpọ̀ fún iṣẹ́ tí ó ṣe fún mi láti ọjọ́ tí mo ti ń tọ̀ ọ́ wá wọ̀nyí mo sì ṣe àkíyèsí pé iṣẹ náà kò jọ̀ lójú ṣùgbọ́n kàkà bẹ́ẹ̀ ó ń fún ọ ní ìrẹ̀lẹ̀ ni.
Ajọ NCDC naa fi ikede naa si oju opo ikansiraẹni Twitter wọn, ti apapọ awọn eniyan to ni arun naa ti wa da 10578.
Ninu ijẹwọ rẹ lo tun ti sọ fun mi pe, oun maa n wo ọpọlọpọ fidio ibalopọ fun ọpọlọpọ wakati.
Ẹgbẹ́ APC n fi ẹtọ awọn ọmọ ẹgbẹ́ dun wọn Igba miran ti Aisah Buhari tun mi ori ẹrọ ayelujara ni asiko ti o sọrọ tako eto idibo abẹle ẹgbẹ oṣelu APC labẹ iṣakoso Adams Oshiomole.
Obasajo so pe “ohun ti a ri ni ikuna.
Igbakeji aarẹ ni ''Eleduwa ti ṣetan lati fun wa ni Naijiria tuntun nibi tawọn ọmọ Naijiria yoo ti rọwọ họri, ati nibi ti iṣokan yoo ti wa laarin ẹlẹyamẹya gbogbo.
Ninu ọrọ kan to kọ sori Twitter, o sọ pe oun lọ si ayẹyẹ asẹmọju kan ti amugbalẹgbẹ D'banj, Franklin pe oun si ni Eko Atlantic.
 Ọ ̀ pọ ̀ lọpọ ̀ fulani ló di mùsùlùmí ni òpin ẹgbẹru ọdun méjìdínlógún .
Wọ́n ń retí mi,bí ẹni retí òjò àkọ́rọ̀.
O jẹ gonima apapọ ni Naijiria laarin ọdun 1960 si ọdun 1963, lẹyin naa lo di aarẹ akọkọ ni orilẹ-ede Naijiria.
” tabi “Kí ni OLUWA wí?
Ọgbẹni Onigbogi sọ pe diẹ lara awọn obi awọn akẹkọọ ileewe naa lo tako ki ileewe Chrisland wọle saa eto ẹkọ tuntun bayii.
Angẹli Oluwa kan bá yọ sí wọn, ògo Oluwa tan ìmọ́lẹ̀ yí wọn ká.
Bí ẹ̀fúùfù ìhà àríwá tíí mú òjò wá,bẹ́ẹ̀ ni òfófó ṣíṣe máa ń fa kí a máa fi ojú burúkú woni.
Iya ẹlẹja kan ni yii ni Nairobi lolu ilu Kenya.
Coronavirus in Nigeria: Ènìyàn 653 ló tún ṣẹ̀ṣẹ̀ lùgbàdì ààrùn Coronavirus ní Nàìjíríà, 129 láti Eko nìkan
 Ó yá ẹ pa òwe kan tí ó ní OMI jẹ jáde nínú è.
Àwọn ìròyìn tí ẹ lè nífẹ̀ẹ́ sí: Ọ̀pọ̀ èrò gbàgbọ́ pé òrìṣà ni àfín jẹ́ láwùjọ Aláàfin ń se ọgọ́rin ọdún, àwọn àwòrán mánigbàgbé Ọ̀jọ̀gbọ́n onímọ̀ ẹrọ tí o ní kí wọ́n wọgi lè ìbò Ààrẹ Nàìjíríà Níbo làwọn òṣèré apanilẹ́rìn ín wọ̀nyí tó pilẹ̀ sínima àgbéléwò Yorùbá wà?
Iya naa jẹ Olorun nipe ni ẹni ọdun mọkanlelọgọrin pẹlu ọpọ ọmọ ati ọmọ-ọmọ to gbẹyin doloogbe naa.
Ìyẹn ni pé ènìyàn ní ànfàní àti lọ síbẹ̀ títí di ọdún tuntun.
Bakan naa, George ni gbogbo ara oun loun fi gbaruku ti eto ẹṣọ alaabo Amotekun tawọn gomina ilẹ Yoruba ṣe agbekalẹ rẹ Bode George ti oun naa fi igba kan ri jẹ gomina ologun ipinlẹ Eko sọ pe Amotekun yoo sọ aye dẹrun pẹlu eto aabo to mẹhẹ ni Naijiria bayii.
Òkè yìí ṣòro láti gùn lọ tó bẹ́ẹ̀ tí mo níláti wí fún àwọn ènìyàn mi kí wọ́n jẹ́ kí èmi nìkan gùn ún lọ, ojú ni rí nǹkan ki n tó gun òkè náà dé orí.
Aare Donald Trump to n tuko orile-ede America ti ba awon toro kan kedun ofo won.
- Trump Bí Amẹrika bá dínà mọ́ Nàíjíríà láti wá sílẹ̀ wọn, ewu ń bẹ fún wa - Lai Muhammed Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ìtàn Olaniyi Balogun, ọ̀jọ̀gbọ́n tó fi Nàìjíríà sílẹ̀ lọ gba iṣẹ̀ àgbẹ̀ l'Ámẹ́ríkà O ṣalaye awọn oun ti oju rẹ ri nigba to n dagba nilẹ Amẹrika, paapaa julọ lori iwa idẹyẹsi ati ẹlẹmẹyamẹya to n waye lagbegbe ti oun dagba si, eyii to jẹ pe awọn alawọ funfun lo pọju nibẹ.
Lọgan ti awọn araalu hu ọrọ naa gbọ ni wọn ba sare bọ sita lọ di gbogbo ọna to de aafin ti wọn si duro ni igbaradi lati koju ẹnikẹni ti yoo ba loun yoo kọlu aafin naa ati kabiyesi wọn.
A wí fún un pé à ń fẹ́ lọ sí ibùdó wa àtipé a kò rò pé a lè sọ̀rọ̀ tí a bá wa mọ́ lákòókò náà.
Ibẹ lo gbe titi di ọdun 1964 to pada silu Ọffa.
Lara rẹ ni pe ti eeyan ba ti le lugbadi arun naa, irufẹ ẹni bẹ ko ni le bọ ninu rẹ titi lailai.
Oríṣun àwòrán, Instagram/John Obi Mikel Mikel ni oun gbe igbesẹ lati fi ẹgbẹ agbabọọlu Naijiria silẹ lati fun awọn ọjẹwẹwẹ agbabọọlu laaye.
3 Kíyèsíi, oko náà ti funfun tán fún ìkórè; nítorínáà, ẹnikẹ́ni tí ó bá fẹ́ láti kórè ẹ jẹ́ kí ó fi dòjé rẹ̀ pẹ̀lú agbára rẹ̀, kí ó sì kórè nígbatí ọjọ́ sì wà, kí òun baà lè fi pamọ́ fún ìgbàlà àìlópin ti ẹ̀mí rẹ̀ ní ìjọba Ọlọ́run.
Àwọn nǹkan wọnyi jẹ́ àpẹẹrẹ fún wa, pé kí á má ṣe kó nǹkan burúkú lé ọkàn, gẹ́gẹ́ bí àwọn ti kó o lé ọkàn.
Ṣugbọn adajọ Nasiru Saminu sọ pe ki Gomina Ganduje k'ọwọ ọmọ bọ aṣọ na lẹyin ti awọn ọmọ ile igbimọ aṣofin ipinlẹ Kano meji, Rabi'u Saleh Gwarzo ati Babangida Yusuf Sulaiman gbe Ganduje lọ sile ẹjọ lori igbesẹ rẹ.
Eto aabo to peye wa ni awon agọ
Àkọlé àwòrán, Ganduje ko ni alatako kankan lati APC Kano Gomina Ganduje Abdullahi Umar nikan lo jade lati tun dije tẹsiwaju lẹẹkan sii gẹgẹ bii gomina Kano.
Ni igba aye rẹ, ọpọ eeyan lo tumọ orukọ MKO si Money, Kudi, Owo, eyi to jẹ owo apekanuko lede Yoruba.
Eyi ṣẹlẹ nigba ti ọkọ baluu to n gbe wọn bọ wale lati Saudi Arabia lọ fi tipatipa balẹ ni papakọ ofurufu ilu Minna ni ipinlẹ Niger.
"Oríṣun àwòrán, @YeleSowore ""Ijọba ti n kọ eti ikun si ọpọ asẹ ileẹjọ lati tu awọn eeyan to wa ni ahamọ silẹ, to si tun n lo agbara apapsẹ waa lati tako awọn eeyan to n fi ẹhonu han lawọn agbegbe kan lorilẹede naa, eyi to n kọ wa lominu pupọ, to si jẹ ẹdun ọkan fun wa."
Má ta mí nù kúrò lọ́dọ̀ rẹ,má sì gba Ẹ̀mí Mímọ́ rẹ lọ́wọ́ mi.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Funke Akindele: Bukunmi Oluwasina ní ọ̀kan lára àlá òun ló wá sí ìmúṣẹ 18 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Oríṣun àwòrán, Instagram/funkejenifaakindele/bukunmioluwasina Yoruba ni inu ẹnu kii dun, ka pa a mọra.
Nítorí náà èmi bẹ̀ ọ́, bá mi wí fún Ọlọ́run Ọba pé, kí ó wá iṣẹ́ mìíràn fún mi.
iṣẹ imọtoto ilu tubọ ni aṣeyọri, abbl.
Ẹ kò gbọdọ̀ ṣe irú turari náà fún ara yín, ṣugbọn ẹ mú un gẹ́gẹ́ bí ohun mímọ́ tí a yà sọ́tọ̀ fún OLUWA.
Àyẹwò yìí, gẹgẹ bí nnkán tí agbẹjọro Kayode Ajulo sọ fún BBC Yoruba nínú ìfòròwánilénuwò, yóò kàn ''ìwé ẹ̀rí tí ẹni náà n gbé ká àti àyẹwò nnkán ìní rẹ.
Gbogbo wọn jẹ́ mejilelogoji, kò sì dá ọ̀kankan ninu wọn sí.
Deji Adenuga : Ìdí tí mo fí jó èèyàn mẹsan mọ ilé
O ri iranwọ diẹ nigba ti lẹta kan wa si ileewe rẹ lati ilu ibi rẹ pe ko ni oluranlọwọ kankan.
Hibeethebarber: Kò sí ẹni tí mi ò lè firun èèyàn yàwòrán rẹ̀
 ni ojo kerin osu kokanla odun 2008 obama wole ibo fun ipo aare ile amerika .
3 485965 Orilẹede Egypt 6854 7.
    Orúkọ ìlú yìí kò fa nni mọ́ra, ṣùgbọ́n bí kò ti fa ni mọ́ra tó yìí náà, a fẹ́ láti lọ mọ ibẹ̀, nítorí a lè lọ dé ibẹ̀ kí a rí ọgbọ́n díẹ̀ kọ́.
Ordega ni ''awọn ko bẹru France,'' o ni ami ayo mẹjọ ti France ka lawọn kii ṣe ohun toju ko riri.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ìsúná 2018 di òfin Ènìyàn 3 kú nínú ìjàmbá afárá l’Eko Eku jẹ $17,600 nínú ẹ̀ro owó Agbẹnusọ fun ile iṣẹ ọlọpaa Aliyu Mukhtar sọ pe, iwọde naa ko yọ awọn obinrin ati ọmọde silẹ.
ayajo isejoba tiwa-n-tiwa ti yoo waye lojo kejila, osu kefa, odun ti a wayii.
 Ìrísí , ìṣe àti ìsọ ̀ rọ ̀ rẹ ̀ pàápàá kún fún ìbẹ ̀ rù nígbàtí ó wà laaye nítorípé ènìyàn la gbọ ́ pé Ṣàngó jẹ ́ tẹ ́ lẹ ̀ kí ó tó di òrìṣà àrá .
Nigba ti ,a de ori aleefa owo ti won n ta epo robi wa sile si mẹ́tàdínlógójì si méjídínlógójì dola,ko to di pe o tun  wa soke si ogójì ati àádọ́ta dola.
Bí mo bá ní ìrètí pé ibojì yóo jẹ́ ilé mi,tí mo tẹ́ ibùsùn mi sinu òkùnkùn,
“Nígbà tí ó yá, a pada sinu aṣálẹ̀ ní ọ̀nà Òkun Pupa, gẹ́gẹ́ bí OLUWA ti pa á láṣẹ fún mi; a sì rìn káàkiri lórí òkè Seiri fún ọpọlọpọ ọjọ́.
wo àwọn nọ́mba ọlọ́pàá tí o lé pé láti mọ ọ̀nà àbáyọ 13 Agẹmo 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 25 Agẹmo 2020 Oríṣun àwòrán, Others Bí ètò ìfórúkọsíll fún ìgbànísíṣẹ̀ ọlọ́pàá kò ṣe ku bí oṣù kan ti yóò kágbá nílẹ̀, ilé iṣẹ́ ọlọ́pàá ti fí ìpè síta lórí ayélujára wọ́n.
Bakan naa, akọwe ijọba ipinlẹ Ọsun, Alhaji Moshood Adeoti, toun naa kopa ninu ibo abẹnu APC lati yan ẹniti yoo soju ẹgbẹ oselu naa, ninu eto idibo gomina to n bọ losu kẹsan ọdun 2018 nipinlẹ Ọsun, amọ to fidi rẹmi, ti kọwe pe oun ko se ẹgbẹ oselu APC mọ.
•Bakan naa ni awọn oju opo ikansiraẹni le gbegile oju opo rẹ ti o ba n lo orisirisi ẹrọ bii foonu, computa lati fi wo oju opo rẹ, ti 'IP address' ti oluwarẹ ba fi n wọle ba ti pọju bo se yẹ lọ, wọn le e gbegile oju opo naa.
“Bí ìjòyè kan bá dẹ́ṣẹ̀, tí ó ṣèèṣì ṣe ọ̀kankan ninu àwọn ohun tí OLUWA Ọlọrun rẹ̀ pa láṣẹ pé ẹnikẹ́ni kò gbọdọ̀ ṣe, tí ó sì jẹ̀bi, 
Ọjọ keji to gbe igbesẹ yii ni ọkọ rẹ ọhun wa si ile baba rẹ naa, to si ṣeleri pe oun ko ni na arabinrin naa mọ.
Ewe, eni akoko ti o gba alejo igbakeji aare teleri ohun ni alaga egbe oselu PDP nipinle naa, Sir John Ngbede ati awon emewa re.
Iroyin ni ọjọ kọkanla, oṣu keji ọdun 2019 ni FIFA ṣe iwadii rẹ lori ọrọ Wilson Raj Perumal pe wọn ṣe magomago ninu idije.
Iwọde naa to ti n gbẹnule ọjọ kẹwaa bayii ni awọn ọdọ Naijiria fi n bere fun fifopin si iwa Baṣọrun Gaa ti awọn oṣiṣẹ ẹka ileeṣẹ ọlọpaa, SARS, n hu si awọn ọdọ ti wọn n fẹsun iwa jibiti kan lọna aitọ.
Àgbẹ̀ tí ń ṣiṣẹ́ lóko ni ó kọ́ ní ẹ̀tọ́ sí ìkórè oko.
Ó dùn mọ yín fún àkókò díẹ̀ láti máa yọ̀ ninu ìmọ́lẹ̀ tí ó fi fun yín.
Prince àti Kiddwaya ní ọpọ́n ilé sún kàn nílé ẹlẹ́gbọ̀n-ọ́n àgbà BBNaija!
Seun ni awọn eeyan kan lo bẹrẹ apejẹ alariwo nla kan ni adugbo oun lati owurọ bi agogo mẹsan abs owurọ, ti wọn ko si dawọ rẹ duro di aṣalẹ.
Leah Sharibu pé ọmọ ọdún 16 ní àhámọ́ Boko Haram Ìyá Leah Sharibu ké gbàjarè sí ìjọba Buhari Saraki pín owó ìyọ̀nda rẹ̀ fún ẹbí Leah Sharibu àtàwọn míì Ọkan lara awọn akẹkọbinrin ile iwe girama Dapchi ni Leah Sharibu ti ikọ Boko Haram jí gbé lọ ni ipinlẹ̀ Yobe ni Ọjọ Kọkandinlogun, Oṣu Keji ọdun 2018.
Ìrírí akọbúlọ́ọ̀gù Zone9 ìlú Ethiopia jẹ́ àpẹẹrẹ.
Ṣugbọn bí wọn kò bá bá yín ré odò Jọdani kọjá, tí wọn kò sì lọ sí ojú ogun pẹlu yín, wọn óo gba ìpín ilẹ̀ ìní tiwọn ní Kenaani bíi àwọn ọmọ Israẹli yòókù.
Ẹni bá sì pa ènìyàn, pípa ni à á pa á.
RUGA: Afenifere, Kunle Akinjide sọ̀rọ̀ lórí ìkéde ìjọba àpapọ̀ láti dáwọ́ dúró lórí RUGA
Síwájú sí i, a kò gbo̩dò̩ ya e̩nìké̩ni só̩tò̩ nítorí irú ìjo̩ba orílè̩‐èdè rè̩ ní àwùjo̩ àwo̩n orílè̩‐èdè tàbí nítorí ètò‐ìs̩èlú tàbí ètò‐ìdájó̩ orílè̩‐èdè rè̩; orílè̩‐èdè náà ìbáà wà ní òmìnira tàbí kí ó wà lábé̩ ìs̩àkóso ilè̩ mìíràn, wo̩n ìbáà má dàá ìjo̩ba ara wo̩n s̩e tàbí kí wó̩n wà lábé̩ ìkáni‐lápá‐kò yòówù tí ìbáà fé̩ dí òmìnira wo̩n ló̩wó̩ gé̩gé̩ bí orílè̩‐èdè.
" N kò mọ ẹni tó fẹ́ gba ìyàwó mi, àmọ́ wọn máa ń sọ pé ó rẹwà - Mike Bamiloye Oríṣun àwòrán, Instagram/gloriabamiloye Se ẹ ti wo awọn sinima yii ri - Ide Esu, Agbara nla (Ayaaaaaaamatanga), Egun aimọ, Ogun atilewa, Ibere opin aye.
Nitori ko ti i si ileeṣẹ apoogun oyinbo kankan to wa ni Naijiria ti yoo nilo igbo, ti gomina n sọrọ nipa rẹ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìkọlù Borno: Obìnrin mẹ́fà ló gbé àdò olóró ní Borno 17 Òkùdu 2018 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 18 Òkùdu 2018 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Báyìí ni àwọn tó sá ń'lé ní Damboa àtàwọn ìlú mìí se ń gbé ní ibùdó tí wọ́n sá lọ Àwọn òsìsẹ́ aláàbò lórílẹ̀èdè Nààjíríà sọ pé àwọn obìnrin agbé àdò olóró ló se ọṣẹ́ tó wáyé ní ìlú apá ìlà oòrùn àríwá Nàìjíríà, Damboa.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Trump impeachment: Àṣírí tùú, àkọsílẹ fihàn bí Trump ṣé béèrè iranwọ lọ́wọ́ ààrẹ Ukraine 25 Owewe 2019 Oríṣun àwòrán, Reuters Àkọlé àwòrán, Wọn ti bẹrẹ igbesẹ lati yẹ aga nidi aarẹ Trump Lorileede Amẹrika, ẹgbẹ oṣelu Democratic Party ti bẹrẹ iwaadi lati ṣe itọpipin aarẹ Trump, eleyi to le ja si ki wọn yọ nipo.
Bí ó ti jé̩ pé àwo̩n o̩mo̩ e̩gbé̩ Àjo̩‐ìsò̩kan orílè̩‐èdè àgbáyé ti jé̩jè̩é̩ láti fo̩wó̩s̩owó̩ pò̩ pè̩lú Àjo̩ náà, kí won lè jo̩ s̩e às̩eyege nípa àmús̩e̩ àwo̩n è̩tó̩ o̩mo̩nìyàn àti òmìnira è̩dá tó jé̩ kò‐s̩eé‐má‐nìí àti láti rí i pé à ń bò̩wò̩ fún àwo̩n è̩tó̩ náà káríayé,
O fikun ọrọ rẹ pe oun ti ẹ ti gba ipe lori ago nigba ti awọn kan fẹ mọ bo ya oun si wa laaye nitori ayederu iroyin ti wọn ti gbọ pe oun ti papoda.
15 Ọ̀wàrà 2020 Oríṣun àwòrán, Facebook/Alaafin Oba Adeyemi III Ẹni ọdun ba laye, o yẹ ko ṣọpẹ.
Nítorí gbolohun kan kó gbogbo òfin já, èyí ni pé “Fẹ́ràn ẹnìkejì rẹ bí ara rẹ.
Adajọ agba ati minisita fun eto idajo lorile ede Naijiria ,Abubakar Malami lo soro yii nigba ti o n si oju ona agbara ati oju popo ona ọkọ to wa ni ila Ariwa, ni ipinle Nasarawa.
Ti a ba fẹ tufọ, a gbọdo wa awọn agbaagba ẹbi ati adugbo silẹ, ki a mu ẹni ti oku ku fun naa wọ iyẹwu, ki a wa maa fi ọgbọn beere nipa ẹni to doloogbe lọwọ ẹni ti ọfọ ṣẹ.
Gbogbo àwọn wọnyi ni wọ́n wà lábẹ́ ọba ní Jerusalẹmu, láìka àwọn tí ó fi sí àwọn ìlú olódi ní gbogbo ilẹ̀ Juda.
Ọtí àti burańdí ló ń dárà
Saulu ọba, ati àwọn ẹ̀gbọ́n Dafidi ati àwọn ọmọ ogun yòókù wà ní àfonífojì Ela níbi tí wọ́n ti ń bá àwọn Filistini jà.
Ninu ifọrọwerọ rẹ pẹlu BBC News Yoruba, Agẹsin Adimula ilu Ila Ọrangun ṣalaye pe awọn ọbalaye kan wa lori itẹ ti wọn kii ṣe ọba bayii eleyi to si n faa ti eku ko fi n ke bi eku ti ẹyẹ ko si maa ke bi ẹyẹ mọ lawọn apa kan ilẹ Yoruba bayii.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù NFF fi #30,000 kún #10,000 owó ìrànwọ́ oṣooṣù fún ìyá Rashidi Yekini àti Samuel Okwaraji 7 Èbibi 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 8 Èbibi 2020 Oríṣun àwòrán, Others Ajọ to n ri si ere bọọlu afẹsẹgba ni Naijiria, NFF ti fi ẹgbẹrun un lọna ọgbọn naira kun ẹgbẹrun mẹwaa ti ẹka ijọba to n ri si ere idaraya ṣeto gẹgẹ bi owo iranwọ oṣooṣu fawọn iya oloogbe agbabọọlu Naijiria tẹlẹ, Rashidi Yekini ati Samuel Okwaraji.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Kano Torture: Inúu gáréèjì ni àwọn ẹlẹ́yinjú àánú ti rí Ahmed tú sílẹ̀ 14 Ògún 2020 Oríṣun àwòrán, oTHERS Ileeṣẹ ọlọpaa ipinlẹ Kano ti fi idaniloju han pe ọdọmọkunrin kan ti wọn timọle fun odidi ọdun meje ninu ile pẹluu mọlẹbi rẹ ti gba itusilẹ bayii.
O ni ki Tinubu ṣọra ki o rii pe oun n ṣe ohun to tọ fun awọn eniyan Naijiria, ko fi t'Olorun ṣe ninu ilepa rẹ.
R Kelly: Èmi kò jẹ̀bi ẹ̀ṣùn fífi ipá bá ọmọdé lòpọ̀
 wọ ́ n tu ṣàpèjúwe olóògbé náà gẹ ́ gẹ ́ bí òntajà àti aláfihàn fàbú lọ ́ nà ìbílẹ ̀ ṣáájú kí ó tó papò da látàrí àìsàn tí ó níṣe pẹ ̀ lú kídìnrín ( kidney related diseases ) , ní ọjọ ́ kẹẹ ̀ dọ ́ gbọ ̀ n oṣù kẹ ́ rin , ọdún 203 .
Ọgbẹni Reno Omokiri naa sọrọ, o ni idunkoko mọ Omotola pẹlu owo ori sisan ko ba ilana ijọba awarawa mu.
Toyin, lásìkò to ń sọ̀rọ̀ lórí eto orí telifisan kan n'ilu Eko ṣàlàyé pé, ọkọ òun, tíì ṣe ẹni tó lọgbọn nínú ìwà àti ọpọlọ, tí mú àyípadà réré bá igbe ayé òun, yàtọ̀ sí ti tẹ́lẹ̀.
Ijoba apapo fi mule pe, iwa ipaniyan ti o gbode kan nipinle Zamfara ti wale rau-rau lataari gbigbogun ti awon omo ogun olote naa.
Jehu bá ké sí wọn, ó ni, “Ẹ Jù ú sílẹ̀.
Tahir – Tanimu to tun je olori abule kan ni ose to koja ni won ti bere pinpin awon ohun eelo naa kaakiri ijoba ibile Sabongari, Soba, Kudan, Makarfi ati Ikara.
Bẹẹ ni ọrọ ri pẹlu mama agba kan, Ọlayinka Ọnabanjọ, ti wọn n pe ni ‘Grandma Maruwa’, ẹni to jẹ akinkanju obinrin to n wa Maruwa nilu Ibadan.
Ramatu Tijani (Kogi)- Minisita abẹle fun olu ilu orilẹede Naijiria, FCT Lai Mohammed- Minisita feto iroyin ati aṣa Gbemisọla Saraki - Minisita abẹle fun igbokegbodo ọkọ Babatunde Faṣọla - Minisita fun iṣẹ ode ati ile gbigbe Sẹnetọ Olọrunnibẹ Mamoora - Minisita abẹle fun eto ilera Mohammed Abdullahi- Minisita abẹle fun imọ sayẹnsi ati imọ ẹrọ.
Coronavirus Update: Báwo lo ṣe leè mọ Oogùn apakòkòrò 'Sanitizer' tó jẹ́ ayédèrú?
Oun funrarẹ naa ni ẹbun yii gẹgẹ bi o ti jẹ ọmọ agba ọjẹ oṣere, Ọmọọba Jide Kosoko.
Yatọ si eyi, o ni o yẹ ki wọn o pe ipade apero pẹlu awọn araalu.
Ti o bá dá ara ẹ lójú, ki ẹni tó n ṣe irun kí n gbọ́?
NLC Kwara-Iṣẹ́ tí èèyàn kò bá tí ṣé, kò yẹ kó gba owó rẹ̀
Nitori iwa aburu ti wọn n hu, awọn ara adugbo Ajegunle ta gba wọn, eyi ti ọwọ ba tẹ ninu wọn ni araalu n jo ni ina, ti wọn si n ju oku wọn soju titi fun gbogbo aye lati ri.
ile-ise olopaa lorile ede Naijiria , adajo agba lorile ede Naijiria ati  akowe agba fun ile-idajo lorile ede Naijiria
Ọwọ́ ọlọ́pàá tẹ afurasí akó-si-akọ nipinlẹ Eko Ọ̀ọ̀ni ilé Ifẹ̀, Buhari ṣèpàdé nílú Abuja Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Bọde George: Àwọn èèyàn mọ ẹni to yìnbọn pa Adeniyi Aboriṣade Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Wọ́n rò pé mo ya wèrè ni Saudi lẹ́yìn ikú ọkọ mi Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Mi o fẹẹkan ni mo fẹ dupo aarẹ' Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 3 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 5 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Manchester United vs Manchester City: Ó ti di ìgbà mẹ́ta ní sáà yìí tí Man U dígbájú ru Man City.
Oríṣun àwòrán, others O tun ni:  Tẹ ba ran awọn ọmọ yín ni iṣẹ, wọn ko ni pada wale, wa jiṣẹ pada fun yin, Gbogbo igun ti mo ba si ta ọfà yii si, ni wọn yoo maa ko yin ni ẹrú ni."
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fọ́nrán ohùn, Àdéhùn ètò ọrọ̀ ajé ilẹ̀ Afirika le lẹ́yìn Sugbọn bi ọpọ anfaani se sodo sinu eto okoowo ọfẹ laarin awọn orilẹ-ede nilẹ Afirika yii, orilẹ-ede Naijiria ati Cameroon ko si lara awọn orilẹ-ede mẹtalelogun ti wọn ti buwọ luu.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'A máa ń bẹ́ orí ẹni tó bá gbé imọlẹ̀ ọdún ìjẹṣu tó bá ṣubú ni' Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Adeleke fọhùn, 'èmi ni gómìnà tí wọ́n dìbò yàn' Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Lẹ́yìn náà Ọlọrun sọ fún Noa ati àwọn ọmọ rẹ̀ pé, 
Ikọ ogun Ibadan máa ń rán alami loore-koore láti mọ bí ogun ìjàyè tí ń ṣe sí, èyí sì lo mú kí wọn mọ pe ìlù ni wọn máa ń lu láti pàṣẹ fun ikọ ogún Ìjàyè pé kí wọn tẹsiwaju láti ibi tí wọ́n tẹ̀dó si.
Ó dùbúlẹ̀, ó ba bíi kinniun, bí abo kinniun tí ó sùn, ta ló lè jí i dìde?
idi niyi ti mo se saaju awon iko eleto aabo lati jo gbogun ti awon odaran yii.
Ijọba ibilẹ mọkanla lo wa labẹ ẹkun idibo yii.
Gbogbo orílẹ̀-èdè yóo parapọ̀ wá sibẹ, níwájú èmi OLUWA, ní Jerusalẹmu, wọn kò ní fi oríkunkun tẹ̀ sí ìmọ̀ burúkú ọkàn wọn mọ́.
Ko pẹ si ni ọjọ kejilelogun oṣu kẹrin ti gomina ọhun moribọ lọwọ arun naa.
Titi oselu bọ ọrọ ẹkọ naa n ko ipalara ba eto ẹkọ.
Sugbọn ọkan ninu awọn ololufẹ rẹ yii, John Andrew, @johnandrew1bb, lasiko to n dahun si ohun ti Dayọ Amusa kọ naa lo ni yoo dara ki osere tiata lobinrin naa tete lọ segbeyawo, ko si ni oyun sinu, bẹẹ lo n bi Dayọ pe, se ko mọ bo se sanra to ni.
"Ìbàlòpọ̀ pẹ̀lú ọ̀rẹ́kùnrin kìí ṣe ìfẹ́, bẹ́ẹ̀ ni ìfẹ́ kọ́ ni ìbálòpọ̀ - Genevieve Nnaji Àwọn Ọba alayé ní Naijiria ṣàbẹ̀wò sí Ọba Eko, Gómìnà Eko àti Bola Tinubu lẹyin ìwọ́de EndSARS Makinde ni, ""O ṣi jẹ ohun ti o nira fun mi."
Nígbà tí ojú rẹ̀ wálẹ̀ tán; Abigaili sọ gbogbo ohun tí ó ṣẹlẹ̀ fún un.
Ṣùgbọ́n Afẹnifẹre ni ẹgbẹ́ ẹnu méjèèjì ni Tinubu fi ń sọ̀rọ̀ àti pé ọ̀rọ̀ rẹ̀ ko ni arígbámu kankan nínú.
Àkọlé àwòrán, Orekelewa Ayaba Olori ni ooreọfẹ Olorun loun n jẹ laafin.
Ninu iwoye tiwọn, bi eeeyan ba ti ku, ọrun laala lati koju idajọ Ọlọrun.
Ijamba afefe gaasi naa waye ni
Nítorí OLUWA Ọlọrun yín yóo bukun yín gẹ́gẹ́ bí ó ti ṣèlérí fun yín.
 Dokita Ryan fikun pe Ero ajẹbiidan kan tilẹ n lọ pe, ofin konile o gbele n ṣiṣẹ daadaa, ati pe mimu ofin konile o gbele kuro yoo ṣiṣẹ pupọ gan ni.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Ninuu gbogbo ẹ tabi ko ma si nkankan Ero awọn oludibo ti n gbe Biden ṣaaju Trump pẹlu nkan bii koko marun si mẹwa ninu idije aarẹ yii ṣugbọn idibo ti yoo waye ninu oṣu kọkanla ṣi jina to si jẹ wipe ọpọ ogun lo ṣi wa niwaju.
Amọ, ajọ eleto ilera lagbaaye, WHO ti ṣalaye pe itakun agbaye 5G ko lagbara to bẹẹ to fi le wọn inu ara eniyan lati fa aarun covid-19.
Mo bá sọ àsọtẹ́lẹ̀ bí ó ti pàṣẹ fún mi.
Oliver skipp ọmọ ọdun mejidinlogun agbabọọlu Tottenham lo di ọkan lara aayo ori papa lataari Eric Dier to n gba itọju nile iwosan fun iṣẹ abẹ to ṣe.
N kò jókòó ti àwọn èké,n kò sì gba ìmọ̀ràn àwọn ẹlẹ́tàn;
tun orile ede yii se, bi won yoo se mu ipinnu won sẹ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù NIPOST àti FIRS ń fi ọ̀rọ̀ kòbákùngbé tú ara wọn làṣìírí lórí ayélujáraTwitter 26 Agẹmo 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 4 Ògún 2020 Oríṣun àwòrán, @firsNigeria/NipostNGn Ori ayelujara Twitter ti n gbona janjan lẹyin ti ileeṣẹ ijọba apapọ to n mojuto ọrọ owo ori, ati ileeṣẹ abanifi nkan ranṣẹ NIPOST, fi ọrọ kobakungbe ranṣẹ si ra wọn.
to n ba awon akoroyin ile akede Naijiria  soro niluu Abuja.
Jọ̀wọ́ gbà wá láàyè kí á gba ilẹ̀ rẹ kọjá.
Awọn aworan yii wa lati ileeṣẹ BBC News Yoruba Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
lọwọ, All Progressives Congress (APC), lo jawe olubori ninu eto idibo to waye
Nígbà tí ó di ọjọ́ ikú rẹ̀, gbogbo ìlú pé láìku ẹnì kan ṣoṣo.
Àwọn mìíràn tún ní Jeremaya ni tabi ọ̀kan ninu àwọn wolii.
"- CAN Ẹ wo àwọn ìlúmọ̀ọ́ká ọmọ Nàíjíríà tó jáde láyé lọ́dún 2020 Ìtàn ìgbé ayé Isola Ogunsola, akọni mánigbàgbé òṣèré tíátà, olórin àti onílù ""Ma a pa ara mi si Cute Abiola lọrun bo ṣe já mi silẹ tori afẹsọna miran"" ""Àwọn akẹ́kọ̀ọ́ àgbà fipá bá ọmọkùnrin mi lòpọ̀ níléèwé Deeper Life, mò ń fẹ́ ìdájọ́"" Wo ọ̀pọ̀ àsọtẹ́lẹ̀ igba tí Primate Ayodele gbé síta fọ́dún 2021 Igba akọkọ kọ niyii ti iru iroyin yii n jade sita nipa pe awọn agbesunmọmi ti wọ ilẹ Yoruba."
Gege bi oro re, “Tori ipinnu mi lori eto oro-aje fun ipinle Edo, emi o le laju mi sile, ki talubo ko wo lori oro eto-abo agbegbe Esan, a ti seleri irinwo eeka ile fun ogbin agbado, a n sise lori ise-akanse osin-elede ni agbegbe ile-eko giga fafiti Ambrose Alli ni Ekpoma, a tun wo osin-maalu pelu,  a fe mu awon nnkan ti o sele lasiko Ogbemudia pada sipo, koda ju bee lo, ni iyanju ati pese ise lopo yanturu fun awon odo langba”.
Awọn ijọ Ọlọrun miran naa maa n lo asiko yii lati bukun awọn ewe ki inu awọn ọmọde le dun.
Nítorí náà, mo jẹ́ kí iná ṣẹ́ ní ààrin rẹ; ó sì jó ọ run; mo sì sọ ọ́ di eérú lórí ilẹ̀ ayé lójú gbogbo àwọn tí ń wò ọ́.
Nítorí náà, kò ṣòro fún àwọn iranṣẹ rẹ̀ láti farahàn bí iranṣẹ tòótọ́.
Bí ó bá jẹ́ pé òtítọ́ ni, tí ìdánilójú sì wà pé ohun ìríra bẹ́ẹ̀ ti ṣẹlẹ̀ ní Israẹli, 
“Nígbà tí ẹ̀mí èṣù bá jáde kúrò ninu ẹnìkan, á máa wá ilẹ̀ gbígbẹ kiri láti sinmi.
O ni iyalẹnu nla lo jẹ pewọn ni lati ti ibudo ayẹwo kan ṣoṣo to wa ni ipinlẹ naa fun ayẹwo arun Coronavirus fun ọjọ mẹfa gbako.
Bi a ti ṣe n sọrọ yi, Sẹnetọ Dino Melaye ko tii fesi pada si ọrọ pe o fẹ pin miliọnu mẹwa Naira fun awọn eeyan.
"Dokita Hong ni ""nigba to fi maa de ile iwosan, ko le pa oju rẹ de mọ, mo fi ẹrọ amunkan tobi sii wo ẹyinju rẹ ni mo ba ri awọn nkan dudu to dabi ẹsẹ kokoro ninu oju rẹ""."
Ó rọ òjò mana sílẹ̀fún wọn láti jẹ,ó sì fún wọn ní ọkà ọ̀run.
Ó sì sọ fún Buhari pé kó gbàgbé sáà kejì, lẹ́hìn náà ni ó sọ pé kí àwọn ọ̀dọ́ má dìbò fun ààrẹ.
Coronavirus in Nigeria: Èèyàn méje l'Eko, mẹ́ta l'Abuja kó àrùn Coronavirus
Ẹ kí àwọn arakunrin tí ó wà ní Laodikia.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ekiti Bank Robbery: Iléeṣẹ́ ọlọ́pàá rí ọkọ̀ mẹ́ta gbà lọ́wọ́ adigunjalè báńkì Iyin-Ekiti 3 Ọ̀wàrà 2020 Oríṣun àwòrán, @tosinsammy_s Ọjọ buruku, Eṣu gbomi mu lọjọ Ẹti, ọjọ keji oṣu kẹwaa ọdun 2020 jẹ niluu Iyin-Ekiti, nibi tawọn adigunjale ti yabo ile ifowopamọ WEMA ti wọn si gbe ẹgbẹlẹgbẹ miliọnu owo naira lọ.
Mo dójúlé yín láti ṣe yín ní ibi.
Oríṣun àwòrán, Ismaila Omipidan x Asp Seyi /Facebook Gomina ọhun sọ pe, bi ikọlu naa ṣe waye fihan pe awọn janduku naa mọọmọ kọlu oun ni.
O jawe bori nínú idibo ti ọdun 1999, èyí tí ó gbé e wo ilẹ̀ ìgbìmò asofin ipinle, Eko nibi ti o ti jẹ agbẹnusọ fún ile naa.
Ojuse ayaba to jẹ agbalagba ninu aafin ni lati kọ awọn olori kekere ni igba titi.
Ọ̀rúnmìlà ni ó kọ́kọ́ lo 'Google' láàgbáyé-Ọ̀ọ̀ni Ìlẹ̀ ifẹ̀ Dokita Stella Adadevoh kò bá pé ọdún 62 Àǹfàní dé fún ọ láti lo internet lọ́fẹ́ Ramesh Nagarajan to jẹ oludari ọja tita nileeṣẹ naa sọ fun BBC pe ohun Naijiria tawọn fi si inu ẹrọ ajuweọna naa ko yatọ si ti ọmọ Naijiria.
Bi o tilẹ jẹ wi pe awọn onimọ n jẹ ko di mimọ pe o ṣeeṣe ko jẹ wi pe nitori pe ipinlẹ Eko ni eto ayẹwo rẹ pọ juls lo fa eyi bakan naa ni ipinlẹ Kano naa ti goke tẹlee pẹlu ibẹrẹ eto ayẹwo nibẹ lẹyin ọpọlọpọ awuyewuye to wọ tọ iku ọwọọwọ ati aisi itọju ati amojuto to peye fun ajakalẹ arun naa nibẹ.
Ó ní kí n máa fún àwọn tí ń ṣọ̀fọ̀ ní Sioni,ní inú dídùn dípò ìkáàánú,kí n fún wọn ní ayọ̀ dípò ìbànújẹ́,kí n jẹ́ kí wọn máa kọrin ìyìn dípò ìrẹ̀wẹ̀sì ọkàn,kí á lè máa pè wọ́n ní igi òdodo,tí OLUWA gbìn,kí á lè máa yìn ín lógo.
"Oríṣun àwòrán, Getty Images Eroja naa ni wọ́n ń pe ni ""White Blood Cell"", èròjà yìí ti wà lara sùgbọ́n ti kò sí ẹni to mọ̀ fún ọ̀pọ̀ ọdun."
"Amofin Afẹ Babalọla ninu atẹjade kan to fi sita lọjọ Aiku ṣalaye pe ""ohun ti ofin la kalẹ ni pe ki igbimọ iṣedajọ lorilẹ-ede Naijiria o kọkọ gbọ ẹsun naa ki wọn si ṣe iwadii rẹ ṣaaju igbimọ kigbimọ, nitori naa ko si awijare kankan ninu igbesẹ lati gbe adajọ agba Naijiria lọ siwaju ile ẹjọ CCT"" ."
''Wọ́n bọ́ mi síhòho, wọ́n fẹ́ fipá bámi lòpọ̀'' Àyájọ́ obìnrin lágbáye, àwọn obìnrin fọnrere ìdẹ́yẹsí Gómìnà Oyetọla tí yi ìlànà ètò ẹ̀kọ Rauf Aregbesola pada Làá hàn mí dé, ètò tó ń ṣàlàyé ohun tó yẹ ká ṣe láti dènà àrùn Coronavirus Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí kan sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
Awọn mii n beere ibeere nla pé bawo la ṣe fẹ mọ pe Abba Kyari ganhan lo ku lasiko yii pé Ta lo le sọ nipato pe Kyari ni wọn n sin pe o ku?
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Abuja-Kaduna: Àwọn arìnrìn àjò ní àwọn ọlọ́pàá kò leè ta pútú 23 Agẹmo 2018 Oríṣun àwòrán, @Omojuwa Àkọlé àwòrán, Àwọn ajínigbé ti sekú pa ológun kan, wọ́n tún jí ọ̀pọ̀ arìnrìniajò lọ lójú ọ́na marosẹ̀ Abuja sí Kaduna lọ́jọ́ Àìkú.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Aràrá bíi tèmi, kó má rò pé kò sì ǹkan tó lè ṣe láyé ju iṣẹ́ agbe lọ' Ṣugbọn awọn ọlọpaa sọ pe ko si nkan to jọ nkan bẹ ẹ.
ati ìlú ńlá tí wọn ń pè ní Reseni tí ó wà láàrin Ninefe ati Kala.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ sí: Kíni ẹ mọ̀ nípa àwọn gbajúgbaja Yollywood?
OLUWA bá bi mí pé, “Jeremaya, kí ni o rí?
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ondo election 2020: Kalejaye ní APC kò ní ṣ'èèrú nínú ìbò gómìnà tó ń bọ̀, Wike má gbé jàgídíjàgan wá 26 Owewe 2020 Oríṣun àwòrán, Facebook/Rotimi Akeredolu, Nyesom Wike Ẹgbẹ oṣelu APC ti kilọ fun Gomina ipinlẹ Rivers Nyesom Wike ko jawọ lapọn ti ko yọ nitori APC ko ni erongba lati yi ibo ninu ibo gomina ipinlẹ Ondo ti yoo waye lọjọ kẹwaa, oṣu kẹwaa, ọdun 2020 yii.
ọmọọ́lé, ọ̀ni, aláǹgbá, agílíńtí ati alágẹmọ.
"Nigba to n sọrọ lori ajọṣepọ rẹ pẹlu Kamilu Compo, o ni "" Adekola Tijani, wa ba mi lati ṣe tiata, mo si mú lọ sọdọ ọga mi, taa si di ibeji ti ki i ya ara wọn lati igba naa, taa si pinnu láti wá sílu Eko papọ."
Klopp ni laisi ani-ani, ara ọtọ ni Messi!
Oúnjẹ wà fún ikùn, ikùn sì wà fún oúnjẹ.
Jolo church attack: Ọpọ èèyàn kú nínú ilé ìjọsìn ní Philippines
Ṣùgbọ́n lónìí ó ti di bàbàrà, oun àtọ́kasí ní ilú Lọndọn o.
wọ́n sì lòdì sí àṣẹ tí OLUWA pa fún wọn pé wọn kó gbọdọ̀ bọ oriṣa.
Ẹni tí kò bá bu ọlá fún Ọmọ kò bu ọlá fún Baba tí ó rán an wá sí ayé.
Rélùwéè Eko: Alágbe tó kú náà jẹ́ ara àwọn tó ń jókòó lẹ́bàá ojú ìrìn
Aare fikun un oro re pe,
Oríṣun àwòrán, NERC SERAP tun n beere pe ki ile ẹjọ kéde pe aarẹ Buhari lo agbara to ni labẹ ofin, lati le fi owo kun owo epo ati ina ni ilokulo ati lọnà to tako ẹjẹ to jẹ labẹ ofin yi kan naa.
Oríṣun àwòrán, @Justapollion Bakan naa ni iye ti Admiralty Circle Plaza, to wa loju ọna marosẹ Lekki-Epe maa n pa lojumọ kan, ko din ni miliọnu mẹrindinlogun naira.
Ta ni Ààrẹ orílè-èdè Egypt, Morsi tó kú nílé ẹjọ́?
Oṣu diẹ sẹyin ni Aarẹ Ọna Kakanfo ilẹ Yoruba, Gani Adams ke gbajare pe oun kẹẹfin nkan bẹ ẹ.
BBC Yoruba gbiyanju lati beere lọwọ alukoro ọlọpaa ni ipinlẹ Kaduna boya wọn ri awọn ajinigbe naa mu ṣugbọn ko gbe aago ipe rẹ titi di igba ti a fi gbe iroyin yii jade.
Wọ́n fa kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ náà ati ọmọ rẹ̀ wá, wọ́n tẹ́ aṣọ lé wọn lórí, Jesu bá mú kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ gùn.
yin ni awon ibudo idibo pata-pata.
“Báwo ni ẹnìkan ṣe lè wọ ilé alágbára lọ, kí ó kó o lẹ́rù, bí kò bá kọ́kọ́ de alágbára náà?
Ìyẹn ni pé nínú gbólóhùn kan ṣoṣo yìí, gbogbo álúfábẹ́ẹ̀tì Gẹ̀ẹ́sì ló péjọ síbẹ̀ láti A dé Z.
afesegba lorile-ede Naijiria, Rafiu Ladipo, sapejuwe Gomina Ambode gege bi eni
Ọwọ́ ti tẹ àwọn ọlọ́pàá tó lú obìnrin kan bí k'ókú nílùú Iwo Òṣèrè tíátà Muideen Oladapo gbàràdá lórí ètò 'Ṣé o láyà?
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ẹ sá àwọn akẹ́kọ̀ọ́ sínú òòrùn fún ọgbọ̀n ìṣẹ́jú lójojúmọ́ - Ìjọba Oyo pàṣẹ Òṣìṣẹ́ LASTMA gún olólùfẹ́ rẹ̀ l'ọ́bẹ, ó tún gba ẹ̀mí ara rẹ̀ l'Eko Ikọ̀ ìjọba Ọ̀yọ́ dé lásìkò tí kò yẹ ni wọn kò ṣe wọlé - Ẹ̀bí Ajimobi fèsì Bakan naa lo dupẹ lọwọ gomina ipinlẹ Ondo, Oluwarotimi Akeredolu to fun oun ni ore ọfẹ ati ṣiṣẹ fun ipinlẹ naa.
"Chekole ni ""Mo ro wi pe ninu baba lee ran mi lọwọ."
Hesekaya ati àwọn ará Jerusalẹmu bá rẹ ara wọn sílẹ̀, wọ́n sì ronupiwada.
Ọlọpaa ni awọn yoo ṣe ifọrọwanilẹnuwo lori eleyii.
Akọroyin kan,Awajis George fi fọnran fidio ibi ti awọn ọlọpaa ti mu afurasi yi sita loju opo Twitter Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
buu- lẹsẹ lasiko eto idibo odun 2019.
Nítorí pé òmùgọ̀ ni àwọn olùṣọ́-aguntan,wọn kò sì ṣe ìwádìí lọ́dọ̀ OLUWA,nítorí náà wọn kò ṣe àṣeyọrí,tí gbogbo agbo wọn sì fi túká.
–Ayé kí wọ́n máa purọ́ mọ́ ara wọn !
Amọṣa, Siasia ti ṣalaye pe oun ko mọ ohunkohun nipa ẹsun naa atipe ko si igba kankan ti ajọ naa pe oun joko lati beere ọrọ lori ẹsun naa ki wọn to gbe idajọ wọn kalẹ.
pupo lowo awon alamojuto eto idibo lati ile-okere ati awon ti o wa lati orile-ede
Ẹni tí ó bá ti bẹ̀rẹ̀ ìrìnàjò olúwarẹ̀ ti gbé àpò ìyà ka èjìká, nítorí ẹni tí ó ti ń sùn lórí ibùsùn ńlá lè di ẹni tí kò ń hanrun lórí ilẹ̀ pẹpẹ, ẹni tí o ti ń fi ẹ̀dọ̀ ẹran jẹun lè di ẹni tí kò rí nǹkan wa gaàrí mu, bẹ́ẹ̀ ni ẹni tí kò tó àbúrrò olúwarẹ̀ lè máa búu kí ó máa ṣépè fún un.
Àrùn kòkòrò àìlèfojúrí afàìsàn ebola ( evd ) tàbí ibà ẹlẹ ́ jẹ ̀ sísun ebola ( ehf ) jẹ ́ àrùn ẹ ̀ dá ènìyàn èyítí kòkòrò àìlèfojúrí afàìsàn ebola n ṣe òkùnfa rẹ ̀ .
nítorí pé èmi ati àwọn olùdámọ̀ràn mi meje ni a rán ọ lọ láti ṣe ìwádìí fínnífínní lórí Juda ati Jerusalẹmu, gẹ́gẹ́ bí òfin Ọlọrun rẹ tí ó wà lọ́wọ́ rẹ, 
Ìròyìn to tẹ BBC lọ́wọ́ sọ pé àwọn ènìyàn péréte lo jáde lọ si ibi idibò náà, sùgbọ́n ìrọwọ́ rọsẹ̀ ni wáye Ilééjọ́!
Iroyin n sọ pé àwọn ẹgbẹ oṣiṣẹ ṣi n sọ pe ẹgbẹrun lọna ọgbọn naira ni awọn fẹ ko jẹ owo oṣu oṣiṣẹ to ba kere julọ.
 Ìjọba ti ń gbìyànjú láti kó àwọn ọ ̀ nà tún tún síbẹ ̀ lóna àti lè mú àdínkù bá súnkẹrẹ fàkẹre ojú pópó náà kí ọkọ ̀ lè ma lọ gaaraga .
Ni eyi ti wọn ni eniyan mẹtalelogun ti gbẹmi mi lati Nganzai ni eyi ti awọn eniyan Badu Kuluwa si wa ninu ipaya.
Kii se igba akọkọ ree ti iru isẹlẹ yii yoo waye, eyi to ti mu ẹmi ọpọ ọmọ Naijiria lọ.
Kini yii wọpọ, bẹẹ si ni awọn obinrin to ni aisan naa maa n rii pe oje to n jade lati oju ara wọn a maa run tuu bi ẹja.
Johesu: A so ìyansẹ́lódì rọ̀ kí ìjíròrò leè já gaara
Orile ede South Africa ni ipinle mẹ́sán
Joramu bèèrè pé, “Ṣé alaafia ni?
O tun fi igba kan jẹ olori awọn oṣiṣẹ nipinlẹ Plateau, bakan naa ni o jẹ alaga igbimọ to n ri si ọrọ aṣa ati igbafẹ nile aṣofin.
Ko sohun tuntun mọ labẹ ọrun, dokita ileewosan kan to saba maa n tọju awọn to fara gba iṣẹlẹ ifipabanilopọ lo sọ eyi.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, CAN: Samson ni ọrọ awọn ajinigbe ti gba àpérò ní Naijiria Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Sọ àsọtẹ́lẹ̀ orílẹ̀èdè tí yóò borí ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ t'òní Ọlọ́pàá ìpínlẹ̀ kọ́ ní ojútùú ìṣòro ìjínigbé ilẹ̀ Yoruba - Onímọ̀ ọ̀rọ̀ ààbò Ìjọ Satani dá MI lóhùn lórí ọ̀rọ̀ Fatoyinbo Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, International Day Against Drug Abuse and Trafficking: ìdí ti mo fi ń mu oògùn olóró Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Ó tún gbé igba ọdún ó lé mọkandinlogun (219) sí i láyé, ó sì bí àwọn ọmọ mìíràn lọkunrin ati lobinrin.
Òròòru ni mana náà máa ń bọ́ nígbà tí ìrì bá ń sẹ̀ ní ibùdó.
" Lukman sàlàyé pé, o pọ̀ndandan ki Oshiomole kọwe fipo rẹ silẹ, paapaa pẹ̀lú ìròyìn to n jáde láti ìpínlẹ̀ Edo pé, àwọn oloye ẹgbẹ̀ APC ti díbò a ò ní ìgbàgbọ́ nínú rẹ̀"" fun Oshiomhole."
Ẹnikẹ́ni ninu yín kò gbọdọ̀ fi ọmọ rẹ̀ rú ẹbọ sísun, kì báà ṣe ọmọ rẹ̀ obinrin tabi ọkunrin.
Ẹwẹ, ijọba ti ṣalaye pe abadofin to ti wa niwaju ile igbimọ aṣofin kii ṣe tuntun bi ko ṣe pe ijọba kan fi awọn nkan kọọkan kun aba naa ni ko le wa ni ibamu pẹlu bi wọn ṣe n ṣe lagbaye.
O salaye pe, bi oun ko ba fi were diẹ diẹ kun ọja ti oun n ta lori ayelujara, ko ni ta bo ṣe yẹ.
 wọ ́ n ní ìlànà tó sọ bí a se n sọmọ lórúkọ àti irú orúkọ tí a le sọ ọmọ torí pé ilé là á wò , kí a tó sọmọ lórúkọ .
Lanre Kuti ni mo fẹ́ - Jaiye Kuti Davido, Fani Kayode, Kemi Olunloyo, sọ̀rọ̀ lórí ẹ̀sùn jìbìtì Allen Onyema Gómìnà Osun ṣàbẹ̀wò síbi ìṣẹ̀lẹ̀ àrá tó sán pa màlúù ní Iba Uganda kó rọ́bà ìdáàbòbò mílíọ̀nù kan kúrò ní ìlú Ọ̀pọ̀ àwọn àlásè máa ń gba ẹkọ fún ọ̀pọ ọdún ki wọn to le gbà wọ́n láàyè láti ṣe irú ẹja bẹ́ẹ̀.
Nkechi Blessing: Ọ̀rọ̀ ìfẹ́ wa dàbí ti Romeo àti Juliet
Àkọlé àwòrán, Awọn ọlọ́pà dìgbòlùjà ti lọ sí àwọn agbègbè tí ọ̀rọ̀ kàn Abẹwo BBC Yoruba si adugbo Old Garage nilu Ado-Ekiti fihan pe ẹgbẹ tuntun to n ṣatilẹyin fun APC ti gbakoso ibudokọ naa, ti awọn ọmọ ẹgbẹ ti oniroyin BBC ri si n fi pankẹrẹ, waya ina ati orisirisi igi nakan-nakan loju opopona.
"Ọ̀gbẹ́ni Vincent Jack, ""papòdà lẹ́yìn tó ti wà ní ìdùbúlẹ̀ àìsàn, èyí tó mú kó ma lè ṣiṣẹ́ rẹ̀ daadaa fún ìgbà díẹ̀."
eyi lo wa mu kawọn araalu maa beere pe se ilana gbigba eso owo nla-nla yii baa ofin Ọlọrun mu ?
 Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Mo n wa'yawo - Falz Lori irinajo rẹ ninu iṣẹ tiata, Afod sọ pe oun ko mọ pe oun le laluyọ nigba ti oun bẹrẹ iṣẹ.
” Lẹ́yìn tí Dafidi lọ, Jonatani pada sí ààrin ìlú.
Ali Ibrahim ti Sudanese Professionals Association (SPA) ẹni to ṣe agbatẹru ifẹhonu han naa sọ fun ile iṣẹ iroyin EFE pe ikọ ogun n yinbọn sinu afẹfẹ lati di awọn oṣiṣẹ alaabo ọhun lọwọọ titu awọn ka nibi ifẹhonu han to n waye ni ita olu ile iṣ ogun.
Ẹ̀yin ọmọ Israẹli, ẹ yin OLUWA,ẹ̀yin ará ilé Aaroni, ẹ yin OLUWA!
Babangida ni oun sọ ọrọ ti Ọgagun Sani Abacha sọ nigba aye rẹ pe '' ti rogbodiyan ba ti ju wakati mẹrinlelogun lọ, oṣiṣẹ ijọba kan wa ni idi iṣẹlẹ naa niyẹn.
Liverpool fí ogun ẹ̀yìn ja Barcelona Ẹni a le mú.
8 4525 Orilẹede Suriname 117 20.
Nítorí pé Ọlọrun ti kìlọ̀ fún wọn tẹ́lẹ̀ ní ojú àlá, wọn kò pada sọ́dọ̀ Hẹrọdu mọ́; ọ̀nà mìíràn ni wọ́n gbà pada lọ sí ìlú wọn.
Òun ati àwọn iranṣẹ rẹ̀ yí àwọn ọ̀tá náà po, wọ́n ṣí wọn nídìí, wọ́n sì lépa wọn títí dé ìlú Hoba ní apá ìhà àríwá Damasku.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Àṣìṣe ọlọ́pàá àti Adájọ́ sọ mí di ẹni tí wọ́n dájọ́ ikú fún, ọpẹ́lọpẹ́ Fayoṣe tí ko buwọlu Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 3 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 5 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Ipinlẹ Eko lo le waju, ti Abuja, Kaduna atawọn ipinlẹ to ku n sare tete tẹle wọn lẹyin.
Wọn gba awọn eeyan nimọran lati maa tẹle ilana eto ilera eyi to fi mọ lilo iboju-bomu nigboro, fifi ọṣẹ ati omi fọwọ ati jijinasiraẹni.
Nígbà tí mo wí báyìí tán àgbọ̀nrín náà dá mi lóhùn ṣùgbọ́n ìdáhùn rẹ̀ lòdì sí ìrètí mi.
Arabinrin Funke Falade-Young salaye ni kikun fun gbogbo wa bi asa iranraenilowo se se pataki nile Yoruba Ẹ fi ara balẹ, kẹ maa ba olukọ wa bọ, lati kẹkọ nipa asa ilẹ Yoruba to da lori eto riran ara ẹni lọwọ.
Kò yẹ kí obìnrin fi ìdí gba ipò tíátà Àwọn ọmọ Yorùbá àtàtà: Báwo lẹ se gbọ́ òwe sí ?
ohun tí OLUWA sọ nípa rẹ̀ ni pé:“Sioni bu ẹnu àtẹ́ lù ọ́, Senakeribu,ó fi ọ́ ṣe ẹlẹ́yà,Jerusalẹmu ń yọ ṣùtì sí ọ.
Ajọ EFCC fi kun unpe iwadii ṣi n lọ ni pẹrẹwu lori iṣẹlẹ ọhun, ti awọn si ti bẹrẹ ifọrọwanilẹnuwo pẹlu awọn afurasi naa.
darajulo  – Megan Rapinoe (Reign FC ati United
Ise-akanse apapo awon omo-ogun Sahel, ti won pago si aarin gbungbun orile-ede Mali, ni o se e se ki won ni awon omo-ogun ti iye won to egberun lona marun-un lati awon ago awon omo-ogun batalionu meje, ni won yoo maa sise iranwo ati idagbasoke ni ekun naa.
Brig Taiwo sọrọ yìí níbi ìjòkò tó ń gbẹjọ ìwà ìpá ọlọ́paàá àti ìṣẹ̀lẹ̀ tó wáye ni Lekki.
Ó tún ga ju gbogbo orúkọ tí eniyan lè dá lọ, kì í ṣe ní ayé yìí nìkan, ṣugbọn ati ní ayé tí ń bọ̀ pẹlu.
Wọ́n dìtẹ̀ mọ́ Amasaya Ọba ní Jerusalẹmu, ó sì sá lọ sí Lakiṣi.
Gbogbo àwọn ará àdúgbò ni wọ́n ti fura pe olé ni.
Ó tún ní, “N kò ní ranti ẹ̀ṣẹ̀ ati ìwà burúkú wọn mọ́.
Wọn ni ṣe ni awọn agbebọn naa ti iye wọn to igba bẹrẹ si ni yinbọn awon lu eeyan to n ṣiṣẹ ni oko kan to wa ni abule Yargamiji.
Femi Adesina ń ṣe iṣẹ́ rẹ̀ ni ṣùgbọ́n mo rán ọ sí Buhari - Gani Adams Ààrẹ Gani Adams sọ ẹni tí Yorùbá yóò dìbò fún ní ọdun 2019 #BBCNigeria2019 Day 8: Bode George dá sí aawọ̀ Buhari, Obasanjo #BBCNigeria2019 Òfin má wàásù láì gbàṣẹ nìpínlẹ̀ Kaduna ti ń gba àpérò Ọ ni ni ti ẹgbẹ OPC atawọn agbaagba Yoruba, wọn n gbiyanju ninu riran awọn eniyan lọwọ ṣugbọn sibẹ, iwọnba ni ohun ti wọn lee ṣe lai si aṣẹ ijọba ko ma lọ di pe wọn n fi ọwọ ofin mu awọn eeyan awọn.
Naijiria k'ọmọogun lati wa'wọn ọmọ Dapchi 'Irọ ni, ko si ologun kankan ni Dapchi' Awọn ibeere ti PDP n bi ijọba Buhari ati ẹgbẹ oṣelu APC A pe ileesẹ aarẹ nija lati wẹ ara rẹ mọ lori awọn ọrọ to yi jiji ti awọn amokunsika Boko Haram ji awọn ọmọ naa gbe.
Nítorí náà ó di ọ̀tá wọn,ó sì dojú ìjà kọ wọ́n.
Ẹlẹṣọ ẹnu n ja waya: Oríṣun àwòrán, Eleso adewale/ facebook Àkọlé àwòrán, Afin to da yatọ ninu sinima ni Adewale Ẹlẹṣọ ti ọpọ mọ si ẹlẹṣọ ẹnu n jawaya Afin to da yatọ ninu sinima ni Adewale Ẹlẹṣọ, ti ọpọ mọ si Ẹlẹṣọ ẹnu n jawaya.
Adari ile-ise  olopaa,Mohammed Adamu  soro yii lasiko to n salaye lori eto aabo
Lẹ́yìn tí ó bí Lamẹki, ó gbé ẹẹdẹgbẹrin ọdún ó lé mejilelọgọrin (782) sí i láyé, ó sì bí àwọn ọmọ mìíràn lọkunrin ati lobinrin.
 o je didasile lati se imuro sinsin awon osuwon pasiparo owo kariaye ati lati segbowo idagbasoke .
Nyagali   gbe nile-ise re lojo Abameta sugbon awon
O ni, koda, ko si si ẹni to mọ ibi ti wọn n da awọn idọti ohun eelo ilera ti wọn n ko si pẹlu.
Awọn ibeere yi lo ṣuyọ lori iroyin kan ti iwe iroyin orileede Germany kan torukọ rẹ n jẹ Bild gbe jade pe arakunrin kan torukọ rẹ n jẹ Adolf Hitler wọle sipo kánsílọ̀ ninu idibo to waye ni Namibia.
Russia); Ikouwem Utin (Enyimba FC); Mikel Agu (Vitoria Setubal, Portugal);
Oríṣun àwòrán, GovSamuelOrtom Yatọ si ikede ijọba yi, ajọ to n mojuto itankalẹ arun ni Naijiria NCDC naa fi si oju opo wọn pe eeyan meje miran naa ti ko aisan naa nilu Eko.
Ó ní: “Ní ọjọ́ kan, afunrugbin kan jáde lọ láti fúnrúgbìn.
Wọn ṣàlàyé pé o sọfun awọn pe abúlé Garin Magaji ati Garin Mallam ní Marwa lariwa Cameroon ní àwọn ọmọ náà wà.
Iroyin sọ pe wọn ti kọkọ n wa ọmọde naa nile, ko to di pe awọn ara adugbo mu iroyin wa fun ẹbí rẹ pe wọn ti ri oku rẹ ninu mọṣalaṣi.
Adewale Elesho ni oju ti ri to ninu irin ajo oun lati ilẹ, o ni oun kewu lẹyin ti oun pari iwe alakọbẹrẹ tan.
fun egbe aya awon iko omo ologun ofurufu (Nigerian Air Force Officers’ Wives
O pade iku rẹ nigba to sare lati lọ doola ọkọ rẹ, ti ko le rin to wa laaye awọn ọkunrin.
Lasun fìdí ọ̀rọ̀ yìí múlẹ̀ lásìkò tó ń bá àwọn àkoròyìn sọ̀rọ̀ lọjọ Aiku ńlùú Oṣogbo, to si tun fọwọ sọya pe, bó tilẹ̀ jẹ́ pé àwọn ọmọ ẹgbẹ́ dìtẹ̀ mọ òun nínú ìdìbò abẹ́lẹ́ náà, sibẹ ẹgbẹ́ APC náà ní òun yóò bá dé èbúté ògò.
orile ede Naijiria ko ni jẹ ki wahala eto iselu lorile ede naa forin sanpọn.
 Bello Husseini-Kazaure lo soro yii, ni orile ede Australia.
Ogun yóo kó àwọn ìlú kéékèèké tí ó wà ní gbogbo agbègbè tí ó yí i ká.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Cancer: Ọjọ́ ‘Má wọ kọ́mú ló wà fún ìtanijí àrùn jẹjẹrẹ ọyàn 8 Ẹrẹ̀nà 2018 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 14 Ọ̀wàrà 2018 Oríṣun àwòrán, Geneva_la_jade Oni ọjọ Satide ni ọjọ Kẹtala osu Kẹwa ọdun 2018, ti awujọ agbaye ya sọtọ gẹgẹ bii ayajọ ‘Ma se wọ Kọmu’ fun awọ Bẹẹ ba si gbagbe, osu Kẹwa ni awujọ agbaye ya sọtọ alti maa fi se itankalẹ iroyin lati dena ọwọja arun jẹjẹrẹ to ti di tọrọ fọn kale ni awujọ wa.
Nnamdi Kanu ati ikọ rẹ ni wọn fẹsun onikoko marun kan, ninu eyi ti ẹsun iwa ọdaran ati iditẹ wa ninu rẹ.
Adari ajafẹtọ fawọn ọmọde to doola ọmọdebinrin naa sọ pe ẹnikan lo ta oun lolobo nipa ọrọ ọmọ ọdun mejila naa lasiko ti oun n gbiyuanju lati doola ọmọde miiran.
Ìdẹ ́ kun lè wáyé bí a bá tètè ṣàwarí àrùn àti àìgba ẹni náà láyè láti kó egbò wọ inú omi mímu .
Àwọn nǹkan ti wọ́n gbà lọ́wọ́ wọ́n ni òògùn, ìbọ́n ìgbàlodé kan, ìbọ̀n ọdẹ kan, àdá méjì, ààké àti gángan mẹ́rin.
Nítorí ọjọ́ ń bọ̀ tí àwọn nǹkan wwọ̀nyí le ṣe aláìsí mọ́ tàbí tí wọ́n lè sú ọ; ṣùgbọ́n bí o bá fẹ́ ènìyàn tí ìwọ kò sì lè sọ nǹkan kan pàtó tí o fi wù ọ́, ìfẹ́ pípẹ́ ni ìfẹ́ rẹ.
" Sultan tun gba awọn ọba alaye nimọran lati maa sọ otitọ lai bẹru pe gomina abi awọn alaga ijọba ibilẹ yoo dunkoko mọ wọn.
O wa rọ ijọba ilẹ Naijiria, awọn asofin, akọroyin ati awọn agbẹjọro lati se ofin ti yoo se ofin ti yoo tẹ gbogbo ọmọ Naijiria lọrun, ti ko si ni jẹ ofin ti yoo fa ori apa kan, da apa kan si.
“Ganduje je gomina ti o feran ere-idaraya pupo, ti o si maa n setan lati ran awon odo lowo nipase kikun won lowo lati mu-gberu ba ebun ti won ni fun anfani awon ara-ilu ati idagbasoke orile-ede.
Ṣugbọn nigba ti BBC Yoruba kan si igbakeji gomina lati gbọ iha tirẹ, agbẹnusọ igbakeji gomina, Tope Okeowo sọ pe irọ gbaa ni ohun to n tan kalẹ pe igbakeji gomina n gbiyanju lati ji ẹru ijọba ko jade.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ìtàn ayé Ọba Seriki Abass ti Badagry, tó ní aya 128, ọmọ 144 Wo ibùdó arẹwà tí ọ̀pọ̀ èrò ń ya lọ ní Abuja Obìnrin kan dèrò ilé ẹjọ́ lórí ẹ̀sùn pé ó fi ọ̀bẹ rẹ́ ọmọ rẹ̀ lọ́rùn Adamu Adamu, Minista ètò ẹ̀kọ́ ti fi òfin àátẹ̀lẹ́ síta kí àwọn ilé ìwé lè wọlé Makinde ti sọ̀rọ̀ lẹ́yìn tí asekúpani Akinyele sálo mọ́ àwọn ọlọ́pàá lọ́wọ́ ní àhámọ́ Olólùfẹ́ mi ṣèèsì fi ọkọ́ gbá mi sí gọ́tà, mo rò pé ọlọ́jọ́ dé ni - Iya Osogbo A ko fẹ fi dandan wa nipo agbara amọ ifẹsẹmulẹ orilẹede wa lo jẹ wa logun, eyi ti yoo fun wa laaye lati seto idibo gbogbo gboo laarin akoko perete, eyi ti yoo ro orilẹede Mali lagbara lati se akoso aye wa."
O tẹsiwaju, o ni ajọ ilera agbaye, WHO ti n fọwọsowọpọ pẹlu orilẹede Naijiria lati rii daju wi pe wọn wa'wọ aarun naa bọlẹ laipẹ ọjọ.
Bákannáà ẹ̀wẹ̀wẹ̀, nínú Oṣù Kejì ọdún tí ó kọjá, ajagun fẹ̀yìntì tí ó tún jẹ́ olórí orílẹ̀-èdè Nàìjíríà láyé ológun, Ibrahim Babangida gba Ààrẹ Buhari ní ìyànjú láti máà du ìje fún ipò Ààrẹ fún ìgbà kejì, nítorí wípé ọgọ́rùn-ún ọdún 21 tí Nàìjíríà wà yìí jẹ́ àsìkò àwọn ọ̀dọ́ tí ó ní ìrírí ìgbàlódé.
Bi ilẹ ọjọ Satide si ti mọ, ni awọn oju opo ikansira ẹni ti kun fun oniruuru aworan ti awọn obinrin, paapa awọn ọmọge, n fi sibẹ, eyi to n se afihan pe wọn n yan ilo Kọmu lodi ni ọjọ naa, ti wọn si wọn si se afihan asọ ti wọn wọ lai lo Kọmu.
Níbẹ̀ a óo sọ fún ọ gbogbo nǹkan tí a ti ṣètò fún ọ láti ṣe.
Walcott ọmọ ọdun mọkanlelọgbọn ṣalaye pe awọn ẹgbẹ agbabọọlu mii fẹ ra oun amọ oun pinnu lati pada si ẹsẹ aarọ ni Southampton.
2 1877 Erekusu Turks and Caicos Island 6 15.
Nígbà tí ó di Ọjọ́ Ìsinmi keji, ó fẹ́rẹ̀ jẹ́ pé gbogbo ìlú ni ó péjọ láti gbọ́ ọ̀rọ̀ Oluwa.
Ìjìyà fún Àwọn Tí Wọn ń Ni Àwọn Talaka Lára.
Awọn to tun kan ni: Ogbomosho South LCDA; Ajorosun LCDA; Ibarapa North West LCDA; Itesiwaju LG; Oyo East LG ati Oyo South East LCDA.
"A wa n rọ awọn araalu lati dẹkun iwa ọyaju, ati atako sawọn ẹya miran to n gbe ni ipinlẹ yin nitori ara isẹ ọwọ awọn ọta to n fẹ ayipada ijọba niyi lai seto idibo.
Ibrahim Chattah Oríṣun àwòrán, Ibrahim Chatta Queen Salawa Abeni Oríṣun àwòrán, Salawa Abeni Èmi àti Sanyeri ti tọrọ oúnjẹ jẹ rí nílé oninawo torí ebi, ká tó di gbajumọ oṣere Toyin Abraham tú àṣírí ohun tí ọlọ́pàá Náìjíríà sọ mọ́lẹ́bí rẹ̀ kan dà Ǹjẹ́ ewu wà nínú lílò ẹ̀rọ FaceApp?
Fásítì Babcock lé akẹ́kọ̀ọ́bìnrin tó hàn nínú fídíò ìbálòpọ̀ lọ sílé INEC mo ko dé, ẹ̀rí rè é to ṣàfihàn èrú ìbò ní Kogi - Dino Melaye Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Erelu Elemure: Ìyá mi rò pé mi ò lè tibi kíkọrin bíi bàbá mi là
Gẹ́gẹ́ bi mo ṣe máa ń sọ pé ọkàn mi kún fún wúrà, sùgbọ́n ọ̀ps àwọn oníkorira ń wá ìsubu mí.
Amugbalẹgbẹ fun gomina lori ọrọ aabo.
O ṣalaye pe idibo gomina ko niyanju lawọn ipinlẹ mẹfa nitori rogbodiyan to bẹ silẹ lawọn ibikan, dida lilo ẹrọ kaadi idibo duro ati wi pe ajọ INEC gan an kuna lati ko ẹrọ kaadi idibo de awọn ibudo idibo kan.
Ijọba mi lo kọ́kọ́ sedasile Igbimọ oludari fáwọn akanda ẹda, koda mo yan amugbalegbe fun ara mi nitori ọ̀rọ̀ wọn."
Gẹgẹ bi iroyin ti ileeṣẹ Premium Times to pẹlu awọn ileeṣẹ to ṣe iwadii naa, ni o ti to ọdun mẹjọ ti banki naa ti bẹrẹ si ni wo igbesẹ Atiku pẹlu owo ti wọn fi n ranṣẹ si oke okun.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Akẹkọ fasiti purọ mọ ọlọpa lẹyin to fowo ileewe ta MMM 15 Ẹrẹ̀nà 2018 Oríṣun àwòrán, Mama Akin Àkọlé àwòrán, Ọlayẹmi fi owo ileewe ta kalokalo, o wa n sare kiri Ọlaniyan Ọlayẹmi Joshua to jẹ akẹkọ ọlọdun kẹin ni fasiti ipinlẹ Ọsun, UNIOSUN ti wa lahamọ awọn ọlọpaa bayii lẹyin ti awọn mọlẹbi atawọn ọrẹ rẹ ti pariwo sita lori ẹrọ ayelujara wi pe agọ ọlọpa to wa l'Ojodu nilu Eko lo sọnu sii.
’Àwọn kan ninu àwọn akéwì yín pàápàá ti sọ ohun tó jọ bẹ́ẹ̀; wọ́n ní,‘Ọmọ rẹ̀ ni a jẹ́.
" Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Èyí ni àwọn nkan tí o gbọ́dọ̀ mọ̀ kó ò tó ṣe onídúùró ẹnikẹ́ni Ni ti ile ẹjọ, awọn ti ẹsun ti wọn fi kan wọn ba fi aaye silẹ pe wọn le maa gba ile wọn wa jẹjọ ni adajọ maa n gba oniduro fun.
Ní bayìí, orilẹ̀-èdè mẹẹdogun ni wọ́n ti fi ofin de láti ma wọ Naijira mọ Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Agbẹnusọ ajọ naa ni ipinlẹ Enugu, Chris Oluka lo fi ikilọ yi sita.
 Bakan naa, koi pe rara ti a tun se itore awon ohun elo igba boolu fun iko agbaboolu ti o to ẹ̀ẹ́dẹ́gbéje ni ipinle yii, eleyi ti o wa lara awon ero wa lati mu igberu ba ere-idaraya nipinle yii.
Iṣẹ idọti ni Adebola pe iṣẹ iru ṣise ati pe o tun mu wahala pupọ dani ti eeyan ba fẹ ṣe iru naa daadaa.
Títí di àkókò yìí, àgọ́ OLUWA tí Mose pa ní aṣálẹ̀, ati pẹpẹ ẹbọ sísun wà ní ibi pẹpẹ ìrúbọ ní Gibeoni.
o kò ní ní ìbànújẹ́ ọkàn pé o ti paniyan rí láìnídìí tabi pé o ti gbẹ̀san ara rẹ.
Theophilus Danjuma, tí òun náà jẹ́ ọ̀gágun tí ó ti jagun fẹ̀yìntì ní oṣù kẹ́ta ọdún tí ó kọjá fi ẹ̀sùn kan “ẹgbẹ́ ológun orílẹ̀-èdè Nàìjíríà wípé ó ń gbárùkù ti ìpànìyàn nípakúpa tí ó ń lọ ní orílẹ̀-èdè Nàìjíríà.
Nítorí a gbọ́ pé àwọn kan ninu yín ń rìn ségesège, wọn kì í ṣiṣẹ́ rárá, ẹsẹ̀ ni wọ́n fi í máa wọ́lẹ̀ kiri.
O si ti yọnda ara rẹ lati ṣe ojuṣe naa.
Mo ti wà ní ipò baba mi, mo ti gorí ìtẹ́ ọba Israẹli, bí OLUWA ti ṣèlérí, mo sì ti kọ́ tẹmpili fún OLUWA Ọlọrun Israẹli.
Ọlọrun mi, Ẹni Mímọ́ mi, a kò ní kú.
“Ẹ gbọdọ̀ pa àwọn ìlànà mi mọ́, ẹ kò gbọdọ̀ jẹ́ kí oríṣìí meji ninu àwọn ohun ọ̀sìn yín gun ara wọn, ẹ kò gbọdọ̀ gbin oríṣìí èso meji sinu oko kan náà, bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò gbọdọ̀ fi oríṣìí aṣọ meji dá ẹ̀wù kan ṣoṣo.
Iroyin fi han wipe ọjọ igbeyawo arabinrin ku diẹ nigba ti alase rẹ naa ṣe iku pa.
Bí Isaaki ti súre fún Jakọbu tán, Jakọbu fẹ́rẹ̀ má tíì jáde kúrò lọ́dọ̀ rẹ̀ tí Esau ẹ̀gbọ́n rẹ̀ fi ti oko ọdẹ dé.
Wọ́n lu odi ìlú, àwọn ọmọ ogun sì gba ibẹ̀ sá jáde lóru.
N óo fi òpin sí ìgbéraga àwọn alágbára wọn, wọn yóo sì sọ àwọn ibi mímọ́ wọn di eléèérí.
Lyìn èyì wàyí ni a ri ìyàwo mi nínú kẹkẹ góòlù tí ẹṣin mẹ́rìndínlógún n fà, àwọn ẹsin wọ̀n-nnì kún fún ohun ọ̀sọ̀ láti òkè dé ìsàlẹ̀, ní apá ọ̀tún àti apá òsì kẹ̀kẹ̀ ìyàwó mi yìí ni kẹ̀kẹ́ bẹ́ẹ̀ méjì tún wà tí ó jẹ́ ti góòlù tí ẹsinn mẹ́rìndínlógún mẹ́rìndínlógún tún ń wọ́, ẹ̀gbọ́n ìyàwó mi ọkùnrin lo wà nínú méjéèjì tí wọ́n jẹ́ ìbátan rẹ̀.
Oṣu mẹta sẹyin ni wọn funra si pe o pa ololufẹ rẹ naa, ṣugbọn aipẹ yii ni aṣiri rẹ tu nigba ti wọn ba ọkan lara ẹyin ọkunrin naa ninu ẹrọ ilọta igbalode.
Ìdí tí mo ṣe wá láì kọminú nìyí nígbà tí o ranṣẹ sí mi.
OLUWA fi ara rẹ̀ búra pé,o óo gbé wọn wọ̀ bí nǹkan ọ̀ṣọ́ ara.
Aipepade awọn ti ko ga pupọ ni iduro ni ko jẹ ka mọ alaga awọn arara.
Ọlọpa kan yinbọn mọ ọga rẹ nitori obinrin Wo ǹkan mẹ́jọ tó yẹ kóo mọ̀ nípa Alex Badeh táwọn agbébọn pa Ọmọ Nàìjíríà r'ẹ́wọ̀n he ní Amẹ́ríkà Ile iṣẹ olootu ijọba ilẹ naa sọ pe ẹsọ naa lo ṣeku pa ọgagun naa pẹlu ọga ọmọ ogun mii, ọgagun Gezai Abera ninu igbiyanju ati fitẹgbajọba.
Àjọ NCDC kéde ènìyàn 195 míràn tó ní ààrùn Covid-19 l'órílẹ̀-èdè Nàìjíríà Ẹ̀dínwó epo bẹntíró tí NNPC kéde kò kan ará ìlú Àwọn ọmọ Nàìjíríà 256 tó há sí ìlú Dubai ti gúnlẹ̀ sí Nàìjíríà Lérò tí Ajayi Solomon, oúnjẹ leè gbé ẹmi ró gẹ́gẹ́ bíi ẹlẹ́ran ara àmọ́ ọ̀rọ̀ Ọlọ́run nìkan ni oúnjẹ ẹ̀mí tí yóò jẹ ká dàgbà nínú ìwà rere, tí yóò sì jẹ ká ye, ó ní ọjà àti sọọsi lo yẹ kí ìjọba sí papọ.
Jẹ́ kí iná tí o dá fún àwọn ọ̀tá rẹ jó wọn run.
Owó oúnjẹ ni mo lọ ọ gbà, oyún ọmọ tí mo jù sí àkìtàn ni mó gbé wálé- Dupe, ìyá Muiz Ènìyàn 156 míràn ló tún kó Coronavirus ní Nàìjíríà ní ọjọ́ Ẹtì Olórin Kano tí wọ́n dájọ́ ikú fún pe ẹjọ́ kòtẹ́milọ́rùn Nàìjíríà làwọn ní ìfẹ́ sí ìpèsè abẹ́rẹ́ àjẹsára Covid-19 tí Russia ṣe Wo ọ̀nà ìsanwó tuntun fún àwọn oníbárà iná mọ̀nàmọ́ná ní Eko (EKDC) Àwọn dókítà yóò bẹ̀rẹ̀ ìyanṣẹ́lódí lọ́jọ́ Ajé Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Fuel hike protest: Àwọn akẹ́kọ̀ọ́ ìpínlẹ̀ Oyo, Osun àti Ondo ṣe ìfẹ̀hónúhàn lórí èlé owó iná àti owó epo8 Owewe 2020 Fídíò, Akomolede ati Aṣa lori BBC: Mọ̀ si nípa oríṣìí ẹ̀ka ìsọ̀rí ọ̀rọ̀ àti ìwúlò wọn8 Owewe 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Ninu ọrọ apilẹkọ rẹ niwaju igbimọ iwadi, Jaafar Jaafar ni ile ise iroyin Daily Nigeria se iwadi ofintoto saaju ki wọn to gbe fidio ibi ti Ganduje ti n gba owo abẹtẹlẹ jade.
O ṣalaye pe bi oun ṣe n bọ lati oko nirọlẹ ọjọ kan ni ọmọkunrin kan ti ko to mi ṣin aiya fun olori abule wa.
Ó bá fà á lọ́wọ́ ọ̀tún, ó gbé e dìde.
'Ààrùn HIV kò lè ràn pẹ̀lú itọ́ tàbí òógùn' Adarí Ilé ìgbìmọ̀ Asòfin tako ètò ìjọba tiwantiwa- Agbẹjọ́rọ̀ Rọ́bà ìdáàbòbò gbówó lórí!
Nkan tí a mọ̀ nìyíì Mo ti kúrò ní ààfin Oyo, kí ìròyìn tó ò jáde pé èmi àti Wasiu Ayinde n fẹ́ ara wa - Olori Badirat Nigba to n sọrọ akọsọ lẹyin to wọle fun saa keji naa, Aarẹ Nana Akufo Addo beere fun irẹpọ laarin awọn ọmọ orilẹede naa, to si tun jẹjẹ lati mu agbega ba igbe aye wọn.
Coronavirus: Àrùn Coronavirus fa'lẹ̀ya láwọn ìletò aláwọ̀dúdú ní Amẹ́ríkà
Adebanji Akintoye ti ṣe senetọ Naijiria ri.
30 Ṣùgbọ́n lõtọ́, lõtọ́, ni mo wí fún ọ, pé gbogbo àwọn tí wọ́n bá gbà mi, àwọn náà ni èmi yíò fi agbára fún láti di ọmọ Ọlọ́run, àní fún àwọn tí wọ́n gbàgbọ́ nínú orúkọ mi.
Iwadii naa ni o ṣeni laanu pe awọn oṣiṣẹ agbefọba ti pataki iṣẹ ilu nbẹ ni ikawọ wọn atawọn to wa ni iṣkoso ofin gan ni a n ba nidi iwa ibajẹ naa.
kí n lọ sí ìsàlẹ̀ àfonífojì ọmọ Hinomu, lẹ́nu Ibodè Àpáàdì; kí n sì kéde ọ̀rọ̀ tí òun óo sọ fún mi níbẹ̀: 
Oríṣun àwòrán, @dinomelaye Àkọlé àwòrán, Ṣẹnatọ Melaye nàá 'fi ọ̀rùn rọ́' lásìkò tó bẹ́ sílẹ̀ nínú ọkọ̀ ọlọ́pàá Ṣùgbọ́n Melaye kọ́ ni olóṣèlú Nàìjíríà tí yóò kọ́kọ́ lọ sílé ẹjọ́ lórí àketè àìsàn.
Àwọn eniyan péjọ láti gbogbo ìlú Juda, wọ́n wá bèèrè ìrànlọ́wọ́ OLUWA.
Ó tún fi ṣe dùùrù ati hapu fún àwọn akọrin.
Ní ọdún kinni tí Dariusi, ọmọ Ahasu-erusi, ará Mede, jọba ní Babiloni, 
Ọmọ iná làá rán síná, Angel Maria fojú ọlá Real Madrid gbolẹ̀ Athletico bu omi la ìgara Christiano Ronaldo, ní Madrid ìjàmbá ọkọ lọnà Èkó gba ẹmí Èniyàn márùn ún!
Ti a ko ba gbagbe, wọn se ibura fun aarẹ Uhuru Kenyeta fun saa keji, losu kọkanla ọdun to kọja.
Idi ni wi pe idibo yii tunbọ fagbara fun fa kin faa laarin wọn lori ẹni ti o lagbara ju lori oselu Kwara.
Ọkùnrin kan gbé ‘búrọ́ọ̀ṣì ìfọyín’ mì Àwọn dókítà ìpínlẹ̀ Eko tó ń yanṣẹ́lódì ti padà s'ẹ́nu iṣẹ́ Ààrẹ Buhari ti fi ọwọ́ òsì júwe ilé fún Ọ̀gá Àjọ ìdánwò NECO àti àwọn mẹ́rin míràn Wo ọ̀rọ̀ 'àbùkù' tí òṣèré sinimá, Adesuwa Etomi Wellington sọ nípa ọbẹ̀ gbẹ̀gìrì Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Oba alade naa fi arọwa yi sita lopin ọsẹ nibi ipade kan pẹlu igbimọ alakoso ile iṣẹ Dangote nilu Eko.
Mose ka gbogbo ọ̀rọ̀ orin náà patapata sí etígbọ̀ọ́ àpéjọ àwọn ọmọ Israẹli.
Ṣugbọn Dafidi gbọ́ nípa rẹ̀, ó sì lọ sá pamọ́ sí ibi òkúta kan tí ó wà ní aṣálẹ̀ Maoni.
“Ohun tí yóo jẹ́ ti àwọn alufaa lára ẹran tí àwọn eniyan bá fi rúbọ nìyí, kì báà jẹ́ akọ mààlúù tabi aguntan ni wọ́n wá fi rúbọ, wọn yóo fún alufaa ní apá ati ẹ̀rẹ̀kẹ́ mejeeji, ati àpòlùkú rẹ̀.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Texas shooting: Ọlapàá ní Seth Ator tó pa ọ̀pọ̀ èèyàn ní Texas ṣẹ̀ṣẹ̀ pàdánù iṣẹ́ rẹ̀ ni 2 Owewe 2019 Oríṣun àwòrán, Instagram/sethator Ileeṣẹ ọlọpaa niluu Odessa lapa iwọ oorun ipinlẹ Texas lorilẹ-ede Amẹrika ti fi orukọ agbebọn, Seth Aaron Atorto to yinbọn fawọn eeyan to to bi ogun lọjọ Satide sita.
Oríṣun àwòrán, Bashir Ahmad Àkọlé àwòrán, Ààrẹ Buhari ní ìjáfáfá ọlọ́pàá yóò fún ìjọba àti aráàlú ní ìfọ̀kànbalẹ̀ tó kúnná 'lati Taraba de Sokoto, de ẹkun aringbungbun gusu orilẹede yii, ọkan ọpọlọpọ araalu kii balẹ ayafi ti wọn ba ri awọn ologun.
  Ní ìgbà òtútù nìkan ni yìnyín máa nṣábàá rọ̀ .
Natani bá tọ Dafidi lọ, ó sì sọ gbogbo nǹkan tí OLUWA fi hàn án fún un.
Buhari jawọ ninu ilana okoowo tuntun fun Afrika
OLUWA nìkan ni ó lè san ẹ̀san fún eniyan burúkú gẹ́gẹ́ bí ìwà ìkà rẹ̀.
Wọn sọ fun ọkọ mi pe, ṣe bi gbogbo ọmọ ti ma a bi yoo ṣe ma a ri niyi?"
" Àkọlé àwòrán, Ọba Adekunle Adebọwale lo ṣoju Ọọni Ninu ọrọ tiẹ, igbakeji oludasile ajọ ẹlẹyinju aanu naa, arabinrin Temitọpẹ Morẹnikẹ Adeṣẹgun ṣe alaye wipe Ọọni Ile-Ife Ọba Ogunwusi ṣe agbekale ajo naa pẹlu ajọṣepọ awọn lajọlajọ mii ti kiiṣe tijọba fun anfani awọn ọmọ orukan ati awọn to kudiẹ kaato fun lojunna ati le fun igbe aye wọn ni itumọ ati ibẹrẹ ọtun.
Ohun tó yẹ kí o mọ̀ nípa ìgbésẹ̀ tí Amẹ́ríkà fẹ́ gbé lórí Nàìjíríà nítorí ọ̀rọ̀ ẹ̀sìn Ṣọ́ọ́ṣì kan sí ìlẹ̀kùn rẹ̀ fún àwọn mùsùlùmí láti kírun Jímọ̀ ní Germany Keresimesi ma n fun awọn Musulumi ni anfaani lati ro ibaṣepọ wọn pẹlu aladugbo to jẹ Kristiẹni."
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Sotitobire Church: E túbọ̀ ní sùúrù, a máa wá ọmọ náà rí- Alukoro ọlọ́pàá Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Sotitobire Church: E túbọ̀ ní sùúrù, a máa wá ọmọ náà rí- Alukoro ọlọ́pàá 27 Ọ̀pẹ̀̀ 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 29 Òkùdu 2020 Ohun to pamọ, oju Olorun lo too ni ọrọ Kolawole Gold to dawati di bayii.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Alcohol Sanitizer: Èèyàn 86 tó mu ọtí ayédèrú d'èrò ọrùn ní India, ìwádìí bẹ̀rẹ̀ 2 Ògún 2020 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Tenant Creek ti ri alekun ninu iwa ipa ati gbigba ẹmi ara ẹni latari ọti amupara O kere tan eeyan mẹrindinlaadọrun lo ti dero ọrun lẹyin ti wọn mu ọti agbelẹrọ ni ipinlẹ Punjab to wa ni ariwa orileede India.
Iwadii yii lo maa fihan ẹbi iyawo awọn nkan to yẹ ki wọn mọ nipa ọdọmọkunrin to fẹ fẹ ọmọ wọn ati iru ẹbi to ti jade wa.
Lootọọ ile iṣẹ aarẹ sọ pe awọn irinajo naa ṣe pataki, ṣugbọn ọpọ ọmọ Naijiria lo sọ pe aarẹ si le ran aṣoju lọ si awọn orilẹ-ede yii k'oun le gbajumọ awọn nnkan mii nile.
Bí ẹwá rí abirun funfun lórí
NCDC fikun pe awọn ipinlẹ ti ọrọ naa kan ni ipinlẹ Eko, Rivers, Oyo, Abuja, Borno, Plateau, Jigawa, Kano, Abia, Ekiti, Delta, Kwara ati Taraba.
gẹ́gẹ́ bí àṣà wọn, arúgbó lo ń ta ọjà, òun ló gbọ́dọ̀ kiri, gbogbo àwọn tí a sì bá nínú ọjà náà kò ju àádọ́ta lọ, gbogbo wọn ni wọ́n sì ti fi gbogbo orí hu ewú pátápátá, wọn ìbá sì tilẹ̀ pọ̀ jù bẹ́l lọ bí ko ṣe pé wọn kò ń pẹ́ kú ní ìlú náà.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, End SARS, End SWAT: Ó pé mi bí SARS kò ṣe sọ mí dolówọ́- Fulani Kwajafa .
Balogun tí ó wà fún oṣù kẹsan-an ni Abieseri ará Anatoti, láti inú ẹ̀yà Bẹnjamini.
"Ohun tí o kò mọ̀ nípa Ebila ""One Million Boys"" àti Ekugbemi, olórí ẹgbẹ́ òkùnkùn méjì tó da ìlú Ibadan rú Bí ẹgbẹ́ One Million Boys ṣe bẹ̀rẹ̀ rèé àti ọṣẹ́ tó ṣe n'Ibadan Àlàyé rèé lórí bí wọ́n ṣe pa Ebila, olórí àwọn ""One million boys"" n'Ibadan Tolulope Arotile: Ọ̀rẹ́ Tolu ṣàlàyé bí ìjàmbá ọkọ̀ tó ṣekúpa á ní Kaduna ti ṣẹlẹ̀ Ọna wo ni awọn eeyan n gba ra Bitcoin?"
Oríṣun àwòrán, Other Ile ẹjọ ni ile aṣofin tapa si ofin yiyan ọba nipinlẹ Kano eyi to lodi sofin.
Wo àwọn nkan tí o le ṣe gẹ́gẹ́ bi aláboyún lásìkò àjàkálẹ̀ ààrùn Covid-19 Wo àwọn ọ̀nà tí o le fi mú ara rẹ gbá yágí-yágí lásìkò ìgbélé yìí Amọṣa, ki lo sun wọn yan orukọ, 'Oshisko twins' ati pe ki ni awọn ipenija ti wọn n dojukọ gẹgẹ bii ọrẹ meji to sọ ara wọn di ibeji ti wọn si tun yan iṣẹ amuludun laayo?
Ni ti abo, o ni ohun ti ko ni jẹ ki nkan buruku sẹlẹ ni ijọba oun yoo gbajumọ.
Mo fẹ́ kọ́ ilé ìsìn fún OLUWA Ọlọrun mi.
Oluranlọwọ si Gomina ipinlẹ Oyo lori ọrọ awọn akẹkọọ, Olojede Victor lo fi ọrọ yi soju opo Twitter rẹ.
Ninu ibojì tirẹ̀ gan-an ni ó sin ín sí.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Diezani gan an ní Hushmummy tó ń bú àwọn Yahoo boys- Àwọn Ọmọ Naijiria lórí Twitter 10 Ògún 2020 Oríṣun àwòrán, SAMUEL KUBANI Awọn ọmọ Naijria ti bu ẹnu atẹ lu ọrọ ti minisita fun ọrọ epo bẹntirolu ni Naijiria tẹlẹri.
Ó ní pẹ̀lú ìjáwé olúborí yìí, ẹgbẹ́ náà ti wá fi ẹsẹ̀ múlẹ̀ ní àwon ìpínlẹ̀ tó wà ní Gúúsù ìwọ̀ Oòrùn Nàìjíríà.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Alápatà fi ìbínú lu ìyàwó rẹ̀ pa ní Ogun 4 Ọ̀pẹ̀̀ 2018 Oríṣun àwòrán, Ogun State Police Command Alápata kan ti orúkọ̀ rẹ̀ ń jẹ́ Sina Kasali ti wọ ihámọ́ ọlọ́pàá lórí ẹ̀sùn pé ó lu ìyàwó rẹ̀ pa ní Agbado, Ijọba Ibílẹ̀ Ifo ní Ìpínlẹ̀ Ogun.
Marz, eni ti o wa ni ipinle Eko lati sagbateru ipate ohun ogbin so pe, o se pataki ki orile-ede Naijiria se alekun eto ogbin re.
Mo dì ọ́ ní àmùrè bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé o kò mọ̀ mí.
Mo ṣe inúnibíni sí ọ̀nà ẹ̀sìn yìí.
Iroyin sọ pe ọkan lara awọn ọmọ ẹgbẹ ẹlẹsin ibilẹ nipinlẹ Osun lo fi ọrọ to ileeṣẹ ọlọpaa l'eti pe, oun ri Jolaosho ninu fidio naa to n hu iwa ibajẹ ninu igbo ọhun.
Àwọn ọmọ Israẹli sì sọ ibẹ̀ ní Horima.
Yahoo Yahoo: Dating , Construction, awọn tó ń ṣe credit card - oríṣi tó wà Ewu ń bẹ lóko lóńgẹ́!
Wo àwọn Gómìnà Naijiria tí àrùn Covid-19 ti bá fínra Bàbá mi Aláàfin, ẹ ṣeun ẹ̀bùn owó tí ẹ fún èmí àti ọkọ mi- Lizzy Anjọrin Ni ana, ọjọ kejilelogun, oṣu keje ni wọn bẹrẹ eto idibo naa nibi ti awọn Oludije mẹjọ ti pàda wako lati mọ ẹni ti yoo ṣoju ẹgbẹ oṣelu Peoples Democratic Party ninu idibo to m bọ.
Ajọ SEC ni wọn fi ara balẹ ṣiṣẹ iwadii ileeṣẹ naa ti wọn fi lọlẹ labẹ Nigerian and Johannesburg Stock Exchange ni.
Eyi lo jẹ ki ileeṣẹ ọlọpaa Naijiria kilọ fawọn ẹgbẹ oṣiṣẹ NLC ati TUC to fẹ gunle iyanṣẹlodi lọla ọjọ Aje lori afikun owo ina ọba ati epo bẹntiro.
 Àwọn ẹ ̀ yà lactobacillus ni ó gba ìlẹ ̀ ká .
Nígbà tí mo jẹ́wọ́ gbogbo ìṣe mi, o dá mi lóhùn;kọ́ mi ní ìlànà rẹ.
ọjọ kiini si Ojọ Abamẹta, ọjọ kẹta oṣu kẹjọ ọdun 2019.
Ni kete ti Dapọ pada sile lati oke okun, lo tun morile ile ẹkọ fasiti ipinlẹ Ekiti lati gba oye ọmọwe, ti a mọ si PhD ninu imọ nipa ìnáwò, to si tun gba oye ọmọwe keji lẹka imọ nipa akoso okoowo nile ẹkọ fasiti Adeleke to wa nilu Ẹdẹ, nipinlẹ Ọṣun.
(Àwọn Sadusi ni wọn kò gbà pé òkú kan a tún máa jinde.
" Oríṣun àwòrán, kamilu-kompo O ṣàlàyé pé, ó dára kí èèyàn ni ẹkọ tó ye kooro nínú gbogbo ohunkóhun ta bá fẹ́ ṣe, ẹnikẹ́ni tó bá di fẹ́ lu aluyọ nínú isẹ tíátà gbọ́dọ̀ ni Ọlọ́run, kò ní ìtẹríba àti apọnle àwọn ọga tó bá lẹ́nu isẹ pẹ̀lú ìfaradà àti aforiti.
Buhari kàn ń kọwọ́ bọ̀wé nílẹ̀ òkèèrè kiri ni, a ò rí ipa ní Nàijíríà- Onímọ̀ ọrọ̀-ajé Tọwọ́ tẹsẹ̀ laá fi gba ìrànwọ́ owó ẹ̀kọ́ Almajiri ní ìpinlẹ̀ Oyo- Alága Subeb Ìbẹ̀rẹ̀ mi kò rọrùn rárá, omi máa ń bọ́ lójú mi tí mo bá rántí àkókò náà - Small Doctor Yewande, Yetunde, Yejide, Iyabọ jé awọn orukọ ti a n sọ ọmọbinrin ti a bi lẹyin iku iya baba rẹ tabi ti iya iya rẹ.
Àwọn ni wọ́n kò júbà ẹranko náà tabi ère rẹ̀, wọn kò sì gba àmì rẹ̀ siwaju wọn tabi sí ọwọ́ wọn.
O salaye pe, iroyin won yoo je ki ijoba ati awon ara-ilu ni agboye ohun ti o n sele ati awon ipenija to o n koju eka eto-ilera naa.
Kíní ǹkan tó wọ́pọ̀ láàrín àwọn tó máa n lo ìwà ipá?
A óo waasu ìyìn rere ìjọba yìí ní gbogbo ayé gẹ́gẹ́ bí ẹ̀rí sí gbogbo orílẹ̀-èdè.
Sugbọn niwọn igba to se pe atori ;aye, to ba lo siwaju, a tun lo sẹyin, iriri aye kan sọ Baba Suwe si adanwo, eyi to mii logbologbo.
Ohun tó kàn ni láti mọ̀ bóyá iléèṣẹ́ ìròyìn míràn gbé e síta lórí ìtàkùn àgbáyé wọn.
Bí Asiria ti dójú tì yín,bẹ́ẹ̀ ni Ijipti náà yóo dójú tì yín.
Bukunmi Oluwasina: Ìmọ̀ràn ọkọ mi nínú eré tí mo bá kọ lo ń jẹ́ kí eré mi dáńtọ́
To̩kùnrin tobìnrin tó bá ti bàlágà ló ní è̩tó̩ láti fé̩ ara wo̩n, kí wó̩n sì dá e̩bí ti wo̩n sílè̩ láìsí ìkanilápá‐kò kankan nípa è̩yà wo̩n, tàbí orílè̩‐èdè wo̩n tàbí è̩sìn wo̩n.
Ninu ọrọ to wa ninu fidio oke yii, Makinde ni oun jẹun to bẹẹ gẹẹ ti oun fi ro wi pe oun yoo ti di sanra lasiko ti ara oun yoo ba fi ya.
Ẹ kọ orin sí OLUWA, ẹ yin orúkọ rẹ̀;ẹ sọ nípa ìgbàlà rẹ̀ láti ọjọ́ dé ọjọ́.
Ile-ise eleto ilera lorile-ede Ethiopia so pe, ile-ise ti o n ri si oro ile okere so pe,”awon omo orile-ede Ethiopia ti won wa ni atimole lorile-ede Mozambique ti pada sile pelu akitiyan ile-ise asoju orile-ede Ethiopia  lorile-ede South Africa ati iko ti o n ri si oro awon arinrinajo lona aibofin-mu ninu ajo isoka agbaye”.
Bawo ni ọrọ kinihun yii ṣe jẹ?
Ohun ti wọn n sọ bayi ni pe se Afẹnifere lasẹ lati sọ ibi ti awọn Yoruba yoo lọ lọdun 2019.
Oríṣun àwòrán, @daily_nigerian Malam Nasir El-Rufai, Kaduna Gomina ipìnlẹ Kaduna, Malam Nasir El-Rufai funra rẹ lo fi fidio kan lede loju opo Twitter ijọba ipinlẹ naa pe oun ti ni arun Coronavirus.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Facebook wọ gau lori aawọ data 20 Ẹrẹ̀nà 2018 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Wọn lo iroyin awọn eniyan lati se ranwọ fun idibo Aare Ilẹ Amẹrika Donald Trump Awọn oloṣelu ni orilẹede Amerika, Yuroopu ati Ilẹ Gẹẹsi ti kan si awọn alaṣẹ oju opo idọrẹ lori itakun agbaye, Facebook lati ṣalaye lori bi ileeṣẹ Cambridge Analytica ṣe ni akọọlẹ iroyin awọn eniyan lai gba aṣẹ latọdọ wọn.
Àwọn agbègbè ní Mekong níbi tí àwọn oníṣẹ́-ìwádìí ti ṣe iṣẹ́.
baba Ladani, baba Amihudu, baba Eliṣama; 
Nínú ẹgbẹ́ yìí, àwọn ọ̀jọ̀gbọ́n, ọ̀mọ̀wé, àwọn olùkọ́ àgbà àti olólùfẹ́ Yorùbá ní ó wà níbí.
Àárẹ̀ lè mú ara ati ẹ̀mí mi,ṣugbọn Ọlọrun ni agbára ẹ̀mí mi,ati ìpín mi títí lae.
gbe di atundi idibo gbọdọ ri i daju pe won  se isẹ wọn bi isẹ, lona ti awon
''Bakan naa lọpọ obinrin ti sọ fun mi pe iriri mi ti fun awọn naa ni igboya lati bori iru iṣoro bayii tawọn naa n doju kọ; Eyi jẹ idunnu fun mi.
Má fi ohunkohun pamọ́; sọ pé,‘Ogun tí kó Babiloni,ojú ti oriṣa Bẹli,oriṣa Merodaki wà ninu ìdààmú.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Mo kàn máa ń lọ́ ayẹyẹ kiri torí ijó láì ṣe pé wọ́n pe mí ló sọ mí di DJ olórin Fuji nìkan' Oludari patapata ajọ naa, Chigwe Ihekweazu fi ọrọ naa lede pe wọn ri tuntun yii lasiko ti awọn onimọ iwadi ijinlẹ nibudo iwadi ijinlẹ nipa awọn ajakalẹ arun nilẹ Afrika (African Center of Excellence for Genomics of Infectious Diseases, ACEGID) ni fasiti Redemmers University, Ede n ṣe iwadi ijinlẹ kan.
Nibayii ọwọ ileeṣẹ ọlọpaa ipinlẹ Ọyọ ti tẹ afurasi kan, bẹẹ sini iṣe iwadii ti n ọ lọwọ lorii ẹsun naa.
3 Ògún 2019 Ọ̀ọ̀nì mẹta ọtọọtọ lo ya bo agbeegbe Vadodara lorilẹede India lẹyin ti ikun omi waye lagbeegbe naa.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ikú Djxgee: DJsosogee ní olóògbé fẹ́ràn ẹbí àti ọmọ 3 Sẹ́rẹ́ 2019 Oríṣun àwòrán, @djxgee Lẹyin ti okiki kan pe gbajugbaja aforin-danilaraya nibi ayẹyẹ, DJ Seun Ọmọgaji, ti ọpọ mọ si DJXGee ti gbẹmi ara rẹ lẹyin wakati diẹ to fi atẹjade kan sita lori ikanni ayelujara Instagram rẹ ni ọjọru, ọpọ awọn ilumọọka adanilaraya ni wọn ti n ṣe idaro rẹ.
Gẹgẹ bi iroyin ti sọ, awọn ọdọ ilu Ẹdẹ ti inu n bi ni wọn lu arakunrin naa pa lẹyin ti wọn ni ere aṣapajude to n fi ọkọ rẹ sa nigba to n gbiyanju ati sa bọ mọ agbofinro lọwọ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Akomolede ati asa Yoruba: Ẹ wá kọ́ nípa àpòtí ìṣura èdè wa lórí BBC Yorùbá Ki lo kọkọ sẹlẹ?
Leyin iku oloogbe Kuti, ile igbafe Afrika Shrine ohun ni o wa labe akoso awon omo re mejeeji, Femi ati Seun, ti won pawo po lati tesiwaju ninu ise orin kiko eyi ti baba won yan laayo.
Ẹ tilẹ̀ lè ṣẹ́ gègé lórí ọmọ òrukàn,ẹ sì lè díye lé ọ̀rẹ́ yín.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù JAMB: Ǹjẹ́ o ma ń bẹ̀rù láti ṣe ìdańwò?
Àjọ ọlọpàá ni ko tí sí ìwé to fi ìdí ọ̀rọ̀ náà múlẹ̀ fún àjọ ọlọ́pàá lóri pé óṣeeṣe ki àwọn ọlọpàá kògbérègbè to kọ́kọ́ mú'àwọn ọ̀daràn náà ti tara wọ́n kó ààrùn Corornavirus.
Mo sì mọ̀ pé Kerubu ni wọ́n.
Ọba bá bi ìyá rẹ̀ pé, “Kí ló dé tí o fi ní kí n fún un ní Abiṣagi nìkan?
Ọpọ gbagbọ pe Buhari kọ lati koju awọn Fulani ti awọ̀n eeyan n fi ẹsun ipaniyan jakejado Naijiria kan, nitori pe o jẹ ẹ̀yà kan naa pẹlu wọn.
Toyin dupe lọpọlọpọ lọwọ gbogbo awọn ololufe rẹ fun atilẹyin ati ifẹ ti wọn ni si i lati ẹyin wa.
 Ó ń ṣe oríṣiríṣi eré ìdárayá nígbà tí ó wà léwe .
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Yemi Osinbajo: Ẹgbẹ́ Arewa ní ọ̀rọ̀ ìgbákejì ààrẹ tún dákún ìṣòro Nàíjíríà ni 14 Agẹmo 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 29 Owewe 2020 Oríṣun àwòrán, @ProfOsinbajo Ẹgbẹ ọmọ Yoruba lorilẹede Naijiria ti satilẹyin fun igbakeji aarẹ lorilẹede, Yemi Osinbajo lori ọrọ to sọ pe, o ṣeeṣe ki Naijiria pin ti awọn adari ko ba kiyesi ara.
akede soro nile-aare to wa niluu Abuja, leyin ipade ti o se pelu igbakeji aare  Yemi Osinbajo.
Alagba kisira tun so pe, ipa pataki ti eko isiro n ko lati mu idagbasoke ba awon eniyan ati orile-ede ko se e foworo seyin , gege bi irinse fun imo sayensi.
Ṣugbọn Boasi dá a lóhùn, ó ní, “Gbogbo ohun tí o ti ṣe fún ìyá ọkọ rẹ, láti ìgbà tí ọkọ rẹ ti kú ni wọ́n ti sọ fún mi patapata, ati bí o ti fi baba ati ìyá rẹ sílẹ̀, tí o kúrò ní ìlú yín, tí o wá sí ọ̀dọ̀ àwọn eniyan tí o kò mọ̀ rí.
Gege bi oludari agba ile-ise VON, ogbeni Osita Okechukwu se so,“Ipinnu wa ni lati gbe awon ede ile okere laruge, papaa julo ede Faranse.
Ọ̀dọ̀ Ọlọrun ni a ti bí ẹnikẹ́ni tí ó bá ní ìfẹ́, ó sì mọ Ọlọrun.
Níbikíbi tí ó bá wọ̀, ìbáà ṣe ní abúlé tabi ninu ìlú, ní ìgbèríko, tabi ní ọjà, wọ́n ń gbé àwọn aláìsàn wá.
Josẹfu sì kó gbogbo owó náà lọ fún Farao.
Awon omo-ogun ijoba Syria ti pami po lati lo kolu awon omo ogun olote ti o fi ilu Ghouta se ibugbe pelu ohun ija ogun oju ofurufu lojo-Ru(Wednesday), ni ona lati pawon ru n patapata.
Tí o bá júbà mi, tìrẹ ni gbogbo rẹ̀ yóo dà.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Abiola Ajimobi: Ẹ wo àwòrán bí ìsìnkú Abiola Ajimobi ṣe lọ!
Bí o bá jẹ́ ẹ̀jẹ́ sí Ọlọrun, má fi falẹ̀, tètè san án, nítorí kò ní inú dídùn sí àwọn òmùgọ̀.
ọkọ ofurufu mẹta ati baalu kekere kan wa loju ofurufu, bi wọn ṣe n wa baalu
wọn óo kó lọ sí Babiloni, níbẹ̀ ni wọn yóo sì wà títí di ọjọ́ tí mo bá ranti wọn.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Adí-àgbọn: Ọ̀jọ̀gbọ́n Fasiti Harvard ní kẹ má mu àdí-àgbọn mọ́ 22 Ògún 2018 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Májèlé ni àdín àgbọn Ọ̀jọ̀gbọ̀n kan ní Fasiti Harvard, Karen Michels ní, májelé pọnbélé ni òróró àgbọn ti à mọ sí àdínagbọn.
Ọmọ Nàìjíríà di agbábọ́ọ̀lù Áfíríkà tí iye owó tí wọ́n rà à ga jù nínú ìtàn!
Amọ, iya ati baba ọmọ ti wọn jigbe lọ fi ẹsun kan Woli Sotitobirẹ pe ko bikita nipa ọmọ ti wọn jigbe lọ naa ni wọn ṣe fun ra sii.
Ẹni tí ẹ̀mí burúkú wà ninu rẹ̀ bá bi wọ́n pé, “Mo mọ Jesu; mo sì mọ Paulu.
Àwọn ọmọ ajebota ò lé mo ooo
O wi fun awọn ọdọ Naijiria pe bi wọn ba si wa ko awọn ikọ SARS pada wa, a o tun tẹsiwaju ninu ifẹhonuhan."
láti ìhà ìlà oòrùn Jọdani, gbogbo ilẹ̀ Gileadi ati ti ẹ̀yà Gadi, ẹ̀yà Reubẹni ati ẹya Manase.
Yóo kígbe, àwọn eniyan náà yóo sì kígbe sókè.
  Ó dàbí bí wọ́n ṣe kùn wọ́n náà ní ìlú New York ni.
Ẹ lọ wádìí ninu ẹ̀kọ́ mímọ́ ati ẹ̀rí.
Ní ọjọ́ keje yóo fá irun orí rẹ̀, ati irùngbọ̀n rẹ̀, ati irun ìpéǹpéjú rẹ̀ ati gbogbo irun ara rẹ̀ patapata, yóo fọ gbogbo aṣọ rẹ̀.
Buhari, o kò ṣe bẹbẹ kankan láì jẹ́ pé o gba Leah Sharibu náà sílẹ̀ Wo àwọn nǹkan to tún nílò NIN fún yàtọ̀ fún ìforúkọsílẹ̀ síìmù Ilé aṣòfin àgbà yọ gómìnà nípò, ẹni tó fi owó ìlú rán ọmọ lọ sí Amẹ́ríkà Amẹ́ríkà yarí pé àwọn agbégbọn tó jí akẹ́kọ̀ọ́ 344 gbọ́dọ̀ fojú winá òfin Ẹ̀ẹ̀kan láàrin ọjọ́ méjì là ń jẹun ní ìgbèkùn, ìyà jẹ wá - Akẹ́kọ̀ọ́ Kankara ṣàlàyé Sé Boko Haram ń pẹ̀ka kiri Nàíjíríà ní ìjínigbé ṣe burú báyìí?
Amọ o ni o ṣeni laanu pe iwa aṣiwere ti ẹgbẹ oṣelu PDP gan wa ju ti APC lọ.
Giwa ni '' ni ọdun meje sẹyin ti a ṣe igbeyawo tan, ni Adebimpe mu mi lọ si ile ahoro kan, to si fimisilẹ nibẹ.
April 23, 2018 Ọ́lọ́pàá nílùú Abuja tún kọlu àwọn IMN lásìkò ìwóde ti awon ajọ ajà fẹ́tọ́ ọmọ ènìyàn si sọ pé ènìyàn márundínlọ́gọ́fà ní wọn mú sí àgọ́ wọ́n May 15, 2018 El-Zakzaky àti ìyàwó rẹ̀ Zeenat ní wọ́n kó wá si ìwájú ilé ẹjọ́ gíga ni ìlú Kaduna níwájú adájọ Gideon Kurada, lóri ẹ̀sù ìpànìyàn, ìpéjọpọ̀ ti kò bá òfin mu, dída omi àláfíà ìlú rú, láàrin ẹ̀sún míràn.
NEC gbé òfin kalẹ̀ pé kí gbogbo darandaran kọ́ ọgbà fún àwọn ẹran ọ̀sìn wọn bẹ̀rẹ̀ láti ìpínlẹ̀ Benue, Taraba, Adamwa, Plateau àti Kaduna kì àláfíà lè jọba ní àwọn ẹkùn wọ̀nyìí.
 wìwẹ ̀ àti fífọ ara nìkan kò tó lati dènà àrùn náà sugbọn ó lè wúlò fún àwọn ọ ̀ nà àtidènà rẹm íràn .
" Alaafia nikan lo lee mu idagbasoke ba ilẹ Naijiria.
Àwọn Abódiakọ-akọ́diabo mìíràn àti àwọn tí kì í ṣe Abódiakọ-akọ́diabo àmọ́ tí ó jẹ́ alátìlẹ́yìn náà kó ipa nínú ìyíde náà àti àṣeyọríi rẹ̀.
Ṣé o ò ní tún sọ wá jí ni,kí àwọn eniyan rẹ lè máa yọ̀ ninu rẹ?
Nítorí wọ́n fẹ́ràn kí wọ́n máa dúró gbadura ninu ilé ìpàdé ati ní ẹ̀bá títì, kí àwọn eniyan lè rí wọn.
ipinle Eko, ogbeni Akinwunmi Ambode ti yan ogbeni Hakeem Olayinka Muri-Okunola gege
àwọn ará ilẹ̀ náà pe àwọn babalóòṣà wọn ati àwọn adáhunṣe wọn jọ, wọ́n bi wọ́n pé, “Báwo ni kí á ti ṣe àpótí OLUWA?
Oríṣun àwòrán, Getty Images Mba salaye siwaju pe Tunmise ni oun ko fipa ba oloogbe naa lopọ, arinyanjiyan lasan si lo ni o waye laarin oun ati arabinrin naa, to jẹ iyawo baba baba onile oun, Raphael Olanrewaju.
Nigba to n dahun ibeere to nii se lori awọn obinrin onitiata to n si ara wọn silẹ lati polowo ọsẹ tabi ipara to n bo ara, Binta salaye pe, ko tọna rara.
ijoba to n bọ lati mọ le ori ipile rere ti isejoba oun ti fi lelẹ, ki won si se
OLUWA, ṣọ́ mi lọ́wọ́ àwọn eniyan burúkú;dáàbò bò mí lọ́wọ́ àwọn oníwà ipá,tí ó ń gbìmọ̀ láti ré mi lẹ́pa.
Wọn ni Uwakwe jẹbi ẹsun lilo owo ajọ naa basubasu gẹgẹ bi ofin ajọ naa ti ọdun 2007 sẹ tako iwa ajẹbanu bẹẹ.
Ara ọrẹ rẹ̀ tún ni: àwo kòtò kan tí wọ́n fi wúrà ṣe, tí ìwọ̀n rẹ̀ jẹ́ ṣekeli mẹ́wàá, tí ó sì kún fún turari, 
” Gbogbo àwọn ọmọ ogun sì gbọ́ nígbà tí Dafidi ń pa àṣẹ yìí fún àwọn ọ̀gágun rẹ̀.
Coronavirus: Wo ilé ìwòsàn kan ti tọmọ-tìyà ti ń kú lẹ̀yìn tí Covid-19 búrẹ́kẹ
Gbogbo àwọn ará ilé Siba sì di iranṣẹ Mẹfiboṣẹti.
Imaamù: Irọ́ ni pé ọkọ leè kọ ìyàwó rẹ̀ nígbà mẹ́ta 'Bíbélì kò ní kí tọkọ taya lu ara wọn pa' 'Òṣòkòmọlẹ̀' ní ẹjọ́ láti jẹ́ lórí owó Káńsù l'Ekiti Soji Ologunde, ẹgbọn Bose ni ko si ohun ti ẹbi n fẹ ju idajọ lọ lori Saidi nitori ko ṣẹṣẹ maa lu Bọsẹ ni alubami di ero ile iwosan ni ọpọ igba.
Kò sí ẹni tí ó lágbára láti dá ẹ̀mí dúró, tabi láti yí ọjọ́ ikú pada, gbèsè ni ikú, kò sí ẹni tí kò ní san án; ìwà ibi àwọn tí ń ṣe ibi kò sì le gbà wọ́n sílẹ̀.
Àwọn ọ̀pọ̀lọ́ náà yóo máa fò mọ́ ìwọ, ati àwọn eniyan rẹ ati àwọn ẹmẹ̀wà rẹ.
Ọpọlọpọ igbe aye rẹ lo gbe ni Algeria ti o si dara pọ mọ ẹgbẹ oṣelu National Liberation Front (FLN) nigba to wa ni ọdọ langba.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Obinrin gbo‘rinyin l'ayajọ awọn obinrin 'Awọn obinrin nilo ajọ iranwọ fun oṣelu' Kí lẹ ò mọ̀ nípa àwọn obinrin Yollywood yìí?
Kòsí àṣà tó faramọ́ fífi èmí ènìyàn ṣe ìrúbọ - Olúwó Ìpínlẹ̀ Ondo ti ní gómìnà tuntun Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Yoruba World Congress: Mi o fi gbogbo ẹnu sọ pé ẹ̀yà Yorùbá yóò tún èrò rẹ̀ pa ní October 1- Akintoye28 Owewe 2020 6:18 Fídíò, Akomolede: Bolaji Faleke ni Olùkọ́ tó ń kọ́ wa ní àṣà oge ṣiṣe lórí BBC Yorùbá, Duration 6,181 Owewe 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Orúkọ Àwọn tí Wọ́n Pada láti Oko Ẹrú.
Covid Update: Ṣé orílẹ̀èdè míì wà l'Áfíríkà tó ń lo rọ́bọ́ọ̀tì ní pápákọ̀ òfurufú bíi ti Nàìjíríà?
Àwọn ọlọ́pàá wú òkú akẹ́kọ̀ọ́ Fásitì Uniport mẹ́ta tí àwọn ajínigbé sin Wo ìmọràn tó lè jẹ kóo gbádùn ṣíṣe iṣẹ láti ilé lásìkò kónílé-ó-gbélé COVID 19 yìí Coronavirus: Kíni àwọn àmì tuntun tó n fihàn?
Eliṣa kúrò níbẹ̀, ó lọ sí Bẹtẹli.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ẹ̀mí kan náà ló n darí ìrìnàjò wa táa fi jọ kọ́lé papọ̀- Ìbejì Amọ ajọ naa n woye wi pe pẹlu ikọlu Boko Haram ni awọn agbegbe ẹkun Ariwa Naijiria, eleyii ti o le fa ki o ma si imọtoto ni agbegbe naa, o seese ki aisan naa pada.
Ṣaaju ni iroyin jade pe yoo fara han niwaju ile ẹjọ lọjọru ọjọ kẹtalelogun oṣu kẹwa ọdun 2019.
 bákan náà ni wọ ́ n ń jẹ àwọn oyè bi baálẹ ̀ , lọ ́ jà ni àwọn ìlú kékèké abẹ ́ wọn.
Ni bayii, Abiodun yoo lo koju Javen Choong lati Malaysia ati Terry Su lati Belize, beesini Jamiu naa yoo lo koju Rohit Pagarani lati Belize.
Ninu oṣu yii to gbajumọ ju, lawọn musulumi maa n gbawẹ ọlọdọọdun.
''Kò yẹ kí Aṣíwájú gẹ́gẹ́ bí àgbàlagbà fi ọ̀wọ̀ rẹ̀ wọ́lẹ̀ nípa dídarapọ̀ mọ́ ọ̀rọ̀ àlùfànsá sísọ eléyìí tó ti di bárakú ẹgbẹ́ oṣèlú rẹ̀ aláìríṣẹ́ṣe."
Isaaki dá a lóhùn, ó ní, “Mo ti fi ṣe olórí rẹ, gbogbo àwọn arakunrin rẹ̀ ni mo sì ti fún un láti fi ṣe iranṣẹ, mo ti fún un ní ọ̀pọ̀ ọkà ati ọtí waini.
"Ninu ọrọ rẹ, o sọ pe ""Kabiesi Alaafin Oyo ko dede fi mi jẹ Mayegun, ọpọ ohun ni wọn fi han mi ki wọn to fi mi jẹ Mayegun, kii si n ṣe ohun ti a ṣe ni kọrọ."
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ọmọ onílẹ̀ wọ gàù, ó kó sí gbaga ọlọ́pàá Ayinla Ọmọwura, orin èébú àti oríyìn lo fi di ọ̀rẹ́ àwọ̀n obìnrin Wo àwòrán ńkan tó ń ṣẹlẹ̀ ní ìpádé ìran Yorùbá ní Ibadan báyìí Olúbàdàn, ẹ bá wa bẹ́ Seyi Makinde kó tú wa sílẹ̀ - Oyo NURTW Buhari san lára owó àjẹmọ́nú Super Eagles!
Sọ fún àwọn ọmọ Israẹli pé kí ẹ ya ara yín sí mímọ́, ẹ óo jẹ ẹran lọ́la.
Wo ohun tí aráàlú ń kojú lọ́jọ́ Aje àkọ́kọ́ tí wọn ti 3rd Mainland Ni idaji kutukutu ọjọ Aje ni ikọ iroyin BBC Yoruba ti jade lati mọ bi eto irinna yoo ti rọrun tabi nira si fun awọn awakọ nilu Eko.
Ní ọjọ́ Jimọ ní ìpínlẹ̀ Kano gbe àtẹjáde kan sítà pé òun ń ró láti gbe gómìnà ìpínlẹ̀ Rivers lọ sí ilé ẹjọ́ nítori ọ̀rọ̀ mọṣálási ti wọ́n wó ni àgbègbé Trans-Amadi ní ìlú Port Harcout.
Ẹ san owó-orí fún ẹni tí owó-orí tọ́ sí.
Pasuma: Ọ̀gáńlá Fújì ní ominú ń kọ òun lórí ọ̀dá àwọn ìràwọ̀ tuntun lágbo orin Fújì
Guro Reiten ti ikọ Norway lo kọkọ gba bọọlu naa si inu awọn ni isẹju mẹtadinlogun ti ifẹsẹwọnsẹ naa bẹrẹ, ko to di wi pe Lisa-Marie Utland naa fi ọba le, to fi jẹ ami ayo meji si odo.
Àwọn ni wọ́n máa ń gbin àwọn òdòdó nì, tí wọ́n a ṣe ìtọ́jú àti ìmójútó wọn ní inú ikọ̀ wọn, tí wọ́n á sì gbìn wọ́n sí ìta gbangba inú ọgbà náà tí wọ́n bá ṣetán.
ole jija ti se atunse si bi  iko SARS yoo
Lóòótọ́ lòògùn owo wà ṣùgbọ́n ayédèrú aláwo ló ń lo ẹ̀yà ara -Ẹlẹ́búìbọn Ǹjẹ́ ẹ mọ̀ pé Peter Fatomilola ni 'Papa Ajasco' àkọ́kọ́?
Ibudo itaja ọhun ni wọn gbagbọ pe o jẹ ti ọmọ orilẹede South Africa, ti wọn si setan lati gbẹsan ikọlu ti awọn ọmọ ilẹ South Africa n se sawọn ọmọ Naijiria to n gbe lọhun.
awon ara ilu ninu , paapaa julọ  awon
Oríṣun àwòrán, Twitter/Abiodun Bashua Àkọlé àwòrán, Iku pa ọjọgbọn meji ọmọ Naijiria Opolopo awọn eniyan lo ti n ṣọfọ ọjọgbọn Bashua lori ayelujara.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù SARS: Awọn ará ìlú fi ẹ̀rí síta nípa ìrírí wọn Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ SARS: Awọn ará ìlú fi ẹ̀rí síta nípa ìrírí wọn 25 Òkùdu 2018 Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí kan sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
Oríṣun àwòrán, Others Àkọlé àwòrán, Eyi ni atupalẹ iye owo ti wọn n ta awọn ọunjẹ kan ki ijọba to ti bọda ati lasiko yii ti wọn ti ṣi ibode.
Ifẹsẹwọnsẹ naa waye ni ọjọ kejila oṣu kẹjọ ọdun 1989 pẹlu orilẹede Angola ni papa iṣere to wa ni Surulere niluu Eko.
Nígbà tí Jesu mọ̀ pé wọn ń fẹ́ wá fi ipá mú òun kí wọ́n sì fi òun jọba, ó yẹra kúrò níbẹ̀, òun nìkan tún pada lọ sórí òkè.
"Ẹ̀bùn Ọlọ́run ni ọmọ bíbí ni mo ṣe bí ọmọ 17 Wole Soyinka rèé láti kékeré EFCC tun tẹsiwaju pe, ""."
Udoma ni ijoba yoo si lo awon akosemose lati Malaysia ti won n je Pemanda Associates ti won n sise ninu ibudo iwadii won ni Malaysia lati satileyin to ye.
” Nígbà tí ó ti jẹ́ pé a ní ẹ̀mí igbagbọ kan náà, àwa náà gbàgbọ́, nítorí náà ni a fi ń sọ̀rọ̀.
Amọṣa, iroyin n sọ pe ọgbẹni Mike Pence ko fara mọ aba naa.
“Ṣugbọn, àwọn ọmọ náà ṣọ̀tẹ̀ sí mi: wọn kò tẹ̀lé ìlànà mi, wọn kò sì fi tọkàntọkàn pa òfin mi mọ́, èyí tí ó jẹ́ pé bí eniyan bá tẹ̀lé ni yóo yè, wọ́n sì tún ba ọjọ́ ìsinmi mi jẹ́.
Wo ohun tó yẹ kí o mọ̀ nípa àwọn obìnrin méje ti Buhari forúkọ wọn ránṣẹ Ṣé irúfẹ́ oúnjẹ tí ò ń jẹ́ lè jẹ́ kí o gbádùn ìbálòpọ̀ rẹ síi?
Ẹ kò gbọdọ̀ fi ohunkohun tí ń fi àyà fà lórí ilẹ̀ sọ ara yín di aláìmọ́.
lati dibo fun gbogbo awon to n dupo ninu  egbe APC.
Judasi keji, (kì í ṣe Judasi Iskariotu), bi í pé, “Oluwa, kí ló dé tí o ṣe wí pé o kò ní fi ara rẹ han aráyé, ṣugbọn àwa ni ìwọ óo fi ara hàn?
Ẹni ti ina ọkọ rẹ ko ba ṣiṣẹ bo ti ṣe yẹ ti tasẹ agẹrẹ sofin irinna.
Àwọn ohun tí o óo máa pa láṣẹ nìyí, kí wọ́n lè jẹ́ aláìlẹ́gàn.
kò sí ohun tí ó dàbí ọmọ ìyá nítorí pé okùn ọmọ ìyá yi púpọ ̀ .
N'isẹ ní orí adé náà fakọyo pẹlu asọ ẹ̀yà Igbo to wọ nibi ayẹyẹ naa.
 bi wọn ba kọ daradara ti wọn ṣetọju rẹ daradara wọn le din ajakalẹ arun ku nipa didinku iye igbọnsẹ eniyan ni awujo lati igbọnsẹ sita gbangba .
Ó tún fi kún un fún wọn pé, “Ilékílé tí ẹ bá wọ̀, níbẹ̀ ni kí ẹ máa gbé títí ẹ óo fi kúrò ní ìlú náà.
Wo Ọ̀jọ̀gbọ́n Ẹlẹka tó ń díje fún ipò gómìnà Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, CUPP: JJ Ọmọjuwa sọ ohun tí ìdàpọ̀ àwọn ẹgbẹ́ yìí yóò jẹ́ Amọ, iroyin ni wipe bi o tilẹ jẹ pe gomina Fayose kéde ìséde ni ìpínlẹ̀ Èkìtì, sugbọn awọn eniyan si jade lọ si ibi ipolongo idibo naa.
Eyi tum si wi pe Pasitọ Babatunde yoo tun lọ lo nkan bii ọsẹ mẹta lọgba ẹwọn ni agbegbe Olokuta.
Atẹjade naa wa kesi Apena fẹgbẹ awo Osugbo, Opa, Akala atawọn olori alawo miran pẹlu awọn eeyan to di asa ilẹ wa mu, lati tete sawari ọpa asẹ ọba Akiolu, ki oju ma ba ti itẹ ọba.
Itan fi ye wa pe, Basọrun Gaa ni olori igbimọ Ọyọmesi, eyi to dabi Olootu ijọba laye ode oni, lẹyin Alaafin, tii se oriade ilu Ọyọ́, Basọrun Gaa lo tun ku.
Ewu wà fún gbogbo àwa tí a wà ninu ọkọ̀ pàápàá.
Ó sì fún wọn ní àmì kan ní ọjọ́ náà, tí wọn yóo fi mọ̀ pé OLUWA ni ó gba ẹnu òun sọ̀rọ̀.
Putin  soro ohun di mimo lasiko ipade apero ojukoju ti won pe ni “Direct Line” Q&A ti o waye lojoBo(Thursday), O toka si bi won se so ayika awon papa isere di ile itaja ninu idije agbaye ti o waye ni Moscow lodun 1990, bee si ni o fi oro naa mule pe, iru re ko gbodo waye.
Ajọ CAF gbe iwe orukọ awọn agbabọọlu naa jade ni ọjọ ẹti ninu eyiti ti wọn yoo ti mu mẹta ti yoo figagbaga fun ami ẹyẹ naa lẹyin o rẹyin.
ibo  15,191,847 lati fi gbewuro si
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ọ̀ṣun Oṣogbo: Èyí ni àwọn ayẹyẹ tí yóò wáyé ní ọjọ́ kọ̀ọ̀kan lásìkò ọdún Ọ̀ṣun Oṣogbo 5 Ògún 2019 Oríṣun àwòrán, Osun Osogbo Inu osu Kẹjọ ọdọọdun ni ọdun Ọṣun Oṣogbo maa n waye ni ojubọ Ọṣun, eyi ti ẹgbẹlẹgbẹ awọn olujọsin ati oluworan maa n peju si jakejado agbaye.
tun  tepele mo eto ẹkọ ,ni eyi ti yoo tẹpẹlẹ
Ó jó gbogbo ilẹ̀ ibẹ̀, ó sì lá gbogbo omi tí ó wà ninu kòtò.
o gbe sita lati maa sapejuwe aare Buhari gege bi aare ana Sani Abacha , ti o fi
Akọwe ijọba tẹlẹ nipinlẹ Ondo naa ni, oun kọwe fi ipo naa silẹ nitori oun ko fẹ ba gomina Akeredolu sisẹ mọ ni.
O rọ awọn ọmọ ẹgbẹ PDP lati fi ọgbọn yanju ọrọ to ba wa laarin wọn ki iṣokan le wa ninu ẹgbẹ.
Ẹ̀yin ará, a kò fẹ́ kí ẹ ṣe aláìmọ̀ nípa ìpọ́njú tí ó tayọ agbára wa tí a ní ní Esia, Ìdààmú náà wọ̀ wá lọ́rùn tó bẹ́ẹ̀ tí ẹ̀mí wa fi fẹ́rẹ̀ bọ́.
Ninu ilẹ̀ ìdajì ẹ̀yà Manase tí ó wà ní ìhà ìlà oòrùn, wọ́n fún àwọn ọmọ Geriṣoni ní ìlú wọnyi, pẹlu àwọn pápá oko tí ó yí wọn ká: Golani ní ilẹ̀ Baṣani, ati Aṣitarotu.
ní ayé àtijọ ́ àwọn àgbẹ ̀ aláròojẹ nìkan ni ó wà , ṣùgbọ ́ n láyé òde òní iṣẹ ́ àgbẹ ̀ ti gbounjẹ fẹ ́ gbẹ ́ ó sì ti gbàwò bọ ̀ .
"Tọkọ taya kú lọ́jọ́ kan náà l'Abeokuta lẹ́yìn ìgbéyàwó ọdún méjìléláàdọ́rin 72 Wo àwọn ọmọ Naijiria mẹ́ta tó jáwé olúborí nínú ìdìbò sílé aṣòfin ilẹ̀ Amẹrika Sunny Ade (KSA) máa ń bá Orlando Owoh kó ""Gloves"" tó fi ń ja ẹ̀ṣẹ́ dání nígbà ayé rẹ̀- Folarin, àbúrò Orlando Owoh Awọn ipinlẹ to ṣe pataki bíi Pennsyvannia, Georgia, Michigan, Wisconsin, Nevada ati Arizona ni Biden ati Trump ti jọ figa gbaga ninu eto idibo ọhun."
orísi àwọn álótrópù kárbọ ̀ nù lọ ́ wà tí èyí tó gbajúmọ ̀ nínú wọn jẹ ́ gráfáìt , díámọ ́ ndì , àti kárbọ ̀ nù àìlétòara .
Seyi: Mo nifẹẹ gbogbo eniyan ninu ile yẹn tori mo kọ ẹkọ kan latara ẹnikọọkan wọn.
 Ó jẹ ́ ìyanu fún n nígbà tí gẹ ̀ ẹ ́ sì fún Índíà lómìnirà ní ọdún 1947 , ó kọjá sí rhodesia lẹ ́ yìn tí ó fẹ ̀ yìntì nínú ajagun òfurufú lẹ ́ yìn ọdún méjì síi .
Bẹ́ẹ̀ ni ó ṣe títí ó fi fi ìwé náà jóná tán.
Ẹni bá láyà kó wá wọ̀ọ́!
Laipẹ yìí ni gómìnà ìpínlẹ̀ kan ní bi ènìyàn ba ti lo ìbòmu-bẹnu, kò nilo láti tèlé àsà ìjìnà si ara ẹni.
”Elija bá dá a lóhùn pé, “Bẹ́ẹ̀ ni, mo tún ti rí ọ; nítorí pé o ti fa ara rẹ kalẹ̀ láti ṣe iṣẹ́ burúkú níwájú OLUWA.
Àrà ọ̀tọ̀ inú orin tó jáde lọ́dún 2018 ní Nàìjíríà 'EFCC mo dé' àti àwọn àṣà míì táwọn olóṣèlú fi dagbo rú ní 2018 Àkójọpọ̀ àwòrán ọdún Kérésìmesì lágbáyé Àwọn ìpànìyàn mánigbàgbé tó wáyé lọ́dún 2018 Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Èpo ọwọn, sunkere-fakere ọkọ àti àwọn olósà jẹ́ ipenija lójú pópó Ọrọ loriṣiiriṣii làwọn ololufẹ BBC Yorùbá ti wọn da si ọrọ idije naa fi lede.
Amọ igbaju igbamu lo maa n bade lọdọ ọga mi, nitori ko fẹ ki n ni ohun kan ṣe pẹlu ileewe,'' Oloye Elebuibon lo ṣalaye bẹẹ.
Alhaji Smith ni ai kii ṣe ere idaraya deede lo faa ti awọn ọlọpaa fi n yọkun ayọju.
Biu tun so pe awon se ayẹyẹ yii lati tun lo
ó gba ìwé lọ́dọ̀ rẹ̀ láti lọ sí àwọn ilé ìpàdé tí ó wà ní Damasku.
O rọrun gan an lati ya, ko le ko si rọ ju, o gun o si ri wọọrọwọ lati ya.
Ìwọ ni yóo máa ṣe olórí ilé mi, gbogbo àṣẹ tí o bá sì pa ni àwọn eniyan mi yóo tẹ̀lé, kìkì pé mo jẹ́ ọba nìkan ni n óo fi jù ọ́ lọ.
Ìwọ ọ̀rẹ́ mi, nígbà tì ọkùnrin náà kú tán, wọ́n mú obìnrin nì, wọ́n sì so ó kọ́ sí orí igi.
Àkọlé àwòrán, ìfọ̀rọ̀wérọ̀ BBC Yorùbá Fun Sẹnetọ Olufẹmi Lanlẹyin, eniyan kan fi ibeere ranṣẹ wi pe baba isalẹ kan lo n pọn ọn sẹyin kiri pe bi o ba di gomina tan ṣe ko ni maa fi ti baba isalẹ yii ṣe akọkọ ninu ohun gbogbo.
ede Naijiria ni iwe lọ jokoo sile , ni eyi ti ile igbimo fẹ jiroro le lori ti
2019 Elections: Níbo la bá ètò ẹ̀kọ́ dé?
Bí mo bá leè rí ọmọ alágbe t'áyé fẹnu sí pé mo fi ẹlẹ́rìndòdò lá lójú, máa kúnlẹ bẹ ẹ - Motara Ẹ wo ìdí tí Oby Ezekwesili ṣe ń pè fún àyẹ̀wò ọpọlọ fún Ààrẹ Buhari Ṣaaju akoko naa ni iroyin ti kọkọ gbode pe họwuhọwu n waye laarin Kabiesi ati Olori yii lẹyin ti awọn kan fẹsun kan Olori ọhun pe o ni ibaṣepọ pẹlu gbajugbaja Olorin fuji kan.
Selofehadi, ọmọ Heferi, ọmọ Gileadi, ọmọ Makiri, ọmọ Manase, kò ní ọmọkunrin rárá, àfi kìkì ọmọbinrin.
Iko olote Boko Haram ti n fa opolopo ijamba lorile ede Naijiria, paapaa julo ni awon ekun ila oorun Ariwa lati odun 2009, ni eyi ti opolopo awon eniyan ti padanu emi won, ti awon miiran si di eni ti ko nile lori mọ.
Eeegun Danafunjo ree lati Oyo to jẹ pe ina lo fi n ṣagbara ni eyi ti ko si paa lara si iyalẹnu gbogbo ero.
O tnu ṣlaaye pe abadofin naa yoo gegi dina ṣiṣe amulo awọn ọmọde fun awọn iru iṣẹ bayii.
O jagun pelu oogun oloro, irobinujẹ ati jijẹ okutaye ki ọlọjọ to de.
Ọkàn àwọn eniyan yìí ti le,etí wọn ti di,wọ́n sì ti di ojú wọn.
Wọn yóo mu yín lọ jẹ́jọ́ níwájú àwọn gomina ati níwájú àwọn ọba nítorí tèmi, kí ẹ lè jẹ́rìí mi níwájú wọn ati níwájú àwọn orílẹ̀-èdè tí kì í ṣe Juu.
Ọ̀pọ̀ èèyàn, to ń pariwo pé àwọn awakọ èrò tún ti bẹ̀rẹ̀ ìkọlù wọn, ló ń sá àsálà fún ẹ̀mí wọn, tí ariwo si n waye làwọn ori redio kan nilu Ibadan pe ki awọn ọlọ́pàá máa lọ sí àgbègbè Iwo Road láti tètè bu omi pá iná wàhálà náà, kó tó fẹ́ ojú sì.
Bakan naa ni ileesẹ rẹ Reach Robots fọwọsi iwe adehun pẹlu ileesẹ Apple lati jẹ ojulowo alagbata fawọn ẹrọ́-deniyan naa Isẹ ọna to sọnu ni Naijiria di riri loke okun Ninu Iroyin mi i ẹwẹ, isẹ ona ilẹ Naijiria kan to ti nu tipẹtipẹ lo sadede suyọ ni filati onile kẹjẹbu kan ni ariwa ilu London.
peye ti wa fun won ni jake-jado ipinle naa.
Ṣùgbọ́n ọ̀rọ̀ náà kò yí àwọn èèyàn lọ́kàn padà, wọ́n sì ń sọ̀rọ̀ tako ìhùwàsí iléeṣẹ́ tẹlifíṣàn yìí.
Muritala Babatunde sọ fún àwọn ọlọ́pàá pé inú bí òun sí Adebisi nítorí kò ka òun sí gẹ́gẹ́ bíi ọkan gbòógi nínú ẹgbẹ́ okùnkùn ní agbègbè náà.
Buhari lo anfaani naa lati kesi gbogbo awọn ti iṣẹ ọwọ wọn ko mọ, paapaa awọn ole, ajinigbe, janduku, agbesunmọmi, ati awọn to tako ọrọ aje Naijiria lati ronupiwada.
Ó ta àwọn aṣọ títa ti ẹnu ọ̀nà àgọ́ náà sí ààyè wọn.
Ohun tí a mọ̀ nìyí nípa ìròyìn Ajimobi kú, kò kú, táyé ń gbé kiri Èèyàn 745 ló lùgbàdì àrùn Coronavirus ní Naijiria ní Ọjọ́bọ̀ Kí ni Hushpuppi ṣe tí àjọ EFCC fi ní ó ní ẹjọ́ láti rò?
Ǹjẹ́ nisinsinyii, OLUWA Ọlọrun Israẹli, mo bẹ̀ ọ́, mú àwọn ìlérí tí o ṣe fún iranṣẹ rẹ, Dafidi, baba mi ṣẹ, pé, arọmọdọmọ rẹ̀ ni yóo máa jọba ní Israẹli títí lae, bí wọ́n bá ṣọ́ra ní ọ̀nà wọn, tí wọ́n sì bá mi rìn bí ìwọ ti bá mi rìn.
Àwọn ọmọ Ìjèbú Jẹ̀ṣà jẹ́ aláfẹ́ púpọ̀ pàápàá nígbà tí ọwọ́ wọn bá dilẹ̀.
Ti o ba jawe olubori ninu ibo abẹle, a jẹ wi pe oun ni yoo tan kangbọn pẹlu Aarẹ Donald Trump ti yoo dije fun saa keji labẹ asia ẹgbẹ oselu Republican.
3 78499 Orilẹede Luxembourg 384 63.
Coronavirus: ''Ìjọba kò tíì pàṣẹ ìlànà ìtakété-síra-ẹni padà nínú BRT la ò ṣe máa tẹ̀le'' Ìjọba gbé ilé ijó oníhòhò tì pa lórí ẹ̀sùn títàpá sí ìlànà àti dẹ́kun coronavirus Wo àwọn oúnjẹ márùn ún tó ń mú kí àtọ̀ ọkùnrin dára síi Nnkan bii igba ọdun sẹyin ni aṣa yii ti bẹrẹ nigba tawọn babanla orilẹ-ede naa fẹ da eto iṣejọba tiwantiwa silẹ.
Ìjọba Nàìjíríà; Ohun burúkú ni láti pa àwọn olùjọ́sìn
Ọkunrin kan wà ninu ilé ìpàdé tí ó ní ẹ̀mí èṣù.
Oríṣun àwòrán, The park Management Oyo State Nigba to n fi ewe ọmọ mọ Auxiliary leti, Kọmisana fun iṣẹ ode ati igboke-gbodo ọkọ nipinlẹ Oyo, Ọjọgbọn Raphael Afonja ni eti ìjọba ipinlẹ Oyo ti kun, lori awọn iwa idaluru ti asaaju igbimọ alakoso gareeji ọkọ ati awọn ọmọlẹyin rẹ n hu nigboro.
Mọ nipa ọkọ afẹsọna rẹ, Lawrence Oyor Yatọ si pe Lawrence jẹ olorin Kristẹni, o kẹkọ gboye ninu imọ ofin ni fasiti ilu Ibadan lọdun 2013 to si tẹsiwaju ninu ẹkọ rẹ nileewe imọ ofin, Yola.
Nínú ọ̀rọ̀ tirẹ̀, Kayode Ogundamisi ní yàtọ si pé ìjọba kéde fífi òfin de ẹka SARS láti maa yẹ àwọn ènìyàn wò lójú pópó, àwọn ìgbésẹ míràn tí ó yẹ kí wọn gbé ni láti pé fún ìwádìí tó daju kí wọ́n sí pé gbogbo àwọn tí ọlọ́pàá yìí ti 'se ọṣẹ́ fún láti wa jẹri lóri amọ́hùmáwòràn ni ojú gbaara gbogbo aye.
Bi orile-ede Mauritius se n gbaradi fun ayeye ayajo ominira adota odun,ijoba ti pinnu lati se agbekale igbese lati yo Aare orile-ede naa, Ameenah Gurib-Fakim kuro nipoWon se ipinnu ohun lasiko ipade igbimo amusese ijoba, eyi ti olori ijoba Pravind Jugnauth dari re, lojo-Bo, ojo kejo osu keta odun ti a wa yii.
Nítorí wọ́n ti pè yín ní ‘Ẹni ìtanù,Sioni tí ẹnikẹ́ni kò bìkítà fún.
Máa bá mi bọ̀ láti òkè Lẹbanoni, iyawo mi,máa bá mi bọ̀ láti òkè Lẹbanoni.
Ọmọ ọdun mejilelogun ni Esther ti o si kawe gboye ninu imọ nipa ofin lati fasiti Olabisi Onabanjo.
Ọdún 1985 ní wọn kọ́kọ́ ta Núdúlù lágbàyé 3.
Bí o ti wù kí ó rí, ẹ ò yó rí mi níbẹ̀ mọ́n láti òní lọ.
Abrahamu bá mú Iṣimaeli ọmọ rẹ̀, ati gbogbo àwọn ẹrukunrin tí wọ́n bí ninu ilé rẹ̀ ati àwọn tí ó fi owó rẹ̀ rà, àní gbogbo ọkunrin tí ó wà ninu ìdílé Abrahamu, ó sì kọ gbogbo wọn ní ilà abẹ́ ní ọjọ́ náà, bí Ọlọrun ti pàṣẹ fún un.
 ní ọdún 2005 orílẹ ̀ -èdè 110 ni ó pèsè àjẹsára náà ní oríṣi yìí .
OLUWA àwọn ọmọ ogun tún bá Sakaraya sọ̀rọ̀, ó ní, 
’ rèé O ni iru iwa yii lo lee mu idarudapọ waye lorilẹede Naijiria, toripe orilẹede yii ko tun le fi oju wina ogun.
Ilé Ṣaroni yóo di ibùjẹ ẹran, àfonífojì Akori yóo sì di ibi tí àwọn ẹran ọ̀sìn yóo máa dùbúlẹ̀ sí,fún àwọn eniyan mi, tí wọ́n wá mi.
Ènìyàn 653 míràn tún kún iye àwọn tó ní COVID-19 ní Nàìjíríà Ikú Barakat Bello ní Akinyele gbé aláàánú pàdé ẹ́bí rẹ̀ Wo ọ̀nà àbáyọ lọ́wọ́ súkẹrẹ fàkẹrẹ ọkọ̀ bí ìjọba ṣe ti afára 3rd Mainland Nibayii eeyan 858 lo ti ṣe alaisi nipasẹ ajakalẹ arun naa lorilẹede Naijiria.
Ẹ̀rọ Medic Mobile ti sọ ayé dẹ̀rọ̀ fáwọn òṣìṣẹ́ elétò ìlera Ìpínlẹ̀ Eko fẹ́ dẹ́kun súnkẹrẹ ọkọ̀ lásìkò ọdún NAFDAC: Ojú wa wà lára ìpara Blac Chyna náà 'Àjùmọ̀sepọ̀ ti fẹ́ bẹ̀rẹ̀ láàrin àwa Ọba Yorùbá' Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí kan sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
Real Madrid, bi iko ohun ba setan lati ra oun.
Ní ọjọ́ kan lẹ́yìn tí yìnyín bọ́ sílẹ̀, ó wọ inú ihò kan lọ, ó sì pa kinniun kan sibẹ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Lagos, Delta Curfew: Sanwo Olu ní kí àwọn òṣìṣẹ́ ìjọba padà sẹ́nu iṣẹ́ ní Eko, Delta sọ tirẹ̀ dí aago mẹ́jọ alẹ́ sí mẹ́fà ìdájí 17 Ọ̀wàrà 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 1 Bélú 2020 Oríṣun àwòrán, others Gomina Bababjide Sanwo Olu to n tukọ ipinlẹ Eko ti kede pe ki awọn oṣiṣẹ ijọba ipinlẹ Eko pada sẹnu iṣẹ lọjọ keji, oṣu kọkanla.
Nígbà tí ọkùnrin náà parí ọ̀rọ̀ yìí mo tún èrò mi pa; nítorí mo rí i pé ọ̀rọ̀ náà ti bọ́ sí orí àfi bí mo bá ń múra de ọjọ́ kejì, bí mo fẹ́ bí mo kọ̀ mo nílatí tún fi orí mi lé ọ̀nà ilé Ikú, ẹni tí ilé rẹ̀ ń bẹ lágbedeméjì ayé òun ọ̀run.
CP Isaac Akinmoyede - CP Plateau Command xxxiv.
Olówó-ayé mi ọ̀wọ́n, mo dúpẹ́ lọ́wọ́ rẹ fún ìba àkókò díẹ̀ tí a jọ gbé ps, mo sì tún dúpẹ́ owó tí o ná fún àwọn ara ilé mi nígbà tí ìwọ ń lọ.
Watch the best of the action from @Uruguay‘s convincing Group A win over hosts @TeamRussia in Samara!
Hove Albion, England); Kenneth Omeruo (CD Leganes, Spain); Jamilu Collins (SC
”Nígbà tí Jesu sọ báyìí tán, ó fara pamọ́ fún wọn.
Lẹyin eyi ni awọn akọroyin BBC Africa Eye kan bẹrẹ iṣẹ iwadii ni kikun lori fidio naa lati mọ ohun to ṣẹlẹ nitootọ.
Agbaboolu owo iwaju fun iko agbaboolu Tottenham Hotspur,  Harry Kane ni ireti pe laipe laijina  oun yoo saaju akegbe re to n kopa fun iko agbaboolu Liverpool FC,  Mohamed Salah ninu idije dupo agbaboolu ti yoo gba boolu sagbon julo (Golden Boot award) ninu idije boolu ile Geesi (English Premier League) ti saa 2017/2018 to n lo lowo yii.
O si jọba fun ọdun marun un si, ko to o ku lọdun 1998.
Ìwádìí bẹ̀rẹ̀ l'órí ikú agbẹjọ́rò Ajah Ẹ̀mí márùń bá ìjà àwọn jàǹdùkú lọ ní Ìjẹ̀bu Ìjọba Germany mú afurasi ọmọ Boko Haram Ọlopaa Kenya kolu awọn oluwọde Bi ìṣẹlẹ naa ṣe ṣẹlẹ Agbebọn kan ti ṣina fun awọn eeyan nile ijọsin kan nilu Pittsburgh Pennsylvania nigba ti wọn ṣe ijọsin lọwọ lọjọ aiku.
ba eto ọrọ  aje yatọ si epo rọbi.
Ní àgbáyé, ọmọ-ìlú ní ẹ̀tọ́ láti wá àìṣedéédé aláṣẹ ìjọba.
ó fún Nàìjíríà l'èsì àwọn ẹ̀sùn tó fi kàn-án Agbẹjọro to ba BBC Yoruba sọrọ ni awọn soja meji ti wọn da silẹ naa, Godwe Mana Didier, Manasse Djakobei Johnathan ko kopa ninu iṣekupani naa, wọn kan tẹle awọn soja to yinbọn pa wọn ni.
Àwọn irinwo pomegiranate tí wọ́n tò sí ìlà meji yí ọpọ́n bìrìkìtì bìrìkìtì orí àwọn òpó náà ká, ní ọgọọgọrun-un.
Ibeere ati idahun wọn Kini ibeere yin da le lori Gbogbo nkan nipa coronavirus Ilera Mi Didaabo bo ara mi ati awọn elomiran Emi ati ẹbi mi Gbogbo nkan nipa coronavirus Ibeere yin Skip Gbogbo nkan nipa coronavirus Kini coronavirus?
Wọ́n gbógun ti àwọn ará Midiani gẹ́gẹ́ bí OLUWA ti pàṣẹ fún Mose, wọ́n sì pa gbogbo àwọn ọkunrin wọn.
Kora bí ọmọkunrin mẹta: Asiri, Elikana ati Abiasafu; àwọn ni ìdílé Kora.
 “Odun meji niyi bayii ti a ti n  pese eto bantansẹ, ẹ̀ẹ́dẹ́gbẹ̀ta bilionu ni owo ti a fi sinu eto isuna fun eto yii, eleyii ko ti I waye ri ninu itan orile ede yii.
Aare orile ede Naijiria Muhammadu Buhari ti sapejuwe  ajodun ijoba tiwa-n-tiwa  to je ikọkandinlogun iru rẹ, gege bi ajodun eto ominira fun jake-jado orile ede yii, bakan naa ni ijoba ko ni kaare lati tubo tepele mo ona atimu awon ileri olokan-o-jokan re, se fun awon ara ilu.
Wo awọn ọna ti obi fi n ṣe si ofin nipa ifiyajẹ ọmọde Ti obi ba fi ami si ara ọmọde lọna ati ba a wi, o ti ṣẹ si ofin ati ọmọ naa Ti o ba fi ẹgba na ọmọ ju ẹẹmeji lọ ni ọwọ rẹ, o ti da ifiyajẹni Obi to ba fi ara ọmọ rẹ jona lọna ati ba a wi, ti ṣẹ si ofin to lodi si ifiyajẹni Ẹni to ba lo abẹ lati kọla si ara ọmọ lọna ati ba a wi, ti fi iya jẹ ọmọ naa Obi ti o ba n sọrọ kobakungbe si ọmọ rẹ nipa ṣiṣẹ epe fun un, ti o le mu ibanujẹ ọkan abi iporuru kan ba ọmọ naa ti fi iya jẹ ẹ Ibalopọ pẹlu ọmọde ti ko i tii pe ọmọ ọdun mejidinlogun ja si ifiyajẹni ati ifipabanilopọ, eleyii ti ofin Naijiria ati ti agbaye koro oju si O lodi si ofin ki ọmọde ma a kiri laarin igboro, nigba ti o yẹ ki o wa ni ile ẹkọ rẹ bi awọn ọmọde bii ti rẹ Fifi ọmọde fun ọkọ lai tii pe ọmọ ọdun mejidinlogun ja si ifiyajẹni labẹ ofin Bakan naa ni o lodi si ofin lati fi ọmọde ṣ'ẹru, tabi fi san gbese bi awọn kan ṣe n se ni awọn agbegbe kọọkan ni orilẹede Naijiria O lodi si ofin naa lati da ọmọbinrin labẹ nitori ko si anfaani kankan ti o n ṣe fun obinrin ti o ba ti dagba, o ma n fa kikorira ibalopọ ati aisan oju ara si wọn ni ara Obi ti o ba kọ ọmọ rẹ silẹ ṣẹ si ofin nitori wi pe awọn ọmọ to yẹ ki obi ṣi maa tọju a wa di alarinkiri ni igboro Ijiya wo lo wa fun obi to ba fi iya jẹ ọmọ rẹ?
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ẹlẹ́wọ̀n: Ọgbà ẹ̀wọ̀n ni mo ti kàwé yege ní ìdánwò Jamb Kini wọn tun ta ni New York?
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Yollywood: Ọ̀pọ̀ òṣèré Yorùbá ń ṣelédè lẹ́yìn Yusuf Satia tó d'olóògbé 22 Agẹmo 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 23 Agẹmo 2020 Oríṣun àwòrán, others Àkọlé àwòrán, Yusuf Satia, òṣèré Nollywood Yorùbá ti di olóògbé Ta ni Yusuf Satia ti iku mu lọ?
Sọ fún àwọn ọmọ Israẹli pé, ‘ÈMI NI ni ó rán mi sí yín.
Ọba bá se àsè ńlá fún àwọn olóyè ati àwọn iranṣẹ rẹ̀ nítorí Ẹsita.
Eyi si jẹ ohun ti ko dara to fun orilẹede bii South Africa.
”Baba Ogunbowale, Gregory, je omo bibi Naijiria, ti o si feran boolu afesegba ati boolu afowogba(rugby), beesini iya re, Yolanda, je omo bibi Amerika ti o sit un je oluko.
Nígbà tí nǹkan bá ń dára fún olódodo,gbogbo ará ìlú a máa yọ̀,nígbà tí eniyan burúkú bá kú,gbogbo ará ìlú a sì hó ìhó ayọ̀.
Ṣugbọn esi ayẹwo oun ati iyawo rẹ fi han pe awọn memeji ko ni arun naa.
" Nigba to n tẹwọgba ami ẹyẹ naa lorukọ ileesẹ iroyin BBC Yoruba ati BBC lagbaye, Olootu ileesẹ iroyin BBC Yoruba, Ọgbẹni Temidayọ Ọlọfinsawo mẹnuba ọpọ isẹ ribiribi tileesẹ wa n se nidi agbega asa ati ede Yoruba, eyi ti ko fi ni jẹ ki awọn ohun ajogunba wa parun.
Sugbọn awọn ohun to nii se pẹlu ounjẹ, oogun ati majele wa labẹ awọn ofin atigbadegba, ko baa lee rọrun fawọn ijọba ipinlẹ lati gbe ofin kalẹ lori wọn.
Nebusaradani olórí àwọn ẹ̀ṣọ́ ati Nebuṣasibani, ìjòyè pataki kan, ati Negali Sareseri olóyè pataki mìíràn ati gbogbo àwọn olóyè jàǹkànjàǹkàn ninu àwọn ìjòyè ọba Babiloni, 
APCOjogbon osinbajo ni ko si orile ede to wa lagbaaye , ti
O tilẹ ti fi igba kan bu ẹnu atẹ lu ajọ to n gboriyin fun awọn eeyan nitori aṣẹyọri wọn, Forbes pe wọn kọ lati fi orukọ oun si ara awọn biliọnia nitori pe oun jẹ alawọ dudu.
Abiade ni igbesẹ yii ko ni ipalara kankan to n ṣe fun obinrin rara dpo bẹẹ o ṣi aye silẹ fun ọpọlọpọ anfani ni.
Dípò tí ọkunrin ìbá máa fi bá obinrin lòpọ̀, ọkunrin ati ọkunrin ni wọ́n ń dìde sí ara wọn ninu ìfẹ́kúfẹ̀ẹ́ wọn.
 O tun so pe “mo ro awon ti inu ba n bi, mo si tun fi n da won loju pe labe isakoso mi, ki I se pe awa naa ko ni se asise sugbon nigba ti e ba ti pe akiyesi wa si awon asise yii, a o lo igboya  wa lati yanju awon asise naa”.
Bí a bá fẹ́ lọ sóde, a ní láti ṣe àgbéyẹ̀wò irú afẹ́fẹ́ tí ènìyàn yóò máa gbà sì mú níbẹ̀, iye ènìyàn tó ṣeéṣe kí o bá pàdé níbẹ̀ àti iye àsìkò tí óò lò.
Ọ̀ọ̀ni Ilé Ifẹ̀: Ọ̀rúnmìlà ni ó kọ́kọ́ lo 'Google' láàgbáyé
‘Èyí ẹ̀kẹfà jẹ́ oníwàrere nínú àwọn ọmọ ènìyàn ṣùgbọ́n bíi ó bá pẹ́ nínú ayé sí i ọ̀pọ̀lọpọ̀  ìyà ni ìbá jẹ́ ẹ́ nítorí àìsàn ńlá kan ìbá ṣe é kò bá sì tí sí oníṣègùn tí ó lè wò ó sàn bẹ́ẹ̀ ní àìsàn yìí kò bá tètè pa á, ìbá fi ìyà jẹ ẹ́ títí kí n tóó lọ mú un.
' Iroyin jẹ jade pe aṣiri lilo orukọ Omale lu jade lasiko ti ẹka to n lo ọgbn ori fi ṣewadii awọn igbesẹ ajọ EFCC n ṣe iwadii wọn.
SERAP ké sí ìjọ̀ba láti mú àdínkù bá owó ìná ìṣèjoba DSS ti fi ẹ̀sọ́ àbò abẹnugan ilé ìgbìmọ̀ asofin tó pa fẹ́ndọ̀ l'Abuja sátìmọ́lé Wọ́n ti rí òkú Alága ẹgbẹ́ APC ní Nasarawa tí àwọn agbébọn jí gbé lọ́jọ́ Satide Òtítọ́ làwọn sọ́jà gbé ìbọn tó lọ́ta gidi nínú lọ sí Lekki Toll Gate lásìkò ìwọ́de EndSARS- Ọ̀gágun Taiwo Awọn afunrasi mejeeji naa oloyun ọmọ ọdun mẹrinlelọgbọn kan pẹlu arakunrin ẹni ọdun mẹtalelogoji ọhun ti n turabayii nileeṣẹ ọlọpaa ọtẹlẹmuyẹ nilu Abuja.
Ọrọ naa buru pupọ laarin igba t'awọn ologun fi n gba ijọba lorileede Naijiria.
Àwọn ẹ̀yà Bẹnjamini gbọ́ pé àwọn ọmọ Israẹli ti kó ara wọn jọ ní Misipa.
Nígbà tí wọ́n dé ọ̀dọ̀ Farao, ọba Ijipti, ó fún Adadi ní ilé ati ilẹ̀, ó sì ń pèsè oúnjẹ fún un déédé.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Kelechi AFC: Ojúlówó alátìlẹyìn Arsenal n kí ìran Yorùbá fún ọdún Ajinde Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Kelechi AFC: Ojúlówó alátìlẹyìn Arsenal n kí ìran Yorùbá fún ọdún Ajinde 21 Ìgbé 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 22 Ìgbé 2019 Loni tii ṣe ọdun Ajinde, a mu ikini pataki wa lati ọdọ ilumọka ololufẹ ẹgbẹ agbabọọlu Arsenal,Dokita Kelechi Anyikude wa fun yin.
Iroyin sọ pe ẹmi to sọnu pọsi nigbati ọkan lara awọ̀n ọkọ naa gbina lyin ti wn kọlu ara wọn.
Bí ọkunrin náà ti dúró lẹ́gbẹ̀ẹ́ mi, mo gbọ́ tí ẹnìkan ń bá mi sọ̀rọ̀ láti inú Tẹmpili, ó ní: 
Ẹ wo àrà tí ''Ayo the Creator'' ń fi sinimá dá Alága, elétò ìdìbò ìpínlẹ̀ Bayelsa, ọjọgbọ́n Remember Ogbe sàlàyé fún BBC pé eto ìdìbò náà wáyé ni ìjọba ìbílẹ̀ mẹ́jọ tó gbé ìpínlẹ̀ Bayelsa ró, ó sì jẹ ìdìbò to lọ ni ìrọwọ́rọsẹ̀ júlọ ní ìpínlẹ̀ Bayelsa.
OLUWA yóo fi ẹnìkan jọba lórí Israẹli tí yóo run ìdílé Jeroboamu lónìí, àní láti ìsinsìnyìí lọ.
Ẹni tí ó gùn ún mú ọrun ati ọfà lọ́wọ́.
 Gomina Makinde tẹsiwaju wi pe omi tuntun ti ru nipinlẹ Ọyọ, igba ọtun si ti de pẹlu."
Gbígbà ati Pípa Ìlú Ai Run.
Àwọn ọmọ Juda gbógun ti ìlú Jerusalẹmu; wọ́n gbà á, wọ́n fi idà pa gbogbo àwọn tí wọn ń gbébẹ̀, wọ́n sì sun ún níná.
Ó bá fa afọ́jú náà lọ́wọ́ jáde lọ sí ẹ̀yìn abúlé, ó tutọ́ sí i lójú.
Awọn ọmọ Naijiria bu ẹnu ẹtẹ lu NTA lori bi kamẹra rẹ ko ṣe le yi sọtun ati sosi, ni abala kini ifẹsẹwọnṣe naa.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Abajade naa ṣalaye pe pẹlu bi iṣẹda kokoro arun naa ṣe ri, o lee gbe ni ags ara fun ọpọlọpọ ọsẹ.
"Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Coronavirus: Gbogbo igbá ti ṣófo láwọn ilé ìtajà káàkiri London O ni ""Igbakeji aarẹ Osinbajọ ṣe ipade ninu ọfiisi rẹ lana pẹlu fidio lori itakun agbaye."
Angẹli kẹrin da ohun tí ó wà ninu àwo rẹ̀ nù sórí oòrùn, a bá fún un lágbára láti máa jó eniyan bí iná.
asofin lati ipinle  Kano , Jubrin
Ìjàmbá Eko: Ṣúnkẹrẹ fàkẹrẹ gba òpópónà Berger kan torí ìjàmbá ọkọ̀
ti pase fun ajo naa lati se iwadii lori isẹlẹ naa.
Orile-ede Sudan ko so pato ohun ti o sokunfa bi o se pe  asoju orile-ede ohun,Abdel Mahmoud Abdel Halim ni ibere osu kinni odun ti a wa yii, amo latari aawo to wa lori talo ni agbegbe Halayeb ti o wa leni ibode Triangle, ati bi orile-ede Egypt se fura si ifenuko laarin awon omo-ogun oju-omi orile-ede Sudan ati orile-ede TurkeyGhandour so fun ile-ise iroyin Reuters lojo-Abameta pe, “Ajosepo to wa laarin awon eniyan ati orile-ede wa je oro itan, ni eyi ti o je ojuse wa lati je ki ajosepo o.
Mo wá mọ̀ nisinsinyii pé OLUWA yóo ran ẹni àmì òróró rẹ̀ lọ́wọ́;OLUWA yóo dá a lóhùn láti ọ̀run mímọ́ rẹ̀ wáyóo sì fi ọwọ́ ọ̀tún rẹ̀ fún un ní ìṣẹ́gun ńlá.
“Ǹjẹ́ o mọ ìgbà tí àwọn ewúrẹ́ orí àpáta ń bímọ?
Eefin naa maa n yipada lati dudu si funfun ni kete ti wọn ba yan poopu tuntun.
Ọ̀run yóo fi ẹ̀ṣẹ̀ rẹ̀ hàn,ilẹ̀ yóo dojú ìjà kọ ọ́.
Nígbà tí Jesu dé ilé, kò jẹ́ kí ẹnikẹ́ni wọlé àfi Peteru, Johanu ati Jakọbu, baba ati ìyá ọmọ náà.
Ilé ẹjọ́ Kano: Ganduje kò lẹ́tọ̀ọ́ láti yan Emir Sanusi wọ gau torí pé o kọrin bù Gómìnà Ganduje Dangote, Fayemi pari ìjà láàrin Ganduje àti Emir Sanusi Ẹ wo àwọn ọ̀dọ́mọdé Naijiria tó ń ṣe bẹbẹ nínú isẹ́ aládaní nílé Yatọ si iyansipo awọn Ọba tuntun wọnyii, Gomina Ganduje buwọlu iwe to ni ki Emir Sanusi Lamido fi ipo rẹ silẹ, lẹyin ti igbimọ lọbalọba ṣe iwaadi lori ẹsun ajẹbanu ti wọn fi kan-an.
Ibi ti Kìnìún bá wà Ẹkùn kò ni dé ibẹ̀, ibi ti Ẹkùn bá wà Kìnìún ò ni dé ibẹ̀.
Aarẹ Buhari dárukọ àwọn òpópónà mẹ́tadinláàdọta kan ti yóò pari láàrin ọdun 2020/2021 to fi mọ àwọn ọ̀na to já si pápákọ ijá ẹrù ojú omi.
Ìtàn tó wà nídi òwe ‘Sebótimọ Ẹlẹ́wà Sàpọ́n’ Taiwo Akinkunmi, ọmọ Ibadan tó ya àsìá Nàíjíríà Taiwo Akinkunmi, ọmọ Ibadan tó ya àsìá Nàíjíríà Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Kayefi BBC Yorùba: Bàbá ọmọ, Mọ́ṣúárì, Ọlọ́pàá kẹ́jọ́ rò nípa òkú ọmọ tó pòórá Ẹwẹ, nigba ti BBC Yoruba bá agbẹnusọ ajọ to n ri si iṣẹlẹ pajawiri LASEMA l'Eko Ọgbẹni Kehinde Adebayo sọ̀rọ̀, o fi aridaju iṣẹlẹ naa ati agbegbe to ti n ṣẹlẹ han ati pe awọn oṣiṣẹ awọn ti wa lna Ijegun ni akoko ti akọroyin BBC Yoruba fọrọ wa a lẹnu wo.
Eré yii ni fiimu Naijiria to n ta julọ nipo kẹrin, ohun naa tun ni sinima to n ta julọ fun igba pipẹ ti awọn ero iworan si n woo julọ.
O si le lo wọn lati ra ọja tabi sanwo fun iṣẹ ti ẹnikan ṣe fun ọ - fun àpẹẹrẹ, o le fi Bitcoin seto irinajo igbafẹ lori ayelujara.
"Nkan tí a mọ̀ nìyíì Mo ti kúrò ní ààfin Oyo, kí ìròyìn tó ò jáde pé èmi àti Wasiu Ayinde n fẹ́ ara wa - Olori Badirat Awijare Malami ni pe aarẹ ti ṣe aṣeyọri to pọ, ""fun bo ṣe da yinyin ado oloro, ipaniyan, ati biba dukia jẹ duro"", ko to o di aarẹ lọdun 2015."
Ọkan lara wọn ku si ilu Madina, nigba ti awọn mẹrin toku ku si ilu Makkah.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Fake news is often published on legitimate-looking websites Ko si ẹri lati fihan pe ọrọ awọn ẹgbẹ ololufẹ ọkunrin s'ọkunrin wa iroyin to tan kalẹ kaakiri ayelujara.
Coronavirus: Iléèṣẹ́ ààrẹ̀ Nàìjíríà sọ pé ọ̀rọ̀ òṣèlú ni sísọ́ pé dandan ní kí Buhari bá ọmọ Nàìjíríà lórí coronavirus
Ibe Kachukwu ti o n mojuto ile iṣẹ epo rọbi.
ati mu imuse ofun ati ilana ise ya ni kiakia.
Àwọn eṣú náà yóo sì bo gbogbo ilẹ̀, tóbẹ́ẹ̀ tí ẹnikẹ́ni kò ní rí ilẹ̀ rárá, wọn yóo sì jẹ gbogbo ohun tí ó ṣẹ́kù tí yìnyín kò pa, wọn yóo jẹ gbogbo igi rẹ tí ó wà ninu pápá oko.
Ikede yi waye loju opo Twitter Ooni lẹyin ọjọ kẹjọ tọmọ naa d'aye ti wọn si ti yoo si ṣe etutu ọlọsẹmẹta tori ki o baa le ri bi o ti ṣe yẹ ko ri.
Òun làgbà òpìtàn tó mọ dúníyàn látìpìlẹ̀.
Ọmọ mi kò tíì mọ̀ pé òun ti di ìlúmọ̀ọ́ká, ó ń wádìí bó ṣe ń rí ara rẹ̀ lórí ayélujára Oríṣun àwòrán, Oreofeoluwa Lawal-Babalola Iya ọmọdekunrin ti fidio rẹ tan kari ayelujara tun ti sọ awọn ohun miran nipa ọmọ rẹ ti orukọ rẹ njẹ, Oreofeoluwa Lawal-Babalola.
Ti a ko ba gbagbe, ọdun to kọja ni wọn juwe orilẹede Afganistan gẹgẹbi orilẹede kẹta to buru ju lagbaye fun awọn akọroyin lati sisẹ wọn bii isẹ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù FIFAWWC: Falcons fìdí rẹmi, sùgbòn ọmọ Nàìjíríà gbóríyìn fún wọn 17 Òkùdu 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 18 Òkùdu 2019 Oríṣun àwòrán, FIFA.
OLUWA sọ fún Hosia pé, “Sọ ọmọ náà ní Jesireeli; nítorí láìpẹ́ yìí ni n óo jẹ ìdílé Jehu níyà nítorí ẹ̀ṣẹ̀ ìpànìyàn tí ó dá ní Jesireeli, n óo sì fi òpin sí ìjọba Israẹli.
Mose bá wí fún OLUWA pé, “Ṣebí ìwọ OLUWA ni o sọ pé kí n kó àwọn eniyan wọnyi wá, ṣugbọn o kò tíì fi ẹni tí o óo rán ṣìkejì mi hàn mí.
O kò gbọdọ̀ bá aya arakunrin rẹ lòpọ̀, nítorí pé, ohun ìtìjú ni, ìhòòhò arakunrin rẹ ni.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ṣẹ́ lóòtọ́ ní ginger àti garlic lè pa àrun Coronavirus?
Ṣebueli, ọmọ Geriṣomu, láti inú ìran Mose, ni olórí àwọn tí ń bojútó ibi ìṣúra.
Bẹẹ ni Ajọ LASTMA wa kesi awọn eniyan lati ṣe jẹjẹ ni oju popo.
Ọba alaye naa ni oun ati ọba yoku nilẹ Yoruba ni inu awọn ko dun si iwe wawi tẹnu rẹ, taa mọ si Query ti Fayemi fun ikọọkan awọn ọba alaye naa, awọn ẹni ti gbogbo aye n bọwọ nla fun, to si n bi wọn pe ki lo de ti wsn ko se wa si ipade lọbalọba lati wa maa fi ori ade tẹ ilẹ niwaju ọmọ inu wọn Alaafin wa ran Fayemi leti nipa ojuse 'Pẹlupẹlu' laarin awọn ọba Ekiti ati bo se kan idagbasoke nilẹ Yoruba, paapa ogun Ekiti Parapọ, taa tun mọ si Ogun Kiriji to waye laarin ọdun 1870 si 1886 Ẹya Yoruba ni itan ju ọpọ ẹya ni agbaye lọ.
Mo ti fọ ẹsẹ̀ mi,báwo ni mo ṣe lè tún dọ̀tí rẹ̀?
Òṣùnwọ̀n homeri ni ó gbọdọ̀ jẹ́ òṣùnwọ̀n tí ẹ óo máa fi ṣiṣẹ́.
Angela Kidjo sọ ọrọ yii sita lasiko ifọrọwerọ to ba BBC ṣe lati sami ayajọ awọn obinrin lagbaye, akọrin gbayi ọmọ orilẹede Benin naa ni awọn obinrin ni lati yẹna ofin to duroore kalẹ lawọn idile wọn ki wọn lee dẹkun aye ẹru ati ọmọ ọdọ ti awọn ọmọ obinrin n gbe ninu ile ti yoo maa se ounjẹ fun awọn ọkunrin ni inu ile.
Bakan naa ni awọn ajọ ti kii ṣe tijọba n di gbaju-gbaja.
Ó ti tán fún mí lọ́dún 2023- Ààrẹ Muhammadu Buhari Nàìjíríà bí ìkókó 26, 039 lónìí ọjọ́ kíní, oṣù kínií, ọdún 2020- UNICEF Ẹ̀kọ́ ọ̀fẹ́, ètò ilera ọ̀fẹ́ àti iná ọba ló jẹ wá lógún- ọmọ Nàìjíríà Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ọbẹ Ẹgusi sise ati jijẹ Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Ibeji ni Lawrence, orukọ ibeji rẹ a si maa jẹ Godswill.
Oríṣun àwòrán, OTHERS Torí ₦300, awakọ̀ ojú omi ṣokùnfà ikú èèyàn méjìlá l'Eko - Ọlọ́pàá Kọmisọna ọlọpaa nipinlẹ Eko, Hakeem Odumosu ti foju awakọ oju omi Bimbo Elebiju han pe oun lo dẹmi awọn eniyan legbodo.
Koda aarẹ funra rẹ pe iyawo mi lori ẹrọ ibanisọrọ ninu oṣu kẹwaa ọdun to kọja to si ṣeleri lati ṣa ipa rẹ ki ọmọ wọn pada wale lalafia.
Gbajúgbajà òǹkọ̀wé èdè Yorùbá, Lawuyi Ogunniran tí gbogbo àwọn olólùfẹ́ ìwé ìtàn Yorùbá mọ̀ sí Eégún Aláré ti dágbére fún ayé ní ẹnì ọdún márùnlélọ́gọ́rin.
Minisita fun iroyin tun wa salaye fun awọn asọju pe ijọba ti mu awọn ileri rẹ sẹ lorilẹ ede Naijiria ,paapaa julọ nipa pipese eto aabo, ni awọn apa ibikan ti awọn omo –oogun olote ti ti gba tele.
DSP Ezekiel Ayorinde lo fi ẹsun kan Rabiu pe O ji Spaghett kan, maltina alagolo kan, ẹlẹrindodo Chivita meji, yogọọti agolo dudu kan, ọra ọṣẹ ifọṣọ Ariel kan ati ankara marun un.
Eyi ko si ṣẹyin awuyewuye to n ṣẹlẹ nipinlẹ Edo lori ọrọ Gomina Obaseki ati Adams Oshiomọlẹ to jẹ alaga ẹgbẹ APC.
Awọn ipa wo ni Oniluola ko nigba to wa loke eepẹ?
" Oríṣun àwòrán, Mike bamiloye/facebook Oluwadarasimi Mike-Bamiliye (gẹgẹ bi apeja orukọ rẹ) kẹkọ gboye ninu imọ ede Gẹẹsi ni fasiti Babcock, Naijiria.
O nira ki Anthony ma bori to ba ja ẹṣẹ tori naa irawọ to tan jade wa lati Naijiria ni ọpọ ka a si, eyii si mu ki ọpọlọpọ ololufẹ rẹ lati Naijiria fẹran rẹ gan.
Kí Ọlọrun dìde, kí àwọn ọ̀tá rẹ tú ká.
Leyin ti o tuko agbaboolu Nigeria lo sorile-ede Russia, iroyin so pe, ajo to n mojuto boolu orile-ede Algeria ti n sa gbogbo ipa won lati gba akonimoogba ohun lowo Naijiria ni erongba lati gba iko agbaboolu orile-ede naa sile kuro ninu ipo aise deede.
Bamiloye ni idi niyi ti ere awọn ṣe wulo fun gbogbo ẹya tabi ẹsin.
Lẹ́yìn gbogbo wọn patapata ni Daniẹli dé, tí a sọ ní Beteṣasari, orúkọ oriṣa mi, Daniẹli yìí ní ẹ̀mí Ọlọrun ninu.
Ọ̀pọ̀ orílẹ̀-èdè ló ní àwọn òfin àti àbádòfin tí ó fún ọmọ ènìyàn ní ẹ̀tọ́ sí òmìnira ọ̀rọ̀ sísọ.
Eyi ni gbajugbaja Pasitọ ijọ Naijiria kan, Chris Oyakhilome sọ ninu iwaasu rẹ loṣu kẹfa.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù 9th Assembly: Àwọn ohùn tó yẹ kí ẹ mọ nípa Femi Gbajabiamila tó di Olórí Ilé Asojú-sòfin Nàìjíríà tuntun 11 Òkùdu 2019 Oríṣun àwòrán, @femigbaja Ọjọ ti pẹ ti Femi Gbajabiamila ti n wa ipo olori ile aṣoju-ṣofin orileede Naijiria, ala naa si ti wa di ohun bayi.
Ojú àwọn èèyàn Ondo ti là pé ìnira ni ẹgbẹ́ APC mú wá - Jegede PDP Eto ipese ẹẹdẹgbẹta naira lao maa fi pamọ fun gbogbo ọmọ ikoko lati ọjọ ti wọn ba ti bi i."
26 Agẹmo 2020 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Anton Szandor LaVey, oludasilẹ ijọ Satani.
Jesu dá a lóhùn pé, “Ẹnikẹ́ni tí ó bá mu ninu omi yìí òùngbẹ yóo tún gbẹ ẹ́.
afẹ, iṣẹ agbẹ, ile kikọ, eto ẹkọ, eto ilera, ipese ohun idagbasoke ilu,
 ) ooru ; Ìgbóna iná máa fa ooru .
Gẹgẹ bi iwadii ti fi ye wa, ogun ọdọ pere lo da ẹgbẹ naa silẹ lati fi jija gbara fun idajọ ododo lagbegbe Ajegunle nilu Eko lọdun mẹfa ṣẹyin.
Àtúnse Nàíjíríà gbọdọ̀ bẹ̀rẹ̀ láti ìdìbò Ọ̀sun - Saraki Ọmọ Yorùbá ni onímọ̀ ẹ̀rọ ‘Rọ́bọ́tì’ tó ń gbowó jùlọ ní UK Olórí ilé asòfin l‘Ọ́sun pàdánù N38m sọ́wọ́ gbájúẹ̀ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Omiyalé Àkútè: N50 si N100 làwọn èèyàn fi ń kọjá lórí ẹ̀kún omi l‘Ákútè Koda, ki a to wi, ka to fọ, iroyin ti kan de ile ipolongo ibo ọkan ninu wọn pe, wọn ti gba lati ṣiṣẹ fún ọkan ninu wọn.
Fadeyi wa fi ọwọ gbaya pe Ileesẹ Ọlọpa ko ni rẹwẹsi titi ti yoo fi ṣe awari awọn onisẹ ibi yika ipinlẹ Oyo.
Ọjọ Abamẹta ni wọn gbe e lọ si ileewosan Karusi ẹyin to n wo idije ere idaraya kan nitosi ile rẹ.
pe gbogbo awọn eniyan ti ọrọ kan ni apa iwọ oorun gusu orilede yii gbọdọ
Ọkùnrin kọ́ ló ra jeep fún Iyabo Ojo, òógùn ojú mi ni mo fi rà á fun Kanu Ejike fipá bá ọmọ ọdún méje lò pọ̀ nínú sọ́ọ̀bù ìyàwó rẹ̀ Amọ o ni o da oun loju pe iya oun n se atilẹyin fun oun lasiko ti oun wa nile BB Naija naa, to si maa n gbadura fun aseyọri oun nitori pe gbogbo ohun ti oun ba dawọle, ni iya oun maa n sugba rẹ.
Lateyin wa, orile-ede Russia ni o ti n satileyin  ipese awon ohun ija ogun fun orile-ede Sudan,  pupo awon omo-ogun oju ofurufu orile-ede Sudan ni won n wa oko ogun oju ofurufu fun orile-ede Russia.
Ṣùgbọ́n ìjọba ìpínlẹ̀ Derbyshire ti la ọ̀nà káàkiri rẹ̀ .
Wọn yóo máa ni ọ́ lára, wọn yóo sì máa jà ọ́ lólè nígbà gbogbo; kò sì ní sí ẹnìkan láti ràn ọ́ lọ́wọ́.
bi o ti le je pe, Frankurt wo oke afara Chelsea tan die bayi lo ku, leyin ti iko mejeeji gba ami ayo kookan(1-1) ti ifesewonse naa fi pari, ki won to lo fojukoju pelu boolu agbesile gba(Penalty Kicks).
Ninu atẹjade ti ileeṣẹ eto ilera naa gbe jade ni, ọmọde to to ẹgbẹrun mejilelogoji si ẹgbẹrun lọna ọgọta ni aisan naa n mulọ lorilẹede Naijiria ni ọdọọdun.
yan aare tuntun ti yoo tuko orile-ede Naijiria fun odun merin miran ati idibo awon
Rabuṣake bá sọ fún wọn pé, “Ẹ sọ fún Hesekaya pé ọba ńlá Asiria ní kí ló gbójú lé rí?
O ni ibẹru itankalẹ arun naa bẹrẹ si n pọ si lẹyin ti awọn oṣiṣẹ ileeṣẹ to n risi eto iforukọsilẹ ati nọmba idanimọ, NIMC, pada ṣenu iṣẹ lẹyin idaṣẹsilẹ ranpẹ ti wọn gunle, ti obitibiti ero si ya bo ileeṣẹ wọn.
,Lalong ni ibo 595,582 lati fi
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Kiniun kii se ara awọn ẹranko ti o yẹ ki awọn eniyan maa sin ninu ile.
Buhari ti seleri pe ijoba apapo yoo ri daju lati da owo t ipinle Ebonyi naa
"Ẹwẹ, yatọ si bo ṣe n lọ laarin awọn ololufẹ wọn lọtọọtọ ti Àwọn olólùfẹ̀ Toyin Abraham ati Liz Anjorin ti gbé ọ̀rọ̀ wọn rù sórí, ẹ wo òjò òkò ọ̀rọ̀ , awọn gbajumọ oṣere ẹgbẹ wọn ti n rọ awọn mejeji ṣugbọn ti wọn kọ lati gbọ pe ""Ẹ lọ́ jáwé gbé jẹ́ẹ́ sọ́wọ́ bí bẹ́ẹ̀ kọ́."
Àtúnṣe òpópónà Lagos-Ibadan àwọn ọ̀ná míràn ti e lè gba Bianca júwe ilé fún Serena Williams nínú ìdíje l'America Ààbò tó péye wà fún àwọn okòwò ará South Africa ni Eko -Sanwo Olu Akeredolu ò ṣe ǹkan àrítọ́kasi ni Ondo- Komísọnà ọ̀rọ̀ to n lọ tẹ́lẹ̀rí Ni ọjọ kọkanlelọgbọn, oṣu karun un, ọdun 2019 ni gomina Seyi Makinde ti wọn ṣẹṣẹ bura fun wọle nigba naa paṣẹ pe eegun ẹgbẹ awakọ ero nipinlẹ naa ko gbọdọ ṣẹyọ mọ fun asiko yii.
Dino to fi fọnran fidio oun ati Kimono sita ni“Ogbantarigiolorin ti re iwalẹ aṣa, ọjọ buruku ni yi.
 láti ọmọomún ni ìyá ajíbógun Ọwá iléṣà ti kú Ìyá agígírì tí ó jẹ ́ ẹ ̀ gbọ ́ n ìyá rẹ ̀ ló wò ó dàgbà , ọmún rẹ ̀ ló sì mún dàgbà .
Ẹ̀ni ọgọ́ta ọdún gbẹ̀mí ara rẹ̀ ní UCH Ibadan ‘Naijiria, Congo ni ìṣẹ́ yóò ti pọ̀jù lágbàáyé ní 2050’ Ọpọ awọn oṣiṣe ijọba to rọ yika oku rẹ ni kayefi ni iṣẹlẹ naa ti wọn si ṣe apejuwe ẹni ọdun mọkandinlaadọta yii gẹgẹ bi oniwa tutu.
Láti ibẹ̀ ó lọ gbógun ti àwọn ará ìlú Debiri.
Nítorí orúkọ rẹ, OLUWA, ṣí ojurere wo ibi mímọ́ rẹ tí ó ti di ahoro.
Ó ní, “Agbára mi dínkù lónìí, bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé òróró ni a fi yàn mí ní ọba.
Ṣugbọn ìwọ wà bákan náà,ọjọ́ ayé rẹ kò sì lópin.
 Ile-isẹ   ọlọpaa  sọ ninu atejade kan, ti  wọn  gbe jade lọjọ Aiku pe ,  awọn  fẹ ki Abẹnugan ile igbimọ asọfin naa wa se alaye lori   awọn  ẹsun ti  awọn  adigunjale marun un ohun sọ.
Ni Gombe, mẹjọ ninu awọn mejidinlaadọta ni arun naa, ti Bauchi, awọn meje ninu mejidinlogoji ni arun naa.
Ọgbẹni Oyekanmi sọ pe awọn seto idibo gomina l'Ọṣun ni ibamu pẹlu bi awọn ṣe maa n ṣe eto idibo lọdọọdun, paapa ọdun 2015.
Igbesẹ yii jẹ jade latari ẹsun ti wọn fi kan adajọ Walter pe ko kede awọn dukia rẹ gẹgẹ bi ọkan lara awọn to di ipo nla mu lawujọ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Papalolo ní ìlépa owó ni ìyàtọ̀ tó wà láàárín àwọn òṣèré tíátà àtijọ́ àti ìsisìnyí Ẹwẹ, awọn sanmọri lagbo idanilaraya lorilẹede Naijiria pẹlu ti sọrọ nipa rẹ lori ikanni ayelujara.
Nibi tawọn kan ti n ri ọkọ tabi iyawo fẹ lori ayelujara, bẹẹ naa ni awọn miran n pade awọn aṣebi loju opo ayelujara.
Iléẹjọ gíga jùlọ da ẹjọ́ SDP àti PDP nù, wọ́n ní Yahaya Bello ló wọlé ìbò gómìnà Kogi Wọ́n ti sún ìdájọ́ àwọn sójà tó pa ìyá àti ọmọ ní ọdun 2018 sí oṣù tó m bọ̀ Ìjà d'ópin, fún ìgbà àkọ́kọ́, bàálù gbéra láti Israel lọ sí UAE Ààrẹ Buhari buwọ́lu gbígbé ìṣàkoso nọ́mbà ìdánimọ̀ (NIMC) lọ sí ẹ̀ka ìjọba tó ń rí sí ìbáraẹnisọ̀rọ̀ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Wo bí Sunday Orimola ṣe gba ikú ẹranko kú ní Ifon ni Ondo lórí ọ̀nà àtijẹ Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Oluwo: Èmi l'ọba lórí òrìṣà, oṣó àti ajẹ́, Olorì tuntun tó ń bọ̀ lẹ́tikẹ31 Ògún 2020 6:18 Fídíò, Natalia Mufutau ìyá Yakub, Kamil àti Adam sọ̀rọ̀ lórí bí wọ́n ń sọ èdè mẹ́rin pàpọ, Duration 6,1831 Ògún 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Pupọ ninu awọn to ti jẹ Gomina ni wọn ti gbiyanju lati yanju wahala to wa loju ọna yi ti wọn ko ri yanju.
daran-daran ati omiyale se lọsẹ, nipa yiya biliọnu mẹ́tàdínlọ́gbọ̀n naira sọtọ lati fi
Ojú tì mí, ìdààmú sì bá mi,nítorí ìtìjú ohun tí mo ṣe nígbà èwe mi dé bá mi.
Ìgbà tí bàbá mi náà kì í sì í ṣe ọmọdé ọdẹ, òun náà hu ìwà àgbàlagbà, ó mú èèso igi tí ẹ̀gbọ́n ìyàwó rẹ̀ fún un, ó sọ ọ́ sí ẹnu, òun náà sì yípadà ó di kìnnìún, kìnnìún sì bẹ̀rẹ̀ sí bá kínnìún jà, gbogbo igbó ń bú ramúramú: àwọn ẹbọra Igbó Olódùmarè sì ń sáré kiri.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Odebiyi: ìgbà gbogbo ni Bàbá mi ń polówó iṣẹ́ mi fáráyé Bi o tilẹ jẹ pe, wọn mọ odi yi ọgba ẹranko ọhun ka bo se yẹ, amọ awọn alasẹ ibẹ ni ko tii ye awọn ọna tawọn ẹranko naa n gba sa bọ sita.
bí ẹ bá ń wádìí lónìí nípa iṣẹ́ rere tí a ṣe fún ọkunrin aláìsàn yìí, bí ẹ bá fẹ́ mọ bí ara rẹ̀ ti ṣe dá, 
N óo wá fún wọn ní olùṣọ́ mìíràn tí yóo tọ́jú wọn.
Òmíràn ní í ṣe pẹ̀lú àwọn àgbàlagbà méjì tí a bá òkúu wọn nínú ilé, ọ̀kan kú ikú ebi.
Ní àkókò yìí, Joṣua ti di àgbàlagbà, ogbó sì ti dé sí i.
Kiné-Fatim Diop, adarí ìpolongo Amnesty International ní Ìwọ̀-oòrùn Ilẹ̀-Adúláwọ̀, sọ̀rọ̀ ní ọdún yìí nípa ìtakora tí ó wà ní àárín ohun tí ó yẹ kí ó jẹ́ ọjọ́ ìṣèrántí-dunnú àti ohun tí ọ̀pọ̀lọpọ̀ ẹbí àwọn olùfarapa ń rò:
aabo ati awon ona ti maa gba lati koju awon idojuko naa.
Ṣugbọn Samsoni sùn títí di ọ̀gànjọ́ òru.
Ẹni tí ó mú yín la aṣálẹ̀ ńlá tí ó bani lẹ́rù já, aṣálẹ̀ tí ó kún fún ejò olóró ati àkeekèé, tí ilẹ̀ rẹ̀ gbẹ, tí kò sì sí omi, OLUWA tí ó mú omi jáde fun yín láti inú akọ òkúta, 
Huramu tún fi bàbà ṣe ìtẹ́lẹ̀ mẹ́wàá, ọ̀kọ̀ọ̀kan wọn gùn ní igbọnwọ mẹrin, wọ́n fẹ̀ ní igbọnwọ mẹrin, wọ́n sì ga ní igbọnwọ mẹta.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Fulani Kidnapping: Owó púpọ̀ la san kí wọ́n tó fi mi sílẹ̀ Ali fikun un pe, awọn ibode naa di titi latari ati lee dẹkun bi awọn kan ṣe n ko ọja wọle sorilẹ-ede yii lọna ti ko tọ.
Awon ohun Elo ile-iwosanEwe, bi a ba wo, owo yii to lati mu igberu ba awon ile-iwosan, bi rira awon ohun elo ile-iwosan igbalode abbl.
Eyi lo mu ki wọn gbe e janto lọ si ile ẹjọ to si ba ara rẹ lọ́gbà ẹwọ́n lati ọjọ kẹwaa, oṣu keji, ọdun 2017.
ọjọ ti iru agbekalẹ abadofin iṣuna owo bayii yoo waye, sugbọn a ko mọ
Sowore: Garba Shehu ni ijọba Buhari ko tii fi akọroyin kankan satimọle lati ọdun 2015
Amọ aba naa wa yọ igbesẹ lilo ẹrọ amunawa fun awọn akanse isẹ to se koko silẹ, ninu eyi ta ti ri ipese iwosan isegun lawọn ile iwosan, papakọ ofurufu ati awọn oju irin reluwe.
Awọn ohun elo ounjẹ gbọdọ wa ni inu ike ti ẹkutele ko lee de bẹ.
Nípòkípò tí mo bá wà, ninu ohun gbogbo, mo ti kọ́ àṣírí bí a ti ń ní ìtẹ́lọ́rùn, kì báà jẹ́ ninu ebi tabi ayo, ninu ọ̀pọ̀ tabi àìní.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Kunle Afolayan: èmi kò fẹ́ fi ogún sílẹ̀ fún ọmọ mi Awọn iroyin mii ti ẹ le nifẹ si Wo ìdí ti ìjọba ṣe ka ẹ̀sùn méje tán yányán mọ́ Sowore lẹ́sẹ̀ Ẹ wo àwọn àwòrán BBC tó lààmì laaka lọ́sẹ̀ yìí.
Àṣẹ mi nìyí; ẹ fẹ́ràn ara yín gẹ́gẹ́ bí mo ti fẹ́ràn yín.
Ṣugbọn orílẹ̀-èdè tí ó lò wọ́n bí ẹrú ni Èmi yóo dá lẹ́jọ́.
Ajọ to n mojuto ajakalẹ aarun, NCDC, kede pe ipinlẹ mejidinlogun, ati ilu Abuja ni awọn esi ayẹwo naa ti jade.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ènìyàn méjìdínlọ́gbọ̀n lo ṣe pẹ̀kí ọlọ́jọ́ wọn ni Mubi 1 Èbibi 2018 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 2 Èbibi 2018 Àkọlé àwòrán, Ènìyàn tó lé laadodota lo fara káasa nínú ìṣẹ̀lẹ̀ náà.
" O ni ko si ẹṣẹ ti Ọlọrun kii dariji, abi?
Mú àwọn kọ̀lọ̀kọ̀lọ̀ wọ̀n-ọn-nì,àwọn kọ̀lọ̀kọ̀lọ̀ kéékèèké tí wọn ń ba ọgbà àjàrà jẹ́,nítorí ọgbà àjàrà wa tí ń tanná.
Ọba Ogunwusi wa jẹjẹ atilẹyin rẹ fun ẹgbẹ awọn to n seto irinajo afẹ lorilẹede yii, to si ni awọn yoo jọ sisẹ pọ lati gbe Naijiria de oke agba.
Olójúkòkòrò kò lè ní inú-dídùn láé bí ayé kéré bí kò ju èèso akèǹgbè lọ.
Àwọn tí wọ́n ráàyè sá àsálà fún ẹ̀mí wọn sá síta kíákíá kúro nínú ewu ìbọn náà.
lílò àjẹsára náà kò léwu .
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Police Killing: Iléeṣẹ́ ní àṣìta ìbọn ló pa obìnrin nílùú Eko lọ́jọ́ Satide 11 Ògún 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Awọn ọlọpaa ko gberegbe Ileeṣẹ ọlọpaa ipinlẹ Eko to ṣalaye aṣita ibọn lati ọwọ ọkan lara awọn ọlọpaa lo ṣekupa obinrin kan nipinlẹ naa lọjọ Abamẹta.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Awujale: Gómìnà Amosun kò fẹ́ràn àwọn ará Ìjẹ̀bú 11 Èbibi 2019 Oríṣun àwòrán, Google Àkọlé àwòrán, Ọba Awujale ti ìlú Ìjẹ̀bu ní bí ó tilẹ̀ jẹ́pẹ́ ọ̀rẹ́ ni òun àti gomina, àmọ́ kò ní ìfẹ́ àwọn ènìyàn òun rárá.
“Kò sí ẹni tí ó mọ ọjọ́ náà ati wakati náà.
Ara rẹ̀ ń dán bí òkúta olówó iyebíye tí à ń pè ní bẹrili.
ransẹ si awon eniyan ipinle Sokoto ati Zamfara fun ikolu buruku ohun, aare ni
 Ó rí ìgbówólórí ( inflation ) gégé bí ìdàmú nlá tó n se jàmbá fún òrò ajé e wa .
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ayodele Fayose: Ẹ̀yin ọ̀tá mi, ẹ lọ dì mọ́ òpò ina lọ́dún 2020 1 Sẹ́rẹ́ 2020 Oríṣun àwòrán, Twitter Àkọlé àwòrán, Gomina ìpínlẹ̀ Ekiti tẹ́lẹ̀rí, Ayodele Fayose ti fèpè ránsẹ́ sí àwọn ọ̀tá rẹ̀ lọ́dún tuntun 2020.
Ìlú tí kò gba ìmọ̀ràn ati ìbáwí, tí kò gbẹ́kẹ̀lé OLUWA, tí kò sì súnmọ́ Ọlọrun rẹ̀.
2 Ògún 2019 Awọn akanlo ede tabi ọrọ Yoruba kan wa ti itumọ wọn fara sin to si jẹ wi pe gẹgẹ bi awọn agba ṣe sọ ọ, ọlọgbọn lo n tu u, ọmanran lo n mọ ọ.
ti awọn kan wọn n fẹhohu han tako igbesẹ Ile lati dibo yọ gomina nipo.
Ó sọ fún àwọn ọmọ Lefi tí wọn ń kọ́ àwọn ọmọ Israẹli, tí wọ́n sì jẹ́ mímọ́ pé, “Ẹ gbé Àpótí mímọ́ náà sinu ilé tí Solomoni ọmọ Dafidi, ọba Israẹli kọ́.
Nítorí èwo ninu àwọn angẹli ni ó fi ìgbà kan sọ fún pé,“Ìwọ ni ọmọ mi,lónìí ni mo bí ọ?
 Ó lé ní àádóje iṣé ọnà tí baker ṣe parí , tí ọ ̀ pọ ̀ lọpọ ̀ sì wà ní àwọ ̀ dúdú àti funfun .
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Osun Accident: Èèyàn méjì pàdánù ẹ̀mí wọn nínú ìjàmbá ọkọ̀ tó wáyé ni Osun 22 Ògún 2020 Oríṣun àwòrán, @FedfireC Ko din ni eeyan meji to jẹ Ọlọrun nipe ninu ijamba ọkọ to waye lẹyin ti ọkọ agbepo kan fori sọ ọkọ to ko ẹja ni ipinlẹ Osun.
Ọ̀rọ̀ tí OLUWA sọ fún Mika, ará Moreṣeti nípa Jerusalẹmu ati Samaria nìyí, ní àkókò ìjọba Jotamu, ati ti Ahasi ati ti Hesekaya, àwọn ọba Juda.
Agbegbe Maiha nipinlẹ Adamawa ni wọn ti mu ẹyẹ igun naa gẹgẹ bii afurasi pé o n ṣalamí fawọn alakatakiti ẹsin Islam, Boko Haram.
Àdó okoró búrẹ́kẹ' 'Boko Haram ti gbilẹ̀ kan nílẹ̀ Hausa, wọ́n ti ń ní Check Point"" láti gba owó lọ́wọ́ àwọn àgbẹ̀' Gẹgẹ bi ile igbimọ aṣofin mejeeji ṣe n ke si aarẹ buhari lati da wa wi tẹnu rẹ ati pe ko gba iṣẹ lọwọ awọn ọga awọn ologun tori wọn ni wọn ti kuna ninu iṣẹ wọn."
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Nigeria 2019 Elections: Jonathan, Buhari, Obasanjọ sọ̀kò ọ̀rọ̀ lórí làáṣìgbò ìbò 19 Èrèlè 2019 Aarẹ Muhammadu Buhari sọ pe ẹnikẹni to ba ji apoti ibo gbe lasiko eto idibo to n bọ, yoo fi ẹmi ara rẹ di, nitori ijọba ti pasẹ fawọn osisẹ agbofinro lati gbe igbesẹ to yẹ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù BBC Africa Eye tú àṣírí ìfiyàjẹni àwọn Ológun, SARS káàkiri Nàìjíríà 10 Èrèlè 2020 Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, BBC Africa Eye tú àṣírí ìfìyàjẹni àwọn òṣìṣẹ́ aláàbò ÌKÌLỌ̀ PÀTÀKÌ: Fọnran yii ni aworan awọn nkan to lee ba ni lọkan jẹ atawọn aworan ifiyajẹni pupọ.
Nígbà náà, ẹ̀mí OLUWA yóo bà lé ọ, o óo sì darapọ̀ mọ́ wọn, o óo sì máa sọ àsọtẹ́lẹ̀, o óo sì yàtọ̀ patapata sí bí o ti wà tẹ́lẹ̀.
Ó ní ìdí tí òun fi jí owó náà gbé nip é òun kò bímọ fún Orímóògùnjẹ́ òun kò sì fẹ́ kì tòun ó gbé sílé rẹ̀ nítorí pé ọmọ tì obìnrin bá bí fún ọkọ ni wọ́n fi máa ń pín ogún ọkọ náà ní ilẹ̀ Yorùbá.
Awọn obinrin ti ina orukọ wọn ko fi igba kan ku lati igba ti iṣejọba tiwantiwa ti bẹrẹ.
O sapejuwe ipẹjọ naa gẹgẹ bi eyi ti ko ni itumọ kan kan, ohun a n gbe pati si ẹgbẹ kan ni Agbẹjọro agba naa fi kun un pe ile itẹwe Fasiti Oxford, ti o fi kun un bi olujẹjọ keji ko ni ejọ ọ ro rara nitori ẹka lasan ni nile ẹkọ fasiti Oxford, ko le da duro fun ijẹjọ.
ati nítorí ẹ̀jẹ̀ aláìṣẹ̀ tí ó ti ta sílẹ̀, nítorí tí ó ta ẹ̀jẹ̀ aláìṣẹ̀ sílẹ̀ ní gbogbo ìgboro Jerusalẹmu, OLUWA kò ní dáríjì í.
Adájọ́ ní Fayoṣe lẹ́tọ̀ọ́ láti ṣe bẹ́ẹ̀ súgbọ́n nígbẹ̀yìngbẹ́yìn, ilé ẹjọ́ sún ìgbẹ́jọ́ náà síwájú di Ọjọ́rú ọ̀sẹ̀ (ọjọ́kẹ́ẹ̀rǹlélógún ọṣù kẹẹ̀wá).
O wa kilọ pe ASUU ko ni ri aaye fun ẹjọ kankan mọ lori wiwọgile iyanṣẹlodi, ti ijọba ba kọ lati san awọn owo ti wọn jẹ.
Bẹ́ẹ̀ ni n óo ṣe fi ààlà sí ààrin àwọn eniyan mi ati àwọn eniyan rẹ̀.
Bi awọn eeyan kan si se faramọ abala ofin naa ni awọn kan ta ko ofin yii @Ibukun_olu, o ni bi o tilẹ jẹ pe ko si ofin kankan to tako ibalopọ ninu ọkọ loju taye, sibẹ, wọn lee gbe awọn eeyan to ba da asa yii wo pẹlu ẹsun aini iwa ọmọluabi.
 Mo nife gbogbo yin” Orisiirisii edun okan ni awon alajosisepo re ti n ko lori ero ayelujara lati fi edun okan won han pelu ohun aro.
Iranṣẹ ikú ni ibinu ọba,ọlọ́gbọ́n eniyan níí tù ú lójú.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Mo fi iṣẹ́ Banki silẹ̀ lọ bẹ̀rẹ̀ alápatà - Derin Ẹmi kan lo maa n dari rẹ, to si maa n ba ẹmi airi sọrọ Iyawo meji lo ni, Mary ati Olubankẹ, to si bi ọmọ marun Akọbi Fagunwa, Olufẹmi ko si laye mọ O le lo to ọsẹ mẹfa tabi ju bẹẹ lọ nin u igbo kiji-kiji lati kọwe.
Awon asoju naa wa si orile ede Eritrean leyin ti  adari tuntun naa Abiy, ya awon eniyan re lenu  ni ibere osu yii, nigba ti o so pe  oun ti gba lati gbe igbese alaafia ni eyi ti yoo fopin si ija ala –ile to maa n waye pelu orile ede Ertrea ni eyi ti opolopo emi sofo nibe.
Ṣugbọn ó dàbí diragoni ninu omi.
Gabriel Heinze lo gba bọọlu si awọn Super eagles ni ọjọ naa ni iṣẹju kẹfa ifẹsẹwọnsẹ ọhun.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ibadan Market looting: Ọjà ẹgbẹ̀lẹ́gbẹ́ mílíọ̀nù ni jàǹdùkú kó lọ́jà Agbeni, wọ́n tún sọná sun ṣọ́ọ̀bù 8 Bélú 2020 Oríṣun àwòrán, @Fedfireoyo Awọn janduku yabo ọja Agbeni Ologede niluu Ibadan lọjọ Abamẹta, nibi ti wọn ti ji ọpọ nnkan ko ninu ṣọọbu mẹẹdogun, ti wọn si sọna si awọn ṣọọbu naa.
"O ni ""Mo ṣẹṣẹ gba esi ayẹwo Covid-19 ti mo ṣe, esi naa si fi han pe mo ti ni arun naa."
Ara àwọn ọrẹ rẹ̀ tún ni àwo kòtò kan tí wọ́n fi wúrà ṣe, tí ìwọ̀n rẹ̀ jẹ́ ṣekeli mẹ́wàá tí ó sì kún fún turari; 
 Awon agbaboolu ohun ni kikun:Awon Asole(Goalkeepers): Francis
1/Via Reuters Ẹwẹ, iha to daa to wu ni lori naa wa ninu ọrọ sisọ rẹ, laarin agbami bi awọn oloṣelu ṣe maa n ka ọrọ jade ninu iwe, Biden ni iranti igba ewe oun fihan pe oun kii fẹran lati maa ka ọrọ lati inu iwe dipo bẹẹ atinu ọkan loun ti maa n sọrọ.
Ta ló sì mọ ìtumọ̀ nǹkan?
Yìnyín àti òtútù ti pa ènìyàn 21 ní America Àlejò àpàndodo ni Fayoṣe, a kò fìwé pèé - Afuye Gbogbo ọjà di títì pa nílùú Akure, ṣugbọ́n nítorí kí ni?
Iléeṣẹ́ ọlọ́pàá sọ afurasí ọlọ́pàá tó yìnbọn fún ọ̀dọ́kùnrin tó fún èèyàn lóyún s'átìmọ́lé Wo bí odò Nile tó gùn jù l'Áfíríkà, ṣe ń fójúu ilẹ̀ Egypt, Ethiopia àti Sudan han màbo Ọ̀wọ́ngógó búrẹ́dì gbòde kàn lẹ́yìn tí àwọn oníbúrẹ́dì da iṣẹ́ sílẹ̀ Oríṣun àwòrán, Twitter/Gboyega Akosile Helicopter crash in Lagos: Ìjọba ìpínlẹ̀ Eko ti bẹ̀rẹ̀ àtúnkọ́ ilé tí bàlúù agbéra pá tó jábọ́ bàjẹ́ ní Eko Ijọba ipinlẹ Eko ti bẹrẹ atunkọ agbegbe Opebi ti ọkọ baalu ẹlikọpita jabọ si ni ọsẹ to kọja.
orile ede ti o fegbe tii ,lati osu kewaa odun 2018 o din ni ẹ̀ẹ́dẹ́gbàárun  awon agbe ti won  gbin orisirisi  ohun ogbin lopo janturu, ni eyi ti won ti pese
Ẹ óo retí wọn títí, ẹ kò ní gbúròó wọn, kò sì ní sí ohunkohun tí ẹ lè ṣe sí i.
O ni igbesẹ ti lọkọlaya yẹ ki wọn gbe ninu Islam tile ba fẹ maa daru.
Yorùbá dùn lédè, ẹ máa sọọ́ Ẹfunroye Tinubu - Ògbóǹtagí oníṣòwò, olówò ẹrú àti afọbajẹ Samuel Ajayi Crowther, òjíṣẹ́ Ọlọ́run tó gbé èdè Yoruba lárugẹ Mọrèmi Àjàṣorò, akọni obìnrin tó gba Ilé Ifẹ̀ sílẹ̀ lóko ẹrú Wọn sọ bi wọn ṣe bẹrẹ niwọnba ko to di nla bayii péki onikaluku bẹrẹ ohun to wuu lati ṣe lọdun 2019.
Ẹ̀rù ati ìṣubú, ìsọdahoro ati ìparun ti dé bá wa.
Kò wúlò kí a máa sọ̀rọ̀ tako ìjìyà abẹ́lé kí a sì tún máa gbèlẹ́yìn àṣàrò ìnáwó tí kò ní ṣe ààbò ètò àwùjọ, ìṣúná àìtó tí gbogbo wa mọ̀ pé ipa òdì ni ó ń kó nínú ayé àwọn obìnrin.
"Dino ninu ọrọ̀ rẹ ni ju gbogbo ẹ lọ ""mo ti bi Ọlọ̀run leere"" yoo si sọ ọ di ṣiṣe fun oun lati di gomina ipinlẹ Kogi."
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Tottenham sọ ọjọ́ ìsinmi olóyin di ''Black Sunday'' mọ́ Arsenal lọ́wọ́ pẹ̀lú ìgbájú-ìgbámú 6 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Oríṣun àwòrán, Getty Images Ti eleyi kii ba ṣe ijamba nla?
 níbẹ ̀ lówà tó ti bẹ ̀ rẹ ̀ sí ní ṣiṣẹ ́ díèdíẹ ̀ gẹ ́ gẹ ́ bíi òṣèré ni nollywood .
Ọjọ kẹtalelogun, oṣu Kejila, ọdun 1969 ni Naijiria tun kọlu wọn.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù #EkitiDecides: Oluṣọla Ẹlẹka sọ ibi tí ìjọbá àná bá Ekiti dé Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ #EkitiDecides: Oluṣọla Ẹlẹka sọ ibi tí ìjọbá àná bá Ekiti dé 11 Agẹmo 2018 Olùdijé fún ipò gómìnà lábẹ́ àsìá ẹ́gbẹ́ òṣèlú PDP, Oluṣọla Ẹlẹka sọ nípa bí àwọn ìjọba tó ṣáájú ti ṣe se ètò ìjọba rí àti èyi tí òun yóò ṣe bó bá wọ́le.
 Minista fun oro abele, Ogagunfeyinti Abdulrahman Dambazau lo so eyi di mimo nilu Abuja leyin to se ipade pelu awon ile ise ijoba atawon ajo torokan lori ona gbigbogunti awon to n lo ibon atohun eelo ija mii bi ikolu to waye laarin awon darandaran atawon agbe.
Alaafin: Olori Aanu Adeyemi aya Oba Lamidi Adeyemi ti ìlú Oyo ní ohun tó bá kúkú wu ọmọ láti jẹ kìí.
Ọdun 1971 ni Buhari gbe e niyawo, ṣugbọn o kọ ọ silẹ l'ọdun 1988.
El-Zakzaky ti lọ sí India fún ìwòsàn - Femi Falana Jẹjẹrẹ ní ìwà akakítí ẹ̀sìn, ẹ yàgà fún ẹ̀kọ́ òdì -Ààrẹ Buhari Àṣìta ìbọn ló pa obìnrin nílùú Eko lọ́jọ́ Satide- Ọlọ́pàá Ẹ ṣe àwárí ọ̀daràn tó bọ́ mọ́ yín lọ́wọ́ - Turkur Buratai Ileeṣẹ ọlọpaa Met ni Kareem kọkọ kọwe beere fun aye lati lọ fun isinmi alaigbowo-oṣu ṣugbọn ko sọ ohun to fẹ lọ ṣe, wọn si fun laaye.
Paradà, OLUWA, jí gìrì sí ọ̀ràn mi,gbèjà mi, Ọlọrun mi, ati OLUWA mi!
Aburo oloogbe naa, Ọmọwe Tokunbo Dosunmu-Awolowo to ba BBC Yoruba ṣalaye pe ni bii deedee aago mejila ọsan ti mama jẹ Ọlọrun nipe.
April Fool's Day: Wo àwọn ẹ̀tàn tí àwọn ènìyàn ti ṣe
 ipẹ ̀ ka rẹ ̀ bẹ ̀ rẹ ̀ láti apá gúsù-Ìwọ ̀ oòrùn nàìjíríà títí dé Àríwá-Ìwọ ̀ oòrùn sudan .
Igba keji si re e to gba ami ẹyẹ naa lera-lera.
Ògòǹgò kò náání àwọn ọmọ rẹ̀,ó ń ṣe sí wọn bí ẹni pé kì í ṣe òun ló bí wọn,kò bìkítà bí wahala rẹ̀ tilẹ̀ já sí asán;
1 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
OLUWA Ọlọrun ní, “Àwọn ará Filistia gbẹ̀san lára àwọn ọ̀tá wọn, wọn sì fi ìkórìíra àtayébáyé pa wọ́n run, 
Bakan naa lo sọ pe ijọba yoo pin ẹgbẹrun meje àbọ̀ Naira fun ikọọkan awọn ọdọ 10,628 to n ṣe iṣẹ pẹpẹẹpẹ fun ijọba ipinlẹ naa.
Trump n wọ ọkọ ofurufu ti aarẹ Amerika yii lọ si California.
Fayoṣe figbe ta pé wọ́n fẹ́ gbẹ̀mí òun Fayose kọ́ ni olóṣèlú tí yóò kọ́kọ́ kán l'ọ́rùn' Ẹ jẹ ki a ran ara wa leti diẹ ninu awọn asiko manigbagbe ni 2018 ati ọrọ ti awọn ọmọ Naijiria ko le gbagbe ati ju bẹ lọ.
Ọ̀pọ̀ àwọn olùkópa wọnyìí ni wọn si tí ń sàlàyé ìdì ti wọn fi wá láti bẹ̀rẹ̀ ohun ti àwọn oludíje yìí fẹ́ ṣe fun ará ìlú, èyí ni wọn sàlàyé pé ti ó ba di ọjọ́ iwájú yóò fun àwọn láànfàní láti lé bi wọn lérèè ohun ti wọn sọ pé àwọn yóò ṣe.
    Ẹjọ́ tí wọ́n ṣe tẹ̀lé èyí, ẹjọ́ ọba ni, ẹnìkan sọ pé bàbá ọba, èyí nì ní Òmùgọ́diméjì, ti jẹ òun ní owó kan kí ó tó kú, pé owó náà jẹ́ kọ́bọ̀ mẹ́rin ó sì fi jàgùdà-páálí lé e pé àfi bí ọba bá san owó náà fún òun ní wéréwérré.
Koda awọn kan n ra ororo naa ti gbowo lori, ẹgbẹrun mọkanla din igba naira ni wọn ta a nisinyi.
Ṣugbọn agbẹjọro telọ sọ pe irọ nla ni, o fidi rẹ mulẹ pe DPO naa ko si lara igbimọ to n ṣewadi iwọde EndSARS.
OLUWA, tẹ́tí sí adura èmi iranṣẹ rẹ, tí mo bẹ̀rù orúkọ rẹ, kí o sì jẹ́ kí n ṣe àṣeyọrí lónìí, kí n sì rí ojurere ọba.
Ọ̀la ni wọ́n máa sin olóògbé àgbàlagbà aṣíwájú yìí.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Femi Fani Kayode: Ọ yẹ kí wọ́n jó Fairstein ní iná ni 10 Òkùdu 2019 Oríṣun àwòrán, @Femi Fani Kayode Àkọlé àwòrán, Linda jẹ ẹlẹyamẹya to jẹ ọmọ ijọ Satani Ki n má purọ, ọmọ ijọ Satani ní Linda Fairstein -Femi Fani Kayode.
Babangida: Èròǹgbà ọmọ Nàíjíríà pọ̀ èyí tó ṣòro láti bá pàdé
Nítorí èyí, Ọlọrun, àní Ọlọrun rẹ, fi òróró yàn ọ́láti gbé ọ ga ju àwọn ẹgbẹ́ rẹ lọ.
Wo àwọn ohun tí a mọ̀ lọ́wọ́ yìí nípa ìṣẹ̀lẹ̀ ikú Barakat Bello Bamidele Olumilua fi òsèlú tiẹ̀ sin Ọlọ́run àti ènìyàn - Mimiko Ẹ̀wọ̀n gbére ni fún ẹnikẹ́ni tó bá fipá bánilòpọ̀ ní ìpínlẹ̀ Ọ̀ṣun June 21 ni pápákọ̀ òfurufú márùn-ún yóò di ṣíṣí padà - Ìjọba àpapọ̀ Wọn ni jiji ti Oloye Ajimọbi ji lọjọ naa lati ṣ'ẹmi ara to si pada ls si inu yara rẹ lo ba ṣubululẹ daku rangbọndan ki awọn ẹṣọ rẹ to gbee digbadigba lọ si ileewosan.
Electoral Commission INEC, Mahmood Yakubu, ti kede aare orile ede Naijiria , Muhammadu
Ẹni to bori: Mali Tunisia vs Morocco.
"'Penis Fish"", ẹ̀ja tuntun tó rí bí ǹkan ọmọkùnrin lùwẹ̀ jáde lórí òkun Kò sí ọkùnrin tí yóò fún obìnrin tó halẹ̀ bíi tèmi lówó - Lizzy Anjorin Èèmọ̀ rèé!"
Lọ́jọ́ àìríjẹ, lọ́jọ́ àìrímu, lọ́jọ́ àìrí-nǹkan-bora, tèmi yìí pọ̀ jù, jọ̀wọ́ bá mi wí fún Ọlọ́run Ọba kí ó ṣàánú kí ó fi mí sí ipò tí ó sàn ju eléyìí lọ.
Wọ́n sọ fún Joṣua pé, “Láìṣe àní àní, OLUWA ti fi ilẹ̀ náà lé wa lọ́wọ́, ìdààmú ọkàn sì ti bá gbogbo àwọn tí wọn ń gbé ilẹ̀ náà nítorí wa.
Oluwatoyin to ni esi ibo ẹgbẹrun meji-le-ọjileẹẹdẹgbẹta (2,540).
lati fi kun awon ẹsọ alaabo ti wọn sọ pe ki wọn lọ pese aabo ni awon gbogbo ile
Bótilẹ̀ jẹ pé ọ̀mì ni wọn gbá, ó dabi pé ǹkan si sẹnure díẹ̀ fún Chelsea Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Òfin ẹbọ sísun ni, ati ti ẹbọ ohun jíjẹ, ti ẹbọ ìmúkúrò ẹ̀ṣẹ̀, ati ti ẹbọ ìmúkúrò ẹ̀bi, ti ẹbọ ìyàsímímọ́, ati ti ẹbọ alaafia; 
2bn fún Obanikoro CBN: A ń pariwo tó lórí MMM fáwọn ọmọ Nàíjíríà Àǹfàní wà láti fí ìwé ìrìnnà ránṣẹ́ ṣùgbọ́n àwọn èèyàn kò lòó ni -NIS Sááju àsìkò yiìí ni Abdulrazaq ti ni ìpejọ́ náà ni ọwọ́ òṣèlú nínú, tó sì fẹ́ dènà ìyànsipò òun gẹ́gẹ́ bi gomina ìpínlẹ̀ Kwara, eyi to wáye ninu loṣù Kẹta ọdun 2019.
"England kéde ìséde ọ̀sẹ́ mẹ́rin míràn láti dẹ́kun ìtànkálẹ̀ Covid 19 Wo awọn iroyin manigbagbe to waye ni ọsẹ yii Wo ojú àwọn òṣèré yìí láì lo ""Make-up"" orí ìtàgé bó ṣe rí gẹ́lẹ́ Gbajúgbajà òṣèré tó ṣe fíìmù James Bond tí jáde láyé lẹ́ní ọdún 90 Oríṣun àwòrán, The Cable Àkọlé àwòrán, Lara awọn ọkọ ti wọn sọ pe awọn janduku bajẹ ni afin na O ni awọn tọọgi ọhun ""ti iye wọn to ogun ya bo afin oun lori ọkada pẹlu ibọn, ada, kondo atawọn ohun ija oloro miran"" lati ṣakọlu si afin naa."
Ti awọn oṣiṣẹ papakọ ofurufu ba ri wi pe oun wukọ lọpọ igba, wọn yoo lọ fi ẹ si yara iyasọtọ nibi ti ajọ NCDC yoo ti wa ṣe ayẹwo Coronavirus fun ẹni naa.
Revolution Now: Àwọn tó ń ṣèwọ́de ní ọta ìbọn ológun àti ọlọ́pàá kò dẹ́rù ba àwọn
Ńṣe ni sẹ́lẹ̀ru ṣọkọléètì ń ṣàn bí omi níbẹ̀.
O ni iwadii n tẹsiwaju lati ri pe awọn to wa nidi ọrọ yi foju ba ile ẹjọ.
Àsikò tó lati ṣe àyípadà, ki a jẹ ohun ti a ba gbin ni ilẹ̀ wa, nitori owó epo rọ̀bì ti gbogbo ilú gbójúlé ti fidi janlẹ̀.
Bakan naa lo ki awọn ẹsẹ fijilante nijọba ibilẹ Irepo, Olorunsogo ati Oorelope fun isẹ takuntakun ti wọn n se ninu Igbo ọhun lati sẹ eegun ẹyin awọn agbesunmọmi yii ati ifẹ ilẹ baba wọn ti wọn ni.
BBC Yorùbá bá òbí ọmọ àkanda kan sọ́rọ̀ lóri ìpàníja tí ń koju lóri ọmọ náà.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Àwòrán ìwọ́de NLC, TUC, ULC lónìí 8 Sẹ́rẹ́ 2019 Gbogbo ìpínlẹ̀ tó wà ní Nàíjíríà ní ìwọ́de tí àpapọ̀ àwọn òṣìṣẹ̀ fi ń jà fún ẹ̀kúnwó owó oṣù wọn ti wáyé Àkọlé àwòrán, Ipade to waye laarin minisita fọ̀rọ̀ osisẹ́ ati ijọba apapọ fori sanpọn nitori igun mejeeji ko lee fi ẹnu ọrọ jona.
Ile-ifowopamo Guaranty Trust Bank lo soke si bi 75k ti o si pajude si N49.
Ijọba ipinlẹ Ekiti ti gbe ileeṣẹ rẹdio People F.
95bn sórí reluwé làti Kano sí Niger Republic- PDP Eto BBNaija ti ọdun yii lami laaka, o kun fun oriṣiiriṣii iṣẹlẹ eyi to ti sọ ọpọ awọn oludije di ilumọọka.
Àwọn eniyan náà bá mú àkàrà tí wọ́n ti pò, ṣugbọn tí wọn kò tíì fi ìwúkàrà sí, wọ́n sì fi aṣọ so ọpọ́n ìpòkàrà wọn, wọ́n gbé e kọ́ èjìká.
"Ninu ọrọ tiẹ, Alaga igbimọ amuṣẹya fun aarun Covid-19, Boss Mustapha, sọ pe ""ki awọn ipinlẹ, ati ijọba ibilẹ o ṣe gbogbo eto to yẹ"", ki eto ẹkọ le tete bẹrẹ pada ninu ilera pipe."
"Mo bura pe igba akọkọ ree ti maa hu iru iwa yii.
gẹ ́ gẹ ́ bí ajàfún-mèkúnnù ( socialist ) ni mussohni ṣe wọ òṣèlú .
Àrà ni mí; èmi kìí ṣe Àrá -Àyánbìnrin Aralola Olamuyiwa Oṣù mẹ́fà ni mó fi kọ́ṣẹ́ oko nígbà ti mó d'Amẹrika-Olaniyi Balogun Bí wọ́n ṣe kó mi mọ́ rógà ìròyìn òfégè kan tó leè kóbá olùdíje Ààrẹ ẹgbẹ́ alátako Àwọn tó ṣiṣẹ́ pẹ̀lú Abacha ní kò kówó jẹ, ó fi pamọ́ fún ìdí kan ni- Sadik Abacha Ǹkan mẹ́jọ tó máa kọ́kọ́ ṣẹlẹ̀ kí olólùfẹ́ méjì tó pa ara wọn Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí 3 sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
Ati pé, fẹ́ràn ẹnìkejì rẹ bí ara rẹ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Aisha Buhari: Òlùrànlọ́wọ́ pàtàkì fi orúkọ mi gba owó 25 Owewe 2018 Oríṣun àwòrán, @aishambuhari Àkọlé àwòrán, Aisha Buhari Ìyàwó ààrẹ orílẹ̀èdè Nàìjíríà, Aisha Buhari ti pàṣẹ pé kí ajọ ọ̀télẹ̀múyẹ́ DSS gbé olùrànlọ́wọ́ pàtàkì ti mọlé rẹ̀ lórí ẹ̀sùn pé ó jà a lólè biliọnu meji aabọ Gẹ́gẹ́ bí àwọ́n tó mọ̀ nípa ìṣẹ̀lẹ̀ náà ṣe fi tò ìwé ìròyìn Premium Times létí, ìyàwò ààrẹ ń fi ẹ̀sùn kan pé ṣe ni arákùnrin náà fí orúkọ òun jalè.
Ọ̀rọ̀ tí kò fìdí múlẹ̀ ni pé àwọn kan tó ti gba ìwòsàn tún padà ní aarun náà, a lè sọ pé bóyá ayẹwo tí wọn koko ṣe ni kò múná doko tó kí wọn tó sọ pé wọn kò ní aarun náà mọ.
Eroja Mitochondria ko ni ṣiṣẹ mọ Ẹya ara ti wọn n pe ni Mitochrondria lo n fun awọn sẹẹli l'agbara, ṣugbọn wọn maa n sọ agbara ti wọn naa nu bi ọdun ṣe n gori ọdun.
Ninu ọrọ tirẹ, ẹgbẹ awọn oludaleeṣẹ silẹ lorilẹede Naijiria,, MAN ṣalaye pe igbesẹ naa yoo mu inira ba awọn ileeṣẹ kerejekereje to ṣẹṣẹ n gbimọran ati ri ẹsẹ walẹ.
Onimọ nipa eto ati asa ilẹ Yoruba, naa wa ni ila kikọ tun n pa owe fun awọn ọmọ ilẹ Yoruba pe ki eniyan to le jọrọ, yi o ṣiṣẹ takuntakun.
Àkíyèsí:- Mo dúpẹ́ ohun ìkọ̀wé tí ẹ fi ránṣẹ́ sí mi.
Yipeeeeee"" pẹlu aworan ijo lẹsẹ ni gbajugbaja oṣere, Toyin Abraham fi ṣafihan ajọyọ rẹ loju opo instagram."
Bẹ́ẹ̀ ni Saulu, àwọn ọmọ rẹ̀ mẹtẹẹta ati àwọn ará ilé rẹ̀ ṣe kú papọ̀.
Ẹ wá jogún ìjọba tí a ti pèsè sílẹ̀ fun yín kí á tó dá ayé.
mọṣalaṣi Ile Igbimọ Aṣofin naa, ṣoju fun.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Kemi Lala: mo ń gbìyànjú láti mú inú òbí mi dùn Araale: Ṣe Seyi ti fẹyawo atipe ṣe ọmọ alawọdudu ni obinrin naa.
Ìmọ̀ràn náà dára lójú Farao ati àwọn iranṣẹ rẹ̀.
Peteru bá sọ fún un pé, “Iniasi, Jesu Kristi wò ọ́ sàn.
Awọn agbegbe to ni awọ pupa ni atẹgun wọn buruju.
Fun Degema: AAC ni ibo 5071, nigba ti PDP ni ibo 12133.
Báyìí ni Ìjàpá fi ẹ̀tanú àti ìwà ọ̀dàlẹ̀ pa ara rẹ̀ tí Ìgbín sì ń jẹ ayé rẹ̀ lọ níbi tí ó tutù títí di òní yìí.
Ìfọwọ́sowọ́pọ̀ nìkan ni ọ̀nà abáyọ sí ìṣòro Nàìjíríà- Olusegun Obasanjo Buhari, o ṣẹ ilẹ̀ Yorùbá púpọ̀, ló àyájọ́ ìbí rẹ̀ láti tọrọ àforíjìn - PDP Ìtura ìgbà díẹ̀ ni bọ́dà tí ìjọba ṣí padà, kò lóòre nínú - Onímọ̀ ọrọ̀ ajé Wo ìdí tí ààrẹ Buhari kìí fi ṣe ẹ̀dà Jubril láti Sudan Àwọn ohun kàyéèfì tó le mú kí ọmọbìnrin ní oyún ìju Atẹjade naa, ti wọn fi ẹda rẹ sọwọ sawọn gomina yoku nilẹ Kaaro Oojire, wa kọminu lori iwa ipaniyan, ijinigbe, ifipabanilopọ atawọn iwa ọdaran mii, to n gogo nilẹ Yoruba.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Africa Eye: Wo ìtàn ìyá kan ìyá kan àtàwọn olè ajọ́mọgbé tó n ta ọmọ ní Kenya Akẹ́kọ̀ọ́ 333 ni a kò tíì le sọ nípa wọn nílé ẹ̀kọ́ Kankara Katsina- Ìjọba Nàìjíríà Oríṣun àwòrán, @Aminu Bello Masari Akẹ́kọ̀ọ́ 333 ni a kò tíì le sọ nípa wọn nílé ẹ̀kọ́ Kankara Katsina- Ìjọba Nàìjíríà Iroyin tuntun nipa awọn akẹkọọ girama GSSS Kankara Katsin nipe pupọ ninu awọn akẹkọọ naa ni ko ti i di riri lẹyin ọjọ kẹta.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Nigeria movie industry: Àgbà òṣèré, Lere Paimo ní àìgbọràn ló ń da ọ̀pọ̀lọpọ̀ àwọn O ni ki wọn maṣe jẹ ki yoroyoro aye tan wọn jẹ, ki wọn si gbagbọ pe ogo Ọlọrun nikan lo le gbe wọn de ipo ọla.
”Ṣugbọn Amnoni kọ̀, kò gbọ́ tirẹ̀.
Iya onile rẹ, Madam Chen lo ṣafihan aworan bi iyara ogbontarigi sọrọsọrọ lori ayelujara naa.
A wa n gbadura pe ki ọba oke tẹ ọlọla Oyinkansola Ajasa aya Abayomi si afẹfẹ rere.
Ó dáwọ́ ogun dúró ní gbogbo ayé,ó ṣẹ́ ọrun, ó rún ọ̀kọ̀,ó dáná sun kẹ̀kẹ́ ogun.
 O ni pe eleyii si ti di aṣa awọn gomina bayii
Ní àkókò náà,orin tí wọn óo máa kọ ní ilẹ̀ Juda ni pé:“A ní ìlú tí ó lágbára,ó fi ìgbàlà ṣe odi ati ibi ààbò.
Ọlọrun wà pẹlu wa, òun fúnrarẹ̀ ni aṣaaju wa.
Ohun ti a gbọ ni pe aisan ranpẹ lo ṣe Pepperito ki o too jẹ Ọlọrun nipe.
Kọmisana feto iroyin Kano Mohammed Garba sọ pe nitori pe awọn fẹ dena itankalẹ Covid-19 lawọn fi ṣe bẹ.
Eléyìí ni ẹni ti ń jẹ́ Ẹyin-Ológbò.
 kò sí abala kan nínú ìgbésí ayé ọmọnìyàn tí a kò ti lè kọrin .
0 420294 Orilẹede Sweden 7067 70.
Superiority A ko le sọ daju pe gbogbo orin to kọ niyii.
Bí ẹ kò bá dárí ji eniyan, Baba yín ọ̀run kò ní dárí ẹ̀ṣẹ̀ yín jì yín.
Èrò ti ó n kú ni ilẹ̀ Aláwọ̀-dúdú nitori ọ̀nà ti kò dára, a i si ilé-ìwòsàn gidi, a i ni ohun amáyédẹrùn bi omi, iná mọ̀nàmọ́ná kò jẹ ki Aláwọ̀-dúdú Àméríkà lè fi orisun wọn yangàn.
Coronavirus: Oṣù kan gbáko lèèyàn 16 mílíọ̀nù yóò fi wà lábẹ́ ìséde ni Italy
A wá di ẹni ẹ̀gàn títí di òní.
Kí a ma sa ba ọ̀rọ̀ náà gùn lọ títí, nígbà ti o tó bí oṣù kan tí mo ti dé ìlú náà, èmi àti àbúrò mi múra, ó di ilé.
Aisaya ṣá sọ ọ́ pé, “Oluwa, ta ni ó gba ohun tí a sọ gbọ́?
Ibadan: Olóòlù kò ni kọ́ja agboolé rẹ̀ fún ọdún eégún ìlú Ibadan tọdún yìí
Apeja orukọ rẹ ni Akinwande Oluwole Babatunde Soyinka ṣugbọn ti gbogbo agbaye m si Wole Soyinka.
AFCON 2019: Ìdíje ife ẹ̀yẹ láàrin orílẹ̀èdè Áfíríkà
jogun ami eye yii lowo atamatase agbaboolu Chelsea, N’Golo Kante, ti o gba
mambila Àwọn ènìyàn yìí wà ní orílẹ ̀ èdè nigeria ati kameroon , wọ ́ n tó ẹgbẹ ̀ rún lọ ́ na mẹ ́ ẹ ̀ dọ ́ gbọ ̀ n wọ ́ n sì múlé ti àwọn ènìyàn bíi kaka , tikong àti bafum .
Sùgbọ́n nígbà tí BBC kan sí gómínà náà láti mọ ǹkan tí ó ń ṣẹlẹ̀, olùrànlọ́wọ́ pàtàki rẹ̀ lórí ọ̀rọ̀ ìfitónilétí, Ebere Nzewuji, ni kò rí bẹ́ẹ̀.
’ Ìgbà ti Fìlásayépọ̀ sì wí báyìí pé, Ìgbà tí ẹ mọ̀ pé ipá yín kò níí ka, ki ni ẹ fẹ́ ẹ sí?
Lẹhin ti àwọn Ìjọba Ológun àti Òṣèlú fi ipò wọn ba ilú jẹ́ tán, bi ori bá fọ́ wọn, wọn á gba ọ̀nà Òkè-Òkun lọ fún ìtọ́jú, dipò ki wọn tú ile-iwé ṣe, wọn a fi owó ti wọn ji pamọ́ rán ọmọ lọ si Òkè-Òkun fún ẹ̀kọ́ ti ó yè kooro.
Gbogbo mààlúù tí wọ́n mú wá fún ọrẹ ẹbọ sísun jẹ́ mejila ati àgbò mejila, ọ̀dọ́ àgbò mejila ọlọ́dún kọ̀ọ̀kan, pẹlu ẹbọ ohun jíjẹ.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Àmì ìdánimọ̀ ni aṣọ àti bàtà rẹ jẹ́ Adajọ Hajiya Fadile Dikko sún ìgbẹ́jọ́ naa siwaju nigba ti ọ́gá ọlọ́pàá Sani Ado beere fun asiko lati ṣe iwadii siwaju síi.
Irọrun ni Joe Biden fi yẹ aga mọ Trump nidii Ohun akọkọ to lee ṣẹlẹ ni ki Joe Biden jaweolubori pẹlu irọrun.
"Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: ""Ọ̀pọ̀ ń gbàdúrà kí àwọn ní HIV báyìí"" Beautiful Nubia - Orin mi kìí ṣe orin lásán Ìjìyà síse ayédèrú isẹ́ onísẹ́ kò kún tó - Jide Kosọkọ Samuel Ladoke Akintọla jẹ́ Agbẹjọ́rò àti Akọ̀ròyìn tí ọ̀rọ̀ dá lẹ́nu rẹ̀ Àràbarà pósí rèé, ibùgbé ìkẹyìn tó jẹ ojú ní gbèsè Ebi sọ ìyá àgbà di awa kẹ̀kẹ́ Maruwa Hubert Ogunde rèé, baba àwọn òsèré tíátà Ọkọ iyawo ẹlẹkun, ẹni to ka ọpọ ohun tawọn araalu sọ nipa aworan naa sita, wa tako ero ọpọ eeyan nipa rẹ."
bi o ba ni irufẹ iba coronavirus, iwọ naa yoo mọ.
Gẹgẹ bi iroyin ṣe sọ awọn ajinigbe lo gbe wọn lasiko ti wọn n rinrin ajo lẹnu oko owo wọn.
37 Àti pé sọ̀rọ̀ pẹ̀lú òmìnira sí gbogbo ènìyàn; bẹ́ẹ̀ni, wàásù, gbani níyànjú, kéde òtítọ́, àní pẹ̀lú ariwo, pẹ̀lú ìró ìdùnnú, ní kíkígbe—Hòsánnà, Hòsánnà, ìbùkún ni fún orúkọ Olúwa Ọlọ́run!
29 Òkùdu 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 30 Òkùdu 2020 Oríṣun àwòrán, Ajimobi lives on Ọrọ ti n ba ọrọ bọ, eegun alare lori igbesẹ ti gomina Seyi Makinde gbe, nipa fifun ẹbi Abiola Ajimobi laaye lati sin oku si ilẹ ijsba GRA, ti ofin ko faaye gba.
Lori iye oṣu ti ijọba yoo ran wọn lọwọ lati san, Ọgbẹni Otubela sọ pe oun ko ti i le sọ, nitori pe ko si ẹni to mọ igba ti Coronavirus yoo to o wa si opin.
Àwọn ọmọ Lefi dúró pẹlu ohun èlò orin Dafidi, àwọn alufaa sì dúró pẹlu fèrè.
Ìlànà Ijó ìta-gbangba náà kò sọnù ní ara Super Blue, ẹni tí ó kọ “Get Something and Wave”, orin tí ó jáwé olúborí nínú Ìwọ́de Ojúnà ọdún-un 1991.
" Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Lockdown in Africa: Nínú Ọlọ́pàá àti Coronavirus, èwo gan an laráàlú ń bẹ̀rù jùlọ?
Bí wọ́n ti dúró tí wọn kò mọ ohun tí wọn yóo ṣe, bẹ́ẹ̀ ni àwọn ọkunrin meji kan bá yọ sí wọn, wọ́n wọ aṣọ dídán.
Gbogbo ilẹ̀ náà ni Joṣua gbà: ó gba àwọn agbègbè olókè, àwọn tí wọ́n wà ní Nẹgẹbu, gbogbo àwọn ìlú tí ó wà ní ilẹ̀ Goṣeni, àwọn ìlú tí ó wà ní ẹsẹ̀ òkè, àwọn tí ó wà ní Araba, ati gbogbo àwọn ìlú tí ó wà lórí àwọn òkè Israẹli ati ẹsẹ̀ òkè rẹ̀.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Obateru Akinruntan: Wíwá ohun tá jẹ títí láé ló gbé wa kúrò nílé Ife Lẹyin wakati mẹrinlelogun ti idajs naa waye, ni akọtun fidio miran tun lu sori ayelujara ninu eyi ti Sẹnatọ Elisha Abbo ti n kesi Naira Marley pe kawọn lọ silu Eko, ls se ariya fun Lekan.
Ṣaaju asiko yii, Igbakeji Aarẹ, Mike Pence sọ pe, ofin ti wọn fi de awọn arinrinajo lati awọn orilẹ-ede to wa ni ilẹ Yuroopu yoo kan ilẹ United Kingdom ati Ireland lọjọ Iṣẹgun.
Ni bayii ti aarẹ Muhammadu Buhari si ti bẹrẹ saa keji rẹ lori aleefa Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí kan sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
 Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Bọ́ síta láti ṣe ìwọ́de mọ́ ìjọba Nàìjíríà lónìí, ko rugi oyin - Iléeṣẹ́ ọlọ́pàá Ẹ̀yin ọlọ́pàá 10,000 tí ọ̀gá ọlọ́pàá gbà ṣíṣẹ́ ní 2019, ẹ padà sílé - Iléẹjọ́ pàṣẹ Ọjọ́ ìbí bàbá mi ni aàrùn ọkàn ṣekúpa màmá mi lójijì- Davido Ìjọba Kwara kéde ọjọ iwọlé àwọn akẹkọọ lẹyìn ìséde Covid 19!"
Ń se ni ojú òpó Twitter kún àkúnfàya nípa ìsẹ̀lẹ̀ yìí.
Olórí òṣìṣẹ́ ìjọba àpapọ̀ ni Umar lo mójú tó ìdúnadúrà naa lásìkò to jẹ́ akọ̀wé ilé iṣẹ́ ǹkan ọ̀gbìn Bákan naa lo ní akọ̀wé ọ̀un tún gbé iṣẹ́ gbígbẹ́ kànga ìgbàlódé méje síta ni bilionu kan ó lé dí lọ́nà àìtọ́.
Nigba to n fesi lori ọrọ Oyedepo naa, Ifedayo Olarinde, ti ọpọ eeyan mọ si Daddy Freeze ni ọrọ radarada ni ojisẹ Ọlọrun naa kọ, ti ko si bojumu.
Ọkùnrin kan pa ara rẹ̀ sínú ọgbà àjọ TRACE tó n mójútọ ìrìnnà ọkọ̀ nípìnlẹ̀ Ogun Ǹjẹ́ o mọ̀ pé ètò ìdìbò kan wà tí erin àti òkúta Dáyámọ́ǹdì leè yí èsì rẹ̀ padà Kí ló dé tí ìjọba ìpínlẹ̀ Oyo kéde fífagilé Sáà ètò ẹ̀kọ́ kẹta fún àwọn akẹ́kọ̀ọ́?
 Ó ní òun ti parí ètò pèlú ilé ise ' gazola nig .
Kì í yọ kọ́kọ́rọ́ ojú kékeré séèfù.
Nígbà tí ọjọ́ bẹ̀rẹ̀ sí pofírí, wọ́n lọ sí ibùdó ogun àwọn ará Siria, nígbà tí wọ́n dé ibẹ̀, wọn kò rí ẹnìkan kan.
Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí 5:44 Fídíò, Alaafin: Olori Aanu Adeyemi aya Oba Lamidi Adeyemi ti ìlú Oyo ní ohun tó bá kúkú wu ọmọ láti jẹ kìí.
Kí ló yẹ ká se sí ẹkùn tó pa ènìyàn márùń?
Wọn ge ọwọ ọmọ ẹlẹgbẹ okunkun mii kan, Sikiru Mufutau, to si ku, bẹẹ ni wọn ba ọpọ dukia jẹ.
“O kò gbọdọ̀ jáfara láti mú ninu ọpọlọpọ ọkà rẹ ati ọpọlọpọ ọtí waini rẹ láti fi rúbọ sí mi.
Eton tọrọ àforíjìn lọ́wọ́ akẹ́kọ̀ọ́ Nàíjíríà lórí ìwà ẹlẹ́yàmẹ̀yà
Ìgbé-ayé irú ẹni bẹ́ẹ̀ sì di titun.
Buhari: Iléeṣẹ́ ọlọ́pàá àti ológun ti kùnà lórí ètò ààbò Nàìjíríà
 mussolini àti ìgbìmọ ̀ fascist party ni wọn jọ ń darí italy .
Tẹgbọn-taburo se igbeyawo ni Anambra Lérò Dókítà Kúnlé Òbílàdé, tíí se onísègùn òyìnbó, ó ní àmúsẹ òfin yìí yóò lẹ́yìn tó burú fún ìlera àwọn ọmọ Nàíjíríà.
Wọn si tun lẹtọọ lati ba Fayemi wi, ki wọn si tun gba a nimọran to ba tasẹ agẹrẹ.
Ó ní ilé làá wò, ká tó sọ ọmọ ní orúkọ̀, nítorí náà, ó yẹ káwọn òsèré náà máa kọ́kọ́ se àkíyèsí inú ilé tí wọn ti jáde wá, kí wọn tóo máa se yàǹga lórí ìtàkùn àgbáyé.
Abuja Nightclub: Àwọn ọmọge wọ gàù nítorí asọ péńpé
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Yollywood òṣèrè, Dayọ Amusa: Ko si eni ti ko ni baba isalẹ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Yollywood òṣèrè, Dayọ Amusa: Ko si eni ti ko ni baba isalẹ 13 Ẹrẹ̀nà 2018 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 30 Ìgbé 2020 Osere tiata Dayo Amusa gboriyin fun awọn to n parọ, o ni isẹ ribiribi ni wọn n se.
Ènìyàn 397 míràn ló tún ṣẹ̀ṣẹ̀ lùgbàdì ààrùn Covid-19 ní Nàìjíria Ajọ to n gbogun ti ajakalẹ aarun lorilẹ-ede Naijiria, NCDC ti kede pe eeyan 397 miran ti kun iye awọn to ti ni aarun COVID-19 ni Naijiria.
Reyder kọ nípa ìṣẹ̀lẹ̀ náà sójú ìwé Facebook rẹ̀.
Nígbà ayé Serubabeli ati Nehemaya, gbogbo àwọn ọmọ Israẹli a máa fún àwọn akọrin ati àwọn olùṣọ́ ẹnu ọ̀nà ní ẹ̀tọ́ wọn ojoojumọ, wọn a máa ya ìpín àwọn ọmọ Lefi náà sọ́tọ̀, àwọn ọmọ Lefi náà a sì máa ya ìpín àwọn ọmọ Aaroni sọ́tọ̀.
Aarẹ Muhammadu Buhari ti ni, kii ṣe wi pe oun ko gbe igbese to lami-laaka lori isekupani awọn Fulani Darandaran nitori pe oun jẹ Fulani ni orilẹede Naijiria.
Ile-ise alabo ile biritiko naa salaye pe, iko mewa ninu ida ogorun-un ado-oloro naa lo ko lati bu gbamu lasiko ogun WWII yii, eyi ti o si soro lati mo oye ti o ku ti a ti sawari re.
eko awon oluko bi  won se pada senu ise
Tabi bí ó bá bèèrè ẹyin tí ó jẹ́ fún un ní àkeekèé?
Oríṣun àwòrán, Paradisenews Ajagunode fikun pe igba karun tawọn janduku naa yoo wa ka oun mọ aafin ree lati igba ti aawọ ilẹ naa ti bẹrẹ.
Ẹkọ to wa lara ogun Agbekoya: Ẹkọ akọkọ ta ri kọ lati ara ogun Agbekoya ni pe, ifikunlukun, asọyepọ ati idunadura ṣe pataki ju ogun jija lọ nitori nigbẹyin ogun, wọn yoo pada joko yanju aawọ naa ni.
Lai Muhammed, ninu ọrọ rẹ ni, kan saara si aya gomina ipinlẹ Ogun, Olufunsọ Amosun, to gbe owo kalẹ lati se onigbọwọ ere ati orin itan igbe aye Mọremi Ajansoro.
" Oríṣun àwòrán, @aishambuhari Awọn kan joko sinu ile wọn jẹjẹ ni lasiko ta n se wahala eto idibo, ṣugbọn niṣe ni wọn ransẹ pe wọn lati wa jẹ olori ileeṣẹ ijọba tabi di minisita.
N1000 tí Ọlọ́pàá ń gbà lẹ́nubodè wa làrùn Coronavirus fi ráyè wọlé-Ìjọba ìpínlẹ̀ Oǹdó Gomina Okowa sọ pe wọn yoo bẹ̀rẹ̀ si ni pin oúnjẹ fun araalu laarin wakati mejilelaadọrin.
A ti gùnlé ìyanṣẹ́lódì ọlọ́jọ́ gbọọrọ ní ìpílẹ̀ Eko- NUPENG A ti bẹ̀rẹ̀ ìwádìí lórí ibì tí owó tí àwọn adigunjalẹ̀ gbé ní banki Okeho wọ̀lẹ̀ sí- Ọlọ́pàá Diezani gan an ní Hushmummy tó ń bú àwọn Yahoo boys- Àwọn Ọmọ Naijiria lórí Twitter Àwọn adarí lágbàyé ṣèpàdé láti ṣèrànwọ́ fún Lebanon lẹ́yìn ìbúgbàmù tó pa ènìyàn 158 Oríṣun àwòrán, Just Event Online Nigba to n fesi si iṣẹlẹ yii, aya Abdulrazaq kede loju opo Twitter rẹ pe oun yoo ran tiya- tọmọ lọwọ lati gbe igbe aye to dẹrun.
’’Ogbeni Shehu wa bu enu ate lu awon oro lorisirisi to gbode kan pe, igbese naa waye lati gbogun ti awon egbe oselu alatako tabi awon eniyan jankan-jankan lorile-ede yii.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìtàn Mánigbàgbé: Mọrèmi Àjàṣorò fi ọmọkùnrin rẹ̀ kanṣoṣo rúbọ fún odò nítorí ìlú 20 Èrèlè 2019 Oríṣun àwòrán, Ooni Adeyeye Ogunwusu, Ojaja 11 Ilu Ile Ifẹ ni orirun ilẹ Yoruba, nibiti ojumọ ti n mọ waye.
Fún nǹkan bí ogoji ọdún ni ó fi ń kẹ́ wọn ní aṣálẹ̀.
Ó jẹ́ ẹni tí a nílati máa rántí láti ìran dé iran wa.
Igbimo ohun tun so ninu oro won pe, iyansipo naa yoo se iranwo, yoo si tun kun awon akegbe re lowo lati tun bo tepamose si.
''Loni mo darapọ mọ ẹgbẹ APC ati aarẹ Muhammadu Buhari lati jijọ pawọpọ gbe Naijiria ga'' Àríyá yá!
Oríṣun àwòrán, @comrade_ahmad Kọmiṣọna ọlọpaa n'ipinlẹ Ọyọ si tete gbe ikọ ọlọpaa SARS, ọlọpaa kogberegbe MOPOL at'awọn ọlọpaa lagbegbe naa dide lati lọ koju wọn Ki wọn si tọ ipasẹ awọn iyoku wọn lọ.
“Nígbà tí aadọrin ọdún Babiloni bá pé, n óo mójú tó ọ̀rọ̀ yín, n óo mú ìlérí mi ṣẹ fun yín, n óo sì ko yín pada sí ibí yìí.
- Àjọ ajàfẹ́tọ̀ọ́ ọmọdé Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Olaitan Olamide: mò lè má nílò ìwé ẹ̀rí mi tí mo bá parí ní LASU 'Mi o lori iṣẹ' Lọdun 2017 ni Ọgbẹni Chekole kẹkọọ gboye to si fẹ gun le wiwa iṣẹ loju ẹsẹ.
Àwọn olùkọ́ fásitì lẹ̀dí àpò pọ̀ mọ́ olóṣèlú láti ṣèrú ìbò - Jega ‘Ìjọba Buhari kò lé è dá ààbò bo àwọn ará ìlú’ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Èmi ò kí ń lu ìyàwó mi' Tani Ọba Oba Folagbade Olateru-Olagbegi III waja?
Koda akọbi ọmọ rẹ to ti n pe ọdun marun lọ bayii ko tii wọ ile iwe tori baba kọ lati ran an lọ.
“Aseyori wa lori eto idanilaraya ati ere-idaraya lagbaye le silekun ibasepo ti o yekooro larin orile-ede Naijiria ati awon orile-ede agbaye yooku, yala lori eto oro aje abbl,”O fikun-un pe,”o se pataki fun awon orile-ede patapata, paapajulo Naijira lati samulo awon ohun elo tabi ebun ti o ni fun idagbasoke ati sise amulo re lati mu ibasepo ti o donmonron jeyo larin orile-ede yooku, ti awon ona miran ba ko lati sise.
Ṣugbọn bi wọ́n ba rii pe o jẹbi, oun gan gba pe ki wọn fi jofin.
Nígbà tí gbogbo àwọn ọba tí wọ́n wà ní agbègbè olókè, ní òdìkejì odò Jọdani ati àwọn tí wọ́n wà ní pẹ̀tẹ́lẹ̀ ní etí òkun Mẹditarenia ní agbègbè Lẹbanoni, àwọn ará Hiti, àwọn ará Amori, àwọn ará Kenaani, àwọn ará Perisi, àwọn ará Hifi, ati àwọn ará Jebusi, gbọ́ nípa ìṣẹ́gun àwọn ọmọ Israẹli, 
Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Oral Sex: Àwọn tó kó àìsàn náà máa ń rí oje lójú ara wọn tó ń rùn bí ẹja29 Ògún 2020 Fídíò, Sex: Ìye ìgbà tóo ní ìbálòpọ̀ kọ́ ló ń jẹ́ kí abẹ́ obìnrin fẹ̀2 Ògún 2020 Fídíò, Africa Eye: Olùkọ́ méjì ní fásitì Eko àti Ghana lùgbàdì ọ̀fíntótó BBC lórí ìwà ìbàjẹ́7 Ọ̀wàrà 2019 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 3 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 5 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
  Ó dàbí pé àwọn oní òwò oúnjẹ agbègbè yìí ti ṣe ìwádìí ibi ti ebi àbí òngbẹ á ti bẹ̀ ẹ̀ rẹ̀ sí ní máa dàmú àwọn onírìnàjò.
 Nigba ti a ba fi dandan si rira iresi wa lati Kebbi, Kano, Jigawa ati Ebonyi, o di dandan ki ise po si lawon ipinle to ba ti n pese iresi.
O ni ti ijọba oun ba ṣe bẹẹ, awọn ẹranko igbẹ to wa ni ọgba naa yoo ni itọju daradara.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Conte gbodo tun iko Chelsea se ki won too koju West Brom Lẹyin eyi, ẹgbẹ agbabọọlu Watford yoo lọ si West Ham ni ọjọ abamẹta nigba ti ẹgbẹ agbabọọlu Chelsea yoo gbalejo ẹgbẹ agbabọọlu West Brom.
Bamigbetan sọ pe ofin naa f'aṣẹ fun awọn ile-ẹkọ giga ni ilu Eko lati gba kirẹdiiti ni ede Yoruba gẹgẹ bi ọkan lara kirẹdiiti marun ti wọn nilo lati wọ ile iwe giga.
Jẹ́ kí á pàgọ́ mẹta, ọ̀kan fún ọ, ọ̀kan fún Mose ati ọ̀kan fún Elija.
Àlàó ni ó kó ogóje náírà (N140.
Fayemi fojú Alufa to fipa bá ọmọde lòpọ̀ síta l'Ekiti Ọwọ tẹ alufa lori ẹsun ijọmọgbe l'Ọsun Biodun Fatoyinbo fi ipò sílẹ̀ lorí ẹ̀sùn ìfipábánilòpọ̀ Agbẹjọro ọgbẹni Texeiria sọ pe awọn yoo tako idajọ yi toun ti pe awọn ẹsun miran ṣi wa nilẹ́ ti wọn fi kan an.
Ile isẹ irinna lorilẹ-ede Naijiria ni awọn ti setan lati gbe orisirisi iwe irinna tuntun jade fun awọn eniyan.
Afurasí afipábánilópọ̀ kàgbákò, obìnrin tó jà lólè fi eyín gé nǹkan ọkùnrin rẹ̀ jábọ́ lásìkò ‘Blow Job’ Àwọn ọba alayé, Mínísítà àti gómìnà nílẹ̀ Yorùbá ṣèpàdé pẹ̀lú ìjọba àpapọ̀, àbọ̀ rèé Iná ṣẹ́yọ nílé ìtajà aya Ajimobi lẹ́yìn ọjọ́ mẹ́ta tó jáde opó Amọ nigba ti ikọ iroyin BBC se abẹwo sibudo itaja naa loni, a se akiyesi pe aayan ti n lọ lati se atunse abala ile itaja to jona naa.
Bakan naa ni Shina Rambo ni eyi to ba oun ninu jẹ julọ ni pe oun ba iya oun lopọ ri, igbakuugba ti oun ba si foju kan iya arugbo naa, ni ibanujẹ maa n gba ọkan oun.
wọ ́ n dá àjọ ( leventis foundation ) ní ọdún 1979kalẹ ̀ ẹ ́ yìn tí a.
Awon olopaa ya wo ibi ti awon alatako ti iye won n lo bi egberun kan si egberun meji lojo-Aiku, ti won si da ipade naa ru.
Ni bayi, Adesanya ṣi ni o jẹ olubori Middle Weight Champion of the World.
Wọn fi ẹsun kan ile iṣe epo Eni ati Shell pe wọn mọ pe owo riba ni owo ti wọn san fun orilẹede Naijiria.
Nígbà tí wọ́n rí i, wọ́n wí fún un pé, “Gbogbo eniyan ní ń wá ọ.
Ninu atẹjade kan to fi sita, Ọọni Ogunwusi ni bi o ti pọn dandan pe ki ijọba daabo bo awọn dukia ilu, ko yẹ ko jẹ awọn ologun to yẹ ko maa daabo bo araalu, ni yoo wa yipada maa yinbọn pa wọn.
Wọn fikun wi pe, awọn ijọba orilẹede Naijiria lọpọ igba, ti fi awọn oṣiṣẹ silẹ lati ri daju wi pe wọn wa ni alaafia lẹnu iṣẹ, ti wọn si n fi ẹmi ẉon wewu, eleyii ti ko yẹ ko ri bẹẹ.
Ìyìn ni fún OLUWA Ọlọrun rẹ, ẹni tí inú rẹ̀ dùn sí ọ, tí ó sì fi ọ́ jọba Israẹli.
Ṣaaju isinku lawọn mọlẹbi ke gbajare pe ki ijọba wadii awọn to sẹku pa awọn ọmọ wọn.
Èrò ọkàn mi ni láti gba owó díẹ̀ ki sì ba àwọn fótò náà jẹ́.
Aarẹ ni o ṣe pataki lati ṣe awọn eto ti yoo jẹ itẹsiwaju 'Vission 2020' eyii ti yoo wa sopin lọdun yii.
 ""O jẹ ibanujẹ ọkàn pe ọmọ naa ti n hu iwa bi ewurẹ, nitori pe o ti pẹ ni aarin wọn."
Ní àpárá, Ọbásanjọ́ ti Goodluck Jónátánì lẹ́yìn nínú ètò ìdìbò tí ó wáyé ní ọdún 2011.
Gègé ṣíṣẹ́ a máa yanjú ọ̀rọ̀a sì parí gbolohun asọ̀ láàrin àwọn alágbára.
Ó dá wọn lóhùn, ó ní, “Kí ni mo ṣe lẹ́gbẹ̀ẹ́ èyí tí ẹ̀yin ṣe?
Ijọba Eko ti sọ pe ohun yoo gbe igbimọ kan dide lati ṣiṣẹ lori ohun ti ẹgbẹ NEPENG fẹ ki ijọba ṣe fun wọn.
Nigba to ya ni Seriki Abass pada sorilẹede Naijiria lẹyin to ti se adehun pẹlu ọga rẹ, Williams pe oun yoo jẹ alabasisẹpọ rẹ ninu owo ẹru.
“Lẹ́yìn ìgbà tí ó bá ti parí ṣíṣe ètùtù fún ibi mímọ́ náà, ati fún Àgọ́ Àjọ náà, ati pẹpẹ náà, yóo fa ààyè ewúrẹ́ náà kalẹ̀.
"'Ǹkan ìṣeré ìbálòpọ̀ mi ńpaná iṣẹ́ mọ́ mi lára' ""Àlùfàá méjì wà lára àwọn mẹ́rin tó fi ipá bámilòpọ̀"" Àwọn ọ̀nà tí obìnrin fi le gbádùn ìbálòpọ̀ Awọn oniroyin l'abẹle sọ pe oju ẹsẹ ni obinrin naa ku nitori pe ori lo kọkọ fi gba ilẹ, ṣugbọn ọkunrin naa ye nitori pe bo ṣe jabọ ni tiẹ, ori obinrin naa lo jabọ le ati koriko to wa ni tosi."
Ṣemaaya, akọ̀wé, ọmọ Netaneli, láti inú ẹ̀yà Lefi, ni ó kọ orúkọ wọn sílẹ̀ níwájú ọba ati àwọn ìjòyè, ati Sadoku, alufaa, ati Ahimeleki, ọmọ Abiatari, ati àwọn baálé baálé ninu ìdílé àwọn alufaa, ati ti àwọn ọmọ Lefi.
Yatọ si ọrọ Gomina to ni ko dari ẹgbẹ bo ti ṣe yẹ, Abbo ni Aarẹ Buhari jẹ iwuri foun nipa pe o kara mọ arisiki awọn ara ilu ju gbogbo awọn aarẹ ti tẹlẹ lọ.
" O tẹsiwaju pe ẹni to wa nidii ọrọ naa ti mu awọn agbofinro lọ si ọdọ awọn to fi eeyan joogun ati pe wọn ti wa ni atimọle.
Ṣugbọn Sedekaya ati àwọn ẹmẹ̀wà rẹ̀ ati àwọn eniyan náà kò pa ọ̀rọ̀ tí OLUWA ní kí Jeremaya wolii sọ fún wọn mọ́.
A kò lágbára tó láti gbógun ti àwọn eniyan náà, wọ́n lágbára jù wá lọ.
Ẹ sọkún tẹ̀dùntẹ̀dùn, ẹ̀yin ọkọ̀ ojú omi Taṣiṣi, nítorí àwọn ilé ìṣọ́ yín tí ó lágbára ti wó.
Báwo ni mo ṣe lè dá nìkan dàyàkọ ìnira yín ati ẹrù yín ati ìjà yín.
Ilé ẹjọ́ tó ga jùlọ ni UK ti pàṣẹ pé títì tí Johnson ti ilé aṣòfin kùnà Awọn alakoso NYSC ni awọn ayederu akẹkọjade Fasiti to wa lati oriṣiriṣi Faisiti kakiri orilẹ-ede yii ni ajọ ọhun ti le kuro ni ipagọ awọn agunbanirọ, ti wọn si fi wọn le ajọ ọlọpaa lọwọ ki wọn le foju ba ile ẹjọ.
Nítorí agọ̀ Ọlọrun gbọ́n ju eniyan lọ, àìlágbára Ọlọrun sì lágbára ju eniyan lọ!
Kọ́ mi láti máa ṣe ìfẹ́ rẹ,nítorí pé ìwọ ni Ọlọrun mi.
 Oríṣun àwòrán, @followlasg Gomina ipinlẹ Eko,Babajide Sanwo-Olu ninu ọrọ tiẹ ni, ilegbe oni filaati mẹrindinlẹẹdẹgbẹta ti wọn n kọ lọwọ si adugbo Igando nilu Eko, eyi ti wọn n gbero lati si losu Kẹjọ ọdun 2019 ni wọn yoo pe ni ilegbe Laeef Jakande."
Síírí, wọn n wí fún wa pá aawa ni a ó ṣẹ́gun, ẹyẹ ẹ̀gà lásán ń wí pé òun ni kí a fi ṣe alaga ni ìpàdé àwọn nígbà tí  a bá ṣẹ́gun tan, ẹyẹ àṣádi kàn tóbi lásán ni.
Ibi tí àwọn ẹyẹ wà dára gidgidi àti àṣádi àti àwọn ẹyẹ kéékèèké gbogbo ni wọ́n jọ ń jókòó tí ọ̀kan kò wá ìpalára èkejì.
,Gege bi akonimooja mi, Dominic Ingle, O ni, Mi o ni le ja fun ose merin-in, afi ti ilera ara mi ba pe ki o to di inu osu kefa.
Ọna lati gba ara wọn silẹ lọwọ ijẹgaba ati ifiyajẹni yii, lo mu ki awọn agbẹ korajọpọ bii ẹlẹgbẹjẹgbẹ, eyi ti wọn sọ ni Agbekoya.
Bí wọ́n bá gba ọ̀nà kan dìde sí ọ, yẹ́lẹyẹ̀lẹ ni wọn óo fọ́nká nígbà tí wọn bá ń sálọ fún ọ.
Ọmọ ò sùn mẹ́gbẹ̀wá ti dọ̀ ara rẹ̀
Ooni Ogunwusi àti Wole Soyinka kòrò ojú sí ìṣẹ̀lẹ̀ Lekki Tollgate 2015 ni mo ti ń kígbe pé gudugbẹ̀ máa já ní Nàíjíríà - Oyedepo Mọ̀ nípa DJ Switch, akíkanjú obìrin tó sàfihàn fídíò ìpànìyàn Lekki bó ṣe ń wáyé Ilẹ̀ Amẹ́ríkà wà lẹ́yìn àwọn olùwọ́de, Buhari dẹ́kun ìpànìyàn - Joe Biden Oríṣun àwòrán, @Auntyadaa Ohun tí ojú ìyàwó mi rí lọ́wọ́ SARS kò ṣe é fẹnusọ- Poju Oyemade Awọn òṣìṣẹ́ SARS ti fi panpẹ́ òfin mú ìyàwó mi rí láì nídìí- Poju Oyemade Oluṣọ agutan agba ijọ Covenant Christian Centre, Poju Oyemade ti ṣalaye ohun ti oju iyawo rẹ ri lọwọ awọn oṣiṣẹ ajọ SARS ki ijọba apapọ to tu wọn ka lẹyin iwọde End SARS.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Alagabagebe: Ẹ fi àmì ohùn Yorùbá sí orí rẹ̀ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Alagabagebe: Ẹ fi àmì ohùn Yorùbá sí orí rẹ̀ 22 Ẹrẹ̀nà 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 20 Èbibi 2020 Ẹ nlẹ n bẹun, gbogbo ọmọ Yoruba atata.
lori bi ibasepo yoo se wa laarin igbimo ijoba ati ile igbimo asoju –sofin , ni
Iwe naa sọ pe esi abajade ti
Misha wa ro ijoba lati san adinku owo lori ina fun awon ise akanse lori ise agbe, awon ti owo-osu won kere ati awon ti won n gbe inu ahere.
to wa ni Life Camp niluu Abuja, nibi ti o ti n gba itọju bayii.
" O ni ko yẹ ki Kunle Afọlayan maa ṣe bi ẹni ti ko mọ pe awọn eeyan kan a maa fi orukọ awọn eekan oṣere lu jibiti ati pe, ajọ EFCC ti ran awọn kan to fi orukọ oun lọ sẹwọn.
Ẹka ijọba to n ri si eto ibaraẹnisọrọ ti wa rọ awọn ọmọ Naijiria lati fi ọrukọ silẹ fun kaadi idanimọ.
aare orile ede Naijiria naa ni, iyawo rẹ,Dolapo; igbakeji abenugan ile igbimo
Omejalile ni, ko tii pẹ ti baba ọmọ naa ku ati wipe iya rẹ ṣi wa ninu opo nigba ti afẹsunkan naa ki i mọlẹ.
Ni ilana aṣa ti ile iṣẹ ogun Naijiria, a maa n buyi fun awọn akọgun a si maa n pọn wọn le nigba ti a ba n ṣelede lẹyin wọn."
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Muyiwa Ademola: A ó jọ rọ́ọ̀kì ọdún 2021 papọ̀ ni lágbára Ọlọ́run 19 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 26 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Oríṣun àwòrán, authenticmuy Ilumọka oṣere fiimu Yoruba, Muyiwa Ademola ti fi ọrọ ranṣẹ si àwọn ololufẹ rẹ ati awọn akẹgbẹ rẹ bo tilẹ jẹ pe o ṣi wa nile iwosan.
Kò sí ènìyàn tí ó dà bí ìyá, obìnrin fẹ́ràn ọmọ.
Fún wákàtí mẹ́rìndílógún gbáko ni òkùnkùn ṣú biribiri, ìyẹn ní Ígíláàndì ní'hàhín.
Yatọ sawọn ẹya miran, ẹsin ko so mọ ipo ọba wa rara amọ asa ati ise lo so mọ ipo ọba wa, ti awọn ẹya miran si ri iyansipo ati irọloye ọba bii isẹ akoso wọn lasan, eyi ti ko ri bẹẹ nilẹ Yoruba Alaafin ni si awọn ẹya mii, ko si ohun kan pataki ninu ipo ọba, amọ nilẹ Yoruba, ipo ọba se pataki, to si nii nkan se pẹlu isẹdalẹ ati ọrọ ẹmi tori awọn ọba wa ni asoju awọn alalẹ nilẹ Yoruba, awọn eeyan to ni ilẹ gangan O wa gba Fayemi nimọran pe awọn ọba n rọọ lati mase fi ọwọ yẹpẹrẹ mu ipo ọba alaye, ko si yago fun ete lati gbe asa ajeji to lee tabuku ba asa ibilẹ wa wọ ilẹ Yoruba.
4 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Vaccine rumours debunked: Àwọn ìròyìn òfegè nípa abẹ́rẹ́ àjẹsára Covid-194 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Military Bruitality: Sójà obìnrin lù mí lálù bami nílùú Ibadan4 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Ayuba Wabba: Ẹ̀yin gómìnà kò lẹ́tọ̀ọ́ sí owó ìfẹ̀yìntì òṣìṣẹ́, ẹ rìn jìnnà si11 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Àdínkù bá owó ojúmọ́ ọlọ́kadà l‘Ọyọ láti ₦200 si ₦100, owó gbígbà bẹ̀rẹ̀ lónìí A fẹ́ ìtọ́jú fún Boko Haram tó bá ronúpìwàdà, ẹ dá iléeṣẹ́ sílẹ̀ fún ìtọ́jú wọn - Ilé aṣòfin Olùkọ́ tó fi tipá gba ìbálé akẹ́kọ̀ọ́ tó fẹ́ wọ fásitì rí ẹ̀wọ̀n ọdún 21 he Fayose, o kò ní àmúyẹ gidi láti di ọmọ ẹgbẹ́ wa, àyè kò sí fún ọ - APC Ekiti Bakan naa ni ileesẹ eto idajọ Amẹrika fikun pe ijọba Naijiria ni ko jẹ ki aayan ilẹ Amẹrika so eso rere lati gba owo to tọpasẹ rẹ de ọdọ Bagudu pada, o ni ijọba Buhari ni adehun ọlọdun mẹtadinlogun ti wa nilẹ, eyi to fun Bagudu lẹtọ si owo naa, ti ko si ni jẹ kijọba seranwọ fun Amẹrika lati gba owo ọhun.
"Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí 2020 in Retrospect: 'Mummy Calm down', 'Sọrọ soke were' àtàwọn àṣà tó milẹ̀ lọ́dún 202027 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Fídíò, Akomolede ati Asa Yoruba: Kí ni ""Future tense"" lédè Yorùbá?"
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Àṣà àti iṣẹṣe Yorùbá dì apewo ní Cotonou Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Akroyin BBC jabọ pe idi ti wọn fi tun sun un siwaju ni lati jẹ ki awọn ọlọpaa le pese gbogbo aridaju ti wọn nilo fun idajọ naa.
Ẹni tí ń rìn pẹlu òtítọ́ inú yóo rí ìgbàlà,ṣugbọn ẹni tí ń rìn ségesège yóo ṣubú sinu kòtò.
 Ọ ̀ jọ ̀ gbọ ́ n bíòbákú ( 1955 ) dábàá wí pé a dá ìlú ilé-ifẹ ̀ sílẹ ̀ láàrin ọ ̀ rùndún kéje àti ìkẹ ́ jọ ( seventh & eighth centuries ) .
Eniyan yóo dàbí àgbọ̀nrín tí ọdẹ ń lé,ati bí aguntan tí kò ní olùṣọ́;olukuluku yóo doríkọ ọ̀dọ̀ àwọn eniyan rẹ̀,wọn óo sì sá lọ sí ilẹ̀ wọn.
Genevieve Nnaji: Ìbálòpọ̀ pẹlú ọ̀rẹ́kùnrin kọ́ ni ìfẹ́, bẹ́ẹ̀ ni ìfẹ́ kìí ṣe ìbálòpọ̀
, ẹgbẹ́ òṣèré tíátà pàṣẹ fún Lizzy àti Toyin Owó ilé ìwé gbígbà ní ìpínlẹ̀ Ogun ti di ìtàn - Gómìnà Ọwọ́ sìkún ọlọ́pàá tẹ afurasí lórí ẹ̀sùn ìpaǹìyàn ni Port Harcourt Wo ìdí ti ìjọba ṣe ka ẹ̀sùn méje tán yányán mọ́ Sowore lẹ́sẹ̀.
Ọdun 2011 ti wọn bẹrẹ fiimu ‘Game of Thrones’ ni ori ẹrọ ikansiraẹni lori ayelujara ti n sọ kutukutu wọwọ, eleyii ti wọn yoo si pari ni ọdun 2019.
Oriṣi oniduro meji lo wa: Amofin ṣalaye pe oriṣi oniduro meji lo wa.
9 5520 Orilẹede Vietnam 35 0.
Ileeṣẹ ijọba ipinlẹ Oyo to wa nilu Ibadan, ni ipade naa ti waye.
Ọdun 1954 ni ọbabinrin ilẹ Gẹ̀ẹ́sì fi oye ọlọla, Sir and Lady, da Oyinkan ati ọkọ rẹ, Kofoworola Abayomi lọla.
Àwọn ṣọ́jà ṣíná ìbọn bolẹ̀ ni Lekki Tollgate Ina ibọn n sọ lala ni agbegbe Lekki Tollgate ni ipinlẹ Eko lalẹ ọjọ Iṣẹgun nibi ti awọn ologun ti yin ibọn ati eroja iṣere fireworks lati tu awọn oluwọde ka.
Ṣugbọn títí ayé ni ìfẹ́ OLUWA tí kì í yẹ̀,sí àwọn tí ó bẹ̀rù rẹ̀,òdodo rẹ̀ wà lára arọmọdọmọ wọn.
Lẹ́yìn náà OLUWA sọ fún Mose pé, “Lọ sí ọ̀dọ̀ Farao, kí o sì wí fún un pé, ‘OLUWA ní, “Jẹ́ kí àwọn eniyan mi lọ sìn mí.
Kẹmi, loju opo ikanni Twitter rẹ lọjọ Ẹti, mọriri gbogbo ọmọ Naijiria nile ati lẹyin odi ti wọn n rọjo adura si nigba ti aarẹ n se, to si n gbadura pe wọn ko ni fi iru rẹ gba.
Wo ìtumọ̀ àti pàtàkì ọ̀pọ̀ oyè ẹ̀ṣìn nínú Islam
Bi o tilẹ jẹ pe iye awọn eeyan rẹ ko pọ, iye erin to wa lorilẹede Botswana lo pọ julọ nilẹ Afirika.
Benue: Ile asofin ni ọga ọlọpa Nigeria ko kajuẹ' Awọn asofin agba yoo sewadi ilẹkun baalu Dana to fo yọ Sugbọn nigba to n ba akọroyin ileesẹ BBC sọrọ, Ọgbeni Ajisebutu ni, ẹnikẹni to ba gbẹmi eeyan, ọdaran ni, pẹlu afikun pe ọdaran nikan lo lee se iku pa ọlọpa to ngbogun tawọn adigunjale.
Ó fi yìnyín ba àjàrà wọn jẹ́;ó sì fi òjò dídì run igi Sikamore wọn.
Ṣugbọn èso ti Ẹ̀mí ni ìfẹ́, ayọ̀, alaafia, sùúrù, àánú, iṣẹ́ rere, ìṣòtítọ́, 
Day 19: Wo ohun àràmàndà tí àwọn olósèlú máa ń ṣe lásìkò ìbò #BBCNigeria2019 Kí ni àwọn olùdíje ìpínlẹ̀ Eko fẹ́ ṣe nípa ètò ìlera?
Ileesẹ Ọgbẹni Ahmadu nigba kan, Drexel Tech, ni wọn gbe isẹ fun ni ọdun 2013, lati seto ilana igbani sisẹ fun ẹgbẹrun mẹrin eniyan, fun awọn ipo to ṣófo nileesẹ ajọ to n risi iwọle-wode ni Naijiria.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Omolola Arohunmolase Welder: Mo ti fí iṣẹ́ 'Welder' gbayì láwùjọ, tó mo fi tọ́ ọmọ yanjú Kini iroyin sọ pe o fa wahala?
O ni ọrọ ti ko to nkan to ṣẹlẹ laarin awọn gomina kan ati Oshiomole ni wọn n sọ di babara.
Lẹyin ti Danladi gba pe oun jẹbi ẹsun ole ti wọn fi kan an, Adajọ majisireeti Omolola Akindele dajọ pe ki o wa gbale ileẹjọ lai si anfaani lati san owo itanran.
Ile-ise aare ti ki egbe oselu alatako,Peoples Democratic Party, PDP nilo lati mase lo ebi aare Muhammadu Buhari gege bi ohun ipolongo idibo ninu eto idibo odun 2019.
Ijoba wa ro, enikeni ti o ba ni eri iwe asaro owo, ti o fihan pe ijoba san lati fi tu awon omo ohun sile ni ikawo re, ki o fi sita fun araye ri.
Ṣugbọn lọ sọ́dọ̀ àwọn arakunrin mi, kí o sọ fún wọn pé, ‘Mò ń gòkè lọ sọ́dọ̀ Baba mi ati Baba yín, Ọlọrun mi ati Ọlọrun yín.
Lootọ ni coronavirus ko ti i de awọn ipinlẹ naa, sugbọn lati igba to ti de Naijiria ni diẹ lara wọn ti gbe awọn igbesẹ lati ri i daju pe ko wọ ipinlẹ wọn, àti ọna ti wọn yoo gba koju rẹ to ba ṣèèṣì wọle.
Gbogbo ohun tẹ bá fẹ́ kí n ṣe, ní máa ṣe.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Qasem Soleimani: Iran ni Trump gbọdọ̀ jẹ́jọ́ lórí ikú ọ̀gágun tí Amerika pa 29 Òkùdu 2020 Oríṣun àwòrán, Reuters Àkọlé àwòrán, Qasem Soleimani padanu ẹmi rẹ ninu ikọlu ado oloro Drone ti Amẹrika yin lu Orileede Iran ti fi iwe ipẹjọ sita pe ki awọn agbofinro mu aarẹ Amẹrika Donald Trump lori iku ọgagun ilẹ wọn kan Qasem Soleimani ti Amẹrika pa.
Nítorí anfaani wo ni ó jẹ́ fún ẹnikẹ́ni, bí ó bá jèrè gbogbo ayé, ṣugbọn tí ó pàdánù ẹ̀mí ara rẹ̀?
Ni ilẹ Yoruba, Ọbaọlọla Olowo, ẹni ti ọba yẹ loye ati eeyan nla ni Alaafin tilu Oyo, Ọba Lamidi Olayiwola Adeyemi Kẹta.
O ni iṣẹlẹ ikọlu awọn ọmọ Naijiria ni orilẹ-ede South Africa ko dara to ṣugbọn ko yẹ ki awọn maa ba nkan jẹ pada.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Tí mo bá tún ayé wá, ó wù mí kí n bí ju ọmọ 17 tí mo bí lọ 13 Agẹmo 2019 Arabinrin Jummai Ibrahim to n gbe nilu Kano sọ fun BBC pe ti oun ba tun aye wa, o wu oun ki oun bi ju ọmọ mẹtadinlogun lọ, nitori pe ibukun lati ọdọ Ọlọrun ni ọmọ jẹ.
Nígbà tí mo bá ti nà án tán n óo dá a sílẹ̀.
Ti awọn kan ba ti n fi ami han ni wsn to o le ko ran ẹlomiran, ṣugbọn awọn miran le ko ran ẹlomiran ki o to o da wọn gunlẹ.
Nigerian Army: Awọn agbẹbọn pa ọ̀gágun tẹ́lẹ̀ Alex Badeh
Ẹni tí ó bá ní ẹ̀bùn láti ṣe aṣiwaju, kí ó ṣe é tọkàntọkàn.
Tabi ẹ lè tan Ọlọrun bí ẹni tan eniyan?
Niwọn igba to si jẹ pe ẹẹmẹta lọsẹ kan n'ile njoko, o jasi wi pe osu mẹtadinlogun ni asofin Jubrin lo n'ile, ki wọn to pee pada.
A fún un ní àṣẹ fún oṣù mejilelogoji.
“leyin ibasepo irin ajo de orile-ede Russia, ajo to n mojuto boolu afesegba lorile-ede Spain ati Fernando Hierro fopin so ibasepo won,”Lataari iberubojo ajo to n mojuto boolu Spain pe, ikunsinu le jeyo laarin awon agbaboolu iko Spain, ti Lopetegui se kede pe oun yoo maa tuko agbaboolu Real Madrid leyin idije boolu agbaye, leyi ti o sokunfa bi ajo naa se fopin si ise re, opo lo ni lokan tele pe iko agbaboolu orile-ede Spain wa lara iko ti o seese ko gba idije agbaye naa, sugbon pabo ni oro ohun jasi.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Yorùbá tone mark: Fífi àmì ohùn sí orí ọ̀rọ̀ Yorùbá ṣe pàtàkì Amọ nigbakugba ti wọn ba ti lu ofin speed limit yii, epo ko ni lọ si ibi to yẹ ko lọ ninu ọkọ, ohun ni yoo mu ki ọkọ naa pana.
Lara wọn ni arabinrin Ayodeji Osowobi to ko arun Coronavirus, to si ri iwosan gba lorilẹede Naijiria.
Ó gba oyè àkọ ́ kọ ́ b.
Ìwọ̀nyí ni a ti pèsè fún lílò ní Ilé Ẹ̀kọ́ àwọn Wòlíì ní Kirtland, Ohio, láti 1834 sí 1835.
Ayeye igbeyawo nla ohun ni ipolongo re ti gbode kan kakaakiri ori ero ayelujara bayii, ni erongba lati fihan pe aremo oba Kenya lofe se igbeyawo.
Ẹnìkan ń bẹ ní ìjọba rẹ tí ó ní ẹ̀mí Ọlọrun Mímọ́ ninu.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Johesu: Òsìsẹ́ ìlera ti bẹrẹ iyanselodi 17 Ìgbé 2018 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 18 Ìgbé 2018 Oríṣun àwòrán, AFP Àkọlé àwòrán, Iyansẹlodi lẹka ilera orileede Naijiria ki se ohun tuntun mọ Àwọn òṣìṣẹ́ elétò ìlera lorilede Naijiria, labẹ àsìá ẹgbẹ apapo awọn oṣiṣẹ ilera Johesu ti bẹrẹ iyansẹlodi loni.
Òun ló mọ́ jùlọ, nítorí pé apá kan ninu ẹbọ sísun sí OLUWA ni.
Nítorí bí ó bá jẹ́ pé ní Tire ati ní Sidoni ni a ti ṣe àwọn iṣẹ́ ìyanu tí a ṣe láàrin yín ni, wọn ìbá ti ronupiwada tipẹ́tipẹ́, tàwọn ti aṣọ ọ̀fọ̀ lára ati eérú lórí.
Ìṣiṣẹ ́ àbínimọ ́ da lori idimu ati imuse oniakinkinni awon abinimo , pelu iwa abinimo ninu ahamo tabi adirajo ( f.
O ṣalaye iṣẹlẹ arakunrin kan to ti oke okun wale wa si ilu Igangan wa dako ṣugbọn tawọn Fulani kan da ẹran lọ jẹ oko rẹ.
O ni eto idibo odun 2019 ni yoo sọ nipa ọjọ
A bi ìyá wa pé a kò tíì rí bàbá wa kékeré l’ọ́jọ́ náà, àti pé a kò mọ kín ni ó ṣe é.
Stoke City - Badfield Ndiaye: Stoke City ti se adehun pẹlu ẹgbẹ agbabọọlu Galatasaray ti ilu Turkey fun Badfield Ndiaye.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Omijé bọ́ lójú mi nígbà tí mo rí olóògbé Pa Kasumu gbẹ̀yìn - Lere Paimo A dúpẹ́ o!
Fulani sọ pe igbogun ti awọn adigunjale lati Adeniji Adele ni ipinlẹ Eko to jẹ olu ilu Naijiria nigba naa wa lara iṣẹ akanṣe to da SARS silẹ.
Ejò lé àwọn aṣòfin ìpínlẹ̀ Ondo kúrò nípàdé Ẹ wo ọmọ ọdún méje tó di Gómìnà l'Ekiti Ajafẹtọ ọmọniyan naa wa gba awọn ara ilu ni imọran lati ma a yan awọn ti o le e gbọran si wọn lẹnu, ti o si le e ṣe ifẹ awọn ara ilu.
 Sugbon omi kan poju oka lo ni.
Sibẹsibẹ, ẹ̀ ń wí pé, ‘ọ̀nà OLUWA kò tọ́.
Nítorí náà, títí di òní, àwọn ọmọ Israẹli kì í jẹ iṣan tí ó bo ihò itan níbi tí itan ti sopọ̀ mọ́ ìbàdí, nítorí pé ihò itan Jakọbu ni ọkunrin náà fọwọ́ kàn, orí iṣan tí ó so ó pọ̀ mọ́ ìbàdí.
Nígbà ti àwọn Boko Haram ri ǹkan ti àwọn ọmọ náà ń ṣe, wọn gbà á, wọ́n sì dáná sún awọn iwe naa.
Ǹjẹ́ o lè ka iye oṣù tí wọ́n fi ń lóyún?
Ìdánilójú wà fún àwọn oníbàrá wa pé àgbéjade ìròyìn wà kìí ṣe nítori ìfẹ́ inú ẹnikẹni, yálà olóṣèlú, tàbí àwọn olókòòwò, tàbí ọlọ́dan ni kànkan.
Nigba ti akọroyin BBC kan si lori ago, o fidi ọrọ yii mulẹ to si ni alẹ ọjọ Eti ni wọn ni ki oun maa pada sile.
Ẹ wo ọ̀nà tí ìjọba Nàìjíríà fẹ́ gbà san owó àwọn olùkọ́ iléèwé aládàni tí kò rówó oṣù gbà Ọlọ́pàá kọ́ lo pa olórí àwọn ''One Million Boys'' Ebila n'Ibadan- Ọ̀gá ọlọ́pàá Oyo Àwọn dókítà Eko bẹ̀rẹ̀ ìyanṣẹ́lódì lórí owó oṣù àti ètò adójútòfò fún ìtọ́jú coronavirus Wole Soyinka rèé láti kékeré Kí ló dé tí Igbákejì Gomina Ondo ní kí wọ́n yọ Abẹnugan Ilé Aṣòfin?
Ní àkókò náà, OLUWA kò tíì pa ìlú Sodomu ati Gomora run.
Gbogbo wa la mọ wipe ni ẹkun iwọ oorun gusu ilẹẹwa, APC o si ni ọkan.
O Fagunwa kú, dúkìá rẹ̀ sì ń fọhùn síbẹ̀, ilé rẹ̀ rèé Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Grandma Maruwa: Ó yẹ kí obìnrin sisẹ́ láì wojú ọkọ kó tó jẹun O sọ pe, bi aarẹ Muhammadu Buhari ba ṣe tete gbe aba ofin naa wa siwaju wọn, ni yoo sọ igba ti yoo di ofin, ti owo oṣu naa yoo si bẹrẹ si ni jẹ sisan.
Ẹwẹ, ọpọ eeyan atawọn eekan ninu awọn oloṣelu lo ti n sọrọ lori iṣẹlẹ ọhun, lara wọn ni alaga ajọ to n ri si ọrọ awọn ọmọ Naijiria to wa nilẹ okere, Abike Dabiri-Erewa to bẹnu ẹtẹ lu iṣẹlẹ naa.
Oríṣun àwòrán, KEYSTONE Ohun to yẹ koo mọ nipa Sultan Qaboos bin Said ti Oman ree Sultan Qaboos ko fẹ́ iyawo bẹẹ si ni ko bimọ kankan tabi ẹni ti yoo gbe ade le lori lẹyin ipapoda rẹ.
Odun yii lo pe ogota odun ti won ti bere ayeye yii ni South Africa ni eyi ti won se pelu awon olorin bii: Sketchy Bongo, DJ Zinhle, Tamara Dey, Lady Zamar ati Nádine.
Eyi ni wọn sọ pe bẹẹ naa ni Gomina Ambọde ati awọn miran ti ṣe abẹwo si Buahri ni Abuja ṣeyin ti ẹgbẹ si pada tun kọ ẹyin si wọn naa ni.
Oríṣun àwòrán, Twitter Àkọlé àwòrán, Ọjọ́ keje, oṣù Kẹjọ ni Adele Aarẹ, Yẹmi Ọsinbajo gba iṣẹ́ lọ́wọ́ rẹ̀ Bakan naa ni wọn ni ko jẹ ki wọn o fi ofin gbe Ọga agba ajọ ọtẹlẹmuyẹ ti National Intelligence Agency, NIA, Ayodele Oke, ti Aarẹ Buhari da duro lẹnu iṣẹ.
 nì ọdún 1974 sí 1976 .
Ààrá ń sán kíkankíkan ní ojú ọ̀run,mànàmáná ń kọ yànràn, gbogbo ayé sì mọ́lẹ̀;ilẹ̀ ayé wárìrì, ó sì mì tìtì.
A mọ̀ pé nígbà tí Jesu Kristi bá yọ, bí ó ti rí ni àwa náà yóo rí, nítorí a óo rí i gẹ́gẹ́ bí ó ti rí.
OLUWA àwọn ọmọ ogun, Ọlọrun Israẹli ní: ‘Ẹ tún ìrìn ẹsẹ̀ yín ati iṣẹ́ ọwọ́ yín ṣe, kí n lè jẹ́ kí ẹ máa gbé ìhín.
Bí ẹni pé enítọ̀hún kò ní owó làti ra ọkọ̀ ayọ́kẹ́lẹ́.
jẹyọ lose to koja lasiko ti oniwasu naa fẹ wọkọ ayọkẹlẹ lọ si Goma lojo Eti.
Ifesewonse ohun yoo waye ni papa isere ilu Port Harcourt, lojo méjídínlọ́gbọ̀n osu karun un odun ti a wayii.
 bartholemew ' s ni london nigba ogun agbaye kiini , o se ìtọ ́ jú àwọn ológun .
Ó fẹnu mi gbolẹ̀,títí yangí fi ká mi léyín;ó gún mi mọ́lẹ̀ ninu eruku
Ni kutu hai owurọ ọjọ Isẹgun si lawọn osisẹ ọlọpaa ti ya bo ibudo naa, ti wọn si ti ẹnu ọna abawọle ibẹ, ki awọn eeyan to n gbero lati se iwọde maa baa ri aaye pejọ.
Ọgbọ́n yóo parẹ́ mọ́ àwọn ọ̀jọ̀gbọ́n ninu,ìmọ̀ràn yóo sì parẹ́ mọ́ àwọn ọ̀mọ̀ràn níkùn.
Ó sì ń mú èrò burúkú jáde.
Toripe, bi won ba pada sile, ibo ni won yoo duro si nigba ti awon ibugbe won ti baje, o ti fi igbese lori oro da wa loju, bakan naa ni won yoo fi oju sunnukun wo awon oro yoku ti a muwa siwaju re, o dami loju pe, gbogbo nnkan yoo dara laipe ojo, mo n dupe lowo Aare naa fun atileyin re, mo mo pe, laasigbo yii ko sese bere lasiko saa tire, ajogun ba ni.
Won n wa ogbeni Bashir nile ejo odaran agbaye ICC fun esun ogun ati isekupani ni ekun Darfur ni eyi to ni iro nip e oun pa awon eeyan nibikibi.
Awon awakọ miran a bọ aṣọ silẹ maa ba ara wọn ja loju popo lai palẹ ọkọ tabi alupupu wọn mọ kuro lọna ki ẹlomii le ri aaye kọja lasiko.
Àwọ̀ ojú pọ̀ bíi àwọ̀ òṣùmàrè, àmọ́ ojú búlúù Risikat kò nílò àtúnṣe- Dókítà Feyi Mínísítà fún ọ̀dọ́ àti eré ìdárayá tí fi ẹ̀bùn owó ránṣẹ́ si ìyá Kausara, ó tún jẹ́jẹ̀ẹ́ ẹ̀kọ́ ọ̀fẹ́ f'áwọn ọmọ rẹ̀ Ogundipe gbé fásitì Unilag ló sí iléẹjọ́ nítórí wọn yọ́ ní ipò VC Ilé ayé mi ti d'ojú bolẹ̀ pẹ̀lú ikú àfẹ́sọ́nà mi- àfẹ́sọ́nà Immaculate Okochu Àgbo Covid-19 Madagascar kò ṣiṣẹ́, àwọn ènìyàn tí bẹ̀rẹ̀ sí ní kú níbẹ̀ Risikat naa fidiẹ mulẹ pe nitootọ ni Wasiu ko le oun nile ṣugbọn iwa rẹ fihan pe ki oun ba ẹsẹ oun sọrọ nigba naa.
Lẹyin ti ajọ eleto ilera l'agbaye, WHO kede pe ajakalẹ aarun ni coronavirus lọjọ kọkanla, osu Kẹta, awọn ilana orisirisi tun jẹyọ.
Arigbamu ti wa bayii nipa iye eeyan to ba isẹlẹ ọpa gaasi to lagbegbe Abule Ado nijọba ibilẹ Amuwo ọdọfin nipinlẹ Eko lọ.
Botilẹjẹ pe awọn itan kan sọ pe awọn oyinbo amunisin ti tu ilana Pelupelu kan l'ọdun 1958, bi oye awọn ọba Ekiti ṣe gbewọn to ni wọn pin si ipele mẹta.
Paulu fẹ́ wọ ibẹ̀ lọ bá àwọn èrò ṣugbọn àwọn ọmọ-ẹ̀yìn Jesu kò gbà fún un.
14 Òkùdu 2019 Oríṣun àwòrán, @aishambuhari Lati wakati yi lọ,'First Lady', eyi tii se obinrin akọkọ ni Naijiria, ni ki ẹ ma pe mi.
Aṣọ alarambara naa ko yọ awọn obi ati ẹbi wọn silẹ rara.
Mo di ẹni àmúpòwe fún ọpọlọpọ eniyan,ṣugbọn ìwọ ni ààbò mi tí ó lágbára.
O ni ki onikaluku dẹkun ibo tita, ki wọn jade gbaruku ti ẹni to ṣetan lati sin ara ilu yatọ si ifẹ inu wọn.
(amọṣa kii ṣe gbogbo ipe ọlọpaa lo nilo iwe aṣẹ ofin lati mu ọ) labẹ ofin ilẹ Naijiria, agbara pupọ n bẹ lọwọ ọlọpaa lati mu s ni ọpọ igba.
Nítorí ọmọkunrin ń tàbùkù baba rẹ̀, ọmọbinrin sì ń dìde sí ìyá rẹ̀, iyawo ń gbógun ti ìyá ọkọ rẹ̀; àwọn ará ilé ẹni sì ni ọ̀tá ẹni.
Iroyin ni oun ni ọkunrin kẹta ti idile Monerville yoo padanu nipasẹ ibọn tabi ọbẹ ni ilu London.
Ṣe ẹ̀ka mẹfa sára ọ̀pá fìtílà náà, mẹta ní ẹ̀gbẹ́ kinni, ati mẹta ní ẹ̀gbẹ́ keji.
Bẹ́ẹ̀ ni Absalomu máa ń ṣe sí gbogbo àwọn eniyan Israẹli, tí wọ́n bá kó ẹjọ́ wá sọ́dọ̀ ọba.
"Oral Sex: Bóo bá ń gba ẹnu ní ìbálòpọ̀, wo àìsàn tóo lè kó lójú ara rẹ ""Lonii, ẹnu gbẹ ni Ṣọọṣi wa tori a o fẹ́ lodi si ofin to ba Coronavirus wa""."
Ọpọ osere tiata lo pin akanse ọrọ yii loju opo Instagram wọn, ti wọn si fi akọle tiwọn sibẹ.
Ilé ẹjọ́ gba béèlì Sẹ́nétọ̀ Adeleke Adeleke yóò borí nílé ẹjọ́ tó gajù lọ- Dele Adeleke Ademọla Adeleke, Fayoṣe, Atiku sọ̀rọ̀ lórí ìdájọ́ ilé ẹjọ́ Amọ ṣa oludije ẹgbẹ oṣelu PDP, Sẹnẹtọ Ademola Adeleke ta ko idajọ yIi to si gba ile ẹjọ giga lọ.
Corona virus update in Nigeria: Ó lé ní N213 bílíọ̀nù tó wọlé fún ìjọba nípasẹ̀ COVID-19
Ẹ kú ẹjọ́ tí Ọlọ́run dá yín.
Amọ ni ọjọ kan, Shina ni oun wọ yara baba oun lasiko to lọ ṣe igbọnsẹ, oun ri ìbọn rẹ to tu kalẹ, ti oun si joko lati to ìbọn naa pada, eyi ti oun ṣe lai si wahala kankan.
Ahasi kó fadaka ati wúrà tí ó wà ninu ilé OLUWA, ati tinú àwọn ilé ìṣúra tí ó wà ní ààfin jọ, ó kó o ranṣẹ sí ọba Asiria.
Children's Day: Àwọn ọmọdé tó ń ṣe bẹbẹ láwùjọ Afíríkà Àwọn ọ̀gá rẹ ní ìjọba ni mò ń bá se - Bobrisky fún ọ̀gá Arts & Culture lésì!
Ẹ̀gà tún bá olóko ti wí.
 ní ìgbà yẹn , òun ní irinṣẹ ́ ìwòràwọ ̀ tí ó tobi jùlọ .
Awon asoju naa lo wa lati gbogbo ipele ijọba apapo, ekun ati ipinle  ati awon obinrin to je  oludije lorile ede Naijiria.
Ojú alágbe ni wọ́n fi ń wo alága ìdúró- Ayo Oladokun Nàìjíríà ló wà nípò kẹfà nínú ewu ikú àìtọ́jọ́ l'ágbàáyé nítorí nkan mímú tó ní ṣúgà Àrà méèrírí , ẹ wo ọkùnrin tí eegun rẹ̀ rọ̀ bíi rọ́bà, tó ń ká bíi ẹja Ọbasanjọ sọ àsírí sàgbàdèwe rẹ̀ Aṣa ati iṣe ati ede Yoruba ṣe pataki pupọ fọmọ Oodua, ẹ jẹ ki gbogbo wa kọ awọn ọmọ wa nipa wọn fun idagbasoke, irẹpọ ati ifẹ ni awujọ wa.
Niwọn igba to jẹ pe ẹni ti yoo ba jẹun gbọin-gbọin, gbọdọ ti ilẹkun gbọin-gbọin, Shina wa agbara kun agbara, o n ṣe oogun abẹnu gọngọ, ko si si ibi ti ko ṣe oogun de.
- Oluwo Ofin ti f'àyè gba ìbálòpọ̀ Akọs'akọ, Abos'abo ní Botswana Ṣaaju ọdun 2019, ọj ikọkandinlọgbn oṣu ikarun un ni orilẹede Naijiria maa n yẹ si tẹlẹ gẹgẹ bi ayajọ ijọba awa ara wa.
Ní gbogbo àwọn ìlú Israẹli ni Josaya ti wó àwọn ilé oriṣa tí àwọn ọba Israẹli kọ́ tí ó bí OLUWA ninu.
Nígbà tí àwọn eniyan burúkú bá kú,ìrètí wọn yóo di asán,bẹ́ẹ̀ ni ìrètí àwọn tí kò mọ Ọlọrun yóo di òfo.
Mo fẹ́ kí ẹ mọ̀ dájúdájú pé ìran yìí ni yóo dáhùn fún ẹ̀jẹ̀ gbogbo wọn.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Yoruba Films: Lizzy Anjorin yẹ́ iyabo Ojo sí kí ọjọ́ ìbí rẹ̀ tó pé 21 Ọ̀pẹ̀̀ 2019 Oríṣun àwòrán, OTHER Bi awọn oṣere fiimu yoruba ṣe maa n ẹ ara wọn si tile tile bi wọn ba n ṣe ohun rere to fi mọ ọjọ ibi tiwọn ati ti mọlẹbi wọn maa n jẹ ohun iwuri to bẹẹ ti awọn ololufẹ wọn gan ko le ṣai da si ikini lori ayelujara.
"Lori eto Akomolede ati Asa lori BBC Yoruba fun tọsẹ yii, ohun ta gbeyẹwo ni kika latinu iwe Akinwumi Iṣola ti akọle rẹ n jẹ ""Nitori Owo""."
Bakan naa lo tun n wa ọkọ nla akẹru, o tun n ṣe eṣọ nile ijo kan ti wọn n pe ni Conga Latin Bistro.
Kà nípa ibi tí wọ́n bí Àrẹ̀mọ tuntun Ọọ̀ni Ife sí, àti orúkọ tó ń jẹ́ Irọ́ ni o!
Ó bá dì í mú, ó fún un lọ́rùn, ó ní; ‘San gbèsè tí o jẹ mí.
  Kódà mo tún rí ibi tí àwọn odidi igi ti ń hù lábẹ́ odò.
"Igboho ni Auxiliary kò tíì máa ṣisẹ ti ìjọba gbé lé e lọ́wọ́ bó ṣe yẹ, tó sì ń rọ gomina Seyi Makinde láti yan àwọn èèyàn tó mọ isẹ àkọ́so gareji ọkọ̀ sípò alága tí Auxiliary wà.
Dípò tí ì bá fi fún bàbá mi lésì ki wọ́n jọ máa sọ̀rọ̀ sí ara wọn, ó rọra gbé ìwé, ó ṣí ibì kan báyìí, ó gbé e sí iwájú bàbá mi, bẹ́ẹ̀ ni onírúurú ẹṣẹ̀ ọmọ aráyé ni wọ́n tò sí ibẹ̀, àti ẹ̀ṣẹ̀ kékeré àti títóbi, ó wí fún bàbá mi pé kí ó búra bí kò bá ṣẹ ẹ̀ṣẹ̀ kan rì nínú wọn.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ìgbẹ́tì: Òkè Ìyámàpó ló gba wàá sílẹ̀ lọ́wọ́ ogun Ajakale àrùn miran tó tún wà ní àkọsílẹ̀ pé ó tún ja ranyin-ranyin lagbaye ni ajakale àrùn kẹta, tí wọn ń pè ní 3rd Plague.
Sugbọn oun to je iyalẹnu ni pe Leonard kosi ni papa isere ibi ti ọmọ rẹ ti gba ife ẹyẹ Grand Slam akọkọ rẹ.
Àkókò yìí ni Èṣù ri ọ̀nà láti ba ìgbésí-ayé ènìyàn jẹ́, tí ó bẹ̀rẹ̀ sí kọ ẹ́hìn wọn sí Ọlọ́run Ọba.
Mo sọ fún ọ pé, yóo sàn fún ilẹ̀ Sodomu ní ọjọ́ ìdájọ́ jù fún ọ lọ.
Wò ó, ọkàn mi fà sí ati máa tẹ̀lé ìlànà rẹ,sọ mí di alààyè nítorí òdodo rẹ!
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù 2019 Elections: INEC fún àwọn èèyàn ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́ ní ìdánilójú ṣáájú ìdìbò ọjọ́ àbámẹ́ta 19 Èrèlè 2019 Àkọlé àwòrán, Kọmisọna ọlọpa nipinlẹ Ọyọ, naa ṣe afihan igbaradi ajọ ọlọpa nibi akanṣe apero naa.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ebola: Nàìjíríà ń ṣọ́ pápákọ̀ òfurufú tórí Ebola 9 Èbibi 2018 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Àjọ tí ó ń rí sí ìwọlé-wọ̀de ní àwọn kó tún ní gba Ebola láàye o.
Ilé ẹjọ́ Eko pàṣẹ, EFCC mú u ṣẹ, Ìjọba gbẹ̀sẹ̀ lé ilé Saraki ní Ilorin Elkana ni lẹ́yin ti ará ìlú tàwọn lolobó ni àwọn gbé ìgbésẹ̀ ti àwọn si mú àwọn obinrin méji, Rukayat Folawewo àti Bunmi Joshua ti wọ́n n ṣe bi ọmọ ìjọ naa ti wọ́n sì ri iṣẹ́ ìyànú ìwòsàn gbà láti ọwọ pásìtọ lẹ́yìn ìjàmba ọkọ̀.
Laarin ọdun 1974 si 1982, Folasade kẹkọ dokita nile ẹkọ fasiti Ile Ife to si gba oye imọ ijinlẹ akọkọ nigba to gba oye imọ ijinlẹ keji nile ẹkọ fasiti Eko.
Ó mọ àwọn ìkòkò, ó rọ ọkọ́ ati àmúga tí wọ́n fi ń mú ẹran, ati gbogbo ohun èlò wọn.
Ọlọrun níí dájọ́ bí ó ti wù ú:á rẹ ẹnìkan sílẹ̀, á sì gbé ẹlòmíràn ga.
Oríṣun àwòrán, facebook/Godswill Obot Akpabio Gbogbo ohun tí Godswill Akpabio sọ níbi ẹ̀sùn ìnákùnàá tí wọ́n fi kàn án rèé Lasiko ti igbẹjọ wọn n lọ lọwọ eyi ti igbimọ to n gbẹjọ nipa ajọ NDDC n ṣe, Sẹnetọ Akpabio ni oun ko ja ilana itọpinpin isuna ajọ naa gba bẹẹ si ni oun ko da ẹnikẹni duro lẹnu iṣẹ.
Ọjọ kẹẹdogun ọsun kọkanla ọdun 2020 ni wọn gbe Adene pada si ilu Eko lati Abuja ni deedee aago mẹsan alẹ.
Láti ìgbà náà ni a ti ń waasu ìyìn rere ti ìjọba Ọlọrun.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Àwọn aláṣẹ n wa àwọn tó ṣalabapade Mínísítà féto ìlera ilẹ̀ Gẹ̀ẹ́sì tó lùgbadì Coronavirus 11 Ẹrẹ̀nà 2020 Aisan Coronavirus ko mọ olowo, ko mọ talaka, koda awọn to dipo ijọba mu gaan ko ribi bọ lọwọ ajakalẹ yi.
OLUWA àwọn ọmọ ogun, Ọlọrun Israẹli ní, “Gbogbo àwọn ohun èlò tí ó ṣẹ́kù ní ilé rẹ, ati ní ààfin ọba Juda, ati ní Jerusalẹmu, ni 
Wàrà ni mo ti fi ń bọ yín, kì í ṣe oúnjẹ gidi, nítorí nígbà náà ẹ kò ì tíì lè jẹ oúnjẹ gidi.
Ọjọ Kẹfa oṣu Kẹrin ọdun 2003 ni Olatunji jade laye nilu California lorilẹ-ede Amẹrika, ti ifẹ rẹ fun ilu lilu si jẹ manigbagbe.
Ayọ̀ tó ń bẹ nínú orin Jazz- Olakunle Tejuoso Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Africa Eye: Olùkọ́ méjì ní fásitì Eko àti Ghana lùgbàdì ọ̀fíntótó BBC lórí ìwà ìbàjẹ́ Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Gbogbo ìgbésẹ́ to yẹ ni a gbé kí ató gba ọ̀daràn to ni ààrun Coronavirus sí ọgbà wa- Agbẹnusọ ọgbà ẹ̀wọ̀n 24 Ìgbé 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 27 Ìgbé 2020 Oríṣun àwòrán, others Àkọlé àwòrán, Gbogbo ìgbésẹ́ to yẹ ni a gbé nígbà ti àwọn ọ̀daràn dé ọgbà wa- Agbẹnusọ ọgbà ẹ̀wọ̀n Ìlé iṣẹ to n moju to ọgba ẹwọn lorilẹ-ede Naijiria ẹka ti ipinlẹ Ondo ní gbogbo ìgbésẹ̀ to yẹ ni àwọn ti gbe ki àwọn afunrasi ninu ikú ọmọ Fasonranti, Funke Olakunrin to de si ọgbà ẹwọn ni Ondo.
Akeredolu tesiwaju pé mo ti safikun awọn ilu to n jẹ anfaani eto itọju tiya-tomo taa mọ si Mother and Child ti ijọba Olusegun Mimiko fi lélẹ̀."
Ó ṣe ohun tí ó dára lójú OLUWA, ṣugbọn kò dàbí ti Dafidi baba ńlá rẹ̀; ohun gbogbo tí Joaṣi baba rẹ̀ ṣe ni òun náà ṣe.
Ọkunrin náà sọ fún wọn pé, “Bí ẹlẹ́ṣẹ̀ ni o, tabi ẹlẹ́ṣẹ̀ kọ́, èmi kò mọ̀.
Mo ṣetán láti kojú Andy Ruiz ni Saudi lọ́jọ́ Sátidé- Anthony Joshua Saheed Balogun sìnkú ìyá rẹ̀, Ogogo ní ẹgbẹ́ agbábọ́ọ̀lù!
Ọ̀kọ̀ọ̀kan ninu àwọn òkúta náà wà ní ẹ̀gbẹ́ kinni keji ọ̀nà náà.
Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí 6:18 Fídíò, Akomolede: Bolaji Faleke ni Olùkọ́ tó ń kọ́ wa ní àṣà oge ṣiṣe lórí BBC Yorùbá, Duration 6,181 Owewe 2020 6:10 Fídíò, Yoruba Language: Akomolede ati Asa Yoruba tọ̀sẹ̀ yí rèé lẹ́nu olùkọ́ wa, Duration 6,1030 Ògún 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Bí mo ṣe jàjà bọ́ lọ́wọ́ àrùn Coronavirus rèé- Ayodeji Osowobi Ń ko tọrọ agbe fún ìyá Awero, Larry àti bàbà Feyikọgbọn, ẹ má sọ ire di ibi mọ́ mi lọ́wọ́ - Foluke Daramola Foluke Daramola ṣalaye kikun lórí ahesọ àwọn eeyan lorí pé òun ń tọrọ owó fáwọn Baba Feyikọgbọn àti Iya Awerolásìkò ìgbélé coronavirus.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù #AFCONU23Q: Nàìjíríà na Libya lálùdákú pẹ̀lú àmì ayò 4-0 25 Ẹrẹ̀nà 2019 Oríṣun àwòrán, Twitter/NFF Àkọlé àwòrán, #AFCONU23Q Alubami ni ikọ agbabọọlu U23 Naijiria lu akẹgbẹ wọn Libya lati pegede fun ipele to kẹyin si idije AFCONU23 Goolu mẹta ọtọtọ ni ẹlẹsẹ ayo Victor Osimhen nikan gba sawọn Libya ti Naijiria si fagba han akẹgbẹ wọn pẹlu àmì ayò mẹ́rin sodo(4-0).
"Nigba ti agọ ara mi mọ iyipada to de baa lasiko ti ọmọ mi bẹrẹ si ni mu ọyan, n se ni awọn omi ọyan yii maa n san si gbogbo ara mi, ti n kii si ni aaye lati sun, tabi sanra tabi wo ara mi ninu digi.
Ẹgbẹ agbabọọlu Dijon fun Enyeama laye lati wa pẹlu wọn di ipari oṣu yii.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Iléẹjọ́ gíga Akure kọ̀ láti gba onídùróó olórí ìjọ Sotitobire Ọkọ̀ agbépo míràn tún gbiná l‘Eko Ẹ fi èmi àti àwọn alága káńṣù APC sílẹ̀, ká yanjú aáwọ̀ wa nítùbí-ǹnùbí - Makinde bẹ iléẹjọ́ Ìjà dópin, ogun tán lórí ìrọ̀lóyè Trump, ilé aṣòfin àgbà ní kó máa bá iṣẹ́ rẹ̀ lọ Ọlọ́pàá tó pa èèyàn pokùnso lọ́jọ́ kejì tó dé àhámọ́ àwọn ọ̀tẹlẹ̀múyẹ́ Kunle ni oun to yẹ ki ijọba ṣe ni ko ba awọn awọn ileeṣẹ ibanisọrọ wi lori awọn aṣemaṣe ti wọn n ṣe, paapa bi wọn ṣe ma n ja owo awọn onibara wọn ni ijakuja.
Mo tilẹ̀ ti mú ègún wá sórí àwọn ohun ìní yín, nítorí pé ẹ kò fi ọ̀rọ̀ mi sọ́kàn.
Tinubu: Nítorí Tinubu, àwọn ọmọge Sanwo-Olu da ìlù bolẹ̀
Lara awọn iwe idanimọ ti eniyan gbọdọ ni ni Kaadi idanimọ orilẹ-ede Naijira, Kaadi Iforukọsilẹ fun idibo, Iwe irinna ọkọ ati iwe irinna ilẹ okeere.
Oríṣun àwòrán, Twitter/Joe Aribo Senong ṣalaye pe ''Super Eagles ni awọn agbabọọlu to dantọ to to gbangba sun lọyẹ, amọ Lesotho le fagba han Naijiria ti wọn ba mura gidigidi.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Toyin Atoyebi mechanic: Ẹ wo Toyin, ọmọbinrin ọdún 16 tó ń tún skadà àti gẹnẹrátọ̀ ṣe ní NLC ni awọn tele ilana ati alakalẹ ti o ṣe koko ki awọn to gunlẹ iyanṣelodi ni ko jẹ ki awọn tete bẹrẹ ifẹhọnuhan di asiko yii.
Bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé à kò lè fì ìdí rẹ̀ múlẹ̀ irúfẹ́ ẹgbẹ òṣèlú tí àwọn janduku náà ń ṣiṣẹ́ fún, sibẹ ẹgbẹ́ òsèlú PDP àti APC ń nàka àlébù si ara wọn lori isẹlẹ naa.
Kelvin Ikeduba: Oríṣun àwòrán, Kelvin Ikeduba Ilu Eko ni oṣere tiata yii gbe dagba, ti ede Yoruba si da lẹnu rẹ sugbọn ọmọ bibi ipinlẹ Delta ni oun naa n ṣe.
maa dun ikooko mọ awon eniyan.
OLUWA àwọn ọmọ ogun ní, “N óo gbógun tì wọ́n, n óo pa orúkọ Babiloni rẹ́ ati ìyókù àwọn eniyan tí ó wà ninu rẹ̀, ati arọmọdọmọ wọn.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Àlàyé rèé lórí àìyọjú mi síbi ìjíròrò fáwọn oludijè sípò ààrẹ - Buhari Day 28: Ezekwisili, akíkanjú obìnrin tó ń dupò ààrẹ #BBCNigeria2019 Atiku wọ orílẹ̀èdè Amẹ́ríkà lẹ́yìn-ò-rẹyìn Lẹ́yìn osù méjì, kò sọ́nà àbáyọ sí ìyanṣẹ́lódì ASUU Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ezekwesili: Àfojúsùn mi ni láti mú ààbò ẹ̀mí ọmọ Nàíjíríà ní ọ̀kúnkúndùn Ọrọ ti oludije fun ipo aarẹ labẹ asia ẹgbẹ oṣelu Young Progressive Party, YPP, Kingsley Moghalu sọ lori bi Buhari ati Atiku ko ṣe yọju ni JJ Omojuwa fi lede loju opo Twitter.
ere boolu afesegba nile Afrika, lo kora jo si papa isere Agege, niluu Eko, lojo
Awọn òṣiṣẹ nipinlẹ Ọṣun ti kede lati bẹrẹ iyanṣẹlodi.
Ọ̀kan ninu àwọn angẹli meje tí wọ́n ní àwo meje náà tọ̀ mí wá, ó ní, “Wá kí n fi ìdájọ́ tí ń bọ̀ sórí gbajúmọ̀ aṣẹ́wó náà hàn ọ́, ìlú tí a kọ́ sójú ọpọlọpọ omi.
Gẹgẹ bi iroyin naa se wi, nibi ayẹyẹ ọjọ ibi ọgọta ọdun Olu tilu Itori, Ọba Abdulfatai Akorede Akamọ ni isẹlẹ naa ti waye, lasiko ti wọn pe Kwam 1, ko wa kọrin nibẹ.
I'll sign in later And we'll keep you signed in.
Òun ni ó jẹ oró ikú, tí Ọlọrun tún wá fi ògo ati ọlá dé e ládé.
Seun Egbegbe Gbajumọ laarin awọn oṣere tiata Yoruba ni Olajide Kareeem, ti ọpọ eeyan mọ si Seun Egbegbe jẹ, koda o gbajumọ to bẹ ti awọn olorin kan ma n kan sara ninu awo wọn.
 a lè fún àwọn ọmọ tó ti dàgbà díẹ ̀ síi àti àwọn àgbàlagbà ní àfikún ìwọ ̀ n egbògi .
Lara awọn ẹru to ni wọn ti ri pada naa ni kẹkẹ ẹlẹsẹ mẹta atawọn ohun elo amohun bu gbamu to jẹ ti ileeṣẹ Calabar International Conference Centre, CIIC.
Nítorí ó níláti jọba títí Ọlọrun yóo fi fi gbogbo àwọn ọ̀tá sí ìkáwọ́ rẹ̀.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Yorùbá tone mark: Fífi àmì ohùn sí orí ọ̀rọ̀ Yorùbá ṣe pàtàkì Bayii, wọn ti tun iṣẹ abẹ pipaarọ kindinrin fun ẹni ti wọn fẹ ṣee fun gangan lọsẹ to tẹlee.
soju ẹgbẹ oselu tabi oludije ni ibi ti wọn ti n ka ibo ni ọjọ idibo.
Awọn onwoye ni apejuwe yi se rẹgi paapa julọ ta ba n sọrọ nipa Aarẹ Musulumi tẹlẹ fun gbogbo ilẹ Yoruba.
Ó ní owó ohun ni ìjọba pín fún ileesẹ tó wà fún ohun amusagbara, isẹ òde, eto ìlera, ètò ẹ̀kọ́ àti ohun àlùmọ́ọ́nì inú omi láti fi ṣe àkànṣe isẹ.
Nítorí olóríkunkun ni wọ́n,àwọn alaiṣootọ ọmọ!
Wọ́n kó owó náà fún àwọn tí ń ṣe àbojútó iṣẹ́ náà.
Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kan 27 Agẹmo 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn wákàtí kan sẹ́yìn Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kan Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí kan sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
Ọjọ meji ni aisan to ṣe Oriṣabunmi fi ṣe, gẹgẹ bi aburo rẹ, iyaafin Toyin Akinoso ṣe ṣalaye fun ileeṣẹ iroyin abẹle kan.
Kàkà bẹ́ẹ̀, ó dà á sílẹ̀ gẹ́gẹ́ bí ẹbọ ohun mímú fún OLUWA.
Wọ́n sọ ọ́ di ahoro,ilẹ̀ pàápàá ń ráhùn sí mi.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Láì lo Kakulétọ̀, mo ní ọpọlọ ìṣirò, tábìlì ìṣirò wà lórí mi - Human Calculator Eré apanilẹ́rìn ké kè ké lórí ayélujára ti ṣí ọ̀pọ̀ ìlẹ̀kùn fún mi - Mr Macaroni Chatta bímọ tuntun, Mide àti Osupa lẹ̀pọ̀, Sanwo-Olu fún Sola Sobowale lámì ẹ̀yẹ Osinbajo wọ́gilé ìrìn-àjò rẹ̀ lẹ́yìn tí ọ̀kan lára ẹ̀ṣọ́ rẹ̀ kú nínú ìjàmbá ọkọ̀ Iroyin ohun jade wi pe, Gomina Fayemi ni wọn lo fi iwe wawitẹnurẹ ranṣẹ si awọn ọba mẹrindinlogun ni ipinlẹ nitori wọn kọ ọrọ si oun lẹnu.
Gbajumọ osere naa ni lẹyin ti oun fi aworan naa sori ayelujara ni ẹrọ ibaraẹnisọrọ oun ku, tawọn eeyan ko si le kan si oun, eyi to mu ki ibẹru gba ọkan wọn.
Akosemose oro oja idokowo kan, ogbeni Peter Ashade ti ro eka onile-ise aladani ati ti ijoba lati fowosowopo mu igberu ba eto oro-aje ati idagbasoke orile-ede Nigeria.
Lẹ́hìn ìgbà tí olúkúlùkù lọ sí ilé rẹ̀ tán, bàbá mi kó àwọn ohun àlùmọ́nì tí wọ́n fi ta á lọ́rẹ jọ, eléyìínì sì mú kí ó di olówó fún ọjọ́ pipẹ́.
Èyí ọkùnrin sì dá mi lóhùn, ó ni, ‘Àlaafìà ni.
Ẹbọ ohun jíjẹ tí ẹ óo rú pẹlu wọn ni ìyẹ̀fun tí a fi òróró pò, ìdámẹ́wàá lọ́nà mẹta òṣùnwọ̀n efa fún akọ mààlúù kan, ati ìdámárùn-ún òṣùnwọ̀n efa fún àgbò kan, 
Ẹniọwọ Ọnaiyekan ba awọn oniroyin sọrọ ṣaaju ipejọpọ ijọ Katoliiki lati sọrọ lori bi awọn eeyan ṣe n lọ kuro lorilẹede Naijiria eleyii ti wọn fẹ ṣe ni ọjọ iṣẹgun.
Ìwádìí BBC lórí àbẹwò sórí ìtàkùn àgbáyé ti fìdí rẹ̀ múlẹ̀ pé, àwọn tó ń wádìí òògùn ìṣẹ́yún lóri ẹ̀rọ ayélujára lágbàyé láti ǹkan bí ọdún mẹwàá sẹ́yìn tí di ìlópo méjì.
OLUWA sì ti fi ìjọba rẹ fún Absalomu, ọmọ rẹ, ìparun ti dé bá ọ, nítorí pé apànìyàn ni ọ́.
Coronavirus: Ẹ wo ọ̀nà tí ọrọ̀ ajé Náíjíríà tó dẹnu kọlẹ̀ yóó fi ṣàkóbá fún aráàlú
Ọwọ́jà coronavirus yóò ṣì wà pẹ̀lú àgbáyé fún ìgbà pípẹ́- Ngozi Okonjo-Iweala Ọba Lamidi Adeyẹmi, òṣìṣẹ́ adójútòfò àti Abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò kó tó jọba Wo ìtàn ọgọ́ta ọdún Nàíjíríà nínú àwòrán mẹ́fà péré Àwọn Ọba Yorùbá kan rèé tí wọ́n rọ̀ lóyè, tí ọba míràn jẹ lójú ayé wọn Bawo ni Fatai Rolling Doller ṣe bẹrẹ iṣe orin gangan?
Ìròyìn ikú ọmọ Dbanj jẹ́ nnkan tí o kò òpó ọmọ orílèèdè Nàìjíríà nínú.
Omowe  Adesina ni oun ti gba awon adari
 ní ọdún 2010 ó fa ikú àwọn ènìyàn tí ó tó 9,000 , èyí tí ó wálẹ ̀ láti iye ènìyàn tí ó tó 34,000 ní ọdún 1990 .
Ogbeni Charles Aniagwu to jẹ agbẹnusọ fun ijọba ipinlẹ Delta ṣalaye fun BBC pe ijanu ọkọ naa ja mọ awakọ naa lọwọ lasiko to n yago fun koto loju titi naa ni ti o si fa ijamba ọhun.
Mọ̀mọ́ Bámidélé aya Ọlátẹ́jú, Bàbá Abímbọ́là Olújídé
Àwọn àgbà Yorùbá ni wọ́n wí bẹ́ẹ̀.
Bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé ọpọ àwọn àgbà òṣèré tíátà náà tí jáde láyé, tí àwọn míràn nínú wọn sì wà lókè eepẹ, síbẹ̀ àwọn ọmọ tí wọn fi iṣẹ lé lọ́wọ́, sì ń ṣe ilédè lọ lẹ́yìn wọn lagbo tíátà.
Ohun ti a gbọ lati ọdọ ajọ eleto idibo orilẹede Ghana, EC ni pe ibo kika si n lọ lọwọ nibi ti w\\\\on ti n ṣe akojọpọ esi niluu Accra.
Ojo kejo niyi ti iyanselodi naa ti bere ni  gbogbo awon ile-iwosan ijoba patapata .
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ọla Adedibu ní Ladoja jẹ̀ tó fi wọlé Gómìnà l‘Oyo labẹ ẹgbẹ́ PDP - Obasanjo Ẹ̀sìn kò fàjà!
A máa fi ẹgbẹrun (1,000) ẹran rú ẹbọ sísun lórí pẹpẹ náà.
Ọjọ keje oṣu kejila ni awọn ara Ghana yoo lọ dibo lati yan adari tuntun fun orilẹede wọn bẹẹ si ni ẹni to wa lori alefa lọwọ lọwọ yii, Nana Akufo-Addo n ni ireti pe labẹ ẹgbẹ oṣelu NPP, oun yoo le ṣe saa keji.
Wọ́n rin etí odò yìí wò, wọ́n rìn síwá wọ́n rìn sẹ̀hìn bẹ́ẹ̀ ni odò náà mọ́lẹ̀ bí i dígí, gbaǹgba ni wọ́n sí ń wo àwọn ẹja wọn-ọnnì bí wọn ti ń tẹ̀lé ara wọn káàkiri inú omi.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, APC: òfin NYSC ti APC fi mú mi ni wọ́n kò lò fi mú Ajimọbi tí a kò jọ sìnrú ìlú Eto idibo naa o waye lọjọ kẹtaleogun, oṣu keji ọdun 2019.
Ẹ́ wo ìrírí tó mú àgbà òṣèré Chief Kanran dí ẹni tí kò rí ilé gbé mọ́, ti irinṣẹ́ jóná Ohun tí a mọ̀ nìyí nípa gbọ́nmi síi omi ò tó lórí ọ̀rọ̀ oyè Babaloja-General ní ìpínlẹ̀ Oyo YWC yọ Ààrẹ Banji Akintoye nípò àbi Akintoye tú ìgbìmọ̀ aláṣẹ YWC ká?
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Mo gbọ́dọ̀ fún ọ lóyún ká tó kúrò nílé BB Naija - Neo sọ fún Vee Tinubu, yé é sọ̀rọ̀ abẹ́lẹ̀, bọ́ sí gbangba láti bèèrè àtúntò Nàíjíríà lọ́dọ̀ Buhari - Afẹnifẹrẹ Wo àànfàní ‘Masturbation’, fífún ara rẹ̀ ní adùn ìbálòpọ̀ Wo àwọn ìlànà tuntun ti o gbọdọ tẹlèé rèé ki ó to le wọkọ̀ òfurufú lọ sókè òkun Ìdí ti mo fi da sọ́ọ̀sì rú lásìkò ìgbéyàwó ìyáwó mi tó ló fẹ́ ọkọ míran- Osadebe Nínú ìwé ìfilọ̀ náà, ti wọ́n pe àkọle rẹ̀ ni ìwádi abẹ́nú lori ọ̀rọ̀ ààbò ìlú"", ileesẹ asọbode ni ìròyìn to ń tẹ̀ òun lọ́wọ́ gẹ́gẹ́ bi ọ̀gá àgba ilé iṣẹ́ yìí fihan pé, àwọn ikọ̀ ọmọ ogun Boko Haram ti wà ní ilu Abuja àti gbogbo agbègbè rẹ̀."
Bótilẹ̀ jẹ́ pé ìjọba kò sọ ìdí pàtó to fi tilẹ̀kùn, nínú àtẹjáde ti kọmísọ́nà ètò ẹkọ́ Muhammed Sanusi fi síta, ọ̀kan lára àwọn òṣìṣẹ́ ilé isẹ́ náà to ba BBC sọ̀rọ̀ ṣàlàyé pé nítori ọ̀rọ̀ ààbò ni wọ́n ṣe tilẹ̀kùn ilé ìwé, pàápàá jùlọ oun ati Katsina jọ pààlà pọ̀.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, INEC ní àjọṣepọ̀ tó rinlẹ láàárín àjọ náà àtàwọn agbófinró ni wọ́n yóò fi k'ápá ìbò rírà Mahmood Yakubu, ti alákòóso fún ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́, Èkìtì, Ọ̀ṣun àti Òǹdó sojú fún, ṣàlàyé pé àjọṣepọ̀ tó rinlẹ ̀láàárín àjọ náà àtàwọn agbófinró ni wọ́n yóò fi k'ápá rẹ̀.
ENDSARS: Ẹ̀yin ọmọ Nàìjíríà, ẹ ṣè ìrànwọ́ irinṣẹ́ fáwọn ọlọ́pàá- Naira Marley bẹ̀bẹ̀ Ààrẹ Donald Trump ti padà sí ilé ìjọba lẹ́yìn ọjọ díẹ̀ tó lùgbàdì ààrùn coronavirus Ẹ̀wọ̀n ni wàá gbẹ̀yìn sí, kò sí bóo ṣe dọ́gbọ́n tó - Seyi Makinde wa ègúná ọ̀rọ̀ lé Fayose Ẹkunrẹrẹ alaye nipa ilana owo osu tuntun fawọn olukọ: Ijọba yoo ṣe agbekalẹ ilana tuntun ti wọn yoo gba lati ma a san owo oṣu awọn olukọ Nibayii, ijọba ti fi ọdun marun kun ọjọ ori ifẹyinti awọn olukọ lati ọgọta ọdun si marundinlaadọrin Bakan naa ni wọn ti fi kun iye ọdun ti olukọ yoo fi ṣiṣẹ ko to fẹyinti, lati ọdun marundinlogoji si ogoji ọdun Awọn olukọ to wa ni igberiko yoo ma gba owo iranwọ pataki Ijọba yoo fikun owo iranwọ imọ sayẹnsi Awọn olukọ yoo ma a gba owo iranwọ pataki Awọn ọmọ olukọ yoo ma lọ si ileewe lọfẹ ni ileewe ti awọn obi wọn ti n ṣiṣẹ Wẹrẹ ti awọn akẹkọọ imọ ẹkọ olukọ ni fasiti ba ti n jade ni ileewe giga, ni wọn yoo ma ri iṣẹ gba lọwọ ijọba Awọn akẹkọọ imọ ẹkọ yoo ma gba owo iranwọ pataki lasiko ti wọn ba wa ni fasiti Owo ami ẹyẹ pataki yoo wa fun awọn akẹkọọ imọ ẹkọ ni fasiti Ijọba yoo ma lo owo iranwọ TETFund lati fun awọn olukọ ni ẹkọ imọ ti wọn nilo lati ṣe iṣẹ wọn bi iṣẹ Awọn akẹkọọjade ni fasiti to yan isẹ olukọ laayo yoo ma tete ri iṣẹ gba lọwọ ijọba Owo iranwọ pataki yoo wa fun awọn olukọ to ti ṣiṣẹ fẹyinti ni Naijiria.
Neri ni ó bí Kiṣi, Kiṣi bí Saulu, Saulu ni baba Jonatani, Malikiṣua, Abinadabu, ati Eṣibaali.
” “ojo kejila, osu kefaa , ni ogunlogo awon omo orile ede Naijiria jade lati fi ehonu won han lori ibo ti won di ni alaafia, irorun , tiko ni mogo-mogo ninu,ti ko si tun si iru ibo bee lati igba ti a ti gba ominira, sugbon ti ijoba ologun fagile.
''A rọ araalu lati yago fun fifi owo abẹtẹlẹ lọ awọn agbofinro wa.
Láìka àwọn iranṣẹkunrin ati àwọn iranṣẹbinrin wọn tí wọ́n jẹ́ ẹẹdẹgbaarin ó lé ojilelọọdunrun ó dín mẹta (7,337).
18 Pa àwọn òfin mi mọ́; pa ẹnu rẹ mọ́; bẹ ẹ̀bẹ̀ sí Ẹ̀mí mi;
O sọrọ nipa ibaṣepọ to wa laarin oun ati awọn ẹbi Mufutau ni Saki ni eyi ti o dara pupọ.
Ọ̀daràn tó wà lẹ́wọ̀n tún wọ́'ke $100miílíọnu - EFCC Oríṣun àwòrán, EFCC Àkọlé àwòrán, Ọdaran tó wà lẹ́wọ̀n tún wóke $100miílíọnu níta-EFCC Ajọ to ń gbógun ti ìwà jẹgúdújẹra ní orílẹ̀èdè Naijiria (EFCC) ní àwọn tí rí àsírí Hope Olusegun Aroke tí wọ́n jù sí ẹwọ̀n ọdún mẹ́rìnlélógun fún ìwà ọdàràn gbájuẹ̀ orí ayélujára pé o tún ni ibánisọrọ kíkún pẹ̀lú àwọn ọdàran mìíràn ti wọ́n si n ṣe ìwádiìí wọ́n lọ́wọ́.
Bẹẹ ba si gbagbe, gbajumọ osere tẹlẹ naa lo fẹ ọkan lara awọn osere tiata lobinrin, Ayo Adesanya, ko to di pe aarin wọn daru.
Burẹdi tí a bù, ṣebí àjọpín ninu ara Kristi ni.
Ni afikun, ipinle Yola ati Enugu ni o ni akosile ti o kere ju mita merinlelogun ninu ida ogorun ati iko mejidinlogbon ninu ida ogorun mita naa.
H Khobo tó paada wá gbẹ́jọ náà sún ìgbẹ́jọ náà síwájú dí ọjọ́kọkàndílọ́gbọ̀n 2019.
Ọkọ ofurufu ọhun gbe oku eeyan nigba ti iṣẹlẹ naa ṣẹlẹ.
Eefin ti awọn ọmọ naa fin si imu lo ṣeku pa wọn.
Nígbà tí Noa di ẹni ẹẹdẹgbẹta (500) ọdún, ó bí Ṣemu, Hamu ati Jafẹti.
"Oríṣun àwòrán, Aisha Buhari Àkọlé àwòrán, Aisha Buhari: Aya ààrẹ orilẹ̀-èdè Naijiria ke gbàjare lori eto ijoba Buhari O ní ""mó rò pé ó yẹ kí wọn lo onírúurú ọ̀nà láti pín ẹ̀ẹ́dẹ́gbẹ̀tá bílíọ̀nù Naira láti ṣe àṣeyori lori ètò náà, ṣùgbọ́n ìlànà ti wọn lò kò yé mi rárá."
Wọ́n ń táràrà ninu òkùnkùn,ó sì mú kí wọ́n máa ta gbọ̀n-ọ́n-gbọ̀n-ọ́n bí ọ̀mùtí.
Ní bayii o ti di ènìyàn òjìlélọ́ọ̀dúnrun àti mẹta to ti ni ààrun coronavirus ni Naijiria, ẹniyan mọ́kànléláàdọ́rún ló ti gba ìtúsill lọ́wọ́ ààrun náà ti ènìyàn mẹ́wàá si ti ba ààrun náà lọ Ipinlẹ mọkandínlogun ni ààsùn náà de dúró.
'Fun emi gẹgẹ bi ẹnikan, ko ṣeesẹ fun mi lati yan ẹnikan laarin Aarẹ Muhammadu Buhari ati Atiku Abubakar - awọn mejeeji lo ni ìtàn to n tọ wọn lẹyin, eyi to mu ki eeyan wa ọna abayọ mi.
Ọrísìírírìí ni wọ́n ṣe létò, àmọ́ èyí tó pabambarì ni Batala tí í ṣe ẹgbẹ́ onílù.
nitori pe ekute lo n tan iba Lassa kaakiri.
Àwọn ọmọ Abrahamu ni Isaaki ati Iṣimaeli.
Òṣèré tíátà míì ń ṣàìsàn láti bí ọdún mẹ́ta, ọkan rèé tó ń bẹ̀bẹ̀ f'ówó Ẹsun akọkọ ni pe olori ile ni apo asunwọn owo mẹrinlelọgọta ni banki, eyi to ni nọmba BVN kan ṣoṣo.
Africa yoo tun ya gbogbo awon eniyan lẹnu gẹgẹ bi ise won , nigba ti won ba n
Ó ní òun óo gba àwọn eniyan òun là láti orílẹ̀-èdè tí ó wà ní ìlà oòrùn ati ti ìwọ̀ rẹ̀, 
Nígbà tí ẹnìkan ninu àwọn tí ó wà níbi àsè gbọ́ ọ̀rọ̀ yìí, ó sọ fún Jesu pé, “Ẹni tí ó bá jẹun ní ìjọba ọ̀run ṣe oríire!
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Alaafin: Olori Aanu Adeyemi ṣàlàyé ìdí tó ṣe gẹ́ Oba Lamidi Adeyemi ti ìlú Oyo Agbẹnusọ ile ẹjọ giga ilu Kano sọ fun BBC pe, arakunbrin ọhun lẹtọ lati pe ẹjọ kotẹmilọrun lori idajọ iku naa.
 Foluke Daramola ni: Kódà èmi àti ọnku Laary ń jó papọ nínú fídíò tí mo gbé síta ni, tí wọn sì sọ fún mi pé àwọn fẹ́ ṣe filọlẹ ìwé táwọn kọ nígbà tí Ìyá Awero ní àwọn fẹ́ ṣe ọjọ́ ìbí.
Bo tilẹ jẹ́ pé àwọn ọkunrin o fẹ́ gba èyi síbẹ̀ o ni o pọ́ndandan nítori àwọn orilẹ-èdè àgbáye toku ti kúrò ni ipele yìi'.
MMM ṣeleri lati fun awọn oludokowo ni ele ìdá ọgbọn (30%) lori iyekiye ti wọn ba fi dokowo.
Ọpọlọpọ yóo wá ní orúkọ mi tí wọ́n yóo wí pé àwọn ni Kristi.
Ewe, lai fi akoko sofo lori oro naa, ogbeni Dogara sagbekale iwe ateranse ohun fun awon asofin akegbe re lati jo jiroro lori ojo naa, eleyi ti oro ohun si fa ariyanjiyan lataari bi ile igbimo asofin agba se fi oro ohun fale di asiko yii.
Sunday Igboho: N kò gba kọ́bọ̀ lọ́wọ́ ẹnikẹ́ni láti wá ọ̀daràn jáde nínú igbó Kishi
Èyí sì ni òfin tí ó jẹmọ́ àìmọ́ rẹ̀, nítorí nǹkan tí ó ti ara rẹ̀ jáde; kì báà jẹ́ pé ó ń dà lọ́wọ́ lọ́wọ́, tabi ó ti dà tán, nǹkan tí ó dà yìí jẹ́ àìmọ́ lára rẹ̀.
Amọ lẹyin o rẹyin, ile asofin ati ẹka alasẹ ipinlẹ Oyo fi ọgbọn agba yanju ede aiyede naa, to si yanju nitubi n nubi.
'Ohun tí àwọn adarí ilẹ̀ Europe fẹ́ jẹ ni wọ́n fi ń wá sí Nàìjíríà'
Àmọ́ ṣá, Yoòbá ti wípé ojú l’alákàn fi ń ṣọ́rí.
 olú-Ìwà ni ẹni tó ṣe atọ ́ nà wọn wá sí ilẹ ̀ Ìjẹ ̀ bú .
Oun ni aṣoju orilẹede Naijiria ni ajọ iṣọkan agbaaye laarin ọdun 1990 si ọdun 1999.
Àwọn àgbààgbà mẹrinlelogun náà ati àwọn ẹ̀dá alààyè mẹrin náà bá dojúbolẹ̀, wọ́n júbà Ọlọrun tí ó jókòó lórí ìtẹ́.
Ìwọ́de PDP ṣaaju idibo Ekiti Ẹgbẹ alatako gboogi lorilẹ-ede yii, PDP, ti n pọnju kẹkẹ si rogbodiyan to waye ni ipinlẹ Ekiti ni ọjọbọ, ti wọn si n kede pe eto iselu wa ni Naijiria n mi lẹsẹ.
Àwọn ọmọdé á lọ lati ilé ẹbi kan si ekeji, ẹbi ti wọn lọ ki, á fún wọn ni oúnjẹ àti owó ọdún.
Ìbéèè yìí ló gba ayé kan nígba tí àwọn fọ́to ṣàfihàn rẹ ninu ìsìn tó wáyé nílé ìjọsìn tó wà nínú ilé ijọba ìpínlẹ̀ náà ní Owerri l'ọ́jọ́ Aiku.
Èmi ni ẹbora kékeré inú ọ̀gán, orúkọ ẹni tí ń jẹ Èṣù-kékeré-òde.
O ni oun ko ni buwọlu eto isuna naa, ti ko ba ya owo nla sọtọ lati se atunse awọn ileẹkọ giga wa.
Ai ṣe ojúṣe Ìjọba nipa ipèsè ilé-iwòsàn ti ó péye, Ilé-iwé, omi mimu àti ohun amáyédẹrùn yoku jẹ ki iṣẹ́ pọ fún olóri ẹbi.
Wọ́n dá a lóhùn pé, “Àwọn kan ní Johanu Onítẹ̀bọmi ni.
Nígbà tí Pọtifari ti fi Josẹfu ṣe alabojuto ilé rẹ̀ ati gbogbo ohun ìní rẹ̀, OLUWA bẹ̀rẹ̀ sí bukun ìdílé Pọtifari, ará Ijipti náà, ati ohun gbogbo tí ó ní nítorí ti Josẹfu.
Kò lè ṣe iṣẹ́ ìyanu pupọ níbẹ̀ nítorí wọn kò ní igbagbọ.
Dáúdà ní rọ́bà tí ó máa ń fi pa ẹmọ́ kiri ní ẹ̀yìnkùlé.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Osun Election 2018: Wọ́n ṣe ìbúra fún Oyetọla gẹ́gẹ́ bí gómìnà tuntun 28 Owewe 2018 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 27 Bélú 2018 Oríṣun àwòrán, Gboyega Oyetola/Facebook Àkọlé àwòrán, Oyetola je olori awọn osisẹ ni ọfisi Gomina Aregbesọla.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Victoria Kolawole: Òṣèré tíátà Yorùbá ní òun kò tíì ṣe ìgbéyáwó àmọ́ òun kò wá ọkọ'' 9 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Oríṣun àwòrán, Instagram/victoriakolawole Oṣere tiata Yoruba Victoria Kolawole sọrọ o fa komookun rẹ yọ ninu ifọrọwerọ pẹlu BBC Yoruba.
Ọkọ ìyàwó ẹlẹ́kún: N kò bá tí ba ẹnu jẹ́ lọ́jọ́ ìgbeyàwó, àwàdà ni mo se
Ènìyàn pàtàkì gbáà ni Ibrahim jẹ́ lórí orílẹ̀ ayé yìí.
Koda, Ọgbẹni Adeoti ti yan ẹgbẹ oselu ADP lẹbi tuntun ti o si ti kede idarapọmọ ẹgbẹ naa.
Lara ohun to ṣe ni pe o kede konile-o-gbele, O tun fi ofin de ipejọpọ ọpọ eniyan, o ti gbogbo ileewe pa, o ti gbogbo ẹnu ibode ipinlẹ naa, Bakan naa lo tun kede pe oun ti fun awọn arugbo àti aláìní ni oúnjẹ ọ̀fẹ́.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ǹjẹ́ o mọ̀ pé orin gbígbọ́ dara fún ọpọlọ ọmọ ìkókó?
A padà san owó ìtanràn fáwọn ajínigbé kí wọ́n to fi àwọn mẹ́tẹ̀ẹ̀ta sílẹ̀- Ẹbí Oga ọlọpaa naa ni ki awọn ọkunrin to n lu aya lọ wagbo dẹkun fun iru iwa yii, nitori o maa n la ẹmi lọ.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Atẹjade kan ti ajọ United Nations fi sita lọjọ Aiku, wa bu ẹnu atẹ lu iwa ipa, rogbodiyan ati pakaleke to gba ilẹ kan ni tibu-tooro orilẹ-ede Naijiria ati awọn orilẹ-ede to yii ka.
Awọn ara adugbo naa ni, ki lo de to jẹ pe gbogbo awọn ni yoo jiya ẹsẹ ti awọn ọdọ kan da, wọn fikun pe, ko si ni dara ki ajọ IBDEC ba ẹnikan ja, ki wọn wa fi ọwọ gun gbogbo ile nimu.
Sibẹ awọn orilẹ-ede kan ni ilẹ Adulawọ wa to n fi aaye gba irinajo si ọdọ wọn lai gba iwe aṣẹ igbelu tabi iwe iwọle niwọn igba ti paali irinajo to pe ye ba ti wa.
'Kò ní sí ìdíwó mó nínú ìṣàmúló ètò ìṣúná ìpínlẹ́ Oyo' Olúbàdàn, ẹ bá wa bẹ́ Seyi Makinde kó tú wa sílẹ̀ - Oyo NURTW Gbogbo ohun tó bá gbà lá máa fún un láti wa àwọn agbébọn náà- Ọlọ́pàá Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ọrọ rè láti ẹnu àwọn Agbẹjọ́rò Makinde àti Adelabu nípa ìdájọ ọ́rọ́ ìdìbò Gómìnà Oyo Asiwaju Adekola Adeoye ni olori ọdọ ẹgbẹ to jẹ kan lara awọn to farapa ninu ijamba kọ naa to si ti n gba itọju nile iwosan.
@ Awon omo oloogun  ati  @olopaa Naijiria ti pinnu lati satileyin fun gomina @SimonLalong, lori  igbiyanju re  lati dekun ikolu buruku yii, ki a si pese ohun amayederun fun awon agbegbe ti isele burku yii sele si.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Poly Ibadan: Lóòtọ́ ni a dáná sún fóònù àwọn akẹ́kọ̀ọ́ tó ṣe màgòmágó nínú ìdánwò 11 Agẹmo 2019 Oríṣun àwòrán, polyibadan Àkọlé àwòrán, Ile ẹkọ gbogboniṣe Poly Ibadan ni ofin ileewe ko fayegba ki akẹkọ gbe ẹrọ ibanisọrọ wọ yara idanwo Ko si irọ nibẹ, a dana sun foonu awọn akẹkọ wa ti wọn tapa si ofin pe ki wọn ma ṣe gbe ẹrọ alagbeka wọ inu yara idanwo.
Àwọn ipinlẹ̀ Yorùbá́ ti gbádùn ohun amáyédẹrùn igbàlódé fún ọjọ́ ti pẹ́, nitori èyi ni a ṣe mbẹ̀ àwọn Gómìnà ipinlẹ̀ Yorùbá pé ki wọn pèsè ‘’omi mi mun’ fún ará ilú gẹ́gẹ́ bi ẹ̀tọ́ lati dá àṣà gbi gbẹ́ ilẹ̀ bi ti Òkété lati wa omi ti kò ṣe e mu ni ọ̀pọ̀ igbà.
Jọ̀wọ́ mú àgbéga bá ojú òpó tó ń gbà wọlé láti ka àwọn ìròyìn yìí Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
‘N óo fi ìdí àwọn ọmọ rẹ múlẹ̀ títí lae,n óo sì gbé ìtẹ́ rẹ ró láti ìran dé ìran.
Guru Maharaj, Gani Adams ati àwọn eekan ilú ló péjú síbi ayẹyẹ ọjọ́ ibi rẹ̀ ni inu oṣu kejila ọdun to kọja.
"Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 2020 in Retrospect: Ìjàmbá iná, ilé tó dàwó, ìwọ́de àti àrùn Covid-19 wà lára ìṣẹ̀lẹ̀ 2020 Ipa wo ni iku Adewole Oniluola yoo ni lori iran Yoruba: Kelani ni ""Isẹlẹ yii n powe fun awa ọmọ Yoruba pe nnkan meremere ti Ọlọrun fun awa ọmọ Yoruba ti n lọ diẹdiẹ niyẹn."
Bí wọ́n ti jáde kúrò ninu ilé ìpàdé, Jesu pẹlu Jakọbu ati Johanu lọ sí ilé Simoni ati Anderu.
Nígbà náà ni Finehasi ọmọ Eleasari, alufaa, ati àwọn olórí kúrò lọ́dọ̀ àwọn ẹ̀yà Reubẹni, ati ẹ̀yà Gadi, ní ilẹ̀ Gileadi; wọ́n pada lọ sí ọ̀dọ̀ àwọn ọmọ Israẹli ní ilẹ̀ Kenaani, wọ́n sì jíṣẹ́ fún wọn.
Ìrísí rẹ̀ bá yipada lójú wọn.
Lẹnu igba ti aawọ laarin Gomina Godwin Obaseki ati alaga ẹgbẹ Adams Oshiomole bẹrẹ yi, a ti ri itu orisirisi lati ọwọ awọn to n kopa ninu ohun to fẹ jọ ere ori itage yii, sugbọn to se pe awọn oloselu ni oṣere to wa ninu rẹ.
Ti awọn onimọ ba ri ayẹwo to poju owo ṣe lati mọ ni to ni arun yi eleyi yoo ṣe anfaani to pọ lati mọ bi arun naa ṣe n tan kaakiri si.
 Siwaju si I, mo lero pe , ti a ba  be igbese to tako ofin egbe , a je pe a n fi ipo pataki ti egbe wa, wa sinu ewu”.
O ni ọm ipinlẹ Ọyọ ni gbogbo awọn oludije ti awọn jọ joko, ẹgbọn ati aburo si ni gbogbo awọn.
Ti eeyan ba feran ko ma ma jẹ ounjẹ aarọ,akoba ọlọjọ pipẹ ni eyi lè mu ba ọpọlọ rẹ.
n reti lati tubo ba orile ede Naijiria se isẹ papọ, ni eyi ti ibasepo to wa
Ni bayii, Super Eagles yoo tun maa gbaradi fun ifesewonse olorejore miran pelu Serbia ti yoo waye nilu London lojo Isegun(Tuesday), beesini Poland yoo maa waako pelu South Korea ni papa isere Silesian.
Ènìyàn 14 kú ní ìjàmbá iná Borno Àdó olóró parí ọdún ìtúnu ààwẹ̀ Ramadan Ọmọ 37,000 yóò jànfani ẹkọ́ ọ̀fẹ́ ní Borno Ajọ agbaye bu ẹnu atẹ lu isekupa osisẹ mẹta Àwọn jàndùkú dáná sun àwọn arìnrìnàjò lásìkò tí wọ́n sùn nínú ọkọ ní Borno Nigba to n fidi isẹlẹ naa mulẹ, Kọmisana ọlọpaa nipinlẹ Bornu, Mohammed Aliyu ni igba mẹta ni ado iku dun gbamu nilu naa.
Oríṣun àwòrán, onogwuMuha Àkọlé àwòrán, Ti pali ti pali ni wọn ji ẹrọ ayẹwo ara olowoiyebiye yi gbe bakan naa ni Lokoja Oríṣun àwòrán, afamefuna.
Ọ̀pọ̀lọpọ̀ rò wi pé nitori Amẹ́rikà ti nṣe Òṣèlú ti wa ntiwa fún igbalélógòji ọdún, ẹni ti wọn yio yan si irú ipò yi á ni iwà àkójọ àti ẹ̀mi àkóso si onírúurú àwọn enia ti ó wà ni gbogbo àgbáyé.
Ṣugbọn mo ní igbẹkẹle ninu Oluwa pé èmi fúnra mi yóo wá láìpẹ́.
Àwọn ará ìlú Israẹli yóo tú síta, wọn yóo dáná sun àwọn ohun ìjà ogun: apata ati asà, ọrun ati ọfà, àáké ati ọ̀kọ̀.
Wọn fi lede wi pe kokoro wa ninu irẹsi naa, ti o si fihan gbangba pe awọn ounjẹ naa ti bajẹ.
"Minisita fun ọrọ abẹnu, Kazembe Kazembe sọ lọsẹ to kọja pe ""ko sohun to jọ mọ ifipagbajọba."
Lara awọn eto naa ni ifẹsẹwọnsẹ laarin ikọ ogogo, (Ogogo All stars) ati ikọ to jẹ ti olori ile aṣofin ipinlẹ Eko, ( Obasa All stars).
Kì báà jẹ́ pé ninu ọ̀rọ̀ wa tabi ninu Ẹ̀mí ni wọ́n ti rò pé a sọ ọ́, tabi bóyá ninu àlàyékálàyé kan tabi ìwé kan tí wọ́n rò pé ọ̀dọ̀ wa ni ó ti wá.
Wọn gbọdọ to tabili takete si ara wọn pẹlu mita marun-un, bẹẹ ni awọn ijoko gbọdọ jina sira wsn ni iwọn mita meji.
Àwọn adẹ́tẹ̀ pọ̀ ní Israẹli ní àkókò wolii Eliṣa.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Temitope Akinnusi: Ọ̀pọ̀ iléeṣẹ́ ló takú láti gbà mí síṣẹ́ torí mo ní ojú kan Ààrẹ Buhari pọ́n ọ̀dọ́ Nàíjíríà lé, ó ya Nov 1st sọ́tọ̀ fún àyájọ́ ọ̀dọ́ Oríṣun àwòrán, Kunle Adeleke Aarẹ Muhammadu Buhari ti fọwọ si yiya ọjọ kan sọtọ lọdun lati maa ṣe ayajọ ọjọ awọ ọdọ jakejado Naijiria.
Onigbagbọ Ododo ati Kristẹni Ṣaaju ogun abẹle, Ọgbẹni Nkurunziza lẹyin to kẹkọọ gboye ninu imọ ikọni ere idaraya, o ṣe iṣẹ olukọni ni fasiti Burundi.
Baaṣa gbógun ti ilẹ̀ Juda, ó sì bẹ̀rẹ̀ sí mọ odi yí Rama po, kí ẹnikẹ́ni má baà rí ààyè lọ sí ọ̀dọ̀ Asa, ọba Juda, tabi kí ẹnikẹ́ni jáde kúrò lọ́dọ̀ rẹ̀.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ẹgbẹ́ Akọ́mọlédè: A kan sáárá sí ìpínlẹ̀ Eko fún sísọ èdè Yorùbá di dandan nílé ẹ̀kọ́ 7 Ògún 2019 Aarẹ ẹgbẹ Akọmọlede ati Aṣa, Arabinrin Ọmọwumi Falẹyẹ ti parọwa si awọn ijọba ipinlẹ to wa nilẹ Kaarọ Oojiire, lati tẹwọgba ede Yoruba, ki wọn si maa se agbega rẹ nigba gbogbo.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Àyájọ́ òṣìṣẹ́: NURTW gba ẹ̀jẹ̀ lára àwọn òsìsẹ Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
'Rọ́bọ́ọ̀tì ni yóò máa yẹ̀ yìn wò kẹ́ẹ tó rìnrìnàjò òfurufú ní Nàìjíríà' Ìgbà mẹ́jọ tí awuyewuye wáyé lórí ìṣèjọba Ajimobi!
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Mild symptoms of coronavirus : Kíni àwọn àmì nàá, àti ọ̀nà tí o le fi dáàbò bo ara rẹ?
Ẹ máa sọ̀rọ̀, kí ẹ sì máa hùwà gẹ́gẹ́ bí ẹni tí ó wà lábẹ́ ìdájọ́ òfin tí ó ń sọ eniyan di òmìnira.
Nígbà tí mo rí i, mo ṣubú lulẹ̀ lẹ́sẹ̀ rẹ̀ bí ẹni tí ó kú.
O tun so pe “A o ri i pe a fiya je  awọn  to hu iru iwa yii, labe ofin, to fi je pe lojo miiran, wọn  ko ni hu iru iwa bẹẹ mo.
Roland ni igbagbọ pe ofo lasan ni ileri ati adehun t'awọn ẹgbẹ okunkun maa n se fawọn ọmọ ẹgbẹ wọn.
Ohùn OLUWA a máa mú abo àgbọ̀nrín bí,a máa wọ́ ewé lára igi oko;gbogbo eniyan ń kígbe ògo rẹ̀ ninu Tẹmpili rẹ̀.
Wo bí ìwọ́de #ENDSARS tí Toyin Abraham ṣe nípínlẹ̀ Oyo ṣe lọ Gbajugbaja oṣere Nollywood, Toyin Abraham naa ti dari iwọde lati polongo pe ki ijọba orilẹ-ede Naijiria fi opin si ẹka ileeṣẹ ọlọpaa SARS.
Ìròyìn Yàjóyàjó - Nàìjíríà kéde èèyàn míràn pẹ̀lúu àrùn Coronavirus Èèyàn kan bá ìṣẹ̀lẹ̀ ilé tó wó ládúgbò Palmgroove lọ Ọmọ Nàìjíríà ni ẹnìkejì tó ní Coronavirus ní Washington Ìdá 90% nínú àwọn olówó Naijiria lo n lọ ilé babaláwo- Mr Latin Agba iranṣẹ ọlọrun naa wa ṣalaye pe gbogbo ọmọniyan lo lẹtọ lati sọ ọrọ ẹnu wọn lai si ẹni ti yoo dawọn lẹkun.
"Èyí ló wá tọ́kan sí pé, àwọn tó ni ""T Cell"" yìí pọ̀ jú bi àwọn onímọ̀ ṣe lérò lọ."
Dafidi dáhùn pé, “Ìgbàkúùgbà tí èmi iranṣẹ rẹ bá ń ṣọ́ agbo aguntan baba mi, tí kinniun tabi ẹranko beari bá gbé ọ̀kan ninu aguntan náà, 
Oronpoto Animation: Akin Alabi ní kò dára bí eré aláwòrán fáwọn ọmọdé ṣe jẹ́ aláwọ̀ funfun
Alaga Ajọ Agbẹnusọ Ipinlẹ Lorilẹ-ede yii tun gboriyin fun awọn ara ilu fun atileyin wọn fun ijọba ẹgbẹ oṣelu All Progressives Congress ati pe pẹlu suuru wọn, gbogbo ileri ijọba naa ni wọn yoo ṣe.
Mo wq fi àsìkò yìí ro gbogbo àwọn ènìyàn ti ìwà wọn jọ tí Ìjàpá ki wón lọ yí padà.
Pẹlu iyansipo Gomina ipinlẹ Bayelsa, Douye Diri ati igbakeji rẹ, Sẹnetọ Lawrence Ewhrujakpo, aye meji ti ṣofo nitori Diri lo n ṣoju ẹkun aarin gbungbun Bayelsa tẹlẹ ti igbakeji rẹ si n ṣoju ẹkun idibo Iwọ Oorun Bayelsa.
Nígbà tí Mesaya bá dé, ẹnikẹ́ni kò ní mọ ibi tí ó ti wá.
Gbogbo àwọn amòye ọba wá, wọn kò lè ka àwọn àkọsílẹ̀ náà, wọn kò sì lè sọ ìtumọ̀ rẹ̀ fún ọba.
Ti a ko ba gbagbe, ọdun to kọja kan naa ni gomina Ajimobi fi ọba mejilelaadọta jẹ kaakiri ipinlẹ Ọyọ, eleyii to seese ko din agbara Olubadan to jẹ ọba to wa ni ipinlẹ Ọyọ tẹlẹ.
Èèyàn 189 ní àrùn Coronavirus tún ṣẹ̀ṣẹ̀ ràn ní Nàìjíríà Ajọ to n gbogun ti ajakalẹ aarun lorilẹ-ede Naijiria, NCDC ti kede pe eeyan 189 miran ti kun iye awọn to ti ni aarun COVID-19 ni Naijiria.
Wọ́n gbé gbogbo àwọn tí àárẹ̀ ti mú gun kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ lọ sí ọ̀dọ̀ àwọn arakunrin wọn ní Jẹriko, ìlú ọlọ́pẹ.
Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Ondo Election 2020: Ẹ wo àwọn olùdíje sípò gómìnà nípínlẹ̀ Ondo tó takò bàbá ìsàlẹ̀26 Owewe 2020 Fídíò, Wole Soyinka sọ ìdí tó fi ni òun a fi màálù Fulani ṣe súyà fáwọn èèyàn abúlé23 Owewe 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 3 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 5 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Ekiti: Ọmọ ọdun méje di ọ̀rẹ́ Gómìnà Ekiti
Buhari kaabọ si orile ede naa ni asoju orile ede Niajiria to wa ni orile ede Niger
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Babatunde Olatunji: E wo ọmọ Yorùbá tó kọ́kọ́ jà fún ẹ̀tọ́ àwọn aláwọ̀dúdú ní America!
UN General Assembly: Buhari ní ìgbà ọtun ni ìyànsípò Bande jẹ́ lẹ́ka òṣèlú
Eyi lo si mu ki oun pe alamojuto ileesẹ ọlọpaa ni adugbo Ikpoba Hill ti iṣẹlẹ naa ti waye.
Minisita so pe“Mo feran iru eniyan bayii lati ba se ise papo, ti ko ba fe nnkan kan , yoo salaye fun mi, a si tun gba mi nimoran, idi ti ko se fe iru re, nitori naa, a feran ara wa.
"Mo ti gbé oogun náà fún àjọ Nafdac, tí wọn si ni àwọn yóò ṣe ìwádìí oogun náà bo ṣe pegede si.
Jesu dá wọn lóhùn pé, “Mo sọ fun yín, ẹ kò gbàgbọ́.
Gbé ojú sókè kí o wò yíká, gbogbo wọn kó ara wọn jọ, wọ́n wá sí ọ̀dọ̀ rẹ;àwọn ọmọ rẹ ọkunrin yóo wá láti òkèèrè,a óo sì gbé àwọn ọmọ rẹ obinrin lé apá wá.
Ṣugbọn wọn yóo máa sin Ọlọrun wọn,ati ti Dafidi, ọba wọn, tí n óo gbé dìde fún wọn.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Google Top Search 2019: Naira Marley na Atiku pa nínú àwọn orúkọ tàwọn èèyàn ń wá jùlọ ní 2019 11 Ọ̀pẹ̀̀ 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 12 Ọ̀pẹ̀̀ 2019 Oríṣun àwòrán, Instagram/nairamarley Àkọlé àwòrán, Orukọ Naira Marley gbode kan lọdun yii lẹyin ti ajọ EFCC fi pampẹ ofin mu lori ẹsun jibiti Ileeṣẹ atẹ imọ oju opo ayelujara Google ti ṣe agbejade orukọ ati awọn nkan tawọn eeyan n wa iroyin nipa rẹ julo loju opo rẹ fọdun 2019.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ọmọ ọdún kan póòrá!
110 ni ìyè àwọn àgbẹ̀ tí Boko haram dúmbú ní Borno tí dì báyìí-UN Ṣe lóòtọ́ ní ọmọ Nàíjíríà mílíọ́nù 25 yóò má ló ìná Solar látí Dec 1, 2020?
Ní gbogbo ibi tí àwọn tí wọ́n ṣẹ́kù ninu àwọn eniyan rẹ̀ ń gbé, kí àwọn aládùúgbò wọn fi fadaka, wúrà, dúkìá, ati ẹran ọ̀sìn ta wọ́n lọ́rẹ, yàtọ̀ sí ọrẹ àtinúwá fún ilé Ọlọrun.
Bí ó bá jẹ́ pé ẹranko burúkú ni ó pa á, bí ó bá ní ohun tí ó lè fi ṣe ẹ̀rí, tí ó sì fi ohun náà han ẹni tí ó ni ẹran náà, kò ní san ẹ̀san ẹran náà pada.
Nítorí ọjọ́ ń bọ̀ tí àwọn ọ̀tá rẹ yóo gbógun tì ọ́, wọn óo yí ọ ká, wọn yóo há ọ mọ́ yípo.
Oga mi lo gba 36m Jamb Ààrẹ Buhari buwọ́lu ẹ̀dínwó ìdánwò NECO àti JAMB JAMB kò tíì leè sọ ìgbà tí èsì yóò jáde JAMB f'ọjọ kun asiko iforukosilẹ Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 3 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 5 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Babajide Sanwo Olu  mu suuru ti awon osise ajo INEC se yanju
Bí ènìyàn bá jókòó lé e, ibikíbi tí ó bá wí pé kí ẹní yìí gbé òun lọ, wéré ni yóò bá ara rẹ̀ níbẹ̀ kò ní ló ju ìṣẹ́jú kan.
Ajo WHO ati NCDC n seto to ye lati gbogun ti arun yii.
Ìjọ̀ba Saudi ti tú Zainab tí wọ́n fẹ̀sùn òògùn olóró kàn sílẹ̀ Bí Zainab ṣe dèrò ẹ̀wọ̀n Saudi lórí ẹ̀sùn ògùn olóró tí kò mọ̀ ‘Bí ẹ se gba Zainab sílẹ̀, ẹ gba Leah Sharibu lọ́wọ́ Boko Haram’ Gbogbo àwọn mọ̀lẹ́bi, ọ̀rẹ́ àti alábagbé Zainab ni wọn dúro ni pápákọ̀ ofurufu làti kíii káàbọ lẹ́yìn oṣ mẹ́rin to ti wà ni ẹwọn ní Saudi Arabia.
Nígbà tí àwọn eniyan rẹ̀ bọ́ sọ́wọ́ ọ̀tá,tí kò sì sí ẹni tí yóo ràn wọ́n lọ́wọ́.
Wọn ìbá má bí mi rárá,kí wọ́n gbé mi láti inú ìyá mi lọ sinu ibojì.
Aarẹ Buhari fọrọ yii lede nibi ti o ti n bawọn ọmọ ologun 17th Brigedi atawọn ọmọogun ofurufu 213 Operational Base niluu Katsina lọjọ Abamẹta.
Arabinrin Omooba Omolola Modupe Oluwa Arohunmọlaṣẹ jẹ obinrin ti ọpọ gba pe o n ṣiṣẹ ọkunrin.
Olupẹjọ ni Ọgbẹni Mallet tun huwa ipa si awọn agbofinro nibi iṣẹlẹ naa.
Fidio kan ṣe afihan pasitọ Alph Lukau, nibi to ti n pariwo sinu poosi kan to si n sọ fun arakunrin kan ti oku rẹ wa ninu rẹ pe ko ji dide, bi awọn ara ijọ ṣe n patẹwọ.
Ta ni ninu yín tí ó lè ṣe àníyàn títí tí ó lè fi kún ọjọ́ ayé rẹ̀?
Bello sọ pe ijọba ipinlẹ naa mọ pe ẹni to ko arun Coronavirus wọ ipinlẹ Ekiti lo akoko diẹ nilu Ibadan.
Ìfihàn náà jẹ́ ìyípadà èdè ti irú àkọsílẹ̀ èyí tí Johannu ṣe sí orí awọ-ẹranko tí ó sì fi pamọ́ fúnra rẹ̀.
Ọpọlọpọ papakọ ofurufu Naijiia kii pa owo wọle Onimọ naa ni yatọ si papakọ to wa ni Eko ati Abuja, awọn yooku ko pa owo ti wọn le fi maa tun wọn ṣe daradara.
    Iṣẹ́ tí mo ń fẹ́ rán ọ náà nìyí, mo fẹ́ kí o wá ṣe asáájú àwọn ọ̀dọ̀ mìíràn, kí ẹ wa lọ sí Òkè Ìrònú, ti ń bẹ nínú Igbó Elẹ́gbèje, kí ẹ wá lọ ká èso igi Ìrònú fún mi wa.
Oríṣun àwòrán, AFP via Getty Àkọlé àwòrán, Former police officer Derek Chauvin was detained on Friday Amofin naa ni ti Trump ba le gunle iṣakoso oju opo ikansiraẹni nilẹ Amẹrika, o tumọ si pe oun funra rẹ lo n fi ẹtọ awọn eeyan lati sọ erongba wọn dun wọn.
Sotitobire: Ìgbẹ́jọ́ Wòlíì Alfa Babatunde Sotitobire ti gúnlẹ̀ sí iléẹjọ́ ní ìtẹ̀síwájú ìgbẹ́jọ́ rẹ̀ Pasitọ Babatunde Alfa ti ọpọ mọ si sọtitobirẹ ti gunlẹ si ileẹjọ bayii nibi ti yoo ti tẹsiwaju igbẹjọ ẹsun ijọmọgbe ti wọn fi kan an.
 Awon osise eleto ilera ti n
O so pe, “orile-ede Naijiria ni lati pada si ese aaro, ti o maa n ko ounje lo si awon orile-ede lagbaye, ijoba orile-ede Naijiria, olori-jori ati awon elegbe-jegbe, gbodo fowosowopo lati mu atunto ba eka eto ogbin, lati le pese ounje lopo yanturu, eyi ye ko je ipinnu fun odun to n bo, won niloo awon ounje ti won pese lorile-ede Naijiria ni awon orile-ede yoku lagbaye”.
Jẹ́ ọlọ́gbọ́n kí o sì ní ìmọ̀.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Ọkọ mi wa ọkọ̀ tẹ Poly Bag"" lásán, àfi gbùùàà!"
Ṣugbọn àwa yóo máa yin OLUWA,láti ìsinsìnyìí lọ, ati títí laelae.
Ṣé o óo wá gbàgbé mi laelae ni?
ijoba ibile Numan eto ayẹwo oruko bẹrẹ ni
 awon ohun to fa ewu ni : osi , airiounjẹ-jẹ , pipa igbó run , ati kikun-ilu .
Oríṣun àwòrán, Google Ibeere nla ti o wa ku lẹyin alaye ti a ṣe yi ni pe kini ti awọn ti ko ri kaadi gba ti NIMC ni wọn gbọdọ san owo ti ọjọ ba pe lori kaadi naa?
Iroyin to n tan kalẹ kan ṣugbọn ti a ko tii le fidi rẹ mulẹ tun sọ pe gomina Makinde paṣẹ lọgan pe ki wọn fun Soun ti Ogbomoso, Oba Jimoh Oyewumi ni Ọgọrun miliọnu naira lati tun aafin ṣe nibi ti awọn olufẹhonuhan EndSARS ti ba ọpọlọpọ nkan jẹ ni ọjọ Aiku ọjọ kọkanla oṣu kẹwa ọdun 2020.
ìlú Eko kọ́ ló léwu jùlọ láti gbé lágbàáyé- Ìjọba Eko Ọjọgbọn Oṣinbajọ ṣalaye siwaju sii pe Eleduwa lo n ṣakoso ohun gbogbo, Oun naa si lo n dari ayanmọ orilẹ-ede gbogbo atawọn eeyan to wa nibẹ.
Aarun yii maa n wa nipa jije ounje to ni majele, awon ounje ti o ti baje.
 láìpé sí ìgbà yìí ni ó ti bẹ ̀ rẹ ̀ sí níí lo ọ ̀ pọ ̀ lọpọ ̀ irin iṣẹ ́ tí wọ ́ n fi ń kọrin .
èmi tí mo sọ àmì àwọn tí ń woṣẹ́ èké di asán, tí mo sì sọ àwọn aláfọ̀ṣẹ di òmùgọ̀.
Alekun ohun waye lataari alekun ti o ba owo dollar lati owo dollar mẹ́rìndínláàdọ́ta si mọ́kànléláàdọ́ta (US$46 si US$51), eleyi ti o mu adinkun ba isuna oro aje.
Ọ̀gá àgbà tuntun nàá gba oyè ìmọ̀ ìjìnlẹ̀ nípa ètò òṣèlú nílé ẹ̀kọ́ gíga fásìtì Ahmadu Bello tó wà nílùú Zaria.
Goodluck Jonathan jẹ́ olùfọkànsìn àti ìwúrí fún ìrandíran ní Nàìjíríà - Buhari Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ẹ wo fídíò Kìnìhún ní ibùgbé rẹ̀ tuntun ní Bogije, Lekki Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Ṣugbọn ọ̀dọ́ aguntan ni kí ẹ máa fi ra àkọ́bí kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ yín tí ó bá jẹ́ akọ pada, tí ẹ kò bá fẹ́ rà á pada, ẹ gbọdọ̀ lọ́ ọ lọ́rùn pa.
Gbogbo ẹranko yoku mọ̀ wi pé iwà wọn kò jọra nitori eyi, ó jẹ́ ìyàlẹ́nu fún wọn irú ọ̀rẹ́ ti wọn bára ṣe.
Aare Muhammadu Buhari yoo kuro niluu Abuja loni lati teko leti lo sorile-ede France fun ipade ipese igbe aye alafia(Paris Peace Forum), ti yoo waye niluu Paris, bere lojo kokanla osu kokanla si ojo ketala odun yii, eleyi ti ijoba orile-ede France ati awon ile-ise aladaani kookan sagbekale re.
A ti kó gbogbo Juda lọ sí ìgbèkùn,gbogbo wọn pátá ni a ti kó lọ.
Iléesẹ̀ ọlọ́pàá: NHRC fẹ́ mọ bàwọn afurasí se dé túbú
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Àwọn ìgbà tí jándùkú òṣèlú tí wáyé ní Nàìjíríà 16 Bélú 2018 Oríṣun àwòrán, Atiku Abubakar/Facebook Oludije fun ipo aarẹ labẹ aburada ẹgbẹ oṣelu Peoples Democratic Party l'ọdun 2019, Atiku Abubakar, ti sọ pe oun mọ orisun ẹgbẹ agbesunmọmi Boko Haram.
Kíní ìtúmọ owó ìrànwọ lórí epo (Fuel Subsidy) tí ìjọba yọ báyìí Ǹkan tí o túmọ sí náà ni pé, ètò ọ̀rọ̀ ajé Nàìjíríà ṣẹ̀ṣẹ̀ bẹ̀rẹ̀ ní, nítóri àsìkò yìí ní àwọn ojúlówó onísòwò epo yóò ṣẹ̀ṣẹ̀ rí tajé ṣe.
Ẹ fẹ́ràn OLUWA Ọlọrun yín, ẹ máa gbọ́ tirẹ̀, kí ẹ sì máa súnmọ́ ọn pẹ́kípẹ́kí, kí ẹ lè wà láàyè, kí ẹ lè pẹ́ láyé, kí ẹ sì lè máa gbé orí ilẹ̀ tí OLUWA búra láti fún àwọn baba yín, àní Abrahamu, Isaaki, ati Jakọbu.
Aṣake jẹ ololufẹ Ajani lati ibẹrẹ ṣugbọn ẹru Baba Kekere aburo baba rẹ to n tọju rẹ n ba a; Lọla jẹ akẹkọọ wọle fasiti to wa ni ipele aṣẹṣẹ wọle nigba ti Sade jẹ ojulumọ Ajani tẹlẹ.
Ṣugbọn akọnimọọgba Liverpool ni Messi ati Ronaldo ti ṣe nnkan manigbagbe ninu ere bọọlu, o ni laelae lawọn eeyan yoo maa ṣe iranti wọn lọjọ iwaju.
Nígbà tí wọn ń jẹun, Jesu mú burẹdi, ó gbadura sí i, ó bù ú, ó bá fi fún àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀; ó ní, “Ẹ gbà, ẹ jẹ ẹ́, èyí ni ara mi.
Nibẹ lo ti gba bọọlu fun ọdun mẹrin pẹlu ẹgbẹ agbabọọlu Vitoria Setubal ni Portugal, to si tun gba ami ẹyẹ ẹni to gba bọọlu wọ inu awọn julọ ninu idije Primeira Liga ni saa ọdun 1993 si 1994.
Fowler kò sí lábẹ́ ìwádìí kankan-Garba Sheu Wo àwọn eléré ìdárayá mẹ́ta tí àjọ FIFA ti fòfin dè títí ayé Yàtọ̀ sí Ọ̀ṣun Òṣogbo, Ṣàǹgó pẹ̀lú a máa ní arugbá lóde Ọ̀yọ̀ Òyìnbó sísọ di èèwọ̀ ní ìpínlẹ̀ Ekiti O tun kawe ni Oladipo Alayande School of Science ko to lọ ka nipa imọ nipa ẹrọ ni Fasiti OAU Ile Ifẹ.
”Ewe, aare egbe NLC ko lati kede pato owo ti igbimo naa fenuko si.
Má wọ Giligali lọ bọ̀rìṣà, má sì gòkè lọ sí Betafeni, má sì lọ búra níbẹ̀ pé, ‘Bí OLUWA tí ń bẹ.
Ìwọ́de, ìkọ̀wéfipò sílẹ̀, ìdìbò abẹ́lé Osun kò fé bí'mọ re Olùdíje ìbò abẹ́nú PDP, APC fárígá l‘Ọ́sun Aṣòfin mẹ́ta míràn fi APC sílẹ̀ lọ darapọ mọ́ ADP Nnkan ko fẹ ṣe deede fún ẹgbẹ oṣelu APC nipinlẹ Ọsun lọwọ yii pẹlu bi awọn ọmọ ileegbimo aṣofin ipinlẹ naa mẹta tun ti ṣe yẹba lọ darapọ mọ ẹgbẹ oṣelu ADP ni ọjọ abameta.
Báwo ni ẹni tí obinrin bí ṣe lè jẹ́ ẹni mímọ́?
Idi rẹ to fi jẹ wipe nigba ti Juventus wa lati beere Sarri, inu Chelsea dun lati jọwọ rẹ.
Sọ àsọtẹ́lẹ̀ orílẹ̀èdè tí yóò borí ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ t'òní Ẹbí dá ẹ̀bi rù ilé ìwòsàn, ilé ìwòsàn ní ìyá ọmọ ní kò fọwọ́sowọ́pọ̀ ṣugbọn wọn ṣe iṣ abẹ fun aboyun yii lai gba aṣẹ lọwọ ọkọ rẹ tabi idile, lo ba gba ibẹ re salakeji tọmọ tọmọ.
Itọju to dara ju to wa fun un, paapa fun aisan ibà ti kokoro aifojuri P.
“O je ohun ibanuje pe awon omo orile ede Naijiria ti won ni ipa pataki lati
Ọjọbọ tii ṣe ọjọ kẹfa oṣu keji ọdun yii ni Olubadan fi atẹjade kan sita, ninu eyi to ti sọ pe n ṣe loun ko ba le awọn Ọba mọkalelogun kuro nilẹ Ibadan, ti oun ba tẹle ohun ti ọpọ ọmọ ilẹ Ibadan n sọ.
''Mo rọ gbogbo ọmọ Naijiria pe ki wọn maa mi kan ti a o fi ṣẹgun arun coronavirus ni Naijiria,'' Atiku lo woye bẹẹ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù America: Ẹ má dúró ju ìṣẹ́jú mẹ́wàá lọ níta ìlú yóò tutù kọjá àlà 30 Sẹ́rẹ́ 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, America yóò tutù ju bó ti yẹ lọ Lọsẹ yii, awọn alasọtẹlẹ oju ọjọ ti ni awọn ara ilẹ Amẹrika yoo gbọn pẹpẹpẹ ninu otutu to lagbara ju bo ti yẹ lọ.
Kí ẹ ràn án lọ́wọ́ ní ọ̀nàkọ́nà tí ó bá fẹ́; nítorí ó jẹ́ ẹni tí ó ran ọpọlọpọ eniyan ati èmi pàápàá lọ́wọ́.
Aisha Buhari: Ọkọ mi yóò parí gbogbo iṣẹ́ tó ti bẹ̀rẹ̀
Ẹ ṣí ilé ìwé padà ní Áfíríkà torí ọjọ́ iwájú àwọn akẹ́kọ̀ọ́ yín - WHO, UNICEF Oríṣun àwòrán, Others Ẹ ṣi awọn ileewe yin pada ni kopẹ kọpẹ, ajọ eleto ilera lagbaye, WHO lo rọ awọn orilẹede ilẹ Afirika bẹẹ Ajọ WHO ni gbigbe ileewe tipa siwaju sii nitori coronavirus yoo ṣakoba fawọn akẹkọọ.
Bi ipinnu Ngozi Okonjo-Iweala lati di Oludari ajọ WTO ṣe n jọ ọ bọ̀ diẹdiẹ Ipinnu Minisita feto ọrọ aje Naijiria tẹlẹ Ngozi Okonjo Iweala lati di ipo adari ajọ idokowo lagbaye WTO mu n sunmọ mimu ṣẹ bọ diẹ diẹ.
Kíni ìtumọ̀n “SIM Card” l’édè Yorùbá?
Amọṣa Dorothy Bachor, ọkan lara awọn olukopa eto agbelewo naa laye n jẹ lẹnu bi iṣu bayii.
Nítorí náà, ó lọ bẹ Aṣipenasi, olórí àwọn ìwẹ̀fà ọba, pé kí ó gba òun láàyè kí òun má sọ ara òun di aláìmọ́.
ede  Naijiria  lati fowosowopo pelu  ijoba , ni eyi ti idagbasoke yoo se de ba orile
Nígbà náà ni Israẹli sọ fún Josẹfu pé, “Àkókò ikú mi súnmọ́ etílé, ṣugbọn Ọlọrun yóo wà pẹlu rẹ, yóo sì mú ọ pada sí ilẹ̀ baba rẹ.
8%) awọn ọkunrin to ko arun Coronavirus yii lo jade laye; bẹẹni ida meji o din diẹ ninu ọgọrun (1.
púpọ ̀ nínú àwọn ènìyàn ni àwọn ará ìlú mìíràn lè dámọ ̀ kódà ìdílé wọn nípa lílo oríkì okùn ìrandíran won .
Ara sì bẹ̀rẹ̀ sí ta mí pàrà.
Mo bá a dá majẹmu yìí kí ó baà lè bẹ̀rù mi; ó sì bẹ̀rù mi, ó bọ̀wọ̀ fún orúkọ mi.
Nítorí ọjọ́ náà yóo dé bá gbogbo eniyan tí ó wà ní ayé.
Saka àti Xhaka Arsenal ṣe Chelsea ṣákaṣàka,3-1 ló bá de lọjọ Boxing Day Àwọn àmi méje tó ń tọ́ka sí pé oò kí ń mu omi bí ó ti tó Ọ̀rọ̀ ààbò kìí se èyí tí a lé fí gbèdéké sí - Femi Adesina Mí ò mọ̀ pé ọ̀rọ̀ ọlọ́pàá ni ìwọ́de #EndSars níṣe pẹ̀lú - Anthony Joshua Kano 35 Nasarawa 25, Bauchi 19, Benue 8, nígbà tí Borno, Edo, Oyo àti Sokoto ni 7, Ogun ni 2 Ìpínlẹ̀ mẹ́ẹ̀dógun ni àjọ NDCD kọ sojú òpó wọ́n pé wọ́n ti rí àwọn tó ni ààrùn yìí wọ́n ko fi iye ènìyàn tó ni ààrun náà ní Jigawa soju òpó wọ́n .
Iko omo-ogun Taliban ti sekupa ogbon omo-ogun ile Afghan ti won si tun gba ibudo awon omo ogun ohun ti o kogun si iwo oorun agbegbe Badghis lojoRu(Wednesday).
Ó mú àáké kan lọ́wọ́, ó fi gé ẹrù igi kan jọ, ó gbé e lé èjìká, ó sì sọ fún àwọn tí wọ́n wà pẹlu rẹ̀ pé, “Ẹ yára ṣe bí ẹ ti rí mi tí mo ṣe.
Ṣugbọn, onimọ nipa oṣelu naa sọ pe pẹlu bi Buhari ko ṣe pada yan sipo minisita fun igba keji, o ṣeeṣe ko ma yege lati di olori oṣiṣẹ rẹ.
Bẹẹ ba gbagbe, ọjọ Isẹgun ni iroyin gbalẹ kan pe awọn ọmọ onilẹ meji ti n pagidina omi alaafia lagbegbe Soka, ti awọn ara adugbo ibẹ si n sa kijokijo kiri.
Matiu se àsè ní ilé rẹ̀.
" Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Coronavirus: Ǹjẹ́ fífi omi àti iyọ̀ yọnu leè dènà àrùn Coronavirus?
Ni ipari ni Omolola gba awọn obinrin ni imọran lori ohun to yẹ ni ṣiṣe.
Ajọ Olọpaa ni wọn ti da awọn ti o risi jijini gbe ẹka ajọ naa lati bẹrẹ si fimu finlẹ lati doola ẹmi awọn ti wọn jigbe naa.
Ọkùnrin kan nílùú Ibadan to ni Sójà obìnrin lù mí lálù bami nílùú Ibadan nílùú Ibadan lẹ́yìn tí òun ba ọmọ rẹ̀ wí pé ó fẹ́ jánà mọ́ mótò òun lẹ́nú ti dero ile iwosan bayii.
Ọkunrin náà sọ fún mi pé: “Èyí ni tabili tí ó wà níwájú OLUWA.
Bakan náà ni ki wọ́n túbọ ṣetò ààbo to gbóipọ̀n ni pápákọ̀ ofurufu.
ifesewonse ohun sipo keji, pelu ami mejo lori tabili, ti orile-ede Uganda si se
Enang ati enikeji rẹ to wa nile igbimo asofin kekere  El-Yaqub lo sọ eleyii di mimọ lojoRu ose yii
Afojusun abadofin naa ni lati daabo bo ketekete lojuna iparun, won wa fi oro naa mule pe eni ti aje ori ofin naa ba si mo lori, iru eni be yoo fi aso pempe roko oba fun odun mewaa gbako.
6 3181 Orilẹede Cyprus 61 5.
Nítorí ìwọ̀nyí ni Ọlọ́run ṣe pàṣẹ fún mi kí n lọ mú un wá síwájú Òun.
biliọnu mejilelaadọrun ni wọn ya sọtọ fun ẹka eto ilera, ẹka igbafẹ, asa ati ọrọ ẹsin gba biliọnu mejila abọ naira nigbati eto ẹkọ ko biliọnu mẹrindinlaadoje naira.
Ireti wa pe, oro Aare oun yoo safihan awon erongba ti yoo fese eto isakoso ijoba tiwa-n-tiwa mule lorile-ede Naijiria, bakan naa ni yoo tun so awon eso rere isakoso isejoba ara wa fun omo orile-ede Nigeria Ronke Osundiya.
Àwọn kan yóo máa ro oko rẹ̀, àwọn kan yóo sì máa kórè àwọn ohun ọ̀gbìn rẹ̀.
ati gbogbo ìdínà tí ó bá gbórí sókè tí ó lòdì sí ìmọ̀ Ọlọrun.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ogundiya: Àṣìṣe Dókítà ló sọ mi di aláàbọ̀ ara lórí kẹ̀kẹ́ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Ogundiya: Àṣìṣe Dókítà ló sọ mi di aláàbọ̀ ara lórí kẹ̀kẹ́ 8 Ògún 2018 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 13 Ìgbé 2020 'Mo kọ̀ láti jẹ́ ki ipenija yii sọ mi di alágbe' Ṣeun Ogundiya sọrọ lori igbesẹ akin to gbe lati lọ kawe nipa iṣẹ olukọni NCE ati ni fasiti OAU ni Ile Ife léyin iṣẹlẹ to gbe oun sori kẹkẹ fun BBC Yoruba.
Femi Adebayo Femi Adebayo ni tiẹ sọ pe jijoko sile lasiko coronavirus yii ti su oun.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Bakan naa, o sọ pe aikawe ọpọn ninu wọn lo ṣokunfa ki ọpọ wọn ti di agbebọn bayii.
Gbogbo àwọn afurasi ati awọn ti ọwọ agbofinro ti tẹ̀ ni wọn ti n ran àwon ọlọpaa lọwọ lati mu àwọn to kù wọn.
Ọ̀fẹ́ ni China yóò kọ́ fásítì $50M ètò ìrìnnà sí Daura ìlú Ààrẹ Buhari- Amaechi Irọ́ ni, kò sí olóyún nínú àwọn tí Tírélà pa ní Ondo ṣùgbọ́n awakọ̀ ti sá lọ- Ọlọ́pàá Ondo Ọba ni mí, mi ò le b'ọ̀rìṣà, Olorì tuntun tó ń bọ̀ já gbogbo ''scale''- Oluwo ti Iwo Iléẹjọ gíga jùlọ da ẹjọ́ SDP àti PDP nù, wọ́n ní Yahaya Bello ló wọlé ìbò gómìnà Kogi Ẹ̀yin ọmọ ìta tó ní Funke Akindele ra ilé fún mi, irọ́ ni o - Ajirebi Ìtàn ayé Henry Fajemirokun, olówó tó fi owó mọ Olúwa àti ènìyàn Suleiman ni igbesẹ Aarẹ yoo fun ẹka ijọba to n ri si eto ibaraẹnisọrọ lati ṣamojuto gbogbo awọn ẹka ti wọn ni ohun kan tabi omiiran ṣe pẹlu kaadi idanimọ daadaa.
Ìwọ́ ni wàá kọ́ ara rẹ láti dá a mọ̀ àti láti rẹra mọ́ ọ."
Ará ìlú fárígá, wọ́n wọ́ alàkóso ìlú nilẹ́ pẹ̀lú ọkọ̀ UNILAG ní kí olùkọ́ míì, Samuel Oladipo to ń bèèrè ìbálòpọ̀ lọ́wọ́ akẹ́kọ̀ọ́ lọ fìdí mọ́lé Ìran Yorùbá: Àṣà ju àṣà lọ!
Ta ló ń sọ ohun tí yóo ṣe fún un,tabi kí ó sọ fún un pé, ‘Ohun tí o ṣe yìí kò dára?
’ Nígbà náà ìwọ yóo ní iyì lójú gbogbo àwọn tí ó wà níbi àsè.
Wọ́n bá gba Jesu lọ́wọ́ Pilatu.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Asisat Oshoala: ìbẹ̀rẹ̀ mi kò rọrùn rárá nínú eré bọ́ọ̀lù Kete ti o si ṣẹlẹ ni ẹni to jẹ akọwe nigba naa Amaechi Akawo lọ sọdọ ẹni to jẹ adari, Hajia Hauwakulu Akinyemi pe bayii bayii lo ri o ti Hajia naa si lọ sọdọ minisita fun ere idaraya.
Àkọlé àwòrán, Aworan awọn musulumi to n kirun Shawwal: Orukọ oṣu yi wa latari bi awọn rankumi ṣe maa n ru ju ti tẹlẹ lọ ti omi mu wọn a si ma kere ju ti tẹlẹ lọ.
"Lanre Kuti ni mo fẹ́ - Jaiye Kuti Iro ni ile Amerika pa mo mi lori esun jibiti- Allen Onyema Ọkọ̀ báàlù mi yóò ṣi padà lọ́ kó ọmọ Nàíjíríà tó kù sí South Africa - Alákoso Airpeace Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 300 mílíọ̀nù náírà ní mò fí gbé àwọn ọmọ Nàìjíríà wálé-Allen Onyeama Ni ti gbajugbaja ori ayelujara fun irufẹ awọn iroyin to ma n gbe sita ati ọna to n gba kọ́ iroyin rẹ, Kemi Olunloyo, o ni ""gbogbo yín lẹ ni iwa jẹgudujẹra lọwọ gẹgẹ bi olori Naira Marley ṣe kọ ọ."
com ni wọ́n fún wa ní ẹ̀bùn yí ní ọ̀fẹ́.
"Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Kebbi jẹ ọkan lara awọn ipinlẹ to jẹ ara waju nibi gbigbin irẹsi ni Naijiria Sanusi sọ wipe: ""Awọn eku naa pẹlu awọn kokoro ba oko ọpọ ninu awọn agbe Argungu jẹ."
Iyanrìn làwọn ẹbí olóògbé bàálù Ethiopia rí gbà dípò òkú Ta ló jáwé olúborí nínú eré ìdíje ní Eko?
Eyi si n waye pẹlu bi ajọ eleto ilera lagbaye, WHO ti ṣe kede didẹyẹsi abẹrẹ ajẹsara, gẹgẹ bii ọkan gboogi lara ohun mẹwa to n ti igi bọ oju eto ilera lagbaye.
Àwọn mààlúù rọ̀pọ̀tọ̀ rọ̀pọ̀tọ̀ meje nnì ati àwọn ṣiiri ọkà meje tí wọ́n yọmọ dúró fún ọdún meje.
Wá kọ́ síi nípa bí àwọn gbọ́mọgbọ́mọ ṣe ń ṣiṣẹ́ láti ọwọ́ Lapade àti Tafa Arabinrin Kikelomo Ogunboye onimọ nipa ede ati aṣa Yoruba dar pupọ lori eto toni.
 Ó léwú láti lò ó nígbàtí ènìyàn bá lóyún .
Dafidi náà sọ pé, “Jẹ́ kí àsè wọn di tàkúté ati àwọ̀n,kí ó gbé wọn ṣubú,kí ó mú ẹ̀san bá wọn.
Nípa oore-ọ̀fẹ́ Ọlọrun ó kú fún gbogbo eniyan.
com Àkọlé àwòrán, Kò sí ẹni tó tíì leè sọ ohun tó fa wíwó ilé náà Ọfọ nla lo ṣẹ lagbegbe Kajọla ni ilu Oṣogbo lọjọ Aiku nigba ti ile alamọ kan da wo ti o si pa ọmọ ọdun mọkanla kan ti wọn pe orukọ rẹ ni Jide.
Ọlọ́pàá Eko ní kí olùkọ́ UNILAG Boniface wá sọ tẹnu rẹ̀ lórí ẹ̀sùn ìfipábánilòpọ̀ A ti mọ òbí 40 nínú 108 t'ọ́mọ wọn bọ́ ní ayédèrú ibùdó atúnwàṣe Ilorin - Ọlọ́pàá Kwara Ìlú kò mọ ohunkóhun nípa iṣẹlẹ màálù tó kú nilu Ikarẹ- Oba Olukarẹ Awọn akanse isẹ naa lo da lori ileeṣẹ to n fọ irẹsi ni Imọta, Imota Rice mill, ọna olobiripo to wa l'Oṣodi ati ina oju popo LED-UK streetlight project ti wọn ni gomina Ambọde ṣe nigba to wa lori aleefa.
Àwọn ọmọ náà ni Ààrùn, Àìsàn, Àìlera àti Àárẹ̀.
Baxter nireti pe ifesewonse ohun ko ni rorun rara lataari bi iko agbaboolu Super Eagles se padanu ifigagbaga ese kinni sowo iko re.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Elisha Abbo: Ilé ẹjọ́ sún ẹjọ́ Sẹ́nétọ̀ tó lu obìnrin síwájú 8 Agẹmo 2019 Oríṣun àwòrán, Elisha Ishaku Abbo/Facebook Àkọlé àwòrán, Elisha Abbo Ile ẹjọ kan ni ilu Abuja ti gba beeli Sẹnetọ Elisha Abbo pẹlu miliọnu marun-un Naira to fi mọ oniduro meji.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Parental Guidance: Ọdún méjì ni kí ẹ ti bẹ̀rẹ̀ kíkọ́ ọmọ nípa ìbálòpọ̀ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, O tó ìdá méjì àwọn ènìyàn àgbáyé to wà nínú ewu àìsàn ibà Kíni ìròyìn òfégè ṣe ṣe pàtàkì?
Amọṣa nigba ti BBC News Yoruba gbe ọrọ kalẹ leti iya Olori Badirat Ajọkẹ Adeyẹmi, ohun ti iya sọ fun wa ni pe ko si ohun to jọ bẹẹ ati pe iroyin ahesọ ni awọn eeyan n gbe kiri.
Bẹ́ẹ si ni ninu ile to n gbe gan eniyan mẹrẹ lo wa ninu iṣẹlẹ naa.
Revolution Now: Deji Adeyanju ní ìwọ́de míràn ń bọ̀ ní Satide tí wọn kò bá fi Sowore sílẹ̀
" Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí 3 sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 2:23 Fídíò, Water Generator: Ó leè ṣiṣẹ fún wákàtí mẹfà, kó tó sinmi, Duration 2,2310 Òkùdu 2020 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
ati pé òun yóo fọ́n àwọn ìran wọn káàkiriàwọn orílẹ̀-èdè.
of Niajiria lọwọ, eto naa waye ni ile ise tuntun ohun to wa ni , plot 1386, Oda
Oríṣun àwòrán, LASEMA Ajọ LASEMA naa wa rọ awọn awakọ lati maṣe sare asapajude loju popo.
Wàhálà bẹ́ sílẹ̀ láàrín àwọn ọ̀dọ́ ní Oke Odo ní ìpínlẹ̀ Eko Mo dáríjì àwọn IPOB tó nà mí ní Germany nítorí wọn o m'ohun tí wọ́n ń ṣe- Ekweremadu Àjọ DSS ti gbọ̀ngàn ìpàdé #RevolutionNow pa ní Ikeja Ẹ wo adúrú ẹnu tí mó n bọ́ - Jaiye Kuti Buhari gbóṣùbà fún D'Tigress lẹ́yìn tí wọ́n lu Senegal gba ife AfroBasketWomen Wọn ni, ijọba apapọ n lọra lati mu adehun ṣẹ pẹlu awọn ẹgbẹ naa.
Obìnrin bíi Ruth Bader ni yóò gba ipò rẹ́ ní iléẹjọ́ tó gajùlọ nílẹ̀ Amerika- Donald Trump Ọwọ́ ọlọ́pàá tẹ afurasí ọkùnrin tó gé akẹ́kọ̀ọ́ ọ̀rẹ́bìnrin rẹ̀ wẹ́lẹ́ wẹ́lẹ́ fún òògùn owó ní Ikorodu Oba Abd-Ganiy sọ eyi lasiko ti ọdun ọrọ bẹrẹ ni aafin Iṣẹyin ni opin ọsẹ.
Mo ti rù láàrin ọ̀sẹ̀ kan, iṣẹ́ Eko kò dẹ́rùn - Sanwo-Olu Bakan naa, ẹlẹsẹ ayo, Asisat Oshoala sọ pe o ṣe ni laanu pe Super Falcons fidi rẹmi ninu ifẹsẹwọnsẹ akọkọ wọn, ṣugbọn o gbagbọ pe nnkan yoo yatọ ti wọn ba koju South Korea.
Iroyin ti tan kalẹ kaakiri lati bi ọjọ melo kan pe ijọba ti ko katakata debi ile naa lati daa wo, amọ, laarọ oni Ọjọbọ ni ijọba pada wo ile naa.
Ó gbé apó ọfà sẹ́yìn, tí ń mì pẹkẹpẹkẹ, pẹlu ọ̀kọ̀tí ń kọ mànà, ati apata.
Ó ń gbé inú aginjù Parani, ìyá rẹ̀ sì fẹ́ aya fún un ní ilẹ̀ Ijipti.
Lasiko naa, ibi ariya ni oun ati awọn ọmọ ẹgbẹ rẹ ti ma n kọrin ni awọn agbegbe Ebute Meta, ati fun awọn ololufẹ rẹ ni Mushin.
ero ( National Agency for Science and Engineering Infrastructure (NASENI) ati
Nígbà tí iwin náà dé, kò ga púpọ̀, o sì sanra o ni iké ńlá kan lẹ́yìn.
Alásè náà bá gbé ẹsẹ̀ ati itan ẹran náà wá, ó gbé e kalẹ̀ níwájú Saulu.
“Yóo bukun àwọn ọmọ rẹ, ati èso ilẹ̀ rẹ, ati àwọn ẹran ọ̀sìn rẹ, ati àwọn ọmọ mààlúù rẹ, ati àwọn ọmọ aguntan rẹ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ìyàtọ̀ láàrín ìgbélé ní Nàìjíríà àti ilẹ̀ òkèèrè O ni ko si oṣiṣẹ ẹṣọ aabo pupo ni ibi ti ijamba naa ti ṣẹlẹ.
ṣùgbọ́n nígbà tí a wòó tí a tún-un wò, a ríi pé nṣe ni ilé náà fi igun kan kanlẹ̀.
Ìbá ti dùn tó bí ó bá bẹ̀rẹ̀ sí jó!
 Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: MKO Abiola, iṣẹ́ aṣẹ́gità ló fi bẹ̀rẹ̀ okoòwò Iṣọla Oyenusi rèé, ẹnití ìfẹ́ obìnrin ṣun dé ìwà ìdigunjalè Taiwo Akinkunmi, ọmọ Ibadan tó ya àsìá Naijiria Ayinla Ọmọwura, orin èébú àti oríyìn lo fi di ọ̀rẹ́ àwọ̀n obìnrin Niwọn igba to jẹ pe bi ọmọ ko ba ba itan, yoo ba arọba, tii se baba itan, itan Ọmọyẹ yii lo ni ọpọ ọgbọ ati oye ninu, paapa fun itọni awọn ọdọ iwoyi, ti ko si yẹ ka ma mọ itumọ owe naa."
Awọn ami ti iya gbọdọ kiyesi pe wọn n fi tipa ba ọmọdebinrin lopọ: Iru ọmọdebinrin bẹẹ yoo maa ni ibanujẹ ni gbogbo igba, yoo maa karijọ tabi ṣe ojo lati sọrọ sita Ọmọ naa yoo maa binu nigba gbogbo, tabi maa hu awọn iwa to ju ọjọ ori rẹ lọ Yoo maa ni idiwọ tabi maa ni ijakulẹ lẹnu ẹkọ rẹ, ti kii si ri i bẹ tẹlẹ Yoo nira fun lati ni ọrẹ ti yoo maa ba sere Iru ọmọ bẹẹ yoo maa ni irora to ṣajoji tabi to kọ lati lọ Yoo maa la alakala lati sun tabi ko ma ri oorun sun lasiko to yẹ lai si idi kan pato Ọmọde naa yoo maa wo su u, ti ọkan rẹ ko ni papọ, bo ba se n mu igba ati awo, ni yoo maa jabọ lọwọ rẹ pẹlu ibẹru Ayipada nla yoo ba bi ọmọde naa se n jẹun deede, adinku lee ba isọwọ jẹun rẹ tabi ko pọ si Iru ọmọdebinrin bẹẹ yoo maa sọ awọn ọrọ kan to ṣeesẹ ko fa ijiroro lori ọrọ ibalopọ ni gbogbo igba tabi ko yago ketekete si ijiroro to nii se pẹlu ibalopọ Bẹẹ ni yoo tun maa ya aworan tabi kọ nkan nipa ibalopọ tabi maa la ala ibalopọ ni ọpọ igba Ọmọ naa yoo maa ṣadeede ni ibẹru tabi sa fun irufẹ eniyan kan tabi agbegbe kan ti wọn ba ti fi tipa ba lopọ Yoo kọ lati sọ ọrọ aṣiri kan to sọ fun agbalagba miran tabi ọmọde to ju lọ diẹ, fun ẹlomiran Yoo maa sọ ọrọ nipa ọrẹ tuntun to ṣẹṣẹ ni, amọ to ju u lọ Ọmọde naa yoo ṣadeede maa ni owo lọwọ, nkan iṣere tabi ẹbun lai si idi pataki fun, ti ko si ni jẹ eyi tawọn obi rẹ fun Yoo maa roun n pe ara oun ko rẹwa to tabi pe oju oun ko dun wo, ti yoo si maa kiyesi ara rẹ nigba gbogbo Iru ọmọ bẹẹ yoo maa hu iwa agbalagba ninu awọn iwa ati ise rẹ, ti yoo si maa fi òye nipa ibalopọ han Nigba miran ti isẹlẹ ifipabanilopọ ba waye, ọmọde naa yoo maa ni irora ninu egungun, da ẹjẹ loju ara tabi ki nkan miran maa jade lati oju ara, iho idi, tabi ẹnu rẹ Ọmọdebinrin ti ko tii balaga to ẹni ọkunrin yoo bẹrẹ si ni rin irinkurin tabi hu iwa agbere Yoo sa kuro nile nigba ti isẹlẹ ifipa bani lopọ naa ba di lemọlemọ fun ninu ile to n gbe, ti ko si lee fara da isẹlẹ naa mọ.
Wọn ti wa sin awọn ara ilu naa ni gbẹrẹ ipakọ pe ki wọn maa foju sọri, titi ti ọwọ awọn alasẹ yoo fi tẹ awọn kiniun ọhun.
Àwọn alálẹ̀ kò ní forí jìn mí tí ń kò bá ṣe ọdún Ṣàngó - Alaafin Awọn ayaba kekere naa, ti wọn jẹ ẹlẹ Daddy ati afẹfẹ ti Alaafin fi n mi ni wọn rọgba yi baba ka, to si ya aworan pẹlu wọn.
Bakan naa ni o tun ga awon onigbagbo nimoran lati maa ka bibeli won fun imo Olorun, ati lati ri daju pe, alaafia joba lorile-ede Naijiria.
Kò nílò pé a tún ń kọ̀wé si yín nípa ọ̀rọ̀ ìfẹ́ láàrin àwọn onigbagbọ, nítorí Ọlọrun ti kọ́ ẹ̀yin fúnra yín láti fẹ́ràn ọmọnikeji yín.
Gómìnà Kẹta – Ọ̀gágun Ori Omi Ndubuisi Kanu – Gómìnà fún ọdún kan – ogójì ọdún titi di ọdún mọ́kàndinlógójì sẹhin
Coronavirus: Wo ohun tí o ní láti ṣe láti dáàbò bo ara rẹ Èèyàn mẹ́rin míì tún ni Coronavirus nípìnlẹ́ Oyo, ó di èèyàn 97 tó níi ní Nàìjíríà Ìjọba ìpínlẹ̀ Eko bẹ̀rẹ̀ oúnjẹ pínpín fún àwọn èèyàn lásìkò ìgbélé Coronavirus Ààrẹ, o ye kí ẹ tí bá ọmọ Naijiria sọ̀rọ̀ nípa àrùn Coronavirus Nibi ọrọ de duro bayi, eeyan mọkanlelaadọfa (111) lo ti lugbadi arun na lorilẹede yii, ti ẹnikan si ti jẹ Ọlọrun nipe.
Wọ́n ìbáà máa kígbe sí mi létí, n kò ní dá wọn lóhùn.
Dókítà ọ̀mùtí ní India se iṣẹ abẹ tó mú ẹmi olóyún àti ọmọ rẹ̀
Wọ́n dáhùn pé, “Yàgò lọ́nà fún wa, ṣebí àjèjì ni ọ́ ní ilẹ̀ yìí?
 orin àpàlà kò ní nǹkan án se pẹ ̀ lú ẹ ̀ sìn , òrìsà tàbí ìbọ kan tí a mọ ̀ ni ilẹ ̀ yorùbá .
Ṣugbọn awọn ọrọ naa pọ to bẹẹ gẹ eyi to mu Wunmi bọ sori ayelujara lati ṣe afihan bi Seyi ṣe ki lasiko ọjọ ibi rẹ, to si ni ohun ko fa wahala mọ rara lori ayelujara nitori oun ti kọgbọn.
Samuel Chukwueze ẹlẹsẹ ayo to ge awọn ọmọ South Afrika lori papa ni wọn ni o n bawọn deye si South Afrika pada Ossai Joshua tilẹ ni Super Eagles fi aṣeyọri wọn ninu ifẹsẹwọnsẹ naa jẹ ogede South Afrika ni.
Ó sin Ọlọrun nígbà ayé Sakaraya, nítorí pé Sakaraya ń kọ́ ọ ní ìbẹ̀rù Ọlọrun.
 wọn le malo omi tabi ki wọn fomi fọ lẹhin ti ẹni mẹta gbọnsẹ sinu ile igbọnsẹ oniho .
Lagos School reopening: Ìjóba ìpínlẹ̀ Eko kéde ṣíṣí àwọn ilé ìwé padà
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fọ́nrán ohùn, Inú mi dùn pé ọmọ obinrin nìkan ni mo bi Iriri mi ree: Mo gbe igbesẹ lati sọ iriri ifipabanilopọ ti mo ni lati rii wi pe iru iṣẹlẹ bẹẹ ko ṣẹlẹ sawọn ọmọbinrin keekeeke bii temi nigba ti mo wa ni ọmọ ọdun mẹtala.
Abike Dabiri-Erewa, ti n ṣe alaga ẹgbẹ naa lo sọ eyi ninu ọrọ to fi lede.
akoroyin pe  aare ti pase fun won ,pe ki
Àwọn ọmọ Israẹli ṣẹgun àwọn ọba wọnyi, wọ́n sì gba gbogbo ilẹ̀ wọn tí ó wà ní apá ìlà oòrùn, ní òdìkejì odò Jọdani, láti àfonífojì Arinoni títí dé òkè Herimoni, pẹlu gbogbo agbègbè Araba ní apá ìlà oòrùn.
Wọ́n fi ẹ̀sùn-un àjẹ́ kàn-án ní ọdún-un 1995.
Bakan naa lo sọ pe awọn eeyan ko gbọdọ lati maa fọ ọwọ wọn loorekoore lasiko yii.
- Trump 24 Sẹ́rẹ́ 2020 Oríṣun àwòrán, Getty Images Ilẹ Amẹrika ti ṣipaya awọn ofin mii lati bẹgi dina irinajo awọn obinrin aboyun lọ si Amẹrika lati lọ bimọ.
Ó sọ pé òun díje fún ipò àarẹ́ pẹ̀lú olóyè Olúsẹ́gun Obásanjọ́ ní ọdún 2007 láti fihàn wí pé òun lẹ́tọ̀ọ́ láti ṣe bẹ́ẹ̀ ni gẹ́gẹ́ bíi ọmọ Nàíjirìa.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 2020 in Retrospect: Ìjàmbá iná, ilé tó dàwó, ìwọ́de àti àrùn Covid-19 wà lára ìṣẹ̀lẹ̀ 2020 Nipinlẹ Ondo, Alaga tẹẹkoto lori kikoju Covid-19 ni ipinlẹ Ondo, Adesegun Fatusi ni, ko daa to ki olori awujọ tabi ẹsin maa kesi awọn eeyan lati tapa si ofin ijọba lori ọrọ ilera.
Wọ́n ń fi ìgbéraga sọ̀rọ̀ jàbùjàbù,gbogbo àwọn aṣebi ní ń fọ́nnu.
Ko si ẹni to le ran mi lọwọ, mi o tiẹ mọ orukọ ti wọn n pe iru nnkan bayẹn,'' Oshonaike lo sọ bẹẹ.
Nígbà tí Jesu kúrò níbẹ̀, àwọn afọ́jú meji kan tẹ̀lé e, wọ́n ń kígbe pé, “Ọmọ Dafidi, ṣàánú wa.
Ajọ Eto Idibo lorilẹede Naijiria lo kede Fayemi gẹgẹ bi ẹni to jawe olubori ninu eto idibo sipo gomina to waye ni ipinlẹ Ekiti.
“Idì ńlá mìíràn tún wà, apá rẹ̀ tóbi, ìyẹ́ rẹ̀ sì pọ̀ lọpọlọpọ.
Ṣé o mọ̀ pé ìwé ẹ̀rí ìgbéyàwó rẹ lè jẹ́ ayédèrú?
Ranti ìlérí tí o ṣe fún Mose, iranṣẹ rẹ, pé, ‘Bí ẹ kò bá jẹ́ olóòótọ́, n óo fọn yín káàkiri sáàrin àwọn orílẹ̀-èdè yòókù, 
”‘‘Okan wa ati adura wa, wa pelu awon ebi ati awon ri o fara kaasa isele ibi yii.
Nítorí náà, ẹni tí ó bá wu Ọlọrun láti ṣàánú, a ṣàánú rẹ̀, ẹni tí ó bá sì wù ú láti dí lọ́kàn, a dí i lọ́kàn.
Nítorí náà, nítorí yín, a óo ro Sioni bí oko, Jerusalẹmu yóo di àlàpà, ahoro tẹmpili yóo sì di igbó kìjikìji.
Nibayii, gbajugbaja onkorin ohun tun ti n sise lori orin miran ti o pe akole re ni ‘Celebrate’  ti yoo tun gbe jade lai pe pelu akegbe re Dj Turbo D.
SARS já wọ ilé àwọn akẹ́ẹ̀kọ́ fásitì Akungba #EndSARS: Pe nọ́mbà wọ̀nyìí láti fẹjọ́ ọlọ́pàá SARS sùn Ìjọba àpapọ̀ ti ń wádìí #EndSARS Buhari san lára owó àjẹmọ́nú Super Eagles!
Awọn oludije APC ni aarẹ Buhari yoo ṣe ipolongo fun.
O ni oun ko lowo lati fi fẹ ọmọge loun fi doju kọ awọn abilekọ ati arugbo.
Nígbà tí ìjà bá sì dópin, kí ẹ lè wà ní ìdúró.
Oloye Lekan Alabi wa gbadura pe ki Ọlọrun tẹ akikanju ọmọ Ibadan naa si afẹfẹ rere.
láti inú ìdílé Heburoni, ọgọrin ọkunrin, Elieli ni olórí wọn, 
Ẹwẹ, ko pẹ rara ni adajọ kede pe wan tun ti sun ẹjọ naa siwaju.
Nigba ti awọn akọroyin fi ọrọ wa lẹnu wo, afurasi naa ni lootọ ọrẹbinrin oun ni, ṣugbọn wahala bẹ silẹ laarin wọn nitori ko gba ki o ba a lo pọ.
Coronavirus in Nigeria: Èèyàn 23 míì tún ti ní àrùn Coronavirus ní Naijiria Oríṣun àwòrán, Getty Images Eniyan mẹtalelogun miran tun ti ni aarun coronavirus ni orilẹ-ede Naijiria.
Ṣùgbọ́n lópin ssẹ̀ tó ṣẹ̀ṣẹ̀ kógbá wọlé yìí ni ìná jó dórí kókó, nígbà ti ọ̀kan nínú wọn Wumi Toriola bọ́ si ojú pópó ìkíraẹni Instagram láti sọ̀kò ọ̀rọ̀ ránṣẹ́ si ẹni to n bá jà.
O ni oun ko figba kankan ro pe Mandrake ko ni jade ninu odo naa lọtẹ yii.
O ni wọn ya ọọdurun miliọnu naira sọtọ lati kọ olu ileeṣẹ ijọba ibilẹ ṣugbọn wọn ko owo naa jẹ.
Ìfẹ́ Ọlọrun sí Àwọn Eniyan Rẹ̀, Ọlọ̀tẹ̀.
ẹ gbọdọ̀ lé gbogbo àwọn eniyan tí ń gbé ilẹ̀ náà kúrò.
Atẹjade naa ni ọja, ile iwosan eeyan ati ti ẹranko, ile iwe ati ọna to dara pẹlu omi to mọ gaara maa wa ninu aagọ kọọkan.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Peter Fatomilola ní àìsí ẹ̀kọ́ ń mú káwọn òṣèré tíátà ó máá ṣe oun tí kò tọ́.
O si seese ki irufẹ isan to gbe oju ara obinrin ro yii dasẹ silẹ lasiko ti nnkan ọkunrin ba n sisẹ lọwọ nibẹ.
    Nígbà tí ọba parí ọ̀rọ̀ rẹ̀ tí mo ń fẹ́ sọ̀rọ̀ ni Ayédèrú-ẹ̀da dìde o ni òun ń fẹ́ sọ̀rọ̀ fún un, nígbà tí o sì máa sọ̀rọ̀ ó ni; Kábíyèsí inú mi dùn láti mọ̀ yín lónìí.
Aguntan kò jẹ́ tẹ̀lé àlejò, sísá ni wọ́n máa ń sá fún un, nítorí wọn kò mọ ohùn àlejò.
Gege bi agbenusoro igbimo to n pese aabo fun awon akoroyin, O ni, akoroyin Afghan meje, ayaworan omo ile faranse,Shah Marai ati ayaworan ile-ise akoroyin Reuters si farapa ranpe.
Eyi lo mu ki o maa ko jọ tabi gba awọn idọti tabi ọra omi ti awọn eniyan ju danu yoo si ran an papọ di oriṣiriṣi ohun to wulo.
Ewe, bio tile je pe, ireti wa pe, yoo pada wa kopa ninu idije Mexican Open ninu osu keji latari kikuna lati pari idije Australian Open, sugbon O ko lati kopa, leyi ti o so di idije marun-un otooto ti ko ti kopa lera won bayii.
Orisun iroyin yii kii ṣe lati oju opo oloṣelu Atiku Abubakar fun ra rẹ.
Ó kó òkúta mejila jọ, òkúta kọ̀ọ̀kan dúró fún ọ̀kọ̀ọ̀kan ninu àwọn ọmọ Jakọbu, ẹni tí OLUWA sọ fún pé, “Israẹli ni orúkọ rẹ yóo máa jẹ́.
"Aluko ṣalaye pe ""Iya n jẹ awọn to n ṣiṣẹ nile iwosan, papa julọ, awọn ile iwosan ijọba ipinlẹ."
"Ijọ ti ẹ ba ti n lọ to ba baa yin lara mu naa ni ki ẹ maa lọ.
Eyi ti gomina ipinlẹ Eko, Babajide Sanwo-Olu ni o n kọ oun lominu gidigidi.
Emerole fikun wipe, iwadi obinrin naa lo jẹ kawọn ri onisegun ibile naa gbamu, tawọn si ri onde, agbo lorisirisi ati erọja ibilẹ ti wọn n lọ nibi ile-iwosan ayederu naa, lati jẹ ko dabi ẹniipe awọn obinrin yi ti loyun amọ ti kọsi si oyun ninu wọn.
Wọn ko ni ẹsun titẹ ẹtọ araalu mọlẹ tabi ṣi ibọn lo.
Bill, iwe  abadofin fun didasilẹ  ile-eko igbafẹ ati itọju awon arinrinajo ti  ijoba apapo (National Institute of
Egypt, Senegal, ati South Africa si lo pọ si julọ.
Eyi ati bi eto ẹnawo ijọba ṣe dẹnu kọlẹ, ti ìṣẹ si pọ laarin ilu mu ki awọn araalu bẹrẹ si ni korira iṣejọba rẹ.
Nígbà tí Ọlọrun rí i pé wọ́n ti pa ìwà burúkú wọn tì, Ọlọrun náà bá yí ìpinnu rẹ̀ pada, kò sì jẹ wọ́n níyà mọ́.
Kò si ẹni ti ki ronú, ṣùgbọ́n àròkàn léwu.
Ó kọ́ gbọ̀ngàn kan tí ó sọ ní gbọ̀ngàn Olópòó.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, #Sweetsweetcodeine: Ẹ wo bí ìròyìn BBC nípa oògùn ikọ́ Codeine ṣe ń tún ayé tó ti bàjẹ́ ṣe Akintola jẹ ko di mimọ pe ipenija yii ti di eyi to de gongon awọn ọmọ Naijiria to si n mu ẹmi ọpọ lọ sii laarin agbami okun Mediterranean fun awọn to n sa gba ibẹ.
Wọ́n kọ ìlànà rẹ̀, wọn kò pa majẹmu tí ó bá àwọn baba ńlá wọn dá mọ́, wọn kò sì fetí sí àwọn ìkìlọ̀ rẹ̀.
 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Awọn obinrin adulawọ ni wọn ti gba ni imọran ki wọn mọ iru irun ti wọn yoo maa di."
"Baba Obasanjọ kò ní àrùn Coronavirus- NCDC NCDC kéde èèyàn 437 míràn tó ṣẹ̀ṣẹ̀ lùgbàdì Covid-19 ní Nàìjíríà, 142 gbàwòsàn Iná jó àwọn ènìyàn 10 tó ń gbà ìwòsàn arùn Coronavirus níbùdó ìtọ́jú Eric ati Tochi ni wọ́n lé kúrò nílé ẹlẹ́gbọ̀n àgbà BBNaija lọ́sẹ̀ yìí ""Àwọn èèyàn ìlú Okeho ló kó gbogbo owó tí wọn rí gbà lọ́wọ́ àwọn adigunjalè tí wọ́n mú"" Wọn ti fẹsun kan awọn olugbe ilu Okeho, to wa ni ijọba ibilẹ Kajola ni ipinlẹ Oyo pe wọn kò obitibiti owo ti wọn gba lọwọ awọn adigunjale to ṣakọlu si banki kan lagbegbe ọhun."
Kò sí ẹni tó mọ bàbá rẹ̀.
Arinrinajo kan tori kọyọ Mohammed Sheriff fidi rẹ mulẹ pe, awọn ọdaran naa ṣọsẹ fun bii wakati kan loju ọna naa.
Ọkan lara ohun ti wọn beere fun ni ki wọn wa ọgagun Hisbah kan lati ijọba ibilẹ Kano to ba wu wọn eyi ti wọn si ti ṣe.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Èmi àti Bọla Tinubu fẹ́ lo ‘German Mercenaries’ láti gbé MKO Abiọla kúrò lẹ́wọ̀n - Dele Momodu Makinde, jọ̀ọ́ kéde Aug 20 ọdọọdún bíi ọjọ́ ìsinmi fún ìṣẹ̀ṣe - Àwọn oníṣẹ̀ṣe Ọyọ Khafi jẹ̀bùn ọkọ̀ ₦7.
Samuẹli ti kú, àwọn Israẹli ti ṣọ̀fọ̀ rẹ̀, wọ́n sì ti sin ín sí Rama ìlú rẹ̀.
Egbe oselu APC gboriyin fun ise takun-takun ajo INEC ninu eto idibo ohun.
Ti titobi agọ ara ba pọju, o le se akoba fagọ ara.
Bí ìrètí bá pẹ́ jù, a máa kó àárẹ̀ bá ọkàn,ṣugbọn kí á tètè rí ohun tí à ń fẹ́ a máa mú ara yá gágá.
O ni awọn ti gbe igbesẹ lati pẹtu si awọn akẹkọ ati olukọ naa ninu pẹlu igbesẹ iranwọ gbogbo lati ọdọ ijọba ibilẹ, ipinlẹ lati rii daju pe ẹru ko ba awọn akẹkọ naa ju bi o ti yẹ lọ.
Wọ́ ní “oòrùn ló ni ọ̀sán, òṣùpá lo ni òru”.
Ẹwẹ, awọn ti ori iṣẹlẹ ko yọ ninu iṣẹlẹ Ọjọru ti wa lahamọ bayii ni Libya lẹyin ti wọn doola ẹmi wọn tan.
Ìtàn ìgbésí ayé Oshodi, ọmọ Tápà léǹpe tó di akọni ní ìlú Eko Ẹ wo bí ìpínlẹ̀ Eko, Ondo àti Oyo yóò ṣe dá ilé ìjọ̀sìn padà Ọlọ́pàá ṣ'orò alẹ́ ẹrẹbẹ̀ fáwọn akọ̀ròyìn, dókítà Ìjẹkújẹ àwọn adarí ìjọba ló sọ mí di alárìnkiri nílẹ̀ òkèèrè-Oluwo Coronavirus ti di ara wa, kò le è kúrò mọ láéláé - WHO Coronavirus cases in Africa- Atọ́nà bí nkàn ṣe ń lọ ní Afirika Ènìyàn 226 ló ní àrùn Coronavirus ní Ọjọ Ìṣẹ́gun Inú jìn!
“Nítorí náà, ẹ má bẹ̀rù àwọn eniyan.
Nigeria Elections 2019: Àwọn ọmọ Nàìjíríà n ṣé hèèmọ̀ bí INEC ṣé dajọ sí ibo
Iye awọn eeyan to ṣẹṣẹ ko arun naa ni ipinlẹ kọọkan ree: Abia-67 FCT-40 Eko -38 Ogun-19 Gombe-16 Edo-14 Imo-9 Kwara-8 Katsina-8 Nasarawa-8 Borno-8 Kaduna-6 Bauchi-5 Ekiti-4 Niger-2 Ondo-2 Plateau-2 Kano-2 Sokoto-2 Èèyàn 389 ló tún lùgbàdì àrùn Coronavirus ní ọjọ́ Àbámẹ́ta ní Naijiria Oríṣun àwòrán, Twitter Ajọ to n gbogun ti ajakalẹ arun ni Naijiria, NCDC ti kede eeyan 389 gẹgẹ bi apapọ awọn tuntun mii to ṣẹṣẹ ni arun Coronavirus ni Naijiria ni Ọjọ Abamẹta.
” Wọ́n kúkú ti gbọ́, nítorí a rí i kà ninu Ìwé Mímọ́ pé,“Ìró wọn ti dé gbogbo orílẹ̀-èdè,àní, ọ̀rọ̀ wọn ti dé òpin ayé.
“OLUWA Ọlọrun wa sọ fún wa ní Horebu pé, a ti pẹ́ tó ní ẹsẹ̀ òkè náà.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Lagos Budget: Onímọ̀ nípa ìsúná ṣàlàyé ìgbésẹ̀ Ambode 6 Èrèlè 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 7 Èrèlè 2019 Oríṣun àwòrán, @followlasg Àkọlé àwòrán, Gomina Ambode nile aṣofin Eko Ọpọlọpọ lo ti n sọ ero wọn nipa eto isuna ti gomina ipinlẹ Eko Akinwumi Ambode ṣẹṣẹ gbe sita.
"Nnkan lee di ariwo ati yanpọnyanrin lasiko ti awọn ọlọpaa ba fẹ mu eniyan.
Iyawo Hosia ati Àwọn Ọmọ Rẹ̀.
Ṣugbọn, Buhari papa yan an sipo.
Ó ranti pé ẹlẹ́ran ara ni wọ́n,afẹ́fẹ́ lásán tí ń fẹ́ kọjá lọ, tí kò sì ní pada mọ́.
Nítorí wọn kò ka ẹ̀mí wọn sí pé ó ṣe iyebíye jù kí wọ́n kú lọ.
Nigbati Ẹkùn dé ibùdó rẹ lati fún àwọn ọmọ rẹ ni ẹran jẹ, àwọn ọmọ rẹ kò pé, ṣ̀ugbọ́n àwọn ọmọ ti ijáyà bá padà wá bá iyá wọn, nigbà yi ni iyá wọn rán wọn leti ikilọ̀ pé wọn kò gbọ́dọ̀ jáyà.
 ""Ẹyin obinrin ẹ ronu o, ọkunrin to korira rẹ le ba ọ sun,"" Genevieve kilọ."
Gege bi ogbeni Ibeleme, O ni, ogbeni Amaechi n soju orile-ede Naijiria ati ile Afrika lowo bayii ninu ipade egbe naa.
Orilẹede Egypt ti o gbalejo idije naa wa ni isọri kinni pẹlu Zimbabwe, DR Congo ati Uganda.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Sleeping Lawmakers: Àwọn ọmọ ilé ìgbìmọ̀ aṣòfin l'Abuja ti wọ́n ń sùn lásìkò ìjókòó ilé 25 Ògún 2020 Oríṣun àwòrán, Others Ọ̀pọ̀ ọmọ Nàìjíríà ló n gba ọ̀rọ̀ náà bi ẹni gba igbá ọti láti ìgbà ti adájọ́ àgbà ilé ẹjọ́ FCT Ishaq Bello ti ni ojú má a ń gbà òun ti nígbà ti òun bá ri ọmọ ilé ìgbìmọ̀ aṣofin (kékeré tabi àgbà ) tó bá ń sùn lásìkò ìjókó ilé.
Ọjọgbọn Bashua ti ṣiṣẹ pẹlu ajọ iṣọkan agbaye(UN) ri, gẹgẹ bi oludari ikọ to n ṣoju
Orin 'Maga don pay' tí Kelly Handsome kọ Oríṣun àwòrán, Kelly Hansome/Instagram Àkọlé àwòrán, Kò fẹ́ẹ̀ sí orin tó gbajúmọ̀ tó 'Maga don pay' tó jáde lọ́dún 2008 Ọdún 2008 nàá ni Kelechi Orji, tí ìnagijẹ rẹ̀ n jẹ́ Kelly Handsome, gbé orin 'Maga don pay' jáde.
Àwọn tí wọ́n rà wọ́n pa wọ́n ní àpagbé; àwọn tí wọn n tà wọ́n sì wí pé, ‘Ìyìn ni fún OLUWA, mo ti di ọlọ́rọ̀’; àwọn tí wọ́n ni wọ́n kò tilẹ̀ ṣàánú wọn.
FUTA Bullies: Ìgbìmọ̀ aláṣẹ fásitì FUTA pàṣẹ lọ rọọ́kún nílé fakẹ́ẹ̀kọ́ méje tó lù akẹgbẹ́ wọ́n
Ipada sipo rẹ gan an fa olori awọn oṣiṣẹ nileeṣẹ aarẹ ati olori ẹka oṣiṣẹ nigba naa, Winifred Oyo-Ita gbe'na woju ara wọn.
Nígbà tí ó wọ inú Àgọ́ Ẹ̀rí ní ọjọ́ keji, ó rí i pé ọ̀pá Aaroni tí ó wà fún ẹ̀yà Lefi ti rúwé, ó ti tanná, ó ti so èso alimọndi, èso náà sì ti pọ̀.
Odun 1951 ni wọn bi Mohammed Morsi ni abule El-Adwah ni ẹkun Nile Delta ti Sharqiya.
Sunday Igboho dá sí ọ̀rọ̀ ìbejì Akeugbagold tí wọ́n jí gbé Ibadan Kidnap: Sunday Igboho ra ọwọ́ ẹ̀bẹ̀ sáwọn ọlọ́pàá láti wá ìbejì Akeugbagold síta Oríṣun àwòrán, others Èèkàn àwùjọ kan, Oloye Sunday Adeyemo, tí gbogbo èèyàn mọ si Sunday Igboho, ti sọ̀rọ̀ lórí ìbejì onímọ̀ kan nípa ẹṣin islam, Sheikh Taofeeq Akeugbagold, tí àwọn gende agbebọn gbé lọ lọ́jọ́ Satide.
Ara ọrẹ rẹ̀ tún ni àwo kòtò kan tí wọ́n fi wúrà ṣe, tí ìwọ̀n rẹ̀ jẹ́ ṣekeli mẹ́wàá, tí ó sì kún fún turari, 
”O tun tesiwaju lati so ipinnu re fun awon omo orile ede Naijiria.
Lẹyin oṣu meje, Ali pada wa gba a pada.
Ọwọ́ tẹ àwọn pásítọ̀ oniíṣẹ́ ìyanu èké méji nílùú Eko Wo àwọn dúkìá ìlú tí a fi sọ orí àwọn akọni Messi ló gb'àmì ẹ̀yẹ Ballon D'or lóòtọ́ọ́, àmọ́ Ronaldo ló dára jùlọ (GOAT)- Mendes N kò mọ̀ pé ojú mi ṣì lè là mọ́ lọ́wọ́ ìgbájú- Boluwatifẹ FUTA Ìya lọ ṣọ́ọ̀ṣì, ló bá pàdánù ọmọ!
Ọlọrun ti Jakọbu kò dàbí àwọn wọnyi,nítorí pé òun ní ẹlẹ́dàá ohun gbogbo;ẹ̀yà Israẹli ni eniyan tirẹ̀,OLUWA àwọn ọmọ ogun sì ni orúkọ rẹ̀.
Bo ṣe bí o ṣe ń ṣe ni, ni o máa ṣe
Bande so pe “ A gbodo fowosowopo lati seto ilana ti yoo mu idagbasoke ba awon  akanse eto ti yoo mu igbe-aye iderun ba awon to wa ni ekun ibi ti iko boko haram kolu.
bi ajo eleto idibo se sun eto ibo naa siwaju pe o je nnkan ibanujẹ lorile ede
Oríṣun àwòrán, @jorowasinda Amọ dipo ki wọn se isẹlẹ naa ni ogun ti yoo ka ni mọle, okeere laa tii ko, se ni wọn, eyi ko ri bẹẹ, tawọn ikọ naa fi wọle ti awọn lọpọ yanturu, ti wọn si bẹrẹ si ni ja ilu naa lole loju ibọn.
Ejò lé àwọn aṣòfin ìpínlẹ̀ Ondo kúrò nípàdé Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
 O ni: “Mo fe ki awon osise ajo eleto idibo orile ede Italy fun sise ise naa bi o ti ye fun gbogbo awon oludije ni eyi to fi je pe Iwobi jawe olubori nin u eto idibo naa laifi ti eya, iran tabi esin se rara.
Eeyan iyi ni Ọgbẹni Ahmadu lorilẹede Naijiria, koda ijọba fi ọkan lara awọn ami ẹyẹ to ga ju nilẹ naa daa lọla lasiko iṣejọba aarẹ Goodluck Jonathan lọdun 2014.
Koda kẹẹ kan fẹ din tabi bọ ẹran ranpẹ jẹ ko ri aye.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Kollington ṣàlàyé bí orin Fuji ṣe bẹ̀rẹ̀ gan an ní Nàiìjíríà Ganduje ni aarẹ ana, Goodluck Jonathan gbe igbesẹ akin lati yọ Sanusi nipo gomina banki apapọ Naijiria nitootọ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ijamba: Ẹmi akẹkọ mọkanlelogun,olukọ meji bọ ni Kano 13 Èrèlè 2018 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Olukọ kan ati akẹkọ soso ni ori ko yọ ninu ijamba mọto naa Awọn ọmọ ileewe girama mọkanlelogun ati olukọ meji ni wọn ti padanu ẹmi wọn ninu ijamba mọto kan to waye lorilẹede Naijiria.
Ọkan ninu awọn obinrin naa ni oun na ọgọrun naira si wọn, ṣugbọn wọn kọ jalẹ.
Eyii to tumọ si pe Ighalo ni ọmọ Naijiria akọkọ ti yoo gba bọọlu fun ikọ Manchester United.
Àlàyé rèé lórí ááwọ̀ Femi Fani-Kayode àti Tunde Bakare30 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Olusegun Obasanjo: Ẹ máṣe bú Ọlọ́run torí ọrọ̀ ajé tí kò dára àti òṣì tó gbalẹ̀ ní Nàíjíríà30 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Adewole Oniluola: Tunde Kelani ni ikú àgbà Àyàn náà tún mú kí ilẹ̀ Yorùbá sọ ohun rere nù30 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 High Profile Corruption Cases in Nigeria: EFCC fọwọ́ òfin mú èèyàn 865 lọ́dún 202031 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 3 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 5 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Ọgbẹ́ni Fabiyi ni kò si ohun to le ti ko ni rọ nítori náà o ti pọ́ndandan láti wá wọ̀rọ̀kọ̀ fi ṣàdá lóri ọ̀rọ̀ náà.
Àwọn ẹ̀yà mìíràn tí a rò pé wọn kò dùn ún wò ni à ń dá lọ́lá jù.
Ẹ wẹ ọwọ́ yín mọ́, ẹ̀yin ẹlẹ́ṣẹ̀, ẹ jẹ́ kí ọkàn yín dá ṣáká, ẹ̀yin oníyèméjì.
" O ti le ni ẹgbẹrun mẹtaledinlogoji eeyan ti Covid-19 ti ran ni Naijiria, awọn to le ni ẹgbẹrin si ti ku.
Chelsea dìgbájú ru Watford bí olè tó jí ike owó Olódo méjì!
Ọ̀pọ̀lọpọ̀ òkú ẹyẹ igún ré bọ́ lọ́jà Eke-Ihe Àwa ò mọ ẹgbẹ́ kankan tó ń jẹ́ fijilanté fulani l'Ondo- Ìjọba ìpínẹ̀ Ondo Àwọn èèyàn jàǹkànjàǹkàn l'Akure bí Funke Olakunrin ti wọ káà ilẹ̀ lọ Àgùnbánirọ̀ akọ̀ròyìn Channels náà ti dágbére fáyé látààrí ìkọlù Shiite l'Abuja Ewu nla ni oṣu mẹsan an ti obinrin fi diwọ́-disẹ̀ sínú fi gbe oyun ikoko naa ki Edumare to sọ ọ kalẹ layọ.
ede Canada, bi o tile je pe o ni iwe igbelu orile ede naa, niwon igba to je pe
Wo àwọn ohun tó yẹ kí o mọ̀ nípa àrùn Coronavirus àti ìbálòpọ̀ akọ àt'abo Wo bí àwọn obìnrin kan ṣe n sọ ara wọn di 'fágìn' lẹ́ẹ̀kejì Coronavirus: ''Ìjọba kò tíì pàṣẹ ìlànà ìtakété-síra-ẹni padà nínú BRT la ò ṣe máa tẹ̀le'' Ìjọba gbé ilé ijó oníhòhò tì pa lórí ẹ̀sùn títàpá sí ìlànà àti dẹ́kun coronavirus 3.
Díẹ̀ lára àwọn òṣèré Nollywood ti wọ́n ti ṣe ìgbéyàwó lẹ́ẹ̀kejì Àwọn òṣèré tíátà kan rèé, tí wọn fẹ́ ara wọn, tí ìgbeyàwó wọn sì pẹ́ Saheed Balogun sìnkú ìyá rẹ̀, Ogogo ní ẹgbẹ́ agbábọ́ọ̀lù!
Ẹsun mẹrin ni wọn fi kan Ibuoye lbrahim, o da omi alaafia agbegbe naa ru, o fi tipa wọ ori ilẹ onilẹ, o ba n kan jẹ, o si tun gbimọ ọtẹ, eyi to si ti ni oun ko jẹbi ikankan ninu awọn ẹsun naa.
Nígbà tí ó sọ fún wọn pé, “Èmi gan-an nìyí,” wọ́n bì sẹ́yìn, ni wọ́n bá ṣubú lulẹ̀.
Magu ati Keyamo ri‘binu ijọba Ileejọ tako iyansipo Magu Ọ̀gá DSS tẹ́lẹ̀ rí Daura kúrò l'àhámọ́ Ǹjẹ o mọ bí 'April Fool's Day' se bẹ̀rẹ̀?
Ile-igbimo asofin ohun ni won se idasile re ni odun 2016, labe iwe ofin tuntun, leyin ipinnu awon ara-ilu.
Nítorí nígbà tí ohùn àṣẹ bá dún, Olórí àwọn angẹli yóo fọhùn, fèrè Ọlọrun yóo dún, Oluwa fúnrarẹ̀ yóo sọ̀kalẹ̀ láti ọ̀run.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Ilẹ Gẹẹsi ni orileede akọkọ lagbaye to ti bẹrẹ si ni lo abẹrẹ ajẹsara ti Pifizer pọn lẹyin ti ijọba fontẹ lu lilo rẹ lọsẹ to kọja.
Nigba to n ba BBC Yoruba sọrọ, Oluwo ni lootọ ni awọn se ipade lọbalọba lootọ ti Ọọni ko si ni asẹ lati ni ki oun lọ rọọkun nile na.
Ninu ọrọ tirẹ nibi apero naa, Aarẹ ile asofin agba lorilẹede Naijiria, Sẹnatọ Bukọla Saraki ni afi ẹni to ba fẹ pamọ si ẹyin ika kan soso ni yoo sọ wipe ohun to n sẹlẹ lorilẹede Naijiria lọwọ yii ko fẹ apero pẹlu bi awọn ileto to ti figbakanri dawọ idunnu ọrẹ s'ọrẹ se di eyi ti wọn n gbe ohun ija oloro fi ba ara wọn ja.
Amọṣa ayọ naa ko pẹ pupọ pẹlu bi Athletico ṣe jẹwọ ọmọ ọkọ fun wọn pẹlu goolu meji ni ṣiṣẹ n tẹle.
 Oríṣun àwòrán, Science Photo Library Bí ohunkóhun nínú ọ̀rọ̀ yìí bá ń bí ọ nínú, o leè rí ìmọ̀ràn tó wúlò lójú èwèBBC Advice fún ìmọ̀ràn."
Ẹnu yà wọ́n, wọ́n ta gìrì sí ohun tí ó ṣẹlẹ̀ sí ọkunrin náà.
Ọ sọ loju opo Instagram rẹ pe ẹrin keke lo gba ẹni oun lonii ọjọ Ẹti tii ṣe ọjọ ibi oun.
“Mo si rọ ẹyin ọdọ naa, ẹnikẹni to ba pe yin pe ki ẹ wa lọ ja, ẹ ma da wọn lohun, nitori Aṣofin Tunde Braimoh gan-an fura wọn ko nifẹ rara si jagidijagan”Alaaja Bilikisu Fọlakẹ Oluwo, Olori Ikọ awọn Obinrin (Women Leader) ni agbegbe Agboyi-Ketu dupẹ gidigidi lọwọ ijọba Ipinlẹ Eko, paapaa Aṣofin Tunde Braimoh fun iṣẹ idagbasoke wọn ni Agboyi-Ketu.
Láti inú ẹ̀yà Efuraimu, a yan Kemueli ọmọ Ṣifitani.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: OAU: Ohùn ọ̀jọ̀gbọ́n Richard Akindele ni wọ́n ká sílẹ̀ SERAP fẹ́ pe UI, AAUA lẹ́jọ́ lórí àfikún owó iléẹ̀kọ́ OAU: Ohùn ọ̀jọ̀gbọ́n Richard Akindele ni wọ́n ká sílẹ̀ Àwọn aláṣẹ fásitì Ọbáfẹ́mi Awólọ́wọ̀, ní àbájáde ìwádìí ìgbìmọ̀ náà ti fìdí rẹ̀ múlẹ̀ wípé lóòótọ́ ni ọwọ́ ọ̀jọ̀gbọ́n Akíndélé kò mọ́ lórí ẹ̀sùn yii.
Ohun to ṣe ni pe o kawọ pọnyin lasiko to ṣe abẹwo si Lekki nibi ti iṣẹlẹ ipaniyan ti waye nitori iwọde ENDSARS.
Ahitubu bí Sadoku, Sadoku sì bí Ṣalumu.
Bẹẹ ni owo tasọrẹ ti ko gbe iwọn koko ti awọn agbẹ ko silẹ, ni ijọba n san fun wọn, eyi to n fa ikunsinu labẹlẹ.
Ọ̀rọ̀ kò wọ̀ mọ́ Ìkamọ̀dù dá òórùn sílẹ̀ l’álẹ́ ihò,
Etí rẹ̀ yíká jẹ́ ìdajì igbọnwọ (idamẹrin mita), pèpéle rẹ̀ sì jẹ́ igbọnwọ kan yíká (ìdajì mita kan).
Gomina ipinle Yobe, Alhaji Ibrahim Gaidam, eni ti alakoso fun oro iroyin ni ipinle naa Alhaji Mala Musty soju fun, gboriyin fun Aare Muhammadu Buhari fun akitiyan re,lati je ki won da awon omode-binrin naa sile.
Alaga ajọ eleto idibo ilẹ wa lo kede iṣẹlẹ naa loju opo Twitter rẹ lọjọ Aiku.
Ninu oro pe, ijoba ile Africa woye pe, awon ko le sakoso awon eniyan won laisi ifowosowopo awon onile ise aladani.
Iroyin so pe, ikolu awon omo ogun olote elesin islam ohun, ti n se egbe (IS) lorile-ede Syria,  ni opin ti n de ba, ti ile Amerika yoo si bere lowo awon ti oro kan gbangban lorile-ede naa lati mo ohun ti won yoo se.
"A ti fi diẹ lara ohun ti wọn lo ransẹ si ibudo ayẹwo, taa si n reti abajade esi rẹ bayii.
Ọpọ iwadii si fihan pe ko ri bẹẹ pe ki awọn to maa ku ni ilẹ Adulawọ pọ ju nitori eto ilera ilẹ Adulawọ ti ko mọnyan lori to.
Ko ti si ẹnikẹni to sọ pe awọn lawọn wa nidi ibugbamu naa.
Osun elections: Ademọla Adeleke, Fayoṣe, Atiku sọ̀rọ̀ lórí ìdájọ́ ilé ẹjọ́
Ilé ìgbìmọ̀ aṣojú ṣòfin bọwọ́ lu #30,000 f'ówó oṣù òṣìṣẹ́ Tani Kingsley Moghalu tó ń dupò ààrẹ Naijiria?
Jesus gbá góòlù sáwọ̀n gba ife Community Shield fún Man City Òṣèré tíátà Toyin Abraham daya Kolawole Ajeyemi Bí Khafi ṣe ní ìbálòpọ̀ ojútáyé tako àṣà Yorùbá - Ìjọba Ekiti Ki wọn to lọ sinmi fun saa akọkọ Arsenal gba goolu miran wọle ṣugbọn oludari ere naa, wọgi lee lẹyin ti ẹrọ VAR ṣe afihan rẹ pe aṣiṣe waye ṣaaju goolu naa.
Angẹli náà sọ fún mi pé, “Iṣẹ́ tí OLUWA àwọn ọmọ ogun rán sí Serubabeli ni pé, ‘Kì í ṣe nípa ipá, kì í ṣe nípa agbára, bíkòṣe nípa ẹ̀mí mi.
Pipadanu awọn ipinlẹ to jẹ ti APC ni 2015 fun PDP lọdun 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Ọpọ awọn alagbara ẹgbẹ oṣelu APC lo ṣi n fapa janu pe awọn iwa ati ọrọ Adams Oshiomole kun ara ohun to fa a ti ẹgbẹ oṣelu APC fi padanu awọn ipinlẹ bii, Zamfara, Imo Oyo ati Adamawa.
17 Kíyèsíi, ẹ̀yin ní ìhìnrere mi níwájú yín, àti àpáta mi, àti ìgbàlà mi.
Bakan naa lo bu ẹnu atẹ bi awọn oṣiṣẹ eleto ilera ṣe bọ aṣọ idaabo bo ara ẹni lọwọ aarun nibi isinku naa.
Ogun abẹ́lé tó ń ja Akeredolu l'Ondo, òní la ó mọ̀ bóyá yó borí rẹ̀ Akẹ́kọ̀ọ́ 333 ni a kò tíì le sọ nípa wọn nílé ẹ̀kọ́ Kankara Katsina- Ìjọba Nàìjíríà Ṣugbọn ki ni imado?
 Won ti bi ọmọ meji bayii (Sasha, ọmọ odun mẹta ati Milan, ọmọ ọdun marun un).
 Oríṣun àwòrán, others Wague fikun pe, ""ki orilẹede Mali maa baa ri si agbami okun aye, ni awa ta jẹ olufẹ ilu se ko ara wa jọ lati gba akoso lọna ati ri daju pe awọn ohun eelo ilu n sisẹ bo se yẹ."
Nibi ipade naa si ni Fasọla ti la ọrọ mọlẹ pe ayafi ti ijọba ba pese owona toto lati gbọ bukata atunse opopona marosẹ Ibadan silu Eko nikan ni ọna abayọ lati pari isẹ naa nitori ọgbọn ko di igi, afi okun nikan.
Ọlọ́pàá fi pańpẹ́ ọba mú Ọmọyele Sowore Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Imperial Majesty ni Olubadadan, Royal Majesty làwa, òfin sì tẹ̀lé e - Ọtun Olubadan Bi ifọrọwerọ BBC Yoruba naa se lọ ree pẹlu Salawa Abẹni Salawa Abẹni sọ pe, ọmọ ọdun mẹtala wa, ti oun fi gbe awo orin waka akọkọ jade lọdun 1976, o ni iranti aarẹ ologun orilẹede Naijiria tẹlẹ ri, ologbe Ọgagun Murtala Muhammed ni awo orin naa da le lori.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ìnú mi kìí dùn nígbà trí mo ń ṣiṣẹ́ ni bánkì tó ìgbà ti mo bẹ̀rẹ̀ mẹkáníìkì Adewetan fikun wi pe ibanujẹ ọkan lo jẹ fun awọn lẹyin isekupani Oloye Bademosi ni inu ile rẹ ni ilu Eko , ati wi pe ọna lati daa lọla ni awọn ṣe fagile ọdun naa.
lẹ ́ yìn ọ ̀ pọ ̀ lọpọ ̀ atótónu lórí ẹ ̀ bi àti àṣìṣe òfin , wọ ́ n ṣe ẹjó johnston ní sens ní ọdún 2003 , ọdún mẹ ́ tàlá sí ìgbà tí ìsẹ ̀ lẹ ̀ náà ṣẹlẹ ̀ .
Eyín ọ̀ọ́kán mi ni Barakat tí wọ́n pa lẹ́yìn tí wọ́n fipá bá a lòpọ̀- Ìyá Barakat Kí ni ìdí tí ilé ẹjọ́ tún ti sún ìgbẹ́jọ́ Alfa Babatunde Sotitobire síwájú Ọmọdé yóò máa sọnù ládùúgbò, arúgbó leè kú láì tọ́jọ́, tí wọn bá jókòó sílé lásìkò ìjọsìn - CAN Àwọn afunrasí lórí ikú Funke Olakunrin ti wà nílé ẹjọ́ ní Akure Ninu iwe ilana naa, wọn ṣalaye iru iṣẹlẹ to lee ṣe okunfa ki wọn gbe oku kuro lati ipinlẹ kan tabi orilẹ ede mii.
Ẹ má mu gaarí mọ́ nítorí ìbà Lassa- Dókítà Boniface Kínla!
ri ninu ero ayelujara ti ajo INEC ,ninu eyi ti oludije fun ipo aare labe asia -egbe
7 àti Iphone iOS 8, àwọn tó ti pẹ́ jù bẹ́ẹ̀ lọ, ṣiṣẹ́.
Ẹ̀yin ni Ọlọrun fi Orebu ati Seebu, àwọn ọmọ ọba Midiani mejeeji lé lọ́wọ́.
Nítorí Ọmọ-Eniyan pàápàá kò wá pé kí eniyan ṣe iranṣẹ fún un, ó wá láti ṣe iranṣẹ ni, ati láti fi ẹ̀mí rẹ̀ ṣe ìràpadà fún ọpọlọpọ eniyan.
Ulrich Salazar, oyinbo kan lati New York ni orilẹ-ede Amẹrika wa lara àwọn alejo to ti de si Oṣogbo to jẹ olu ilu ipinlẹ Oṣun fọ́fọ́.
   Gege bi alaga egbe awon osise  Sunday Adeleye,se so, o ni oun ro awon igbimo
Bí ẹnìkan bá hùwà ọ̀dàlẹ̀, tí ó ṣòfófó àwọn ọ̀rẹ́,kí ó lè pín ninu ohun ìní wọn,àwọn ọmọ olúwarẹ̀ yóo jìyà.
Ninu atẹjade naa wọn rọ awọn oṣiṣẹ alaabo lati fi ijiya to tọ jẹ awọn to ba kopa ninu iwa janduku tabi jiji apoti ibo gbe.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Nigeria's Under-19: Ẹ wo bí Ikọ̀ Cricket Naijiria ṣé mí àgbáyé titi Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Nigeria's Under-19: Ẹ wo bí Ikọ̀ Cricket Naijiria ṣé mí àgbáyé titi 21 Sẹ́rẹ́ 2020 Ikọ agbabọọlu ere alafigigba ta mọ si Cricket lọrilẹede Naijiria ti ni o da bi ala loju awọn pẹlu bi awọn ṣe pegede lati kopa ninu idije Ife Agbaye Cricket fun igba akọkọ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Chef Adefunkẹ: Òórùn ewé tí wọ́n n pọ́n ìrẹsì ọ̀fadà si jẹ́ adùn lọ́tọ̀ Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Oríṣun àwòrán, Getty Images Nitori ajakalẹ arun Coronavirus lọdun yii, miliọnu mejilelọgọrin eeyan lo ti fi erongba wọn lede lati dibo nipase awọn ileeṣẹ ifiweranṣẹ.
Fọnran to wa kaakiri ẹrọ ayelujara ṣafihan awọn arinrinajo ti wọn n gba ọna àbùjá ọkọ baalu naa lati sa asala fun ẹmi wọn ninu baalu Aeroflot.
Bakan naa lo rọ ijọba ati awọn agbanisiṣẹ lati ṣe awọn alakalẹ eto ninu eto isejọba ti yoo fun awọn obinrin ni anfaani lati fun awọn ọmọ wọn ni ọyan nikan ṣoṣo fun oṣu mẹfa akọkọ lai ni abula.
" Ẹwẹ, lori ẹrọ ayelujara, awọn ololufẹ FalZ ti bẹrẹ si ni da si ọrọ nipa orin naa ati fidio rẹ.
Ẹgbẹ́ òṣèlú Congress for Progressive Change (CPC) ti Buhari jẹ ọmọ ẹgbẹ́ ní ìgbẹ̀yìngbẹ́yín parapọ̀ mọ́ ACN, wọ́n sì di ọkàn nínú oṣù Kejì ọdún 2013, èyí tí ó ṣe okùnfà ìdásílẹ̀ ẹgbẹ́ òṣèlú tuntun tí orúkọ rẹ̀ ń jẹ́ Àjọ Ìtẹ̀síwájú Gbogboògbò (APC).
lati ile-ise to n mojuto eto ogbin lorile ede Naijiria.
Orile-ede naa ni apa ila oorun ile Afirika ,ti o kun fun awon eniyan ti o le ni millionu  lona ogorun ni won n koju laasigbo eleyameya ninu eyi ti ogunlogo ti so emi won nu ,ti awon eniyan ti o le ni million kan si ti di alainilelori, Abiodun Popoola.
Ọlọ́pàá Ondo: Dírẹ́bà ọkọ̀ nìkan ni wọ́n jígbé kìí se àwọn 18
Bi ẹ ko ba gbagbe, Aubameyang lo gba pẹnariti ẹlẹẹkarun un to kẹyin wọle fun Arsenal lẹyin to ti kọkọ mi awọn titi ninu ere bọọlu naa ni papa iṣere Wembley.
ni Sẹnẹto Melaye @dinomelaye14 kọkọ fi bẹrẹ loju opo Twitter.
Jesu dáhùn pé, “Èyí tí ó ṣe pataki jùlọ nìyí, ‘Gbọ́, Israẹli, Oluwa Ọlọrun wa nìkan ni Oluwa.
 Mi o ki n se oloselu nikan.
Nítorí olódodo ni OLUWA, ó sì fẹ́ràn òdodo;àwọn olóòótọ́ ni yóo rí ojú rẹ̀.
Ọpọlọpọ obinrin ode oni lo n fi gbogbo iṣẹ lẹ fun ọmọ ọdọ.
Ko to gori oye Emir, Sanusi ma n sọrọ pẹlu igboya lori ọrọ iṣejọba ati ọrọ aje orilẹ-ede Naijiria.
O ni nítorí pé àwọn kò fi ọwọ́ yẹpẹrẹ mú ọ̀rọ̀ ẹmi rara ninu iṣẹ ologun.
Àwọn Ẹbọ Tí A Sun Lódidi.
Kíá ni ó sọ ìkòkò omi rẹ̀ kúrò ní èjìká, tí ó sì wí pé, ‘Omi nìyí, mu, n óo pọn fún àwọn ràkúnmí rẹ pẹlu.
PREMIUM TIMES earlier reported how Saudi Arabia had announced that the Ramadan should commence on Thursday.
Òun sì ni àbíkẹ́yìn Yéwándé Bándélé jẹ́ ọmọ odún mẹ́jọ.
Eleyii lee maa tete ya fun awọn idi kan tabi omiran.
Ṣugbọn Naamani fi ibinu kúrò níbẹ̀, ó ní, “Mo rò pé yóo jáde wá, yóo gbadura sí OLUWA Ọlọrun rẹ̀, yóo fi ọwọ́ rẹ̀ pa ibẹ̀, yóo sì ṣe àwòtán ẹ̀tẹ̀ náà ni.
’ rèé Afọnja, ẹni tó finú wénú ní Ilọrin, àmọ́ tó jẹ iwọ Ẹfunsetan Aniwura, obìnrin tó ju ọkùnrin lọ Ọ̀rọ̀ǹpọ̀tọ̀niyùn, Aláàfin obìnrin àkọ́kọ́ rèé, tó ní nǹkan ọkùnrin Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Kachikwu ó ṣeun, wá lọ simi- Ààrẹ Muhammadu Buhari 27 Òkùdu 2019 Oríṣun àwòrán, Google Àkọlé àwòrán, Thomas John Ààrẹ Muhammadu Buhari ti yan Thomas John gẹ́gẹ́ bíí adele alága NNPC èyi to mú sáà Ibe Kachikwu wá sópin gẹ́gẹ́ bii mínísita epo rọ̀bì.
 Bo tile je pe opolopo emi lo maa n sonu lodooodun nibi ile-riri ni Nyatike , sibe eyi ko so pe ki awon ara ilu naa yako fun gusa wiwa lati inu-ile.
Ẹfunsetan Aniwura, ọmọ Ẹ̀gbá tó di akíkanjú obìnrin nílẹ̀ Ibadan Nínú òkuǹkùn birimù birimù ni mo wà báyìí ni ilé Ìjọba - Igbakeji Gomina Kogi àná Òṣìṣẹ́ Fásitì Ìbàdàn méje dèrò àtìmọ́lé lórí àyídáyidà ìdánwò Iṣẹ́ oko ni Saraki fẹ́ fi ilẹ̀ tíléẹjọ́ gbẹ́sẹ̀lé ṣe - Àwọn alágbàṣe Ogunjọ oṣu karun un ọdun yii ni EFCC kọkọ gbe Naira marley lọ sile ẹjọ, ti wọn si fi ẹsun mọkanla kan an.
Ọ̀rọ̀ òtítọ́ ni yóo ti ẹnu mi jáde,nítorí mo kórìíra ọ̀rọ̀ burúkú.
Lónìí ni a rí i tí Ọlọrun bá eniyan sọ̀rọ̀, tí olúwarẹ̀ sì tún wà láàyè.
Ọpọ igba lo maa n gbe aworan ara rẹ sori ayelujara eyi ti awọn èrò púpọ̀ máa n jẹ dòdò rẹ, ṣugbọn ti wọn maa n padà wá sá fun un ni kete ti wọn ba ti ri Folaṣade ni ojukoju pe akanda ẹda ni.
Oríṣun àwòrán, @Aminu Bello Masari Gomina Bello Masari fi kun ọrọ rẹ pe oun ti ṣe ipade pẹlu awọn lọga-lọga nileesẹ ologun, lẹyin ti oun ṣe abẹwo si ile ẹ̀kọ́ naa, ati aarin ilu to wa.
Kọmisanna fi kun pe awọn ile sinima ko gbọdọ ṣi ilẹkun wọn tayọ aago mẹrin idaji si mẹwaa alẹ, ni ibamu pẹlu ofin isede to wa nita.
Bákan náà lo tún leè gba agbẹjọ́rò bíi ààdọ́ta lórí ojú òpó yìí láti jà fún ọ.
Òtútù ikú Ajimobi sì ń mú mi, ń kò le sọ̀rọ̀- Akala, Ayefele Bi ọdẹ ba ku, ọdẹ ni soro lẹyin ọdẹ, bẹẹ si ni ba ba ku laa dere, eeyan ko sunwọn laaye.
Ẹni tí ó ni talaka lára kí ó lè ní ohun ìní pupọ,tabi tí ó ń ta ọlọ́rọ̀ lọ́rẹ yóo pada di talaka.
Gẹgẹbi iroyin se sọ, awọn ọmọ ileewe yii atawọn olukọ wọn n rin irin ajo ifinimọlu lọ si ilu kano, lẹkun iwọ oorun ariwa Naijiria lati ilu Misau, to wa lagbegbe ila oorun ariwa orilẹede yi, nigba ti ijamba naa sẹlẹ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Àṣìṣe ọlọ́pàá àti Adájọ́ sọ mí di ẹni tí wọ́n dájọ́ ikú fún, ọpẹ́lọpẹ́ Fayoṣe tí ko buwọlu Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Sunday Shodipe: Ilé ẹjọ́ fi Sunday Shodipe, afurasí ìṣekúpani l'Akinyele pamọ́ sí ọgbà ẹ̀wọ̀n21 Owewe 2020 Fídíò, Akomolede: Bolaji Faleke ni Olùkọ́ tó ń kọ́ wa ní àṣà oge ṣiṣe lórí BBC Yorùbá1 Owewe 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 3 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 5 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Ninu atẹjade kan to fisita lọjọ Aje, alukoro ileeṣẹ ọlọpaa nipinlẹ Eko, Bala Elkana, sọ pe ẹri lati ẹnu awọn ti iṣẹlẹ naa ṣoju wọn lo fun ileeṣẹ ọlọpaa ni anfaani lati da ikọ ọlọpaa to hu iwa ipaniyan naa.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Cholera Vaccine: NAFDAC kìlọ̀ lórí ayédèrú òògùn ààrùn onígbáméjì 2 Ìgbé 2019 Oríṣun àwòrán, Twitter/NAFDAC Nigeria Àkọlé àwòrán, Oogun ayederu ma n ṣakoba fun aggọ ara ni Ajọ to n mojuto aṣilo oogun ati ounjẹ, NAFDAC ti kilọ fawọn ọmọ Naijiria pe ayederu oogun aarun onigbameji ti ọpọ mọ si Kọlẹra ti gbode kan bayii lorilẹ-ede Bangladesh.
Èdè jẹ́ ohun ètò tí a máa ń lò láti ṣe àròyinlẹ̀.
Iṣẹlẹ naa si ti mu ki sunkẹrẹ, fakẹrẹ ọkọ o gbode ni awọn agbegbe to o yi ibi to ti waye ka.
Ọkùnrin kan tó yasó nínú ọkọ̀ Uber rí ẹ̀wọn he Mo bu ẹnu atẹ lu ikọlu to waye yii mi o si laye laye gbe lẹyin mọndaru ati iwa ipa si araalu""."
O fikun un oro naa pe, won da awon arinrin-ajo naa pada pelu iranwo ajo to n mojuto oro irin-ajo nile okere International Organisation for Migration (IOM).
Lẹyin naa ni ọpọ awọn ọmọ Naijiria ti dide lodi si nkan ti ọdọmọde senetọ yii ṣe.
Àwọn apanirun ti dé sí gbogbo àwọn òkè inú pápá,nítorí pé idà Ọlọrun ni ó ń run eniyan, jákèjádò ilẹ̀ náà;ẹnikẹ́ni kò ní alaafia,
eleyii ti a o si tun duro digbi lati fi eto isejoba tiwa-n-tiwa mule sinsin sii
Ikọlu yi n waye lẹhin ti ile isẹ ọmọogun orilẹede Naijiria ti figa gbaya wipe awọn ti bori Boko Haram.
Ile igbimọ aṣofin ipinlẹ Eko ni Ọjọru ni wọn fun Ambọde lati farahan, ki o lee wa ṣe afọmọ ọrọ nipa awọn inawo kan to waye ni saa iṣejọba rẹ.
Oríṣun àwòrán, @GovUmarGanduje Ṣe irọ ni fidio to ṣafihan Gomina Ganduje?
Awọn agbegbe kan lorilẹede Naijiria lo ti nni iriri ojo lati bii ọsẹ meji sẹyin to fi mọ olu ilu ilẹ wa Abuja ati ipinlẹ Eko.
"Gbogbo ìgbà tí mo bá ni ìbálòpọ̀ ni ọkàn mi máa ń bàjẹ́, mo máa ń dá ara mi lẹ́bi dípò ni ti mo bá lájọṣepọ̀.
Ó fi owó yìí kó àwọn oníjàgídíjàgan ati ìpátá kan jọ wọ́n sì ń tẹ̀lé e kiri.
Nígbà tí ẹ̀fúùfù náà fẹ́ dé ọ̀dọ̀ mi ojú mi rí nǹkan, nítorí ẹ̀fúùfù eléyìí tún wáá pọ̀ ju èyí ó lé mi kúrò ní ihò mi lọ; nígbà ti ẹ̀fúùfù náà fẹ́ dé ọ̀dọ̀ mi nǹkan kò ṣeé fi ẹnu sọ: gbogbo igi ń fi orí lu ara wọn; ìtàkùn ń kọlu ìtàkùn, ewé gba ojú ọrùn kankan, imọ̀ ọ̀pẹ wà ni hílàhílo; igi ń rọ́ kẹ̀lẹ̀, ogunlọ́gọ̀ wọn sì ń wó lúlẹ̀ lẹ́bàá ọ̀dọ̀ mi.
Nígbà tí a wọ ọkọ̀ láti Tiroasi, a lọ tààrà sí Samotirake.
O dúdú  tó bẹ́ẹ̀ ìtàkùn sì pọ̀ tó bẹ́ẹ̀ igi gígga sì tún wà tó bẹ́ẹ̀ ti o ṣọ̀ro láti ṣe àpèjúwe.
Lilo awọn ọmọ ogun labẹnu Ajọsepọ Russia lẹka ologun ati aabo kọja kiko ohun ijagun lọ silẹ okeere, nigba miran, o tun maa n lo awọn ikọ ologun aladani labẹnu.
Ó fi wúrà tí ó dára jùlọ ṣe àwọn òdòdó, àwọn fìtílà ati àwọn ẹ̀mú.
Àwọn ọnà ti Olusegun Aroke ń gba wọ́'ke owó nínú ọgbà ẹ̀wọ̀n rèé 'Àwọn olósèlú rán aṣọ ọlọ́pàá f'àwọn ayédèrú ọlọ́pàá ní Kogi ati Bayelsa' Ọba Lekan Balogun, lasiko to n ba BBC Yoruba sọrọ kede pe, igbesẹ naa ko bojumu, ti awọn ko si faramọ rara nitori pe wọn kii fari lẹyin olori.
peye da awon ara ilu loju lakooko ti won ba n se ojuse won, o fikun oro re pe,
 Amọ ẹnikan ti isẹlẹ naa soju rẹ, amọ to kọ lati foju han lori aworan BBC Yoruba ni, iye awọn eeyan to ku ninu ijamba yii ko lonka, ti wọn ti ha sinu ina ọhun."
Nígbà tí ọwọ́ iná ẹbọ náà bẹ̀rẹ̀ sí yọ sókè láti orí pẹpẹ, angẹli OLUWA náà bẹ̀rẹ̀ sí gòkè lọ ninu ọwọ́ iná orí pẹpẹ náà, bí Manoa ati iyawo rẹ̀ ti ń wò ó.
 carr jẹ ́ kí àwọn london board of education ri wípé dídá ilé ìwé yìí sílẹ ̀ maa mú ìtẹ ̀ síwájú bá ètò wọ ́ n nípa ẹ ̀ kọ ́ ní àwùjọ .
Lọdun 2016,o soju orilẹẹde rẹ nibi idije Winter Youth Olympics ni Norway.
(Aṣojú iléeṣẹ́ BlaBlaCar fún ìbánisọ̀rọ̀ pẹ̀lú àwùjọ): Bẹ́ẹ̀ ni, Ìyẹn dára
Tani ẹni to n sakoso iwa ọtẹlẹmuyẹ fun awọn eto abo nibẹ ati pe igbesẹ wo ni wsn gbe lati so okun abo ko le daindain ni agbegbe naa?
Ẹ kí Tirufina ati Tirufosa, àwọn tí wọn ń ṣe iṣẹ́ Oluwa.
Nisinsinyii, kò sí ohunkohun tí mo mọ̀ ní àmọ̀tán.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Owó tí mo ń rí lórí Garri ni mo fi ń ran ọkọ lọ́wọ́' Bakan naa, o ni Iya Rainbow maa n pe oun ni ọkọ oun, ti inu oun si maa n dun, amọ nigba to ya lo ye oun pe, gbogbo ọkunrin ni iya naa maa n pe ni ọkọ rẹ, eyi si tumọ si pe iya naa ko tilẹ mọ iye ọkọ to ni, eyi si lo mu ki oun maa pe ni Aṣẹwo haun-haun.
" Kásà, ewé sunko fún àgbà òṣèré tíátà, Fádèyí Olóró Làá hàn mí dé, ètò tó ń ṣàlàyé ohun tó yẹ ká ṣe láti dènà àrùn Coronavirus 'Obinrin lo mu mi fẹran orin kikọ' Fọlọrunṣọ Alakija: Obinrin nilo imọ Angelique kidjo pe fun anfani f'awọn obinrin Mo fẹ́ di obinrin to dára júlọ lágbàyé-Bobrisky Kíni ìdí ti wọn fi ń lọ ọmú obinrin Ninu ọrọ tiwọn, ajọ iṣọkan agbaye rọ awọn eeyan gbogbo lati ji giri gbogun ti awọn ipenija aidọgba laarin ẹya ẹda gbogbo.
Àwọn ènìyàn bíi mílíọ ̀ nù méjè ni ó ń sọ èdè yìí ní pàtàkì ní orílẹ ̀ -èdè ghana .
Leah Sharibu pé ọmọ ọdún 16 ní àhámọ́ Boko Haram 'Boko haram kọ́ ló fa ìbúgbàmù Mubi' 'A ti pa Boko Haram run patapata' Ologun Nigeria gbakoso ibuba Boko Haram Ọkan lara awọn asaaju agbegbe ti iṣẹlẹ yii ti ṣẹlẹ, Bunu Bukar Mustapha ti o ba awọn ile iṣẹ iroyin AFP sọrọ ṣalaye pe lati abule Badu Kuluwu lẹba Goni Abachari ni awọn eeyan naa ti n dari bọ nibi ti wọn ti lọ sin oku kan.
 Iwobi ti wọn bi nilu Gusau lorilẹede Naijiria, amọ to ngbe nilu Italy latọdun 1970 lo jẹ alatilẹyin nla fẹgbẹ oselu League lati bii ogun ọdun sẹyin."
Nígbà tí ó di ẹẹkeje, lẹ́yìn tí àwọn alufaa fọn fèrè wọn, Joṣua pàṣẹ fún àwọn eniyan náà pé, “Ẹ hó yèè!
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Bisi Alimi: Ìyà mi rò pé n kò leè ṣe ni àmọ́ n kò ní ìfẹ́ abo ni mo ṣe fẹ́ akọ Ajọ naa wa parọwa si gbogbo awọn ti ọrọ naa kan lati ri wi pe wọn se ojuse wọn ki eto aabo orilẹede naa ma ba a mẹhẹ.
Ààrùn Coronavirus tún ti ran ènìyàn 571 l'órílẹ̀-èdè Nàìjíríà Wọ́n ti yìnbọn pa olórí ẹgbẹ́ jàndùkú ''One Million Boys'' ní Ibadan’ Mama Arsenal: Ẹgbẹ́ kan ti fún màmá ní ẹ̀bùn owó Gbajúgbajà òṣèré India, ọmọ, ìyàwó ọmọ àti ọmọ-ọmọ rẹ̀ lùgbàdì ààrùn Coronavirus Amọ, Adajọ Agba naa ko gba iwe ti wọn fi ranṣẹ sii, nitori iye awọn to dibo lati yọ igbakeji naa ko to ida meji ninu mẹta awọn ọmọ Ile Igbimọ Aṣofin.
O ti to nnkan bi ọdun diẹ sẹyin ti ijọba Naijiria ti ni oun yoo wa ojutu si ija laarin awọn darandaran atawọn agbẹ, ṣugbọn kaka k'ewe agbọn ọrọ naa dẹ, lile lo tun n le si.
Fintiri ti fi igba kan jẹ adele gomina ipinlẹ naa nigba kan ri, ni akojọpọ ibo 376,552, lati fi bori gomina ipinlẹ naa lọwọlọwọ, to dije labẹ ẹgbẹ oṣelu All Progressives Congress, Jibrilla Bindow to ni ibo 336, 386.
Wo ohun tó ń fa àfikún epo lóòrèkóòrè ní Nàìjíríà Awọn ile ọti ati ile ijo ko gbọdọ ṣilẹkun Ajọ NYSC yoo bẹrẹ imurasilẹ fun igba ti awọn ileewe yoo di ṣiṣi pada Ajọ INEC yoo ri daju pe o tẹle ilana lori coronavirus- ẹni ti ko ba lo ibomu ko gbọdọ dibo.
Kò sì sí ohun kan tí ó wù mí láyé yìí bíkòṣe ìwọ.
Josẹfu bá ra gbogbo ilẹ̀ Ijipti fún Farao, nítorí pé gbogbo àwọn ará Ijipti ni wọ́n ta ilẹ̀ wọn, nítorí ìyàn náà dà wọ́n láàmú pupọ.
Wo àwọn ohun tó yẹ kí o mọ̀ nípa àrùn Coronavirus àti ìbálòpọ̀ akọ àt'abo Bẹ́mídíje ni mí, mo kọjá ẹni tí Coronavirus lè fi ta'yín- Ṣeyi Makinde Kí ló pa bàbá Adeboye, bàbá Davido àti Ọ̀ọ̀ni Ifẹ̀ pọ̀ lásìkò ìgbélé l'Ọ́ṣun?
Nígbà tí ẹni tí ó wà ní òkè ilé bá sọ̀kalẹ̀, kí ó má ṣe wọ ilé lọ láti mú ohunkohun jáde.
Seyi Makinde ni Alága ẹgbẹ́ òsèlú PDP fún ètò ìdìbò sípò gómìnà tí yóò wáyé ní Ọjọ Kẹrindinlogun, Osu Kọkanla, odun 2019.
Nítorí náà, ẹ kì í tún ṣe àlejò ní ìlú àjèjì mọ́, ṣugbọn ẹ jẹ́ ọmọ-ìbílẹ̀ pẹlu àwọn onigbagbọ, ẹ sì di mọ̀lẹ́bí ninu agbo-ilé Ọlọrun.
Elebuibọn ni ki wọn to yan Ooni, tabi Ọba nilẹ Yoruba, idile ti oye ba kan lo maa fa ẹni ti wọn ba n fẹ ko dori itẹ silẹ, ti awọn afọbajẹ yoo si di ifa lati mọ boya asiko irufẹ Ọba bẹẹ yoo san awọn ara ilu.
''Gbogbo iléèṣẹ́ ìròyìn ló ní àfojúsùn.
Awọn miran tiẹ gbagbọ pe ipolongo bi West n fi ọgbọn ṣe fun awo orin rẹ tuntun, nitori pe o pẹ ẹ darapọ mọ idije fun idibo naa.
Nígbà tí OLUWA gbọ́ òórùn dídùn ẹbọ náà, ó wí ninu ara rẹ̀ pé, “N kò ní fi ilẹ̀ gégùn-ún mọ́ nítorí eniyan, nítorí pé, láti ìgbà èwe wọn wá ni èrò inú wọn ti jẹ́ kìkì ibi.
Awọn asofin ni k'ijọba apapọ o dawọ owo ori ọja lati okeere duro Awọn oloselu Naijiria ati awọn ẹbun ifẹ wọn Iroyin fi han wipe isẹlẹ naa le pupọ ninu ijọba ibilẹ Augie, Argungu, Bagudo, Dandi, Kalgo, Bunza ati Suru.
Gomina Bamidele Olumilua lo wa lori òye nígbà tí ìtẹ́ Ọlọwọ ṣófo, tó sì la ọ̀nà fún Ọba James Titus Olateru-Olagbegi kejì láti padà sí orí ìtẹ́ àwọn baba ńlá rẹ lọ́dún 1993, lẹ́yìn ọdún kẹẹdọgbọn tí wọn tí yọ kúrò lórí ìtẹ́, àsọtẹ́lẹ̀ ifa kejì sì sẹ nípa ọba alaye náà.
Iṣọri keji ni ofin to de iṣẹ ọba ati ti aladani: Ofin yii lo n sewuri fun iṣẹ asekara, dide ibi isẹ lakoko ati ikorira asa gbigba abẹtẹlẹ lẹnu isẹ.
Ọba bá ka ìwé majẹmu tí wọ́n rí ninu ilé OLUWA sí etígbọ̀ọ́ wọn.
Mo wá rí obinrin náà tí ó ti mu ẹ̀jẹ̀ àwọn eniyan Ọlọrun ní àmuyó, pẹlu ẹ̀jẹ̀ àwọn tí wọ́n jẹ́rìí igbagbọ ninu Jesu.
Níbẹ̀ ni ààlà náà ti yipada lọ sí apá ìwọ̀ oòrùn sí Asinotu Tabori.
Nígbà tí ẹ dé etí òkun, àwọn ará Ijipti kó kẹ̀kẹ́ ogun ati àwọn ẹlẹ́ṣin, wọ́n sì lé àwọn baba yín títí dé etí Òkun Pupa.
Ọbẹ̀ ẹ̀fọ́ pẹlu ìfẹ́,sàn ju ẹran mààlúù tòun ti ìkórìíra lọ.
Nítorí ati a kọlà ni, ati a kò kọlà ni, kò sí èyí tí ó já mọ́ nǹkankan.
Nígbà tí ó bá di ọjọ́ keje, kí alufaa yẹ àrùn ẹ̀yi náà wò, tí àrùn náà kò bá tàn káàkiri sí i, tí kò sì jìn ju awọ ara lọ, kí alufaa pè é ní mímọ́, kí ó fọ aṣọ rẹ̀, kí ó sì di mímọ́.
2kg àti 70cm ní gígùn nígbà ti wọ́n bii.
  Kì báà jẹ́ pé àwọn ọkọ̀ tiwọn tuntun nini yàtọ̀ sí tiwa 🙂
Wọn ni eyi ni yoo jẹ ki awọn eniyan le mọ bi wọn o ṣe maa dahun nigba yoowu ti wọn ba kọwe beere fun iwe irinna.
Ẹ wo bí Babiloni ti di ohun àríbẹ̀rù, láàrin àwọn orílẹ̀-èdè.
Àsẹ̀hìnwwá-àsẹ̀hìnbọ onírúurú àwọn kòkòrò wọn-ọnnì lọo sí agbárí ọkùnrin náà, orí rrẹ̀ sì yí, ó di asínwín, ó kó àkísà bọ ọrùn, ó ń rin ìhòhò láti ìlkú dé ìl’, irun orí rẹ̀ kún ó sì ń pupa bí ara ewéko ojú ọ̀nà mọ́tọ̀, ó ń sùn nínú òtútù láàrin òde, ó ń jẹ́ àjẹkù àwọn ènìyàn káà kiri ilé, àwọn ọmọdé sí ń sọ òkò lù ú bí ó bá tí ń rìn lọ.
 Àwọn fọ ́ nrán ìhun tí a lè pe àkíyèsí sí yìí ni a lè yí sódì .
OLUWA sọ fún Joṣua pé, “Má bẹ̀rù, má sì ṣe jẹ́ kí àyà fò ọ́, kó gbogbo àwọn ọmọ ogun rẹ kí o lọ sí ìlú Ai.
Ileesẹ iroyin ori ayelujara kan, 'Premium times' lo gbee sita pe minisita naa ko ṣe isinruulu lẹyin to pari ẹkọ giga rẹ ni fasiti Polytechnic of East London ni ilẹ Gẹẹsi, gẹgẹ bi ofin ṣe laa silẹ fun gbogbo awọn ọdọ ti ọjọ ori wọn ko tii to ọgbọn ọdun lorilẹede Naijiria.
Kíkọ́ ẹ̀kọ́ gboyè nínú iṣẹ́ ìṣègùn ìbílẹ̀ yóò pèsè ìtọ́jú tó péye fọ́mọ Nàìjíríà- Ẹgbẹ́ àwọn dókítà Wọ́n mú ọjọ́ ìgbẹ́jọ́ agbésúnmọ́mí 9/11 tó ṣẹlẹ̀ l'Amẹrika Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
" lẹ ́ hìn rẹ ̀ ni alárẹ ̀ kúrò ní ilẹ ̀ wàdáì ; tí ó gba aṣálẹ ̀ núbíà dẹ ́ ilé-ifẹ ̀ , tí ó sì ṣe "" ẹ-ǹlẹ ́ -ń bẹ ̀ un o "" fún odùdùwà ."
Ṣugbọn bí mo ti máa ń gbé Kristi ga ninu ara mi pẹlu ìgboyà nígbà gbogbo, bẹ́ẹ̀ gan-an náà ni n óo tún máa gbé e ga nisinsinyii ìbáà jẹ́ pé mo wà láàyè tabi pé mo kú.
Ko si ipo ti ẹda ko lee de laye ti eeyan ko ba ti sọ ireti nu laye ti o dẹ tẹpa mọṣẹ pẹlu igbagbọ ninu Olodumare fun iranlọwọ ayanmọ ẹni.
Iṣe akọni ọmọluwabi to ṣe yii jẹ ki Aarẹ Muhammadu Buhari to n tukọ Naijiria lasiko yii gboriyin fun Bashir.
maa gba  ami ayeye naa ni ojo kọ́kàndínlọ́gbọ̀n , osu keta odun 2019 ni ile itura ti prestigious
oṣelu PDP ni ẹgbẹrun meji-le-ẹgbẹtalelaadọta ati ookan (2,651).
Aaroni ati Huri bá a gbé apá rẹ̀ sókè, ẹnìkan gbé apá ọ̀tún, ẹnìkejì sì gbé apá òsì.
Oríṣun àwòrán, Facebook/Adoration Ministry Enugu Ojisẹ Ọlọrun naa tun salaye pe ibeere to yẹ ka maa bi awọn asaaju wa ni pe ki ni wọn n fi owo epo wa se, se wọn kan fi n ra dukia silu Dubai ni.
“ ‘Nítorí pé ò ń fẹ́ràn ati máa ṣe ọ̀tá lọ títí, o sì fa àwọn ọmọ Israẹli fún ogun pa nígbà tí ìṣòro dé bá wọn, tí wọn ń jìyà ẹ̀ṣẹ̀ wọn.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ #HowGodMademechallenge: Ṣe lóòtọ́ bí àwọn olólùfẹ́ BBC Yoruba ṣe rí rè é?
PÀJÁWÌRÌ Àjọ Sebin kan fìdíi rẹ̀ múlẹ̀ pé akọ̀ròyìn Luis Carlos Diaz ti wà ní àhámọ́ àwọn ọlọ́pàá yẹn.
Ọpọlọpọ àkóléyà ní ń mú kí eniyan máa lá àlákálàá, ọ̀pọ̀ ọ̀rọ̀ ni eniyan sì fi ń mọ òmùgọ̀.
Jẹ́ kí àwọn tí ń gbé Sioni wí pé,‘Kí ibi tí àwọn ará Babiloni ṣe sí wa ati sí àwọn arakunrin wa dà lé wọn lórí.
Ẹ mú ìpara díẹ̀, oyin díẹ̀, turari díẹ̀ ati òjíá díẹ̀, ẹ mú èso pistakio ati èso alimọndi pẹlu.
"Lara ohun ti eeyan le ma mọ nipa eyi ni wi pe o lee ṣakoba fun iriran ẹni bẹẹ ti oju naa yoo si maa ṣe bakan-bakan si ina to ba mọlẹ yan an""."
Danjuma so pe, awon ologun orile-ede Naijiria ti darapo mo awon ajijangbara ati awon odaran miiran, eyi ti ko je ki won le pese abo to peye fun emi ati dukia awon omo ipinle Taraba, ni eyi ti o n pe awon omo bibi ipinle naa lati dide fun idaabobo ara won.
Ṣugbọn àkókò ń bọ̀ nígbà tí n kò ní fi òwe ba yín sọ̀rọ̀ mọ́, kedere ni n óo máa sọ̀rọ̀ nípa Baba fun yín nígbà náà.
"Gbedeke ọjọ mẹrinla ni wọn fun aarẹ lati bẹẹrẹ iwaadi gomina Ganduje nitori, ""ẹsun riba gbigba tabi ṣiṣi ipo iṣejọba lo ti wọn ba fi kan ẹnikẹni nipinlẹ yoowu lorilẹede Naijiria kan gbogbo ọmọ Naijiria, nitori naa o si yẹ ko kọ iṣejọba rẹ lominu pẹlu."
Ohun ti wọn sọ ni pe ida aadọrun ninu awọn lo n gbe ni ilu Eko ti ko si si idi fun ijọba lati maa ru awọn lọ si ilu Abuja.
Nítorí OLUWA yóo gbèjà wọn,yóo fìyà jẹ àwọn tí wọn ń jẹ wọ́n níyà.
Àwọn ìjòyè ẹ̀yà Edomu nìwọ̀nyí: Timna, Alia, ati Jeteti; 
Ìgbàgbọ ́ lóri ìwáríì ẹ ̀ rọ ìbánisọ ̀ rọ ̀ dúró sí àríyànjìyàn .
Wọ́n fi àwọn ọmọkunrin ati ọmọbinrin wọn bọ oriṣa.
Àjẹsára rubella jẹ ́ àjẹsára tí a fi ń dáàbò bo ara ẹni lọ ́ wọ ́ àkóràn kòkòrò àìlèfojúrí ti o n fa àìsàn kan tí à ń pè ní rubella .
Mo kí i òun náà sì kí mi dáadáa, mo gbé aga fún un, ó jókòó, èmi náà jókòó lé àga kan mo kọjú sii.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ìdílé márùn-ún tó gbajúmọ̀ fún òwò ẹrú nílẹ̀ Yorùbá Ìtàn Ọba Yorùbá tí wọ́n yẹgi fún torí ó jí ọmọ gbé ṣe ètùtù Mọ̀ síi nípa Shina Rambo tó pàdé Jesu lọ́gbà ẹ̀wọn lẹ́yìn tó ti jalè Ogun Àgbẹ́kọ̀yà, ìjà òmìnira fáwọn àgbẹ̀ ni àbí ìfẹ̀míṣòfò?
Ọlọ́pàá Bayelsa ní àwọn ti kán lugbó láti wá ìyá Siasia 'Kò sí ǹkan tó jọ tòmátò tó ní májèlé ní Nàìjíríà' ‘Àwọn Fulani gbọ́dọ̀ kúrò ní ìpínlẹ̀ Ondo’ 'Ọ̀nà láti dá dúró ló mú mi fi iṣẹ́ báńkì sílẹ̀ di alápatà ẹran' Adaku ṣalaye iru eeyan ti Funkẹ Akindele jẹ pẹ kii fi iṣẹ rẹ ṣere koda a le sọ pe ó burú.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Chibok girls: 'Ìjọba ń ṣe bí ẹni pé ọ ń ṣe àwọn òbí tí Boko Haram kọ lọ́mọ́ ló lóore ni' 12 Ìgbé 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 13 Ìgbé 2019 Oríṣun àwòrán, STEFAN HEUNIS Àkọlé àwòrán, Awọm ọmọbinrin Chibok mẹtadinlaadọfa lo ti pada wale Mejilelaadọfa ọmọbinrin Chibok ti ikọ Boko Haram ji gbe ni ọdun marun un sẹyin ni o ṣi wa ni igbekun, ṣugbọn awọn obi wọn ti fi ẹsun kan ijọba apapọ wipe wọn ko tilẹ náání àwọn mọ.
Ali kede pe ijọba ologun igba naa ti mu ele ba owo oúnjẹ akẹkọọ lati naira kan ati aadọta kọbọ (N1.
Oríṣun àwòrán, @Okediji f/bk Ni igbeyin iwe yii, onkọwe Oladejo Okediji fi ọrọ yaworan gbogbo iwa ibi to n sẹlẹ nigba naa, eyi to si ba igba mu di asiko yii.
"Ọgbẹni Nwajiuba ti ko sọ pato ọjọ ti awọn ọmọ yoo wọle pada, sọ pe ""O di igba ti a ba to o ni idaniloju pe awọn ọmọde le lọ sileewe, pada sile laalafia, lai ko aarun Covid-19 pada sile, la to o ṣetan""."
Lorile-ede Malaysia ofin faaye gba ki ọkunrin fẹ to iyawo mẹrin ni ibamu pẹlu ẹsin Islam.
Bakan naa lo fi ọrọ ikini ranṣẹ si gbogbo ẹni to ti kagbako ifiyajẹni ọlọpaa ni Naijiria.
Awọn aṣoju akẹkọọ ile iwe naa ati awọn akọroyin lo peju si ibi ti wọn ti dana sun awọn foonu wọnyi.
Ṣe àwọn ọlọ́lá wọn bí o ti ṣe Orebu ati Seebu;ṣe àwọn ìjòyè wọn bí o ti ṣe Seba ati Salumuna,
Eld Kabir in Nigeria: Mùṣùlùmí àti Kristiẹni sọ̀rọ̀ nípa àdun oúnjẹ́ àti ẹran ọdún Ileya
"Gẹgẹ bii ologun lorilẹede Naijiria, ko lee ṣeeṣe fun mi lati lọ si ileewe ẹkọṣẹ ologun ni india ni ọdun 1973 ati ile ẹkọṣẹ ologun orilẹede 1979.
ọjọ ti pẹ ti wọn ti kọ ile naa.
Gẹgẹ bi Dokita Francis Ezenwankwo se wi, lasiko to n ba BBC sọrọ, bi nnkan ọkunrin ba ha soju ara obinrin, eyi ni oloyinbo n pe ni 'Penis Captivus.
Garri jẹ ounjẹ to gbajumọ laaarin awọn ọmọ orilẹede yi.
Bobriksky ti fí ọ̀rọ̀ léde pé òun ti ṣetan láti fi àkàrà òyìnbó tí ó yẹ fún ayẹyẹ náà tọrẹ fún tọkọ́taya tí bá fẹ́ ṣe ìyàwó láìpẹ́ yìí.
Nígbà tí ó yá, Elija bá kúrò níbẹ̀, bí ó ti ń lọ ó bá Eliṣa ọmọ Ṣafati níbi tí ó tí ń fi àjàgà mààlúù mejila kọ ilẹ̀.
Ọpọlọpọ awọn onile lori wọn gẹgẹ bi ẹni ti ko nilari nitori wọn ko lade lori, ti o si ṣeeṣe ki wọn ma le e naa owo ile lasiko.
Ẹ kò mọ̀ pé dandan ni fún mi kí n wà ninu ilé Baba mi?
 O je eri gbangban fun mi bayii pe, Naijiria yoo di olu awon orile-ede ti o samulo ero amohunmaworan igbalode nile Afrika laarin odun perete.
Gbajúgbajà òṣèré tíátà, Baba Suwe ń ṣe àìsàn Saaju la ti mu iroyin wa fun yin pe lẹyin ti iroyin jade wi pe Baba Suwe n se aisan, awọn akẹẹgbẹ rẹ ti kesi awọn ọmọ Naijiria lati dide iranwọ si Baba Suwe.
Daramola ni, ki iko omo oogun ofurufu maa se atunse ati abewo lori oko ofurufu  , wa lara erongba awon adari iko omo oogun ofurufu orile ede yii.
ectropion jẹ ́ àrùn tí ìdéjú ìsàlẹ ̀ ṣí sí ìta .
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Àwọn ọ̀dọ́ Naijiria ti sọ̀rọ̀ síta lórí ohun ti wọ́n ń retí lọ́dọ̀ minista tuntun Ààrẹ Muhammadu Buhari tún fi ìdí èyí múlẹ̀ lásikò tó ń yàn wọ́n sípò nílé ìjọba pé àwọn ti wọ́n yà sọ́tọ̀ yìí jẹ́ ọ̀nà láti fẹ́ ètò ìjọba lóju síi.
O óo pọ gbogbo òkèlè tí o jẹ,gbogbo ọ̀rọ̀ dídùn tí o sọ yóo sì jẹ́ àsọdànù.
Eto ilera ofe naa waye ni gbagede
Ẹ fi irin ọkọ́ yín rọ idà,ẹ fi dòjé yín rọ ọ̀kọ̀,kí àwọn tí wọn kò lágbára wí pé, “Ọmọ ogun ni mí.
Ẹ fẹ́ dójú ti àwọn aláìní, àbí bẹ́ẹ̀ kọ́?
Mo ti dá igi ìdè àjàgà yín kí ẹ lè máa rìn lóòró gangan.
Ẹni to bori: Algeria Algeria Owo nla to n wọle lati ẹka ohun amuṣagbara ati owo nla ti wọn n fi pamọ sinu apo ẹdawo fun ifẹsẹmulẹ epo robi ti fun orilẹede Algeria lanfani lati fẹẹ san gbese ti wọn jẹ silẹ okere tan, eyi to jẹ idameta ati aabọ ninu gbogbo owo to n wọle fun orilẹede naa lọdun 2017.
Àwọn ni wọ́n jẹ́ akọni ati olókìkí nígbà náà.
Ajimobi tako àṣẹ iléẹjọ́ pẹ̀lu ìbò ìjọba ìbílẹ̀ tó ṣe - Ìjọba Ọyọ Kéré o!
Irú adura báyìí dára, ó sì ṣe ìtẹ́wọ́gbà níwájú Ọlọrun Olùgbàlà wa, 
Election Update 2019: Àwọn ọlọ́pàá dá ìpàdé àwọn alátakò Tinubu dúró l'Eko
Kí wọn má ya ọ̀lẹ ninu iṣẹ́ ilé, kí wọn sì jẹ́ onínú rere.
9 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Oyo physically challenged protest: Ìdí rèé táwọn àkàndá ẹ̀dá fi dí iwájú iléeṣẹ́ ìjọba ìpínlẹ̀ Oyo pa l'Agodi n'Ibadan7 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Bí òun ti gbe ẹrù pàṣán lée èjìká bẹ́l náà ni àpò ńlá kan ń bẹ ni ọrùn rẹ̀tí ó ba ni lẹ́rù gidigidi.
Àwọn orílẹ̀-èdè bá dójú lé e,wọ́n dẹ tàkúté fún un ní gbogbo ọ̀nà,wọ́n da àwọ̀n wọn bò ó,wọ́n sì mú un ninu kòtò tí wọn gbẹ́ fún un.
Oríṣun àwòrán, Presidency nigeria Igbesẹ naa si wa lara awọn igbesẹ to wa nilẹ eyi ti igbims naa ni, pẹlu ifọwọsi aarẹ muhammadu Buhari, ṣi n tẹsiwaju.
Koda, alamojuto agba fun ijọ Mountain of Fire and miracles Minisirties (MFM), Pasitọ Daniel Olukọya naa ko gbẹyin.
 Oun ni o je omo ile Adulawo akoko to sere ni O2 Arena ni London nibi ti o le ni egberun ogun eniyan ti wa woran.
A na sare ni Liverpool lu Arsenal ninu ifẹsẹwọnsẹ Premier League nirọlẹ ọjọ Satide.
Bẹẹ naa ni isẹ ere itage sise jẹ, tori Hubert Adedeji Ogunde ni ọpọ eeyan gba pe o bẹrẹ ere tiata lede Yoruba, eyi to wa di itẹwọgba lode oni.
Ninu ero Ava, o ni ẹnikẹni to ba fi ọwọ si pe ki wọn yẹgi fun arakunrin ọhun ko yẹ ni ẹni to yẹ ko maa gbe papọ pẹlu awọn ọmọ Naijiria tootọ.
Iya ọmọ naa lo sọ eyi, o n gbe ni ibudo awọn ti ko rile gbe ni Shahrak e Sabz lẹba Herat, iwọ oorun Afghanistan.
D Tuluen ni ijọba ibilẹ Gboko nipinlẹ Benue, lọjọ Abamẹta.
s , àwọn olórí ẹgbẹ ́ ní amẹ ́ ríkà sì fi ọwọ ́ sí bí wọ ́ ṣe yọ thi lóyẹ ̀ .
kaarẹ lati tubọ maa se atileyin fun aare Buhari lati ri i pe awon ipinnu rere
Ẹnìkan tí ó tún kẹ̀yìn sí Solomoni ni ọ̀kan ninu àwọn òṣìṣẹ́ rẹ̀ tí ń jẹ́ Jeroboamu, ọmọ Nebati, ará Sereda, ninu ẹ̀yà Efuraimu, obinrin opó kan tí ń jẹ́ Serua ni ìyá rẹ̀.
Sibẹsibẹ àwọn eniyan náà lọ, bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé Àpótí Majẹmu OLUWA tabi Mose kò kúrò ní ibùdó.
Ní àkókò yìí Jeremaya sì ń rìn káàkiri láàrin àwọn eniyan, nítorí wọn kò tíì jù ú sẹ́wọ̀n nígbà náà.
 “Basem al-Hashimi al-Soul so nigba naa pe,  “Saif al-Islam Gaddafi, ti o je omo bibi Aare teleri lorile-ede Libya ni atileyin pupo awon eya ti o wa lorile-ede Libya, eyi ti je ki o le dije ninu eto idibo ti yoo waye ninu odun ti a wa yii”.
Nítorí tiwọn, ó ranti majẹmu tí ó dá,ó sì yí ìpinnu rẹ̀ pada nítorí ọ̀pọ̀ ìfẹ́ rẹ̀ tí kì í yẹ̀.
Ọmọ gbajugbaja oṣere ni, Adeyẹmi Afọlayan ti ọpọ mọ si Ade love ni Moji.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Wo bó ṣe le bèèrè láti ṣàtìpó ní Canada bí DJ Switch Ìdàlúrú gbòde, ìjọba kéde ìṣéde torí nǹkan ọ̀pọ̀ ọkùnrin tó ń pòórá Òkò gbọnin lórí ìjọba àpápọ̀ tórí pé ó pe àwọn olùwọ́de EndSARS ní agbésùnmọ̀mí Ẹ gbà mí o!
Awọn oloselu Kwara a ma saba seto pipin ipo oselu laarin awn ẹkun idibo to wa ni ipinlẹ naa.
Fà wọ́n jáde bí aguntan tí wọn ń mú lọ pa,yà wọ́n sọ́tọ̀ fún ọjọ́ ìparun.
O so pe”A o kogbon nibi ikolu buruku yii, lati je ki a fun okun wa le lona ti a o se mu eto aabo lokun-kundun, nipa pipese eto aabo to peye  niluu ofa ati fun omo orile  ede  Naijiria lapapo”.
Ọ̀gá iléeṣẹ́ gbé £10 mílíọ̀nù ẹ̀bùn owó fún òṣìṣẹ́, èyí lohun tó pawọ́n pọ̀ Ìjọba Katsina ní kí àwọn iléèwé wà ṣì ní títìpa nítorí arùn Coronavirus OPC láwọn mú afurasí agbébọn ajínigbé mẹ́rin l'Oyo, ọlọ́pàá ní àpapọ̀ òṣìṣẹ́ elétò aàbò ló ṣiṣẹ́ náa Tí ìjọba bá gbé òfin kónílé-ó-gbélé ọlọ́jọ́ pípẹ́ míì kalẹ̀ nítori Covid-19, ǹkan yóò bàjẹ́ ní Naijiria- Dokita INEC fún Obaseki ní ìwé-ẹ̀rí moyege gẹ́gẹ́ bí gómìnà tí wọ́n ṣẹ̀ṣẹ̀ dìbò yàn Ọgbẹni Ibe ni awọn to n gbe iroyin ofege naa kiri n ṣe bẹẹ nitori igbesẹ orilẹede Amẹrika to fofin de awọn ọmọ Naijiria kan laipẹ yii lati rinrin ajo lọ si Amẹrika ṣaaju idibo gomina Edo.
Ẹlomiran ninu ọrọ tirẹ ni ati minisita, ati ọba ilu o, ko sẹni ti kii ṣe ayẹwo ni papakọ ofurufu""."
Alaga PDP naa sọ pe ohun to yẹ ki ijọba Gomina AbdulRahman AbdulRazaq sẹ ni pe ko paṣẹ ki ijọba gba owo ilẹ naa lọwọ awọn ẹbi Oloye to ba tiẹ jẹ pe Oloye ko sanwo ilẹ ọhun nigba naa.
Ahiṣari ni olùdarí gbogbo àwọn tí ń ṣiṣẹ́ ninu ààfin.
Gbogbo àwọn ẹmẹ̀wà rẹ wọnyi yóo sì tọ̀ mí wá, wọn yóo fi orí balẹ̀ fún mi, wọn yóo wí pé kí n máa lọ, èmi ati gbogbo àwọn eniyan mi!
Ìgbà tí mo retí kí ó so èso dídùn,kí ló dé tí ó fi so èso kíkan?
Samuẹli bi Saulu pé, “Kí ló dé tí o fi ń yọ mí lẹ́nu?
" Ọjọ Aje ni ijọba Naijiria ranṣẹ pe igbakeji aṣoju orilẹ-ede Ghana, Arabinrin Iva Denoo, lori bi awọn kan ṣe wó abala kan ni ileeṣẹ aṣoju Naijiria ni Ghana.
Wọ́n gbé òkú Absalomu jù sinu ihò jíjìn kan ninu igbó, wọ́n sì kó ọpọlọpọ òkúta jọ sórí òkú rẹ̀.
Akori fun ti odun 2018 yii ni, “Eto-ilera lagbaye: Gbogbo eniyan, Nibi gbogbo”.
 Ọba Lamidi Adeyẹmi, òṣìṣẹ́ adójútòfò àti Abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò kó tó jọba Yatọ̀ fún orí ìtàgé, wo ohun tí o kò mọ̀ nípà Mr Latin 'Ọwọ́ wa tún tẹ ojúkòó tí wọ́n tí ń bá àwọn ọmọdékùnrin lò pọ̀ ní Daura' Ṣé lónìí ni ọ̀rọ̀ owó oṣù tuntun yóò yanjú àbí yóò tún d'ọjọ́ míràn?"
"Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: ""Àwọn akẹ́kọ̀ọ́ àgbà fipá bá ọmọkùnrin mi lòpọ̀ níléèwé Deeper Life, mò ń fẹ́ ìdájọ́"" Ẹ̀ lajú yín, ayédèrú ìwé ẹ̀rí àyẹ̀wò COVID-19 gbòde kan l‘Eko - Ìjọba figbe ta Ẹ wo àwọn èèkàn eléré ìdárayá tó bá ọdún 2020 lọ Wo ọ̀pọ̀ àsọtẹ́lẹ̀ igba tí Primate Ayodele gbé síta fọ́dún 2021 ₦9."
Ati wi pe ayẹwo ti wọn ṣe fun ọkunrin naa ni papakọ ofurufu ilu Eko ko fihan pe o ni aarun naa nitori pe aarun naa kii tete fi apẹẹrẹ han lara.
Sibẹ, o ti ta wá nù o sì ti rẹ̀ wá sílẹ̀,o ò sì bá àwọn ọmọ ogun wa jáde lọ sójú ogun mọ́.
Oloogbe Yemi Adeniran ti gbogbo eeyan mọ si Likedat ti fi igba kan jẹ olori ẹgbẹ awọn akẹkọọ Naijiria (NANS) to si lorukọ laarin awọn ọdọ oloṣelu ni ilu Ibadan.
Èdè àwọn àjèjì nìkan ni wọ́n gbọ́.
" O ni oun fẹ ki ilana yiyan kọmiṣọna si ijọba oun jẹ eyi ti yoo ko akoyawọ lo tun faa, ti igbesẹ naa fi n falẹ.
”O wa ro awon akoroyin lati mu ise won gege bi ise, ni ona lati mo bi won yoo se maa gbe awon iroyin won lolokan-o-jokan sita lai se afinkun tabi so asodun ti o le fa rogbodiyan funlu.
Ní ọdún kọkanlelọgbọn tí Asa, ọba Juda ti wà lórí oyè, ni Omiri gorí oyè ní Israẹli.
Orúkọ yìí ni ó si fi lọ fi owó pamọ́ sí bánkì.
“Kí ìwọ Ẹsira, lo ọgbọ́n tí Ọlọrun rẹ fún ọ, kí o yan àwọn alákòóso ati àwọn adájọ́ tí wọ́n mọ òfin Ọlọrun rẹ, kí wọ́n lè máa ṣe ìdájọ́ àwọn tí wọ́n wà ní agbègbè òdìkejì odò.
O ni ki ẹni ti wọn kede ni ipinlẹ Ebonyi yii kuro ni ipo naa nitori naa lo ṣe da ibo to gbe e wọle nu.
Buhari  yan arabinrin Sharon gege bi
Ìlù Ìjẹ ̀ bú - jẹ ̀ ṣà jẹ ́ ìlú kan pàtàkì ní ilẹ ̀ Ìjẹ ̀ ṣà .
Owe Yoruba so wipe “Bi Ẹlẹ́bọ kò bá peni, Àṣefín kò yẹni”.
 Ó sì di ọmọ ilẹ ́ asòfin ilẹ ̀ slovenia ni ọdún 1986 .
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Fulani Ilorin l'ọkọ mi' Ki lo bi apero yii lati ibẹrẹ?
Ẹ fi àṣẹ tí mo pa fun yín lónìí sọ́kàn, 
Nígbà tí Saulu bèèrè lọ́wọ́ OLUWA ohun tí yóo ṣe, OLUWA kò dá a lóhùn yálà nípa àlá tabi nípa Urimu tabi nípasẹ̀ àwọn wolii.
Ọ̀kan ninu wọn ni yóo jọba lórí wọn,ààrin wọn ni a óo sì ti yan olórí wọn;n óo fà á mọ́ra, yóo sì súnmọ́ mi,nítorí pé kò sí ẹni tí ó lè fúnra rẹ̀ súnmọ́ mi.
Àwọn wọnyi ni igi olifi meji ati ọ̀pá fìtílà meji tí ó dúró níwájú Oluwa ayé.
O ni oun yoo ṣapa lati rii wi pe awọn ọmọ orileede China to wa ni Kano yoku pawọpọ lati ni ibaṣepọ to dara pẹlu awọn eeyan Kano.
Ladugbo Freeman Street ni Isalẹ Eko ni ijamba yi ti waye lowurọ ọjọ Abamẹta.
Service base tariff ni wọn n pe ilana naa.
Bẹ́ẹ̀ kì í ṣe aláì- má- wǎ ní ọjọ́ Satídé.
Nígbà tí àwọn eṣú náà ti jẹ gbogbo koríko ilẹ̀ náà tán, mo ní, “OLUWA Ọlọrun, jọ̀wọ́ dáríjì àwọn eniyan rẹ.
Kiriati Ariba (tí à ń pè ní Heburoni), ati Siori, gbogbo ìlú ati ìletò wọn jẹ́ mẹsan-an.
Agbẹjọro rẹ Abdelmoula El Marouri sọ pe: ''iyalẹnu ni idajọ yi jẹ fun wa'' ti o si sọ pe niṣe lo yẹ ki wọn tu u silẹ pẹlu gbogbo ẹri ti awọn gbe wa siwaju ile ẹjọ.
Ijọba ipinlẹ Ọṣun ni awọn gbe igbesẹ yii lẹyin oniruuru agbeyẹwo lawọn ileewe lati mọ bi igbaradi wọn lati pada si eto ẹkọ kikọ ṣe ja fafa si.
Awọn agba ibeji naa ree Àkọlé àwòrán, Awọn ibeji to ni ‘swagger‘ ree o, wọn ta san-san Àkọlé àwòrán, N jẹ ẹyin mọ iyatọ laarin awọn ibeji yii?
Wọ́n lọ́wọ́, ṣugbọn wọn kò lè lò ó,wọ́n lẹ́sẹ̀, ṣugbọn wọn kò lè rìn,bẹ́ẹ̀ ni wọn kò lè gbin.
Hushpuppi di gbajúmọ̀ ẹlẹ́wọ̀n tó ní nọ́ńbà l‘Amẹrika, orúkọ̀ rẹ̀ wà lórí ayélujára N kò gba ₦4bn lọ́wọ́ Magu, ẹ má ró àjẹbánu mọ́ mi láṣọ - Osinbajo pariwo Ọwọ́ ọlọ́pàá ìpínlẹ̀ Oyo tẹ àwọn afurasí lórí ìpànìyàn tó wáyé ní Akinyele Ilu Chicago ni ọfiisi Gal Pissetzky wa, ṣugbọn jakejado orilẹ-ede Amẹrika lo ti maa n ṣoju awọn onibaara rẹ.
Igbakeji aarẹ orilẹede Naijiria, Ọjọgbọn Yẹmi Oṣinbajo lo fi eyi to BBC leti.
Aisha Buhari ṣalaye ọrọ yii ninu ọrọ kan to sọ lori ileeṣẹ Mohunmaworan abẹle kan lorilẹede Naijiria.
Yoo si tun bura wọle fun saa ọlọdun meje mi i, eyi ti yoo mu ko pe ọdun marundinlogoji to ti wa nipo.
Atiku lo fi ẹdun ọkan rẹ lede loju opo Twitter rẹ nibi to ti gbadura pe ki Ọlọrun tẹ ẹ si afẹfẹ rere.
Ọjọ kinni, oṣu Ṣẹẹrẹ (January), ọdun 1,000 Poopu ijọ Katoliki kan, Pope Sylvester II atawọn adari ẹsin Kristẹni kan lo sọ tẹlẹ pe ọdun 999 lọjọ aisun ọdun laye yoo wa sopin Sugbọn lẹyin ti ọpọlọpọ eeyan rọ lọ si ile ijọsin fun aisun ọdun tuntun ni ijọ Katoliki St.
Amọ ko daju pe apero eleyi ti wọn ṣe loju ẹrọ ayelujara lọtẹ yii, yoo ṣe iwuri bi tatẹyinwa fawọn ọmọ ẹgbẹ naa.
Ọmọwe Olajide fikun ọrọ rẹ pe ko si idi kankan to le mu ki Osinbajo kọwe fipo silẹ niwọn igba to jẹ pe awọn ọmọ Naijiria jọ dibo yan oun ati aarẹ Buhari papọ ni.
Ẹ̀yin ará, mo fẹ́ kí ẹ mọ̀ pé ìyìn rere tí mò ń waasu kì í ṣe láti ọ̀dọ̀ eniyan.
Ohun tí ó yẹ kí á ṣe ni a ti ṣe.
Chelsea lu West Brom pẹlu ami ayo mẹta s'odo
 nomba adaju ( fun apere nomba gidi todaju , nomba onipin todaju , nomba odidi todaju ) je nomba topoju odo lo , fun apere formula _ 1 , 1.
O menuba agbara re lati se ohun to ye lai gba abetele lowo egbe NRA pelu esun to fi kan Asojusofin Pat Toomey lati ipinle Pennsylvania pe o beru egbe NRA ni eyi ti Asofin Chris Murphy lati egbe oselu Democratic ni Connecticut naa faramo.
O bá àwọn onigbeeraga wí, àwọn ẹni ègún,tí wọn kò pa òfin rẹ mọ́.
Àwọn ọkọ̀ ojú omi Hiramu ọba, tí ó kó wúrà wá láti Ofiri kó ọpọlọpọ igi alimugi ati òkúta olówó iyebíye bọ̀ pẹlu.
 Oun ti o n ran wa lọwọ lati igba ti iya wa ti ku ree."
Èṣù tún sọ̀rọ̀ ó ni, ‘kò mọ̀ pé ìfẹ́ ojú ló ní sí òun, ó fi ara sílẹ̀ ó jẹ́ kí ó fà òun sínú odò.
Bakan naa, iwa irẹlẹ arakunrin yii kọja sisọ pẹlu bo ṣe maa n ba awọn ara abule jẹ̀ lawọn ilu igberiko to ti maa n lo akoko rẹ ju.
O bi biotilẹjẹpe awọn bọwọ fun ẹtọ awọn araalu lati ṣe ifẹhọnuhan, amọ awọn ko le e ma wo ki awọn onijanduku ma a ba dukia ati ohun ini awọn eniyan jẹ.
Lisabi Agbongbo Akala rèé, ẹni tó fi ìfẹ́, ìṣọ̀kan àti ìrẹ́pọ̀ gba ilẹ̀ Ẹ̀gbá lọ́wọ́ ìmúnisìn Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí kan sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
Lẹyin ti wọn pa ọ̀pọ̀lọpọ̀ laípẹ nigbe wọn de etí ijọba apapọ Nàìjíríà, ti Aare Buhari si ni ki ikọ̀ àwọn ọmọ ogun ati agbofinro kan kó lọ sibẹ.
Mo wá tún rí àmì mìíràn ní ọ̀run: Ẹranko Ewèlè ńlá kan tí ó pupa bí iná, tí ó ní orí meje ati ìwo mẹ́wàá, ó dé adé meje.
Iroyin naa mu awuyewuye lọwọ laarin awọn ọmọ Yoruba, bi awọn kan se tako Dokita to ni bi ololufẹ meji ba lẹpọ, kii se magun, lawọn miran fara mọ.
Ọgbẹni Mcconnell gbagbọ pe Trump ti ṣe nnkan to le mu ki awọn aṣofin yọ ọ nipo.
Olùforukọsilẹ̀ gbọdọ̀ jẹ́ ọmọ orilẹ̀-èdè Nàìjíríà, ọjọ́ ori rẹ sì gbọdọ̀ wà láàrin ọdún méjìdínlógún sí márùndínlogójì O gbọdọ̀ ti kẹ́kọ̀ọ́ jáde kí o si ti sín ilẹ̀ baba rẹ̀.
nítorí gbogbo àwọn ọmọ Ọlọrun ti ṣẹgun ayé.
Nínú àtẹ̀jáde kan tí Ààrẹ ẹgbẹ́ NLC Ayuba Wabba fọwọ́ sí, wọ́n ní ẹgbẹ́ àwọn gomínà Nàìjíríà kò lẹ́tọ̀ọ́ láti sọ̀rọ̀ lórúkọ ìpínlẹ̀ kọ̀ọ̀kan wọ́n sì lọ́ èyí mọ́ alága wọn lẹ́sẹ̀.
Àkọlé àwòrán, Gomina Abiola Ajimobi ti ìpínlẹ̀ Oyo, Ayodele Fayose Ekiti, Akinwumi Ambode ti ìpínlẹ̀ Eko, Ìbikunle Amosun Tun wẹ, Gomina Abiola Ajimobi ti ìpínlẹ̀ Oyo, Ayodele Fayose ti Ekiti, Akinwumi Ambode ti ìpínlẹ̀ Eko, Ìbikunle Amosun ti ìpínlẹ̀ Ogun, Raufu Aregbesola ti Ọsun àti Rotimi Akeredolu ti Ondo, ló bá gbogbo Musulumi jákèjádo orilẹ̀-èdè yìí àti káàkiri àgbáyé dáwọ ìdunnu, lóri ọdun iléya to wole dé.
Ọkan ti waye bẹ ri ni 2011, nigba ti ọkunrin aadọta ọdun kan ji ninu mọṣuari kan to wa ni Cape Town, to si bẹrẹ si ni pariwo.
O ba BBC News Yoruba sọ diẹ nipa ọrọ ọhun.
Sugbọn iroyin ibanujẹ ni o jẹ pe igba akọkọ ti arakunrin ọun o fojú ba ile iwosan fun itoju ni esi ayẹwo sọ pe o ni arun jẹjẹrẹ.
Yóo ya wọ Juda, yóo sì bò ó mọ́lẹ̀ bí ó ti ń ṣàn kọjá lọ, títí yóo fi mù ún dé ọrùn.
Ṣé lóòtọ́ ni ìjà ti parí láàrin ìdílé Ayinde Barrister àti Kwam 1?
Fashola ni ohun aṣọ ti wọn fi n nu oju ni ohun fi mu ẹrọ amohunmaworan naa nilẹ, ti oun si fun Gomina ipinlẹ Eko, Babajide Sanwo-Olu.
O ni ojuko ti ijọba Oyo ti n gba nnkan ayẹwo coronavirus le ni mẹwaa kaakiri ipinlẹ naa, ati pe ida mẹwaa ninu ọgọrun awọn to ṣayẹwo arun naa lo ni ni ipinlẹ ọhun.
Mo ni lati wa ọkọ funraami lati Abuja lọ si Lokoja lati lọ sọ fun iya rẹ tori iru ọr yii ko ṣee sọ lorii foonu.
    Ìgbà tí o ṣe ni a rí àwọn ọmọ ogun èranko níwájú wa.
Gbogbo ara òkè tí wọn tí ń fi ọkọ́ ro tẹ́lẹ̀, ẹnikẹ́ni kò ní lè débẹ̀ mọ́, nítorí ìbẹ̀rù ẹ̀wọ̀n agogo ati ẹ̀gún ọ̀gàn, gbogbo ibẹ̀ yóo wá di ibi tí mààlúù ati aguntan yóo ti máa jẹko.
“Ẹ tọ Ọlọrun lọ fún èmi ati àwọn eniyan tí wọ́n kù ní Juda ati ní Israẹli, ẹ ṣe ìwádìí ohun tí a kọ sinu ìwé náà; nítorí pé àwọn baba ńlá wa tàpá sí ọ̀rọ̀ OLUWA, wọn kò sì ṣe ohun tí a kọ sinu ìwé yìí ni OLUWA ṣe bínú sí wa lọpọlọpọ.
Dafidi sọ fún un pé, “Ọ̀la ni ọjọ́ àjọ̀dún oṣù tuntun, n kò sì gbọdọ̀ má bá ọba jókòó jẹun.
Adelaja so oro ebe yii nibi ipolongo itoju kindinrin olosu kan tile iwosan naa bere.
Oríṣun àwòrán, FACEBOOK /EMMANUEL BABAYARO Àkọlé àwòrán, Ẹyin odi o dẹrun Emmanuel Babayaro to ti figba kàn je agbaboolu fún orile-ede Naijiria ni àìní ìfẹ ìlú a ma ṣokunfa bi awọn eléré ìdárayá mi ma fin salo.
Akonimoogba agba tuntun ohun Baxter, loti tuko egbe agba-boolu naa teleri lodun 2004 si 2005, ti o si pinnu lati sabewo si awon agba-boolu re ti won gba boolu ni ile okere.
 Ìru nkan báyìí maa ń wáyé lẹ ́ ẹ ̀ kan ní bíi 5.
Ṣaaju lo ti fesi si ẹsun ti Dakolo fi kan an pe oun ko fi ipa ba ẹnikẹni lo pọ ri.
Nígbà tí ọkùnrin náà bẹ̀rẹ̀ sí ọ̀rọ̀ í sọ o dáhùn, ó ní, ìwọ ìránṣẹ́ Ẹlẹ́dàá ayé, ìwọ iranṣẹ́ Ẹlẹ́dàá ọ̀run, ohun tí mo fẹ́ẹ́ béèrè jẹ́ ìṣoòro, ṣùgbọ́n mo bẹ̀ ọ́, má ṣàì ṣe ó fún mi.
Ṣugbọn Dafidi kọ̀, kò mu ún.
Nibayii, eeyan 1,061 lo ti ba ajakalẹ arun naa lọ ni Naijiria.
Ilẹ̀ mì tìtì, ìdámẹ́wàá ìlú bá wó.
Igbákejì ààre Osinbajọ yan Tolani Alli gẹ́gẹ́ bíi ayàwòrán rẹ́ tuntun
Ọ̀kan ninu àwọn ọmọ rẹ̀ yóo jọba ní ipò rẹ̀, yóo wá pẹlu ogun, yóo wọ ìlú olódi ọba Siria, yóo bá wọn jagun, yóo sì ṣẹgun wọn.
ṣugbọn o óo lọ sí ìlú mi, lọ́dọ̀ àwọn ẹbí mi, láti fẹ́ aya fún Isaaki, ọmọ mi.
Alakoso opopona ijọba apapọ nilu Eko, Ọgbẹni Adedamọla Kuti lo fi idi rẹ mulẹ pe apapkan afara Eko bridge yoo wa ni titi pa ki wọn lee ṣe awọn eto atunṣe gbogbo to ba yẹ nibẹ.
Ní ọ̀nà mìíràn, bí orin tí ó dára gan-an bá pẹ́ jù kí ó tó jáde, àwọn ayírapadà lè máà ní àyè tí ó tó fún wọn láti mọ ọ̀rọ̀ orin náà ní ìgbáradì kí ọjọ́ Ijó ìta-gbangba ó tó dé.
" Oríṣun àwòrán, Adebayo Adelabu Adelabu fikun pe nigba ti ẹgbẹ oselu APC fa oun kalẹ gẹgẹ bi oludije fun ẹgbẹ naa, wọn mọ pe oun ni oludije to dantọ julọ laarin ọpọ oludije to yọju lati wa du ipo naa, ti oun si sisẹ kara kara lati safihan akọsilẹ ipinnu ti oun ni lati se atunto awọn ohun alumọọni to wa nipinlẹ Ọyọ.
Lọ́nà kejì, kí àìsàn yìí tóó ṣẹlẹ̀ ẹ̀ẹ̀mẹta ni àwọn olè ń fẹ́ẹ́ pa á tí ọwọ́ kò bà á, ní ẹ̀ẹ̀kẹta wọn ṣá a lọ́gbẹ́ ṣùgbọ́n ọwọ́ kò rí àyè bà á dáadáa ṣùgbọ́n síbẹ̀ náà wọ́n gé àtàǹpàkò ọwọ́ rẹ̀ ọ̀tún sọnù, ibi tí ó sì ti ń sá lọ ó jìn sí kòtò eguneegun ẹsẹ̀ rẹ̀ ọ̀tún sì rún wómúwómú.
Ohun ta gbọ ni pe o mọ nipa bi Tehran ṣe mori bọ ninu ijiya Amẹrika nipa ile iṣẹ kan ti wọn pe orukọ rẹ ni Skycom.
Ayenakin pari ọrọ rẹ pe ofin ko faye gba ọlọpaa kankan lati fiya jẹ ara ilu nitori pe o wuwa ọdaran.
Gomina Fayose ko tii sọrọ lori iṣẹlẹ yii.
Ìyìn rere Ọmọ Ọlọrun tí a bí ninu ìdílé Dafidi nípa ti ara.
O tẹsiwaju ninu ọrọ rẹ pe iru awọn iwa bẹ ẹ jẹ ọkan lara awọn nkan ti ofin iṣẹ nọọsi ko faaye gba.
Awọn oṣiṣẹ ti iṣẹ wọn ṣe koko bi i ẹka epo bẹtiro, ounjẹ, iṣẹ agbẹ ati bẹẹbẹ lọ nikan ni ofin yii ko de.
Oríṣun àwòrán, TWITTER/KEMI ADEOSUN Àkọlé àwòrán, Oju ọna mẹẹdogbọn ni ijọba fẹ fi owo Sukuk se atunse wọn Ijọba apapọ ni ọgorun billionu (100 billion Naira naira) ni apapọ owo naa je.
Ní àkókò náà, Israẹli yóo ṣìkẹta Ijipti ati Asiria, wọn yóo sì jẹ́ ibukun lórí ilẹ̀ fún àwọn ará Ijipti, àwọn eniyan mi.
 Ẹ ̀ gbọ ́ n ni ó jẹ ́ fún ilésanmí .
Ọ̀gá àgbà ọlọ́pàá ṣèwúrí fáwọn ọlọ́pàá tó kúrò lójú pópó fún ọjọ́ márùn-ún Ọmọ ọdún mọ́kànlá tó bá wọn fọ́ àgọ́ ọlọ́pàá, wọ gàù ọlọ́pàá ní Edo Wo bí o ṣe le fi orúkọ sílẹ̀ láti gbà nínú N75b tí ìjọba fẹ́ ẹ̀ fún àwọn ọ̀dọ́ láti dá iṣẹ́ sílẹ̀ Ẹ gbọ́ Ohun tí Desmond Elliot àti Mojisola Alli-Macaulay sọ lórí ayélujára táwọn ọmọ Nàìjíríà fi ìbínú Ọjọ Aiku to kọja ni ijọba ti kọkọ dẹ okun aṣẹ konile-o-gbele to n ṣiṣẹ lọwọ ni ipinlẹ naa.
Yollywood: Ben Murray Bruce, jọ̀ọ́ ṣàánú ajé, kó sàfihàn sinimá mí táyé ń fẹ́"""
" Kolawole sọ pe ohun to ṣe pataki ju ni ki ara ilu mọ bi ijọba ṣe n ṣeto ọrọ ilu, yato si bi gbogbo nkan ṣe ṣokunkun si wọn.
tun wa ninu eto ilana ijoba yii lati je ki atunse ba eto idajo, paapaa julo
Iran Fulani ni Musa Yar'adua lati ilu Katsina, baba rẹ ti jẹ Minisita fun ilu Eko ri nigba ti Naijiria ṣẹṣẹ gba ominira.
Gbogbo àwọn eniyan náà lọ, wọ́n jẹ, wọ́n mu, wọ́n sì fi oúnjẹ ati ohun mímu ranṣẹ sí àwọn eniyan wọn, wọ́n ń yọ ayọ̀ ńlá nítorí pé ọ̀rọ̀ tí wọ́n gbọ́ yé wọn.
Jonathan: Mó ń sàtilẹyìn fún Atiku kí ìsoro Nàíjíríà má baà fọ́n wa ká
Aarẹ Muhammadu Buhari yoo ba awọn ọmọ orilẹede Naijiria sọrọ ni agogo meje ọjọbọ.
Ọjọgbọn Osinbajo ni ''mo mọ pe ẹ n binu, o si yẹ bẹẹ.
Èmi náà jẹ́rìí sí i, o sì mọ̀ pé òtítọ́ ni ẹ̀rí mi.
“Òpin ọ̀rọ̀ nípa ìran náà nìyí.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ogbologbo ijapa l'aafin Sọun Ni kete tawọn agbẹ ati ọdẹ gbọ nipa iporogan to n waye laarin ilu, wọn faraya, awọn naa bẹrẹ iwọde lọ saarin ilu, bẹẹ ni wọn n kọrin owe, tawọn ọlọpaa si n koju wọn.
Nítorí ìdí èyí, inú òkúta kan báyìí ni bàbá mi àti àwọn obìnrin wọ̀nnì sùn mọ́jù ọjọ́ náà.
Ninu atẹjade ti ẹgbẹ APC fi sita ni ọjọ ipade naa sọ pe wọn gbe igbese naa ki awọn eniyan to n bọ lati awọn ipinlẹ le de ibi ti ipade naa yoo ti waye lasiko.
Nítorí náà, Dafidi kò gbé Àpótí Majẹmu sọ́dọ̀ ara rẹ̀ ní ìlú Dafidi, kàkà bẹ́ẹ̀, ó gbé e yà sí ilé Obedi Edomu, ará Giti.
Ẹgbẹ Oselu AAC gbe igbesẹ yii ni ipade gbogboogbo ti wọn se ni ilu Owerri, ni ipinlẹ Imo.
A gbọ pe eto ayẹwo kan tun ti wa nilẹ, lati maa tọ pinpin awọn oluworan lati igba ti wọn ba ti wọ papa iṣere, titi wọn yoo fi jade.
Nítorí náà, Daniẹli sọ fún ẹni tí olórí àwọn ìwẹ̀fà yàn láti máa tọ́jú òun ati àwọn ọ̀rẹ́ rẹ̀ mẹtẹẹta pé, 
Bo tilẹ jẹ pe akọnimọgba ikọ Chelsea naa parọ lara awọn ikilọ rẹ, ti wọn gbiyanju lati sọ ayo miiran sinu awọn.
Ipò wo ni ó wà tí Ọlọrun fi kà á sí ẹni rere: lẹ́yìn tí ó ti kọlà ni tabi kí ó tó kọlà?
Leah Sharibu pé ọmọ ọdún 16 ní àhámọ́ Boko Haram Ìyá Leah Sharibu ké gbàjarè sí ìjọba Buhari Dapchi School ṣí padà lẹ́yìn oṣù mẹ́sàn án 'Àwọn ọ̀tẹlẹ̀múyẹ́ tí n ṣèwádí ohùn Leah Sharibu' Titi di isinyi ni ijọba Naijiria labẹ akoso aarẹ Buhari ṣi n kede pe awọn ti bori Boko Haram.
Ileeṣẹ ọlọpaa ni eeyan kan ṣoṣo ni ọkọ̀ arakunrin naa gba.
Ilé ẹjọ́ ti sún ìgbẹ́jọ́ si Ọjọ́-Bo̩ Wọ́n gbé òkú ọgá iléẹ̀kọ́ àti òṣìṣẹ́ méjì míì tó kú nínú ìbúgbàmù lọ sílé ìgbókùsí ológun ojú omi l‘Eko Ajá kìí rorò kó ṣọ́ ojú'lé méjì, kò tọ́ ọ́ sí Alaafin láti dásí ọ̀rọ̀ ọba l‘Ekiti - Peter Fatomilọla Ìjọba Somalia gbẹ́sẹ̀ lé ìrìn àjò òkè òkun lẹ́yìn tí Coronavirus báwọn lálejò Nigba to n gbe idajọ rẹ kalẹ, adajọ naa kilọ fun awọn ti ọrọ ọhun lati ma gbe igbeṣẹ ti yoo tako idajọ to gbe kalẹ.
Olè gbé òrùka ìgbéyàwó mì ní Eko Agolo akẹ́rù Apapa kò pa ènìyàn ṣùgbọ́n ó ba ọ̀pọ̀ ọkọ̀ jẹ́- Ọ̀ga RRS O le mu u kiri mọ inu ibi kọlọfin kan nigba miiran lati ri i pe iṣẹ di ṣiṣe.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: A kò sí lára àwọn tó ń ṣèwọ́de tako èlé owó epo àti iná ọba - NLC Jàńdùkú olóṣèlú gbàkóso ilé aṣòfin l‘Ondo Temitope Akinnusi: Ọ̀pọ̀ iléeṣẹ́ ló takú láti gbà mí síṣẹ́ torí mo ní ojú kan Eruku ìjà sọ lálá lórí ayelujára láàrin Oyedepo àti Daddy Freeze Ọmọ Nàíjíríà kó N6m jọ lórí ayélujára fún Erica tí wọn lé ní BB Naija Mo fòpin sí àjẹbánu lórí owó ìrànwọ́ epo àti iná ọba, ní èlé ṣe wáyé - Buhari Ọ̀nà láti mọ òkodoro ọ̀rọ̀ ló mú kí BBC News Yoruba bá olóyè Tola Adeniyi, ọjọ̀gbọ́n Banji Akintoye àti ọ̀túnba Deji Osibogun sọ̀rọ̀, láti tan ìmalẹ̀ sí awuyewuye náà.
Lodun 2019 ni wọn fun ọjọgbọn Yoshino ni ami ẹyẹ to ga julọ lagbaye ninu Chemistry to jẹ imọ sayẹnsi.
AMAA 2018 Ami eye orin to dara ju
Aare wa ba ẹbi, ọrẹ ati awon akẹgbẹ re ,ati ijoba ipinle
Ati pé ní orúkọ rẹ̀, kí á máa waasu ìrònúpìwàdà ati ìdáríjì ẹ̀ṣẹ̀ ní gbogbo orílẹ̀-èdè, ohun tí ó bẹ̀rẹ̀ láti Jerusalẹmu.
Naijiria ti gbegile gbogbo ibo ti awon eniyan di fun egbe oselu All
“Ṣé ọmọ mi ọ̀wọ́n ni Efuraimu ni?
Láti 1999 títí di 2019, wo àwọn ààrẹ tó jẹ ní Nàìjíríà Èyí tí a wò jùlọ 5:03 Fídíò, Omolola Arohunmolase Welder: Mo ti fí iṣẹ́ 'Welder' gbayì láwùjọ, tó mo fi tọ́ ọmọ yanjú, Duration 5,039 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 5:39 Fídíò, Akomolede ati Asa lori BBC: Olùkọ́ Kikelomo Ogunboye tan ìmọ́lẹ̀ sí ìwà olè ọ̀gá ọlọ́pàá Audu gẹ́gẹ́ bí àwòkọ́ṣe àsìkò yìí, Duration 5,398 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 4:11 Fídíò, Oba Adeyeye Ogunwusi: Ojú mi ti rí lọ́pọ̀ lọpọ̀, ọ̀pọ̀ èèyàn ni kò tilẹ̀ gbàgbọ́ pé mo lè jọba- Ooni, Duration 4,117 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 4:43 Fídíò, Promise Akinlade: ọmọ ọdún mọ́kànlá tó ń fi ìlù dárà bíi àgbàlagbà sọ̀rọ̀ nípa tálẹ́ǹtì rẹ̀, Duration 4,437 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 0:59 Gbọ́, Ìsẹ̀lẹ̀ jákèjádò orílẹ̀èdè àgbáyé láàárín ìṣẹ́jú kan, Duration 0,59wákàtí 5 sẹ́yìn 7:03 Fídíò, Olumuyiwa Bolade Adedeji Military Bruitality: Bí arákùnrin onípèníjà ara tí sọ́jà lù ṣe dé, Duration 7,035 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 4:45 Fídíò, Yoruba Films: Ẹ̀ẹ́ bẹ̀ mi kúrò láyé ni, mi ò lè kú - Fadeyi Oloro, Duration 4,4526 Èrèlè 2020 2:48 Fídíò, Esther Ajayi: Èmi náà ti borí ìṣòro rí ló ń mu mi ṣojú àánú, Duration 2,481 Ògún 2019 6:08 Fídíò, Adebola Ademilua: Àìrísẹ́ ṣè lẹ́yìn ìwé kíkà ló sọ mi dí ìyá onírú, mo dúpẹ́ tèmi, Duration 6,0827 Bélú 2020 5:55 Fídíò, Soyinka Cancer: Àṣe ara mi ni iso ti n run gbogbo bí mo ṣe n ṣèrànwọ́ lórí jẹjẹrẹ, Duration 5,5527 Bélú 2019 BBC News, Yorùbá Ìdí tí ẹ fi le è nígbàagbọ́ nínú ìròyìn BBC Ìlànà Lílò Nípa BBC Òfin Àṣírí Cookies Kàn sí.
Awọn janduku naa bẹrẹ si ni yinbọn, ibọn wọn lo si ba arakunrin kan to n kọja lọ."
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Seun Fakorede di kọmísánà ní ìpínlẹ̀ Oyo O ni ti gbogbo àwọn àgbààgbà ilé iṣẹ́ ijọba ti wọn pin oun si bá ni ìfẹ́ ìpínlẹ̀ Oyo lọ́kàn, kò sí ẹni ti yóò ṣe ọ̀tẹ̀ bíkòṣe pe kí wọ́n fọ́wọ́sowọ́pọ̀ pẹ̀lú oun fún àṣeyọri.
E je ki n fi daa yin loju pe, iku
World Aniti-Corruption day: Awolowo, Azikwe, Abacha àtàwọn olórí ìjọba tí aje ìwà ìjẹkújẹ ti ṣí mọ́ lórí rí ní Nàìjíríà
Ninu atẹjade kan ti Abdurahaman Balogun fi sita lorukọ ileesẹ NIDCOM, Arabirin Kafayat Amusan bi ọmọ ọkunrin lantilanti sinu baalu ileesẹ Emirate to n bọ wa si Eko lati Dubai.
Ṣugbọn ni tawọn Democrats wọn ni abawọn leleyi yoo jẹ lasiko tawọn eeyan ba fẹ dibo fun Trump gẹgẹ bi aarẹ.
Awọn idajọ yii lo ti mu ki awọn kan to ti wa nipo tẹlẹ kẹru wọn pada sile, lara awọn ti ileẹjọ da pada sile lẹyin ipẹjọ idibo ree.
Dá ọkàn mímọ́ sí inú mi, Ọlọrun,kí o sì fi ẹ̀mí ọ̀tun ati ẹ̀mí ìṣòótọ́ sí mi lọ́kàn.
Oríṣun àwòrán, Presidency Àkọlé àwòrán, Olori awọn oṣiṣẹ nile ijọba apapọ Naijiria, Abba Kyari ni coronavirus Gbogbo igbiyanju BBC lati gbọ ohun to n ṣẹlẹ bayii lẹnu Garba Shehu lo ja si pabo.
Ó tún wí pé, “Ta ni ó lè sọ fún Abrahamu pé Sara yóo fún ọmọ lọ́mú?
"LASEMA ni ""ati gbé ìgbésẹ̀, bákan náà ni a ó maa fi tó yín létí bi ó bá ṣe ń lọ""."
Kí ló dé tí ẹ fi tẹjú mọ́ wa bí ẹni pé nípa agbára wa tabi nítorí pé a jẹ́ olùfọkànsìn ni a fi mú kí ọkunrin yìí rìn?
Ayò mẹ́ta ni Giroud fi fakọyọ fún ikọ̀ Chelsea nínú Europa League
Oríṣun àwòrán, @Ogundamisi Àkọlé àwòrán, Fayose sọ wi pe awọn ọlọpaa lo ṣe ohun leṣe Nibi ipolongo ẹgbẹ oselu PDP lasiko ti idibo gomina waye ni ipinlẹ Ekiti, ni Fayose ti fara han lori ẹrọ amohunmaworan ti o si figbe ta wi pe awọn ọlọpaa na oun.
Dokita Ezenwankwo ni ko si ohun to jọ Magun tabi oogun abẹnu gọngọ ninu isẹlẹ yii, abuda ara lo n sisẹ tiẹ.
Fiimu Isoken lo gba eyi ti won dari dara julo nigba ti Ik Osakioduwa lati Naijiria ati Dlamini Jones lati South Africa gbalejo eto akanse naa.
Wọn ni awọn tọ ipasẹ rẹ lọ si ile- iwosan aladani kan nibi ti wọn ti lọ fi panpẹ ọba mu lẹlẹkeeji.
38 ilopomeji kilometer , o si ni iye awon eniyan to je 899,833 .
Bíótilẹ̀jẹ́pé iṣẹ́ àti àwọn ojúṣe wa ò kí nṣábàá gbàwá láàyè láti dá àkókò ìsinmi sí lójoojúmọ́.
àwọn ọmọ Jaala, àwọn ọmọ Dakoni, ati àwọn ọmọ Gideli, 
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Nàìjíríà ń ṣọ́ pápákọ̀ òfurufú tórí Ebola Àjọ WHO ní ''ìtànkálẹ̀ àìsàn náà ní agbára láti pọ̀ ju ti tẹ́lẹ̀ lọ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ìyá àkàndá ẹ̀dá: Àwọn ẹbí mi fẹ́ kí n pa ọmọ mi torí ó jẹ́ àkàndá ẹ̀dá Aṣoju aarẹ nile aṣofin, Ita Enang to fi ikede naa sita ṣalaye fun awọn akọroyin lalẹ Ọjọru pe ofin tuntun ọhun, ni yoo ma rii daju pe awọn ileeṣẹ tabi ẹnikọọkan to ba hu iwa ti ko tọ si akanda ẹda jẹ iya to tọ labẹ ofin.
" kí olùdásílẹ ̀ rẹ ̀ mohammed yusuf , tó kú , wọ ́ n mọ ẹgbẹ ́ yìí sí "" yusifiyya "" ."
Aare Buhari soro yii lojo Aje
UI- Ìwádìí àyẹwò nìkan ló lè sọ ohùn tó pá olùkọ́ tó kù nínú ilé to jo
Oríṣun àwòrán, Getty Images Naijiria: Ní ìpínlẹ̀ Kano lórílẹ̀-èdè Nàìjíríà láàrìn kan ó tó ẹgbẹ̀rún ènìyàn tó ń kú ni inú oṣù kẹrin ọdún, sùgbọ́n ìjọba kò ti fi ìdí rẹ múlẹ̀ títí di àsìkò yìí, àwọn ti ó jẹ́ ikú Covid-19 nibẹ̀.
Ayọ Ajewọle, adẹrinposonu ti gbogbo eeyan mọ si Wolii Agba naa ko kẹyin ninu awọn gbajumọ to sọrọ sita tako ikọlu naa.
Gomina Oyetọla ni iroyin pe alaafia ni ibagbeps awọn eeyan ilu naa pẹlu awọn darandaran fulani nibẹ jẹ idunnu fun ohun gẹgẹ bii iṣẹlẹ naa tun ṣe jẹ ibanujẹ ọkan fun oun.
Ọ̀rọ̀ tí ó ti ẹnu mi jáde kò tún lè ṣàjèjì sí ọ.
 ní ìdàkejì sí cellulitis , erysipelas jẹ ́ àkóràn kòkòrò àìlèfojúrí bacteria tí ó ní ṣe pẹ ̀ lú àwọn ipele ògééré awọ ara tí ó wà pẹ ̀ lú ibi pípọ ́ n àti àwọn igun tí ó hàn kedere , tí ó sì maa ń fa ibà .
Ajo eleto idibo lorile-ede naa so pe, awon egbe oselu merindinlogun ni won yoo figa-gbaga ninu eto idibo naa.
Kini awọn apẹrẹ to n safihan pe eniyan ko mu omi to.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Sudan protest in pictures: Bó ṣe ń lọ lórílẹ̀èdè Sudan 13 Ìgbé 2019 Wọ̀nyìí ni àwọn àwòrán tó fakọyọ ju láti orílẹ̀èdè Sudan lọ̀sẹ̀ yìí.
Ninu àwòrán naa, ọkan lara awọn ọlọpaa naa ti wọn ko dárúkọ, n gun ọrùn obìnrin naa to jẹ olookowo ọtí mọlẹ.
Ẹ gbọ́ ìkìlọ̀ tí mò ń ṣe fun yín,bí bẹ́ẹ̀ kọ́, èmi pẹlu yín óo pínyà,n óo sì sọ Jerusalẹmu di ahoro,ẹnikẹ́ni kò sì ní gbé ibẹ̀ mọ́.
iṣuna-owo naa wọle, ki wọn si
Ṣugbọn àwọn ọmọ-ẹ̀yìn yòókù ń bọ̀ ninu ọkọ̀, nítorí wọn kò jìnnà sí èbúté, wọn kò jù bí ìwọ̀n ọgọrun-un ìgbésẹ̀ lọ.
Jehu tún kọ ìwé mìíràn sí wọn, ó ní, “Bí ó bá jẹ́ pé ẹ wà lẹ́yìn mi, ẹ sì ṣetán láti tẹ̀lé àṣẹ mi, ẹ kó orí àwọn ọmọ ọba Ahabu wá fún mi ní Jesireeli ní àkókò yìí ní ọ̀la.
Gẹgẹ bi Omolere tii se akọwe feto iroyin fun igbakeji Gomina, onimọ ẹrọ Raufu Olaniyan ti se sọ, Igbakeji Gomina, olori awọn oṣiṣẹ ijọba, Alhaja Amidat Agboola ati Kọmisana fọrọ ilẹ, Abiodun Abdul Raheem wa lara awọn ti wọn ko ribi wọle sibi adura Fidau naa.
"Wọ́n tún sọ pé ""ibi tí èfúùfù ti ń gbé kẹ̀tẹ̀pẹ̀ Ogi tí èlùbọ́ ni òun yóò ṣe ọmọ ìta""."
Oniroyin BBC Halima Umar, to fidi kalẹ si Abuja ni o jọ pe ijọba ko tete gba isẹlẹ yii wọle ati wipe lẹyin orẹyin ni wọn to gba wipe wọn ji awọn ọmọbirin naa gbe.
Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Fídíò, Akomolede ati Asa: Mọ̀ si nípa àwọn ọ̀nà tí Yorùbá ń gbà ran ara wọn lọ́wọ́22 Ọ̀wàrà 2020 EndSARS: Olórí ilé aṣofín-ṣòfin ní ìṣúnà 2020 gbọdọ̀ pèsè owó fún ASUU bí bẹ́ẹ́kọ̀.
 san juan ní ibi gbóógì méta : san juan àtijó , bííṣì àti agbègbè ríṣọ ́ ọ ́ tì àti bẹẹbè lọ .
 nǹkan bì centiuri mẹ ́ fà sẹ ́ yìn àwọn kirisitẹni aramaic nìkan ní ó jẹ ́ èdè to gbalè nígbà náà bi ó tilẹ ̀ jẹ pé àwọn èdè tí á ń ṣọ ni ìlètò ti tàn kariaye ìwọ ̀ Òòrùn aramaic / ma ' lula ( 15 ) turoyo ( 70 ) èdè tí á ń pe láàrín àwọn olùṣo èdè ní assyrian ( 200 ) .
29 Ọ̀wàrà 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Akọwe ẹgbẹ Arẹwa ni, ẹgbẹ naa kẹyin si oludije fun ipo aarẹ labẹ asia ẹgbẹ oselu PDP, Atiku Abubakar, nitori bo se n polongo kiri pe oun yoo se atunto ilẹ yii, ti oun yoo si tun ta awọn dukia ajọni wa kan bii ileesẹ NNPC.
Ki ni owo yi le da ṣe ni orilẹ-ede Naijiria?
àwọn òpó rẹ̀ yóo jẹ́ ogún, ìtẹ́lẹ̀ rẹ̀ yóo sì jẹ́ ogún bákan náà, idẹ ni o óo fi ṣe wọ́n, ṣugbọn fadaka ni kí o fi ṣe àwọn ìkọ́ ati òpó rẹ̀.
 Oko ofurufu Saratov Airlines gbera nilu Orsk ni ekun Orenburg to to iwon egberun kan abo kilomita si ila oorun olu ilu Moscow.
ní ìparí , ogun kìí ṣe nǹkan tí ó dára .
Ninu àtẹ̀jáde kékeré kan lórí ẹrọ ayélujára twitter ni gómìnà Nasir El-Rufai ti kéde àṣẹ kónílé ó gbélé yìí.
NGACMR: Ohùn tí àwọn alatilẹyin Super Eagles sọ lẹ́yìn tí Nàìjíríà borí Cameroon
Ìdájọ́ lórí Àwọn Orílẹ̀-Èdè Tí Wọ́n Wà ní Agbègbè Israẹli.
Awon asoju gbogbo lo fenuko pe ki Naijiria gbalejo naa lodun yii.
Wo ipò tí Buhari fún Faṣọla, Lai Mohammed, Saraki àti bẹ́ẹ̀ bẹ́ẹ̀ lọ Ta ni Seun Fakorede, ọmọ ọdún 27 tó fẹ́ di kọmiṣọna?
 Àwọn kòkòrò àìlèfojúrí afàìsàn wọ ̀ nyí ló má a ń sábà ṣe òkùnfà ìgbẹ ́ gbuuru tó lágbára púpọ ̀ láàárín àwọn ọmọdé .
Mo mọ̀ wípé àwọn ìṣẹ̀lẹ̀ tí ó ń ṣẹlẹ̀ ní òde òní jẹ́ ẹ̀rí wípé àtúnṣe pọ̀ láti ṣe.
Amọṣa nigba ti ọrọ yii n ja ranyinranyin, oniruuru ọrọ ni awọn ololufẹ awọn lọkọlaya yii atawọn ọmọ Naijiria kan sọ.
Wo nkan ti awọn olukopa to ti já kuro lori eto naa jẹ Triky tee O jẹ N3,359,000 Ohun elo inu ile Irinajo silu Dubai fun ayẹyẹ One Africa Music Fest Ọ̀dà Ẹẹdẹgbẹta Dọla owo Bitcoin Ozo O jẹ N2,780,000 gẹgẹ bi ẹbun owo Ọkọ ayọkẹlẹ Irinajo silu Abuja Ẹẹdẹgbẹta Dọla owo Bitcoin Irinajo silu Dubai fun ayẹyẹ One Africa Music Fest Prince Oun naa jẹ N2,570,000 Ohun elo inu ile Irinajo silu Abuja Ẹẹdẹgbẹta Dọla owo Bitcoin Irinajo silu Dubai fun ayẹyẹ One Africa Music Fest Kiddwaya O jẹ ẹbun owo: N1,720,000 Foonu tuntun Ọ̀dà Ẹẹdẹgbẹta Dọla owo Bitcoin Wathoni O jẹ ẹbun owo: N1,250,000 Eroja iṣaraloge Ẹẹdẹgbẹta Dọla owo Bitcoin Brighto O jẹ ẹbun owo: N970,000 Ọ̀dà Ẹẹdẹgbẹta Dọla owo Bitcoin Tolanibaj O jẹ ẹbun owo: N825,000 Irinajo silu Abuja Ẹẹdẹgbẹta Dọla owo Bitcoin Praise O jẹ ẹbun owo: N770,000 Ẹẹdẹgbẹta Dọla owo Bitcoin Lucy O jẹ ẹbun owo: N570,000 Ọ̀dà Ẹẹdẹgbẹta Dọla owo Bitcoin Kaisha O jẹ ẹbun owo: N570,000 Ọ̀dà Ẹẹdẹgbẹta Dọla owo Bitcoin Tochi O jẹ ẹbun owo: N220,000 Ẹẹdẹgbẹta Dọla owo Bitcoin Eric Ẹẹdẹgbẹta Dọla owo Bitcoin Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí BBNaija 2020: Trikytee àti Ozo ní wọ́n fọ́wọ́ òsì júwe ile fún ni bbnaija lọ́sẹ̀ yìí20 Owewe 2020 BBNaija: Terry Waya sọ oun tó fojú Kiddwaya rí nílé nígbà tó ń bẹ̀bẹ̀ láti lọ BBNaija28 Ògún 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Ẹ wo bí àwọn akikanju tí ń ṣubú!
Gómìnà Amosun f'ohùn sílẹ̀ láti kúrò ní APC Àyájọ́ ọmọbìnrin gba gbogbo ayélujára tán 'Ìjọba ò fọwọ́ sí #30,000 fún òṣìṣẹ̀' Ijọba apapọ ti sọ pe oun ko fọwọ si ẹgbẹrun lọna ọgbọn Naira gẹgẹ bi owo oṣiṣẹ to kere julọ lorilẹede Naijiria eyi ti ẹgbẹ oṣiṣẹ n beere fun.
A wa laaye, a wa papọ a ko si ni jẹ ki ẹnikẹni yawa'' Pupọ awọn Mọsalaṣi kaakiri orileede naa ni wọn gba alejo ti awọn eeyan si rọgba yika lati se idaabo bo awọn olujọsin ni afihan idaro.
Bí ẹ rí ẹni tó fi ọ̀pá tẹlẹ̀
 ní oṣù kiní ọdún 2016 ni ààrùn yíì wáyé ní àwọn ẹkùn ogún nílu ti amẹ ́ ríkà .
“Lẹ́yìn náà, mú ọ̀kan ninu àwọn àgbò mejeeji, kí Aaroni ati àwọn ọmọ rẹ̀ gbé ọwọ́ lé e lórí.
Sọ fún wọn pé OLUWA Ọlọrun Israẹli ní, ‘Ẹnikẹ́ni tí kò bá gba ọ̀rọ̀ majẹmu 
 iye àwọn ènìyàn tó tó 20 sí 25 % a má a ní ìrora ní ojú ibi abẹ ́ rẹ ́ náà , àwọn bíi 2 % a sì má a ní ibà .
"Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Yomi Fabiyi ló ni ki òun àti ìyàwó rẹ̀ yàgò fún ra wọn ""Ohun ti ijọba Jonathan ṣe ni lila eto owooya sọgbin ọlọgọrun un bilọnu naira (N100billion) kalẹ fun banki apapọ."
Eyi jẹ ki goolu rẹ pe mẹfa ti oun funra rẹ si ran awọn meta lọwọ lati jẹ goolu ninu idije ife ẹyẹ agbaye naa.
Ẹ lọ mú ẹ̀rí ibi tí a ti gba owó wá- NLC/TUC
Oṣere ni, olukọtan ni, o tun jẹ olootu to ṣe wi pe bi awọn eniyan ṣe bẹrẹ si ni mọ ọ jẹ ara ọtọ paapaa pẹlu ere rẹ to fi gba orukọ, Jennifer.
Wo àànfàní ‘Masturbation’, fífún ara rẹ̀ ní adùn ìbálòpọ̀ Hubert Ogunde rèé, baba àwọn òsèré tíátà Bakan naa ni yoo sọ fun wa orisi isọri ọrọ to wa, ba se n lo wọn ati anfaani wọn.
Ọkùnrin kan rí ẹ̀wọ̀n ọdún mẹ́rin he lẹ́yìn tó jí ẹ̀rọ ìléwọ́ iPhone ní ìpínlẹ̀ Ogun Ẹ fún wa lówó oṣù wa tàbí kí a gùnlé ìyanṣẹ́lódì ọlọ́jọ́ gbọọrọ- Àwọn dokita ìpínlẹ̀ Ondo Wo àfipábánilòpọ̀ ẹni ọdún 51 tí ìjọba ìpínlẹ̀ Ekiti tú làṣirí ní gbangba Ilé aṣòfin ìpínlẹ̀ Oyo jáwée lọ sinmi nílé fún alága ìgbìmọ̀ mẹ́tàlá káàkiri ìjọba ìpínlẹ̀ Ajọ ajafẹtọ ọmọniyan, Amnesty International, sọ pe awọn ọmọ ologun Naijiria ṣina ibọn bolẹ fun awọn oluwọde ọhun lẹnu iloro Lekki Toll Gate, ti ọpọ ku, nigba ti awọn miran si farapa.
Aaroni bá gbé e kalẹ̀ níwájú àpótí ẹ̀rí, gẹ́gẹ́ bí àṣẹ tí OLUWA ti pa fún Mose.
"Bakan naa lo sọ pe ""ilana ti Ajimobi la kalẹ, lo jẹ ipilẹ diẹ lara awọn iṣẹ ti iṣakoso wa n ṣe."
Ẹni tí ó bá ń sin Kristi báyìí jẹ́ ẹni tí inú Ọlọrun dùn sí, tí àwọn eniyan sì gbà fún.
Kò si ẹ̀yà tàbi ẹ̀sìn Nigeria ti kò si ni Èkó.
ọjọ kọkanla oṣu kẹta ni Gomina El-Rufai tun fun Sanusi ni ipo mii.
Ìtàn ìgbé ayé Isola Ogunsola 'I-sho Pepper', ògbóǹtagí òṣèré tíátà tó sẹré Yorùbá yíká Nàìjíríà Ènìyàn 229 ló tún ṣẹ̀ṣẹ̀ ní ààrùn Covid-19 ní Nàìjíríà Ọwọ́ ọlọ́pàá tẹ ẹ̀gbọ́n tó dáná sun àbúrò rẹ̀ toyúntoyún nílùú Eko Èrò ọmọ Nàìjíríà sọ̀tọ̀tọ̀ lórí fàákájáa láàrin Abike Dabiri-Erewa àti mínísítà ètò ìbárẹ̀nisọrọ̀, Ìkìlọ̀ yìí kò sẹ̀yìn ìwé ìkìlọ̀ tí wọ́n fun akọ̀wé àgbà ilé iṣẹ́ tó n rí sí ìmọ̀ sáyẹ́nsì Mohammed Bello Umar fún ríra ilé tí wọn ò kọ́ tan ni bilionu méje náírà fún ilé iṣẹ́ to n rí sí ǹkan ọ̀gbìn bo ṣe lu síta lórí ayélujára.
Jonatani ọmọ Geriṣomu, ọmọ Mose ati àwọn ọmọ rẹ̀ ni wọ́n jẹ́ alufaa fún àwọn ẹ̀yà Dani títí di àkókò tí wọ́n kó gbogbo agbègbè wọn ní ìgbèkùn.
Oríṣun àwòrán, Temitope olatoye Àkọlé àwòrán, Sugar fara gba ọta ibọn ni lalupọn lasiko idibo lọjọ abamẹta Kansilọ ni ijọba ibilẹ Ọdẹda lo fi bẹrẹ irinajo oṣelu rẹ.
Tí ó bá di ọdún keje, ẹ gbọdọ̀ dá a sílẹ̀, kí ó sì máa lọ.
Oju opo Barack Obama, Bill Gates, Elon Musk, Jeff Bezos ati Joe Biden to fi mọ Kanye West lo lugbadi awọn gbajuẹ naa.
Harry Kane's goal as seen by the Spurs away fans…Incredible 🙌#NoFilterUCL pic.
" Bakan naa, igbakeji gomina ipinlẹ Edo, Phillip Shaibu pẹlu ti kọwe fi ẹgbẹ oṣelu APC silẹ.
Ẹ̀yin ń jẹ ẹran ọlọ́ràá, ẹ̀ ń fi irun aguntan bo ara yín, ẹ̀ ń pa aguntan tí ó sanra jẹ; ṣugbọn ẹ kò fún àwọn aguntan ní oúnjẹ.
Wọ́n ń sọ pé, “Báwo ni igi ọ̀pọ̀tọ́ náà ṣe gbẹ lẹsẹkẹsẹ.
Ẹ pe gbogbo eniyan jọ,kí ẹ sì ya ìjọ eniyan sí mímọ́.
Nígbà tí àwọn òbí rẹ̀ rí i, ẹnu yà wọ́n.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù SARS: Awọn ará ìlú fi ẹ̀rí síta nípa ìrírí wọn 25 Òkùdu 2018 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 26 Òkùdu 2018 Oríṣun àwòrán, Police/twitter Àkọlé àwòrán, Àwọn tó bá ikọ ìròyìn BBC sọ̀rọ̀ láti ìlú Èkó, Ibadan àti Oshogbo sàlàyé ìrírí wọn lọwọ́ SARS Láìpẹ́ yìí ní Fídíò kan tó gbilẹ̀ lórí ẹ̀rọ ayélujára láti fòpin sí àjọ ọlọ́pàá tó wà fún gbígbógun ti ìwà olè (SARS).
Oríṣun àwòrán, Instagram O ṣeeṣe ki Okeke lọ to ogun ọdun ni ọgba ẹwọn fun ẹsun wiwu iwa ọdaran lori ẹrọ ayelujara.
“Ẹ ranti ohun tí àwọn ará Amaleki ṣe sí yín nígbà tí ẹ̀ ń bọ̀ láti Ijipti.
Aare tun so pe“A gbodo gbogun ti iwa ibajẹ ni gbogbo ona.
Aṣọ́nà bá dáhùn, ó ní:“Ilẹ̀ ń ṣú, ilẹ̀ sì ń mọ́.
 O ni, ”bi wọn ba le sọ abadofin yii di ofin tan yoo le jẹ ki awọn ara ilu ṣamulo anfani to wa ni ẹka irinajo-afẹ, bi a ba si mu idagbasoke ba a, yoo le polongo Ipinlẹ Eko gẹgẹ bi ibi ti irinajo-afẹ ti kọkọ mulẹ daadaa ni orilẹ-ede Naijiria.
Ile-ise ti o n ri si isiro lorile-ede Nigeria, The National Bureau of Statistics (NBS) so pe, awon olugbe ipinle Ondo, Rivers ati ipinle Bayelsa lo san owo okada ti o won julo ninu osu kinni odun.
Ǹjẹ́ gbogbo àwọn eniyan wọnyi kò ní máa kẹ́gàn rẹ̀, kí wọ́n sì máa fi ṣe ẹlẹ́yà pé, “Ègbé ni fún ẹni tí ń kó ohun tí kì í ṣe tirẹ̀ jọ.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Obìnrin gbọdọ̀ ṣe ara wọn lọ́kan láti gba ara wọn sílẹ̀ lọ́wọ́ ìfìyàjẹni - Olùdásìlẹ̀ ẹgbẹ́ FIN Sinimá oríta, àwòòtán.
        Ki n tó máa bá ọ̀rọ̀ mi lọ, mo níláti kọ́ dúpẹ́ lọ́wọ́ yín fín ìwé yin tí mo rí gbà láìpẹ́.
Sotitobire: Ìdí tí a fi ń 'wọ́dìí' Wòlíì Alfa Babatunde Sotitobire-DSS Ọpọ eeyan lo ti n beere ibeere lori idi to fi jẹ pe awọn ẹṣọ agbofinro ọtẹlẹmuyẹ apapọ, DSS lo n ṣe ẹjọ ijinigbe ti wọn n fi kan ilumọọka wolii Alfa Babatunde Sọtitobirẹ ni ilu Akurẹ.
O fikun pe, Maiyegun naa ma n dunadura laarin awọn ọmọ Yoruba, lọna ati mu idẹru, alaafia, igbeleke asa ati alaafia gbilẹ si ni ilẹ Yoruba.
Gbé àwọn ẹbọ ohun jíjẹ náà wá siwaju OLUWA.
soro , pe ijoba ologun ni yoo maa sakoso orile ede naa fun odun meji , ni eyi
Nígbà tí ikọ ilé ìṣe BBC Yoruba bá alukoro àjọ ọlọ́pàá ipinle Ondo sọ̀rọ̀, ASP Tee Loko, ó ṣàlàyé pé, ìyàlẹ́nu ni ikú náà je ti o si sọ wípé, kí Olúwa tú ẹbi olóògbé nínú.
Bobrisky: Olusegun Runsẹwẹ, o kéré sí nọ́mbà àwọn tí mò ń bá se!
Ajọ eleto idibo ni ohun yoo ṣa gbogbo agbara ohun lati ri pe ko si aṣiṣe kankan akojọpọ esi ibo naa.
O ṣe afikun ọrọ wi pe, gbogbo awọn aṣoju Amọtẹkun ni yoo maa ṣe amojuto awọn agbegbe kọọkan pẹlu oye ede ati aṣa awọn agbegbe naa.
Ni ọjọ Isegun, awọn aṣofin Ilẹ Gẹẹsi n dibo lori ipinnu adari ijọba, Theresa May lati ko orilẹ-ede naa kuro ninu ajọ European Union.
Patako ẹsẹ ti adiyẹ ma fi n lele a wu soke.
ni eyi ti o gbe jawe olubori lati di gomina ipinle naa.
Ṣugbọn bí mo bá lọ, n óo rán an si yín.
 Ko tan sibẹ, osere tiata obinrin miran, Tayo Sobola, to mura bii ẹni ti ọfọ sẹ loju opo Instagram rẹ ni imura oun lo n se afihan ipo ibanujẹ ti oun wa nitori inu oun bajẹ lori idajọ iku ti wọn se fun Maryam Sanda."
Iwaasu Yusuf a maa da lori bi awọn olori yoo ti ṣe ṣe deede laarin awọn alaini ati awọn to ni lawujo.
Iwadii nipa eto idibo to to waye sẹyin fi han pe, iye awọn ọmọ ẹgbẹ Democrat to n dibo nipasẹ ileeṣẹ ifiweranṣẹ pọ ju ti Republican lọ.
Lara awọn to ti kẹnu bọ ọrọ abadofin yii ni Ọjọgbọn Wole Soyinka, gomina Samuel Otorm ti ipinlẹ Benue, ẹgbẹ awọn oṣiṣẹ́, Afenifere ati bẹẹ bẹẹ lọ tori naa, o lee koba irẹpọ orilẹede.
" Oríṣun àwòrán, @MoshoodAdeoti Àkọlé àwòrán, Atẹjade kan ti Adeoti fi ransẹ si wọọdu idibo rẹ, tii se Wọọdu kejila, nijọba ibilẹ Iwo, fihan pe o ti fi ẹgbẹ oselu APC silẹ.
 láti fi ilé - ifẹ ̀ sílẹ ̀ kí wọn si wá ibùjókòó tuntun fún ara wọn níbi tí wọ ́ n yóò ti máa ṣe ìjọba wọn .
O Fagunwa, Adebayo Faleti, Akinwumi Iṣọla, Lawuyi Ogunniran àti Oladejo Okediji ṣiṣẹ silẹ ki wọn to lọ3 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Èyí tí a wò jùlọ 5:03 Fídíò, Omolola Arohunmolase Welder: Mo ti fí iṣẹ́ 'Welder' gbayì láwùjọ, tó mo fi tọ́ ọmọ yanjú, Duration 5,039 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 5:39 Fídíò, Akomolede ati Asa lori BBC: Olùkọ́ Kikelomo Ogunboye tan ìmọ́lẹ̀ sí ìwà olè ọ̀gá ọlọ́pàá Audu gẹ́gẹ́ bí àwòkọ́ṣe àsìkò yìí, Duration 5,398 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 4:11 Fídíò, Oba Adeyeye Ogunwusi: Ojú mi ti rí lọ́pọ̀ lọpọ̀, ọ̀pọ̀ èèyàn ni kò tilẹ̀ gbàgbọ́ pé mo lè jọba- Ooni, Duration 4,117 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 4:43 Fídíò, Promise Akinlade: ọmọ ọdún mọ́kànlá tó ń fi ìlù dárà bíi àgbàlagbà sọ̀rọ̀ nípa tálẹ́ǹtì rẹ̀, Duration 4,437 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 0:59 Gbọ́, Ìsẹ̀lẹ̀ jákèjádò orílẹ̀èdè àgbáyé láàárín ìṣẹ́jú kan, Duration 0,59wákàtí 5 sẹ́yìn 7:03 Fídíò, Olumuyiwa Bolade Adedeji Military Bruitality: Bí arákùnrin onípèníjà ara tí sọ́jà lù ṣe dé, Duration 7,035 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 4:45 Fídíò, Yoruba Films: Ẹ̀ẹ́ bẹ̀ mi kúrò láyé ni, mi ò lè kú - Fadeyi Oloro, Duration 4,4526 Èrèlè 2020 2:48 Fídíò, Esther Ajayi: Èmi náà ti borí ìṣòro rí ló ń mu mi ṣojú àánú, Duration 2,481 Ògún 2019 6:08 Fídíò, Adebola Ademilua: Àìrísẹ́ ṣè lẹ́yìn ìwé kíkà ló sọ mi dí ìyá onírú, mo dúpẹ́ tèmi, Duration 6,0827 Bélú 2020 2:36 Fídíò, Sotitobire: Ìdájọ́ òdòdò ló fẹsẹ̀ múlẹ̀ lórí ọ̀rọ̀ Pásítọ̀ Sotitobire - Agbẹjọ́rò fún ìjọba, Duration 2,367 Ọ̀wàrà 2020 BBC News, Yorùbá Ìdí tí ẹ fi le è nígbàagbọ́ nínú ìròyìn BBC Ìlànà Lílò Nípa BBC Òfin Àṣírí Cookies Kàn sí.
Nítorí ìpọ́njú yóo wà ní àkókò náà, irú èyí tí kò sí rí láti ìṣẹ̀dálẹ̀ ayé, láti ìgbà tí Ọlọrun ti dá ohun gbogbo títí di àkókò yìí, kò sì ní sí irú rẹ̀ mọ́ lae.
Ṣugbọn a lé ìwọ kúrò ninu ibojì rẹ,bí ọmọ tí a bí kí oṣù rẹ̀ tó pé,tí a gbé òkú rẹ̀ sọnù;tí a jù sáàrin òkú àwọn jagunjagun tí a pa lójú ogun;àwọn tí a jù sinu kòtò olókùúta,bí àwọn tí a tẹ̀ ní àtẹ̀pa.
Ohun mẹ́fà tí ọ̀pọ̀ kò mọ̀ nípa ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ Arsenal àti Machester City Real Madrid gbadé ògo La Liga, Messi ní Barcelona ò lè ta pútú mọ́ Ayé le!
Ṣe é bí àwọn ìpara olóòórùn dídùn, yóo jẹ́ òróró ìyàsímímọ́ fún OLUWA.
Ki Buhari wa nkan ṣe si itajẹsilẹ O ti pẹ ti ija ẹsin ati ẹ̀yà ti n waye ni orilẹede Naijiria, paapa ni ẹkùn Ariwa.
apapo toro kan gbongbon lorile-ede Naijiria(Federal Executive Council)yoo waye loni ojoBo(Thursday),
Wòlíì Kasali ní Dolapo Awosika kò lé ìyàwó òun jáde A gbọ pe Da Rocha ba owo nile ni, tori pe baba rẹ ni owo lọwọ, amọ ti Candido funra rẹ ṣiṣẹ mo owo to ba nile.
Fọto imurasilẹ fun igbeyawo, 'pre-wedding shoot' awọn mejeeji jade sori ayelujara lọdun to kọja.
Ẹ níláti jẹ́ eniyan ọ̀tọ̀ ati olùfọkànsìn, 
Morocco Journalist: Wọ́n gbé Akọ̀ròyìn ní Morocco lọ sílé ẹjọ́ lórí ẹ̀sùn àgbèrè àti oyún ṣíṣẹ́
Oríṣun àwòrán, Odunlade Adekola Àkọlé àwòrán, Ọdunlade ọmọ Adekọla, agba n bọ wa kan ọ o Bakan naa ni olori ẹgbẹ oselu to kereju ni Ile Igbimọ Asofin Agba ni orilẹede Amerika, Chuck Schumer ti ke si ẹka to n sewadi lorilẹede naa, FBI lati se iwadii ile isẹ FaceApp to jẹ ti orilẹede Russia.
Ko si awijare kankan ti eeyan le ni lati fi gbẹmi alaiṣẹ'' Wọn ko ti darukọ awọn to farakasa ninu iṣẹlẹ naa amọ Aarẹ Mrexico sọ pe awọn ọmọ orilẹede oun mẹta wa ninu wọn gẹgẹ bi ile iṣẹ iroyin Reuters ṣe j'abọ.
Dotun Ojon Nínú ọ̀rọ̀ rẹ̀, Oludije yi sọ pe nkan ti oun maa se yatọ ti oun ba jawe olu bori ni ọrọ idaari (leadership) O ni eto idari doju kọ ibi kan da apa kan si ni ipinlẹ Ondo.
Tẹle ohùn tawon aláṣẹ bá sọ pe ko se.
Lagos/Ibadan Expressway: Èèyàn mẹ́jọ ló kù nínú ìjàmbá ọkọ̀ kìí ṣé mẹ́ẹ̀dógún
O fi kún pé àwọn ile iṣẹ́ Radio mi fààyè gba ọ̀rọ̀ ìbàjẹ́ àti àwọn ọ̀rọ̀ tó lé dá rògbòdiyàn sílẹ̀ láwùjọ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Mobile Wash: iṣẹ́ fífọ́ mọ́tò tà ni mó yàn láààyò- Slay Mama Ki ni o ti kọkọ ṣẹlẹ lori mimu awọn Invictus àti Hushpuppi Invictus Obi, Hushpuppi, àwọn ọ̀dọ́ Nàìjíríà méjì tí ẹ̀sùn gbájúẹ̀ wà lọ́rùn wọn Oríṣun àwòrán, Instagram Ajọ to n koju iwa jẹgudujẹra lorilẹede Naijiria, EFCC ti ni Ramoni Igbalode, alias Ray hushpuppy ni ẹjọ lati jẹ ni ọdọ wọn.
 Ó ní àwọ ̀ búlu tí ó fẹ ́ mọ ́ díẹ ̀ pẹ ̀ lú ìrísí bi ti ọkọ ̀ maersk tókù láì wo tí àsíá ìforúkọsílẹ ̀ wọn .
Bo tilẹ jẹ pẹ Musulumi ni iya Halimat, o ni ọrọ ọmọ naa ti sọ oun di ẹni to n lọ si iṣọ oru ni ṣọọṣi, ti oun si n gbaawẹ ati adura ki ọmọ le e di riri.
Ó rí àwọn ọkọ̀ meji létí òkun.
Lẹsẹkẹsẹ ni awakọ sa lọ ti awọn ọdọ kan si dana sun ọkọ akero naa.
Ǹjẹ́ nígbà tí Ọmọ-Eniyan bá dé, yóo bá igbagbọ ní ayé mọ́?
Dangote-BRT Accident: Lasema ní ìjánu ọkọ̀ Dangote tó já ló fa ìjàǹbá náà
Awọn ipinlẹ naa re e: Ọrọ owo ọna meji tabi ọna mẹta fawọn to di ipo mu tẹlẹ naa jẹ ohun ti o n kan awọn eeyan lominu.
Nibẹ ni wọn si ti ṣalaye wi pe awọn ti ṣe awari awọn ijọba ibilẹ ti arun Coronavirus ti fidimulẹ julọ lorilẹede Naijiria.
Àlàyé rèé lórí ááwọ̀ Femi Fani-Kayode àti Tunde Bakare
Nitori naa, wọn ṣalaye pe idi fun iforukọsilẹ ori ayelujara yii ni lati le foju to awọn ile iṣẹ wọnyẹ ki idanimọ fun ọlọ́dani le daju to bẹẹ ti eeyan ba san owo, wọn mọ pe ni to yẹ ni wọn n san an fun.
Àwọn ọmọ Diṣani ni: Usi ati Arani.
 bákan náà ló jẹ ́ pé gbobgo ọdún ìbílẹ ̀ tí wọ ́ n ń ṣe ní ifẹ ̀ náà ni wọ ́ n ń ṣe ní Òkè-igbó àti ifẹ ̀ ẹ ́ tẹ ̀ dó .
Eleyi si tayọ ibeji marun un pere to ma a n wa ninu awọn ọmọ ẹgbẹrun kan ti wọn ba bi ni gbogbo ilẹ Yuroopu.
Àkọlé àwòrán, Taiwo Ogunjobi di oloogbe Wọn fẹsun wi pe o wa lara awọn mẹrin ti o mọ nipa bi miliọnu mẹjọ owo dọla ti poora lasiko ti idije ife ẹyẹ agbaye n lọ lọwọ lọdun 2010.
IṢẸ́ ẸNI Iṣẹ́ ẹni ni iṣẹ́ ẹni Má tijú iṣẹ́ rẹ Ikán kì í tijú à ń mọlé Èèrà kì í tijú à ń lànà Alápàáǹdẹ̀dẹ̀ kì í tijú à ń fò kiri ní gbangba Iṣẹ́ ẹni niṣẹ́ ẹni Má tijú iṣẹ́ rẹ Bígi lo bá ń gé ṣowó Bí wọ́n sì gbà ọ́ pé kí o gbálẹ̀ ọjà Bíràn-ánṣẹ́ lo sì jẹ́ lábẹ́ ìjọba Iṣẹ́ ẹni ni iṣẹ́ ẹni Má tijú iṣẹ́ rẹ Ò bá à ṣàgbẹ̀ Ò bá à ṣakọ̀wé Bó o jẹ́ ìnájà Bó o jóníwóróbo Iṣẹ́ ẹni niṣẹ́ ẹni Ṣiṣẹ́, iṣẹ́ kì í pani Àìṣe rẹ̀ gan-an làbùkù.
Gẹ́gẹ́ bí ààrẹ ṣe sọ, mímú idagbasoke ba awon ara ìlú ni ó jé ìjọba lógún lásìkò yìí.
Orji Uzor Kalu - Delta Ile ẹjọ to n gbọ ẹjọ ẹsun to ni i se pẹlu idibo sile igbimọ aṣofin ni ipinlẹ Delta naa tun ti wọgile ibo to gbe Orji Uzor Kalu wọle.
Ṣebí nípa pípa àwọn ọmọ ogun wa ni.
Ó dàbí ẹyọ wóró musitadi kan, tí ẹnìkan mú, tí ó gbìn sí oko rẹ̀.
Wọn ni gbgobo ọ̀rọ̀ tó bá tó ba ti jọ mọ́ ǹkan ti kò dára ní wọn máa ń da ẹ̀bi rẹ̀ ru Sàtánì; bẹẹ Satani ti àwọn n sìn kìí ṣe buruku.
Kìí ṣé òjò àrọ̀rọ̀ọ̀dá nìkan, ọkọ̀ aképo tó dànù náà fà súnkẹrẹ-fàkẹrẹ l'Eko Ẹ̀kún omi mú ọ̀pọ̀ ẹ̀mí lọ l‘Eko torí adágún odò tí wọn ṣí ní Abẹokuta Seun Egbegbe lo ọdún méjì àti oṣù méje lẹ́wọ̀n láì tìí san béèlì rẹ̀ Lati owurọ ni ijamba naa ti fa ọpọlọpọ sunkẹrẹ fakẹrẹ ọkọ loju popo ni iha kinni ati iha keji ọna gan ti ijamba ko ti ṣẹlẹ tori ọpọlọpọ awakọ to n lọ lo dara duro lati woran.
Ẹ wo àwòrán tó làmìlaaka níbi ọjọ́ ìbí Gomina ìpínlẹ̀ Ọyọ Bakan naa ni fifi opin si aṣẹ ti ko jẹ ki wọn o gbe awọn oṣiṣẹ lati ibikan si omii, gbigba awọn oṣiṣẹ ti wsn da duro lọna aitọ pada, ajẹsilẹ owo oṣu awọn olukọ ileewe alakọbẹrẹ ati awsn oṣiṣẹ ijọba ibilẹ kan.
Àwọn ìtàn mánigbàgbé tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Wo àwọn gbajúmọ̀ òṣèré Yorùbá tí kìí ṣe ọmọ káàárọ̀ oòjíire Ǹjẹ́ o mọ àwọn òṣèré bí Oyin Adejọbi, Funmi Martins àtàwọn míì tó ti dágbére fáyé?
Ọba wa wa ni coma bayii, wọn ti jo aafin atawọn ọkọ ọba wa, ti ọba wa si n gbọn, koda ile ti wọn bajẹ ni agbegbe wa le ni ọgọjọ, to fi mọ ile temi gan alara."
Ègbé ni fún àwọn tí ó ń kọ́lé mọ́lé,tí wọn ń gba ilẹ̀ kún ilẹ̀,títí tí kò fi sí ilẹ̀ mọ́,kí ẹ̀yin nìkan baà lè máa gbé ilẹ̀ náà.
"Oríṣun àwòrán, Odunlade Adekola Lasiko ti wọn n kadii eto naa nilẹ ti awọn agbaagba jọ wa laarin ara wọn ni Jide Kosoko fi ẹrọ gbohungbohun kọ ọrọ rẹ lorin pe ""."
Bẹẹ ba gbagbe, Ọjọru ana ni wọn sun igbẹjọ naa siwaju di Ọjọbọ oni nitori pe ijọba ipinlẹ Ondo gbe ẹjọ ọhun kuro nile ẹjọ Magisireti lọ sile ẹjọ giga.
Wọ́n ṣí àpótí ìṣúra wọn, wọ́n fún un ní ẹ̀bùn: wúrà, turari ati òjíá.
Gẹgẹ bo ti maa n ṣe ni kete to ba ti de ile ẹjọ nipa fifọ ọwọ ati lilo sanitaisa ko to wọ ile ẹjọ lọ.
Adebayọ shittu sọrọ ni kikun lori ohun to ṣokunfa ija laarin wọn, eyi to pe ni Abosi lọdọ Ajimọbi.
Iru awọn iroyin ti ẹ le nifẹ si: Fọlọrunṣọ Alakija: Imọ ṣe koko 'Ara sisan kii ṣe arun' Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 3 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 5 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Ṣugbọn èmi wá ń sọ fun yín pé, ẹ má ṣe búra rárá; ìbáà ṣe pé kí ẹ fi ọ̀run búra, nítorí ìtẹ́ Ọlọrun ni; 
Ó rú ẹbọ ohun mímu, ó sì da ẹ̀jẹ̀ ẹbọ alaafia rẹ̀ sí ara rẹ̀.
Bí ti ìfẹ́ ni, bí ti ìkórìíra ni, ẹnìkan kò mọ̀.
Oríṣun àwòrán, @Chadwick Wo ọ̀rọ̀ tí gbogbo agbàyé fẹ́ràn jùlọ lójú òpó Twitter Gbogbo aye lo ṣedaro iku gbajumọ oṣere tiata to ṣe ere Black Panther, Chadwick Boseman to jade laye lẹni ọdun mẹtalelogoji.
Ilé iṣẹ́ ọlọpàá ìlú Abuja ní awọn tí ń gbìyànjú láti ṣe awári ọkúnrin náà.
Àwọn alasẹ ọgbà ẹ̀wọ̀n sọ pe ẹlẹ́wọ̀n to to ẹgbẹrun meji, 1,900,lo sa kuro lasiko ikọlu naa.
Ibérè yìí lo múmi fẹ́ kọ àkọsílẹ̀ ránpẹ́ yìí nítoripé kò ṣeé dáhùn ní gbólóhùn kan lásán.
Wo bí ètò ìsìnkú Isa Funtua ṣe wáyé ní ìlú Abuja A yìnbọn lu Precious láti dáa dúró ni, akò mọ̀ pé o máa kú- Ọlọ́pàá Awọn ọmọ Yoruba ti a n sọrọ wọn yii ti laami-laaka to bẹẹ ti wọn fi jẹ aridunnu fun iran Yoruba, o si yẹ ki a maa gbe wọn larugẹ.
Bakan naa ni Aṣofin Ọbasa ki ẹgbẹ oṣelu All Progressives Congress, APC lapapọ ku arafẹraku ọkan lara eniyan pataki laarin ẹgbẹ oṣelu naa to papo da.
Oríṣun àwòrán, @adebolaolu2019 Àkọlé àwòrán, Ọmọ ọdún márùn-ún àti àgbà mẹ́rin ló bá ìṣẹ̀lẹ̀ ọ̀pá epo bẹntiróò tó gbiná ní Abule Egba lọ láìpẹ́ yìí.
Olukuluku alufaa yóo kó ohun tí wọ́n bá mú wá sọ́dọ̀ rẹ̀.
" Wolii Jeremiah Omoto Fufeyin: Wolii kẹrin to kede nipa asọtẹlẹ rẹ saaju lori rogbodiyan ati iwọde EndSARS ni Wolii Jeremiah Omoto Fufeyin.
Kí ni n ò ṣe tán?
Wo ohun àràmàndà tí àwọn olósèlú máa ń ṣe lásìkò ìbò
Àwọn tí ó wà nínú ẹgbẹ ́ eastern austronesian náà tó ẹ ̀ ẹ ́ dẹ ́ gbẹ ̀ ta èdè .
Àsọtẹ́lẹ̀ Fada Mbaka, tó yẹ àga mọ́ gómìnà Imo nídìí rèè: Ọ̀gá mi fẹ́ fi tipá bámi lòpọ̀ ní Lebanon àmọ́ ìjọba yọ mí l'óko ẹrú - Ọmọ Nàíjíríà míì Bí ìtàn ayé Toyosi Arigbabuwo ṣe lọ rèé láti ẹnu Musiliu Dasofunjo àti Ogun Majek Wo ohun tó yẹ kó mọ̀ nípa Gomina Imo ti ilé ẹjọ́ giga ye àga mọ́ nídí Àkọlé àwòrán, Malami ní ìjọba àpapọ̀ nìkan ló ni ojúṣe ètò ààbò Bakan naa ni agbajọwọ eniyan lẹtọ lati daabo bo ara wọn.
Òun sì ni ẹni tí ó kéré jùlọ ti aarun náà tí pá ní ilẹ̀ Gẹ̀ẹ́sì.
oorun Kebbi ati akowe re Barau Jibrin, lati ila oorun Kano.
Eyín rẹ dàbí ọ̀wọ́ aguntan,tí wọn ṣẹ̀ṣẹ̀ wẹ̀ tán,gbogbo wọn gún régé,kò sì sí ọ̀kan tí ó yọ ninu wọn,
foju ba ile -ejo nitori awon eri ti won ri gbamu lori ise ibi won.
Ìwọ ni mo sọ wọ́n di mímọ̀ fún lónìí, àní ìwọ,kí ó le jẹ́ pé OLUWA ni o gbẹ́kẹ̀lé.
o ni awn ologun kọkọ pa kẹ́kẹ́ nigba to ya ni wọn gbiyanju lati le awọn oṣiṣẹ alaabo naa lọ.
A kò ṣẹ̀ṣẹ̀ jọ máa pàdé ara wa!
Bí àpẹẹrẹ, bí ẹnìkan bá lọ sinu igbó pẹlu aládùúgbò rẹ̀ láti gé igi, bí ó ti ń fi àáké gé igi lọ́wọ́, bí irin àáké náà bá yọ, tí ó lọ bá aládùúgbò rẹ̀, tí ó sì pa á; irú ẹni bẹ́ẹ̀ lè sálọ sí ọ̀kan ninu àwọn ìlú náà, kí ó sì gba ẹ̀mí ara rẹ̀ là.
Oríṣun àwòrán, Tim Graham Bẹẹ ni ṣugbọn awọn ọmọ ọba mẹfa lo wa nilẹ siwaju rẹ ti awọn naa le jọba.
Gbogbo wọn ni a kọ orúkọ wọn sinu ìwé.
Pupọ ninu awọn olugbe ile naa lo padanu owo, awọn ohun elo to n lo ina ijọba, ati ọpọlọpọ dukia sinu iṣẹlẹ naa.
Igboho wa fi ọwọ gbaya pe, bi okunkun pẹ titi, imọlẹ yoo tan, laipẹ laijinna, ominira yoo si tẹ ilẹ Yoruba lọwọ.
Jẹ́ kí ìparun dé bá wọn lójijì,jẹ́ kí àwọ̀n tí wọ́n dẹ sílẹ̀ dè mí mú wọn;jẹ́ kí wọ́n kó sinu rẹ̀, kí wọ́n sì parun!
Ìdajì wọn dúró níwájú òkè Ebali bí Mose, iranṣẹ OLUWA, ti pàṣẹ fún wọn pé kí wọ́n ṣe máa súre fún àwọn ọmọ Israẹli.
N jẹ ipo rẹ bi aarẹ ile asofin agba ko ni mu u gbún ẹgbẹ oselu APC lẹẹkan sii?
 ní ibi tí ó bá ti wáyé báyìí owó ẹyọ ni a fi máa ń mọ orí ọpọ ́ n , owó ẹyọ yìí náà ni a fi máa ń tan ìyẹ ̀ ròsùn lójú ọpọ ́ n náà .
Òṣìṣẹ́ Inec Ọ̀jọ̀gbọ́n Tuluen fara gbọta ní Benue A kẹ̀yìn sí Atiku torí àtúntò Nàíjíríà tó fẹ́ ṣe - Árẹ̀wá 2019 Election: Bí Buhari ba le lọ Kóòtù ní ẹ̀ẹ̀mẹ́ta- Obasanjo Leah Sharibu ni wòlíì wa ní àgọ́ Boko Haram - Obìnrin tó jàjàbọ́ Ọjọ Abamẹta ọjọ kẹtalelogun oṣu kẹta ni atundi idibo ọhun waye nipinlẹ Kano.
Idi ni pe wọn ti sun ọjọ ti sinima naa yoo jade siwaju .
Alukoro fun ajọ FRSC, Bisi Kareem to ba BBC sọrọ fidi rẹ mu lẹ pe awọn aṣofin ti ko pada sile le lo nọmba yii laarin ọdun 2015 titi di oṣu kẹfa, ọdun 2019.
Ẹẹdẹgbẹrin eeyan lo ṣeeṣe ko padanu iṣẹ wọn nitori ajakalẹ aarun covid-19, ọtale lugba o din meji awọn eeyan yii lo n ṣiṣẹ nile itura atawọn ile ounjẹ.
Bí ó ti ń rìn káàkiri níbẹ̀, ó rí obinrin kan tí ń wẹ̀, obinrin náà jẹ́ arẹwà gidigidi.
Ìre tí ó sú fún Abrahamu yóo mọ́ ìwọ ati àwọn ọmọ rẹ lórí.
wọ́n ní, “OLUWA pàṣẹ fun yín pé kí ẹ fi gègé pín ilẹ̀ náà fún àwọn eniyan Israẹli.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Kofi Annan: Àkàndá ìbejì to gbọ́ ọ̀pọ̀lọ́pọ̀ èdè, to tún fẹ́ ọmọ Yoruba níyàwó 18 Ògún 2018 Oríṣun àwòrán, MODERNGHANA.
A máa ka òmùgọ̀ pàápàá kún ọlọ́gbọ́n,bí ó bá pa ẹnu rẹ̀ mọ́,olóye ni àwọn eniyan yóo pè é,bí ó bá panu mọ́ tí kò sọ̀rọ̀.
Eeyan 403 tuntun mii lo ṣẹṣẹ lugbadi arun Coronavirus ni Naijiria.
Ìtẹ́lẹ̀ mẹrin mẹrin ló wà ní orígun mẹrẹẹrin àwọn ìtẹ́dìí náà, ẹyọ kan náà ni wọ́n ṣe àwọn ìtẹ́lẹ̀ pẹlu ìtẹ́dìí yìí.
nítorí Ẹ̀mí Mímọ́ kò ì tíì bà lé ẹnikẹ́ni ninu wọn.
Bíótilẹ̀jẹ́pé ọ̀pọ̀ ni kò fẹ́ràn láti máa sọ èdè Yorùbá lẹ́nu mọ́n, dájú-dájú púpọ̀ nínú àwọn wọ̀nyí gbọ́ ọ l’ágbọ̀ọ́yé, wọn kò kàn kí ń sọ ọ́ ni.
Orilẹ-ede Togo lo tẹle e, pẹlu ìdá mọkandinlọgọta, ati South Africa pẹlu ìdá mẹtadinlogoji.
Coronavirus tún ti ṣe ọṣẹ́ lórí iṣẹ́ líla ojú ọ̀nà relùwe láti Eko sí Ibadan - Ìjọba àpapọ̀ Àrùn Coronavirus fa'lẹ̀ya láwọn ìletò aláwọ̀dúdú ní Amẹ́ríkà Lockdown in Nigeria: Kí ni Ààrẹ Buhari yóò fi $30bn owoya tó gbà lọ́wọ́ àjọ IMF ṣe?
Ti ọtẹ yii fẹ dabi eyi to fẹẹ buru julọ fun iyansipo awọn obinrin ninu eto iṣejọba lorilẹede Naijiria.
Ṣugbọn OLUWA sọ fún un pé nítòótọ́, ìfẹ́ ọkàn rẹ̀ ni láti kọ́ ilé fún mi, ó sì dára bẹ́ẹ̀, 
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Kemi Dairo: Iṣẹ́ abẹ nínú ọpọlọ àti ẹ̀rọ ni mo fi ń gbọ́ ọ̀rọ̀ báyìí Oṣu kẹwaa ọdun to kọja ni akanṣe iroyin BBC kan jade to tu aṣiri awọn aṣemaṣe ibalopọ to n wa latọwọ awọn olukọ fasiti ni ile iwe giga fasiti meji pataki kan nilẹ Afirika.
Titun gbogbo ileegbe awọn ọlọpaa kọ ni ibamu pẹlu ilana igbalode.
 Fadeyi ni ""awọn ara ilu ko laṣẹ lati ṣe idajọ lati ọwọ ara wọn, idi niyẹn ti ọlọpaa fi wa laarin ilu."
Nisinsinyii, ẹ fetí sílẹ̀, ẹ̀yin ọmọ mi,ẹ farabalẹ̀ gbọ́ nǹkan tí mò ń sọ.
Huṣai bá pada, ó dé Jerusalẹmu bí Absalomu tí ń wọ ìlú bọ̀ gẹ́lẹ́.
Ó kọjá lọ lẹ́bàá Hesironi títí dé Adari, kí ó tó wá yípo lọ sí ìhà Kaka.
Adegbenro Adebanjo sọ pe awọn n ṣe itọju fun akẹkọọ ti wọn lu ninu fọnran fidio naa.
Bẹ́ẹ̀ ni àfiwé ìfarahàn ògo OLUWA rí.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ademọla Adeleke ni yóò sojú PDP nínú ìbò gómìnà Ọ̀sun Àwọn àwòrán mánigbàgbé nípa ìdìbò abẹnu nipinlẹ Osun Oyetola ni yóò sójú APC nínú ìbò Gómìnà Osun Oríṣun àwòrán, Yemi Akintunde Àkọlé àwòrán, Nisẹ ni awọn alatileyin Ogunbiyi fariga pẹ oun lo jawe olubori ninu idibo abẹnu to waye lopin ọsẹ Àwọn alatilẹyin Akin Ogunbiyi ní, ti ẹgbẹ ba tẹsiwaju láti fà Ademola Adeleke kalẹ gẹgẹ bí Oludije ẹgbẹ PDP nínú ìdìbò Gómìnà ti yoo waye loṣù kẹsán, o ṣé ṣé kí ẹgbẹ náà padanu ipò Gómìnà.
Nítorí náà nígbà tí OLUWA Ọlọrun yín bá fun yín ní ìṣẹ́gun lórí gbogbo àwọn ọ̀tá yín tí wọ́n wà ní àyíká yín, ní ilẹ̀ tí OLUWA Ọlọrun yín fun yín, pípa ni kí ẹ pa àwọn ará Amaleki run lórí ilẹ̀ ayé.
 Awon ni ireti wa fun iran to m bo ni Naijiria.
Bí àkànlù àtakò àti ìjàbọ̀ ṣe ń lọ lọ́wọ́ lórí ayélujára, àpapọ̀ àwọn akẹ́kọ̀ọ́ kan tí gbógun lọ sí ọ́fíìsì ìgbìmọ̀ akẹ́kọ̀ọ́ láti lọ pè fún gbígbé èsì ìdìbò ọ̀hún yẹ̀wò.
Niṣe ni awọn ọdọ Naijiria kan fi ara wọn jin lati maa ṣa awọn idọti lẹyin awọn iwọde lojoojumọ.
Gbígbé nínú ìrètí Lọwọ lọwọ, idunu jina si idile naa nitori wọn ni ko si ẹnikẹni lati ran wọn lọwọ.
” Siba dá a lóhùn pé, “Mo mú àwọn kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ wọnyi wá kí àwọn ìdílé Kabiyesi lè rí nǹkan gùn, mo mú burẹdi, ati èso wọnyi wá kí àwọn ọdọmọkunrin tí wọ́n wà pẹlu rẹ lè rí nǹkan jẹ; ati ọtí waini, kí àwọn tí àárẹ̀ bá mú ninu aṣálẹ̀ lè rí nǹkan mu.
Ẹmẹrin ọtọọtọ ni Joshua ṣubu ṣere ko to gba pe Ruiz lọga nigba ti ija de ipele keje ti Ruiz si gba igbanu mẹta ti Joshua gbe wa.
Aaroni ati àwọn ọmọ rẹ̀ ni yóo jẹ ìyókù, láì fi ìwúkàrà sí i.
Nígbà tí ó mú ife, ó dúpẹ́, ó fi fún wọn, ó ní “Gbogbo yín ẹ mu ninu rẹ̀.
Àwọ̀ Amida dàbí ti ẹja tí ó sì ma ń fa ìnira fun.
Ìrúnú rẹ bò mí mọ́lẹ̀;ẹ̀rù rẹ sì bà mí dójú ikú.
Wọn ì báà ju òmùgọ̀ sinu odó,kí wọn fi ọmọ odó gún un pọ̀ mọ́ ọkà,ẹnìkan kò lè gba ìwà òmùgọ̀ lọ́wọ́ rẹ̀.
Wo nkan ti o ni lati mọ ki o to ṣe ere ere idaraya Kegel O sẹ pataki lati da orisun awọn iṣan naa mọ.
"Àwọn ìròyìn mìíràn tí ẹ lè nífẹ̀ẹ́ sí: Don Jazzy, MrP, Kate Henshaw àtàwọn èèkàn ìlú míràn sọ̀rọ̀ lórí Sẹ́nétọ̀ tó lu obìnrin l'Abuja Jọ̀ọ́, má wé orúkọ mi mọ́ ìjákulẹ̀ tó bá ọ - Seyi Makinde kìlọ̀ fún Lanlẹ́yin Ọwọ́ mi mọ́ lórí eto Gàá darandaran, RUGA- Goodluck Jonathan ""Grandpa àti Uncle mi, ń fipá bá mi lòpọ̀ láti ọmọ ọdún mẹ́rin"" Amọṣa, nigba ti BBC News Yoruba pe agbẹnusọ fun aarẹ, Garba Shehu lati mọ otitọ to wa ninu ọrọ naa, o ni oun gbogbo yoo han kedere sawọn ọmọ Naijiria lẹyin ipade ti igbakeji aarẹ, Yẹmi Oṣibajo n ṣe pẹlawọn gomina nilu Abuja."
Kí wọn tó lọ, wọ́n pín ẹrù tàbí ohun ìní bàbá wọn líifi nnkan kan sílẹ̀ fún àbúro wọn – Ajíbógun.
8 6745 Orilẹede Nicaragua 167 2.
Maurice Paige – Pop Lock ‘N’ Roll
ti ṣagbekalẹ eto iṣuna owo yii niwaju awọn ọmọ ẹgbẹ Ile, o si yẹ ki o
Oríṣun àwòrán, @HQNigerianArmy Ọgagun Aminu Illyasu, tii se agbẹnusọ fun ileesẹ ologun ilẹ wa, ninu atẹjade naa ni iwadi ti fihan pe owo ti awọn ọmọ ẹgbẹ Boko Haram ọhun ba ri nidi katakara ẹja gbigbẹ ni wọn n lo lati fi gbọ bukata ara wọn ati isẹ ibi ti wọn n se.
Ó sọ pé, “Ati fún irú-ọmọ rẹ.
Igbesẹ yii nwaaye lẹyin nkan bii ọdun kan ti minisita feto iroyin, Lai Mohammed ti jẹjẹ wipe ijọba apapọ ko ni da si ohun ti awọn eniyan nsọ lori ikanni ayelujara (social media).
 Gege bi okan lara olugbe agbegbe ti isele naa ti waye,“Gbogbo ohun ini mi ni iji yii ti baje, ibusun, awon abo ounje abbl, ni bayii mi o nibi ti mo le fori pamo si.
Awọn nnkan mii bi ọṣẹ ifọwọ ati oogun ikọ olomi ti ileeṣẹ naa n ṣe si n ta warawara ṣugbọn ọja rọba idaabobo nikan lo wa lẹ.
Ṣùgbọ́n ẹ̀fúùfù náà yóò lágbára gidigidi, nítorí bí àwọn igi ti ń fi orí balẹ̀ náà ni wọn óò tún máa dìde.
Awọn eeyan to le ni miliọnu mẹta abọ lo maa n ṣabẹwo silẹ naa lọdọọdun.
OLUWA ní, “Ìwọ ọmọ eniyan, dojú kọ àwọn ọmọbinrin àwọn eniyan rẹ, tí wọn ń sọ àsọtẹ́lẹ̀ ti ọkàn wọn.
Àkọlé àwòrán, Sùgbọ́n Afẹnifẹre ni ẹgbẹ́ ẹnu méjèèjì ni Tinubu fi ń sọ̀rọ̀ àti pé ọ̀rọ̀ rẹ̀ ko ni arígbámu kankan nínú.
Lati jẹ anfaani yi, eeyan gbọdọ jẹ ẹni ọdun mejidinlogun si marundinlogoji.
Èyí ni àgbèrè tìrẹ fi yàtọ̀ sí ti àwọn ẹlòmíràn.
Ogbeni Iliev, ti isakoso bi atunse yoo se ba papa isere ohun wa lowo re, salaye fun gomina Simon Lalong pe, iyara itunra se(dressing room), awon aga ijoko(the seats), awon iyara igbonse, baluwe abbl ni gbogbo re yoo ti wa ni tuntun se ki o to di inu osu karun-un ohun.
Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi
Ṣugbọn láti ìgbà èwe wa ni ohun ìtìjú yìíti pa gbogbo ohun tí àwọn baba ńlá wa ṣiṣẹ́ fún run:ẹran ọ̀sìn wọn, ati agbo mààlúù wọn,àwọn ọmọ wọn lọkunrin ati lobinrin.
APC àti PDP takora wọn lórí Olùsirò owó àgba Ọsun tó fisẹ́ sílẹ̀
Iko agbaboolu FC Barcelona lo soro ohun di mimo lori ero ayelujara won.
Abọ iwadii naa fihan pe idunnu ti pọ si ni Naijiria ju ti tẹlẹ lọ.
Ohun tí ẹ̀tọ́ wí ni pé, kí á fi ẹ̀mí dípò ẹ̀mí.
Gift tí wọn gbìyàjú àti jà lólè sàlàyé pé wọn yọ ààké sí oun láti orí ọ̀kadà tí wọn wà sùgbọ́n ariwo tí oun pa ló mú kí àwọn ọlọ́pàá RRS tó wà ní láyípò náà lé wọ tí wọn si gba fóònù fún oun.
Idi ti Roland fi di ọmọ ẹgbẹ Buccaneer Ipinu Roland lati di ọmọ ẹgbẹ okunkun ko sẹyin pe wọn yoo daaboboo ni fasiti rẹ to wa ni ẹkun ila oorun Naijiria.
O fikun un pe ohun ti awọn ajnigbe naa ṣe ni pe wọn yinbọn lu ọkọ naa, titi ti ko fi le rin mọ, ki wọn to wa ji wọn gbe.
Sanwo-Olu: Àtàrí Àjànàkú ni àkóso Eko, kì í ṣe ẹrù ọmọdé
I Language Centre: Yorùbá ló làṣà àti èdè Bakan naa ni o lọ si ile iwe Queens College, ni ilu Eko, laarin ọdun 1949 si 1953.
Alexis Sanchez lóun kò kabamọ ìgbà tóun ló ní Man United
Sanusi: Ìyọnípò mi kò ṣẹ̀yìn Ọlọ́run Èyí ni àwọn ìdí tí ìjọba ìpínlẹ̀ Kano ṣe rọ Emir Sanusi Lamido l'óyè Ìròyìn Yàjóyàjó - Nàìjíríà kéde èèyàn míràn pẹ̀lúu àrùn Coronavirus Ànọ́bì ni màá tẹ́lè.
Bakan naa ni agbẹnusọ un ileeṣẹ ọlọpaa nipinlẹ Kaduna, ASP Mohammed Jagile sọ pe lootọ ni.
Kíni à ń pè ní ọ̀rọ̀ ajé dẹnu kọlẹ̀ (Reccession) Ọrọ̀ ajé dẹnukọlẹ̀ ti àwọn ǹkan ti orílẹ̀-èdè ń pèsè fún títà (GDP) kò bá ko ba kún ojú oṣùwọ̀n dáadáa fún oṣù mẹ́rín -mẹ́rìn tẹ̀lé ara wọn.
Sarai Bareman, ti o je osise ajo FIFA ati akegbe re Rhiannon Martin ni won yoo jo maa sakoso iyikoto ohun.
Ẹrọ ayélujára sí ti sọ pe wọn ni ki oṣiṣẹ wọn maa jẹ aayan tí wọn kò bá ba afojusun idiyele ọja wọn Wàhálà bẹ́ sílẹ̀ láàrin àwọn ọlọ́jà ni Ògùnpa, Ìbàdàn Èrò àwọn ọmọ Nàìjíríà ṣọ̀tọ̀ọ̀tọ̀ lóri oúnjẹ #3.
The Platinum Award, aare ajo FIFA Infantino.
Ẹgbẹ oṣiṣẹ eleto ilera marun un lo wa labẹ ẹgbẹ oṣiṣẹ JOHESU.
Ṣugbọn bí àwọn olórí alufaa ati àwọn àgbà ti ń fi ẹ̀sùn kàn án tó, kò fèsì rárá.
O si maa mu ilu to ni alaafia wa.
NHIS: Aarẹ Buhari da Usman Yusuf pada s'ipo gẹgẹ bi akowe eto ilera
Ipinlẹ Eko ati Osun ni iha Guusu-Iwọ Oorun ti ni awọn ileewe yoo di ṣiṣi lọjọ kẹrinla ati ikọkanlelogun oṣu kẹsan ọdun 2020.
Ọ̀dá owó ṣèdíwọ́ fún Blarabe Musa láti tẹ ìwé ìpolongo ìbò ààrẹ ní 2003 Wọ́n dajọ́ ikú fún òṣeré Kannywood Rahama Sadau, eré àbí òótọ́?
A ti lu àwọn ọmọ ogun wọn bolẹ̀,wọ́n sì ń sálọ pẹlu ìkánjú;wọn kò bojú wẹ̀yìn, ìpayà yí wọn ká!
Osun State Elections: Ilé ẹjọ́ sún ìgbẹ́jọ́ Adeleke síwájú
"Ìyá àádọ́rin ọdún sọ bí ọkùnrin ọdún márùndínlọ́gbọ̀n ṣe fipá bá òun lòpọ̀ Afipábánilòpọ̀ méjì tún ṣọṣẹ́ lára ọmọ ọdún 17 l'Ekiti Ọmọ pupa làwọn olólùfẹ́ wa fẹ́ wò nínú fíìmù làwọn òṣèré tíátà fi ń bóra- Muka Ray Olorì Anu Adeyemi ń ṣe ọjọ ìbí, ẹ gbọ́ ǹkan tò sọ sí Kábíyésì Nǹkan oṣù obìnrin le jáde ní imú tàbí ìdodo yàtọ̀ sí ojú ara - Dókítà ""Okodoro ọrọ ni Umar sọ kalẹ yii lai si iwa imọtaraẹni nìkan nibẹ, ti ẹnu si ya mi pe iru iwa bayii n sẹlẹ."
Jìnnìjìnnì bo gbogbo ilẹ̀ náà,wọ́n wà ninu ìrora,nítorí pé OLUWA kò yí ìpinnu rẹ̀ lórí Babiloni pada,láti sọ ilẹ̀ náà di ahoro,láìsí ẹnìkan kan ninu rẹ̀ mọ́.
Nígbà tí ẹ bá dé ilẹ̀ tí mò ń mu yín lọ, 
Studies) ni agbegbe  aafin ọba  Shehu  Borno ,ni eyi ti o ni ibudo idibo  mẹ́wàá ti awon  oludibo  ti o foruko sile si  le ni  egberun márùndínláàdọ́ta.
Má sọ pé, “Bí lágbájá ti ṣe sí mi,bẹ́ẹ̀ ni èmi náà yóo ṣe sí i,n óo san ẹ̀san ohun tí ó ṣe fún un.
Ṣugbọn yóo pinnu ní ọkàn rẹ̀ láti gbógun ti majẹmu mímọ́ Ọlọrun ati Israẹli.
Anthony Obiagbaoso Enukeme: Àkójọpọ̀ àwòrán àràǹbarà nípa ìsìnkú ọlọ́rọ̀ ọmọ Nàíjíríà
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Emir of Kano: Èyí ni àwọn ohun márùn ún tó yẹ kí o mọ̀ nípa Sanusi tí wọ́n yọ nípò Emir 10 Ẹrẹ̀nà 2020 Oríṣun àwòrán, @ayemojubar Ọjọ Aje, ọjọ kẹsan an oṣu Kẹta ọdun 2020 ni ijọba ipinlẹ Kano yọ Sanusi Lamido Sanusi nipo gẹgẹ bi Emir ilu Kano, lẹyin ede ayede to waye laarin rẹ atiu ijọba ipinlẹ naa.
Wọn kì í jẹ ìrora kankan,ara wọn dá pé, ó sì jọ̀lọ̀.
Oríṣìíríṣìí iṣẹ́ iranṣẹ ni ó wà, ṣugbọn Oluwa kan náà ni à ń sìn.
Ọlọ́rọ̀ gbọ́n lójú ara rẹ̀,ṣugbọn talaka tí ó gbọ́n yóo rídìí rẹ̀.
Ọ̀rọ̀ ìbàjẹ́ kankan kò gbọdọ̀ ti ẹnu yín jáde.
Bí ó ti ń rò ó pé kí ni ìtumọ̀ ohun tí òun rí yìí, àwọn tí Kọniliu rán sí i ti wádìí ibi tí ilé Simoni wà, wọ́n ti dé ẹnu ọ̀nà.
Àwọn ará Afimu ni wọ́n ti ń gbé àwọn ìletò tí wọ́n wà títí dé Gasa tẹ́lẹ̀ rí, ṣugbọn àwọn kan tí wọ́n wá láti Kafitori ni wọ́n pa wọ́n run, tí wọ́n sì tẹ̀dó sí ilẹ̀ wọn.
Bí ó ti ń lọ lórí kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ rẹ̀ pẹlu àwọn iranṣẹ rẹ̀ meji, angẹli OLUWA dúró ní ojú ọ̀nà rẹ̀ ó dínà fún un.
Nítorí orílẹ̀-èdè yóo dìde sí orílẹ̀-èdè; ìjọba yóo dìde sí ìjọba.
Godwin Obaseki ti darapọ̀ mọ́ ẹgbẹ́ òṣèlú People's Democratic Party Oríṣun àwòrán, Others Àkọlé àwòrán, Edo state news: Godwin Obaseki ti darapọ̀ mọ́ ẹgbẹ́ òṣèlú PDP Gómìnà ìpínlẹ̀ Edo Godwin Obaseki ti kúrò ní ẹgbẹ́ òṣèlú All Progressive Party lọ si ẹgbẹ́ òṣèlú People's Democratic Party.
Fun apẹrẹ, olorin ọmọ Naijiria mii ti wọn mọ si Runtown toun naa lero lẹyin loju opo ayelujara naa wa lara awọn to n ṣagbatẹru iwọde yii.
’ rèé Afọnja, ẹni tó finú wénú ní Ilọrin, àmọ́ tó jẹ iwọ Ẹfunsetan Aniwura, obìnrin tó ju ọkùnrin lọ Ọ̀rọ̀ǹpọ̀tọ̀niyùn, Aláàfin obìnrin àkọ́kọ́ rèé, tó ní nǹkan ọkùnrin Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Iya Adura Esther Ajayi sọ àṣírí owó rẹ̀ tó fi ń ṣàánú Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Ninu atẹjade kan to fi s'ita, ileeṣẹ ipọnpo rọbi Eni ni o da awọn loju wipe eto idajọ yoo fi idi ootọ mulẹ wipe ọwọ awọn mọ.
Mourinho n gbe ni ilu London, ti o si ti gba ami ẹyẹ Premier League mẹta ati FA Cup pẹlu ikọ Chelsea, bẹẹ lo si gba Europa League and Carabao Cup pẹlu ikọ Manchester United.
Oríṣun àwòrán, Ogun State Governor's office Àkọlé àwòrán, Ipinlẹ Ogun lo maa n gbalejo awọn aṣoju ati akopa lati orilẹede bii mẹtalelogun kaakiri ilẹ Afirika.
Minisita fun iroyin ati aṣa, Alhaji Lai Mohammed sọ ninu atẹjade kan pe bawọn ọmọ Naijiria kan ti fi ibinu kọlu awọn ileeṣẹ to jẹ ti orilẹede South Africa lọjọ Iṣẹgun ku diẹ kaato.
Coronavirus tún ti ṣe ọṣẹ́ lórí iṣẹ́ líla ojú ọ̀nà relùwe láti Eko sí Ibadan - Ìjọba àpapọ̀ Àrùn Coronavirus fa'lẹ̀ya láwọn ìletò aláwọ̀dúdú ní Amẹ́ríkà Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí kan sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
Àwọn aláìgbọ́n kú nítorí pé wọn kò gba ẹ̀kọ́aibikita àwọn òmùgọ̀ ni yóo pa wọ́n run.
Funke Olakunrin Burial: Ọ̀gọ̀rọ̀ èèyàn péjú síbi ìṣẹ̀yẹ ìkẹyìn f'ẹ́ni re tó lọ
Awọn irufẹ oyin ti wọn fẹran ilaagun bayii maa n saaba ba si ara eniyan lati la ilaagun ara wọn ni.
“Ìwọ ní tìrẹ, Israẹli iranṣẹ mi, Jakọbu, ìwọ tí mo ti yàn,ọmọ bíbí inú Abrahamu, ọ̀rẹ́ mi.
Drone àti CCTV ni yóò máa ṣọ́ ọ̀pọ̀ igbó tó wà nílẹ̀ Yorùbá - Ooni Iṣọla Oyenusi rèé, ẹnití ìfẹ́ obìnrin ṣun dé ìwà ìdigunjalè Taiwo Akinkunmi, ọmọ Ibadan tó ya àsìá Naijiria Ayinla Ọmọwura, orin èébú àti oríyìn lo fi di ọ̀rẹ́ àwọ̀n obìnrin ''Wàhálà Ikẹja ló sọ mí di oníṣẹ́ ọwọ́ àgbọn ní Badagry'' Aarẹ Donald Trump ẹwẹ naa wa nilu Jamestown nipinlẹ Virginia lọsẹ yii lati bawọn sami irinwo ọdun ti ijọba awa ara wa lati ipasẹ awọn asoju bẹrẹ lagbegbe naa.
Onidajọ Oluṣẹgun Oduṣọla ni idajọ ododo loun wa fun nitori naa agbẹjọro yoowu to ba fẹ daṣọ bo otitọ lori ẹjọ naa lee kan idin ninu iyọ nitori oun ko ni faye gba irufẹ igbesẹ bẹẹ.
- Kemi Afolabi Awọn Yoruba man fi ìgbá si i, bẹẹ ni awọn Igbo ma n fi efirin tabi ẹfọ ugwu si i, ko le ni orun didun.
Italy da ọ̀pọ̀ Aláboyún àt'àwọn arìnrìnàjò obinrin padà níbodè
asobode lati se ise won ni agbegbe naa.
Ní ìkẹyìn, iná ni a óo dá sun ún.
Ìyè wà ninu ojurere ọba,ojurere rẹ̀ sì dàbí ṣíṣú òjò ní àkókò òjò àkọ́rọ̀.
Ó bá pa ìwé náà dé, ó fi í fún olùtọ́jú ilé ìpàdé, ó bá jókòó.
Ẹ̀yin ẹ wo àwòrán kọfí tí mo yà ní ìjẹta.
Musa fikun pe, lootọ ni ileesẹ ologun ilẹ wa yoo fi awọn ọmọ ogun sọwọ fun eto aabo to peye lasiko eto idibo naa, amọ wọn ko ni duro sawọn agọ idibo gangan bikose awọn agbegbe to sun mọ ibẹ.
Oruko awon olukopa ohun ni: Faith Obazuaye, Nasiru Bello, Tajudeen Agunbiade ati Olufemi Alabi ti akonimoogba won si n je, Anderson Bankole, leni ti o n tuko boolu ori tabili awon abarapa lorile-ede Naijiria.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù APC fun ijọba ipinlẹ lagbara fun isakoso ohun alumọọni 26 Sẹ́rẹ́ 2018 Oríṣun àwòrán, @elrufai Àkọlé àwòrán, Ẹgbẹ APC n tiraka lati se atunto Naijiria Igbimọ to wa fun agbeyewo ilana aparo kan ko ga ju ọkan lọ ati agbeyẹwo ilẹ Naijiria, ti ẹgbẹ oselu APC gbe kalẹ, eyiti Gomina ipinlẹ Kaduna, Mallam Nasir El-Rufai ko sodi ti gbe abọ iwadi rẹ kalẹ.
Jeroboamu ya ọjọ́ kẹẹdogun oṣù kẹjọ sọ́tọ̀ fún àjọ̀dún, gẹ́gẹ́ bí àjọ̀dún ilẹ̀ Juda, ó sì rúbọ lórí pẹpẹ sí akọ mààlúù tí ó fi wúrà ṣe ní ìlú Bẹtẹli.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù #BBCOGUNDEBATE: Ìjọba mi yóo dé gbogbo ẹsẹ̀kùkú àti ìgbèríko -Akinlade 8 Èrèlè 2019 Àkọlé àwòrán, #BBCOGUNDEBATE: O ṣe pataki láti yan àwọn akanda ẹda si ipò kọmisọna.
Oluwa yóo tọ́ ọkàn yín láti mọ ìfẹ́ Ọlọrun ati ohun tí Kristi faradà nítorí yín.
Ẹgbẹ́ òṣèlú PDP ní ìpínlẹ̀ Bayelsa jáwé olúbori nínú ìdìbò ìjọba ìbílẹ̀ Jesu orí ayélujára kan rèé tó wa fun isoji ni Afirika Drone àti CCTV ni yóò máa ṣọ́ ọ̀pọ̀ igbó tó wà nílẹ̀ Yorùbá - Ooni Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Cancer: Àṣe ara mi ni iso ti n run gbogbo bí mo ṣe n ṣèrànwọ́ lórí jẹjẹrẹ Ọ̀pọ̀ èèyàn tó kú láti ipase àrùn òtútù aya lo wà láàrin ọmọ oojọ́ si ọdún márùn-ún, pelu awon arúgbó.
Àkọlé àwòrán, Ikogosi ni ipinlẹ Ekiti jẹ ọkan lara awọn ibudo igbafẹ towa nilẹ Yoruba nibiti ọpọlọpọ awọn arinrinajo maa n ṣe abẹwo si lojoojumọ Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ere okunrin kan ton fo okuta ni oju ona adugbo Oke Aregba ni igboro Abeokuta, ni ipinlẹ Ogun Àkọlé àwòrán, Awọn eniyan kii pa ẹja ni Odo Erin nilu Ẹrijiyan Ekiti nitori igbagbọ wipe ẹja inu odo yi, kii jina bi o tile wu ki wọn se e to Àkọlé àwòrán, Omi arinta oni ipele meje wa nilu Ipọle-iIoro-Ekiti.
Yóo fún ọ ní ọpọlọpọ ìgbàlà, ati ọgbọ́n, ati ìmọ̀,ìbẹ̀rù OLUWA ni ìṣúra rẹ̀.
chabas kọ ́ kọ ́ lọ sí united states ní ọdún 1914 fún abala ìyàwòrán kan .
Káàkàkiiri àgbáyé ni àwọn ènìyàn ti rin ìrìnkèrindò dé Aquae Sulis pé kí àwọn lè rí ìwòsàn.
Eni ti o se ipo kini ninu idije ọun ni Abraham Kiprotich ti o jẹ ọmọbibi ilẹ Faranse sugbọn ti o n soju orilẹede Kenya.
Ọ̀rọ̀ ìkẹyìn Dafidi nìyí; àní, ọ̀rọ̀ ìjìnlẹ̀ Dafidi, ọmọ Jese, tí a gbé ga ní Israẹli, ẹni àmì òróró Ọlọrun Jakọbu, olórin dídùn ní Israẹli:
"O ni ""ọpọ ẹmi alaiṣẹ lo ti ṣofo, nitori ọwọ lile ati ọna aitọ ti awọn ọlọpaa fi n ṣiṣẹ wọn."
Yẹ ibomu-bẹnu naa wo boya ko ni aleebu kankan tabi ya.
Osinbajo: Igbákejì ààrẹ Yemi Osinbajo ni ìwà àjẹbánu lẹ́nu iṣẹ́ ọba ló le jù nínú ìṣòro Nàìjíríà
Ó wa àwọn ènìyàn burúkú ti wọ́n wádìí tí wọ́n sì ti mọ ibi tí ọmọ rẹ̀ ń gbé.
Ìwọ ni mo fi lu ẹṣin ati ẹni tí ń gùn ún pa;ìwọ ni mo fi wó kẹ̀kẹ́ ogun ati àwọn tí ń bẹ ninu wọn.
Auxiliary ń ní wá lára pẹ̀lú gbígba owó aitọ, a ń ko ọkọ̀ wa kúrò lójú pópó - Awakọ èrò Ayẹwò kò dáwọ́ dúro botílẹ̀ jẹ́ pé èròjà ayẹwò (Reagents) kò si mọ́ Ayinla Ọmọwura, orin èébú àti oríyìn lo fi di ọ̀rẹ́ àwọ̀n obìnrin Ọwọ́jà coronavirus yóò ṣì wà pẹ̀lú àgbáyé fún ìgbà pípẹ́- Ngozi Okonjo-Iweala Ewẹ o ti wa ni ile iwosan kan ni Dubai to ti n gba itọju ti iya ati ọmọ tuntun naa si wa lalaafia.
Àwọn onírẹ̀lẹ̀ yóo rí i,inú wọn yóo dùn;ẹ̀yin tí ẹ̀ ń wá Ọlọrun, ẹ jẹ́ kí ọkàn yín sọjí.
Bí Maria ti gbọ́, ó dìde kíá, ó bá lọ sọ́dọ̀ Jesu.
Awọn mẹjọ naa si ti wa ni ihamọ nitori ọrọ wọn ti de ile ẹjọ.
Oga agba fun ile-ise omo-ogun, ogagun Tukur Yusufu Buratai, awon oga agba miiran nile-ise omo ogun ohun ati awon ti won ba tun fi iwe pe, nireti wa pe won yoo wa nikale lojo na.
ENDSARS, End SWAT: Gomina Obiano yọ ọ̀gá ikọ̀ SARS nípò
" A ma n da ara wa mọ laarin eero.
OLUWA tìkararẹ̀ ni ó ti ká ọ lọ́wọ́ kò láti má ta ẹ̀jẹ̀ sílẹ̀ ati láti má gbẹ̀san.
BURKINA FASO: Ofẹ ni iwe igbelu orilẹ ede yii ti o wa ni Iwọ Oorun Alawọ dudu.
Ó pa ẹran ẹbọ sísun, àwọn ọmọ rẹ̀ sì gbé ẹ̀jẹ̀ rẹ̀ tọ̀ ọ́ lọ, ó sì dà á sí ara pẹpẹ yípo.
Òyìnbó ẹni ọdún 46 wá ṣe mọ̀'mí n mọ̀ ọ́ ní Kano pẹ̀lú Isah olólùfẹ́ rẹ̀ Ìlẹ̀kẹ̀ ìdí mi ló kó mi yọ lọ́wọ́ àwọn afipábánilòpọ̀ ní Lebanon 'Ẹ yé pè wá ní NEPA mọ́ tí ẹ bá fẹ́ ká fún yín ní iná, DisCos ni wá' Ọwọ́ ọlọ́pàá tẹ afurasí tó ní òun ló jí ọmọ gbé láti parọ́ mọ́ pásítọ̀ ìjọ Sotitobire Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, O leè má mọ̀ bóyá o ní àrùn HIV/AIDS o!
Olugbenga Ashafa, to je alaga igbimo eto irinna nile naa safikun soro Saraki pe ise irinna naa de Onitsha si Aba; ilu meji to kun fun karakata julo ni ekun guusu ila oorun Naijiria.
Amọ, igbesẹ rẹ yii ko dun mọ awọn afẹhọnuhan ninu nitori wọn ri gẹgẹ bi ọkan gboogi ninu awọn ti wọn n wo bi awokọṣe ni awujọ.
Ọdun ń lọ sópin, ariwo 'ń sọ̀ ní ilé ńlá l'Abuja Ẹjọ́ Sowore bọ́ sọnù lọ́wọ́ àjọ DSS Ẹ́ wo ojú àwọn òṣèré tíátà tó péjú sí Ibadan fún ìpàdé ọlọ́dọọdún Ìtàn Àrọ̀gìdìgbà jẹ́ kí ń rò pé bàbá mi yan Yemọ̀ja ní àlè - Ọmọ Fagunwa Inu ibanujẹ ni ọkọ afẹsọna naa wa, ti ko si le ba ẹnikẹni sọrọ lori ẹrọ ibaraẹnisọrọ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Akure Kidnap: Àwọn abiyamọ fẹ̀hónúhàn lórí ọmọ tí wan jígbé nílé ìjọsìn Akurẹ Ọpọlọpọ lo ti fẹhonu han lori ọ̀rọ̀ yii nigba ti wn ko ri ki ohunkohun ṣẹlẹ lati igba ti iya ọmọ ti figbe ta.
Ẹ ṣe orí kunkun sí àṣẹ OLUWA Ọlọrun yín, ẹ kò gbà á gbọ́, ẹ kò sì tẹ̀lé ọ̀rọ̀ rẹ̀.
Iroyin sọ pe, oniruuru ohun ija bii apola igi ati ogun abẹnugọngọ ni awọn janduku naa ko da ni ti wọn si n kọlu ẹnikẹni ti wọn ba ri to wọ aṣọ alawọ rẹsurẹsu , iyẹn awọ ti wọn mọ mọ awọn ololufẹ Dapọ Abiọdun, oludije ipo gomina ni ipinlẹ Ogun.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù #TUNNGR: Ẹyẹ j’ẹyẹ lọ!
Agbẹjọ́rò Maina yọ ọwọ́ kúrò nínú ìgbẹ́jọ́, Ó lóun kò ṣé mọ̀ Lootọ ọrọ Bill Gates ko ba pọ ju ọrọ rẹ lọ kani ki i ṣe ti itọrẹ aanu ti Bill Gates n ṣe kaakiri agbaye.
Ọwọ́ ọlọ́pàá ti tẹ afurasí mẹ́ta tó lọ́wọ́ nínú ìjínigbé alága Iganna l'Oyo A ó ṣèrànwọ́ fáwọn ẹbí ọlọ́pàá tó bá rògbòdìyàn EndSARS lọ láti inú N500m tí a yà sọ́tọ̀- Makinde Wo ọ̀nà àbáyọ fún àwọn akẹ́kọ̀ọ́ tí àjọ WAEC gbẹ́sẹ̀ lé èsì ìdánwò wọn Èmi kọ́ ló pàṣẹ fún àwọn sọ́jà láti má a pa èèyàn ní Oyigbo - Nyesom Wike Ni nnkan bi ọjọ diẹ si idibo naa ni arun Covid-19 lekenka si l'Amẹrika, eyii to mu Biden sọ ninu ọkan lara ipolongo rẹ pe Trump ti kuna nipa eto ilera ilẹ Amẹrika.
Ẹ fi mí sílẹ̀,nítorí ọjọ́ ayé mi dàbí èémí lásán.
Ọpọlọpọ wọn ló kan sadankata sigbakeji aarẹ pé o ṣiṣẹ silu Ikenne bii kikọ ọja tuntun, lila gọta, kikọ ile iwe.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìsẹ̀lẹ̀ jákèjádò orílẹ̀èdè àgbáyé láàárín ìṣẹ́jú kan Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Ìsẹ̀lẹ̀ jákèjádò orílẹ̀èdè àgbáyé láàárín ìṣẹ́jú kan 27 Agẹmo 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn wákàtí 5 sẹ́yìn Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kan Èyí tí a wò jùlọ 5:03 Fídíò, Omolola Arohunmolase Welder: Mo ti fí iṣẹ́ 'Welder' gbayì láwùjọ, tó mo fi tọ́ ọmọ yanjú, Duration 5,039 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 5:39 Fídíò, Akomolede ati Asa lori BBC: Olùkọ́ Kikelomo Ogunboye tan ìmọ́lẹ̀ sí ìwà olè ọ̀gá ọlọ́pàá Audu gẹ́gẹ́ bí àwòkọ́ṣe àsìkò yìí, Duration 5,398 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 4:11 Fídíò, Oba Adeyeye Ogunwusi: Ojú mi ti rí lọ́pọ̀ lọpọ̀, ọ̀pọ̀ èèyàn ni kò tilẹ̀ gbàgbọ́ pé mo lè jọba- Ooni, Duration 4,117 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 4:43 Fídíò, Promise Akinlade: ọmọ ọdún mọ́kànlá tó ń fi ìlù dárà bíi àgbàlagbà sọ̀rọ̀ nípa tálẹ́ǹtì rẹ̀, Duration 4,437 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 0:59 Gbọ́, Ìsẹ̀lẹ̀ jákèjádò orílẹ̀èdè àgbáyé láàárín ìṣẹ́jú kan, Duration 0,59wákàtí 5 sẹ́yìn 7:03 Fídíò, Olumuyiwa Bolade Adedeji Military Bruitality: Bí arákùnrin onípèníjà ara tí sọ́jà lù ṣe dé, Duration 7,035 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 4:45 Fídíò, Yoruba Films: Ẹ̀ẹ́ bẹ̀ mi kúrò láyé ni, mi ò lè kú - Fadeyi Oloro, Duration 4,4526 Èrèlè 2020 2:48 Fídíò, Esther Ajayi: Èmi náà ti borí ìṣòro rí ló ń mu mi ṣojú àánú, Duration 2,481 Ògún 2019 6:08 Fídíò, Adebola Ademilua: Àìrísẹ́ ṣè lẹ́yìn ìwé kíkà ló sọ mi dí ìyá onírú, mo dúpẹ́ tèmi, Duration 6,0827 Bélú 2020 2:36 Fídíò, Sotitobire: Ìdájọ́ òdòdò ló fẹsẹ̀ múlẹ̀ lórí ọ̀rọ̀ Pásítọ̀ Sotitobire - Agbẹjọ́rò fún ìjọba, Duration 2,367 Ọ̀wàrà 2020 BBC News, Yorùbá Ìdí tí ẹ fi le è nígbàagbọ́ nínú ìròyìn BBC Ìlànà Lílò Nípa BBC Òfin Àṣírí Cookies Kàn sí.
Oríṣun àwòrán, @RotimiAkeredolu Àkọlé àwòrán, Kọmisọnna fún ètò ìsúná nípínlẹ̀ Ondo ní pé òkun tó jìn jùlọ ní ilẹ̀ Afirika àti bitumen wà nì ìpínlẹ̀ Ondo.
January 7, 2018 Akẹkọ meji ku lọwọ awọn oṣiṣẹ́ alaabo lasiko iwọde ni Kaduna, Ila Oorun ariwa Naijiria.
Ninu awọn nkan to sọnu ninu ere sinima ode oni, o sọ pe ti a baa n tiraka lati sọ itan oyinbo fun oyinbo, a ko le tẹsiwaju.
Ìlẹ̀kùn mẹta wà ní ìhà ìlà oòrùn, mẹta wà ní ìhà àríwá, mẹta wà ni ìhà gúsù, mẹta wà ní ìhà ìwọ̀ oòrùn.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Pope Election: Èyí ni bí wọ́n ṣe n dìbò yan Póópù tuntun nínú ìjọ Àgùdà 25 Ọ̀pẹ̀̀ 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ilekun ile mimọ ti awọn eeyan ti n jọsin Igbimọ awọn cardinal wa to maa n pejọpọ lati dibo yan Poopu tuntun.
Awon olori orile-ede merindinlaadota lo kopa ninu ipade naa ti awon yoku si je minisita fun oro ile okeere lorile-ede won.
Wolii Sotitobire atawọn ọmọ ijọ rẹ mẹfa miran dẹni to n kawọ pọn tojọ niwaju adajọ lẹyin ti ọmọ ọdun kan, Kolawole Gold, dede poora ninu ijọ rẹ lopin ọdun 2019.
A ko le sọ pato boya anfaani wa tabi ko si ninu yiyan ọkọ abi aya lori ayelujara nitori iriri onikaluku se ọtọọtọ.
Ẹni to bori: Nigeria Côte d'Ivoire vs Algeria.
Ṣugbọn iṣẹlẹ yii kan mu ki ohun gbogbo lọju pọ loju awọn ara Harare ni.
Àkeekèé jókòó láàrin àwọn kòkòrò, ó ti fi oró pamọ́ sílé.
Saulu ń wá a lojoojumọ láti pa á, ṣugbọn Ọlọrun kò fi Dafidi lé e lọ́wọ́.
Saraki ni tori ọrọ yi ni Ile Igbimọ Aṣofin agba ṣe kó awọn ti ọrọ naa kan jọ ni Ipinle Kano ni osu Kejila odun 2017.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ekiti Assembly: Ilé ìgbìmọ̀ aṣòfin júwe ilé fáwọn alága ìjọba ìbílẹ̀ 18 Ọ̀pẹ̀̀ 2018 Oríṣun àwòrán, Ekiti@official Àkọlé àwòrán, Ekiti Assembly: Ilé ìgbìmọ̀ aṣòfin júwe ilé fáwọn alága ìjọba ìbílẹ̀ Ilé ìgbìmọ aṣòfin ìpínlẹ̀ Ekiti tí fún àwọn alága ìjọba ìbílẹ̀ mẹ́rẹ̀rìndílógún, awọn kansẹlọ mẹ́tàdínlọ́gọ́sàn àtí àwọn èèkàn olóṣèlú níjọba ìbílẹ̀ ní ìwé ló rókún níle aláìní gbèdéke nítori ẹ̀sùn níná owó ìjọba ìbílẹ̀ mákumaku.
Arsenal náà laná bí Manchester United Goolu Mẹrin labala kini Abala ikini ifẹsẹwọnsẹ naa ko dẹrun rara.
 ""Ajimọbi wọ ọrun rere, o si wa pẹlu Ọlọrun bayii."
O fikun wi pe, awọn ajinigbe naa ko i ti i kan si ẹbi ati ara ẹni ti wọn jigbe.
Ifetosọmọbibi: Idẹyẹ si gẹgẹ bi obinrin ni wọn ti fihan wi pe oun ṣe akoba fun ifeto si ọmọ bibi lorilẹede Naijiria.
Oríṣun àwòrán, Wizkid official Àkọlé àwòrán, Gbajugbaja olorin takasufe ni Wizkid, to si ti ṣe àwọn ori to mìlú titi jáde Oríṣun àwòrán, Wizkidofficial Àkọlé àwòrán, Awọn ìmúra tó dá orí ayélujára rú jùlọ lọ́dún 2018 EfCC I'M HERE Òkan gbòógì ní yìí bakan náà lásìkò ti àjọ EFCC pé gómìnà àná ní ìpínlẹ̀ Ekiti, Ayọdele Fayoṣe láti wa wi ti ẹnu rẹ̀ to ba ti kúrò nípò gẹ́gẹ́ bii gómìnà.
Ilu Abu Dhabi, United Arab Emirates lawọn mejeeji yoo ti waako lọjọ Aiku.
Lọwọ ti a wa yii, Naira Marley ti fẹ di oriṣa akunlẹbọ fun ọpọlọpọ awọn ọdọ.
Adajo ana fun ipinle Kwara, Idris Haroon ni yoo je alaga egbe tuntun ohun, eyi abenugan ile-igbimo asofin agba se onigbonwo re.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Drivers lincense renewal: Ẹgbẹ̀lẹ́gẹ̀ àwakọ ló ń lo iwé ìrinà ọ̀kọ̀ tí kò koju oṣùwọn- FRSC 16 Èbibi 2019 Oríṣun àwòrán, Pius Utomi Ekpei Àkọlé àwòrán, Operation show your drivers license: Ẹgbẹ̀lẹ́gẹ̀ àwakọ ló ń lo iwé ìrinà ọ̀kọ̀ tí kò koju oṣùwọn- FRSC Àjọ ẹsọ ojú pópó ní orílẹ̀-èdè Nàìjíríà (FRSC), ẹ̀ka ti ìpínlẹ̀ Eko sọ pé ẹgbẹgbẹrún ọ̀pọ̀ àwọn awakọ ní ìpínlẹ̀ Eko kò lo ojúlówó ìwé àṣẹ ìrina awakọ, yálà iwe ti wọn gbà lásiko ti wọn kọ ẹkọ́ móto tan lo wà lọ́wọ́ ọ̀pọ̀lọpọ̀ àwọn awakọ.
Kolawole ni awọn oṣere tiata ti awọn eeyan n wo bi aṣaaju ni wọn n gbe ẹtẹ ara wọn sode lori ẹrọ ayelujara, ti ko si yẹ ko ri bẹẹ.
Gbogbo àwọn eniyan Israẹli bá ṣe bí àṣẹ tí OLUWA pa fún Mose ati Aaroni.
 Àwọn ènìyàn tí ó tó 30,000 ni ó ní àrùn náà báyìí , pẹ ̀ lú àkóràn 7000 titun ní ọdún 2012 .
”Alexey Shebarshin  tun salaye pe“Mo ni ireti pe ife ẹyẹ agbaye ti yoo waye lorile ede Russia yoo je ki opolopo orile ede wa si Russia , yoo tun  tubo je ki ibasepo to dan monran wa laarin Russia ati  awon orile ede naa.
Solomoni dá Ọlọrun lóhùn, ó ní “O ti fi ìfẹ́ ńlá tí kìí yẹ̀ han Dafidi, baba mi, o sì ti fi mí jọba nípò rẹ̀.
Afurasí lórí ikú Tolulope Arotile ti dé ilé ẹjọ́, èyí ni ẹ̀sùn tí wọ́n fi kàn án Ẹ̀yin gómìnà, Ifá nìkan ló le tọ yín sọ́nà láì kùnà lórí Amotekun - Babaláwo Ṣé o fẹ́ ṣiṣẹ́ ológun?
** The past data for new cases is a three day rolling average.
eto idibo ti gomina yoo si waye ni  ojo
" Ko si orilẹ-ede to n sayẹwo to wa, koda, o n ṣiṣẹ fun wa gan ni, a n ṣe ayẹwo, a si n ri awọn ẹgbẹgbẹrun eniyan to ni aarun naa Ni ọjọ kejila oṣu kẹsan Trump ni, abẹrẹ ajẹsara Coronavirus ko ni pẹ yanju sugbọn bo de bi ko de, a o bori rẹ Ayẹwo Coronavirus ti a n se ju milọnu mẹẹdọgbọn lọ, eyi sì ni o mu ki wọn maa ri wa bí pe, arun yii pọju lọdọ wa ju awọn orileede miran lọ.
A ko ni ki fiimu ile okeere ma di wiwo ni Naijiria sugbon a gbodo daabo bo awon ero iworan wa ni Naijiria ki won si tele ilana ajo yii ki won ma ni ejo lorun.
Tí a bá sì jẹ́ ajogún, a jẹ́ pé àwa pẹlu Kristi ni a óo jọ jogún pọ̀, bí a bá bá Kristi jìyà, a óo bá a gba iyì pẹlu.
Amọṣa o kọọ pe ara oun ji pepe, gbogbo ami to si maa n farahan lara ẹni to ba ni arun naa ko jẹyọ lara oun o oun si ti fi ara oun si igbele lati igba ti oun ti fidi rẹ mulẹ pe oun ni arun yii' Tom Hanks ati iyawo rẹ, Rita Wilson Oríṣun àwòrán, Getty Images Bakan naa, Tom Hanks ati Rita Wilson lorilẹede Naijiria naa ti koo."
Ẹ yé irọ́ pa, mí o fún Super Eagles ní ẹbùn owó kánkan -Sanwo Olu Háà!
Ẹgbẹ́ Boko Haram pa àwọn òṣìṣẹ́ UN márùn ún tó wá ṣiṣẹ́ ìrànwọ́ ní Nàìjíríà Ọmọ Yorùbá mẹ́wàá tó jẹ́ àmúlùúdùn ní Amẹ́ríkà àti Yúróòpù Wo ohun tí ìrìnàjò ààrẹ Buhari fún ìgbà àkọ́kọ́ lásìkò Coronavirus lọ sí Mali yóò bá bọ̀ Àwọn alágbára ni mo bá díje ṣùgbọ́n mo ti gbà f'Olọrun- Agboola Ajayi Ile iṣẹ naa ni awọn ti fi orukọ awọn ẹgbẹrun to le ni ẹẹdẹgbẹta awọn to wa labẹ eto N- Power sọwọ si ofiisi akọwe owo ijọba ati ti awon ẹgbẹrun mejilelẹẹdẹgbẹta naa si ti ri owo wọn lati ori eto GIFMIS ti ijoba la silẹ lati maa fi san owo ọhun.
Alix Fox,: O ṣe pàtàkì láti máa jẹ alábòójútó ẹni kejì wá àti fún àwa arawa, tí ó bá jẹ pe iwọ lọ rí àmì tí ó sì kó pé ó ti fi ẹnu kò àwọn ènìyàn lenu, ó ṣe pàtàkì kí je ki awon eniyan naa mọ, bti bá sì jẹ́ pé ìwọ náà lọ rí àmì lẹ́yìn tí ó fi ẹnu kò enikeni lẹ́nu, ó ṣe pàtàkì kí ó fi ara rẹ pamọ.
Bíi kinniun tí ó fi ihò rẹ̀ sílẹ̀,bẹ́ẹ̀ ni OLUWA fi àwọn eniyan rẹ̀ sílẹ̀,ilẹ̀ wọn sì ti di ahoronítorí idà apanirun ati ibinu gbígbóná OLUWA.
Ṣugbọn nígbà tí ó kọ̀ tí kò ṣí ìlẹ̀kùn, wọ́n bá mú kọ́kọ́rọ́, wọ́n ṣí àwọn ìlẹ̀kùn; wọ́n bá bá òkú oluwa wọn nílẹ̀.
" a ṣe àgbéjáde àjẹsára náà láti ara kòkòrò àìlèfojúrí kan tí à ń pè ní "" mycobacterium bovis "" èyítí a má a ń sábà rí lára àwọn mààlúù ."
Wo bí àwọn jàndùkú ṣe yabò àwọn olùwọ́de #ENDSARS ní Alausa l'Eko àti Abuja O sọ ninu atẹjade ọhun to fi si oju opo Facebook ileeṣẹ ologun ori ilẹ pe Aarẹ Muhammadu le fi ọkan tan awọn ọmọ-ogun Naijiria lọjọkọjọ.
Kí ló mú àwọn adarí Nàìjíríà tako ra wọn lórí ikú ọmọ alága ẹgbẹ́ Afenifere?
Ọjọ Kẹrin, Oṣu Karun un, ọdun 2012 ni agbabọọlu Naijiria naa papoda ni ilu Ibadan ni ẹni ọdun mejidinlaadọta.
Ẹ kí Ubanu alábàáṣiṣẹ́ mi ninu iṣẹ́ Kristi ati Sitaku àyànfẹ́ mi.
Ti wọn ba fẹ ẹ gba, wọn a gba.
Dìde, OLUWA, má jẹ́ kí eniyan ó borí,jẹ́ kí á ṣe ìdájọ́ àwọn orílẹ̀-èdè níwájú rẹ.
Kí o kó wọn sílẹ̀ níwájú Àpótí Ẹ̀rí ninu Àgọ́ Àjọ mi, níbi tí mo ti máa ń pàdé rẹ.
Sugbọn ni bayi Usmanov ti ṣetan lati ta ipin rẹ fun Kroenke lẹyin ti o kọ lati ta ikọ naa.
“Ẹni tí ó bá ṣẹgun ni n óo fún ní àṣẹ láti jẹ ninu èso igi ìyè tí ó wà ninu ọgbà Ọlọrun.
Idi ree ti iran Yoruba ko fi lee gbagbe ipa manigbagbe ti Ọba Seriki Ifaremilekun Williams Abass Fagbemi se nigba aye rẹ.
Ìjọba Kaduna kéde ọjọ́ mẹ́ta fún ìdárò Emir Zazzau, Buhari, Tinubu, Babangida náà ń ṣèdárò Èèyàn mẹ́jọ jónà ráúráú nínú ìjàmbá ọkọ̀ akérò tó ṣẹlẹ̀ ní mọ́rosẹ̀ Eko sí Ibadan Sudan tí bẹ̀rẹ̀ ìjìròrò lórí bí US yóò ṣe yọ òrúkọ̀ wọn kúrò nínù ikọ̀ agbẹ́sùnmọ̀mí àgbáyé Áṣẹyin kìlọ̀ fáwọn adarí olóṣèlú Nàìjíríà láti ṣe ohun tó yẹ nítorí ará ọ̀run ń wò wọ́n!
Ile-ise to n mojuto eto iroyin
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Petrol Price Hike: Ilé aṣojú-ṣòfin dúró ìṣẹ́jú kan fún Buruji Kashamu àti Rose Okoh 4 Owewe 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 30 Owewe 2020 Oríṣun àwòrán, @SpeakerGbaja Ile igbimọ asoju sofin Naijiria ti rọ ijọba apapọ, lati tẹle adehun ti wọn ṣe pẹlu ẹgbẹ oṣiṣẹ, eyi to mu ki wọn ṣẹwele ipinu lati gunle iyansẹlodi ati ifẹhonu han.
Ijoba ipinle Nasarawa ti kẹdun pelu ebi, ara ati ore awon eniyan ti o fara kaasa isele ibugbamu afefe gassi eleyi ti o waye losan aje(Monday) ni olu ilu ipinle ohun ti n se Lafia.
"Saraki bẹrẹ awijare nileẹjọ CCB Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ọlọpaa di ẹnu ọna ile Saraki pa ''Saraki farada ìnira púpọ̀"" Eto ẹkọ ọmọ Baba Oloye kii ṣe gbẹfẹ Olusọla ko ginra rara lati fun arẹmọ-kunrin rẹ, Bukola ni awọn ohun mere-mere to n mu ki aye dun fun ọmọde, to si tun n pese ọmọ fun ipo giga ni ọjọ ọla, paapaa, ta a ba wo awọn irufẹ ile ẹkọ to ran Bukọla lọ."
Ọjọ́ kẹjọ, oṣù kẹjọ ni ọ̀rọ̀ náà ṣẹlẹ̀ ni déedé ààgọ mẹ́ta ọ̀sán, nígbà ti ilé iṣẹ ọlọpàá gba ipe láti ọdọ Anugu Valentine kan, pé àwọn ọkunrin méji kan dá oun lọna lóri ọkàda ti wọn si gba Iphone oun ti owó rẹ̀ din díẹ̀ ni ẹgbẹ̀rún lọ́nà ẹẹdẹ́gẹ̀tá náìra ni àgbègbè Iba.
Aisha Buhari gbe imọran yii kalẹ lasiko to ṣabẹwo sawọn akẹkọ ileewe alakọbẹrẹ, atawọn obinrin to lugbadi ijamba ile to wo naa nileewosan.
65 usd fún ìwọ ̀ n egbògi náà kanṣoṣo ní ọdún 2014 .
Ìwà ọ̀lẹ a máa múni sùn fọnfọn,ebi níí sìí pa alápá-má-ṣiṣẹ́.
Agbẹjọro agba Richard Akinjide: Oloye Osuolale Abimbola Richard Akinjide kii ṣe aimọ lagbo awọn ọtọkulu nilẹ Naijiria, paapa ni ẹka imọ nipa ofin.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Akọ́mọlédè àti Àṣà lórí BBC Yorùbá: Kọ̀ síi nípa iṣẹ́ tí oúnjẹ ń ṣe lára níbí Oloye Ọbasanjọ ṣalaye ninu atẹjade naa pe, 'Lootọ ni mo bẹ Oloye Ayọ Adebanjọ wo ni ile rẹ to wa ni agbegbe Lekki Phase 1 ni ọjọ keji oṣu Kejila ọdun 2020 ti mo si pa Gani Adams nibẹ'.
Báyìí ni Aṣojú-Olódùmarè ṣe tí ó lọ tí kò sì tún padà mọ́, fi eléyìí ṣe àríkọ́gbọ́n, ìwọ Olówó-ayé, ọ̀rẹ́ mi.
Enwonwu parọwa si awọn eeyan awujọ lati ọrọ to ileeṣẹ ọlọpaa leti ti wọn kẹẹfin awọn ọdaran to ji awọn ohun elo ijagun ọlọpaa lọ.
Nípa ti ìrànlọ́wọ́ fún àwọn onigbagbọ, kò nílò pé kí n tún kọ ìwé si yín mọ́.
’ Òun ni Ọlọrun rán angẹli sí, tí ó farahàn án ninu ìgbẹ́ tí ń jó, láti jẹ́ olórí ati olùdáǹdè.
Gẹgẹ bi a se ka loju opo Wikipedia lori itakun agbaye, kii kuku se aafin ọba ni wọn ti wo Ọba Adeyẹmi nigba to wa lewe, nitori pe a ri ka pe o ti gbe nilu Abẹokuta, Isẹyin ati Eko gan an ri.
Bẹ́ẹ̀ ni Solomoni ṣe parí kíkọ́ ilé ìsìn náà.
eto ti  ile igbimo asofin yoo maa tẹle.
Alufaa kó àwọn burẹdi mímọ́ náà fún Dafidi, nítorí pé kò sí òmíràn níbẹ̀, àfi burẹdi ìfihàn tí wọ́n kó kúrò níwájú OLUWA láti fi òmíràn rọ́pò rẹ̀.
Ko si si bi adajọ ṣe fẹ ẹ mọ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Fulani Kidnapping: Owó púpọ̀ la san kí wọ́n tó fi mi sílẹ̀ Awọn tọrọ kan ti aarẹ Buhari pe si ọrọ yii ni bii ẹgbẹ awọn to n pese ọja lorilẹede Naijiria, ẹgbẹ awọn oniṣowo, to fi mọ awọn ijọba ipinlẹ gan lati rii pe wọn ṣe iṣẹ to yẹ ki wọn ṣe na lori igbesẹ pataki yii ki wn to gbe e.
’ rèé Afọnja, ẹni tó finú wénú ní Ilọrin, àmọ́ tó jẹ iwọ Ẹfunsetan Aniwura, obìnrin tó ju ọkùnrin lọ Ọ̀rọ̀ǹpọ̀tọ̀niyùn, Aláàfin obìnrin àkọ́kọ́ rèé, tó ní nǹkan ọkùnrin Afurasi naa gba ara odi ile wọ ibi ayẹyẹ ti wọn n ṣe gẹgẹ bi ọlọpaa ṣe royin.
Nítorí náà, nígbà tí gbogbo ìjọ bá péjọ pọ̀ sí ibìkan náà, tí gbogbo yín bá ń fi èdè àjèjì sọ̀rọ̀, tí àwọn tí ó ṣẹ̀ṣẹ̀ ń kọ́ nǹkan nípa igbagbọ, tabi àwọn alaigbagbọ bá wọlé, ǹjẹ́ wọn kò ní sọ pé ẹ̀ ń ṣiwèrè ni?
Yewande bí'mọ tuntun jòjòló, Mercy Aigbe pàdánù èèyàn rẹ̀, Toyin Abraham fèsì lórí aṣoju NCDC Ìtàn Manigbagbe: Àwọn àjakalẹ-àrun to ti wáyé rí ṣáájú Coronavirus Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí 2 sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
Ijinigbe gbogbo ati ipaniyan jakejado Naijiria, ṣe ti ainiṣẹ lọwọ awọn ọdọ ni abi kini gan-an.
Ewe, Gomina Ortom wa so pe, Oun yoo pese aabo ti  o peye fun ohun osin awon darandaran bakan naa, Oun yoo si tun pese aabo fun ohun ogbin aon agbe naa.
Ó lọ pàdé rẹ̀, ó kí i tọ̀wọ̀tọ̀wọ̀, ó sì dojúbolẹ̀ níwájú rẹ̀.
6 180089 Orilẹede Moldova 2419 59.
Loootọ emi ni olori gbogbo Ọbalaye ni ilẹ Yoruba, sibẹ awọn agba ọba n bẹ ti mo ba lori itẹ ti mo si ni lati fi ọwọ fun gẹgẹ bi agba lori ilẹ.
Ọ̀fẹ́ ló bá dé, a kò san kọ́bọ̀ fún ìdáǹdè akẹ́kọ̀ọ́ 334 - Masari Orin lọfẹ-lọfẹ ni baba fun wa lo gba ẹnu ijọba apapọ Naijiria kan lori itusilẹ awọn akẹkọ-kunrin ni Katsina, ti Boko Haram mu sigbekun.
Iku Mavrodi: Àwọn olùdókòwò MMM ń fi apá jánú
kí ó má baà sí ìyapa ninu ara, ṣugbọn kí gbogbo àwọn ẹ̀yà ara lè máa ṣe aájò kan náà fún ara wọn.
Ṣaaju ni awọn eeyan ti n reti remu pe Ọbabinrin Ilẹ̀ Gẹ̀ẹ́sì àti Ọmọọba Harry yóò sèpàdé ní Ọjọ́ Ajé.
Africa Eye: Olùkọ́ méjì ní fásitì Eko àti Ghana lùgbàdì ọ̀fíntótó BBC lórí ìwà ìbàjẹ́
 ) ìkáwó ; Àwon iwé náà wà ní ìkáwó mi .
Elimeleki ati Ìdílé Rẹ̀ Lọ láti Máa Gbé ní Ilẹ̀ Moabu.
1 210951 Orilẹede Morrocco 7888 21.
Ara ohun tó ba iyì rẹ̀ jẹ́ ni - bí o ṣe fi ọwọ́ sí sí so àjókù táyà mọ́ ẹni tó bá lùgbàdì ibi.
ise akanse –  Hadiza Bala UsmanIgbakeji oludari
Agbẹnuso ọlọpàá ìpínlẹ̀ Eko, Bala Elkana sọ èyí di mímọ nínú àtẹjáde kan to fọ́wọ́ si.
Ẹ ṣee, ẹ ku idide, ẹ ku iranlọwọ.
 Àwọn orísìíríṣìí kílíìkì wọnyi ló mú kí èdè khoisan yàtọ ̀ .
27 Ògún 2020 Oríṣun àwòrán, OTHERS Bi a ba n tọka si awọn ọmọ Yoruba to dantọ, to si jẹ awokọse rere, ọkan pataki ni Ajagunfẹyinti Tunde Idiagbon jẹ.
0 226549 Orilẹede Armenia 2974 100.
Ṣugbọn ìdùnnú yi ko pẹ to fi tun di ìbànújẹ nitori awọn ọmọ ogun ko dawọ ija duro.
Kábíyèsí, kí Ọọ́run bùn yín lẹ́miìí o.
wọlé Òjó ni wọ ́ n bí ní ọjọ ́ kẹfà oṣù kẹfà , ọdún 19884 .
Loni ni igbimọ adari ere bọọlu alafẹsẹgba UEFA yoo kede ẹlẹsẹ ayo tọdun yii nilẹ Yuroopu.
Amọ o ni eyí le maa le ṣeṣe fún ẹní to pa ènìyàn nitori ko le ni ore-ọ̀fẹ́ láti dá ẹmi ènìyàn pada.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Thomas Crowther ṣe àtúpalẹ̀ ìwádìí yìí ni orilẹ-ede àádọrin ní àgbáyé Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Thomas Crowther ṣe àtúpalẹ̀ ìwádìí yìí ni orilẹ-ede àádọrin ní àgbáyé 14 Agẹmo 2019 Igi n fún kòkòrò ní ṣúgà -Thomas Crowther Iwadii yii ni akọkọ iru rẹ lagbaye to maa ṣe atupalẹ aṣiri igbe aye awọn igi ninu igbo.
Boko Haram 601 parí iléẹ̀kọ́, ìjọba yóò san ₦20,000 lóṣù fún ẹnì ìkọ̀ọ̀kan Àwọn wọ́n ti ìjìyà ki iṣẹ́ bọ́ lọ́wọ́ wọn tọ́ si ni ex-Sgt Sola Akano àti ex- Cpl Babatunde Glorious.
Lọjọ Kẹrinlelogun, oṣu Kẹwaa ni awọn agbebon ṣina bo'lẹ ti wọn pa ọmọdé meje t'awọn mejila miran si farapa ni ile ẹkọ Mother Francisca International Bilingual Academy, Fiango Kumba, ni iwọ oorun guusu Cameroon.
“Ìwọ ọba ni igi yìí, ìwọ ni o dàgbà, tí o di igi ńlá, tí o sì lágbára.
Ajá dóòlà ọmọ tuntun tí ìyá rẹ̀ bò mọ́lẹ̀ láàyè Nàìjíríà á bí ọmọ 25, 685 lọjọ́ kínni, oṣù kinni, ọdún 2019.
idi si ni pe wọn ti ṣe ayẹwo iṣegun fun wọn ti wọn si ti fi han pe wọn wẹ mọ lọwọ arun COVID-19.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù NEMA: Ǹkan méje ló ń fa omíyale ní orílẹ̀-èdè Nàìjíríà 27 Owewe 2018 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 18 Ọ̀wàrà 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ipinle Niger, Kogi, Anambra ati Delta lo faragba julo.
Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Kano: Ọkùnrin mẹrin wọ gàù 'torí ìgbéyàwó orí Facebook12 Agẹmo 2019 Emir of Kano: Oríṣiríṣi ẹ̀sùn ni ìjọba ìpínlẹ̀ Kano kà sí Sanusi l'ẹ́sẹ̀9 Ẹrẹ̀nà 2020 Kano Sharia Police: Ènìyàn Kano ọgọ́rin lo ti wà látìmọ́lé nítorí wọn jẹun nínú ààwẹ̀.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Mayowa Omoniyi: Kò sí orin Obey, Sunny Ade abí tàkasúfèé tí ń kò le ta gìtá sí '' Ibi isinku mọlẹbi rẹ, ni wọn wa ti wọn ti gba ipe wi pe Chris, tii se aburo Paul Sodje, wa ni panpẹ awọn ajinigbe, ti wọn si ni ki wọn mu ọgọrun miliọnu wa lati tu silẹ.
Nígbà tí ó yá, ọmọ ọba Farao, iyawo Solomoni kó kúrò ní ìlú Dafidi, ó lọ sí ilé tí Solomoni kọ́ fún un.
Jehu tún ń lọ, ó pàdé Jehonadabu, ọmọ Rekabu, tí ń bọ̀ wá pàdé rẹ̀.
NIPOST sọ pe ofin tuntun naa yo ṣe iranlọwọ fun awọn 'ojulowo' ileesẹ abani fi nkan ránṣẹ.
Igboho wa rọ awọn ọdọ Yoruba lati duro fun isọkan ilẹ wọn, ati lati ṣetan lati sisẹ fun irẹpọ.
#Adewura Latifa Bello: Àwọn ará àdúgbò sọ nípa ihò yìí
Idije Adria Tour wa lara awọn idije tẹniisii to ṣẹṣẹ bẹrẹ laipẹ yii.
Awọn oṣiṣẹ baalu gbọdọ wọ awọn aṣọ naa, ki wsn o si tẹle ilana titakete sira ẹni.
Ìpínlẹ̀ Kaduna wà lára àwọn ìpínlẹ̀ ti ààrun Covid-19 tún ti n peléke sii lọ́wọ́lọ́wọ́ gẹ́gẹ́ bi àtẹjáde ojoojúmọ́ àjọ NCDC, èyí sì ló mú kí gọmìnà El-Rufai pinu láti tilẹ̀kùn ilé-ẹ̀kọ́.
Ofin konile o gbele to l'agbara yoo tun bẹrẹ lọjọ Aje ni Belgium.
 bí ó tilẹ ̀ jẹ ́ pé àjẹsára àkọ ́ kọ ́ jẹ ́ oríṣi tí a fi kòkòrò afàìsàn àìlèfojúrí tí a ti pa ṣe , àwọn àgbéjáde tó tẹ ̀ lé èyí jẹ ́ àwọn tí a fi kòkòrò afàìsàn àìlèfojúrí tó ṣì wà láàyè , ṣùgbọ ́ n tí a ti sọ di aláìlágbára , ṣe .
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Njẹ Chloroquine nipa kankan lati le koju Coronavirus Awọn case-fatality ratio ti wọ́n pe ni CFR ni ilẹ Adulawọ ni iye awọn to ba iṣẹlẹ naa rin ni Afirika kere jọjọ si awọn ilẹ to ku ni agbaye.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù 9th Assembly: Èrò ṣe ọ̀tọ̀ọ̀tọ̀ lórí ẹní tí àṣẹ ilé aṣòfin àgbà Nàìjíríà yóò já mọ́ lọ́wọ́ 11 Òkùdu 2019 Àkọlé àwòrán, Ko ti daju ẹni ti yoo jamọ lọwọ laarin Lawal ati Ndume Ipo igba kini ninu oṣelu awa ara wa ṣe pataki ṣugbọn a ko le fi ọwọ rọ awọn igba to ku naa ṣẹyin.
Koda loju òpó BBC Yoruba gan an, awọn eeyan mi n gbadura ki ori awọn naa di apesin bii ti Makinde.
ede yii, Muhammadu Buhari,fun iwa akin ati igbese ti o gbe lati san gbogbo awon
 nítòótọ ́ , a máa sọ pé ìwúlò wò ni ó wà nínú kí a máa sọ ̀ rọ ̀ nípa àwon ohun tí a kò rí nínú èdè wa !
ipa ribi-ribi ti awon osise n ko lawujo , a tun gbodo gbosuba fun aare orile
Wọn óo wá mọ̀ nígbà náà pé èmi ni OLUWA Ọlọrun wọn.
Oríṣun àwòrán, NPF Nkan pataki marun-un nipa SWAT to yẹ ki o mọ Ọmọ ikọ SARS kankan ko ni i si ninu SWAT Iṣẹ ikọ SWAT ni lati ṣe akojọpọ akọsilẹ nipa eto aabo Awọn ọmọ ikọ SWAT ko ni aṣẹ tabi ẹtọ lati yẹ foonu, kọmputa agbeletan 'laptop' ati awọn ẹrọ ayarabiaṣa igbalode, ẹnikẹni wo lọna aitọ.
" Oríṣun àwòrán, others Àkọlé àwòrán, Lai Mohammed sọ pe Aarẹ Buhari ni iku Kyari maa dùn ju nitori pe o jẹ ẹnikan ti aarẹ gbarale pupọ fun imọran.
láti fi hàn bí ó bá jẹ́ mímọ́, tabi kò jẹ́ mímọ́.
Alakoso feto abẹle, asa ati irinajo afẹ nipinlẹ Ọsun, Ọmọwe Ọbawale Adebisi lo fọwọ idaniloju yii sọya lorukọ ijọba ipinlẹ naa, lasiko to lọ se abẹwo si ileesẹ kan to n soju fun ileesẹ eto irinajo afẹ ni Naijiria ati ibudo ise nkan isẹmbaye lọjọ si, eyi ti Ọgbẹni Toye Arulogun n dari rẹ.
Ondo Oríṣun àwòrán, Akinfe Akintunde Awọn akẹkọọ ni ipinlẹ Ondo ṣẹṣẹ wọle ni Ọjọ Aje, ọjọ kọkandinlogun ni lẹyin ti wọn ti fi iwe kikọ ni kilaasi rẹ ni oṣu kẹta ọdun yii nitori ajakalẹ arun COVID-19.
Gbogbo nkan ti yoo jẹ ki awọn ibudo ilera kekeke ni fun iṣẹ ni ijọba rẹ yoo pese.
Bí a bá ká olè mọ́ ibi tí ó ti ń fọ́lé lóru, tí a sì lù ú pa, ẹni tí ó lù ú pa kò jẹ̀bi.
Bakan naa ni wọn n kan saara si awọn ọdẹ atamatase ọhun fun isẹ takuntakun ti wọn se lati fi oju awọn ole naa ri mabo.
Jaredi bí Enọku, Enọku bí Metusela, Metusela bí Lamẹki; 
Ìrúnú rẹ̀ a máa ru jáde bí ahọ́n iná,a sì máa fọ́ àwọn àpáta níwájú rẹ̀.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Adesanya UFC253: Wo ìlúmọ̀ọ́ká akànṣẹ́ mẹ́ta ọmọ Nàìjíríà tó ń ṣe bẹbẹ lágbàáyé 26 Owewe 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 27 Owewe 2020 Oríṣun àwòrán, Instagram Bi ọmọ ẹni ba daa, ẹ jẹ ki a wi, kii se pe a kuku fẹ fi ṣe aya ni.
O fi kun un pe ninu awọn meji to ti jẹ oye naa ṣaaju, iyẹn Oloye Amubikahun, Oloye Ladapọ to jade laye ni oṣu kẹfa, ọdun 2020, ijọba ipinlẹ Ọyọ lo maa n ṣe agbatẹru rẹ.
Abrahamu bá dìde, ó tẹríba níwájú wọn, 
Wo àwọn àwòrán ìgbà ayé Aretha Franklin ‘Ó kò lé gba ìwé ìgbéèlú U.
Ó bẹ̀rẹ̀ pẹlu ìwé Mose, títí dé gbogbo ìwé àwọn wolii.
Wọn si tun fọwọ sọya fun awọn ọmọ Naijiria pe awọn yoo ṣe ohun gbogbo to yẹ fun awọn ifsẹwọnsẹ to n bọ.
Obinrin náà sọ fún un pé, “Alàgbà, fún mi ní omi yìí kí òùngbẹ má baà gbẹ mí mọ́, kí n má baà tún wá pọn omi níhìn-ín mọ́.
 fún àyẹ ̀ wò tí ó bá jẹmọ ́ àyẹ ̀ wò ohun pàtàkì míràn tàbí ohun pàtàkì ọjọ ́ iwájú nípa olùsàyẹ ̀ wò tàbí fún ìpinnu pàtàkì , babaláwo yóò lo ikin ifá , èyí tí wọ ́ n gbà pé ó jẹ ́ olùrọ ́ pò Ọ ̀ rúnmìlà .
Seyi Makinde: Àwọn jàǹdùkú Mali ń gba Saki wọlé àmọ́ Amotekun kápá wọn
Lẹ́yìn náà, Èṣù fi í sílẹ̀.
Onwoye eto oṣelu lawujọ, Yemisi Fadairo ni ija ati asọ to n ṣẹlẹ ni ẹgbẹ oṣelu le mu ki awọn eniyan dibo fun ẹgbẹ oselu miran to yatọ ẹgbẹ oselu APC ati PDP.
 Ó le jẹ ́ pé tí a bá ka ìlà orin méjì sí mẹ ́ ta ni a óò tó rí èrò tí orin kan gbé jáde .
eto agbẹ, ọrọ aje,idokoowo, idagbasoke igberiko ati ounje .
Wọ́n pè é wá fún Dafidi, Dafidi sì bi í pé, “Ṣé ìwọ ni Siba?
O óo fi ọwọ́ rọrí kú ni.
N óo wá fi èémí si yín ninu, ẹ óo di alààyè, ẹ óo sì mọ̀ pé èmi ni OLUWA.
Nígbà tí àwọn ẹbí rẹ̀ gbọ́, wọ́n jáde lọ láti fi agbára mú un nítorí àwọn eniyan ń wí pé, “Orí rẹ̀ ti dàrú.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Bi ìyàwọ mi ṣe n jábọ́ sí kọ́tà ló jẹ́ kí n kọ́ka fura pé kò ríran mọ́- ọkọ Dorcas Akufo Addo ni ohun ko fẹ mọ irufẹ ajeji tabi orilẹ-ede ti onitọhun lee ti wa, yala China tabi Naijiria, gbogbo wọn ni ofin orilẹ-ede Ghana ti paṣẹ pe ko gbọdọ ta ọja Ghana.
Ará Bẹtisaida, ìlú Anderu ati ti Peteru, ni Filipi.
Àṣà Tí A kò Gbọdọ̀ Dá tí A bá ń Ṣọ̀fọ̀.
Ijọba ologun ti i mọle fun ọdun kan, ki ijọba to gbe e lọ si ile ẹjọ ti wọn si dajọ iku fun wọn nipa yiyẹgi fun awọn mẹsan an naa.
king ' s college , lagos jẹ ́ ilé ẹ ̀ kọ ́ sẹ ́ kọ ́ ndìrì ní Ìpínlẹ ̀ Èkó .
Wọn a máa jẹ ilé àwọn opó run.
Oríṣun àwòrán, Twitter/BorisJohnson Esi yi n fi han pe o ṣeeṣe ki adari igbimọ ijọba, Boris Johnson yoo wọle lẹẹkeji.
Ṣugbọn Man City ji pada ninu ere bọọlu ọhun eleyi to mu ki Bernardo Silva dayo kan pada.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Coronavirus Update in Namibia vs elephant: Ṣé òótọ́ ni pé ìgbẹ́ erin le è wo arùn Covid-19 sàn?
O ni orilẹede yii ko tun lee bọ sinu ogun abẹle miran lasiko yii nitori pe ko ni lee bọ ninu rẹ bii ti akọkọ, ina eesi ko si tun yẹ ko jo Naijiria lẹẹkeji nidi ogun abẹle.
Emi ko fẹ aarẹ Buhari -Sadiya Umar Farouq Eni ti a ba sọrọ ni ọdọ Hajiya Sadiya Umar Farouq to jẹ minista tuntun tijọba Buhari yan fun ileeṣẹ ijọba apapọ tuntun ni Abuja ni Hajiya Sadiya wa ni Geneva bayii ni eyi to fihan pe irọ pata to jina si otitọ ni ọrọ naa.
Eyi ni esi Seyi gẹgẹ bi awọn eeyan ṣe fẹ mọ idi pato to fi lọ fun eto yii tori wọn mọ pe olorukọ ati onile ọlọna ni.
Má bọ́ sọ́wọ́ gbájúẹ̀, wo ìlànà FRSC láti gba nọ́mbà àdáni fún ọkọ̀ rẹ Buhari, pàṣẹ fún Pantami kó lọ tọwọ́ ọmọ rẹ̀ bọ aṣọ lórí ìforúkọsílẹ̀ NIN-SERAP Buhari, pàṣẹ f'àwọn Gómìnà pé kí wọ́n jáwọ́ nínú èróǹgbà láti ná N17trillion owó ìfẹ̀yìntì òṣìṣẹ́ Ọrọ ikede afikun yi waye ninu atjade kan ti ileeṣẹ ibaranisọrọ ati eto ọrọ aje ayelujara fi sita lọjọ Aje tii ṣe ọj kọkanlelogun oṣu Kejila.
Ajíṣafínní ni ó bá a dá sí ọ̀rọ̀ ilẹ̀ tí ó rà náà.
Ní àkọ́kọ́ ó ní, “Kì í ṣe ẹbọ ati ọrẹ tabi ẹbọ sísun ati ẹbọ ìmúkúrò ẹ̀ṣẹ̀ ni o fẹ́, kì í ṣe àwọn ni inú rẹ dùn sí.
EndSARS, EndSWAT Protests: Òbí agbábọ́ọ̀lù Kazim Tiamiyu Kaka àtàwọn míì tí ọlọ́pàá pa sọ̀rọ̀, omijé bọ́ lójú ''Àjọ NERC ti fún Disco láṣẹ láti padà sí owó tàríìfù tuntun iná mọ̀nàmọ́ná'' Ẹ dẹ̀kun lílo Sniper àti Dichlorvos fún ìtọ́jú oúnjẹ- NAFDAC kìlọ̀ Ajọ WAEC gbé èsì ìdánwò ọdun 2020 jáde Amọ, Ajọ EFCC naa ko sọ iru iwadii ti wọn n ṣe, ti wọn fi fi iwe pe e.
àwọn ìlàjì ni inú ìlù nígbà tí àwọn ìlàjì yókù sì wà ní ìgberíko tí wọ ́ n ń ṣisẹ ́ àgbẹ ̀ .
afẹfẹ ire, ki Olorun si tun, tu ẹbi awon to padanu ẹmi won ninu .
Aṣofin Ọbasa gba ipo naa lọwọ Aṣofin Ismaila Kamba ti Ipinlẹ Kebbi ti saa rẹ wa si opin.
Ó sọ̀rọ̀, wọ́n yọ́,ó fẹ́ afẹ́fẹ́, omi sì bẹ̀rẹ̀ sí ṣàn.
Ilé ẹjọ́ dájọ́ ẹgba mẹ́ẹ̀dóògún fún ọ̀daràn tó jí Iphone ní Kaduna Wo awọn iroyin manigbagbe to waye ni ọsẹ yii Ìtàn Manigbagbe: Àwọn àjakalẹ-àrun to ti wáyé rí ṣáájú Coronavirus í gọ́tà, mo rò pé ọlọ́jọ́ dé ni - Iya Osogbo Wo igba ewe Fatai Rolling Doller: Gẹgẹ bi ọmọ idile oye, wọn bi i lọdun 1927 si idile Oloye Olagunju ni Ede, ipinlẹ Oṣun.
Ninu ifẹsẹwọnsẹ mejila ti wọn ti gba lati igba naa, wọn bori mẹwaa wọn si ta ọmi meji.
Ní ti orílẹ̀-èdè Nàìjíríà, ofín tiẹ̀ le púpọ̀ fún ìṣẹ́yún, àmọ́ wọn fi ààyè gba ìṣẹyún tí obìnrin náà bá wà nínú ewu nìkan Ní orílẹ̀-èdè Ghana, wọ́n fààyè gba oyún ṣíṣẹ́ tí wọn bá fi ipá bá obìnrin lò pọ̀, tí baba bá bá ọmọ rẹ̀ lò pọ̀, tí ọmọ inu bá jẹ́ aláàbọ̀ ara tàbí tí oyún inú náà bá le sọ obìnrin di ọlọ́dẹ orí.
Nígbà náà ni àwọn eniyan wí fún Saulu pé, “Ṣé a óo pa Jonatani ni, ẹni tí ó ti ṣẹ́ ogun ńlá fún Israẹli?
Ti a ko ba gbagbe, ija laarin Toyin Abraham ati Yomi Fabiyi bẹrẹ ni nkan bii ọdun diẹ sẹyin, lẹyin ti Yomi Fabiyi pe Toyin Abraham ni alagabagebe nitori ija to wa laaarin Toyin Abraham ati oṣerebinrin miiran, Mercy Aigbe.
Afẹ́fẹ́ gáàsì gbiná ní Ijora ìpínlẹ̀ Eko, bó ṣe n ṣẹlẹ̀ rèé Agolo afẹ́fẹ́ gáàsì kan ti gbina ni agbegbe IJora nipinlẹ Eko lọsan Ọjọbọ, ko si tii lojutuu ni akoko ti a n ko iroyin yii jọ.
Àwa Juu mọ ẹni tí à ń sìn, nítorí láti ọ̀dọ̀ wa ni ìgbàlà ti wá.
Ọpọ awọn asa yii ni awọn asaaju wa n lo lati se akoso awujọ wa, ki ohun gbogbo lee tuba-tusẹ nitori ilu ti ko ba si ofin, ẹsẹ ko si nibẹ.
Orúkọ wọn ni: Adina, Josabadi, Jediaeli, ati Mikaeli; Josabadi, Elihu ati Siletai, olórí ẹgbẹẹgbẹrun àwọn ọmọ ogun ninu ẹ̀yà Manase.
Èso tí igi kan bá so ni a óo fi mọ̀ ọ́n.
Àwọn àjèjì náà bá fa Lọti wọlé, wọ́n ti ìlẹ̀kùn, 
Ẹ ranti pé ati àwọn, ati ẹ̀yin, ẹ ní Oluwa kan lọ́run, tí kì í ṣe ojuṣaaju.
Bo tilẹ jẹ pe nọmba naa ko wọle nigba ti a pe e, ṣugbọn Gomina Sanwo-Olu ti ni awọn eeyan le bẹrẹ si n pe awọn nọmba naa lati ọsẹ to n bọ.
A wá fún ọ̀kọ̀ọ̀kan wọn ní aṣọ funfun.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Spaghetti, milíìkì, Chivita àti Àǹkàrá sọ Rabiu dèrò ẹ̀wọn ni Eko 29 Ògún 2019 Oríṣun àwòrán, @others Àkọlé àwòrán, Ìbí kò gbọdọ ju ìbí nínú eto ìdájọ́ Adajọ ni ki Kabiru lọ kọ ẹkọ iwa ootọ sii nile ikọni lẹkọ ọmọluwabi tijọba.
Oríṣun àwòrán, AFP Àkọlé àwòrán, Aubameyang ati Mkhitaryan Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 3 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 5 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Mú èrò ìgbéraga kúrò lọ́kàn rẹ, kí o sì ní ọkàn ìbẹ̀rù.
O kilo pe iru iwa ibajẹ bayii maa n se akoba fun awon mekunnu ati awon ara ilu.
Ṣé lónìí ni ọ̀rọ̀ owó oṣù tuntun yóò yanjú àbí yóò tún d'ọjọ́ míràn?
trillion Naira), eleyii ti o ju apapo owo isuna 
Amọ ọjọ Kẹjọ, oṣu Keje, ọdun 2020 ni wọn si papakọ ofurufu ti ilu Abuja ati Eko fun irinajo labẹle.
Ninu pápá tí ó tẹ́jú ni ẹ óo kú sí; èmi OLUWA Ọlọrun, ni mo sọ bẹ́ẹ̀.
Coronavirus in Nigeria: Èèyàn mẹ́jọ kú, 1,024 míràn tún lùgbàdì ààrùn náà ní Nàìjíria
Kí ló dé tí ẹ kò lè dárí ẹ̀ṣẹ̀ mi jì míkí ẹ sì fojú fo àìdára mi?
MTN àti BBC World Service bẹ̀rẹ̀ àjọṣepọ̀ lórí ìròyìn ìṣẹ́jú kan BBC Akọsilẹ sọ pe awọn Qarmatians ṣekupa ọpọlọpọ awọn musulumi to lọ fun Hajj lọdun yii, wọn si ji okuta dudu Kaaba lọ eyi tawọn musulumi gbagbọ pe o wa lati ọrun.
Gomina Makinde, ẹni to ba awọn eeyan to padanu ẹmi ati dukia ninu isẹlẹ ijamba ina naa, wa seleri pe oun yoo kọ ọja igbalode pada fun wọn, ti isẹlẹ naa yoo si di ile ọba to jo, ẹwa lo bu kun.
Iṣoro aisi ina pẹlu bi wọn ṣe pọ to Ina ti wọn yoo ri latara rẹ lee to gbogbo araalu wọn ti yoo tun ṣẹku lati ta fun awọn orilẹede agbegbe.
Ṣùgbọ́n ǹkan wọ̀nyí kò ṣe é ṣe, nítorí bi òun ti ń múra bí kìnnìún bẹ́l náà ni Èṣù-kékeré ń mura bí àjànàkú tí èruku ńlá ń sọ lójú ọ̀run.
Ó dúró jẹ́ẹ́,ṣugbọn n kò mọ̀ bí ó ti rí.
Ẹ̀yin ọmọ mi, ẹ bá ìyá yín sọ̀rọ̀; nítorí pé kì í ṣe aya mi mọ́, ati pé èmi náà kì í sì í ṣe ọkọ rẹ̀ mọ́.
“Kọ ìwé yìí sí angẹli ìjọ Simana:“Báyìí ni ẹni kinni ati ẹni ìkẹyìn wí, ẹni tí ó kú, tí ó tún wà láàyè: 
Ẹ ka iye ilé tí ó wà ní Jerusalẹmu, ẹ sì wó àwọn kan palẹ̀ ninu wọn, kí ẹ lè rí òkúta tún odi ìlú ṣe.
Wakabi ni Olùdarí Àgbà Ìfọwọ́sowọ́pọ̀ Ètò-ìmúlò Ìmọ̀-ẹ̀rọ Gbogboògbò fún Ìlà-Oòrùn àti Gúúsù Ilẹ̀ Adúláwò (CIPESA), ọ̀kan gbòógì nínú ilé-iṣẹ́ tí ó ń ṣe ètò tí ó dá lórí ètò-ìmúlò ẹ̀rọ ayélujára àti òmìnira ọ̀rọ̀ sísọ ní orí ayélujára ní ilẹ̀ Adúláwò.
O si yẹ ko ye wa pe gbogbo ẹmi lo jẹ ti Ọlọrun, to fi mọ ẹmi awn ẹranko, ti Ọlọrun si ti setan lati gba ẹsan lara ẹnikẹni to ba da ẹmi alaisẹ legbodo, ki ọdun yii to pari.
Ó wá sọ pé ọ̀nà àbáyọ kan ṣoṣo ni pé kí ìjọba dẹ́kun irọ́ pípa fún aráàlú lórí ohun tí apá wọn ká láti ṣe.
 Ni nkan bii ago marun, eeyan kan pe mi pe ṣe mo ti gburo rẹ, mo si ni bẹẹ ni, lo ba ni ki n tun un pe mo si ṣe bẹẹ ṣugbọn mi o gbọ esi""."
" eléyìí ni ó wá di "" Àkúrẹ ́ ' títí dòní yìí ."
Kí ẹnikẹ́ni má ṣe tan ara rẹ̀ jẹ.
Mo wá rí ẹṣin kan tí àwọ̀ rẹ̀ rí bíi ti ewéko tútù.
Iyalẹnu nla lo jẹ fawọn eeyan to peju si kootu ibilẹ to wa nilu ikorodu lọjọbọ nigbati igbeyawo ọgbọn ọdun di pẹẹ ntuka nitori ẹsun iwa pansaga.
Lori ọrọ bi idọti ṣe pọ kaakiri ipinlẹ Eko bayii, o ni Ile naa ko mọ si ile-iṣẹ tuntun ti o n mojuto idọti ati imọtoto ilu bayii ni Ipinlẹ Eko, iyen ‘Visionscope’, pe sibẹ Ile Igbimọ Aṣofin naa ti n da si ọrọ naa.
Nítorí pé o óo lé wọn sá;nígbà tí o bá fi ọfà rẹ sun ojú wọn.
    Nígbà tí o di ọjọ́ kan.
Wọn ta gita yii ni $340, 000 eyi to jẹ ẹgberun marundinlaadọrin le ni igba owo pọun ilẹ Gẹẹsi.
"Àkọlé àwòrán, ìfọ̀rọ̀wérọ̀ BBC Yorùbá l'Ọyọ Àkọlé àwòrán, ìfọ̀rọ̀wérọ̀ BBC Yorùbá l'Ọyọ Nipa eto ẹkọ o ni ""wọn kò fẹ́ kọ́mọ́ mẹ́kúnù di Dókítà"" nitori naa oun yoo mojuto eto ẹkọ."
Bí Lámọ́ín bá ra mọ́tò, ó di orí ayélujára, bí làkásègbè bá ra ilé, ó di orí ìtàkùn àgbáyé, se orí afẹ́fẹ́ ni èèyàn ti ń se ilé ayé ni ?
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Làá hàn mí: Ètò yìí ló ń kìlọ̀ fún wa láti mú ìmọ́tótó ní pàtàkì láti dènà Coronavirus Lọwọ yii, o jọ bi pe awọn to n jẹ Ọlọrun nipe nipasẹ arun naa kere jọjọ, bi ida kan si meji ninu ida ọgọrun.
Atẹ́gùn wá ń fẹ́ ọkọ̀ lọ sí èbúté.
Lawọn ipinlẹ bii Ogun, Eko ati Abuja, igbele oṣu kan gbako lawọn araalu ti wa bayii, eleyii to n mu ki ọpọ maa beere nigba wo ni igbele awọn yoo pari?
ribiribi ni orile-ede Naijiria nko lati ri pe orile-ede kookan lagbaye ati ile
Tayọ̀tayọ̀ ni ẹ óo fi máa rí ìgbàlàbí ẹni pọn omi láti inú kànga.
Tani o le salaye lati so nipa ipa pataki oju
Ninu ọrọ to sọ tẹdun-tẹdun, Abilekọ May sọ pe ''oun ti ṣe eyi ti agbara oun ka'' lati ṣe ègbè lẹyin abajade idibo apapọ ilẹ Yuroopu to waye l'ọdun 2016.
Edinson Cavani dero Manchester United Oríṣun àwòrán, Getty Images Yoruba bọ, wọn ni bi a ko ba ri adan, a mọ fi obẹ ṣe ẹbọ.
Komisanan naa sọ wipe ipinlẹ naa ti ra ogun eku ati ti kokoro ti wọn yoo fin lati okere nitori ati gb'ogun ti awọn nkan ti wọn yo awọn oko naa lẹnu.
 a tun le ríi gẹ ́ gẹ ̣ ́ bí ìgbésíayé ayé tí onígbàgbọ ̀ ń gbé .
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Àwọn jàndùkú ṣe yabò àwọn olùwọ́de #ENDSARS ní Alausa l'Eko Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Ondo Accident: Kíní ọ̀nà àbáyọ sí ìjàmbá ọkọ̀ tó ń wáyé lemọ́lemọ́ ní Ọjà Akungba,ní Ondo?
Nigba ti fada Mbaka si wọnu ile, awọn ikọ iroyin BBC wa ninu ọkọ wọn nita, ni Fada Obiekezie ba wọnu ile lati lọ jiroro pẹlu fada Mbaka, amọ ko pẹ ni awọn gende ọkunrin bii ogun yi mọto ikọ iroyin BBC ka.
 O sapejuwe iyawo rẹ gẹgẹ bi iwe akaikatan, nitori pe bi mo ṣe n ka ọ si, ni mo n mọ awọn adun ati anfaani rẹ si.
 Oríṣun àwòrán, STREET PRIESTS Àkọlé àwòrán, Inyang Edem (ninu asọ pupa) lo ran Okina lọwọ lati san owo ileewe awọn ọmọ akọkọ O ṣalaye pe, Ko pọn dandan ki ẹnikẹni fi aami ororo yan an ọ.
Bi ijọba ipinlẹ Kano ṣe fi awọn Emir mẹẹrin miran jẹ, jẹ apẹẹrẹ pe agbara ti Emir Sanusi ni ti dinku.
Lẹyin naa ni akọsilẹ ẹni keji waye lọjọ kẹsàn-án, oṣu Kẹta.
"O ni ""Ọkọ mi ni wọn sọ pe o fẹ gbe iyawo, kii ṣe emi, nitori mi o si nile."
Ṣugbọn kò ní sí ìṣúdudu fún ẹni tí ó wà ninu ìnira.
gẹ́gẹ́ bí ó ti wà ní àkọsílẹ̀ pé, “Ọlọrun fún wọn ní iyè tí ó ra,ojú tí kò ríran,ati etí tí kò gbọ́ràn títí di òní olónìí.
Eyi gan lo difa fun Sẹgilọla, iya agba to n ṣiṣẹ afaworan ṣoge, (modelling) ti ọpọ mọ mọ awọn omidan.
Olóri Ijọ, Olóri ilú àti Òṣèlú ti ó ja Ijọ àti ilú ni olè ni ará ilú bẹ̀rẹ̀ si i bọ ju àwọn Olóri ti kò lo ipò lati kó owó ijọ àti ilú fún ara wọn.
O ṣoju mi koro ni awọn ọlọpaa meji ni awọn janduku naa pa, ti wọn si dana sun wọn.
Ẹni tí kò jẹ, kò jẹ ẹ́ nítorí Oluwa, ọpẹ́ ni òun náà ń fi fún Ọlọrun.
Bakan naa lo ni, awsn ti n wa ile ifiniwọ si fun awọn ti omiyale naa ti ss di alainile lori.
Báwo la ṣe lè ṣe àpèjúwèé olóògbé Mandela ná?
N óo gbin igi kedari sinu aṣálẹ̀,pẹlu igi akasia ati igi mitili ati igi olifi.
N óo gba àwọn eniyan mi lọ́wọ́ yín, nígbà náà, ni ẹ óo wá mọ̀ pé èmi ni OLUWA.
Mínísítà tó ń mójú tó ọ̀rọ̀ náà Mariam Katagum ni àwọn ìpínlẹ̀ tó fi orúkọ sílẹ̀ jùlọ ni Kano, Kaduna , Lagos, Katsina ati Abuja, sùgbọ́n Kano Kaduna àti Lagos ló n léwájú.
Àwọn Ọ̀tẹlẹ̀múyẹ́ ròyìn pé wọn bá owó rẹpẹtẹ, pàtàki oriṣiriṣi owó òkè òkun, ni ilé awon Adájọ́ wọnyi.
Alebu ati ohun ti wọn n foju ri ladugbo kii ṣe kekere.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ìlú Eko ló jẹ gbèsè jù ní Nàìjíríà lẹ́yìn ìjọba àpapọ̀ Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
ó ń sùn lálẹ́, ó ń jí ní òwúrọ̀, irúgbìn ń hù, ó ń dàgbà ní ọ̀nà tí ọkunrin náà kò mọ̀.
Ẹ̀yin ará, à ń bẹ̀ yín nípa ọ̀rọ̀ lórí ìgbà tí Oluwa yóo farahàn ati ìgbà tí yóo kó wa jọ sọ́dọ̀ ara rẹ̀, 
Ko ni fẹ ki o sunmọ ọrẹ tabi alabaṣe to le kọ ọ si oun lọjọ iwaju.
Ẹ̀wọ̀n ayérayé ni Ọlọrun fi dè wọ́n mọ́ inú òkùnkùn biribiri títí di ọjọ́ ńlá nnì tíí ṣe ọjọ́ ìdájọ́.
Fasiti, Ahmadu Bello, ABU ni Zaria lo ti kẹkọ gboye imọ ijinlẹ ninu ogun pipo lọdun 1980 ṣugbọn Buhari ko lọ si fasiti yii.
Ileeṣẹ ọlọpaa ni ọwọ awọn tẹ Zainab Justina Adamu to jẹ ẹni ọdun marundinlọgbọn to gbimọ pọ pẹlu ọrẹ rẹ Ruth Kenneth lati ta ọmọ rẹ jojolo.
O fún wọn ní ẹ̀mí rere rẹ láti máa kọ́ wọn, o kò dá mana rẹ dúró, o fi ń bọ́ wọn.
Adìẹ funfun kò mọ ara rẹ̀lágbà
Bẹ́ẹ̀ ni ó máa ń sọ lójoojúmọ́, nígbà tí ó bá sì nà mí ní pàṣán títí, tí mo kérora títí, a lọ sí ọ̀dọ̀ ayédèrú ẹ̀gbọ́n tí ó ti kú a máa bẹ̀ ẹ́ kí ó ti ọ̀run wáá rí òun.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Oko òkú rèé, níbití òkú ti ń jẹrà mọ́lẹ̀ fún àyẹ̀wò Ayinla Ọmọwura, orin èébú àti oríyìn lo fi di ọ̀rẹ́ àwọ̀n obìnrin Iṣọla Oyenusi rèé, ẹnití ìfẹ́ obìnrin ṣun dé ìwà ìdigunjalè Orúkọ àwọn orílẹ̀èdè tí yóò kópa ní AFCON 2019 rèé Makinde ẹni to ni ti ko si ba si igi lẹyin ọgba, ọgba yoo wo, wa tọka si pe awọn ileesẹ nla nla n se aseyọri nitori igbimọ olugbaninimọran ti wọn gbe kalẹ nibẹ ni.
Àwo ati abọ́ náà kún fún ìyẹ̀fun kíkúnná tí a fi òróró pò, fún ẹbọ ohun jíjẹ; 
Àwọn kan wá láti ilé ìpàdé kan tí à ń pè ní ti àwọn Olómìnira, ti àwọn ará Kurene ati àwọn ará Alẹkisandria; wọ́n tako Stefanu.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ibadan Refuse: Kọmísánà fọ́rọ̀ àyíká ní ìṣẹ̀lẹ̀ náà ní bó ṣe jẹ́, kò ṣàdédé wáyé 13 Bélú 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 14 Bélú 2019 Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ibadan: awon araalu figbe bonu pe ilu doti Oriṣiriṣi awọn panti ati ilẹ ti awọn eeyan n da si aarin igboro, ti sọ awọn adugbo kan ni ilu ibadan ti o jẹ olu ilu ipinlẹ Ọyọ ti aatan.
gbodo sora ki awon ile ise aladaani maa baa se ipalara fun  awon ile ise okoowo  keekeeke.
Ṣugbọn àwọn eniyan mi ti gbàgbé mi,wọ́n ń sun turari sí oriṣa èké.
Nígbà náà ni n óo máa sọ̀rọ̀ òdodo rẹ,n óo sì máa yìn ọ́ tọ̀sán-tòru.
-Kollington fésí sí ìbéèrè ńlá Mo ti kó kúrò nílé Olu Jacobs rí lẹ́ẹ̀mejì- Joke Silva Àṣírí mẹ́wàá tí mo mọ̀ nípa Boko Haram-Naomi Adamu Muraina wa rọ ajọ OSUCCIMA lati pese awọn ohun eelo ibaraẹnisọrọ igbalode feto idokowo fun awọn ileesẹ ti yoo fọwọsowọpọ pẹlu ajọ naa, ki wọn lee ba ilana katakara lagbaye fun saa onka ẹgbẹrun ọdun ta wa yii mu.
Sẹ́nétọ̀ Dino Melaye kéde láti dupò gómìnà Kogi Ìròyìn ìbúrawọlé jákèjádò orílẹ̀èdè Nàìjíríà ní ẹ̀kúnrẹ́rẹ́.
Ileesẹ Channels fẹ so isẹ rọ: Wayi o, ileesẹ agbohunsafẹfẹ Channels, to gbaju gbaja yika agbaye ti n kede pe kawọn osisẹ rẹ fi agbegbe ileesẹ naa silẹ, ki wọn si maa lọ sile wọn.
 kíkọ ́ ilé ìwé yìí kò yára rárá nítorí ogun àgbáyé tí ó jẹ ́ kí gbogbo nkan ìkọ ́ lé gbówó lórí .
Elebuibon sọ fawọn akọroyin pe, lati ọmọ ọdun mẹrin ni oun ti n fi ọfọ se iwosan fawọn ọrẹ oun.
Nígbà tí kì í tíí ṣe pé ẹ ti ń ṣe é nìkan ni, ṣugbọn tìfẹ́tìfẹ́ ni ẹ ti fi ń ṣe é láti ọdún tí ó kọjá, 
Ẹ má fi ààyè gba Èṣù.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù ENDSARS: Wo ìgbà mẹ́rin tí ìjọba ti tú ikọ̀ ọlọ́pàá SARS ká sẹ́yìn ṣùgbọ́n.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Sina Jesu ní orúkọ́ mi báyìí, ń kò jẹ́ Shina Rambo mọ́ - Adigunjalè tẹ́lẹ̀ kìlọ̀ Mọ̀ síi nípa Shina Rambo tó pàdé Jesu lọ́gbà ẹ̀wọn lẹ́yìn tó ti jalè Abẹ́rẹ́ àjẹsára tó dájú fún ìdènà àrùn Coronavirus ti jáde Wàhálà míì dé!
Mo ṣiṣẹ́ bi mo ṣe ni agbára to láti ṣee, ṣùgbọ́n o di dandan fún mi láti fipò yìi sílẹ̀, ki n lè gbájúmọ́ iṣẹ́ òṣèlù ti mo fẹ́ tọrun bọ̀ bayii.
Nítorí náà ni mo ṣe pè ọ́, pé kí o lè sọ ohun tí n óo ṣe fún mi.
Walter Onnoghen: Ṣé lòótọ́ ní pé adájọ àgbà Nàìjíríà tí wọ́n ní kó lọ rọ́ọ́kún nílé tí kọwe fiṣẹ sílẹ?
bi adari eka amusese nipinle naa, Head of Service (HOS).
"Àkọlé àwòrán, ìfọ̀rọ̀wérọ̀ BBC Yorùbá l'Ọyọ Bakan naa, oun lo ni ""àtàrí àjànàkú ni ọ̀rọ̀ ìpínlẹ̀ Ọyọ ."
Bakan naa laipẹ yii, ipaniyan n peleke sii nilu Eko paapaa eyi to n waye lọna aitọ latọwọ awọn agbofinro bii ọlọpaa ati awn SARS to bẹẹ ti ọga agba awn ọlọpaa, Adamu Mohammed ṣebẹwo si ilu Eko lati fa wọn leti ati lati fi ofin ati ijiya kalẹ fun agbofinro to ba ru ofin.
"Ibi ti gbogbo eeyan ti n wa kaakiri agbaye lati ṣe tutu, lo lọ ọ mu abawọn ba.
 Ìmò elédè nípa èdè rè ni yóò je wá lógún nínú ìdánilékòó yìí .
Loju opo Twitter awọn eeyan bi Ahmed Salkida n ṣe idaro Dele Giwa.
Ṣugbọn jẹ́ kí n lọ farapamọ́ sinu pápá títí di ìrọ̀lẹ́ ọjọ́ kẹta.
Gẹ́gẹ́ bí alábàáṣiṣẹ́pọ̀, à ń bẹ̀ yín pé kí ẹ má ṣe jẹ́ kí gbígbà tí ẹ gba oore-ọ̀fẹ́ Ọlọrun jẹ́ lásán.
Lẹyin idibo si ipo gominato waye lorilẹede Naijiria ni ọjs kẹsan oṣu kẹta, ọdun 2019, idibo ni awọn ipinlẹ mẹfa kan bii Adamawa, Bauchi, Benue, Kano, Plateau ati Sokotoni ajọ INEC kede gẹgẹ bii eyi ti ko pari.
Aṣọ ìkélé tí ó wà ninu Tẹmpili bá ya sí meji láti òkè dé ilẹ̀.
Bí ere orí itage si ni ìṣẹ̀lẹ̀ náà ri nigbati bàbá kan, Arákùnrin Babafemi, yari kanlẹ pé ọmọ òun tó ṣẹ̀ṣẹ̀ ti ìlú Èkó de, gbọ́dọ̀ ṣe ayẹwo àrùn Coronavirus, kí òun tó gbà á sínú ilé .
Omowe Michael Ojo, to je oludari ajo Global Alliance for Improved Nutrition (GAIN) fun Naijiria ni ise iwadii ti fihan pe Naijiria n padanu o kere tan bilionu mewaa owo naira lodoodun lori awon ere oko to baje nitori pe ko si ona ifipamo to munadoko to.
Ìyá mi kì í ṣe ènìyàn rárá, iwin ni.
Ile igbimo asofin ti fonte lu
Bah N'Daw àti Assimi Goita di adarí tuntun láti tukọ̀ orílẹ̀-èdè Mali ní ọdún kan àti aàbọ̀ Ọ̀gá iléeṣẹ́ gbé £10 mílíọ̀nù ẹ̀bùn owó fún òṣìṣẹ́, èyí lohun tó pawọ́n pọ̀ Orílẹ̀èdè Amẹrika ti bẹ̀rẹ̀ sí ní wo wọlé-wọ̀de Atiku, àwọn ìyàwo rẹ̀ lórí owó tí wọ́n kó lọ sí òkèèrè Oríṣun àwòrán, others 48 yr old woman wrote WAEC: Wo ìyá ọlọ́mọ mẹ́ta tó ti pé ọdún 48 tó ń ṣe ìdánwò WAEC, kó le di nọ́ọ́sí Ọjọ ti pẹ ti Arabinrin Christina Samuel ti ni erongba láti di nọọsi, sugbọn afojusun rẹ ko wa si ìmúṣẹ, nitori pe o yára lọ sile ọkọ.
International Stadium niluu Aba, ki o to tun teko lati lo sipinle Imo.
Ninu atẹjade ti ajọ naa fi si oju oppo ikansiraẹni Twitter wọn ni ajọ naa ti fi lede bẹẹ.
Ó dára púpọ̀ fún ara ẹni, ó sì fúnni ní àlékún ìlera tó yànjú.
láti mú wọn jókòó láàrin àwọn ìjòyè,àní, àwọn ìjòyè àwọn eniyan rẹ̀.
Igba meji ọtọọtọ ni aba adehun iyapa naa ti ba ijakulẹ pade ni ile aṣofin ilẹ Gẹẹsi.
Aare orile ede Naijiria Muhammadu Buhari ti wa ni ipinle Bauchi lati se ikedun leyin isele iji lile ati ijamba ina to ba opolopo nnkan je nibe.
Oríṣun àwòrán, Jubril Gawat Àkọlé àwòrán, Tinubu pe fun Atunto ẹka ipese ina ọba Laipẹ yii ni iroyin jade pe ijọba apapọ ti n gbero lati fi kun owo ori sisan lori awọn ọja rira ati tita lorilẹede Naijiria.
Àwọn agbo ẹran tí a fun yín dà,àwọn ẹran ọ̀sìn yín tí ó lẹ́wà àwọn dà?
Ní ọjọ́ náà,a óo fun fèrè ogun ńlá,àwọn tí ó ti sọnù sí ilẹ̀ Asiriaati àwọn tí a lé lọ sí ilẹ̀ Ijiptiyóo wá sin OLUWA lórí òkè mímọ́ ní Jerusalẹmu.
 bíótilẹ ̀ jẹ ́ pé agbẹjọ ́ rò fún ijọba gbà pé , ìdádúró ẹjọ ́ náà jẹ ́  ibàlórúkọjẹ ́ "" àti pé àwọ ́ n mọ ̀ lẹ ́ bí àwọn tí ìṣẹ ̀ lwẹ ̀ yìí ṣẹlẹ ̀ sí lè gba owó lọ ́ wọ ́ ìjọba faransé , adájọ ́ kọ ̀ lati gbá atótónu pé kí wọ ́ n da ẹjọ ́ náà nù ."
Naira Marley gba àṣẹ onídúró nílé ẹjọ́ pẹ̀lú mílíọ́nù méjì náírà
A ti beere lọwọ awọn ologun boya wọn kii yinbọn fun ẹnikẹni to ba di aṣia orilẹede mu, ṣugbọn wọn ko tii dahun.
26 Bélú 2020 Fídíò, Akọ́mọlédè àti Àṣà lórí BBC Yorùbá: Kọ́ síi nípa iṣẹ́ tí oúnjẹ ń ṣe lára níbí24 Bélú 2020 Ilé ẹjọ́ tú ìgbéyàwó ọdún mẹ́wàá ká nítorí ẹ̀sùn ìbálòpọ̀ ọlọ́jọ́ gbọọrọ àti òògùn owó26 Bélú 2020 Fídíò, Oba Adedokun Abolarin ti Oke Ila: Ó ya ọ̀pọ̀ tó súnmọ́ mi lẹ́nu bí mo ṣe ń kọ́ àwọn akẹ́kọ̀ọ́ pẹ̀lú ipò Ọba23 Bélú 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Ọdọmọkunrin náà kó kúrò ní Bẹtilẹhẹmu ní ilẹ̀ Juda, láti lọ máa gbé ibikíbi tí ó bá ti rí ààyè.
Nàìjíríà ní ìgboyà láti kojú ilẹ̀ South Africa - Foluṣọ Philips A kò lè padà sí South Africa mọ́ láè- ọ̀kan lára àwọn tó ṣẹ̀ṣẹ̀ dé A fẹ́ ìdájọ́ òdodo lórí ìsẹkúpani- àwọn akẹ́kọ̀ọ́ Iru iwa ifarajin bayi ṣọwọn lawujọ ti pupọ awọn ọmọ Naijiria si ti n kan sara si fun igbesẹ to gbe yi.
Èyí tí ó burú ju gbogbo ọ̀rọ̀ yìí lọ ni pé iná ti kú bẹ́ẹ̀ igi ìṣáná kan ni ó kù sí inú ilé ìṣáná kí n tóó lọ, òjò sì ti pa ìṣáná náà tó bẹ́ẹ̀ tí ibi rógódó tí a fi ń ṣáná ni orí rẹ̀ ti bó sọnù.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Helen Paul sọ idi tó fi gba orúkọ ní kékere Nigba ti awọn oniroyin lọ si ile iwosan naa, wọn ko jẹ ki wọn ri oju iya ọlọmọ naa, wọn ni nitori o ṣi jẹ ẹlẹwọn.
Lẹyin o rẹyin ni aṣiri Dupẹ tu sọwọ ẹbi, ara ati ọlọpaa.
kí ó ye yín pé àwọn ẹni tí ó bá gbàgbọ́ ni ọmọ Abrahamu.
Mo ti ṣe ìdájọ́ ẹni tí ó ṣe nǹkan bẹ́ẹ̀ ní orúkọ Jesu Oluwa bí ẹni pé mo wà lọ́dọ̀ yín.
O ni ''O di dandan lati wa wọrọkọ fi ṣ'ada lori idasilẹ ọlọọpa agbegbe.
wa fun awon ile-ise ati lati  lee  jẹ ki awon onisowo lati ilẹ okeere wa da isẹ
 Òun àti àwọn alátìlẹ ́ yìn rẹ ̀ dórí kọ ilẹ ̀ àìmọ ̀ rí fún ibùgbé .
Nígbà tí Ṣela di ẹni ọgbọ̀n ọdún ni ó bí Eberi.
Ni bayii, gbaju-gbaja elese omo ile biritiko, Anthony Joshua ti n se ipade lori gbagede igbaradi ti yoo lo saaju ifigagbaga pelu elese ile New York,  Jarrell Miller ti won yoo jo maa waako fun ife-eye agbaye.
Bi Neo ṣe kuro lori eto naa, ni Fireboy tun pada sori itage lati kọ orin fun igbadun awọn olukopa, ati awọn ololufẹ eto naa.
"nàìjíríà ( ) tó jẹ ́ mìmọ ̀ fún ibiṣẹ ́ gẹ ́ gẹ ́ bíi orílẹ ̀ -èdè olómìnira Àpapọ ̀ ilẹ ̀ nàìjíríà ( "" nigeria "" ni èdè gẹ ̀ ẹ ́ sì ) jẹ ́ orílẹ ̀ -èdè ìjọba àpapọ ̀ olómìnira pẹ ̀ lú ìlànà-ìbágbépọ ̀ , to je pinpin si ìpínlẹ ̀ mẹ ́ rindínlógójì àti agbègbè olúìlú Ìjọba Àpapọ ̀ ."
#BBCNigeria2019 Ilé aṣojú-ṣòfin bọwọ́ lu #30,000 owó oṣù òṣìṣẹ́ tuntun Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fọ́nrán ohùn, Ondo: Iya lu ọmọ pa nítori ẹgbẹ̀rún mọkànlélógun Naira Awọn ti ọrọ naa soju rẹ wi pe Abilekọ Ajọkẹ Adebayo lo fi lulu ba ti ọmọ rẹ jẹ, lẹyin to ni ọmọ ọdun mẹrinla naa ji ẹgbẹ̀rún mọkànlélógun Naira(21,000) kuro ninu apo isuna rẹ ni ile ifowopamọsi.
Ṣaaju ninu ọoṣu yii ni ajs liigi ilẹ Gẹẹsi ti ṣalaye pe o digba ti alaafia ba ti pada ki awọn to ṣi ilẹkun liigi pada.
Eyi ko si sẹyin ofin tita kete sira ẹni to wa nita, awọn to si peju sin asofin naa ko pe mẹwa niye.
ṣamulo eleyii fun pipari awọn iṣẹ akanṣe to n lọ kaakiri.
 ‘‘Ẹ gbọdọ maa la awon eniyan
Ajetunmobi, ti won bi lojo kewaa, osu kewaa, odun 1985 lo ku lataari afefe gaasi to wi moo nilu Eko.
Agbẹjọro fun Gboluja Ikengboju to jẹ asofin to n ṣoju ẹkun Okitipupa/Ilajẹ ni ipinlẹ Ondo n'ile Igbimọ Asofin, Olumide Ogunjẹ ti ni awọn ko fara mọ idajo ile ẹjọ to n gbẹsun to nii ṣe pẹlu eto idibo ni Naijiria.
Àyànfẹ́ arakunrin ni, ati iranṣẹ tí ó ṣe é gbẹ́kẹ̀lé ninu iṣẹ́ Oluwa.
Nǹkan márùn ún tí awuyewuye òṣèlú ìpínlẹ̀ Edo kọ́ wa nípa òṣèlú Nàìjíríà Igbákejì gómìnà ìpínlẹ̀ Ondo Agboola Ajayi ti fẹgbẹ́ APC sílẹ̀ lọ PDP Báwó ni òògùn dexamethasone ṣe ń ṣiṣẹ́ lára Wo orin l'édè Yoruba àti Zulu tí Burna Boy fi fa ayélujára ya Ìdílé márùn-ún tó gbajúmọ̀ fún òwò ẹrú nílẹ̀ Yorùbá Wo obìnrin tó ń fi táyà ọkọ̀ ṣe àga àti àwọn ẹ̀ṣọ́ ilé Ẹ wo bí àwọn ọmọ Yoruba ṣe làlùyọ nídìí iṣẹ́ àgbẹ̀ ní Amerika Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí 3 sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 2:23 Fídíò, Water Generator: Ó leè ṣiṣẹ fún wákàtí mẹfà, kó tó sinmi, Duration 2,2310 Òkùdu 2020 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
Ofin ogún ni awọn alaṣẹ la kalẹ fun gbogbo akọroyin lati maa tẹle, diẹ lara wọn niyii: Ẹri pe o jẹ ọmọ ẹgbẹ akọroyin ni Naijiria, NUJ Iwe ẹri lati ọdọ ile iyawe-kawe apapọ Nigeria (National Library of Nigeria) Ileeṣẹ iwe iroyin to n ba a ṣiṣẹ gbọdọ maa pin ogoji ẹgbẹrun iwe iroyin lojoojumọ Aadọta ẹgbẹrun eniyan gbọdọ maa bẹ oju opo ayelujara iwe iroyin ori ayelujara wo lojumọ, iwe iroyin bẹ si gbọdọ ti wa fun ọdun maarun Iwe ẹri owo ori ọdun meji fun ileeṣẹ iroyin rẹ Ileeṣẹ iroyin rẹ gbọdọ ni ọọfisi si ilu Abuja, o si gbọdọ ni oṣiṣẹ ti ko din ni maarun Ileeṣẹ amohunmaworan ti wọn n wo jake-jado Naijiria tabi ogbontagi oniroyin nikan ni yoo ni anfaani lati ṣiṣẹ nile aṣofin apapọ Akọroyin gbọdọ ni iriri ọdun meji lori ọrọ ile aṣofin Ẹgbẹ oniroyin, NUJ, koro oju si awọn ilana tuntun naa Ẹgbẹ oniroyin (NUJ), ẹgbẹ awọn olootu iroyin, ati awọn oniroyin mi i ti bu ẹtẹ lu awọn ilana tuntun yii.
Abuku oloronbo ni Liverpool fi kan Man City ninu ifẹsẹwọnsẹ ti wọn gba kẹyin ninu idije Premier League, ami ayo mẹta sodo ni Liverpool fi ṣẹwọn leegun ẹyin.
tí wọn ń ṣe ohun tí yóo mú mi bínú,níṣojú mi, nígbà gbogbo.
Ó ní, “Nǹkan kan náà ni kí ẹ máa wí fún Esau, nígbà tí ẹ bá pàdé rẹ̀.
Bíótilẹ̀jẹ́pé ó ṣòro ó lò lákọ̀ọ́kọ́, nítorí kò mọ́n mi lára, kò pẹ́ náà tó fi mọ́nra.
Iwà ibàjẹ́ kò ni orúkọ meji, ẹni ba jalè ba ọmọ jẹ́.
"Eniola tun ṣalaye nipa bi awọ eeyan ṣe maa n bu lojojumọ nitori o jẹ ẹni to sanra, o si sọ pe eyii ko dun mọ oun ninu.
Ogbeni Amangbo tenumo ipinnu ile ifowopamo Zenith lati maa satileyin fun iko kookan lorile-ede Naijiria, ti o si tun seleri ibasepo ti o donmonron lojuna ati ran iko kookan lowo lati saseyori ninu awon idije won gbogbo.
Nígbàtí ìyá-àgbà bá nṣe iṣẹ́ òwú “Sányán” lọ́wọ́, a ṣa òkúta wẹ́wẹ́ fún ọmọ-ọmọ rẹ̀ lati ṣe ìṣirò ni èdè Yorùbá.
Ìrìnàjò China: Nnkan márùn ún tó ṣẹlẹ nigba tí Buhari ko sì nílé
Ìlú kan tí ó ṣe pàtàkì nínú ìtàn ni naples .
 fún ìdí èyí , bí okùnrin bá kú , àwọn ìyàwó irú ẹni bẹ ́ ẹ ̀ máa ṣe opó pẹ ̀ lú ìlànà àti àṣà yorùbá .
Ó ní, “Nígbà tí mo bá dé ibẹ̀, ó yẹ kí n fojú ba Romu náà.
Nígbà tí Batiṣeba gbọ́ pé wọ́n ti pa ọkọ òun, ó ṣọ̀fọ̀ rẹ̀.
Lagos Beach: Àwòrán tó làmììlaaka nípa àwọn òsìsẹ́ ẹ̀ṣọ́ etí òkún
Ọ̀jọ̀gbọ́n Margaret Read, obìnrin ni, ó sì yẹ kí ọmọ Yorùbá kọ́ ọgbọ́n lára obìnrin yìí, púpọ̀ nínú wa ni o sì ń wí pé kí ni obìnrin lé ṣe, pẹ̀lú ìrọ́jú sí ni àwọn òbí mìíràn fi ń fi ọmọ wọn sí ilé ìwé bí o bá sá ti lè jẹ́ obìnrin.
Dafidi sì bá wọn dá majẹmu níbẹ̀ níwájú OLUWA.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Nigeria Police: Ọ̀gá Àgbà Ọlọ́pàá ní kí àwọn ọlọ́pàá jà fún ara wọn 30 Ọ̀wàrà 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 1 Bélú 2020 Oríṣun àwòrán, NPF Ọga Agba Ọlọpaa lorilẹ-ede Naijiria, Mohammed Adamu ti paṣẹ fun awọn ọlọpaa kaakiri lati gbe ija ara wọn ja, ti ẹnikẹni ba kọju ija si wọn ni igbooro.
Jonatani dá a lóhùn pé, “Mo ti ọ̀pá tí mo mú lọ́wọ́ bọ inú oyin, mo sì lá a.
nítorí pé àwọn ọ̀mùtí ati àwọn wọ̀bìà yóo di talaka,oorun àsùnjù a sì máa sọ eniyan di alákìísà.
Ǹjẹ́ òfin wá lòdì sí àwọn ìlérí Ọlọrun ni bí?
Peru: Omi ara ọpọlọ ti wọn ti rẹ ni awọn fi n se ara rindin, ti wọn si tun n ta a fun awọn eniyan gẹgẹbi omi ẹlẹrindodo to n mu araji pepe.
Ninu àwọn ọmọ Adonikamu,orúkọ àwọn tí wọ́n dé lẹ́yìn àwọn tí wọ́n kọ́ dé ni:Elifeleti, Jeueli ati Ṣemaaya; orúkọ ọgọta eniyan ni wọ́n kọ sílẹ̀ pẹlu wọn.
Owó tí àwọn olùdásílẹ̀ wọn fẹ́ ẹ pa ní àfojúsùn wọn.
Àyájọ́ ọmọbìnrin gba gbogbo ayélujára tán Ìyá Leah Sharibu ké gbàjarè sí ìjọba Buhari 'Àwọn ọ̀tẹlẹ̀múyẹ́ tí n ṣèwádí ohùn Leah Sharibu' Ìdí tí Bàbá Leah Sharibu fi yarí pé ọmọ òun kò kú Ojuti nla ni akẹkọ Dapchi kan ti ko ti de Olubadamọran fun aarẹ Buhari lori eto iroyin ati ifitonileti gbogbo, Garba Shehu lo sọrọ itunu yii pe ijọbamọ pe Leah ṣi wa laaye.
Nítorí náà, èmi náà óo lo àwọn eniyan lásánlàsànláti mu àwọn náà jowú,n óo sì lo aṣiwèrè orílẹ̀-èdè lásánlàsàn kanláti mú wọn bínú.
Ni ọjọ Ẹti ti kọja l'awọn igara ọlọṣa kan ya wọ ilu Isanlu ni ipinlẹ Kogi nibi ti wọn ti pa awọn ọlọpaa ataraalu nibẹ l'asiko ti wọn lọ digun ja banki kan lole nibẹ Alhaja Kudirat Abiola akọni obìnrin, tó gba ọkùnrin mẹ́fà kí wọ́n tó leè pa á Abacha àtàwọn ọba àlàyé ló jọ pinnu láti kó owó pamọ́ sókè òkun - Al Mustafa Bí Gómìnà Makinde bá ṣẹ̀ mí, lẹ́tà lásán ló jẹ mí- Aláàfin Ọ̀yọ́ Irú èpè wo ni Aláàfin Aolẹ ṣẹ́ fún ìran Yorùbá?
Won ni lo lati ma ri ise agbe gege-bi ise akanse ti yoo mu owo wole ju ohun igbafe lo.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Hospital Wedding: Oṣù kan péré ni Tash fi ṣe ìgbéyàwó pẹ̀lú Simon kó tó kú Bakan naa lo salaye pe awọn to n bọ Ọsun kii se abọrisa, ajọdun omi si ni ọdun naa, nitori omi lo n gbe ẹmi wa ro.
Àwọn tí ẹ kórìíra ni yóo máa jọba lórí yín, ẹ óo sì máa sá nígbà tí ẹnikẹ́ni kò le yín.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Hajj 2020: ìjọba Saudi ní kò sí ààyè fáwọn alálàájì láti fi ọwọ́ kàn Ka'aba 23 Òkùdu 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 7 Agẹmo 2020 Oríṣun àwòrán, AFP Awọn eleto Hajj lorileede Saudi Arabia ti kede pe, ko ni saye fawọn alalaji lati fọwọ kan Ka'abah lasiko Hajj ọdun yi.
Oríṣun àwòrán, @Tambuwal_2019 T ambuwal, tó ṣojú ẹgbẹ́ PDP ló ní ìbò 512,002 nínú àpapọ̀ ìbò tí wọn kede rẹ, nigbati alátakò rẹ̀ látinú APC, Ahmada Aliyu ní 511,661.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Cancer: Àṣe ara mi ni iso ti n run gbogbo bí mo ṣe n ṣèrànwọ́ lórí jẹjẹrẹ Kini o ya awọn agba ọjẹ yii sọtọ ninu litireso itan arosọ Yoruba?
OLUWA sọ fún mi ní ìgbà ayé ọba Josaya pé: “Ṣé o rí ohun tí Israẹli, alaiṣootọ ẹ̀dá ṣe?
Ṣugbọn nítorí pé iranṣẹ mi, Kalebu, ní ẹ̀mí tí ó yàtọ̀, ó sì jẹ́ olóòótọ́ sí mi, n óo mú un dé ilẹ̀ tí ó lọ wò, ilẹ̀ náà yóo sì jẹ́ ti àwọn ọmọ rẹ̀.
Afirika ni awon amuye to to fun sise iwe iroyin atigbadegba yii nitori pe awon aso won ati awon amunidara to mose gidi kun ile yii ni awon ti ise won ti je itewogba kaakiri agbaye”.
Ohun tí ó dára ni pé kí ọkàn yín gba agbára nípa oore-ọ̀fẹ́ Ọlọrun, kì í ṣe nípa ìlànà ohun tí a jẹ, tabi ohun tí a kò jẹ, irú ìlànà bẹ́ẹ̀ kò ṣe àwọn tí ó ń tẹ̀lé e ní anfaani.
Ọba bá jáde kúrò ní ìlú, gbogbo ìdílé rẹ̀, ati àwọn iranṣẹ rẹ̀ sì tẹ̀lé e.
Wò ó bí Alaafin àti aya àkọ́fẹ́ rẹ̀, Olorì Abibat ṣe pàdé ní èwe Coronavirus ti fa ọ̀wọ́ngógó oúnjẹ ní ìpínlẹ̀ Eko, Kano, Rivers àti Abuja- NBS Àwọn èrò yarí lórí sísan owó àyẹwò covid-19 bí bàálù ilẹ̀ òkèèrè ti ba s'Abuja lẹyìn oṣù márùn ún Ẹ wo ààrẹ orílẹ̀-èdè tó ń ṣèdárò Ẹja akóredé tó d'olóògbé Nibayii, eeyan 1,070 lo ti ba ajakalẹ arun naa lọ ni Naijiria.
 Obasanjo wa tẹnumọ pe o yẹ ka sisẹ lorilẹede yii, gẹgẹ ba se n gbadura ninu ọdun tuntun 2021, ko le jẹ ọdun ologo fun wa, amọ lai jẹ pe a sisẹ, eyi ko le ri bẹẹ."
N óo dáná sun odi Damasku, yóo sì jó ibi ààbò Benhadadi.
House help: Ìgbà márùn ún rèé tí àwọn ọmọ ọ̀dọ̀ ti gé ẹ̀mí ọgá wọn kúrú
Ẹ̀yin náà ṣá fi ojú yín rí ohun tí mo ṣe sí àwọn ará Ijipti.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Diego Maradona: Ohun mẹ́wàá pàtàkì nípa Maradona àti ìbáṣepọ̀ rẹ̀ pẹ̀lú ẹlẹ́sẹ̀ ayò Diego Costa rèé 26 Bélú 2020 Oríṣun àwòrán, Getty Images Erin wo, ajanaku sun bi oke!
Vector ayarasọrọ gbajugbaja oju tawọn ọmọ Naijiria n gba fun lasiko yii ni wọn jọ kopa ninu eré onijo-lorin ọhun.
Gbogbo wa ti ṣáko lọ bí aguntan, olukuluku wa yà sí ọ̀nà tirẹ̀,OLUWA sì ti kó ẹ̀ṣẹ̀ gbogbo wa lé e lórí.
Ki o si mu 'Cardless Withdrawal' lara awọn igbesẹ ti o ba gbe wa fun ọ.
Daddy Freeze: 'Kátàkárà ni owó orí gbígbà lórí ọmọbìnrin jẹ́'
Bí a óo bá dá a pada sí ibi tí wọ́n ti gbé e wá, kí ni kí á fi ranṣẹ pẹlu rẹ̀?
Àwọn ọmọ Kohati ni: Amramu, Iṣari, Heburoni, ati Usieli.
Ní ọjọ́ kan, Ọlọrun sọ fún Abramu pé, “Jáde kúrò ní ilẹ̀ rẹ, láàrin àwọn ìbátan rẹ, ati kúrò ní ilé baba rẹ lọ sí ilẹ̀ kan tí n óo fi hàn ọ́.
"Ó sì yẹ kí á ní àpérò lórí rẹ̀.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Security Meeting: A fẹ́ àgbékalẹ̀ ọlọ́pàá agbègbè láti pèsè ààbò tó rinlẹ̀ 25 Òkùdu 2019 Awọn gomina mẹfẹẹfa to n bẹ nilẹ kaarọ-oojiire lo peju-pesẹ lati jiroro, lori eto aabo jakejado awọn ipinlẹ ti wọn n ṣoju fun.
Ìrí tí mo rí, ṣe mo rí atare?
Awọn yoku ni Festus Ojewunmi ati Wole Oladapo lati Virtues Restorative Justice Initiative.
Nítorí mo sọ fun yín pé láti àkókò yìí lọ, n kò tún ní mu ninu èso àjàrà mọ́ títí ìgbà tí ìjọba Ọlọrun yóo fi dé.
Nitori naa ni BBC Yoruba fi ṣe alaye lẹkunrẹrẹ nipa ẹni to ṣeeṣe ko gbade BBNaija ti ọdun yii.
” Baraki bá sọ̀kalẹ̀ láti orí òkè Tabori pẹlu ẹgbaarun (10,000) ọmọ ogun lẹ́yìn rẹ̀.
Sùgbọ́n ó jọ bi ẹni pe wọ́n ti ṣe ileri fún wọ́n pé wọ́n o rówó gbà ni ọjọ ẹtì ọ̀la yìí.
Ó si tun ti awọn papakọ ọkọ ofurufu pa lẹyin ti Naijiria ti ni akọsilẹ ajakalẹ arun coronavirus.
iye ibo 1,033, 695 lati gbo ewuro si alatako rẹ 
Ọgbẹni trump sọ pe ijọba idunkukulaja mọ ni ti Soleimani n dari ti wa sopin pẹlu ikọlu to waye ni papakọ ofurufu Iraq lọjọ ẹti.
- Ọ̀gá àgbà ọlọ́páà Awakọ̀ agbókùú, ọlọ́pàá, ológun, oníròyìn ló máa ń kọ́kọ́ dìbò ní Ghana, bó ṣe ń lọ rèé Aarẹ Nana Akufo Addo lo ni ida ibo mọkanleladọọta o le diẹ ninu ọgọrun, ninu ibo aarẹ to waye lorilẹede Ghana lọjọ Aje, ti alatako rẹ si ni ida ibo mẹtadinlaadọta ati diẹ ninu ọgọrun.
Mika gbé ẹẹdẹgbẹfa (1,100) owó fadaka náà pada fún ìyá rẹ̀.
Ikọ̀ ọlọ́pàá tó ní ǹkan ìjà, ìsọ̀rí mẹ́ta ọlọ́pàá àti àwọn irinsẹ́ amólè ni ọ̀gá àgbà pátápátá àwọn ọlọ́pàá kó ráńsẹ́ sí ìpinlẹ Kwara.
Baraba ni kí o dá sílẹ̀!
àwọn irinwo òdòdó idẹ tí wọ́n fi ṣe ọnà ní ìlà meji meji yí ọpọ́n orí àwọn òpó náà ká.
Kí ẹ ṣe àfarawé igbagbọ wọn.
Ṣùgbọ́n pé o mọ̀ pé ayédèrú ìròyìn wà, kò túmọ̀ sí pé o le daa mọ̀ tí o bá ri i.
Lẹ́yìn ọ̀sẹ̀ kan, CAF ní kí Esperance dá ife ẹ̀yẹ CAF Champions League padà ‘Buhari gbà wá o, Seyi Makinde n fi jàǹdùkú halẹ̀ mọ́ wa láti kúrò lọ́ọ́fìsì’ Ganduje ń bèèrè bí Emir Sanusi ṣe se owó ìlú mọ́kumọ̀ku Ilé ìgbìmọ̀ aṣòfin ikẹ̀jọ kógbá sílé l'Abuja Bayii ni ajọ NBC ti kede pe ileeṣẹ mejeeji to jẹ ti DAAR Communications ko gbọdọ ṣiṣẹ titi awọn yoo fi gbẹsẹ kuro lori ofin to de wọn yii.
Lẹka karakata ati owo ṣiṣe, Israel Adebajọ lalẹ gaara, ti orukọ ile iṣẹ itawe rẹ Stationery Stores si kale ka'ko.
Ajo eto idibo INEC tun ti fi kun ọjọ ti won fopin si  iforuko sile lati gba kaadi idibo si ọjọ kọ́kànlélọ́gbọ̀n, yato si ọjọ kẹ́tàdínlógún osu kẹjọ.
Ninu oro eyi ti oludari iko omo ogun ni eka iforotonileti ati igbodegba, ogagun Texas Chukwu, so pe, iko omo ogun mejilelogun tise akanse Operation Lafiya Dole lo ja ijagbara tu awon eniyan naa sile kuro nipo ahamo.
Olajide Omotayo fagbahan Chee Feng  olukopa fun Malaysia pelu ami-ayo metala si mokanla(13-11), marundinlogun si metala(15-13), mokanla si meje(11-7) ni itele n tele.
EndSARS Protest: Àwọn olùwọ́de ní ''májèlè ni oúnjẹ tí MC Oluomo gbé wá fún wa, a ò jẹ''
Ó wà ní àkọsílẹ̀ pé, “Kí ìwọ Ọlọrun lè jẹ́ olódodo ninu ọ̀rọ̀ rẹ,kí o lè borí nígbà tí wọ́n bá pè ọ́ lẹ́jọ́.
Jesu sọ fún un pé, “Máa tẹ̀lé mi.
US Election 2020: Wo ìyàtọ̀ láàrin ìjọba Joe Biden sí ti Donald Trump bó ṣe kan orílẹ̀èdè àgbáyé
Mínísita fun ọ̀rọ̀ irinajo ofurufu Hadi Sirika, ti kọkọ sọrọ naa tẹlẹ pe ìjọba yóò gbé papakọ ofurufu mejeeji pa.
Lara awọn to tun wa ni papa ofurufu naa ni Oji Ngofa, asoju orile ede Naijiria fun orile ede Netherlands,ogbeni Robert Petri  to je asoju orile ede Netherlands fun orile ede Naijiria , ogagun Veenhuijzen,oluranwo oba orile ede Netherlands ati awọn oga agba fun ile-ise to n ri si oro ile okeere lorile ede Netherlands .
Spaghetti, mílíìkì, Chivita àti Àǹkàrá sọ Rabiu dèrò ẹ̀wọn ni Eko N650,000 péré ni mò ń gbà gẹ́gẹ́ bíi owó oṣù -Gomina Ọyọ Amọ, o fikun un wi pe ko ba ofin ipinlẹ Eko mu, ki ọgọọrọ eniyan wọ ipinlẹ Eko lati ṣiṣẹ wiwa ọkada lai ni iwe aṣẹ tabi papakọ ti wọn ti n ṣiṣẹ.
Oríṣun àwòrán, Others Àkọlé àwòrán, Edo state news: Godwin Obaseki ti darapọ̀ mọ́ ẹgbẹ́ òṣèlú PDP Godwin Obaseki ti darapọ̀ mọ́ ẹgbẹ́ òṣèlú People's Democratic Party Gómìnà ìpínlẹ̀ Edo Godwin Obaseki ti kúrò ní ẹgbẹ́ òṣèlú All Progressive Party lọ si ẹgbẹ́ òṣèlú People's Democratic Party.
 "" Lasiko yìí, ǹkan ti a mọ ni pe ọ̀pọ̀ àwọn ènìyàn to ni ààrun náà ni la'ti ara ènìyàn si eniyan"" Nkan ti a mọ nipa Coronavirus Aisan, ti wọ́n n pe ni 2019-nCov, ni iru àisan coronavirus to tun n wa lode nisinyi jẹ èyi ti ko si lára ènìyàn tẹ́lẹ̀ Coronavirus jẹ aisan aifojuri mẹfa iru rẹ̀ lo si wà, sùgbọ́n eleyii ni ẹlẹkeje iru rẹ̀, ohun si ni àwọn onimọ sọ pe o n tà ka Ajọ WHO ti gba àwọn ènìyàn niyanju láti ma ni ibaṣepọ pẹlu ẹranko abẹmi, ki wọ́n si se ẹran ati éyin wọ́n daradara."
Yobe Desert Stars 16:00Kano Pillars ?
wọ ̣ ́ n bí rodney johnson ní ọjọ ́ karùndínọ ́ gbọ ̀ n oṣù kẹ ́ sàán , ọdún 1965 ( october 25 , 1965 ) sí ìdílé david e.
Akiṣi sọ fún Dafidi pé, “Ìwọ ati àwọn ọkunrin tí wọ́n wà pẹlu rẹ yóo jà fún mi.
“Bí ẹnikẹ́ni bá dẹ́ṣẹ̀, tí ó ṣe ọ̀kan ninu àwọn nǹkan tí OLUWA pa láṣẹ pé ẹnikẹ́ni kò gbọdọ̀ ṣe, bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé kò mọ̀, sibẹ ó jẹ̀bi, yóo sì san ìtanràn ẹ̀ṣẹ̀ rẹ̀.
Ṣugbọn nígbà tí ó di àṣáálẹ́, Lea ni wọ́n mú wá fún Jakọbu dípò Rakẹli, Jakọbu sì bá a lòpọ̀.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Wasiu Ayinde: Èmi kìí ṣe Mayegun olórin àmọ́ mo fẹ́ jẹ́ olùlàjà nílẹ̀ Yorùbá 15 Sẹ́rẹ́ 2020 Oríṣun àwòrán, Wasiu Ayinde Gbajugbaja olorin fuji, Wasiu Ayinde to ṣẹṣẹ jẹ oye mayegun Ilẹ Yoruba ti sọ pe, oye naa kii ṣe lati buga, ṣugbọn o jẹ lati tun ilẹ Yoruba ṣe.
Èmi nìyí, n kò lè roko.
Iwọ, Òmùgọ́diméjì, ẹni tí o pè ọ ní Òmùgọ̀diméjì kò pè ọ́ bí o ti yẹ kí ó pè ọ.
N óo wá kọ orúkọ Ọlọrun mi ati orúkọ mi titun sí i lára, ati ti Jerusalẹmu titun, ìlú Ọlọrun mi, tí ń sọ̀kalẹ̀ bọ̀ láti ọ̀run, láti ọ̀dọ̀ Ọlọrun mi.
Lẹyin ọpọ awuyewuye to waye lori ẹsun ifipabanilopọ ti iyawo gbajugbaja olorin ni, Dakolo, iyẹn Busọla fi kan alufa agba ijọ Commonwealth of Zion Assembly, COZA, Biọdun Fatoyinbo, alufaa ijọ naa ni oun ti kọwe fi ipo silẹ fun saa diẹ.
"O sọ pe ""Afojusun wa ni awọn eeyan to n lo opo ikansiraẹni lati fi pin iroyin ẹlẹjẹ ati ọrọ ikorira, leyi to lewu fun irẹpọ wa gẹgẹ bi orilẹ-ede kan."
" Ikọlu ati ipaniyan laarin awọn darandaran fulani ati awọn agbẹ olohun ọsin to ti di kale-n-kako lawọn ipinlẹ bii Benue, Taraba, Adamawa ati oniruru ijinigbe kaakiri kun ara ohun to sokunfa bii awọn asofin apapọ se gbe apero ọrọ abo silẹ lati jiroro sna abayọ.
O ni iyanselodi ti won bere lati ojo kerinla osu kokanla odun 2017 lati fi beere fun ile isewadii to kunoju owo ti n di nkan miran bayii.
Iwọde ko ni k'awọn eeyan ma sokun ifẹ pọ; ki wọn tun ṣe ayẹyẹ ọjọ ibi Iwọde yii ti bi ọmọ orisirisi.
Lẹ́yìn náà, gbogbo àwọn ọkunrin inú ìdílé Matiri bẹ̀rẹ̀ sí tò kọjá, gègé sì mú Saulu ọmọ Kiṣi.
” Bẹ́ẹ̀ ni ọba ati Hamani ṣe lọ sí ibi àsè tí Ẹsita ti sè sílẹ̀.
O ni Kayode gbẹyin awọn ọmọ ṣẹ rẹ lati sọ fun Obinrin naa ko san owo ẹgbẹrun lọna ọgọrun Naira ki o ba le fi ọrọ naa ṣe oku ọrun.
O ni: Ibi ti wọn so o mọ pẹlu awọn ewurẹ, ni a ti ba ọmọ naa ninu igbọnsẹ gbígbẹ to jẹ ti ẹ ati ti ewurẹ."
Mo wà níbẹ̀ nígbà tí ó dá ojú ọ̀run sí ààyè rẹ̀,tí ó ṣe àmì bìrìkìtì sórí ibú,ní ibi tí ó dàbí ẹni pé ilẹ̀ ati ọ̀run ti pàdé,
Gbogbo wọn ni a ti kọ́ ní ogun jíjà tí wọ́n sì jẹ́ akọni.
Ṣugbọn bayii ti ojú ti la sii, ti wọn ti n ri ògo ti Ramla n gbe wa fun Somalia, o ni gbogbo eeyan ti tẹwọgba iṣẹ́ Ramla.
Ọrọ atunṣe awọn iyara ikawe yii yẹ ko kari gbogbo fasiti ni.
Ṣé Olodumare a máa yí òdodo pada?
Asofin Enang fikun un oro re pe,
Wọn ní àwọn n ṣé iwọde náà láti fi ehonu hàn lórí àbájáde èsì ìdìbò abẹnu ẹgbẹ òṣèlú PDP to waye lopin ọsẹ to kọjá.
jiroro le lori fun igba akọkọ lojo isegun ni oludari omo egbe ti o poju nile
Bí o bá rí kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ ẹni tí ó kórìíra rẹ, tí ẹrù wó kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ náà mọ́lẹ̀, tí kò lè lọ mọ́, o kò gbọdọ̀ gbójú kúrò kí o fi sílẹ̀ níbẹ̀, o níláti bá a sọ ẹrù náà kalẹ̀.
Nọmba naa ati orukọ aṣedanwo yoo wa papọ, nitorinaa ma ṣe gbagbe àwọn nkan wọnyi.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Boko Haram: Ọwọ́ iléeṣẹ́ ológun tẹ afurasí tó pa akẹẹgbẹ́ rẹ̀ 1 Èrèlè 2018 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 30 Agẹmo 2020 Oríṣun àwòrán, Others Ileeṣẹ oloogun Naijiria ti sọ pe, akẹgbẹ ọmọ ogun Lẹfutanaati Babakaka Shehu Ngorgi, ti ọpọlọ rẹ ko ṣiṣẹ dede mọ lo ṣeku pa a ni ipinlẹ Bornu.
Èmi gbin irúgbìn, Apolo bomi rin ohun tí mo gbìn, ṣugbọn Ọlọrun ni ó ń mú kí ohun ọ̀gbìn dàgbà.
8bn) lọdun 2017, igbagbọ si wa pe yoo di ilọpo meji nigba ti yoo ba fi di ọdun 2027.
Mo ti rí i, mo wá ń jẹ́rìí pé òun ni Ọmọ Ọlọrun.
Ni ọdun to kọja, iyẹn 2019 nikan, igba mọkanla ọtọọtọ ni itakun ina pinpin lorilẹede Naijiria daku ti gbogbo orilẹede Naijiria si wa laisi ina ọba.
Royal baby: Harry ní ojú gbogbo yóò rí ọmọọba tuntun ní ọjọ́ méjì sásìkò yí
Ṣugbọn nisinsinyii ó wúlò fún ọ ati fún mi.
Enu ọna ilu naa ni eniyan ti le gba iwe irinna bakan naa.
O sì fi ògo ati ọlá dé e ládé.
-Olugbo Obateru Akinruntan Oloye Abdul Tawab Olaitan Ile-Aje Adeniyi ni o kopa gẹgẹ bi ''Toromagbe'' ninu fiimu naa, to si jẹ ọkọ fun ''ọwọ otori'' ti wọn gbe ninu aginju.
Akọgun Tola Adeniyi: Oríṣun àwòrán, Others Nínú ọ̀rọ̀ rẹ̀ Akọgun Tola Adeniyi sàlàyé pé, nǹkan to ṣe gbòógi jùlọ ni pé, YWC ko fi ìgba kan yan Akintoye gẹ́gẹ́ bi olórí, fìdí hẹ́ẹ lásan ni.
Agbenusọ ilé iṣẹ́ ọlọ́pàá ní ìpínlẹ̀ náà, Abímbọ́lá Oyèyẹmí, sọ fún BBC wípé ọmọ olóògbé Agholor ló fi tó àwọn ọlọ́pàá létí wí pé bàbá òun ti yìn'bọn pa ara rẹ̀ lẹ́yìn tí ó jí tí ó sì wẹ̀ ni ọjọ́ Ọjọ́bọ ní ilé rẹ̀ tó wà lágbègbè Sheraton Estate tí ó wà ní Ìjokò.
Koda Elebuibon ni oun ti kọ awọn akẹkọọ fasiti ipinlẹ San Francisco ri l'Amerika.
Kòsí ẹnikẹ́ni tí ó nràn án lọ́wọ́, kò sì ní ajá-afọ́jú rárá, àfi ọ̀pá-afọ́jú tí o mú dání.
Ayẹyẹ àṣà ọnà Yorùbá ló ṣẹlẹ̀ ní ọgbà Clissold fún ọjọ́ méjì gbáko.
sọ fún àwọn ọmọ Israẹli pé, “Nígbà tí ẹ bá dé ilẹ̀ tí n óo fun yín, tí ẹ bá sì ń kórè nǹkan inú rẹ̀, ẹ níláti gbé ìtí ọkà kan lára àkọ́so oko yín tọ alufaa lọ.
Akintola pada si ilu Ogbomoṣo lọdun 1922 lati maa gbe pẹlu awọn baba baba rẹ, nibẹ lo ti lọ ile iwe Baptist day school.
" Nibayii, iwadii ti n lọ lori ọrọ naa.
EFCC gbé Mompha afurasí ọmọ Yahoo lọ ilé ẹjọ́ lònìí Darandaran Fúlàní kankan kò ṣí kúrò l'Ọ́ṣun - olórí Fulani A ṣe tán láti yọ ìjìyà ikú kúrò nínú àbá ọ̀rọ̀ ìkórìra- Sẹ́nẹ́tọ̀ Sabi Eyi gan an fẹẹ lo faa ti gomina ipinlẹ Eko, Babatunde Sanwo-olu fi kede pe laipẹ gbogbo irinna ọkọ to ba jẹ ajagbe ni wọn yoo fi mọọ si alẹ dipo ọsan tabi ojumọmọ.
Ni ọjọ kọkanlelọgbọn oṣu Keje ọdun 2019, Amusan kọwe fi ipo rẹ silẹ gẹgẹ bi adari ati alaga igbimọ adari ileeṣẹ Resourcery Plc.
Ọmọ ọdún mẹ́rìnlá kàwé gboyè jáde ni Oxford N650,000 péré ni mò ń gbà gẹ́gẹ́ bíi owó oṣù -Gomina Ọyọ Van Dijk gbadé UEFA mọ́ Messi àti Ronaldo lọ́wọ́ Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Lati kekere ni wọn ti maa n fi Ruiz ṣe yẹyẹ nitori bo ṣe sanra, amọ bayii, o ti 'd'oju ti awọn ẹlẹgan, ti ọrọ rẹ si di ẹni ti a ro pe ko le pagọ, to kọ ile alarinrin.
Toyin Abraham ní ìròyìn òfégè pé, òun ti di asojú àjọ to n gbógun ti ààrùn Corornavirus ní Naijiria (NCDC), Toyin Abrahim ni ìròyìn òfégè ní àti pé an fi kú pé, òun gba ipo akẹgbẹ́ òun kan láti di aṣojú àjọ NCDC ni.
Gbogbo ìlú tí àwọn Filistini ti gbà lọ́wọ́ àwọn ọmọ Israẹli, láti Ekironi títí dé Gati, ni wọ́n dá pada fún wọn.
Arakunrin yii ni Inú oun si dùn láti sọ ọ́ pé ò ń fi owó Yahoo Yahoo ran ara oun lọ́wọ́ nílé ìwé.
Awọn miran tilẹ fi awon iroyin ti Adedayọ ti kọ fun awọn ile isẹ iroyin kọọkan han, nibi to ti tako isejọba ẹgbẹ APC to wa lode.
Ninu ikede ti ajọ to n gbogun ti ajakalẹ arun lorilẹede Naijiria, NCDC fi sita lọjọru, ọgọrin ninu wọn lo wa lati ipinlẹ Kano, mẹrundinlaadọta ninu wọn wa lati ilu Eko, mejila ninu wọn wa lati ilu Gombe, mẹsan ninu wọn wa lati Bauchi ati Sokoto.
Ní orí òkè náà ni mo ti rí nkan ìyàlẹ́nu.
Nisinsinyii, mo ti ṣe ìpinnu láti kọ́ ilé fún OLUWA Ọlọrun mi, gẹ́gẹ́ bí ìlérí rẹ̀ sí Dafidi, baba mi, pé ọmọ rẹ̀, tí yóo gun orí oyè lẹ́yìn rẹ̀, ni yóo kọ́ ilé ìsìn fún òun.
2025,ni eyi ti o tumo si pe yoo wa lori aleefa titi di odun 2030.
Àwọn asamọ àti òwe tó jẹ mọ́ ogun ìjàyè: Asamọ tó nii ṣe pẹlu ogun ìjàyè lo ni ọpẹ Ìjàyè là bá bí léèrè ogún Ogunmola""Òwe tó sì rọ mọ ogun náà lo ní ""A kì ni, n jẹ a kì ni, a fi ní hàn, n jẹ a fi ní hàn, èwo ni ọọku ara Ìjàyè ni ojúde Ogunmola""Ẹ̀kọ́ tí ìtàn ogún Ìjàyè kọ́ wa: Ẹ̀kọ́ àkọ́kọ́ tí ogún Ìjàyè kọ wá ni pé, ká ṣe ara wa ni ọkàn nilẹ Yoruba."
Ilẹ Amẹrika ni Ajagba to ti ṣoju orilẹede Naijiria ri ninu idije ''Olympics'' fi ṣe ibugbe bayii lẹyin to ti wa niluu Eko fun ọpọlọpọ ọdun.
L'Ọjọrun ọsẹ to n bọ ni Man City yoo tun koju alatako wọn miran to lami laaka, Manchester United.
OLUWA bá Jeremaya sọ̀rọ̀ lẹ́yìn tí Nebusaradani, olórí àwọn tí ń ṣọ́ ọba Babiloni, tú u sílẹ̀ ní Rama.
Ó wá bi wọ́n pé, “Ta ni ninu yín tí ọmọ rẹ̀, tabi mààlúù rẹ̀ yóo já sinu kànga ní Ọjọ́ Ìsinmi, tí kò ní fà á yọ lẹsẹkẹsẹ?
Lẹ́yìn tí wọ́n ti gúnlẹ̀, wọ́n dé ilẹ̀ Genesarẹti.
N óo fi ìdí ìdílé rẹ̀ múlẹ̀, yóo sì máa ṣe iṣẹ́ alufaa níwájú ẹni àmì òróró mi.
iroyin ootọ yin ni isẹ gidigidi ti o lee se lati dekun awọn iroyin eke.
Baba agba kan nilu naa ni igba ikẹyin ti ẹnikan mu ẹyẹ abami igun yii wa si agbegbe wọn ni Boko Haram.
Ọ̀rọ̀ tí mo ti ba yín sọ jẹ́ ọ̀rọ̀ ẹ̀mí ati ti ìyè.
Iru awọn ironu yii le mu ọ ni itura lati oju oorun rẹ, o si le ji ọ pada s'áyé.
Ajọ NFF lo kede iku rẹ loju opo Twitter wọn.
Ademọla Adeleke: Àwọn akẹẹgbẹ́ mi ní iléẹ̀kọ́ girama mọ̀ mi bíi ìsáná ẹlẹ́ẹ́ta
Báyìí ló ṣe fún ọdún meji, tí ó fi jẹ́ pé gbogbo àwọn tí ń gbé Esia: ati Juu ati Giriki, ni ó gbọ́ ọ̀rọ̀ Oluwa.
Coronavirus: Agbábọ́ọ̀lù Man U tẹ́lẹ̀, Marouane Fellaini, Paulo Dybala àti ọ̀rẹ́bìnrin rẹ̀ lùgbàdì covid-19
Jẹẹsí Super Eagles: N5,000, N3000, N2,500.
Iṣẹ́ burúkú wọn ju ti àwọn baba ńlá wọn lọ.
 Òun ni ìlú tí ó tóbi ṣe ẹ ̀ kẹ ́ ta ní ilẹ ̀ italy .
ati àwọn àlejò tí wọ́n wà láàrin wọn.
Awọn obi miran tun ni ti ọmọdebinrin Amina, ti wọn ni afurasi naa ba lopọ lọmọ osu mẹsan ati awọn obi Khadijat, ti wọn ni ọmọ ọdun kan ati osu marun ni Aliyu ti ba a lopọ.
O ni oun lo fun iṣẹ ẹgbẹ oselu PDP ni ipinlẹ Ondo, sugbọn oun fun ori ade ni atilẹyin lati yan Babalọja Ìpínlẹ̀ Oyọ.
Ní ọjọ́ kẹsan-an oṣù kẹrin, ìyàn mú ní ààrin ìlú tóbẹ́ẹ̀ tí àwọn ará ìlú kò fi rí oúnjẹ jẹ mọ́.
George Floyd Funeral: Bí ètò ìsìnkú George Floyd ṣe lọ rèé ní ìlú rẹ̀ Oríṣun àwòrán, Getty Images Ọjọ kẹsan an oṣu kẹfa ọdun 2020 ni George Floyd wọ kaa ilẹ sun ni ilu ibi rẹ, Houston.
Ẹẹmeji ọtọọtọ ni ikọ Super Eagles paarọ agbabọọlu; Awaziem lo kọkọ rọpo Shehu ni iṣẹju mọkanlelogoji, ti Mohammed Musa na si wọle sori papa lati rọpo Mikel Obi iṣẹju mẹtadinlaadọta ni idije naa.
25 Bélú 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 26 Bélú 2020 Oríṣun àwòrán, @Ooni Ni kopẹkopẹ yii ni okiki kan kaakiri pe ilu Ile Ifẹ ti ni Arẹmọ tuntun.
Sunday James ṣalaye pe igbesẹ yii waye lataari aṣẹ lati ọdọ Aarẹ Buhari pé ki wọn ṣeto iforukọ silẹ àwọn alejo to n wọ Naijiria.
Oríṣun àwòrán, Mike bamiloye/facebook Ọmọ Eleme ni ipinlẹ Rivers ni Lawrence Oyor, wọn bi i lọjọ kẹrindinlogun oṣu kẹfa ọdun 1992.
Nítorí Oluwa Ọlọrun wa, Olodumare jọba.
Awọn eniyan kan si padanu ẹmi wọn.
Ọwọ tẹ àwọn ọlọ́pàá tó fìyà jẹ obìnrin kan lọ́nà àìtọ́ n'Ibadan Obìnrin àti ọmọdé tó há sábẹ́ ilé tó wó ní Ebute Meta ti ń gba ìtọ́jú, LASEMA ń ṣàyẹ̀wò ilé náà lọ́wọ́ Yakubu Dogara padà sí APC, Buhari kí i kúàbọ̀ ní Aso Rock Wo àwọn tí wòlíì ríran sí pé COVID-19 yóò pa ní ìpínlẹ̀ Edo l'óṣù kẹsàn án Gẹgẹ bi ohun to sọ, oun ati ololufẹ rẹ ọhu ti n bara wọn bọ lati nnkan bi ọdun mẹrinla gbako.
"Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ìdí tí mo fi pa irọ́ ìgbéyàwó lórí Facebook Àwọn ìbejì yabo Igbó Ọrà fọ́dún ìbejì lágbàáyé ‘Alẹ́ làwọn ọkùnrin fẹ́ bá mi jáde, torí mo kọ ilà’ Àlàyé rèé lórí ìdí tí Atiku fi yan Peter Obi ní igbakejí ààrẹ Ẹlẹ́wọ̀n, ẹni ọgọ́rùn ọdún n bẹ̀bẹ̀ fún òmìnira Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ọrẹ Falọmọ: Buhari yóò rí ìbò Yorùbá gbà ju Atiku, Ọbasanjọ lọ ""Ilẹ Afrika ko leebori ibẹru ogun okoowo titi ti yoo fi ni aseyọri bii ida aadọta ninu eto okoowo laarin awọn oril-ede to wa nibẹ."
Gege bi o se so , o ni lojo Aje ni minisita fun oro ise lorile ede Naijiria, Chris Ngige ti gbe iye owo ti  awon osise fe maa gba, wa si ipade fun won lati gbaa yewo.
”Wọ́n bá mú owó fadaka kan fún un.
Ida mẹfa ninu mẹwaa awọn ti PERC ṣe fihan pe niṣe lo yẹ ki ijọba kọọkan ṣi okowo pada ki awọn eeyan si maa ba karakata lọ ṣugbọn ki wọn ṣi maa bọwọ fun ofin asiko isede naa Nigba ti awọn miran fi ibẹru han lori jijade pada, ṣugbọn, awọn miran ni ebi kii wọnu ki ọrọ miran bii Covid 19 bo ṣe lagbara to naa tun wọ ọ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù CAF Champions League: CAF pàṣẹ àtúngbá ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ àṣekágbá CAF Champions League 6 Òkùdu 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, CAF ní ifẹ ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ àṣekágbá tí wọ́n kọ́kọ́ gbá tako àṣẹ àtò ìdíje bọ́ọ̀lu Ajọ to n ṣakoso ere bọọlu afẹsẹgba ni ilẹ Afirika, CAF ti paṣẹ ki wọn tun ifẹsẹwọnsẹ aṣekagba idije CAF Champions league to waye ni ọjọ kọkanlelọgbọn oṣu karun ọdun 2019 gba.
Àmí ẹ̀yẹ yìí túmọ̀ si pé àwọn mẹ́tà yìí ló gbá bọọlù sáwọn jùlọ nínú ìdíje Premier League.
wákàtí 3 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBCwákàtí 6 sẹ́yìn Ìjọba ìpínlẹ̀ Ondo kéde òfin konile-o-gbele ní Ode ati Ishinigbo lẹ̀yìn rògbòdìyàn tó wáyé níbẹ̀wákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Tottenham sọ ọjọ́ ìsinmi olóyin di ''Black Sunday'' mọ́ Arsenal lọ́wọ́ pẹ̀lú ìgbájú-ìgbámú6 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Báyìí ni àgbàọ̀jẹ̀ agbábọ́ọ̀lù Diego Maradona ṣe wọ káà ilẹ̀ lọ lólú ìlú Argentina27 Bélú 2020 Ohun mẹ́wàá pàtàkì nípa Maradona àti ìbáṣepọ̀ rẹ̀ pẹ̀lú ẹlẹ́sẹ̀ ayò Diego Costa rèé26 Bélú 2020 Àwòrán rèé nípa bí 'Hand of God' ṣé dí inagijẹ Diego Maradona25 Bélú 2020 Àrẹ̀mọ Ooni Adeyeye Ogunwusi ti wọ Ààfin Ile Ife fún ìgbà àkọ́kọ́9 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Ṣé ẹ rántí àkọ́lé àwọn ìwé àkàgbádùn yìí?
Dípò èyí, ẹ lo ara yín fún iṣẹ́ òdodo, kí ẹ sì fi í fún Ọlọrun, ẹni tí ó lè sọ òkú dààyè.
Ni ọjọ aje ni wọn pẹjọ naa ni ile ẹjọ giga ipinlẹ Ọṣun eyi to fi ikalẹ si ilu Ikirun.
Fún ìdí èyí, kò yẹ kí ilé náà di àdàwólulẹ̀.
Ti o ba ti wọ inu ọkọ, yago fun awọn ọkọ ti wọn ti fa ala si wi pe ki o ma ṣe joko si Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Láàrín ìdílé ẹlẹ́ni márùn ún yìí, ọmọ kan ṣoṣo ló léè sọ̀rọ̀ Ko si ẹni ti yoo fun ọ ni ounjẹ ninu ọkọ nitori naa ma ṣe yọ ibomu rẹ, amọ omi yoo wa fun ọ.
Awọn aṣofin si ti sọ ipade ijiroro wọn di ọjọ miran, ọjọ ire titi ti atunṣe yoo fi de ba gbọngan ile aṣofin.
 iye ìṣẹ ̀ lẹ ̀ àwọn àrùn bíi guillian-barre syndrome ( nínú èyítí àwọn ẹ ̀ yà ara tí nkojú kòkòrò àrùn yóò bẹ ̀ rẹ ̀ síí gbógun ti iṣan ara ) , autism ( àrùn ọpọlọ tí nmú ni má lè sọ ọ ̀ rọ ̀ tó já geere tàbí bá àwọn ẹlòmíràn ṣe ní àwùjọ ) àti inflammatory bowel disease ( àrún dídáranjẹ ̀ ìfun ) dàbí èyítí kò fi bẹ ́ ẹ ̀ wọ ́ pọ ̀ mọ ́ .
Irinajo si Igbo Olodumare lati ilu Okegbo, to wa loju ọna Ife si Ondo si to ogun Kilomita.
Oríṣun àwòrán, Kayọde Fayẹmi/Facebook Àkọlé àwòrán, Ìgbà kejì nìyíì tí Fayẹmi yóò jẹ gómìnà l'Ekiti O jẹ olugbani nimọran pataki fun igbimọ Oputa Panel ti Olusẹgun Ọbasanjọ gbe kalẹ lọdun 1999 lati sewadi awọn iwa titẹ ẹtọ ọmọniyan loju to waye ni Naijiria laarin ọdun 1966 si 1999.
O ti rí gbogbo ìgbẹ̀san wọn,ati gbogbo ète wọn lórí mi.
Awakọ̀ 700 kò sí páńpẹ́ òfin, 191 ṣẹ̀wọ̀n lórí ẹsùn wíwakọ̀ lẹ́yìn tí wọ́n mu ọtí À ṣé olóòrùn ni ayálégbé mi tó ń fojóojúmọ́ ṣakọ lórí ayélujára- Onílé Lisa Li Wo ohun tó ń ṣẹlẹ̀ níbi ayẹyẹ àyájọ́ ọdún òmìnira ní ìpínlẹ̀ Oyo Ilẹ China ń sàmì àádọrin ọdun tí wọn gbòmìnira pẹ̀lú ìfẹ̀hònúhàn 7.
Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Nigerian Youth Investment Fund: Ijọba àpapọ̀ yóò kó bílíọnù 75 owó ẹyá fún àwọn ilé ìfowópamọ́ kéékèké fún ìṣòwò àwọn ọ̀dọ́25 Agẹmo 2020 Delta petrol tanker explosion: O ti lé ní ènìyàn mẹ́wàá tí ina jó gúrúgúrú nínú ìjàmbá tó wáyé ní Delta23 Agẹmo 2020 Fídíò, Peters Ijagbemi dá àrá lórí ètò 'Ṣé o láyà' ti BBC Yorùbá lọ̀sẹ̀ yìí25 Agẹmo 2020 Iya Jogbo Dead: Ọ̀pọ̀ olólùfẹ́ Emmanuella Pobeni Adepoju kẹ́dùn ikú rẹ̀25 Agẹmo 2020 Marina-Eko Bridge: Ìjọba gbóṣùbà fún àtìlẹyìn aráàlú lásìkò tí wọn ti afárá méjèèjì pa18 Ọ̀wàrà 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Dafidi bá dìde gẹ́gẹ́ bí ọ̀rọ̀ Gadi, tí ó sọ ní orúkọ OLÚWA.
Awọn iroyin ti ẹ le nifẹ̀ si: Charles Okah gba'dajọ ẹwọn gbere 'Naijiria ko laṣeyọri lori gbigbogun t'iwa ijẹkujẹ' Rufai Imam di adajọ agba ile ẹjọ Sharia ‘A ko mọ ibi ti Nnamdi Kanu wa’ Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 3 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 5 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Kódà, àfi bí ẹni pé ẹlòmíràn kórira èdè abínibí tirẹ̀ gan-an ni.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Wo ọmọ Nàíjíríà tí wọn fi pósí ‘₦34m’ sin Yéèpà, òfin ìtakété síra ẹni forí ṣánpọ́n lásìkò ọdún Osun Osogbo Ẹ fura, iyọ̀ onímájèlé tó dóde ti gbẹ̀mí èèyàn méje!
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: 'Ìpòrúuru bá ìyàwó mi bó ṣe gbọ ohun ọmọ wa' L'Ekiti, ẹgbẹ́ òṣìṣẹ́ fòfinde adarí òṣìṣẹ́ méjì Bi o tilẹ jẹ pe ko si ẹni to lee sọ ni pato iye ẹmi to lọ sii, awọn olugbe adugbo Ita Oloki nilu Ẹdẹ ni eeyan mẹrin lo tun ku yatọ si akẹkọọ to n wa ọna ati wọle si ileewe naa.
 Ọ ̀ kan tàbí méjì àmì tí ó máa ń tẹ ̀ lé àmì yíi níwọ ̀ nyí : Ìrìn hánran-hànran , ìdùnnú àìlékoníjànu , ìbẹ ̀ rù omi , àìlegbé àwọn ẹ ̀ yà ara kan , ìpòrúúru , àti àìlèrántí ohun .
Oríṣun àwòrán, others Àkọlé àwòrán, iku ogun lo n pa akikanju bi iku odo ṣe n pa omuwẹ Awọn wo lo ti ba iṣẹlẹ naa rin?
ede  Naijiria Muhammadu Buhari  se ipade pọ pelu awon adari onisowo orisi mẹfa
Ọdún Hijri mùsùlùmí tuntun wọlé dé, ẹ wo kókó pàtàkì nípa rẹ̀ Wo ìdí tí Osun fi kede ìsinmi fún ọdún ìṣẹ̀ṣe, tàwọn ìpínlẹ̀ yókù kò dáhùn, Oríṣun àwòrán, Twitter/ seyi makinde Makinde ti sọ̀rọ̀ lẹ́yìn tí asekúpani Akinyele sálo mọ́ àwọn ọlọ́pàá lọ́wọ́ ní àhámọ́ Gomina Ọyọ, Seyin Makinde ti sọrọ fun igba akọkọ lẹyin ti afurasi to lọwọ ninu iku ọpọ obinrin ni Akinyele, Sunday Shodipe, sa kuro ni ahamọ awọn ọlo Gomina ipinlẹ Ọyọ, Seyin Makinde ti sọrọ fun igba akọkọ lẹyin ti afurasi to lọwọ ninu iku ọpọ iku awọn obinrin ni Akinyele, Sunday Shodipe, sa kuro ni ahamọ awọn ọlọpaa.
” Mo sì dáhùn pé, “Agbọ̀n èso ìgbà ẹ̀ẹ̀rùn ni.
Awọn ọmọ rẹ naa, Gabriella, Mark ati Simon, ni àwọn kò ni wo 'Cartoon' ati 'PJ max' ti awọn fẹran julọ ki baba wọn, Ọgbẹni James le ṣatilẹyin to yẹ fun Super Eagles.
Inu ike rọba ni wọn n tọ si, inu ọra ni wọn si n ṣe igbọnsẹ si.
Lẹyin ọjọ yii ni ajọ isọkan agbaye wa ya gbogbo ọjọ ikọkandinlogun, oṣu kẹfa sọtọ lati maa ṣe ayajọ ipolongo aisan foniku fọla dide lagbaye.
Adu, ẹni to jẹ ọmọ Naijiria to n gbe ni orilẹede Amẹrika salaye pe Naijiria lo mu awọn mẹrin lati soju rẹ ninu idije Chess lai gbe owo kalẹ fi se agbatẹru wọn.
Ó tún wá ṣe ṣoṣoro lókè, ó dàbí ẹni pé ó fẹ́ gún ojú-ọ̀run lábẹ́rẹ́.
Àjọ elétò ìlera àgbáyé (WHO) lo fidi eyi mulẹ.
Wo diẹ lara bi iwọde naa ṣe n lọ: Kinni awọn ibeere wọn lẹyin ti wọn tu SARS ka?
Bẹẹ naa ni o lọ ile iwe imọ nipa owo ni orilẹede Amerika, Ilẹ Geesi ati ni Ilu Eko.
Turari tí ọbabinrin Ṣeba fún Solomoni pọ̀ tóbẹ́ẹ̀ tí ó fi jẹ́ pé Solomoni kò rí irú rẹ̀ gbà ní ẹ̀bùn mọ́.
 o tun je ikan ninu awon agbaboolu ti won ti gba premier league , ife-eye fa , champions league , ife-eye uefa ati eso wura olympiki .
Ọpọlọpọ awuyewuye lo si rọ mọ ipapoda Oba alade yii gẹgẹ bi a ṣe ṣewadii.
Bí ó ti fẹ́ máa lọ sí Siria, ó rí i pé àwọn Juu ń dìtẹ̀ sí òun, ó bá gba Masedonia pada.
 Àwọn gan-an pàápàá sì tilẹ ̀ fi ọwọ ́ sọ àyà pé láti ilé-ifẹ ̀ ni àwọn ti wá .
Àkọlé àwòrán, Ife ẹyẹ agbaye yoo wa fun wiwo ni ọjọ abamẹta nilu Eko O ni ife naa yoo wa ilu Eko fun gbogbo eniyan lati woo ni ọjọ abamẹta.
kò sí ohun tí ale pè ní ewì ní ilẹ ̀ yorùbá tí a ò ní bá onírúurú ọnà-èdè níbẹ ̀ .
Nigba ti BBC kan si ileeṣẹ ọlọpaa lati bere bi o ṣe kú ni agbẹnusọ wọn ni ile ẹjọ nikan lo le ṣalaye.
Wọn fikun wi pe ijọba yoo pese owo fun awọn ileewe lati le fi awọn eto yii lele ni awọn ileewe kaakiri Naijiria lati da abo bo awọn akẹẹkọ lọwọ aarun Coronavirus.
Gbogbo aráyé kò jámọ́ nǹkankan lójú rẹ̀;a sì máa ṣe bí ó ti wù ú láàrin àwọn aráyéati láàrin àwọn ogun ọ̀run.
Olόwό-Ìbínú fẹ́ràn owó ju ẹ̀mí ara rẹ̀ lọ.
Alukoro Taofik Adebayo ṣalaye siwaju pe ọga igbimọ amuṣẹya yi Olayinka Egbeyemi sọ pe lootọ ni iroyin to gbode pe ọlọpaa ọmọ igbimọ naa lo gba owo abẹtẹlẹ.
Ó pé ọdún mẹ́rìnlélàádọ̀ta tí Akintola kú, ìdí abájọ ìja rẹ̀ pẹ̀lú Awolowo rè é Ìtàn Gbọnka àti Timi, akọni méjì tó borí Aláàfin Ṣango Ọkunrin naa, ni oun koju ọpọ ipenija nile iwe lati ọdọ akẹẹgbẹ oun amọ eyi ko di oun lọwọ lati kawe jade titi de ile ẹkọ fasiti.
Lẹ́yìn ọjọ́ meji, Jesu jáde kúrò níbẹ̀ lọ sí Galili.
Ọlọrun wà pẹlu ọmọ náà, ó dàgbà, ó ń gbé ninu aginjù, ó sì mọ ọfà ta tóbẹ́ẹ̀ tí ó di atamátàsé.
Awon ohun ti Buhari ti gbe seO ni : “Ki i se pe a n satileyin fun aare  Muhammadu Buhari nitori pe o jẹ baba wa.
Mercy ló gbadé BBNaija ọdún 2019 Ọlọpọlọ pipe ni Ebuka jẹ ni eyi to fi ṣe idanwo igbanisile iwe girama lati ipele iwe alakọbẹrẹ kẹrin.
 Àwọn kan kó ara wọn jọ , tí wọ ́ n já ìjọba gbà tipátipá ṣùgbọ ́ n kò pẹ ́ tí ìjọba fi ṣẹ ́ gun wọn pẹ ̀ lú ohun èlò ogun .
Ajọ ọlọpaa ni awọn ile ifowopamọ to wa ní Naijiria ti wọn ko owo naa pamọsi ni awọn ti ṣawari owo naa.
Fi ojúlówó wúrà ṣe àwọn àwo ati àwo kòtò fún turari ati ìgò ati abọ́ tí wọn yóo fi máa ta ohun mímu sílẹ̀ fún ètùtù.
Àwọn ni kò lè to ilé wọn gún régé
Ṣé fífi òrí pa ọwọ́ rẹ leè dáàbò bò ọ́ lọ́wọ́ Coronavirus?
lori ọna ti o le mu ilọsiwaju ba ẹkun wa”.
Bi awọn kan ṣe n fi ẹmi imoore han si ololufẹ wọn, lawọn miran n fi ẹdun wọn han fun ijọba, ti awọn miran pẹlu si ṣe ẹyẹ ikẹyin fun arugbo wọn to papoda.
Iku akin to n pa akinkanju lo pada mu ẹmi oloogbe Emmanuel Ilori lọ.
1 37017 Orilẹede Congo 344 0.
"Ọgbẹni Macro ni ""bi gbogbo ọmọ orilẹ-ede mi, inu mi bajẹ lalẹ yii lati ri ibi to n jona yii""."
Oríṣun àwòrán, AUDU MARTE Àkọlé àwòrán, Boko Haram máa ń kọlu àwọn tí wọ́n ń lọ sìnkú.
Ṣugbọn irú ìgbésẹ̀ tí Jeroboamu gbé ni ìwọ náà gbé, ìwọ náà mú kí àwọn eniyan mi dẹ́ṣẹ̀; ẹ̀ṣẹ̀ wọn sì ti mú mi bínú gidigidi.
Ni ọsẹ mẹtalelogun iyẹn nkan bii oṣu mẹrin abọ, dipo oṣu mẹsan ti iya fi n gbe ọmọ ni wọn fi iṣẹ abẹ pajawiri gbe e jade ninu iya rẹ.
Ise akanse yii je pelu ajosepo IFPRI ati ile iwe giga Michigan nile amerika ati iranlowo ajo isokan fun idagbasoke ile ise orile ede Amerika USAID.
Mama ọmọ naa to ba BBC Yoruba sọrọ Fasilat Balogun ṣalaye janduku kan Fọlọrunṣọ Aderibigbe ti orukọ inagijẹ rẹ n jẹ ''Ṣẹrẹrẹ'' lo yinbọn fọmọ oun lẹsẹ.
DSS tu akọroyin ti wọn mu silẹ Osisẹ ijọba Eko gba irinsẹ akọroyin agba BBC ‘Ẹ̀yin Akọ̀ròyìn, ẹ sọ́ra nípa kíkọ ìròyìn tó léwu fétò ààbò’ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fọ́nrán ohùn, NUJ: A fẹ mọ ẹsẹ awọn akọroyin tẹ da duro Bakan naa ni awọn akọroyin ku ni orilẹede Amẹrika naa pẹlu.
Lionel Messi gba àṣẹ àmì ìdánimọ̀ lágbàyé
Alukoro ileeṣẹ ọlọpaa nipinlẹ Osun, Opalola Yemisi sọ fun BBC pe wọn o gbe Jolaosho lọ sile ẹjọ, ti iwadii ba pari.
Ẹnu olódodo dàbí orísun omi ìyè,ṣugbọn eniyan burúkú a máa fi ìwà ìkà sinu,a sì máa sọ̀rọ̀ rere jáde lẹ́nu.
Robert Runcie to je asoju ekun naa ni ojo buruku esu gbomi mu ni ojo Ru je fun won nile iwe olomo egbeurn meta ohun.
Ami dogba-dogba tabi fifagbahan iko South Africa, yoo fun iko Super Eagles lanfaani lati pegede fun idije naa ti yoo waye lorile-ede Cameroon.
Sọ fún un pé OLUWA Ọlọrun ní:Tire, ìwọ tí ò ń sọ pé,o dára tóbẹ́ẹ̀, tí ẹwà rẹ kò kù síbìkan!
Ìwà tí Àwọn Eniyan Yóo Máa Hù ní Ọjọ́ Ìkẹyìn.
Lẹyin ọdun mẹtalelọgbọn ati ọjọ kan ti Ooni ti tẹlẹ naa ṣe iwuye ni ti Ooni naa waye eyi ti gomina Old Oyo nigba naa lọhun, Oloogbe Bola Ige ti gbe ọpa aṣẹ le e lọwọ.
To n tumọ si pe aarun naa ti rapala wọ ipinlẹ mẹsan an lorilẹ-ede Naijiria.
esi idibo akọkọ to waye ni ọjọ Kẹ́sán án ati
Ṣé àwọn ènìyàn-àn mi wà ní àlàáfíà?
Mo gbìyànjú títí pé kí n pa á mọ́ra,ṣugbọn kò ṣeéṣe.
Ẹ kéde rẹ̀ ní ipadò Anoni, pé,‘Moabu ti parẹ́, ó ti di òkítì àlàpà.
Wo àwọn ìṣesí ojoojúmọ́ mẹ́wàá tó le ṣàkóbá fún ọpọlọ rẹ Irọ́ ni pé ọba tuntun má a ń jẹ ọkàn ọba tó bá wàjà ní ìpèbí - Elebuibon Mo ti ní ìyàwó àfẹ́sọ́nà, ayẹyẹ ìgbeyàwó mi ń bọ̀ láìpẹ́ - Lateef Adedimeji Opral Benson, ẹni ti oge ṣíṣe sọ di gbajúmọ̀ àti Yeye Oge ìlú Eko ''Kilode ti ijọba ṣe fẹ ṣe ileewe pada nigba ti ko tii si eto to mọyan lori lati rii pe ko ni ṣi ewu fawọn akẹkọọ lori ọrọ coronavirus ti wọn ba wọle pada bayii?
Kayode Fayemi jẹ ọmọ Ilu Isan-Ekiti ni ijọba ibilẹ Oye nipinlẹ Ekiti.
Ó kú ní ọdún mẹ́ta sáájú ọkọ rẹ̀.
Ṣalimaneseri Ọba Asiria gbógun tì í; Hoṣea bá jọ̀wọ́ ara rẹ̀ fún un, ó sì ń san ìṣákọ́lẹ̀ fún un ní ọdọọdún.
Bakan náà ní ìlé iṣẹ́ ọlọpàá tí dá dúro bayìí kuro labẹ ileṣẹ ijọba apapọ ti ọrọ abẹle ti Mohammed Maigari Dangadi (Sokoto) ń soju.
Wo àwọn èèyàn jáńkán tí yóò ṣe ọdún tuntun ní ọgbà ẹ̀wọ̀n Má jẹ́ kí Whatsapp rẹ gbàbọ̀dè, tètè ‘Update’ Facebook gbégilé àwọn ojú òpó ayédèrú Ilééṣẹ́ Facebook leè mọ ìgbà tí àwọn tó wà lójú òpó wọn ń ní ìbálòpọ̀ Ẹrọ alagbeka mii ti yoo tun ni imọlara ipada lẹyin ẹni yii latinu oṣu keji ọdun 2020 ni awọn iPhone to n lo ilana iṣiṣẹ iOS 8 ati awọn foonu Android to ni ẹda 2.
N jẹ taa wa ni Miliọnia akọkọ nilẹ Yoruba naa, Da Rocha?
“Ẹ máa bu ọlá fún àwọn ogbó, kí ẹ máa bọ̀wọ̀ fún àwọn àgbà; kí ẹ sì máa bẹ̀rù Ọlọrun yín.
    Ẹsẹ̀ Èṣù dàbí ẹsẹ̀ ògòǹgò, síbẹ̀, ó ṣebi ọba, nítorí ẹ̀wù tí ó wọ̀ sọ̀rùn, ti góòlù ni, ṣùgbọ́n góòlù náà ti dípẹtà èérí dúdú dúdú gbogbo ti bò ó, kò dán bi góòlù mọ́ bẹ́ẹ̀ ni góòlù ni.
Ṣugbọn nisinsinyii náà, mo mọ̀ pé ohunkohun tí o bá bèèrè lọ́wọ́ Ọlọrun, yóo ṣe é fún ọ.
To n daamu ẹkun ariwa Naijiria.
Igbakeji aare wa ki mi lasiko ti mo n saisan , ti o si fi oju ara re ri I pe ara mi ti n ya.
Ìnilára ati ìtẹ̀mọ́lẹ̀ ni ẹ óo máa rí nígbà gbogbo, 
Agbẹjọro ijọba ni bi wọn ti ṣe mu akọroyin naa ko ni ohun kankan ṣe pẹlu pe o jakọroyin ati pe ile iwosan aboyun to lọ lawọn agbofinro ti n ṣọ ọ tẹlẹ nitori pe wọn fura si pe awọn eeyan n ṣe oyun nibẹ lọna to tako ofin.
Wọ́n wá sọ pé, “A jẹ́ pé angẹli rẹ̀ ni!
Baba rẹ ni Alani ti ilu Ido-Ani, Oluwatomiloye I.
ó fi ẹ̀sùn kàn án pé ó ti ṣe ìṣekúṣe.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Kí ni àmì ohùn orí 'Aifagbafẹnikan' Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Kí ni àmì ohùn orí 'Aifagbafẹnikan' 3 Èbibi 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 7 Èbibi 2020 Ede Yoruba dun lọrọ, paapaa julọ pẹlu ami ohun.
Nínú àbájáde àyẹ̀wò tí ọjọ́rú, ìpínlẹ̀ Plateau náà lo tú wà lókè ténté pẹ̀lú ènìyàn ọgọ́ta, o fi mẹ́wàá pọ̀ ju ti àná lọ.
Wọ́n dá majẹmu pé àwọn yóo máa sin OLUWA Ọlọrun baba àwọn tọkàntọkàn àwọn; 
Aarẹ Andry Rajoelina sọ pe eweko bi i Artemisia, ti wọn fi n tọju aisan iba, ni wọn fi ṣe agbo naa.
Àwọn ọmọ ti Sebuluni ni: Seredi, Eloni, ati Jaleeli.
Kí n tó dákẹ́ adura mi, Rebeka yọ pẹlu ìkòkò omi ní èjìká rẹ̀.
Kayọde Ajulọ tesiwaju pe ''bi a ba pada de ile,ao se agbeyẹwo oro naa ki a to le so igbese to ba kan.
Nípa èyí tí o sì béèrè nípa Igbó Olódùmarè, n kò lè purọ́ fún ọ, ojú mi rí nǹkan.
Arúgbó náà jẹ́ ènìà rere, àánú rẹ̀ a sì máa ṣe gbogbo onírìnàjò.
Nígbà tí mo bá dé ìkangun àgọ́ náà, ẹ ṣe bí mo bá ti ṣe.
Mo ń retí ìmísí ọ̀nà tí ẹ ó gbà tún un ṣe.
 nínú ìtàn yìí a ri i pe Ọbàlùfọ ̀ n aláyémọrẹ mọ àsìkò ti Ọ ̀ rànmíyàn wà láyé .
O ni oun pa ọrẹbinrin ọga oun nitori obinrin naa lo fa ariyanjiyan laarin awọn memeji lẹyin ti ko jẹ ko fun oun lowo ti oun bere lọwọ rẹ.
Amọ orukọ miran, Elija Emeka Chibuke ni wọn fi kọ iroyin naa nipa oniwaasu ọhun.
Ninu ifọrọwanilẹnuwo pẹlu ile iṣẹ BBC Yoruba, Ọjọgbọn Adetokunbo Akintayo ṣalaye pe kii ṣe pe o wu ọpọ awọn eeyan lati file silẹ bi kii ṣe pe nnkan ko rọgbọ.
ng Ijọba ipinlẹ Ogun ti kede pe, eto ayẹwo arun Coronavirus ti di ọfẹ fawọn akẹkọọ ile ẹkọ girama to fẹ wọle pada.
Àwọn iranṣẹ rẹ̀ bá gbà á níyànjú pé, “Baba, ṣé bí wolii náà bá sọ pé kí o ṣe ohun tí ó le ju èyí lọ, ṣé o kò ní ṣe é?
Bí Peteru ti ń ronú lórí ìran yìí, Ẹ̀mí sọ fún un pé, “Àwọn ọkunrin mẹta ń wá ọ.
Aṣofin Yusuf sọ pe Ile Igbimọ Aṣofin Ipinlẹ Eko ti fọwọ si iwe abadofin mọkanlelogoji, ti wọn si ti sọ ọgbọn di ofin, eleyii to wulo pupo fun wiwa ojutu si awọn ipenija kan ati fun idagbasoke ilu kaakiriri ipinlẹ yii.
O de ago olopaa naa ni aago 1125 GMT pelu awon iwe nlanla lowo re.
WAEC ni laarin ọjọ marundinlaadota ni awọn yoo gbe esi idanwo naa sita.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ekiti: Ọmọ ọdun méje di ọ̀rẹ́ Gómìnà Ekiti 25 Agẹmo 2019 Oríṣun àwòrán, @ekitistategov Awọn Yoruba maa n ni b'eegun ẹni ba mọọ jo, ori a maa ya atọkun.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ifayemi Elebuibon: Mo jẹ páànù ìyà nítori mo fẹ́ mọ̀ọ́kọ, mọ̀ọ́kà 16 Sẹ́rẹ́ 2021 Awọn agba bọ, wọn ni ọmọ ti yoo ba jẹ Aṣamu, ati kekere ni iru wọn ti maa n ṣẹnu ṣamu ṣamu.
 Àwọn ènìyàn ti o fẹ ́ ràn àlàáfíà , ìfẹ ́ àti ìrẹ ́ pọ ̀ láàárin onílé àti àlejò sì ni wọ ́ n pẹ ̀ lú .
Aare ana lorile ede Naijiria Olusegun Obasanjo naa
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Kano: Omidan, rìn jáde láago mẹ́jọ alẹ́ ko rẹ́wọ̀n he 3 Ẹrẹ̀nà 2018 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 12 Ọ̀wàrà 2018 Àkọlé àwòrán, Ọkan nínú àwọn ọmọbinrin tí wọn mú tó wà níbẹ̀ sàlàyé fún BBC pé òun jáde nílé láti lọ kí ọ̀rẹ́ oun ní Omi tuntun ti rú, ẹja tuntun sì ti wọ̀ọ́ ní ìpínlẹ̀ Kano báyìí, túntun tó ṣẹlẹ̀ ní pé, ààyè kò si fún ọlọ́mọge láti jáde alẹ.
 Ẹ ̀ yà méta ẹranko yìí tí di mímọ ̀ .
Ìfihàn tí a fi fúnni nípasẹ̀ Wòlíì Joseph Smith sí bàbá rẹ̀, Joseph Smith Àgbà, ní Harmony, Pennsylvania, Oṣù kejì ọdún 1829.
Àkọlé àwòrán, Gbogbo eto ti to saaju ibuwarawọle fun gomina nipinlẹ Ogun Àkọlé àwòrán, Dapo Abiodun ati Noimot Salaki Oyedele ni wọn yoo ma a bura fun gẹgẹ bi gomina ati igbakeji rẹ.
tẹ́tí sílẹ̀, bojú wò mí, kí o sì fetí sí adura èmi iranṣẹ rẹ, tí mò ń gbà tọ̀sán-tòru nítorí àwọn ọmọ Israẹli, iranṣẹ rẹ, tí mo sì ń jẹ́wọ́ ẹ̀ṣẹ̀ tí a ṣẹ̀ ọ́.
Gbogbo ẹja inú odò náà yóo kú, odò náà yóo sì máa rùn, tóbẹ́ẹ̀ tí àwọn ará Ijipti kò ní lè mu omi inú rẹ̀ mọ́.
Mo bá dáhùn pé, “OLUWA, ṣebí ìwọ náà mọ̀?
Lara awon gomina ti yoo maa tẹle
Onnoghen: Ilé ẹjọ́ kòtẹ́milọ́rùn ní ẹjọ́ náà kò lẹ́sẹ̀ ńlẹ̀
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Abayọmi Aranmọlatẹ, Dr Laser: Vagino Plasty àti iṣẹ́ abẹ ẹwà Obìnrin ló jẹ mí lógún Eleyii pẹlu ohun to mu ki ija ati ikunsinu to wa laarin gomina ipinlẹ Edo, Obaseki ati gomina ana nipinlẹ naa, Adams Oshiomolẹ to jẹ alaga ẹgbẹ oṣelu APC nigba naa.
Ó fi òkúta mejeejila náà kọ́ pẹpẹ ní orúkọ OLUWA.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Germany football naked protest: Àwọn olùfẹ̀hónúhàn bọ́ra sí ìhòhò lórí pápá lòdì sí sísọ eré bọ́ọ̀lù di jẹunjẹun 17 Ògún 2020 Awọn eeyan kan lorilẹ-ede Germany ti lọ sori papa ni ihoho ọmọluabi lọna ati ṣefẹhonuhan lodi si sisọ ere bọọlu di jẹunjẹun.
Wọ́n fún mi ní ọ̀pá kan, bí èyí tí wọ́n fi ń wọn aṣọ.
Wọn ṣadeedee ni Grace dide kuro laarin wọn lati lọ rẹju diẹ ninu ile oniwaasu ti ẹbi rẹ n gbe.
Ẹ gbọ́ òhun tí àwọn olùdíjé sípò gómìnà nípínlẹ̀ Ondo sọ nípa Bàbá ìsàlẹ̀.
org Àkọlé àwòrán, Odu ni Atiku lagbo oselu Naijiria Lai pẹ yi ni ijọba Naijiria fesi si ẹsun ti Oludije sipo Aarẹ, Atiku Abubakar fi kan awọn oṣiṣẹ papakọ ofurufu to wa ni ilu Abuja pe wọn fi abuku kan oun lasiko ti ọkọ ofurufu oun balẹ si papakọ naa.
Idi ti ọgba ẹwọn fi nkun akunfaya ni Naijiria Àwọn Fadá mẹ́rin gbà itusílẹ̀ lọwọ àwọn ajínigbé 'Gómìnà Akeredolu lọ́wọ́ nínú wàhálà ilé aṣòfin Ondo' Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, O tó ìdá méjì àwọn ènìyàn àgbáyé to wà nínú ewu àìsàn ibà Banky W padanu ọmọ Oríṣun àwòrán, Instagram/iambangalee Àkọlé àwòrán, Ọmọ ọdún kan ní Daniel ọmọ Dbanj tó kù s'omi Ìkíni ibanikẹdun ko dúró lórí ikú ọmọ Dbanj Ìròyìn ikú ọmọ Dbanj jẹ́ nnkan tí o kò òpó ọmọ orílèèdè Nàìjíríà nínú.
6 6255 Orilẹede Aruba 52 49.
Nígbà náà, ẹ óo dá wọn lóhùn pé omi odò Jọdani pín sí meji níwájú Àpótí Majẹmu OLUWA nígbà tí wọn gbé e kọjá odò náà.
O sọ fun awọn eniyan South Africa pé ijọba oun a pese aabo to peye fun ileeṣẹ wọn ati awọn okowo wọn.
"Oríṣun àwòrán, @aishambuhari Àkọlé àwòrán, 'A n fi asiko yii ronu lori isẹlẹ ibanujẹ jiji awọn ọmọbinrin wa gbe, paapaa julọ ni Dapchi ipinlẹ Yobe' ""Loni, mo ki awọn obinrin orilẹede Naijiria ku oriire ayajọ awọn obinrin."
Ta ni ìyàwó Chadwick Boseman, tó jẹ́ àwòkọ́ṣe rere f'áwọn ọ̀dọ́ Adúláwọ̀?
Ẹ wo bí orílẹ̀èdè Amẹrika ṣe dóòlà ẹ̀mí ọmọ ilẹ̀ wọn tí wọ́n jígbé ní Naijiria US Citizen Rescue: Ẹ wo bí orílẹ̀èdè Amẹrika ṣe dóòlà ẹ̀mí ọmọ ilẹ̀ wọn tí wọ́n jígbé ní Naijiria Ọ̀sẹ yii ni wọn ji arakunrin Philip Walton gbe ni iha ariwa orilẹede Naijiria.
"Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ọlọ́pàá yọ ìbọn sí mí pé kí n tọwọ́ bọ ìwé ní tipá - Busola Dakolo Ọmọ Yorùbá míràn tún dé ipò gíga l‘Amẹrika ""Mo fẹ́ pa ara mi torí ojú àbùkù tí wọn ń fi wò mí pé mo fi iṣẹ́ abẹ bímọ"" Owó dé!"
" Lati ọjọ naa si ni wọn ti maa n fi isẹlẹ yii pa owe fun ohun to ba ti kọja atunṣe, to ti bọwọ sori, ti ko si ni ojutu mọ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Police brutality during lockdown: Nínú Ọlọ́pàá àti Coronavirus, èwo gan an laráàlú ń bẹ̀rù jùlọ?
Osisẹ ijọba Eko gba irinsẹ akọroyin agba BBC BBC koro oju si ikọlu ijọba ipinlẹ Eko Wọ́n gbé Akọ̀ròyìn ní Morocco lọ sílé ẹjọ́ lórí ẹ̀sùn àgbèrè àti oyún ṣíṣẹ́ Lai Mohammed: A kò ní bojú wẹ̀yìn lórí àbádòfin ìṣàkóso ẹ̀rọ ayélujára ''Mo bere lọwọ Minisita tẹlẹri ọhun pe ta ni ni to san owo abẹwo rẹ si awn ipinlẹ ti o n ṣe abẹwo si kaakiri Naijiria.
Eyi lo si mu ki wọn o maa kọ ni oriṣiriṣi nkan, ti oun naa si tete n mọ ọ.
Ẹ má bínú pé mo kọ́kọ́ ní akẹ́kọ̀ọ́ mẹ́wàá péré ni wọn kó nílé ìwé Kankara - Garba Shehu Sé Boko Haram ń pẹ̀ka kiri Nàíjíríà ní ìjínigbé ṣe burú báyìí?
 Kíni ọlọ́pàá àti ẹgbẹ́ alátakò ń sọ?"
Ó ní ìwọ Jeroboamu ni òun óo mú, tí òun óo sì fi jọba ní Israẹli, o óo sì máa jọba lórí gbogbo agbègbè tí ó bá wù ọ́.
Kanu ni ijọba apapọ nigba tó n lo ile ẹjọ giga to wa ni Abuja lati gbẹṣẹ le aṣẹ ti o fun oun ni beeli tẹlẹ, ṣugbọn ti wọn ti yii pada ba yii lati fi panpẹ ọba mu oun, nipa lilo awọn ọlọpaa agbaye, eyi to jasi pabo.
Nigba ti oun pẹlu n sọrọ lẹyin ti o tọwọ bọwe adehun rẹ tan, Frank Lampard ni iyi nla lo jẹ fun oun lati di olukọni agba fun ẹgbẹ agbabọọlu Chelsea ati pe afojusun oun bayii ni 'lati mura giri fun iṣẹ naa ati lati pese ikọ naa silẹ gidigidi fun saa ere bọọlu to n bọ lọna' Ìtàn tó wà nídi òwe ‘Sebótimọ Ẹlẹ́wà Sàpọ́n’ Taiwo Akinkunmi, ọmọ Ibadan tó ya àsìá Nàíjíríà Taiwo Akinkunmi, ọmọ Ibadan tó ya àsìá Nàíjíríà Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Kunle Afolayan: èmi kò fẹ́ fi ogún sílẹ̀ fún ọmọ mi Frank Lampard n bọ si ipo naa lẹyin ti Mario Sarri to wa nibẹ tẹlẹ ti lọ darapọ mọ Juventus lorilẹede Italy.
Ẹgbẹ Amnesty International wa funpe si awọn ọmọ ogun oju ofurufu (ti wọn ti gba ikọni to to latọdọ awọn ọmọ ogun orilẹede UK ati ilẹ Amẹrika) lati jọwọ fidio ti wọn ni yii ati gbogbo irooyin ti wọn ba ni fun awọn alasẹ, to fi mọ adajọ agba orilẹede Naijiria ati minisita fun ọrọ abo fun iwadii.
Lẹyin naa lo wa rọ awọn ọmọ ipinlẹ ọmọluabi lati maa ṣe ohun gbogbo ni ẹsọ pẹlẹ, ati pe ijọba yoo mu eto abo awọn eeyan naa ni ọkunkundun.
ilera ati ẹkọ  fun  awon ọmọde.
Afghanistan ṣi ni orilẹede to buru ju fun awọn akọroyin.
Awon ohun to n tona si igbona ni ofinkin, ki eeyan maa sin, iko, oju pipon ati ara gbigbona ati ki ara maa su leyin ojo melo kan.
Olugbe agbegbe Lagos Island sọ wi pe awọn to ṣekọlu si ile iya gomina Sanwo-Olu naa lo ṣekọlu si ile ọba naa.
Bí àjálù ìbúgbàmù tó gb'ẹ̀mí ọ̀pọ̀ nìlùú Eko ṣe wáyé nìyí Buhari fárígá, ó ní kò s'óṣìṣẹ́ ìjọba tó gbọ́dọ̀ rìnrìnàjò sílẹ̀ òkèèrè lọ́wọ́ yìí Nítorí coronavirus, Mikel Obi sá kúrò ní ikọ̀ Trabzonspor Bí Fayemi bá tasẹ̀ àgẹ̀rẹ̀, àwọn oníbáwí rẹ̀ wà l'Ekiti-Peter Fatomilọla Ṣé lóòtọ́ ni Ọọ̀ni ilé ifẹ̀ ti parí aáwọ̀ lọ́balọ́ba l'Ékìtì?
wọ́n sì sọ̀rọ̀ òdì sí Ọlọrun ati Mose, wọ́n ní, “Kí ló dé tí ẹ fi kó wa wá láti Ijipti, pé kí á wá kú ninu aṣálẹ̀ yìí?
"Mo rántí ọkan lara àwọn orẹ mi nigba naa to n kaya soke lori pe Ọ̀jọ̀gbọ̀n Akindele dẹ̀nu ibalopọ̀ kọ̀ oun.
O ni nitori eyi lo ṣe ṣe pataki ki awọn agbẹ o gba lati fi orukọ silẹ."
Èyí ni ẹ̀rí tí Johanu jẹ́ nígbà tí àwọn Juu ranṣẹ sí i láti Jerusalẹmu.
Bàbá Wande ni, ti òun kò bá ṣe ère tíátà, bóyá agbabọọlu ni oun kò bá jẹ, èyí tí yóò sì fún oun ní òkìkí gidi bíi ère tíátà.
Ikorodu Festival: Àwọn olórò ní ọdún Màgbó ló ń gbá ibi lọ, kó ire wọlé ní Ikorodu
Ẹ̀gbọ́n àti àbúrò wà ní ilé ẹ̀jọ́ lórí ikú Tolulope Arotile Ogun Àgbẹ́kọ̀yà, ẹ̀kọ́ wo ló yẹ́ kí àwá ọ̀dọ́ kọ́ níbẹ̀?
Àwọn ará àdúgbò so pé n'isẹ ní ìyá ọmọ náà n sunkun nígbà tí àwọn oṣiṣẹ pajawiri n ṣápá láti tọjú ọmọ náà.
Iroyin sọ pe ilu Lọndon ni Aarẹ Buhari ti sọ ọrọ naa lasiko to fi n ba igbimọ kan sọrọ nibi ipade awọn olori orilẹede to wa labẹ ajọ Commonwealth.
Nigba ti M wa fun Male, eyiun ọkunrin, F wa fun Female, eyiun obinrin, abala I naa gbọdọ wa fun awọn eeyan to ni oju ara meji, eyi tii se Intersex.
Super Eagles ti mbọ̀ wálé Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Germany to gba ife ẹyẹ gbẹyin náà kógbá wọlé ni Russia 2018 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Mertens náà kò gbẹ́yìn nínú ìdíje tòní bí o se ran Belgium lọ́wọ́ láti jáwe olúbori Àkọlé àwòrán, Croatia gbo ewúro sójú Argentina ní World Cup 2018 Awọn wo lo kù?
Bí ọmọ náà ti lọ tán, ni Dafidi jáde láti ibi òkúta tí ó sápamọ́ sí, ó sì dojúbolẹ̀, ó tẹríba lẹẹmẹta.
Fidio iṣẹlẹ ṣi n tan ka ori ẹrọ ayelujara.
Èyí ni àwọn arẹwà ‘ẹ̀lẹ̀ Daddy’, àfẹ́fẹ́ tí Aláàfin fi ń mí Ìjọba Nàìjíríà ti parí ìwádìí lórí àgbo Covid-Organics ti Madagascar kó ránṣẹ́ sí i Wo ọ̀nà tí àwọn ‘ẹ̀lẹ̀ Daddy’ gbà dé ààfin Ọyọ Kùdìẹ̀kudiẹ wà nínú ìbò abẹ́nú APC tó yan Akeredolu, ṣùgbọ́n.
Àwọn ọmọ Gadi ní ìdílé-ìdílé nìwọ̀nyí: ìdílé Sefoni, ìdílé Hagi, ati ìdílé Ṣuni; 
Àwọn ẹbọra alágbára àti àwọn jàgídíjàgan àǹjànnú ni wọ́n si ń jùmọ̀ ṣe ọ̀rẹ́ pọ̀, bẹ́ẹ̀ ni àwọn ejò alákọrí gbogbo a tun máa dẹ́rùba àwọn ọdẹ nítorí ibẹ̀ ni ilé olórí ejò ayé gbogbo, Ojòlá-ìbínú ni orúkọ rẹ̀ ń jẹ́.
Lisa Hanna: Ojú kìí rí arẹwà kó má kí i.
Ẹwẹ, ọgọjọ eeyan tuntun miran lo ri iwosan ti wọn si ti ni ki wọn maa lọ ile wọn.
alatako rẹ to n dije ninu egbe Peoples Democratic Party, Atiku Abubakar loju ,
Wo ipò tí Buhari fún Faṣọla, Lai Mohammed, Saraki àti bẹ́ẹ̀ bẹ́ẹ̀ lọ Èrò àwọn ọmọ Naijiria ṣọ̀tọ̀ọ̀tọ̀ lórí àwọn ti Sanwo Olu yàn sípò BBC fọrọ wa awọn ti wọn n gun kẹkẹ daadaa bii Akin Salami, Fadekemi Adeleye atawọn mii lẹnuwo lori pataki kẹkẹ wiwa lasiko yii.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Victor Agunbiade ni ojú àlá ni Ọlọrun ti yan iṣẹ́ ọmọ ogun ojú omi fún òun ní America Awọn eeyan mẹta naa wa lara awon mẹsan an ti wọn ti kọkọ fi ẹsun ijinigbe ati igbesunmọmi kan, fun ipa ti wọn ko lori bi awọn kan ṣe gba ẹgbẹrun lọna igba Dọla ($200,000), ki wọn o to tú awọn oṣiṣẹ ọkọ oju omi akẹru kan, to jẹ ti orilẹ-ede Equatorial Guinea, Vessel MV ELOBEY VI.
Tọkàntọkàn ni wọ́n fi ń ṣe iṣẹ́ náà, ó sì ń tẹ̀síwájú.
"Lórí ìmọ̀ràn Sunday Igboho, Ẹlẹbubọn ní yóò dára kí Yorùbá padà sí àmúlò èròjà ìbílẹ̀ fún ààbò Sowore ṣèpàdé pẹ̀lú Nnamdi Kanu láti dojú ìjọba Nàíjíríà bolẹ̀ - Àjọ DSS ""Bí Zakzaky yóò bá lọ gba ìtọ́jú ní India, ó gbọdọ̀ ṣe àwọn nǹkan wọ̀nyìí"" Igbakeji Agbẹnusọ fun gomina ipinlẹ Eko ni o ni awọn ti ko gbogbo oju -agbara ni ipinlẹ Eko, nitori naa o da awọn loju wi pe ẹkun omi ko le e waye ni ipinlẹ Eko."
 Ó dá egbé òsèlú sílè ní 1923 .
Irúgbìn mìíràn bọ́ sí ilẹ̀ tí ó dára, wọ́n yọ sókè, wọ́n ń dàgbà, wọ́n sì ń so èso, òmíràn ọgbọ̀n, òmíràn ọgọta, òmíràn ọgọrun-un.
Bákan náà ni ẹni ti wọ́n bá dá lẹ́jọ́ ní ilé ẹjọ́ Sharia le pé ẹjọ́ kòtẹmilọ́run tàbi ilé ẹjọ́ tọ ga jùlọ ní àwọn ilé ẹjọ́ ìjọba orílẹ̀-èdè Naijiria.
Nígbà tí Samuẹli fi ojú kan Saulu, OLUWA wí fún un pé, “Ọkunrin tí mo sọ̀rọ̀ rẹ̀ fún ọ nìyí.
‘Alẹ́ làwọn ọkùnrin fẹ́ bá mi jáde, torí mo kọ ilà’ Olórí ilé asòfin l‘Ọ́sun pàdánù N38m sọ́wọ́ gbájúẹ̀ O fẹ́ yọ́ wọ ààyè ibùsùn àwọn obìnrin lọwọ́ ọlọ́pàá bá tẹ̀ ẹ!
"Osinbajo kò gbàdúrà ikú fún Buhari lórí àìsàn, ẹ sinmi ìbàjẹ́- Agbẹnusọ Osinbajo Wo bí wọ́n ṣe ṣe ọjọ́ ìbí Anabi ní Abuja ati ní Ghana ""Àwọn tó jí ọmọ mi gbé nílé ìjọsìn ní ń kò gbọdọ̀ wa tàbí kí ẹ̀mí mi lọ si"" Ẹ dẹ́kun àbùkù tẹ fi ń kan Nàíjíríà, ẹ fi Sowore sílẹ̀ láhàmọ́- Soyinka Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?"
Bótilẹ jẹ́ pé àwọn méjèjì gbá góòlù mẹ́rinlélógóji sáwọn fún iikọ agbábọọlu Liverpool, kò mu wọn jáwé olúbori ninu àṣekágbá Premier League bí Manchester City ṣe gba ife ẹyẹ naa.
Ọdun 2012 ni iṣẹ ọwọ Boko Haram lọ soke, to si n ṣe ikọlu titi de orilẹ-ede Niger ati Chad, to mule ti Naijiria.
"A ti se gbogbo ẹnubode, titipa gbọingbọin ni ipinlẹ yii wa bayii, bẹẹ lawọn eeyan ipinlẹ wa naa n ṣe imọtoto boti tọ ati bo ṣe yẹ.
Laarin oṣu kẹta si oṣu karun un ni awọn eeyan fi dẹkun itankalẹ naa diẹ pẹlu gbigbe igbesẹ to yẹ.
Kola ni esi idibo to jẹ ògidì to wa lọwọ PDP lori idibo Ekiti fihan pe Eleka Olusola to dije labẹ PDP lo wọle gegẹ bii gomina ipinlẹ Ekiti ni eyi to yatọ si ti ajọ INEC.
 ojo ori re bere lati igbajoun , olugbe ibe nibere 2009 je egbegberun meji awon eniyan .
O ni o pẹ ki oun to fẹ iyawo sile nitori pe igbesẹ to gba ọgbọn ni, fun ẹni to ba jẹ oṣere, ko ma ba ṣe igbeyawo ti yoo pana ogo isẹ rẹ.
Olukuluku ń tan ọ̀rẹ́ rẹ̀ jẹ,kò sì sí ẹnìkan tí ń sọ òtítọ́.
Sarah jẹ ọmọ orukan to jẹ ẹni ọdun mẹtadinlogun nigba to gboyun.
Nitorina eniyan gbọdọ rọra jẹun nigba aawẹ Ramadan Eniyan gbọdọ kọkọ mu omi ki o to jẹun Eso dara lọpọlọpọ lasiko awẹ Orisirisi ẹfọ tutu ati sise dara Awọn ounjẹ oni koro bii ẹwa ati agbado naa dara Miliiki ti ko ni adun igbalode naa dara lasiko naa.
Gẹgẹ bo ṣe sọ, o ni Mo gburo ọkada ti wọn pọ rẹrẹ, ti wọn n pariwo, ti wọn si n kọ orin bi ẹni to n lọ soju ogun, bẹẹ naa ni wọn n pariwo Adele da, Adele da!"
Ṣugbọn o ni bi wọn ṣe jẹ ohun ẹlẹgẹ, naa ni wọn ṣe lagbara to, pẹlu afikun pe ti Eleduwa ba fi obinrin rere jinki ọkunrin kan, iru ọkunrin bẹẹ ti ri ibukun, idunnu ati ẹmi gigun gba lọdọ Ọlọrun.
"Ohun tí gómìnà Seyi Makinde fẹ́ ṣe lórí ìwọ́dé EndSARS lẹ́yìn ìpàdé rẹ̀ pẹ̀ láwọn tọ́rọ̀ọ kàn Mo ti tọrọ aṣọ àti yẹtí etí rí, kí n tó leè ṣe àwo orin - Tope Alabi Ohun tí gómìnà Seyi Makinde fẹ́ ṣe lórí ìwọ́dé EndSARS lẹ́yìn ìpàdé rẹ̀ pẹ̀ láwọn tọ́rọ̀ọ kàn Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Àjẹ́ ké lánàá, ọmọ kú lónìí ni ọ̀rọ̀ Tinubu àti ìṣẹ̀lẹ̀ Lekki Tollgate - Bode George Lara wọn ni alaga adugbo naa, Arakunrin Nureni Adejumo ti gbogbo eeyan mọ si ""Master"" wa."
Ran olufẹ mi lọ́wọ́ nípa ọ̀ràn yí nítorí apá rẹ̀ nìkan kò ká a; apá tèmi pàápàá kò le ká a: ọgbọ́n ọmọdé kò le dúró lára ọgbọ́n àgbàlagbà.
Làásìgbò òṣèlú wáyé nílùú Ondo, ọ̀pọ̀ èèyàn fara pa Àmọ̀tẹ́kùn gbéra!
Saaju ko to busẹkun nibi to ti gba fọọmu ìfèróngbà rẹ ni igbakeji Aarẹ nigba kan ri lorileede Naijiria,Atiku Abubakar, ti se abẹwo si awọn olori ẹgbẹ Afẹnifẹre to jẹ ẹgbẹ awọn ọmọ Yoruba.
Bí ọwọ kò sí ti gbọdọ̀ ṣe àfojúdi sí orí, tí ẹsẹ̀ kò gbọdọ̀ wí pé òun kò sí lábẹ́ ààbò rẹ̀ ni n kò to ẹni ti ń ṣe orí kunkun sí yín.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ #Sima Sarkar 'Yorùbá gbà pé òrìṣà bí ìyá kò sí!
Tó ba jẹ́ pé eré ìdáraya lókùnrin ati lobinrin ló fẹ́ fi orúkọ silẹ̀ fún, o gbọdọ̀ sàfihan iwe ẹri pé iṣẹ́ ti ó yàn láàyò ni, iwé ẹ̀rí àti awọn àmì ẹ̀yẹ ti ti gbà gọds wà níbl pẹ̀lú.
1 x Locally Made Dane Gun.
 Wayii o, abewo ohun lo fara han pe, igbimo ohun pada sinu egbe oselu APC leyin ti won ti figba kan kuro ninu egbe APC seyin.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Osun Tribunal Judgement: 'Àwa ènìyàn Ọṣun kọ ìdájọ́ tó ní Oyetọla kọ́ ló wọlé sípò gómìnà' 27 Ẹrẹ̀nà 2019 Oríṣun àwòrán, Adejare Taofeek Kẹtikẹti ni awọn olugbe ipinlẹ Ọṣun tu sita lọjọru lati ṣe iwọde tako idajọ igbimọ to sọ pe Sẹnetọ Ademọla Adeleke ti ẹgbẹ osẹlu Peoples Democratic Party lo jawe olubori ninu idibo sipo gomina ipinlẹ naa to waye lọdun 2018.
O ni awọn ṣẹṣẹ ṣe igbeyawo ni ati wi pe iyawo oun n pada lọ si ibiṣẹ ni.
Ẹ wá wo obinrin yìí, ọmọ Abrahamu, tí Satani ti dè fún ọdún mejidinlogun.
Bẹẹ, ọmọ ti yoo jẹ aṣamu ti gbọdọ ṣe ẹnu ṣamuṣamu lati kekere, o ni o le ni ogun ọdun ti oun ti n ṣiṣẹ yii.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Lagos missing children: Ọ̀kan lára ìyá àwọn ọmọ tó sọnù náà ti ń sínwín 22 Ògún 2020 Inu ibanujẹ ati iporuru ọkan ni awọn obi kan wa lati nnkan bi ọdun kan abọ sẹyin ni agbegbe Otto, ni ipinlẹ Eko lẹyin ti awọn gbọmọ-gbọmọ ṣadede ji ọmọ wọn gbe lọ.
Kinni mo le ṣe ti mo ba ni arun Coronavirus?
Wọn fẹsun kan Austine pe o ṣe iku pa Ebuka Okoli ni agbegbe Durban ni ẹkun Kwa Zulu-Natal ni orilẹ-ede South Africa.
OLUWA ní,“Nítorí pé mo fẹ́ ẹ̀tọ́,mo sì kórìíra ìfipá jalè ati ohun tí kò tọ́.
Floyd: Adarí ètò àbò ní ilẹ̀ Amẹ́ríkà ti fẹ̀sùn kan ààrẹ Trump lórí ọ̀rọ̀ ẹlẹ́yàmẹ̀yà Oríṣun àwòrán, Reuters Àkọlé àwòrán, Ọpọlọpọ eniyan lo ti bu ẹnu atẹ lu bi Aarẹ ilẹ Amerika, Donald Trump ṣe n wuwa lori iṣekupani George Floyd Adari eto aabo lorilẹede Amerika tẹlẹri, James Mattis ti fẹsun Aarẹ orilẹede Amerika, Donald Trump pe oun gan an lo n da wahala ẹlẹyamẹya silẹ ni ilẹ Amerika.
Irúgbìn ti orí ilẹ̀ olókùúta ni ẹni tí ó gbọ́ ọ̀rọ̀ náà, tí ó fi tayọ̀tayọ̀ gbà á lẹsẹkẹsẹ.
Ẹ ṣe ìdájọ́ òdodo fún àwọn mẹ̀kúnnù ati àwọn ọmọ aláìníbaba;ẹ sì máa ṣe ẹ̀tọ́ fún àwọn tí ojú ń pọ́n ati àwọn talaka.
pupo ninu awon gomina yii ni won ko se ojuse wọn.
kí ó sọ fún àwọn ọmọ Israẹli pé, “Nígbà tí ẹ bá ré odò Jọdani kọjá sí ilẹ̀ Kenaani, 
” Ara obinrin náà bá dá láti àkókò náà lọ.
Àwọn eniyan mi yóo máa gbé pẹlu alaafia,ní ibùgbé tí ó ní ààbò ati ibi ìsinmi tí ó ní ìbàlẹ̀ àyà.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ìtàn ayé Henry Fajemirokun, olówó tó fi owó mọ Olúwa àti ènìyàn Iléesẹ́ rẹ́kọ́ọ̀dù tí mo ti bẹ̀bẹ̀ láti kọrin, padà di tèmi lónìí - Ebenezer Obey Ọ̀pá epo NNPC bú gbàmú ní Benin, òṣìṣẹ́ méje kàgbákò ikú òjijì Ọ̀fọ̀ ńlá ṣẹ̀ ní Ivory Coast, Olóòtú ìjọba, Amadou Gon Coulibaly jáde láye Tó o bá fẹ́ wọ bàálù lásìkò yìí, wo òfin tuntun tó tẹ̀lé Ọpọlọpọ ifẹhọnu han lo waye ni Oṣu Karun, ọdun 2020 lẹyin iku George Floyd.
8 345661 Orilẹede Algeria 2516 6.
OLUWA ní,“Israẹli, mo fẹ́ fi ọ́ ṣe ọ̀kan ninu àwọn ọmọ mi,tí n óo sì fún ọ ní ilẹ̀ tí ó dára,kí n sì fún ọ ní ogún tí ó dára jù,láàrin gbogbo orílẹ̀-èdè yòókù.
Iroyin to tẹ wa leti sọ pe ninu ile rẹ ni agbebe Samaru nipinlẹ Kaduna ni wọn ti ba oku rẹ pẹlu lẹta to kọ silẹ to fi dagbere fun awọn ọrẹ rẹ.
Joshua tó gba ìgbànú ẹ̀yẹ Olympic, tí ṣaájú gba àmì ẹ̀yẹ àpọ́nlé MBE ní ààfin Buckingham l'ọ́dún 2013.
kí ó kọ ìwé sí Asafu, olùṣọ́ igbó ọba, kí ó fún mi ní igi kí n fi ṣe odi ẹnu ọ̀nà tẹmpili, ati ti odi ìlú, ati èyí tí n óo fi kọ́ ilé tí n óo máa gbé.
AMAA 2018 Ami eye fun oludari to dara ju
Gomina Ibrahim Hassan Dankwambo to n tuko ipinle Gombe ti parowa sawon gomina ipinle to ku ti won si ni ibudo Asatipo ni agbegbe won pe ki won tete tu won ka.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Amy Coney Barrett di adajọ́ àgbà nílé ẹjọ́ tó ga jùlọ l'Amẹrika 27 Ọ̀wàrà 2020 Oríṣun àwòrán, EPA Àkọlé àwòrán, Supreme Court Justice Clarence Thomas administered the oath of office in the presence of Donald Trump Ile igbimọ aṣofin agba ilẹ Amẹrika ti buwọlu iyansipo adajọ Amy Coney Barrett gẹgẹ bí adajọ àgbà nile ẹjọ gigajulọ ilẹ náà.
"Ṣugbọn o ni, ko wa tumọ si pe ohun gbogbo ti bajẹ o, tun lee pada lọ si oju opo kan naa lati kọwe ranṣẹ pe ẹ fẹ gba iwe ẹri igbeyawo""."
Iroyin naa ni isẹlẹ naa buru to bẹẹ ti ẹmi osisẹ ọlọpa kan gan bọ ninu isẹlẹ naa.
Aare orile ede Naijiria Muhammadu Buhari ti sapejuwe ijoba tiwa-n-tiwa lorile ede Gambia ati igbese alaafia to n lo lowo gege bi ona ti yoo je ki ibasepo to dan moran tubo joba laarin ile Afirika.
Minisita fun eto ilera ni agbara aisan COVID-19 ko re 'bikan o pe o lewu to si n gba ẹmi awọn eniyan.
Eyi to ṣẹ tun gbe jade ni fidio orin to kọ lati fi sọ oko ọrọ si awọn ẹgbẹ tabi ọlọdani lawujọ.
Ẹrọ alagbeka kan ati nọmba kan ṣoṣo ni aṣedanwo lee lo.
Olùfẹ́, ẹ má ṣe gba gbogbo ẹni tí ó bá wí pé òun ní Ẹ̀mí Ọlọrun gbọ́.
9 Agẹmo 2019 Maleebu ki ara rẹ de gongo, ẹyin ẹ̀ṣà ògbín dá?
Ohun ti mo kan ri nibẹ ni pe aya gomina Kwara ran awọn eeyan wa pe awọn fẹ ka pari aawọ to wa laarin wa, ka si maa sọrọ sira wa.
Ṣugbọn Jesu tún tẹnu mọ́ ọn pé, “Ẹnìkan fọwọ́ kàn mí sẹ́ẹ̀, nítorí mo mọ̀ pé agbára ti ara mi jáde.
" A koro oju si iwa àwọn onimọtara ẹni nikan, to fi ẹ̀mí ọpọlọpọ ọmọ orilẹ-ede Uganda sinu ewu, nitori pe wọn n wa owo.
igbimo asofin ti yoo waye ni ojo kẹ́rìndínlógún yoo se ri jade.
Àbí, ta ni àpáta, àfi Ọlọrun wa?
Lásìkò tí àbúrò Sẹnatọ Dino, Bolarinwa Moses Melaye bá BBC Yorùbá sọ̀rọ̀ lóri ẹ̀rọ ìbánisọ̀rọ̀, ó sàlàyé pé àwọn ò mọ ibi ti ẹgbọ́n àwọn wà, àti pé àwọn ìgbésẹ̀ ti ọlọ́páà ń gbé le jẹ́ ìpálara fún ilera ẹgbọ́n òun.
Esi ifẹwọnsẹ naa jẹ iyalẹnu fun ọpọlọpọ awọn ololufẹ ere bọọlu lẹyin ti Naijiria lu Qatar ni aludaku pẹlu ami ayo mẹrin sodo ninu ifẹsẹwọnsẹ ti wọn kọkọ gba ninu idije ọhun.
O sọ pe itura ti atẹgun ba fun ara a rẹ yoo sọ fun ara rẹ pe asiko ti to lati sinmi.
Oríṣun àwòrán, @BuhariMediaORG Àkọlé àwòrán, Buhari ko ni ba Audu Ogbeh, Isaac Adewwole, Solomon Dalung atawọn mii ṣiṣẹ ni sa yii Solomon Dalung, minista fun eto ọdọ ati ere idaraya.
Ọga ọlọpaa Abubakar tun ṣalaye siwaju sii pe, ko si ootọ ninu ọrọ naa nitori pe ọkunrin ti wọn ni o n yirapada naa ṣi wa ninu atimọle, ṣugbọn awọn ti lọ mu ẹyẹ igun ti wọn n sọ naa wa si ahamọ.
Ogagun David Adeniran, to gba ise lowo ogagun Emuekpere  so pe oun yoo pari awon ise to ku nilẹ , o tun wa bebe lowo awon iko omo ogun naa ,awon adari agbegbe ati awon ara ilu fun ifowosowopo won.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Aregbesola: mí ò gba owó oṣù gómìnà rí Ọ̀gbìn ìrẹsì dìrọ̀rùn, ìjọba àpapọ̀ yóò yá àgbẹ lówó Àmàlà ṣekúpa ènìyàn mẹ́rin ní Ilorin Ayefẹlẹ bá BBC sọ̀rọ̀ lórí ilé orin rẹ̀ tí Ajimọbí ń tún kọ́ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ìfipábánilòpọ̀: Abiamọ bú sẹ́kún nígbà tí ọkùnrin kan fi tipá bá ọmọ méjì lòpọ̀ Atẹjade kan ti Oludari feto idanilẹkọ ati itaniji fawọn araalu labẹ ajọ Inec, Oluwọle Osaze-Uzzi fisita lo sisọ loju ọrọ.
Mo sọ fun yín, bẹ́ẹ̀ gan-an ni, ayọ̀ tí yóo wà ní ọ̀run nítorí ẹlẹ́ṣẹ̀ kan tí ó ronupiwada ju ti ìtorí àwọn olódodo mọkandinlọgọrun-un tí kò nílò ìrònúpìwàdà lọ.
Ó lé ní ogún ọdún dáadáa kí báálẹ tó wà lórí àlééfa lọ́wọ́lọ́wọ́ tó jẹ, èyíkò ṣàì rí bẹ̀ bí óti jẹ́ pe, ogun ọtẹ ló kó ìlú ní pápá mọ́ra.
Nibayii, ti Romero ti kuro, ọna la fun ija laarin Adesanya to wa loke tente atẹ igbelewọn awọn akanṣẹ ni ipele Middlewieght, ija ẹṣẹ ati ipa kikan UFC248 lati koju Paulo Costa to wa ni ipo keji lori atẹ naa.
Àwọn olùdíje mẹ́ta míràn tún ti jọ̀wọ́ àgá fún Akeredolu níbi ètò ìdìbò abẹ́lé APC ìpínlẹ̀ Ondo Adelé Ọ̀gá Àgbà àjọ NDDC dákú rangbọndan lásìkò tí ìwádìí n lọ lórí ẹ̀sùn ìnákúnàá Wo bí Dorathy Bachor ṣe di gbajúmọ̀ lóríi Instagram lẹ́yìn tí ètò àgbéléwò BBNaija bẹ̀rẹ̀ Ó yẹ kí ìjọba gbé ilé ìwé tì pa títí di ọdún 2021- ASUU West ni oun faramọ ki awọn eniyan ni eto labẹ ofin lati ṣẹ oyun, amọ ki ijọba ṣe ipese owo fun awọn oloyun ti ko ba ri owo lati tọju ara wọn.
26 Bélú 2020 6:08 Fídíò, Adebola Ademilua: Àìrísẹ́ ṣè lẹ́yìn ìwé kíkà ló sọ mi dí ìyá onírú, mo dúpẹ́ tèmi, Duration 6,0827 Bélú 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Nítorí náà, inú bí OLUWA sí àtòun ati Juda ati Jerusalẹmu.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù NHIS: Ìjọba àpapọ̀ gbé ìgbìmọ̀ ẹlẹ́ni méje kalẹ̀ lórí wàhálà iléeṣẹ́ adójútòfò ìlera 23 Ọ̀wàrà 2018 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 31 Ọ̀wàrà 2018 Oríṣun àwòrán, NHIS Nigeria Àkọlé àwòrán, Inu awọn oṣiṣẹ NHIS ko dun si bi ọga agba ajọ naa ko ṣe tẹle aṣẹ lọ rọọ kun nile ti wọn fun un Lẹyin ọpọlọpọ awuyewuye, ijọba apapọ ti ran akọwe agba ajọ adojutofo ilera lorilẹede Naijiria, NHIS, Ọjọgbọn Usman Yusuf lọ si isimi ni kiakia bayii.
Minisita fun ọrọ ilẹ okeere Mlaes Alem ti ni “isẹ ti bẹrẹ ni pẹrẹu  lati  se atunse si ebute  ọkọ  to wa ni Assab laipẹ Oju ona  ọkọ  to lo si ebute  ọkọ  Assab.
Ni ọjọ ẹti ti o kọja ni awọn aṣofin mejidinlogun ninu mẹrindinlọgbọn to wa ni ile naa dibo yọ olori ile naa ati igbakeji rẹ lori ẹsun iwa aitọ, ṣiṣe owo baṣubaṣu, ṣiṣi agbara lo ati aikun oju iwọn lẹnu iṣẹ."
Èyí pẹlu yóo jẹ́ ẹ̀ṣẹ̀,tí adájọ́ gbọdọ̀ jẹ mí níyà fún;nítorí yóo jẹ́ aiṣootọ sí Ọlọrun ọ̀run.
"O tẹsiwaju pe ""Yatọ̀ si iru ọna ati mu adinku ba owo ti ijọba n na yii, ohun to ṣe pataki ni ki ìjọba mú ọrọ igbaye gbadun ara ilu lọkunkundun."
    “Ṣùgbọ́n, ọmọ mi, sràn ìdálẹ̀ ṣòro.
Ọpọ wọn si lo maa n ba se ere tiata tabi kọ orin, tawọn ọmọ rẹ kan si n sere tiata di oni Ogunde gba ọpọlọpọ ami ẹyẹ lati mọ riri isẹ takuntakun to se fun iran ọmọniyan ati ijijagbara iran Yoruba Lẹyin to ya ere kan tan, to pe akọle rẹ ni ‘Mr Johnson’ ni Hubert Adedeji Ogunde dubulẹ aisan, to si juwọ si aye pe o digbose lọjọ Kẹrin, osu Kẹrin ọdun 1990 ni ilu London.
Lẹ́yìn náà, Dafidi lọ sí aṣálẹ̀ Parani.
Lori eto ẹkọ, Seyi Makinde salaye pe nigba ti esi idanwo WAEC yoo ba fi jade lọdun to n bọ, ipo kẹrindinlọgbọn ti ipinlẹ Ọyọ wa yoo ti sun siwaju nitori ijọba ti n se aayan lati gba awsn olukọ si, to si ti n pese awọn iwe idanwo to ti kọja fun awọn akẹkọ lati fi gbaradi fun idanwo naa.
Òun nìkan ni nígbà tí mo pè é,tí mo súre fún un,tí mo sì sọ ọ́ di ọpọlọpọ eniyan.
Ó dá wọn lóhùn, ó ní, “Bí ẹ ti wí gan-an ni yóo rí.
Bakan naa ni oludije fun ipo gomina lẹgbẹ Oṣelu APC nipinlẹ Eko Babajide Sanwo-Olu ati igbakeji rẹ, Fẹmi Hamzat naa wa nibẹ pẹlu.
Àkọlé àwòrán, Ile ẹkọ 'The International School, UI' ti wọle pada lẹhin rogbodiyan ọlọsẹ kan gbako lori ọrọ Hijab Wamu-wamu ni awọn ẹṣọ aabo duro lẹnu ọna abawọle ileẹkọ naa, ti wọn ko si fi aye gba ikọ iroyin BBC Yoruba naa lati wọle.
Ó ní, “Àwọn ọkunrin meji kan gòkè lọ sí Tẹmpili wọ́n lọ gbadura.
Ati pe Aarẹ Buhari ko ni sinmi titi ti gbogbo awọn ọmọbinrin wa yoo fi gba itusilẹ.
Abubakar n lo awọn ibọn to ba ra lọwọ Talatu lati jale ati lati ji awọn eeyan gbe fun owo, ko si irọ kankan nibi ọrọ naa, ileeṣẹ lo sọ bẹẹ.
Olayinka lo so oro yi di mimo lasiko ti awon egbe
WHO ni o ṣeeṣe ki afẹfẹ gbe arun naa ni ibi ti ero ba pọ si ati ibi ti ko ba si atẹgun, amọ ajọ naa ni iwadii ṣi n lọ lọwọ lati fidiẹ mulẹ daadaa.
O ni nigba ti oun fẹ jade kuro nile loun rii pe wọn ti gbe ọkọ di oun ti oun si ti n wa awọn to wa ọkọ di oun mọle ti onitọun si yọju to n pe ki oun ṣimẹdọ loun ba fi igbaju daa lohun.
Ẹlomiran, @mubaraq_a tun kin ọrọ @funshi lẹyin, o ni Naira Marley nikan ni Ọlọrun fihan ojiṣẹ Ọlọrun naa.
Fayemi: Gbèsè tí mo bá nílẹ̀ ni kò jẹ́ kí n ti yan kọmíṣọ́nà Agbébọn pa ènìyàn 14, ọmọọ̀gun Naijiria sígun ni Kaduna Ilé ẹjọ́ rán ọjọ̀gbọ́n fasiti OAU lọ sẹ́wọ̀n ọdún méjì Ó ní lẹ́yìn tí ìgbìmọ tẹẹ́kótó lóri iwé owó tí wọn gbé iṣẹ́ fún jábọ lóri abájáde ìwádìí wọn lóri ìṣúnà àwọn ìjọba ìbílẹ̀ ní arídájú ti jẹyọ pé wọn ń ṣe owó ìlú mọkumọku tí ìgbìmọ ò sí lé mójúkúrò ''A ṣiṣẹ́ lórí àwọ ìwé wọn à sì rí àrídájú pé àwọn alága ìjọba ìbílẹ̀ ṣe ǹkan tó wù wọn láti ṣe i'sẹ́ àkànṣe tó ju ǹkan tó yẹ kí wọn ṣe lọ, èyí ló fún wọn ní ànfàní láti hùwà jẹgúdújẹra'' Aribisogan bẹnu àtẹ lu àhesọ ọ̀rọ̀ pé àwọn alága fún ilé ìgbìmọ aṣofin ní mílíọ̀nù mẹ́jọ láti dáwọ́ ìdádúró náá dúró, ó fi kún-un pé àwọn ọmọ ìgbìmọ tẹ̀ẹ́kótó nìkan ló sàbẹ̀wó sí gbogbo ètò tó wáye ní àwọn ìjọba.
Ọlọrun ti dárí gbogbo ẹ̀ṣẹ̀ wa jì wá.
Lóòtọ́ ni mo yìnbọn níbi yánpọnyánrin tó wáyé ládúgbò mi-Seun Kuti ''Buhari àti Tinubu ṣ'àdéhùn pé Yorùbá ni yóò jẹ́ olùdíje ipò ààrẹ APC lọ́dún 2023'' Ṣé lóòtọ́ọ́ làwọn ọlọ́ṣà tún gbẹ̀mí èèyàn kan ní Moniya, Ibadan?
Idahun: Bẹẹni, o le e lọ forukọ silẹ bayii ti o ba nifẹ si eto igbanisiṣẹ naa.
Igbesẹ yiyọ aarẹ naa nipo ko sẹyin ipa to ko ninu wahala to waye nile aṣofin apapọ orilẹede Amẹrika lọsẹ to kọja.
Ko fẹrẹẹ si iyatọ pupọ ninu nnkan ti Sẹnẹtọ Lawan naa fẹ ṣe ti o ba di aarẹ ile asofin agba.
Oṣù Kínní ọdún 2020 ti pẹ́ jù, ẹ ṣe ìgbẹ́jọ́ mi kíákíaá - Donald Trump Àhámọ́ EFCC ni Adoke Mohammed yóò ti ṣe kérésì Ijọ Sotitobire: Òótọ́ àti irọ́ tó wà nínú iṣẹ̀lẹ̀ náà Ọmọ ọdun mẹtadinlogoji naa ti fi igba kan ṣe iṣẹ ni ikọ Arsenal yii ati ikọ Everton ri.
Oya ijo naa fi kun pe, igba ti wọn nile nitori gbese owó ilé ọdun meji, ijọ fun ni yara kan ki o maa gbe.
Messi gọ̀ láti sọ fun akọ́nimọ̀ọ́gbá Brazil pé kó gbẹ́nu dákẹ́- Thiago Silva Ilé ẹjọ́ ni agbábọ́ọ̀lù ọmọ Nàìjíríà, Dickson Etuhu jẹ́bi ẹ̀sùn títa ìdíje Sweden Àwọn ọmọ Nàìjíríà bu ẹnu ẹ̀tẹ́ lu NTA lórí ìgbóhùnsáfẹ́fẹ́ ìdíje bọ́ọ̀lù Igba akọkọ ni yii ti akọnimọọgba naa yoo ma a tukọ ẹgbẹ agbabọọlu Tottenham lẹyin ti wọn le ni ikọ Chelsea ati Manchester United.
Oniruuru iwọde lo ti n waye niorilẹede Sudan ninu eyi ti ọpọ araalu ti n pe fun igbejọbasilẹ aarẹ Omar al-Bashir.
Lọwọ lọwọ bayii, Seyi Edun ko tii fesi si ọrọ Wunmi yii, amọ a lero pe ija naa yoo wa sopin laipẹ laijinna.
Ẹ̀ka rẹ̀ tí ó lágbárani a fi gbẹ́ ọ̀pá àṣẹ fún àwọn olórí.
Bí ó ti ń pada lọ sí Sikilagi, àwọn ará Manase kan wá, wọ́n bá darapọ̀ mọ́ àwọn ọmọlẹ́yìn Dafidi.
Nígbà tí ó tí aṣojú-Olódùmarè tún wáá bẹ̀ wọ́n wò, wọn kò yẹ́ ẹ sí bíi tí àtẹ̀yìnwá, nígbà tí òun sì bi wọ́n ìdí rẹ̀, wọ́n wí fún un pé ipò ti Ọlọ́run fí àwọn ssí kò tó, àwọn kò ní ìtẹ́lọ́rùn sí ipò àwọn.
8th National Assembly: Ilé ìgbìmọ̀ aṣòfin kẹ̀jọ kógbá sílé lónìí
Ẹ̀kọ́ fún Ìjọba tiwa ntiwa ni orilẹ̀ èdè Nigeria ni wi pé iwá ibàjẹ́ ti àwọn Òṣèlú nhu ni Àbùjá lai fi eti si ará ilú pé àwọn ẹ̀yà mẹ́yà orilẹ̀ èdè Nigeria fẹ́ dá Ìjọba wọn ṣe ju ki Òṣèlú joko si Àbùjá lati maa na owó gbogbo ará ilú.
Ọ̀gágun náà rí Elija níbi tí ó jókòó sí ní téńté òkè, ó sì wí fún un pé, “Ìwọ eniyan Ọlọrun, ọba sọ pé kí o sọ̀kalẹ̀ wá.
8 Yíò sí ṣe, pé bí ìwọ bá béèrè lọ́wọ̀ Bàbá ní orúkọ mi, pẹ̀lú ìgbágbọ́, ìwọ yíò gba Ẹ̀mí Mímọ́, èyí tí ó ńfun ni ní ọ̀rọ̀ sísọ, kí ìwọ kí ó lè dúró gẹ́gẹ́bí ẹlẹ́rìí àwọn ohun tí ìwọ yíò rí àti tí ìwọ yíò gbọ́, àti bákannáà pé kí ìwọ kí ó lè kéde ironúpìwàdà sí ìran yìí.
"Àwọn olóṣèlú Nàìjíríà márùn ùn tó sọ̀rọ̀ tí ará ìlú fà ìbínú yọ Báyìí ni 50 Kobo ṣe dá ìfẹ̀hónú ""Ali Must go"" sílẹ̀ tó mú ọ̀pọ̀ ẹ̀mí akẹ́kọ̀ọ́ lọ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Egbò tó ti fẹ́ẹ̀ jiná ni ìtàn bí wọ́n ṣe pa Soun Ogbomoso, Ọba Olayode tẹ ń bèrè' Oríṣun àwòrán, EPA/Nigeria Police Ọ̀gá àgbà ọlọ́pàá kọ àbájáde àjọ Amnesty International lórí ìṣẹ̀lẹ̀ EndSARS ní Lekki Ọga agba ọlọpaa lorilẹede Naijiria, Mohammed Adamu ti kọ àbájáde ọ̀rọ̀ tí ajọ Amnesty International sọ pe awọn ọlọpaa yinbọn pa awọn oluwọde EndSARS."
Nígbà tí wọ́n jẹ ọkà tí wọ́n rà ní Ijipti tán, baba wọn pè wọ́n, ó ní, “Ẹ tún wá lọ ra oúnjẹ díẹ̀ sí i.
Fayoṣe ni ikọlu yii jẹ ikọlu fun gbogbo ẹya Igbo ati orilẹede Naijiria lapapọ nitori Sẹnẹtọ Ekweremadu jẹ ọkan lara awọn to jẹ ki ijọba awarawa fidi mu lẹ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Sex For Grades: Four Square Church tí ní kí olùkọ́ fásitì Pasitọ̀ Boniface lọ fìdímọ́lé 7 Ọ̀wàrà 2019 Oríṣun àwòrán, @unilag Àkọlé àwòrán, UNILAG ko fọwọ si iwa ibajẹ biba akẹkọọ sun nitori maaki rara.
 abala ìtàn yí fi yéwa wípé jagun jagun ni odùduwà jẹ ́ pẹ ̀ lú bí ó ṣe wọ ̀ éwù ogun onírin .
Wọn yóo wá kọrin lórí òkè Sioni,wọn óo sì yọ̀ lórí nǹkan ọ̀pọ̀ oore tí OLUWA yóo ṣe fún wọn:Wọ́n óo yọ̀ nítorí oore ọkà ati waini ati òróró,ati aguntan ati ẹgbọ̀rọ̀ mààlúù;ayé wọn óo dàbí ọgbà tí à ń bomi rin, wọn kò ní dààmú mọ́.
1–5, Àwọn ìwé mímọ́ fi ọ̀nà tí a lè fi gbé ìjọ kalẹ̀ hàn, 6–8, Ayé ńbàjẹ́ síi nínú àìṣedéédé; 9–16, Àwọn ọkàn ṣe iyebíye púpọ̀; 17–25, Láti jẹ èrè ìgbàlà, àwọn ènìyàn gbọ́dọ̀ gba orúkọ Krísti sí orí wọn; 26–36, Pípè àti iṣẹ́ ìránṣẹ́ àwọn Méjìlá ni a fi hàn; 37–39, Oliver Cowdery àti David Whitmer yíò ṣe àwárí àwọn Méjìlá; 40–47, Láti jẹ èrè ìgbàlà, àwọn ènìyàn gbọ́dọ̀ ronúpìwàdà, kí a sì rì wọ́n bọmi, kí wọ́n ó sì pa àwọn òfin mọ́.
Mo bá da aṣọ mi bò ọ́, mo fi bo ìhòòhò rẹ.
Òun ní ń yí ìgbà ati àkókò pada;òun níí mú ọba kan kúrò lórí ìtẹ́,tíí sì í fi òmíràn jẹ.
Adari eto to n bojuto ayika ni ipinlẹ Eko naa wa parọwa si awọn eniyan lati fi ọkan balẹ wi pe, ko si ẹwu fun awọn ara ipinlẹ Eko ati wi pe o ṣeeṣe ki wọn fi awọn ọlọkada yii silẹ laipẹ.
Tí ẹ o bá gbàgbé àwọn ọmọ orílẹ̀-èdè South Africa tí ń ko sọọbu ti wọ́n sì ń pa àwọn ọmọ Nàìjíríà ni orilẹ̀-èdè wọ́n.
 a rí àwọn olóyè bí Ọbaálá , rísàwẹ ́ , Ọ ̀ dọlé , léjòfi sàlórò Àrápatẹ ́ àti Ọbádò ni Ìjẹ ̀ bú-jèṣà bí wọ ́ n ti wà ni iléṣà .
Bakanna ni awọn afunrasi naa fi ẹsun kan awọn ọlọpaa pe wọn pa awọn Fulani maarun ati ọlọpaa tẹlẹri kan Micheal Adikwu ti o jẹ olori awọn adigunjale Offa naa.
“ Ohun to ye lati se ni eto idibo egbe , ni kete ti  akoko to ye ki awon alakoso egbe naa ,yoo lo  lori ipo ba  ti n  pari  lọ, igbimo alabe sekele ko lee se nnkankan  bayii .
Igbesẹ yii lo n waye lẹyin ti ijọba apapọ pinnu pe awọn ile iwe Unity Schools ko ni kopa ninu idanwo aṣekagba WAEC to yẹ ko bẹrẹ lọjọ kẹrin oṣu kẹjọ ọdun yii.
''O ti di dandan lati se agbeyewo ibasepọ laarin awọn ọlọdani ati ẹka ijọba ti a mọ si PPP'' Arinrinajo lọ si ilẹ okere fun ẹkọ tabi ilera yoo mọ asiko yi lara Ninu awọn ti Ọjọgbọn Nazifi Abdullahi Darma sọ pe yoo mọ asiko yi lara ju ni awọb ti wọn ma n na owo dọla yala lati fi gba itọju nilẹ okere ni tabi fẹkọ ni oke okun.
Awọn ọkọ agbepo to le ẹgbẹrun un kan to fẹ gbepo kọja ni ibode Naijiria sawọn orilẹede to wa layika ni a gbọ pe awọn ile iṣẹ aṣọbode ti gbẹsẹ le ti wọn ko si jẹ ki wọn kọja.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, India: Ẹ wo bí àwọn ènìyàn ṣe dóòlà èmí erin tó jálulẹ̀ O salaye pe ni ọpọlọpọ igba, ọrọ gbọyi-sọyi ati iroyin eke lati ọdọ awọn onworan tiata, ẹbi wọn ati awujọ lapapọ, lo maa n saba da igbeyawo ilumọọka onitiata ru.
Uzoho (Anorthosis Famagusta, Cyprus); Ikechukwu Ezenwa (Katsina United); Daniel
Man City ti wọn jijọ wa nilu kanna kii ṣe ẹni ti wọn jijọ n fẹyin si ara wọn.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Chinonso Eche: Mo fẹ́ dà bíi Messi, Ronaldo àti Okocha Portugal ati France gba ọmi ninu ifẹsẹwọnsẹ ti wọn gba kẹyin lọjọ Aiku ti awọn ati France si jọ ni iye ami ayo kan naa lori afara.
Iranṣẹ náà mú mẹ́wàá ninu àwọn ràkúnmí oluwa rẹ̀, ó gba oríṣìíríṣìí ẹ̀bùn àtàtà lọ́wọ́ oluwa rẹ̀, ó jáde lọ sí ilẹ̀ Mesopotamia, sí ìlú Nahori.
Oríṣun àwòrán, AFP Àkọlé àwòrán, Meji ninu awọn \\pmọ ogun Calvary ti ile Oba Dutch lasiko ayẹyẹ iranti iṣoro ayipada oju ọjọ lagbaye.
Bẹ́ẹ̀ náà ni wọ́n gbèrò láti ṣe ìkéde nípa ìdààbò bo àwọn ilé àjogúnbá tí ọ̀rán kàn.
Ara ọrẹ rẹ̀ tún ni: àwo kòtò kan, tí wọ́n fi wúrà ṣe tí ìwọ̀n rẹ̀ jẹ́ ṣekeli mẹ́wàá, tí ó sì kún fún turari.
Nigeria Labour Congress NLC, Ayuba Wabba lo soro yii lasiko ifọrọwanilẹnuwo ti
N óo dúró pẹlu baba mi ní orí pápá lọ́la níbi tí o bá farapamọ́ sí, n óo sì bá a sọ̀rọ̀ nípa rẹ, ohunkohun tí mo bá sì gbọ́ lẹ́nu rẹ̀, n óo sọ fún ọ.
N óo máa pa òfin rẹ mọ́,má kọ̀ mí sílẹ̀ patapata.
Iye ènìyàn tí ó ń gbé ní ilẹ̀-tí-omí-fẹ́rẹ̀ẹ́-yíká Kowloon tó bíi èèyàn 40,000 ní orí ìwọ̀n kìlómítà kọ̀ọ̀kan, àti bí i ènìyàn 20,000 ni ó ń gbé Yau Ma Tei.
Awọn asofin fẹ mọ iye tijọba nna lati tẹ owo ẹyọ Ninu ọrọ rẹ, igbakeji aarẹ ile igbimọ asofin agba lorilẹede Naijiria, Sẹnatọ Ike Ekweremadu ni, igbesẹ titẹ awọn owo nla jẹ ohun kan to n fa isoro, paapaa nilẹ Afirika eyi to n nipa ti ko tọ lara awọn owo kekeeke.
Olori naa, to bi ibeji fun Alaafin wa kede fun araye pe bi ijamba kankan ba ṣe oun atawọn ọmọ oun, Alaafin ni kí wọn mu.
Ẹgbẹ́ Akọ́mọlédè àti Àṣà Yorùbá Nàìjíríà pé àádọ́ta ọdún Gbígba onídùròó Zakzaky ṣàfihàn àṣeyọrí ìfaradà wa lásìkò ìfìyajẹni - Shiite Ìwọ́de #RevolutionNow forí ṣánpọ́n ní Ibadan, àgbófinró gbàkóso ojú pópó Ọlọ́pàá àti àwọn olùfẹ̀hónúhàn gbéná wojú ara wọn níbi ìwọ́de Revolution Now Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Ẹ má jẹ́ kí á pa á, nítorí arakunrin wa ni, ara kan náà ni wá.
Yala ni awọn ilu kekeeke tabi lawọn ilu nla bi Abuja, Eko tabi Port-Harcourt, ipenija yii jẹ ohun to n kọ awọn eeyan lominu.
Nítorí pé, ní ọjọ́ náà ni wọn yóo máa ṣe ètùtù fun yín, tí yóo sọ yín di mímọ́ kúrò ninu gbogbo ẹ̀ṣẹ̀ yín, kí ẹ lè jẹ́ mímọ́ níwájú OLUWA.
O tun sọ fun ajọ naa wipe, ki wọn gbiyanju lati pin gbogbo oun elo idibo laarin akoko yii si ọjọ Satide, ki wọn si ri daju pe awọn ẹgbẹ oṣelu ni anfani lati yẹ awọn ẹrọ naa wo finifini, ki idibo to bẹrẹ ni ọjọ Satide.
Oniruuru ikọlu lawọn oniroyin n doju kọ lẹnu isẹ wọn, ọpọ igba lo si jẹ wi pe wọn kii fi awọn agbofinro to lọwọ ninu ikọlu bẹẹ jofin.
Gẹgẹ bi PDP ti wi, o ni awọn n fọwọ lẹran maa woye ohun ti yoo jẹ atubọtan ẹgbẹ oselu APC ati isejọba rẹ, nibayii ti akoso ile asofin agba ti bọ sọwọ wọn gẹgẹ bi wọn se n poungbẹ rẹ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Barcelona Vs Liverpool: Barca sọ ara rẹ̀ di ìbákà, orin góòlù mẹ́ta ló kọ sí etíi Liverpool.
Àwọn ọmọ Lefi ni: Ṣemaaya, ọmọ Haṣubu, ọmọ Asirikamu, ọmọ Haṣabaya, ọmọ Bunni.
Ǹjẹ́ ojú a tilẹ̀ máa tì wọ́n nígbà tí wọ́n bá ń hu ìwà ìbàjẹ́?
Lẹyin naa ni ẹkun aaringbungbun ariwa orilẹ-ede Naijiria, (North central 32.
Ni ọjọ kinni oṣu kejila ọdun ni ile igbimọ aṣoju-ṣofin da abaa ki wọn pe aarẹ Buhari lati wa jabọ fun wọn lorii otitọ to wa nidii ọrọ abo lorilẹede Naijiria.
Ọbìnrin Gẹ̀ẹ́sì tó wá fún ìsinmi ní Nàíjíríà ṣàgbákò ikú Awọn ọmọogun Indonesia n mu ẹjẹ ejo A yoo ṣe àyẹ̀wò ọpọlọ fàwọn òṣìṣẹ́ FSARS - Iléesẹ́ ọlọ́pàá Ọmọ ọdún márùn-ún wọ gàú ajínigbé ní Warri, ọlọ́pàá ri he ní Lafia Ti obinrin kan to ra a lọwọ wọn si fi maa n ṣọfa fun awọn onibara ti yo maa mu kiri.
Jẹjẹrẹ ní ìwà akakítí ẹ̀sìn, ẹ yàgà fún ẹ̀kọ́ òdì -Ààrẹ Buhari El-Zakzaky: Arúfin ni ijọba Muhammadu Buhari gan-an - Ladoja Ẹ̀yin mùsùlùmí, ẹ yàgò fún ìwà ipá- Buhari Ẹgbẹ́ òṣèlú PDP ní ìpínlẹ̀ Bayelsa jáwé olúbori nínú ìdìbò ìjọba ìbílẹ̀ Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 3 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 5 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
 kọ ́ lá ni ó ràn wọ ́ n lọ ́ wọ ́ láti mọ ilé yìí .
Gbogbo àwọn ọmọ ogun rẹ̀ ní a óo parun ní ọjọ́ náà.
"Minisita Ehanire ni ""ko si aniani pe, ojuṣe awọn dokita ati gbogbo awọn oṣiṣẹ eleto ilera ni lati doola ẹmi."
" bí ó bá ti ń ṣe bẹ ́ ẹ ̀ ni yóò máa pe orúkọ ẹni tí ó ti kú náà tí a sì fẹ ́ "" sẹ ́ ' eégún rẹ ̀ yìí ."
Ó dàbí igbó ṣúúrú ninu aṣálẹ̀,nǹkan rere kan kò lè ṣẹlẹ̀ sí i.
Awọn iroyin ti ẹ lee nifẹẹ si: Weah se ibura wọle gẹgẹ bi aarẹ Liberia Olori ẹgbẹ oselu alatako Kenya di aarẹ Aarẹ Frank-Walter Steinmeier lo ti kọkọ yan Merkel ko to di pe o sebura nile asofin kekere.
O fẹrẹ ma si agbalagba onkawe ede Yoruba ti ko tii ni ka awọn iwe yii nitori wọn kun fun ẹkọ to dara lati ṣamulo laye ode oni Ọdún mẹ́ta lẹ́yìn Adebayo Faleti, ìran Yorùbá ń ṣe ilédè rẹ!
Amọ ija to de lorin di owe laarin Gomina ipinlẹ naa, Udom Gabriel ati Akpabio lẹyin to kuro ni ẹgbẹ oselu PDP lọ si ẹgbẹ oṣelu APC.
"Gẹgẹ bo ṣe sọ, òní ""ṣiṣe eyii yóò mú kí àwọn Ọba alaye mọ ohun tó n lọ ati ohun ti awọn èèyàn n dojukọ, yóò sì tún gb'awọn láàyè lati ṣiṣẹ ipẹtu sí aawọ."
Nígbà tí Peteru bojú wẹ̀yìn, ó rí ọmọ-ẹ̀yìn tí Jesu fẹ́ràn tí ó ń tẹ̀lé e.
Orilẹede Japan naa a ma a jẹ ounjẹ yii.
Wo ohun tó yẹ kí o mọ̀ nípa Laycon, akẹ́kọ̀ọ́jáde UNILAG tó ń kópa nínú BBNaija 2020 Òògùn ìtura dé fún Coronavirus!
Ṣugbọn mo ní nǹkan wí sí ọ.
Ìjiyàn kan wà láàrin àwọn ọmọ-ẹ̀yìn pé ta ni ó jẹ́ ẹni pataki jùlọ.
A lé e kúrò láàrin àwọn ọmọ eniyan, ọkàn rẹ̀ dàbí ti ẹranko.
Wo bí ètò ìdìbò abẹ́lé APC yóò ṣe lọ ní ìpínlẹ̀ Ondo lónìí Èèyàn 789 gbèkuru jẹ lọ́wọ́ ẹbọra nítorí COVID-19 ní Nàìjíríà Chelsea fún Man United lóúnjẹ ẹ̀tẹ́ jẹ, Cuppy bínú yí jọ̀lọ́ọ̀fù dànù Ǹjẹ o yẹ kí èèyàn máa sùn lẹ́nu iṣẹ́?
Lẹka ipinlẹ, ko si iyatọ lori ọrọ naa pẹlu bi awọn alamojuto ilera ni ipinlẹ pẹlu se n sọ wi pe ọsan ko so didun lẹka naa.
Ìyẹn ni kò jẹ́ kí wọ́n sọ fún bàbá wọn mọ́.
 Ọ ̀ pọ ̀ àwọn tí àrùn náà mú ni wọn jẹ ́ akúṣẹ ̀ ẹ ́ tí ó tún jẹ ́ pé ọ ̀ pọ ̀ nínú wọn ni kò tilẹ ̀ mọ ̀ pé àwọn ní àrùn náà lára .
Mo múra, mo ń lọ ọ̀dọ̀ rẹ̀.
Ó bá kígbe mọ́ wolii ará Juda yìí, ó ní, “OLUWA ní, nítorí pé o ti ṣe àìgbọràn sí òun, o kò sì ṣe ohun tí òun OLUWA Ọlọrun rẹ pa láṣẹ fún ọ.
"Oríṣun àwòrán, FACEBOOK/Senator Oba Àkọlé àwòrán, Senato Akpan ni oun ati Omokore tin se ọrẹ bọ ọjọ ti pẹ EFCC ni, abẹtẹlẹ ni àwọn ọkọ naa jẹ sugbon Senato Akpan fèsì pé, ẹbun ní àwọn ọkọ náà ti ''ọre òun Omokore"" fi ta oun lọrẹ gẹgẹ bí ọrẹ sí ọrẹ ''."
Ẹni tí ó bá sì fẹ́ gba ẹ̀mí rẹ̀ là yóo pàdánù rẹ̀; ṣugbọn ẹni tí ó bá pàdánù ẹ̀mí rẹ̀ nítorí mi yóo jèrè rẹ̀.
Ileeṣẹ iroyin Bristol Live lorilẹede Uk fẹsun kan ọkunrin pe o yaso o si tun ṣe ikọlu fun awakọ Uber nitori pe oun fi ẹhonu han.
ISIS: Orílẹ̀-èdè mẹ́wàá tí ẹgbẹ́ alákatakiti Islamic State n fínna mọ́ ní àgbáyé
Nkan ti o ba sọ fun wa ni a o ṣe ni igbesẹ.
Afárá Third mainland gba ẹ̀gbọ́n Àwọn olè ń ṣọṣẹ nínú súnkẹrẹ-fàkẹrẹ ọkọ̀ tó ń wáyé nítorí afárá 3rd Mainland tí ìjọba tì Wo ohun tí Adájọ́ ṣe sí àṣùwọ̀n ìfowópamọ́sí Wòlíì Sotitobire Alága àjọ EFCC Ibrahim Magu yóò tún bẹ ìgbìmọ̀ olùwádìí Aàrẹ wò lónìí Ìkúnlẹ̀ ló bá dé fún Oshiomole, Ize-Iyamu láti bẹ̀bẹ̀ fún ìbò aráàlú ní Edo Ìkúnlẹ̀ ló bá dé fún Oshiomole, Ize-Iyamu láti bẹ̀bẹ̀ fún ìbò aráàlú ní Edo Buruji Kashamu ti tẹ́rí gbasọ Senatọ tó n sojú ẹkùn Ogun East nígbà kan rí, Buruji Kasahamu ti jẹ́ Ọlọrun nípe.
Má ṣe fi ojú pamọ́ fún èmi, iranṣẹ rẹ,nítorí tí mo wà ninu ìdààmú,yára dá mi lóhùn.
Ẹni tí ó bá fẹ́ pè ọ́ lẹ́jọ́ láti gba àwọ̀tẹ́lẹ̀ rẹ, jẹ́ kí ó gba ẹ̀wù àwọ̀lékè rẹ náà.
Bóyá OLUWA lè wo ìpọ́njú mi, kí ó sì fi ìre dípò èpè tí ó ń ṣẹ́ lé mi.
Àwọn ọba tí wọ́n jẹ ní ilẹ̀ Edomu kí ó tó di pé ẹnikẹ́ni jọba ní ilẹ̀ Israẹli nìwọ̀nyí: 
Orilẹ-ede mẹtalelọgbọn lo bẹrẹ idije Russia 2018 pe ki ife ẹyẹ agbaye lè tẹle wọn lọ sile ṣugbọn France lo gbaa lọ bayii bi wọn ṣe na Croatia sipo keji ti Belgium si gba ipo kẹta.
Pupo ninu àwọn tó máa n sọnù máa n ṣé bẹẹ, torí pé wọn kò tẹlé ètò ti wọn gbé kalẹ.
awon to n ta ọja nipa eto TraderMoni ati  MarketMoniOjogbon  Osinbajo ni ijoba ko
 “Nitori naa, ti e ba gba owo yii, a ro yin ki e da owo naa pada;ko ni èlé ninu;ti e ba gbaa , e o daa pada laarin osu mefa;mo fe ki gbogbo yii lo foruko sile , ki e le ri owo naa gba.
Kí wọ́n baà lè rú ẹbọ tí yóo jẹ́ ìtẹ́wọ́gbà sí Ọlọrun ọ̀run, kí wọ́n sì lè máa gbadura ibukun fún èmi ati àwọn ọmọ mi.
Ni odun 2002, o n lo bi irinwo awon eniyan ti won padanu-emi won nigba ti oko oju-irin akero kan gbana ni apa gusu ilu Cairo ti n se olu ilu orile-ede Egypt.
Oloogbe Oladejo Okediji tun ko iwe Agbalagba Akan gẹgẹ bii abala keji iwe Aja lo lẹru ti a n gbeyẹwo yii.
Gẹgẹ bi iroyin kan latẹnu awọn eeyan to n kopa nilu Mecca ti wi, wọn ti gbe osere tiata naa lọ sile iwosan nigba ti ara rẹ ko da pe mọ lati tẹsiwaju pẹlu isẹ hajj naa.
Oríṣun àwòrán, other Àkọlé àwòrán, Ronke Oshodi Oke Bimbo Thomas Lọ́sẹ̀ yìí bákan náà gbájúgbajà òṣèré Bimbo Thomas gbe e jáde lójú òpó Instagram rẹ̀ láti fi ìdunu rẹ̀ hàn lórí ọjọ́ ìbí ọmọ náà.
Rii wi pe iṣọkan wa laarin eto idajọ Naijiria.
Bourdain ṣe igbeyawo leẹẹmeji, ó-+kọ awọn obinrin mejeeji silẹ ṣugbọn o ni ọmọbinrin kan nibi igbeyawo rẹ keji.
Eyi ko ṣẹyin ẹsun ti ileeṣẹ banki naa ṣe ni awọn araalu gan an lo gba owo ti awọn adigunjale naa jigbe lọ, ti wọn si pin laarin ara wọn.
Èdè bàntú ni wón ń so , wón sì wà ní tanzania àti mozambique .
Ọdun 2018 ni Ajọ to n gbogun ti iwa ibajẹ, EFCC fi ẹsun kan Kalu pe o ji iye owo to le ni biliọnu meje Naira, (N7.
eleto ilera Live Well Initiative se fun awon egbe naa, lara won lati ri : Hepatisis
Ìwọ ọba ni o pàṣẹ pé nígbàkúùgbà tí ẹnikẹ́ni bá ti gbọ́ ìró fèrè, dùùrù, ìlù, hapu, ati oniruuru orin, kí ó wólẹ̀, kí ó tẹríba fún ère tí o gbé kalẹ̀, 
Bakan naa, gomina ipinlẹ Ekiti tẹlẹ, Ayo Fayoṣe ni ẹni ilẹ ti wọn kii tẹni funh lawọn to fiya jẹ Ekweremadu lorilẹede Germany.
Ṣugbọn Jesu pè wọ́n, ó ní, “Ẹ jẹ́ kí àwọn ọmọde wá sọ́dọ̀ mi, ẹ má dá wọn dúró, nítorí irú wọn ni ìjọba Ọlọrun.
" Asoju ajọ isọkan ilẹ Yuroopu, Eulorilẹede Naijiria, Ketil Karlsen ati igbakeji asoju ijọ̀ba ilẹẹ Gẹẹsi lorilẹede Naijiria, ti awọ̀n pẹ̀lu kopa nibi ijiroro naa asiko ati karamasiki gbigbogunti fifi awọn eeyan sowo ẹru niyi fun gbogbo awọn alẹnulọrọ.
Oríṣun àwòrán, Osi_Suave Àkọlé àwòrán, Awon olorin ati osere tiata Awọn alejo miran ti awọn eniyan n ṣe awada pe o ti de sibi eto naa ni: Oríṣun àwòrán, Iwara139 Àkọlé àwòrán, Bobbriski lo wọ pepper-dem green yii oo Oríṣun àwòrán, Optimistic-Ade Àkọlé àwòrán, Abubakar Atiku bawọn n dáwọ idunnu nibẹ Oríṣun àwòrán, Hassan winger Àkọlé àwòrán, Dino ati àwọn ẹmẹwaa rẹ sááju ọjọ igbeyawo lọ ki Baba Buhari Ayẹyẹ yiìí ko yọ Trump silẹ bi o se fí ohun ránsẹ pé òun ko ni le raye wá.
Sugbọn agbabọọlu ẹlẹsẹ ayo, Kelechi Iheanacho ati Ṣemi Ajayi ko ni ba wọn lọ.
O ni owo ori ti o san ko ju ẹgbẹrun marundinlọgbọn naira lọ.
ṣugbọn tí ó ń jẹ ẹbọ lórí àwọn òkè, tí ó ń bá aya aládùúgbò rẹ̀ lòpọ̀; 
N óo tún ahoro rẹ̀ mọ,n óo sì gbé e ró.
Ènìyàn 254 ló lùgbàdì àrùn Coronavirus ní ìpínlẹ̀ Eko nìkan ní Ọ̀jọ́ Ẹtì!
Oríṣun àwòrán, @NGRSenate Àkọlé àwòrán, 'Mo kan saara si awọn obinrin ti wọn ti ko ipa ribiribi ti wọn si tun si n ko ipa ribiribi ninu idagbasoke orilẹede wa-ni ẹka gbogbo' Loni, tii se ọjọ awọn obinrin lagbaye, mo ba awọn iya wa, aburo ati ẹgbọn wa lobinrin, awọn ọmọbinrin wa, ara ati ọrẹ lobinrin ti wọn n ji lojoojumọ lati rii wi pe ile aye dun un gbe fun tẹru tọmọ."
Ìdí tí wọ́n fi la àwọn ọ̀nà wọ̀nyìí ni pé inú igbó yìí ṣẹ pàtàkì fún àwọn ará ìpínlẹ̀ òhún gẹ́ gẹ́ bíi ọ̀nà àfẹsẹ̀rìn láti ìlúdélùú.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Eko Akete yóò gbàlejò BBC Yoruba Falz tun mẹnu ba ọrọ awọn oloṣelu to ma n rinrinajo lọ oke okun loore koore, nipa ipolongo idibo, nipa awọn ọmọ Yahoo Yahoo, awọn ọmọ oloṣo ati igbe aye olowo gee gee tawọn pasitọ kan n gbe.
“Ninu aṣálẹ̀ ni ó ti rí wọn,níbi tí kò sí igi tabi koríko, àfi kìkì yanrìn.
N kò jẹ́ sọ nǹkankan àfi àwọn nǹkan tí Kristi tọwọ́ mi ṣe, láti mú kí àwọn tí wọn kì í ṣe Juu lè gbọ́ràn sí Ọlọrun.
Bakan naa ni o ṣalaye pe awọn ọmọ ẹgbẹ alakatakiti naa ti wọn to igba ni iye kii ṣe alawọ dudu, wọn fara jọ awọn larubawa ti wọn fi lawani bo ori pẹlu awọn ibọn atamatase ni ọwọ wọn.
Ọkunrin mejila ni àwa tí a jẹ́ ọmọ baba kan náà, ọ̀kan ninu wa ti kú, èyí tí ó kéré jù sì wà lọ́dọ̀ baba wa ní ilẹ̀ Kenaani.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Obateru Akinruntan: Wíwá ohun tá jẹ títí láé ló gbé wa kúrò nílé Ife O ni onijibiti ẹda gbaa ni ati pe o ti lu ọpọlọpọ awọn obinrin ni jibiti, bẹẹ lo tun pe osere tiata naa ni gbajuẹ.
Àwọn ọlọ́gbọ́n rọ epo sinu ìgò, wọ́n gbé e lọ́wọ́ pẹlu àtùpà wọn.
OLUWA ní,“Ní ọjọ́ náà, n óo dáhùn adura ojú ọ̀run,ojú ọ̀run yó sì dáhùn adura ilẹ̀.
Sugbọn, ko ti i sọ ohunkohun lati igba ti awọn ọlọpaa ti mu u.
Awọn ileesẹ iroyin kan ni Naijiria si ti sọ pe ẹgbẹrun lọna aadọsan Euro ni Madagascar fẹ ẹ gba lori agbo naa lọwọ Naijiria.
Bóo la ti wá fẹ́ ṣe é o?
Aare Muhammadu Buhari banu je pupo leyin ti o gbo pe Emir ipinle Nasarawa, Alhaji Hassan Ahmed Abubakar II ti di oloogbe.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Jiti Ogunye: Ọjà òkùnkùn ni àyẹ̀wò Minisita ní Ilé Asòfin 26 Agẹmo 2019 Oríṣun àwòrán, Google Àkọlé àwòrán, Awuyewuye ti jẹyo lori bi awọn Asofin Agba se kọ lati se ifọrọwanilẹnuwo lẹkunrẹrẹ fun awọn Minisita ti Aarẹ Buhari fi sọwọ si Ile Asofin Agba.
Ní ọjọ́ kẹrin, wọ́n péjọ ní àfonífojì Beraka.
Toyin Abraham ati Nkechi Blessing Ọjọ kẹta, ọsu Kejila yii ni Nkechi Blessing fi ọrọ kan lede loju opo Instagram rẹ, nibi to ti n tọrọ aforoji lọwọ Toyin Abraham.
Ajiboye sọ pe ''nigba ti Gomina Akeredolu lugbadi Covid-19, wọn kede fun ara wọn, ti iyawo wọn naa ba ni Coronavirus, ko si awo kankan nibẹ, wọn yoo kede rẹ.
Ni bayii, eeyan ẹgbẹrun meje, ati ojilelẹgbẹrin din ẹyọkan (7839) ni akọsilẹ wa pa o ti ni aarun naa ni Naijiria.
Àwọn ni baálé ìdílé wọn, wọ́n sì jẹ́ akọni jagunjagun.
Ó kéré tán, ẹ̀mí méjì míì ti lọ lórí ìfẹ̀hónú han Sagamu láàrin Ọlọ́pàá àti aráàlú Ìdí ti mo fi ṣe iṣẹ́ àmúrelé mi lábẹ́ ATM rèé - Dele Ohun tí o kò mọ̀ nípa Hosni Mubarak, Ààrẹ Egypt tó papòdà Dípò ilé, Ẹ̀wọ̀n ọdún méje gbáko ni Olisa Metuh ń gbà lọ́!
A kò mọ̀ bóyá a le è san owó osù tuntun fún òsìsẹ́ - Ìjọba Ondo, Oyo, Kwara jẹ́wọ́ Òwe: Kí ni ìtumọ̀ òwe ikú tó ń pa ojúgbà ẹni?
Ija yii fẹ loju gan to jẹ awọn mejeji a fi saa diẹ tun wu ara wọn, to ba ya a si tun ka kuro tititi ti wọn fi papa pinya.
Nígbà gbogbo ni mò ń gbadura fún gbogbo yín pẹlu ayọ̀ ninu ọkàn mi.
Mọ̀ síi nípa Shina Rambo tó pàdé Jesu lọ́gbà ẹ̀wọn lẹ́yìn tó ti jalè Lẹyin naa lo tẹ ọkọ leti lọ si ilẹ Gẹẹsi, to si tun kọ ẹkọ si ni fasiti Wales laarin ọdun 1992 si 1997.
Pussypedia: Ṣé gbogbo obìnrin ló ń damira lójú ara lásìkò tó bá fẹ́ rí ọkùnrin?
Nítorí náà, Dariusi ọba fi ọwọ́ sí òfin náà, ó sì fi òǹtẹ̀ tẹ̀ ẹ́.
Olori agba yii, ti ọpọ eeyan ninu aafin n pe ni Iya Adodo ko ni mọra, a si lee ni ori rẹ lo sunwọn, to ran igba awọn ayaba miran ti wọn tẹle lati wa fẹ Ọba Adeyemi.
Àkọlé àwòrán, Àwọn ajinigbe ń ṣọṣẹ́ ni Birnin Gwari Wọn ni àwọn agbebọn fipa ń da ọkọ duro ti wọn si n ko èrò wọ inu igbó lọ.
Lẹ́yìn náà mo kọ́ gbèrò ati fi ibinu pa wọ́n run patapata ninu aṣálẹ̀.
Ṣugbọn àwọn ọmọ Aṣeri ń gbé ààrin àwọn ará Kenaani tí wọ́n bá ní ilẹ̀ náà, nítorí pé wọn kò lé wọn jáde.
Ki ẹnikẹni ma ṣe ro ara rẹ pin.
Mo ti gbọ́ gbogbo kíkùn tí wọn ń kùn sí mi.
Ó mọ̀ pé ọjọ́ òkùnkùn ti súnmọ́ tòsí.
Ikare Monarch: Ọdún méjìdínláàdọ́ta ní Oba Adegbite-Adedoyin ló lókè èèpẹ̀, kó tó mí kanlẹ̀
"''Lẹyin ti Naijiria ba parọwa si South Afrika ti wọ́n ko gbọ, ohun to yẹ ni ki wọn paṣẹ ki aṣoju Naijiria ni South Afrika pada wa sile ni kiakia'' OPC, Miyetti Allah, agbófinró yóò wà nínú ìgbìmọ̀ aláàbò nílẹ̀ Yorùbá A fẹ́ gba ₦1bn lọ́wọ́ ìjọba Eko pé ó dẹ́yẹ sí wa - 123 Ọlọ́kadà Jigawa ""A kò ní ra ọjà South Africa mọ́, a ó gbẹ̀san oró tí wọn ń dá wa - Ọmọ Nàíjíríà fárígá"" O tun ṣalaye pe ti igbeṣẹ yii ba kọ ti ko dẹkun ọrọ naa, ki Naijiria ti ileeṣẹ asoju South Afrika to wa ni Naijiria pa, ki wọn si da aṣoju wọn pada si ilẹ wọn."
A ti kọja odó náà lẹ́ẹ̀kan, ni kété tí a kúrò ní ìlú àwọn Èdàdàrẹ̀ tí ó jẹ́ pé ọkọ̀ kékeré kan ni wọ́n fi tu gbogbo wa gòkè, ṣùgbọ́n ti ẹ̀ẹ̀kejì yìí, àfi bí ẹni pé kìí ṣe odò náà ni mọ́.
ìjọba Nàìjíríà ti kéde ìsinmi lọ́jọ́ Ìṣẹ́gun àti Ọjọ́rú Kini Pásítọ̀ Kumuyi fi ṣẹ ọmọ Naijiria?
Aisha kawe gboye ninu imọ ofin ni fasiti Lead City, o si tun kawe gboye onipele kini mii ninu imọ ẹkọ Public Administration.
Ẹ wo ọkùnrin tó dáná bẹntiróò sún ọ̀rẹ́bìnrin rẹ̀ torí kó gbà látí jẹ́ aya rẹ̀ Ọpẹ́ o!
Ẹwẹ, alaga ẹgbẹ oṣelu PDP ni wọọdu Apoi keji, Ọgbẹni Festus Oboro ti tẹwọ gba ikọwefiposilẹ igbakeji gomina Ondo gẹgẹ bi ọmọ ẹgbẹ naa.
Ka to wi ka to fọ, ajọ eleto ilere lagbaaye, WHO yoo ti ni fifọ ọwọ loorekoore jẹ ohun akọkọ ninu gbigbena woju Covid-19.
Gomina Makinde, to sọ ọrọ yii ni ibi ayẹyẹ ọjọ ibi Olugbọn ti Orile Igbon, Ọba Francis Alao, tun sọ wipe eto aabo wa lara awọn ohun ti isejọba oun duro fun.
Àwọn amòfin ati àwọn Farisi ń ṣọ́ Jesu bí yóo ṣe ìwòsàn ní Ọjọ́ Ìsinmi kí wọ́n lè rí ẹ̀sùn fi kàn án.
Amọran yii waye lẹyin ti ẹgbẹ apapọ awọn oṣiṣẹ ni naijiria kede pe iyanṣẹlodi yoo bẹrẹ lọjọ Aje lati fi ẹhonu han lori bi ijọba apapọ ti ṣe afikun owo ina ọba ati epo bẹntiro.
Amọ, ọpọ eeyan to ka iroyin naa lo n beere pe, bawo ni Alaafin, ẹni to ti le ni ọdun mọkanlelọgọrin loke eepẹ, se dẹnu ifẹ kọ awọn arẹwa yii?
Bakan naa ni mo ra awọn aṣọ tuntun, mo n ṣe irun ori mi deede.
Dafidi kọ orin arò kan fún Abineri báyìí pé:“Kí ló dé tí Abineri fi kú bí aṣiwèrè?
Modekai fún Hataki ní ìwé òfin tí wọ́n ṣe ní Susa láti pa gbogbo àwọn Juu run patapata, pé kí ó fi ìwé náà han Ẹsita, kí ó sì là á yé e, kí ó lè lọ siwaju ọba láti bẹ̀ ẹ́ pé kí ó ṣàánú àwọn eniyan rẹ̀.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Alasiya Lagos Killing: Oun tójú àwọn ará àdúgbò rí nìyìí 15 Ìgbé 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Igboro ilu Eko Ara adugbo Alasiya kan nibi ti iṣẹlẹ ẹsun pe awọn ẹlẹgbẹ okunkun kan bẹ ori eniyan mẹta ni agbegbe naa ti ṣẹlẹ ni oun gbọ ọpọlọpọ iro ibọn lọganjọ oru.
Religion tolerance in Nigeria: Obìnrin Mùsùlùmí ní òun ṣe ilé àlùfà ní ọ̀ṣọ́ kérésì láti polongo ìrẹ́pọ̀
Adé wà ní orí wọn tí ó dàbí adé wúrà.
Nígbà tí Jesu kúrò níbẹ̀, ó lọ sí ẹ̀bá òkun Galili; ó gun orí òkè lọ, ó bá jókòó níbẹ̀.
Alao Akala ti ẹgbẹ oṣelu ADC juwe ara rẹ gẹgẹ bi aloku ọlọpaa.
O lọ ilé ìwé girama Holy Child College nilu Eko, bákan náà ló ka èdè Oyinbo (English) ní fásítì Eko, o tún kàwé ni ibudo nipa ere tiata ti Webber Douglas Academy of Dramatic Art ní London.
N kò rí Tẹmpili ninu ìlú náà.
AMAA 2018 Ami eye fun osere to kere julo to sese bere
Wọ́n jẹ́ ọ̀tún ní àárọ̀; títóbi ni òdodo rẹ̀.
Ìyà Tí Ọlọrun óo Fi Jẹ Edomu.
Kii ṣe ẹẹkan, tabi ẹẹmeji ni iroyin ti jade nipa wọn pe awọn mejeeji n fẹ ara wọn.
Jẹ́ kí ojú ti àwọn eniyan burúkú;jẹ́ kí ẹnu wọn wọ wòwò títí wọ ibojì.
Ní ọdún kẹrindinlọgbọn tí Asa jọba ní Juda, ni Ela, ọmọ Baaṣa, gorí oyè ní ilẹ̀ Israẹli; ó sì jọba ní Tirisa fún ọdún meji.
Serena Williams gba ife ẹ̀yẹ àkọ́kọ́ láàrin ọdún mẹ́ta sẹ́yìn
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Agbẹjọro àgbà fẹ́ bẹrẹ ẹjọ Dino pada Ọṣìnbàjò pe ìpàdé lórí Bukola Saraki Jẹẹsí àwọn orílẹ́èdè tó ń lọ Russia 2018 ree Ile aṣofin mejeeji tun paṣẹ nibi ipade naa, fun gbogbo ajọ eleto aabo ni orilẹede Naijiria, lati maa daabo bo awọn ọmọ orilẹede yìí.
Ṣugbọn ìrètí ń bẹ fún ẹni tí ó wà láàyè, nítorí pé ààyè ajá wúlò ju òkú kinniun lọ.
Àwọn ìròyìn mìíràn tí ẹ lè nífẹ̀ẹ́ sí: Àwọn ajínigbé bèèrè N20m fún ìyàwó ọba Ẹ̀mí ológun kan bọ́, ọ̀pọ̀ arìnrìn àjò bọ́ sọ́wọ́ ajínigbé Ọlọ́pàá dóòlà àgùnbánirọ̀ 5 lọ́wọ́ ajínigbé Ilé ẹjọ́ dája ikú fáwọn ajínigbé ni Benue Ni oṣu keje, ọdun 2018, ile ẹjọ kan ni Ipinlẹ Benue dajọ iku fun awọn ajinigbe meji kan ti wọn ji alufaa ijọ Aguda kan gbe ni ipinlẹ naa, ti wọn si paa, lẹyin ọdun meji ti wọn ṣiṣẹ laabi naa.
Ẹ ṣe ètò ìrìn àjò fún un ní alaafia, kí ó lè wá sọ́dọ̀ mi, nítorí èmi ati àwọn arakunrin ń retí rẹ̀.
Gbà á lọ́wọ́ mi, kí n lè lọ sin aya mi sibẹ.
Nígbà tí Dafidi gbọ́ pé Saulu ń gbèrò ibi, ó pe Abiatari alufaa kí ó mú aṣọ efodu wá, láti ṣe ìwádìí lọ́wọ́ Ọlọrun.
Èyí ni ìtàn Ọkùnrin tó rí ẹ̀wọ̀n he nítorí àkùkọ aládúgbò rẹ̀ tó pa Oríṣun àwòrán, @others Èyí ni ìtàn Ọkùnrin tó rí ẹ̀wọ̀n he nítorí àkùkọ aládúgbò rẹ̀ tó pa Arakunrin kan lorilẹede France yo lọ ṣe ẹwọn oṣu marun un lori ẹsun pe o yinbọn pa akukọ kan to ni o n pariwo di oun leti.
 Ó ṣe wàhálà púpọ ̀ kí ó tó mọ ̀ pé fọláṣadé tí ó tún ń jẹ ́ filísíà nì ó jí owó orímóògùnjẹ ́ kó .
Lati idaji oni ọjọ Aje, ni awọn agbofinro ti duro wa wa wa si ẹnu ọna abawọle ile ẹjọ naa, ti wọn si n se ayẹwo awn eeyan to fẹ wọle sibẹ.
O ni iyalẹnu lo jẹ pe ipinlẹ kogi le di bo se da pẹlu gbigbin igbo.
Wọn ji Musa Umar, to jẹ Magajin Garin abule Daura ni Ipinlẹ Katsina gbe ni oṣu Kẹrin ọdun 2019.
Awo ti wọn n fọwọ si to n lo oorun: Richard Kwarteng to n ṣe bata ni Ghana ati ibatan rẹ lo ṣe awo lọna ati gba awọn eeyan orilẹ-ede naa niyanju lati maa fọ ọwọ wọn ni igba de igba gẹgẹ bi ilana eto ilera.
Amọṣa, kaka ki Ambọde farahan, ile ẹjọ lo gba lọ toun ti lọya rẹ, Tayọ Oyetibọ, SAN lati gba iwe ile ẹjọ ti yoo ka awọn aṣofin ipinlẹ Eko lọwọ ko lori ohun ti wọn fẹ ṣe naa.
Ṣugbọn gbolohun yìí kò yé wọn, nítorí a ti fi ìtumọ̀ rẹ̀ pamọ́ fún wọn, kí ó má baà yé wọn.
Nítorí Ẹ̀mí Mímọ́ yóo kọ yín ní ohun tí ó yẹ kí ẹ sọ ní àkókò náà.
Osinbajo ta kété sí ọ̀rọ̀ 'Ruga Settlement' Buhari fi àmì ẹ̀yẹ dá olóògbé Adadevoh tó dènà Ebola l'ọ́lá Ọlọ́pàá ìpínlẹ̀ kọ́ ní ojútùú ìṣòro ìjínigbé ilẹ̀ Yoruba - Onímọ̀ ọ̀rọ̀ ààbò Àwòrán apanilẹ́rìn-ín fún ọ̀sẹ̀ yìí, ìtọ́wò rèé Àkọlé àwòrán, Ariwo ifipabanilopọ gbọdọ dopin ni wọn n pa ni Abuja.
Ní òwúrọ̀ ọjọ́run ni ọkunrin awakùsà kan kú ní Goma níbi ti ènìyàn tó le ni miliọnù meji ń gbé.
O ni oun yọ awọn mejeeji nitori pe wọn fi ara pa ṣaaju idije to kọja.
Sibẹsibẹ, ninu ìnira wọn, ó ṣàánú wọn,nígbà tí ó gbọ́ igbe wọn.
A kò ní gbọ́ ìró ọlọ mọ́, bẹ́ẹ̀ ni kò ní sí iná fìtílà mọ́.
Àwọn tí kò kú lára wọn fọ́nká, tóbẹ́ẹ̀ tí kò fi sí eniyan meji tí wọ́n dúró papọ̀.
Ẹ̀n… Ẹ ti fìgbà kan ní ọkùnrin tó dára ní ipò náà, àbí bẹ́ẹ̀ kọ́?
Gé ẹran àgbò náà sí wẹ́wẹ́, kí o fọ àwọn nǹkan inú rẹ̀ ati ẹsẹ̀ rẹ̀.
Egypt ni yoo sagbateru idije Africa Cup of Nations todun 2019.
Kíni ìjọba n ṣe láti dín ìtànkálẹ̀ ààrùn nàá kù?
Ipo kẹjọ ni Arsenal wa bayii lori tabili idije Premier League eleyi to jẹ ki ọpọ alatilẹyin Arsenal maa kọminu.
“Nígbà tí OLUWA Ọlọrun yín bá ko yín wọ ilẹ̀ tí ẹ̀ ń wọ̀ lọ yìí, tí ẹ bá gba ilẹ̀ náà, tí OLUWA sì lé ọpọlọpọ orílẹ̀-èdè jáde fun yín, àwọn orílẹ̀-èdè bíi Hiti, Girigaṣi, Amori, Kenaani, Perisi, Hifi, Jebusi, àní àwọn orílẹ̀-èdè meje tí wọ́n tóbi jù yín lọ, tí wọ́n sì lágbára jù yín lọ; 
 Àwọn krómósómù ṣe pàtàkì fún ìpínyà àhámọ ́ , wọ ́ n sì gbọdọ ̀ jẹ ́ títúndá , pínpín , àti jẹ ́ kíkó sínú àwọn àhámọ ́ ọmọ wọn láìsí sòró láti baà ridájú pé orísirísi àbímọ ́ àti ìwàláàyè wà fún àwọn ọmọọmọ wọn .
Àsọtẹ́lẹ̀ èké ni wọ́n ń sọ fun yín, wọ́n fẹ́ kí á ko yín jìnnà sí ilẹ̀ yín ni.
Lara awọn ẹgbẹ okunkun ti wọn si jọ n jija ìwọ ko ju mi, emi ko ju ọ ni ẹgbẹ Indomie ati Abẹ-igi aanu nitori wọn siwaju ẹgbẹ one million boys bẹrẹ iṣẹ nilu Ibadan.
Iru awọn iroyin ti ẹ le nifẹ si: Fọlọrunṣọ Alakija: Imọ ṣe koko 'Ara sisan kii ṣe arun' Aarẹ Trump ati Kim yoo ṣe'pade Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Àwọn eniyan sì jẹ́ ẹgbaa mẹjọ (16,000).
"Oríṣun àwòrán, Buhari Salihu Marafa, lasiko to n ba BBC sọrọ ni ""eto iforukọsilẹ ti wọn gunle naa kii se ara isẹ wọn, yoo kan tubọ da ẹgbẹ ru ni."
Wọ́n ń wádìí nípa ẹni náà ati àkókò náà, tí Ẹ̀mí Kristi tí ó wà ninu wọn ń sọ̀rọ̀ nípa rẹ̀ nígbà tí ó sọ àsọtẹ́lẹ̀ nípa ìyà tí Kristi níláti jẹ, ati bí yóo ti ṣe bọ́ sinu ògo lẹ́yìn ìjìyà rẹ̀.
"Ẹgbẹ ALGON Oyo ni ""a fẹ fi yee yin pe, Sẹnetọ wa Abiola Ajimobi, adari wa ko ku, ko si ni ku bi ko ṣe yiye""."
Ikọlu yi lo waye ni Mahala View Lodge, ti o jẹ ile oloogbe naa, ni ila-oorun Pretoria.
    Ní ìgbà ìyàwó mi, òun àti àbúrò ìyàwó mi ti bbẹ̀rẹ̀ si i ṣe ọ̀rẹ́ pẹ̀lú ara wọn, ọ̀rẹ́ wọn yìí kò kúkú hàn sí wa jù bẹ́ẹ̀ lọ, ṣùgbọ́n wọ́n ti ń pàdé ara wọn ni ìkọ̀kọ̀ lẹ́ẹ́kọ̀ọ̀kan kí ó tó di nǹkan bí osù méjì lẹ́yìn tí mo gbéyàwó.
 Ó jẹ ́ ọ ̀ kan nínú àwọn ẹbí èdè tí ó tóbi jù .
Saulu sì bèèrè lọ́wọ́ Mikali pé, “Kí ló dé tí o fi tàn mí, tí o sì jẹ́ kí ọ̀tá mi sá àsálà?
Ewe, ile itoju naa wa ni ile iwosan itoju awon obinrin ati awon omode e King Fahad Women and Children Hospital, nilu Gusau.
Ẹnikẹ́ni tí ó bá súnmọ́ wọn, pípa ni kí wọ́n pa á.
Iyawo to fẹ gbẹyin ni Folake Doherty lọdun 1989.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ọmọ Nàíjíríà tó jẹ́ Ìmáàmù mọ́ṣálásí tí wọn kọlù ní New Zealand ṣàlàyé ìṣẹ̀lẹ̀ Yorùbá, ọmọ ọdún mẹ́jọ tà ọmọ òyìnbò yọ nínú ayò Chess l‘Amẹrika Pius Adesanmi ní kò bá rọ́pò Wole Soyinka tí kò bá kú - ọmọ Naijiríà Àwọn tó gboriyin àti àwọn tó gbàbuku lórí ìṣẹlẹ New Zealand Àìsàn tó ń ṣe ọ ní ohun ṣe pẹlú oorun rẹ - Onímọ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Aṣọ òkè: Alákọ̀wé ní ọ̀nà láti wá oúnjẹ fáwọn tó ń ṣe aṣọ òkè ló ṣún òun débẹ̀ Ìròyìn fi ye ní pé, ọgá aṣọ́bodè àti àwọn ìsọ̀gbè rẹ̀ kọ owó àbẹ̀tẹ́lẹ̀ náà, wọn si fi ìdí àwọn àjàgbé tó kúń fún àwọn oogun náà gúnlẹ̀, èyí tó lé ní bílíọ̀nù méje naira.
Alagba Oyewole Isaac lati ile ẹkọ Awaye Comprehensive Grammar School ni Ilẹ Oluji ni ipinlẹ Ondo ni olukọ wa lonii.
Bakanna ni awọn orile-ede kan ti n pe fun didẹyẹ si awọn eroja ti ilẹ Faranse n pese.
O ni ko si itẹsiwaju kan bikose pe nkan ń buru sii ni.
ni ijoba yoo tẹpẹlẹ mọ eto  ẹkọ  ati ilera.
O ti di mímọ̀ pé aàrùn Covid-19 sáabà lágbára lórí àwọn tó ti dàgbà.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Trump impeachment: Trump kò fìdí janlẹ̀ tán, àmọ́ níbo ni yóò jásì?
Ohun ti eyi tumọ si ni pe wọn yoo ma ṣe ayẹwo ẹgbẹrun mẹwa lojumọ ni iyatọ si ẹgbẹrun meji din diẹ ti wọn n ṣe tẹlẹ.
O ni awọn ọmọ ẹgbẹ ati awọn olori ẹgbẹ lo korajọ pọ silu Ẹdẹ, ti i ṣe ilu abinibi Ademọla Adeleke fun eto adura naa.
Awọn iroyin ti ẹ lee nifẹẹ si: Soyinka ni awọn ọdọ lokan lati ṣe'jọba Aworan aṣa ati iṣe awọn ọmọ Yoruba Èyí tí a wò jùlọ 5:03 Fídíò, Omolola Arohunmolase Welder: Mo ti fí iṣẹ́ 'Welder' gbayì láwùjọ, tó mo fi tọ́ ọmọ yanjú, Duration 5,039 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 5:39 Fídíò, Akomolede ati Asa lori BBC: Olùkọ́ Kikelomo Ogunboye tan ìmọ́lẹ̀ sí ìwà olè ọ̀gá ọlọ́pàá Audu gẹ́gẹ́ bí àwòkọ́ṣe àsìkò yìí, Duration 5,398 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 4:11 Fídíò, Oba Adeyeye Ogunwusi: Ojú mi ti rí lọ́pọ̀ lọpọ̀, ọ̀pọ̀ èèyàn ni kò tilẹ̀ gbàgbọ́ pé mo lè jọba- Ooni, Duration 4,117 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 4:43 Fídíò, Promise Akinlade: ọmọ ọdún mọ́kànlá tó ń fi ìlù dárà bíi àgbàlagbà sọ̀rọ̀ nípa tálẹ́ǹtì rẹ̀, Duration 4,437 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 0:59 Gbọ́, Ìsẹ̀lẹ̀ jákèjádò orílẹ̀èdè àgbáyé láàárín ìṣẹ́jú kan, Duration 0,59wákàtí 5 sẹ́yìn 7:03 Fídíò, Olumuyiwa Bolade Adedeji Military Bruitality: Bí arákùnrin onípèníjà ara tí sọ́jà lù ṣe dé, Duration 7,035 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 4:45 Fídíò, Yoruba Films: Ẹ̀ẹ́ bẹ̀ mi kúrò láyé ni, mi ò lè kú - Fadeyi Oloro, Duration 4,4526 Èrèlè 2020 2:48 Fídíò, Esther Ajayi: Èmi náà ti borí ìṣòro rí ló ń mu mi ṣojú àánú, Duration 2,481 Ògún 2019 6:08 Fídíò, Adebola Ademilua: Àìrísẹ́ ṣè lẹ́yìn ìwé kíkà ló sọ mi dí ìyá onírú, mo dúpẹ́ tèmi, Duration 6,0827 Bélú 2020 5:55 Fídíò, Soyinka Cancer: Àṣe ara mi ni iso ti n run gbogbo bí mo ṣe n ṣèrànwọ́ lórí jẹjẹrẹ, Duration 5,5527 Bélú 2019 BBC News, Yorùbá Ìdí tí ẹ fi le è nígbàagbọ́ nínú ìròyìn BBC Ìlànà Lílò Nípa BBC Òfin Àṣírí Cookies Kàn sí.
Kìí ṣe ǹkan tuntun pé ọ̀pọ ilé-ẹ̀kọ́ ni ìhà àríwá Nàìjíríà ló ti kéde pé àwọn ti gbé ìlẹ̀kùn ilé ẹ̀kọ́ tì, nítorí yálà ètò ààbò tó mẹ́hẹ tàbí nítóri àrùn Coronavirus to tun pada dé.
Gbogbo ìgbà ni ọmọdé yìí máa ń tọju ìbàntẹ́ bàbá rẹ̀ nípa fífọ̀ àti kíká wá sí ilé.
Joselu naa da kun iya fun Real Madrid lẹyin aṣiṣe asọle Madrid Thibaut Courtois.
Ọdun 2019 ni ọgbẹni Lai kọkọ kede pe aarẹ Muhammadu Buhari ti buwọlu afikun owo itanran ọhun eyii ti wọn fi sinu akọsilẹ iwe ofin to rọ mọ igbohunsafẹfẹ.
Gẹgẹ bi akikanju ọmọ Yoruba, o gba pe ibi to ba le, la n ba ọmọkunrin, iwa ojo si ni ki oun duro silẹ okeere, ile baba ọmọ kii sa ba ọmọ lẹru.
Adamu, ẹni to kede bẹẹ lasiko ipade r pẹlu awọn Kọmisọna ọlọpaa lawọn ipinlẹ gbogbo nilẹ yii nilu Abuja, tun salaye pe abẹ awọn Kọmisọna ọlọpa lawọn ipinlẹ ni ikọ SARS yoo maa wa bayii.
Akanbi mi, má fọ̀ ọ́, mo wà pẹ̀lú ẹ; Ẹni tó ṣe ìgbéyàwó olórùka ló l'ọkọ- Lizzy Anjorin Gbogbo orin egúngún bìkiafù tí wọ́n kọ sí mi l'étí nípa Ajayi tí mi o gbọ̀ ló bu mí lọ́wọ́- Akeredolu Báwó ni òògùn dexamethasone ṣe ń ṣiṣẹ́ lára Ǹjẹ o yẹ kí èèyàn máa sùn lẹ́nu iṣẹ́?
Ẹ gbọdọ̀ mọ ìyàtọ̀, láàrin ohun tí a yà sọ́tọ̀ fún OLUWA ati ohun tí ó wà fún ìlò gbogbo eniyan; ẹ níláti mọ ìyàtọ̀, láàrin àwọn ohun tí wọ́n jẹ́ mímọ́ ati àwọn ohun tí wọ́n jẹ́ aláìmọ́; 
 Ó ní yunifásítì kan tí wọ ́ n dá sílẹ ̀ ní 1494 .
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù PDP Osun: A fẹ́ fún Ademola Adeleke ní tíkẹ́ẹ́tì ọ̀fẹ́ láti díje dupò gómìnà ní 2022 11 Agẹmo 2019 Oríṣun àwòrán, Ademola Adeleke Alaga ẹgbẹ oselu PDP ni ipinlẹ Ọsun, Soji Adagunodo ti fesi lori ọrọ ti ẹgbọn Ademọla Adeleke, eyiun Deji sọ lori ibo gomina Ọṣun lọdun 2022.
Ọ̀rọ̀ ọgbọ́n ní ń jáde láti ẹnu rẹ̀,a sì máa kọ́ni ní ẹ̀kọ́ àánú.
Ṣugbọn bí aṣiwaju yìí bá ti kú, kíá, wọn a tún ti yipada, wọn a sì tún ti máa ṣe ohun tí ó burú ju ohun tí àwọn baba wọn ti ṣe lọ.
Lẹ́yìn ọdún keje, obinrin náà pada sí Israẹli, ó sì lọ sọ́dọ̀ ọba láti bẹ̀ ẹ́ pé kí ó dá ilé ati ilẹ̀ òun pada.
Ìgbéyàwó Harry àti Markle: Ẹni ńlá ní ń ṣe ohun ńlá
Iwe ipe yi waye bi orile-ede Zimbabwe n gbaradi fun eto idibo eyi ti ti Aare Emmerson Mnangagwa so wipe ko ni si magomago.
Ṣugbọn ta ni ó pa àwọn wọnyi?
O ni ida ọgọrin awọn to n ko o lọjọ ori wọn wa laarin ọdun mọkanlelọgbọn si ogoji eyi to ṣapejuwe bi awọn ti ara wọn ṣi ji pepe laarin gbogbo ọmọ Naijiria.
Iwe iroyin The New Times to jẹ aladani jabọ iroyin pe ọsẹ to lọ ni igbesẹ naa bẹrẹ, to si jẹ wipe ẹẹdẹgbẹrin le mẹrinla ṣọọsi ati mọsalaasi kan lo ti faragba ninu igbesẹ naa.
O ni gbajugbaja oṣere yii koju aarẹ ana to doloogbe Umaru Yar'ardua gan an.
Eleyii lo farahan ninu iroyin yii bi o tilẹ jẹ wipe o fara jọ iroyin ejo akowomi lorilẹede Naijiria, sugbọn owo anabọ ni ohun jẹ.
Mo gbọ́, àyà mi sì lù kìkì,ètè mi gbọ̀n pẹ̀pẹ̀nígbà tí mo gbọ́ ìró rẹ̀;egungun mi bẹ̀rẹ̀ sí rà,ẹsẹ̀ mi ń gbọ̀n rìrì nílẹ̀.
 nígbà míràn a lè gbọ ́ tọ ́ bí ìtàn méjì , mẹ ́ ta , tàbí ju bẹ ́ ẹ ̀ lọ nípa bí ìlú kan ṣe ṣẹ ́ .
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Obinrin Akansẹ: Ẹsẹ kiku bi ojo kọ mi lati di alagbara Mi mọ pe o ko dabi awọn obinrin yooku jẹ ọgbẹ ọkan, ṣugbọn o kan nilo lati gba bẹ, ki o si wa ẹni ti o le fi ọrọ lọ.
N óo mú kí àwọn nǹkan wọnyi dé bá Moabunígbà tí àkókò ìjìyà rẹ̀ bá tó.
Lagos traffic: Ohun márùn ún tó ń fa súnkẹrẹ-fàkẹrẹ nílùú Eko
Àwọn míràn tó tún ni ànfààní ni àwọn tó n mójútó ètò ìdìbò àti àwọn elétò ìdìbò gan.
Bi awọn kan ti ṣe ni lootọ lawọn ri awọn nkan to ka silẹ gẹgẹ bi aṣeyọri ijọba lawan mii ni awọn ko ri ohun to n pe ni aṣeyọri Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ìdílé tí ọkọ da ọmọ síta tóríi ojú Búlùú tí wọ́n ní bá BBC sọ̀rọ̀ Ìgbìmọ̀ ọ̀tẹ̀ ní ọ̀rọ̀ àwọn àgbààgbà ẹkùn àríwá pé ìjọba Buhari ti kùnà- Femi Adesina Oludamọran pataki fun aarẹ Muhammadu Buhari, Femi Adesina ti bu ẹnu atẹ lu ọrọ ti àjọ ìgbìmọ̀ àwọn àgbààgbà ẹkùn àríwá Naijiria, NEF sọ lori iṣejọba Naijiria labẹ iṣakoso aarẹ Buhari.
" Ọsẹ mẹwaa gbako ni wọn o lo ninu ile Big Brother ẹlẹkaarun yii, se Kaisha yoo le farada lato duro bayii lati gba ife ẹyẹ eto yii.
 sùgbọ ́ n , gbogbo wọn tún sì wà lábẹ ́ aláké gẹ ́ gẹ ́ bii ọba gbogbo gbò ni .
Má tìtorí tèmi dójúti àwọn tí ó gbẹ́kẹ̀lé ọ,OLUWA Ọlọrun àwọn ọmọ ogun,má sì tìtorí mi sọ àwọn tí ń wá ọ di ẹni àbùkù,Ọlọrun Israẹli.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ikú Caruana Daphne: Bí mo ṣe jà fún ìdájọ́ òdodo lórí ìyá mi tí wọ́n ṣekú pa By Matthew Caruana Galizia World Press Freedom Day 3 Èbibi 2019 Oríṣun àwòrán, Reuters Àkọlé àwòrán, Daphne Caruana Galizia fi atẹjade sita nipa iwa jẹgudujẹra ijọba Nigba kọọkan, mo ni lati joko si inu yara kan lati jiroro pẹlu ẹni to n ṣe iwadii iku to pa iya mi.
Oko òkú rèé, níbití òkú ti ń jẹrà mọ́lẹ̀ fún àyẹ̀wò Kàyééfì, oyún inú nínú ilé ìgbọ̀nsẹ ọkọ̀ òfurufú NFF sadehun pẹlu Dennerby fun Falcons Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
“Ṣugbọn tí ẹ bá kọ̀, tí ẹ kò gbọ́ tèmi, tí ẹ kò sì pa gbogbo àwọn òfin mi mọ́, 
Láti orígun mẹ́rẹ̀ẹ̀rin àgbáyé, igbe ńlá ni ó gba àwọn akọbúlọ́ọ̀gù Zone9 sílẹ̀ lọ́wọ́ ìjọba ilẹ̀ Ethiopia.
Ìhà wo ní àwọn ọmọ orilẹ̀-èdè Nàìjíríà kọ si ọ̀rọ̀ yìí Ọ̀pọ̀ àwọn ọmọ orílẹ̀-èdè Naàìjíríà ló ti ń nàka àlébù sí ilé iṣẹ́ ààrẹ pé kò wá wọ̀rọ̀kọ̀ fi sàdá lóri ọ̀rọ̀ Kẹ́mi Adeosun Eyi ni ohun ti Femi Fani Kayode àti àwọn ọmọ Nàìjíríà míìràn sọ lori ọ̀rọ̀ náà Oríṣun àwòrán, ogundamisi/twitter Àkọlé àwòrán, Àwọn ọmọ Nàìjíríà ti gbé onírúurú àwòrán Kẹmi Adeọṣun nínú ẹ̀wù àgùnbánirọ̀ jáde lórí ẹ̀rọ ayélujára Àwọn míràn tilẹ̀ ń nàka àlébù sí àwọn ọmọ ilé ìgbìmọ asòfin pe wọn mọ àṣírí ọ̀rọ̀ náà lásìkò ti wọn ń ṣe ìfọ̀rọwanilẹ́nu wo fún Kemi Adeosun, sùgbọ́n wọn bo ọ̀rọ̀ náà mọ abẹ́ aṣọ Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
A bá jókòó, a bá àwọn obinrin tí ó péjọ níbẹ̀ sọ̀rọ̀.
Taiwo Akinkunmi, ọmọ Ibadan tó ya àsìá Nàíjíríà Iṣọla Oyenusi rèé, ẹnití ìfẹ́ obìnrin ṣun dé ìwà ìdigunjalè Ayinla Ọmọwura, orin èébú àti oríyìn lo fi di ọ̀rẹ́ àwọ̀n obìnrin Ẹfunroye Tinubu - Ògbóǹtagí oníṣòwò, olówò ẹrú àti afọbajẹ Samuel Ajayi Crowther, òjíṣẹ́ Ọlọ́run tó gbé èdè Yoruba lárugẹ Ẹ̀wẹ̀, àwọn ọmọ Nàìjíríà tí ń sọ̀rọ̀ lóri ìgbẹ́sẹ̀ àjọ ICPC láti gbé Lai Mohammed lo ile éjọ.
Makinde ninu ọrọ rẹ sọ wi pe, iya oun to jẹ ọmọ ilu Akure fihan gbangba pe, awọn ara ilu Akure jẹ eniyan ọtọ to ṣe e fi ọkan tan.
Bí èso rẹ̀ tí ń pọ̀ sí i, bẹ́ẹ̀ ni pẹpẹ oriṣa wọn ń pọ̀ sí i.
agbofinro ati olopaa lati gbogun ti iwa buruku yii.
Òun ni ó sọ wá di mímọ́, tí ó dá wa nídè.
Ọgaagun Abdulsalami Abubakar jẹ adari orilẹede Naijiria ni ọdun 1998 si ọdun 1999.
Òfin to de ìpéjọpọ̀ sì wá síbẹ̀.
O fi imoore han si Olorun pe oun ṣi wa laye lasiko ajakalẹ arun Covid 19 yii.
Oríṣun àwòrán, Instagram/Bashir Ahmad Minisita keji fun eto iṣuna ṣalaye pe ijọba ṣe ifilọlẹ eto lati mu owo wọle sii nigba didan inawo ijọba ku.
Arabinrin Toyin Tijani ninu ọrọ rẹ ṣalaye pe, 'ọpọ awọn opo lo n da bukata atijẹ ati atimu ọmọ wọn gbọ.
 Àwọn olùgbé ilé-ifẹ ̀ tó iye bí ẹgbẹ ̀ rún lọ ́ nà àádọọ ́ ta , ọgọ ́ rùún méjì ólé mọ ́ kàndínláàdọ ́ ta àti àti mọ ́ kàndínlọ ́ gọ ́ eùún ènìyàn ( 50,000-249,999 ) .
Adebayo Adekola Adelabu - O yege8.
Ẹ mọ àmì ilẹ̀ ati ti ojú sánmà, ṣugbọn ẹ kò mọ àmì àkókò yìí!
Ọ̀pọ̀ ènìyàn tó ń gbé ní Eko, Ibadan, Osogbo ló ti kú."
Ninu ọrọ ti Aisha Buhari sọ, ko darukọ ẹni kankan pe o tapa si ofin ma rina lasiko Covid 19.
Àwọn ẹranko ìgbẹ́ yóo máa yìn mí lógo,ati àwọn ọ̀fàfà ati ògòǹgò;nítorí pé mo ti ṣe odò ńlá fún wọn ninu aṣálẹ̀,kí àwọn àyànfẹ́ mi lè máa rí omi mu:
O ni awọn oyinbo lo ma n ṣe bẹẹ, kii ṣẹ aṣa tiwa pẹlu afikun pe, ti ọkunrin ba fẹ gbeyawo laye ijọun nilẹ Yoruba, n ṣe lo maa n kọkọ ṣe iwaadi iru ile ti obinrin bẹẹ ti jade wa.
Ọgbẹni Salami sọ pe ẹlẹẹkeji to da bii rẹ ni pe ajọ to n ri si idanwo aṣejade nile iwe girama, eyun ni WAEC jẹri nile ẹjọ tẹlẹ pe Adeleke pari iwe mẹwaa ti ofin la kalẹ gẹgẹ bi amuyẹ fun ẹnikẹni to ba fẹ dije fun ipo gomina ni Naijiria.
Yinka Ayefele le è dúró kọrin pẹ̀lú kẹ̀kẹ́ tuntun Mílíọ́nù kan Naira ni wọ́n fún wa láti pa Uwaila sínú ṣọ́ọ́ṣì ní Benin - Afurasí O tun ti fi igba kan ri ṣoju ipinlẹ Cross River nile aṣoju-ṣofin l'Abuja.
Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí 3:38 Fídíò, Falz: Èmi kò ní sàtúnse fídíò tó sọ àsìse Nàíjíríà náà, Duration 3,386 Òkùdu 2018 Tope Alabi: Mo ti tọrọ aṣọ àti yẹtí etí rí, kí n tó leè ṣe àwo orin27 Ọ̀wàrà 2020 Femi Gbajabiamila: DSS ti fi ẹ̀sọ́ àbò Gbajabiamila tó pa fẹ́ndọ̀ l'Abuja sátìmọ́lé23 Bélú 2020 Omo Ghetto: Funke Akindele ṣàlàyé bí àwọn agbébọn ṣe kọlù wọn làsíkò tí wọ́n ń ya fíìmù29 Bélú 2020 Lekki Toll Gate: CNN vs Lai Mohamamed rèé o!
Èèyàn 2,040 làwọn agbésùnmọ̀mí ti pa ní Nàìjíríà lọ́dún yìí- Ìwádìí Ẹ wo àwọn ọ̀dọ́mọdé Naijiria tó ń ṣe bẹbẹ nínú isẹ́ aládaní nílé Gbogbo ohun tó bá gbà lá máa fún un láti wa àwọn agbébọn náà- Ọlọ́pàá Èwo nínú àwọn amóhùnmáwòrán yìí lẹ rántí?
Ìwà rere, orúkọ rere ṣe pàtàkì fún àwọn Yorùbá nítorí náà ni wọ́n ṣe máa ń sọ pé orúkọ rere sàn ju wúrà àti fàdákà lọ.
Asofin Samuel anyawu ni ki Banki Baijiria foopin si tite owo naira Naijiria nile okeere mo nitoir pea won ile ise nlanla ni Naijiria ni agbara lati te owo nile yii fun ra won.
Awọn ẹya Fulani to ngbe pẹlu awọn Yoruba
Josẹfu kò lè mú ọ̀rọ̀ yìí mọ́ra mọ́ lójú gbogbo àwọn tí wọ́n wà lọ́dọ̀ rẹ̀, ó bá kígbe, ó ní, “Gbogbo yín patapata, ẹ jáde kúrò lọ́dọ̀ mi.
Awọn alaṣẹ naa ni iwadii si ti bẹrẹ ni pẹrẹu.
Magun Majẹkengbe: Bi ọkunrin to ba lu iru Magun yii ba ti jẹ kengbe, ọrun laala.
OLUWA dáhùn pé, “Mo ti dáríjì wọ́n gẹ́gẹ́ bí ẹ̀bẹ̀ rẹ.
Bí ẹnikẹ́ni bá fẹ́ jẹ́ iranṣẹ mi, ó níláti tẹ̀lé mi.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Bi ìdibò wọ́ọ̀dù APC ṣe lọ kákàkiri rèé 'Kò dín ní ẹ̀mí 51 tó bọ́ ní ìkọlù Kaduna' Ìdigunjale Offa: Ọlọ́pàá gbé N5m sílẹ̀ Ogbẹ́ni Adéníyì Táíwò Kunu, tó jẹ́ òǹwòye nípa ọ̀rọ̀ tó ń lọ láwùjọ ba BBC Yorùbá sọ̀rọ̀.
Ìyá Leah Sharibu ké gbàjarè sí ìjọba Buhari Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ọkọ àti ìyàwó sọ àsọtẹ́lẹ̀ tani yóò wọlé nínú PDP tàbí APC Liverpool naa pẹlu na Bournemouth, eleyii to ti mu ki ẹgbẹ agbabọọlu naa si wa ni ipo keji ni ori tabili.
Kì í ṣe agbára ẹṣin ni inú rẹ̀ dùn sí,kì í sì í ṣe inú agbára eniyan ni ayọ̀ rẹ̀ wà.
Ẹ̀rù yóo ba eniyan,tí eniyan bá mọ ìtumọ̀ ìkìlọ̀ náà.
Kí ni ọkunrin bíi wèrè yìí ń wá lọ́dọ̀ rẹ?
Buhari ṣàlàyé pe, Muammar Gaddafi lo kò awọn darandaran ní ìwà ipá, to sì kó òhun ija fún wọn.
 bàbá rẹ ̀ ṣe àkíyèsí wípé ó lè fẹ ́ ṣeré ní ìgbà tí ọwọ ́ rẹ ̀ bá dilẹ ̀ , ó sí gbàá ní ìyànjú wípé kí ó mú eré ìdárayá gẹ ́ gẹ ́ bi iṣẹ ́ àṣelà .
Ọjọ kẹjọ oṣu kọkanla ọdun 2018 (Ọrọ apilẹkọ ti o ka ni gbọngan nla ile ijọba nilu Abuja) Ayẹwo<br>lati mọ otitọ.
"Chelsea fẹ́ Ajax dànú bí abẹ̀bẹ̀ nílé wọ̀n Arsenal sì wà lọ́mọ ìkókó lẹ́yìn ọdún mẹ́wàá- Patrice Evra ""Ọ̀pọ̀ èèyàn ń bá mi ṣùn, ṣẹ́yún fún mi níbùdó ọmọ aláìgbọràn"" Ambode, wá sọ tẹnu rẹ lọ́jọ́rùú lórí owó àwọn àkànṣe iṣẹ́ to ná - Ilé aṣòfin Eko Kíni ìdí ti àwọn ọmọ ogun fi n ṣọ́ àwọn Imaam ni Mecca?"
 o gba ife-eye awon idije wta tour enikan meje , ipo re to gajulo ni world no.
Mo ti rù láàrin ọ̀sẹ̀ kan, iṣẹ́ Eko kò dẹ́rùn - Sanwo-Olu Super Eagles kò ní já àwọn ọmọ Nàìjíríà kulẹ̀- Musa O ni ti gomina ba ṣe e, o ṣe e lati mu ori awọn agbabọọlu naa wu ni fun bi wọn ṣe na ẹgbẹ agbabọọlu Camreoon.
Ṣé a kò ní ẹ̀tọ́ láti jẹ ati láti mu ni?
Bí n kò bá ṣe irú iṣẹ́ tí ẹnikẹ́ni kò ṣe rí, wọn kì bá tí ní ẹ̀ṣẹ̀.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Èmi ò kí ń lu ìyàwó mi' Bakan naa lo ni Ile Igbimọ Asofin n fi ọrọ aabo to kan awọn ara ilu falẹ, nitori wọn ni asẹ lati se awọn ofin ti yoo pese eto aabo to gboro fun awọn eniyan.
Wiliams sọ bi o ṣe pade ogbontarigi adigunjale Ishola Oyenusi to gbajumọ nigba aye rẹ fun dida ilu ru.
Ajá ni o n ṣe ìtọ́jú àwọn ẹranko nítorí òun ti gbé à[rin àwọn ènìyàn rí, ológbò ni o ń ran ajá lọ́wọ́.
Bekinbo wa ro ijoba ipinle Plateau lati tete pese owo tire fun ise-akanse naa, ni iyanju ati je ki ipese ohun elo naa tan kaakiri awon ijoba ibile yoku.
Nigba ti wọn koju rẹ lati mọ ibi ti o n ko awọn ọmọ naa lọ, o sọ pe ohun n ko wọn lọ ba ọkọ ohun arakunrin Chukwunonso Happiness .
Ile iṣẹ ọmoogun Naijiria ti ni Daily Trust fi gbogbo aṣiri bi awọn ṣe n gbogun ti Boko Haram lede ni awọn ṣe ti ọọfisi wọn pa.
Akọwe agba ajọ naa, Abdulkadir Saidu ṣalayekikun ni pa igbeṣe inu fifi owo sori epo.
Ǹjẹ́ èyí ha ni ìgbà àkọ́kọ́ tí mo bá a ṣe ìwádìí lọ́dọ̀ Ọlọ́run?
Ṣaaju ni BBC ti ba awọn obi oloogbe sọrọ, ti wọn si sọ pe ọrọ iku ọmọkunrin naa jẹ kayeefi, ti kii ṣe lasan.
Ọmọdé-bìnrin, ọmọ ọdún mẹ́rìnlá kan, tó wá láti ìlú mi, tíí se ìlú Èkó, ni ọkàn àwọn òbí rẹ̀ rẹ̀wẹ̀sì, tí wọn kò sì mọ ọ̀nà tí wọn leè gbà ràn-án lọ́wọ́.
Nígbà náà, ẹ̀rù yóo ba àwọn tí wọ́n jẹ́ akikanju jùlọ ninu àwọn eniyan rẹ, tí wọ́n sì láyà bíi kinniun; nítorí pé, gbogbo eniyan ní Israẹli ni ó mọ̀ pé akọni jagunjagun ni baba rẹ, akikanju sì ni àwọn eniyan tí wọ́n wà pẹlu rẹ̀.
Agadagodo mẹfa ati ẹwon lo fi so ara rẹ ni odo Hooghly ki wọn to maa waa ni odo ni West Bengal.
Ìyá rẹ̀ pa gbogbo ọ̀rọ̀ wọnyi mọ́ ní ọkàn rẹ̀.
Bí wọ́n ti dé ibi ìpakà Nakoni, àwọn mààlúù tí ń fa kẹ̀kẹ́ tí àpótí ẹ̀rí wà lórí rẹ̀ kọsẹ̀, Usa bá yára di àpótí ẹ̀rí náà mú.
Day 25: Àwọn ọmọ Nàìjíríà sọ̀rọ̀ lórí níní adarí tó ju ọdún 70 ló lọ́jọ́ orí #BBCNigeria2019 Kí ló mú àwọn obìririn meji yìí pa bàbá wọ́n?
Minisita oun jise pataki fun Aare Buhari, ninu eyi ti Aare orile-ede Tunisia Beji Caid Essebsi, ti ki olori orile-ede Nigeria ku oriire fun aseyori ninu eto-abo, oro-aje ati ipa ti o n ko ni ile Afrika.
O ṣe akoso ẹka iṣakoso nileeṣẹ ọlọpaa ipinlẹ Eko.
Ṣé o lè darí àkójọpọ̀ àwọn ìràwọ̀, ní àkókò wọn,tabi kí o ṣe atọ́nà ìràwọ̀ Beari ati àwọn ọmọ rẹ̀?
Coronavirus and OCD: 'Mo fi ogún ọdún gbáradì fún àjàkálẹ̀ ààrùn yìí' Ta ló da 'ewé' bo N4.
Moriki, Science Secondary School Shinkafi, Science Secondary School Dansadau, ati Science Secondary School ni Bukkuyum.
Ninu ọrọ to ba BBC Yoruba sọ, agbẹnusọ fun Olori ié aṣofin ipinlẹ Kogi, Ọgbẹni Fẹmi Olugbemi ni igbesẹ ti Achuba gbe lati lọ sọ ọrọ ile si ita gbangba dipo ko wa siwaju ile naa lati fi ẹjọ ọga rẹ sun, iyẹn bi ọga rẹ ba ṣẹ ẹ nitotọ lo jẹ ki wọn gbe igbesẹ naa.
Awọn iwe iroyin kan jabọ pe titi di ago mẹrin irọlẹ ọjọ abamẹta, wọn ṣi wa lahamọ ọlọpaa.
Láìsì nọ́mbà ìdánimọ̀ NIN ní 2020; kò sí ìdánwò- JAMB Ẹ dẹ́kun lílo ilé ìwòsàn àwọn nọ́ọ̀sì abẹ́lé - HEFAMAA Gbogbo iṣé àṣepatì ni yóò di mìmù ṣe lọgán- Alaṣọadura Kí wọ́n tún ìbò Kogi dì nígbà 2,000 Dino ló máa wọle- Dino Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
O yẹ ki wọn t'ọwọbọ'we loni-sọla.
 O si jẹ akoko pataki lati fi ifẹ han sira wa pẹlu alaafia, ki a si maa gbadura fun iṣọkan orilẹ-ede yii lapapọ”.
Ní ọjọ́ kẹrinlelogun oṣù kan náà, àwọn ọmọ Israẹli péjọ pọ̀, wọ́n gbààwẹ̀, wọ́n wọ aṣọ ọ̀fọ̀, wọ́n sì ku eruku sí orí wọn.
Ó rọ gbogbo awọn oludije to ku àti awon eeyan ipinle ogun kí wọn ran oun nise.
Ẹ̀yin olólùfẹ́ mi àti ẹbí ni mo bẹ̀ Ìjà Toyin àti Lizzy kìí ṣe àkọ́kọ́, àwọn òṣèré t'ọ́rọ̀ ìjà kàn rí rèé Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Kini awọn ololufẹ Lisa ṣe lori ayelujara?
Chiejine ni balogun ẹgbẹ agbabọọlu obinrin Naijiria akọkọ tọjọ ori wọn ko ju ọdun mọkandinlogun lọ ninu idije ife ẹyẹ agbaye lọdun 2002.
Abẹ́ ìṣọ́ ọlọ́pàá ni yóò wà fún àkókò yìí.
 Ìdí ni wí pé ọ ̀ pọ ̀ ìgbà ni àwọn alásẹ ń fi ojú òfin òwò ẹrú gbo ilẹ ̀ pẹ ̀ lú ọgbọ ́ n àlùmọ ̀ kọ ́ rọ ́ yí .
"Àwọn ọmọ Yorùbá bẹ̀rẹ̀ ìwọ́de àláfíà fún ìtẹ́wọ́gbà ètò Amotekun Agbarijọpọ ẹgbẹ ẹya Yoruba, Yoruba World Congress n bẹrẹ iwọde alaafia lati kede atilẹyin wọn fun ifilọlẹ eto aabo alajumṣe nilẹ Yoruba ti wọn pe ni ""Operaton AMOTEKUN""."
Nítorí pẹlu àṣẹ ati agbára ni ó fi bá àwọn ẹ̀mí èṣù wí, wọ́n sì ń jáde!
Wọn ji awọn eeyan naa gbe nigba ti wọn n rinrin ajo lọna to wọ ilu Ibadan ni nnkan bi ọjọ mẹfa sẹyin.
Ọ̀rọ̀ yìí á ti yé àwọn afẹ̀rọyàwòrán ẹgbẹ́ mi.
Opopona kan nilu Eko lo n jẹ Bode Thomas lagbegbe Surulere amọ lẹyin ti Naijiria fi ẹyin South Afrika janlẹ, o gba itumọ miiran Oríṣun àwòrán, Google Awọn Iroyin ti ẹ le nifẹ si Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, A ó jà fitafita láti ríi pé a ò já kulẹ̀ lónìí - Genort Rohr Ìtàn tó wà nídi òwe ‘Sebótimọ Ẹlẹ́wà Sàpọ́n’ Ṣẹ gbọ́ nípa Alájọ Ṣómólú, tó ta mọ́tò ra kẹ̀kẹ́?
Mi o le dá omije oju mi duro Fortunate Mukankuranga ni igboya lati jẹwọ ẹsẹ rẹ lẹyin ọdun mẹrin ti wọn ti dajọ rẹ lọdun 2007.
Tí a fiṣọwọ́ ní 11:05 29 Èbibi 201911:05 29 Èbibi 2019 Aarẹ Buhari ko ba awọn ọmọ Naijiria sọrọ lẹyin ibura Ni kete ti Aarẹ Muhammadu Buhari burawọle fun saa keji - Aarẹ kan ka ọrọ ibura rẹ ni.
" Nigba ti wọn bi Lizzy leere nipa ohun to jẹ atọna fun, o dahun pe ipamọra ni ati oore ọfẹ Ọlọrun, pẹlu afikun pe eeyan gbọdọ le diẹ ko to lee se aseyọri okoowo nilẹ Naijiria nitori irora pọ ninu sise isẹ aje nilẹ yii.
Ẹ̀yin ọkọ, ẹ fẹ́ràn àwọn aya yín.
Mẹfiboṣẹti dáhùn pé, “Kabiyesi, gẹ́gẹ́ bí ìwọ náà ti mọ̀, arọ ni mí.
David Oyelowo: Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, David Oyelowo wo Dashiki nibi afihan sinima Black Panther Oxford nilu ọba ni wọn ti bi David Oyelowo.
Oríṣun àwòrán, @MBuhari Atẹjade yii ni oun gba pe wọn ko tii gbe awọn igbesẹ ti yoo wa ojutu sawọn ohun to n fa ẹhonu awọn oluwọde.
State Assembly: Adebo, Oluomo di adarí ilé aṣòfin ìpínlẹ̀ Oyo, Ogun
Lati Ọjọ Kọkandinlọgbọn, Osu Kẹsan an, ni wọn bẹrẹ si ni ko owo naa jọ, ti wọn si ti ri owo to to miliọnu mọkanla Naira ($30,000) ni aarin ọjọ kan.
Jerusalema Remix: Wo orin l'édè Yoruba àti Zulu tí Burna Boy fi fa ayélujára ya
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Falz f'ohùn lẹ̀ fún PDP, APC, MURIC, àwọn ọmọ Yahoo 2019 elections: Ìgbésẹ̀ méje fún ìdìbò 2019 tí ó yẹ kí o mọ̀ Eko Akete yóò gbàlejò BBC Yoruba 'Ọkùnrin tí kò bá sanwó iléèwé ọmọ, kó lọ wẹrí' Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí kan sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Black women live matters: Ọdún 2015 ní àwọn ọlọ́pàá pa India Kager láìní ìdí- Gina Best Oniruuru eto idibo to waye lasiko ti ẹgbẹ one milionu boys n tan kalẹ nilu Ibadan tun mu agbega ba agbara wọn.
“Ìdí rẹ̀ nìyí tí Baba fi fẹ́ràn mi nítorí mo ṣetán láti kú, kí n lè tún wà láàyè.
ẸBỌRA  ÌGBÉRAGA-ÌBÁNÚJẸ́ ÀTI AHỌ́NDIWÚRÀ ÌYÀWÓ RẸ̀
aiyé kún fún ibùgbé ìyanu , ọba bí Ọlọ ́ rûn kò sí , olódùmarè ní ńṣe alákǒso ohun gbogbo tí ńbẹ ní òde aiyé àti òde ọ ̀ run , ìyanu ní aiyé pàápàá jẹ ́ : aiyé kún fún ènìà ẹlẹ ́ sẹ ̀ méji ati eranko ẹlẹ ́ sẹ ̀ mẹ ́ rin , ejò afàiyàfà àti ẹja tí ńkákìiri inú omi , ẹiyẹ tí nkọrin bí fèrè àti alágẹmọ tí olódùmarè wọ ̀ ní onírúnrú asọ.
Àwọn olùdíje Ọṣun jẹ́wọ́ ara wọ́n Arẹgbẹṣọla: 'Lóòtọ́ ni mo jẹ gbèsè l'Ọṣun ṣùgbọ́n gbèsè ayọ̀ ni' Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Bọla Tinubu: Ìpínlẹ̀ Ọ̀ṣun kò ní owó mi lọ́wọ́ Ninu ọrọ ti rẹ, oludije si ipo gomina labẹ ẹgbẹ oselu ADC, Fatai Akinbade ni awọn yoo da ogo ipinlẹ Osun pada nipa mimu eto ẹkọ lọkunkundun.
Aarẹ Trump lo fọrọ yii lede fun ra rẹ ninu atẹjade kan fi sita nile ijọba, White House.
Isabel Dos Santos wa ni ipo kẹ́jọ pẹlu biliọnu $2.
O fikun ọrọ rẹ pe yoo dara julọ ti Naijiria ba le fagba han France, nitori yoo fun wọn ni igboya lati koju ẹnikẹni ni ipele ẹlẹnimẹrindinlogun.
iwa akin ati adari rere ti o jẹ.
#BigBrotherNaija g'ori afẹfẹ Seyi Awolowo, ọmọ-ọmọ Awolowo, kí ló ń wà lórí ètò BB Naija?
Ti a ba tele Olorun , ti a si  tera mo ise wa, o di dandan ki iyipada rere ba orile ede yii.
Obasanjo, Osinbajo, Shonekan àtàwọn èèkàn ọmọ Ogun nínú ìṣèjọba Nàìjíríà.
Buhari ní òun kò tètè fọwọ́sí ìwé àdéhùn lóríi ètò ìdókówó ọ̀fẹ́ jádè-jádò àgbáyé, nítorí pé òun lọ́ra láti kàwé.
Eyí jẹ ǹkan to wáye lásìkò ti wọ́n ṣe ìdájọ Abdullahi Dikko, to jẹ ọga aṣọ́bode tẹ́lẹ̀rí ti ilé ẹjọ́ to ga jùlọ l'Abuja si paa lásẹ pe, ajọ tó n gbógùn ti ìwà jẹgudújẹra ní Nàìjíríà kò lẹ́tọ̀ọ́ láti gbe lọ si ilé ẹjọ́ mọ.
Idi ni pe awọn isẹlẹ manigbagbe lo waye nibi igbeyawo naa, ti ko fẹ sẹlẹ ri lorilẹede Naijiria.
Oríṣun àwòrán, RCCG Lọdọọdun nigbakuugba ti eto yii ba n waye, ṣuaaa lẹ o ri ero afi bi omi ninu ilu nla ti wọn n pe ni Redeem Camp.
O si kere tan ọkunrin mẹẹdogun lo n ba mi lopọ ni ojoojumọ.
“Awon n kan ti a polongo le lori ni eyi, ti e si dibo fun wa, a ko si le e gbagbe lailai,” Ewe, lara awon ti a wa nibi ipolongo ohun ni: alaga egbe oselu AP, Adams Oshiomhole, gomina ipinle Bauchi, Plateau, Kano, Imo, ati awon toro kan miiran ninu egbe oselu naa “O wa ro awon olugbe agbegbe gusuu ipinle Bauchi lati dibo fun ogbeni Yahaya ninu eto idibo to n bo lona.
ObianoGomina ipinle Anambra , Willie Obiano naa tun wa lati ri aare
Yẹ̀yẹ́ ni àwọn ẹ̀gbọ́n rẹ̀ fi i ṣe.
Aisaya pàápàá kò jẹ́ kí ọ̀rọ̀ kọ́ òun lẹ́nu, ó ní,“Àwọn tí kò wá mi ni wọ́n rí mi,àwọn tí kò bèèrè mi ni mo fi ara hàn fún.
Nígbà tí Samuẹli ń rúbọ lọ́wọ́, àwọn ará Filistia ń súnmọ́ ọ̀dọ̀ àwọn ọmọ Israẹli, láti bá wọn jagun.
Iṣẹ́ àgbẹ̀ tí mo ń ṣe kò ṣe mí ní àǹfààní nítorí ilẹ̀ náà kò dárá – iṣu kò ta, ọ̀gẹ̀dẹ̀ kò yọ ọmọ, ẹ̀gúsí kòo so, n kò sì ń rí ju àgbọ̀n erèé méjì lọ̀dún kan.
Oniruuru eniyan bá kún ibi àsè igbeyawo.
Njẹ́ ẹ mọ̀ pé 'orílẹ̀èdè Nàìjíríà n wo 'Blue film' jù?
7m kó sí páńpẹ́ EFCC Dokita Aarẹ Trump ni aṣiṣọ ọrọ ni wi pe aarẹ Trump ti ni aarun Coronavirus ki o to di wi pe o yọju si ileewosan.
Eniyan rẹ sá ni wọ́n, ìwọ ni o sì ni wọ́n, ìwọ ni o kó wọn jáde láti ilẹ̀ Ijipti, ilẹ̀ tí ó gbóná janjan bí iná ìléru.
Sùgbọ́n kan tó wà nínú ọ̀rọ̀ yìí ni pé ìròyìn sọ pé gómínà náà kò gbà pé ààrùn coronavirus wà nípínlẹ̀ Kogi.
Onírúurú èèyàn ni wọ́n rán lọ sipẹ fún Kurunmi àmọ́ tí kò gbà rárá láti tẹ síbi tí àwọn ìlú yòókù nilẹ Yoruba tẹ sì.
Nítorí náà èmi OLUWA àwọn ọmọ ogun, Ọlọrun Israẹli, ni mo sọ pé n óo jẹ ọba Babiloni ati ilẹ̀ rẹ̀ níyà, bí mo ṣe jẹ ọba Asiria níyà.
Lẹ́yìn rẹ̀ ni Ṣemaaya, ọmọ Ṣekanaya, olùṣọ́ ẹnu ọ̀nà ìhà ìlà oòrùn, ṣe àtúnṣe ọ̀dọ̀ tirẹ̀.
Oríṣun àwòrán, Seyi Makinde Sugbọn o salaye pe bi ohun gbogbo ba lọ botiyẹ, o ṣeeṣe ki owo osu oṣiṣẹ nipinlẹ Ọyọ jẹ eyi ti yoo pọ julọ loriẹede Naijiria.
Nígbà tí Pelegi di ẹni ọgbọ̀n ọdún ni ó bí Reu.
O di igbakeji aarẹ Umaru Musa Yar'adua lọdun 2007 nigba ti wọn bura wọle fun un gẹgẹ bi aarẹ.
Gege-bi oro re ,oloogbe naa je eni amuyangan fun gbogbo obirin ile Afirika ati gbogbo omo ile Afirika lapapo.
 isẹ ́ àgbẹ ̀ de adẹ ́ mu apẹja ati ode jẹ ́ àwọn isẹ ́ ọkùnrin woyo.
Ẹlẹ́wọ̀n Kirikiri tó ń wọ́ke, olùdarí ọgbà ẹ̀wọ̀n ló ṣe onígbọ̀wọ́ fun - EFCC A ṣe tán láti yọ ìjìyà ikú kúrò nínú àbá ọ̀rọ̀ ìkórìra- Sẹ́nẹ́tọ̀ Sabi Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Buns ni ọmọ mi jẹ tán ní ṣọ́ọ̀ṣì, ló bá di àwátì' Esi ti ijọba Gomina Matawalle fi sita ni pe o jẹ iyalẹnu fawọn pe Yari yoo ma beere owo yi nitori ko si Gomina kankan to ti foye silẹ to n kọwe beere owo ti wọn jẹ wọn.
O ni ko si gomina ipinlẹ kankan to lasẹ lori ileesẹ ologun ilẹ wa ati bi wọn se n sisẹ wọn.
Wọ́n ń gba àbẹ̀tẹ́lẹ̀ láti paniyan láàrin ìlú, wọ́n ń gba owó èlé, ẹ̀ ń ní àníkún, ẹ sì ń fi ipá gba owó lọ́wọ́ aládùúgbò yín, ẹ ti gbàgbé mi, èmi OLUWA Ọlọrun ni mo sọ bẹ́ẹ̀.
Ọ̀nà nlá yìí ni àwọn ọkọ̀ ayọ́kẹ́lẹ́ àti ọkọ̀ akérò ngbà láti ìlú dé ìlú.
iṣuna owo ọdun 2019 fun Ipinlẹ Eko.
 O le ni egberun marun un eniyan to kopa ninu ayeye Wazobia todun yii nibi ti awon gbajugbaja osere bii Ice Prince, Phyno, Kiss Daniel ati Falz atawon miran.
 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ijọba gomina Akinwunmi Ambode tọrọ aforijin lori ikọlu tawọn osisẹ rẹ se si akọroyin BBC Ijọba Eko tọrọ Aforijin lọdọ BBC Ni aarọ ọjọ aje, kọmisọna fọrọ ayika nipinlẹ Eko, Babatunde Durosinmi-Ẹtti fi atẹjade kan sita fun ileesẹ BBC, o ni "" Ni orukọ ileesẹ naa, mo tọrọ aforijin, kii se lorukọ ileesẹ naa nikan, ati lorukọ ijọba ipinlẹ Eko pẹlu, a si pada se agbeyẹwo isẹlẹ yii."
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Minimum Wage: Alága òṣìṣẹ́ Ekiti ní òǹyẹ̀ kò leè yẹ sísan ₦30,000 owó oṣù 27 Ògún 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Alága ẹgbẹ́ òṣìsẹ́ ìpínlẹ̀ Ekiti, Kolapọ Olatunde ti kéde pé ,ìjọba àpapọ yóò san ẹgbẹ̀rún lọna ọgbọn náírà owó oṣù òṣìsẹ́ tó kére jùlọ losù kẹ́sàn ọdún yìí.
Àwọn obinrin àdúgbò bá sọ ọmọ náà ní Obedi, wọ́n ń sọ káàkiri pé, “A bí ọmọkunrin kan fún Naomi.
Ṣugbọn tí ẹ bá ń jowú ara yín kíkankíkan, tí ẹ ní ọkàn ìmọ-tara-ẹni-nìkan, ẹ má máa gbéraga, kí ẹ má sì purọ́ mọ́.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Sẹ́gílọlá: Arúgbó awẹ́lẹ́wà tó ń ṣiṣẹ́ omidan Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Sẹ́gílọlá: Arúgbó awẹ́lẹ́wà tó ń ṣiṣẹ́ omidan 21 Ẹrẹ̀nà 2019 Awọn agba bọ wọn ni arugbo ṣoge ri akisa lo igba ri.
Ojogbon Muhammd soro yii  lasiko to n fun aare Muhammadu Buhari ni iwe
Ọmọ Naijiiria ni mí, ọ̀rọ APC kò lésì -Atiku 'Ilé iṣẹ́ DSS kò mú òṣìṣẹ́ INEC kankan lórí ọ̀rọ̀ Atiku' Lẹ́yìn igbe Atiku, Ààrẹ Ilé Ẹjọ́ kòtẹ́milọ́rùn yọra rẹ̀ nínú ìgbẹ́jọ́ èsì ìdìbò ààrẹ Awọn adajọ naa sọ pe nibi ti nkan de bayii, igbimọ ọhun ko tun le ti ọwọ bọ wahala boya INEC lo ẹrọ ayelujara lati ṣafihan esi idibo tabi ko lo o.
Àwọn ọmọ ogun Ijipti bá wí láàrin ara wọn pé, “Ẹ jẹ́ kí á sá fún àwọn ọmọ Israẹli, nítorí pé, OLUWA Ọlọrun ń bá wa jà nítorí wọn.
Ọpọlọpọ ọdún ni o óo sì lò lórí ilẹ̀ alààyè.
Awọn ile iwosan ikọṣẹ iṣegun oyinbo to wa ni ilu Calabar, Port Harcourt ati Enugu, ni wọn ṣe iwadii naa.
Oríṣun àwòrán, PA Media Ẹ o ranti wipe aarun tuntun yii ti gbilẹ ni orilẹede South Africa to si ti wọ United Kingdom pẹlu.
Nítorí òtítọ́ ni ọ̀rọ̀ mi;ẹni tí ìmọ̀ rẹ̀ péye ni èmi tí mò ń bá ọ sọ̀rọ̀ yìí.
Shkodran Mustafi lo kọkọ gba bọọlu sinu awọn nisẹju mẹjọ si igba ti wọn bẹrẹ ere.
Wọ́n ń dẹ́rù ba àwọn eniyan nígbà tí wọ́n wà láàyè.
New WAEC timetable 2020: Ọjọ́ Kẹrin oṣu Kẹ́jọ ni ìdánwò WAEC yóò bẹ̀rẹ̀ - Mínísítà ètò ẹ̀kọ́ Oríṣun àwòrán, dnt Ijọba apapọ ti kede pe idanwo aṣepari ni ileewe girama, WAEC, yoo bẹrẹ lọjọ kẹrin oṣun Kẹjọ ọdun 2020.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Ilé ìwòsàn ṣi abẹ́rẹ́ Formalin gún mí; n kò lè dá ìgbẹ́ àti ìtọ̀ dúró mọ́' Ọ̀gá àgbà DSS tuntun ọ̀hún ni iléèṣẹ́ Ààrẹ́ ní yóò ṣe àmúlò àwọn ìrírí tó ti ní nínú iṣẹ́ ìwádìí, àtúpalẹ̀ iṣẹ́ ìwádìí, ìpẹ̀tù sí àáwọ̀, ìpèsè àábò,tó fi mọ́ kíkópa nínú àwọn ìṣẹ́ tó léwu àti èyí tó jẹ́ ẹlẹgẹ́.
Ó ni ọ̀pọ̀ ìgbà ni àwọn ti sọ fún Akintoye pé kìí ṣe gbogbo aṣọ ni à n sá lóòrùn, sùgbọ́n gbogbo àṣírí ẹgbẹ́ ni ọjọ̀gbọ́n máá n pe ará ìta sí.
Ifọrọwerọ Oluwo lori awuyewuye pẹlu awọn Ọba Ènìyàn 65 ló ti ní ààrùn Coronavirus ní Nàìjíríà Ọsẹ̀ mẹ́ta gbáko lorílẹ́èdè South Afrika yóò fi wà lábẹ́ òfìin kónílé-ó-gbélé Ìjọba Ethiopia pàṣẹ pé kí wọ̀n tú ẹ̀gbẹ̀rún mẹ́rin ẹlẹ́wọ̀n silẹ̀ nítorí coronavirus Ọ̀ọ̀ni jẹ ọkùnrin kan tí kò pa òfin kónílé-ó-gbélé nítorí coronavirus mọ́ Eyi lo mu ikọ Kayeefi ti BBC News Yoruba lati lọ ṣe finlẹfinlẹ bi aawọ naa ṣe bẹrẹ ati ohun to faa.
Ní ọdún 1998, òpópónà kan ni New York náà tún yi orukọ pada láti máà jẹ́ Kudirat Abiola Corner.
afurasi odaran mokanla(11) to lowo ninu jija oko to ko ero amunawa (SUMEC
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ọjọ kẹsan an, oṣu kẹfa ọdun 2019 lo yẹ ki saa wọ́n wà sópin 2 Ìgbé 2019 Oríṣun àwòrán, @NGRSENATE Yoruba bọ, wọn ni ibẹrẹ kii ṣe oniṣẹ, ọpọ ọmọ Naijiria ló n woye ibi ti awọn ọmọ ile igbimọ aṣofin kẹjọ yii ba iṣẹ ilu de.
Ikọ̀ aláàbò Nàìjìríà dojú kọ Shiite Ọlọ́pàá mú 115 ẹlẹ́sìn Shiite Èmi kò ní kí Shiite má ṣe ẹ̀sìn won o -Muhammadu Buhari Àgùnbánirọ̀ akọ̀ròyìn Channels náà ti dágbére fáyé látààrí ìkọlù Shiite l'Abuja Bakan naa ni o fikun un wi pe o dabi ẹni pe ijọba n lo ọrọ El-Zakzakky lati ja ija ẹsin, nitori ẹgbẹ musulumi Sunni ni awọn to wa ni ijọba lọwọlọwọ.
Buhari ló borí ní ìgbẹ́jọ́ ìdìbò 2019!
Olódodo ni OLUWA ninu gbogbo ọ̀nà rẹ̀,aláàánú sì ni ninu gbogbo ìṣe rẹ̀.
O ní Minisita fun Ìroyìn, Lai Mohammed, ni ó pàrọwà sí òun lóríi lẹ́tà tí ààrẹ àná, ìyeń, Olóyè Olusegun Ọbásanjọ́ kọ nínú èyí tí ó sọ àwọn ìdí tí kò yẹ kí òun fi padà sorí àleéfà lẹ́ẹ̀kejì.
Ó bá rá mọ́ wọn lójú.
Nǹkan kò ṣẹnuure fáwọn obìnrin nínú ìgbìmọ̀ ìṣèjọba Buhari Wọn ni kẹkẹ wiwa dara nitori pe o wa fun ere idaraya ati ara lile.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù PDP:Buhari ni kẹ dalẹ́bi tí wahala ìdìbò bá bẹ́ sílẹ̀ 18 Èrèlè 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 19 Èrèlè 2019 Oríṣun àwòrán, Twitter/@OfficialPDPNig/Getty Àkọlé àwòrán, Buhari Ẹgbẹ oṣelu Peoples Democratic Party PDP ti figbe sita pe ijọba to wa lori oye ati ẹgbẹ oṣelu APC n gbero lati doju eto ijọba arawa bole ki wọn si da wahala silẹ lorileede Naijiria.
Ẹ̀mí eniyan ni fìtílà OLUWA,tíí máa wá gbogbo kọ́lọ́fín inú rẹ̀ kiri.
Oyinbo naa jẹjẹ pe oun yoo mu awọn ọmọ ọba naa pada, ti oun ba n bọ pada wa silu Eko sugbọn ọrọ naa ko mu ọkan ọba balẹ.
ohun ni ajo EFCC gbamu ni agbegbe Akobo Estate ati Elebu  niluu Ibadan, ni
Wọ́n ní wọ́n ń gbé òkú bọ̀, ìwọ Ìyábọ̀ ń yọjú.
FA Cup final Arsenal vs Chelsea: Lampard laná!
Onimọ nipa ọrọ aabo, Olatubosun Abolarinwa to ba BBC Yoruba sọrọ lo fidi ọrọ yii mulẹ pe ifura loogun agba.
Lòde òní, nnkan ti ń yàtọ̀ díẹ̀díẹ̀ nítorí pé àjọṣẹ tí ó péye ti ń wàyé láàárín ọ̀gbọ́n náà àti àwọn ọ̀gbọ́n yòókù.
Yóo máa rí oúnjẹ jẹ déédé,yóo sì máa rí omi mu lásìkò, lásìkò.
”O wa ro awon akẹkọọ gboye jade
Ṣugbọn ninu aworan yii, o lo yẹti, eyi to jẹ ọkan lara awọn idi ti o fi ṣoro lati gbagbọ pe fọto igbeyawo gidi ni A tun ṣakiyesi pe, ko si ẹnikẹni ninu awọn akẹẹgbẹ wọn ninu isẹ tiata, to ki wọn ku oriire ayẹyẹ igbeyawo Eyi jẹ nkan to ṣe ajeji lagbo Yollywood.
Kí ni ìjọba Ogun sọ nípa N25, 000 owó àyẹ̀wò COVID-19 fáwọn akẹ́kọ̀ọ́ tí yóò wọlé padà?
Ọwọ́ sìkún ọlọ́pàá tẹ afurasí lórí ẹ̀sùn ìpaǹìyàn ni Port Harcourt Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Kì bá jẹ́ fi àṣírí ọgbọ́n hàn ọ́,nítorí ìmọ̀ rẹ̀ pọ̀ lọpọlọpọ.
Ranti Jesu Kristi tí a jí dìde kúrò ninu òkú, tí a bí ninu ìdílé Dafidi.
" ‘Irọ́ ni Tinubu ń pa, PDP ló ni ilẹ̀ Yorùbá’ Àwọn àwòrán mánigbàgbé nípa Ààrẹ Muhammadu Buhari Ìgbà tí Aisha Buhari ti f'ọ̀rọ̀ da ìgboro rú lórí ìjọba ọkọ rẹ̀ O ṣalaye pe papa iṣere miran ti ijọba yọnda ko le gba gbogbo awọn eniyan ẹkùn Niger Delta to n bọ fun eto naa.
EFCC: Ọ̀gá ẹlẹ́wọ̀n àti dókítà gba ẹlẹ́wọ̀n láàyè láti kúrò láhàmọ́ọ́ fún ìtọ́jú
O óo wá àwọn tí ń bá ọ jà tì,o kò ní rí wọn.
Aare Bio to jẹ alatako  fun egbe aare Koroma sugbon ti o jawe olubori ninu ibo to waye ni osu keta  leyin ipolongo idibo lati mu atunse ba orile ede naa.
Ile-ejo to ga julo naa so pe
Oun naa yoo ma lọ si ile rẹ.
Iwadii ti fihan pe o ni awọn akoko kan ti oogun le ṣiṣẹ daadaa lara eniyan ti o ba lo o.
19 Bẹ́ẹ̀ni, fi ara mọ́ mi pẹ̀lú gbogbo ọkàn rẹ, kí ìwọ lè ṣe ìrànlọ́wọ́ láti mú wá sí ìmọ́lẹ̀ àwọn ohun wọ̃nnì nípa èyí tí a ti sọ—bẹ́ẹ̀ni, ṣíṣe ìtumọ̀ iṣẹ́ mi; ní sùúrù títí ìwọ yíò fi ṣe é yọrí.
Eyi ni ajọ gomina n fapa janu fun.
Ẹ máa fún eniyan lẹ́bùn, Ọlọrun yóo sì fun yín ní ẹ̀bùn.
Èmi fúnra mi jẹ́rìí ara mi, Baba tí ó rán mi níṣẹ́ náà sì ń jẹ́rìí mi.
Nibẹ ni wọn ti rii pe wọ́n ti tàá fún àwọn kan to wa láti ìpinlẹ̀ Kano ní ẹgbẹ̀run mẹ́rin Naira tí wọ́n si mú ènìyàn mẹ́ta to ní i ṣe pẹ̀lú rẹ̀ ati pe o lọwọ kan awọn oṣiṣẹ ibẹ ninu.
Onnoghen: CCT ní Onnoghen kò gbọdọ̀ di ipò ìlú mú fún ọdún mẹ́wà
Ohunkohun tí ó bá dùbúlẹ̀ lé lórí, tabi tí ó jókòó lé lórí ní gbogbo àkókò àìmọ́ rẹ̀ yóo di aláìmọ́.
ni woodu kokanla to wa ni ile- eko  Girama Oluyole (Oluyole Community Grammar
Aaroni gbé àwọn fìtílà náà ka orí ọ̀pá wọn, kí wọ́n lè tan ìmọ́lẹ̀ siwaju, gẹ́gẹ́ bí OLUWA ti pàṣẹ fún Mose.
Ẹ̀wẹ̀, Ilé iṣẹ́ BBC pe ọ̀kan lára àwọn afọbajẹ ti wọ́n buwọ́lu iwé ẹsùn Yekini Oosa ti wọ́n fi síta pé ki o sàlàye lórí ìdí tí wọ́n fi fk yọ Oluwo.
Ọba ni mí, mi ò le b'ọ̀rìṣà, Olorì tuntun tó ń bọ̀ já gbogbo ''scale''- Oluwo ti Iwo Oyenusi ló mú mi wọ ẹgbẹ́ adigunjalè kó tó di pé mo b'Ólúwa pàdé - Kayode Williams Tunde Idiagbon, ọ̀gágun kògbagbẹ̀rẹ́ tó ní ẹ̀ẹ̀kan lóṣù ló yẹ kí ológun máa rẹ́rìín Ìjọba Ghana ṣí iléeṣẹ́ àwọn ọmọ Nàìjíríà padà.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Joke Silva: Olu, ó tó gẹ́ pẹ̀lú obìnrin yìí níkan tó ń ba ẹ ṣeré ìfẹ́ nínú sinimá!
Bí wọ́n ti ń jẹun, Jesu mú burẹdi, ó gbadura sí i, ó bù ú, ó fún wọn.
won yoo wa ninu igbimo naa.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Sanusi Lamido Sanusi: Ashraf, ọmọ Lamido Sanusi ní ìṣọ̀kan ṣì wà nínú ẹbi Emir àná náà pẹ̀lú gbogbo ohun tí wọ́n là kọjá 25 Ìgbé 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 11 Èbibi 2020 Oríṣun àwòrán, Governor kaduna Laipẹ yii ni iroyin kan wọ ilu ti gbogbo ilu si mi titi.
Àwọn akẹ́kọ̀ọ́-bìnrin Naijiria fẹyin US ati China gbolẹ nidije ìmọ ẹrọ Ohun tí ojú opó ń rí láwùjọ kò kéré"" Alárùn ọpọlọ lu àwọn nọ́ọ̀sì àti dókítà agba níléèwòsàn ní àlùdákú Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!"
Kí ló dé tí yóo kàn máa gbilẹ̀ lásán?
"A ń fikunlukun pẹ̀lú FBI láti mú àwọn ""Yahoo Boys"" tó kù- EFCC Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!"
Iléẹ̀kọ́ gbogboùnṣe ìgbájọ lé gíwá rẹ̀ lórí ẹ̀sùn ayédèrú ìwé ẹ̀rí
Gomina ohun woye pe, ipinle Benue ni igbagbo ninu isokan orile-ede Naijiria, ni eyi ti a o maa satileyin fun Aare Buhari lati gbe orile-ede Najiria de ile ileri.
Bakan naa, ni awon omo orile ede Naijiria, si n kedun iku oloogbe naa.
Awokọse nla ni wọn jẹ fun wa lasiko yi'' Jakejado agbaye ni ọwọngogo fẹntilatọ ti jẹ ipenija.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Arakunrin Fulani ni aigbede ara eni ni orisun ija pelu agbe Bakan naa ni Adamu ni inu oun ko dun si ki arugbo maa fomije ṣọfọ ọmọ wọn lagbalgba.
Ohun ìríra ni wọn yóo jẹ́ fun yín, ẹ kò gbọdọ̀ jẹ ẹran wọn, ohun ìríra ni òkú wọn gbọdọ̀ jẹ́ fun yín pẹlu.
Ọmọwe Ariyo sọ bakan naa pe ounjẹ jijẹ nikan ko to o.
“Wọn ni ọwọ to ba dilẹ ni eṣu n bẹ lọwẹ, ẹ jẹ ki a ro awọn ọdọ wa lagbara.
Láti Punoni wọ́n lọ sí Obotu.
Lọwọ lọwọ bayii, Temitope Akinnusi wa lara awọn akọsẹmọsẹ ati gbajumọ ayaworan nipinlẹ Ondo pẹlu oju kan soso to ni.
Àwọn tí wọ́n wà lábẹ́ ọ̀págun ẹ̀yà Juda ni wọ́n kọ́kọ́ ṣí, wọ́n tò ní ìsọ̀rí-ìsọ̀rí.
Kii se ìròyìn tuntun mọ pe orílẹ̀ èdè Nàìjíríà tún ti padanu ọkàn lára ojúlówó ọmọ orílẹ̀ èdè yìí, èèkàn ìlú àti àgbà amofin, Olóògbé olóyè Richard OSUOLALE Abimbola Akinjide.
Wọn ni atilẹyin awọn Yoruba kan to n ba wọn ra ẹya ara eniyan ti ẹbi rẹ ko ba tete san owo itanran.
Ìbéèrè tó ti wá gba orí ẹ̀rọ ayélujára ni pé, ṣé àjọ tí kò rówó ṣiṣẹ́ yẹ kó ná mílíọ́nù mẹ́rìndínlógún láti fi kọ́lè.
Eyi lo si ti jẹ ki ijọba Abuja gbe igbesẹ to yẹ pe: Ijọba ni wọn rii pe awọn ohun eelo aabo ara ẹni lọwọ ajakalẹ aarun coronavirus naa wa kaakiri iboju oku naa Ṣugbọn bayii, wọn ti lọ palẹmọ gbogbo ohun to wa nilẹ kaakiri itẹ oku ni Gudu nilu Abuja.
Nítorí bí ẹ kò bá gbàgbọ́ pé, ‘Èmi ni,’ ẹ óo kú sinu ẹ̀ṣẹ̀ yín.
ó pàṣẹ fún àwọn ọmọ Lefi tí wọ́n ru àpótí majẹmu OLUWA, 
Ṣé YouTube ń jèrè nínú lílo ayédèrú fídíò ìwòsàn ààrùn jẹjẹrẹ?
Àwọn Ọba alayé ní Naijiria ṣàbẹ̀wò sí Ọba Eko, Gómìnà Eko àti Bola Tinubu lẹyin ìwọ́de EndSARS Díẹ̀ ló kù kí ọjọ́ ìkúnlẹ̀ di ọjọ́ ikú fún ìyá mi lọ́jọ́ tó bí mi - Seyi Makinde Nínú oṣù kẹjọ, ọdún 2019 ní ààrẹ Donald Trump sọ owó físà ilẹ̀ Amerika di gọbọi láti fi gbẹ̀sàn lára Nàìjíríà fun owo gọbọi tti Nàìjíríà n gbà lọ́wọ́ ará Amẹrika to fẹ gba físà Nàìjíríà.
Nítorí náà, mo máa fẹ́ ọ, ìwọ́ ni yóó sì ṣe baálé mi.
Wo àṣírí tó gbé ìgbéyàwó Remi àti Bola Tinubu dúró bó tilẹ̀ jẹ́ pé ẹ̀sìn wọn yàtọ̀
Kò pẹ́ púpọ̀ lẹ́jìn èyí ni ó bá lọ jà ogun kan, ṣùgbọ́n kí ó tó padà dé, ọmọ rẹ̀ kan gbà òtẹ́ ńlá kan jọ tí ó fi jẹ́ wí pé Agígírì kò lè padà sí ilée Bajimọ mọ́.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Pẹ̀lú gbogbo bùkátà, Bàbá 80 gboyè Masters Ọrọ yii jade ninu ọrọ ti aarẹ ẹgbẹ awakọ ero NURTW, Najeem Yasin fi ranṣẹ lati orilẹ-ede Saudi Arabia nibi ti o ti lọ ṣe Umrah fun ọdun Ramadan.
Àwọn orílẹ̀-èdè yóo rí i, ojú agbára wọn yóo tì wọ́n; wọn óo pa ẹnu wọn mọ́; etí wọn óo sì di; 
Ọpọlọpọ eniyan ni agbaye si bẹnu atẹ lu.
Ẹ̀yin ará Jeṣuruni,kò sí ẹni tí ó dàbí Ọlọrun yín,tí ó gun awọsanma lẹ́ṣin ninu ọlá ńlá rẹ̀,láti wá ràn yín lọ́wọ́.
Oríṣun àwòrán, @Daily Trust Iléesẹ́ ológun Nàíjíríà ti Daily Trust pa ní Maiduguri àti Abuja Oríṣun àwòrán, @Daily Trust Ko pe si igba ti wọn yabo ileeṣẹ iroyin naa ni Maiduguri, ni awọn ọmọogun tun ṣigun lọ si ile iṣẹ iroyin naa ni Abuja lọjọ aiku kanna ti wọn si ko awọn Komputa awọn akoroyin nibẹ.
Oloyede ni awọn afẹsunkan naa kopa ninu idanwo naa ni oṣu kẹrin ọdun yii, ti ẹrọ ayaworan ti wọn fi si awọn gbọngan idanwo si fi han wipe wọn ṣe magomago ni akoko idanwo naa.
 Ẹ toju ohun alumọọni yin daadaa.
O fi kun pe, aarẹ ẹgbẹ agbabọọlu naa tẹlẹ ati adari ile iṣẹ to n ri si ọrọ ere idaraya lọwọ, nikan ni wọn le buwọlu iwe owo akanti ọhun.
Mo fẹ́ kí ẹ mọ̀ dájúdájú pé: ẹrú kò ju oluwa rẹ̀ lọ, iranṣẹ kò ju ẹni tí ó rán an níṣẹ́ lọ.
Lasiko ti Soyinka n ba BBC sọrọ lori ẹrọ ibanisọrọ lo ti ni o yẹ ki awọn adari ijọ tabi mọṣalaṣi bẹẹ le kọ ẹkọ to yẹ lai yọ awọn olujọsin ti ko naani ẹmi ara wọn silẹ.
5 1,629 New Zealand 25 0.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ọmọ Nàíjíríà: Eré ìtàgé lágbo òsèlú bẹ̀rẹ̀ lẹ́yìn BB Naija 25 Ìgbé 2018 Oríṣun àwòrán, @dino_melaye Àkọlé àwòrán, Ó tó ọ̀sẹ̀ méjì tí ọlọ́pàá ti kéde pé wọn ń wá Mélayé Níwọ̀n ìgbà tó jẹ́ pé onírúnirú ọ̀bẹ làá rí lọ́jọ́ ikú erin, èyí ló mú kí èrò àwọn ọmọ Nàíjíríà se ọ̀tọ̀ọ̀tọ̀ nípa bí ìjọba àpapọ̀ se mú Sẹ́nẹ́tọ̀ Dino Mélayé àti ọ̀pọ ìsẹ̀lẹ̀ míì tó tẹ̀le, tó fi mọ́ bí wọn se ló jábọ́ lẹ́yìn ọkọ̀.
Ajọsepọ wo lo wa laarin Saheed ati Fathia Balogun: Ọjọ karun osu keji ni wọn bi Saheed ati Fathia, bi o tilẹ jẹ pe ọdun 1967 ni wọn bi Saheed nigba ti wọn bi Fathia lọdun 1969 Eyi tumọ si pe ọjọ to pe ọdun meji geerege ti wọn bi Saheed, ni Fathia naa dele aye Ilu Enugu ni wọn bi Saheed si nigba ti wọn bi Fathia si Ikeja, nilu Eko Ọmọbibi ilu Ibadan nipinlẹ Ọyọ, ni agboole Balogun Kọbọmọjẹ ni Saheed nigba ti Fathia jẹ ọmọ ilu Ukwara, nipinlẹ Delta Saheed ka iwe alakọbẹrẹ ati girama rẹ ni ipinlẹ Ọyọ, ko to morile ile ẹkọ gbogbo nse Poly tipinlẹ Kwara lati tẹsiwaju Fathia kawe alakọbẹrẹ ati girama nilu Eko, koun naa to morile ileẹkọ gbogbo nse Poly tipinlẹ Kwara yii kannaa lati tẹsiwaju ninu ẹkọ rẹ Iwe ẹri Diploma ni awọn mejeeji dijọ gba jade nile ẹkọ naa, ti wsn si dijọ gba idi ere tiata lọ Ilumọọka osere tiata, adari sinima ati olootu ere tiata ni Saheed ati Fathia Balogun, ti wọn si dijọ kopa to giriki ninu ere tiata lorisirisi Lara awọn ere tiata to gbajumọ ti Saheed ti kopa ni Mo dupẹ temi, Gbogbo ere, Eti Kẹta, Ofin Mose ati bẹẹ bẹẹ lọ Lara awọn ere to gbajugbaja julọ ti Fathia ntiẹ ti kopa ni Iransẹ Aje, Iya Alalakẹ, Farayọla, Ajẹ mẹta, Awawu, Tẹni tika, Ọmọ Ale, Basira Badia, Sola Arikusa ati bẹẹ bẹẹ lọ Saheed ati Fathia gba ami ẹyẹ ti ko lonka ninu isẹ ti wọn yan laayo yii lorilẹede Naijiria ati loke okun Saheed ati Fathia di tọkọtaya, ti wọn si bi ọmọ meji fun ara wọn, orukọ awọn ọmọ naa ni Khalid, ti wọn bi lọdun 2002 ati Aliyah Balogun, ti wsn bi lọdun 2005 Ọdun 2006 ni Saheed ati Fathia pinya bii tọkọ taya, amọ ofin sẹsẹ pin wọn ka lọdun 2014 ni bi o tilẹ jẹ pe awọn mejeeji si n sisẹ papọ Oríṣun àwòrán, Saheed Balogun A wa n ki Saheed ati Fathia Balogun ku oriire ọjọ ibi wọn.
Ènìyàn lè kó kòkòrò àìlèfojúrí afàìsàn náà bí ó bá farakan ẹ ̀ jẹ ̀ tàbí àwọn omi ara ẹranko tó ní àrùn náà ( pàápàá jùlọ àwọn ọ ̀ bọ tàbí àwọn àdán ẹlẹ ́ nu gígùn pẹ ̀ lú ojú nlánlá ) .
Ṣugbọn kì í ṣe nípa òun nìkan ṣoṣo ni a kọ ọ́ pé a ka igbagbọ sí iṣẹ́ rere.
Ṣé o kò ní dáwọ́ ibinu rẹ dúró ni?
O ṣoju mi koro mii ti o ba awọn oniroyin sọrọ ṣe alaye wi pe ọlọkada ni awọn eeyan mẹrẹẹrin to padanu ẹmi wọn sinu ijamba naa.
Mose ka àwọn eniyan náà, ó sì yan iṣẹ́ fún olukuluku wọn gẹ́gẹ́ bí àṣẹ tí OLUWA pa fún un.
Tinubu - BBC News Yorùbá BBC News, YorùbáFò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Borno Zabarmani massacre: Ípànìyàn tó wáyé ní Borno fihàn pé omi n bẹ lámù fún ètò ààbò - Tinubu 1 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 3 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Ípànìyàn tó wáyé ní Borno lọ́jọ́ Sátidé fihàn pé omi n bẹ lámù fún ètò ààbò ní Naijiria - Tinubu Bí Boko Haram ṣe pa àwọn àgbẹ̀ ní Borno fihàn pé ọ̀rọ̀ ààbò Naijiria n fẹ́ akitiyan si - Bola Tinubu Oloye ẹgbẹ oṣelu All Progressives Congress, APC, Bola Tinubu ti sọ pe bi Boko Haram ṣe pa awọn agbẹ onirẹsi nipinlẹ Borno lọjọ Satide fihan pe igbogun ti awọn agbesunmọmi ṣi nilo akitiyan si ko to o le wa sopin.
Njẹ́ ẹni tó fẹ́ jẹ ọbẹ̀ ilá yíò kọ́kọ́ rẹ́’lá.
A Majẹkodunmi lati rọpo awọn adari ibẹ Lọdun 1963 ni wọn da Akintọla pada gẹgẹ bii olootu ijọba fẹkun iwọ oorun guusu Naijiria Akintọla bori ibo pada bii Olootu ijọba ẹkun iwọ oorun Naijiria lọdun 1965 gẹgẹ bii asaaju ẹgbẹ oselu NNDP, to ni ajọsepọ pẹlu NPC to n sejọba loke Akintọla jẹ eeyan to ni ẹbun agbekalẹ ọrọ sisọ, to jẹ ẹni to kọ ile ẹkọ fasiti Ile Ifẹ, taa mọ si fasiti Ọbafẹmi Awolọwọ pari lọdun 1962 gẹgẹ Olootu ijọba ẹkun iwọ oorun Naijiria O tun lọwọ ninu kikọ Ile Itura Premier atawọn ibudo miran, ti wọn si fi Ile ẹkọ fasiti Ladoke Akintọla to wa nilu Ogbomọsọ sọri rẹ Oloye Faderera Akintọla ni aya Samuel Ladoke, ti Ọlọrun si fi ọmọ marun ta wọn lọrẹ Samuel Ladoke Akintọla fi aye silẹ nigba ti awọn ologun to fẹ ditẹ gbajọba gbẹmi rẹ ninu ete iditẹ gbajọba akọkọ to waye ni Naijiria lọjọ Kẹẹdogun, osu Kinni ọdun 1966.
Wọ́n rí i níwọ̀n ogoji ọjọ́, ó sì ń bá wọn sọ̀rọ̀ nípa nǹkan tí ó jẹ mọ́ ti ìjọba Ọlọrun.
méjèèjì ni ó bófin mu nítorí méjèèjì ni a máa ń so nínú èdè yorùbá .
Natalia Mufutau ìyá Yakub, Kamil àti Adam sọ̀rọ̀ lórí bí wọ́n ń sọ èdè mẹ́rin pàpọ
Lẹ́yìn náà, ni mo ro gbogbo iṣẹ́ ọwọ́ mi, ati gbogbo làálàá mi lórí rẹ̀; sibẹ: mo wòye pé asán ati ìmúlẹ̀mófo ni gbogbo rẹ̀, kò sì sí èrè kankan láyé.
 Ó kalẹ ̀ sí agbègbè àwọn ará brazil , ní àárín èkò níbi tí ọrọ ̀ ajé ti ń lọ .
Asofin saraki tun so pe oun ni
Nítorí bí a ò bá ṣọ́ra, a óo dé ilé ẹjọ́ fún ìrúkèrúdò ọjọ́ òní, kò sì sí ohun tí a lè sọ pé ó fà á bí wọ́n bá bi wá.
Koda Duncan Mighty funra rẹ ṣalaye ninu ifọrọwanilẹnuwo kan pe ajọṣepọ yii lo ta julọ lẹyin Fake Love ti oun ṣe sẹyin.
Ajọ CAF ko fi alaye kankan sita lori isunsiwaju yii.
#BBCNigeria2019 Ìgbà tí Aisha Buhari ti f'ọ̀rọ̀ da ìgboro rú lórí ìjọba ọkọ rẹ̀ Ìṣẹ̀lẹ̀ Bakana: àwọn tórí kó yọ fẹ́ bẹ̀rẹ̀ ètò ìrànlọ́wọ́ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 2019 Elections: Èrò àwọn ọmọ Nàíjíríà se ọ̀tọ̀ọ̀tọ̀ lóri ètó àlùfáà tàbí ìmámù lásìkò ìbò Ọba Umar Faruk Umar: Lọwọlọwọ, oun ni Emir ilu Daura.
Ọ̀pọ̀ àwọn kan ní eré oritage ninu òṣèlú lásán ni nígbà ti àwọn míràn gbàgbọ́ pé èyí yóò lánà fún ìtàkurọsọ tí yóò ṣe ànfani lọ́jọ́ iwájú.
Hadi Sirika ti laa ni ẹṣẹẹsẹ, awọn igbesẹ ti awọn eniyan gbọdọ tẹlẹ ti wọn ba ṣe n de papakọ ofurufu: Ọ gbọdọ yẹra fun fifi ọwọ kan ohunkohun ni bẹ Awọn arinrinajọ gbọdọ yago fun awọn oṣiṣẹ papako ofurufu O ti gbọdọ de papakọ ni nkan bii wakati mẹta ki o tọ wọ ọkọ baalu nitori awọn eto ti o gbọdọ tẹle.
Ó tún àwọn ìlú olódi ṣe, wọ́n lágbára, níbẹ̀ ni ó fi àwọn olórí ogun sí, ó sì kó ọpọlọpọ oúnjẹ, epo ati ọtí waini pamọ́ sibẹ.
O ni ọmọbinrin naa nilo igbimọ alagbara ti yoo ja fun lati pada sile ẹkọ rẹ nitori ko nilo lati se alaye kankan fun ileewe rẹ lori bi fidio naa se jẹ.
O so pe, “ a ko ni jafara lati bere iyaselodi pada ti ijoba ba kuna lati fi adehun ifenuko wa se, tabi ti o ba fi adehun naa fale lona-kona”.
Egbe oselu ohun n reti ki Aare Zuma kowe fipo sile lonii, bi bee ko, ile-igbimo asofin yoo gbe igbese iyoni-nipo re.
Adetunji ati awon oloye igbimo olubadan ti won gbega si ipo oba niwon odun kan
Ní àkókò náà,OLUWA yóo fìyà jẹ àwọn ogun ọ̀run, lọ́run;ati àwọn ọba ayé, lórí ilẹ̀ ayé.
Àwọn alufaa ati àwọn ọmọ Lefi tí wọ́n wà ní gbogbo ilẹ̀ Israẹli sì fara mọ́ Rehoboamu.
House on water: Ǹjẹ́ ìwọ lè gbé ilé tó wà lórí omi?
 Ijoba ile Amerika gba pe won kii pin iranlowo naa daadaa sugbon ajo UNRWA ni inu won ko dun si igbese ijoba Trump yii nitori pe losu kejila odun 2017 ni ijoba ile Palestine ati Amerika si jo tow obo adehun tuntun fun iranlowo naa.
Ṣugbọn bí Kristi bá ń gbé inú yín, bí ara yín yóo tilẹ̀ kú nítorí ẹ̀ṣẹ̀, sibẹ ẹ̀mí yín yóo wà láàyè nítorí pé Ọlọrun ti da yín láre.
Baba yóo máa pa ọmọ wọn jẹ láàrin yín; ọmọ yóo sì máa pa àwọn baba jẹ.
Bí àwọn akọrin ń kọrin, n kò lè gbọ́ orin wọn mọ́.
Apapọ awọn to ti ni arun naa kaaakiri orilẹ-ede Naijiria ti wa di 12486 bayii.
Ìtàn míràn sọ fún wa pé ọmọ ìyá ni Agígírì àti Ajíbógun ni Ilé-Ifẹ̀.
Agbófinró mú ọkùnrin tó ń gun bààlu tó fẹ́ gbéra Ìyàwó mi fẹ́ràn ìrìnàjò òfurufú ni mo ṣe kọ́ ilé Bàálù yìí fún un Ọkọ̀ òfúrufú gbiná nítorí obìnrin tó ń fa Shisha!
Gẹ́gẹ́ bí ìròyìn tó tẹ wá lọ́wọ́, agádágodo ló wà ni gbogbo ẹnu ọ̀nà ilé ẹgbẹ́ náà l'Abuja.
Mú burẹdi kan, àkàrà dídùn kan pẹlu òróró, ati burẹdi pẹlẹbẹ láti inú agbọ̀n burẹdi tí kò ní ìwúkàrà ninu, tí ó wà níwájú OLUWA.
Iroyin so pe awon eniyan koti ikun si  ipe gomina Ayo Fayose ti o  pe lori  ero agbohunsafefe pe  ki won ma se jade kuro nile won lati lo ki aare kaabo.
A kò ní fi adé wa sílẹ̀ nítorí Olubadan - Àwọn Ọba 27 Arẹ́májà kò sí, Olubadan fi tìlù-tìfọn kí àwọn ìjòyè káàbọ̀ lẹ́yìn ọdún méjì Amotekun: Kí ni iṣẹ́ tí Amotekun yóò máa ṣe gangan?
O si lawọn ibi ti awọn oludije yoo ti gbegba oroke koda awọn ipinlẹ kan jẹ oju ina lasiko idibo yi.
Ilé ẹjọ lé Ọba Èrúwà kúrò lórí Àpèrè lẹ́yìn ọdun 21 Awọn ofin miran: Ma ṣe sare asapajude loju popo Ri i wi pe gbogbo awọn taya ọkọ rẹ jẹ eyi to dara to ṣi n ba oju titi ṣọrẹ lalaafia Ni ohun eelo taa fi n pa ina ninu ọkọ rẹ (fire extinguisher) Mọ wi pe ijọba ko gbe awọn ofin wọnyi kalẹ lati fi iya jẹ eeyan bi kii ṣe lati daabo bo ẹmi Ri wi pe o tẹle awọn ofin yi ki o ma ba ri ibinu awọn ajọ ẹsọ aabo oju popo iyẹn 'Federal Road Safety Commission (FRSC)' Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Wòólì Alfred kú lọ́dún 1964, ó tún padà wà sí ìlú Agelu f'ọ́jọ́ mẹ́rìnlá!
 Àwọn ọ ̀ nà tí a ń gbà pèsè nǹkan rírọ ti yàtò báyìí .
Mustapha ni ẹnu n ya oun lori bi ọpọ eeyan ṣe n sọrọ abuku nipa Abacha nitori pe asiko to gori oye, owo ti Naijiria ni nipamọ loke okun ko to biliọnu meji dọla rara.
Ronaldo tun rọjo goolu gẹgẹ bi iṣe rẹ pẹlu goolu mẹta nibi ifẹsẹwọnsẹ ẹgbẹ agbabọọlu Juventus pẹlu Cagliari ni liigi Serie A.
Alukoro fun ile-ise olopaa ni ipinle Sokoto ,DSP Cordelia Nwawe, lo soro yii lasiko to n ba awon akoroyin soro lojo Aje.
dọgbọn  lati maa gba owo lọwọ  rẹ.
9 Owewe 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 20 Owewe 2020 Oríṣun àwòrán, Google Ileeṣẹ ọlọpaa ni ipinlẹ Bauchi ti fi panpẹ ọlọpaa mu arakunrin ẹni aadọta ọdun, Bawada Audu fun ẹsun pe o sin ọmọ-ọmọ rẹ laaye.
Oríṣun àwòrán, @Dray4lyf Iwa ipani nipakupa naa n dakun wahala yii, ti ọpọ ẹya ko si ni igbẹkẹle mọ ninu orilẹede Naijiria.
Nítorí kò ní sọ ọ̀rọ̀ ti ara rẹ̀; gbogbo ohun tí ó bá gbọ́ ni yóo sọ.
Nígbà tí àwọn arakunrin Josẹfu rí i pé baba àwọn ti kú, wọ́n ní, “Ó ṣeéṣe kí Josẹfu kórìíra wa, kí ó sì gbẹ̀san gbogbo ibi tí a ti ṣe sí i.
Bakan naa ni ileeṣẹ ọlọpaa sọ ninu atẹjade naa to fi si oju opo Facebook rẹ pe awọn yoo tun ṣe iwadii ọhun to wa ninu fọnran naa boya ọlọpaa ni ni tootọọ tabi ọdaran to kan wọ aṣọ ọlọpaa lasan.
Ede aiyede bẹ silẹ laarin gomina Rotimi Akeredolu ati igbakeji rẹ, Agboola Ajayi lẹyin ti Ajayi yapa kuro ninu ẹgbẹ oṣelu APC lọ si ẹgbẹ oṣelu PDP.
"rainat komolafe jẹ oludari ati oludasilẹ "" babiesessence "" ."
Ẹ ti ya ara yín kúrò lọ́dọ̀ Kristi, ẹ̀yin tí ẹ̀ ń fẹ́ ìdáláre nípa òfin.
Ẹ̀kọ́ mẹ́jọ tó yẹ kí ilẹ̀ Afirika kọ́ lára àjàkálẹ̀ aàrùn coronavirus Ẹfunroye Tinubu - Ògbóǹtagí oníṣòwò, olówò ẹrú àti afọbajẹ Samuel Ajayi Crowther, òjíṣẹ́ Ọlọ́run tó gbé èdè Yoruba lárugẹ Mọrèmi Àjàṣorò, akọni obìnrin tó gba Ilé Ifẹ̀ sílẹ̀ lóko ẹrú Ọ̀rọ̀ǹpọ̀tọ̀niyùn, Aláàfin obìnrin àkọ́kọ́ rèé, tó ní nǹkan ọkùnrin Ṣé ìwọ mọ odò adágún Adó Àwáyè tí kò ní òpin ní ìsàlẹ̀?
 Awon bii: Ola Aina, Kenneth Omeruo, Wilfred Ndidi, Ahmed Musa ati Alex Iwobi wa lati iko agbaboolu Premier League nigba ti Odion Ighalo  gba fun Watford die ko to lo si Chinese Super League.
Àwọn àfojúsùn bẹ̀ ẹ́ sì maa n mú ègbè dání nígbà míràn, pàápàá àwọn ayédèrú ìtàkùn àgbáyé maa n ní àfojúsùn tí wọ́n n lépa.
Òtítọ́ ni mò ń sọ, n kò purọ́, pé ohun tí a yàn mí láti jẹ́ akéde ati aposteli sí ni pé kí n jẹ́ olùkọ́ni fún àwọn tí kì í ṣe Juu nípa nǹkan tí ó jẹ mọ́ igbagbọ ati òtítọ́ Ọlọrun.
Emefielel pe ki o tesiwaju gege bi adari ile ifowopamo ti ijoba apapo ati fifi
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ìkúnlẹ̀ ló bá dé fún Oshiomole, Ize-Iyamu láti bẹ̀bẹ̀ fún ìbò aráàlú ní Edo Sunday Igboho yari, o fohun ransẹ sawọn eeyan to n pẹgan rẹ Ikú Barakat Bello ní Akinyele gbé aláàánú pàdé ẹ́bí rẹ̀ A ṣe ọdún Ọ̀ṣun lásìkò yìí láti kó Coronavirus lọ ni - Ooni ṣàlàyé Wo àwọn nǹkan tí o kò mọ̀ nípa 'Church of Satan' Àwọn afurasí ajínigbé tó tan oníṣòwò jáde ní ṣọ́ọ́sì wọ gàù Ọlọpaa Ọdọọdún làwọn ọmọ ònilẹ̀ ń dà wá láàmú ní Soka, kí Sunday Igboho tó gbà wá sílẹ̀ - Àwọn olùgbé Soka Oríṣun àwòrán, Instagram/Sunday Igboho Awọn olugbe agbegbe Soka niluu Ibadan ṣe alaye fun ikọ BBC Yoruba wi pe, lati nnkan bii ọdun mẹta sẹyin ni wahala awọn ọmọ onilẹ ti n waye ni lemọlemọ ni adugbo naa ki o to di wi pe Sunday Igboho da sii lọdun yii.
Oríṣun àwòrán, Daily Trust Kí ni Amnesty International sọ?
Ọkunrin to n fọn iyarun bii fere naa ni, lati igba ti wọn ti ya iyarun naa si mimọ ninu ẹgbẹ akọrin nile ijọsin oun, ni ohun gbogbo ti yipada.
Èmi yóo ri òkúta ìpìlẹ̀ ilé kan mọ́lẹ̀ ní Sioni,yóo jẹ́ òkúta tí ó lágbára,òkúta igun ilé iyebíye, tí ó ní ìpìlẹ̀ tí ó dájú:Ẹnikẹ́ni tí ó bá gbà á gbọ́, ojú kò níí kán an.
oro re pe, ile-ise to n sagbekale eto lorisirisi nile ise aare ko ni salai ma
Lẹyin lo rọ awọn eeyan to n gbe lagbegbe ibi ti iṣẹlẹ naa ti waye lati fi to ileeṣẹ ọlọpaa leti nipa ohunkohun ti wọn ba mọ tabi ẹni ti wọn ba fura si lọna ati lee jẹ ki wọn pari iwadii naa lai fi akoko ṣofo.
O ni oun nbẹ ileẹjọ lati mase ya awọn nitori ọkọ oun ko fi igba kankan ka ọkunrin mọ mi lori.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Aisha Buhari: Ìjọba kò le è ṣe àmúṣẹ ìlérí rẹ̀ tó bá yan alátakò sípò 20 Òkùdu 2019 Oríṣun àwòrán, @aishmbuhari Yoruba ni bi ara ile ẹni ba n jẹ kokoro buruku, ti a ko ba tete sọ fun, hẹrẹ-huru rẹ ko ni jẹ ka sun lori.
"Ilé aṣọ̀fin Nàìjíríà ń gbèrò ẹ̀wọ̀n f'áwọn olùkọ̀ tó bá dẹnu ìfẹ́ kọ akẹ́kọ̀bìnrin Ìṣòro Nàíjíríà kọjá kí Bobrisky àtàwọn ẹlẹgbẹ́ rẹ̀ dá ní ilé ìgbọ̀nsẹ̀ lọ́tọ̀"" ""Èmi ò r'óhun tó burú kí obìnrin opó fẹ́ ọkọ míì sínú ilé ọkọ rẹ̀"" Efunjoke Coker: Abiyamọ́ tó ṣé atọna àwọn akẹ́kọ̀ọ́bìnrin Queens College 2."
‘Ẹ wò ó, ẹ̀yin ẹlẹ́gàn, kí ó yà yín lẹ́nu, kí ẹ sì parun!
Ninu ifọrọwerọ lori eto redio ọhun ni Obesere ti sọ pe oloogbe Sikiru Ayinde Barrister ati Alhaji Ayinla Kollington nikan lo jẹ baba fun oun ninu iṣẹ orin Fuji.
Alaga igbimọ ile aṣoju-ṣofin sọ pe eeyan bi ẹẹdẹgbẹta lo n ni arun coronavirus lojumọ nigba tawọn ileewe wa ni titi pa.
Ọrọ yi waye lataari ibugbamu afẹfẹ gaasi to ṣe akoba fun dukia ati ẹmi awọn eeyan ni adugbo Ajao Estate ni ilu Eko.
Ọdún meje ni wọn yóo fi dáná sun wọ́n.
Nígbà mìíràn ẹ̀wẹ̀, ẹ dúró láì yẹsẹ̀ pẹlu àwọn tí wọ́n ti jẹ irú ìyà bẹ́ẹ̀.
Gbogbo iyoku, iriri ni mo ka wọn si.
Ọmọ ọdun mọkandinlogun ni ọmọbìnrin naa ti iṣẹlẹ yii ṣẹlẹ si.
Sọ fún wọn pé,‘Ta ni ó lẹ́wà jùlọ?
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Kò sí Nnamdi Kanu nílùú wa o - Ìjọba Israel Irọ́ ni pé Shonekan ti re'bi àgbà á rè Fayẹmi ni ipadàbọ̀ òun kìí ṣe láti gbẹ̀san Awọn agbẹjọro rẹ beere fun ore ọfẹ ile ẹjọ naa lati lee gba oniduro rẹ ẹyin ti wọn ni awọn ti kọwe ẹbẹ fun gbigba oniduro rẹ ranṣẹ siwaju ile ẹjọ naa ṣaaju ni ọjọ ẹti.
Awon olootu lorile-ede Naijriia ti pe ajo to n mojuto eto idibo lorile-ede Naijiria Independent National Electoral Commission (INEC), lati fi ooto ati iwa ododo siwaju ise won, papaa julo ninu eto idibo gbogbogbo to n bo lona lọdun 2019.
Ohun tawọn olutaja n sọ ni pe awọn ko tilẹ ri irẹsi ti wọn n gbin ni Naijiria ra, eyi jẹ ko nira lati mọ iye ti wọn ta gan an.
" Ni ọrọ Alex Thurston to jẹ ajọgbọn ims nipa oṣelu ati ọrọ ẹsin ni fasiti Miami ni Ohio.
tubo maa fọwọsowọpọ pẹlu awọn ọba , awon olori 
Ọ̀rọ̀ náà dun Mose, ibinu OLUWA sì ru sí àwọn eniyan náà.
Nítorí n kò lè bẹ́ láti orí òkè gíga sí ilẹ̀, bí mo bá ṣe èyínì àti apá àti ẹsẹ̀ mi ni yóò yún wómúwómú.
Mo ni Sir, botilẹ jẹ pe ẹ ko sọ fun wa ẹni to n gbọ bukaata yin, ko jẹ ki n pari ibeere mi, to fi han mi pọnkan."
Ifẹsẹwọnsẹ to kangun si aṣekagba keji laarin ẹgbẹ agbabọọlu England ati Croatia ti yoo waye l'Ọjọru.
Ṣé o láyà: Ẹ̀ gbọ́ orúkọ míràn wo ni Yoruba ń pe àṣáró?
Ese ṣalaye ninu ọrọ kan to kọ sori Instagram nigba naa pe D'banj fi ẹgbẹrun lna igba Naira lọ ọrẹ oun lati ba lopọ, ṣugbọn ó kọ̀.
Láti inú ẹ̀yà Nafutali, a yan Pedaheli ọmọ Amihudu.
 Igbese sisanwo yii je eyi ti a je ko han kedere si awon eniyan.
Oríṣun àwòrán, PAPILO Àkọlé àwòrán, Ǹjẹ́ o mọ ǹkan wọ̀nyíi nípa Kanu Nnwankwo?
Ẹbọ ohun jíjẹ tí ẹ óo máa rú pẹlu wọn ni ìyẹ̀fun tí a fi òróró pò: ìdámẹ́wàá lọ́nà mẹta òṣùnwọ̀n efa fún akọ mààlúù kan, ati ìdámárùn-ún òṣùnwọ̀n efa fún àgbò kan, 
Coronavirus updates: Wo àwọn oníròyìn méje tó kú láàrin ọjọ́ méje ní Nàìjíríà
Lara awọn to ti bẹrẹ si n kii ni ajọ to n ri si ọrọ awọn ọmọ naijiria nilẹ okeere, NIDCOM.
O ni o di igba ti iwe aṣẹ ijọba, 'whitepaper' ba jade ki ẹnikẹni to lee sọ ohun gan ti aarẹ fẹ lori rẹ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Fulani Kidnapping: Owó púpọ̀ la san kí wọ́n tó fi mi sílẹ̀ Lẹyin to ki alagba Rueben Faṣọranti tan ni Igbakeji aarẹ Yẹmi Oṣinbajo to kọwọrin lọ sibẹ pẹlu gomina Rotimi Akeredolu ti ipinlẹ Ondo.
82 ati ipinle Katsina ti won n san N70.
Ninu oro tire, alaga egbe awon agba osise lorilede
OLUWA ní, “Tó bá di ìgbà náà, ojora yóo mú ọba ati àwọn ìjòyè, àwọn alufaa yóo dààmú, ẹnu yóo ya àwọn wolii.
Awọn miran gba pe ọjọ pinpin ẹbun fun awọn alaini, opo ati awọn ẹbi ni.
Àkọlé àwòrán, Inu ọpọ ọdọ lo ti n dun si igbesẹ ipinlẹ Oyo yii O ni pe: Laise ani-ani, ile igbimọ asofin ipinle Ọyọ ti gba orukọ Fakorede gẹgẹ bi okan laran awọn ti yoo di kọmiṣọna ni Ọ́yọ.
Kiko awọn ẹsọ alaabo kuro lẹyin gomina Fayose saaju ki awọn agbofinro to taku si ẹnu ọna ile ijọba eyi to fidi rẹ mulẹ pe wọn n dete lati gbẹmi Fayose, ti wọn too si ni ibọn seesi baa ni.
Nigba to n ba BBC Yoruba sọrọ lẹyin ijoko ile, Asofin Gbenga Omole, tii se alaga igbimọ ile feto iroyin kede pe ile ko tii gba irufẹ iwe ikede bẹẹ.
ni  igboya pe, pelu gbogbo awon eniyan to
awon adajo agba mẹ́rìndínlógójì lo wa
Atẹjade kan ti ajọ to n ri si igbogun ti ajakalẹ arun lorilẹede Naijiria, NCDC fi sita loju opo Twitter rẹ ṣalaye pe, ọgọrin ninu awọn eeyan naa wa ni ipinlẹ Eko, mejidinlogoji wa lati ilu Kano.
A lè fi ò̀we Yorùbá “Bi Ọdẹ bá ro ìṣẹ́ ro ìyà inú igbó, ti ó bá pa ẹran kòní fẹ́nì kan jẹ” wé ìyá ti àwọn ti ó wà ni Ìlúọba/Ò̀kèòkun njẹ nínú òtútù lati pa owó.
"Wabba ni ""A ti joko jiroro lori ọrọ to nii se pẹlu owo osu, amọ a pinnu nibi ipade naa lati sun ijiroro naa siwaju di ọjọ Aje, ka to lee fi ẹnu ọrọ jona nipa aawọ to wa nilẹ."
Bi ẹ bá sì rántí, ọjọ́ Ajé, ọjọ́ kẹrin, oṣù karùn-ún ni ìjọba Naijiria tún kéde pé, òun rí owó tó lè díẹ̀ ni mílíọ̀nù lọ́nà okoolelọọdunrun ó dín mẹsan an dọla ($311,797,866m) miran gbà padà láti orílẹ̀-èdè Amẹ́ríkà, Eyi jẹ nínú owó ilẹ wá ti olórí ìjọba ológun náà fi ọ̀nà aitọ kó lọ sókè òkun.
Ogbeni Okechukwu Enelamah  to ka ase meji ninu awon ase naa to tun je minista fun okowo ati ile ise nlanla ni iran tijoba Buhari n wo lookan ni lati sun orile-ede Naijiria sunmo oke ninu awon ogun akoko ni agbaye.
Kí ni a óo fi san án fun yín?
Yahaya Jammeh: Obìnrin mẹ́ta ọ̀tọ̀ọ̀tọ̀ fẹ̀ṣùn ìfipábánilòpọ̀ kan ààrẹ Gambia
Ọpẹ́ ló yẹ ki èniyàn dá ju igbèsè ji jẹ lati ṣe àṣe hàn ni àsikò ọdún.
Ó bá ní kí òun parí ìjà fún wọn.
Oríṣun àwòrán, Facebook/Lawrence Oyor Lawrence lee sọ ede mẹta - Gẹẹsi, Yoruba ati Ibibio-Efik.
Ní orí òkè yìí ènìà á rí ibìkan tí àwọn àgbẹ̀ ilú nrọ́ imíi màlúù sí.
 Òrìṣà kilima tàbí noro ni wọ ́ n ń bọ gẹ ́ gẹ ́ bí ẹlẹ ́ dàá , wọn a sì máa bọ ara náà .
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Oun pẹlu igbakeji rẹ, Patrick Kluivert ni wọn jijọ n fi ipo silẹ bayii.
Ìbéèrè yìí ò sòro dáhùn o.
N ò tilẹ̀ le sọ bí mo ti ṣe kúrò ní pálọ̀ wa ní ọjọ́ náà.
O mẹnuba ipa pataki ti ajọ LASTMA ko lati jẹ ki oun riran pada lẹyin iṣẹlẹ yii to ja si pabo.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ohun tó burú ni ‘Dìbò ko sebẹ̀’, ìyà ló bá de - Olùdíje ANRP Ọbasanjọ kọ́ ni yóò sọ ibi tí Yorùbá yóò dìbò sí ní 2019 - Falọmọ Èyí ni àwọn ọ̀nà tí o fi lé mú ọpọlọ ọmọ rẹ̀ jì pépé Kí ni àyájọ́ ‘Má wọ kọ́mú’ wà fún?
Awọn eleto aabo - Ojuṣe awọn to wa ni ẹka yii ni lati daabo bo ile ijọin, awọn oṣiṣẹ ati awọn olujọsin ati dukia wọn, lọwọ ole, ati awọn iṣẹlẹ buruku miran.
Ẹ̀yin ọ̀gá, bákan náà ni kí ẹ máa ṣe sí àwọn ẹrú yín.
Dejo Tunfulu Dejo Tunfulu ti ke si ijọba apapọ lati fọwọsowọpọ pẹlu awọn oṣere tiata ni Naijiria ki nnkan le ṣenu ire fun wọn.
"Lakọkọ naa, lati kekere ni mo ti maa n la ala pe emi naa yoo ni ile itaja rẹkọọdu temi.
Aare  Hery Rajaonarimampianina,so pe  leyin ijiroro ni awon fenuko lati  yan ijoba ti gbogbo awon ti oro kan naa yoo wa nibe.
“Ẹ má ṣe rò pé mo wá pa Òfin Mose ati ọ̀rọ̀ àwọn wolii run ni.
 Bi a se nse ajọyọ yii, o se pataki ki awọn baba ati asiwaju wa gbogbo maa ranti lati rii pe awọn iya, iyawo ati awọn obinrin lapapọ n gba iyi to yẹ lai naani ipo tabi aaye ti wọn ba ara wọn."
PPRV : Eyi ni iwe ti orukọ awọn ti o ti se
Awọn kan gba pe iwọde to ṣẹlẹ lasiko ijọba Morsi yi lo buru ju lẹyin ti Hosni Mubarak to ṣẹlẹ lọdun 2011.
asiko yii kan naa ni awọn ara Ibadan tun dide ogun ti Ogedengbe si gba lati jẹ Balogun Ijeṣa ati Ekiti lati koju ilu Ibadan.
Lizzy Anjorin sun ẹkún ìyàwó, èèyàn kan fún un lẹ́bùn aṣọ funfun láti mọ ìbálé rẹ̀ Wo bí ètò ìdìbò abẹ́lé ẹgbẹ́ òṣẹ́lú PDP ṣe ń lọ ní ìlú Akure Pásítọ̀ ìjọ Sotitobire padà yọjú sílé ẹjọ́ lónìí, àbọ̀o rèé.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Children's Day: Èwe ni ọjọ́ ìwájú ìran ènìyàn-Adeyeye Enitan Ogunwusi 27 Èbibi 2019 Àkọlé àwòrán, Kabiesi Ojaja 11 sami ayẹyẹ ayajọ àwọn ewe pẹlu àrà Ooni Adeyeye Enitan Ogunwusi Ojaja II gbalejo awọn ewe kaakiri ile iwe ni Ile Ife ati agbegbe rẹ.
Ìró ààrá ń kéde bíbọ̀ rẹ̀,àwọn ẹran ọ̀sìn sì mọ̀ pé ó súnmọ́ tòsí.
Nítorí pé Fẹstu ń wá ojurere àwọn Juu, ó bi Paulu pé, “Ṣé o óo kálọ sí Jerusalẹmu, kí n dá ẹjọ́ yìí níbẹ̀?
Ẹni tí ó bá ń bẹ̀rù kò ì tíì di pípé ninu ìfẹ́.
 tí wọ ́ n bá ti ń lu ìlù báyìí , àgbà Ọ ̀ jẹ ̀ kan yóò máa mú ọ ̀ kọ ̀ ọ ̀ kan nínú pàṣán yẹn , yóò.
Ogagun  Bulama Biu,adele oga agba fun iko omo ogun
Alága ẹgbẹ́ APC ní ìpínlẹ̀ Ogun, Olóyè Derin Adebiyi tó bá BBC sọ̀rọ̀ ní nkan bii aago mọ́kànlá òwúrọ̀ ọjọ́ Àìkú tó yẹ kí ìdìbò nàá wáyé, sọ pé àwọn kò tìí rí àwọn èròjà ìdìbò gbà láti olú ilé ẹgbẹ́ nàá tó wà ní ìlú Abuja.
Ṣùgbọ́n, ìwọ, ọmọ ènìyàn, ni ó wà lẹ́mìí mi.
Mo wá di ẹni yẹ̀yẹ́lọ́dọ̀ gbogbo eniyan,ẹni tí wọ́n fi ń kọrin tọ̀sán-tòru.
Bẹ́ẹ̀ ni wọ́n ṣe mú ìròyìn burúkú wá nípa ilẹ̀ tí wọ́n lọ wò.
Lampard ni aṣeyọri awọn ko ṣẹyin agbabọọlu tuntun, Ben Chilwell ti wọn ra fun miliọnu marundinlaadọta pọun.
Aṣọ otutu Kurt Cobain di aṣọ to wọn julọ ni gbogbo agbaye nigba ti wọn taa ni ẹgbẹrun mẹrinlelọgbọn o le ni ọọdunrun owo dọla ilẹ Amerika ni eyi to jẹ miliọnu mọkanlelọgọfa naira o le ni ẹgbẹrun irinwo naira.
Bóò ṣe lè yẹra fún ikú nígbà òjò - Onímọ̀ Ehi Iden Kò sí àyè fún fíìmù eré ìfẹ ṣíṣe ni Kannywood mọ́ Aisha Buhari ké gbàjare pé ètò ìjọba Buhari kò ṣànfàní f'óbìrin NBC fọwọ́ sí ìdásílẹ̀ ilé iṣẹ́ Fulani Radio Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Bode George: òòtọ́ ni ìkìlọ̀ Obasanjọ ati Soyinka Miliọnu mẹwaa Naira ni mọlẹbi Muazu san ki wọn o to tu wọn silẹ.
Laipẹ yii ni awọn iwe iroyin abẹle kan gbee pe iwe ijsba kan wa ti adari eto abo lorilẹede Naijiria, Babagana Monguno ti n fi ẹsun kan Abba Kyari pe o ṣe ayọjuran lọna to lewu si ọrọ eto abo orilẹede Naijiria.
Kí wọn má ṣe di irun wọn ní aláràbarà fún àṣehàn.
Wo àwọn ohun márùn ún tó yẹ kí o mọ̀ nípa Sanusi Èyí ni àwọn ìdí tí ìjọba ìpínlẹ̀ Kano ṣe rọ Emir Sanusi Lamido l'óyè Ipade oṣelu Nilẹ Amẹrika, Sẹnatọ Bernie Sanders ati igbakeji aarẹ tẹlẹ, Jospeh Biden naa sun ipolongo idibo sipo aarẹ to yẹ ko waye lọjọ Kẹwa Oṣu Kẹta ọdun yii ni Ohio siwaju latari ibẹru arun Coronavirus.
Kaka ki Liverpool gba liigi, wọn ko ni kọ ki Man City gba amọ ki eleyi to le ṣẹlẹ wọn yoo fara gba idojuti ki Man City bori wọn.
Ọmọ Hemani, aríran ọba, ni gbogbo wọn, gẹ́gẹ́ bí ìlérí tí Ọlọrun ṣe láti gbé Hemani ga; Ọlọrun fún un ní ọmọkunrin mẹrinla ati ọmọbinrin mẹta.
 Àjèjì náà fi yé wọ ́ n pé Ògbòrògánńdá-ajogun ni orúkọ òun .
Ṣugbọn ẹ̀mí tí ó wà ninu eniyan,tíí ṣe èémí Olodumare,ni ó ń fún eniyan ní ìmọ̀.
"Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Mama Arsenal: Màmá àgbà yìí máa ń lọ sí ìbùdó tí wọ́n ti ń wo bọ́ọ́lù láti wòran Nigba to n ba ileeṣẹ iroyin Spanish TV sọrọ lẹyin ifẹṣwọnsẹ ọhun, Messi sọ pe ""Esi ti a ri kọ la lero pe a o ri, ẹgbẹ agbabọọlu wa ko lagbara to."
Ní ọjọ́ kẹjọ, yóo kó wọn tọ alufaa wá ní ẹnu ọ̀nà Àgọ́ Àjọ, níwájú OLUWA fún ìwẹ̀nùmọ́ rẹ̀.
"Oluwatoyin jẹ ko di mimọ wi pe ""ko si nkan ti ẹda alaye le da ẹ duro fun lati di nkan ti o fẹ di, bi o ba ṣaa ti le gbadura""."
À ń retí ìdájọ́ òdodo, ṣugbọn kò sí;à ń retí ìgbàlà, ṣugbọn ó jìnnà sí wa.
Ẹgbẹgbẹ̀rún ọmọ Naijiria ní yóò má a kú lójoojúmọ́ tí wọn bá gbà wọ́n láàyè láti gbébọn dání- Amofin Ṣé ìrànwọ̀ ni Kamala, ìgbákejì tí Biden yàn yóò jẹ́ fún un tàbí ìpalára?
Muhammadu Buhari (APC) tabi Atiku Abubakar (PDP)TANI IWỌ ROBI YOO JAWE OLUBORI NINU ETO IDIBO AARẸ TI YOO WAYE NI  ỌLA  YII(ọjọ Abamẹta)Muhammadu Buhari (APC) tabi Atiku Abubakar (PDP).
Èmi OLUWA ni mo sọ bẹ́ẹ̀, n óo sì mú un ṣẹ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Coronavirus in Oyo: Ìjọba ní gbogbo ìpéjọpọ̀ tí kò bá tẹ̀lé òfin ìdènà àrùn ni òun yóò tìpa 8 Bélú 2020 Oríṣun àwòrán, @seyiamakinde Ijọba ipinlẹ ti gbe ilẹkun ileẹkọ giga kan tipa nitori ajakalẹ arun Coronavirus to suyọ nibẹ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù EndSARS Protest Update: Ọwọ́ pálábá àwọn tó fọ́ ShopRite fún ìgbà kejì ségi 18 Ọ̀wàrà 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 24 Ọ̀wàrà 2020 Awọn janduku to kọlu ile itaja ShopRite ladugbo Fate, ni ilu Ilorin ko fi ti isede ti ijọba kede ṣe, eyi to bẹrẹ lọjọ Abamẹta.
ipinle Akwa Ibom,ti so fun awon akoroyin niluu Uyo pe bi egbe oselu APC se fe
Oríṣun àwòrán, AFP Àkọlé àwòrán, Lọpọ igba ni Iran ti bu ẹnu atẹ lu igbiyanju aarẹ Trump lati se adehun tuntun Bakan naa, olori orilẹede Germany, Angela Merkel, yoo se abẹwo si ilẹ Amerika ni Ọjọbọ ọsẹ yii, lati jiroro pẹlu Aarẹ Trump, lati mase fagile adehun ti wọn se pẹlu Iran.
Ẹ jẹ́ n mẹ́nu kúro ní bẹ̀un jàre.
Nítorí bí a ti ní ẹ̀yà ara pupọ ninu ara kan, tí gbogbo àwọn ẹ̀yà ara wọnyi kì í sìí ṣe iṣẹ́ kan náà, 
Gbọ́ ohùn ẹ̀bẹ̀ mi,bí mo ti ń kígbe sí ọ pé kí o ràn mí lọ́wọ́;tí mo gbé ọwọ́ mi sókèsí ìhà ilé mímọ́ rẹ.
Wo àdéhùn méje tí Buhari ṣe pẹ̀lú ilẹ̀ Russia Ìlé ẹjọ́ ti pàṣẹ pé kí ilé iṣẹ́ ọ̀lọ́pàá dá ìgbaniwolé dúró Ohun mẹ́wàá tó yẹ kóo mọ̀ nípa Kunle Afod Ninu oṣu karun ọdun 2019 ni ajọ to n ri si iwa jẹgudujẹra lorilẹede Naijiria, EFCC gbe Naira Marley atawọn mẹrin mii, Zlatan Ibile, Rahmon Jago, Guccy Branch ati eeyan kan.
"Ìbọn ba èèyàn wa kan lórí bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé a ń gbàdúrà pé kó máà kú.
Ó fi ìwà àgàbàgedè dé ipò gíga, ó dé ipò gíga tán kò jẹ́ kí ọwọ́ àwọn èrò ẹ̀hìn gòkè, bẹ́ẹ̀ ni ìrìra ni ó jẹ́ níwájú Olódùmarè ìwà ẹ̀gbin sì ni níwájú àwọn ẹ̀dá ọ̀run, wí pé, kí ẹni tí ó dé ibi gíga máa wá ọ̀nà ìdíwọ́ fún àwọn tí ń bọ̀ lẹ́hìn, bẹ́ẹ̀ ni ọkùnrin náà gbàgbé ará ayé, ó gbàgbé ará ọ̀run, ó sì tún gbàgbé Ọlọ́run Ọba.
Year end: Gbogbo ènìyàn ló wọ agbádá ikú, ẹni tó kàn lẹnìkan kò mọ̀
 ""Ẹmi ifọkansin ti mo si ni fun ere bọọlu ṣi wa sibẹ, atilẹyin fun awọn akẹẹgbẹ mi ninu igbimọ oludari ko ni i dinku."
Abike ṣalaye pe, ọkunrin naa yoo jẹjọ lẹyin tawọn ọlọpaa ti fi panpẹ ofin mu un.
Àwọn yìí nìkan ni wọ́n kọlà ninu àwọn alábàáṣiṣẹ́ mi ninu iṣẹ́ ìjọba Ọlọrun.
Ọpọ igba lo ti wa lara awọn oludije ti BBNaijia fẹ le lọle, ṣugbọn awọn olukopa bii Prince ati Ozo lo lọ dipo rẹ.
Ẹ ṣọ́ra nígbà tí ẹ bá gbé ojú yín sókè sí ojú ọ̀run, tí ẹ bá rí oòrùn, òṣùpá, ati àwọn ìràwọ̀, ati ogunlọ́gọ̀ àwọn ohun tí ó wà ní ojú ọ̀run, kí ọkàn yín má baà fà sí wọn, kí ẹ sì máa bọ àwọn ohun tí OLUWA Ọlọrun yín fún gbogbo eniyan láyé.
Ohunkohun tí ẹ bá ń ṣe, ẹ ṣe é tọkàntọkàn, bí ẹni pé Oluwa ni ẹ̀ ń ṣe é fún, kì í ṣe fún eniyan, 
Shittu Adebayọ to jẹ m,inista fun etp ibararaẹnisọrọ lati ipinlẹ Oyo naa ko ba a.
Jesu wí fún un pé, kí ó máa lọ sí ilé rẹ̀, kí ó má ṣe wọ inú abúlé lọ.
Àkọlé àwòrán, Wákàtí àwẹ̀ káàkiri àgbáyé Àgbègbè àwẹ̀ ọlọjọgbòòrò Ki a kọkọ fi ìbéèrè ṣọwọ́ pe ṣe ẹ mọ ìbí ti wọn n pé ní Greenland?
Gomina Fayemi, ẹni to kede bẹẹ lasiko to n kopa lori eto BBC Yoruba kan, wa ṣẹ lori ahesọ ọrọ to n ja rainrain nilẹ pe oun fẹ du ipo aarẹ lodun 2023, ni oun ṣe n ṣe kokari eto Amotekun.
O Fagunwa; Ǹkankan máa ń darí wọn lọ ibi tí a kò mọ̀ 22 Ọ̀wàrà 2018 A bí i ní ìlú Oke Igbo, ìpínlẹ̀ Ondo ní ọdún 1903.
“Ohun tí o óo máa fi rú ẹbọ lórí pẹpẹ lojoojumọ ni: ọ̀dọ́ aguntan meji, tí ó jẹ́ ọlọ́dún kan.
Nígbà tí Naamani gbọ́, ó sọ ohun tí ọmọbinrin náà sọ fún ọba.
Àwọn tó wà nínú ìjàmbá ọkọ̀ órí afára Otedola ń lọ ìpínlẹ̀ míì láti Eko ni - LASTMA 'Ìbọn dún láàfin Ọ̀ọ̀ni ilé ifẹ̀ lóòtọ́, ṣùgbọ́n kò séwù' Àwọn tó wà nínú ìjàmbá ọkọ̀ órí afára Otedola ń lọ ìpínlẹ̀ míì láti Eko ni - LASTMA Àwọn ìbejì Akeugbagold kò le rìn dáadáa mọ́ lẹ́yìn tí wọ́n dáwọn padà Awọn awada ori ayelujara ti ọpọ oṣere tiata ṣe lọsẹ yii : Femi Adebayo di agba aafa onilawani: Oríṣun àwòrán, femi adebayo Femi Adebayo, ti awọn eeyan kan tun n pe ni Jelili oniso, lo di agba aafa musulumi loju opo Instagram rẹ lọsẹ yii, bo si ṣe n ṣe waasi, naa lo n da orin waka lati kilọ iwa.
'Kò tọ̀ọ́ kí olórí Nàìjíríà tó bá ní coronavirus gba ìtọ́jú ní ìlú tí kìí ṣe tirẹ̀' Èyí ni bí gómìnà Babajide SanwoOlu ti ìpínlẹ̀ Eko ṣe kó COVID-19 Ìjọba ìpínlẹ̀ Kaduna gbé iléèwé tì pa nítorí ọ̀wọ́ kejì àjàkálẹ̀ COVID-19 Coronavirus: ''Ìjọba kò tíì pàṣẹ ìlànà ìtakété-síra-ẹni padà nínú BRT la ò ṣe máa tẹ̀le'' Onidajọ Saulawa sọ pe ilu Dubai, ni orilẹ-ede United Arab Emirate, ni Tanko Muhammad wa, to ti n gba itọju.
orile ede Naijiria fun saa keji .
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fọ́nrán ohùn, Iparọwa si gbogbo awọn tọrọ naa kan lati ri wipe aba ofin naa mulẹ lorilẹede Naijiria Nigba ti ajakalẹ arun bẹ silẹ ni London ni ọdun 1665, wọn ni ki awọn ọmọ wẹwẹ maa fa taba ni ile iwe.
Nígbà tí wọ́n súnmọ́ Jebusi, ilẹ̀ ti ń ṣú lọ, iranṣẹ rẹ̀ sọ fún un pé, “Jẹ́ kí á dúró ní ìlú àwọn ará Jebusi yìí kí á sì sùn níbẹ̀ lónìí.
Ǹjẹ́ o tilẹ̀ mọ Samuel Okwaraji, agbábọ́ọ̀lù Nàìjíríà tó 'ṣubú lójú ìjà?
Iṣẹ awọn oṣiṣẹ ọba to yẹ ko waye ni ọna kan ti n waye lọna pupọ, nitori bi wọn ṣe n da awọn ẹka ileesẹ ati lajọ-lajọ ti ojuse wọn jọra silẹ, eyi ti ko tun jẹ ki iṣẹ awọn oṣiṣẹ ọba pegede si.
"O tẹsiwaju pe ""Bi mo ti se wa nile yi, o fun mi laanfaani lati mu asiko isinmi mi ni koko yatọ si ti mo ba wa ni ibisẹ'' Bakan naa wiwa nile a maa mu ki awọn eeyan mi maa sare lati pari isẹ ti wọn n se, awọn eleyi ti wọn yan fun ara wọn ati isẹ ile lẹẹkan naa."
He was committed to improving humankind through the fairness, kindness, optimism and intelligence he brought to bear on all his undertakings, and through the righteousness, humanness and harmony he promoted in the US as a human rights activist and indeed across the world.
Ìjọba ìpínlẹ̀ Eko ti bẹ̀rẹ̀ àtúnkọ́ ilé tí ẹlikọ́pútà tó jábọ́ bàjẹ́ ní ìlú Eko Ọmọ Nàìjíríà, àfikún owó iná tuntun bẹ̀rẹ̀ lónìí: ọjọ́ kínní, oṣù kẹsàn án, ọdún 2020- NERC, Disco Ọwá Ale Ikarẹ, Oba Adegbite-Adedoyin papòdà lẹ́ni ọdún márùndínláàdọ́rùn ún!
Owó nàá pọ̀ kọjá bó ṣeyẹ láti fi kọ́ ìlé alájà mẹ́wàá Ilé alájà mẹ́wàá ọ̀hún tó wà ní ìlú Abuja, ni ìrètí wà pé Ààrẹ Muhammadu Buhari yóò ṣí lọ́jọ́ kẹẹ̀dógún, oṣù Karùn ún.
Kikọ lati ṣe eré ìdárayá niwọn ti o yẹ fun agọ ara ati lasiko to yẹ.
Ẹnikẹ́ni tí ó bá jẹ òkú ẹran náà níláti fọ aṣọ rẹ̀, yóo sì jẹ́ aláìmọ́ títí di ìrọ̀lẹ́.
Yatọ ti ti awọn ileeṣẹ aladani, ijọba paapaa yoo ṣe atungbeyẹwo awọn akanṣe iṣẹ, eyi to le mu ki awọn eeyan kan padanu iṣẹ wọn.
Ẹwẹ, lorukọ awọn ẹgbẹ mi ninu Ile Igbimọ Aṣofin Ipinlẹ Eko, mo ki gbogbo yin pe ẹ ku Ayajọ Ijọba Oṣelu Tiwantiwa yii.
Ṣugbọn Absalomu sá lọ sọ́dọ̀ Talimai, ọmọ Amihudu, ọba Geṣuri, Dafidi sì ń ṣọ̀fọ̀ ọmọ rẹ̀ lojoojumọ.
Mo gbé e fún àwọn ọ̀rẹ̀ mi, a jọ kà á, mo sì bẹ̀rẹ̀ sí í ṣe oríṣìíríṣì ìbéèrè.
agbaboolu odo Naijiria, tojo ori won ko ju ogun odun lo, Flying Eagles ti
Ọjọgbọn Dikirulahi Adewale Yagboyaju, tii ṣe olukọ agba ni ẹka imọ eto oselu ni ile ẹkọ giga fasiti Ibadan, lo sọ ọrọ yi ninu ifọrọwerọ rẹ pẹlu BBC Yoruba.
Fatai Mojeed, ẹni tii ṣe alaga igbimọ naa sọ ninu ifọrọwerọ rẹ pẹlu BBC pe, iwadii ti wọn n ṣe nipa bi Ambode ṣe na owo lori awọn ọkọ akero naa jẹ ojuṣe awọn aṣofin ipinlẹ Eko.
 Ìyá rè jé sofia khatun .
Jonatani dáhùn pé, “Ohun tí baba mi ṣe sí àwọn eniyan wọnyi kò dára, wò ó bí ojú mi ti wálẹ̀ nígbà tí mo lá oyin díẹ̀.
"Ọ̀sẹ̀ yìí ni orúkọ àwọn mínísítà yóò tẹ̀ wá lọ́wọ́ - Ilé aṣòfin àgbà Ìgbín ní èmi àti ìyá mi máa ń he kiri, ká tó lee jẹun - Lizzy Anjọrin Ìjọba mi ṣetán láti mú àgbéga bá ètò ààbò l‘Ọyọ - Seyi Makinde Ṣugbọn ni bayii, ""maa rii daju pe mo foju balẹ ki n le ri imu"", eyi tumọ si pe awọn ti aarẹ mọ daadaa ni yoo yan lati ba a ṣiṣẹ."
Ṣugbọn lọpọ igba, awọn obinrin naa maa n gori itẹ baba wọn gẹgẹ bi adele titi ti awọn afọbajẹ yoo fi yan ẹni ti ade tọ si.
 Adura wa ni pe,emi wa to bere re layo yoo pari re layo ati alaafia, emi wa yoo si se opolopo re laye.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Kini Pásítọ̀ Kumuyi fi ṣẹ ọmọ Naijiria?
 orin yìí ni ó jẹ ́ orin àkọ ́ kọ ́ tí obìnrin yóò kó jáde lédè yorùbá tí ó sì tà iye tí ó lé ní mílíọ ́ nù kan ní ilẹ ̀ nàìjíríà .
1 288 Erekusu Saint Lucia 2 1.
Komisona fun ifitonileti, Ogbeni Charles Udoh ni won yoo pin milionu meedogun din ni oodunrin naira fun awon egbe alajeseku ki won fi seto ogbin naa nigba ti won yoo lo owo to ku fun ise inu siso gbaguda naa di ohun jije bii gaari, fufu atawon nkan miran.
Èmi náà ni mo sì máa ń sọ òfin Ọlọrun, ati àwọn ìpinnu rẹ̀ fún wọn.
 Àwọn méjèèjì ni ó kó ipa mọyàmí nínú mímú ẹ ̀ yà orin yìí di ìlúmọ ̀ ọ ́ ká , ó sì yàtọ ̀ sí , ó dàgbà ju , ó sì nira káká láti mọ ̀ ju fújì lọ .
Awọn obi rẹ gbiyanju titi wọn ṣa ipa wọn, wọn gbe e kaakiri fun ayẹwo ati itọju.
8 657 Orilẹede Brunei 3 0.
Ààrẹ Buhari sún eré ìdárayá àpapọ̀ Edo 2020 síwájú Paul Pogba gbé ètò owó dídá kalẹ̀ fún ààrùn Coronavirus Ighalo d'àràbà!
Ohun kan tí a sá fẹ́ ni pé kí ẹ jẹ́ kí á kọjá.
Wọ́n n ta ikán ní mèlemèle.
Mo bu ọlọ́pàá jẹ nígbà tó fẹ́ yí mi lọ́rùn ní Mushin- Àáfà Fatai Àwọn jàndùkú kọlu Ọba Eko àti Gomina ìpínlẹ̀ Edo lọ́nà ilé Oshiomole Àwọn orílẹ̀-èdè tí ààrẹ Buhari ti lọ láàrin ọdún márun Ileeṣẹ ọlọpaa lawọn ti doola awọn ọmọ naa bayi ti awọn si rọ ẹni to ba mọ obi awọn ọmọ naa lati kan si agọ Ọlọpaa.
Àwọn igi eléso rẹ yóo máa so jìnwìnnì ní ilẹ̀ tí OLUWA Ọlọrun rẹ búra fún àwọn baba rẹ, pé òun yóo fún ọ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Trump kò yẹ láti jẹ́ ààrẹ- Adarí FBI tẹ́lẹ̀rí 16 Ìgbé 2018 Oríṣun àwòrán, AFP Àkọlé àwòrán, Comey ní ẹnití wọ́n bá pè ní ààrẹ gbọdọ̀ máa bọ̀wọ̀ fún àwọn èèyàn Olùdarí àgbà tẹ́lẹ̀ fún iléeṣẹ́ ọ̀tẹlẹ̀múyẹ́ ní orílẹ̀èdè Amẹ́ríkà (FBI), James Comey ní, Donald Trump kò ní ìwà tó yẹ láti jẹ́ ààrẹ nítorí ó máa ń ṣe àwọn obìnrin bíi ekìrí ẹran.
Àwọn iròyin tì ẹ leè nífẹ̀ síí: SERAP fẹ́ pe UI, AAUA lẹ́jọ́ lórí àfikún owó iléẹ̀kọ́ Ní Àwòrán: Ìsìnkú Winnie Mandela Bùhárí sọ ìdí tó fi ń díje lẹ́ẹ̀kejì Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 3 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 5 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ko si ẹni ti ogo ko le kan ninu ami ẹyẹ gbigba Van Dijk ló ti jé akọni pataki ni Liverpool lati igba to ti kuro ni Southampton nibi ti wọn ti bori Champions League ni saa to lọ.
Nítorí náà, gẹ́gẹ́ bí àṣẹ OLUWA, àwọn ọmọ Israẹli fún àwọn ọmọ Lefi ní àwọn ìlú ati pápá tí ó yí wọn ká, ninu ilẹ̀ ìní wọn.
''Ṣùgbọ́n nkan ẹyọkan tí ẹbí mi n bá mi sọ ni ìgbà tí màá ṣe ìgbéyàwó - òhun ló ṣe pàtàkì jù ní ìlú tí mo ti wá ní Uganda - ìgbà tí màá bímọ ló sì tẹ le.
Oríṣun àwòrán, Instagram Oríṣun àwòrán, Twitter Eyi ni akojọpọ ohun mẹfa to le fa ki wọn wọgile oju opo Instagram, Twitter ati Facebook; Ninu osu keje ọdún 2019 ni ile iṣẹnaa gbe awọn fin yii jade pe ẹnikẹni to ba lugbadi rẹ yoo geka abamọ jẹ.
“Ẹ ka ìsinmi ọdún keje keje yìí lọ́nà meje, kí ọdún keje náà fi jẹ́ ọdún mọkandinlaadọta.
Apapọ ibo mẹrinlelọgọrun ni oun nikan ni, ninu ibo mẹrinlelọgọjọ ti awọn aṣoju di.
" MKO Abiola, iṣẹ́ aṣẹ́gità ló fi bẹ̀rẹ̀ okoòwò Iṣọla Oyenusi rèé, ẹnití ìfẹ́ obìnrin ṣun dé ìwà ìdigunjalè Taiwo Akinkunmi, ọmọ Ibadan tó ya àsìá Naijiria Ayinla Ọmọwura, orin èébú àti oríyìn lo fi di ọ̀rẹ́ àwọ̀n obìnrin Ohun ti aṣiwaju ẹsin Shiite naa n sọ fun araye bayi ni pe, awọn osiṣẹ alaabo ti ilẹ yii ati orilẹede India ko faye gba a lati ri awọn dokita rẹ.
Al Mustapha lasiko to n kopa lori eto kan ni ikanni BBC Hausa salaye pe olootọ ilu, ni ika ilu ni ọrọ Sani Abacha, kii sì ṣe ẹni abuku rara nitori ọpọ aṣeyọri to ṣe.
May 27: Nàìjíríà se Àyájọ́ ọjọ́ àwọn èwe
Huramu gbọ́n, ó lóye, ó sì mọ bí a tíí fi idẹ ṣe oríṣìíríṣìí iṣẹ́ ọnà.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Kí ìjọ mi ní Sagamu le gbòòrò ni mo fi ń ṣiṣẹ́ ajínigbé pawó - Pásítọ̀ Àwa àti fijilanté pẹ̀lú ọdẹ́ ìbílẹ̀ ló dojú kọ adigunjalè ní First Bank Okeho - Iléeṣẹ́ ọlọ́pàá Ìtàn ọba Yorùbá tí wọn yẹgi fún torí ó jí ọmọ gbé ṣe ètùtù Ẹ káàbọ̀ sọ́jọ́ Arafat, tí Ọlọ́run yóò fi ààwẹ̀ Mùsùlùmí pa ẹ̀ṣẹ̀ wọn rẹ́ Ọmọ mi kò tíì mọ̀ pé òun ti di ìlúmọ̀ọ́ká, ó ń wádìí bó ṣe ń rí ara rẹ̀ lórí ayélujára"" Boko Haram da ìbọn bo ọkọ̀ gómìnà Borno, ẹ̀ṣọ́ àláàbò rẹ̀ farapa Ni Ọjọbọ ni iroyin gbe e pe, awọn eniyan tun pejọ pọ si banki naa lasiko ti awọn ọlọpaa wa ṣe ayẹwo sibẹ, lati mọ iru ijamba to waye nibẹ."
Ninu iye awon eniyan ti won foruko sile ohun, awon akanda eniyan ti iye won n lo bi irinwo,350 ni won yoo gbe esi idanwo tiwon jade laipe, bakan naa won yoo seto idanwo fun awon akekoo lati ile okere ninu osu kerin odun ti a wa yii.
O salaye pe aṣẹ ile ẹjọ ni Aarẹ tele lati yọ Onnoghen nipo ti ko si ni nkankan ṣe pẹlu lilo agbara.
Bi oloselu ba gbe igba ibo, abẹ ilana yiii ni yoo fi gbe eto ati erongba isejọba rẹ kalẹ.
Ṣebí bákan náà ni Rahabu aṣẹ́wó gba ìdáláre nípa iṣẹ́, nígbà tí ó ṣe àwọn amí ní àlejò, tí ó jẹ́ kí wọ́n bá ọ̀nà mìíràn pada lọ?
OLUWA bá rọ òjò imí ọjọ́ ati iná láti ọ̀run wá sórí Sodomu ati Gomora, 
7 151142 Orilẹede Libya 1651 24.
Ẹni to bori: Morocco Tanzania vs Uganda.
Bí ó bá jẹ́ ọmọ oṣù kan sí ọmọ ọdún marun-un, tí ó sì jẹ́ ọkunrin, yóo san ìwọ̀n ṣekeli fadaka marun-un, bí ó bá jẹ́ obinrin, yóo san ìwọ̀n ṣekeli fadaka mẹta.
 “Orile-ede yii ti la orisirisi idojuko koja, eleyi ti won gbero lati wo ipile isokan wa, sugbon pelu atileyin Olorun a maa n bori nigbogbo igba ni.
Inu BBC si dun pe a ni anfani lati ni ajọsepọ to dan mọran pẹlu awọn ọdọ latari igbesẹ yi'' Ọga agba ẹka ẹrọ ayelujara fun MTN, Srinivas Rao ni: ''Iwuri ni ibasepọ yi jẹ fun MTN ati pe ọna kan gboogi tawọn ọdọ Naijiria yoo maa fi ri iroyin to peye si lo jẹ'' Ninu ọrọ tirẹ, Kolawole Oyeyemi to jẹ oludari eto to n risi igbadun onibara MTN sọ pe: ''Igbesẹ yi n safihan iru igbadun to gaju lọ ti awọn onibara wa yoo ma ri bi wọn ba ti lo My MTN App'' Mary Lusiba to jẹ olori ẹka idagbasoke eto karakata ileesẹ BBC World Service ni tirẹ sapejuwe ibasepọ yi gẹgẹ bi eleyi ti yoo ''jẹ ki awọn ọdọ mọ si i nipa BBC.
Iṣẹlẹ manigabgbe yii lo waye ni dede ago mejila oru ọjọ kinni, oṣu Keji ọdun 2020.
4 72 Orilẹede Montserrat 1 20.
APC ní yóò jáwe olúbori ni Bayelsa ati Kogi- Tinubu Yahaya Bello lẹ́ẹ̀kan síi ni APC ṣe ní ìdìbò abẹ́lé ní Kogi Sẹ́nétọ̀ Dino Melaye kéde láti dupò gómìnà Kogi Wike kìí ṣe dọ́là tí Ganduje leè kó sápò- Agbẹ́nuso ìjọba ìpínlẹ Rivers Oludije mẹtala ni yoo kopa ninu idibo abẹle naa ti a si ri ninu wọn gomina nigba kan ri nipinlẹ Kogi, Ibrahim Wada ati gbajugbaja oloṣelu Sẹnẹtọ Dino Melaye.
Bakan ni Amofin Mohammed Fawehinmi naa yi i mọ.
“Ẹ kò gbọdọ̀ ṣèrú nígbà tí ẹ bá ń wọn nǹkan fún eniyan, kì báà jẹ́ ohun tí a fi ọ̀pá wọ̀n, tabi ohun tí a fi òṣùnwọ̀n wọ̀n, tabi ohun tí a kà, 
Bola Tinubu, ẹni to foju han ninu atẹjade kan to fisita pe o n se atilẹyin fun eto Amotekun, wa fikun pe agbekalẹ eto naa ko dunkoko rara mọ ifẹsẹmulẹ orilẹede Naijiria.
Ase yii tun tapa si ojuse ti ofin la sile fun awọn  ijọba meteeta.
Efunjoke Coker: Abiyamọ́ tó ṣé atọna àwọn akẹ́kọ̀ọ́bìnrin Queens College Sanusi Adebisi Idikan rèé, olówó tó ń san owó orí fún gbogbo ọkunrin ilẹ̀ Ibadan Wo ìdí to fi gbọdọ̀ yàgò fún Bobrisky, akọ tó ń ṣe bíi abo Gbèsè niye èèyàn tó pọ̀ ní Nàìjíríà kìí ṣe dúkìá- Emir Sanusi Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
SEC: Tinubu kò gbọdọ̀ ṣe olúdarí iléeṣẹ kankan fódùn márùn ún Sẹ́nétọ̀ Dino Melaye kéde láti dupò gómìnà Kogi Amẹ́ríkà ń béèrè ìròyìn facebook, email arìnrìnàjò tó f'ẹ́ gbà'wé àṣẹ Ilé wó pa Jide, ọmọ ọdún mọ́kànlá, l'Oṣogbo Ọpọ awọn ọmọ ẹgbẹ oṣelu naa ni ko ṣebi ẹni dunnu si bi awọn adari ẹgbẹ oṣelu naa ṣe mu ọrọ naa.
Yemi My Lover: Ìdí rèé tí orin kíkọ fi máa ń pò nínú sinimá mi.
Ó rán mànàmáná rẹ̀ sí wọn jákèjádò ojú ọ̀run,títí dé òpin ilẹ̀ ayé.
Ọjọ́ ìjìyà tí àwọn wolii wọn kéde ti dé; ìdàrúdàpọ̀ wọn sì ti kù sí dẹ̀dẹ̀.
N óo da yín dúró lẹ́nu iṣẹ́ olùṣọ́-aguntan, ẹ kò sì ní rí ààyè bọ́ ara yín mọ́.
igbakeji aare naa bale , ni opolopo awon eniyan jade sita lati agbegbe naa lati
Olórí ẹ̀yà Nafutali sì ni Ahira ọmọ Enani.
Ìpele ikọ̀ mẹrindinlogun Congo DR vs Kenya.
ti ipinle  Kebbi , Gomina  Simon Lalong ti ipinle Plateau  ati awon osise ile ise eto ogbin ati
Ohun tí ẹ̀ ń rí, tí ẹ sì ń gbọ́ nìyí.
Peteru bi í pé, “Oluwa, kí ló dé tí n kò lè tẹ̀lé ọ nisinsinyii?
Sakiu bá dìde dúró, ó sọ fún Oluwa pé, “N óo pín ààbọ̀ ohun tí mo ní fún àwọn talaka.
tí mo pa láṣẹ fún àwọn baba ńlá yín, gbé!
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Coronavirus: Gbogbo igbá ti ṣófo láwọn ilé ìtajà káàkiri London Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
N óo bi àwọn eniyan burúkú ṣubú; n óo pa eniyan run lórí ilẹ̀.
"Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Caracas, Venezuela Venezuela jẹ orilẹede to jẹ wi pe lati ọdun 1948 lo ti wọ ijọba ologun, koko ọrọ aatẹle wọn si ni ""a o tẹsiwaju bi a ba n kọ ile""."
 láàrin ìgbà tí ẹnìkan kó àìsàn náà sí àkókò tí yóò farahàn máa n tó bí i ọ ̀ ṣ ̀ ẹ ̀ méjì sí mẹ ́ fà .
Amugbalẹgbẹ fun alaga ajọ INEC lori eto iroyin, Rotimi Oyekanmi fi idi rẹ mulẹ fun ileeṣẹ iroyin abẹle kan lorilẹede Naijiria pe lootọ ni iṣẹlẹ naa waye.
Amọ, idẹyẹsini ti o maa n waye si awọn to ba ni iru ipenija yii kii jẹ ki wọn le ke gbajare sita tabi ki wọn lọ si ileewosan fun itọju.
Ṣaaju ni Obaseki fi ẹgbẹ oṣelu APC silẹ lọ si ẹgbẹ PDP lẹyin ti o fidi rẹmi ninu idibo abẹle fun ipo gomina ẹgbẹ oṣelu APC.
Bo ba se n lọ, a mu to ẹyin akọroyin leti.
Bakan naa ni wọn beere fun aye lati rin lati agbeegbe kan si omiran yatọ si ipinlẹ Kano titi ti ileẹjọ yoo fi gbọ ẹjọ wọn.
Mọrèmi Àjàṣorò, akọni obìnrin tó gba Ilé Ifẹ̀ sílẹ̀ lóko ẹrú Ta ni Funmilayọ Ransome-Kuti?
BBC 100 Women ati BBC Monitoring ṣe iwadi nipa awọn obinrin ti ọrọ iṣekupani wọn yi kan.
com/BxkHQYpx30C L I N I C A L 🎯🏆 #UEL pic.
Sugbọn Sẹnetọ Melaye ti ni ti adajọ ni o n sọ, oun yoo pe ejọ kotẹmilọrun.
O ni yiyan isẹ fun onikaluku se pataki bẹẹ si ni o yẹ ki eeyan maa nasẹ sita lẹẹkọọkan naa se pataki.
Nigba ti aṣoju BBC ṣe abẹwo si ileeṣẹ panapana ni ilu Akwa, ti ko jina si ibi ti iṣẹlẹ naa ti ṣẹ, o ni gbogbo awọn oṣiṣe ileeṣẹ ọhun ti fẹsẹ fẹẹ nitori ibẹru awọn ọdọ ilu ti wọn sọ pe wọn fẹ se ikọlu si wọn.
Fun Dokita Ogunfunmilayọ, ayọ yii pẹ pupọ fun un nitori o pe ọmọ ọdun mẹtadinlaadọrin, 67 ki o to rọmọ bi.
Ipinlẹ Kwara: Oríṣun àwòrán, @TheLonerMan Àkọlé àwòrán, Ilorin Orita Challenge ni awọn oluwọde End SARS fi ipade wọn si ni ilu Ilorin, bakan naa ni wọn tun gbe iwọde naa de Tanke Tipper Garage, ki wọn to fi abọ si ile ijọba ipinlẹ ọhun.
N ó sa ipá mi fún ọ, n ó sa ipá mi fún ọkọ rẹ, n ó si múra gidi, ó yá, ẹ jẹ́ kí á máa lọ.
Wọn kò mọ nǹkan, bẹ́ẹ̀ ni òye kò yé wọn.
Ayọ̀ ni ìwà òmùgọ̀ jẹ́ fún aláìgbọ́n,ṣugbọn ẹni tí ó ní òye a máa rìn ní ọ̀nà ẹ̀tọ́.
Kanga naa ṣi wa nilu Daura titi di oni, wọn si n pọn omi ninu rẹ.
Orilẹede Croatia lo ṣepo keji ninu idije ife ẹyẹ agbaye naa, nigba ti France jawe olubori.
Tariqul, ọkọ iyawo to jẹ ọmọ ọdun metadinlọgbọn sọ fun BBC pe lẹyin igbesẹ akin iyawo oun ni awọn ẹbi mejeeji pada wa fi tọwọtẹsẹ si igbeyawo awọn mejeeji.
Nípa igbagbọ, Abrahamu ní agbára láti bímọ, bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé Sara yàgàn, ó sì ti dàgbà kọjá ọmọ bíbí, Abrahamu gbà pé ẹni tí ó ṣèlérí tó gbẹ́kẹ̀lé.
Iléẹjọ́ ní kí Yakubu lọ gé oko àgọ́ ọlọ́pàá fọ́jọ́ méjì lẹ́yìn tó jí fóònù N8,700 Ẹ yé parọ́ kiri!
Ortom ni eto ẹkọ gbọdọ peleke si, ki awọn eniyan, paapaa ọdọ ba le kẹkọ nipa ọna bi o ṣe yẹ ki eniyan ma a wuwa ni awujọ.
”Nigba ti o n tẹnu mọ pataki Ile Igbimọ Aṣofin ninu iṣakoso ijọba tiwantiwa, Aṣofin Ọbasa rọ ẹka Amuṣẹṣe Ijọba lati tubọ fẹsẹ ẹka yii mulẹ lati maa ṣe ojụṣe to yẹ, ki ibaṣepọ to dan mọran le wa, ko ma baa si aigbora ẹni ye laarin ilu.
Sẹnetọ Gbemisola Saraki ti ni oun yoo rii daju pe oludije labẹ ẹgbẹ oṣelu APC fun ipo gomina nipinlẹ Kwara ni yoo jawe olubori ninu idibo ọjọ kẹsan an, oṣu kẹta, ọdun 2019.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Oba Adedokun Abolarin ti Oke Ila: Ó ya ọ̀pọ̀ tó súnmọ́ mi lẹ́nu bí mo ṣe ń kọ́ Araalu ko ni le dokoowo daadaa - Idi ni pe ibẹru ko ni jẹ ki awọn ileeọẹ gbe awọn igbesẹ kan lati gba awọn oludokoowo.
Wọn ni awọn iku ọhun ki ba mati waye, ṣugbọn ko si awọn ti yoo ṣetọju awọn ọhun ni, fun apẹrẹ, alaboyun to nilo iṣẹ abẹ.
Tí a fiṣọwọ́ ní 11:15 10 Ọ̀pẹ̀ 202011:15 10 Ọ̀pẹ̀ 2020 Ọlọ́pàá tún yìnbọn pa awakọ̀ Márúwá, ìwọ́de gba Portharcourt kan Agbẹnusọ fun ileesẹ ọlọpaa nipinlẹ Rivers ni wọn ti mu ọlọpaa ti aje iwa ika ọhun si mọ lori, ti iwadii si ti bẹrẹ nipa isẹlẹ naa.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Bishop Oyedepo: Ifedayo Olarinde tó ń jẹ́ Daddy Freeze tọrọ àforíjì pé o sọ ọ̀rọ̀ ẹ̀gbin sí David Oyedepo 7 Owewe 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 13 Owewe 2020 Oríṣun àwòrán, Others Oludari ẹgbẹ Free the Sheeple Movement ati Free Nation in Christ, Ifedayo Olarinde, ti awọn ololufẹ rẹ tun mọ si DaddyFreeze, sọ pe oun tọrọ aforiji lori ọrọ kan ti oun sọ si oludasilẹ ijọ Living Faith Church (Winner's Chapel), Biṣọpu David Oyedepo.
Ojogbon  Gbemiga Adewale ti pe fun alekun isuna eto
Lẹsẹkẹsẹ ó ní kí àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ wọ ọkọ̀ ojú omi, kí wọn ṣiwaju rẹ̀ lọ sí òdìkejì òkun ní agbègbè Bẹtisaida.
Nínú àwọn orílẹ̀-èdè yìí, bíi Burundi ti Nàìjíríà kọ́kọ́ bá gbá, Mauritanian àti Madagascar ń kópà ninu ìdíje AFCON fún ìgbà àkọ́kọ́.
Opo n lero pe o ṣeeṣe ki Van Dijk gbegba oroke mọ Messi ati Ronaldo lara lọdun yii.
Ọ̀pọ̀ àwọn òsèré tíátà, tí wọn jẹ́ akẹẹgbẹ́ rẹ̀ ni wọ́n ń se ìdárò ikú ìlúmọ̀ọ́ká òsèrè tíátá obìnrin náà láwọn ojú òpó ìkànsíra ẹni wọn lórí ìtàkùn àgbáyé Facebook àti Instagram.
O tun seese ki iran Yoruba ma lee gbagbe Afọnja nitori ipa to ko nilu Ilọrin ati awọn isẹlẹ to sẹlẹ nibẹ eyi to si n ja rainrain nilẹ titi di asiko ta wa yii.
Òun náà se oúnjẹ aládùn, ó gbé e tọ baba rẹ̀ wá, ó wí fún un pé, “Baba mi, dìde, kí o jẹ ninu ẹran tí èmi ọmọ rẹ pa, kí o lè súre fún mi.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù South Africa Election: Ẹgbẹ́ òsèlú 50 ló ń kópa nínú ìdìbò 8 Èbibi 2019 Àkọlé àwòrán, Ààrẹ Cyril Ramophosa láti ẹgbẹ́ òsèlú ANC náà ń díje dupò láàárín orísirísi ẹ̀sùn ìwà àjẹbánu nínú ẹgbẹ́ òsèlú náà.
nànì, nání, bi ọmọ ọdẹ ṣe n nání apó, ti ọmọ aṣẹgita n naaani epo igi naa lo ṣe yẹ ki awọn ijọba Naijiria naani odo adagun Ado Awaye yii.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, nnnnnn Ọlọpaa ni agbegbe naa ni awọn ẹbi ati awọn ara naa ko ri sabuke iwe eri pe o ti ju jade.
Jesu ń sọ ninu ẹ̀kọ́ rẹ̀ pé, “Ẹ ṣọ́ra fún àwọn amòfin tí wọ́n fẹ́ràn ati máa wọ agbádá ńlá káàkiri òde, kí eniyan máa kí wọn ní ọjà, ati láti gba ìjókòó pataki ní ilé ìpàdé.
Olisa Metu: Ilé ẹjọ́ rán Olisa Metuh sẹ́wọ̀n ọdún méje
Super Eagles fi iyọ̀ sójú Seychelles pẹ̀lú àmì ayò 3-1 Agbábọ́ọ́lù Sunderland nígbà kan rí jáde lẹ́wọ̀n lẹ́yin ọdún mẹ́ta Òṣìṣẹ́ Inec Ọ̀jọ̀gbọ́n Tuluen fara gbọta ní Benue A kẹ̀yìn sí Atiku torí àtúntò Nàíjíríà tó fẹ́ ṣe - Árẹ̀wá Leah Sharibu ni wòlíì wa ní àgọ́ Boko Haram - Obìnrin tó jàjàbọ́ Ikọ agbabọọlu Amuneke lo ṣepo keji ni isọri 'L' ti ẹgbẹ agbabọọlu Cranes of Uganda si ṣe ipo kinni.
Gbogbo awọn ọmọ to wa laarin Olori Abibat ni wọn n se daadaa, ti wọn si ti laami laaka ninu isẹ ti wọn yan laayo.
Cameroun: Awọn sọja tu mi sihoho-obinrin to satipo
A kò mọ ohun tí a lè ṣe, ìwọ ni a gbójú sókè tí à ń wò.
Labani sọ ibẹ̀ ní Jegari Sahaduta, ṣugbọn Jakọbu pè é ní Galeedi.
Bí ó ti ń fúnrúgbìn, àwọn irúgbìn kan bọ́ sẹ́bàá ọ̀nà.
Ti o ba yege bọ si ipele keji eto igbani sisẹ naa, o o nilo lati tẹ (print) imeeli ti wọn fi ránṣẹ si ọ pe o ti bọ si ipele keji.
Idi si ree ti ọpọ obinrin kii ṣe jafara pẹlu awọn eroja ti wọn fi n ṣe nnkan osu wọn, bi o tilẹ jẹ pe eyi lee ni nnkan ṣe pẹlu iwa imototo.
to soju aare Buhari, ninu ipade apero naa so pe ipade naa waye lasiko ti o da
Ní òru ọjọ́ náà, OLUWA sọ fún Gideoni pé, “Mú akọ mààlúù baba rẹ ati akọ mààlúù mìíràn tí ó jẹ́ ọlọ́dún meje, wó pẹpẹ oriṣa Baali baba rẹ lulẹ̀, kí o sì gé ère oriṣa Aṣera tí ó wà lẹ́gbẹ̀ẹ́ rẹ̀.
Elon Musk ti goke lori atẹ awọn eeyan to lowo ju lagbaye.
Man United vs Tottenham: Tottenham ya aṣọ iyì mọ́ Manchester United lára nírọ̀lẹ́ ọ̀jọ́ ìsinmi
 Àyájọ hepataitisi l ' ágbàáyé máa n wáyé ní ọjọ ́ kejìdínlọ ́ gbọ ̀ n oṣù keje lọ ́ dọọdún láti ṣí àwọn ènìyàn létí sí kòkòrò-àrùn hepataitisi .
Abẹ́ tí wọ́n dá fún mí kò jẹ kí ìbálòpọ̀ wùnmi Bí àbá yìí bá di òfin tan, ẹ̀yin olùkọ́ tó bá bá àkẹ́kọ̀ọ́ lòpọ̀ rugi oyin Fásítì Babcock lé akẹ́kọ̀ọ́bìnrin tó hàn nínú fídíò ìbálòpọ̀ lọ sílé Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Africa Eye: Olùkọ́ méjì ní fásitì Eko àti Ghana lùgbàdì ọ̀fíntótó BBC lórí ìwà ìbàjẹ́ Ṣaaju ni awọn onimọ kan sọ pe ọmọ bibi yoo pọ lọdun 2021, nitori pe ofin konile-o-gble ti mu ki ọpọ tọkọ-taya o wa papọ.
Ẹ ṣá má ti ṣe oríkunkun sí OLUWA, tabi kí ẹ sọ gbogbo wa di olóríkunkun nípa títẹ́ pẹpẹ mìíràn, yàtọ̀ sí pẹpẹ OLUWA Ọlọrun wa.
Ọgbẹni Tunde Shamsudeen to jẹ amugbalẹgbẹ rẹ ṣalaye pe oloogbe Ogunjobi lọ si ile iwosan lọjọ Abamẹta ki awọn dokita to ni ko lọ sinmi.
Adájọ́ Ijeoma Ojukwu, lásìkò tó ń gbé àṣẹ náà kalẹ tun kéde pé, owó ìlú ni Ojerinde fi kó àwọn dúkìá náà jọ, èyí tíì ṣe ere tó rí láti ara ìwà ajẹbanu tó lòdì sofin.
”Jesu wí fún un pé, “Èmi náà kò dá ọ lẹ́bi.
 lẹ ́ hìn ọdun kan , ènìyàn yóòní ìgbóná ara nígbà tí òbí aràn bá fa ọgbẹ ́ sí àwọ ̀ , pàápàá lábẹ ́ ẹsẹ ̀ .
Buhari ti fi edun okan re han lori iku igbakeji aare awon olootu akoroyin
Jean Mensa ni alaga ajọ eleto idibo naa to ṣe kookari eto idibo ọhun ni ọjọ aje , ọjọ keje, oṣu kejila ọdun 2020.
Amọ riro ni ti eniyan, sise ni ti Ọlọrun, lẹyin ti ọmọ yii kuna lati ni maaki tileẹkọ naa n beere fun lori imọ isẹ to fẹ se, ni baba ọmọdebinrin naa ba tọ Baruwa lọ.
Ṣé kò sí ìwọ̀ra ní Gileadi ni?
Igba meji lo ti ṣegbeyawo Oríṣun àwòrán, CHRISTOPHE SIMON Àkọlé àwòrán, Chantal Biya Aarẹ Biya ti fi igba kan jẹ́ ọmọ ile ẹkọṣẹ alufaa Katoliiki, ko to di pe o fẹ iyawo rẹ akọkọ, ti ko bimọ fun un.
Ṣugbọn àwọn ọmọ Manase kò lè gba àwọn ìlú náà, àwọn ará Kenaani sì ń gbé ilẹ̀ náà.
Ṣe Micheal Jackson a tun ma jẹ Mukaila Ajasin?
Oríṣun àwòrán, Getty Images Ija naa gan an kii ṣe ti Ruiz.
Nígbà tí Jesu jókòó ní orí Òkè Olifi, tí ó dojú kọ Tẹmpili, Peteru, Jakọbu, Johanu ati Anderu bi í níkọ̀kọ̀ pé, 
Ṣe a le sọ pe eyi n fidi rẹ mulẹ pe lootọ ni awọn oloṣelu n lo janduku ṣaaju, lasiko ati lẹyin eto idibo?
re ati ile-igbimo asofin lojuna ati dekun fifale ofin ati ilana ti o ba romo ile-ise
Eagles  yoo maa koju akegbe won lati
Minista abele fun ile ise ijoba apapo to n mojuto eto ilera, Onisegun oyinbo Osagie Ehanire lo so eyi  di mimo nilu Abuja lasiko ti won n sami ayajo odun isegun ibile nile Adulawo.
 nathan , o koko je biburafun ni september 1 , 1999 .
Kí á máa gbé ìgbé-ayé òdodo, kí á sì jẹ́ olùfọkànsìn ní ayé yìí.
Ẹni to bori: South Africa Nigeria vs Morocco.
Nibi abẹwo ti Babatunde Fasola ṣe yii lo ti paṣẹ pe o to gẹẹ fun awọn ọkọ agbepo ati ọkọ akẹru to n duro si opopona marosẹ yii ni eyi to n fa sunkẹrẹ-fakẹrẹ ọkọ.
Ẹkẹfa sì ni Itireamu, ọmọ Egila.
O kere tan awon eniyan ti iye won to edegbeta ni won padanu-emi won nigba ti oko nla kan bu gbamu nilu Mogadishu ti n se olu ilu orile-ede naa.
Ẹ̀ṣọ́ NSCDC ṣèèṣì yìnbọ̀n pa ọlọ́pàá ọ̀tẹlẹ̀múyẹ́ DSS l'Osun Yoruba wo ló fẹ́ gbé Oduduwa Republic tẹ́ n pariwo?
34,120 akẹ́ẹ̀kọ́ ni kò ní èsì ìdańwò JAMB Ilé ẹjọ́ ní kí Gómìnà Ganduje ṣe mẹ̀dọ̀ lórí ọ̀rọ̀ Emir Kano 'Àwọn kọ́ńsítébù t'ílé iṣẹ́ ọlọ́pàá fẹ́ gbà kò ní gbébọn' Awọn eniyan to wa ni ibi ti awujale ti sọ ọrọ yii fi atẹwọ yẹ ọba naa si.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Aarẹ Buhari ṣ'eleri ati pese iṣẹ fun ọpọlọpọ 9 Ẹrẹ̀nà 2018 Oríṣun àwòrán, @BashirAhmaad Àkọlé àwòrán, Aarẹ Buhari ṣ'eleri iṣẹ fun ọpọlọpọ Aarẹ Muhammadu Buhari ni ijọba ṣetan ati tẹpẹlẹmo akiyantiyan lori pipese iṣẹ fun awọn ọdọ ọmọ orilẹede Naijiria.
Òfin ìfipábánilòpọ̀ tuntun yóò fààye gba fífi kẹ́míkà tẹ ọkùnrin lọ́dàá Ẹwẹ, ko ye ni pato ewo ninu gbogbo idi ti aarẹ Buhari ka ti wọn fi ti awọn ibode ọhun pa ti o wa gbagbọ pe o ti wa si imuṣẹ tori awọn mii n sọ pe erongba ti aabo ko yọri si rere.
Wọn óo jẹ́ ìtẹ́wọ́gbà lórí pẹpẹ mi,ilé mi lógo, ṣugbọn n óo tún ṣe é lógo sí i.
Yato si iṣẹ oṣere, Mercy tun n ta awọn ohun ẹsọ ara gbogbo.
Awọn oludije ọhun ni Ife Oyedele, Jimi Odimayo.
Mo lọ sí yàrá èmi àti ẹ̀gbọ́n mi.
Yóo jẹ́ àmì ìrántí fun yín níwájú Ọlọrun yín.
Awọn ọkọ olomi yoo lee ṣiṣẹ laarin agogo mẹfa aarọ si mẹfa irọlẹgbogbo awọn ile ijo,, ilee sinima ati ibudo igbafẹ etiokun gbogbo ni yoo ṣi wa ni titi pa gbọingbọin.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Yemi Elebuibon: Babaláwo èké kò le è kii ẹsẹ mẹ́rin nínú odù ifá 10 Agẹmo 2019 Oríṣun àwòrán, Ile-ifa.
Ní ọjọ́ náà, wọ́n kà ninu ìwé Mose sí etígbọ̀ọ́ àwọn eniyan, ibẹ̀ sì ni a ti rí i kà pé àwọn ará Amoni ati àwọn ọmọ Moabu kò gbọdọ̀ wọ àwùjọ àwọn eniyan Ọlọrun, 
" Minisita tun sọ pe awọn n gbeero lati fin oogun apakokoro si awọn ileewe ṣaaju iwọle pada.
Eto adura ko tun waye lọdun 2013.
Gbogbo ẹ̀ á wá tutù nini.
ogun lorisirisi ni nile eko ikoni-nija iko omo ogun “Army Special Forces school”,
Ẹ yẹ ara yín wò bí ẹ bá ń gbé ìgbé-ayé ti igbagbọ.
27 Bélú 2020 Ọkùnrin kan dèrò ẹ̀wọ̀n lẹ́yìn tó jí súùtì àti àwọ̀tẹ́lẹ̀ ọkùnrin nílé ìtàjà ìgbàlódé Abuja27 Bélú 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
pẹlu àwọn ìlú ati àwọn ìletò wọn tí ó wà ninu ilẹ̀ ẹ̀yà Manase, ṣugbọn tí a fi fún ẹ̀yà Efuraimu.
Èèyàn mẹ́rin ló tí kú ninú otẹ́ẹ́li àyẹwò Coronavirus to dà wó ni China Israel Adesanya ṣetán láti gbéná wòjú Romero Mo lóbìnrin tó bímọ fún mi, ṣùgbọ́n ọ̀rọ̀ ìyàwó kò tíì yọ fún mi báyìí-Pasuma Kásà, ewé sunko fún àgbà òṣèré tíátà, Fádèyí Olóró Àyájọ́ obìrin lágbáye, àwọn obìrin fọnrere ìdẹ́yẹsí Ti o ba ri bẹẹ, ki wa gan an lo n fa iyatọ laarin bi ọṣẹ arun yii ṣe le si laarin ẹya akọ atabo tabi ara awọn ọmọ wẹwẹ ati agbalagba?
Lẹ́yìn náà, Mẹfiboṣẹti, ọmọ ọmọ Saulu, wá pàdé ọba.
Laipẹ, ko ṣe daada nileewe mọ, a si maa fa wahala loorekoore.
O sàn ká wà láyé láì lówó lọ́wọ́ ju ká ya sinimá, ká kó Coronavirus lọ - Latin pariwo fáwọn òṣèré tíátà Aláàfin gbé àṣẹ kalẹ̀ láti dènà àtúnṣẹ̀ ìṣẹ̀lẹ̀ 'Soka'nílùú Ọ̀yọ̀ 'Ìnira ńlá ni coronavirus mú bá èmi àtàwọn ọmọ mi gẹ́gẹ́bí opó tó fọ́jú' Mo kábàámọ̀ pé n kò kàwé, kí n tó bẹ̀rẹ̀ iṣẹ́ tíátà - Sanyeri Ìdí táwọn apòògùn Nàìjíríà fi tako oògùn Coronavirus láti Madagascar Ọọni, Aláàfin, Ojisẹ Ọlọ́run àti oniṣẹ ìwádìí fi Ògún gbari pé òògùn ìbílẹ̀ le wo Covid-19 Bakan naa lo sisọ loju rẹ pe ile ẹkọ fasiti Obafemi Awolowo gba oun wọle sile ẹkọ fasiti naa, ti oun si ni lẹta igbaniwọle si fasiti naa lọwọ amọ fun iyalẹnu oun, asiko ti oun fẹ ṣe iforukọsilẹ nile ẹkọ naa ni oun ri pe, wọn ti yọ orukọ oun kuro ninu awọn to fẹ wọle sile ẹkọ naa.
Nítori pé ibẹ̀ jẹ́ àdúgbo tí wọn kọ ilé pako sí ti kò si ni ètò kankan tẹ́lẹ̀, gẹ́gẹ́ bi ijọba ṣe ni agbára lati wó ibi ti ko ba bóju mu, ìjọba fi kun nígbà náà pé àwọn ni ètò míràn fún àdúgbò náà.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Lai Mohammed: A ti gba 800 bílíọ̀nù padà lọ́wọ́ àwọn tó jíi kó, àwọn 1,400 ti dèrò ẹ̀wọ̀n 28 Agẹmo 2020 Oríṣun àwòrán, @thebridgenewsng Ijọba apapọ ti sọ pe oun ti gba owo to le ni ẹgbẹrin bilọnu naira pada lọwọ awọn to jii ko.
Omiran tun ni ti ọmọdekunrin kan to bọ lọwọ awọn afiniṣetutu, eyi ti oju rẹ kun fun apa ada ti wọn gbiyanju lati fi da a duro.
Wo ìdí tí àwọn obìnrin kan fi n yọ ilé ọmọ wọn kúrò EFCC ń wádìí iléeṣẹ́ 'Bola Tinubu,' Alpha Beta Consulting Ltd' Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Fídíò BBC yọ àwọn èèyàn FIFA níṣẹ́ ṣááju Russia 2018 Ibrahim Kargo: Elomii ti ajọ FIFA tun ti fofin ayeraye de ninu awọn ọmọ Adulawọ ni Ibrahim Kargo.
N kò jẹ ninu ìdámẹ́wàá mi nígbà tí mò ń ṣọ̀fọ̀, bẹ́ẹ̀ ni n kò kó èyíkéyìí jáde kúrò ninu ilé mi nígbà tí mo jẹ́ aláìmọ́, tabi kí n fi èyíkéyìí ninu wọn bọ òkú ọ̀run.
Ó jọba fún ogoji ọdún; ó jọba fún ọdún meje ní Heburoni, ó sì jọba fún ọdún mẹtalelọgbọn ní Jerusalẹmu.
 apa kan jẹ màjẹ ̀ mu láíláí tí a ti ọwọ ́ àwọn wòlíì kọ nígbàtí májẹ ̀ mu títun jẹ ẹ ̀ yí tí a ti ọwọ ́ àwọn àpósítélì kọ nípa jésù láti fi tan ìwàásù jesu kálè .
láti inú ẹ̀yà Efuraimu, ó rán Hoṣea ọmọ Nuni; 
Eyi to tumọ si pe o ṣe e ṣe ki ijọba fun wọn ni àṣẹ láti ṣe bẹẹ.
Ó di ahoro bí èyí tí àwọn àjèjì wó palẹ̀.
Amọṣa ẹgbẹ awọn olukọ fasiti miran eleyi to yapa kuro lara ẹgbẹ ASUU ni fasiti naa, ti wọn si pe orukọ ara wọn ni Congress of University Academy (CONUA) pẹlu gbe ikede jade pe digbi ni awọn wa lẹnu iṣẹ ni tawọn nitori aṣẹ ASUU ko kan awọn.
Tí a fiṣọwọ́ ní 4:434:43 Èèyàn 1,598 míì tún ti lùgbàdì covid-19 ní Nàijíríà, 1,420 ló ti kú báyìí Lapapọ, eeyan 108,943 ni akọsilẹ fihan pe wọn ti larun covid-19 ni Naijiria nigba ti 85,367 ti ri iwosan.
Ẹ̀dá tí kò ní olórí, tabi alabojuto, tabi aláṣẹ
Pẹ̀lú gbogbo bùkátà, Bàbá 80 gboyè Masters Wo àwọn ìlérí tàwọn Gómìnà tuntun ṣe nínú ìbúra wọn Ọba Adesoji Aderemi, Ọọ̀ni Ifẹ̀ tó gba ipò ọba mọ́ tòṣèlú Àìle è ka kéú ló sọ mí di Krìstíẹ̀nì - Adewale Ayuba Aliaume Leroy, Benjamin Strick atawọn mii ni Africa Eye niwadii wọn fihan pe iṣẹ akọroyin le gba odindin orilẹ-ede silẹ ki wọn si tu aṣiri awọn oniṣẹ ibi.
”Mo bá pe àwọn alufaa, mo sì mú kí wọ́n jẹ́jẹ̀ẹ́ láti ṣe ohun tí wọ́n ṣèlérí pé àwọn yóo ṣe.
O wa ninu isẹ ologun ati ninu ẹsin Sufi.
Lẹyin o rẹyin, Saraki fi ẹgbẹ PDP silẹ lọ dara pọ mọ APC pẹlu awọn sẹnẹtọ mẹwaa miran.
Nitori akoko, awn isele miran rẹ eleyi ti ẹ le ri ka loju opo BBC Yoruba.
”Ṣugbọn Eli dá a lóhùn pé, “N kò pè ọ́, pada lọ sùn.
Ojú OLUWA wà níbi gbogbo,ó ń ṣọ́ àwọn eniyan burúkú ati àwọn eniyan rere.
Alahaji ọkọ oloyun wa lara awọn eekan to mu iṣegun ibilẹ tọ ọna igbalode lọ nipa ṣiṣe ogun ibilẹ si igo gẹgẹ bii olomi ati ni koro bi awọn ogun oyinbo.
Kó má baà wá di pé ẹ̀ ń fẹ́mọ lọ́wọ́ wọn fún àwọn ọmọkunrin yín, kí àwọn ọmọbinrin yín má baà máa ṣe ìṣekúṣe nídìí oriṣa, kí wọ́n sì mú kí àwọn ọmọkunrin yín náà máa ṣe ìṣekúṣe nídìí oriṣa wọn.
Iroyin ni wọn de ọdọ Aarẹ Norway nibi ti eniyan mẹta ti lugbadi arun Coronavirus ti wọn si ti fi eniyan aadọta pamọ fun ayẹwo.
Wo bóo ṣe lè mọ̀ ayédèrú Àìsàn ìtọ̀ súgà kò túmọ̀ sí pé èèyàn ti gba ọjọ́ ikú- Dókítà Wilson Pósí ní mo fi ṣe igbá ọṣẹ́ - Afurasí ọmọ ‘Yahoo’ kà fún EFCC Awọn to n po ọti wọnyii a ma saba lo kẹmika kan ti orukọ rẹ n jẹ Methanol' lati le jẹ ki ọti naa lagbara si.
Koda ofin orileede Naijiria fi ofin gbe awọn agbofinro lẹyin, lati se amusẹ idajọ iku tile ẹjọ ba da, lẹyin ti Gomina ipinlẹ tabi Aarẹ ba ti buwọlu aṣẹ yii.
Igbeyawo: Idapọ ọgbọn ọdun fori sanpọn
O ni: Aarẹ Muhammadu Buhari kii saba da si ọrọ aawọ yala ninu ẹgbẹ rẹ nipinlẹ to ti wa ni tabi lorile-ede Naijiria lapapọ."
Ifidirẹmi Saraki-Kì ló túmọ̀ sí nínú òṣèlú Kwara?
O ṣe apẹrẹ pe awọn omo Naijiria to n gbe ni South Africa le ni 800,000 ni eyi ti ko le fi rọrun lati kan palẹ wọn mọ maa bọ nile.
Ǹjẹ́ ẹnìkan lè sápamọ́ sí ìkọ̀kọ̀ kan tí n kò fi ní rí i?
O salaye pe, labe eto ohun, ogoro awon agbe igberiko ni won ti je anfaani awon ohun elo fun eto ogbin pelu irorun, ni eyi ti o fi kun pe, eto ohun ti mu alekun ba ipese iresi ni ijoba ibile naa.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Wo bí Sunday Orimola ṣe gba ikú ẹranko kú ní Ifon ni Ondo lórí ọ̀nà àtijẹ ''Olori mii ti yoo rọpo Chanel Chin ti wa ni ṣẹpẹ ṣẹpẹ bayii, eleyi lẹtikẹ,'' Oluwo lo ṣalaye bẹẹ.
Nítorí gbogbo ẹni tí ó bá bèèrè ni yóo rí gbà; ẹni tí ó bá wá kiri yóo rí; ẹni tí ó bá sì kan ìlẹ̀kùn ni a óo ṣí i fún.
O ni eyi lo mú ki oun si beere lọwọ àwọn iyawo baba rẹ ohun to fa a, o ni wọn fun oun ni esi pe nitori pe ọmọ naa ko gbọ́n daadaa ni.
Àkọlé àwòrán, Lara tiata ti Aisha se ni Omoge Campus Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Mo ní, “Ta ni kí n bá sọ̀rọ̀, tí yóo gbọ́?
Lọwọlọwọ, eniyan ẹgbẹrun meje ati ọtalerugba le yọkan (7261) lo ti ni Covid-19 ni Naijiria.
Oun naa lo tun yan ẹlomii, Iba Gani Adams, lati rọpo Abiola lọdun 2017.
oselu ANC ,African National Congress ti sọ oju abẹ nikoo pe eto idibo to  n lọ lọwọ-lọwọ yii ko ni rọrun fun egbe won
Ẹ wo nkan tí àwọn akẹẹgbẹ́ Lateef Adedimeji sọ nípa f'ọ́tò ìgbéyàwó òun àti Adebimpe tó jáde Ṣé lóòtọ́ ni Bimpe Oyebade lóyún fún Lateef Adedimeji?
Bakan naa ni Fayẹmi tun pe fun agbekalẹ ofin, ti yoo kan nipa fun ijọba to ba n fipo silẹ lati fun eyi to fẹ wọle lanfani, si gbogbo iroyin nipa eto ati iṣẹ ijọba gbogbo nitori gẹgẹ bi ọrọ rẹ, ijọba Fayoṣe kuna lati fi anfani silẹ fun igbimọ rẹ lati mọ ibi ti nnkan de duro nidi isejọba rẹ.
Ọrọ ti Oluwatoyin fi sita kẹhin re ki o to di pe awọn ọlọpaa ri oku rẹ Gẹgẹ bi ohun ti awọn ọlọpaa sọ ni nkan bi ago mẹsan alẹ kọja isẹju mẹẹdogun lọjọ kẹtala osu Kẹfa ni awọn oluwadi de si ile ibugbe 2100 block to wa ni Monday Road lati se iwaadi to ni se pẹlu eeyan kan ti wọn ni o di awati, iyẹn Oluwatoyin Salau.
- arìnrìn oge Ọmọ ọdún méjìlá ni mo ti ń ṣe bàálù, ọkọ̀, ilé àti ọkọ̀ ojú omi - Ọdọ́mọdé ‘Engineer’ Ọlabisi Ajala rèé, ó gun ọ̀kadà yíká àgbáyé, tó sì dé orílẹ̀èdè 87 Ọ̀nà láti sọ fásitì Lautech di ti Ọyọ nìkan ni Makinde ń sán - Ìjọba Ọṣun Ìkọlù sáwọn àjèjì kò tíì tán ní South Africa, ètò ń lọ láti kó ọmọ Nàíjíríà wálé Láìpẹ́, ará ìlú rẹ ni ọlọ́pàá tí yóò máa ṣọ́ ìlú rẹ Ṣugbọn ọpọ eeyan to gbọ nipa iroyin yii lawọn oju opo ikansira ẹni lori itakun agbaye lo n fi abuku kan Ikechukwu pe alailero ati ope ninu ẹsin ni.
Oṣu Kẹjọ ọdun 2020 ni ajọ Coalition Against Covid-19, CACOVID, ni o oun bẹrẹ si n pin awọn ounjẹ iranwọ naa, ṣugbọn ti ọpọ awọn ọmọ Naijiria sọ pe awọn ko ri ohunkohun.
Ọ̀pọ̀ ẹ̀mí sọnù sínú ìjàmbá iná l'órílẹ̀èdè Ghana
Ajọ FIFA ni Chelsea tapa sofin ninu bi wọn ṣe ara agbabọọlu mọkandinlọgbọn ninu agbabọọlu mejilelaadọrun ti wọn ṣe iwadi lori wọn.
Adanna ni awọn ounjẹ yii dara fun ọkan ṣugbọn ajẹju wọ ko dara.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Oluwo: Inú ìwé kíkà ni ọja ọ̀la àwọn Fulani wà 18 Agẹmo 2019 Oríṣun àwòrán, Instagram/Oluwo of Iwoland Oluwo ti ilu Iwo, Ọba Abdulrosheed Adewale Akanbi, Telu Kinni, ti kesi ijọba apapọ lorilẹede Naijiria lati sọ ileewe lilọ di dandan fun awọn ọmọ ẹya Fulani.
Gbogbo ara ile Òmùgọ́parapọ̀ ni o ní ìyàwó, ṣùgbọ́n àpọ́n ni wọn.
Ibuba wọn naa, ti wọn pe ni ‘Camp Zero‘, lawọn ọmọogun Naijiria kọlu lasiko ti wọn sigun lọ ka Boko Haram mọle eyiti wọn pe ni operation DEEP PUNCH II.
"Ninu iwe ibura to ṣe ni ile ẹjọ giga apapọ naa, o ni ""iyalẹnu nla lo jẹ fun mi nitori n ko sọ fun ẹnikẹni pe mo nii lọkan lati gbe ẹnikẹni lọ si ile ẹjọ, ambọsibọsi, oludije ẹgbẹ oṣelu PDP ti mo n fi gbogbo igba ṣe atilẹyin fun."
ní Hasariṣuali ati ní Beeriṣeba, ati àwọn ìletò àyíká rẹ̀, 
Gbogbo ẹbọ ohun jíjẹ tí a yan ati gbogbo èyí tí a sè ninu apẹ tabi ninu àwo pẹrẹsẹ jẹ́ ti alufaa tí ó fi wọ́n rúbọ.
Toyin Abraham jọ̀wọ́ dáríjì mí - Yomi Fabiyi Àwọn àṣà àti ìse tó yọ obìnrin sílẹ̀ nílẹ̀ Yorùbá Ọ̀sẹ̀ méjì péré la fẹ́ kí iṣẹ́ reluwe Eko sí Ibadan parí - Amaechi Ẹ sọ́ra, ọ̀pọ̀ èèyàn ni yóò lọ sẹ́wọ̀n ní 2019 - EFCC Ṣaaju ọjọ ti o ku ni o ti lọ gba itọju ni ileewosan.
ipinle Gombe, DSP Mary Malum,wa so pe alaafia ti bere si n joba ni ipinle
Yinka Ayefele di bàbá ìbẹta Ẹ̀yin obìnrin tẹ́ẹ fẹ́ wá bímọ ní America, ọ̀nà ti tì pa látònì!
Lẹ́yìn náà, o óo wí báyìí níwájú OLUWA Ọlọrun rẹ pé, ‘Ará Aramea, alárìnká, ni baba ńlá mi, ó lọ sí ilẹ̀ Ijipti, ó sì jẹ́ àlejò níbẹ̀.
Ìgbà t;i àbíkẹ́yìn ta ọfà tiẹ̀, ọfà rẹ̀ ta ti ọ̀gbọ́n rẹ̀ ìṣáájú yọ, àsẹ̀yìnwá àsẹ̀yìnbọ̀ ọba ṣe ìdájọ́ báyìí pé, níwọ̀n ìgbà tí a kò ti mọ ibi tí ọfa àtẹ̀lé dé, oun kò le ṣe ọkọ obinrin yìí, níwọ̀n ìgbà tí ọfa tí ẹ̀gbọ́n ta kò dé sì ti dé ibi tí àbíkẹ́yìn, òun náà kò le ṣe ọkọ Ẹwadapọ̀.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Sex for Grades: Àjọ ọlọ́pàá ìpínlẹ̀ Eko fìwé pe olùkọ́ UNILAG Boniface Igbeneghu 25 Ọ̀wàrà 2019 Oríṣun àwòrán, Facebook/Boniface Igbeneghu Ajọ ọlọpaa ipinlẹ Eko ti fi iwe pe Boniface Igbeneghu, to jẹ olukọ agba ni Fasiti Eko ti ọrọ kan lori fiimu fifi ibalopọ gba maaki ti ileeṣẹ BBC gbe jade laipẹ yii.
Idi ree ti BBC Yoruba fi n tanna wadi ibi ti owo yii wọlẹ si, abi ejo miran tun ti mi owo ijọba ipinlẹ Oyo ni?
Nkan tí a mọ̀ nìyíì Mo ti kúrò ní ààfin Oyo, kí ìròyìn tó ò jáde pé èmi àti Wasiu Ayinde n fẹ́ ara wa - Olori Badirat O si pẹ diẹ, ki Maina to yaju saye.
Dafidi ni àbíkẹ́yìn patapata; àwọn ẹ̀gbọ́n rẹ̀ mẹta náà sì wà ninu àwọn ọmọ ogun Saulu.
À ń dúpẹ́ lọ́wọ́ Ọlọrun, Baba Oluwa wa, Jesu Kristi, nígbà gbogbo tí a bá ń gbadura fun yín.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù 41 Days Fasting: Akẹ́kọ̀ọ́ kan gba ààwẹ̀ ọlọ́jọ́ 41, ó dèrò ilé ìwòsàn 7 Owewe 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Laipẹ yii ni iroyin gbalẹ kan pe akẹkọ kan nile ẹkọ fasiti ipinlẹ Ebonyi, Ikechukwu Oke, gba aawẹ ọlọjọ mọkanlelogoji, to si ti ru kan egungun.
Ayọ̀ ń bẹ fún àwọn tí ọkàn wọn mọ́,nítorí wọn yóo rí Ọlọrun.
Wọ́n nhùwà aláìgbọ́n nítorí oun tí wọ́n ó jẹ ni wọ́n nwá.
Jàǹdùkú ba iṣẹ́ àkànṣe Dino jẹ́ ni Kogi Dino Melaye yóò f'ojú balé ẹjọ̀ Gẹgẹ bi oun ti Gideon sọ, o ní pẹlu bi àwọn kan ṣe sọnà sí ileewe méjì ti Dino fe se ìfilọ́lẹ̀ wọn, àwọn ṣì tẹsíwájú pẹlú eto náà lọjọ kejidinlogun osu yii.
sagbon ti akegbe re Philippe Coutinho si gba iketa wole.
Fayemi sọrọ yii nibi ipade awọn tọrọ kan lori iwọde EndSARS to waye sẹyin niluu Ado Ekiti lọjọ Aiku ọjọ kẹẹdogun oṣu kọkanla ọdun 2020.
Àkọlé àwòrán, Wọn ti paṣẹ ki wọn ṣi Daily Trust pada Buhari ṣèlérí àti dẹ́kun Boko Haram pátápátá DSS tu akọroyin ti wọn mu silẹ Akọ̀ròyìn Reuters méjì rẹ́wọ̀n he ní Myanmar Ẹ̀sun olè ají-ìwé-àkọsílẹ̀ ní a fi kan Akoroyin Samuel Ninu ọrọ ti iwe iroyin naa kọ, wọn ni awọn fura si wi pe igbesẹ awọn ọmọogun Naijiria yi ko sẹyin iroyin kan ti awọn gbe jade lọjọ aiku nipa iṣẹ awọn ologun lagbegbe ila oorun ariwa Naijiria.
A gba ilẹ̀ wọn, a sì fi fún ẹ̀yà Reubẹni, ati ẹ̀yà Gadi ati ìdajì ẹ̀yà Manase, gẹ́gẹ́ bí ìpín tiwọn.
Àbí eniyan ni igi inú igbó, tí ẹ óo fi máa gbé ogun tì í?
Lápapọ̀, àwọn plánẹ̀tì mẹ́rẹ̀rin yìí jẹ́ pípè nígbà míràn bíi plánẹ̀tì Jofia.
Bàbá ẹni ọgọ́ta ọdún dèrò ilé ẹjọ́ nítorí ó wọ inú oko Obasanjo láì gba àṣẹ Wo ohun tó ń fa àfikún epo lóòrèkóòrè ní Nàìjíríà Gbajabiamila balẹ̀ sí Ghana láti pẹ̀tù sááwọ̀ láàrin Nàìjíríà àti Ghana E wo ọmọ Yorùbá àkọ́kọ́ tó jà fún ẹ̀tọ́ àwọn aláwọ̀dúdú ní America!
Ó dá àwọn baba wa lóró, ó mú kí wọ́n máa sọ ọmọ nù, kí wọ́n baà lè kú.
4 Nítorí nínú wọn ni a kọ ohun gbogbo sí nípa ìpìlẹ̀ ìjọ mi, ìhìnrere mi, àti àpáta mi.
Yakubu Dogara padà sí APC, Buhari kí i kú àbọ̀ ní Aso Rock Oríṣun àwòrán, @BashirAhmaad Gẹgẹ bi a ṣe gbọ ọ, adari ile igbimọ aṣoju ṣofin tẹlẹ, Yakubu Dogara ti pada si ẹgbẹ oṣelu All Peogresives Congress, APC.
Oríṣun àwòrán, Twitter/Michaela Moye Àkọlé àwòrán, Ọlọrun ló yọ Michaela Moye lẹ́yìn tí àwọn ọlọ́pàá gba kámẹ́rà lọ́wọ́ rẹ̀ Awọn ọlọpaa kọkọ fiya jẹ Segun Salami to n ba Channels Television ṣiṣẹ nile ijọba ipinlẹ Kogi ki wọn to mu u ni ọjọ kejidinlogun, oṣu kẹjọ, ọdun 2017 ni iṣẹlẹ naa ṣẹlẹ nilu Lokoja Oríṣun àwòrán, Facebook/Segun Salami Àkọlé àwòrán, Àwọn ọlapàá ilé ìjọba ìpínlẹ̀ Kogi ni wọ́n kọlù oníròyìn Segun Salami Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ta ni ọmọ Naijiria tí wọ́n gún pa ní London?
Nígbà tí mo ṣe akiyesi ojú ọ̀run, iṣẹ́ ọwọ́ rẹ,òṣùpá, ati àwọn ìràwọ̀, tí o sọlọ́jọ̀–
Diddy Agba ọjẹ olorin, ati oludasilẹ ileeṣẹ kan to n gbe orin jade nilẹ America, Sean John Combs, ti ọpọ mọ si Diddy, naa da si ọrọ ipolongo #ENDSARS.
Ile iwe girama lo wa lọdun 2010 nigba to gori itẹ baba rẹ gẹgẹ bi Adele.
Osibanjo tun ni “Laarin odun kan bayii, Olorun ti fi aanu re han ni gbogbo ona ;ohun ti Olorun ti fi han orile ede Najiria pe odun to n bo yoo dara.
Cucumber yii tun dara fun awọ ara ti yoo si mu ko maa dan yọyọ, ti yoo si mọ kedere.
Ní àkókò àwọn ìjọba wọnyi ni Ọlọrun ọ̀run yóo gbé ìjọba kan dìde tí a kò ní lè parun, a kò sì ní fi ìjọba náà fún ẹlòmíràn.
 lẹ ́ yìn abẹ ́ rẹ ́ àjẹsára ẹ ̀ ẹ ̀ kejì , àyẹ ̀ wò ẹ ̀ jẹ ̀ á tẹ ̀ le láàárìn oṣù kan sí mẹrin fún àrídájú iṣẹ ́ rẹ ̀ .
ijamba naa ṣẹlẹ lowurọ Ọjọru ọsẹ ninu eyi ti ọkọ agbepo kan ati ọpọlọpọ ọkọ akẹru atawọn ọkọ mii wa.
OLUWA gbọ́ ohùn àwọn ọmọ Israẹli, ó sì ràn wọ́n lọ́wọ́ láti ṣẹgun àwọn ará Kenaani.
Stars Ladies, ogbeni AbdulRahmon Abolore se so; “A gba Nwosu ki o maa tuko yii latari
Agbenusoro Yakubu Dogara so pe ko si ojo kankan ti ile-ise aare yan lati wa se agbekale iwe isuna ohun tile igbimo naa da pada.
” Báyìí ni wọ́n ń fi ohùn líle bá obinrin náà wí.
Ibi ti ariwo ti n waye ni obinrin naa ti ya aṣọ kan ṣoṣo ti iya Oladele maa n wọ jade, mọ ọ lọrun.
Modekai kọ gbogbo nǹkan wọnyi sílẹ̀, Ó sì fi ranṣẹ sí àwọn Juu tí wọ́n wà ní gbogbo ilẹ̀ ìjọba Ahasu-erusi ọba, ati àwọn tí wọ́n wà nítòsí ati àwọn tí wọ́n wà ní òkèèrè, 
Obinrin oun ni won gbagbo pe, o je arinrinajo omo orile-ede Russia, eyi ti o bimo sinu okun pupa pelu iranlowo onisegun oyinbo omo orile-ede Russia ti o je akosemose ninu bibi omo sinu omi.
Sheraton Hotel & Towers, Ikeja, to wa ni ipinle Eko .
Ẹ ti gbàgbé ọ̀rọ̀ ìyànjú inú Ìwé Mímọ́ níbi tí ó ti pè yín ní ọmọ, nígbà tí ó sọ pé,Ọmọ mi, má ṣe ka ìtọ́sọ́nà Oluwa sí nǹkan yẹpẹrẹmá sì jẹ́ kí ọkàn rẹ rẹ̀wẹ̀sì nígbà tí ó bá ń bá ọ wí.
Ṣugbọn ohunkohun tí ó ń gbé inú òkun, tabi inú odò, ninu gbogbo àwọn ẹ̀dá alààyè tí wọn ń káàkiri inú omi, èyíkéyìí tí kò bá ní lẹbẹ ati ìpẹ́, ohun ìríra ni fun yín.
OLUWA ní, “Ẹ̀yin ará Babiloni, tí ẹ kó àwọn eniyan mi,bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé inú yín dùn ẹ sì ń yọ̀,tí ẹ sì ń ṣe ojúkòkòrò, bí akọ mààlúù tí ń jẹko ninu pápá,tí ẹ sì ń yan bí akọ ẹṣin:
’ Bí ó ti wí báyìí, pẹ̀rẹ́ ni ilẹ̀ là tí a sì rí àtẹ̀gùn dídára ka báyìí tí ó ba ihò ilẹ̀ lọ, gbogbo wa sá bẹ̀rẹ̀ síí tọ àtẹ̀gùn yìí bá ìsàlẹ̀ lọ.
Lẹ́yìn náà, ó mú mààlúù ìmúkúrò ẹ̀ṣẹ̀ jáde, Aaroni ati àwọn ọmọ rẹ̀ ọkunrin gbé ọwọ́ lé e lórí.
Kí ló dé tí o gbèrò irú nǹkan yìí?
Pupọ ninu àwọn Juu ni ó ka àkọlé náà ní èdè Heberu ati ti Latini ati ti Giriki.
Gomina Abdul Razak fi ofin de ipejọpọ ọpọ eniyan, o ti awọn ọjà pa, o ti gbogbo ileewe pa, to fi mọ igbokegbodo ọkọ.
OLUWA ní òun óo gba Hesekaya lọ́wọ́ ọba Asiria, òun óo gbèjà ìlú Jerusalẹmu, òun óo sì dáàbò bò ó.
Eto aabo nipa Boko Haram: Aarẹ Buhari dupe lọwọ Aarẹ Trump fun iranlọwọ awọn ologun ilẹ Amẹrika, to kopa ninu kikọ awọn oloogun orilẹede Naijiria lọna ti wọn yoo gba fi sẹgun ikọ ẹsin o kọku Boko Haram: Awọn adari mejeeji sọ wipe opin yoo deba gbogbo ikọlu Boko Haram laipẹ.
Àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ sì tẹ̀lé e.
Ajo naa salaye pe oun yoo ri i daju pe awon afurasi ohun gbogbo foju ba ile ẹjọ ni kete ti awon ba ti pari isẹ iwadi won.
"Ọdun 1987 lo jẹ ọba, sugbọn wọn le e kuro lori itẹ lọdun 2012 nitori pe ""wọn ṣèèṣì yàn án sípò ọba ni""."
Kini ìdí ti ó fi ń lo àwọn irinṣẹ́ aṣàwári tí àwọn ènìyàn ńlá ń lò, ọ̀pọ̀ àwọn irinṣẹ́ aṣàwári wà ti yóò ràn ó lọ́wọ́ láti yọ ìpólówó ọjà kúrò àti àwọn ǹkan míràn ti kò ṣe pàtàkì Coronavirus: Ǹjẹ́ àwọn dókítà tó ń tọ́jú eyín ń ṣisẹ́ lásìkò pàjáwìrì?
Ẹwẹ, BBC bere pe ki ni ipa ti wiwẹ ẹsẹ yii nko, alufa agba Olukayode ni ipa to n ko ni ki onigbagbọ kọ iwa irẹlẹ, iwa pẹlẹ bii ti Jesu.
O Fagunwa, eyiun Diipọ Fagunwa ti n selede lẹyin baba rẹ to si n sọ awọn ohun meremere ti agba onkọwe naa ti gbe ile aye se lasiko to wa loke eepẹ.
Kankia kede pe Ọmọwe Kurami ni ibo 20,444 eyi ti o fi la oludije PDP, Magaji mọlẹ.
Majid al-Mohandis n kọrin nilu Taif nigba ti obinrin naa lọ dimọ lasiko tawọn ẹlẹṣọ n gbiyanju lati faa kuro.
 Iko mẹrindinlogun ninu ida ọgọrun-un (16%) awọn idọti yii ni wọn jẹ ike.
Àwọn ẹ̀gbọ́n rẹ̀ kò fẹ́ràn ohun tí ó ń ṣe yìí, wọ́n sì máa ń fi ẹjọ́ rẹ̀ sun bàbá wọn.
Lẹyin naa nii gomina Ipinlẹ Eko nigba kan ri Babatunde Fashola yan gẹgẹ bii kọmiṣọna fun eto iṣẹ laarin ọdun 2011 si 2015.
23 Ìgbé 2018 Oríṣun àwòrán, Twitter/Nigerian Presidency Àkọlé àwòrán, Orílẹ̀èdè mẹ́rìndínlógún ni Ọbabìnrin Elizabeth keji jẹ́ olórí fún nínú àjọ Commonwealth Laipẹ yii ni ilẹ Gẹẹsi gba alejo awọn olori ajọ commonwealth ninu ipade kan to waye ni London.
Akowe agba fun ile-ise to n seto iranwo owo fun ijamba pajawiri , omowe Habiba Lawal , wa ro awon abule ati igberiko to je anfaani yii lati ri I pe wahala ijoba ko jaa si asan.
Àwọn ohun tó yẹ́ kí o mọ̀ nípa Ọ̀gá DSS tuntun #beyond fake news Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Lẹsẹkẹsẹ bí ó ti dé, Judasi lọ sí ọ̀dọ̀ Jesu, ó kí i, ó ní, “Olùkọ́ni!
    “Ibo lẹ̀ ń lọ báwọ̀nyí ẹ̀yín ọmọ ènìyàn?
Bakan naa ni igbakeji aarẹ naa fikun wi pe ki awọn yoo mu atunto ba ikọ ọlọpaa naa.
Iroyin yii gbinlẹ loṣu Kẹta ọdun 2020, nigba ti Bil gates sọ ninu ifọrọwerọ kan pe wọn yoo lo ẹrọ kọmputa lati mọ awọn to ti moribọ lọwọ arun naa.
O ni ọna lati ṣe aṣeyọri SWAT wa lọwọ irufẹ awọn ti ijọba ba gba sibẹ ati Adari tuntun ti wọn ba yan fun SWAT.
“Gbogbo ìjọ eniyan Ọlọrun ní kí á bèèrè lọ́wọ́ yín pé, irú ìwà ọ̀dàlẹ̀ wo ni ẹ hù sí OLUWA Ọlọrun Israẹli yìí?
Ọlọrun ni ó ń fún un ní ara tí ó bá fẹ́, a fún irúgbìn kọ̀ọ̀kan ní ara tirẹ̀.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ìjọba àpapọ̀ rán 1000 ọmọ ogún lọ sí Zamfara Ẹgbẹ̀rún kan ènìyàn gba òmìnira lọ́wọ́ B/H Ìjọba àpapọ̀ rán 1000 ọmọ ogún lọ sí Zamfara Busuyi, tó jẹ́ ọkan lára mọ̀lébi rẹ̀ fìdí ọ̀rọ̀ náà múlẹ̀ pé, wọn jíi ẹ̀gbọ́n òun gbé ní dédé ààgò mẹ́ta osan pẹ́lù ẹgbọn rẹ̀, tí àwọn ajínigbé náà kò sì tíì bá ẹ̀bí sọ̀rọ̀ rárá lórí ohun tí wọn fẹ́ gbà.
A gbiyanju lati ba baba oloogbe sọrọ(nitori iya rẹ naa ti di oloogbe), ṣugbọn a ko ri baba ọmọbinrin naa lasiko ti a ṣe abẹwo si ile wọn.
Ọrọ̀ a máa mú kí eniyan ní ọpọlọpọ ọ̀rẹ́ titun,ṣugbọn àwọn ọ̀rẹ́ talaka a máa kọ̀ ọ́ sílẹ̀.
Organisation of Islamic Cooperation: Àǹfààní wo ló wà nínú ẹgbẹ́ OIC?
"Mo ni ọpọ awọn ọrẹ to pọ ninu iṣẹ iroyin, ti mo si ti ṣẹ wọn nipa ihuwasi mi nipa lilo awọn ọrọ ti ko ṣe e gbọ seti naa.
 Sibẹ, o ni Ile naa ti gbe Igbimọ kan kalẹ ti o n ṣagbeyẹwo ati ṣadinku owo naa.
Aisha Buhari lasiko to n gbalejo lati ṣayẹyẹ bi ọkọ rẹ ṣe jawe olubori sọ wi pe, aarẹ yoo gbogun ti iwa ibajẹ, iṣẹ ti oṣi eleyii ti yoo mu opin ba alafo to wa laaarin awọn olowo ati awọn alaini ni awujọ.
Segun, Máàkì tóo ní kọ́ ni yóò ṣé atọ́nà oríire rẹ láyé Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fọ́nrán ohùn, Àwọn ènìyàn sọ àwọn ewu tí wọn pàdé nínú lílo òògùn ẹ̀fọn  Rara o, wọn gbe e lọ si ile iwosan mii lati ile iwe wa, lati ibẹ wọn si tun gbe e lọ si ile iwosan ti ijọba to wa ni LASU."
 ní báǹkì , wọ ́ n pàdé kọ ́ lá .
Òkú Amasa, tí ẹ̀jẹ̀ ti bò, wà ní ojú ọ̀nà gbangba, ẹnikẹ́ni tí ó bá ń kọjá, tí ó bá rí i ń dúró.
Àwọn ọmọ aráyé yóo máa yọ̀ wọ́n, inú wọn yóo sì máa dùn.
Ṣugbọn nígbà tí ó bá ku òun ati àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀, a máa túmọ̀ gbogbo rẹ̀ fún wọn.
Kò sì tíì pẹ́ pupọ tí o dé, kí ló dé tí o fi fẹ́ máa bá mi káàkiri ninu ìrìnkèrindò mi?
Idi ni pe ni ọjọ kinni, oṣu Kẹwaa, to jẹ ayẹyẹ ọgọta ọdun ti Naijiria gba ominira, aṣọ to jẹ awọ kan naa pẹlu asia Naijiria lo wọ.
20 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Sudan removed from terrorist list: America yọ Sudan kúrò nínú ìwé orílẹ̀-èdè tó ń ṣagbátẹrù ẹgbẹ́ agbésùnmọ̀mí lágbàyé14 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
" Ajọ EFCC mọ pe ilẹ Yuroopu lo fi ara pamọ si.
Coronavirus tún ti ṣe ọṣẹ́ lórí iṣẹ́ líla ojú ọ̀nà relùwe láti Eko sí Ibadan - Ìjọba àpapọ̀ Àrùn Coronavirus fa'lẹ̀ya láwọn ìletò aláwọ̀dúdú ní Amẹ́ríkà Aworan atọnisọna Iye awọn to ti ni arun naa lagbaye Sunmọ aworan Àgbáyé Orilẹede Afrika Ariwa Amẹrika Apa Latin Amẹrika ati Caribbean Ilẹ Asia Ilẹ Yuroopu Agbegbe Middle East Erekusu Oceania Fihan 93418283 iye iṣẹlẹ arun naa 2000905 Iye awọn to ku Group 4 Jọwọ ṣe atunṣe ilana ikansi ayelujara rẹ lati ri ẹkunrẹrẹ rẹ Aworan n ṣafihan awọn ti ayẹwo ti fi han lorilẹede kọọkan Orisun: Johns Hopkins University atawọn ajọ eto ilera ilu Igba ti wọn kede iṣiro awọn to nii kẹyin 15 Oṣù Ṣẹ́rẹ́ 2021 20:44 WAT+3 Ẹkunrẹrẹ data Sun atẹ wa silẹ tabi oke lati ri ẹkunrẹrẹ akọsilẹ *Iye awọn to tọwọ aisan ku ni isọri eeyan ẹgbẹrun lọna ọgọrun Gbe e yẹwo: Àgbáyé Orilẹede Afrika Ariwa Amẹrika Apa Latin Amẹrika ati Caribbean Ilẹ Asia Ilẹ Yuroopu Agbegbe Middle East Erekusu Oceania Iye to ti ku Iye awọn to ku %* Apapọ awọn iṣẹlẹ arun Akọtun arun yii 0 10 100 1000 10000 ** Orilẹede Amẹrika 387741 118.
Inú OLUWA dùn fún ohun tí Solomoni bèèrè.
Ọjọ Abamẹta, ọjọ kẹjọ, oṣu Kejila, ọdun 2018 ni Iyalode ilu Ibadan, Oloye Aminat Abiọdun jade laye.
A ti fi ẹ̀tọ́ àwọn abódiakọ-akọ́diabo yí iyẹ̀pẹ̀.
ÌPINYÀ PẸ̀LÚ BABA-ONÍRÙNGBỌ̀N-YẸ́ÚKẸ́ Ẹ́NI TÍ Ń GBÉ IBI GEGELE ÒKÚTA
Nígbà tí ọjọ́ rọ̀ Jesu ati àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ jáde kúrò ní ìlú.
Oríṣun àwòrán, Nigeria police force Ọrọ yii di iṣu ata yan an yan an laarin ileeṣẹ ọlọpaa ati ileeṣẹ ọmọ ogun lorilẹ-ede Naijiria.
Ninu atẹjade kan ti agbẹnusọ rẹ Kehinde Akinyemi fi sita Obasanjo gba Makinde lamọran pe ko''ma ṣe ba wọn kopa ninu oṣelu ti yoo ṣanfaaani fun awọn apa kaan'' Oríṣun àwòrán, @seyiamakinde Àkọlé àwòrán, Makinde tun ṣe abẹwo si alagba Fasoranti nilu Ondo Aarẹ ana ohun sọ pe Gomina ti wọn ṣẹṣẹ dibo yan naa ni iṣe lati ṣe nipa mimu idagbasoke ba ipinlẹ Oyo to si tun kesi awọn eeyan ipinlẹ naa lati gbaruku ti.
Bí mo ti ń wo àwọn ẹ̀dá alààyè náà, mo rí àgbá kẹ̀kẹ́ mẹrin lórí ilẹ̀ lẹ́gbẹ̀ẹ́ wọn, àgbá kọ̀ọ̀kan fún ọ̀kọ̀ọ̀kan.
Ìyè ainipẹkun yìí tí ó wá láti ọ̀dọ̀ Baba, tí ó ti farahàn fún wa, ni a wá ń kéde fun yín.
N óo mú ninu wọn, n óo fi ṣe alufaa ati ọmọ Lefi.
Nurudeen ṣalaye pe lai tilẹ la ẹnu sọrọ, bi ọkunrin ba lu ohun elo orin yii bakan, obinrin lee gba fun un lọwọ kan.
Ninu atejade kan ti Ologbondiyan gbe jade pe: “ Bi  ilana eto idibo se lọ nipa yiyi esi eto idibo, fifi iya jẹ awọn alaisẹ, didunkooko mọ awọn omo egbe wa, lati odo awọn agbofinro tako eto ijọba tiwa-n-tiwa ati ẹtọ awọn eniyan lati yan ẹni to wu wọn.
6 38323 Orilẹede Angola 354 1.
Lootọ Naijiria ni ọja to pọ sugbọn eto ọrọ aje rẹ ko gbe Ọgbẹni Iyaniwura ni lootọ ni awọn orilẹede bii kenya, Ethiopia ati South Africa ni eto ọrọ aje to dara ju ti Naijiria lọ eyi si tumọ si wi pe awọn orilẹede wọnyi ni yoo maa janfani ọja to fẹ lorilẹede Naijiria."
Mò ń wá ìyàwó- Gbajúgbajà òǹkọrin Falz Èyí ni ìdí tí a kò fi yọ̀nda El-Zakzaky pẹ̀lúù Sowore àti Dasuki- Malami Bi àwọn kan ṣé n jẹ àsun ní àwọn míì n ṣeré lórí omí láti gbádùn Kérésì àná Ibi tí o bá dágbére fún ẹbí àti ará ní kí wọ́n ti ba ọ lásìkò ọdún Kérésì yìí- Akọ́ṣẹ́mọ́ṣẹ́ Larisa ni oun ko jẹ ki ọjọ ori oun di oun lọwọ nigba ti asiko to lati yan iṣẹ miran laayo.
Ayẹwo ti a ṣe si oju opo ikansiraẹni rẹ lori itakun agbaye fi han pe ọmọdekunrin naa, Kyle Rittenhouse fẹran awọn agbofinro.
Riliwan Akiolu ti Ipinlẹ Eko ni o sọrọ iṣiti yii nibi ayẹyẹ idanilẹkọọ
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Iléesẹ́ ológun Nàìjíríà bẹnu àtẹ́ lu ìwádìí Amnesty International 17 Ọ̀pẹ̀̀ 2018 Oríṣun àwòrán, AFP Àkọlé àwòrán, Awọn ọmọogun ko sinmi fifigba gbaga pẹlu awọn janduku orisirisi ni Naijiria Ileeṣẹ ologun orileede Naijiria ti tutọ soke foju gba lori abajade iwadi kan ti ajọ to n tọpinpin ẹtọ ọmọniyan lagbaye, Amnesty International,gbe jade nipa Naijiria.
Àwọn wọnyi ni wọ́n ń ya ara wọn sọ́tọ̀.
Ọbasanjọ yòǹbó Atiku, ó ní kò ní já Nàíjíríà kulẹ̀ 137 obìnrin ni ikú ń pa lójúmọ́ lágbàáyé Labẹ eto ẹkunwo oṣu tuntun ti Buhari fọwọ si yii, owo oṣu, ajẹmọnu ati owo ifẹyinti awọn ọlọpaa ni yoo gbẹnusoke.
Ní ọdún kẹrin tí Ahabu, ọba Israẹli, gun orí oyè, ni Jehoṣafati, ọmọ Asa, gun orí oyè ní ilẹ̀ Juda.
O fikun pe itara ijọba oun lati gba idande awọn akẹkọ Chibok lo mu ko seese fun wọn lati ri akẹkọ bii ọgọrun gba pada wale.
 Eyi ko tako ofin egbe tabi ofin orile ede Naijiria”.
O kere nilẹ ju Ronaldo lọ, amọ o n fi bọọlu dabira nla lori papa, koda pẹlu irọrun lo maa fi n ṣe ohun gbogbo.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ibrahim Chatta: Tí olólùfẹ́ méjì bá ti ń na ara wọn, ọ̀kan má a pa èkejì!
Amọṣa o dabi ẹni pe igbesẹ yii dun mọ ọpọlọpọ awọn araalu ninu nitori nigba ti BBC beere lọwọ awọn eeyan nigboro, wọn ni awọn faramọ ọ.
Ambode ní kò sí gìrì, eré ọwọ́ lásán ni EFCC ń ṣe Ta ni Seun Fakorede, ọmọ ọdún 27 tó fẹ́ di kọmiṣọna?
Ni Dafidi ati gbogbo àwọn tí wọ́n wà pẹlu rẹ̀ bá fa aṣọ wọn ya láti fi ìbànújẹ́ wọn hàn.
Nítorí náà, ẹ̀yin ará, ẹ máa tiraka láti sọ àsọtẹ́lẹ̀.
Ọjọgbọn Daud kehinde Sangodoyin ni Gomina Ipinlẹ Oyo kede rẹ gẹgẹ bi kọmiṣọna fun eto ẹkọ.
NCDC ní, ìpínlẹ̀ Eko ní ènìyàn mẹ́tàdílọ́gọ́ta, mẹ́tàdínlọ́gbọ̀n láti Kano, nígbà tí ìpínlẹ̀ Kwara ni èèyàn mẹ́wàá sí, èèyàn Mẹ́sàn ni Edo ní lọ́tẹ̀ yìí.
”Wọ́n dáhùn pé, “Àwa ni ẹlẹ́rìí.
Awọn kọlọransi agbefọba wọnyii ni wọn maa n lo ipo wọn ni ileeṣẹ ijọba lati wa bi wọn yoo ṣe gbowo lọwọ awọn awakọ ni tipatipa.
Ile-ise to n ri si eto irin ajo lorile-ede naa so wi pe,ki awon omo orile-ede naa yago fun irin ajo lo si awon agbegbe eyi ti aawo naa ti n waye lati osu kewa odun 2017.
Yoòbá ní “Aiyé nyí lọ biri-biri bí òkúta”.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Fulani Kidnapping: Owó púpọ̀ la san kí wọ́n tó fi mi sílẹ̀ Ni ti Atiku Abubakar, o bu ẹnu atẹ lu ipaniyan to ba ni lọkan jẹ pupọ yii o si pe awọn oṣiṣẹ alaabo lati bẹrẹ iwadii gidi lati mu awọn to ṣekupa arabinrin naa.
Nígbà tí ẹ bá kà á, ẹ óo rí i pé mo ní òye àṣírí Kristi, 
Ki lo n mu awọn obinrin gbe iru igbesẹ yii?
O ni kii ṣe pe wọn yoo gbin kọmputa ti eeyan ko le foji ri si agọ ara eeyan lati mọ ibi ti wọn wa ni gbogbo igba.
    Bí mo ti ń kọ̀wé yìí, ojú mi ń wo ọkọ mi tuntun, ẹni ti ó dúró rọ̀gbọ̀dọ̀ kanlẹ̀, ẹni tí ó pupa bí epo inú ṣágo, ọ̀pẹ́lẹ́ńgẹ́, awẹlẹ́wà, ọ̀dágọ̀dọ̀, ìbàdì àrán, báálé mi àpé.
Ó dúró níbẹ̀ fún ìgbà díẹ̀.
 Ìdí ni wí pé sabino ní ó síwájú rògbòdìyàn yìí , ó sì ṣe é ṣe kí bàbá gama kópa nínú rògbòdìyàn yìí .
    Ìgbà tí ilẹ̀ ọjọ́ kejì mọ́, a lọ ó dí ibẹ̀.
Igbokegbodo ọkọ ti pada si ilaji bo se ri ni Beijing ati Shanghai lọdun 2019.
WhatsApp: Àwọn fóònù wọ̀nyìí kò ni lè ṣe WhatsApp láti ọdún 2020
"Jijẹ iru nkan bẹ ko yatọ si jijẹ majele, ile iwosan si ni wọn gbọdọ gbe ẹni naa lọ ni kiakia.
Oluwateru:Oju bọrọ kò ṣé gbọmọ lọ́wọ́ ekurọ South Afrika lori Xenophobia Ninu atẹjade ti Ogbẹni Gboyega Akosile to jẹ akowe eto iroyin fun gomina Sanwo Olu fi ọwọ si lo ti paṣẹ aabo yii.
Coronavirus in Nigeria: Davido ní àyẹ̀wò kejì fún àrùn Coronavirus fihàn pé ṣáká lara le Oríṣun àwòrán, Davido/instagram Gbajugbaja akọrin takasufe, Divid Adeleke ti ọpọ eeyan mọ si Davido tun ti wẹ yan kainkain lọwọ arun coronavirus.
O ni, oun kabamo ikolu ti o tun sele lagbegbe Okpokwu nipinle naa, O wa ro awon osise alaabo lati se ise won bi ise, besini ki won fowo-sinkun mu darandaran ti oro naa ba si mo lori.
Pẹlu ipo olori ti Nengi wa bayii, o ti lanfaani lati wa nile ẹlẹgbọn ọn agba di ọsẹ ti eto naa yoo kasẹ nilẹ.
ati tun fi ese isejoba mule si lorile-ede yii.
Kollington Ayinla ti sọ ẹni tó dá orin Fuji sílẹ̀ gan an ní Nàiìjíríà Wo àwọn Adelé-Ọba aládé méje tó jẹ́ obìnrin nílẹ̀ Yorùbá Àṣeyọrí Anthony Joshua fi hàn pé owó tí à ń ná lórí eré ìdarayá kò lọ lásán - Dapo Abiodun Wọ́n ti fi Omah Lay sínú ọgbà ẹ̀wọ̀n ní Uganda Ìjọba gbé ilé ijó oníhòhò tì pa lórí ẹ̀sùn títàpá sí ìlànà àti dẹ́kun coronavirus Ọkọ̀ àjàgbé agbépo kan tún dànù l'Eko Wo ohun tí yóò ṣẹlẹ̀ ní ìpàdé àwọn èèkàn Yorùbá láti mú kẹ́ẹ dìbò fún Tinubu ní 2023 Agbẹnusọ ile iwe giga naa ṣalaye pe alaga ẹgbẹ awọn olukọ ASUP nile ẹkọ naa, Ọgbẹni Adekunle Masopa ti fi igbesẹ igbimọ alaṣẹ to awọn olukọ ileewe ọhun leti Ọgbẹni Masopa alaga igbimọ alaṣẹ sọ idi mọkanlelogun tawọn fi ni ki ọga agba ileewe naa lọ rọkun nile.
Gege bi Martial se so, “Mo dupe pupo lowo Ole ati awon akonimoogba yooku fun igbagbo won lori mi, nitori pe won ranmi lowo pupo lati mu igberu ba ti mo se n kopa si.
Èèyàn 195 ní àrùn Coronavirus tún ṣẹ̀ṣẹ̀ ràn ní Nàìjíríà ní Ọjọ́ Ajé Ajọ to n gbogun ti ajakalẹ aarun lorilẹ-ede Naijiria, NCDC ti kede pe eeyan 195 miran ti kun iye awọn to ti ni aarun COVID-19 ni Naijiria.
 Bakan naa ni a ṣe ofin ti o nii ṣe pẹlu gbigbogun
6 Àti pé òun ti túmọ̀ ìwé náà, àní abala èyí tí mo paláṣẹ fún un, àti pé bí Olúwa àti Ọlọ́run yín ṣe wà láàyè ó jẹ́ òtítọ́.
 wọ ́ n á pèsè ajá fún ìrúbọ .
Nígbà náà ni alufaa yóo gba ẹbọ ohun jíjẹ ti owú náà lọ́wọ́ obinrin náà yóo sì fì í níwájú OLUWA, lẹ́yìn èyí, yóo gbé e sórí pẹpẹ.
Lọ́jọ́ tí mo bá ti lá àlá báyìí, jíjí tí mo bá jí ẹkún ni mo máa ń sun.
Báwo ni mo ṣe lè bá a rojọ́?
Bákanáà ló tún sọ nípa àwọn kọ́mú tó ní fùkẹ̀fùkẹ̀ (Foam) nínú àti àwọn èyí tí kò ní, àwọn tó lápá àti àwọn èyí tí kò ní pẹ̀lú irúfẹ́ asọ tí a leè wọ̀ wọ́n sí.
Nípa irú ìlànà wo ni kò fi sí mọ́?
Solomoni ọba ṣe pẹpẹ idẹ kan tí ó gùn ní ogún igbọnwọ (mita 9), ìbú rẹ̀ náà sì jẹ́ ogún igbọnwọ (mita 9).
Ilé ẹjọ́ kòtẹ́mílọ́rùn yọ alága ẹgbẹ́ òṣèlú APC Adams Oshiomhole nípò Agbẹjọ́rò ni n kò bá jẹ́, tí n kò bá bá bàbá mi ṣe tíátà - Sola Kosoko Iléeṣé tó ní bàálù tí Naira Marley lo lọ Abuja tọrọ àforíjìn lówó Mínístà Eeyan 5,623 lo ti ri iwosan gba, nigba ti awọn 455 ti dero ọrun nitori arun ọhun.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Iye goolu ti Salah ti wọnu awọn ni saa ere bọọlu yii ti di mẹtalelogoji Ni bayii, iye goolu ti Salah ti wọnu awọn ni saa ere bọọlu yii ti di mẹtalelogoji.
Ọ̀pọ̀lọpọ̀ òkú ẹyẹ igún ré bọ́ lọ́jà Eke-Ihe Àwa ò mọ ẹgbẹ́ kankan tó ń jẹ́ fijilanté fulani l'Ondo- Ìjọba ìpínẹ̀ Ondo Femi Adesina parọwa fawọn olujọsin Shiite pe ki wọn ni suuru nitori ọjọ Aje to m bọ nigbẹjọ yoo waye nile ẹjọ ni Kaduna.
Ó tún ìlú náà kọ́ yípo, bẹ̀rẹ̀ láti Milo, ibi tí a ti kun ilẹ̀ náà yíká.
Oríṣun àwòrán, @GovAyoFayose Àkọlé àwòrán, Ọmọ to jọ ‘Daddy’ gan ree.
Abimeleki yára dìde ní òwúrọ̀ kutukutu ọjọ́ keji, ó pe gbogbo àwọn iranṣẹ rẹ̀ jọ, ó ro gbogbo nǹkan wọnyi fún wọn, ẹ̀rù sì bà wọ́n gidigidi.
 titi to fi di 2011 , revels je ikan ninu awon omo afrika amerika mefa pere ti won ti diboyan si ile alagba amerika .
Wang Qiang, ọmọ orilẹede China lo bomi pana ala yii lẹẹkan sii nibi idije Australian Open to n lọ lọwọ.
O ti lọkọ Bidemi Kosọkọ di ìyá ìkókó lọdun 2019.
Paroparo ni agbegbe naa da ti iwọnba awọn eeyan melookan to n wọle si n ks ọrọ idaro wọn si iwe ibanikẹkun ti wọn ṣi pẹlu aworan oloogbe naa.
Lẹ́yìn ọjọ́ keje, OLUWA bá mi sọ̀rọ̀, ó ní: 
 Abiola niluu Abeokuta, ni ipinle Ogun.
Adeleke  to je oludije fun ipo gomina
Ṣaaju ni awọn oniwosan ibilẹ kan ti kọkọ sọ pe igbẹ erin le e koju aisan ọfinkin, ori fifọ ati lati dawọ ẹjẹ to n ṣan lati imu duro ti wọn ba le e gbe igbẹ naa gbona ki wọn si fi imu.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Àwọn dókítà LUTH daṣẹ́ lẹ̀ ṣè ìwọ́de lórí àìsí ààbò 22 Èbibi 2019 Awọn dokita ile iwosan ikọsẹ iṣegun ti ijọba apapọ to wa ni Ipinlẹ Eko, LUTH, ti da irinṣẹ silẹ lati ṣe iwọde loni.
 Ṣé ẹ mọ àdúgbò ìlú yín dada
Dájúdájú Ọlọrun kì í gbọ́ igbe asán,Olodumare kò tilẹ̀ náání rẹ̀.
 Wọn ti sin oloogbe naa nilana ẹsin Musulumi lọjọ Aje."
Eekan ọmọ ẹgbẹ oṣelu Republican nile aṣoju-ṣofin ilẹ Amerika, Liz Cheney sọ pe, oun ṣetan lati dibo yọ Trump nipo lori iṣẹlẹ ikọlu to waye nile aṣofin to wa ni Capitol lọsẹ to lọ.
Bakan naa ni, adari ile-ejo to wa lorile ede Naijiria ,  Ibrahim Tanko  Muhammed ti  bura fun igbakeji aare orile ede Naijiria Ojogbon Yemi Osinbajo.
Ajọ naa sọ pe lootọ ni Saudi sọ fun awọn l'oṣu Kẹta pe ki wọn o dawọ ipalẹmọ fun Hajj duro fun awọn arinrinajo lati Naijiria.
Ijọba ṣalaye pe bi o tilẹ jẹ pe ijọba ti fọwọ lilo hijab lawọn ileewe, kii ṣe dandan fun awọn akẹkọọ maa wọ papaa julọ awọn akẹkọọ ti kii ṣe ẹlẹsin musulumi.
Kí àwọn tí ó bẹ̀rù OLUWA wí pé,“Ìfẹ́ rẹ̀ tí kì í yẹ̀ wà títí lae.
Ajayi: ṣé ìwọ mọ irúfẹ́ ọmọ tí Yorùbá ń pè bẹ́ẹ̀?
Nígbà ti ẹ̀tù tán, mo bẹ̀rẹ̀ sí okùn-dídẹ sí ojú ọ̀nà àwọn ẹranko mo sì ń fi àdá mi pa ẹja káà kiri inú omí ṣùgbọ́n síbẹ̀síbẹ̀ mo ń yí inú igbó kiri mo sì ń wá èèso igi tí n ó jẹ.
 mo nawọ ́ mú oorun yìí lójú páálí .
Liverpool fí ogun ẹ̀yìn ja Barcelona Ta ni Ọ̀jọ̀gbọ́n Tijjani Bande tó di Ààrẹ ẹ̀ka Isọ̀kan Àgbáyé UNGA?
Ṣugbọn àwọn ìjòyè ilẹ̀ Amoni sọ fún ọba pé, “Ṣé o rò pé Dafidi ń bọ̀wọ̀ fún baba rẹ ni ó ṣe rán oníṣẹ́ láti wá bá ọ kẹ́dùn?
Ọpọlọpọ orile-ede to jagun Ebola lo lo igbesẹ ti wọn fi bori Ebola lati fi koju ajakalẹ arun Coronavirus.
Ọba Adesoji Aderemi, Ọọ̀ni Ifẹ̀ tó gba ipò ọba mọ́ tòṣèlú MKO Abiola, iṣẹ́ aṣẹ́gità ló fi bẹ̀rẹ̀ okoòwò Iṣọla Oyenusi rèé, ẹnití ìfẹ́ obìnrin ṣun dé ìwà ìdigunjalè Taiwo Akinkunmi, ọmọ Ibadan tó ya àsìá Naijiria Koda, ẹgbẹ awọn agbẹjọro nipinlẹ Eko naa ti ikede ati fọnran aworan sita loju opo Twitter pe, awọn yoo gba ẹjọ ro lọfẹ fun ẹnikẹni tawọn agbofinro ba mu sahamọ nitori iwọde naa nitori awọn ọmọ Naijiria ni asẹ labẹ ofin lati se iwọde alaafia.
Wèrè tí mò ń ṣe ní Facebook ló pawó fún mi-Esabod Ìtàn Aláàfin Aole rèé, tó gbé ìran Yòrùbá ṣépè Ẹ̀yin ẹlẹ́gbẹ́ òkùnkùn tẹ fẹ́ ṣe àjọ̀dún lónìí, lákọ la ń dúró dè yín - Iléeṣẹ́ ọlọ́pàá Bí àwọn adarí ìjọba ṣe ń kó Coronavirus, ń kọ wá lóminú - Ìjọba àpapọ̀ Kini a le sọ pe o fa eyi lasiko yii?
Àkọlé àwòrán, Àwọn alátìlẹyìn Fayoṣe tẹ̀lè lọ sílé ẹjọ́ Wọn si ti sun igbẹjọ si ọjọ kọkandinlogun, oṣu Kọkanla, ọdun 2018.
Àkọlé àwòrán, Aarẹ Trump ṣabẹwo akọkọ si orilẹ-ede Afghanista Aarẹ Trump kọkọ ya si papa ọkọ ofurufu Bagram Airfield lati sọro iwuri fawọn ọmnọ ogun to wa nibẹ.
Ni wọ́n bá dáhùn pé, “Ẹlẹ́rìí wo ni a tún ń wá?
Ó pàṣẹ pé kí àwọn tí ó bá lè lúwẹ̀ẹ́ kọ́kọ́ bọ́ sómi, kí wọ́n lúwẹ̀ẹ́ lọ sí èbúté.
Tí a fiṣọwọ́ ní 6:26 16 Sẹ́rẹ́ 20216:26 16 Sẹ́rẹ́ 2021 Ẹ wo ọba kan nílẹ̀ Yorùbá, tí kò ṣe ètùtù tàbí náwó ànájù, kó tó jọba Omogoriola Hassan ni kò dìgbà tí wọn bá fi èèyàn ṣe ìrúbọ, ká tó jọba, oun ko si nawo rara ti oun fi gori itẹ, awọn ilu lo se inawo iwuye oun.
Lara ẹsun ti wọn fi kan woli naa ati awọn eeyan rẹ ni iditẹ lati ji ọmọ gbe ati ẹsun jiji ọmọ gbe.
Ẹ máa fi Orin Dafidi ati orin ìyìn ati orin àtọkànwá bá ara yín sọ̀rọ̀.
idije ti yoo waye lonii yii .
Bakan naa ni akọni obinrin yii tun jẹ ọmọ Naijiria akọkọ ti yoo jẹ alakoso fun ẹgbẹ Girls Guides lọdun 1931.
Àwọn tí wọn ń da ọtí nù ni n óo rán, tí wọn óo wá tẹ̀ ẹ́ bí ìgò ọtíwọn óo dà á nù patapata, wọn óo sì fọ́ ìgò rẹ̀.
Ipade alatilekun mori naa bere laago mewa owurọ nile-ise aare niluu Abuja.
Òmùgọ̀ ni ẹni tí ó gbẹ́kẹ̀lé ara rẹ̀,ẹni tí ń fi ọgbọ́n rìn yóo là.
Nígbà tí Atalaya gbọ́ híhó àwọn eniyan, ati bí wọ́n ti ń sá kiri tí wọ́n sì ń yin ọba, ó lọ sí ilé OLUWA níbi tí àwọn eniyan péjọ sí, 
Ọmọ náà ń dàgbà, ó sì ń lágbára sí i lára ati lẹ́mìí.
Baba-baba-baba rẹ ni Daniel Adebambo Joshua, ọlọrọ onilẹ ati oniṣowo ti wọn gbagbọ pe o yan orukọ kẹta rẹ nigba to di ọmọlẹyin Kristi.
''Rasheed tabuku lu wa nitori pe o pe wa ni ẹgbẹ ti ko ni oye nipa iṣẹ to n ṣẹ'' ''Nitori naa ni bayii, ko si ọmọ ẹgbẹ wa kankan ti yoo lo orin Kwam 1 lori eto wa kaakiri iwo oorun orilẹede Naijiria.
Awọn agbesunmọmi Boko Haram tẹlẹ gba idande Ileesẹ Ologun ilẹ wa ti da awọn ọmọogun Boko Haram toto okoolerugba ati mẹrin silẹ lahamọ pẹlu afikun pe wọn ti se idanilẹkọ to yẹ fun wọn lati ri daju pe wọn jawọ kuro ninu iwa ipanle, ki wọn to tu wọn silẹ.
– Seyi Makinde 2019 Elections: NBC na Channels TV àti ilé iṣẹ́ ìròyìn 44 ní pàsán Ètò tí mo ní fún Kwara yàtọ̀ sí ti ANRP ni mo ṣe fẹgbẹ́ wọ́n sílẹ̀ - Yinka Ajia Wolii David Aderemi Babalola Atiku Abubakar ni oludije ti wolii yi sọ pe oun riran si ti o si fẹ le fi ogun rẹ gbari pe bẹẹ ni yoo ri.
Mo gbọ́ tí idì kan tí ń fò ní agbede meji ọ̀run ń kígbe pé, “Ó ṣe!
Falalu A Dorayi Nàìjíríà á bí ọmọ 25, 685 lọjọ́ kínni, oṣù kinni, ọdún 2019.
 Nigba to n sọrọ lori ibasepọ rẹ pẹlu awọn oṣere tiata, Oluomo ni iyọ̀ aye ati amuludun ni awọn oṣere tiata, iwọnba ti mo le ṣe, ni mo fi n ran wọn lọwọ, ohunkohun to ba sì wu awọn eeyan ni ki wọn sọ nipa ibasepọ wa.
Awọn si ni oludije akọkọ lati ilẹ Afirika ti yoo maa dije nibi ere idaraya ori yinyin lagbaye ti wọn n pe ni Winter Olympics.
Lẹ́yìn ìgbà tí wọn ju Johanu sinu ẹ̀wọ̀n, Jesu wá sí Galili, ó ń waasu ìyìn rere tí ó ti ọ̀dọ̀ Ọlọrun wá.
Mo fẹ ki ẹ ri ibi gẹgẹ bi ile yin ki ẹ si bọwọ fun awọn ọmọ iya yin to jẹ Yoruba'' Oríṣun àwòrán, CHIEF SUNDAY JUDE IYOKE Ninu alaye rẹ lori ọrọ naa, Ọjọgbọn Chidi ni ẹri jẹmi pe iran Igbo ṣẹ́ wa lati ile Ifẹ jẹyọ ninu orukọ awọn nnkan nilẹ Yoruba.
Ẹẹmẹta ni mo bẹ Oluwa nítorí rẹ̀ pé kí ó mú un kúrò lára mi.
Ó ní, “Ọkunrin kan wà níhìn-ín tí Fẹliksi fi sílẹ̀ lọ́gbà ẹ̀wọ̀n.
Bee si ni, gbogbo egbe oselu mejidinlaadọta ti o foruko sile fun idibo naa ni yoo tun kopa ninu atundi idibo ohun.
Ní àkókò yìí kannáà òun àti Olíver Cowdery ni a yàn sí Oyè-àlùfáà ti Áarónì láti ọwọ́ Jòhánnù Onítẹ̀bọmi nínú Oṣù Karũn 1829 (wo Ẹ&M 13), àti ní kété lẹ́hìnnáà a yàn wọ́n sí Oyè-àlùfáà ti Melkisédekì láti ọwọ́ àwọn Àpóstélì ìgbàanì Petérù, Jamesì, àti Jòhánnù (wo Ẹ&M 27:12).
O menuba pataki itoju aisan gbogbo lasiko nigba ti ko tii di eyi ti o n gbebo lowo awon alaisan ni eyi ti won le tete mo nipa re nipa sise ayewo loorekoore nile iwosan dipo mimu agbo atawon egbeoogi miran ti ko ni osuwon.
Ṣugbọn ìfẹ́ tèmi kọ́, ìfẹ́ tìrẹ ni kí ó ṣẹ.
"Wọn tẹsiwaju pe ''A o gbe igbesẹ to ba yẹ lori ọrọ yii nigba ti a ba pari iwadii wa""."
Mo ṣebí ẹni tí ó dá òde, òun náà ni ó dá inú.
Èèyà 315 ló lùgbàdì àrùn Coronavirus ní Naijiria ní ọjọ́ Ajé Nǹkan mẹ́wàá tó yẹ kí o mọ̀ nipa George Floyd tí ọlọ́pàá fún lọ́rùn pa rèé Pásìtọ̀ ìjọ Sotitobire Alfa Babatunde padà s'ẹ́wọ̀n, Iléẹjọ́ sún ìgbẹ́jọ́ sí ọjọ́ Ajé tó ń bọ̀ Ìrántí Sani Abacha, apàṣẹ wàá tó tún kó owó Nàìjíríà mì Lẹyin ọjọ diẹ ti awọn agbofinro ti n wa obinrin naa ni ọwọ tẹẹ ni Ọja Ọba nibi to ti n ta aṣọ 'Okirika' laarin ilu Akure.
”Ó dun Peteru nítorí Jesu bi í ní ẹẹkẹta pé, “Ǹjẹ́ o fẹ́ràn mi?
Ṣé kò yẹ kí á tú u sílẹ̀ ninu ìdè yìí ní Ọjọ́ Ìsinmi?
Awọn kan ti ẹ n sọ pe boya Minisita fun ọrọ abẹle tẹlẹ, Abdulrahman Dambazau le gba ipo naa, nitori pe o ti n dafun tolo si tipẹ.
Lagos Impeachment: Tinubu parí aáws Ambode àtàwọn aṣòfin ìpínlẹ̀ Eko
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Awọn agbẹ ti fẹhonuhan ni ọpọ igba sẹyin lori ohun ti ko tẹ wọn lọrun Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Agbekoya War: Ọta ìbọn kan ṣoṣo ló fa ogun tó fi ọ̀pọ̀ ẹ̀mí ṣòfò nínú ìtàn mánigbàgbé lẹ̀ Yorùbá13 Ògún 2020 Biafra at 50: Ọ̀nà tí ẹja panla gbà di gbajúgbajà nínú ìṣasùn nìyí14 Sẹ́rẹ́ 2020 Àtẹ Àwòrán, Biafra at 50: Àwòrán mánigbàgbé nípa ogun abẹ́lé Nàíjíríà15 Sẹ́rẹ́ 2020 Biafra at 51: Àwọn àgbààgbà ní àwọn ohun tó pilẹ̀ ogun abẹ́le kò tí dópin ní Naijiria15 Sẹ́rẹ́ 2021 Biafra at 50: Ó tó mílíọ̀nù mẹ́ta èèyàn tó bá ogun náà lọ6 Agẹmo 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Alaga ajọ INEC Ọjọgbọn Mahmood Yakubu lo sọ eyi di mimọ nigba ti ikọ awọn obinrin kan ti aṣoju obinrin fun ajọ iṣọkan agbaye lorilẹede Naijiria ati ajọ ECOWAS ko sodi bẹẹ wo ni ọfiisi rẹ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Kọmíṣọ́nà ọlọ́pàá ó ṣeṣe kó jẹ́ pé ará ló sán pa ènìyàn mẹ́ta 21 Ẹrẹ̀nà 2019 Oríṣun àwòrán, Dan (catching up) Flikr Ara ti san pa eniyan mẹta ni ijọba ibilẹ Guusu Ughelli ni Ipinlẹ Delta.
Ikọ Iswap to ṣe pe awọn ni wọn wa nidi ikọlu naa, yapa kuro lara Boko Haram to bẹrẹ ikọlu lọdun mẹwa sẹyin.
Igbakeji oga-agba  ile-ise naa, Zhao Qiang so pe, ile-ise fun oro ile-kiko lorile-ede Egypt, yoo senawo iko medogun ninu ida ogorun ti o ku, ti ile-ifowopamo orile-ede China ko na ohun.
Oluwo ṣalaye pe, ẹgbẹrun lọna ọgọsan owo naira loun kọkọ fi ranṣẹ si mama oun lọjọ ibi rẹ laipẹ yii, ki oun to tun ṣe afikun owo naa pẹlu ẹgbẹrun mẹtadinlọgọta mii.
HSBC ati UBS Oríṣun àwòrán, Reuters Awọn ileeṣẹ mejeji yii naa lorukọ nigba aye wọn, ṣugbọn ọdun 2018 ni wọn tilẹkun ṣọọbu lai sọ eredi ti wọn fi gbe igbesẹ naa.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Iwa ṣiṣe gaa yi ko yọ agba naa silẹ O salaye pe, pupo ninu awọn aisan ti o ma n ba ẹdọ inu ara jẹ, bii Hepatitis A ati Typhoid, maa n wọwa latara bi igbọnse ṣe ma n dapọ mọ omi mumu.
Awọn ọmọ Naijiria to n ṣe bẹbẹ lagbo eṣẹ kikan lagbaaye lo bi ọrọ yii.
" Báwo ni gbogbo alága kánsú Kwara ṣe de àhàmọ́ EFCC?
iwe abadofin pe ki orile ede Naijiria maa se ayẹyẹ eto ijọba
Ṣugbọn ileeṣẹ aarẹ, lati ẹnu Garba Shehu, ṣalaye pe gbogbo awọn oludije to wa lati abẹ aṣia ẹgbẹ oṣelu APC kaakiri orilẹede Naijiria ni aarẹ Buhari yoo ṣe ipolongo fun.
Mo fi ènìyàn sọ ọ kí wọ́n yìnbọn lù ú lẹ́ẹ̀mẹta, wọ́n yìn ín, ṣùgbọ́n kò bá a, nígbẹ̀yìn, òun pàápàá pa Ojúayédùn ti mo tún ni kí ó ba mi yìnbọn ní ẹ̀ẹ̀kẹrin.
Larisa: Má jẹ́ kí ọjọ́ orí rẹ dí ẹ lọ́wọ́ láti bẹ̀rẹ̀ ohunkóhun to wù ọ
O ni ti wọn ba gbe owo le owo ọkọ wọn lori, awọn eeyan ko ni ba awọn ileeṣẹ naa duna dura mọ, to n tumọ si pe awọn awakọ awọn ileeṣẹ naa yoo padanu iṣẹ wọn."
Awọn iroyin kan ti ẹ sọ pe, Elenu ma n sọrọ iwuri nipa rẹ si afurasi gbajuẹ naa.
Òdodo a máa dáàbò bo ẹni tí ọ̀nà rẹ̀ bá tọ́,ṣugbọn ẹ̀ṣẹ̀ a máa bi eniyan burúkú ṣubú.
Bakan naa ni awọn alaṣẹ sọ pe ko si nkan to jọ pe awọn ko fun wọn ni ounjẹ daada.
ifowopamo AFDB yoo satileyin fun awon ile ifowopamo aladaani to wa lorile ede
Ìbú rẹ̀ jẹ́ igbọnwọ kan (ìdajì mita kan).
Nígbà kan, àwọn ọba mẹrin kan: Amrafeli, ọba Babiloni, Arioku, ọba Elasari, Kedorilaomeri, ọba Elamu, ati Tidali, ọba Goiimu, 
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Yoruba Culture: ọjọ́ méje ni wọ́n fí n rẹ ẹ̀kú Danafojura kó tó jáde Yatọ si ti ajẹ, ọrun ni wọn ti ma n ya emere, wọn kii fun yan.
ipinle ti ijamba ogun ati omiyale sẹlẹ si jẹ N8,558,529,755 ,
Mo dìde, mo wò yíká, mo bá sọ fún àwọn ọlọ́lá ati àwọn ìjòyè, ati àwọn eniyan yòókù pé, “Ẹ má jẹ́ kí ẹ̀rù wọn bà yín.
Aare gbadura fun ogbeni Wlliams pe Olorun yoo tesiwaju lati ma a fun logbon lati je orisun awokose fun awon odo to n bo leyin.
Ìwà burúkú wo ni mo hù?
yan ohun ti won ba fe, boya won fe daabobo ojo iwaju orile ede yii tabi won fe
Tacha àti BBNaija: Bobrisky fẹ́ fi mílíọ̀nù kan náírà tọrẹ fún Tacha lẹ́yìn tí wọ́n lé e ní BBNaija
Láti inú ìdajì ẹ̀yà Manase, ẹgbaasan-an (18,000) wá; yíyàn ni wọ́n yàn wọ́n láti lọ fi Dafidi jọba.
'Awọn obinrin nilo ajọ iranwọ fun oṣelu' Ọ̀nà láti sọ fásitì Lautech di ti Ọyọ nìkan ni Makinde ń sán - Ìjọba Ọṣun Kí ni àyájọ́ ‘Má wọ kọ́mú’ wà fún?
Ọpẹmipọ Bamgbọpa: Obìnrin gbọdọ̀ kó ara rẹ̀ níjànu lórí ọ̀rọ̀ ìfẹ́ nínú tíátà
Alukoro Ajọ ọlopaa ni ipinlẹ Eko, Bala Elkana to fi idi ọrọ naa mulẹ fun BBC sọ wi pe akinkanju akẹẹkọ obinrin kan lo lọ fi ẹjọ oluko naa sun, lẹyin to ni olukọ naa sọ wi pe oun ko ni jẹ ki oun tẹsiwaju lo si SS3 ti oun ko ba baalopọ.
Mi ò m'àwọn ẹgbẹ́ tó ń gbé ''Tinubu 2023'' kiri- Bola Tinubu Iṣu ló wà nínú mọ́tò mi, kìí ṣe èèyàn ni mo sọ di iṣu - Afurasí Ajínigbé figbe ta ''Wàhálà Ikẹja ló sọ mí di oníṣẹ́ ọwọ́ àgbọn ní Badagry'' O ti le ni osu kan bayii ti aarẹ Buhari ti sebura fun saa keji sugbọn ti ko ti kede awọn minisita ti yoo wa ninu ijọba rẹ.
Super Blue tí ṣe àgbékalẹ̀ ìlànà fún irúfẹ́ orin kan tí ó dára fún ojú ọ̀nà: ó tún jáwé olúborí ní èèkàn sí i ní ọdún-un 1995 pẹ̀lú orin-in rẹ̀ ewì sí agbábọ́ọ̀lù kríkẹ́ẹ̀tì Brian Lara, tí ó pa á ní àṣẹ fún àwọn olùwòran láti “na pátákóo wọn sí òkè kí wọn ó ṣe àríyá”.
lọ ́ nà kìnní , gbogbo Ẹ ̀ gbá ló gbà abẹ ́ òkúta sí ìlú wọn.
Ọdun mẹẹdọgbọn ni yii ti orilẹede South Afirica gba ominira, eleyii to faye silẹ fun iran gbogbo to wa lorilẹede naa lati dibo yan ẹni ti o ba wu wọn.
Internet fraud: Ọwọ́ EFCC tẹ afurasú 'Yahoo boy' Olawale àti pásítọ̀ CAC tó lu Hayatou ní jìbìtì N12.
Isẹ kekere kọ ni Funmilayo ko nidi isẹ tiata loju aye ati lẹyin iku ọkọ rẹ, ki iku to yọ ọwọ rẹ lawo lasiko aisan ranpẹ.
Kogi: Ilé aṣòfin ti bẹ́rẹ́ ìgbésẹ̀ àti rọ igbákejì gómìnà ìpínlẹ̀ Kogi lóyè
Wọ́n létí, ṣugbọn wọn kò lè gbọ́ràn,bẹ́ẹ̀ ni kò sí èémí kan ní ẹnu wọn.
Àwọn ni wọn yóo jẹ́ orí fun yín, ẹ̀yin yóo sì jẹ́ ìrù fún wọn.
Iyawo Rehoboamu yìí bí ọmọkunrin mẹta fún un; wọ́n ń jẹ́: Jeuṣi, Ṣemaraya ati Sahamu.
Lasiko agbekale oro ohun, ogbeni Abubakar Chika Adamu ti o n sakoso fun ekun kan nipinle Niger salaye pe, opo egbe oselu miiran ni o kuna lati se idibo abele, eleyi ti ko si wa ni ibamu pelu ofin ati ilana ajo INEC.
    Báyìí ni Òmùgọ́diméjì bẹ̀rẹ̀ síí ṣe títí ó fi di alẹ́ ọjọ́ kẹfà tí ó ránṣẹ́ pé kí a wá rí òun ní nǹkan bí agogo mẹ́wàá dípò agogo méjìlá tí o dá, ọjọ́ náà la sì kọ ríì.
ko tii sọ igba ti won yoo kede esi idibo naa.
mojuto eto irinna ofurufu (International Civil Aviation Organization, ICAO) se onigbọnwọ
Wo aworan igbeyawo ọmọ gomina Ọyọ ati ti Kano Igbakeji aarẹ fẹ s'eyawo ọmọ rẹ Ogunlogo awọn oloselu lo pe si mọṣalaṣi nla to wa l'Abuja ati ile ijọba nibi igbeyawo ọhun.
(Ibẹ̀ ni wọ́n ń pè ní ilẹ̀ Refaimu, nítorí pé, àwọn Refaimu ni wọ́n ti ń gbé ibẹ̀ tẹ́lẹ̀, ṣugbọn àwọn ará Amoni a máa pè wọ́n ní Samsumimu.
ti yoo gba ijoba nimoran lona ti won yoo gba lati maa san ekunwo owo osu awon
Ẹ ṣọ́ra kí ẹnikẹ́ni ninu yín má fà sẹ́yìn kúrò ninu oore-ọ̀fẹ́ Ọlọrun.
Àwọn ọmọ Ateri tí wọn ń jẹ́ Hesekaya jẹ́ mejidinlọgọrun-un.
Bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé à ń sọ̀rọ̀ báyìí, sibẹ ó dá wa lójú nípa tiyín, ẹ̀yin àyànfẹ́, pé ipò yín dára jù bẹ́ẹ̀ lọ, ẹ ní ohun tí ó yẹ fún ìgbàlà.
O dabi ẹni pe ofin ijọba ni awọn ibikan pe ki olukulu joko sile rẹ ti n fidimulẹ ni awọn ilu kan ni Naijiria.
Amofin Abiade Abiola bá BBC Yorùbá sọrọ lori ìrírí rẹ̀ ninu igbeyawo pẹlu imọran fawọn ènìyàn pé nitootọ ifẹ dara ṣugbọn ko gbọdọ mu iku dani.
Ẹ kò gbọdọ̀ ṣàánú rẹ̀ rárá, ṣugbọn ẹ níláti mú ẹ̀bi ẹ̀jẹ̀ aláìṣẹ̀ kúrò láàrin Israẹli, kí ó lè dára fun yín.
Ibudo ikepo si bu gbamu nipinlẹ eko
Iniesta gba ife-eyẹ mọ́kànlélọ́gbọ̀n pẹ̀lú ikọ̀ Barcelona.
Ẹ kò gbọdọ̀ gbé ẹnìkan ga ju ẹnìkejì lọ.
"Ṣugbọn, ibatan Miller kan, fi iwe ẹri iku iya agba naa sita, ninu eyi ti wọn kọ ọ si pe aile mi daada, ati pe Covid-19 ""jẹ pataki"" ninu nkan to fa iku Arabinrin Glosser."
O fẹsun kan Ajimọbi pe ko fun oun nipo ẹgbẹ kankan nigba ti awọn jọ wa papọ.
Ọpọ awọn onwoye lo n beere pe ṣe erongba ibudo okoowo ilẹ Afrika ọhun ko ni foriṣanpọn bayii, nigba ti orilẹede Naijiria to ni eto ọrọ aje to tobi ju lọ ni Afrika, to tun jẹ olori ẹkun Afrika yọwọ kuro ninu rẹ nigba ti awọn to ku n dara pọ mọ ọ.
N óo jẹ ẹ́ níyà fún àwọn ọjọ́ tí ó yà sọ́tọ̀, tí ó fi ń sun turari sí àwọn oriṣa Baali, tí ó kó àwọn ohun ọ̀ṣọ́ rẹ̀ sára, tí ó ń sá tẹ̀lé àwọn olólùfẹ́ rẹ̀, tí ó sì gbàgbé mi.
N óo mú kí eniyan máa gbé orí yín bí ìgbà àtijọ́, nǹkan ó sì dára fun yín ju ti àtẹ̀yìnwá lọ.
Ó ní, “Kí á má rí i pé mo ṣe nǹkan yìí níwájú Ọlọrun mi.
"Igbákejì mínísíta fún ìlera ní Iran ti kó Coronavirus Ẹ jọ̀ọ́, ẹ má jẹ́ kí ikú ọmọ mi lọ lásán - Ìyá Tiamiyu tí ọlọ́páà pa Ààrẹ Buhari ṣí ilé iṣẹ́ àti afára ní ìpínlẹ̀ Ondo Ìjọba Germany mú afurasi ọmọ Boko Haram ""Àwọn ọ̀tá fẹ́ kí n kú ni ṣùgbọ́n Ọ̀lọ́run mi ò jẹ́, ẹ ó bẹ̀ mi kúrò láyé ni""."
Oríṣun àwòrán, @followlasg Àkọlé àwòrán, Akintọla Williams pe ẹni ọdun mọkandinlọgọrun bayii.
“Mi o Gbagbo pe, wahala wa ninu ajo NFF, ohun ti o se pataki julo fun mi ni lati koju mo ise mi.
Bi idiyele Bitcoin ba ṣe ri ni yoo sọ boya ẹni to fẹ ẹ ta yoo jere.
Ọjọgbọn Madhi tẹnumọ ọ pe o ti to ọsẹ mẹfa ti oun ti n sọ pe o yẹ ki wọn ra awọn ohun eelo eemi ṣugbọn pabo lo ja si.
Koda, iwadii kan fi han wi pe, ọkan ninu obinrin mẹta to jẹ ọmọ adulawọ dudu, ni o n ba aisan orí pipa ja.
Osinbajo so wí pé ọmọ tuntun ti atunto SARS yoo bí gbọdọ máa ṣíṣe lọnà to tọ ati eyi to yẹ.
Oríṣun àwòrán, Google Àkọlé àwòrán, Ile Ijọsin Sinagọọgu Tree of Life ni Pittsburg ti iṣẹlẹ naa ti ṣẹlẹ Awọn olujọsin ṣalaye pe isin akọkọ n lọ lọwọ ni nkan bii aago mẹwaa aaro ni ọkunrin yii wọle to si n yinbọn.
Amọ wọn ṣeleri pe awọn yoo ya Ajọ Nigerian Royal Museum ni lara wọn, ti yoo bẹrẹ iṣẹ ni ọdun 2021.
Awọn miran ni Bónírèsé Lawuyi ò fíngbá mọ́ èyí tó ti fín ò lè parun.
lo fa ogbeni Akinlade sile gege bi oludije fun ipo gomina.
Nígbà náà ni OLUWA sọ fún mi pé, “Lọ pa owó náà mọ́ sílé ìṣúra.
Fi ẹ̀wọ̀n wúrà mejeeji bọ inú òrùka mejeeji yìí.
ni, ogbeni  Abdulkadir Adebara ti o je
A bá wà níbẹ̀ fún ọjọ́ mélòó kan.
Ìdí tí mo fi gún olólùfẹ́ mi tẹ́lẹ̀ pa
Ọpọ awọn eeyan jankan ati awọn gomina ilẹ Yoruba lo ti n ṣelede lẹyin rẹ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Auxiliary: Alága àjọ Park Management System, gbé àwọn tó ń ja ìjọba lólè ní ibùdókọ̀ lọ sí ilèẹjọ́ 3 Owewe 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 9 Owewe 2020 Oríṣun àwòrán, Oyo Vanguard Alaga ajọ to n mojuto awọn ibudokọ nipinlẹ Oyo, Park Management System, Alhaji Mukaila Lamidi ti ọpọ mọ si Auxiliary ti gbe eeyan mẹfa to n jawee ayederu fawọn awakọ lọ sile ẹjọ.
O ni akojọpọ ibo 105,720, ti gomina tẹlẹri nipinlẹ Ọyọ Abiọla Ajimobi si ṣẹ ipo keji pẹlu onka ibo 92,218.
Segun mu òògùn apakòkòrò tórí máàkì 167 nínú JAMB ‘Emefiele kò jí owó o, ọ̀nà àbáyọ ló ń wa - CBN Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Lórí iṣẹ́ ikàn yìí, a ti kọ́ ilé, ọmọ ti lọ ilé ìwé' Amọ, kọmisọnna fun eto iroyin ni ipinlẹ Ondo,Yemi Olowolabi lasiko to n fẹsi si ẹsun yii ni awọn oloselu ni oun lo awọn adari awọn akẹẹkọ, ati wi pe awọn akẹẹkọ n san owo ile iwe lasiko lai si isoro kankan.
O fẹ ọpọ iyawo lati maa ba sere, ti wọn si n tẹle yika gbogbo ilu to ba n lọ.
O ṣalaye pe ileeṣẹ ọlọpaa naa n ṣe iwadii, ati pe ileewe Deeper Life High School ti sọ nkan to mọ nipa iṣẹlẹ naa.
Oorun rẹ buru jai o si n ṣafihan pe ẹni bẹẹ ni aisan igbẹ gbuuru.
Buhari: A lágbára láti san gbogbo gbèsè tí a jẹ
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ikọlu Dapchi: Awọn akẹkọ pada sile lẹyin ipade pẹlu Buhari 26 Ẹrẹ̀nà 2018 Oríṣun àwòrán, Nigeria Airforce Àkọlé àwòrán, Awọn ikọ ọmọogun ilẹ Naijiria lo sin wọn dele O le ni ọgọrun awọn akẹkọbinrin Dapchi ti awọn ikọ agbesunmọmi Boko Haram da pada, ti awọn ologun orilẹede Naijiria ti da pada sọdọ awọn obi wọn bayii ni ilu Dapchi.
Omọkunrin a dọbalẹ; ọmọbinrin a kunlẹ ki awọn to juu lọ.
Ramat ni orin to wa ninu Kengbe lilu maa n danilaraya, kọ ni lọgbọn, to si tun maa n pa ni lẹrin, paapa awọn orin aro, awada, idọwẹkẹ, amusẹya ati ẹẹkẹ eebu to kun inu rẹ.
Ebi kò ní pa wọ́n, òùngbẹ kò sì ní gbẹ wọ́n,atẹ́gùn gbígbóná kò ní fẹ́ lù wọ́n,bẹ́ẹ̀ ni oòrùn kò ní pa wọ́n,nítorí ẹni tí ó ṣàánú wọn ni yóo máa darí wọn,yóo sì mú wọn gba ẹ̀gbẹ́ omi tí ń ṣàn.
Aya Buhari pe ipe yii, nigba ti o n gba awon obinrin adari egbe oselu APC ni alejo lojo Abameta nile aare, to wa niluu Abuja.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù South Africa elections: Ǹjẹ́ àlàfo tó wà láàrin àwọn olówó àti tálákà n fẹ̀ si ni?
wo àwọn nọ́mba ọlọ́pàá tí o lé pé láti mọ ọ̀nà àbáyọ
Oríṣun àwòrán, osun state government/ twitter Ìjọba ìpínlẹ̀ Ogun fún àwọn ọmọ ilé ìwé ní ìgbéga sí kílààsì tó kàn láì ṣe ìdánwó nítori Covid-19 Ijọba ipinlẹ Ogun ti kede igbega si kilaasi to kan lai ṣe idannwo fun awọn ọmọ ile iwe alakọbẹrẹ ati girama ipinlẹ naa ni kete ti wọn ba pada ṣenu ẹkọ wọn.
O ko oruko apele oye re ni omobakunrin nigba ti won ko fun un lade lodun 2016 bo se fokan si gege bi ilana ile Faranse.
Lori ija oun ati Lizzy Anjorin, Ronke Oshodi ni aarin awọn ko fi bẹẹ dan mọran, amọ oun ti kii ku oriire fun ti igbeyawo rẹ.
Oríṣun àwòrán, @raufaregbesola Agbeyẹwo awọnohun ti Arẹgbẹsọla gbe ori aleefa se lọọkọkan.
O ni ipa ti o nipọn ni OPC yoo ko lori eto abo naa lati mu irọrun ba teru tọmọ.
Babajide Sanwo-Olu: Ìjọba ní Gómìnà Eko kò ní ṣ'àyẹ̀wò covid-19 míì
Ijọba ipinlẹ Eko lẹyin iṣẹlẹ Ita Faji ti bẹrẹ si ni wo awọn ile ti ko duro daada lati dena ijamba ẹmi ati dukia.
Àwọn tí ó béèrè ẹwà ara kábàámọ́ gidigidi, ẹlòmíràn tí ó wí pé orí òun tóbi jù ti rí orí mìíràn tí kò ju èèso òroǹbó lọ, èyí tí ó wí pé ẹsẹ̀ òun tẹ́ẹ́rẹ́ ti rí ẹsẹ̀ míràn tí ó dà bí ẹsẹ̀ erin, olójú kékeré ní ojú tì ó dà bí ojú agogo, olójú títóbi sì rí ojú tí ó dà bí ti adìẹ̀.
O n bẹ awọn eniyan lati lọ si awọn ile-iṣẹ ati ọja wọn deede laisi ibẹru ipaniyan tabi ipalara lati ọdọ ẹnikẹni bi awọn ọlọpa ati awọn eleto ile-isẹ aabo miiran ti wa lori ni pẹsẹ lati rii daju pe aabo to peye wa fun gbogbo eniyan.
Wọ́n dìbò yàn án sí ipò sẹ́nétọ̀ láti ṣojú ẹkùn ìdìbò ìlà oòrùn Ọṣun l'ábẹ́ àsìá ẹgbẹ́ òṣèlú PDP láàrin ọdún 2003 sí 2007, wọ́n tún padà dìbò yàn án ní 2007.
Nítorí náà, pẹlu ìtìjú ńlá ni Senakeribu fi pada lọ sí ìlú rẹ̀.
Wọn ni awọn osìsẹ́ Nàíjíríà wà lóórùn, náwónáwó àwọn olósèlú wà ní bòòji, ti wọn ko si naani eto idẹrun awọn osisẹ.
Ẹ wo awọn aworan diẹ lara awọn ohun to ṣelẹ nibẹ.
O óo lóyún, o óo sì bí ọmọkunrin kan, Jesu ni o óo pe orúkọ rẹ̀.
Ò dara pọ̀ mọ́ àwọn eléré Tíátà Nàìjíríà nípasẹ̀ Charles Olumọ tí gbogbo ènìyàn mọ̀ sí Agbako ẹni tó ń gbé ní ìlú rẹ̀ nígbà náà.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Port harcourt Bole: Mi kò mọ́ pé bọ̀ọ̀lì títà lè gbé mi dé ipò yìí láyé mi!
16 million ni ọmọ ọdún 65 àti jù bẹ́ẹ̀ lọ ní Hong Kong ìyẹn 15.
Oríṣun àwòrán, @tokstarr Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
 O ni, abajade naa waye lai fi igba kan bo kan ninu lataari bi eto idibo ohun se lo.
Kí ẹ tó fi mí lọ́rùn sílẹ̀kí n rí ààyè dá itọ́ mì?
, Duration 8,0016 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 6:56 Fídíò, Wòlíì Kasali sọ̀rọ̀ nípa awuyewuye pé ó lé ìyàwó rẹ̀ jáde nílé, Duration 6,5628 Ọ̀pẹ̀̀ 2018 8:23 Fídíò, Deborah Adebola Fasoyin: Èmi kọ́ ló gbé orin ọdún ń lọ sópin kalẹ̀, CAC ló ni í ni mó n ṣe àkójọ orin- Fasoyin, Duration 8,2331 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 2:23 Fídíò, Water Generator: Ó leè ṣiṣẹ fún wákàtí mẹfà, kó tó sinmi, Duration 2,2310 Òkùdu 2020 BBC News, Yorùbá Ìdí tí ẹ fi le è nígbàagbọ́ nínú ìròyìn BBC Ìlànà Lílò Nípa BBC Òfin Àṣírí Cookies Kàn sí.
Àlàyé rèé lóríi ìdí tí wọ́n fi ń pe aya ní ìyàwó Lisabi Agbongbo Akala rèé, ẹni tó fi ìfẹ́, ìṣọ̀kan àti ìrẹ́pọ̀ gba ilẹ̀ Ẹ̀gbá lọ́wọ́ ìmúnisìn Afọnja, ẹni tó finú wénú ní Ilọrin, àmọ́ tó jẹ iwọ Ọba Lamidi Adeyẹmi, òṣìṣẹ́ adójútòfò àti Abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò kó tó jọba A gbọ pe eku dúdú táa mọ sí Black Rats, to máa ń jẹ ohun ọ̀gbìn onihoro bíi àgbàdo àti ọkà bàbà lo ni kòkòrò aifojuri àrùn náà lára.
Ọ̀sẹ̀ ilẹ̀ Afíríkà rèé nínú àwòràn: 31 May
Ọ̀pọ̀lọpọ̀ ńláǹlà ni a pín sí kéékèèké.
Ní ọjọ́ náà gan-an ni Joṣua gba ìlú Makeda, ó sì fi idà pa àwọn eniyan inú rẹ̀ ati ọba wọn.
Ó ń tẹ̀lé Paulu ati àwa náà, ó ń kígbe pé, “Àwọn ọkunrin yìí ni iranṣẹ Ọlọrun Ọ̀gá Ògo; àwọn ni wọ́n ń waasu ọ̀nà ìgbàlà fun yín.
Lisabi Agbongbo Akala rèé, ẹni tó fi ìfẹ́, ìṣọ̀kan àti ìrẹ́pọ̀ gba ilẹ̀ Ẹ̀gbá lọ́wọ́ ìmúnisìn Ọmọ Nàìjíríà yarí lórí àbá láti mójútó ayélujára, ilé aṣòfin láwọn ń tẹ̀síwájú lórí ẹ̀ Marie Stopes ṣalaye siwaju pe awọn ni idaniloju pe ipele meji naa ni to paali rọba idaabobo ojilelọọdunrun o dín marun un ni eyi to le ni miliọnu kan rọba idaabobo kọọkan.
Gbogbo wọn yóo máa sọkún tẹ̀dùntẹ̀dùn olukuluku yóo máa dárò nítorí ẹ̀ṣẹ̀ rẹ̀.
Nitori báyìí ni OLUWA Ọlọrun wí, “Ẹ̀yin ń pàtẹ́wọ́, ẹ̀ ń fò sókè, ẹ sì ń yọ àwọn ọmọ Israẹli.
Ẹni tí a bá bí ní bíbí ti ẹran-ara, ẹran-ara ni.
Jose Antonio Reyes: Agbábọ́ọ́lù Arsenal nígbà kan rí kú ní ẹni ọdún márùndínlógójì
Ni iná bá sọ̀kalẹ̀ láti ọ̀run, ó bá jó wọn run patapata.
Ó sì sọ fún Kora ati àwọn ẹgbẹ́ rẹ̀ pé, “Ní ọ̀la OLUWA yóo fi ẹni tí í ṣe tirẹ̀ tí ó jẹ́ ẹni mímọ́ hàn.
Awọn ti iṣẹlẹ naa ṣoju wọn ni ṣaa deede ni ṣọọbu naa deede gab ina ni agbegbe Sabon Tasha ni Kaduna.
Nítorí bí Baba ti ń jí àwọn òkú dìde, tí ó ń sọ wọ́n di alààyè, bẹ́ẹ̀ gan-an ni, ẹnikẹ́ni tí Ọmọ bá fẹ́ ni ó ń sọ di alààyè.
Oríṣun àwòrán, Skye Bank release Eyi lo mu ki ajọ Amcon gbẹsẹ le awọn dukia rẹ kan to fi ṣe oniduro.
Ara a mi ko gba a, mi o si fẹ ẹ gba bọọlu niru ipo bayii.
Ẹ̀wẹ̀, nigba ti BBC Yoruba kan si alaga ẹgbẹ awọn olukọni ile iwe giga naa ASUP, Ọgbẹni Ijawo Rafiu jẹ ko di mimọ pe oun woye pe tori iwọde alafia ti awọn gun le lo fa a.
Ileeṣẹ Aarẹ nigba ti wọn n fesi sọ wi pe Obasanjo gan an ni mọndaru to n pin orilẹede Naijiria, ti o si n sọrọ ẹlẹyamẹya lati igba de igba.
 a ) àti ìkẹta ( ph.
“Ṣugbọn bí olódodo bá yipada kúrò ninu ìwà òdodo rẹ̀, tí ó bá bẹ̀rẹ̀ sí dẹ́ṣẹ̀, tí ó ń ṣe àwọn ohun ìríra tí àwọn eniyan burúkú ń ṣe; ṣé irú ẹni bẹ́ẹ̀ leè yè?
 Aare tun lo anfaani ohun lati
Lapapọ, Giroud ti gba goolu mejilelogoji sawọn bayii fun orilẹede Faranse ninu ọgọrun un bọọlu to ti ṣoju ilẹ naa.
Ile isẹ ọlọpa ni ati bii ọjọ mẹwa ni ọmọ ọdun meje naa ko ti ba baba rẹ sọrọ ninu ile, ko to di wi pe ile isẹ ọlọpaa naa wa pẹtu si aawọ laarin baba ati ọmọ.
Oríṣun àwòrán, @others Àkọlé àwòrán, Iwa ọmọluwabi ṣe pataki pupọ nilẹ Adulawọ Akitiyan ileeṣe BBC lati ba aṣoju ile iṣẹ ti n ṣe amojuto ọrọ aṣa ati iṣe ni Naijiria ati ajọ BBNaija sọrọ lori koko ọhun bayii lo ja si pabo.
igbomina Ẹ ̀ ka-èdè Ìgbómìnà jẹ ́ ẹ ̀ yà èdè yorùbá tí àwọn Ìgbómìnà ń sọ .
Lẹ́yìn tí wọ́n rí àwọn onigbagbọ, tí wọ́n sì gbà wọ́n níyànjú, wọ́n kúrò níbẹ̀.
Bí mààlúù ẹnìkan bá pa ti ẹlòmíràn, àwọn mejeeji yóo ta mààlúù tí ó jẹ́ ààyè, wọn yóo pín owó rẹ̀, wọn yóo sì pín òkú mààlúù náà pẹlu.
Ó ní onítọ̀hún gbọdọ sún mọ́ Ọlọ́run dáadáa, kí àjọṣepọ̀ rẹ pẹlu Ọlọ́run sì dán mọran.
OLUWA, da ẹ̀rùjẹ̀jẹ̀ bò wọ́n,jẹ́ kí àwọn orílẹ̀-èdè mọ̀ pé aláìlágbára eniyan ni àwọn.
Ijọba gbe igbesẹ naa nitori rogbodiyan to bẹ silẹ laarin ifẹhọnuhan EndSars.
Eto oro ajeAare ni ijoba ohun ti da kiko iresi lati oke okun wa si orile ede Naijiria duro, paapaa julo iresi.
Ṣugbọn n óo ka àkọsílẹ̀ náà fún ọba, n óo sì túmọ̀ rẹ̀.
Bàbá ọmọ tí Mammadou Gassama dóòlà ẹ̀mí rẹ̀ lọ ẹ́wọ̀n Buhari, Merkel fọwọ́ sí àdéhùn lórí ìrìnàjò ọmọ Nàìjíríà sí Germany Ọlọ́pàá ní àwọn ṣì ń ṣèwádìí ẹni tó bẹ́rí ní Alasiya l'Eko Kílódé tí ìjọba Nàíjíríà kò fòpin sí lílo ike rọ́bà lẹ́ẹ̀kan?
APC news in Ondo State: Yahaya Bello ni alága ìgbìmọ ìdìbò abẹ́lé gónìnà ìpińlẹ̀ Ondo
 Àwọn iṣé àpilẹ ̀ kọ tó ti tẹ ̀ jáde láti ọdún 1958 ní ó jẹ ́ ọ ̀ kan gbòógì nínú àwọn iṣẹ ́ ìbèrè-pẹ ̀ pẹ ̀ èdè yorùbá .
Ìdábẹ ́ fún ọmọbìrin ní orílẹ ̀ èdè nàìjíríà jẹ ́ àṣà tí wọ ́ n ti fòfin dè .
Oríṣun àwòrán, facebook/Ooni ile ife Àkọlé àwòrán, Awuyewuye sọ nigba ti Olúwó ni Emir ni orùkọ oyè tí òun fẹ́ máa lo Bákan náà ni, Kábíyèsí Ọọ̀ni ilé ifẹ̀,Oba Adeyeye Ogunwusi Ọ̀jájá kẹ́ta tun yànnàná pataki iṣọ̀kan laarin àwọn lọ́balọ́ba ní ilẹ̀ Yorùbá.
Naira Marley: Ilé ẹjọ́ ní Naira Marley ń rìn ní bèbè ẹ̀wọ̀n lọ́dún 2020 bí kò bá fara hàn lórí ẹ̀sùn ìjọ́kọ̀gbé
Ebi yóo pa yín tóbẹ́ẹ̀ tí ẹ óo máa pa àwọn ọmọ yín jẹ.
 Won sapejuwe re gege bii Jane Austen ti Kano to n ko iwe itan aroso to da lori ife ti won tun n pe ni Littattafan Soyayya (iwe ife).
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, India: Ẹ wo bí àwọn ènìyàn ṣe dóòlà èmí erin tó jálulẹ̀ APC lo wọle atundi ibo ile aṣofin Katsina Ọmọwe Ibrahim Aminu Kurami lo bori ninu atundi ibo ile igbimọ aṣofin ipinlẹ Katsina ti ẹkun Bakori.
 Àkọsílẹ ̀ lórí turkic wà ní nǹkan bíi sẹ ́ ńtúrì kẹ ́ jọ ( 8th century ) ṣùgbọ ́ n a kọ ̀ mọ nǹkan kan nípa mongolian ṣáájú sẹ ́ ńtúrì kẹtàlá ( 13th century ) .
OLUWA sọ fún Aisaya ọmọ Amosi pé, “Dìde, bọ́ aṣọ ọ̀fọ̀ tí o lọ́ mọ́ra, sì bọ́ bàtà tí o wọ̀ sí ẹsẹ̀.
Ighalo ti gba goolu mẹrin sawọn lẹẹmẹrin ninu ifẹsẹwọnsẹ mẹjọ to lanfaani lati ṣoju Man U ninu rẹ ki o to di wi pe wọn so ere bọọlu rọ nilẹ Gẹẹsi nitori ajakalẹ aarun coronavirus.
Lẹyin gbogbo sinima orita awoo wo tan to ti ṣẹlẹ sẹyin ni ipinlẹ Ondo, Gomina Rotimi Akeredolu to ti tukọ ipinlẹ naa lọdun mẹrin sẹyin ni o tun ri tikẹẹti gba lẹẹkan sii Mo káàbámọ̀ pé mo yan Ajayi gẹ́gẹ́ bíi igbákejì mi- Akeredolu .
Won ń ké báyìí, ‘A kì í wó o, ẹ yàgò fùn un, ẹ yàgò fún un.
OAU: Ọ̀jọ̀gbọ́n jẹ̀bi ìbèèrè ìbálòpọ̀ fún máákì
Ta ni ó dà bí olùfẹ́ mi nínú ayé!
A ká a mọ́ ibi tí ó ti fẹ́ mú ohun ẹ̀gbin wọ inú Tẹmpili, a bá mú un.
Ni ilú Àmẹ́ríkà ni àwọn ti ó fi ẹsin Ìgbàgbọ́ bojú ti kó si abẹ́ àwọn Aṣòfin ilú Àmẹ́ríkà ni ayé àtijọ́ pé Aláwọ̀dúdú ki ṣe èniyàn, nitori eyi, ó lòdi si òfin ki Aláwọ̀dúdú fẹ́ Aláwọ̀funfun, bi wọn bá fẹ́ra, wọn kò kà wọn kún tàbi ka irú ọmọ bẹ ẹ si èniyàn gidi.
Florida: Ọọ̀nì àléégbà dé ba Mary lálejò lọ́gànjọ́ òru
Laipẹ́, ọmọ tí kò bá pé ọdún méjìdínlógún kò ní leè jáde girama l’Ọṣun
Akinola ni ohun to jẹ gomina Seyi Makinde lọkan ni lati mu igbe aye irọrun ba awọn eeyan ipinlẹ Oyo.
Nígbà ti ọọrundunrun mẹ́jọ míràn tún gùn ún, oníṣègùn òyìnbó kan tó jẹ́ ọmọ ilẹ̀ Gẹ́ẹ̀sì Edward Jenner wá woye pe àwọn ọmọ tó ń fún omi ọmu Mààlú ní àìsàn to nííṣe pẹ̀lú àwọn màálu yìí sùgbọ́n àìsàn ṣàpọ̀ná (Smallpox) o mú wọ̀n.
Oríṣun àwòrán, others O ni iyawo oun tun mu abikẹyin awọn lọ si ọdọ mama rẹ lai gbaṣẹ lọwọ oun.
Super Eagles: Akojọpọ aworan asọ fun ife ẹyẹ agbaye
OLUWA ti bukun oluwa mi lọpọlọpọ, ó sì ti di eniyan ńlá.
 ní ilẹ ̀ aláwọ ̀ dúdú .
Awọn ibudo ifinipamọsi fun ayẹwo awọn ti wọn kẹẹfin pe o seese ko ni arun iba lassa yii jẹ mẹta tijọba ipinlẹ Ọsun gbe kalẹ, eyi to jẹ ara igbesẹ lati dena itankalẹ arun yii.
Ó to àwọn ọ̀pá wọnyi siwaju àwọn ẹran níbi tí wọ́n ti ń mu omi, nítorí pé, nígbà tí wọ́n bá wá mu omi ni wọ́n máa ń gùn.
Ṣé ò ní ìpinnu ọdún tuntunt?
Nigba to n ba BBC Yoruba sọrọ, Yemi Adenuga ni o se ni laanu pe awa alawọ dudu gangan ni ọta ara wa nitori awọn ọmọ Naijiria gan lo dide tako oun pe oun ko ni wọle ibo kanselọ naa.
Awọn ami wo lo ma n jẹyọ ti obinrin ba ti dawọ nkan osu?
Ebuka jẹ agbohunsafẹfẹ lori ẹrọ amohunmaworan to ni awọn ololufẹ to pọ pupọ.
Ẹ ṣe àyẹ̀wò àpẹrẹ ẹrú ati owó àna fún Idilé Arinmájàgbẹ̀ ni Ìbòròpa-Àkókó, Ipinlẹ̀ Ondó ni ojú iwé yi.
Gbogbo ohun tí ó wà lórí ẹ̀mí wọn ni pé kí wọ́n ṣá rí owó lọ́nàkọnà.
Lori atẹ igbelewọn ajọ to n mojuto bọọlu l'agbaye, ipo kejidinlaadọfa ni Madagascar wa ti Naijiria si wa ni ipo kejilelogoji.
Bakan naa, igbakeji Aarẹ orilẹede Naijiria, Yẹmi Ọṣinbajo ti oun naa jẹ ọkan lara awọn olujiroro nibi eto naas ọ pe wahala nla ni gbigbe ayederu iroyin n da silẹ ni awujọ.
ati sí ara tabili, ati gbogbo àwọn ohun èlò orí rẹ̀, ati sí ara ọ̀pá fìtílà ati gbogbo àwọn ohun èlò rẹ̀, ati sí ara pẹpẹ turari, 
Premier league: Manchester United jẹ àjẹkún ìyà góòlù méjì lọ́wọ́ Westham United
FCT-258 Lagos-248 Kaduna-117 Katsina-52 Ogun-27 Kwara-23 Gombe-22 Adamawa-17 Plateau-15 Kano-6 Rivers-2 Ondo-2 Ekiti-2 Nasarawa-2 Sokoto-2 Taraba-1 Eeyan 675 tun ni COVID-19 ni Naijiria Eeyan ẹgbẹta ati marundinlọgọrin ni esi ayẹwo coronavirus ti ajọ NCDC fi sita ni ọjọ kẹwaa, oṣu Kejila dun 2020 fihan pe o tun ti ni aarun naa ni Naijiria.
Gege bi oro Andu, ipinle Benue n koju ipenija eto-abo , nipa ikolu ati iseku pa awon ara-ilu, ti o n fi igba gbogbo waye, bakan naa,  biba awon dukia ati eto oro-aje ipinle naa je, eyi ti o n pe fun isokan awon omo ipinle Benue lati le bori awon ipenija naa.
Sisọrọ kubakugbe niiṣe pẹlu sisọ ọrọ tabi lilo aworan ti o le ṣe ipalara tabi tabuku ba ẹni ti wọn n sọ ọ si lawujọ.
Arabinrin Kafayat fi to wa leti wi pe, iku Barakat mu ayipada nla de ba ile ti wọn n gbe, nipasẹ awọn alaanu to dide si wọn.
Oríṣun àwòrán, @APCUKingdom Nabena salaye pe ẹsun gbigbe owo ilu lọ sẹyin odi ti wọn fi n kan awọn eekan PDP naa ls silu Dubai lati ipasẹ Hushpuppi lo yẹ ki wọn tanna wadi rẹ.
"B Joshua-Angel Gomes Mò ń ronú láti padà sí ẹgbẹ́ agbábọ́ọ̀lù Nàìjíríà, Super Eagles láìpẹ́- Odion Ighalo Mo fẹ́ kí Ighalo gba ife pẹ̀lú Manchester United kó tó kúrò lọ́dún 2021- Solskjaer Arsenal rántí ""Invincibles,"" ó pé ọdún mẹ́rìndínlógún tí Arsenal gba ife Premier League Lọjọru ni ifẹsẹwọnsẹ idije Premiership ilẹ Gẹẹsi yoo tun gbinaya lẹyin idaduro oṣu bii mẹta nitori arun coronavirus to bẹ silẹ kaakiri agbaye."
Akẹkọọbinrin kan ti orukọ rẹ n jẹ doyinsola sọ pe o ṣe pataki lati fun ọmọbinrin ni ẹkọ to ye kooro nitori eyi lo maa jẹki idagbasoke ba orilẹede lapapọ O salaye pe oun fẹ lọ kẹkọ ni fasiti pẹlu erongba lati ṣe imoriwu fun awọn ọmọbinrin lagbaye.
Ó súnmọ́ òde ọ̀run ju òkè Láńgbòdó lọ nítorí ọjọ́ mẹ́sàn-án ni àwọn ará ibẹ́ máa ń ná ọjà pẹ̀lú àwọn ará òde ọ̀run.
Ile-ejo giga ohun wa dajo pe, gbogbo
" Ẹgbẹ́ òṣèlú PDP, ẹ̀ka ìpínlẹ̀ Eko fún Fayose lọ́jọ́ méje láti bẹ àwọn adarí ẹgbẹ́ Ẹgbẹ́ òṣelú People's Democratic Party (PDP) ni ìpińlẹ Eko ti fún gómìnà àná ní ìpínlẹ̀ Ekiti Ayodele Fayose ni gbédéke ọjọ méje láti rawọ́ ẹ̀bẹ̀ sí àwọn àgbà ẹgbẹ́ PDP.
Lẹ́yìn oṣù márùn ún, Buhari kọ̀ láti yọ ọ̀ga NHIS Ìjọba àpapọ̀ bẹ̀rẹ̀ ìwáàdí ẹ̀sùn tí wọ́n fi kan Usman Yusuf Buhari d'akọwe eto ilera pada s'ẹnu iṣẹSoyinka s'ọrọ lori ipaniyan awọn darandaran Ọlọ́pàá dóòlà àgùnbánirọ̀ 5 lọ́wọ́ ajínigbé Bakan naa ni aarẹ Buhari ti gba pé ki wọn tu ile awọn ọmọ igbimọ adari ajọ adojutofo NHIS ka.
Filistini náà sì ń rìn bọ̀ wá pàdé Dafidi; ẹni tí ń ru asà rẹ̀ sì wà níwájú rẹ̀.
“Orúkọ àwọn ọmọ Israẹli yóo máa wà lára Aaroni, lórí ìgbàyà ìdájọ́, ní oókan àyà rẹ̀, nígbà tí ó bá wọ ibi mímọ́ lọ, fún ìrántí nígbà gbogbo níwájú OLUWA.
Ọkan o jọkan eto ni ajọ to n lewaju ipe fun itusilẹ awọn akẹkọbinrin yii ti la kalẹ bayii.
Ó rán àwọn oníṣẹ́ sí ààrin ìlú pé kí wọ́n sọ fún Ahabu, ọba Israẹli pé, “Benhadadi ọba ní, 
’ Èmi OLUWA Ọlọrun ni mo sọ bẹ́ẹ̀.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, AFCON2019: Idije òní á yàtọ̀ láàrin Super Eagles ati BafanaBafana Ṣugbọn Akọṣile yi tẹnumọọ fun BBC pé oun duro lori ọrọ àkọ́sọ oun pé Sanwo Olu kò fún ẹgbẹ agbabọọlu Super Eagles lowo.
Níwọ̀n ìgbà tí ẹ̀ ń pe Ọlọrun ní Baba tí kì í ṣe ojuṣaaju, tí ó jẹ́ pé bí iṣẹ́ olukuluku bá ti rí ní ó fi ń ṣe ìdájọ́, ẹ máa fi ìbẹ̀rù gbé ìgbé-ayé yín ní ìwọ̀nba àkókò tí ẹ ní.
Awon alase so pe, awon eniyan tinu-n-bi n ju okuta lu awon olopaa, nigba ti awon  olopaa n gbiyanju ati pale mo opopona ti awon awako aladani duro si.
Akọwe Arẹwa to salaye ọrọ yii fawọn akọroyin , tun fikun pe, ẹgbẹ Arẹwa kede atilẹyin rẹ fun oludije fẹgbẹ oselu APC, aarẹ Muhammadu Buhari lẹyin to ti se agbeyẹwo afojusun ẹgbẹ oselu kọọkan, ileri ohun ti wọn fẹ se se ati bi oludije kọọkan se kun oju osuwọn si.
 Àlà ilẹ ̀ wà ní abẹ ́ lẹ ̀ pẹ ́ lú àwọ ̀ ewé àti ojú ọ ̀ run tó búlúù .
Oríṣun àwòrán, Science Photo Library 5.
Sọra lati ma a gbe ọwọ le nkan ni ita gbangba tabi ATM; Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Eégun àti orò, bí wọ́n ṣe jọ bí Ẹ̀ṣà Egúngún nílẹ̀ Yorùba rèé O lewu lati ma a gbe ọwọ le ohun gbogbo ti o ba ri ni itagbangba nitori ẹni to ti lugbadi arun Coronavirus ti le lọ ibẹ, Eleyii ti o le mu ki eniyan ko arun naa, to fi mọ kiosk, ile igbọnsẹ, ati bẹẹ bẹẹ lọ.
báwo ni a óo ti ṣe sá àsálà, tí a bá kọ etí-ikún sí ìgbàlà tí ó tóbi tó báyìí?
E̩nì kò̩ò̩kan ló ní è̩tó̩ láti jé̩ o̩mo̩ orílè̩‐èdè kan.
Thunder lati odun 2016, ti o ti dẹnu kole.
Nígbà náà ni ó mú mi lọ sí ẹnu ọ̀nà tí ó wà ní ìhà àríwá ilé OLUWA.
”Wọ́n tún bi í pé, “Ìwọ ni wolii tí à ń retí bí?
Ara ti awọn oyinbo ko lee da, ọmọ Naijiria kan ree to n daa, nipa sise agbekalẹ ẹrọ kan to n pese ina ọba latipasẹ amulo omi lasan.
''O fẹ ba mi lorukọ jẹ ni.
Ọfiisi akọwe ijọba apapọ lo fi ọrọ yii lede lọjọ Ẹti, bakan naa lọrọ naa wa loju opo Twitter ileeṣẹ Aarẹ.
Leah Sharibu pé ọmọ ọdún 16 ní àhámọ́ Boko Haram Èmi kò ní kí Shiite má ṣe ẹ̀sìn won o -Muhammadu Buhari Ẹgbẹ́ agbésùmọ̀mí ISWAP ti ní adarí tuntun Ologun Nigeria gbakoso ibuba Boko Haram Ọpọ ti di alaini ile lori ti karakata lagbegbe ibi ti Boko Haram ti n ṣoro ti dẹnukọlẹ lariwa Naijiria.
Jesu dá a lóhùn pé, “Ó wà ní àkọsílẹ̀ pé, ‘Kì í ṣe oúnjẹ nìkan ni yóo mú kí eniyan wà láàyè.
Àwọn tí ó ń yá àwọn ère náà dàbí wọn,bẹ́ẹ̀ sì ni àwọn tí wọ́n gbẹ́kẹ̀lé wọn.
Oludari KADECO onimo ero Lawal Lawal, wa salaye pe ida mejo ninu ogorun un ni ile-ise yii letoo si, ni eyi ti won n pin si ipinle Kaduna, Sokoto, Zamfara ati Kebbi.
Koda awọn arinrinajo to n lọ ọna jinjin ko lee ṣi kuro loju kan tori ijamba yii.
Ṣe bi eeyan ba ku nibi kan, o leepada lọ di alaaye ni ilu miran?
Nítorí àwọn ẹlòmíràn jẹ́ akúra kí á tó bí wọn, eniyan sọ àwọn mìíràn di akúra; àwọn ẹlòmíràn sì sọ ara wọn di akúra nítorí ti ìjọba ọ̀run.
Lojo Eti to koja ni ijob aamerika labe are Trump pinnu lati dekun ipese iranwo yii fun UNRWA.
O ni asiko yii si jẹ ígbà tí àwọn ń wa iṣẹ́ tí àwọn yóò máa ṣe láti fi rí owó.
àwọn alatilẹyin Liverpool yóò gbè lẹyìn Man Utd
 nítorípé , ìyí ayípadà kan tí kò ní agbènọ ́ mbàga lórí jẹ ́ ókan .
A níláti tọ́ka sí i pé Ìjẹ̀bú ti Ìjẹ̀ṣà yí lè ní nnkan kan í ṣe pẹ̀lú Ìjẹ̀bu ti Ìjẹ̀bù –Òde.
Koda, Bukola Saraki to jẹ ọmọ bibi Dokita Olusola Saraki sebi ẹni tako baba rẹ pẹlu bi ko se gbaruku ti aburo rẹ, Sẹnẹtọ Gbemi Saraki ti baba rẹ fẹ ki o jẹ Gomina lẹyin rẹ.
Ọlọ́pàá ilẹ̀ Gẹ̀ẹ́sì ti sanwó ìtaràn £2500 fún oníwàásù ọmọ Nàìjíríà tí wọn mú lọnà àìtọ́
Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Fídíò, Natalia Mufutau ìyá Yakub, Kamil àti Adam sọ̀rọ̀ lórí bí wọ́n ń sọ èdè mẹ́rin pàpọ31 Ògún 2020 Fídíò, Wole Soyinka sọ ìdí tó fi ni òun a fi màálù Fulani ṣe súyà fáwọn èèyàn abúlé23 Owewe 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Bakan naa, ifigagbaga pelu Iceland yoo waye ni papa isere Volgograd lojo kejilelogun inu osu kannaa, ti won yoo si lo gba ifesewonse keta pelu Argentina ni papa isere Saint Petersburg lojo kerindinlogbon inu osu kefa.
Stella Obasanjo Motherless: A ti rí àwọn ọmọ tó sọnù ní ilé àwọn ọmọ òrukàn ní Abeokuta
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ere bọọlu ilẹ Afirika Keshi ti orukọ inangijẹ rẹ jẹ ''Big Boss'' lagbo ere bọọlu ni Naijiria naa lo tun ko ẹgbẹ agbabọọlu Mali lọ si idije AFCON lọdun 2010.
Nígbà tí ọba Babiloni gbọ́ ìró wọn,ọwọ́ rẹ̀ rọ,ìrora sì mú un bíi ti obinrin tí ń rọbí.
Ìwọ tóò forúkọ sílẹ̀ lórí ẹ̀rọ ayelujára, owó ìfẹ̀yìntì rẹ lo fi ń ṣeré"" #FreeSowore: Àwọn ọmọ Naijiria fi gbe ta lórí Sowore ti DSS mú!"
Nelson Chamisa ti o je igbakeji adari egbe oselu naa ni won yan gege bi Aare fidihe, bi awon alatileyin egbe oselu ohun se kora won jo siwaju olu ile-ise naa lojo-Isegun lati kedun iku ologbe Tsvangirai.
Ẹnìkan tí ìṣẹ̀lẹ̀ nàá ṣojú rẹ̀, Adeyẹye Ishọla, sọ fún BBC Yoruba pé àwọn kan lára ọmọ ẹgbẹ́ NURTW ọ̀hún ló fẹ́ yọ alága ẹgbẹ́ wọn tó ti wà nípò láti àsìkò ìṣàkóso gómìnà Ayọdele Fayose, tí àwọn alátìlẹyìn ti ẹ̀ nàá sì gbáná wojú wọn.
Eyi ti fihan wipe bi awọn agbalagba se n pọ si lawujọ ni ọpọlọpọ ọkunrin n ku nitori aisan jẹjẹrẹ asẹtọ.
Kọmisana tuntun naa ní orílẹ̀ èdè Nigeria jẹ́ ibi ti ìbọ̀wọ̀ fún ni ti ṣe pàtàkì, tí òun si ti ṣetan láti rii dájú pé òun ṣe ojúṣe oun botitọ́ àti botiyẹ, àti bibọwọ fun gbogbo ẹni tó ba tọ pẹ̀lú ìrẹ̀lẹ̀.
Eniyan mọkanlelogojilenigba ninu awọn to ni arun ọhun ni Naijiria ti ri iwosan gba, ṣugbọn ogoji eniyan ti filẹ ṣaṣọ bora.
Ọkan lara awọn ibudo yii ni ti ibudo isẹmbaye to wa ni ilu Porto Novo, Cotonou ni orileede Benin.
Osere tiata naa tun gbarata pe bi o tilẹ jẹ pe ilumọọka osere ni oun, sibẹ, oun n sisẹ kara laisinmi ni, to fi mọ ọpọ akẹẹgbẹ oun, tawọn si n ko okoowo meji, mẹta papọ ki awọn baa lee ri ọwọ mu lọ sẹnu.
Igba ti mo bi ọmọ mi kekere omi kọ, ko jade.
Usieli bí ọmọkunrin mẹta: Miṣaeli, Elisafani ati Sitiri.
Jọ̀wọ́, jẹ́ kí Solomoni ọmọ mi, fi gbogbo ọkàn rẹ̀ pa òfin, àṣẹ ati ìlànà rẹ mọ́, kí ó lè ṣe ohun gbogbo, kí ó sì lè kọ́ tẹmpili tí mo ti múra rẹ̀ sílẹ̀ fún.
Laipẹ yii ni ile ẹjọ giga ti ijọba apapọ Naijiria, to wa ni ilu Umuahia nipinlẹ Abia, gba oniduro oludasilẹ ijọ Satani, Ifekwe Udo.
Bá mi mú àwọn ìwé mi náà bọ̀, pataki jùlọ àwọn ìwé aláwọ mi.
Lasiko ijokoo ile naa, asofin mẹsan lo fọwọsi iwe pe awọn ko fara mọ iyọnipo igbakeji gomina naa.
"Mo dúpẹ́ lọwọ Ọlọ́run, àwọn ọlọ́pàá Ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́, àwọn akin èèyàn ti wọn dúró ti mi bíi oloye Sunday Igboho, Alhaji Mutiu Onimaalu àti àwọn èèyàn tó fi owó rán mi lọ́wọ́ láti san fún àwọn ajomogbe naa ""Mo tún dúpẹ́ lọ́wọ́ gomina Oyo tẹ́lẹ̀, Abiola Ajimobi, gomina Seyi Makinde àti gbogbo àwùjọ àgbáyé fún atilẹyin wọn."
Síbẹ̀síbẹ̀, ó ṣe kókó láti mọ̀ wípé wọn máa ń lo ìwà pálapàla yìí fi gba tara àwọn obìnrin, kò sì kìí ṣe ìdí tí ó ń fà á pàtó.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìtàn Mánigbàgbé: Ìnà ẹgba mẹ́sàn-án ni Jesu Oyingbo fi ń kí ọmọ ìjọ ọ́kùnrin tuntun káàbọ̀ 22 Ìgbé 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 31 Èbibi 2020 Oríṣun àwòrán, @Nigerianmuseum Bi aye ba n yi, a maa ba aye yii ni nitori ko si ohun tuntun labẹ ọrun mọ, a ko si ri iru eyi ri, a fi n da ẹru ba ọlọrọ ni.
Ìpín kẹ ̣ ́ ta ni àwọn èmí àìrí bíi iwin , ẹ ̀ bọra , àti ọ ̀ rọ ̀ .
“Àwọn eniyan a máa hú òkúta ààlà kúrò,láti gba ilẹ̀ ẹlòmíràn kún tiwọn,wọn a máa fi ipá sọ agbo ẹran ẹlòmíràn di tiwọn.
“Ṣugbọn bí adẹ́tẹ̀ náà bá talaka tóbẹ́ẹ̀ tí apá rẹ̀ kò ká àwọn nǹkan tí a kà sílẹ̀ wọnyi, ó lè mú àgbò kan fún ẹbọ ìmúkúrò ẹ̀bi, tí alufaa yóo fì, láti fi ṣe ètùtù fún un.
Ẹni to bori: Côte d'Ivoire Guinea vs Guinea-Bissau.
Ìrù rẹ̀ dúró ṣánṣán bí igi kedari,gbogbo iṣan itan rẹ̀ dì pọ̀.
Nígbà tí ó rí Jesu, ó dojúbolẹ̀ níwájú rẹ̀, 
Gbajabiamila sọ oun ko ni i fi ọwọ l'ẹran, ko si ma a wo ki ẹnikan ba ile aṣofin naa l'orukọ jẹ, nitori pe o fẹ ẹ ki oju kuro lara ẹsun iwa ibajẹ ti wọn fi kan-an.
Awọn to n kọ orin: Ohun kan Pataki to mu iwọde End SARS ladun to si jẹ ki ijọba mọ ohun ti wọn n bere fun ni orin End SARS ti awọn oluwọde n kọ leralera.
Ninu osu kejila ọdun 2016 ni Aarẹ Buhari sin ọmọ rẹ, Zahra, nigba to fi fun Ahmed Indimi.
Ni ojo kẹ́sán án ,osu kẹ́rin,ni aare orile ede Naijiria fi ipinnu re han lati dije fun ipo aare leekeji .
    Nígbà tí ó pẹ́ tí ara mi kò gbà á mọ́, mo wí fún àwọn enìkejì mi pé obìnrin náà ti ta ọfà ifẹ́ lù mi, àti pé oró ọfà náà ti bẹ̀rẹ̀ síí mú mi.
Akọnimọọgba fidihẹ ni yoo dari ikọ agbabọọlu naa titi di ipari saa bọọlu yii, lẹyin naa ni awọn alaṣẹ ikọ Man U yoo ṣe ifọrọwanilẹnuwo lati gba akọnimọọgba tuntun.
Ooni: Ayẹyẹ ọdún Moremi yóò wà fún ìtẹ̀síwájú àwọn obìnrin
si asa ni ipinle Eko si n fi orin ki aare kaabọ.
Ìjàmbá iná: Ọkọ̀ epo ló gbiná, tó ran ogún ọkọ̀ míì
Nahori tún ní obinrin mìíràn tí orúkọ rẹ̀ ń jẹ́ Reuma, òun ni ó bí Teba, Gahamu, Tahaṣi, ati Mahaka fún Nahori.
Wọnyii ni iye igba ti ẹgbẹ oṣiṣẹ atawọn ọmọ Naijiria ti fẹhonuhan lori afikun owo epo bẹntiro lati ọdun 2003 ti Naijiria ti pada si ijọba awarawa.
Kọmíṣọ́nà Ọlọ́pàá kó gbogbo ọlọ́pàá ẹkùn Ondo lọ fún àyẹ̀wò COVID-19 Lẹyin ti ayẹwo fihan pe ọlọpaa mẹta ko arun coronavirus ni ipinlẹ Ondo, kọmiṣọna ọlọpaa ni ipinlẹ naa, Undie Adie paṣẹ pe ki wọn ko gbogbo ọlọpaa to wa ni ileeṣẹ ọlọpaa Yaba division ni ilu Ondo lọ fun ayẹwo arun COVID-19 lẹyẹ o ṣọka.
ìwọ tí ó sọ nípa Ẹ̀mí Mímọ́ láti ẹnu baba ńlá wa, Dafidi, ọmọ rẹ pé, ‘Kí ló dé tí àwọn orílẹ̀-èdè fi ń di rìkíṣí,tí àwọn ará ilẹ̀ òkèèrè ń gbèrò asán?
Ẹ̀bi ni a sì rí gbà ninu rẹ̀.
Awọn ibeere ọhun ni: Ta ni aarẹ tuntun ni Amẹrika?
Idajo iku, nipa yiyegi fun enikeni ti aje iwa odaran iseku pani ba simo lori lorile-ede Botswana.
Tesiwaju si, ti a ba ranti pe, aare Muhammad Buhari sagbekale igbimo alabe sekele kan, eleyi ti akowe agba ijoba tele ri, iyaafin Amma Pepple n dari re, lati mojuto bi otun yoo se de ba owo osu awon osise jake-jado orile-ede yii.
Adajọ Maureen Onyekenu lo dajọ naa lẹyin ti Akindele yi ọrọ 'mi o jẹbi' rẹ si 'mo jẹ bi'.
Iroyin to n tẹ wa lọwọ ti sọ pe ọga agba ajọ ọtẹlẹmuyẹ DSS, Lawal Daura, ti adele Aarẹ, Yemi Osinbajo yọ nipo ti kuro lahamọ bayii.
Ẹ̀yin gan-an ti ṣe ohun tí ó burú ju ti àwọn baba yín lọ, ẹ wò bí olukuluku yín tí ń tẹ̀lé agídí ọkàn rẹ̀, tí ẹ kọ̀, tí ẹ kò sì gbọ́ tèmi.
Ṣugbọn ẹru ma n ba wa lati sọ pe nkan bayii ni a jẹ.
Drowning: Ẹni ọdún mẹ́ẹ̀dọ́gbọ̀n àti ọmọ rẹ̀ oṣù mẹ́tàlélógún kú sómi
wo ilu Eko ni irole ojoBo(Thursday).
Nínú àwọn ìfihàn náà a nrí ìmúpadàbọ̀-sípò àti ìfarahàn ìhìnrere Jésù Krístì àti gbígbà wọlé ti ẹ̀kúnrẹ́rẹ́ àwọn àkókò.
Mo gba ẹ̀gbẹ́ oko ọ̀lẹ kan kọjá,mo kọjá lẹ́gbẹ̀ẹ́ ọgbà àjàrà ẹnìkan tí kò lóye.
 egbògi agbógun ti àkóràn doxycycline , bí a bá lòó láti fi dènà àkóràn àrùn láàárín àwọn arìnrìnàjò , kò ní ànfààní kan pàtó tó yanjú .
O ni iṣẹlẹ to n waye yii ko ṣe oun lanfani kankan nipa ti oṣelu tabi na miiran bikoṣe pe o tun ba ọrọ jẹ fun oun ni toripe ọpọ eeyan lo n tabuku ba oun lọna aitọ si ohun ti oun ko mọwọ mẹsẹ.
òṣèré àti ọ̀jọ̀gbọ́n Tiatia, Ayo Akinwale jáde láyé Afurasí kan yin Oloruntoba níbọn nítorí èdèàìyedè nílé oní Sharwama Ìtàn ọ̀rẹ́ tó fi ògùn gba ọkọ ọ̀rẹ́ rẹ̀ ni Akomolede BBC Yorùbá fẹ́ kọ́ wa lònìí Ǹjẹ́ o mọ̀ pé àwọn tó wá láti ìdílé ẹrú kìí lọ́kọ tàbí aya láyé òde òni ní Nàìjíríà?
Àbí ẹ kò mọ̀ pé kò sí alaiṣododo kan tí yóo jogún ìjọba Ọlọrun?
ri gba nibi eto ti ijoba Muhammadu Buhari gbe kale naa.
Nígbà tí àwọn ọmọ-ẹ̀yìn Johanu gbọ́, wọ́n wá gbé òkú rẹ̀, wọ́n sin ín sinu ibojì.
Èmi ni mo ni ẹ̀mí gbogbo eniyan, tèmi ni ẹ̀mí baba ati ẹ̀mí ọmọ; ẹni yòówù tó bá dẹ́ṣẹ̀ ni yóo kú.
Agbarac awọn ẹṣọ fasiti yi kere jọj si t'awọn ọmọ ẹgbẹ okunkun to n gbe ibọn ati awọn ohun ija oloro mii rin kaakiri.
5 - 'Àwọn iléèṣẹ́ ìròyìn nlá kò ní ì gbé irú ìròyìn bẹ̀ ẹ́ Àwọn ènìyàn kan an gbàgbọ́ pé àwọn iléèṣẹ́ ìròyìn nlá maá n ṣègbè.
Fun imọ ẹkọ giga, Eniola kawe gboye ninu imọ iṣiro owo ni ile iwe akọṣẹmọṣẹ Yaba College of Technology ko to lọ si fasiti ilu Eko lati kọ imọ iṣiro owo.
O ṣalaye pe awọn Ọlọpaa Ọtẹlẹmuye mu ni oju ọna ọja Alaba nibi to ti fẹ wọ ọkọ lọ si Onitsha pẹlu awọn ọmọ naa,Joshua James ọmọọdun mẹfa ati Samuel Gbawune ọmọọdun mẹta.
Lataari jijawe olubori ninu asekagba ere-ije ogorun mita ti idije 2018 African Senior Athletics Championship  ti o waye niluu Asaba, oludije omo ile Ivory coast, Ta Lou Marie Josée‏ dupe pupo lowo awon ololufe re fun atileyin won gbogbo.
Àfì sí ẹ̀yìn ni Man City fi ìyà tí wọ́n jẹ l'ọ́wọ́ọ Norwich lọ́sẹ̀ tó kọjá nígbà tí wọ́n na Shakhtar Donetsk mọ́lé nínú ìdíje Champions League l'Ọ́jọ́rú.
Oríṣun àwòrán, kano state government Ijọba ipinlẹ Kano ti gba lẹyin o rẹyin bayii pe lootọ ni ọpọlọpọ awọn eeyan n ku ni ipinlẹ naa.
Bẹ́ẹ̀ ni ọkunrin náà sọ gbogbo ẹran ọ̀sìn ati gbogbo ẹyẹ ati ẹranko ní orúkọ, ṣugbọn ninu gbogbo wọn, kò sí ọ̀kan tí ó le jẹ́ olùrànlọ́wọ́ tí ó yẹ ẹ́.
Oríṣun àwòrán, @MBuhari Buhari salaye pe oun mọọmọ fi papa isere idaraya ilẹ wa sọri oloye MKO Abiọla ni, nitori oun nigbagbọ pe awọn ọdọ lọjọ ọla, yoo fẹ mọ idi ti wọn se fi papa isere nla naa sọri MKO Abiọla.
(Nítorí náà, OLUWA rán olùgbàlà kan sí Israẹli láti gbà wọ́n lọ́wọ́ àwọn ará Siria, ọkàn àwọn eniyan Israẹli sì balẹ̀ bíi ti ìgbà àtijọ́.
Lẹyin tawọn asofin apapọ kẹyin si adehun ti May se, ọjọ Kọkanlelọgbọn osu Kẹwa ọdun 2019 ni gbedeke ọjọ ti ilk Gẹẹsi ni mọ lati yẹra kuro ninu ajọ isọkan ilẹ Yuroopu patapata.
28 Ẹrẹ̀nà 2019 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Ó dá wọn láti máa wá òun Ọlọrun, bí ó bá ṣeéṣe, kí wọ́n fọwọ́ kàn án, kí wọ́n rí i.
Ó dàbí pé iṣẹ́ òwò kan tí wọn sẹ ni wọ́n ti jèrè rẹpẹtẹ, ti wọ́n fi nyọ̀ bẹ́ẹ̀.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Àwọn kan fẹ́ da Naijiria rú torí ààbò tó mẹ́hẹ - Osinbajo gbarata Ọ̀rọ̀ ti ń gba ibòmíràn yọ lórí ẹ̀ṣùn ìfipábánilòpọ̀ - Timi Dakolo Pariwo Ọjọ́ kìí pẹ́, àlàyé àti fídíò rèé lóríi bí èèyàn ṣe rìn lórí Òsùpá ní ààdọ́ta ọdún sẹ́yìn Fulani nìkan kọ́ ló ń pa ènìyàn ní Naijiria -Tinubu Ajọ SERAP ni eyi tumọ si iwa ipa ati iwa ọdaran si awọn ọmọde.
Mo tún mọ̀ bákan náà pé, ìyàwọ mi yìí lè ṣàì bímọ fún mi, bí èyí bá jẹ́ ìpín mi, n kò gbọdọ̀ jẹ́ kí èyí ba àlàáfíà ilé wa jẹ.
Dalung so ninu oro re eleyi ti amugbalegbe pataki re lori oro igbodegba ati ifitonileti, Nneka Ikem-Anibeze, gbe jade lojoBo(Thursday) nilu Abuja, O gboriyin fun iko ohun fun gbogbo akitiyan won, ibasepo ati iwa akinkanju ti won ni saaju idije naa to n ti n sun mole bayii .
Àwọn wolii ń sọ fún wọn pé, wọn kò ní fojú kan ogun, tabi ìyàn, ati pé, alaafia tòótọ́ ni o óo fún wọn ní ibí yìí.
Kí a gbaju mọ nkan mi kọ́ lọrọ kan bayi?
Bí àìmọ́ ati ẹ̀ṣẹ̀ wọn ti pọ̀ tó, bẹ́ẹ̀ ni mo fìyà jẹ wọ́n tó, mo sì gbé ojú mi kúrò lọ́dọ̀ wọn.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Bakan naa ni onimọ nipa eto aabo, Slyvester Emiantor fikun pe ijọba ni ipa lati ko nipa aabo araalu.
Ijoba ipinle Kano ti o wa labe isakoso gomina Abdullahi  Ganduje, ti se itore milionu metala aabo nairia (N13.
IAAF vs AFN: Ó ṣeé ṣe kí Nàìjíríà má lè kópa nínú eré ìdárayá àgbáyé
Wọ́n pinnu lọ́kàn wọn pé, “A óo bá wọn kanlẹ̀ patapata.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Nigeria Custom: A kò tí ẹnu Bodè pa rárá- iléeṣẹ́ Aṣọ́bodè 22 Ògún 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, A n ṣiṣẹ lori eto aabo ni agbegbe yii ni Ileeṣẹ Aṣọbode Naijiria ni iroyin ofege ni pe awọn ti ẹnubode pa ni Sẹmẹ.
OLUWA ni ó lè sọni di aláìní,òun náà ni ó sì lè sọ eniyan di ọlọ́rọ̀.
A si maa n gba wọn ni imọran pe ki wọn o ma wọ aṣọ sun, nitori pe yoo mu ki ara wọn o balẹ dara-dara ti wọn ba fẹ ẹ sun.
Bí ẹni ń ṣe òkú kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ ni wọ́n óo ṣe òkú rẹ̀;ẹ̀yìn odi Jerusalẹmu ni wọn yóo wọ́ ọ jù sí.
"Oríṣun àwòrán, @ngoamazing2009 Ninu fidio naa, ni ọkunrin naa, Grandson Adeyinka ti sọ pe ""awọn fun gbogbo awọn eeyan ẹya Igbo to n gbe nilẹ Yoruba ni gbedeke wakati mejidinlaadọta, to bẹrẹ ni ọjọ Ẹti, ọjọ kẹtalelogun si ọjọ Aiku, ọjọ kẹẹdọgbọn, oṣu Kẹwaa, lati pada si ilu abinibi wọn."
Nítorí bí ẹ bá fẹ́ràn àwọn tí ó fẹ́ràn yín, èrè wo ni ó wà níbẹ̀?
Ó sì bẹ̀rẹ̀ sí fi òwe sọ̀rọ̀, pé,“Ọ̀rọ̀ Balaamu ọmọ Beori nìyí,ọ̀rọ̀ ẹni tí ó ríran dájúdájú.
Ni ọjọ mẹjọ si ni ikomọjade ọmọ tuntun nilẹ Yoruba.
Awọn dokita nilu Australia fẹ f'ofin de ọti mimu f'ọdun marun
''Asiko ọ̀dọ́ ni ọdun mẹrin to n bọ lọna.
Èròkérò yóo jìnnà sí ọkàn mi,n kò sì ní ṣe ohun ibi kankan,
Wo ọmọbìnrin ọdún méjìlá tó ṣè'gbéyàwó pẹ̀lú ọkùnrin méjì láàrin oṣù kan Ibrahim Magu gba idasilẹ rẹ lẹyin to lo ọjọ mẹwaa ni ahamọ igbimọ oluwadi ti aarẹ gbe kalẹ lati wadi ẹsun kotọ ati iwa magomago ti agbẹjọro agba lorilẹede Naijira, Amofin Abubakar Malami fi kan an.
Ìjòyè kan bi Jesu léèrè pé, “Olùkọ́ni rere, kí ni kí n ṣe kí n lè jogún ìyè ainipẹkun?
Joabu bá wọlé tọ ọba lọ, ó wí fún un pé, “O ti dójúti àwọn ọmọ ogun rẹ lónìí, àwọn tí wọ́n gba ẹ̀mí rẹ là, ati ẹ̀mí àwọn ọmọ rẹ, ati ti àwọn aya rẹ, ati àwọn obinrin rẹ; 
Nile iwosan si ni awọn dokita ti jẹ ko ye wọn pe oku ni ọmọ naa, ki wọn to gbee de ileewosan.
Àlùkò ló losùn, ki ráhùn osùn
Pẹ̀lú bí ètò ìdìbò ọdún 2019 ṣe n kanlẹ̀kùn l'órílẹ̀-èdè Nàìjíríà, àwọn ìròyìn kan ti jáde tó jẹ́ ayédèrú.
awon ọmọ ile-iwe alakọọbẹrẹ lati ipele kiini de ipele kẹta ni eto naa wa fun
Saaju akoko yii, awọn alawọ dudu kii saba kopa ni iru idije omidan bayii lagbaye, nitori wọn lee ma bori.
Ó fi ẹ̀mí rẹ̀ wéwu, kí ó lè rọ́pò yín ninu ohun tí ó kù tí ó yẹ kí ẹ ṣe gẹ́gẹ́ bí iṣẹ́ fún mi.
Ẹ ṣọ́ra kí ẹ lè máa tẹ̀lé àwọn ìlànà wọnyi.
"Gbogbo ọjọ́ kẹtàdínlọ́gbọ̀n, oṣù karùn ún, ọdọọdún ni ó máa ń wáye, ṣùgbọ́n ní ọ̀dún yìí àjọ náà pé àkọlé rẹ̀ ní ""Gbogbo ọmọ ló ní ẹ̀tọ́"" Àjọ UNICEF ní pé bó tilẹ̀ jẹ pé àwọn ò sinmi, sùgbọ́n àwọn ọmọde ní Nàìjíríà kò sì tii ní ẹ̀tọ́ sí ètò ìlera, oúnjẹ, ètò ẹ̀kọ́ àtí àwọn ẹ̀tọ́ mìíràn."
O rọ awọn nọọsi lati ba ijọba sọ ohunkohun ti o ba n dun wọn ni itubi-inubi.
Àwọn èrò nígboro Eko fẹ́ lu obìnrin kan pa, pé ó mú nǹkan ọmọkùnrin pòórá A ó máa tẹ àwọn afipábánilòpọ̀ lọ́dàá ni báyìí - Ìjọba Ekiti Dokita àti Nọ́ọ̀sì fìyà jẹ mí lásìkò tí mò ń rọbí- Alaboyún Wo gbèsè tí Nàìjíríà ti jẹ láàrin ọdún 2015 sí 2019 Aarẹ Trump sọ fun awọn oniroyin lọjọru pe, ilẹ Amẹrika ti n ko awọn ọmọ ogun IS to buru julọ kuro ni Syria.
Yóo wà ninu àgọ́ àjọ, lọ́wọ́ ìta aṣọ títa tí ó wà níwájú àpótí ẹ̀rí, kí Aaroni ati àwọn ọmọ rẹ̀ máa tọ́jú rẹ̀ níwájú OLUWA láti àṣáálẹ́ títí di òwúrọ̀.
O tenumo pe, “A ti fi oro ohun to awon torokan gbangban ti o ran wa wa bi leti, ti o ajo to n ri si ere idaraya, ti o fi mo aare igbimo to n ri si sisakoso idije Olympic  ni Cameroon (National Olympic Committee of Cameroon).
Àmọ́ àwọn ènìyàn kan lórí Weibo kò rí ọ̀rọ̀ ọlọgbọ́n kankan nínú àríyànjiyàn wọ̀nyí.
Aare ni oun yoo sa ipa oun lati mu ipinnu awon omo orile ede Niajiria sẹ.
Ẹlòmíràn ní igbagbọ, láti ọ̀dọ̀ Ẹ̀mí kan náà, ẹlòmíràn ní ẹ̀bùn láti ṣe ìwòsàn, láti ọ̀dọ̀ Ẹ̀mí kan náà; 
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Akọ́mọlédè àti Àṣà lórí BBC Yorùbá: Kọ̀ síi nípa iṣẹ́ tí oúnjẹ ń ṣe lára níbí Kilo tun wa ninu lẹta naa?
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù English Premier league: Liverpool gun Chelsea bí ẹṣin lójúde rẹ̀ ní Stamford bridge 22 Owewe 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Awọn agba bọ wọn ni bi ale iya ẹni ba ju baba ẹni lọ, baba laa pe.
Ijọba naa sọ wipe owo naa wa fun ile-gbigbẹ, iwe ati ounjẹ.
Ẹ kúrò lọ́dọ̀ mi, ẹ̀yin aṣebi,kí n lè pa òfin Ọlọrun mi mọ́.
Alákòóso Olùgbé Àjọ Ìṣọ̀kan Àgbáyé náà papàá ti ní àìsàn ibà-ẹ̀fọn.
"Policeman smoking shisha: Iléeṣẹ́ ọlọ́pàá ti bẹ̀rẹ̀ ìwádìí lórí fídíò ọkùnrin kan tó ń mu \""shisha\"""
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìkọlù Plateau: Ẹyìn aṣáájú ìlú gbọdọ mojuto àlàfíà 27 Òkùdu 2018 Oríṣun àwòrán, @NGRPresident Àkọlé àwòrán, Aarẹ Buhari ti saaju pase ki awọn osise alabo pẹtu si aawọ naa Ààrẹ Mùhámádù Buhari ti orílẹ̀èdè Naijirià ti ke si àwọn olórí ìlú nipinle Plateau láti mú ibasepọ àlàfíà láàrin àwọn èèyàn wọn n'isẹ.
Ìgbé-ayé tí mò ń gbé ninu ara nisinsinyii, nípa igbagbọ ninu Ọmọ Ọlọrun tí ó fẹ́ràn mi ni.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Mo ń ṣa ike jọ láti san owó ilé iwé ọmọ mẹ́ta' Gomina Abiodun sọ eyi ninu atẹjade to fi sita lati ki awọn ẹlẹsin musulumi ku ọdun itunu aawẹ Ramadan.
waye ni ipinle Osun, ti kede  Ademola Adeleke
Shittu sọ pe owoyaa naa wa lara biliọnu mẹwa dollar eyi ti orilẹede India la kalẹ fun awọn orilẹede ilẹ Afirika lati ṣeranwọ fun oniruuru iṣẹ akanṣe ti wọn nii ṣe.
Níbi tí gbogbo ikán ti ń lé ‘mú òórùn bébé.
"Ilu Abuja ni Obasanjo fi kede bẹẹ ninu ọrọ apilẹkọ rẹ to pe akori rk ni ""Ẹ jẹ ka rin jinna si isubu"", to gbe kalẹ nibi ipade apero kan."
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Dele Momodu : Lẹ́yìn Buhari àti Atiku, èrò ọjà làwọn olùdíje yóòkù ní ìdìbò 2019 Mallam Lanre Issa Onilu ṣalaye pe atẹjade ṣi ni Amerika gbe jade ati pe wọn ko tii darukọ awọn ti wọn fi ofin de lati ma gba iwe irinna lọ si Amẹrika.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Kenya Covid-19 fund: Aàrẹ pàṣẹ pé kí ìwádìí bẹ̀rẹ̀ lórí àwọn tó lu owó ìtọ́jú aláìsàn ní póńpó 1 Owewe 2020 Oríṣun àwòrán, Reuters Aarẹ orile-ede Kenya, Uhuru Kenyatta ti paṣẹ ki ileeṣẹ eto ilera ṣe afihan gbogbo iwe to ni i ṣe pẹlu ohun ti wọn ra nipa kikoju ajakalẹ arun Covid-19 ni Kenya.
Aare naa, ti o je ogbontarigi onimo ijinle, so fun ile-ise oniroyin Radio Plus pe, oun ko ni fi ori alefa sile“Mi o ni kowe fi alefa sile, je ki won gbe lo sile-ejo, maa ri I to ba  ya, boya mo jebi, lati odun 2017, ni mo ti da owo naa padaO sese ki won pe ile-igbimo asofin lose to n bo, leyin ti won ba pari ayeye isami ayojo odun ominira ti yoo waye lojo kejila osu keta, igbese lilo ofin to wa labe ipele ogbon, apa kinni section 30(1) iwe ofin orile-ede naa, ni yoo je koko ti won yoo soro le lori.
Wo àwọn òṣìṣẹ́ kólẹ̀-kódọ̀tí tó ń fi ẹ̀mí wọn wéwu kí Abuja leè mọ́ tónítóní Ọkùnrin kan pa ara rẹ̀ sínú ọgbà àjọ TRACE tó n mójútọ ìrìnnà ọkọ̀ nípìnlẹ̀ Ogun Wo àwọn nkan tó yẹ́ kí o mọ̀ nípa 'Awawa Boys', ọ̀kan lára ẹgbẹ́ òkùnkùn tó n dá Eko rú Lẹ́yìn gbogbo sinimá oríta ní Ondo, Akẹti jáwé olúborí ní APC Mallam Adamu Hardo Fun awọn ti ko mọ, ọkunrin yii lo bi Aarẹ Buhari.
Onani dá Dafidi lóhùn pé, “olúwa mi, mú gbogbo rẹ̀, kí o sì ṣe ohun tí o bá fẹ́ níbẹ̀.
O ni oun ko korira ẹnikẹni ni Mali nitori ifẹ ti oun ni si orilẹede Mali ko ni jẹ ki oun ṣe bẹẹ.
Bí Buhari wọ́gilé wíwọ bàálù olówó gọbọi fún òṣìṣẹ́ ìjọba kó ṣe aráàlú láǹfàní - SERAP Ọmọ Nàìjíríà, ẹ forijì mí!
Pasitọ ṣalaye pe lai si eyi, gbogbo igbiyanju lati jẹ ki igbeyawo naa ba ofin mu ko lee jẹ itẹwọgba tori awọn ofin to rọ mọ eyi lorilẹede Naijiria.
Ẹni tí ó bá ń tẹ̀lé mi kò ní rìn ninu òkùnkùn, ṣugbọn yóo wá sinu ìmọ́lẹ̀ ìyè.
awon omo orile ede Naijiria lati tubo maa gbadura fun alaafia , itesiwaju ati
Eyi si tako ileri ti ijọba ṣe lati pese ohun elo idaabo bo ara ẹni fun awọn akẹkọọ.
"Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Aráàlú faraya torí èèyàn 63 tó dèrò ọ̀run ní Gúúṣù Kàdúná láàrin ọ̀sẹ̀ kan Hospital Wedding: Oṣù kan péré ni Tash fi ṣe ìgbéyàwó pẹ̀lú Simon kó tó kú Èèyàn 11 kú, èèyàn 438 míràn tún kó COVID-19 ní Nàìjíríà l'Ọ́jọ́ Àbámẹ́ta Bí o ṣe lè forúkọ silẹ̀ fún ètò ""N75BN Nigerian Youth Investment Fund"" rèé."
ibi Jesu ati ayajọ ọdun ominira.
Mílíọ́nù mẹ́wàá Náírà ni ilé ẹjọ́ ni kí Kábíyèsí san gẹ́gẹ́ bí owó ìtaran ilẹ̀ tí ó gbà lọ́nà àìtọ́ Iṣu ata yáan yàan!
Ni ọjọ aje, ọjọ kẹjọ oṣu kẹrin ni iṣẹlẹ ijamba iná yii waye ní pápákọ̀ òfurufú ìpínlẹ̀ Imo.
Ọ̀pọ̀ ìròyìn ló ti kàn káàkiri ṣáájú àsìkò yìí pé àárín àwọn ọba alayé méjèèjì ilẹ̀ Yorùbá yìí kò gún, ṣùgbọ́n níbi ìpàdé náà, wọ́n ní kò sí ohun tó jọọ́.
Nítorí OLUWA ń dáàbò bo àwọn olódodo,ṣugbọn àwọn eniyan burúkú yóo ṣègbé.
Bó tilẹ̀ jẹ́ pé ọ̀pọ̀ ǹkan lọ tí yí padà lágbàáyé lẹ́nu lọ́lọ́lọ́ yìí, ọ̀pọ̀ àwọn nọ́ọ̀sì agbẹ̀bí lọ sì ti ń ṣe ìrànwọ́ fún àwọn aboyún lat máa dá wọn lóhùn láti orí aago ìbánisọ̀rọ̀.
Ṣugbọn dárí ẹ̀bi ẹ̀ṣẹ̀ ìtàjẹ̀sílẹ̀ náà jì wọ́n.
Wọ́n mú un lọ tipátipá, lẹ́yìn tí wọ́n ti dá a lẹ́jọ́,ta ni ninu ìran rẹ̀ tí ó ṣe akiyesi péwọ́n ti pa á run lórí ilẹ̀ alààyè,ati pé nítorí ẹ̀ṣẹ̀ àwọn eniyan mi, ni wọ́n ṣe nà án?
Ìgbà kinni nìyí tí wọn yóo tẹ̀síwájú gẹ́gẹ́ bí àṣẹ tí OLUWA pa láti ẹnu Mose.
O jẹ obinrin ilẹ Jamaica kẹta ti wn yoo de lade obinrin to rẹwa julọ lagbaye lọdun 1993.
Ṣùgbọ́n, ohun tó n kọ ọ̀pọ̀lọpọ̀ lóminú ni pé, ọdún yìí kò ti dé ìlàjì, tí nkan tó tó bẹ̀ ti ṣẹlẹ̀.
Ní ayé Dafidi ọba, àwọn akikanju jagunjagun wọnyi jẹ́ ẹgbaa mọkanla ó lé ẹgbẹta (22,600).
ẹni tí bá ń gbìyànjú láti dá irú obinrin bẹ́ẹ̀ lẹ́kundàbí ẹni tí ń gbìyànjú láti dá afẹ́fẹ́ dúró,tabi ẹni tó fẹ́ fi ọwọ́ mú epo.
Lẹ́yìn rẹ̀, Binui, ọmọ Henadadi ṣe àtúnṣe apá ọ̀dọ̀ tirẹ̀: láti ilé Asaraya títí dé ibi Igun Odi.
lẹyin ti wọn ba ri abawọn tabi aisedede ninu iforukọsilẹ ti wọn se.
Nítorí pé láti Sioni ni òfin Ọlọrun yóo ti jáde wáọ̀rọ̀ OLUWA yóo sì wá láti Jerusalẹmu.
Ṣugbọn nítorí majẹmu tí ó wà láàrin Dafidi ati Jonatani, Dafidi kò fi ọwọ́ kan Mẹfiboṣẹti, ọmọ Jonatani, ọmọ Saulu.
Adẹrinpoṣonu ti ko lafiwe ni Sunday Ọmọbọlanle ti ọpọ eeyan mọ si 'Aluwẹ' tabi 'Papi luwẹ'.
ounje lojoojumọ lati igba ti won ti bere awẹ Ramadan ohun.
Ẹ gbé ẹrù yín nílẹ̀,ẹ̀yin tí ọ̀tá dótì wọnyi!
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ọ̀rẹ́ Léanne ní kó máa dá a ṣe pẹ̀lú ara rẹ̀.
Èyí ni bí gómìnà Babajide SanwoOlu ti ìpínlẹ̀ Eko ṣe kó COVID-19 Iléeṣẹ́ epo rọ̀bì ná ₦116m lórí báírò, ìwé ìkọ̀wé, àwọn aṣòfin fìka hánu Igbo Olodumare rèé, níbi tí Ìgbín ti tóbi ju Ìjàpá lọ Àádọ́ta Náírà tí báńkì ń yọ nínú owó ìpamọ́ oníbàárà kò tọ̀nà - Iléejọ́ Agbébọn tún gbẹ̀mí àgbẹ̀ míì lọ́nà oko lágbègbè Ibarapa 'Ẹ̀ṣọ́ ọgbà ẹ̀wọ̀n bọ́ mi sí ìhòhò, ó ki ìka rẹ̀ bọ ìdí mi látẹ̀yìn' Ẹwẹ, igbimọ alaṣẹ ẹgbẹ oṣelu APC, NEC labẹ adari aarẹ Buhari ṣe afiku akoko ti igbimọ amuṣẹya ti Mai Mala Buni ṣagbatẹru pẹlu oṣu mẹfa sii.
''Awọn eniyan ro pe arun Ebola kii ṣe otitọ.
 Nigbẹyin gbẹyin mo ti ri orin ti mo le foju jọ, Soapy ti Naira Marley.
Àwọn onímọ̀ ṣàwárí 'ihò ìyọ̀ tó gùn jù láyé' nítòsí ìbì tí ìyàwó Lọti inú Bíbélì ti di iyọ̀ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ìnú mi kìí dùn nígbà trí mo ń ṣiṣẹ́ ni bánkì tó ìgbà ti mo bẹ̀rẹ̀ mẹkáníìkì Sultana to wa lati abule kan lorilẹede Bangladesh, lo bi ọmọ rẹ akọkọ si ile iwosan Khulna Medical College ni ẹkùn Khulna.
O wa ke si gbogbo olorin Fuji lati fọwọ ṣo ọwọ pọ lati gbe orin Fuji larugẹ, ki wọn si gbagbe ariyanjiyan lori ẹni to da Fuji silẹ.
Mo ti rí ọ̀pọ̀lọpọ̀ àdánwò látọ̀dọ̀ obìnrín.
Èsì ìdánwò òhun tí a ṣé síwájú là n bá fínra báyìí ní Nàìjíríà- Yemi Shodimu Wo àwọn òfin tuntun tíjọba fí síta lórí lílọ ìrìnàjò sílẹ̀ òkèèrè Ọwọ́ ọlọ́pàá tẹ afurasí olóògùn owó tó fẹ́ gé ọmú obìnrin kan nílé ìtura Àwọn èèyàn ìpínlẹ̀ Oyo gbarata lórí àlékún owó epo bẹntiróò Nigeria Police Recruitment 2020: Àwọn ohun tí ẹ nílò fún àyẹ̀wò ìgbanisíṣẹ́ ọlọ́pàá tí yóò bẹ̀rẹ̀ ní Mon, Aug 24 Ileeṣẹ ọlọpaa ni ipinlẹ Eko, Oyo, Osun, Cross River ati Bayelsa yoo bẹrẹ ayẹwo igbanisiṣẹ fun awọn to ti forukọ silẹ lati darapọ mọ ọ bẹrẹ lati ọjo Aje, ọjọ kẹrinlelogun, oṣu Kẹjọ, ọdun 2020.
Àwọn Ọlọ́rọ̀ Ilẹ̀ Aláwọ̀dúdú kò kọ́ ọgbọ́n ninú itàn igbẹhin Ọba àti Ìjòyè ti kò lo ipò wọn dáradára, àwọn ti ó fi èrú kó ọrọ̀ jọ, tàbi ti ó lo ipò wọn lati fi tẹ ará ilú mọ́lẹ̀ ni àtijọ́.
Ni ilú kan ti a mọ̀ si “Ayégbẹgẹ́”, àwọn àlejò ọkùnrin meji kan wa ti orúkọ wọn njẹ́ – Miòṣé àti Moṣétán.
Ẹ gbọ́ bí àwọn kinniun ti ń bú ramúramù,nítorí igbó tí wọn ń gbélẹ́bàá odò Jọdani ti parun!
Ogagun Omozoje wa fi emi imoore han nipa fifi  ebun sowo si egbe akoroyin obinrin ipinle
Aare Muhammadu Buhari yoo lo si orile ede England lonii, to je ojo kejo, osu karun un, lati lo ri dokita re fun itoju ilera ara re, eleyi ti yoo si wa ni be fun ojo merin.
Gomina Abdulfatai Ahmed lohun si ofin yii ofin to tako ọti tita ati rira nigboro ilu Ilọrin lọjọ isẹgun lẹyin tile asofin ipinlẹ naa ti buwọlu abadofin ọhun.
Oluwa Kristi ni ẹ̀ ń ṣe iṣẹ́ ẹrú fún.
Aare Buhari ni won pe gege bii alejo pataki eni ti yoo soro iside nibi eto naa to je ara oto.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Border Closure: Ilé aṣòfin àpapọ̀ pàṣẹ fáwọn àṣọbodè láti fààyè gba èpo lẹ́nu bodè 12 Bélú 2019 Oríṣun àwòrán, @anaedoonline Yoruba ni agba kii wa lọja, ki ori ọmọ tuntun wọ, eyi lo mu kile asofin apapọ ilẹ wa tete dasi ọwọn gogo epo pẹtirolu to n waye lawọn eti bode Naijiria.
Iroyin ti a gbọ ni pe iṣẹlẹ ọhun waye ninu yara kan tawọn eeyan naa sun si.
Ṣugbọn bi wọn ṣe n kọlu awọn oṣiṣẹ eto ilera ti fa idiwọ fun pinpin abẹrẹ naa, eyi si ti mu ki aarun naa tan kalẹ si.
”Aare Buhari wa so pe ijoba yoo sagbekale igbimo amusẹya ti
Eto ayẹwo ọlọjọ mẹwaa ni wọn ti kọkọ ṣe fun awọn olukopa laarin ogunjọ oṣu karun un si ọgbọn ọjọ oṣu karun un kan naa.
Ẹ̀ bá jẹ́ pa ẹnu yín mọ́ ni,à bá pè yín ní ọlọ́gbọ́n!
ati lati mojuto awon ohun amayedẹrun .
Wọ́n fi òróró yìí tọ́jú òkú Jesu, wọ́n bá wé e ní aṣọ-ọ̀gbọ̀ gẹ́gẹ́ bí àṣà ìsìnkú àwọn Juu.
 Àwọn ará gúúsù tókù gbà fọ ́ lọ ́ run , ṣùgbọ ́ n booth dúró lórí ìgbàgbọ ́ rẹ ̀ .
Ni ko pẹ ti abala keji idije naa gbera sọ ni Alexandre Lacazette tun fọbale goolu Arsenal , ti Aubameyang si tun gba goolu meji miiran wọle , lati sọ ami ayo Arsenal di mẹrin.
Ó tó fún ẹrú bí ó bá dàbí oluwa rẹ̀.
Labẹ pe ibẹrẹ kọ l'onisẹ, afi ẹni ba laa ja, awọn ti o fi ẹgbẹ oselu APC silẹ fun Oshiomole bi aarẹ ile asofin agba tẹlẹ ri Bukola Saraki ni wọn wa n gba Godwin Obaseki lalejo ninu ẹgbẹ oselu PDP bayi.
Olóye eniyan a máa fi ìmọ̀ ṣe ohun gbogbo,ṣugbọn òmùgọ̀ a máa fi agọ̀ rẹ̀ yangàn.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ọdún 1998 ni ikọ̀ France ti gba ife ẹ̀yẹ àgbáyé kẹ́yìn Kylian Mbappe ti oun naa jẹ ọmọbibi ilẹ France ni ami ayo mẹta ninu idije ife ẹyẹ agbaye to n lọ.
Oríṣun àwòrán, Facebook/Femi Gbajabiamila Àkọlé àwòrán, Ibo ile aṣoju ṣofin Asofin Femi Gbajabiamila lo sagbatẹru aba kan eleyi ti yoo yanju aawọ ọrọ owo ina ti ọpọ ara ilu n ke irora si sugbọn aba naa ko ti di ofin.
Bákan náà ni Kristi, nígbà tí a ti fi rúbọ lẹ́ẹ̀kan láti kó ẹ̀ṣẹ̀ ọpọlọpọ lọ, yóo tún pada lẹẹkeji, kì í ṣe láti tún ru ẹ̀ṣẹ̀ mọ́, ṣugbọn láti gba àwọn tí ó ń fi ìtara retí rẹ̀ là.
nípa ti ẹ ̀ sìn , àwọn oríṣìí ẹ ̀ sìn mẹ ́ ta pàtàkì tí a lè rí lóde òní ní ilẹ ̀ yorùbá náà ló wà ní Ọ ̀ gbàgì .
Àwọn oníṣòwò tí ń lo ràkúnmíyà kúrò ní ọ̀nà wọn, wọ́n ń wá omi kiriwọ́n kiri títí wọ́n fi ṣègbé ninu aṣálẹ̀.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Àwọn fíìmì òde òní ń kọ́mọ lólè àti ọ̀pọ̀ ìwà burúkú Ọmọ Atiku ni ìròyìn sọ pé o de láti orilẹ̀-ède Switzerland si orill-èdè naijiria ti o si jẹ ọkàn lára àwọn orilẹ̀-è[de ti o n bààrun Coronavirus fira Mò n lọ fun ìgbélé nítori mo ṣe alábapàdé ọmọ Atiku- Gomina Bauchi Gomina ìpínlẹ̀ Bauchi, Bala Muhammed ti kéde pé òun náà yóò lọ fi ara òun si ìgbélé, lẹ́yìn ti ìgbákeji ààrẹ àná lórilẹ̀-èdè Naijiria fi léde pé pé ọmọ oun ti lugbàdi ààrun Coronavirus.
Ẹ wá wo ohun tí Ọlọrun ṣe,iṣẹ́ tí ó ń ṣe láàrin ọmọ eniyan bani lẹ́rù.
Owó lítà epo ní Nàíjíríà ló kéré jùlọ l'Áfíríkà - Lai Muhammed Ijọba apapọ lorilẹede Naijiria ti sọ wi pe naira mejilelọgọjọ ti wọn n ta lita epo pẹtiro kan lo kere julọ ni ilẹ Afrika.
A gbọ pe awọn janduku naa ja wọ ọfiisi adari ile, Olakunle Oluomo ti wọn si ji ọpa aṣẹ gbe lọ.
Ajo ohun so eyi di mimo ninu akosile iroyin re fun ti awon onibara ti a mo si Consumer Price Index (CPI)  ti o gbe jade ni osu kinni odun 2018 lojo-Ru  nilu AbujaCPI eyi ti o se osuwon owon-gogo owo ori oja, bere si ni alekun iko medogun o le15.
Awọn ẹgbẹ oselu naa wa parọwa si ijọba lati yẹ igbese yii wo nitori awọn ẹgbẹ oselu miran ni ẹtọ lati ba awọn eniyan wọn sọrọ.
Ẹsira ka ìwé òfin náà sí etígbọ̀ọ́ wọn.
Ẹ kò lè jẹ ninu oúnjẹ orí tabili Oluwa, kí ẹ tún lọ jẹ ninu oúnjẹ orí tabili ẹ̀mí burúkú.
2019 African Cup of Nations ti won yoo gba pelu
Ó rí i bí ó ti ga, tí ẹ̀ka rẹ̀ sì pọ̀.
Oríṣun àwòrán, @Bashir Ahmaad Akorede sọ siwaju pe, awọn ọdọ naa ni Gambari pẹ̀lú àwọn ọ̀tẹlẹ̀múyẹ́ tó lé ní ogun, tó fí mọ àgba ẹgbẹ́ òṣèlú APC kan, Cook Gani Olododo, ní wọn ri níbi ti wọn ti ń fún àwọn ènìyàn lówó, kí wọn báa lè dìbò fún ẹgbẹ́ wọn.
Lẹni ọdun mejidinlogoji, ireti ọpọ nigba ti idije Australian open ti ọdun 2020 bẹrẹ ni pe ilakaka Serena Williams yoo so eso rere ki o to di pe o pade Wang Qiang ọmọ orilẹede China ni ipele kẹta idije naa.
Lootọ o, lasiko ti arun naa ṣẹṣẹ bẹẹ, o ṣoro diẹ fun awọn ọmọde lati ko kokoro arun naa.
gbowo lati tako alafia eto idibo naa yoo foju ba ida ba.
Kí alaafia ati ìfẹ́ pẹlu igbagbọ láti ọ̀dọ̀ Ọlọrun Baba ati Oluwa Jesu Kristi, kí ó wà pẹlu àwọn onigbagbọ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Kí ló máa ń wú ìyá Nike Davies lori láti wé gèlè ràbàtá?
Kí ni Buhari sọ nípa ààrẹ tó kàn lọ́dún 2023?
Àwọn ẹlẹ́sìn ìbílẹ̀ ń bèèrè owó lọ́wọ́ àwọn Alfa lórí ìsìnkú ẹni tó pokùnso Ọkùnrin tó bẹ́ sì òdò ọ̀sà pa ọ̀rẹ́bìnrin rẹ̀, lòun náà fi fẹ́ kú - Iléeṣẹ́ ọlọ́pàá A máa ná N10.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Oluwo ti Iwo: O yẹ́ ká rán àwọn Fulani lọ ìlú òyìnbó láti kẹ́kọ̀ọ́ 26 Agẹmo 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 27 Agẹmo 2019 Oríṣun àwòrán, emperortelu1 Àkọlé àwòrán, Oluwo ti Iwo Oluwo ti ilu Iwo, Ọba Abdulrasheed Akanbi ti ni wahala to ṣẹ n de ni Naijiria yii, kii ṣe oni lo ti bẹrẹ.
"Tí òṣèré tíátà yóò fi kú, eré ni wọn yóò ló ń ṣe - Ibrahim Chatta Ẹ wo nkan tí àwọn akẹẹgbẹ́ Lateef Adedimeji sọ nípa f'ọ́tò ìgbéyàwó òun àti Adebimpe tó jáde Ọkọ Funke Akindele kó eléré àti òṣìṣẹ́ jọ fi ṣe ""Surprise Pato"" fún un lọ́jọ́ ìbí rẹ̀ Ọdún méjì, wàhálà méjì lójúbọ Osun Osogbo, O ni oun ti n ṣe akitiyan pẹlu awọn eeyan mii lati gbe eto kan kalẹ lati maa fi ṣe iranti oloogbe Barrister gẹgẹ bi eto ti wọn maa fi n ranti olorin Afro, Fela Anikulapo Kuti lọdọọdun."
Wọ́n sì tún ní igba (200) akọrin lọkunrin, ati lobinrin.
Kábíyèsí, ẹ kíyèsí àwọn kòkòrò tí í máa jẹ ohun ọ̀gbìn wọn-ọnnì, bì wọ́n ti ń ba iṣu jẹ́, tí wọ́n ń ba ọ̀gẹ̀dẹ̀ jẹ́, tí wọn kò sì jẹ́ kí àgbàdo yọ ọmọ, òwe ni Olódùmarè ń pa fún wa nì, nítorí bẹ́ẹ̀ gẹ́gẹ́ ni àwọn aláìmoore ri, kòkòrò búburú ni wọ́n, wọ́n á bẹ̀rẹ̀ sí jẹ ọmọnìkejì wọn ní gbòǹgbò, kí onítọ̀hún máa baà lè dàgbà sóké, kí òun baà dúró sí ojú kan bi adágún omi.
Oludamọran aarẹ kilọ fawọn to n gbe iroyin ofege kiri pe ki wọn jawọn lapọn ti ko yọ nitori ọrọ Naijiria ti kọja iru iwa bẹẹ.
iyen INEC lati se eeru ibo fun omo egbe won.
Ṣugbọn ẹni tí ó bá sọ̀rọ̀ tí kò dára sí Ẹ̀mí Mímọ́ kò ní rí ìdáríjì láyé yìí ati ní ayé tí ń bọ.
Balaamu dáhùn pé, “Balaki ọba àwọn ará Moabu ni ó rán wọn sí mi pé, 
Ilé ẹjọ́ ni agbábọ́ọ̀lù ọmọ Nàìjíríà, Dickson Etuhu jẹ́bi ẹ̀sùn títa ìdíje Sweden Èèyàn mẹ́tàlá dèrò ọ̀run nínú ìjàmbá ọkọ̀ lópòpónà Ìbàdàn s'ÈKó Zlatan: Èyí mo ṣé tó, àsìkò tó láti tèsíwájú nínú ìrìnàjò mi Wo ohun tó yẹ kí o mọ̀ nípa akínkanjú obìnrin alága àjọ elétò ìdìbò Ghana 2020 O ṣalaye pe, bi oun ṣe n rọbi lọwọ ni wọn gbe oun sori alupupu, ṣugbọn ki wọn to de ile iwosan ni ọmọ naa di ologbe si oun ninu.
Agbẹ ti lọ soko idije bẹẹ ko ranti ọkọ ni ọrọ Super Eagles loni.
O sọ pe kii se pe ipinlẹ Ondo ko ni alumọni tabi awọn to kawe daada sugbọn eto idari ku diẹ kaato.
Amọ, Kollington fun ra rẹ naa ti fi kọ orin pe ''Edumare fiṣẹ yin wa gbogbo wa, lagbaja lo da Fuji silẹ, ọrọ awawi, tamẹdo lo da Fuji silẹ, Edumare fiṣẹ yin wa gbogbo wa.
Ijọba fi ẹsun kan Daniel Lewis, ati isọngbe rẹ kan, pe wọn pa eeyan mẹta ninu ìdílé kan naa lọdun 1996.
 Àjẹsára náà kò wọ ́ n púpọ ̀ .
 bí ilẹ ̀ russia ṣe ṣe èyí tán ni ilè germany kìtọ ̀ fúnwọ ̀ n pé tí wọ ́ n bá danwò , àwọn yíò gbógun tìwọ ́ n .
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Footballers: ìkà láwọn aṣojú agbábọ̀ọ̀lù míì lágbàyé Amọ ṣaa, lẹyin ipade kan to waye laarin gbogbo ẹgbẹ oṣiṣẹ ijọba nipinlẹ Ọyọ, Akọwe ẹgbẹ NLC ati akọwe igbimọ to n ṣoju ijọba jọ buwọlu atẹjade kan pe ijọba gbọdọ san o kere tan, owo oṣu kan.
ó da ẹ̀gàn lu àwọn ìjòyè,ó sì mú kí wọn máa rìn kiri ní aṣálẹ̀,níbi tí kò sí ọ̀nà.
Bí ó bá jẹ́ pé ẹ̀mí ni ó sọ̀rọ̀ fún un ńkọ́?
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Anthony Joshua: Lẹ́yìn ìjà rẹ̀ pẹ̀lú Luiz, Anthony Joshua bẹ Ọba ìlú rẹ̀, Àkárìgbò wò 20 Èrèlè 2020 Oríṣun àwòrán, CockFM Radio Ṣe awọn agba bọ wọn ni ọmọ ale ni fi ọwọ osi juwe ile baba rẹ.
Kò sí ohun kan ní ọkàn wa si yín.
O ni awon osise eleto ilera ti setan lati pada senu ise, ni kete ti ijoba ba ti yanju aawo to wa laarin won.
Nigige soro yii nigba to n ba awon to jawe olubori ninu eto idibo egbe APC to waye ni  Ojoto  to  wa ni ijoba ibile Idemii , ila -Gusu ti ipinle     Anambra.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Oba Adedokun Abolarin ti Oke Ila: Ó ya ọ̀pọ̀ tó súnmọ́ mi lẹ́nu bí mo ṣe ń kọ́ Bi o tilẹ jẹ pe arakunrin naa ko sẹ pe oun ko si pẹlu awọn janduku miran nibi ti iṣẹlẹ naa ti waye.
”Ṣugbọn ọ̀rọ̀ àwọn ará ilẹ̀ Juda le ju ti àwọn ará ilẹ̀ Israẹli lọ.
Ṣugbọn àwọn alágbàro yìí lù ú, wọ́n bá dá a pada ní ọwọ́ òfo.
Ọkunrin náà bá wí pé,“Mo ṣẹ̀ṣẹ̀ rí ẹni tí ó dàbí mi,ẹni tí a mú jáde láti inú egungun ati ẹran ara mi;obinrin ni yóo máa jẹ́,nítorí pé láti ara ọkunrin ni a ti mú un jáde.
Pupọ ninu àwọn onigbagbọ ni wọ́n jẹ́wọ́ ohun tí wọ́n ti ṣe, tí wọ́n tún tú àṣírí idán tí wọn ń pa.
Núdùlù to gùn jùlọ ní kìlómítà mẹ́ta lóròó Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Awọn aládugbò Yangzhou ní China kóra jọp;ọ̀ ní 2015 láti ṣe núdùlù tí yóò gùn tó mítà ọgọ́rùn mẹ́ta Orílẹ̀-èdè China ló gba Núdùlù tó gùn jùlọ nínú ìwé ìránti àwọn iṣẹ̀lẹ̀ málegbàgbé làgbáyé nítori wọn ni ile ounjẹ tó ń ṣe daradara lẹ̀yìn ti wọn se Núdùlù kan tó gùn tó ẹgbẹ̀rún mẹ́ta ó lé mẹ́rìn lélọ́gọ́rin míta.
Fathia fikun pe, lasiko ti ọja Yaba, nilu Eko jona ni imisi wa fun oun lati se sinima Aje ọja, nitori lasiko naa ni oun gbọ pe, bi ọja kan ba ti jona, aje kii pada sibẹ mọ.
Nínú Oṣù keje, ilẹ Amẹrika ti ní gbogbo ẹni tó ba ń fẹ́ láti gba iwé ìrìnà ilẹ̀ Amẹrika gbọ̀dọ̀ sàfihan àwọn ojú opó ayélujara wọn, èyí jẹ́ ọkan pàtàkì lárá òfin tuntun ti wọ́n yàn Wọn fi kún pé arinrin ajo yóò mú orukọ to n lọ loju opo ayelujara rẹ̀ kalẹ̀, pelu gbogb atẹjisẹ tó ti gbà láti ọdún márun ṣẹyin àti nọmba foonu wọ́n Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí FBI List: EFCC join recover $314,000 and N373m from yahoo yahoo pipo27 Ògún 2019 US visa: America sama Nigeria do-me-I-do-you issuance fee for application dem approve27 Ògún 2019 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
“Ẹ mọ̀ pé lẹ́yìn ọjọ́ meji ni Àjọ̀dún Ìrékọjá, a óo fi Ọmọ-Eniyan lé àwọn ọ̀tá lọ́wọ́ láti kàn mọ́ agbelebu.
Wọn ti fi oju ara eeyan ati ekute ṣe sampu ayẹwo lati wo bi kokoro naa ṣe n huwa si lara ẹni.
Ẹnu sì ya gbogbo àwọn tí ó gbọ́ ohun tí àwọn olùṣọ́-aguntan náà sọ fún wọn.
EndSars Protest: A kò lọwọ́ sí ìwé ìpẹ̀jọ́ tó tako ìdásílẹ̀ ìgbìmò ìwádìí aṣemáṣe ikọ̀ SARS
Minisita fun oro osise ati eto ise lorile ede Naijiria, asofin Chris Ngige ti soro idaniloju pe aare Muhammadu Buhari ni yoo tun jawe olubori ninu eto idibo aare  2019 to n bo.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Yomi Shogunle di èro Nkalagu lórí ọ̀rọ̀ tó sọ lórí Twitter 4 Èbibi 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 5 Èbibi 2019 Oríṣun àwòrán, Yomi Shogunle/Twitter Adari ẹka ileeṣe ọlọpaa to n boju to ẹhonu ara ilu, Yomi Shogunle ti di ero Nkalagu ni Ipinlẹ Ebonyi, nibi ti wọn gbe lọ si nigba ti wọń yọ kuro nipo ni olu ileeṣẹ ọlọpaa to wa ni Abuja.
Ojọgbọn Naijiria miran naa ṣalaisi ninu ijamba ọkọ ofurufu ọhun Ohun ti a tun gbọ ni pe Ọjọgbọn Abiọbun Bashua wa lara awọn ọmọ Naijiria to lugbadi iku ojiji ninu iṣẹlẹ baalu Ethiopia naa.
Kò sí ẹni tí ó dàbí rẹ, bẹ́ẹ̀ ni kò sí Ọlọrun mìíràn lẹ́yìn rẹ, nítorí gbogbo ohun tí a ti fi etí wa gbọ́.
Wọn yóo ra oko ní ilẹ̀ yìí, ilẹ̀ tí ẹ̀ ń sọ pé ó ti di ahoro, tí kò sí eniyan tabi ẹranko ninu rẹ̀, tí ẹ̀ ń sọ pé a ti fi lé àwọn ará Kalidea lọ́wọ́.
Wo ìdí tí Tẹni, ọ̀dọ́mọdé olórin obìnrin kìí fi ń ṣí ìhòhò rẹ silẹ̀ Wo ìgbà mẹ́rin tí ìjọba ti tú ikọ̀ ọlọ́pàá SARS ká sẹ̀yín ṣùgbọ́n.
Nítorí ọjọ́ ayé mi ń kọjá lọ bí èéfín,eegun mi gbóná bí iná ààrò.
Nigba ti Osinbajo n ba awon eniyan soro lede oyinbo Pidgin so pe  awon yoo ro awon  oloja olokoowo keekeeke, lagbara nipa eto eyawo fun awon oloja.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Bakare Mubarak: ọ̀pọ̀ èèyàn ló máa ń fẹ́ dúró sí ẹgbẹ́ mí tójú si máa n tì mí Ibẹrẹ Ogun Abẹle Ijọba Naijiria ko awọn ọlọpaa sita lati gba agbegbe to yapa pada.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ṣé òfin kónílé-ó-gbélé lè mú àdínkù bá ìtànkálẹ̀ Coronavirus?
Bakan naa lo tun fi kun pe, gbogbo igbiyanju lati ji oun gbe lo ja si pabo, idi si ree ti oun ko fi le panumọ rara mọ, o ti to gẹ.
ọmọ Simeoni, ọmọ Juda, ọmọ Josẹfu, ọmọ Jonamu, ọmọ Eliakimu, 
Sinimá àwòdamiẹnu, Ẹ̀fáńjẹ́líìsì jìyà àjẹmumi nílé aṣẹ́wó l'Ejigbo ní ìlú Eko Ọba Saudi Arabia yọ ọmọ rẹ̀ àti àbúrò rẹ̀ kúrò nípò nítorí ìwà àjẹbánu lórí owó tó yẹ fún ààbò ìlú Èèyàn 239 míràn ṣẹ̀ṣẹ̀ kó COVID-19 ní Nàìjíríà Àwọn ará ìlú Ikarẹ Akoko ń ṣọ̀fọ̀ Ọba Adegbite, Ọwá Ale Ikarẹ tó wàjà Atẹjade kan ti agbẹnusọ fun Adams Oshiomhole fi sita ṣalaye pe ni nnkan bii agogo mejila ọsan ni iṣẹlẹ naa ṣẹ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Osun 2018: Àwọn aráàlú da ìbéèrè bo àwọn olùdíje ìpínlẹ̀ Ọṣun 20 Agẹmo 2018 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 17 Owewe 2018 Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Osun 2018: Àwọn olùdíje ADC, ADP, APC, SDP bá aráàlú sọ̀rọ̀ lórí èròǹgbà wọn Kọntínúítì, gbèsè, fásitì Lautech àti àwọn ìbéèrè mìíràn lo jẹyọ ní ìpàdé ìtagbangba Ọṣun Ipade itagbangba ti ile ise iroyin BBC Yoruba se fun awọn oludije sipo Gomina nipinlẹ Osun ti waye.
Gbogbo nǹkan wọnyi yé Kabiyesi, nítorí náà ni mo ṣe ń sọ ọ́ láìfòyà.
Èmi pàápàá ń fẹ́ sọ̀rọ̀ ṣùgbọ́n nígbà tí mo rí àwọn ẹnìkejì mi gbogbo tí wọ́n sìde èmi jókòó mo sì wí fún  Filásayépọ̀ àti Olójúmájèlé kí wọn jókòó kí wọn jẹ́ kí Kùmọ́diran sọ̀rọ̀, nítorí òun ló kọ́ sáajú gbogbo wa dìde.
Ẹ̀rù bà á láti jẹ́wọ́ fún wọn pé iyawo òun ni, nítorí ó rò pé àwọn ará ìlú náà lè pa òun nítorí pe Rebeka jẹ́ arẹwà obinrin.
Oyo state: 615, nọ́mbà tuntun fún ìdáàbòbò àwọn èèyàn ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ̀
” Ọkunrin náà bá dìde dúró.
Ṣaaju ni iroyin kan kan ti gbode pe aarẹ yoo ba awọn ọmọ Naijiria sọrọ lalẹ ọjọ Aje, papa julọ lori igbesẹ to kan lori igbele to n lọ lọwọ lawọn ipinlẹ kan nitori arun Coronavirus.
Ọdun 2016 ni wọn gba beeli rẹ ni ile ẹjọ kotẹmilọrun nitori wn ti gbe ẹjọ naa lọ si ile ẹjọ.
Ọmọ ọgbọ́n ọdún pa bàbá rẹ̀ ní ìpínlẹ̀ Ogun Abiyamọ ò!
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Child Trafficking: Àwọn ọmọ ọdun mẹ́fà sí mẹ́wàá pọ̀ tí a ti tú sílẹ̀ 9 Òkùdu 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Fifi ọmọ sẹ ẹru Tẹlẹ ipinlẹ Edo lo n ṣaaju, ninu awọn ipinlẹ Naijiria to n fini s'owo ẹru.
Yatọ si eyi, igbagbọ wa pe o yẹ ki Super Eagles tun na Algeria gẹgẹ bi wọn ṣe ṣe ninu idije kikopa fun ife ẹyẹ agbaye tọdun 2018 to kọja.
Blankson nikan l'oku ninu ijamba ọkọ oju omi naa to waye l'ọjọ Abamẹta naa.
Bí òṣìṣẹ́ Amotekun bá fi orúkọ sílẹ̀ lórí ayélujára, àwọn ọ̀daràn yóò tètè fojú hàn - Oludari Amotekun l'Oyo Àwọn dókítà Eko bẹ̀rẹ̀ ìyanṣẹ́lódì lórí owó oṣù àti ètò adójútòfò fún ìtọ́jú coronavirus Kò sí ìfòyà, ọkọ̀ bààlù wà tí ìjọba ba ti afárá 3rd Mainland lósù yìí Àlùbami ní Kamuru na Jorge Masvidal láti dí Àmí Ẹ̀yẹ UFC Welterweight Champion rẹ mú!
UNICEF: Ẹ̀rọ ìbánisọ̀rọ̀ pọ̀ ju ilé ìgbọ̀nsẹ̀ lọ l'órílẹ̀-èdè Nàìjíríà
OLUWA, ìwọ ni Ọlọrun wa, má jẹ́ kí ẹnikẹ́ni ṣẹgun rẹ.
 ilésanmí rọ ́ àlà tí ó lá fún akin atọ ̀ pinpin ọmọ olúṣínà .
Ẹ̀yin fúnra yín sì mọ̀ bẹ́ẹ̀.
OLUWA tún sọ fún Hosia pé, “Sọ ọmọ náà ní, ‘Kò sí Àánú’; nítorí n kò ní ṣàánú àwọn eniyan Israẹli mọ́, 
Ile ti wa pasẹ fun gomina Ambọde pe ko yọju sibi ijoko ile ti yoo waye lọjọ kẹrin osu keji ọdun yii lati wa wi awuijare rẹ.
Ni ipinlẹ Eko nikan, eniyan 254 lo ti lugbadi arun naa ni Ọjọ Eti.
Ìbẹ̀rù OLUWA ni orísun ìyè,òun níí mú ká yẹra fún tàkúté ikú.
Àkọ́já ewé akọ́nimọ̀ọ́gbá fìdíhẹẹ́ Everton, ìyà ló bádé fún Chelsea Ilẹ n yọ gbe Chelsea ṣubu yakata ni Goodison Park ti ṣe papa iṣere Everton Ẹgbẹ agbabọọlu Everton ṣẹṣẹ le akọnimọọgba wọn Marco Silva lọ ni, ki wọn to yan Duncan Ferguson gẹgẹ bi akọnimọọgba fidihẹ.
Jakọbu ń gbé ilẹ̀ Kenaani, níbi tí àwọn baba rẹ̀ ti ṣe àtìpó.
Tobaya ará Amoni náà sì fara mọ́ ọ̀rọ̀ rẹ̀, ó ní, “Bẹ́ẹ̀ ni, bí kọ̀lọ̀kọ̀lọ̀ bá gun orí ohun tí wọ́n mọ, tí wọn ń pè ní odi olókùúta, wíwó ni yóo wó o lulẹ̀!
EndSARS Protest Update: Ìjọba ìpínlẹ̀ Eko ní àwọn ń wádìí èèyàn 229 lọ́wọ́ lórí làásìgbò tó wáyé l'Eko
Onidajọ Banjoko dajọ pe Nyame, to tun jẹ pasitọ, ja awọn eniyan to fi ẹmi igbagbọ sinu rẹ kulẹ lasiko to fi jẹ gomina ipinlẹ Taraba, lasiko to na ọtalerugba din mẹwa miliọnu Naira (250m) ni inakuna.
Bẹẹni Aarẹ Addo ko mu ẹnu lọ si ori ọrọ nipa ẹkunwo epo bẹntiroolu lorilẹede naa eleyi ti awọn ọmọ orilẹede naa kan tori rẹ se iwọde ni ọjọọru.
Ni obinrin naa ba wa sile wọn, to si pariwo le iya rẹ lori lati san owo naa.
OLUWA ní, “Ẹ wá ná, ẹ jẹ́ kí á jọ sọ àsọyé pọ̀.
Tijo tayọ ni Mama fi n dupẹ lọwọ Ọlọrun to da ẹmi rẹ si, ati awọn to yọju sibi ayẹyẹ ọjọ ibi rẹ ọhun pe aanu Oluwa ni oun ri gbà!
Bí ẹ̀yà ara kan bá ń jẹ ìrora, gbogbo àwọn ẹ̀yà yòókù níí máa bá a jẹ ìrora.
Lara awọn eeyan to n gbarata lori bi wọn se n se awọn ọmọ Naijiria ni isekuse ni South Africa ni awọn gbajumọ ati ilu mọọka lawujọ, to fi mọ awọn osere tiata.
Ẹ̀kọ́ miran ti ogun náà tún kọ wa ni pe, ko si èrè kankan ta fẹ́ jẹ́ nínú ogun jija, a kàn fi ẹ̀mí ṣòfò ni.
A gbé e dìde lórí ẹsẹ̀ rẹ̀ mejeeji bí eniyan.
Minisita fun eto iroyin ati asa, ogbeni Lai Mohammed ati awon kongila ti won n se ise naa ,lo soro yii.
Aṣofin Moshood Oshun lo daba ọrọ naa labẹ ipele ọrọ pajawiri ara ilu.
Ọjọ ́ tí a kò bá dá ni kì í pé , kò pẹ ́ , kò jìnnà tí ọjọ ́ ìpàdé ẹbí láṣòrè fi kò gẹ ́ gẹ ́ bí ìpinnu wọn .
Ibo lo buru ju fun awọn akọroyin?
Kini o ṣẹlẹ ni New Zealand?
ni onikaluku lanu silẹ pe kini owo yii wa fun?
Oríṣun àwòrán, Science Photo Library Àkọlé àwòrán, Aisan jẹjẹrẹ ko jẹ ki Savastano gbadun owo rẹ Savastano ni a gbọ pe o ti siwaju asiko yii sọ fun ile ise iyikoto ọun pe owo ti oun jẹ ọun yoo yi ìgbé ayé oun pada patapata.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Kano Supplementary Election: Àwọn ẹgbẹ́ òṣèlú 42 tàpá sí èsì ìbò àtúndì Kano 26 Ẹrẹ̀nà 2019 Àkọlé àwòrán, Gómìnà Ganduje ti ẹgbẹ́ APC àti akẹgbẹ́ rẹ̀ láti ẹgbẹ́ PDP Ẹgbẹ oṣelu mejilelogoji ti tako esi ibo atundi Gomina to waye laipẹ yi nipinlẹ Kano.
Toyin Abraham bí ọmọkùnrin jòjòló Èmi àti Saheed kìí ṣe ọmọdé, a ti jọ ṣe Sinimá papọ̀, èyí túmọ̀ sí pé ìjà ti parí - Fathia Balogun Ọ̀pọ̀ èèyàn bẹnu ẹ̀tẹ́ lu Mercy Aigbe lórí bó ṣe ki Adeniyi Johnson Daddy Freeze to fọrọ yii lede loju opo Instagram rẹ.
Àwọn òṣèré, olórin Yorùbá gbàdúrà fún MC Oluomo 2019 elections: Ìgbésẹ̀ méje fún ìdìbò 2019 tí ó yẹ kí o mọ̀ Àwọn ọmọ Nàìjíríà tahùn sí SERAP lórí ẹjọ́ Onnoghen Tani DCP Kayọde Ẹgbẹdokun, ọ̀gá ọlọ́pàá tuntun ní ìpínlẹ̀ Eko?
Ikeja / General Hospital flyover Bridge, Ijọba ibilẹ Ikeja 25.
Eniyan kan ṣoṣo ni o korira rẹ debi to fi le pa.
OLUWA dá àwọn eniyan rẹ̀ lóhùn pé,“Wò ó!
”Eto AaboAjo eleto aabo bi I agbofinro, ajo eleto aabo ara ati ilu( Nigeria Security and Civil Defence Corps),  ajo ẹsọ  oju ona ( Federal Road Safety Corps) ni won duro ni sẹpẹ si awon orita kan laarin ilu.
Adari ẹgbẹ naa ni Naijiria, Dokita Francis Faduyile ni ofin to de awọn ilokulo oogun ni orilẹede Naijiria ko fẹsẹrinlẹ to nitori wipe awọn alaṣe ko ṣiṣẹ wọn to, eyi to fa ti ọpọlọpọ ṣe n ṣi oogun lo.
ìlú Eko kọ́ ló léwu jùlọ láti gbé lágbàáyé- Ìjọba Eko Aarẹ ati akọwe ẹgbẹ to n ṣewọde naa, Etuk Williams ati Abubakar Ibrahim ṣapejuwe idajọ naa gẹgẹ idoju otitọ bo lẹ.
Lóde ni àwọn ajá yóo wà ati àwọn oṣó ati àwọn àgbèrè, ati àwọn apànìyàn ati àwọn abọ̀rìṣà ati àwọn tí wọ́n fẹ́ràn láti máa ṣe èké.
Ẹgbẹ ajafẹtọẹni nfẹ iwadi tuntun lori ifọnkalẹ epo rọbi
wọ́n ń kọ orin Mose iranṣẹ Ọlọrun ati orin Ọ̀dọ́ Aguntan náà pé,“Iṣẹ́ ńlá ati iṣẹ́ ìyanu ni iṣẹ́ rẹ,Oluwa, Ọlọrun Olodumare.
Bakan naa ni agbẹnusọ awọn ọlọpaa naa ni awọn yoo ṣe afihan awọn adigunjale naa laipẹ ti awọn yoo si fi abajade iwadii awọn fihan awọn ọlọpaa.
Oríṣun àwòrán, Seyi Makinde Lẹyin ọjọ meji ti awọn ọdọ ilu Ogbomoso yabo aafin lati lọ fẹhonuhan, a gbọ iroyin pe gomina ipinlẹ Oyo, Seyi Makinde ti ṣebẹwo si aafin Soun.
United); Daniel Akpeyi (Kaizer Chiefs, South Africa)Awon agbaboolu
nítorí pé kò sí ìrètí fún ẹni ibi,a óo sì pa àtùpà eniyan burúkú.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Baba Sala gba ẹ̀yẹ ìkẹyìn Ọ̀rúnmìlà ni ó kọ́kọ́ lo 'Google' láàgbáyé-Ọ̀ọ̀ni Ìlẹ̀ ifẹ̀ Lẹyin ti eto gbogbo to, ọjọ keje oṣu kejila ọdun 2015 ni gomina ipinlẹ Ọṣun nigba naa, Rauf Arẹgbẹṣọla gbe ọpa aṣẹ fun un nibi ayẹyẹ nla to waye ni gbagede Ẹnuwa ni aafin Oodua ni ilu ile Ifẹ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Amotekun: Ìdí táwọn àgbà Nàìjíríà fi ń forí gbárí àti ohun tó yẹ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Amotekun: Ìdí táwọn àgbà Nàìjíríà fi ń forí gbárí àti ohun tó yẹ 24 Sẹ́rẹ́ 2020 Ṣé ẹ rántí pé lọ́jọ́ kẹwa oṣu kinni ni awọn gomina iha Guusu-Iwọ Oorun Naijiria korajọ ni ipinlẹ Oyo lati ṣe ifilọlẹ ikọ alaabo Amotekun.
Ṣugbọn owó fadaka kọ̀ọ̀kan ni àwọn náà gbà.
Ẹni to bori: Nigeria Nigeria Orilẹede Naijiria lo n lewaju ninu awọn orilẹede to n dije fun ife ẹyẹ́ ilẹ Afirika, AFCON, ti inu wọn dun julọ̀, gẹgẹ bi abọ iwadi idunnu lagbaye tọdun 2019 ti wi, eyi to se agbeyẹwo awọn nkan wọnyii: owo to n wọle, awọn eeyan ti ara wọn ji pepe, atilẹyin lati ọdọ awujọ, ominira, aisi iwa ajẹbanu ati ififunni.
Nítorí bí n kò tilẹ̀ sí lọ́dọ̀ yín nípa ti ara, sibẹ mo wà pẹlu yín ninu ẹ̀mí.
Wo pàtàkì ayájọ́ ‘Má wọ kọ́mú’ tó kò lónìí Buhari ti fòfin de àwọn mínísítà láti rìnrìn àjò lọ sí ilẹ̀ òkèrè Odunlade fijó bẹ́ẹ, Lizzy padà sọ́dún 2012, Toyin Abraham tọ̀ lẹ́ẹ̀mẹwàá Ọ̀pọ̀ èèyàn bẹnu ẹ̀tẹ́ lu Mercy Aigbe lórí bó ṣe ki Adeniyi Johnson Ni papa iṣere orilẹede Naijiria to wa l'Abuja ni Brazil ti lu Super Eagles lalu bolẹ pẹlu ami ayo mẹta sodo.
Koda iyawo Gomina ipinlẹ Kwara sọ wipe, oun yoo gbiyanju lati pari ija laarin awọn mejeeji.
Lẹyin naa, gbe itan soke, na ọwọ si iwaju, ki o si ka orunkun rẹ ko.
Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Sowore Revolution Now Protest: Foto, videos, hot tori as e dey happun on August 5 across Nigeria5 Ògún 2019 Revolution protest: DSS explain why dem arrest Omoyele Sowore4 Ògún 2019 Revolution protest: Nigeria Police don tag Sowore march as treasonable offence4 Ògún 2019 Omoyele Sowore say na im still be AAC party chairmo, nobody comot am13 Èbibi 2019 Nigeria 2019 election: Waec, school certificate, oda qualification of candidates wey wan be presido26 Ọ̀wàrà 2018 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Buhari, Minisita f'ọrọ okeere nilẹ Amẹrika, Tillerson n ṣe'pade lọwọ 12 Ẹrẹ̀nà 2018 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 13 Ẹrẹ̀nà 2018 Oríṣun àwòrán, STATE HOUSE Àkọlé àwòrán, Tillerson wa lẹnu abẹwo rẹ akọkọ si ilẹ Afirika Minisita fun ọrọ ilẹ okeere lorilẹede Amẹrika, Ọgbẹni Rex Tillerson yoo lo n se ipade lọwọ pẹlu aarẹ orilẹede Naijiria, Muhammadu Buhari lnile ijọba.
Ìgbà ti mo ni ibbùgbé àwọn òkú tán ni mo wá sí aginjù Ìdákẹ́rọ́rọ́ ti mo fi òkìtì ọ̀gán ṣe ilé mi.
(44,157) esi ibo, nigba ti akẹgbẹ rẹ lati ẹgbẹ oṣelu PDP ni ẹgbẹrun
Bàbá mi náà sì fèsì ọlọgbọ́, ó ní, Mo fẹ́ràn rẹ ṣùgbọ́n ìdí ìfẹ́ náà kò yé èmi pàápàá, bí mo bá ti ń ríi ọ mo sáà ń fẹ́ràn rẹ ni.
Urueme Adu: Àìsí àfojúsùn mú eléré ìdárayá sá lọ
Ó wá gbọ́ ohùn ẹnìkan tí ó ń bá a sọ̀rọ̀, ó ní, “Peteru dìde, pa ẹran kí o jẹ ẹ́!
Nítorí pé ó ranti ìlérí mímọ́ rẹ̀,ati Abrahamu, iranṣẹ rẹ̀.
Ó wá sọ fún wọn pé, “Nítorí èyí ni amòfin tí ó bá ti kọ́ nípa ìjọba ọ̀run ṣe dàbí baálé ilé kan, tí ó ń mú nǹkan titun ati nǹkan àtijọ́ jáde láti inú àpò ìṣúra rẹ̀.
Ọlọ́gbọ́n ọdọmọde tí ó jẹ́ talaka, sàn ju òmùgọ̀ àgbàlagbà ọba, tí kò jẹ́ gba ìmọ̀ràn lọ, 
"O ni ""o kan rẹ ẹ diẹ ni, kii ṣe aarẹ to buru."
Àwọn agbẹjọ́rò sì ti ń wọ'ṣẹ́ ní ìgbáradì fún ẹjọ́ náà.
Ṣugbọn ẹ̀yin ní tiyín, ẹ má jẹ́ kí wọ́n pè yín ní ‘Olùkọ́ni,’ nítorí ẹnìkan ṣoṣo ni olùkọ́ni yín; arakunrin ni gbogbo yín jẹ́.
Bi èniyàn bá ṣe nkan èèwọ̀, ó lè ṣé gbé ti kò bá si ẹlẹri lati ṣe àkóbá tàbi ki ó fi ẹnu ṣe àkóbá fún ara rẹ̀.
Kofi Annan: Àkàndá ìbejì to gbọ́ ọ̀pọ̀lọ́pọ̀ èdè, to tún fẹ́ ọmọ Yoruba níyàwó
Awon omo oba Camilla, Harry ati Williams ni won kopa ninu ipade naa.
Àárẹ̀ mú wa bí a ti ń fi ọwọ́ ara wa ṣiṣẹ́ oúnjẹ òòjọ́ wa.
Sara ni oun tiẹ ranti pe oun maa n ri awọn ọmọde alawọ dudu lori tẹlifisan, ti esinsin maa n kun wọn, ti eruku yoo si bo gbogbo ara wọn, eyi to mu ki oun gba pe awọn eeyan to nilo aanu ati iranwọ lo wa ni Afrika, ti ko si yẹ ki eeyan tilẹ doju kọ wọn.
Nígbà tí ó ń fi àwọn ọmọ Israẹli ṣe ẹlẹ́yà, Jonatani, ọmọ Ṣimea, arakunrin Dafidi bá pa á.
Osinbajo gbarata lórí ìṣẹ̀lẹ̀ Lekki, ó ní ìdájọ́ òdodo yóò wà Oríṣun àwòrán, @ProfOsinbajo Igbakeji aarẹ nilẹ wa, Ọjọgbọn Yemi Osinbajo ti sọrọ lori isẹlẹ to waye ni ẹnu iloro bode Lekki lọjọ Isẹgun.
''Wo Alaafin kii ṣe ọkunrin lasan, to kan le jẹ (owo rẹ), ti wa wa salọ'' Bakan naa ni ẹnikan naa sọ loju opo BBC pe, ko yẹ ki olori maa tu aṣiri ohun to ṣẹlẹ ni kọkọ faraye gbọ.
Awọn ẹlẹ wọnyii lo n gbe ẹmi Ọba Lamidi Olayiwola Adeyemi kẹta ro, ni aafin rẹ lọwọlọwọ.
Ìgbà mẹ́wàá ni o sì pa owó ọ̀yà mi dà.
Wo àwọn tó ti dákú bíi Maina níwájú ìjẹ́jọ́ Wo ìgbéyàwó olówó iyebíye tí awakọ̀ Kabúkabú ti jẹ̀bùn ọkọ N3.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù BBC Yoruba beere itumọ 'Staircase' ni Yoruba Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ BBC Yoruba beere itumọ 'Staircase' ni Yoruba 14 Ẹrẹ̀nà 2018 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 1 Èbibi 2020 BBC Yoruba lọ si igboro lati beere itumọ 'Staircase' ni Yoruba lọwọ awọn araalu.
 bákan náà ló tún jẹ ́ ìmọ ̀ ọ ̀ nà ìwádìí tí elédùà yọ ̀ nda fú Ọ ̀ rúnmìlà baba Àgbọnìrègún láti fi ṣọmọ aráyé lóore .
Mo di ẹni ìríra lọ́dọ̀ wọn,wọ́n ń rí mi sá,ara kò tì wọ́n láti tutọ́ sí mi lójú.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Dino fàgilè ìfilọ́lẹ̀ àti ìsìn idupẹ 21 Agẹmo 2018 Oríṣun àwòrán, @dino_melaye Àkọlé àwòrán, Ọrọ kìí sì lẹyìn alábahun Dino Melaye Sẹ́nètọ̀ tó ń sojú ẹkùn ìdìbò ìlà oórùn Kogí, Dino Mélayé ti fàgilè ìfilọ́lẹ̀ akanse ise àti ìsìn idupe to ye ki o se fun awọn eeyan ẹkun idibo rẹ.
'Kò sí ìrètí pé wọn yóò rí agbábọ́ọ̀lù Cardiff tó pòórá' Oba Adeyinka Onakade -Moruwafu1 nilu Ikẹnnẹ naa ba BBC sọrọ lori ipa Osinbajo nilu rẹ pẹlu imọran fun gbogbo oloṣelu pé ti Ẹde ba bajẹ, ẹ̀ẹ̀dẹ̀ leeyan n pada si, pé ki onikaluku má gbagbe orisun rẹ̀.
Ṣùgbọ́n èyí tí o ṣe pátákí jùlọ nínú ìjà náà ni pe àwa ni a jà kẹ́yìn, ìgbà tí a jà titi ti a kò gbé ara wa wọ́nlẹ̀ Ìnàkí-ìbẹ̀rù bẹ̀rẹ̀ si i yípadà sí orísìírísìí nǹkan láti bá mi jà èmi náà ń yípadà pẹ̀lú.
lati ri i pe gbogbo ilana ofin  ni awon tẹle
Baba yóo lòdì sí ọmọ, ọmọ yóo lòdì sí baba.
Oṣu Ṣẹẹrẹ (January), ọdun 2000 Igba yii ni ohun ti wọn n pe ni Y2K bug gbode kan ti awọn eeyan si gbagbọ pe gbogbo ẹrọ ayarabiaṣa (computer) lagbaye yoo pafuka lọjọ kọkanlelọgbọn, oṣu kejila, ọdun 1999.
Wọ́n bá dá a lóhùn pé, ‘Alàgbà, ṣebí òun ti ní owó wúrà mẹ́wàá!
Nítorí náà nígbà tí OLUWA gbọ́,inú bí i;iná mọ́ ìdílé Jakọbu,inú OLUWA sì ru sí àwọn ọmọ Israẹli;
O Abiola: Eyi ni àwọn ńkan tó yẹ kí ẹ mọ̀ nípa rẹ̀ Àrọ́bá June 12: Ó yẹ MKO Abiọla, ẹ̀gàn ni hẹ̀ẹ̀ Yahaya Bello, Gomina ìpínlẹ̀ Kogi kéde Onoja ní ìgbákejì tuntun Toun ti pe wọn tara ṣaṣa gbe e lọ si ile iwosan, Kayode sọ pe ibẹ ni o dakẹ si.
Ọ̀dá owó ṣèdíwọ́ fún Balarabe Musa láti tẹ ìwé ìpolongo ìbò ààrẹ ní 2003 Wọ́n dajọ́ ikú fún òṣeré Kannywood Rahama Sadau, eré àbí òótọ́?
Nàìjíríà yóò dá ṣèríà fún Senegal lónìí- Balógun Flying Eagles Balogun ẹgbẹ agbabọọlu Flying Eagles Naijiria, Ikouwem Utin sọ pe oun ati awọn akẹgbẹ rẹ ti ṣetan lati gbẹyẹ lọwọ ẹgbẹ agbabọọlu Sẹnegal.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: 'Àjọṣepọ̀ àwọn olùdíje l'ọ̀nà àbáyọ fún APC' Aṣojúdìbò 51 ló kú ṣáájú ìbò APC l'Ékìtì Ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́ búra fún àwọn alága tuntun Ireti wa wi pe, Aarẹ Buhari yoo ṣe abẹwo sawọn iṣẹ akanṣe kan ni agbegbe Hadejia, Auyo ati Dutse ni ipinlẹ Jigawa lasiko abẹwo ọhun.
Bakan naa ni Monguna ti fẹsun kan Abba Kyari pe o n paṣẹ fun awọn olori ileeṣẹ alaabo gbogbo lorilẹede Naijiria, eleyi ti aarẹ funrarẹ kii mọ si lọpọ igba.
ti o ni ibo to pọju ninu eto idibo  ti
Wọ́n tẹ́ ibùsùn fún Elamu láàrin àwọn tí wọ́n kú sójú ogun pẹlu ogunlọ́gọ̀ àwọn eniyan rẹ̀.
Ọkọ̀ ojú omi ni ọjà yìí máa ń bá dé.
O wa gba wọn nimoran lati mase jẹ káwọn oloselu si wọn lọna.
ṣagbatéru rẹ, ni ijọba ti ṣafikun iye owo ina mọnamọna ati owo epo bẹntiro, ti ọpọ awọn ọmọ Naijiria si bu ẹnu atẹ lu igbesẹ naa.
Seyi Awolowo, ọmọ-ọmọ Awolowo, kí ló ń wà lórí ètò BB Naija?
Ajọ to n gbogun ti iwa jẹgudujẹra lorilẹede Naijiria, EFCC ti kesi Aarẹ Ile Igbimọ Asofin Agba, Bukola Saraki wi pe ko ni ohunkohun lati bẹru ti ko ba ti hu iwa ibajẹ.
N-Power Health: ₦30,000 - si ₦40,000 loṣu.
Ọpọlọpọ àwọn wolii èké ni yóo dìde, wọn yóo tan ọpọlọpọ jẹ.
Sugbọn sa, awọn ọmọbinrin wọnyi lawọn yoo se fẹntilatọ tawọn niye owo ti ko to ẹgbẹta dọla lẹyọ kọọkan.
Gẹ́gẹ bi agbẹjọro ICPC Henry Emore ṣe sọ fún ilé ẹjọ pe sísan bílíọnu méjì le fún pinnacle gẹ́gẹ́ bii àsan-an lẹ ní kọlọfin nínú nítori pé ilé iṣẹ́ ìjọba níkan ló ni ànfani láti gba irú owó bẹ́ẹ̀''.
Lea tún lóyún, ó bí ọkunrin kẹfa.
Ahmed ni sadede ni ọkunrin afurasi naa gbe mọto rẹ duro lẹba oun, to si ni ki oun wọle sinu mọto, to si gbe oun wa silu Eko loni.
Ọ̀ràn dandan sì ni pé bí ó bá ti jí ní kùtùkùtù òwúrọ̀, ẹnìkan níláti nà án ní kùmọ̀ mẹ́fà lẹ́yìn ọrùn, kí o nà án ní mẹ́fà ní ìbàdí kí ó sì kàn án ni ẹ̀sẹ̀ mẹ́fà ni igbá àyà kí ó tó jẹun, bí kò bá sí bẹ́ẹ̀ ara kùmọ́ddìran kò níí le lọ́jọ́ náà, a ní orí ń fọ́ òun a ní inú ń run òun, a sì bẹ̀rẹ̀ síí ṣe bí arúgbó kiri.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù WBC title: Deontay Wilder lu Dominic Breazeale bí ẹni lu bàrà láti di ìgbánú ẹ̀yẹ WBC mú 19 Èbibi 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Afẹsẹkubiojo Deontay Wilder to jẹ ọmọ ọdun mẹtalelọgbọn lo ba ọmọ ilẹ Amerika ẹgbẹ rẹ,Dominic Breazeale ja.
Báyìí ni a ṣe tí a kú[ro ní ìlú àwọn ejò wọn-ọnnì níbi tì Òjòlá-ìbínú ti ń ṣe ọba wọn.
Nígbà tí gbogbo àwọn olùṣọ́-aguntan bá da aguntan wọn dé ìdí kànga yìí ni wọ́n tó ń yí òkúta náà kúrò lẹ́nu kànga.
Oríṣun àwòrán, Aisha Buhari Àkọlé àwòrán, Aisha ni tí ènìyàn tó le ni mílíọ̀nù mẹ́ẹ̀dogún ba le dibo yan ọkọ òun wọle ti àwọn ènìyàn meji dondo si gba ìjọba láti keyin wọn si ààrẹ O ni alága ẹgbẹ́ ń farun iwaju pọ̀ mọ ti ìpàkọ́ fún gbogbo àwọn ọmọ égbẹ́, èyí sì ló ń dá yánpón-yanrin silẹ̀ ninu ẹgbẹ́ APC.
Àwọn nǹkan wọnyi ni mò ń ranti,bí mo ti ń tú ẹ̀dùn ọkàn mi jáde:bí mo ṣe máa ń bá ogunlọ́gọ̀ eniyan rìn,tí mò ń ṣáájú wọn, bí a bá ti ń rìn lọ́wọ̀ọ̀wọ́lọ sí ilé Ọlọrun;pẹlu ìhó ayọ̀ ati orin ọpẹ́,láàrin ogunlọ́gọ̀ eniyan tí ń ṣe àjọ̀dún.
Lekki Shooting: Wole Soyinka ní ìnú òun dùn pé àwọn ọ̀dọ́ ń jà fọ́jọ́ ìwajú wọn lójú ayé òun
Oladejo Okediji àti ìgbé ayé ìtàn kíkọ rẹ̀ Ìlúmọ̀ọ́ká òǹkọ̀wé Yorùbá bàbá Oladejo Okediji ti rèwàlẹ̀ àsà, ìdájí Ọjọ́rú ni bàbá tẹ́rí gbaṣọ.
Ní tèmi, OLUWA ti tọ́ mi sọ́nà tààrà, sí ilé àwọn ìbátan oluwa mi.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, FFK: Buhari ló ń fún àwọn Fulani láàyè láti máa pa ènìyàn' Awọn ọdọ ọmọ African-American mẹrin ati Hispanic kan ni wọn ṣe aṣiṣe fẹsun kan ti wọn si ran sẹwọn lọdun 1989.
Ilé ìgbìmọ aṣofin ti dájọ tí wọn ó fọwọsi àbádofin ìsúna 2019 ‘Kò tọ́sí Adeleke láti díje dupò gomina Ọṣun’ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Àyà mi kọ́kọ́ máa ń já nígbà ti mo ṣẹ̀ṣẹ̀ bẹ̀rẹ̀ -Alaga iduro ọkùnrin Ẹni to tẹle gomina Wike ninu esi idibo naa ni oludije labẹ ẹgbẹ oselu African Action Congress AAC, Biokpomabo Awara.
bi ile-ise se n lọ si, iyaafin, Hajo Sani lo soro yii lasiko to dari awon
Ní ọjọ́ kan àwọn ẹ̀yà Juda wá sí ọ̀dọ̀ Joṣua ní Giligali.
Lẹyin orẹyin, ala d'ohun BBC Yoruba ti de!
Agbẹnusọ fun Oba Saliu Adetunji, Oloko Adeola fi kun un wi pe Olubadan ni baba gbogbo Ibadan nitori naa ni Olubadan ko lee fẹ ki ilu o tu.
" Ẹwẹ, ninu atẹjade kan ti banki ọhun fi lede loju opo Twitter rẹ, o ni ootọ ni pe oun gbeṣẹle apo awọn awọn onibara oun mẹjọ, ṣugbọn ki ṣe ẹbi oun nitori oun gbọdọ tẹlẹ aṣe banki apapọ Naijiria.
klorídì alumíníọ ́ mù ( alcl ) ni àdàpọ ̀ pàtàkì ti alumíníọ ́ mù àti klorínì .
Wọ́n wọ ọkọ̀ ojú omi láti ibẹ̀ lọ sí Antioku ní Siria níbi tí wọ́n ti kọ́ fi wọ́n sábẹ́ ojurere Ọlọrun fún iṣẹ́ tí wọ́n ṣẹ̀ṣẹ̀ parí.
kuna ninu ojuse oun lati pese eto igbaye-gbadun fun gbogbo omo orile ede
Kollington Ayinla ti sọ ẹni tó dá orin Fuji sílẹ̀ gan an ní Nàiìjíríà Wo àwọn Adelé-Ọba aládé méje tó jẹ́ obìnrin nílẹ̀ Yorùbá Àṣeyọrí Anthony Joshua fi hàn pé owó tí à ń ná lórí eré ìdarayá kò lọ lásán - Dapo Abiodun Igbo Olodumare rèé, níbi tí Ìgbín ti tóbi ju Ìjàpá lọ Wọ́n ti fi Omah Lay sínú ọgbà ẹ̀wọ̀n ní Uganda Wọ́n ní kí ọ̀gá àgbà Pólì Ede lọ rọ́kún ńlé lórí ẹ̀sùn pé 'ó kan bẹ́ẹ̀dì sí ọ́fíìsì' Ọgbẹni Imana to jẹ ẹni ọdun mọkandinlogoji ṣalaye pe iyawo oun ko lọ ba ọkunrin mii nigba ti iṣẹ gbe oun lọ si ipinlẹ Borno.
 ""O yẹ ki gbogbo eniyan o wa nile pẹlu idile wọn ati awọn ẹbi niru asiko yii."
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Seun Fakorede di kọmísánà ní ìpínlẹ̀ Oyo Ta ni Ọjọgbọn Adebanji Akintoye?
 ohun ni obinrin alawodudu akoko to soju fun ipinle georgia ni ile asofin .
"Mo fẹ sọọ laifọtape wipe, ko si ẹyọ ologun kan soso bayii ni ilu Dapchi lasiko ti isẹlẹ yii sẹlẹ.
O gboriyin fun ijọba fun yiya June 12 sọtọ ni ọjọ iṣejọba awa ara wa ni Naijiria.
Orin tí a gbé jáde ní ìgbà tí ó yẹ.
Gbogbo ẹja tí ó wà ninu odò náà kú, odò sì bẹ̀rẹ̀ sí rùn tóbẹ́ẹ̀ tí àwọn ará Ijipti kò fi lè mu omi rẹ̀.
0 656 Erekusu Faroe Island 1 2.
Láti inú ìdílé Jakọbu ni àṣẹ ọba yóo ti jáde wá,yóo sì pa àwọn tí ó kù ninu ìlú náà run.
UN salaye pe, akọsilẹ ajọ eleto ilera lagbaye fi ye ni pe akirimadalesi ni arun Ẹ̀yi lọdun yii, nitori ko si ẹkun kankan ni awujọ agbaye ti ko fi ọwọba, tabi ba lalejo.
Wọn di awọn ologun lọwọ irina fun ọpọlọpọ wakati ki wọn to ri wọn bori""."
Eyi jẹyọ lasiko to lọ ki oriade laafin fun ti ayẹyẹ ayajọ ọjọ ibi ọdun mejilelaadọrun.
eyin ati awon omo orile ede Naijiria kan ,se ran awon eniyan lọwọ  lati mọ nipa 
Àwọn ọmọ Bigifai jẹ́ ẹgbaa ó lé mẹtadinlaadọrin (2,067).
ipinle Ebonyi ti ni won ti dana sun ile-ikabo  ajo eleto idibo to wa ni Ezza  ni ijoba ibile Ariwa to wa ni ipinle Ebonyi.
Èyí ni òfin tí ó jẹmọ́ ti ẹni tí ó ní àrùn ẹ̀tẹ̀, ṣugbọn tí apá rẹ̀ kò ká àwọn ohun ìrúbọ fún ìwẹ̀nùmọ́ rẹ̀.
A fẹ́ kí OLUWA Ọlọrun rẹ lè fi ọ̀nà tí a óo gbà hàn wá, kí ó sọ ohun tí a óo ṣe fún wa.
“Ẹ kò gbọdọ̀ rú ẹbọ àjọ ìrékọjá láàrin èyíkéyìí ninu àwọn ìlú tí OLUWA Ọlọrun yín yóo fi fun yín.
Arábínrin Anne Marie jẹ ọkan lara awọn ti ẹmi rẹ ko ba lọ si i.
Mo mú ìwé ilẹ̀ náà tí a ti fi òǹtẹ̀ tẹ̀ ati ẹ̀dà rẹ̀, 
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ṣe lóòtọ́ ni ejò ń pọ owó fún Ginimbi, ọ̀dọ́mọdé olówó kó tó jáde láyé?
Ìdí nìyí tí wọ́n fi ń pe ọjọ́ náà ní Purimu gẹ́gẹ́ bí orúkọ Purimu, gègé tí Hamani ṣẹ́.
20 Bélú 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 23 Bélú 2020 Oríṣun àwòrán, Genesis Global Idile ẹlẹsin musulumi ni wọn bi Woli Israel Oladele si.
“Ijoba fi da awon omo orile-ede loju lati seto bi o ti to ati bi o ti ye saaju awon ifesewonse olorejore wa yooku ti a o gba pelu, DR Congo, England ati Czech Republic.
Eyi ko ṣẹyin bi ọlọpaa kan ṣe ni ki arabinrin kan yọ nkan iledi to dabi idigo ti awọn oloyinbo n pe ni Tampoon to fi n ṣe nkan oṣu rẹ nitori o fẹ yẹ ara rẹ wo lọna ati ṣe ofintoto.
Ohun táa wádìí nípa Tolulope Arotile, Ajagun-wakọ̀ òfurufú tó d'olóògbé lẹ́ni ọdún 24 Oríṣun àwòrán, Facebook/Nigerian Airforce O fẹrẹẹ sunmọ oru ọjọ iṣẹgun ọjọ kẹrinla oṣu keje ọdun 2020 ti ileeṣẹ ogun oju ofurufu Naijiria tufọ iku ọdọbinrin Tolulope Arotile.
Déjì Àkúrẹ́ Ọba Aládélúsi Ògúnladé-Aládétóyìnbó pari gbogbo ètùtù ibilẹ ti Ọba Àkúrẹ́ ma nṣe lati gori oyè ni Ọjọ́rú, ọjọ́ kẹjọ, oṣù keje, ọdún Ẹgbãlemẹ̃dógún, lati di Ọba Kejidinlãdọta ilú Àkúrẹ́ ni ipinlẹ̀ Ondó ti ila-oorun orilẹ̀ èdè Nigeria.
Lati igba ti ipolongo ibo ọhun ti bẹrẹ ni Joe Bide ti n tiraka lati bori ninu idibo naa.
" "" ogun Àjàyè ' , "" owọ ́ blow ' , "" aṣéwó kánò ' , "" agbo Ọ ̀ dájú ' , "" Ṣaworoidẹ ' , "" Ìdè ' , abbl ."
Iru awọn iroyin ti ẹ le nifẹ si: 'Esi Jamb ko nii jade lẹsẹkẹsẹ' 'Ẹ yee wipe igbadun wa lọrun' Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí kan sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
 Ó dá dúró funra rẹ ̀ ní sẹ ́ ńtúrì kẹ ́ jọ lẹ ́ yìn ikú olúwa wa .
Ni bayii, omo odun méjílélọ́gbọ̀n ti o darajulo lagbaye ohun ti gba apapo ife-eye mẹ́tàdínlógún, lati wa leyin akegbe re Roger Federer.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ebila: Ọ̀pọ̀ ẹ̀mí àti dúkìá ni ẹgbẹ́ One Million Boys ṣe lọ́ṣẹ́ ni Ibadan 15 Agẹmo 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 21 Owewe 2020 Oríṣun àwòrán, OTHER Ẹgbẹ okunkun ti wọn n pe ni one million boys mi ilẹ gidi nitori iṣẹ ole ati ipaniyan ti wọn n ṣe.
Wọ́n ń da àwọ̀n sí inú òkun, nítorí apẹja ni wọ́n.
EFCC gbé agbẹjọ́rò àti àna Atiku lọ iléẹjọ́ lórí ẹ̀sùn gbígbé owó tùùlù rìn Oríṣun àwòrán, Twitter/EFCC Ajọ to n gbogun ti iwa ajẹbanu ni Naijiria, EFCC gbe Ọgbẹni Abdullahi Babalele tawọn kan sọ pe oun ni ọkọ ọkan lara awọn ọmọbinrin Alhaji Atiku Abubakar lọ ileẹjọ l'Ọjọru.
Ileeṣẹ ọlọpaa si ti fi ofin sita lati bẹgi dina irina lawọn ijọba ibilẹ yii laarin ago mẹfa owurọ si mẹfa irọlẹ.
Iroyin so pe, egbe ohun fe agbedide ijoba Peulh, ti a mo si Djeelgogji, eyi ti orile-ede Faranse fun lominira ni odun1800.
Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Alaafin: Ẹ máa kọ́ àwọn ọmọ wa ní èdé àti àṣà Yorùbá26 Ògún 2019 Oba Lamidi Adeyemi: Aláàfin àkọ́kọ́ tí yóò lo àádọ́ta ọdún lórí ìtẹ́14 Sẹ́rẹ́ 2021 Alaafin Ọyọ Queens: Ǹjẹ́ o mọ àwọn olorì àkọ́fẹ́ Aláàfin Adeyẹmi?
Habona, ọ̀kan ninu àwọn ìwẹ̀fà ọba, bá sọ fún ọba pé, “Igi kan, tí ó ga ní aadọta igbọnwọ (mita 22) wà ní ilé rẹ̀, tí ó ti rì mọ́lẹ̀ láti gbé Modekai kọ́ sí, Modekai tí ó gba ẹ̀mí rẹ là.
isuna ile benin je ti alaidagbasoke , o si gbojule ise agbe aroje , ogbin owu ati okowo agbegbe .
Èyí jẹ́ àbájáde àtúnṣe òfin tí ilé ìgbìmọ̀ asojú-sofin gùnlé, láti ṣẹ àtúnṣe sí àwọn òfin kan nínú ìwé òfin orílẹ̀-èdè Nàìjíríà tọdún 1999.
ohun tí ó ṣẹ̀ lórí Abeli títí dé orí Sakaraya tí a pa láàrin ibi pẹpẹ ìrúbọ ati Ilé Ìrúbọ.
EFCC ni awọn mu awọn afurasi naa lẹyin ti wọn ṣe iwadii finifini ni ọ̀wọ alẹ lẹyin ti awọn gbọ pe awọn oniṣẹ magomago ati gbajuẹ n fi agbegbe naa ṣe ibugbe.
Ọpọlọpọ awọn janduku naa ni ko ni iṣẹ ọwọ, okoowo tabi iṣẹ to n mu owo wọle fun wọn.
"Orisabunmi ti jáde láyé, ohun tí a mọ̀ nípa ayé àti ikú rẹ̀ nìyí ""Ikọ́ lásán ló pa Orisabunmi"" Ẹ̀kúnrẹ́rẹ́ àlàyé rèé lórí àyẹ̀wò DNA Wo ọ̀nà tí Yoruba ń gbà dá ọmọ àlè mọ̀ nínú ìdílé- Elebuibon ''Ewu ń bẹ pẹ̀lú coronavirus táwọn akẹ́kọ̀ọ́ ba wọlé padà báyìí l'Eko'' Ẹ̀gbọ́n baba Barakat ṣàlàyé bí ó ti gbé e lọ sílé kọmísọ́nà Ogun tí wọ́n ní kó lọ rọ́kún nílé Iléeṣẹ́ ọlọ́pàá Ondo mú ọmọ ẹ̀kọ́ṣẹ́ tó gbé ọmọ ọ̀gá rẹ̀ àti káàdì ìgbowó ATM sálọ Awọn osisẹ to ku ninu rẹ farapa diẹ ti wọn si ti n gba itọju nile iwosan."
Oríkì* jẹ ọ̀rọ̀ ìwúrí ti Yorùbá ma nlò lati fi sọ ìtàn àṣà àti ìṣe ìdílé lati ìran dé ìran.
Ẹ̀yin ará mi, ẹ kà á sí ayọ̀ gidi nígbà tí oríṣìíríṣìí ìdánwò bá dé ba yín.
Ibìkan náà ni gbogbo wọn ń lọ; inú erùpẹ̀ ni gbogbo wọn ti wá, inú erùpẹ̀ ni wọn yóo sì pada sí.
Lori erongba ijọba ipinlẹ Ogun lati ṣi ile ijọsin ati mọṣalaaṣi, kọmisọnna ni ijọba ti ṣepade pẹlu awọn olori ẹsin lori awọn ilana eto aabo lati dena covid-19 ti ile ijọsin ba di ṣiṣi pada.
Báyìí ni àkọsílẹ̀ kan ṣẹ tí ó wí pé, “A kà á kún àwọn arúfin.
Gómìnà Akeredolu la Jegede mọ́lẹ̀ wọlé ìbò gómìnà Ondo fún sáà kejì Gomina Rotimi Akeredolu ti wọle ibo gomina ipinlẹ Ondo to waye lọjọ Abamẹta, ọjọ kẹwaa, oṣu kẹwaa, ọdun 2020.
Ipa tí Fathia Balogun kó nínú bí mo ṣe dèèyàn lágbo òṣèré fíìmù Yorùba rèé - Baba Ijesha Covid-19 ti rékọjáa 1 Miliọ̀nù l'Áfíríkà!
“Ṣé o kò tíì gbọ́ pé láti ìgbà pípẹ́,ni mo ti pinnu ohun tí mò ń mú ṣẹ nisinsinyii?
Oríṣun àwòrán, Gbemi Jesuleke Àkọlé àwòrán, Gómìnà tuntun Ìpínlẹ̀ Osun Adegboyega Oyetola gbàwé ẹ̀rí Ademọla Adeleke to jẹ oludije fun ipo gomina labẹ asia ẹgbẹ PDP to se ikeji ninu idibo naa ni eeru wa ninu esi idibo ọhun, ṣugbọn ajọ INEC Oyetọla lo jawe olubori.
Nígbà tí o ń ṣàlàyé fún ikọ asoju BBC News Yoruba, Alukoro àjọ Olopaa, Femi Joseph, sọ wí pé, ìlú Portharcourt ni ọwọ tí tẹ Chibuzor nígbà tí ò n bèèrè fún owó tí ó tó ẹgbẹrun lọna ẹgbẹrin (800k) lọ́wọ́ òbí ọmọ náà.
Ọmọ-ẹ̀yìn kò ju olùkọ́ rẹ̀ lọ.
Ayaworan: Samuel Agbaje Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí 5:52 Fídíò, Akomolede àti Aṣa: Ọ̀rọ̀ Ẹ̀yán ni Bunmi Femi Amao ń kọ́ wa lórí ètò Akọ́mọlédè àti Àṣà lórí BBC Yorùbá, Duration 5,5224 Owewe 2020 OPC láwọn mú afurasí agbébọn ajínigbé mẹ́rin l'Oyo, ọlọ́pàá ní àpapọ̀ òṣìṣẹ́ elétò aàbò ló ṣiṣẹ́ náa22 Owewe 2020 Èyí tí a wò jùlọ 5:03 Fídíò, Omolola Arohunmolase Welder: Mo ti fí iṣẹ́ 'Welder' gbayì láwùjọ, tó mo fi tọ́ ọmọ yanjú, Duration 5,039 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 5:39 Fídíò, Akomolede ati Asa lori BBC: Olùkọ́ Kikelomo Ogunboye tan ìmọ́lẹ̀ sí ìwà olè ọ̀gá ọlọ́pàá Audu gẹ́gẹ́ bí àwòkọ́ṣe àsìkò yìí, Duration 5,398 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 4:11 Fídíò, Oba Adeyeye Ogunwusi: Ojú mi ti rí lọ́pọ̀ lọpọ̀, ọ̀pọ̀ èèyàn ni kò tilẹ̀ gbàgbọ́ pé mo lè jọba- Ooni, Duration 4,117 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 4:43 Fídíò, Promise Akinlade: ọmọ ọdún mọ́kànlá tó ń fi ìlù dárà bíi àgbàlagbà sọ̀rọ̀ nípa tálẹ́ǹtì rẹ̀, Duration 4,437 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 0:59 Gbọ́, Ìsẹ̀lẹ̀ jákèjádò orílẹ̀èdè àgbáyé láàárín ìṣẹ́jú kan, Duration 0,59wákàtí 5 sẹ́yìn 7:03 Fídíò, Olumuyiwa Bolade Adedeji Military Bruitality: Bí arákùnrin onípèníjà ara tí sọ́jà lù ṣe dé, Duration 7,035 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 4:45 Fídíò, Yoruba Films: Ẹ̀ẹ́ bẹ̀ mi kúrò láyé ni, mi ò lè kú - Fadeyi Oloro, Duration 4,4526 Èrèlè 2020 2:48 Fídíò, Esther Ajayi: Èmi náà ti borí ìṣòro rí ló ń mu mi ṣojú àánú, Duration 2,481 Ògún 2019 6:08 Fídíò, Adebola Ademilua: Àìrísẹ́ ṣè lẹ́yìn ìwé kíkà ló sọ mi dí ìyá onírú, mo dúpẹ́ tèmi, Duration 6,0827 Bélú 2020 2:36 Fídíò, Sotitobire: Ìdájọ́ òdòdò ló fẹsẹ̀ múlẹ̀ lórí ọ̀rọ̀ Pásítọ̀ Sotitobire - Agbẹjọ́rò fún ìjọba, Duration 2,367 Ọ̀wàrà 2020 BBC News, Yorùbá Ìdí tí ẹ fi le è nígbàagbọ́ nínú ìròyìn BBC Ìlànà Lílò Nípa BBC Òfin Àṣírí Cookies Kàn sí.
Minisita si ṣeleri lati san an.
Ó tún sọ pé, “Kí ni ǹ bá fi ìjọba Ọlọrun wé?
Corovavirus: Àjọ WHO tí bẹ̀rẹ̀ ètò láti ràn àwọn orílẹ̀-èdè Afrika lọ́wọ́ Uber ni mo fẹ́ máa gbé báyìí, mi ò tún fẹsẹ̀ rìn mọ́ - Agunbaniro to n gba N33,000 Sùgban àwọn ilé iṣẹ́ ọkọ ofurufu náà ni ìdi ti àwọ̀n fi le wan kuro ni pe kìí ṣe nitori ẹsìn bíkòṣe pé àwọn àlábara wọ́n to ku ń kùn pé wọ́n ni òòrun ara pàápàá jùlọ ọgbẹ́ni Adlers Ipẹjọ náà ti wọ́n pe ni Texas sàlàye pe ìbanilórukọ jẹ́ ni wọ́n se fun ẹbi ọhùn , ti èyi si fa iréwési ọkàn fun àwọn ẹbi náà to si tàkà àbuku si ẹsìn wọ́n Oríṣun àwòrán, AFP Àkọlé àwòrán, Idíle kan gbé ilé iṣẹ́ ọkọ̀ òfurufu lọ ilé ẹjọ lẹ́yin ti wọ́n lẹwọ̀n dànu ninu ọkọ pé ara wọ́n ńrun Ogẹni Alder ni lẹyin iṣkju marun ti a[wọn ti wa ninu ọkọ ni ọkan ninu àwọn òsìsẹ́ wọ́n wa sọ pe ìṣẹ̀lẹ̀ pajawiri sẹlẹ̀ wọ́n si ni lati sọkalẹ.
Ki Àgbàdo tó di Ẹ̀kọ, a lọ̀ ọ́ pa pọ̀: Ògì Ṣí ṣe
Nibiṣani, Ìlú Iyọ̀, ati Engedi; gbogbo ìlú ati ìletò wọn jẹ́ mẹfa.
Ninu tẹmpili rẹ, Ọlọrun,à ń ṣe àṣàrò lórí ìfẹ́ rẹ tí kì í yẹ̀.
Igbẹjọ awọn afunrasi Boko Haram bẹrẹ loni Ọmọogun sọsẹ́ fun Boko Haram ni Gonori Aṣoju ijọba ipinlẹ Kaduna sọ fun igbimọ oluwadi naa wipe ojilelọọdunrun ati meje oku ni ileeṣẹ ologun jọwọ fun isinku aṣepapọ.
Pe awon o ba ajo INEC ja nitori pe ofin wa leyin won ati pe o sese ki won ni ipenija ni won fi sun idibo naa siwaju.
Wọn fẹsun kan Ihetuge Ifeanyi pe o ji ẹrọ ibaraẹnisọrọ ti iye owo rẹ to N950,000.
Ẹni tí ń gba ẹ̀mí àwọn ìjòyè,tí ó ń ṣe ẹ̀rù ba àwọn ọba ayé.
Oríṣun àwòrán, Emma Russell Eyi ko tumọ si pe eeyan n ro erokero, awọn nkan wọn yii lo mu ki a máa kiyesara.
Ṣebí ẹnu ara rẹ̀ ni ó fi sọ pé arabinrin òun ni, tí obinrin náà sì sọ pé arakunrin òun ni.
Ìbúgbàmù àdó olóró pa èèyàn kan ni Mubi
Ọlọrun tún sọ fún Abrahamu pé, “Ìwọ pàápàá gbọdọ̀ pa majẹmu mi mọ́, ìwọ ati atọmọdọmọ rẹ láti ìrandíran wọn.
"Lẹyin ìgbà díẹ̀ to ṣe laalaa nilu Eko, o ri isẹ lati maa lu Agidigbo pẹlu ẹgbẹ́ ""Willie Payne band"" lẹ́yìn eyi to darapọ mọ ẹgbẹ́ akọrin ""JO Araba band"" lọdun 1953."
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù America blacklisted Nigeria: Amẹ́ríkà fi orukọ Nàìjíríà sínú ìwé 'mágùn' nítorí òmìnira ẹ̀sìn.
" O fikun pe o dara bi awọn arugbo ba joko sile, amọ wahala ni wọn fẹ da silẹ pẹlu ọmọde ti wọn ni ko jokoo sile, tori awọn ọmọde ko ni pẹ maa sọnu ladugbo.
Mo tun fẹ fi asiko yii fi da awọn eeyan Oyo loju daadaa pe iṣejọba wa yoo tẹsiwaju lati maa fi ti ẹyin araalu ṣaaju""."
Ẹ padà sílé èyin ọmọ wa tó n ṣiṣẹ́ darandaran - NEF ti Fulani Oyo TUC: A ṣì fa ìjọ̀ba léti ni pẹ̀lú ìyanṣẹ́lódì Kògbérèégbè mẹ́ta nínú òṣèré Yorùbá Nàìjíríà yóò ní iná, kò ní ní, di ìtahùn síra láàrin TCN, TUC Oṣu kẹta ọdun 2019 ni awọn aṣofin agba tẹwọ gba sisan ẹgbẹrun lọna ọgbọn ti wọn si fọwọ sii gẹgẹ bii owo oṣu oṣiṣẹ to kere julọ.
Ọpọlọpọ iwe itẹka ibo yala loju koroju tabi lori ayelujara ni wọn maa n fi ẹrọ ka.
Oluranlọwọ agba fun igbakeji aarẹ lori ọrọ to n lọ, Laolu Akande lo fi ọrọ naa lede loju opo Twitter.
 ojú ayé nìkan kọ ́ ni a fi í wò ó ; a máa fi ojú-inú àti ojú ẹ ̀ mí pàápàá wò ó .
Nígbà náà ni ọkunrin náà yóo bọ́ ninu ẹ̀bi, ṣugbọn obinrin náà yóo forí ru ẹ̀bi àìdára tí ó ṣe.
Lẹ́yìn náà Aisaya wolii tọ Hesekaya ọba lọ, ó bi í pé, “Kí ni àwọn ọkunrin wọnyi wí, láti ibo ni wọ́n sì ti wá sọ́dọ̀ rẹ?
Ó sì tún ṣe é ṣe kí o nira láti ri ìwé ìrìnà lọ si ilẹ Gẹ̀ẹ́sì.
Ninu ifesewonse iko agbaboolu Bayern Munich pelu Sevilla, esi naa to Bayern lati tesiwaju ninu idije ohun, leyin ti won fagbahan Sevilla ni apapo ami-ayo meji sookan(2-1), leyin ti won gba oomi ninu ifigagbaga ese keji.
Idaji owo ọhun ni wọn na lati fi ṣe ipolongo lori ẹrọ tẹlifiṣọn ati lori awọn ikani miran.
Gẹ́gẹ́ bí a ti mọ̀ pé kò pọn dandan kí Aliyev ṣàfihàn ara rẹ̀ bí ó ṣe tó  Azerbaijan kòì tí ì dìbò tí kò sí kọ́mí-n-kọ́họ lẹ́yìn ọdún 37 tí ó ti gba òmìnira  kíni ó mú u ṣe èyí?
Ikú ni irú iṣẹ́ bẹ́ẹ̀ máa ń yọrí sí.
Lucas Moura, wo sunsun, lo ba tun f'ọba le pẹlu gbigba goolu kẹẹta sawọn Ajax , eyi to mu ki Tottenham pegede fun aṣekagba idije Champions League ti saa yii.
Ati pé, mo ṣú Rutu, ará Moabu, opó Maloni lópó, ó sì di aya mi; kí orúkọ òkú má baà parun lára ohun ìní rẹ̀, ati pé kí á má baà mú orúkọ rẹ̀ kúrò láàrin àwọn arakunrin rẹ̀ ati ní ẹnu ọ̀nà àtiwọ ìlú baba rẹ̀.
Oluṣọla Sanwo olu lo gba aṣẹ lati bẹrẹ si ni tukọ ipinlẹ Eko ni ọjọ kọkandinlọgbọn, oṣu karun un, ọdun 2019.
O kawe gboye gẹgẹ bi amofin ni ile ẹko awọn agbẹjọro to wa ni ipinlẹ Eko lọdun 1997.
Ọkùnrin tó ṣe òfegè fọ́nran àwòrán ìgbéyàwó Buhari pẹ̀lú Mínísítà d'èrò ilé ẹjọ́ Ọ̀dá owó ṣèdíwọ́ fún Balarabe Musa láti tẹ ìwé ìpolongo ìbò ààrẹ ní 2003 Ṣé lóòtọ́ ni olorì méjì míì tún ti kúrò láàfin Oyo?
Nile ẹjọ, wọn wo awọn fọran kọọkan lori ifọrọwanilẹnuwo to waye pẹlu Wolii naa.
Aarẹ Orilẹede Naijiria, ni awọn gbe igbesẹ naa lẹyin ti igbimọ amuṣẹya ti ijọba apapọ gbe kalẹ lori ọrs Coronavirus mu aba naa wa ni ifẹgbẹkẹgbẹ pẹluu awọn gomina atawọn igbimọ miran gbogbo ti ijọba gbe kalẹ.
Àwọn ọmọ ogun Babiloni dó ti Jerusalẹmu ní àkókò yìí, Jeremaya wolii sì wà ní ẹ̀wọ̀n tí wọ́n sọ ọ́ sí, ní àgbàlá ààfin ọba Juda.
Ó ní, “Ìbá ti dára tó lónìí, bí o bá mọ̀ lónìí ohun tí ó jẹ́ ọ̀nà alaafia rẹ!
Josẹfu bá fi baba ati àwọn arakunrin rẹ̀ sí ibi tí ó dára jùlọ ní ilẹ̀ Ijipti, ninu ilẹ̀ Ramesesi, gẹ́gẹ́ bí Farao ti pa á láṣẹ.
Erin wo, Ajanaku sun bi oke, leyin ti agbaboolu iko Barcelona ati Spain teleri, Enrique Castro ti awon eyan mo si ‘Quini’ jade laye lojo Isegun(Tuesday).
Lẹyin naa o ti ṣe daada funra rẹ, o gba oye ọmọwe ninu ẹkọ bi a ṣe n ya fiimu igbalode ni Digital Film Academy ni New York.
Ẹẹmarun nikan lati ọdun naa ni wọn ko gba nkankan lọ ile.
8 Síbẹ̀ ó yẹ kí o jẹ́ olõtọ́, àti pé òun ìbá na apá rẹ̀ kí ó sì dáàbò bò ọ lọ́wọ́ gbogbo àwọn ọfà iná ọ̀tá; òun ìbá sì wà pẹ̀lú rẹ ní gbogbo ìgbà wàhálà.
Nítorí yóo yọ ọ́ ninu okùn àwọn pẹyẹpẹyẹati ninu àjàkálẹ̀ àrùn apanirun.
Titi di owurọ oni, apa ibọn ati ẹjẹ awọn oloogbe ṣi wa ni agbegbe naa.
Awọn olukọni ile ẹkọ giga gbogbo-nse Poly naa n beere fun sisan ẹkunrẹrẹ ajẹẹlẹ owo oṣu wọn fun oṣu mejidinlogun ati gbogbo adehun to wa laarin awọn ati ijọba.
Wo àwọn ọmọ ilé ìgbìmọ̀ aṣòfin l'Abuja tó sùn fọnfọn lásìkò ìjókòó ilé 'Ó tẹ́mi lọ́rùn kí n pàdánù ẹsẹ̀ mi, ju kí ǹkan ṣe oyún inú mi' Ẹ má rán ọmọ lọ ilé ìwé ní Cyprus mọ́ - Abike Dabiri Adigunjalè pa oníbàárà báńki tó ṣẹ̀ṣẹ̀ gba owó n'Ibadan Ohun to wa ninu adehun ti Messi ṣe pẹlu Barca ni pe oun le fi ẹgbẹ agbabọọlu naa silẹ lọfẹẹ, ṣugbọn Barca ni o gbọdọ jẹ ipari oṣu karun ti saa bọọlu yoo pari.
Taa gan ló ni Lekki Toll gate láàrin aráàlú àti Asiwaju Tinubu?
Gbajumọ oṣere naa to it n ṣe ere fun bi ọdun mẹtalelogun sọ pe, oun ko le fẹhinti lailai nidi iṣẹ naa, niwọn igba ti oun ba ṣi ni okun ati agbara.
Eniayn 389 tuntun ni akọsilẹ wa pe o ti ni aarun naa, o si ti wọ ipinlẹ marundinlogoji, ati ilu Abuja.
Ọrẹ timọtimọ Ogun Majek, Musiliu Dasofunjo ni ilu wọn ni agbegbe Elesude, lọna Ọmi ni ilu Ibadan ni wọn yoo sin wọn si.
Àwọn ènìyàn ọ̀gbọ́n náà ń fẹ́ máa hùwà gẹ́gẹ́ bí ìtàn ìgbà ìwásẹ̀ ti fi hàn wí pé wọn kò ní nnkan kan í ṣe pẹ̀lú Ìjẹ̀bú Jẹ̀ṣà.
 káyọ ̀ dé kú nínú ìjà ̀ nb ́ a ọkọ ní northern arizona ní oṣù october 1994.
Ẹ sọ fún Ọlọrun pé,“Iṣẹ́ rẹ bani lẹ́rù pupọ,agbára rẹ pọ̀ tóbẹ́ẹ̀ gẹ́ẹ́,tí àwọn ọ̀tá rẹ fi ń fi ìbẹ̀rù tẹríba fún ọ.
Awọn àṣòfin fi kún un pé ni àye òdé òní, ọ̀pọ̀ àwọn ilé ìṣẹ́ ìròyìn tí ayelujara ló n dá omi aláafia ilú rú, ìlú ti kò si sí òfìn ẹ̀ṣẹ̀ ò sí ni bẹ, nítori náà òfin yìí jẹ ki olúkulùkù súnraki nítori ìjìyà to wà nibẹ̀ Oríṣun àwòrán, Senate Àkọlé àwòrán, Wọ́n fi kún un pé ń ọ̀pọ ìgbà èyí a máa dá èdè àiyede sílẹ̀ láàrín àrá ìlú Ìjìyà to wà fún ẹni ti ó ba rú òfin yìí Ilé ìgbìmọ̀ àṣofin tí ṣe àgékalẹ̀ ẹgẹ̀rún lọ́nà ọọdúrún naíra fun ọlọdani to ba lùgbàdi ẹṣẹ̀ yìí àti mílíọnù mẹ́wàá naira fún ilé iṣẹ́.
' Ile ẹjọ to n gbọ igbẹjọ lẹyin eto idibo fagile ibo ijọba ibilẹ mẹta ti o gbe Ọsunsanya wọle lataari magomago ti oludije ninu ẹgbẹ oṣelu PDP fi kan an.
Shagari gbe apoti ibo saa ọlọdun mẹrin fun igba keji lọdun 1983, o si tun wọle.
Ẹni ti gomina ba yan si ipo naa ni yoo ma a mojuto bi awọn to ti kọ ọkọ tabi iyawo wọn silẹ yoo se pada ni ololufẹ miran, paapaa nitori pe ijọba maa n ṣe ayẹyẹ igbeyawo alasepọ fun wọn.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Lapapapọ bayii okoolelẹẹdẹgbẹrin ati mẹjọ (1728) eeyan ni ayẹwo fihan pe wọn ti ko arun yii lorilẹede Naijiria bayii.
Arúfin ni Seyi Makinde pẹ̀lú bó ṣe gbà kí wọ́n sin Ajimobi sí GRA - Amòfin Bibori ẹlẹyamẹya Akọroyin kan, Chakhaza, sọ fun BBC pe, isẹ nla lo wa nilẹ fun aarẹ tuntun lati ma a fi ẹ̀yà yan ẹnikẹni si ipo, gẹgẹ bi ijọba to kuro nipo to fi ẹlẹyamẹya ṣe e lai fi bò.
Oríṣun àwòrán, @inecnigeria Àkọlé àwòrán, Atẹjade Inec Ajọ Inec ni awọn ko ni ko irẹwẹsi ọkan lati pari eto idibo nibi ti awọn ti kede esi ibo.
Bi awọn kan ti ṣe n dawọ idunnu laarin awọn oṣere, bẹẹ ni ibanujẹ n dori agbarijọpọ awọn oṣere kodo nitori ipapoda agba oṣere kan.
Ṣamai ló bí Maoni, Maoni sì bí Betisuri.
" Ẹrí rè é, Sanwo-Olu ṣèlérí lóòtó lórí súnkẹrẹ-fàkẹrẹ Apapa Agbekoya: Bí a bá na oògùn abẹnugọ̀ngọ̀ s'ókè, ìjínigbé á d'ópin!
Ni ti awọn alabaṣiṣẹ igbakeji gomina naa, ti ijọba ipinlẹ Ondo gbaṣẹ lọwọ wọn, Ajiboye sọ pe ẹni to ba fun ni ni iṣẹ le gba iṣẹ naa lọwọ, ẹni lọrọ naa ri."
Ipele kò-mẹsẹ̀-o-yọ nìdíje dé, O ku orilẹ-ede meji pere ni Russia, iyẹn France ati Croatia nigba ti Belgium ti gba ipo kẹta lẹyin ti wọn ṣíná fún England.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Yoruba Films: Òṣèrè tíátà Muideen Oladapo gbàràdá lórí ètò 'Ṣé o láyà?
Mose kó gbogbo àwọn ọ̀pá náà siwaju OLUWA ninu Àgọ́ Ẹ̀rí.
N kò ní àṣẹ kan láti ọ̀dọ̀ Oluwa láti pa fún àwọn wundia.
Ẹ wo àwọn gbajúmọ̀ òṣèré tíátà tó jogún eré ṣíṣe lọ́dọ̀ òbí wọn Coronavirus: Arsenal padà sórí pápá, Premier League lè bẹ̀rẹ́ padà lóṣù kẹfa Irrfan Khan, Osere sinima India jáde láyé Àkàsọ, Àkàbà àti awọn ọrọ miran ni eti BBC gbọ loni lẹnu awọn ti a fọrọwa lẹnu wo Iru awọn iroyin ti ẹ le nifẹ si: Kini 'barber' ni Yoruba?
Idi niyi ti ijọba fi paṣẹ pe, ki awọn dokita agba lawọn ile iwosan ijọba apapọ maa lo dokita agunbanirọ, lati maa tọ awọn to n gba itọju pajawiri lọdọ wọn.
Awọn eleyii ti wọn ti kede ni owurọ Ọjọru lasiko ti wọn bẹrẹ kika fihan wi pe oludije sipo gomina labẹ ẹgbẹ oselu PDP, Nyesom Wike lo n saaju pẹlu ibo to ju ẹgbẹrun lọna ẹẹdẹgbẹta.
Àkọlé àwòrán, Awọn ọmọ Yoruba ni Austria Ọdun 2000 ni wọn ṣe iṣẹdalẹ Ẹgbẹ Ọmọ Oduduwa lati maa gbe aṣa Yoruba larugẹ, lati ri si mim'aye rrun fun awọn Yoruba to n gbe ni Austria ati mimọ ara ẹni fun idokoowo lagbaye.
Daniẹli gba àṣẹ lọ́wọ́ ọba, ó fi Ṣadiraki, Meṣaki, ati Abedinego ṣe alákòóso àwọn agbègbè Babiloni, ṣugbọn òun wà ní ààfin.
Kò sí ìsinmi ìdajì táàmù fáwọn akẹ́kọ̀ọ́ ìjọba l‘Ọyọ - Seyi Makinde Ìjọba mi ṣetán láti mú àgbéga bá ètò ààbò l‘Ọyọ - Seyi Makinde Lẹ́yìn ò rẹyìn Seyi Makinde búra fún ìgbìmọ̀ olùgbaninímọ̀ràn Awọn orukọ naa ni: Hon Barrister Adeniyi John Farito Mr Adeniyi Adebisi Hon Muyiwa Jacob Ojekunle Prof Oyelowo Oyewo Barrister Olasunkanmi Olaleye Barrister Seun Asamu Mr Rahman Abiodun AbdulRaheem Chief Bayo Lawal Hon Funmilayo Orisadeyi Dr Bashir Bello Hon Wasiu Olatunbosun Prof Daud kehinde Sangodoyin Mr Akinola Ojo Rt Hon Kehinde Ayoola Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
je baba Zainab so lasiko to n ba akoroyin Voice of Nigeria soro,”Mo dupe pupo
Ìwọ ni mo kígbe pè, OLUWA,nítorí iná ti jó gbogbo pápá oko run,ó sì ti jó gbogbo igi oko run.
Àjèjì ati àlejò ni a jẹ́ ní ojú rẹ, gẹ́gẹ́ bí àwọn baba ńlá wa.
Gbogbo pákó tí a fi dárà sí ara ògirini wọ́n fi àáké ati òòlù fọ́.
Awọn tọrọkan lati ajo to n
Bí o tí ń jẹun lọ́wọ́, jẹ́ kí ọwọ́ rẹ máa gbọ̀n, kí o sì máa fi ìwárìrì ati ìbẹ̀rù mu omi rẹ.
1 11677 Orilẹede Cyprus 70 5.
Ìtàn Mánigbàgbé: Bode Thomas ní ọpọlọ pípé, ó jẹ́ aṣaájú àmọ́ ó ní inú fùfù
Wọ́n fẹ́ràn ìjókòó ọlá níbi àsè.
Iyalufa bi ọmọbinrin meji, ọkan n jẹ Ọmọyẹni nigba ti ekeji si n jẹ Ọmọlufa, ti wọn mu lati ara orukọ iya rẹ.
Ibanujẹ kẹta fun idile Monverville A gbọ wọn gun David to jẹ ẹni ọdun mejidinlogoji ni ọbẹ pa lẹyin ti ija bẹ silẹ laarin awọn kan ni adugbo rẹ ti wọn si in fi ọbẹ, ada ati igi ja.
Ó ranṣẹ sí Dafidi láti ròyìn fún un pé, “Mo ti gbógun ti Raba, mo sì ti gba ìlú tí orísun omi wọn wà, 
Ivanka sọ loju opo Twitter rẹ pe idile Donald Trump ko le gbagbe Robert laelae.
Adari New Zealand naa n fi awọn omode lọkan balẹ bo ti yẹ.
Ilé iṣẹ́ ọkọ ofurufu náà lé Yehuda Yosef Adler, iyawo rẹ̀ Jennie àti ọmọ wọ́n obinrin kékéré kuro ninu ọkọ ofurufu Detroit ni inú oṣù kini ọdun to kọja.
N óo fún ọ ní ilẹ̀ tí mo fún Abrahamu ati Isaaki, àwọn ọmọ rẹ ni yóo sì jogún rẹ̀.
Adari ẹgbẹ awọn Imaamu naa, Abu Muhammad ni Gomina naa takọ ofin ijọba apapọ lori yiyago funraẹni ti ijọba apapọ gbe kalẹ lati koju itankalẹ arun Coronavirus to n ja rain lorilẹede Naijiria.
ìwọ ni omijé ti inú ẹyinjú
idanileko fun gbogbo awon ti oro naa kan bii awon oluko ile iwe alakọọbẹrẹ,
Bẹ́ẹ̀ ni àwọn baba yín ṣe nígbà tí mo rán wọn láti Kadeṣi Banea láti lọ ṣe amí ilẹ̀ náà.
”Ewe, bi a ko ba gbagbe wipe, Totti darapo mo iko Rome lodun 1989, ireti re ni wipe iko Roma yoo gba akegbe re ti won jo kopa ninu idije boolu agbaye lodun 2006, Gennaro Gattuso gege bi  akonimoogba tuntun iko naa, sugbon  won ko jale ti won si lo gba Paulo Fonseca lati inu iko agbaboolu Shakhtar Donetsk lose ti o koja.
Ọpọlọpọ awọn alatilẹyin ijọba ni o n dunu lori iku iya mi ni gbangba.
Nígbà náà a óo fìdí ìtẹ́ múlẹ̀ pẹlu ìfẹ́ tí kì í yẹ̀.
”Dafidi bá bá tirẹ̀ lọ, Saulu sì pada sí ilé rẹ̀.
Aarẹ tun paṣẹ fun ileeṣẹ eporọbi Naijiria, NNPC, lati din owo epo bẹtiro ku.
Ṣugbọn kí inú àwọn olódodo máa dùn,kí wọn máa yọ̀ níwájú Ọlọrun;kí wọn máa yọ̀ ṣẹ̀ṣẹ̀.
Ninu alaye agbẹjọro Ghali Alaaya ti ile iṣẹ agbẹjọro Tafa Ahmed & Co, o ni ''ilu ti ọdaran ba ti da ẹsẹ ti ile ẹjọ to si kaju oṣunwọn lati gbẹjọ naa ba ti wa nibẹ lo jẹ ibi akọkọ ti a ti n gbọ iru ẹjọ bẹẹ.
Lójú ẹni tí ara tù,ìṣòro kì í báni láìnídìí.
Nígbà tó bá yá, tí mo bá dá ire Juda ati ti Jerusalẹmu pada,
"Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Wo díẹ̀ lára dúkìá tí jàǹdùkú sun níná l‘Eko torí ìwọ́de EndSARS Á ràgà bo CCTV Lekki bí i ẹ̀rí tó dájú fún ìwádìí ìpànìyàn - Sanwo-Olu SERAP gbé ìjọba àpapọ̀ lọ ilé ẹjọ́ àgbáyé ICC lọrí ẹ̀sùn ìpànìyàn ""Jàǹdùkú gún ẹ̀gbọ́n mi lọ́rùn, jó ilé àti mọ́tò wa méjì, kòròfò la wà"" Olùwọ́de 12 kú ni Lekki, 38 lapapọ kú lọ́jọ́ Isẹ́gun, 56 ni àròpọ̀ àwọn tó bá ìwọ́de lọ - Amnesty International Osinbajo gbarata lórí ìṣẹ̀lẹ̀ Lekki, ó ní ìdájọ́ òdodo yóò wà Ooni Ogunwusi àti Wole Soyinka kòrò ojú sí ìṣẹ̀lẹ̀ Lekki Tollgate O wa sapejuwe agba oselu naa bii ""ẹni to rọrun lati ri, onirẹlẹ ẹda, to si n se atilẹyin fawọn ọdọ lasiko ti wọn n se iwọde alaafia EndSARS."
Wọn dẹ ti n ṣe awọn ayẹwo ati iwadii ipo ilera wọn ṣaaju ki wọn to o pade Aarẹ Muhammadu Buhari.
Ìtàn Mánigbàgbé: Ẹfunsetan Aniwura lọ́lá, ó lówó, ó sì tún gbajúmọ̀
Àṣírí ilé ìmúni nígbèkùn míràn tú síta ni Katsina World Food Day: Wo àwọn oúnjẹ ìṣẹ̀mbáyé Yorùbá tó ti ń di àpatì Akẹ́kọ̀ọ́ Ilaro Poly tó pegedé jù jẹ ẹ̀bùn iṣẹ́ ọ̀fẹ́ lọ́wọ́ Gómìnà Abiodun Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Dino Melaye lo n soju ẹkun idibo iwọ oorun Kogi ni ile igbimọ asofin agba lorilẹede Naijiria.
Odò yìí ni wọ́n npè ní odòo Bradford.
Awọn aralu to ṣoju wọn koro sọ fun awọn oniroyin pe ọkọ Peugeot 406 Saloon ati Toyota Kilux ni awọn ajinigbe naa wa.
Wo ohun tí ìwọ́de #EndSARS sọ iléèwé dà ní Oyo, Ekiti, Ondo, Eko Kò sáyè iwọ́de mọ́ l'Eko ẹ lọ tọwọ́ yín bọṣọ - Ọlọ́pàá Buhari, jáde bá ọmọ Nàíjíríà sọ̀rọ̀, orí àgbá ẹ̀tù la dúró lé - NUJ pariwo Ìpínlẹ̀ Oyo àti Osun sàlàyé ìdí tí wọn kò fi tí ṣè ifilolẹ ìgbìmò igbẹjọ aṣemáṣe SARS Wole Soyinka Ọjọgbọn ati onkọwe Wole Soyinka jẹ eniyan kan gboogi to n fa fun ẹtọ awọn ọmọ Niajiria, awọn alawodudu nile ati loko ni ọpọlọpọ igba.
Nígbà tí mo pè wọ́n, gbogbo wọn jọ yọ síta.
Ibi ti wọn yoo ti ribi du ipo lọkan wọn a maa wa.
Báwo ni àìdára ati ẹ̀ṣẹ̀ mi ti pọ̀ tó?
tí Nebukadinesari, ọba Babiloni, kò kó lọ, nígbà tí ó kó Jehoiakini, ọba Juda, ọmọ Jehoiakimu, ati gbogbo àwọn ọlọ́lá Juda ati ti Jerusalẹmu lọ sí Babiloni.
Ó kéré tán, ẹ̀mí 95 ti sọnù nínú ìkọlù Fulani ní Mali Agbegbe Sobane-Kou nitosi Sanga ni iṣẹlẹ yii ti ṣẹlẹ ni aarin gbungubn orilẹ-ede Mali.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Osun Osogbo festival 2019: Báwo ni àjọ̀dún Ọ̀ṣun Òṣogbo ṣe lọ lọ́dún yìí?
Awọn onibara ileeṣẹ ina ọba Eko yoo maa san naira mẹtalelogoji ni wakati kan ti wọn lo ina fun wakati mejila o kere tan lojumọ.
Oríṣun àwòrán, @thenff Alaga igbimọ to n se kokari eto idibo NFF naa, Muhammed Katu lo kede esi ibo ọhun.
Omijé fẹ́ bọ́ lójú mi tí mo bá ṣàfiwé SARS tí mo dá sílẹ̀ àti SARS tó wà níta báyìí- Fulani Kwajafa Ìdí táwọn olùwọ́de EndSARS fi kọ oúnjẹ àti ọtí ẹlẹ́rìndòdò tí MC Oluomo gbé wá rèé Ajínigbé tú ìyá àti ọmọ ọdún mẹ́ta sílẹ̀ lẹ́yìn tí wọ́n gba ₦1.
Oyun oṣu mẹjọ lo wa ninu obinrin naa.
OLUWA bá sọ fún un pé, “Lọ káàkiri ìlú Jerusalẹmu, kí o fi àmì sí iwájú àwọn eniyan tí wọ́n bá ń kẹ́dùn, tí gbogbo nǹkan ìríra tí àwọn eniyan ń ṣe láàrin ìlú náà sì dùn wọ́n dọ́kàn.
Baba Obasanjọ tun sapejuwe Olu Bajọwa gẹgẹ bi ẹni to jẹ akinkanju ologun, to si saaju ọwọ kọkanla ikọ ọmọ ogun ilẹ wa, 11 battallion, lasiko ogun abẹle to waye lorilẹede Naijiria.
" Nigba ti Ebenezer Obey n sọrọ lori irufẹ obinrin to fẹ, o ṣalaye pe oun ko wa obinrin ti yoo tun maa bimọ mọ bayii bikoṣe nitori ati lee jọ maa wa pọ.
 bàbá yìí wá dó sí ìbi ti a mo sí kútò lónìí .
Ní ogúnjọ́ oṣù keji, ní ọdún keji tí àwọn ọmọ Israẹli jáde kúrò ní Ijipti, ìkùukùu tí ó wà ní orí ibi mímọ́ gbéra sókè.
Ó yẹ ká yẹra fún un nígbà gbogbo, kí ó má baà ṣe àkóbá fún wa.
AWỌN TO NI AARUN COVID-19 NI NAIJIRIA NI 27/05/2020 Apapọ awọn to ni aarun coronavirus ni Naijiria ti pe ẹgbẹrun mẹjọ ati ojilelọọdunrun le mẹẹrin (8344).
Bí wọ́n bá pe baálé ilé ní Beelisebulu, kí ni wọn yóo pe àwọn ẹni tí ó ń gbé inú ilé rẹ̀!
 ) opin eré ìje ; òpin .
Èyí tó túmọ sí míliọ̀nù kàn ààbọ Náìrà lósù ( ₦1.
O wa fikun un wi pe ti Aarẹ Buhari ba tun ya ọgbọn biliọnu ti o fẹ ya, irandiran awọn ọmọ Naijiria ni yoo san owo naa.
Èyí tí yóo bá kú ninu yín kí ó kú, èyí tí yóo bá ṣègbé, kí ó ṣègbé, kí àwọn tí wọ́n bá ṣẹ́kù sì máa pa ara wọn jẹ.
Ileeṣẹ naa ni ki awọn ọmọ Naijiria darapọ mọ 'Facebook Live' ni Ọjọru, ọjọ kẹtadinlogun, oṣu kẹrin, laago meji ọsan lati gbọ ẹkunrẹrẹ alaye lori awọn ibeere lori 'DS 160'.
Rabiu Yusuf, ìgbákejì ọ̀gá àgbà ọlọ́pàá Nàìjíríà (AIG) lẹ́kùn Katsina jáde láyé Ọ̀fẹ́ ni China yóò kọ́ fásítì $50M ètò ìrìnnà sí Daura ìlú Ààrẹ Buhari- Amaechi Ìjọba Ghana ṣí iléeṣẹ́ àwọn ọmọ Nàìjíríà padà.
Ondo Kidnap: Afurasí ní òun kàn fẹ́ fi ọmọ tó sọnù gba owó lọ́wọ́ Sọtitobire
Mo bá gbadura pe,“Tẹ́tí sí ọ̀rọ̀ mi, OLUWA,kí o sì gbọ́ ẹ̀bẹ̀ mi.
Ẹ̀rù ò b'odò bí Atiku bá lọ ṣèpàdé ní Dubai Ọgọrọ eeyan lo ti fesi lori ẹrọ ayelujara sọrọ ti abẹnugan ẹgbẹ oṣelu APC Asiwaju Bola Tinubu sọ lori ipade oludije fun ipo Aarẹ labé asia ẹgbẹ oṣelu PDP Atiku Abubakar ati awọn alatilẹyin rẹ ṣe ni ilu Dubai.
Bí Ọlọrun bá tiẹ fún mi ní irun àgbọn, máà dúpẹ, àwọn kan wa to jẹ pe kodoro bayii ni."
Nítorí kò sí ohun tí òfin sọ di pípé.
Nítorí pé ó dàbí iná alágbẹ̀dẹ tí ń yọ́ irin, ati bí ọṣẹ alágbàfọ̀ tí ń fọ nǹkan mọ́.
Davido, to pe orukọ ara rẹ ni ‘peace of mind’, ti sọ lori itakun ibaraẹnisọrọ Twitter rẹ pe, oun ti ra ọkọ baalu lẹyin ọkọ̀ ‘assurance’, iyen ọkọ ayọkẹlẹ to ra fun ọrẹbinrin rẹ, Chioma.
Ṣugbọn Fẹstu dá wọn lóhùn pé, “Àwọn ọmọ-ogun ń ṣọ́ Paulu ní Kesaria; èmi náà kò sì ní pẹ́ pada sibẹ.
Oríṣun àwòrán, Nigeria Presidency Àkọlé àwòrán, Ife ẹyẹ agbaye yoo farahan ni ileesẹ BBC to wa ni ilu Eko ni ọjọ ẹti gẹgẹbii ara ilakalẹ ajọ FIFA Ninu ọrọ tirẹ, minisita fun ere idaraya lorilẹede Naijiria, Ọgbẹni Solomọn Dalung ṣalaye wipe bi ikọ agbabọọlu orilẹede Naijiria se pegede lati kopa nibi idije ife ẹyẹ agbaye fun idije bọọlu afẹsẹgba lo fa a ti ife ẹyẹ naa fi de orilẹede Naijiria.
Atiku náà kéde àtìlẹ́yìn rẹ̀ fún ẹ̀ṣọ́ alábòò Amọtẹkun Mo kàn fẹ́ fi ọmọ tó sọnù gba owó lọ́wọ́ Sọtitobire ni - Afurasí Àwọn ará South-Africa yarí nítorí torí gbọ̀ngàn kọ̀ ìgbéyàwó abo-sábo Ẹ̀yin ẹ máà wò ó, ó ṣeéṣe kí APC túká lẹ́yìn ìṣèjọ́ba Buhari!
O ni ipakọ ko gbọ́ suti nitori ori ẹ̀lẹ́gan lo ba jẹ.
Iwadii n lo lowo bayii lori esun ti won fi kan aare orile-ede France tele ri, ogbeni Nicolas Sarkozy pe oloogbe olori omo-ogun olote Libya Muammar Gaddafi sagbeteru eto idibo odun 2007 ti o fi jawe olubori.
Obiulale ni lẹsẹkẹsẹ loun bẹrẹ si ni ke pe ''ẹ gbami, ẹ gbami, ọta ibọn ti ba mi, mo fẹ ri ọmọbinrin ati ọmọkunrin mi, mi o fẹ ku sibi.
" Oṣú mẹ́fà ni òṣìṣẹ́ ìjọba tó bá bímọ yóò máa lò nílé kó tó wọṣẹ́ padà- Seyi Makinde Ọ̀rọ̀ ìjókòó ìgbìmọ̀ ìwádìí #EndSARS náà dé ìpínlẹ̀ Ogun ₦50 bílíọ́nù ni a pín fún gbogbo ìpínlẹ̀ ní Naijiria láti kojú àrùn Covid-19- Ìjọba àpapọ̀ Ẹ fún wa lówó oṣù wa tàbí kí a gùnlé ìyanṣẹ́lódì ọlọ́jọ́ gbọọrọ- Àwọn dokita ìpínlẹ̀ Ondo Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Kabex End SARS: Àwọn ìṣẹ̀lẹ̀ tó làmìlaaka tó wáyé nínú oṣù Kẹ́wàá ọdún 20206 Bélú 2020 Oyinkan Abayomi: Ajàfẹ́tọ̀ọ́ ẹni tó dá ẹgbẹ́ òṣèlú obìnrin àkọ́kọ́ sílẹ̀, tó tún jà fún ètò ẹ̀kọ́, ìṣèlú àti òmìnira obìnrin5 Bélú 2020 Yoruba movie: Ẹ wo ohun tí mama Ire, Toyin Abraham ní òun yóò máa fi ìyókù ọdún yìí ṣe6 Bélú 2020 Fídíò, Orlando Owoh: Ayé ti sú mi, àdúrà ikú ìrọ̀rùn ló wù mí- Christiana, Ìyá Orlando Owoh tó ti pé ọdún 1105 Bélú 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
egbe oselu APC ko seto idibo inu egbe , ni eyi ti o yẹ ki won fi yan oludupo ti
CAF President: Wọ́n ti fòfin ọdún márùn ún de Aàrẹ̀ CAF, Ahmad Ahmad
Awọn aburo pe mi lori foonu pe o ni ọkan oun daru nibi to ti ya ara rẹ sọtọ to si ni bi oun ko ba gba ibukun lẹnu mi, oun ko ni lọ, ni wọn ba n bẹ mi pe ki n fi aṣẹ sii""."
Bakan naa, o ṣalaye lori ohun to maa n fa ki ọyan obinrin da wa silẹ.
"A ko tii mu ọjọ iyawo, amọ wọn saa fẹ se, ki wa ni mo fẹ se?
nítorí pé wọn kò gbé oúnjẹ ati omi lọ pàdé àwọn ọmọ Israẹli, kàkà bẹ́ẹ̀, wọ́n bẹ Balaamu lọ́wẹ̀ láti máa gbé àwọn ọmọ Israẹli ṣépè, ṣugbọn Ọlọrun wa yí èpè náà pada sí ìre fún Israẹli.
Eyi tumọ si pe wọn ti gbe ami tabi akọle  Ma ṣe gbe ọkọ rẹ silẹ sibi yii""."
O ni bi ede ṣe n gbooro si ni agbegbe kan ni awọn eniyan a maa lo bi o ṣe wulọ si fun ohun ti wọn nilo rẹ fun.
Mo ni ọwọ nla fun Afrika-Trump Trump tọrọ aforiji lori asise rẹ Aṣoju orilẹẹde South Korea kan, Chun Eiu yong ti o ti ṣe ipade pẹlu awọn olori mejeeji lọsẹyi lo sọ wi pe Aarẹ Kim ti gba lati dawọ duro lori didan ado oloro wo.
Toke MAkinwa funra rẹ ti sọrọ sita pe: Toke Makinwa ṣi wa ninu ile rẹ o!
Àwọn alufaa nìwọ̀nyí: àwọn ọmọ Jedaaya, tí wọ́n jẹ́ ti ìdílé Jeṣua, jẹ́ ẹẹdẹgbẹrun ó lé mẹtalelaadọrin (973).
gbosuba fun awon ara ilu lori bi won se dibo won ni irọwọ ati irọsẹ .
Oorun yìí wọ̀ mi lára nítorí pé àárẹ̀ ti mú mi kí ó tóó di pé mo sùn, bí mo sì ti bẹ̀rẹ̀ sí lá àlá dídùn kan ni ẹnì kan déédéé jí mi.
Ninu ọrọ to ba awọn eeyan ipinlẹ sun sọ lati fi sami ọdun kan ti o gori aleefa gẹgẹ bi gomina ipinlẹ Oṣun, ni Oyetola ti fidi ọrọ yii mulẹ.
Orilẹede wo lo ni ibudo ajogunba ti Unesco julọ lagbaye?
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Sarumi Ni obìnrin àkọ́kọ́ tí yóò gbégbá ipò gómìnà l'Ọyọ 27 Èbibi 2019 Oríṣun àwòrán, Bolasarumialiyu Àkọlé àwòrán, Oun ni obìnrin àkọ́kọ́ tó ń dupò gómìnà ní ìpínlẹ̀ ọyọ Ojoojumọ kọ ni a n gbọ pe obinrin n dupo gomina ni ipinlẹ Ọyọ, lati igba ti wọn ti da ipinlẹ naa silẹ ni ọdun 1976.
Ẹ má dàbí àwọn baba yín ati àwọn arakunrin yín tí wọ́n ṣe alaiṣootọ sí OLUWA, Ọlọrun àwọn baba wọn, tí ó sì sọ ilẹ̀ wọn di ahoro bí ẹ ti rí i yìí.
Ewé ti a kó sọnù wúlò fún àyiká ju ọ̀rá igbàlódé lọ.
BBC News Yoruba kuku tẹlee debẹ lati mọ ohun gan to ri lọbẹ to fi wa ro ọwọ.
Ní ọjọ́ náà, n óo dẹ́rùba àwọn ẹṣin, n óo sì fi wèrè kọlu àwọn tí wọn ń gùn wọ́n.
Gbogbo àwa yìí sì ni ẹlẹ́rìí.
Ní agogo mẹta ọ̀sán, Peteru ati Johanu gòkè lọ sí Tẹmpili ní àkókò adura.
Fi agbára rẹ hàn, Ọlọrun,fi agbára tí o ti fi jà fún wa hàn.
Èrò pọ̀ tí wọ́n wá wòran rẹ̀.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù EndSARS Protest Updates: Feminist Coalition sọ fáwọn ọ̀dọ́ láti fòpin sí ìwọ́de 23 Ọ̀wàrà 2020 Ẹgbẹ kan to n lewaju ninu eto akoso iwọde EndSARS ni Nigeria, The Feminist Coalition, ti kede pe oun ti yọwọ yọsẹ kuro ninu iwọde naa.
Bakan naa, ni kane tun n gbero lati ran iko agbaboolu re lowo lati pari idije saa EPL todun yii sipo ti o dara lori tabili, bee si ni, O n gbero lati pari idije saa yii gege bi agbaboolu ti o gba boolu sagbon julo fun igba keta lera won.
O ni awọn kan ṣa dede ji ni awọn gbọ iroyin wi pe owo epo ti sun lọ soke pe iye bayii ni epo tun un ba jade.
Oríṣun àwòrán, others Sultan tilu Sokoto, tíì tún ṣe aarẹ àpapọ̀ fàwọn musulumi ni Naijiria, Alhaji Sa'ad Abubakar Kẹta tí kesi àwọn Mùsùlùmí ni Naijiria lati máṣe kí irun àpapọ̀ fún ìbẹ̀rẹ̀ oṣù aawẹ.
Kayọde Fayemi jáwé oluúborí ní Tribunal Ile ẹjo to n gbọ ẹjọ to suyọ lasiko idibo ti fa ọwọ Kayode Fayemi soke gẹgẹ bi gomina to wọle ni tootọ ni gomina ipinlẹ Ekiti lodun to kọja.
Nígbà tí ẹ̀mí Èṣù náà ti jáde tán ọkunrin odi náà sọ̀rọ̀, ẹnu wá ya àwọn eniyan.
Awọn ọlọpaa sọ pe, awọn ti yọnda Tekno, ṣugbọn iwadii ṣi n tẹsiwaju.
Ni ọdun 2017, iroyin ṣi kuro ni ori bi iṣẹ iranṣẹ rẹ ṣe lagbara to si igbohunsilẹ ti wọn ni o fi han nibi ti o ti n sọ ọrọ ifẹ fun arabinrin kan ti orukọ rẹ n jẹ Rita Ibeni.
OLUWA sọ fún Mose ati Aaroni pé kí wọn bu ẹ̀kúnwọ́ eérú bíi mélòó kan ninu ẹbu, kí Mose dà á sí ojú ọ̀run lójú Farao, 
"Ó gbé àwo orin rẹ ̀ "" Ẹyẹ Àdàb ̀ a "" , tí ó dá kọ jáde ní orílẹ ̀ èdè bàbá rẹ ̀ nàìjíríà tí ọ ̀ pọ ̀ lọpọ ̀ àwọn ènìyàn sì ti ń gbọ ́ orin rẹ ̀ ."
Eyi lo mu ki a ba onímọ̀ nipa irinajo ifẹ laarin ọkunrin ati obinrin, pe kini awọn iwa tabi ẹsẹ to tun buru ju agbere lọ ninu igbeyawo tako igbagbọ ọpọlọpọ pe oun lo buru ju.
Túndé Atọ̀pinpin àti ẹ̀gbọ́n rẹ̀ máa ń sùn ní ilé Àkàngbé nígbà ti wọ́n bá ń lọ sí ìhà Odò Ọya.
Kí n lè mọ̀ pé o fẹ́ràn mi,nígbà tí ọ̀tá kò bá borí mi.
Má fòwúrọ̀ ṣeré, ọ̀rẹ́ mi, múra sí iṣẹ́ ọjọ́ n lọ
Itan igbe aye Majek Fashek Ni ọdun 1988, ni okiki Majek Fashek kọkọ jade to bẹrẹ si ni lo Majek Fashek gẹgẹ bii orukọ apejẹ rẹ ti awo orin rẹ ti o pe akọle rẹ ni 'Prisoner of conscience' jade to si di wọọ ki ilu mọ nigba ti ọkan lara awọn orin inu awo naa, Send down the rain di gbajugbaja to fun ni ami ẹyẹ ti ko din ni mẹfa lọdun 1989 nikan.
Ile ẹjọ giga ni ipinlẹ Eko ti fun ijọba orilẹede Naijiria laṣẹ lati gbe ẹṣẹ le ohun ẹsọ ara Minisita fun ọrọ epo bẹntirol tẹlẹri, Diezani Allison-Madueke.
salaye pe awon omo egbe igbimo asoju lo tọrọ  pe ki won sun ijiroro naa siwaju , nitori pe
Òfin tí ó yẹ kí ó mú ìyè wá, ni ó wá di ọ̀ràn ikú fún mi.
Àwọn ọmọ Nàìjíríà ń sáré wálé torí àṣẹ ìjọba tó wọ́gilé ìrìnàjò láti òké òkun Dandan kọ́ ni kí Buhari ó bá ayín sọ̀rọ̀ lórí coronavirus, ó ti ṣe gbogbo nkan tó yẹ kó ṣe - Iléèṣẹ́ ààrẹ Ilé ẹjọ́ dá pásítọ̀ ìjọ Sotitobire padà sọ́gbà ẹ̀wọ̀n, ó sún ẹjọ́ síwájú Coronavirus:Ọmọ mi to ṣẹ̀sẹ̀ dé láti UK ko fi àmi Coronavirus han, sùgbọ́n.
Fun ikọ Liverpool, agbabọọlu ọmọ ilẹ Afirika mẹrin lo wa ninu ikọ naa.
Oríṣun àwòrán, v@AlaafinofOyo Awọn Alaafin to lo ọdun to pọ diẹ nipo yatọ si Ọba Adeyemi: Akọsilẹ fi ye wa pe Alaafin to fẹ sunmọ aadọta ọdun lori oye lẹyin Ọba Adeyemi ni Alaafin Siyanbola Ladigbolu to jọba laarin ọdun 1911 si 1944, ẹni to lo ọdun mẹtalelọgbọn nipo.
O ni ọrọ ti aarẹ ba awọn ọmọ Naijiria sọ ko jọ bi eyi to ti inu ọkan rẹ wa, afi bii pe n ṣe ni wọn kan an nipa fun un.
Àwọn ni ìlú ati ìletò tí ó wà ninu ilẹ̀ tí ó kan ẹ̀yà Sebuluni gẹ́gẹ́ bí iye ìdílé wọn.
Bee si ni isuna awon to n mojuto eto idajo naa tun gbenu soke si lati bilionu mewa naira si bilionu mẹ́rìnlélógójì naira.
Saulu jáde ninu ihò náà, ó bá ọ̀nà rẹ̀ lọ.
Ẹwẹ, orilẹede Iran ti leri pe afi ki awọn gba ẹsan iku rẹ.
O ni iko naa se aseyege lati
O kì í wo ojú eniyan kí o tó sọ̀rọ̀.
Idahun: Nkan akọkọ ti o nilo lati ṣe ni pe ki o lọ si itakun agbaye ileesẹ ọlọpaa, www.
O Fagunwa kú, dúkìá rẹ̀ sì ń fọhùn síbẹ̀, ilé rẹ̀ rèé Samuel Ladoke Akintọla jẹ́ Agbẹjọ́rò àti Akọ̀ròyìn tí ọ̀rọ̀ dá lẹ́nu rẹ̀ Ayinla Ọmọwura, orin èébú àti oríyìn lo fi di ọ̀rẹ́ àwọ̀n obìnrin Taiwo Akinkunmi, ọmọ Ibadan tó ya àsìá Nàíjíríà Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí 2 sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 2:23 Fídíò, Water Generator: Ó leè ṣiṣẹ fún wákàtí mẹfà, kó tó sinmi, Duration 2,2310 Òkùdu 2020 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
'Ọdún 2019 pẹ̀lú àwọn àsọtẹ́lẹ̀ tó kó lọ́wọ́ dé' Ki gaan lawọn amọran yii?
wọn yóo fi ìbẹ̀rùbojo fò wá bí ẹyẹ láti ilẹ̀ Ijipti, ati bí ẹyẹ àdàbà láti ilẹ̀ Asiria; n óo sì dá wọn pada sí ilé wọn.
si ipinle Eko fun irinajo ọlọjọ kan .
"Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Èré Ọṣun: Àtáója ní wọn kò jí ère Ọṣun, ó sì wà níbi tó wà ""Pẹlu bi APC ati Buhari ti n se yii, o ti foju han pe wọn ko ni ẹri to daju lati gbe kalẹ niwaju igbimọ olugbẹjọ ibo, lati tako PDP to ni wọn se eru ibo aarẹ ni."
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Àmì ohùn ṣe pàtàkì nínú èdè Yorùbá púpọ̀ Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Joṣua ni yóo sì jẹ́ olórí, tí yóo máa ṣiwaju yín lọ, gẹ́gẹ́ bí OLUWA ti wí.
Dalung, Audu Ogbe, Shittu Adebayo àti Isaac Adewole kò wọlé Ìdí ti a fi kọ̀ láti fi El-ZakZakky sílẹ̀ -Ileeṣẹ Aarẹ Buhari Èèmọ̀!
Kí a mú un láti Ìdádúró Tanzania tí ó dá lóríi ìtànká “ìròyìn irọ́, ìtànjẹ, tàbí ìròyìn tí ò pé ojú òṣùwọ̀n” lórí ayélujára títí kan owó-orí Uganda fún ìlò ẹ̀rọ-alátagbà fún ìgbógunti “àhesọ”, ariwo orí ẹ̀rọ-ayárabíaṣá ń já àwọn ìjọba aninilára láyà.
Nígbà tí Eliṣa dé ilé náà, ó bá òkú ọmọ náà lórí ibùsùn.
Ẹwẹ, ireti wa fun awọn ti ko tii ṣe igbeyawo atawọn ti ko da loju pe ojulowo ni igbeyawo awọn.
OLUWA bá tún sọ fún Mose pé, “Dìde ní òwúrọ̀ kutukutu, kí o lọ dúró de ọba Farao bí ó bá ti ń jáde lọ sétí odò, wí fún un pé, kí ó gbọ́ ohun tí èmi OLUWA wí, pé kí ó jẹ́ kí àwọn eniyan mi lọ sìn mí.
com Àkọlé àwòrán, Aarẹ Buhari ba Damilọla Osinbajo ati ọkọ rẹ sajọyọ Aarẹ orilẹede yii Muhammadu Buhari ni o ti ba igbakeji rẹ Yẹmi Osinbajo sayẹyẹ igbeyawo ọmọ rẹ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ekiti Election: Ẹgbẹ́ awakọ̀ Ekiti pa ìjọba dà lẹ́yìn tí wọ́n kéde Fayẹmi Ni ọpọ igba ni iru ija bẹẹ maa n da lori ipo aṣaaju ninu ẹgbẹ naa.
Ọjọ Ẹti ni eyi waye lẹyin ariya alẹ ti wọn ṣe.
kí wọ́n yan ìlú mẹfa fún ìlú ààbò tí ẹni tí ó bá ṣèèṣì paniyan lè sá lọ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsèjẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọ 2) Igbesẹ Kejì: Fi iwe ti o ti fi forukọ silẹ si ṣọwọ si wọn.
Ajimobi sọ eyi lasiko to n ba awọn ọdọ sọrọ nibi ipade Young African Leaders Initiative fun awọn olokowo kekeeke lorilẹede Naijiria.
Nítorí ẹ̀ṣẹ̀ yín ni a ṣe tà yín,nítorí àìdára yín ni mo ṣe kọ̀ yín sílẹ̀.
Ninu atẹjade kan ti agbẹnusọ fun aarẹ, Fẹmi Adeṣina fi sita, Aarẹ Buhari gba a ladura pe, ki Ọlọrun tu awọn ẹbi rẹ ninu.
A ó gbé'gbésẹ̀ lẹ́yìn ìwádìí fídíò tí Dino ti ń náwó lójú agbo- Ọlọ́pàá Àwọn obìnrin ilé ìgbìmọ̀ aṣòfin Amẹrika fọnmú sí ọ̀rọ̀ Trump Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Láti ibi tí ó dàbí ìbàdí rẹ̀ dé ilẹ̀ jẹ́ iná, ibi ìbàdí rẹ̀ sókè ń kọ mànàmànà bí idẹ dídán.
OLUWA Ọlọrun ní: “Ninu ẹgbẹrun ọmọ ogun tí ìlú Israẹli kan bá rán jáde, ọgọrun-un péré ni yóo kù.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Nigeria 2019 Elections: Àwòrán bí Ilọrin ṣe gbàlejò Yẹmi Ọṣinbajo 21 Èrèlè 2019 Wọnyi ni akojọpọ aworan abẹwo Igbakeji Aarẹ, Yemi Osinbajo si Ilu Ilorin.
Ikọ̀ Àmọ̀tẹ́kùn ṣèsì yìnbọn pa akẹ́kọ̀ọ́ nílùú Ibadan Oríṣun àwòrán, Oyo Ikọ Amọtẹkun ni ipinlẹ Ọyọ ti ṣeṣi pa arabinrin, Tosin Thomas ni ilu Ibadan, nipinlẹ Ọyọ.
Bu ọlá fún àwọn opó tí wọ́n jẹ́ alailẹnikan.
Laarin oṣu kan, ko din leeyan marun un, ninu eyi ti alaboyun kan ati awọn akẹkọọ meji wa, ti wọn ti ṣa pa lagbegbe ọhun.
“Ẹ kò gbọdọ̀ jẹ ohunkohun tí ó jẹ́ ohun ìríra.
Lọdun 2012 si 2016 ni John Mahama polongo nipa ipese ohun amayederun O kọ awọn ile iwosan, opopona, ati awọn nkan mii ti awọn eeyan n mọ riri rẹ lẹyin to kuro nipo.
Awọn ikọ ologun ti lo wọn fun ogun jija ati ni ona miran, eyi to ti mu wọn ri ọpọ iṣẹlẹ iku, ipaniyan ati ijamba.
Abiola Ajimobi: APC àti ALGON ti mú àbá tuntun jáde lórí ọ̀rọ̀ gómìnà Ọyọ àná
Kọla Ologbondiyan sọ pé èsì ìbò tí INEC kéde ní ìpínlẹ̀ Ọṣun kò bá òfin mu, tó sì yẹ kí ọ̀gá àgbà fún INEC, Mahmood Yakubu kọ̀wé fi ipò rẹ̀ sílẹ̀ Oríṣun àwòrán, PDP Àkọlé àwòrán, Saraki léwájú ẹgbẹ́ PDP láti fẹ̀hónú hàn nítorí ìbò Ọṣun Oyekanmi sọ pe 'eto idibo to waye l'Ọṣun gan an lo ti i daraju ninu gbogbo idibo gomina ti ajọ naa ti ṣe, nitori bi awọn eroja idibo ṣe tete de si awọn ibudo idibo, ati pe ni nkan bi i aago mẹjọ aarọ ni ida mejidinlọgọrun awọn ibudo naa ti wa ni ṣiṣi.
Ẹ óo wá mi, ẹ kò ní rí mi, ibi tí mo bá wà, ẹ kò ní lè dé ibẹ̀.
Ọpọlọpọ awọn ọjọgbọn lere tiata lo si ti n pariwo pe eku ko ke bi eku mọ lori ipa ti tiata n ko lori idagbasoke awujọ.
Amọṣa bi awọn eeyan loniranran ṣe n kii ku oriire, ẹnu o gba iroyin ohun ti awọn ọmọ Naijiria kan fi oju Minisita keji fun ọrọ oṣiṣẹ ati idaleeṣẹ silẹ, Festus Keyamọ ri loju opo twitter rẹ kọja sisọ o.
Wo ọ̀nà tí o fi lè dáàbò bo ọmọ rẹ lọ́wọ́ COVID-19 níléèwé Iléẹjọ́ ní kí Yakubu lọ gé oko àgọ́ ọlọ́pàá fọ́jọ́ méjì lẹ́yìn tó jí fóònù N8,700 Ẹ yé parọ́ kiri!
Toò, kí ng wá gbé orin Aṣa kan síi ojàre.
”Ronaldo fi iko naa sile, leyin ti o di agbaboolu ti o gba boolu sagbon julo ninu itan iko agbaboolu Real Madrid pelu ami-ayo irinwó le mọ́kànléláàdọ́ta ninu ifesewonse irinwó le méjídínlógójì ti o gba fun iko naa.
Oun naa ni inira pẹlu mimi Wọn lo ẹrọ to n se iranwọ mimi fun sugbọ pabo lo ja si.
Jesu dá wọn lóhùn pé, “Nítorí líle ọkàn yín ni Mose fi gbà fun yín láti kọ aya yín sílẹ̀.
Ìbejì ọmọ ọdún méjì Mínísítà fún ọ̀rọ̀ omi bá odò lọ 'Wọ́n ní a kò lówó tó láti díje dupò ní Nàìjíríà' D'Banj fọhùn lẹ́yìn ọjọ́ mẹ́wàá tó pàdánù ọmọ Oríṣun àwòrán, AFP Àkọlé àwòrán, Diẹ lara awọn eniyan ti wọn n ṣajọyọ ọdun Fatchue ni Ivory Coast.
OLUWA Ọlọrun yín tìkalára rẹ̀ ni yóo ṣiwaju yín lọ, yóo ba yín pa gbogbo àwọn orílẹ̀-èdè náà run, tí ẹ ó fi lè gba ilẹ̀ wọn.
, Duration 8,0016 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 8:23 Fídíò, Deborah Adebola Fasoyin: Èmi kọ́ ló gbé orin ọdún ń lọ sópin kalẹ̀, CAC ló ni í ni mó n ṣe àkójọ orin- Fasoyin, Duration 8,2331 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 2:23 Fídíò, Water Generator: Ó leè ṣiṣẹ fún wákàtí mẹfà, kó tó sinmi, Duration 2,2310 Òkùdu 2020 6:56 Fídíò, Wòlíì Kasali sọ̀rọ̀ nípa awuyewuye pé ó lé ìyàwó rẹ̀ jáde nílé, Duration 6,5628 Ọ̀pẹ̀̀ 2018 BBC News, Yorùbá Ìdí tí ẹ fi le è nígbàagbọ́ nínú ìròyìn BBC Ìlànà Lílò Nípa BBC Òfin Àṣírí Cookies Kàn sí.
Ẹran ti Ọ̀sanyìnnínbí jí gbé ni ó jẹ́ kí wọ́n ní ànfààní láti yẹ ilé rẹ̀ wo.
Bí a ba ti ṣe atúnṣe si ǹkan ti a ti kọ síta tẹ́lẹ̀, a máá ń pe àkíyesí àwọn alábàráà wà sí àkíyàsí pé à ti ṣe àtúnṣe, pèlú àsìkò ti ìrú àtúnṣe bẹ́ẹ̀ wáye.
Buhari: Ọwọ́ fẹ́rẹ̀ tẹ àwọn agbébọn lókè Ọya
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Wọn ko da Baba Kerei alaṣọ pupa ati funfun silẹ lati polowo Coke.
O ti pẹ diẹ ti wahala ti wa ninu ajọ NFF, lori ẹni to jẹ olori ajọ naa laarin Chris Giwa ati Amaju Pinnick.
Ọmọ rẹ ni n óo já ìjọba gbà mọ́ lọ́wọ́.
Ẹ múra o, epo rọ̀bì di òkùtà lọ́jà torí Coronavirus, ìlú yóò le koko - NNPC figbe ta Saaju la ti sọ fun yin pe oludari agba fun ajọ elepo rọbi nilẹ wa, NNPC Mele Kiyari ti fi iboosi bọnu pe kawọn ọmọ Naijiria tete gbaradi fun ilu ti yoo le laipẹ, nitori bi owo epo rọbi se n ja wa silẹ lọja agbaye.
olopaa ni ahesọ ọrọ  lasan ni eyi.
"Yatọ si Dino Melaye, awọn eekan miran to wa nibi ifilọlẹ iwe yi ti wọn pe akọle rẹ ni ""Dear President Goodluck Jonathan (An Open Letter),"" ti akọroyin kan Bonaventure Philips Melah kọ, tunbọ gbosuba kare fun Jonathan."
Orukọ rẹ Gwandiku Tita jẹ orukọ tawọn eeyan to wa lati ilu Bali ni orileede Cameroon n jẹ.
Ọjọ Abamẹta to lọ ni awọn DSS mu Ṣowore ṣaaju iwode #RevolutionNow protest.
’ rèé Afọnja, ẹni tó finú wénú ní Ilọrin, àmọ́ tó jẹ iwọ Niwọn igba to si jẹ pe ọba kii kọ obinrin, agbalagba si maa n gba mọra ni.
32 Bí ó tilẹ̀ ríbẹ́ẹ̀, ẹnití ó bá ronúpìwàdà tí ó sì nṣe àwọn òfin Olúwa yíò rí ìdáríjì.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ó dára kí obìnrin níṣẹ́ lọ́wọ́ - Toyin Lawani Ronke Oshodi-Oke ṣalaye ọrọ naa ninu ifọrọwerọ kan to ṣe pẹlu iwe iroyin The Punch.
O mọ ohun tí Ọlọrun fẹ́.
Ẹwẹ, awọn afurasi mẹjọ lawọn ọlọpaa ti mu bayii, nigba ti iwadii si n lọ lọwọ Ọlọ́pàá kàn pàdánù ẹmi rẹ́ lọ́wọ́ awọ̀n adigunjalè ní Ekiti Irú ètùtù wo ni ìlú Ijare fẹ́ ṣe kí wọ́n tó lè yanjú màálù 36 tí àrá sán pa?
Lasiko to wa ni ijọba, oniruuru iwa ijẹgaba le awọn oniroyin ti ko ba fọnrere ijọba atawọn ẹgbẹ oṣelu alatako lo waye.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Nigeria Senate: Àwọn àbádòfin pàtàkì márùn ún áti ipa wọn nílùú láàrin ọdún kan tí wó̩n fi ṣiṣẹ́ 11 Òkùdu 2020 Oríṣun àwòrán, Nigeria senate Ka to ṣiju pẹẹ, ọdun kan ti yaa pe ti wọn ṣe ifilọọlẹ ile igbimọ aṣofin Naijiria ikẹsan lọjọ kọkanla oṣu kẹfa ọdun 2019 ti yoo si kasẹ nlẹ lọjọ kọkanla oṣu kẹfa ọdun 2023.
Wọ́n ṣígbọnlẹ̀ bí àwọn ọmọ Anaki.
Bakan naa, gege bi ajo NBF (Nigeria Basketball Federation), won ni, iko  D’Tigress yoo pago silu Atlanta, Georgia, lorile-ede USA fun igbaradi idije naa ni kikun.
Amọ, Samuel Major tun fọba lee fun Hungary lẹyin iṣẹju mẹjọ ki Usman Ibrahim to dayo naa pada eleyi to sọ di ọmi alayo mejimeji.
O gba lati tẹ le wọn, ṣugbọn iyalẹnu lo jẹ pe oko ọmọ ọdọ ni wọn ta a si l'ọhun.
Gomina Rotimi Akeredolu fi ogun rẹ gbari pe eto ilera nipinlẹ Ondo ti lọ soke lati igba toun ti de ipo gomina.
Oríṣun àwòrán, Oyo Police Lọwọlọwọ, oriṣiriṣi ni awọn ileeṣẹ iroyin ti n gbe nipa rẹ.
 nígbà tí wọ ́ n dé ibẹ ̀ , òògùn ni Ọ ̀ sanyìnnínbí wá ṣe .
Onimọ ẹsin Islam kan,Sheikh Garangamawa to ba BBC sọrọ ṣalaye pe kii ṣe awọn ọmọ igbimọ to n wa oṣu nikan lo le wa oṣu bi kii ṣe pe iwọ gbogbo musulumi ni.
Kò gbọdọ̀ kó aya jọ kí ọkàn rẹ̀ má baà yipada; bẹ́ẹ̀ ni kò gbọdọ̀ kó wúrà ati fadaka jọ fún ara rẹ̀.
O fi ẹsun kan Ṣoworẹ pe o kuna lati ṣeto ipade oloṣu mẹta-mẹta igbimọ adari ẹgbẹ oṣelu naa pẹlu ẹsun ṣiṣe owo ẹgbẹ baṣubaṣu.
Ẹ óo tún máa gbọ́ ti OLUWA, ẹ óo sì máa pa àwọn òfin rẹ̀ tí mò ń fun yín lónìí mọ́.
O dá òṣùpá láti máa sàmì àkókò,oòrùn sì mọ àkókò wíwọ̀ rẹ̀.
Aishat Lagos flood: Lẹ́yìn wákàtí 24 ní wọ́n rí òkú ọmọbìnrin náà tí àgbàrá òjò gbé lọ ní Suurulere
Bakan naa, Moses Simon wa labe isakoso katakara Tony Harris.
Alufaa yóo mú díẹ̀ ninu ẹ̀jẹ̀ ẹbọ ìmúkúrò ẹ̀ṣẹ̀, yóo fi sí ara òpó ìlẹ̀kùn tẹmpili, ati orígun mẹrẹẹrin pẹpẹ ati òpó ìlẹ̀kùn àbáwọlé gbọ̀ngàn ààrin ilé.
 Ẹ̀bùn ránpé wà fún ẹni tí ó bá gba ÌBÉÈRÈ yìí
Pásítọ̀ gún ìyàwó rẹ̀ lọ́bẹ nínú ṣọ́ọ̀ṣì, ló bá tì í bọ ara rẹ̀ náà níkùn 'Ohun gbogbo ka mi lara gan' Gbogbo saa ẹkọ rẹ nileewe lo fun un ni wahala tori o ni lati ra aṣọ ileewe eyi ti ko si lowo rẹ.
Nítorí o ti fi ìfaradà pa ọ̀rọ̀ mi mọ́, Èmi náà yóo pa ọ́ mọ́ ní àkókò ìdánwò tí ń bọ̀ wá bá ayé, nígbà tí a óo dán gbogbo àwọn tí ó ń gbé inú ayé wò.
"ShopRite Ibadan gbé ìlẹ̀kùn tìpa torí ìkọlù àwọn tó ń fẹ̀hónú hàn Àwọn èèyàn to n fẹ̀hónú hàn dáná ṣun iléeṣẹ́ MTN n‘Ibadan ""Ọjà àìmọye mílíọ̀nù naira ni wọ́n kó nílé ìtajà mi torí ìgbẹ̀san ìkọlù South Africa"" ""Naijiria gbọdọ̀ kẹ̀yìn sí ìrẹ́pọ̀ pẹ̀lú South Africa"" Xenophobic Attack: Àwọn ọmọ Nàìjírìá bínú kọlu Shoprite l'Eko Koda, awọn eeyan to n fẹhonu han naa dana si oju popo, ti eefin si gba gbogbo agbegbe naa kan."
Ti a o ba gbagbe pe laarin ose to koja ni gomina Orhtom kuro ninu egbe APC lati dara pọ egbe alatako, PDP.
Ijoba apapo ti so pe, ohun yoo mu igberu ba eto ipolowo-oja ori Television latari ati pa alekun owo ti o to igba si irinwo milionu owo dollars si ile-ise naa.
Wọn igbiyanju lati kọkọ́ ba rẹ ko yọri si rere.
Olùkọ́ fásitì méjì ń bèèrè ìbálòpọ̀ lọ́wọ́ akẹ́kọ̀ọ́ fún máákì Fídíò rèé nípa bí Aláké tuntun ṣe ń gba ìwúre lábẹ́ Olúmọ kó tó gba adé Ọdún ìbejì sọkutu-wọ̀wọ̀ ní Igboọrà, àṣírí bí wọn ṣe ń bí ìbejì tú Sanusi Adebisi Idikan rèé, olówó tó ń san owó orí fún gbogbo ọkunrin ilẹ̀ Ibadan Àwọn Ìyá àwọn ọmọ Yahoo ti ń kórajọ láti dá ẹgbẹ́ sílẹ̀ - Magu O si tun rọ awujọ wa lati dẹkun nina obinrin tabi dẹyẹ si wọn, bẹẹ ni ko yẹ ki wọn maa ri obinrin bii ẹni ti ko ni ọpọlọ tabi ti ko gbọn lati se ipinnu.
Àwọn ìjòyè Sukotu dá a lóhùn, wọ́n ní, “Ṣé ọwọ́ rẹ ti tẹ Seba ati Salimuna ni, tí a óo fi fún ìwọ ati àwọn ọmọ ogun rẹ ní oúnjẹ?
Gbogbo ọfiisi gomina ipinlẹ Ọyọ lo dakẹ rọrọ ti oju gbogbo si faro ni idaro iku rẹ; eleyi ti gomina ipinlẹ Ọyọ ni o jẹ ibanujẹ nla fun oun nitori pe ọrẹ ni oloogbe naa jẹ si oun.
Àwọn ọmọ rẹ ti kọ̀ mí sílẹ̀,wọ́n sì ti ń fi àwọn ohun tí kì í ṣe ọlọrun búra.
To ba di ọrọ asajẹ ninu oyun, o ṣeeṣe ko ni aṣa to rọ mọọ: Oyun kii se nkan to rọrun rara, o si maa n gba asiko eniyan, o tun jẹ ohun to nira lati la kọja ti ko ba si oluranlọwọ nitosi eeyan.
Ní òru ọjọ́ kan, agbọ́tí ọba ati olórí alásè náà lá àlá kan, àlá tí olukuluku lá sì ní ìtumọ̀ tirẹ̀.
Ọpẹ́ ni fún Ọlọrun tí ó fi irú ìtara kan náà tí mo ní sí ọkàn Titu.
O tẹti si mi, ṣugbọn mo sọ fun pe 'oun lo ni ara rẹ o, ko ṣe e to ba ṣe wu.
Ọlọ́pàá rí òkú ọ̀gá àgbà iléèṣẹ́ ńlá kan tí wọn ń wá, lójú omi l‘Eko A gbé òfin 1960 jáde, màálù tó bá jẹ oko àgbẹ̀, tí olówo rẹ̀ kò sanwó, títà ni - Buhari Ìjọba fẹ́ kọ́lé 300,000, pẹ̀lú ìrànwọ́ fún àgbẹ̀ 4m láti mú àdínkù bá ìṣẹ́ - Osinbajo Wò ó bí Alaafin àti aya àkọ́fẹ́ rẹ̀, Olorì Abibat ṣe pàdé ní èwe Coronavirus ti fa ọ̀wọ́ngógó oúnjẹ ní ìpínlẹ̀ Eko, Kano, Rivers àti Abuja- NBS Amọ ogiri oju ara obinrin, to kun fun isan, lee ran lati tobi si tabi kere si lasiko ibalopọ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Trump picture: ọjọ́ tí Trump kí mi kú iṣẹ́ lórí 'twitter' ní inú mi dùn jù- Oyedele Iroyin sọ pe, awọn arundinlọgọtalelọọdunrun yii ni ile iwe naa pe pada sẹnu iṣẹ bayii lara awọn eeyan naa.
O si kawe jade ni Fasiti ijọba apapọ to wa ni ilu Eko, UNILAG, ko to tẹsiwaju ni Leeds Metropolitan nilẹ Gẹẹsi.
” Bí àwọn onísọkúsọ kan ti ń sọ pé à ń sọ.
Àwọn ẹ̀mí náà bẹ̀ ẹ́ pé kí ó jẹ́ kí àwọn kó sí inú agbo ẹlẹ́dẹ̀ náà.
Bakan naa ni awọn eeyan naa sọ pe ibi ti wọn ko wọn si ko dara rara, nitori ko si oúnjẹ ati omi.
Ile ise olopaa lorile-ede naa so pe, won ko ri awon agbesunmomi naa, bee si ni idi ti won fi sekupa arabinrin ohun koi ti ye won bayii.
November 14, 2016 Wọ́n pa ọmọ ẹgbẹ́ Shiite mẹ́jọ̀ àti ọlọ́pàá kan ní ìwọ̀de ẹ̀sìn kan ní Kano.
Àtẹ̀jáde kan tí agbenusọ ìyàwó ààre náà, Suleiman Haruna, fi síta sọ pé arábìrin Aisha Muhammadu Buhari ń bá àwọn ìṣẹ̀lẹ̀ tó rọ̀ mọ́ ìwádìí tí ilé iṣẹ́ ọ̀tẹlẹ̀múyẹ́ (DSS) ń ṣe nípa ìwà jìbìtì kan.
Wọ́n ń kó ojúlówó ẹ̀wù aṣọ aláwọ̀ aró wá tà fún ọ, ati aṣọ tí wọ́n ṣe iṣẹ́ ọnà sí lára, ati ẹni tí ó ní oríṣìíríṣìí àwọ̀, tí wọ́n fi ìko hun.
kí wọ́n sì lọ mú baba rẹ̀ ati gbogbo àwọn ará ilé rẹ̀ wá sọ́dọ̀ òun.
Lagos-642 FCT-407 Plateau-160 Kaduna-83 Rivers-62 Adamawa-47 Nasarawa-38 Abia-29 Edo-28 Anambra-27 Niger-24 Ogun-24 Imo-15 Oyo-14 Kano-12 Osun-12 Borno-9 Delta-7 Enugu-7 Bauchi-5 Ekiti-5 Sokoto-5 Jigawa-2 Ènìyàn 1354 míràn ló tún ṣẹ̀ṣẹ̀ lùgbàdì ààrùn Covid-19 ní Nàìjíria Ajọ to n gbogun ti ajakalẹ aarun lorilẹ-ede Naijiria, NCDC ti kede pe Ẹgbẹrun kan o le ọọdunrun ati mẹrinlalaadọta eeyan (1354) miran ti kun iye awọn to ti ni aarun COVID-19 ni Naijiria.
Nígbà tí àwọn Farisi péjọ pọ̀, Jesu bi wọ́n pé, 
" Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ọwọ́ DSS ba ayédèrú ìyàwó Gómínà A ò fẹ àwáwí, owó wa ni ẹ san - àwọn òṣìṣẹ́ ilé aṣòfin Hubert Ogunde rèé, baba àwọn òsèré tíátà Samuel Ladoke Akintọla jẹ́ Agbẹjọ́rò àti Akọ̀ròyìn tí ọ̀rọ̀ dá lẹ́nu rẹ̀ Ìtàn tó wà nídi òwe ‘Sebótimọ Ẹlẹ́wà Sàpọ́n’ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ìbejì Oníbẹ̀mbẹ́ Òru: Owó, ọmọ àbí aya kò leè yà wá O fikun pe orilede Naijiria ati il Afrika lapapọ, ni Ọlọrun setan lati gba lọwọ awọn aninilara ati ọrọ aje to mẹhẹ.
Awọn ọlọpaa lo fi aridaju han pe Chanchal Lahiri ko ye e.
Ẹ wọ ẹnubodè rẹ̀ tẹ̀yin tọpẹ́,kí ẹ sì wọ inú àgbàlá rẹ̀ tẹ̀yin tìyìn.
Nígbà tí a dé iwájú Òjòlá-ìbínú èrò ọkàn mi padà.
Filipi lọ sọ fún Anderu, Anderu ati Filipi bá jọ lọ sọ fún Jesu.
Aarẹ sọ pe orilẹede Naijiria lagbara lati yọ ọgọrun miliọnu ọmọ Nigeria ninu iṣẹ laarin ọdun mẹwaa.
Koda Immaculate ti fi ikede idana rẹ pẹlu ọkọ afẹsọna rẹ to pe ni OG (Etomi) sita ninu oṣu kẹta ọdun 2020.
Sotitobire: Adájọ́ dá Pásítọ̀ Alfa Babatunde padà s'ẹ́wọ̀n fún ọjọ́ mọ́kàndílógún A ó sọ jálà bẹntiróò di N97 pẹ̀lúu lílo afẹ́fẹ́ gáàsì fún ọkọ̀ - Ìjọba Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Wo àwọn ìbejì tó lẹ́ pọ̀ lẹ́yìn àṣeyọrí ìṣẹ́ abẹ dókìtà 70 Oríṣun àwòrán, Others Àkọlé àwòrán, Ọjọ Kẹrinla, osu Kẹta, ọdọọdun si ni ayajọ Lasabi naa maa n waye nilu Abẹokuta.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Lilo ede: Kini ‘technology’ ni ede Yoruba?
Àwọn nǹkan tí wọ́n kó kalẹ̀ fún ẹbọ alaafia ni: akọ mààlúù mẹrinlelogun pẹlu ọgọta àgbò; ọgọta òbúkọ, ọgọta ọ̀dọ́ àgbò ọlọ́dún kọ̀ọ̀kan.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fọ́nrán ohùn, Gómìnà Zamfara kò lágbára ní tòtọ́ọ́ lórí ọ̀rọ̀ ààbò- amòfin Atẹjade ajọ naa ni awọn agbofinro naa pa ju ẹgbẹrun mẹrin eniyan lọ (4,068) laarin ọdun mẹrin yii, Àwọn ìròyìn mìíràn tí ẹ lè nífẹ̀ẹ́ sí: Gani Adams kilọ f'awọn darandaran Ganduje pe awọn darandaran si Kano Ọwọ ologun tẹ darandaran mẹwa ni Benue 'Amulo ologun ko lee yanju ikọlu darandaran' 'Ologun ko lee koju Boko Haram' ‘Ìkọlù darandaran pa èèyàn 2000’ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Odumakin sọrọ lori Fulani darandaran Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Àwọn ẹyẹ tí wọ́n wá sí ojú ìjà kò ju èkùrọ́ lọ, ìgbà ti wọ́n bá sì fò dé, wọ́n á bà lé ni lápá, lẹ́sẹ̀, ni góngó imú àti ni ibikibi lójú bẹ́ẹ̀ ni kò sí bi a ti ń pa wọ́n to tí a ri wọn gbé ṣe, bí ọ̀kan ti ń kú ni ekejì ń fò dípò rẹ̀, ọ̀ràn náà sì buru tó bẹ́ẹ̀ tí púpọ̀ nínú àwọn ọdẹ kò tilẹ̀ rí àyè gbé ibọn, ọwọ́ ló kù tí wọ́n fi ń jagun.
8 8472 Orilẹede Sri Lanka 146 0.
 ̣ yàtọ ̀ sí àwọn fíìmù tí ó níí ṣe pẹ ̀ lú ẹ ̀ sìn lóríṣìíríṣìrí , a tún ní àwọn tí ó níí ṣe pẹ ̀ lú ìdàrúdàpọ ̀ tí ó máa ń ṣẹlẹ ̀ nígbà tí àwọn tí ó níí ṣe pẹ ̀ lú ìdàrúdàpọ ̀ tí ó máa ń ṣẹlẹ ̀ nígbà tí àwọn ẹ ̀ sìn méjì ọ ̀ tọ ̀ ọ ̀ tọ ̀ bá kọlu ara wọn , yálà nígbà tí àwọn ọmọ wọn bá fé láti fẹ ́ ara wọn tàbí nígbà tí ọ ̀ rọ ̀ ilẹ ̀ bá dạ ̀ wọ ́ n pọ ̀ .
Mr Latin: Ó ṣeéṣe kí TAMPAN àti ANTP di ọkàn lọ́jọ́ iwájú, tí.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù COZA: Wo ohun tó ṣẹlẹ̀ ni ṣọ́ọ́ṣì COZA láàrọ́ yìí 30 Òkùdu 2019 Oríṣun àwòrán, Instagram/modele fatoyinbo Saaju ni Busola Dakolo aya gbajugbaja olorin Timi Dakolo fẹsun kan Pasitọ Biodun Fatoyinbo ti ijọ COZA pe o fipa ba oun lo pọ nigba kan.
Wolii yìí bá mú aṣọ kan, ó fi wé ojú rẹ̀.
ile igbimo asofin agba, Bukola Saraki, ni ile igbimo  agba ti seleri lati satileyin fun ile-ise
Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Fídíò, Soyinka Cancer: Àṣe ara mi ni iso ti n run gbogbo bí mo ṣe n ṣèrànwọ́ lórí jẹjẹrẹ27 Bélú 2019 Ibadan: Oluwapọ̀nmile sọ ìrírí rẹ̀ lọ́wọ́ àwọn sójà tó fìyàjẹ́ ní Ibadan3 Bélú 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 3 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 5 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Ó wù ú láti fi ibinu ati agbára rẹ̀ hàn.
Bakan naa, ile tun buwọlu iyansipo Ọmọwe Nureni Adeniran gẹgẹ bi alaga igbimọ to ri si eto ẹkọ kariaye nipinlẹ Oyo, State Universal Basic Education Board(SUBEB), ti Ọgbẹni Akeem Oladeji ati Ọgbẹni Dayo Ogungbenro si jẹ ọmọ igbimọ naa.
Lorile-ede Ghana lowurọ ọjọ Isẹgun, ọrọ kan ti yoo ma ja ranyin ranyin ni eleyi to nii ṣe pẹlu ifidirẹmi ikọ agbabọọlu Black Stars lọwọ Tunisia ninu idije AFCON.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù SERAP: SERAP gbé ìjọba Nàìjíríà lọ iléẹjọ́ ọ̀daràn lágbàáyé, ICC 21 Agẹmo 2019 Oríṣun àwòrán, @Danjauro Ajọ SERAP ti gbe awọn alaṣẹ ijọba orilẹede Naijria lati ọdun 1999 di isinsinyi lọ sile ẹjọ agbaye, ICC to n gbẹjọ iwa ọdaran, lori ẹsun pe wọn ko jẹ ki awọn ọmọde to le ni miliọnu mẹtala lanfani si eto ẹkọ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Nnamdi Kanu: Mo lè dá wàhálà sílẹ̀ ní Nàíjíríà, tí ìjọba bá bími nínú 1 Ìgbé 2019 Oríṣun àwòrán, Elliot Ugochukwu-Ukoh Àkọlé àwòrán, Opo igba ni Kanu ti ṣeleri pé oun to dari Biafra ti iran Igbo ba ya kuro lara Naijiria Awọn ọmọ Naijiria ti fesi si ọrọ ti adari awọn to n ja fun idasilẹ orilẹ-ede Biafra, Nnamdi Kanu sọ.
 A lero pe pelu gbogbo ibasepo yii, yoo ran wa lowo pupo lati jere apapo okan awon omo ile yii, ti yoo maa wo awon ifesewonse wa gbogbo.
Ọlá hàn lára mi,agbára mi sì ń di titun nígbà gbogbo.
Ajo eleto idibo lorile-ede Sierra Leone gbe iko marundinladorin 75% ninu ida ogorun abajade esi ibo Aare  sita lojo-Aiku.
Ọ̀rọ̀ Ọlọrun bẹ̀rẹ̀ sí fìdí múlẹ̀ sí i, ó sì túbọ̀ ń tàn káàkiri.
Oríṣun àwòrán, Ekiti state government Bakan naa lo paṣẹ pe awọn onimọto nibẹ ko gbọdọ gbe ju eeyan kan ni iwaju ati ero mẹta-mẹta ni ila aga kọọkan ninu ọkọ wọn.
àwọn mejeeji yóo wá di ọ̀kan.
Ẹ ṣe àyẹ̀wò àwòrán lilo ewé lójú iwé yi.
OLUWA ṣeun fún gbogbo eniyan,àánú rẹ̀ sì ń bẹ lórí gbogbo ohun tí ó dá.
Ènìyàn 156 ló tún ṣẹ̀ṣẹ̀ lùgbàdì ààrùn Coronavirus ní ìpínlẹ̀ Eko Bakan naa lo fikun pe ọna to n gba ṣe akoso ẹnawo rẹ ni yoo sọ bo ṣe lowo si nitori ọpọ isoro ti ẹda n koju la le e tọ ipasẹ rẹ de idi ibasepọ rẹ pẹlu owo."
Nítorí náà fi ìwà ìríra tí wọ́n hù hàn wọ́n.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ìyàwó mi fẹ́ràn ìrìnàjò òfurufú ni mo ṣe kọ́ ilé Bàálù yìí fún un Àwọn ẹni òkùnkùn ló já ìṣẹ́gun mi gbà, mò ń lọ sílé ẹjọ́ tó ga jùlọ - Bayo Adelabu Alàwàdà láwọn tó pàṣẹ lọ gbèlé rẹ̀ fún Adams Oshiomole - APC Ẹ gbà wá o!
Sadiya Umar Farouq ti wọn pori ẹ ninu ọrọ yii paapaa ni oun ko si ni Naijiria lasiko yii nitori o ti ba ọrọ bi yoo ṣe dara lọ si Geneva lati bii ọjọ melo sẹyin.
ECOWAS , ni yoo je alejo Pataki lojo ayẹyẹ ọhun , ni eyi ti awon adari orile ede
Bẹ́ẹ̀ ni ó yẹ kí ẹni tí ó bá jẹ́ olórí ìlú máa fa gbogbo ayé mọ́ra.
Iro ibọn n dun lakọ-lakọ, ti ọpọ ẹmi si n bọ titi ti ilẹ fi su lọjọ naa, koda, iya agba to ba wa sọrọ ni diẹ lo ku ki ibọn ba oun lasiko ti oun n tilẹkun isọ awọn.
Naijiria lati yọ awon isoro ati idiwọ ti ko je ki awon agbe ri owo ya gba lati
Ṣugbọn Philomina atawọn meji yoku lawọn o jẹbi ẹsun ti kan wọn.
awon omo orilẹ-ede Naijiria jake-jado agbaye lo n ṣe daro oloogbe Ọjọgbọn Pius
 Ọ ̀ wọ ́ àkọ ́ kọ ́ ni wọ ́ n wà lábẹ ́ olú-Ìwà tí àwọn ẹ ̀ gbọ ́ n rẹ ̀ ajẹ ́ bu àti olóde tẹ ̀ lé àwọn wọ ̀ nyìí ni wọ ́ n tẹ ọ ̀ pọ ̀ lọpọ ̀ ìletò dó ní ìlú Ìjẹ ̀ bú-Òde .
Itan igbesi aye rẹ fi ye wa wi pe, atapata dide ni MKO Abiọla sugbọn nipa ifọkansin ati itẹpamọsẹ, o di eeyan pataki.
Ero amohun-maworan to gbinle bayii gbedi dina bi ijoba ko se kowo sori  amugbooro ilana aworan ti o peye lorile-ede Nigeria.
Buhari, APC Oyo North; Olubunmi Adetunmbi, APC Ekiti North; Chimaroke Nnamani,
Àwọn ará Edomu tún dáhùn pé, “Rárá o, ẹ kò lè kọjá.
Ilé iṣẹ́ ìròyìn New Vision lo já ojú ọ̀rọ̀ náà lẹ̀yìn ti baba Aguti, olùsọ-aguntan Peter Ogwang lo kó àwọn ẹbi ẹ lọ láti le àwọn ọkọ ọmọ rẹ̀ jáde kuro nile.
Argentina to ti gba ife eye idije naa fun igba kẹfa lo kọkọ pegede lati kopa fun idije ọhun lati ilẹ South Amerika.
Ipinlẹ Ondo lo bí ipinlẹ Ekiti.
N kò mọ ọ̀rọ̀ sọ, nítorí pé ọmọde ni mí.
Kó o kalẹ̀ níwájú àwọn ìbátan mi ati àwọn ìbátan rẹ, kí wọ́n lè dájọ́ láàrin wa.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Coronavirus treatments: Ọ̀gá àgbà ọlọ́pàá pàṣẹ pé kò gbọdọ̀ sí ìdádúró fún àwọn tí iṣẹ́ wọn ṣe kókó lásíkò ìséde 19 Ẹrẹ̀nà 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 21 Èbibi 2020 Oríṣun àwòrán, UNITED STATES AFRICA COMMAND Ẹgbẹ awọn dokita onimọ iṣegun oyinbo ni Naijiria ti fagile iyanṣẹlodi ti wọn bẹrẹ, nitori bi awọn ọlọpaa ṣe fiyajẹ awọn ọmọ ẹgbẹ wọn kan lasiko isede coronavirus.
Bakan naa ni Ayo Ajewole ti awọn ololufẹ rẹ mọ si Wolii Agba wa nibẹ, pẹlu Sule Alao Malaika, Keji Osundara atawọn eeyan gbajumọ miran.
’ rèé Olè wọ ilégbèé obìnrin ní fásitì Ibadan, àkẹ́kọ̀ọ́ méjì farapa Orí mi wú, Joke Silva kọ ewì ìfẹ́ lọ́jọ́ ìbí Olu Jacobs Ọkùnrin mẹrin wọ gàù torí ìgbéyàwó orí Facebook Ìgbín ní èmi àti ìyá mi máa ń he kiri, ká tó lee jẹun - Lizzy Anjọrin Oloye Laduntan Oyekanmi, tii se ẹni ọ̀dun mẹrindinlaadọrun, nii se ọmọbibi agboole Ladapọ ladugbo Abẹbi ati agboole Balogun Ibikunle ladugbo Ayẹyẹ nilu Ibadan.
Iyaafin Olufunkẹ Ọdẹbiyi to jẹ iya oloogbe ṣalaye fun BBC pé, ko sẹni to lé mu awọn SARS to pa ọmọ oun, ayafi Olodumare.
Wo báwọn mùsùlùmí ti ṣe ọdun ìtúnu ààwẹ̀ káàkiri ilẹ̀ Afirika lásìkò covid-19 yìí Ṣọ́ọ́ṣì kan sí ìlẹ̀kùn rẹ̀ fún àwọn mùsùlùmí láti kírun Jímọ̀ ní Germany Òṣèré tíátà, Ọmọba Femi Oyewunmi tí ọ̀pọ̀ mọ̀ sí Laditi ti jáde láyé Mo wọ bàtà àti fìlà wọ pẹpẹ Cele láti ṣe wáàsí, kò sí ṣọ́ọ̀ṣì tí n kò le wọ̀ - Sheik Buhari ọmọ Musa Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Gbogbo ènìyàn ni ό gba Olόwό-Ìbínú ní imọ̀ràn kí ό máṣe fẹ́ Ìdààmú-Ayé ṣùgbọ́n ό kọ̀ jalẹ̀.
”Lara awon to wa sibi idanilekoo olojo kan naa ni ogagun lagbaja lati ile- ise Ologun, hajia Rafat Salami, ti o je akowe agba fun awon akoroyin niluu Abuja, asoju orile ede Egypt, asoju eka ile-ise to n mojuto iwa ibajẹ ati sise owo ilu kumo-kumo.
”Iwadii so pe, ko si agbẹjọro
Jeremaya wolii kọ ìwé kan ranṣẹ láti Jerusalẹmu, ó kọ ọ́ sí àwọn àgbààgbà láàrin àwọn tí a kó ní ìgbèkùn; ati sí àwọn alufaa ati àwọn wolii, ati gbogbo àwọn eniyan tí Nebukadinesari kó ní ìgbèkùn lọ sí Babiloni, láti Jerusalẹmu.
Ẹbi yóò sèwádìí ohun tò pa Michael Adéyẹmọ
Ó bá mú un lọ sọ́dọ̀ Jesu.
Nina ti ikọ ti orilẹ ede Naijiria na ojugba wọn yii fihan wi pe igba akọkọ re lati bii ọdun 2007 lẹyin ẹẹmarun ti wọn ti gbiyanju.
‘O bá ìyá rẹ lọ́dọ̀ rẹ̀ bí’?
 o ní àwọn ẹ ̀ yà Ẹ ̀ gbá tòótọ ́ lé ti orírun wọn de Ọ ̀ yọ ́ .
wọ ́ n bí victor ndoma-egba ní ọjọ ́ kẹjọ oṣù kẹta ọdún 1956 ní ilù ikom , Ìpínlẹ ̀ cross river .
Ẹ yìnbọn pa ọ̀daràn tí ẹ bá rí níbi kíbi, Buhari pàṣẹ fáwọn ológun Fulani kò leè dúró, táa bá lo ohun ta jogún lọ́dọ̀ àwọn bàbá wa - Sunday Igboho 'El-Zakzaky lè má láńfààní láti lọ gba ìtọ́jú mọ́ lókè òkun' Ayédèrú Ọ̀ṣun ni wọ́n ń bọ lónìí, kìí ṣe ojúlówó - Bàbá Ọlọ́ṣun tún figbe ta Fayemi fojú Alufa to fipa bá ọmọde lòpọ̀ síta l'Ekiti Wo orílẹ́èdè tí wọ́n tí ń dáwó ìsìnkú ara wọn pámọ́ Èmi àti Saheed kìí ṣe ọmọdé, a ti jọ ṣe Sinimá papọ̀, èyí túmọ̀ sí pé ìjà ti parí - Fathia Balogun Ike Ekweremadu, igbákejì ààrẹ ilé aṣòfin àgbà tẹ́lẹ́ rí èèmọ̀ he nilùú Germany!
Adajọ Ilellah wa sun ẹjọ naa siwaju di ọjọ ikejilelogun oṣu keje ọdun yii.
Ọga awọn ẹṣọ Amọtẹkun l'Osun, Amitolu Shittu ló ṣi aṣọ loju eegun ọrọ yii.
Kò sí ẹni tí ó tọ̀ ọ́ lọ, tí ó pada rí,bẹ́ẹ̀ ni wọn kì í tún pada sí ọ̀nà ìyè.
Àbí kì í ṣe láti ẹnu Ọ̀gá Ògoni rere ati burúkú ti ń jáde?
Nípa bẹ́ẹ̀, o óo rí ojurere ati iyì lọ́dọ̀ Ọlọrun ati eniyan.
Ṣama, ará Harari, Ahiamu, ọmọ Ṣarari, ará Harari; 
Lalupon, niluu Ibadan ti o je olu ilu ipinle Oyo.
Iredi ti ikọ naa fi ṣe bẹẹ ni ko si han si ẹnikẹni titi di asiko yii.
Awon ti o kopa ninu ipade ti o waye lojoBo(Thursday) ni: akowe agba ajo to n mojuto eto eko, ogbeni Sonny Echonu, ati aare egbe ASUU teleri, dokita Isa Fagge.
Amọṣa, ọgbẹni Sajoh di ẹbi ibugbamu naa le awọn majeṣin kan ti wọn n ṣa ilẹ kiri lawọn ibudo idalẹ si kan nibẹ ati pe kii ṣe awọn agbesumọmi lo ṣọṣẹ.
Wọn kilọ̀ pé bi wọn kò bá wá nkan ṣe si Ayé Móoru yi, ayé yio parẹ́.
Ó ṣeéṣe kí OLUWA Ọlọrun rẹ ti gbọ́ iṣẹ́ tí ọba Asiria rán Rabuṣake, iranṣẹ rẹ̀, pé kí ó wá fi Ọlọrun alààyè ṣe ẹlẹ́yà, kí OLUWA Ọlọrun rẹ ṣe ìdájọ́ tí ó tọ́ lórí irú ọ̀rọ̀ bẹ́ẹ̀!
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù UK, Europe, US, Canada: Ọ̀pọ̀lọ̀pọ̀ ọkọ̀ ayókẹ́lẹ́ ló ti rì sàbẹ̀ yìnyín 2 Èrèlè 2019 Oríṣun àwòrán, Press Eye Àkọlé àwòrán, Òtútù àti yìnyín ló ti ń sọsẹ́ nílẹ̀ Europe àti Amẹrika,Canada ati Ilẹ̀ Gẹ̀ẹ́sì lo faragba ninu otutu yii.
Arakunrin Abayomi Adebiyi gba Aarẹ Buhari ni imọran ‘lati ko ara wọn ni ijanu’, ki wọn si ma se sọ ohun to le da orilẹede Naijria ru.
O ni ofin faye gba ara ilu lati foju ba ile ẹjọ, ko si sọ tẹnu rẹ lori ohun ti wọn ba ka mọ lọwọ kaka ki ọlọpaa fi iya jẹ iru ẹni bẹẹ.
Iko Super Eagles ti gba ifesewonse
Ni àtijọ́, àṣà Yorùbá ni lati wá idi bi enia ti kó ọrọ̀ jọ, ṣùgbọ́n ni ayé òde oni, olówó ni wọ́n mbọ, bi ó bá ti ẹ jalè tàbi ti ẹ̀wọ̀n de nitori iṣẹ́ ibi.
“Ninu eto abo lorile-ede yii, papaa julo ni eka ila oorun, a ri wi pe ilosiwaju n ba eto abo lorile-ede yii.
Oríṣun àwòrán, @PoliceNG Asiko to si n se iranwọ lati mu Aisha fo oju titi lasiko ti ọmọdebinrin naa n pada bọ nile iwe ni Abdullahi ji gbe pamọlaimọ si awọn obi ọmọ naa.
Lọwọ bi a se n ko ìròyìn yìí, Senato Akpan wa ni àhámọ́ lọdọ ile iṣẹ to n gbogun ti jegudujera lorílè-èdè Nàìjíríà, EFCC.
“Ayọ̀ ń bẹ fún ẹni tí Ọlọrun bá bá wí,nítorí náà, má ṣe kẹ́gàn ìbáwí Olodumare.
Ẹgbẹ Majeobaje wa n kọminu lori idi ti ikọ Amotekun ko se tii bẹrẹ isẹ to jọju nidi idaabo bo ẹmi ati dukia nilẹ Yoruba, gẹgẹ bi awọn araalu ti n foju sọna fun.
O ni àwọn oṣiṣẹ ati ijọba ni wọn jọ wa nibẹ.
Bo tilẹ jẹ pe Arabinrin Carrington ko sọ nkan to pa a, o ni o ku wọọrọwọ ni lasiko ti awọn ẹbí rẹ yi i ka.
Ajọ naa ni ko si ibikibi ti wọn ti n fi owo ṣe ayẹwo COVID-19 fun ẹnikẹni lorilẹede Naijiria.
Wọn óo run ilẹ̀ náà, n kò sì ní gba ẹnikẹ́ni lọ́wọ́ wọn.
Ọ̀rọ̀ ọ̀hún fẹ́ ṣe bí òwe.
Àwọn kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ igbó dúró lórí òkè,wọ́n ń mí hẹlẹhẹlẹ bí ajáko.
Al-Qaeda, ISIS: Amẹ́ríkà ké gbàjarè pé ẹgbẹ́ agbésùmọ̀mí n palẹ̀mọ́ láti wọ Nàìjíríà
Gẹgẹ bi atẹjade kan ṣe sọ, wọn ti gbe oku arakunrin naa lọ sileewosan nla ijsba to wa lagbegbe Mọniya.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Lekan Kingkong: Níbikíbi tí mo bá wà, màá gbé àṣà Yorùbá ga Ile ẹjọ sọ pe ẹsun naa n bẹ labẹ abala ti wọn pe ni 'aikọbi ara si nkan' labẹ ofin orilẹede Naijiria.
“Ẹnikẹ́ni kò sì gbọdọ̀ wá siwaju mi ní ọwọ́ òfo láti sìn mí.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Jiti Ogunye: Ìjọba àkóbá lológun gbé kalẹ̀ ni 1999 Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Jiti Ogunye: Ìjọba àkóbá lológun gbé kalẹ̀ ni 1999 25 Èbibi 2019 Ọ̀rọ̀ Naijiria tojú súni -Jiti Ogunye, àgbà ọjẹ agbẹjọrọ ni Naijiria.
Wọn kò mu ọtí níbi tí wọ́n ti ń kọrin mọ́ọtí líle sì korò lẹ́nu àwọn tí ń mu ún.
Ó bá rí ọ̀kan ninu àwọn ará rẹ̀ tí ará Ijipti ń jẹ níyà.
" Olori Anu naa wa pari ọrọ rẹ pe oun dupẹ pe ẹ fi oye gbe alaye oun.
N óo fi ẹ̀mí gígùn tẹ́ ẹ lọ́rùn,n óo sì gbà á là.
O ni ileeṣẹ abaniraja SHOPFORME to da silẹ ni aṣeyọri to ga julọ ti oun ti ṣe.
Lati igba ti ijọba aarẹ Buhari ti de ori aleefa ni ẹka irinna ti jẹ ọkan lara awọn ẹka ti wọn gbajumọ paapa julọ nipa atunṣe awọn papakọ ofurufu kan lorile-ede Naijiria.
OLUWA bá mú un jáde, ó sì sọ fún un pé, “Wo ojú ọ̀run, kí o ka gbogbo ìràwọ̀ tí ó wà níbẹ̀ bí o bá lè kà wọ́n.
Laarin akoko ti wọn mu awọn eeyan naa, iwọn oogun oloro to to kilo ẹgbẹrun lọna mẹjọ o din diẹ, ni wọn ka mọ wọn lọwọ.
labe asia egbe oselu  Peoples Democratic
Máa gbé kẹ̀kẹ́ rẹ lọ, àwọn akọròyìn kọ̀ ìpàkọ́ sí Femi Fani Kayọde Victoria Rubadir ọmọ Kenya ló gba àmì ẹ̀yẹ Komla Dumor BBC World News Ohun tí a mọ̀ nìyí nípa gbọ́nmi síi omi ò tó lórí ọ̀rọ̀ oyè Babaloja-General ní ìpínlẹ̀ Oyo Ọkùnrin kan da ṣọ́ọ̀ṣì rú lásìkò ìgbéyàwó, Ó ní òun lọkọ àárọ̀ ìyàwó tuntun Ẹgbẹ́ wa ò dàrú o!
Ìrè-Èkìtì jẹ ́ ìlú kan ní agbègbè àríwá Èkìtì ní ìpínlẹ ̀ oǹdó ; èyí tí ó jẹ ́ ọ ̀ kan nínú àwọn ọmọ bíbí inú ìpínlẹ ̀ ìwọ ̀ -oòrùn àtijọ ́ .
Koda titi de awọn orilẹede bii Amẹrika, ilẹ Gẹẹsi ati Canada, ka fi mọọ nibẹ, ni wọn gba iroyin naa ti wọn si da sii pẹlu.
 o je orile-ede olominira sistemu aare die alasepapo to ni ipinle ijoba 83 .
Tinubu bu ẹnu atẹ lu igbesẹ ti awọn ọmọ ogun naa gbe.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Canadian Kidnap: Ghana ti mu àwọn afurasí ajínigbé ọmọ Naijiria 13 Òkùdu 2019 Oríṣun àwòrán, @Ghana mins Àkọlé àwòrán, Ghana ti mu àwọn afurasí ajínigbé ọmọ Naijiria Lọjọru ni awọn eleto aabo orilẹ-ede Ghana mu àwọn mejọ.
Shehu Sani ti wa ni Ile Igbimọ Asofin labẹ aarẹ tẹlẹri Bukola Saraki.
Eko bridge: Ìjọba ń ṣe afárá Eko Bridge l'Eko, àwọn ọ̀nà àbùdá tí ẹ lèè gbà nìyí
  Ẹ jẹ́ mọ̀n pé ibi àwọn ẹyìn bá rẹ̀ sí, ibẹ̀ náà ni wọ́ ń rà sí o!
Minisita to n ri si oro ile-okere lorile-ede North Korea, ogbeni Ri Yong Ho so pe oun yoo sabewo si Russia laarin osu kerin-in odun ti a wa yii.
Ìkookò inú aṣálẹ̀ ni yóo wá jẹ wọ́n run.
Kehinde Ayinde, agba-boolu fun iko egbe ABS FC lo gba ami akoko wole pelu ori re ni iseju kerinla saa ifesewonse ohun, ti Dele Olorundare agba-boolu fun iko egbe El-kanemi Warriors si da ami kan wole pada ki saa akoko to pari.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Pa Kasumu: Lere Paimo ní àìrìríjẹ́, àìrímú tàbí ìrònú má a ń jẹ́ kí ọjọ́ ogbó dagun Wọn sun ọjọ ti sinima Fate of Alakada yoo jade Awọn ololufẹ Toyin Abraham ati Broda Shagi to ti n foju sọna sinima Fate of Alakada yoo ni lati ṣe suuru diẹ.
Gbogbo ọ̀rọ̀ àbáláyé tí ó ti di àkosílẹ̀ nísinsìnyí nínú ọpọlọ́ àwọn baba ńlá wa ni wọ́n wà tẹ́lẹ̀.
Boris Johnson ni ẹnikeji ti ipo rẹ gaju lẹyin olootu ijọba Ilẹ Gẹẹsi naa, Theresa May.
“Ẹ kò gbọdọ̀ bọ oriṣa, nítorí èmi OLUWA, tí orúkọ rẹ̀ ń jẹ́ owú, Ọlọrun tíí máa jowú ni mí.
Ẹ wo ẹyẹ ayékòótọ́ tó kó olówó rẹ̀ yọ lọ́wọ́ ikú gbígbóná N400m ló ń sọnù ní ọdọọdún nítorí àwọn tó ń gba owó òṣù láì ṣiṣẹ́ - Fayemi A ti gbé ìwádìí dìde lórí ìpànìyàn tó wáyé lásìkò ìwọ́de EndSARS- Ilé ẹjọ́ àgbáyé, ICC A kó ní sanwó oṣú ASUU láìjẹ́ pé wọ́n gba IPPIS- Ìjọba Àpapọ̀ Esther Agbaje ni ọmọ Naijiria akọkọ tii yo jẹ ọmọ ile aṣoju-ṣofin ni Minnesota.
OLUWA, Ọlọrun, Olùgbàlà mi, mo ké pè ọ́ fún ìrànlọ́wọ́ ní ọ̀sán;mo ké níwájú rẹ ní òru.
Dokita Akinbodewa n sọrọ lori bi awọn eniyan ṣe kọ lati ma ṣe yoju si ileewosan fun ayẹwo nipa arun Coronavirus.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ẹ wo fídíò Kìnìhún ní ibùgbé rẹ̀ tuntun ní Bogije, Lekki Abajade iwadi yii fihan pe ikọlu igbesunmọmi lorilẹ-ede Naijiria pọ ju ti orilẹ-ede Syria to wa ni ipo kẹrin pẹlu ikọlu ọtalelẹgbẹta ati meji, 662to sọ eeyan mọkanlelogoje, 131 di ero ọrun alakeji.
07bilion), ileeṣẹ ọrọ abo yoo gba ojilenirinwo o din marun un biliọnu naira (N435.
Ṣùgbọ́n ẹlẹ́sẹ̀ kò ní í lọ láìjìyà àfi bí ẹlẹ́ṣẹ̀ náà bá tètè ronù pìwàdà.
Ẹni tí ó bá bẹ̀rù OLUWAni OLUWA yóo kọ́ ní ọ̀nà tí yóo yàn.
Ẹni to bori: Algeria Aṣekagba Nigeria Algeria Nigeria vs Algeria.
orò ni wọn ń lò láti da sẹ ̀ ríà fún arúfin ti ẹ ̀ sẹ ̀ rẹ tòbi .
Olowo ẹru kan nilu Dahomey ti orukọ rẹ n jẹ Abass si lo mu lẹru lasiko ogun Dahomey ati Egba nigba to wa ni ọmọ ọdun mẹfa, to si pa orukọ rẹ da si ti ọga rẹ.
Àwọn ọmọ Eli mejeeji, Hofini ati Finehasi, sì tẹ̀lé àpótí ẹ̀rí náà.
Nígbà tí ehoro pári ọ̀rọ̀ rẹ̀ ó ki iré mọ́lẹ̀, ó sáré tagbáratagbára: ò ku èmi nìkan sí orí igi, ètè mi gbẹ, itọ́ ẹnu mi yí, ikùn mi rí pẹlẹbẹ, ojú mi rí kan-ǹ-do, mo lé góńgó lórí igi, mo dà bí ìjìmèrè, mo fi ara wé ìnàkí, mo rántí ilé, mo rántí ọ̀rẹ́, àárò sọ mi, ìyà, ẹgbẹ̀ta jẹ mí, -àbùkù ẹgbẹ̀rin tọ lé mi, mo pa òṣé ńlá, mo sọkún àgbàlagbà, mo fa ojú ro, mo wo òkè, mo wo ìsàlẹ̀, mo rónú títí, bẹ́ẹ̀ ni n kò ri nǹkan ṣe nǹkan.
Ẹgbẹ agbabọọlu Arsenal ti kuna ni igba mẹrin ninu maarun, ti wọn ti de asekagba idije naa, ti wọn si jawe olubori ni 1994 CWC.
Ìwọ tí ò ń pe ara rẹ ní Juu, o gbójú lé Òfin, o wá ń fọ́nnu pé o mọ Ọlọrun.
’ ” (Èyí ni, láti mú Kristi jáde kúrò láàrin àwọn òkú.
Oríṣun àwòrán, Bukola Saraki/Facebook Àkọlé àwòrán, Saraki léwájú ẹgbẹ́ PDP láti fẹ̀hónú hàn nítorí ìbò Ọṣun Asọjú ẹgbẹ́ APC, Gboyega Oyetọla ni wọ́n kéde lẹ́yìn tí àtúndì ìbò wáyé.
Mama Risikat ni lọpọ igba ni oun pe ọkọ rẹ lati pẹtu si aawọ to wa laarin wọn, ṣugbọn oun rii wi pe ọkọ Risikat ko ni nnkan ṣe.
ṣugbọn àdàbà náà kò rí ibi tí ó lè bà sí nítorí pé omi bo gbogbo ilẹ̀, ó bá fò pada tọ Noa lọ ninu ọkọ̀.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù coronavirus updates: TB Joshua, Apostle Suleman, Odumeje, D.
Lẹyin naa si ni oun ati iyawo oun yoo maa lọ si America.
Bakan naa, Sheik Muideen Ajani Bello, tii se oniwaasi agbaye to se waasi nibi akanse eto adura naa ni ijoko adura naa ti to fun waasi nikan.
Ayodele Fayose: Ẹ̀yin ọ̀tá mi, ẹ lọ dì mọ́ òpò ina lọ́dún 2020
Wọn ni pipe fun iwọde alaafia kii se ete lati dijẹ gbajọba, bẹẹ si ni ẹjọ ti wọn n ba Sowore se ti tako ẹtọ to ni labẹ ofin lati sọ ohun to ba wu, pipejọ sibi to wu ati ẹtọ si igbẹjọ lai fi falẹ.
wón bí akíntôlá ní ojó karùn ún osù karùn-ún odún 1970 bàbá rè jé omo bíbí ìpínlè oyo tí ìyá rè sì jé omo bíbí Ìpínlẹ ̀ edo .
Ẹ̀tàn ń bẹ lọ́kàn àwọn tí ń pète ibi,ṣugbọn àwọn tí ń gbèrò rere ní ayọ̀.
Ibi tí a bá ti rí ẹ̀gbọ́n ni a ó ti rí abúrò.
nnkankan, ti bo si je pe awon gan an ni ole , ti won tun fe lati wa ja ilu ni
ibo, ni eyi ti ẹri to daju wa ”.
Toke Makinwa nínú ọ̀rọ̀ rẹ̀ kò dá òbi kankan si ni ilẹ̀ Afrika, o ní pàápàá jùlọ ọ̀na ti wọ́n ń gbà tọ ọmọ nípa ìbásepọ láàrin ọ̀kùnrin àti obìrin, ìdúró wọ́n lóri ǹkan ti o gbọdọ̀ ka ni Fasiti àti fífi ìbẹ̀rù si ọmọ lọ́kàn.
Èyí àkọ́bí pupa, gbogbo ara rẹ̀ dàbí aṣọ onírun.
Nílé ẹjọ lónìí, Babatunde ni òun kò jẹ̀bi ẹ̀sùn ti wọ́n fi kan òun.
Ọba Akinruntan sọ ọrọ yii di mimọ lasiko to fi n ṣe ajọyọ ayẹyẹ ọdun kọkanla ti o n lo lori itẹ gẹgẹ bii Olugbo ti ilu Ugbo.
Tí ènìyàn bá jẹ ẹ jù, o lé fa inú rírùn àti ati inira.
Wo àwọn akọrin Nàìjíríà tó fakọyọ ní àmì ẹ̀yẹ AFRIMA Wo bí o ṣe lè ṣe eré ìdárayá tí yóò fún ọ ní adùn àti okun fún ìbálòpọ̀ Iléeṣẹ́ ọlọ́pàá ṣàfihàn ojú àwọn afurasí tó se ẹran ara ọlọ́pàá jẹ ní Ibadan Mílíọ́nù mẹ́wàá Náírà ni ilé ẹjọ́ ni kí Kábíyèsí san gẹ́gẹ́ bí owó ìtaran ilẹ̀ tí ó gbà lọ́nà àìtọ́ Àkọ́jọpọ̀ to gbé jade náà ta ẹgbẹ̀rún lọ́nà ogójì lọ́jọ ti ó kọ́kọ́ jáde.
 lẹ ́ yìn èyí ni ó wá di olú-ìlú fún ìjọba sialy àti naples .
Jálà epo bẹntiróò di N600 nítorí ibodè títìpa Ọwọn gogo epo bẹntiro ti gbode kan bayii lawọn awujọ to sun mọ ibode orilẹede Naijiria sawọn orilẹede miiran nitori ibode Naijiria to ṣi wa ni titi pa.
awọn ile-iṣẹ aṣagbeyẹwo iṣuna owo yoo maa ṣamulo awọn ilana naa.
Ènìyàn mẹ́jọ ló lùgbàdì ààrùn náà ni Bauchi, méje ló tún jẹyọ láti Yobe, Oyo àti Kebbi ni mẹrin, Kastsina àti Niger ni mẹ́ta, Plateau, Borno, Sokoto àti Benue ní méjì nígbà ti Gombe, Ebonyi, Ogun, FCT àti Rivers ní èèyàn kọ̀ọ̀kan Oríṣun àwòrán, NCDC Àkọlé àwòrán, Àjọ NCDC kéde èèyàn 146 míràn tó ni ààrùn Covid-19 lórílẹ̀-èdè Naijíríà Àjọ NCDC kéde èèyàn 242 míràn tó ni ààrùn Covid-19 lórílẹ̀-èdè Naijíríà Àkọlé àwòrán, Àjọ NCDC kéde èèyàn 242 míràn tó ni ààrùn Covid-19 lórílẹ̀-èdè Naijíríà Àjọ tó ń gbógun ti àjàkálẹ̀ ààrùn lórílẹ̀-èdè Nàìjíríà NCDC ti kéde pé ènìyàn ìgbàléméjìlélógójì ni àyẹ̀wò tún fi hàn pé ó ti ní ààrùn Coronavirus lórílè-èdè yìí ti àpapọ̀ àwọn tó ní ààrùn náà Nàìjíríà sì ti di ẹgbẹ̀rún mẹ́rin àti ẹgbẹ̀taléméjílèlógójì.
Nígbà tí ó bá yá, á máa buni ṣán bí ejò,oró rẹ̀ á sì dàbí ti ejò paramọ́lẹ̀.
O ti figba ri jẹ oludari awọn ọlọpaa to n pẹtu sija, bẹẹ lo si ṣiṣẹ gẹgẹ ọga ọlọpaa nipinlẹ Enugu ki o to di igbakeji ọga ọlọpaa lorilẹede Naijiria.
Àkókò ìkórè ọkà nìyí, àbí bẹ́ẹ̀ kọ́?
Abramu, tí a tún ń pè ní Abrahamu.
 o ni olugbe bi 320,000 ati apapo iye aala .
Èrò Bode George PDP lórí ikú Aboriṣade, alaga PDP Apapa.
“Mo ké pe orúkọ rẹ, OLUWA, láti inú kòtò jíjìn.
Monument Bank (FCMB), Ogbeni opeyemi Agbaje ti rọ ijoba orile ede Naijiria lati
Ọkan nínú àwọn òṣìṣẹ́ tó tó n ri sí ìjáde àti iwolé lorilẹ̀-èdè Amerika sọ pé òun ri èròngba ẹnikan lóri Facebook rẹ̀ tó n sọrọ òṣèlú lòdi si ìjọba orilẹ̀ èdè Amérika"" ""Mo sọ fún wọ́n pé mí o ni ǹkankan ṣe pẹ̀lú àwọn èròngba náà, bákan náà ni mí o si gbé ìgbéṣẹ kankan lóri ǹkan ti ó kọ, mo sàlàyé pé kò yẹ ki wan múmi fún ẹ̀ṣẹ̀ ti mí o mọ nípa rẹ̀"" Agbẹnusọ Aṣobode àti alábo ilẹ̀ Amerika (CBP) Michael McCarthy sàlàyé pé àwọn gbe ìgbésẹ̀ náà látàri àwọn ǹkan tí àwọn ti ṣe àwári lásìkò tí wọ́n ń ṣe àyẹwò (CBP) Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Harvard University say dem dey try to settle di mata before class go begin McCarthy kò sàlàyé jù báyìí lọ nítori pé ṣe ǹkan tí àwọn gbọdọ máà fi gbogbo ẹni sọ."
B Joshua lo ni ilu Eko lati beere iranwọ lọdọ Ọlọrun.
Bí wọ́n bá rán iṣẹ́ alaafia pada, tí wọ́n sì ṣí ìlẹ̀kùn wọn fun yín, kí ẹ kó gbogbo àwọn ará ìlú náà lẹ́rú kí wọ́n sì máa sìn yín.
Baba Olumilua jade laye ni owurọ Ọjọbọ.
Ọkọ ayokẹle Toyota ti ikọ Boko Haram naa n lo lati sa kuro lagbeegbe naa lo gbina, lẹyin ti wọn gun ori ado oloro ti wọn fi dẹkun silẹ.
Awọn ilu to n foju wina ọwọn gogo epo yii wa ni ipinlẹ Ogun, Eko, Adamawa, Katsina ati ipinlẹ Sokoto.
Ó bá wí fún ẹni tí ń wa kẹ̀kẹ́ ogun rẹ̀ pé kí ó gbé òun kúrò lójú ogun, nítorí pé òun ti fara gbọgbẹ́.
 Èyí jẹ ́ kí àwọn fíìmù wọ ̀ nyí di gbajúmọ ̀ ní ilẹ ̀ nàíjíríà àti ní òkèèrè .
Ko si si tọmọde tagba ti ko fẹran rẹ nitori oniruuru ipa ti o ti ko ninu awọn ere itage yala apanilẹrin ni tabi eyi to da lori iwa ọdaran.
Nígbà tí Abija ọba kú, wọ́n sin ín sinu ibojì àwọn baba rẹ̀ ní ìlú Dafidi.
ile-ejo lo fun idaniloju  labẹ ofin boya
Ninu akanṣe iṣẹ to le lọgọrun pẹlu mẹrinla ni awọn ijọba ibilẹ ti ri ọna bii meji meji gba to si ti yanju ninu oṣu karun ọdun kan naa.
Bakan naa o ṣalaye ohun to wa nibi bi awọn to tara arun Coronavirus ku ko fi pọ.
Makun (AY), Daniel Amokachi, Tijani Babangida, igbakeji gomina ipinle Edo,
ofin Section 292 ti orile ede Naijiria la sile fun won.
Diego Costa ni igbagbo pe, jijawe olubori Spain ninu ifesewonse olorejore pelu Argentina laisi atamatase ohun, Messi ninu iko naa se afihan bii Messi se se pataki fun Argentina to.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Natalia Mufuta ìyá Yakub, Kamil àti Adam sọ̀rọ̀ lórí bí wọ́n ń sọ èdè mẹ́rin pàpọ Biggie bu omi ikilọ wọn Nengi ati Kaisha lara fun ija ti wọn ja ninu ile ẹlẹgbọn agba Saaju ni ẹlẹgbọn agba funrarẹ ti bu omi ikilọ wọn Nengi ati Kaisha larafun wahala to bẹ silẹ laarin lowurọ ọjọ Abamẹta.
A jẹ́ pé ẹ̀yin ni ẹ fa ìparun wọn.
Kola ni PDP yoo kede igbesẹ ti wọn fẹ gbe lẹyin ti wọn ba pari àtòjọ ẹ̀rí wọn.
da ibugbe awon dara-daran silẹ  ni awon
Àwòráń ọdún Ashura àwọn ẹlẹ́sìn Shiite tí ọ̀pọ̀ ń sọ̀rọ̀ nípa rẹ̀ lórí ayélujára Risikat olójú búlù dí aya Wasiu ní ìlànà Islam, tẹbí tará péjú síbẹ̀ Ó ń bọ̀ lọ́nà!
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Sowore Revolution Now: Nǹkan tó yẹ kí o mọ̀ nípà Omoyele Sowore tó ń ṣe agbátẹrù ìfẹ̀hónú hàn jákèjádo Nàìjíríà 5 Ògún 2019 Oríṣun àwòrán, Omoyele Sowore Àkọlé àwòrán, Sowore ti pe omo ọdun mejidinlaadota Ní kété ti àwọn ọmọ Naijiria jí lónìí, ọjọ karun oṣù kẹjọ ní wọ́n ri pe ìwóde ìfẹhonuhan lóri ètò ìjọba ti kò lọ botitọ tí Omoyele Sowore ń se agbátẹru rẹ wáye ní tootọ lẹ́yìn tí wọ́n ti fí àgbétẹru rẹ̀ si àtìmọlé láti ọjọ sátide to kọja.
Aare wa gbadura fun awon to padanu
ó wí fún un pé, “Mo ti gbọ́ adura ati ẹ̀bẹ̀ rẹ, mo sì ti ya ilé tí o kọ́ yìí sí mímọ́.
Àwọn nǹkan ẹlẹ́mìí tí ń fò lófuurufú wà.
Oríṣun àwòrán, Reuters Imaamu mọsalasi naa sọ fun ileesẹ iroyin Reuters pe ''apẹẹrẹ nla leleyi jẹ, ti o si mu ayọ ati idunnu wa lasiko ifoya yii''.
A seto rira oko alagbeka ohun nitori pe a ko ni agbara lati si ibudo ayewo ati itoju onilana igbalode fun wiwo arun jejere san lasiko yii.
Ninu iwe orukọ oludije lẹta 'H' ni wọn fi kọ Hitler to wa ninu orukọ rẹ ṣugbọn ninu iwe ẹri abajade ibo,wọn kọ ẹkunrẹrẹ orukọ rẹ sibẹ gbagada ni.
Ajọ naa n gbero lati ṣewadi awọn dukia naa ni ẹka ijọba to n ṣabojuto ọrọ ilẹ, ile ifowopamọ ati awọn ile iṣẹ ti wọn ba ni, ati eyi ti wọn ba nipin ninu rẹ.
Kí ó máa jiyàn lórí ọ̀rọ̀ tí kò wúlò,tabi ọ̀rọ̀ tí kò níláárí?
A gúnlẹ̀ ní ìlú Tire, nítorí níbẹ̀ ni wọ́n fẹ́ já ẹrù ọkọ̀ sí.
Nígbà náà ni Hagai tún bi wọ́n pé, “Ǹjẹ́ bí ẹnìkan bá di aláìmọ́ nítorí pé ó farakan òkú, tí ó sì fọwọ́ kan ọ̀kan ninu àwọn ohun tí a kà sílẹ̀ wọnyi ǹjẹ́ kò ní di aláìmọ́?
Eyi lo wa n faa ti ọpọ fi n ṣe beere boya ohun rere kan tilẹ lee ti Nasarẹti yii jade.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ayodeji Amodu Photoshop: Aláráǹbàraà!
"Ọkọ mi kìí bọ òkun, ""Elder"" ni ní ṣọ́ọ̀ṣì àmọ́ ìdí nìyí tó fi bọ̀wọ̀ fún ìpè mi - Olokun Omolara Ninu ifọrọwerọ rẹ pẹlu ileeṣẹ FUJI: A Opera, Kollington gba pe oloogbe Ayinde Barrister lo da ere Fuji silẹ nigba ti oun tẹ le e ninu iṣẹ orin Fuji."
OLUWA kò ní dáríjì olúwarẹ̀, kàkà bẹ́ẹ̀, ibinu ńlá OLUWA ni yóo bá a.
Akonimoogba agba iko agbaboolu Super Eagles, Gernot Rohr ati awon agbaboolu mejilelogun ti bere igbaradi ni papa isere Stephen Keshi lojo Isegun(Tuesday), niluu Asaba, saaju ifesewonse ipegede fun idije boolu afesegba ile Afrika(2019 Africa Cup of Nations), ti iko ohun yoo gba pelu iko agbaboolu orile-ede South-Africa(Bafana Bafana) ni papa isere FNB, niluu Johannesburg lojo abameta(Saturday).
Game of Thrones vs Ìrèké Oníbùdó: Ǹjẹ́ ìfarapẹ́ra wà nínú fíìmù méjèèjì?
“Mo ni ise pupo lati se ninu ayeye ibere ohun, leyi ti o je idi ti mo fid a ikede ohun duro doni,’’.
O jọ bi ẹní pe àwọn olólùfẹ́ Manchester United ko ni fi bẹ́ẹ̀ ba Chelsea kẹ́dùn bí ìdíje yìí ṣe jẹ èsì tó tíì dára júlọ ni old Trafford pẹ̀lú Chelsea láti ọdun 1965 Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Man Utd sign defender Maguire from Leicester hand for £80m5 Ògún 2019 Lukaku: Inter Milan don sign Belgium striker from Manchester United for £74m8 Ògún 2019 Alex Iwobi: Di midfielder transfer from Arsenal make Nigerians squeeze face9 Ògún 2019 Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
"Lẹyin naa lo kọ akọle kan to sọ pe ""lati ọdọ wa si yin, a ki yin ku ọdun Keresimesi."
"Ọ̀rọ̀ Sotitobire tí a dá sí, àwọn aṣòfin àtàwọn àjọ kan ló fi lọ̀ wá- DSS Oyún oṣù méje ló ń bẹ nínú Azeezat, kí wọ́n tó f'òkúta fọ́ ọ lórí Òní ni ètò ìsìnkú George Floyd yóò wáyé Ẹ̀yin tí ẹ lọ ra aṣọ àlòkù ní Ọjà Ọba Akure, ẹ lọ ṣàyẹ̀wò Coronavirus - Akeredolu figbe ta Oluomo fikun pe ""ọdọ ẹni to ku ni iya fun mama mi nilu Abeokuta la n gbe lọdọ rẹ, Mama mi n gbalẹ titi ni Eko, n ko ri itọju to, ni mo ṣe sa kuro nile lọmọ ọdun mẹtala, ti mo si n ṣe kọndọ lati Abeokuta wa si Eko."
Lasiko ipade naa, olugbani nimoran lori eto iroyin, Iliya Kure, eni ti o dari ipade naa so ni ipade ohun pe, o se pataki lati se agbekale ilana naa, eyi ti yoo je ki egbe naa ri owo lati le polongo fifaye sile laarin omo, bakan naa lati seto itaniji fun iran ti o bo lojo iwaju.
Àwọn arakunrin rẹ̀ bá bẹ̀rẹ̀ sí ṣe ìlara rẹ̀, ṣugbọn baba rẹ̀ kò gbàgbé ọ̀rọ̀ náà, ó ń rò ó ní ọkàn rẹ̀.
Nígbà tí ọjọ́ pé, pupọ ninu wọn wá kí i.
Agbẹjọro wọn pe wa lorii foonu lonii lati ki wa, igba yẹn la n sọ fun un pe ko lọ wo ori iwe iroyin bayi bayi pẹlu ohun ti wọn kọ sita.
Àwọn ọmọ Meṣelemaya ati àwọn arakunrin rẹ̀ tí wọ́n lágbára jẹ́ mejidinlogun.
Dide ti awọn eniyan de ibẹ ni wọn ri nkan iyalẹnu pe, oju ọna naa ti la si meji, ti ọpọlọpọ ile naa si di awo ku.
Amọ awọn ọlọpaa ni awọn ọdọ naa gbe paali pẹlu orisirisi akori, ti wọn si n lọ lọwọọwọ.
Awon miran to wa ninu oruko o pegede naa ni Ariana Grande , Adwoa Aboah to je omo Ghana to n safihan aso atawon meje miran.
Awọn ọti lile yi, si ni wọn ti sọ ni orisirisi orukọ bii pẹlẹbẹ, rubutu ati gbọọrọ Oniruuru ileesẹ si lo nse awọn ọti lile yi sita, ti wọn si sọ wọn ni orisirisi orukọ bii Karaole, origin, Pakurumọ, Doro webo, Ọsọmọ, Black wood, Ogidiga, Agbara, Bitter Action, Kick and Start.
Adiẹyinmu ikọ agbabọọlu obinrin Naijiria, Onome Ebi lo gba ami ẹyẹ obinrin to fakọyọ pẹlu ipa ribiribi to ko nigba ti ikọ Super Falcons gba ife ẹyẹ Africa Women's Cup of Nations (AWCON) ni 2018.
Ẹ óo yan ìlú mẹfa fún èyí.
Lẹyin naa lo darapọ mọ awọn ti wọn ti kawe gboye mii lapa iwo oorun Naijiria lati da ẹgbẹ oṣelu Action Group (AG) silẹ pẹlu ifari Oloye Obafemi Awolowo.
 Àrùn weil àti àkópọ ̀ àmì àrùn ẹ ̀ jẹ ̀ ṣíṣe láti inú ẹ ̀ dọ ̀ fóró tó burú púpọ ̀ a má a fa ikú tó ju 10 % àti 50 % lọ lọ ́ kọ ̀ ọ ̀ kan , bí a bá tilẹ ̀ ṣe ìtọ ́ jú pàápàá .
jẹ eni to n fi gbogbo igba wa awawi niwaju awon ti e n dari won, o le ba gbogbo
Ki ni idi gan ti wọn fẹ fi gunle iyanṣẹlodi yii?
Ní ọjọ́ kẹrin oṣù kẹsan-an, tíí ṣe oṣù Kisilefi, ní ọdún kẹrin ìjọba Dariusi, ni OLUWA rán mi níṣẹ́ yìí.
Bakan naa ni Minisita fun irinna ọkọ ofurufu, Hadi Sirika ni ẹnikẹni to ba ni iba tabi to n wu kọ lati ma ṣe wa si papakọ ofurufu, nitori wọn ko ni gba ki ẹnikẹni to ba ni ami to farajọ ti arun Coronavirus wọ ọkọ ofurufu.
Nigerian Traffic Laws: Ohùn tó yẹ ní mímọ nípa òfin ojú pópó
Wole Soyinka rèé láti kékeré Nàìjíríà kò ní olórí, ẹ pín sí ẹlẹ́kùnjẹkùn - Soyinka Ṣé o ti gbọ́ ohun ti Ọọni Ifẹ́ àti Soyinka parí ọ̀rọ̀ Yorùbá sí?
   ati olori egbe oselu tuntun  ba kopa nibi eto isinku omo oun.
Mo ní kín ni n ó sọ fún wọn pé mò ń ṣe.
Bí Paulu ati Banaba ti ń jáde lọ, bẹ́ẹ̀ ni àwọn eniyan ń bẹ̀ wọ́n pé kí wọ́n tún pada wá bá wọn sọ irú ọ̀rọ̀ yìí ní ọ̀sẹ̀ tí ó ń bọ̀.
Ta ni Lisa Hanna, arẹwà obìnrin tí àwọn ọmọ Nàìjíríà fẹ́ kó di àárẹ wọn?
" lẹ ́ yìn tí ó ti ní orísirísi ìrírí iṣẹ ́ , patrick tèmítọ ́ pẹ ́ Àlàbí padà sí iṣẹ ́ eré orí ìtàgé gẹ ́ gẹ ́ bí ó ṣe darapọ ̀ mọ ́ ẹgbẹ ́ olókìkí nǹi "" Àlàdé arómirẹ ́ theartre group "" ní ọdún 1994 ."
ipade apero pelu awon akoroyin, ni eyi ti yoo waye ni ipari osu kefa.
Nítorí ẹni tí ó bá gbé ara rẹ̀ ga ni a óo rẹ̀ sílẹ̀; ẹni tí ó bá rẹ ara rẹ̀ sílẹ̀ ni a óo gbé ga.
Ohun ti awọn apaniyan naa kọkọ maa n ṣe ni pe, wọn yoo fi orukọ ati aworan wọn sita lori Facebook gẹgẹ bi ọdaran.
Lewis Gilbert, omo ile Geesi to dari awon fiimu agbelewo maleegbagbe Alfie, Educating Rita ati ere James Bond meteeta ti dagbere faye pe o digbose lomo odun metadinlogorun un.
"Ibi ti gbajugbaja olorin yii ti gba orukọ rẹ, Sarkin Waka eyi to tumọ si ""Ọba Orin"" wa latọdọ Emir ana ipinlẹ Kano, Sanusi Lamido Sanusi."
Aarẹ Buhari ni ijọba oun ti yanju igbesẹ gbogbo to yẹ lati jẹ ki awọn ọmọ Naijiria kuro ninu ikọlu South Africa.
0 388 Orilẹede Dominican 0 0.
Òun ni ó gbà mí lálejò bí ó ti gba gbogbo ìjọ lálejò.
Akor to ni oun ti na obitibiti owo si idi oko-owo naa ni oun ko si le gba lati padanu gbogbo rẹ, Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Baby abandoned on dunmpsite: Mo ti bímọ mẹ́rin tẹ́lẹ̀ fún bàbá méjì nínú òṣí- Dupe Ogbomos Akor ni ilu Owo nipinlẹ Ondo ni oun ti kọ iṣẹ igbo gbingbin Afunrasi oun n wa ẹkun mu bi omi ni, to si n gbiyanju lati dena awọn NDLEA lati ma ba oko naa jẹ.
    Nígbà tí ó di alẹ́ ọjọ́ tí a dé ibẹ̀ yìí, iwin náà wí fún ni pé oùn ní iṣẹ́ kan láti ṣe àti pé oùn sì fẹ́ kí a ran òun lọ́wọ́ láti ṣe nínú iṣẹ náà.
Gbogbo wọn ni wọn ṣe ayẹwo ti a si n reti esi ayẹwo wọn lẹyin sjs marun un nitori lẹyin ọjọ marun un ni wọn sọ fun wa pe esi ayẹwo wọn yoo jade.
Baba-onírùngbọ̀n-yẹ́úkẹ́ o ṣe e o, bí ìmàle ti ń rántí Ànábì tí onígbàgbọ́ ń rántí Ọlọ́run Ọba bẹ́ẹ̀ náà ni n ó máa rántí rẹ láéláé.
O wa pase fun ajo to n ri si eto ẹkọ lati pe ipade ti won yoo fi jiroro lori ona ti won yoo gba  lati pese owo fun eto ẹkọ lorile ede Naijiria.
Ile igbimọ asofin agba ni igbagbo wipe ijiroro itagbangba naa yoo wa ọnọ abayo si idojukọ awọn oludokowo pẹlu awọn ile-isẹ ifowopamọ gbogbo.
oludibo si ipo, lẹyin ti awọn to wa nibẹ tẹlẹ ba ti pari saa wọn.
Nígbà tí ìpàdé túká, ọpọlọpọ àwọn Juu ati àwọn tí wọ́n ti di ẹlẹ́sìn àwọn Juu ń tẹ̀lé Paulu ati Banaba.
ẹsẹ̀ Dafidi, ó bẹ̀ ẹ́ pé, “Jọ̀wọ́ oluwa mi, gbọ́ ti èmi iranṣẹbinrin rẹ, kí o sì jẹ́ kí n ru ẹ̀bi àṣìṣe Nabali.
Ọgbẹni Odinga se ibura wọ'le fun ara rẹ lẹyin ti o wipe ohun ni awọn eniyan dibo fun gege bi aarẹ orilẹede naa ninu idibo sipo aarẹ lọdun to kọja.
Fiimu rẹ ''Jẹnifa'' jẹ ilumọọka sinima tawọn eniyan fẹran lati maa wo ni, to si muni rẹrin takiti.
Nítorí nígbà tí a sọ pé kí ó wá sọ́dọ̀ yín, pẹlu ayọ̀ ni ó fi gbà láti wá.
Ọdun 2020 lo tun ti wọlẹ de wẹrẹ ni eyi ti onikaluku n dupẹ ẹ̀mí pe awọn ri.
Amaṣisai, ọmọ Asareli, ọmọ Asai, ọmọ Meṣilemoti, ọmọ Imeri, 
Joṣua bá fi idà pa Amaleki ati àwọn eniyan rẹ̀ ní ìpakúpa.
Gbogbo wa jọ wa gẹgẹ bi ọrẹ lasan ni.
Ògbójú Ọdẹ nínú igbó olódùmarè jẹ ́ ìwé-ìtàn àròsọ méèrírí tí Ọgb ́ eni daniel o.
Àwọn ẹ̀yà ara tí kò dùn ún wò ni à ń yẹ́ sí jùlọ.
Cameroon Football Federation (Fecafoot) don announce say 2021 Africa Cup of Nations go happun for January 9.
Agbébọn yabo àgọ́ ọ́lọ́pàá, wọ́n pa DPO àti ọlọ́pàá mẹ́ta míràn Ọlọ́pàá gba àna ADC Buhari silẹ̀ lọ́wọ́ ajínigbé Wọ́n lu àbúrò mi ló jẹ́ kí ń fi ìbínú lu òǹtàjà l‘Abuja - Sẹ́nétọ̀ tó lu obìnrin ṣàlàyé 'Èèyàn mi mẹ́ta ló wà nínú ọkọ̀ ojú omi tó dà nù l'Eko!
Eliabu bí Nemueli, Datani ati Abiramu.
Eyi si lo fa sababi pe a nilo aabo abẹle.
Fún wákàtí mẹ́rìndílógún gbáko ni òkùnkùn ṣú biribiri, ìyẹn ní Ígíláàndì ní’hàhín.
Wọ́n fọn fèrè, wọ́n sì fọ́ àwọn ìkòkò tí ó wà lọ́wọ́ wọn mọ́lẹ̀.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Galiiki dara fun ilera lootọ, ko le dena arun coronavirus.
Àkọlé àwòrán, Ko si ohun ta mu wa saye, ko si ohun ta mu lọ sọrun.
Bakannaa, iwe ti wọn kọ si Festus Keyamo ko s'alaye ẹni to paa l'asẹ ati gbe Danladi Umar lo si ile ẹjọ.
 Ìtọ ́ jú a má a rọrùn síi nígbàtí a bá ṣàkíyèsi àrùn náà lásìkò àti ṣáájú àkókò tí àwọn ààmì àìsàn iṣan ara yóò bẹ ̀ rẹ ̀ sí farahàn .
Bí ẹ tilẹ̀ rú ẹbọ sísun ati ẹbọ ohun jíjẹ yín sí mi, n kò ní gbà wọ́n, bẹ́ẹ̀ ni n kò ní fojú rere wo ẹran àbọ́pa tí ẹ mú wá bí ọrẹ ẹbọ alaafia.
Ọ̀gá ọlọ́pàá tó wà ní 'Check Point' kàgbákò ikú òjijì lọ́wọ́ awakọ̀ l'Eko Olanrewaju Bamidele fi 'Screw driver' gún ìyáwo rẹ̀ pa Mobile Wash: iṣẹ́ mọ́tò fífọ́ ni mó yàn láàyò- Slay Mama Bakan naa bii eeyan ogun lo fara pa ṣugbọn ti wọn tọju wọn loju ẹsẹ nibi iṣẹlẹ naa.
Ninu ẹ̀yà Reubẹni, tíí ṣe àkọ́bí Israẹli, àwọn tí wọ́n jẹ́ ẹni ogún ọdún sókè, tí wọ́n tó lọ sójú ogun, gẹ́gẹ́ bí àkọsílẹ̀ wọn ní ìdílé-ìdílé 
"O daju wipe itaniji ati awọn elere idije bọọlu Tennis ti yoo tipasẹ bẹẹ jade yoo dara pupọ fun idagbasoke ere idaraya naa l'Afirika"" Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Serena: orilẹede Kenya lo wa lọkan oun lati ṣe e Nigba ti wọn bii siwaju sii wipe orilẹede wo ni yoo fẹ lati gbe idije bẹẹ lọ, Serena ni 'orilẹede Kenya lo wa lọkan oun lati ṣe e'."
6 milion Naira 15 Òkùdu 2019 Akojọpọ awọn aworan to lamilaaka: Oríṣun àwòrán, @mko_abiola Àkọlé àwòrán, Ọjọbọ ọsẹ yii ni orilẹede Naijiria se Ayajọ Ọjọ ominira Naijiria lati fi da Oloye Moshood Kashimawo Ọlawale Abiọla lọla.
Ranti ìyà ati ìbànújẹ́ mi,ati ìrora ọkàn mi!
" Akinbinu tẹsiwaju pe O ṣeṣe ki ọpọ ninu awọn to n ba gomina Akeredolu ṣiṣẹ tẹle igbakeji rẹ lọ sinu ẹgbẹ oṣelu PDP"" O ṣalaye pe Agboola Ajayi ko ba má jẹ nkan ni ipinlẹ Ondo ti kii ba ṣe ti gomina Rotimi Akeredolu."
''Pẹlu bi a ti ṣe n koju Covid-19, ijamba omiyale naa to ba ṣẹlẹ ko ni jẹ ki nkan rọrun rara'' Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Isheri Flood: Àwọn olùgbé Isheri ń sanwó fún ọkọ̀ ojú omi láti rìn ní àdúgbò Ọga NEMA wa salaye pe awọn ti bẹrẹ si ni ko ounjẹ pamọ de asiko omiyale nitori awọn ko mi iru akoba ti o le ṣe fara ilu.
Baba iyawo rẹ̀ wí fún un pé, “Mo rò pé lóòótọ́ ni o kórìíra iyawo rẹ, nítorí náà, mo ti fi fún ẹni tí ó jẹ́ ọrẹ rẹ tímọ́tímọ́, ninu àwọn ẹlẹgbẹ́ rẹ.
Awọn afunrasí ọ̀daràn náà, tí wọ́n kéde orúkọ wọn gẹ́gẹ́bíi Kazeem Abdulsalam, ọmọ ọdún mẹ́rìnléláàádọ́ta, tó wá láti ìlú Omù àrán pẹ̀lú Adamu Hussein láti ìlú Ilọrin, lọ́wọ́ àwọn agbófiró àbò-ara-ẹni-làbò-ìlú, Civil defence tẹ̀, ní ibùba ìjínigbépa wọn tó wà ní ìletò Afọn Ọ̀lẹ́yọ̀ ǹípínlẹ̀ Kwara.
Kunle Olajide ni Ìjọba tó ń tẹ̀lé òfin kò ní wu ìwà tí Buhari ń wù Oríṣun àwòrán, @MBuhari Awọn ọmọ Naijiria kan tun ti sọ ero ọkan wọn lori ọrọ ti Aarẹ Muhammadu Buhari ba wọn sọ lẹyin rogbodiyan to waye nitori iwọde EndSARS.
Sowore pàtẹ ìfẹ̀hónú hàn míì lónìí Oríṣun àwòrán, @yelesowore Oludije fun ipo aarẹ ati asaaju ẹgbẹ ajafẹtọ ẹni Revolution Now, Omoyele Sowore ti fi sita pe akọtun iwọde miran ti bẹrẹ kaakiri awọn ipinlẹ Naijiria.
Wọn yóo wọ aṣọ mìíràn kí wọn má baà sọ àwọn eniyan náà di mímọ́ nítorí ẹ̀wù wọn.
O sọ fun akọroyin kan, Joab Chakhaza lasiko ifọrọwanilẹnu kan lọdun 2017 pé lootọ lo ni afojusun lati di dokita, nitori o gbagbọ pe oun ko nilo lati ba ipejọpọ ọpọ eniyan sọrọ nípa jíjẹ oṣiṣẹ eto ilera, nitori o jẹ ẹni to maa n tijú.
Ka ṣáà dúpẹ pé, kò sí èmí to ba isẹlẹ naa rin.
Minisita fọ́rọ̀ ilẹ̀ òkèèrè kọ̀wẹ́ fipò sílẹ̀ Aláàfin Ọyọ pé ọdún 48 lórí àpèrè Orílẹ́-èdè 5 tí takọ-tabo kò gbọdọ̀ fẹnu ko ara wọn lẹ́nu Ki lo n ṣẹlẹ pẹlu ẹgbẹ alatako?
Iroyin naa si lo gba ori ayelujara kan lati bii ọjọ melo kan, ti Risikat ti kígbe sita nipa iriri rẹ naa loju opo Facebook.
Àwọn èrò ọ̀nà kò sì ní kí ẹni tí ń gé e pé:“OLUWA óo fèrè síṣẹ́ o!
Nibi ayẹyẹ naa ni Igboho ti sọ pe akoko ti to fun awọn ọmọ Yoruba lati parapọ sisẹ ni ọkan soso.
Gani Adams gb'oriyin fun'pinlẹ Eko lori igbelarugẹ ede Yoruba
ati àwọn olórí mẹ́wàá; wọ́n yan olórí kọ̀ọ̀kan láti inú ìdílé Israẹli kọ̀ọ̀kan, olukuluku wọn sì jẹ́ baálé ninu ìdílé wọn.
Ẹ ṣe àyẹ̀wò wi wé gèlè Aṣọ-Òkè ninú àwòrán àti àpèjúwe ojú iwé yi:
Asaheli bẹ̀rẹ̀ sí lé Abineri lọ, bí ó sì ti ń lé e lọ, kò wo ọ̀tún, bẹ́ẹ̀ ni kò wo òsì.
Wọ́n sún ìsìnkú Abiola Ajimobi di ọ̀la Satide Iroyin to n tẹ wa lọwọ bayii ti fihan pe eto isinku oloogbe Sẹnatọ Abiola Ajimobi to yẹ ko waye loni ni wọn ti sun siwaju.
INEC fún Obaseki ní ìwé-ẹ̀rí moyege gẹ́gẹ́ bí gómìnà tí wọ́n ṣẹ̀ṣẹ̀ dìbò yàn Ìjọba Katsina ní kí àwọn iléèwé wà ṣì ní títìpa nítorí arùn Coronavirus Lawuyi Ogunniran, àgbà ọ̀jẹ̀ òǹkọ̀wé Eégún Aláré dágbére fáyé!
Ni wọ́n bá lọ sí ìletò mìíràn.
Oríṣun àwòrán, Thailand DNP Àkọlé àwòrán, Erin mẹ́fa d'olóògbé níbi tí wọ́n ti fẹ́ dóòlà ẹ̀mí ara wọn Awọn oṣiṣẹ ọgba ẹranko lorilẹ-ede Thailand sọ pe awọn kan lo ṣaa deede pe akiyesi awọn lọjọ Abamẹta to kọja si awọn erin ti wọn duro soju ọna to lọ si ibi ida omi ọhun.
Ọga Bello ni, aigbọn lo n da ọpọ wọn laamu, ti oun si maa n ba wọn da si aawọ naa nigba mii.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ìtàn rèé nípa bí Ogbomoso ṣe pa ọba, yọ nǹkan ọkùnrin rẹ jó kiri ìlú Alámì ẹ̀yẹ Scrabble Paul Sodje àti ọ̀rẹ́ rẹ́ kú lásìkò tó fẹ́ lọ́ sanwó ìdóòlà ẹ̀mí àbúrò rẹ̀, tí afurasí darandaran jí gbé Ìjàmbá iná míràn tún wáyé ní pápákọ̀ ojú omi Beirut Ẹ fi dókítà àgùnbánirọ̀ rọ́pò àwọn dókítà tó ń yanṣẹ́ lódì - Ìjọba àpapọ̀ pàṣẹ Afenifere fara ya lórí bí Tinubu ṣe jókòó kí Ooni Háà ilẹ̀ wẹ!
Aare Koroma gori alefa ni odun 2007 labe asia egbe oselu All People’s Congress (APC),bakan naa ni o tun jawe olubori ninu eto idibo ti o waye ni odun 2012 fun saa elekeji.
"Ọkọ kan lo gba kẹkẹ ti mo wa ninu rẹ lati ẹyin, ti a si fi ori sọ ọkọ akolẹ-ko idọti PSP to n bọ niwaju.
Ó sọ fún iranṣẹ rẹ̀ pé, ‘Tètè lọ sí gbogbo títì ati ọ̀nà ẹ̀bùrú ìlú, kí o lọ kó àwọn aláìní, àwọn aláàbọ̀ ara, àwọn afọ́jú, ati àwọn arọ wá síhìn-ín.
Atẹjade kan ti ileesẹ aṣojú ìjọba Amẹ́ríkà fisita ni Ọjọru lo sísọ lójú ọ̀rọ̀ yìí pẹlu àfikún pé, ọgọ́jọ mílíọ̀nù àti méje dọla ($167m) ni Abacha ko pamọ sì ilẹ̀ Faranse nígbà tí mílíọ̀nù mejilelaadọjọ dọla ($152m) miran tún wà ní ilẹ̀ UK, tí wọn sì ti gbé ọ̀rọ̀ náà lọ sile ẹjọ́.
Ọjọ ibo ṣi jina, oju ree iran re lọrọ to wa nilẹ yi.
Ọ̀tọ̀ ni wọ́n kọ́ ilé fún un tí ó ń dá gbé; nítorí wọ́n yọ ọ́ kúrò ninu ilé OLUWA.
Akọwe rẹ, Smith Toby sọ fun BBC ni ọjọru ọsẹ wi pe ṣe ni awọn ri ejo dudu meji ninu ọfiisi ẹka to n ri si ọrọ ilẹ okeere tii ṣe ibi to jẹ ọfiisi naa gangan.
Oludari eka oro ifitonileti NAF, balogun Olatokunbo Adesanya naa fikun-un pe,  “nini oye iforotonileti yoo tun mu adinkun ba siso iroyin wa, ti ko si ni fi ayesile fun asodun tabi afikun oro.
Kika ọjọ ti o forukọ silẹ, nọmba ẹrọ alagbeka rẹ ati atẹranṣẹ lati ọfiisi JAMB yóò wọle.
Ni ayé àtijọ́, àṣà ṣì ṣúpó wọ́pọ̀ ni Ilẹ̀ Yorùbá.
Sotitobire church: Àwọn ọ̀dọ́ ilu dáná sun ilé ìjọsìn
kopa dara-dara to ninu idije ohun, sugbon iwonba ipa re to fun Rohr lati pe ki
Tẹra mú Abramu ọmọ rẹ̀, ati Lọti, ọmọ Harani tíí ṣe ọmọ Tẹra, ati Sarai aya Abramu, ó kó gbogbo wọn jáde kúrò ní Uri ti ilẹ̀ Kalidea, wọ́n ń lọ sí ilẹ̀ Kenaani.
60 -55 ni wọn fi fagbahan ikọ Senegal to gbalejo idije naa nibi ti o le ni ẹgbẹrun mẹẹdogun oluworan ti kopa.
Se lawọn ọmọde ati agba, alaboyun ati awọn iyalọmọ, to fi mọ awọn arugbo n sa asala fun ẹmi wọn, ti awọn to si laya lati beere pe ki lo fa isẹlẹ naa, jẹ ajẹkun iya.
Ohun kan ṣoṣo tí ó wà ninu àpótí náà ni tabili meji tí Mose kó sibẹ ní òkè Horebu, níbi tí Ọlọrun ti bá àwọn ọmọ Israẹli dá majẹmu nígbà tí wọ́n jáde kúrò ní Ijipti.
Àgbò Man City tó tàdí mẹ́yìn fi ìkanra na Watford bolẹ̀
 Ṣugbọn, ọga patapata fun ẹgbẹ SDS, Arabinrin Safiya sọ pe irọ ni ẹsun naa."
Ọ̀nà tí a fi mọ̀ pé a wà ninu rẹ̀ nìyí 
4 4,973 South Sudan 63 0.
OLUWA Ọlọrun Israẹli bà fi Sihoni ati gbogbo àwọn eniyan rẹ̀ lé Israẹli lọ́wọ́, Israẹli ṣẹgun wọn, wọ́n sì gba ilẹ̀ àwọn ará Amori tí wọ́n ń gbé agbègbè náà.
àwọn tí ọ̀nà wọn wọ́,tí wọ́n kún fún ìwà àrékérekè.
Ni bayii, olori ile aṣofin ipinlẹ Ondo, Bamidele Oloyelogun ati igbakeji rẹ, ti wọn yọ kuro nipo atawọn aṣofin mẹwa to jẹ tirẹ ti so ijoko ile aṣofin naa rọ di ọjọ miran ọjọ ire.
 Wọn ni niwọn to jẹ pe awọn eniyan kan ti ni iru eto madanidofo eto ilera bayii, ko yẹ ki o jẹ dandan fun gbogbo ara ilu nitori yoo ja si sisan owo bẹẹ lẹẹmeji tabi jubẹẹ lọ.
Ann Grace Aguti: Obìnrin kan to fẹ́ ọkọ mẹ́ta lẹ́ẹkàn ṣoṣo
Oríṣun àwòrán, Aishabuhari Àkọlé àwòrán, Aisha Buhari: ọ̀rọ̀ yìí kọnilóminú púpọ̀ Aisha Buhari sọ ninu atẹjade kan lori Instagram pe ki awọn agbofinro, aṣofin ati awọn tí o n ṣe oogun sọ ọrọ naa di ija ti awọn funra wọn yoo ja lati dẹkun ilokulo oogun.
A ti kọ àwọn ohun ìkọ̀kọ̀ tíí máa ti eniyan lójú sílẹ̀.
Nítorí náà ni àwọn eniyan fi ń rìn káàkiri bí aguntan tí kò ní olùṣọ́.
Ó bá mú ọmọde kan, ó gbé e dúró lẹ́gbẹ̀ẹ́ rẹ̀.
O so pe “oloogbe Mustapha Akanbi je olukose rere fun awon musulumi, ati eto idajo .
Nígbà tí ilẹ̀ mọ́, ó pe àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀, ó yan àwọn mejila ninu wọn, tí ó pè ní aposteli.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Waste to Wealth: Ẹ̀gbin tìrẹ ni èròjà táwọn èèyàn míràn fi n ṣiṣẹ́ ajé, okoòwò ńlá ni Ijakulẹ yii ni igba kẹrin ti ikọ agbabọọlu Livepool yoo fidi rẹmi ninu ifẹsẹwọnsẹ mẹfa ọtọọtọ amọ wọn si ni pọnti mẹẹdọgbọn lati wa loke idije liigi premier.
O soro lori afihan awon ise re tuntun to pe ni “ipade India nilu Abuja” pe o je ise irufe ti mosaic to  gba oun ni osu meji lati pari.
15 Èbibi 2019 Oríṣun àwòrán, Patrick van Katwijk Àkọlé àwòrán, Emir Muhammadu Sanusi jẹ gómìnà báǹkì àpapọ̀ Nàìjíríà láàrin 2009-2014kó to dí Emir ìlú Kano Ìròyìn tó gbòde láìpẹ yìí lóri ìpinu ìjọba láti pin ààfin ọba to tóbi jùlọ ni orílẹ̀-èdè Nàjíríà ìyẹn pínpín ọba jíjẹ si ọ̀nà márùn ni ìpínlẹ̀ Kano ní o ti ń mú onírúurú àwọn awuyewuye jẹyọ láàrín ọmọ Naijíríà, ti ọ̀pọ̀ sì ń sọ pé èté ìjọba lásán ni láti sọ ọbá ìpínlẹ̀ Kano Muhammed Sanusi dí aláìlágbára bí àwọn ènìyàn ṣe ni ìgbàgbọ́ pé kìí fi ọ̀rọ̀ sábẹ ahọn sọ fún ìjọba tó ń bẹ lóde ni ìpínlẹ̀ Kano.
 Ṣaaju ọdun 2018, mo ri pe awọn eeyan maa n ta wọn sẹyin, idi ree ti mo ṣe fi ara mi jin lati maa gbọ tiwọn.
“Ẹni tí ó bá ní etí láti fi gbọ́ràn, kí ó gbọ́!
4m òògùn ikọ́ codeine Ẹ̀wọ̀n ọdún méjì fún awọ̀n tó ń lo Codeine Ọmọ Nàíjíríà tako Nafdac lórí ọ̀rọ̀ Codine Tramadol tó ń polówó ikú tantan-tan Aṣe awọn oṣiṣẹ ijọba kan tun wa to n lo aṣẹ ọba lati fòntẹ̀ jan ki awọn alagbata maa ta ogun yii lọna aitọ.
Ẹni to bori: Mauritania Tunisia vs Algeria.
Ayédèrú òògùn ààrùn onígbáméjì tó wà ní ta rèé Àjọ INEC ti bẹ̀rẹ̀ ìkéde èsì ìdìbò gómìnà ìpínlẹ̀ Rivers Ahmed Musa gbàmì ẹ̀yẹ agbábọ́ọ̀lù tó pegede ní ọdún 2018 Ẹ̀ wo bí àwọn ẹ̀ṣọ́ ojú etí òkun ṣe ń ṣiṣẹ́ l'Eko Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Okùnrin SARS náà sọ pé òun máa pa èèyàn síbi ni- Aladugbo Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Ìyanṣẹ́lódì òṣìṣẹ́ ilé aṣòfin bẹ̀rẹ̀ ní pẹrẹwu nílé aṣòfin Nàìjíríà Abiyamọ ju abiyamọ lọ ni ọ̀rọ̀ Sima Sarkar Agbébọn pa ènìyàn 14, ọmọọ̀gun Naijiria sígun ni Kaduna Fayemi: Gbèsè tí mo bá nílẹ̀ ni kò jẹ́ kí n ti yan kọmíṣọ́nà Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí kan sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
Iye tí ó bá tó gan-an ni kí o tà á fún mi, kí àjàkálẹ̀ àrùn yìí lè dáwọ́ dúró.
” Wọ́n bá fi aṣọ mímọ́ wé e lórí, wọ́n wọ̀ ọ́ ní aṣọ funfun, angẹli OLUWA sì dúró tì í.
Mo yọ̀ púpọ̀ pé mmo mọ̀ ọ́ lónìí, ọ̀rọ̀ tí ìwọ sì sọ ń bẹ ni ìsàlẹ̀ odò ikùn mi.
 Ṣé ṣaájú àsìkò yìí lòun pàápàá ti gbìyànjú , tó ti nawọ ́ fífẹ ́ sí jìjì , àmọ ́ tónítibi kì í ṣe bí ẹni rí i .
Àbí ẹni tí ó dá ojú, ni kò ní ríran?
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Coronavirus: 'Gbogbo àgbáyé gbọ́dọ̀ pawọ́pọ̀ láti borí àrùn Coronavirus' 12 Ẹrẹ̀nà 2020 Àkọlé àwòrán, Ènìyàn méjì ló tí lùgbàdì àrùn náà lórílẹ̀ède Naijiria, tó sí ti pa ẹgbẹgbẹrun ènìyàn káàkiri àgbáyé.
Pẹlu eyi, yoo mu iwọn oju ọjọ walẹ si 53C (-64F).
APC Kogi Primaries: Yahaya Bello la àwọn olùdíje mẹ́sàn án mọ́lẹ̀ fún àṣíá gómìnà ìpínlẹ̀ Kogi
Àwọn tí wọ́n mọ́ lójú ara wọn,ṣugbọn a kò tíì wẹ èérí wọn nù.
Ṣugbọn OLUWA mú kí ọkàn Farao le, kò sì gbọ́ tiwọn, gẹ́gẹ́ bí OLUWA ti sọ fún Mose.
Gbogbo nǹkan yòókù tí Baaṣa ṣe, ati gbogbo iṣẹ́ akikanju rẹ̀, ni a kọ sinu Ìwé Ìtàn Àwọn Ọba Israẹli.
Ninu ọpọlọpọ òwò tí ó ń ṣe, o bẹ̀rẹ̀ sí hu ìwà jàgídíjàgan, o sì dẹ́ṣẹ̀, nítorí náà mo lé ọ jáde bí ohun ìríra kúrò lórí òkè Ọlọrun.
O ni awọn ounjẹ ti o maa n ṣafikun eroja ìmúfẹ̀ẹ́ laarin ololufẹ meji ti wọn ti fidiẹ mulẹ pe o nii ṣe pẹlu owo ati aṣeyọri.
Ta ni Daura DSS tó ń bi oriṣii awuyewuye yìí?
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: A kọ òfin gígé nǹkan ọkùnrin tó bá fipá bá obìnrin lòpọ̀ - Àwọn Alfa yarí Agolo gáásì kéeké tó ń jò bú gbàmù l‘Eko, ẹ̀mí kan bọ́, mẹ́ta fara pa Ewé ṣunko!
Ìyẹn ni pé ìgbà ọ̀gìnìntìn ti ré kọjá, a ti bọ́ sí ìgbà ọ̀tun.
Jesu wí fún un pé, “Èmi ni ajinde ati ìyè.
Ashade so pe, eka ile-ise ipese nnkan ti jiya lopolopo lasiko teto oro aje orile-ede denu-kole, ati pe, pupo awon ile-ise ni won kogba wole, ti ogoro eniyan si padanu ise won.
Bẹ́ẹ̀ ni nǹkan náà rí jágbajàgba réderède, nítorí Ọlọ́run Ọba kò dá nǹkan tí àwọn ọmọ ènìyàn ń béèrè wọn-ọnnì mọ́ wọn.
Eto idibo ipele kinni, ti a o ti dibo
"Wọn ni: ""Hushpuppi ati awọn yooku rẹ lo ọgbọn ẹwẹ lati tan ẹka kan nilee amofin naa, Wọn ni pe ki wọn o san owo kan ti ọkan lara awọn oníbàráà wọn fẹ ẹ fi ra ile si aṣunwọn banki kan ti oun ati awọn yooku rẹ n mojuto""."
Àìní wá ṣùgbọ́n ìyàwó-o rẹ̀ Àkísà kò le-è wá nítorí Òṣì ọ̀rẹ́-ẹ rẹ̀ ńṣe ọjọ́ ìbí.
Gaya Melon Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, O le fa ikú ti ènìyàn ba n jẹ ni gbogbo igbà Èyí dàbi bara ègúsí ti a ri ni orílẹ̀-èdè Indonesia.
Esaradoni ọmọ rẹ̀ bá jọba lẹ́yìn rẹ̀.
Ko tan sibẹ o, owo eporọbi naa le ma duro soju kan, o tun ṣi le ja walẹ si.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Hisbah Kano fi òfin de lílo èdè 'Black Friday', àwọn ọmọ Naijiria kan yarí lórí ayélujára 27 Bélú 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 29 Bélú 2020 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àjọ Hisbah tó jẹ́ ọlọ́pàá Sharia ní Kano kọ lẹ́tà ìkìlọ̀ lórí lílo èdè 'Black Friday'.
ohun ro gbogbo gomina ekun Gusu ohun, lati fi oselu sile ki won si  fowosowopo lati wa ojutuu si eto aabo ,eleyii
"Ko si ipinlẹ kankan to ti bọ yanyan lọwọ arun COVID-19, ko si nkankan.
N óo fún gbogbo àwọn ọba Arabia mu ati gbogbo àwọn ọba oríṣìíríṣìí ẹ̀yà tí wọn ń gbé aṣálẹ̀.
Ọjọ kẹẹdọgbọn, osu keje, ọdun 1969 ni Israel Adebajo dagbere faye!
Wọ́n fi ẹ̀sùn kàn án pé ó pa aṣọ́gbà tí ń ṣọ́ ilé àlùfáà yìí.
O ni bi awọn ṣe n ta epo ni owọngogo naa n kopa buburu lori eto iṣuna awọn nitori yoo kan ẹbi, ara ati ọrẹ awọn to n ta epo naa.
Ètò láti fi Òpin sí Igbeyawo láàrin àwọn Juu ati àwọn tí Wọn kì í ṣe Juu.
Ẹ gbẹ́kẹ̀lé e nígbà gbogbo, ẹ̀yin eniyan;ẹ tú ẹ̀dùn ọkàn yín palẹ̀ níwájú rẹ̀;OLUWA ni ààbò wa.
Ọ̀rọ̀ tí Solomoni Bá Àwọn Eniyan Sọ.
Bi iye awọn eeyan to ṣẹṣẹ ko arun naa nipinlẹ kọọkan ni Naijiria ṣe lọ ree: Lagos-697 FCT-201 Nasarawa-80 Plateau-74 Rivers-72 Edo-46 Adamawa-43 Osun-39 Akwa Ibom-35 Delta-31 Anambra-27 Oyo-24 Kano-21 Abia-19 Enugu-19 Ogun-18 Sokoto-12 Bauchi-7 Taraba-7 Ekiti-4 Gombe-4 Imo-4 Bayelsa-2 Jigawa-2 Zamfara-1 Èèyàn mẹ́sàn án kú, 1,398 míràn tún lùgbàdì Coronavirus ní Nàìjíria Oríṣun àwòrán, @Chikwe_I Ajọ to n gbogun ti ajakalẹ aarun lorilẹ-ede Naijiria, NCDC ti kede pe eeyan 1,398 miran ti kun iye awọn to ti ni aarun COVID-19 ni Naijiria.
Bi won ba ko lati sika adẹhun ti wọn se pẹlu wa, awọn ile iwosan ìjọba ìpínlè àti ìbílẹ̀ naa yóò darapo mọ iyansẹlodi náà.
Oríṣun àwòrán, MOD Àkọlé àwòrán, Awọn ẹṣọ ologun DI Coldstreams gbe asia orilẹede mẹtalelaadọta to jẹ ọmọ ẹgbẹ́ Commonwealth Gẹgẹ bi iroyin ti iwe iroyin Daily Telegraph to kọkọ gbe iroyin igbanisiṣẹ ọhun sita l'ọjọ Aje ti wi, ileeṣẹ ologun oju ofurufu ati ori omi, yoo bẹrẹ eto igbanisiṣẹ ti wọn loju ẹsẹ, ti ileeṣẹ ologun ori ilẹ yoo si bẹrẹ ti ẹ ni ibẹrẹ ọdun 2019.
Ó wà ninu ipò ẹrú pẹlu àwọn ọmọ rẹ̀.
Ṣugbọn ọpọ awọn ọmọ Naijiria lo ti bẹrẹ si n sọ ero wọn lẹyin ti atẹjade ọhun jade lori ayelujara, bi awọn kan ṣe n sọ pe ootọ ni Obasanjo sọ, lawọn mi n sọ pe agbalagba kii sọrọ tan lẹnu.
Ọrọ ifipabanilopọ ṣi n peleke sii ni Naijiria, ti wọn si n ri iru isẹlẹ yii kaakiri igun orilẹede.
Ipongbe fun awon arinrinajo ti won n bo sile Isreal lasiko odun ajinde lo ta awon olori elesin Kristi ji pe ki won fi si ijo mimo naa pelu ifehonuhan to waye tele.
“Rán ẹ̀wù ati àmùrè, ati fìlà fún àwọn ọmọ Aaroni fún ògo ati ẹwà.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Asisat Oshoala: ìbẹ̀rẹ̀ mi kò rọrùn rárá nínú eré bọ́ọ̀lù Aarẹ CAF, Ahmad Ahmad ni ẹnu ti n kùn loriṣiiri'sii lori ẹsun ni eyi ti oun naa ti ni oun ko jẹbi wọn.
Àṣẹ bá jáde láti Susa, wọ́n sì so àwọn ọmọ Hamani rọ̀ sí orí igi.
Awọn ọmọ Naijiria kan lo fi oju laifi wo igbesẹ naa lori ayelujara, ti wọn si ni igbesẹ arufin gbaa ni Makinde gbe, pẹlu bo se fi ontẹ lu isinku Ajimobi sori ilẹ GRA.
O sọ pe pupọ ninu wọn yoo kan darukọ ileeṣẹ iroyin to ba wu wọn, lati le ni anfaani lati wọ ile aṣofin lati tọrọ owo, jale tabi yẹyẹ awọn aṣofin.
Ní ọjọ́ kan, níbi tí ó ti ń mu ọtí àmupara ní ilé Arisa, alabojuto ààfin, ní Tirisa, 
Sugbọn bi onirese Daniel Ọlọrunfẹmi Fagunwa ko ba fingba mọ, awọn eyi to ti fin silẹ, ko lee parun.
Lẹyìn tí mo figbe ta, INEC mú PVC mi wá bá mi nílé - Gani Adams Ṣaaju ọjọ oni, awọn akopa ti forukọ silẹ rẹpẹtẹ lori itakun ti BBC Yoruba fi silẹ loju opo wọn.
Oríṣun àwòrán, @yinkaayefele/@tolanialli Àkọlé àwòrán, Yinka Ayefẹlẹ ní àwọn olóṣèlú ló ní kí Gómìnà Ajimọbi wó iléèṣẹ́ rédíò òun Gbajugbaja olorin ni, Yinka Ayefẹlẹ ni kọmisana fun eto iroyin ati aṣa nipinlẹ Ọyọ, Toye Arulogun lo wa nidi bi ijọba ṣe fẹ ẹ wo ileeṣẹ igbohun s'afẹfẹ oun, Fresh FM, to wa nilu Ibadan.
Ṣaaju ki Akufo-Addo to o pe Aarẹ Buhari, ọwọ tẹ awọn afurasi kan, wọn yoo si gbe wọn lọ si ile ẹjọ.
1 lowó àdéhùn tó wà láàrin wa àti Buhari, kìí ṣe bílíọ́nù N208
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Makinde: Ẹgbẹ́ òṣìṣẹ́ faramọ́ wíwọ́gilé ₦3000 táwọn akẹ́kọ̀ọ́ girama ń san Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Makinde: Ẹgbẹ́ òṣìṣẹ́ faramọ́ wíwọ́gilé ₦3000 táwọn akẹ́kọ̀ọ́ girama ń san 30 Èbibi 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 31 Èbibi 2019 Tilu tifọn ni awọn osisẹ nipinlẹ Ọyọ fi n ki gomina tuntun, Onimọ-ẹrọ Seyi Makinde kaabọ si ọọfisi ni aarọ Ọjọbọ.
ati gẹgẹ bi ilu-nla karun-un ti ọrọ-aje rẹ gbooro  julọ ni ilẹ Afirika.
A yọ awọn ijọba ibilẹ mẹfa to wa lẹkun Ijẹsa kuro lara agbegbe ta n pin ina ọba de, titi ti wọn yoo fi se awari awọn eeyan to kọlu awọn osisẹ wa."
N óo bá àwọn tí ó ń bá ọ jà jà,n óo sì gba àwọn ọmọ rẹ là.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Arsenal vs Manchester United: Arsenal borí i Manchester United ní Premier league 10 Ẹrẹ̀nà 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Arsenal lo fi o to gẹẹ si irinajo olubori ti Manchester United ti bẹrẹ si nii rin lati igba ti olukọni wọn, Ole Gun Solkjaer ti gba iṣẹ Ẹgbẹ agbabọọlu Arsenal gbo ewuro si oju Manchester United lọjọ aiku ninu ifẹsẹwọnsẹ Premier league ilẹ Gẹẹsi to waye ni papa iṣire Emirate.
Idaraenilebi wọpọ lori isuna ọdun 2018 laarin ijoba ati awọn asofin.
“Ṣugbọn nisinsinyii àwọn tí wọ́n kéré sí mi ń fi mí ṣe ẹlẹ́yà,àwọn tí baba wọn kò tó fi wé àwọn ajátí ń ṣọ́ agbo ẹran mi.
 Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Obateru Akinruntan: Wíwá ohun tá jẹ títí láé ló gbé wa kúrò nílé Ife Ti Fayose ba to bẹẹ, ko bọ si aarin wa nilu Eko, ko maa bọ, yoo ri ẹẹkẹ rẹ lai gbe digi, ọmọ ọdun melo lo wa nigba temi se gomina lọdọ wọn, awa maa tun kọ ni Eko, tori Fayose gọ, o si fi ẹnu họra, wọn ko si bi re.
Nígbà tí ó ṣe a yọ sí ilé Ikú, a ń wwo ilé ná lọ́kàn-án-kan, nígbà tí mo sì súnmọ ọn mo rí òkìtì ńlá méje tí ó bá ojú ọ̀run lọ wọ́n kún fún egungun.
Bo tilẹ jẹ pe awọn miran n ku lataari awọn aisan to ti wa lara wọn tẹlẹ.
Eyi lo fa owe: a sọ ọmọ ni Sódé, o lọ sajo o dé; A sọ ọmọ ni Ṣóbọ̀, o lọ sajo, o bọ̀; A wa sọ ọmọ ni Ṣorinlọ, ko wa pada wa sile mọ!
Nínú ọ̀rọ̀ tirẹ agbẹnusọ ilé iṣẹ́ ọlọpàá ní ìpínlẹ̀ Eko Bala Elkana sàlàyé pé, okú ti wọ́n ri yìí lo dá rúkèrúdò sílẹ̀ ní agbègbè náà àti pé ilé iṣẹ́ ọlọ́pàá ṣì ń wá Eze.
Kayefi: Dókítà ló ṣe iṣẹ́ abẹ tó pa ìyàwó mi láì gba àṣẹ lọ́wọ́ mi Èèmọ̀ rèé o!
O ni awọn ó lé awọn ikọ̀ agbesunmọmi ọun de ibikibi ti wọn ba lọ.
"Ikọ̀ ìwádìí BBC ṣí àwọn tó ń jí ìkókó gbé sí gbangba Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Lady Peller: Ọjọ́ ni ọjọ́ tí idán yíwọ́ fún ọkọ mi lẹ́yìn tó gé mi sí méjì, mo kú tán15 Bélú 2020 Yoruba World Assembly: Ìlú Ibadan ni wọ́n tí ṣe àgbẹ́kalẹ̀ ẹgbẹ́ ọmọ Yorúbá tuntun16 Bélú 2020 End SARS protest: Nítorí ""Access Bank"" gbẹ́sèlé owó àwon olùwọ́de EndSARS ni a ṣe kó owó wa kúrò níbẹ̀17 Bélú 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!"
Ta ni ẹ̀ ń ya ẹnu ní ìyàkuyà sítí ẹ yọ ṣùtì sí?
OLUWA pàṣẹ fún wolii kan, ará Juda, pé kí ó lọ sí Bẹtẹli; nígbà tí ó débẹ̀ ó bá Jeroboamu tí ó dúró níwájú pẹpẹ láti sun turari.
Oniruuru nlkan si ni wọn fi maa n se akawe ọrọ bii owe, akanlo ede, afiwe ati awọn isẹlẹ miran to kọ ni lọgbọn.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ghana Floods: Èèyàn méje pàdánú ẹ̀mí wọn nínú ìjàmbá ẹ̀kún omi 15 Ìgbé 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ẹkun omi ni Ghana Ojo arọọrọda ti gbẹmi eeyan meje niluu Accra tii ṣe olu ilu orilẹ-ede Ghana.
” Nítorí pé gbogbo wọn ni wọ́n ń sọkún nígbà tí wọn ń gbọ́ ọ̀rọ̀ inú òfin náà.
Nigba to n fidi iṣẹlẹ ọhun mulẹ, agbẹnusọ ọlọpaa, DSP Onome Onowakpoyeya sọ pe ṣaaju ni afurasi naa ti kọkọ sẹ pe ohun ko mọ ohunkohunn nipa ẹsun naa, ṣugbọn o jẹwọ lẹyin to foju gan ni aworan ara rẹ lori CCTV.
Ekiti Election: Ǹkan mẹ́wàá tó yẹ kí o mọ̀ nípa Kayọde Fayẹmi
Bí Ọlọrun kò bá dín àwọn ọjọ́ náà kù ni, ẹ̀dá kankan kì bá tí là.
Àwọn ọmọ Adonikamu jẹ́ ẹgbẹta ó lé mẹrindinlaadọrin (666)
Ó ní, “Baba mi, bí kò bá ṣeéṣe pé kí ife kíkorò yìí fò mí ru, tí ó jẹ́ ohun tí ó níláti ṣẹlẹ̀ sí mi, ìfẹ́ tìrẹ ni ṣíṣe.
Lẹ́yìn náà, àwọn alufaa gbé Àpótí Ẹ̀rí OLUWA wá sí ààyè rẹ̀ ninu ibi mímọ́ ti inú, ní Ibi-Mímọ́-Jùlọ, lábẹ́ ìyẹ́ àwọn kerubu.
Amọ, awọn eniyan 103 lo ri iwosan gba lọwọ arun naa ni Ọjọ Iṣẹgun ohun.
Olùrànlọ́wọ́ pàtàkì fún ọ̀rọ̀ ibojì òkú, àti àwọn ipò òṣèlú mìíràn tó jẹ́ kàyééfì ní Nàìjíríà Buruji Kashamu jẹ́ ènìyàn tó nífẹ̀ aráàlú- Gómínà Dapo Abiodun Baba Obasanjọ kò ní àrùn Coronavirus- NCDC NCDC kéde èèyàn 437 míràn tó ṣẹ̀ṣẹ̀ lùgbàdì Covid-19 ní Nàìjíríà, 142 gbàwòsàn O ni awọn eeyan naa kọlu awọn adigunjale ọhun, wọn mu mẹrin lara wọn, wọn si lu wọn ni ilu bara.
74 Nígbànáà ni òun yíò ri ẹni náà lọ́kùnrin tàbí lóbìnrin bọ inú omi, yíò sì tún mú un jade wá láti inú omi náà.
Ibib tí mo wà yìí ni ìpẹ̀kun ayé, ògiri tí ó sì yí ilé mi ká ni ó pín mi ìyà pẹ̀lú àwọn ara ọ̀run, nínú àgbàlá mi yìí pẹ̀lú, púpọ̀ nínú àwọn ara ọ̀run ni a jọ ń ṣiré pẹ̀lú ara wa, nígbà tí ìwọ bá sí jẹun tán, n óò mú lọ si ilé ẹbọra pàtàkì nì, ẹni tí orúkọ rẹ̀ ń jẹ́ Ikú, nítorí bí òun ti ni ilé kan sí òde ọ̀run bẹ́ẹ̀ ni ó tún ni ilé kan sí ọ̀hún nì, níbi tí ó jẹ́ agbedeméjì ayé òun ọ̀run.
Bóyá àrùn náà yóò tún yà irú òmírànGbogbo àwọn kòkòrò aifojuri lọ má ń tú gbile sí irú òmíràn ni gbogbo igba, sugbon awon iyato tí wọn ní yìí kii sábà farahàn tó bẹ́ẹ̀.
Oríṣun àwòrán, Jasmine Zeleny Àkọlé àwòrán, Onimọ nipa ejo, Jasmine Zeleny sọ pe omi lo gbe ejo ọhun de inu ile igbọnsẹ naa Ẹni to mu ejo naa, Jasmine Zeleny sọ pe o wọpọ lati ri ejo ninu ile igbọnsẹ, paapa ni asiko ooru, nitori pe awọn ejo maa n wa omi lasiko naa.
N kò mọ bí wọ́n ṣe n bá obìnrin sọ̀rọ̀ ìfẹ́ - Aláàfin Kí ló mú Olorì Badrat Ajoke kúrò ní ààfin Oyo lọ́jọ́ Iléyá?
Ọmọ erin naa n gbiyanju ati kọja loju opopona naa pẹlu awọn ẹranko ẹgbẹ rẹ kan lagbegbe Chanthaburi lorilẹede lorilẹede Thailand.
Àwọn ọmọ-ẹ̀yìn bá pa ẹnu mọ̀, wọn kò sọ ohun tí wọ́n gbọ́ ati ohun tí wọ́n rí ní àkókò náà fún ẹnikẹ́ni.
Koda, mo ni iṣoro nileewe debi i pe wọn fẹ le mi danu.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Pẹ̀lú gbogbo bùkátà, Bàbá 80 gboyè Masters Kawu ni AIT ṣafihan iṣẹ iwadii kan lasiko idibo to kọja ni Naijiria, eyi ti ọrọ eto idibo aarẹ nipa rẹ dẹ ṣi wa nile ẹjọ.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, D Banj lo gbogo nibi eto Brixton Academy ni London.
Nígbà tí ó rí i pé àjàkálẹ̀ àrùn ti bẹ́ sílẹ̀, ó fi turari sí i, ó sì ṣe ètùtù fún wọn.
Ọmọ ilu Ogidi Ijumu ni ipinlẹ Kogi nii ṣe.
Ó yan àwọn alufaa sí ipò wọn, ó sì gbà wọ́n níyànjú kí wọ́n ṣe iṣẹ́ wọn ninu ilé OLUWA.
Óńjẹ ọ̀sán tó jẹ, a ò mà rí wọn o.
Gbogbo ènìyàn bẹ̀rẹ̀ sí fi ṣe yẹ̀yẹ́ pé ohun tí ẹlẹ́sẹ̀ mẹ́wàá kò rí mú wálé ni ẹlẹ́sẹ̀ kan fẹ́ dánwò.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Wo bí Sunday Orimola ṣe gba ikú ẹranko kú ní Ifon ni Ondo lórí ọ̀nà àtijẹ Kìí ṣe torí ìbèérè ni mo ṣe bẹ́ Fani-Kayode, àwọn akẹẹgbẹ́ mi ló kó mi láyà jẹ - Eyo Charles Akọroyin iwe iroyin Daily Trust, Eyo Charles, ti Femi Fani-Kayode, sọ ọrọ kobakungbe si sọ pe oun ti dariji i.
uk Rii pe ko si ọrọ ija, ọ̀rọ̀ aworan iwokuwo/iṣekuṣe (Pornography), igbesunmọmi, ohunkohun to le ba awujọ jẹ tabi rogbodiyan ninu arokọ rẹ.
Lalai si awọn alabasisẹ ti yoo tawọn lolobo pe asiko ti to lati lọ jẹun tabi ki wọn nasẹ diẹ, eeyan o kan maa sisẹ lọ bi aago ni.
Ọpọlọpọ ninu àwọn ọmọ ogun Israẹli kú, àwọn yòókù sì sá.
Nítorí pé OLUWA àwọn ọmọ ogun ti pàṣẹ fún àwọn ọ̀tá pé:“Ẹ gé àwọn igi tí ó yí Jerusalẹmu ká lulẹ̀;kí ẹ fi mọ òkítì kí ẹ sì dótì í.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Akomolede ati asa Yoruba: Ẹ wá kọ́ nípa àpòtí ìṣura èdè wa lórí BBC Yorùbá Qatar ti pese aaye ayẹwo ni papakọ ofurufu Hamad International Airport nibi ti wọn yoo ti ṣe ayẹwo yi Ohun to n kan awọn eeyan lominu bayi ni asiko ti wọn yoo fi ri esi ayẹwo yi gba.
Ìgbà tí mo tún bẹ̀rẹ̀ si i rí àmì wọ̀nyí, mo túbọ̀ mú ara dúró, kí n ma ba wá lọ̀ bọ́ sí ọwọ́ Ẹlẹ́gbára.
Ninu awọn to n pe ipe yii ni igbakeji Adams Oshiomohle gan funrarẹ fun iha ariwa, Sẹnetọ Lawan Shu'aib ati alaga ẹgbẹ naa to fi ipo silẹ.
nitori naa, o jawe olubori  , o si yege
Ninu bí ọ̀kẹ́ meji (40,000) ọkunrin tí wọ́n wà ní Israẹli,ǹjẹ́ a rí ẹnikẹ́ni tí ó ní apata tabi ọ̀kọ̀?
Ninu awọn mẹrin ti orukọ wọn lewaju pe wọn le lọ sile, awọn ni iye ibo ti wọn ri kere ju lọ.
"Kii se dandan ki awọn eeyan ri wa loju koroju pe a n se iwọde ni ibikibi lorilẹede Naijiria, amọ gẹgẹ bi awọn ọmọ Naijiria ti n joko sile, maa fi ẹhonu han ninu ọkan wọn, naa ni awa naa fẹ maa se pẹlu.
Ara àwọn ìlú tí ó wà níbẹ̀ ni, Kata, Nahalali, Ṣimironi, Idala, ati Bẹtilẹhẹmu, gbogbo ìlú ati ìletò wọn jẹ́ mejila.
Wọn a fẹ́ wá bí ìjì, wọn a sì tún fẹ́ lọ, àwọn olubi eniyan, tí agbára wọn jẹ́ ọlọrun wọn.
Batiṣeba wólẹ̀ níwájú ọba, ó dojúbolẹ̀, ó ní, “Kabiyesi, oluwa mi, kí ẹ̀mí ọba ó gùn.
Nígbà tí Olodumare tú àwọn ọba ká,ní òkè Salimoni, yìnyín bọ́.
Isaaki bá wí tìfura-tìfura pé, “Súnmọ́ mi, kí n fọwọ́ kàn ọ́, kí n lè mọ̀ bóyá Esau ọmọ mi ni ọ́ lóòótọ́.
Nígbà tó ń ṣàlàyé bo se dára pọ mọ eto òṣèlú, Femi ni ìjọba Abdulfatai Ahmed tó kogba wọlé ni Kwara, lo yàn òun sì ipò Oludanimọran, tí òun si rí ìpè náà, bíi ọ̀nà láti súnmọ́ àwọn mẹkunnu ni.
O fikun-un pe, o kere tan ẹ̀ẹ́dẹ́gbẹ̀ta eniyan lo ti padanu emi won ninu ikolu ohun, ti awon miran si farapa yanayana.
Nítorí pé oníwọ̀ra ni,tí ọkàn rẹ̀ bá nàró sí nǹkankan,kò lè pa á mọ́ra.
Ó ní kí wọ́n máa tẹríba fún un, kí wọn sì máa rúbọ sí i.
O tun ni pe: lootọ ni pe oun hu iwa buruku yi.
Ẹ ó rántí wípe ikọ̀ IRT ni o mú afẹsùnkan Chukwudi Onuamadike tí ọ̀pọ̀ eniyan mọ̀ sí Evans ní ọdún tó kọja lórí ẹ̀sùn pé oun lo sagbátẹrù ìjínigbe tí ó burú jù ní orilẹ̀èdè Naijiria.
Health workers Strike: Àwọn òṣìṣẹ́ elétò ìlera lábẹ́ àsìá JOHESU fagilé ìyanṣẹ́lódì káàkiri Nàìjíríà
Ajao Estate Gas Explosion: Alága ìjọba ìbílẹ̀ Isolo ní àwọn yóò fi òfin dè títà afẹ́fẹ́ gáàsì létílé
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ìdílé tó gba olùkọ́ èdè Yorùbá fún àwọn ọmọ nílẹ̀ Gẹ̀ẹ́sì O ni wọn kan ma maa tan aarẹ ni ṣugbọn wọn ko ni maa so ootọ ọrọ to nilo lati maa gbọ loorekoore fun idagbasoke ilẹ̀ South Africa.
Ó gbá ikun Ọ̀bọ titi ó fi ya igbẹ́ gbi gbóná ki ó tó tu silẹ̀.
Àwọn eniyan díẹ̀ ni wọn yóo sá àsálà kúrò ní ilẹ̀ Ijipti lọ sí ilẹ̀ Juda.
45 Àwọn alàgbà ni wọ́n nílati darí àwọn ìpàdé bí Ẹ̀mí Mímọ́ bá ṣe darí wọn, ní ìbámu pẹ̀lú àwọn òfin àti àwọn ìfihàn ti Ọlọ́run.
Gege bi ebi oloogbe ohun , Maryan Abdullahi so pe, awon agbebon naa sekupa lasiko to n lo si ile itaja Bakara ti o wa ni olu-ilu orile-ede ohun ti n se Mogadishu lati lo ra awon ohun elo fun igbeyawo re ti o ye ko waye lose to n bo.
Oríṣun àwòrán, Twitter Àkọlé àwòrán, Ọjọ́ keje, oṣù Kẹjọ ni Adele Aarẹ, Yẹmi Ọsinbajo gba iṣẹ́ lọ́wọ́ rẹ̀ Bakan naa ni wọn ko jẹ ki wọn o fi ofin gbe Ọga agba ajọ ọtẹlẹmuyẹ National Intelligence Agency, NIA, Ayodele Oke, ti Aarẹ Buhari da duro lẹnu iṣẹ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Lionel Messi gba àṣẹ àmì ìdánimọ̀ lágbàyé 26 Ìgbé 2018 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 27 Ìgbé 2018 Àkọlé àwòrán, Ìlúmọ̀ọ̀ká agbábọ́ọ̀lù ni Lionel Messi jẹ́.
Liverpool fí ogun ẹ̀yìn ja Barcelona Ayé le, ìbòsí ò!
Ondo:O d‘èèwọ̀ láti tí ojú pópó pa fún ayẹyẹ
O ni ṣe ló yẹ káráàlú ó máa dunnú pẹ̀lú bí àwọn alágbára ṣe ń tú àṣírí ara wọn.
Ẹni tí ó ṣe ojurere fún àwọn talaka, OLUWA ni ó ṣe é fún,OLUWA yóo sì san ẹ̀san rẹ̀ fún un.
“Wò ó, mo rán angẹli kan ṣiwaju rẹ láti pa ọ́ mọ́ ní ọ̀nà rẹ, ati láti mú ọ wá sí ibi tí mo ti tọ́jú fún ọ.
5 owó naira ni ọọfiisi àjọ INEC ni Zamfara Wo àwọn orílẹ̀-èdè márùn ún tó fún àwọn obìnrin làńfàní tuntun sí ẹ̀tọ́ wọn Nínú ọ̀rọ̀ tìrẹ, asoju ilé iṣẹ́ to n pese iranlọwọ ṣugbọn ti kìí ṣe ti ìjọba, Women Consortium of Nigeria, Morenike Omaiboje naa gboriyin fun awọn ọmọ obinrin.
Aare Muhammadu Buhari yoo farahan niwaju ile igbimo asofin ki ile oni to su lati wa salaye lori igbese to n gbe lati dekun bi won se n pa awon  eniyan alailese ni awon ipinle Benue, Taraba, Zamfara ati  awon ipinle miiran  lorile ede Naijiria.
Latọwọ aṣofin Wilfred Onyema ni abadofin yii naa ti wa eyi to pe fun ọrọ agbekalẹ Fasiti torukọ rẹ wa loke yii ati aridaju pe idọgba wa fun imọ ẹkọ ile iwe giga kaakiri Naijiria.
Atamataṣe ẹgbẹ agbabọọlu Arsenal, Alexander Lacazzette lo sọ bẹẹ, to si ni awọn ko fẹ ki ife yi bọ mọ awọn lọwọ.
miiran yoo pọ pupọ ju bi won se se lọdun merin seyin lo.
Nípa ẹ̀kọ́ rẹ ni mo fi ní òye,nítorí náà mo kórìíra gbogbo ìwà èké.
Idahun ibeere yi ni wipe ko mu inu Abramovich dun.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Japan visit: Iléeṣẹ́ ààrẹ ní ẹgbẹ́ IPOB kò tako Buhari ní Japan 26 Ògún 2019 Oríṣun àwòrán, Twitter/Bashir Ahmad Irọ funfun balau ni iroyin kan to n tan kaakiri lori ayelujara pe awọn ọmọ ẹgbẹ IPOB ti wọn yabo igbakeji ile igbimọ aṣofin agba l'Abuja tẹlẹ, Sẹnẹtọ Ike Ekweremadu lorilẹede Germany ṣewọde lati tako Aarẹ Muhammadu Buhari nigba to gunlẹ si orilẹede Japan lọjọ Aje.
(Mo ti tọwọ́ bọ̀wé,kí Olodumare dá mi lóhùn!
Iroyin ni, wọn n beere ibeere nipa ijọ naa lọwọ awọn olujọsin to n wọle ki wọn le mọ boya ọmọ ijọ ni wọn ni tootọ ki wọn to jẹ ki wọn wọle.
”Wọ́n ní, “Ìrìbọmi ti Johanu ni.
NBS sọ pe afaimọ ki iyan ma bẹ silẹ ni Naijiria nitori awọn mẹkunnu ti n ke wi pe awọn ko rowo ra ounjẹ mọ.
Àwọn tí wọ́n bá fọ aṣọ wọn ṣe oríire.
Ó bá jókòó, ó ń kọ́ wọn lẹ́kọ̀ọ́.
Oríṣun àwòrán, Instagram/oonirisa Àkọlé àwòrán, Ọba Adeyẹye Ogunwusi, Ọjaja Keji ti kede iyawo tuntun laafin, lẹyin ti o se ayẹyẹ ọjọ ibi ọdun kẹrinlelogoji.
Tabi kí ó lè jókòó lórí aṣọ ọ̀fọ̀ ati eérú nìkan?
ti o gbe gbogbo awon oludije dupo labe asia 
Bi esi ayẹwo naa ṣe lọ niyii: Ni bayii, ẹgbẹrun meji ati ọtalelẹẹdẹgbẹta (2558) eniyan lo ti ni aarun naa ni Naijiria.
Comrade Aremu wa ki ogbeni ,
 o dinku si egberun meji aabọ sq km.
Omoyele Sowore : Àwọn orílẹ̀èdè márùn-ún tí ìjìyà ti wà fún ẹni tó bá bú ààrẹ
Iroyin to tan ka lana ni wi pe lójúnà ìrìnàjò wọn lọ síbi ìpàdé àdùrà níbi ìpàgọ́ ńlá RCCG ni wọn ti bọ́ sí ọwọ awọn ajinigbe ọhun.
Ẹwẹ, ẹgbẹ agbabọọlu Arsenal, Tottenham, West Ham ati Brighton ti ṣi papa iṣere wọn fawọn agbabọọlu wọ lati ma ṣe igbaradi ọlọdanni.
O Fagunwa, Adebayo Faleti, Akinwumi Iṣọla, Lawuyi Ogunniran àti Oladejo Okediji ṣiṣẹ silẹ ki wọn to lọ3 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Èyí tí a wò jùlọ 5:03 Fídíò, Omolola Arohunmolase Welder: Mo ti fí iṣẹ́ 'Welder' gbayì láwùjọ, tó mo fi tọ́ ọmọ yanjú, Duration 5,039 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 5:39 Fídíò, Akomolede ati Asa lori BBC: Olùkọ́ Kikelomo Ogunboye tan ìmọ́lẹ̀ sí ìwà olè ọ̀gá ọlọ́pàá Audu gẹ́gẹ́ bí àwòkọ́ṣe àsìkò yìí, Duration 5,398 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 4:11 Fídíò, Oba Adeyeye Ogunwusi: Ojú mi ti rí lọ́pọ̀ lọpọ̀, ọ̀pọ̀ èèyàn ni kò tilẹ̀ gbàgbọ́ pé mo lè jọba- Ooni, Duration 4,117 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 4:43 Fídíò, Promise Akinlade: ọmọ ọdún mọ́kànlá tó ń fi ìlù dárà bíi àgbàlagbà sọ̀rọ̀ nípa tálẹ́ǹtì rẹ̀, Duration 4,437 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 0:59 Gbọ́, Ìsẹ̀lẹ̀ jákèjádò orílẹ̀èdè àgbáyé láàárín ìṣẹ́jú kan, Duration 0,59wákàtí 5 sẹ́yìn 7:03 Fídíò, Olumuyiwa Bolade Adedeji Military Bruitality: Bí arákùnrin onípèníjà ara tí sọ́jà lù ṣe dé, Duration 7,035 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 4:45 Fídíò, Yoruba Films: Ẹ̀ẹ́ bẹ̀ mi kúrò láyé ni, mi ò lè kú - Fadeyi Oloro, Duration 4,4526 Èrèlè 2020 2:48 Fídíò, Esther Ajayi: Èmi náà ti borí ìṣòro rí ló ń mu mi ṣojú àánú, Duration 2,481 Ògún 2019 6:08 Fídíò, Adebola Ademilua: Àìrísẹ́ ṣè lẹ́yìn ìwé kíkà ló sọ mi dí ìyá onírú, mo dúpẹ́ tèmi, Duration 6,0827 Bélú 2020 5:55 Fídíò, Soyinka Cancer: Àṣe ara mi ni iso ti n run gbogbo bí mo ṣe n ṣèrànwọ́ lórí jẹjẹrẹ, Duration 5,5527 Bélú 2019 BBC News, Yorùbá Ìdí tí ẹ fi le è nígbàagbọ́ nínú ìròyìn BBC Ìlànà Lílò Nípa BBC Òfin Àṣírí Cookies Kàn sí.
kí ọkàn mi lè máa yìn ọ́ láìdákẹ́.
Ṣaaju ayipada owo naa, nọmba atẹgbana kan ṣoṣo ni onibara yoo gba bi o ba ti sanwo lori ayeluja Amọṣa ni kete ti ayipada naa de, nọmba atẹsanwo gba ina mẹta ni yoo waye.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Mo ti kó kúrò nílé Olu Jacobs rí lẹ́ẹ̀mejì- Joke Silva Àkúntúnkú, ìgbà márùn ún rè é tí Shekahu kú tí wọ́n ní kò kú mọ Kò sí ìfòyà lásìkò ọdún iléyá ní òpópónà Marosẹ Eko si Ibadan Ibadan NURTW: Àwọn ti Auxilliary àtàwọn tí Ajanaku gangan ló ń dàgboro rú Lara ojuse minisita tuntun yii si ni sise agbekalẹ ofin to nii se pẹlu igba ewe awọn ọmọde, abẹwo wọn ati ofin to de akoso wọn.
Ó bá bẹ̀rẹ̀ sí rìn kiri ní ìhòòhò, láìwọ bàtà.
Ijọba ipinlẹ Kano ti fagile idajọ ile ejọ giga to sọ wi pe Gomina ipinlẹ naa ko laṣẹ lati yan Emir tuntun ni ipinlẹ naa.
 Àkọlé àwòrán, Dokita iwosan oju, ṣalaye pe aimọkan, aisi iroyin to to ati ọwọngogo itọju aisan oju n ṣe akoba fun awọn ti oju n yọ lẹnu lorilẹede Naijiria Bakan naa lawọn to laisan oju ti wọn wa sibi eto iwosan ọfẹ lori aisan oju naa ni wọn pariwo sita pe asiko to fun ijọba lati ṣe iranwọ ti yoo mu adinku ba iye owo ti wọn n san fun itọju aisan oju lorilẹ-ede Naijiria."
Láti ọjọ́ tí mo ti ń rìn káa kiri ayé yìí n kò bá irú ilé náà pàdé rí, ó tilẹ̀ dára ju àa[fin ọba Igbó Olódùmarè lọ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Kano Sharia Police: Ènìyàn Kano ọgọ́rin lo ti wà látìmọ́lé nítorí wọn jẹun nínú ààwẹ̀.
Bí òdòdó lílì ti rí láàrin ẹ̀gún,ni olólùfẹ́ mi rí láàrin àwọn ọmọge.
Ọgbẹni Aminu Othman Zubair ni iroyin kan so pe o gbẹmi ara rẹ ninu iṣẹlẹ ti ina ti jo filati rẹ nikan.
Ìyẹ̀fun kíkúnná ni kí o fi ṣe wọ́n.
Ìwádìí BBC: Àwọn ará Èkìtì ń sáré gba N4,000 sáájú ìbò 'Ẹnu lásán kò lè sàn owó oṣu oṣiṣẹ l'Ekiti' Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí kan sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
Ọba yìí ni ó bá ọba Moabu jà, ó sì gba ilẹ̀ rẹ̀ títí dé odò Arinoni.
Ẹ̀jẹ̀ tí ń ṣàn láti ojú ọgbẹ́ rẹ̀ sì ti dà sí ìsàlẹ̀ kẹ̀kẹ́ ogun náà.
Covid, Covid, Covid O ṣe e ṣe ko jẹ pe nkan gboogi to mu Biden bori , jẹ nkan to kọja agbara rẹ.
"Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, PDP kóTinubu ní ìjánu Ẹgbẹ́ oṣèlú PDP nínú àtẹ̀jáde rẹ̀ tí akọ̀wé ẹgbẹ́, Kọla Ọlọgbọ́ndíyàn fọwọ́ sí sọ wí pé ""èèyàn bíi Tinubu leè ṣe òṣèlú rẹ̀ láì dá sí lílo ọ̀rọ̀ òdì èyí tí kò bọ̀wọ̀ fún ènìyàn bíi Atiku ẹni tí gbogbo Nàìjíríà káàkírí ti gbà láti jẹ́ Ààrẹ wọn tó mbọ̀."
 wọn lágbára láti yọ ọba lóyè .
O ni oun ti fi ara oun si atimọle , ti iwosan si ti bẹrẹ fun oun lẹsẹkẹsẹ.
" Ẹ jẹ ka ye tan ara wa mọ.
èmi tí ó jẹ́ pé tẹ́lẹ̀ rí mo kẹ́gàn rẹ̀, mo ṣe inúnibíni sí i, mo tún fi àbùkù kàn án.
4 226002 Orilẹede Chech 14029 131.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù National ID: Anthony Joshua gba nọ́mbà ìdánimọ̀ NIN, wo èsì àwọn ọmọ Nàìjíríà 19 Èrèlè 2020 Oríṣun àwòrán, NIMC Eto iforukọsilẹ fun nọmba idanimọ awọn ọmọ orilẹede yii ki ṣe eyi ti o ṣokunkun si ọpọ mọ bayii paapaa julọ lẹnu lọwọlọwọ yii.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ẹgbẹ́ òṣèlú ANC fẹ́ ki Jacob Zuma o kọ̀wé fi ipò sílẹ̀ gẹ́gẹ́ bi ààrẹ South Africa Ẹgbẹ oselu ANC ko i ti fi abajade ipade rẹ sita, sugbọn lara awọn ọmọ ẹgbẹ oselu naa lo fi ọrọ naa lede fun awọn oniroyin lorilẹede South Africa ati ile isẹ iroyin Reuters News Agency.
Uzoma ni ki awọn ọmọ Naijiria paapa julọ awọn ololufẹ rẹ ma ṣe binu nitori pe Covid-19 lo ṣokunfa bi wọn ko ti ṣe le sin ni Naijiria.
 Akọwe iroyin aya gomina tẹsiwaju pe lẹyin eyi ni wọn yoo gba iwe asẹ lati maa ta oogun fun obinrin naa, ti wọn yoo si ra oogun kun inu sọọbu rẹ fun tita."
Gbogbo ẹ̀yà ilẹ̀ ayé yóo dárò nígbà tí wọ́n bá rí i.
Ìparun yóo bá wọn ninu ọ̀nà ìparun wọn.
Orile ede Naijiria n gbe epo robi bi milionu tonu wole lodoodun latari bi awon ile ise ifopo mereerin to wa lorile ede Naijiria se  denu kole.
Bẹẹ naa la n ṣe nibi iṣẹ agbaṣe ti eleyi ko si jẹ ki idagbasoke ba Naijiria.
Oríṣun àwòrán, Instagram/profosinbajo Lọwọ yii, eeyan mẹrindinlaadọta lo ti ni arun naa lorilẹ-ede Naijiria, leyi to ti mu ki ijọba apapọ ti ilekun gbogbo ileewe, ti awọn ijọba ipinlẹ kan si ti gbe agadagodo sẹnu ọna ileeṣẹ ati ọja wọn.
Gbogbo ohun èlò ilé Ọlọrun ni Ahasi gé wẹ́wẹ́, ó sì ti ìlẹ̀kùn ibẹ̀; ó wá tẹ́ pẹpẹ oriṣa káàkiri Jerusalẹmu.
Ajọ to n ṣe aayan idije liigi ilẹ Gẹẹsi ṣalaye pe afojusun wọn ni lati pari awọn ifẹsẹwọnsẹ to ku.
Lẹyin to kọ ọkọ akọkọ silẹ, Toyin simi fun igba diẹ ki o to tun mu orin ifẹ bọnu.
Nibayii, Ọjọgbọn naa ti gba agbẹjọrọ agba ni Naijiria, Mike Ozekhome lati lọ ṣoju rẹ ni ileẹjọ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ondo Accident: Kíní ọ̀nà àbáyọ sí ìjàmbá ọkọ̀ tó ń wáyé lemọ́lemọ́ ní Ọjà Akungba,ní Ondo?
Aare Buhari lo soro yii  fun igbakeji ile ifowopamo ti awon musulumi ,
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Xenophobic Attacks: Ìjọba South Africa ní k'áwọn agbófinró ṣisẹ́ wọn bíi iṣẹ́ 31 Ẹrẹ̀nà 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Minisita fun ọrọ ilẹ okere lorilẹede South Africa Lindiwe Sisulu ti pepade pajawiri pẹlu awọn aṣoju orilẹede miran lẹyin ti awọn ọmọ ilẹ South Africa kan ṣeku pa awọn ọmọ ilẹ okere.
Section 98 Abala yii n sọ pe lilo omi yoo nilo gbigba iwe aṣẹ paapaa ko to bẹrẹ iṣẹ akanṣe.
Orí kó Ọ̀sinbajo yọ lọ́wọ́ ìjàmbá bàálù 'Awakọ̀ bàálù Ethiopia Airline tó já kò jẹ̀bi' Iyanrìn làwọn ẹbí olóògbé bàálù Ethiopia rí gbà dípò òkú Awọn ile iṣẹ iroyin orilẹede Russia jabọ pe ọmọde meji ati oṣiṣẹ inu baalu kan wa lara awọn to ba iṣẹlẹ naa rin.
Irúfẹ́ àrà náà ni mo mà máa ń rí lọ́nà ibiṣẹ́ o.
Nígbà tí ó pẹ́, ó wá bá ara rẹ̀ sọ pé, ‘Bí n kò tilẹ̀ bìkítà fún ẹnikẹ́ni, ìbáà ṣe Ọlọrun tabi eniyan, 
OLUWA ní kí n pàṣẹ pé, ‘Ilẹ̀ tí ẹ óo là kọjá yìí jẹ́ ilẹ̀ àwọn ọmọ Esau, àwọn arakunrin yín, tí wọn ń gbé òkè Seiri.
Ẹ gbọ alaye Dokita Obilade siwaju sii.
A wá sọ́dọ̀ rẹ,nítorí ìwọ ni OLUWA Ọlọrun wa.
igbimo asofin ni apa Gusu ijoba ibile Ijaw ni ipinle Bayelsa.
Kọ wọ́n sílẹ̀ lójú wọn, kí wọ́n lè máa pa àwọn àṣẹ ati òfin rẹ̀ mọ́.
Nígbà kan èdè kan ṣoṣo ni ó wà láyé, ọ̀rọ̀ bíi mélòó kan ni gbogbo wọ́n sì ń lò.
Àwọn ìròyìn mìíràn tí ẹ lè nífẹ̀ẹ́ sí: ''Mi ò ṣe àrífín Sultan àmọ́ mi ò lè bẹ̀rẹ̀ àwẹ̀ láì fojú r'óṣù' Lásìkò Ramadan, wo àwọn orílẹ̀èdè tí wákàtí ààwẹ̀ wọn gùn ju ti Nàìjíríà lọ Jàǹdùku ya bo àwọn tó ń fẹ̀hónú hàn nílé Ngige Ìyá 73 rọ ọmọ ní oúnjẹ dèrò ẹ̀wọ̀n l'Ámẹ́ríkà Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí kan sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
Pẹ̀lú gbogbo rẹ̀, ìjọba kò ì tíì sọ tó, tàbí kí ó kéde láti sọ bóyá òun yóò mú ìdíyelé náà wálẹ̀.
Aarẹ Adams sọ ọrọ yii ninu ifọrọwanilẹnuwo to ṣe pẹlu BBC Yoruba ni ifesi si ipade to laarin rẹ ati aṣoju ọga agba ileeṣẹ ọlọpaa orilẹede Naijiria nilu Eko lọjọ Iṣẹgun.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Alága SUBEB: A ṣetán lá ti gba owó ìrànwọ́ Almajiri ní ìpínlẹ̀ Oyo 28 Ọ̀wàrà 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Ile iṣẹ to n mojuto eto ẹkọ kariaye nipinlẹ Oyo ta mọ si UBE lawọn ko ti ri iwe gba lati ọdọ ijọba apapọ nipa eto iranwọ ẹkọ Almajiri ni ipinlẹ naa.
    Èmi ni Ìnàkí-ìbẹ̀rù tíí ṣe olórí ogun àwọn ẹranko, mo wa ni orúkọ gbogbo àwọn ẹranko, ti ẹyẹ, tí ẹja, ti ejò àti ti àwọn igi láti fi ẹ̀sùn sùn yín.
Bí ilé -iṣé ààrẹ ṣé ń sọ pé ààrẹ kò bèrè fún ìwé ẹri ìdánwò àṣekágbá rẹ̀, ní àjọ WAEC náà ń tẹnu mọ́ọ pé ààrẹ ló bèrè fún iwé ẹrí tó ní òun ṣe lọ́dún 1961.
Awọn akọni mẹta ni wọn jọ n du ami ẹyẹ yii: adiẹyin ẹgbẹ agbabọọlu Liverpool, Virgil Van Dijk, Cristiano Ronaldo ti Juventus ati Lionel Messi to n gba bọọlu fun Barcelona.
Bakan naa o ni ọran ti wọn ni oun da ko si ninu ofin rara.
 tíátà nípa àwùjọ nì àwọn eléré ìtàgé fi ń se ọ ̀ pọ ̀ lópọ ̀ àyípadà sí àwọn àlébù àti kùdìẹ ̀ -kudiẹ tó kù nínú àwùjọ wa lónìí .
Mo tẹ́wọ́ mi méjèèjì sí ọ
“Ìgbà mẹta láàrin ọdún kan ni gbogbo àwọn ọkunrin yín yóo máa farahàn níwájú OLUWA níbi tí OLUWA bá yàn pé kí ẹ ti máa sin òun; àkókò àjọ̀dún burẹdi tí kò ní ìwúkàrà ninu, ati àkókò àjọ̀dún ìkórè, ati àkókò àjọ̀dún àgọ́.
A ó rántí pé kòkó ní Ajíṣefínní ń tà.
Nigba to n ba awọn akọroyin sọrọ lori iṣẹlẹ naa, Aderibigbe ni ọjọ pẹ ti oun ti kuro lẹnu iṣẹ olukọ, ti oun si n ṣe akọwe fun Aarẹ musulumi ilẹ Yoruba lati ọdun mọkanlelogoji sẹyin.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Jude Chukwuka: Wò ó bí òwé Yorùbá ṣe yọ̀ lẹ́nu ọmọ Igbo Deborah Okezie ṣalaye pe oun fẹ ki idajọ waye lori ọrọ naa, fun gbogbo awọn ọmọ to ti la nkan bẹ ẹ kọja ri.
Oríṣun àwòrán, Big Brother Naija / Twitter Ko tan sibẹ o, nibi ipade oniroyin naa ni wọn ti fun Olamilekan Agbeleshebioba 'Laycon', ni sọwedowo ọgbọn miliọnu Naira, ati awọn ẹbun miran to jẹ, gẹgẹ bi olubori ninu eto naa.
Shushaidah tẹnumọ pe ''okunrin gbọdọ ni idi to fẹsẹrinlẹ ki o to le ni ohun fẹ fẹ iyawo mi'' O gbọdọ fi ẹri han wi pe o le toju iyawo akọkọ ati eleekeji to fẹ gbe wole.
Dokita Len Tarivonda to jẹ oludari eto ilera nilẹ naa sọ pe ọpọ ọmọ orilẹede naa tawọn eeyan rẹ ko ju ẹgbẹrun un lọna ọdunrun un lọ ko fẹ ki ijọba ṣi ibode pada.
Saaju ipade yi, awọn onwoye agbo oselu Naijiria ti n sọ pe abẹwo rẹ si Aarẹ ko ni yi ohun ti yoo ba sẹlẹ si i pada.
Nítorí wọ́n ń dẹ́rù bani nígbà tí wọ́n wà láàyè.
Chukwueze (Villarreal FC, Spain)Awon ti o ni se pe(Six On
Aare Muhammadu Buhari ki iko agbaboolu Super Falcons ku oriire jijawe olubori ninu asekagba idije boolu afesegba tawon obinrin nile Afrika(Africa Women Cup of Nations, AWCON), ti o waye laarin iko ohun ati iko agbaboolu Banyana Banyana ti orile-ede South Africa lojo abameta(Saturday).
1 600397 Orilẹede Chile 15774 84.
OLUWA, ìwọ nìkan ni mo ní;mo ṣe ìlérí láti pa òfin rẹ mọ́.
 nígbà tí ó fi ma di ọdún 1984 , Ṣẹ ́ gun adéwálé ti si gbajúgbajà olórin yo-pop .
Muhammadu Buhari tun wa lo anfaani naa lati tẹpẹlẹ mọ ipinnu ijoba re lati pese
Bakan naa ni wọn n se akojọpọ awọn akọsilẹ to se pataki lati ipasẹ isẹ iwadi yii, eyi ti yoo seranwọ lati wa ojutu si awọn iwa ọdaran loniranran, ti agbega yoo si ba ọna ti wọn n gba se idamọ ẹda kọọkan.
Èmi ọba, tí orúkọ mi ń jẹ́ OLUWA àwọn ọmọ ogun, ni ó sọ bẹ́ẹ̀.
11 Bélú 2020 Oríṣun àwòrán, Instagram/Queen Anu/Queen Dami Iroyin kan to n lọ lori ayelujara ni pe, olori meji tun ti kuro ni aafin Alaafin ilu Oyo, Ọba Lamidi Adeyemi kẹta.
''Awọn ẹṣọ alaabo yoo si wa nita lati ṣọ lilọ ati bibọ awọn eniyan ati bi wọn ṣe tẹle ofin si ''.
Báyìí ni mo sọ̀rọ̀ dídùn ṣùgbọ́n síbẹ̀síbẹ̀ èsì ehoro tún lòdì sí ìrètí mi.
Ó ní òun gẹ́gẹ́ bí ẹ̀gbọn, òun lè dáàbò bo ara òun, ò sí kó ogún tó kù wá sí ibùdo rè ni Ijẹ̀bú-Jẹ̀ṣà.
Lootọ Aarẹ Buhari lo paṣẹ naa, ṣugbọn gomina ipinlẹ Eko, Babajide Sanwo-Olu ti fi awọn ilana ti awọn eeyan gbọdọ tẹle sita.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Everton vs Liverpool: VAR gba Everton sílẹ̀ lọ́wọ́ ogun ẹ̀yìn Liverpool, ọ̀mì ayò 2-2 ní wọ́n gbá ní Merseyside 17 Ọ̀wàrà 2020 Oríṣun àwòrán, Premierleague.
 odùduwà fún un ni adé tó sì n jẹ ́ Ọba láayè .
Ọmọlúwàbí ni Baba-onírùngbọ̀n-yẹ́úkẹ́ ẹni tí ń gbé ibi gegele [[okúta.
Gege bi oro Bekinbo, erongba pipese awon ohun amayederun ohun ni, lati je awon omode gbe igbe aye alaafia, nipa nini anfaani si omi to mo gaara ati ayika ti o dun-un wo.
Ta ni a ti fi agbára OLUWA hàn?
8bn owó àìtọ́ lọ́wọ́ mi ní tipá - Ẹlẹ́rìí Ìkúnlẹ̀ ló bá dé fún Oshiomole, Ize-Iyamu láti bẹ̀bẹ̀ fún ìbò aráàlú ní Edo Àwọn iléesẹ́ abáni fi ẹrù ránṣẹ bẹ̀rẹ̀ ìyaṣẹ́lódì tako àfikún owó Nipost Ikú Barakat Bello ní Akinyele gbé aláàánú pàdé ẹ́bí rẹ̀ A ṣe ọdún Ọ̀ṣun lásìkò yìí láti kó Coronavirus lọ ni - Ooni ṣàlàyé Wo àwọn nǹkan tí o kò mọ̀ nípa 'Church of Satan' Àwọn afurasí ajínigbé tó tan oníṣòwò jáde ní ṣọ́ọ́sì wọ gàù Ọlọpaa Bakan naa lo tun n kọminu lori aisan owo osu osisẹ lasiko ati bi gomina Bala Muhammed se kuna lati seto idibo ijọba ibilẹ laarin osu mẹfa akọkọ to gori oye, gẹgẹ bo ti seleri.
Ẹ̀yin ará, ó dá mi lójú pé ẹ̀yin fúnra yín kún fún inú rere, ẹ ní ìmọ̀ ohun gbogbo, ẹ mọ irú ìmọ̀ràn tí ẹ lè máa gba ara yín.
 lẹ ́ yìn èyí ni ó lọ sí ilé-ìwé àkọ ́ ṣẹ ́ -mọṣẹ ́ ti yaba polytechnic láti kọ ́ nípa ìmọ ̀ òǹtẹ ̀ wé àti àwọn iṣẹ ́ ọwọ ́ mìíràn .
Nígbà náà ni wọn yóo rí Ọmọ-Eniyan tí yóo máa bọ̀ ninu awọsanma pẹlu agbára ńlá ati ògo.
bí ó ti wà ní àkọsílẹ̀ pé, “Mo gbé òkúta kan kalẹ̀ ní Sionití yóo mú eniyan kọsẹ̀,tí yóo gbé eniyan ṣubú.
Bakan naa, ni ikolu miiran tun waye ni olu ilu orile-ede India ti n se, Delhi ti o si gbemi awon miiran lopolopo.
Ninu ikede kan ti Akọwe iroyin fún Gomina Seyi Makinde, fi sita lo ti dabi ẹni pe ijọba gbiyanju lati wẹ ara rẹ mọ.
"Ọwọ́ wa ti tẹ àwọn afurasí tó lọ́wọ́ nínú ikú Olufon ti Ifon, Oba Israel Adeusi - Amotekun Wo bí ìlànà tuntun lórí gbígba físà UK lẹyìn Brexit ṣe kàn ọ́ Abẹ́rẹ́ àjẹsára Covid-19 ti Pfizer ṣe yóò di lílò láti ọ̀sẹ̀ tó ń bọ̀ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Ọkọ mi wa ọkọ̀ tẹ ""Poly Bag"" lásán, àfi gbùùàà!"
Tẹ́ẹ sọ pé ilé ayé tí mo wá, orin ni kí n máa kọ, kí n máa fi jẹun
 O ni oun yoo mojuto owo osu  ati ajemonu awon osise , bakan naa ni oun yoo tun ba aare Muhammadu Buhari soro lori ipa ti yoo ko lati mu idagbasoke ba eto oro aje ipinle Ekiti.
Oríṣun àwòrán, Tunji Ojo Àkọlé àwòrán, Alága ìgbìmọ̀ tó n wádìí ẹ̀sùn ìnákúnàá nínú àjọ NDDC l'óun kò ṣe mọ́ Ọsẹ to lọ ni awọn alaṣẹ ajọ NDDC, ti Pondei jẹ ọkan lara wọn, binu kuro niwaju igbimọ oluwadii, lẹyin ti wọn fi ẹsun kan Tunji-Ojo pe, ọwọ ti ẹ naa ko mọ́ lori ọrọ naa.
Laarin Trump ati Clinton nigba naa, ami ayo diẹ ni wọn fi ju ara wọn lọ.
Ọpọ̀ èèyàn ní kó mọ pẹ pápákọ̀ ofurufú ń bẹ nílùú Ibadan- Òṣìṣẹ́ Òwò ẹrú pé irinwó ọdún tó bẹ̀rẹ̀, àwọn Amẹrika tó jẹ́ dúdú wá sí Afirika láti bẹ ilé wò Lẹyin isẹ abẹ oni wakati marun-un, ni wọn yọ eyin to le ni ẹẹdẹgbẹta ni agbọn rẹ.
Ṣugbọn o jẹ ohun iyalẹnu pe ijọba ṣe akitiyan ti ko kere lati kapa arun naa to bẹ gẹẹ, ti ajọ eleto ilera agbaye, WHO fi gboṣuba kare fun Naijiria fun akitiyan rẹ.
O sọ pe, oun wa ninu apoti oni gilaasi ọhun ti wọn gbe sinu ọkọ akẹru, ti oun si n lọ lati ibikan si ibomiran lati ya fidio awo orin tuntun.
"Adajọ Akinlade kasẹ rẹ nilẹ pẹlu sisọ pe ""ki ọlọrun ṣaanu fun ẹmi rẹ""."
Access Bank beere fun nọmba apo ikowosi mama ati ẹka ileeṣẹ wọn ti iya naa lọ, ki awọn le sẹ iwadii to peye lori ohun to ṣẹlẹ.
Ọgbẹni Ibukun ṣalaye pe ọrọ naa ṣẹlẹ ni ọjọ kẹẹdogun, oṣu Karun, ọdun 2020.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Adejare Adeboye: Àwọn kan ní ṣé ọ̀nà láti gba owó oṣù àkọ́kọ́ lọ́wọ́ ọmọ ìjọ kọ́ ní ìkéde ààwẹ̀ ọlọ́jọ́ 63 11 Sẹ́rẹ́ 2021 Oríṣun àwòrán, @PastorEAAdeboye Awọn eeyan lori ayelujara ti ko ẹnu bo Pasitọ igba fun ijọ Redeemed, RCCG, Olusọagutan Enoch Adeboye lori aawẹ ọlọjọ mẹtalelọgọta to kede .
Minisita to n mojuto eto isuna lorile-ede Nigeria tele ri, Ngozi Okonjo-Iweala, ni won ti yan bayii sara igbimo oludari ero ayelujara Twitter Inc.
Nítorí náà, ẹ fi tọkàntọkàn wá OLUWA Ọlọrun yín nisinsinyii.
Ìbá ti dára tótí mo bá lè dúró ṣinṣin ninu ìlànà rẹ!
“Èmi Atasasesi ọba pàṣẹ fún àwọn olùtọ́jú ilé ìṣúra ní agbègbè òdìkejì odò láti pèsè gbogbo nǹkan tí Ẹsira, alufaa akọ̀wé òfin Ọlọrun ọ̀run, bá fẹ́ fún un.
Pe Jese wá sí ibi ẹbọ náà, n óo sì sọ ohun tí o óo ṣe fún ọ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Zainab Habib Arábìnrin wà ní àhámọ́ ní Saudi lórí ẹsùn tí kò mọ 30 Ìgbé 2019 Oríṣun àwòrán, Hajara Habib Àkọlé àwòrán, Aworan Zainab Habib Awọn akẹkọ fasiti Yusuf Maitama Sule nilu Kano yoo ṣe iwọde lọjọ Iṣẹgun tori akẹgbẹ wọn kan Zainab Habib Aliyu ti wọn fẹsun gbigbe ogun oloro kan lorileede Saudi.
Àjọ Lasema rí òkú èèyàn nínú èèrù iná àwọn ọkọ̀ agbépo tó jóná ní afárá Kara Ọkọ̀ agbépo tó da epo nù fa súnkẹrẹ-fàkẹrẹ lòpópónà márosẹ̀ Eko sí Ibadan Ọkọ̀ agbépo míràn tún gbiná l‘Eko Osanyintolu ṣalaye pe epo naa ti da silẹ lasiko tawọn de ibi iṣẹlẹ naa ati pe awọn ṣi dawọ duro lati da epo naa si ọkọ mi.
Ekinni ń ké sí ekeji pé:“Mímọ́, mímọ́, mímọ́ ni OLUWA àwọn ọmọ ogun;gbogbo ayé kún fún ògo rẹ̀.
Bí mo bá rí ọmọ bí n o dúpẹ́ lọ́wọ́ Olódùmarè, bí n kò bá sì bí, n kò ní gbé wàhálà ka ara mi láyà, ki n rò pé ayé mi ti bàjẹ́, ki n máa ti ilé dé ilé, ki ń di oníyẹ̀yẹ́ obìnrin, nítorí ó sàn ní ìgbà ẹgbẹ̀rún, kí ènìyàn kú láì ní ọmọ, ju pé kí oluwárẹ̀ di oníyẹ̀yẹ́ sí ààrin ìta.
Nígbà tí Jesu wọ inú ilé Peteru, ó rí ìyá iyawo Peteru tí ibà dá dùbúlẹ̀.
“Gẹ́gẹ́ bí OLUWA Ọlọrun wa ti pàṣẹ fún wa nígbà náà, a gbéra ní Horebu, a sì la àwọn aṣálẹ̀ ńláńlá tí wọ́n bani lẹ́rù kọjá, gẹ́gẹ́ bí ẹ̀yin náà ṣe rí i ní ojú ọ̀nà àwọn agbègbè olókè àwọn ará Amori; a sì dé Kadeṣi Banea.
’ ”Bẹ́ẹ̀ ni ó ṣe fi Efuraimu ṣáájú Manase.
Obinrin ará Tekoa náà bá tọ ọba lọ, ó wólẹ̀ níwájú rẹ̀, ó dojúbolẹ̀, ó sì kí i tọ̀wọ̀tọ̀wọ̀, ó wí fún un báyìí pé, “Kabiyesi, gbà mí.
Bákan nàá ni ipá àwọn ọlọ́pàá kò ká wọn, àyàfi ìgbà tí wọ́n tó ò kó àwọn ọlọ́pàá adìgbòlùjà, MOPOL, wá ni nkan ṣẹ̀ṣẹ̀ n rọlẹ̀.
Gbogbo eyi da lori itumọ ti o ba fun ariwo to n gbọ.
Wọn ni awọn agbabọọlu Naijiria ti dagba, wọn ko dẹ karamọ iṣẹ naa bo ṣe yẹ.
Ni kete ti ijọba apapẹ dẹwọ igbele naa lọjọ Aje, ọjọ kẹrin oṣu karun ọdun 2020, ohun akọkọ tawọn eeyan naa ṣe ni abẹwo sile ifowopamọ ti wọn n lo lati gba owo wọn.
"Ọlọ́pàá kan jáde láyé, èèyàn méjì fara gbọta lásìkò ìdigunjalè ní Falomo l‘Eko ""$2,600 àǹtí mi ni mo jí láti lọ sókè òkun àmọ́ àbámọ̀ ló gbẹ̀yìn ọ̀rọ̀ mi"" ""Olóṣèlú ní Kogi àti Bayelsa ti ń pín Irẹ̀sì, iyọ̀ lásìkò ìpolongo ìbò, INEC, ẹ mú wọn"" Wo díẹ̀ lára àwọn ọ̀rọ̀ ìkẹyìn ti Alexander Akinyele fi léde kó tó papódà Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 3 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 5 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!"
Kò dẹ̀ sí ẹnikẹ́ni tó nsọ̀rọ̀ síi.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: A kò ní fi adé wa sílẹ̀ nítorí Olubadan - Àwọn Ọba 27 Ọpọ̀ èèyàn ní kó mọ pẹ pápákọ̀ ofurufú ń bẹ nílùú Ibadan- Òṣìṣẹ́ Mo rò pé mò ń jà fún Islam ni, ó pẹ́ kó tó yé mi – Boko Haram tẹ́lẹ̀ Èèmọ̀ rèé o, Dókítà yọ eyín 526 lẹ́nu ọmọ ọdún méje Ẹ̀yin òṣìṣẹ́, ẹ kọ ìyà tí wọ́n fi ń jẹ yín lórí owó oṣù tuntun - Oshiomole gbarata Bakan naa, awọn ọmọ orilẹede Naijiria to wa loke okun naa yoo darapọ mọ ifẹhonu han ọhun kaakiri agbaye.
Ogunlọ́gọ̀ àwọn orílẹ̀-èdè tí ń bá ìlú tí ń jẹ́ pẹpẹ Ọlọrun jà,yóo parẹ́ bí àlá,gbogbo àwọn tí ń bá ìlú olódi rẹ jà,tí wọn ń ni í lára yóo parẹ́ bí ìran òru.
Oríṣun àwòrán, Sajetiologa Saje ni ọpọlọpọ awọn olosere lo dide lati ara rẹ, ti gbogbo wọn si mọ Dagunro si ẹni to nifẹ si iserere awọn akẹgbẹ rẹ.
Iwadii ti fihan pe ata ni eroja Capsaicin to maa n jẹ ki aṣaraloore endorphines pọ sii lara eniyan.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù BBC Yoruba: Àwọn ìròyìn tó tayọ lọ́sẹ̀ yìí 19 Agẹmo 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 20 Agẹmo 2019 Oríṣun àwòrán, BBC, OTHERS Àkọlé àwòrán, Akojọpọ Iroyin Lati ọjọ́ aiku ti ọsẹ n bẹrẹ, oniruuru ni awọn iroyin to maa n jade lati akata BBC Yoruba.
Ọgbun akọkọ ni ipinya ati aisi isọkan to wa laarin ẹgbẹ oselu ANC lorilẹede South Africa lọwọ yii.
Ni meni meji, a o ma gbe awọn ọrọ wọn yi wo ati iru ipa ti wọn ko lasiko idibo aarẹ to kọja.
“Aare sese sefilole ipolongo eto idibo re ti o pe akori re ni ‘IPELE TO KAN’ eleyi ti o safihan awon ise rere ti o se sile ti o tun gbero ati tesiwaju si.
Ó wí fún Josẹfu pé, “N kò lérò pé mo tún lè fi ojú kàn ọ́ mọ́, ṣugbọn Ọlọrun mú kí ó ṣeéṣe fún mi láti rí àwọn ọmọ rẹ.
di dandan ki itesiwaju de ba  eto oro aje
Àkọlé àwòrán, Àwọn olùgbé Madaka ní ìpínlẹ̀ Niger ṣàlàyé ìsòro tí wọ́n ń dojúkọ fún BBC látàrí àìsí òpópónà gidi.
Fatai Rolling Dollar gba ọna ojú omi sa lọ pelu ọkọ ojú omi kan nigba to wa lọmọ ọdun mokandinlogun.
Bungudu so pe, sise idasile ile-itoju ohun wa lara erongba ijoba ipinle naa lati ri daju pe aabo ti o peye wa fun awon alabarapa ati awon ti o ku die kaato fun ni awon agbegbe ipinle naa.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù BBC Gov Debate: Àwọn olùdíje gómìnà Oyo gbà lati san 30,000N owó osù òsìsẹ́ 1 Èrèlè 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 2 Èrèlè 2019 Àkọlé àwòrán, Àwọn olùdíje gómìnà Oyo Awon oludije mẹrin lo kopa nibi ipade itagbangba BBC News Yoruba to waye nilu Ibadan.
Ọrilẹede mẹtalelaadọta ninu awọn orilẹede to jẹ ọmọ ẹgbẹ OIC lo jẹ awọn orilẹede ti awọn ẹlẹsin musulumi ti pọ ju.
Ẹ óo rí mi, n óo dá ire yín pada, n óo ko yín jọ láti gbogbo orílẹ̀-èdè ati láti gbogbo ibi tí mo ti le yín lọ; n óo sì ko yín pada sí ibi tí mo ti le yín kúrò lọ sí ìgbèkùn.
Fun apẹrẹ, ajọ ẹṣọ oju popo lorilẹede Naijiria, FRSC ti wọn ti kede ọjọ aje gẹgẹ bii ọjọ ti wọn yoo bẹrẹ akanṣe eto kan lori fifi iwe aṣẹ iwakọ han, 'Show your Drivers Licence' ni ipinlẹ Eko lọjọ aje ko lee bẹrẹ rẹ nitori awọn gan ko gbẹyin ninu ṣiṣeranwọ lori ki irinna ọkọ lee ja geere.
Fọnran naa fihan bi iyawo aarẹ, Aisha Buhari ṣe fariga pe wọ́n tilẹkun mọ oun ninu ile ijọba to wa l'Abuja pẹlu bi awọn aṣọna si ṣe wa ninu ile ṣi n tu ọrọ sita kaakiri itakun ayelujara Taló ya fídíò ibi tí Aisha Buhari ti ń bínú ní Aso Rock?
Ṣé ọ̀dọ̀ yín ni ọ̀rọ̀ Ọlọrun ti kọ́ bẹ̀rẹ̀ ni àbí ẹ̀yin nìkan ni ẹ mọ̀ nípa ọ̀rọ̀ Ọlọrun?
Ẹni tuntun tó dàgbà jù lọ lágbàyé Ǹjẹ́ ewu wà nínú lílò ẹ̀rọ FaceApp?
Agbègbè Igoba ni ìṣẹ̀lẹ̀ náà tí wáyé nígbà tí Obìnrin náà forí pamọ sì inú ilé ìjọsìn kan nibẹ, kí ògiri ilé náà sì ya, tí ó sì ṣe èmi arábìnrin náà lè gbodo.
4 322474 Orilẹede Bugaria 4797 68.
 Eleyii ṣe pataki, ki nnkan le lọ ni irọwọ, irọsẹ lọjọ idibo.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Iléeṣẹ́ Ọlọ́pàá di ẹ̀bi rògbòdìyàin ní Kogi ru ìwà kòtọ́ àwọn olóṣèlú 16 Bélú 2019 Ileeṣẹ ọlọpaa ni ko din ni eeyan mejilelogun ni ọwọ ti tẹ lori rogbodiyan to waye lasiko idibo nipinlẹ Kogi.
Super Eagles ti orile ede Naijiria  tẹsiwaju
Wọn kò gbọdọ̀ jẹ, wọn kò sì gbọdọ̀ mu.
Wọn o tun ni ina ọba lati gbọ rẹdio tabi tẹlifisan nipa Coronavirus ati ọna ti ijọba n polongo pe wọn le gba dena rẹ.
ilana sise idasile ibugbe awon daran-daran kii se kanpa fun gbogbo awon ipinle
Balogun àwọn ọmọ ogun OLUWA dá Joṣua lóhùn pé, “Bọ́ bàtà ẹsẹ̀ rẹ, nítorí ibi tí o dúró sí yìí, ilẹ̀ mímọ́ ni.
Ambode, wá jẹ́jọ́ lórí ọkọ̀ BRT 5000 tó o ₦45b rà, àmọ́ 820 péré ló kó wá Ile aṣofin ipinlẹ Eko ti ṣe agbekalẹ igbimọ kan lati ṣe iwadii bi Gomina ana nipinlẹ naa, Akinwumi Ambode ṣe na biliọnu marundinlaadọta naira to fi ra ọkọ akero .
Lara wọn ni: Iwọpopo: eto ti wọn maa n ṣe lati gba ilu mọ kuro lọwọ ibi gbogbo.
"Keyamo lásìkò tó ń ba ilé iṣẹ́ ìròyìn ""The Nation""ní ààrẹ ló pé òun laṣẹ́ kí òun tẹ̀síwájú, àti pé ọ̀rọ̀ àwọn ọmọ ilé ìgbmọ̀ aṣòfin kò láṣẹ láti dá ètò náà dúró."
Laipẹ yii ni Kọmisana feto ilera ipinlẹ Osun, ati akẹgbẹ rẹ nilu Eko sọ pe, bi awọn eeyan ko ba sọra ijọba yoo gbe ofin konile o gbele miran kalẹ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Lassa fever: ìpínlẹ̀ Èkó kéde èèyàn kan pẹ̀lú ibà Lassa 19 Èrèlè 2020 Oríṣun àwòrán, Getty Images Iba Ọrẹrẹ, ti aye mọ si iba Lassa ti wọ ipinlẹ Eko bayii!
Ènìyàn merinla péré ni àwọn aláṣẹ Uganda ṣẹṣẹ fi idi rẹ mulẹ pé wọn ní aarun náà tó fi mọ ọmọdébìnrin oṣù mejo kan.
 nam díje fún ipò Àrẹ gúúsù nínú ètò ìdìbò ti ọdún 1971 .
Èdè Yorùbá ni ibamu pẹlu asa obínibí Yorùbá.
Ọkunrin kan wà tí ń jẹ́ Demeteriu, alágbẹ̀dẹ fadaka.
Ẹsẹ̀ wọn yára láti ta ẹ̀jẹ̀ sílẹ̀.
Abrahamu bá dìde ní òwúrọ̀ kutukutu, ó mú oúnjẹ ati omi sinu ìgò aláwọ kan, ó dì wọ́n fún Hagari, ó kó wọn kọ́ ọ léjìká, ó fa ọmọ rẹ̀ lé e lọ́wọ́, ó ní kí wọn ó jáde kúrò nílé.
Manchester United: Gunnar Solskjaer di akónimọ̀ọ́gbá tuntun
Jollof rice: Ṣé lóòtọ́ ni ìrẹsì jọ̀lọ́ọ̀fù Ghana dùn ju ìrẹsì jọ̀lọ́ọ̀fù Nàìjíríà lọ?
Gbogbo ile Ivory Coast lo n se ádùrá kikan-kikan kí Cameroon fidiremi.
Ó tó àkókò ná wáyí tí mo níláti padà sí ibib tí mo ti ń wá, bí Ọlọ́run bá sì dá ẹ̀mí sí, ọjọ́ ń bọ̀ tí a óò tún fi ojú rí ara wa.
Ìjànbáforítì ń ré kọká lọ lọ́jọ́ kan ni ó déédéé rí ọwọ́ ìjà erin nínú odò.
Nigba to n ba awọn akọroyin sọrọ, obinrin to ra ọmọ tuntun naa sọ wipe oun san owo naa fawọn tọkọtaya to ta ọmọ wọn.
Mo wa duro nitosi ibẹ, lati wo boya ẹnikẹni yoo gbe.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Kemi Dairo: Iṣẹ́ abẹ nínú ọpọlọ àti ẹ̀rọ ni mo fi ń gbọ́ ọ̀rọ̀ báyìí Awọn ipa manigbagbe ti Henry Fajemirokun ko si iranwọ ọmọniyan: Gẹgẹ bi orin ti Ebenezer Obey kọ fun Fajemirokun, ilumọọka ọlọrọ naa fi owo rẹ mọ Oluwa, to si tun fi mọ eniyan nitori nile isẹ rẹ, aimọye eniyan ni wọn n jẹ, ti wọn n mu Bo si se n sisẹ aanu rẹ labẹle lorilẹ-ede Naijiria, naa lo tun n se nilẹ okeere.
Oríṣun àwòrán, others Àkọlé àwòrán, Ede Aiyede laarin ẹni meji di nla ni ileepo Gẹgẹ bi a ṣe gbọ, ni ọja Oke odo ni ija naa ti waye, bẹẹni ọpọ dukia lo parẹ sinu iṣẹlẹ naa ti ọpọ eeyan si fara pa pẹlu.
Ìgbà tí gbogbo wa wọlé tán, ìlẹ̀kùn padé, bí a sì ti wo ẹ̀yìn ni a rí ẹnìkan tí o gbé àáké ssókè tí o n tẹ̀lé wa.
Ṣugbọn ìwọ OLUWA mọ̀ mí,O rí mi, o sì ti yẹ ọkàn mi wòo mọ èrò mi sí ọ.
Abiade jẹ ko di mimọ pe ọpọlọpọ igba ni obinrin maa ni anfani lati jẹ olori ni ipo kan tabi omiran ṣugbọn ti anfani naa ko ni bọ si i lọwọ tori wn a ni ipinlẹ rẹ ti yipada niwọn igba to ti lọkọ.
nikalẹ nibi ti igbakeji aare ti dibo  tọrọ
Eyi waye lẹyin ti fidio kan to ṣafihan àwọn ọlọpaa kan tó yinbọn si ọkunrin kan ati idile rẹ, gba ori ayelujara.
Ijẹri ohun to ṣe ni ileewe girama.
Ẹ̀yìn ọkọ̀ kò kanlẹ̀, ìgbì wá bẹ̀rẹ̀ sí fọ́ ọ bí ó ti ń bì lù ú.
 bí wọ ́ n ṣe ń ṣe èyí ni ilẹ ̀ russia tí ó jẹ ́ ọ ̀ rẹ ́ ilẹ ̀ serbia kéde pé àwọn yíò gbógun tí ilẹ ̀ austria-hungary .
Ninu ìran náà, mo rí i pé mo wà ní Susa, olú-ìlú tí ó wà ní agbègbè Elamu.
Eeyan 55,456 ni apapọ ni wọn ti fara ko aarun Coronavirus, ti awọn 43, 334 si ti ri iwosan gba lọwọ ajakalẹ arun ọhun.
Gbajugbaja ni Kudirat, orukọ rẹ kari aye, o si jẹ apẹrẹ ara ọtọ aronilagbara ẹda to n ja fun idọgba ati ijọba awa ara wa jakejado Afirika.
Yatọ si awọn onílù to maa n kopa, awọn akọrin, awọn arinrinajo afẹ ati awọn to fẹran aṣa naa kii gbẹhin nibi ajọdun naa.
Bí n bá tilẹ̀ kọ́ ọ tán èmi ìbá wa àdó náà fún ọ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Kàyééfì Promo: Ìyá, ọmọ tuntun àti olubi ló wà níbùdó ìgbókùsí, àmọ́ òkú ọmọ di àwátì Adebamiwo Adeọsun jẹ ẹni ọdun mẹtalelogoji, to si jẹ ọmọ ile Matọ nilu Ibadan.
O ni pe iwe ifisun ti awọn eekan ilu ati lajọlajọ bii ileegbimọ aṣofin ipinlẹ Ondo, ajọ ajafẹtọ ọmọniyan, Nigeria Human rights commission, atawọn ajọ miran kọ si ileeṣẹ agbofinro ọtẹlẹmuyẹ DSS lẹyin ti iṣẹlẹ naa ṣẹlẹ loṣu kọkọanla, ọdun 2019 lo le awọn oṣiṣẹ ajọ naa lati ti ẹsẹ bọ iwadii ọrọ ọhun.
Osoosu ni orile ede Naijiria n gbe ipin idokoowo jade lati fi  pese owo fun eto isuna re.
Amọ sa, Abdulwasiu wa fidi rẹ mulẹ pe laipẹ laijinna, oun ati iyawo oun yoo tun tun yigi so, ti idile oun yoo si pada duro re.
Lẹ́yìn tí ó bá jọba, ìjọba rẹ̀ yóo pín sí ọ̀nà mẹrin.
ti o wa nile ise ijoba ni agbegbe Agodi niluu Ibadan , ni ipinle Oyo to wa ni Gusu
Amọ, Alawe ti ilu Ilawẹ Ekiti, Ọba Adebanji Ajibade Alabi, Afuntade Kinni, to ba BBC Yoruba sọrọ salaye pe ko si ohun to kan Alaafin ninu ọrọ naa, eyi to oun naa kọ lẹta si Gomina ipinlẹ Ọyọ, Seyi Makinde wi pe ko kilọ fun Alaafin lori ọrọ naa.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ooni: EFCC, ẹ se àtúnse sí ìgbé ayé àwọn ọdaràn tẹ bá mú 5 Owewe 2019 Àkọlé àwòrán, Ooni ti Ile-Ifẹ, Oba Adeyeye Ogunwusi ti ní ó seése kí àwọn ọdaràn má mọ ìjàmbá tí wọ́n ń se fún ará ìlú.
Nígbà tí àwọn ìjòyè ọba Farao rí i, wọ́n pọ́n ọn lójú Farao, wọ́n sì mú un wá sí ààfin rẹ̀.
Ijọba ni ajọ agbofinro ati ara ilu tuntun ni awọn yoo ṣe agbekalẹ re lati ma risi ẹsun to ni i ṣe pẹlu ara ilu.
(amọṣa kii ṣe gbogbo ipe ọlọpaa lo nilo iwe aṣẹ ofin lati yẹ ọ wo) Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, African in Greenland: Kí ló sún ilẹ̀ Afirika dénú gbígbé inú yìnyín?
19 Ọ̀wàrà 2019 Oríṣun àwòrán, Google Àkọlé àwòrán, Lẹ́yìn ọdún mẹ́tàlélọ́gbọ̀n; àwọn èèyàn sí n bèèrè pé: Ta ló pa Dele Giwa?
Aisha sọ pe 'ti ọkọ mi ko ba wa atunṣe si awọn kudiẹ-kudiẹ to wa ninu iṣakoso rẹ titi di ọdun 2019, mi o ni jade lọ ba a polongo ibo tabi kesi obinrin kankan lati dibo fun un.
Ile ise ile Euroopu to n risi wiwon isele oju ojo nibudo Seismological ni ile riri naa jin to iwon kilomita ogosan sinu ile.
Ṣugbọn, bi Ọbasanjọ ṣe ti wa a yi ero rẹ pada pẹlu bi o ti se fori jin Atiku, to si tun sọ pe oun ''ṣetan lati ṣatilẹyin fun lati di aarẹ Naijiria'' ti n mu iriwisi ọtọọtọ wa lori ayelujara.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Tóyìn Adégbọlá: Kò yẹ kí obìnrin fi ìdí gba ipò tíátà Iwadii Kansas Entomological Society fihan pé omi ẹkun ojú kun fun eroja oriṣii.
Tí wọ́n bá gbé ọwọ́ wọn sókè, tí wọ́n sì kọjú sí ilé ìsìn yìí, 
Nitori aṣọ ni itẹdi kò gba omi dúró, bi ọmọ bá tọ̀ tàbi ya ìgbẹ́, á yi aṣọ ìyá tàbi ẹni ti ó gbé ọmọ.
Orile-ede America ko  lati topinpin eto-idibo orile-ede naa lati odun 2002 lakoko ti iwa titabuku ba eto omo eniyan gbile lorile-ede naa.
Ohun to ku ni lati maa foju sọna si igba ti ọmọ naa yoo de.
Èmi ni Alfa ati Omega, ẹni àkọ́kọ́ ati ẹni ìkẹyìn, ìbẹ̀rẹ̀ ati òpin.
idagbasoke to mọnyan lori ba  awon orile
8 6781799 Orilẹede India 142186 10.
Abiola Ajimobi: Àwọn ìgbà tí aráàlú fajúro lórí ìṣèjọba rẹ̀!
Ṣugbọn Joabu dáhùn pé, “Kí Ọlọrun jẹ́ kí àwọn eniyan rẹ̀ pọ̀ síi ní ìlọ́po ìlọ́po lọ́nà ọgọrun-un, ju iye tí wọ́n jẹ́ nisinsinyii lọ!
Hormes gba wọn niyanju pe ti o ba n ṣe ọ bi ko maa jẹ șokoleeti saa, jẹ eyi ti o dara, ki o si jẹ̀ ẹ niwọnba loojọ, ki o si tẹsiwaju ninu igbe aye rẹ.
Nítorí náà má ṣe tijú láti jẹ́rìí fún Oluwa wa tabi fún èmi tí mo wà lẹ́wọ̀n nítorí rẹ̀.
Ija naa tẹsiwaju ni ọdun 2018 nigba ti aarẹ Trump fopin si adehun pẹlu ilẹ Iran lori ohun ija Nuclear, ti wọn si fofin de wọn.
Àkọlé àwòrán, Mo kabamọ pe mi o gba abẹrẹ ajẹsara fun ọmọ mi Ọpọlọpọ iwadii lo ti fihan pé ọmọ ti ko ba gba abẹrẹ ajẹsara lasiko to yẹ ko gbaa le pada lugbadi arun rọparọsẹ ati awọn ikọlu miran lọjọ iwaju.
Rẹgi ni owe yii si ṣe pẹlu bi awọn obinrin ode oni ti ṣe bọ si oju ayelujara lati maa wa ọkọ, ti wọn si gbagbe asa wa to so mọ eto igbeyawo ati alarina.
Jesu dá wọn lóhùn pé, “àwọn ọ̀rẹ́ ọkọ iyawo kò lè máa gbààwẹ̀ níwọ̀n ìgbà tí ọkọ iyawo bá wà pẹlu wọn.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Imperial Majesty ni Olubadadan, Royal Majesty làwa, òfin sì tẹ̀lé e - Ọtun Olubadan Abimbola Oyeyemi jẹ ko di mim pe ati ri awn mẹrin to ku doola ko dẹrun tori bi awọn ọlọpaa ṣe n ri wn ko kuro ninu igbo lawọn ajinigbepa ọhun naa n gbiyanju ati doju kọ wọn.
Aare soro yii lasiko to n tewogba
Ìjìyà ẹlẹ́yà a máa mú kí òpè gbọ́n,tí a bá ń kọ́ ọlọ́gbọ́n, yóo ní ìmọ̀ sí i.
20 Ẹ máṣe ja ìjàdù pẹ̀lú ìjọ kankan, àfi bí ó bá jẹ́ ìjọ ti èṣù.
Kí ẹnikẹ́ni má baà wí pé orúkọ mi ni wọ́n fi ṣe ìrìbọmi fún òun.
Adájọ́ Dogo tí wọ́n jí gbé ti gba ìtúsílẹ̀ Ramil, omọ ogun ilẹ̀ ní Russia yìnbọn pa akẹgbẹ́ rẹ̀ mẹ́jọ!
Kí ẹ fún un ní ìwúrí.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Coronavirus: BBC News Yorùbá ní kí ẹ dúró nílé bí ẹ kò bá ní ìdí láti jáde NAFDAC ti ṣetán láti ṣ'àyẹ̀wò àgbo covid-19 tì Madagascar fi ránṣẹ́ ní kíákíá!
Ẹlẹbuibọn, to jẹ eekan ni idi isegun ati ẹsin ibilẹ wa parọwa sawọn eniyan lati ma sakiyesi finifini, nipa ẹni ti wọn yoo tọ lọ bi babalawo.
Ó ní, “N kò lọ́wọ́ ninu ikú ọkunrin yìí.
Ọ̀kọ̀ọ̀kan ninu ẹ̀gbẹ́ mẹrẹẹrin ìlú náà yóo gùn ní ẹgbaa meji ó lé ẹẹdẹgbẹta (4,500) igbọnwọ (mita 2,250), ati ti ìlà oòrùn, ati ti ìwọ̀ oòrùn, ati ti àríwá ati ti gúsù.
    Bí ìyàwó mi ti ń wí pé ‘o dìgbà’ ni ẹsẹ̀ rẹ̀ n wọ ilẹ̀ lọ; ddíẹ̀ díẹ̀ lo ń wọ ilẹ̀ lọ, ara mi gbọ́n, mo sì bẹ̀rẹ̀ sii bẹ̀ ẹ́ kí ó jọ̀wọ́ dáríjì mí, ṣùgbọ́n kò gbọ́, ọ̀ràn náà ti dùn ún jù.
Igbesẹ Kẹta: Igbakeji Gomina naa le kọ iwe esi ranṣẹ pada lori ẹsun ti wọn fi kan an, ti o ba wu u.
lo ti bẹrẹ iṣẹ nipa biboju to oniruuru ẹka ile iṣẹ epo naa.
"Babaláwo rèé pẹ̀lú afurasí adigunjalè mẹ́rin láhàmọ́ọ́ ọlọ́pàá ""Nkan ti wọn ṣe yii ko bojumu, ko si le gbe wọn niyi."
Ṣùgbọ́n ẹni tí kò ì dé ibẹ̀ yóò rò pe Ìgbèríko ni.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Sunday Igboho: Ẹ fi Ògún búra fún wa láti jà fún ilẹ̀ Yorùbá láì gbé Amotekun sábẹ́ ìjọba Keita jẹ oloṣelu lorilẹ-ede Mali, to si jẹ aarẹ lati ọdun 2013 si 2020 lẹyin ti wọn ni ko kọwe fipo silẹ bi tulaasi nitori iditẹ gba ijọba.
Láàrin irú àwọn eniyan wọnyi ni ẹ̀ ń tàn bí ìmọ́lẹ̀ ninu ayé, 
Nígbà tí àríyànjiyàn náà pọ̀ pupọ, ẹ̀rù ba ọ̀gágun pé kí wọn má baà fa Paulu ya.
Oral Sex: Àwọn tó kó àìsàn náà máa ń rí oje lójú ara wọn tó ń rùn bí ẹja
Ìgbà yìí a máa rẹwà púpọ̀.
NaijaTV gbe sita wipe, igba meji ọtọọtọ ni pasitọ naa fipa ba oun lo pọ.
Kìí ṣe ààrùn Covid-19 ló pa adájọ́ àgba ìpínlẹ̀ Kogi-Kọmísọ́nà ìlera Ìgbà mẹ́jọ tí awuyewuye wáyé lórí ìṣèjọba Ajimobi!
Magu ni pataki apero yii ni lati gbogun ti iwa ibajẹ ati lati dẹkun gbogbo iwa iluni ni jibiti ori ẹrọ ayelujara.
 iye ìwọ ̀ n owó tí àrùn náà ngbà ni a ṣírò sí bíi bílíọ ̀ nù 3 usd lọ ́ dún .
Bí o bá wà ní agbègbè tí wọ́n ti ń pọ́n talaka lójú, tí kò sì sí ìdájọ́ òdodo ati ẹ̀tọ́, má jẹ́ kí èyí yà ọ́ lẹ́nu.
Ọba dìde kúrò ní ibi àsè náà pẹlu ibinu, ó jáde lọ sinu àgbàlá ààfin.
Ó ń bọ̀,ó ń fò lórí àwọn òkè ńlá,ó sì ń bẹ́ lórí àwọn òkè kéékèèké.
láti inú ẹ̀yà Josẹfu, tí í ṣe ẹ̀yà Manase, ó rán Gadi, ọmọ Susi; 
asa olugbe kuba ni orin , ijo ati esin .
” Ó bá bọ́ sóde, ó sọkún gidigidi.
Sùgbọ́n lẹ́yìn tí àwọn ọmọ Nàìjíríà kan ta ko àjọ EFCC pé wọ́n ń gbè lẹ́yìn ẹnìkan ni EFCC ti yọ àtẹ̀jáde náà kúrò lóri Twitter wọn.
Eleyi wa ninu atẹjade kan ti NUPENG ati ipinlẹ jọ fi sita lọjọ Aje.
Ohun ẹkẹrin ni lati ni ẹkọ ati imọ nipa ọna ati daabobo ara ẹni gba ọwọ awọn onimọ nipa eto aabo.
"nínú àwọn onírúiyepúpọ ̀ tí wọn ní ayípadà kan , àwọn ọ ̀ rọ ̀ wọn únjẹ ́ títò gẹ ́ gẹ ́ bíi ìyí wọn , bóyá ní bi "" àwọn agbára "" x "" ṣe ún kéré sí "" , pẹ ̀ lú ọ ̀ rọ ̀ tó ní ìyí títóbijùlọ níbẹ ̀ rẹ ̀ , tàbí ní bí "" àwọn agbára "" x "" bá ṣe ún pọ ̀ sí "" ."
Àwọn mọ̀lẹ́bí Whitmer ti ní ìfẹ́ púpọ̀ sí iṣẹ́ ìtumọ̀ Ìwé Ti Mọ́mọ́nì.
Wọn ni nigba ti wọn ko da awọn lohun lo mu ki awọn fun ẹlomiran to fẹ ra ilẹ naa ni iwe aṣẹ lori ilẹ yi kanna.
votes), ti egbe oselu PDP si ni, apapo ibo (283,847 votes)</.
Ileejọ sọ pe o jẹbi ẹsun idigunjale, ipaniyan, idaluru ati bẹẹ bẹẹ lọ, ti adajọ si ni ki wọn lọ fi ẹyin rẹ ti agba, ki wọn rọ ibọn fun oun ati awọn ikọ adigunjale rẹ, titi ti ẹmi yoo fi bọ lara rẹ Ọjọ ni ọjọ ti wọn fi ẹmi Oyenusi ti agba, pẹpẹyẹ pọnmọ.
Ikọ̀ Boko Haram àti gbogbò àwọn tó ń sàtìlẹyìn fún wọn kò ní rí ọdún 2021 - Pásítọ̀ Adeboye Asaaju ẹgbẹ oselu PDP naa ni oun seranwọ fun Fayose lati moke ni igba meji gẹgẹ bii gomina ipinlẹ Ekiti, o si ya oun lẹnu pe o le pada ri oun fin.
Lamidi Adeyẹmi: Ọmọọba mẹ́wàá ló du òyè pẹ̀lú Adeyẹmi, tó sì já mọ́ ọ lọ́wọ́
Àwọn àgbààgbà ninu àwọn eniyan náà yóo gbé ọwọ́ wọn lé orí akọ mààlúù yìí níwájú OLUWA, wọn óo sì pa á níbẹ̀.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Fake Kidnap: Ọlọ́pàá Eko ń wá arákùnrin tó parọ́ gba owó ìjínigbé 700k lọ́wọ́ mọ̀lẹ́bí ọ̀rẹ́bìnrin rẹ̀ 8 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Oríṣun àwòrán, LagosPoliceng Ọwọ palaba arabinrin kan to gbimọran pẹlu ọrẹkunrin r pe ko ji oun gbe ti ṣegi.
Ó tú àwọn tí àwọn ọba dè mọ́lẹ̀,ó sì so ẹ̀wọ̀n mọ́ àwọn ọba gan-an nídìí.
Láti inú oṣù kẹta tí owó epo ti jáwálẹ̀ lágbàyé ni PPPRA ti bẹ̀rẹ̀ ìgbésẹ̀ tuntun yìí ti àwọn ilé epo aládàni míràn sì ketí ọ̀gbọin sí ikéde olóṣooṣù náà.
O kì bá tí wọ ìlú àwọn eniyan miní ọjọ́ ìpọ́njú wọn;o kì bá tí fi wọ́n ṣẹ̀sínní ọjọ́ àjálù wọn;o kì bá tí kó wọn lẹ́rùní ọjọ́ ìpọ́njú wọn.
Awakọ oloogbe sọ fun BBC Yoruba pe ọjọ Aiku ni oun ati ọga oun mu afurasi alase naa to jẹ ọmọ orilẹede Togo,wa lati Ondo, ti wọn si fura si pe o gun ọga rẹ pa lọjọ kẹrin.
Iba ọrẹrẹ ti a tun mọ si iba lassa ti gbilẹ lorilẹede Naijiria fun asiko diẹ bayii eleyii to ti gba ẹmi ọpọlọpọ.
Kọmiṣọnna for ohun amuṣagbara ati ohun alumọnni nipinlẹ Eko, Olalere Odusote ati igbakeji aarẹ NUPENG, Solomon Kilanko lo jọ buwọ luwe naa.
Irú ẹni bẹ́ẹ̀ óo fẹ́ràn láti máa ṣe òfintótó ọ̀ràn, ati iyàn jíjà, àwọn ohun tí ó ń mú owú-jíjẹ, ìjà, ìsọkúsọ, ìfura burúkú, 
Ṣugbọn iye bíríkì tí ẹ̀ ń mọ tẹ́lẹ̀ kò gbọdọ̀ dín!
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Cancer: Àṣe ara mi ni iso ti n run gbogbo bí mo ṣe n ṣèrànwọ́ lórí jẹjẹrẹ O eso bi ''apple'' ati ''strawberries'' jẹ eso aṣara loore ati pe ko ni jẹ ki ọra pọju ninu agọ ara.
iselu , ni eyi ti o mu idagbasoke ba eto ijọba tiwa-n-tiwa lorile ede Naijiria.
Nítorí ẹ kò sọ ohun tí ó tọ́ nípa mi, bí Jobu iranṣẹ mi ti ṣe.
Inú OLUWA kò ní rọ̀ títí yóo fi ṣe ohun tí ó pinnu lọ́kàn rẹ̀.
Nígbà tí àwọn ọmọ àwọn wolii tí wọ́n wà ní Jẹriko rí i, wọ́n ní, “Ẹ̀mí Elija ti wà lára Eliṣa!
Ile itaja rẹkọọdu, The Jazzhole ti o wa ni opopona Awolọwọ ni ilu Eko bẹrẹ karakata ni ọdun 1991 ni ile kekere kan ni apa ibi kan nilu Eko kan naa.
À ń gbadura sí Ọlọrun pé kí ẹ má ṣe nǹkan burúkú kan, kì í ṣe pé nítorí kí á lè farahàn bí ẹni tí kò kùnà, ṣugbọn kí ẹ̀yin lè máa ṣe rere, bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé àwa dàbí ẹni tí ó kùnà.
 Ṣùgbọ́n wọ́n bí agbábọ́ọ̀lù náà sí ilú Dublin ní
" Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Fasoranti: Dẹ́rẹ́bà tó wa ọmọ Fasoranti ṣàlàyé bí wọ́n ṣe pa Funke Olakunrin Kii ṣe pe mo n gba ẹnu rẹ sọrọ, ẹnikẹni lo le sọ niwaju ile ẹjọ pe mo ṣe nkan ti mo ṣe labẹ pe wọn mu inu bi mi.
Ọ̀wọ̀n ìkùukùu kò fi ìgbà kan kúrò níwájú àwọn eniyan náà ní ọ̀sán, bẹ́ẹ̀ náà sì ni ọ̀wọ̀n iná ní òru.
Sugbọn ijọba lai ba wa sọ tẹlẹ, lọ fi ofin de lilo kẹkẹ Maruwa O fikun pe awọn akanda ẹda yii setan lati fọwọsowọpọ pẹlu ijọba, amọ o wa n beere pe, se ijọba setan lati fun awọn lowo ranpẹ, kawọn fi joko sile tabi kawọn maa gba owo osu lọwọ wọn."
Oríṣun àwòrán, Others Amọ, Khalil fikun pe ipinnu awọn ko tun mọ si pe awọn gba ifipabanilọpọ laaye, abi awọn n ṣe agbatẹru fun awọn to n wu iwa buruku yii.
Nígbà tí wọ́n dínkù, tí a rẹ̀ wọ́n sílẹ̀,nípa ìnira, ìpọ́njú, ati ìṣòro,
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Nigeria: Awọn asofin nwadi ibiti owo ẹyọ lọ 13 Èrèlè 2018 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ọwọngogo owo wẹẹrẹ ti mu isoro ba karakata awọn mẹkunnu Awọn asofin agba lorilẹede Naijiria ti pinnu lati se iwadi lori ọwọngogo awọn owo ẹyọ lẹyin ti ile ti jiroro lori bi awọn owo wẹẹrẹ yi se jina si ikawọ awọn araalu.
Nígbà tí ó bá ti wọ ẹ̀sìn tán, ẹ wá sọ ọ́ di ẹni ọ̀run àpáàdì ní ìlọ́po meji ju ẹ̀yin alára lọ.
'Ìjà fún ìdájọ́ òdodo lórí ìyá mi tí wọ́n ṣekú pa' Irọ́ ni ò,ọwọ́ wà kò tí tẹ afurasí to jí olórí ìlú Buhari gbé Thai king: Ọ̀nà wo ní ẹ̀ṣọ́ ọba gbà di olorì láàfin?
Àwọn ọmọ Naijiria ti wá n fi èrò wọn hàn lórí ọ̀rọ̀ nàá lórí ìkànni Twitter.
isuna odun 2019, yoo je ipenija fun ijoba oun lati mu ipinnu ti yoo je  ki igbe aye rọrun fun awon omo orile ede
Awọn ti ofin tuntun yi kan Bukola Saraki (Aare ile asofin agba).
"Genevieve ni ""itanra ẹni jẹ ní kí obinrin maa ro pe oun le mu ki ọkunrin nifẹ oun nipa fífi ara rẹ silẹ fun Ibalopọ."
Ibrahim di ọ̀gá àgbà àjọ NYSC 26 Ìgbé 2019 Oríṣun àwòrán, NYSC Àkọlé àwòrán, NYSC Ile iṣẹ ologun orilede Naijiria ti yan Ọgagun S.
N óo tún mú kí ọkàn Farao le, yóo lépa yín, n óo sì gba ògo lórí Farao ati ogun rẹ̀, àwọn ará Ijipti yóo wá mọ̀ pé èmi ni OLUWA.
Ilu Ìjàyè yìí jẹ́ ìlú kékeré kan tí wọ́n dá silẹ lọ́dún 1785, o si wà lójú ọna Ibadan si Isẹyin, tí gbogbo wọn wa ni Ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́ báyìí.
Rape Castration: Ìpínlẹ̀ Bauchi láwọn náà fẹ máà tẹ àwọn afipábánilopọ̀ lọ́dàá bíi ti Kaduna
Bí mo bá dé ọ̀dọ̀ àwọn ìbátan òun, tí wọ́n bá kọ̀, tí wọn kò jẹ́ kí ọmọbinrin wọn bá mi wá, ọrùn mi yóo mọ́ kúrò ninu ìbúra tí mo bú.
Èmi sì ní Oluwo tilẹ̀ Iwo, kò sí ìgbìmọ̀ ọba kankan tó lè ní kí ń rọ́ọ́kún nílé - Oluwo Toyin Abraham ọkọ rẹ̀ àti Ire ní London, Odunlade 'kòlábò' pẹ̀lú Mercy Aigbe Èlé owó iná ọba kọ́ ló kàn, ẹ kọ́ ṣàtúnṣe sí ìlànà àdánú tẹ́ ń ṣe fún wa - Iléeṣẹ́ apínná sọ fún ìjọba Eleyi ni wọn fa titi, ki ile ẹjọ to gba wọn laye lati lọ yanju ọrọ naa ni tubi inubi laarin ara wọn.
Awọn gbajugbaja ileeṣẹ agborinjade bii Tabansi records, CBS Nigeria, Interscope records ni Majek Fashek ba ṣiṣẹ nigba ti orin rẹ n gberu.
Love Making at Old Age: Eré ìfẹ́ wa kò wà láti bímọ, a kàn ń tẹ̀ẹ́ sójú rẹ̀ ni
eto idibo  aare naa jẹ aseyọri.
Tolani fẹran lati maa wo ere idaraya bọọlu alajusawọn ati ko maa tun ẹrọ kọmputa ṣe tabi ko kuku maa kawe akagbadun ninu ile.
Amotekun ni oun ti gbe igbesẹ lati se ipade pẹlu awọn lọbalọba ni ẹkun naa lati dena iru iwa bayii.
Ṣugbọn agbẹnusọ ajọ EFCC, Toni Orilade ni, Fayose kan n lo ọpọlọ awọn ara ilu lasan ni.
A ó máa mú ẹ̀kúnrẹ́rẹ́ ìròyìn náà wá fún un yín.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Toyin Atoyebi mechanic: Ẹ wo Toyin, ọmọbinrin ọdún 16 tó ń tún skadà àti gẹnẹrátọ̀ ṣe ní Ohun ti a n gbọ ni pe ọpọ lo farapa ti awọn agbesunmọmi yi si gba ọpọ ọkọ lọwọ wọn.
Òwe Yorùbá ni “Ọbẹ̀ tó dùn, owó ló pá”, ṣùgbọ́n kò ri bẹ̃ fún ẹni ti kò mọ ọbẹ̀ se.
Wọ́n fi ajinde ti Jesu ṣe àpẹẹrẹ.
Akoko ti aawọ wa laarin Afonja ati Aole yii ni Shehu Alimi ati awọn eeyan rẹ, tii ṣe ẹya Fulani ja ogun itankalẹ ẹṣin Islam de ilu Ilorin níbi ti Afonja n gbe Afọnja ko gbe Ọyọ nitori pe eewọ ni ki Aarẹ Ọna Kakanfo ba Alaafin gbe nilu Oyo, agbo meji ko lee mu omi ninu koto kan ṣoṣo.
Omiyalé ní Ghana, èèyàn 28 dolóògbé!
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Kudirat Abiola: Akọni obìnrin tó jẹ́ igilẹ́yìn ọgbà fún ọkọ rẹ̀ 4 Òkùdu 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 5 Òkùdu 2019 Oríṣun àwòrán, Yusuf A Àkọlé àwòrán, A bí Kudirat Abiola ni ọdún 1951 ní ]ilú Zaria, òun ni ìyàwó keji ti Abiola fẹ́ tó si bi ọmọ mẹ́fa.
Omi inú agbada náà sì ni àwọn alufaa máa ń lò láti fi wẹ̀.
Àwọn ni òtítọ́ òwe yìí ṣẹ mọ́ lára pé, “Ajá tún pada lọ kó èébì rẹ̀ jẹ.
lawujo, ti awon miiran si n padanu emi won nipase ohun ti a le e dena ko maa
"Ko si oṣere to ma a sọ pe oun ko se aṣiṣe ri .
Ní ètò ìtàkùrọ̀sọ wọn, wọ́n gbé orí yìn fún ìpolongo Ohùn Àgbáyé tí ó ṣe iṣẹ́ ribiribi tí ó mú àwọn wà láyé.
Ṣugbọn Joaṣi dá àwọn tí wọ́n dìde sí Gideoni lóhùn, ó ní, “Ṣé ẹ fẹ́ gbèjà oriṣa Baali ni, àbí ẹ fẹ́ dáàbò bò ó?
Bia ta n gbe kiri yii, ni awọn oloyinbo ni pe o ni ohun ti a n pe ni 'Calorie' eyi to n mu ki eeyan sanra, ti ohun mimu naa si wuwo ninu ara.
5 Ẹrẹ̀nà 2020 US 2020 election: The ultimate celebrity endorsement quiz2 Ẹrẹ̀nà 2020 US election 2020: Five charts on the Democratic race to take on Trump2 Ẹrẹ̀nà 2020 US election 2020: Meet the Democratic candidates vying to take on Trump5 Ẹrẹ̀nà 2020 Bernie Sanders: Who is the Democratic White House hopeful?
Eniyan ogun lo padanu ẹmi wọn ninu ikọlu to waye labule Birane ni ijọba ibilẹ Zurmi lọsẹ to kọja ni Zamfara.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Tunde Kelani k'ẹdun iku Akinwunmi Ishola Ọjọgbọn Akinwunmi Ishola (1939 - 2018) Olukọni to yanranti, onkọwe agba lorilẹede Naijiria ti o ṣiṣẹ fun igbega ede Yoruba Wọn bii nilu Ibadan ni ọdun 1939, ti o si lọ si Ile-ẹkọ Methodist ati Wesley College.
Ìsinmi ilẹ̀ yìí ni yóo mú kí oúnjẹ wà fun yín: ati ẹ̀yin alára, tọkunrin tobinrin yín, ati àwọn ẹrú, ati àwọn alágbàṣe yín, ati àwọn àlejò tí wọ́n ń ba yín gbé, 
Ni ọjọ kejila oṣu kẹwaa ọdun 2020 ni ijọba ipinlẹ Eko kede wiwọle ni Ọjọ kọkandinlogun oṣu kẹwaa.
Amọ o ni gomina ana, Abiọla Ajimọbi ko fontẹ lu ibeere awọn, ti wọn si n rọ ijọba to wa lode nipinlẹ Ọyọ bayii, labẹ gomina Seyi Makinde lati dahun si ibeere naa, gẹgẹ bi akẹẹgbẹ rẹ ni ipinlẹ Ọsun ti se.
Àwọn ta ni ó búra pé wọn kò ní wọ inú ìsinmi òun?
Dino Melaye ní ikọ́ sẹ́mìí-sẹ́mìí, ìlera rẹ̀ jẹ wá lógún - Ẹbí Dino ‘DJXgee lọ sòde eré lọ́jọ́ ọdún tuntun láìmọ̀ pé yóò gbẹ̀mí ara rẹ̀’ Àwọn àṣà àti ìse tó yọ obìnrin sílẹ̀ nílẹ̀ Yorùbá Iko BBC Yoruba tọ Woli Kasalai lọ lati beere ọrọ nipa iṣe rẹ ati awọn nnkan miran to fi mọ iroyin to n ja rainrain nipa oun ati iyawo rẹ ti wọn ni o le sita.
Ìròyìn tó ń tẹ̀ wá lọ́wọ́ ni wí pé ìlera pípé ni olówó oníṣòwò náà wà súgbọ́n ó fara pa lọ́wọ́ àti ẹsẹ̀ nítorí ẹ̀wọ̀n irin tí wọ́n kò síì lọ́wọ́.
Èyí ni ó mú kí Ìwé Mímọ́ ṣẹ tí ó sọ pé, “Abrahamu gba Ọlọrun gbọ́, Ọlọrun sì kà á sí olódodo.
Ohunkohun tí o bá sì tú ní ayé, ó di títú ní ọ̀run.
darapo mo awon akegbe re lati orile ede Afirika ati Europe nibi ijiroro ti yoo
Ọmọbìnrin ọdún 25 gún ọ̀rẹ́kùnrin rẹ̀ pa nítorí ó ní ko lọ ṣẹ́ oyún Adebayo ni lẹyin toun ati awọn ọmọ iṣẹ rẹ mu awakọ obinrin kan Didi Ekanem to n gba One Way lọjọ Kejidinlogun oṣu Kọkanla, wọn gbe ọkọ rẹ lọ si Alausa ni ibamu pẹlu ofin.
Eyi to mu ẹmi ọkan lọ laarin wọn.
Lẹ́yìn tí wọ́n ti forí-korí, wọ́n fi owó náà ra ilẹ̀ amọ̀kòkò fún ìsìnkú àwọn àlejò.
Wà á bí ọkùnrin, bí obìnrin, tí ọjọ́ bá yá o.
Oríṣun àwòrán, AfricanDrumFestival Àkọlé àwòrán, Aarẹ Muhammadu Buhari ṣe ileri atilẹyin fun idagbasoke aṣa Ninu ọrọ tirẹ,Aarẹ Muhammadu Buhari ti minisita fun eto iroyin ati aṣa, Alhaji Lai Mohammed ṣoju fun ni iṣejọba to wa lode bayii ṣetan lati lo anfani to soodo si ẹka aṣa fun igbeleke ọrọ aje awọn eeyan orilẹede naijiria.
Olówó-ayé, mo fẹ́ ìtàn kékeré kan fún ọ lónìí mo sì fẹ́ kí o ṣe àkíyèsí ìtàn náà bóyá o lè rí ọgbọ́n kan tàbí méjì fà yọ nínú rẹ̀.
Ṣugbọn itan naa fi ye ni pe ki Aole to gba lati ku gẹgẹ bi Afonja ti paṣẹ fun, Alaafin Aole ṣẹ epe nla fun iran Yoruba, Epe yii ni eyi ti awọn kan gba pe egun naa lo n ja iran Yoruba titi di oni, ti imọ wọn ko fi ṣe ọkan.
Nítorí pé òun alára wà lábẹ́ àwọn olùtọ́jú, ohun ìní rẹ̀ sì wà ní ìkáwọ́ àwọn alámòójútó títí di àkókò tí baba rẹ̀ ti dá.
Aare Buhari wa n ro awon adari joba ati ajo agbaye lati fowosowopo pelu orile ede Naijiria lati gbogun ti iwa ibajẹ yii.
Elija dá a lóhùn pé, “Èmi ni, lọ sọ fún oluwa rẹ, ọba, pé èmi Elija wà níhìn-ín.
21 Èbibi 2018 Eyi ni awọn akojọpọ iroyin ti toni.
Ogbeni Godwin Ezeemo to je okan lara awon onile ise nla to n ro awon ohun eelo ni Naijiria ti parowa fawon eniyan orile-ede yii lati tubo maa ra awon ohun eelo agbelero ti a se nile funra wa ki a le jo so eto oro-aje Naijiria ji papo.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù 80 years Masters Graduate: Mo ṣi máa kàwé gboyè PhD Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ 80 years Masters Graduate: Mo ṣi máa kàwé gboyè PhD 4 Òkùdu 2019 Haruna Igboro jẹ apẹrẹ ẹni to maa ni ọkan lile ninu ohunkohun to ba fẹ ṣe.
Ewe, eyi ni o sokunfa bi ile biritiko se se gafara si isejoba re, ti won si yo owo kuro nipa ipese iranwo owo ina fun idagbasoke eto oro aje orile-ede naa.
O ki ọba Iwo bo se yẹ, to si tun mu ẹbun dani fun ọba.
Iya àgbà naa sọ ninu fidio kan lọdun to kọja pe Lootọ ni Daniel ba aye mi jẹ, sugbọn mi o gbagbọ pe gbigba ẹ̀mí rẹ yoo mu ayipada ba mi""."
Imọ ti wọn ni ko ju eyi ti wọn yoo fi ṣe owo nọbi wọn loju popo orilẹede Italy.
"Sùgbọ́n fún àwọn to ṣe àisàn tó wà nílé ìwòsàn, èyí túmọ̀ sí pé ""T Cell yìí kò ṣiṣẹ́ fún wọ́n, ọ̀pọ̀ T Cell ẹlomíràn sì ló ti fara kásá, èyí sì buru jái, nítori yóò tún pa àwọn sẹ́ẹ̀lì míràn ninu ara."
Amọ sibẹ sibẹ, mo duro lẹyin awọn ọmọ Naijiria digbi lati ṣe iwọde alafia.
 O tẹsiwaju pe to ba jẹ niti emi ni o, Access bank ti di oku si mi, mi o si fẹ ni nnkankan ṣe pẹlu wọn mọ.
 Bayii Aba nipinle Abia ni a ti n se ise olopo yanturu lasiko yii ni eyi to ye ko kari laipe.
 bákan náà ni àwọn awúsá náàvma ń lu sákárà níbi ayẹyẹ wọn pẹ ̀ lú .
Àwọn ni yóo máa ru Àgọ́ náà ati gbogbo ohun èlò tí ó wà ninu rẹ̀, wọn yóo sì máa ṣe iṣẹ́ ìsìn níbẹ̀.
Lagos School resumption: Ìpínlẹ̀ Eko kéde ọjọ́ tuntun Jan.
Titi di igba ti Aarẹ yan John, Ibe kachikwu to jẹ minisita abẹle ni alaga igbimọ adari ajọ NNPC.
Ìlérì náà ni a fi fún Joseph àti Oliver pé nígbàtí àkókò bá tó òyè àlufáà gíga yìí yíó di fífi lé wọn lórí.
Ẹka katakara ile isẹ Multichoice to se agbekalẹ eto naa pẹlu awọn onigbọwọ wọn sọ pe lai si ani ani, abala ọtun eto yii seleri lati jẹ eyi to dun ju ninu gbogbo apapọ eto Big Brother to wa nilẹ Afirika.
Ó ní,‘Lọ sọ fún àwọn eniyan yìí pé:Ẹ óo fetí yín gbọ́, ṣugbọn kò ní ye yín;Ẹ óo wò ó títí, ṣugbọn ẹ kò ní mọ̀ ọ́n.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Malaga:Brown Ideye di aayo agbabọọlu tuntun 29 Sẹ́rẹ́ 2018 Oríṣun àwòrán, Ideye Brown/Twitter Àkọlé àwòrán, Ẹgbẹ agbabọọlu Malaga tọwọ bọ iwe adehun pẹlu Brown Ideye Atamatase agbabọọlu to jẹ ọmọ orilẹẹde Naijiria, Brown Ideye ti darapọ mọ ẹgbẹ agbabọọlu Malaga fun osu mẹfa.
Ile-ise olopaa, Nigeria Police Force yoo gba, “bilionu mẹ́tàdínlọ́gbọ̀n le lọ́ọ̀dúnrún naira (=N=27, 341,317,432.
Ise yin ni I se pelu omoniyan, ko si owo ti o le san awon ise ribi-ribi ti e n gbe se.
”Joabu dá a lóhùn pé, “Mò ń gbọ́.
Ṣugbọn baba ọmọbinrin náà rọ̀ ọ́ pé kí ó jẹ oúnjẹ díẹ̀ kí ó tó máa lọ, kí ó lè lágbára.
Abadofin náà tun fààye gba ìdásílẹ̀ àjọ Amọtẹkun, ti ko si gbọdun din ni sáà ọdun mẹrin.
Tinubu parí aáwọ̀ Ambode àtàwọn aṣòfin ìpínlẹ̀ Eko #BBCNigeria2019 Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'A ni òfin púpọ̀ ní Naijiria ṣùgbọ́n a kò bọ́wọ́ fún un ni' Oríṣun àwòrán, AFP Àkọlé àwòrán, Awọn ọdọ Naijiria a ma gbaruku ti Sowore lọpọ ibi to ba ti n ṣe ipolongo Lọdun 1989 o kopa ninu iwọde awọn akẹkọ fasiti ilu Eko(Unilag) eleyi ti awọn akẹkọ ṣe lati tako awọn gbedeke to rọmọ owo iya ọgọfa miliọnu ti ijọba fẹ gba lọwọ ile ifowopamọ agbaye nii IMF.
Ẹ kún fún àdúrà nítorí ìdájọ́ kóòtù àgbà lórí gómìnà l'Ọ́ṣun-APC Ọṣun Don Jazzy ke si igbakeji aarẹ Osinbajo lati rii pe Sẹnetọ naa ko ṣai jiya iwa to hu yii.
Ọjọ Iṣẹgun ni Miller kede sita pe oun ti ni coronavirus.
Nítorí pé ọkàn mi kún fún ìyọnu;mo sì súnmọ́ isà òkú.
Awọn gan an lo n ba ẹka ofin jẹ ni Naijiria.
Daniel Ekugo, to jẹ ọga agba fun ileeṣẹ to n daabo bo ẹtọ awọn onraja, fi idi rẹ mulẹ pe lootọ ni awọn oniṣowo kan n lo 'sniper' lati fi tọju ẹwa ti wọn n ta, ati lati fi pa awọn kokoro ro n sapamọ sinu ẹwa.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Lagos: Olùkọ́ fipá bá akẹ́ẹ̀kọ́ girama lòpò nítorí máàkì 29 Ẹrẹ̀nà 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 30 Ẹrẹ̀nà 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Akẹ́ẹ̀kọ́ obìnrin ilé iwé girama Fazir-I-Omar ní agbègbè Iwaya, Yaba ní ìpínlẹ̀ Eko ló fi ẹjọ́ olùkọ́ náà sùn ilé isẹ́ ọlọ́pàá.
Attack to woman is attack to the nation #BudgetKE2019 #JusticeForFatumaGedi pic.
Lọwọ-lọwọ, aarẹ orilẹ-ede Tanzania, Guinea-Bissau, ati Comoros ti ṣeto lati ra agbo naa.
Ileesẹ ologun ati ọlọpaa ti n tako ra lori idi tawọ̀n ologun se yinbọn pa ọlọpa mẹta ati araalu kan lasiko ti wọn gbe gbajumọ ajinigbe kan.
Bakan naa nibi eti adura to waye ni Mọṣalaṣi Sẹnetọ Ishaq Abiola Ajimobi, ori ayelujara ni wọn ti ni ki gbogbo eeyan maa wo o.
Ọkọ̀ aképo náà forí sọ òpó iná ló fi laná ní Gowon Estate l'Èkó Òjò ló lè mú kí ìtànkálẹ̀ àrun ìgbẹ́ ọ̀rìn má tètè dópin ni Eko- Iléeṣẹ́ ìlera Emir Bornu lé àwọn aṣẹ́wó léré, ó ní kò sáyè fúnwọn nípìnlẹ̀ òun Burna Boy fẹ́ yọ̀ǹda owó tó bá pá lóde àríyá f'áwọn tó farakásá ìṣẹ̀lẹ̀ Xenophobia O ṣójú mí kóró bí wọ́n ṣé fí àdó olóró pa Dele Giwa lọdún 1986- Soyinka Ta ni Ken Saro-Wiwa tí ìjọba ológun sekúpa?
Igbéyàwó àti ayẹyẹ ṣi ṣe ni òkèrè, jẹ́ ikan ninú àṣà ti ó mba owó ilú jẹ́.
”Ọkunrin náà dáhùn pé, “Bẹ́ẹ̀ ni.
soro ninu atejade kan ti o gbe sita pe awon ko ni faramo  ẹgbẹrun mẹ́tàdínlọ́gbọ̀n ekunwo owo osu ti ijoba
Nítorí ní wakati kan ni ìparun dé bá ọ.
Wọn bọwọ fun ara wọn, inu ọkọ dun, inu iyawo naa si dun pẹlu.
Ajax kọkọ gbo ewuro soju Tottenham nile wọn pẹlu ami ayo kan sodo ninu ipele akọkọ ifẹsẹwọnsẹ to kangun si aṣekagba idije Champions League.
Àwa àgbọ̀nrín kì í gun igi nítorí àwa yàtọ́ sí ejò àti ọ̀kẹ́rẹ́, bẹ́ẹ̀ni àwa kò bá ọ̀bọ àti ìjímère mu.
2007-N272bn 2008 -N631bn 2009 -N469bn 2010 -N667bn 2011 -N2.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: APC fẹ́ fa ìṣọwọ́-ṣiṣẹ́ ẹ̀rọ káàdì ìbò sẹ́yìn - Atiku Ẹ́ wo iye ààrẹ Nàíjíríà tó sọ̀rọ̀ ìjayà lásìkò ìbò Àwọn ìgbà tí ẹ̀ṣọ́ aṣọ́bodè ti pànìyàn lọ́nà àìtọ́ Ihalẹ Buhari: PDP na ìká àbuku sí Buhari lẹyìn ìpàdé wọn Nigba to n salaye siwaju lati tako ẹsun naa, Onilu ni awọn isẹ rere ti ẹgbẹ APC ti se sẹyin ni Naijiria ni yoo sisẹ fun, kii se sise magomago ibo lo gbẹkẹle.
Ijoba orile-ede Naijiria ti tenumo ipinnu re lati maa seranwo fun awon obinrin lojuna ati ron won lowo lati maa sojuse won gege bi abiamo.
Gomina Yahaya Bello ti Kogi àti David Lyon ti Bayelsa gba ìwé ẹ̀rí INEC Fásítì Babcock lé akẹ́kọ̀ọ́bìnrin tó hàn nínú fídíò ìbálòpọ̀ lọ sílé Nigba to n fidi isẹlẹ naa mulẹ, agbẹnusọ fun ileesẹ ọlọpaa nipinlẹ Ọyọ, Gbenga Fadeyi salaye pe agbegbe ile Kọmiṣọ́nna naa ni Olunde Academy nilu Ibadan ni isẹlẹ naa ti waye.
Àwọn àtúnṣe tókọjá sí ojúewé yìí
Ọgbọn ọjọ oṣu Kẹfa ọdun 2020 ni gomina ọhun kede pe oun ti ti lugbadi arun naa, lẹyin ọjọ diẹ si ni kọmiṣọna eto ilera ipinlẹ ọhun, Wahab Adegbenro dagbere faye.
Nígbà tí ìyàwó mi yọ sí i ó bẹ̀rẹ̀ sí bínú, ó ní, Ó ti pẹ́ jù lónìí, ìgbà tí o mọ̀ pé o kò lé wá kí ní ṣe tí o kò sọ bẹ́ẹ̀ lánàá, n kò fẹ́ kí ènìyàn máa fi mi ṣe fáàrì tí kò níláárí kan rárá, o kò gbọdọ̀ ṣe bẹ́ẹ̀ mọ́ láéláé o.
Ní gbolohun kan, ẹ̀yin ará mi, ẹ máa yọ̀ ninu Oluwa.
 Ìgbìyànjú mẹrin ọ ̀ tọ ̀ ọ ̀ tò lati já ọkọ ̀ náà gbà jásí pàbó lẹ ́ yìn ọdún náà ní ọdún 2010 àti 2011 .
O ni Atiku pẹlu ẹbi rẹ ko ṣe nkan etufu debi wi pe yoo maa kiyesi ẹkule.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Lagos King: Mátikú ọba tó lo lo ọdun mẹta lórí oyé latari rogbodiyan Eko Ṣugbọn ṣe ootọ ni pe ọmọ tuntun ti Ooni ṣẹṣẹ bi ni yoo jẹ Ooni lọjọ iwaju?
Nígbà tí ó di ọjọ́ kan, Ẹlẹ́dàá mi ní kí n lọ mu un wá, kí àwọn aráyé baà lè mọ̀ pé kò sí àìṣòdodo lọ́wọ́ Olódùmarè, olúkulùkù kò ní ṣàìjèrè iṣẹ́ rẹ̀, yálà ní òde ayé, tàbí ní òde ọ̀run.
Oríṣun àwòrán, Olayomi Koiki Nigba to n sọrọ nibi ipejọpọ naa, Sunday Igboho koro oju si bi ọpọ eeyan, to n leri leka tẹlẹ, se sa sẹyin lati bawọn peju se iwọde naa.
” Guterres tun so pe awon omo leyin ijo musulumi ti Islamic Movement ti n fehonu han lori bi won se ti oga won mo atimole ati nipa wahala to be sile ni Niger Delta ati bi awon ajijagbara tun ti n pariwo pe awon yoo tun bere lati maa se ikolu lorile ede Naijiria.
” Mo bá dáhùn pé, “Okùn ìwọ̀n àwọn mọlémọlé.
Ọ̀rọ̀ yìí kò kọ́kọ́ yé Ọba ṣùgbọ́n nígbà tí ìgbín tí fọwọ́ sọ̀yà pé òun yíò fi ojú ẹni tí ó pa abuké Ọba hàn, Ọba kò Jáà níyàn ó ṣe bí ó ti wí.
Awọn ipinlẹ yooku ni : Enugu-20 Kaduna-11 Oyo-11 Plateau-8 Ondo-7 Anambra-4 Nasarawa-3 Osun-3 Ebonyi-2 Imo-2 Benue-1 Katsina-1 Ogun-1 Èèyàn 163 ló tún ṣẹ̀ṣẹ̀ ní àrùn coronavirus ní Nàìjíríà Ipinlẹ Eko ati Kaduna lo wa ni ipo kinni, ati ikeji, ninu esi ayẹwo ti ajọ NCDC gbe sita nipa awọn to ni coronavirus.
Ni ipari O gba awon agbe nimoran lati tubo dako lopo yanturu ki ounje le sinwa bo ni Naijiria.
”Aare Buhari tun gba awon ile-ise onimo ero igbalode niyanju, paapaa julo awon to n mojuto ero ayara bi asa lati mo awon ona kan tabi keji ti won yoo gba lati dekun wahala eleyi ti ero ohun dasile  lawujo ,“A ko lee laju wa sile ki talubo ko wo, fun idi eyi, mo gba awon ile-ise onimo ero yii niyanju lati wa bi won yoo se dekun  wahala bi ija ẹsin, ija ẹlẹyamẹya, iroyin to lee da wahala sile laarin ilu kan si ikeji, tabi eleyii ti o lee tu awon orile ede kaa  abbl, eyi ti ero igbalode ohun dasile layika ati lawujo wa gbogbo.
Aare Buhari ro awon omo orile-ede Naijiria lati tunbo ku fun adura fun alaafia awon omodebinrin naati won si wa ninu igbekun.
Wọ́n sì ni ki gbogbo ènìyàn maa fójú sónà láti mọ idí abaájọ ńkan ti àwọn fẹ́ ṣe.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Coffee Painter: Adebukola ní kò sí ìrànwọ́ lẹ́yìn ẹ̀kọ́ girama lòun ṣe ń ya àwòrán O ni lẹyin ti awakọ ọkọ akoyọyọ naa n gbiyanju ati wa ọkọ naa jade ninu gọta to bọ ha si lo fọ ọpa epo naa, ti gaasi inu rẹ si fọn sita.
Kogi, Bayelsa Governorship Elections: INEC kéde ọjọ́ tuntun
Oríṣun àwòrán, Getty Images Oríṣun àwòrán, Getty Images Ohun miran to ta abuku ba ifẹsẹwọnsẹ naa ni bi awọn alatilẹyin Tottenham kan ti ṣe n fi eebu eleyameya ranṣẹ si agbabọọlu Chelsea Rudiger.
Ajọ naa kede pe, ohun to fa igbesẹ yii ni arun Coronavirus to ti wa di tọrọ fọnkale yii eleyii to ti mu ki ijọba apapọ paapaa o wọgile idije ere idaraya apapọ orilẹede Naijiria, National Sports festival to yẹ ko waye nipinlẹ Edo lọdun yii.
Olori ile iṣẹ ologun lorilẹede Naijiria Lt.
Gbogbo eeyan lo n kan saara si nigba naa amọ ko pẹ lẹyin naa ti Ajimobi fi ko ọrọ naa jẹ, to si beere fun ipo Sẹnatọ .
Nítorí gbogbo Olórí Alufaa tí a bá yàn, a yàn wọ́n pé kí wọ́n máa mú ẹ̀bùn ati ẹbọ àwọn eniyan wá siwaju Ọlọrun ni.
@nwoguprestige fi fọto ọkunrin kan ti wọn lo fi ẹgbẹrun meji naira(#2000) ranṣẹ si ọmọbinrin to ṣẹṣẹ pade laarin ọjọ mẹta lori Facebook.
OLUWA tún bi mí lẹẹkeji, ó ní, “Kí ni o rí?
Àwọn amòfin kan ninu àwọn Farisi dìde, wọ́n tẹnu mọ́ ọn pé, “Àwa kò rí nǹkan burúkú tí ọkunrin yìí ṣe.
Nítorí Ẹsira fi gbogbo ọkàn rẹ̀ sí kíkọ́ òfin OLUWA, ati pípa á mọ́ ati kíkọ́ gbogbo àwọn ọmọ Israẹli.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Jiti Ogunye: Ìjọba àkóbá lológun gbé kalẹ̀ ni 1999 Ganduje: mo ṣetań lati pèsè ẹkọ ọ̀fẹ́ fawọn Akanda ẹ̀dá Gomina ipinlẹ Kano to ṣe ibura lẹẹkeji, Abdullahi Umar Ganduje ni saa keji oun yii, awọn akanda ẹda a gbadun ẹkọ ọfe lati ile iwe alakọbẹrẹ titi de ti girama ni.
lati da eto ijoba tiwa-n-tiwa pada sorile ede Sudan si n ba egbe alatako sọrọ
Abenugan ile igbimo asoju Yakubu Dogara ti ro awon omo orile ede Naijiria lati je awokose ojise Olorun ninu iwa rere, iwa otito,olufokansin ati alaaanu.
Nìgbà tí Ọba Ìjẹ̀bù -Jẹ̀ṣà bá ń bọ̀ wálé lẹ́hìn ọ̀pọ̀ ọjọ́ tí ó ti lọ̀ ni Ilẹ́ṣà fún ọdún ògún, ọtáforíjọfa ni àwọ̀n ènìyàn rẹ̀ ti gbọ́dọ̀ pàdé rẹ̀.
Yóo fi ọmọbinrin rẹ̀ fún ọba Ijipti ní aya, kí ó lè ṣẹgun ọba Ijipti.
Ti Wasiu ba na mi ni kọrọ, o to eeyan to le na mi, amọ eyi to se ni gbangba lo ku diẹ kaa to.
Peter Fatomilola ní 'Ọ̀gbẹ́ni' lásán ni ọba tí kò rí ọ̀pá àṣẹ rẹ̀ O ṣalaye pe etutu ni wọn o ṣe lati ri ọ̀pá àṣẹ naa, ati lẹyin ti wọn ba da a pada tan, ki gbogbo nkan le tuba, ko le tu ṣẹ.
Eyi ti ó burú jù ni ki èniyàn jade, kó má mọ igbà ti ó ma padà wọlé nipa li lo bi wákàti mẹ́fà tàbi ju bẹ́ ẹ̀ lọ ninú sún kẹẹrẹ fa kẹẹrẹ ọkọ̀, nitori ọ̀nà kò tó, bẹni kò dára, iwà-kuwà pọ̀ fún awakọ̀, ọkọ̀ àti èrò pọ̀ ju òpópó ọ̀nà lọ.
 níṣe ni ó dàbí ẹni tó ṣòwò tí kò jèrè .
" Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Aarẹ MOSOP akoba epo rọbi pọ pupọ fun ayika awọn eeyan agbegbe Ogoni Awọn ẹgbẹ mejeeji ọhun tun kọminu pe ninu iwoye awọn, ko jọ bi ẹni pe ileeṣẹ ọrọ ayika nijọba apapọ ati ileeṣẹ to n mojuto atunṣẹ idibajẹ to waye nipasẹ epo rọbi, HYPREP ṣetan lati ṣe afọmọ idibajẹ ọrọ ayika to sodo si agbegbe Niger Delta.
Wọn kò lè rí ìrànwọ́ tabi anfaani kankan níbẹ̀, bíkòṣe ìtìjú ati ẹ̀gàn.
Ijoba Ipinle Oyo ati ijoba apapo ti pari adehun lori iye
Ajafẹtọ ọmọniyan ati agbẹjọro, Jiti Ogunye ti bu ẹnu ẹ̀tẹ́ lu iṣesi awọn aṣofin to kọ lati se ifọrọwanilẹnuwo fun awọn minisita ti Aarẹ Buhari fi sọwọ si Ile Igbimọ Asofin.
 Àwọn ààmì àìsàn náà lè farahàn lára ènìyàn ní ṣókí , wọn sì lè má farahàn rárá fún ọ ̀ pọ ̀ lọpọ ̀ ọdún .
Kí ni kí á wá wí?
Ìkórìíra náà pọ̀ tóbẹ́ẹ̀ tí ó tún wá ju bí ó ti nífẹ̀ẹ́ rẹ̀ tẹ́lẹ̀ lọ.
ipolongo eyi ti o fun oun ni agbara lati lee se aseyori lori ise oun.
“Ẹ bọ́ sí apá kan kí n lè rí ààyè pa àwọn eniyan náà run ní ìṣẹ́jú kan.
Ṣugbọn awọn ọdọ mẹta ni abule naa ja lẹkun wọle, wọn si ra afẹsunkan naa mu, ki wọn to de e lọwọ ati ẹsẹ.
Nínú èsì kan sí TJournal, tí ó jẹ́ iléeṣẹ́ onímọ̀-ẹ̀rọ àti ìròyìn ẹ̀rọ alátagbà àti orí ayélujára.
Àwọn kan wà tí ojú wọ́n ga,lókè lókè ni ojú wọn wà.
Nigba ti gomina ipinle Eko, Akinwunmi Ambode, eni ti igbakeji re omowe Idiat Adebule so pe, etikun Lekki je eyin adiye ti o niye lori jojo, ti o n wa ona ati mu igberu ba eto oro-aje.
Ìbànújẹ́ nlá ni eléyìí jẹ́ fún gbogbo ará ìlú àti gbogbo Amẹrika lápapọ̀.
ún sile ẹjọ to ga julọ
Igbesẹ yi waye lẹyin ti iwọde #EndSARS gbode kan kaakiri orilẹede Naijiria.
O wa fi kun pe, pẹlu bi ọrọ ti ṣe ri yii, ijijagbara ẹya Yoruba ti n debi to lapẹrẹ.
Oríṣun àwòrán, Others Ọ̀pọ̀ àwọn ènìyàn ló ti bọ́ sórí ayélujára láti fẹ̀hónú hàn lórí ìgbéṣẹ̀ tuntun yìí, wọ́n ni ìgbésẹ̀ yìí lé lé àwọn olókoòwò kéékèké wọlé.
BBC Yoruba yoo kan si awọn obi rẹ lai pẹ lati mọ boya wọn ti fi ọwọ si pe ki ọmọ wọn di asoju ajọ ọhun, ta si mu abọ wa fun yin.
Ṣaaju ni Yakubu kede lọjọ Abamẹta to kọja pe, ko si aaye fun ẹgbẹ oṣelu kankan lati tẹsiwaju ninu ipolongo ibo nitori pe ajọ naa sun idibo siwaju.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ibadan VC Appointment: Ẹgbẹ́ ọmọ Ibadan fẹ́ kí ààrẹ Buhari yan ọmọ wọ́n gẹ́gẹ́ bí ọgá fásitì Ibadan 3 Ògún 2020 Oríṣun àwòrán, UI Agbarijọpọ awọn ọmọ bibi ilu Ibadan ti ke gbajare si aarẹ Muhammadu Buhari lati foju aanu wo awọn ko fi yan ọmọ bibi ilu Ibadan si ipo ọga agba fasiti ilu Ibadan.
Temilolu sọ pe inu ile igbọnsẹ ni oun farapamọ si lọjọ naa ki awọn janduku ọhun to fi tipatikuku wọ oun jade lọ si aafin Owa ilu Idanre, Ọba Frederick Aroloye.
Ninu ipo ate ajo to n ri si boolu afesegba lagbaye FIFA, ti o sese jade, Naijiria bo si ipo mẹ́tàdínláàdọ́ta  lagbaye, ti won si di ipo kefa mu nile Afrika pelu apapo ami ẹgbẹ̀ta  le márùndínlógójì ti iko ohun ni.
gan ti igbimo Olubadan fi n fa seyin laafin ti won ko si se deede ninu ojuse
mojuto ile-eko gbogbonse to je ti ipinle ati ti awon aladaani lati wa ona ti won
Wọ́n a máa gba adura gígùn láti ṣe àṣehàn.
Awọn adigunjale ọhun, ti wọn to meje niye la gbọ pe wọn sisẹ idigunjale ọhun, ti wsn si lo ohun eelo ibugbamu lati ri aaye wọle sinu ile ifowopamọ naa.
Wọ́n tẹ́ ẹ̀wù wọn sórí kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ náà, wọ́n bá gbé Jesu gùn ún.
Ọ̀pọ̀lọ́ ni oúnjẹ wọn òun ni wọ́n sì fi ń ṣe ara wọn ní àlejò.
Lara awon agbaboolu ohun ni: Christy Ohiaeriaku (Confluence Queens), Tochukwu Oluehi (Rivers Angels),  Chioma Nwankwo (Nasarawa Amazons),  Emmanuella Ingenue (Pelican Stars),  Rebecca Ajiga (Edo Queens),  Gineka Ikeh (Bayelsa Queens) and  Sarah Nnodim (Nasarawa Amazons).
Lati bi ogójì ọdún sẹhin, Epo-rọ̀bi nikan ni okùn ọrọ̀ ajé orilẹ̀ èdè Nigeria, ó si ti pa owó ribiribi wọlé fún ilú.
Àkànṣe owó oṣù lá wa olùkọ́ ń fẹ́ yàtọ̀ sí tàwọn òṣìṣẹ́ ìjọba míì - NUT A gbẹ́sẹ̀ lé ilé kan tó jẹ́ ti Bukola Saraki, torí àpò ìjọba ló ti mú owó sanwó ilẹ̀ - Ilé aṣòfin Lasiko to n sọrọ nipa aseyori rẹ, Adesanya ni ọpọ igba ni awọn eniyan ti ma n mu imu oun sẹjẹ, sugbọn ni bayii oun ti mu imu Whittaker naa sẹjẹ.
Òun ni ìbẹ̀rẹ̀, àkọ́bí tí a jí dìde láti inú òkú, kí ó lè wà ní ipò tí ó ga ju gbogbo nǹkan lọ.
 ""Amọ mo mọ pe ọpọ anfaani lo wa fun ijọba lati samulo rẹ lori ipese idẹrun fun awọn ọdọ, aarẹ, gẹgẹ bii baba orilẹede ati awọn ọdọ, to si ni ọmọ tirẹ, o yẹ ko mọ bi awọn ọdọ ti le huwa."
Bẹ́ẹ̀ náà ni nkan tó jọ ohùn kẹ́lẹ́-kẹ́lẹ́  a máa ti ọ̀dọ̀ àwọn igi náà wá.
Elifeleti, ọmọ Ahasibai, ará Maaka, Eliamu, ọmọ Ahitofẹli, ará Gilo; 
"Oríṣun àwòrán, Getty Images Nigba ti aṣọ Kokomba bands ko wọ igba mọ, lo ba bẹrẹ si ni lu ìlù ""Agidigbo""."
Ninu atẹjade kan ti agbenusọ rẹ, Stephane Dujarric, fi sita, o ba awọn mọlẹbi to padanu eeyan wọn ninu iṣẹlẹ naa, to si tun gbadura fun ilera awọn to farapa.
Ipo ti a fẹ du ṣe pataki ju ilana ẹgbẹ lọ Lawọn orile-ede kan, eeyan a maa da ẹgbẹ oselu mọ pẹlu ilana wọn ati ohun to jẹ afojusun to mu wọn da ẹgbẹ silẹ.
“Ìwọ ọmọ eniyan, kọ orin arò nípa ìlú Tire.
“Òun Senakeribu, ọba Asiria ní, kí ni wọ́n gbójú lé tí wọ́n fi dúró sí Jerusalẹmu, ìlú tí ogun dó tì?
Àkọlé àwòrán, Gomina Ganduje yan ọba onipo kini mẹrin Gbogbo ohun tó bá gbà lá máa fún un láti wa àwọn agbébọn náà- Ọlọ́pàá Èwo nínú àwọn amóhùnmáwòrán yìí lẹ rántí?
@Thereal_TommyB ṣe sandankata fun Fẹla , o ni Abami Ẹda sọrọ ko too ku pe oun ko le ku laelae nitori apo oun niku wa.
Alága ẹgbẹ́ APC ní ìpínlẹ̀ Ogun, Olóyè Derin Adebiyi tó bá BBC sọ̀rọ̀ ní nkan bi i aago mọ́kànlá òwúrọ̀ ọjọ́ Àìkú tó yẹ kí ìdìbò nàá wáyé, sọ pé àwọn kò tìí rí àwọn èròjà ìdìbò gbà láti olú ilé ẹgbẹ́ nàá tó wà ní ìlú Abuja.
Kín ni àwọn ọmọ Nàìjíríà n sọ lórí ọ̀rọ̀ Fayoṣe?
Osinbajo fikun pe oun yoo gba èsì ìdìbò òní wọlé to bá ti lọ bóṣe yẹ.
Baba Turad Sha'aban jẹ aṣofin tẹlẹri ni Ile Igbimọ Aṣofin to ṣoju ẹkun Zaria ni ọdun 2003 si 2007.
Ẹ̀mí ati ara lòdì sí ara wọn.
Yóo yọ́nú sí ọ, tí o bá farabalẹ̀ gba ìyọ́nú rẹ̀, bí bẹ́ẹ̀ kọ́, yóo gé ìwọ náà kúrò pẹlu.
Àkókò ń bọ̀, ó tilẹ̀ ti dé, nígbà tí ẹ óo túká, tí olukuluku yín yóo lọ sí ilé rẹ̀, tí ẹ óo fi èmi nìkan sílẹ̀.
Sugbọn ko si idaniloju pe bi aarun tuntun yii ṣe n ṣe niyẹn.
Oríṣun àwòrán, @tokstarr Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Ìgbà tí ayé bá ṣe èèyán tán
Ohun tí ó ṣẹlẹ̀ sí ọ yìí, kí OLUWA jẹ́ kí ohun tí ó burú jù bẹ́ẹ̀ lọ bá mi, bí mo bá jẹ́ kí ohunkohun yà mí kúrò lẹ́yìn rẹ, ìbáà tilẹ̀ jẹ́ ikú.
"Samuel Veronica to jẹ iya iya Dele kẹnu bọ ọrọ pe ai ri owo ina san ti iya onile awọn si yọ ina awọn ""O ti tó oṣù mẹ́jọ tí wọ́n ti yọ ina wa ló jẹ́ kí ọmọ yẹn lọ ṣe iṣẹ́ àmúrelé nídìí ẹ̀rọ ATM."
26 Ìgbé 2020 Orisirisi iroyin ni ileeṣẹ BBC Yoruba ma n gbe jadeki awon araalu le mo bo ṣe n lọ lagbaye.
Idile Kuti ni mo ti lọ́kọ̀ latinu ọgbọnjọ, oṣu ikẹjọ ọdun 2000.
Orlando Owoh: Ayé ti sú mi, àdúrà ikú ìrọ̀rùn ló wù mí- Christiana, Ìyá Orlando Owoh tó ti pé ọdún 110
Wọn ni wi pe eyi yoo sọ ẹran aja jijẹ di ohun itan ni ilu naa.
Kíkọ́ ẹ̀kọ́ gboyè nínú iṣẹ́ ìṣègùn ìbílẹ̀ yóò pèsè ìtọ́jú tó péye fọ́mọ Nàìjíríà- Ẹgbẹ́ àwọn dókítà Wo àwọn àwòràn tó làmìlaaka nílẹ̀ Adúláwọ̀ lọ́sẹ̀ yìí Kí ni ó gbé ọlọ́pàá dé ibi àjọ̀dún ọjọ́ ìbí i Bobrisky?
O ni ko sẹni to n ṣọ gomina lọwọ lẹsẹ gẹgẹ bi awuye wuye naa ṣe n lọ lawọn ibi kọọkan ṣugbọn koko ni pe riru ofin yii jẹ ohun ti ile aṣofin ko lee moju kuro lara rẹ.
Adeyemi ti ẹgbẹ osẹlu APC ni ibo 88,373 nigba ti Dino to dije labẹ asia ẹgbẹ oṣelu PDP ni ibo 62,133 ninu atundi ibo ọhun.
Awọn iroyin nipa eto ọrọ aje Eco currency L'opin ọdun 2019, Aarẹ France, Emmanuel Macron kede pe l'ọdun 2020, awọn yoo ṣe owo 'ECO currency' fun awọn orilẹede Africa to n sọ ede Faranse, to si n na cefas yoo ma a na.
Obìnrin ará Morocco pa olólùfẹ́ rẹ̀, ó fi se ìrẹsì 21 Bélú 2018 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 3 Èbibi 2020 Oríṣun àwòrán, Alamy Àkọlé àwòrán, The woman served up her boyfriend's remains in a traditional Emirati dish like this Obinrin ara Morocco kan ni United Arab Emirates ni wọn ti fi ẹsun kan pe o pa ololufẹ rẹ ti o si se oku rẹ fun awọn oṣiṣẹ ọmọ Pakistan jẹ.
"Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Mi ò kí ń ṣèèyàn burúkú tàbí Babalawo bí ẹ ṣe mọ̀ mí nínú eré - Fadeyi Oloro O ni ""ti Kazeem ba n wo ifẹsẹwọnsẹ bọọlu lori tẹlifisan, o ma n woye ọjọ iwaju rẹ, to si ma n sọ pe ibi giga ti oun n lọ niyẹn."
Okechukwu Enelamah ṣalaye fun akọroyin BBC pe kii kan kii ṣe fun awọn alagbara ilu nikan, oniruuru ọna lo fi le kan ọmọ Naijiria kọọkan.
 a pé àwọn ọ ̀ rọ ̀ yìí ní ọ ̀ rọ ̀ aṣẹ ̀ dá , nítorí pé wọn kì í ṣe ọ ̀ rọ ̀ oní-mọ ́ fíìmù kan .
Oga ọlọpaa ni ipinlẹ Eko, Edgal Imohimi ti ni ki awọn ọlọpaa gbe oku naa lọ mọṣuari, ki awọn ọlọpaa to n ṣe iwadi ipaniyan ati awọn to n lo imọ sayẹnsi si bẹrẹ iwadii lori ọrọ naa.
Eto ibura fun aare Muhammadu Buhari ati Osinbajo ti fẹ bẹrẹ
awon ara ilu lati tele ikede yii.
Ohun to wa nfoju han gbangba ni pe olori Badra ti n mọ ọpọ gbajumọ nilu Eko, paapa lẹnu ọrọ aje rẹ, to si n fi wsn soju opo ayelujara rẹ.
Ninu fọnran ọhun, a ri i bi awọn janduku ṣe ba nkan jẹ lorisirisi.
Abẹṣẹ-ku-ojo ọmọ ilẹ Amẹrika kan, Patrick Day ti dero ọrun lẹyin to fi ori ṣeeṣe nigba to ba Charles Conwell ja.
julo awon papa ofurufu to wa ni ipinle  Eko,
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Òǹyẹ̀ kò leè yẹ èlé owó osù - Ẹgbẹ́ òsìsẹ́ Ààbọ̀ ìpàdé Bùhárí rèé pẹ̀lú Trump Ìpànìyàn gbọdọ̀ dópin ní Nàíjíríà - Trump Nígbàtí aféfé wàhálà náà yóò fi rọlẹ̀, ọ̀pọ̀ àwọn òṣìṣẹ́ ni wọ́n ti farapa.
Adamawa , ni won jọ se onigbonwo eto naa.
Titi di asiko yii, ileeṣẹ irina ofurufu to ni ọkọ baalu meji pere lo n bẹ ni papakọ naa, irinajo ti wọn si n lọ ju ni lati Ibadan si ilu Abuja.
Bí ìwọ bá rí ẹni tí kò ní ìtìjú, mo fẹ́ kí o mọ̀ pé ojú-inú eléyìínì ti fọ́.
" Ọwọ́ sìnkún àwọn agbófinro tẹ Kelly ní Chicago, pẹ̀lú ẹsùn oní kókó mẹ́wàá tó jẹ mọ ẹsun fífi ipá bá àwọn ọmọ mẹ́rin sùn, ti mẹ́ta nínú wọn sí jẹ ọmọde lásìkò ti ọ̀rọ̀ náà sẹlẹ̀.
 Ìdíwọ ́ yìí parí lẹ ̀ yin akitiyan ológun ojú omi u.
 Elebuibon sọ pe ọwọ ileeṣẹ ọlọpaa ti tẹ ọmọkunrin naa."
Lẹ́yìn ọdun mẹ́ta tó kú, ilé ẹjọ́ dájọ́ ikú fún alásè tó pa Temidayo Adeleke Àwọn ohun tó ń fa ariwo nípa Huawei tó yẹ kóo mọ̀?
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù World Habitat Day: 'Ìjọba, ẹ ṣèrànwọ́ fáwọn tí kò rílé gbé ní Nàìjíríà' 7 Ọ̀wàrà 2019 Oríṣun àwòrán, Twitter/Amnesty Int.
Sugbọn lọwọlọwọ bayii, oju opo ayelujara ti kun nipa awọn iwe idanwo Waec, paapaa Isiro, tawọn eeyan kan n pin kiri.
Mo lòdì sí àwọn wolii tí wọn ń sọ àsọtẹ́lẹ̀ àlá irọ́, tí wọn ń rọ́ àlá irọ́ wọn, tí wọn fí ń ṣi àwọn eniyan mi lọ́nà pẹlu irọ́ ati ìṣekúṣe wọn, nígbà tí n kò rán wọn níṣẹ́, tí n kò sì fún wọn láṣẹ.
The house of representatives in Nigeria has passed a bill that allows married women to choose their state of origin.
Ede ati aṣa Yoruba ti di itẹwọgba ni oke okun ni eyi to n mu awọn akẹkọọ oyinbo ilẹ Amerika lati wa kọ nipa rẹ sii ni Naijiria.
O kọkọ sẹ pe oun ko mọ ohunkohun nipa iku arakunrin ọhun, ṣugbọn lẹyin ti wọn fi fidio ori ẹrọ CCTV inu ile to ti gba ẹmi ọga rẹ ọhun han, o jẹwọ.
Àwọn kan ń sọ̀rọ̀ Kristi nítorí ohun tí wọn óo rí gbà níbẹ̀, kì í ṣe pẹlu inú kan, wọ́n rò pé àwọn lè mú kí ìrora mi ninu ẹ̀wọ̀n pọ̀ sí i.
5 owó naira ni ọọfiisi àjọ INEC ni Zamfara Ǹkan mẹ́jọ tó máa kọ́kọ́ ṣẹlẹ̀ kí olólùfẹ́ méjì tó pa ara wọn Bakan naa lo ni ọpọ ko fun oun ni wahala ni pataki ilẹ Senegal ti wọn fẹran eniyan dudu ti wọn si n kẹ gbogbo eniyan ibaa ṣe dudu tabi funfun.
 “Inu mi baje pupo, isele ijamba ina yii wa lara isele buruku ti o tun lagbara ti ma a foju mi ri”Aare Buhari wa ro ile-ise to n ri si isele pajawiri ti o fi mo awon osise alaabo lati ri daju pe won se awon ohun ti o to lakoko, lati dena pipadanu emi tabi awon ohun ini miran.
 bí Ọgbọ ́ n kan kò bá parí iṣẹ ́ , Ọgbọ ́ n mìíràn yóó gbè é lẹ ́ yìn .
Ọpọ ogun lo ti waye ṣẹyin nilẹ Yoruba, eyi ti ko lonka amọ manigbagbe nla ni ogun Agbekoya jẹ.
Kí o máa wá tọ̀ mí lẹ́yìn.
Toun ti akitiyan Napoli, goolu ti Alexander Lacazette jẹ ninu ifẹsẹwọnsẹ naa lo la ija laarin awọn mejeeji ti Arsenal si fi pegede.
Bobrisky dárò pé EFCC gbé Mompha, ọ̀dọ́mọdé olówó tó ń lo aago ₦20m Agbarijọpọ awọn agbofinro ti ọga ọlọpaa Gokana dari wọn ati ọmọ ikọ fijilanti ni wọn jijọ mu ọdaran yi.
E Maha kọ lati gbọ ẹjọ lori ọrọ yi ti o si ni ohun yoo nawọ ẹjọ naa si adajọ agba lati gbe fun adajọ miran nitori pe isinmi ọdọọdun ohun yoo pari ni ọjọ kẹrin osu kini.
Bẹ́ẹ̀ ni kí á má máa jowú.
Njẹ o si tọ ki awọn kan ma gbadun ina ọba nitori pe wọn ni agbara lati san owo ina ọba ju awọn akẹgbẹ wọn lọ?
0 17513 Orilẹede Quatar 239 8.
Àwọn mélòó kan ninu àwọn oníṣẹ́ òkùnkùn kó ìwé idán wọn jọ, wọ́n bá dáná sun wọ́n lójú gbogbo eniyan.
Bakan naa, egbe oselu APC ti bere
” (Ọlọ́ṣà paraku ni Baraba yìí.
O ni to ba ti jẹ ẹni to ti yo ifẹẹ rẹ, o ti di Maga niyẹn.
Wasiu tun kọ ninu orin pe awọn to n binu Pasitọ Ogundipe le maa binu lasan nitori ẹni ti Ọlọrun gba fun un ni.
Dapo Abiodun tun ṣalaye pe o ṣeeṣe lati ṣe ipade pẹlu ileeṣẹ to n mojuto ọrọ owo ori lati ori ayelujara laidaamu wa sileeṣẹ wọn rara.
"Ninu ọrọ rẹ, Iyabọ ni ""mo wa lorilẹede Naijiria, mo si n sisẹ tọsan-toru, mo n tiraka lati bọ ọpọ eeyan."
eyi waye lẹyin ipade rẹ pẹlu Boris Johnson.
Ọjọ ori Olori Abibat ko fi bẹẹ kere si ti Alaafin, koda, a gbọ pe ọjọ ori wọn sunmọ ara wọn nitori mama yii naa ti se ọjọ ibi ọdun kọkanlelọgọrin loke eepẹ.
orile ede Naijiiria lati maa pese ina mona-mona funra won.
Aarẹ Buhari ti ni ki wọn bẹrẹ si ni san owo yii lati oṣu kẹrin ọdun fawọn ti ọrọ kan.
Coronavirus in Nigeria: Esì àyẹwò ọmọ ati ìyáwọ ọmọ Atiku ti jáde
Monica ni òun mọ̀ọ́mọ̀ ká ìbánisọ̀rọ̀ òun àti ọ̀jọ̀gbọ́n náà sílẹ̀ ni Àmọ́ o, Ọ̀mọ̀wé Abíọ́lá Akínyọdé Afọlábí ní, akẹ́kọ̀ọ́ náà sọọ́ di mímọ̀ níwájú ìgbìmọ̀ ọ̀hún pé, òun mọ̀ọ́mọ̀ ká ìbánisọ̀rọ̀ tó wáyé láàárín òun àti ọ̀jọ̀gbọ́n Akíndélé sílẹ̀ ni gẹ́gẹ́bíi ẹ̀rí.
Bakan naa ni won tun  ro ijoba lati pese eto-ilera ofe ni awon igberiko agbegbe naa, lati le se adinku iku alaboyun ati omo-wewe.
O ni fifẹ Roshan yoo mu Gauri kuro nitosi abule wọn.
Ṣé o kò mọ̀ bẹ́ẹ̀ láti ìgbà àtijọ́,láti ìgbà tí wọ́n ti dá eniyan sórí ilẹ̀ ayé,
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Nigeria Police: Eko, Oyo, Kwara, Anambra gba Ọ̀gá Ọ̀lọ́pàá tuntun 7 Èrèlè 2019 Oríṣun àwòrán, @PoliceNG Àkọlé àwòrán, Oga Olopaa Adele ọga agba awọn ọlọpaa Naijiria, Mohammed Adamu ti kede orukọ awọn lọga lọga ni iṣẹ ọlọpaa to yan sipo.
"Ninu ọrọ to kọ si oju opo Twitter rẹ, o ni oun wa pẹlu awọn arakunrin ati arabinrin oun ni Naijiria, lati fi opin si ifiyajẹni lati ọwọ ọlọpaa, ati pe ""ijọba gbọdọ dahun ibeere awọn eniyan""."
 ibẹ ̀ náà ni olọ ́ ọ ̀ gbẹ ́ Ìgè kọ ́ ilẹ ́ rẹ ̀ sí .
Wọ́n bá rú àwọn eniyan nídìí, láti sọ pé, “A gbọ́ nígbà tí ó ń sọ ìsọkúsọ sí Mose ati sí Ọlọrun.
Oju ọna irin naa, tó jẹ kilomita 248 ni ireti wa pe yoo sisẹ fun gbigbe eporọbi.
Lati igba ti o si ti jade si eti araye ni ọpọ awọn eeyan nilẹ yii ati loke okun ti n fi ero wọn han lori igbesẹ naa.
Ayọ̀ ń bẹ fún orílẹ̀-èdè tí OLUWA jẹ́ Ọlọrun wọn,àní àwọn eniyan tí ó yàn gẹ́gẹ́ bí ìní rẹ̀!
Bí bẹ́ẹ̀ kọ́, gbàrà tí kabiyesi bá ti kú tán, bí wọ́n ti ń ṣe àwọn arúfin ni wọn yóo ṣe èmi ati Solomoni ọmọ rẹ.
Ewe, aare Buhari ro awon agbaboolu ati awon olukonimoogba won lati tun bo sa gbogbo ipa won ati afojusun lati gba ife eye ohun wale lojo aiku (Sunday).
Ìjọba Tanzania fi Ajìjàgbara Ọmọ Orílẹ̀-èdèe Uganda sí àtìmọ́lé, wọ́n sì lé e kúrò nílùú
Bolu Akin Olugbade: Ọkọ̀ olówó iyebíye Roll Royce Limousine mẹ́wàá nìkan ni ọlọ́lá yìí gùn nígbà ayé rẹ̀
Àkọlé àwòrán, Awọn oludije gomina l‘Ekiti Bii Àwòrán ìbò Èkìtì lọ́dún 2014 fún àwòkọ́gbọ́n ti o dabi ibẹrẹ iṣẹle Fayoṣe ati Fayẹmi, 'Fayẹmi ṣì ní ẹ́jọ́ láti jẹ́ ní Ékìtì' ọpọlọpọ awuyewuye lo ti waye laarin awọn ẹgbẹ oselu mejeeji eyi ti Aarẹ Buhari fi wa si Ekiti fun ipolongo alaafia pe ‘Àláfíà ọmọ Naijiria lo jẹ mí logun'.
Ko si ohun to ni ibere ti ko lopin, idije ile geesi ti o bere lojo kinni ana ti pari lojo Aiku(Sunday), ojo kejila osu karun un odun, 2019.
Iroyin ni awọn ajinigbe naa bere pe awọn yoo gba owo ti iye rẹ to igba miliọnu naira ki wọn to tu awọn eeyan naa silẹ.
Oríṣun àwòrán, Nigerian Police Bakan naa ni ileeṣẹ ọlọpaa sọ pe oniruuru iya ni wọn fi jẹ awọn eeyan ọun.
bí a bá fẹ ́ ṣẹ ̀ dá gbólóhùn àkíyèsí alátẹnumọ ́ , fọ ́ nrán ìhun tí a bá fẹ ́ pe àkíyèsí sí ni a ó gbé sí iwájú gbólóhùn ìpìlẹ ̀ .
Àwọn 'ẹ̀bùn' tí ikú George Floyd fún àgbáyé Ẹ̀yin tí ẹ lọ ra aṣọ àlòkù ní Ọjà Ọba Akure, ẹ lọ ṣàyẹ̀wò Coronavirus - Akeredolu figbe ta Ojú pópó ni mo dàgbà sí àmọ́ n kò mu igbó, sìgá tàbí ọtí líle rí - MC Oluomo Iṣẹ́ ọpọlọ ló yẹ ká ṣe nínú tíátà, kìí ṣe àfihàn ara bíbó àbí ìhòòhò wa - Binta Mọgaji Bakan naa, awọn akọṣẹmọ ni igbẹ aarọ dara lai tii wẹ tabi jẹun.
Bush, ààrẹ Amerika tẹ́lẹ̀ jáde láyé 1 Ọ̀pẹ̀̀ 2018 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ọdun mẹrinlelaadọrun ni ki o to jade laye George H.
Ọjọ Aiku, ọjọ karun un oṣu karun un ni o pe ọdun mẹsan-an gerege ti aarẹ orilẹede Naijiria nigba kan ri, Umaru Musa Yar'adua re iwalẹ asa.
Ati pe a ṣi wa laye ni ahamọ wọn Ọlọ́pàá fi páńpẹ́ ọba mú ọmọ ogun ilẹ̀ Naijiria Ọlọ́pàá fi páńpẹ́ ọba mú ọmọ ogun ilẹ̀ Naijiria Kí ló mú ọlọ́pàá ilẹ̀ Gẹ̀ẹ́sì san owó gbà má bínú £2500 fún pásítọ̀ yí?
Àlàyé rèé lóríi àjọṣepọ̀ tó wà láàrin èmi àti MC Oluomo - Ronke Oshodi Oke Ọ̀nà kan ò wọjà fáwọn òṣèré tíátà, bí wọn ṣe ń ta ìpara ìbóra ni wọ́n ń ta aṣọ ẹbí Kíni ẹ mọ̀ nípa àwọn gbajúgbaja Yollywood?
Ile gẹri-gẹri itaketesiraẹni: Lẹyin ti Covid-19 gbode ni awọn gẹri-gẹri kan ni Ethiopia kọ ṣọọbu ti wọn ti le e maa gẹrun fun awọn onibara wọn lai fara kanra.
Ajọ Amnesty International sọ pe ọkọ rẹ maa n fiya jẹ ti o si kọ lati jawe fun ati wi pe awọn ọlọpaa ko ya si ọrọ rẹ.
Samuẹli bá sọ gbogbo rẹ̀ patapata, kò fi nǹkankan pamọ́ fún un.
Awọn to ṣe eto ipade oniroyin naa ti kọkọ rii daju pe iwọnba aṣayan awọn akọroyin ni wọn pe, wọn si fi kun un pe iwọnba awọn ti wọn fi iwe pe nikan lo yọju nibẹ.
#BigBrotherNaija g'ori afẹfẹ Ọtunba Roṣẹwẹ sọ pe oun ti fi ọrọ naa lọ ajọ to n mojuto igbohun safẹfẹ lorilẹ-ede yi, iyẹn NBC.
Ó gbé òdodo wọ̀ bí ìgbàyà, ó fi àṣíborí ìgbàlà borí.
Ohun ti awọn alaṣẹ ileewe naa n gbereo lati ṣe ni pe lori ayelujara ni awọn akẹkọọ ile iwe naa yoo ti maa gbẹkọọ.
Wàhálà àyípadà ojú-ọjọ́ ní ọdún-un 2019 jẹ́ ohun tí ó nílò àbójútó kíákíá ju ti ìdúnrin lọ, àti ní Jamaica, àwọn ará ìgbèríko tí ó jẹ́ àgbẹ̀, àwọn apẹja ń gbọ́ ìpè itanijí yìí.
    Bí a ti fẹ́ wọle ni ọkùnrin náà dá ni padà o ni a kò tí i gbọdọ wọlé, a níláti sùn niwájú igbó náà dí ọjọ́ kejì nítorí pé àwọn ẹranko àti ẹyẹ ti wí fún òun pé àwọn fẹ́ bá ni sọ̀rọ̀, bí àwọn bá lè pari ọ̀rọ̀ náà ẹ̀lú ìdẹ̀lọ́rùn àwọn kò ní ṣe nǹkan kan, ṣùgbọ́n bí bẹ́ẹ̀ kọ́, àwọn ó ba ni jagun.
    Kábíyèsí, mo fẹ́ kí ẹ ṣe kiní kan fún mi.
Kọ́ mi ní ohun tí n kò rí,bí mo bá ti ṣẹ̀ rí, n kò ní ṣe bẹ́ẹ̀ mọ́?
1 4180 Orilẹede Rwanda 53 0.
Mo ti ba awon adari egbe osise sọrọ
Nígbà tí wọ́n ló yẹ ilé Ọ̀sanyìnnínbí wò, owó tí wọ́n bá ní ibẹ̀ jẹ́ ọgọ́sàn-án náírà (N180.
Ìfẹ́ ru bò ó lójú bí ẹmu inú akèǹgbè, Olówó-ayé ti ìtorí ẹwà ó gbàgbé ìwà, ó ti ìtorí ojú dídán ó gbàgbé ọgbọ́n, ó ti ìtorí eyín ffunfun ó sọ ara rẹ̀ di baálé àjẹ́, àti ọjọ́ náà ni bàbá mi sì ti gbé ìjàgbọ̀n lẹ́hìn tí ó ń pe ìjàngbọ̀n lóbìnrin.
Iroyin sọ pe awọn ọkọ to gbe epo bẹtiro ati gaasi ti isede ka mọ ori afara Kara nilu Eko gbina lẹyin ti ibugbamu kan waye.
Ìyá ọkọ rẹ̀ bi í léèrè, ó ní, “Níbo ni o ti ṣa ọkà lónìí, níbo ni o sì ti ṣiṣẹ́?
Olori North Korea, Kim Jong-un ni o wu oun ki ajosepo to wa laarin guusu ati ariwa Korea tubo rinle sii.
ati tabili náà, pẹlu gbogbo àwọn ohun èlò rẹ̀ ati burẹdi ìfihàn.
Oríṣun àwòrán, Twitter/Bashirahmad Alaga igbimọ eleto ijọba lori Covid-19 Boss Mustapha lo lede ọrọ yi lasiko to n jabọ ilana ti yoo de ipele keji idẹwọ isede ti ijọba gbe kalẹ.
INEC ni igbesẹ yi wa ni ibamu pẹlu ofin idibo orileede Naijiria.
Ohun ti mo ri jẹ nnkan ibanujẹ nitori pe ko si iyẹwu ninu awọn ile-ẹwọn mọ sugbon o dabii ile itaja ti a ha awọn eniyan ti o ju ẹgbẹrun marun lọ si dipo awọn ẹlẹwọn ẹgbẹrin ti wọn kọ ibẹ fun.
Onimọ nipa ọrọ ina mọnamọna ni Naijiria, Taiwo Adebulu sọ pe ilana tuntun naa yoo daabo bo awọn talika, ti yoo si mu ki awọn olowo ma a san owo gọbọi fun ina.
Kò wọ ẹ̀wù bẹ́l ni kò wọ ṣòkòtò, kò dé fìlà bẹ́ẹ̀ ni kò ssán ìbàǹtẹ́, ewé ni alákọrí fi ń bo àṣírí ìdí kiri, ojú kan ṣoṣo ni òun ní, eléyìí sì gún rébété bí òṣùpá títòbi, Èṣù-kékeré kò ní imú rárá, níotrí ojú ti tóbi rékọjà ibi tí ojú mọ, ẹnu rẹ̀ sì gbòòrò bi ibú àtẹ́lewọ́, eyin ẹnu rẹ̀ dàbí ti kìnnìún bẹ́ẹ̀ ni àwọn eyín wọ̀n-ọnnì pupa bi ìgbà tí kìnnìún bá ṣẹ̀ṣẹ̀ jẹ ẹran tútù tán.
Williams fagbahan akegbe re Zarina Diyas pelu ami-ayo ,meje si marun(7-5), mefa si meta(6-3), ninu ifigagbaga kinni ti o waye lorile-ede India.
Lati igba naa ni gbọnmi si i omi ko ti to laarin awọn mejeji ti Wumi si jẹ́ ki araye mọ pe Toyin kii ṣe ọga oun, kii si ṣe fiimu rẹ lo gbe ohun dide.
Mo dáríjì àwọn IPOB tó nà mí ní Germany nítorí wọn o m'ohun tí wọ́n ń ṣe- Ekweremadu Ẹsẹ̀ kò gbèrò ní ọdún Ọ̀ṣun Òṣogbo Fayemi fojú Alufa to fipa bá ọmọde lòpọ̀ síta l'Ekiti Ayọ̀ abara bíńtín!
Bi awọn eeyan kan se pọn sẹyin oun ti Daddy Freeze sọ, lawọn miran n ta koo, ti wọn si n gbe sẹyin Oyedepo ati Ibiyeomie.
Igba to jade pada ni mo ṣakiyesi pe ẹdà kọkọrọ lo fi wọ yaara naa.
Iye awon eniyan ti o  jade lati yẹ aarẹ si ko kere .
Ni Babcock, awọn ohun to yẹ kẹẹ mọ niyii Oríṣun àwòrán, Image copyright@BABCOCK_UNIV TWITTER Gbogbo akoko isinmi ni wọn maa n mu ni pataki.
Amọ lati oṣu Kẹrin, ikọ ipolongo Biden yipada di eyi to n bẹbẹ fun ikowojọ - o si pada ni owo l'apo ju ikọ Trump lọ - boya nitori pe ikọ Trump n na owo ni inakuna.
Ologbondiyan ni ọgbọn ati ko owo jẹ naa ni gbogbo ohun ti ijọba apapọ n ṣe pẹlu ṣiṣe ojuurin lọ si ilẹ Niger.
Níwájú gbogbo ìjọ níhìn-ín wọ́n jẹ́rìí sí oríṣìíríṣìí ọ̀nà tí ó fi ràn wọ́n lọ́wọ́ ninu ìrìn àjò wọn gẹ́gẹ́ bí ó ti yẹ fún òṣìṣẹ́ Ọlọrun.
Laipẹ yii ni Femi Fani Kayode tọrọ aforijin lọwọ akọroyin ileeṣẹ Daily Trust ti o sọrọ kubakugbe si naa.
Kí wọ́n fi òróró po ìyẹ̀fun náà dáradára, kí wọ́n tó yan án lórí ààrò, lẹ́yìn náà kí wọ́n rún un gẹ́gẹ́ bí ẹbọ ohun jíjẹ, kí wọ́n sì fi rú ẹbọ olóòórùn dídùn sí OLUWA.
Abiola, ti ọpọ eeyan mọ si Cute Abiola, Ankara Gucci abi Laywer Kunle lori ayelujara gba pe ko rọrun rara lati pa iṣẹ ologun mọ awada sise lori ayelujara.
Bakan naa lo tun koro oju si bi wọn se ni kawọn eeyan to ba fẹ se Amotekun wa maa fi orukọ silẹ lori ayelujara, eyi to ni ko bojumu.
Nítorí Oluwa ń ṣọ́ àwọn olódodo,ó sì dẹ etí sí ẹ̀bẹ̀ wọn.
Agbẹnusọ fún ẹgbẹ́ Shiite sọ fún BBC pé ẹgbẹ́ nàá n ṣe ìwọ́de ẹ̀sìn tó l'ápẹrẹ ní ọ̀sán ọjọ́ Aje, ni àwọn ọmọ ogun yabò wọ́n.
Amọ, o ni o di igba ti awọn eniyan ba to o yi ihuwasi wọn pada si awọn ti wọn bi pẹlu HIV, ki awọn alarun naa to ma a gbe igbe aye ominira, tabi ni ọrẹ ati ololufẹ lai si ibẹru ati idiwọ.
Àìle è ka kéú ló sọ mí di Krìstíẹ̀nì - Adewale Ayuba Mi ò ní ìyàwó nílé, àmọ́ mo ní ọmọ tó pọ̀-Saheed Oṣupa Alábàárù ni mò ń ṣe lọ́jà Ketu àti Mile 12, kí ń tó bẹ̀rẹ̀ Fuji - Atawẹ́wẹ́ Èmi kò gbé pọ̀ pẹ̀lú Kollington Ayinla àmọ́ ọjà t'ọ́mọ ti wọ̀ lọ̀rọ̀ àwa méjééjì - Salawa Abẹni Ajebori ni orin Apala ni Baba oun n kọ ti iya rẹ́naa si jẹ olorin pẹlu.
AfroBasketWomen: Buhari kí D'Tigress lẹ́yìn tí wọ́n ṣíná ìyà fún Senegal gba ife
Ejò bu abóyún jẹ nílé ìyàgbẹ́, ó kú pẹ̀lú oyún oṣù mẹ́jọ ní Kaduna Ẹ̀yin ọmọ Kwara, ẹ seun fún àtilẹ́yìn yin lórí ilé Arugbo - Bukola Saraki Ojú ẹni t'ọlọ́pàá ló wà lẹ́yìn ìdigunjalẹ̀ Báńkì Abuja rèé Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Inu mi bàjẹ́ nígbà tí mo bí i, odidi oṣù mẹ́ta, mi ò lè gbàdúrà s'Ọ́lọ́run' Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
"Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Osusan Oluwatobi tricycle accident: Ààrin ìṣẹ́jú kan tí mo wọ 'Maruwa' ni ìjàmbá tó gbá ẹsẹ̀ mi wáyé 25 Ògún 2020 ""Ko to iṣẹju kan ti mo wọ kẹẹkẹ Marwa, ni mo deede gbọ ariwo ti awọn eeyan n pa lati doola ẹmi mi."
Ile iṣẹ ọlọpaa sọ pe, eleyi ṣeeṣe pẹlu iranlọwọ ajọ NAPTIP to n gbogun ti fifi eeyan ṣe owo ẹru lorilẹede Naijiria.
Oxford English Dictionary: 'Àwọn ọ̀rọ̀ Nàìjíríà ti wọ́n fi kún un lọ́dun 2020
Obasanjo wá sàlàyé pé nígbà ti Ọlọ́run ti ṣe irú oore yìí fún oun, kò si ǹkankan to ku fun oun ju láti máa dúpẹ́ lọ.
Oríṣun àwòrán, Karaye Emirate Àkọlé àwòrán, Emir ilu Karaye to yi orukọ ilu naa pada Adari ilu na, Mallam Abdullahi Tsoho sọ fun BBC pe awọn gba orukọ naa ni aadọrin ọdun sẹyin nitori orukọ odo to la ilu naa kọja.
ni Ipinlẹ Ọyọ,  ni deede agogo kan koja
O ni ka ni kii ṣe bẹẹ ni, ohun ti o ṣẹlẹ ko ba buru ju bi o ti ri naa lọ.
Ipo ta fẹ du ṣe pataki ju ilana ẹgbẹ lọ Lawọn orileede kan, eeyan a ma da ẹgbẹ oselu mọ pẹlu ilana wọn ati ohun to jẹ afojusun to mu wọn da ẹgbẹ silẹ.
Naijiria, ojogbon Yemi Osinbajo ati awon asoju miiran yoo lo fun ayeye
Báwo ni wọ́n ṣe rí ààyè kúrò nílé ìwòsàn?
Alaga INEC, ọjọgbọn Mahmoud Yakubu ni o sọ bẹẹ nigba ti o gbe eto iṣuna idibo 2019 ti ajọ naa gbé siwaju ile igbimo aṣojuṣofin ni Abuja l'Ọjọru.
APCYemi osinbajo naa ni ijoba si n fikun-lukun pleu awon
Alaga igbimo alamoju to ijoba ajo NACA, abileko Pauline Tallen pe fun iyanju  ati fopin si atagba aarun HIV latodo iya si omo inu re.
Àwọn òfin rẹ kìí yipada,ìwà mímọ́ ni ó yẹ ilé rẹ títí lae, OLUWA.
Kolade Johnson; Iléeṣẹ́ ọlọ́pàá ní ọwọ́ ti tẹ àwọn afurasí ọlọ́pàá tó ṣekúpaá
Àwọn ajàfúnẹ̀tọ́ tí ó ń lé iwájú nínú òmìnira ọ̀rọ̀ sísọ ní ìlú-Gúúsù-Aṣálẹ̀-Sàhárà àti káríayé kò gbọdọ̀ ṣe aláì máà wá wọ̀rọ̀kọ̀ fi ṣ'àdá lórí ọ̀ràn yìí.
Ní ọjọ́ keje ẹ óo yípo ìlú náà nígbà meje, àwọn alufaa yóo máa fọn fèrè ogun wọn.
Adeleke: 'Èmi ò kú o, koko lara mi le'
Ajẹ́pé ó di gbére, ó di àrìnàkò, ó di ojú àlá.
Farao ní kí wọ́n lọ sin OLUWA Ọlọrun wọn, ṣugbọn ó bèèrè pé àwọn wo gan-an ni yóo lọ?
Ọsẹ bi i melo kan si ni ileeṣẹ eto idajọ ilẹ Amerika yoo gbe ẹni ọdun mẹtadinlogoji ọhun lọ si ilu Los Angeles, lati jẹjọ lori ẹsun lilu jibiti.
0 120147 Orilẹede Hungary 6622 68.
Oríṣun àwòrán, Instagram/abiolaajimobi Ẹ dari aṣiṣe mi ji mi, amọ emi nikan kọ ni mo ṣe aṣisẹ, awọn miiran naa ṣe aṣiṣe bi temi, gomina ipinlẹ Oyo tẹlẹ, Sẹnẹtọ Abiola Ajimobi lo sọrọ yii nibi ipade igbimọ to n pẹtu si aawọ ninu ẹgbẹ oṣelu APC.
O ni iba lasan lo ṣe Oloogbe Oriṣabunmi to fi lọ si ileewosan nibi ti o ti jade laye.
Wọ́n sì dá àwọn eniyan náà lẹ́kun pé kí wọ́n má mú ọrẹ wá mọ́; 
Òun ni pé, apá kan ninu àwọn ọmọ Israẹli yóo jẹ́ alágídí ọkàn títí di ìgbà tí iye àwọn tí a yàn láti àwọn orílẹ̀-èdè yòókù yóo fi dé ọ̀dọ̀ Ọlọrun lẹ́kùn-únrẹ́rẹ́.
Awọn odiwọn ti ajọ UNICEF fi gba pe awọn ọmọ tuntun naa a waye niyi: India lo wa ni ipo akọkọ pẹlu ọmọ 69, 944 China ni ipo keji pẹlu ọmọ 44, 940 Naijiria ipo kẹta lagbaye, ipo kinni ni Adulawọ pẹlu ọmọ 25, 685.
O tun so pe, o se pataki fun awon omo orile-ede yii lati se arawon gege bi osusu owo, lai wo eya tabi eka ti o ni kaluku ti wa ni ona lati sun orile-ede yii siwaju.
@Oluwaroll1 naa n beere pe se ileesẹ́ MTN ati banki oun , GTB ti pawọpọ ni lati ba owo jẹ mọ awọn eeyan lọwọ?
Mi ò ní wọ Uber mọ́ tí wọ́n bá leè fi owó lée nítorí àfikún owó orí tí Sanwo Olu ṣe Àwọn nkan tó yẹ kí o mọ̀ nípa ṣíṣe ìṣirò àsìkò tí o bá n yé ẹyin Wo bí o ṣe le fi ẹjọ́ sun àjọ FCCPC tí o bá ra ọjà tó ti 'expire' 'Àwa ọmọ Nàìjíríà tó farapa fẹ́ wálé láti Lebanon, ìjọba kó wa pamọ́' Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Victor Agunbiade ni ojú àlá ni Ọlọrun ti yan iṣẹ́ ọmọ ogun ojú omi fún òun ní America Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí 6:18 Fídíò, Natalia Mufutau ìyá Yakub, Kamil àti Adam sọ̀rọ̀ lórí bí wọ́n ń sọ èdè mẹ́rin pàpọ, Duration 6,1831 Ògún 2020 6:10 Fídíò, Yoruba Language: Akomolede ati Asa Yoruba tọ̀sẹ̀ yí rèé lẹ́nu olùkọ́ wa, Duration 6,1030 Ògún 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
lati ṣatunṣe si ofin to jẹ mọ ilana agbeyẹwo isuna owo ilu, lati tubọ mu
Ẹwẹ, iroyin sọ pe aarẹ orilede Russia, Vladmir Putin ti gbọ si i o si ti ba awọn ẹbi awọn to ba iṣẹlẹ naa rin kẹdun.
Van Dijk ni o yẹ kawọn tubọ maa gbaṣoba rabandẹ fun anjannu agbabọọlu ti wọn n pe ni Messi.
#EndSARS: Shogunlẹ ní ẹ̀sùn ìdigunjalẹ̀, ìjínigbé ni FSARS yóò mójútó
bee si ni won ko milionu merin in abo dola($4.
Bẹ́ẹ̀ gan-an ni, Kristi náà kò yan ògo yìí fúnrarẹ̀, láti jẹ́ olórí alufaa.
Báyìí ni wọ́n ṣe mọ àwọn ìtẹ́lẹ̀ náà: wọ́n ní ìtẹ́dìí, àwọn ìtẹ́dìí yìí sì ní igun mẹrin mẹrin, 
Ọ̀kọ̀ Iṣibibenobu yìí wọ̀n tó ọọdunrun ṣekeli idẹ, ó sì so idà tuntun mọ́ ẹ̀gbẹ́.
Ẹ̀jẹ̀ rẹ̀ yóo wà lórí ara rẹ̀ nítorí pé ó ṣépè lé baba tabi ìyá rẹ̀.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Wo Adigun ọmọ ọdún mẹ́rin tí òwe Yorùbá àti ìtúmọ̀ gbó lẹ́nu rẹ̀ ju tìrẹ̀ lọ Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí EndSARS Protest Update: Aisha Yesufu ní Buhari jẹ́wọ́ pé òun kò láànú aráàlú nínú ọ̀rọ̀ rẹ̀23 Ọ̀wàrà 2020 Fídíò, Wole Soyinka sọ ìdí tó fi ni òun a fi màálù Fulani ṣe súyà fáwọn èèyàn abúlé23 Owewe 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Awon agbegbe miiran ti won tun fenuko le lori ni: ajosepo lori ekose owo, riro-ni-lagbara, ile-ise ipese nnkan ati oro kara-kata, eto-eko eto-ilera, ipolongo eto idokowo imo-ijinle ero igbalode, abbl.
Ó ṣeéṣe kí ilé ìjọsìn, mọ́sálásí àti ọkọ òfurufú ṣí, Ẹ wo àwọn ìlànà tuntun tí ìjọba là sílẹ̀ Awọn àkẹkọ̀ọ́ Uniben wọ́de ìfẹ̀hónú hàn nítórí akẹgbẹ́ wọ́n tí wọ́n fipa bálòpọ̀ Gómínà Kogi pàṣẹ kóníléógbélé ní ìjọba ìbílẹ̀ kan ní Kogi Ọwọ́ bàtá Auxiliary tó ń ró ní àrójù, leè ya láìpẹ́ - Ìjọba Oyo dúnkookò Ighalo ti gba goolu mẹrin sawọn lẹẹmẹrin ninu ifẹsẹwọnsẹ mẹjọ to lanfaani lati ṣoju Man U ninu rẹ ki o to di wi pe wọn so ere bọọlu rọ nilẹ Gẹẹsi nitori ajakalẹ aarun coronavirus.
" O ṣalaye pe, ibi ti oun ti jẹ oye naa ko ni nnkan ṣe pẹlu iṣẹ to rọ mọ oye ọhun, nitori gbogbo awọn to ṣe pataki nilẹ Yoruba lo peju sibi ifinijoye naa, leyi to tumọ si pe wọn fọwọ sii.
yege ninu esi abajade ibo to waye ni awon agọ idibo márùndínlógójì  (35)to wa ni ijoba ibilẹ Kebbe,amosa o jawe
Oba Abdullah II ti Jordan lo
Jíjí tí mo jí ní kùtù-kùtù,
Gẹ́gẹ́ bí ohun tí OLUWA ti sọ, wọ́n ta òṣùnwọ̀n ìyẹ̀fun kíkúnná kan ní ìwọ̀n ṣekeli kan.
Gẹgẹ bi o ti ṣe sọ, o ni 'Adedibu fi ipa manigbagbelelẹ lagbami oṣelu ilẹ kaarọ o jiire.
 O ni “bi a ba pori akọni ami a maa fara han”.
Nkan kejì tó kù díẹ̀ káàtó ni pé àwọn àwo orin tí wọ́n lù, àsán azonto ni.
Wọ́n wá ròyìn ohun gbogbo tí Ọlọrun ti ṣe fún wọ́n.
Lati ọjọ meje sẹyin, oniroyin ati akọroyin meje lo ti ku iku Coronavirus ati iku ti ku nise pẹlu aarun naa.
Ẹ fetí sílẹ̀ sí ọ̀rọ̀ mi, ẹ̀yin ará ilẹ̀ òkèèrè,láti inú oyún ni OLUWA ti pè mí,láti inú ìyá mi wá ni ó ti dárúkọ mi.
”Filipi dá a lóhùn pé, “Wá wò ó.
Wọn óo gbé àwọn eniyan tí wọn ń sọ àsọtẹ́lẹ̀ fún sọ síta ní òkú ní ìgboro Jerusalẹmu, nígbà tí ìyàn ati ogun bá pa wọ́n tán.
Edward Kallon, to je asoju ajo agbaye ni eka eto iranwo fun orile ede Najiria soro ni New York nibi ipade kan pe orile ede Naijiria n koju awon isoro pupo.
Abíọ́lá: Ọmọ tí a bí sínú ọlá tàbí lásìkò tí àwọn òbí rẹ̀ ní ọlá púpọ̀
Bi wọn bá soko tán lọjọ yii, ti wọn sì fà ori wọn, wọn lè e bọ asọ naa kuro lara, sugbọn awon obirin kìí bá wọn wọ asọ Ihram yii.
ohun ti a n pe ni ijoba tiwa-n-tiwa niyi.
Ṣugbọn nígbàkúùgbà tí mo bá wí pé n kò ní dárúkọ rẹ̀ mọ́,bẹ́ẹ̀ ni n kò ní sọ̀rọ̀ ní orúkọ rẹ̀ mọ́,ọ̀rọ̀ rẹ a máa jó mi ninu bí iná,a sì máa ro mí ninu egungun.
Iroyin sọ pe awọn eeyan kan lo ṣa dede lọ pẹlu awọn ohun ija oloro ti wọn si da majele si inu odo naa ti wọn fi n pese omi ẹrọ fawọn akẹkọ ati olugbe inu ileewe naa.
Òṣìṣẹ́ LASTMA kan àgbákò ikú lọ́wọ́ àwọn jàǹdùkú méjì nílùú Èkó Erin mẹ́fa wó níbi tí wọ́n ti fẹ́ dóòlà ẹ̀mí ara wọn Iná ẹ̀lẹ́ńtíríkì pa ẹlẹ́wọ̀n márùn ún lọ́gbà ẹ̀wọ̀n l'Eko Àwọn ìmúra málegbàgbé Dino Melaye níle aṣòfin àgbà Ọlọ́pàá South Africa rí ẹ̀wọ̀n ọgbọ̀n ọdún he torí ikú ọmọ Nàìjíríà Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, World Aids Day: Wo bí kòkòrò ààrùn HIV se bẹ̀rẹ̀ lágbàyé!
Benue: ‘Operation Cat Race’ ko lee yanju ikọlu darandaran
ti won yoo gbe maa se ayewo  ati ibi ti
Atiku ni , oun ro pe awon osise
 Láaláa tó r'òkè , ilè ni ń bọ̀.
 O ni ki Tinubu pari aawo aarin awon olori gbogbo ati tawon omo egbe tinu won ko dun to nipinle ati nijoba apapo.
Àwọn kan ninu àwọn ọmọ ogun ṣáájú àwọn alufaa tí wọn ń fọn fèrè ogun, àwọn kan sì tẹ̀lé Àpótí Majẹmu.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Àwọn ajínigbé: 'Ẹ mú N20m wá tàbí ká pa ìyàwó ọba' 26 Òkùdu 2018 Oríṣun àwòrán, AFP Àkọlé àwòrán, Jíjínigbé wọ́pọ̀ l'ágbègbè Niger Delta Awọn ajinigbe ti wọn ji iyawo Ọba Alauga ti ilu Auga-Akoko ni Ipinlẹ Ondo ti beere fun ogun miliọnu owo naira(N20 million) ki wọn to le fi silẹ.
Daddy Freeze sẹleri pe oun ko ni gba owo ori lori awọn ọmọbinrin ti Eleduwa fi ta oun lọrẹ to ba to asiko fun wọn lati ṣe igbeyawo.
Bayii eto iwosan lati lọ ri dokita naa ti yipada bayii, Dokita Funmi Adeara to jẹ oniṣegun oyinbo lasiko Covid 19 ba BBC sọrọ lori awọn irufẹ ayipada wọnyii.
Ni awọn ibudo idibo bii mẹwa ti BBC de, idibo ko tii bẹrẹ rara, ohun ti awọn oludibo si n sọ ni pe nṣe lawọn janduku n le awọn oludibo atawọn aṣoju ẹgbẹ alatako kuro ni ibudo idibo.
Fún bí ọ̀sẹ̀ méji ni àwọn ọlọ́pàá fi ń wá Adebisi ati Julian to jẹ́ ọmọ ọdún méjìdínlógún.
Lónìí, o ti fi bí o ti jẹ́ eniyan rere sí mi tó hàn mí, nítorí pé o kò pa mí, bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé OLUWA fi mí lé ọ lọ́wọ́.
Eyi kii ṣe lati ṣe awawi, ṣugbọn ohun to ṣe pataki ni pe a n ti n lo ọna miran lati ṣiṣẹ.
Ẹsun naa jade lẹyin ti D'banj darapọ mọ awọn gbajumọ bi ti ẹ lati polongo tako ifipabanilopọ.
Máa gun ẹṣin ìṣẹ́gun lọ ninu ọlá ńlá rẹ,máa jà fún òtítọ́ ati ẹ̀tọ́,kí ọwọ́ ọ̀tún rẹ fún ọ ní ìṣẹ́gun ńlá.
Lọdun 2012, ọwọ ọlọpaa tẹ awọn bi aadoje to jẹ ọmọ ẹgbẹ naa ni adugbo Apapa ati Ajegunle.
Lọpọ igba awọn to n pa awọn ẹranko wọnyii a ma ta ẹya ara wọn lowo iyebiye.
Agbarijọpọ ẹgbẹ awọn osisẹ ni Naijiria, NLC ati TUC ti n leri leka pe ọjọ isẹgun yoo ro lorilẹede Naijiria.
Eyín akọ̀ròyìn fò yọ lásìkò tó n ka ìròyìn lọ́wọ́ lórí tẹlifísàn Ààrẹ ilé ìwòsàn obinrin Boston, Ọniṣegun oyinbo Lawrence Epstein, sọ pé o lé ni èèyan ààdọrin mílíọnù to ni ìṣòrò oorun ni ilẹ̀ Amerika.
Oyedepo sọ pe fifi ẹmi awọn alaiṣẹ Kristẹni ṣofo, papa julọ laarin gbungbun orilẹede Naijiria ti to gẹẹ.
 À n sọ pé ọ ̀ rò kòòkan , bó jé ọ ̀ rò orúkọ tàbí òrọ ̀ ìse , máa ṇ ̣ ̣ ̣ wá pẹ ̀ lú àwọn nnkan .
Ó jọ l’ójú mi l’ọ́jọ́ náà pé bí a ṣegbàdúrà tán, ẹ̀gbọ́n wa àgbà kò ní í kú mọ́.
Ní Bunong, tí ó wà ní àríwá ìwọ-oòrùn Cambodia, àwọn àlọ́ tí ó sọ nípa ètùtù fún àtúnṣe sí ìgbéyàwó tí kò ní adùn àti ètùtù ìfọ́nrúgbìn àti ìkórè tí Khoeuk Keosineam jẹ́ asọ̀tàn.
Oríṣun àwòrán, omoyele sowore Bákan náà ni adajọ Onyetenu gbà pé, ìjọba fi ẹtọ Ogungbeje to pé ẹjọ́ ní orúkọ àwọn Oluwọde yoku dùn wọn, nítorí abala kejidinlogoji, ikokandinlogoji àti ogójì òfin ilẹ̀ wá ti ọdún 1999, tí fun wọn ní àǹfààní láti ṣe bẹ́ẹ̀.
Bakan naa, Olamilekan Solomon (Iwọ oorun) jawe olu bori pẹlu ibo 378,906 nigba ti alatako rẹ Kayode Opeifa ni ibo 1,179.
Wọn yóo mu yín lọ siwaju àwọn aláṣẹ ati àwọn ọba nítorí mi kí ẹ lè jẹ́rìí ìyìn rere fún wọn.
O ni eyi yoo si tun mu airiṣẹṣe àti airílégbé dání.
Eyi ko ṣẹyin gbọnmisi omi oto to n waye ni ẹgbẹ oṣelu lẹyin ti ajọ amuṣẹya ẹgbẹ naa yan eniyan mẹta gẹgẹ bi alaga ẹgbẹ laarin wakati mẹrinlelogun.
Association of Stingy Men: Akeugbagold ní àpẹẹrẹ wèrè díẹ̀díẹ̀ ni k'ẹ́ni tó lówó láhun sí obìnrin
Ninu ikede ti ajọ to n gbogun ti ajakalẹ́ arun lorileede Naijiria NCDC fi sita lalẹ ọjọ Ẹti, wọn ni eeyan 462 tuntun miran lo lugbadi arun naa.
Super Eagles  ti orile ede Naijiria ni anfaani
Ṣugbọn mo ṣe bí adití, n kò gbọ́,mo dàbí odi tí kò le sọ̀rọ̀.
 Ipade naa lo je  akoko ti yoo ba won se labe akoso ijoba aare Muhammadu Buhari .
Bí Adonija ati gbogbo àwọn tí ó pè sí ibi àsè rẹ̀ ti ń parí àsè, wọ́n gbọ́ ariwo náà.
Ó ti kópa nínú fíìmù bíi Jenifa, Gone to America, Divorce Not Allowed, Ghetto Bred àti bẹ́ẹ̀ bẹ́ẹ̀ lọ.
Ẹni tí ó ń fi aiṣododo kọ́ ilé rẹ̀ gbé,tí ó ń fi ọ̀nà èrú kọ́ òrùlé rẹ̀.
Hisba ni: Nitori eyi, a rọ yin lati fi opin si pipe ọjọ naa ni 'Black Friday', ni kiakia."
Ọba Asiria rán Rabuṣake (olórí ogun rẹ̀), pẹlu ọpọlọpọ ọmọ ogun; láti Lakiṣi sí ọba Hesekaya ní Jerusalẹmu.
Leah Sharibu ṣì wà láàyè - Iléeṣẹ́ Aarẹ Buhari Laipẹ́, ọmọ tí kò bá pé ọdún méjìdínlógún kò ní leè jáde girama l’Ọṣun South Africa, Algeria ati Morocco to gbalejo idije naa ni wọn jọ fi jẹ marun un loke tente atẹ idije tọdun yii.
Igbimọ Aṣofin Ipinlẹ naa ni ọjọ kejidinlọgbọn oṣu kejila ọdun
Kí àwọn alufaa, àwọn ọmọ Lefi, bá wọn lọ pẹlu; nítorí àwọn ni OLUWA Ọlọrun yín yàn láti máa ṣe alufaa ati láti máa súre fún àwọn eniyan ní orúkọ OLUWA; ati pé àwọn ni OLUWA Ọlọrun yàn láti parí àríyànjiyàn ati ẹjọ́.
Ọmọwe Dokita, Shina Adetona ni wọn fẹsun kan ni tirẹ pe o ṣẹ jibiti, to si ṣe magomago pẹlu akọsilẹ awọn oṣiṣẹ.
Ẹ̀mí mi yóo ní ànító ati àníṣẹ́kù;n óo sì fi ayọ̀ kọ orin ìyìn sí ọ.
#U20WC: Flying Eagles fìyà ṣínu ààwẹ̀ lórílẹ́èdè Poland Buhari gba ife ẹyẹ agbaye Ko da Ronaldo tun sọ pe ami ayo mẹta si ẹyọ kan ni Liverpool yoo fi la Tottenham mọ lẹ ninu ifẹsẹwọnsẹ ọhun ti yoo waye niluu Madrid.
Nígbà tí ó tó àkókò tí ọba ti pàṣẹ pé kí wọ́n kó wọn wá, olórí ìwẹ̀fà kó gbogbo wọn wá siwaju rẹ̀.
Oríṣun àwòrán, AFP Àkọlé àwòrán, Fulani Darandaran Ìbẹ̀rẹ̀ ọrọ yii gan ni asiko ti ijọba apapọ ni awọn fẹ da eto RUGA Settlement silẹ eyi ti ọpọlọpọ ti fun ni itumọ tiwọn ti wọn si fẹ loju kaakiri gbogbo ipinlẹ orilẹede Naijiria.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Prepaid Meter: èrò àwọn èèyàn ṣọ̀tọ̀ọ̀tọ̀ lórí 'sisan owó iná ní Nàìjíríà Bawo ni Shisha ṣe kọja ayẹwo ni papakọ ọkọ ofurufu Eko?
Aráyé ti ìhà àríwá là ń wí sẹ́ẹ̀.
Ṣugbọn bí OLUWA Ọlọrun yín ti mú ìlérí rẹ̀ ṣẹ nípa àwọn nǹkan dáradára tí ó pinnu láti ṣe fun yín, bákan náà ni yóo mú kí gbogbo àwọn nǹkan burúkú tí ó ti ṣèlérí wá sórí yín, títí tí yóo fi run yín patapata lórí ilẹ̀ dáradára tí ó fun yín, 
Nítorí náà mo wẹ̀ wọ́n mọ́ ninu gbogbo nǹkan àjèjì, mo sì fi ìdí iṣẹ́ wọn múlẹ̀ gẹ́gẹ́ bí alufaa ati ọmọ Lefi.
Aláàfin ń se ọgọ́rin ọdún, àwọn àwòrán mánigbàgbé Aarẹ ọna kakanfo Yoruba Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí kan sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
Ẹ̀yin ará, mò ń rọ̀ yín, ẹ túbọ̀ máa ṣe bẹ́ẹ̀ ati jù bẹ́ẹ̀ lọ.
Bí wọn bá gbéra nílẹ̀, àwọn náà á gbéra, nítorí pé ẹ̀mí àwọn ẹ̀dá alààyè náà wà ninu wọn.
wa ojutuu si iwa  Ipaniyan,Yiyara gbẹmi- ara -ẹni
Gẹ́gẹ́ bíi apanilẹ́rìín, ó ti ń gòkè nínú iṣẹ́ ìdánilárayá.
Sadiya Umar Farouq ti ní pé ọwọ òun mọ lórí N2.
láti fihàn pé olóòótọ́ ni OLUWA;òun ni àpáta mi, kò sì sí aiṣododo lọ́wọ́ rẹ̀.
Ko sọ igba ti wọn yoo yi ipinnu naa pada.
Ni ipari, awon olokoowo to n se pasipaaro owo ina ohun wa so o ekunwo ti o ba owo naa mo ile ifowopamo agba CBN lataari pasipaaro lati oju oja ti ile okere.
Olúkúlùkù ni ó mú àwo tirẹ̀ ti ilé wá, tí ó mú ṣíbí tí ó sì mú ife.
Ọmọ Yorùbá ni onímọ̀ ẹ̀rọ ‘Rọ́bọ́tì’ tó ń gbowó jùlọ ní UK Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí 3 sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 2:23 Fídíò, Water Generator: Ó leè ṣiṣẹ fún wákàtí mẹfà, kó tó sinmi, Duration 2,2310 Òkùdu 2020 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
Ọsẹ meji lẹyin naa ni ọwọ tẹ Tanko ni ipinlẹ Taraba.
Lọdun 2018,Angola na ida mẹtadinlgọta ninu ida ọgọrun owo ijọba lati fi san gbese ti wọn si mu adinku ba iye ti ijọba n na pẹlu ida mọkandinlogun laarin ọdun 2016 si 2018.
Oríṣun àwòrán, @andybes50484929 Bi ijọba ko se lee dẹkun ati wawọ isẹ laabi awọn darandaran yii wọlẹ, lo n dunkooko mọ isọkan ati irẹpọ Naijiria, ti gbogbo ẹya si n kọrin ki Ọlọmu da ọmu iya rẹ gbe.
Oríṣun àwòrán, Google Amọ, Ajọ EU ni awọn ko mọ nkankan nipa ẹrọ ‘server’ ti ẹgbẹ oselu PDP sọ wi pe Ajọ INEC fi ko esi idibo jọ lasiko idibo gbogboogbo to waye.
Oluranlọwọ fun Ọbasanjọ, Kehinde Akinyẹmi lo fi ikede naa sita fun awọn akọroyin.
    Nígbà tí ó di ọjọ́ keje ni ọba ránṣẹ́ wá tí o ni òun ti rí ẹni ti òun ó fi lé mi lọ sí ìgbèríko àti pé ki n jẹ́ kí òun mọ ìgbà tí yóò dẹ̀ mi lọ́rùn àti lọ.
Ǹjẹ́ ẹ̀yin rántí orúkọ ti a n pe kòkòrò yìí àti ǹkan tí àwọn ọ̀dọ́mọdé'bìnrin máa fi ń ṣe.
Ọgbẹni Zelensky ko ni wọ ọkọ akero wa sibi ayẹyẹ ibura rẹ ṣugbọn o ti saaju fi fọnran fidio kan sita loju opo ayelujara pe oun tọrọ aforijin lọdọ ara ilu nitori sunkere fakẹrẹ ti ayẹyẹ naa yoo da silẹ.
ile-ise kookan ti awon minisita ti o sese yan sipo labe isakoso isejoba tuntun
O ni gẹgẹ bi ẹni to ti ṣe igbakeji gomina banki ile ifowopamọ to ga ju ri nitori naa ati ṣe gomina ko le nira.
Ninu fidio yii ni Lizzy ti sọ pe, ẹbẹ ti oun bẹ ṣaaju kii ṣe fun Toyin, ṣugbọn fun awọn ẹbi ati awọn ololufe oun ni.
Kí ó tó pé ọdún meji, òun óo kó gbogbo ohun èlò tẹmpili òun pada, tí Nebukadinesari ọba Babiloni kó láti ibí yìí lọ sí Babiloni.
Ewe, leyin ti ife-eye ohun ti lo kaakiri ogbon orile-ede lati inu osu kinni ti o ti bere irin ajo re, ife-eye ti o gbayi julo ohun pada bale silu Abuja, leyin ti  Christian Karembeu.
naa ko wa ni ilana ofin pelu ẹri to wa niwaju adajo naa nitori naa  “Idajo naa ko ni wa ni  ibamu ofin.
Bi àwọn tí ó ti gbọ́ ohun tí mo sọ fún wọn; wọ́n mọ ohun tí mo sọ.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Kí ló ń fa ikú ọ̀wọwọ̀ọ́ níjọba ìbílẹ̀ Lagelu, n‘Ibadan?
Láti gba ẹ̀mí là ni tabi láti pa ẹ̀mí run?
Àṣàkù yóo kù níbẹ̀,bí ìgbà tí eniyan gbọn igi olifi,yóo ku meji tabi mẹta péré ní góńgó orí igi,tabi bíi mẹrin tabi marun-un lórí ẹ̀ka igi.
Sisan owo adinku ori yii bẹrẹ lati ọdun 2018.
Ọdun 2018 ni ijọba ipinlẹ Kaduna fẹsun ipaniyan kan oun ati iyawo rẹ, Zeenah Ibrahim ti wọn si gbe wọn lọ ile ẹjọ lẹyin ti awọn ọmọ lẹyin rẹ dena olori ologun Naijiria ni Kaduna.
Ìgbẹ́tì: Òkè Ìyámàpó ló gbà wá sílẹ̀ lọ́wọ́ ogun
lọjọ  Ẹti ni Kajuru ni ipinle Kaduna,ijọba
Agbẹjọro ẹbi oloogbe George, Ọgbẹni Ben Crump ṣalaye pe ilu rẹ ni Houston ni wọn yoo sin George sii Leonard Ellerbe to jẹ adari ileeṣẹ Mayweather Promotions lo fidi ọrọ naa mulẹ fawọn akọroyin.
Nkechi to sọrọ yii lori ayelujara ṣalaye pe o san fun oun ki oun ni ayọ lai tii lọkọ ju ki oun wa lọọdẹ ọkọ pẹlu inanujẹ ọkan lọ.
Lati wa idi òtitọ́, wọn lè kó àwọn ti ó njà lọ si ojúbọ Òriṣà lati búra.
"Mo lero wi pe apapọ awọn ọmọ ogun ni wọn ko gbiyanju to.
Isẹ ati osi si peleke si.
Yorùbá tone mark: Fífi àmì ohùn sí orí ọ̀rọ̀ Yorùbá ṣe pàtàkì
Ogun abẹ́lé àti ṣi ṣe Òfin Àpapọ̀ tuntun lẹhin ogun, ni wọn fi gba àwọn Aláwọ̀dúdú silẹ̀ ni ilú Àmẹ́ríkà.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Supplementary Election: Ijọba ìbilẹ Nasarawa nílò àfikun ọlọpàá ló jẹ ká fi kún un"" 23 Ẹrẹ̀nà 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Supplementary Election: ""Ijọba ìbilẹ Nasarawa nílò àfikun ọlọpàá ló jẹ ká fi kún"" Ilé iṣẹ́ ọlọ́pàá ìpínlẹ̀ Kano ti tún kó àwọm ọlọpàá míràn lọ si Wọọdu Gama ní ìjọba ìbílẹ̀ Nasarawa láti túbọ mú kí ètò ààbò gbópọn síi."
Èyí ni ìfẹ́ ẹni tí ó rán mi níṣẹ́, pé kí n má ṣe sọ ẹnikẹ́ni nù ninu àwọn tí ó fi fún mi, ṣugbọn kí n jí wọn dìde ní ọjọ́ ìkẹyìn.
Amitabh Bachchan: Òṣèré India, Amitabh Bachchan tó lùgbàdì ààrùn Coronavirus ti móríbọ́
Mò ń sọ fun yín, ìyapa ni mo mú wá.
Wo ojú Akeem t'Ọlọ́pàá mú pé ó fipá bá ọ̀dọ́mọbìnrin kan sùn létí odò l'Oṣun Yàtọ̀ sí Eko, wo ohun t'áwọn ìpínlẹ̀ meje míràn ń sọ nípa ìwọlé àwọn akẹ́kọ̀ọ́ Wòlí àti Pásítọ́ ló máa ń rọ̀jọ̀ àdúrà sórí ibọ́n wa kí a tó lọ digunjalè- Kayode Williams Máa gbé kẹ̀kẹ́ rẹ lọ, àwọn akọròyìn kọ̀ ìpàkọ́ sí Femi Fani Kayọde Ọwá Ale Ikarẹ, Oba Adegbite-Adedoyin papòdà lẹ́ni ọdún márùndínláàdọ́rùn ún!
Mo tún rí i tí ṣiiri ọkà meje mìíràn yọ lẹ́yìn wọn, wọ́n tínínrín, wọn kò sì ní ọmọ ninu rárá, nítorí afẹ́fẹ́ ìhà ìlà oòrùn ti pa ọlá mọ́ wọn lára.
Alagba Peter Fatomilola sọ pe, to ba jẹ pe laye àtijọ́ ni, gbogbo ilu yoo sọ pe ki ọba naa wa a lọ nitori pe kii ṣe oun lo ni i, fun gbogbo ọba to ba jẹ ni.
O ni olorukọ nla lawujọ ni gomina ana naa ti ko si lee sa mọ ofin lọwọ paapaa julọ pẹlu bi o ṣe jẹ wi pe ko si akọsilẹ pe irufẹ igbesẹ bẹẹ ṣẹlẹ ri sii.
 Ó jẹ ́ ìwé-ìtà àròsọ àkọ ́ kọ ́ tí a kọ lédè yorùbá àti ní ilẹ ̀ adúláwò ̣ Áfíríkà .
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ahmed Lawan: Àwọn ohun tó yẹ ko mọ̀ nípa ààrẹ aṣòfin àgbà tuntun 11 Òkùdu 2019 Oríṣun àwòrán, @nassnigeria Ọjọ Isẹgun ọjọ Kọkanla osu Kẹfa ọdun 2019 jẹ ọjọ manigbagbe ninu itan igbesi aye Ahmed Ibrahim Lawan nigba ti awọn akẹẹgbẹ rẹ dibo yan gẹgẹ bii aarẹ ile asofin agba ilẹ Naijiria tuntun.
Gani Adams kilọ f'awọn darandaran Darandaran gun awakọ pa l'Ondo Ganduje pe awọn darandaran si Kano Ọmọogun pa darandaran mẹwa ni Adamawa O ni awọn ti Babandede n sọ ni awọn ti ko ni iwe aṣẹ lati gbe Naijiria ati pe Ọ̀FẸ́ ni wọn yoo ṣeto gbigba iwe igbeluu yii laarin oṣu mẹta to sọ.
Ṣaaju, gbajugbaja oloṣelu ati minisita f'eto ofurufu tẹlẹri ni Naijiria, Femi fani Kayode fi si oju opo Twitter rẹ pe bi wọn ba fi ẹsun kan eeyan, ko tii tumọ si pe o daju.
 ijala yi ni nwọn yio fi ki i ni awujọ ọdẹ .
Wasiu Ayinde ni, ìkórira pé òun jẹ Mayegun ilẹ̀ Yorùbá lo mu ki wọn pa irọ mọ òun, ó ní lérò àwọn èèyàn náà, oyè ọhun kò tó sí òun.
Oríṣun àwòrán, yso olaniyi Àkọlé àwòrán, Diẹ lara awọn ọkada to ku sinu ile naa lẹyin ti awọn janduku ko lọ lara rẹ.
Aworan Mide ati Afeez Owo lo han gbagada lori paali sinima ''SALAWA'' naa.
Kò tíì pẹ́ tí a dá wọn,ẹ kò gbọ́ nípa wọn rí, àfi òní.
Awon egbe ajafeto omo eniyan ti n bu enu ate lu ijoba orile-ede Ethiopia latari bi won se n fi owo sinkun mu awon eniyan ati bi won se n fi awon egbe oselu alatako ati awon oniroyin sile sogba ewon fun igba pipe.
OLUWA ní: “A máa ṣe pé mo ní inú dídùn sí ikú ẹlẹ́ṣẹ̀ ni?
Akinyẹmi ni, lootọ ni Ọbasanjọ ti foriji wọn ni ibamu pẹlu ohun ti Bibeli sọ, sugbọn ẹgbẹ alajumọṣe African Democratic Congress, ADC, ṣi ni yoo gbe e leke.
Gbọingbọin lọmọ Nàìjíríà wà lẹ́yìn iléẹjọ́ gíga jùlọ lórí ìdájọ́ ìbò Bayelsa- Atiku Àwọn ọmọ onílẹ̀ lọ ṣe àmúṣẹ àṣẹ iléẹjọ́ ní Soka, làwọn ‘Jàǹdùkú’ fi dá wọn lọ̀nà - Iléeṣẹ́ ọlọ́pàá Ọyọ Bàbá àti ìyá mi kò fẹ́ kí n ṣe eré tíátà - Wale Akorede Okunnu Ẹ̀yin òṣèrè tíátà, ẹ ní ṣùúrù de àsìkò Ọlọ́run, ẹ máṣe kánjú kọjá kádàrá - Madam Ṣajẹ Awọn dokita ati onimọ nipa ounjẹ asaraloore ni ọra ikun naa lee maa pọ si to ba se ayipada awọn eroja ounjẹ to n jẹ, paapa apọju awọn ounjẹ to ni eroja suga atawọn ounjẹ afun ara lagbara.
Ẹ má ṣe gbẹ́kẹ̀lé ọ̀rọ̀ ẹ̀tàn yìí pé: “Tẹmpili OLUWA nìyí, kò séwu, tẹmpili OLUWA nìyí.
Ṣekeli mẹ́wàá sì gbọdọ̀ pé ṣekeli mẹ́wàá; òṣùnwọ̀n mina sì gbọdọ̀ pé aadọta ṣekeli.
Àwọn ọmọ Satu jẹ́ ojilelẹgbẹrin ó lé marun-un (845).
Nítorí pé, nígbà tí ìpọ́njú bá dé,yóo fi mí pamọ́ sinu àgọ́ rẹ̀,lábẹ́ ààbò, ninu àgọ́ rẹ̀, ni yóo fi mí pamọ́ sí;yóo sì gbé mi sókè ka orí àpáta.
Ó yẹ kí ojú ti ìwọ pàápàá, nítorí o ti jẹ́ kí ìdájọ́ gbe àwọn arabinrin rẹ, nítorí nǹkan ìríra tí o ṣe ju tiwọn lọ.
Amọṣa ọrọ ko ni ri bẹẹ fun ti twitter yii.
ki teru-tomo awon osise lee jegbadun ekunwo owo osu naa.
 Àlàbí padà di òǹkọrin ìgbàgbọ ́ lẹ ́ yín tí ó di onígbàgbọ ́ tòótọ ́ .
Owó tí ó gbà jẹ́ egbeje ìwọ̀n ṣekeli fadaka ó dín marundinlogoji (1,365), gẹ́gẹ́ bí ìwọ̀n ṣekeli tí wọn ń lò ní ibi mímọ́.
 nítorí náà a gba orin èébú ní Òkè-igbó àti ifẹ ̀ ẹ ́ tẹ ̀ dó .
Ati ìdámẹ́wàá òṣùnwọ̀n ìyẹ̀fun tí a fi òróró pò fún ọ̀dọ́ aguntan kan.
leyin ojo meloo kan, to yẹ ki eto idibo gomina waye ni ipinle naa, lati tako
Ẹwẹ, o fikun ọrọ rẹ pe o le ni ẹjọ ẹgbẹrun meji to nii ṣe pẹlu lilo akoto ifiweranṣẹ awọn eeyan lori ayelujara lọna aitọ ti awọn n tọ pinpin rẹ lati dun 2018.
’ Ó wò mí, ó mú mi lọ́wọ́ d́ní bí ẹni pé kò le dá dúró mọ́.
Ẹwẹ, ọpọ awọn tọrọ kan lo fi ẹhonu han, paapaa tako atunṣe abala kẹfa ofin naa ti o fẹ ṣe eto naa ni kanpa fun gbogbo olugbe ipinlẹ Eko.
Mo muu ni dandan pe ki n ba obinrin naa sọrọ lati mọ boya o faramọ ki ọkọ rẹ fẹ iyawo keji.
Bukọla Saraki fori sọlẹ sile aye ni ọjọ kọkandinlogun, oṣu Kejila, ọdun 1962, si idile oloogbe Olusola Saraki, ti oun naa jẹ agba oselu ati gbaju-gbaja ni awujọ wa.
Trump sọ̀rọ̀ náà nígbà tí ó ń gbàlejò akẹgbẹ́ẹ rẹ̀ láti Nàíjíríà, Àarẹ Muhammadu Buhari nílé ìjọba Amẹ́rika, White House.
Koda o tun fẹ dije ni igba kẹrin.
Eyi lo ti bi eso ti aarẹ ile igbimọ aṣofin ti fi yọ Festus Adedayọ nipoKò dùn mí pé mo sọ̀rọ̀ tako Buhari -Adedayo Festus Sanwo-Olu kò lè tori ìjà Ọjọta fòfin de NURTW ní Eko - Agbẹnusọ gómínà Wo àwọn ẹranko tí wọ́n máa figagbaga ni Egypt Wo ohun tuntun tó n ṣẹlẹ̀ lágboolé CAF Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Abrahamu ti darúgbó, Ọlọrun sì ti bukun un ní gbogbo ọ̀nà.
Ibrahim lati ile iwe giga fasiti ti awọn ologun to wa ni Biu gẹgẹ bi ọga agba tuntun ti ajọ to n ri si agunbanirọ ni Naijiria, NYSC.
Nígbà tí iná ti jó o, tí ó ti di èédú, ṣé eniyan tún lè fi ṣe ohunkohun?
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Lati orilẹede Japan, China ati Korea ni ajọ NAFDAC ni ẹja yii ti n wa si orilẹede orilẹede Naijiria Gẹgẹ bi wọn ṣe sọ, bi eeyan se ẹja yii tabi koo pamọ sinu ẹrọ amohuntutu, kaka ki majele ara rẹ parẹ, n ṣe ni yoo maa rin kaakiri agọ ara rẹ.
Solomoni ṣe àwọn nǹkan wọnyi sí ilé Ọlọrun: pẹpẹ wúrà, tabili fún burẹdi ìfihàn.
Wọ́n ro ẹjọ́ Paulu fún gomina.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, APC: òfin NYSC ti APC fi mú mi ni wọ́n kò lò fi mú Ajimọbi tí a kò jọ sìnrú ìlú Kini fidio yii da le lori?
Ẹ kò ní jẹ̀bi nígbà tí ẹ bá jẹ ẹ́, níwọ̀n ìgbà tí ẹ ti san ìdámẹ́wàá ninu èyí tí ó dára jù.
 Àpèjá orúko yìí ni ó di Ìjèbú-Òde lónìí yìí .
Àwọn ọmọ Bebai jẹ́ ẹgbẹta lé mejidinlọgbọn (628).
A óo wí fún àwọn eniyan yìí, ati àwọn ará Jerusalẹmu ní ìgbà náà pé afẹ́fẹ́ gbígbóná kan ń fẹ́ bọ̀ láti orí àwọn òkè, ninu pápá, ó ń fẹ́ bọ̀ sọ́dọ̀ àwọn eniyan mi; kì í ṣe afẹ́fẹ́ lásán tíí fẹ́ pàǹtí ati ìdọ̀tí dànù.
Ó ṣeéṣe kí ènìyàn 12,000 máa kú lójoojúmọ́ lẹ́yìn Covid-19 Orílẹ̀-èdè mẹ́wàá tí ẹgbẹ́ alákatakítí Islamic State n fínna mọ́ ní àgbáyé N kò gba ₦4bn lọ́wọ́ Magu, ẹ má ró àjẹbánu mọ́ mi láṣọ - Osinbajo pariwo Mi ò tíì gba ìwé ìfitónilétí pé wọ́n fẹ́ yọ mí nípò igbákejì gómìnà ìpínlẹ̀ Ondo- Agboola Ajayi Èyí tí a wò jùlọ 5:03 Fídíò, Omolola Arohunmolase Welder: Mo ti fí iṣẹ́ 'Welder' gbayì láwùjọ, tó mo fi tọ́ ọmọ yanjú, Duration 5,039 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 5:39 Fídíò, Akomolede ati Asa lori BBC: Olùkọ́ Kikelomo Ogunboye tan ìmọ́lẹ̀ sí ìwà olè ọ̀gá ọlọ́pàá Audu gẹ́gẹ́ bí àwòkọ́ṣe àsìkò yìí, Duration 5,398 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 4:11 Fídíò, Oba Adeyeye Ogunwusi: Ojú mi ti rí lọ́pọ̀ lọpọ̀, ọ̀pọ̀ èèyàn ni kò tilẹ̀ gbàgbọ́ pé mo lè jọba- Ooni, Duration 4,117 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 4:43 Fídíò, Promise Akinlade: ọmọ ọdún mọ́kànlá tó ń fi ìlù dárà bíi àgbàlagbà sọ̀rọ̀ nípa tálẹ́ǹtì rẹ̀, Duration 4,437 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 0:59 Gbọ́, Ìsẹ̀lẹ̀ jákèjádò orílẹ̀èdè àgbáyé láàárín ìṣẹ́jú kan, Duration 0,59wákàtí 5 sẹ́yìn 7:03 Fídíò, Olumuyiwa Bolade Adedeji Military Bruitality: Bí arákùnrin onípèníjà ara tí sọ́jà lù ṣe dé, Duration 7,035 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 4:45 Fídíò, Yoruba Films: Ẹ̀ẹ́ bẹ̀ mi kúrò láyé ni, mi ò lè kú - Fadeyi Oloro, Duration 4,4526 Èrèlè 2020 2:48 Fídíò, Esther Ajayi: Èmi náà ti borí ìṣòro rí ló ń mu mi ṣojú àánú, Duration 2,481 Ògún 2019 6:08 Fídíò, Adebola Ademilua: Àìrísẹ́ ṣè lẹ́yìn ìwé kíkà ló sọ mi dí ìyá onírú, mo dúpẹ́ tèmi, Duration 6,0827 Bélú 2020 5:55 Fídíò, Soyinka Cancer: Àṣe ara mi ni iso ti n run gbogbo bí mo ṣe n ṣèrànwọ́ lórí jẹjẹrẹ, Duration 5,5527 Bélú 2019 BBC News, Yorùbá Ìdí tí ẹ fi le è nígbàagbọ́ nínú ìròyìn BBC Ìlànà Lílò Nípa BBC Òfin Àṣírí Cookies Kàn sí.
Akọrin naa ni oun lọ ba Will Smitt, tii se ọkọ to fẹ obinrin osere tiata naa sile, lati gba asẹ lọwọ rẹ pe ki oun maa fẹ iyawo rẹ.
A kò tíì lè sọ pé ọmọ Ọba tuntun ni yóò jẹ Ooni lọ́jọ́ iwájú - Elebuibọn Wo àwọn èèkàn, ìlúmọ̀ọ́ka olórin tó ṣàbẹ̀wò sí ijọ Celestial Church ti Genesis Global CCC Genesis Global: Ǹkan mẹ́wàá tí ẹ ò gbọ́ rí nípa Israel Oladele, Woli ìjọ Genesis Global Ẹ̀tanú pé Olùṣọ́ Genesis kò fẹ́ Laide Williams-Oni ló ṣe rán an lọ́ sí ẹ̀wọ̀n ọdún kan - CCC Genesis Global Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Tí mo ba ti múra bí ọkùnrin fi kọrin, kò sí ọ̀dọ̀ ààrẹ́ tí mi ò lè wọ̀- Erelu, ọmọ Elemure Ekiti Baron Trump to jẹ ọmọ ọdun mẹrinla ti kọkọ lugbadi rẹ loṣu to kọja ṣugbọn ara tirẹ tete ya.
won ko ni pẹ lati bẹrẹ ifọrọwanilẹwo pelu won , lẹyin naa, won yoo tun foju
Ogbeni Salawu Balogun, alapata ẹran lo jẹ baba to bi Sikiru Ayinde Barrister nigba ti iya rẹ jẹ oniṣowo pẹẹpẹẹpẹ.
Ọmọ ọgbọn ọdun ni Seyi Awolowo ti a si gbọ pe o jẹ oluda ile iṣẹ silẹ.
Bí wọ́n bá bi ọ́ pé kí ló dé tí o fi ń mí ìmí ẹ̀dùn, sọ fún wọn pé nítorí ìròyìn tí o gbọ́ ni.
Idunnu nla, Ijo ati ariwo ayọ ni wọn n pa ni ayika ile ẹjọ naa to bẹẹ gẹ ti gomina ana naa ni lati ke si wọn ki wọn dakẹ ariwo nitori gbagede ile ẹjọ ni wọn wa.
Lẹyin eyi ni ọpọlọpọ awọn ọmọ Naijiria sọrọ sita pe iwa ifipabanilopọ gbọdọ di ohun igbagbe ni awujọ wa.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù MC Oluomo: Àánú ni mo rí gbà láti di alága NURTW Eko 6 Owewe 2019 Oríṣun àwòrán, @mcoluomo Alhaji Musiliu Akinsanya, ti gbogbo eniyan mọ si Mc Oluomo, ti wọn sẹsẹ yan gẹgẹ bi alaga fidiẹ fun ẹgbẹ awọn awakọ ero, NURTW, ẹka ti ipinlẹ Eko, ti n dupẹ lọwọ Ọlọrun fun iyansipo rẹ naa.
Igbe ọmọde yii ni awọn ara adugbo gbọ ti wọn si fi mọ pe ọfọ ti ṣẹ.
Wọn a máa tọ́ ọ sí ẹ̀kọ mímu.
Ile-ise omo ogun ohun wa fi mule pe, ko si wahala mo bi o se le
Eyi ko ṣẹyin fidio kan ti awọn ololufẹ eto naa fi sita loru ọjọ kan, to si ṣafihan awọn 'ololufẹ' mejeeji nibi ti wọn ti n 'fun ara wọn ni eso ifẹ jẹ'.
Gbogbo àwọn tí wọ́n kópa ninu iṣẹ́ náà fi tagbára tagbára ṣe é.
”Ewe, awon ti yoo maa kopa ninu ipade ohun nireti wa pe, won yoo mu olokan-o-jokan iriri ati idojuko ti orile-ede won la koja, eleyi ti won yoo koju ninu ipade ohun.
N ṣe ni ọkunrin bẹẹ yoo maa pongbẹ omi, koda bi wọn gbe odindi odo fun un pe ko mu, ko ni tan oungbẹ naa.
Ó tún pẹpẹ OLUWA tí ó wà níwájú yàrá àbáwọlé ilé OLUWA ṣe.
Ìfẹ́ òtítọ́ gbudọ̀ wà nínú ìgbéyàwó - BBC News Yorùbá BBC News, YorùbáFò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Imam Fuad Adeyemi: Mọ̀wádà - Ìfẹ́ òtítọ́ gbudọ̀ wà nínú ìgbéyàwó Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Imam Fuad Adeyemi: Mọ̀wádà - Ìfẹ́ òtítọ́ gbudọ̀ wà nínú ìgbéyàwó 14 Owewe 2018 Ìwà ipá nínú ilé ti rìn jìnà gẹ́gẹ́ bíi kòkòrò ajẹnirun tó ti ń tú ọ̀pọ̀lọpọ̀ ìdílé ká.
'Gómìnà Akeredolu lọ́wọ́ nínú wàhálà ilé aṣòfin Ondo' Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Olamide George lori olori tuntun ile asofin Ondo Aṣofin Olamide George ti wọn yan sipo lẹyin ti awọn aṣofin kan panupọ yọ olori ile aṣofin ipinlẹ Ondo nipo ti fi ẹsun kan gomina ipinlẹ naa, Rotimi Akeredolu pe o lọwọ ninu wahala ti o n waye laarin aṣofin ipinlẹ naa.
Ikilọ yii kun ikede ti ileeṣẹ ọlọpaa Naijiria lapapọ ti fi sita ṣaaju pe, awọn yoo da ọlọpaa sita jakejado Naijiria lati dena iwa kankan ti yoo ṣakoba fun alafiaa ilu.
Amọ, Alaga ẹgbẹ oṣiṣẹ nipinlẹ Eko naa ni, awọn ko le e ṣe ohunkohun lẹyin aṣẹ ti awọn adari oṣiṣẹ pa fun wọn, nitori naa ni awọn ṣe pana iyanṣẹlodi ohun.
Baba Suwe ni ọpọ eeyan mọ si adẹrinposonu, to si tun maa n da awọn eeyan laraya fun spọlọpọ ọdun.
Igún ń’írun lórí, ẹbọ l’ó m’órí Igún
Kò séwu nínú ìdìbò tó ń bọ̀ l'Ondo àfi gìrì àparò- Akeredolu ‘Àwọn òlóṣèlú kò ní ìwà ọmọlúwàbí ló jẹ́ kí wọ́n má a lọ láti ẹgbẹ́ òṣèlú kan lọ sí òmìràn’ Joe Biden ni yoo gbena woju Aarẹ Donald Trump ninu idibo sipo Aarẹ ilẹ naa ti yoo waye lọjọ kẹta, oṣu Kọkanla, ọdun 2020.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Buns ni ọmọ mi jẹ tán ní ṣọ́ọ̀ṣì, ló bá di àwátì' Bẹẹ ba gbagbe, ọsẹ meji sẹyin ree ti gomina Akeredolu lọ silu Abuja lati lọ kede pe oun fẹ dije fun saa keji lori aleefa, ọpọ eeyan si lo di mọ lati ya aworan.
[Ìròyìn tí ó tẹ̀ wá lọ́wọ́] Àjọ àwọn Òṣìṣẹ́ Ìròyìn (SNTP lédè Spanish) jábọ̀ pé àwọn Agbófinró Ọ̀tẹlẹ̀múyẹ́ Bolivaria (SEBIN) ti fi Luis Carlos sí àtìmọ́lé.
Níkẹyìn, wọ́n wá sí Beeriṣeba ní apá ìhà gúsù Juda.
Ǹjẹ́ àti ní aarun CORONAVIRUS tí tèmi ga ju ti ẹlòmíràn lọ tí mo bá ní aarun HIV Alix Fox: Dókítà Michael Brady ni Terrance Higgins Trust tí fi àwọn imoran kán síta lórí èyí, tí ó bá jẹ pe oun lọ oogun rẹ loore koore nítorí aarun HIV tí sì jí CD4 tó dára èyí timo sì lè a ó lè ka ó mọ àwọn tí èròjà tó bá àìsàn woyaja rẹ kò lágbára tó, nítorí náà tí ó bá ní aarun HIV, tesiwaju láti máa lọ oogun rẹ kì o sì tẹ́lẹ̀ àwọn ìlànà tí ó yẹ bí ó bá ti ṣe alabapade ẹni tí ó ní aarun Coronavirus.
" ni osu april 2007 , "" newsweek "" pe ni "" osere to lagbarajulo ni hollywood "" ."
Ọba bíi léèrè bí òun ti ó sọ dáa lójú.
Òkè gíga ni ilé ewúrẹ́ igbó,abẹ́ àpáta sì ni ibùgbé ehoro.
Iroyin ti a gbọ sọ pe ọpọ awọn ẹlẹwọn miran ni wọn wa lẹsẹkan aye, ẹsẹ kan ọrun bayii nitori iṣẹlẹ naa.
Ní ọ̀sán gangan ọjọ́ kan, OLUWA fara han Abrahamu bí ó ti jókòó ní ẹnu ọ̀nà àgọ́ rẹ̀, lẹ́bàá igi Oaku ti Mamure.
Ẹni tí ó bá kórìíra mi, kórìíra Baba mi.
" Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Ìyá Fasoyin sàlàyé pé lẹ́yin àdúra àti àwẹ́ ní wọn yóò wá mú àwọn ti ẹmi mímọ bá fí sí wọ́n lakan láti gbé síta.
Wọn yoo ṣeto ilana isinku naa pẹlu ilakalẹ to yẹ pẹlu bi gbogbo agbaye ṣe n koju ajakalẹ arun Coronavirus ni.
Oríṣun àwòrán, Lagos State Government Àkọlé àwòrán, Iwadi fihan lọdun 2014 pe ida kan ninu mẹrin obinrin lorilẹede Naijiria lo ti fara kaasa iwa ipa labẹle Ohun ti o n sẹlẹ yii jẹ iwa ibajẹ ti o n sọ awọn obinrin di ohun itẹmọlẹ lawujọ leyi ti o ti n mu ọpọ ninu wọn maa sunkun asunmi."
Àwọn kan tí wọ́n jẹ́ Farisi tí wọ́n wà láàrin àwọn eniyan sọ fún un pé, “Olùkọ́ni, bá àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ wí.
Prince ati Kiddwaya ni olugbe ile ẹlẹgbọn ti wọn ni ko ma kẹru wọn lọ sile lọsẹ yi.
Nigeria Security Tracker: Ọ̀pọ̀ ọmọ Naijiria ti kú sí rògbòdìyàn ó n ṣẹlẹ̀
Aarẹ orilẹ ede Naijiria Buhari ti darapọ mọ
Labẹ isọrii awọn mẹwa to pọju tawọn eeyan n bi google leere nipa wọn ju, awọn olorin ọmọ Naijiria bii Rema, Naira Marley, Omah Lay ati ajaweolubori eto ile Ẹlẹgbọn agba (Big Brother Naija Lock down Season 5), Laycon naa wa nibẹ.
Púpọ̀ nínú àwọn ìpín ìbẹ́rẹ̀ ní í ṣe pẹ̀lú àwọn ọ̀rọ̀ nípa ìyírọ̀padà àti ṣíṣe àtẹ̀jade Ìwé ti Mọ́mọ́nì (wo àwọn ìpín 3, 5, 10, 17, àti 19).
tokunbo; Aloku taya oko mokanlelogota; Aloku oko ayokele Peugeot 406 kan; Aloku
Ninu ọrọ tirẹ lo ti fi ẹsun kan awọn ileeṣẹ to n ṣakoso lilọ ile iwosan awọn eeyan (HMO) pe awọn ni wọn n ṣe owo awọn eniyan niṣekuṣe.
nítorí pé wọn kò gba Ọlọrun gbọ́;wọn kò sì gbẹ́kẹ̀lé agbára ìgbàlà rẹ̀.
Bí Jesu ti ń rìn kiri ninu Tẹmpili, àwọn olórí alufaa, ati àwọn amòfin, ati àwọn àgbà wá sí ọ̀dọ̀ rẹ̀.
Ballot paper (Iwe idibo) : Iwe idibo ni iwe ti orukọ
Rehoboamu, ọmọ rẹ̀, ni ó jọba lẹ́yìn rẹ̀.
Ọ̀rẹ́ mi tímọ́tímọ́ tí a jọ ń ja ogun Biafra ní kí n yìnbọn pa òun- Gabriel Aladejebi Àsọtẹ́lẹ̀ Fada Mbaka, tó yẹ àga mọ́ gómìnà Imo nídìí rèè Ilé ẹjọ́ rán ọmọ ìjọ lẹ́wọ̀n ọdún 18 lórí ẹ̀sùn pé ó jí ₦ 15m owo ìjọ Ìjàmbà ọkọ̀ akẹ́rù ní Ikòròdú fa súnkẹrẹ-fàkẹrẹ ọkọ̀ ní Márosẹ̀ Edeaiyede laarin Awolowo ati Akintola Awolowo fẹsun kan Akintola pe o fẹ fi eeru gba ipo olori ẹgbẹ oṣelu AG mọ oun lọwọ.
Eyi lo n jẹ ki awọn ọmọ wa maa sa fun aṣa.
Oríṣun àwòrán, EPA Àkọlé àwòrán, Greta Thunberg to jẹ ajijangbara lori itọju ayika n ya fọto pẹlu Militza Flaco.
Àwọn ọmọ Israẹli tún ṣí, wọ́n gba ọ̀nà Baṣani.
Ẹ yé irọ́ pa, mí o fún Super Eagles ní ẹbùn owó kánkan -Sanwo Olu Kí l'ànfàní àdéhùn okoòwò kan l'Afíríkà, AfCFTA tí Buhari tọ́wọ́ bọ̀?
’’O tun wa ro ajo eleto idibo iyen INEC ati
Iwe yi fun wọn lẹtọ si ilẹ eeka mẹrin to wa ladugbo Osu Mantse Layout.
Ó ni àwọn kan to fẹ́ jẹ ọba ni wọ́n ń fẹ yọ Olúwo kúrò nípò, nítori ìwà ọ̀tẹ ni Èyí ni ọ̀rọ̀ tí Báálẹ̀ ìlú papa Ademola Adegoke tó sójú gbogbo àwọn Baálẹ jákèjádò gbogbo ilú Iwo, tó sàlàyé pé, Ilúfẹmilóye ni Oluwo jẹ gbogbo àwọn ọmọ ilú ló sì wà ni ẹ̀yin rẹ.
Ọọ̀ni obìnrin, Lúwòó Gbàgídà rèé, akọni tó ń gun ọkùnrin ní ẹṣin rìn Amọ ọrọ ti yi pada lẹyin ti wọn ri fọnran fidio kan to ṣafihan arabinrin naa gẹgẹ bi oludije ipo aarẹ ni Jamaica.
Onímọ̀ nípà ètò ẹ̀kọ́ Isa Sani tó n gbé ìlú Kano sàlàyé fún BBC pé ǹkan tó ṣẹlẹ̀ ni ìpińlẹ̀ Katsina, nibi ti ọmọ tó lé ni irinwo ti dàwátì, lẹ́yìn ti awọn agbébọ̀n yabo ilé ìwé GSSS ni ìlú Kankara jẹ ọ̀kan pàtàkì lára ìdí ti ọ̀pọ̀ àwọn ilé ẹ̀kọ́ fi ti ilẹ̀kùn wọ́n.
”O fikun oro re pe, awon obayeje, aselu kumokumo ti o le wa nidi rogbodiyan lasiko idibo ni awon ti ko fe ilosiwaju isejoba aare Muhammadu Buhari latari ipinnu re lati fi owo iwa ibajẹ bole lorile-ede Naijiria.
Bí wọ́n ti ń lọ, àwọn kan ninu àwọn tí wọ́n fi ṣọ́ ibojì lọ sí inú ìlú láti sọ ohun gbogbo tí ó ṣẹlẹ̀ fún àwọn olórí alufaa.
Awosanya wa lara awọn ti ijọba apapọ bẹ lọwẹ lati ṣatungbeyẹwo ikọ SARS ko to parada di FSARS.
Gen Taiwo tí fi ẹnu rẹ̀ sọ pé olórí ilé ìtajà SPAR pe òun láti wá ran òun lọ́wọ́ ni agbègbè náà lẹ́yìn tí ìṣẹ̀lẹ̀ Lekki Shooting.
Pelumi Olajengbesi ti o jẹ agbẹjọro to n ṣoju Dakolo ni owo naa jẹ owo iṣẹ oun gẹgẹ bi agbẹjọro Busọla ni.
Ọjọ́ mẹ́tamẹ́ta ni ó máa ń kiri wá, torí èyí , gbogbo èèyàn ìletò náà ti mọ̀ ọ́n.
Oríṣun àwòrán, @afcbournemouth Ẹgbẹ agbabọọlu Tottenham wa lara awọn ikọ to n lepa ipo mẹrin akọkọ lori akasọ igbelewọn liigi Premiership ti saa 2018/2019 eyi ti o jẹ pe ikọ meji, Manchester city ati Liverpool nikan lo ṣi daju fun.
Mama Rainbow pe 77 lónìí, àwọn òṣèré tíátà kọrin re kìí Buhari ti fòfin de àwọn mínísítà láti rìnrìn àjò lọ sí ilẹ̀ òkèrè Ọkọ̀ agbépo tó gba iná ṣe àkóbá ní ọjà Onitsha Èrò yapa ní mọ́ṣáláṣí Jimọ̀h láti wá fójú lóúnjẹ lórí ìgbéyàwó òfegè Buhari.
Mi o lero pe mo le dariji lailai, nitori pe nkan to ṣe naa dun mi gan an ni.
”Ó tún dá a lóhùn pé, “Bẹ́ẹ̀ ni Oluwa, o mọ̀ pé mo fẹ́ràn rẹ.
Èyí ni à ń gbadura fún, pé kí ẹ tún ìgbé-ayé yín ṣe.
Nigeria Elections 2019: IPMAN kéde àdínkù ìyè owó epo bẹntiróòlù
Oríṣun àwòrán, Getty Images Ko si ipejọpọ lawujọ mọ Asiko owambẹ ti lọ!
Awọn ọlọpaa ri ọkunrin naa mu lẹyin ti awọn ara adugbo ta wọn lolobo pe ọkunrin kan ti fẹ pa ọmọ rẹ kekere.
Àwọn ọmọ Israẹli tún ṣe ohun tí ó burú lójú OLUWA, OLUWA sì fún Egiloni, ọba ilẹ̀ Moabu, lágbára lórí wọn, nítorí pé wọ́n ṣe ohun tí ó burú lójú OLUWA.
Kódà àwọn míràn tí ṣèdájọ́ ojú ẹsẹ̀ tí pé o yẹ kí ààrẹ gbaṣẹ́ lọ́wọ́ Pantami ni fún irú igbésẹ̀ bẹ́ẹ̀.
Koda ohun ti a n wi yii kọ ni a o ba maa wi to ba jẹ pe ayo kẹrin ti Sheffield fẹ gba sawọn wọle Chelsea ni.
Ri wi pe o tẹ iwe ẹri jade ti yoo ṣafihan pe o ti pari ipele yi ko si ṣakiyesi nọmba idanimọ ti yoo wulo fun ni ipele miran ninu eto igbaniwọle.
Èmi àti Sanyeri ti tọrọ oúnjẹ jẹ rí nílé oninawo torí ebi, ká tó di gbajumọ oṣere Ile ẹjọ to ga julọ lorilẹede Naijiria woye pe Onidajọ Mohammed Liman to dajọ naa kii ṣe adajọ mọ nigba to gbe idajọ kalẹ lori ẹjọ naa.
Sugbọn ọpọlọpọ lo fẹran gaari ni mumu.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Akinjide Isola: Ara fu mí ní ọdún márùń sẹ́yìn pé bàbá fẹ́ pa’pòdà Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Akinjide Isola: Ara fu mí ní ọdún márùń sẹ́yìn pé bàbá fẹ́ pa’pòdà 14 Ìgbé 2018 Àkọ́bí olóògbé, Akinjide Isola sọ fún BBC Yorùbá wípé ara fu òun ní ọdún márùń sẹ́yìn pé bàbá Akínwùnmí Iṣọ̀lá fẹ́ pa’pòdà.
awon to wa niluu Osgbo se gbọ iroyinpe gomina Gboyega Oyetola lo tun jawe
" Fun awọn ti wọn ko le ṣa asala fun ẹmi wọn, Esther ni imọran mii.
Láti ọdún 2025 lọ, to bá ṣe ìgbọ̀nsẹ̀ sigboro, o rugi oyin - Buhari Oye ọlajingiri ni orilẹ-ede Naijiria jẹ lori igbelewọn naa nitori ipo kẹta yii kan naa ni wọn wa ni ọdun 2018.
Ní Ijipti, à ń jẹ ẹja ati apálà, ẹ̀gúsí, ewébẹ̀, alubọsa ati galiki.
Kollington kede eyi lasiko to n dahun ibeere lori eto BBC Yoruba, tun salaye pe obinrin to bi ọmọ fun ni, ti kuro ni ale ẹni, ọmọ mẹta si ni Salawa Abẹni bi fun oun, nitori naa, iyawo oun nii se.
ti iko Manchester United yoo tun ni lero lati jawe olubori ifesewonse akoko
Natani bá dá a lóhùn pé, “Ṣe gbogbo nǹkan tí ó wà lọ́kàn rẹ, nítorí pé Ọlọrun wà pẹlu rẹ.
ó lọ títí dé Beti Hogila, ó lọ dé ìhà àríwá Betaraba, ó tún lọ títí dé ibi òkúta Bohani ọmọ Reubẹni.
Ẹni to n ṣe nkan oṣù lè fi ẹjẹ silẹ.
Oríṣun àwòrán, @tokstarr Iya mi ko ni tun ọrọ rẹ sọ lẹẹmeji, o dara koo yaa la eti rẹ daadaa koo ma baa jẹ ẹgba."
Wọn ti lo ọdun meje tabi jubẹẹ lọ lẹnu iṣẹ ọlọpaa 4.
Nígbà tí wọ́n dé, wọ́n da ẹja kún inú ọkọ̀ mejeeji, tóbẹ́ẹ̀ tí wọ́n fi fẹ́ rì.
Kí àwọn alufaa meje mú fèrè ogun kọ̀ọ̀kan tí wọ́n fi ìwo àgbò ṣe lọ́wọ́ níwájú Àpótí Majẹmu.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù NGA vs RSA: 'Bode Thomas' àti àwọn àṣà mííràn tó jẹyọ nínú ìdíje AFCON 11 Agẹmo 2019 Oríṣun àwòrán, GIUSEPPE CACACE Igbakiigba ti ọrọ ba ti pa Naijiria ati South Afrika pọ,bi igba pe wọn jọ fẹ doju ija kọ ara wọn ni o maa n jẹ.
Ní àgbegbe Jankande ni Lekki ní ọkunrin kan ti fi móto gbá móto tí Bobrisky rà ní ẹgbẹ̀lẹgbẹ̀ mílíọ̀nu naira lásìkò tó ṣe ayẹyẹ ọjọ ibí rẹ̀ nínú oṣu kẹjọ.
Ẹfunsetan Aniwura, obìnrin tó ju ọkùnrin lọ Ọ̀rọ̀ǹpọ̀tọ̀niyùn, Aláàfin obìnrin àkọ́kọ́ rèé, tó ní nǹkan ọkùnrin Gẹgẹ bi ọpọlọpọ ṣe n sọ pe o ti ya Seyi ju lati maa gbe awọn igbesẹ kọọkan, Oloye Ladoja sọ pe Ajimobi to lọ lo pẹ ju lati gbe igbesẹ kii ṣe pe o ya Seyi.
Kòkòrò búburú tí í fa àjàkálẹ̀ ààrùn.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Sunday Igboho: Ẹ fi Ògún búra fún wa láti jà fún ilẹ̀ Yorùbá láì gbé Amotekun sábẹ́ ìjọba Bẹẹ ba gbagbe, ọjọ Isẹgun ni ikọ ologun ditẹ gba ijọba lorilẹede Mali, to si mu aarẹ ati olootu ijọba si ahamọ.
First Lady: Kí ló mú Aisha Buhari gbà oyè tó kọ tẹlẹ?
Ayaba Suliat Motunrayo Adeyemi: Oríṣun àwòrán, Ayaba Motunrayo Adeyemi Ọkan lara awọn olori aagba to n sikẹ Ọba Adeyemi ni Ayaba Suliat Motunrayo Abeke Adeyemi.
2019 Elections: Oshiomole ní Buhari yóò wọlé láìsí àtìlẹ́yìn Ọbasanjọ
Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Coronavirus Update: Olóòtú Ilẹ̀ Gẹ̀ẹ́sì, Boris Johnson ti kó àrùn Coronavirus!
Bi arun naa ṣe n da ẹmi awọn eeyan legbodo na lo n fa idaduro si oriṣiriṣi awọn ayẹye, eto, ipade, ere idaraya atawọn nkan mii to yẹ ko waye.
Èmi OLUWA ni mo sọ bẹ́ẹ̀; bẹ́ẹ̀ ni n óo sì ṣe.
A kò lè gbàgbé rẹ láíláí Mandela.
Ikọlu naa waye lafẹmọjumọ Ọjọbọ ọjọ keji oṣu kejila ni nkan bii ago kan oru ọganjọ lopopona Murtala Mohammed Highway lẹbaa ileeṣẹ Pepsi.
Alukoro fun ile-ise awon omo oogun ofurufu, ogagun Ibikunle Daramola ti ni sise atunse lori awon oko ofurufu lorile ede yii se pataki, paapaa julo lori aseyori ti awon akekoo  ati awon onimo ero iko omo oogun oko ofurufu yii se, latari atunse oni wakati irinwó ti won se lori oko ija-ofurufu F-7, ti o waye ni Makurdi.
Orilẹ-ede United Kingdom ati Soviet Union ni alatilẹyin gboogi fun ijọba Naijiria, nigba ti France, Israel ati awọn orilẹ-ede kan faramọ Biafra.
Funke Akindele Gbajugbaja osere ni arabinrin yii.
Oṣu kẹta ọdun 2018 ni awsn agbebọn Boko Haram ji gbe pẹlu awọn oṣiṣẹ ajọ alagbelebu pupa, Red Cross ni ileewosan naa to wani ilu Rann ni agbegbe Maiduguri nipinlẹ Borno.
Koda, Donald Trump paapaa sọ pe bẹ ẹ ni nkan ri, lasiko to ku diẹ ki ipolongo ibo gbogboogbo wa sopin.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Wọ́n rò pé mo ya wèrè ni Saudi lẹ́yìn ikú ọkọ mi Bo tilẹ jẹ pe Ọba Saudi Arabia n fun awọn obinrin ni awọn ẹtọ kan nigba to de, bi i ki obinrin ni anfani lati maa wa ọkọ.
Àkọlé àwòrán, Sunday Shodipe sọ pe ibi ti oun ti n ṣe iṣẹ alabaru ni ọja Bodija ni ọkunrin kan ti mu oun.
Ẹ máa ṣe èyí ní ìrántí mi.
lowe ti Tinubu fi bọnu lori bi Atiku Abubakar ti lọ ṣepade nilu Dubai.
"O ni ""Gbogbo eeyan lo mọ pe aafin yii jẹ ibi aṣa ati iṣe, ti ẹ ba ri ti awọn onilu ba n lu ilu wọn ninu aafin, oriṣiriṣi nnkan ni ilu naa n tumọ si."
Fun ọpọ eeyan apẹrẹ arun naa diẹ ni o ma n jẹyọ lara wọn sugbọn awọn ẹlọmiran a ma ba lọ.
Ireti awọn eeyan ni pe aarẹ yoo ṣi aṣọ loju eegun fun araalu lati ms igbesẹ to kan lori aṣẹ konile-o-gbele jakejado orilẹede Naijiria.
Ẹwẹ, nigba ti a kan si ileeṣẹ Ọlọpaa ati Onikoyi ti Ikoyi Ile, Oba Abdul-Yekeen Atilola Oladipupo ko tii f fesi si ọrọ yii to si sọ fun akọroyin BBC pe oun yoo kan si wọn bo ba ya.
Wọnyi ni awọn orilẹ-ede ti ko faye gba a ki ọdọkunrin ati ọdọbinrin ti ko ti se igbeyawo, maa di mọ ara wọn.
Èwo ni ó rọrùn jù: Láti wí fún arọ náà pé, ‘A dárí ẹ̀ṣẹ̀ rẹ jì ọ́,’ tabi láti wí pé, ‘Dìde, gbé ibùsùn rẹ, kí o máa rìn?
Ni bayii, akonimoogba agba iko ohun, Thomas Dennerby ti pe agbaboolu merindinlogbon, ti o fimo awon ti o fi ile okere se ibugbe.
Oríṣun àwòrán, lasema Àkọlé àwòrán, Iṣẹ n tẹsiwaju lọjọ Iṣẹgun Ile alaja mẹta lo deede dà wó ni ilu Jos ni ipinlẹ Plateau ni ariwa Naijiria.
Nítorí Ìwé Mímọ́ sọ níbìkan nípa ọjọ́ keje pé, “Ọlọrun sinmi ninu gbogbo iṣẹ́ rẹ̀ ní ọjọ́ keje.
Gbajugbaja olorin Afeez Fashola ti gbogbo eniyan mọ si Naira Marley ti papa fara han niwaju ile ẹjọ giga ti ipinlẹ Eko lori ẹsun ṣiṣe magomago lori ayelujara.
Ọkan ninu wọn, Sani ṣalaye pe nigba ti ofin igbele wa nilẹ, ọpọ ile ni wọn ko jẹ ki oun wọ mọ lati ko idọti wọn nitori ibẹru ajakalẹ arun coronavirus.
Àwọn Alakoso gareji ló ko ìbọn àti ada tọ ọlọkada wá ní Soka, Igboho kò lọ́wọ́ nibẹ - Alága ẹgbẹ́ ọlọkada l'OyoẸgbẹ́ àwọn ọlọkada nipinlẹ Ọ̀yọ́ tí ṣàlàyé ni ẹ̀kúnrẹ́rẹ́ nípa rògbòdìyàn tó wáyé lọ́jọ́bọ ládùúgbò Soka nílùú Ibadan èyí tó kàn àwọn ọlọkada.
Ní ọdún 1991 ní orílẹ̀èdè Jamaní ni wọ́n ti ṣẹ̀dá ẹ̀.
Bakare to jẹ Ọga agba ileewe girama kan ṣalaye pe igbesẹ ti Gomina Fayẹmi fẹ gbe naa yoo nira diẹ.
Ká tó kọ̀wé ìkọ́ni, Ká tó pète pèròo kíkọ́ni lákọ̀ọ́yé.
Lọdun 2017 ni Ahmad di aarẹ CAF.
’ Nígbà tí mo wí bẹ́ẹ̀ mo tilẹ̀ rò pé yóò wí pé òun fẹ́ bá mi jà ni, àfi bí mo ṣe ri i ti o ń tún ṣòkòtò rẹ̀ ṣe dáadáa, ṣòkòtò ọdẹ tí ó wọ̀ tí ó padà tí ó wí pé òun ń lọ bá àwọn iwin náà jà nítorí eyí tí mo wí.
Adé á pẹ́ lóri o, bàtà á pẹ́ lẹ́sẹ̀.
Nígbà tí ó di ọjọ́ kejì tí ọkùnrin yìí lọ sí ibi ọ̀pẹ  wọn-ọnnì ó bá àwọn akèǹgbè tí ó ti so mọ́ ọ̀pẹ ní ilẹ̀ ní fífọ́.
A ti pa diẹ lara awọn imọran ti ẹyin naa fi sọwọ pẹlu ti wọn.
O lé má a wa ọkọ̀ ni ìwàkuwa, a gbọdọ mójútó bo ti n sáré tó bá n wakọ̀ ju bi ó ṣe máa n sáré tẹ́lẹ̀ lọ, tàbi kí o maa mú ọtí àmupara tàbi ki o maa ló òògun kọja ǹkan ti wọn fún láti lòo Ó le má a sọ̀rọ̀ àsọjù.
Ṣugbọn ni orilẹede Naijiria, ọpọ nnkan lo n fa atẹgun ti ko dara.
Àkọlé àwòrán, Ohun ayo ni iroyin iṣẹju kan BBC yoo jẹ fun awọn ọdọ Naijiria Toyosi sọ pe: ''Ajọsepọ yi pẹlu MTN safIhan ifarajin BBC lati mu iroyin de ọdọ awọn eeyan nibikibi ti wọn ba wa ni Naijiria.
Ìrora mi pọ̀ ọkàn mi sì rẹ̀wẹ̀sì.
Àwọn òkúta ńláńlá meji kan wà ní ọ̀nà kan, tí ó wà ní àfonífojì Mikimaṣi.
Mi ò ní ìyàwó nílé, àmọ́ mo ní ọmọ tó pọ̀-Saheed Oṣupa Ọ̀pọ̀ ló ṣì n ṣelédè lẹ́yìn Barrywonder!
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ohun tó sọ Okorocha di olóròróó ọ̀sán gangan 4 Òkùdu 2018 Oríṣun àwòrán, IGBERE TV Àkọlé àwòrán, Àwọn mìíràn ní bóyá Rochas Okorocha ti sọ ara rẹ̀ di wòlíì ni Gómínà ìpínlẹ̀ Imo, Rochas Okorocha, di ẹni tí ń ṣe ìfàmi-òróró-yàn fún àwọn ará ijọ nínú ilé ijọ́sìn?
Oluwo ti ìlú Iwó kìí ṣe ẹgbẹ́ Àtaọjà Osogbo - Alaafin ìlú Ọ̀yọ́ Ẹni mọ́kànléláàdọ́fà 111 ló lùgbàdì àrùn covid-19 ní Nàìjíríà lọ́jọ́ Àìkú Ìbẹ̀rù-bojo gbalẹ̀ ní Oyigbo lẹ́yìn tí ọlọ́páà mẹ́ta àti sọ́jà kú nínú rògbòdìyàn EndSARS Mọ̀ sí i nípa àwọn ọmọ Nàìjíríà mẹ́sàn-án tó ń díje nínú ìdìbò ilẹ America lọ́jọ́ Ìṣẹ́gun Lọdun 1994, Ọgbẹni Biden, jẹ ọkan pataki lara awọn to polongo ofin iwa ọdaran.
Ada ni ó bí Jabali, tíí ṣe baba ńlá gbogbo àwọn tí wọn ń gbé inú àgọ́, tí wọ́n sì ń sin ẹran ọ̀sìn.
Àwọn orílè-èdè àti ẹyà orísirísi ló má n kópa nínú Arafat yii.
Imaam agba niluu Ibadan, Sheikh Abdul Ganiyy, A-gbọ-tọmọ-kekere
Yóo mu oró ejò,ahọ́n paramọ́lẹ̀ yóo pa á.
Laarin oṣu kan sẹyin ko din ni omidan mẹrin ti awọn oniṣẹ ibi kan ti fipabalopọ ti wọn si tun gbẹmi wọn eleyii to mu ki ohun awọn eeyan tun goke sii lori ipe fun wiwojuutu si wahala ifipabanilopọ lawujọ wa.
”Nítorí náà, ọ̀rọ̀ OLUWA tí mò ń kéde sọ mí di ẹni yẹ̀yẹ́ tọ̀sán-tòru.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ooni ile Ife: Iná sọ láàfín Ọọ̀ni Ilé Ifẹ̀, Ọọ̀ni ilé ifẹ̀ ní kò sí ẹ̀mí tó báa lọ 13 Ògún 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 19 Ògún 2020 Oríṣun àwòrán, Ile oodua Ina sọ ni ile Oodua tii ṣe afin Ọọni ile Ifẹ, Ọba Adeyẹye Ogunwusi l'Ọjọbọ.
Bí Jesu ti ń sọ ọ̀rọ̀ yìí, obinrin kan láàrin àwọn eniyan fọhùn sókè pé, “Ẹni tí ó bí ọ, tí ó wò ọ́ dàgbà náà ṣe oríire lọpọlọpọ.
Má jẹ́ kí oúnjẹ aládìídùn rẹ̀ wọ̀ ọ́ lójú,nítorí ó lè jẹ́ oúnjẹ ẹ̀tàn.
Bakan naa, awọn obi yii maa n sufe kọrin fun awọn ọmọ wọn ni, ti wọn si maa n hu lati pe awọn ọmọ to ti dagba.
Sovereign Conference: Àwọn òǹwòye ní ìpàdé àpérò dára ṣùgbọ́n kò lè tàn ìṣòro Nàìjíríà
Gbogbo ileeṣẹ iroyin nilẹ America, to fi de Europe lo fẹ ẹ ni aṣoju nibi eto igbeyawo naa, lati kọ nipa ara meeriri igbeyawo ọhun.
Àsọtẹ́lẹ̀ tó ṣẹ nípa ìfẹsẹ̀wónsẹ̀ Naijiria Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, SARS ti bẹ̀rẹ̀ ìgbésẹ̀ láti yọ àwọn ọ̀bàyéjẹ́ kúro Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
A ti se ohun ti gbogbo aye fi n ri orile ede yii gẹgẹ bi awokọse nipa eto idibo, nitori naa, a gbọdọ ri i pe ina aseyọri yii ko jo ajo rẹyin rara.
mo ms pé ti mo ba ni èròjà yìí tótó milionu páálí kan lọ́wọ́, mo mọ̀ pé màá tàá tán lọ́sẹ̀ kan ṣoṣo.
A ti pe fun iwadii nipa oun to ṣẹlẹ ti ko fi jẹ ki wọn dena ipaniyan akọroyin to lokiki ju ni Malta.
pese ero ayelujara lati tubọ mojuto ojuse wọn, aare tun so pe , “A
N óo fi òpin sí ẹ̀rín ati ìró ayọ̀ ní Jerusalẹmu, a kò sì ní gbọ́ ohùn ọkọ iyawo ati ohùn iyawo àṣẹ̀ṣẹ̀gbé níbẹ̀ mọ́; nítorí pé n óo sọ ilẹ̀ náà di ahoro.
Oriṣiriṣi iwa 'to ba tako ẹsin Islam' ni wọn ma n mu awọn eeyan si, ti wọn si ma n fi ofin Sharia ṣe idajọ wọn.
O ju isẹ iranṣẹ lọ, àmọ́ dandan ni fun mi lati ṣe iṣẹ ẹni to ran mi.
Yóo máa jó tọ̀sán-tòru, kò ní kú, yóo máa rú èéfín sókè títí lae.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Oko oloyun: Àwọn agbébọn pa gbajúgbajà apòògùn ìbílẹ̀, Àláájì Fàtáì ọkọ olóyún 24 Sẹ́rẹ́ 2020 Oríṣun àwòrán, others Gbajugbaja, oniṣegun ibilẹ, Alhaji Fatai Yusuf ti ọpọ mọ si ọkọ oloyun lawọn eeyan kan yinbọn pa ni irọlẹ Ọjọbọ ni ipinlẹ Ọyọ.
Ni ariwo ńlá bá bẹ́ sílẹ̀.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Loom Money Nigeria: Ṣáájú Loom Money Nigeria, àwọn ètò sogún-dogójì púpọ̀ ti ta pàù lórílẹ̀èdè 17 Èbibi 2019 Ajọ to n risi eto idokowo l'orilẹede Naijiria ti kilọ fun awọn ọmọ Naijiria lati maa kopa ninu eto sogun-dogoji tuntun to gbode, 'Loom Money Nigeria'.
Lẹyin naa lo ṣeleri pe oun yoo tẹsiwaju lati maa gbe aṣa ati iṣe Yoruba ga, ko ma ba parun.
Amọṣa, ileeṣẹ mọnamọna ẹkun Ibadan, IBEDC ti darukọ awọn ti ina gbe naa ti wọn si pe orukọ wọn ni Ọgbẹni Ọladeji Ọlatunji pẹlu Arabinrin Kẹmi Degoke.
Àwọn àmi méje tó ń tọ́ka sí pé oò kí ń mu omi bí ó ti tó 'Mo máa tó dìde lórí àìsàn', Muyiwa Ademola sọ̀rọ̀ látorí àkéte àìsàn rẹ̀ Ohun tí a mọ̀ nìyí nípa #IGotSurvivalFund owó ìrànwọ̀ Àìsàn Muyiwa kò lè la ẹ̀mí lọ - Agbẹnusọ Òṣèré, Muyiwa Ademola Ìrẹsì ọ̀fadà, ikọ́kọre, àti àwọn oúnjẹ míì tóo lè fí gbádùn ẹ̀mí rẹ lásìkò Kérésì Nínú kó o fi omi fọ ìdi tàbí lo tííṣù fi fá a, Èwo ló rọrùn?
Osinbajo: Ikẹnnẹ yẹ kó jẹ́ Mẹ́kà òṣèlú ni
Wọ́n bá rán àwọn ọmọ-ẹ̀yìn wọn pẹlu àwọn ọmọ-ẹ̀yìn Hẹrọdu láti bi í pé, “Olùkọ́ni, a mọ̀ pé olóòótọ́ ni ọ́, ati pé pẹlu òtítọ́ ni o fi ń kọ́ eniyan ní ọ̀nà Ọlọrun; o kì í ṣe ojuṣaaju fún ẹnikẹ́ni nítorí o kì í wojú eniyan kí o tó sọ̀rọ̀.
#BBCNigeria2019 'Obìnrin tórí ẹ̀ pé lè tọ́ ọmọ láì nílò ọkọ rẹ̀' Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ẹ wo ọ̀nà àbáyọ tí àwọn olùdíje gómìnà pèsè sí ìṣòro Eko Ipade to yẹ ki igbimọ naa ṣe laipe yi ko waye nitori pe adajọ agba Walter Onnoghen sun un siwaju.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, ‘Mo fẹ́ mọ ẹni tó jáwé olúborí nínú ìdìbò June 1993’ - Abdulmumini Abiola 'Ààrẹ Buhari, a dúpẹ́ ìdùnnú ńlá ni fún wa' Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 3 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 5 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Islamic State bẹ́ àwọn Kristiẹni mẹ́wàá lórí ní Bornu Awakọ̀ Maruwa tó bá gbé okùnrin àti obìnrin papọ ní Kano yóò jẹ búlálà mẹ́wàá- Hisbah Funke Akindele, Toyin Abraham, Bimbo Oshin ṣe Kérésìmesì lọ́nà àrà Igboke ni òun lọ si sọọbu Arinze lojọ ti iṣẹ̀lẹ̀ yìí ṣẹ̀ láti bẹ̀ ẹ́ pe ki o fun òun lówó lati ra bàtà ọdún fún ọmọ lẹ́yin ti òun ti lọ ra aṣọ pé ṣùgbọ́n kàkà bẹ́ẹ̀ ṣe ni o ti òun ti o si ku díẹ̀ ki òun ko si ẹnu ọkada o ni ìbinu yìí ni òun fi mu ọ̀bẹ láti dààbo bo ara òun ṣùgbọn òun kò mọ ìgbà ti òun gun pa.
Àwọn ọmọ Nàìjíríà 320 yóò padà wálé láti South Africa lọ́jọ́rú - Adama Ẹ ṣèwádìí ikú Ọ̀jọ̀gbọ́n Gideon Okedayọ - ASUU Nigba ti ikọ ile isẹ BBC Yoruba n ba abẹnugan gomina naa Kunle Abiodun sọrọ ni alaye naa ti jẹyọ.
Bakan naa ni Doris n ṣe ere Yoruba ati Ede Gẹẹsi.
Gẹgẹ bi Shina Rambo ti salaye, baba oun maa n lo aṣọ ati irinsẹ ologun lati ja awọn eeyan lole, to si maa n ko owo pupọ wa sile.
Eyi si mu ki kaluku wọn maa ṣe boṣe wu wọn lẹnu iṣẹ.
Ó tún tẹ fìlà rẹ̀ síwájú bí ó ti máa ń ṣe, fìlà rẹ̀ ri kọ̀ǹgọ̀ bí ẹnu ẹyẹ.
Jẹ́ kí ó máa gbèjà àwọn eniyan tí ìyà ń jẹ;kí ó máa gba àwọn ọmọ talaka sílẹ̀;kí ó sì rún àwọn aninilára wómúwómú.
Ọ̀kọ̀ọ̀kan wọn ní iwájú mẹrin mẹrin ati ìyẹ́ mẹrin mẹrin, wọ́n sì ní ọwọ́ bí ọwọ́ eniyan lábẹ́ ìyẹ́ wọn.
Seun Egbegbe lo ọdún méjì àti oṣù méje lẹ́wọ̀n láì tìí san béèlì rẹ̀ À ń gbé ìjọba ìpínlẹ̀ Ọyọ lọ si ilé ẹjọ- Ẹgbẹ́ Fulani darandaran Ta ni Funmilayọ Ransome-Kuti?
Iroyin ni awọn maalu naa ku nigba ti wọn ṣeṣi rin lọ ori oke kan ti Oba ilu naa ti maa n lọ ṣe etutu ọlọdọọdun.
Opọlọpọ ẹmi ati dukia lo ti sọnu lati igba ti awọn ẹlẹsin Shiite ni ariwa Naijiria ti bẹrẹ ifẹhonuhan lori olori wọn El Zakzakky to wa ni atimọleỌlọ́pàá mú 115 ẹlẹ́sìn Shiite.
    Ìgbẹ̀yìn ọ̀ràn ọ̀ǹgọ̀ṣútàkìtì burú púpọ̀, nítorí ìgbà tí àwọn iwin ti yọ́ ọ lójú ni ọkàn rẹ̀ ti kúrò nínú ayé, nígbà tí ó ṣe, ko jẹun mọ́ bẹ́ẹ̀ ni kò mu omi, àsẹ̀yìnwá àsẹ̀yìnbọ̀, ó ṣubú lulẹ̀, a gbé e, a fẹ́ òyì si i, ṣùgbọ́n kò gbọ́, ìgbà tí ó ṣe, ó pa ojú dé, a fún ata sii lójú, kò sọ̀rọ̀, a pa ọfọ̀ sii, kò dá ni lóhùn mọ́, ó kú, okàn rẹ̀ ti lọ, ara rẹ̀ ti tutù, ikú dé.
Ewe, awon afehonu han ohun so lasiko ifehonu han naa pe, ile Zaffico je okan lara ile-ise to fun awon ara ilu nise julo lorile-ede naa.
Baba rẹ, tí ó rí ohun tí ó wà ní ìkọ̀kọ̀, yóo san ẹ̀san fún ọ.
Baba olódodo ọmọ yóo láyọ̀ pupọ,inú ẹni tí ó bí ọlọ́gbọ́n ọmọ yóo dùn.
Wọ́n sì gbọdọ̀ yẹra fún ohun gbogbo tí wọn bá ṣe ìlérí láti yẹra fún.
O tun sọrọ lori iṣorọ ti oun koju lasiko iloyun fun oṣù mẹsan.
Nígbà tí wọ́n jí ní òwúrọ̀ ọjọ́ keji, tí oòrùn ń ràn sórí omi náà, àwọn ará Moabu rí i pé omi tí ó wà níwájú àwọn pọ́n bí ẹ̀jẹ̀.
Kí gbogbo eniyan máa wí pé, “Amin!
Bakan naa lo jiroro pẹlu awọn ọlọpaa lori igbesẹ ti ijọba maa gbe lori awọn ti ọwọ tẹ lọsẹ yii pe wọn n ba nkan awọn ara South Africa jẹ nileeṣẹ wọn.
Ṣaaju igbesẹ yii naa ni ẹgbẹ akọroyin ni ipinlẹ Akwa Ibom naa ti gbe igbesẹ yii.
 wọ ́ n bí adams ní 1735 .
O sọ pe awọn ṣe bẹ nitori itankalẹ aarun coronavirus.
Lẹyin ọpọlọpọ ariwo ni aarẹ Buhari to ni ki wọn le e nipo ki wọn le ṣe iwadii rẹ bi o ti yẹ.
O ni ope ni gbogbo awon ti won
"Mo n sunkun nitori pe mo n ṣafẹri ọkọ mi.
fun idagbasoke ọjọ iwaju rere  orile ede
A ní ìrírí ìbànújẹ́ nígbà gbogbo, sibẹ à ń yọ̀.
Tí ẹ o bá gbàgbé , oṣù mẹ́fà ni àfárá náà yóò fi wà bẹ́ẹ̀.
Ó kó àwọn ọkunrin tí wọ́n wà lọ́dọ̀ rẹ̀ lọ́wọ́ pẹlu, ati gbogbo ìdílé wọn, wọ́n sì ń gbé àwọn ìlú tí wọ́n wà ní agbègbè Heburoni.
Ohun tí a rí nílé Ajimobi rèé lẹ́yìn ìròyìn òfégè pé ó jáde láyé Yẹ̀kínì kan kò lè yẹ ipinnu wa láti ṣí iléèwé pàda lóṣù yí - ìjọba ìpínlẹ̀ Oyo Kí ló mú ọlọ́pàá wú òkú géńdé nínú sàréè l'Ondo Ìjọba Amẹrika fi ojú àwọn ọmọ Yahoo mẹ́fà léde, wọ́n gbẹ́sẹ̀ lé dúkìá wọn 3.
Èmi ni mo dá alágbẹ̀dẹ,tí ó fi ẹwìrì fẹ́ná,tí ó sì rọ àwọn ohun ìjà, fún ìlò rẹ̀,èmi náà ni mo dá apanirun,pé kí ó máa panirun.
Gomina Ajimobi wa gba gbogbo won niyanju pe ojuse won ni
Oríṣun àwòrán, djswitch_ Ni kete ti iroyin gbode pe awọn ọmọ ileeṣẹ ologun ti kalẹ si Lekki Toll Gate ni ilu Eko, ti iro ibọn si n dun lọtun losi ni DJ Switch bẹrẹ si n ṣe fidio lati lati agbegbe naa loju opo Instagram rẹ lori bo ṣe n lọ.
ida ogorin olugbe kuba ngbe ni igboro , ida ogbon ngbe ni abule .
Oríṣun àwòrán, omoyele Ọjọ kẹẹdọgbọn, Oṣu keji, 2018 ni o kede erongba rẹ lati du ipo Aarẹ orileede Naijiria ṣugbọn saaju igba naa ni o ti n dasi oselu Naijiria.
Agbófinró, tó bá wa ọkada àbí kẹkẹ maruwa l'Eko, o rugi oyin - Sanwo-Olu Lagos Okada ban: Ìjọba Eko ní òun yóò pèsè ọkọ ti yoo rọpo ọkada ati kẹkẹ láìpẹ́ Oríṣun àwòrán, Others Ijọba ipinlẹ Eko ti sọ pe agbofinro kankan ti ọwọ ba tẹ pe o n ṣe ọkada tabi wa kẹkẹ maruwa yoo foju wina ofin.
” Wọ́n bá gbéra, wọ́n lọ sí agbègbè olókè ti Efuraimu.
Bakare ni ọrọ oun ko nii se pẹlu atilẹyin fun oludije kankan, amọ ohun ti Naijiria nilo ni ikọ oloselu ti yoo mu atunto ba ilẹ yii, ti ko ni jẹ alajẹbanu, ti yoo sisẹ pẹlu ẹka alasẹ ati asofin lati mu isọkan ba ilẹ yii.
BBNaija 2019: Ta làwọn ọmọ Yorùbá tó ń kópa nínú ètò BB Naija
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Shiite kọ̀wé pe àwọn pásítọ̀ láti darapọ̀ mọ́ ìwọ́de wọn Saraki ní kí Yorùbá dìbò ààrẹ fún Atiku Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Papalolo ní ìlépa owó ni ìyàtọ̀ tó wà láàárín àwọn òṣèré tíátà àtijọ́ àti ìsisìnyí Agbẹnusọ fun ile iṣẹ ọlọpaa kọ lati sọ bo ya awọn ajinigbe ọun gba owo ki wọn to fi wọn silẹ.
 Barack Obama ti Trump gba ipo lowo re naa koko lo sile Egypt ki o to sabewo si orile-ede mii nile Afirika.
Oríṣun àwòrán, saharareporter Àkọlé àwòrán, ọkọ ti ọjọgbọn Pius ti fi kọkọ ni ijamba ọkọ Nigba ti BBC kan si awọn eniyan to mọọ daadaa bii akọwe fun gomina nile ijọba ipinlẹ Kogi, Petra Akiti-Oyegbule, ẹkun ni wọn bu si lori aago.
Ohun tí yóo jẹ́ àmì majẹmu tí mo ń bá ẹ̀yin ati gbogbo ẹ̀dá alààyè dá, tí yóo sì wà fún atọmọdọmọ yín ní ọjọ́ iwájú nìyí: 
LASEMA - BBC News Yorùbá BBC News, YorùbáFò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Lagos Collapsed Buildings: Ẹ yọ ilé náà kúrò pátápátá - LASEMA 11 Agẹmo 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 12 Agẹmo 2020 Oríṣun àwòrán, LASEMA Eeyan mẹta lo padanu ẹmi ninu iṣẹlẹ ijamba ile alaja mẹta kan to dawo nilu Eko.
Nítorí àwọn tí a bá ti là lójú, tí wọ́n ti tọ́wò ninu ẹ̀bùn tí ó ti ọ̀run wá, àwọn tí wọ́n ti ní ìpín ninu ẹ̀bùn Ẹ̀mí Mímọ́, 
Bí ó bá dàbí ẹni pé ó ń pẹ́, ìwọ ṣá dúró kí o máa retí rẹ̀, dájúdájú, yóo ṣẹ, láìpẹ́.
O ni o rọrun lati gbe nilẹ adulawọ ju ati gbe ni Amẹrika lọ nitori iṣe ni oun maa n ṣe ni gbogbo igba latari awọn owo ori gọbọi atawọn nnkan miran.
Kò níláti di ẹrù wọn lé ìjọ Ọlọrun lórí, kí ìjọ lè mójútó àwọn tí wọ́n jẹ́ opó gidi.
O tun so pe “Leyin ti orile ede India ati orile ede Naijiria ti tọwọbọ iwe akosile
Ọjọgbọn sọ pe ninu awọn ọlọgbọn eeyan ni Alaafin, koda o ni ẹbun nla ni Oba Adeyemi jẹ fun ilẹ Afirika.
Ọlọ́pàá gbé N5m silẹ̀ láti ṣàwárí àwọn adigunjalè Offa
Ṣiiri àjàrà yìí tóbi tóbẹ́ẹ̀ tí ó fi jẹ́ pé àwọn meji ni wọ́n fi ọ̀pá gbé e.
Latin sọ pe o ṣeeṣe ki ẹgbẹ TAMPAN ati ANTP pada ni ajọsẹpọ lọjọ iwaju, ṣugbọn kii ṣe nkan to le waye bayi.
Ile ẹjọ Majisireeti kan niluu Osogbo tii ṣe olu ilu ipinlẹ Osun ti pe Tobiloba Jolaosho atawọn marun mii ti wọn jọ wa latimọle ọlọpaa ki wọn wa jẹ́jọ́.
NUPENG Strike: Ẹgbẹ́ àwọn awakọ̀ epo rọ̀bì NUPENG so ìyanṣẹ́lódì tí wọ́n gùnlé l'Eko rọ̀
Saraki sọ ọrọ ọhun l'Ọjọru nibi aṣekagba ipolongo ibo to waye ni gbagede 'Freedom Park' ilu Oṣogbo fun oludije si ipo gomina lati inu ẹgbẹ oṣelu PDP, Sẹnatọ Ademọla Adeleke.
àwọn tí wọ́n sọ pé àwọn kò ka òbí àwọn sí, ju ìwọ OLUWA lọ;wọ́n kọ àwọn arakunrin wọn sílẹ̀,wọ́n sì ṣá àwọn ọmọ wọn tì.
 Ọmọ ilẹ Italy naa wọ sile itura kan to sunmọ papakọ ofurufu ilu Eko ni kete to gunlẹ si Naijiria, ko to lọ si ipinlẹ Ogun fun iṣẹ aje."
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, CAN: Samson ni ọrọ awọn ajinigbe ti gba àpérò ní Naijiria Bakan naa ni amofin Lawal Oyewọle ni ọwọ ofin yoo tẹ ẹnikẹni to ba n hu iru iwa buruku yii.
Wọ́n ti mú ayọ̀ ati ìdùnnú kúrò ní ilẹ̀ ọlọ́ràá Moabu;mo ti mú kí ọtí waini tán níbi tí wọ́n ti ń ṣe é,kò sí ẹni tí ó ń ṣe ọtí waini pẹlu ariwo ayọ̀ mọ́, ariwo tí wọn ń pa kì í ṣe ti ayọ̀.
O wa kilọ fun awọn gbọyi-sọyi lati sọra gidi.
 Papa isere  Eagles Square ti n kun bayii bi awon eniyan se wo lo sibe, lati se ayeye ogun odun eto ijoba tiwa-n-tiwa lorile ede Naijiria.
' Ọmọ Ibadan, Peace Busari tí wọ́n fẹ́ tà lórí Facebook ti dé sí Naijiria láti Lebanon Ṣugbọn oun ati ọkọ rẹ ti pada pari ija to wa laarin wọn bayii, ni ọrọ ṣe di akara tu sepo lẹnu ọjọ melo kan sẹyin.
“O kò gbọdọ̀ kẹ́gàn Ọlọrun, o kò sì gbọdọ̀ gbé ìjòyè àwọn eniyan rẹ ṣépè.
Àwọn ọmọ ogun Amoni múra ogun, wọ́n pàgọ́ sí Gileadi, àwọn ọmọ ogun Israẹli náà bá kó ara wọn jọ, wọ́n pàgọ́ tiwọn sí Misipa.
 bàbá àti Ìyá jìjì náà ti dé sí ìpàdé , àwọn náà ń wo ọ ̀ nà fẹ ̀ fẹ ̀ .
Ikọlu awọn ologun labẹ alaṣẹ Napoleon eyi to tako ijọba akonilẹru ilẹ Gẹẹsi ni ẹkun naa ko fun ọpọ musulumi laye lati ṣiṣẹ Hajj laarin ọdun 1798 si 1801.
lori alaafia ati eto abo ti Ijoba re ni fun odun mejo lori  awon igbese
Jọ̀wọ́ mú ohunkohun tí ó bá wà ní àrọ́wọ́tó rẹ fún àwọn iranṣẹ rẹ, ati fún èmi Dafidi, ọmọ rẹ.
Mo kábàámọ̀ pé ń kò bẹ Baba Legba wò, nígbà tó pè mí - Foluke Daramola Ilumọọka osere tiata lobinrin, Foluke Daramola Salako ti n gbarata lori iku to mu agba ọjẹ osere tiata miran, Alhaji Yekeen Omobolanle lọ.
Ìgbéraga bẹ̀rẹ̀ si ṣe àṣejù, kò dúró lati má a fi ọrọ̀ rẹ yangà si gbogbo ará ilú pàtàki si àwọn ẹ̀gbọ́n rẹ, ó jọ ara rẹ lójú, ó si nsọ ọ̀rọ̀ lai ronú tàbi gba ikilọ̀ àwọn àgbà ti wọn mọ ìbẹ̀rẹ̀ rẹ.
Alaafin ilu Ọyọ, iku baba yeye, Ọba Lamidi Adeyẹmi kẹta naa ti wa kọ lẹta tirẹ ranṣẹ si aarẹ bayii; ori ọrọ ijinigbe ati gulegule awọn darandaran Fulani ni ilẹ Yoruba naa ni koko inu iwe lẹta rẹ.
 kò pọn dandan kí ọkọ ̀ ní àwọn ìgbánú ijoko .
Gómìnà ìpínlẹ̀ Benue, Samuel Ortom ti parí ìjà láàrin akọ̀ròyìn Channels TV, Pius Angbo àti Ifeyinwa Angbo, ìyàwó rẹ̀
Oríṣun àwòrán, @bedmate Àkọlé àwòrán, Ko seni to n fẹ ku sile itura Ọkan lara awọn oṣiṣẹ ile itura naa John Chuks ni o tete pe akiyesi awọn eniyan si iṣẹlẹ naa ti obinrin naa si di awati.
Iwe aṣẹ ipadabọ sẹnu iṣẹ naa to ni nọmba Ref.
Miliọnu mẹta eniyan si lo ti sanwo silẹ ki aṣọ naa to jade fun tita.
Oba Adedokun Abolarin ti Oke Ila: Ó ya ọ̀pọ̀ tó súnmọ́ mi lẹ́nu bí mo ṣe ń kọ́ àwọn akẹ́kọ̀ọ́ pẹ̀lú ipò Ọba
Tí ó bá jẹ́ pé ọdún pupọ ni ó kù, owó ilẹ̀ náà yóo pọ̀, ṣugbọn bí ó bá jẹ́ pé ọdún díẹ̀ ni, owó rẹ̀ yóo wálẹ̀; nítorí pé, iye ọdún tí ó bá lè fi gbin ohun ọ̀gbìn sórí ilẹ̀ náà ni yóo wò láti ta ilẹ̀ náà.
"Oríṣun àwòrán, Facebook/Oba Michael Odunayo Ajayi ""Awọn eeyan to n sisẹ ibi yii kii se ara ibi, gbogbo awọn isẹlẹ naa si la ti gbe wa si iwaju ijọba, asofin atawọn agbofinro pe ki wọn dojukọ agbegbe yii daada."
Ó bá pàṣẹ kí àwọn eniyan jókòó ní ilẹ̀.
Ni akotan , ko ṣai dupe pupọ lọwọ awọn ti o jẹ olubadamọnran rẹ.
Ile-iṣẹ Isakoso ipe pajawiri ni ipinlẹ Eko (LASEMA) sọ fun BBC pe ijamba ibugbamu ina yii sẹlẹ ni ileesẹ epo Stallionaire Oil ni nkan bii agogo mẹta ọsan.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Premier league: Ìjà orogún London, Arsenal ati Tottenham ranjú mọ ara wọn, ṣùgbọn iná ojú wọn kò ran tábà 1 Owewe 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Diẹ lo ku ki omi tẹyin wọ igbin Arsenal lẹnu loni nibi ifẹsẹwọnsẹ awọn ati orogun wọn ni ilu Londọn, iyẹn Tottenham.
Agbébọn yabo àgọ́ ọ́lọ́pàá, wọ́n pa DPO àti ọlọ́pàá mẹ́ta míràn Ọlọ́pàá gba àna ADC Buhari silẹ̀ lọ́wọ́ ajínigbé Wọ́n lu àbúrò mi ló jẹ́ kí ń fi ìbínú lu òǹtàjà l‘Abuja - Sẹ́nétọ̀ tó lu obìnrin ṣàlàyé Jọ̀ọ́, má wé orúkọ mi mọ́ ìjákulẹ̀ tó bá ọ - Seyi Makinde kìlọ̀ fún Lanlẹ́yin Amọ ṣa, lẹyin ti a ṣe agbeyẹwo ohun ti wọn n sọ, a rii pe awọn idi ti a ka silẹ wọn yii lo n mu ikunsinu wa: Ki lo de ti wọn ṣe pee ni Ruga ti ko jẹ orukọ miran?
Aworan ori ero ayelujara safihan bi awon ile-itaja, awon ile-ise ti o wa ni ilu naa se wa ni titi pa, bakan naa ni ko si irinnaa oko oju-popo, igbese ohun ni lati fehonu-han tako bi ijoba se kede ilu-o-fara ro lojo kerindinlogun osu keji odun ti a wa yii.
alaboyun lee di afiseyin ti eegun n fi asọ lorilede Naijiria.
Ọbasanjọ wa se kare, obinrin bii ọkunrin ni ọ si aya aarẹ, fun bi ko se bu ẹẹkẹ diwọ lasiko yii ti ara ko rọ okun, ti ko si rọ adiẹ lẹka eto aabo wa lorilẹede Naijiria.
Ojú ara wọn yóo tì wọ́n nítorí ibi tí wọ́n ṣe, ati nítorí gbogbo ìwà ìríra wọn.
gbogbo omo ile  igbimo asofin se fimo sokan
” Tamari bá ń gbé ilé Absalomu.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Amotekun : Gómìnà ìpínlẹ̀ Ondo, Akeredolu buwọ́lu àbádòfin nípa Àmọ̀tẹ́kùn 5 Ẹrẹ̀nà 2020 Oríṣun àwòrán, TWITTER Gomina ipinlẹ Ondo, Oluwarotimi Akeredolu ti buwọlu abadofin to ṣe ifilọlẹ ikọ amọtẹkun ni ipinlẹ Ondo.
Oríṣun àwòrán, Presidency Àkọlé àwòrán, Onimọ nipa eto ọrọ-aje ati owo nina ni Ọgbẹni Bismark Rewane Bakan naa ni Ọgbẹni Rewane sọ pe lootọ lo ṣeeṣe ki owo gun iye ti wọn n ta awọn nkan l'ọja, amọ ko ni ni ipa ti ko dara lara owo to n wọ apo oṣiṣẹ.
I am, therefore, using this medium to add my voice to theirs in recognizing his outstanding commitment and devotion to the advancement of humanity.
Ondo Kidnap: Géńdé agbébọn jí adájọ́ gbé lọ ní ìpínlẹ̀ Ondo
Gbogbo àwọn ará Juda fi Usaya, ọmọ ọdún mẹrindinlogun jọba lẹ́yìn ikú Amasaya baba rẹ̀.
Sugbọn Adajọ naa gba pe lootọ ni ẹka ni ile itẹwe Oxford jẹ ko si le duro fun ijẹjọ nitori naa ki wọn yọ kuro ninu igbẹjọ naa.
Bi ẹ ba n wa ọkọ ti ẹru tabi ero pọju deede ohun to yẹ, ẹ ti tasẹ agẹrẹ sofin ni yẹn.
Nigba naa lọhun o ni oun a ma ṣere alarinjo kaakiri Naijiria paapa julọ, ni ilu Jebba ni ipinlẹ Kwara.
Nigba naa lọun, iya mi ti kọ itan kan lori ayelujara ninu eyi to ti fi oludije ipo aarẹ kan ṣe yẹyẹ ni ọjọ idibo.
Gomina Ipinlẹ naa, Dapọ Abiodun, lo sọrọ yii nigba ti oun ba awọn ẹni ọrọ kan sọrọ.
Kíni Gómìnà ìpínlẹ̀ Ekiti, Kayode Fayemi ṣe fun baba tó ni ọmọ òun ko gbọdọ tèlé oun déle?
Oríṣun àwòrán, Reuters Ọgbẹni Opeyemi ni adaimọ ki iyan ma bẹ silẹ lẹyin ti covid-19 ba tan nilẹ, ayafi ti ko ba pẹ ju loku.
Oríṣun àwòrán, Danny Lawson/PA Wire Àkọlé àwòrán, Ẹwọn HMP Moorland to wa lẹgbẹ Doncaster ni Johnson ti lo ọdun mẹta Johnson, to gba bọọlu fun ikọ England nigba mejila ni wọn da silẹ ni ẹwọn lẹyin to ti lo ilaji ẹwọn rẹ.
N óo sì fi ògo mi hàn láàrin rẹ.
Olóri Ẹbi jẹ àkọ́bi ọkùnrin ni idilé.
OLUWA, là mí ní ohùn,n óo sì máa ròyìn iṣẹ́ ńlá rẹ.
Ẹlẹbubọn wa ke pe awọn agbaagba ilẹ Yoruba lati ṣatunṣe ''awọn eto ogun ko jalu to wa nilẹ Yoruba kọọkan'', o ni ''ọrọ eto aabo to mẹhẹ ti gba iṣọra ati ifura bayii.
Ẹ óo sì tún ní tí yóo ṣẹ́kù fún ohun rere gbogbo.
Buhari woye adinku to niye ninu iye awọn to n lanfani si eto igbọnṣẹ to kunna to da lori oniruuru ile igbọnsẹ, omi to jagaara fun didana ati mimu.
Olóri Òṣèlú Nigeria Muhammadu Buhari pẹ̀lú àwọn àgbà Òsèlú, àwọn Ọba àti  Ìjòyè, ọmọdé àti àgbà ilú dara pọ̀ pẹ̀lú ẹbi àti àwọn ọmọ Olóògbé lati ṣe ẹ̀yẹ ikẹhin fún Olóògbé, Olóyè Hannah Ìdòwú Dideolú Awólọ́wọ̀ ni ọjọ́ karùndinlọ́gbọ̀n, oṣù kọkanla ọdún Ẹgbàálemẹ̃dógún.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Man United vs Tottenham: Tottenham ya aṣọ iyì mọ́ Manchester United lára nírọ̀lẹ́ ọ̀jọ́ ìsinmi 4 Ọ̀wàrà 2020 Oríṣun àwòrán, EPA Ọjọ buruku Eṣu gbomi mu lọjọ isinmi ọjọ kẹrin oṣu kẹwaa ọdun 2020 jẹ fun ẹgbẹ agbabọọlu Manchester United.
 “O maa n jẹ iṣoro lati ri omi lo fun iṣẹ wa yii, paapaa ni asiko ẹrun bayii.
Ìyibọ́npaniyan ile-iwe Florida: Eeyan mẹ́tadinlogun ti ku
Oríṣun àwòrán, INSTAGRAM/HUSHPUPPI Ṣaaju ni ileesẹ ọtẹlẹmuyẹ ilẹ Amẹrika, FBI.
Nítorí náà, OLUWA Ọlọrun ní kí n fi àsọtẹ́lẹ̀ bá Gogu wí pé, OLUWA Ọlọrun ní: “Ní ọjọ́ tí àwọn eniyan mi, àwọn ọmọ Israẹli, bá ń gbé láìléwu, ìwọ óo gbéra ní ààyè rẹ 
Níbikíbi tí Ẹ̀mí Oluwa bá wà, òmìnira wà níbẹ̀.
Ronaldo ba awon akoroyin soro leyin ayeye isafihan re ti o waye ni papa isere Allianz pe, oun ti setan lati tun fida laale ninu idije Serie A.
Wòlíì Kasali ní Dolapo Awosika kò lé ìyàwó òun jáde Olootu ileesẹ iroyin BBC Yoruba fikun pe lootọ ni ko rọrun rara lati dari awọn osisẹ oun to jẹ ọlọpọlọ pipe, sugbọn iriri ati ọgbọn ori wọn lo mu ki BBC Yoruba tayọ laarin ọdun kan.
Ọpọlọpọ nkan lo ṣẹlẹ ni eyi ti Fayoṣe figbe ta pé wọ́n fẹ́ gbẹ̀mí òun lẹyin to dara nibi ipolongo ko to di ero ile iwosan.
Wọn gbé igbesẹ yii lẹyin ti wọn ti paṣẹ fun kọmiṣọna ọlọpaa nibẹ tẹlẹ, Edgal Imohimi, pé ko lọ gba ipo gẹgẹ bii ọga ọlọpaa tuntun fun ẹka to n n mojuto iṣẹlẹ ibugbamu ni olu ileeṣẹ ọlọpaa orilẹ-ede Naijiria to wa ni ilu Abuja.
Àkọlé àwòrán, Fidiò náà ṣe àfihàn Kwesi Nyantakyi bí ó ṣe gba ẹgbẹ̀rún lọ́nà márunléọgọ́ta dọ́là gẹ́gẹ́bíi rìbá Àtẹ̀jáde orílẹ̀-èdè Ghana rèé lórí ọ̀rọ̀ náà: Oríṣun àwòrán, GHANA PRESIDENCY Àwọn ọmọ ilẹ́ Afrika tó ń gbábọ́ọ́lù fún orílẹ̀èdè míràn Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ẹtàn ni àwọn ọ̀rẹ́ fi ń tan èèyàn lọ si Libya pé iṣẹ́ gidi wà níbẹ̀ Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Jonathan: Mó ń sàtilẹyìn fún Atiku kí ìsoro Nàíjíríà má baà fọ́n wa ká 2 Ọ̀pẹ̀̀ 2018 Oríṣun àwòrán, @GEJonathan Aarẹ orilẹ ede Naijiria ana, Goodluck Jonathan ti salaye pe irọ nla ni pe ẹgbẹ oselu PDP ko se daadaa to fun ọdun mẹrindinlogun to fi tukọ orilẹede yii.
"Norrison ní ""ìyàwó oníbàárà òun ló pe òun lórí ẹ̀rọ ìbánisọ̀rọ̀ pé ìléèwòsàn ti gba ọkọ òun nítẹ̀ẹ́."
Mo fi Ijipti, lélẹ̀, láti rà ọ́ pada,mo sì fi Etiopia ati Seba lélẹ̀ mo ti fi ṣe pàṣípààrọ̀ rẹ.
Ni papakọ ofurufu Murtala Muhammed nilu Eko ni wọn ti da awọn dokita naa pada nibi ti wọn ti fẹ wọ baalu kan to wa lati London to fẹ gbe ero pada.
"Don Davis fikan ọrọ rẹ pe, wọn ko fun oun ni ounjẹ, wọn si tun dẹru ba oun pe ""oun yoo di oku, toun ba fi le ṣaroye kankan""."
Lizzy Anjọrin ree to ba buruburu niwaju Alaaafin lati fi ẹmi imoore rẹ han si bi ori ade naa se wa yẹ si ni ọjọ iwuye rẹ.
Bi idunnu ti ṣubu layọ fun Madrid lẹyin ti wọn fagba han Villareal eyi to mu wọn gba ife ẹyẹ La Liga fun igba kẹrinlelọgbọn, nnkan ko ṣẹnu ire fun Barca ni ti wọn.
Kí wọ́n dàbí ewé inú okoati bíi koríko tí ó ṣẹ̀ṣẹ̀ hùbí koríko tí ó hù lórí òrùlé,tíí gbẹ kí ó tó dàgbà.
Lọdun 2002 ni Mohammed Yusuf da Boko Haram silẹ lati tako ẹkọ nilana oloyinbo nibi ti aye laju si loni.
Ọ̀pọ̀lọpọ̀ òkú ẹyẹ igún ré bọ́ lọ́jà Eke-Ihe Mo mọ̀ọ́mọ̀ dá €37,000 ti mo rí he padà ni -Ọmọ ogun Bashir Awọn woo gan an ni ọrọ yi kan?
Oríṣun àwòrán, Olubadan Palace Iyalode Ilẹ Ibadan tuntun yii fẹyinti gẹgẹ bii Nọọsi nile iwosan Oritamẹfa (UCH) nilu Ibadan.
Ilé ẹjọ́ gíga lEko - BBC News Yorùbá BBC News, YorùbáFò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Patience Jonathan gbójú kúrò lára owó ẹ - Ilé ẹjọ́ gíga lEko 1 Agẹmo 2019 Oríṣun àwòrán, Google Àkọlé àwòrán, Patience Jonathan Ìyàwó ààrẹ orílẹ̀èdè Nàìjíríà tẹ́lẹ̀ rí, Dame Patience Jonathan ti pàdánù $8.
Àwọn tí Rakẹli bí ni: Josẹfu ati Bẹnjamini.
Ti Man City ba fidi rẹmi lọwọ Man U, Liverpool yoo sunmọ ki wọn gba liigi, eyi ko si jẹ nkan ti awọn alatilẹyin Man U faramọ.
Grandpa àti Uncle mi, ń fipá bá mi lòpọ̀ láti ọmọ ọdún mẹ́rin Àwọn àmì tó fi mọ̀ pé wọn ń fipá bá ọmọdébìnrin rẹ lòpọ̀ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fọ́nrán ohùn, Kọ́ ọmọ rẹ lẹ́kọ̀ọ́ ìbálọ̀pọ̀- Ọ̀jọ̀gbọ́n Fagbohungbe Makinwa ni àwọn obi ni wọ́n maa n fẹ́ láti da'ri ayé ọmọ ti ọmọ náà ko si ni ẹ̀tọ lati sọ ǹkan to fẹ́ nítori wọ́n ti ko ọmọ láya jẹ tán.
9 Nítorínáà, ìwọ ti gbé àwọn nkan wọ̀nyí sílẹ̀, bẹ́ẹ̀ni, èyíinì tí ó jẹ́ mímọ́, sí inũ búburú.
Iṣẹ́ yìí kan náà ni mo jẹ́ fún Sedekaya ọba Juda.
Ami ayo ookan si ookan ni wọn jọ wa ti ikọ agbabọọlu mejeeji n tiraka ki rẹfiri to ni ki France gba kọju-simi-n-gbaa sile lataari pe ọwọ ọmọ Croatia kan bọọlu.
Ta ló lè ṣe àwárí ohun tó jìnnà gbáà, tí ó jinlẹ̀ gan-an?
Iṣu ewura ni wọn fi n ṣe Ọjọjọ.
Awọn eeyan naa ti wọn kọwọọ rin lọ sí olu ileeṣẹ ijọba ipinlẹ Oyo ni Agodi nibi ti wọn ti gbe oriṣiriṣi beba lọwọ p\\wlu akọle oniruuru.
Nnkan bii agogo marun abọ irọlẹ ọjọ Aje ni gomina Makinde tẹwọ gba esi ayẹwo rẹ ninu eyi to ti mọ pe oun ti ko arun naa.
Nollywood: Wo àwọn òṣèré tíátà Yorùbá tó ti kú àmọ́ tí iṣẹ́ wọn ń fọhùn síbẹ̀
Wọ́n fi ọọdunrun ó lé mejila (312) kilogiramu wúrà ẹgbẹsan (1,800) kilogiramu fadaka ati ọgọrun-un (100) ẹ̀wù alufaa, ṣe ẹ̀bùn fún ilé OLUWA.
Ṣugbọn nisinsinyii, OLUWA ní, “Nígbà tí a óo fi rí ọdún mẹta, tíí ṣe iye ọdún alágbàṣe, a óo ti sọ ògo Moabu di ilẹ̀.
“Nisinsinyii OLUWA ti mú ìlérí rẹ̀ ṣẹ.
Ó ní, “Ó wá yé mi gan-an pé Ọlọrun kì í ṣe ojuṣaaju.
Oríṣun àwòrán, NDLEA Ninu wọn ni iwọn ẹgbẹrun meje o le diẹ kilo Igbo mimu wa, ti iyoku si jẹ oogun oloro Cocaine.
Àkọlé àwòrán, Opọ lo ti n foju sọna lati mọ ẹni ti yoo tukọ ipinlẹ rivers fọdun mẹrin to m bọ Ahmed Musa gbàmì ẹ̀yẹ agbábọ́ọ̀lù tó pegede ní ọdún 2018 Ẹ̀ wo bí àwọn ẹ̀ṣọ́ ojú etí òkun ṣe ń ṣiṣẹ́ l'Eko Awakọ̀ òfúrufú Ethiopian Airlines pariwo 'lọ sókè!
Selofehadi ọmọ Heferi kò bí ọmọkunrin kankan, àfi ọmọbinrin.
pajawiri yoo fi wa  lorile ede naa.
CP Ahmed Iliyasu - CP Ogun State Command xxv.
Luiz kii ṣe ajeji si irufẹ awsn aṣiṣẹ epo n biyọ bayii to si ti mu ki ọpọlọpọ onwoye bọọlu o maa pe fun ori rẹ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ogbomsho shooting, End Sars, End SWAT: Isiaka fi ọmọbìnrin kan àti ìyàwó tó lóyún sínú síl 5.
"Jumoke Odetola Oríṣun àwòrán, @TernopilInkling Àkọlé àwòrán, Ilu Eko ni wọn bi Jumoke si lọdun 1983 Lọseyi ni gbajugbaja oṣere tiata Yoruba yii ti ọpọ n pe ni ""Higi-haga"" ṣe ọjọ ibi rẹ."
Agbenuso fun ile ise oko akero Dana, Ogbeni Kingsley Ezenwa gboriyin fun awako ofurufu naa fun igbese akoni lati koko doola emi awon ero naa saaju ohunkohun.
”O tun tesiwaju pe, “Aare nigbagbo lati pese eto iranwo fun awon orile ede to fẹgbẹkẹgbẹ pelu orile ede Naijiria, idi niyi ti aare se pese eto iranwo fun won.
Ibẹ̀ ni kí ẹ máa mú gbogbo ẹbọ sísun yín, ati àwọn ẹbọ yòókù wá, ati ìdámẹ́wàá yín, ati ọrẹ àtinúwá yín, ati ẹ̀jẹ́ yín tí ẹ bá jẹ́ fún OLUWA, ati àkọ́bí mààlúù yín, ati ti aguntan yín.
Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Olórin, Small Doctor, gba ìtúsílẹ̀ nínú àhámọ́4 Ọ̀pẹ̀̀ 2018 Àwọn ọlọ́pàá tó mú Evans 'ajọ́mọgbé' gbá igbega20 Ìgbé 2018 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Femi Adesina ni nitootọ ni o jẹ pe Adajọ agba ni Naijiria to paṣẹ itusilẹ El Zakzakky ati aya rẹ kuro ninu tubu ṣe eyi gẹgẹ bii agbara ofin ni.
Buhari nìkan kọ́ ni aṣíwájú táwọn èèyàn dẹ́yẹsí 'Mí ò sí lára awọ̀n aṣòfin tó bú Buhari'' Amọ ṣa, niṣe ni Bukọla Saraki ati Yakubu Dogara ati awọn ọmọ ẹgbẹ oṣelu PDP gba 'ọna ẹburu' lati ṣeto idibo naa laisi awọn ọmọ ẹgbẹ APC nile, botilẹjẹ pe ọmọ ẹgbẹ naa ni awọn naa jẹ.
léhìn alárè ni lúwà ( olÙ-ÌwÀ ) náà dé láti asálè núbíà .
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Awọn ọmọogun jẹwọ idi ti wọn ko fi lee pa ina Boko haram 8 Ẹrẹ̀nà 2018 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Aisi iroyin to kuna n se akoba fun gbigbogun ti Boko Haram Ileesẹ ọmọ ogun lorilẹede Naijiria ti jẹwọ ohun to faa ti o fi n mẹhẹ ninu pipese eto abo to pegede ati mimoke ninu gbigbogun ti awọn ikọ agbesunmọmi lorilẹẹede naa.
Ìjọba Ìpínlẹ̀ Ogun ti kéde ìbẹ̀rẹ̀ ètò ẹ̀kọ́ ọ̀fẹ́
Ondo missing baby: Òkú ọmọ tuntun di àwátì nílé ìgbókúpamọ́sí ìjọba nílùú Akurẹ
yoo ti waye, ti o fi mo ifesewonse ipegede keyin fun
Ni ti awọn ti ko gba ti ọ̀rọ̀ ti Pasitọ Adeboye fi sita yii, ṣe ni wọn n bu ẹnu atẹ lu u.
Ọrọ gbigba ibale iyawo lo dabi ẹnipe ko mọ laarin iran Yoruba nikan, eyi to ti n fa wahala fun awọn idile kan jakejado agbaye.
Mo n fi owo naa ran ara mi lọwọ ni nile iwe.
Àmọ́ ẹ ríi pé ẹ dáàbò bo ẹ̀mí yín - Ọ̀gá àgbà ọlọ́pàá Mo pinu láti dá Iphone tì mo mú padà kí ọlọ́pàá tó mú mi Ẹ gbọ́ Ohun tí Desmond Elliot àti Mojisola Alli-Macaulay sọ lórí ayélujára táwọn ọmọ Nàìjíríà fi ìbínú Ofuleue sọ pe iye owo ti awọn eeyan n san lọwọ yii naa ṣi ni iye ti wọn n san tẹlẹ ki wọn to gbe aba idiyele owo tuntun naa jade.
Ọba ranṣẹ pé kí wọ́n tú u sílẹ̀,aláṣẹ àwọn orílẹ̀-èdè sì dá a sílẹ̀.
Nígbà tí ó bá ṣe bí ó ti fẹ́ tán, yóo pada sí ilẹ̀ rẹ̀.
Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí 6:18 Fídíò, Akomolede: Bolaji Faleke ni Olùkọ́ tó ń kọ́ wa ní àṣà oge ṣiṣe lórí BBC Yorùbá, Duration 6,181 Owewe 2020 Fídíò, Yoruba Language: Akomolede ati Asa Yoruba tọ̀sẹ̀ yí rèé lẹ́nu olùkọ́ wa30 Ògún 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
-Kollington fésí sí ìbéèrè ńlá Mo ti kó kúrò nílé Olu Jacobs rí lẹ́ẹ̀mejì- Joke Silva Àṣírí mẹ́wàá tí mo mọ̀ nípa Boko Haram-Naomi Adamu Shiek Yahaya Samadaani- Ọdún 2020 yìí á sàn ẹni tó bá fọkàn sín Olorun Igboho sọ siwaju si pe ọpọ awọn eeyan to mọ iru itu ti oun pa lasiko ogun Modakẹkẹ ati Ifẹ lo maa n kan saara si oun, to fi mọ bi oun se duro ti Rashidi Ladọja lasiko to wa nipo gomina nipinlẹ Ọyọ ti wọn ko fi lee yan jẹ.
But he did not stop it there, he offered me political asylum by his government in the US.
tun ni ile –ise to n ri si, bi oju ojo se n lo (National Space Research and Development
Wọn de ọrọ yi lade pẹlu atejade kan leyin Ipade to waye ni ọjọru pe gboyin gboyin lawọn wa lẹyin oga ọlọpaa lati se atunto ileesẹ ọlọpaa.
Awọn arinrinajo Hajj yoo bẹrẹ si sanwo ori Hajj: Ǹjẹ́ o mọ pàtàkì Ọjọ́ Àràfá fún àwọn mùsùlùmí?
Ma sise takuntakun lati ri daju pe, a mu gbogbo afojusun wa patapata wa si imuse,”.
Nígbà tí a rìn súnmọ́ ilé náà díẹ̀ Ikú yọ jáde láti inú ilé, ó ń bọ̀ wáá pàdè wa.
Àwọn ọmọ ogun Israẹli ati ti Juda hó ìhó ogun, wọ́n sì bẹ̀rẹ̀ sí lé àwọn Filistini lọ.
EFCC fi ẹ̀sùn kan Nwobike pé ó fẹ́ fi owó ránṣẹ́ si adájọ́ àgbà méjì, Mohammed Yunusa ati Hyeladzira Nganjiwa, láti rí i pé wọ́n dá ẹjọ́ tí yóò tẹ lọ́rùn.
Genevieve Nnaji gba awọn obinrin ni imọran ohun loju opo ikansiraẹni Facebook rẹ.
Ẹni ti a n sọrọ rẹ ni Adebayo Ogunlesi-ọmọ bibi ilu Makun nipinlẹ Ogun to si jẹ ilumọọka oludokowo lagbaye nii ṣe.
Oyo state paternity leave: Ìjọba ìpínlẹ̀ Oyo bẹ̀rẹ̀ ìgbésẹ̀ lórí bí àwọn ọkùnrin ṣe leè máa gba ìsinmi ìtọ́mọ (Paternity leave)
Àrùn Coronavirus ti mú ẹ̀mí ẹni àkọ́kọ́ lọ nílẹ̀ Madagascar Oríṣun àwòrán, @Scara_King Ijọba ilẹ Madagascar ti kede ẹni akọkọ ti yoo gbẹmi mi nitori arun Coronavirus lorilẹede naa.
Toyin sọ síwájú pé, òun rí pe Ọlọ́run ló ń fi agbára rẹ hàn wá nípa àrùn Covid-19 yìí, nítorí ohun gbogbo kò leè rí bíi ti àtẹ̀yìnwá mọ, lẹ́yìn ti àrùn náà bá kasẹ nilẹ.
Bakan naa ni awọn araalu to n gba ọna naa kọja, ni ikọ Boko Haram ma n da lọna, ti wọn a si gba owo lọwọ wọn, ji wọn gbe tabi ki wọn pa wọn.
Egbe oselu (PDP) ti ni awọn ko ni gba abajade esi idibo gomina to waye ni ipinle Ekiti.
Ministry of Labour and Employment), William Alo, lo n beere iranlowo yii “ Lati
Lẹhin òwò ẹrú, li lo ẹ̀rọ igbàlódé fún iṣẹ́ oko jẹ ki Aláwọ̀funfun lè dúró pẹ̀lú àṣà fi fẹ́ iyàwó kan.
Ile iṣẹ ọlọ́pàá nílu Abuja ni awọn tí mú ọmọ ẹgbẹ́ Shi'ite márùndínlọ́gọ́fà to kópa nínú iwode tó wáyé nílu Abuja lọjo ajé.
Adari ile isẹ irinna naa, Mohammad Babandede lo sọ ọrọ yii nibi ipade awọn Ọga Agba irinna to waye ni Benin, lorilẹ-ede Naijira.
2 mílíọ ́ nù ní àwọn ọdún 1980 .
Ọlọrun yóo wá nu gbogbo omijé kúrò ní ojú wọn.
Nígbà tí a kọ́ ń pe gbogbo àwọn ẹ̀yà tí èdè wọ́n papọ̀ yìí ní Yorùbá tàbí Yóòbá, wọn kò fi tara tara fẹ́ èyí nítorí pé àwọn ẹ̀yà Yorùbá ìyókù gbà pé àwọn Ọ̀yọ́ nìkan ni Yorùbá.
O sọrọ lori owo gba-ma-binu $800,000 ti wọn fun ẹbi pe ko da ẹmi ọmọ oun pada.
Ṣugbọn tí ó bá jẹ́ ìtìjú fún obinrin láti gé irun rẹ̀ mọ́lẹ̀ tabi láti fá orí rẹ̀ a jẹ́ pé ó níláti bo orí rẹ̀.
Inú àwọn orílẹ̀-èdè ru,ṣugbọn àkókò ibinu rẹ dé,ó tó àkókò láti ṣe ìdájọ́ àwọn òkú,ati láti fi èrè fún àwọn iranṣẹ rẹ, àwọn wolii, àwọn eniyan rẹ,ati àwọn tí ó bẹ̀rù orúkọ rẹ, ìbáà ṣe àwọn mẹ̀kúnnù tabi àwọn eniyan ńláńlá.
Jesu bá dá a lóhùn, ó ní, “Pada kúrò lẹ́yìn mi, Satani.
Adenuga fikun pe, bi ilu se ri lo gbe oun kuro ni Naijiria, to fi mọ ọrọ ẹbi oun, wiwa ọjọ ọla fun awọn ọmọ ati ki iya oun lee jẹ ounjẹ ọmọ lọjọ alẹ.
Bí ó bá tún yí padà á dàbí ejò ńlá, a máa yọ ahọ́n jáde bérébéré lẹ́nu.
Ninu ẹ̀yà Efuraimu àwọn tí wọ́n tó ẹni ogún ọdún, tí wọ́n tó lọ sójú ogun, gẹ́gẹ́ bí àkọsílẹ̀ wọn ní ìdílé-ìdílé 
setan lati mu atileyin ati ibasepo to munadoko jeyo laarin re ati ile-igbimo
Oríṣun àwòrán, Lizzy Anjorin Mama oloye tuntun ree lagbo, Bọrọkinni Adinni tuntun, to wọ asọ olowo iyebiye, ti oju rẹ si dun wo Oríṣun àwòrán, Lizzy Anjorin Lara awọn eekan ilu lagbo orin kikọ to yẹ Bọrọkinni Adinni tuntun si ni Alhaja Salawa Abẹni ati Wasiu Alabi pasuma.
        Bí emi àti baálé mi ti fi ẹ̀ọ̀ ẹran jẹun tán ní òwúrọ̀ yìí, tí ìṣaasùn ọbẹ yí mi ká, tí ìkókó èlùbọ́ fẹ́yìntì ni yààrá, tí àkàṣù ẹkọ sì kún ilé mi kítikìti, mo tọrọ ààyè lọ́wọ́ ọkọ mi tuntun náà láti kọ ìwé yìí sí ọ.
 Besini, a fin da awon ololufe wa ati ijoba ipinle Eko loju pe, a ko ni jawon kule nigba Kankan.
Kadir Obafemi Hamzat - O yege (Bayii, o ti ju awà silẹ fun Jide Sanya-Olu, pe oun yọ̀ǹda ipinlẹ Eko fun Sanya-Olu lasiko yii)3.
" Fabiyi tun fi kun pe, awọn osere tiata lee se afihan bi awọn agbofinro se tẹ ẹtọ ọmọniyan loju mọlẹ, to ba jẹ pe wọn yoo se afihan iya ti iru agbofinro naa jẹ lori iwa aidaa to hu ọhun.
Ó rẹ ẹni ọdún 49 tó ri ẹ̀wọ̀n ọgọ́ta ọdún he lẹ̀yìn tó bá ọmọ ọdún méjì lòpọ̀ Mo pàṣẹ pé kí ọ̀gá owó ìfẹ̀yìntì tẹ́lẹ̀, Maina sì wà látìmọ́lé- Adájọ́ Ṣé irúfẹ́ oúnjẹ tí ò ń jẹ́ lè jẹ́ kí o gbádùn ìbálòpọ̀ rẹ síi?
Ǹjẹ́ Itesiwaju tí dé bá wa ní orílè èdè Nàìjíríà?
 Ọ ̀ pọ ̀ ọ ̀ nà ni a ń ṣàwarí mímọ ̀ àrùn náà èyí tí ó wà lára : ṣíṣe ìṣàyẹ ̀ wò omi ara ti àwọ ̀ ara si omi iyọ ̀ ara bí ó ti yẹ àti wíwò kí ìdin náà ó jáde , wíwo ojú fún ìdin náà , àti wíwo inú aẁọn ara wíwú lábẹ ́ àwọ ̀ ara fún àwọn àràn ńlá .
Amọ adajọ to n gbọ ẹjọ naa, Jeffrey Gilbert, ẹni to wo igbẹjọ naa lati ori ayelujara ni Chicago kọ lati gba oniduro Hushpuppi.
Èyí ni iṣẹ́ tí a fi fún mi nípa ẹ̀bùn oore-ọ̀fẹ́ Ọlọrun gẹ́gẹ́ bí iṣẹ́ agbára rẹ̀.
Bi a ko ba gbagbe pe, awe awon musulumi ti o sese bere ohun lojo karun un, osu karun un, odun ti a wayii, ti pe marun un loni.
ilẹ okeere  ti o ba kọ lati gba iwe igbelu
Megan Rapinoe ni Balogun ikọ ẹgbẹ agbabọọlu obinrin fun orilẹ-ede America lọdun 2019.
Oríṣun àwòrán, @DanielOE16 Sugbọn ẹnikan to pe ara rẹ ni aburo oloogbe, Daniel, jade sita pe awọn janduku lo wọle gun ẹgbọn ohun lọrun pa, kii si se asita ibọn ọlọpaa lo baa.
Ki lo mu papa fipo silẹ?
Osai tun tesiwaju pe”ase ijọba apapo to wa ninu ofin kefa, ni lati tẹ ojuse ati agbara igbimo asofin  ati awọn  adajọ mọle nipa sise ofin ati lati  itumo rẹ.
Nígbà tí ó sì ti parí ọ̀rọ̀ rẹ̀ ni àwọn ọmọ náà ti kúrò ní ibi tí wọ́n ti ń ṣiré, wọ́n tẹ̀lé ìyá wọn wọ́n ń wá oúnjẹ òójọ́ wọn lọ.
Eyi ko ṣeyin iṣẹlẹ to waye nile ijọsin ọhun loṣu to kọja lataari bi ọmọdekunrin jojolọ kan ṣe di awati nibẹMissing Child: Òbí àti asọ́nà ṣọ́ọ̀ṣì 14, lọ́ búra nì'dí imọlẹ̀ l'Akure .
O ni eyi lo mu ki oun pinnu lati dawọ duro naa.
Amọ o, awọn ọmọ ẹgbẹ alatako ti fesi pe ki ijọba mase fọwọ kan awọn patako ipolongo wọn.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Olusegun Obasanjo: Ọmú ìyá mi ti mo fi ń mùkọ ni kekere ló jẹ ki ń lókun Ni ti igbakeji aarẹ Ọjọgbọn Osinbajo, nigba ti a gbe fọọmu naa yẹ wo, ko si ayipada kan sàán to yatọ si ohun ti a kede lọdun mẹrin sẹyin""."
Aare Ernest Bai Koroma, ti o wa lori aleefa  fun odun maarun lemeeji otooto labe egbe oselu All People’s Congress (APC).
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Sunday Igboho: Ẹ fi Ògún búra fún wa láti jà fún ilẹ̀ Yorùbá láì gbé Amotekun sábẹ́ ìjọba O ni Ifa nikan lo le ṣalaye ọna ti wọn le rin ti wọn ko fi ni kuna, Akoda Awo ni lọdọ awọn babalawo si ni Ifa wa.
Ijọba apapọ paṣẹ pe ki wọn fi awọn dokita agunbanirọ to n sinru ilu lọwọ, rọpo awọn dokita iṣegun to n yanṣẹ lodi lawọn ileewosan to jẹ ti ijọba apapọ naa.
1 12664 Orilẹede Olominira Congo 112 2.
ẹ̀ báà bú mi di ọ̀la - Ọ̀gá Amotekun l'Osun Nipa mimu awọn to wa nidi iṣẹlẹ yi, alukoro yi ni afurasi mẹta lawọn ti mu ti wọn si ti n wi tẹnu wọn nipa iṣẹlẹ yi.
Ayọ̀ọlá: Tí ó bá jẹ́ bẹ̀, ẹ ta ẹ̀wà múrí kan àbọ̀ wá
    Nígbà ti ó sọ̀kàlẹ̀ tán, ó bá ara nínú ààfin tí ó kún fun dúkìá gbogbo, bí o sì ti wo iwaju ó rí obìnrin arẹwà kan tí ó jókòó lé orí àga ńlá kan.
O ti fẹrẹ to ẹgbẹrun marun un eniyan to ti lugbadi arun Coronavirus lorilẹede Naijiria, ti eniyan mejidinlọgọjọ si ti papoda.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Abba Kyari: Àwọn ojúṣe olórí àwọn òṣìṣẹ́ fún ààrẹ Nàìjíríà 20 Ìgbé 2020 Oríṣun àwòrán, Others Olori awọn oṣiṣẹ fun Aarẹ Naijiria jẹ alarina laarin aarẹ ati ijọba.
Ann Grace Aguti ẹni ọdun mẹ́rìndinlógójì fẹ́ ọkúnrin mẹta, Richard Alich, John Peter Oluka àti Michael Enyaku ti gbogbo wọ́n si jọ ń gbe pọ.
Shkodran Mustafi lo kọkọ sẹesi gbayo sawọn Arsenal lẹyin iṣẹju mẹfa ti wọn bẹrẹ ere bọọlu ọhun.
Apple ni èso tó n tà julọ lẹ́yìn ọgẹdẹ ní orílẹ̀-èdè Amẹrika.
Àwọn aṣòfin ìpínlẹ̀ Ogun pariwo sí Gómìnà wọn Ọpọlọpọ eeyan lo si ti bu ẹnu ẹtẹ lu ipaniyan naa.
Ṣugbọn kò gbà; ẹ̀wọ̀n ni ó ní kí wọ́n lọ jù ú sí títí yóo fi san gbèsè tí ó jẹ.
Ẹ kọ orin titun sí OLUWA,nítorí tí ó ti ṣe ohun ìyanu;agbára ọwọ́ ọ̀tún rẹ̀, ati apá mímọ́ rẹ̀ ni ó fi ṣẹgun.
Àwọn jẹsí tó gbajúmọ̀ nínú ìtàn ìdíje bọ́ọ́lù Ebi àṣeyọrí ló n pa mí báyìí lẹ́yìn àkókò mi tó ti ṣòfò - Paul Pogba ''Ronaldo ṣì lè padà sí ẹgbẹ́ agbábọ́ọ̀lù Real Madrid'' Agbábọ́ọ̀lù Brazil tẹ́lẹ̀, Ronaldinho gba ìtúsílẹ̀ kúrò lọ́gbà ẹwọ̀n, àmọ́.
Ki ipade ohun to bere, eleyi
Elédùmarè nìkan ṣo ló lè tù yín nínú
Nígbà tí ó fún afẹ́fẹ́ ní agbára,tí ó sì ṣe ìdíwọ̀n omi,
Láti oṣù tuntun dé oṣù tuntun, ati láti ọjọ́ ìsinmi kan dé ekeji, ni gbogbo eniyan yóo máa wá jọ́sìn níwájú mi.
Aga to wa ninu yara Daniel Ọlọrunfẹmi Fagunwa ree, eyi ti baba lo nigba aye rẹ.
" Adeleke sọ̀rọ̀ lórí àhesọ ọ̀rọ̀ pé ó kú Wàhálà bẹ́ sílẹ̀ láàrin àwọn ọlọ́jà ni Ògùnpa, Ìbàdàn Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ìwà olè, jìbìtì àti ìjẹkújẹ ló n jé káwọn mii yí ọjọ́ orí wọn padà IMN fidirẹmulẹ pe lootọ ni ileeṣẹ ọtẹlẹmuyẹ DSS, ti gbe El-Zakzaky kuro ni ilu Abuja lọ si ipinlẹ Kaduna, ṣugbọn wọn ko ti i gba beeli rẹ.
Newcastle run Manchester United mọ́lẹ̀ jégéjégé Tottenham tasẹ̀ àgẹ̀rẹ̀ bí Tacha fara káásá ìyà lọ́wọ́ Brighton Israel Adesanya fi ẹ̀ṣẹ́ mú ẹ̀jẹ̀ jáde nímú Whittaker láti gba àmì ẹ̀yẹ UFC Evra ṣalaye pe ọmọ ikoko loun maa n pe wọn ni bii ọdun mẹwaa sẹyin nigba kugba tawọn ati Man U ba koju ara wọn.
Bakan naa lo gba awọn eeyan niyanju lati maa mu omi to mọ daadaa nigba gbogbo ki wọn le fi rọpo eyi to n jade lati ilaagun lasiko yii.
Bẹ́ẹ̀ ni lọ́jọ́ tí Ọba Igbó Olódùmarè àti èmi fi ojú rí ara wa, ayọ̀ pàdé ayọ̀, ẹ̀rín ń gbé ẹ̀rín ní ìyàwó, ijó ń bá ijó ṣiré, oúnjẹ ń pádè oúnjẹ, ènìyàn àti ẹbọra ń fi ọwọ́ kọ́ ara wọn lọ́rùn, òkìkí gba inú Igbó Olódùmarè kankan.
Iyalẹnu lo jẹ fun gbogbo awon
lati odun 2019 si odun 2022.
A doola ẹmi awakọ ero naa, ta si ti gbe lọ sile iwosan kan to wa nitori."
Ilu gbona, awọn akẹkọọ ti awọn opopona pa, rogbodiyan gbode, ijọba yari, ko yi ipinnu rẹ pada, awọn akẹkọọ naa si gbọnmu pe awọn ko ni gba.
Àkọlé àwòrán, ìpàdé ìfọ̀rọ̀wérọ̀ BBC Yorùbá Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, #BBCGovDebate: Olùdíje 5 ni yóò kópa nínú ìpàdé ìtagbangba l‘Ogun Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Bode George dá sí aawọ̀ Buhari, Obasanjo Àkọlé àwòrán, ìpàdé ìfọ̀rọ̀wérọ̀ BBC Yorùbá Gbogbo eto lo ti to bayii nibi gbọngan ipade naa eyi tii ṣe gbọngan igbalejo Oluṣẹgun Ọbasanjọ Library to wa ni ilu Abeokuta gẹgẹ bi awọn akopa ṣe ti bẹrẹ si ni fi orukọ silẹ.
Lẹ́yìn náà, kí o wá fi wá wé àwọn tí wọn ń jẹ lára oúnjẹ àdídùn tí ọba ń jẹ, bí o bá ti wá rí àwa iranṣẹ rẹ sí ni kí o ṣe ṣe sí wa.
Ọkọ̀ akérò BRT gbiná lórí afárá 3rd Mainland Ọmọ Nàíjíríà 218 padà dé láti Libya Àti lọ s'Amẹrika ti yàtọ̀ báàyí Diẹ lara awọn nnkan ti igbesẹ yi yoo mu ba awọn ọmọ Naijiria nibẹ ni: Gbigba pali idanimọ orileede Naijiria eleyi ti o ba ti jọba le fẹ soro diẹ.
Oríṣun àwòrán, @UNICEF_Nigeria Malami ni yatọ si pe eyi yoo mu kawọn ọdọ setan lati sisẹ olukọ, bakan naa tun ni ijọba yoo seto idanilẹkọ atigbadegba fun wọn.
A mọ̀ pé kò sí ọmọ Ọlọrun kan tíí máa gbé inú ẹ̀ṣẹ̀, nítorí pé Jesu Kristi Ọmọ Ọlọrun ń pa á mọ́, Èṣù kò sì ní fọwọ́ kàn án.
Ẹgbẹ oṣelu PDP fi kun un pe gbogbo awọn to n sọ ọ kaakiri pe gomina Makinde kii pe aarẹ tabi baa sọrọ ko sọ otitọ nitori ko si ofin to sọ pe ajọṣepọ tabi ajọsọ ọrọ to ba waye laarin Gomina Makinde ati aarẹ gbọdọ di eyi ti a n polongo fun aye ri.
Modekai jáde ní ààfin ninu aṣọ ọba aláwọ̀ aró ati funfun pẹlu adé wúrà ńlá.
Àwọn ìròyìn mìíràn tí ẹ lè nífẹ̀ẹ́ sí: 'Ẹwọn ọdun mẹẹdọgbọn ko pọ ju fun afipabanilopọ' Damasus, Omotola, Ezekwesili, Funmi Iyanda dá sí ẹ̀sùn ìfipábánilòpọ̀ Fatoyinbo Ẹ̀sùn ìfipábánilòpọ̀: Orí Twitter ló ti bẹ̀rẹ̀, ikú ló já sí COZA: Mi ò fípá bá obìrin lò pọ̀ rí láyé mi - Pásítọ̀ Fatoyinbo Ààrẹ fi nǹkan ọkùnrin rẹ̀ pa mí lójú, kó tó fipá bámi lòpọ̀ - Ọmọge Arẹwà O wa rawọ ẹbẹ si tọkunrin-tobinrin ọmọ orilẹede yii lati wa aaye ninu ọkan wọn fi fori jin oun nitori eniyan lo n dẹsẹ, Ọlọrun si lo maa n fori jin ni.
Oju ọna irin ko tii fi bẹẹ yanju bẹẹ si ni oju ọna omiko tii gbaju gbaja to laarin awọn eniyan ipinlẹ Eko.
Lẹ́yìn náà wọ́n wá gbogbo ilẹ̀ Bẹnjamini, sibẹsibẹ wọn kò rí wọn.
Ṣé ohun tí ẹ ti ń rò ni pé à ń wí àwíjàre níwájú yín?
Tí a fiṣọwọ́ ní 9:459:45 Ọmọ Naijiria hú ẹ̀sùn ìfipá bánilòpọ̀ tí wọ́n fi kan Fatoyinbo síta lẹ́yìn tó lọ sí Shiloh Ariyanjiyan n waye lori bi iroyin ṣe ni Pasitọ Agba ijọ COZA, Biodun Fatoyinbo, lọ fun isin Shiloh ni ṣọọṣi Oyedepo.
”Ewe, oba Ofem dupe pupo lowo aare fun pe, O yan omo Yakuur sara isajoba re, ti o fi mo oga agba ile ise omo ogun ori omi, minisita to n mojuto oro Niger Delta ati abbl.
Ọpọ ọmọ Naijiria lo n beere pe ki ni awọn ọdọ ri ti wọn se n suru bo eto naa nigba to jẹ pe awọn ọrọ miran to se koko wa nilẹ Naijiria, eyi to nilo ki wọn kọbi ara si wọn.
Oríṣun àwòrán, Others Eyi si lo tako iroyin to n ja rainrain nilẹ kiri pe, awọn ọlọpa to le ni ọọdunrun niye, to tẹle awọn ọmọ onilẹ meji naa, to fẹ wa gba ilẹ wọn, lo n fiya jẹ awọn ara adugbo Soka yii, ti wọn fi n sa kijokijo kiri.
Tí won ò sì lè sọ léṣèkannaa ìlú tí ènìyàn kan ti wá ní kété tí a bá rí.
Wọ́n wá ń kúnlẹ̀ níwájú rẹ̀, wọ́n ń fi ṣe yẹ̀yẹ́; wọ́n ń wí pé, “Kabiyesi, ọba àwọn Juu.
Nínú àtẹjáde ti olubadamọ̀ràn pàtàkì lóri igbòhùn sáfẹ́fẹ́ rẹ, Umar Gwandu fọwọ́sí sàlàyé pe, Àmọtẹ́kùn kìí ṣe èyi to ba òfin orilẹ̀-èdè Naijiria mu.
Láàrin ìsinyìí sí ọdún marundinlaadọrin, Efuraimu yóo fọ́nká, kò sì ní jẹ́ orílẹ̀-èdè mọ́.
Aidawọ iṣẹlẹ yii duro lo mu ki awọn eniyan maa figbe sita lati sọ ẹdun ọkan wọn, bi awọn kan ṣe n dabaa ijiya iku, lawọn mii n fi epe ranṣẹ si awọn to n ṣe iru iṣẹ laabi yii kaakiri.
” Isaaki bá dáhùn pé, “Mo rò pé wọ́n lè pa mí nítorí rẹ̀ ni.
Wọn yóo gbógun tì ọ́, ṣugbọn wọn kò ní ṣẹgun rẹ, nítorí pé mo wà pẹlu rẹ láti gbà ọ́, ati láti yọ ọ́.
Àwa la mọ báa ṣe mú Sunday Shodipe táa fà a lé ọlọ́pàá lọ́wọ́ - Ọlọ́dẹ Soludero Iròyìn àyọ, àdínkù tún bá iye ènìyàn tó lùgbàdì Covid -19 ní Nàìjíríà lọ́jọ́ Àìkú Owó dé!
“Juu ni mí, Tasu ní ilẹ̀ Silisia la gbé bí mi.
Ẹni to bori: Ghana Congo DR vs Kenya.
Ṣugbọn ileeṣẹ ọlọpaa ti tako ọrọ yi pe awọn ko yinbọn pa ọmọ ẹgbẹ Shitte kankan bi kii ṣe pe awọn tu awọn to pejo lati ṣe iwọde ka.
Ère kinniun mejila wà lórí àwọn àtẹ̀gùn mẹfẹẹfa, meji meji lórí àtẹ̀gùn kọ̀ọ̀kan, ní ẹ̀gbẹ́ kinni keji àtẹ̀gùn náà; kò sí ìjọba orílẹ̀-èdè kankan tí ó tún ní irú ìtẹ́ náà.
Mo ti fi gbogbo ilẹ̀ Edomu ní òkè Seiri fún arọmọdọmọ Esau, gẹ́gẹ́ bí ìní wọn.
Àlàyé rèé lórí ìdí tí Sẹnẹtọ Ishaku Abbo fi kọ̀wé fi PDP sílẹ̀ Nàìjíríà fohùn ránṣẹ́ padà sílé aṣofin UK pé ọ̀rọ̀ EndSars kò sí lẹ́nú wọn láìgbọ́ ìwádìí tán!
Ẹlẹbuibọn sọ pe oriṣiriṣi nkan lo ma n fa akufa ninu ẹbi kan.
Ǹkan tí ó yẹ ki o mọ̀ nípa Burna Boy Àwọn nkan tó yẹ kí o mọ̀ nípa ṣíṣe ìṣirò àsìkò tí o bá n yé ẹyin Natalie wa gba awọn obi Yoruba ni imọran lati dide si iṣẹ iya ni pataki lati kọ ọmọ wọn ni aṣa ati iṣe bii ibówọfagba ti o jẹ Yoruba logun ninu iwa ọmọluwabi.
Asofin ẹgbẹ PDP naa, to tọrọ aforijin pẹlu lọwọ ẹgbẹ oselu rẹ, awọn mọlẹbi, ọrẹ tun mẹnuba pe, iwa bayii se ajeji si oun lati ẹyin wa, ti oun si kabamọ fun iwa toun hu yii, lainaani ohun to bi oun ninu lati se bẹẹ.
Bulgaria, Croatia ati Romania wa lara awọn orileede ajọ EU bo tilẹ jẹ pe wọn ko si ni agbegbe ti ibode Schengen kan.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Nigeria movie industry: Àgbà òṣèré, Lere Paimo ní àìgbọràn ló ń da ọ̀pọ̀lọpọ̀ àwọn Olusola jẹ ọkan lara awọn agba ọjẹ oṣere tiata to da ẹgbẹ awọn oṣere taa mọ si ANTP silẹ lọdun 1976, to si jẹ akọwe owo akọkọ fun ẹgbẹ naa laarin ọdun 1976 si 1989, bẹẹ lo tun gbe ọpọ ere jade ni ede Yoruba.
Olori ijoba egbe oselu alatako ti so fun Aare naa lati kowe fipo re sile.
Ogun Accident: FRSC ní Sokoto làwọn èrò náà ti ń bọ̀ wá sí Ijẹbú Ode
Sudan coup: Ṣé ìfipágbàjọba àwọn ológun kò maa pọ̀ si l'Afirika?
O n lọ irinajo lati laarin Adis Ababa ati Nairobi nibi ti eniyan mẹtadinlogojo ti doloogbe.
Iyọnipo aarẹ ọhun ti da awuyewuye silẹ ni ilu Washington.
Ko si nkan ti awọn eniyan ko le tà tabi ra ni ọja agbaye!
Ìdí rèé tí ilẹ̀ Afirika fi gbọdọ̀ kópa nínú dídán abẹ́rẹ́ coronavirus wò Gómìnà márùn ún tó fojú winá ìbínú bàbá ìsàlẹ̀ wọ̀n Ṣé lóòtọ́ ni Sẹ́netọ̀ Bayo Osinowo ní ìfura ikú ara rẹ̀?
Awon elesin krisiteni ti n saroye fun igba pipe  lori ideye  awon latodo awon elesin Islam lorile-ede naa, eyi ti won si n fi igba gbogbo se ikolu si won.
O salaye pe, o seese ki orile-ede Naijiria pada sipo re, lati maa ko ounje lo sile okere, bi ijoba ba tepele mo ipese ounje.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Xenophobia: Àdúgbò Lugbe kan gbínrín torí ìkọlù àwọn olùfẹ̀hónú hàn 4 Owewe 2019 Ọrọ di boo lọ, ko yago fun mi ladugbo Lugbe, nilu Abuja lọjọru nigba ti awọn eeyan kan to n fẹhonu han yari kanlẹ pe awọn yoo sun ile itaja ShopRite to wa ladugbo naa.
 thomson gba 1906 ebun nobel ninu fisiksi ni 1906 fun iwari elektronu ati fun ise re lori igbasinu iseitanna ninu awon efuufu .
Ni bayii, yoo gberadi lati koju Petra Martic nilu California.
Bakan naa ni Woolsworth ṣe lọdun 2014.
Ninu ọrọ akọsọ Agbẹnusọ Ile Ìgbìmọ Aṣofin Ipinlẹ Eko, Aṣofin Mudashiru Ọbasa, ẹni ti igbakeji  Agbẹnusọ Ile naa, Aṣofin Sanni Eṣinlokun ṣoju fun, o ni niwọn ti ipinlẹ Eko ko fi ọrọ awọn ara ilu ṣere, eleyii ni ko ni jẹ ki awọn fi ọrọ ilera bayii falẹ, ti o fi ṣe pataki ki awọn ṣe atunṣe si ofin naa ti wọn gbe kalẹ ni ọdun 2015.
Ẹnikẹ́ni tí ó bá gbèjà rẹ̀, pípa ni a óo pa á kí ilẹ̀ tó mọ́.
''Bi wọn ko ba ni mo lu lukudi, wọn a ni mo ṣẹso, tabi ki wọn tiẹ sọ pe mo fi igbo pamọ sinu irinsẹ mi.
Ọjọ Iṣẹgun ọsẹ to n bọ lo yẹ ki Man City gbalejo ifẹsẹwọnsẹ ọhun tẹlẹ ki ajọ UEFA to wọgilee.
Oluwa mi, ranti pé o bi àwa iranṣẹ rẹ pé, ‘Ǹjẹ́ ẹ ní baba tabi arakunrin mìíràn?
Bàbá, iyá àti ọmọ ni wọn mọ si Idilé ni Òkè-òkun ṣùgbọ́n ni ilẹ̀ Yorùbá kò ri bẹ́ ẹ̀, nitori ẹbi Eg bàbá, ẹ̀gbọ́n àti àbúrò ẹni, ọmọ, ọkọ àti aya wọn ni a mọ̀ si Idilé.
O ni ẹẹkan lọsẹ nikan ni awọn ile ijọsin lanfani lati pe jọ pọ ti wn si lee ko isin pupọ jọ loojọ bi wọn ba ṣaa ti tẹle ofin aadọta olujọsin.
Bakan naa lo dupẹ lọwọ Buhari fun anfaani lati sin in pẹlu ipo tp yan si i.
Naijiria kun fun ọrọ pupọ pe ko yẹki  won
nígbà tí àwọn tí ń ṣọ́ ilé yóo máa gbọ̀n pẹ̀pẹ̀, tí ẹ̀yìn àwọn alágbára yóo tẹ̀, tí àwọn òòlọ̀ yóo dákẹ́ jẹ́ẹ́, nítorí pé wọn kò pọ̀ mọ́, tí àwọn tí ń wo ìta láti ojú fèrèsé yóo máa ríran bàìbàì; 
Adesina ni kin ni o tun ku ti awọn alatako Aarẹ Buhari fẹ sọ bayii, lẹyin ajọ WAEC ti safihan iwe ẹri ti wọn ni Buhari o ni.
Eeyan 40,532 ni apapọ ni arun naa ti fara kan labẹ ayẹwo lorilẹede Naijiria.
Idi ni pe ko si akọsilẹ to daju nipa igbe aye akọni obinrin naa.
" Ayinla Ọmọwura, orin èébú àti oríyìn lo fi di ọ̀rẹ́ àwọ̀n obìnrin Ẹrí rè é, Sanwo-Olu ṣèlérí lóòtó lórí súnkẹrẹ-fàkẹrẹ Apapa Gani Adams: Iléèṣẹ́ ọlọ́pàá ti kàn sí OPC lórí ètò ààbò Ènìyàn 721 fi ayédèrú ìwé ẹ̀rí gba iṣẹ́ ìjọba àpapọ̀ - ICPC Ọpọ eniyan lo gbagbọ pé awọn Aina maa n ni ìpinnu to ga ti ko rọrun fun ẹlomii lati yipada fun wọn.
Bí ọkunrin yìí kò bá wá láti ọ̀dọ̀ Ọlọrun, kì bá tí lè ṣe ohunkohun.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Coronavirus: Ǹjẹ́ àwọn dókítà tó ń tọ́jú eyín ń ṣisẹ́ lásìkò pàjáwìrì?
Bakan naa ni Dokita Obafemi Hamzat, tii se igbakeji Gomina ipinlẹ Eko, Oloye Adebayo Adelabu, Ọmọwe Onikepo Akande, ati adele giwa fasiti Ibadan, Ọjọgbọn Babatunde Ekanọla ko gbẹyin nibi eto idanilẹkọ naa.
Wọ́n gbé àpótí OLUWA sinu kẹ̀kẹ́ ẹrù náà, pẹlu àpótí tí wọ́n kó àwọn èkúté wúrà ati kókó ọlọ́yún wúrà náà sí.
Gbogbo ọjọ́ ayé ẹni tí a ni lára kún fún ìpọ́njú,ṣugbọn ojoojumọ ni ọdún fún ẹni tí inú rẹ̀ dùn.
Àwọn ohun tí ẹ̀ bá mójútó nìyí, láì gbàgbé ìdámẹ́wàá.
Orí yìí ní wọ́n ti wá mọ orúkọ ọmọge tí Akin Olúṣínà ra ọtí fún nígbà tí wọ́n ń lọ sí Ifẹ̀ tí a ti mẹ́nu bà ṣáájú.
Bakan naa lo kẹkọọ jade ni ile iwe giga akọṣẹmọṣẹ ti ilu Ibadan nibi to ti kẹkọọ gboye OND ninu imọ eto isuna ko to lọ si fasiti ilu Eko lati lọ kẹkọọ gboye ninu imọ Tiata.
 Ìgbà tí a gbé àwon òrò wònyí kúrò láàyè tí wón wà ní ( 66 ) lo sí iwájú ni a ní ( 63 ) .
”Bẹnaya bá pada lọ sọ ohun tí Joabu wí fún ọba.
Mo gbadun bi mo ṣe maa n pade eniyan, bi mo ṣe maa n mu ara wọn wa lọna tabi ko jẹ awọn lo mu ara temi wa lọna."
Àwọn ará South-Africa yarí nítorí torí gbọ̀ngàn kọ̀ ìgbéyàwó abo-sábo Mo kàn fẹ́ fi ọmọ tó sọnù gba owó lọ́wọ́ Sọtitobire ni - Afurasí 11.
“Ẹ kò gbọdọ̀ so àjàgà kan náà mọ́ akọ mààlúù ati kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ lọ́rùn, láti fi wọ́n ṣiṣẹ́ ninu oko.
Ẹsun ikowojẹ, nini apo ikowo si ni banki tẹni kan o mọ ati iwa jibiti ni wọn fi kan Maina Yoruba Culture: ọjọ́ méje ni wọ́n fí n rẹ ẹ̀kú Danafojura kó tó jáde Wọ́n ti ṣí ilé oúńjẹ oní ọgbọ̀n náírà (N30) ní Kano Ta ni Funmilayọ Ransome-Kuti?
Gba ìbéèrè yìí kí o je Ẹ̀bùn ránpé.
" Abike Dabiri fi kún pé ni kété ti àjàkálẹ̀ ààrùn Covid-19 bá ti kásẹ̀ nílẹ, ìjọba yóò ṣe àbẹ̀wò si ibẹ̀ láti le mọ bi ǹkan ṣe ń lọ.
Ọmọ orilẹede Mexico naa si lo gba ami ẹyẹ ọhun dani fun bi oṣu diẹ, nibi ija wọn to waye ni gbagede Diriyah Arena lorilẹede Saudi Arabia.
O ni ti oun naa ba n wo 'Okunnu' ninu ere, emi gan maa n rẹrin arin takiti, amọ Wale Akorede maa n tiju gan an ti ko baa tii ri ẹrọ kamẹra.
Ẹ̀rù àti oríkunkun ló mú kíjọba máa fi ọlọ́pàá, ológun halẹ̀ mọ́ aráàlú - Ṣoyinka Toyin Abraham kìí bá èmi náà yọ̀, ni kò jẹ́ kí ń gbé e lárugẹ fún ayọ̀ ọmọ - Lizzy Anjorin Iṣẹ́ ọpọlọ ló yẹ ká ṣe nínú tíátà, kìí ṣe àfihàn ara bíbó àbí ìhòòhò wa - Binta Mọgaji Ìdẹ̀ra dé, Gẹnẹrátọ̀ tó ń lo omi dé, a bọ́ lọ́wọ́ òkùnkùn SERAP ni ko yẹ ko si ọrọ a n ṣe ọrọ orukọ awọn akowolujẹ ni awo mọ, nitori o ti de gbangba kii ṣe agbekọrọ yara gbọ mọ.
Ó yẹ kí àwa tí a jẹ́ alágbára ninu igbagbọ máa fara da àwọn nǹkan tí àwọn tí igbagbọ wọn kò tíì fẹsẹ̀ múlẹ̀ bá ń ṣiyèméjì lé lórí.
Bola Tinubu: Àwọn màlúù dà níbí tí wọ́n ti pa ọmọ Fasoranti?
Ẹ̀yin tí ẹ yó nisinsinyii, ẹ gbé,nítorí ebi ń bọ̀ wá pa yín.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ibadan Death: Àwọn ará àdúgbò Akinyele ké sita lórí iṣékúpani tó ń wáyé ní ìlú Ibadan.
N óo fún un ní ìsinmi kúrò lọ́wọ́ gbogbo àwọn ọ̀tá rẹ̀.
Ajafẹto Awosanya ni Linda ti padanu ẹjẹ de bi pe, wọn ko le doola ẹmi rẹ.
Adura wa ni pe ki Olorun dari ese ati awon a-se-deede re jin in, ki Olorun si fun un ni Al-janah Firdaos.
Fi wúrà ṣe ìgbátí yí gbogbo etí rẹ̀ po.
Traffic gridlock: Sanwo-Olu fẹ́ sún ìrìnnà ọkọ̀ àjàgbé kúrò lọ́sàn sí òru l'Eko
Wọn fikun pe ajọ eleto idibo, INEC gbọdọ sa ipa wọn lati ri wi pe idibo ti ko ni magomago ninu lo waye ni ipinlẹ Edo ati Ondo.
Amọṣa, igbesẹ ati kọ ipakọ si abẹrẹ ajẹsara lewu fun awọn to ba ni arun yii ati awujọ wọn.
O ní ọpọlọpọ òṣìṣẹ́: àwọn agbẹ́kùúta, àwọn ọ̀mọ̀lé, àwọn gbẹ́nàgbẹ́nà, ati oríṣìíríṣìí àwọn oníṣẹ́ ọnà tí kò lóǹkà, 
Nitori eyi ijọba apapọ wa ni awọn ti tọrọ aforiji lọwọ ijọba orilẹede India fun 'iwa aṣemaṣe'ti El-Zakzaky hu Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!"
Iléeṣẹ́ ọlọ́pàá sọ afurasí ọlọ́pàá tó yìnbọn fún ọ̀dọ́kùnrin tó fún èèyàn lóyún s'átìmọ́lé
Sheffield faṣọ iyì ya mọ́ Chelsea lára lọ́nà ìrìnàjò sí Champions League Àlùbami ní Kamuru na Jorge Masvidal láti dí Àmí Ẹ̀yẹ UFC Welterweight Champion rẹ mú!
Lẹyin to pada wale, Folasade bẹrẹ iṣẹ ni ile ẹkọ ẹkọṣẹ imọ isegun ni fasiti Eko, to si ni igbega de ipo ọga agba ibudo naa.
Deborah Adebola Fasoyin: Èmi kọ́ ló gbé orin ọdún ń lọ sópin kalẹ̀, CAC ló ni í ni mó n ṣe àkójọ orin- Fasoyin
OLUWA, kọ́ mi ní ọ̀nà rẹ,kí n lè máa rìn ninu òtítọ́ rẹ;kí n lè pa ọkàn pọ̀ láti máa bẹ̀rù orúkọ rẹ.
Bí ọ̀rọ̀ ara mi ti wá rí nìyí: ní ìdà kinni, mò ń tẹ̀lé ìlànà òfin Ọlọrun ninu àwọn èrò ọkàn mi: ní ìdà keji ẹ̀wẹ̀, èmi yìí kan náà, gẹ́gẹ́ bí ẹlẹ́ran-ara, mo tún ń tọ ọ̀nà ẹ̀ṣẹ̀.
Ìpín ti Nafutali yóo wà lẹ́gbẹ̀ẹ́ ti Aṣeri, láti ìlà oòrùn títí dé ìwọ̀ oòrùn.
Iléèṣẹ́ ọlọ́pàá: ìwádìí bẹ́rẹ́ lórí ikú ọdaran tó tojú orun dójú ikú'
N kò ní ṣàánú àwọn ọmọ rẹ̀, nítorí ọmọ àgbèrè ni wọ́n.
Kamilu wá rọ awon eeyan tó ń sọ ahesọ ọ̀rọ̀ kiri pé òun ni ìyàwó mẹrin, pé kí wọn dẹkun sísọ ohun tí ojú wọn ko tó nítorí èyí kò rí bẹ́ẹ̀ rárá, ìyàwó kan soso ni òun ni.
O ti fi omijé bọ́ wọn bí oúnjẹ,o sì ti fún wọn ní omijé mu ní àmuyó.
Ẹ kò tọ́jú àwọn tí wọn kò lágbára, ẹ kò tọ́jú àwọn tí ń ṣàìsàn, ẹ kò tọ́jú ẹsẹ̀ àwọn tí wọn dá lẹ́sẹ̀, ẹ kò mú àwọn tí wọn ń ṣáko lọ pada wálé; ẹ kò sì wá àwọn tí wọ́n sọnù.
Ayé ati ìfẹ́kúfẹ̀ẹ́ ń kọjá lọ, ṣugbọn ẹni tí ó bá ń ṣe ìfẹ́ Ọlọrun yóo wà títí lae.
 Ogbẹni Salulahu Salau, ti o jẹ gbajumo oniṣe epo puoa ni ilu Mamu Ijẹbu rọ ijọba lati pese ona orisun omi bii ọpọ kanga-dẹrọ, omi ẹrọ ati awọn kanga igbalode miiran ti yoo mu iṣẹ wọn rọrun paapaa nigba ẹrun ti omi maa n wọn gogo.
Ìyàwó mi ló ṣì ń dáná, bu oúnjẹ mi, gé èékáná fún mi - Pásítọ̀ Adeboye Ọkùnrin kan fipá bámi lòpọ̀ lọ́mọ ọdún mọ́kàndínlógún- Funke Oshonaike Ààrùn Coronavirus tún ti ran ènìyàn 595 l'órílẹ̀-èdè Nàìjíríà Ẹ wo ọ̀nà tí ìjọba Nàìjíríà fẹ́ gbà san owó àwọn olùkọ́ iléèwé aládàni tí kò rówó oṣù gbà Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Ẹlẹ́ẹ̀kẹjọ t'óyún máà bàjẹ́ lára mi ni mo tó rí àànú gbà' Pupọ lara owo naa lo wa fun ṣiṣeto amayedẹrun fun awọn araalu ṣugbọn to jẹ pe titi di asiko yii, iye ohun taraalu fi oju ri ko tii lee dọgba pẹlu owo naa.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Alaafin: Olori Aanu Adeyemi ṣàlàyé ìdí tó ṣe gẹ́ Oba Lamidi Adeyemi ti ìlú Oyo Mama Risikat ni lootọ ko wu oun pe ki Risikat ni ọkọ miiran nigba ti ọkọ akọkọ rẹ si wa laaye, ṣugbọn ibanujẹ lo maa n jẹ f'oun pe Wasiu ko tọju Risikat.
Ó sọ fún mi pé, “Kọ ọ́ sílẹ̀: àwọn tí a pè sí àsè igbeyawo ti Ọ̀dọ́ Aguntan náà ṣe oríire.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Kàyééfì Promo: Ìyá, ọmọ tuntun àti olubi ló wà níbùdó ìgbókùsí, àmọ́ òkú ọmọ di àwátì Oríṣun àwòrán, @noaoyodirect Niwọn igba to jẹ pe arise ni arika, arika si ni baba iregun, ohun ta ba se loni, ọrọ itan ni yoo da bo ba dọla, asia ti Taiwo Akinkunmi se lọdun gbọọrọ sẹyin, naa ni orilẹede Naijiria n lo titi di oni.
Ọjọ Aiku to kọja ni fidio kan gba ori ẹrọ ayelujara, eyi to ṣafihan gomina Abdullahi Umar Ganduje to n gba 'riba lọwọ agbaṣẹṣe kan.
“Ẹni tí kò bá sí lẹ́yìn mi, olúwarẹ̀ lòdì sí mi ni, ẹni tí kò bá ti bá mi kó nǹkan jọ, a jẹ́ pé títú ni ó ń tú wọn ká.
 INEC sun siwaju ti o fa orisirisi ikunsunu, gbonmi si omi o to laarin awon egbe oselu, awon omo orile-ede Naijiria jake-jado lo ti de  wẹrẹ bayii.
" Wíwó laá wó àwọn ilé ìkẹ́rùpamọ̀sí tó wà láwọn ibodè wa Ṣugbọn o ni gbogbo asọtẹlẹ ti oun ma n sọ maa wa ni akọsilẹ.
Lóòótọ́ ìwọ ti ń bá ènìyàn pàdé ìwwọ sì ń sọ wọ́n di èrò inú ìṣaasùn ọbẹ̀.
ilu Eko, Oba Rilwan Akiolu; Alake ile Egba, Oba Adedotun Gbadebo; ati awon Ori
Àkọlé àwòrán, Fọfọ̀ ni ẹnu ọna ẹka ijọ COZA to wa ni ilu Eko kun fun awọn to n ṣewọde pe ki Pasitọ̀ Fatoyinbo fi ipo rẹ silẹ Àkọlé àwòrán, Ọ̀kan lara awọn akọle yii n sọ pe didaabo bo ẹni to fi ipa banilopọ kii ṣe iwa Kristi Àkọlé àwòrán, Pasitọ kii ṣe Ọlọrun; Ọlọrun le dariji ọ l'ẹwọn Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí MI ní 'Òjíṣẹ́ Satani' ni pásítọ̀ kan; ni ìjọ Satani bá da lóhùn30 Òkùdu 2019 Biodun Fatoyinbo: Mò ń gbé Busola Dakolo lọ ilé ẹjọ́29 Òkùdu 2019 BBC News, Yorùbá Ìdí tí ẹ fi le è nígbàagbọ́ nínú ìròyìn BBC Ìlànà Lílò Nípa BBC Òfin Àṣírí Cookies Kàn sí.
Nítorí náà, àwọn ará Siria kò wá ran àwọn ará Amoni lọ́wọ́ mọ́.
 wọ ́ n fi ìdí rẹ ̀ múlẹ ̀ ní ilẹ ̀ taiwan , níbi tí wọ ́ n tí ṣètò gbígba abẹ ́ rẹ ́ àjẹsára jẹ ̀ dọ ̀ jẹ ̀ dọ ̀ b kárí gbogbio àgbáyé ní odún 1984 wípé gbígba abẹ ́ rẹ ́ àjẹsára náà má a ń dín ìṣẹ ̀ lẹ ̀ àrùn tí wọ ́ n ń pè ní hepatocellular carcinoma kù láàárìn àwon ọmọdé .
''Emi Sẹnẹtọ Dino Melaye mo sọ nitagbangba pe lẹyin ọpọ isẹlẹ ati awọn ohun toju wa ti ri bayi, mo fẹ sọ pe nigba kan loju mi di, ṣugbọn bayi o ti la kedere'' Bẹẹ naa ni Melaye gbosuba kare fun Aarẹ Jonathan fun igbesẹ pipe aarẹ Buhari lori ago lati gba pe oun padanu ibo ọdun 2015.
Èmi Paulu, kì í ṣe eniyan ni ó pè mí láti jẹ́ aposteli, n kò sì ti ọ̀dọ̀ eniyan gba ìpè, Jesu Kristi ati Ọlọrun Baba, tí ó jí Jesu dìde, ni ó pè mí.
nínú àwọn ìtán òkè yí àwọn méjì ló sọ bí a ṣe sọ ìlú náà ní Ìjẹ ̀ bú ṣùgbọ ́ n ó dàbí ẹni pé a lè gba ti irúfé èyí tí ó sọ pé Ìjẹ ̀ bú - Òde ni Ọba Ìjẹ ̀ bú jẹ ̀ ṣà ti mú orúkọ náà wá ní eléyìí ti ó bójú mu díẹ ̀ .
0 36 Orilẹede Timor-Laste 0 0.
Agba ọjẹ nínú isẹ tíátà náà tún ṣiṣọ lójú rẹ pé, olóògbé Ojo Ladipo, ti ọpọ èèyàn mọ si bàbá Mero, ní ọga to kọ òun ni iṣẹ tíátà, òun si lo sọ òun ni inagijẹ Ọga Bello nínú eré tíátà, láti ọdún 1973.
Nígbà tí ẹ bá dá a sílẹ̀ pé kí ó máa lọ, ẹ kò gbọdọ̀ jẹ́ kí ó lọ ní ọwọ́ òfo.
Akonimoogba agba iko agbaboolu Super Eagles, Gernot Rohr ti mu agbaboolu meji lara iko CHAN Eagles lati kopa ninu idije boolu agbaye to n bo lona.
Triliọnu mọkanla yoo kọ aadọta afara keji Niger (Second Niger Bridge).
‘ASUU da ìyanṣẹ́lódì dúró' Ìyansẹ́lódì ẹgbẹ́ olùkọ́ fásitì ASUU ń tẹ̀síwájú Njẹ́ lóòtọ́ ni pé ASUU fẹ́ bẹ̀rẹ̀ ìyanṣẹ́lódì oṣù mẹ́ta mì í?
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Senator Ishaku Abbo: ìdí rèé tí mò fi fi kọ̀wé fi PDP sílẹ̀ darapọ̀ mọ́ ẹgbẹ́ òṣèlú APC 25 Bélú 2020 Oríṣun àwòrán, senatorishakuabbo Sẹnẹtọ Elisha Abbo, ti wọn fi ẹsun kan pe o lu obinrin kan nile itaja eroja ibalopo nilu Abuja ti fi ẹgbẹ oṣelu PDP silẹ.
Roger Federer sayeye ipada sipo kinni re lagbaye pelu gbigba ife-eye Rotterdam Open lojo Aiku(Sunday), eyi ti o je ife-eye metadinlogorun lapapo ti o ti gba bayi.
“Áà, Ọlọrun wa, kí ni a tún lè wí lẹ́yìn èyí?
afẹhonuhan ka, sugbọn ki wọn maa lo ohun eelo afẹfẹ taju-taju, ki wọn ma
Alákọ̀wé Yorùbá, ẹni Olú Ọ̀run dá lọ́lá, mo dé ibi igbó nì tí wọ́n ń pè ní Igbó Funfun.
Oríṣun àwòrán, Twitter Àkọlé àwòrán, Adebayo Shittu wà lára awọn to fẹ́ díje fun ipò gómìnà ìpínlẹ̀ Ọyọ A gbọ pe ẹgbẹ oselu APC ni Shittu ko wẹ yan kain-kain lati kopa ninu idibo abẹle fawọn oludije fun ipo gomina naa, nitori pe ko seto isinru ilu lẹyin to jade nile ẹkọ fasiti, gẹgẹ bi ofin ilẹ wa se laa kalẹ.
Ọjọ ori Bi eeyan ṣe n dagba si irinkerindo inu maa n dinku, ifun lee fun pọ eyi to le maa fa idiwọ fun igbẹ lati kọja wọọrọwọ.
Oríṣun àwòrán, Reuters Iroyin to tẹ wa lọwọ lati orilẹede China fidi rẹ mulẹ pe, awọn dokita onimọ iṣegun ti dan oogun naa wo lara awọn to laarun coronavirus nile iwosan mẹwaa, wọn si ri pe o ṣiṣẹ daadaa.
N óo la ọ̀nà ninu aginjù,n óo sì mú kí omi máa ṣàn ninu aṣálẹ̀.
Ẹ ̀ gbá òkè-ọnà ló tẹ lẹ ́ Ẹ ̀ gbá aláké .
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ẹlẹ́sìn Aghoris: Wọ́n ń jẹ ènìyàn, wọn a sì fi orí rẹ̀ mumi 15 Sẹ́rẹ́ 2019 Oríṣun àwòrán, EPA Àkọlé àwòrán, Awọn ẹlẹsin Aghoris ma n jade lasiko ọdun Kunbh Mela Ọ̀pọ̀lọpọ̀ ènìyàn ló ń tẹ̀lẹ́ àwọn ọkùnrin tí wọ́n bá òkú lòpò yíí, tí wọ́n sì ń jẹ ẹran ara ènìyàn.
Ọjọ́ kẹrìndínlógún, oṣù Keje, ni ayẹyẹ ìgbéyàwó nàá wáyé, ṣùgbọ́n ọjọ kejì ní ìròyìn nàá tó jáde.
Fake Lawyer: ₦300,000 ló gbà lọ́wọ́ obìnrin kan, tó sì fẹsẹ̀ fẹ
O ni ijọba ipinlẹ naa ti n fọnrere idaabobo to peye fun awọn smọde ati awọn obinrin nitori naa gbogbo igbesẹ to ba yẹ naa ni wọn yoo gbe lati fi idi eyi mulẹ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Fasoranti: Osinbajo ìṣẹ̀lẹ̀ ààbò tó mẹ́hẹ kò mọ níbì kan, káàkiri Nàìjíríà ni 14 Agẹmo 2019 Àkọlé àwòrán, O ni ijọba n sa ipa rẹ lati da abo to jọju pada sorilẹede Naijiria Lẹyin ti iroyin iku ọmọ rẹ, Funkẹ aya Olakunrin lu si eti araye ni ọjọ Ẹti, ẹsẹ ko gbero ni ile agba ilẹ Yoruba, Alagba Rueben Faṣọranti lati ba a kẹdun.
 Àwọn ọlọ ́ dún wọǹyí yìò sì máa fún àwọn asunrárà náà lẹ ́ bùn .
Báwó ni òògùn dexamethasone ṣe ń ṣiṣẹ́ lára Wo ìdí tí Risikat Moromoke Azeez n'Ilorin fi ní Blue Eyes"" - Dókítà Asojú ìjọba orílẹ̀-èdè Lebanon ti kọ̀wé fipò silẹ̀ nítorí ìbágbàmù tó gbẹ̀mi ènìyàn 200 Àjọ JAMB kéde ìlànà ìgbà ni wọlé tuntun fún àwọn ilé ẹ̀kọ́ gíga Link Amọ, Ajọ Eleto Ilera lagbaye, WHO ni oogun 'Sputnik V' ko i tii si lara awọn oogun arun Coronavirus mẹfa lagbaye, ti wọn ti kọja ipele ikẹta ayẹwo rẹ lara awọn eniyan."
Omotara: Mo kábámọ̀ ìwà tí mo hù sí ọmọ alágbe, mo wá a títí ṣùgbọ́n mi ò mọ ibi tó wà
Ninu ọrọ rẹ, Ahmed wa sapejuwe ileẹkọ Roemichs gẹgẹ bii ile ẹkọ to wa lara awọn ibudo ikẹkọọ to ni akọsilẹ eto ẹkọ to pegedejulọ.
Njẹ a lee pe e ni ija ẹṣẹ kikan to dun julọ ninu itan bi?
Ni kete ti o pari ipade pẹlu awọn oniroyin yii ni o pada laarin ọpọ ọkọ, awọn janduku ọmọ ẹgbẹ ọlọkọ ero NURTW ati awọn oṣiṣẹ alaabo lọ si ile aṣofin naa nibi ti oun ati awọn aṣofin mẹwa ti wọn fẹ tirẹ ni ile naa tun ti gbe ijoko mira kalẹ ti wọn si yọ paṣẹ lọ rọkun nile fun awọn aṣofin marundinlogun ti wọn ni wọn fi gbogbo ara kopa ninu igbesẹ lati yọọ nipo.
Pa àwọn òfin mi mọ́ nínú ohun gbogbo.
eniyan maa n gbe ti wọn ko ba faramọ atẹjade ti Ajọ INEC fi sita lasiko ti wọn
Nǹkan bíi ọ̀kẹ́ meji (40,000) ọkunrin tí wọ́n ti múra ogun, ni wọ́n rékọjá níwájú OLUWA lọ sí pẹ̀tẹ́lẹ̀ Jẹriko.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Anthony Joshua vs Andy Ruiz: Págà!
Wọnyi ni awọn ile iṣẹ ti gomina Makinde ni ko to di gomina ipinlẹ Oyo- Makon Engineering & Technical Services Limited, Energy Traders & Technical Services Limited, Makon Oil & Gas Limited, Makon Group Limited, Makon Construction Limited & Makon Power System Limited ati bẹẹ bẹẹ lọ.
Iroyin ti kọkọ gbale kan wipe awọn darandaran ni wọn pa ọlọpa naa.
Oríṣun àwòrán, @MrKunleRoy_ Dokita Dipo Awojide ni tirẹ ni pẹlu ọrọ ti Obasanjo sọ, sẹ lo dabi ẹni pe baba ko ni ẹmi idariji latari ohun to ti ṣelẹ sẹyin laarin rẹ ati Kashamu.
Àkọlé àwòrán, Ajọdun ilu nilẹ Afirika Bakan naa ni afihan ijo ati aṣọ oriṣiriṣi ẹya kaakiri Naijiria maa n waye.
Minimum wage: Ẹgbẹ́ òṣìṣẹ́ àti ìjọba àpapọ̀ fẹnukò lórí àbá òfin ẹ̀kúnwó oṣù
Bí oúnjẹ ti parí ni ó dìde tíi ó gbé àpò ọdẹ rẹ̀ kọ́ apá o sì gbé àkọ̀ àdá kọ́ èjìká pẹ̀lúu ìbọn tí o dúdú tí ó sì kún fún ẹ̀jẹ̀ gbogbo.
 Aṣofin Eṣinlokun wa fi oriki Ọba kasẹ ọrọ rẹ nilẹ.
Yinka Odumakin ni bíí ìfira-ẹni-wọ́lẹ̀ ni ti àwọn ba péju sibi ìpàdé náà ati pe awọn ẹgbẹ agba iran bii Ohaneze naa ti ni awọn ko ni kopa.
Nígbà tí Benhadadi gbọ́ iṣẹ́ yìí níbi tí ó ti ń mu ọtí pẹlu àwọn ọba yòókù ninu àgọ́, ó pàṣẹ fún àwọn eniyan rẹ̀ pé kí wọ́n lọ múra ogun.
Àwọn tí wọn ń kú lọ ń kérora ní ìgboro,àwọn tí a pa lára ń ké fún ìrànlọ́wọ́,ṣugbọn Ọlọrun kò fetísí adura wọn.
Awon olori orile-ede metalelaadota naa peju si aafin Buckingham lati pinnu lori eni ti yo gba ipo naa.
Bẹẹ ba si gbagbe, iroyin naa lo fẹsun kan Olori Badrat Olaitan Ajọke Adeyemi pe o n ni ifẹ ikọkọ pẹlu ọba olorin fuji kan, Alhaji Wasiu Ayinde Kwam 1.
com Àkọlé àwòrán, Ayipada ti de ba inawo ṣiṣe bayii Wọn yoo si maa bu u fun awọn to ba nifẹ si iyan ni gbigbona.
Ọkan pataki lara àwọn koko ti BBC yan nàná pẹlu wọn ni ohun ti onikaluku ni lọkan fun gbigbogun ti ìwa jẹgudujẹra nipinlẹ Ọṣun.
“Mo ha gbọdọ̀ yọwọ́ lọ́rọ̀ yín ẹ̀yin Efuraimu?
" Igbakeji aarẹ ana ọhun ni, bo tilẹ jẹ pe Naijiria n dojukjọ ọpọlọpọ iṣoro, ọla yoo dara fun orilẹ-ede yi.
Sugbọn lẹyin atotonu, ijọba pada sọwipe iye awọn ọmọ to sọnu ni ọgọrun ati mẹwa.
Ọdun 2018 ni wọn bẹrẹ agbo ijo awọn obinrin nikan naa, ti erongba idasilẹ rẹ si kọja jijẹ igbadun alẹ ọjọ kan.
Inú yàrá kan naa ni Paul àti bàbá rẹ̀ jọ wà l'ọ́gbà ẹ̀wọ̀n, pẹ̀lú àwọn ẹlẹ́wọ̀n mi i tó n retí ìdájọ́ ikú.
Ọọni Adeyẹye Ogunwusi sọrọ yii lasiko ti Emir ilu Kano, Alhaji Ado Bayero bẹ ẹ wo ni aafin rẹ nilu Ile Ifẹ.
32 Àti, kíyèsíi, ẹ̀yin ni awọn náà tí a yàn láti ọwọ́ mi lati yan àwọn àlùfáà àti àwọn olùkọ́ni; lati kéde ìhìnrere mi, gẹ́gẹ́bí agbára Ẹ̀mí Mímọ́ tí ó wà nínú yin, àti gẹ́gẹ́bí àwọn ìpè àti àwọn ẹ̀bùn Ọlọ́run sí àwọn ènìyàn;
Amọ ṣa, o rọ ẹnikẹni to ba ni iroyin nipa awọn sogundogoji yi lati fi ṣọwọ si ajọ naa.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù The Polytechnic Ibadan: Ẹ̀rọ abẹ́lé tó ń fọ ọwọ́ àti ‘Ventilator’ ló ṣẹ̀ṣẹ̀ gbé jáde Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ The Polytechnic Ibadan: Ẹ̀rọ abẹ́lé tó ń fọ ọwọ́ àti ‘Ventilator’ ló ṣẹ̀ṣẹ̀ gbé jáde 16 Ògún 2020 Oriire ti de fun orilẹede Naijiria lati ipasẹ agbekalẹ erọ tuntun meji ti ile ẹkọ gbogbonse Poly Ibadan gbe jade.
Rárá o, ẹ kò ní lọ láìjìyà nítorí pé mo ti pàṣẹ pé kí gbogbo àwọn tí wọn ń gbé orí ilẹ̀ ayé kú ikú idà, èmi OLUWA àwọn ọmọ ogun ni mo sọ bẹ́ẹ̀.
O ni Wọn ko tii fun mi ni iwe ifitonileti kankan o, mi o tii gba iwe kankan."
Liliya ni botilẹ jẹ́ pe o nira láti gba bí òun ṣe ri síbẹ̀ òun ti ni ìdunu báyìí.
N óo sọ àwọn ọmọ rẹ di pupọ, n óo sì sọ ọ́ di ọpọlọpọ orílẹ̀ èdè, ọpọlọpọ ọba ni yóo sì ti ara rẹ jáde.
Ọga ọlọpaa Yakubu Sabo to jẹ alukoro ọlọpaa ni Kaduna ṣalaye pe ọlọpaa ko pa ẹnikẹni.
Kò gba àwọn alufaa náà láàyè láti ṣiṣẹ́ ninu ilé OLUWA, ṣugbọn wọ́n lè jẹ ninu àkàrà tí wọn kò fi ìwúkàrà ṣe, tí ó jẹ́ ti àwọn alufaa ẹlẹgbẹ́ wọn.
Amọ ṣa, CAF ti fun wọn ni anfaani miiran lati tun ọmọluabi wọn ṣe pẹlu gbigba alejo idije lọdun meji si isinsinyi.
Victor Agunbiade ni ojú àlá ni Ọlọrun ti yan iṣẹ́ ọmọ ogun ojú omi fún òun ní America
Ìdí tí mo ṣì fi sọ bẹẹ ni lati ṣe ìwúrí fún àwọn ọ́dọ́, ki wọ́n baa le ṣe dáadáa níbi ẹ̀kọ́ wọn'' Ó tèsíwájú pé nigba ti òun wa ni ilé ẹ̀kọ́ ìmọ̀ òfin l'ọ́dún 1979 ''èmi ni mo tayọ láàrin àwọn tí a jọ wà ní kíláàsì kan na.
"Aṣọ otutu ti aṣaaju akọrin awọn ọmọ ẹgbẹ Nirvana, Kurt Cobain wọ to jẹ aṣọ otutu alawọ eweko to di akunlẹbọ yii lo fi ṣere ""Unplugged"" MTV lọdun 1993."
Onidajọ Falola dajọ pe ki wọn o yẹgi fun awọn mẹtẹẹta titi ti ẹmi yoo fi bọ l'ẹnu wọn, to si tun paṣẹ pe ki awọn ibọn ti ileeṣẹ ọlọpaa gba lọwọ wọn o di ti ileeṣẹ ọlọpaa, ki owo ti wọn gba lọwọ wọn o si di ti ijọba ipinlẹ Ọṣun.
Nítorí Ọlọrun rí ẹ̀ṣẹ̀ kà sí wọn lọ́rùn ni ó fi sọ pé,“Oluwa wí pé:Ọjọ́ ń bọ̀ tí èmi yóo bá ilé Israẹli ati ilé Juda dá majẹmu titun.
INEC: Kò sí ìká tí o kò lè fí dìbò, ṣáà tí tẹ̀ ẹ́ sójú ẹ dáadáa Àwọn ohùn tó ṣé kókó tó yẹ ká mọ ṣáájú ìdìbò 2019 Ǹjẹ́ o mọ̀ pé ọdọ 43m ló wà lára olùdìbò?
Wọ́n pada wá jábọ̀ fún Eliṣa ní Jẹriko, ó sì wí fún wọn pé, “Ṣebí mo ti sọ fun yín pé kí ẹ má lọ?
b ) ni ó pa àwọn ẹ ̀ gbọ ́ n rẹ .
Nítorí o kò sọ ohun tí ó tọ́ nípa mi gẹ́gẹ́ bí Jobu iranṣẹ mi ti ṣe.
Olùkọ́ fásitì méjì ń bèèrè ìbálòpọ̀ lọ́wọ́ akẹ́kọ̀ọ́ fún máákì Wo ìdí to fi gbọdọ̀ yàgò fún Bobrisky, akọ tó ń ṣe bíi abo Músò!
'Rọ́bọ́ọ̀tì ni yóò máa yẹ̀ yìn wò kẹ́ẹ tó rìnrìnàjò òfurufú ní Nàìjíríà' Peter Okoye, ìyàwó àti ọmọ lùgbàdì ààrùn Coronavirus Lọsẹ to kọja, iyawo rẹ ti kun awọn ẹlẹri to si sọ ohun to mọ, bakan naa ni awọn eeyan ogun mii naa ti n jẹri ohun ti wọn mọ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Awọn eni jankanjankan ti lu wa lontẹ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Awọn eni jankanjankan ti lu wa lontẹ 19 Èrèlè 2018 Awọn eni jankanjankan ti lu wa lontẹ.
Mi ò mọ̀ nípa àwọn tọ́ọ̀gì tó da ìwọ́de EndSARS Alausa rú, mo ṣì wà lẹ́yìn yín digbí!
Ajakale àrùn náà sì lọ wà ní àkọsílẹ̀ pé ó burú julọ nítorí iye èèyàn tó pa.
Toma sọ pe ọlọrun ni ayaworan àkọkọ àti pe yiya aworan ti ran oun lọwọ láti fi èrò ìnu oun han ní ọpọ igba.
Nibi ti o ti n sa asala fun ẹmi rẹ lo ti pade baba naa ti o si ṣeku pa.
Botilẹjẹ wi pe ẹgbẹrun mẹtadinlọgbọn ni igbimọ naa gba ijọba niyanju lati maa san, ọgbọn ẹgbẹrun Naira ni awọn aṣofin fi ọwọ si.
igbese yii lasiko ti ile ise asobode ekun ohun se abewo si ile-ise  gomina ipinle Oyo, onimo ero Seyi Makinde ni
Bí mo ti ń sọ̀rọ̀ lọ́wọ́lọ́wọ́ yìí, gbogbo wọn wà níbi tí wọ́n ti ń jẹ, tí wọn ń mu, tí wọn ń pariwo pé, ‘Kí Adonija ọba kí ó pẹ́.
Òun ni ẹni tí ó lè gba ẹ̀mí là, tí ó sì lè pa ẹ̀mí run; Ṣugbọn ìwọ, ta ni ọ́ tí o fi ń dá ẹnìkejì rẹ lẹ́jọ́?
Ajọ naa sọ pe, awọn ijọba ibilẹ mejilelọgọrun ni ipinlẹ mejidinlọgbọn lo wa ninu ewu omiyale lọdun yi.
Ìyanṣẹ́lódì òṣìṣẹ́ ilé aṣòfin bẹ̀rẹ̀ ní pẹrẹwu nílé aṣòfin Nàìjíríà Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Tayọ̀tayọ̀ ni mó fẹ́ ṣiṣẹ́ pẹ̀lú INEC ki ìdìbò 2019 lé dára' Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Alápinni: Kò sí ẹni to fẹ́ kọ́kọ́ kọ́ iṣẹ́ òṣèré bíi ti àtẹ̀yìnwá Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Iroyin naa ni ko din ni eniyan mẹẹdogun lapapọ to fara pa ati ti wọn ba iṣẹlẹ naa rin.
Nibi apero ti awọn gomina ipinlẹ Yoruba pe ni Ibadan ni wọn ti fẹnuko pe nini awọn agbofinro ipinlẹ ti ṣe pataki lasiko yii.
Akéde ṣe ikilọ̀ pé ẹni ti ó bá jẹ Igún, ikùn rẹ yio wu titi yio fi kú ni.
Bakan naa, ni gbogbo awon ori ade ati odo to peju nibi
Oludije ẹgbẹ oṣelu PDP, Sẹnetọ Ademọla Adeleke lo pe ẹjọ niwaju igbimọ naa lati fi tako esi ibo ti ajọ INEC kede pe oludije ẹgbẹ oṣelu APC, Gboyega Oyetọla, lo jawe olubori ninu idibo naa.
Ó kúrò níbẹ̀ lọ sí Penueli, ó sọ ohun kan náà fún wọn, ṣugbọn irú èsì tí àwọn ará Sukotu fún un ni àwọn ará Penueli náà fún un.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ife Ẹ̀yẹ Àgbáyé kó gbogbo ẹrù rẹ̀ lọ sí France!
Nigeria road accident record in 2020: Èèyàn 1,076ni ìjàmbá mọ́tò ti sọ di olóògbé láti oṣù mẹ́ta sẹ́yìn ní Nàìjíríà- FRSC
N óo fi iṣan bò yín lára; lẹ́yìn náà n óo fi ara ẹran bò yín, n óo sì da awọ bò yín lára.
Mo ṣílẹ̀kùn fún olùfẹ́ mi,ṣugbọn ó ti yipada, ó ti lọ.
“Ninu ogún tìrẹ tí ó bá kàn ọ́ ninu ilẹ̀ tí OLUWA Ọlọrun yín fun yín láti gbà, o kò gbọdọ̀ sún ohun tí àwọn baba ńlá rẹ bá fi pààlà ilẹ̀.
"Mi o mọ nkankan nipa ọrọ SARS ni gbogbo asiko ti mo ti lo ni Naijiria, nitori naa nigba ti ifẹhonuhan naa bẹrẹ, mo ro pe ọrọ ajakalẹ aarun SARS ni, lọjọ kan lẹyin ti mo ṣe igbaradi tan , ara ile mi kan pe iyẹn ki awọn soja to lọ yinbọn ni Lekki, bi wakati marun si igba ti wọn yinbọ ni Lekki lo salaye nkan to n ṣẹlẹ gan fun mi, O ni awon eniyan Naijiria fẹran mi, wọn si fẹ mọ iha ti mo kọ si ọrọ naa.
Ó ṣe ọgbà yí i ká; ó wa ilẹ̀ ìfúntí sibẹ; ó kọ́ ilé-ìṣọ́ sí i; ó bá fi í lé àwọn alágbàro lọ́wọ́, ó lọ sí ìdálẹ̀.
Ninu abajade iwadi rẹ kan to gbe jade lopin ọsẹ, ajọ naa n fi ẹsun kan awọn ileesẹ apọnpo rọbi Shell ati Eni pe aibikita wọn lo sokunfa bi epo rọbi se n fọnka si ayika lẹkun naa eleyi to ti di wahala ibajẹ ayika ati agbegbe nibẹ.
Ẹgbẹ ololufẹ ọkunrin s'ọkunrin fọwọ si oludije ipo aarẹ Kinni iroyin naa?
osise,yala ni ipinle tabi  ijoba apapo.
Òpó marun-un ni wọ́n ṣe fún àwọn aṣọ títa náà, wọ́n sì ṣe ìkọ́ sí ọ̀kọ̀ọ̀kan wọn.
Nígbà tí wọ́n ṣe ìlara sí Mose ninu ibùdó,ati sí Aaroni, ẹni mímọ́ OLÚWA.
Ó fi ranṣẹ sí àwọn tí wọ́n wà ní Bẹtẹli, ati àwọn tí wọ́n wà ní Ramoti ti Nẹgẹbu, ati Jatiri; 
Bí ó bá tún jẹ jáde lára ẹ̀wù, tabi lára aṣọ, tabi ohun èlò aláwọ náà, a jẹ́ pé ó bẹ̀rẹ̀ sí tàn káàkiri nìyí, jíjó ni kí ó jó ohun èlò náà níná.
Lara awon ti o kopa ninu ipade apero kẹ́rìnlélógójì ajo ECOWAS ni: aare orile-ede Naijiria, Muhammadu Buhari,  aare ile Burkina Faso, Roch Kabore, aare Côte d’Ivoire, Alassane Ouattara, aare ile Ghana, Nana Akufo-Addo, aare orile-ede Guinea, Alpha Conde, aare ile Guinea Bissau José Mário Vaz abbl.
Ọjọ kinni, oṣu Kẹjọ si ọjọ keje ni wọn ya sọtọ lati polongo pe ki awọn obinrin maa fun awọn ọmọ wọn lọyan, o kere tan, oṣu mẹfa.
Ìbá ṣe pé ènìyàn ń san owó fún ìmọ̀ràn ni, òmíràn ìbá ju ẹgbẹ̀rùn pọ̀nùn lọ.
Lékèélékèé ní kí a bá òun rẹ ọ̀kín sílẹ̀ níto’ri òun lẹwa ju ọ̀kín lọ, gbogbo ara òun ni o funfun daadaa, nítorí náà oun ni ki a fi jẹ́ baálẹ̀ àwọn ẹyẹ ti n gbé ilé.
Nígbà tí ọ̀pọ̀ eniyan péjọ yí i ká, ó bẹ̀rẹ̀ sí wí pé, “Ìran burúkú ni ìran yìí; ó ń wá àmì.
Èyí tí ó dúdú, ó dúdú gan-an ni, èyí tí ó pupa, ó pupa gan-ni; èyí tí ó funfun, ó funfun gan-an ni.
Awọn nkan mẹsan an to maa n fihan pe o ti n darugbo niyii - lara ẹranko ati eniyan Oríṣun àwòrán, Getty Àkọlé àwòrán, Awọn nkan to ti bajẹ ninu eroja ajogunba, DNA, yoo ma pọ si bi a ṣe n dagba 1.
Iyaafin Dabiri-Erewa  ba awon molebi oku yii kedun , o tun gbadura fun won pe ki olorun dun won ninu.
Ile ti wọn fi wa si ko ni orule rara."
yoo maa waako ninu ifesewonse kinni pelu iko agbaboolu Norwich City, ti iko
Iṣẹlẹ yii waye lẹyin ti awọn agbẹ ṣe ipade tan lori ati wa ojutu si iṣẹlẹ iṣekupani awọn Fulani darandaran niluu Ibadan.
Osiomohole dupe pupo lowo gomina ipinle naa Dave Umahi, fun anfaani ti o fun
OLUWA ní,“Idà ni yóo pa àwọn ará Kalidea,idà ni yóo pa àwọn ará Babiloni,ati àwọn ìjòyè wọn,ati àwọn amòye wọn!
pada wa si orile ede Naijiria lojo Isegun.
Awon eso Aare Erdogan jaa si ita Peteru mimo ni opopona opo ero ti won tipa fun eto aabo re.
Ó dùbúlẹ̀ lábẹ́ igi lotusi,lábẹ́ ọ̀pá ìyè ninu ẹrẹ̀.
Bakan naa, Dokita Wahab Adegbenro to jẹ kọmiṣọna feto ilera ni ipinlẹ Ondo ṣalaye pe wọn ti fa ọrọ naa le awọn ọlọpaa lọwọ.
Kí wọn má ṣe kó ohun ọ̀ṣọ́ bíi wúrà ati ìlẹ̀kẹ̀ tabi aṣọ olówó ńlá sára.
" A o si jọ sọ papọ pe bọlọhun fẹ, oju o ni wa a ti""."
Oríṣun àwòrán, Bhenji Àkọlé àwòrán, Nítorí COVID-19, ìjọba ìpínlẹ̀ Kwara kó ọ̀dọ́ 50 tó lọ sí ilé ijó sí gbaga Eyi lo jẹ ki igbakeji gomina nibẹ fi ọwọ ofin ko awọn awọn ọmọ igbimọ naa sodi lọ sileejo naa.
Spartan in Ogun: Èèyàn márùn-ún ní ọlọ́pàá sọ pé afurasí náà pa léraléra
Ileeṣẹ MultiChoice Group to ni ileeṣẹ amohunmaworan DSTV ti ṣalaye fawọn ọmọ Naijiria ohun to ṣe okunfa bi wọn ti gbowo le tariifu ẹrọ amohunmaworan naa.
Biu awọn ipinlẹ to ku ṣe lọ ree: Plateau-24 Katsina-21 Kano-16 Yobe-14 Ondo-10 Ogun-9 Edo-7 Bayelsa-5 Rivers-4 Borno-4 Osun-2 Ekiti-2 Èèyàn mẹ́fà kú, 920 tuntun míràn tún lùgbàdì Coronavirus ní Naijiria Esi ayẹwo Coronavirus lati ipinlẹ mejidinlogun ti ajọ NCDC kede loru ọjọ Abamẹta, ọjọ kọkandinlogun, oṣu Kejila, ọdun 2020, fihan pe, eeyan ẹ̀ẹ́dẹ́gbàárun le ogun tuntun miran lo ṣẹṣẹ ni aarun naa ni Naijiria.
"Oníṣẹ́ ọwọ́, oníṣẹ́ àdáni, awakọ̀, ẹ wo ọ̀nà láti gba lára owó ìrànwọ́ Covid-19 tí ìjọba gbékalẹ̀ Wo ohun to yẹ kóo mọ̀ nípa fọ́ọ̀mù 'self-certification' tí ìjọba àpapọ̀ ṣẹ̀ṣẹ̀ gbé kalẹ̀ àtàwọn tó kàn Ẹ̀kọ́ ọ̀fẹ́ déé fáwọn ọmọ Ọlọ́pàá tó kú lásìkò EndSARS, Gómìnà ìpìnlẹ̀ Eko kéde Báyìí ni 50kobo ṣe dá ìfẹ̀hónú ""Ali Must go"" sílẹ̀ tó mú ọ̀pọ̀ ẹ̀mí akẹ́kọ̀ọ́ lọ Aago mẹ́fà òwúrọ̀ sí mẹ́jọ alẹ́ ni ọ̀kadà yóò láǹfàní láti máa ṣiṣẹ́ ní Osun - Gómìnà Oyetola Bọ́ọ̀sì ìrìnà 106 tuntun yóò máa ná Ibadan sí Eko àtàwọn ìpínlẹ̀ míì - Seyi Makinde Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Kété tí wọ́n bá ti báa yín sùn tàn torí pé ẹ tóbi, ẹ gbà pé ìfẹ́ yẹn ti parí - Auntie Remi Ọlọ́yàn ńlá Oluranlọwọ aarẹ Buhari lori ọrọ iroyin ori ayelujara, Bashir Ahmad lo fi ọrọ yi soju opo Twitter."
Ninu èyí tí ó kù, kí àwọn tí wọ́n ní iyawo ṣe bí ẹni pé wọn kò ní.
" Asiko ti mo n ṣe iwadii nipa ọrọ #ENDSARS yii ni mo tun fi la ara mi lọyẹ lori awọn nkan miran to n ṣẹlẹ ni Naijiria.
Gẹgẹ bo ṣe sọ, o ni ẹsun naa tapa si ofin to rọ mọ iwa ọdaran to wa ni abala 225 ninu iwe ofin.
Ọpọ ma n ri i pe eleyii ma n dun ju ki eeyan kan dede jokoo sinu ile lati da wo ifẹsẹwọnsẹ naa ayafi ti awọn ololufẹ bọọlu bii tiwọn ba wa nibẹ.
O ni ko tilẹ yẹ ko jẹ bi wọn ṣe n yan ọba ni awọn asofin naa yoo jiroro le lori, nitori ki ilu lee tuba, ko tuṣẹ ni wọn se ma n ṣe etutu fun ọba, ni ilẹ Yoruba.
Ni ọjọ Aiku ni ikọ naa dana sun awọn arinrinajo to to ọgbọn, mọ inu ọkọ ni Auno.
Yato si ayeye isami ayajo ogofa odun ogun Adwa naa, Akon tun soro nibi ipade apero ajo isokan ile Africa, lori oro irinajo lona aibofin mu awon odo.
Ó wa ṣe, àwọn mẹ́tẹ́ẹ̀ta yìí jùmọ̀ ń rìn lọ nínú igbó lọ́jọ́ kan, nítorí ọdẹ ni gbogbo wọn.
Bi o ti le je pe, iko agbaboolu Ibom Angels FC se gudugudu meje ohun yaya mefa lati da ami-ayo naa pada, sugbon omi poju oka lo.
”“Tabi ibi ti won ti  fenuko lori ogbon egberun naira?
Sugbọn sa, atamatase ẹgbẹ́ agbabọọlu Brighton, Glenn Murray sọ pe awọn ilana kan ti wọn la kalẹ le ma a ṣíṣẹ, paapa ibomu lilo nitori pe awọn agbabọọlu yoo ma a yọ sọnu lasiko ti wọn ba n gba bọọlu""."
Saulu ati àwọn eniyan rẹ̀ wà ní apá kan òkè náà, Dafidi ati àwọn eniyan rẹ̀ sì wà ní apá keji.
Carlos ni lootọọ ni Messi ati Ronaldo n tii fi bọọlu dara, fun bi ọdun mẹẹdogun bayii, o ni Ronaldo Delima si ni baba wọn.
Ó kọ́ pẹpẹ kan sibẹ fún OLUWA, ó sì rú ẹbọ sísun ati ẹbọ alaafia.
Oríṣun àwòrán, Others Gomina Ganduje Abdullahi yan Yakubu Nagoda sipo olubadamọran lori ọrọ iboji oku.
Àkọlé àwòrán, Agbaagba mẹta to wà nidi ẹẹta pe ki iku Blankson lodo Bakana ma ja si asán Wọn ni ẹ̀rù omi ti ń ba àwọn lati igba ti ọrọ yii ti ṣẹlẹ, ṣugbọn bayii, wọn fe bẹrẹ ajọ aranilọwọ ti kii ṣe tijọba 'Boat Safety Minders Foundation' ti wọn yoo fi ṣeto iwe akọsilẹ awon arinrin ajo ọkọ oju omi tori iṣẹlẹ idagiri bayii.
Ohun ti o nilo lati se ni ki eniyan lọ si ori ẹrọ ayelujara wọn lori ẹrọ ilẹwọ wọn, pe ọkọ ile igbọnsẹ yoo de ibi to o wa lẹsẹkẹsẹ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Corruption: Ìwádìí àjọ aṣèṣirò òde, NBS gbé e jáde pé àwọn ọlọ́pàá, adájọ́ àtàwọn aṣọ́bodè ló gba rìbá jùlọ ní Nàìjíríà 7 Ọ̀pẹ̀̀ 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 9 Ọ̀pẹ̀̀ 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Iwadii naa tun fihan pe ọpọ awọn to riṣẹ ijọba lo fi owo ra iṣẹ ijọba laarin ọdun 2016 si asiko yii.
O wa lara awọn oṣu to gbajumọ laarin awọn larubawa.
Arabirin Kafayat ni Baraka ati aburo rẹ ọmọkunrin ẹni ọdun bii meje si mẹjọ ni wọn fi silẹ ni ọjọ ti iṣẹlẹ naa ṣẹlẹ.
Nígbà tí Dafidi gbọ́, ó kó gbogbo ọmọ ogun Israẹli jọ, wọ́n rékọjá odò Jọdani, wọ́n lọ dojú kọ ogun Siria, àwọn ọmọ ogun Siria bá bẹ̀rẹ̀ sí bá Dafidi jagun.
Orukọ Ndidi ati Iheanacho wa lara awọn ti wọn fi orukọ wọn silẹ lori itakun ayelujara ikọ agbabọọlu Leicester City fun ami ẹyẹ mejeeji.
nipa lilo ajo eleto aabo lasiko idibo , lona ti ajo naa yoo se yago fun didun
Nations, iko agbaboolu Super Eagles pari idije ohun sipo keta pelu ami-eye ide,
Messi ti gba ami ẹyẹ Ballon D'or nigba mẹfa ọtọtọ, nigba ti Ronaldo naa ti gbami ẹyẹ ọhun nigba marun un.
salaye fun awọn akọroyin pe won ti pa ọkan lara won Manir Usman ni Gobirawa
Lẹ́ẹ̀kan sí i, ẹ óo tún rí ìyàtọ̀ láàrin àwọn eniyan rere tí wọn ń sin Ọlọrun, ati àwọn ẹni ibi tí wọn kì í sìn ín.
Nígbà tí ó di ọ̀sán ọjọ́ kejì àwọn ìránńṣẹ́ Òjòlá-ìbínú wá wọ́n tún mú ẹnì kan tí ó sanra nínú wa wọ́n pa á fún ọba wọn.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù FIFA U-20 World Cup: Mali pa ẹ̀rùjẹ̀jẹ̀ Argentina lẹ́kún kúrò ni Poland 5 Òkùdu 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Idije FIFA U-20 Bi awada bi ere, ẹgbẹ agbabọọlu Mali ṣe bẹẹ le ẹrujẹjẹ ikọ agbabọọlu Argentina lọ le ninu idije ife ẹyẹ agbaye FIFA U-20 lorilẹ-ede Poland.
Ìpànìyàn l'Eko: Ilé ẹjọ́ dá ẹjọ́ ikú fún ọkùnrin tó pa ìyàwó rẹ̀
Ìgbà ọtun ti dé fún àwọn oníṣẹ́ ọwọ́ Nàìjíríà Àìsí owó ń fọ́ ọ̀pọ̀lọpọ̀ èèyàn lójú tó jẹ́ ìmọ́lẹ ara À lágbára láti san gbogbo gbèsè tá jẹ Nigba ti awọn ọlọpàá tẹ le Kehinde dele, wọn ni lati ja lẹkun wọle ni.
Idà ni ẹ̀ ń bẹ̀rù, idà náà ni n óo sì jẹ́ kí ó pa yín.
Ṣugbọn Aarẹ Weah to gboye agbabọọlu to pegede julọ lagbaye lọdun 1995 ko le gba ikọ agbabọọlu orilẹede rẹ silẹ lẹyin ti ẹgbẹ agbabọọlu Naijiria fiya jẹ wọn pẹlu ami ayo meji si ẹyọkan.
FRSC dá N443,180 padà fún ẹbí ẹni to ní ìjàmbá mọ́tò
N óo wó àwọn ilé ìsìn yín gbogbo tí wọ́n wà lórí òkè, n óo wó àwọn pẹpẹ turari yín lulẹ̀; n óo kó òkú yín dà sórí àwọn oriṣa yín, ọkàn mi yóo sì kórìíra yín.
tí ó fi ìfẹ́ rẹ̀ tí kì í yẹ̀ hàn mí níwájú ọba, pẹlu àwọn ìgbìmọ̀ ati àwọn ẹmẹ̀wà rẹ̀ pataki pataki.
" Oríṣun àwòrán, Others Àkọlé àwòrán, Gbolagade Akinpelu ti ọpọ eeyan mọ si Ogun Majek ti n ṣe àìsàn láti ọjọ́ mẹ́ta kan, kó tó kú ní Ọjọru.
Fayoṣe ní ìbéèrè mẹ́rin fún Buhari lórí ìwé ẹ̀rí rẹ̀ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ireti Yusuf: Ìsòro àti fẹjọ́ sùn ló ń mú kí ìwà ìfipábánilòpọ̀ gbilẹ̀ si ASUU ati SSANU kọ̀ lati sọ̀rọ̀ Gbogbo igbiyanju lati ba awọn aṣoju ẹgbẹ ASUU, ẹka ile ẹkọ giga naa sọrọ lo ja si pabo, gẹgẹ bi ọkan lara awọn aṣoju ẹgbẹ naa, Deji Ọmọle ṣe s'alaye wipe ko tii t'asiko lati ba awọn oniroyin sọrọ.
O ni awọn ṣi tun gbọ pe awọn kan n ko ounjẹ wọle lọna aitọ ṣugbọn o ni ileeṣẹ to n ri si iwọle-wọde n ṣe iṣẹ wọn bii iṣẹ.
Bí a bá faradà á, a óo bá a jọba.
7% jẹ́ àwọn tó ti pé ogójì ọdún ti kú ní America.
Ṣugbọn Jesu sọ fún un pé, “Ti idà rẹ bọ inú akọ rẹ̀ pada, nítorí gbogbo àwọn tí ó bá ń fa idà yọ, idà ni a óo fi pa wọ́n.
Eyi ko si tun di lọwọ lati ṣe nkan to yẹ.
 Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Oyenusi ló mú mi wọ ẹgbẹ́ adigunjalè kó tó di pé mo b'Ólúwa pàdé' Kini idi ti Eyo Charles fi bẹ Fani-Kayode ninu fidio naa?"
wo àwọn nọ́mba ọlọ́pàá tí o lé pé láti mọ ọ̀nà àbáyọ25 Agẹmo 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
O ni iya ọkọ aarọ oun ko fẹ ki oun fẹe gbadun nigba ti ọkọ keji lahun ti ko si ni itọju obinrin lọwọ.
Nǹkan kò tíì ṣẹnu ire fún àwọn ọmọ orílẹ̀-èdè yìí - Atiku Kí ni pàtàkì nọ́mbà 615 láàrín àwọn èèyàn ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ̀ Àṣẹ olóòrùn ni ayálégbé mi - Onílé kan Aṣòfin Nàìjíríà tó jẹ́ ọmọ orílẹ̀èdè méjì jáwé olúborí nílé ẹjọ́ Ṣaaju ni obinrin akọroyin naa ti sọ wi pe ọlọpaa kan ti kọkọ kọ oju ibọn si oun ni agọ wọn.
Kí Ọlọrun óo ṣàánú wa, kí ó bukun wa;kí ojú rẹ̀ tan ìmọ́lẹ̀ sí wa lára;
O ni rinrin deede ati ṣiṣe ododo ni ko jẹ koko ọrọ wọn ni gbogbo igba.
Nígbà tí Jesu mọ̀ pé àwọn Farisi ti gbọ́ ìròyìn yìí, ó kúrò ní Judia, ó tún pada lọ sí Galili.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ìpàdé náà kò sẹ̀yìn bí Ọmọbakùnrin Harry àti ìyàwó rẹ̀, Meghan Markle se ní àwọn fẹ́ fi ipò sílẹ̀ gẹ́gẹ́ bí òkan gbòógì nínú ìdílé ọba.
Mo bẹ Ẹlẹ́dàá mi pé bí ti jẹ́ aṣáájú àwọn ọdẹ wọ̀n-ọnnì, kí ó jẹ́ kí n jẹ́ aṣáájú rere.
Bákan náà, ẹ̀tọ́ ọmọnìyàn ti wó lulẹ̀ nínú ìṣàkóso ìjọba rẹ̀, pẹ̀lú àìjẹ̀yà àti ìṣowó-ìlú-mọ̀kumọ̀ku ní ibi gíga nínú ìjọba.
Olùkọ́ tó kù nínú ìṣẹlẹ ilé to jo nínú ọgbà UI tí kọ̀wé fipo silẹ̀ tipẹ-Alukoro fásitì Ta ló gé orí ọkùnrin mẹ́ta ní Lekki?
ní ọjọ ́ kẹtàlá , oṣù kárùn-ún ọdún 1888 , tí ó jẹ ́ ọdún kẹfà lẹ ́ yìn ikú luiz ganzaga pinto da gama ni aba tí ó fagi lé òwò ẹrú di òfin ní ilẹ ̀ brazil .
Nigba to di ọdun 2006, wọn yan sipo Minisita fun ọrọ abẹle, ko to wa di olugbani nimọran si aarẹ ologun ati akọwe apapọ fun ijọba ẹgbẹ CNDD-FDD to n dari orilẹ-ede naa.
Mose bá kígbe sí OLUWA, OLUWA fi igi kan hàn án.
Eyi ni igba akọkọ ti Messi yoo gba ami ẹyẹ Ballon D'or lati ọdun 2015, Ronaldo lo gbami ami ẹyẹ naa lọdun 2016 ati 2017, nigba ti Luka Modric Real Madrid gba a lọdun 2018.
Bi iwe ofin ba ti se la ijiya kale ni adajọ yoo se tele.
 Eleyii ti o fi han pe gbgbo ipa ni Ile Igbimọ Aṣofin Ipinlẹ Eko n sa, paapaa labẹ Agbẹnusọ Ile naa bayii, Aṣofin Mudashiru Ọbasa, lati ri i daju pe awọn ara ilu ri riri pe wọn n ṣoju awọn ni tootọ pelu iṣakoso ijọba rere”.
Ẹwẹ, awọn ololufẹ awọn mejeji lo n fi ọrọ sita nigbakuugba ti ọrọ ba jade lẹnu ọkan ninu wọn to jẹ ọrọ to lee fa wahala.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fọ́nrán ohùn, Onímọ̀ kan ńfẹ́ kí Nàíjíríà lo igbó fún ìwòsàn Àmọ́ èyí tó wù kó jẹ́, ó yẹ kí á se ohun gbogbo ní ìwọ̀n tunwọ̀nsì.
Nígbà tí Mustapha Kolo, ẹni ọdún mẹ́tàdínlógún mu òògùn pupa tó dùn wò lójú náà, ó dà bíi pé ó leè hú igi.
Ṣùgbọ́n nígbà tí mo bá tún rò ó wò lọ́nà kejì mo tún rí i pé bí kò bá sí irú bẹ́ẹ̀ ayé pàápàá kì bá tí dùn tó bí ó ti dùn yìí.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Awọn Obinrin Dahomey: Awọn obinrin ilẹ Afirika ti wọn yii itan pada re e Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Obinrin Akansẹ: Ẹsẹ kiku bi ojo kọ mi lati di alagbara BBC 100 Women fẹ waadi nipa awọn obinrin ti wọn ku wọn yi .
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ọba Olutayọ: ìgbésẹ̀ Ọọni àti Alaafin ti ń mú ìṣọ̀kàn dé sáàrin àwọn Ọba Yorùbá Alayegun ilu Ọdẹ-Omu, Akire ilu Ikire, Akirun ti Ikirun, Aree ti Ire, Olunisha ti Inisha (gbogbo wọn wa nipinlẹ Ọṣun) gba ade nipasẹ Alaafin.
Ogbeni Aiye  ni oun yoo ri i pe iyipada de ba  isejoba 
Oríṣun àwòrán, Getty Images Ologun ni Hosni Mubarak; ṣugbọn iru ologun tirẹ, ẹni to gbe opo ifarajin orilede rẹ si alafia agbaye.
n óo mú àwọn ọmọ Israẹli kúrò lórí ilẹ̀ tí mo fún wọn, n óo sì kọ ilé ìsìn tí mo ti yà sí mímọ́ fún orúkọ mi sílẹ̀.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ile Asofin Eko: Ọjọ́ Kẹrin oṣù Kejì ni Ambọde yóò yọjú síwájú ilé 28 Sẹ́rẹ́ 2019 Oríṣun àwòrán, Google Àkọlé àwòrán, Ọjọ Aje ni iroyin gba ilẹ kan pe ile asofin ni ipinlẹ Eko ti n gbe igbesẹ lati yọ gomina Ambode kuro ni ipo.
O sọ pe ilana yii ṣe pataki pupọ fun awọn agbẹ nitori pe wọn yoo fẹ mọ ibi ti maalu ti wa, ati ọjọ ori maalu naa, nitori pe wọn fẹran ẹran maalu ti ọjọ ori rẹ ko ju oṣu mẹẹdogun si ọdun meji lọ.
 Ti mo ba fi àwọ̀n boju lati dẹru ba Jessica, sibẹ yoo fi ọwọ kan oju mi, yoo si fẹnu ko mi lẹnu.
 Ẹnu ya wa nipa awijare ileesẹ ologun lori igbesẹ lile awọn eeyan yii, niwọn igba ti wọn mọ pe ko si ofin kankan lorilẹede Naijiria to fi aaye gba igbesẹ wiwo ile awọn araalu tabi fifi iya jẹ wọn lọna to lodi sofin.
Àṣẹ yìí jẹ́ ọ̀kan lára alàálẹ̀ ìjọba ipinlẹ Eko lórí ìlera ará ìlú to fi síta lọ́jọ́ Eti.
“Nítorí náà a bá dúró sí àfonífojì, ní òdìkejì Betipeori.
Ìbẹ̀ǹbẹ́ olókùnrùn pàápàá kò ní ìpalára, a jọ gòkè ni.
Ọrọ owo oṣu sisan nipasẹ IPPIS yii jẹ eleyi tawọn olukọ fasiti Naijiria naa fi tori rẹ fariga, ti wọn si ti kọ lati ṣiṣẹ fun nnkan bi oṣu mẹfa bayi.
Oríṣun àwòrán, Facebook/Asiwaju Bola Tinubu Tinubu ni ohun to n ṣe awọn to fẹ yọ Oshiomole nipo ni pe, wọn fẹ ki gbogbo ọrọ lori ibo ọdun 2023 ko yanju tan ninu ẹgbẹ lọdun 2020 yii.
Gomina ipinlẹ Osun lọdun naa, Ọgbẹni Rauf Aregbesola lo gbe ọpa aṣẹ le Oluwo lọwọ.
Igbó mímu lè ṣe kóríyá, kò lé fi kún orín ẹnu òṣèré - 9ice Ìtàn tó wà nídi òwe ‘Sebótimọ Ẹlẹ́wà Sàpọ́n’ Ọba Adesoji Aderemi, Ọọ̀ni Ifẹ̀ tó gba ipò ọba mọ́ tòṣèlú MKO Abiola, iṣẹ́ aṣẹ́gità ló fi bẹ̀rẹ̀ okoòwò Iṣọla Oyenusi rèé, ẹnití ìfẹ́ obìnrin ṣun dé ìwà ìdigunjalè Adegbọrọ n mojuto isẹ ara rẹ funra ara rẹ, ti ko si fi ọwọ mẹwẹẹwa jẹun.
Tẹ́lẹ̀ rí òun ni àwọn eniyan kà kún, tí idán tí ó ń pa ń yà wọ́n lẹ́nu.
O ṣalaye pe awọn ni idaniloju to peye ninu esi ibo to gbe ẹgbẹ APC wọle, ṣugbọn awọn ko gbọdọ ma gba adura si Ọlọrun.
Yorùbá kìí ṣe egúngún oníhòhò, ìwà wèrè ni sinimá oníhòhò táwọn òṣèré kan ń ṣe- Lere Paimo Pásítọ̀ Adeboye ṣelérí àti fojú aṣebi hàn lórí ikú Omozuwa, Amnesty International pẹ̀lú kọminú Coronavirus dé ọ̀dọ̀ ará ọ̀run, ọdún Egúngún kò ní wáyé nílùú Ibadan nítorí coronavirus Ènìyàn 307 ló lùgbàdì àrùn Coronavirus ní Ọjọ́ Aiku Auxiliary leri leka bẹẹ, lasiko ti Ileesẹ ode ati igbokegbodo ọkọ pẹlu ajọ to n ṣe akoso oju popo nipinlẹ Oyo, ṣeto ilanilọyẹ fawọn ọmọ igbimọ alakoso gareeji, lori bi isẹ wọn ko fi ni lọwọ jagidijagan ninu.
Buhari, o kò ṣe bẹbẹ kankan láì jẹ́ pé o gba Leah Sharibu náà sílẹ̀ Wo àwọn nǹkan to tún nílò NIN fún yàtọ̀ fún ìforúkọsílẹ̀ síìmù Ilé aṣòfin àgbà yọ gómìnà nípò, ẹni tó fi owó ìlú rán ọmọ lọ sí Amẹ́ríkà Amẹ́ríkà yarí pé àwọn agbégbọn tó jí akẹ́kọ̀ọ́ 344 gbọ́dọ̀ fojú winá òfin Ko pe ti iṣẹlẹ naa waye ti Shehu sọ fun ileeṣẹ iroyin BBC pe, awọn akẹkọọ mẹwaa pere ni awọn agbebọn naa ji gbe, bo tilẹ jẹ pe ijọba ipinlẹ Katsina ni awọn akẹkọọ to to ojilelọọdunrun ati mẹrin, 344 lo poora.
Ẹgbẹ́ IPOB ò tako Ààrẹ Buhari ní Japan- Iléeṣẹ́ Ààrẹ Òfin nìkan ló lè gbadé lórí àwa Ọba ìlú lbadan- Oba Lekan Balogun ‘Pussypedia’ rèé, ojú òpó tó ń mú àdínkù bá ìṣòro ìmọ̀ nípa ẹ̀yà ara obìnrin To bá fẹ́ jàǹfààní iná ọba tí kò ṣẹ́jú látọ̀dọ̀ ìjọba, ọ̀nà ẹ̀bùrú tó gbà rèé Omi ara Ọ̀pọ̀lọ́, ẹ̀jẹ̀ Ẹlẹ́dẹ̀ àti wáìnì tí wọn fi Èkúté ṣe ń mára jípépé, ẹ máa mú O dùn mí pé Buhari kò yàn mí sípò Mínísítà lẹ́ẹ̀kejì àmọ́ mò gbà kádàrá - Adebayo Shittu Kanselọ alawọ dudu akọkọ ni Ireland naa wa rọ awọn ọmọ Naijiria nile ati loke okun, lati mu ayipada rere ba orukọ buruku ti wọn sọ orilẹede Naijiria lẹyin odi, ka si jẹ ki wọn mọ pe ohun rere lee ti orilẹede Naijiria jade wa, gẹgẹ bi oun ti se.
Oríṣun àwòrán, PA Àkọlé àwòrán, Joshua ti di ẹlẹṣẹ agbaye - pẹlu igbanu ẹyẹ mẹta , ati ade IBO , igbanu ẹyẹ WBC nikan lo ku fun Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 3 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 5 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Wọn fa fidio naa yọ lori ayelujara lẹyin ti eeyan miliọnu mẹrinla ti wo o.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ebi ló ń pami ti mo fi já sọọbu láti jí bisikitì- Afurasi Asuquo 28 Ọ̀wàrà 2019 Oríṣun àwòrán, @the News Àkọlé àwòrán, Ebi ló ń pami ti mo fi já sọọbu láti jí bisikitì- Afunrasi Ẹni ọdun mẹẹdọgbọn kan, Destiny Asuquo ni ọwọ́ sìnkún ọlọpàá tí tẹ ni ìlú Port Harcourt lágbègbè Rumuodara ni ìpínlẹ̀ Rivers.
mu awon to lọwọ nibi isele buruku naa” .
Wọn tun ni agbara lati fi ọrọ wa awọn oṣiṣẹ SARS ti ijọba apapọ ti tuka lẹnuwo lori awọn ẹsun naa ki wọn si yọ okodoro.
Ewe, aare Buhari kuro nilu Washington DC lojo Isegun(Tuesday), leyin abewo re si aare Donald Trump lojo Aje(Monday), ki o to ni idaduro nilu London, lorile-ede England.
Aṣofin Bisi Yusuff naa ṣapejuwe Ọba Akiolu gẹgẹ bi Ọba to ni ọgbọn ati oye to pe, ti o si jẹ akinkanju Ọba ti ko bẹru ẹni kokan afi Ọlọrun Ọba, ti osi n wa alaafia ilu ni gbogbo ọna.
Awon miran ti won wa ni bi apeje oniwakati merin naa ni: Ri Sol-ju, to je aya Ogbeni Kim ti kii fi bee yoju sita ati abure re obinrin Kim Yo-jong to wa lara awon iko to n risi idije Olymoics lati North Korea.
Iṣẹlẹ yi mu ki awọn dokita to jẹ akẹkọọ bẹrẹ iwọde lati fi ẹhonu han lori iku rẹ.
Ọkan ninu awsn imọran naa le jẹ otitọ, ṣugbọn awọn to ku nkọ?
Jeroboamu ọba Israẹli mọ odi yí ìlú Ṣekemu, tí ó wà ní agbègbè olókè ti Efuraimu ká, ó sì ń gbé ibẹ̀.
Ede, aṣa, àti ìtàn orirun wà lára nkan to ya ogidi ọmọ Yorùbá sọtọ ni gbogbo agbaye.
Super Eagles f'ìyẹ́ bo Carthage Eagles Tunisia mọ́ 'lẹ̀ Oniruuru oye ni wọn ti fi da a lọla latari ko maa gbe aṣa ibilẹ ga, lara rẹ ni Yeye Agbaṣaga.
Ọjọgbọn Wole Soyinka ti kesi ijọba apapọ lati fi Omoyele Sowore silẹ, ki itiju to n ba orilẹede Naijiria ba le dinku.
Ọlọrun ni ó fihàn mí lójúran ni mo fi lọ.
Bayajidda Ọpọlọpọ eniyan gbagbọ pe orilẹ-ede Baghdad ni orisun Bayajidda, ko to o di pe o wa si Borno nibi to gbe fun igba diẹ.
Kete ti Ibrahim Oloriegbe yẹ aga nidi Sẹnetọ Saraki pẹlu atilẹyin o to gẹẹ ni awọn kan nilu Eko naa bẹrẹ #Otogelagos.
9 6049 Agbegbe French Polynesia 91 32.
Akeredolu lo fi ọrọ naa lede nigba to n jabọ ibi iṣẹ de duro lori bi ipinlẹ naa ṣe n gbogun ti ajakalẹ arun ọhun lọjọ Aje.
Ajo to n gbogun ti iwa ibajẹ lorilẹede Naijiria, EFCC ti gbe ọga ile isẹ to n risi owo awọn osisẹfẹyinti ( pension) tẹlẹri, Abdurasheed Maina ati ọmọ rẹ Fraisal lọ si ile ẹjọ giga to wa ni ilu Abuja.
A lè fi ò́we yi bá awọn obinrin ti o nṣe àṣejù tabi àṣehàn, nipa ki kó owó nlá lóri àti ra gèlè lati òkè òkun.
Eleyii yoo si mu ara ẹni to ba ni aarun naa ji pepe pada.
Egypt to n gbalejo idije naa ati Cameroon to gba ife ẹy naa ninu idije to kọja ti di ero ile bakan naa.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù RCCG: Ọlọ́pàá Ogun dóòlà àwọn ọmọ ìjọ Redeem mẹ́rin tó kù!
Ẹ̀yin ará Filistini, ẹ máa gbọ̀n jìnnìjìnnìnítorí pé àwọn ọmọ ogun kan ń rọ́ bọ̀ bí èéfín, láti ìhà àríwá,kò sí ọ̀kan ninu àwọn ọmọ ogun wọntí ó ń ṣe dìẹ̀dìẹ̀ bọ̀ lẹ́yìn.
Àwọn ọmọ Israẹli bá bèèrè lọ́wọ́ Samuẹli pé, “Níbo ni àwọn tí wọ́n sọ pé kò yẹ kí Saulu jẹ ọba wa wà?
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Àwọn ọmọ ogun ilẹ̀ Nàìjíríà dóòlà ẹ̀mí ẹni méjì ní Owena ní Ondo 25 Agẹmo 2020 Oríṣun àwòrán, others Awọn ọmọ ogun Naijiria ti ẹka 32 Artillery Bridgade ni Bareke Owena ni Ondo ti doola ẹmi awọn eniyan meji lọwọ awọn ajinigbe.
Daddy atẹgun ti gbe gbogbo paanu o.
Agbẹjọro fun ijọba inpinlẹ Ondo, to jẹ olupẹjo, so wi pe, botilẹ̀ jẹ pe ko wu ijọba lati jẹ ki ẹjọ naa pẹ nilẹ, agbẹjọro fun Sotitobire bẹbẹ ki ileẹjọ sun igbẹjọ naa siwaju.
ni ipagọ ijọ Redeem to wa lopopona ilu Eko si Ibadan.
Abumere/BBC Àkọlé àwòrán, The Jazzhole Lasiko yii to jẹ wi pe orin takasufe Afrobeats lo gbode kan lori awọn ileeṣẹ redio ati ile ijo gbogbo, The Jazzhole ṣi gbin ara rẹ kalẹ gẹgẹ bii ibudo akojọpọ oniruuru orin.
 Sibẹ iwadii ti bẹrẹ lori iku rẹ.
Níbẹ̀ ni wọ́n ti kàn án mọ́ agbelebu, òun ati àwọn meji kan, ọ̀kan ní ẹ̀gbẹ́ ọ̀tún, ọ̀kan ní ẹ̀gbẹ́ òsì, Jesu wá wà láàrin.
Àwọn Òfin Tí Wọ́n Jẹmọ́ Ẹ̀tọ́ ati Jíjẹ́ Mímọ́.
Zidane to sọrọ loju opo Twitter rẹ f'ọwọ sọya pe lọwọ yii o, Modric lo pegede julọ ninu awọn agbabọọlu ọkunrin lagbaye.
 ní àwọn 20 ọdún sẹ ́ yìn , 16 mílíọ ́ nù àwọn ènìyàn lágbayé ni o ti rí ìwosàn lọ ́ wọ ẹ ̀ tẹ ̀ .
Ta ló mọ̀ dájúdájú, pé ẹ̀mí eniyan a máa gòkè lọ sọ́run; tí ti ẹranko sì ń sọ̀kalẹ̀ lọ sinu ilẹ̀?
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ooni Ile Ife: Ooni Adeyeye Ogunwusi àti Olòrì Naomi gbé Àrẹ̀mọ tuntun wọ ààfin Ilé Oòduà 8 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 9 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Oríṣun àwòrán, Ooni Palace Ọọni ti Ile Ife to tun jẹ Arole Oodua, Ọọni Adeyeye Enitan Ogunwusi, Ọjaja II ti fi oju ọmọ wọn han faraye fun igba akọkọ lọjọ Iṣẹgun ọsẹ.
Ẹgbẹ oṣelu PDP ti ke gbajare sita pe awọn ohun to n waye paapaajulọ lasiko ajakalẹ arun coronavirus to n waye lọwọ ko ni ohunkohun n ṣe eyi to lee tọka si pe gomina Makinde tabi ijọba ipinlẹ Ọyọ n wọ iya ija pẹlu ijọba apapọ atawọn ileeṣẹ rẹ gbogbo.
Nígbàtí èmi àti àwọn ọ̀rẹ́ mi dé'lé a se ìwádìí nípa ilé náà lórí Ayélujára.
Bákan náà ni ìtàn àtọwọ́dọ́wọ́ọ erin tí Chhot Pich sọ ṣe àfihàn bí àwọn òrìṣà ṣe sọ àwọn ará abúlé tí ó fi májèlé sí inú odò di erin.
Nisinsinyii, OLUWA Ọlọrun wa, gbà wá lọ́wọ́ rẹ̀, kí gbogbo ìjọba ayé lè mọ̀ pé ìwọ nìkan ni OLUWA.
Bí ẹ bá tún fẹ́ bèèrè,ẹ pada wá, kí ẹ tún wá bèèrè.
Nígbà tí àwọn ará Edomu kò jẹ́ kí àwọn ọmọ Israẹli gba ilẹ̀ wọn kọjá, wọ́n bá gba ọ̀nà ibòmíràn.
Oṣu to kọja ni gbajugbaja oṣere, Ogun Majek naa jade laye lẹyin aisan.
Èmi pẹlu yín, a wà ní oko ní ọjọ́ kan, à ń di ìtí ọkà, mo rí i tí ìtí ọkà tèmi wà lóòró, ó dúró ṣánṣán, àwọn ìtí ọkà tiyín sì yí i ká, wọ́n ń foríbalẹ̀ fún un.
Lasiko ti akọroyin BBC kaakiri agbegbe Eyitayo Jegede, ni ṣe lo pa lọlọ ti ko si si ẹni to n dunnu ni agbegbe naa.
Ohun tí a lè ṣe ni pé kí á dá wọn sí, kí ibinu OLUWA má baà wá sórí wa, nítorí ìbúra tí a ti ṣe fún wọn.
Alaga Ile Igbimọ Asofin lori ọrọ to jẹ mọ ile ifowopamọsi ati owo ile wa, Victor Nwokolo le awọn akọroyin jade lasiko ti banki apapọ Naijiria n ṣalaye eto iṣuna wọn.
O ti to bi ọjọ mẹta ti ko si ẹni to ri ninu ere agbelewo Yoruba kankan mọ.
ni Joy fi n jẹ irora ina ti o joo ni gbogbo ara, ti ko si ni oluranlowo
O ni ki awon egbe Kankan maa
Nítorí náà, ẹni tí ẹ̀ṣẹ̀ rẹ̀ pọ̀jù ni ẹni tí ó fà mí lé ọ lọ́wọ́.
Wayi o, ni ọjọ ẹti(Friday) ni wọn yoo ṣe aṣayan awọn ẹgbẹ
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fọ́nrán ohùn, Ruga settlement: YCE ní ìjọba àpapọ̀ ko tó bẹ̀ẹ́ láti kọ́ àgọ́ Fulani sílẹ̀ Yoruba O fi kun ọrọ rẹ pe ''awọn eleyi ko ni nnkankan ṣe ni,laipẹ yi awọn to yẹ yoo da wọn loun'' Lọjọbọ ni iroyin gbode pe awọn ọmọ ẹgbẹ YCE kan pamọran pọ lati yọ Dokita Kunle Olajide gẹgẹ bi akọwe ẹgbẹ.
Wọn bi Awolowo ni ọjọ kẹfa, oṣu kẹta, ọdun 1909 ni ilu Ikenne, ni ipinlẹ Ogun ni guusu Naijiria.
Saulu ati àwọn ọmọ rẹ̀ pàápàá sá lójú ogun.
Ọlọrun, OLUWA, ni agbára mi;Ó mú kí ẹsẹ̀ mi yá nílẹ̀ bíi ti àgbọ̀nrín,ó mú mi rìn lórí àwọn òkè gíga.
 Ó tún lọ sí yunifásítì ti Èkó ní akọkà .
Okoye ni faabada oun ko le fun onijagidijagan eeyan lẹbun owo.
"Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Bí ẹ ṣe mọ̀wé tó, ẹ wá dánrawò níbí pẹ̀lú ""Àpólà Ọ̀rọ̀ Orúkọ - Noun Phrase Wọn ṣapejuwe baba ni Olufọkansin tootọ, Ọrẹ atata, Baba rere to huwa igbe aye atata to tun jẹ abinu funfun bi ẹmu Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Abule Ado explosion: Irọ́ ńlá ní NNPC pa lórí ìbúghbàmù Abule Ado níbí tí ẹ̀mí èèyàn 23 Lára àwọn ìwé tí olóògbé Lawuyi Ogunniran kọ nígbà ayé wọn ní wọ́nyí: Àrẹ Àgó Aríkúyẹrí Àwọn ọba Yorùbá kan rèé tí wọ́n rọ̀ lóyè, tí ọba míràn jẹ lójú ayé wọn Duro Ladipọ, ìlúmọ̀ọ́ká òṣèré tíátà àti ọmọ àlúfà tí kò gbàgbé àṣà ìbílẹ̀ Ọọ̀ni obìnrin, Lúwòó Gbàgídà rèé, akọni tó ń gun ọkùnrin ní ẹṣin rìn Ayinla Ọmọwura, orin èébú àti oríyìn lo fi di ọ̀rẹ́ àwọ̀n obìnrin Ǹ jẹ́ o mọ àwọn èèyaǹ wọ̀nyí tó jà fún òmìnira Nàìjíríà?"
Oṣu Kẹta ni ijọba Naijiria ti fofin de irinajo oju ofurufu, nitori itankalẹ coronavirus.
Ki lawọn wole wole n ṣe?
O kede loju opo Facebook rẹ pe oun gba idaniloju imularada oun lẹyin ayẹwo ni ileewosan ati pe lọwọ yii oun ti kuro ni ileewosan, bi o tilẹ jẹ wipe yara iyasọtọ ni oun yoo ṣi wa.
Lẹyin ti o sa lọ lo tun lọ ṣekupa pa arabinrin kan ni agbegbe Akinyẹle, bẹẹ sini o tun da ọgbẹ si ẹlomii lara.
lọjọ kẹ́sán án, osu kẹ́ta  ti ajo INEC kede ibo ti wọn kọkọ di ni ipinle
Njẹ Wole Soyinka lọwọ si idasilẹ awọn ẹgbẹ okunkun?
Ìwọ ọmọ ènìyàn, mo dúpẹ́ lọ́wọ́ rẹ lónìí tí ìwọ wáá kí mi ní ilé mi, mo sì fẹ́ẹ́ rán ọ sí àwọn ọmọ aráyé, lónìí yìí, ní ọjọ́ kẹrìndín-lógún oṣù kọkànlá, ní ẹ̀ẹ́dẹ̀gbẹ̀wá ọdún ó lé mẹ́tàlálógójì lẹ́hìn ikú Olúwa wa, wí pé, kí àwọn ọmọ ènìyàn jọ̀wọ́ ṣe àforíjì, kí wọ́n dín iṣẹ́ mi kù díẹ̀ nípa ìtọ́jú ara wọn.
Oríṣun àwòrán, iyaboojofespris Àkọlé àwòrán, Gbogbo faaji ni lọjọ́ naa.
Akọwe agba fun ajọ irinajo afẹ lagbaye, UNWTO, Ogbeni Zurab Pololikashvili, ti kede pe ipinlẹ Eko yoo ko ipa pataki ninu eto irinajo afẹ lagbaye.
‘UK yóò pèsè isẹ́ 100,000 ní Nàìjíríà’ Bukola Saraki fẹ́ rẹ ọmọ Nàìjíríà lẹ̀kún ní 2019 Amọ, abẹwo olootu ijọba Germany naa waye ni asiko ti awọn eniyan n fi ẹhọnu han lori ofin to de irina awọn eniyan wa si orilẹede Germany.
Ninu ọrọ tiẹ, Kọmiṣọnna eto ẹkọ nipinlẹ Ekiti, Ọgbẹni Foluso Daramola, sọ pe ipinlẹ Ekiti yoo gba kawọn akẹkọọ ṣe idanwo WAEC ṣugbọn eyi yoo da lori igbesẹ awọn ijọba ilẹ Yoruba.
U lati wa ojutu si iririnrin ajo awon odo lona aibofin mu ti o gbode kan bayii.
Àwọn irúgbìn tí wọ́n ń gbìn fún àrojẹ ni, iṣu, ẹ̀gẹ́ (gbáàgúdá) ikókó, ìrẹsì, àgbàdo, kọfí, òwù àti obì sì jẹ́ àwọn irù-gbìn tó ń mówó wálé fún wọn.
Ajọ LASEMA, awọn ọlọpaa, ileeṣẹ panapana Eko atawọn oṣiṣẹ alaabo mii lo tara ṣaṣa lọ sibi iṣẹlẹ ọhun ti wọn si gbakoso gbogbo adugbo naa ki iṣẹlẹ ọhun ma baa bimọ mii.
Lẹyin iṣẹju mẹrindinlọgọrun un ni ifẹsẹwọnsẹ naa pari ni ikọ Chelsea fẹ Ajax danu bi abẹbẹ pẹlu ami ayo kan si odo.
ni won ti ri yọ nibi ile to wo naa, ti  awon kan si ti padanu emi won bayii.
Kun Aguero naa tun gba boolu agbesile mi wo le lati so
Bí nǹkankan bá wà tí wọ́n fẹ́ mọ̀, kí wọ́n bi àwọn ọkọ wọn ní ilé.
Sunday fi kun ọrọ rẹ pe, bẹẹ ni ko si se lẹyin baba ti oun n ba ṣiṣẹ naa bo tilẹ jẹ wi pe baba naa n bẹ ninu gbaga ọlọpaa.
Ile ọlọjọ pipẹ naa to wa ni agboole Kegbe ni agbegbe Kajọla ni ilu Oṣogbo da wo lu Jide lasiko to fi n gba ẹgbẹ ile naa kọja lọ ni tirẹ.
Ọba tí ó tóbi kò tó ìránńṣẹ́ lọ́wọ́ Ọlọ́run Ọba.
Ogbeni Aregbesola soro yii nibi iwọde ti abenugan ile igbimo asofin ipinle .
Wọn kò gbọdọ̀ ṣe iṣẹ́ níbẹ̀ mọ́, 
Sanwo-Olu, nigba to n sọrọ lórí bó ṣe di olùdíje ati awọn ọ̀rọ̀ míràn tí ayé ti ń mẹ́nu bà láti ìgba tí ìdìbò abẹ́lé APC ti waye, O ni awọn isẹlẹ to n waye lo safihàn pé àwọn ọmọ ẹgbẹ́ náà kò fẹ́ Gomina Akinwúnmí Ambode fun sáà kejì.
O ni lẹyin naa ni Mallet bẹrẹ si ni ba Bonchev ja ti o si fọwọ ba a lori.
11 Ẹrẹ̀nà 2019 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Ìjòyè náà dáhùn pé, “Gbogbo òfin wọnyi ni mo ti ń pamọ́ láti ìgbà tí mo ti wà ní ọdọmọkunrin.
Awọn akọroyin BBC, Nduka Orjinmo ati Mansur Abubakar se agbeyẹwo ohun to n sẹlẹ pẹlu bi awọn kan ni ariwa Naijiria ti se pe fun iwọgile eto ẹkọ almajiri.
A gbọ́ pé ọ̀gá àgbà àwọn ọlọ́pàá ní wọ́n gbúdọ̀ ṣe ìwádìí ọ̀rọ̀ náà lẹ́sẹ̀kẹsẹ̀ bẹ́ẹ̀ náà sì ni wọ́n bá ya lọ ilé olùrànlọ́wọ́ ọ̀hún.
Kí ni kí á wá wí sí gbogbo nǹkan wọnyi?
Mo wà ní àìlẹ́bi níwájú rẹ̀,mo sì ti yẹra fún ẹ̀ṣẹ̀.
Ní orí Twitter, àwọn eniyan kò mẹ́nu kúrò lórí ọ̀rọ̀ ẹlẹ́dẹ̀ nàá nítóri wọ́n ní oun ni ó ríran pé Naijiria wà lára orílẹ̀ede mẹ́rin tí yóò wọ ipele kejì sí àsekágbá ife ẹ̀yẹ̀ àgbáyé tó ń lọ lọ́wọ́ ní Russia.
Iroyin taa gbọ sọ pe, bi Sheu ṣe fi iwe idahun idanwo rẹ le awọn alamojuto idanwo lọwọ lo ba ṣubu lulẹ ti wọn si gbee digba-digba lọ si ileewosan.
Alhaji Agbongoluro Muftau, n ki igbakeji aare ku aabọ, o wa pe akiyeesi  igbakeji aare si awon ohun amayederun ti won
Wọ́n ń sun turari ní gbogbo orí òkè, gẹ́gẹ́ bí ìṣe àwọn tí OLUWA lé jáde kúrò ní ilẹ̀ náà.
Wọ́n bá gbé òkúta náà kúrò.
Ọpọ ti lẹ n kesi awọn gomina ipinlẹ wọn lati ma gba eto naa laaye ni ipinlẹ wọn.
Nínú ọ̀rọ̀ tirẹ̀ agbẹnusọ àwọn ọlógun ti ẹka 4 Brigdade Army, Cap Maidawa Mohammed sọ pé ìwà ti ọmọ ogun Oguche hù yìí kò ba òfin àti àlàsílẹ̀ iṣẹ́ àwọn mú.
Èyí ni àtẹ̀jáde tó wá láti ọ̀dọ̀ àjọ tó ńrísí ìkànìyàn lórílẹ́èdè Nàìjíríá eléyìí tó fi orílẹ̀èdè yìí sí ipò keje nínú àwọn orílẹ̀èdè tó pọ̀ jù lágbayé.
Awọn dokita Australia lọgun lori ọti mimu Johesu ń dí wa lọ́wọ́ isẹ́ nílé ìwòsàn Ifẹ̀ - Dókítà Iya ọmọ naa, Nicola Adcock, ni ẹjọ naa ko mu inu oun dun rara.
Àwọn ọmọ Harimu jẹ́ ẹgbẹrun ó lé mẹtadinlogun (1,017).
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìdìbò Gómìnà ìpínlẹ̀ Ondo 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Wike, má gbé jàgídíjàgan wá sí Ondo, APC kò ní ṣ'èèrú nínú ìdìbò gómìnà tó ń bọ̀- Kalejaye Ẹgbẹ APC ohun ko nilo lati ṣe eeru ninu ibo ni ipinlẹ tawọn araalu ti gba ẹgbẹ naa tọwọ teṣẹ lọdun mẹrin sẹyin.
Ní ìgbà ayé Ṣamgari, ọmọ Anati,ati nígbà ayé Jaeli, ọ̀wọ́ èrò kò rin ilẹ̀ yìí mọ́,àwọn arìnrìnàjò sì ń gba ọ̀nà kọ̀rọ̀.
Inú mi dùn nígbà tí mo rí àwọn ènìyàn mi.
Ọmọ Lefi, ọkọ obinrin tí wọ́n pa, bá dáhùn pé, “Èmi ati obinrin mi ni a yà sí Gibea ní ilẹ̀ àwọn ará Bẹnjamini pé kí á sùn níbẹ̀.
Ọ̀rọ̀ ẹnu olódodo a máa ṣe ọpọlọpọ eniyan ní anfaani,ṣugbọn òmùgọ̀ eniyan a máa kú nítorí àìgbọ́n.
Bí mo ti gbé ojú sókè, mo rí i tí àgbò kan dúró létí odò, ó ní ìwo meji tí ó ga sókè, ṣugbọn ọ̀kan gùn ju ekeji lọ.
maa se aseyori, sugbon ki won maa lo ọgbọn atinuda won lati wa ojutuu si awon
Nígbà tí ó tún di òwúrọ̀ kutukutu wọ́n tún bá a tí ère náà tún ti ṣubú tí ó tún ti dojú bolẹ̀ níwájú àpótí OLUWA, ati pé orí ati ọwọ́ rẹ̀ mejeeji ti gé kúrò, wọ́n wà nílẹ̀ ní ẹnu ọ̀nà, ara rẹ̀ nìkan ni ó kù.
Bí n kò bá tíì fìdí majẹmu mi múlẹ̀ pẹlu ọ̀sán ati òru, tí n kò sì ṣe ìlànà fún ọ̀run ati ayé, 
Ó kígbe pé, “Bí ẹnikẹ́ni bá júbà ẹranko náà ati ère rẹ̀, tí ó gba àmì rẹ̀ siwaju rẹ̀ tabi sí ọwọ́ rẹ̀, 
Eyi lo mu ki Obaseki lọ sinu ẹgbẹ oṣelu PDP, nibi to wọle ibo gomina ipinlẹ lẹẹkeji.
Láti ọdún-un 2016, ẹ̀ka- ìlú náà ti di ibùdó fún  “20,000 ọ̀nà láti gbà kú ní Yau Ma Tei”, ìtọ́nà “ìrìnàjò afẹ́ ìpànìyàn” tí Melody Chan àti èmitìkarami ṣe olùdásílẹ̀, tí ó ti ń gbé àdúgbò náà fún ọdún púpọ̀.
Lara awọn to fi ara gba ninu aisan naa ni awọn oṣiṣẹ eto ilera mẹrinla, ninu eyi ti mẹẹrin ti j'ọlọrun nipe.
SERAP gbé Fashola lọ sílé ẹjọ́ nítorí ìpèsè iná mànàmáná
Kọmiṣọna feto ilera nipinlẹ Ekiti, Dokita Mojisọla Yaya Kọlade ṣalaye ninu atẹjade naa ṣalaye pe gbogbo ilana to yẹ ni titẹle ni wọn n tẹle gẹgẹ bi ajọ to n gbogun ti ajakalẹ arun lorilẹede Naijiria, NCDC ṣe laa kalẹ.
 Eleyii ti wọn ṣaṣẹyege ninu ọpọ ẹjọ ni Ile-Ẹjo Giga julọ orilẹ-ede yii, eleyii ti o ti fun ipinlẹ Eko ni ọpọ agbara, ti awọn ara ilu naa ti janfani wọn.
Ọpọlọpọ igba ni awọn to lọ ṣiṣẹ nilẹ okeere maa n nilati fi owo ranṣẹ sile ki nkan tun le rọrun sii fun ẹbi, ara ati iyekan ti wọn ti fi silẹ ni ilu wọn.
Ọ̀nà yìí já sí ọ̀nà míràn tí ènìà bá tọ̀ọ́ já tán.
Ajo to n mojuto isele pajawiri National Emergency Management Agency (NEMA) ti gba ogoji omo orile-ede Naijiria lati orile-ede Libya ti won n gbero lati wo ile-okere, sugbon ti irin-ajo ohun ja si paboOsise ajo NEMA to n mojuto eto pajawiri , ogbeni Segun Afolayan, soro ohun di mimo nilu Eko lojo Eti(Friday) pe, awon arinrin-ajo naa bale si papako ofurufu Murtala Muhammed International Airport, Ikeja, nilu Eko laago mesan an aabo lojoBo(Thursday).
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Manchester City vs Chelsea:Manchester City pàdí ọrẹ dà f'ogun ẹ̀yìn ja Chelsea 23 Bélú 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Frank Lampard to jẹ akọnimọọgba Chelsea funra rẹ ti figba kan gba bọọlu fun Man City lẹyin to kuro ni Chelsea.
Oríṣun àwòrán, @Pear video Àkọlé àwòrán, Ileegbe Arewa kan Iya onile Lisa ni oun mọọmọ gbe fidio naa sita ni ki Lisa le yipada lẹyin ọpọlọpọ igba ti oun ti kilọ iwa ibajẹ yii fun un ni kọrọ ati ni gbangba.
Ó dàbí wípé ajílẹ̀ ni wọ́n nfi ìgbẹ́ẹ màlúù yìi ṣẹ nítorípé ìgbẹ́ ọ̀ hún pọ̀ púpọ̀ tí wọ́n rọ́ sí ojúkan.
Mo dùbúlẹ̀, mo sùn, mo sì jí,nítorí OLUWA ni ó ń gbé mi ró.
Eto idibo ẹgbẹ oṣere tiata Yoruba, TAMPAN ẹka ti ilẹ Gẹẹsi Laarin ọsẹ yii naa ni wọn ṣe eto idibo fun igbimọ alakoso ẹgbẹ oṣere tiata TAMPAN ni ilu London.
àwọn ọmọ Bakibuki, àwọn ọmọ Akufa, àwọn ọmọ Hahuri,
Wàyí ò, tí a bá jẹ́ ọmọ, ajogún ni wá.
Ìkànìyàn: A ti tó igba mílíọ́nù èèyàn ní Nàìjíríá
'Ejò lọwọ nínú lórí ikọlù àwọn ọmọ ogun Nàìjíríà' Boko Haram pa èèyàn 25 ní Màìdúgùri Ṣé ẹ̀mí Super Falcons gbé e lálẹ́ òní pẹ̀lú France?
Àkọlé àwòrán, Tayọtayọ ni aarẹ Buhari fi kede pe orukọ MKO Abiola ni wọn yoo maa fi pe papa iṣere ọhun Onworan ẹgbẹrun lọna ọgọta ni papa iṣere yii le gablejo rẹ nijoko kan ṣoṣo.
Ṣelemaya ni gègé mú fún ẹnu ọ̀nà tí ó wà ní apá ìlà oòrùn.
Mo sì rò pé ẹ̀yìn náà yóò mọ̀ bí mi ti rí sí yín ki ó tó di pé mo níláti ránṣẹ́ wí pé kí wọ́n lọ wò yín wá fún mi.
Ni bayii awọn panapana ti dawọ ina naa duro, ti ohun gbogbo si ti pada si ipo.
Koda, ko yọ awọn ọkọ silẹ.
 Asofin  Ibrahim Oloriegben lo mu aba naa wa siwaju
F ODUNJO GẸGẸ BO ṢE WA LOJU OPO ITAKUN AGBAYE: Joseph Folahan Odunjo de ile aye lọdun 1904, to si fori sọlẹ si agbegbe Ibara nilu Abẹokuta J.
Contortionist: Mo lè gbé ìfun mi pamọ́ ki n tún sé èémí pẹ́!
Kété tí ọba sì joyè tán ni ọkùnrin náà kú bẹ́ẹ̀ ni ọ̀rẹ́ òun àti ọba pọ̀ gan-an ni.
Àwọn eniyan yóo sá kúrò ní ìlú Gasa; ìlú Aṣikeloni yóo dahoro; a óo lé àwọn ará ìlú Aṣidodu jáde lọ́sàn-án gangan, a óo sì tú ìlú Ekironi ká.
Nígbà tí Ibrahim ṣetán láti pa ọmọ rẹ́ náà gẹ́gẹ́ bí ẹbọ, tó gbọ́wọ́ idà sókè ni Ọlọ́run fi ọmọ àgùntàn ránṣẹ́ láti fi rọ́pò ọmọ ènìà.
O tun fesi lori bi awọn eeyan kan ti n sọ pe ileeṣẹ naa ko ṣe eto iranwọ fawọn ọmọ Naijiria lasiko coronavirus, MultiChoice Group ni ohun ti gbe biliọnu kan naira fun ijọba apapọ gẹgẹ bi owo iranwọ.
Aṣiwaju Tinubu sọrọ yii lasiko to fi n ki awọn eeyan ku abaṣe nibi apero ti wọn gbe kalẹ fun ayẹyẹ ọjọ ibi rẹ, Bola Tinubu Colloquium to waye ni ọjọbọ nilu Abuja.
“Ọlọrun ni yóo dájọ́ fún yín, ẹ̀yin tí ẹ sọ wá di ẹni ìríra níwájú Farao ati àwọn iranṣẹ rẹ̀, ẹ sì ti yọ idà lé wọn lọ́wọ́ kí wọ́n fi pa wá.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Owo tabua ni owo ti ọgagun Abacha fi iye ọdun to wa ni ijọba ko 116,100,000,000.
Aare ajo to n mojuto boolu afowogba lorile-ede Naijiria, Sam Ocheho ti so pe, eto ti n lo lowo pelu ajo to n mojuto boolu afowogba nile okere lati wa se idanileko fawon akonimoogba ere idaraya ohun ni Naijiria.
Nígbà tí ọ̀gágun ati àwọn tí ó wà pẹlu rẹ̀ tí wọn ń ṣọ́ Jesu rí ilẹ̀ tí ó mì ati gbogbo ohun tí ó ṣẹlẹ̀, ẹ̀rù bà wọ́n pupọ.
 gbogbo àjẹsára ni o ń dábòbò ó kéré hpv 16 ati 18 tí ó ń ṣòkunfa ewu kòkòrò jẹjẹrẹ abẹ ́ obìnrin tí ó léwu jùlọ .
Ìkọlù Ọ̀ffà pa èèyàn mẹ́tàdínlógún — Ọlọ́pàá Òkú sùn nínú ìṣẹ̀lẹ̀ ìdigunjalè ní Ọ̀ffà Àwọn adigunjalè ṣọṣẹ́ l'Èkìtì Awọn aworan awọn afurasi yooku ti ọlọpaa gbe jade ree: Oríṣun àwòrán, NIGERIA POLICE Àkọlé àwòrán, Ọwọ ti tẹ awọn afurasi kan, sugbọn wọn ṣi n wa awọn miran Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Ibojì rẹ̀ wà ní ìpẹ̀kun isà òkú.
Dafidi ati gbogbo àwọn ọmọ Lefi tí wọ́n ru Àpótí Majẹmu, ati àwọn akọrin ati Kenanaya, olórí àwọn akọrin wọ aṣọ funfun tí ń dán, Dafidi sì wọ efodu funfun.
O ti su Lulu Jemimah láti maa gba ìdánilẹ́kọ̀ọ́ lórí ìdì tó fi gbọdọ̀ l'ọ́kọ.
Kábíyèsí gbé osuba káre fún Iléesẹ́ BBC Àkọlé àwòrán, Aṣojú ilé iṣẹ́ BBC Yorùbá Aṣojú ilé iṣẹ́ BBC Yorùbá, Jelilat Opẹyẹmi Ọlawale tó jẹ́ alámójúto ìtàkùn ìkànsíra ẹni lójú òpó BBC Yorùbá tẹnu mọ́ pàtàkì ìfọwọ́sowọ́pọ̀ àwọn ojogbon ninu èdè ati asa Yoruba pelu BBC Yoruba.
O ni orile ede South Sudan ti se atunse si orile ede rẹ sibẹ won nilo iranwọ  nipa eto aabo ,atunse ofin ati eto idagbasoke  ohun amayederun lati orile ede Naijiria.
O wa rọ gbogbo awọn ti irufẹ iṣẹlẹ bayii ti ṣẹ si lati ọdọ iranṣẹ Ọlọrun naa bọ si gbangba lati wa wi tẹnu wọn Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Kayefi BBC Yorùba: Bàbá ọmọ, Mọ́ṣúárì, Ọlọ́pàá kẹ́jọ́ rò nípa òkú ọmọ tó pòórá Ni tirẹ, eekan oloṣelu, Abikẹ Dabiri-Erewa to jẹ alaga ajọ awọn ọmọ orilẹede Naijiria loke okun naa ti ṣe afihan atilẹyin rẹ fun Busọla bẹẹni o kan sara si iyawo iransẹ Ọlọrun naa gẹgẹ bii obinrin to lọkan akin ati igboya pẹlu iroyin ẹsun ifipabanilopọ ti wọn fi n kan ọks rẹ lọpọ igba bayii.
Nitori ete iditẹ gba ijọba to fori ṣanpọn lọdun 2015, ogunlọgọ awọn ọmọ orilẹede Burundi lo sa kuro nilẹ naa lọ sawọn ibudo atipo ni awọn orilẹede to mule ti wọn.
Ìdí èyí ni pé kí wọ́n wà ní òmìnira kí wọ́n sì darapọ̀ mọ́n àwọn ẹranko ìyókù nínú igbó.
rẹ lori iroyin ati ikede,Malam Garba Shehu niluu Abuja , pe aare ba awon ebi
Asofin Fatai Mojeed to n ṣoju Ibeju Lekki ni ile aṣofin Eko ni ko dari igbimọ ti yoo ṣe iwadii yi ti wọn si ni ko jabọ fun ile bi ọrọ ba ti ṣe ri.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Hagia Sophia: Tayọ̀tayọ̀ làwọn Musulumi fi kí Jimọ níbẹ̀ 10 Agẹmo 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 25 Agẹmo 2020 Oríṣun àwòrán, EPA Ọpọlọpọ Musulumi lo ya lọ si ile iṣembaye Hagai Sophia to wa ni Istanbul lorilẹ-ede Turkey.
Pada, kí o lọ dúró ti ọba, àlejò ni ọ́, sísá ni o sá kúrò ní ìlú rẹ wá síhìn-ín.
Awọn alẹnulọrọ nibi ipade itagbangba lori atunṣe si abadofin atunṣe si ofin  to nii ṣe pẹlu owo-ori ori ilẹ ni Ipinlẹ Eko, eleyii to waye ni gbagede Ile Igbimọ Aṣofin Ipinlẹ Eko lọjọ Iṣẹgun Tuesday fi mulẹ pe ki ijọba da owo-ori naa pada si ibi to wa.
mojuto bi fifi aye gba igbe-aye alafia, eto aabo, isejoba tiwan-n-tiwan ati
Bàbá Eréko kò le tí ì kú!
jẹ́ kí ẹlòmíràn kórè oko mi,kí o sì fa ohun ọ̀gbìn mi tu.
Akọroyin naa ni o ṣeṣe nibi egbe oju rẹ ti awọn oludoola ẹmi si yara si i ki wọn to gbee lọ si ile iwosan.
Àwọ̀ wọn jẹ́ funfun nini, wọn kò sì ní ewé kankan lórí rárá.
Nígbà náà ni mo wí pé, “Ohun tí ó bà mí lọ́kàn jẹ́ ni péỌ̀gá Ògo kò jẹ́wọ́ agbára mọ́.
Ó dàbí ẹni tí àwọn eniyan ń wò ní àwòpajúdà.
Mo gbọ́, mo sì fẹ́ wò ó, ṣùgbọ́n ìyá wa àgbà kan lé mi sẹ́hìn.
Oríṣun àwòrán, AFP Àkọlé àwòrán, L'ọjọ Aje (Monday), gbajugbaja agbegi-lere Kenya, Edward Njenga (lapa ọtun), ti wọn bi l'ọdun 1922, o n tun ere okuta rẹ ti wọn pe ni Women's Guild Member ṣe pẹlu atilẹyin ọmọ-ọmọ rẹ, ti orukọ rẹ naa n jẹ Edward Njenga, ni ileese rẹ ni Nairobi.
Gbogbo akitiyan BBC Yoruba lati fi idi ọrọ ọhun mulẹ nigba ti o sẹlẹ lo n ja si pabo pẹlu bi ko ṣe si ẹnikẹni ni ijọba ti a kan si, tabi minisita naa fun ara rẹ to fẹ sọrọ lori rẹ.
soro leyin ipade ti won se pelu aare.
Awọn nkan miran to tọka si ni pe ki ọkùnrin mọ pe oun ko le ba obinrin ni ajọsepọ, sugbọn ti ko sọ fun iyawo rẹ ki wọn o to o segbeyawo, to jẹ pe inu igbeyawo ni asiri ti tu.
No reception wedding: Adewale ni àpèjẹ kò ṣe pàtàkì sí òun
" Iroyin sọ pe, afi bi Gomina Makinde ṣe gba ipe lati ọdọ agba oloṣelu kan, pe ko yọnda ilẹ bi plot mejidinlaadọta fun idile Ajimobi.
Ìjà Aole àti Afonja 'tó bí èpè' fún Yorùbá, ẹ̀bi ta ni?
Ilu Sani sun mo Madarumfa ti o wa ni orileede Niger .
Awọn iroyin ti ẹ lee nifẹ si: Awọn afurasi darandaran pa agbẹ l'Ekiti Ijọba ipinlẹ Ekiti f'ofin de Fayemi fun ọdun mẹwa Soyinka s'ọrọ lori ipaniyan awọn darandaran Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Ikọkanla mú Asareli, òun ati àwọn ọmọ rẹ̀ ọkunrin, ati àwọn arakunrin rẹ̀ jẹ́ mejila.
Ẹ yáa tètè fún mi l’ésì o, nítorí òde tí mò ń lọ náà, àrin àwọn onífáàrí gidi ni.
Njẹ àwọn èèyàn kò tí gbàgbé Dagrin, akọrin ‘Rap’ bí?
Ọpọlọpọ ami ẹyẹ ni Tolani ti gba lẹnu iṣẹ aworan yiya to yan laayo.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìtàn Mánigbàgbé: Bode Thomas ní ọpọlọ pípé, ó jẹ́ aṣaájú àmọ́ ó ní inú fùfù 16 Sẹ́rẹ́ 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 19 Sẹ́rẹ́ 2020 Oríṣun àwòrán, Others Àkọlé àwòrán, Bode Thomas ní ọpọlọ pípé, ó jẹ́ aṣaájú àmọ́ ó ní inú fùfù Orukọ Ọmọọba Alfred Olabode Akanni Thomas, ti gbogbo eeyan mọ si Olabode Thomas, lee ma nitumọ mọ niwaju awọn ọdọ iwoyi amọ arugbo rẹ ti se oge ri nilẹ yii, ekisa rẹ si ti lo igba ri.
Ondo PFN - BBC News Yorùbá BBC News, YorùbáFò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Coronavirus: Ìjọ kò ní tilẹ̀kùn ilé ìjọsìn nítorí Coronavirus - Ondo PFN 19 Ẹrẹ̀nà 2020 Oríṣun àwòrán, RCCG Alaga ẹgbẹ ọmọlẹyin Kristi ti ijọ igbalode PFN ni ipinlẹ Ondo, Joshua Kolawole Opayinka ti sọ pe, ijọ ko ni gbe kọkọrọ sẹnu ile ijọsin nitori arun Coronavirus.
A lero lati san owo ile ati owo sọọbu rẹ papọ ni, amọ a gbọ pe ẹlomiran ti gba sọọbu ta fẹ sanwo rẹ naa, idi ree ta fi sanwo ile nikan, ta si ni ki obinrin naa lọ wa sọọbu miran.
Wo ọ̀pọ̀ àsọtẹ́lẹ̀ igba tí Primate Ayodele gbé síta fọ́dún 2021 Amọṣa, oniruru iroyin lo n waye lori ohun to ṣokunfa bi wọn ṣe dana sun arakunrin ti wọn pa lagbegbe Oke-Ado.
Bisoobu ni lati odun 1976 ni oun ti n rẹrin lati igba ti oun ti sawari ẹ̀sẹ̀ Bibeli Mathew 6: 33 ni eyi to si oju oun si fifi satani se yẹ̀yẹ̀ ki oun si maa rẹrin bi oun se n sin Olorun.
 ilo irin , iseamo ati okuta didan gbera larin odun 1500 ati 1000 sk .
Joṣua lọ sí ọ̀dọ̀ rẹ̀, ó bi í pé, “Tiwa ni ò ń ṣe ni, tabi ti àwọn ọ̀tá wa?
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Uzoka jẹ ọmọ to mọwe Bawo lo ṣe ṣẹlẹ Isẹ modẹli ni Uzoka ati ọrẹ́binrin rẹ jijọ n se.
Ẹ má lọ nítorí OLUWA kò ní wà pẹlu yín, àwọn ọ̀tá yín yóo sì ṣẹgun yín.
Anthony Joshua vs Andy Ruiz: DJ Cuppy ní ìgbà gbogbo ni ọlọ́kàn bí Joshua maa ń borí
Ọba Gabriel Adekunle Aromọlan, Owa Obokun ti Ilẹ Ijẹṣa ni Ipinlẹ Oṣun ṣe  abẹwo Ile Igbimọ Aṣofin Ipinlẹ Eko lapa Iwọ-oorun orilẹ-ede Naijiria nibi ti wọn ti gboriyin fun iṣẹ akin Ile Igbiimọ Aṣofin naa fun ilakaka wọn lati gbe ede ati aṣa Yoruba larugẹ.
Èmi a máa sọ pé: ‘Àbá mi yóo ṣẹ,n óo sì mú ìpinnu mi ṣẹ.
Titọ yii n jẹ jade latari awọn agbẹ onirẹsi tawọn Boko Haram dumbu bi ẹran ni Borno ti ko si tii si ojutuu.
Ó ń bẹ̀ ẹ́ kí ó lé ẹ̀mí èṣù náà jáde kúrò ninu ọdọmọbinrin òun.
 lẹ ́ yìn tí ìyá rẹ ̀ ti ja kalẹ ̀ láti ọmọdé tí ẹnìkan tí ó jẹ ́ african american sì gbàá tọ ́ àmọ ́ òun àti bàbá rẹ ̀ tó ń bẹ ní nàìjíríà ń sọ ̀ rọ ̀ déédé .
Dípò òkúta, irin ni n óo mú wá.
Ṣugbọn ilẹjọ ti sun igbẹjọ siwaju si ọjọ kọkandinlogun oṣu kẹjọ ọdun yii.
Salawa ní òun kọ ni ẹni àkkọ́kọ́ ti ọmọkùnrin yìí ṣe irú rẹ̀ fún, sùgbọ́n òun dúpẹ́ fún ìfẹ́ àti àdúrótì gbogbo ènìyàn Àwòrán ìhòhò: Salawa Abeni ti sọ̀rọ̀, ẹgbọ́ ohun tó wí Salawa Abeni: Mi ò leè gbà kẹ́nikẹ́ni bàmí lórúkọ jẹ́ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Salawa abeni Gbajugbaja olorin waka, Salawa Abẹni ti sọ pe, oun ti fi ẹjọ abanilorukọjẹ to fẹ fi aworan ihoho oun lede lori itakun agbaye sun ijọba.
Àwọn mejeeji tí ó pa láìṣẹ̀ yìí ṣe olóòótọ́ ju òun pàápàá lọ.
Ilẹ ti Afọnja mu pẹlu Alaafin Abiọdun, ti ko si fẹ dalẹ, lo sokunfa aawọ to waye laarin rẹ ati Alaafin Aolẹ nitori pe Afọnja kọ jalẹ lati lọ fi ogun ja ilu Iwere Ile, tii se ilu iya Alaafin Abiọdun, ko si sẹni to ye lori idi ti Alaafin Aolẹ fi fẹ ko ogun ja ilu iya baba rẹ Imulẹ ati Epe si ti wa nilẹ tẹlẹ ti Alaafin Abiọdun ṣẹ pe Aarẹ Ọna Kakanfo to ba ko ogun ja ilu Iwere Ile yoo ku iku radarada , rederede ni, idi si ree ti Afọnja se fi aake kọri lati mu asẹ Alaafin Aolẹ ṣẹ Amọ Aolẹ fi ẹjẹ dudu sinu, to si n tu itọ funfun jade lori isẹlẹ naa, lo ba ran Afọnja ni isẹ miran lọdun 1795, pe ko lọ ko ogun ja ilu Apomu, to wa labẹ ilu Ile Ifẹ lasiko naa, tii se orirun iran Yoruba Afọnja se isẹ ti Aolẹ ran lootọ, amọ ni kete to pada de lo gba aafin Ọyọ lọ, to si ni ki Alaafin Aolẹ funra ara rẹ fi ori apere silẹ, eyi si lo mu ki Aolẹ gbe nkan jẹ, to si gbẹmi ara rẹ Lootọ lawọn Alaafin kan jẹ lẹyin Aolẹ, amọ ko pẹ ti gbogbo wọn fi waja, titi di ọdun 1802 ti Alaafin Majotu jọba, lati akoko yii si ni Afọnja ti n tiraka lati fi agbara kun agbara rẹ eyi to papa bu lọwọ Afọnja gba ilu Ilọrin labẹ akoso ilu Ọyọ, to si kede pe ilu naa ti di ilu olominira.
Kíkọ́ tí wọ́n kọ́ ilé náà sí inú igbó tún yàwá lẹ́nù díẹ̀.
Ikọ̀ aláàbò Nàìjìríà dojú kọ Shiite Ọlọ́pàá mú 115 ẹlẹ́sìn Shiite Èmi kò ní kí Shiite má ṣe ẹ̀sìn won o -Muhammadu Buhari Musa ni o ṣeeṣe ki iye eeyan to ku ṣi lekun si nitori bi awọn ọmọ ẹgbẹ wn ti ṣe faragbọta.
Asoju orile ede Naijiria ni Poland, Eric Adagogo Bell-Gam wa gbosuba fun awon omo orile ede Naijiria  to n gbe orile ede Poland , bi won se n je asoju rere fun orile ede Naijiria.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Coronavirus Vaccine: Ṣé abẹrẹ àjẹsára ti wà fún àrùn COVID-19?
Oríṣun àwòrán, Saraki/twitter Bákan náà ni ààrẹ ilé ìgbìmọ asofin Bukola Saraki, ti rọ awọn ọmọ orilẹ̀-èdè Nàìjíríà láti nífẹ̀ ọmọnikejì wọn lọ́kan, kí wọn gbé ìgbé ayé ìrẹ́pọ̀ àti ìwà àláfíà pẹ́lú gbogbo alábágbé wọn, láì fi tàsìkò ọdun yìí nìkan ṣe.
Iṣẹ́ bọ́ lọ́wọ́ ọlọ́pàá ọ̀mùtí ní ìlú Eko O ni oun ti fi ọrọ naa to awọn agbofinro leti.
’ rèé Ẹ̀yin èèyàn Oyo, ẹ sọ tẹnu yín lórí àbá àjẹbánu tí Makinde dá - SERAP Sanwoolu ṣe é dáa fún wa níbodè Lekki, Ikoyi - Awakọ̀ ní Lekki Poly Ibadan: Ọjọ́ iwájú la rò táa fí dáná sún fóònù àwọn akẹ́kọ̀ọ́ Ninu iṣẹ ikini ku ọdun ti iyawo rẹ, ti oun naa jẹ oṣere, Joke Silva, ran si ọkọ rẹ, o ṣapejuwe Olu Jacobs gẹgẹ bi itansan oorun to ṣe iyebiye.
4 Agẹmo 2020 Oríṣun àwòrán, others Àkọlé àwòrán, Àkójọpọ̀ mẹ́wàá lára àwọn Ọba Ilẹ̀ Yorùbá tí wọ́n lé kúrò ní ipò Ọba.
Jose Mourihno fakọ yọ pẹ̀lú bí Tottenham se na West Ham!
Ọ̀rọ̀ Ìtùnú fún Àwọn Ọmọ Israẹli.
ọgọ́rùn ún awọn ọmọde  ti won
Ọjọ kẹtalelogun, oṣu Kẹta, ni ijọba Naijria da eto irinna oju ofurufu duro fun awọn baalu ilẹ okeere, nitori itankalẹ aarun coronavirus.
Èyí ni pé nígbà tí ẹnikẹ́ni bá wà ninu Kristi, ó di ẹ̀dá titun.
Ọ̀rọ̀ wọn náà wà di ti ajá tí kì í lọ kí korokoro rẹ̀ gbélẹ̀.
Gbà mí, kí o sì yọ mí nítorí òdodo rẹ;tẹ́tí sí mi kí o sì gbà mí là!
Ajọyọ ni ijọba ibilẹ Fayẹmi 06:37am At'agba at'ọmọde ni ijọba ibilẹ Ọyẹ ti oludije fun ipo gomina ni ẹgbẹ oṣelu APC, Kayọde Fayẹmi ti wa tu sita lowurọ kutu hai fun ajọyọ pe Fayẹmi n jawe olubori ninu idibo naa.
Akọnimọọgba fun ikọ orilẹede Bulgeria, Benid Amar, ni oun fi oju ri i bi awọn elere idaraya kan ṣe koju wahala ni papakọ ọkọ ofurufu ilu Eko fun ọjọ meji.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Gọngọ sọ, ẹlẹ́há pàdé àwọn tó lùú ní jìbìtì nílùú Eko lọ́jà Ibadan Oxfam fi kun wi pe pẹlu u bi Naijiria se jẹ orilẹ-ede to n pese epo rọbi julọ ni ilẹ Afirika, ko ye ki wọn jiya amọ iwa ibajẹ ati jẹgudujẹra lo n fa ifaseyin fun awọn araalu.
Oríṣun àwòrán, Lawma Lagos Igbimọ ẹlẹni ogún ọhun ni yoo mojuto gbigba ọdọ ẹgbẹrun lọna ogún si iṣẹ nipinlẹ Oyo ati Eko, nigba tawọn ọmọ igbimọ mii naa wa kaakiri awọn ipinlẹ yoku yika Naijiria.
 orisi mẹtẹẹta lo se e yẹwo labe ẹrọ mikroskopu .
Aworan arabinrin kan ti o bimo sinu odo Red Sea ti o wa ni apa gusu Sinai lorile-ede Egypt ti tan kaakiri ori ero ayelujara, nigba ti arinrinajo afe omo orile-ede Russia ya foto arabinrin naa lati ori petesi re, ti o se gbe sori ero ayelujara.
Nítorí náà, ẹ kó àwọn aláìníláárí eniyan tí wọn ń hu ìwà ìkà ní Gibea jáde fún wa, kí á sì pa wọ́n, kí á mú ibi kúrò láàrin Israẹli.
“ ‘Wo bí àwọn ọ̀tá ti mọ òkítì sí ara odi wa láti gba ìlú wa.
2019 Elections: Àwọn olùdíje ipò Gómìnà ní Kwara yóò sọ ààtò wọn
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Kí ní Khafi BB Naija yóò pàdánu tí iṣẹ́ ba bọ́ lọ́wọ́ rẹ̀?
Jotamu bá sá lọ sí Beeri, ó sì ń gbé ibẹ̀, nítorí ó bẹ̀rù Abimeleki arakunrin rẹ̀.
Igi tó dá kìí pẹ́ nígbó
Gbogbo awọn fọto/aworan wọnyi wà labẹ koko aṣẹ fun lilo wọn.
Ẹ kò ní rí àwọn aláfojúdi náà mọ́,àwọn tí wọn ń fọ èdè tí kò ní ìtumọ̀ si yín,tí wọn ń kólòlò ní èdè tí ẹ kò gbọ́.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Access Bank: Babaláwo ní òun yóò t'ọwọ́ Ifá bọ̀ọ́, tí Access Bank kò bá dá owó ìyá òun pádà 21 Ògún 2020 Oríṣun àwòrán, Instagram/Oluwu Jogbodo Orunmila Ṣe kii ṣe pe ile ifowopamọ Access bank n fi ori ọka họ imu bayii?
Nítorí náà, sọ fún àwọn ọmọ Israẹli pé èmi OLUWA Ọlọrun ní ṣé ẹ óo máa ba ara yín jẹ́ gẹ́gẹ́ bí àwọn baba yín, ẹ óo sì máa ṣìnà tẹ̀lé àwọn nǹkan ìríra wọn?
Eeyan mẹta si wa ninu isesi to l'ewu lasiko ti eeyan mẹta miran wa ninu isesi to balẹ.
Pọfu Pọọfu atawọn ipanu mii Oríṣun àwòrán, Getty Images Yoo ya yin lẹnu pe awọn nkan to ṣee wọn sẹnu lai fi akoko ṣofo maa n ta daadaa lasiko ipade adura yii.
Àwọn tó jí ìbejì mi gbé ti pè mí ṣùgbọ́n N50 mílíọ̀nù tí wọ́n ń béèrè pọ̀ ju agbára mi lọ-Akeugbagold Yorùbá rẹwà, kọ́ nípa àwọn ọ̀rọ̀ tí ìró ẹnu wọn jọra àmọ́ tí ìtumọ̀ wọn yàtọ̀ TB Joshua, Apostle Suleman, Odumeje, D.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Nigeria Slave Trade Descendant: Wo àwọn ìran ẹrú tí kìí lọ́kọ tàbí aya ní Nàìjíríà 15 Owewe 2020 Oríṣun àwòrán, Getty Images Owo ẹru ni Naijiria waye nigba ti awọn alawọ funfun ko ilẹ Afrika ni ẹru, amọ o ṣeni laanu wi pe titi di ọdun 2020 ti a wa ninu rẹ lọwọlọwọ yii, bi kii ba ṣe lati idile ẹru, awọn idile ẹru naa ko le fẹ ọkọ tabi aya.
apapo awon omo orile-ede Naijiria lati samulo akoko awe yii fi panupo gbadura ki
Wọn ke si ijọba ipinlẹ Ọyọ lati daṣọ ro wọn lori awọn orule ti atẹgun ojo ṣi lọ.
Sotitobire: Àwọn ọmọ ìjọ yarí, wọ́n ní ejò lọ́wọ́ nínú lórí ìdájọ́ tí wọ́n dá fún Alfa Babatunde
Oríṣun àwòrán, Twitter/Muhammadu Buhari Ohun ti a gbọ ni pe ọkunrin ti ni arun itọ ṣuga ati arun jẹjẹrẹ lara tẹlẹ ki o to lugbadi coronavirus.
Kàkà bẹ́ẹ̀, ọ̀rọ̀ rere, tí ó lè jẹ́ ìrànlọ́wọ́ nígbàkúùgbà ni kí ẹ máa sọ jáde lẹ́nu.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Osinbajo: Igbákejì ààrẹ Yemi Osinbajo ni ìwà àjẹbánu lẹ́nu iṣẹ́ ọba ló le jù nínú ìṣòro Nàìjíríà 22 Owewe 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, O ni iṣoro NAijiria ko lee din ku ninu ojuṣe rẹ rẹ gẹgẹ bii aṣiwaju ilẹ Afirika Igbakeji aarẹ orilẹ-ede Naijiria, Ọjọgbọn Yẹmi Oṣinbajo ti ṣalaye pe yiyan awọn ọlọpọlọ pipe si ipo gbogbo lo tọna.
Igberu ti ba eto oro aje orile-ede Ethiopia, amo, laasigbo ti o n waye naa ti sakoba lopo-lopo lorile-ede ohun.
Ọkunrin ọlọ́rọ̀ kan wà, orúkọ rẹ̀ ń jẹ́ Kiṣi, ọmọ Abieli, ọmọ Serori, ọmọ Bekorati, ọmọ Afaya láti inú ẹ̀yà Bẹnjamini.
O ni wahala laarin awọn agbẹ olohun ọgbin atawọn darandaran to jẹ Fulani ti pẹ bi ọwọ aṣọ, awsn eeyan kan lo kan fẹ bẹrẹ si ni fi oṣelu pọn jẹbẹtẹ lakisa lori rẹ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Kí ló máa ń wú ìyá Nike Davies lori láti wé gèlè ràbàtá?
Ẹgbọn iya oloogbe ti o ba wa sọrọ, Arakunrin Ọlalẹyẹ Dauda ni Baraka nikan lo le ṣe alaye bi ẹmi ṣe bọ lọrun oun.
Nítorí náà, bí ó bá jẹ́ pé ètò iṣẹ́ alufaa ti ìdílé Lefi kò ní àbùkù, tí ó sì jẹ́ pé nípa rẹ̀ ni àwọn eniyan fi gba òfin, kí ló dé tí a fi tún ṣe ètò alufaa ní ìgbésẹ̀ Mẹlikisẹdẹki, tí kò fi jẹ́ ti Aaroni?
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Obadiah Mailafia: DSS ti fi igbákejì gómìnà CBN tó ní gómìnà kan ní Àríwá Naijiria ní Ọ̀gá Boko Haram sílẹ̀ 14 Ògún 2020 Oríṣun àwòrán, FACEBOOK/OBADIAH MAILAFIA Igbakeji Gomina Banki Apapọ Naijiria (CBN) tẹlẹri, Obadiah Mailafia ti ni oun ko mọ wi pe wọn ka ohun oun silẹ lasiko ti oun ṣe ifọrọwanilẹnuwo pẹlu ileeṣẹ redio.
Jẹfuta bá kó gbogbo àwọn ọkunrin Gileadi jọ, wọ́n gbógun ti àwọn ará Efuraimu, wọ́n sì bẹ̀rẹ̀ sí pa wọ́n, nítorí pé àwọn ará Efuraimu pe àwọn ará Gileadi ní ìsáǹsá Efuraimu, tí ó wà láàrin ẹ̀yà Efuraimu ati ẹ̀yà Manase.
 Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Promise Akinlade: ọmọ ọdún mọ́kànlá tó ń fi ìlù dárà bíi àgbàlagbà sọ̀rọ̀ nípa tálẹ́ǹtì rẹ Ohun to yẹ ki o mọ niyi: *Ṣaaju ninu atẹjade to fi sita ni ibẹrẹ ọdun yii, ileeṣẹ ọrọ okeere l'Amẹrika ti kọminu lori igbesẹ ti ijọba apapọ atijọba ipinlẹ ni Naijiria n gbe lori ọrọ ẹsin."
Bí àwọn eniyan rẹ bá bi ọ́ pé kí ni ìtumọ̀ ohun tí ò ń ṣe yìí?
Uzoma wa dupẹ lọwọ gbogbo awọn to gbaruku ti mọlẹbi ti o si ni nigba ti gbogbo nkan yoo ba fi lọlẹ awọn yoo ṣeto iranti isinku rẹ lọdun to n bọ Oríṣun àwòrán, Instagram/official_Majek Fashek Ìdí rèé tí a ṣe fẹ́ sin Majek Fashek sílẹ̀ Amerika- Randy Fashek Idile gbajugbaja akọrin Raggae ni, Majek Fashek to ti di oloogbe bayii ti sọ pe orilẹede Amerika ni yoo ti wọ kaa ilẹ lọ.
’ “Gbogbo àwọn eniyan yóo sì dáhùn pé, ‘Amin.
O sọ eyi gẹgẹ bi esi si iroyin ti awọn ileeṣẹ iroyin kan gbe jade lọjọ kẹrinla, oṣu Keje pe ajọ Aṣọbode ti kilọ pe ki awọn eniyan ṣọra fun tomato alagolo onimajele to ti wa ni ọja.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù PTF Nigeria Covid-19: Ààrẹ Buhari ní iṣẹ́ sí wà nílẹ̀ tí ìgbìmọ̀ yóò ṣé kí wọ́n sì wá níbẹ̀ dì 2021 21 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 22 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Oríṣun àwòrán, @MBuhari Aarẹ orileede Naijiria Muhammadu Buhari ti fontẹ lu ki igbimọ amuṣẹya lori kikoju arun Covid-19 ni Naijiria PTF maa ba iṣẹ wọn lọ di ọdun 2021.
O fi kun un pe oun yoo sa ipa oun gẹgẹ bii aṣiwaju lati mu idagbasoke ba awọn ọdọ to ba fẹ yan orin Fuji laayo Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Adari ẹka UNGA ti o n fi ipo silẹ, María Fernanda Espinosa Garcés lo fi eyi lede lasiko to n se ipade ijiroro pẹlu Aarẹ Muhammadu Buhari ni ilu Abuja.
Hodia fẹ́ arabinrin Nahamu, àwọn ọmọ wọn ni wọ́n ṣẹ ẹ̀yà Garimi, tí wọn ń gbé ìlú Keila sílẹ̀, ati àwọn ìran Maakati tí wọn ń gbé ìlú Eṣitemoa.
Ẹ bá mi wá nọ́ńbà ìpè òbí ọmọ Mummy Calm Down jáde - Yinka Ayefele Ọlọ́pàá sálọ fún aráàlú l‘Okeho, nígbà tí wọn yari láti ṣun olè méjì tó kù Èèyàn 481 míràn tún kó COVID-19 ní Nàìjíríà l'Ọ́jọ́bo Ọmọ Ọba Dubai yóò san owó ìtọ́jú ọmọ Nàìjíríà tó bí ìbẹrin sí Dubai tí kò sí rówó san Oríṣun àwòrán, @BBCSport Lẹyin to sọ goolu mejidinlogun ṣawọn fu ikọ Lille ni saa to kọja ni oju ti wa lara rẹ pe o ṣeeṣe ko tẹkọ leti lọ si Napoli laipẹ.
Ọmọ orilẹ-ede France ọhun sọ pe oun yoo sọ owo naa di ilọpo meji, to ba ti pe ẹgbẹrun mẹtadinlọgbọn Pọhun, to jẹ afojusun oun.
Kò ní kígbe, kò sì ní pariwo,kò ní jẹ́ kí á gbọ́ ohùn rẹ̀ ní ìta gbangba.
O wa ro awon adari egbe osise
Fayemi kọ ni alaṣẹ ijọba ti yoo kọkọ ni Covid-19 ni Naijiria.
Ọmọ Nàìjíríà kan gbé Fásitì Oxford lọ sílé ẹjọ́ tàko oríkí ọrọ 'Mortgage' nínú ìwé àtúmọ̀ ọrọ A tun rinrin ajo de agbegbe Tipper Garrage nilu Ibadan: Awakọ ero kan ti o ba wa sọrọ nibẹ fi ẹhonu han wi pe awọn adari orilẹede yii ko nifẹ ara ilu bo ti n wu ko mọ.
Ìyípadà ọkàn yín kì í ṣe láti ọ̀dọ̀ Ọlọrun tí ó pè yín.
Sugbọn kan to wa nibẹ ni pe wọn le kọja bose yẹ.
Èmi Paulu, aposteli Kristi Jesu, nípa ìfẹ́ Ọlọrun gẹ́gẹ́ bí ìlérí ìyè tí ó wà ninu Kristi Jesu, èmi ni mò ń kọ ìwé yìí–
Ariwo wíwó odi Babiloni yóo mi ilẹ̀ tìtì, a óo sì gbọ́ ìró rẹ̀ káàkiri àwọn orílẹ̀-èdè.
Ijọba ipinlẹ Delta:Gomina ipinlẹ Delta, ti kede pe ko gbọdọ si lílọ ati bibọ laarin aago meje irọlẹ si meje àárọ̀ nitori aarun coronavirus.
Tí a fiṣọwọ́ ní 5:31 3 Ọ̀pẹ̀ 20205:31 3 Ọ̀pẹ̀ 2020 Ìdí tí mi ò fi lè parí ìjà pẹ̀lú Ààrẹ Ọ̀nà kakanfò, Gani Adams - Obasanjo Ọpọ iroyin lo ti waye lori pe boya gbungbungbun n bẹ laarin awọn aṣiwaju ilẹ Yoruba mejeeji yii.
Àwọn ọmọ rẹ̀ a máa lọ jẹ àsè ninu ilé ara wọn.
Nígbà tó yá, Elija wí fún gbogbo àwọn eniyan náà pé, “Ẹ súnmọ́ mi níhìn-ín.
Wọ́n rán àwọn amí kí wọ́n ṣe bí eniyan rere, kí wọ́n lè ká ọ̀rọ̀ mọ́ ọn lẹ́nu, kí wọn wá fi lé gomina lọ́wọ́, kí gomina dá sẹ̀ría fún un.
Eeyan irinwo le ni mọkandinlogoji lo farako arun naa ti eeyan mẹfa si baa lọ.
Oríṣun àwòrán, Min edu Oríṣun àwòrán, Ministry of edu À ó ṣe àtúngbéyẹ̀wò àsìkò ìwọ́le àwọn akẹ̀kọ̀ọ́-Ìjọba apapọ̀ Oríṣun àwòrán, Adamu Adamu Ìjọba àpàpọ̀ ni ni òun yóò ṣe àtúngbéyẹ̀wò àsìkò ìwọ̀lé àwọn akẹ́kọ̀ọ́ ní Nàìjíríà.
nitori iwa otito ati ododo to n lo lasiko ijoba rẹ.
Itsekiri lati ipinle Delta, pe ki Olorun fun un ni alaafia ati emi gigun lorile
Gẹ́gẹ́ bí mo ti sọ ṣáájú, n kò fẹ́ràn obìnrin ṣáájú àkókò náà, wọn tilẹ̀ n máa rùn sì mi ni, n kò sì mọ ohun tí ó fa ti fífẹ́ tí mo déédéé wá fẹ́ràn obìnrin náà ju ti ìtọ́jú mi tí o ṣe nígbà náà lọ, ṣùgbọ́n kí má sa fà á gùn lọ títí, góńgó orí ẹ̀mí mi ni ọmọ náà dúró lé, ọ̀rọ̀ rẹ̀ kìí síí kírò lẹ́nu mi tó bẹ́ẹ̀ tí ó jẹ́ pé àwọn enìkejì mi máa ń fi mi ṣe yẹ́yẹ́ ṣa ni.
N óo fi ẹsẹ̀ rẹ̀ múlẹ̀ ní ilé mi ati ninu ìjọba mi títí lae.
Ṣugbọn OLUWA dá a lóhùn pé, “Alaafia ni, má bẹ̀rù, o kò ní kú.
Eeyan 55,829 ni apapọ ni wọn ti fara ko aarun Coronavirus, ti awọn 43, 610 si ti ri iwosan gba lọwọ ajakalẹ arun ọhun.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Natalia Mufuta ìyá Yakub, Kamil àti Adam sọ̀rọ̀ lórí bí wọ́n ń sọ èdè mẹ́rin pàpọ Gbogbo oṣiṣẹ ileewe to jẹ olukọni atawọn ti ko kọni to fi mọ awọn ọmọ ileewe gbudọ maa wọ ibomu wọn, ijọba yoo si pese awọn ibomu to ṣee tun lo fun wọn.
Àkọlé àwòrán, Miche nigba ti o wa lọmọ oṣu mẹjọ pẹlu Michael Lẹyin eyi ni wọn ri aridaju pe wọn ji Zephany gbe nile iwosan Groote Schuur ti wọn bii si ni Cape Town.
Ẹwẹ, ileeṣẹ ọlọpaa Avon & Somerset ti fi atẹjade sita pe awọn agbofinro yoo ṣewadi awọn ti wọn ere naa.
Mò ń ṣọ̀fọ̀, ìdààmú sì bá mi.
pe awon alase egbe APC kuna lati mu ife won sẹ.
Ko yanilẹnu rara pe Arẹmu ọmọ agba oṣere tiata Yoruba ti o ti doloogbe, Adeyẹmi Josiah Afọlayan, ti ọpọ mọ ni Ade Love naa wọ ọkan lara awọn oṣere tiata Yoruba lọkunrin ti oju wọn gunrege.
Biodun Fatoyinbo fi ipò sílẹ̀ lorí ẹ̀sùn ìfipábánilòpọ̀ Ìpínlẹ̀ Oyo àti Eko kò nífẹ̀ẹ́ láti gba 'Ruga Settlement' láyè Seyi Awolowo, ọmọ-ọmọ Awolowo, kí ló ń wà lórí ètò BB Naija?
Bakan naa lo sọ pe ida ẹgbẹ yoo ge oṣere yoowu to ba ru ofin naa.
Lara awọn to wa nibi eto irin ẹyẹ naa ni igbakeji gomina ipinlẹ Eko, Ọmọwe Oluranti Adebule, adajọ agba ipinlẹ naa, Onidajọ Olufunmilayo Oke, Aya gomina ipinlẹ Eko, Arabinrin Bolanle Ambode, Kọmisọna ọlọpaa Imohimi Edgal pẹlu Amofin agba ni ipinlẹ naa, Ọgbẹni Adeniji Kazeem.
Ṣugbọn wọn o ba a mọ nibi awọn nkan to ṣee foju ri lawujọ nikan o, wọn tun n ṣe igbelarugẹ ọrọ ibalopọ laarin lakọ labo.
Ó mú kí ẹ gbọ́ ohùn rẹ̀ láti ọ̀run wá, kí ó lè kọ yín; ó sì mú kí ẹ rí iná ńlá rẹ̀ láyé, ẹ sì gbọ́ ohùn rẹ̀ láàrin iná náà.
Bakan naa o ni ẹjọ ti wọn kọkọ da ko faaye gba gbigbọ ẹjọ lati ẹnu gbogbo awọn tọrọ kan.
Awọn to sunmọ mọlẹbi rẹ ṣalaye fun BBC News pe ọjọ Satide ni wọn ti gbe edigbadigba lọ sileewosan aladani kanẸni aadọta ọdun ni Abdullahi Lawal nigba to jade laye ni ọjọ Aiku.
Ni ọjọ iṣẹgun ni Fayoṣe farahan ni ileeṣẹ ajọ to n gbogun ti iwa ijẹkujẹ lorilẹede Naijiria, EFCC gẹgẹ bii ileri rẹ to ṣe ninu lẹta kan to ti kọ lasiko ti o ṣi fi wa lori ipo gomina.
” Mose bá fi tìbínú-tìbínú jáde kúrò níwájú Farao.
Ọ̀wọ́ngógó epo bẹntirò: NNPC ni 'ìròyìn ẹlẹ́jẹ̀' ni Kínni ife ẹ̀yẹ ti Tiger Woods gbà ní Augusta fi yàtọ́?
Ki a si to wi, ki a to fọ, eeyan mẹrin ti di oku lẹyin ti ọta ibọn ba wọn.
Wolii obinrin kan, tí orúkọ rẹ̀ ń jẹ́ Debora aya Lapidotu, ni adájọ́ ní ilẹ̀ Israẹli nígbà náà.
O ni wọn ti gbe oku ọmọ tuntun naa pada fun awọn araalu lati lọ sin ọmọ naa.
Ẹwẹ, awọn oloye naa fi ọrọ̀ sita lootọ, awọn ti pari ija ṣugbọn kii ṣe bii ti ki awọn wa bọ ade ori awọn silẹ gẹgẹ bii ọba.
Ṣé Ọlọrun kò ṣe ẹ̀tọ́ láti bínú sí wa ni?
Ìròyìn ìwà ipá ati ti jàgídíjàgan ń kọlura wọn ninu rẹ̀,àìsàn ati ìpalára ni à ń rí níbẹ̀ nígbà gbogbo.
Iwadii kan ti ẹ fihan pe awọn orilẹ-ede ti aarun naa pọ si - awọn ibi to ti n tan kiri nipa ifarakanra - ní oju ọjọ to jẹ ko gbona-kò tutu, ju awọn agbegbe ti aarun naa ko ti wọpọ.
Ẹ jẹ ki a sé atupalẹ wọn lọọkọọkan.
Dafidi bá kọ orin arò fún Saulu, ati Jonatani, ọmọ rẹ̀, 
Oríṣun àwòrán, Tope Alabi O tun salaye pe, oun ko mọ ohunkohun nipa boya awọn alawo lo sin oku adari ijọ to n lọ tẹlẹ nilu Eko, Oloogbe, Oluṣọagutan Iretiọla Ajanaku.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Awọn ọmọogun jẹwọ idi ti wọn ko fi lee pa ina Boko haram Awọn miran n sọrọ si aarẹ Buhari pé o yẹ ko ṣe ohun to yẹ gẹgẹ bii ọgagun to mọ nipa iṣakoso ati pe o yẹ ki wọn fiya to tọ jẹ awọn ọmọ ogun to ṣe eyi Awọn miran fi lede pe, ọmọ ẹbi kan naa ni Daily Trust ati APC fun idi eyi.
Ọ̀kùnrin ọdún 75 bẹ̀ sínú odò Ọ̀sà l'Eko Àwọn ohun tó yẹ kí o mọ̀ nípa igbákejì Jimi Agbaje PDP kó Tinubu ní ìjánu lórí ọ̀rọ̀ rẹ̀ sí Atiku Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Òṣìṣẹ́ Bánkì ni mí l'Amẹ́ríkà kí n tó bẹ̀rẹ̀ Tíátà' Lẹta naa sọ wi pe Gomina ipinlẹ Kano naa ko gba riba ri lati igba ti wọn ti bii, ati wi pe iruẹsun ajẹbanu pẹlu fidio yii ti sẹlẹ si Gomina Ipinle naa tẹlẹri, Ibrahima Shekarau ati Emir ti Kano.
Òun fúnrarẹ̀ ni ọ̀nà ìwẹ̀mọ́ ẹ̀ṣẹ̀ wa.
Wọ́n gba ìlú náà ní ọjọ́ náà, wọ́n sì fi idà pa gbogbo àwọn eniyan ibẹ̀ patapata gẹ́gẹ́ bí wọ́n ti ṣe sí àwọn ará Lakiṣi.
Gbogbo iṣẹ́ agbára ati ipá rẹ̀, ati bí ó ṣe gbé Modekai ga sí ipò ọlá, ni a kọ sinu ìwé ìtàn àwọn ọba Media ati ti Pasia.
Igbimọ apapọ ajọ DSS, ICPC, àti FRSC ni wọn jọ jade ki ọwọ wọn to tẹ awọn oṣiṣẹ ti ọwọ tẹ.
Ipa tí Fathia Balogun kó nínú bí mo ṣe dèèyàn lágbo òṣèré fíìmù Yorùba rèé - Baba Ijesha A ó fún ẹbí akẹ́kọ̀ọ́ Fásitì Ibadan tó dolóògbé ní owóo gbà mábìnú - Ìjọba Oyo Aya gómìnà Kwara fẹ́ ran tìyá- tọmọ olójú búlúù lọ́wọ́ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ohun tẹ́ẹ gbúdọ mọ nípa kókó orí ọyàn yín lásìkò fífọ́mọlọ́yàn Adarí ilé iṣẹ́ ètò ìlera náà sàlàyé pé, ìwádìí ti fi hàn pé, ìwọ́ ọmọ mii ó wùlò jùlọ fún ìtọ́jú àwọn ààrùn kan ti o sì lé wúlò fun ìtọ́jú àwọn ààrùn márùndínláàdọ́rún kan.
Awon olopaa ti sawari oku omo
Atiku Abubakar bẹ̀rẹ̀ ìpolongo ìdìbò rẹ̀ fún 2019 Ìlérí àsan ni Atiku ń se lórí àtúntò Nàíjíríà - APC Ilé iṣẹ́ ọ̀tẹlẹ̀múyẹ́ sọ pé Amina Muhammed tí kọ́kọ́ sọ pé oun ní aya gómìnà Kogi lójúnà àti rí ààyè wọ Aso Rock ní ìlú Abuja.
Gbogbo ara ati ọrẹ lo si mọ wi pe ti Banke ba ti ri baalu, se ni mo ma ma kọrin baalu odaabọ, ba mi ki iya mi ẹlẹkọ'' Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ sí: Ìdigunjale Offa: Ọlọ́pàá gbé N5m sílẹ̀ 'Irọ́ ni pé Boko Haram pa ọmọ ogun ọgbọ̀n ní Borno' Ètíko Onígẹdú, Sinimá tó gba àmì ẹ̀yẹ̀ AMVCA Ifẹ ti Khadijat ni fun ọkọ baalu yii ti di ooto pẹlu bi o ti se gba iwe ẹri di awakọ̀ òfurufú obìnrin àkọ́kọ́ tó wá láti ẹkùn gúusù ìpínlẹ̀ Kwara.
Ọga Agba fun bi iṣẹ ṣe n lọ si ni ajọ NIMC, Abdulhamid Umar lo sọ bẹ ẹ fun awọn akọroyin BBC nilu Abuja.
Bí ọkùnrin náà ti sọ báyìí tan ni a tọrọ àforíjì lọ́wọ́ ọba pé a kò mọ̀ pé òun ni.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ọọ̀ni ilé Ifẹ̀, Ọba Adeyeye Ẹnitan Ogunwusi, Ọ̀jájá Kejì ń ṣe ayẹyẹ ọjọ́ ìbi ọdúnKẹrinlelo Ojaja II ati Akọgun Iṣara fẹnuko pe ki gbogbo ogidi ọmọ Oodua daabo bo ogun idile rẹ.
Aare orile ede Naijiria ,Muhammadu Buhari ti ro awon omo orile ede Naijiria lati mu suuru , o si tun fokan won bale pe” Gbogbo ipa wa la o sa lati je ki gbogbo  awon odaran  yii jeya labe ofin, a o tun dekun iru isele buruku yii lojo iwaju .
Koso-Thomas fikun ọrọ rẹ pe ''ọmọ bibi, oogun lilo ati wahala le fa ki ori obinrin pa.
Iranṣẹbinrin kan ni ó máa ń lọ sọ ohun tí ó bá ti ṣẹlẹ̀ fún wọn, àwọn náà á lọ sọ fún Dafidi.
Davidson tíí ṣe alákòóso ẹ̀kọ́ ní nììjííríà lákòókò yìí jẹ́ ẹnìkaan tí o ti pẹ ní ilẹ̀ wa.
    Nígbà tí ọkùnrin yìí yọ sí ìlú bàbá rẹ̀, ariwo ta, nígbà tí ó sì dé iwájú bàbá rẹ̀ tí ó dọ̀bálẹ̀, tí bàbá rẹ̀ náà sì mọ̀ pé òun ni, ó yọ̀ bí ẹni pé ọjọ náà ni wọ́n ṣẹ̀ṣẹ̀ fi jọba.
Losu kẹjọ ọdun yii ni a gbọ iroyin awọn ẹbi kan nilu Port Harcourt ti wọn dero ọrun latara bi eefin ẹrọ amunawa ṣe ṣeku pa wọn.
Gẹ́gẹ́ bí ìwé ìròyìn tí ò sí ní abẹ́ ìṣàkóso ìjọba  Novaya Gazeta ti ṣe sọ, ó yẹ kí ètò náà tí yóò ṣe àfihàn àwọn ajìjàǹgbara LGBT ní Yaroslavl wáyé ní òwúrọ̀ Ọjọ́rú 23, ní oṣù Ṣẹẹrẹ.
Ọ̀pọ̀ aráàlú Owo wà nílé ìwòsàn, síbẹ̀ APC àti PDP kò gba ẹ̀bi Makinde gba àwọn òṣìṣẹ́ LAUTECH 41 tí ìjọba Ajimobi dá dúró lẹ́nu iṣẹ́ padà Obabinrin Elizabeth kejì kí Nàìjíríà kú oríire òmìnira ọgọ́ta ọdún Aarẹ wa woye pe, kò mú ọpọlọ lọ́wọ́ kí owó epo bẹntiróòlù ní Nàìjíríà dinwo ju ti orilẹede Saudi Arabia lọ.
Awọn ọmọ Naijiria ti wọn fi orilẹ-ede South Africa ṣe ibuje ṣalaye pe ki ọlọjọ to de lawọn ọmọ ilẹ naa yoo ti maa fowo pamọ fun eto isinku wọn eleyi ti ẹnikan ko gbọdọ da iru laṣa lorilẹede Naijiria.
Ó fi ọmọ rẹ̀ rú ẹbọ sísun, a máa ṣe àyẹ̀wò lọ́dọ̀ àwọn aláfọ̀ṣẹ, a sì máa ṣe àlúpàyídà.
Dafidi pè é, ó ní, “Mẹfiboṣẹti!
Èmi ò fi etí mi gbọ́ orin Yoòbá ẹyọkan ṣoṣo níbẹ̀ o.
" Bawo l'oṣe gbọ pe ọkọ rẹ ku?
Laarin aago mọkanla si mọkanla aabọ lojoojumọ si ni eto naa yoo maa waye, ninu igbiyanju lati mu adinku ba itankalẹ aarun aifojuri, ‘Coronavirus’.
Ṣugbọn irun orí yín kankan kò ní ṣègbé.
Ẹ̀yin olùfẹ́ mi, ẹ má jẹ́ kí ó jọ yín lójú bí wọ́n bá wa iná jó yín láti dán yín wò, bí ẹni pé ohun tí ojú kò rí rí ni ó dé.
Bakan naa ni wọn ti rọ awọn arinrinajo lati ṣe pẹlẹpẹlẹ ni agbeegbe naa, ki ohun gbogbo le lọ leto leto.
Àkọlé àwòrán, Góòlù pọ̀ ní ìlú Madaka ṣùgbọ́n wọn kò ní ọ̀nà fún ọgọ́rùn ún ọdún Fred Achem to jẹ dokita obinrin naa sọ fun BBC pe, bi awọn alaboyun ṣe n ngba inu odo kọja, wọn le fara ko aisan, eyi to maa n ṣe ijamba fun ọmọ inu.
Ọba ni mí, mi ò le b'ọ̀rìṣà, Olorì tuntun tó ń bọ̀ já gbogbo ''scale''- Oluwo ti Iwo Oral Sex: Bóo bá ń gba ẹnu ní ìbálòpọ̀, wo àìsàn tóo lè kó lójú ara rẹ Ọkùnrin kan di èrò ọ̀run nítorí pé o fi ẹ̀sùn kan alájọgbélé rẹ̀ pé o n yan ìyàwó ẹnìkan lálè Mọ̀ síi nípa Shina Rambo tó pàdé Jesu lọ́gbà ẹ̀wọn lẹ́yìn tó ti jalè Àmọ̀tekún kò tọ́ lábẹ́ ìjọba, ẹ búra fún wá, ká bọ́ sígbó láti ṣeré ọwọ́ pẹ̀lú ọ̀daràn - Sunday Igboho Ọlọ́pàá Funso ló fi ààyè sílẹ̀ fún mi láti sá kúrò ní àgọ́ ọlọ́pàá tó wà ní Mokola - Sunday Shodipe Ọmọ ẹgbẹ kan, Ọmọbabinrin Tanimowo Okusaga lo fọrọ yii lede ninu atẹjade kan to gbe sita lorukọ gbogbo ẹgbẹ YWC.
Awọn eniyan mẹwa ni wọn sọ pe wọn ti ba okun lọ""."
Ẹfunsetan Aniwura, obìnrin tó ju ọkùnrin lọ Hubert Ogunde rèé, baba àwọn òsèré tíátà Awọn afurasi naa ni agbẹjọro ajọ EFCC, salaye pe wọn n sa nile ẹjọ lati igba ti ẹjọ naa ti bẹrẹ ni ọdun 2017 ti ajọ̀ naa ti n ba ileepo Shell, Eni Spa atawọ̀n yoku se ẹ́jọ̀.
Ki ilẹ ọjọ naa to ṣu ,Fayose sun gbalaja sori ibusun alaisan ti gbogbo aye si ri bi wọn ti ṣe gbe digbadigba wọnu ọkọ alaisan.
O ni imo eko, asa, iselu ti awon omo orile ede Naijiria n mulo, lo je pe lati orile ede Britain ni won ti kọọ.
 But I think football today has not been fair to us,” Enrique said.
ayo,ata-ma-tase  Odion Ighalo gba bọọlu  akọkọ wọle sawọn iko agbabọọlu ti orile ede
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù EndSARS Ogbomosho: Gómìnà Makinde f'òkò kan pẹyẹ méjì nílé àwọn tó kàgbákò ìwọ́de EndSARS àti ààfin Soun 10 Ọ̀wàrà 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 13 Ọ̀wàrà 2020 Oríṣun àwòrán, Seyi Makinde Loju opo Twitter gomina Seyi Makinde, o jẹ ko di mimọ pe oun ti ṣe ibẹwo si idile mẹta ti awọn ọdọ mẹta ti ṣalabapade iku nitori iwọde EndSARS.
Raji Adio ni kaadi idanimọ rẹ fihan pe ọmọ ọgọta ọdun nii ṣe.
lẹ ́ yìn ìgbà tí ọ ̀ làjú wọ agbo ilẹ ́ yorùbá ni ọ ̀ nà tí a ń gba ṣe nǹkan tó yàtọ ̀ .
Àkọlé àwòrán, Mi o joye lati buga, ṣugbọn oye yii wa lati ṣi awọn eeyan leti Ni ti pe Mayegun ko lee dọbalẹ fun elomiran mọ, o ni Alaafin ko ni ki oun ma bọwọ fun awọn to yẹ lati bọwọ fun, gẹgẹ bi ọmọ Yoruba.
Sunday Igboho: A lè kojú Fulani táwọn ọba alayé àti àgbà Yorùbá bá tì wá lẹ́yìn
Uganda gbówó orí lé Whatsapp, Facebook Facebook wọ gau lori aawọ data Whatsapp to jẹ wi pe Facebook lo ni i, sọ wi pe awọn aṣebajẹ yii n lepa awọn eniyan kan ni wọn se se eyi, ati wi pe awọn gboogi ni ẹka imọ ẹrọ lo se isẹ naa.
"Bray wa fikun pe, ""Ominu n kọ wa, ti awọn iroyin yii si n ka wa lara, a o si tọ awọn eeyan ti ọrọ yii gberu lọ lati fi idi okodoro isẹlẹ naa mulẹ."
Ọba Ogunwunsi ni oju oun ti ri lọpọ lọpọ ninu irin ajo ki oun to jọba.
 Eyi yoo tun le mojuto awọn kudiẹkudiẹ to wa ninu ofin yii, ti ilana
Àwọn ọmọ Israẹli tún ṣe ohun tí ó burú lójú OLUWA, OLUWA sì fi wọ́n lé àwọn ará Filistia lọ́wọ́.
Ootọ ni adele adari ajọ NDDC naa ni aṣẹ labẹ ofin lati dahun gbogbo ohun to ṣẹlẹ ni ẹka naa, amọ adele naa ko lee dahun ibeere awọn aṣofin naa nitori pe ko si ni bẹ ni ọdun 2008 si 2012 ti iwa jẹgudujẹra waye ni bẹ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Promise Akinlade: ọmọ ọdún mọ́kànlá tó ń fi ìlù dárà bíi àgbàlagbà sọ̀rọ̀ nípa tálẹ́ǹtì rẹ Wọn ni awọn n rawọ ẹbẹ si Gomina Makinde lati wa nkan ṣe si ọrọ naa.
40 billion ninu oja idokow 4,356.
Bakan naa, ẹgbẹ oselu APC ti sun ipade gbogboogbo rẹ si iwaju di irọlẹ Ọjọ Kẹfa, Ọsu Kẹwa, ọdun 2018.
Èwo ni ìwọ náà rò pé ó dára jù; kí o jẹ́ alufaa fún ilé ẹnìkan ni tabi fún odidi ẹ̀yà kan ati ìdílé kan ní Israẹli?
Ọdun marun sẹyin ni Blankson ati Mercy sẹgbeyawo, ti wọn si bi ọmọ mẹta, sugbọn akọbi wọn obinrin di oloogbe l'oṣu Kejila, 2016.
Oríṣun àwòrán, Other Àkọlé àwòrán, A bi Akintola lọjọ kefa, oṣu keje, ọdun 1910 si idile Akintola Akinbola and Akanke niluu Ogbomoṣo to wa labẹ ipinlẹ Oyo bayii.
A pade ni ikọkọ fun osu diẹ lọdun 2008, ti mo si loyun lọdun 2009.
Jijawe olubori ohun ni o di igbaketa ti Djokovic yoo gba ife-eye idije U.
Coronavirus ti na'wọ́ gán Mínísítà fétò ìlera nílẹ̀ẹ Gẹ̀ẹ́sì Ìròyìn Yàjóyàjó - Nàìjíríà kéde èèyàn míràn pẹ̀lúu àrùn Coronavirus Nínú ọkùnrin àt'obìnrin, ta ni Coronavirus yóò tètè ṣe lọ́ṣẹ́?
Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Teni entertainer: Idi ti mí kìí fi ṣí ìhòhò mi bi àwọn olórin obinrin míran13 Ọ̀wàrà 2020 Fídíò, Ondo election 2020: Àwọn ara ìpínlẹ̀ Ondo ránṣẹ́ sí Akeredolu ohun ti wọ́n ń retí ní báyìí12 Ọ̀wàrà 2020 EndSARS Protest Update: Aisha Yesufu ní Buhari jẹ́wọ́ pé òun kò láànú aráàlú nínú ọ̀rọ̀ rẹ̀23 Ọ̀wàrà 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Ṣugbọn ìgbẹ̀yìn wọn yóo rí bí iṣẹ́ wọn.
Ìgbẹ̀yìn ẹni ti ń la ọwọ́ ni iyì, ṣùgbọ́n ẹ̀tẹ́ ni ìgbẹ̀yìn aláhun.
Mose yìí ni aṣaaju wọn, tí ó ṣe iṣẹ́ ìyanu ati iṣẹ́ abàmì ní ilẹ̀ Ijipti ní Òkun Pupa ati ní ilẹ̀ aṣálẹ̀ fún ogoji ọdún.
Àwọn ẹ̀sùn náà jẹ́yọ nínú àtẹ̀jade kan ti akọ̀wé rẹ̀ Simon Ebebgulem fọwọ́si nílùú Abuja.
Akọ̀ròyin BBC to wa nibi abẹwo gbiyanju lati wadii boya Mustapha wa jiṣẹ Aarẹ Muhammadu Buhari ni, ṣugbọn ko si aridaju ni asiko ti iroyin yi wọle.
Ẹwẹ, Gómínà ìpínlẹ̀ Kwara, AbdulFatah Ahmed náà kò gbẹ́yìn nínú àwọn gómìnà to tí ń kí àwọn ọmọ Nàìjíríà kú ọdun, nínú àtẹjáde kan ti àkọwé rẹ feto iroyin, Abdulwahab Oba kọ, ó rọ àwọn Musulumi lati kẹ́kọ̀ọ́ ìfàràji sí gbogbo ìkọ́ni Ọlọrun, ki wọn sì jẹ olùgbóran sí gbogbo àṣẹ̀ Allah àti pé, ó pọndandan láti jẹ àlàbò fun arákùnrín wọn.
Ileeṣẹ America ni Naijiria fi alaye ọrọ naa sita ni oju opo Facebook rẹ sọ pe awọn awọn ibeere kan ti wọn maa n beere lọwọ awọn to ba kọwe beere fun iwe irinna silẹ America ni kii ṣaba ye awọn to kọwe naa, eyi to maa n fa ki wọn o maa ri iwe irinna wọn gba.
Fara balẹ̀ parí àwọn ètò ọ̀sẹ̀ igbeyawo ti eléyìí, n óo sì fún ọ ní ekeji náà, ṣugbọn o óo tún sìn mí ní ọdún meje sí i.
O fi kun un wi pe o yẹ ki Aarẹ Buhari to n gbogun ti iwa ibajẹ kan an ni dandan wi pe, ko gbọdọ si ẹni ti yoo lọ si oke okun lati lọ se ipade ni okeere.
Ó ti ṣẹ́ gègé fún wọn, ó ti fi okùn wọ̀n ọ́n kalẹ̀ fún wọn.
O ni ise akoroyin je ise to lagbara to ni awon ilana-aatele ati amuye to n mu alaafia dagba sii pelu ifarada laarin awon eniyan.
Awọn oludije lati ẹgbẹ oselu mejidinlaadọta ni wọn yoo figagbaga lasiko eto idibo naa.
Richard Mofe Damijo – Cross Roads
NCS: Òǹwòye kan ní kí ìjọba ṣe àtúnṣe ọgbà ẹ̀wọ̀n àti ìtọ́jú ẹlẹ́wọ̀n
Borno Zabarmani massacre: Ípànìyàn tó wáyé ní Borno fihàn pé omi n bẹ lámù fún ètò ààbò
OLUWA, ìwọ ni mo sá di;má jẹ́ kí ojú ó tì mí laelae!
Óṣeéṣe kí ìjọba yí ètò ẹ̀kọ́ sí ẹ̀kọ́ àárọ̀ àti ìrọ̀lẹ́ láti ṣí iléèwé padà ní Nàìjíríà Iléeṣẹ́ ọlọ́pàá dóòlà ẹ̀mí ọmọ ogun orí omi tí wọ́n jígbé ní ìpínlẹ̀ Ondo Ìjọba kéde àwọn ìlànà tuntun fún òkú sínsín ní ìpínlẹ̀ Ọ̀ṣun Igbagbọ meje nipa nnkan oṣu obinrin ti ko fi idi mulẹ Nnkan oṣu n ba oogun ibilẹ jẹ: Igbagbọ Yoruba ni pe obìnrin to ba n ṣe nnkan oṣu ko mọ rara, ohun ẹgbin si ni.
Nígbà tí ó ṣe, Esau kó àwọn aya rẹ̀, àwọn ọmọ rẹ̀ lọkunrin ati lobinrin, gbogbo àwọn ará ilé rẹ̀, àwọn mààlúù rẹ̀, àwọn ẹran ọ̀sìn rẹ̀, ati gbogbo ohun ìní rẹ̀ tí ó ti kójọ ní ilẹ̀ Kenaani, ó kó kúrò ní ilẹ̀ Kenaani lọ́dọ̀ Jakọbu, arakunrin rẹ̀.
“Yóo ti pẹ́ tó tí àwọn eniyan burúkú wọnyi yóo fi máa kùn sí mi?
títí ìgbà tí ohun tí ó sọ fi ṣẹ,tí OLUWA sì jẹ́rìí sí ọ̀rọ̀ rẹ̀.
Agbegbe àríwá Áfíríkà ni ọwọja àrùn náà ti tàn yíká àgbáyé, títí tó fi dé orile-ede Italy àti Rome, tí wọn ń darí àgbáyé nígbà náà.
ismark Rewane - BBC News Yorùbá BBC News, YorùbáFò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Minimum wage tuntun kò túmọ̀ sí pé #30,000 ni yóò gun owó oṣù rẹ - Bismark Rewane 19 Ìgbé 2019 Oríṣun àwòrán, NLC Àkọlé àwòrán, Aworan awọn oṣiṣẹ Alaga igbimọ amusẹya to gba ijọba apapọ Naijiria nimọran lori ọna ti wọn yoo gba sanwo oṣu tuntun fun awọn oṣiṣẹ, Bismark Rewane, sọ pe kii ṣe gbogbo owo ti oṣiṣẹ n gba ni ẹkunwo naa yoo ba.
" Wòlíì Arole ni, ẹ̀bùn ni awada òun, tí ayé fi ń ko o jẹ, òun kii sì roo awada ti tẹ́lẹ̀, kí òun tó sọ síta, èyí tó máa ń jẹ ìtẹ́wọ́gbà lọdọ aráyé.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù #Fake News: Irọ́ ni!
Ṣugbọn iyatọ le ba eyi nitori pe kii ṣe gbogbo awọn to ba ni aarun naa lo n sọ sita.
Nígbà tí Finehasi, ọmọ Eleasari, ọmọ Aaroni, alufaa, rí i, ó dìde láàrin àwọn eniyan, ó sì mú ọ̀kọ̀ kan, 
Ohun tí Israẹli ń wá kò tẹ̀ ẹ́ lọ́wọ́.
Loju opo Instagram rẹ si lo ti kọkọ se alabapin iroyin naa, to si tun tun sọ lẹyin ti rogbodiyan suyọ lẹyin iwọde EndSARS.
Ọwọ́ ọba Babiloni yóo tẹ̀ ọ́, wọn yóo sì dáná sun ìlú yìí.
Ṣugbọn ó yọ Lọti tí ó jẹ́ olódodo eniyan, tí ọkàn rẹ̀ bàjẹ́ nítorí ìwàkiwà àwọn tí ń ṣe ìfẹ́kúfẹ̀ẹ́ ara wọn.
”A bi oloogbe Mustapha Akanbi ni ojo kokanla,osu kesan an ,odun 1932 ni Accra to je orile ede Ghana.
Ẹ̀rù ati kòtò, ati tàkúté ń bẹ níwájú yín ẹ̀yin tí ẹ̀ ń gbé ilẹ̀ ayé.
Odumosu ni iṣẹlẹ naa waye ni ọjọ kọkandinlọgbọn, osu keje ọdun yii.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Olaitan Olamide: mò lè má nílò ìwé ẹ̀rí mi tí mo bá parí ní LASU Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
'Bí ọlọ́pàá ṣe yìnbọn pa àbúrò mi ni Abuja' Ẹgbẹ oselu APC pín sí méjì Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ìjà ọlọ́pàá àti alápatà ni Bodija gbẹ̀mí Sulia aláìṣẹ̀ ni UCH Adari ajọ WAEC ni orilẹede naijiria, Olu Adenipekun sọ fun awọn akọroyin wi pe awọn to pegede ninu idanwo WAEC naa ni ipinlẹ Ekodin pẹlu ida mẹwa.
Góòlù àrámọ̀ndà ló fi gbẹyẹ lọ́wọ́ LASK fún Manchester United ní ìdíje Europa Àyẹ̀wò gbogbo irinṣẹ́ ètò ìlera ti di dandan báyìí lẹ́yìn ikú Chineme Martins- NFF Wọn yoo lo owo naa lati fi ra awọn eroja itsju alaisan bi i ibọwọ, iboju fun iṣẹ abẹ, ati gilaasi oju fun awọn oṣiṣẹ eto ilera.
Botilẹjẹpe ofin ṣi de awọn ile faaji, ijọba sọ pe oun ti gbẹsẹ kuro lori ofin to de lilọ si awọn ọgba igbafẹ, ṣugbọn ko gbsdọ si ifarakan ara nibẹ.
Olukuluku àwọn ọmọ Israẹli bá kúrò ní ààyè rẹ̀, wọ́n lọ tò ní Baalitamari.
Ninu ẹjọ Nganjiwa ati ijọba orilẹ-ede Naijiria to waye niwaju ile ẹjọ kotẹmilọrun, ko si ẹsun kankan ti a lee fi kan oṣiṣẹ eto idajọ kankan ni ile ẹjọ, ninu eyi ti adajọ agba orilẹ-ede Naijiria wa lai kọkọ gbẹsun naa lọ siwaju igbimọ iṣedajọ orilẹ-ede Naijiria, NJC"" Kini awọn aṣofin n sọ?"
Tinubu ni ofege ati ẹbu ni iroyin to n ja kiri ori ayelujara nipa isẹlẹ ipaniyan to waye ni Lekki lọjọ Isẹgun.
Wọn yóo mọ̀ pé èmi ni OLUWA nígbà tí mo bá dáná sun Ijipti, tí gbogbo àwọn olùrànlọ́wọ́ rẹ̀ bá ṣubú.
O si kọ ọrọ si abẹ fidio naa pe 'funfun ni ọwọ oun mọ, titi ti wọn ba fi da oun l'ẹbi'.
Ní ìgbà tirẹ̀, Israẹli yóo wà ní alaafia ati àìléwu.
Nigba to nba ileesẹ BBC sọrọ lori isẹlẹ yi, Aarẹ ẹgbẹ akọroyin ni Naijiria, Waheed Odusile gbọnmu lori bi ileesẹ agbohunsafẹfẹ AIT ati ileesẹ itẹwe iroyin The Sun se juwe ọna ile fawọn osisẹ toto ọọdunrun niye.
Ṣugbọn bí mo ti ń pè wọ́n tó,bẹ́ẹ̀ náà ni wọ́n ń sá fún mi,wọ́n ń rúbọ sí àwọn oriṣa Baali,wọ́n ń sun turari sí ère.
Nígbà tí kìnnìún yìí lọ tán, obìnrin nì wọ inú ilé tí mo wà, òun àti àwọn arẹwà ti wọ́n tẹ̀lé e.
Díndín ni, bíbọ̀ ni, yíyan ni, gbogbo rẹ̀ á péjọ lórí abọ́ á máa ṣọ̀rá siìnkìn.
o fikun oro re pe, awon osise alaabo yoo ri daju lati daabo bo awon ayika idibo
awon omo orile ede Naijiria loju pe , ijoba ko  ni fi aaye gba ohun ti o le se idiwọ fun eto
Oríṣun àwòrán, Efcc Ajọ EFCC, nipasẹ agbẹjọro rẹ, Rotimi Oyedepo, ṣalaye fun ile ẹjọ pe inu ile Madueke ni wọn ti ko awọn nkan iṣaraloge ọhun.
Àbẹ̀wò Buhari: Mo fẹ́ kí òjò rọ̀ ní Eko, kó sì ba àbẹ̀wò Buhari jẹ́
com Ni Ọjọru ni ileẹjọ kotẹmilọrun to fikalẹ si ilu Ibadan gbe idajọ rẹ sita lori ẹjọ to n waye lori bi ijọba ipinlẹ Ọyọ labẹ Gomina Makinde ṣe tu awọn igbimọ ijọba ibilẹ ka nibẹ.
Ida marundinlọgọrin ninu ọgọrun awọn olowo Afrika lo ṣeeṣe ki owo wọn wa loke okun.
O soro yii lasiko ti Adari ajo to n pese iranwo ojiji fawon Naijiria, NEMA, Iyen Hajia Amina Ahman n sabewo sile ijoba in Gombe.
O ṣalaye siwaju si pe oun ko le sọ bi Gomina Ahmadu Fintri ipinlẹ Adamawa to jẹ alaga eto idibo abẹnu naa ṣe mo ri bọ nigba tawọn agbebọn dabọn bo lẹ.
Ewe, ifarapa ohun lo fihan pe, Messi ko ni kopa ninu ifesewonse ‘E Clasico’ pelu iko agbaboolu akegbe won Real Madrid ti yoo waye lojo kejidinlogbon osu kewa odun ti a wayii.
Awọn akẹgbẹ rẹ yoo ma ka iye igba to n fo soke lori okun.
Nígbà tó yá ni mo bẹ̀rẹ̀ sí ń gbóòórùn nkan tó ń tasánsán bí ọbẹ̀ ata.
 awon iwe re ko ipa pataki ninu idagbasoke esin kristi apaiwoorun .
Ọba orin Saheed Osupa naa ti saaro Dagunro.
Wunmi Toriola: Ọ̀pọ̀ olólùfẹ́ rẹ̀ kò fẹ́ kó bá Seyi Edun ṣe ọ̀rẹ́ mọ́.
 wón n lo sí ilè ìlérí kénáànì .
Kolade Johnson; Iléeṣẹ́ ọlọ́pàá ní ọwọ́ ti tẹ àwọn afurasí ọlọ́pàá tó ṣekúpaá Awakọ̀ òfúrufú Ethiopian Airlines pariwo 'lọ sókè!
Olùṣọ́ bá tún jíṣẹ́ fun ọba pé, “Oníṣẹ́ náà dé ọ̀dọ̀ wọn, ṣugbọn kò pada.
5 miliọnu loṣu lati bọ Ibrahim El-Zakzaky tumọ si ẹgbẹrun lọna mẹrindinlọgọfa (N116,000) lojumọ.
Bi ẹ o ba gbagbe, sẹnetọ Abiola Ajimobi to jẹ wipe ara rẹ ko ya nitori pe o lugbadi COVID-19, ni awọn kan n tan iroyin kalẹ pe o ti ku.
Gege bi ile-ise akoroyin Amaq, won ni ikolu ohun waye lenu ibode awon omo-ogun Marshal Fahim ti o kogun si aarin gusu iwo-orun olu-ilu orile-ede naa ni Kabul,.
Ẹgbọn rẹ, Jamilu Abdullahi to ba BBC sọrọ ni, awọn yoo wa owo itanran lọdọ ọlọpaa lẹyin ti wọn ba tu silẹ.
"Orukọ apejọ ti wọn fun saa ti ọdun to kọja ni Big brother ""perpperdem""."
 Awọn naa ni eto aabo, eto irinna ọkọ, ọrọ-aje lẹka irin-ajo
Amọ, Femi Fani Kayode lasiko to n fesi si atẹjade naa sọ wi pe iroyin naa tabuku oun, to si ba oun lorukọ jẹ.
" O fi kun ikede naa pe, wọn yoo ko gbogbo awọn oṣiṣẹ FSARS ti ko koju oṣuwọn, lọ si ẹka mi i nileeṣẹ ọlọpa, ti wọn yoo si gba awọn akikanju mi i lati rọpo wọn.
Mo kí gbogbo yín ẹ kú àtijọ́ o.
Atiku Abubakar to jẹ ọmọ ọdun mẹ́rìnléláàdọ́rin to si dipo igbakeji aarẹ mu rlaarin ọdun 1999 si 2007 ni awọn eeyan gbagbọ pe oun ni alatako gboogi ti Aarẹ Buhari ni.
N óo sọ yín di ahoro ati ohun ẹ̀sín láàrin àwọn orílẹ̀-èdè tí ó yi yín ká ati lójú gbogbo àwọn tí wọn ń rékọjá lọ.
Isegbe wa gboriyin fun awon eso enu-ibode lori akitiyan won, lati satileyin fun igbese ajo NAQS lati le se aseyori,toripe, ko rorun fun ajo naa lati se aseyori laisi atileyin ohun, sugbon inu wa dun pe, a ni atileyin ile-ise eso eni ibode” Ronke Osundiya.
Wọ́n lọ sí ìlú Bẹtẹli níbi tí wolii àgbàlagbà náà ń gbé, wọ́n sì ròyìn ohun tí wọ́n rí fún un.
Wọ́n dájọ́ ikú nípa yíyẹgi fún David West tó ń pa àwọn obìnrin ní PortHarcourt lónìí Wọn ni Wolii Babatunde ko mọwọ ko mẹsẹ nipa ọrọ to ṣẹlẹ ọhun, koda wọn ni ko si ninu ile ijọsin naa nigba ti iṣẹlẹ naa sẹlẹ.
Asiko ojo ati ara nla yii na si ni Duro Ladipọ mi kanlẹ, ti akukọ si kọ lẹyin ọmọkunrin rẹ.
Yollywood Yemi Shodimu sọ̀rọ̀ pé àṣìlò ẹ̀bùn kò jẹ́ kí Nàìjíríà dàgbà sókè mọ́
Atiku Abubakar naa n ba awon eniyan soro pe , gege bi oun se je onisowo oun mo
Lagos building collapse: Àtúnṣe tí kò bófin mu ló fa ilé tó wó lu ènìyàn méjì ní Oshodi
Jerusalẹmu ati àwọn ìlú Juda, àwọn ọba ilẹ̀ Juda ati àwọn ìjòyè wọn, kí wọn lè di ahoro ati òkítì àlàpà, nǹkan àrípòṣé ati ohun tí à ń fi í ṣépè, bí ó ti rí ní òní yìí.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Àwọn obi ọmọ Obìnrin Chibok ni wọn tí lọkọ ní Cameroon 28 Ọ̀wàrà 2018 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Inu ibanujẹ lọpọ awọn obi ọmọ Obìnrin Chibok wa Àwọn òbí àwọn ọmọ akẹkọ obìnrin Chibok ti boko-haram ji gbé ti figbe síta pé àwọn ní ìròyìn tó dájú wí pé metadinlogota nínú àwọn ọmọ obinrin Chibok lo wà ní àríwá orílèèdè Cameroon.
maa  fọwọsowọpọ  pẹlu iko omo ogun naa ati awon ẹsọ eleto aabo
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Sex for Marks: Aago 9.
Ninu ọrọ tirẹ, olori ipolongo fun Gbajabiamila, aṣoju ṣofin Mumin Jibrin ni Gbajabiamila lo to gbangba sun lọyẹ lati jẹ adari ile aṣoju ṣofin l'Abuja.
'Àìjáfáfá àwọn panápaná ló mú kí ọṣẹ́ iná Akure pọ̀' Èèyàn 573 ló lùgbàdì àrùn Coronavirus ní Naijiria ní Ọjọ́ Aje Ìyà ń jẹ wá ló jẹ́ kí a daṣẹ́ sílẹ̀ - ẹgbẹ́ àwọn dókítà Ohun tí a mọ̀ nípa Ṣẹnetọ Adebayo Osinowo tó dágbére fáyé Dele Momodu ni ọrọ pọ ninu iwe kọbọ pẹlu ọrọ June 12.
Morocco: Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ọkunrin ati obinrin ko le fa ara wọn lọwọ lawọn ilu kan Orilẹ-ede Morocco lodi si ki ọkunrin ati obinrin fa ara wọn lọwọ, di mọ ara wọn tabi fẹnu ko ara wọn lẹnu.
 Wayii o, iwe abadofin ohun tun ta ajo ECOWAS lolobo lati ri daju pe ajo naa pese atileyin ti o se pataki fun aseyori  eto idibo orile-ede mejeeji.
Nígbà tí ó ṣe, iwin burúkú yìí fò mọ́ bàbá mi lágbedeméjì, ibi tí bàbá mi sì ti ń gbìyànjú àti dì i ní ẹsẹ̀ mú ó tún fò si i ni èjìká, nígbà tí ó si di bàbá mi ni ọrùn mú ó gbá a létí tagbáratagbára.
Mo fẹ́ kí ẹ mọ̀ dájúdájú pé àkókò ń bọ̀, ó tilẹ̀ dé tán báyìí, tí àwọn òkú yóo gbọ́ ohùn Ọmọ Ọlọrun, àwọn tí ó bá gbọ́ yóo yè.
Nítorí pé, inú igbó ni ó ti kì í mọ́lẹ̀.
ifẹsẹwọnsẹ mẹrindinlọgọta ọtọtọ ni Ronaldo ti gba goolu mẹta wọle, eleyii ti ko si agbabọọlu miran to tii dan iru bẹbẹ bẹ wo.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ilé ẹjọ́ pàṣẹ kí EFCC gbẹ̀sẹ̀ lé àpò àsùwọ̀n kan tó ní nkan ṣe pẹ̀lú Akinwumi Ambode Ọjà Àgbáláta ní Badagry rèé, níbití ẹran ejò ti dùn ju ẹran adìẹ lọ Fulani kò leè dúró, táa bá lo ohun ta jogún lọ́dọ̀ àwọn bàbá wa - Sunday Igboho Ọlọ́run yóò ṣe ìdájọ́ nkan tó wà láàrin èmi àti Ireti Ajanaku - Tope Alabi Gomina Makinde ni oun gbe igbesẹ naa lati le se koriya fun awọn akẹkọ imọ ofin, ki wọn lee tẹra mọ iwe wọn fun aseyori to lamilaaka.
Ẹsita bá dáhùn pé, “Ìbéèrè ati ẹ̀bẹ̀ mi ni pé, 
ọhun ni Komisona agba fun ajo INEC, alamojuto agba fun  ajo eleto idibo INEC , alamojuto ajo INEC fun
Eto yii jẹ eyi ti BBC n ṣe pẹlu ajọṣepọ ẹgbẹ onimọ Yoruba, iyẹn YSAN ati apapọ ẹgbẹ akomolede ati Aṣa ni Naijiria.
Línda rìnrìn àjò lọ sí ìlú òyìnbó láti lọ bí ọmọ náà tó sì kédé rẹ lóri àtẹ̀jíṣẹ́ instagram rẹ̀ lówùrọ̀ òní.
23 Bélú 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Polio: Bàbá kọ abẹ́rẹ́ àjẹsára kí ọmọ rẹ̀ tó ní àìsàn polio!
Saraki pín owó ìyọ̀nda rẹ̀ fún ẹbí Leah Sharibu àtàwọn míì Ta ni ipò ààrẹ ilé aṣòfin àpapọ̀ tọ́ sí?
Aarẹ Buhari to fọrọ naa lede lati ẹnu oluranlọwọ rẹ lori ọrọ iroyin, Garba Shehu, wa rọ awọn eeyan Adara ati awọn Fulani lati faye gba alaafia laarin wọn.
Oodua Redemption Alliance, Majiyagbe Oodua Vanguard, Awari ọmọ Oodua, Sheik Abdulkareem Aduranigba, Olori Imam ilẹ Yoruba atawọn aṣoju lati ipinlẹ Kwara ati Kogi naa wa lara awọn to kopa nibẹ.
Àyìndé bí mo bá dejò, ó sá di igi oko
Tẹbi tọrẹ ki KWAM 1 fayẹyẹ ọjọ ibi Ọdun 1957 ni wọn bi gbaju-gbaja akọrin Fuji, Olasunkanmi Wasiu Ishola Anifowoshe, ti ọpọ eeyan mọ ọ si Wasiu Ayinde.
Ó fi igi sipirẹsi tẹ́ gbogbo inú gbọ̀ngàn rẹ̀.
gbogbo awon fayawo lati wa ise miran se nitori ile ise Asobode ekun yii ko ni
Ni asiko yii gan ni awọn alakatakiti ẹlẹṣin Maitatsine n ṣe ọṣẹ nipinlẹ to jẹ Gombe lonii, ti ọpọ ẹmi si n sọnu, bẹẹ ni agbara ijọba Shagari ko ka ọpọ itajẹsilẹ to n waye yika Naijiria.
Nítorí pé mọ́jú òní, ojú mi rí nǹkan lójú àlá nípa rẹ̀.
Agbaboolu owo eyin, iko Super Eagles, Kenneth Omeruo ti so pe oun yoo gba iko agbaboolu CD Leganes ni
Wọn mu Ọlọrunwa ni Ebute Meta nilu Eko.
Adesọkan tun fikun pe ẹni to ba n ba eto Amotekun ja, lo n ba iran Yoruba ja, to si kesi awọn gomina ilẹ Yoruba lati mase bẹru nitori digbi ni awọn wa lẹyin wọn.
Kin ni àwọn ohun to yẹ ki o mọ nipa idije naa?
Wọn ka ibo naa de idaji, ni ijọba ologun nigba naa lọhun lai ni idi kan pato kede pe, wọn ko gbọdọ ka esi ibo naa mọ.
Wọn óo máa fi ìyẹ́ fò lọ sókè bí ẹyẹ idì.
Nítorí èyí, kì báà jẹ́ pé a wà ninu ilé ti ibí, tabi kí á bọ́ sinu ilé ti ọ̀hún, àníyàn wa ni pé kí á sá jẹ́ ẹni ìtẹ́wọ́gbà lọ́dọ̀ Oluwa.
Wo díẹ̀ lára àwọn ọ̀rọ̀ ìkẹyìn ti Alexander Akinyele fi léde kó tó papódà Ohun tó ṣe pàtàkì nípa Edgal Imohimi, Kọmisánà ọlọ́pàá tuntun fún ìpínlẹ̀ Ogun Àyẹ̀wò ẹ̀jẹ̀ ti di dandan fáwọn tó bá fẹ́ ṣèyàwó ní Nàìjíríà- Ilé aṣojú-ṣòfin Ìbínú ẹlẹ́wọ̀n!
Ki o to lọ si Arsenal, Unai Emery ti kọkọ ṣakoso ikọ Sevilla ati Valencia lorilẹede Spain.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Búrẹ́dì tí wọn ó fi jẹ ẹ̀wà ni wọ́n lọ rà ni wọ́n pàdé ikú gbígbóná' O ni bi awọn Ọbalaye ba n tẹriba fun iṣẹṣe ati iṣẹdalẹ ilu wọn ni yoo mu ki ilu o toro ki o si tuṣẹ.
Àwọn iranṣẹ mi yóo gé igi náà ní Lẹbanoni, wọn yóo kó wọn wá sí etí òkun.
Ẹni to bori: Morocco Nigeria vs South Africa.
Olori Badrat to bi ọmọ mẹta fun Ọba Adeyemi, rọra se ajọyọ ọjọ ibi ọdun Kọkanlelọgbọn rẹ lori ayelujara naa ni lẹwọlẹ.
Wọ́n dàbí ìkùukùu tí afẹ́fẹ́ ń gbá kiri tí kò rọ òjò.
(Baraba ti dá ìrúkèrúdò sílẹ̀ ninu ìlú nígbà kan, ó sì paniyan, ni wọ́n fi sọ ọ́ sẹ́wọ̀n.
Ati pe mo ni anfanni lati duro ki n fi bimọ, to si jẹ pe oṣu mẹfa lẹyin ti mo ba bimọ tan ni wọn to o le ṣe e, ki ọmọ mi le mu ọyan diẹ.
“Aare ana fun orile ede Naijiria Goodluck Jonathan naa so pe “orile ede Naijiria n koju ipenija , ni eyi ti o nilo olugbala ti yoo gba won sile.
Àjẹ́ àti Aṣẹ́wó ní ìyá Rainbow - Òjòpagogo Ọkọ̀ akẹ́rù tí ìjánu rẹ̀ já ló kọlù ọkọ̀ agbépo tó fa ìjàmbá iná ní Otedola- LASEMA Cardi B ṣàlàyé ohun tó gbé fọ́tò ìhòhò rẹ̀ d'órí ayélujára Instagram Ìdí táwọn olùwọ́de EndSARS fi kọ oúnjẹ àti ọtí ẹlẹ́rìndòdò tí MC Oluomo gbé wá rèé Wo nọ́mbà tí o le è pè láti gba owó gbà-má-bínú tí ọlọ́pàá bá fìyà jẹ ọ́ lọ́nà àìtọ́ l'Eko Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Fídíò, End SARS, End SWAT: Ó pé mi bí SARS kò ṣe sọ mí dolówọ́- Fulani Kwajafa17 Ọ̀wàrà 2020 Fídíò, Soyinka Cancer: Àṣe ara mi ni iso ti n run gbogbo bí mo ṣe n ṣèrànwọ́ lórí jẹjẹrẹ27 Bélú 2019 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Lori ọrọ ipenija aabo to n ranju mọọ mọ Naijiria yii ni ẹgbẹ awọn agba loke ọya Naijiria, Northern Elders Forum (NEF) ati agbarijọpọ awọn ẹgbẹ kan nibẹ ti ni kawọn darandaran fulani o ṣẹri wale si apa oke ọya.
Ni igbà miran kò si ohun ti èniyàn lè ṣe lati yẹ àròkàn pàtàki ẹni ti ọ̀fọ̀ ṣẹ, á ro  àròkàn ṣùgbọ́n ọ̀pọ̀ igbà àwọn ohun miran wà ni ikáwọ́ lati ṣe lati din àròkàn kù.
Nigba to n salaye fun akọroyin BBC Yoruba lori bi isẹlẹ naa se waye, agbẹnusọ fun ileesẹ Civil Defence nipinlẹ Ondo, Ọgbẹni Samuel Ọladapọ sọ pe Ibrahim Ahmed, tii se ọmọkunrin oloogbe naa lo wa si ọọfisi awọn.
Ni kete ti wọn ba ti de ijọba tan, imọ ti ara wọn ati ẹbi wọn nikan lo ku.
#BBCNigeria2019 Ààrẹ ní kí wọ́n wádìí oun tó fa ìjàmbá bààlú Osinbajo Ninu ọrọ to ba awọn oniroyin ss lẹyin ipade naa, Tinubu ṣalaye pe, 'loots ni edeaiyede ti n waye laarin ẹka iṣejọba mejeeji yii lati nnkan bii ọsẹ kan bayii.
ASUU strike: Ẹgbẹ́ olùkọ́ fásitì ń tẹ̀síwájú pẹ̀lú ìyanṣẹ́lódì
Mose ati Aaroni bá wọ inú Àgọ́ Àjọ lọ.
Ní ọjọ́ keji a gúnlẹ̀ ní Neapoli.
Nínú ìkòkò dúdú ni ẹ̀kọ funfun ti ń jade Ìwà rere lẹ̀ṣọ́ ènìyàn Ojú tó rí ibi tí kò fọ́ ire ló ń dúró dè A kì í mọ̀ọ́ gún mọ̀ọ́ tẹ̀ kí iyán ewùrà má lẹ́mọ Ẹni tó láṣọ tí ò léèyàn ìhòhò ló wà Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Ati pe ọpọ ko ni omi to dara, eyi ti yoo mu ko ṣoro fun awọn akẹkọọ naa lati tẹlẹ ilana ijinasiraẹni ati imọtoto ara ẹni.
Hamutali, ọmọ Jeremaya ará Libina ni ìyá rẹ̀.
ọ̀rẹ́ gidi ń bẹ bíi ká f’ẹ́ni dé’nú
    Ìgbà tí ọba tún dìde tan, o ni àfi bí òun tún jà si i àti pé bí kò ba ṣe pé a tètè mú àwọn ni, òun ìbá yí obìnrin náà kúrò lórí òun, eléiìí náà ni a sì ń sọ tí ó já ọwọ́ rẹ̀ gbà lọ́wọ́ wa tí ó tún pa guuru sí obìnrin náà, kí á tó tún ṣẹ ojú pẹ́, ìpàkọ́ ọba ni a tún ń wò ní ilẹ̀, àwọn ará ilé ọba tún mú wọn.
Aarẹ Muhammadu Buhari ti gboriyin fun awọn ikọ agbabọọlu alapẹrẹ Naijiria, D'Tigress pe wọn ku iṣẹ.
Àwọn àgbààgbà ati àwọn ọlọ́lá wọn ni orí,àwọn wolii tí ń kọ́ àwọn eniyan ní ẹ̀kọ́ èké sì ni ìrù
’ A ti mọ òbí 40 nínú 108 t'ọ́mọ wọn bọ́ ní ayédèrú ibùdó atúnwàṣe Ilorin - Ọlọ́pàá Kwara Eto yi la gbọ pe ipinlẹ mẹwaa yoo jẹ anfaani rẹ ti ipinlẹ Oyo si jẹ ọkan lara wọn.
Ṣemaaya, àkọ́bí Obedi Edomu, bí ọmọ mẹfa, àwọn ni olórí ninu ìdílé wọn nítorí pé alágbára eniyan ni wọ́n.
Ṣé o mọ̀ pé o leè forúkọ̀ iléeṣẹ́ rẹ̀ sílẹ̀ lọ́fẹ̀ẹ́?
O dáhùn ó ni, ‘Èmi ni ọmọ aládé ìsàlẹ̀ ilẹ̀, ìkáwọ́ bàbá mi ni gbogbo wúrà, fàdákà, díámọ́ǹdì àti gbogbo òkúta olówó iyebíye inú ilẹ̀ ń bẹ.
Ẹfunsetan Aniwura, ọmọ Ẹ̀gbá tó di akíkanjú obìnrin nílẹ̀ Ibadan Àwọn ọba Yorùbá kan rèé tí wọ́n rọ̀ lóyè, tí ọba míràn jẹ lójú ayé wọn Àjakalẹ-àrun miran to tí wáyé sẹ́yìn, tó tún burú ju Coronavirus lọ ní ajakale àrùn Òfinkin àbí òtútù aya taa mọ sì Spanish Flu Eyí to wáyé láàárín ọdún 1918 sì 1920.
Nibo ni ọrọ ofin ọti mimu ati tita de duro?
 Boya , o ni oro tabi o ko ni, ibi to wu ki o ti bere,ogbon atinuda lo se koko iyen ni yoo  , ran o  lowo lati le mu iyipada rere wa si orile ede re.
Africa 23 Ìgbé 2018 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ìwà ìkórííra n pọ̀si ní orílẹ̀èdè South Africa Olùrànlọ́wọ́ pàtàkì fún ààrẹ Muhammadu Buhari lórí ọ̀rọ̀ ilẹ̀ òkèrè, Abike Dabiri-Erewa sọ pé ọwọ́ òfin ti ba ọlọ́pàá mẹ́rin tó n fi ẹ̀mí àwọn ọmọ ilẹ̀ Nàíjììrà ṣòfò ní orílẹ̀èdè South Africa.
31 Àti nísisìyí èmi báa yín sọ̀rọ̀, ẹ̀yin Méjìlá—Ẹ kíyèsíi, oore ọ̀fẹ́ mi tó fún yin; ẹ gbọ́dọ̀ rìn ní títọ́ níwájú mi kí ẹ sì máṣe dẹ́ṣẹ̀.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Idẹnukọlẹ ìṣèjọba Amẹrika: Ọ́fíìsì Amẹrika ni Nàìjíríà ṣi ń pín ìwé ìrìnna 31 Ọ̀pẹ̀̀ 2018 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 2 Sẹ́rẹ́ 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ise ti bere fun eni to ba fe gba iwe irinna Idẹnukọlẹ ìṣèjọba Amẹrika lo nawo d'orile-ede Naijiria pẹlu bi wọn ti ṣe so iṣẹ gbogbo rọ nileeṣẹ Amerika to wa ni Naijiria lọsẹ to kọja.
Gbogbo Jerusalẹmu kún fún ayọ̀ nítorí kò tíì tún sí irú rẹ̀ mọ́ láti ìgbà Solomoni, ọmọ Dafidi, ọba Israẹli.
Bromage sọ pé Ọ̀rọ̀ sísọ le ṣe àfikún kòkòrò to jáde bíi mẹ́wàá sí igba láàrin ìṣẹ́jú kan, bákan náà ni ariwo pípa tàbí orin kíkọ leè fi kún iye kòkòrò tó ń jáde sínú afẹ́fẹ́.
Kí lo wá fẹ́ ṣe, nítorí orúkọ ńlá rẹ?
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Mr Macaroni sọ nípa eré tí Fraky freaky, Sugar Daddy, You are doing well, freaky spicy fẹ́ Ewu to wa ninu lilo tabi jijẹ ọja ti ọjọ ti lọ lori rẹ Onimọ nipa eto ilera, Dokita Habibat Alimọ sọ pe bi ọjọ ba ti lọ lori nkan jijẹ tabi lilo tumọ si pe, anfaani ati iwulo rẹ ti n dinku tabi bajẹ.
Kí ló dé tí àwọn orílẹ̀-èdè yóo fi bèèrè pé,níbo ni Ọlọrun wa wà?
Bái àwọn adíẹ̀  wọ̀nyí ti lọ tán ni ọkùnrin náà mú ọkọ́ tí ó mú àáké tí ó gbé àwọn ohun èlò tí ènìyàn lè fi wwa ilẹ̀ tí ó sì bẹ̀rẹ̀ sí wa ilẹ̀ ibẹ̀ lọ.
Ẹ mú arakunrin yín náà lọ́wọ́, kí ẹ sì tọ ọkunrin náà lọ.
Tipátipá ni wọ́n fi ń bá àwọn obinrin lòpọ̀ ní Sioni,ati àwọn ọmọbinrin tí wọn kò tíì mọ ọkunrin ní Juda.
” Wọ́n bá lọ sí ìlú tí eniyan Ọlọrun yìí wà.
How to wear face mask properly : Kìí ṣe gbogbo ìbòmù ló ń dá coronavirus dúró
Àwọn Olúkọ ìpínlẹ̀ Oyo fakọyọ lórí ètò Akọ́mọlédè àti Àṣà púpọ̀ Rògbòdìyàn bẹ́ sílẹ̀ láàrin àwọn ọlọ́kadà àti àwọn òṣìṣẹ́ ọgbà ẹ̀wọ̀n ní Ibadan Wo àwọn oúnjẹ márùn ún tó ń mú kí àtọ̀ ọkùnrin dára síi Ogunyemi sọ siwaju si pe ijọba ko le reti ki a kan dede pada sile iwe bẹẹ lai tii ri owo to jẹ wa gba."
 fun amojuto , naijiria je pinpin si igberiko apaariwa ati apaguusu ati imusin eko .
O sọ pe o ṣeeṣe ki aarun ọpọlọ ma damu aarẹ pẹlu iru awọn igbesẹ to gbe eleyi ti ku diẹ kaa to.
 Leyin eyi ni mo lo silu Oyinbo, nile Amerika, lati lo ko eko ise nipa olutoju alaisan.
Amin ẹyẹ mẹrindinlọ́gbọ̀n fún ènìyànn mẹrindinlọgbọ̀n Amin ẹyẹ AMVCA ti ọdun yìí yóò ṣe àgbéjáde orísi ẹbun mẹrindinlọ́gbọ̀n Méje nínú àwọ̀n ipele yìí ni wọ́n ti gbé sita fún ìdìbò Àkọlé àwòrán, MVCA Award: Ronke Odusanya, Oyebade Adebimpe, Funke Akindele àti Toyin Abrham tani ami ẹyẹ yoo já mọ lọ́wọ́?
"Oun naa yoo dahun pe ""Aṣẹẹjẹ o."
Wọn ra iṣẹ ona Tutu ni miliọnu pọun kan ni London
Ìgbéyawó yìí lárinrin Szu Ping Chan Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Ogbeni Chukwunonye Madubuike, tó jẹ́ ọ̀gá àgbà ẹ̀ka ọjà tita ni Iléesẹ́ Emzor pharmaceuticals náà ló ta ọgọ́ta ìgò òògùn ikọ́ olómi tó ní èròjà codeine nínú nílé ìtura kan nilu Eko.
Bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé, èmi ni mo tọ́ wọn dàgbà, tí mo sì fún wọn lókun, sibẹsibẹ wọ́n ń gbèrò ibi sí mi.
" Gómìnà Zamfara kò lágbára ní tòtọ́ọ́ lórí ọ̀rọ̀ ààbò- amòfin Oríṣun àwòrán, Facebook/Abdul’aziz Yari Àkọlé àwòrán, Ọrọ aabo Amofin Oyeyemi Balogun sọ pe otitọ ni ọrọ ti gomina ipinlẹ Zamfara governor pe oun ko lagbara to to lati paṣẹ fawon soja ati awọn agbofinro mii lati dẹkun ipaniyan to n ṣẹlẹ ni ipinlẹ naa.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Àlàyé rèé lórí bí mo ṣe fi ọsàn híhó fẹ́ ìyàwó mi"" Wo àmì márùn-un tí o fi le mọ ẹni tó fẹ́ gbẹ̀mí ara rẹ̀ Típà tẹ dẹ́rẹ́bà pa ní Epe Ọwọ́ tẹ ọkùnrin kan ní pápákọ̀ òfurufú l‘Eko tó ń kó ike ATM 2,886 lọ si Dubai Lẹ́yìn ọ̀pọ̀ ọdún, ìjọba Kwara fẹ́ sọ orúkọ Rashidi Yẹkini di mánigbàgbé Ọ̀kẹ àìmọye ẹ̀rọ àyẹ̀wò káàdì olùdìbò jóná mọ́lé l' Ondo Wo iye àwọn tó ti gbẹ̀mí ara wọn ní Nàìjíríà láàrin ọdún mẹ́rin ìjọba Buhari Bakan naa ni aarẹ fikun wi pe, ki awọn ọdọ to ba fẹ ṣiṣẹ gba oko lọ lati lọ ṣe iṣẹ ọgbin."
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Kí lo kàn ìlànà iyansipo àti ìwé ẹrí NYSC lorílè-èdè Nàìjíríà?
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Sogidi Lake: Kòṣẹja-kòṣèèyàn lá bá nínú adágún odò náà -Ojedele Iru obinrin bẹẹ si ni yoo nira fun lati ri ọkọ miran ti yoo fẹ, tawọn obi ati ẹbi rẹ yoo si maa fi se ẹsin ati ẹlẹya to ba pada sile wọn.
Ewe, ireti wa pe yoo dibo ni
Gẹgẹ bi nnkan ti ijọba ipinlẹ naa sọ, ounjẹ naa wa fun pinpin fun awọn eeyan ilu, ṣugbọn wọn n duro de aṣẹ lati ọdọ ọọfisi CACOVID ni Abuja ki wọn to bẹrẹ pinpin rẹ.
Amọ, Saraki sọ pe rara, ọ̀rọ̀ ko ri bẹ.
O ni anfaani ti ofin tuntun naa yoo tun ni mimọ iye awọn alarun ọpọlọ to wa ni Ipinlẹ Eko ati awọn iroyin nipa wọn.
Ẹ kò gbọdọ̀ ṣe àìdára sí ara yín, ṣugbọn ẹ bẹ̀rù Ọlọrun yín; nítorí èmi ni OLUWA Ọlọrun yín.
Wọ́n gbé orí Iṣiboṣẹti, wọ́n sì sin ín sí ibojì Abineri ní Heburoni.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Itsey Sagay: Irọ́ ni Ahmed Lawan pa pe ₦750,000 ni Sẹ́nétọ̀ kan nń gbà lóṣù 26 Òkùdu 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 27 Òkùdu 2019 Oríṣun àwòrán, @Social_NG Alaga fun igbimọ̀ oludaninimọran fun aarẹ Buhari lori iwa ajẹ́banu, Ọjọgbọn Itsay Sagay ti fesi pada lati tako ọrọ ti aarẹ ile asofin agba, Ahmed Lawan sọ pe ko si asofin agba to n fi apo sakasaka di owo lọ̀ sile.
Nítorí náà Jehoṣafati jọba ní alaafia, nítorí pé Ọlọrun fún un ní ìsinmi ní gbogbo àyíká rẹ̀.
baluu adanikan fo ti ileesẹ ọmọogun ofurufu Naijiria sẹsẹ se naa lee sisẹ kọja wakati mẹwa lai duro ti yoo si fo si iwọn bata ẹgbẹrun marundinlogun so.
Awọn ere ti wọn gbe kalẹ ni iranti awsn eeyan to niiṣe pẹlu owo ẹru atawọn iwa ipa ati ẹlẹyamẹya gbogbo ni wọn di wiwo kalẹ.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Lunar Eclipse: Ifá letùtù wa lẹyìn Òṣùpádẹ̀jẹ̀ Aworan ìṣẹlẹ òṣùpádeje káàkiri àgbáyé Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Passport Nàìjírìa: ìjọba ti sọ gbèdéke ori ìwé ìrìnnà di ọdun mẹ́wàá Ni ọjọ kejidinlọgbọn oṣu kẹfa ni ọkọ ajagbe elepo kan to gbe jala epo ẹgbẹrun mẹtalelọgbọn gbina lẹyin ti o ṣubu ti o si da epo silẹ kaakiri ori afara naa.
Àkọlé àwòrán, Okan ninu awon odo naa niyi ti o ni lati sanwo fawon odo lati ba e ru alupupu re koja odo Ni nkan bii 1800 ni awọn oyinbo amunisin ti gbe ni agbegbe Madaka nitori pe goolu pọ nibẹ ki wọn to kuro lọdun 1946 nigba ti goolu di ọpọ yanturu kaakiri.
"O da mi loju pe awọn alasẹ Naijiria ko lee sọ pe awọn ko ti awọn apaniyan lẹyin nitori gbogbo awọn eeyan tawọn agbofinro mu pe wọn n pa eniyan, ni ijọba ti tu silẹ patapata.
Ó bẹ̀rẹ̀ iṣẹ́ ní ẹ̀ka ètò àábò ní ìlú Kano, lẹ́yìn èyí ló sì darapọ̀ mọ́ àjọ elétò àábò Nigerian Security Organization (NSO), tó ti kógbá sílé báyìí.
Awọn ọmọ Naijiria to tun wọ ọkọ to ja lulẹ naa ri ti n fi ibanujẹ wọn han lori iṣẹlẹ naa.
Atirobẹ́lẹ́ṣindọ́gba ni ọ̀pọ̀ ọ̀dọ́ ní ìsin yìí-Ọlọ́fàiná Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí kan sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
APC caretaker committee: Nkan márùn ún tí àwọn adarí ẹgbẹ́ gbọdọ́ ṣe kíákíá kí nkan ó má lọ yíwọ́
Ìkébé mi tóbí ju ohun tí mo lè dọwọ́ bò lọ, n kìí fí ṣakọ- Nkechi Blessing Ẹ̀yin òṣìṣẹ́, ẹ má ṣáì lọ síbi iṣẹ́ lọ́jọ́ Ajé, olórí àwọn òṣìṣẹ́ ní Nàìjíríà tako ìyanṣẹ́lódì Nipinlẹ Ọyọ ẹwẹ, ijọba tun ti fi ilana miran sita lori ilana eto ẹkọ fawọn akẹkọọ to sẹsẹ pada sile ẹkọ lọjọ Aje to kọja.
Ọlọ́pàá kọ́ lo pa olórí àwọn ''One Million Boys'' Ebila n'Ibadan- Ọ̀gá ọlọ́pàá Oyo Ẹ wo ọ̀nà tí ìjọba Nàìjíríà fẹ́ gbà san owó àwọn olùkọ́ iléèwé aládàni tí kò rówó oṣù gbà Bí òṣìṣẹ́ Amotekun bá fi orúkọ sílẹ̀ lórí ayélujára, àwọn ọ̀daràn yóò tètè fojú hàn - Oludari Amotekun l'Oyo Kí ló fa ìjà láàrin Wunmi Toriola àti Seyi Edun?
Wọ́n rí òkú ọmọ ọdún mẹ́fà tí wọ́n fipá bálopọ̀ nínú mọ́ṣálàáṣí ní Kaduna Bẹ́ ẹ fẹ́, bẹ́ ẹ kọ̀, July ni ẹjọ́ Sotitobire yóò parí - Adájọ́ gbọmú Ẹ̀kọ́ mẹ́jọ tó yẹ kí ilẹ̀ Afirika kọ́ lára àjàkálẹ̀ aàrùn coronavirus Arúfin ni Seyi Makinde pẹ̀lú bó ṣe gbà kí wọ́n sin Ajimobi sí GRA - Amòfin Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Africa Eye: Ọwọ́ tẹ ayédèrú dókítà Abdallah tó ń tà oògùn Coronavirus Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 3 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 5 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Labẹ òfin Naijiria, o ní oṣuwọn ìwé ẹ̀rí tí èèyàn lè fí di ipò yìí mú.
Ilẹ̀ tí ó kù lẹ́gbẹ̀ẹ́ ilẹ̀ mímọ́ náà yóo jẹ́ ẹgbaarun (10,000) igbọnwọ (kilomita 5) ní ẹ̀gbẹ́ ìlà oòrùn, ati ẹgbaarun (10,000) igbọnwọ (kilomita 5) ní ẹ̀gbẹ́ ìwọ̀ oòrùn.
Ó sọ mí sinu ẹrẹ̀,mo dàbí eruku ati eérú.
Lẹ́yìn ọ̀pọ̀lọpọ̀ oṣù tí a tẹ ọ̀kanòjọ̀kan ìròyìn jáde àti ìgbélárugẹ ìtàkùrọ̀sọ ọ̀ràn wọn lórí Twitter, ìdálébi ìfàṣẹmú àti àtìmọ́lé gba ojúlé ìjọba àti àwọn alẹ́nulọ́rọ̀ ajàfúnẹ̀tọ́ ọmọnìyàn ní àgbáyé kọjá, láì gbàgbé àwọn ọgọọ́gọ̀rún àti ẹgbẹẹ̀gbẹ̀rún alátìlẹ́yìn orí ẹ̀rọ-ayélujára.
Oríṣun àwòrán, Other Ẹni ọgọta ọdun ni oloogbe naa nigba to jade laye lẹyin iku ọkọ rẹ, to si ko ipa manigbagbe ninu iṣẹ tiata pẹlu ọkọ rẹ.
Lẹ́yìn náà, ṣe aadọta ìkọ́ wúrà, kí o fi kọ́ àwọn ojóbó àránpọ̀ aṣọ mejeeji, kí àgọ́ náà lè dúró ní odidi kan ṣoṣo.
3) Déjì ìlú Akurẹ - Ọba Oluwadamilare Adesina: Osupa Kẹta Ko jọ ẹ̀sín, ko jọ itiju ni Ọba Oluwadamilare Adesina fi kuro lori oye.
Oludije fun ipo gomina labẹ asia ẹgbẹ oselu APC, Babajide
Ẹni ori yọ ipade di ile ni ọrọ da nilu Ogbomosho nibi ti awọn ọdọ kan ti yabo aafin Soun Ogbomoso.
Olori Ile Isẹ igbimọ alakoso fun ere bọọlu orilẹede Naijiria, (NFF), Amaju Pinnick ti o fi ọrọ yi si ori opo ayelujare Twitta rẹ loni sọ wi pe adehun naa fun Dennerby lati dari awọn ọmọ ẹgbẹ agbabọọlu obinrin ti orile-ede Naijiria, Super Falcons fun ọdun meji.
Osun Osogbo Shrine Porn Video: Wo ìgbà méjì láàrín ọdún méjì tí ojúbọ Osun Osogbo ti mú ìròyìn àìtọ́ lọ́wọ́
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Manchester United vs Tottenham: Man United ré Mourinho àti Tottenham lẹ́pa lórí pápá Old Trafford 4 Ọ̀pẹ̀̀ 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Papa iṣere Old Trafford yeruku lala lẹyin ti Tottenham ati manchester United tutọ sira wọn loju ninu ifẹsẹwọnsẹ Premier League to waye lalẹ Ọjọru.
Buhari: Isa Funtua ti wọ káà ilẹ̀ sùn ní ìlú Abuja
Mose bá sọ fún Farao pé, “OLUWA ní, nígbà tí ó bá di ọ̀gànjọ́ òru, òun yóo la ilẹ̀ Ijipti kọjá, 
Aàre Donald Trump pàrọwà pé kí wọ́n sún ọjọ́ ìdìbò dí ọjọ́ míràn nítorí Covid 19 Oríṣun àwòrán, @GeigerNews Aare Donald Trump to n tukọ orilẹ-ede America ti parọwa fun awọn ikọ to n seto idibo naa lati sun un siwaju kuro ni osu kọkanla, ọdun 2020 to yẹ ko waye.
'Bóo rántí ikú Gáà kóo ṣòótọ́ ni ọ̀rọ̀ Abacha' Italy dá àwọn aboyun àt'ọmọ wẹ́wẹ́ pada Ǹjẹ́ ìwọ mọ Oloye M K O Abiọla dáadáa?
Asiko isin yii lawọn ile ìjọsìn máa n fi sadura ati ìsìn lati fi sure nkan daada ti wọn ba n fẹ lọdun tuntun.
A ti gbúròó igbagbọ yín ninu Kristi Jesu ati ìfẹ́ tí ẹ ní sí gbogbo àwọn eniyan Ọlọrun.
Àwọn míran ní ìdìtẹ̀ láti yọ ààrẹ ilé ìgbìmọ̀ Bukola Saraki àti Ike Ìkweremadu ìgbákejì rẹ̀ nípò.
Àlékún ọgbọ́n, àlékún ìmọ̀, àlékún òye ọmọ ènìyàn láti ìrandéran ti mú ìlọsíwájú kànkà bá àwa ọmọ ènìyàn gbáà.
Oṣu Kejila ọdun 2018 ni awọn agbofinro nilẹ naa mu Zainab nigba ti o lọ ṣe Umrah.
Oga agba iko omo ogun naa, balogun Chukwuka, wa ro awon onisegun oyinbo naa lati samulo eto idanileko ohun lojuna lati ma a wo awon omo ogun ti o ba fara pa san loju ogun.
Dodo Farm: Ẹ wo bí àwọn ọmọ Yoruba ṣe làlùyọ nídìí iṣẹ́ àgbẹ̀ ní Amerika
O ṣalaye wipe, dokita kan to wa ni oju ọna nigba iṣẹlẹ naa tilẹ n ran ọkunrin naa lọwọ, ki o to di pe ẹlikoputa naa wa gbe.
Eyi ko ṣẹyin Baba kan ni ipinlẹ Ogun to fi idi ọmọ rẹ jona lọna ati ba ọmọ naa wi nitori pe o ji ẹja.
Komisona fun irin ajo afe, asa ati ise ona, Ogbeni Steve Ayorinde salaye lori awon ayipada rere ti yoo de ba eto oro aje ipinle Eko ti won ba gba imoran  yii wole.
Alukoro ile iwosan naa, ọgbẹni Toye Akinrinlọla, lasiko ifọrọwerọ kan pẹlu BBC Yoruba lo fi idi ọrọ yi mulẹ Ta ni Olatoye Temitope 'Sugar' tó di olóògbé?
Nítorí èyí, mo bẹ̀ ọ́ gidigidi, ìwọ arẹwà ọkùnrin, má ṣe rò mi si alábùkù nípa ìbéèrè ti n ó ṣe.
Ṣugbọn wọn kò fi ọwọ́ kan ẹrù wọn.
Bí mo tí ń ronú nípa rẹ̀, mo rí i tí òbúkọ kan ti ìhà ìwọ̀ oòrùn la gbogbo ayé kọjá wá láìfi ẹsẹ̀ kan ilẹ̀, ó sì ní ìwo ńlá kan láàrin ojú rẹ̀ mejeeji.
Nisinsinyii, OLUWA Ọlọrun, dìde, lọ sí ibùjókòó rẹ, ìwọ ati àpótí ẹ̀rí agbára rẹ.
Ọjọ́ tí mo sọ fún àwọn òbí mi pé mo fẹ kọ iṣẹ teelọ, wọn ni ki n duro di ọdun mẹwaa."
2018 films: Sinimá ju sinimá lọ táwọn ọmọ Naijiria gbádùn
Gẹgẹ bi akọsilẹ ajọ eto ilera ni agbaye, WHO, aisan iba n ṣeku pa ọmọde ni iṣẹju meji-meji, eniyan to le ni igba miliọnu si ni akọsilẹ wa pe o n ni aisan yii l'ọdun.
Olatunde sàlàyé èyí nílu Ado -Ekiti, lásikò tó fi n dá àwọn àkọroyin lójú pé, kò sí ǹkan tó le yẹ aigbowó osù fáwọ́n òṣìṣẹ́ nínú ọ̀ṣẹ̀ àkọ́kọ́ nínú òṣù tọ ń bọ̀ yìí.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ìtàn ayé Henry Fajemirokun, olówó tó fi owó mọ Olúwa àti ènìyàn Báwo ni Coronavirus ṣe n tànkálẹ̀ l'Afrika?
Aarẹ Ile aṣofin agba lorilẹede Naijiria ni awọn yoo fi afẹnuko wọn sọwọ si akọwe agba ijọba apapọ lati rii daju wi pe gbogbo awọn ileeṣẹ ijọba ati lajọlajọ yii ni wọn ṣe ayẹwo iwe owo wọn ki wọn si fi sọwọ.
Nígbà náà ni OLUWA dá a lóhùn pé, “ìwọ ń káàánú ìtàkùn lásánlàsàn, tí o kò ṣiṣẹ́ fún, tí kì í sìí ṣe ìwọ ni o mú un dàgbà, àní ìtàkùn tí ó hù ní òru ọjọ́ kan, tí ó sì gbẹ ní ọjọ́ keji.
Ó sùn níbẹ̀ ní alẹ́ ọjọ́ náà, ó sì mú ninu ohun ìní rẹ̀ láti fi ṣe ẹ̀bùn fún Esau arakunrin rẹ̀.
"Ọga ileewe girama ti Sẹnetọ Adeleke lọ ti jẹri labẹ ibura niwaju ile ẹjọ giga kan ni agbegbe Bwari pe lootọ ni ileewe naa fun un ni iwe ẹri.
Pẹlu awọn ohun ti olori Badra kọ sori ayelujara naa, o ti n foju han pe o seese ko ma si lara awọn olori to n gbe pẹlu Ọba Adeyemi mọ, ninu aafin rẹ nilu Oyo.
gbogbo awon musulumi bi won se n bẹrẹ awẹ
Oríṣun àwòrán, Getty Images Nitootọ lo jẹ pe iye awọn ti wọn n ṣe ayẹwo coronavirus fun kere niye.
Ìgbà tí o wí báyìí tán, ìyá mi wọ inú ilẹ̀ lọ.
je agbejero ati oloselu kuro lorile ede Kenya je iwa ti o tako eto omoniyan, ni
Lọdun 2017 ni wọn tun forigbari nigba ti ajọ EFCC to n risi ọrọ ṣiṣe owo ilu ni mọkumọku fẹ tojubọ bi wọn ṣe n na owo iranwọ ojiji ti Paris Club tijọba apapọ pin fun wọn.
Helicopter crash in Lagos: Gbogbo arìnrìnàjò inú ẹlíkọ́pítà tó já ní Opebi ti tẹ́rí gbaṣọ!
Ó lé ní ẹ́gbẹ́ta àwọn ọmọ Naijiria tí wọ́n ti ṣetàn láti padà sílé!
Ẹ wo ohun tó yẹ kí ẹ mọ̀ nípa oògùn 'Sputnik V' Russia tó ń wo àrùn Coronavirus Kí ló wà nínú àbá àkóso ajakalẹ àrùn tó fi ní àtakò?
Nígbà tí mo jí ṣe ni mo ń mí hẹlẹhẹlẹ bí ẹni tí ń sáré ije tí ọkàn mi ń lù kìkì bí ọkọ̀ òfuurufú – Háà!
Apọnbeporẹ, ẹlẹyinju ẹgẹ, ibadi aran, idi ilẹkẹ ayilukọ ni Wuraọla, ko si si ẹni ti yoo pade omidan yii lọna, ti ko ni gbadura pe ki ori jẹ ki oun fi se aya, tori ọba oke pari isẹ si lara.
Kí Ọlọ́run fún ni ní ìyàwó àlàáfíà.
com Bi o ṣe gbọdọ bọ ibomu-bẹnu rẹ Ma ṣe fi ọwọ kan inu ibomu-bẹnu naa nibi to ti bo imu ati ẹnu rẹ, nitori pe o le ti ko kokoro aifojuri lati ara eemi rẹ, tabi ti o ba hukọ tabi sin.
Nigba to ya ni oju rẹ di gbjumọ ninu awọn ere sinima bii, Adun Ewuro, Konkobilo, Oba Alatise ati bẹẹ bẹẹ lọ.
Òwe Yorùbá yi ṣe gba àwọn ti o nbẹ̀rù nigba gbogbo níyànjú wí pé ó yẹ ki èniyàn fara balẹ̀ lati ṣe iwadi ohun ti ó fẹ́ ṣẹlẹ̀ ki ó tó “kú sílẹ̀ de ikú”.
Ajọ FAAN ti kọkọ kede pe hun ti fin oogun apakokoro si awọn papakọ ọkọ ofurufu, ṣaaju ki wọn o to o ṣi wọn pada.
Arábìnrin lẹ̀dì àpò pọ̀ pẹ̀lú ọ̀rẹ́kùnrin rẹ̀ pé kó ó jí òun gbe, ọ̀rẹ́kùnrin gba 700k tán ló bá sálọ Wo oríṣìí oúnjẹ márùn ún tó lè dẹ́kun ikùn yíyọ àti ara àsanjù Amọṣa, nigba ti yoo fi di ọdun 1962, owooya to le ni miliọnu meji abọ pọun (£2.
paṣẹ fun Akọwe-agba Ile Igbimọ Aṣofin yii, Ọgbẹni Azeez Sanni lati fi ẹda
igbagbo pe, ibasepo to wa laarin orile ede Naijiria ati Guinea yoo tun tubo
Adari orile-ede Germany, Angela Merkel  ti bale sile aare ti n se Aso Rock niluu Abuja bayii.
 Lati bi awon ose meloo kan seyin ni pupo ninu awon omo egbe APC ti yapa kuro ninu egbe naa lo sinu alatako nitori idi kan tabi ikeji.
 iṣẹ ́ yìí ṣe àyèwò ohun tó ń mú kí àwọn asefíìmù ó máa ṣe àgbéjáde fíìmù yorùbá ajemó òràn dídá tó lu ìgboro pa báyìí , a sì tún wo orísirísi ìjìyà tí àwọn ọ ̀ daràn máa ń gbà .
Oyetola ni oun fun wọn di Ọjọọru lati da awọn ohun ini naa pada ati ti awọn eniyan ni awọn janduku naa ko lọ.
Ronaldo Delima gba gbajugbaja ami ẹyẹ Ballon d'Or lẹẹmeji, o si tun gba ife ẹyẹ agbaye lọdun 1994 ati 2002.
Oríṣun àwòrán, NJC Ninu oṣu kẹrin, ọdun 2016 ni EFCC kọkọ gbe awọn mejeeji lọ sile ẹjọ, ṣugbọn wọn ni awọn ko jẹbi ẹsun ti wọn fi kan wọn nigba ti igbẹjọ naa bẹrẹ.
“Bí òjò ati yìnyín, tí ń rọ̀ láti ojú ọ̀run, tí wọn kì í pada sibẹ mọ́,ṣugbọn tí wọn ń bomi rin ilẹ̀,tí ń mú kí nǹkan hù jáde;kí àgbẹ̀ lè rí èso gbìn,kí eniyan sì rí oúnjẹ jẹ.
SERAP si Buhari: Pàṣẹ fún amòfin àgbà, EFCC láti ṣèwáàdí Ganduje
Wundia ni wọ́n, wọn a sì máa sọ àsọtẹ́lẹ̀.
Àánú ṣe Jesu ó bá na ọwọ́ ó fi kàn án, ó ní, “Mo fẹ́.
Ẹni tí ó ní òye a máa wá ìmọ̀,ṣugbọn agọ̀ ni oúnjẹ òmùgọ̀.
Oríṣun àwòrán, @NGRPresident Àkọlé àwòrán, Aarẹ Buhari tun se ifilọlẹ ipese eto ilera alabọde latọwọ awọn majẹobajẹ CHIPS Mo gba gbogbo ọmọ Naijiria nimọran wipe ki wọn jinna si igbesẹ gbigba ẹsan nitori asẹ ti wa lọwọ awọn agbofinro lati fi ofin gbe ẹnikẹni ti wọn ba ba ibọn tabi ohun ija oloro yoowu lọwọ rẹ, ki wọn si fi jofin."
ede  China fun ayẹwo bi ise se n lo ni
Oun ko duro ki arun coronavirus tankalẹ rara, ọna to gba ni pe o kuku pa arun naa rẹ ni orile-ede rẹ.
alamojuto Ajo Inec to wa ni ipinle naa ojogbon  Godswill Obioma, o ni oun yoo ba awon akoroyin
Àwọn ìlú tí wọ́n pín fún wọn, ninu ilẹ̀ ẹ̀yà Bẹnjamini nìwọ̀nyí: Geba, Alemeti, ati Anatoti, pẹlu pápá oko tí ó yí wọn ká.
Ní alẹ́ ọjọ́ kan, Paulu rí ìran kan.
Talaka kan wà tí ó ń jẹ́ Lasaru, tíí máa ń jókòó lẹ́nu ọ̀nà ilé ọlọ́rọ̀ yìí.
Sẹ́nétọ̀ Dino Melaye kéde láti dupò gómìnà Kogi Amẹ́ríkà ń béèrè ìròyìn facebook, email arìnrìnàjò tó f'ẹ́ gbà'wé àṣẹ Àwọn òṣìṣẹ́ aláàbò kọlu àwọn tó n ṣe ìwọ́de ní Sudan 'Ọmọ SS 1 mu èso olómi, ṣùgbọ́n ilé ìwé wa kọ́ ló kú sí' Naijiria ko tii gba ife ẹyẹ agbaye FIFA U-20 ri, ṣugbọn wọn ti wọ ipele aṣekagba idije naa lẹẹmeji ọtọtọ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Oba Adedokun Abolarin ti Oke Ila: Ó ya ọ̀pọ̀ tó súnmọ́ mi lẹ́nu bí mo ṣe ń kọ́ Eko ipari: Ọpọ onkọwe miran lo ti dide lasiko yii sugbọn ko si bi a maa se pa itan iwe akagbadun iwe litireso Yoruba ti a ko ni fi ida Daniel Olorunfemi Fagunwa, Adebayo Faleti, Akinwumi Orojide Isola, Lawuyi Ogunniran, ati Oladejo Okediji lale gaaraga.
Sultan pàṣẹ fún àwọn mùsùlùmí láti ṣ'ọdẹ òṣùpá lónìí Kí ni àwọn ẹ̀ṣẹ̀ àti ẹ̀sùn tó ń da Oshiomole láàmú?
Ṣùgbọ́n àtòun àtàwọn ọ̀rẹ́ rẹ̀ ni àwọn ènìyàn fi ojú sí lára gẹ́gẹ́ bí ọlọ́ṣà.
Ladọja ni oun kọ lati jẹ ki Adedibu lu owo ipinlẹ naa ni ponpo lẹyin ti Adedibu ni ki oun maa fi ida marundinlọgbọn owo Security Vote to to miliọnu marundinlogun Naira si apo oun ni oṣoosu.
Ẹ ṣọ́ra kí ẹnikẹ́ni má ṣe fi ọ̀rọ̀ ọgbọ́n ayé ati ìtànjẹ lásán sọ yín di ẹrú gẹ́gẹ́ bí àṣà eniyan, ati ìlànà àwọn ẹ̀mí tí a kò fi ojú rí, tí ó yàtọ̀ sí ètò ti Kristi.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Baruwa Gas Explosion: Àwọn tó forí sọta ìjàmbá iná ń bẹ ìjọba láti dìde ìrànwọ́ Ọna to le gba lati ri nọmba idanimọ NIN rẹ gba?
À ń tì yín síwá sẹ́yìn.
‘OLUWA kì í tètè bínú, àánú rẹ̀ sì pọ̀.
Awon oludije dupo merindinlogun lara eyi ti a ti ri awon obinrin meji ni won n figa-gbaga fun ipo Aare naa.
"O so fun BBC pe ""Ẹmi mii fẹ ba lọ"" Loṣu Kẹta 1994, wọn gbe ibọn si lori ti wọn si gun labẹrẹ ti ko mọ ohun to wa ninu rẹ."
Wo àwọn ojúṣe àti èèwọ̀ fún ikọ̀ ọlọ́pàá SWAT tó gba iṣẹ́ lọ́wọ́ SARS Ọlọ́pàá mẹ́sàn án tó farapa nínú ìjàmbá ọkọ̀ Akure t'éèyàn méjì ti kú sì wà nílé ìwòsàn Ìjàmbá ọkọ̀ akérò àti tírélà pa èèyàn mẹ́rin lọ́nà mọ́rosẹ̀ Ore sí Benin Àwọn ìṣẹ̀lẹ̀ mánigbàgbé tó wáyé nibi ìwọ́de ENDSARS Nàìjíríà Ẹgbẹ́ Agbẹjọ́rò NBA ti kéde pé àwọn yóò ṣojú awọn Olùwọ́de #EndSARS lọ́fẹ̀ẹ́ nílé ẹjọ́ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Eegunjobi Omotanbaje Ajobiewe- Èébú ní wọ́n kọ́kọ́ ń bù mí nígbà tí mo bẹ̀rẹ̀ ẹ̀ṣà pípé ní Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí 2:23 Fídíò, EndSars, EndSwat: Ọlọ́pàá ti fi ìbọn lù mí láyà rí torí mó ní 'extra tyre' méjì- afẹ́hònúhàn, Duration 2,2315 Ọ̀wàrà 2020 Fídíò, Soyinka Cancer: Àṣe ara mi ni iso ti n run gbogbo bí mo ṣe n ṣèrànwọ́ lórí jẹjẹrẹ27 Bélú 2019 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Ta ni ki n wọlé tọ̀ ki ń sọ̀rọ̀ ẹ̀dùn ọkàn!
Olokoowo naa to n ta asọ, lo n jọsin ni sọọsi lọwọ nigba ti awọn afurasi ajinigbe naa pe e, ti wọn si parọ pe awọn fẹ ra obitibiti asọ olowo iyebiye.
Ile –ise to n mojuto eto irinna oko ofurufu (FAAN)wa lo
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Wòlíì Sotitobire yóò gba ìdájọ́ lórí ẹ̀ṣùn ìjọ́mọgbé lọ́la Tani Akeredolu tó ń díje dupò gómìnà fún ìgbà kejì nípìnlẹ̀ Ondo?
Ìpínlẹ̀ Ọ̀ṣun ń sàìsàn, òṣìṣẹ́ ọba ti pọ̀ jù - Oluwo Leah Sharibu ni wòlíì wa ní àgọ́ Boko Haram - Obìnrin tó jàjàbọ́ Lalong borí ní Plateau, nǹkan ò fararọ ní Sokoto, Kano Ìdí tí Adeleke kò fi tíì lè kó lọ ilé ìjọba ìpínlẹ̀ Ọṣun Èmi ṣì ni Gómìnà ìpínlẹ̀ Ọṣun-Oyetọla Ilé ẹjọ́ kéde Ademọla Adeleke gẹ́gẹ́ bíi gómìnà ìpínlẹ̀ Ọṣun Ni ọjọ ẹti ni ile ẹjọ naa dajọ pe, Ademọla Adeleke ti ẹgbẹ oṣelu PDP lo yẹ ki ajọ eleto idibo, INEC kede gẹgẹ bii gomina dipo Oyetọla; ṣugbọn Oyetọla ti sọ pe, ko si ooyẹ kan to lee yẹ idi oun lori aga gomina ipinlẹ Ọṣun nitori pe, o da oun loju ṣaka pe oun lo bori ibo naa.
Issa onilu ní òun gbẹ oríyìn fún ẹgbẹ́ òṣèlú PDP fún ìgbésẹ̀ tí wọ́n gbé láti lọ si ilé ẹjọ́ lórí ọ̀rọ̀ náà, nítori ọ̀na to tọ ni , súgbọ̀n ìgbẹ́jọ náà ti dé òpin báyìí, ó si pọ́ndadan ki wọ́n fún ààrẹ Buhari láàyè láti ṣe ijọba O wá rọ ẹgbẹ́ náà láti ṣẹ́wẹ́lé ìpínu wọ́n láti da orilẹ̀-èdè rú pẹ́lú àwọn ìròyìn ẹlẹjẹ́ nítori àbájáde ìdájọ ilé ẹjọ́, o ní nigba ti o ti já si ibi ti o já si nítori pé orilẹ̀-èdè Naijiria kii ṣe tí ẹnikan, o si ṣe pàtàkì kí ifọ́wọ́sowọpọ̀ wà ki ilọsiwáju le ba ìlú.
" Adẹrinposonu naa, to kẹẹkọọ nipa akoso okoowo nile ẹkọ fasiti aladani kan nilu Oyo tun ni, wọn le oun kuro nile ẹkọ fasiti kan Ilorin, ki oun to gba ile ẹkọ fasiti aladani lọ.
lati dibo fun ẹni ti won fẹ.
Ogún ni àwọn òpó aṣọ títa, àwọn ìtẹ́lẹ̀ wọn náà sì jẹ́ ogún.
Ìtàn ìran Noa nìyí: Noa jẹ́ olódodo, òun nìkan ṣoṣo ni eniyan pípé ní àkókò tirẹ̀, ó sì wà ní ìrẹ́pọ̀ pẹlu OLUWA.
Komisona naa tun ya wo Owerri Ezukala Cave ati Waterfall ti UNESCO ti fowo si tele fun ibudo irinajo afe nipinle Anambra.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Awọn ọmọlẹ́yìn El-Zakzaky: Ọlọ́pàá ló ń fa rúkèrúdò lásìkò ìwọ́de wọn 17 Ìgbé 2018 Oríṣun àwòrán, @OfficialPDPNig Àkọlé àwòrán, Wahala bẹ́ sílẹ̀ nílùú Àbúja lọ́jọ́ ajé láàárín àwọn ọlọ́pàá àti àwọn ọmọ ìjọ ẹ̀sìn shi'ite Àwọn ọmọ ìjọ ẹ̀sìn shi'ite ti fi ẹ̀sùn kan iléeṣẹ́ ọlọ́pàá lórílẹ̀èdè Nàìjíríà pé àwọn gan an ló ń ṣokùnfà rúkèrúdò tó máa ń wáyé ní gbogbo ìgbà tí wọ́n bá ṣe ìwọ́de wọn.
Miòṣé fi ọ̀rọ̀ àṣiri yi sinú lai si nkan ti ó ṣe gbogbo àwọn ti ó jẹ Igún pẹ̀lú rẹ.
 ilu Abuja to je olu –ilu orile ede Naijiria
Ta ni kí n kìlọ̀ fún tí yóo gbà?
SPL Malaria in 2017 435,000 died of malaria worldwide 219m infectedAfrica saw more than 90% of cases and deathsSource: WHO Malawi in orileede akọkọ ninu awọn mẹta ti wọn yoo ti bẹrẹ lilo abẹrẹ ajsara yi .
Mo fẹ́ kí ẹ mọ̀ dájúdájú pé, títí ọ̀run ati ayé yóo fi kọjá, kínńkínní, tabi ẹyọ ọ̀rọ̀ kan ninu òfin, kò ní yẹ̀ títí gbogbo rẹ̀ yóo fi ṣẹ.
Aare egbe akekoo nipa Alaafia ati Ise (Society for Peace
Nígbà gbogbo tí mo bá ń ranti rẹ ninu adura ni mò ń dúpẹ́ lọ́wọ́ Ọlọrun.
 Oríṣun àwòrán, @GovUmarGanduje Lai pẹ yii ni awọn fidio kan bọ si ori ẹrọ ayelujara eyi ti o ṣafihan gomina ipinlẹ Kano ti o n gba owo dọla ilẹ Amẹrika lọpọ yanturu lọwọ ẹnikan ti wọn funra pe o jẹ Kọngila."
Ẹ wo èrò bìbà níbi ìwọ́de #EndSARS ní ìlú Ibadan Ooni ṣalaye pe irufẹ iriri tawọn ọdọ n koju lọdọ oṣiṣẹ SARS ti ṣẹlẹ si ọmọ bibi oun lobirin koda o fẹ ẹ padanu mi rẹ lọwọ wọn.
Aarẹ ẹgbẹ naa, Samson Ayokunle sọ ninu atẹjade to fi sita lati ipasẹ gba ọwọ oluranlọwọ pataki lori eto iroyin, Adebayo Oladeji pe ki ijọba wa nkan ṣe si ni kiakia.
 Lati wa ṣaṣeyọri eyi, ijọba oke gbọdọ fun awọn ijọba ipinlẹ ni agbara kikun lati le ṣe amojuto awọn ohun alumọni wọn funra wọn.
O ni o yẹ ki awọn ọmọde mọ ohun to yẹ ati eyi ti ko yẹ ni lilo ninu ẹro ibanisọrọ ti wọn ba gbe dani.
Oríṣun àwòrán, @nmanigeria Àkọlé àwòrán, Ẹgbẹ NMA ni asiko to fun ijọba apapọ lati jara mọ agbekalẹ eto ilera tẹru-tọmọ, Universal health coverage Alaga ẹgbẹ dokita isegun oyinbo, NMA ni ipinlẹ Kwara, Dokita Kunle Ọlawepo salaye wi pe lẹyin Ọjọgbọn Olukoye Ransome-Kuti to sa ipa ribiribi fun idagbasoke ẹka ilera alabọde lasiko to fi jẹ minisita feto ilera, ko si ijọba to tun gbe ọwọ idagbasoke lẹka eto ilera alabọde soke mọ.
Ní ìlú ọba níhìín, fún wákàtí mẹ́rìndínlógún àti ìṣẹ́jú méjìdínlógójì ni oòrùn yíò ran ìmọ́lẹ̀ rẹ̀ kalẹ̀ yanyanyan léwa lórí kó tó wọ̀ ni nkan bí i aago mẹ́sàn-án kọjá ìṣẹ́jú mọ́kànlélógún.
Awọn ọlọpaa lo fẹsun ole kan Danladi ẹni ọdun marunlelọgbọn.
Salami to ni pàtàkì ǹkan to jẹ òun lógun ni ìmọ ẹ̀kọ́ àwọn ọmọ wẹ́wẹ́, sàláyé pe orin tàkasúfèé náà ni ọ̀nà láti mu ki ọpọlọ àwọn ọmọ ilé-ìwé alákọbẹ́rẹ́ ẹkọ ìmọ isirò ṣí kíákíá.
Oyedepo so pe, awon onigbagbo gbodo wa ni ibamu pelu oro Olorun, ni eyi ti o fi kun oro re pe, won ni agbara lati pase alaafia ni gbogbo ona.
Ni ó bá wí fún un pé, “Nítorí pé o ṣàìgbọràn sí àṣẹ OLUWA, bí o bá ti ń kúrò lọ́dọ̀ mi gẹ́lẹ́ ni kinniun yóo pa ọ́.
'Mi o fọ́wọ́ sí bí ọmọ mi, Kiddwaya ṣe lọ fún BBNaija - Terry Waya Ipò kíní ré sórí ìpínlẹ̀ Plateau!
Ẹni ọdun marundinlọgọta ni Baba Kiddwaya, amọ o ti fi igba kan ko si panpẹ awọn agbofinro ni Ilẹ Gẹẹsi, ni ọdun 2006 si 2008.
Russia2018: àwọn àsìkò mọ́legbàgbé nínú ìdíje ife ẹ̀yẹ àgbáyé
A o mojuto bi awon eniyan se n wole tabi jade kuro ninu ilu yii .
Gẹgẹ bi awọn eeyan agbegbe naa ṣe sọ, ni nnkan bii agogo mẹwaa abọ aarọ ọjọ Satide ni iṣẹlẹ naa ṣẹlẹ lagbegbe Aerodome.
" orúkọ ìnagijẹ rẹ ̀ ni "" chief commander "" ."
Pasitọ Philip ati Owolabi jẹwọ pe lootọ lawọn pa Favour lati fi ṣe oogun owo, amọ ẹlẹda ọmọbinrin naa ko jẹ ni ni oogun owo.
Koda awọn eekan to ti lugbadi arun naa ti boode lati sọ pe awọn ti bọ.
Ó máa ń jí ọkọ̀ gbẹ, ó sì máa ń fọ́ báńkì pẹ̀lú.
Sugar: Ilé ìwòsàn UCH ló dákẹ́ sí torí ọgbẹ́ ọta ìbọn
"Sugbọn wọn da epo bẹtiro si wọn lara, wọn si tun fi wọn ẹ̀sín.
Sanusi fikun oro re pe, ohun iwuri ti o gba oriyin ni lati ri gomina ipinle otooto meji, bee si ni ti egbe oselu won ko tun papo, ki won o jo joko po maa jiroro awon ona ti igberu le gba de ba idagbasoke orile-ede yii.
 bí àwọn ààmì báwà wọ ́ n sábà maa ńjẹ ́ ibà , ẹyin ojú pípọ ́ n , àwọ ́ ká , èfọrí , àti maculopapular rash .
Ó tún bèèrè lọ́wọ́ mi pé, “Ṣé o kò mọ ohun tí wọ́n jẹ́ ni?
Jesu sọ fún un pé, “Judasi!
Ile ti iṣẹlẹ naa ti ṣẹlẹ wa ni opoponaa Abeje ni Markaz to wa l'Agege.
Gbogbo ara rẹ̀ ba ara wọn mu: orí kò tóbi ju ibi tí ó yẹ, ọrùn kò kéré kọjá ìwọ̀n, bẹ́ẹ̀ ni tapátẹsẹ̀ bá ara wọn jọ, ọmọ dára tán, \wà tún ṣubú lù ú, Ẹwadàpọ̀ kò rí bẹ́ẹ̀, ìwọ̀ntunwọ̀nsì lobìnrin.
 Saraki àgbà ló kọ́ ilé yìí fáwa arúgbó kìí ṣe Bùkọ́lá- Arúgbó Ilọrin Àwọn fóònù wọ̀nyìí kò ní lè ṣe WhatsApp láti ọdún 2020 Àfàìmọ̀ kí Naira Marley má fi ẹ̀wọ̀n bẹ̀rẹ̀ ọdún 2020 Odunlade àti Femi Adebayọ: Wo ohun tó yà wá sọ́tọ̀ nínú àwọn arẹwà ọkùnrin Kọmisọnna ọlọpàá ìpínlẹ̀ Eko, Hakeem Odunmosu ti dari ẹka to n ri si ìwádii (CIID) ti Yaba láti gba iṣẹ́ náà ki wọ́n si gbe wọ́n lọ ilé ẹjọ bi o ti yẹ."
Nibayii, owo iyẹfun ti a n ra ni N10,000 si N12,000, ti da N14,000 bayii.
Ọjọ́ kejì ọjà Ajágbénulékè ni Àṣàkẹ́ rí kọ́kọ́rọ́ tí ó fi dán séèfù wò nínú yàrá rẹ̀.
Ọ̀rẹ́ mi náà ló pẹ́ díẹ̀ kó tó dé ti mo fi lọ́ dúró dèé ní Starbucks kan tí nbẹ lẹ́bàá ibi tí a fìpàdé sí.
Nígbà tí a dé ilé rẹ̀ lọ́hùn-ún tí mo fẹ́ẹ́ jókòó, Baba-onírùngbọ̀n ṣẹ́ ojú sí mi pé kí n má ṣe bẹ́ẹ̀, ṣùggbọ́n ohun tí ó yà mí lẹ́nu jùlọ nínú ilé náà jẹ́ méjì.
Iléeṣẹ́ ọmọ ogun dá Bashir tó ri owó he lọ́lá Ṣé irúfẹ́ oúnjẹ tí ò ń jẹ́ lè jẹ́ kí o gbádùn ìbálòpọ̀ rẹ síi?
Ko si ohun to jọ bẹẹ rara!
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Christmas: Ẹni ti ọdun ba ti bá láyé yẹ kó dúpẹ́ Akọṣile ni: ''Ohun to yẹ gẹgẹ bi orile-ede ni ki a fi ẹmi imoore han ki a si woye nkan to ṣẹlẹ kọja ninu ọdun yi.
Oludari ile iṣẹ naa ti gbọ si iṣẹlẹ naa ti awọn asoju wọn si ti de lati mojuto iṣẹlẹ ọhun, bakan naa ni wọn ti fi ọrọ naa to ọlọpaa leti.
Won bi Onimo ero Seyi Makinde  ni ojo keedogbon osu kejila, odun 1966 si
Kete ti idajọ yi di mimọ ni awọn agbẹjọro Gomina Oyetola gbaile ẹjọ kotẹmilọrun lọ lati tako idajọ naa.
Ijọba Ipinlẹ Kaduna ti ran awọn ọmọogun lọ si agbègbè Ungwan Pa-Gwandara ni ijọba ibilẹ Jema'a, lẹyin ti awọn agbebọn sigun bo agbegbe na.
Igbesẹ Kẹfa: Igbimọ yii gbọdọ fi esi iwadii rẹ sita laarin oṣu mẹta ti wọn ba gbe kalẹ, ti yoo fi iwadii rẹ ṣọwọ si Ile asofin Ipinlẹ Lasiko ti Igbimọ naa ba n ṣe iwadii wọn, Igbakeji Gomina ni anfaani lati ro ẹjọ tako ẹsun ti wọn fi kan an, bẹẹ lo si ni aṣẹ lati gba agbẹjoro ti yoo tako ẹsun naa.
Awọn oludari ileeṣẹ to ni ibi ti Richard ti ku ni awọn yoo gbe atẹjade sita lori iku Richard ṣugbọn titi di asiko ti a fi n ṣe akojọpọ iroyin yii, wọn ko ti fi sita.
Ó bá wí fún angẹli náà pé, “Ó tó gẹ́ẹ́, dáwọ́ dúró.
Amọ ka ba le mọ bi ẹyẹ yii se pọ to fun Ọba Adeyemi gẹgẹ bi Alaafin akọkọ ti yoo lo aadọta ọdun nipo, o yẹ ka woju wẹyin wo iye ọdun ti diẹ lara awọn baba nla rẹ to jẹ Alaafin lo, to fẹ ẹ sun mọ adota ọdun.
Ti a ko ba gbagbe, laipẹ yii ni Aarẹ Buhari se adehun pẹlu awọn ọba ni iwọ-oorun orilẹede Naijiria wi pe, oun yoo sa ipa oun lati ri wi pe awọn ipinlẹ yii tete ri ẹrọ drone gba, lati gbogun ti eto aabo to mẹhẹ.
Olèpani, ỌMỌ dúdú ilé komobe ṣe níjósí
Mo rí ògiri kan tí ó yí ibi tí tẹmpili wà ká.
Iná míràn tún fẹ́ ràn lẹ́ka ilera Nàìjíríà Ẹgbẹ́ akọ̀ròyìn NUJ ìpínlẹ Oyo bà àwọn ọmọ ẹgbẹ́ tó lọ ìpàdé tí Femi Fani Kayode pè ní Ibadan wí Àjọ ECOWAS yan Aàrẹ Ghana, Nana Akufo-Addo gẹgẹ bíi aàrẹ tuntun Fìdíhẹẹ́ ní Banji Akintoye nínú YWC, lílọ ni yóò lọ - Tola Adeniyi Oríṣun àwòrán, Getty Images Ki lo ti ṣẹlẹ sẹyin?
Hanks kede faraye pe oun ati iyawo oun, Rita ti ko arun naa lorilẹede Australia.
Nibayii wọn ti n foju ba ile ẹjọ.
Ẹ ṣe àwárí ọ̀daràn tó bọ́ mọ́ yín lọ́wọ́ - Turkur Buratai Sowore àti àwọn ọmọ ẹgbẹ Revolution Now kò ṣẹ̀ ṣófin lórí ìwọ́de, ẹ tú wọn sílẹ̀ - NLC Bí ọlọ́pàá bá mú ọ, kí ló yẹ kí o ṣe?
Ọkọ̀ akẹ́rù Dangote rọ́lu BRT lọ́nà Ikorodu, èèyàn kan kú, 59 farapa, ẹsẹ̀ dẹ́rẹ́bà gé Owó dé!
Batiṣeba dá a lóhùn pé, “Fi Abiṣagi, ará Ṣunemu fún Adonija arakunrin rẹ, kí ó fi ṣe aya.
44 fún lítà kan 8 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Oríṣun àwòrán, Twitter Ijọba apapọ ti kede adinku owo epo pẹtiroolu, lati Naira mejidinlaadọjọ si Naira mejilelaadọjọ, ati Kobo mẹrinlelogoji.
Ó jẹ́ ohun ìbànújẹ́ wípé kò sí ẹni tí ó fura sí irú ìgbé ayé ìjìyà àwọn àgbàlagbà méjì.
Niṣe ni okan rin lọ lalai sọ nnkankan si mi.
Lara awọn ohun amuyẹ ti wọn si n wo ni iriri nipa iṣẹ eto aabo ati ilera to dantọ.
Gbigbe asia Naijiria lọwọ ko le gba ọ lọwọ ologun: Iroyin yii gba ori ayelujara kan pe tawọn oluwọde ba ti mu asia orilẹede Naijiria lọwọ, awọn ologun ko ni kọju ibọn si wọn.
Messi gọ̀ láti sọ fun akọ́nimọ̀ọ́gbá Brazil pé kó gbẹ́nu dákẹ́- Thiago Silva Osimhen jẹ́wọ́ ara rẹ̀ bí Nàìjíríà ṣe lu Lesotho lálùbolẹ̀ mọ́lé wọn Ilé ẹjọ́ ni agbábọ́ọ̀lù ọmọ Nàìjíríà, Dickson Etuhu jẹ́bi ẹ̀sùn títa ìdíje Sweden Lọpọ igba ni o ti kọ isẹ akọnimọọgba ni orilẹede China, Spain, Portugal lati igba to ti kuro ni Manchester United.
"Ẹ wo ọmọ Yoruba, Adewale Adeyemo tí yóò jẹ igbákejì akọ̀wé akápò ní ilẹ̀ Amẹrika Awakọ̀ agbókùú, ọlọ́pàá, ológun, oníròyìn ló máa ń kọ́kọ́ dìbò ní Ghana, bó ṣe ń lọ rèé Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Kí ni ""Present tense"" lédè Yorùbá?"
Sugbọn a gbọ pe ijakulẹ diẹ ba eto naa nitori bi ọjọ ti lọ lori iwe irinna awọn ọmọ Naijiria kan to fẹ wa sile.
"Bákan náà ni agbẹnusọ fún ilé iṣẹ́ ọkọ̀ òfurufú British Airways tí àwọn akọ̀ròyìn abẹ́lé ni Nàìjíríà sọ pé ó bá rìnrìnàjò, Yinka Kola sọ pé òun kò ní lè pèsè ìròyìn kankan fún wọn ''nítorí àṣírí ni ohunkóhun tí gbogbo oníbarà wọn bá ṣe jẹ́ sí oníbarà tìkárarẹ̀""."
20 Àti pé kí àwọn ará Lámánì le ní ìmọ̀ nípa àwọn bàbá wọn, àti kí wọn le mọ àwọn ìlérí Olúwa, àti kí wọn le gbà ìhìnrere gbọ́ kí wọn ó sì le gbẹ́kẹ̀lé àwọn iṣẹ́ òdodo Jesu Kristi, ati kí wọn ó di ìṣelógo nípasẹ̀ ìgbàgbọ́ nínú orúkọ rẹ̀, àti pé nípasẹ̀ ìrònúpìwàdà wọn kí a lè gbà wọ́n là.
Eyi lo n se ikilọ fun awọn obinrin lati maa pọn ọmọ sẹyin daada, yatọ si pe ọmọ to ba jabọ lee di ero ọrun, tabi ko di alaabọ ara, Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Kíni ìwọ mọ̀ nípa Funmilayọ Ransome-Kuti?
Gbogbo akitiyan BBC Yoruba lati kan si Uber tabi Bolt lo ja si pabo.
“Ẹ ti gbọ́ tí a ti sọ pé, ‘Fẹ́ràn aládùúgbò rẹ, kí o kórìíra ọ̀tá rẹ.
Àpẹrẹ miran ti a lè fi ṣe àlàyé pé “Ọ̀run nyabọ̀, ki ṣé ọ̀rọ̀ ẹnìkan”, ni ẹni ti ó sọ pé ohun ri amin pé ayé ti fẹ parẹ́, àwọn kan gbàgbọ́, wọn bẹ̀rẹ̀ si ta ohun ìní wọn.
o koja pelu iji ti o lagbara eleyi ti o gba gbogbo ilu ohun kan.
Koda, Adebisi kọ ile agbayanu ati awodamiẹnu kan si agbegbe Idikan nilu Ibadan, eyi to ni ojule to lee ni ọgọrun un, eyi si lo mu kawọn ọmọ Yoruba fi maa powe pe 'N o kọle mi bii ti Adebisi, esu aini kọ ọkankan ni' Awọn ohun arikọgbọn nipa Sanusi Adebisi Idikan: Adesina ni orukọ baba Adebisi, ilu Ẹfọn Alaaye si lo ti wa tẹdo silu Ibadan Ile Lanasẹ ni adugbo Arẹmọ ni Adesina kọkọ gbe pẹlu aburo rẹ kan to n jẹ Alabi, to si maa n hun asọ ofi rẹ, bẹẹ lo tun maa n difa fun Alaafin Atiba nilu Ọyọ Idi ree ti Alaafin Atiba se fi ọmọbinrin rẹ kan, Ogboja ta Adesina lọrẹ to si bi ọmọ mẹta fun-un, orukọ wọn n jẹ Adetinrin, Adeoti Ati Adebisi, tii se abikẹyin Ọdun 1882 ni Adebisi Idikan dele aye, Aarẹ Latoosa si lo wa lori itẹ bii Baalẹ Ibadan nigba ti wọn bii Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Èmi gan máa ń béèrè lọ́wọ́ ara mi pé ta ni Wole Soyinka gangan' Okoowo asọ ofi tita ni Adebisi Idikan ati awọn ọmọ baba rẹ yoku yan laayo, ti wọn si maa n kiri yika igboro ilu Ibadan ati agbegbe rẹ Adebisi funra ara rẹ lo maa n hun asọ oke to n ta pẹlu awọn yoku rẹ, eyi to jẹ ko di kori kosun awọn eeyan to ba ni ọjọ ayẹyẹ lọna bii igbeyawo sise, oku agba ati isọmọlorukọ Koda, nigba ti Adebisi yoo fi di ẹni ọdun mejidinlogun, o ti ni awọn onibara kaakiri ni ọja Iwo, Ile Ogbo, Ikire, Osogbo, Ifẹ, Ondo titi de ilu Benin ati awọn agbegbe miran ti wọn ti n lo asọ oke Eyi to mu ki Adebisi Idikan di olowo ati ọlọrọ tabua nigba aye rẹ Nigba ti owo de, Adebisi ko di owo pamọ sinu saka rara, tabi ko maa nawo bii ẹlẹda laini itumọ, sugbọn o tun ya sidi okoowo miran, eyi ti ko ni jẹ ki owo rẹ tete run Adebisi Idikan tun ya lọ sidi isẹ ọgbin, to si mu ilẹ si abule Asipa lẹba oko Mámu lọna Ijẹbu, to si dawọle ọgbin koko lọpọ yanturu, lẹyin eyi lo tun lọ mu oko si adugbo Apata nilu Ibadan nibi to ti ni sare ilẹ bii igba to fi se ọgbin koko Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Sogidi Lake: Kòṣẹja-kòṣèèyàn lá bá nínú adágún odò náà -Ojedele Adebisi ni itan tun sọ fun wa pe oun ni ọmọ Ibadan akọkọ ti yoo ra mọto yatọ si ẹsin tawọn gbajumọ maa n lo laye igba naa Nitori aseyọri to ni nidi ọgbin koko yii ati buruji to wa lapo rẹ, lawọn olokoowo koko yoku ti wọn dijọ n se ẹgbẹ, fi jẹ olori wọn Wọn si n pe e ni Giwa ẹgbẹ onikoko, idi si ree to se fi Giwa sẹyin orukọ rẹ, to si n jẹ Sanusi Adebisi Giwa Lasiko ti buruji ji sọwọ Adebisi, dandan lowo ori nilu Ibadan nigba naa, gẹgẹ bi asọ ibora naa se jẹ tulaasi lasiko ọyẹ Awọn eebo amunisin kii fi ọrọ owo ori sere nigba naa pẹlu awọn ọdọ ati ọkunrin abarapa, ẹnikẹni ninu wọn to ba si fi aake kọri pe oun ko ni san owo ori, yoo jẹ iyan rẹ nisu loke Mapo lọdọ awọn eebo Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ikogosi-Ekiti: Ilu ti omi tutu ti dapọ mọ gbigbona Idi niyi ti Adebisi se maa n tiraka lati ba awọn akẹgbẹ, ẹbi, ara, ọrẹ ati awọn ojulumọ rẹ san owo ori, ki awọn oyinbo ma baa kọ oju wọn si oorun ọsan gangan loke Mapo Sugbọn ọrọ naa papa bẹyin yọ lori sisan owo ori yii nigba ti Balogun ilẹ Ibadan nigba naa,Ola gbẹmi ara rẹ nitori pe o ni o san ki oun ku, ju ki oun maa ri awọn ọkunrin Ibadan ki wọn maa lọ sẹwọn nitori aisan owo ori Lẹyin isẹlẹ yii, ni omi aanu to maa n san loju Adebisi lọpọ igba tun bẹrẹ si san, to si tọ awọn eebo lọ loke Mapo pe oun ṣetan lati maa san owo ori gbogbo ọkunrin to ba to owo ori san nilu Ibadan, ki ijọba si dẹkun yiyọ àwọn eeyan Ibadan lẹnu mọ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Coronavirus symptoms in Nigeria: Pẹ̀lú èròjà olùgbèjà ara 'Antibodies' Lati igba naa wa, ni eebo to n gba owo ori yoo se akojọpọ apapọ iye owo ori to yẹ ki gbogbo ọkunrin nilẹ Ibadan san, ti yoo si lọ gba a nile Adebisi Idikan Adebisi kọ ile awodamiẹnu si adugbo Idikan nilu Ibadan lọdun 1927, to si tun ra ile nla kan lojule kẹrinlelọgbọn, opopona Whitman ladugbo Ebute-Mẹta nilu Eko Lọjọ Kẹrindinlọgbọn, osu Kọkanla, ọdun 1926 ni wọn fi Adebisi jẹ oye Asiwaju ilẹ Ibadan Kokoro ko jẹ kawọn ọmọ Ibadan gbadun obi Asiwaju Sanusi Adebisi Giwa Idikan dọjọ alẹ, nitori ọjọ Ẹti, ọjọ Kọkanlelogun, osu Kẹfa, ọdun 1938 ni ẹlẹyinju aanu naa jẹ ipe Ọlọrun lẹni ọdun mẹrindinlọgọta (56) lasiko aisan ranpẹ eyi to fihan pe igi to tọ, kii pẹ nigbo.
Bakan naa ni Covid-19 hun tun ṣekupa eeyan mẹfa.
Bilidadi ará Ṣuha bá dáhùn pé,
Ẹ kò lè ṣẹgun ẹni tí ó kéré jùlọ ninu àwọn ọ̀gágun ọba Asiria, sibẹ o rò pé àwọn kẹ̀kẹ́ ogun ati àwọn ẹlẹ́ṣin ọba Ijipti yóo ràn ọ́ lọ́wọ́.
Gbogbo orílẹ̀-èdè tí ó wà ní agbègbè ilẹ̀ yìí ni n óo parun patapata, tí n óo sọ di àríbẹ̀rù, ati àrípòṣé, ati ohun ẹ̀gàn títí lae.
 gbọ ́ nmisi , omi ò to kò yé wáyé láàárín ìlú sí ilu , abúléko sí abúléko .
Bí mo bá sùn lóru,n óo máa ronú pé,‘Ìgbà wo ni ilẹ̀ óo mọ́ tí n óo dìde?
Baalẹ naa fi kun pe loju ẹsẹ si ni gbogbo eniyan ti n sa wọ inu igbo lọ.
 Àwọn tí ó ń sọ àwọn èdè yìí tó àádọ ́ rin lé ní igba mílíọ ̀ nù ( 270 million ) .
Ṣugbọn ẹgbẹta (600) ọkunrin ninu wọn sá lọ sí apá aṣálẹ̀, síbi àpáta Rimoni, wọ́n sì ń gbé inú àpáta Rimoni náà fún oṣù mẹrin.
A fipá wọ́ ọ kúrò ninu àgọ́ rẹ̀ tí ó gbẹ́kẹ̀lé,a sì mú un lọ sọ́dọ̀ Ọba Ẹ̀rù jẹ̀jẹ̀.
Bí wọ́n ti ń gbadura, ibi tí wọ́n péjọ sí mì tìtì, gbogbo wọn bá kún fún Ẹ̀mí Mímọ́, wọ́n bá ń fi ìgboyà sọ ọ̀rọ̀ Ọlọrun.
Awon osise alaabo tp n ri si isele pajawiri ti o fi mo awon omo-ogun orile-ede naa, lo n sise takun-takun lowo lati ri daju pe itoju wa fun awon ti o fara kaasa isele naa.
Àwọn ni OLUWA pàṣẹ fún láti pín ilẹ̀ ìní náà fún àwọn ọmọ Israẹli ní ilẹ̀ Kenaani.
NÍTORÍ ÌDÍ ÈYÍ, ẹnikẹ́ni  TÍ KÒ BÁ NÍ ÌFORÍTÌ KÒ Gbọdọ̀ Lọ SÍ IGBÓ YÌÍ Lọ ṣe ọdẹ LÁÉLÁÉ.
6 390788 Orilẹede Saudi Arabia 6313 18.
Okon Owoefiak - Ọmọ ẹgbẹ́ 5.
Nítorí náà, ẹ sọ fún mi bí ẹ óo bá ṣe ẹ̀tọ́ pẹlu oluwa mi tabi ẹ kò ní ṣe ẹ̀tọ́, kí n lè mọ̀ bí n óo ṣe rìn.
O ti kọ àkọsílẹ̀ burúkú nípa mi,o mú mi jìyà ẹ̀ṣẹ̀ ìgbà èwe mi.
Lẹ́hìn ìgbà tí ojú ọba rọ̀ tán ó pinnu lọ́kàn ara rẹ̀ láti wá ìddí àwọn ẹja yìí, ẹja tí ó jẹ́ pé ènìyàn kò gbọdọ̀ sè afi bí olúwaarẹ̀ múra sílẹ̀ àti máa sáré ìje, ọba wí fún ọkùnrin apẹja náà pé kí ó múra ní òwúrọ̀ ọjọ́ kejì ki ó mú òun àti àwọn ìjòyè òun lọ sí odò tí ó ti ń pá àwọn ẹja wọn-ọnnì wá.
Igbakeji alaga apapọ ẹgbẹ oṣelu APC fun ẹkun iwọ orun gusu Naijiria, Bankọle Oluwajana lo sọ bẹẹ.
Erongba idanilekoo ohun ni lati lati la awon akoroyin eto-ilera loye, lori ipa  ribi-ribi ti ajo WHO n ko lorile-ede Naijiria.
Ó sì pa àgọ́ lé e lórí.
lo fi forukọ rẹ ranṣẹ sile aṣofin.
Ilà kíkọ: Adetutu ní ilà tóun kọ̀ ni kò jẹ́ kí òun lọ ilé-ẹ̀kọ́ fásitì
Aare fi iwe yii ranse lori atẹ Twitter rẹ lati odo oluranlowo lori
Ọpọlọpọ ọrọ ni gomina Seyi Makinde sọ nibi ayẹyẹ ọjọ ibi ti iya rẹ ṣe gbẹyin eyi to fihan pe o mọ riri iya yii ko si ko iyan rẹ kere.
Ẹ gbéra nílẹ̀, ẹ̀yin eniyan mi,ẹ wọ inú yàrá yín,kí ẹ sì ti ìlẹ̀kùn mọ́rí;ẹ farapamọ́ fún ìgbà díẹ̀,títí tí ibinu OLUWA yóo fi kọjá.
8 Lõtọ́ ni mo wí fún yín, ẹ̀yin méjèèjì yíò rí gbà gẹ́gẹ́bí ìfẹ́-inú yín, nítorí ẹ ní ayọ̀ nínú ohun tí ẹ ti fẹ́.
O óo sì rí ìmọ̀ Ọlọrun.
"24 Agẹmo 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 25 Agẹmo 2020 Oríṣun àwòrán, Getty/Screenshot ""Lẹyin ti a ṣewadii iwa aidaa si ọmọniyan ti awọn ọlọpaa kan wu si ọmọbinrin kan ti a ri ninu fọnran to gbalẹ kan lọjọru ọjọ kejilelogun oṣu karun ọdun 2020, ileeṣẹ ọlọpaa Naijiria ti da ọlọpaa mẹta mọ to ṣe e ati araalu kan to ba wọn kopa ninu iwa aibofin mu yii""."
"Àjọ tó ń mójú tó ìsẹ̀gùn àti àwọn irinsẹ ìsẹ̀gùn tí jan ẹ̀rọ CPAP lọ́ntẹ̀ Ẹ wo bí ẹ ṣe lè ṣe ""hand sanitizer"" nínú ilé yín láàrín ìṣẹ́jú díẹ̀ Ǹjẹ́ fífi omi àti iyọ̀ yọnu leè dènà àrùn Coronavirus?"
Adoke ati onisowo kan, Aliyu Abubakar ni wọn dijọ n koju ẹsun jẹgudujẹra naa ni ileẹjọ giga ti ilu Abuja.
''Awọn miran le e ni iṣẹ ti wọn n ṣe nibẹ ati pe, ti a ba gbe wọn pada, ki ni wọn fẹ́ maa wa ṣe nile?
Ilẹ̀ kẹfa tí wọ́n ṣẹ́ gègé lé lórí bọ́ sí ọwọ́ ẹ̀yà Nafutali, 
" Ni ọsẹ to kọja, agbenusọ ajọ EFCC lọwọ-lọwọ, Tony Orilade, sọ fun BBC pe ẹjọ si wa nilẹ fun Ọgbẹni Ahmadu lati jẹ.
Nígbà tí Paulu kí wọn tán, ó ròyìn lẹ́sẹẹsẹ iṣẹ́ tí Ọlọrun lo òun láti ṣe láàrin àwọn tí kì í ṣe Juu.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Iriwisi àwọn ará ìlú ṣe ọtọtọ lórí èsì ìdìbò Osun Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Adeleke: Àwọn ará Ẹdẹ bẹ síta pẹ̀lú ìdùnnú lórí ìdájọ́ èsì ìdìbò gómínà Ọṣun Ẹwe, aburo Senetọ Ademola Adeleke kan ti orukọ rẹ n jẹ Dele Adeleke naa ni ohun lohun gba iwe naa nile ẹjọ kotẹmilọrun lAbuja Aworan ikede naa re e Oríṣun àwòrán, Dele Adeleke Kini idajọ yi da lori Ni ọjọ kejilelogun oṣu Kẹta ọdun yi ni ile ẹjọ to n gbejọ lori ọrọ idibo Gomina ipinlẹ Osun gbe idajọ kalẹ pe Senetọ Ademola Adeleke lo jawe olubori ninu ibi Gomina ipinlẹ Osun.
Oríṣun àwòrán, @ojedeletemitayo Àkọlé àwòrán, Awọn akẹkọ ileewe giga fasiti Ọbafẹmi Awolowo ni ilu Ile ifẹ naa ko ṣai fara gba ajalu naa Awọn akẹkọ ileewe giga fasiti Ọbafẹmi Awolowo ni ilu Ile ifẹ, naa ko ṣai fara gba ajalu naa.
Ẹni to bori: Guinea Congo DR vs Kenya.
    Báyìí ni èmi àti àwọn ẹnìkéjì mi ṣe ìrànlọ́wọ́ pàtàkì fún Ìgbéraga-ìdànújẹ́ ọmọ Ìmọ́lẹ̀ òun òkùnkùn, ti ń gbé ìpàdé ayé òun ọ̀run àti ìyàwó rẹ̀, Ahọ́ndiwúrà, tíì ṣe ìyá Ìṣubú àti Ìparun, ọmọ Àjàkálẹ́-àrùn òun Ikú, tí í ṣe ìyá ọkọ Ìbànújẹ́-òde.
 O ni “pẹlu ifọwọsowọpọ yii, a o gbe Ipinlẹ Eko de ebute ogo”Ninu ọrọ ikinikaabọ, Agbẹnusọ Ile Igbimọ Aṣofin Ipinlẹ Eko, Aṣofin Mudashiru Ọbasa sọ pe laarin ọdun mẹta ti awọn aṣofin naa ti wa ni ipo, awọn ti sọ awọn abadofin mejidinlọgbọn di ofin ati ọgọrun-un awọn ipinnu ile ti awọn ti ṣe, eyi ti ọpọ wọn nii ṣe pẹlu ẹka eto aabo ilu, eto ẹkọ, eto ilera, ina mọnamọna, eto irinna ọkọ ati ọrọ ayika fun anfani awọn ara ilu.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ondo: Dejí sun ọmọ méje àtagbalagba meji mọ́lé nítorí pé ó ń bínú Agbẹjọro wọn rọ ileẹjọ lati pe ki adajọ fun wọn ni beeli nibi igbẹjọ ọhun.
Cambridge Graduate University ni Massachusetts fun Kashamu ni oye ifidanilọla ti ọmọwe ninu eto akanse ti wọn ṣe fun un ni ipinlẹ Eko.
Minisita tun so pe ijoba apapo ti yan igbimo nla kan lati ye awon ohun ti awon osise yii n beere fun, ki won si wa ojutuu si isoro naa.
Igbesẹ yii lo waye lẹyin ti aarẹ John Magafuli paṣẹ ni nnkan bi oṣẹ diẹ sẹyin pe ki wọn ṣi awọn ile iwe pada.
Má kọ̀wé fipò sílẹ̀, àwọn àgbààgbà Yorùbá sọ fún Osinbajo Àráàlú yarí fún fásitì Babcock fún bo ṣe lé akẹ́kọ̀ọ́ tí wọn bá lòpọ̀ nínú fídíò Aarẹ Buhari ni yatọ si ọjọ ori oun, o ni oun ti bura pẹlu iwe mimọ pe oun ko ni ṣe ohun kohun to lodi si iwe ofin orilẹede Naijiria.
Àyíká ìlú náà yóo jẹ́ ọ̀kẹ́ kan ó dín ẹgbaa (18,000) igbọnwọ (mita 9,000).
Ayipada ba iye ida onibara naa ki osu kejila odun 2017 si ipari osu kinni odun 2018, eyi ti o ni alekun iko merinlelogun o le die, ju bi o se wa latiyin wa.
Wilder to jẹ abẹṣẹ ku bi ojo ọmọbibi ilẹ Amẹrika fidi rẹmi ninu ija fun igba akọkọ nigba ti oun ati Futy waako loṣu keji ọdun 2020 yii niluu Las Vegas l'Amẹrika.
Amọ alukoro ileeṣẹ ọlọpaa ipinlẹ Rivers, Nnamdi Omoni sọ fun BBC pe oun ko gbọ pe awọn agbofinro n mu awọn eeyan kan ni Oyigbo.
agbaye ni ijoba ti ni silos , ninu eyi ti wọn ra awọn oka ni opin ikore ati irugbin.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Àgbàrá omíyalé Katsina ru ìyàwó mi lọ si orílẹ̀-èdè Niger 17 Agẹmo 2018 Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, È gbọ òun ti ojú awọn ara ipinle Ogun rí lọwọ ìṣẹlẹ omiyale Nǹkan kò rọgbọ fún àwọn tí ọ farakaaṣa omíyalé to sẹlẹ laipẹ yi láwọn ìpínlè mẹta lorílè-èdè Nàìjíríà.
To o ba ṣa ti jẹ akanda ẹ̀dá, mímú ni.
Lati igbati Gomina Aregbesọla ti n se ijọba lati ma'n fi ọrọ jomitoro ọrọ lati yanju ọrọ laarin ara wa.
Lalẹ ọjọ Aiku nijọba apapọ Naijiria fidi rẹ mulẹ pe ipinlẹ to ba wu lo le darapọ mọ eto Ruga settlement.
Bí ó ti rí igi ọ̀pọ̀tọ́ kan lọ́nà, ó yà lọ sí ìdí rẹ̀, ṣugbọn, kò rí nǹkankan lórí rẹ̀ àfi kìkì ewé.
Awọn gomina ilẹ Yoruba sefilslẹ eto alaabo kan ti wọn pe ni Amotekun, ti ileesẹ Ọlọpaa si tii lẹyin amọ agbẹjọro agba nilẹ yi, Abubakar Malami ta ko pe ko bofin mu."
Ninu awọn to ti n fi ikini orire ranṣẹ́ si wọn la ti ri oludije fun ipo Aarẹ Kingsley Moghalu.
"Emi naa ba gba fun, lai jiyan pẹlu rẹ, ti mi o si ronu pe yoo lẹyin.
Má ṣe bá oníyẹ̀yẹ́ eniyan wí,kí ó má baà kórìíra rẹ,bá ọlọ́gbọ́n wí, yóo sì fẹ́ràn rẹ.
Adajọ Shyam Gyanda lo da ẹjọ naa lẹyin gbogbo atotonu awọn agbẹjọro.
Àmọ́ ẹ ríi pé ẹ dáàbò bo ẹ̀mí yín - Ọ̀gá àgbà ọlọ́pàá Ojúmọ́ kan, ìdàmú kan ni mo fi lo ogún ọdún àkọ́kọ́ lórí oyè - Alaafin Tí iye iná tí ẹ rí gbà bá kéré ju owó tí ẹ rà á lọ, ẹ ti jẹ gbèsè tẹ́lẹ̀ ni - Iléeṣẹ́ apínnáká Bakan naa lo sọ pe awọn janduku ọhun ba gbogbo ọkọ to wa ninu afin naa jẹ, bẹẹ ni wọn tun ko awọn ohun ini oun bii ounjẹ, ọti ẹlẹrindodo, aṣọ olowo iyebiye, ohun ẹṣọ ara, ẹrọ kọmputa alagbeka ati owo lọ.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ni ọdun 2013 logun abẹle bẹ silẹ lorilẹede South Sudan Ọpọ igba ni wọn ti fi ẹsun kan ijọba orilẹede ọhun pe o ndena eto iranwọ ti wọn fi nransẹ sawọn agbegbe kan, ti awọn agbẹ si tun ti sa kuro ni oko wọn pẹlu ibẹru fun ẹmi wọn eleyi to ti mu adinku nlanla ba ipese ounjẹ nibẹ.
Miriamu ati Aaroni sọ̀rọ̀ òdì sí Mose nítorí pé ó fẹ́ ọmọbinrin ará Kuṣi ní iyawo.
Ó pè é, ó ní, “Hagari, ẹrubinrin Sarai, níbo ni o ti ń bọ̀, níbo ni o sì ń lọ?
Ẹgbẹ naa ni ilọsiwaju ọmọ Yoruba ninu ọrọ aje, ihuwasi, eto ẹkọ ati ẹsin gbọdọ wa ni ifimọsọkan fun ilọsiwaju.
Wọ́n wá bẹ̀rẹ̀ sí kí i pé, “Kabiyesi!
 Àwọn àgbà bọ ̀ wọ ́ n ní ẹni tí ogun ba pa kù ní ń ròyìn ogun .
Ṣe ni ọjọ kẹfa, oṣu kẹwaa, ọdun yii ni Nabango, ọmọ ilẹ Uganda, ti a bi si ilẹ Amẹrika pari rinrin gbogbo orilẹ-ede agbaye ti o jẹ Aarundinnigba tan.
Oríṣun àwòrán, @EKEDP ''Ijọba ni lati mu atunto ba ẹka ina ọba ki awọn ara ilu baa le jẹ mudunmudun eto ijọba awarawa.
4 2478 Orilẹede Martinique 43 11.
Kàkà bẹ́ẹ̀, ẹ̀ṣẹ̀ ni ó ń dá kún ẹ̀ṣẹ̀.
ti o ran an lowo lati jawe olubori  gege
Xherdan Shaqiri ló bá Liverpool jẹ bọ́ọ̀lù méjì ní ìṣẹ́jú mẹ́tàléàádọ́rin (73) àti ọgọ́rin (80) ìṣẹ́jú sí ìgbà tí wọ́n bẹ̀rẹ̀ eré.
Lẹ́yin ọdun kan ti asoju ẹgbẹ́ Democratic ti darapọ mọ idije láti dupo pẹ̀lú ààrẹ to wà lori oyè Donald Trump, o ti wá de Super Tuesday bayii.
Oríṣun àwòrán, Reuters Àkọlé àwòrán, Ọgbẹni Mattis gbe osuba nla fun awọn ọmọogun ilẹ Indonesia paapaa pẹlu bi wọn se nfi ọgbọn mu awọn ejo naa ki to pa wọn ti wọn si mu ẹjẹ wọn.
Nítorí náà, Eleasari, ati Itamari di alufaa.
Banki apapọ Naijiria(CBN) yoo ran ipinlẹ Ogun lọwọ lati gbogun ti omiyale Agbẹnusọ fun ipinlẹ Ogun, Kunle Somori ni ijọba n sa gbogbo ipa wọn lati ri wi pe omiyale ko sẹlẹ ni ipinlẹ Ogun lasiko yii.
Eto ounje naa wa lara  bilionu ẹ̀ẹ́dẹ́gbẹ̀ta ti  ijoba aare Muhammadu Buhari ya sọtọ fun eto
O ni ipade pẹlu ile igbimọ asofin ko tii ni iyanju.
Minisita fun ọrọ ilẹ okeere, Geoffrey Onyeama sọ ninu ikede kan lọjọ Aje pe mo ranṣẹ pe Arabinrin Iva Denoo, pe ko wa ṣalaye ni kiakia lori ikọlu to waye laipẹ yii si ọ̀kan lara awọn ile to wa ni inu ọgba ileeṣẹ aṣoju Naijiria""."
Ẹni tí ó ni ilé náà yóo wá sọ fún alufaa pé, ‘Ó dàbí ẹni pé àrùn kan wà ní ilé mi.
Ẹ gbọ́ ohun tí OLUWA, Ẹlẹ́dàá yín wí,ẹni tí ó ṣẹ̀dá yín láti inú oyún,tí yóo sì ràn yín lọ́wọ́:Ẹ má bẹ̀rù ẹ̀yin ọmọ Jakọbu, iranṣẹ mi,Jeṣuruni, ẹni tí mo yàn.
Iná sọ ní abáwọlé Eko, ọkọ̀ agbépo tún tí gbiná lórí afárá Magboro Ìdí tí a fi pa àwọn àgbẹ̀ onírẹ̀sì ní Borno, Boko Haram ṣàlàyé nínú fídíò tuntun ''Ijọba gomina Dapo Abiodun ti kọwe si gbogbo awọn ti ọrọ naa kan ati awọn ẹṣọ aabo lati ri wi pe otitọ jọba.
Ijọba ibilẹ Nembe ni ipinlẹ Bayelsa ni iha Guusu Naijiria ni wọn ti bi awọn ọmọ naa ti wọn si gbe wọn wa si iha Ariwa nipinlẹ Adamawa latinu oṣu kini ọdun yii fun iṣẹ abẹ.
Eniyan lè fi ọwọ́ mú aláǹgbá,sibẹsibẹ wọ́n pọ̀ ní ààfin ọba.
Idi eyii lo mu ki awọn ọmọ Naijiria bu ẹnu ẹtẹ lu ileeṣẹ naa loju opo Twitter pẹlu ami #ShameOnNTA.
Ẹgbetokun ni ǹkan to buru jù ni pé, lẹ́yìn ti àwọn fi àwọn ọlọ́pàá náà si abẹ́ ìbáwí tán ni wọ́n bẹ̀rl si ni kọ ìwé ẹdun si ọga ọlọ́pàá pátápáta pé, ilé iṣẹ́ ọlọ́pàá Kwara n fi ìyà jẹ àwọn nítori pé àwọn jẹ́ olóòtọ́ ni.
Dókítà ọmuti ṣe iṣẹ́ abẹ tó pa olóyún àti ọmọ rẹ̀ Italy dá àwọn aboyun àt'ọmọ wẹ́wẹ́ pada Orí kó aboyún 19 yọ lọ́wọ́ àwọn tó ń tá ọmọ ní gbàǹjo ₦300,000 Ǹ jẹ́ o mọ àwọn èèyaǹ wọ̀nyí tó jà fún òmìnira Nàìjíríà?
Peter Mutharika di ààrẹ ilẹ̀ Malawi lẹ́ẹ̀kejì 'À ń bẹ Ààrẹ Buhari kó pèsè ààbò fún àwa ọ̀dọ́bìnrin' Ọọ̀ni Ilé Ifẹ̀ gbàlejò àwọn èwé sí ìdùnnú àwọn ọ̀dọ́ Omiyalé ní Ghana, èèyàn 28 dolóògbé!
Ó ṣe dáadáa ní tòótọ́ nítorí pé gbogbo àwọn tí ó kàn símí lẹ́yin tí wón gbọ́ èsì wa ni wọ́n sọ wí pé Lai Mohammed ṣe dáadáa.
Aare Macron funra re dupe pupo lowo Gassama, ni eyi ti o fun ni ami eye fadaka fun emi igboya, ni eyi ti o tun so pe, oun yoo so di osise pana-pana.
Ninu ifigagbaga onipele ohun, Djokovic n fagbahan akegbe re lowo pelu ami ayo mefa sookan(6-1), meji sookam( 2-1), ki omobibi ile Bosnia naa o to teriba ninu ikolu naa lataari ifarapa.
Ṣugbọn Farisi kan ninu àwọn ìgbìmọ̀ dìde.
Ifigagbaga idije 2018 Caf Super Cup , ni o maa n waye larin iko ti o ba gba ife-eye 2017 Caf Champions League ati iko agbaboolu ti o ba gba ife-eye 2017 Caf Confederation Cup.
Ó bẹ ̀ rẹ ̀ iṣẹ ́ orin rẹ ̀ ní ọdún 1953 , ó sì ti kọ ́ ọ ̀ pọ ̀ lọpọ ̀ olórin níṣẹ ́ orin .
Awon ara ilu naa lokunrin, lobinrin, lomode lagba ni won gboriyin fun olori mejeeji yii pe ki won tun pada wa leekan sii.
Ó ń ṣe àlàyé fún wọn, ó tún ń tọ́ka sí àkọsílẹ̀ inú Ìwé Mímọ́ láti fihàn pé dandan ni kí Mesaya jìyà, kí ó jinde kúrò ninu òkú.
Àwọn Juu mẹta kan tí ń jẹ́ Ṣadiraki, Meṣaki ati Abedinego, tí o fi ṣe alákòóso àwọn agbègbè ní ìjọba Babiloni tàpá sí àṣẹ ọba, wọn kò sin ère wúrà tí o gbé kalẹ̀.
Bí o bá fẹ́ wọ inú ìyè, pa àwọn òfin mọ́.
Gbogbo àwọn àkọ́so tí ó pọ́n ní ilẹ̀ náà tí wọn bá mú wá fún OLUWA yóo jẹ́ tìrẹ, ẹnikẹ́ni tí ó bá jẹ́ mímọ́ ninu ilé rẹ lè jẹ ẹ́.
Ogun tí a sì jà lẹ́yìn èyí, àwọn ẹyẹ àti ẹranko kò tẹriba fún Ìnàkí-ìbẹ̀rù mọ, wéré ni a ṣẹ́gun wọn.
Yoruba bo won ni ojo gbogbo ni tole, ojo kan ni tolohun.
”‘ oro iwuri’Minista fun eto iroyin ati asa  salaye pe ti ise oju opopona naa ba pari yoo din sunkere-gbakere oko ku paapaa julo awon oko to n bo lati ilu Eko lo si Shagamu.
Owo gọbọi ni awọn agbero ati ọlọkọ gbe awọn ero ni alẹ ana ọjọ Ẹti nitori ọpọ ero to wa ni titi ti wọn ko fẹ ki awọn ṣe kongẹ idamu ọrọ afara titunṣe naa.
Oríṣun àwòrán, @nigimmigration ''Gbogbo agbara la n ṣa lati yanju ọrọ yii.
Ọmọ naa n mura lati du ipo gomina ipinlẹ Delaware, lọdun 2016.
Ẹnu tí ìgbín sì fib ú òrìṣà yóò fi lọlẹ̀ dandan ni” Ọmọ náà tẹríba fún bàbá rẹ́ ó sì mọ̀ àgbà légbọ̀n-ọ́n.
Eberi ni baálé ní ìdílé Amoku,Haṣabaya ni baálé ní ìdílé Hilikaya,Netaneli ni baálé ní ìdílé Jedaaya.
Lẹ́yìn tí ó mu omi tán, ojú rẹ̀ wálẹ̀, nítorí náà, wọ́n sọ ibẹ̀ ní Enhakore.
O ti di ipo to le ni mẹtadinlogun mu ni fasiti kaakiri Naijiria ati loke okun.
Arabinrin naa sọ eyi ninu fidio kan to n ja ranyinranyin lori ayelujara, nibi ti o ti n sọrọ ni ipade ti wọn ṣe fun awọn ọmọbibi ilu Ijaw lori ayelujara.
'Mo Salah ni agbabọọlu to fakọyọ julọ lagbaye bayii' 'Mo Salah ti gbana jẹ' 'Mo Salah, Mo Salah, n da bi ẹdun' 'Mohammed Salah, ọlọwọ idan' 'Wo ohun tawọ̀n ololufẹ̀ Liverpool ṣe lẹ̀yin ti Salah fakọ̀yọ̀ loni' 'Ku iṣẹ Mohammed Salah' Chamberlain da àwọn olólùfẹ́ Liverpool, ilẹ̀Gẹ̀ẹ́sì sí hílàhílo Oríṣun àwòrán, Reuters Àkọlé àwòrán, Alex Oxlade-Chamberlain ṣe fi ẹsẹ ṣeṣe ti wọn si gbee jade Amọ ṣa o, nnkan kan ba ayọ aṣalẹ ọjọ iṣẹgun jẹ fun Liverpool.
" Wo ìdí tí wọ́n fi ta ẹyẹlé kan ṣoṣo ní ₦724,000,000 Àwọn ọmọ Naijiria kó owó wọn kúrò ní Access Bank lẹ́yìn tó gbẹ́sẹ̀lé àpò owó àwọn olùwọ́de EndSARS Jegede: Àwọn kan ń lépa ẹ̀mí mi; Akeredolu: Yẹ̀yẹ́ lásán, kò sọ́rọ̀ níbẹ̀ 'Banji Akintoye kìí ṣe adarí àwọn ọmọ Yorùbá mọ́, a ti ní ẹgbẹ́ tuntun' Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Bí o bá bá ààrùn ìpẹ́pẹ́ gbígbẹ lára arẹwà obìnrin rẹ̀, kí loó ṣe?
Ogu ninu ějọ to pe niwaju adajọ I.
Ṣugbọn Ọlọrun fihàn wá pé òun fẹ́ràn wa ní ti pé nígbà tí a ṣì jẹ́ ẹlẹ́ṣẹ̀, Kristi kú fún wa.
Ti wọn yoo si wa fun iṣẹ afi-ara-ẹni-jin bii isinru ilu ọlọdun kan ṣugbọn ti anfaani si n bẹ fẹni to ba fẹ sun siwaju si i.
Ọ̀tọ̀ ni ẹwà ti àwọn tí ń fò lófuurufú.
Adari ileewosan ijọba ni agbegbe Salem, Dokita Balajinathan ni wọn gbe alaarẹ naa wa pẹlu bi o ṣe n gbọn naa, amọ o ku lẹyin ti o lugbadi aisan ọna ọfun.
Kíní a npè ni T Cell""?"
O ni oun ti sọ fun minisita feto ọgbin lati hu akọsilẹ ofin ijọba nibẹrẹ ọdun 1960 jade eyi to sọ nipa awọn oju ọna tawọn maalu le gba.
S bí ó bá ṣe pé owó ló ń wá kiri.
Esau sáré pàdé rẹ̀, ó dì mọ́ ọn, ó so mọ́ ọn lọ́rùn, ó fi ẹnu kò ó lẹ́nu, àwọn mejeeji sì sọkún.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù SARS ti bẹ̀rẹ̀ ìgbésẹ̀ láti yọ àwọn ọ̀bàyéjẹ́ kúro níṣẹ́ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ SARS ti bẹ̀rẹ̀ ìgbésẹ̀ láti yọ àwọn ọ̀bàyéjẹ́ kúro níṣẹ́ 23 Òkùdu 2018 Kọmiṣọna fun ọlọ́pàá kògbérégbè sọ̀rọ̀ lórí àtúntò to ti wọ iṣẹ SARS.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ogun Stolen Mace: Bí wọ́n ṣe rí ọ̀pá àṣẹ ìpínlẹ̀ Ogun ní Eko rèé 3 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn wákàtí 5 sẹ́yìn Oríṣun àwòrán, Lagos PPRO Iroyin ayọ lo de ba awọn ọmọ ile igbimọ aṣofin ipinlẹ Ogun gẹgẹ bi awọn ọlọpaa ṣe sọ lọjọ Ẹti pe wọn ti ri ọpa aṣẹ ti wọn jigbe pada.
Sowore ṣèpàdé pẹ̀lú Nnamdi Kanu láti dojú ìjọba Nàíjíríà bolẹ̀ - Àjọ DSS Ilé-isẹ́ Ológun gbọdọ̀ sèwádìí bí ọmọogun se pa ọlọ́pàá - Buhari Lórí ìmọ̀ràn Sunday Igboho, Ẹlẹbubọn ní yóò dára kí Yorùbá padà sí àmúlò èròjà ìbílẹ̀ fún ààbò Àwọn ọ̀nà ti ẹ lè gbà kojú omí yale àgbára ya ṣọọbù Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Kayeefi: Facebook ni Wolii Arole Jesu fi tàn an wọ agbo, orí rẹ̀ ni wọ́n fi s'owó Lábẹ́ òfin túntún yìí, kò ni sí ààyè fú ẹnikẹ́ni láti ṣe ìwóde lóju pópó, láàrín ìlú tàbí ní agbègbè ilé ìjọba.
”Leyin ti aare kuro nibe tan, lo n bere si n dahun ibeere lati odo awon akoroyin ti o tele lati ile –ise aare pe awon to n da wahala sile lorile ede Naijiria’’ je alailekoo ati alaimokan.
1 667 Orilẹede Mauritius 10 0.
Fún Mekong Watch àti àwọn agbègbè ní ìlú náà tí àkóbá ti bá, ìpamọ́ àwọn ìtàn wọ̀nyí ṣe kókó nínú ìpolongo ìkọjú-ìjà sí àwọn iṣẹ́ tí yóò lé ẹgbẹẹgbẹ̀rún  olùgbé Mekong kúrò ní ilée wọn:
Iye àwọn eniyan náà tó ọgbọ̀n ọ̀kẹ́ (600,000) ọkunrin, láìka àwọn obinrin ati àwọn ọmọde.
- Olukoya ti ìjọ MFM Idi ti EFCC ṣe mu Sheu Sani S'ahamọ.
Eniyan burúkú ń ṣọ́ olódodo,ó ń wá ọ̀nà ati pa á.
Aago mọkanla alẹ tawọn ọlọpaa safihan ori ọmọ naa, ti wọn ti ge, lo to mọ pe ina jo oun, to si mu wa de ile akọpati ti wọn ti ge ori ọmọ rẹ.
Àwọn ni mo kó wá fún ọ yìí, Dafidi, oluwa mi.
O ni awon mu awon odo lati gbogbo ijoba ibile  to wa lorile ede Naijiria, lati kopa ninu ifigagbaga naa.
Gẹ́gẹ́ bi a ti kọ tẹ́lẹ̀, ẹrù àti owó àna yàtọ̀ lati idilé kan si ekeji, ṣùgbọ́n àwọn ohun àdúrà bára mu ni ilẹ̀ Yorùbá pàtàki Oyin, Obi, Ataare, Orógbó.
Solomoni ọba ati gbogbo àwọn ọmọ Israẹli péjọ níwájú Àpótí Ẹ̀rí OLUWA, wọ́n sì fi ọpọlọpọ aguntan ati mààlúù tí ẹnikẹ́ni kò lè kà rúbọ.
Ṣugbọn tí ìyìn rere wa bá ṣókùnkùn, àwọn tí yóo ṣègbé ni ó ṣókùnkùn sí.
Ifọrọwerọ yii wa pẹlu meji lara awọn ti wọn ti rin irinajo yii.
Adajọ Akinyemi gbọ si agbẹjọro naa lẹnu, o si wipe ki ẹniti wọn f'ẹsun ole kan naa o wa latimọle ajọ EFCC, titi wọn yoo fi gbọ ẹjọ beeli rẹ.
Àwọn alufaa kò sì lè wọ inú tẹmpili lọ mọ́ nítorí ògo OLUWA ti kún ibẹ̀.
Ó wọ́mi déegun, ó wọ̀ ṣìnkun akínyẹmí ará mi lógán
Ìdí táwọn èèyàn fi gbádún ìtàkurọ̀sọ àwọn ìgbákejì Trump àti Biden ju tiwọn lọ rèé Jíjáwé borí Joe Biden jẹ ìborí ìmọ́lẹ̀ lórí òkùnkùn-Obasanjo Àwọn àkọ́lé ìròyìn mẹ́ta tó leè tẹ̀lẹ́ ìdìbò Ààrẹ ilẹ̀ Amẹrika Iya rẹ jẹ ọmọ ilẹ India ti Baba rẹ si jẹ ọmọ Jamaica.
A ti rí ìdí abájọ, ojú ti ẹ̀yin ọmọ kòkòrò!
Ajọ NFF ṣe iranti rẹ lori opo Twitter, wọn kii fun ọpọlọpọ aṣeyọri to ṣe ninu ere bọọlu l'orilẹ-ede Naijiria Keshi ni akọnimọọgba to ko ikọ Super Eagles lọ si ife ẹyẹ agbaye ọdun 2006.
Láti àkókò yìí, ẹ ti mọ̀ ọ́n, ẹ sì ti rí i.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Nkan bii miliọnu mẹrin lawọn eeyan ti ogun ti le kuro nile lorilẹede Sudan O ni awọn agbegbe ti wahala ọwọngogo ounjẹ yii n ba finra julọ lawọn ibi ti rogbodiyan ogun ti n waye lorilẹede South Sudan.
ṣagbekalẹ ilana fun iṣakoso, awọn ohun to yẹ fun iṣọwọ ṣiṣẹ ati owo
Àwọn tí ń jẹ eniyan mi bí ẹni jẹun,àní àwọn tí kì í ké pe Ọlọrun.
“Bí ẹ bá lòdì sí mi, tí ẹ kò sì gbọ́ tèmi, n óo jẹ yín níyà ní ìlọ́po meje, fún àwọn ẹ̀ṣẹ̀ yín.
 Ni kete ta ri awọn ọmọ naa, la gbe wọn lọ sile iwosan, nibẹ si ni asiri ti tu pe awọn ọmọ mejeeji yii ko le rin daadaa nitori ọgbẹ ti obinrin naa da si wọn lara lasiko to n na wọn ni anadojubolẹ.
“Ṣugbọn ẹ̀yin alufaa ti yapa kúrò ní ọ̀nà òtítọ́, ẹ ti mú ọ̀pọ̀ eniyan kọsẹ̀ nípa ẹ̀kọ́ yín, ẹ sì ti da majẹmu tí mo bá Lefi dá.
Damaturu, Borno ati Yobe,ni eyi ti o ti seleri lati mu idagbasoke ba eto aabo
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Wo ọmọ Nàíjíríà tí wọn fi pósí ‘₦34m’ sin Ẹ fura, iyọ̀ onímájèlé tó dóde ti gbẹ̀mí èèyàn méje!
"Fọọmu Amotekun naa ko le rara lati ṣe.
Àgbàrá omíyalé ba ilé 500 jẹ́ ní Nàìjíríà Àyẹ̀wò DNA bẹ̀rẹ̀ lẹ́yìn ìjàmbá iná Eko Ẹmi mejila ṣofo ninu ijamba ọkọ l'ondo Ládugbó Oke Sokori, alàgbà James Oluyinka Okebujola di ẹbí ìṣẹlẹ náà rú ìjọba.
Kíni ẹ̀yin rántí nínú ǹkan ti o ti ṣẹlẹ lọ́dun díẹ̀ sẹ́yìn àti nísìnyìí Sanusi Adebisi Idikan rèé, olówó tó ń san owó orí fún gbogbo ọkunrin ilẹ̀ Ibadan 3.
Ibẹru ohun ti arun CoronaVirus yii le bi to ba bẹ silẹ ni Ghana lo n jẹ ki awọn eeyan kan beere pe ki wọn fi Aarẹ Akufo-Addo pamọ bo ti yẹ.
“O kò gbọdọ̀ lọ́wọ́ sí àhesọ tí kò ní òtítọ́ ninu.
Aarẹ orilẹede Naijiria tẹlẹri, Olusegun Obasanjo ti ni orilẹede Naijiria n tọ ipasẹ iparun labẹ isejọba Aarẹ Muhammadu Buhari.
Ọmọ ogun kan tó bá ikọ̀ ìròyìn AFP sọ̀rọ̀, ní ''wọ́n ya bo ibùdó iléèṣẹ́ ọmọ ogun nàá, tí wọ́n sì jọ kojú ara wọn fún bi i wákàtí kan.
Ẹ̀sun olè ají-ìwé-àkọsílẹ̀ ní a fi kan Akoroyin Samuel DSS tu akọroyin ti wọn mu silẹ Lọdun to kọja ni awọn agbofinro mu Wa Lone ati Kyaw Soe Oo fun pe wọn ni iwe ijọba eleyi ti awọn ọlọpa fun wọn.
 o je ikan ninu awon oludasile ati olori egbe komunisti ile itali , o je jiju si ogba ewa latowo ijoba fasisti benito mussolini .
Gẹgẹ bi awọn olukọ kilaasi alakọbẹrẹ ṣe maa n kọ awọn ọjẹ wẹwẹ ni àwọn obi yii atawọn ọmọ wọn ṣe di ọmọ kilaasi kan naa lati le kọ ede Yoruba.
Wọn kò ní jẹ́ ìjẹ fún àwọn orílẹ̀-èdè mìíràn mọ́; bẹ́ẹ̀ ni àwọn ẹranko ilẹ̀ yìí kò ní pa wọ́n jẹ mọ́.
A wà lẹ́yìn rẹ, nítorí náà ṣe ọkàn gírí.
Ẹ̀mí mẹ́rin bọ́ sọnù, ọ̀pọ̀ èèyàn fara pa nínú ìjàmbá ọkọ̀ l'Ogbomoṣọ Àwọn ọmọ Nàìjíríà tó há sí ilẹ̀ Gẹ̀ẹ́sì padà sílé Ilé ẹjọ́ tó ga jùlọ ní Nàìjíríà wọ́gilé ẹ̀wọ̀n Orji Uzor Kalu, pàṣẹ ìgbẹ́jọ́ tuntun Ó tesiwaju pé, pupọ nínú wọn ni kò lè san owó ilé mọ, tí wọn kò sì lè rà epo sì moto lọ sí ibise.
Ileesẹ eto ẹkọ wa rọ awọn araalu ati awọn eeyan tọrọ naa gberu lati ṣe akiyesi bi saa eto ẹkọ naa yoo ṣe lọ.
Má wulẹ̀ lọ dààmú gbogbo àwọn eniyan lásán, nítorí pé àwọn ará Ai kò pọ̀ rárá.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Mo máa n forin mi kìlọ̀ ìwà ìbàjẹ́ láwùjọ ni -Hameen 'Awọn to wa ninu ile itaja naa lo kọkọ lu aburo mi bolẹ, ti wọn si gba ẹjẹ lẹnu rẹ ni emi ṣe lu awọn naa bolẹ.
Bakan naa, South Africa yoo koju Equatorial Guinea loni ninu ifesewonse keji ninu idije naa.
Ẹwẹ arabinrin hun ni oun ko mọ idi to fi n sọ tabi to tilẹ fi nilo aaye lọwọ ọkọ oun tori awọn ti pinya nigba naa.
Nínú ìwé òfin bákan náà, òfin sọ pé èèyàn lè ṣe aṣojú nílé aṣòfin àgbà tó bá tí ní ò kéré tán ìwé ẹrí ileewe gírámà.
Ẹ tún wá ń bi mí pé, Kí ló ń ṣe mí?
Àwọn eniyan ń wọ́ lọ sọ́dọ̀ rẹ̀, ó sì ń ṣe ìrìbọmi fún wọn.
A gbúròó wọn, ọwọ́ wa rọ;ìdààmú dé bá wa,bí ìrora obinrin tí ó ń rọbí.
Eyi lo mu ki ọpọ maa beere ibi ti ijọba ipinlẹ Ogun ti wa ri ẹdinwo owo ayẹwo kokoro arun COVID-19 ti wọn ni awọn n ṣe ati pe ẹgbẹrun marundinlọgbọn naira ti wọn fẹ maa gba naa, owo ayẹwo ni ibudo wo ni?
Makinde ko jẹ ki ijakulẹ rẹ fun igba akọkọ da omi tutu si i lọkan, o tun gbe apoti ibo lati ṣoju ẹkun idibo kan naa lọdun 2011 ṣugbọn nibi idibo abẹle lo ti fidi re'mi.
Ó súnmọ́ àgbò tí ó ní ìwo meji, tí mo kọ́ rí tí ó dúró létí odò, ó sì pa kuuru sí i pẹlu ibinu ńlá.
Ẹ mú un, kí ẹ fà á lọ, ẹ má jẹ́ kí ó bọ́.
Bí ẹgbẹ́ One Million Boys ṣe bẹ̀rẹ̀ rèé àti ọṣẹ́ tó ṣe n'Ibadan Háà, àṣé Pastor Adeboye kò léè dá èékánná ara rẹ̀ gé, àwọn ọmọ Nàìjíríà kan pariwo Ọmọ Nàìjíríà sọ òkò ọ̀rọ̀ sí Osinbajo lórí ìkíni rẹ sí Wole Soyinka Ọlọ́pàá tún dé o!
Oriṣiriṣi ailera lo ti de ba awọn oṣiṣẹ fẹyinti wọnyi ti ko fi jẹ ki eto igbesẹ ijọba rọrun fun wọn rara.
Awon awako naa ko gbeyin lati se ojuse won, nipa
Ojojo kii ṣ'ogun ajinde ara yoo maa jẹ fun Ebony Alhaji ni o.
Mọrèmi Àjàṣorò, akọni obìnrin tó gba Ilé Ifẹ̀ sílẹ̀ lóko ẹrú Ọ̀rọ̀ǹpọ̀tọ̀niyùn, Aláàfin obìnrin àkọ́kọ́ rèé, tó ní nǹkan ọkùnrin Ìtàn tó wà nídi òwe ‘Sebótimọ Ẹlẹ́wà Sàpọ́n’ Piera Aiello - Oloselu ni Italy Piera ni wọn n pe ni 'Iwin' oloselu to n poora, ẹni to du ipo oselu pklu iboju loju rẹ, nitori idunkooko lati ọdọ awọn ọgbẹ imulẹ mafia.
Ti o ba bimọ fun ọkọ mi, tayọ-tayọ ni ma a fi gba a."
A yipada a sì gba ọ̀nà aṣálẹ̀ Moabu.
Wọn ni wọn tilẹ kọkọ gbowo lọwọ awọn ẹbi alufaa naa bii pe wọn fẹ fi silẹ.
Oladejo Okediji jẹ agba ọjẹ onkọwe itan arosọ ni nigba aye rẹ ki ọlọjọ to de sii lẹni ọdun mọkandinlaadọrun.
Yeyemoja bá tún ké sí Alákàn  pé kí ó bá òhun lọ sin gbèsè.
Ọrọ Covid 19 ti n mu ọwọ kan oṣelu da ni ni South Africa Ẹgbẹ oṣelu alatako ni South Africa, Democratic Alliance (DA) ti n lo anfani yii lati fa oju awọn araalu mọra lasiko yii nitori naa wọn n kẹnu bọ ọrọ awọn alakalẹ ti ijọba gbe silẹ gẹgẹ bi ofin.
Oríṣun àwòrán, Twitter O fikun wi pe, ajọṣepọ laarin awọn gomina ni ilẹ Yoruba yoo sọ airiṣẹṣe awọn ọdọ ati iṣẹ, di ohun igbagbe ni ilẹ Yoruba.
 O ni, ilana eto ohun salaye  bi won yoo se maa samulo awon ohun ipese elo lorisirisi eyi ti o ti wa nile tele lorile-ede Amerika fun amugberu ile Afrika.
NURTW l‘Abuja yóò kàn sí Makinde láìpẹ́ lórí bó ṣe fòfin dè wá l‘Ọyọ - Ejiogbe N kò lẹ́bi pé ejò kó ₦36m owó àjọ JAMB mì -Philomina Ajimobi tako àṣẹ iléẹjọ́ pẹ̀lu ìbò ìjọba ìbílẹ̀ tó ṣe - Ìjọba Ọyọ Ọpọlọpẹ awọn oṣiṣẹ alaabo ileewe naa ni ko jẹ ki wọn raaye ati sun gbogbo ileewosan naa ni ina.
Mo sì dá a lóhùn pé, ‘Èmi nìyí.
Pẹlu ìdánilójú pé o óo ṣe bí mo ti wí ni mo fi kọ ìwé yìí sí ọ; mo sì mọ̀ pé o óo tilẹ̀ ṣe jù bẹ́ẹ̀ lọ.
”Mo bá dáhùn pé, “Mo rí ìkòkò kan tí ó ń hó lórí iná, ó tẹ̀ láti ìhà àríwá sí ìhà gúsù.
‘Wàhálà yín pọ lórí Bayelsa ati Zamfara, àwa náà yóò ṣé àyẹwò ìdájọ tó gbé Buhari wọlé’ Ẹ wọ aṣọ fẹ́lẹ́fẹ́lẹ́ láti kojú ooru gbígbóná lásìkò yìí - Dokita Sagamu: Ìkọlù ń wáyé bí ará ìlú ṣe gbéná wòjú ọlọ́pàá torí ikú agbábọ́ọ̀lù Elédùmarè ló rán mi sí gbogbo Ọba Yorùbá - Oluwo Awọn ile iwosan ti wọn ti n ṣe ayẹwo naa wa ni Ile iwosan ni Abuja, ile ẹkọ iwosan ni Edo ati ile ẹkọ iwosan ni ilu Eko.
Hisbah Kano fi òfin de lílo èdè 'Black Friday', àwọn ọmọ Naijiria kan yarí lórí ayélujára
Èrèdí àbẹ̀wò Theresa May sí orílẹ̀-èdè Nàìjíríà ní láti ṣe àdéhùn lórí ètò kátàkárà tí yóò nípa láàrín Afíríkà àti Brexit.
 Bee si ni mo tun pade Fabiana ni
Wọn kò ní fi òkúta kan sílẹ̀ lórí ekeji ninu rẹ, nítorí o kò fura nígbà tí Ọlọrun wá bẹ̀ ọ́ wò!
Wakati kan ati ogun iṣẹju ni wọn fi ṣiṣẹ abẹ ọhun fun Maradona.
Oríṣun àwòrán, NAiraland Àkọlé àwòrán, Ilé-Isẹ́ Ọlọ́pàá Ìpínlẹ Ondo ti fi pańpẹ́ ọlọ́pàá mú arákùnrin eléégún tó sekúpa ọmọkùnrin kan ní ìlú Akure.
Mo wá ṣe àlàyé níwájú àwọn aṣaaju nípa ìyìn rere tí mò ń waasu fún àwọn tí kì í ṣe Juu.
Eyi lo ti wa di ẹgbẹ okunkun to n da awọn ile iwe giga ati igboro ru lode oni.
Pẹlu ẹ̀ka igi lọ́wọ́, ẹ bẹ̀rẹ̀ ayẹyẹ ìwọ́de ẹbọ náà,títí dé ibi ìwo pẹpẹ.
Bayii si ni esi ibo naa ṣe lọ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ìdílé tí ọkọ da ọmọ síta tóríi ojú Búlùú tí wọ́n ní bá BBC sọ̀rọ̀ Lọṣe yii, mejidinlogun ninu awọn eeyan ogun to n kopa ninu eto agbelewo yi ni wọn kọkọ forukọ wọn sita, ti awọn ara ile si dibo lati yọ awọn ti yoo palẹmọ ẹru lọ sile.
Oríṣun àwòrán, @FACEBOOK/UTHMAN ABUBAKAR/IBRAHIM SAWAB Àkọlé àwòrán, Awọn oṣojumikoro ni awọn mejeeji ni awọn ọmọogun gbe lo nigba ti wọn wa si ile iṣẹ iroyin naa Ileeṣẹ iroyin ko ti sọrọ nipa ohun to fa iṣẹlẹ yi titi di bi a ti ṣe nkoroyin yi.
Ọ̀pọ̀ èrò gbàgbọ́ pé òrìṣà ni àfín jẹ́ láwùjọ 'Dokita ilé ìwòsàn ló gba ẹsẹ̀ lọ́wọ́ mi' Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí kan sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
Awọn iroyin ti ẹ lee nifẹẹ si: Itan Omi Erin Ogbologbo ijapa l'aafin Sọun Èmi kìí ṣe ọmọ eléégún ṣùgbọ́n mò ń pe kísà sí ẹ̀ṣà- Òkòtò akéwì 'Kò tọ̀ọ́ kí olórí Nàìjíríà tó bá ní coronavirus gba ìtọ́jú ní ìlú tí kìí ṣe tirẹ̀' Oke mẹrindinlogun lo wa nilu Igbẹti ni Oke Ogun nipinlẹ Oyo, ṣugbọn Oke Iyamopo lo tobi ju.
Awọn mejeeji wa rọ ijọba lati fun awọn ọba alaye ni ojuse pataki lati se lagbegbe wọn, dipo ki wọn kan fi wọn di gẹrẹu lasan.
Ní ọjọ́ kan, Rutu sọ fún Naomi, ó ní, “Jẹ́ kí n lọ sí oko ẹnìkan, tí OLUWA bá jẹ́ kí n bá ojurere rẹ̀ pàdé, n ó máa ṣa ọkà tí àwọn tí wọ́n ń kórè ọkà bá gbàgbé sílẹ̀.
ASSU Strike: Ìpàdé ASUU àti ìjọba tún forí sánpọ́n
 ní àtètèkọ ́ ṣe ni ọ ̀ rọ ̀ wà .
Nítorí àwọn òkúta rẹ̀ ṣe iyebíye lójú àwọn iranṣẹ rẹ,àánú rẹ̀ sì ṣeni bí ó tilẹ̀ ti wó dà sinu erùpẹ̀.
Oríṣun àwòrán, Getty Àkọlé àwòrán, Imọ sayẹnsi ati egboogi oyinbo ti ranwa lọwọ lati ma dagba daada 7.
Ọba bá pàṣẹ fún àwọn iranṣẹ rẹ̀ pé, ‘Ẹ dì í tọwọ́-tẹsẹ̀, kí ẹ sọ ọ́ sinu òkùnkùn biribiri.
Bola Tinubu 2023: Babachir Lawal sọ pé APC gbọdọ̀ fààye gba Tinubu láti díje fún ipò ààrẹ
Ni kete ti awọn ara abule naa si ri pe ọrọ aje awọn ni awọn kan n bajẹ yii, wọn ba kọju si Gbadero lati beere pe ki lo de, ti oun naa si da wọn lohun pe lati ọdun 1970 ni oun ti ra ilẹ naa pamọ.
Oríṣun àwòrán, Ghana web Ajọ African Network of Entrepreneurs (TANOE) fi orukọ Mensa s'ara awọn ọgọta akikanju adari obinrin ni Ghana fọdun 2017.
''Mẹkunu ti ko ni iṣẹ, ti oun jẹ iya ni igbesẹ ijọba n fi aye ni lara.
Ise akoroyin jẹ isẹ  ti eniyan fi n sin
Wo atẹ ilana bi eto naa yoo ṣe lọ Ninu atẹ oke yii, awọn oniṣowo nikan to si wa labẹ ẹka eto ẹkọ lo le forukọ silẹ laago mẹwaa lọjọ Aje, ọjọ kọkanlelogun oṣu kẹsan.
Farao bá pe Mose ati Aaroni, ó ní, “Ẹ lọ rúbọ sí Ọlọrun yín, ṣugbọn ní ilẹ̀ yìí ni kí ẹ ti rú u.
Ṣugbọn àwọn Juu dé láti Antioku ati Ikoniomu, wọ́n yí ọkàn àwọn eniyan pada, wọ́n sọ Paulu ní òkúta, wọ́n sì wọ́ ọ lọ sẹ́yìn odi, wọ́n ṣebí ó ti kú.
''Mo ti wa ni ilé fún nnkán bi ọdún mọkanla sẹyìn.
Aṣẹ ti a n sọ yi ni eleyi ti o wa lati ọdọ awọn adari ẹgbẹ to fi mọ aarẹ Buhari pe ki awọn ọmọ gbẹ dibo fun sẹnẹtọ Lawan ati Omo Agege gẹgẹ bi aarẹ ati igbakeji aarẹ.
Ìlè mẹta mẹta òkúta gbígbẹ́ tí a fi ìlé kan igi kedari là láàrin, ni wọ́n fi kọ́ àgbàlá ńlá náà yípo.
Lásìkò tí àjọ náà ń pe ìpàdé akọròyìn ló sàlàyé pé nígbà ti yóò fi di òpín ọdún yìí ènìyàn ẹgbẹ̀rún méjílà léé maa kú lóòjọ́, Oríṣun àwòrán, Getty Images Eyí ju iye ènìyàn ti Coronavirus ń pa lójúmọ̀ lọ lati ìgbà ti ọ ti di rànto nínú oṣù kérin ọdún yìí.
Oríṣun àwòrán, Adesoji Aderemi family Ọba Adesọji Aderẹmi ni ọpọ iyawo ati ọmọ, alagbo nla si la le e pe, ọkan ninu awọn ọmọ rẹ si ni Arabinrin Tẹjumade Alakija, to ti di oloogbe A wa gbadura pe Ọlọrun yoo tubọ dẹ ilẹ fun ni Ọba Ọlọla Titus Martins Adesọji Tadeniawo Aderẹmi, Atọbatẹlẹ Kinni, tii se Ọọni tilu Ile Ifẹ to se gudugudu meje ati yaya mẹfa fun iran Yoruba.
Àkọlé àwòrán, Lara ija wọn ni kikoro oju si aba ofin to lodi si iroyin ori ayelujara labẹ eyi ti wọn ti ke si ijọba pe ki wọn da Omoyele Sowore oniroyin silẹ lahamọ to wa lati ọjọ yii.
M aa ri daju pee gbogbo Yunifasiti ní yoo wa ni gbogbo ẹkun ipinlẹ Ogun ti mo ba di Gomina.
Ighalo bẹrẹ si ni di gbajumọ nidi iṣẹ bọọlu nigba to wa ni ẹgbẹ agbabọọlu Julius Berger ni Naijiria, ko to lọ si ikọ Udinese lorilẹ-ede Italy.
orile-ede Naijiria ati Israel yoo pe ọgọ́ta, bi a
Òun ni ó ń bá Jìnádù jà.
Honest Digbara ti inagijẹ rẹ Bobosky fẹ fara pẹ orukọ gbajumọ nii, Bobrisky la gbọ pe awọn ọlọpaa mu ni nkan bi ago meji abo oru ni adugbo Korokoro Tai ni ijọba ibilẹ Gokana.
Wọ́n ní kí ó máa lọ àgbàdo ninu ilé ẹ̀wọ̀n.
Ẹ̀yin àyànfẹ́ mi, èyí ni ìwé keji tí mo kọ si yín.
Gbogbo awọn adajọ maraarun lo panupọ gbe idajọ naa kalẹ Ninu idajọ gbogbo wa lo fọwọsi, ti wọn gbe kalẹ, igbimọ onidajọ ẹlẹni marun ileẹjọ naa gbe idajọ kalẹ wipe, ẹjọ kotẹmilọrun ti Gomina Akeredolu pe ko lẹsẹ nlẹ.
Kì í bẹ̀rù nítorí ìdílé rẹ̀ nígbà òtútù,nítorí gbogbo wọn ni ó ti bá hun aṣọ tí ó móoru.
Amọ, ninu atẹjade kan ti alukoro ẹgbẹ oṣelu APC ẹka ti Ondo, Alex Kalejaye fi sita lọjọ Ẹti, APC sọ pe kaka ki awọn yi ibo, ohun ti awọn yoo sọ fun araalu ni pe ki wọn dibo fun Gomina Rotimi Akeredolu lẹẹkan si i lẹyin iṣẹ ribiribi to ti ṣe laarin ọdun mẹrin akọkọ.
N óo dójú lé wọn, bí wọn tilẹ̀ yọ jáde ninu iná, sibẹsibẹ iná ni yóo jó wọn.
Nipari o ni Ayisha Buhari ti lọ si London lati bii oṣu mẹrin sẹyin ni eyi ti o ni nitootọ ni irinajo yii ti n fa wahala diẹdiẹ laarin aarẹ Buhari ati Aisha aya rẹ.
 awon ni won poju ti won ungbe ni sahara ni arin ariwa afrika .
Nígbà náà ni ìsàlẹ̀ òkun hàn ketekete,ìpìlẹ̀ ayé sì fojú hàn gbangba nítorí ìbáwí rẹ, OLUWA,ati nítorí agbára èémí ihò imú rẹ.
Aago meje owurọ lo yẹ ki baalu akọkọ o gbera lati ilu Eko si Abuja, ṣugbọn, akọroyin BBC ri i pe, wọn ko ti ẹ ti i ṣe ilẹkun papakọ laago maarun owurọ.
Wọ́n ṣe agídí, wọ́n kọ̀ wọn kò gbọ́ òfin ati ọ̀rọ̀ tí OLUWA àwọn ọmọ ogun fi agbára ẹ̀mí rẹ̀ rán sí wọn, láti ẹnu àwọn wolii.
Arabinrin Barrow pelu aya aare orile ede Naijiria, Aisha Buhari ni won jo lo sile iwosan Maitama to wa niluu Abuja lati fun awon omode to n gba itoju iwosan ni awon ebun pataki.
Bi ọkùnrin kan wu obìnrin láti fẹ́ àti sọ ọ́ jade lẹ́nu á di ìṣòro fún obìnrin.
Ó gbadura sí OLUWA, OLUWA gbọ́ adura rẹ̀, ó sì mú un pada wá sórí ìtẹ́ rẹ̀ ní Jerusalẹmu.
Agbenusọ ajọ Nigeria Atomic Energy Commission fidi ẹ mulẹ fun akọroyin BBC pe, nigba ti Ojọgbọn Simon lọ gẹ irun ori rẹ ni ọkan lara awọn ile igẹrun lẹgbẹ ile itaja gaasi naa ni iṣẹlẹ naa waye.
Ṣugbọn ní ọdún keje, o gbọdọ̀ fi oko náà sílẹ̀ kí ó sinmi, kí àwọn talaka ninu yín náà lè rí oúnjẹ jẹ, kí àwọn ẹranko sì jẹ ninu èyí tí àwọn talaka bá jẹ kù.
Mo fi í ṣe olórí fún àwọn eniyan,olórí ati aláṣẹ àwọn orílẹ̀-èdè.
Wọn ni eleyii ba ofin ilẹ Amẹrika mu nitori iye ti ijọba Naijiria n gba lọwọ awọn ara ilẹ Amerika to ba fẹ wọ orilẹede Naijiria ju iye owo ti orilẹede Amerika n gba ni ọwọ awọn ọmọ Naijiria.
Iroyin to jade lati ajo to n mojuto okoowo ati ile-ise ni pe ki won ma se gba  awon ti ki i se omo orile ede Ghana laaye  lati  da okoowo sile mo on lati ojo ketadinlogbon ,osu keje .
"Ko tan si bẹ o, aworan miran tun fi awọn mejeeji han, nibi ti wọn ti n rẹẹrin sira wọn lori ijoko to jọ pe, Alaafin n sọ fun Fayemi pe, ""eeyan o ki n ṣe bayẹn."
”Aare tenumo oro re pe,“Ijoba apapo ti pinnu lati fopin si ikolu awon omo ogun olote ohun, ti alafia yoo si tun bere si ni n joba pada.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Hospital Wedding: Oṣù kan péré ni Tash fi ṣe ìgbéyàwó pẹ̀lú Simon kó tó kú Lẹyin eyi ni ija bẹ silẹ, ti Gomina Obaseki si kuro nibẹ lọ si papa iṣere Samuel Ogbemudia to wa ni ilu Benin, ni ipinlẹ Edo.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Omar Victor Diop: Ipa Áfíríkà nínú àkọsílẹ̀ ìwé kọja ògo tí wọ́n ń fún un lágbáyé Ganduje kọ̀ láti yọjú sí Ilé Asòfin lórí ẹ̀sùn àjẹbànu Oríṣun àwòrán, GANDUJE HALLACCI Àkọlé àwòrán, Ja'afar Ja'afar tí ò ń jẹ́jọ́ lórí fídìo tó s'àfihàn bí gomina ipinlẹ Kano ti ń gba rìbá dúró lórí ẹsẹ̀ rẹ̀ pé òtítọ́ ni.
Oríṣun àwòrán, @SenGbengaAshafa Àkọlé àwòrán, Akpabio ni ọmọ ẹgbẹ PDP to nipo julo to fi ẹgbẹ silẹ lọ si APC Lẹnu ọjọ mẹta yi O ṣapejuwe ohun to n ṣẹlẹ lọwọlọwọ ni Naijiria gẹgẹ bi 'ogun laarin awọn onilọsiwaju ati awọn to wa l'oju kan.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Akomolede ati Asa lori BBC: Olùkọ́ Kikelomo Ogunboye tan ìmalẹ̀ sí ìwà olè ọ̀gá ọlọ́pàá Awọn ohun ti o nilo lati mọ nipa ẹnubode ti ijọba aarẹ Buhari tipa niyi: Ni oṣu kẹjọ ọdun 2019 ni ijọba ti awọn ẹnubode lati dẹkun fayawọ ogun, ohun ija oloro, ounjẹ atiohun elo ọgbin wọ orilẹede Naijiria.
"Ṣe ni o yẹ ki o kọ iwe lati fi to Aarẹ Ile Igbimọ Aṣofin Agba, ati abẹnugan Ile Igbimọ Aṣoju-ṣofin leti,"" Bẹẹ gẹgẹ ni amofin Ozekhome naa ṣọ."
O ni kete ti oun ba ti gun pepele gbagede ija bayii ni agbara oun maa de ti ọkan oun maa le pe iṣẹ ti bẹrẹ naa niyẹn.
“Nígbà tí OLUWA rí ohun tí àwọn ọmọ rẹ̀ ń ṣe,ó kọ̀ wọ́n sílẹ̀,nítorí pé, wọ́n mú un bínú.
Ẹ fún ọ̀já kó le, lítà epo kan le tó ₦250 àbí ju ₦300 lọ Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Sotitobire: Adájọ́ sọ̀rọ̀ nípa ọjọ́ ìdájọ́ fún Wòlíì Sotitobire Alfa Babatunde18 Owewe 2020 Fídíò, Taiwo Bamidele Ondo Dwarf Judge: Ọlọ́run kò ṣe àṣìṣe pé ó dá mi ní aràrá14 Owewe 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
tabili, ti iko agbaboolu Liverpool si tele won pelu ami mẹ́tàdínlọ́gọ́rùn ún(97points).
Ṣugbọn wolii tí ó bá fi orúkọ mi jẹ́ iṣẹ́ tí n kò rán an, tabi tí ó jẹ́ iṣẹ́ kan fun yín ní orúkọ àwọn oriṣa, wolii náà gbọdọ̀ kú ni.
“Bí ẹnikẹ́ni bá yá eniyan ní nǹkankan, kò gbọdọ̀ gba ọlọ tabi ọmọ ọlọ tí ẹni náà fi ń lọ ọkà gẹ́gẹ́ bíi ìdógò, nítorí pé bí ó bá gba èyíkéyìí ninu mejeeji, bí ìgbà tí ó gba ẹ̀mí eniyan ni.
“Ìkọkúkọ [lórí àwòrán Ààrẹ] jẹ́ ẹ̀ṣẹ̀ tí ó mú ìjìyà dání lábẹ́ òfin ilẹ̀ Burundi gẹ́gẹ́ bí àbọ̀ ìwádìí Reuters kan ṣe sọ.
 Eyi ni iku gbigbona lara asiyin ibon nile iwe  to sele lasiko yii leyin eyi to gbemi eniyan merindinlogun to sele ni Connecticut lati owo Sandy Hook lodun 2012.
“Ẹ sọ fún ọdọmọbinrin, Sioni, pé, Wo ọba rẹ tí ó ń bọ̀ wá sọ́dọ̀ rẹ;pẹlu ìrẹ̀lẹ̀, ó gun kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́,àní ọmọ kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́,ẹranko tí à ń lò láti rẹrù.
Ó bá dáhùn, ó ní, “Àwọn wọnyi ni àwọn meji tí a ti fi òróró yàn láti jẹ́ òjíṣẹ́ OLUWA gbogbo ayé.
Farao bá dìde ní ọ̀gànjọ́ òru, òun ati gbogbo àwọn ẹmẹ̀wà rẹ̀, ati gbogbo àwọn ará Ijipti.
ní ìhà ìlà oòrùn Jọdani ní òdìkejì Jẹriko.
Ó ń sin Ọlọrun bí ó ti tẹríba lórí ọ̀pá rẹ̀.
’ Ṣugbọn lẹ́yìn ìgbà díẹ̀, ó ronupiwada, ó bá lọ.
Mose bá dáhùn, ó ní, “Bí o ti wí gan-an ni yóo rí.
Èékán ọwọ́ rẹ a máa dúdú fún èérí, nítorí ẹ̀ẹ̀kan lọ́dún ni ìwọ ń ré e, irún orí rẹ dàbí ìtàkùn ara igi nítorí ẹ̀ẹ̀kan lọ́dún ni ìwọ ń já a, ara rẹ̀ dúdú bí ìdí ìkòkò, nítorí ẹ̀ẹ̀kan lọ́dún ni ìwọ ń wẹ̀ ẹ́.
Ohun ti wọn sọ ni pe awọn fẹ daabo bo awọn ere tawọn eeyan kan n wo lulẹ notori wọn nii ṣe pẹlu ẹlẹyamẹya.
Aisaya ọmọ Amosi bá ranṣẹ sí Hesekaya, pé OLUWA, Ọlọrun Israẹli ní, nítorí pé Hesekaya ti gbadura sí òun nípa Senakeribu ọba Asiria, 
Ó pada lọ bá àwọn arakunrin rẹ̀, ó wí fún wọn pé, “Ọmọ náà kò sí níbẹ̀?
” Nítorí ó ń waasu nípa Jesu ati ajinde.
Olubadan: ìbànújẹ́ ọkàn ló jẹ́ fún mi pé Ọlọwọ ti Ọwọ jade láyé
"Oríṣun àwòrán, Facebook/Adoration Ministry Enugu ""SARS kọ ni isoro kansoso taa ni, lẹyin isoro SARS yii, awọn isoro wa yoo si maa tẹsiwaju, abi bawo ni awọn ọdọ ko se ni risẹ oojọ se."
Ko si ibi ti wọn o gbe mi de.
Ibaṣepọ ti mo ni pẹlu iya mi ko lẹgbẹ.
Lẹ́yìn náà, sọ̀rọ̀, n óo sì fèsì;tabi kí o jẹ́ kí èmi sọ̀rọ̀, kí o sì fún mi lésì.
"Lẹ́yìn àyẹ̀wò, kò sí alárùn Coronavirus ní Nàíjíríà, sáká lara wa dá - Mínísítà ""Àbámọ̀ ló gbẹ̀yìn bí mo ṣe yípadà láti obìnrin sí ọkùnrin, ń kò bá tí ṣe bẹ́ẹ̀"" Kaduna tún gbàlejò ìkọlù àwọn agbébọn, àádọ́ta èèyàn míì rọ̀run ọ̀sán gangan Gómìnà Oyetọla tí yi ìlànà ètò ẹ̀kọ Rauf Aregbesola pada Obìnrin tó ń ṣiṣẹ́ ẹrú ní Oman tó bá fẹ́ òmìnira, yóò bá ọ̀gá rẹ̀ ṣùn - obìnrin méjì tó ti oko ẹrú dé Nigba to n sọrọ lori ohun ti Oluwo lee se, ti oun yoo fi gbe ẹjọ naa kuro nileẹjọ, tawọn yoo si yanju rẹ nitubi n nubi, Ọba Akinrọpo ni Oluwo gbọdọ lọ pada tun oun se nibi gbogbo to ti ba orukọ oun jẹ de, paapa lọdọ awọn ileesẹ iroyin gbogbo, nibi to ti n pe oun ni baalẹ lasan-lasan, pe ko si ohun ti oun lee se."
Kò pé nígbà tí ìgbéyàwó mi parí tí a rí ọwọ́ òsì Ayédèrú-ẹ̀dá tí ó rọ, ọwọ́ ọ̀tún lo fi ń gbé ìbọn láti ìgbà náà lọ a kò sì mọ ìdí, rẹ̀ tí ọwọ́ náà fi rọ.
Theresa May bú sẹ́kún, ó ní òun kò ṣe olóòtú ìjọba UK mọ́
 jésù fúnrarẹ ̀ pe ara rè lọ ́ mo ọlọ ́ run nínú ọ ̀ pòlòpò ẹsẹ ̣ bíbélì pàápàá jùlọ nínú àdúrà olúwa tí ó kọ ́ àwọn ọmọ ẹ ̀ yìn rẹ ̀ láti máa gbà ( matheu 6 : 9-13 , luke 11 : 2-4 ) .
 lati lo daabobo awon to n gbe adugbo naa.
Ati Gomina Kayode Fayemi, ati obi Daniel Olutope to fi mọ awọn olukọ rẹ ni ori wọn wu si iṣe-daradara rẹ.
Ẹ o ranti wipe, ọrọ ti nja rain rain tẹ́lẹ̀ lori pe Daddy Freeze fesi si ọ̀rọ̀ pasitọ̀ Adeboye lori sisan idamẹ́wa leyii ti Freeze fesi pe idamẹ́wo ko pọn dandan.
Awọn orilẹede ti ọrọ naa kan ni Nigeria, Senegal, Togo, Angola, Niger ati Tunisia pẹlu awọn agbeegbe kọọkan lati Latin America ati South East Asia.
Ọọni ogunwusi bẹrẹ abẹwo si orilẹede Brazil
Abilekọ naa sọ pe inu oun maa n dun pupọ ni ayajọ ọjọ bi eniyan ṣe pọ to laye, ti ori oun si maa n wu pe oun bi ọmọ to pọ.
    “Lẹ́jẹ́ kan mo ríi ó wọ ẹ̀wù agbádá dáradára kan báyìí, ara rẹ̀ sì dàbí ara ọmọ kékeré, ó lé wà gidigidi.
Iṣẹ́ rẹ lò ń ṣe rìnrìn àjò lọ́jọ́ burúkú yìí
2m dọlà ni obìnrin yìí ń gbà tó bá kọ ǹkan sí ojú òpó Instagram rẹ̀ Kò lè ṣééṣe kí Ruga wà lápá gúúsù Nàìjíríà fáwọn Fulani- Ganduje Gomina ipinlẹ Ọyọ naa ni awọn gomina ni ẹkun naa n se ipade igba de igba lati wa ọna abayọ si eto aabo to dẹnu kọlẹ, eleyii ti o ti jasi iku fun awọn eniyan kan ni agbeegbe naa.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù APC: O jẹ́ tètè jẹ́wọ́ àwọn tó rán ọ níṣẹ́ torí àwa kìí fún apààyàn lówó 25 Ògún 2019 Oríṣun àwòrán, @PoliceNG Yoruba ni to ba buru tan, iwọ nikan ni yoo ku.
Àwọn ọ̀tá mi ń ro ibi sí mi, wọ́n ń wí pé,“Nígbà wo ni yóo kú, tí orúkọ rẹ̀ yóo parẹ́?
"Oríṣun àwòrán, @KvngLerry Ẹwẹ, ile igbimọ aṣoju-ṣofin orilẹede Amẹrika ti ni awọn yoo ṣe agbekalẹ abadofin ""ma dina mọ ẹnikẹni"" lodi si igbesẹ ti aarẹ Donald Trump gbe."
Ọbásanjọ́ nìkan sì kọ́ ni ọ̀gágun tí ó ti jagun fẹ̀yìntì tí ó ń tàbùkù Buhari.
Ìwọ tí ó jẹ́ bí ẹ̀ka igi olifi tí ó la ilẹ̀ hù ninu ìgbẹ́, tí a lọ́ mọ́ ara igi olifi inú oko, tí ẹ̀dá wọn yàtọ̀ sí ara wọn, báwo ni yóo ti rọrùn tó láti tún lọ́ àwọn tí ó jẹ́ ara igi olifi inú oko tẹ́lẹ̀ mọ́ ara igi tí a ti gé wọn kúrò!
 Adari orile ede Naijiria, gbosuba fun awon akegbe rẹ , pe yiyan ti won yan oun, o ni oun ko fi ara oun sile lati dibo “Sugbon ẹ kọ jalẹ lati yan mi.
Oludari ile akede Naijiria so pe , o se ni laaanu pe, ko si gbolohun kan ninu iwe akosile naa, to gbosuba fun aare Muhammadu Buhari nipa igbiyanju re lori atunse to se si oju-popo Enugu si Onitsha , oju ona PortHarcourt, oke afara keji ti Niger ati awon oju-popo ijoba apapo to wa lekun naa, ati opa gaasi , ile-ise eedu ati eto ogbin.
Ẹwẹ, Ọọ̀ni ti wọ 'léédì ọlọ́jọ́ méje láti ṣíde ayẹyẹ ọdún Ọlọ́jọ́ ti ọdun 2018.
A ro pe eniyan buruku ni wọn ti wọn fẹ pa wa.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù JAMB 2019: JAMB ní ẹ̀rọ tó ń wo bó ṣe ń lọ ni ibùdó ìdánwò Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ JAMB 2019: JAMB ní ẹ̀rọ tó ń wo bó ṣe ń lọ ni ibùdó ìdánwò 11 Ìgbé 2019 Idanwo aṣewọ ile iwe giga JAMB ti gberasọ lonii, ọjọ kọkanla ti yoo si waye titi di ọjọ kẹtadinlogun, oṣu kẹrin ọdun 2019.
ABS FC ti ipinle Kwara, lojo Aiku fagba han alejo won lati ilu Maiduguri, El-Kanemi Warriors FC pelu ami ayo 2-1 ni arin gbungbun papa isere ipinle ohun ni ilu Ilorin.
Aare awon egbe akekoo lorile ede Naijiria( National Association of Nigerian Students ,NANS), Mr Danielson Akpan wa ro ijoba ati egbe oluko fafiti lati yanju aawo naa ni irowo-irose.
Ẹ jẹ́ kí á pa á, kí ogún rẹ̀ lè di tiwa.
Gbogbo àdúgbò ọ̀hún á wá rẹwà lójú dáadáa.
Petahaya ọmọ Meṣesabeli, lára àwọn ọmọ Sera, ọmọ Juda, ni aṣojú ọba nípa gbogbo nǹkan tí ó bá jẹ mọ́ ti àwọn ọmọ Israẹli.
Ilé iwé kan náà ni Musa àti Tolu jọ lọ, ìyẹn ilé iwé alákọbẹ̀rẹ̀ Nigeria Airforce ní ìlú Kaduna ti wọn sì ti n ṣe ọ̀rẹ́ láti ìgbà náà titi wọ́n fi dàgbà, Tolu gbà láti ṣe iṣẹ́ ọmọ ogun ofurufu nígbà ti Musa lọ fún ìmọ̀ ẹ̀kọ́ Chemistry ni fasiti Uthman Dan fodio ni Sokoto, ṣùgbọ́n ọ̀rẹ́ wan kò yà títí di ọjọ́ ikú.
Báyìí ni àwọn alátìlẹ́yìn Super Eagles ṣe ń dá músò ṣáájú ìdíje tòní
Tabi kí èèsún hù níbi tí kò sí omi?
Ṣugbọn èmi ké pe Ọlọrun;OLUWA yóo sì gbà mí.
Risikat fikun pe, nigba to ya ni wọn tun ni ki eeyan kan wa wọn oun ati ọkọ oun, ti yoo ba awọn ran asọ wa, ti onitọun si gbe ankoo naa wa ni ọjọ keji.
3 Àti pé lẹ́hìn tí ẹ bá ti ní ìgbàgbọ́, tí ẹ sì ti rí wọn pẹ̀lú ojú yín, ẹ̀yin yíò jẹ́rìí sí wọn, nípa agbára Ọlọ́run;
Canada yá, àti àwọn ọ̀nà mì t'ọmọ Nàìjíríá fi bínú sí sísún ìdìbò ‘Irọ́ ni pé Ọmọ ọdọ̀ Ọpẹ Bademosi kú’ Day 19: Wo ohun àràmàndà tí àwọn olósèlú máa ń ṣe lásìkò ìbò #BBCNigeria2019 Njẹ́ o dá ayédèrú ìròyìn mọ̀ tí o bá ri i?
Nígbà tí Eberi di ẹni ọdún mẹrinlelọgbọn ni ó bí Pelegi.
Àkọsílẹ̀ kan sọ pé, “Mo gbàgbọ́, nítorí náà ni mo fi sọ̀rọ̀.
Lẹ́yìn tí wọ́n fi kakata hú gbogbo iṣú àti ẹ̀gẹ́ mí, wọ́n tún ṣá àwọn ọmọ mi ládàá-Guru Maharaj Ji Wo agbábọ́ọ̀lù Super Eagles Nàìjíríà àkọ́kọ́ tó lùgbàdì coronavirus Báwo ni Coronavirus ṣe n tànkálẹ̀ l'Afrika?
Àwọn ọmọ-ẹ̀yìn Johanu bá wá, wọ́n gbé òkú rẹ̀ lọ, wọ́n sin ín; wọ́n sì lọ ròyìn fún Jesu.
Ènìyàn 653 míràn tún kún iye àwọn tó ní COVID-19 ní Nàìjíríà Ohun mẹ́fà tí ọ̀pọ̀ kò mọ̀ nípa ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ Arsenal àti Machester City Èèmọ̀!
Gẹ́gẹ́bí Wòlíì ti sọ, ìfihàn yìí sọọ́ di mímọ̀ “ìpè ti àwọn àpóstélì méjìlá ní àwọn ọjọ́ tí ó gbẹ̀hìn wọ̀nyí, àti bákannáà àwọn òfin tí ó ní ṣe sí mímú Ìjọ dàgbà.
Oríṣun àwòrán, Screenshot/ Dubai police Àkọlé àwòrán, Gal Pissetzky tó ń ṣojú Hushpuppi fẹ̀sùn ajínigbé kan FBI lórí ọ̀rọ̀ Ramọni Abass Ọsẹ diẹ sẹyin ni ọmọ Naijiria naa, ti ilẹ Amẹrika fi ẹsun ṣiṣe jibiti lori ayelujara kan, Ramon Igbalode, ti inagijẹ rẹ n jẹ Hushpuppi yọju sile ẹjọ lonii.
32 Àti, kíyèsíi, wọn yíò tẹ èyí jade, àti pé Sátánì yíò sé ọkàn àwọn ènìyàn le láti ru wọ́n sókè lati bínú lòdì sí ọ, kí wọn má baà gba àwọn ọ̀rọ̀ mi gbọ́.
Nígbà tí wọ́n dé, ó kó gbogbo ohun tí ojú rẹ̀ rí ó rò ó fún wọn ó sì tún wí fún wọn pẹ̀lú pé òun ń fẹ́ kí nǹkan náà ṣẹlẹ̀ lójú gbogbo wọn.
Akọwe agba fun ijọba apapọ, ọgbẹni Boss Mustapha lo fi ọrọ na sita ninu atẹjade kan to fi sọwọ si awọn akọroyin labuja.
"Nitori ojojo to n se ogun ọrọ aje orilẹede wa, mo n sọ fun yin pe lati akoko yi lọ, ma se adinku owo osu ati ajẹmọnu mi pẹlu ida mẹẹdọgbọn, ti maa si ko sinu apo asunwọn owo idagbasoke orilẹede Liberia.
OLUWA yóo da irú oówo tí ó fi bá àwọn ará Ijipti jà bò ọ́, ati egbò, èkúkú ati ẹ̀yi, tí ẹnikẹ́ni kò ní lè wòsàn.
Ọ̀lẹ gbọ́n lójú ara rẹ̀ju eniyan meje tí wọ́n lè dáhùn ọ̀rọ̀ pẹlu ọgbọ́n lọ.
O ni oun ti bẹrẹ si ja fẹtọ ọmọniyan lati igba ti oun ti wa nile iwe giga Fasiti Eko titi di asiko yii.
Coronavirus symtoms and cure: Seyi Makinde ní òun kìí ṣe dókítà tí yóò yan ògùn Coronavirus fún ẹnikẹ́ni
Òkú ọmọ tuntun pòórá nílé ìgbókúpamọ́sí nílùú Akurẹ Alaga igbimọ eto iroyin ati ilanilọyẹ fawọn oludibo, Fẹstus Okoye lo sọ eyi di mimọ niluu Enugu, nibi apero lori bawọn oniroyin ṣe ṣiṣẹ si lasiko idibo 2019.
Ọwọn-gogo epo ti o ruyọ lopin ọdun to kọja ti fa awuyewuye lori boya ijọba apapọ yoo fikun owo epo tabi wọn ko ni se bẹẹ.
Òfo ni gbogbo làálàá yín já sí!
Ṣugbọn ẹ má ṣe tẹ̀lé ìwà wọn, nítorí ọ̀tọ̀ ni ohun tí wọn óo sọ, ọ̀tọ̀ ni ohun tí wọn óo ṣe.
Ajinhinrere Bamiloye tẹsiwaju ninu ọrọ rẹ pe, oun ko ni koko isẹ kankan lọwọ ju ere ori itage lọ nigba ti oun gbe Gloria niyawo.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: ₦147m la rí kójọ fún ìwọ́de, a kò fẹ́ owó mọ́, ìwọ́de ti parí - Feminist Coalition Wo ìròyìn, àwòrán àti fídíò èké nípa ìwọ́de EndSARS Super Eagles, ẹ máṣe gbá bọ́ọ̀lù fún Nàìjíríà mọ́ nítorí ìhà tí ìjọba kọ sí ìwọ́de EndSARS - John Ogu Ará Eko, ẹ pariwo ó tó gẹ́ẹ́ lórí làásìgbò tó gbòde torí ìwọ́de EndSARS - Sanwo-Olu Ọ̀tá Yorùbá ló lo ìwọ́de láti dojú ogun kọ wá - OPC Àwọn ọ̀tá Nàíjíríà tó fẹ́ dojú ìjọba bolẹ̀ ló wà lẹ́yìn ìwọ́de EndSARS"" Ó parí ni ohùn tó gbẹnu ọ̀pọ̀ ọmọ Nàíjíríà lẹ́yìn ọ̀rọ̀ Buhari Ìwọ́de EndSARS kìí ṣe ọ̀rọ̀ ẹlẹ́yàmẹ̀yà, ara ti kan àwọn èèyàn ni - Afenifere Araba ilu Osogbo, Oloye Ifayemi Elebuibon ati Alagba Peter Fatomilola, panupọ sọ pe, ọ̀pá àṣẹ ọba kii ṣe ohun amusere."
ShopRite, SPAR, Cash 'N' Carry àtàwọn dúkìá míì tí jàǹdùkú jó níná Oríṣun àwòrán, Reuters Lati igba ti iṣẹlẹ isekupani awọn oluwọde End SARS ti waye ni Lekki, ni awọn janduku ti bẹrẹ si n da ilu ru ni ipinlẹ Eko.
Ọ̀dọ̀ OLUWA àwọn ọmọ ogun ni ìmọ̀ yìí ti ń wá pẹlu,ìmọ̀ràn rẹ̀ yani lẹ́nu;ọgbọ́n rẹ̀ ni ó sì ga jùlọ.
Kẹ̀kẹ́ jẹ́ nkan pàtàkì gidi fún wọn níbí.
” Gege bi Igbakeji aare orile ede Liberia ,  Dokita Jewel Taylornaa,”inu mi dun lati wa nibi yii, gege bi a se mo pe, Orin je idunnu fun okan”.
asoju -sofin jiroro lori ona ti a o se mu awon ileri wa sẹ.
Naomi Osaka fagbahan akegbe re Serena Williams ni oju agbami papa isere Flushing Meadows.
Dafidi ọba wí pé, “N óo ṣe ẹ̀tọ́ fún Hanuni, ọmọ Nahaṣi gẹ́gẹ́ bí baba rẹ̀ ti ṣe ẹ̀tọ́ fún mi.
Wọ́n bá bẹ̀rẹ̀ sí kígbe, wọ́n ń wí pé, “Oriṣa ńlá ni Atẹmisi, oriṣa àwọn ará Efesu!
Bí ọba ati gbogbo àwọn eniyan rẹ̀ ti ń jáde kúrò ní ìlú, wọ́n dúró níbi ilé tí ó wà ní ìpẹ̀kun ìlú.
Igbese yii waye leyin ti awon ifehonuhan lorisirisi n waye lorile ede
Arun Coronavirus ma n tan kan nigba ti ẹni to ba ti lugbadi arun naa ba wukọ, ti afẹfẹ si gbe.
Báwo ní èyí yóò ṣe kan ọlọ́dani àti àwọn olókoòwò?
Day 25: Àwọn àkànlò èdè lásìkò ìdìbò #BBCNigeria2019 Awọn aworan nibi ti awọn oloselu ti n ṣe nkan aramanda Oríṣun àwòrán, Facebook Àkọlé àwòrán, Oludije si ipo sẹnetọ ni ipinlẹ Kaduna pin redio fun awọn eniyan bi o tilẹ je pe o ni ko ni i se pẹlu oselu, amọ fun Ayajọ Ọjọ Radio lagbaye.
Máṣe sọ tíì eléwé àti kọfí rẹ nù, ó lè sọ ọ́ di olówó Wò ó ọ̀nà láti mú ara rẹ dé ibi tó ga jùlọ nínú ìbálòpọ̀ pẹ̀lú ìlànà Tantra Láì lo Kakulétọ̀, mo ní ọpọlọ ìṣirò, tábìlì ìṣirò wà lórí mi - Human Calculator Bí Fayemi bá tasẹ̀ àgẹ̀rẹ̀, àwọn oníbáwí rẹ̀ wà l'Ekiti-Peter Fatomilọla Àwọn ọba Yorùbá kan rèé tí wọ́n rọ̀ lóyè, tí ọba míràn jẹ lójú ayé wọn Araba awo ilu Osogbo, Baba Ifayẹmi Ẹlẹbuibọn ṣalaye ọrọ lori oṣolẹ, awure ati bi yoruba ṣe n lo wọn nigba iwaṣẹ.
Ṣe ọda olukọ ti n da wọn l'Ọṣun ni?
”    Alaga naa wa so pe awon oloye egbe ni yoo fontẹ lu ijiroro ti awon agba egbe naa se ,nigba ti awon ba n se ipade won lojoBo.
Ṣaaju ni ile ẹjọ kotẹmilọrun ti sọ pe Oyetola lo jawe olubori ninu idibo naa.
Aarẹ Buhari pàṣẹ pé kí wọ́n ṣàwárí àwọn oníṣẹ́ ibi tó pa èèyàn 65 ni Borno Ọlọ́pàá fi páńpẹ́ ọba mú ọmọ ogun ilẹ̀ Naijiria Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Shiite: Ẹ̀mí àti ara wa kọ ohun tí ìjọba ń ṣe sìwa láti 2015 Lẹyin atotonu awọn aṣofin si gba Aregbesola laaye ki o tẹriba niwaju ile ko si maa lọ.
Àwọn ẹnìkan mú afọ́jú kan wá sí ọ̀dọ̀ rẹ̀, wọ́n ń bẹ̀ ẹ́ pé kí ó fọwọ́ kàn án.
Oòrùn bá dúró jẹ́ẹ́, òṣùpá náà sì dúró jẹ́ẹ́, títí tí àwọn ọmọ Israẹli fi gbẹ̀san tán lára àwọn ọ̀tá wọn.
Oríṣun àwòrán, OTHERS Gẹgẹ bi ofin Naijiria se la a kalẹ, ọmọ bibi Naijiria ni asẹ lati dije dupo lorilẹede Naijiria.
“Ṣugbọn Ọlọrun kò jẹ́ fi àwọn olóòótọ́ sílẹ̀,bẹ́ẹ̀ ni kò jẹ́ ran ẹni ibi lọ́wọ́.
nígbà tí ọ ̀ rọ ̀ ti rí bí eléyìí ni àwọn ẹbí láṣòrè ti lọ fi ọ ̀ rọ ̀ tó ọba létí .
 “Awon ipinle to ba nifee si eto yii ni ,yoo mu
ni  eemeji otooto won le kuro ni osu keji
Ó sọ fún wọn pé kí wọ́n yá ère ẹranko tí a ti fi idà ṣá lọ́gbẹ́ tí ó tún yè.
O ni ọjọ mẹrin gbako ni iṣẹ naa maa n gba wọn ko to di odindin.
 iṣẹ ́ àgbéyẹ ̀ wò méjì ni pèpéle yìí ń ṣe , àwọn ni : : * Ṣíṣàgbéyẹ ̀ wò sinimá .
Orúkọ wọn yóo máa jẹ́ ẹnubodè Reubẹni, ẹnubodè Juda ati ẹnubodè Lefi.
Ni ipari, won fun arabinrin Aisha Buhari  ni ami ẹyẹ  asiwaju rere fun awon obinrin inu egbe APC.
Amọ, awọn oṣere ori tiata Yoruba naa ko gbẹyin nibi iwọde ọhun.
Ìpínlẹ̀ Oyo sọ àsìá Nàìjíríà kalẹ̀ láti dárò Abiola Ajimobi Abiola Ajimobi, Gómìnà tí ọ̀rọ̀ kìí kú mọ lára, à fi kó fèsì Òtútù ikú Ajimobi sì ń mú mi, ń kò le sọ̀rọ̀- Akala, Ayefele Aworan ree nipa bí Abiola Ajimobi ṣe lo ayé rẹ̀ Ọmọ atàpátadìde ni mí, télọ̀ ni bàbá mi- Abiola Ajimobi Bakan naa la tun gbọ pe, awọn ikọ to n se amojuto arun Coronavirus ni yoo gbe oku Ajimobi wa lati ilu Eko, lati wa sin.
Ó ní kí o gbógun tì wọ́n títí o óo fi pa wọ́n run patapata.
'À ń fẹ́ epo ọ̀fẹ́ tàbí gbà má bínú lọ́wọ́ ìjọba' 'A ò lè ṣọ dájú pé èèyàn 66 ló kú ní Kaduna - Iléeṣẹ́ ọlọ́pàá, NEMA Ṣé o fẹ́ lọ sí Canada?
Ọ̀pọ̀ aráàlú Owo wà nílé ìwòsàn, síbẹ̀ APC àti PDP kò gba ẹ̀bi Makinde gba àwọn òṣìṣẹ́ LAUTECH 41 tí ìjọba Ajimobi dá dúró lẹ́nu iṣẹ́ padà Obabinrin Elizabeth kejì kí Nàìjíríà kú oríire òmìnira ọgọ́ta ọdún Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
"Wọn ba a niwaju ile rẹ ni Kwanar Agam wọn si ji i gbe ni nkan bi agogo meje alẹ lẹyin irun Mọgrib.
Oxford lóri ayelujara rẹ̀ sàlàyé pé bi Naijiria ṣe n fi kun èdè Gẹ̀ẹ́sì ju gbogbo àwọn èdè àgbáye míràn lọ.
Corornavirus: Ṣe lilo ìbọ̀wọ́ le dènà ààrùn Coronavirus
Eniyan lè jókòó kí ó ṣètò ìgbésẹ̀ rẹ̀,ṣugbọn OLUWA níí tọ́ ìṣísẹ̀ ẹni.
 O pẹ diẹ ki Iyalufa to pade ẹnikan to n ti ọja naa bọ, to si beere pe ṣe o ba oun ri Ọmọyẹ lọna ọja ni ihooho, tori oun fẹ fun un lasọ ti yoo fi bo ihooho rẹ ni."
Lẹ́yìn èyí, Benhadadi, ọba Siria, kó gbogbo àwọn ọmọ ogun rẹ̀ jọ láti bá Israẹli jagun, wọ́n sì dóti ìlú Samaria.
Oluranlọwọ fun aarẹ Muhammadu Buhari, Bashir Ahmad lo fi lede bẹẹ loju opo ikansiraẹni Twitter.
Gbogbo nǹkan yòókù tí Ahasaya ṣe ni a kọ sinu Ìwé Ìtàn Àwọn Ọba Israẹli.
Aisha Buhari tọrọ ìdáríjì lórí fídìo tó jáde Segun Sega Awosanya ti apele rẹ n jẹ Segalinks ni tirẹ ni, igbesẹ aarẹ naa jẹ ọna lati ka ọkan ara ilu kuro ninu ohun to ṣe pataki ni.
Amirah si ni asiwaju tabi apasẹ fun awọn obinrin.
Awọn oṣerebinrin bii Iyabo Ojo, Ronke Oshodi Oke loju opo instagram wọn gbadura pe ki MC Oluomo tete dara ya.
O ni iyawo ọjọ naa Gloria ti segbeyawo tẹlẹ ati pe Iyawo oun ni o si bi ọmọ fun oun.
27 Ẹrẹ̀nà 2019 Oríṣun àwòrán, @LoksattaLive Àkọlé àwòrán, Awọn kẹẹkẹ naa jẹ ọna irinna to yatọ si eleyi to ti wa nilẹ tẹlẹ bi Uber Bi ẹ ba laanfaani lati lọ si ilu ọba, ẹ ri wi pe ẹ foju sita boya ẹ o ṣe alabapade 'Kẹẹkẹ Napep' iru eleyi ti o n gbe ero lawọn ilu kaakiri Naijiria.
Ileeṣẹ to ṣe oogun naa, Gilead pharmaceutical company sọ pe oun yoo fun ijọba ni miliọnu kan aabọ igo oogun naa lati lo.
Ikeokwu ṣalaye pe wọn ko ṣẹkẹṣẹkẹ si Duncan Mighty lọwọ lẹyin to gba miliọnu mọkanla lọwọ ipinlẹ Imo fun iṣẹ orin ati awọn nnkan mii, ti ko si ṣe iṣe ọhun.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Oluwo kò gbọdọ̀ kọrin òwe tàbí bá àkọ̀ròyìn sọ̀rọ̀, kó má baà ba ẹjọ́ ara rẹ̀ jẹ́ - Ọ̀ràngún ṣàlàyé BBC Yorùbá gba àmì ẹ̀yẹ akọni nídìí àgbéga àṣà àti èdè abínibí Ẹ má sọ Amotekun di ẹgbẹ́ OPC, ẹ fi wá sínú ẹ̀ṣọ́ aláàbò - Miyetti Allah Buhari, kí ló dé tó fẹ́ dá $100m owó Abacha padà fún gómìnà Kebbi?
Fún àwọn tí ó pọ̀ ní ilẹ̀ pupọ, sì fún àwọn tí ó kéré ní ilẹ̀ kékeré.
Ẹkọ ibi yii ni pe, o ṣeeṣe ki wọn gbe ọ sipo airotẹlẹ, gbiyanju koo tara, koo sa ipa rẹ lati rii pe o ṣe ohun to yẹ ni ṣiṣe lasiko.
Elomiran lè lo ọ̀kẹ́ àimọye owó lati fi se ọbẹ̀ kó má dùn nitori, bi iyọ̀ ò ja, ata á pọ̀jù tàbi ki omi pọ̀jù.
Bẹ́ẹ̀ ni tòótọ́ ni ile alágbẹ̀dẹ kan wà ni ẹ̀hìnkùlé wa, ọmọbìnrin àjẹ́ kan sì ti ń gbe ilé náà tẹ́lẹ̀ kí ó tóó di pe Olówó-ayé bẹ̀rẹ̀ si máa káàkiri igbó ọdẹ, ó sì ti pẹ́ ti bàbá mi ti rí ọmọbìnrin náà mọ.
 wọ ́ n sì ń pe abàmì ọmọ náà níolúgbẹ ̀ rẹ ́ Àgan .
àwọn ọmọ Lebana, àwọn ọmọ Hagaba ati àwọn ọmọ Akubu;
Ìdájọ́ ẹ̀tọ́ ni n óo fi ṣe okùn ìwọnlẹ̀,òdodo ni n óo fi ṣe ìwọ̀n ògiri.
 Ìwé yìí jẹ ́ àbájáde ètò kan tí ó ṣe pàtàkì lórí rédíò .
gẹ́gẹ́ bí àwọn ọdọmọkunrin ti gbà á nímọ̀ràn.
Koda, lọwọ lọwọ, o to awọn ẹlẹyinju ẹgẹ, apọnbeporẹ ati orekelẹwa obinrin bii marun-un ti wọn wa ni aafin ọba alaye naa, ti wọn n ṣe abiyamọ, yatọ si awọn olori agba to wa ni aafin tẹlẹ.
Onírúirú abala sì ló wà nínú ètò ọ̀hún.
Èyí ni ẹ̀rí pé, Ọlọrun ṣe ètò pé kí gbogbo eniyan lè ní ìgbàlà nígbà tí àkókò rẹ̀ tó.
7 1770715 Orilẹede Peru 38564 120.
'Èmi àti Toyin Abraham ṣẹ̀ sọ̀rọ̀ fún ìgbà àkọ́kọ́ láti ọdún méjì torí ìjà òun àti Lizzy' Ẹ wo ohun tó yẹ kí ẹ mọ̀ nípa gbajúgbajà òṣèré tíátà Yoruba Tóyìn Afọlayan Fún ojú lóúnjẹ lórí ohun tó n ṣẹlẹ̀ nílé Oba Idowu Oniru tó wàjà Gowon ni oun gbagbọ pe Ọlọrun to ti n da Naijiria si lati igba ominira si wa sibẹ lati maa daabo boo, ṣugbọn awọn ọmọ Naijiria gbọdọ kun fun adura.
"Ipadabọ mi yoo dabi ti abijawara bi ẹkun.
Àsìkò yìí gan ni àwọn ọlọ́pàá mẹ́rin kan dé sí ọgbà ilé ìtura náà pẹ̀lú ọkọ̀ ọlọ́pàá tó ni Nọ́mbà PF 600- WSH.
Bawo lọrọ naa ṣe ṣẹlẹ gan?
Ṣùgbọ́n, Èṣù-kékeré-òde, má ṣe gbàgbé pé adíẹ̀ ju adíẹ̀, ẹwúrẹ́ ju ewurẹ́; àgùntàn ju àgùntàn; ẹyẹ ju eyẹ; ènìyàn ju ènìyàn; ọdẹ ju ọdẹ - èmi ni mo wí fún ọ, èmi jù wọ́n lọ, èmi kì í ṣe ẹgbẹ́ wọn, ẹgbẹ́ bàbá wọn ni èmi ń ṣe, onígbéraga ni ọ́, ìwọ ẹbọra kékeré inú ọ̀gán, ìwọ Èṣù-kékeré-òde, n kì í ṣe ẹgbẹ́ ìyá ńlá rẹ, ṣíọ̀ rẹ, kí lo jámọ́, síọ̀ rẹ̀ lẹ́ẹ̀meje, nǹkan dé lónìí, múra jẹ́ ki á kọlu ara wa.
Jacinda Arden Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Olootu ijọba Jacinda Ardern ṣe gudugudu meje Olootu ijọba orileede New Zealand ni Jacinda Ardern, ti o si ti gba oriyin lọdọ awọn eeyan kaakiri agbalaye fun ipa to ko lasiko iṣẹlẹ naa.
Saaju lowurọ ọjọ Iṣẹgun ni ẹgbẹ naa ti ni awọn ọlọpaa yabo awọn ọmọ ẹgbẹ wọn kaakiri ibi ti wn ti ṣe iwọde ni Naijiria.
Ìdí rẹ̀ nìyí tí mo ṣe ń dàníyàn láti waasu ìyìn rere fún ẹ̀yin tí ẹ wà ní Romu náà.
Eleyi ni yoo jẹ eri pe o yẹ ni ẹni to le gbe eeyan si inu ọkọ.
Burnley lo kọkọ jẹ ki Chelsea to da pada.
Juda bá sọ fún Israẹli, ó ní, “Fa ọmọ náà lé mi lọ́wọ́, a óo sì lọ kí á lè wà láàyè, kí ebi má baà pa ẹnikẹ́ni kú ninu wa, ati àwọn ọmọ wa kéékèèké.
Iṣẹlẹ ọhun ni a gbọ pe, o da ibẹru-bojo silẹ lagbegbe naa lẹyin tawọn eeyan n gbọ iro ibọn nigba tawọn ẹṣọ Operation Burst kọju ija si awọn janduku naa.
Wọ́n fi owó sílẹ̀ fún àwọn tí wọn ń gbẹ́ òkúta ati fún àwọn gbẹ́nàgbẹ́nà.
Lorilẹede Naijiria bayii, iye awọn eniyan to ti ni arun Coronavirus naa ti da ẹgbẹrun marun ati mọkanlelogunlelẹgbẹta (5,621).
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù 2019 Elections: Níbo la bá ètò ẹ̀kọ́ dé?
Nibi apero kan to waye lori eto aabo loṣu keje ọdun 2019, lawọn gomina mẹfẹẹfa ti pinnu lati gbe eto Amọtẹkun kalẹ lẹyin ti iṣẹlẹ ijinigbe pọ kaakiri ilẹ Yoruba lọdun to kọja Awọn eeyan to n ṣe fijilante, awọn onimọ lori ọrọ eto aabo atawọn ọlọpaa yoo wa ninu ẹṣọ Amọtẹkun naa.
Angẹli tí ń bá mi sọ̀rọ̀ bá bọ́ siwaju, angẹli mìíràn sì lọ pàdé rẹ̀, Angẹli àkọ́kọ́ sọ fún ekeji pé, 
Kí ni ǹ bá fi ṣe àkàwé rẹ̀?
Láìpẹ́ ó kan àwọn àpò owó tí adíẹ̀ náà sọ̀rọ̀ rẹ̀ ó sì bẹ̀rẹ̀ sí kó wọn.
Àkọlé àwòrán, Ayẹyẹ ikẹyin fun Baba Sala Isin idagbere ikẹhin n lọ lọwọ nile ijọsin ti Baba Sala ti jẹ oluṣọ aguntan, 'The Sacred Cherubim & Seraphim Church of Nigeria and Overseas Inc.
Ẹbọ sísun ni; ẹbọ tí a fi iná sun, tí ó ní òórùn dídùn, tí inú OLUWA dùn sí.
''Ọrọ yii kii ṣe nipa bi oju eeyan ba ṣe gurege si tabi dunwo si nitori ọpọ arẹwa obinrin atawọn ọkunrin ni wọn jọ wa nile Ẹlẹgbọn Agba, ṣugbọn nkankan wa to jẹ ki ọpọ eeyan fẹran Laycom yatọ,'' Blessing lo woye bẹẹ.
“Nítorí náà, ẹ fi èyí lékàn, ẹ̀yin tí ẹ gbàgbé Ọlọrun,kí n má baà fà yín ya pẹ́rẹpẹ̀rẹ, kò sì ní sí ẹni tí yóo gbà yín kalẹ̀.
Àmọ́ nígbàtí mo fẹ́ máa padà lọ sílẹ̀, ni nkan tó jọmí lójú jùlọ ṣẹlẹ̀.
Ẹni to bori: Burundi Angola vs Cameroon.
Oríṣun àwòrán, @HQNigerianArmy Idà ahun pa ahun!
'Aisan owo osu ki se nnkan ti oju ko ri ri' Gbagbaagba ni wọn ti abawọle ile isẹ ijọba nipinlẹ Ọṣun pẹlu bi awọ́n osise ti ṣe bẹrẹ iyansẹlodi ikilọ ọlọjọ mẹta.
A kò gbọdọ̀ ṣe ìgbéraga pupọ ju bí ó ti yẹ lọ lórí iṣẹ́ àwọn ẹlòmíràn.
Arinrin ajo lona aibofin mu omo orile-ede Mali,  ti o di akoni leyin ti o gun ile alaja merin lati gbemi omode-kunrin kan ti o ji diro-diro lori bakoni kan la nilu Paris, ni yoo di omo onilu lorile-ede Faranse.
Ó wá ku Jakọbu nìkan, ọkunrin kan bá a wọ ìjàkadì títí di àfẹ̀mọ́jú ọjọ́ keji.
Orilẹede Ghana naa ni oun n'ifẹ si eto yii, nitori pe awọn orilẹede to wa ni Iwọ Oorun Africa ti n jiroro lati maa na owo kan naa, gẹgẹ bi ọna lari ran eto okoowo lọwọ.
Ni bayi, fun igba-akoko won yoo lo ero igbalode Fonran, Video Assistant Referee [VAR] nile Afrika ni papa isere Stade Mohammed V, Casablanca lojo Aiku(Saturday).
Emi náà ṣe òkú bí ipá mi ti mọ, ṣùgbọ́n bí mo ti náwó tó, ọkàn mi kò kúrò lára bàbá mi, bí mo bá sì ń rẹ́rìn-ín lójú báyìí, ìbànújẹ́ á bo ìsàlẹ̀ inú mi bí ìkùùku.
Lara awon to wa pelu Igbakeji
Lara awọn ẹru ti wọn ri ni ibuba awọn afurasi ajinigbe lasiko abẹwo wọn naa ni ibọn AK 47 mẹrin, ibọn AK 49 kan, ọpọ ọta ibọn, awọn ẹrọ foonu alagbeka ati owo beba pupọ.
Oúnjẹ alẹ́ ni wọ́n ń fi Ọ̀ọ̀nì ṣe níbí Òṣèrè tíátà Muideen Oladapo gbàràdá lórí ètò 'Ṣé o láyà?
 A máa n kó ara wa ni ìjánu gidi, nítori pé ǹkan ti à n ṣe amóhùmáwòrán lásán ni."
Òdògo nìkan ni kò fi ara mọ́ èlò yí tó bẹ́ẹ̀ nítorí ìtàn tó bí i fi hàn pé ìlú ọ̀tọ̀ gédégédé ni òun.
Abọ ree ninu ifọrọwanilẹwo yii o.
Bakan naa ni abẹnugan ile tun ka iwe ẹbẹ aarẹ, to n bere fun ibuwọlu ile lati san idapada owo fun awọn ipinlẹ marun kan, lori awọn opopona ti wọn ṣe lati inu apo ijọba ipinlẹ wọn.
Awọn ayederu iroyin nipa Coronavirus: Eyi ni awọn ọpọ ayederu iroyin tawọn araalu n pin kiri nipa arun Coronavirus to n waye nilẹ Afirika.
Pẹlu iye awọn eeyan tuntun yii, o ti le ni ẹgbẹrun mẹrinlelaadọta ati ojilelugba ati meje, 54,247 eeyan to ti larun naa lorilẹede Naijiria bayii.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: ''Buhari, Zamfara là fẹ kí o lọ, kìí ṣé Jordan'' “Kò sí àgbègbè Nàìjíríà kánkan tó wà lábẹ́ àkóso Boko haram” Àwọn adigunjalè pa èèyàn mẹ́fà ní báńkì kan nìpínlẹ̀ Ondo Awọn ete ati oju rẹ lo n lọ soke sisalẹ bo se yẹ lasiko to n sọ awọn ede naa, sugbọn awọn ohun to n jade lo dabi ti ohun awọn eeyan ti ori ko yọ lọwọ aisan iba.
"Harrison, ti salaye pe itumọ ọrọ ti wọn fun ""mortgagee"" ati ""mortgator ninu iwe atumọ ọrọ Oxford ti ile itẹwe Oxford Press ki se eyi to tẹwọn rara."
Ìfọ̀rọ̀-wáni-lẹ́nuwò oníwákàtí kan ọ̀hún tí ó wáyé lọ́jọ́ 12 oṣù yìí, pẹ̀lú oníròyìn ìjọba Mirshahin Aghayev  tí a ti mọ̀ tẹ́lẹ̀ rí fún ìdúróṣinṣin aìfi òlò p'ohùn  di gbígbésáfẹ́fẹ́ ní ilé ìṣẹ́ amóhùn-máwòrán aládàáni agbè fún ìjọba REAL TV.
Oríṣun àwòrán, Getty Images / flev O wa rọ awọn adari lorilẹede Naijiria pe ki wọn ṣee re nitori ohun wọn ba ṣe silẹ n labọwaba.
 ijeoma balogun je alara to logbon pelu opolopo iriri aye .
Gbogbo àwọn eniyan tí wọn kó lẹ́rú jẹ́ ẹgbaaji lé ẹgbẹta (4,600).
Mo ní, “Fi ọrùn rẹ sinu àjàgà ọba Babiloni, kí o sin òun ati àwọn eniyan rẹ̀, kí o lè wà láàyè.
Nítorí Fẹliksi ń wá ojurere àwọn Juu, ó fi Paulu sílẹ̀ lọ́gbà ẹ̀wọ̀n.
" majemu tuntun se apejuwe re bi wundia ( griiki "" παρθένος , parthénos "" ) ."
Lójijì, angẹli kan fi ọwọ́ kàn án, ó sì wí fún un pé, “Dìde kí o jẹun.
Bakan naa ni a tun fi owo sinkun mu ogbeni Micah Audu, eni ti o jewo pe, oun je okan lara omo egbe odaran naa.
Ṣaju eyi ni iroyin sọ pe awọn alaṣẹ ileeṣẹ naa ko jẹ ki ikọ ti ijọba ran lọ wọle lọjọbọ ọsẹ.
Ọjọ́ yìí, tún jẹ́ àyájọ́ ọjọ́ tí orílẹ̀-èdè Mauritania gba òmìnira lọ́wọ́ France ní ọdún 1960, lé góńgó sọ́kàn àwọn ọmọ orílẹ̀-èdè Mauritania kan tí wọ́n ń wá ìdájọ́ òdodo fún ìpakúpa tí wọ́n pa àwọn ọkùnrin 28 yìí, tí gbogbo wọn sì jẹ́ aláwọ̀ dúdú.
Alaga apapọ ẹgbẹ Ancopss lorilẹede yii, Anselm Izuagie ni haa-hii ni ikede ijọba apapọ naa si jẹ fun awọn, lẹyin ọjọ kan ti minisita feto ẹkọ ti fi ikede ọhun sita.
"Ebi yóò ti lu Nàíjíríà pa, tó bá jẹ́ PDP kò se dáadáa - Jonathan Ọbasanjọ fèsì lórí $16bn owó iná ọba Ẹ gbé Etete, Adoke àtàwọn míràn lórí ọ̀rọ̀ epo Malabu - Iléẹjọ́ O ni ""Aarẹ tẹlẹri ko bere tabi gba abẹtẹlẹ."
'Òkú bí àádọ́ta ni iná jó gúrú-gúrú ní mọ́ṣúárì l'Anambra' Ìwádìí bẹ̀rẹ̀ l'órí ikú agbẹjọ́rò Ajah Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Obìnrin tí kó ba fẹ́ òṣìṣẹ́ Mọ́ṣúárì, ìpinu rẹ̀ mẹ́hẹ' Ileeṣẹ agbokujo mẹta ti kede faraye pe igbesẹ pasitọ naa ba orukọ awọn jẹ, nitori naa, awọn n lọ ile ẹjọ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Teach your children Yoruba: Wo àwọn òyìnbó tó ń kẹ́kọ̀ọ́ èdè Yorùbá ní Michigan, America Ìjọba fí ìlànà tuntun lédé lórí àti ṣí iléèwé káàkiri Nàíjíríà láì fí ọjọ́ tí wọn yóò ṣí iléèwé sí bẹ̀ Igbesẹ ijọba lati fi ilana ofin ti awọn olukọ ati akẹkọọ gbọdọ tẹlẹ lai fi ọjọ ti wọn yoo ṣi ileewe lede ti fa ariyanjiyan.
Eeyan mẹta le ni iwaadi naa ni iru iku bẹ a ma pa laarin awọn eeyan ẹgbẹrun lọna ọgọrun.
Sidibe salaye pe, “mo ni anfaani lati kede pe, Aisha Buhari  ti gba lati je asoju patati fun ajo UNAIDS lorile-ede Naijiria.
Ẹ fetí sí ọ̀rọ̀ mi dáradára,kí ẹ sì jẹ ohun tí ó dára,ẹ jẹ oúnjẹ aládùn, kí inú yín ó dùn.
Èbúté kan ní Kirete ni Fonike; ó kọjú sí ẹ̀gbẹ́ ìwọ̀ oòrùn gúsù ati ìwọ̀ oòrùn àríwá Kirete.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, afin pupa Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Ewe, gege bi isiro iwe isuna imusese
Ẹ̀kọ́ nípa àwùjọ-ẹ̀dá jẹ́ ẹ̀kọ́ kan pàtàkì tí kò ṣe é fọwọ́ rọ́ sẹ́yìn.
“Ní àkókò náà, lẹ́yìn ìpọ́njú yìí oòrùn yóo ṣókùnkùn, òṣùpá kò ní tan ìmọ́lẹ̀ rẹ̀.
Abineri ọmọ Neri ati àwọn iranṣẹ Iṣiboṣẹti, ọmọ Saulu, ṣígun láti Mahanaimu, lọ sí ìlú Gibeoni.
Oríṣun àwòrán, Ololufe BBC Àkọlé àwòrán, Ewe ni mama ti le lo fi bo ẹu wọn lọwọ arun Coronavirus Oríṣun àwòrán, others Àkọlé àwòrán, Eyi tun leku.
Nígbà náà ni wọn óo rí Ọmọ-Eniyan tí óo máa bọ̀ ninu ìkùukùu pẹlu agbára ati ògo ńlá.
Koda awọn aworan kan to n jade lori ayelujara ṣe afihan Shaibu nibi to ti n yọ aṣia ẹgbẹ oṣelu naa danu ti o si n pariwo 'o digba fun ẹgbẹ oṣelu APC ni ileejọba ipinlẹ Edo' Ni ọjọ Iṣẹgun, ọjọ kẹrindinlogun oṣu kẹfa ni gomina Obaseki kọwe fi ẹgbẹ oṣelu APC silẹ lẹyin ti wọn yọ ọwọ rẹ kuro lawo idije fun aṣia ẹgbẹ oṣelu naa gẹgẹ bi oludije ipo gomina nibẹ.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Pẹ̀lú abẹ̀rẹ̀ àjẹsára yìí, ẹ̀fọn kankan kò lè mú àìsàn ibà wá Tó bá fi nọ́mbà ìpè rẹ sílẹ̀, ẹ̀wọn ọdún mẹ́ẹ̀dọ́ọ́gbọ̀n lo fi ń ṣeré - NCC Iṣẹ́ àkànṣe tí kò parí ni Buhari ń bọ̀ wá ṣí l‘Eko - Aráàlú figbe ta Joseph sọ pe ọmọkunrin naa n fẹ ọmọbinrin kan ninu ẹbi naa , Titi Saanu, ko to o di pe Titi ja okun ifẹ naa pe oun ko ṣe mọ.
Mo ní ìrètí láti wá sọ́dọ̀ rẹ láìpẹ́, ṣugbọn mò ń kọ ìwé yìí, 
Nibayii, iwọde ṣi n lọ o lati dẹkun gulegule iwa komẹtọ tawọn ọẹọpaa ikọ naa n hu.
Bí ètò ilé ẹlẹ́gbọ̀n àgbà ṣe ń káṣẹ̀ nílẹ̀ wẹ́rẹ́wẹ́rẹ́, àrà ọ̀tọ̀ ni bí wan ṣe fẹ́ yàn àwọn ti yóò lọ kúrò nínu ilé lónìí.
Ṣugbọn níbẹ̀ ni OLUWA, ninu ògo rẹ̀,yóo jẹ́ odò ńlá ati odò tí ń ṣàn fún wa;níbi tí ọkọ̀ ọlọ́pọ́n kò lè dé,ọkọ̀ ojú omi kò sì ní lè kọjá níbẹ̀.
Ẹ̀yin Oníbàárà wa ọ̀wọ́n, ẹ má mikàn, a ti ń dá gbogbo iná yín padà - TCN 110 ni ìyè àwọn àgbẹ̀ tí Boko haram dúmbú ní Borno tí dì báyìí-UN Wo ohun tó ṣẹlẹ̀ sí àwọn ọba tó kọ ifá sílẹ̀ gbé Bíbélì àti Kùránì Omo Ghetto: Funke Akindele ṣàlàyé bí àwọn agbébọn ṣe kọlù wọn làsíkò tí wọ́n ń ya fíìmù Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ọkùnrin tó fẹ́ fipábámilòpọ̀ fín ǹkan sí mi lójú ló ṣe rọ́nà wọlé sí mi lára Omotara kan ìdin nínú iyọ̀, àwọn ọmọ ilẹ̀ Faranse náà bínú síi nítorí alágbe tó fi ṣe yẹ̀yẹ́.
Ọ̀pọ̀lọpọ̀ ayẹyẹ yi ló mú ipèsè jijẹ, mimu, ilù àti ijó lati ṣe àlejò fún ẹbi, ará àti ọ̀rẹ́ ti ó wá báni ṣe ayẹyẹ.
Kí ni eniyan jẹ́, tí ó fi lè mọ́ níwájú Ọlọrun?
Igbakeji Aarẹ Naijiria, Yemi Osinbajo ti gomina ipinlẹ Kogi Yahaya Bello kọwọrin pẹlu lo sọ eyi lasiko to se abẹwo si ibudo awọn to lugbaji omiyale ni ile iwe Saint Luke's ni Koton-Karfe, ipinlẹ Kogi.
ki ẹka ij̣ọba mẹtẹẹta ṣiṣẹ papọ fun idagbasoke ọrọ-aje ati ara ilu
Bí àwọn ẹṣin tí wọ́n jẹ́ kàláńkìnní ti jáde, wọ́n ń kánjú láti lọ máa rin ayé ká.
To ba ti de ipele yii, isẹ abẹ ni ọna abayọ, ki okuta naa ma ba a tú sinu ikun.
O ti kọkọ sọ fun BBC pe laipẹ ni iyawo oun a to bimọ ikoko tuntunÀwọn olórin Nàìjíríà kẹ́dùn ikú ọmọ DBanj DBanj gbé àwo tuntun jáde lẹ́yìn ikú ọmọ rẹ̀ Ẹbí D'banj sọ̀rọ̀ lórí ikú ọmọ ọdún kan rẹ̀ Abiyamọ ò!
Èmi gan-an ni n óo ká aṣọ lára yín,n óo sì fi bò yín lójú, kí ayé lè rí ìhòòhò yín.
O ni:  “O le ni orisii 50,000 ewe ati egbo to wa fun itoju ilera ara ati pe gege bi iwadii Ojogbon  Maurice Iwu se so pe titi di asiko yii a ko tii lo egberun meji ninu aadota egberun naa rara ni eyi ti Naijirira ni to egberun mejo ninu re”.
 Ètùtù tí wọ ́ n ṣe yí ni ó di danadan láti ṣe lásìkọ ́ ọdún gẹ ̀ lẹ ̀ dẹ ́ , tí wọnbyóò sì ma ṣe ẹ ̀ fẹ ̀ lásìkò náà .
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ondo Election Tribunal: APC jáwé olúborí ní ìdìbò sílé asojúsòfin 1 Ògún 2019 Oríṣun àwòrán, OTHERS Àkọlé àwòrán, Ilé ẹjọ́ wọ́gilé ìbò tó gbé Ikengboju Gboluga tó ń sojú ẹkùn ìdìbò Okitipupa/Irele nítorí ó jẹ́ ọmọ orílẹ̀èdè méjì.
O n ka awọn ibudo agbaye to wa ni orilẹede kọọkan Ẹ gbiyanju akori ọrọ miran wo to-top Awọn Asia orilẹede Algeria Angola Benin Burundi Cameroon Congo DR Côte d'Ivoire Egypt Ghana Guinea Guinea-Bissau Kenya Madagascar Mali Mauritania Morocco Namibia Nigeria Senegal South Africa Tanzania Tunisia Uganda Zimbabwe Orisun Olawale Malomo ati Elisabetta Tollardo lo jẹ olootu isẹ yii, Olawale Malomo lo mu agbega baa, Millicent Wachira lo se agbekalẹ rẹ, Aaron Akinyẹmi, Anthony Makokha ati Muthoni Muchiri si lo se afikun isẹ iwadi nipa rẹ.
Èkúté mi ọ̀wọ́n, ìwọ kò ddàbí àwọn wọ̀nyí; mo sì bẹ̀ ọ́ kí o má ṣàì fi ìwà òdodo rẹ hàn mi lónìí, kí o má ṣàì fi òótọ́-inú bá mi lò, kí o wí fún mi nísisìyí pàtó, ọ̀nà tí mo lè gbà fi yọ kúrò nínú ìhámọ́ yìí, níbi tí ìwà òmùgọ̀ gbé mi lé téńté.
Ẹnikẹ́ni tí ó bá sì gbà mí, gba ẹni tí ó fi iṣẹ́ rán mi.
" Bakan naa ni Adesina mu wa si iranti pe akọroyin kan wa, Lindasay Barret to jẹ ọrẹ ọlọjọ pipẹ fun Buhari, to si ran oun lati ki aarẹ fun oun.
ba ti dagba lojo ori, ko to loyun, irufẹ obinrin bẹẹ n fi ẹmi rẹ wewu ni ,o si
 ) Ìfi ojú sọ ́ nà tí ó mọ ́ gbọ ́ n dání wà pé àwọn gbèsè rẹ ̀ yóò di sísan .
Wọn ni ẹbi baba agba yii ni awọn eniyan ti ọwọ tẹ naa ti wọn ni wọn fura pe oṣo ni baba yii.
Agbẹnusọ fun gomina ipinlẹ Edo, ọgbẹni Crusoe Osagie fi ẹsun kan gomina ana ni ipinlẹ naa, Adams Oshiomhole to tun jẹ alaga ana fun ẹgbẹ oselu APC lo n gbiyanju lati fi ipa gba ile aṣofin naa.
”Asoju naa tun wa jabọ ikinni
Ó ní, “Ọmọdebinrin mi ń kú lọ, wá gbé ọwọ́ lé e, kí ó lè yè.
Awon olori ọdọ lati eka idibo apapọ, Agunbaniro kan, Alaga ajọ ajafẹto araalu kan, alaga ehbe ọdọ ni ipinlẹ Anam ra Aṣoju ẹka ọdọ lẹgbẹ Ohaneze, Alaga ẹka ọdọ lẹgbẹ ilu gbogbo ni Anambra Ajínigbé tú ìyá àti ọmọ ọdún mẹ́ta sílẹ̀ lẹ́yìn tí wọ́n gba ₦1.
okeere ati minisita fun eto idajọ lorile ede Naijiria.
“O kò gbọdọ̀ bọ ọmọ ẹran ninu omi wàrà ìyá rẹ̀.
Kò sí ohun tí Mose pa láṣẹ tí Joṣua kò kà sí etígbọ̀ọ́ gbogbo ìjọ ọmọ Israẹli, ati ọkunrin ati obinrin, ati ọmọde ati àlejò tí wọ́n wà ní ààrin wọn.
- Ìjọba àpapọ̀ Ọlọ́lá jù lọ Terry Waya ni Bàbá Terseer Kiddwaya tó ń kópa nínú BBNaija 2020 Wọ́n kí irún Jimọ àkọ́kọ́ ní Hagai Sophia lẹ́yìn ọdún 85 ní Turkey Ọ̀pọ̀ olólùfẹ́ Iya Jogbo banújẹ́ lórí ìròyìn ikú rẹ̀ Oríṣun àwòrán, SUNDAY DARE/TWITTER Àkọlé àwòrán, Mínísítà fun àwọn ọdọ́ ṣe afilọ́lẹ̀ ètò DEEL fún àwọn ọdọ́ Naijiria nílù Abuja ninu oṣù kọkanlá, ọdún 2019 Mínísítà fún ọ̀dọ́ àti eré ìdárayá sọ pé ètò owó idokoowò náà yóò dabi ilé ìfowópamọ fún àwọn ọdọ́ láti le maa yáwó fun okoòwò wọ́n.
Ki ni awọn ọmọ Naijiria n sọ?
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Àwọn ǹkan tí yóò t'ẹyin kíkógbá iléeṣẹ́ tó n sójú Nàìjíríà nílẹ̀ láwọn orílè-èdè márùn 22 Èbibi 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Owo ni b'oun o ba si nile ki wọn ma da imọran kankan lẹyin ohun.
Kí òun ati ẹni tí ó rà á jọ ṣírò iye ọdún tí ó fi ta ara rẹ̀, láti ọdún tí ó ti ta ara rẹ̀ fún un títí di ọdún jubili.
Ẹni tí ń ru asà rẹ̀ sì ń rìn níwájú rẹ̀.
Àwa àti fijilanté pẹ̀lú ọdẹ́ ìbílẹ̀ ló dojú kọ adigunjalè ní First Bank Okeho - Iléeṣẹ́ ọlọ́pàá Ìtàn ọba Yorùbá tí wọn yẹgi fún torí ó jí ọmọ gbé ṣe ètùtù Ẹ káàbọ̀ sọ́jọ́ Arafat, tí Ọlọ́run yóò fi ààwẹ̀ Mùsùlùmí pa ẹ̀ṣẹ̀ wọn rẹ́ Boko Haram da ìbọn bo ọkọ̀ gómìnà Borno, ẹ̀ṣọ́ àláàbò rẹ̀ farapa Ìtàn Ọba Yorùbá tí wọ́n yẹgi fún torí ó jí ọmọ gbé ṣe ètùtù O fikun pe, oun fẹran orin kikọ, ti oun si ṣetan lati ma a gbe awo orin jade bi iru eleyii ti oun ṣe pẹlu 'Nice', ati eleyii ti oun kọ fun MC Oluomo ni ayajọ ọjọ ibi rẹ.
Alamojuto Toke Makinwa ni irọ ni gbogbo ahesọ naa ati pe awọn ko le maa dahun si gbogbo ahesọ ti awọn eeyan ba n sọ nipa oju oge sọrọsọrọ naa.
Bakan naa lo tun dunkooko pe, igbimọ alaṣẹ ti oun n dari ko ni roo ni ẹẹmeji, ko to le ọmọ igbimọ rẹ to ba huwa ọdaran.
Ẹgbẹ́ òṣìṣẹ́ ìpínlẹ̀ Ọyọ bẹ̀rẹ̀ ìyanṣẹ́lódì aláìní gbèdéke Àáyá bẹ sílẹ o bẹ sáré,wábiwọ́sí ìyá ni Flying Eagles fi bẹrẹ fún Qatar 82% ọkùnrin ní kó mọ̀ pé òun ní àìsàn jẹjẹrẹ asẹtọ ní Naijiria Ọlọ́pàá Adamawa ni #30,000 ni wọ́n fi bọ́ igún látìmọ́lé Ni ipari, Jiti Ogunye ta awọn eniyan Naijiria jí pé ọwọ wa ni agbara wa lasiko yii.
soro, fi asiko ohun ro awon onise iroyin lati tubo tenumo pataki ilera oju fun
“ ‘Ẹni ìfibú ni ẹnikẹ́ni tí ó bá bá arabinrin rẹ̀ lòpọ̀, kì báà jẹ́ ọmọ ìyá rẹ̀ tabi ọmọ baba rẹ̀.
Lẹ́yìn náà Ọlọrun wí fún obinrin náà pé,“N óo fi kún ìnira rẹ nígbà tí o bá lóyún,ninu ìrora ni o óo máa bímọ.
falciparum' ba fa le yọri aisan to n pani.
Èèyàn 562 tuntun ló tún ti lùgbàdì COVID-19 ní Nàìjíríà ní àná Wo ohun tó yẹ kí o mọ̀ nípa Laycon, akẹ́kọ̀ọ́jáde UNILAG tó ń kópa nínú BBNaija 2020 Gbogbo ohun tí Godswill Akpabio sọ níbi ẹ̀sùn ìnákùnàá tí wọ́n fi kàn án rèé Bí ẹgbẹ́ One Million Boys ṣe bẹ̀rẹ̀ rèé àti ọṣẹ́ tó ṣe n'Ibadan Wo àwọn nkan tó yẹ́ kí o mọ̀ nípa 'Awawa Boys', ọ̀kan lára ẹgbẹ́ òkùnkùn tó n dá Eko rú Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Bẹẹ naa ni awọn miran n ni iwa ika inu awọn ọkunrin oniṣẹ ibi kan ni o faa.
Aini iwe yi jẹ ọna kan gboogi tawọn eeyan fi n tako ofin irina.
Nígbà tó ń sọ̀rọ̀ nípa àjọṣepọ̀ rẹ pẹlu gbajumọ oṣere tíátà míì, Odunlade Adekola, Gọlugọ ni onirẹlẹ ẹ̀dá ni, tí kìí fi ojú pá ẹnikẹni rẹ, tó si máa ń fi ọwọ sọwọ́pọ̀ pẹ̀lú àwọn akẹẹgbẹ rẹ nígbà kuugba.
Ọlọ́gbọ́n eniyan a máa wá ìmọ̀ kún ìmọ̀,ṣugbọn ọ̀rọ̀ òmùgọ̀ máa ń fa ìparun mọ́ra.
Ilé iṣẹ́ Nigeria Immigration Service ni orílẹ̀-èdè Nàìjíríà ti ni kò si àjòjì darandaran kankan lórílẹ̀-èdè Nàìjíríà gẹ́gẹ́ bi àwọn ènìyàn ṣe ń sọ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìwà ipá nínú ìdílé máa ń bí ìgè àti àdùbí ni tó lè já sí ikú Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Ìwà ipá nínú ìdílé máa ń bí ìgè àti àdùbí ni tó lè já sí ikú 2 Sẹ́rẹ́ 2019 Ọpọ ẹ̀mí ọkọ àti aya ló sọnù ní Naijiria lọdun 2018 látàrí ìwà ipá nínú ìdílé.
 Oríṣun àwòrán, Facebook/Femi Fani-Kayode Nínú atẹ́jáde náà ni Fani-Kayode ti ń bèèrè pé kí ló le ṣẹlẹ̀ sí Tunde Bakare to fẹnu sátá Bola Ahmed Tinubu ní ǹkan bi oṣù mẹ́rinlá sẹ́yìn, tó wá yí bìrí ni àsìkò yìí tó tún ń kọrin ìyìn rẹ̀?"
Bẹ́ẹ̀ ni ọ̀pọ̀lọpọ̀ ènìyàn wà nínú ayé wa yìí tí wọ́n ń fi ẹnu pe ara wọn ní babaláwo ṣùgbọ́n tí wọn kò ní àyà àti sa oògùn tí wọ́n mọ̀, wọ́n á fi ìbẹ̀rù sọ ara wọn di ènìyàn yẹpẹrẹ.
Kó wọn jáde fún wa, a fẹ́ bá wọn lòpọ̀.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Akomolede àti Aṣa: Ọ̀rọ̀ Ẹ̀yán ni Bunmi Femi Amao ń kọ́ wa lórí ètò Akọ́mọlédè àti Àṣà lóri BBC Yoruba Koda, ninu iwe ifitonileti ti ayaba Badra fisita nipa sọọbu asọ tuntun to fẹ si laipẹ yii, o n kesi awọn ololufẹ rẹ pe ki wọn wa pade oun lọjọ naa nilu Eko, ki wọn si tun wa foju kan Bobrisky, ọkunrin to n mura bii obinrin, ẹni ti oun yoo maa gba lalejo.
Kí ni ìdí ti èèyàn fi ń ṣàìsàn?
Usman darapọ mọ awọn ti wọn n ṣe ere idaraya gidigbo lọdun keji to wọ ile iwe girama Bowie ni Arlington nipinlẹ Texas l'Amẹrika.
Wọ́n bá fi ipá mú un láti ru agbelebu Jesu.
Nígbà tí àwọn arakunrin rẹ̀ ati ìdílé baba rẹ̀ gbọ́, wọ́n wá sọ́dọ̀ rẹ̀.
Akeredolu lo ṣo ọrọ naa nigba to n jabọ ibi iṣẹ de duro lori ọrọ Covi-19 ni ipinlẹ ọhun.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Coronavirus Update: Ebi lé pa ènìyàn 12,000 lójoojúmọ́ lẹ́yìn Covid-19- Oxfam International 9 Agẹmo 2020 Oríṣun àwòrán, others Àjọ kan tí kìí ṣe ti ìjọba, Oxfam International ti kéde pé, ó ṣee ṣe kí ikú tó jọ́ mọ́ ebi lú ènìyàn ẹgbẹ̀run méjìlá pa lọ́joojúmọ́ lẹ́yìn ti àrùn Colvid-19 bá kásẹ nílẹ̀.
Nígbà tí mo bá dá ire wọn pada, ati ní àwọn agbègbè Jerusalẹmu, ní àwọn ìlú Juda, ati àwọn ìlú agbègbè olókè, ní àwọn ìlú pẹ̀tẹ́lẹ̀ Ṣefela, ati àwọn ìlú ilẹ̀ Nẹgẹbu.
Ọmọ-ọ̀dọ̀ náà wá rò ninu ara rẹ̀ pé, ‘Kí ni n óo ṣe o, nítorí ọ̀gá mi yóo dá mi dúró lẹ́nu iṣẹ́.
O so pe “Aare ti fun mi ni awon imoran ni eyi ti maa si mu lo, orile ede Naijiria je alatileyin fun orile ede Guinea Bissau;eto iforuko sile si n lo lowo.
Ṣugbọn ohun to daju nipe ileeṣẹ ọlọpa ko ni duro tabi fọwọ lẹran ti ọwọ yoo fi tẹ awọn amokunṣika naa.
ede Naijiria yoo maa san lori epo robi yoo pọ pupọ.
Àsikò òtútù ni àlejò ma ńṣe iranti ilé.
Aare Buhari ni o parowa yii ninu oro iranse  re fun odun ajinde ti odun 2018 nilu Abuja.
Oríṣun àwòrán, PA Àkọlé àwòrán, Awa ara wa la ri ara wa, bi ologinni ba ri ọmọ ẹkun 'Air Force One' ni ọkọ baalu to gbe Trump wa si UK nibi ti wọn ti kọkọ lọ si ọdọ aṣoju ilẹ Amerika fun UK ni agbegbe Central London.
Lẹ́yìn náà gbogbo àwọn olórí ogun ati Johanani, ọmọ Karea ati Asaraya, ọmọ Hoṣaaya, ati gbogbo àwọn ará Juda, lọ́mọdé ati lágbà, tọ wolii Jeremaya lọ.
O sọ eyi ni ifesi si bi adẹẹrinpoṣonu kan, Volodymyr Zelensky ṣe di aarẹ orilẹede Ukraine.
Kò pẹ́ pupọ lẹ́yìn náà, Dafidi, ọba kú, wọ́n sì sin ín sí ìlú Dafidi.
Ìpele ikọ̀ mẹrindinlogun Egypt vs Tanzania.
Buhari ṣẹṣẹ dari irinajo kan si orileede Senegal ni nibi ti wọn ti bura wole sipo fun aarẹ Macky Sall.
Ṣugbọn bí a bá bọ́ sinu ìdájọ́ Oluwa, ó fi ń bá wa wí ni, kí ó má baà dá wa lẹ́bi pẹlu àwọn yòókù.
” Rutu bá jókòó lọ́dọ̀ àwọn tí wọn ń kórè ọkà, Boasi gbé ọkà yíyan nawọ́ sí i; ó sì jẹ àjẹyó ati àjẹṣẹ́kù.
Ahabu bèèrè pé, “Ta ni yóo ṣáájú ogun?
Coronavirus Nigeria : Àwọn gómìnà Naijiria mẹ́rin tó tí ní àrùn Coronavirus
Láìpẹ́ yìí ni orílẹ̀èdè Nàìjíríà ńsọ̀rọ̀ lórí ẹ̀sùn akẹ́kọ̀ọ́bìnrin kan tó ká ọ̀rọ̀ láàrín òun àti olùkọ́ fásitì sílẹ̀ nígbà tó mbèrè fún ìbálòpọ̀ gẹ́gẹ́ bíi pàsípàrọ̀ máàkì dáradára.
Gẹ́gẹ́ bi ìṣe àwọn ọmọ Naijiria, àwọ́n kan pé ara wọ́n ní Ellites (àwọn yìí ló wà fún Erica ) nígbà ti àwọn kan pe àra wọ́n ni Icon (àwọn ti Laycon), àwọn ẹ̀ka méjèèjì yìí ti ń gba ọ̀rọ̀ náà bí ẹni gbagbá ọtí.
Coronavirus bí èso rere nílẹ̀ Adúláwọ̀, wo díẹ̀ lára èso náà.
Kì í ṣe irú majẹmu tí mo bá àwọn baba wọn dání ọjọ́ tí mo fà wọ́n lọ́wọ́ jáde kúrò ní ilẹ̀ Ijipti.
20 Agẹmo 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Aworan to n sọ itan Ọpọ ọmọ Yoruba lo maa n leri pe awọn dantọ ninu imọ ijinlẹ ede Yoruba ati nipa aṣa ibilẹ wa.
Oludije ni ẹgbẹ oselu PDP ninu atundi idibo sipo sẹnetọ to n soju ẹkun idibo iwọ oorun Kogi ti lo dibo rẹ Ni owurọ ọjọ Satide ni Melaye fi soju ẹrọ ikansiraẹni Twitter rẹ pe oun ti lọ dibo.
Ìdí tí a fi pa àwọn àgbẹ̀ onírẹ̀sì ní Borno, Boko Haram ṣàlàyé nínú fídíò tuntun COVID-19 gbẹ̀mí èèyàn kan lọ́jọ́rú, èèyàn 122 tún ti ní COVID-19 ní Nàìjíríà 'Àwọn ọmọ 5 kọ́ ló sọnù, ọmọ 28 ló sálọ síléeṣẹ́ foyúngbowó nípinlẹ̀ Ogun' Ìwé àkàgbádùn láti ọwọ́ Fagunwa, Faleti, Iṣọla, Ogunniran àti Okediji tó yẹ kí o kà lásìkò yìí.
Àwọn ọlọ́pàá tí ọ̀rọ̀ náà kan ni (ASP) Yaro Edward, Insìpẹ́kítọ̀ Ayodeji Erinfolami, Insìpẹ́kítọ̀ Aderibigbe Adegbenro, Insìpẹ́kítọ̀ Samsom Ehibor, sájẹ́ntì Bejide Abiodun àti Insìpẹ́kítọ̀ Igoche Cornelius.
" yorùbá bọ ̀ wọ ́ n ní , "" eku tó bá ti ní òpó nílẹ ̀ , kì í si aré sá ."
Mo yáa mọ̀’wọ̀n ara mi, mo dìde kúrò ni ìkọ̀ oújẹ wọn, mo gba Pizza Express kan tí ń bẹ ní ẹ̀bá ibẹ̀ lọ.
Àwọn ọmọ Merari gba ìlú mejila lọ́wọ́ àwọn ẹ̀yà Reubẹni, ẹ̀yà Gadi ati ẹ̀yà Sebuluni.
 orúkọ rẹ ̀ ní àwọn abẹnugan tíọ ́ rì náà fí ń pe ìlànà wọn .
Ti a ba de ile ẹjọ giga pẹlu awọn ẹri ti a ni, a o ri ade to daju'' Nipa boya awọn agbẹjọro wọn ti bẹrẹ igbesẹ lati tẹsiwaju lọ si ile ẹjọ giga, o sọ pe''Laipẹ yi ni wọn yoo bẹrẹ igbesẹ wọn'' Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Àwọn onímọ̀ ṣàwárí 'ihò ìyọ̀ tó gùn jù láyé' nítòsí ìbì tí ìyàwó Lọti inú Bíbélì ti di iyọ̀ Awari tuntun yii tayọ ọ̀kan to waye lọdun 2006 to ṣafihan iho iyọ Cave of the Three Nudes to wa ni Erekusu Qeshm lorilẹede Iran.
Ẹ̀ẹ̀kan lọ́sẹ̀ lètò náà ó máa wáyé lórí ìkànnì YouTube mi, tàbí ní alakowe.
Kò sọ ohunkohun fún wọn láì lo òwe; 
- Ilé ẹjọ́ ìpínlẹ̀ Ondo Ilé ìwòsàn kan rèé tó ń fi àtùpà gbẹ̀bí aláboyún Se ẹni ti yoo ga, ẹsẹ rẹ yoo tiirin, ọmọ ọdun mẹjọ ni Adesọji wa, to fi padanu baba rẹ, iya rẹ nikan si lo n gbọ bukata rẹ.
Atiku Abubakar ni “Inu mi dun bi awon eniyan se jade lati wa
Ọba bá pàṣẹ fún wọn pé, “Ẹ kó gbogbo àwọn òṣìṣẹ́ mi lẹ́yìn, kí ẹ sì gbé Solomoni gun ìbaaka mi, kí ẹ mú un lọ sí odò Gihoni, 
Wọn ti kọ ile sori awọn ọpa epo naa, ti wọn si n fa epo ta lọna aitọ.
Nígbà tí obìnrin náà parì ọ̀rọ̀ rẹ̀ díde, ó ní, ‘Máa ǹṣó, wáá lọ fi àwọn ẹja náà hàn mí’, àwọn méjèéjì sì jùmọ̀ ń lọ.
Eyi ko ṣẹyin pe ile Ifẹ ni ojumọ ti kọkọ mọ wa, ibẹ si ni orirun ilẹ Yoruba, Nitori naa, bi aṣa ati iṣe Yoruba ko ba tilẹ ni itumọ ni ibikibi, o ni lati ni nile Ifẹ to wa ni ipinlẹ Osun ni iwọ oorun guusu Naijiria.
Ẹ óo tẹ àwọn eniyan burúkú mọ́lẹ̀, nítorí wọn yóo di eérú lábẹ́ àtẹ́lẹsẹ̀ yín, ní ọjọ́ tí mo bá fi agbára mi hàn.
Lára wọn ni àwọn orílẹ̀-èdè ti tàn ká gbogbo ayé lẹ́yìn ìkún omi.
Àwọn òṣìṣẹ́ náà gba gbogbo àwọn ọrẹ àtinúwá tí àwọn ọmọ Israẹli mú wá láti fi ṣe iṣẹ́ àgọ́ mímọ́ náà lọ́wọ́ Mose.
Dokita naa ni ohun ko le sọ ni pato, igba ti arakunrin naa ti wa ninu yara igbokusi ninu otutu naa.
Ibrahim di ọ̀gá àgbà àjọ NYSC
Ambode gbé ilé aṣòfin Eko relé ẹjọ́ APC, ẹ bá wa bẹ Buhari kó ṣí bodè ká kó ìrẹsì wọlé - Ìjọba Vietnam ń bẹ̀bẹ̀ Àwọn ológun tó fẹ́ maa yẹ káádì ìdánimọ́ aráàlú wò, ìwà àìríṣẹ́ ṣe ni - Ilé aṣòfin Ọjọ́ mẹ́rin sí ìgbéyàwó wa ní ìyàwó mi b'ómi lọ- Ibrahim Abubakar Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Wọn ò kó owó àbẹ̀tẹ́lẹ̀ yi dúró ni ilú, wọn nko lọ si Òkè-Òkun, eyi ló ba iná mọ̀nàmọ́ná, ilé-ìwòsàn, ilé-iwé, ọ̀nà, omi mi-mun àti ohun amáyédẹrùn yoku jẹ́.
Bakan naa ni Attah ko sọ ni pato, ijiya ti yoo wa fun oṣiṣẹ aṣọbode to yinbọn pa ọkunrin naa, tabi boya owo ti wọn fẹ ẹ gba lọwọ awakọ bọọsi naa ni wọn ṣe daa duro.
Àwọn ọdẹ ti kò ba níí lọ yóò de ni kutukutu wọn ó dúró ni àráádọ́ta ẹsẹ sí ara wọn ní méjì méejì ti wọn kọjú sí ara wọn, ọ̀kan ni apá ọ̀tún ọkan ní apá òsì ojú ọ̀nà tí awa yóò máa gbà rìn kọjá lọ, bí a bá ti ń dé ọdọ ọ̀kọ̀ọ̀kan nínú àwọn ọdẹ wọ̀n-ọnì àwọn méjì tí wọ́n kọ́jú sí ara wọn, níláti yinbọn sí ojú ọ̀run lẹ́ẹ̀kan ṣoṣo.
SSIEC (Ajọ eleto idibo ni ipinlẹ.
Koda iya yii ni Eremosele ja fitafita fun awọn ọlọpaa Naijiria ti wọn si wa n rẹrin musẹ bayii ti wọn n gba owo oṣu gọbọi nitoripe igbesẹ awọn ọdọ Naijiria mu wọn ja gbangba.
Àwon olóòtú jẹ ́ àwon tó ń kọ àyọkà wikipedia láì gbowó , wọ ́ n yàtọ ̀ sí àwon tó ń ka àyọkà lásán .
Kìí ṣe ẹ̀bi wa pé ètò ìsìnkú Abiola Ajimobi falẹ̀ - ìjọba ìpínlè Oyo Bi ẹbí àtàwọn ará Oyo ṣe dágbére fún góminà Abiola Ajimobi rèé Idí tí mo fi faramọ́ ìpinnu NEC- Oshiomole Eyi jẹ ọsẹ kan lẹyin ti Ibrahim Shaibu Atadoga to jẹ aarẹ ile ẹjọ magisrati ipinlẹ naa, jade laye.
Gbogbo awn aworan ta lo yi la ti fi ofin de lilo wọn Akoroyin: Krupa Padhy Olootu: Georgina Pearce Iwaadi: BBC Monitoring Iroyin kikọ: Christine Jeavans and Clara Guibourg.
Àwọn eniyan ń bú wa, ṣugbọn àwa ń súre fún wọn.
Adonija lọ siwaju ọba, ó sì wólẹ̀.
Joke Jacobs - BBC News Yorùbá BBC News, YorùbáFò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ọkọ mi kò kú, ó ń palẹ̀ ọjọ́ ìbí 78 rẹ̀ mọ́ lọ́wọ́ - Joke Jacobs 10 Òkùdu 2020 Oríṣun àwòrán, Instagram/olujacobs Irọlẹ Ọjọru ni ariwo ta pe gbajugbaja osere tiata kan ni ede Yoruba ati oyinbo, Olu Jacobs, ti jáde laye.
Ó dá wọn lóhùn pé, “Irú èyí kò ṣe é lé jáde, àfi pẹlu adura [ati ààwẹ̀.
“OLUWA bá wí fún mi pé, 
OLUWA yóo wá jọba ní gbogbo ayé; Ọlọrun nìkan ni gbogbo aráyé yóo máa sìn nígbà náà, orúkọ kanṣoṣo ni wọn yóo sì mọ̀ ọ́n.
Bakan naa ni ijọba ko gbagbe ẹka to n pese ina ọba, eto irinna oju irin ati eto ẹkọ alakọbẹrẹ ati ipese ilera alabọde ninu eto isuna naa.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Bobrisky:'Mo bá ẹni tó kọlu mọ́tò mi jà bí pé mo mu ǹkan ní' 22 Ọ̀wàrà 2019 Oríṣun àwòrán, @Bobrisky Àkọlé àwòrán, Ìjà ìgboro rèé o, ṣe bí ọkun ni Bobrisky ṣe ba ọkùnrin ẹgbẹ́ rẹ̀ jà ní?
Èyí dá mi lójú, nítorí náà mo mọ̀ pé n óo wà láàyè.
Bi o ti le je pe, gudu-gudu ni Anthony Joshua  ko figba kan kan tura sile, leyin ti o ti n gbaradi ti pe  fun ifigagbaga naa.
“Àwọn tí ń bá mi ṣọ̀tá láìnídìí ń dọdẹ mibí ìgbà tí eniyan ń dọdẹ ẹyẹ.
Ni ipinlẹ Bauchi, awọn agunbanirọ to le ni maarun ni iroyin gbe e pe awọn onijagidija gan ọhun pa.
Agogo mẹrin ìdájí kú díẹ̀ ni bàálù tó kó wọn balẹ̀ sí pápákọ̀ òfúrufú ìlú Èkó.
Lanlong bori atundi ibo ni Plateau Wayi o, gomina Lalong ti ipinlẹ Plateau naa ti bori idibo gomina ni ipinlẹ Plateau, lati pada fun saa keji ni ile ijọba ipinlẹ naa.
Oríṣun àwòrán, omah_lay Yatọ si eyi, wọn ni ọwọ àwọn tun ti pada tẹ akọrin obinrin ti oun na jẹ ọmọ Naijiria, Temilade Openiyi 'Tems', fun ẹsun kan náà.
Nítorí ìdí èyí, ó dámọràn wí pé kí bàbá òun ránńṣẹ́ pe ọkọ náà kí ó bà òun béèrè ọ̀rọ̀ tí wọ́n ń sọ, àti pẹ̀lú pé bí ọkùnrin náà kò bá lè sọ ohun tí ó ń pa á lẹ̀rìn-ín a jẹ́ wwí pé ó fi ojú di ọba.
Awọn eeyan naa ni won gba ọna ẹyin wọ inu ile itaja naa laarọ ọjọ Satide lati ko ẹrun nibẹ fun igba keji.
Bàbá mi ni ẹni ti ń jẹ Oyińdayépọ̀ tí ó dúró gẹ́gẹ́ bi Mọ́gàjí ni Ilé Alárìnkiri.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Cancer: Àṣe ara mi ni iso ti n run gbogbo bí mo ṣe n ṣèrànwọ́ lórí jẹjẹrẹ Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Enuduisu Odili sexual Port Harcourt death: Ọkùnrin kan gba ibi ìbálòpọ̀ jásí ọ̀run alákeji6 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Lagos Senatorial Elections: Abiru ṣ'àbẹ̀wò sí Tinubu lẹ́yìn tó wọlé àtúndi ìbò Sẹnẹtọ ìlà oòrùn ìpínlẹ̀ Eko7 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Adolf Hitler: Kíni ẹ̀yin rántí tàbí mọ̀ nípa Adolf Hitler yìí?
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Police vs Shiite: Ẹ̀mí sùn níbi ìkọlù Shiite àti àwọn ọlọ́pàá l'Abuja 22 Agẹmo 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 23 Agẹmo 2019 Àkọlé àwòrán, ọfọ ṣẹ lagbo ile akọroyin!
Ó yẹ kí o mọ̀ nípa ọ̀nà láti dáàbò bo ara rẹ lọ́wọ́ Coronavirus Eyi waye gẹgẹ bi orilẹede Naijiria ṣi ṣe n ba arun coronavirus finra eyi to ti mu ẹgbẹrun marunlelọgbọn o din diẹ to si ti pa eniyan to din diẹ lẹgbẹrin titii ọjọ Ẹti ọjọ ikẹtadionlogun oṣu keje ọdun 2020.
fun Ilera  to pe ,ti o fun un lasiko eto
Èrò ọmọ Nàíjíríà sọ̀tọ̀ọ̀tọ̀ lórí ₦30,000 owó osù òsìsẹ́ Awọn ọmọ Naijiria ti fesi si igbesẹ Aarẹ Muhammadu Buhari lati gbe aba owo osu tuntun naa lọ si Ile Igbimọ Asofin lẹyin to tẹwọgba àbá ẹkunwo owó oṣù òṣìṣẹ́ ti igbimo naa gbe kalẹ.
Lọwọlọwọ, akẹkọọ ni James Omiyinka ni ipele aṣekagba ni fasiti ilu Eko nibi to ti n kọ imọ ẹkọ Tiata to si sọ ninu fidio ifọrọwanilẹnuwo wa pẹlu rẹ awọn nkan tuntun ti ẹ o maa reti latọdọ rẹ.
”Fun idi eyi, ogagun Benson wa ro
Nígbà tí Balaamu rí i pé OLUWA ń súre fún àwọn ọmọ Israẹli, kò lọ bíi ti iṣaaju láti bá OLUWA pàdé.
 Aare ana ni ibudo ayewo naa je tigbalode to ba ti ode oni mu.
Ẹ̀yin ń bèèrè pé, ‘Ìwọ idà OLUWA,yóo ti pẹ́ tó kí o tó sinmi?
O ni idi ti kamẹra naa fi dakẹ iṣẹ ni pe tori irinṣẹ ti wọn so o mọ ti ni iṣoro nibikan.
Oríṣun àwòrán, Fellipe Abreu Àkọlé àwòrán, Oniruuru awọn posi alarabara ree, eyi to ba wu eeyan kan ni yoo mu nibẹ.
Awọn oṣere tiata to bi ibeji: Femi Adebayo: Gbajumọ oṣere tiata lede Yoruba ni Femi Adebayo, ọwọ baba rẹ, Adebayo Salami taa mọ si Ọga Bello, si lo ti jogun iṣẹ ere ṣíṣe.
Eto naa ti ọdun to kọja jẹ aseyọri nla eleyi to ti fa oju ọpọlọpọ ti ko tilẹ mọ nipa rẹ mọra.
Ni ti ipinlẹ Ogun, awọn tun sọ pe, ko ni si lilọ bibọ ọlọkada bẹrẹ lati alẹ ọgbọnjọ oṣu Kẹsan titi di owurọ ọjọ keji oṣu Kẹwa.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Dapo Abiodun wà lára àwọn tó ta ohun ìjà olóró fún mi - Amoṣun Ìdí tí ilé fi wó lu ènìyàn méjì ní Oshodi -LASEMA Ipò ètò ààbò ń já àwa gómìnà láyà, ó ń kọ wá lóminú - Àwọn gómìnà Buhari san lára owó àjẹmọ́nú Super Eagles!
Tipátipá ni a fi ń lọ lẹ́bàá èbúté títí a fi dé ibìkan tí wọn ń pè ní Èbúté-rere tí kò jìnnà sí ìlú Lasia.
Nítorí ó wà ní àkọsílẹ̀ pé, ‘Yóo pàṣẹ fún àwọn angẹli rẹ̀ nítorí rẹ pé kí wọn pa ọ́ mọ́.
Lara awọn to wa nibi apero naa ni adari ileeṣẹ to n ri si ọrọ iṣẹ agbegbe ipinlẹ Eko, Olukayode Popoola; kọmiṣọnna eto irinna, Frederic Oladeinde ati olubadamọran pataki fun Gomina Babajide Sanwo-Olu lori ọrọ iṣẹ, Aramide Adeyoye.
Lẹsẹkẹsẹ ohùn Sakaraya bá là, okùn ahọ́n rẹ̀ tú, ó bá ń sọ̀rọ̀, ó ń yin Ọlọrun.
Awọn afọ́jú, arọ, adití, obìnrin ati arugbo ni wọn ko kuro lopopona gbogbo.
Kí ló kàn olórí ọmọ ilé aṣòfin Osun pẹlú ìdájọ kòtẹ́milọ́rùn Sẹnẹtọ Adeleke?
Ti a ba se akawe laarin ilu bi Eko tabi Johannesburg ti wọn jẹ olu ilu Nigeria ati South Africa,ko fẹ si wahala pupọni Dar es Salaam.
" Awọn alaṣẹ ijọba kọọkan ni yoo samoju to eto yidi ni agbegbe wọn lati rii daju pe awọn olujọsin tẹle ilana ijọba lori Covid-19 ""Alaye Garba ree"" Bí Coronavirus ṣé jẹ́ kí Awujalẹ wọ́gilé Ojúde Ọba ní Ijẹbu-Ode, bẹ́ẹ̀ náà ló tún ti jẹ́ kí Ganduje wọ́gilé ayẹyẹ 'Hawan Daushe' to máa n waye ninu ọdun Ileya ni Kano."
Gbogbo àwọn ara ilé mi kí ọ dáadáa,
Ẹ ti yapa, ẹ sì ti ṣáko lọ.
Pa ìṣúra rere náà mọ́ pẹlu agbára Ẹ̀mí Mímọ́ tí ó ń gbé inú rẹ.
Bakan naa, Ẹgbẹ oṣiṣẹ NLC fẹ gunle iyanselodi ni Ọjọ Iṣẹgun, Osu Mọkanla, Osu 2018 lati beere fun afikun gbedeke owo oṣu osisẹ to kere julọ lati ẹgbẹrun mejidinlogun si ẹgbẹrun lọna ọgbọn naira.
Àti pé bí wọ́n ṣe kùn wọ́n ní ọ̀dà àláwọ̀ kánnáà jẹ́ kí wọ́n dùn-ún wò lójú.
Àwọn ọba Arabia ati àwọn gomina àwọn agbègbè ìjọba rẹ̀ náà a máa mú wúrà ati fadaka wá fún un.
Wọ́n ní ìbọn tí àwọn ọlọ́pàá yìn bá lára àwọn afẹ̀hónú ọ̀hún.
Àwọn kan ní ẹ̀jẹ̀ ni àmọ́ wọn kò fẹ́ rí oòrùn
wé wọn mọ́ ìka rẹ,kí o sì kọ wọ́n sí oókan àyà rẹ.
Oríṣun àwòrán, others Amọ ọjọ Kẹtadinlogun oṣu kọkanla ọdun 1993 ni Abacha yẹ aga mọ Sonekan nidi, toun gangan si di aarẹ ologun ni Naijiria.
Wiwo iko naa lati okere wa, maa n je ohun iwuri fun.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Apapọ awọn to ti ni arun naa kaaakiri orilẹ-ede Naijiria ti wa di 25,694 bayii.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Oronpoto Animation: Akin Alabi ní kò dára bí eré aláwòrán fáwọn ọmọdé ṣe jẹ́ aláwọ̀ funfun Sugbọn, adajọ ile ẹjọ Majisireti naa, Arabinrin Nnenna Onuoha, ti pàṣẹ pe, ki wọn o taari iwe ẹjọ naa si ọfiisi ikọ agbẹjọro ijọba fun igbesẹ to yẹ, O ni ile ẹjọ majisireti naa ko ni agbara lati gbọ ẹjọ naa, to si sún igbẹjọ si ọjọ keje, oṣu Kẹjọ ọdun 2020.
Bí ilumọọka agbabọọlu Drogba ṣe dáwọ ogun dúró ní Ivory Coast Àwọn olùgbé ìlúu Abidjan ló kò àrùn Coronavirus wọ Ọ̀ṣun-Gómìnà Oyètọ́lá Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Coronavirus in Nigeria: Ẹ wo àǹfààní tó wà nínú àrùn Coronavirus Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Coronavirus: Ṣé ọtí leè dènà tàbí pa àrùn Coronavirus bi?
Nguma sọ wipe ''wọn na wa , wọn si bo wa sihoho, lẹyin nan ni wọn ju wa si inu odo.
Ilé ẹjọ́ sún ìgbẹ́jọ́ Sẹ́nétọ̀ Elisha Abbo tó lu obìrin Ile ẹjọ Majisireeti kan niluu Abuja ti sun ẹjọ Sẹnetọ Elisha Abbo ti wọn fi ẹsun kan pe o lu obinrin nile itaja nkan iṣere ibalopọ siwaju di ogunjọ oṣu kẹjọ ọdun yii.
Buhari gba ife ẹyẹ agbaye Abẹwo Aarẹ Buhari si Plateau Ọgbẹni Okwoche ṣalaye pe ayẹyẹ ọhun fun awọn ololufẹ eree bọọlu ni anfani lati jẹ ẹbun rẹpẹtẹ ati lati ri ife eye naa.
Iru awọn ọmọ yii ti ma n ni adehun pẹlu awọn ẹgbẹ wọn l'ode ọrun nipa asiko ti wọn fẹ ẹ fi aye silẹ.
BBC ṣe ayẹwo itan bi awọn ologun ṣe dasi iṣejọba lorilẹede Sudan ati kaakiri ilẹ Adalawọ.
” Jesu sọ fún un pé, “Ìwọ kò gbọdọ̀ pa eniyan.
Ṣugbọn mo dá a lóhùn pé, “Ṣé irú mi ni ó yẹ kí ó sá lọ?
Bí mo bá ti yí ẹsẹ̀ kúrò ní ọ̀nà tààrà,tí mò ń ṣe ojúkòkòrò,tí ọwọ́ mi kò sì mọ́,
Ẹ máa yin OLUWA, gbogbo ẹ̀yin orílẹ̀-èdè!
Ẹ̀rù ń bà wọ́n kí wọn má forí ọkọ̀ sọ ilẹ̀ iyanrìn ní Sitisi, wọ́n bá ta aṣọ-ọkọ̀, kí atẹ́gùn lè máa gbé ọkọ̀ náà lọ.
Àwọn ẹgbẹta (600) ọkunrin ará Dani tí wọ́n dira ogun dúró ní ẹnu ibodè.
” Wọ́n bá lọ, wọ́n sì ti iná bọ oko Joabu.
Bakan naa ni o so pe, “ijoba ipinle yoo mu alekun ba gbigba owo wole nipa mimu igberu ba imo ero igbalode, latari ati mu awon owo ti won n gba wole sapo ijoba ni awon ile-ise , awon eleka-jeka ati awon iko ile-ise ijoba si apo kan, ati lati se ayewo ati mumu igberu ba ilana ofin.
Ẹ fojú sona fun iroyin yooku Ademola Adepoju.
Coronavirus: Àwọn ohun tí a kò tíì mọ̀ nípa àrùn Covid-19 Àrùn Coronavirus fa'lẹ̀ya láwọn ìletò aláwọ̀dúdú ní Amẹ́ríkà Kí lo mọ̀ nípa fẹntilétọ̀, ohun èlò aṣèrànwọ́ èémí Èyí ni ìdí tí coronavirus ṣe n pa àwọn kan, tí kò sì pa àwọn kan Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
ibá-ìṣẹ ̀ lẹ ̀ àìṣetán bárakú máa ń tọ ́ ka sí ìṣẹ ̀ lẹ ̀ tí ó máa ń ṣẹlẹ ̀ ní gbogbo ìgbà .
Lẹ́yìn náà, ó fara han àwọn meji kan ninu wọn ní ọ̀nà mìíràn, bí wọ́n ti ń rìn lọ sí ìgbèríko kan.
Nebusaradani rí Jeremaya tí wọ́n fi ṣẹ́kẹ́ṣẹkẹ̀ dè é, wọ́n sì kó o pọ̀ mọ́ àwọn tí wọn kó kúrò ní ìlú Jerusalẹmu ati ní ilẹ̀ Juda tí wọn ń kó lọ sí Babiloni.
Oríṣun àwòrán, Ekiti state government Wọn ni ṣiṣe ayọjuran si ọrọ awọn lọbalọba ko le bimọ ire fun idagbasoke orililẹede Naijiria lapaapọ.
Ọba titun, Ọọni Ifẹ̀ Kọkànlélaadọta gba Adé
Àwọn kan ti ń gbéraga bí ẹni pé n kò ní wá sọ́dọ̀ yín.
Labran Abdulmadari, to wa lati ekun Wabara, lo kọkọ dabaa pe ki  wọn yọ abẹnugan ile Igbimọ naa,ti Abdulahi Yaryasa to wa lati ekun Tudun Wada, si keyin re lori esun pe o lọwọ ninu iwa sise owo kumo-kumo ati pe ko tun je ki awọn ọmọ Igbimọ asofin mọ nipa awọn igbese to n gbe .
Bibeli tuntun yii si ni ko tii rinlẹ laarin awọn onigbagbọ, to si tun kun ara awọn Bibeli miran to ti wa nilẹ tẹlẹ.
Ẹ jẹ́ kí wọ́n máa yin orúkọ OLUWA,nítorí nípa àṣẹ rẹ̀ ni a fi dá wọn.
Ni Oṣu Kẹfa,ọdun 2020 yii ni iru iṣẹlẹ naa waye, ti ikọ Boko Haram kọlu ọkọ gomina Zulum, eyi to jẹ ko pada si Maiduguri to ti n bọ.
Ọlọ́pàá gba àna ADC Buhari silẹ̀ lọ́wọ́ ajínigbé Ìdí rèé táwọn ọmọ Nàíjíríà kan ṣe ń tako ìdásílẹ̀ ‘Ruga Settlement’ Wọ́n lu àbúrò mi ló jẹ́ kí ń fi ìbínú lu òǹtàjà l‘Abuja - Sẹ́nétọ̀ tó lu obìnrin ṣàlàyé Wọ́n lu àbúrò mi ló jẹ́ kí ń fi ìbínú lu òǹtàjà l‘Abuja - Sẹ́nétọ̀ tó lu obìnrin ṣàlàyé Alufaa yi ke gbajare si gbogob agbaye lati dide wa ran Naijiria lọwọ lati koju eto aabo wa.
APC sí Atiku: Kò tọ́ sí Atiku láti du ìpò nítorí ọmọ Cameroon ni
6 8487 Orilẹede ajikistan 88 1.
Àwọn ẹ̀yà Reubẹni, ati ẹ̀yà Gadi, ati ìdajì ẹ̀yà Manase náà gòkè odò pẹlu ihamọra ogun níwájú àwọn ọmọ Israẹli, gẹ́gẹ́ bí Mose ti pàṣẹ fún wọn.
Ọlọpaa ni lasiko wahala yii ni wọn yinbọn pa meji ninu wọn ti wọn si gba awọn ibọn ati roolu ọta ibọn lọwọ wọn.
Àwọn ni ìran Aṣeri, wọ́n jẹ́ baálé baálé ni ìdílé baba wọn, àṣàyàn akọni jagunjagun, ati olórí láàrin àwọn ìjòyè.
Ilumọọka oniroyin lorilẹ-ede Ghana, to tun jẹ minisita tẹlẹ ri, Elizabeth Ohene lo sọ iriri rẹ lori bi wọn ṣe fipa ba a lopọ ni bi ọdun mẹtadinlaadọrin sẹyin.
O ni iṣẹlẹ naa fihan pe bi afunrasi lori ẹsun to le bii ipaniyan ọlọwọọwọ ba lee sa mọ ọlọpaa lọwọ, ko si ẹmi ẹni to de lagbegbe naa niyẹn.
Gomina Babajide Sanwo-Olu lo sọ igbesẹ naa di mimọ lọjọ Satide, lasiko to n ba awọn araalu sọrọ lori ibi ti nkan de duro nipa aarun naa nipinlẹ Eko.
EFCC /FBI: Ọwọ́ EFCC / FBI tẹ àwọn gbájúẹ̀ 167, wọ́n gbà owó púpọ̀ padà
com Lẹyin naa ni ki o ju sinu ile idalẹsi loju ẹsẹ, ki o si fọ ọwọ rẹ.
" Ẹwẹ, Aarẹ Muhammadu Buhari ti foju ganni awọn akẹkọọ naa lẹyin ti wọn moribọ ni igbekun awọn to ji wọn gbe.
Ni ọjọ kejidinlogun oṣu kejila ni awọn agbebọn kan yinbọn pa Ọgagun agba Alex Badeh ni opopona marosẹ Keffi si Abuja.
“Ẹ kò gbọdọ̀ ṣe oriṣa-koriṣa kan fún ara yín, tabi kí ẹ gbé ère gbígbẹ́ kalẹ̀, tabi kí ẹ ri ọ̀wọ̀n òkúta gbígbẹ́ mọ́lẹ̀, kí ẹ sì máa bọ wọ́n, ní gbogbo ilẹ̀ yín, nítorí pé èmi ni OLUWA Ọlọrun yín.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Àjẹ́, eégún, kí ni wọn ò pè mí tán tórí Vitiligo lára mi' Bakan naa ni ọrọ ri fun Winnie Orende, to ti pe ẹni ọdun mẹtadinlọgbọn bayii.
O n dije lati ṣoju Ẹkùn Colombia, labẹ ẹgbẹ oṣelu Democrat.
Oríṣun àwòrán, Instagram/Telu_1, Chanel Chin Ọba Akanbi ni nnkan lo wa lọkan Chin to fi n ka gbogbo ohun to n ṣẹlẹ laafin nigba to wa nibẹ.
Ọpọ ninu wọn lo sọ pe awọn ẹbi awọn lo mu awọn lọ sibẹ nitori wọn ro pe ileewe ẹkọ nipa ẹsin ni.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Goitre Patients: Àwọn èèyàn tó ní àrùn gẹ̀gẹ̀ ní ọ̀pọ̀ ìkórira àti ìdẹ́yẹsí ní àwọn ń kojú Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Ènìyàn 603 ló ní Covid-19 ní Nàìjíríà ní 04/07/2020 Ajọ to n mojuto ajakalẹ aarun ni Naijiria, NCDC, sọ pe esi ayẹwo aarun coronavirus t'oun kede lọjọ Abamẹta fihan pe, eniyan mẹtalelẹgbẹta lo tun ti ni aarun naa.
Akitoye ati Kosoko tun doju ija kọ ara wọn, ti Oshodi si wa lẹyin Kosoko digbi nitori ọmọ alaanu rẹ, iyẹn Ọba Eshinlokun, nii ṣe, ti aja rẹ ko si gbagbe oloore ẹkọ.
Wọ́n sọ fún Solomoni ọba pé ẹ̀rù rẹ ń ba Adonija ati pé ó wà níbi tí ó ti di ìwo pẹpẹ mú, tí ó sì wí pé, àfi kí Solomoni ọba fi ìbúra ṣèlérí pé kò ní pa òun.
''Ọrọ ti mo sọ fun kẹyin ni wi pe ko ṣe jẹjẹ.
Wo ìyàtọ̀ tó wà láàrin Àjọ, Àáró àti ọ̀wẹ̀, tí wọn jẹ́ àṣà ìran ara ẹni lọ́wọ́ nílẹ̀ Yorùbá Kí lo mọ̀ nípa ìgbeyàwó Àbẹ̀ẹ́lẹ̀, Àṣàǹte, Ọkọ Káalẹ́ àti Gbàmí o ràmí?
Ogun gbígbóná bẹ́ sílẹ̀ ní ọjọ́ náà, ṣugbọn àwọn eniyan Dafidi ṣẹgun Abineri ati àwọn eniyan Israẹli.
Igbimọ naa yoo ni agbara lati
Ìròyìn sọ pé wọ́n ran awọn elétò ààbò lọ si ibẹ̀ ni ààrín òrú láti ma sọ ibẹ̀ Sáájú àsìkò yìí ni àwọn tó n ṣe agbátẹrù ètò ìfẹ̀hónúhàn #Endsars ti kéde pé ìwọ́de míràn yóò bẹ̀rẹ̀ ni Eko Abuja àti Port Harcourt àti àwọn ìpińlẹ̀ míràn yóò wáyé.
Nítorí àwọn ohun ti àtijọ́ ti kọjá lọ.
Kingdom, Cameroon, Benin Republic, Cöte d’Ivoire, South Africa ati  Saudi Arabia.
Ó bá sọ fún mi, pé: “Ọmọ eniyan, gbójú sókè sí apá àríwá.
Ṣugbọn ajọ to n ri si eto ilera lagbaye, WHO ti kilọ pe ki awọn eeyan ṣora fun ogun ti awọn onimọ nipa eto ilera ko ba fọwọ si.
Láti lè mọ òwe ati àkàwé ọ̀rọ̀,ọ̀rọ̀ ọlọ́gbọ́n ati àdììtú ọ̀rọ̀.
Adigunjalè pa oníbàárà báńki tó ṣẹ̀ṣẹ̀ gba owó n'Ibadan Èkúté gbà ìjọba ilé ìwòsan, Mínísítà ìlera fárígá, ó ní k'àwọn alákóso wà jẹ́jọ́ Irú ẹ̀dá wo ni Ọjọgbọn Folasade Ogunsola jẹ́?
 O sọ pe ""mo wa lati ba gomina kẹdun, ati lati tọrọ aaye lọwọ rẹ lati ṣe abẹwo si diẹ lara awọn to farapa, to ṣi wa nile iwosan, ati lati mọ bi ao ṣe pese iranlọwọ lori igbesẹ ti ijọba fẹ ẹ gbe."
Wọn yóo fà yín lọ siwaju àwọn ìgbìmọ̀.
Ile ẹjọ giga dasi ọrọ naa ti o si sọ pe ofin ko fun Gomina tabi aarẹ orile-ede lagbara lati yọ adajọ kankan yala nipinlẹ tabi adajọ agba lorile-ede.
Ǹkan míràn tó tún lé yí ǹkan padà ni pé, tí gbogbo ìjọba ìbílẹ̀ mẹẹ̀dógún tó kù bá wá pinu láti gbárùkù tí ẹni kan nínú àwọn olùdíje yìí, láti bórí àwọn Ijọba ìbílẹ̀ mẹ́ta tó kù.
Ẹwẹ, Gomina Babajide Sanwo-Olu naa wa lara awọn to kopa ninu ere eje-gigun naa to waye niluu Eko lọjọ Abamẹta, ọjọ kẹjọ oṣu keji ọdun 2020.
Fidio yii lo ṣafihan bi ibi ina naa ṣe ri nigba ti awọn oṣiṣẹ to n koju iṣẹlẹ pajawiri de ibẹ.
Bí mo tilẹ̀ wà ninu ìpọ́njú,sibẹ, o dá mi sí;o dojú ìjà kọ ibinu àwọn ọ̀tá mi,o sì fi ọwọ́ agbára rẹ gbà mí.
59 Iranwọ owo fawọn ẹbi oloogbe - N40,228,174.
1 979111 Orilẹede South Africa 22747 39.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Restructuring: Àgbékalẹ̀ orílẹ̀èdè Nàìjíríà lọ́wọ́ yìí kò lè fàyè O ni eto oṣelu ni Naijiria ko yẹ ko wa fun awọn to lowo atawọn to ni baba isalẹ nikan.
O wa sapejuwe iwa dida idọti soju agbara bii ohun to n ṣe n akoba fun sisan omi ni irọwọrọsẹ.
Ọ́lọ́jọ́2018: Aṣọ ń pe aṣọ ránṣẹ́ nílé Ifẹ̀
Mo bá dé Teli Abibu lọ́dọ̀ àwọn ìgbèkùn tí wọn ń gbé ẹ̀bá odò Kebari.
Seyi Makinde bẹrẹ ile iwe alakọbẹrẹ ni St.
Ìró wọn dàbí ìró kẹ̀kẹ́ ogun,wọ́n ń bẹ́ lórí àwọn òkè ńlá.
Super Eagles kò rántí kó ohun eèlò ìgbábọọlu wọn dání
Ṣugbọn ẹni ti kò bá mọ ọnà tí wọn ṣe n ṣe, yóò kàn f'ebi pa inú lásán ni.
Asiri pada tu pe o ti ni aarun naa ki emi ati ẹ to o pade.
20 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Ondo politics: Ilé ẹjọ́ da ìpèjọ́ pé Akeredolu kọ ló wọlé ìdìbò ìpińlẹ̀ Ondo nù16 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Sudan removed from terrorist list: America yọ Sudan kúrò nínú ìwé orílẹ̀-èdè tó ń ṣagbátẹrù ẹgbẹ́ agbésùnmọ̀mí lágbàyé14 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 US election 2020: Àlàyé rèé lórí bí èèyàn 538 ṣe ń yan ààrẹ lé èèyàn mílíọ̀nù 331 ní Amẹ́ríkà15 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí kan sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
Alásè rí i pé ìtumọ̀ rẹ̀ dára, ó wí fún Josẹfu pé, “Èmi náà lá àlá kan, mo ru agbọ̀n àkàrà mẹta lórí, lójú àlá.
Ìbúgbàmù ńlá wáyé nílùú Beirut ṣáájú àbọ̀ ìdájọ́ ikú Hariri Ariwo ayọ̀ sọ nílé Remi Surutu, ọmọ rẹ̀ mú ọkọ wale Ṣé òótọ́ ni pé Tayo Amusan ni yóò gba ìṣàkóso ilé ìtajà Shoprite?
Mo sọ fun yín pé ẹnikẹ́ni tí ó bá kọ aya rẹ̀ sílẹ̀ tí kò bá jẹ́ nítorí àgbèrè, tí ó bá fẹ́ ẹlòmíràn, ó ṣe àgbèrè.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Trump Impeachment: Aṣòfin 232 ló dìbò yọ ààrẹ nígbà tí 197 tako ìgbésẹ̀ náà 11 Sẹ́rẹ́ 2021 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 14 Sẹ́rẹ́ 2021 Ile asofin tawọn asoju lorilẹede Amẹrika ti dibo yọ aarẹ Donald trump nipo fun igba keji lori ẹsun pe o se koriya fun iwa idaluru lọsẹ to kọja.
O ni wahala ni yoo da silẹ ti awọn gomina ba bẹrẹ si ni jẹ ọlọpaa ni owo.
Lẹyin eyi agbẹjọro Sotitobire bọ ẹwu ofin to si jade nile ẹjọ.
Mo maa n ji lọganjọ oru lati fun ọmọ lọyan, ti maa si da wa pẹlu ọmọ mi nikan, ti maa si yapa kuro ni awujọ agbaye, bẹẹ ni mo n da nikan ronu nipa akoko sise iyalọmọ laisi ẹni ti maa kọju si fun iranlọwọ.
Ti a ko ba gbagbe, ẹgbẹ oselu APC pin si meji lori boya Ahmed Lawan ni yoo dije dupo tabi Sẹnetọ ali ndume ni yoo soju ẹgbẹ gẹgẹ bi oludije sipo Aarẹ Ile Asofin.
OLUWA ní, “Gbogbo ìwà burúkú wọn wà ní Giligali, ibẹ̀ ni mo ti bẹ̀rẹ̀ sí kórìíra wọn.
Ṣùgbọ́n kíyè sí ọ̀rọ̀ tí mo máa bá ọ sọ nítorí ki ìwọ ba lè tètè yọ, ogunlọ́gọ̀ ènìyàn ni ó ti hu irú ìwà tí ìwọ hù yìí rí, ṣùgbọ́n o;lúkúlùkù wọn ló kú sí orí igi.
Ìbéèrè yìí ló ń tawọ́-tasẹ̀ nínú awọn ọmọ orilẹede Naijirià nígbà tí iroyin gbalẹ pe, Senato kan, Bassey Akpan, gbà ọkọ ayọkẹlẹ ti owo rẹ le ni ọ́ọ̀dúnrún mílíọ̀nù Náírà lọwọ oníṣòwò elépo robi kan, Babajide Ọmọkore, lati fí dáàbò bo ẹmi re.
”Angẹli yìí bá sọ fún un pé, “Adura rẹ ti gbà; iṣẹ́ àánú rẹ ti gòkè lọ siwaju Ọlọrun.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Nigeria Population: Báwọn ọmọ Nàíjíríà ṣe ń pọ̀ si jẹ́ ìpèníjà fún Buhari Odun 2018 ni wọn pari afara naa ti yoo maa gbe awọn arinrinajo lati Hong Kong lọ Zhuhai.
Ipade apero ALFS keyin todun 2017 ti o waye lorile-ede Malawi fi ayesile lopolopo lati jiroro po ni ona lati fowosowopo lati koju awon isoro to n koju eto abo.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Coronavirus: Ẹ̀kọ́ márùn ún tí orílẹ̀-èdè àgbáyé lè kọ́ lára Naijiria lórí ìdènà àjàkálẹ̀ àrùn 13 Ẹrẹ̀nà 2020 Oríṣun àwòrán, Getty Images Arun Coronavirus ti tan de orilẹ-ede mẹrinlelaadọfa lagbaye lati igba to ti bẹ silẹ nilu Wuhan, lorilẹ-ede China lọdun 2019.
Ní ọdún kẹrinla tí Ọba Hesekaya jọba, Senakeribu, ọba Asiria gbógun ti gbogbo ìlú olódi Juda, ó sì kó wọn.
abenugan lati tuko re fun odun kan gbako.
Eleyii jẹ ohun to ba ni ninu jẹ pupọ, pe orilẹ-ede South Africa le huwa
Omo Oba Tapa Joshua Alaba Agoro ni baba rẹ nigba ti iya rẹ si jẹ Dorcas Oyejola Asabi agoro to tun jẹ iya ni Isreli ni ile Oluwa.
Ninu osu ti o koja, aare Assad salaye pe, lati se atunse si ile Syria lo je ohun logun julo, leyin ti ogunlogo awon omo orile-ede Iran ti padanu emi won ti awon miiran si padanu ile ati awon ohun ini won sinu olokan-o-jokan ijamba naa.
Àkọlé àwòrán, Ọ̀pọ̀ akẹ́kọ̀ọ́ ni yóò jókòó sílé nítorí èlé iléèwé Nínú àtẹ̀jáde kan lọ́jọ́ọ̀bọ tí igbákejì ọ̀gáàgbà àjọ SERAP, Timothy Adéwálé fi síta, ọgbọ́n àti sé ọ̀nà ìmọ̀ mọ́ àwọn ọ̀dọ́ ni ìgbésẹ̀ àfikún owó iléẹ̀kọ́náà yóò padà jásí.
'Hijab tí mò n lò kọ́kọ́ jẹ́ ìyàlẹ́nu fún àwọn agbábọ́ọ̀lù mi' Ìyàwó gún ọkọ rẹ̀ pa Iléeṣẹ́ ọlọ́pàá ti dárúkọ àwọn SARS to pa Kolade Àwọn àsọtẹ́lẹ̀ tó já s'ófo lórí ìdìbò 2019 BBC Yorùbá jade sọ fun awọn eniyan ki wọn fi ami sori ọrọ Olorun o sun.
Nítorí náà ẹ kò gbọ́rọ̀ sí mi lẹ́nu pé kí olukuluku kéde òmìnira fún arakunrin rẹ̀ ati ọmọnikeji rẹ̀.
Oríṣun àwòrán, AFP Bakan naa nipinlẹ Bauchi, ọwọ wa tun tẹ ẹlomiran ninu awọn alakoso idanwo yii, taa ni ki wọn kin wa lẹyin, amọ ti wọn n fi ẹgun sọwọ.
Wọn ni Baba arabinrin naa ki ọmọkunrin jojolo naa mọlẹ to si lọ ri i mọlẹ si ẹyinkunle ile rẹ.
Nítorí náà mo ń tọ́jú ìyàwó mi púpọ̀ púpọ̀ ní àkókò yìí, mo ń kẹ́ ẹ gan-an ni, nígbà tí ó sì sọ̀rọ̀ ẹyẹ àparò mo pinnu àti wá àparò dé góńgó.
" O ni ile ọhun ko ti sọ abadofin kankan di ofin lasiko yii, nitori oriṣiriṣi ilana lo rọ mọ sisọ abadofin di ofin.
Lẹ́yìn náà, ó mú mi wá sí ibi gbọ̀ngàn ti òde, mo rí àwọn yàrá ati pèpéle yíká àgbàlá náà.
Ìyàtọ̀ kékeré kọ́ ló wà láàárín oyè Elétù Òdìbò àti Báálẹ̀.
Soyinka: Ti mo ba dara pọ mọ ẹgbẹ Obasanjọ, wọn gbọdọ yẹ mi lọpọlọ wo Bakana lori leta oloye Ọbasanjọ̀ ati ogagun Babangida, Soyinka sọ wipe o yẹ̀ ki awọn eniyan maa funra ti awọn ologun ba ti n kọlẹta si ara wọn.
Mele Kolo Kyari ni aarẹ Buhari yan lati rọpo Maikanti Baru to ti n dari ajọ naa tẹlẹ.
Igbakuugba si ni wọn le fi opin si jijẹ ọmọ ẹgbẹ fun ẹni naa.
Nicholas Olukọtan kan ni Fasiti Manitoba, Gerry Bowler, ṣalaye pe nitori pe Ẹni Ọwọ Nicholas maa n pin ẹbun fun awọn eniyan, ni wọn ba bẹrẹ sii ri gẹgẹ bi baba-isalẹ awọn ọmọde ati onidan to maa n fun nii ni nkan.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù O tó ìdá méjì àwọn ènìyàn àgbáyé to wà nínú ewu àìsàn ibà Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ O tó ìdá méjì àwọn ènìyàn àgbáyé to wà nínú ewu àìsàn ibà 10 Bélú 2018 Iṣẹ iwadii yii yoo wulo ni papakọ ofurufu àti awọn ibudokọ lati fi gbogun ti itankalẹ aisan ibà lagbaye.
Awọn aworan wọnyi ti o ya ni opin ọdun 2017 pẹlu ajọsepo ajọ alaanu to npese iranwọ omi (Water Aid) fun akojọpọ aworan kan ti wọn pe ni 'Untapped Appeal' eleyi ti afihan rẹ yio waye titi di opin osu kini ọdun yii.
Báyìí ni ọmọkùnrin yìí sọ, níbà tí ó parí ọ̀rọ̀ rẹ̀ tán, ó fa àdá yọ ó sì ṣá ara rẹ̀ lọ́gbẹ́ ni inú tó bẹ́ẹ̀ tí ìfun fi tú jáde: ikú dé.
“Níbo ni ọgbọ́n ti ń wá;níbo sì ni ìmọ̀ wà?
Titi de opin ẹmi mi ni ma a ni ifẹ rẹ.
Pierre Nkurunziza ti jẹ ààrẹ ilẹ̀ Burundi láti ọdún 2005.
Bi iye awọn eeyan to n na owo ti ko to dọla meji lojumọ ṣe n dinku ni ilẹ Asia, bẹẹ lo n pọ si ni Afrika'' Ọga agba ni Oxfam, Winnie Byanyima ni ''Afrika ṣetan lati dagbasoke ṣugbọn ko le ṣeeṣe ti awọn olori ko ba lẹmi lati gbaruku ti awọn to fẹ ṣiṣẹ mu agbega ba araalu dipo awọn olowo'' Esi iwadi naa ṣe agbekalẹ ohun ti awọn orileede Afrika n ṣe lati mu opin ba iṣẹ oun oṣi.
Wahab Raheem ati Adam Habeeb ti ẹgbẹ oselu APC lo gbe Ademọla Adeleke lọ si ile ẹjo wi pe ko ni ju sabuke ile ẹkọ girama, eleyii ti yoo fun ni anfaani lati dije.
Mò ń kìlọ̀ fún gbogbo ẹni tí ó bá gbọ́ àwọn ọ̀rọ̀ àsọtẹ́lẹ̀ ìwé yìí.
Ọkùnrin kan tí ó wí pé òun ń fẹ́ẹ́ di olówó ti di olówó kí Aṣojú-Olódùmarè tóó dé ṣùgbọ́n inú àìsàn ní ẹ̀dá ọ̀run náà bá a nítorí nígbà tí ó di olówó tán kò mọ àwọn àgblagbà mọ́, ó bẹ̀rẹ̀ sí yáájú sí gbogbo àwọn ènìyàn kiri, àṣẹ̀hhìnwá-àsẹ̀hìnbọ̀ àìsàn kan kọlù ú bẹ́ẹ̀ ni dókítà kò sí ní ìtòòsì, àwọn àgbàlagbà tí wọ́n sì mọ oògùn àti ràn án lọ́wọ́ nítorí ó ti yáájú si gbogbo wọn.
” Wọ́n mọ̀ pé Oluwa ni.
Wọ́n dáhùn pé, “Àwọn kan ní Johanu Onítẹ̀bọmi ni ọ́, ṣugbọn àwọn mìíràn ní, Elija ni ọ.
Idije ọun waye laarin ẹgbẹ agbabọọlu Haleluya FC to jẹ ẹgbẹ agbabọọlu Nkurunziza funra rẹ ati ẹgbẹ agbabọọlu mii to wa lati ilu kan ti wọn pe ni Kiremba.
Iṣimaeli, ọmọ Netanaya ati àwọn mẹ́wàá tí wọ́n bá a wá dìde, wọ́n bá fi idà pa Gedalaya tí ọba Babiloni fi ṣe gomina ilẹ̀ náà.
A fi gbogbo rẹ le Ọlọrun lọwọ a si n reti idajọ Ọlọrun""."
O ni nitori naa, oun yoo duro laye ara oun.
Nítorí náà, ó ranṣẹ sí ọlọ́gbọ́n obinrin kan, tí ń gbé Tekoa.
Nígbà tí mo parí ọ̀rọ̀ mi tán gbogbo wa múra láti sọ̀ kalẹ̀ sí ìsàlẹ̀ pẹ̀tẹ́ẹ̀sì náà, ṣùgbọ́n nígbà tí Baba-onírùngbọ̀n dìde, ẹnu yà mí gidigidi: nítorí ìgbà náà ni mo túbọ̀ wáá rí ‘rùngbọ̀n ńlá yìí tí ó gba gbogbo orí òkúta.
Ṣugbọn nítorí ojurere mi ni mo fi ṣàánú fún ọ.
"Kó ti dáju iye ènìyàn to wà ninú ilé ti bàálù naa jálù Gómìnà Kasivita fidi rẹ̀ múlẹ̀ pé ""ìṣẹ̀lẹ̀ yìí ti gba ẹmi àwọn ará ilú wa"" bẹ́ẹ̀ lo fi ọ̀rs ìyànjú ránṣẹ́ si àwọn ẹbi ti àjálù náà dé bá àti awọn to farapa."
ọba aláde o gbọdọ kọ iyàwó rẹ̀ sílẹ̀ Láná òde yìí ní Oluwo ti ìlú Iwo nípínlẹ̀ Oṣun fi léde pé ìbásepọ̀ gẹ́gẹ́ bi lọ́kọláya tó wà láàrin òun àti ìyàwó rẹ̀ Chanel ti dé òpin nítori àwọn kùdìẹ̀-kudíẹ̀ kan ti ko ṣe pari Ọ̀rọ̀ èmi àti Olorì Chanel Chin kò yé ara wa mọ́ nínú ilé- Oluwo.
Eleyi yatọ si bi o ti ri tẹlẹ to jẹ pe ipin awọn to n lo ina nile wọn, awọn to n ṣ'owo to niṣe pẹlu ina atawọn ileeṣẹ nla to n lo ina.
Alifabẹẹti to jẹ ohùn Oduduwa ree ti wọn fi n kọ awọn ọmọ ni Port Novo ni eyi ti wọn fi gba pé èdè yoruba kò fi ni parun.
Kò sí ibùdó ayẹwo àrùn Coronavirus ní UCH, ẹ má wá fún ayẹwo lọ́dọ̀ wa - Ọga àgbà UCH Ọ̀ga àgbà fún ilé iwosan UCH, Ọjọgbọn Jesse Abiodun Otegbayo lọ sísọ lójú ọ̀rọ̀ yìí lásìkò tó ń gbalejo kọmisana feto ìlera nipinlẹ Ọ̀yọ́, Dókítà Bashir Bello nílé ìwòsàn náà.
Ṣugbọn ọgọọrọ eeyan lo ti n kerora pe awọn ọlọpaa SARs n fi ẹtọ wọn dun wọn.
Lẹ́hìn èyí, ẹni tí mo tún ṣe àkíyèsí ni ọkùnrin kan báyìí orúkọ ẹni tí ń jẹ́ Ìbànújẹ́-ìsàlẹ̀.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Akintọla Williams: Àwọn nkan tó ṣe pàtàkì tó yẹ kí o mọ̀ nípa Olùṣirò owó Àgbà àkọ́kọ́ ní Afrika 10 Ògún 2018 Oríṣun àwòrán, Facebook /Lagos State Government Àkọlé àwòrán, Akintọla Williams ni Aarẹ akọkọ fun Institute of Chartered Accountants, ICAN Olóyè Akintọla Williams ni Oluṣiro owo Agba akọkọ ni ilẹ Afrika, Chartered Accountant.
Gomina Sanwo-Olu pari ọrọ rẹ pe oun yoo nifẹ lati foju ganni ọmọdekunrin naa laipẹ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Oronpoto Animation: Akin Alabi ní kò dára bí eré aláwòrán fáwọn ọmọdé ṣe jẹ́ aláwọ̀ funfun Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Agbẹnusọ Ile Igbimọ Aṣofin Ipinlẹ Eko, Aṣofin Mudashiru Ọbasa ti gboriyin fun awọn oṣiṣẹ lorilẹ-ede Naijiria fun iṣẹ takuntakun ati ifọkanjin wọn lẹnu iṣẹ.
Gbogbo awọn gomina naa ni wọn pe fun agbekale ọlọpaa agbegbe si agbegbe, ki eto aabo lee fi ẹsẹ mulẹ bi o ti yẹ.
Oríṣun àwòrán, Reuters Àkọlé àwòrán, Ohun ta n gbọ ni pe eeyan ogun lo padanu ẹmi wọn Aarẹ Buhari rọ awọn alaṣẹ lorilẹede Sri Lanka lati wa awọn afẹmẹṣofo to wa nidi iṣẹlẹ naa, ki wọn si fi wọn jofin.
Gassama so pe, oun n koja lo nigba ti oun ri awon eniyan ti won kora won jo niwaju ile naa.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Christmas: Ẹni ti ọdun ba ti bá láyé yẹ kó dúpẹ́ Lorilẹ-ede wa nibi, ọjọ yii jẹ ọjọ faaji ati ọjọ igablejo loriṣiriṣi fun ọpọ eeyan.
Oore OLUWA fún Àwọn Eniyan Rẹ̀.
niluu Portharcourt, ni ipinle Rivers ,lojo Isegun.
Iweregbu di ẹni to n kawọ pọnyin rojọ niwaju adajọ lẹyin to ko sọwọ ajọ EFCC ni ipinlẹ Eko.
Ṣugbọn Lamorde sọ fun BBC nigba naa pe, nitori pe ajọ EFCC n ṣe iwadii ọkunrin to fi ẹsun naa kan oun, lo ṣe ṣe bẹ ẹ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Fayemi: Ẹ̀sùn àjẹbánu àti lílo owó básubàsu la fi kàn wọn 23 Sẹ́rẹ́ 2019 Oríṣun àwòrán, Twitter Àkọlé àwòrán, Awọn tí ìfipòsílẹ̀ náà kàn ni adarí ilé ẹ̀kọ́ fásitì EKSU, adarí ilé ìwòsàn tó wà ní ìpínlẹ̀ Ekiti, EKSUTH.
Yíyin OLUWA ni ó yẹ ẹ̀yin olóòótọ́.
Ìwọ jìnnà sí irú àwọn eniyan bẹ́ẹ̀.
Ipinlẹ Georgia yoo tun idibo ka lati agbegbe kan si omiran Amọ, ikọ eleto idibo ni Georgia ti ni awọn ti ri ibo 2,600 ti wọn ko ka mọ esi idibo naa, ti won si ṣetan lati tun ibo ka.
Ẹwẹ, ile ẹjọ naa tun ni, wọn yoo ni ki awọn olukopa ninu eto naa fi ọwọ si iwe pe alaafia yoo jọba lasiko ti wọn ba n ṣe ọdun wọn.
O ni ki wọn o si tun maa gbadura fun iṣọkan ati ilọsiwaju Naijiria.
NLC: A fẹ́ kí ìjọba bẹ̀rẹ̀ sí san owó oṣù tuntun kíákíá Èèwọ̀!
Ìṣẹlẹ yí ki se akọkọ irú rẹ lorílè-èdè Amerika.
Ẹwẹ, ajọ to n ri si ere bọọlu afẹsẹgba ni Naijiria, NFF sọ loju opo Twitter rẹ pe ibanujẹ nla ni iku awọn agbabọọlu mejeeji jẹ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ìwà ipá nínú ìdílé máa ń bí ìgè àti àdùbí ni tó lè já sí ikú Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Lẹyin eyi ni ileeṣẹ ọlọpaa tun kọwe si ile ẹjọ lati fun wọn laṣẹ lati ti i mọle fun ọgbọn ọjọ mii ki wn lee raye ṣe iwadii wọn daadaa.
Rán àwọn ọmọ ogun rẹ wá, OLUWA.
 Ti ifẹhonu han kankan ba si waye nibikibi lorilẹede yii, a jẹ pe atẹjade yii ko tii tẹ awọn to wa nibẹ lọwọ ni, tabi pe wọn si ọrọ yii gbọ abi awọn agbofinro lo wa nidi isẹlẹ naa, gẹgẹ bi wsn ti n se lati latẹyinwa lati ta ẹrẹ si asọ ala wa, lọna ati mu kawọn eeyan maa fi oju arufin wo wa, dipo oju awọn eeyan ti wọn n fi iya jẹ lati ọdun 2015.
Nítorí náà, nígbà tí ó bá di òwúrọ̀ ọ̀la, a óo mú gbogbo yín wá siwaju OLUWA ní ẹ̀yà kọ̀ọ̀kan; ẹ̀yà tí OLUWA bá mú yóo wá ní agbo-ilé agbo-ilé.
” Kò rí Elija mọ́, ó bá fa aṣọ rẹ̀ ya sí meji láti fi ìbànújẹ́ rẹ̀ hàn.
Adajọ agba ni Naijiria, Mohammed, adajọ to ka idajọ ileẹjọ, Okoro ati Abba-Aji atawọn ọmọ igbimọ igbẹjọ mii lo fẹnu ko lori idajọ naa.
Àwọn akọni mẹta náà bá la àgọ́ àwọn ọmọ ogun Filistia já, dé ibi kànga náà, wọ́n sì bu omi náà wá fún Dafidi.
Ṣugbọn ṣa, iyawo Ọrunmila, tii se Ilẹ, gbọ lasiko ti awọn ẹlẹyẹ ṣe imulẹ naa.
Ṣugbọn ẹ mọ bí Timoti ti wúlò tó, nítorí bí ọmọ tíí ṣe pẹlu baba rẹ̀ ni ó ń ṣe iṣẹ́ iranṣẹ pẹlu mi ninu iṣẹ́ ìyìn rere.
Lẹ́yìn náà Jese sọ fún Ṣama pé kí ó kọjá níwájú Samuẹli.
tyn Ìkúnlẹ̀ ló bá dé fún Oshiomole, Ize-Iyamu láti bẹ̀bẹ̀ fún ìbò aráàlú ní Edo Oríṣun àwòrán, Twitter Àkọlé àwòrán, Idibo sipo gomina ni ipinlẹ Edo naa yoo waye ni Ọjọ Kọkandinlogun, Oṣu Kẹsan, ọdun 2020.
Awọn kan wa n beere lọwọ aarẹ pe ṣe orilẹede Naijiria ni ala kankan to n fi oju sun ni, ti awọn miran si ni pẹlu ọpọ ẹsun ajẹbanu to wa lọrun awọn asaaju oloselu, ti Naijiria yoo de ibi to yẹ ko de bi?
Ìṣẹ̀lẹ̀ náà wáyé ni agbègbè Akai Effa, tawọ́n si fi tipa fun àwọn afurasi náà ni fóònù láti pe àwọn ẹbí wọ́n láti sọ fún wọ́n pé, wọ́n ti fẹ́ dána sun àwọn nítorí àwọn jalè ki wọ́n to dána sun wọ́n.
Yoruba gba pẹ ẹnu ẹni la fi n kọ meje ni ọrọ asọtẹlẹ, eyi to ba wuni lati gbà ni eeyan n gbà nibẹ.
Eniyan á rù hangangan,wọn a sì fẹ́rẹ̀ lè máa ka egungun rẹ̀.
Lẹyin ogun ọdun ti ọrọ JUNE 12 ṣẹlẹ ni Naijiria, aarẹ Buhari ṣe iranti oloogbe MKO Abiọla.
Ẹ kọrin sí OLUWA,ẹ yin OLUWA.
Ní gbogbo àkókò Solomoni, gbogbo àwọn ọmọ Juda ati àwọn ọmọ Israẹli wà ní alaafia láti ìlú Dani títí dé Beeriṣeba.
Ọ̀pọ̀ àwọn ènìyàn tún kú ní àwọn ìpinlẹ̀ mọ́kànlá míràn.
"O ni alabasisẹ pọ oun lo wa naka si i pe itumọ ti ""Oxford Dictionary"" kọ kii ṣe eyi to mu itumọ pipe jade ati pe lati igba naa, awọn alajumọ ṣiṣẹ pọ oun kii bere ibere tabi imọran to ba jẹ mọ isẹ lọwọ oun mọ Ogu rọ ile ẹjọ lati sọ fun Fasiti Oxford ati ile itẹwe Oxford lati san miliọnu mẹwaa naira gẹgẹ bi owo itanran ati bibani lorukọ jẹ."
Wòlíì náà beerè lọ́wọ́ Olúwa, ìfihàn yìí ni a sì fi fúnni ní ìdáhùn nípasẹ̀ Urímù àti Túmmímù.
Bakan naa lo gba ìwé ẹ̀rí ẹlẹ́kẹẹji nínú ìmọ ìsejoba láti Fasiti Colombia E become Presidential Candidate of di African Action Congress during di February 2019 Presidential election for Nigeria.
Iko omo-ogun Naijiria, ti fowo sinkun mu iko agbesunmomi ti o kun fun eniyan mejo lasiko ise akanse iwode  ti won pe ni, ‘operation whirl stroke’ ni agbegbe Manya–Gangun ni ijoba ibile Ussa Local Government nipinle Taraba.
Awon olutoju alaisan naa ti n
Musa tun gba ami ẹyẹ fun goolu to fakọyọ pẹlu goolu rẹ eleyi ti o gba wọ awọn Iceland ninu idije agbaye Russia 2019.
Mọ̀ síi nípa Oyedele Adedokun tó ya àwòràn Donald Trump tó lu ayélujára pa Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Fun awọn ti wọn ba n gbọ orukọ rẹ fun igba akọkọ nigba ti wọn kede rẹ pe o fidi akẹgbẹ rẹ, Umar Bago janlẹ, anfaani ree lati mọ nipa ẹni ti Fẹmi Gbajabiamila jẹ.
Nisinsinyii, farabalẹ̀ ṣàkíyèsí ọ̀rọ̀ náà, kí òye ìran náà sì yé ọ.
Wọn maa n ti ilu kan lọ si ekeji lati wa ti aje ṣe, ti ọpọ ajeji si maa n di ọmọ onilu lẹyin o rẹyin nigba ti Ọba oke ba bukun wọn.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù PDP ni ki Buhari dẹkun ẹkun alabosi lori ijinigbe Yobe 26 Èrèlè 2018 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, PDP ni idarudapọ iroyin ati aigbọraẹniye laarin ẹka isejọba gbogbo kun ara ohun to mu awari awọn akẹkọ falẹ Ẹgbẹ oṣelu Peoples Democratic Party, PDP to n lewaju ẹgbẹ alatako lorilẹede Naijiria ti ke si ijọba labẹ isejọba APC lati dẹkun ẹkun alabosi to n sun lori iṣẹlẹ ijinigbe ti o waye nileewẹ girama kan ni ipinlẹ Yobe.
Ati pé darandaran ni wọ́n, ìtọ́jú ẹran ọ̀sìn ni iṣẹ́ wọn, wọ́n sì kó gbogbo agbo mààlúù ati agbo ewúrẹ́, ati ohun gbogbo tí wọ́n ní lọ́wọ́ wá.
America pàdánù ọ̀kan gbòógì nínú olósèlú wọn.
Bí kò bá so èso, gé e.
Ṣúgbọ́n ìgbá tí ó tún dé ilé ayé ìwà rẹ̀ kò fii sílẹ̀.
“Olúwa rẹ̀ dá a lóhùn pé, ‘Ìwọ olubi ati onímẹ̀ẹ́lẹ́ ẹrú yìí.
O ní ó ṣe ni láànú pé Buhari tún ń fí tayọ̀tayọ̀ lo ọlọ́pàá, ọmọogun àti àwọn agbófinro miran láti maa yìnbọn ní bùdó ìdìbò tí wọn si ji àwọn àpóti ìdìbò gbé lọ Ó fẹ́sùn kan Buhari pé kìí ṣe àdrí tó bòwọ̀ fun ìjọba àwa-arawa rárá Níbo ni Fayose wa: Àwọn ọmọ orílẹ̀-èdè Nàìjíríà ti ń bèrè pé níbo ni Gómìnà Ayọdele Fayoṣe wà láti ìgbà tí wọ́n ti kéde èsì ìdìbò náà ní ọjọ́ àìkú.
Ṣe ni mo rí i tí o kọjú sí mi tí ó sì da omi kan báyìí lù mí lára, ò ké lóhùn rara, mo sì ta gìrì, ó ní, ‘Mo pa á láṣẹ wí pé kí àyípadà dé bá ìwọ ọkùnrin tí ń fi olùfẹ́ mi ṣe yẹ̀yẹ̀, kí ìwọ yípadà láti ẹsẹ̀dé èkít’[i ìdí sí òkúta, kí ìwọ sì jókòó títí si ibi tí ìwọ wà yìí, títí ọjọ́ tí mo bá tú ọ sílẹ̀.
O tẹsiwaju pe ''A ko ti bọ kuro ninu a n fi owo kun owo epo, owo ina, ki laa jẹ, ki laa mu, awọn nkan to n jo wa bi ina labẹ aṣọ pọ ti a gbọdọ fi han agbaye.
Ṣugbọn Esau dáhùn pé, “Èyí tí mo ní ti tó mi, arakunrin mi, máa fi tìrẹ sọ́wọ́.
Igba ti a to o bẹrẹ si ni lọ fun idanilẹkọ igbeyawo, ni imọlẹ to o tan si aye ọkọ mi.
Òdodo ati ẹ̀tọ́ ni ìpìlẹ̀ ìtẹ́ rẹ;ìfẹ́ tí kì í yẹ̀ ati òtítọ́ ń lọ ṣiwaju rẹ.
abadofin ti yoo satunse si oro amojuto ayika ati aabo to peye labe iwe ofin
Minimum wage: 30,000 Naira ni ẹgbẹ́ òṣìṣẹ́ n bèèrè fún
Ilé tí ó kọ́ dàbí òwú aláǹtakùn,àní bí àgọ́ àwọn tí wọn ń ṣọ́nà.
O ni o jẹ nkan itiju pe iru iṣẹlẹ yii n waye ni orile-ede to ti pe ọgọta ọdun, ijọba ko le pese nnkan tó ṣe koko lara nnkan ti ara ilu nilo, eyi to jẹ aabo to peye.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ọ̀ṣun Oṣogbo 2019: Ìyán gbígbóná ní wọn kọ́ fi bẹ̀rẹ̀ ọdún 16 Ògún 2019 Àkọlé àwòrán, Iwaju aafin ti n rọ kẹkẹ fun ọdun Àkọlé àwòrán, Ẹ poore yeeeye ooo, Ọṣun jọọ, fun wa lowo, fun wa ni ọmọ, fun wa ni alaafia Àkọlé àwòrán, Iya olomi tutu ti Osogbo naa ti setan ọdun Àkọlé àwòrán, Iyan gbigbona ni aarọ ni awọn obinrin kọkọ monuto Àkọlé àwòrán, Haa, ọrọ yii gba ki awọn ọkunrin gba odo iyan Àkọlé àwòrán, Tọmọde-tagba lo ti n ta mọra lati mura fun ọdun Àkọlé àwòrán, Bi awọn ọkunrin se n palẹmọ, naa ni awọn ọkunrin n se Àkọlé àwòrán, Aje yoo kuku bu igba jẹ́ fun awọn eeyan kan lonii Àkọlé àwòrán, Ọrọ̀ aje yii naa ko yọ awọn ọkunrin silẹ, tọkunrin-tobinrin lo n wa owo Àkọlé àwòrán, Bi esinsin ba ta firi, awa setan lati wọn lasiko ọdun ni awọn agbofinro yii n wi Àkọlé àwòrán, Ni ṣẹpẹ la wa fun ọdun Ọṣun ni ọdun yii, ọdun yii ko yẹ Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Alaga ajọ naa Ọjọgbọn Mahmood Yakubu lo kede ọrọ yi lỌjọbọ ni olu ilẹ naa Abuja.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Love Making at Old Age: Eré ìfẹ́ wa kò wà láti bímọ, a kàn ń tẹ̀ẹ́ sójú rẹ̀ ni Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Love Making at Old Age: Eré ìfẹ́ wa kò wà láti bímọ, a kàn ń tẹ̀ẹ́ sójú rẹ̀ ni 18 Ọ̀wàrà 2020 Awọn tọkọ-taya meji yii ba BBC Yoruba sọrọ lori awọn ohun ti wọn n ṣe to ran wọn lọwọ lati ri ọjọ alẹ papọ gẹgẹ bii tọkọ-taya.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Nigeria Swearing in 2019: Seyi Makinde di gómìnà tuntun 27 Sẹ́rẹ́ 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 29 Èbibi 2019 Ọjọ kẹẹdọgbọn oṣu kejila ọdun 1967 ni wọn bi Oluwaseyi Abiodun Makinde si idile oloogbe Pa Olatunbosun Makinde ati iyaafin Abigael Makinde ni agbo ile Aigbọfa Oja'aba, ilu Ibadan.
Aare Tayyip Erdogan to n tuko orile-ede Turkey ti se ipade pelu Poopu Francis lojo Aje lori oro Jerusalem ati isele pelu Aare Donald Trump tile America lori gbigba Jerusalem gege bii olu ilu Isreal ni eyi ti won jo gba pe o le se akoba fun alaafia ekun aarin gbungbun ila oorun agbaye lasiko.
Oríṣun àwòrán, Twitter Lẹyin eto ti wọn ti le Lilo ati Ka3na pada sile lalẹ ọjọ Aiku, ni iṣẹlẹ naa waye.
”Ogbeni Ogun ni awon ise akanse to lagbara ti ilera iru eni naa ti mu iberu dani nikan ni minista fun eto ilera yoo maa fowosi gbigbe lo sile okeere lataari pe ko see se ni Naijiria.
Wọ́n wá bẹ̀rẹ̀ sí ṣọ́ ọ.
WAEC: ANCOPSS ní òun àti ẹgbẹ́ olùkọ́ yóò ṣèpàdé lọ́jọ́ Ẹti lórí ìpínu ìjọba àpapọ̀
Adágún iná yìí ni ikú keji.
”Wọ́n dá a lóhùn pé, “Àwa kì í ṣe ọmọ àlè, baba kan ni a ní, òun náà sì ni Ọlọrun.
Ni ọdun 1990 ni Oyetola gba iwe ẹri imọ oye onimọ nipa eto ọrọ aje ni fasiti Eko kan naa.
Àjẹsára meningococcal di èyí tó wà fún lílò ní ìgbà àkọ ́ kọ ́ ní ọdún 1970s .
Fatima Ganduje Ajimọbi to jẹ ọmọ gomina Abdullahi Ganduje to n tukó ipinlẹ Kano to fẹ ọmọkunrin Abiola Ajimobi fi ọrọ naa lede loju opo twitter rẹ pe irọ ni.
' Sowore pàtẹ ìfẹ̀hónú hàn míì lónìí Àgbáríjọ àwọn nọ́ọ̀sì fẹ́ gbé Olamide Baddo lọ sílé ẹjọ́ fún ìbanilórúkọjẹ́ Èèyàn 78 kú ó lé ní 4000 tó farapa níbi ìbúgbàmù tó wáyé ní Beirut, Lebanon Amọ ṣa ọrọ naa ṣeni ni kayeefi bi awọn ile ijọsin kan ti ṣe n kerora lori ofin to tako tita ọti yi nitori pe awọn ko ni ribi jọsin bo ti ṣe yẹ.
Awọn obi ni lati maa ṣamojuto awọn ọmọ wọn nile iwe ti wọn fi wọn si.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ní oṣù kọkànlá ọdun 2018 ni àwọn olùkọ́ fásitì lórílẹ̀èdè Nàìjíríà bẹ̀rẹ̀ ìyanṣẹ́lódì Ọjọgbọn Ogunyẹmi ni ipele mẹta ni ohun ti awọn n ja fun wa.
lo n dẹru ba awọn eniyan lati wa se eto ayẹwo orukọ wọn sugbon o se e se ki won
Ọjọ Abamẹta ni ijọba n gbero tẹlẹ lati fun awọn Emir tuntun to ba yan ni iwe ẹri tẹlẹ ki ile ẹjọ to daa duro.
Àkọlé àwòrán, Aago mẹjọ̀ owurọ ni awọn oludibo ti jade lati yẹ orukọ wo ati iforukọsilẹ.
" lẹ ́ yìn ikú "" olùdáàbòbò "" duchesne , champaigne ṣiṣẹ ́ pẹ ̀ lú ìyá olorì , marie de medicis , tí o ti wa lára àwọn tí ó ṣe ààfin luxembourg lẹ ́ ṣọ ́ ."
Bẹ́ẹ̀ sì ni nípa ìlérí ni Ọlọrun fún Abrahamu ní ogún.
Ó ní, “Ìjọba ọ̀run dàbí ìwúkàrà tí obinrin kan mú, tí ó pò mọ́ òṣùnwọ̀n ìyẹ̀fun ńláńlá mẹta títí gbogbo rẹ̀ fi wú sókè.
Nígbà tí Jesu parí gbogbo ọ̀rọ̀ wọnyi, ó sọ fún àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ pé, 
Oríṣun àwòrán, Twitter O fikun wi pe magomago ati iwa ipa to ṣẹlẹ lasiko idibo naa ko jẹ ki idibo naa kẹsẹjari, eleyii ti Dino ni pe ko yẹ ki o waye.
Abẹnugan ile igbimọ asofin ti ipinlẹ,
Ṣugbọn kò sí ẹnìkan tí ó tíì dáyé ninu wọn nígbà tí Mose ati Aaroni alufaa, ka àwọn ọmọ Israẹli ní aṣálẹ̀ Sinai.
" wọ ́ n á ní "" Òkènísà orí ayé "" ."
 lára kókó tí ewì ayaba máa ń dá lé lórí ni ìjúwe àwọn ayaba gẹ ́ gẹ ́ bí i aya aládé , àrẹ ̀ mọ ọba tàbí abọ ́ baṣèlú .
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Efunsetan Aniwura: Àwọn fíìmù òde òní ń kọ́mọ lólè àti ọ̀pọ̀ ìwà burúkú Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Efunsetan Aniwura: Àwọn fíìmù òde òní ń kọ́mọ lólè àti ọ̀pọ̀ ìwà burúkú 23 Ẹrẹ̀nà 2020 Ajihinrere Felicia Iyabode Ogunsola ti gbogbo eeyan mọ si Efunsetan Aniwura, Iyalode ilu Ibadan ti kilọ fawọn oṣere tiata lati dẹkun aṣa ṣiṣira silẹ ninu fiimu.
Mo fi tọkàntọkàn pinnu láti fi ọgbọ́n wádìí gbogbo ohun tí eniyan ń ṣe láyé.
roald engelbregt gravning amundsen ( ; 16 july 1872 - c .
” Ọba sì wí pé, “Ẹ jẹ́ kí ó wọlé.
Cyclone Idai: Ààrẹ Mozambique ní òun rí ọ̀pọ̀ òkú tó lé téńté lórí odò
Iko agbaboolu obinrin Rivers Angels FC tilu Port Harcourt gba ife-eye idije AITEO, ti eka tawon obinrin, eleyi ti o je igba ekeejo ti ohun yoo gba ife-eye idije naa saaju iko agbaboolu Pelican Stars, Ufuoma Babes ati Delta Queens.
 Aṣofin Ọbasa fi kun ọrọ rẹ bayii.
Ọjọ́ orí tàbí ìrírí; kíni agbanisíṣẹ́ n wá?
Ipinlẹ Dallas ti tẹwọ gba ofin to kan an ni dandan fawọn ọlọpaa lati maa da awọn akẹgbẹ wọn to ba n huwa aitọ lọwọ kọ.
Ṣé o ranti pé owó tí a bá lẹ́nu àpò wa, a mú un pada ti ilẹ̀ Kenaani wá fún ọ?
 Ohun ti ofin ko fẹ ni aṣilo agbara ti
Awọn to ti ri iwosan ti wọn ti pada sile wọn jẹ: 11,069.
 Bimbo pari ọrọ pe A o pade lọdun 2020 ni orukọ Jesu.
16 Wọn kò wá Olúwa láti fi ẹsẹ̀ òdodo rẹ̀ múlẹ̀, ṣùgbọ́n olúkúlùkù ènìyàn ńrìn ní ọ̀nà tirẹ̀, àti ní títẹ̀lé àwòrán ọlọ́run tirẹ̀, èyí tí àwòrán rẹ̀ wà ní ìrí ti ayé, àti èyí tí ohun ìní inú rẹ̀ jẹ́ ti òrìṣà kan, èyítí ó di ogbó tí yíò sì ṣègbé nínú Bábilónì, àní Babiloni nlá, èyítí yíò ṣubú.
Òdodo yóo máa rìn lọ níwájú rẹ̀,yóo sì sọ ipasẹ̀ rẹ̀ di ọ̀nà.
Èrò àwọn ènìyàn sọ̀tọ̀ọ̀tọ̀ lórí ẹ̀sùn Onnoghen UNO bẹnu àtẹ́ lu ìdàdúró Onnoghen ‘Ìjọba kò tẹ̀lẹ́ ìlànà òfin lòrí ọ̀rọ̀ Onnoghen’ Agbẹjọ́rò rẹ̀ Oloye Chris Uche (SAN) ní o bẹ̀bẹ̀ lọ́wọ́ ile ẹjọ́ lati sun igbẹjọ́ naa di ẹyin idibo.
N óo mú ẹ̀gàn ati ẹ̀sín ba yín, tí ẹ kò ní gbàgbé títí ayérayé.
– ó tì o – kìí ṣe bẹ́ẹ̀ rárá.
Abẹ́rẹ́ ajẹsára ti ṣe ìrànwọ́ láti séwélé àwọn aburu ti àwọn aisan ti ṣe ni awọn sẹnturi sẹyin.
Ọ̀gágun náà bá dá a lóhùn pé, “Ọpọlọpọ owó ni mo ná kí n tó di ọmọ-ìbílẹ̀ Romu.
Gbogbo ẹran wọn jẹ́ tìrẹ, gẹ́gẹ́ bí àyà tí a fì níwájú pẹpẹ, ati itan ọ̀tún ṣe jẹ́ tìrẹ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìbúgbàmù Somalia: Àwọn ọmọ ilé ìwé farapa nínú ìbúgbàmù 2 Owewe 2018 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 3 Owewe 2018 Oríṣun àwòrán, Reuters Àkọlé àwòrán, Obinrin kan n sa kuro nibi ti ibugbamu ti waye ni Mogadishu Eeyan kan to wa ọkọ ti o ko ado oloro si inu rẹ ti se okunfa ibugbamu kan to se akoba fun ile isẹ ijọba kan ni olu ilu Somalia, Mogadishu ti o si tun ko ipalara ba ile iwe kan to sunmọ ibi iṣẹlẹ naa.
Fayemi gẹgẹ akọkọ ni ilẹ iwe giga fasiti Ilu Eko(UNILAG), bẹẹ lo gba oye keji ni fasiti Ile Ife.
Ṣugbọn ṣa, ajọ naa ko ti i sọ iye eeyan to ku ni pato.
" O ni ọwọ ti iku fi n wọle mu tọmọde tagba lọ lagbegbe Ogoni, papaa ni ileto Bodo nijọba ibilẹ Gokana nibi ti o ni o kere mọ, lọsẹ kan, eeyan mẹwa yoo dagbere faye, n kọ ọpọ lominu.
4 17590 Orilẹede Gambia 126 5.
Ẹ ṣọ́ra ní òpópónà AIT, ọkọ̀ agbépo kan ti yí dánù lọ́nà agbègbè Alagbado Ileeṣe to n ri si iṣẹlẹ pajawiri ni ipinlẹ Eko, LASEMA, ti kede pe ọkọ agbepo kan ti yi danu lagbegbe Alagbado ni Eko.
Hesekaya ọba gba ìwé náà lọ́wọ́ àwọn iranṣẹ, ó kà á.
Wọ́n dúró lọ́dọ̀ rẹ̀ ní ọjọ́ náà, nítorí ó ti tó bí nǹkan agogo mẹrin ìrọ̀lẹ́.
Ènìyàn 653 míràn tún kún iye àwọn tó ní COVID-19 ní Nàìjíríà Wo àwọn òṣìṣẹ́ kólẹ̀-kódọ̀tí tó ń fi ẹ̀mí wọn wéwu kí Abuja leè mọ́ tónítóní Wo àwọn nkan tó yẹ́ kí o mọ̀ nípa 'Awawa Boys', ọ̀kan lára ẹgbẹ́ òkùnkùn tó n dá Eko rú Adarí àjọ NDDC, Pondei ṣetán láti sọ ohun tó mọ̀ nípa ìwàdíì tó bá ti gbádùn- NDDC Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Olofa ina: ẹ parí òwe yìí pé ìgbà tí ara bá tu ìgbẹ́ láà ri eṣú.
Bẹẹ, awọn lo yẹ ki wọn ni imọ kikun lori iṣẹ awọn oṣiṣẹ eleto ilera bii dokita ati nọọsi.
Nibẹ lo ti gbe awo orin kan to pe akọle rẹ ni 'Laycon'.
Wọ́n sì pàgọ́ wọn sí ẹ̀bá odò Jọdani láti Beti Jeṣimotu títí dé Abeli Ṣitimu ní pẹ̀tẹ́lẹ̀ Moabu.
Costa so pe, “O farahan gbangba-gbangba pe, bi Messi ko ba kopa ninu iko Argentina, o maa n niira fun iko ohun lati sise po, leyi ti o wa lara bi a se fagbahan won pelu ami-ayo ti o to yii.
Olaniyi Mikail Afonja Awọn eniyan mọọ si ''Sanyẹri''.
Ni nkan bii alẹ ana ni olorin naa, August Alsina ba bọ soju opo Twitter lati ta a pada si Jada ati ọkọ rẹ pe: Mi o mọ bi ẹ o ṣe le kojumọ owo to pee yin."
Àwọn ọ̀tá bẹ̀rẹ̀ sí yọ̀ ọ́,wọ́n sì ń fi ṣẹ̀sín nítorí ìṣubú rẹ̀.
Inú wọn a máa dùn sí irọ́.
0 88380 Orilẹede Oman 1452 30.
Bakan naa ni oṣiṣẹ ajọ EFCC naa tun ni ẹlomiran to jẹ ẹlẹri, Adamu Modibbo to mọ nipa ọrọ ti Maina kojọ lọna eru naa ti jade laye nitori arun Coronavirus.
Wo àwọn míniístà mẹ́fà tí ẹnu ń kùn jùlọ Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí kan sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
PDP tá ko ìgbésẹ̀ Gómìnà Kwara lórí àwọn alága ìjọba ìbílẹ̀ Ọdún Odùduwa lórílẹ̀èdè Austria Amọ, iroyin naa fikun wi pe, awọn ko mọ boya wọn san owo itusilẹ.
Ó dá wọn lóhùn pé, “Ẹ̀yin náà kò ní òye?
Seun kawe nipa ṣiṣẹ alamojuto ni Swiss E- Learning Institute ni Switzerland lọdun 2013.
Nígbà tí Bela kú, Jobabu, ọmọ Sera, ará Bosara, jọba tẹ̀lé e.
Mo fún ọba lésì pé, “Bí ó bá tẹ́ kabiyesi lọ́rùn bẹ́ẹ̀, kí kabiyesi kọ̀wé lé mi lọ́wọ́ kí n lọ fún àwọn gomina ìgbèríko òdìkejì odò, kí wọ́n lè jẹ́ kí n rékọjá lọ sí Juda, 
Ìjalèlókun jẹ ́ ìwa olèjíjà tàbí ìwà ọ ̀ daràn ní okun .
Ṣugbọn dokita Bala ni irọ ni ati pe awọn dokita n ṣiṣẹ takun taklun bayii lati rii pe wọn n gbe igbese lati dẹkun itankalẹ arun coronavirus ni ipinlẹ Kano.
mi , asofin Bala ku ori-ire aseyọri eto idibo yii.
Èyí jẹyọ lẹ́yìn ti àjọ tó n rí sí ìbáraẹnisọ̀rọ̀ (NCC) fún gbogbo ẹni tó ń lo ẹ̀rọ iléwọ́ láti lọ gba NIN wọ́n tàbi kí wọ́n pàdànú síìmù wọ́n.
’ Ó ní, ‘Ẹgbẹrun òṣùnwọ̀n àgbàdo.
Ọgọfa ọjọ si ni ijọba ni lati gbe igbesẹ ko ile aṣofin le buwọlu.
Ó kébòòsí pé, “Kí ni ó pa èmi ati ìwọ pọ̀, Jesu, ọmọ Ọlọrun Ọ̀gá Ògo?
Esi ifesewonse iko agbaboolu Real madrid pelu Juventus ti o fi mo Bayern Munich ati Sevilla ti o waye lojoRU(Wednesday), ti to fun iko agbaboolu Real madrid ati Bayern Munich lati pegede sipele keji si asekagba idije Uefa Champions League.
"Ọdun 2012 lo da ẹgbẹ YYF silẹ, lati le ""tun ero awọn ọdọ Yoruba ṣe, ati lati le ja fun iṣejọba ẹlẹkun-jẹkun""."
Ijọba awọn oyinbo aláwọ̀ funfun lo rọ ọ loye, nitori pe o n fi ẹtọ awọn ijoye rẹ meji pataki (Lisa ati Losi ilu Rẹmọ) lara ajẹmọnu ti ijọba n fun wọn dùn wọn.
Gmina ni àrun náà ko dá ojú ẹnikẹni mọ, yala, olwo tabi talaka, ẹni to n gbe ilé ijọba tabi ẹni to n gba Mushin, sùgbọ́n títẹle ìlàna ijọba yóò ṣe ànfani to pọ fun gbogbo èniyan.
Atundi eto idibo si ipo Aare yoo waye laarin awon oludije meji ti won gbegba oroke laarin ose meji ti esi idibo ba jade, ayafi ti eni to ba jawe olubori ba ni iko marundinlogota 55% ninu ida ogorun, ni atundi idibo ko ni waye.
Farao sọ fún gbogbo wọn pé, “Ẹ tọ Josẹfu lọ, ohunkohun tí ó bá wí fun yín ni kí ẹ ṣe.
Burundi gba ida meje le ni mein, Kenya gba ida mejo le ni merin, Ethiopia gba ida meta le ni marun un nigba ti Uganda gba ida marun un le ni merin.
Àti àwọn ìbéèrè míràn Ailera ti Peter ni mu ki o rọrun fun-un lati mọ bi o ṣe le gbe igbe aye to ni itumọ lasiko ajakalẹ aarun Covid-19.
"'"" Alhaji Usman rọ gbogbo òbi ti o ni irú ọmọ bẹ́ẹ̀ láti wádìí ǹkan ti wọ́n fẹ́ràn nítori ó ṣe pàtàkì láti fi ọjọ iwáju wọ́n léwọn lọ́wọ́ Kò sẹ́ni tó wù láti jẹ́ àkàndá, ẹ má dẹ́yẹ sí wọn mọ́- Fola 'Mo ti gbà pé lóòtọ́ ni ọmọ mi ní àárùn ọpọlọ ‘Ọ̀rẹ́ mi ní kí n fi ‘acid’ sí oúnjẹ ọmọ mi’ Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí 2 sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn."
Ṣugbọn Abramu dáhùn pé, “OLUWA Ọlọrun, kí ni o óo fún mi, n kò tíì bímọ títí di ìsinsìnyìí!
Kì í ṣe nǹkan ti òde ara ni eniyan fi ń jẹ́ Juu, bẹ́ẹ̀ ni ìkọlà kì í ṣe kí á fabẹ gé ara.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ọba Saudi fìwé pe Ààrẹ Buhari fún ìjọ́sìn Umrah Idí tí àwọn dókítà ọpọlọ kò fi faramọ́ lílo igbó fún ìtọ́jú àìsàn Ẹwẹ, agbẹnusọ fun Gomina tẹlẹ ri Lere Olayinka ti fi ọrọ ti rẹ naa sita loju opo Facebook pe Fayose iwa ika gba ni bi ijọba Fayemi ti ṣe yọ eeyan ẹgbẹrun meji ti ijọba Fayose gba siṣẹ.
Nígbà tí mo bá dé, n óo kọ ìwé lé àwọn tí ẹ bá yàn lọ́wọ́, n óo rán wọn láti mú ọrẹ yín lọ sí Jerusalẹmu.
ó jẹ́ ọ̀kan nínú àwọn wọn-ọnnì ti wọn ti ni ìwà burúkú nì pé kí wọ́n máa fa ojú ro nígbà gbogbo, kò sí ẹni tí ó ń mọ ìgbà tí inú wọ́n bá dùn yàtọ̀ si ìgbà tí kò dùn.
Wọ́n bá rán Peteru ati Johanu sí wọn.
Ìwádìí náà ran ni lọ́wọ́ lati mọ̀ àṣepọ̀ tó wà láàrin ìròyìn òfégè àti òṣèlu lórí ayélujára.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù EFCC: Á sọ iye èèyàn ta rán lẹ́wọ̀n di ìlọ́po méjì ní 2019 4 Sẹ́rẹ́ 2019 Oríṣun àwòrán, @officialEFCC Adele alaga fun ajọ EFCC, Ibrahim Magu ti n leri, leka, to si n fi ọwọ sọya pe, mariwo lasan lawọn ọmọ Naijiria ri, nidi iye eeyan ti ajọ EFCC ran lọ sẹwọn lọdun 2018.
Ọrọ Revolution Now ti fẹ ba ibo mii yọ fun ọmọyẹle Soworẹ bayii gẹgẹ bi ijọba apapọ ṣe di ẹsun meje ru le e lori.
Àwọn oriṣa láàrin àwọn òkúta ọ̀bọ̀rọ́, ninu àfonífojì,àwọn ni ẹ̀ ń sìn,àwọn ni ò ń da ẹbọ ohun mímu lé lórí,àwọn ni ò ń fi nǹkan jíjẹ rúbọ sí.
Ẹ̀ ń pe ara yín ní ará ìlú mímọ́,ẹ fẹ̀yìn ti Ọlọrun Israẹli,tí orúkọ rẹ̀ ń jẹ́ OLUWA àwọn ọmọ ogun.
Iléẹjọ́ kún fọ́fọ́ fún èrò nítẹ̀síwájú ẹ̀ṣùn ìjọ́mọgbé tí wọn fi kan aṣaájú ìjọ Sotitobire Ileẹjọ giga ilu Akurẹ tun kun fọfọ lọjọ Aje nitẹsiwaju ẹjọ Asaaju ijọ Sotitobirẹ, Alfa Babatunde, tijọba ipinlẹ Ondo fi ẹsun ajọmọgbe kan.
OLUWA àwọn ọmọ ogun ní, “Wò ó!
O ní láti tọ́jú arà rẹ, kí o má jẹ̌ kí eṣù tán ọ̀ jẹ kí o lọ bá ọkùnrin ṣe eré ìṣekúṣe.
Amọ, aarẹ ile asofin naa nigba to n fesi ni ibanilorukọjẹ ni ohun ti ajọ EFCC n se, ati wi pe ohun ko ṣẹ ẹsẹ kankan, wọn kan n ditẹ mọ oun ni.
Gege bi akosile to fi sita se so pe Hajia Adama Abdulkrim to je oga agba ile iwe naa ati Asofin Mohammed Lami to je komisona fun eto eko nipinle Yobe ni akekoo mefa leni ogorun un mesan an lo wa nile iwe naa ni ojo ti oro yii sele ni eyi ti won ko tii ri aadofa titi di asiko yii.
Ẹni to bori: Uganda Ìpele to kangun si aṣakagba Namibia vs Burundi.
kaakiri orilẹ-ede Naijiria loruko awọn aṣofin akẹgbẹ rẹ to ku ninu Ile Igbimọ
Coronavirus ti di ara wa, kò le è kúrò mọ láéláé - WHO Ǹjẹ́ ènìyàn tó ní àrùn coronavirus rí lè níi lẹ́ẹ̀kejì?
Lẹ́yìn náà, wọ́n tọ́jú tiwọn ati ti àwọn alufaa, àwọn ọmọ Aaroni.
L'ọdún 2016 ni India fòfin de kí iléeṣẹ́ oríṣíi máa po òògùn ikọ́ olómi tó ní èròjà codeine síta látàri pe àwón kan ti ń ṣìí lò.
Láì lọ́wọ́ ẹ̀yin aráàlú nínú, yóò nira fún Boko Haram láti ṣọṣẹ́ - Buhari sọ fáwọn èèyàn Borno Oríṣun àwòrán, @SegunAde88 Se ni awọn ilu Maiduguri tii se olu ilu ipinlẹ Borno, tu ya ya jade lọjọru lati pade aarẹ ilẹ wa, Muhammadu Buhari to se abẹwo sipinlẹ naa.
Èèyàn 20 ni coronavirus pa l'Ọ́jọ́bọ nìkan Ọmọ Yorùbá mẹ́wàá tó jẹ́ àmúlùúdùn ní Amẹ́ríkà àti Yúróòpù Wo àwọn ọ̀nà míràn tí o leè gbà lẹ́yìn tí wọ́n bá ti afára Third Mainland Alakoso ileeṣẹ ijọba apapọ to n ri ọrọ iṣẹ agbegbe, Olukayode Popoola ti sọ pe ijọba ko ni boju wẹyin tabi sun ọjọ siwaju lori atunṣe afara Third Mainland to wa ni ilu Eko.
"Oríṣun àwòrán, Facebook/Seyi Makinde Ijoko Olubadan naa ati awọn ijoye rẹ to wu oju ri, to si jẹ pe oju gbogbo n wo wọn nibi ipade apero ọhun, lo mu ki gomina Makinde ni ""inu mi dun lati ri awọn ijoye ti wọn kọwọ rin pẹlu Olubadan wa sibi."
Mo mọ nǹkan tí ẹ ṣe fún mi, èrè yín sì ń bẹ ní ọwọ́ Ẹlẹ́dàá ohun gbogbo, àǹfààní yín ń bọ̀ láti ọ̀run alákeji.
Ile ijọsin mẹta ni Negombo, Batticaloa ati agbegbe Kochchikade ni awọn ikọlu naa ti waye nigba ti isin Ajinde n lọ lọwọ.
Olùkọ́ àgbà tó fipá bá ọmọ ọdún 13 lò yóò fojú ba ilé ẹjọ́ ni Benue Odunlade fijó bẹ́ẹ, Lizzy padà sọ́dún 2012, Toyin Abraham tọ̀ lẹ́ẹ̀mẹwàá Kìí ṣé òjò àrọ̀rọ̀ọ̀dá nìkan, ọkọ̀ aképo tó dànù náà fà súnkẹrẹ-fàkẹrẹ l'Eko Ajọ Amnesty International ní kò dín ní 119 ọmọ Nàìjíríà ti wọ́n ti gba ìdájọ́ ikú ní Malaysia Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fọ́nrán ohùn, Inú mi dùn pé ọmọ obinrin nìkan ni mo bi Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Ṣugbọn ẹ̀ṣẹ̀ àwọn ẹlòmíràn a máa pẹ́ kí ó tó hàn sóde.
Baalẹ Ile-Ogbo di ọba, Olu ti Ile-Ogbo lọdun 1995, Olubu ti Ilobu nigba naa gba ade lọdun 1986.
Bi wọn ṣe n tẹ ẹtọ awọn eniyan loju mọlẹ yii lagbara.
Wọ́n ní kí gbogbo ilé kúnlẹ̀ kí á gbàdúrà.
Gbogbo wúrà tí wọ́n lò fún kíkọ́ àgọ́ náà jẹ́ ìwọ̀n talẹnti mọkandinlọgbọn ati ẹẹdẹgbẹrin ìwọ̀n ṣekeli ó lé ọgbọ̀n (730), ìwọ̀n tí wọn ń lò ninu àgọ́ ni wọ́n fi wọ̀n ọ́n.
Sugbọn lara awọn osere to gbe ẹka amuludun naa de ipo nla to wa loni, ni awọn adẹrinpoṣonu ti wọn wa lasiko ipilẹ sinima Yoruba.
Amitabh Bachchan bọ́ lọ́wọ́ COVID-19 'Ẹ̀yin obìnrin ẹ wá kẹ́kọ̀ọ́ ìbálòpọ̀ láti tẹ ọkọ yín lọ́rùn' Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Irú ẹ̀dá wo ni Bukọla Saraki jẹ́ ?
Jesu wá sọ fún un pé, “Má sọ fún ẹnikẹ́ni.
O mọ̀ pé níbi tí n kò fi nǹkan sí ni mo máa ń wá a sí, ati pé níbi tí n kò fúnrúgbìn sí ni mo ti máa ń kórè.
Ní ìbẹ̀rẹ̀, nígbà tí Ọlọrun dá ọ̀run ati ayé, 
7086 au , perihelon re je 2.
O Fagunwa kú, dúkìá rẹ̀ sì ń fọhùn síbẹ̀, ilé rẹ̀ rèé Ààrẹ Trump kọ̀wé lọ gbélé rẹ fún Agbẹjọ́rọ̀ Àgbà Kí ló fà á tí àwọn ọmọ Obasanjo ń ta kò ó ní gbangba?
O tako oro yii lojo Aiku ni orile ede Poland lasiko to n  ba awon omo orile ede Naijiria to wa ni orile ede Poland soro.
Bí wọn bá kọ̀ tí wọn kò gba ife náà lọ́wọ́ rẹ kí wọ́n sì mu ún, wí fún wọn pé, OLUWA àwọn ọmọ ogun ní wọ́n gbọdọ̀ mu ún ni!
, won ko ni gba oruko oludije kankan lati iko egbe APC mejeeji silẹ, ni eyi to
Solomoni ọba yipada, ó kọjú sí àwọn eniyan níbi tí wọ́n dúró sí, ó sì súre fún wọn.
"Ajimọbi ja fafa ninu iwe lati ewe, o jẹ ẹni to nimọ toto, o gbafẹ, to si ni iwa asaaju rere lati igba ta ti wa ni kekere, osu mẹwaa si lo fi ju mi lọ.
soro naa di mimo lasiko to n se ikede imurasile eto idibo gbogbogb-o ti yoo
Ọba Asiria bá pada sí ilẹ̀ rẹ̀.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ta ló wà nidi wàhálà ílé aṣòfin Nàíjíríà?
1 1728878 Orilẹede France 55155 84.
Nítorí a kò ní ìlú tí yóo wà títí níhìn-ín, ṣugbọn à ń retí èyí tí ó ń bọ̀!
Ọmọwe Femi Damilola Oke-Osanyitolu to jẹ adari ajọ naa lo fi soju opo wọn.
Bí wọ́n ti rí i tí ó yọ lókèèrè, kí ó tilẹ̀ tó súnmọ́ ọ̀dọ̀ wọn, wọ́n dìtẹ̀ mọ́ ọn láti pa á.
Èèyàn 162 ló kó àrùn Coronavirus ní Nàìjíríà lọ́jọ́ Àbámẹ́tà Ènìyàn 162 lo tun ṣẹṣẹ lugbadi aarun Covid-19 ni Naijiria.
Oríṣun àwòrán, @jidesanwoolu Ọkọ nla marun la padanu lanaa, ti wọn si tun kọlu ọkọ ipe pajawiri wa, wọn jo ileesẹ LASEMA, tawọn osisẹ ibẹ si sa asala fun ẹmi wọn, eyi ti ko jẹ ki wọn le lọ pa ina to jo awọn idudo lanaa.
Bákan náà ni àwọn olórí alufaa ati àwọn amòfin ati àwọn àgbà, àwọn náà ń fi í ṣe ẹlẹ́yà.
Kamala Harris lo leke ju lati jẹ igbakeji Joe Biden ọkan lara awọn oludije ipo aarẹ Amẹrika to wa lẹgbẹ oṣelu Democrat latinu oṣu kẹta to ti kede pe obinrin ni oun yoo yan gẹgẹ bi igbakeji oun.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ọmọ̀bìnrin tí wọ̀n bí láì ní ẹsẹ̀: Ati kekere ni ìyá mí ti kọ̀mí sílẹ̀ Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Ó bá bi wọ́n pé, “Kí ni ẹ̀ ń bá ara yín sọ bí ẹ ti ń rìn bọ̀?
Deji Adenuga funra rẹ, Iya Titi, Jumọkẹ, ẹgbọn Titi, Dokita to n tọju Titi, Oga ọlọpaa ti ẹjọ naa wa lọdọ rẹ, Oba ilu Igbodigo, Oba ilu Deji to ti sẹ̀ wá, àwọn ara ilu ati alafojuri ti ọrọ naa ṣoju wọn atawọn mii ni a ba sọrọ tan ki a le fidi okodoro ọrọ yii mulẹ.
Igba akọkọ niyi ti Ronaldo yoo gba goolu mẹta wọle ni ifẹsẹwọnsẹ kan naa lati igba to ti dara pọ mọ Juventus lọdun 2018.
Ṣùgbọ́n nígbà tí ódi ẹ̀ẹ̀kẹta wàyí tí bàbá mi tún wo ẹ̀hìn obìnrinyìí tún wò ó ti òun rẹ́rìn-ín ti obìnrin náà rẹ́rìn-ín, tí eyín arẹwà yí sì funfun bí ẹ̀gbẹ́ ògiri tí ènìyàn kùnní ẹfun, Olówó-ayé yí ojú padà, ọkùnrin kọ ìpàkọ́ si ọ̀nà igbó Olódùmarè, bàbá mi tọ obìnrin lọ - kí Olódùmarè gba àwọn ọmọ aráyé lọ́wọ́ obìnrin ìjàngbọ̀n, ti wọ́n ń wé gèlè wọn sí ibi iwájú gẹngẹ.
Ìjọba Gomina Raman Razak padà wólé arúgbó ní Ilọrin!
Ọ̀ọ̀nì wọ iya ija pẹlu aja!
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Àwọn ọ̀dọ́ ẹ̀yà Hausa kan àtàwọn ọmọ ẹgbẹ́ òkùnkùn 'Awawa boys' da ìgboro Eko rú Ilana ti Awawa Boys n gba ṣoro Wọn maa n pọ babi lasiko ti wọn ba fẹ ẹ ṣisẹ.
Ipade to waye laaarin ijọba apapọ ati awọn adari ẹgbẹ awọn oluko fasiti ASUU ti fori sanpọn.
Nítorí òru ni àwọn tí ń sùn ń sùn, òru sì ni àwọn tí ó ń mutí ń mutí.
a ní ilé ẹ ̀ kọ ́ fásitì , tí ó sì kọ ́ kọ ́ jẹ ́ olùdásílẹ ̀ ilé ìwé gíga sẹ ́ kọ ́ ndìrì àkọ ́ kọ ́ tí a mọ ̀ sí ní ìlú Ìbàdàn grammar school ni ìlú Ìbàdàn .
“Bí wọ́n bá ta arakunrin yín lẹ́rú fun yín, kì báà jẹ́ ọkunrin tabi obinrin, tí ó bá ti jẹ́ Heberu, ọdún mẹfa ni yóo fi sìn yín.
Nigba miran, wọn le paarọ ọmọbinrin si ọkunrin tabi ọkunrin si obinrin, ti iya ti wọn paarọ ọmọ rẹ ko si ni mọ pe ọmọ ọlọmọ ni wọn gbe fun oun.
Oluwo ti Ilu Iwo Oríṣun àwòrán, Oluwo of Iwo, amazon Stories Oba Abdulrasheed Adewale Akanbi gba pa aṣẹ gẹgẹ bi Alayeluwa ti ilu Iwo ni ọjọ kẹrindinlogun oṣu kini ọdun 2016.
Facebook gbégilé àwọn ojú òpó ayédèrú Atunse Facebook fa idinku alamulo rẹ Ọ̀rọ̀ ń bọ́ lóríi fídíò Codeine Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Wo ọna ti o le gba lati fi daabo bo ara rẹ lori Facebook.
Lọwọlọwọ,iye ti ijọba n na lapapọ lori ilera jẹ $81, 640,000,00 amọ iye awọn ara ilu to n jẹ anfaani eto ilera ọfẹ ko to ida maarun ninu ida ọgọrun.
Ó fà wọ́n sókè, ó sì gbé wọn ní gbogbo ìgbà àtijọ́.
Èyí mú kí inú gbogbo àwọn onigbagbọ tí wọ́n gbọ́ dùn pupọ.
Bakanna, aarẹ ati akọwe agba ẹgbẹ awọn olorin Fuji naa peju pesẹ sibi ipade ati pẹtu sija ọhun.
Solomoni fi ọ̀kẹ́ kan ati ẹgbaa (22,000) mààlúù, ati ọ̀kẹ́ mẹfa (120,000) aguntan rú ẹbọ alaafia sí OLUWA.
Wọ́n gbé orí rẹ̀ wá ninu àwo pẹrẹsẹ, wọ́n gbé e fún ọdọmọbinrin náà.
Iroyin to n tẹ wa lọwọ bayii fi ye ni pe ọrọ naa ko ti ni ojutu, ti awọn alaga ibilẹ naa si ti pawọpọ kọ lẹta kan si aarẹ Muhammadu Buhari pe ko gba awọn silẹ lọwọ gomina Seyi Makinde.
Bakan naa ni Valerie Boglo to je amunidara tara oto lasiko yii naa so fun awon akoroyin pe ijoba ti n fife han sise awon amunidara bayii pe: “Ijoba ti n pese iranlowo niwon ba fun awon aranse igbalode nipa ipese owo iranwo ti mo gbadura pe ko tubo tesiwaju fun idagbasoke ise amunidara lapapo”.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Chancellor orílẹ̀èdè Germany, Angela Merkel ti gúnlẹ̀ sí Naijiria fún ìbásepọ̀ tó dán mọ́rán láàárín Ilẹ̀ Germany àti Naijiria.
Ọ̀pọ̀ èèyàn ló ti n bèèrè lábẹ́lẹ̀ pé kíló fàá tí olólùfẹ́ méjèéjì kò tètè di tọkọtaya, lẹ́yìn tí Lizzy kọ ọ́ sórí Instagram pe ọkọ òun ti wà pẹ́lù òun fún ọdún mẹ́rìnlá.
Àwọn ìròyìn mìíràn tí ẹ lè nífẹ̀ẹ́ sí: Yẹmi Oṣinbajo di 'Ààrẹ̀ Nàìjíríà' ''Buhari, Zamfara là fẹ kí o lọ, kìí ṣé Jordan'' Òhun tí o sẹlẹ nigba ti Buhari lọ China Buhari padà dé lẹ́yìn àbẹ̀wò ìlera sí London Èrè ìpàdé Commonwealth fún Nàìjíríà.
Òpọ̀lọpọ̀ ìgbà ni ìjà ti wáyé tó já sí ikú àti òfò dúkìá.
Ṣugbọn Aṣofin Babatunde Ọlatunji ṣai m'ẹnu ba awọn ipenija ti o maa n waye lori awọn igbesẹ wọnyii paapaa gbedeke asiko ti o maa n wa fun eto naa eleyi ti kii ba iwadi iwe ẹri d'ọrẹ nitori gẹgẹ bii ọrọ rẹ,  ọpọ igba lo jẹ pe bi ẹ ba kọ iwe si awọn ileewe ti awọn eeyan wọnyii lawọn ti gba iwe ẹri, ko ni si idahun lasiko, eleyi si maa n ṣe ipenija tirẹ pẹlu."
Ẹni tí kò bá wọ'ṣọ òjò, òtútù ni olúwarẹ̀ ń fi ṣeré.
23 A kàn an mọ́ àgbélèbú, Ó kú, Ó sì tún jínde ní ọjọ́ kẹta;
tí ọkunrin mìíràn bá bá a lòpọ̀, ṣugbọn tí ọkọ rẹ̀ kò ká wọn mọ́; ṣugbọn tí ó di ẹni ìbàjẹ́ bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé kò sí ẹlẹ́rìí nítorí pé ẹnìkankan kò rí wọn; 
Ibon yiyan fun un yi ko mu ki o yi okan rẹ pada nipa ọjọ iwaju rẹ.
Ilé ẹjọ́ sún ẹjọ́ Sẹ́nétọ̀ Abbo síwájú pẹ̀lú béèlì mílíọ̀nù márùn-ún Ilé iṣẹ́ ọlọ́pàá ti bẹ̀rẹ̀ ìwádìí sí ọ̀rọ̀ Sẹ́nétọ̀ Abbo Ìjọba ló ń ṣe kóríyá fún àlàfo ńlá láàrin ọlọ́rọ̀ àti mẹ̀kúnnù - Oxfam Dúkìá àti ọkọ̀ jóná, ọlọ́pàá mẹ́sàn-án fara gbọta lásìkò ìwọ́de Shiite Bayii, ti ẹjọ naa ti wa nile ẹjọ ti wọn si ti gba oniduro Senetọ Elisha ti ọrọ kan ni aarẹ ile igbimọ asọfin yan igibmọ kan lati ṣe iwadii ọrọ naa.
Bẹ́ẹ̀ ni ọkùnrin yìí pa ojú dé, tí ó kí ayépé ó dìgbòóṣe.
Party of Nigeria, UPN  n ba awon akoroyin
"O mọ Ọlọrun ju mi lọ"" Pasitọ Victor Camibon naa to padanu ọmọ rẹ ni oun ko ni gbagbe bi ""o ti ṣe maa n lu ilu ninu ijọ ti a si maa ba wa ṣi ferese ile ijọsin wa"" Oríṣun àwòrán, Evelyne Metuge Ajọ ajafeto-omoniyan, Human Rights ti kesi ijọba Cameroon la ti ṣe iwadii tó tọ ki wọn si fi iya jẹ awọn to lọwọ ninu ipaniyan to waye ni Kumba."
O so pe, “nigba ti a ba n soro omi, o je ipenija ni gbogbo agbaye, amo awon awujo ni iru omi ti won n fe, fun idi eyi, tori pe a mo riri omi ninu igbesi aye omo eda, ni paapaa awon omode, ti won je ogo ojo ola wa, bi a ko ba lo daadaa, ti a ko ba se amulo re bi o ti to ati bi o se ye, ki o si se ojuse re nigba ti o ba niloo re, oluwa re le padanu re lai tojo”O wa n ro awon ti won nise-akanse olomi ni awon ilu, lati fi sanfaani fun awon ara-iluAyajo ojo omi lagbaye maa n waye lodoodun, ni ojo kejilelogun osu keta, pelu erongba lati je ki awon eniyan mo pataki omi ti o mo gaara.
 awon onibugbe ibe ti po to 38 legbegberun .
ninu eto idibo aare odun 2019.
Ọ̀nà láti sọ fásitì Lautech di ti Ọyọ nìkan ni Makinde ń sán - Ìjọba Ọṣun Ìkọlù sáwọn àjèjì kò tíì tán ní South Africa, ètò ń lọ láti kó ọmọ Nàíjíríà wálé Omíyalé àgbàrà ti ya ṣọ́ọ̀bù ní Niger Láìpẹ́, ará ìlú rẹ ni ọlọ́pàá tí yóò máa ṣọ́ ìlú rẹ Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí kan sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
Ìgbà tí ọba rii pé àti pada jẹ́ ìṣòro, ó gba kọ́bọ̀ kọọkan lórí ìyàwó kọọkan, gbogbo rẹ̀ jẹ́ tọ́rọ́-bẹ́ẹ̀ ló sì wá jẹ́ pé tẹ́rẹ́ lowó obìnrin mẹta ni ìlú àwọn Èdìadàrẹ́.
ti o gbomi ewuro  lọjọ Aiku yii  si ẹni ti won jọ n dupo fun ipo gomina, Ahmed
Bí Ọlọrun kò bá ní ẹ̀tọ́ láti bínú, báwo ni yóo ṣe wá ṣe ìdájọ́ aráyé?
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Nigeria Independence Day: Sé ẹ mọ̀ pé ọdún 1956 ló yẹ́ ká ti dòmìnira ṣùgbọ́n.
N'isẹ ní àwọn ajafeto n dunu níwájú ilé ẹjọ ti awọn kan sì bẹrẹ sí ní sunkún ìdùnnú lẹyìn ìkéde ìdájọ náà Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Ẹ̀yin ará Juda, ẹ fá irun orí yín láti ṣọ̀fọ̀ nítorí àwọn ọmọ yín tí ẹ fẹ́ràn; kí orí yín pá bí orí igún, nítorí a óo kó àwọn ọmọ yín ní ìgbèkùn kúrò lọ́dọ̀ yín.
Ẹgbẹ́ ọ̀mùtí ni wọ́n, wọ́n fi ara wọn fún ìwà àgbèrè, ìtìjú yá wọn lára ju ògo lọ.
Amotekun: Toogun ní àwọn sá fún ariwo ni wọ́n ṣe ń ṣàyẹ̀wò fún ọ̀dọ́ 47,000 tó bèèrè iṣẹ́
Pool drown: Ìbejì ọmọ ọdún méjì Mínísítà fún ọ̀rọ̀ omi bá odò lọ
Kò si ẹni ti kò ni nkankan.
"Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Bí ẹ ṣe mọ̀wé tó, ẹ wá dánrawò níbí pẹ̀lú ""Àpólà Ọ̀rọ̀ Orúkọ - Noun Phrase 'Mo lè fọwọ̀ sọ̀yà fún yín pé Sunday Shodipe ti wà láhàmọ́ wa - Alukoro Ọlọ́pàá Oyo Ọkùnrin tó dàgbà jù lágbàyé jáde láyé lẹ́ni ọdún 116 Nigeria Police Recruitment 2020: Àwọn ohun tí ẹ nílò fún àyẹ̀wò ìgbanisíṣẹ́ ọlọ́pàá tí yóò bẹ̀rẹ̀ ní Mon, Aug 24 'Ẹ̀pa ò bóró mọ́!"
"Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: ""Apena fẹ́gbẹ́ Oṣugbo, Opa, Akala àtẹ̀yin awo, ẹ wa ọ̀pá àṣẹ Ọ́ba Akiolu jáde"" Ẹ wo ọ̀rọ̀ àwọn Wòlíì tó ti sọ àsọtẹ́lẹ̀ saájú nípa làásìgbò EndSARS Májèlé olóró lẹ jí l‘Ekiti dípò èròjà oúnjẹ Covid-19 - Ariwo sọ lórí ayélujára Ẹ sọ́ra fún ìwà olè àti jàgídíjàgan nílẹ̀ Yorùbá-Sunday Igboho ₦147m la rí kójọ fún ìwọ́de, a kò fẹ́ owó mọ́, ìwọ́de ti parí - Feminist Coalition Sanwo-Olu kéde ìlànà ìséde tuntun l'Eko Ìjọba ìpínlẹ̀ Kwara sọ̀rọ̀ lórí bí àwọn kan se lọ pín ""CaCovid 19 Palliative"" ní Ilorin pé."
Ati kekere ni arabinrin naa ti n kọrin.
Nígbà náà ni mo bi í ọmọ ẹni tí í ṣe.
Ohun ti o fa ina naa ni ẹrọ amuletutu to bajẹ, ti ina si sọ nibẹ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Florida: Ọ̀ọ̀nì àléègbà dé ba Mary lálejò lọ́gànjọ́ òru Awọn bii Abdul Karim Niyizigimana to jẹ adiẹyin ile mu naa ni awọn ti wa ni sẹpẹ lati gbogo fun Burundi loni.
Mínístà fún ètò ìrìnà òfurufú Naijiria, ọgbẹni Hadi Sirika ti sáájú fí ọrọ síta láti kí àwọn èèyàn Naijirià ku ojú lọnà àjínde ọkọ̀ òfurufú orílè-èdè Nàìjíríà.
Ẹwẹ, awọn alatako sọ pe bi o ṣe n fi panpẹ ọba mu gbogbo awọn eekan ilu, o n dọgbọn san gbogbo igbo didi ti ko jẹ ko de ori oye lọjọ iwaju ni.
Ojuelegba Bridge, Ijọba ibilẹ Surulere / Lagos Mainland 8.
Itan aye Ọba Seriki Ifaremilekun Abass Williams Fagbemi: Abule Joga-Orile lagbegbe ilu Ilaro nipinlẹ Ogun bayii ni wọn ti bi Ifaremilekun, ti orukọ baba rẹ si n jẹ Fagbemi.
Agbára ati ọlá ni ó fi ń bora bí aṣọ,ó sì ní ìrètí ayọ̀ nípa ọjọ́ iwájú.
Aare orile ede Kenya, Uhuru Kenyatta so pe ajosepo to wa laarin orile ede United Kingdom ati Kenya yoo tun fese mule sii leyin iwe adehun ti won tọwọbọ yii.
Ní ìgbà èwe àwọn ọdọmọkunrin wa,jẹ́ kí wọ́n dàbí igi tí a gbìn tí ó dàgbà,kí àwọn ọdọmọbinrin wa dàbí òpó igun ilé,tí a ṣiṣẹ́ ọnà sí bíi ti ààfin ọba.
Èèyàn 389 ló tún lùgbàdì àrùn Coronavirus ní ọjọ́ Àbámẹ́ta ní Naijiria Ẹ sọ ìlò afẹ́fẹ́ aláta àti ìbọn ònírọ́bà di òfin fáwọn obìnrin - Oluwo Òṣèré tíátà míì ń ṣàìsàn láti ọdún kẹta, ó bẹ̀bẹ̀ f'ówó Nàìjíríà kò ní olórí, ẹ pín sí ẹlẹ́kùnjẹkùn - Soyinka Oríṣun àwòrán, @RotimiAkeredolu Wọn ni ibi ti obinrin naa ti n ta aṣọ aloku ni ọwọ ti tẹ ẹ.
Morgan Bẹẹ ni, nitori ọmọ ilẹ Amẹrika ṣi ni mama rẹ Meghan, fun idi eyi, ọmọ naa laṣẹ lati jẹ ọmọbibi orilẹede Amẹrika.
Èyí àbúrò náà bí ọmọkunrin kan, ó sọ ọ́ ní Bẹnami, òun ni baba ńlá àwọn ẹ̀yà Amoni títí di òní olónìí.
so pe“Emi naa maa darapọ mọ, ọkẹ aimọye omo orile ede yii lati  maa wo o yin bi ẹ se n se lori papa .
 “Igbese ti igbimo ipinle gbe lori
Aago mefa aabo idaji owurọ yii, ni okan lara awon osise  ajo eleto idibo ,arabinrin  Alawode Abidemi ti de si ile-idibo, polling unit 1, ward 3,ijoba ibilẹ  Ifon, Oloru.
Kí àwọn yòókù wá tẹ̀lé wọn, kí wọ́n dì mọ́ pákó tabi kí wọ́n dì mọ́ ara ọkọ̀ tí ó ti fọ́.
Iku rẹ ti ṣe okunfa ifẹhonuhan kaakiri agbaye papaajulọ lorilẹede Amẹrika ati ilẹ Gẹẹsi.
Ẹ óo kọ̀ wọ́n sílẹ̀ bí nǹkan aláìmọ́.
Ṣugbọn o fidi rẹ mulẹ pe awọn ọlọpaa yoo duro de ayẹwo awọn dokita ki awọn to le sọ pato ohun to ṣẹlẹ.
fọ́n owó ká fáwọn èrò lẹ́yìn tó pariwo 'Merry Christmas' Bakan naa ni Oludije sipo aarẹ lẹgbẹ oṣelu PDP, Atiku Abubakar naa parọwa ifẹ fun gbogbo Kristiẹni pe ifẹ lakoja ofin Atiku gbadura ọjọ iwaju rere pẹlu ireti fun awọn ọmọ Naijiria.
Kí ni o mọ̀, tí àwa náà kò mọ̀?
Ọ́ ní yíya àwọnran pẹ̀lú ìlẹ̀kẹ̀ wẹ́wẹ́ jẹ ohun to gbà sùúrù gídi síbẹ̀ ó yàn láàyò láti yàtọ láàrin akẹgbẹ́ rẹ̀.
Agbabọọlu tẹlẹ ri Weah to jẹ alawọdudu akọkọ ti yoo gba ami ẹyẹ agbabọọlu to pegede julọ lagbaye wa lori papa fun iṣẹju mọkandinlọgọrin ki wọn to paarọ rẹ.
"Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ipenija ojú kò di Ademola lọ́wọ́ láti kẹkọọ gboye ""Ẹwẹ, ofin naa fi mulẹ pe gbogbo ileeṣẹ ijọba gbọdọ fi aaye ida maarun silẹ fun awọn akanda ẹda ninu eto igbanisiṣẹ wọn."
Nigba to n ba ileesẹ BBC sọrọ, Ọgbẹni Anthony Fasọla ni oun maa n ra awọn ọti yi lati fi wo jẹdijẹdi.
Nígbà tí Aaroni rí i bẹ́ẹ̀, ó tẹ́ pẹpẹ kan siwaju ère náà, ó sì kéde pé, “Ọ̀la yóo jẹ́ ọjọ́ àjọ fún OLUWA.
Oba Adetunji wa salaye pe, oun gege bii Olubadan lagbara
Omoyele Sowore tí dé ilé ẹjọ́ ní Abuja!
Láti inú oyún ni àwọn eniyan burúkú ti ṣìnà,láti ọjọ́ tí a ti bí wọn ni wọ́n tí ń ṣìṣe,tí wọn ń purọ́.
Iwadii ajọ BMJ lo fidi ọrọ yìi múlẹ.
Makinde ní ọ̀sẹ̀ tó ń bọ̀ ni ìjọba rẹ̀ yóò ṣe àgbékalẹ̀ ìgbìmọ̀ ìwádìí lórí ìfìyàjẹni ọlọ́pàá ní Ìpínlẹ̀ náà.
"Coronavirus dé ọ̀dọ̀ ará ọ̀run, ọdún Egúngún di kò ní wáyé nílùú Ibadan nítorí coronavirus Inú káàdì ìránti tí mo rí he ní mó tí rí fọ́tò ìhòhò Salawa, mó kàn fẹ́ gbà owó díẹ̀ ni- Afurasí ""Fájìn ni àbúrò mi ti wọn fipá bálopọ̀ nínú sọ́ọ́sì, tí wọ́n sì tún fọ́ lórí"" Jesu Oyingbo rèé, pásítọ̀ tó láṣẹ ìbálòpọ̀ lóri ọmọ ìjọ obìnrin Adeboye ni ọkan lara awọn nnkan nla nla ti yoo sẹlẹ tori igbele Covid-19 ni afikun yanturu ti yoo ba ọmọ bibi jakejado agbaye."
Òun ni yóo ran yín létí àwọn ohun tí mo fi ń ṣe ìwà hù ninu ìgbé-ayé titun ní ìṣọ̀kan pẹlu Kristi Jesu, gẹ́gẹ́ bí mo ti ń kọ́ gbogbo àwọn ìjọ níbi gbogbo.
Coronavirus: Ìpínlẹ̀ méjìlá tó wà ní ìṣọ̀rí àkọ́kọ́ ní yóò gba owó ìrànwọ́ lọ́sẹ̀ yìí
Ẹgbẹ oṣiṣẹ fasiti ni Naijiria ti bẹnu atẹ lu biliọnu méjídínláàdọ́fà Naira owo iranwọ ti ijọba Naijiria buwọlu fawọn ile ẹkọ giga lorileede naa.
" Ofulue ni awọn to wa ni isọri D ati E ko ni nipin ninu idiyele owo tuntun naa nitori akoko ti wọn fi n ri ina lo ko pọ to ti awọn to wa ni isọri A, B ati C.
Ibi àyẹ̀wò mẹ́ta ló wà fún Coronavirus ní Naijiria Ijọba orilẹede Naijiria ti sọ wi po ile iwosan to n ṣe ayẹwo coronavirus mẹta lo wa ni lorilẹede Naijiria.
Akẹkọ mẹẹdọgbọn pere lo lee wa ninu kilaasi kan naa ni ẹka ti awọn agba girama onipele ikeji.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó Ó sàlàyé pé òun yóò túbọ̀ sàlàyé lórí ọ̀rọ̀ náà ti ìwádìí bá parí, sùgbọ́n ó fi kun pé, àwọn Àmọ̀tẹ́kùn ń lo ìbọ̀n, kò si ni bójú mu ki wọ́n ti ṣe ọdaran léṣe tan, kí wọn wá gbé e wá si agọ́ ọlọ́pàá, kí ọ̀daràn lọ ku síbẹ̀"" Fadeyi ni ""wọn kò lé gbé ọdaran tí wọ́n ti ṣe léṣé, tí o sì ti ku ẹ̀mí kan lẹ́nu rẹ̀ wá sí àgọ́ ọlọ́pàá, ọlọ́pàá ko ni gbà a, àwọn lo mọ bí wọ́n ṣe mú wọ́n, ta ló fẹjọ́ sùn wọ́n, ọlọ́pàá kìí ṣe iṣẹ́ wọn bẹ́ẹ̀"" Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Ebila: Ọ̀pọ̀ ẹ̀mí àti dúkìá ni ẹgbẹ́ One Million Boys ṣe lọ́ṣẹ́ ni Ibadan21 Owewe 2020 Ebila of Ibadan: Ikọ̀ Operation Burst"" ní àwọn ló pa Ebila, olórí àwọn ""One million boys"" n'Ibadan14 Agẹmo 2020 Secret Cults in Nigeria: Ọwọ́ ọlọ́pàá tẹ àwọn ọmọ ẹgbẹ́ òkùnkùn tó yìnbọn28 Owewe 2020 Abiola Ebila: ''Operation Burst'' ti mú arákùnrin Eji olórí ''One Million Boys'' tó gba ipò Ebila21 Owewe 2020 Spain: Ọwọ ọlọpa tẹ gbajugbaja DJ lati Naijiria to n ṣowo nọbi23 Ẹrẹ̀nà 2018 Spartan in Ogun: Èèyàn márùn-ún ní ọlọ́pàá sọ pé afurasí náà pa léraléra26 Ògún 2020 Secret Cults in Nigeria: Iléèṣẹ́ ọlọ́pàá ní kò sí ààyè fún àjọ̀dún 7/7 ní ìpínlẹ̀ Oyo, Ogun7 Agẹmo 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 3 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 5 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!"
 “Sugbon awon kan to n pariwo pe, eto idibo yii
Ẹ gba mi gbọ, n ko ronu jinlẹ rara lori oju tawọn ara ilu yoo fi wo mi, ki n to lọ se tattoo yii.
Ninu ọrọ wọn, wọn ni arọrọda ojo ni asiko ojo yii ti fa ijamba ọkọ ati wipe ọpọlọpọ eniyan lo farapa ninu isẹlẹ omiyale naa.
Nigba to si wo firi, ti ko ri ẹnikẹni nitosi, lo ba he ọmọ naa lapa, to si gbe e bọ abẹ agbada rẹ lọ sile rẹ.
Nígbà tí ẹ bá sì ń rú ẹbọ ọpẹ́ sí OLUWA, ẹ gbọdọ̀ rú u ní ọ̀nà tí yóo fi jẹ́ ìtẹ́wọ́gbà.
Afipábánilòpọ̀ méjì tún ṣọṣẹ́ lára ọmọ ọdún 17 l'Ekiti Ayálégbé wa tó fi tipá já àbálé mi ṣe àkóbá fún ìgbé ayé mi - Foluke Daramola #JusticeforTina: Àwọn obi Tina Ezekwe ń bèrè fún ìdájọ́ òdodo pẹ̀lú omijé lójú Ọmọ pupa làwọn olólùfẹ́ wa fẹ́ wò nínú fíìmù làwọn òṣèré tíátà fi ń bóra- Muka Ray Nǹkan oṣù obìnrin le jáde ní imú tàbí ìdodo yàtọ̀ sí ojú ara - Dókítà Níbo ni Sẹ́nétọ̀ Abiola Ajimobi, gómìnà àná ní ìpínlẹ̀ Oyo wà?
Ibùdó Amúnáwá kọsẹ́ lẹ́ẹ̀mejì lọ́jọ́ márùn ùn 'Fashọla, o ò sì bẹ̀rù Ọlọ́run!
 Ìgbà tí ó sí kú , ìlù yí náà ni àwọn ọmọ Ìjẹ ̀ bú - jẹ ̀ ṣà máa ń lú tí ogun bá wà , ó sì di dandan kí àwọn áà borí irú ogun bẹ ́ ẹ ̀ .
Ẹ pada tọ OLUWA Ọlọrun yín lọ, ẹ̀yin ọmọ Israẹli, nítorí pé ẹ ti kọsẹ̀ nítorí ẹ̀ṣẹ̀ yín.
Ẹwẹ, TBlak ati awọn afurasi to ku ni awọn ko jẹbi ẹsun ti wọn fi kan wọn.
Àwọn ni ìlú ati ìletò náà tí ó wà ninu ilẹ̀ tí ó kan ẹ̀yà Isakari gẹ́gẹ́ bí iye ìdílé wọn.
Barrister gbe orin kikọ de ilẹ okeere, to si ṣe ariya ita gbangba ni awọn ilu bi London lọdun 1990 ati 1993.
Ita gbangba ni wọn yoo ti maa gbalejo wọn Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Snake Market: Àwọn òńtàjà ẹran ejò ní ẹran ejò dùn ju ẹran adìẹ lọ Bakan naa lo ni ọwọ afunrasi ni wọn yoo fi mu ọkunrin kankan ti o ba n rin gberegbere kaakiri ibugbe awọn obinrin nileewe naa kọja agogo mẹjọ abọ alẹ.
( v ) Èka Ìlárògún : Èka yìí náà kò ní í je wá lógún tó béè tàbí jù béè lo nínú ìdánilékòó yìí .
kí ó tó já Kolade Johnson; Iléeṣẹ́ ọlọ́pàá ní ọwọ́ ti tẹ àwọn afurasí ọlọ́pàá tó ṣekúpaá Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Okùnrin SARS náà sọ pé òun máa pa èèyàn síbi ni- Aladugbo Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ojojúmọ ní mọ ń kẹ́kọ̀ọ́ lára ọmọ mi to jẹ akanda Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Pulev to jẹ ọmọ ọdun mẹtadinlogoji sọ pe orẹ loun ati arabinrin naa ṣugbọn Ravalo ni oun ṣẹṣẹ pada rẹ ni.
Ríi dáju pé o lọ ṣe èyí ki o máà ba lo ju iye ti o yẹ ki o lo lọ láàrin iye gbèdéke ti o ba fi si bẹ.
"Ti a ba ni akoko ati awọn nkan to yẹ, o ṣeeṣe ki a ṣi ri arigbamu.
Ọpọlọpọ ninu àwọn Juu tí ó wá sọ́dọ̀ Maria gba Jesu gbọ́ nígbà tí wọ́n rí ohun tí ó ṣe.
Yóo dá gbogbo eniyan lẹ́jọ́,yóo fi idà pa àwọn eniyan burúkú,OLUWA ló sọ bẹ́ẹ̀.
Oríṣun àwòrán, others Àkọlé àwòrán, Kò sí ìwé ìrìnnà 'VISA' fáwọn ọmọ Naijiria tó hùwà àìtọ́ nígbà ìdìbò Agbenusọ ilẹ Amerika ni ofin yii kii ṣe fun gbogbo ọmọ Naijiria rara bikoṣe fun awọn to huwa ipa lasiko idibo to kọja nikan.
Ní ọjọ́ ajé ni wọ́n kéde ikú Winnie Madikizela-Mandela lẹ́ni ọdún mọ́kànlélọ́gọ́rin.
Ẹ san owó-odè fún ẹni tí owó-odè yẹ.
setan lati se agbekale ile ise ti yoo maa so idọti di ọrọ (waste to wealth) ni
Gẹgẹ bi ohun ti ileeṣẹ iroyin ABC News sọ, Ọgbẹni Faria sọ pe ẹmi Dokita ọgbọn ati awọn ẹmi miiran lo ma n wọ inu ara ohun ti a si maa fun oun lagbara lati ṣe iwosan fawọn eeyan.
Ariwo ati ijo ayọ laarin awọn ololufẹ Fayose lẹyin idajọ naa.
Àkókò tó, ọjọ́ ti súnmọ́lé, ọjọ́ ìdàrúdàpọ̀, tí kì í ṣe ọjọ́ ariwo ayọ̀ lórí àwọn òkè.
” Ó sọ èyí nítorí kò mọ ohun tíì bá sọ.
Bakan naa ni wọn fikun wi pe, wọn ti gbe awọn to ku naa lọ si ile igbokusi to wa ni ilu Ondo.
Folúkẹ́ ní òun rí nnkan kan bí ológbò ní àpò rẹ̀ ni ọjọ́ kan.
“Bí àwọn eniyan bá ń jà, tí wọ́n sì ṣe aboyún léṣe, tóbẹ́ẹ̀ tí oyún rẹ̀ bàjẹ́ mọ́ ọn lára, ṣugbọn tí òun gan-an kò kú, ẹni tí ó ṣe aboyún náà léṣe níláti san iyekíye tí ọkọ rẹ̀ bá sọ pé òun yóo gbà bí owó ìtanràn, tí onídàájọ́ bá ti fi ọwọ́ sí i.
Awọn ọlọpaa sọ pe, o ṣeeṣe ki awọn eku naa raye wọle loju iho ti waya gba kọja lọ sinu ẹrọ owo ọhun.
Bẹ́ẹ̀ ni ọkàn wa fà sọ́dọ̀ yín; kì í ṣe ìyìn rere nìkan ni a fẹ́ fun yín, ṣugbọn ó dàbí ẹni pé kí á gbé gbogbo ara wa fun yín, nítorí ẹ ṣọ̀wọ́n fún wa.
Wolii ará Juda yìí bá bá wolii àgbàlagbà náà pada lọ sí ilé rẹ̀, ó sì jẹun níbẹ̀.
Ṣugbọn kò sí ẹni tí ó lè fi ẹ̀wọ̀n de ọ̀rọ̀ Ọlọrun.
Dokita Hong Chi Ting ti ile iwosan Fasiti Fooyin ni Taiwan ṣalaye fun BBC pẹ ẹnu ya gbogbo àwọn nile iwosan naa nigba ti awọn ri oyin mẹrin ti ikọọkan wọn to iwọn milimita mẹrin yọ loju arabinrin naa.
Awọn yoku ti ọrọ naa kan ni Raph Wetzels, Casula Roberto, Pujato Stefeno, ati Burrato Sebastiano, ti wọn si gbe wọn lọ siwaju adajọ Senchi lọjọru oni, lori ẹsun pe wọn kọ lati wa yọju lori ẹsun ti wọn fi kan wọn naa.
Lórí ìrìnàjò Buhari sí London: Garba Shehu ni ààrẹ lè ṣe ìjọba níbikíbi
Bí ó bá rí ilẹ̀ oko, a yẹ̀ ẹ́ wò, a sì rà á,a sì fi èrè iṣẹ́ rẹ̀ gbin ọgbà àjàrà.
Bí Abrahamu ti gbé orí sókè, tí ó wo ẹ̀yìn rẹ̀, ó rí àgbò kan tí ó fi ìwo kọ́ pàǹtí.
Agbẹnusọ iyawo Aarẹ, Aliyu Abdulahi lo fi ọrọ naa to BBC leti.
Nebusaradani kó àwọn tí wọ́n kù láàrin ìlú ati àwọn tí wọ́n sá tọ ọba Babiloni lọ, pẹlu ogunlọ́gọ̀ àwọn yòókù lọ sí ìgbèkùn.
Awọn iroyin miran ti ẹ le nifẹ si: ‘Aawọ abẹnu lee koba APC ni 2019’ Dino Melaye tun k'ọrin miran Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 3 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 5 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Ile-ise ogba ewon lorile-ede Botswana so pe, Joseph Tselayarona omo odun mejidinlogbon ni won yeku pa lojo-Abameta, leyin  ti o seku pa orebinrin ati omo odun meta ni odun 2010.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Lizzy Anjorin: Ẹ̀yin tẹ bímọ fún ọkọ mi, ẹ kó ọmọ wa ká ṣe àyẹ̀wò DNA fún wọn 22 Ògún 2020 Oríṣun àwòrán, lizzyanjorin_original Ilumọọka osere tiata lobinrin to tun gbajumọ lawọn oju opo ayelujara rẹ, Lizzy Anjorin Lawal ti kede pe igbe aye to dakẹ rọrọ ko wu oun.
Amọ agbẹjọro to ṣoju awọn olujẹjọ, Akinyemi Omoware, sọ fun BBC pe awọn yoo pe ẹjọ kotẹmilọrun lori idajọ ile ẹjọ giga ọhun.
Amọ ṣa, ijọba ti n fi awọn ọmọ ogun ṣọ diẹ lara awọn ile iwosan ti wọn ti wọn ṣẹṣẹ da silẹ.
Kò tọ́ sí Ọlọ́pàá láti ti ọmọ mi mọ́lé tórí ore tó ṣe lásìkò ìwọ́de EndSARS - Iya Eremosele Ohun marun t'ejo n jẹ Jegede: Àwọn kan ń lépa ẹ̀mí mi; Akeredolu: Yẹ̀yẹ́ lásán, kò sọ́rọ̀ níbẹ̀ Àwọn ọmọ Naijiria kó owó wọn kúrò ní Áccess Bank' lẹ́yìn tó gbẹ́sẹ̀lé àpò owó àwọn olùwọ́de EndSARS 'Banji Akintoye kìí ṣe adarí àwọn ọmọ Yorùbá mọ́, a ti ní ẹgbẹ́ tuntun' Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Bí o bá bá ààrùn ìpẹ́pẹ́ gbígbẹ lára arẹwà obìnrin rẹ̀, kí loó ṣe?
Gbogbo èèyàn ló bara jẹ́ tí wọ́n ṣe bí ẹni pé wọn kò tilẹ̀ rí àwa ọmọdé- ilé.
Kò sí, àfi bí mo bá ṣe àlàyé nípa ìfihàn, tabi ìmọ̀, tabi iwaasu, tabi ẹ̀kọ́ tí mo fi èdè àjèjì sọ.
Mose jẹ́ ẹni ọgọfa (120) ọdún nígbà tí ó kú, ojú rẹ̀ kò ṣe bàìbàì, bẹ́ẹ̀ ni agbára rẹ̀ kò dínkù.
 bí ọ ̀ rọ ̀ kan bá délẹ ̀ nípa iṣẹ ́ ìlú , wọn máa ń rúnpá-rúnsẹ ̀ sí i , wọ ́ n á sì mú sòkòtò wọn wọ ̀ láti yanjú irú ọ ̀ rọ ̀ náà .
Ṣe fún un bí òun náà ti ṣe fún eniyan.
Akọroyin BBC, Matthew Kenyon naa ṣe iranti bi ikọlu naa ṣe mu ẹmi awọn agbabọọlu orilẹede Togo meji lọ.
Oju opo intagram Dorathy ti gbina jẹ bayii pẹlu bi awọn to n tẹ lee loju opo naa ti gbera sọ lati igba to ti wọ inu ile ẹlẹgbọn agba fun eto agbelewo BBNaija.
Lasiko yii ẹwẹ, akọsilẹ awọn ẹbun pataki ti iyawo tuntun aṣẹṣẹgbe gba fun igbeyawo rẹ pẹlu aayo ọkan rẹ, Akanbi ti wọn ṣẹṣẹ so yigi igbeyawo lopin ọsẹ to kọja lo fi sita.
Mo kọ̀wé ranṣẹ́ sí ọrẹ́ mi sórí alágbèéká rẹ̀ pé kó wá bámi níbẹ̀ tó bá dé.
Josẹfu dáhùn pé, “Àwọn arakunrin mi ni mò ń wá, jọ̀wọ́, ǹjẹ́ o mọ ibi tí wọ́n da agbo ẹran wọn lọ?
Owo naa ju miliọnu mẹtadinlaadọrin dọla owo ilẹ Amẹrika, iyẹn biliọnu mẹrinlelogun naira, ti Arsenal ra Pierre-Emerick Aubameyang lati ẹgbẹ agbabọọlu Borussia Dortmund lọ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Dele Momodu: Gbogbo aáyan àwa Nadeco láti tú Abiola sílẹ̀ ni kò hàn sí Kọla Abiọla Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Dele Momodu: Gbogbo aáyan àwa Nadeco láti tú Abiola sílẹ̀ ni kò hàn sí Kọla Abiọla 26 Ògún 2019 Oloye Dele Momodu, tii se ọkan lara awọn ọmọ ẹgbẹ Nadeco to sa kuro lorilẹede yii lasiko ti oloogbe Sani Abacha gbe Oloye MKO Abiọla ju sẹwọn, ti ba BBC Yoruba sọrọ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Bọla Tinubu: Ìpínlẹ̀ Ọ̀ṣun kò ní owó mi lọ́wọ́ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Bọla Tinubu: Ìpínlẹ̀ Ọ̀ṣun kò ní owó mi lọ́wọ́ 9 Owewe 2018 Asiwaju fẹgbẹ oselu APC nilẹ yii, Oloye Asiwaju Bọla Ahmed Tinubu, ti sọ ni ilu Oṣogbo, lasiko to lewaju ikọ ipolongo ẹgbẹ oṣelu APC lọ si aafin Ataọja ti ilu Oṣogbo pe ki wọn tẹ́wọ́gba oludije fun ipo gomina fẹ́gbẹ́ oselu APC nipinlẹ́ Ọsun, Gboyega Oyetọ̀la, nitori ko ni ji wọ̀n wọ̀n lowo.
11 Òkùdu 2020 Oríṣun àwòrán, others Ni ọpọ igba ti aigbọraẹniye ba waye laarin awọn ọmọ Yoruba, ọpọ eeyan lo maa n mẹnuba a pe 'epe Aole lo n ja wa, ni isọkan ko ṣe wa ni aarin wa.
Orúkọ ẹ̀gbọ́n ń jẹ́ Ohola, ti àbúrò sì ń jẹ́ Oholiba.
Igbimọ Aṣofin Ipinlẹ Eko duro lati fun awọn ẹṣọ abẹle ipinle laṣẹ ati
Àwọn olórí àwọn eniyan náà ń gbé Jerusalẹmu, àwọn tí wọ́n ṣẹ́kù dìbò láti yan ẹnìkọ̀ọ̀kan ninu eniyan mẹ́wàá mẹ́wàá láti lọ máa gbé Jerusalẹmu, ìlú mímọ́, àwọn mẹsan-an yòókù sì ń gbé àwọn ìlú yòókù.
Agbegbe Kukawa ko fi bẹẹ jina si orilẹ-ede Lake Chad.
Ìkádìí Isiaka Adegboyega ti wọn bi ni ilu Iragbiji, ni ijọba ibilẹ Boripe ni ipinlẹ Ọsun.
7 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Ghana Election 2020: Ẹ dín iye ìgbà tẹ n gorí obìnrin kù kẹ́ẹ lè lágbára.
Jehu ranṣẹ sí àwọn ẹlẹ́sìn Baali ní gbogbo ilẹ̀ Israẹli; kò sí ẹnìkan ninu wọn tí kò wá.
Òun níí sọ àwọn orílẹ̀-èdè di ńlá,òun náà níí sìí tún pa wọ́n run:Òun níí kó àwọn orílẹ̀-èdè jọ,òun náà níí sì ń tú wọn ká.
“Bí ẹnìkan bá ń lọ ṣe àyẹ̀wò lọ́dọ̀ àwọn abókùúsọ̀rọ̀, tabi àwọn oṣó, tí ó sì ń tọ̀ wọ́n lẹ́yìn, n óo kẹ̀yìn sí olúwarẹ̀, n óo sì yọ ọ́ kúrò láàrin àwọn eniyan rẹ̀.
Ko din ni eeyan mẹwa, meji ninu eyi to jẹ ajoji ni wọn ti kagbako iku ojiji laarin ọsẹ kan sẹyin.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Community policing: Ọ̀gá ọlọ́pàá Mohammed Adamu ní ètò ń lọ fún ọlọ́pàá agbègbè 6 Owewe 2019 Oríṣun àwòrán, @PoliceNG Ọga ọlọpaa patapata lorilẹede Naijiria, Mohammed Adamu ti ṣalaye pe eto ọlọpaa agbegbe yoo bẹrẹ jakejado Naijiria ni kiakia.
Ọba Sodomu sọ fún Abramu pé, “Jọ̀wọ́, máa kó gbogbo ìkógun lọ, ṣugbọn dá àwọn eniyan mi pada fún mi.
Àkọsílẹ̀ ìran Esau, baba àwọn ará Edomu, tí ń gbé orí òkè Seiri nìyí: 
Bí àjálù ìbúgbàmù tó gb'ẹ̀mí ọ̀pọ̀ nìlùú Eko ṣe wáyé nìyí Àjọ NYSC sé ilẹ̀kùn ibùdó ìfinimọlé nítorí Coronavirus Àwọn ọba Yorùbá kan rèé tí wọ́n rọ̀ lóyè, tí ọba míràn jẹ lójú ayé wọn Coronavirus: Wo ohun tí o ní láti ṣe láti dáàbò bo ara rẹ Coronavirus: Ọmọ ìkókó kan wà lára àwọn márùn ún míràn tó ṣẹ̀ṣẹ̀ kó àrùn coronavirus lórílẹ̀èdè Nàìjíríà Oríṣun àwòrán, Getty Images Minisita feto ilera lorilẹede Naijiria, Dokita Osagie Ehanire ti fi soju gbangba pe ọmọ ikoko kan wa lara awọn eeyan marun un ti wọn ṣẹṣẹ ri wi pe o ni arun Coronavirus lorilẹede Naijiria.
Awọn mejeeji sọ fun BBc pe pẹlu idunnu ati ayọ ni awọn fi ṣeto igbeyawo naa.
Coronavirus: Ọmọ márùn ún ni mo ní, ṣùgbọ́n kò sí oúnjẹ fún wa lásìkò ìgbélé yìí -Olùgbé ìlú Eko ''O lè kó coronavirus nípa ṣíṣe eré ìdárayá, ẹ gbélé yín lásìkò yìí,''- onímọ̀ ètò ìlera Coronavirus in Nigeria: ''Èèyàn lè kó coronavirus nípa ṣíṣe eré ìdárayá, ẹ gbélé yín lásìkò yìí,'' Onimọ nipa eto ilera, Dokita Ikubese Wilson ṣe atupalẹ bi eeya ti le ko aarun coronavirus nipasẹ ṣiṣe ere idaraya.
Ohun ti a n pe ni ijẹ ọba inu ẹsẹ ifa lo wa Ifa ni yoo yan Ọba gẹgẹ bi oloye Agẹṣin Adimula ṣe sọ, koda, ifa ni wọn n ṣe fun ọba to fii di Ọba alade ni ilẹ Yoruba, kii ṣe ẹdọ jijẹ gẹgẹ bi awọn eeyan kan ṣe maa n sọ."
Bíótilẹ̀jẹ́pé ó dàbí ẹni pé arábìnrin Knežević ti yọ ara rẹ̀ kúrò lórí Facebook, bóyá láti lè jẹ́ kí ọ̀ràn náà ó silẹ̀, ó fi àlàyé-nípa-ara rẹ̀ orí Twitter sílẹ̀.
Ní ìparí, ẹ̀yin ará, ó dìgbà!
Ó bèèrè pé, “Kí ló ṣẹlẹ̀ tí gbogbo eniyan fi ń sọkún?
Lagos Okada ban: Àwọn àkàndá ẹ̀dá ní àwìn làwọn gba kẹ̀kẹ́ táwọn fi ń jẹun
 E je ki a jo fowosowopo gbe  ile Adulawo”.
Ìtùmò : ní àtijó àdúgbò kookan ni ó ní ise ìdamo won .
iko naa, Simon Msuwa, Erasto Nyoni ati Aggrey Morris ti o gba ami-ayo ohun wole,
Bí ẹ̀rù bá ń bà ọ́ láti sọ òótọ́ máṣe gbàgbé Bísọ̀bù Phillips olódodo nítorí Bísọ̀bù yìí tí ó jẹ́ asáájú pàtàkì fún ni kò fi èké kọ́ ìwọ́ àti èmi.
Wọn yóo sun oorun àsùnrayè,wọn kò sì ní jí mọ́ laelae.
Ọmọ ọdún mẹ́rìnlá kàwé gboyè jáde ni Oxford Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Osinbajo: Ikẹnnẹ yẹ kó jẹ́ Mẹ́kà òṣèlú ni Erongba abẹwo igbakeji aare si Amerika ni pe gba fun Raji nile to difa fun gba fun Gbada loko yoo ṣẹlẹ laarin Naijiria ati Amẹrika ti ohun gbogbo ba lọ bi o ti yẹ.
Nítorí náà, Ọlọrun fi wọ́n sílẹ̀ fún ìfẹ́kúfẹ̀ẹ́ tí ó ti eniyan lójú.
" Fáyẹmí dúpẹ́ lọ́wọ́ gbogbo àwọn ará ìlú, àgbààgbà ẹgbẹ APC àti mọ̀lẹ́bí rẹ̀.
Sọ fún un pé èmi OLUWA Ọlọrun ní, ìwọ ìlú tí wọ́n ti ń paniyan ní ìpakúpa kí àkókò ìjìyà rẹ̀ lè tètè dé, ìlú tí ń fi oriṣa ba ara rẹ̀ jẹ́!
A o maa mu ẹkunrẹrẹ wa fun yin loju opo yii bo ba ṣe n lọ.
Nígbà tí àwọn ọmọ-ẹ̀yìn Jesu rí i, inú bí wọn.
Oludije ipo aarẹ fun ẹgbẹ oṣelu SDP ni Oloye Moshood Kashimawo Ọlawale Abiọla, ti gbogbo eeyan mọ si MKO Abiọla, nigbati igbakeji rẹ jẹ Alhaji Babagana Kingibe.
yoo dibo ni abule rẹ nile iidbo ni Ajia ni ipinle Adamawa.
san owo osu osise; igbiyanju ijoba lati gba iwe ase pada  lowo ile- ise to n pese ina mona-mona; ki awon
- BBC News Yorùbá BBC News, YorùbáFò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Europa League - ìnàkunà ni Arsenal na ojúgbà rẹ ti Frankurt.
Nítorí pé, wọn óo yí àwọn ọmọ yín lọ́kàn pada, wọn kò ní jẹ́ kí wọ́n tẹ̀lé èmi OLUWA mọ́.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù India Wedding: Ìyàwó kan ní India wọ sòkòtò fún ayẹyẹ ìgbéyàwó rẹ̀- Wo ìdí tó fi ṣe bẹ́ẹ̀ By Geeta Pandey BBC News, Delhi 25 Bélú 2020 Oríṣun àwòrán, Sanjana Rishi Ọbinrin onisowo India ati Amẹrika kan, Sanjana Rishi ti salaye idi ti o fi wọ sokoto fun ayẹyẹ imana igbeyawo rẹ ni India.
”OLUWA bá sọ fún mi pé,“Tú ibinu mi dà sórí àwọn ọmọde ní ìta gbangba,ati àwọn ọdọmọkunrin níbi tí wọ́n péjọ sí.
Aṣojú Phillipine ti di ẹni àkọ́kọ́ tó ṣe onígbọ̀wọ́ Coronavirus wọ New York Oríṣun àwòrán, Getty Images Ayẹwo ti wọn se fun asoju orilẹede Phillipine ni New York lorilẹede Amẹrika ti fara han pe o ni kokoro arun Coronavirus, eyi tii se akọkọ arun naa ti yoo foju han ni olu ileesẹ ajọ isọkan orilẹede agbaye.
Nígbà tí ó yá, apá bẹ̀rẹ̀ sí ro Mose, wọ́n gbé òkúta kan fún un láti fi jókòó, ó sì jókòó lórí rẹ̀.
Ki ni Yoruba n pe ni Akufa?
O ṣalaye pe awa ko gba iṣẹ akanṣe jọ fun awọn ẹbi wa ṣugbọn a pin in ko kan taraale tara oko to tọ si ni.
Awọn eeyan to n gbe lagbegbe ibi ti iṣẹlẹ naa ti waye sọ pe irinwo le mẹfa ni wọn ti ri lara awọn ọmọ ile iwe naa, ṣugbọn wọn ko le sọ ibi ti awọn to ku wa.
Mo gbọ́ ohùn kan tí ń wí pé, “Kígbe!
Nitori naa, ki eeyan wukọ tabi sin sinu igbọnwọ, ṣiṣọra fun fifi ọwọ ti eeyan ko fọ kan oju ẹni, ati yiyẹba fun awọn to ni ti ni arun naa jẹ ọna kan pataki lati jina rere si arun ọhun.
Fayemi, Fayose ń tahùn sí ara wọn nítorí gbèsè owó oṣù òṣìṣẹ́ Oògùn olóró cocaine ni Toyin Abraham fi ń sayé - Lizzy Anjorin Àwọn ará ń kẹ́dùn ọ̀pọ̀ ẹ̀mí tó ṣòfò lópòpónà Ọrẹ̀ si Èkó O ni ohun ti Toyin ṣe fun oun jẹ ohun to buru jọjọ, fun idi eyi oun ko le rawọ ẹbe si Toyin, bẹẹ ni oun ko ni simi agabja.
Nípasẹ̀ rẹ̀ ni a ti rí ìdáríjì gbà fún àwọn ìrékọjá wa, gẹ́gẹ́ bí ọ̀pọ̀ oore-ọ̀fẹ́ rẹ̀.
ti ijoba apapo orile ede Naijria ti fi san ajemonu owo awon osise ile iwe giga
N óo fi títóbi mi ati ìwà mímọ́ mi hàn lójú àwọn orílẹ̀-èdè, wọn yóo wá mọ̀ pé èmi ni OLUWA.
Ẹ dákẹ́, kí n ráyè sọ tèmi,kí ohun tí yóo bá dé bá mi dé bá mi.
“Nítorí náà, ẹ máa ṣọ́nà, nítorí ẹ kò mọ ọjọ́ tí Oluwa yín ń bọ̀.
Lẹyin eyi, ọpọlọpọ iwe lo ti ka kun un.
” Baraki bá bá a wọlé lọ, ó sì bá Sisera nílẹ̀ níbi tí ó kú sí, pẹlu èèkàn àgọ́ tí wọn gbá mọ́ ọn lẹ́bàá etí.
Ẹni tí ó ń jẹ oríṣìíríṣìí oúnjẹ, ó ń jẹ ẹ́ nítorí Oluwa.
Amọ, ile ẹjọ fun Obi lanfaani lati san owo itanran to le igba miliọnu (N252 million) fun ẹsun ti wọn kan an.
tí a jẹ́rìí sí iṣẹ́ rere rẹ̀, tí ó tọ́ àwọn ọmọ rẹ̀ dáradára, tí ó máa ń ṣe eniyan lálejò, tí kò sí iṣẹ́ tí ó kéré jù tí kò lè ṣe fún àwọn onigbagbọ, tí ó ti ran àwọn tí ó wà ninu ìyọnu lọ́wọ́.
Ó rán àwọn oníṣẹ́ ní ìgbà kẹta, àwọn náà tún ń sọ àsọtẹ́lẹ̀.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Kaduna sex party: Mọ̀ si nípa àríyá oníhòhò àti ìbálòpọ̀ tó yẹ́ kó wáyé ní Kaduna 30 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Oríṣun àwòrán, ABDUL85 / TWITTER Awọn ọlọpaa ti mu awọn to ṣe agbatẹru ariya ibalopọ ti wọn polongo rẹ pe yoo waye nipinlẹ Kaduna, lọjọ kẹtadinlọgbọn, oṣu Kejila, ọdun 2020.
O ni: Ë je ki a fowosopo pelu awon osise eleto aabo wa kaakiri ipinle kookan ki a le jo koju awon onise ibi ti won fe maa dun kooko mo aato aabo awon eniyan wa.
Àjọ Ìlera Àgbáyé ( who ) gba ni nímọ ̀ ràn láti má a gba àjẹsára lóòrèkóòrè ní gbogbo orílẹ ̀ -èdè tí àrùn náà ti wọ ́ pọ ̀ .
Pẹ̀lú ayọ̀ ni àwọn ọdẹ fi yan Inúlayéwà sí ipò Ayédèrú-ẹ̀dá, tí o di pe oun ni igbá kejì mi.
Bakan naa lo ni wọn se tun se awọn ẹrọ ọhun lati seranwọ fun araalu ni lasiko ajakalẹ arun Coronavirus yii.
Ọjọ kan lẹyin rẹ naa ni ajọ ilẹ Yuroopu naa ṣe bẹ ẹ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ibadan Kings: 2,000 si 5,000 ni Oyè Ibadan, àmọ̀ Olubadan ń gba N30m 18 Èrèlè 2020 Oríṣun àwòrán, Others Otun ti ilu Ibadan, Lekan Balogun ti ni oye ni ilu Ibadan kii ṣe fun tita bi Olubadan ṣe n ta oye fun awọn eniyan.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ìròyìn Yàjóyàjó - Ogun Majek jáde láyé Eji Gbadero, ọmọ Ibadan àti jayé-jayé ọmọ ónílẹ̀ ti wọn yẹgi fun l'Eko Èyí ni àwọn arẹwà ‘ẹ̀lẹ̀ Daddy’, àfẹ́fẹ́ tí Aláàfin fi ń mí Mùjẹ̀-mùjẹ̀ ní Akinyele tún ti mu ẹ̀jẹ̀ obìnrin míràn lónìí Oyè adelé alága APC bọ́ lọ́wọ́ Ajimobi, Buhari fòǹtẹ̀ lu Giadom Ọkùnrin kan bá ọmọ oṣù mẹ́ta lòpọ̀, ìfun ọmọ tú jáde!
Mo ti pèsè ilẹ̀ náà fun yín, ẹ lọ, kí ẹ sì gbà á; Èmi OLUWA ti búra láti fún Abrahamu ati Isaaki, ati Jakọbu, àwọn baba ńlá yín ati arọmọdọmọ wọn.
Nítorí ó wà ní àkọsílẹ̀ pé, “Àwọn eniyan náà jókòó láti jẹ ati láti mu, wọ́n sì dìde láti ṣe àríyá.
 O fikun ọrọ rẹ pe Arabinrin Ade sọ fun oun pe gule-gule ọmọ naa ti pọju ninu ṣọọṣi."
ipinle Zamfara lati tun ko awon omo ogun wo ipinle naa si.
"Bí gbogbo ètò ìdìbò 2019 ṣe ń kógbá wole a rọ gbogbo àwọn tí ọ̀rọ̀ kan láti ri d;aju pé wọn ṣiṣẹ tọ ìdìbo ti kò ni kọ́nukọ́họ ninu ti o si ni àláfíà pàápàá jùlọ gbogbo àwọn ti yóò jade lọ́ dibo "" A tún rọ gbogbo àwọn ti ọ̀rọ̀ kan tó fi mọ àjọ INEC, àwọn ẹgbẹ́ òṣèlú àti àwọn eleto ààbò lati tẹ̀siwaju nínú mímu eto ìdìbò gúnregé lọ́jọ́ iwájú Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 3 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 5 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!"
Àwọn nkan wọnyi àti iwà ibàjẹ́ àti ojúkòkòrò Ijọba Ológun àti Alágbádá (Òṣèlú) ló sọ Èkó di aginjù laarin àwọn olú ilú àgbáyé.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Mobile Wash: iṣẹ́ fífọ́ mọ́tò tà ni mó yàn láààyò- Slay Mama Iru awọn eeyan ti N-Power 2020 n wa?
O ni ko si ohun to buru ninu igbesẹ yii ṣugbọn kii ṣe gbogbo obi lo faramọ ọ.
Gege bi oro re, ijoba orile-ede Japan yoo fowosowopo pelu awon ile-ise ijoba orile-ede Nigeria lati mu igberu ba eto oro-aje naa, nipase siseto idanilekoo latari ati mo awon ayederu nnkan.
Nítorí ó sàn fun yín tí ó bá jẹ́ ìfẹ́ Ọlọrun pé kí ẹ jìyà, nítorí pé ẹ̀ ń ṣe rere, jù pé ẹ̀ ń ṣe ibi lọ.
Ìlú Ninefe dàbí adágún odòtí omi rẹ̀ ti ṣàn lọ.
Ajo to n mojuto gbigbe fiimu agbelewo jade ni Naijiria ti a mo si: The Nigerian Film Corporation ti bere idanilekoo fawon odo nilu Eko.
Gomina Oluwarotimi Akeredolu n dije dupo labẹ ẹgbẹ oṣelu APC, nigba ti Eyitayo Jegede n dije labẹ ẹgbẹ oṣelu PDP.
''Inu mii yoo dun ti ẹ ba le fi ọmọ mi sinu adura yin, ki onikaluku rọra maa ṣe nitori otitọ ni pe arun coronavirus wa nita,'' Atiku lo sọ bẹẹ.
Ṣèbí tí ìyà nlá bá gbeni ṣánlẹ̀, kékèké a sì máa gorí ẹni.
Ki lo ṣẹlẹ ni idibo abẹlé Enugu tẹlẹ?
Bakan naa lo sọ pe ijọba ti ṣiṣẹ lori awọn fidio ati aworan to jade sori ayelujara ni Ọjọbọ, eyi to safihan bi awọn janduku to kọlu awọn oluwọde kan ni Alausa, ṣe n sọkalẹ ninu ọkọ BRT to jẹ ti ijọba.
O ni awọn eeyan kan ti n dokoowo ile itura si adugbo wọn ni wọn n fa inira fun oun atawọn aladugbo oun.
Bakan naa lo ni iwa buruku ni awọn ikọ ọmọogun to yinbọn naa hu, nitori owo ori awọn ọmọ Naijiria ni wọn fi n sanwo oṣu wọn, ti wọn si fi ra ibọn naa fun wọn.
Aramide Praise Oikelome Aramide Praise ku lana, Ogunjọ ọsu kẹfa bakan naa.
”“iru agbaboolu bi Messi ko se bu enu ate lu.
Àròkàn kò lè tú nkan ṣe à fi ki ó bá nkan jẹ si.
Ó fi òkúta olówó iyebíye ṣe iṣẹ́ ọnà sára ilé náà, wúrà tí ó rà wá láti ilẹ̀ Pafaimu ni ó lò.
Wọ́n hú wọn jáde ninu àgọ́ rẹ̀, wọ́n kó wọn wá siwaju Joṣua ati gbogbo àwọn ọmọ Israẹli, wọ́n sì tẹ́ wọn kalẹ̀ níwájú OLUWA.
" Bakan naa ni lẹta naa tun kilọ fun CNN pe Naijiria ni ẹtọ lati gbe igbesẹ labẹ ofin, lati di ileeṣẹ iroyin lọwọ ko ma ba a dakun wahala END SARS.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ọọni Ogunwusi Adeyẹye pe fun itọju awọn ọdọ Wo awọn idi pataki yii: Akọkọ ni pe, nitori ibọwọ fun aṣa ati iṣe Yoruba ni, yoo ni iru abẹ ti wọn yoo lo, kii kan ṣe abẹ kan ṣa ni wọn yoo fi fa irun ori Arẹmọ tuntun.
Láti ṣe ìtànká ìmọ̀ nípa àrùn Kògbóògùn,  àti láti ṣe ìkìlọ̀ fún gbogbo gbòò nípa àrùn náà.
Wọn yóo run ẹran ọ̀sìn yín,ati àwọn mààlúù yín.
Lẹsẹkẹsẹ, ọmọkunrin náà bẹ̀rẹ̀ sí tẹ̀lé e,bíi mààlúù tí wọn ń fà lọ pa,tabi bí àgbọ̀nrín tí ó tẹsẹ̀ bọ tàkúté,
Lai Mohammed - BBC News Yorùbá BBC News, YorùbáFò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Hate speech: Ero wa kò yípadà lórí àbádòfin ìṣàkóso ẹ̀rọ ayélujára - Lai Mohammed 15 Bélú 2019 Oríṣun àwòrán, @first_reports Àkọlé àwòrán, Afojusun ijọba ni awọn to n lo opo ikansiraẹni lati fi sọrọ ikorira Ijọba apapọ ti sọ pe, oun ki yoo boju wẹyin lori aba lati ṣakoso opo ikansiraẹni lori itakun agbaye.
Alaga Ajọ EFCC, Ibrahim Magu lo fi eyi lede lasiko to ṣe abẹwo si ẹka ileeṣẹ EFCC to wa ni ilu Ibadan.
Kí n tilẹ̀ sọ òtítọ́, inu wa máa ń dùn nígbà kigbà tí ó bá wá lọ.
27 Kíyèsíi, èmi nsọ̀rọ̀ sí gbogbo ènìyàn tí ó ní ìfẹ́ inú rere, tí wọn sì ti fi dòjé wọn láti kórè.
Ọjọ kẹrindinlogun, oṣu karun un ni ọmọge campus re ibi agba n re lọmọ ọdun mejilelogoji.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Governorship Election Updates: Sanwo-Olu se abẹwo idupẹ si Bọla Tinubu Gboyega Akosile ni kete ti awọn ọmọ ile igbimọ aṣofin ipinle Eko ba ti ṣe ayẹwo to yẹ ni wọn yoo buwọlu u bi o ti yẹ labẹ ofin.
Ijọba ti tun awọn ọna gbegbe kọọkan ṣe ki sunkẹrẹ fakẹrẹ ọkọ le dinku ni awọn ẹkun naa.
Lẹsẹkẹsẹ, Daniẹli lọ bẹ̀bẹ̀ lọ́dọ̀ ọba pé kí ó dá àkókò fún òun, kí òun lè wá rọ́ àlá náà fún ọba, kí òun sì sọ ìtumọ̀ rẹ̀.
Ọmọ Yahoo fẹ́ pa ìyá rẹ̀ ṣ'owó l'Eko Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ileya: Àgbò wọ́n torí ọjà ẹran mẹ́ta ni wọ́n tìpa lókè ọya torí Boko Haram Ó tun rán àwọn Musulumi léti pé, àsìkò ọdún Eid-ul-Adha wà láti ránti pé, o ṣe pàtàkì láti fara wọn sílẹ̀ fún ìtọ́ni ẹlẹ́dàá wọn, èyí to fí kọ àyé nípa fifi ara wọn jìn fún ìgbáyé-gbádun ọmọlakeji wọn.
Ola Aina tó ń gbá fún ẹyìn apá òsì  Asoju awa ikọ Super Eagles ati igbákeji rl pè wá jọ, wan si ni e wó ẹ tẹti, sááju oun gbogbo isẹ́ ni awá ṣe nibi, iṣk ki a gbá bọ́ọ̀lù si ni, ẹ jẹ́ ki a ṣe ǹkan to yẹ ki a ṣe láti sojú orílẹ̀-èdè wa, láti sóju ara wa àti awọn ẹbi wa, sááju ohun gbogbo a ni iṣẹ́ láti ṣe ǹkan to gbé wa wá sibi nìyìí, ẹ jẹ ki a gbá bọọ́lù ki a si mú èsì gidi jáde."
“Ohun tí a bá fẹ́ ni a lè ṣe.
awon ipinle to wa lorile ede Naijiria lati gbaradi fun sisan ẹkunwo ọgbọ̀n ẹ̀gbẹ̀rún
Tọ̀sán-tòru ni wọ́n ń da ọ̀rọ̀ mi rú;ibi ni gbogbo èrò tí wọn ń gbà sí mi.
Imọran to se koko fun Alalaaji lasiko Hajj: Ri wípé o ni ókun ninu dáadáa nítorí iṣẹ Hajj gba agbara diẹ.
Ìdáhùn pẹ̀lẹ́ a máa mú kí ibinu rọlẹ̀,ṣugbọn ọ̀rọ̀ líle níí ru ibinu sókè.
Ìyá òòṣà fẹ̀sùn àjẹ́ kan ìyá ẹni ọdún 90, aráàlú bá sọ ọ́ lókò pa Nàìjíríà ṣí àwọn ilé ìwé padà; Ìdánwò WAEC á bẹrẹ lẹyìn ọdún Iléyá!
Àwọn ará Harani, Kane, Edẹni, Aṣuri ati Kilimadi ń bá ọ ṣòwò.
Abrahamu sọ ọmọkunrin náà ní Isaaki.
Lẹyin eyi ni ọpọ ọmọ Naijiria ba Aarẹ Buhari ṣeto igbeyawo ofegenaa lori ayelujara Bó tilẹ̀ jẹ́ pé ìròyìn òfegè ni pé Buhari fẹ fẹ́ Sadiya, síbẹ̀ àwọn ọmọ Nàìjíríà ń ṣètò ìyàwò náà lórí ayélujára Ni ọjọ Eti ti awọn eniyan gba pe Aarẹ Buhari fẹ gbe minista Sadiya Umar Farouq ni iyawo ni Èrò yapa ní mọ́ṣáláṣí Jimọ̀h láti wá fójú lóúnjẹ lórí ìgbéyàwó òfegè Buhari.
Bi aarẹ ko ba gbagbe, o ti gba aarẹ Jonathan nimọran ri pe ko fipo aarẹ silẹ nigba ti o fi ẹsun kan Jonathan pe o ja Naijiria kulẹ lẹka didaabo bo Naijiria.
Òfin kò fẹsẹ̀ múlẹ̀ mọ́, bẹ́ẹ̀ ni kò sí ìdájọ́ òdodo.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Nigeria Police Force: Buhari f'òǹtẹ̀ lu Mohammed Adamu gẹ́gẹ́ bí Ọ̀gá ọlọ́pàá tuntun.
“Ní ọjọ́ kẹta, ẹ óo máa fi ẹgbọ̀rọ̀ akọ mààlúù mọkanla, àgbò meji ati ọ̀dọ́ àgbò mẹrinla ọlọ́dún kan tí kò ní àbààwọ́n rúbọ.
Lati ọwọ Maeve McGoldrick James Gallagher Akọroyin eto ilera Iya maa n daabo bo ọmọ wọn pẹlu omi ọyan Ti agọ ara rẹ baa n pese eroja to n gbogunti i yoo ba coronavirus ja ni eyi ti o o le fi sara ọmọ rẹ nipasẹ omi ọyan Ki abiyamọ to n fun ọmọ lọyan naa tẹle imọran awọn eeyan to ku nipa bibo ẹnu rẹ nigba ti o ba n hukọ tabi sin, sisọ tíṣu ti o lo danu sile ilẹ lẹsẹkẹsẹ, fifọ ọwọ rẹ loorekoore, ma fi ọwọ kan oju, imu ati ẹnu rẹ pẹlu ọwọ to dọti Ewu wo lo wa nibẹ fawọn ọmọde?
"O ni ""Awọn to ṣe iru nnkan bayii yii n fẹ ki awọn eeyan ro pe owo ipinlẹ Ondo ni a fi n po ọti"" Ẹ wo bí Hushpuppi ṣe farahàn nílé ẹjọ́ l'Amẹrika fún ìgbà àkọ́kọ́ láti jẹ́jọ́ Ìjọba Nàìjíríà ti mú Dókítà Anu tí àwọn kan f'ẹ̀sùn kàn pé ayédèrú iṣẹ́ abẹ ìdí ló n ṣe Erépá ní bàbá àti ìyá mi ṣe tí wọ́n fi bí mi, wọn kò fẹ́ra wọn- Funsho Adeolu Àjọ NCDC kéde ènìyàn 454 tó tún ṣẹ̀ṣẹ̀ ní Coronavirus ní Nàìjíríà Atẹjade naa tẹsiwaju pe ""Yatọ si eyi, a ṣi n reti ki awọn eeyan to wa nidi igo ọti naa ṣe awọn nnkan miran, ṣugbọn gomina ti gbe igbesẹ lati ṣawari awọn to wa nidi iṣẹlẹ ọhun."
Ẹwẹ, ọpọ awọn ololufẹ Arsenal ni iroyin yii dun mọ, niṣe ni wọn n sọ loju opo ayelujara Twitter pe ki Dangote tete wa ra ẹgbẹ agbabọọlu naa.
"Ẹ wá dánrawò níbí pẹ̀lú Àpólà Ọ̀rọ̀ Orúkọ, ""Noun Phrase"" Olùkọ́ Bunmi Femi Amao ló ń kọ́ wa ní Ọ̀rọ̀ Ẹ̀yán lonìí Wo àfipábánilòpọ̀ ẹni ọdún 51 tí ìjọba ìpínlẹ̀ Ekiti tú làṣirí ní gbangba Àwọn oúnjẹ ilẹ̀ Yorùbá ní à ń kọ nínú Akọ́mọlédè àti Àṣà lónìí Ẹ ṣúnmọ́ bí láti kọ́ ẹ̀kọ́ nípa ìsọ̀rí ọ̀rọ̀ nínú gbólóhùn Yorùbá Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Kankara Abduction: Àwọn ológun ṣàlàyé ìdí tí wọ́n fi yọ̀nda àwọn tó jí àwọn akẹ́kọ̀ọ́ gbé."
Trump, Oniṣòwò nlá ti kò ṣe iṣẹ́ Ìjọba kankan ri fún ẹgbẹ́ (Republican) àti Gary Johnson fún ẹgbẹ́ kẹta (Libertarian).
Ikú tí ń pa ọmọ aláìgbọ́ràn, ìjàgbọ̀n lórí àwọn ọmọ ènìyàn, alágbára lórí àwọn ọmọ olóríkunkun.
O ni oun fẹ wo bi minisita Dalung tabi minisita tuntun ti aarẹ Muhammadu Buhari fẹ yan yoo ṣe ti ọrọ ba gbẹyin yọ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Tacha àti BBNaija: Bobrisky fẹ́ fi mílíọ̀nù kan náírà tọrẹ fún Tacha lẹ́yìn tí wọ́n lé e ní BBNaija 28 Owewe 2019 Oríṣun àwòrán, DSTV NIGERIA Lẹyin ti Tacha ti gba idajọ kuro ni sakani mi nile ẹlẹbọn agba lọjọ Ẹti, oniruuru iha ni awọn eeyan ti kọ si ijade rẹ.
Imọ ẹrọ artificial intelligence (AI) ni wọn n lo lati fi ma a se atunse oju, enu ati ẹrẹkẹ awọn fọtọ ti wọn ba lo.
Bi o tilẹ jẹ pe ko si imọ sayẹnsi to gbe e lẹsẹ, o le ni ogun orilẹede ti awọn ayẹwo abale ti wọn n fipa ṣe yii ti n waye gẹgẹ bi ajọ iṣọkan agbaye ṣe sọ.
oselu ti iye won je mọ́kànléláàdọ́rùn
Jesu dá a lóhùn pé, “Ní gbangba ni èmi tí máa ń bá aráyé sọ̀rọ̀.
Tabi kí á fi ọ̀kọ̀ lu ihò sí imú rẹ̀?
Ẹni tí ó bá ṣe àgbèrè kò lọ́gbọ́n lórí,ẹni tí ó bá dán an wò, ara rẹ̀ ni ó ń parun.
Ajọ naa ni ewe dongoyaro ko tiẹ le ṣe adinku aarun naa lara alaisan.
Agbaye sami ayajo ojo Redio ni eyi ti ajo UNESCO fi afojusun re si ere idaraya ati asoromagbesi.
”Oba Ofem seleri atileyin awon eniyan ilu re fun aare Buhari saaju erongba re lati gba orile-ede Naijiria kuro nipo irakoro.
Ọtalelẹgbẹta ó lé mẹfa (666) ìwọ̀n talẹnti wúrà ni ó ń wọlé fún Solomoni ọba lọdọọdun, 
Mo ṣetán tí n óo gba ohun tí ń dùn ọ́ ninu lọ́wọ́ rẹ.
Ǹjẹ ó dára fún ìlera rẹ?
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìdí tí Obìnrin fi lé saǹ ìdajì owó láti ra fọ́ọ̀mù ìfèróngbà hàn 18 Owewe 2018 Oríṣun àwòrán, @Apcofficials Àkọlé àwòrán, Ìdí tí Obìnrin fi lé saǹ ìdajì owó láti ra fọ́ọ̀mù ìfèróngbà han Owó gọọbọi ní olóṣelú tó bá ń gbìyanjú láti gba fọ́ọ̀mù ìfèróngbà han lórílẹ̀-èdè Nàìjíríà nílò.
Awon miran ti won jo n finukonu si ona abayo lori isoro eto aabo Naijiria ni oga agab eso alaabo oju popo, Boboye Oyeyemi, alase awon ajo asobode; alase ile ise ijoba papo to n risi igbokegbodo irinajo awon eniyan, Mohammed Babandede ati alase ogba ewon, Jaáfarau ahmed atawon miran.
Bloomberd to bi ọmọ meji jẹ ọkan lara awọn eeyan to lọrọ ju lagbaye nigba ti wọn ṣi ohun ini rẹ si biliọnu mẹtalelaadọta.
    Nígbà tí ilẹ̀ ọjọ́ kejì mọ́, ogun tún bẹ̀rẹ̀, àwọn ẹyẹ wọ́n ja ìjà ọjọ́ kejì ní pátákí kìí ṣe àwọn ẹyẹ ńlá bí aṣdi, agbe tábì àlùkò ni wọ́n bá wa jà.
”Jonatani bá wí fún ọdọmọkunrin náà pé, “Tẹ̀lé mi, OLUWA ti fún Israẹli ní ìṣẹ́gun lórí wọn.
Nípa igbagbọ ni Noa fi kan ọkọ̀ kan, nígbà tí Ọlọrun ti fi àṣírí ohun tí yóo ṣẹlẹ̀ hàn án.
Nibẹ lo ti bẹrẹ si ni 'gun oke ẹmi', ti ko si ni mọ nkan to n lọ ni ayika rẹ fun bi ọjọ meje, lai mu omi tabi jẹun, to si sọ n sọ asọtẹlẹ.
so, o seese ki omo odun mejidinlogun ohun lo darapo mo iko agbaboolu Celtic,
Ede Yoruba kun fun owe, aṣayan ọrọ, akanlo ede, afiwe ọrọ ati awọn ọrọ akọnilẹnu.
Oríṣun àwòrán, Google Awọn ọlọpaa ni gbogbo wọn kọ ni ibọn ba lara tori gilaasi mọto lo ṣe awọn miran leṣe nibẹ.
French Open: Serena kò gbọdọ̀ wọ aṣọ 'Black Panther' mọ́
Aarẹ orile ede Amerika , Donald Trump ti so pe ohun yoo  satunse si baalu ofurufu ti ile-ise aarẹ nipa kikun un ni pupa, funfun ati buluu.
A kò fòfin de owó naira tó ti pẹ́ ní Naijiria -CBN Ẹ yé gba owó orí níbi ìdána ìyàwó mọ́, sísọmọbìnrin s'óko ẹrú ni- Daddy Freeze Ọwọ́ ọlọ́pàá ti tẹ ọkùnrin kan tó pa ọ̀rẹ́ rẹ̀ nítorí N40 ní Kano Wọ́n mú ọjọ́ ìgbẹ́jọ́ agbésúnmọ́mí 9/11 tó ṣẹlẹ̀ l'Amẹrika Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
N óo kéde òmìnira fun yín: òmìnira sí ọwọ́ ogun, àjàkálẹ̀ àrùn ati ìyàn, èmi OLUWA ni mo sọ bẹ́ẹ̀.
"Olori Aanu nu: ""Ọkọ mi ko dagba ju fun mi o, ohun to wu mi ni mo fi igbe aye nmi ṣe"" Oríṣun àwòrán, Instablog9ja O ni awọn kan tilẹ tun n sọrọ si oun pe oun jọ Bobrisky."
Ẹ wo ìṣẹ̀lẹ̀ nípa ẹ̀sùn ìfipábánilòpọ̀ tí wọ́n fi kan D'banj ní sísẹ̀-n-tẹ̀lé Ó ṣeéṣe kó jẹ́ pé àwọn alágbara ló ń fi agbára hàn lórí arábìnrin tó fẹ̀sùn ìfipábánilòpọ̀ kan kọmíṣọ́nà Kogi -Agbẹjọ́rò Bíbéèrè fún ìbálòpọ̀ gbogbo ìgbà sọ ìyàwó ilé dèrò ilé ìwòsàn Wo àfipábánilòpọ̀ ẹni ọdún 51 tí ìjọba ìpínlẹ̀ Ekiti tú làṣirí ní gbangba Ìdí rèé tí mo fi ṣẹ̀ṣẹ̀ sọ̀rọ̀ lẹ́yìn tí wọ́n fipá bámi lopọ̀ lọ́mọ ọdún méje lọ́gọ́ta ọdún sẹ́yìn-Eli Agbẹnusọ fun ileeṣẹ ọlọpaa ni agbagbe naa, ASP Godwin Ahianyo si fidi iṣẹlẹ naa mulẹ fun BBC.
Ọrọ ati alaye le pọ ninu iroyin naa, eyi si mu ki o rọrun lati gba a gbọ.
Elẹ́ẹ̀kẹrin ni awọn ti wọn ba fi àmì ẹ̀yẹ ijọba àpapọ̀ da lọ́lá.
Iko Eaglets fagbahan Ghana pelu ami-ayo meta sookan(3-1) ninu boolu agbesile gba(penalty shootout) lojo abameta(Saturday) lati pegede fun idije U17 AFCON.
Nipost, tíí ṣe orogún wa, kò lẹ́tọ̀ọ́ láti díye lé wa - Iléeṣẹ́ abáni fi ẹrù ránṣẹ́ yarí Wo ọkùnrin tó fipá bá ìyá ọdún 60 lò nítorí 'ìkébè rẹ̀ tó ń mì Akpabio ni Nwaboachi ti gba iṣẹ́ kọngilá tọ tó mẹ́tàléláàdọ́ta lọ́wọ́ àjọ náà.
Florence tahun si igbakeji gomina ipinlẹ Oyo, Rauf Olaniyan to lewaju igbimọ alasẹ ìjọba ipinlẹ Oyo wa ba kẹdun iku ọkọ rẹ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Human trafficking: Ààrẹ Buhari, ẹ̀yin gómìnà ìpínlẹ̀ Yorùbá, ẹ rántí wa ní Oman, àwọn ọmọ Wọn tun gbajumọ fun lilo adalu oogun oloro bi i Codeine, Rephnol, Tramadol, ati igbó.
 Àwọn ọmọ yorùbá ń jẹ ogójì mílíọ ̀ nù papò , wọn dẹ ́ jẹ ìkan nínú àwọn ẹ ̀ yà tó tóbi jú ní Áfríkà .
Ọgbọ́n níye lóríó ju ohun ọ̀ṣọ́ olówó iyebíye lọ,kò sí ohun tí o lè fi wé e,ninu gbogbo ohun tí ọkàn rẹ lè fẹ́.
Ó bí ọmọkunrin kan fún un, ṣugbọn inú OLUWA kò dùn sí ohun tí Dafidi ṣe.
( a ) Àgẹ ̀ rẹ ̀ : - eyí ni ìlù to tobi ju pátápátá .
Fun idi eyi, ololufẹ ẹni ma n ni aye lati ṣe bo ṣe wu nigba ti ọwọ wọn ba ti dinlẹ, igba yẹn gan ni wọn ma n ri aye lati fa wahala lẹsẹ.
Eyi ko ṣẹyin awuyewuye to n waye lori boya ki awọn ọmọ Naijiria ma a gbe ibọn ilẹwọ bii AK47 lati koju eto aabo to mẹhẹ.
Akeredolu, lasiko to n foju laifi wo amulo baba isalẹ to fojuhan ni Edo, tun fikun pe o foju han gbangba ninu idibo naa pe agbara awọn baba isalẹ ti n lọ silẹ ni Naijiria.
27 Òkùdu 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 12 Èbibi 2020 BBC Yorùba ń gbìyànjú látí gbé àṣà Yorùbá díde padà.
  Sirika so pe nigba ti  ajo to n mujoto eto irinna fẹ  ra baalu naa, opolopo  awọn  eniyan  ni wọn  pe  lati se ifọrọwanilẹnuwo fun un, lara  awọn  ni  awọn  oloselu, ile-ise aladaani,  awọn  onimo, omo ile –iwe ati  awọn  eniyan jake-jado orilẹ ede  Naijiria.
Irúgbìn rere ni àwọn ọmọ ìjọba ọ̀run.
Ninu ipinu wọn, ajọ ti ń se amojuto ilana isẹ ere bọọlu afẹsẹgba naa wipe ọgbeni Siasia jẹbi lodi si ilana ti FIFA gbekale.
Aago mẹjọ ọjọ Aiku to kọja ti eto idibo naa pari ni wọn ti bẹrẹ si ni ka esi idibo naa lati ẹkun kan si ikeji.
Ṣugbọn àwọn yòókù ń sọ pé, “Fi í sílẹ̀!
Ọba fẹ́ràn rẹ̀ ju gbogbo àwọn obinrin yòókù lọ, ó sì rí ojurere ọba ju gbogbo àwọn wundia yòókù lọ.
” Irú ìbéèrè bẹ́ẹ̀ kò mọ́gbọ́n lọ́wọ́.
Ousmane Dembele ropo Messi niseju márùndínlọ́gbọ̀n leyin ti dokita iko agbaboolu naa jabo pe ko ni le e tesiwaju mo.
” Wọ́n sì dá a lóhùn pé, “Alaafia ni, wò ó, Rakẹli, ọmọbinrin rẹ̀, ni ó ń da aguntan bọ̀ ní ọ̀kánkán yìí.
Wọn kédé Narendra, oludije ẹgbẹ́ BJP ni India pẹ̀lú ariwo ńla Ìjí líle, Cyclone Fani, kọlu Ìlà-Oòrùn India Kí ló yẹ ká se sí ẹkùn tó pa ènìyàn márùń?
Nigba ti o n tẹnu mọ akitiyan Ajọ INEC lati tubọ kaaramasiki akitiyan ati ṣaṣeyori ju ti eto idibo ọdun 2015, Alakoso ajọ Eleto Idibo naa sọ pe ni bayii, igberu ti ba awọn ọna iṣiṣẹ wọn, bii awọn ohun eelo ti wọn n lo, awọn oṣiṣẹ wọn, ati bi wọn ṣe n fesi ibo ranṣẹ lati awọn ibudo idibo.
A óo sì fi wọ́n lé e lọ́wọ́ fún ọdún mẹta ati ààbọ̀.
 wọ ́ n fún ní ẹ ̀ bùn góòlú ní exposition universelle of 1900 àti ní ọdun 1912 tí ó gba médaille d ' honneur .
Ẹ̀kún omi ṣọṣẹ́ ní Ogun, ìjọba yarí láti wó ilé ojú odò Mà á gbẹ̀san bàálù àjọ UN tó já ní Borno - Buhari yarí Nǹkan yan ní Ghana, ààrẹ fojú kan alárùn Coronavirus, ló bá yara rẹ̀ sọ́tọ̀ Òṣìṣẹ́ LASTMA gún olólùfẹ́ rẹ̀ l'ọ́bẹ, ó tún gba ẹ̀mí ara rẹ̀ l'Eko Ìjọba fọkàn àwọn olùgbé ìlú Eko balẹ̀ lórí afárá Ẹka ijọba to n ri si ọrọ ina mọnamọna, iṣẹ ṣiṣe ati ile gbigbe ti kede wi pe ko sewu pẹlu afara Third Mainland niluu Eko.
O wá àwọn ẹlẹ́rìí tuntun pé kí wọ́n dojú kọ mí,O tún bẹ̀rẹ̀ sí bínú sí mi lọpọlọpọ,O mú kí ogun mìíràn dó tì mí.
Tẹmpili tí à ń tún kọ́ yìí, ọba olókìkí kan ni ó kọ́ ọ parí ní ọpọlọpọ ọdún sẹ́yìn.
Ó tún pa òwe mìíràn fún wọn.
(A pa orukọ Nazanin da ni lati le da abo bo o) Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Bí àwọn Gomina ṣe ń gbé sàdánkata kare fun Asiwaju Ahmed Tinubu fun àwọn kókó ọ̀rọ̀ to fi síta àti pé àwọn yóò ṣe àmúlò àwọn ìmọràn to wà níbẹ̀, ẹgbẹ́ Afẹnifẹre ni ọ̀rọ̀ ti Asiwaju sọ ko ni ohun arígbámu kankan.
Nítorí náà, kì í ṣe ẹ̀yin ni ẹ gbé mi dé ìhín, Ọlọrun ni, ó sì ti fi mí ṣe baba fún Farao, ati oluwa ninu gbogbo ilé rẹ̀ ati alákòóso gbogbo ilẹ̀ Ijipti.
Funmilayọ Ransome Kuti jẹ ọmọ iya aranṣọ àti agbẹ ti baba rẹ ti oko ẹru de ni ilẹ Saro.
Àwọn nǹkankan wà tíí mi ilẹ̀ tìtì,ọ̀pọ̀ nǹkan wà tí ilẹ̀ kò lè gbà mọ́ra:
Ajọ NDDC lo fi lede pe o ti to ọsẹ meji ti Pondei ti n ṣe aisan ti dokita si kilọ fun un pe ko ma lọ fun ifọrọwanilẹnuwo to waye ni Ile Igbimọ Aṣofin naa.
Jonatani bá bá Dafidi dá majẹmu, nítorí pé ó fẹ́ràn rẹ̀ gẹ́gẹ́ bí ẹ̀mí ara rẹ̀.
Orúkọ àbíkẹ́yìn tí ó jẹ́ obìnrin sì ni Ìparun.
Awọn ẹlomiran a ma tu kẹlẹbẹ.
Tedros dipo Margaret Chan ti saa re yoo tan ni ipari osu kefa odun ti a wa yii, leyin ti o ti dipo naa mu fun odidi odun mewaa gbako.
Ẹ̀bẹ̀ ni talaka bẹ̀,ṣugbọn ọlọ́rọ̀ á dáhùn tìkanra-tìkanra.
Ó ṣàlàyé pé May sọ pé àwọn yóò rán orile-ede lábẹ́ Commonwealth lọwọ láti fi ààyè gba ètò ìgbéyàwó ọkùnrin ṣókùnkùn àti obìnrin sobinrin nínú ìwé òfin orile-ede kòwá wọn tó setan láti fàyè gbà á.
gbogun ti fifi omo se okoowo.
Sugbọn nigba ti a kan si kọmisana fun eto iroyin ati aṣa nipinlẹ Ọyọ, Ọgbẹni Toye Arulogun, ti Yinka Ayefẹlẹ fi ẹsun kan pe oun lo wa nidi iṣẹlẹ naa, Arulogun ni 'ti wọn ba sọ pe oun ni, oun naa ni.
 carlos chagas ni ó kọ ́ kọ ́ ṣàpéjúwe àrùn yìí ní ọdun 1909 .
Ṣaaju ni awọn dokita ọhun ti kọkọ gunle iyanṣẹlodi ọlọjọ mẹta lati fa ijọba leti lẹyin ti wọn ni o jẹ wọn lowo oṣu mẹrin.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Minimum wage: 30,000 Naira ni ẹgbẹ́ òṣìṣẹ́ n bèèrè fún 22 Sẹ́rẹ́ 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ọ̀rọ̀ ẹ̀kúnwó oṣù tuntun ló ń fa èdèàìyedè láàárín ìjọba àpapọ̀ àti àwọn ẹgbẹ́ òṣìṣẹ́ lórílẹ̀èdè Nàìjíríà Ẹgbẹ osisẹ lorilẹ-ede Naijiria ti kọ lati gba ẹgbẹrun lọna mẹtadinlọgbọn gẹgẹ bi gbẹndeke owo osu awọn osisẹ lorilẹ-ede Naijiria.
MTN, Banki mẹ́rin wọ gàù CBN Àwọn osisẹ yabo iléesé MTN ní Nàìjíríà CBN gbé òfin tuntun jáde fún àwọn Báǹkì ‘UK yóò pèsè isẹ́ 100,000 ní Nàìjíríà’ Àjọ Nigeria Communications Commission (NCC) to n mojuto ọrọ eto ibanisọrọ ni Naijiria fifidi ẹ mulẹ pe awọn ti ri ifitonileti banki lori owó naa gbà lọjọ Eti.
Rykardo Agbor: Oríṣun àwòrán, Rykardo Agbor Ọmọ bibi ipinlẹ Delta naa ni Rykardo Agbor amọ to gbe ilu Eko dagba.
Ṣugbọn aṣálẹ̀ ni ó máa ń lọ láti dá gbadura.
Lọwọ yii, Israel ni igbanu ''UFC Middleweight'' wa lọwọ rẹ lagbaaye.
Ikọ BBC Yoruba ṣe abẹwo si agbegbe naa l'ọjọ Iṣegun, ohun ti a fi oju ri si ba ni lọkan jẹ pupọ.
O le ni ọgọ́ta awon eniyan ti won ti gba iwe idije fun awon ipo to si sile ninu egbe APC fun eto idibo to n bo.
Ọwọ ṣìkún òfin ti tẹ Maina, alága àná fún ọrọ owó ìfèyìntì - DSS Ẹ tètè pè fún àjọ tó ní irònú pìwàdà kó tó pẹjù- NLC/TUC Ilééṣẹ́ Aṣọ́bodè Naijiria n pa bílíọ̀nù N5.
Wọ́n gbẹ́ àwòrán igi ọ̀pẹ ati kerubu sí ara ìlẹ̀kùn ibi mímọ́ jùlọ, bí èyí tí wọ́n gbẹ́ sí ara àwọn ògiri.
Mo bá dá a lóhùn pé, “Alàgbà, ìwọ ni ó mọ̀ wọ́n.
” Wọ́n bá jáde lọ sí inú àwọn ẹlẹ́dẹ̀.
Ẹgbẹrun kan oṣiṣẹ si ni wọn o gba sisẹ ni ijọba ibilẹ kọọkan, eyi tumọ si pe ẹgbẹrun lọna ọrinlelẹẹdẹgbẹrin din mẹfa ni apapọ awọn ọdọ ti ijọba apapọ yoo gba sisẹ.
Arafat Day: Wo àwọn ohun márùn-ún tí ayájọ́ òní fi lọ́lá jùlọ nínú Islam
Ariṣe ni arika, arika ni baba iregun ni ero awọn mii pe aya aarẹ ti lo iru ọgbọn arekereke yii sẹyin lati fi ri ohun to n fẹ ni, ati pe ina èṣìṣì kii jo ni lẹẹmeji.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Bimpe: Èèyàn bíi tiyín ni àfín, ẹ dẹ́kun dídẹ́yẹsí àfín 5.
OLUWA tí ó kọ́ ilé gíga rẹ̀ sí ojú ọ̀run,tí ó gbé awọsanma lé orí ilẹ̀ ayétí ó pe omi òkun jáde,tí ó sì dà á sórí ilẹ̀,OLUWA ni orúkọ rẹ̀.
Àkọsílẹ̀ ìran Tẹra nìyí: Tẹra ni baba Abramu, Nahori ati Harani.
Bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé Yomi Ogunmola tí di ará ilẹ̀, sibẹ, Peju sì wà láyé, tó ń dá bíi ẹdun, rọ bíi oowe lagbo tíátà, ìlú Òkè Imesi nipinlẹ Ekiti, si ni ilu abinibi wọn.
Kí ni Wòlíì Sotitobire yóò bá bọ̀ nílé ẹjọ́ lónìí?
Ìwọ ni ibi ìsásí mi;o pa mí mọ́ kúrò ninu ìṣòro;o sì fi ìgbàlà yí mi ká.
Eto bibuwọlu ilana tuntun naa yẹ ko waye ni ọjọ isẹgun, ọjọ kọkanlelogun osu kẹta ọdun 2018.
Kíyèsí i ìwọ rí ìyyà tíóń jẹ ọkùnrin náà nínú ilé mi, má ṣe rò pé ìkàni a ń ṣe sí i nì, nítorí nígbà tí ọkùnrin yìí wà ní òde ayé, tí ó wà ní ipò giga, ó ti pàṣẹ kí wọ́n bẹ́ ọ̀pọ̀lọpọ̀ ènìyàn lórí, kí wọ́n ṣá ọ̀pọ̀lọpọ̀ ènìyàn lọ́gbẹ́, kí wọ́n fi ìyà búburú jẹ ogunlọ́gọ̀ àwọn ọmọ ènìyàn láìníddìí.
Kí ló dé tí o fi kó ìkógun, tí o sì ṣe nǹkan burúkú lójú OLUWA?
Iyẹn ni pe, Kabiesi wa pẹlu awọn baba nla rẹ to si jẹ pe nnkan to ba foju ba le e ni apẹrẹ paapaa julọ to ba jẹ ikoko.
Lẹ́yìn náà ó lọ sí ìdálẹ̀.
Nígbà tí wọ́n dé àtẹ̀gùn ilé, gbígbé ni àwọn ọmọ-ogun níláti gbé Paulu wọlé nítorí ojú àwọn èrò ti ranko.
Ken Saro-Wiwa n sọrọ tako ijọba ologun ti Ọgagun Abacha ati ile isẹ iwako epo lati ilẹ okeere, Anglo-Dutch petroleum company, Royal/Dutch/Shell fun bi wọn be se n ṣe akoba fun agbegbe naa ti wọn ti n wa epo rọbi.
Kà nípa ibi tí wọ́n bí Àrẹ̀mọ tuntun Ọọ̀ni Ife sí, àti orúkọ tó ń jẹ́ Kílódé tí Ọọni Ife, Oba Ogunwusi kò fi gbọdọ̀ rí ọmọ rẹ̀ tuntun ti Olorì Naomi bí títí di bíi ẹ̀yìn oṣù mẹ́fà?
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ladoja: Àwọn èèyàn Oyo fì ìbò sọ̀rọ̀ pé ìjọba Ajimobi kò dára Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Iba Gani Adams: Bẹ́ẹ gbé màláíkà kan lọ sí Aso Rock, kò lè ṣàṣeyọrí Ọjọ kọkandinlọgbọn yoo kan jẹ ọjọ ifilọlẹ ati iburawọle ijọba tuntun lorilẹede Naijiria.
Kò sí ohun tí ó jọ bẹ́ẹ̀.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Lagos-Ibadan: Èèyàn mẹ́tàlá dèrò ọ̀run nínú ìjàmbá ọkọ̀ lọ́nà Ìbàdàn sí ÈKó 14 Bélú 2019 Oríṣun àwòrán, others Àkọlé àwòrán, Lara awọn to ba iṣẹlẹ ọhun lọ ni okunrin mẹrin, obinrin meje ati ọmọde meji Ajọ ẹṣọ oju popo, FRSC sọ pe, ijamba ọkọ to waye lopopona Ibadan si ilu Eko ti mu ẹmi eeyan mẹtala lọ.
N óo tú ọgbà tí mo ṣe yí i ká,iná yóo sì jó o.
Ṣugbọn Jesu dá a lóhùn pé, “Kò dára láti sọ oúnjẹ ọmọ eniyan sóde sí àwọn ajá!
Sowore ni kiakia lohun yoo yan awọn ti yoo ṣe ijọba ti awọn ko si ni dawọ iṣejọba duro.
Hanifa Zaara ninu lẹta to kọ si ile isẹ ọlọpaa sọ wi pe baba oun rẹ oun jẹ nitori naa ki wọn fi panpẹ ọlọpaa gbe.
Wúrà wọn yóo sì dàbí ohun àìmọ́.
Di ẹ̀rí náà, fi èdìdì di ẹ̀kọ́ náà láàrin àwọn ọmọ ẹ̀yìn mi.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ sí: EFCC fẹ́ bẹ̀rẹ̀ ìwádìí Fayoṣe Ekiti!
ibi taya  ati igi ti won n jo, bakan naa
orile ede Naijiria, Super Eagles ti fimu  iko agbabọọlu Bafana Bafana ti  orile ede South Africa fọn fere Aworawọ inu
Buhari tun ki gbogbo idile Jonathan pe ọpọ ọdun ni yoo ṣe loke eepẹ.
Ọba sì ń gbèrò láti fi gbogbo ọ̀rọ̀ ìjọba lé e lọ́wọ́.
Dokita onimọ ijinlẹ nipa aisan, Tunji Abolarin salaye fun BBC pe irọ ni wi pe ẹni ti ojo ba pa le e ni aisan iba, ati wi pe ẹrọ amuletutu kii pa ẹfọn.
'Ojú mi rí tóó, àwọn ìyàwó kìí ṣiṣẹ́, ọkọ àtàwa ọmọ-ọ̀dọ̀ laláṣekú lórílẹ̀èdè Oman' Ǹjẹ́ ẹ mọ̀ pé Cameroon ni wọ́n ti ru Kìnìhún VI wá?
Àwọn eniyan inú rẹ̀ ń jìyà ẹ̀ṣẹ̀ wọn,iná ń jó àwọn olùgbé inú rẹ̀,eniyan díẹ̀ ni ó sì kù.
Nítorí náà, ẹ gbé àánú wọ̀ bí ẹ̀wù, ati inú rere, ìrẹ̀lẹ̀, ìwà pẹ̀lẹ́ ati sùúrù, bí ó ti yẹ àwọn ẹni tí Ọlọrun yàn, tí wọ́n sì jẹ́ eniyan Ọlọrun ati àyànfẹ́ rẹ̀.
 Besini, ewu tuntun ohun ni Nike pese lati buyi kun asa orile-ede yii.
Yorùbá má ńpe Egúngún/Eégún ni “Ará Ọ̀run”.
Evariste Ndayishimiye di ààrẹ tuntun lórílẹ̀èdè Burundi Wo bí o ṣe leè lo èròjà agbohùnsílẹ̀ tuntun tí Twitter gbé dé Òjò àrọ̀ọ̀rọ̀dá dá wàhálà sílẹ̀ l'Eko Gómìnà márùn ún tó fojú winá ìbínú bàbá ìsàlẹ̀ wọ̀n Nibi ijoko ile aṣofin agba nibi ti wọn ti gbe ijoko kan kalẹ lati fi daro eekan orilẹ-ede Naijiria kan to jade laye ni o ti ṣẹlẹ Gbogbo awọn aṣofin agba ni wọn sọrọ ni ṣiṣẹ n tẹle lori oloogbe naa laiyọ Pepperito naa silẹ.
A o ni gba jiji apoti ibo gbe tabi ọrọ to lee mu wahala dani laaye ki eto idibo to bere, lasiko eto ibo tabi lẹyin eto idibo.
Nollywood: Àwọn obìnrin Yollywood tó ń tà wàrà-wàrà
Nínú fọnran ohùn kan tó wà nígboro ní Leah Sharibu tí ń rọ ìjọba orilẹ̀-èdè Nàìjíríà láti yọ ohun kúrò lọ́wọ́ ikọ̀ Boko Haram.
Gbogbo àwọn ọmọ Israẹli bá túká lọ́dọ̀ Mose.
Èmi kò forí ṣọta ìjàmbá ọkọ̀ òfúrufú kankan - Obasanjo Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Jiti Ogunye: Ìjọba àkóbá lológun gbé kalẹ̀ ni 1999 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ondo 2020: Afẹnifẹrẹ ní kí Tinubu sọ fún ẹgbẹ́ APC láti ṣe àmúṣẹ́ ilérí rẹ̀ fọ́mọ Nàíjíríà 6 Owewe 2020 Oríṣun àwòrán, Twitter Àkọlé àwòrán, Asiwaju Bola Ahmed Tinubu nibi iside ipolongo idibo gomina ipinlẹ Ondo lo ti pe fun atunto lori bi owo ṣe n wọle fun Naijiria labẹle.
Abilekọ Madikizela-Mandela ni oun ko jẹbi iwa buburu kankan.
"Bí ẹ bá rántí rẹ,̀ ẹ kọ ""Bẹ́ẹ̀ni"", bí ẹ ò bá rántí rẹ̀, ẹ kọ ""bẹ́ẹ̀kọ́"", bí ẹ ò bá gbọ́ ọ rí, ẹ kọ ""Mi ò mọ̀ ọ́n o"
Bakan naa lo ti jẹ ẹbun lati polowo ọja, eroja iṣaraloge, ounjẹ ọfẹ, ohun elo inu ile, aṣoju ileeṣẹ, irinajo si Scotland, ati ẹẹdẹgblta Dọla owo Bitcoin.
Ọbásanjọ́ tẹnu mọ́ ọn wípé Buhari kò leè “ṣe ètò ìbò tí ó kẹ́sẹjárí”, àti wípé ìsèjọba tiwantiwa ní abẹ́ ìṣàkóso Buhari ni a lè fi wé tí ìjọba ológun fàmílétè-kí-n-tutọ́ọ ti Abacha.
Aájò mi tí ẹ ṣe ní ọjọ́ tí Ẹlẹ́gbára fi lé mi tí mo já lu omi kò le ṣé e gbágbé bí mo tilẹ̀ gbàgbé ẹ̀yin pàápàá.
Ojú sì ń tì mí láti máa ṣagbe.
Njẹ idibo alatẹjiṣẹ imeeli maa n ṣokunfa iwa ole ninu idibo?
”O ni erongba aare Muhammadu Buhari lo mu ipade iketa yii wa si imusẹ.
Ẹ máa tọ́jú wọn kí ẹ sì máa pa wọ́n mọ́ títí tí ẹ óo fi wọ̀n wọ́n níwájú àwọn olórí alufaa, àwọn ọmọ Lefi ati àwọn baálé baálé Israẹli ní Jerusalẹmu ninu yàrá ilé OLUWA.
Olayinka Olayanju nígbà ti àwọn oníròyìn kàn sí ló sàlàyé pé òun yóò yọjú síbẹ̀ láti mọ ìdí ǹkan tó ṣẹlẹ̀ ni pàtó, sùgbọ́n pàbó ló jásí pẹ̀lú gbogbo ìgbìyànjú BBC lati gbọ abábọ ìṣẹ̀lẹ̀ náàbi àgbẹnusọ ikọ̀ àmọtẹ́kùn ko ṣe gbé aago wọ́n mọ́.
"Gbogbo ẹbi mi ló ti lọ fún àyẹwò, a ń duró fún èsì àyẹwò wọ́n,"" Kí ló ṣẹlẹ̀ tí àwọn ọmọogun Nàìjíríà tó lé ní 350 fẹ́ kọ̀we fi iṣẹ́ sílẹ̀?"
Lodun 2015 lo koko sagbekale itakun agbaye fun gbigbe Trump lo sise nile ijoba ile Amerika, iyen, White House ki won to gba a gege bi oludari ipolongo.
Ìran Eleasari ati àwọn arọmọdọmọ rẹ̀ nìwọ̀nyí: Eleasari ni baba Finehasi, Finehasi ni ó bí Abiṣua; 
Iye awọn to ti ri iwosan ti jẹ 3122, ti awọn to si ti ku nitori arun naa lorileede Naijiria ti jẹ 299.
Ó pín ẹran náà fún àwọn eniyan, wọ́n sì jẹ ẹ́.
"  Nkò le sọ jù bẹ́ẹ̀ lọ, à ń ṣe ìwádiìí ọ̀rọ̀ náà lọ́wọ́"" O ní ọkunrin tó ń wa ọkọ ayọkẹlẹ Benz náà jọ bi ẹni pé ó tí mu oti yó ti kò si si nọmba idákọmọ nígbà ti ìṣẹ̀lẹ̀ náà ṣẹlẹ̀."
Ni Mọsuari ileeṣẹ ologun to wa niluu Abuja ni wọn yoo sin Tolu si.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Odebiyi: ìgbà gbogbo ni Bàbá mi ń polówó iṣẹ́ mi fáráyé Nigba to n sọ pataki orin Fuji fun iran Yoruba, gbajugbaja olorin Bọnsue naa rọ ọmọ Yoruba kọọkan, lati tẹwọgba orin Fuji .
Lagbaye, o le ni igba milionu obinrin ti won ti la asa yii koja seyin ni eyi ti awon odobinrin ti ojo ori won ko ju omo odun merinla lo ti to milionu merinlelogoji ti won ti da abe fun.
Èyí kò rí bí ajàfẹ́tọ̀ọ́ AL náà ti ṣe wí, kò sí ohun tó jọ ọ́, kò sí àṣẹ tí ó ní kí wọ́n tà tàbí wó ilé tí à ń sọ̀rọ̀ọ rẹ̀ yìí.
Aarẹ Ọna Kakanfo wa n kọminu pe ilẹ Yoruba ti n di ibudo fáwọn afẹjẹwẹ ati adunkooko mọni, to n dibọn bii darandaran.
Joke Silva: Alágbàtọ́ ló gbà á nílé ọmọ aláìníyá, tó sì wò ó dàgbà
Adajọ ni ọga ọlọpaa Gwazah ko ni idi bo ti le wu kori lati ma yọju sile ẹjọ, to ba jẹ pe ọrọ naa ka a lara.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Russia 2018: Àwòrán nọ́mbà jẹẹsí Super Eagles fún Russia rèé 4 Òkùdu 2018 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 6 Òkùdu 2018 Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Super Eagles: Àwòrán nọ́mbà jẹẹsí Super eagles fún Russia rèé Ajọ NFF ti fi orukọ ati nọmba jẹẹsi awọn agbabọọlu Super eagles ti yoo kopa ninu idije ife ẹyẹ agbaye ni Russia sita.
Agbenuso kan fun ile-ise iroyin AFP so pe, “orire ni lati ri akikanju ati akoni eniyan ti o gboju-gboya lati le lo gbe omo naa sokale”.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ sí: Àwọn ọ̀nà tí obìnrin fi le gbádùn ìbálòpọ̀ Emmerson Mnangagwa jáwé olúbori ní Zimbabwe Láì déènà pẹnu lórí iṣẹ́ tí a gbudọ̀ mú ṣe, èto kan lórí BBC Crossing Continent tí fi ọ̀pọ̀ àkókò sínú ìwádìí láti mọ oriṣi ọna ìbálòpọ̀ lágbàyé.
A ní ìrọwọ́-rọsẹ̀ tó ti wà láti ìbẹ̀rẹ̀pẹ̀pẹ̀ àgbáyé yìí ò tẹ́ wa lọ́rùn o.
Ibalopọ lati ri ojurere lọdọ awọn okunrin je idojukọ nla fun awọn agbabọọlu Super Falcons
Ọpọlọpọ awọn ọmọ Naijiria lo n ja ara jẹ pe ọrs naa fẹ ṣebi eyi to mu ifunra dani.
Ẹwẹ, ẹgbẹ agbabọọlu Arsenal gbarada lẹyin ti wọn run Norwich mọlẹ jegejege ni papa isẹre Emirates pẹlu ayo mẹrin ọtọtọ sodo.
DOMINICA: Ookanlelogun ọjọ pere ni anfani mọ ni ilu yii.
Ó ní ẹ̀ ń ranti wa sí rere nígbà gbogbo, ati pé bí ọkàn yin ti ń fà wá, bẹ́ẹ̀ ni ọkàn ti àwa náà ń fà yín.
Ńṣe ni n óo wó àwọn abà mi.
O tun sọ pe owo gọbọi l'oun gba lọwọ Kenyamo fun iṣẹ t'oun ṣe, ṣugbọn owo oogu oju oun lowo.
ẹ̀rù wọn ba òun ati àwọn eniyan rẹ̀ lọpọlọpọ, nítorí pé wọ́n pọ̀.
Eyi lo difa fun oṣere tiata Yoruba, Wunmi Toriola bimọ rẹ akọkọ silu Amẹrika lọjọ kẹrinla, oṣu kẹwaa ọdun 2019.
Àwọn 'ẹ̀bùn' tí ikú George Floyd fún àgbáyé Ìwọ́de gbòde kán lórílẹ̀èdè Amẹ́ríkà nítorí ikú George Floyd Coronavirus in Kenya: Ojú òpó Facebook Live ni mo ti wo ìsìnkú ìbátan mi 'Bí Covid19 bá peléke síi l'Eko, ilé la ó ti máa tọ́jú àwọn kan' - Ìjọba ìpínlẹ̀ Eko Ikú tó pa Igbákèjì adarí òṣìṣẹ́ ní Osun kìí ṣe Coronavirus - Gomina Oyetola Nǹkan oṣù obìnrin le jáde ní imú tàbí ìdodo yàtọ̀ sí ojú ara - Dókítà Ileeṣẹ ọlọpaa Met ti fote le iwọde ṣiṣe nitori ohun to ṣẹlẹ nigba tawọn eeyan kan n fẹhonuhan lopin ọsẹ to lọ.
agbegbe ati  mimojuto  imototo agbegbe soro  ni gbongan awon lọba-lọba
Bí ológoṣẹ́ tí ń rábàbà kiri,ati bí alápàáǹdẹ̀dẹ̀ tí ń fò ká,bẹ́ẹ̀ ni èpè tí kò nídìí, kì í balẹ̀ síbìkan.
ohun lagbaye iko agbaboolu Belgium dipo kinni won mu, France dipo keji mu, Brazil
Abialiboni ará Araba, ati Asimafeti ará Bahurimu; 
"Ijọba sọ fun wa pe a ko gbọdọ jade lọ se agbe loju popo, a gbọ si wọn lẹnu, a si pa owo wa pọ lati ra kẹkẹ Maruwa, ko lee maa mu owo wale fun wa.
Ẹyọ ẹnìkan ṣoṣo ṣe lè lé ẹgbẹrun eniyan?
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Omolola Arohunmolase Welder: Mo ti fí iṣẹ́ 'Welder' gbayì láwùjọ, tó mo fi tọ́ ọmọ yanjú Igbesẹ Mbaka yii gan lo sewuri fun awọn gende ọkunrin naa lati maa tẹsiwaju nidi ikọlu ti wọn n se, ti Fada Mbaka naa si n pariwo lati maa bu wa."
Mo tún bèèrè lẹẹkeji pé, “Kí ni ìtumọ̀ ẹ̀ka olifi meji, tí ó wà lẹ́gbẹ̀ẹ́ fèrè wúrà meji, tí òróró olifi ń ṣàn jáde ninu wọn?
Megan Rapinoe jẹ ọmọ ọdun mẹrinlelọgbọn to ti wa lẹnu owo bọọlu gbigba lọdun melo sẹyin.
Àwọn tí wọ́n tẹ̀lé Joabu jókòó sí ẹ̀gbẹ́ kan adágún náà, àwọn tí wọ́n wà lẹ́yìn Abineri náà sì jókòó sí òdìkejì.
Tijo tayọ lawọn to dari fi balẹ silu Eko ti awọn aṣoju ijọba Naijiria si wa sda wọn ni kaabọ.
OLUWA, ṣebí òtítọ́ ni ò ń fẹ́?
Lọjọ kinni, oṣu keje lawọn ileeṣẹ ina ọba fẹ kawọn onibara wọn bẹrẹ si ni san owo ina tuntun tẹlẹ, Ṣugbọn ile igbimọ aṣofin agba l'Abuja ni ki wọn duro di ibẹrẹ ọdun 2021 nitori bi ilu ṣe ri bayii.
Lati inu ọdun 2015 ni wọn ti fi El-Zakzaky satimọle.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Election Update 2019: Aráàlú ní ẹ́yìn lílọ Saraki, Kwara yóò ṣún síwájú ni Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Election Update 2019: Aráàlú ní ẹ́yìn lílọ Saraki, Kwara yóò ṣún síwájú ni 26 Èrèlè 2019 BBC Yorùbá lọ yíká ìgboro ìlú Ilọrin, láti mọ ipa tí ìfìdírẹmi ààrẹ ilé aṣòfin àgbà, Bukọla Saraki nínú ìbò sílé aṣòfin àgbà, yóò ní lórí àwọn èèyàn ìpínlẹ̀ náà.
jẹ ki erongba ati afojusun ijoba to wa lode pelu Oga agba ile -ise ọlọpaa
Ohun tí o kò mọ̀ nípa Hosni Mubarak, Ààrẹ Egypt tó papòdà Saaju ki iroyin to gbe e pe oṣiṣẹ eleto ilẹra maa n fi sun omi lara pupọ pupọ lasiko to n ba awọn eniyan sọrọ ninu ẹrọ tẹlifisan ni ọjọ aje.
Ọba ti fi àṣẹ lélẹ̀ nípa iṣẹ́ àwọn akọrin, ètò sì wà fún ohun tí wọ́n gbọdọ̀ máa fún wọn lojoojumọ.
Bi wọn ṣe n ṣe akara oyinbo.
Wọn yóo sì tà wọ́n fún àwọn ará Sabea, orílẹ̀-èdè tí ó jìnnà réré; nítorí OLUWA ni ó sọ bẹ́ẹ̀.
Báyìí ni Àrẹ̀mọ Ooni Adeyeye Ogunwusi ṣe wọ ṣọ́ọ̀ṣì fún ìgbà àkọ́kọ́ láti bá bàbá rẹ̀ ṣe ìdúpẹ́ ìwúyè Wo ìdí tí ọmọ ọdún mẹ́wàá ṣe ti àbúrò rẹ̀ ọmọ ọdun kan àbọ̀ sínú kàǹga 'Ìdí tí a ò fi pa àwọn ajínigbé tó gbé àwọn akẹ́kọ̀ọ́ Kankara nìyìí' Mo gbóríyìn fún Buhari bó ṣe dóòlà ẹ̀mí àwọn akẹ́kọ̀ọ́ tí wọ́n jí gbé ní Kankara Aya gómìnà Kwara gba ilé fún Risikat olójú búlúù àti ọkọ rẹ̀ Risikat, ìyá àwọn ọmọ olójú búlù tí bẹ̀rẹ̀ sí ní kọ́sẹ́ aṣojú lóge Báwo ni mo ṣe fẹ́ fi ìyàwó àfẹ́sọ́nà mi akáta hàn fáwọn òbí mi?
Ní ìbẹ̀rẹ̀ ìjọba Ahasu-erusi, àwọn kan kọ ìwé wọ́n fi ẹ̀sùn kan àwọn tí ń gbé Juda ati Jerusalẹmu.
--------------------------------------------------------------------------------------------------------------- Naira Marley rẹwọn he, o gba ipo kinni lori Google Trend Afeez Fashola ti ọpọ mọ si Naira Marley jẹ gbajugbaja akọrin takasufe lorilẹede Naijiria.
Nigba ti o n se ipolongo eyi ti o dale, “fi awon omobinrin wa sile”o sapejuwe jiji awon omodebinrin akekoo naa gbe gege bi iwa aida si obinrin.
Àwọn ọmọ Mikimaṣi jẹ́ mejilelọgọfa (122)
Ẹ gbọ ki lo fa a ti Oloṣun kii jẹ aja, ti ọlọya kii jẹ ẹran agbo?
Àjọ tó ń rí sí eré bọ́ọ̀lù àfẹsẹ̀gbá ní Cameroon ń wá ẹni tí yóò rọ́pò Hugo Broos látàrí bí orílẹ́-èdè náà ti kùnà láti yege nínú àwọn tí yóò kópa nínú ife ẹ̀yẹ àgbáyé ọdún yìí ní orílẹ́-èdè Russia.
Apapọ awọn to ti ni arun naa kaaakiri orilẹ-ede Naijiria ti wa di 24,567 bayii.
com Àkọlé àwòrán, Awọn gaari ti wọn n da silẹ lo n fa eku to ni aisan lassa lati tọ si ori garri yii, eleyi ti yoo fa aarun Lassa fun gbogbo ẹni to ba jẹ garri naa Ọna ti a le gba dina aisan ti o wa lati ara ẹran igbẹ papa eku inu ile: Ẹ sọra fun jijẹ eku tabi ẹran igbẹ.
tí à ń gbà yín níyànjú, tí à ń rọ̀ yín, tí à ń kìlọ̀ fun yín nípa bí ó ti yẹ kí ẹ máa gbé ìgbé-ayé yín bí ẹni tí Ọlọrun pè sinu ìjọba ati ògo rẹ̀.
Balogun tí ó wà fún oṣù kọkanla ni Bẹnaya, ará Piratoni, láti inú ẹ̀yà Efuraimu; iye àwọn tí wọ́n wà ninu ìpín rẹ̀ jẹ́ ọ̀kẹ́ kan ó lé ẹgbaaji (24,000).
Awọn ọlọpa sọ pe ori lo ko Lawal yọ ninu iṣẹlẹ ipaniyan yii ti o si gbọ'gbẹ pẹlu ọgbẹ ibọn.
Ẹ̀yin ọmọ Yorùbá lókè òkun, ẹ má bẹ̀rù mọ́ láti wálé - Akeredolu Ibadan Fire: Iná míràn tún ṣẹyọ nilú Ibadan Bàbá akẹ́kọ̀ọ́ LASU tí ọ̀rẹ́kùnrin rẹ̀ àti pásítọ̀ fi ṣ'oògùn owó ń bèèrè fún ìdájọ́ òdodo A fẹ́ máa f'ọwọ́ ara wa ṣíṣẹ́ ajé - Ọmọọba ilẹ̀ Gẹ̀ẹ́sì, Harry Ìfẹ́ èmi àti olólùfẹ́ mi bẹ̀rẹ̀ lẹ́yìn ta jẹ ètè ara wa nínú sinimá - Nkechi Blessing Bakan naa ni Abdullahi sọ pe, ile iṣẹ ọlọpaa tun tu awọn mẹjọ miiran silẹ nile awọn ọmọ alailobi Du Merci to wa niluu Kaduna.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Wo imọran Fọlọrunṣọ Alakija fun awọn ọdọ adulawọ Atunṣe ofin yii ti yoo fun awọn abilekọ lanfani ati yan ipinlẹ to wu wọn lati maa lo ninu ti ọkọ tabi ti baba to bi wọn lọmọ ni arabinrin Abiade ni igbesẹ to daa ni.
Obìnrin òun ti kò fẹ ki a dá orukó òun sàlàye pé ó ṣe patakì láti máa dúpẹ nínú ohun gbogbo nítori pe àwọn ọmọ náà jẹ ẹbun pàtaki, sùgbọ́n nítori pe oye rẹ bi wọn ṣe ri kò ti ye ọpọ ènìyàn láwujọ pàápàá ni Nàìjírìà.
Ẹlẹ́wọ̀n Kirikiri tó ń wọ́ke, olùdarí ọgbà ẹ̀wọ̀n ló ṣe onígbọ̀wọ́ fun - EFCC Eku gba ìjọba ní Estonia, ìjọba pàdánù owó gọbọi Àwọtẹ́lẹ̀ ọkùnrin àti Ìdọ̀tí Kilo méje ṣekú pa Ìgalà EFCC fẹ́ gbẹ́sẹ̀ lé ilé tí mo fi owó ìfẹ̀yìntì kọ́ nílùú Ilorin- Saraki Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Yorùbá tone mark: Fífi àmì ohùn sí orí ọ̀rọ̀ Yorùbá ṣe pàtàkì Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
olubori gege bi gomina ninu eto idibo atundi to waye ni ipinle naa.
Goolu mẹsan an ni Henry fi ju Giroud lọ eyi ti o si lanfaani lati ba a ati lati ju u lọ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Osun Osogbo: Àwọn èèbó aláwọ̀ funfun gbé Ọ̀ṣun lárugẹ 16 Ògún 2019 Ilu Oṣogbo sọkutu wọwọ loni pẹlu obitibiti ero lasiko asekagba ọdun Ọṣun Oṣogbo to waye loni.
;* Ile igbimo asofin naa tun rọ  minisita to n mojuto oro amusagbara Ina, Ise
ó ṣe, iṣẹ́ ìyanu ní ilẹ̀ Hamu,ati ohun ẹ̀rù lẹ́bàá òkun pupa.
Ọgbẹ́ni Sunday James to jẹ agbẹnusọ fún NIS ló sàlàyé ọ̀rọ̀ náà lásìkò tó ń ba BBC sọ̀rọ̀ lónìí ọjọ́ Ajé.
Wọ́n ni àfi ti Leah Sharibu ba dari wálé ni ìjọba tó ṣe ǹkan tó tọ́.
    Ọ̀pọ̀lọpọ̀ nǹkan ni a tún rí ní pàkúté Èṣù ní ọ̀run Àpáàdì ṣùgbọ́n kò sí àyè láti to gbogbo wọn lẹ́sẹẹsẹ.
Bi ko ba ni gbagbe, laipẹ yii ni iroyin jẹyọ pe ọkan lara awọn olori laafin Kabiyesi Alaafin ti ko jade laafin eleyi ti aafin iku baba yeye ati olori naa ti sẹ jalẹ pe irọ lasan ni iroyin naa.
' Oríṣun àwòrán, AFP 'A ni ju igba akọroyin lọwọlọwọ to n ṣiṣẹ nile aṣofin, eyi si ti mu ki eero o pọju nile aṣofin.
Níbi ìpàdé náà ni Ààrẹ Macron ti kàn saara sí Mammadou Gassama fún iwà akin tó hù.
"Tẹ àdírẹ̀ẹ̀sí méèlì rẹ síbẹ̀ Tẹ bọ́tìnì ti wọ́n kọ ""Submit"" si Oríṣun àwòrán, MTN Kóòdù tí ó lè lò fún MTN Ó tún le tẹ *785# Yóò bèrè pé kí ẹ tẹ nọ́mbà mọ́kànlá tí àjọ NIMC fún ọ yóò sọ fún ọ pé ó ti yege."
Kini ajọsepọ to wa laaarin ‘Game of Thrones‘ ati ‘Ireke Onibudo’?
Ṣùgbọ́n ìgbésẹ̀ yìí leè kí omi máa wo inú ẹ̀dọ̀ fòòró èyí sì lọ máa ń fà tí èémí yọ fi nira fún irú ẹni bẹ́ẹ̀ tí afẹ́fẹ́ tó ń wọ ara yóò sì dínkù.
Mose wo gbogbo iṣẹ́ náà, ó rí i pé wọ́n ṣe é gẹ́gẹ́ bí OLUWA ti pa á láṣẹ, Mose sì súre fún wọn.
Ti ọwọ wa yoo si tẹ wọn.
Chelsea gbiyanju lati da goolu kan pada amọ ẹpa ko boro mọ.
Wọn ní àwọn ọmọogun máa ń fipá bá àwọn obìnrin sùn ti wọn sì ń fiwọn fọ́kọ pẹ̀lúu túlàsì, Amnesty ni wọn rí èyí ṣe ní ìdápadà fún oúnjẹ àti ààbò.
Nípa ìyìn rere yìí ni a fi ń gbà yín là, tí ẹ bá dì mọ́ ọ̀rọ̀ ìyìn rere tí mo fi waasu fun yín, bí bẹ́ẹ̀ kọ́ asán ni igbagbọ yín.
ipade naa ni gomina  Abubakar Atiku-Bagudu
Ami ayo marun si mẹrin ni Arsenal fi gbẹyẹ lọwọ Liverpool eyi to mu wọn gba ife ẹyẹ Community Shield.
Nítorí ninu Kristi Jesu, èmi ni mo bi yín nípa ọ̀rọ̀ ìyìn rere.
Ajọ to n woye nipa ẹtọ ọmọniyan ni Naijiria, National Human Rights Watch jabọ pe lọjọ keji ọjọ ti wọn kede esi ibo, ọjọ kẹtadinlogun, oṣu Kẹrin ni awọn ololufẹ Muhammadu Buhari bẹrẹ iwọde ni Ariwa Naijiria.
Gẹ́gẹ́ bí Ọlọrun ti sọ, pé, “N óo máa gbé ààrin wọn,n óo máa káàkiri ní ààrin wọn.
Amọ ki lo ṣe okunfa ijakulẹ Trump ninu eto idibo tawọn ọmọ ilẹ Amẹrika ti tu yaaya ta yaaya jade dibo?
2 20468 Orilẹede Kyrgyzstan 1307 20.
Nígbà tí ó dé Lehi, àwọn Filistia wá hó pàdé rẹ̀.
Ọ̀rọ̀ǹpọ̀tọ̀niyùn, Aláàfin obìnrin àkọ́kọ́ rèé, tó ní nǹkan ọkùnrin Irinajo ti gbérasọ padà ní pápákọ̀ òfurufú ìpínlẹ̀ Imo lẹ́yìn ìjàmbá iná Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Hakeem: Mo lè sọ arúgbó dí ọmọge nígbà tó bá wù mí Gẹgẹ bii ọrọ ti alukoro ileewe naa, Biọdun Ọlarewaju ba BBC News Yoruba sọ, awọn oṣiṣẹ alaabo ileewe fasiti naa to ri awọn eeyan naa ni ibi ti wọn ti gbe n ṣiṣẹ laabi yii lo pariwo sita ti awo ọrọ naa si fi lu sita faye gbọ.
Ohun tí OLUWA Ọlọrun Israẹli sì ní kí n wí fún ọ nìyí; ó ní, ‘Mo fi ọ́ jọba lórí Israẹli, mo sì gbà ọ́ kúrò lọ́wọ́ Saulu.
Gbogbo ọdún tí Adamu gbé láyé jẹ́ ẹẹdẹgbẹrun ọdún ó lé ọgbọ̀n (930), kí ó tó kú.
Muhammadu Buhari ati igbakeji rẹ ojogbon  Yemi Osinbajo fun aseyori eto idibo aare yii.
Bakan naa lo ni Gomina Rotimi Akeredolu, ati awọn olori ijọba kan ti ṣe abẹwo si agbegbe naa, lati ba wọn kẹdun.
Ṣebí gbogbo àwọn tí wọ́n bá Mose jáde kúrò ní Ijipti ni.
Igba ti iya mi ku, mo fẹ lo ile fun eto isinku sugbọn iyawo mi ko lati bami lo nitori o ni ni ibi ti oun ti wa eewo ni ki iyawo ti wọn o san nkan ori rě lọ iru iriajo bẹ bakan naa lo kọ lati jẹ ki n mu ọmọ mi Nigba ti mo de abule awọn awọn agbaagba ile ba mi wi pe kilode tinmi o fi mu iyawo mi wa gẹgẹ bi akọbi ọkunrin iya mi, wọn bu ẹgbẹrun lona ogoji Naira fun mi gẹgẹ bi owo itanran, lẹyin ti ọrọ itiju yii ṣẹlẹ, mo jẹjẹ lati san nkan ori rẹ.
80 years Masters Graduate: Mo ṣi máa kàwé gboyè PhD
Oríṣun àwòrán, @Olafaremoses Àkọlé àwòrán, Inu àwọn ọdọ dun nibudo Aṣatipo Wasa Wọn pin ounjẹ loriṣiiriṣi, egbogi oyinbo, awọn irinṣẹ fun ọgbin ati awọn ohun eelo eré idalaraya bii àwọ̀n bọọlu alafẹsẹgba, aṣọ wiwọ fun ere idaraya fawọn aṣatipo nibudo naa.
27 Àti nísisìyí mo pàṣẹ fún ọ, pé bí o bá ní àwọn ìfẹ́ rere—ìfẹ́ láti to ìṣura jọ fún ara rẹ ní ọ̀run—nígbànáà ni ìwọ yíò ṣe ìrànlọ́wọ́ ní mímú wá sí ìmọ́lẹ̀, pẹ̀lú ẹ̀bùn rẹ, àwọn abala wọ̃nnì lára àwọn ìwé mímọ́ mi tí a ti fipamọ́ nítorí àìṣedédé.
Oríṣun àwòrán, AFP Kùdìẹ̀kudiẹ wà nínú ìbò abẹ́nú APC tó yan Akeredolu, ṣùgbọ́n.
Bakan naa ni ijọba ti sọ fawọn olugbe ilu naa ti wọn miliọnu mọkanla lati yago fun apejọ ti ọpọ eeyan wa.
Ìdí tí ètò ìdìbò ìpínlẹ̀ Kogi fi yàtọ̀!
"Oríṣun àwòrán, @jidesanwoolu ""A gbọdọ fopin si iwa ibinu yowu to le wa nitori ilu Eko nikan ni ko ti si iwa ẹlẹya mẹya abi ẹlẹsinjẹsin, nitori ọkan soso ni wa."
Àsàmú tí ó jẹ́ ọ̀kan nínú àwọn ọmọ Àlàó ni ó ṣe àlàyé fún bàbá rẹ̀ ìdí tí wọn kò ṣe kọ ẹsẹ kejì orin náà.
Àkọlé àwòrán, Pasito kuro nipo re Ni ipinlẹ Eko, awọn eniyan ti n korajọ pọ lati ṣe iwọde lodi si ifipabanilopọ.
Bákan náà, oríṣìíríṣìí àdúgbò ni a rí ti orúkọ wọn bá ara wọn mu ní àwọn ìlú méjèèjì yí fún apẹẹrẹ bí a ṣe rí Ọ̀gbọ́n Ìlọ́rọ̀ ni Ìjẹ̀bú-Jẹ̀ṣà náà ni a rí i ní Iléṣà, Òkèníṣà wà ní Ìjẹ̀bú-Jẹ̀ṣà, Òkèṣà sì wà ní ìléṣà.
Ninu àwọn mejeeji, ta ni yóo fẹ́ràn rẹ̀ jù?
, Duration 4,2617 Bélú 2020 Taye Currency: Seyi Makinde fún Taye Currency lẹ́bùn ọkọ̀ bọ̀kìnnì Toyota Prado 202022 Bélú 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Afcon Qualifiers: Àmì ayò 2-1 ni Naijiria fi ṣàgbà Benin Republic 13 Bélú 2019 Oríṣun àwòrán, Others Àkọlé àwòrán, Ikọ̀ Super Eagles ló wà lókè téńté àtẹ pẹ̀lú àmì ayò mẹ́ta nígbà tí Sierra Leone àti Lesotho gbá ọ̀mì ayò kan.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Kemi Dairo: Iṣẹ́ abẹ nínú ọpọlọ àti ẹ̀rọ ni mo fi ń gbọ́ ọ̀rọ̀ báyìí EFCC fẹsun gbigba N400m lọwọ Sambo Dasuki kan Olisah Metuh: Ajọ EFCC fi ẹsun kan akọwe ẹgbẹ oṣelu PDP tẹlẹ, Olisa Metuh pe o gba irinwo miliọnu naira lọwọ oludamọran lori ọrọ aabo, Sambo Dasuki.
Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Fídíò, NigeriaDecides2019: Àwọn èèyàn Ekó figbe ta pé ìṣúnsíwájú ìbò ṣàkóbá fáwọn16 Èrèlè 2019 Fídíò, NigeriaDecides2019: Àwọn èèyàn Ìpínlẹ̀ Oyo ní ìṣúnsíwájú ìbò ààrẹ kù díẹ̀ káàtó16 Èrèlè 2019 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Ọmọdé ológun bíi 900 ti gba ìtúsílẹ̀ - UNICEF Ilé ẹjọ́ kòtẹ́milọ́rùn da ẹjọ́ Onnoghen nù Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ǹjẹ́ o mọ Yoruba daju?
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Akomolede ati Asa: Mọ̀ si nípa àwọn ọ̀nà tí Yorùbá ń gbà ran ara wọn lọ́wọ́ Ipinlẹ Edo: Gomina ipinlẹ Edo, Godwin Obaseki ti paṣẹ ki ofin konile o-gbele ọlọjọyipo o rọlẹ si ni ipinlẹ naa lẹyin ti rogbodiyan bẹ silẹ.
Ó bá gbà á, ó jẹ ẹ́ lójú wọn.
A lee pe Fagunwa ni 'Oso' nipa itan akọsilẹ: Fagunwa jẹ 'oso' ninu ka sọ itan ati ka kọ ọ silẹ, to si maa n kọ itan nipa irinajo sawọn ilu aims ati airi pẹlu ọna to ya ni lẹnu Fagunwa nikan lo mọ ibi ta n pe ni Igbo Irunmọlẹ, Oke Langbodo to fi mọ awọn akọni meje Oun naa lo mọ baba onirungbọn yẹukẹ to n gbe nibi gegele okuta, to si tun jẹ ọrẹ Akara Oogun, tii se ogboju ọdẹ ninu Igbo Irunmọlẹ Bakan naa ni Jaaniini se apejuwe Aramọnda ọkunrin bii ajeji ọkunrin ti otutu maa n mu lasiko ti oorun mu, ti ooru si maa n mu lasiko ti otutu ba mu gbogbo eeyan.
"Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, '500 level'' ni mo wà nígbà tí mo di adélé Ọba' ""Lọ́dọọdún kí ààwẹ ramadan tó dé ni à máa àkanṣe jákejádo láti mú àwọn tó ń hu ìwà ti kò bójú mu nílana ẹsin wa."
Kókó ohun tí mò ń sọ ni pé òfin tí ó dé lẹ́yìn ọgbọnlenirinwo (430) ọdún kò lè pa majẹmu tí Ọlọrun ti ṣe rẹ́.
Watford na West Ham pẹ̀lú àmì ayò méjì sí òdo nígbà tí Bournemouth náà Brighton
Ewe, ile-iwe Secondiri marundinlogun ni o kopa, Madonna Secondary School Garki se ipo kinni, Gifted Secondary School Gwagwalada se ipo keji ti Government Girls Secondary School Dutse si se ipo keta.
OLUWA bojú wo ilẹ̀, láti ọ̀run wá,ó wo àwọn ọmọ eniyan,láti mọ̀ bí àwọn kan bá wà tí wọ́n gbọ́n,tí wọn ń wá Ọlọrun.
Mo dojú kọ ọ́,ìwọ onigbeeraga yìí,nítorí pé ọjọ́ ti pé tí n óo jẹ ọ́ níyà.
Amọ, Kọmisọnna naa koju oro si iru iwa bayii ti o le fa ki aarun naa tankalẹ si.
Dafidi kó ọpọlọpọ àwọn ìkógun mìíràn ninu ìlú náà.
"Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Òṣìṣẹ́ Bánkì ni mí l'Amẹ́ríkà kí n tó bẹ̀rẹ̀ Tíátà' ""Ìjánú ọkọ náà kùnà lójijì nítori eré àsá pajude to n sa àti pé ilẹ̀ kò i tíí mọ dáadáa, o subu si ẹ̀gbẹ́ kan "" Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 2020: Oloye Awurela Ifaleke ti wúré ọdún ìgbéga fún kóówá Akinyibi ni okú àwọn ènìyàn náà ti wa ni ilé ikoku si FOS ni Ipara Remo nipinlẹ Ogun nigba ti àwọn to fara pa wà ni ilé iwosan Idera ni Sagamu."
Shelly-Ann Fraser-Pryce to jẹ ọlọmọ kan tun ni ẹni to dagba ju l'gbaye to gba ife ẹyẹ naa lẹyin to gba ife wura ni idije agbaye to n lọ lọwọ ni Doha, lorilẹ-ede Qatar.
Ile igbimo asofin tun rọ ijoba apapo lati tun  da ile-ise kan o kere tan ni ijoba ibile kookan to wa lorile ede yii sile, ki eleyii tun lee din wahala ati awon iwa janduku to maa n sele lawujo ku.
Bí ènìyàn bá ti ń ní ọjọ́ lórí tó, bẹ́ẹ̀ náà ni ọgbọ́n orí rẹ̀ yóò túbọ̀ máa pọ̀ sí i.
Wọ́n ń dì mọ́ ọn, wọ́n ń fi ẹnu kò ó lẹ́nu.
Okunrin kan to ti gbe burọọṣi ifọyin me sẹyin ni orilẹ-ede Kenya naa n ranti bi o ṣe nilo iṣẹ abẹ nigba naa.
àwọn tí wọ́n gbẹ́kẹ̀lé ọrọ̀ wọn,tí wọ́n sì ń yangàn nítorí wọ́n ní ọrọ̀ pupọ?
Ìpalẹ ̀ mọ ́ fún ayẹyẹ ọdún bẹ ̀ rẹ ̀ láti ó ku ìtàdógún , àwòrò Ògún yóò kéde rírí oṣù tuntun ( èyí tí wọ ́ n gbọ ́ dọ ̀ rí kí wọ ́ n tó lè bẹ ̀ rẹ ̀ ọdún ) nípa fífọn ùpé ( fèrè ìbílẹ ̀ ) fún ọjọ ́ méje .
"Nigbati iṣẹlẹ ina yi waye ni igba akọkọ, ijọba ṣe iranlọwọ fun wa lati tun awọn ile itaja wa kọ fun wa laigbowo.
Eyi to ṣe iku pa o le ni aadọta le ni igba eniyan ati ikọlu ẹsan ti wọn ṣe pada sawọn alakatakiti ẹsin Islam to n fa wahala.
Onilu ni bi Atiku ti ṣe n tẹnumọ oju opo Inec yi mu ifura lọwọ nitori pe ''o jọ bi ẹ ni wi pe ohun ati ẹgbẹ PDP fẹ fi ọgbọn alumọkọrọyi lu oju opo naa lati ṣe akoba fun'' Bi a ko ba gbagbe,Atiku Abubakar ti sọ lọjọru pe ohun fi ibo miliọnu kan le ẹgbẹta ṣagba Buhari ninu ibo aarẹ ti o si tọ ki Inec kede ohun gẹgẹ bi ẹni to jawe olubori.
Ninu ohun ti o sọ, o ni ko si ẹmi kankan to padanu ninu iṣẹlẹ naa ati wi pe ijọba ti ṣami si ile naa gẹgẹ bi ọkan lara awọn ile ti wọn fẹ wo.
Gbogbo igbesẹ bi i ka jina sira ẹni nibi ti kii ba se ile mi, ọwọ fifọ lẹyin ti mo ba fi ọwọ kan nkan ti ẹlomiran ti fọwọ́ kan, to fi mọ fifi ọsẹ fọ awọn oúnjẹ ti mo ba ra, ni mo ti gbe ni gbogbo ọjọ aye mi.
Lẹ́yìn náà, ó wọn ògiri tẹmpili, ó nípọn ní igbọnwọ mẹfa (mita 3), ìbú àwọn yàrá ẹ̀gbẹ́ jẹ́ igbọnwọ mẹrin (bíi mita 2) yípo Tẹmpili náà.
Ọwọ tẹ agbofinro meji lori iṣowo ọmọniyan
Àwọn tí ó rán bá lọ, wọ́n rí ohun gbogbo bí ó ti sọ fún wọn.
Ọrọ yi ti fẹ di aṣeju ti o si yẹ ki atunto waye ni kiakia'' Àwọn òṣèré tíátà Yorùbá ọkùnrin táyé ni wọ́n rẹwà Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Afro Brazilians: ìlú Rio ni a máa kọ ilé ìṣẹmbáyé náà sí Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 3 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 5 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Afara ero ese tuntun kan ti won sese ko ni Florida nitosi Florida International University ja lojo Bo ni eyi to se iku pa eniyan merin.
padanu  eniyan wọn kẹdun, ni eyi to jẹ pe
Ní ọjọ́ kẹta, wọ́n ń ṣe igbeyawo kan ní Kana, ìlú kan ní Galili.
Ologbondiyan ni aiṣoro Aarẹ Buhari burujai nitori oun ni ọgagun orilẹede Naijiria, ti gbogbo aṣẹ si wa ni ọdọ rẹ.
Àfi ibi tí OLUWA Ọlọrun yín bá yàn pé kí ẹ ti máa sin òun, níbẹ̀ ni ẹ ti gbọdọ̀ máa rú ẹbọ àjọ ìrékọjá ní ìrọ̀lẹ́, nígbà tí oòrùn ń lọ wọ̀ ní àkókò tí ẹ jáde kúrò ní ilẹ̀ Ijipti.
Nisinsinyii, OLUWA Ọlọrun mi, ìwọ ni o jẹ́ kí èmi iranṣẹ rẹ gun orí oyè lẹ́yìn baba mi, bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé ọmọde ni mí, n kò sì mọ̀ bí wọ́n ti ń ṣe àkóso.
Ìyàwó mi ló ṣì ń dáná, bu oúnjẹ mi, gé èékáná fún mi - Pásítọ̀ Adeboye Kò sí ìfòyà, ọkọ̀ bààlù wà tí ìjọba ba ti afárá 3rd Mainland lósù yìí Ẹ wo Daniel tí wọ́n fẹ́ yẹgi fún lẹ́yìn tí US kò ṣe irú ẹ̀ fún odidi ọdún 17 Àwọn dókítà Eko bẹ̀rẹ̀ ìyanṣẹ́lódì lórí owó oṣù àti ètò adójútòfò fún ìtọ́jú coronavirus Taló pa olórí àwọn ''One Million Boys'' Ebila n'Ibadan?
 a le ṣe kònkárí àwọn òpó ìgbàgbọ ́ tó wà nínú èsìn ìgbàgbọ ́ ní ọ ̀ nà márùn-ún.
Nicholas Ouma Odhiambo  so pe  “Awon egbe naa fun oun ni anfaani lati fakọyọ ninu ere ijo naa.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Guru Maharaji: Ó yẹ kí ìjọba àpapọ̀ fíkún owó oṣù òṣìṣẹ́ àti ti adájọ́ 5 Òkùdu 2019 Àkọlé àwòrán, Ààrẹ Buhari fí mí jẹ olùrànlọ́wọ́ pàtàkì lóri epo rọ̀ọ̀bì- Guru Maharaji Ohun tó ba ń dun ni, ṣebí wọ́n ni òhun ló máa ń pọ̀ lọ́rọ́ ẹni, adari àti olùdásilẹ̀ One Love Family, Sat Guru Maharaji ti ke pe ààrẹ Muhammedu Buhari, láti yan òun gẹ́gẹ́ bi olùbádámọ̀ràn pàtàkì fọ́rọ̀ epo rọ̀bi.
Àwọn àwòrán ìṣẹ̀lẹ̀ tó làmìlaaka láti ilẹ̀ Áfríkà l'ose tó kọjá Kolade Johnson; Iléeṣẹ́ ọlọ́pàá ní ọwọ́ ti tẹ àwọn afurasí ọlọ́pàá tó ṣekúpaá Àwọn olùgbé Fiditi pé fún ìrànlọ́wọ́ lórí àwọn òrùlé tí atẹ́gùn ojó ṣí lọ 'Fashọla, o ò sì bẹ̀rù Ọlọ́run!
Oniroyin ọmọ orilẹede South Africa miran firoyin ọhun lede lori opo Twitter Wọn ti onirururu ẹsun iwa ibajẹ kan Ọgbẹni Zuma ti awọn ti ẹ ti n ṣo fun pe ko kọwe fipo silẹ.
4 495228 Orilẹede Portugal 8543 83.
Abiola Ajimobi: Igbákeji ààrẹ sàbẹwò sí ìyàwó Ajimọbi
Nígbà tí ó wà ní odidi, kò wúlò fún nǹkankan.
Ṣùgbọ́n isàlẹ̀ díẹ̀ ni òun náà bá dúro sí.
Èmi kò kọ ikú, èmi kò kọ àrùn, èmi kò kọ ibànújẹ́ ọ̀sán, bẹ́ẹ̀ ni n kò kọ hílàhílo ààrin òru.
Lẹ́yìn tí àwọn angẹli náà ti pada kúrò lọ́dọ̀ wọn lọ sí ọ̀run, àwọn olùṣọ́-aguntan ń sọ láàrin ara wọn pé, “Ẹ jẹ́ kí á lọ sí Bẹtilẹhẹmu tààrà, kí á lè rí ohun tí ó ṣẹlẹ̀, tí Oluwa bùn wá gbọ́.
Ẹfunsetan Aniwura, obìnrin tó ju ọkùnrin lọ Ọ̀rọ̀ǹpọ̀tọ̀niyùn, Aláàfin obìnrin àkọ́kọ́ rèé, tó ní nǹkan ọkùnrin Awọn kan lori ayelujara sọ pe agbalẹ ni ọkunrin naa jẹ ni adugbo ibi ti iṣẹlẹ yii ti waye, ati pe ibọn awọn ọlọpaa SARS to n le awọn to n mu igbo lo pa a.
Awọn eeyan naa lo darapọ mọ awọn agbesumọmi ọhun ni ilẹ Gẹẹsi ki wọn to rinrin ajo lọ si Syria, sugbọn ijọba orilẹ-ede United Kingdom ti kọ̀ wọn gẹgẹ bi ọmọ orilẹ-ede rẹ.
Tibi tire ni nkan to ṣẹlẹ si wa'' ''Nipa Eden mo lero pe, mo si ni igbagbọ pe kii ṣe nkankan to lagbara pupọ.
Ti a ko ba gbagbe ,Ààrẹ àná lórílẹ̀-èdè Nàìjíríà Oluṣegun Obasanjọ ti saaju sàbẹ̀wò sí adarí ẹgbẹ́ Afenifere, Pa.
Se ni wọn si ti awọn opopona to gbajumọ pa nilu Eko, to si nira fawn eeyan ati ọkọ lati kọja lati adugbo kan si omiran.
Lọ́gán gbogbo ìlẹ̀kùn ṣí; gbogbo ẹ̀wọ̀n tí a fi de àwọn ẹlẹ́wọ̀n sì tú.
Nígbà tí àwọn ọmọ yín bá sì bi yín léèrè pé, ‘Kí ni ìtumọ̀ ìsìn yìí?
“Mo ni idaniloju pe leyin idanilekoo yii, awon olukopa yoo ni imo kikun lori awon ilana ofin ibanisoro lagbaye lori oro to je mo abadofin ati ise awon asojusofin”.
 Nígbà tó ń sọ̀rọ̀ lórí àwọn ìpènijà tó ti là kọjá sẹ́yìn, Wòlíì Arole ni ọjọ́ kan wà tí wọn gba òun sì ẹgbẹ́ níbi ayẹyẹ kan torí pé òun kò tíì ní òkìkí nígbà náà àmọ́ òun dúpẹ́ fún ibi tí Ọlọ́run mú òun de lónìí."
Ojogbon Osinbajo soro yii nile ijosin ti Commonwealth of Zion Assembly (COZA),to wa niluu Abuja.
Oríṣun àwòrán, Others Nibi ayẹyẹ isinku rẹ, igbakeji Gomina ipinlẹ Oyo, Rauf Aderemi Olaniyan sapejuwe rẹ gẹgẹ bi awokọse fun oun, ti o si gbadura ki ẹlẹda tẹ si afẹfẹ rere.
ẹkun un rẹrẹ iroyin naa n bọ laipẹ…Ademola Adepoju.
À ì sí owó já wọn ní tàn mọ́ọ̀ láti tẹ̀ síwájú síi.
Oríṣun àwòrán, @HQNigerianArmy Amosun ni irọ to jinna sootọ ni pe wọn tete fa awọn ohun ija oloro naa le awọn ọlọpa lọwọ, ki gomina tuntun to fẹ gba akoso, Dapọ Abiọdun ma baa ri wọn.
Ó wí fún àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ pé, “Ẹ jókòó níhìn-ín nígbà tí mo bá lọ gbadura.
Ẹ sọ pé ó tì o, ẹ̀yin óo gun ẹṣin sálọ ni.
Titi di asiko yii, ipo adele alaga ajọ EFCCC ṣi ni Ibrahim Magu wa, ile aṣofin ko fọwọ si iyansipo rẹ bi alaga, eyi ti inu awọn aṣofin ko dun si i.
Ọmọ Israẹli ni, láti inú àwọn ọmọ Mahili, ninu ẹ̀yà Lefi: wọ́n fi ranṣẹ pẹlu àwọn ọmọ ati àwọn arakunrin rẹ̀.
Oju opo Twitter mì titi lẹyin ifẹsẹwonse naa pẹlu bi awon ololufẹ ikọ Super Eagles ṣe gboriyin fun ikọ Super Falcons nitori wọn gbiyanju lati se daradara ju ikọ France.
Fún àwon iṣẹ́ ribiribi yi, olóògbé Adébáyọ̀ Fálétí gba ọ̀pọ̀lọpọ̀ ẹ̀bùn àpínfún ni orilẹ̀ èdè Nigeria àti ni òkè-òkun.
Muhammadu Buhari ti rọ ikọ agbabọọlu orile ede Naijiria, Super Eagles  lati fagba han awon akegbe won ninu idije boolu
Wọ́n ń bá ara wọn jíròrò lórí gbogbo ohun tí ó ṣẹlẹ̀.
Oríṣun àwòrán, Others Àkọlé àwòrán, Ìjọba ìpínlẹ̀ Eko fẹ̀sùn kan Lekan Shonde pé ó lu ìyàwó rẹ̀ pa, lẹ̀yín to fi ẹ̀sùn kan pé iyawo rẹ̀ pé óún yan àlè.
Ileri: Idasilẹ eto iranlọwọ owo fun awọn to ku diẹ kaato fun lawujọ Eto Ilera Ileri: O sọ pe oun yoo ri i daju pe ọmọ Naijiria ko ni idi kankan lati lọ gba iwosan nilẹ okeere.
Gẹ́gẹ́ bíi ohun tí ifá sọ, Titus de ipò àwọn baba ńlá rẹ lóòótọ́, tó sì di ọba James Titus Olateru-Olagbegi Kejì, Ọlọwọ tilu Ọwọ ni ọjọ́ Kẹtàlá oṣù Kẹta ọ́dún 1941.
A ti gbé kọ́kọ́rọ́ sẹ́nu ibodè Nàìjíríà kí ọrọ̀ ajé wa leè gbé pẹ́lí- ìjọba àpapọ̀ Ẹ dẹkun ere sísá lójú pópó láti dẹkun ìjàmbá- FRSC Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ti o bá dá ara ẹ lójú, ki ẹni tó n ṣe irun kí n gbọ́?
Aṣòfin 18 sá àsálà kúrò nípínlẹ̀ Ondo Awọn aṣofin mejidinlogun ti wọn yọ olori ile aṣofin ipinlẹ Ondo ati igbakeji rẹ, ti sa fi ipinlẹ naa silẹ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Mr Macaroni sọ nípa eré tí Fraky freaky, Sugar Daddy, You are doing well, freaky spicy fẹ́ Owo naa si jẹ ara biliọnu kan dọla ti wọn gbẹsẹle jakejado agbaye.
INEC: Òpómúléró ni ASUU jẹ́ fún àṣeyọrí ìbò 2019
Nígbà náà ni Jehoiada gbé àpótí kan, ó lu ihò sí orí rẹ̀, ó gbé e sí ẹ̀bá pẹpẹ ìrúbọ ní ọwọ́ ọ̀tún tí eniyan bá wọ ilé OLUWA.
Oríṣun àwòrán, Victoria Haydn Ni iwoyi saa liigi premiership to lọ, ọmọ iṣẹ ni Mikel Arteta jẹ labẹ Pep Guardiola ki wọn to yan an gẹgẹ bi olukọni tuntun fun ẹgbẹ agbabọọlu Arsenal.
A ríi ka pé, ọba àlàyé náà ni ọpọlọpọ ìyàwó, táwọn ọmọ rẹ sì tó ogoje, tí mọkanlelọgọfa nínú wọn si jẹ akẹ́kọ̀ọ́ jáde ní Fáṣítì.
Àgbádárìgì tí a kọ ́ kọ ́ mọ ̀ sí gbagle láti ìbèrè jẹ ́ ìlú ẹ ̀ bádò àti ìjoba ìbílè ní ipínlè Èkó , lórílẹ ̀ -èdè nàìjíría .
Nítorí wọn kò pa majẹmu mi mọ́,mo bá kẹ̀yìn sí wọn.
Esun ti won fi kan alatako naa ni pe , o fe fipa gba ijoba pelu awon eniyan ọgbọ̀n, lasiko ti won n ju okuta lu oko aare orile ede naa.
Oun ati Ẹgbọn rẹ lo ja, to fi wa gbe lọdọ mi.
Mi o bẹru coronavirus nitori bi mi o ṣe mi o le e jẹ- Ibrahim Bi ọpọlọpọ awọn ọdọkunrin miran ti wọn ti rinrinajo kuro lawọn ipinlẹ miran lorilẹ-ede Naijiria wa si Abuja ni Ibrahim lati lee ri igbe aye to dara sii.
3 Bélú 2020 Fídíò, Soyinka Cancer: Àṣe ara mi ni iso ti n run gbogbo bí mo ṣe n ṣèrànwọ́ lórí jẹjẹrẹ27 Bélú 2019 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Ọgọfa (120) ìwọ̀n talẹnti wúrà ni Hiramu ti fi ranṣẹ sí Solomoni ọba.
Fun awọn obinrin, ere idaraya le fun ile itọ ati ẹya ara to wa fun ọmọ bibi, ni okun.
Nitori naa, asisọ ọrọ ni ki eeyan kan ni Amotekun n dunkooko mọ oun tabi jẹ ewu fun aabo ẹmi ati dukia, ọrọ naa ko ye mi.
Amọ ẹni ti a gboju okun le, ti ko jọ ẹni agba ni olukọ naa, tori o fi tipa ba ọmọdebinrin naa lopọ ni aago mẹsan kọja isẹju mẹẹdọgbọn aarọ ni yara kẹjọ to wa ni ọọfisi ẹkọ nipa isẹ okoowo.
  Bákan náà ni àwọn olùjọsìn yoo tẹ̀lé gbogbo ìlànà ìjìnà síraẹni ti ìjọbá là sílẹ̀ lórí ọ̀rọ̀ COVID-19.
Nadal ti tara ji pada bayii, leyin ti o fidi remi lojo melo kan seyin,
Wọ́n sì gbọdọ̀ kọ́ wọn láti mọ ìyàtọ̀ láàrin nǹkan tí kò mọ́ ati àwọn nǹkan mímọ́.
Èyí yóo jẹ́ kí n fi ayọ̀ wá sọ́dọ̀ yín, bí Ọlọrun bá fẹ́, tí ọkàn mi yóo fi balẹ̀ nígbà tí mo bá wà lọ́dọ̀ yín.
Adele alaga ẹgbẹ awọn olukọ ileewe giga naa, Comrade Oluṣẹgun Lana ṣalaye lẹyin ipade ẹgbẹ naa, to waye lọgba ileewe ẹkọṣẹ olukọni agba to wa nilu Ilesa pe, gbogbo igba ni ijọba n kuna lati ṣika adehun to ṣe pẹlu ẹgbẹ naa lati igba ti ijọba ana ti wa nipo.
Ṣugbọn àwọn oko tí wọ́n yí ìlú náà ká ati àwọn ìletò rẹ̀ ni wọ́n fi fún Kalebu ọmọ Jefune gẹ́gẹ́ bí ìpín tirẹ̀.
Àkọlé àwòrán, Gomina Ambode Ọgbẹni Agunbiade ni ile aṣofin pinu lati ṣe ayipada iroyin ati iwoye ti kii ṣe ootọ́ to n ja kiri lori ipinu ile nipa Ambode lọjọ aje ọsẹ.
Ibadan: Bode Akindele, Richard Akinjide àti àwọn èèkàn míì tó kú lọdún 2020
 títí di òní , àdúgbò tí apèbí tí pàdé Ògbòrògánńdà ni à ń pè ní ÌjÀdÀ .
Ará Yúróòpù ẹ fìdí mọ́lé yín, mo ti gbé ìlẹ̀kùn Amẹ́ríkà tìpa torí Coronavirus - Trump Aarẹ orileede Amẹrika, Donald Trump ti kede awọn igbesẹ tuntun lati koju itankalẹ aisan Coronavirus, eleyi to ni ṣe pẹlu irinajo lati Yuroopu si Amẹrika.
Ǹjẹ́ o lè máa wò wá níran títí tí a óo fi kú, ati àwa, ati ilẹ̀ wa?
Ọlọ́run kò ní í ṣe é ní àáró o.
”Obinrin náà dá Gehasi lóhùn pé, “Alaafia ni gbogbo wa wà.
Atejade ohun so pe, won yoo sami ayeye yiyan sipo ohun ninu osu kerin odun 2018, nigba ti ogbeni Sidibe ba wa silu Abuja.
Ọgbẹni Ikolo ni ṣa deedee lawọn lawọn gbọ iro ibọn lati ile ọlọpaa ọun eyi to kọju si ago ọlọpaa to ti n ṣiṣẹ niluu Akungba Akoko Ẹ yọmí kúrò ní àhámọ́!
Orisun: Iwe akọsilẹ ajọ to n sewadi iwa ọdaran, CIA World Factbook, akojọp iye eeyan ldun 2018 Orilẹede wo lo ni ilẹ to pọ julọ?
"Nitori idi eyi, mo ti wa kede isede oni wakati mẹrinlelogun yika gbogbo ipinlẹ Eko, bẹrẹ lati aago mẹrin irọlẹ oni.
Aarin gbungbun Epetedo ni aafin Oshodi wa, ti wọn si pin agbegbe naa si agboole mọkanlelogun, lara wọn ni agboole Oshodi, Akinyemi, Ewumi ati Alagbede.
Wo àwọn ìṣẹ̀lẹ̀ tó mú Naira Marley di òrìṣà àkúnlẹ̀bọ ní 2019 Ìdí tí a ṣe yọ ọwọ́ Naira Marley kúrò láwo Headies Award ọdún yìí rèé - HipTV 'Soapy', àwo orin tuntun Naira Marley tó ń milẹ̀ tìtì Ọgbà ẹ̀wọ̀n ni Naira Marley yóò ti wo ìbúra Buhari ní May 29 Ilé ẹjọ́ gba onídúró Naira Marley pẹ̀lú mílíọ́nù méjì náírà Ọgbà ẹ̀wọ̀n ni Naira Marley yóò ti wo ìbúra Buhari ní May 29 Ilé ẹjọ́ gba onídúró Naira Marley pẹ̀lú mílíọ́nù méjì náírà Mi ò gbè lẹ́yìn Naira Mailey fún ìwà ìbàjẹ́- Daddy Showkey Naira Marley gba ipò mọ́ Atiku lọ́wọ́ gẹ́gẹ́ bí èèyàn tí wọ́n ń wá jùlọ ní Google lọ́dún 2019 Ojo ni Adajọ ti sun ẹjọ naa siwaju di ọjọ Kẹtadinlọgbọn ati Ikejidinlọgbọn osu Keji ọdun 2020, to si tun kede pe isunsiwaju ẹjọ naa ko da irẹwẹsi si awọn lọkan laya.
Bakan naa lo sọ pe awọn eeyan to n gbe ni awọn agbegbe ti awọn onibara naa ti n tọrọ owo sọ pe wọn n ba agbegbe awọn jẹ.
Oríṣun àwòrán, Others Itan ti igbe aye Ọba Seriki Abass Williams kọ wa: Itan aye Ọba Seriki Abass Williams kọ wa lati lu aluyọ lai naani bi ibẹrẹ aye wa se ri O tun kọ wa lati jẹ olotitọ si awọn eeyan to jẹ asiwaju wa boya ọga wa lẹnu isẹ abi obi wa Itan yii tun kọ wa pe ka maa ranti ile ni orilẹede korilẹede taa ba wa.
Gẹgẹ bii ara apẹrẹ iji naa ni bi ile aṣofin ipinlẹ kogi ṣe bẹrẹ igbesẹ ati rọọ loye ni ọjọ iṣẹgun.
Mbaka, ninu fidio kan to fi soju opo Facebook ijọ rẹ, Adoration Ministry, ni ọpọ igba loun ti maa n ke sawọn ọdọ lati taji loju oorun wọn.
Ati pe awọn ko ni tu ẹni ti wọn ka si keferi ti ko tii gba Islam silẹ.
Gómìnà fi ọ̀rọ̀ yìí léde lóri àtẹjíṣẹ́ twitter rẹ̀ pé, lẹ́yìn ìjíròrò pẹlú ìgbìmọ amúṣẹ́ṣe lóri Corornavirus ní àwọn fẹnukò lórí ìgbésẹ̀ yìí pẹlú àwọn àlàálẹ̀.
 Gomina tun ni bo tile je pe
Ijọba orilẹ-ede Saudi-Arabia ti wa pese awọn ohun eelo ati osisẹ to yẹ lati jẹki isẹ Haji naa lọ laisi wahala kan-kan, ko si tun yọri si rere.
Babaláwo rèé pẹ̀lú afurasí adigunjalè mẹ́rin láhàmọ́ọ́ ọlọ́pàá Botilẹjẹ pe awọn kan sọ oko eebu si iwe iroyin naa, fun pe o gbe 'iroyin ti ko ni itumọ' jáde, awọn kan sọ pe ko tọ ọ bi orúkọ Obasanjo ko ṣe sí nibẹ.
Oshisko twins, àwọn 'ìbejì' tó ń dẹ́rìn ín p'òṣónú Wọ́n ta ère Ọ̀ṣun Osogbo sí Togo - Bàbá Ọṣun figbe ta Iṣẹ́ Kudirat Abiọla ṣì ń fọhùn síbẹ̀, lẹ́yìn ọdún 23 tó papòdà Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Olusegun Obasanjo: Ọmú ìyá mi ti mo fi ń mùkọ ni kekere ló jẹ ki ń lókun Bawo ni idibo naa yoo ti ṣe lọ?
O ni, ti ẹ ba ranti pe gomina Abdullahi Danbaba ti fi egbe oselu APC sile lọ sinu egbe PDP lati lọ se atunse to monyan lori ninu egbe naa.
Oríṣun àwòrán, Genesis Global Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Prophet Israel Oladele: Ẹ̀tanú pé Olùṣọ́ CCC Genesis Global kò fẹ́ Laide Williams-Oni ló ṣe rán an lọ́ sí ẹ̀wọ̀n ọdún kan20 Bélú 2020 Prophet Shepherd Bushiri: Iléẹjọ́ gbẹ́sẹ̀ lé ilé wòlíì tí iye rẹ̀ tó $350,00021 Bélú 2020 Professor Peller: Ọlọ́wọ́ idán àkọ́kọ́ nílẹ̀ Áfíríkà tó ń pidán fáwọn aṣaájú orílẹ̀èdè19 Bélú 2020 2:26 Fídíò, Queen Ereba Psoriasis: Níṣe ló dàbíi pé mo wà nínú àhámọ́ tí mi ò ṣẹ̀dá fúnra mi, Duration 2,2618 Bélú 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Atẹjade kan ti aarẹ ẹgbẹ Nurtw nilẹ wa, Alhaji Najim Yasin fisita ni aisan to nii se pẹlu kindinrin Fẹlẹ to da isẹ silẹ, lo se okunfa iku rẹ.
Nigba to n ba BBC Yoruba sọ̀rọ̀, SOB Agunbiade ni ohun tawọn eeyan n pin kaakiri gẹgẹ bi iroyin yii jẹ amọọmṣe awọn kan lati gbẹ́ oun lẹsẹ gẹgẹ bi oloṣelu ni.
Nitori ọpọ awọn eeyan lo n ṣiṣẹ ni Eko ti wọn si n fi ipinlẹ Ogun ṣebugbe, papa lawọn agbegbe kan bi Berger, Mowe ati Ibafo."
Ṣé ọlá àbàtà ni í mú odò ṣàn.
ẹni tí ó bá wà ní ipò gíga wọn kò jẹ́ tìí lẹ́yìn, àfi bí wọ́n ja a tilẹ̀.
To ba si n wa aaye kan ninu ara rẹ, ti wọn ko ya Tattoo si, o tiraka diẹ ko to lee ri.
Kí ọ̀rọ̀ tí wolii nì sọ lè ṣẹ pé,
To ba ya, ìrora naa yoo bọ si ẹgbẹ osi ni isalẹ ikun.
Wọ́n ní ọpọlọpọ ojú níwájú ati lẹ́yìn.
Nígbà tí àwọn marun-un náà lọ sí ilé Mika tí wọ́n sì kó àwọn ère rẹ̀ ati àwọn nǹkan oriṣa rẹ̀, alufaa náà bi wọ́n léèrè pé, “Irú kí ni ẹ̀ ń ṣe yìí?
tun fẹsẹ  mulẹ  sii ni orile ede Naijiria ati lati tun jẹ ki
Tìrẹ ni àwọn eniyan mi, bẹ́ẹ̀ sì ni àwọn ẹṣin mi pẹlu.
Idẹ ni kí o fi ṣe asẹ́ ààrò rẹ̀, kí o sì ṣe òrùka idẹ mẹrin, ọ̀kọ̀ọ̀kan sí igun mẹrẹẹrin asẹ́ náà.
Ajalu inu aye Fatai Rolling doller: Lọdun 1977, ajalu kan kọlu Fatai, o pàdánù gbogbo irinṣe to fi ń ṣòwò si ọwọ àwọn adigunjale.
Èyí tí wọ́n ṣe tó kọ̀ tí kòjẹ́ oo; yéèèèè
Iroyin so pe, Aare Omar al-Bashir kede lojo-Bo agbekale eto kan pelu orile-ede Russia, eyi ti erongba re dale riro awon omo-ogun orile-ede Sudan lagbara.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Akomolede ati Aṣa lori BBC:Wo ìrúfẹ́ ìgbeyàwó méje tó wà nílẹ̀ Yorùbá àti ojúṣe Alárinà Bí abẹnugan ilé ṣe ń kọja ló fún Ifeanyi ni ẹgbẹrun mẹ́sán náírà pé kí ó pin pẹ̀lú àwọn tó kù rẹ̀, kí a tí wí ká tó fọ̀, ní Abdullahi yìn ni ìbọ̀n lórí ni ìgbà mẹ̀rin.
Àwọn pidánpidán kò lè dúró níwájú Mose, nítorí pe oówo bo àwọn náà ati gbogbo àwọn eniyan ilẹ̀ Ijipti.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Onitsha Building Collapse: Ilé alájà mẹ́ta wó lúlẹ̀, ènìyàn kan ti kú 22 Èbibi 2019 Oríṣun àwòrán, Nnamdi Nwoye Àkọlé àwòrán, Eniyanrin ti di eero ile iwosan Ile alaja mẹta kan ti wọn n kọ lọwọ ti dawo lulẹ nilu Onitsha, nipinlẹ Anambra.
"Dino, èyí o ṣe yìí kù díẹ̀ káàtó"" Agolo akẹ́rù Apapa kò pa ènìyàn ṣùgbọ́n ó ba ọ̀pọ̀ ọkọ̀ jẹ́- Ọ̀ga RRS Olè gbé òrùka ìgbéyàwó mì ní Eko Ṣé ẹ̀mí Super Falcons gbé e lálẹ́ òní pẹ̀lú France?"
Ọmi ni wọn ta ni ipele akọkọ ere bọọlu ọhun nitori ẹgbẹ agbabọọlu Ajax dayo ti Ronaldo gba wọ le pada.
Lionel Newton – Pop Lock ‘N’ Roll
Iná sọ nínú ilé Big Brother tó ń lọ lọ́wọ́ ní Cameroon Oníṣẹ́ ikú Coronavirus tún ti jẹ́ fún wọn ní orílẹ̀èdè Cameroon Mo ti buwọ́lu àdínkù owó orí nítorí ìrọ̀rùn àwọn èèyàn ìpínlẹ̀ Ogun lásìkò Covid 19- Dapo Abiodun Aya gómìnà Kwara fẹ́ ran tìyá- tọmọ olójú búlúù lọ́wọ́ Gomina ni botilẹ jẹ pe àwọn ko jọ si ninu ẹgbẹ oṣelu kan naa, sibẹ oun mọ pe sẹnetọ naa ti ran awọn eniyan lọwọ gidigidi.
Ẹni to bori: Egypt Ìpele to ṣaaju eyi to kangun si aṣekagba Congo DR vs South Africa.
Oríṣun àwòrán, Reuters Eniyan 158 lo ku ninu iṣẹlẹ ibugbamu naa, ti èniyan 5,000 si farapa nigba ti èniyan 3000 ko ri ile gbe nitori iṣẹlẹ ohun.
 ní àwọn agbègbè kan ní gúsù amẹ ́ ríkà , afrika àti eṣíà , iye àwọn ènìyàn tó tó mẹwa nínú ọgọrun ( 10 % ) nínú gbogbo akójọpọ ̀ ènìyàn tó wà ní agbègbè náà ni àrùn náà má a nràn .
Bó ti ń pa àwọn ọdọmọkunrin, bẹ́ẹ̀ ni yóo máa pa àwọn ọdọmọbinrin,ati àwọn ọmọ wẹ́wẹ́ ati àwọn arúgbó kùjọ́kùjọ́,gbogbo wọn ni ikú gbígbóná yóo máa mú lọ.
Èmi kò ní kí Shiite má ṣe ẹ̀sìn won o -Muhammadu Buhari 1.
Gbogbo kíkùn tí ẹ̀ ń kùn, àwa kọ́ ni ẹ̀ ń kùn sí, OLUWA gan-an ni ẹ̀ ń kùn sí.
Yatọ si awọn oṣiṣẹ ijọba to wa ni ipele Kejila lọ si oke, ko ni si awọn oṣiṣẹ mii ti yoo wa si ibiṣ lasiko yi.
Gege bi Shehu se so, “Aare
Fidio alaye ti arabinrin Ọmọlọla se ree, eyi to gba ori ayelujara kan: Ninu atẹjade kan ti Gomina ipinlẹ Kwara, Abdulrazaq fi sita, ijọba ipinlẹ Kwara ni oun ko ni gba iwa bẹẹ laaye mọ rara.
Bi a ṣe ko si abẹ rẹ niyẹn.
Orilẹede mẹwa, ninu eyi ti Naijiria wa ninu wọn, ni wọn ti kọ lati tọwọ bọ iwe adehun naa.
Ọrọ pọ ninu iwe kọbọ Njẹ ẹ mọ pe kii ṣe ilu Ibadan nìkan ni orúkọ ẹgbẹ janduku, One Million Boys, ti gbajúmọ?
OLUWA tí ó ní ipá tí ó sì lágbára,OLUWA tí ó lágbára lógun.
Mose ní, “OLUWA tìkararẹ̀ ni yóo fún yín ní ẹran ní ìrọ̀lẹ́, ati burẹdi ní òwúrọ̀.
Ojú kò ní ti ẹni tí ó bá gbà á gbọ́.
Bakan naa, o ṣafihan pe lọdun 2014, ọga agba Ọlọpaa kan lọwọ ninu ifiyajẹ ọmọkunrin kan to pada ku tori bi wọn ṣe fiya jẹ ẹ.
maa se maa towobo iwe abadofin eto isuna yii, erongba mi ni lati ba ile igbimo
Ìjọba Nàìjíríà, ẹ wá ohun kan gbòógì fi sọri ọmọ Adésànmí
Iyabo Ojo gé okùn àjọṣepọ̀ rẹ̀ pẹ̀lú olóṣèlú nínú ẹgbẹ́ APC ati PDP Mo ti tọrọ aṣọ àti yẹtí etí rí, kí n tó leè ṣe àwo orin - Tope Alabi Àbí, ẹyín ni ẹrànko kìí ṣe àìsàn?
Aare ro awon asofin ohun lati gba oun laaye lati wa se agbekale iwe isuna naa lojo ti omu ohun.
Orilẹede South Africa ni ijọ yii wa.
“Nítorí náà ni mo ṣe ń dárò Moabu ati àwọn ará Kiri Heresi bí ẹni fi fèrè kọ orin arò nítorí pé gbogbo ọrọ̀ tí wọ́n kó jọ ti ṣègbé.
  Ọdún tuntun tó wọlé dé yìí, á mú’re tọ̀wá wá.
Reno Omokiri, to jẹ eekan ninu ẹgbẹ oṣelu PDP sọrọ loju opo Twitter rẹ pe, Atiku rinrin ajo fun wakati mẹjila gbako pada wale lati orilẹede Amẹrika, lati wa kopa ninu ijiroro naa.
 Lati lee dena wahala tabi iwa
Ileeṣẹ ọlọpaa ni ipinlẹ Eko ti kede pe wọn n wa ọkunrin kan, Mustapha Adekunle, ti inagijẹ rẹ n jẹ seigo.
Àsìkò tó fún ilẹ̀ Yorùbá láti dẹ́rù ba ẹ̀rù fúnra rẹ̀ pẹ̀lú Amotekun - Seyi Makinde Lẹ́yin o rẹyin, eto ifilọlẹ Amotekun to yẹ ko ti bẹrẹ lati aago mẹsan aarọ, ti gberasọ bayii, tawọn eeyan jankan-jankan, to fi mọ awọn gomina mẹfẹẹfa nilẹ Yoruba, si ti de sibi eto naa.
 Èyí tó pọ ̀ jù nínú àwọn ọmọ yorùbá máà ń sọ èdè yorùbá .
Idris ni idi ree to fi pọn dandan fun aarẹ ile asofin agba ilẹ wa naa lati wa yọju si ileesẹ ọlọpaa ni Abuja.
Ki Ọlọrun bukun orile ede yii, ki Ọlọrun si tun gbe ijoba tiwa-n-tiwa ga
Ẹsun mọkanla ni ajọ EFCC fi kan Fayose lati ọjọ kejilelogun oṣu kẹwa ọdun 2018 toun tu ile iṣẹ kan to n jẹ Spotless Investment Ltd.
Orilẹ-ede Uganda ni ireti pe ti oun ba kọ ile iṣẹmbaye to ṣafihan igba ogun wọn ti ọfọ loriṣiiriṣii ṣe wọn, o di dandan ko mu ero pupọ si wa ṣabẹwo si Uganda.
0 1385 Orilẹede Singapore 29 0.
Esi ere bọọlu yii jẹ iyalẹnu fun awọn ololufẹ ẹgbẹ agbabọọlu Arsenal lẹyin ti wọn na Napoli tan ninu idijẹ Europa League.
Chatta ni abẹ oun ni Juwọn yii ti n sisẹ nigba to kọkọ de si agbo isẹ tiata gẹgẹ bii alakoso ibi ti ere de duro, to si tun maa n sisẹ awakọ laarin awọn, ki owo lee to na fun.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Bukola Saraki ni adari wa' - Razaq Atunwa, Kwara Ki adajọ to da jọ rẹ nitori aabo ati lati ma gba idiwọ kankan laye, o kọkọ paṣẹ pe ki wọn ti gbogbo ilẹkun ile ẹjọ pa ki wọn si ko kọkọrọ fun un.
Lọpọ igba ni iporogan maa n waye, tawọn osisẹfẹyinti yoo si gba oju popo kan lati se iwọde pe ki ijọba Arẹgbẹsọla san owo osu awọn.
Àkọlé àwòrán, Pasito Fatoyinbo yẹba lẹyin iwọde yii Ninu fọnran fidio kan to n tàn kalẹ ni wọn ti ri alaga CAN fun FCT ati alaga CAN fun aarin gbungbun Naijiria, ti wọn n kede atilẹyin wọn fun pasitọ COZA.
Adams ni pẹlu atilẹyin awọn eniyan naa, yoo rọrun lati le awọn agbebọn ọhun kuro lagbegbe Oke Ogun.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù ASUU strike: Ìjọba Nàìjíríà ti gbà láti san N30b owó àjẹmọ́nú fún ASUU 16 Ọ̀wàrà 2020 Oríṣun àwòrán, @ui Àkọlé àwòrán, Oṣu mẹfa ni iyanṣẹlodi naa fi waye Ijọba apapọ Naijiria ti gba lati yọnda biliọnu lọna ọgbọn Naira, fun ajẹmọnu awọn olukọ fasiti ni Naijiria.
Dókítà Alex: Bí ẹ ó bá fi ọwọ kan nkan Obìnrin/Ọkùnrin enikeji rẹ, o ni lati je pe e tí ń fi ẹnu kò ara yín lẹ́nu, èyí sì ni góńgó orí rẹ nítorí ati ara ìtó ni aarun náà ń gba wo àgó ara nítorí náà ayé de fìdí láti gbé aarun náà fún enikeji, sugbon nkan ti ṣe pàtàkì jù ni pé ó ṣe pàtàkì kí olójú fe méjì wá lábé òrùlé kan náà, kí ẹ sì mọ ipò tí olúkúlùkù wa.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Barister lo bi gbogbo oníṣẹ́ fújì -Oṣupa Okoye ni ọwọ ni wọn fi kọ esi ibo ni gbogbo ibudo idibo kaakiri orilẹ-ede Naijiria, eleyi ti gbogbo awọn aṣoju ẹgbẹ osẹlu to wa nibẹ foju ri ti wọn si ni ẹda rẹ.
"Daurama si di iya nla ẹya Hausa ati awọn eniyan rẹ.
ọrọ ikini-kaabọ rẹ, Aṣofin Adefunmilayọ Tẹjuoṣo, Alaga Igbimọ to n ri
Àwọn akọrin tí wọ́n jẹ́ ọmọ Asafu dúró ní ipò wọn gẹ́gẹ́ bí àṣẹ Dafidi.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Ọ̀jọ̀gbọ́n náà ṣàlàyé pé bótilẹ̀ jẹ́ pé àríyànjiyàn wà lórí iye kòkòrò àìfojúrí tí èèyàn ti fa símú ki o tó ni ààrùn naa, síbẹ̀ ó ṣeéṣe kí o gba èyí láàrin èémí kan tàbí mẹ́wàá, èyíkéyìí le mú ènìyàn ni ààrùn náà.
Bí ẹ bá dán ọ̀rọ̀ kòbákùngbé wò - Lai Mohammed Bìlísì wáyé nígbà táwọn ṣọ́jà ya bo olú iléeṣẹ́ ọlọ́pàá l'Osogbo Mo kan wàhálà lálẹ ọjọ ìgbeyàwó torí ìbálé mi kò ṣe ẹ̀jẹ̀ - Ìyàwó ọ̀sìngín Lasiko ti iṣẹlẹ yii waye, iye ẹlẹwọn ti ọgba ẹwọn yii ni jẹ ọtalerugba o din mẹta.
Oríṣun àwòrán, Twitter/MBuhari Oluyẹweowo wo agba naa fi kun un pe, nṣe ni wọn wa pin inawo naa si wẹwẹ kaakiri awọn agbaṣẹṣe mẹrin, lati rii pe iṣẹ agbaṣe to kan ọkọọkan wọn ko ju miliọnu marun naira ti ofin fun oludari agba ileeṣẹ ijọba lagbara lati buwọlu lọ.
Òjò rọ̀, àgbàrá dé, ẹ̀fúùfù sì kọlu ilé náà.
Wo àwọn ojúṣe àti èèwọ̀ fún ikọ̀ ọlọ́pàá SWAT tó gba iṣẹ́ lọ́wọ́ SARS Ìjàmbá ọkọ̀ akérò àti tírélà pa èèyàn mẹ́rin lọ́nà mọ́rosẹ̀ Ore sí Benin Àwọn ìṣẹ̀lẹ̀ mánigbàgbé tó wáyé nibi ìwọ́de ENDSARS Nàìjíríà Ẹgbẹ́ Agbẹjọ́rò NBA ti kéde pé àwọn yóò ṣojú awọn Olùwọ́de #EndSARS lọ́fẹ̀ẹ́ nílé ẹjọ́ Ọlọ́pàá mẹ́sàn án tó farapa nínú ìjàmbá ọkọ̀ Akure t'éèyàn méjì ti kú sì wà nílé ìwòsàn Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Fídíò, Obalende Building Collapse: Gbogbo àwọn to há sọ́bẹ́ ilé tó wó la mọ̀14 Ọ̀wàrà 2020 Fídíò, Soyinka Cancer: Àṣe ara mi ni iso ti n run gbogbo bí mo ṣe n ṣèrànwọ́ lórí jẹjẹrẹ27 Bélú 2019 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
O óo pa àwọn ọmọ wọn run lórí ilẹ̀ ayé,o óo sì run ìran wọn láàrin àwọn eniyan.
Lati inu oyun ni mo ti pinnu pe, ma wa ibi kan ju u si ti mo ba bi.
Oríṣun àwòrán, Babajide sanwo-olu Ọjọ ọla ṣu dẹdẹ fun iṣẹ awọn oṣiṣẹ Bi awọn dokita atawọn oṣiṣẹ eto ilera miran ṣe n foju wina arun coronavirus lẹnu iṣẹ lawọn oṣiṣẹ miran n foju winna rẹ nipa yala pipadanu iṣẹ ni tabi aimọ igba ti owo oṣu yoo wọle.
Nigba to n kadi ọrọ rẹ nilẹ, Akeredolu wa rọ awọn araalu lati wo ọpọlọpọ àṣeyọrí oun ni saa akọkọ, lati dibo fun oun ni ẹkeji nitori oun yoo ṣe bẹbẹ siwaju si.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, International Day Against Drug Abuse and Trafficking: ìdí ti mo fi ń mu oògùn olóró Madagascar ninu idije AFCON 2019: Omi ayo meji si meji ni Madagascar ati orilẹ-ede Guinea gbá ni papa iṣere Alexandra ni Egypt to n gbalejo AFCON.
Lootọ ni ọpọ isu wa lẹyin mọto ọkunrin naa, amọ a ko lee sọ boya eeyan lo sọ di isu abi bẹẹ kọ, amọ se lo n kigbe pe isu lasan ni wọn, kii se eeyan ni oun sọ di isu, Awọn ọlọpa to wa ni adugbo Ikoyi ti wa gbe ọkunrin afurasi naa, ati ọmọdekunrin ti wọn lo ji gbe, lọ si agọ wọn.
Igba ti yoo darapọ mọ awọn akẹgbẹ rẹ ni ko tii han si araye.
 Ọ̀pọ̀ àwọn olólùfẹ́ rẹ̀ náà ni wọ́n ń dáwọ ìdùnù fún ayẹyẹ náà."
 Èyí ni ọba tó tẹ ̀ dó sorí òkè ṣùgbọ ́ n lónìí ọ ̀ bàkè ni wọn ń pe ibẹ ̀ .
Ṣugbọn àwọn obinrin kan láàrin wa sọ ohun tí ó yà wá lẹ́nu.
O wa kilọ fawọn arinrinajo lati san owo fun awọn ile iwosan ayẹwo ti ijọba buwọlu nikan.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Penis Captivus: Nǹkan márùn-ún tí obìnrin àti ọkùnrin tó lẹ̀pọ̀ yóò ṣe láti yọ rèé 9 Owewe 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 12 Owewe 2020 Oríṣun àwòrán, Youtube viral Laipẹ yii ni iroyin jade nipa ọkunrin ati obinrin kan ti wọn lẹpọ loju ara ni ibi ti wọn ti n ba ara wọn lo pọ ni ọpọ ọrọ ti jade pe ki lo n faa irufẹ eyii.
” Ṣimei sì wà ní Jerusalẹmu fún ìgbà pípẹ́.
Àkọlé àwòrán, Ọrọ wa maa to ye ara wa nitori aabo awọn to yan wa sipo ṣe pataki Awọn ladelade, loyeloye, ẹgbẹ awujọ ati awọn oniruuru ajọ eleto aabo lo ti pejo si Ibadan bayii.
Àwọn ti wọn ti ni arun kogboogun HIV, Hepatitis, arun ibalopọ Syphilis, tabi ikọ́ ife ati awọn ajakalẹ arun to n ràn lati ara ẹni kan si ikeji ko le fi ẹjẹ silẹ.
Toyin Ajeyemi foju hande fun igba akọkọ lati sọrọ lati igba ti aawọ ti suyọ laarin ohun ati akẹgbẹ rẹ, Lizzy Anjọrin.
"Ààrẹ Buhari sàlàyé pé, ""ọ̀rọ̀ ìdánilóju yìí kìí ṣe lóri ọ̀rọ̀ Boko Haram nìkan bíkóse ti ìjínigbe àti àwọn ìwà ìbàjẹ míràn, a ò ni gbọ̀jẹ̀gẹ́ titi tí à ó fi fa gbogbo àwọn oniṣe ibi tu ni orilẹ̀-èdè Ẹwẹ̀, ọ̀pọ̀ ọmọ Nàìjíríà ló tí ń fẹ̀sì si ọ̀rọ̀ ààrẹ lóri Twitter bákan náà Bí ọdún Ọ̀ṣun Oṣogbo ṣe bẹ̀rẹ̀ rèé àti pàtàkì rẹ̀ fún Nàíjíríà Ìpínlẹ̀ Ogun, Eko ti gbáradì fún ẹ̀kún omi yalé Togo sòfin aago ti olùfẹ̀hónú han lè jáde àtí àsìkò tí ó wọlé Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Kayeefi: Facebook ni Wolii Arole Jesu fi tàn an wọ agbo, orí rẹ̀ ni wọ́n fi s'owó Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!"
Ó sì sọ ibẹ̀ ní Bẹtẹli.
Ayẹwo oku fihan pe arun ikọlu ọkan to ṣekupa Maradona lẹyin ọsẹ meji to ṣe iṣẹ abẹ ọpọlọ lati ko ẹjọ to da sii lọpọlọ kuro.
Ẹ ṣọ́ra, ẹ má máa rú ẹbọ sísun yín níbikíbi tí ẹ bá ti rí.
Akọkọ, wọn le fi ẹsẹ rin lori koriko lati gun oke arẹwa ọhun.
Ó pani lẹ́rìn-ín pé láti ìgbà yìí wá tí mo ti ń ṣiṣẹ́ gẹ́gẹ́ bí igbá-kejì ààrẹ, bí mo ti ṣe ń ṣe ètò oríṣiríṣi tí n ò sì yé fi àwọn àṣàyàn ìhùwàsí mi l'éde, ṣùgbọ́n kò sí ẹni tí ó ti wádìí nípa àwọn ọ̀nà òṣèlú tí mo yàn ní ààyò.
O óo bá a ní ibi tí ó gbé ń gbadura.
 Kenolisa ni ọlọlajulọ, ẹ jọ ibeere temi ni pe, ki ni ohun gan pato ti ẹ ni fun awọn ọdọ orilẹ-ede yii?
Ṣé ẹ fẹ́ kí á tún jẹ yín níyà sí i ni,àbí kí ló dé tí ẹ kò fi jáwọ́ ninu ìwà ọ̀tẹ̀ tí ẹ̀ ń hù?
N kò gba owó rí lọ́wọ́ olùdíje kó tó dé ipò - Oyedepo Obìnrin tí kò bá rẹwà ló ń ṣí ara sílẹ̀ - Ṣọla Allyson Kọmisọna feto iroyin, aṣa ati irinajo igbafẹ ni ipinlẹ Ọyọ, Toye Arulogun ni, ilu Igbo Ọra ni ibeji pọ si julọ ni gbogbo agbaye, ko si si ile kan ni ilu naa, ti wọn ko ti bi ibeji tabi ju bẹẹ lọ.
 ní ọdún 1994 ni ó gba oyè b.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ọlọ́pàá fi panpẹ ọba mú ọmọṣẹ̀ ológun Wàhálà bẹ́ sílẹ̀ nígbà ti ọkọ̀ ti wọ́n fi maa n fa ọkọ to bàjẹ̀ ti olóògbé n wà lọ fí ara họ ọkọ ayọkẹlẹ Nissan Primera pẹlu Nọmba Abuja KWL 811 AP to jé ti ọmọ ológun yìí.
Ìwọ kò jẹ́ kí n tẹ́ lójú ẹgbẹ́, ìwọ kò tú àṣírí mi níwájú ọ̀rẹ́, n kò sì béèrè nǹkan lọ́wọ́ rẹ kí ìwọ kọ etí dídí sí mi.
Iṣẹ ti bọ lọwọ akọnimọọgba Quique Setien lẹyin abuku nla naa, koda wọn ti le Eric Abidal naa to n ri sí katakara ati pasiparọ awọn agbabọọlu fun Barca lọ.
Ọ̀nà tó fi le è mọ gbájúẹ̀ babaláwo - Ẹlẹ́buìbọn Èrò àwọn ọmọ Naijiria ṣọ̀tọ̀ọ̀tọ̀ lórí Tinubu àti Abbo Agbẹnusọ fun ajọ NNPC, Ndu Ughamadu ṣalaye pe, lootọ̀ ni oludari agba ajọ NNPC lọ sọdọ aarẹ ile aṣofin agba, Sẹnatọ Ahmad Lawan.
Nigerian Police: Àgbègbè odogbolu ní ìpínlẹ̀ Ogun ní ìṣẹ̀lẹ̀ náà ti wáyé
pe ise yii kii se ojuse ijoba nikan sugbon  ara ilu naa  ni ipa pataki lati ko.
 Àṣà yìí kò wọ ́ pọ ̀ ní àríwá nàìjíríà , àti pé àwọn fúlàní kìí dábẹ ́ fún ọmọ wọn .
Ìgbìmọ̀ ìgbẹ́jọ́ wọ́gilé ẹ́jọ tó takò iyansipo Sanwo Olu Háà!
Ẹ óo máa rú ẹbọ yìí pẹlu ẹbọ ohun jíjẹ ati ẹbọ ohun mímu rẹ̀ gẹ́gẹ́ bíi ìlànà ti ọjọ́ kinni; 
"Ọlọ́pàá fi afẹ́fẹ́ tajú-tajú àti omi tú àwọn tó fẹ́ ṣun ìbùgbé ìtajà ShopRite l‘Abuja ká ShopRite Ibadan gbé ìlẹ̀kùn tìpa torí ìkọlù àwọn tó ń fẹ̀hónú hàn Àwọn èèyàn to n fẹ̀hónú hàn dáná ṣun iléeṣẹ́ MTN n‘Ibadan ""Ọjà àìmọye mílíọ̀nù naira ni wọ́n kó nílé ìtajà mi torí ìgbẹ̀san ìkọlù South Africa"" ""Naijiria gbọdọ̀ kẹ̀yìn sí ìrẹ́pọ̀ pẹ̀lú South Africa"" Xenophobic Attack: Àwọn ọmọ Nàìjírìá bínú kọlu Shoprite l'Eko Loju opo Twitter, Instagram ati Facebook si ti kun fun ọpọ awọn ilumọọka yii ti wọn ko kawọ gbera lori isẹlẹ to n waye naa yika orilẹede Naijiria ati ni South Africa."
Faari Buhari PDP: Ẹní jẹ fùfú lará ń fu, ọmọ ẹgbẹ́ wà kò hùwà àìtọ́ lásìkò ìdìbò Àwọn àwòrán mánigbàgbé nípa Ààrẹ Muhammadu Buhari Ṣé irúfẹ́ oúnjẹ tí ò ń jẹ́ lè jẹ́ kí o gbádùn ìbálòpọ̀ rẹ síi?
Ṣugbọn kini ki a wa sọ fún ẹni ti nkan n ṣe lọpọlọ pe ki o lo?
Ìlú tí a tẹ̀dó sórí òkè, kò ṣe é gbé pamọ́.
Ni igba naa, igbakeji ọga ọlọpaa to n risi iwa ọdaran lawujọ, Peter Ogunyonwo lo kede rẹ lasiko ti wọn n ba awọn ẹbi Tiamiyu kẹdun lẹyin iku ọmọ wọn.
Dunlop ati Michelin Oríṣun àwòrán, DUNLOP/FACEBOOK Taya ọkọ ni ileeṣẹ Dunlop ati Michelin n ṣe ni Naijiria, wọn si lamilaaka laye igba tiwọn.
Oríṣun àwòrán, LASEMA ''A ṣi wa nibi iṣẹlẹ naa bayi ti a ṣi n gbiyanju lati doola ẹmi awọn miran ninu ijamba yi.
Plane crash: Díẹ̀ ló kù kí bàlúù arìnrìnàjò sílẹ̀ mímọ́ Hajj gbaná ní Minna
Ooni Ifẹ bu ẹnu ẹ̀tẹ́ lú ètò BBNaija nítorí ó tàbùkù àsà Yoruba Kí ló dé táwọn ọ̀dọ́ dìbò 140m fún BBNaija àmọ́ tí ìbò ààrẹ Nàíjíríà jẹ́ 28m?
Ìtàn tó wà nídi òwe ‘Sebótimọ Ẹlẹ́wà Sàpọ́n’ Ni ọjọ Ẹti to kọja ni Makinde paṣẹ pe eegun ẹgbẹ awakọ ero, NURTW ko gbọdọ ṣẹyọ fun igba diẹ nipinlẹ Ọyọ lẹyin ti wọn fi ẹsun kan awọn ọmọ ẹgbẹ naa pe wọn n da omi alaafia ru lọna ati gba ibudokọ lọwọ ara wọn.
Nígbà tí mo rí eléyìí mo pe àwọn ẹgbgẹ́ mi sí ìkọ̀kọ̀ mo sì wí fún wọn ohun tí mo ṣe àkíyèsí àti nǹkan tí mo gbọ́, mo sì tún sọ fún wọn pé mo ní àkàrà kan nínú àpò mi tí kò lè tán bí ó ti wù kí á jẹ́ ẹ́ tó àti pé àkàrà náà ni mo rò pé ó yẹ kí á máa jẹ.
O bẹbẹ pe ki Ọlọrun tubọ maa bukun fun oun bi oun tun ti le ọdun si.
N óo mójú kúrò lọ́dọ̀ wọn, kí wọ́n lè sọ ibi dídára mi di eléèérí.
Nítorí ẹni tí ó ti kú ti bọ́ lọ́wọ́ ẹ̀ṣẹ̀.
Nígbà tí Ọlọrun bá Mose sọ̀rọ̀ tán lórí òkè Sinai, ó fún un ní wàláà òkúta meji gẹ́gẹ́ bí ẹ̀rí.
Ọkan lara awọn dokita ilẹ naa, Roberts sọ pe ile iwosan ti kun fun awọn alaisan Coronavirus.
N óo jẹ́ kí omi òkun Babiloni gbẹ,n óo sì jẹ́ kí orísun odò rẹ̀ gbẹ.
Igi kedari tí ó wà ninu ọgbà Ọlọrun kò lè farawé e.
Ètè rẹ̀ dàbí òdòdó lílì,tí òróró òjíá ń kán níbẹ̀.
Àwọn ìwo mẹ́wàá dúró fún àwọn ọba mẹ́wàá, tí yóo jáde lára ìjọba kẹrin yìí.
 Ó tún jẹ ́ apá ibi tí Ọba Èkó ń gbé ( king of lagos ) .
 A gbodo fọwọsowọpọ lati ja ija naa,ki a si bori.
" Chris Dalzell gba pe sise ọsọ ara pẹlu Tattoo ti di baraku fun oun.
Dana d'awọn ero lẹbi ilẹkun to fo yọ Ọwọ tẹ agbofinro meji lori iṣowo ọmọniyan Amnesty: Ọmọ ogun Nigeria ko naani ẹmi 'Súnkẹrẹ-fàkẹrẹ ọkọ̀ ló kó mí yọ lọ́wọ́ ìjàmbá ọkọ̀ òfurufú' O ni nigba ti Tiffani a fi ji saye, gbogbo ibẹ ti dudu.
Bí a bá lọ sinu ìlú ebi yóo pa wá kú nítorí ìyàn wà níbẹ̀, bí a bá sì dúró níbí, a óo kú bákan náà.
Togun tẹsiwaju pe nigba ti fọọmu jade, o wa lori itakun ayelujara fun nnkan bi i ọjọ mẹjọ, wọn si fopin si i."
Ṣugbọn ohun tí eniyan bá sọ láti inú ọkàn rẹ̀ wá, èyí ni ó ń sọ eniyan di aláìmọ́.
Pẹlu iye awọn eeyan tuntun yii, o ti pe 56,,956 eeyan to ti ni arun naa l'orilẹede Naijiria bayii.
Ẹ wo àwọn gbajúmọ̀ òṣèré tíátà tó jogún eré ṣíṣe lọ́dọ̀ òbí wọn Àwọn tó jí kọmíṣọ́nnà gbé l'Ekiti ń bèèrè fún N30 mílìọnù kí wọ́n tó le è tú u sílẹ̀ Ogun buru jai, to si maa n ba ọpọ dukia jẹ, tabi mu ẹmi eeyan lọ.
Bẹ́ẹ̀ ni wọ́n ṣe pa ọ̀kẹ́ meji ati ẹgbaa (42,000) eniyan, ninu àwọn ará Efuraimu ní ọjọ́ náà.
Èmi náà ni, títí di ọjọ́ ogbó yín,n óo gbé yín títí tí ẹ óo fi hewú lórí.
O le ni aadorin obinrin ti won fesun kan oludasile ile ise Miramax film studio ati Weinstein Co pe o n fipa ba won lo po lati odun to ti pe.
Oríṣun àwòrán, Facebook/Adebayo Solihu Àkọlé àwòrán, Agbẹjọro Solihu Adebayo ni aṣilo agbara ni ki awọn ẹka ijọba miran ma yọ adajọ nipo ''Ẹka ẹyọ kan ṣoṣo ti ofin sọ ti o si ni agbara lati yọ adajọ ni Naijiria ni NJC'' O salaye siwaju pe ''ko si ẹni ti ko le kọ iwe ẹsun nipa adajọ,koda ara ilu le kọ ti wọn ba fura si pe irin ẹsẹ adajọ ko mọ'' Nipa iroyin to n ja rain wi pe ijọba ipinlẹ Kogi fẹ lo awọn ọmọ ogun ati ọlọpaa lati yọ adajọ naa nipo,o ni eleyi tako ofin ''Ati ọlọpaa, ati awọn ọmọ ogun ti o ja si pe wọn wa labẹ ẹka alasẹ, ko si ẹni ti ofin gba laye ninu wọnlati yọwọ adajọ lawo bi kii ṣe wi pe aṣẹ na wa lati ọdọ ẹka idajọ fun arawọn'' .
Ìdí abájọ ni pé ní ìdílé kan, a lè rí ẹnìkan tó jẹ́ Mùsùlùmí, kí ẹ̀gbọ́n tàbí àbúrò onítọ̀hún jẹ́ Kìrìstẹ́nì.
"ki Ọlọrun ko fi ifẹ kun ile yin, ki o si gba gbogbo adura yin.
Bakan naa lo ni ti inu oun ko ba dun, ẹnikẹni to ba ya aworan oun sinu fidio ko ni ri lo rara, tori aworan naa yoo ti parẹ nigba to ba dele.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Coronavirus: Wo èròjà tó wà lára àwọn èèyàn kan, tí Covid-19 fi di èèwọ̀ fún wọn 13 Sẹ́rẹ́ 2021 Oríṣun àwòrán, @iamseunalaofin Bí àwọn onímọ̀ ṣe n gbìyànjú láti wá ojutùú sí àjàkálẹ̀ àrùn Covid-19, tí ọ̀pọ̀ ń wá òògun tàbi abẹ́rẹ́ ti yóò yanju àrùn náà pátápáta, ní àwọn míràn ń mojú tó èròjà tí kò le jẹ́ kí àwọn míràn ni coronavirus.
Àwọn eniyan náà kò ronupiwada kúrò ninu ìwà ìpànìyàn, ìwà oṣó, ìwà àgbèrè ati ìwà olè wọn.
Oríṣun àwòrán, others Iṣẹlẹ naa waye lọjọ kẹrin, oṣu karunnun ọdun 2018.
ede Naijiria , ogagun agba Tukur Buratai so pe , “ Ẹ duro fun oludari awon gbofinro ,”
Nígbà náà ni yóo gbẹ̀san lára àwọn tí kò mọ Ọlọrun ati àwọn tí kò gba ọ̀rọ̀ ìyìn rere Oluwa wa Jesu.
Ní gbogbo ọ̀nà tí mo ti k’etí ikún sí Ọ
O salaye wi pe,  oko oju omi ti o je ti orile-ede Libya, ti orile-ede Greece gbese le ni nnkan bi ojo meloo kan seyin, ti won yin ado-oloro lu, ki I se lati dun koko mo orile-ede Libya nikan bikose gbogbo ekun naa”.
Bi iyàwó bá kú, wọn kò jẹ́ fi ọkọ rẹ jogún fún ẹbi iyàwó.
Ilé aṣòfin ti buwọ́lu Tanko Muhammad gẹ́gẹ́ bi adájọ́ àgbà Nàìjíríà Ẹ padà sílé èyin ọmọ wa tó n ṣiṣẹ́ darandaran - NEF ti Fulani Ẹgbẹ́ àwọn òṣìṣẹ́ TUC fárígá sí ìjọba Naijiria lórí owó oṣù tuntun CAN kò rán ẹnikẹ́ni lọ ṣọ́ọ̀ṣì COZA, iṣẹ́ ara wọn ní wọ́n lọ jẹ́ -Samson Ayokunle Ikọ Super Eagles jawe olubori ninu ifẹsẹwọnsẹ meji ti wọn kọkọ gba pẹlu Burundi ati Guinea ki Madagascar to fiya jẹ wọn lai ro tẹlẹ.
Ọkùnrin kọ́ ló ra jeep fún Iyabo Ojo, òógùn ojú mi ni mo fi rà á fun"" Kanu Ejike fipá bá ọmọ ọdún méje lò pọ̀ nínú sọ́ọ̀bù ìyàwó rẹ̀ Owo ẹya fun awọn olokoowo ke ke ke- N100 bn Owo ẹya fun eto iwosan ati ipoogun - N100 bn Owoya fun awọn ileeṣẹ eto ọgbin ati ipese iṣẹ nla nla - N1 trn Ajọ to n ri si idagbasoke agbegbe Niger Delta - N63."
ẹni tí ó kó kẹ̀kẹ́ ogun ati ẹṣin jáde, ogun, ati àwọn ọmọ-ogun;wọ́n dùbúlẹ̀ wọn kò lè dìde mọ́,wọ́n kú bí iná fìtílà.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ibùdó amúnáwá kan bú gbàmù n‘Ibadan, ni iná bá ṣẹ́yọ Saheed àti Fathia Balogun dìjọ ń ṣe ọjọ́ ìbí lónìí, ẹ wo àjọṣepọ̀ tó wà láàrin wọn Wo àtúpalẹ̀ ìlànà tuntun nípa gbígba físà Nàíjíríà tí Buhari gbé jáde Ọ̀pọ̀ nǹkan tí kò yé èmi àti Bàbá Wande, ló fa ìjà lórí sinimá Tolúwa Nilẹ̀ - Tunde Kelani Nigba ti wọn n se alaye nipa ohun to fa bi wọn se sun ẹjọ ọhun siwaju, awọn osisẹ ileẹjọ sọ fun akọroyin BBC Yoruba to wa nile ẹjọ pe, ijọba ipinlẹ Ondo ti gbe ẹjọ ọhun kuro niwaju ileẹjọ Magistrate lọ sile ẹjọ giga ipinlẹ naa.
Igba marun un ọtọọtọ si ni awọn ontaja ọmọ orilẹ-ede Ghana ti sọ agadangodo si ṣọọbu awọn ọmọ Naijiria to n taja lawọn ọjọ abẹle gbogbo nibẹ.
Oluwa mọ ọ̀nà láti yọ àwọn olùfọkànsìn kúrò ninu ìdánwò, ṣugbọn ó pa àwọn alaiṣododo mọ́ de ìyà Ọjọ́ Ìdájọ́.
PDP lo jawe olubori ninu gbogbo idibo to waye ni ipinle naa ,ayafi ẹyọ  kan ti Kabiru Hassan to je oludije fun ipo
Lẹyin naa ni awọn eeyan miran tun le e pẹlu ibọn lọwọ ti oun naa si da pada fun wọn.
O salaye pe, “oja tomati maa n lo nigba miiran, toripe o ni asiko, ni eyi ti alekun ti ba owo ori re  lati ipinle Kano, Sokoto, Zaria ni awon ibi ti a ti n ra won”.
wa nikawọ adari rere, inu wa dun pupọ.
Ipenija ni eyi jẹ fun gbogbo ogidi ọmọ ku-ootu-oojiire-bi?
Ọkan ninu awọn isẹlẹ to kọ ni lọgbọn, ti wọn sọ di owe, to si di ohun manigbagbe ni itan kan to nii se pẹlu Ọmọyẹ ati ọmọ iya rẹ.
O tun rọ awọn olugbe adugbo Ekpetiama atawọn eeyan ipinlẹ Bayelsa lapapọ lati se suuru, ki wọn si fun awọn ọlọpa ni iroyin to ba yẹ, eyi ti yoo se iranwọ fun awọn ọlọpaa ninu iwadi wọn lati tete sawari awọn ọdaran naa.
Wọ́n tún fún wọn ní Mahanaimu, 
Ọlọ́pàá tún ọ̀daràn mú lẹ́yìn ọjọ́ karún tó kurò lẹ́wọ̀n Ọjọ abamẹta ọjọ ikẹẹdogun oṣu kẹfa ni iṣẹlẹ yii ṣẹ ti awọn ọmọ Naijiria to ṣoju wn si ti sare ke si ijọba lati tara ṣaṣa si i.
A gbé ọ ga, nítorí agbára rẹ, OLUWA!
Ìrètí mi ni láti ri yín, kí ẹ lè ràn mí lọ́wọ́, kí n lè débẹ̀, lẹ́yìn tí mo bá ti ní anfaani láti dúró lọ́dọ̀ yín fún ìgbà díẹ̀.
Muyiwa Ademọla Oríṣun àwòrán, Muyiwa ademola/ instagram Sinima 'Ori'lo fọnrere Muyiwa Ademọla, ti ọpọ ṣaaju mọ si Muyiwa Authentic, sita.
Ìwo meje ni ó ní ati ojú meje.
Ní ọjọ́ kẹrin Elisuri ọmọ Ṣedeuri, olórí ẹ̀yà Reubẹni mú ọrẹ tirẹ̀ wá.
Nípa ọ̀rọ̀ tí èmi pẹlu rẹ jọ sọ, ranti pé OLUWA wà láàrin wa laelae.
Ohun tí ọ n tẹ BBC Yoruba leti n'ipe yatọ si iwe adehun ajumose ti ẹgbẹ oṣelu SDP gbe ka iwaju APC, ẹgbẹ oṣelu naa tun se ileri ipo Sẹnetọ kan, ipo ile aṣoju aṣofin meji, komisona meji bi oyetola ba Wọle ati ipo ile aṣofin mẹrin fún un.
Láti ibẹ̀, ó lọ títí dé Hukoku, ó lọ kan ilẹ̀ ẹ̀yà Sebuluni ní apá ìhà gúsù, ó sì kan ilẹ̀ ẹ̀yà Aṣeri lápá ìwọ̀ oòrùn, ati ti Juda ní apá ìlà oòrùn létí odò Jọdani.
Oríṣun àwòrán, @SimonLalong Àkọlé àwòrán, Oniruuru ẹsun iwa jagidijagan lo n kaakiri bayii lori bi awọn janduku ṣe fi oju awọn oludibo ati oniroyin ri mabo nilu Kano lasiko atundi ibo naa Lalong ni ibo 595,582 lati gbẹyẹ mọ Ọgagunfẹyinti, Jeremiah Useni ti ẹgbẹ oṣelu PDP, ẹni to ni ibo 546,813.
Coronavirus in Nigeria: Àwọn ìlànà tó tọ̀nà láti tọ̀ tí o bá fura pé o ní àrùn Coronavirus
Ọpọ àwọn olugbe iyana Borno Way ati adugbo Kano ni Yaba nilu Eko ni o n kọminú nípa òkú arakunrin kan ti wọn ba ninu agbá ni adugbo naa ni ọjọ Aiku.
Lẹ́yìn tí àwọn ará Dani ti kó oriṣa Mika, tí wọ́n sì ti gba alufaa rẹ̀, wọ́n lọ sí Laiṣi, wọ́n gbógun ti àwọn eniyan náà níbi tí wọ́n jókòó sí jẹ́jẹ́ láì bẹ̀rù; wọ́n pa wọ́n, wọ́n sì dáná sun ìlú wọn.
Egbe oselu All Progressives Congress ni iye ibo  152,224 nigba ti egbe alatako  Peoples Democratic Party  PDP  ni iye ibo 259, 997, nitori naa won jawe olubori ninu eto idibo aarẹ.
Láìpẹ́ ọkùnrin yìí mú ẹja mẹ́ta tí ó rí bíi tí ìṣáájú wá, ọba sì bá ìyàwó rẹ̀ lọ sí ilé oúnjẹ; nígbà tí ó dá ọ̀hún ó ní kí ìyàwó òun bẹ̀rẹ̀ sí se ọbẹ náà lójú òun.
OLUWA kórìíra ẹnikẹ́ni tí ó bá jẹ́ agbéraga,dájúdájú kò ní lọ láìjìyà.
2 Òun yíò sì gbìn sí ọkàn àwọn ọmọ awọn ìlérí tí a ṣe fún àwọn bàbá, ati ọkàn ti àwọn ọmọ yíò sì yí sí ọ̀dọ̀ àwọn bàbá wọn.
"Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Mayowa Omoniyi: Kò sí orin Obey, Sunny Ade abí tàkasúfèé tí ń kò le ta gìtá sí Aarẹ Egbelade ni ""a fẹ ki ijoba kede ọlude logunjo, oṣu kẹjọ lọdọọdun gẹgẹ bi ayajọ ọjọ Iṣẹẹṣe."
Iko ohun so pe, “won sakiyesi idi ti won fi niloo atileyin awon alamoju to eto idibo lagbaaye, aseyori eto idibo ohun je ojuse awon omo orile-ede Sierra Leone”.
Ilu Koutiala nilu abinibi rẹ, to si lọ ile iwe ni Lycee Janson-de-sally ni Pari at Bamako.
Àkójọpọ̀ àwòrán Òjò òwúrọ̀ Ọjọ Àjé l'Eko Aisha Buhari ké gbàjare pé ètò ìjọba Buhari kò ṣànfàní f'óbìrin Awọn ìgbésẹ tí Ehi ni o le doola ara ilu nigba ojo ree: 1.
Lẹ́yìn tí ilé alájà mẹ́ta dà wó ní ìlú Èkó l'Ọjọru níbi tí Ogún èèyàn ti pàdánù ẹ̀mí wọn, atún gbó wípé ilé alájà mẹ́ta mìíràn tí wọ́n ń kọ lọ́wọ́ tún ti wó ní ìlú Ìbàdàn.
Amọ sibẹsibẹ, eyi ko ni ki o ma figa gbaga pẹlu awọn ọmọ oye yoku to fẹ jọba nikete ti Alaafin Gbadegesin Ladigbolu keji waja lọdun 1970.
A ti kọ ọ́ sílẹ̀ pé, “Olùdáǹdè yóo wá láti Sioni,yóo mú gbogbo ìwàkiwà kúrò ní ilé Jakọbu.
Ogunjemilusi, mni - Directing Staff NIPPS xii.
US presidential election 2020: Kíni Kọ́lẹ̀jì ìdìbò, àwọn ìpińlẹ̀ tó le gbé olùdíje wọlé àti àwọn ǹkan ti o yé kí o mọ̀ nípa ìdìbò ilẹ̀ Amerika.
O ni ẹru n ba oun pe wọn yoo sọ opopona ọhun di akọpati ni lẹyin ti Buhari ba ti si tan gẹgẹ bi wọn ti se ni ibudokọ to wa ni Ikẹja.
Ileeṣẹ to n risi iṣẹlẹ pajawiri ipinlẹ EKo, LASEMA, ati ileeṣẹ ijọba apapọ to n risi iṣelẹ pajawiri, NEMA ti n ṣiṣẹ takuntakun lojukjo iṣẹlẹ ọhun lati ṣe iwaadi okodoro lori ibugbamu ọhun.
Ọsinbajo sọ lori itakun Twitter rẹ wipe, iroyin ofege ti wọpọ ni orilẹede Nigeria nitori oṣelu.
Nitori naa, wọn n fẹ ki wọn so ikede esi naa rọ titi wọn yoo fi koju iṣẹlẹ to waye ni ijọba ibilẹ Ilejemeje.
 kété tí Ògúnmólá padà dé Ìbàdàn ni ó lo wà àwon omo ogun kúnra pèlú ìrànlówó ogórùún àti mókànlélógójì ìlú ( 141 ) , láti fi bá Ààre kúrunmí jà .
Nígbà náà ni mo wí fún wọn pé, “Bí ó bá tọ́ lójú yín, ẹ fún mi ní owó iṣẹ́ mi, bí bẹ́ẹ̀ kọ́, ẹ máa mú un lọ.
Gideoni wí fún Ọlọrun pé, “Bí ó bá jẹ́ pé èmi ni o fẹ́ lò láti gba Israẹli kalẹ̀, gẹ́gẹ́ bí o ti wí, 
Oríṣun àwòrán, Instagram/abiolaajimobi Oloye Tinubu yannana ọrọ yii ninu ọrọ to fi ranṣẹ sibi apero ọlọdọọdun ti wọn fi sọri oloogbe Abiọla Ajimọbi, eyi to waye nilu Ibadan.
Awọn kan sọ wi pe Gomina Obaseki to wa ni idi bi wọn ṣe le Obaseki kuro ni ẹgbẹ oṣelu APC ni wọọdu rẹ, Oshiomole naa si ri daju pe Obaseki to jawe olubori ninu idije sipo gomina labẹle ni ẹgbẹ oṣelu APC, ti Pasito Osagie Ize-Iyamu si bori.
Àwọn eniyan Israẹli pe orúkọ oúnjẹ náà ní mana, ó rí rínbíntín-rínbíntín, ó dàbí èso igi korianda, ó funfun, ó sì dùn lẹ́nu bíi burẹdi fẹ́lẹ́fẹ́lẹ́ tí wọ́n fi oyin ṣe.
Awọn ọsisẹ ajọ to nse iranwọ f'awọn eniti ajalu deba ni Naijiria so wipe awọn eeyan to sa asala fun ẹmi wọn to le ni egberun lọna ogoji ni wọn yaa wọ orilẹede Naijiria lati orilẹede Cameroun to mule ti Naijiria.
Alága àjọ CAN ni Ìpínlẹ̀ Òndó, Ẹni ọwọ Ayọ̀ Oladapo tó bá BBC Yorùbá sọ̀rọ̀ ṣàlàyé pé àṣẹ láti ọ̀dọ̀ Ààrẹ CAN ni ìwọde náà láti pé àkíyèsí ìjọba sí ipaniyan jákèjádò.
Òfin mejeeji wọnyi ni gbogbo òfin ìyókù ati ọ̀rọ̀ inú ìwé àwọn wolii rọ̀ mọ́.
Gomina Babajide Sanwo-Olu ti sọ tẹlẹ pe ijọba ipinlẹ Eko yoo san ju ọgbọn ẹgbẹrun un naira ti ijọba apapọ kede gẹgẹ bi owo oṣu oṣiṣẹ to kere julọ lọ.
Ìwà ìkà àti ìbanilórúkọ jẹ́ ni, mo sì sọ gbangba-gbàǹgbà pé, a kò tii fi ìgbà kan ké si ISWAP tàbi ẹgbk agbésùmọ̀mí kankan fún ohunkóhun.
Kí ó gbé ọwọ́ lé orí ẹbọ sísun náà, OLUWA yóo sì gbà á gẹ́gẹ́ bí ẹbọ láti kó ẹ̀ṣẹ̀ rẹ̀ lọ.
“Bi ojú bá mọ́, Agbe á yalé Aláró, Àlùkò á yalé Olósùn, Lékeléke á yalé Ẹlẹ́fun”
" Inu wahala yii ni obinrin ti ko jade kuro nile ọkọ rẹ lẹyin osu kan pere to bimọ, to si n lọ gbe lọdọ ẹgbọn rẹ obinrin kan pẹlu ọmọ rẹ laisi owo kankan ti yoo fi tọju ọmọ ọhun.
O ni Inu mi dun lati kede Gboluga Ikengboju gẹgẹ bi igbakeji mi ti a o jọ ṣiṣẹ papọ lati tukọ ijọba ipinlẹ Ondo ninu idibo to n bọ lọjọ kẹwaa, oṣu Kẹwaa, ọdun 2020."
LaVey gbagbọ pe, Ọlọrun awọn Kristiẹni ko ni òye tabi ni imọ nipa bi ko ṣe rọrun lati jẹ eniyan ẹlẹran ara.
Iroyin sọpe orilẹede Niger ni awọn ẹgbẹ alakatakiti yii ti ṣẹ wọ ẹkun iwọ oorun ariwa orilẹede Naijiria.
Eyi ni koko marun un ninu awọn ọrọ ti Aarẹ Buhari sọ ninu ifọrọwerọ naa.
Àwọn tí mo ti yàn ni yóo jogún rẹ̀,àwọn iranṣẹ mi ni yóo sì máa gbé ibẹ̀.
Nítorí láti inú ọkàn eniyan ni ète burúkú ti ń jáde: ìṣekúṣe, olè jíjà, ìpànìyàn, 
Iyaafin  Aisha Buhari naa wa pẹlu aare lasiko to n gba
Nígbà tí Dafidi pada dé Sikilagi, ó fi ẹ̀bùn ranṣẹ sí àwọn ọ̀rẹ́ rẹ̀ tí wọ́n jẹ́ olórí Juda; ó mú ninu ìkógun náà, ó ní, “Ẹ̀bùn yín nìyí lára ìkógun tí a kó láti ọ̀dọ̀ àwọn ọ̀tá OLUWA.
Kí o sì mú meji meji ninu gbogbo ohun alààyè, kí wọ́n lè wà láàyè pẹlu rẹ, takọ-tabo ni kí o mú wọn.
Omo odun mejo ni nigba ti o bere orin kiko ni awon ibudo igbafe.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ebola Virus: ìdí tí Ebola fi ń tàn kálẹ̀ Lai ti i pe ọdun kan, awọn to ti ni aarun naa ti pe ẹgbẹrun meji.
Ọkan lara awọn obinrin Chibok to sọrọ ninu fọnran naa, wipe awon ko ni pada sọdọ awọn obi awọn, ti wọn si rọ awọn obi wọn lati gba esin Musulumi.
Gbogbo ètò iṣẹ́ ati pípín àwọn alufaa ati àwọn ọmọ Lefi ninu tẹmpili ni a ti ṣe fínnífínní.
Ninu ọrọ rẹ, oni ''awọn se agbatẹru ọrọ ti igbakeji aarẹ, sọ wipe o pọn dandan ki ipinlẹ kọọkan o maa se isakoso awọn ọlọpaa wọn''.
Oríṣun àwòrán, @ovieali Àkọlé àwòrán, Ibudo darndaran ni ona abayo Buhari Gẹgẹ bi ohun ti akọroyin BBC, to se iwadi iroyin yii ti ṣe salaye, awọn darandaran maa n tẹdo si ibi ti wọn ba ti ri omi ati ounjẹ fawọn nnkan ọsin wọn.
Àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ bá pín in fún àwọn eniyan.
Bakan náà ni ìjọba tún kéde pé gbogbo àwọn ilé ọtí àti gbogbo ibi ìtura gbogbo tó fi mọ́ àwọn ilé ijọ àti sinimá níwọ̀n ìgbà ti wọ́n ba ti tẹ̀lé àwọn ìlànà lati dena ìtàkálẹ̀ ààrùn Covid-19.
Papa-ko ofurufu naa ni won tipa lojo Aje(Monday), ti won si si pada lojo isegun(Tuesday), leyin ti won gbe ado-oloro ohun kuro nibe.
Lasiko ọdun oro ni ilu Ikorodu ti BBC Yoruba peju si, Oloye Kazeem Adeniyi Roga salaye pe, igi ìto ni yoo sọ fun awọn pe akoko ọdun oro, ti wọn n pe ni Màgbó ti to, ti igi naa yoo si wọwe.
Kano: Ìlú àwọn ‘òmùgò’ gba orúkọ tuntun lẹ́yìn àádọ́rin ọdún
Àwọn ọkunrin náà wá bi wọ́n pé, “Kí ló dé tí ẹ fi ń wá alààyè láàrin àwọn òkú?
    Lẹ́yìn èyí, mo tún yan ẹlòmíràn sí òde.
Ìgbà ti o sì jẹ́ pé àti ìyàwó mi àti àbúrò rẹ̀ ko sí ẹni ti ó dárukọ Ayédèrú-ẹ̀dá nígbà tí wọn ń sọ̀rọ̀, n kò lè sọ pàtó pé irọ́ ni ayédèrù-ẹ̀dá pa.
Ìdí nìyí tí àwọn tí ń lépa nǹkan ti ẹran-ara nìkan fi jẹ́ ọ̀tá Ọlọrun, nítorí àwọn ẹni bẹ́ẹ̀ kò lè fara wọn sábẹ́ àṣẹ Ọlọrun; wọn kò tilẹ̀ lè ṣe é rárá ni.
INEC sun ibo naa siwaju lowurọ ọjọ kẹrindinlogun si ọjọ kẹtalelogun oṣu keji
Awọn oniṣegun oyinbo ni Harare ti bẹrẹ iyanṣẹlodi lati igba ti awọn oṣiṣẹ eleto ilera nile iṣẹ aarẹ ti padanu iṣẹ wọn.
bi awon adari ile-ise eleto aabo yooku se kunna lati wa fun ipade yii.
" Ìdí nìyí tí Àwọn Yorùbá fi ma ń sọ pé ""Ẹ̀kìrì bíkan pàdímó"
 láti dunadura ẹ ̀ bẹ ̀ rẹ , À fi idajo míràn kún ìdájọ ́ rẹ ní , tí ó wà sọ ìdájọ ́ rẹ lápapò sì ọkàn dín laadota , ṣiṣe ni u ni apaniyan apania keji ti o ga julọ ni itan amẹrika ni ibamu si awọn ipaniyan timo timo .
Lori oju opo Twitter rẹ ni Fayose ti ki awọn ololufẹ rẹ ku ọdun tuntun, amọ to ni oun jẹ ẹfọri fun awọn to jẹ ọta oun.
Ileeṣẹ Apple ni anfani itakun tuntun yii niyẹn.
Ajaalẹ yii ni asiri tu pe awọn ajọmọgbe n lo lati maa ta ẹya ara eeyan, eyi ti wọn sọ ni ajaalẹ Soka.
Ifẹsẹwọnsẹ mọkandinlaadọta ni Arsenal gba lai padanu ọkankan ninu wọn.
Wo àwọn olùdíje < Padà lọ sí ọ̀dọ̀ Olùdíje Ìkádìí A gbọ pe, ọlọpaa fi panpẹ mu ọga agba ile iwe naa, Alhaji Aregbeṣọla Mufutau, olukọ to forukọ Adeleke silẹ, Ogbẹni Gbadamosi Ojo, ati olukan keji kan, Dare Olutope.
Okoroafor so pe, ko si ofin to daadobo awon onisowo atawon oludokowo oja owo takada lorile-ede Nigeria, tori naa ko si ile-ejo ti yoo dajo iru idokowo naa, biru okowo bee ba fori sanpon lojo iwaju.
Ati atunse awọn ile gbigbe ati ọọfiisi ti wọn yoo ti na: N153,693,262 ati N5,244,027,241.
Aisaya ní, àmì tí OLUWA fún Hesekaya tí yóo mú kí ó dá a lójú pé òun OLUWA yóo ṣe ohun tí òun ṣèlérí nìyí: 
Eyii to mu ko rọ ile ẹjọ naa pe ki wọn ṣe ayẹwo arun ọpọlọ fun arabinrin ọhun, gẹgẹ bo ṣe wa ninu iwe ofin ọdun 2019.
Koda, idi Erica ṣi silẹ ya-n-ya, ti ọwọ Kidd si bu idi naa so.
Àwọn akẹ́kọ̀ọ́-bìnrin Naijiria fẹyin US ati China gbolẹ nidije ìmọ ẹrọ Àbúrò fẹyin ẹgbọn balẹ nínú ìdìbò Tanka epo tó jóná gbẹ̀mí àdájọ́, ọmọkùnrin rẹ àtàwọn míì Ọlọ́pàá mẹ́rin d‘òkú lásìkò tí wọn wọ̀yá ìjà pẹ̀lú agbébọn Ilé Delesolu ti ọọni yii n gbe sẹ̀ wá lati Ijẹru de agbegbe Oje nilu Ibadan ni ipinlẹ Oyo ni guusu Naijiria.
Bitcoin: Wo àwọn nkan tí ó yẹ kí o mọ̀ nípa Bitcoin, kí o tó ó dáwọ́ le e
Oríṣun àwòrán, @DAWNCommission Bakan naa lo fi kun un pe, ijọba ipinlẹ Ọyọ yoo san owo oṣu kẹtala fun awọn oṣiṣẹ ikọ Amọtẹkun ni ipinlẹ Ọyọ.
Oríṣun àwòrán, Twitter/oluwaseunfunmi Iléeṣẹ́ Ọmọogun ní òun yóò bẹ́ ‘speaker’ lórí ìṣẹ̀lẹ̀ Lekki ṣùgbọ́n.
ENDSARS: Nítorí ìwọ́de #EndSARS, ìjọba gbé iléèwé tì pa ní Oyo, Ekiti, Ondo, Eko, Edo, Plateau àti Osun
"Mo bẹ wọn pupọ, ti mo si ni ki wọn mase jẹ ki awọn akẹkọ yi wa pẹlu wọn fun igba pipẹ, fun ẹgbẹrun ọjọ tabi ju bẹẹ lọ bii tawọn akẹẹkọ Chibok, amọ wọn ko sọ ohunkohun.
Ọmọbinrin South Africa tó ń sare ori pápá Caster Semenya ti kúna ló ẹsún to fi kan ajọ to n moju to ere ori pápá lágbàye International Association of Athletics Federation (IAAF) to sọ pe kò tọnà láti máa jẹ ki èní to ni okún jú àwọn akẹgbẹ rẹ lọ, tí wọn pè ni (testosterone) láti mú àdíku báà nítori pé ìdẹ́yẹsi ni ni.
Àkọsílẹ̀ gbogbo nǹkan yòókù tí Ahasi ṣe, láti ìbẹ̀rẹ̀ títí dé òpin, wà ninu ìwé ìtàn àwọn ọba Juda ati ti Israẹli.
Nítorí àkókò ẹ̀san ni àkókò náà, nígbà tí ohun gbogbo tí ó wà ní àkọsílẹ̀ yóo ṣẹ.
7 151 Erekusu Cayman Island 2 3.
Gomina Obaseki naa n ṣe iṣide ipolongo rẹ saaju idibo sipo gomina ni ipinlẹ Edo ti yoo waye ni Ọjọ Kọkandinlogun, Oṣu Kẹsan, ọdun 2020.
Ẹgbẹ naa ni igbesẹ yii ko ṣẹyin bi ijọba apapọ ko ṣe mu adehun ṣẹ lori awọn ohun ti wọn jọ fẹnuko le lori.
Nítorí láìsí àṣẹ rẹ̀, ta ló lè jẹun, tabi kí ó gbádùn ohunkohun.
Mo ti sa gbogbo ipa mi lati ri ọkọ mi ti wọn jigbe pada - Flora Sodje Nibayii, inu ibanujẹ ni ẹbi ati ara Paul Sodje wa lọwọlọwọ, paapaa iyawo Chris Sodje, Flora, ti ko tilẹ mọ boya ọkọ rẹ wa laye abi o ti ku.
 ní àfikún , ní àárìn àwọn aláwọ ̀ dúdú , àsìkò yìí ni dúkùú ń wáyé láti ọ ̀ dọ ̀ àwọn dúdú lórí ìlòdì sí òwò ẹrú .
O seese ki awon arinrinajo naa koju ewu tabi lilo sewon, bi won ba pada si orile-ede won, orile-ede Israel n gbero lati ko won lo si orile-ede miiran nile Africa ti ko daruko, eyi ti awon arinrinajo lona aibofin mu naa ati awon osise aseranwo so pe, o le je orile-ede Rwanda tabi Uganda ni won n ko won lo.
26 Bélú 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 3 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 5 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Ipinlẹ Eko, Aṣofin Mudashiru Obasa pe awọn ipele abadofin naa lọkọọkan
Nisinsinyii, kò sí ìdálẹ́bi kan mọ́ fún àwọn tí ó wà ní ìṣọ̀kan pẹlu Kristi Jesu.
Ṣebí Sadoku ati Abiatari, àwọn alufaa mejeeji wà níbẹ̀, gbogbo ohun tí o bá ti gbọ́ ninu ààfin ọba ni kí o máa sọ fún wọn.
Ìgbàgbọ́ wa tí ó tún hàn nínú òwe yìí ni pé irú orúkọ tí á bá fún ọmọ kó ipa pàtàkì nítorí a kì í fẹ́ ba orúkọ ara ẹni tàbí ẹbí ẹni jẹ́ àfi àwọn ènìyàn lásán ni kì í bìkítà fún orúkọ rere wọn tàbí orúkọ ẹbí wọn.
Josaya ọba fọ́ àwọn òpó òkúta túútúú, ó gé àwọn ère oriṣa Aṣera, ó sì kó egungun eniyan sí ibi tí wọ́n ti hú wọn jáde.
Jesu bá wọ inú ọ̀kan ninu àwọn ọkọ̀ náà tí ó jẹ́ ti Simoni, ó ní kí wọ́n tù ú kúrò létí òkun díẹ̀.
Ta fi n jo ọkọ akero ijaba ati ile ẹjọ to ti wa lati aye baye?
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Nigeria 2019 election: 'Torí ǹkan tí mo fẹ́ ni mo ṣe máa dìbò' Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Nigeria 2019 election: 'Torí ǹkan tí mo fẹ́ ni mo ṣe máa dìbò' 18 Èrèlè 2019 Gẹgẹ bi idibo ti aj INEC sun siwaju naa ṣe ti n sunmọ, awọn ọdọ paapaa awọn ti yoo dibo fun igba akọkọ sọ ireti latọdọ ijọba ti yoo ba wọle.
Lẹyin ọdun mejila to mọ nipa ailera rẹ yii lo sọ itan igbesi aye rẹ fun BBC.
Ni nkan bi aarin oṣu kẹta ọdun yi, awọn eeyan fi ifẹ han si igbesẹ rẹ to gbe nipa pipese owo iranwọ aadọta biliọnu dọla fawọn ipinlẹ Amẹrika lati koju ajakalẹ yi.
Ìlú àwọn Èdìdàrẹ́ ní ibì tí Òmùgọ́díméjì ti ń ṣe ọba wọn
Gbogbo àwọn eniyan sì ṣe ìlérí láti pa majẹmu náà mọ́.
Àwọn olórí alufaa ń fi ẹ̀sùn pupọ kàn án.
Oba Lamidi Olayiwola Adeyemi fikun wi pe, ki awọn lọbalọba ri wi pe alaafia jọba ni agbegbe wọn nitori ipa ti oun ko lasiko ifẹhọnuhan naa ni ko jẹ ki o jasi rogbodiyan ni agbegbe oun.
“ ‘Ya ọjọ́ ìsinmi sọ́tọ̀, kí o sì ṣe é ní ọjọ́ mímọ́, gẹ́gẹ́ bí OLUWA Ọlọrun rẹ ti pàṣẹ fún ọ.
Adajọ fẹyinti Oloyede sọ pe, o ṣe ni laanu pe ajọ CCB ti mọ nipa ẹsun yii lati ọdun 2016, o si kọ lati fẹsun kan adajọ agba Onnoghen to fi di asiko yii.
Bí àwọn tí ogun Babiloni pa ní àwọn orílẹ̀-èdè ayé,ti ṣubú níwájú rẹ̀.
iṣẹ naa koju osunwọn Nigba ti o
Abramu ní dúkìá pupọ ní àkókò yìí, ó ní ẹran ọ̀sìn, fadaka ati wúrà lọpọlọpọ.
Odò Ado Awaye ni adágún odó ti iwadii fihan pé kò kún rí ní kò sí bi òjò ṣe rọ̀ tó; bẹẹ kò lọlẹ sii ri bó ti wu ki ọ̀gbẹlẹ̀ mu tó lasiko ẹ̀rùn.
Bí mo bá ṣẹ̀, kí ni ẹ̀ṣẹ̀ tí mo ṣẹ̀ yín,ẹ̀yin tí ẹ̀ ń ṣọ́ mi?
Wọn tilẹ jẹ ko di mimọ fun mi nipa awọn nnkan to ṣẹlẹ si awọn aarẹ Ọna Kakanfo ti ko yan igbimọ oloye wọn ‘Yorùbá, ẹ dìbò fún Buhari láti bu ọlá fún M."
Oríṣun àwòrán, Reuters O si ti han gbangba bayii pe ọwọ araalu ni agbara wa.
OLUWA Ọlọrun ní, “Bí ọba bá fún ọ̀kankan ninu àwọn ọmọ rẹ̀ ní ẹ̀bùn lára ilẹ̀ rẹ̀, ilẹ̀ náà di ti àwọn ọmọ rẹ̀, ó di ohun ìní wọn tí wọ́n jogún.
Ipò ètò ààbò ń já àwa gómìnà láyà, ó ń kọ wá lóminú - Àwọn gómìnà Ọmọọ̀dọ̀ tó pa Ope Bademosi ti rí ẹ̀wọ̀n gbére he!
Crystal Palace lo kọkọ gba bọọlu sawọn ṣugbọn Manchester United dayo naa pada.
Bí wọn bá ń fi yín ṣe yẹ̀yẹ́ nítorí orúkọ Kristi, ẹ ṣe oríire, nítorí Ẹ̀mí tí ó lógo nnì, Ẹ̀mí Ọlọrun, ti bà lé yín lórí.
Bí idà tilẹ̀ bá a, kò ràn án,bẹ́ẹ̀ náà ni ọ̀kọ̀, ati ọfà, ati ẹ̀sín.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Walter Onnoghen: UNO bẹnu àtẹ́ lu ìdàdúró adájọ́ àgbà 11 Èrèlè 2019 Oríṣun àwòrán, NJC Àkọlé àwòrán, Ọrọ lori idaduro Onnoghen Ajọ iṣokan agbaye iyẹn UNO ti bu ẹnu atẹ lu bi wọn ṣe ni ki adajọ agba lorilẹede Naijiria Wallter Onnoghen lọ rọkun nle.
“Bí ẹnìkan bá lu ẹrukunrin tabi ẹrubinrin rẹ̀ ní kùmọ̀, tí ẹrú náà bá kú mọ́ ọn lọ́wọ́, olúwarẹ̀ yóo jìyà.
Ẹgbẹ oselu PDP to jẹ alatako APC ko tile jẹ ki ọrọ naa pẹ nilẹ ki wọn to gbe aworan kan ti o ruju sita.
Ẹ wo àbájáde ìwádìí wa Bàbá mi Aláàfin, ẹ ṣeun ẹ̀bùn owó tí ẹ fún èmí àti ọkọ mi- Lizzy Anjọrin Pásítọ̀ ìjọ Sotitobire padà yọjú sílé ẹjọ́ lónìí, àbọ̀o rèé.
Nígbà tí wọ́n gbọ́, inú bí wọn pupọ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Tanko Muhammad: Ààrẹ Buhari fikún sàá Muhammad Tanko nípò adelé adájọ́ àgbà 20 Ìgbé 2019 Oríṣun àwòrán, AsoRockVilla Àkọlé àwòrán, Aa Buhari yan Tanko Ibrahim lati dele de adajọ Onnoghen Iroyin kan ti a ko ti i fi bẹẹ fi mulẹ sọ pe Aarẹ Muhammadu Buhari ti fi oṣu mẹta kun ọjọ to yẹ ki adele Adajọ Agba Naijiria, Tanko Muhammad lọ n'ipo.
Pilatu bá pe àwọn olórí alufaa, ati àwọn ìjòyè, ati àwọn eniyan jọ, 
ede wolof jẹ èdè tí à ń sọ ni atí bèbè senegal mílíọ ̀ nù méjì-àbọ ̀ niye àwọn tó ń sọ .
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, NLC: Àwọn olósèlú ń la títì láì sanwó osù torí owó tí wọn yóò rí lórí àkànse isẹ́ APC gbe orukọ awọn oludije gomina jade Igbimọ amusẹya fẹgbẹ oselu APC jake-jado Naijiria, ti gbe orukọ awọn oludije fun ipo gomina, ti wọn ti wẹ yan kain-kain lẹyin ayẹwo kinni-kinni labẹ ẹgbẹ oselu naa jade.
"Wo àwọn ojúṣe àti èèwọ̀ fún ikọ̀ ọlọ́pàá SWAT tó gba iṣẹ́ lọ́wọ́ SARS Ọlọ́pàá mú afurasí 31 tó ń dúnkokò máwọn ọmọdé lórí ayélujára Pásítọ̀ Enoch Adeboye darapọ̀ mọ̀ #ENDSARS, ó fún ìjọba Nàìjíríà ní ìmọ̀ràn ọ̀nà àbáyọ Mọ̀ nípa iPhone 12, fóònù ológo 5G tí kìí lo ""Charger” tó ṣẹ̀ṣẹ̀ jáde Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Eegunjobi Omotanbaje Ajobiewe- Èébú ní wọ́n kọ́kọ́ ń bù mí nígbà tí mo bẹ̀rẹ̀ ẹ̀ṣà pípé ní Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Lamidi Adeyẹmi, Anthony Joshua: Ọmọọba mẹ́wàá ló du òyè pẹ̀lú Adeyẹmi, tó sì já mọ́ ọ lọ́wọ́15 Ọ̀wàrà 2020 EndSARS Protest: Àwọn olùwọ́de ní ''májèlè ni oúnjẹ tí MC Oluomo gbé wá fún wa, a ò jẹ''17 Ọ̀wàrà 2020 Fídíò, Soyinka Cancer: Àṣe ara mi ni iso ti n run gbogbo bí mo ṣe n ṣèrànwọ́ lórí jẹjẹrẹ27 Bélú 2019 End SARS, End SWAT: MC Oluomo ní òun kọ́ ló rán àwọn jàǹdùkú sáwọn olùwọ́de l'Eko15 Ọ̀wàrà 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!"
Àwọn ìmàdò inú ìgbẹ́ ń jẹ ẹ́ ní àjẹrun,gbogbo àwọn nǹkan tí ń káàkiri ninu oko sì ń jẹ ẹ́.
98 to din diẹ ni ilaji awọn to ṣee) si pegede ninu idanwo Ẹkọ Isiro (Mathematics ) ati Ẹkọ Ede Gẹẹsi(English Language).
Nítorí Ibú Ìbànújẹ́ ni wọ́n ti ṣe ìgbéyàwό, Ọ̀run Àpáàdì sì ni ìwé ẹ̀rì-i wọn-ọ́n ti jáde.
Ninu fọran fidio kan ti wọn ṣe ranṣẹ si ileeṣẹ BBC News Yoruba lati fi kan si ijọba ni wọn ti pe fun iranwọ naa.
Ahabu ọba bá lọ sójú ogun, ó kó ọpọlọpọ ẹṣin ati kẹ̀kẹ́ ogun; ó ṣẹgun àwọn ọmọ ogun Siria, ó sì pa ọpọlọpọ ninu wọn.
Awa Bike: Kẹ̀kẹ́ tiwa wà fún eré ìdárayá àti díndín èéfín agbègbè kù
Aare soro yii lasiko ipade to waye ni Paris , aare ni orile ede Naijria ti satunse si awon ofin ati ilana re lati gbogun ti iwa ibajẹ ati lati gba awon owo ti awon oniwa ibajẹ kan ko salo si orile ede miiran, ki won si tun fi imu awon obayeje naa jofin.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ọjọgbọn 'Bisoye Ẹlẹsin ni o yẹ ka kọ ọmọ l'ede Yoruba Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Ọjọgbọn 'Bisoye Ẹlẹsin ni o yẹ ka kọ ọmọ l'ede Yoruba 21 Èrèlè 2018 Ọjọgbọn 'Bisoye Ẹlẹsin ti parọwa fun awọn ọmọ kaarọ oojire lati maa kọ awọn ọmọde ni ede Yoruba.
Iya a mi tẹle mi lọ si ileewosan, nkan ti dokita si sọ fun ba a l'ẹru.
Yàtọ sí bí ǹkan ṣe rí ní àwọn ìpínlẹ̀ míràn tí ọmọ obìrin lè wọlé tàbí jáde ní àṣìkò tó bá wù wọn, ní ti ìpínlẹ̀ Kano, ọ̀tọ̀ lọmọ́ sorí o.
Oríṣun àwòrán, Facebook/Benjamin Uwajumogu Saa meji ni Sẹnẹtọ Uwajumogu lo nile aṣofin agba niluu Abuja.
Orí mi ìbá jẹ́ kìkì omi,kí ojú mi sì jẹ́ orísun omijé;tọ̀sán-tòru ni ǹ bá fi máa sọkún,nítorí àwọn eniyan mi tí ogun ti pa.
  Àwọn igi kọ̀ọ̀kan wà tí àwọn ẹnìkan ya àworan sí lára.
Ilu Ikoyi-Ile jẹ ilu iṣẹmbaye kan ni ijọba ibilẹ Orire ni ipinlẹ Oyo eyi ti ilu to fẹẹ to ẹẹdẹgbẹrin yii ka bii ilu Olode-Elelu, Animashaun, Obamo, Igboayin, Laomi.
70, eyi to pajude si N571.
Fuel Price Hike: Onímọ̀ ní oṣooṣù ni owó lítà epò kan yóò máa yàtọ̀, ó le léwó tàbí dínwó
Revolution protest: Àjọ DSS ṣàlàyé ìdí tí wọ́n fi gbé Sowore
Ninu ọrọ to ba awọn oniroyin sọ, afurasi naa sọ pe ni agọ ọlọpaa to n bẹ ni agbegbe Mọkọla ni oun ti salọ nigba ti wọn ṣi oun ati awọn ọdaran mii ti wọn jọ wa ni atimọle silẹ lati lọ wẹ.
Obedi Edomu ni gègé mú fún ẹnu ọ̀nà ti ìhà gúsù; àwọn ọmọ rẹ̀ ni a sì yàn láti máa ṣọ́ ilé ìṣúra.
Iroyin yii jẹ ọkan lara awọn ofege ti BBC n la awọn eeyan lọyẹ lori rẹ- iṣoro lagbaye ti o doju kọ bi a ti n pin iroyin, ti a ṣe n gbọ layika wa.
Lọrọ oselu ati ẹsin ,o ko ipa manigbagbe.
Taló pa olórí àwọn ''One Million Boys'' Ebila n'Ibadan?
OLUWA kórìíra ẹni tí ń parọ́,ṣugbọn inú rẹ̀ dùn sí olóòótọ́.
“Nítorí kò sí ohun kan tí ó pamọ́ tí kò ní fara hàn, kò sì sí nǹkan bòńkẹ́lẹ́ kan tí eniyan kò ní mọ̀.
Wọ́n fi aṣọ bò ó lójú, wọ́n wá ń sọ ọ́ ní ẹ̀ṣẹ́.
Ohun tí ọlọ́pàá ń ṣe rèé láti sàwárí àwọn ‘mùjẹ̀-mùjẹ̀’ ní Akinyele Àjọ ọlọ́pàá, Ìjọba ìpínlẹ̀ Ọyọ jẹ́jẹ̀ẹ́ láti ṣàwárí òòsà tó ń mu ẹ̀jẹ̀ nílùú Ìbàdàn Mo dúpẹ́ pé Ọlọ́run dá mi láre lórí ikú Sugar, tí adájọ́ sì tú mi silẹ̀ - Akinmoyede Oko Oloyun: Ta ló pa Àlhájì Fataì Yusuf?
Bí ẹsẹ̀ arọ, tí kò wúlò,ni òwe rí lẹ́nu òmùgọ̀.
Jesu dá wọn lóhùn pé, “Ẹ ṣìnà, nítorí pé ẹ kò mọ Ìwé Mímọ́ ati agbára Ọlọrun.
Ẹ dúpẹ́ lọ́wọ́ OLUWA tí ó ju gbogbo àwọn oluwa lọ,nítorí pé ìfẹ́ rẹ̀ tí kì í yẹ̀ wà títí lae.
Ikede ewu yii yoo je kijoba ri owo na bi o ti ye si ipese awon ohun amayederun bakan naa ni yoo tun je kijoba mojuto igbese ipese omi sii.
Ibi ori da ni si laa gbe ni igbagbọ iran Yoruba.
Gẹgẹ bi àtẹ to wa l'oke ṣe fihan, ẹnikan n mu ju lita ẹlẹrindodo kan lọ l'ojumọ ni orilẹede China.
Oríṣun àwòrán, AFP SERAP ni, ọpọ ọmọde lo ti ku iku aitọjọ, ti ọpọ si wa ninu ewu nla nitori aisi nile iwe, eyi to jẹ ikuna ijọba ni Naijiria.
Awọn oṣiṣẹ ajọ ẹṣọ oju popo to wa nibi iṣẹlẹ naa ni eeyan meji lo ku ninu iṣẹlẹ naa ṣugbọn awọn miran fi ara pa.
O ni oun ko ni ikunsinu kankan si gomina Makinde lori bi o ṣe ni ki ọga ọlọpaa lorilẹede Naijiria o gbe ọwọ naa lọ si Agọ arẹ dipo ilu Ọyọ ti alaafin n ja fun.
Kí a ma sa fà á gùn lọ títí, ó bèèrè ibi tí mo dé sí, mo sọ fún un, o sì sọ ibi ti òun náà ń gbé fún mi, ó wi fún mi pé òun n bọ̀ wá bẹ̀ mi wò ní ọjọ́ kejì.
Arsenal àti Manchester United kọ́wọ̀ọ́ rìn lọ Europa Beckham, àgbábọ́ọ́lù tẹ́lẹ̀ rèé tó ń sọ èdè Yorùbá Ayé le, ìbòsí ò!
Wọn óo sì kó gbogbo àwọn ará yín bọ̀ láti orílẹ̀-èdè gbogbo, wọn óo kó wọn wá gẹ́gẹ́ bí ọrẹ fún OLUWA.
Adajọ Inyang Ekwo lofi idájọ náà jànlẹ pe ki wọ́n dááduro titi ti igbẹ́jọ́ tí ajọ ọlọpàá pe.
Bí ẹnìkan bá bí ọgọrun-un ọmọ, tí ó sì gbé ọpọlọpọ ọdún láyé, ṣugbọn tí kò gbádùn àwọn ohun tí ó dára láyé, tí wọn kò sì sin òkú rẹ̀, ọmọ tí a bí lókùú sàn jù ú lọ.
Ó sọ ibẹ̀ ní Bẹtẹli, ṣugbọn Lusi ni orúkọ ìlú náà tẹ́lẹ̀ rí.
Lara awọn agbegbe naa la ti ri ijọba ibile bii Akoko South-West, Akure South, Idanre, Owo, Akoko South-East ati Ese-Odo.
“Àwọn eniyan wọnyi ń kó nǹkan tí wọ́n fi ipá ati ìdigunjalè gbà sí ibi ààbò wọn, wọn kò mọ̀ bí à á tíí ṣe rere.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù NCAA: A fún àwọn adarí ní ọ̀sẹ̀ méjì si láti dá wọn lóhùn 2 Sẹ́rẹ́ 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Murtala Muhammed international Airport 2 Àpapọ̀ àwọn òṣìṣẹ́ ẹka irina ofurufu iyẹn NUATE ati ATSSSAN ti fagile iyansẹlodi ti wọn sọ wi pe awọn yoo gunle ni Ọjọ Keji, Osu Kini, ọdun 2019.
Wo àwọn orílẹ̀-èdè márùn ún tó fún àwọn obìnrin làńfàní tuntun sí ẹ̀tọ́ wọn Àwọn alálẹ̀ kò ní forí jìn mí tí ń kò bá ṣe ọdún Ṣàngó - Alaafin 'Ekute jẹ ogun oloro lagọ ọlọpa' ‘Lootọ ni nkan pa emi ati Baba Suwe pọ’ iṣe kafinta ni baba rẹ n ṣe nibi to ti maa n wo baba rẹ.
O sọ irinajo ọkọ rẹ ni ọgba DSS ati ohun ti oju wọn ri to fun BBC Yoruba.
Ìpínlẹ̀ to kù ni Pleatue àti Bayelsa pẹ̀lú ènìyàn mẹ́rin Kastina mẹ́ta, Ekiti àti Imo ni ènìyàn meji.
Ọlọ́run yóò ṣe é mọ bẹ́ẹ̀.
•Kurani •Sunna (ìyẹn ojúlówó hadiit) •Qiyas (Èrò pípé àwọn onímọ) •Ijma ( eyi ni ìfẹnukò èròngbà àwọn onímọ òfin ) •Àwọn ilé ẹkọ́ ìmọ̀ òfin bi Hanafi, Mailki, Shafi'i Hanbali àti Jafari, àwọn yìí ni wọ́n ń ṣètò bi wọ́n ṣe mú àwọn ìlàna tí wọ́n fi n lo òfin Sharia jade nínú Kùránì •Mu amalat ( ìbásepọ àwujọ •ibadat (etutu) Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, jkkkkk Báwo ni òfin Sharia ṣe n ṣiṣẹ́ ni Naijiria?
O ni igba ti oun wo lẹta naa o jẹ lẹta ikosilẹ lati kootu Ninu ọrọ rẹ iyawo oludasile ile ijọ ti igbeyawo naa ti waye Ebube Evans salaye pe oun ti mo Gloria ati Osadebe ti pẹ nigba ti wọn wa si ile ijọsin ni nkan bi ọdun meji sẹyin.
Èèyàn 16 kú lẹ́yìn tí bàálù Air India já lulẹ̀ , tó sì kán sí méjì ní Kerala Ilé ẹjọ́ ti dájọ́ Naira Marley, wọ́n ní kó san owó ìtànràn, kó tún tọrọ àforíjì Kọ́ńdọ̀mù tó bẹ́ gbé iléèṣẹ́ ìjọba àti aládáni kan dé ilé ẹjọ́ Wo ohun tí Adájọ́ ṣe sí àṣùwọ̀n ìfowópamọ́sí Wòlíì Sotitobire O ṣalaye siwaju si pe iwa Baṣọrun Gaa ni gomina ọhun wu ati pe o ti ja ireti awọn eeyan to n ṣejọba le lori kulẹ.
Ikede yi ti ọpọ ileeṣẹ iroyin ni Naijiria ti gbe lọjọru jẹ eyi ti BBC ko ti ribi fidi rẹ mulẹ.
Nigeria kidnap: Àwọn jàndùkú jí agbábọ́ọ̀lù Nàìjíríà méjì gbé lópòpónà Owo sí Benin
6bn ohun ìní Nàìjíríà Laipẹ́, ọmọ tí kò bá pé ọdún méjìdínlógún kò ní leè jáde girama l’Ọṣun Dino Melaye tó ń díje dupò gómínà Kogi ni irọ́ ni pé òun ti ju awà sílẹ̀ Babatunde Akinbiyi to jẹ́ agbenusọ ilé iṣẹ́ náà sàlàyé pé nítori àtunṣe to n ṣẹlẹ̀ ní ìhà Berger -Ogun River kí awọn awakọ rin òpópónà Ìyànà ìpájà/ Ota/Abeokuta/Sagamu-Benin Ore.
Nígbà tí iranṣẹ náà ti ṣe bẹ́ẹ̀ tán, ó ní, ‘Alàgbà, a ti ṣe bí o ti pàṣẹ, sibẹ àyè tún kù.
Fídíò òògùn ikọ́ Codeine: Àpọ̀jù rẹ̀ ń ya ọ̀dọ́ ní wèrè
imo ero igbalode yoo tun waye lati ibi ipade yii.
Ikọ Agbabọọlu yii ko kopa ri ninu idije ifẹ ẹyẹ agbaye.
 Dokita Ryan ni oun ko gbagbọ pe ẹnikẹni le e sọ asọtẹlẹ nipa akoko ti arun yii yoo poora.
ṣe srs mi ń ye ẹ?
Ajọ to ti baba dibajẹ, to fi mọ didi agbo ọdaran lo ti wa pada bọ sipo si ohun to yẹ ko jẹ iyẹn ajọ to n mu agbega ba bọọlu alafẹsẹgba o si ti wa di eyi to ni ọwọ mimọ ati ootọ inu.
Sotitobire: Ẹlẹ́rìí mẹ́rìn ló tẹ̀lé Alfa Babatunde wá síwájú ilé ẹjọ́ lonìí Ọlọ́pàá tún dé o!
O niiku to ṣe gbogbo ẹbi ni kayefi ni iku Oriṣabunmi.
Loju opo ajọ to n mojuto ajakalẹ aarun ni Naijiria (NCDC) niṣe ni wọn kede pe eeyan ẹgbẹrun kan ati marundinlaadọjọ,1,145 tuntun miran ti lugbadi arun naa lọjọbọ.
Ẹlẹsẹ ayo Rashford tun fakọyọ kete ti wọn bẹrẹ ipele keji ifẹsẹwọnsẹ naa lẹyin to gba pẹnariti wọle Tottenham eleyi to mu ki Man U pada maa siwaju.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ààrẹ George Weah padà sórí pápá 'EFCC gbẹ́sẹ̀ lé owó Davido, Adeleke' Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Láti ọmọ̀ oṣù mẹ́ta ló ti gbọ́ ìlù' Henrikh Mkhitaryan lo rọpo Aubameyang ni iṣẹju mọkandinlaadọrin ninu ifẹsẹwọnsẹ ọhun to waye ni papa iṣere St.
ifesewonse kinni ti o waye lojo abameta ohun, iko agbábọ́ọ̀lù Arsenal fagbahan Burnley
Won tun se ikolu oju ofurufu kan tako awon ibi ile-iso agbara awon  alakata-kiti elesin Islam Sirte ni odun 2016, bi awon omo-ogun ijoba se n gbiyanju ati le awon alakata-kiti naa kuro nilu naa.
Mo tún pinnu láti kẹ́kọ̀ọ́, láti ṣe ìwádìí, ati láti wá ọgbọ́n, kí n mọ gbogbo nǹkan, ati ibi tí ń bẹ ninu ìwà òmùgọ̀, ati àìlóye tí ó wà ninu ìwà wèrè.
Abiola Ajimobi: Makinde fẹ́ fọwọ́ rọ́ àṣeyọrí ọlọ́dún mẹ́jọ mi sẹ́yìn
Wọn ni ẹgbẹ oṣelu awọn lo gbe 'gba oroke, ko si ootọ ninu iye ibo ti wọn kede.
Kenasi bí ọmọ meji: Otinieli ati Seraaya.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù State Police: Buhari pariwo síta, ó ní èmi kò buwọ́lu ètò ọlọ́pàá agbègbè o!
Ipinlẹ Kogi jẹ eyi ti wọn n pe ni Confluence state nitori pe olu ilu rẹ, Lokoja ni odo Benue ati Niger wa papọ.
O gboye imọ ijinlẹ gẹgẹ bi olukọ ni nileewe giga Teachers Training College to wa ni Zaria, nipinlẹ Kaduna.
Ìwọ náà mọ ohun tí ó yẹ kí o ṣe gẹ́gẹ́ bí ọlọ́gbọ́n ọmọ, o kò gbọdọ̀ jẹ́ kí ó fi ọwọ́ rọrí kú.
Àjọ NCC fí gbèdéke ọ̀sẹ̀ méjì sílẹ̀, ìyẹn ọgbọ̀njọ́, oṣù kejìlá pá kí gbogbo àwọ́n ilé iṣẹ̀ tó mójútó ọ̀rọ̀ síìmù tí síìmù ẹni ti kò bá ní NIN pa.
Atẹjade naa, wa n kesi gomina ipinlẹ Ondo pe ko tete wa wọrọkọ fi se ada lori didaabo bo awọn osisẹ eleto ilera nipinlẹ naa, ti ina arun Coronavirus ti bọ si ọpọ wọn labẹ asọ.
Ní ọjọ́ náà gan-an tí wọ́n pa àwọn ọmọ wọn, tí wọ́n fi wọ́n rúbọ sí oriṣa wọn, ni wọ́n tún wá sí ilé ìsìn mi, tí wọ́n sọ ọ́ di eléèérí.
’Òun náà sì tún dáhùn ó ni, ‘Ó ta mi ní ìpá díẹ̀, ṣùgbọ́n ẹsẹ̀ rẹ̀ kò bá mi ni ibi burúku.
Òní yìí ni ẹnìkan tó tọ́ka ilé rẹ hàn mí tí mo fi wá ṣe báyìí rí ọ.
Oríṣun àwòrán, @YIAGA Àkọlé àwòrán, Sadede ni Saraki fi ayẹyẹ wa kéde èro rẹ láti dije ipò Ààrẹ Nàìjíríà.
Ilééṣẹ́ Facebook leè mọ ìgbà tí àwọn tó wà lójú òpó wọn ń ní ìbálòpọ̀ Ìpínlẹ̀ Ogun fẹ́ fi òfin wọ́gilé ìsìnkú ọba lọ́nà ìṣẹ̀mbáyé Awakọ̀-èrò, ọlọ́kadà farakásá àṣẹ ìjọba Ekiti láti dẹ́kun Coronavirus Ẹ wo ǹkan to sẹlẹ̀ sí ọmọ àti ìyàwó ọmọ Atikú tó lùgbàdì ààrun Coronavirus Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Awọn obinrin miiran ko tilẹ mọ pe wọn ta awọn lori ayelujara Ẹnikan to n lo ẹrọ naa ta ọmọ fun miliọnu kan ati ẹgbẹrun un lọna ọdunrun un naira, $3,800 Coronavirus ti di ara wa, kò le è kúrò mọ láéláé - WHO Wo orílẹ́èdè tí wọ́n tí ń dáwó ìsìnkú ara wọn pámọ́ Ìdí rèé tí ilẹ̀ Afirika fi gbọdọ̀ kópa nínú dídán abẹ́rẹ́ coronavirus wò Àwọn ọkùnrin tó wà nínú ayé wa gbúdọ̀ bọ̀wọ̀ fún wa - Olùdásílẹ̀ FIN Obìnrin kan pa ara rẹ̀ látàri pé ọ̀kọ̀ rẹ ń dẹ́yẹ síi pé o dúdú jù Ati wi pe awọn ọlọpaa n ran wa lọwọ lati ru ofin.
Ó dára kí eniyan dúró jẹ́ẹ́, de ìgbàlà OLUWA.
Nnkan ti mo n sọ ni pe ọrọ ìṣẹ́ ati oṣi la n ba a finra lọwọlọwọ.
Nígbà náà ni Amasaya, alufaa Bẹtẹli, ranṣẹ sí Jeroboamu, ọba Israẹli pé: “Amosi ń dìtẹ̀ mọ́ ọ láàrin àwọn ọmọ Israẹli, ọ̀rọ̀ rẹ̀ yóo sì ba gbogbo ilẹ̀ yìí jẹ́.
Kíni ẹ mọ̀ nípa Ọmọ́táyọ̀ Olútóyè, Ọ̀jọ̀gbọ́n obìnrin àkọ́kọ́ nínú ẹkọ́ èdè Yorùbá lágbàyé UK fẹ́ so ìjókòó ilé rọ̀, kíni èyí túmọ̀ sí?
Iyawo rẹ̀ ni Mehetabeli, ọmọ Matiredi, ìyá rẹ̀ àgbà ni Mesahabu.
Oríṣun àwòrán, @NGRPresident Àkọlé àwòrán, Sẹnatọ Bukọla Saraki ni abajade iwadi igbimọ ile naa ti fihan wipe orilẹede Naijiria ko se aseyọri kankan ninu igbesẹ gbigbogun ti iwa ibajẹ Ti a ba ri ileeṣẹ ijọba mẹtadinlaadọta pere to n tẹle ofin ninu mẹtadin lẹẹdẹgbẹta, mo ro wi pe iṣoro n la gba leyii.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Zainab Aliyu: Mo sọkún títí, ojé tán lójú mi ní àhámọ Saudi Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Zainab Aliyu: Mo sọkún títí, ojé tán lójú mi ní àhámọ Saudi 15 Èbibi 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 16 Èbibi 2019 Oṣu mẹ́rin ni Zainab Aliyu lo ni ahamọ ni orilẹede Saudi Arabia to n reti iku lẹyin ti wọn fẹsun kan pe o gbe oogun oloro wọ orilẹede naa.
Coronavirus: Ṣẹ́ lóòtọ́ ní ginger àti garlic lè pa àrun Coronavirus?
o tẹramọsẹ, kìí si se ọ̀lẹ̀.
Kí n má fa ọ̀reọ̀ mi gùn lọ, baálé mi, mo ní nǹkan pàtàkì láti tọrọ lọ́wọ́ yín.
adéolókun fakọyọ fún ikọ ̀ rẹ ̀ ( connacht ) ní ọjọ ́ kẹfà oṣù kẹ ́ sàạn ọdún 2014 , nígbà tí wọ ́ n gbá pẹ ̀ lú ikọ ̀ newport gwent dragons nị ́ bi ìfẹsẹ ̀ -wọnsẹ ̀ ìṣíde òpin ọ ̀ sè ní 2014-15 pro12 , níbi tí ó tí ṣe ìrànwọ ́ fún akẹgbẹ ́ rẹ ̀ eoin mckeon .
” Lẹ́sẹ̀ kan náà, iná wá láti ọ̀run, ó sì jó ọ̀gágun náà ati gbogbo àwọn ọmọ ogun rẹ̀.
Kí Oluwa fi agbára fun yín, kí ọkàn yín lè wà ní ipò mímọ́, láìní àléébù, níwájú Ọlọrun Baba wa nígbà tí Oluwa wa Jesu bá farahàn pẹlu gbogbo àwọn ẹni mímọ́ rẹ̀.
O wa gboriyin fun ijoba latari bi o se n se amulo awon ohun alumoni ipinle naa.
Oríṣun àwòrán, @bankyw Àkọlé àwòrán, Mo ti ṣetan láti ṣoju àwọn eniyan Eti ọsa lAbuja O sọrọ nipa àwọn nkan bii ọgbọn inú ati ootọ inu ti oun fẹ lo fi dupo aṣojuṣofin fun àwọn eniyan Eti Ọsa nilu Abuja to jẹ olu ilu Naijiria.
Ninu iwadii ti ajọ naa ṣe, wọn fi han wipe orilẹede Naijiria ni ikẹrin ni agbaye ti atẹgun buburu ti n pa awọn eniyan ju.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Omolola Arohunmolase Welder: Mo ti fí iṣẹ́ 'Welder' gbayì láwùjọ, tó mo fi tọ́ ọmọ yanjú Arun foniku-fọlande: Dokita Musa ni arun kan to wọ pọ ninu awọn arun ti igbeyawo laarin ẹbi maa n fa, ni arun foniku-fọlande, taa mọ si sickle cell.
Idi ree tawọn miran ko fi ti i mu ọmọ wọn lọ si ile iwe.
Orí ló mọ iṣẹ́ àṣelà 'Iṣẹ́ aṣẹ́wó ni iṣẹ́ tó ni mi lára jùlọ láti ṣe nínú tíátà' Orin mi ń gbé àṣà Áfíríkà ga lókè òkun - Kakaki 1 Ogbẹni Yesufa Olawale ṣalaye fun BBC Yoruba bi oju rẹ ṣe deede ṣalai riran mọ laisko to wa lẹnu iṣẹ ni Oregun ni Ikeja ni ipinlẹ Eko.
O kesi awọn ọmọ Naijiria lati gbe ni alaafia pẹlu ara wọn,paapaa lasiko arun Coronavirus yii ti gbogbo eniyan ni agbaye n la kọja.
Awọn afurasi wọn yii ti ọlọpaa ṣafihan wọn wa lara awọn ọdaran marundinlogoji, ti ileeṣẹ ọlọpaa ṣafihan wọn fun orisirisi iwa ọdaran.
 Òun ni ó kọ ́ kọ ́ lọ ṣe ambassador ilẹ ̀ oní-republic tuntun yìí ní ilẹ ̀ gẹ ̀ ẹ ́ sì .
Lẹ́yìn èyí, àwọn ará Moabu, ati àwọn ará Amoni, ati díẹ̀ ninu àwọn ará Meuni kó ara wọn jọ láti bá Jehoṣafati jagun.
 orílẹ ̀ èdè nàìjíríà ni àṣà dídábẹ ́ fún ọmọbìnrin tí wọ ́ pọ ̀ jù ní gbogbo àgbáyé .
" Gẹgẹ bi ohun ti Joseph sọ, ọkan lara awọn mẹta ti wọn ji gbe jẹ olukọ ni ileewe gbogbonise Rufus Giwa to wa ni ilu Ọwọ nipinlẹ Ondo.
Alhaja maa n bo ori ni, kii si oju silẹ kí asiri rẹ ma ba a tete tu pe abara meji ni, ko si si ẹni to maa n ri oju rẹ rara.
Àwọn tó kù ni Awodeyi Akinsehinwa Akinola Colinus, Olubukola Adetula, Dr.
Jakọbu bá bi wọ́n léèrè pé, “Ẹ̀yin arakunrin mi, níbo ni ẹ ti wá?
“Ní ìwọ̀ oòrùn, Òkun Ńlá ni yóo jẹ́ ààlà ilẹ̀ yín, yóo lọ títí dé òdìkejì ẹnu ọ̀nà Hamati.
Láé láé, ìjọba Buhari kò tẹ ojú ẹ̀tọ́ ará ìlú mọ́lẹ̀ - Lai Mohammed Ìdí tí Ààrẹ Trump fi dínà mọ́ Nàìjíríà àtí orílẹ̀èdè márùn ún míì láti má wọ Amẹ́ríkà Ní ìgbẹ̀yìngbẹ́yín, orílẹ̀èdè UK fi àjọ EU sílẹ̀ 'Orin tàkasúfèé ló wù mí kí n máa kọ ṣùgbọ́n Hijab kò jẹ́' Bimbo Akinsanya Oríṣun àwòrán, Bimbo Akinsanya/Facebook Molumọọka oṣerebinrin Bimbo Akinsanya ni tirẹ ni lati lee doola ẹmi ara oun loun ṣe fi igbeyawo oun silẹ.
Bí mo ti dúró tí mo ń wò wọ́n ni mo déédéé rí i tí gbogbo wọ́n bẹ̀rẹ̀ sí kọrin lẹ́ẹ̀kan ṣoṣo, wọ́n ń yin Ọlọ́run lógo.
Afurasi tó fa ìpayà nílé ìwé Port Harcourt ti wọ gàù Àwọn bàbá ìsàlẹ̀ òṣèlú tó bá ìtìjú bọ̀ nínú ìbò Gómìnà rèé Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Àsìkò Amojúẹ̀rọ Seyi ni ló fi wọlé l'Oyo, kìí ṣe àsìkò èmi Omobolanle' Kareem Waris (NAIJIRIA) Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Waris Kareem: Emmanuel Macron kan sáárá lórí àwòrán tó yà Gbájúgbaja ayàwòrán yìí di ìlúmọ̀ọ́ká nígbà ti ààrẹ orílẹ̀èdè Faranse, Emmanuel Macron ti gbé oríyìn fún un.
Ẹ fi owó tí ẹ fi ń san owó-orí hàn mí.
Agbenuso ile-igbimo asofin orile-ede Libya so pe, awon asofin yoo se agbekale ilana ofin tuntun kan, leyin ti won ba ti gba ofin naa woleAwon orile-ede Lagbaye ti n so fun awon oloselu ti won pin yele-yele lorile-ede naa lati sise papo fun eto idibo ti yoo waye ninu odun ti a wa yii.
Àwọn abiyamọ figbe ta lórí ọmọ ọdún kan ti wọn wá nílé ìjọsìn l'Akure Mo kàn fẹ́ fi ọmọ tó sọnù gba owó lọ́wọ́ Sọtitobire ni - Afurasí Ẹ má gbàbọ̀de kankan láti tú Wolii ìjọ Sotitobire sílẹ̀ o!
 ise agbe ati ise apeja ni won se ju nibe .
Gege bi aare Buhari,‘‘Idagbasoke pupo ti  ba eto oro aje orile-ede Naijiria ju bo se wa tele lo.
Lọja agbaye, Huawei yoo ṣi ma jẹ aayo ọpọ nitori iye ti o n ta ọja tirẹ.
Wọ́n jagun gba Beti Ṣemeṣi, Aijaloni, ati Gederotu, wọ́n sì gba Soko, Timna, ati Gimso pẹlu àwọn ìletò ìgbèríko wọn, wọ́n bá ń gbé ibẹ̀.
Ni ipari, lasiko aare npinle Borno, igbakeji aare, ojogbon Yemi Osinbajo yoo dari ipade ijoba ti o maa n waye losoose loni.
Ọlọ́pàá dènà ìwọ́de fún àtìlẹyìn ikọ̀ Amotekun ní Eko Digbí ni mo wà lẹ́yìn Amotekun, máà ṣèrànwọ́ mílíọ̀nú èèyàn fun - Nnamdi Kanu Ẹ̀bùn ọdún tuntun tó yááyì ni ikọ̀ Amotekun - Soyinka Ànfààní ńlá wà nínú ètò Amọtẹkun, àwọn agbẹjọ́rò ló lè sọ bó yá kò bá òfin mu- Olu Falae Soyinka ni oun to ma n da wahala silẹ ni ''ki awọn eeyan kan ma mu ọrọ ibẹru gẹgẹ bi ọrọ ododo tabi ki ijọba ati awọn ẹya kan ma gbe igbesẹ latari ibẹru to gba ọkan wọn'' O ni iru iwa bayi kii labọ nitorinaa o wu oun ki Balarabe yẹra fun iru ọrọ tabi iwa bayi.
Dìbò fún un níbí Bakan naa, o ṣalaye wi pe o jẹ ọjọ ti Jesu Kristi da gbigba ara oluwa silẹ eyi ti awọn ẹlẹsin Kristẹni n pe ni isin idapọ mimọ lode oni.
bí ìwọ bá fi ẹnu rẹ jẹ́wọ́ pé, “Jesu ni Oluwa,” tí o sì gbàgbọ́ lọ́kàn rẹ pé Ọlọrun jí i dìde kúrò ninu òkú, a óo gbà ọ́ là.
Kiddwaya, Lilo, Wathoni, Eric àti Tolanibaj ló ń jètè àra wọ́n lásìkò àríya sátide àkọ́kọ́ lórí móghùmáwòràn ti gbogbo ènìyàn si ń ni ànfani láti maa wò wọ́n bí wọ́n ṣe.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ọ̀pọ̀ ẹ̀mí sọnù sínú ìjàmbá iná World water day: Ẹrin Ijesa, Ọ̀ṣun Oṣogbo, àwọn ibùdó ìgbafẹ́ omi tí ó yẹ kí o mọ̀ Ilé ẹjọ kò pàṣẹ dá kíkà èsì ìbò ìpínlẹ̀ Rivers dúró-INEC Àkọlé àwòrán, Ni ọjọ kejilelogun oṣu kẹsan ọdun 2018 ni eto idibo ati yan gomina fun ipinlẹ Ọṣun waye Lónìí nilé ẹjọ́ yóò dá ẹjọ́ ìdìbò gómìnà ìpínlẹ̀ Ọṣun Ṣe wọn ni irawe kan ko ni dajọ ilẹ ko sunna.
lẹ́yìn rẹ̀, Ahara, lẹ́yìn rẹ̀, Nohahi, àbíkẹ́yìn rẹ̀ ni, Rafa.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Noodles: Oúnjẹ aládùn ni àgbáyé mọ Nódùùlù sí 25 Ọ̀wàrà 2018 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ebi ń pa yín bi?
Igbesẹ yi waye lẹyin ijiroro ọlọjọ mẹta lori awọn koko to wa ninu abadofin yi ti aarẹ pe orukọ rẹ ni aba isuna idapada ati iduro sinsin ọrọ aje Naijiria.
Abiṣua bí Buki, Buki sì bí Usi.
 obìnrin ko le da ọkọ dó laì ri ọkunrin .
Baba Mutallab wa rawọ ẹbẹ sawọn alasẹ pe ki wọn tun idajọ ti wọn se fun ọmọ oun yẹwo bi o tilẹ jẹ pe lootọ lo gba pe oun jẹbi gbogbo awsn ẹsun ti wọn ka si lọrun.
Eyi ko sẹyin bi oludije fun ẹgbẹ osẹlu PDP se kọkọ yari pe eto atundi idibo naa ko ni waye nitori magomago ati iwa ipa to sẹlẹ, to si fa atundi idibo naa.
Ìjàmbá iná l'Eko: Ọkọ̀ aképo gbiná ní òpópónà Eko sí Badagry
Àwọn ọmọ Juda kan, ati àwọn ọmọ Bẹnjamini kan ń gbé Jerusalẹmu.
O ni isede to n bẹrẹ laago mẹwa alẹ ṣi wa sibẹ.
Ahmed Musa padanu ìyá rẹ̀ lẹyin aisan ranpẹ
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Bí ẹ ṣe mọ̀wé tó, ẹ wá dánrawò níbí pẹ̀lú Àpólà Ọ̀rọ̀ Orúkọ - Noun Phrase Ìdí tí mo fi gbàdúrà ìyàwó bíi Chanel Chin fáwọn tó d'ẹ̀bi ìkọ̀sílẹ̀ rẹ̀ rù mí rèé - Oluwo Oral Sex: Bóo bá ń gba ẹnu ní ìbálòpọ̀, wo àìsàn tóo lè kó lójú ara rẹ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Ìgbà tí mo máa fi lajú sáyé padà, ọ̀fọ̀ ikú mi ní wọ́n ń kígbe' Oríṣun àwòrán, Others Agbegbe Ọfin ni isalẹ Eko nilu Eko ni William Abass tẹdo si nigba to ti orilẹede Portugal de, ti ọpọ arọmọdọmọ rẹ to wa nisalẹ Eko lonii si n jẹ Williams, nigba tawọn miran pa orukọ mejeeji pọ, William Abass."
Lẹyin rẹ si lawọn adigunjale yoku to ti fi Naijiria logbologbo to si Sugbọn ọjọ gbogbo ni ti ole, amọ ọjọ kansoso pere ni ti olohun.
Oluwo: Ẹ má gbé ẹ̀kú eégún 1960, tó ń rùn wọ ààfin mi
Gege bi ile-ise aare se so: “igbese tuntun ti  a pe ni EO 6, ko waye lati gbogunti awon egbe oselu alatako tabi awon eniyan jankan-jankan bi o se le wu ko mo lorile-ede yii, bi ko ba i se lati gbogunti iwa ibajẹ ti o joba lorile-ede Naijiria.
Balarabe gẹgẹ bi ohun ti iwe iroyin kan sọ lo ni idasilẹ Amẹtẹkun jẹ ọna kan ti ẹya Yoruba fẹ gba lati mu ipinya Naijiria wa.
ohun tó dára níta tí kò dára nínú .
Aare ni oun yoo wo igbese lilo awon eniyan ipinle Plateau sispo gege bi ibeere gomina naa bakan naa lo ran an leti pe ijoba oun n lo ona igbanisise nipa ipinle koowa nijoba apappo gege bio ilana ofin se laa kale ni.
Awọn Ọlọ́pàa mẹta la gbọ pe o wa lara awọn to ti ku ṣugbọn awọn alaṣe ko ti sọ pato iye eeyan to ba iṣẹlẹ naa lọ.
Bakan naa ni iwe ofin Section 66(1) fofin de ẹni to jẹjẹ fun orilẹede miran lati dije dupo ti o ba rufin ẹka ofin (Sections 25-28).
Mo yan àwọn kan ninu àwọn ọmọ yín ní wolii mi, mo sì yan àwọn mìíràn ninu wọn ní Nasiri.
àwọn àgbààgbà mẹrinlelogun náà á dojúbolẹ̀ níwájú ẹni tí ó jókòó lórí ìtẹ́, wọn a júbà ẹni tí ó wà láàyè lae ati laelae, wọn a fi adé wọn lélẹ̀ níwájú ìtẹ́ náà, wọ́n a máa wí pé,
"Giwa UITH fi kún pé, oníruuru ẹ̀ka ìṣègùn mẹ́rìndílógún ni àwọn ti sa àwọn dókítà tí wọ́n ṣiṣẹ́ náà jọ láti ṣe aṣeyọri "" Nígbà tí wọ́n gbé àwọn ọmọ náà dé, à kò tilẹ̀ kọ́kọ́ mọ ibi ti wan ti lẹ̀pọ̀ ni pàtó, A kàn gbiyanju láti ṣeranwọ ní, nítori ko si irinṣẹ́ tó yẹ."
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Oke Obi-Enadhuze:, Lekkitollgate, EndSars: Mọ̀ síí nípa Oke Obi 22 Ọ̀wàrà 2020 Oríṣun àwòrán, @DanielOE16 Gẹgẹ bi akọsilẹ nipa rẹ to wa ni oju opo ayelujara LinkedIn rẹ, Oke kekọọ gboyè imọ ijinlẹ akọkọ ninu imọ kọmputa ni Fasiti eto ọgbin ti ijọba apapọ to wa niluu Abeokuta, nipinlẹ Ogun laarin ọdun 2016 si 2020.
Fadaka ni kí o fi bo gbogbo òpó inú àgọ́ náà, fadaka náà ni kí o sì fi ṣe gbogbo ìkọ́ àwọn òpó náà, àfi àwọn ìtẹ́lẹ̀ rẹ̀ ni kí o fi idẹ ṣe.
Ìtàn ayé Henry Fajemirokun, olówó tó fi owó mọ Olúwa àti ènìyàn Mi ò tíì gba ìwé ìfitónilétí pé wọ́n fẹ́ yọ mí nípò igbákejì gómìnà ìpínlẹ̀ Ondo- Agboola Ajayi N kò gba ₦4bn lọ́wọ́ Magu, ẹ má ró àjẹbánu mọ́ mi láṣọ - Osinbajo pariwo Coronavirus tún gbẹ̀mí dókítà míì l'Ondo WWF ni awọn inaki naa n sa fun eeyan, bẹẹ ni iyatọ diẹ wa laarin wọn atawọn inaki miran, fun apẹẹrẹ, ori wọn kere, ọwọ wọn gun, bẹẹ naa ni irun ara wọn funfun diẹ ju ti awọn inaki mii lọ.
Ọkùnrin kan gba mẹta ninú àwọn ìyàwó ọba, àwọn mẹ́tẹ́ẹ̀ta sì wa síwájú ọba, wọnh ń ro ẹjọ ara rẹ̀ fún un.
 Iyawo Harold, Lady Antonia Fraser ni inu oun di si eto ami ẹyẹ naa.
Oba Folagbade Olateru-Olagbegi wàjà lẹ́ni ọdún 77 Ajibade Ogunoye di Ọlọ́wọ̀ tuntun fún ìlú Ọwọ Thai king: Ọ̀nà wo ní ẹ̀ṣọ́ ọba gbà di olorì láàfin?
" Ìjàmbá ọkọ̀ bàálu gbẹ̀mí ọmọdé méjì àtàwọn arìnrìǹàjò míì Kínni ẹ̀yin lè rántí nípa Ààrẹ Nàìjíríà tẹ́lẹ̀ rí, Umaru Musa Yar'Adua?
Wọn gba idajọ naa lori bi wọn sese agbatẹru ado oloro to bu nilu Abuja lọjọ kinni osu kẹwa ọdun 2010 ati nilu Warri lọjọ kẹẹdogun osu kẹta ọdun 2010 kannaa.
O ni lati ibẹrẹ oṣu kinni si ipari oṣu ọdun 2020, owo to din diẹ ni tiriliọnu meji(N1.
Ní ihà àríwá  ilé-aiyé àti ihà gùsù aiyé pẹ̀lú, ọjọ́ ò dọ́gba rara.
Ọ̀pọ̀lọpọ̀ ènìyàn ló yí orúkọ wọn po nígbà tí orúkọ bẹ́ẹ̀ bá orúkọ àwọn ọlọ́ṣà, adigun- jalẹ̀ mu.
Iroyin gbe e jade pe adari ẹsin musulumi ni ariwa Naijiria, Sheikh Dahiru Usman to wa pẹlu awọn aadọta asojusofin ti wọn dibo yan naa ti buwọlu Gbajabiamila gẹgẹ bi ẹni ti yoo jẹ adari Ile Asojusofin lorilẹede Naijiria.
Igbakeji gomina ipinle  Nasarawa , ogbeni  Silas Agara,naa tun so pe o ye ki orile ede Naijiria naa dupe lowo Olorun fun itona re lori aare orile ede yii Muhammadu Buhari ati Osinbajo laarin odun meta ti won ti wa lori aleefa.
Ìdí èyí ni a fi rí orúkọ abo òrìṣà yìí nínu “E(o)strogen” fún àpẹrẹ.
 Àwọn ni wọn ń kojú ogun .
Obi kọ si oju opo ayelujara Instagram rẹ pe awọn nkan miran to ṣe iyebiye ju bọọlu gbigba wa l'aye."
Awọn lo ma n ya aworan ati fidio ti isin ba n lọ lọwọ, ati amojuto iṣẹ iranṣẹ ori amohunmaworan ijọ naa.
"Baba ni ""lati ọmọ ọdun mẹrin ni aisan warapa ti n yọ ọmọkunrin wa lẹnu a o si lowo fun itọju rẹ"" Nigba ti titiraka yii pọ lati doola mi ọmọkunrin wọn ni ẹbi gba lati ta ọmọbinrin wọn."
Ooni Ile ife, Ààrẹ Gani Adams fárígá lórí ikú ọmọ Fasoranti Derin sọ pataki nini ọyaya pẹlu iṣẹ ti eeyan ba n ṣe.
 Ọlọrun ọ ̀ gá ògo to da ayé .
Ẹ fara balẹ gbọ eto yii lẹkunrẹrẹ lati mọ nipa awọn igbeyawo to ku ati ojuse awọn alarina ninu igbeyawo.
Ìbànújẹ́ nípa èyí wọ̀ mi lọ́rùn bí ẹni wọ ẹ̀wù ni, bẹ́ẹ̀ ni ìwà rẹ̀ ló lọ gbé ìfẹ́ mi dìde nibi ti ìfẹ́ mi ti sùn sí.
"Nínú ọ̀rọ̀ tirẹ̀ Akọnumọọgba wọ́n Gernot Rohr"" Ọ̀rọ̀ mí si àwọn olólùfẹ ikọ super Eagles ni pe ki jẹ ki awọn ọmọ agbábọọlu Nàìjíría ma wú wọ́n lóri, nítori wọ́n n sapa wọ̀n láti gbe ogo fún Nàìjíríà nínú ìdíje AFCON."
Jeruṣa, ọmọ Sadoku ni ìyá rẹ̀.
Ẹ ri òpó mọ́lẹ̀ lọ fún ara yín,ẹ sàmì sí àwọn ojú ọ̀nà.
"Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ọrọ rè láti ẹnu àwọn Agbẹjọ́rò Makinde àti Adelabu nípa ìdájọ ọ́rọ́ ìdìbò Gómìnà Oyo ""Idajọ ileejọ Kotẹmilọrun yii lo tun sọ ireti mi ji pada ninu ilana eto idibo ati ẹka eto idajọ ninu igbesẹ wa lati ni akọọlẹ ninu itan."
“Ṣé o ti wọ àwọn ilé ìkẹ́rùsí, tí mò ń kó yìnyín pamọ́ sí rí,tabi ibi tí mò ń kó òjò dídì sí,
akanse naa gbe iwe atunyewo isuna re jade.
Weah sisẹ agbabọọlu nilẹ Yuroopu laarin ọdun 1990 si 2002.
Nítorí Adamu ni a kọ́kọ́ dá, kí á tó dá Efa.
England); Wilfred Ndidi (Leicester City, England); Oghenekaro Etebo (Stoke City
to wa nikalẹ lasiko ti awon eniyan naa de si orile ede Naijiria ni , ajo to n
Àkọlé àwòrán, Ayẹyẹ ikẹyin fun Baba Sala Ọjọ keje ọṣu kẹẹwa ọdun 2018 ni Baba Sala jade laye lẹni ọdunmọkanlelọgọrin.
 Òwò ṣíṣe , oríṣìíríṣìí iṣẹ ́ ọnà tàbí iṣẹ ́ ọwọ ́ bí i agbọ ̀ n híhun , irun gígẹ ̀ , iṣẹ ́ alágbẹ ̀ dẹ , ilé mímọ àti iṣẹ ́ gbẹ ́ nàgbẹ ́ nà .
Èyí le túmọ̀ sí pé o mọ ìtàkùn àgbáyé(website) tí o fẹ́ yẹ̀ wò.
Kòsí oun tí ń gbani lọ́wọ́ omi àfi ikú.
Busola Dakolo, ẹjọ́ ẹ ti kọjá odún mẹ́fà - Ileẹjọ Ile ẹjọ giga ni ilu Abuja ti fi ọwọ osi da ẹjọ ti ilumọọka ayaworan, Busola Fatoyinbo pe mọ pasitọ agba ile ijọsin Commonwealth of Zion Assembly (COZA).
Ọlọrun mi óo wá sọ́dọ̀ mi ninu ìfẹ́ rẹ̀ tí kì í yẹ̀;Ọlọrun óo fún mi ní ìṣẹ́gun lórí àwọn ọ̀tá mi.
Oríṣun àwòrán, others Àkọlé àwòrán, Ohun méje tí o kò gbọ́ rí nípa aláìsàn fòníkú fọ̀ladìde 2.
Ọrọ ẹsun agbere rẹ fa awuyewuye lọpọlọpọ ni ọdun 2013 nigba ti arabinrin kan ti orukọ rẹ n jẹ Ese Walter jade lati jẹwọ agbere to ni awọn jọ ṣe.
Òtútù kọ̀ ó l'óun ò ní dá gbére lótẹ̀ yìí.
Ẹnu ti n kun ọpọ onidajọ lorilẹede Naijiria fun igba diẹ bayii, paapaa julọ lẹyin tawọn osisẹ ileesẹ ọtẹlẹmuyẹ ni Naijiria, DSS, kọlu ile awọn adajọ kan loru, lọdun 2016 pẹlu ẹsun pe ejo wọn lọwọ ninu lori awọn ẹsun iwa ibajẹ ati ijẹkujẹ gbogbo.
Gege bi oro lati ile-ise aare ile-igbimo ohun, ipade naa yoo da lori bi won yoo se jiroro fenuko bowolu isuna eto idibo odun 2019.
Wọn rọ àwọn aláṣẹ ilé-ìwé ọ̀hún láti yọ ọ́ kúrò l'órí òye náà.
Àdó okoró búrẹ́kẹ' Aarẹ Ọbasanjọ ṣalaye pe sababi ni ipade oun ati Iba Gani Adams ni ile agba ilẹ Yoruba to tun jẹ aṣiwaju ẹgbẹ Afẹnifẹre ni agbegbe Lekki Phase 1 jẹ, kii ṣe lati pari ija kankan.
Ní ọjọ́ náà, n óo mú kí oòrùn wọ̀ ní ọjọ́kanrí, ilẹ̀ yóo sì ṣókùnkùn ní ọ̀sán gangan.
Won soro nile igbimo asofin pe awon alufaa obinrin merin lati ipinle Delta lo  ti wa nikawo awon agbesunmomi bayii, igbimo asoin tun bu enu ate lu bi won se n dun ikooko mo awon olori elesin ati bi won se n ji awon eniyan gbe ni ipinle naa.
Lasiko ìsinmi tí Hajj kò bá ti bẹrẹ, máṣe daamu ará rẹ torí iṣẹ sí wà níwájú.
Ọba Lamidi Adeyẹmi, òṣìṣẹ́ adójútòfò àti Abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò kó tó jọba Jesu Oyingbo rèé, pásítọ̀ tó láṣẹ ìbálòpọ̀ lóri ọmọ ìjọ obìnrin Ìtàn tó rọ̀ mọ́ òwe ‘aṣọ kò bá Ọ́mọ́yẹ mọ́.
 Odun 2017 ni wọn bẹrẹ ifẹ wọn ni eyi ti wọn ti bi ọmo obinrin kan.
Lórí ìwọ pẹpẹ yìí ni yóo ti fi àwọn alufaa oriṣa tí ń sun turari lórí rẹ rúbọ.
Gomina ti Ipinlẹ Bauchi, Mohammed Abubakar, sọ eyi fun awọn oniroyin lẹyin ipade awọn igbimọ ti o ga julọ lori eto ọrọ aje orilẹede (NEC) pẹlu igbakeji aarẹ Yemi Osinbajo lọjọbọ.
Àtunbọ̀tán òjò òwúrọ̀ ọjọ́ ajé nílùú Eko Ọlọ́pàá mú ẹyẹ igún sí àtìmọ́lé ní ìpínlẹ̀ Adamawa Ọgbà ẹ̀wọ̀n ni Naira Marley yóò ti wo ìbúra Buhari ní May 29 Omidan Folasade Odoro ni igbiyanju ti n lọ lọwọ lati doola awọn ti wn ji gbe ọhun.
Ohunkohun tí o bá pinnu láti mú ṣe,yóo ṣeéṣe fún ọ,ìmọ́lẹ̀ yóo sì tàn sí ọ̀nà rẹ.
ibaje ati sise owo ilu kumọ- kumọ, EFCC  to wa ni ilu  Ibadan , ni ipinle Oyo ti ekun Gusu orile ede
Wọ́n fún obìnrin kan lọrùn pa, awuyewuye ti ń wáyé Ààrẹ Muhammadu Buhari gbè sẹ́yìn Keyamo lórí ètò ìṣẹ́ 774,000 Ìyàwó mi ló ṣì ń dáná, bu oúnjẹ mi, gé èékáná fún mi - Pásítọ̀ Adeboye Ìjọba fí ìlànà tuntun lédé lórí àti ṣí iléèwé káàkiri Nàíjíríà láì fí ọjọ́ tí wọn yóò ṣí iléèwé sí bẹ̀ Kí ló fa ìjà láàrin Wunmi Toriola àti Seyi Edun?
Mo mú ìdáǹdè mi wá sí tòsí, kò jìnnà mọ́,ìgbàlà mi kò ní pẹ́ dé.
Oga ile ise naa wa so pe aseyori awon ko seyin iranlowo
wọ́n bẹ̀rẹ̀ sí bẹ̀bẹ̀, wọ́n ní, “Jọ̀wọ́ oluwa mi, a ti kọ́kọ́ wá ra oúnjẹ níhìn-ín nígbà kan.
Oloye Rotimi Jogunosinmi to je mogaji agboole Jogunosinmi ni adugbo Oja Oba to tun je omo oloogbe lo fidi e mule.
Ramoni wole arugbo Ilorin pari Àkọlé àwòrán, Tokada-tokada ni wọn fi wo ile naa lai ku nkan pẹlu awọn nkan inu rẹ.
"Obìnrin kan wọ gàù lẹ́yìn tó kan ìṣó mọ́ ọmọ ọ̀dọ̀ rẹ̀ ẹni ọdún mẹ́wàá lórí Mi ò mọ ohunkóhun nípa ""Aketi Whyski"" - Akeredolu ké gbàjarì Báwo ní 'Aṣọ ẹbí' ṣe bẹ̀rẹ̀ ní ilẹ̀ Yorùbá?"
Lọjọ ti igbẹjọ kọkọ waye, wọn ṣe afihan rẹ lori amohunmaworan, eyi ti ko waye ri ni orilẹede South Africa.
CS Mum: Omotolani Ekene ní ọ̀pọ̀ èèyàn gbà pé ọ̀lẹ, arugún, aláìlera ni ẹni tó fi abẹ bímọ
Ó ní, “Ọmọ eniyan, mo rán ọ sí àwọn ọmọ Israẹli, orílẹ̀-èdè àwọn ọlọ̀tẹ̀, àwọn tí wọ́n ń ṣọ̀tẹ̀ sí mi.
Mari gẹgẹ bi ọmọ ọba Ọdun 1882 ni wọn bi Marie Bonaparte, nilu Paris, sinu idile to gbajumọ, to si lowo lọwọ.
Baalẹ ilu Dangora, Mallam Ahmadu Ya'u naa ba akọroyin BBC sọrọ pe o ti pẹ ti tonile talejo ti n gbadura pe ki ọwọ tẹ oniṣẹ ibi yii ni eyi ti o dẹ ti jasi ọpẹ nla fun gbogbo olugbe Dangora lasiko yii.
Awọn oun to sọ ree: 1.
 Àgbádárìgì gúnwà láàárín Ìlú Èkó àti orílẹ ̣ ̀ -èdè olómìnira benin .
Ọba Siria ṣẹgun rẹ̀, ó sì kó àwọn eniyan rẹ̀ lẹ́rú lọ sí Damasku.
Abineri tún pe Asaheli, ó tún sọ fún un pé, “Pada lẹ́yìn mi, má jẹ́ kí n pa ọ́?
Jesu wí fún wọn pé, “Ẹ gbé òkúta náà kúrò.
Kwara: Ọti tita ati rira di eewọ nilu Ilọrin
" O wa sọ pe oun ti gba pe bi Ọlọrun ṣe fẹ ki ọrọ aye mi ri niyii.
Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Fídíò, Akomolede ati Aṣa lori BBC:Wo ìrúfẹ́ ìgbeyàwó méje tó wà nílẹ̀ Yorùbá àti ojúṣe Alárinà10 Bélú 2020 Healthy lifestyle: Wo irú ìgbé ayé tó lè mú ẹ̀mí rẹ gùn11 Bélú 2020 Nigeria road accident record in 2020: Èèyàn 1,076ni ìjàmbá mọ́tò ti sọ di olóògbé láti oṣù mẹ́ta sẹ́yìn ní Nàìjíríà- FRSC11 Bélú 2020 Divorce: Ilé ẹjọ́ tú ìgbéyàwó ọdún mọ́kànlá ká nítórí pé ìyàwó fí ìbálòpọ̀ dun ọkọ rẹ̀12 Bélú 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Ṣé lóòótọ́ ni pé Buhari ló fa àdínkù owó Dangote?
Bó pẹ́, bó yá, ohun ayé á b’áyé lọ
A óo ké pè ọ́ ninu ìyọnu wa, o óo gbọ́ tiwa, o óo sì gbà wá.
Awuyewuye ọhún bẹrẹ nígbà tí Ayobami ati ọrẹ rẹ, Sulaimon n jiyàn lori iha ti ìjọba ìpínlè Oyo, labẹ iṣakoso Gomina Seyi Makinde kọ sí àjàkálẹ̀ àrùn Coronavirus to ń ba gbogbo agbaye fínra.
Ọyọ crisis: Àwọn ọmọ Nàìjíríà fẹ́ kí Gómìnà Seyi Makinde ó pe ìpàdé àlááfíà láàrín Sunday Igboho àti Auxilliary Oríṣun àwòrán, seyi makinde Awọn ọmọ Naijiria ti ke si gomina ipinlẹ Ọyọ, Seyi Makinde pe ko wa nnkan ṣe si iṣudẹdẹ ojo wahala to ṣu ni ipinlẹ naa bayii pẹlu bi awọn eekan meji kan, Sunday Igboho ati aṣiwaju ẹgbẹ ọlọkọ ero Lamidi Mukaila ti ọpọ mọ si Auxilliary.
Má wo ti oríkunkun àwọn eniyan wọnyi, tabi ìwà burúkú wọn, ati ẹ̀ṣẹ̀ wọn,’ 
Àkọlé àwòrán, Yusha'u Abdulhamid Iriwisi ti Yusha'u Abdulhamid tun fẹ lagbara diẹ O ni idi ti ohun kii ba awọn Musulumi to ku gba awẹ ni pe ''ohun ti ọkan oun ba sọ nikan loun ma n tẹle'' ''Oṣu Ramadan to ba yọ,awa musulumi ta wa ni Kano gbọdọ ri,bẹẹ lo si yẹ ko ri fawọn ti ipinl mii.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Àwọn òṣèré, olórin Yorùbá gbàdúrà fún MC Oluomo 13 Sẹ́rẹ́ 2019 Oríṣun àwòrán, Ronkeoshodioke, iyaboojo Àkọlé àwòrán, Ronke Oshodi Oke gbadura fun imularada MC Oluomo Àwọn gbajugbaja òṣèré ati olórin Yorùbá lorilẹede Naijiria n ṣe asúgbàá oloye ẹgbẹ awọn awakọ Naijiria, Musiliu Akinsanya ti gbogbo eeyan mọ si MC Oluomo.
Ebila of Ibadan: Ikọ̀ Operation Burst\ ní àwọn ló pa Ebila, olórí àwọn \""One million boys\"" n'Ibadan"
Gbogbo ohun tí ó ń ṣe yóo dàbí ẹni tí ń dífá irọ́ lójú àwọn ará ìlú, nítorí pé majẹmu tí wọ́n ti dá yóo ti kì wọ́n láyà; ṣugbọn ọba Babiloni yóo mú wọn ranti ẹ̀ṣẹ̀ wọn, yóo ṣẹgun wọn yóo sì kó wọn lọ.
O ti mú kí àwọn aládùúgbò wa máa jìjàdù lórí wa;àwọn ọ̀tá wa sì ń fi wá rẹ́rìn-ín láàrin ara wọn.
Nítorí mo sọ fun yín pé n kò tún ní jẹ ẹ́ mọ́ títí di àkókò tí yóo fi ní ìtumọ̀ tí ó pé ní ìjọba Ọlọrun.
Minisita naa lasiko to n ba awọn oniroyin sọrọ ni orilẹede Naijiria ko ni awọn ohun elo to to lati ṣe ayẹwo ni awọn papakọ ofurufu ati ibudokọ kaakiri Naijiria.
Ẹ jẹ ka fi itan igbe aye Samuel Taiwo Ọrẹdẹin kọgbọn, ka maa sọra se.
Coronavirus in Nigeria: Ǹjẹ àgbo lè ṣe òògùn coronavirus?
“Èmi Kirusi, ọba Pasia kéde pé: OLUWA Ọlọrun ọ̀run ti fi gbogbo ìjọba ayé fún mi, ó sì ti pàṣẹ fún mi pé kí n kọ́ ilé kan fún òun ní Jerusalẹmu ní ilẹ̀ Juda.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Prophet Israel Oladele: Wo bi wọ́n ṣe n ṣe àmójútó ilé ìjọsìn CCC Genesis Global 22 Bélú 2020 Oríṣun àwòrán, Genesis global Gẹgẹ bi akọsilẹ to wa lori ayelujara itakun agbaye ijọ CCC Genesis Global ṣe sọ, oun ni ijọ Celestial to tobi julọ, to si n yara dagba soke julọ ni agbaye.
Àkọlé àwòrán, Ẹ̀wẹ̀, aarẹ apapọ fun ẹgbẹ osisẹ NLC, Ayuba Wabba ati akẹẹgbẹ rẹ fun TUC, Kaigama Bobboi, sọ fun awọn akọroyin pe lootọ ni ilọsiwaju wa nipa aawọ to wa nilẹ.
"orin tí ó gbajúmọ ̀ jù nínú àwo náà "" heartbeat "" jẹ ́ àdákọ rẹ ̀ akọkọ tí ó wọ ikọ orin ilẹ ̀ jamaní aláàdọ ́ ta àkọ ́ kọ ́ , ní oṣù kẹsan-an 2009 orin náà wọ ikọ orin àdákọ ilẹ ̀ gẹ ̀ ẹ ́ sì ní ipò ogún ."
Nígbà tí wọ́n bá mu yín lọ fún ìdájọ́, ẹ má dààmú nípa ohun tí ẹ óo sọ tabi bí ẹ óo ti sọ ọ́; nítorí Ọlọrun yóo fi ohun tí ẹ óo sọ fun yín ní àkókò náà.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù APC Crisis: Àwọn ọmọ ẹgbọ́ APC kan ti n yarí nítorí àì tí ṣe ìpàgọ́ ẹgbẹ́ 9 Bélú 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 10 Bélú 2020 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Alaga Ẹgbẹ́ òsèlú APC ní Èkìtì ni àwọn kò ní ṣé ipolongo ti ko ba sì ààbò tó péye Awọn iroyin kan ti n lọ labẹnu pe, o ṣe e se ki igbimọ alakoso ẹgbẹ oṣelu All Progressives Congress, APC, ṣe ipade apapọ ko to o di ọjọ Keresi, ọjọ kẹẹdọgbọn, oṣu Kejila ọdun 2020.
Àwọn ẹ̀mí èṣù yìí bá jáde kúrò ninu ọkunrin tí à ń wí yìí, wọ́n wọ inú àwọn ẹlẹ́dẹ̀, ni agbo ẹlẹ́dẹ̀ bá sáré láti gẹ̀rẹ́gẹ̀rẹ́ òkè lọ sí inú òkun, wọ́n bá rì sómi.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Akomolede ati asa Yoruba: Ẹ wá kọ́ nípa àpòtí ìṣura èdè wa lórí BBC Yorùbá 1) Lasiko Ijọba Ologun Buhari / Idiagbon Eyi to gbajumọ julọ ninu iṣẹlẹ igbẹsan ti ijọba Naijiria ṣe lo waye ni asiko ologun ni ti Umaru Dikko.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Iléẹjọ́ Ekiti: Bàbá àti ọmọ jí igi gẹdú tó tó ₦100,000 26 Òkùdu 2019 Àkọlé àwòrán, Nítori igi gẹdú, bábá àti ọmọ rẹ̀ méji dèrò ẹwọ̀n Ilé ẹjọ́ májísírèèti kan ni Igede Ekiti ni ìpínlẹ̀ Ekiti, ti ran bàbá kan ẹni ààdọ̀rin ọdún, Adeyeye Olorunyomi àti ọmọkúnrin rẹ̀ méji, lọ si ẹ̀wọ̀n oṣù mẹ́fa.
Lẹyin naa ni o maa lọ ka awọn ohun amuyẹ to yẹ ki o ni lati darapọ mọ SSC tabi DSSC naa.
ṣugbọn Hesekaya ṣe ìgbéraga, kò fi ẹ̀mí ìmoore hàn fún ohun tí Ọlọrun ṣe fún un.
Ati pe, O maa n ṣeto ipade laarin awọn obinrin naa, o si máa n ṣe iṣẹ alarina fún awọn to ba fẹ ẹ pada ni ọkọ.
 teletele o ti je omo ile-igbimo asofin fun bole-bamboi ati omo ile-igbimo asofin gbogbo afrika lati ghana .
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Temitope Akinnusi: Ọ̀pọ̀ iléeṣẹ́ ló takú láti gbà mí síṣẹ́ torí mo ní ojú kan Irisi rẹ gan jọ tawọn ara Somalia, iwọ to lee to ile rẹ, o ko niyawo ninu ile, o wa n tabuku baba mi, bi gbogbo eeyan ko ba sọrọ, maa sọrọ, maa si fa onitọun ya pẹrẹpẹrẹ.
Ṣugbọn oṣu kẹwaa ọhun wa ko si si igbasoke ayanfe kankan.
Osinbajo so pe, o ye ki awon eniyan wo awokose ile-ise Nestle bi o se n da awon ile-ise sile lorile-ede Nigeria, gege bi a se mo pe, orile-ede Nigeria nikan nibi ti o rorun julo lati da  idokowo sile.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Tanker Accident: Ọ̀pọ̀ èèyàn tó ń lọ sẹ́nu iṣẹ́ àti okoòwò ló tàn sílẹ̀ 31 Agẹmo 2019 Oríṣun àwòrán, @Gidi_Traffic Se ni ohun gbogbo lọju pọ ni opopona Eko si Ibadan lọjọru, ti awọn ero si duro gogogo soju popo lai ri ọkọ wọ lasiko ti ọkọ epo kan to ko epo disu danu soju popo.
 Adaralegbe ṣalaye pe Ọmọdekunrin naa jẹ akinkanju; ohun to ṣe naa ṣi n jẹ ko ye gbogbo wa pe ninu gbogbo iṣoro ti a ba n dojukọ nile aye, o yẹ ka maa ni suuru.
Nítorí Ẹni Burúkú yìí yóo farahàn pẹlu agbára Èṣù: yóo máa pidán, yóo ṣe iṣẹ́ àmì, yóo ṣe iṣẹ́ ìtànjẹ tí ó yani lẹ́nu.
Ó fi òtítọ́ èyí han gbogbo eniyan nígbà tí ó jí ẹni náà dìde kúrò ninu òkú.
Ọ̀pọ̀ òjò ti rọ̀ ti ilẹ̀ si ti fi mu, ọ̀pọ̀ ẹ̀mi dúkìá àti ilé ló ti bá àwọn ìṣẹ̀lẹ̀ tí o wáyé lẹ́yìn náà lọ.
O ni wọn so ipade naa rọ ki awọn akọṣẹmọṣẹ lè wo awọn akọsile bi owo oṣu naa a ṣe ri daadaa.
Ronkẹ ni MC Oluọmọ seun o, to maa n tẹti si oun, to si tun seun, to jẹ ọrẹ nla si oun.
Ko wọ pọ lati ri iru isẹlẹ bayii ninu ere ori papa lorilẹede Naijiria, awọn eniyan kan tilẹ wipe o jẹ iyalẹnu nitori ọpọlọpọ obinrin to n figa gbaga ninu oniruuru idije ori papa.
Amọ ṣaa, iyalẹnu lo jhẹ nigba ti eto naa pada foriṣanpọn l'oṣu Kejila, ọdun 2016, ti ẹgbẹẹgbẹrun ọmọ Naijiria si padanu owo wọn.
Nígbà tí ọjọ́ ìkúnlẹ̀ rẹ̀ pé, ìbejì ni ó bí nítòótọ́.
Ṣugbọn, lati kekere ni ibanujẹ ti wọ aye rẹ, nitori pe diẹ lo ku, ko kú lasiko ti iya rẹ fẹ ẹ bi.
O ni owo ti wọn fi n ra ọda lati fi ya aworan ti kọja agbara oun, ni oun se yan lati maa lo awọn eroja naa, ti owo wọn ko gunpa rara.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ọọni Adeyeye gbé orúkọ àrẹ̀mọ rẹ̀ jáde, ẹ kọ́ ẹ̀kọ́ nípa àwọn ǹkan tí wọ́n fi gbàdúrà f'ọ́mọ ọba 21 Bélú 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 27 Bélú 2020 Oríṣun àwòrán, Ooniadimula Ilẹ Yoruba ni asa isọmọlorukọ ara ọtọ Bẹẹ idalu kuku ni iṣelu ni awon agba n sọ.
Ipade naa wa gẹgẹ bi ọna abayọ si idamu sunkẹrẹ fakẹrẹ ọkọ ati iṣẹlẹ omiyale ni agbegbe Lekki mọ Ajah.
Ọpọ eeyan lo bọ sawọn oju opo ikansira ẹni lati sami ayajọ Ma lo kọmu yii, ti wọn si n la awọn eeyan lọyẹ ni oniruuru ọna lori awọn ọna ti wọn fi lee dena arun jẹjẹrẹ ọyan.
Bí o kò bá ṣá ti sọ ohun tí a wá ṣe níhìn-ín fún ẹnikẹ́ni, a óo ṣe ọ́ dáradára, a óo sì jẹ́ olóòótọ́ sí ọ nígbà tí OLUWA bá fi ilẹ̀ náà lé wa lọ́wọ́.
Eto idibo 2019 lo ti n kanlẹkun gbọngbọn ni eyi ti awọn oludije ti n tẹra mọ eto ipolongo wọn kaakiri Naijiria.
Ẹ run gbogbo àwọn oriṣa tí wọ́n fi òkúta ati irin ṣe ati gbogbo ilé oriṣa wọn.
Láti ìbẹ̀rẹ̀ ni mo ti jẹ́ olóòótọ́ sí Saulu baba rẹ, àwọn arakunrin rẹ̀ ati àwọn ọ̀rẹ́ rẹ̀, èmi ni n kò sì ti jẹ́ kí apá Dafidi ká ọ.
ọgbẹni Babachir Lawal ti wa ni ahamọ fun ifọrọwanilẹnuwo lati ọjọru.
Ṣé èmi ni mo lóyún wọn ni, àbí èmi ni mo bí wọn, tí o fi sọ fún mi pé kí n gbé wọn gẹ́gẹ́ bí ọmọ ọmú lọ sí ilẹ̀ tí o ti ṣe ìlérí fún àwọn baba wọn.
Nígbà tí Joiakimu jẹ́ olórí alufaa, àwọn alufaa wọnyi ní olórí baálé ní ìdílé tí a dárúkọ wọnyi:Meraya ni baálé ní ìdílé Seraaya,Hananaya ni baálé ní ìdílé Jeremaya,
Lẹyin to gba ẹyẹ lọwọ Holyfield, George Foreman to jẹ Ọmọ ọdun marunlaadọta nigba naa ni Moorer gba lati ba ja ṣugbọn Foreman naa bi ejo aijẹ.
Ó dá a lóhùn, ó ní, “Èdìdì rẹ pẹlu okùn rẹ, ati ọ̀pá tí ó wà ní ọwọ́ rẹ.
Kò sì jẹ́wọ́ pé òun ni òun kó owó tí ó wà níbẹ̀.
Agbẹnusọ fun agbaninimọran kan fun ileeṣẹ naa, Ọgbẹni Ini Achibong sọ fun akọroyin BBC pe o ti ṣe diẹ ti ileeṣẹ naa ti polowo wiwa awọn ti yoo ra a, ṣugbọn ohunkohun ko yipada.
Ọ̀gìnìntìn dákun kẹ́rù rẹ máa lọ.
Alukoro ileeṣẹ ọlọpaa ipinlẹ Eko, Muyiwa Adejobi sọ fun BBC Yoruba pe, awọn janduku ti jo ọọfisi ọlọpaa marundinlogun lapapọ.
BBc Yoruba jade lati dara pọ mọ awọn ololufẹ ikọ Super Eagles lati jọ wo ifẹsẹwọnsẹ AFCON 2019 to n waye lọwọ lọwọ.
Tọkọ-tayà Osinbajo kò gbẹ́yìn níbi ayẹyẹ ọjọ́ ìbi Folu Adeboye
Kelechi AFC: Ojúlówó alátìlẹyìn Arsenal n kí ìran Yorùbá fún ọdún Ajinde
Arakunrin marun-un ni mo ní; kí ó lọ kìlọ̀ fún wọn kí àwọn náà má baà wá sí ibi oró yìí.
” Dafidi bá yọ́ kẹ́lẹ́kẹ́lẹ́ lọ sí ibi tí Saulu wà, ó sì gé etí aṣọ rẹ̀.
Nítòótọ́, ẹ̀tàn ni àwọn òkè,ati gbogbo ohun tí wọn ń lọ ṣe níbẹ̀;dájúdájú lọ́dọ̀ OLUWA Ọlọrun wa ni ìgbàlà Israẹli wà.
Ninu fidio naa Ofori leri leka pe ''Ti mi o ba pa aburo yin ayederu Pasitọ ni mi'' Lẹyin to leri yi ni kamẹra CCTV ṣafihan bi Pasitọ naa ti ṣe yinbọn lu iyawo rẹ lẹẹmeeje.
Kí o sọ fún un pé, ṣọ́ra, farabalẹ̀, má sì bẹ̀rù.
Joṣua tẹ́ pẹpẹ kan fún OLUWA Ọlọrun Israẹli ní orí òkè Ebali, 
Leanne ti wá pé ọmọ ọdún méjìdínlọ́gbọ̀n báyìí pẹ̀lú ọ̀rẹ́ ìbálòpọ̀ rẹ̀ ọlọ́dún márùn-ún Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Oríṣiríṣi ọ̀nà ni obìnrin fi lè gbádùn ìbálòpọ̀ Ṣé olólùfẹ́ mi fẹ́ràn rẹ̀ lásìkò ìbálòpọ̀ wa Inú wọn máa ń dùn wọ́n sì ń gbádùn ìbálòpọ̀.
Adari ijoba orile ede Britain tun so pe oun wa pelu awon asoju re to ni imo ẹrọ, ni eyi ti ilu Eko lee je anfaani re.
Wọn gbe omi fun Merkel amọ o kọ lati mu u.
Àwọn igi ọ̀pọ̀tọ́ tí ń so èso,àjàrà tí ń tanná,ìtànná wọn sì ń tú òórùn dídùn jáde.
Nnkan osu obinrin lee dawọ duro to ba ti pe ẹni ọdun marundinlaadọta si aadọta, homoonu kan ti wọn n pe ni Oestrogen si la gbọ pe o n fa idaduro nkan osu naa.
July 10, 2019 Àwọn ọmọ ilé ìgbìmọ̀ asofin ké pe ìjọba Nàìjíríà láti fi El-Zakzaky silẹ̀ ní ìbámu pẹ́lu ìdájọ ti ilé ẹjọ dá July 18, 2019 Adájọ D.
Bí a ti gbọ́ ni jìnnìjìnnì ti bò wá, ìrẹ̀wẹ̀sì ọkàn sì ti bá gbogbo eniyan nítorí yín, nítorí pé OLUWA Ọlọrun yín ni Ọlọrun ọ̀run ati ayé.
NURTW l‘Abuja yóò kàn sí Makinde láìpẹ́ lórí bó ṣe fòfin dè wá l‘Ọyọ - Ejiogbe Aṣa yii jẹ itẹwọgba kaakiri agbegbe yii ni eyi to n sọ fun awọn ọkunrin boya omidan tabi adelebọ ni obinrin ti wọn pade laini lati beere.
” “Awon omo orile ede Naijiria yoo tun dibo fun un, ti yoo si  tun jawe olubori lodun 2019.
O ni ẹnikẹni ti ko ba da awọn ohun ti wọn jigbe lọ pada, yoo foju wina ofin.
- Lizzy Anjorin Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ondo Elections 2020: Ọgọ́rùn-ún ọdún tí a máa lò lórí oyè l'Ondo, ẹ ó rí àrà - Ojon YPP Gẹ́gẹ́ bí ọgá àgbà LASEMA ṣe sọ, ìná náà bẹ̀rẹ̀ ni dédé ààgo mẹ́fa owúrọ ọjọbọ ọsẹ.
Ọgaagba ileesẹ ọgba ẹwọn lorilẹede Naijiria, Ahmed Ja'afaru sọ pe eleyi kun ara ohun to n sokunfa akunfọ ati akunfaya ọgba ẹwọn lorilẹede Naijiria.
Awọn ohun aramọnda to wa ninu Igbo Olodumare: Abawọle Igbo Olodumare: Ni ẹnu ọna abawọle igbo ẹrujẹjẹ naa ni akọle kan wa to n se apejuwe ọna sinu igbo ọhun.
Oṣuba nla ree fun Dokita Onyema Ogbuagbu ni fasiti Yale fun sise iranwọ lati ṣawari abẹrẹ ajẹsara fun arun COVID-19 lorilẹ-ede Amẹrika!
Opolopo gbà pé ki àwọn olori Naijiria yàgò fún ìwà Tani o mumi àti kẹnimani ninu eto idibo 2019 to m bọ yii.
Ó ní ọjọ́ ẹtì tó kọjá ni wọ́n ṣẹ̀ṣẹ̀ fi tó àwọn létí tí àwọn sì ti kọ̀wé láti gba oníduró.
 Àrokò àkókó ni àrokò àlááfíà , èkejì ni àrokò ogun .
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: ‘Fayose ń lo owó osù òsìsẹ́ fún ara rẹ̀’ Wo Ọ̀jọ̀gbọ́n Ẹlẹka tó ń díje fún ipò gómìnà Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Ìjọba tó lọ ti yá owó kọjá agbára ìpínlẹ̀' Sugbon awọn egbe oseelu PPD ni igbesẹ naa tumọ si idojukọ fun Gomina Ipinlẹ Ekiti Ayo Fayoṣe.
A ti gùnlé ìyanṣẹ́lódì ọlọ́jọ́ gbọọrọ ní ìpílẹ̀ Eko- NUPENG Ẹgbẹ awọn awakọ epo rọbi ni Naijiria, NUPENG ti gunle iyanṣẹlodi ọlọjọm gbọọrọ ni ipinlẹ Eko.
Iwe ikẹyin ti wọn kọ silẹ ni wipe 'A ko le fe ara wa nitori igbagbọ awọn baba nla wa'.
4 Àti pé ohùn ìkìlọ̀ yíò wá fún gbogbo ènìyàn lati ẹnu àwọn ọmọ-ẹhìn mi, àwọn tí mo ti yàn ní awọn ọjọ́ ìkẹ́hìn yìí.
Ẹ̀ṣọ́ tún ní, “Ẹni tí ó ṣáájú tí mo rí yìí jọ Ahimaasi.
Ninu awọn mẹfa naa ni a ti ri Dokita Stella Adadevoh.
Lẹsẹkẹsẹ, wọ́n fi ọkọ̀ ati baba wọn sílẹ̀, wọ́n tẹ̀lé e.
agbenusoro nile ise to n ri si ise omoniyan, ogbeni Saviano Abreu so pe isele naa koja bi won se lero ni awon agbegbe Macomia
"Okina ni, ""Nigba ti o fun mi ni owo naa, ko mọ wipe oun n bẹrẹ nnkan ti o di nla loni."
Ẹgbẹ agbabọọlu Liverpool ati Tottenham ni yoo maa figagbaga ni ipele aṣekagba idije naa lalẹ ọjọ Satide.
Ninu atẹjade kan to fi sita, alaga ijọba fidihẹ ni ijọba ibilẹ Ifọ, Họnọrebu Fọla Salami ni iwadii ti bẹrẹ lori ọrọ naa ati pe gbogbo awọn oṣiṣẹ ti ọrọ naa kan lo ti gba aṣẹ lọ rọọkun nile ti wọn ko si ni gba owo oṣu.
Nítorí pé alufaa jẹ́ ẹni mímọ́ fún Ọlọrun rẹ̀, kò gbọdọ̀ gbé aṣẹ́wó ní iyawo, tabi obinrin tí ó ti di aláìmọ́, tabi obinrin tí ó ti kọ ọkọ rẹ̀ sílẹ̀.
Shaw sọ fun BBC pe oun ba Apidan naa sọrọ ko too bẹ sodo.
Amọ, iroyin fi lede wipe aarẹ Buhari ko ro ti ẹsun ti wọn fi kan an, ki o to o da akọwe ajọ naa pada s'ẹnu iṣẹ.
Yóo máa fi ẹ̀tàn bá àwọn orílẹ̀-èdè dá majẹmu.
" Ẹwẹ, agbẹnusọ ileeṣẹ ọlọpaa ipinlẹ Oyo, Olugbenga Fadeyi sọ pe oun ko ti gbọ nipa iṣẹlẹ naa nitori ọwọ oun kun fun iṣẹ igbaniwọle awọn ọlọpaa tuntun to n lọ lọwọ.
Lara awọn to n kopa ninu fiimu ọhun ni Mide Funmi Martins funra rẹ, Omotayo Amokade ti ọpọ mọ si Ijebu, atawọn oṣere n la mii lo kopa ninu ere ọhun.
 omo odún méjìdínlógójì ni murtala ramat muhammed nígbà tí àwon ológun fi je alákoso rópò gowon .
Sani ti wa paṣẹ pe ki wọn gbe ẹjọ naa re lọ si ọfiisi awọn ọtẹlẹmuyẹ.
Lonii, ẹgbẹ Amnesty International sọ wipe ninu osu kini ọdun 2018 nikan, ikọlu laarin awọn Fulani daran daran atawọn agbẹ ni ipinlẹ marun ti fa iku eniyan mejidinlọgọjọ.
Ogunlogo awon eniyan ni o wa ninu ihamo lati odun meerin eyi ti laasigbo ti bere lorile-ede naa.
Odunlade àti Femi Adebayọ: Wo ohun tó yà wá sọ́tọ̀ nínú àwọn arẹwà ọkùnrin Àfàìmọ̀ kí Naira Marley má fi ẹ̀wọ̀n bẹ̀rẹ̀ ọdún 2020 Idi ti EFCC ṣe mu Sheu Sani S'ahamọ.
àwọn eniyan lásán kan láàrin yín ń tan àwọn ará ìlú náà jẹ, wọ́n ń wí pé, ‘Ẹ jẹ́ kí á lọ bọ oriṣa.
Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí End SARS, End SWAT: MC Oluomo ní òun kọ́ ló rán àwọn jàǹdùkú sáwọn olùwọ́de l'Eko15 Ọ̀wàrà 2020 Fídíò, Wole Soyinka sọ ìdí tó fi ni òun a fi màálù Fulani ṣe súyà fáwọn èèyàn abúlé23 Owewe 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
won kiri  lati jẹ koriko bẹẹ ni awon agbe
Bẹẹ ni ọrọ ri fun gomina tẹlẹ nipinlẹ Ondo ijọun, tii tun ṣe agba oselu ati majẹobajẹ ilu, Bamidele Isola Olumilua to jade laye ni aarọ Ọjọru.
Ju gbogbo rẹ lọ, ko si nkan ti eeyan ko le foriji, sugbọn eyi ko tumọ si pe irinajo ifẹ naa yoo ri bo ṣe ri tẹlẹ."
 akin lọ gbowó ní bàǹkì .
N4,200 la fẹ́ fi pèsè oúnjẹ fún akẹ́kọ̀ọ́ kọ̀ọ̀kan láti ìdílé tó lé ní mílíọ̀nù mẹ́ta yíká Nàìjíríà - ìjọba àpapọ̀.
 O si gba ladura pe emi gbogbo won yoo se opolopo odun
Idí tí mo fi faramọ́ ìpinnu NEC- Oshiomole Yàtọ̀ sí coronavirus, wo ìgbà mẹ́wàá míì táwọn mùsùlùmí kò lè ṣiṣẹ́ Hajj Ẹbí Abiola Ajimobi kéde bí ètò ìsìnkú rẹ̀ yóò ṣe rí pé.
" Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Toyin Atoyebi mechanic: Ẹ wo Toyin, ọmọbinrin ọdún 16 tó ń tún skadà àti gẹnẹrátọ̀ ṣe ní Iyabo fikun pe awọn osisẹ asọbode tun fẹ gba owo lọwọ oun si lori awijare pe awọn ẹru to ba kọja ẹgbẹrun lọna aadọta naira, oun yoo sanwo itanran fun.
Kenneth Omeruo lo gba bọọlu kan ṣoṣo ti Naijiria fi bori sinu àwọ̀n nibi idije naa to waye ni papa iṣere Alexandria, nilu Alexandria.
Lẹ́yìn tí ó mu omi tán mo tún wa jókòó, ibi ti mo sì ti ń pète kì n béèrè bí mo ti ṣe déedée ríi ni ọ̀gànjọ́ òru ni òun náà bẹ̀rẹ̀ sí ọ̀rọ̀ í sọ ó ní:
Oríṣun àwòrán, TOBI JAMES Nigba ti oun ba awọn ọdọ naa sọrọ, gomina tẹlẹri naa ni awọn eniyan nilo lati ma a ni ero rere, ki ilọsiwaju to jọju le de ba aye awọn eniyan.
Gẹ́gẹ́ bí a ti sọ tẹ́lẹ̀, Yéwándé máa ń bá Orímóògùnjẹ́ mú owó nínú séèfù rẹ̀ ṣùgbọ́n ó tó oṣù kan sí ìgbà tí Orímóògùnjẹ́ tó kú tí ó ti rán an mú owó nínú rẹ̀ gbèyìn.
O salaye pe, “ni awon orile-ede mejeeji yii, iye osuwon ati alekun owo ti o n pa wole nipase ipolowo oja je okunfa awon ohun elo igbalode ti won n lo.
ó wí fún wọn pé, “Gbogbo ohun tí Mose, iranṣẹ OLUWA pa láṣẹ fun yín ni ẹ ti ṣe; ẹ sì ti ṣe gbogbo ohun tí èmi náà pa láṣẹ fun yín.
Mo fi ọ́ jọba lórí Israẹli ati Juda.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ sí: Nàìjíríà, Benin bẹ̀rẹ̀ ìgbésẹ̀ lórí reluwé, fàyàwọ́ ìrẹsì Ìpinu Gómìnà Ortom ya ni lẹ́nu - APC Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Fídíò òògùn ikọ́ Codeine: Àpọ̀jù rẹ̀ ń ya ọ̀dọ́ ní wèrè Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
O wa gba awọn eeyan nimọran lati fi owo pamọ daadaa lasiko Coronavirus yii, ki wọn ma si jẹ alajẹtan.
Tí a fiṣọwọ́ ní 14:45 11 Sẹ́rẹ́ 202114:45 11 Sẹ́rẹ́ 2021 Àfàìmọ̀ ká máa dá ìforúkọsílẹ NIN dúró tórí ewu coronavirus- Mamora O ni ewu kiko coronavirus wa ninu bi ọpọ eeyan ṣe n to si ibudo iforukọsilẹ kaadi kaakiri Naijiria.
Ibi tí ọdún Kérésì ti ń lọ ni kẹlẹlẹ.
Orilẹ-ede Egypt lo n gbalejo awọn orilẹ-ede mẹrinlelogun ti wọn jọ n koju ara wọn ki ẹnikan to gba ife ẹyẹ lọ.
Mario Mandzukic jere lara aṣiṣe Lloris layo ba di 4-2.
Wọn ni kii jẹ ki eniyan wuwo lalẹ to ba fẹ sun.
Etí rẹ̀ dàbí etí ife omi, ó tẹ̀ ní àtẹ̀sóde bí ìsàlẹ̀ òdòdó lílì.
Oríṣun àwòrán, AFP Àkọlé àwòrán, Omi sọ ọna marose ilu naa di odo.
Fiimu Elevator Baby si lo mu ko gba ami ẹyẹ naa.
Èmi àti ẹgbẹẹgbẹ̀rún ènìyàn tí a wá pàdé rẹ lọ́jọ́ náà.
Olùkọ́ fásitì gba ìdájọ́ iku 'torí pé ó sọ̀rọ̀ òdì sí Ànọ́bí lórí ayélujára
Lukes, to wa ni Molete lo lọ.
Emir Sanusi sọ pé òun yóò pe ẹjọ́ kòtẹ́milọ́rùn fún bí wọ́n ṣe lé e kúró nílùú Kano Awọn agbẹjọro Emir ilu Kano ti wọn ṣẹṣẹ rọ l'oye ti sọ pe awọn yoo pe ẹjọ kotẹmilọrun tako igbesẹ ijọba ipinlẹ Kano.
OLUWA tún sọ fún Hosia pé: “Sọ ọmọ náà ní ‘Kì í ṣe Eniyan Mi’, nítorí pé ẹ̀yin ọmọ Israẹli kì í ṣe eniyan mi, èmi náà kì í sì í ṣe Ọlọrun yín.
Tori oun ko dede de ipo ti o wa bayii.
“A ki i fi ọjọ́ kan bọ́ ọmọ tó rù”: Ìmọ̀ràn fún Òṣèlú tuntun àti àwọn ará ilú Nigeria
Oríṣun àwòrán, Olori Memunat Adeyemi Facebook Asa awọn olori Alaafin ni pe ki wọn maa ki ara wọn ku ayẹyẹ ọjọ ibi tara wọn tabi ti ọmọ wọn.
Ìpọ́njú tí mo rí ṣe mí ní anfaani,ó mú kí n kọ́ nípa ìlànà rẹ.
Awọn Iroyin mii ti ẹ le nifẹ sii Barrister ló sọ mí di èèyàn ńlá - Ayinla Kollington Ìtàn tó wà nídi òwe ‘Sebótimọ Ẹlẹ́wà Sàpọ́n’ Ilu Iwo ló yẹ kó kọ́kọ́ jẹ́ Sultan àkọ́kọ́ ní Nàìjíríà - Oluwo WAEC gbé èsì ìdánwò WASSCE jáde Etí ìjọba Buhari di sí ìmọ̀ràn àwọn ará ìlú -Jiti Ogunye Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Ẹ máa yẹ́ gbogbo eniyan sí.
Ni Kumba nibudo idibo kan, ẹgbẹrun lọna mẹtadinlogun eeyan lo fẹ dibo ṣugbọn bi wọn ṣe bẹrẹ si ni gbọ iro ibọn, wọn o tilẹ ri to eeyan igba rara lati dibo.
Awọn eto naa jẹ ọna lati mọ bi awọn ẹni tuntun naa ṣe ni igboya si.
Bakan naa lo yẹ ka maa bi ara wa leere pe ti mo ba lọ tan, ki ni aye yoo maa wi nipa temi?
Ọlọrun sì sọ ọ̀rọ̀ wọnyii, ó ní, 
” Abramu sì gba ọ̀rọ̀ Sarai aya rẹ̀.
Idi ree ti BBC Yoruba fi kan si ijọba Osun lati gbọ tẹnu wọn lori isẹlẹ ọhun nitori bawọn ọmọde ba n ge igi ninu igbo, awọn agba lo maa n mọ ibi ti igi naa yoo wo si.
Ni oṣu kẹta ọdun yii ni Gomina El-Rufai ti kọkọ lugbadi aarun naa.
Mo wi fún ọ̀rẹ́ mi wí pé: 
#EndSARS lu ayélujára pa lórí ikú Kolade Johnson ‘Ọ̀rọ ẹnu lásán ni wàhálà tí Nnamdi Kanu ní òun lè dásílẹ̀ ní Nàíjíríà’ Awakọ̀ òfúrufú Ethiopian Airlines pariwo 'lọ sókè!
 O tun so pe “lopo igba ni ija maa n waye laarin awon agbe ati adaran ni awon agbegbe aarin gbungbun lorile ede Naijiria bi i ipinle Edo, Ebonyi ati Kogi , ni eyi ti opolopo emi  ati dukia ti sofo nibe, ti awon kan si di alainile lori.
Ní apá ìhà àríwá, ààlà náà yípo lọ sí Hanatoni, ó sì pin sí àfonífojì Ifitaeli.
Ẹ óo jẹ àwọn nǹkan oko tí ẹ kó sí inú abà fún ọjọ́ pípẹ́, ẹ óo sì máa ru ìyókù wọn dànù kí ẹ lè rí ààyè kó tuntun sí.
Gbajugbaja pasitọ to jẹ Alamojuto agba fun ijọ RCCG lagbaye, Pasitọ Enoch Adeboye, Ọọni ile Ifẹ, Ọba Adeyẹye Ogunwusi pẹlu gbajugbaja oniṣowo to tun jẹ baba akọrin takasufe ni, Davido, Ọmọwe Deji Adeleke, obinrin to lowo ju nilẹ Afirika Iyaafin Fọlọrunhọ Alakija wa ninu awọn eekan ilu ti ijọba ipinlẹ Ọṣun ṣẹṣẹ ko jọ lati wa ọna ti wọn yoo fi ṣetọ arẹmọlẹkun fawọn eeyan ipinlẹ Ọṣun lasiko igbele coronavirus yii.
Amofin Olabiwonninu wa n beere pe, ka ni mẹkunu ni Abiola Ajimobi, n jẹ ijọba le gba ki wọn sin oku rẹ si GRA?"
5 58273 Orilẹede Iceland 27 8.
6, 7 ati 8 ti ajọ EFCC fi kan wọn nile ẹjọ lọjọ kejila, oṣu kẹrin, ọdun 2016.
Ikubese ni ko yẹ ki ijọba kede konileogbele nikan, o yẹ ko ṣe ipese awọn ohun amayedẹrun fun awọn ara ilu.
Marun-un ninu wọn jẹ́ òmùgọ̀, marun-un sì jẹ́ ọlọ́gbọ́n.
O wa gba awon eniyan nimoran lati yago fun ohunkohun to le sokunfa laasigbo naa leekan si.
O wi pe gomina Bello ko tii da awọn kọmiṣọna ati awọn alaga ibilẹ duro lẹnu iṣẹ, ati wi pe ẹni ti wọn ba da duro kọ ni wọn maa n pe pada s'ẹnu iṣẹ.
Ẹ ranti gbogbo ọ̀nà tí OLUWA Ọlọrun yín ti mú yín tọ̀ ninu aṣálẹ̀ fún ogoji ọdún yìí wá, láti tẹ orí yín ba; ó dán yín wò láti rí ọkàn yín, bóyá ẹ óo pa òfin rẹ̀ mọ́ tabi ẹ kò ní pa á mọ́.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Xenophobic Attack: Ìjọba rọ ọmọ Nàìjíríà pé kí wọ́n dẹ́kun kíkọlu iléeṣẹ́ South Africa 3 Owewe 2019 Oríṣun àwòrán, Twitter/@Julisco Okun kii ho ruru ka wa ruru!
Aaroni yóo máa ṣe ètùtù lórí àwọn ìwo rẹ̀ lẹ́ẹ̀kan lọ́dún.
8m), ni awọn afurasi naa sọ pe awọn naa owo ti wọn gba fun itusilẹ awọn ọmọ naa ku.
 Níbití erin méjì bá ti ń jà, koríko ibè kò ní gbé rí mó.
Ọ jókòó sí ọ̀hún ó ddà bí ọba láàárin àwọn ènìyàn, ìgbéraga wọ̀ ọ nínú ọkàn lọ òun sì bẹ̀rẹ̀ sí rò nínú ara rẹ̀ pé kò sí ẹni tí ó dàbí òun.
Oríṣun àwòrán, Twitter Àwọn akẹgbẹ́ ẹ̀ṣọ́ àjọ FRSC mẹ́ta tí àrá sán pa l'Ogun gbọdọ̀ ṣ'ètùtù- Elebuibọn Gómìnà márùn ún tó fojú winá ìbínú bàbá ìsàlẹ̀ wọ̀n Àwọn ohun tuntun tí a mọ̀ nípa ìgbẹ́jọ́ Wòlíì Sotitobire Ṣé lóòtọ́ ni Sẹ́netọ̀ Bayo Osinowo ní ìfura ikú ara rẹ̀?
ifá wo ẹwà inú àwọn obìnrin ni oríṣìírìṣí ọ ̀ nà aabo jẹ ìrànlọ ́ wọ ́ fún òrúnmìlà nigba to lalèjo mẹta iku , Àrùn àti Èsù .
"Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Bala Mohammed, Gòmínà Bauchi tó n jé ẹjọ́ lọ́wọ́ dèrò ilé ìwòsàn ní London Naira Marley ti tèṣù mọ́lẹ̀ nílé ẹjọ́ májísíréètì lórí ẹ̀sùn ìjọ́kọ̀gbé Abdularahaman, Ọmọ ọdún 17 kó sí páńpẹ́ EFCC lórí ẹ̀sùn yahoo-yahoo ní Ibadan Àwọn ọjọ́ ìsìnmi tó máa wà nínú ọdún 2020 ní Nàìjíríà Àtẹjáde náà ka bayìí pé "" ìwé òfin orílẹ̀-èdè Naijiria ti ọdun 1999 ti fi idí rẹ̀ múlẹ̀ pé, ọmọogun orilẹ̀, ọmọogun ojú omi, àti ọmọ omọogun ojú ofurufu, ọlọpàá àti àwọn to farapẹ́ nìkàn lo wà fún ètò ààbò Naijiria."
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Osinbajo gbarata lórí ìṣẹ̀lẹ̀ Lekki, ó ní ìdájọ́ òdodo yóò wà Ooni Ogunwusi àti Wole Soyinka kòrò ojú sí ìṣẹ̀lẹ̀ Lekki Tollgate Ọ̀rọ̀ Nàíjíríà kúrò ní sinimá àwòrẹ́rìn-ìn, Buhari gbé ìgbésẹ̀ bíi òbí àti olórí - Obasanjo gbarata Ilẹ̀ Amẹ́ríkà wà lẹ́yìn àwọn olùwọ́de, Buhari dẹ́kun ìpànìyàn - Joe Biden Mọ̀ nípa DJ Switch, akíkanjú obìrin sàfihàn fídíò ìpànìyàn Lekki bó ṣe ń wáyé Buhari, máṣe gbá ìpànìyàn Lekki sórí ààtàn, kò yẹ́ kí ológun yin ọ̀dọ́ níbọn - Bode George Ọ̀kan lára olùwọ́de tó fara gbọgbẹ́ ní Lekki jáde láyé - Sanwo-Olu Bakan naa lo ni iwa isekupani ọhun tun waye ni Alausa, tawọn osisẹ sọja ati ọlọpaa to pa wọn si gbe oku wọn pamọ, gẹgẹ bi wọn ti maa n se.
Rivers Governorship Election: Àwọn janduku àti ọmọ ilé ìṣẹ́ ológun ló wà nìdí ìdìbò tó dàrú
Ọmọkùnrin, ọmọ ọdún mọ́kànlá náà, nígbà tó ya àwórán ààrẹ náà láàrin wákàti méjì tó sì gbé e fún un ní Africa Shrine.
Awọn sẹnetọ PDP fẹ̀sùn kan APC pe wọn fẹ yọ Saraki l'óyè Awọn sẹnetọ kan ninu ẹgbẹ oṣelu alatako, PDP, ni gbogbo iṣẹlẹ to waye nile igbimọ aṣofin jẹ ọna lati mu ki awọn ọgbọn sẹnetọ to jẹ ti ẹgbẹ oṣelu APC yọ aarẹ ile asọfin agba.
''Ijiya to tọ la o fi jẹ ẹni to ba ni ọkọ yi gẹgẹ bi ofin ti ṣe laa kalẹ.
Amọ, awọn miran n gba awọn eniyan ni imọran lati ni igbagbọ ninu Aarẹ Buhari wi pe yoo ṣe ohun to tọ fun awọn ọmọ Naijiria.
][ Ó lọ sọ fún àwọn tí ó ti ń bá Jesu gbé níbi tí wọn ti ń ṣọ̀fọ̀, tí wọn ń sunkún.
Awọn eso bii ọgẹdẹ, carrot, ọsan, berries naa n ṣiṣẹ takuntakun lati jẹ ki atọ ọkunrin dara si.
Koda, o sọ pe ọwọ tẹ awọn ọkọ ileeṣẹ nla kan mẹfa, to yẹ ko ko ounjẹ, ṣugbọn wsn tun fi ko awọn eeyan lọna aitọ.
Ninu ifọrọwanilẹnuwo naa lo tun ti sọ pe, bi ere ṣise oun ati Odunlade Adekola ṣe jọ ara wọn jẹ iṣoro fun oun nigba ti oun ṣẹṣẹ bẹrẹ ere ṣiṣe.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìpàdé Buhari àti Trump: Ọ̀rọ̀ pọ̀ nínú ìwé kọ́bọ̀ 1 Èbibi 2018 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ìgbà àkọ́kọ́ nì yìí tí àwọn ààrẹ méjéèjì yóò máa pàdé Aarẹ orilẹede Naijiria, Muhammadu Buhari ti sepade papọ pẹlu Aarẹ Ilẹ Amerika , Donald Trump ni ile aarẹ ni Washington ( White House ) .
Bi kii ba ṣe ti ariwo ẹiyẹ rẹ yi to ta ji loju orun,o ṣeeṣe ki o jona mọ ile ti eeyan kankan ko si ni mọ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Minimum wage: Ẹgbẹ́ òṣìṣẹ́ àti ìjọba àpapọ̀ fẹnukò lórí àbá òfin ẹ̀kúnwó oṣù 8 Sẹ́rẹ́ 2019 Àkọlé àwòrán, Ọjọ́ kẹtàlélógún oṣù kíní ni ìjọba yóò gbé àbá òfin náà lọ síwájú ilé aṣòfin àpapọ̀.
"Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Afurasí afipábánilópọ̀ kàgbákò, obìnrin tó jà lólè fi eyín gé nǹkan ọkùnrin rẹ̀ jábọ́ lásìkò ‘Blow Job’ ""Ìyá mi sì wà ní páńpẹ́ ajínigbé, ọlọ́pàá, irọ́ lẹ̀ ń pa pé ó ti gba ìdáǹdè"" Iná ṣẹ́yọ nílé ìtajà aya Ajimobi lẹ́yìn ọjọ́ mẹ́ta tó jáde opó Ìjọba Eko fẹ́ tú olùwọ́de EndSARs 253 sílẹ̀ lọ́jọ́ Ajé nínú 361 tó wà láhàámọ́ ""Ìfẹ́ akọ sákọ àti abo sábo tó wọ́pọ̀ ní Àríwá Nàíjíríà ló fa ìbínú Ọlọ́run"" Ọ̀pá àṣẹ Ọba Akiolu tẹ gbé, a kò ní fọwọ́ yẹpẹrẹ mu - Ìgbìmọ̀ Ọba l‘Eko yarí Olori Badra sọ̀rọ̀ nípa ayé rẹ̀, ó ní ẹ́ bá òun sọkún Aarẹ Muhammadu Buhari si lo se atọna ipade ọhun lẹyin iwọde EndSARS ati rogbodiyan to tẹle, eyi to se okunfa ole jija, idaluru ati biba alaafia ilu jẹ, paapaa nilu Eko."
Kollington, Bàbá Suwe, Ogun Majek wà lára àwọn gbajúmọ̀ òṣèré tí ayé ti parọ́ ikú mọ́ sẹ́yìn Akọroyin wa jabọ pe nigba ti ẹgbọn rẹ naa dide kuro laarin awọn ti wọn jọ n kọ jita lo ba Grace nihoho ti ẹjẹ si bo o.
Ní ọjọ́ keji a gúnlẹ̀ ní Sidoni.
Ta ni aya akọkọ fun ọba Adeyemi: Abibat Nihinlola Oladele ni orukọ abisọ olori agba laafin Ọyọ lọwọlọwọ bayii, ọjọ kẹtalelogun osu Kejila ọdun 1938 si lo dele aye.
Nkan to yẹ ko o mọ nipa Baba Kunle Olasope: Ọmọ bibi ilu Ẹfọn Alaaye nipinlẹ Ekiti ni Kunle Ọlasọpe, ti orukọ baba rẹ si n jẹ Julius Ọlasọpe Ilu Ibadan, ni ipinlẹ Ọyọ ni wọn bi Olasope si ni Ọjọ Kẹjọ, Osu Karun un, ọdun 1937 ladugbo Oke Padi Olasope lọ si ile iwe alakọbẹrẹ Agbeni Methodist ni ilu Ibadan, ti o si wọle si ile iwe girama Igbobi, ni Yaba ni ilu Eko lọdun 1951 Bakan naa lo jẹ́ olori awọn akẹkọ nile ẹkọ girama naa, ko to kẹkọ jade Fun eto ẹkọ fasiti, Olasope lọ si ibudo ẹkọ irọlẹ tii se ẹka ileẹkọ fasiti Ile Ife to kalẹ silu Ibadan Nigba ti ẹrọ amọhunmaworan de si Naijiria lọdun 1959, Kunle Olasope pẹlu Anike Agbaje-Williams ati John Edyang ni wọn bẹrẹ ikede ni ile isẹ mohunmaworan WNTV, tii se akọkọ nilẹ Afirika Gẹgẹ bi ẹni akọkọ to ka Iwe lroyin lori ẹrọ amohunmaworan, Olasope kopa ninu bi ile isẹ iroyin naa se gbe afihan asa ilẹ wa, taa mọ si FESTAC 77 si ori afẹfẹ jakejado Naijiria Kunle Olasopegba ọpọ ami ẹyẹ, diẹ lara rẹ ni ami ẹyẹ Naijiria (MON) lọdun 2000, tijọba ipinlẹ Ekiti naa si fi ami ẹyẹ daa lọla lọdun 2004 Olasọpe, nigba aye rẹ ma n parọwa si awọn ọdọ lati jara mọ isẹ ti wọn n se, ki wọn si yago fun wiwa owo ojiji Nigba to jẹ pe ile ni abọ sinmi oko, Kunle Olasope ko lọ silu Ẹfọn Alaaye lẹyin to fẹyinti lẹnu isẹ, to si n kopa lọkan o jọkan si idagbasoke ilu naa Olasope ni iyawo, to si bi ọpọ ọmọ ki iku to pa oju rẹ de lẹni ọdun mejilelọgọrin ọdun.
Mo ti di àlejò lọ́dọ̀ àwọn arakunrin mi,mo sì di àjèjì lọ́dọ̀ àwọn ọmọ ìyá mi.
Ohun to ṣe koko ni pe, ẹnikẹ́ni to ba fẹ ẹ dokowo Bitcoin gbọdọ ni òye kíkún nipa rẹ, ko si ni ikiyesara.
Àwọn aginjù ńlá mìíràn ń bẹ lójú ọ̀nà, bẹ́ẹ̀ náà si ni àwọn odò tí ó tóbi gbogbo, tí wọ́n ń ṣàn tì wọ́n si ń pariwo ńlá bi wọ́n ti ń sọ̀kalẹ̀ lórí àpáta.
Bí n kò bá wá láti bá wọn sọ̀rọ̀, wọn kì bá tí ní ẹ̀ṣẹ̀.
OLUWA tún bá mi sọ̀rọ̀, ó ní: 
Bí o óo ti kan ọkọ̀ náà nìyí: kí gígùn rẹ̀ jẹ́ ọọdunrun (300) igbọnwọ, ìbú rẹ̀ yóo jẹ́ aadọta igbọnwọ, gíga rẹ̀ yóo jẹ́ ọgbọ̀n igbọnwọ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ibi gbogbo là n kádìyẹ alẹ,èkúté jẹ ìdì oògùn olóró lagọ ọlọpaa ni Kenya 16 Èrèlè 2018 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 12 Èbibi 2020 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Isẹlẹ yii n waye lẹyin ti ọkan lara awọn osisẹ ajọ to n se idanwo si ile ẹkọ giga fasiti ni Naijiria, JAMB ti kede faye gbọ pe ejo mi miliọnu mẹrindinlogoji Naira Awọn ọlọpaa kan lorilẹ-ede Kenya ti sọ fun ileẹjọ kan nilu Kwale wi pe awọn ẹru ofin to poora ni ibi ti wọn ko si ni agọ ọlọpaa wọn ko sa deede poora bikose awọn eku adugbo to ko wọn jẹ tan pata.
Nítorí náà, ẹ pe gbogbo àwọn wolii Baali ati àwọn tí ń bọ ọ́ ati àwọn alufaa rẹ̀ wá fún mi.
Nipost, tíí ṣe orogún wa, kò lẹ́tọ̀ọ́ láti díye lé wa - Iléeṣẹ́ abáni fi ẹrù ránṣẹ́ yarí Ọkan lara awọn onileesẹ abani fi ẹrun ransẹ ti salaye pe, bi igba ti wọn fẹ ẹ fi ara ni araalu, ni afikun owo fawọn onileesẹ naa.
Bí eniyan ti wù kí ó pẹ́ láyé tó, kí ó máa yọ̀ ní gbogbo ọjọ́ ayé rẹ̀, ṣugbọn kí ó ranti pé ọjọ́ tí òun yóo lò ninu ibojì yóo pọ̀ ju èyí tí òun yóo lò láyé lọ.
+ Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ọbasanjọ ti ṣe nnkan ìtùfù sẹyin lo ṣe n kíyèsí ẹninkule rẹ̀ Ẹní jẹ fufu lára n fu lọ̀rọ̀ Ọbasanjọ.
Wọ́n sọ ohun tí Ahitofeli ti gbèrò láti ṣe sí Dafidi.
Eniyan burúkú dìtẹ̀ mọ́ olódodo;ó sì ń wò ó bíi kíkú bíi yíyè.
O kò gbọdọ̀ fi ọmọ ìyá, tabi ọmọ baba iyawo rẹ ṣe aya níwọ̀n ìgbà tí aya rẹ tí í ṣe ẹ̀gbọ́n rẹ̀ bá wà láàyè.
De aago ọwọ lasiko idanwo, lati le mọ igba ati akoko ti o fẹ lo lori ibeere kọọkan lasiko idanwo naa.
Ẹ̀gàn ti mú kí inú mi bàjẹ́,tóbẹ́ẹ̀ tí ọkàn mi rẹ̀wẹ̀sìmò ń retí àánú ṣugbọn kò sí;mò ń retí olùtùnú, ṣugbọn n kò rí ẹnìkan.
Oríṣun àwòrán, @GovAyoFayose Àkọlé àwòrán, Ni ibẹrẹ ọdun 2018 ni Gomina Fayose ti ipinlẹ Ekiti se ipade pẹlu awọn ọdẹ ni ilu Ado Ekiti Bi wọn si ti se n salọ lawọn fulani naa mu Tunde, ti wọn si sa a yannayanna.
8 305693 Orilẹede Tunisia 3561 30.
si gbẹmi mi nile ẹjọ ,gege bi ile-ise akoroyin se sọ, lojo Aje.
Ó ní ọkọ̀ náà yóò máa gbéra láti pápákọ̀ òfurufú Muritala Muhammed Way sí Ozumba Mbadiwe láti ààgo méje owúrọ tit di ààgo mẹ́rin ìrọ̀lẹ́ Sùgbọ́n ìbéèrè ni pé, ènìyàn mélòó ni ètò yìí le ṣe ìrànwọ́ fún láàrin oṣù mẹ́fà ti ìjọba yóò fi ti pápákọ̀ òfurufu.
Ìpàdé ìjọba ati ASUU forí sánpọ́n ‘Ọ̀wọ́ngógó owó ilé ìwé ló jẹ́ kí àwọn akẹ́ẹ̀kọ́ máa fi fásitì sílẹ̀’ ''Owo ti wọn san yi, TETFUND lo n ṣe akoso rẹ wọn yoo si pin fun fasiti awọn ile ẹkọ poly ati ile ẹkọ awọn olukọni.
Nítorí ọjọ́ ń bọ̀ nígbà tí ẹ óo sọ pé, ‘Àwọn àgàn tí kò bímọ rí, tí wọn kò sì fún ọmọ lọ́mú rí ṣe oríire.
 Ó yẹ kí á fi kun un pé , ọpọ ́ n ìmọ ̀ ẹ ̀ rọ ti sún síwájú báyìí .
Gideoni ọmọ Joaṣi ṣaláìsí lẹ́yìn tí ó ti di arúgbó, wọ́n sin ín sinu ibojì Joaṣi, baba rẹ̀, ní Ofira àwọn ọmọ Abieseri.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Italy da ọ̀pọ̀ Aláboyún àt'àwọn arìnrìnàjò obinrin padà níbodè 11 Òkùdu 2018 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Mínísítà Italy fún ọ̀rọ̀ abẹ́lé, Matteo Salvini ni kò sí ààyè fún ìrìnàjò ti kò tọ́ ní Italy mọ Nàìjírìà ní orílẹ̀-èdè kẹ̀ta tó pòjù lọ tó ń kọjá lọ sórílẹ̀-èdè Libya lọna àìtọ́ lẹ́yìn Syria àti Afgan.
Ọrọ yi ka Lisa lara debi wi pe o kọ apilẹkọ kan lati fi da awọn to n tabuku r lohun.
Ekun  Ila oorun ,Iwo oorun– igbakeji alaga fun iwo oorun, igbakeji alaga , akapo , akowe agba fun amojuto igbaye-gbadun ,igbakeji akowe agba fun eto.
Gẹ́gẹ́ bí OLUWA ti pàṣẹ fún Mose, ni àwọn eniyan Israẹli ṣe gbogbo iṣẹ́ náà.
Ẹ má ṣe jẹ́ ọlọ́gbọ́n lójú ara yín.
Lọwọlọwọ bayii, awọn ipinlẹ bii Ogun, Oyo ati awọn apa kan Kwara ati Eko ti n koju ipenija omiyale, ti ọpọ dukia si ti ṣofo ninu rẹ.
Omisore ni oun mọ wipe wọn tun ti fi owo ra ibo awọn ara ilu ti wọn si lo ebi to n pa awọn eniyan lati ra ibo.
Ijoba ipinle Kano ti ro awon obi lati mu eto abere ajara lokunkun-dun fun awon omo won lojuna ati dena awon arun to n seku-pa omode ni isese bere aye won, papaa julo ki i awon omo ohun le ba ni ilera ti o peye.
Bawo wa ni eroja aka ohun silẹ yii yoo ṣe maa ṣiṣẹ?
 “Ko si enikankan ti o ku nibi ikọlu naa , ayafi awon olote nikan , ti won gbọna ẹburu lati wa se ijamba sinu ilu naa sugbon ti ipinnu won ja si asan.
Ipinlẹ Anambra naa ko gbẹyin:Ọjọ kọkanla, oṣu Kẹrin, ni ipinlẹ naa kede ẹni akọkọ to ni aarun coronavirus ni ipinlẹ naa.
" Owó Naira yóò sì tún padà níyì láwùjọ àwọn owó orílẹ̀-èdè tó gbé pẹ́ẹ́lí jùlọ lágbàáyé- Adeboye Igbo Olodumare rèé, níbi tí Ìgbín ti tóbi ju Ìjàpá lọ Àwọn jàndùkú agbébọn''jí àwọn akẹ́kọ̀ọ́ lọ nílé ìwé girama Katsina'' lẹ́yìn tí Buhari gúnlẹ̀ sí bẹ̀ Kí gan ló pa Dapo Ojora, ẹ̀gbọ́n ìyàwó Bukola Saraki l'Eko?
bí ó ti sọ ninu Ìwé Hosia pé, “Èmi yóo pe àwọn tí kì í ṣe eniyan mi ní ‘Eniyan mi.
Nítorí náà, ẹ mọ̀ ninu ara yín pé, gẹ́gẹ́ bí baba ti máa ń bá ọmọ rẹ̀ wí ni OLUWA ń ba yín wí.
Cotonou Museum: Àṣà àti ìṣẹ̀ṣe Yorùbá di àpéwò ní Porto-Novo
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Yoruba Films: Adewale Elesho ní àìkàwé ló ṣàkóbá fún òun nínú iṣẹ́ tíátà 23 Òkùdu 2020 Oríṣun àwòrán, Instagram/officialyemielesho Gudugbẹ ja ninu ifọrọwẹro BBC Yoruba pẹlu gbajumọ oṣere tiata, Adewale Adeoye Elesho ati ọmọ rẹ, Yemi Elesho.
Ọ̀run ati ayé yóo kọjá lọ ṣugbọn ọ̀rọ̀ mi kò ní kọjá lọ.
Lẹ́yìn ìpolongo ìdìbò ẹgbẹ́ APC, ààrẹ gbóríyìn fún olùdíje ẹgbẹ́ òṣèlú APC àtàwọn alátìlẹ́yìn ẹgbẹ́ fún iṣẹ́ takun takun tí wọ́n ṣe láti ja àjàyè.
Lati ipinle Enugu, ipolongo lilo ero igbalode ohun yoo koja lo si ipinle Osun, bee ni a o maa tewiwaju jake-jado orile-ede Naijiria”.
Àwọn tí wọ́n pa ninu wọ́n tó ọgbọ̀n eniyan.
Ọwọ wa ni ọna abayọ wa, iṣẹ gbogbo wa si ni, gbogbo wa si la gbọdọ ko ipa tiwa si ọna lati dẹkun ajakalẹ arun naa."
Wo àwọn ojúṣe àti èèwọ̀ fún ikọ̀ ọlọ́pàá SWAT tó gba iṣẹ́ lọ́wọ́ SARS Ìyá gómìnà Seyi Makinde dágbére fáyé lẹ́ni ọdún 81 Àjọ elétò ìdìbò kéde ọjọ́ tí ìdìbò aàrẹ Nàìjíríà 2023 yóò wáyé Ìjọba kéde ọjọ́ ìwọlé àwọn àgùnbánirọ̀ sí ìpàgọ́ lẹ́yìn Covid 19- Sunday Dare Toyin Abraham tú àṣírí ohun tí ọlọ́pàá Náìjíríà sọ mọ́lẹ́bí rẹ̀ kan dà Ninu ọrọ tiẹ, Razak Ọlayiwọla, ti gbogbo eeyan mọ si Ojopagogo kede pe, Ajẹ pọnbele ati Aṣẹwo haun-haun ni Iya Rainbow.
Ìwé Àṣírí Amòòkùnṣìkà Tú ní Sókí
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Covid 19 Palliative: Mínísítà dèrò àgọ́ ọlọ́pàá nítorí ẹ̀sùn kíkó owó ìrànwọ́ Covid-19 sápò 16 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Oríṣun àwòrán, NCDC/Twitter Mínísítà dèrò àtìmọ́lé lẹ́yìn tí wọ́n fẹ̀sùn kàn án pé ó lu owó ìrànwọ́ Covid-19 ní pónpó.
Oríṣun àwòrán, Reuters Ọlọpaa tẹlẹri naa, Derek Chauvin to jẹ alawọ fun fun lo fi erunkun fun ọrun George Floyd to jẹ ọkunrin adunlawọ.
OLUWA fi èyí hàn yín, kí ẹ lè mọ̀ pé òun ni Ọlọrun, ati pé kò sí Ọlọrun mìíràn àfi òun nìkan.
Oríṣun àwòrán, @others Àkọlé àwòrán, Nọ́mbà 3: Ilekile ti a ba ti ri amohunmaworan yii laye igbaa ni, a jẹ pe wọn ṣẹsọ owo nibẹ ni ti wọn ri jájẹ daadaa lagboole nigba naa Oríṣun àwòrán, @others Àkọlé àwòrán, Nọ́mbà 4: Amohunmaworan yii jẹ eyi ti ẹ ko le ji tàn laarin oru nitori pe yiyi rẹ yoo dun de ibi pe Baba eeyan yoo gbọ ninu iyara ni eyi to ṣeeṣẹ ki eeyan jẹ igba ti si laarin oru pe o ṣe fọwọ kan an Oríṣun àwòrán, @others Àkọlé àwòrán, Nọ́mbà 5: Awọn kan tun da ajọ ki wọn to ri owo ra amohumaworan oniwo meji ṣaaraṣaara yii lọdun naa lọhun!
Eyi si ti mu ki ọpọlọpọ ọmọ Naijiria maa beere nipa iru ibaṣepọ to wa laarin tọkọ-taya ọhun, tabi iru ọkọ ti Aarẹ Buhari jẹ ninu ile.
Yemi Osinbajo Agbẹjọro ati ajafẹtọ ọmọniyan, Olukayode Ajulo ti sọ wi pe Igbakeji Aarẹ orilẹede Naijiria ko lasẹ labẹ ofin Naijiria lati yọ ofin amuniti (imunity) rẹ kuro nitori o fẹ se ẹjọ.
Nítorí náà, OLUWA fi àwọn orílẹ̀-èdè náà sílẹ̀ ninu ilẹ̀ náà, kò tètè lé wọn jáde bí kò ti fún Joṣua lágbára láti ṣẹgun wọn.
AFCON 2019: Àmì ayò tí Nàíjíríà àti South Afrika gbá rèé
Iko ti o n ri si oro eko awon omode ninu ajo isokan orile-ede agbaye UNCEF so pe,  aabo to peye gbodo wa fun awon akekoo ati awon ile-eko kaakiri orile-ede Naijiria.
Ó gbé ẹbọ ohun jíjẹ wá, ó bu ẹ̀kúnwọ́ kan ninu rẹ̀, ó sì sun ún lórí pẹpẹ ní ẹ̀gbẹ́ ẹbọ sísun ti òwúrọ̀.
Ṣugbọn ẹnikẹ́ni tí ó bá sẹ́ mi níwájú eniyan, èmi náà yóo sẹ́ ẹ níwájú Baba mi tí ń bẹ lọ́run.
O ni ijọba ti pa aṣẹ fun gbogbo awọn ileeṣẹ ọ̀kọ̀ ofurufu ki wọn ma jẹ ki ẹnikẹni ti ko ba ni awọn iwe yii rinrinajo pẹlu wọn.
Ahasaya ọmọ rẹ̀ sì jọba lẹ́yìn rẹ̀.
Bi iye awọn to ni ni awọn ipinlẹ to ku ṣe lọ ni yii; Eko-188 FCT-44 Ogun-19 Kaduna-14 Oyo-12 Bayelsa-9 Gombe-5 Kano-3 Delta-3 Imo-2 Rivers-2 Niger-2 Bauchi-2 Plateau-1 Kwara-1 Ọjọ́ Satide ni ìgbà àkọ́kọ́ tí ènìyan 553 yóò kó àrùn Coronavirus léékan naa ní Naijiria Ajọ NCDC ti kede eniyan 553 gẹgẹ bi apapọ eniyan to ni arun Coronavirus lorilẹede Naijiria ni Ọjọ Satide lorilẹede Naijiria.
Amọ, o ni ohun to ṣe ni laanu ni wi pe, ijọba lo ma n pe eniyan lẹjọ to ba ru ofin to de lilo ilẹ ijọba.
Ẹrù ìyà ni Norway dì lé Super Falcons lórí ní 2019 Women's World Cup Beckham, àgbábọ́ọ́lù tẹ́lẹ̀ rèé tó ń sọ èdè Yorùbá Ọba Adesoji Aderemi, Ọọ̀ni Ifẹ̀ tó gba ipò ọba mọ́ tòṣèlú Háà!
Echono wa so pe igbese ti aare ni ki won gbe yii , yoo je ohun kan pataki ti won yoo jiroro le lori ,nibi ipade igbimo to n ri si eto ẹkọ ti yoo waye niluu Abuja lose yii.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Toun ti pe ofin tuntun ni ki wọn mase san owo fawọn to di ipo miran mu lẹyin ti wọn fi ipo Gomina tabi igbakeji silẹ, wọn ko wọgile sisan owo yii bi ipinlẹ Zamfara ti ṣe ṣe.
OLUWA fún mi ní ọmọ pupọ, ṣugbọn ninu gbogbo wọn, ó yan Solomoni láti jọba lórí ìtẹ́ ìjọba rẹ̀ lórí Israẹli.
Ọwọ́ òfin ti tẹ ọ̀pọ̀ ọmọ Nàìjíríà lórí ẹ̀sùn jìbìtì l'Amẹrika- FBI Ohun mẹ́fà tí kò yẹ́ kí o gbàgbé nípa Gómìnà Ambode Ẹgbẹ́ Ilẹ̀ Yorubà gba Aṣíwájú tuntun!
Oríṣun àwòrán, oTHER Àkọlé àwòrán, Ikọlu Shiite Iroyin tilẹ sọ pe ọga ọlọpaa kan naa tẹri gbaṣọ nibi iṣẹlẹ ọhun ṣugbọn ile isẹ ọlọpaa ko tii fidii ọrọ naa mulẹ.
Ọlọ́pàá fi páńpẹ́ ọba mú ọmọ ogun ilẹ̀ Naijiria Iléeṣẹ́ ọmọ ogun dá Bashir tó ri owó he lọ́lá Ọmọ Yorùbá tó bá ti rú òfin, ẹ gbé e jàntò - Oluwo Ọlọ́pàá Kwara ti rí ọmọ orílẹ̀-èdè Turkey mẹ́rin gbà padà lọ́wọ́ ajínigbé!
Já mi gbà kúrò lẹ́nu kinniun nnìgbà mí kúrò lọ́wọ́ ìwo ẹhànnà mààlúù!
Aare so pe, iwa ipaniyan to waye lojo Eti ,ni ijoba ibile Kajuru ni
Oludari ile iwosan naa, dokita Suleiman Ahmed fi idunnu re han bi won se yọju si awon alaisan naa, o ni ki i se ebun nikan ni o maa n mu  awon  alaisan san,bi ki i se ife ti awon eniyna n fihan si won.
Ìjọ tí Ọlọrun yàn, ẹlẹgbẹ́ yín tí ó wà ní Babiloni ki yín.
Ṣùgbọ́n nígbà tí ènìyàn wo wọ́n bí ọ̀kẹ́ àìmọye, ti ìbọn kò ṣe é fi pa wọ́n, ti ó sá jẹ́ pá wọ́n ń ge ni lẹ́sẹ̀ jẹ ni, ìbà díẹ̀ ni a lè ṣe.
 Ó jẹ ́ oníṣòẁò , òǹtẹ ̀ wé , olóṣèlú àti olóyè ilẹ ̀ yorùbá Ẹ ̀ gbá pàtàpátá .
Ẹ̀yà ẹranko kan kò jẹ́ rí àwa ọmọ ènìyàn fín, àyàfi tó bá ń wa àbùkù òun ìparun.
        Nínú ìwé rẹ tí o kọ gbẹ̀yìn, mo rí i pé o tún sọ̀rọ̀ kan ti wí pé kí ó le ṣeéṣe kí a jọ máa gbé pọ̀ níjọ́ mìíràn.
Nítorí náà ni okùn dídẹ fi yí ọ ká,tí jìnnìjìnnì sì bò ọ́ lójijì.
Lẹ́yìn náà ni alufaa tí a fi òróró yàn yóo mú ninu ẹ̀jẹ̀ akọ mààlúù yìí wá sinu Àgọ́ Àjọ.
Lara isẹ tuntun ti wọn gbe le Tinubu lọwọ yii, ni pipẹtu si aawọ laarin awọn ọmọ ẹgbẹ oselu naa, ati laarin awọn asiwaju ẹgbẹ pẹlu awọn to di ipo oselu mu nibẹ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Mamman Daura: Ojú òpó ayélujára ń gbóná lórí ìlàkàkà ọmọ Nàíjíríà láti mọ́ ipò tí ìlera rẹ̀ wà 20 Ògún 2020 Oríṣun àwòrán, Others Lowurọ ọjọbọ ni oju opo Twitter n gbona fẹlifẹli pklu ibeere awọn ọmọ ilẹ yii pe, ki ileesẹ aarẹ se alaye lori irinsi Daura.
Bauchi State: Okú 596 ló ṣì ń gba owó oṣù Irú kí lèyì!
5m owó oúnjẹ El-Zakzaky lè bọ́ ẹlẹ́wọ̀n 208 ní oṣù kan Àjọ NEMA fèsì ẹ̀sùn táwọn aṣòfin fi kan Ọṣinbajo Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fọ́nrán ohùn, ''Oúnjẹ òkèlè àti òróró le fa ẹ̀jẹ̀ rúru àti àrùn rọpárọsẹ̀'' O ni gomina Akeredolu lo ko awọn agbofinro fun olori ile ti wọn yọ, Bamidele Ọlẹyẹlogun lati pada lọ ṣi ijoko ile lẹyin ti wọn ti yọọ.
Ninu ifọrọwerọ rẹ pẹlu wa, Baba Ọlọsun ni ere Ọsun ti wọn n bọ loni kere pupọ si eyi ti wọn bọ ni ọdun to kọja, to si dabi agolo bọnfita.
Fun igba akọkọ, ko si akọsilẹ ija, wahala, iwa ipa, ibo yiyi idunkooko mọni, jiji apoti ibo gbe, rogbodiyan ati laasigbo rara lasiko eto ibo ọjọ Kejila osu Kẹfa ọdun 1993, eyi to yatọ si ohun to n sẹlẹ lasiko taa wa yii Igba akọkọ ree tawọn ọmọ Naijiria yoo dibo, ti wọn ko ni kede ẹni to wọle bii aarẹ ninu eto idibo naa Eto ibo ọjọ Kejila osu Kẹfa ọdun 1993 lo sọ Oloye MKO Abisla di akọni ijọba awa ara wa, ti orukọ rẹ si di manigbagbe ninu eto oselu lorilẹede Naijiria.
Ni ọdun 1999 ni wọn fi ṣe olori ikọ alaabo fun gomina ipinlẹ Eko nigba naa, Aṣiwaju Bọla Ahmed Tinubu.
tí ó sì wí pé, ‘Ìdí nìyí tí ọkunrin yóo fi fi baba ati ìyá rẹ́ sílẹ̀ tí yóo fara mọ́ iyawo rẹ̀.
Oríṣun àwòrán, @Haramain NAPTIP gba ọmọbìnrin mẹ́tàlá láhàmọ́ọ́ A ti mọ òbí 40 nínú 108 t'ọ́mọ wọn bọ́ ní ayédèrú ibùdó atúnwàṣe Ilorin - Ọlọ́pàá Kwara Ọlọ́pàá Eko ní kí olùkọ́ UNILAG Boniface wá sọ tẹnu rẹ̀ lórí ẹ̀sùn ìfipábánilòpọ̀ Ṣé irúfẹ́ oúnjẹ tí ò ń jẹ́ lè jẹ́ kí o gbádùn ìbálòpọ̀ rẹ síi?
O la ayé kọjá pẹlu ibinu,o sì fi ibinu tẹ àwọn orílẹ̀-èdè mọ́lẹ̀.
Nígbà tí Dafidi pada sí ibùdó lẹ́yìn tí ó ti pa Goliati, Abineri mú un lọ siwaju Saulu, pẹlu orí Goliati ní ọwọ́ rẹ̀.
Nítorí ìwé tí Modekai kọ ati gbogbo ohun tí ó ṣẹlẹ̀ sí wọn, 
ó ní òun ń kìlọ̀ fun yín pé kí ẹ má jẹ́ kí Hesekaya tàn yín jẹ, kò lè gbà yín sílẹ̀.
Oríṣun àwòrán, Elizabeth Oyeniyi O sọ pe wọn ko ti i yanju ọrọ naa, nitori pe ọpọ eeyan to jẹ gbajumọ nilu ni orukọ wọn ti jẹyọ ninu ẹsun naa.
Ìdánilẹ́kọ̀ọ́ ṣe kókó fún àjọ ọlọ́pàá àti oníṣègùn nítorí àwọn ni kì í mú ayé rọrùn fún Abódiakọ-akọ́diabo ènìyàn tí ó bá ra ọwọ́ ẹ̀bẹ̀ tàbí nílò ìrànlọ́wọ́ ètò ìlera.
22 Nitorí wọn kò tíi lè gba ẹran báyìí, ṣùgbọ́n wàrà ni wọ́n gbọdọ̀ gbà; nítorí-èyí, wọn kò gbọdọ̀ mọ àwọn ohun wọnyìí, bí bẹ́ẹ̀ kọ́ wọ́n yío ṣègbé.
Irinajo ti gbérasọ padà ní pápákọ̀ òfurufú ìpínlẹ̀ Imo lẹ́yìn ìjàmbá iná Beckham, àgbábọ́ọ́lù tẹ́lẹ̀ rèé tó ń sọ èdè Yorùbá Àwọn adigunjalè pa èèyàn mẹ́fà ní báńkì kan nìpínlẹ̀ Ondo Iròyìn NAN fi yẹ ni pé, ẹsẹ̀ kò gbà àgọ ìwọ̀kọ ojú ìrìn tó n rin Abuja si Kaduna mọ, nítori iwa ìjínigbé tó ń wáye lopopona Kaduna si Abuja lójoojúmọ.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Bale ni yóò rọ́pò Ronaldo nínú Super Cup Awọn ọmọ ìjọ sàtánì ń bínú sí Nàìjíríà 'Adeleke ṣì ni olùdíje PDP fún ipò gómìnà Ọ̀ṣun' Tinubu ni 'ki awọn to n gbimọ ika jawọ, nitori pe 'ko ni ṣeeṣe fun alangba lati ba ẹtu ja.
Ó ti fi àwọn eniyan pamọ́ sinu yàrá inú.
Chief Samuel Sambo - Ọmọ ẹgbẹ́ 5.
Omobakunrin Henrik doloogbe ni aafin Fredensborg lojo ketala osu keji odun 2018 gege bi Reuters se so.
Ilana ohun ni ireti wa pe, yoo gba osu meji gbako, won se agbekale ilana ohun nibi ipade awon omo egbe naa ninu osu odun ti a wa yii ni ipinle Kaduna, ti o wa ni apa ariwa orile-ede Naijiria.
Yóo mú ninu ẹ̀jẹ̀ tí ó kù, yóo fi sára àwọn ìwo pẹpẹ tí ó wà níwájú OLUWA ninu Àgọ́ Àjọ, yóo sì da ẹ̀jẹ̀ yòókù sílẹ̀ ní ìdí pẹpẹ ẹbọ sísun tí ó wà ní ẹnu ọ̀nà Àgọ́ Àjọ.
"Toyin Abraham kìí bá èmi náà yọ̀, ni kò jẹ́ kí ń gbé e lárugẹ fún ayọ̀ ọmọ - Lizzy Anjorin Ìlú ò rẹ́rìn ín rárá, Alaafin Adeyemi III fárígá fún Buhari nínú lẹ́tà tuntun Èyí ni àwọn arẹwà ‘ẹ̀lẹ̀ Daddy’, àfẹ́fẹ́ tí Aláàfin fi ń mí N kò mọ bí wọ́n ṣe n bá obìnrin sọ̀rọ̀ ìfẹ́ - Aláàfin ""Wọn sọ fun mi pe baba mi Alaafin n bọ lọna lati wa ki mi, ti wọn si ni Alaafin ni oun ko ni kuro nilu Eko lai fi oju kan emi ati ọkọ mi."
Yinka Ayefẹlẹ, loju opo Instagram rẹ ti salaye pe ofo, ọjọ keji ọja ni iroyin kan to n ja rain-rain nilẹ pe iyawo oun bi ibẹta ni orilẹede Amẹrika ni owurọ ọjobọ.
Jesu ń káàkiri gbogbo àwọn abúlé tí ó wà yíká, ó ń kọ́ àwọn eniyan.
Ọkunrin yìí bá dìde ní òwúrọ̀ ọjọ́ keji, nígbà tí ó ṣílẹ̀kùn ilé náà tí ó sì jáde pé kí òun máa lọ, òkú obinrin rẹ̀ ni ó rí, tí ó nà sílẹ̀ gbalaja lẹ́nu ọ̀nà, lẹ́bàá ìlẹ̀kùn, pẹlu ọwọ́ tí ó nà tí ó fẹ́ ṣílẹ̀kùn.
Ta ni ninu yín, tí ọmọ rẹ̀ bá bèèrè àkàrà, tí ó jẹ́ fún un ní òkúta?
Coronavirus: Ọṣẹ́ wo ni Coronavirus ń ṣe ní àgọ́ ara?
Osuolale ṣe gùdù gùdù meje àti ya ya mẹ́fà nídìí isẹ agbẹjọro ni Nàìjíríà, tí òkìkí rẹ sì kan yíká ilẹ̀ yìí àti lókè òkun, a kò sì lè e gbàgbé inagijẹ Mr two third tí wọn ń pé olóògbé náà.
Ko tii si opin si ariyanjuyan yii lẹyin tawọn mejeeji ti tayọ ju awọn akẹgbẹ wọn lagbaaye lọ fun bi ọdun mẹwaa sẹyin bayii.
Mohamed Salah  darapo mo iko agbaboolu Liverpool lati AS Roma ni saa ti o lo.
Awa yoo duro si orile ede yii lati satunse si i.
Awọn akọsẹmọṣẹ waa lagbegbe kọọkanso pe awọn ka obinrin mẹtadinlaadọta ti iku wọn waye nitori pe wọn jẹ obinrin ni orileede mọkanlelogun kaakiri agbaye.
ti ẹkun idibo Ẹpẹ kinni ni esi ibo ẹgbẹrun mọkandinlogun-le-mejidinlọgbọn
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: 'Báyìí la ṣe rìn ín láti pápákọ̀ òfurufú Abuja sí Eko bí ìrìnà òfurufú abẹ́lé ṣe bẹ̀rẹ̀' Wọ́n fi ikú Tunde Braimoh dá wa lóró ni o - Ẹbí pariwo Ẹ̀yin ọmọ ìta tó ní Funke Akindele ra ilé fún mi, irọ́ ni o - Ajirebi Ìtàn ayé Henry Fajemirokun, olówó tó fi owó mọ Olúwa àti ènìyàn Báwo ni Coronavirus ṣe n tànkálẹ̀ l'Afrika?
’ Sowore takú, kò jẹun ní àgọ́ ọlọ́pàá torí májèlé - Deji Adeyanju Lórí ìmọ̀ràn Sunday Igboho, Ẹlẹbubọn ní yóò dára kí Yorùbá padà sí àmúlò èròjà ìbílẹ̀ fún ààbò Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Sunday Igboho: Fulani kò leè dúró, táa bá lo ohun ta jogún lọ́dọ̀ àwọ̀n bàbá wa Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Oro Festival: Àwọn olórò ní ọdún Màgbó ló ń gba ibi lọ, kó ire wọlé ní Ikorodu Nibi ti wọn ti n yinbọn ọhun lọta ibọn ti ba alaboyun kan to si paa.
Ebi ló pa mí ní ìrọ̀lẹ́ òní tó mún mi ya ilé oúnjẹ olókìkí nì tí wọ́n ń pè ní KFC.
Kí á máa dúró de ibukun tí à ń retí, ati ìfarahàn ògo Ọlọrun ẹni ńlá, ati ti Olùgbàlà wa Jesu Kristi, 
Ṣùgbọ́n lásìkò àjàkálẹ̀ ààrùn Coronavirus yìí, ọ̀pọ̀ aboyún ni ẹ̀rù ń bà.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù June 12: Buhari fi orúkọ Abiola sọ pápá ìṣeré l'Abuja 12 Òkùdu 2019 Aarẹ Muhammadu Buhari kede pe papa iṣere ijọba apapọ to wa l'Abuja yoo maa jẹ Moshood Olawale Abiola Stadium bayii.
Orí irin ni ọpọ wá máa ń wà ní àìmọye ìgbà àmọ́ lasiko yìí, Ọlọ́run pá ìsinmi wá pọ, tá sì ń lo asiko yii lati se nkan míì, a kò sì fi ṣòfò rárá.
Gbajugbaja oṣere Yoruba naa ni ọlọpọ pipe ni Laycom, eyi lo jẹ ki oun maa dibo fun un.
Balaki wí fún un pé, “Kí ló dé tí o kò fi wá nígbà tí mo ranṣẹ sí ọ lákọ̀ọ́kọ́?
Alliance (DA) si n tẹle won, ti egbe oselu leftist Economic Freedom Fighters
Nítorí gbogbo nǹkan tí ó wà ninu ayé: ìfẹ́kúfẹ̀ẹ́ ara, ìwòkúwò ojú ati afẹfẹyẹ̀yẹ̀ ayé kò wá láti ọ̀dọ̀ Baba bíkòṣe láti inú ayé.
“lasiko to je alaga akoko  fun ajo to n ri si sise owo ilu kumo-kumo , o fi ipa rere  sile fun ajo naa, opolopo awon oniwa ibaje lo gbe lo sile ejo.
Amọ, ijinigbe ọlọgọọrọ yii safihan alaye miran.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Hospital Wedding: Oṣù kan péré ni Tash fi ṣe ìgbéyàwó pẹ̀lú Simon kó tó kú O fikun pe oun yoo maa fa omi tabi pọn omi gẹgẹ bi oun ti n se tẹlẹ, ti oun yoo si maa rọ omi sinu ike ti wọn n gbe sinu ẹrọ amomitutu.
Wéré èmi náà dìde lórí àpáta mo bá ilé lọ.
Idi ni pe o le ni eeyan ẹgbẹrun lọna mẹtadinlaadọta to yọju lọjọru, nibi eto igbanisisẹ fun ikọ alaabo Amotekun to bẹrẹ.
Àwọn ọmọ Diṣoni ni Hemdani, Eṣibani, Itirani, ati Kerani.
Bi ọkọ tó ń sáré ṣe bá ara rẹ lórí àjà ilé onílé kàn rèé
Àwọn ẹni ibi dòòyì ká olódodo, wọ́n sì ń yí ìdájọ́ òdodo po.
Lojoojumọ, fún ọjọ́ meje, ẹ óo máa mú ewúrẹ́ kọ̀ọ̀kan ati akọ mààlúù kọ̀ọ̀kan ati àgbò kọ̀ọ̀kan tí kò ní àbààwọ́n láti inú agbo ẹran, ẹ óo máa fi rú ẹbọ ìmúkúrò ẹ̀ṣẹ̀.
“Èmi OLUWA fi ara mi búra pé, ní ilẹ̀ Babiloni, ní ilẹ̀ ọba tí ó fi í sórí oyè ọba tí kò náání, tí ó sì da majẹmu rẹ̀, níbẹ̀ ni yóo kú sí.
Ọba alágbára, ìwọ tí o fẹ́ràn òdodo,o ti fi ìdí ẹ̀tọ́ múlẹ̀;o ti dá ẹjọ́ ẹ̀tọ́ ati òdodo ní ilẹ̀ Jakọbu.
LASU Murder: Àwọn ẹbí ní ìwádìí ọlọ́pàá ṣì ń tẹ̀síwájú ni wọn kò ṣe rí òkú gbà
Dokita Tarivonda ni ''ohun ti wọn sọ nipe awọn ko fẹ ko aarun nitori awọn ko pọ tẹlẹ lorilẹede naa, bi bẹẹ kọọ, gbogbo eeyan le ku tan patapata.
Igbaniṣiṣẹ awọn kọnsitebu ti ile iṣẹ ọlọpaa yoo kede rẹ laipẹ niroyin sọ pe ijọba apapọ gan an fọwọ si.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, #Queen Dihya: Obinrin tó gbógun tàwọn agbésùnmọ̀mí ni Algeria Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Ijọba apapọ Naijiria ni lootọ ni awọn gbọ nipa fọnran kan to niṣe pẹlu akẹkọbinrin Dapchi to ku si ahamọ ikọ Boko Haram, Leah Sharibu.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ọbasanjọ yòǹbó Atiku, ó ní kò ní já Nàíjíríà kulẹ̀ Saraki pè fún ìwádìí ikú olórí ikọ̀ adigunjalè tó ṣọsẹ́ ní Offa 'Èrè tó tọ́ ni Jonathan, Ọbasanjọ jẹ lórí iṣẹ́ ọpọlọ jíjí' SERAP ní kí Buhari gbé Dasuki, Jonathan lọ síwaju kóòtù àgbáyé Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Adedoyin: Tí mo bá rí Buhari, màá sọ fun kó rántí pé Ọlọ́run wà Lori iwe ti ẹgbẹ PDP kọ si ajọ iṣọkan agbaye pe, ijọba amunisin nijọba Buhari to wa lode, Oshiomole ni ko si ohun to jọ bẹẹ.
Akor, ẹni ọdun mejilelogoji lati ilu Enabo nijoba ibilẹ Ankpa, ipinlẹ Kogi ati alajumọkẹgbẹpọ rẹ David Ameh lọ n bẹbẹ bẹẹ lẹyin ti awọn ajọ NDLEA ipinlẹ Kogi mu wọn.
Ọmọ Naijiiria ni mí, ọ̀rọ APC kò lésì -Atiku 'Ilé iṣẹ́ DSS kò mú òṣìṣẹ́ INEC kankan lórí ọ̀rọ̀ Atiku' Bo tilẹ jẹ pe igbimọ naa ti ni ko si ootọ kankan ninu wi pe Bulkachuwa n ṣ'egbe lẹyin APC nitori awọn ẹbi rẹ, o ni oun yọ ara oun ninu igbimọ ẹlẹni marun un naa fun idi ti oun ko ni sọ.
Joṣua bá yipada, ó gba ìlú Hasori, ó sì fi idà pa ọba wọn, nítorí pé Hasori ni olú-ìlú ìjọba ilẹ̀ náà tẹ́lẹ̀ rí.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ned Nwoko: Regina Daniels kàn wù mí ni, mo nàwọ́ sí i ó sì di tèmi 3 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Oríṣun àwòrán, Regina daniels/instagram Ọkọ gbajugbaja oṣerebinrin, Regina Daniels, Ned Nwoko sọ pe aarin ọsẹ mẹta pere ni oun fẹ iyawo oun Kẹfa, Regina.
6 5956 Erekusu Saint Martin ( Agbegbe ti France) 27 72.
Iye awọn eeyan to ṣẹṣẹ ko arun naa ni ipinlẹ kọọkan ree: Eko -201 FCT- 85 Delta- 22 Edo- 16 Nasarawa- 14 Borno- 14 Kaduna- 14 Bauchi-10 Rivers-9 Enugu- 5 Kano- 5 Ogun- 4 Ondo- 4 Bayelsa- 2 Kebbi- 2 Plateau- 2 Èèyàn 663 ló lùgbàdì àrùn Coronavirus ní Naijiria lọ́jọ́ Ìṣẹ́gun nìkan ṣoṣo Oríṣun àwòrán, Getty Images Ajọ to n gbogun ti ajakalẹ arun ni Naijiria, NCDC ti kede eeyan 663 gẹgẹ bi apapọ awọn tuntun mii to ṣẹṣẹ ni arun Coronavirus ni Naijiria lọjọ Iṣẹgun.
kí n sì sọ fún wọn pé, OLUWA àwọn ọmọ ogun ní, “Bí ẹni fọ́ ìkòkò amọ̀ ni n óo ṣe fọ́ àwọn eniyan yìí ati ìlú yìí, kò sì ní ní àtúnṣe mọ́.
Ṣugbọn, OLUWA, ìwọ ni mò ń dúró dè;OLUWA, Ọlọrun mi, ìwọ ni o óo dá mi lóhùn.
Iwe iroyin Daily Moitor royin pe Sheikh Abdul Noor Kakande to jẹ adajọ agba Musulumi (regional kadhi) fun ẹkun naa sọ pe iṣẹlẹ naa ṣe ni laanu jọjọ awn si ti n ṣewadi Imam naa.
Ninu ìdílé Bebai: Jehohanani, Hananaya, Sabai, ati Atilai.
Eyi lo difa fun awujale ilẹ Ijẹbu Ọba Sikiru Adetọna, to fi fa awọn eeyan rẹ leti pe, a lee pe yoo pẹ ko ya, a si le pe yoo ya ko pẹ.
“Bí eniyan tíí wòye pé ọtí wà lára ìdì èso àjàrà,tí wọn sìí sọ pé, ‘Ẹ má bà á jẹ́,nítorí ohun rere wà ninu rẹ̀,’bẹ́ẹ̀ ni n óo ṣe nítorí iranṣẹ mi,n kò ní pa gbogbo wọn run.
O wa tẹsiwaju pe lowurọ ọjọ ẹti,eeyan mẹrinla,agbalagba mẹewa ati ọmọde mẹrin, ṣi n gba itọju fun oniruuru ipenija ilera ti awọn si ni ireti pe nigba ti ile o ba fi ṣu awọn dokita yoo da wọn silẹ lati lba mọlẹbi wọn.
o kopa ni kikun: Oloye Olusegun Obasanjo, Abdulsalami Abubakar ati Goodluck
"Oríṣun àwòrán, Screenshot Ninu fidio naa, ti ileesẹ kan gbe sita lo ti n pariwo pe ""Iran ti mo ri niyi, ẹ fa awọn ọdọ yin mọra, mo ri ijijagbara awọn araalu tii se Revolution."
awakọ̀ míràn a máa wa àwàsaré.
 Bi a ko ba tete wa woroko fi sada, o seese ki agbegbe maa ni odo feyin ti lojo iwaju.
16 Àti nísisìyí, bí ayọ̀ yín yíò bá pọ̀ pẹ̀lú ọkàn kan tí ẹ̀yin mú wá sí ọ̀dọ̀ mi sínú ìjọba Bàbá mi, báwo ni ayọ̀ yín yíò ṣe pọ̀ tó bí ẹ̀yin bá lè mú ọ̀pọ̀lọpọ̀ ọkàn wá sí ọ̀dọ̀ mi!
Wọ́n ń tẹ̀ ẹ́ mọ́lẹ̀,bí àwọn òtòṣì tí ń tẹ̀ ẹ́ mọ́lẹ̀bẹ́ẹ̀ ni àwọn aláìní ń tẹ̀ ẹ́.
- Agbẹnusọ Kassim Ọmọbíbí ìlú Benin di ìlúmọ̀ọ́ká akẹ̀ṣẹ́ lágbàáyé Anthony Joshua darapọ̀ mọ́ Mohammed Alli, Lenox Lewis ati Holyfield Abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Patrick Day dèrò ọ̀run lẹ́yìn tó gba ẹ̀ṣẹ́ s'órí!
ati gbogbo ìdílé Josẹfu àwọn arakunrin rẹ̀ ati ìdílé baba rẹ̀, àfi àwọn ọmọde, àwọn agbo ẹran, ati àwọn mààlúù nìkan ni ó kù sí ilẹ̀ Goṣeni.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ọmọ ọdún méjìlá yìí sọ bó ṣe di téélọ̀ táwọn àgbà ń bẹ́rí fún Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Nínú oṣù Kẹfà, ọdún 2000, ni ọwọ́ ọlọ́pàá tẹ̀ wọ́n, kó tó di pé wọ́n dájọ́ ikú fún bàbá àti ọmọ ní ọdún 2014.
Awon minisita fun oro ile-okere orile-ede mejeeji, Geoffrey Onyeama ati akegbe re lorile-ede Tunisia, Khemaies Jhinaoui, ni won fowo siwe aduhun igbore-eni-ye naa leyin ipade apero igbimo apapo awon minisita elekarun iru re niluu Abuja.
Awọn to wa ninu ikọ SWAT ko gbọdọ lọwọ ninu iwa ọdaran, paapa eyi to ni i ṣe pẹlu lilo ibọn bi ko ṣe yẹ, tabi titẹ ẹtọ ọmọniyan loju.
"A maa nrii daju pe a pa gbogbo awọn ina mọnamọna ni oja ki a too lọ.
Kí ó tilẹ̀ tóó di pé bàbá mi fi ayé sílẹ̀, kò sí ọjọ́ náà tí ó máa sọ ìtàn yìí fún wa tí ẹ̀rín kì í pa ni.
Ṣùgbọ́n kò pẹ́ tí ó dúró báyìí tí ó rí kìnnìún kan tí ó ń bọ̀, nígbà tí ó sì rí i ó sálọ fi ara pamọ́ sí inú ihò òkúta kan ṣùgbọ́n aṣọ rẹ̀ kan bọ́ sílẹ̀ nibi tí ó ti ń sálọ.
Jesu bá wí fún un pé, “Tètè ṣe ohun tí o níí ṣe.
Mo ma gbe igbesẹ lati koju ipenija aabo: Aarẹ Buhari lasiko abẹwo rẹ ba awọn ara ilu Maiduguri kẹdun, ti o si sọ pe oun yoo tẹramọ igbiyanju lati koju ipenija aabo to n ba wọn.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Fire: Táńkà epo méjì tó forí gbárí ló fa sábàbí iná ọ̀hún 29 Èbibi 2019 Oríṣun àwòrán, Trace Nibi ti awọn alayọ ti n yọ fun ayẹyẹ ibura aarẹ Muhammadu Buhari ati tawọn gomina gbogbo lawọn ipinlẹ lọjọru, ijamba ati ofo nla lo n ba awọn eeyan kan to gba opopona marosẹ ibadan silu Eko kọja lọjọ naa.
Ọmọ ọba Mohammed bin Salman gba oniruuru iyin lọwọ ilẹ okere nigba to jẹjẹ atipade oniruuru ti yoo ba eto ọrọ aje ati igbayegbadun ara ilu nigba to gori oye lọdun 2016.
Oriṣiriṣi ẹya orin ni wọn ma fi yan olorin ti wn yoo si baa gbe orin sita titi ti wọn yoo fi ṣe agbata rẹ kaakiri agbaye ati lati jẹ ki awọn to fẹran orin wọn tun ni iriri ọtun nipa wọn.
AFCON 2019: Nàìjíríà wà ní ìsọ̀rí kan náà pẹ̀lú Burundi, Madagascar àti Guinea
Èmi náà sì tún dáhùn, mo ní, Olóhùn-un-dùùrù tí ń kọrin bí ẹyẹ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Mimiko: Mo ti jáwọ́ lórí ìdíje ààrẹ, Sẹ́nétọ̀ ni mo fẹ́ báyìí 13 Owewe 2018 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 16 Bélú 2018 Oríṣun àwòrán, @Segunmimiko Àkọlé àwòrán, Gboye Adegbenro to n dije fun ipo sẹnetọ ni ẹkun idibo Ondo Central tẹlẹ, ni oun pẹlu ti yọ ọwọ lati fun Mimiko laaye lati dije.
Èmi Ọba tí wọ́n ń kó jẹ nígboro- Oluwo ti ilú Iwo Wọn ni ọkọ epo ọhun subu ni orita meta Koko ni opopona Benin- Sapele nigba to n gbiyanju lati sa fun koto laarin ọna ọhun Iroyin sọ pe, iṣẹlẹ naa waye ni nkan bi aago mọkanla owurọ yii, lẹyin ti ọkọ epo naa subu lo bẹrẹ si ni jo epo inu rẹ, bẹẹ lawọn eniyan lọ sibẹ lọ maa gbọn epo, bayii ni ina bu gbamu.
Buhari ti se aseyege lori ipinnu mejo ti o gunle lara won ni yiyan awon eniyan
Lionel Messi tun ti gbe ise ara re yo, leyin ti o ran iko re lowo lati gbo
Ni kete ti wọn kede esi ibo ọdun 2015 tan ni aarẹ naa lọ sibi igbeyawo Bello El-Rufai to jẹ ọmọ gomina ipinlẹ, Kaduna, Nasir Ahmad El-Rufai.
Ni ọjọ kẹrindinlogun oṣu kejila ọdun 2019 ni wọn kọkọ gbe wọn lọ siwaju ile ẹjọ naa, ṣugbọn Naira Marley ko ysju sile ẹjọ.
“Olùkọ́ni, òfin wo ni ó ṣe pataki jùlọ ninu Ìwé Òfin?
Mo fẹ́ máa kọ Classical"" lédé Ijebu, Hausa, Igbo Pidgin - Abiodun Koya 'Olódo ni mí nílé ìwé kí n tó ṣàwárí ẹ̀bùn mi' Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí kan sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn."
Nígbà tí Delila bẹ̀rẹ̀ sí yọ ọ́ lẹ́nu lemọ́lemọ́, tí ó sì ń rọ̀ ọ́ lojoojumọ, ọ̀rọ̀ náà sú Samsoni patapata.
Lẹ́hìn eléyìí ọ̀ràn náà sú bàbá mi óo sì ki ọwọ́ bọ àpò rẹ̀ ó ń wá oògùn kiri, ṣùgbọ́n ibi tí ó ti ń ṣe eléyìí ni ó ti rrí fèèrè àtìrandíran tí ń bẹ ní ilé wa, bẹ́l ni ó mú fèèrè náà sì gba gbogbo àgbègbè kankan.
O ti wa ni ile ẹjọ ba yii, ti gbogbo eto si ti to lati gbo ẹsun ati idi ti ijọba fi kọ lati tu u silẹ, lẹyin ti ile ẹjọ pasẹ ki wọn tui silẹ.
Àkọlé àwòrán, Ayẹyẹ ikẹyin fun Baba Sala Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 3 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 5 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Àwọn aṣòfin àpapọ̀ l'Amerika fa ìrètí Donald Trump ya, wọ́n buwọ́lu Joe Biden gẹ́gẹ́ bí ààrẹ Orisabunmi ti jáde láyé, ohun tí a mọ̀ nípa ayé àti ikú rẹ̀ nìyí 'Òkú Orisabunmi' dá wàhálà sí 'Afeez Ọwọ' lọ́rùn Ẹ̀gbọ́n baba Barakat ṣàlàyé bí ó ti gbé e lọ sílé kọmísọ́nà Ogun tí wọ́n ní kó lọ rọ́kún nílé Wo ilana lati lo 'App' naa O le gba app naa sori ẹ̀rọ ibanisọrọ rẹ lati Google play store to ba jẹ pe foonu Android lo n lo, tabi Apple App store to ba n lo IPhone.
Wọn ni ko yẹra fun igba diẹ ki wọn fi ṣe iwadii lori awọn ẹsun ọhun, ṣugbọn Ọjọgbọn Yusuf kọ jalẹ ko tẹle aṣẹ yii lo ba tun gba ileeṣẹ naa lọ ni ọjọ aje.
53 ni won yoo ta ni osu keta lodun 2025 ati ida ogorun un 13.
Ajọ to n risi idena ati amojuto ajakalẹ aarun, NCDC lo fi ikede naa sita lalẹ ọjọ Aiku loju opo Twitter rẹ.
Ni bayii, awọn Mogaji ilẹ Ibadan naa ti kilọ fun Gomina Kayode Fayemi tipinlẹ Ekiti wi pe ko so ewe agbejẹ mọwọ lori igbesẹ rẹ lati rọ awọn ọba kan loye nipinlẹ ọhun.
Atalaya fa aṣọ rẹ̀ ya láti fi ìbànújẹ́ rẹ̀ hàn, ó sì kígbe pé, “Ọ̀tẹ̀ nìyí!
Jeroboamu kú, wọ́n sin òkú rẹ̀ sinu ibojì àwọn ọba, Sakaraya, ọmọ rẹ̀ sì jọba lẹ́yìn rẹ̀.
Adajọ Charity Adeyanju paṣẹ pe ki wọn ṣi wa latimọle titi di ọjọ Aje ọsẹ to n bọ tii ṣe ogunjọ oṣu kinni ti igbẹjọ wọn yoo tẹsiwaju.
Ìgbà gbogbo ni òun máa ń fi ìyà jẹ  wọ́n, ìgbà tí ìjà bá sì dé láàrin òun àti ìyàwó rẹ̀, bí ẹnikẹ́ni wí pé kí wọn má jà kò ní í gbọ́ sí olúwarẹ̀ lẹ́nu – wọ́n ti sọ ọ́ lórukọ: aláràngbọ́ gbé ẹ̀wù ìtìjú wọ̀, ẹni tí ó bá ń jà tí a dá sí ìjà rẹ̀, a fẹ́ràn rẹ̀ ni.
Gege bi komisona awon olopaa, Henry Durant se so, “okunrin afurasi naa farabale wo arin awon eniyan, ti o si bere si ni siwa wu.
Gomina ipinle Eko , Akinwunmi Ambode gba adari ijoba orile ede  Britain , Theresa May  lalejo , o so fun un pe ipinle Eko jẹ ibi ti awon onisowo tẹdo si.
" Ìlànà tuntun ìjọba yìí kó bá àwọn oníṣòwò míràn wí, tó jẹ́ pé nínú àwọn òṣìṣẹ́ láti ilẹ̀ òkèrè ni iṣẹ́ òòjọ́ wọ́n fi n tẹ̀ síwájú.
O menuba Pataki idagbasoke to ye ki a se fun awon odun asa orile ede Naijiria bii ti Osun Osogbo, Iri ji, Argungu, Ofala, Iguel ti Benin, Nupe, Gembu Mambila ni Taraba ati Eyo ni Eko.
Ajafẹtọmọniyan lawọn obinrin mẹta ọhun lẹgbẹ oṣelu MDC ti wọn si n foju wina ofin lori ẹsun pe wọn parọ pe wọn ji awọn gbe wọn si fipa ba wọn lopọ loṣu to kọja.
Ifẹ̀họ̀núhàn ń lọ lọ́wọ́ ní Belarus lẹ́yìn tí ìdìbò tùn gbé Ààrẹ̀ Lukashenko tó ti wà nípò fún ọdún 26 wọlé Àjọ JAMB kéde ìlànà ìgbà ni wọlé tuntun fún àwọn ilé ẹ̀kọ́ gíga Dẹ́rẹ́bà kẹ̀kẹ́ Maruwa rí ẹ̀wọ̀n gbére he lẹ̀yìn tó fi ipá bá ọmọ ọdún mẹ́rìnlá lòpọ̀ Wọ́n ti sún ọjọ́ ìjà Mike Tyson pẹ̀lú Roy Jones Jr síwájú Ìdí tí ìjóba ìpínlẹ̀ Eko fí ṣí àwọn ilé ìwé kan padà A ti bẹ̀rẹ̀ ìwádìí lórí ibì tí owó tí àwọn adigunjalẹ̀ gbé ní banki Okeho wọ̀lẹ̀ sí- Ọlọ́pàá Diezani gan an ní Hushmummy tó ń bú àwọn Yahoo boys- Àwọn Ọmọ Naijiria lórí Twitter Olùrànlọ́wọ́ pàtàkì fún ọ̀rọ̀ ibojì òkú, àti àwọn ipò òṣèlú mìíràn tó jẹ́ kàyééfì ní Nàìjíríà Asojú ìjọba orílẹ̀-èdè Lebanon ti kọ̀wé fipò silẹ̀ nítorí ìbágbàmù tó gbẹ̀mi ènìyàn 200 Èèyàn 290 míràn ló ṣẹ̀ṣẹ̀ fara káásá àrùn Covid-19 ní Nàìjíríà, 160 gbàwòsàn Ki lo ti ṣẹlẹ sẹyin?
Òun ni ó ṣe ìwádìí owó tí ó sọnù.
Wéré tí ẹ̀dá yìí ti gbúròó oúnjẹ di dídé lo dìde tí o tẹ̀lé mi tí à ń kó rẹirẹi lọ, bẹ́ẹ̀ náà lo sì ń bá wa kiri títí a fi padà dé ìlú wa.
Àwọn ọkunrin kan tí wọn ń kọjá lọ rí òkú ọkunrin yìí lójú ọ̀nà, ati kinniun tí ó dúró tì í.
Àbí ẹ kò mọ̀ pé àwọn onigbagbọ ni yóo ṣe ìdájọ́ ayé?
won to wa sile itura naa.
Atalaya ni ìyá rẹ̀, ọmọ Omiri, ọba ilẹ̀ Israẹli.
Rárá o, ẹ kò gbọdọ̀ sìnkú akẹ́kọ̀ọ́ LASU tí wọn fi ṣe òògun owó - Ìjọba Eko yarí Ọlọ́pàá hú òkú akẹ́kọ̀ọ́ fásítì LASU tí ọ̀rẹ́kùnrin rẹ̀ àti pásítọ̀ ṣekúpa Irọ́ ni pé a fẹ́ fowó kún owó iná mọ̀nàmọ̀nà- NERC Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Inu mi bàjẹ́ nígbà tí mo bí i, odidi oṣù mẹ́ta, mi ò lè gbàdúrà s'Ọ́lọ́run' Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Elebuibon sọ wi pe o ti pe ti wọn ti yii pada ti ọba kii jẹ ọkan ọba mọ ati wi pe wn ti fi ọkan ẹran rọpọ rẹ.
O ni JSS 3 loun wa nile iwe girama ki oun to kuro nile iwe, amọ o sọ pe oun o kaba Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Oo ni anfani lati kọ owo idọti ti banki ba fẹ fun ọ o si le fi ẹj wọn sun ile ifowopamọ to ga ju bi wọn ba kọ lati parọ rẹ.
Ibi afara akọkọ lẹba ile ọ̀fíìsì ijọba kan ni Mokola ni wọn yi pada bayii si Trasmsformation Flyover 2.
ng Bo ba wọle tan, wa ri atọka lọwọ oke pe ki o wa orukọ awọn ti ijọba yan lati gba iwe lọwọ awọn to fẹ forukọsilẹ Waa ni lati yan orukọ mẹta ti o le sọ ileeṣ rẹẹ Aworan idanimọ pasipọọti meji Ojulowo ami idanimọ Nọmba ẹrọ alagbeka rẹ ati imeeli rẹ Àwọn ọmọ ogun Nàìjíríà tú àṣírí ẹni tó rán wọn níṣẹ́ lọ kojú àwọn olùwọ́de EndSARS ní Lekki Tollgate Kò sí àfikún ọjọ́ ìdáríjì fáwọn jàndùkú tó jí ohun iyebíye gbé lọ nípinlẹ̀ Osun - Gómìnà Oyetola Àgbàrá òjò gbé alága àdúgbò àti èèyàn méjì mìí lọ nílùú Ibadan Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Àjẹ́ ké lánàá, ọmọ kú lónìí ni ọ̀rọ̀ Tinubu àti ìṣẹ̀lẹ̀ Lekki Tollgate - Bode George Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Labẹ eyi, o ni ikọ ileesẹ naa to n gbe ibọn n ṣiṣẹ takuntakun lati wa ojutu si ọrọ ọhun.
Ọkùnrin kan lu ìyàwó rẹ̀ pa"" nítorí ó lọ síbi ayẹyẹ ìsọmọlórúkọ Àwọn Olúkọ ìpínlẹ̀ Oyo fakọyọ lórí ètò Akọ́mọlédè àti Àṣà púpọ̀ Wo àwọn oúnjẹ márùn ún tó ń mú kí àtọ̀ ọkùnrin dára síi Ogunkolade ṣalaye siwaju pe awọn ti ṣaaju kilọ fun ijọba apapọ lati ma ṣe tọwọ bọ owo ifẹyinti awọn oṣiṣẹ to si fi kun pe awọn ni yoo san owo yi pada tawọn Gomina ko ba ribi daa pada."
Bẹ́ẹ̀ ni ọ̀rọ̀ ẹni tíó gbàgbé Ọlọrun rí;ìrètí ẹni tí kò mọ Ọlọrun yóo parun.
Ẹ̀ka ìjọ kérúbù àti Serafu ní ọkunrinn náà nígbà tó wà ni Nàìjíríà.
Nọmba idanimọ gẹgẹ ọmọ Naijiria, NIN.
Ṣé títí lae ni yóo sì máa pa àwọn orílẹ̀-èdè run láìláàánú?
Tofunmi Bello ni tiẹ sọ pe ọrọ naa ti toju su oun, o ni oun ko tiẹ le kawe mọ nitori oun ko mọ igba ti idanwo naa yo ya.
Gẹgẹ bi atẹjade ti akọwe iroyin ijọba Amẹrika White House, Stephanie Grisham fi sita, ofin yii ti mulẹ lati oni ọjọ kẹrinlelogun oṣu kinni ọdun 2020.
Ṣugbọn Sisera sá lọ sí àgọ́ Jaeli, aya Heberi, ará Keni, nítorí pé alaafia wà ní ààrin Jabini, ọba Hasori, ati ìdílé Heberi ará Keni.
#Balance for better: Obìnrin ni mí, mo pé lọ́lá!
Khadiza jẹ ọmọ ọdun mọkandinlogun ti o ti ni ifẹ Tariqul Islam lọkan ti pẹ.
Òun nìkan ni àpáta ati olùgbàlà mi,òun ni odi mi, a kì yóo tì mí kúrò.
Ekiti Decides: Abiọdun Aluko ní báwọn se kàwé tó l‘Ekiti, ìyà sì ń jẹ àwọn
fun aare tun so pe aare Buhari ti seleri pe eto idibo to n bo yii yoo lo ni
Genotype: Kí làwọn àǹfàni àti ewu tí ẹ̀yà jínótáìpù rẹ le mú bá ìgbé ayé rẹ̀?
7 bilìọ̀nù kojúu àrùn Coro réé- Ìjọba ìpínlẹ̀ Oyo Ipinlẹ Oyo ni awọn ti na owo to to N2,779,000,000 lati koju arun COVID-19 nipinlẹ naa.
Nígbà tí o bá kúrò ní ọ̀dọ̀ mi lónìí, o óo pàdé àwọn ọkunrin meji kan lẹ́bàá ibojì Rakẹli, ní Selisa, ní agbègbè Bẹnjamini.
Ilé iṣẹ́ ológun Nàìjíríà korò ojú lórí fídíò ayédèrú
Ewe, ni kete ti saa keji ifesewonse ohun bere, asise asole iko agbaboolu Bayern, Sven Ulreich ni o sokunfa bi Benzema tun se gba ami-ayo  keji wole.
Awọn ọlọpaa lo gba Asif silẹ, ti wọn si mu lọ si agọ ọlọpaa to wa nitosi ibi ti ọrọ ti waye - ṣugbọn awọn ẹbi iyawo ma tun tẹle wọn debẹ lati gbẹsan.
Balaamu sọ fún Balaki pé, “Tẹ́ pẹpẹ meje sí ibí yìí fún mi kí o sì pèsè akọ mààlúù meje ati àgbò meje.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ẹ wo fídíò bí eyín akọ̀ròyìn ṣe fò yọ lásìkò tó n ka ìròyìn lọ́wọ́ lórí tẹlifísàn 18 Agẹmo 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 19 Agẹmo 2020 Oríṣun àwòrán, MARICHKA PADALKO/NSTAGRAM Ara meeriri, ni ọrọ obinrin akaroyin kan l'orilẹ-ede Ukraine, Marichka Padalko, ti eyin ẹnu rẹ fo yọ lasiko to n ka iroyin lori tẹlifisan.
tun tesiwaju nipa eto irawo N-Power ti won n se, ni eyi ti yoo tun fi lee ran
Ìyẹn ni pé láti ìgbà tí ìdíje yìí ti bẹ̀rẹ̀, Yakubu ni ipò kíní pátápátá.
Ahmad Salkida kan, akọroyin ti awọn eniyan mọ gẹgẹ bii ọkan gboogi ninu ọmọ Naijiria to maa n ri aaye wọ ọdọ awọn adari ẹgbẹ Boko Haram lo ṣe ikede yii lori ayelujara Twitter ni ọjọ Aje.
Àwọn ẹlòmíràn kò tilẹ̀ sọ̀rọ̀ nípa ojú rárá ṣùgbọ́n dípò bẹ́ẹ̀ wọ́n ń sọ̀rọ̀ nípa ẹnu, wọ́n ń wí pé ẹnu àwọn rí pẹlẹbẹ, ẹnu àwọn rí gbẹ̀rẹ̀gẹ̀dẹ̀, ẹnu àwọn rí róbótó àti wí pé eyín ẹnu àwọn ń pupa.
Ó bá dá wọn lóhùn, ó ní, “Bí ẹ bá mú mi pada wálé, láti bá àwọn ará Amoni jagun, bí OLUWA bá sì fi wọ́n lé mi lọ́wọ́ tí mo ṣẹgun wọn, ṣé ẹ gbà pé kí n máa ṣe olórí yín?
Uma, Afeki, ati Rehobu wà, gbogbo ìlú ati ìletò wọn jẹ́ mejilelogun.
Àkóràn arùn pọ ́ njú-pọ ́ ntọ ̀ ni okùnfà arùn náà èyí tí gígéjẹ abo ẹfọn ń tànká .
Agbarijọpọ awọn ọlọpaa, ọmọ ogun ni wọn jijọ sisẹ naa, ti wọn si ri awọn nkan ija oloro gba lọwọ awọn afunrasi yii.
Àwọn àfonífojì dáradára yín kún fún kẹ̀kẹ́-ogunàwọn ẹlẹ́ṣin sì dúró sí ipò wọn lẹ́nu ibodè;
Igbakeji aare tun tesiwaju pe, “Inu wa dun pe awon onisowo fi ifẹ wọn
Olupẹjọ naa tun salaye siwaju pé, oun tí kọkọ kọwe saaju ni ọjọ kẹẹdọgbọn oṣu keji ọdun 2020 si gomina Seyi Makinde lori iṣẹlẹ yii, amọ titi di akoko yii, ko tii fesi pada fun oun tabi ransẹ pe oun kawọn dijọ sọrọ lori rẹ.
Ọpọlọpọ iṣẹ lo sọnu ti awọn okowo miran jo ina ajorẹyin lasiko isede to pọ.
Oríṣun àwòrán, Inec Ogbẹni Okoye ni awọn iwe ẹri ti wọn gba papda naa ni wọn gba fun awọn ọmọ ẹgbẹ oṣelu kan naa ti ile ẹjs dajọ pe awọn gan lo yẹ ko dije ṣoju ẹgbẹ oṣelu wọn.
Israẹli bá dáhùn, ó ní, “Josẹfu, ọmọ mi wà láàyè!
Èyí ya àwọn olódodo lẹ́nu,aláìlẹ́bi sì dojú kọ ẹni tí kò mọ Ọlọrun.
Ẹ̀rù jẹ̀jẹ̀ ati jìnnìjìnnì ti dà bò wọ́n,nítorí títóbi agbára rẹ, OLUWA,wọ́n dúró bí òkúta,títí tí àwọn eniyan rẹ fi kọjá lọ,àní àwọn tí o ti rà pada.
Lacazette gba sagbon ati Pierre-Emerick Aubameyang gbegile ami-ayo ti atamatase
Iléeṣẹ́ ọlọ́pàá: Irọ́ ni kìí ṣe èèsì, ẹ mọ̀ pé ọlọ́pàá ni wọ́n, kẹ tó yìnbọn
Agbẹnusọ fun ileesẹ ologun orilẹ lorilẹede Naijiria, ọgagun Sani Usman lo kede eyi nilu Maiduguri.
Ohun tí mo ní sọ fun yín nìyí.
O fikun pe ẹgbẹ osisẹ fẹ ri daju pe wọn gbe aba sisan owo osu naa lọ sile asofin apapọ lati buwọlu, ki owo osu to kere julọ naa lee de apo awọn osisẹ kọọkan .
O ni aare ti yan asoju lo si
Mo tún rán arakunrin wa pẹlu rẹ̀.
Èyí ẹ̀gbọ́n ni ó kọ́ ta ọfà rẹ̀, ọfà náà sì rìn gidigidi, ṣùgbọ́n nígbà tí è’yi àtẹ̀lé ta ọfà tirẹ̀, o lọ títí wọ́n wá a, wọn kò ri i.
Ìjọba ni owo naa ni òun fẹ́ fi ṣe àwọn àkànṣe isẹ tó yà kalẹ ninu eto isuna ọdún 2020.
O ti to aadọta ọdun ti mo ti mọ Dapo, ta si jọ maa n gba Polo papọ, o si jẹ ọkan lara awọn alaanu ti mo sun mọ julọ.
Ninu ifọrọwanilẹnu kan to ṣe pẹlu BBC Igbo lo ti fi asiri ọrọ naa sita.
Nigba ti awọn gomina naa yoo si fi jade kuro nibi ipade wọn, abọ ti wọn jẹ faraalu ni ipe si adajọ agba naa pe ko gbọdọ farahan niwaju ile ẹjọ naa.
Awọn sinima bii Ti oluwa ni ile (1993), Obukọ Dudu, Ẹkun Ọkọ Oke, Ayọ ni mo fẹ (1994), Nkan asiri (2005), Oyatọ (2002) Obinrin Sọwanu(2004), Aya mi ọwọn: Madam Dearest (2005) Durodọla (2005) Atanpako ọtun (2007) ati bẹẹbẹẹ lọ ni diẹ lara awọn iṣẹ ti Baba wande ti ṣe.
Kí ó tó di pé a mọ ara wa, obìnrin máa ń rùn sí mi ni - ẹ jọ̀wọ́ kí ẹ forijì mí- ṣùgbọ́n òótọ́ ni mo sọ, bí ìgbọ̀nsẹ̀ ni obìnrin ti máa ń rùn sí mi.
Olusola ni abigbẹyin ninu ọmọ mẹrin ti awọn obi rẹ bi, abule Olokuta, ni ẹba Alahọ to wa nijọba ibilẹ Oluyole nilu Ibadan si lo ti lo igba kekere rẹ, ibẹ si lo ti lọ sile ẹkọ alakọbẹrẹ Christ School, Olokuta.
Bẹ ẹ lo ri fun emi naa, sugbọn o tun ti da ji awọn ipaya mi kọọkan dide.
Àwọn ojú oge Yollywood t'ọ́jà wọ́n ṣì ń tà wàràwàrà Kunle Afolayan, òṣìṣẹ́ báńkì tẹ́lẹ̀ kó tó di gbajúgbajà òṣèré Àwọn arẹwà obinrin Yollywood, tá ló mọ iṣẹ́ rẹ̀ jù?
Chukwuemeka Ohanemera ni olusọaguntan agba ni ilé ijọsin 'Mountain of Holy Ghost Intervention and Deliverance Ministry' ní ilú Onisha ipinlẹ Anambra.
Igbakeji gomina ipinlẹ Oyo tẹlẹ, Taofeek Arapaja, sẹnẹtọ to n ṣoju ẹkun ariwa Oyo tẹlẹ, Dokita Gbenga Babalola atawọn eekan inu ẹgbẹ oṣelu ADC to fi mọ oludije fun ipo gomina nipinlẹ Osun, Alhaji Fatai Akinbade lo darapọ mọ PDP nibi ipade ọhun.
Naṣoni ọmọ Aminadabu ni yóo jẹ́ olórí láti inú ẹ̀yà Juda.
"Oríṣun àwòrán, @MBuhari Adesina wa n bi awọn eeyan to n siyemeji nipa Buhari pe ""Se ti kii ba se aarẹ lo n ba oun sọrọ, bawo ni yoo se mọ orukọ oun, ti yoo si tun mọ pe oun kii saba wọ asọ agbada?"
Bi eto ayẹyẹ ayajọ eto ijoba tiwa-n-tiwa se n bere ni pereu  lorile ede Naijiria niluu Abuja ni papa isere Eagles Square  to wa niluu Abuja.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Fasoranti: Ẹ̀mí àwọ̀n darandaran Fulani kò dè mọ́ ní Gúsù Nàìjíríà, kí wọ́n padà sókè ọya ní kíákíá 17 Agẹmo 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ẹgbẹ àgbà òkè ọya Nàìjíríà, NEF ni ọrọ idunkukulaja to n waye lẹnu awọn agba iha Gusu Naijiria lo n mu ki aṣẹ naa waye Hmmm.
Wọn yoo tun maa ṣeto ilanilọyẹ nipa eto aabo fun ẹmi loju omi ni Pọtá pẹlu iranlọwọ awọn ara ìlú.
Ọga ile iwe gbiyanju lati gbe Chadia lọ si ile iwosan, amọ, ẹpa ko boro mọ lẹyin ti dokita sọ fun un pe ọmọ naa ti ku ki wọn to gbe e de.
Lẹ́sẹ̀ kan náà mo tají, mo wò yíká, oorun tí mo sùn sì dùn mọ́ mi.
Owó ìfẹ̀yìntì àwọn Gómìnà ní ìpínlẹ̀ Zamfara dì àlọrámirámi Makinde sàbẹ̀wò sí LAUTECH, ó gbé owó ₦500m kalẹ̀ láti tán ìyanṣẹ́lódì àwọn olùkọ́ Àṣírí tú!
Awọn onwoye ṣalaye nigba naa pe wahala ati ifẹhonuhan awọn oṣiṣẹ ẹka naa lo fa didaku ti ina manamana naa daku.
Mose, pẹlu gbogbo àwọn àgbààgbà Israẹli, sọ fún àwọn eniyan náà pé, “Ẹ máa pa gbogbo òfin tí mo fun yín lónìí mọ́.
'Ṣọ́ọ́ṣì ni mọ ti ń bọ̀ kí n tó pàdé àwọn sójà tó fi abẹ gẹ irun fún mi' Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Olapade Agoro: Olùdíje dùpo aàrẹ Nàìjíríà rí, Owatapa ti Itapa Ijesha, Wolii Olapade Agoro jáde láyé2 Bélú 2020 Fídíò, Soyinka Cancer: Àṣe ara mi ni iso ti n run gbogbo bí mo ṣe n ṣèrànwọ́ lórí jẹjẹrẹ27 Bélú 2019 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Fídíò, Akomolede ati Aṣa lori BBC:Wo ìrúfẹ́ ìgbeyàwó méje tó wà nílẹ̀ Yorùbá àti ojúṣe Alárinà10 Bélú 2020 Healthy lifestyle: Wo irú ìgbé ayé tó lè mú ẹ̀mí rẹ gùn11 Bélú 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Wo iye àwọn tó ti gbẹ̀mí ara wọn ní Nàìjíríà láàrin ọdún mẹ́rin ìjọba Buhari Gbèsè Nàìjíríà ti lé ní 18 tírílíọ́ọ́nù lábẹ́ ìṣèjọba Ààrẹ Buhari- DMO Wo bí iṣẹ́ abẹ wákàtí mẹ́fà, tí wọ́n fi dóòlà ẹ̀mí ìjàpá tí ọkọ̀ tẹ̀, ṣe lọ Kò sóhun tó ń jẹ́ ‘Captivus’ nílẹ̀ Oodua, mágùn ni mágùn ńjẹ́ - Babaláwo Wo àwọn obìnrin abúlé kan tó dáwó ra ọkọ̀ láti máa gbé aláboyún lọ ilé ìwòsàn Ìtàn rèé nípa bí Ogbomoso ṣe pa ọba, yọ nǹkan ọkùnrin rẹ jó kiri ìlú Ọkan lara awọn kọmiṣọna agba fajọ INEC, Amofin Festus Okoye to wa ni ipinlẹ̀ Ondo lọ̀wọ bayii lori ọrọ idibo naa la gbọ pe o sa kijokijo lọ si olu ileeṣẹ ajọ INEC naa lati mọ bi ọwọ̀ja rẹ ṣe pọ to.
ile-ise olopaa lorile ede Naijiria, ti ekun Zona 5, Alkali Usman ti ro awon
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ojú àwọn èèyàn Ondo ti là pé ìnira ni ẹgbẹ́ APC mú wá - Jegede PDP Bakan naa ni aarẹ Buhari tun sisọ loju r pe, lati akoko yii lọ, awọn olukọ ko ni fẹyin ti mọ lẹnu isẹ lẹyin ti wọn ba ti lo ọdun marundinlogoji, amọ o tun fi ọdun marun kun ọdun ifẹyinti wọn.
Okiki ẹgbẹ one million boys yii kan gidi nitori ojoojumọ ni wọn n lowo lọwọ, wọn n fẹ ọmọge to wu wọn, ti awọn ẹgbẹ okunkun miran si n jowu wọn.
Farao bá ranṣẹ lọ wo àwọn ẹran ọ̀sìn àwọn ọmọ Israẹli, ó sì rí i pé ẹyọ kan kò kú ninu wọn.
    O ya ni lẹ́nu láti ri i pé wọ́n ṣe ilẹkun sí ẹnu ọ̀nà igbo náà, ṣùgbọ́n bí a ti n súnmọ́ ọ ni ìlẹ̀kùn ṣí fúnrarẹ̀ ti ẹnìkan kùǹtà báyìí jáde sí wa.
Bii, ẹgbẹrun lona ọgọrun dọla owo ile Amẹrika, eyi to n ja si bii ogoji miliọnu naira lowo osu wọn lọdun.
orò tún jẹ ́ ẹ ̀ sìn kan tó so wọ ́ n pọ ̀ .
 bákan náà lo tún kẹ ́ kọ ̀ ọ ́ gboyè ìmọ ̀ ìjìnlẹ ̀ nínú lítíŕeṣ ̀ ọ èdè yorùbá ní ilé ẹ ̀ kọ ́ àgbà ti ìlú Èkó ( university of lagos ) ní ọdún 1978 ṣáájú kí ó tó bẹ ̀ rẹ ̀ iṣé gẹ ́ gẹ ́ bí olùkọ ́ ni ní ilé ẹ ̀ kọ ́ gíga ti ( Ọbáfẹ ́ mi awólọ ́ wọ ̀ university ) ní ilé-ifẹ ̀ .
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Alapinni Oosa ṣàdúrà fún gogbo ọmọ kúoótù, oò jíire bí?
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Okunrounmu: Ijọba Buhari jẹ ijiya Ọlọrun fun Naijiria Linda ṣiṣẹ gẹgẹ bii adari ẹka ẹsun ibalopọ laarin ọdun 1976 si ọdun 2002.
Ni bayii,Ranieri ti tuko agbaboolu Fulham jawe olubori ifesewonse kan, ami dogba-dogbakan ti won si padanu okan ni apapo ifesewonse meta ti o ti tuko ikon aa gba.
"Ọwọ́ ọlọ́pàá tẹ ọkùnrin mẹ́rin pẹ̀lú orí èèyàn ní ìlú Akure Oríṣun àwòrán, ""PoliceNG/Twitter Ọwọ ṣikun awọn ọlọpaa ipinlẹ Ondo ti tẹ awọn mẹrin kan ti wọn ka ori eeyan mọ lọwọ nilu Akure."
Oríṣun àwòrán, Nimc Oríṣun àwòrán, Nimc Koda, ajọ to n ri si owo ifẹhinti, to fi mọ ajọ to n ṣe onka iye eeyan ti wa ni Naijiria, ati ileeṣẹ ifiwe ranṣẹ naa wa lara wn.
” Ó bá gba òkú ọmọ náà lọ́wọ́ rẹ̀, ó gbé e gun orí òkè ilé lọ sinu yàrá tí ó ń gbé, ó sì tẹ́ ẹ sórí ibùsùn rẹ̀.
Bi itan igbe aye Timi Agbale Ọlọfa ina ati Gbọnka Ebiri se lọ ree: Apetan orukọ Timi Agbale ni Timi Kubọlajẹ Agbọnran, ti orukọ baba rẹ si n jẹ Lalẹmọ.
Alufaa yóo ṣe ètùtù niwaju pẹpẹ fún olúwarẹ̀ tí ó ṣe àṣìṣe, a óo sì dáríjì í.
Ìtàn yìí kọ́ wa wípé kò yẹ kí á máa ṣe ìlara ẹnìkejì wa.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Akure Kidnap: Àwọn abiyamọ fẹ̀hónúhàn lórí ọmọ tí wan jígbé nílé ìjọsìn Akurẹ Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù COZA: Ọpọ èrò ló jáde ṣe lòdì sí ẹ̀sùn ìfipábánilòpọ̀ Fatoyinbo Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ COZA: Ọpọ èrò ló jáde ṣe lòdì sí ẹ̀sùn ìfipábánilòpọ̀ Fatoyinbo 1 Agẹmo 2019 Busola Dakolo ló jáde fẹ̀sùn kan Pasitọ Biodun Fatoyinbo pé o fipá bá òun lò pọ̀ ni èyí tó mú kí àwọn èèyàn jáde sọ̀rọ̀.
julọ,tun wa aaye lati wo awon ohun adayeba to wa ni ijoba ibilẹ Abi ni ipinle
ọrọ rẹ, Agbẹnusọ Ile Igbimọ Aṣofin Ipinlẹ Eko, Aṣofin Mudasiru Ọbasa
Gbajabiamila balẹ̀ sí Ghana láti pẹ̀tù sááwọ̀ láàrin Nàìjíríà àti Ghana Dáa padà Buhari, èmi kìí s'ọ̀lẹ Ẹ fọkànbalẹ̀, kọ́bọ̀ kò ní gun owó epo pẹtiró - NNPC Iléeṣẹ́ ìròyìn Daily Trust gbọdọ̀ san N6 bilion nítorí ìbanilórúkọjẹ́- Femi Fani Kayode Ìjàmbá ọkọ̀ tó ṣẹlẹ̀ sí Adams Oshiomole kìí ṣe ojú lásan, àwọn kan ló fẹ́ pa á- APC Ẹwẹ, Ayodele Fayose to figba kan jẹ Gomina ipinlẹ Ekirti naa ti bẹnu at lu ẹkunwo owo jala epo ti ijọba Naijiria kede.
Ki wọn ti ẹ jẹ gbajuẹ, ṣe bi ẹ le mu wọn lọ si agọ ọlọpaa.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Géńdé agbébọn yabo àgọ́ ọlọ́pàá n‘Ibadan, ẹ̀mí ọlọ́pàá kan bọ́ Ọba Ilorin ló pàṣẹ pé kí ń padà sọ́dọ̀ ọkọ mi - Risikat olójú búlúù A fí ara mọ́ ìdájọ́ ikú Sharia tó tọ́ sí Olórin Yahaya- ẹgbẹ́ Amòfin Mùsùlùmí ẹ̀ka ìpínlẹ̀ Kano Wo bí ọkùnrin ọmọ òrukàn yìí ṣe ń ran àwọn opó tí ọkọ wọn kú sójú ogun lọ́wọ́ Deji Akure pàṣẹ kí wọ́n ti gbogbo ọjà pa fún ọjọ́ méjì, ohun tó fàá nìyí Wo ohun tó ṣẹlẹ̀ sí Saka, Sunkanmi Omobolanle àtàwọn òṣèré sinimá míràn lọ́sẹ̀ yìí Bakan naa ni eto irinna oju irin yoo tun bẹrẹ lati ilu Itakpe lọ si Warri de Ore, laipẹ laijinna si ni wsn yoo si eto naa.
Nítorí kí ni àwọn kan ṣe ń ṣe ìrìbọmi nítorí àwọn tí ó kú?
Mò ń pa àṣẹ rẹ mọ́,mo fẹ́ràn wọn gidigidi.
Jesu pẹlu àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ yẹra lọ sí ẹ̀bá òkun.
n le orukọ awọn to forukọsilẹ fun eto idibo.
Awon omo-ogun orile-ede America ti maa n se ikolu , eyi ti won fi n dode awon omo-ogun olote lorile-ede Libya, lati bi odun meloo kan seyin.
Coronavirus: Ààrẹ Ghana lọ sílẹ̀ Yúróópò fún ọjọ́ méjìlá níbití àrùn náà wà.
Ibinu rẹ̀ ń jó mi bí iná,ó kà mí kún ọ̀tá rẹ̀.
 Bakan naa, ni aare yoo maa  darapo mo awon akegbe re ,aare a tun maa soro nibi ipade olojo mejila ti COP24.
Adeola Smart and Malivehood Wedding: Diamond kún ara aṣọ ìyàwó, Cake jẹ́ alájá 16
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù South West Security: Ọlọ́pàá Ogun àti Ọ̀ṣun ni àwọn kò lọ́wọ́ nínú àjọṣepọ̀ ọ̀hún 15 Ògún 2019 Oríṣun àwòrán, @PoliceNG Àkọlé àwòrán, Ileeṣẹ Ọlọpaa ni eto abo agbegbe lawọn n tẹle; OPC ni ọrọ naa ko ti fẹnu jona sibikan Ọrọ eto aabo to n mẹhẹ ni agbegbe iwọ oorun guusu Naijiria nibi ti ẹya Yoruba ṣodo si, ti di irawọ ọsan to n ba awọn agba lẹru bayii.
Ẹ má ṣe làálàá nítorí oúnjẹ ti yóo bàjẹ́, ṣugbọn ẹ ṣiṣẹ́ fún oúnjẹ tí ọmọ eniyan yóo fun yín, tí yóo wà títí di ìyè ainipẹkun, nítorí ọmọ eniyan ni Ọlọrun Baba fún ní àṣẹ.
”Ogbeni Sulaiman soju fun alaga ajo ECOWAS, ti akegbe re Fuchs si soro dipo asoju ajo EU lori oro ile okere ati ilana eto aabo.
Nítorí náà, èmi tí mo di ẹlẹ́wọ̀n nítorí ti Oluwa, ń bẹ̀ yín pé kí ẹ máa hùwà gẹ́gẹ́ bí ó ti yẹ, bí irú ìpè tí Ọlọrun pè yín.
Osinbajo: Ààrẹ Buhari rán mi láti wá àbáyọ sí ààbò tó mẹ́hẹ
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Báyìí ni àwọn alátìlẹ́yìn Super Eagles ṣe ń dá músò ṣáájú ìdíje tòní 6 Agẹmo 2019 Ẹgbẹ alatilẹyin ikọ Super Eagles lorilẹede Egypt n fi idunu wọn han pe ifẹsẹwọnsẹ oni yoo ṣẹnu 're fun Nàìjíríà.
Oríṣun àwòrán, Nigeria prison Sevice Bi a ko ba gbagbe awọn ẹlẹwọn kan sa lọgba ẹwọn nigba ti awọn eeyan kan ti wọn fura si pe wọn lawọn n se iwọde ENDSARS, yabo ọgba ẹwọn ilu Benin-City ati Oko.
Ẹ kúrò lọ́dọ̀ mi, gbogbo ẹ̀yin oníṣẹ́ ibi.
"Ṣugbọn mo fi ohun gbogbo le Ọlọrun lọwọ"" ni iya Favour sọ."
O ra ile kan si Lekki, nilu Eko.
Àwọn kan ninu àwọn ọmọ ogun rẹ̀ yóo wá, wọn yóo sọ Tẹmpili ati ibi ààbò di aláìmọ́, wọn yóo dáwọ́ ẹbọ sísun ìgbà gbogbo dúró, wọn yóo sì gbé ohun ìríra tíí fa ìsọdahoro kalẹ̀.
Wọ́n mú un lọ sí ààrin òpó mejeeji pé kí ó dúró níbẹ̀.
Ẹgbẹ awọn oṣiṣẹ awakọ ofurufu, The National Association of Aircraft Pilots and Engineers(NAAPE) ti gun le iyanṣẹlodi lati tako igbese ileeṣẹ Bristow naa, lai fun awon oṣiṣẹ ni ajẹmọnu to tọ si wọn.
Olùkọ́ àgbà tó fipá bá ọmọ ọdún 13 lò yóò fojú ba ilé ẹjọ́ ni Benue Dokita àti Nọ́ọ̀sì fìyà jẹ mí lásìkò tí mò ń rọbí- Alaboyún Ǹjẹ́ o mọ ẹni tó ran àjọ ọ̀tẹlẹ̀mùyẹ́ CIA lọ́wọ́ láti rí Bin Laden mú?
Nigba to n ba BBC Yoruba sọrọ, Onisegun oyinbo kan, Dokita Afeez Oladele ni aisan otutu aya ko ni ohunkohun se pẹlu otutu rara nitori eeyan lee sun si ori ilẹ lasan tabi si aya si ẹrọ amuletutu lai wọ asọ, ti onitọun ko si ni ni otutu aya rara.
Ìwọ ni olùrànlọ́wọ́ mi, ṣe gírí láti ràn mí lọ́wọ́!
Ti ẹ ba j ẹni to n fi ọkan tele ere bọọlu paapa julọ ni English Premiership, ẹ o ti ri Dokita Kelelchi pẹlu irukẹrẹ lọwọ nibi ti o ti n fi ifẹ han si ẹgbẹ agbabọọlu Arsenal Ilu London ni Dokita Kelechi fi ṣe ibujukọ o si jẹ ọmọ iran Igbo.
Wo ìdí to fi gbọdọ̀ yàgò fún Bobrisky, akọ tó ń ṣe bíi abo Sanusi Adebisi Idikan rèé, olówó tó ń san owó orí fún gbogbo ọkunrin ilẹ̀ Ibadan Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Africa Eye: Olùkọ́ méjì ní fásitì Eko àti Ghana lùgbàdì ọ̀fíntótó BBC lórí ìwà ìbàjẹ́ Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
atileyin fun egbe akoroyin obinrin nigbakuugba ti won ba pe fun un.
Ọjọ Kejilelogun, Osu Kewaa ni Adajo Agba, Folasade Giwa-Ogunbanjo ti ile ẹjo giga pasẹ ki Maina fi dukia ile mẹtalelogun to ni silẹ.
Èyí ni iye àwọn tí Mose ati Aaroni kà ninu àwọn ọmọ Geriṣoni tí wọ́n lè ṣiṣẹ́ ninu Àgọ́ Àjọ gẹ́gẹ́ bí OLUWA ti pàṣẹ fún wọn.
Ó tún mú ife, ó dúpẹ́ lọ́wọ́ Ọlọrun, ó bá gbé e fún wọn.
Ikọ ọhun ti wa ni pupọ awọn ọmọ ẹgbẹ agbabọọlu naa ni wọn yoo fi si apapmọ fun ayẹwo.
(2/2)While in Kano, @CAS_AMSadique also commissioned a state-of-art modular theatre at 465 NAF Hospital.
Ṣugbọn obinrin yìí fi òróró olóòórùn dídùn kùn mí lẹ́sẹ̀.
Ijọba ni awọn yọ owo iranwọ to wa lori epo bẹntirol ati awọn ẹka miran, lọna ati le lo owo ori ti awọn eniyan ba san lọna to tọ, yatọ si sise afikun owo epo.
Mali Coup: Ẹgbẹ̀lẹ́gbẹ̀ èèyàn tú jáde ní Bamako láti yọ̀ pé wọ́n rẹ́yìn ààrẹ àná
Lẹyin ọjọ meji ti Ọba naa waja ni wọn fi akọbi ọmọ rẹ obinrin, Temilolu Akinboola, sori oye gẹgẹ Adele, ṣugbọn o da bii pe igbesẹ yii ko dun mọ awọn kan ninu.
Peter Tabichi, to jẹ ọkan lara awọn ẹgbẹ ijọ aguda ti a mọ si Francisca order, ni o gba ami ẹyẹ naa to jẹ eyi ti wọn gbe kalẹ fun awọn olukọ to gbayi ju ni agbaye.
Bẹ́ẹ̀ sì ni pẹpẹ wúrà náà, ati òróró ìyàsímímọ́, ati turari olóòórùn dídùn, ati aṣọ títa fún ìlẹ̀kùn àgọ́ mímọ́ náà; 
Para dà, OLUWA, kí ló dé tí o fi ń sùn?
66 usd fún ìwọ ̀ n egbògi náà kanṣoṣo ní ọdún 2014 .
Iyalẹnu to tun wa lori ọrọ owó yii ni pe, ọpọ àwọn to n lo o kii fi ra nkan.
mapped Confirmed cases around the world Zoom to The world Africa North America Latin America & Caribbean Asia Europe Middle East Oceania Show 93,418,283 cases 2,000,905 deaths Group 4 Please upgrade your browser to see the full interactive Circles show number of confirmed coronavirus cases per country.
"Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Àwa àti fijilanté pẹ̀lú ọdẹ́ ìbílẹ̀ ló dojú kọ adigunjalè ní First Bank Okeho - Iléeṣẹ́ ọlọ́pàá ""Ọmọ mi kò tíì mọ̀ pé òun ti di ìlúmọ̀ọ́ká, ó ń wádìí bó ṣe ń rí ara rẹ̀ lórí ayélujára"" Ìtàn ọba Yorùbá tí wọn yẹgi fún torí ó jí ọmọ gbé ṣe ètùtù Ẹ káàbọ̀ sọ́jọ́ Arafat, tí Ọlọ́run yóò fi ààwẹ̀ Mùsùlùmí pa ẹ̀ṣẹ̀ wọn rẹ́ Kọmisana feto iroyin ati ilanilọyẹ araalu nipinlẹ naa, Funke Egbemode, ninu atẹjade naa ni ijọba ipinlẹ Osun mọriri gbogbo aseyọri agba oselu naa nigba aye rẹ, paapaa ipo asaaju to dimu ninu oselu."
Jiti Ogunye nigba to n ba BBC sọrọ lori bii awọn asofin se sigun kuro ni ẹgbẹ oselu APC losi PDP saaju idibo gbogboogbo ni ọdun 2019.
Oríṣun àwòrán, @MBuhari O fikun pe Abiọla lo awọn ohun alumọsni ti ọba oke fi jinki rẹ ati gbogbo agbara to ni lati fi gba awọn ọmọ Naijiria niyanju pe ohun kan soso ti oun n fẹ ni orilẹede Naijiria ti yoo duro digbi, ko si si ohunkohun miran ti oun n wa.
ṣùgbọ́n bàbá rẹ̀ fun un ní idà kan – Idà Ajàṣẹ́gun ni, ó ni kí ó máa lé awọn ẹ̀gbọ́n rẹ̀ lọ pé ibikíbi tí ó bá bá wọn, kí ọ bèèrè ohun ìní tirẹ̀ lọ́wọ́ wọn.
Ìyà kan náà ni ẹ̀yin alufaa ati àwọn eniyan yóo jẹ, n óo jẹ yín níyà nítorí ìwà burúkú yín, n óo sì gbẹ̀san lára yín nítorí ìṣe yín.
ẹ̀yin kò mọ̀ pé ìyàlẹ́nu ni ìwọ̀nyí!
Ẹni ti ó bá rí ọ̀rẹ́ mi yìí, ó yẹ kí olúwarẹ̀ kíi dáadáa, Ọmọlúàbí ni.
Aarẹ Muhammadu Buhari ti buwọlu iyansipo rẹ gẹgẹ bi ọkan lara awọn oluran lọwọ tuntun lofiisi aya aarẹ.
 lára àwọn òpìtàn yìí tilẹ ̀ lérò pé ẹni tó tẹ ìlú Ẹ ̀ fọ ̀ n-aláayè dó rọ ̀ lati ojú ọ ̀ run sílé ayé .
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Obafemi Awolowo University: Olùkọ́ fásitì OAU gbòmìnira lọ́wọ́ àwọn ajínigbé 7 Èbibi 2019 Oríṣun àwòrán, Facebook/Adegbehingbe Olukọ agba fasiti Ọbafẹmi Awolọwọ to wa nilu ile Ifẹ, Ọjọgbọn Yinka Adegbehingbe ti wọn ji gbe ti gba ominira lọwọ awọn ajinigbe.
O tun wipe ijọba aarẹ Buhari yọ ọmọ ọgbẹni Mathew Seiyeifa to jẹ ọmọ Niger Delta kuro ni ipo ọga ile iṣẹ ọtẹlẹmuyẹ lọna ti ko tọ.
Buhari ló kòwé bèrè ìwé ẹrí rẹ̀ lọ́wọ́ àjọ wa- WAEC Oríṣun àwòrán, @WAECofficial Àkọlé àwòrán, WAEC: ilé ẹjọ́ àti Buhari nìkan ló le bèrè fún ìwé ẹ̀rí.
Bakan naa, ẹgbẹ oṣelu AAC kede pe siso iṣẹ Sowore gẹgẹ bi alaga atawọn ọmọ ẹgbẹ mii rọ bẹrẹ lati ọjọ kẹtadinlọgbọn oṣu kẹta ọdun yii ti yoo si wa fun oṣu mẹfa ayafi ti ipade apero gbogbo ti ẹgbẹ ba ṣasugbaa iyipada rẹ.
Ilu Unguwar Wawaye jẹ agbegbe to wa ni ijọba ibilẹ Rogo ni ilu Kano to wa ni Ariwa orilẹ-ede Naijiria ni o ti gba orukọ tuntun yii.
Àwọn ọ̀rẹ́ àti ojúlùmọ̀ pẹ̀lú àwọn ìbátanmi gbogbo ti wọn gbúròó mi ni wọ́n tú jáde tí wọ́n dàpọ̀ mọ́ wa ttí a jọ ń jó lọ, ìgbà tí mo sì fi máa dé ilé, àwọn ènìyàn pọ̀ lọ bẹẹrẹ, mo náwó púpọ̀ lọ́jọ́ yìí, ọjọ́ ìdárayá ni.
Yemi Elesho, ìlúmọ̀ọ́ká adẹ́rínpòṣónú jẹ́wọ́ pé ẹnu nìkan kọ́ lòun ní lórí 'Ṣé o láyà?
Ọpọ́n kọ̀ọ̀kan wà lórí òpó mejeeji, lórí ibi tí ó yọ jáde tí ó rí bìrìkìtì lára àwọn òpó, lẹ́gbẹ̀ẹ́ iṣẹ́ ọnà náà.
Akọnimọọgba Egypt, Hector Cuper, ti ni Mohamed Salah yoo kopa ninu idije to m bọ lọla laarin Russia to n gbalejo idije World Cup 2018 ati Egypt ti o ba ti yege ninu ayẹwo to fẹ ṣe.
A kò lè mọ bí máa pe ara ẹni tàbí bí a ó ti máa tọ́kasí ènìyàn kọ̀ọ̀kan bí ó bá jẹ́ pé a kò ní orúkọ ọ̀tọ̀ọ̀tọ̀.
" Oríṣun àwòrán, lizzyanjorin_original Lizzy salaye siwaju si pe ọmọ sisẹ sisẹ ni oun, ti oun si maa n lọ soke okun lati lọ ra awọn asọ ati ẹsọ ara ti oun n ta ninu ile itaja oun to wa ni adugbo Ikọta nilu Eko.
OLUWA yóo gbé wọn mì ninu ibinu rẹ̀;iná yóo sì jó wọn ní àjórun.
Ẹran ìgbẹ bi Ìgalà, Àgbọ̀nrín àti , ẹran ọ̀sìn bi Àgùntàn, Ewurẹ, Òbúkọ, Ẹlẹ́dẹ̀ jẹ ẹran tí o wọ́pọ̀ fún jíjẹ ni ayé àtijọ dípò ẹran Mãlu tí ó wá wọpọ láyé òde òní.
Nígbà tí ó dé etí ihò ó dáhùn, ó ní, Oùfẹ́ mi, mo ti ṣee bí o ti wí o, máa bọ̀ ìwọ tí í ṣe olúwa mi.
- Oshonaike Ṣugbọn awọn ọlọpaa agbegbe fi ẹsun kan ẹni ọdun mọkandinlọgbọn naa ti orukọ rẹ n jẹ Monday pe o n tọju adugbo lai gba aṣẹ lọwọ awọn alakoso ibẹ.
Gbogbo wọn ni wọ́n ti kú ikú ogun.
Lati igba yìí ko si ẹni to gburo rẹ ninu ere agbelewo Nollywood Yoruba mọ.
Jonatani sọ fún Dafidi pé, “Kí OLUWA Ọlọrun Israẹli ṣe ẹlẹ́rìí láàrin èmi pẹlu rẹ.
Aare Buhari tun ki gomina Lalong fun pipari awon ise akanse ti awon ijoba to kogba wole bere ti won ko le pari tele.
Ọgbà ẹ̀wọ̀n ni wọ́n ti já ìbálé Esra lábẹ́ àwáwí àyẹ̀wò wúndíá
‘Gboingboin ni Ilẹ̀ Gẹ̀ẹ́sì wà lẹ́yìn ìgbógun ti Boko Haram’ Àwọn ọmọge wọ gàù l'Abuja nítorí asọ péńpé Fashola fi orúkọ àwọn ilé isẹ́ tó jẹ́ àjẹbánu síta.
”“ikeji,Igbo to ba je aare orile ede Naijiria lodun 2023 , yoo se awon atunse to ye lati mu Igbo pada wa si aarin gbungbun ijoba  orile ede Naijiria, ati lati se awon atunse si ibi ti won gbe n foworo igbo seyin ninu ijoba.
Baldwin sọ pe eniyan miliọnu mẹta lati awọn agbegbe ti iya ati isẹ wa ni orilẹ-ede Naijiria ni wọn yoo mu ibugboro ba igbe aye wọn nipa pi pese ohun amayedẹrun fun awọn eniyan.
Gẹgẹ bi atẹjade ọhun ṣe sọ, ipinlẹ Eko lo tẹle e pẹlu eeyan mẹtadinlọgbọn.
O tun ni ”Nigba ti, wọn bura fun aare  Muhammadu Buhari ni ojo kọ́kàndínlọ́gbọ̀n, osu kárùn ún, odun 2015.
pé kí àwọn ọmọbinrin Israẹli máa lọ láti ṣọ̀fọ̀ ọmọbinrin Jẹfuta, ará Gileadi fún ọjọ́ mẹrin lọdọọdun.
Àwọn aposteli ati àwọn àgbà ìjọ pẹlu gbogbo ìjọ wá pinnu láti yan àwọn eniyan láàrin wọn, láti rán lọ sí Antioku pẹlu Paulu ati Banaba.
Bi aye ṣe d'ẹnu kọlẹ Ka ma parọ, orisirisi ọna ni wọn ti fi n koju coronavirus.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù NNPC n ronu afikun owo epo bentirolu 16 Èrèlè 2018 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ọwọn owo epo bentiroolu ti wa ni Naijiria latọjọ pipẹ Igbimọ ti o ga julọ lori eto ọrọ aje orilẹede (NEC) sọ wipe oun ti bẹrẹ ifọrọjomitoro ọrọ pẹlu ile iṣẹ ajọ elepo rọbi lori afikun owo epo bentirolu lorilẹede Naijiria.
Wọn si gbọdọ lọ si ori ayelujara www.
Ojude Ọba 2019: Àwọn èèkàn lórílẹ̀-èdè Nàìjíríà ti péjú fún ayẹyẹ ojúde Ọba
2 Èmi, lẹ́hìn tí mo ti ṣetán tí mo sì parí ìfẹ́ inú ẹni náà tí èmi í ṣe tirẹ̀, àní Bàbá náà, nípa èmi—tí mo ti ṣe èyí kí èmi ó baà lè mú ohun gbogbo wá sábẹ́ àkóso èmi tìkara mi—
Joabu bá pada lẹ́yìn àwọn ará Amoni, ó sì lọ sí Jerusalẹmu.
Kimbele Crenshaw to jẹ ajijangbara lori awọn obinrin alawọ dudu nilẹ america naa sọrọ lori ewu nla to n koju obinrin alawọ dudu nibẹ.
Lẹ́yìn èyí, àwọn ọmọ Israẹli wí fún Gideoni pé, “Máa jọba lórí wa, ìwọ ati ọmọ rẹ, ati àwọn ọmọ ọmọ rẹ pẹlu, nítorí pé ìwọ ni o gbà wá lọ́wọ́ àwọn ará Midiani.
Ọjọ meji lẹyin ti iṣẹlẹ naa waye ni awọn ara ṣọọṣi obinrin naa wa wa sile, ti wọn ba ilẹkun ile naa ni titi lati ita.
 Àwọn Ìpínlẹ̀ tí coronavirus kò tíì dé ní Nàìjíríà, àti ìgbésẹ̀ tí wọ́n ń gbé láti dènà rẹ̀ Ìtàn Manigbagbe: Àwọn àjakalẹ-àrun to ti wáyé rí ṣáájú Coronavirus Mileva, aya rẹ jẹ oluranlọwọ pataki si ayanmọ rẹ lati ibẹrẹ aye wọn."
11 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Oríṣun àwòrán, Getty Images Ibẹrẹ Anthony Joshua Wọn mọ ẹbi Joshua daadaa ni ilu Sagamu, ti wọn si mọ itan awọn baba nla rẹ daadaa.
Peteru wí fún Jesu pé, “Olùkọ́ni, ó dára tí a wà níhìn-ín.
Orúkọ àwọn ọmọ Geriṣoni ni Libini ati Ṣimei.
Awọn owo naa lo wa latọwọ awọn lajọlajọ, lẹgbẹlẹgbẹ ati awọn eekan lawujọ fun ọkọọkan awọn ijọba naa eyi ti akojọpọ rẹ ti le ni igba biliọnu naira.
Àkọlé àwòrán, Obìnrin àkọ́kọ́ tó gboyè ọ̀jọ̀gb an nílẹ̀ Afrika, Adetoun Ogunsẹyẹ nàá wà níkàlẹ̀ Àwọn iléèwé láti ìjọba ìpínlẹ̀ mọ́kànlá tó wà ní Ibadan ló kópa níbi ìdíje nàá tó wáyé lọ́gbà Fáṣitì Ìbàdàn.
Ninu alaye rẹ, o sọ siwaju sii pe ''ori ni Olubadan jẹ fun awọn ọba, bẹẹ ni wọn ko si le di iru laelae.
Awuyewuye ti kọjáa ti gbàgede orí ẹ̀rọ-alátagbà, ó kàn dé ilé-ìwé àti àjọ ìlú.
"Bi mo se n dagba ni mo bẹrẹ si ni mọ pe amunisin ni ẹni to n jẹ orukọ yi nigba aye rẹ"" Germany ko Namibia l'ẹru lẹyin ti ogun agbaye kini pari ṣaaju igba ti Hitler bọ sori aleefa."
Ọpọ okun ni awọn eeyan fi sofo lati dabaru eto yii dipo ki wọn wa ọna abayọ si Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Ìwọ tí o jẹ́ alátìlẹyìn pataki fún Israẹli!
OLUWA ń sọ fún ilé Israẹli pé: “Ẹ wá mi, kí ẹ sì yè; 
Ilé ẹjọ́ rán àwọn mérìndínlógún lẹ́wọ̀n gbére fún dídáná-sun Nusrat Ẹ wo ojú owó ìrẹ̀sì báyìí lẹ́yìn tí ìjọba ti ibodè pa Rhoda ṣalaye pe ọmọ ti wón ba fi ipa balo ni kekere naa nilo iranlọwọ awọn dokita to ni imọ nipa ihuwasi eniyann ati ọpọlọ.
South Africa Lions: Àwọn aláṣẹ rọ àwọn ará abúlé tí kìnìún wà láti má a fojú sọ́rí
Niṣe ni Cardi B sare pa fọto naa rẹ, to si gba pe oun ṣe aṣiṣe.
Bákan náà ni kí ẹ ka ara yín bí ẹni tí ó ti kú ní ayé ẹ̀ṣẹ̀, tí ó tún wà láàyè pẹlu Ọlọrun ninu Kristi.
Ará rọ̀ ọ́ ju Ikú lọ, òun si dà bi ọ̀gá nínú ilé náà.
Ní àkókò náà, àwọn ará Filistia kó ara wọn jọ láti gbógun ti àwọn ọmọ Israẹli, àwọn ọmọ Israẹli náà bá kó ogun jáde láti bá wọn jà.
Kì í ṣe pé kí ẹ yẹra patapata fún àwọn alaigbagbọ tí ń hùwà àgbèrè, tabi tí ó ní ojúkòkòrò, tabi oníjìbìtì, tabi abọ̀rìṣà.
Orebanjo Temitope sọ pé ati joko sile kii ṣe ìṣòro, ṣugbọn àti jẹun ni wàhálà.
Ọkan lara wọn ti a fi orukọ bo ni aṣiri, Josh, sọ pe nigba ti ololufẹ oun yoo kọkọ bẹrẹ si ni mu oun ni tipa-tipa lati ni ibalopọ, o maa n ṣe ara a rẹ l'eṣe, to si jẹ pe ọpọ igba ni wọn sare gbe e lọ sile iwosan fun itọju.
, bi orin ẹnikan oke ọhun.
Iye àwọn tí ó wà ninu ìpín rẹ̀ jẹ́ ọ̀kẹ́ kan ó lé ẹgbaaji (24,000).
Israel Adesanya fi ẹ̀ṣẹ́ mú ẹ̀jẹ̀ jáde nímú Whittaker láti gba àmì ẹ̀yẹ UFC A kò mọ̀ bóyá a le è san owó osù tuntun fún òsìsẹ́ - Ìjọba Ondo, Oyo, Kwara jẹ́wọ́ 'Àwọn ti Micra ló jẹ̀bi rògbòdìyàn awakọ̀ tó wáyé lánàá n'Ìbàdàn' Seun Egbegbe lo ọdún méjì àti oṣù méje lẹ́wọ̀n láì tìí san béèlì rẹ̀ Gbogbo akitiyan Quincy Promes ninu abala keji ifẹsẹwọnsẹ naa lati sọ bọọlu sinu awọn ikọ Chelsea lo ja si pabo, ko to di pe wọn parọ rẹ.
Dájúdájú, yóo ba yín wí,bí ẹ bá ń ṣe ojuṣaaju níkọ̀kọ̀.
Oríṣun àwòrán, @AnasAda04084492 Iwe naa ni osu mẹfa gbako ni Bagudu lo ni atimọle awọn nilu Texas nigba ti wọn fẹ di lapanyaka lọ si erekusu kan ni Jersey amọ se lo yara tete gba lati da miliọnu lọna mẹtalelọgọjọ dọla pada si Naijiria, ti wọn si fa le ilẹ Naijiria lọwọ pe ko lọ foju wina ẹsun kiko owo tuulu lọ soke okun.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Akọ́mọlédè àti Àṣà lórí BBC Yorùbá: Kọ̀ síi nípa iṣẹ́ tí oúnjẹ ń ṣe lára níbí Omotara pàdánù isẹ́ olówó ńlá nítorí ó fi ọtí ẹlẹ́rìndòdò sódà lá ọmọ alágbe lójú Aibọwọ fọmọlakeji ti koba gbajugbaja orí ayélujára kan to fi padanu ìṣe àkànṣe olówó ńlá to n ṣe fun ileeṣẹ ọti ẹlẹrindodo Naijiria kan.
Ó wí fún ọkọ rẹ̀ pé, “Bí mo bá ti gba ọmú lẹ́nu ọmọ yìí ni n óo mú un lọ sí ilé OLUWA, níbẹ̀ ni yóo sì máa gbé títí ọjọ́ ayé rẹ̀.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Baṣọ̀run Gáà, tó yan ọba mẹ́rin, pa ọba mẹ́rin àmọ́ ọba karùn-ún ló pa á Ẹfunsetan Aniwura, obìnrin tó ju ọkùnrin lọ Hubert Ogunde rèé, baba àwọn òsèré tíátà Wo bí o ṣe lè kọ́ ọmọ rẹ lẹ́kọ̀ọ́ ìbálòpọ̀ Itan naa ni bi ko ba si ẹsẹ, ẹsẹ kii deede sẹ, bẹẹ si ni bi ko ba ni idi, obinrin kii jẹ Kumolu.
O ni awọn ọmọ ileewe ti oun ri ni agbegbe kan n di mọ ara wọn lai tẹlẹ ofin ijinasiraẹni nitori wi pe o ti pẹ ti wọn ti ri ara wọn gbẹyin.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Fani-Kayode: Iwà Dino dójútini gẹ́gẹ́ bí olóṣèlú 25 Ìgbé 2018 Oríṣun àwòrán, Twitter Àkọlé àwòrán, Fídíò ṣe àfihàn Dino níbi tí o joko sí ilẹ̀ l'ojú títì ní Ábuja Mínísítà nígbà kan rí, Femi Fani-Kayode, ti bẹnu àtẹ́ lu ìwà Sẹ́nétọ̀ Dino Melaye, nígbà tí àwọn ọlọ́pàá ń gbée látì Abuja lọ sí Kogi tí ó sì fẹsẹ̀ fẹ.
Idi ree ti BBC Yoruba ṣe kan si ọmọ ile igbimọ aṣofin tẹlẹri ati amofin, Boluwaji Kunlere, to ti figba kan ri ṣoju ẹkun Guusu ipinlẹ Ondo nile igbimọ aṣofin l'Abuja.
Jẹ́ kí àwọn aya ati àwọn ọmọ mi máa bá mi lọ, nítorí wọn ni mo ṣe sìn ọ́.
Odunlade fẹ́ j'ọba, Bolanle Ninalowo fun ìyàwó rẹ̀ ni ẹ̀bun kanka, Pá Kasumu rebi àgbà ree Àbádòfin láti ṣàmójútó ayélujára kò lè fẹsẹ̀ múlẹ̀ láéláé, Sowore fàáké kọ́rí Sanusi dèrò ìpínlẹ̀ Nasarawa lẹ́yìn tí ìjọba Ganduje rọ̀ ọ́ lóyè Minisita fun ere idaraya ati ọrọ ọdọ, Sunday Dare fi aidunnnu rẹ han loju opo Twitter rẹ nibi to ti sọ pe o ṣeeṣe ki Martins maa ku tawọn irinṣẹ eto ilera gidi ba wa ni papa iṣere ti iṣẹlẹ naa ti ṣẹlẹ.
"Eleyi ti mu ki apapọ iye awọn to ti laarun naa lorilẹede Naijiria o di ẹgbẹrun mẹtalelaadọta ati okoolelẹẹdẹgbẹrin ati meje (53,727) Ajọ NCDC ṣalaye loju opo Twitter rẹ pe "" ni ọjọ kọkandinlọgbọn oṣu kẹjọ ọdun 2020, Igba o le aadọta eeyan lo tun kun iye awọn to ni aarun naa bẹẹni ko si ẹni to ku nipasẹ ajakalẹ aarun ọhun."
Ọjo Arafa ni Ọjọ keji Hajj ti awọn musulumi jakejado agbaye to lọ si Mecca yoo gun oke aanu arafa to sun mọ Makkah.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ẹfunroye Tinubu - Ògbóǹtagí oníṣòwò, olówò ẹrú àti afọbajẹ Samuel Ajayi Crowther, òjíṣẹ́ Ọlọ́run tó gbé èdè Yoruba lárugẹ Mọrèmi Àjàṣorò, akọni obìnrin tó gba Ilé Ifẹ̀ sílẹ̀ lóko ẹrú Ọ̀rọ̀ǹpọ̀tọ̀niyùn, Aláàfin obìnrin àkọ́kọ́ rèé, tó ní nǹkan ọkùnrin Ṣé ìwọ mọ odò adágún Adó Àwáyè tí kò ní òpin ní ìsàlẹ̀?
Gbogbo ẹ̀dá pátá: ati ẹranko ni, ati ẹyẹ, ati àwọn ohun tí ń fàyà fà, ati àwọn ẹran omi, gbogbo wọn ni eniyan lè so lójú rọ̀.
Adajọ Ayeye ni ki wọn maa gbe Udeme lọ si ọgba éwón Kirikiri nitori pe kò si aaye fún obìnrin ni ọgba ẹwọn ikoyi bayii, ṣugbọn, ó ni ki wọn fún olujẹjọ naa laaye lati maa ri ẹbí àti agbẹjọrọ rẹ̀ nidakóńkọ́.
Nítorí kì í ṣe àwọn angẹli ni ó fún ní àṣẹ láti ṣe àkóso ayé tí ń bọ̀, èyí tí à ń sọ̀rọ̀ rẹ̀.
ni eyi je, ko si afehonu han Kankan ti won yin ibon mo tabi to padanu emi re
Ogoro awon eniyan ni won ti padanu-emi won lati bi odun meta ti ifehonu-han tako ijoba ti n waye.
Ògiri ìlú náà yóo sì wó.
O ni awọn ọlọpaa ri awọn owo ati oogun naa, ṣugbọn awọn afurasi ọhun na papa bora.
Ọmọ baba kan náà ni gbogbo wa, olóòótọ́ eniyan sì ni wá, a kì í ṣe amí.
Mishram tun salaye lori awon ipenija to n dojuko ile-ise naa , pe ida ogota ninu ogorun un ni awon eniyan ti ki i sanwo ina sugbon ti won n lo ina mona-mona.
O wa ro awon ti oro kan lati
OLUWA Ọlọrun fi ọkunrin tí ó dá sinu ọgbà Edẹni, kí ó máa ro ó, kí ó sì máa tọ́jú rẹ̀.
“A ti di ẹ̀ṣẹ̀ Efuraimu ní ìtí ìtí, a ti kó ẹ̀ṣẹ̀ rẹ̀ pamọ́.
Seraaya sì ni baba Joabu, baba àwọn ará Geharaṣimu, ìlú àwọn oníṣọ̀nà.
Èmi Paulu, aposteli Kristi Jesu, nípa ìfẹ́ Ọlọrun, ati Timoti arakunrin wa, àwa ni à ń kọ ìwé yìí–
Ìyá Bándélé ni ẹni tí ó fi kọ́kọ́rọ́ dan séèfù wò náà Orímóògùnjẹ́ kò sọ ọ̀rọ̀ eni tí ó fi kọ́kọ́rọ́ dán séèfù wò yìí fún Àlàó.
com ni ọpọ eeyan bẹrẹ si ni maa kaa.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Stolen phone: Fóònù mi ni mo lọ́ tún ṣe lọlọ́pàá bá he mí pé mo jí fóònù Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 3 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Dan Bazzau to jẹ minista to n mojuto ọrọ eto abẹlẹ naa ko ni ba Buhari ṣe ijọba tuntun.
Ọlọ́mọge kan yóo lóyún yóo sì bí ọmọkunrin kan, yóo pe orúkọ rẹ̀ ní Imanuẹli.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Osun Cabinet: Kí ló fàá tí gómìna ìpínlẹ̀ osun kò fi yan kọmíṣọ́nà lẹ́yìn oṣù mẹ́sàn án?
Umar fi kun ọ̀rọ̀ rẹ̀ pé àwọn ti ń kófìrí ikọ̀ Boko Haram ní àgbègbè náà ní ọjọ́ mẹ́ta sí ìgbà ti ìṣẹ̀lẹ̀ náà wáyé.
Ibugbamu ibudo epo ni Ijegun Ibugbamu afẹfẹ gaasi meji pa ọpọ eniyan nipinlẹ Eko Alhaja Rehanat Salami, Obinrin oludari ọja naa (Iyalọja) sọ pe ina mọnamọna ijọba lo ṣe okunfa ijamba ina naa.
” Dafidi bá ra ibi ìpakà ati àwọn akọ mààlúù náà, ní aadọta ṣekeli owó fadaka.
un oro re pe, irufe ise akanse oko ojurin, eleyi ti yoo wa lati ilu Warri siluu
JAMB 2019: Wo àwọn ibùdó CBT tó wà nítòsí rẹ
Nígbà tí eniyan bẹ̀rẹ̀ sí pọ̀ sí i lórí ilẹ̀, tí wọ́n sì ń bí ọmọbinrin, 
Àwọn ololufẹ wọn si gba ti ẹ titi di òní.
won ti bura fun un ni ojo kọ́kàndínlọ́gbọ̀n osu
Folayan ni, lootọ ni wi pe Abdulfatah Yahaya Seriki Gambari, lo wa ninu awọran naa ṣugbọn wọn ko ya aworan naa ni ibudo idibo to wa ni ilu Ẹkan meje.
bí a bá tọ ́ jú ènìyàn lásìkò , àwọn egbògi agbógun ti àkóràn fún ọ ̀ sẹ ̀ mẹ ́ jọ a má a ní ipa lórí ìwọ ̀ n ọgọ ́ rin nínú ọgọrun ( 80 % ) ìṣẹ ̀ lẹ ̀ àrùn náà .
Wọn kò ní kọ́lé fún ẹlòmíràn gbé,wọn kò sì ní gbin ọgbà àjàrà fún ẹlòmíràn jẹ.
Yéèpà, òfin ìtakété síra ẹni forí ṣánpọ́n lásìkò ọdún Osun Osogbo Mo ní ọ̀rẹ́kùnrin àmọ́ n kò le ṣe abiyamọ gẹ́gẹ́ bí Adelé - Moyinolouwa Falowo Wo ọmọ Nàíjíríà tí wọn fi pósí ‘₦34m’ sin O ni ile iṣẹ ọlọpaa yoo ba àwọn ara ilu sọrọ laipẹ lori ọrọ naa, pẹlu afikun pe, iwadii n lọ lọwọ lori akọtun isẹlẹ ipaniyan to tun waye ni Akinyele lọjọ Ẹti to kọja.
Adari ajọ to n ṣo ìgbòkègbòdò àwọn to n wọ orilẹ-ede Naijiria, Ọgagun Muhammad Babandede ni iroyin ni o ṣe ikede yii.
Lọwọlọwọ, ẹgbẹrun mẹta ati ẹẹdẹgbẹta le mẹẹrindinlọgbọn (3526) eniyan to ti ni aarun naa ni Naijiria.
Ẹ máa lo ẹ̀bùn yín fún ire ọmọnikeji yín, gẹ́gẹ́ bí ìríjú oríṣìíríṣìí oore-ọ̀fẹ́ Ọlọrun.
Nítorí ọmọ ìmọ́lẹ̀ ni gbogbo yín; ọmọ tí a bí ní àkókò tí ojú ti là sí òtítọ́, ẹ kì í ṣe àwọn tí a bí ní àkókò àìmọ̀kan; ẹ kì í ṣe ọmọ òkùnkùn.
Ọwọ́ ọlọ́pàá tẹ afurasí ọkùnrin tó fipá bá ìyàwó rẹ̀ lòpọ̀, tí obìnrin náà sì gbabẹ̀ kú Awọn agbofinro ti mu afurasi kan lori ẹsun wi pe o fipa ba iyawo rẹ lopọ ti obinrin naa si gba ibẹ dreo ọrun.
Àkọlé àwòrán, Won ti ri oku Aishat leyin wakati merinlelogun ti agbara ojo gbe e lo Bakan naa ni wọn wa parọwa si awọn eniyan lati ri i wi pe wọn gbaradi fun ojo arọọrọda naa, ki gbogbo oju omi to wa layika wọn si mọ, ki omi le raaye lọ lai yawọ ile tabi sọọbu ni agbegbe wọn.
Ilé ẹjọ́ pàṣẹ kí Sẹ́nétọ̀ Elisha Abbo san N50m fún obìnrin tó fìyà jẹ Mi o fi ìgbà kankan sọ pé Buhari ni yóò jẹ ààrẹ kẹ́yìn ní Nàìjíríà- Akintoye Ninu ọrọ tirẹ, Akọwe ẹgbẹ afẹnifẹre, Yinka Odumakin ni, ọrọ akọni ni Osinbajo sọ, eleyii to fihan wi pe, ko ṣe magomago pẹlu gbogbo iṣẹlẹ to n waye ni Naijiria.
Ṣaṣa ninu awọn ọmọ Yoruba, paapaa awọn ọmọ aye ode oni ni ko tilẹ mọ iru ẹranko to n jẹ imado, anbelete itumọ owe naa.
"Bíbéèrè fún ìbálòpọ̀ gbogbo ìgbà sọ ìyàwó ilé dèrò ilé ìwòsàn Ẹ wo ìṣẹ̀lẹ̀ nípa ẹ̀sùn ìfipábánilòpọ̀ tí wọ́n fi kan D'banj ní sísẹ̀-n-tẹ̀lé Wo ojú Akeem t'Ọlọ́pàá mú pé ó fipá bá ọ̀dọ́mọbìnrin kan sùn létí odò l'Oṣun Olùkọ́ tó fi tipá gba ìbálé akẹ́kọ̀ọ́ tó fẹ́ wọ fásitì rí ẹ̀wọ̀n ọdún 21 he Ilé aṣọ̀fin Nàìjíríà ń gbèrò ẹ̀wọ̀n f'áwọn olùkọ̀ tó bá dẹnu ìfẹ́ kọ akẹ́kọ̀bìnrin Fasiti Eko ti ""Cold Room"" ni Staff Club wọn pa látàri ìwádìí BBC lórí àwọn olùkọ́ kan Iroyin sọ pe, akẹkọọbinrin naa jẹwọ pe lati igba ti awọn ti pada sileewe, ni imurasilẹ fun idanwo aṣejade, WAEC, ni olukọ naa ti n ba oun ni ibalopọ."
"Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Fásitì Bowen nílùú Ìwó di títìpa Ipinlẹ Eko kò sí lóko ẹ̀rú ẹnì kankan - Sanwo-Olu Ẹrin Ijesa, Ọ̀ṣun Oṣogbo, àwọn ibùdó ìgbafẹ́ tí ó yẹ kí o mọ̀ Olatunji added that: ""We also wish to acknowledge the fatherly role of President Muhammadu Buhari in seeking to sustain the tenets of democracy, fairness and equity in the resolution of the crisis in Ogun APC."
Patrick Day: Akẹ̀ṣẹ́ kan, Day dèrò ọ̀run lẹ́yìn tó gba ẹ̀ṣẹ́ s'órí
“Kí ló dé tí aṣọ rẹ fi pupa,tí ó dàbí ti ẹni tí ń fún ọtí waini?
Igba miran ni asiko eto idibo gomina to waye nipinlẹ Ekiti l'ọdun 2018.
N óo run gbogbo àwọn tí wọ́n ṣẹ́kù ní ilẹ̀ Juda tí wọ́n gbójú lé àtilọ máa gbé ilẹ̀ Ijipti, wọn kò ní ku ẹyọ kan ní ilẹ̀ Ijipti.
Ko si ẹni to wọ jẹsi rẹ nọmba 10 lati igba naa Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ipenija lilo oogun oloro jẹ iṣoro kan to ba Maradona finra to si mu ki o maa tobi Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Maradona ati Messi lasiko to n ṣe akọnimọọgba Argentina Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Mraadona di aṣọ ti wọn ya aworan rẹ si lasiko ti Argentina n koju Naijiria Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Iye awọn ti yoo farahan niwaju ile naa ko mọ sibẹ o.
ṣẹ fara mọ́ọ tí wọ́n sì tìí lẹ́hìn gbaingbain.
Gbogbo bi Kiddwaya àti Trikytee ṣe gbìyànjú tó lati pẹtù si, Erica ò gbọ́ rárá.
Reno ni Atiku salaye pe, o jẹ iyalẹnu fun oun pe, aarẹ Buhari ko si nibẹ, eyi lo jẹ ki oun naa kọ lati kopa ninu eto ọhun.
Nítorí gbogbo ẹni tí ó ti ṣe ìrìbọmi nípa igbagbọ ninu Kristi ti gbé Kristi wọ̀.
Ó da òrùka wúrà mẹrin, ó jó ọ̀kọ̀ọ̀kan mọ́ igun kọ̀ọ̀kan àpótí ẹ̀rí náà, òrùka meji lẹ́gbẹ̀ẹ́ kinni, meji lẹ́gbẹ̀ẹ́ keji.
Ọkunrin náà tún jáde lọ ní agogo mejila ọ̀sán ati ní agogo mẹta ọ̀sán, ó tún ṣe bákan náà.
Ọlọpaa Naijiria lo n gba owo to kere julọ Ẹẹdẹgbẹsan dọla owo Amẹrika, iyen ẹgbẹrun lọna ẹẹdẹgbẹrin o din diẹ Naira ni wọn fi n yanju bukata ile aye wọn lodun.
Oríṣun àwòrán, NTANewsNow/NCDCgov Apapọ awọn to ni arun ọhun bayii ti pe 105,478, awọn 83,830 ti ri iwosan nigba ti awọn 1,405 ti jẹ |olọrun nipe.
Ẹnu mi yóo máa sọ̀rọ̀ ìyìn OLUWA;kí gbogbo ẹ̀dá máa yin orúkọ rẹ̀ lae ati laelae.
Àdó okoró búrẹ́kẹ' Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 3 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 5 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Ẹ̀san ohun tí mo ṣe sí wọn ni Ọlọrun ń san fún mi yìí.
 Ìletò kan tí kò jìnnà sí lápá-edé ni Ògìrììyàndá , fún ìdí èyí bí ènìyàn só fẹ ́ ẹ ́ lásán , wọ ́ n á gbọ ́ ní Ògìriìyàndá .
Igi tí ó tóbí àti ọ̀pẹ tí ó ga pẹ̀lú àfòmọ́ ara wọn pọ̀ gidigidi, àwọn ẹranko mìíràn sì ń gbé orí ọ̀pẹ tí ó tóbi; àwọn ẹyẹ tí ẹnu wọ́n rí ṣóńṣó kò jẹ fi ọrùn ọ̀pẹ siré nítorí kí wọn má ba pa àdánù àtiri ẹyìn ọ̀pẹ jẹ, ọ̀kẹ́rẹ́ kì í fẹ́ẹ́ pínyà pẹ̀lú ìtàkùn, àwọn ejò tẹ́ẹ̀rẹ́ a máa wá ibi kọ́lọ́fin kiri, ejò ọká ń ba búrúbú’r lábẹ̀ koríko, òjòlà ń gbé etí odò, bẹ́ẹ̀ ni ogunlọ́gọ̀ ejò olóró kò jẹ́ fi inú ihò ṣirè; ìgbín fẹ́ràn ibi tútù, ìjàpá fẹ́ ìtí, ẹ̀lúùlu ń fò lágbeedeméjì, ṣùgbọ́n àdàbà ń káàkiri ibi gíga, ẹyẹ náà sì dúró bí àkùkọ inú aginjù tí ń ràn àwọn ọdẹ létí àkókò; àwọn igi tí ó ti wó lulẹ̀ láti ọjọ́ tí í ti pẹ́ kò lágbára mọ́, olú ń hù lára wọn; ojú ọ̀nà àwọn ẹrnako yàtọ̀ sí ara won, ojú ọ̀nà èekúté rí tẹ́ẹ́rẹ́ ó si ń dán kooro, ṣùgbọ́n ojú ọ̀nà ìmàdò gbòòrò púpọ̀, ó rí gbẹ̀rẹ̀gẹ̀dẹ̀-gbẹrẹgẹdẹ.
Ẹwẹ, ajọ ẹlẹyinju aanu miran, Mercy Corps kede lọjọru pe awọn alaṣẹ Naijria ti sọ agadagodo si ileeṣẹ awọn to wa ni Maiduguri ti wọn si ni kawọn dawọ iṣẹ duro lagbegbe naa.
INEC ṣalaye pe ogun ninu awsn iwe ẹrin marundinlọgbọn ti wọn gba pada naa lo kan awọn oludije ẹgbẹ oṣelu APC, meji kan awọn oludije ẹgbẹ oṣelu PDP.
Sugbọn ọrọ naa bẹyin yọ, ti awọn ọdọ yii si din dundun iya fawọn osisẹ ajọ amunawa naa ni ọọfisi wọn.
Ṣugbọn ko ri èrè kankan jẹ nibẹ.
Iléeṣẹ́ Ọlọ́pàá tí kọ́kọ́ kéde ẹ̀bùn owó #500, 000 fún ẹni tó bá rí Sunday Shodipe, afurasí tó sọnù lórí ikú àwọn èèyàn Akinyẹle Oríṣun àwòrán, Nigeria police force Ileeṣẹ ọlọpaa ipinlẹ Oyo ti kede ẹgbẹrun lọna ẹẹdẹgbẹta naira gẹgẹ bi owo ti oun yoo fun ẹnikẹni to ba le e ṣamọna bi wọn ṣe le e mu afurasi to lọwọ ninu iṣekupani to waye ni ipinlẹ naa, Sunday Shodipe.
Orúkọ tí ó sì sọ wọ́n ni wọ́n ń jẹ́.
Ẹnu ọ̀nà náà ní àwọn fèrèsé tóóró tóóró yíká, tí ó ga kan àwọn àtẹ́rígbà àwọn yàrá ẹ̀gbẹ́.
Ẹ sin ọba Babiloni, kí ẹ lè wà láàyè.
Nípasẹ̀ Kristi ni a ti ní ìdáǹdè nítorí ẹ̀jẹ̀ tí ó ta sílẹ̀.
O ní ìjọba olọgun ló de, to ba gbogbo ètò ìṣèjọba Nàìjíríà jẹ́ gẹ́gẹ́ bi ìlàna ìwé ofin, nítori pe ẹyàmẹya ló pa Nàìjíríà pọ, kìí ṣe ẹ̀yà kan náà.
Lara awọn ọmọ Yoruba jankan-jankan miran to tun ba ọdun 2020 naa lọ ni Oloye Harry Makinde, Abayomi Jolaoso, Gbolabo Ogunsanwo ati Richard Akinjide.
Ni kete ti ile ẹjọ paṣẹ ki Adams Oshiomole o fi ipo silẹ ni ẹgbẹ oṣelu APC ti kede rẹ pe Sẹnetọ Abiola Ajimọbi gẹgẹ bi adele alaga apapọ ẹgbẹ oṣelu naa.
“O kò gbọdọ̀ ṣe ojúkòkòrò sí ilé ọmọnikeji rẹ, tabi sí aya rẹ̀ tabi sí iranṣẹ rẹ̀ lọkunrin ati lobinrin, tabi sí akọ mààlúù rẹ̀, tabi sí kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ rẹ̀, tabi sí ohunkohun tí ó jẹ́ ti ọmọnikeji rẹ.
 bí a bá sọ pé orin kan dára , èdè rẹ ̀ ló wuyì .
Ẹgbẹ agbabọọlu naa ti ba awọn ẹbi ati ọrẹ Reyes kẹdun lori Twitter.
“Ní àkókò ìkórè, kò ní sí èso lórí àjàrà,igi ọ̀pọ̀tọ́ kò ní ní èso lórí,àwọn ewé pàápàá yóo gbẹ,ohun tí mo fún wọn yóo di ti ẹlòmíràn.
Gbajabiamila kéde èróńgbà rẹ̀ láti jẹ adarí ilé aṣojú ṣòfin l'Abuja Awakọ̀ òfúrufú Ethiopian Airlines pariwo 'lọ sókè!
Nítorí pé o tóbi, o sì ń ṣe ohun ìyanu;ìwọ nìkan ni Ọlọrun.
Coronavirus in Osun: Ènìyàn mẹ́fà míràn ní àrùn Coronavirus ní ìpínlẹ̀ Ọ̀ṣun Ajọ to n gbogun ti ajakalẹ arun lorilẹede Naijiria, NCDC ti kede pe awọn tun ti ṣawari eeyan mẹfa miran to ni arun Coronavirus ni ipinlẹ Ọṣun.
"Iya ni ọpọ eeyan ti ko yin Ajimobi loju aye rẹ, amọ ti wọn n yin lẹyin to ku tan yoo jẹ niwaju Ọlọrun, nitori igba to wa laye lo yẹ ki wsn sọ daada nipa rẹ.
Ìtàn fi ye wá pé ó tó mílíọ̀nù lọ́nà àádọ́ta èèyàn ló bá ajakalẹ àrùn Maáwú-maáwú yìí lọ, èyí tó bẹ silẹ laarin ọdún 482 sí 565 CE, to sì gba to ọdún metalelọgọrin kò to kaṣẹ nilẹ.
Gernot Rohr, akọ́nimọ̀ọ̀gbá Super Eagles ti ni Ola Aina àti Chidozie Awaziem lo máa di ẹ̀yìn ilé mú nínú ìdíje òní.
Aisha Buhari, ohun mẹ́fà tò fi yàtọ̀ sí àwọn aya ààrẹ tó ti jẹ kọjá!
Ọ̀nà tí a fi mọ̀ pé Ọlọrun ń gbé inú wa ni nípa Ẹ̀mí tí ó ti fi fún wa.
Àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ ranti àkọsílẹ̀ kan tí ó kà báyìí, “Ìtara ilé rẹ ti jẹ mí lógún patapata.
Ọga agba ileeṣẹ naa, Olajide Oduyoye lo fi idi ọrọ naa mulẹ fun BBC.
Ibeere to n suyọ lẹnu awọn ọmọ Naijiria ni wi pe kini yoo sẹlẹ si isẹ awọn osisẹ Diamond Bank, lẹyin ti ile ifowopamọsi naa kede wi pe awọn yoo darapọ mọ ile ifowopamọsi Access.
Lẹ́yìn náà, Amasaya ranṣẹ sí Jehoaṣi, ọmọ Jehoahasi, ọmọ Jehu, ọba Israẹli, láti pè é níjà sí ogun.
O fi iye arinrinajo yii we eleyi ti papakọ ofurufu South Africa n ri ni lọdọọdun.
Ilé aṣòfin àgbà yọ gómìnà nípò, ẹni tó fi owó ìlú rán ọmọ lọ sí Amẹ́ríkà Amẹ́ríkà yarí pé àwọn agbégbọn tó jí akẹ́kọ̀ọ́ 344 gbọ́dọ̀ fojú winá òfin Ẹ̀ẹ̀kan láàrin ọjọ́ méjì là ń jẹun ní ìgbèkùn, ìyà jẹ wá - Akẹ́kọ̀ọ́ Kankara ṣàlàyé Sé Boko Haram ń pẹ̀ka kiri Nàíjíríà ní ìjínigbé ṣe burú báyìí?
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìgbàjọba Seyi Makinde: Hosea Agboọla, Bisi Ilaka wà lára ọmọ ìgbìmọ̀ 4 Ìgbé 2019 Oríṣun àwòrán, Seyi makinde Gbogbo eto lo ti de bayii fun igbesẹ igbejọbakalẹ lati ọwọ Gomina to wa lori oye Abiọla Ajimọbi si eleyi ti araluu dibo yan nipinlẹ Oyo, Seyi Makinde.
Ọjọ iṣẹgun ni awọn olukọ labẹ ASUU lọgba fasiti naa to darapọ mọ iyanṣẹlodi lẹyin ipade wọn.
Ọpọ ọmọ orilẹede yii, paapaa julọ awọn ti wọn fi si idi iṣẹse ẹya kọọkan ni wọn ti n fi ẹhonu han lori ohun ti o n faa gan an ti ijọba kii fi kede isinmi lẹnu iṣẹ fun awọn oṣiṣẹ lasiko awọn ọdun iṣẹse.
Rẹrẹ run Àkọlé àwòrán, Isẹ kekere kọ ni awọn panapana se lati ka ọwọja ina ọhun ko, kekere kọ.
Ẹkọ na mi lowo gaan"", eyi lo sọ."
Titi di aṣalẹ ọjọ Aiku tii ṣe ọjọ kẹrindinlọgbọn oṣu kẹrin ọdun 2020, ipinlẹ mejilelọgbọn lo ti ni aarun Coronavirus lorilẹede Naijira pẹlu olu ilu ilẹẹwa, Abuja.
Gbogbo nǹkan yìí ló ṣẹlẹ̀ sí wa,bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé a kò gbàgbé rẹ,bẹ́ẹ̀ ni a kò yẹ majẹmu rẹ.
Wọ́n mọ kànnàkànnà ta, tóbẹ́ẹ̀ tí ó jẹ́ pé wọ́n lè ta á mọ́ fọ́nrán òwú láì tàsé.
EndSARS Protest: Wo bí olùwọ́de EndSARS, Eremosele Adene ṣe gba òmìnira lọ́wọ́ ọlọ́pàá
1 Nísisìyí, kíyèsíi, mo wí fún ọ, pé nítorí tí o gbé àwọn ohun kíkọ wọ̃nnì tí a ti fi agbára fún ọ láti túmọ̀ nípasẹ̀ Urímù àti Túmmímù, sílẹ̀ sí ọwọ́ ènìyàn búburú, ìwọ ti sọ wọ́n nù.
Ẹ̀mí sùn níbi ìkọlù ìpínlẹ̀ Zamfara Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Adigunjalè pa ọ̀pọ̀lọpọ̀ ní ìpínlẹ̀ Zamfarà Àwọn agbébọn kọlu ìlú Kabaro àti ìlú méjì míì ní ìjọba ìbílẹ̀ Maru, ìpínlẹ̀ Zamfara lápá ìwọ̀ oòrùn àríwá orílẹ̀èdè Nàìjíríà.
nínú mathematiki , àwon nọ ́ mbà àdábáyé , tàbí nọ ́ mbà àdábá ( natural number ) lé jé òkan nínú àkójopò { 1 , 2 , 3 .
''Ẹyin ti ẹ lo hydroxychloroquine ti ara yin si ya, ẹ bọsita wa jẹri mi'' Dokita Stella Immanuel ti kesi gbogbo awọn ti oun ati awọn Dokita miran ti tọju pẹlu oogun hydroxychloroquine lati yọju lati wa jẹri si iṣẹ rere ti oogun yi ṣe lagọ ara wọn.
N óo gba àwọn aguntan mi sílẹ̀, wọn kò ní jẹ́ ìjẹ mọ́, n óo sì ṣe ìdájọ́ láàrin aguntan kan ati aguntan keji.
Wọn fikun wi pe igbese ti bẹrẹ lati ri wi pe wọn dẹkun bi awọn eniyan ṣe n da idọti si oju omi, eleyii to ti fa ki oju odo o kun ni akunfaya.
Má ṣe kọ ọgbọ́n sílẹ̀, yóo pa ọ́ mọ́,fẹ́ràn rẹ̀, yóo sì dáàbò bò ọ́.
yoo si jẹ anfaani awon ara ilu” .
O fikun pe ilẹ Yoruba yoo mọ iku agba oselu naa lara, to si gbadura pe ki Ọlọrun tẹ si afẹfẹ rere.
Ògiri ni mí,ọmú mi sì dàbí ilé-ìṣọ́;ní ojú olùfẹ́ mi,mo ní alaafia ati ìtẹ́lọ́rùn.
Pẹ̀lú abẹ̀rẹ̀ àjẹsára yìí, ẹ̀fọn kankan kò lè mú àìsàn ibà wá NMA: Ngige kò nímọ̀ nípa àwọn dókítà Naijiria, irọ́ ló ń pa Ṣé o mọ̀ pé láàrín ìṣẹ́jú méjì, ọmọdé kan ń kú?
Oríṣun àwòrán, WCS Nigeria Iroyin ni awọn ẹranko naa n gbe lawọn ibi to ni oke giga ni Naijiria, ati ni orilẹ-ede Cameroon, ṣugbọn wọn ṣoro lati ri.
"Ṣugbọn bi ko ba si bori, gbogbo atilẹyin ti awọn ọmọ Naijiria n fun un wu mi lori jọjọ""."
Oríṣun àwòrán, AFP Olori alatako Buhari ninu eto idibo to n bọ, Atiku Atiku Abubakar, sọ pe eto ọrọ aje Naijiria ko buru to boṣe wa bayi ri.
OLUWA bá mi sọ̀rọ̀; ó ní, “Dúró sí gbọ̀ngàn ilé OLUWA, kí o sọ gbogbo ọ̀rọ̀ tí mo pa láṣẹ fún ọ pé kí o sọ fún gbogbo àwọn ará ìlú Juda tí wọn ń wá jọ́sìn níbẹ̀.
" Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Alaafin: Olori Aanu Adeyemi ṣàlàyé ìdí tó ṣe gẹ́ Oba Lamidi Adeyemi ti ìlú Oyo O ni oun ko tun jẹ ni ọkọ nile olorogun mọ, nitori iriri ti oun ni.
wa ni agbegbe Agodi nilu Ibadan, to je olu-ilu ipinle Oyo ni ekun  Gusu , orile ede Naijiria.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ojú òpó ajàfẹ́tọ̀ọ́ ẹni: Àádọ́ta lọ́yà ló wà ń bẹ̀ láti jà fún ọ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Ojú òpó ajàfẹ́tọ̀ọ́ ẹni: Àádọ́ta lọ́yà ló wà ń bẹ̀ láti jà fún ọ 1 Èbibi 2018 Ǹ jẹ́ o mọ ẹ̀tọ́ rẹ lábẹ́ òfin?
Naijiria ati awon orile ede ekun Chad yoo ri to milionu mejidinlaadofa nigba ti agbegbe South Sudan yoo ri milionu merinlelogosan ti Ethiopia yoo ri aadofa milionu dola owo dola.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Tani: Boko Haram ló lé àwọn òbí rẹ̀ lọ sí Amẹrika 18 Ẹrẹ̀nà 2019 Ọmọ ọdun mẹjọ ni Tanitoluwa Adewunmi wa, to fi kopa pẹ́lu awọn akẹẹgbẹ rẹ ti wọn jẹ ọjẹ wẹwẹ nilẹ́ Amẹrika, fun idije ẹni to pegede julọ ninu idije ayo Chess.
Jibri sọ ọrọ naa gẹgẹ bi alatilẹyin ẹgbẹ awọn oniṣowo aṣọ ni Naijiiria, lẹyin to ti ṣe iṣẹ gẹgẹ bi oniṣowo aṣọ fun ọdun marundinlaadọta.
Ẹ gbọ́ ọ̀rọ̀ yìí, ẹ̀yin ará ilé Jakọbu,ẹ̀yin tí à ń fi orúkọ Israẹli pè,ọmọ bíbí inú Juda,ẹ̀yin tí ẹ̀ ń forúkọ OLUWA búra,tí ẹ jẹ́wọ́ Ọlọrun Israẹli,ṣugbọn tí kì í ṣe pẹlu òdodo tabi òtítọ́.
Dalemoṣu yii lo sa ere ori papa naa larin iṣẹju mẹwaa o le diẹ, lati gba ife ẹlẹẹkẹjọ iru rẹ ti yoo gba.
Àwọn ọmọ Israẹli pa ọ̀kẹ́ kan ati ẹgbẹẹdọgbọn ó lé ọgọrun-un (25,100) eniyan ninu àwọn ará Bẹnjamini lọ́jọ́ náà.
Àwọn obinrin náà sì mú kí ọkàn rẹ̀ ṣí kúrò lọ́dọ̀ Ọlọrun.
ati pé kí wọ́n máa ranti àwọn ọjọ́ wọnyi, kí wọ́n sì máa pa wọ́n mọ́ láti ìrandíran, ní gbogbo ìdílé, ní gbogbo agbègbè ati ìlú.
O kilọ fun awon ti won  ba gbiyanju lati da wahala silẹ lasiko eto
Oúnjẹ yìí lékenkà tóbẹ́ẹ̀gẹ́ ó sì jẹ́ nkan ìwúrí fún orílẹ̀èdè yìí.
Pius Adesanmi: Ọ̀gọ̀ọ̀rọ̀ èèyàn ń dárò ọ̀jọ̀gbọ́n ọmọ Nàìjíríà tó kú nínú ìjàmbá bàálù Ethiopia
Mà á fún àwọn ọba alayé ní ojúṣe nínú ìjọba mi - Seyi Makinde Seyi Makinde yan obìnrin míràn sípò akọ̀wé ìjọba SSG Àjọ DSS ti gbọ̀ngàn ìpàdé #RevolutionNow pa ní Ikeja O tó gẹ́; A kò fẹ́ ìwòkuwò mọ́ ní Nàijíríà- Roṣẹwẹ (NCAC) Kọmiṣonna nigba kan ri naa beere fun asiko diẹ sii ki oju fi fara balẹ rimu ki wọn fi le gbe igbesẹ to yẹ lati koju iṣoro kari aye yii.
ati àwọn aṣọ fẹ́lẹ́fẹ́lẹ́ funfun, àwọn ìborùn olówó ńlá.
Lati ọwọ Marje ni Montreal ni Canada Iroyin BBC Ikọ eleto ilera O ṣeeṣe ki Covid 19 ja si otutu Niumoníà nigba kọọkan lara awọn to ni ailera ẹdọ-fooro tẹlẹ Sugbọn nitori pe arun tuntun ni coronavirus jẹ, ko si ẹni to le ni ohun eelo igbogun ti ni agọ ara yala Niumonia tabi Sars ti wa lara wọn ri End of Ilera Mi Didaabo bo ara mi ati awọn elomiran Ibeere yin Skip Didaabo bo ara mi ati awọn elomiran Ki lo de ti ijọba n gbe igbesẹ nla yii nipa coronavirus nigba ti otutu ọginiti n ṣọṣẹ to buru juu lọ?
Oun ni abẹnugan ile igbimọ aṣofin ipinlẹ Imo laarin ọdun 2011 si 2015.
Láti ìṣẹ̀dálẹ̀ ayé a kò rí i gbọ́ pé ẹnikẹ́ni la ojú ẹni tí wọ́n bí ní afọ́jú rí.
Awọn alulu fọba ti orilẹ ede naa ti wa lẹnu rẹ bayii bii Ogoji Ọdun.
Àwọn aládùúgbò rẹ̀ ati àwọn mọ̀lẹ́bí rẹ̀ gbọ́ pé Oluwa ti ṣàánú pupọ fún un, wọ́n wá bá a yọ̀.
Bi nnkan ti ṣe ri lọwọ yi, o ṣeeṣẹ ki ile asofin ma yanju ọrọ Magu ki Magu si ma ba isẹ rẹ lọ titi ti awọn asofin mii yoo fi wọle.
O sọ pe awọn doola ẹmi awọn akẹkọọ wọnyi ti wọn si ti darapọ mọ awọn mọlẹbi wọn.
microbiota ojú ara tí kò lárùn ní àwọn ẹ ̀ yà tí kò kìí ṣe okùnfà àmì , àkóràn tàbí àkóbá fún oyún .
Èrò àwọn ọmọ Naijiria ṣọ̀tọ̀ọ̀tọ̀ lórí Tinubu àti Abbo Kíló burú nínú kí Sanwo-Olu fún Super Eagles lówó?
Kò ṣe bẹ́ẹ̀ fún orílẹ̀-èdè kankan rí,wọn kò sì mọ ìlànà rẹ̀.
Awon akoroyin ti won je omo igbimo tuntun yii yoo seto ipolongo tuntun lori oro ifetosomobibi ti yoo fi see maa jiroro le lori nibi gbogbo.
Pẹlu gbogbo ọrọ alaye yii, ohun to daju nipe o digba ti Ifa ba to paṣẹ pe ki wọn ṣe bẹẹ fun ọmọ Ọọni tuntun ki o to lee ri bẹẹ.
Olówó-ayé, ojú ẹbọra ń wò ọ́, ojú ènìyàn ń wò ọ́, gbogbo alààyè ló pé sí inú Igbó Olódùmarè bámúbámú, àti bẹ́ẹ̀ bẹ́ẹ̀ lọ, àti bẹ́ẹ̀ bẹ́ẹ̀ lọ.
Adeleke Shittu to jawe olubori ninu idibo abẹlẹ ẹgbẹ oselu PDP ni iroyin fi lede wi pe o fi ipo rẹ silẹ fun sẹnetọ naa.
Tory leadership: Àwọn olùdíje náà ni Boris Johnson, Michael Gove àti Jeremy
Wọn ni o ma n fi agbara kun agbara wọn.
'Àwa ọmọ Nàìjíríà tó farapa fẹ́ wálé láti Lebanon, ìjọba kó wa pamọ́' Ọlọ́run nìkan ló mọ bí ìrìnàjò ìfẹ́ ẹ̀dá á ṣe rí láyé, ọ̀dọ́ Aláàfin ní orí gbémí yà sí, ó sì tẹ́milọ́rùn- Olorì Aanu Èèyàn 334 ló gbàwòsàn lọ́wọ́ Covid-19 l'Ọjọru, 453 míì tún lùgbàdì rẹ̀- NCDC Alakoso iboji Abbatuwa, Malam Danbaba Muhammad ni o yẹ ki ijọba ipinlẹ Kano kọ awọn iboji tuntun.
Bí o kò bá sì fẹ́ bẹ́ẹ̀, ibi tí ó bá wù ọ́ láti lọ ni kí o lọ.
A máa rán mi ni iṣẹ́ lọ́sàn-án a máa rán mi ni iṣẹ́ lóru, a máa rán mi ní ìṣẹ́ ní ìkọ̀kọ̀, amáa rán mi ní iṣẹ́ ní gbangba, kò kí mi ‘kú iṣẹ́’ lọ́jọ́ kan rí a sì máa fa ojú ro láti òwúrọ̀ di ojú alẹ̀ koko, nítorí èmi bẹ̀ ọ́, bá mi wí fún Ọlọ́run Ọba wí pé kí Ó fi mí sí abẹ́ ẹlòmíràn tí yóó maa ṣe ìtọ́jù mi.
Wọn ri i daju pe ifarahan rẹ ni gbangba ko pọju, wọn fi alafo diẹdiẹ si ipolongo ibo, eyi to mu ki adinku ba aarẹ tabi isọkusọ to le fa wahala.
Ìjàpá kì í lọ kí igbá ẹ̀hìn rẹ̀ gbé ilẹ̀, ibi tí ìgbín bá ń lọ tòun tìkarawun ní ń lọ.
Nitori idi eyi nikan, o fihan pe Tinubu ni onilu to lu fun iromi Buhari , ati idagbasoke ẹgbẹ APC.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Demilade Adepegba: Mo má a ń gbàgbé fèrè ni, tí mo bá wà nílé ìwé Bayii ni Musa bẹrẹ si ni ṣe ijọba lẹyin ti ẹgbọn rẹ lọ ajo aremabọ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Child marriage: $3,500 la gbà láti fa ọmọ ọdún márùn-ún f'ọ́kọ 26 Ìgbé 2019 Oríṣun àwòrán, iSok Àkọlé àwòrán, Omobinrin Ọdun marun ni Nazanin ti ni ọrẹkunrin ti yoo fẹ.
O pọn dandan ki a bere amọran lọwọ awọn onimọ nipa irinajo nitori wọn ni imọ pupọ nipa ibi ti a n lo, ati iru ijamba tabi ewu to wa nibẹ.
Ni bayii, Enrique yoo ropo Julen Lopetegui, eni ti ajo naa gba ise lowo re losan kan oru kan ki idije boolu agbaye bere lataari ifenuko re pelu iko agbaboolu Real Madrid lati maa tuko won.
Ẹsẹ̀ ni yóo fi tẹ adé ìgbéragaàwọn ọ̀mùtí ilẹ̀ Efuraimu.
Ẹni tí ó bá fi ara da ìdánwò kú oríire, nítorí nígbà tí ó bá yege tán, yóo gba adé ìyè tí Ọlọrun ṣe ìlérí fún àwọn tí ó fẹ́ràn rẹ̀.
Eero ti Nikks Omotoso Bolarinwa yatọ gedegbe.
Ọba Israẹli bá ranṣẹ sí àwọn eniyan tí ń gbé ibi tí Eliṣa kilọ̀ fún un nípa rẹ̀.
Oni oun gbe igbesẹ naa latari ilokulo oògùn ikọ́ ti o ni codeine ninu ni orile-ede yii.
“Ṣugbọn ẹ má bẹ̀rù, ẹ̀yin ọmọ Jakọbu, iranṣẹ mi,ọmọ Israẹli, ẹ má fòyà;n óo gbà yín là láti ọ̀nà jíjìn,n óo kó arọmọdọmọ yín yọ ní ilẹ̀ ìgbèkùn.
O fi kun ọrọ rẹ pe tohun ti pe awon ribi sa asala kuro lọwọ awọn to mu awọn, oju buruku lawọn to ku ni aaye t'awọn atipo fori pamọ si to wa ni Bama ni Iwọ oorun ariwa Naijiria fi n wo awọn.
Ẹ ro ẹjọ́ yín fún wọn, wọn yóo sì bá yín dá a.
Yusuf lo pilẹ ẹgbẹ naa amọ lẹyin iku rẹ lọwọ awọn ọlọpaa lọdun 2009 ni Abubakar Shekau kede ara rẹ lẹyin ọdun meji iku Yusuf gẹgẹ bi olori Boko Haram.
Tí a o ba tètè pẹ̀ka ìrókò rẹ̀ nísinyìí ẹbọ ni yoo ma gba.
Eyín oníròyìn fò yọ lásìkò tó n ka ìròyìn lọ́wọ́ lórí tẹlifísàn Ààrẹ Buhari fi ọ́fíìsì reluwé tó wà ní ìlú Agbor sọríi ààrẹ àná, Goodluck Jonathan Àwọn ọ̀dọ́ ilẹ̀ Yoruba kò gbọdọ̀ gbàgbé àṣà ati ohun àdàyébá wọn - Ooni Ile Ife Ipinlẹ Eko lo moke julọ pẹlu eeyan marundinlọgọfa ti Kwara si tẹle e pẹlu eeyan marundinlaadọrun ti Enugu ati olu ilu ilẹẹwa Abuja si tẹlee pẹlu ọgọrin ati mejidinlọgọrin ni ṣiṣẹ n tẹle.
Àkọlé àwòrán, Àwọn obinrin Kano naa jade wa dibo abẹlẹ APC Akọroyin BBC to wa ni Adamasingba ni ọpọ awọn oludibo lo ṣi wa nita abawọle papa iṣere naa ti wọn koi tii raaye wọle, bẹẹ, ko tii si oludije kankan to tii de.
Imo to jinle ati ipinnu to yanranti ninu ise-akanse awon omo-ogun ijoba, ti a mo si ‘Operation Deep Punch 2’ lo sokunfa isubu aginju Sambisa, ti o wa ni apa ariwa ila-orun orile-ede Naijiria.
O ni ọpọlọpọ awon obinrin naa ni yoo ti bimọ, ki wọn to de ileewosan.
Nítorí náà, bí Ọmọ bá sọ yín di òmìnira, ẹ óo di òmìnira nítòótọ́.
ẹ ṣọ́ra kí ẹ má baà gbàgbé OLUWA tí ó mú yín jáde láti ilẹ̀ Ijipti, níbi tí ẹ ti jẹ́ ẹrú.
”Siba dá ọba lóhùn pé, “Ó wà ní ilé Makiri, ọmọ Amieli, ní Lodebari.
pelu orile-ede Egypt, Democratic Republic of Congo ati Uganda Bi idije AFCON Egypt 2019 yoo se je igba mejidinlogun ti orile-ede Naijiria yoo kopa ninu idije AFCON, idije todun yii ti orile-ede Zimbabwe yoo kopa ninu re ni yoo di igba merin in pere ti  Zimbabwe yoo kopa fun idije AFCON.
Bẹẹ ni ọrọ ri fun ilumọọka osere tiata Yoruba lobinrin, Esther Idowu Phillips taa mọ si Mama Rainbow, ẹni to pe ọdun mẹtadinlọgọrin loke eepẹ loni.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Àràbarà pósí rèé, ibùgbé ìkẹyìn tó jẹ ojú ní gbèsè Hubert Ogunde rèé, baba àwọn òsèré tíátà Samuel Ladoke Akintọla jẹ́ Agbẹjọ́rò àti Akọ̀ròyìn tí ọ̀rọ̀ dá lẹ́nu rẹ̀ OPC ní olórí tuntun, igun New Era OPC yarí Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Tọkọ-taya Aràrá: Àwọn èèyàn máa ń wò wá, ta bá fa ọwọ́ ara wa ní títì Wayi o, Gomina ipinlẹ Kwara, Abdulfatah Ahmed ti ba Emir tilu Lafiagi, Alhaji Saadu Kawu Haliru kẹdun,lori iku awọn eeyan to ba ijamba omi naa lọ.
O sọ fun awọn ọtẹlẹmuyẹ pe owo lo fa ede ayede laarin oun ati ọmọ ogun ọhun ti oun fi da ẹmi rẹ legbodo.
Lara awọn dukia naa ni ile ti Toke n gbe.
Ilẹ̀ náà kún fún ìpànìyàn, ìlú yìí sì kún fún ìwà àìṣẹ̀tọ́.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ọṣun Decides:'Màá san gbogbo owó oṣù òṣìṣẹ́ lékunréré'-Akinbade Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Ọṣun Decides:'Màá san gbogbo owó oṣù òṣìṣẹ́ lékunréré'-Akinbade 18 Owewe 2018 Akinbade ni òun kò gbàgbọ́ nínú ìdajì owó oṣù.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Pẹlu ilana tí ijọba gbe kalẹ yii, ọpọ àwọn ilé ìjọsìn n gbero lati ko idaji ọmọ ijọ wọn jọ lati ṣe ìsìn, ki gbedeke akoko isede to to.
Mo wá gbọ́ ohùn OLUWA ó ní, “Ta ni kí n rán?
Bí a bá rí ẹni kankan tí ó dà bíi pé ó ní àìsàn kankan, a ó fa ẹni náà lé àwọn òṣìṣẹ́ ìlera tó wà ní pápákọ̀ òfurufú lọ́wọ́ lẹ́sẹ̀kẹsẹ̀."
Lẹ́yìn náà ni Solomoni kọ́ ìlú Milo.
Lara awon to tele igbakeji aare ni minisita fun ipinle lori  eto ile-ise ati okoowo, Aisha Abubakar ati minisita fun ipinle lori  eto isuna ati eto ilana ise ,Zainab Ahmed Ademola Adepoju.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Èyí ni díẹ̀ lára ìgbà tí Buhari àti àwọn aṣòfin gbéná wojú ara wọn 15 Èbibi 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images/Yakubu Dogara Lọjọ Iṣẹgun ni Aarẹ Muhammadu Buhari sọ pe oun ko ni ibaṣepọ to dara pẹlu ile aṣofin ikẹjọ l'orilẹede Naijiria.
9% Owo tijọba yoo maa pa wọle yoo ru gọgọ si ti yoo ba fi di osu Kinni ọdun 2020, ti yoo si di biliọnu mẹta naira lai jẹ pe owo ori awọn araale fo soke si Gomina Makinde wa fi ọwọ gbaya pe gbogbo owo ti oun ba na, ni oun yoo se atupalẹ rẹ fun araalu, ti eto isuna ọdun 2020 yoo se amusẹ rẹ doju ami Makinde wa rọ ile asofin lati tete se agbeyẹwo aba isuna naa, ki wọn si fọwọsi, ki amusẹ rẹ lee gberasọ loju ọjọ.
Bí ẹni pé, gbogbo àìdára tí Ahabu ọba ṣe bíi ti Jeroboamu, ọmọ Nebati, kò burú tó, ó tún lọ fẹ́ Jesebẹli ọmọbinrin Etibaali, ọba Sidoni, ó sì ń bọ oriṣa Baali.
Mose sọ fún àwọn olórí àwọn ẹ̀yà Israẹli àwọn ohun tí OLUWA pa láṣẹ: 
Ọ̀rọ̀ sísọ lórí ayélujára ti ń rí ìfúnpa láti ọwọ́ ìjọba díẹ̀ díẹ̀.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: ‘N5000 ni wọ́n ta ìbò Ondó,Edo àti Anambra’ Ìkọlùkọgbà ńrúgbó bọ̀ pẹ̀lú ènìyàn 200m Winne aya Mandela - Ó dìgbà Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
 Ó hàn pé ó dára fún ẹ ̀ mí .
Èmi náà óo fèsì lé e,n óo sì sọ èrò ọkàn tèmi.
Ní ọjọ́ kan, Sarai pe Abramu, ó sọ fún un pé, “Ṣé o rí i pé OLUWA kò jẹ́ kí n bímọ, nítorí náà bá ẹrubinrin mi yìí lòpọ̀, ó le jẹ́ pé láti ọ̀dọ̀ rẹ̀ ni n óo ti ní ọmọ.
" Awọn afadura jagun Mo tun gbera, o di ijọ Mountain of Fire and Miracles Ministry, MFM to wa ni ipinlẹ Ogun.
Lẹ́yìn oṣù mẹ́ta tí ẹ̀ka tó ń gbẹ́jọ́ aráàlú ní kánmọ́-kánmọ́ nilé iṣẹ́ ọlọ́pàá (PCRRU) sèlérí láti wádìí ìṣẹ̀lẹ̀ náà tí wọ́n sì jẹ́ kó di mímọ̀ fún àwọn aráàlù, òṣìṣẹ́ SARS náà ti gba ìwé ìdádúró lẹ́nu iṣẹ́ báyìí.
Akeugbagold naa, ti awọn ọlọpaa ṣe afihan awọn afurasi agbebọn to gbe awọn ibeji rẹ gba owo, lo bọ soju opo Facebook rẹ, to si n gbarata pe, ọkan lara awọn afurasi ti ọlọpaa fi oju wọn han naa, lo jẹ Judasi to da oun.
Nǹkan sì bẹ̀rẹ̀ sí lọ dáradára ní ilẹ̀ Juda.
Ipò ètò ààbò ń já àwa gómìnà láyà, ó ń kọ wá lóminú - Àwọn gómìnà Wo àwòrán ńkan tó ń ṣẹlẹ̀ ní ìpádé ìran Yorùbá ní Ibadan báyìí Awọn asofin sun ijiroro lori aabo s'iwaju Awọn Gomina f'aramọ ọlọpaa ipinlẹ Agbamu sọ fun BBC Yoruba pe ko ṣeeṣẹ ki awọn ipinlẹ ti ko tii le san owo oṣu awọn oṣiṣẹ wọn ko le ṣakoso ọlọpaa Ipinlẹ.
O ni Alaafin Adeyẹmi tasẹ agẹrẹ ni o.
4 Nítorínáà èyí ni ẹ̀bùn rẹ; ṣe àmúlò rẹ̀, àti pé alábùkúnfún ni ìwọ, nítorí èyí yíò gbà ọ́ sílẹ̀ ní ọwọ̀ àwọn ọ̀tá rẹ, nígbàtí, bí kò bá rí bẹ́ẹ̀, wọn yíò pa ọ́, kí wọn sì mú ọkàn rẹ wá sí ìparun.
Amọ o paṣẹ fun Niyi lati ma a fun wọn ni ẹgbẹrun mẹwa, loṣooṣu fun owo ounjẹ.
Ọba désì ìwé náà pada sí Rehumu, olórí ogun ati Ṣimiṣai, akọ̀wé, ati sí àwọn ẹlẹgbẹ́ wọn yòókù tí wọn ń gbé Samaria ati agbègbè òdìkejì odò yòókù.
Bí o tilẹ̀ jẹ́ pé oríṣirísi ìwádìí ló wáyé lẹ́yìn ikú Kudirat, ní ọ̀pọ̀ ọdún lẹ̀yìn ti ó ti kú, gẹ́gẹ́ bí ohun ti ìròyìn sọ, wọn pàṣẹ fún ènìyàn ẹlẹni mẹ́fà kan láti parí iṣẹ́ ọhun ni.
Ìṣèlú ilẹ ̀ bòtswánà je ti orile-ede bòtswánà .
Ọga patapata fajọ naa, AVM Muhammadu Muhammed, lo fidi ọrọ naa mulẹ nigba to n ba awọn oniroyin sọrọ l'Abuja, nipa ipalẹmọ ati igbesẹ tawọn n gbe lati koju omiyale, to le sẹlẹ lọdun yii.
Oríṣun àwòrán, @officialnyscng Awọn eeyan naa ni wọn ri mu ni ibi abala keji ipagọ awọn agunbanirọ to waye kaakiri lorilẹ-ede yii.
Iye àwọn ọkunrin tí ó jẹ oúnjẹ náà jẹ́ ẹgbẹẹdọgbọn (5000).
Oríṣun àwòrán, TWITTER/NIGERIAN PRESIDENCY Àkọlé àwòrán, Bill Gates ati orileede Naijiria ni asepo lati koju ààrùn rọmọlapa rọmọlẹsẹ ati aironje asaraloge jẹ fun awọn ọmọde.
Abdullahi gba fun Naijiria ninu idije awọn ọdọ ti ọjọ ori wọn ko kọja ogun ọdun nilẹ Turkey lọdun 2013.
“Bakan naa ,awon gomina ni ila Ariwa naa n gbiyanju lati mu idagbasoke ba ohun amayederun ni ekun ila oorun.
Kò sì sí ọlọrun náà tí ó lè gbà yín kúrò lọ́wọ́ mi?
Ẹ tun le wo awon iroyin yin ti Facebook ni, ti ẹ ba lọ si setting"" lori oju opo naa."
Dìde, OLUWA, gbà mí, Ọlọrun mi!
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Rahul Gandhi ati Priyanka to jẹ arabinrin rẹ gbọdọ ṣiṣẹ ju ti atẹyinwa lọ Olori ẹgbẹ alatako fún Modi ni Rahul Gandhi to ni awọn ero lẹyin lẹgbẹ Congress party rẹ.
Ọpọ nínú Alalaaji yóò ti ra ẹni kékeré lọwọ láti fi sun níbẹ.
15 Bélú 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Ọkunrin kan, tí à ń pè ní Jabesi, jẹ́ eniyan pataki ju àwọn arakunrin rẹ̀ lọ.
Ọrẹ rẹ̀ ni àwo fadaka kan tí ìwọ̀n rẹ̀ jẹ́ aadoje (130) ṣekeli, abọ́ fadaka kan tí ìwọ̀n rẹ̀ jẹ́ aadọrin ṣekeli.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Omidan jáde láyé lẹ́yìn tí ìlú lù ú, jáa sí ìhòhò lórí ẹ̀ṣẹ̀ tí kò ṣẹ̀ Tẹti leko fun iroyin to kuna lori arun yii ki o Ma si ṣe gbagbe lati maa tẹle awọnilana eto ilera tawọn alaṣẹ ijọba lagbegbe rẹ ba fi sita.
Wọ́n yọ́ wúrà bo àwọn òpó náà, ati àwọn ọ̀pá tí wọ́n fi gbé àwọn aṣọ títa náà kọ́, ṣugbọn idẹ ni wọ́n fi ṣe ìtẹ́lẹ̀ àwọn maraarun.
O ni gbogbo lalakunfẹfẹ ariwo Kemi Afolabi yii ko ṣẹyin ija to ṣẹlẹ laarin Kemi ati ọrẹbinrin oun, Gloria lori ọrọ oṣerekunrin, Gida.
“Gbogbo kòkòrò tí ó ní ìyẹ́, tí ó sì ń fi ẹsẹ̀ mẹrẹẹrin rìn, ìríra ni wọ́n jẹ́ fun yín.
Àwọn òṣìṣẹ́ BBC News Yorùbá sọ̀rọ̀ ìdùnnú lórí ayẹyẹ ọdún kan iléeṣẹ́ náà
Ẹ wo òtítọ́ ọ̀rọ̀ nàá Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí NIN Registration:Àjọ NIMC sọ pé ọ̀fẹ́ ni gbígba nọ́mbà NIN NIMC kéde ìlànà tuntun fún gbígba NIN bẹ̀rẹ̀ láti ọgbọ̀njọ́, oṣù Kejìlá, ọdún 2020.
Wo àwọn orílẹ̀-èdè márùn ún tó fún àwọn obìnrin làńfàní tuntun sí ẹ̀tọ́ wọn Nàìjíríà kò nílò sénétọ̀ kankan- Fayemi 'Títẹ àwọn afipábánilopọ̀ lọ́dàá kọ́ ni ọ̀nà àbáyọ sí ìwà ìfipábánilopọ̀' Jessica Nabongo ni obìnrin àkọkọ nílẹ Adúláwọ tó rin gbogbo àgbáyé.
Nígbà tí ó tó bíi wakati kan, ọkunrin kan tún sọ pẹlu ìdánilójú pé, “Láìsí àní-àní ọkunrin yìí wà pẹlu Jesu, nítorí ará Galili ni.
Orisun: Ajọ to n se kokari ere idaraya Olympics, IOC titi di ọdun 2016.
Aare Muhammadu Buhari to n tuko orile-ede Naijiria bayii ti seleri lati fopin si ikolu ojoojumo to n ba eto aabo Naijiria finra lasiko yii.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, FFK: Buhari ló ń fún àwọn Fulani láàyè láti máa pa ènìyàn' Ẹwẹ, Femi Fani Kayode ni oun ti ba arakunrin oun, Yinka Odumakin to jẹ agbẹnusọ fun ẹgbẹ Afenifere to si sọ fun oun pe awọn Fulani daran daran lo pa Ọmọ Baba Fasoranti.
 Ó ṣeé ṣe kí a máṣe nílò láti ṣe ìtọ ́ jú àrùn náà tí kò bá kan ètò iṣan inú ara .
Ayọ̀ ń bẹ fún ẹni tí OLUWA kò ka ẹ̀ṣẹ̀ sí lọ́rùn,tí ẹ̀tàn kò sì sí ninu ọkàn rẹ̀.
Ohun tí ó gba ọgbọ́n nìyí.
Irọ ni pé to ba ya Tatuu tabi da ara lu ko nile fi ẹjẹ silẹ: O ṣeeṣe fun ẹni to da ara lu tabi to ya Tatuu sara rẹ lati fi ẹjẹ silẹ.
"O ni ""a o nilo lati mu u fun ajọ INEC."
Kristi yìí ni à ń kéde fun yín, tí à ń kìlọ̀ rẹ̀ fún gbogbo eniyan, tí a fi ń kọ́ gbogbo eniyan ní gbogbo ọgbọ́n, kí á lè sọ gbogbo eniyan di pípé ninu Kristi.
Daramola wá ń ké sí àwọn ẹlẹyinju àánú ọmọ Naijiria, lati dìde ìranwọ fún Ogun Majek ko lee ri owo to to owó láti fi ṣe ìtọ́jú ara rẹ nílé ìwòsàn, ó ní káwọn aráàlú dakun, ogún Majek nílò iranlọwọ wọn.
South Africa: Ìyàtọ̀ tó wà láàrin ìṣesí Nàìjíríà àti South Africa
Ipolongo ibo rẹ waye lọna ti ẹnikẹni ko fi ọkan si i, nitori ajakalẹ aarun Covid-19 to wa l'ode.
Ẹ̀yin ọmọ Israẹli, ẹ ní ìrètí ninu OLUWA,láti ìsinsìnyìí lọ ati títí laelae.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Atiku FinCEN Files: Atiku ní iró ni pé orílẹ̀èdè Amẹrika ń ṣọ́ wọlé-wọ̀de òun àti ìdílé rẹ̀ 22 Owewe 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 24 Owewe 2020 Oríṣun àwòrán, Google Oludije fun ipo aarẹ ninu idibo aarẹ ọdun 2019, Atiku Abubakar ti fesi si iroyin kan to sọ pe ijọba orilẹede Amẹrika ti bẹrẹ si ni wo wọle-wọde rẹ ati iyawo rẹ to fi mọ awọn ẹbi rẹ.
0 724 Orilẹede Papua New Guinea 7 0.
Hananaya bá sọ níṣojú gbogbo eniyan pé OLUWA ní bẹ́ẹ̀ ni òun óo ṣẹ́ àjàgà Nebukadinesari ọba Babiloni kúrò lọ́rùn gbogbo àwọn orílẹ̀-èdè kí ọdún meji tó pé.
Ṣugbọn kòkòrò lásán ni mí, n kì í ṣe eniyan;ayé kẹ́gàn mi, gbogbo eniyan sì ń fi mí ṣe ẹlẹ́yà.
    ‘Ìlú àwọn Èdìdàrẹ́ níbi tí òmùgọ́diméjì ti ń ṣe ọba wọn.
Lọjọ kẹtalelogun, oṣu kẹta, ọdun ni wọn ni o kere tan ọgọjọ awọn jagunjagun ni aja awọn ọlọdẹ pa ni agbegbe Ogossagou to sunmọ Burkina Faso.
 Ọ ̀ pọ ̀ lọpọ ̀ olósèlú ni bá tí sọ ayé di tàwọn nìkan , bí kò bá sí ti àwọn aléré ìtàgé tábì ti àgbéléwò tí óun pi ìwà ìbàjẹ ́ wọn léde .
Enikeni ti aarun ba n ba ja, yoo maa ri awon ami bi: iba, ara riro, eyi ti o ma n dabi igbe gbuuruOga agba yii se ikinlo yii latari alami latodo ajo isokan UN pe, o seese ki orile-ede Naijiria ati awon orile-ede marun miiran fara kasa iseyo aarun yii.
Oríṣun àwòrán, others Àkọlé àwòrán, Ọdun 2018 ni wọn ti afara ọhun kẹyin fun ọjọ mẹta lọna ati ṣe iwadii awọn iha to ti n dẹnukọlẹ lori rẹ July 24 ní ìjọba àpapọ̀ yóò ti afárá Third Mainland fún àtúnṣe Ijọba apapọ Naijiria ti n gbaradi lati ti afara Third Mainland to wa ni ipinlẹ Eko fun oṣu mẹfa lọna ati bẹrẹ iṣẹ atunṣe lori rẹ.
Nítorí pé kí ó tó di ìgbà ìkórè,lẹ́yìn tí ìtànná àjàrà bá ti rẹ̀, tí ó di èso,tí àjàrà bẹ̀rẹ̀ sí gbó, tí ó ń pọ́n bọ̀,ọ̀tá yóo ti dòjé bọ àwọn ìtàkùn àjàrà,yóo sì gé gbogbo ẹ̀ka rẹ̀ kúrò.
OLUWA Ọlọrun sọ fún ọba Ijipti pé, “Ọba Babiloni yóo fi idà pa yín.
Ìrìn gbé mi dé ìlú kan tí ń jẹ́ Bath.
Bauchi State: Okú 596 ló ṣì ń gba owó oṣù
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Èèyàn mẹ́ta pàdánù ẹ̀mí wọn nínú ìjàmbá ọkọ̀ akérò tó ya wọ ọjà ní Ibadan 3 Èbibi 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 4 Èbibi 2019 Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ọkọ̀ akérò ya wọ ọjà ní òkè Mapo,èèyàn mẹ́ta pàdánù ẹ̀mí wọn Ọkọ akero nla kan ti ṣeku pa eeyan mẹta ni ọja to wa ni oju titi to kọja ni iwaju Oke Mapo nilu Ibadan.
Lẹnu lọọlọ yi, ǹkan ko ṣẹnu re laarin iyawo Aarẹ Naijiria atiwọn kan to n naka si pe wọn ko jẹ ki aarẹ ṣe ijọba fun ra rẹ.
30 Owewe 2019 Oríṣun àwòrán, EDUCATION MINISTRY/TWITTER Àkọlé àwòrán, Ìjọba ilẹ̀ Mexico tó bá obìnrin náà yọ̀ sọ pé obinrin náà ti setán láti lọ sí ilé-ìwá girama láti parí ẹkọ́ rẹ̀.
Ọ̀rọ̀ òkú ọmọ, òkú ìyá àti olubi ọmọ tí wọ́n gbé tó sì pé lọ sí ilé ìgbókùú pamọ́ sí ṣùgbọ́n tí òkú ọmọ wa di àwátì lọ́jọ́ ìsìnkú ló ṣí ẹnu BBC Yorùbá sílẹ̀ gbáà.
obinrin ro alaafia ara re, ko ri pe alafo wa laarin omo kan si ikeji ,ki iku
Laipẹ yii ni ileeṣẹ aṣọ Mr Price dawọ okoowo rẹ ni Naijiria duro.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Kogi: Ilé aṣòfin ti bẹ́rẹ́ ìgbésẹ̀ àti rọ igbákejì gómìnà ìpínlẹ̀ Kogi lóyè 20 Ògún 2019 Oríṣun àwòrán, dailypost Afaimọ ki ipinlẹ Kogi maa ni igbakeji gomina miran laipẹ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Buns ni ọmọ mi jẹ tán ní ṣọ́ọ̀ṣì, ló bá di àwátì' O ni EFCC tun n tako ọrọ adajọ agba patapata ni Naijiria, Ibrahim Tanko Muhammed to sọ pe gbogbo ẹka ijọba gbọdọ bọwọ fun ofin orilẹ-ede Naijiria.
Dìde, Ọlọrun, ṣe ìdájọ́ ayé,nítorí tìrẹ ni gbogbo orílẹ̀-èdè!
Awọn mejeeji ọhun, ni wọn gbe loju ọna to so Ikẹrẹ, Isẹ ati Emure pọ, ni nnkan bi aago mẹjọ alẹ.
Onyema ati Ejiroghene Eghagha to jẹ alakoso eto inawo ile iṣẹ ọkọ ofurufu Air Peace ni wọn jọ fẹsun kan papọ.
Ijọba apapọ ko ro ero rẹ daadaa ko to gbe sita.
eni to padanu bayii, nitori pe ajo INEC ko ti i gbe esi ibo sita.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Òṣèré tíátà Yorùbá mẹ́ta gbàmì ẹ̀yẹ pé wọ́n pegedé Òkú ṣùn nínú ìbúgbàmú tó wáyé l‘Eko Àwọn kókó ohun tó wà nínú lẹ́tà tí Aláàfin kọ sí Fayemi rèé N kò ní ìjà pẹ̀lú Fayemi, ipò mi bíi aláàbò àṣà Yorùbá ní mó ṣe kọ lẹ́tà sí gómìnà Ekiti - Aláàfin Wò ó ọ̀nà láti mú ara rẹ dé ibi tó ga jùlọ nínú ìbálòpọ̀ pẹ̀lú ìlànà Tantra Ọ̀sẹ̀ yìí laá gbàwọn ẹ̀sọ́ Amotekun sísẹ́, ìparí oṣù kẹta ni iṣẹ́ yóò bẹ̀rẹ̀ - Akeredolu Ìpele tuntun ló kàn nínú ìrìnàjò ayé mi, ń kò pe ẹjọ́ lóri ìrọ̀lóyé - Sanusi Idi ni pe Gomina ipinlẹ Ekiti, Kayode Fayemi ti lọ se ago laafin sọdọ Alaafin tilu Oyo, Ọba Lamide Ọlayiwọla Adeyemi kẹta lọsan ọjọ Aiku.
ṣugbọn awọn onimọ sayẹnsi ni omiran le tete ni apẹrẹ Ajọ eleto ilera agbaye, (WHO) gba imọran pe o ṣeeṣe ko pe ọjọ mẹrinla lara ni eyi ti iwadii ni o le to ọjọ mẹrinlelogun O ṣe pataki lati mọ iwọn asiko ti o fi le duro lara ko to fojuhan.
Àwọn tí ó f’ara kááṣá wọ̀nyìí ni àwọn Adivasis, Harijans àti Dalits.
Nigba aye rẹ, Kyari ṣiṣẹ amofin pẹlu gbaju-gbaja oloṣelu, oloogbe Fani-Kayode.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Agbabọọlu Chelsea, Giroud lo kọkọ si san bantẹ iya fun Arsenal to jẹ ikọ rẹ tẹlẹri, ki Pedro ati Hazard to pari iya naa fun Arsenal.
Ọ̀kẹ́ kan ati ẹgbaarun (30,000) ni ọmọ ogun Filistini pa ninu àwọn ọmọ ogun Israẹli tí ń fi ẹsẹ̀ rìn.
' Dapọ Abiọdun: Mo kọ̀ láti ko ẹ̀bi mi nikan si ijọba mi Gomina tuntun ti wọn bura fun lati tukọ ipinlẹ Ogun di 2023 ni ko nii si adanikan jẹ ninu iṣejọba oun nipinlẹ Ogun rara.
“Nítorí náà, ẹ fẹ́ràn OLUWA Ọlọrun yín, kí ẹ sì máa tẹ̀lé gbogbo ìkìlọ̀ ati ìlànà, ati ìdájọ́, ati òfin rẹ̀ nígbà gbogbo.
ẹkunwo  owo osu awọn osisẹ lasti sọ di
 Odun 2015 ni Messi gba ami-eye ohun keyin,
pataki ki olukuluku wa yago fun ohunkohun ti o le fa iyapa laarin wa.
Wọn ni igba ti wọn n gbe e lọ ninu ọkọ wọn ni wọn ti ti i lati inu ọkọ naa, to si ko sẹnu ọkọ mii to n bọ, leyi to mu ko jẹ Ọlọrun nipe.
Wò ó, OLUWA, àwọn ọ̀tá rẹ yóo parun;gbogbo àwọn aṣebi yóo sì fọ́n ká.
Nítorí kí ó tó mú un lọ, Ìwé Mímọ́ sọ nípa rẹ̀ pé, “Ó ṣe ohun tí ó wu Ọlọrun.
Ipolowo ọja nla ni ibaṣepo ẹgbẹ agbabọọlu naa jẹ fun ile iṣẹ Adebajo ti eleyi si mu ki okiki rẹ ati owo rẹ maa pọ sii.
Ṣugbọn Ọlọrun bá Mose ati Aaroni sọ̀rọ̀, ó wá pàṣẹ ohun tí wọn yóo sọ fún àwọn eniyan Israẹli ati fún Farao, ọba Ijipti, pé kí ó kó àwọn eniyan Israẹli jáde kúrò ní ilẹ̀ Ijipti.
Làálàá lásán ni iṣẹ́ tí Ọlọrun fún ọmọ eniyan ṣe lórí ilẹ̀ ayé.
Nigba ti awọn ọmọogun yoo fi de ibi ti wọn ni olori ikọ Boko Haram lugọ si, o ti na papa bora.
''Iru rẹ ṣẹlẹ laipẹ yii nijọba ibilẹ Batsari nipinlẹ Katsina, nibi ti awọn ọkunrin ati obinrin kan ti wọn jẹ ọmọ ibeji ti fẹ ara wọn.
Chukwurah ni eeyan mẹjọ ni ijamba naa kan lara awọn to n bẹ ninu ọkọ akero kan, ọkọ ayọkẹlẹ kan ati ọlọkada, ṣugbọn ọlọkada yẹn nikan lo gbẹmi mi.
Ijoba Bashir si n koju alatako pelu awon ifehonuhan to n waye kaakiri
Ìbẹ̀rù-bojo yóo dé ba yín, ojú yóo sì tì yín; nítorí Kuṣi ati Ijipti tí ẹ gbójú lé.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ayekofẹnifọrọ: Ó yá, ẹ fi àmì sórí ọ̀rọ̀ náà.
A kò lè s̩àdédé gba è̩tó̩ jíjé̩ o̩mo̩ orílè̩‐èdè e̩ni ló̩wó̩ e̩nìké̩ni láìnídìí tàbí kí a kò̩ fún e̩nìké̩ni láti yàn láti jé̩ o̩mo̩ orílè̩‐èdè mìíràn.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Aso Villa: Wàhàlà kankan kò rúgbó nílé Ààrẹ 21 Òkùdu 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 14 Òkùdu 2020 Oríṣun àwòrán, @Aishambuhari Àkọlé àwòrán, Aso Villa: Wàhàlà kankan kò rúgbó nílé Ààrẹ Iroyin ti jade pe aarẹ orilẹede Naijiria Muhammadu Buhari ko ni arun ko si rin ni igberi ewu kankan to ni ṣe pẹlu ajakalẹ arun tabi iroyin to n tan kalẹ nipa iṣẹlẹ to waye laarin awọn ẹṣọ ile aarẹ eyi ti wọn n ṣewadii rẹ lọwọlọwọ.
" Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Oronpoto Animation: Akin Alabi ní kò dára bí eré aláwòrán fáwọn ọmọdé ṣe jẹ́ aláwọ̀ funfun Bobrisky, ẹni to kede pe Michael Jackson ni awokọse oun, tun ni oun kii se awokọse buburu fawọn ọdọ gẹgẹ bawọn eeyan kan se ri oun, arọwa oun sawọn ọdọ si ni lati lee da duro funra wọn.
 “Ti a ba tu ka, ko lee tan isoro ti a n dojukọ gẹgẹ
Iwadii kan fi han pe ogunlọgọ awọn oloufẹ Trump lo n gbe ni awọn ilu nla kan bii Florida, Ohio, Tennessee, Pennsylvania, North Carolina, Georgia ati Virginia.
Awọn abilekọ, Baale ile ati ọmọde lo wa lara awọn arinrinajo naa.
27 Ẹrẹ̀nà 2018 BBC Yorùbá fọ̀rọ̀ wá àwọn ọmọ Yorùbá àtàtà lẹ́nu wò nípa bí wọ̀n se gbọ́ òwe sí.
Ni idaji ojo Ru ni Wajeeh Nusseibeh, to n tilekun ile ijosin naa ti sii.
Awọn aafaa diẹ nikan lo peju sibẹ.
Ọpọ awọn ọmọ ẹgbẹ naa ati awọn ọmọ naa atawọn ara ilu lo peju sibi ọhun iwọde ọhun.
Àṣé ìtàkùn tí mo dì mọ́, ara igi mìíràn ló ti dìde; nígbà tí atẹ́gùn sì bẹ̀rẹ́ tí igi tí mo jókòó lé ń fẹ́ lọ foríbalẹ̀ igi tí ìtàkùn náà dì mọ́ dìde dúró ṣe ni mo sì bá ara mi tí mo ń fi dirodiro.
 Orile-ede South Sudan ti o gba ominira kuro  lorile-ede Sudan ni odun 2011, bere ogun abele ni odun 2013, leyin opolopo osu kan ti Aare Salva Kiir yo igbakeji  re, Riek Machar kuro nipo, ni eyi ti ogunlogo eniyan ti padanu emi, ti ogoro awon eniyan si ti di alainile lori.
O ni tori rẹ gan lo fa a ti ọkọ rẹ fi le wọn kuro nile.
méjìdínlógún ni ọjọBọ, ọjọ keje osu kẹta odun 2019.
O soro naa di mimo ni kete ti won pari ayeye isiso loju eegun lati bere idije ohun, ti won si kede iko ti yoo maa soju Naijiria.
Kì í rẹ̀ ẹ́, bẹ́ẹ̀ ni agara kì í dá a.
Àkọlé àwòrán, Ko sẹni to le wọle tabi jade bayii nile ijọba ipinlẹ Kwara Akọroyin BBC to wa ni Ilorin bayii ṣalaye pe ko si ẹni to le wọle tabi jade lasiko yii nile ijọba ni Ilorin.
Ninu atẹjade kan ni Ọgbẹni Mele Kyari ti ṣalaye ọrọ yii lori oju opo Twitter rẹ.
Murray Bruce ni iwadi oun nipa ọrọ naa ti fi han pe, owo idana ni gomina Ganduje n gba lori ọmọ rẹ obinrin, kii se owo abẹtẹlẹ lori isẹ agbase.
Awọn ologun mu awọn mẹfa ọhun lẹyin ti wọn ti pa mẹwa ninu wọn to gbiyanju ati ba awọn ọmọogun fibọn pẹẹta.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Arsenal rántí Invincibles,"" ó pé ọdún mẹ́rìndínlógún tí Arsenal gba ife Premier League 28 Ìgbé 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 17 Èbibi 2020 Oríṣun àwòrán, @GilbertoSilva Àkọlé àwòrán, Ifẹsẹwọnsẹ mọkandinlaadọta ni Arsenal gba lai padanu ọkankan ninu wọn."
Ó ti fi odi ààfin rẹ̀ lé àwọn ọ̀tá lọ́wọ́;wọ́n pariwo ńlá ninu ilé OLUWAgẹ́gẹ́ bíi ti ọjọ́ àjọ̀dún tí a yà sọ́tọ̀.
Mo sọ fun yín, ẹ bẹ̀rù olúwarẹ̀.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Yoruba Culture: ọjọ́ méje ni wọ́n fí n rẹ ẹ̀kú Danafojura kó tó jáde Awọn mi a ma kowo sidi ẹgbẹ okunkun.
Iyalẹnu lo si jẹ nigba ti o bẹrẹ si ni i ka oriṣiriṣi nkan.
Mo sọ gbogbo nkan to ti ṣẹlẹ si mi fun un - titi dori bi emi ati ẹ ṣe jọ n kọ ile kan, ati bi ao ṣe gbe papọ, ko to o di pe a tuka.
Ṣugbọn tí ẹ bá ń ṣe ojuṣaaju, ẹ di arúfin, ati ẹni ìbáwí lábẹ́ òfin gẹ́gẹ́ bí arúfin.
Ohun tí ó sọ nípa àwọn angẹli ni pé,“Ẹni tí ó ṣe àwọn angẹli rẹ̀ ní ẹ̀fúùfù,tí ó ṣe àwọn òjíṣẹ́ rẹ̀ ní ọwọ́ iná.
Àwọn ìròyìn kọ̀ọ̀kan sọ wí pé ó ti kúrò nílùú lọ sí ilẹ̀ Faranse sugbọn àwọn kan sọ wí pé ó ṣì wà ní ìpínlẹ̀ Ekiti.
Lara awọn orilẹede ti Ọgbẹni Rex Tillerson ti de ni Ethiopia, Kenya ati Chad.
Labani bá wá inú àgọ́ Jakọbu, ati ti Lea ati ti àwọn iranṣẹbinrin mejeeji, ṣugbọn kò rí àwọn ère oriṣa rẹ̀.
"Lizzy Anjorin ""Owo, ọmọ, alaafia ati ẹmi gigun ni mo beere."
 Àìní ìmọ ́ tótó , kí èrò pọ ̀ jù ní ibi gbígbé , àti àìtó omi tó mọ ́ gaara pẹ ̀ lú àwọn ilé-ìgbọ ̀ nsẹ ̀ tó dọ ̀ tí tún máa n tètè tan àìsàn náà kiri .
Kii ṣe nitori pe olorin kan tabi elere idaraya kan sọ ọrọ to mu awuyeyewuye wa bi kii ṣe pe ọrọ iwaasu lati ẹnu woli agba kan lo n mu iriwisi orisirisi wa.
NDLEA: Ó sàn kí ẹ pa mí ju kí ẹ ba oko tí mo gbin igbó sí jẹ́ lọ- Afurasi Clement Akor ní Kogi
Ninu ìdílé Paṣuri: Elioenai, Maaseaya, Iṣimaeli, Netaneli, Josabadi, ati Elasa.
Dokita Ikebese Wilson sọ fun BBC Yoruba pe iwadii imọ sayẹnsi nipa ohun to se okunfa iku to pa awọn eeyan ẹbi Orisabunmi (Post mortem) nikan lo le fihan boya orisun kan naa ni iku wọn ti wa.
O sọ pe ti ẹnikan ko jọ ti ẹnikeji - nitori igbeaye ti ẹnikọọkan n gbe, sugbọn wọn ko le ṣe alaisẹlẹ.
Ṣe lori idibo ọjọ kẹtalelogun osu keji ọdun yii ti Balogun ni ibo 105,720 nigba ti Ajimọbi ni 92,218.
Ó dùn ún gùn, a sì máa mú ara ẹni le kokooko bí ọta.
Ṣe ijinigbe wọ pọ ni Dar es Salaam Lati ọwọ Athuman Mtulya,Akoroyin BBC Africa, Dar es Salaam Lati inu ede larubawa ni wọn ti ya orukọ ilu Dar es Salaam ti o tunmọ si ''Agọ Alafia'' city's name comes from Arabic, and literally means Abode of Peace.
"Oríṣun àwòrán, dele momodu Momoodu ni ""Ọpọlọpọ owó tí awọn eniyan kan ní Tinubu kò yìí, kii na fún ara rẹ nìkan nítorí pé ó ní ojú àánú pupọ, tó sì máa ń rán aráàlú lọ́wọ́,koda tipátipá lọ máa ń fi jẹun."
Ẹ gbọ́ orin ayọ̀ ìṣẹ́gun,ninu àgọ́ àwọn olódodo.
Ẹnu lasan ati akatakiti ko to ṣe oselu Naijiria Agbẹjọro Gani Fawehinmi ati Fela Anikulapo Kuti jẹ awọn to ti saaju gbe iru igbese ti Sowore n gbe yi sugbọn ti wọn ko ribi ruu ja.
Ẹ̀wù ọmọ ogun ni Joabu wọ̀; ó sán ìgbànú kan, idà rẹ̀ sì wà ninu àkọ̀ lára ìgbànú tí ó ti sán mọ́ ìbàdí.
 ará ìlú Àdùnní ni olófìn-íntótó , ọmọ adéṣínà .
Obinrin náà dáhùn pé, “OLUWA Ọlọrun rẹ ń gbọ́, n kò ní oúnjẹ rárá.
Ọgbẹni Joseph ni iṣẹ iwadii ṣi n lọ lori ọrọ naa, pẹlu afikun pe ko yẹ ki ẹgbẹ OPC maa dunkoko mọ awọn ọlọpaa nitori iṣẹ iwadii lori iṣekupani maa n gba suuru ati akoko.
Liverpool pègúnrẹ́, wọ́n gbé ife ẹ̀yẹ̀ Premier league lẹ́yìn ọgbọ̀n ọdún Wo àwọn Gómìnà Naijiria tí àrùn Covid-19 ti bá fínra Kini o ti ṣẹlẹ sẹyin?
kopa ninu idije Uefa Champions League saa to n bo.
Àwọn ọmọ rẹ̀, Isaaki ati Iṣimaeli, sin òkú rẹ̀ sinu ihò òkúta Makipela, ninu pápá Efuroni, ọmọ Sohari, ará Hiti, níwájú Mamure.
Bi Èkó ti tóbi tó, ibùdókọ òfúrufú kan ló wà lójú kan naa ni Ìkẹjà fún àwọn ti ó nlọ si gbogbo àgbáyé àti àwọn ti ó fẹ́ lọ si ilú Nigeria miran.
Àkọlé àwòrán, Opolopo ẹbun ni awọn ọmọ ko lọ sile pẹlu idunnu lẹyin ti wọn ti yan bi ologun tan fun Oba atawọn alejo to wa nibẹ.
Ní ìbẹ̀rẹ̀ oṣù yìí, ìjọba Burundi ti ọ́fíìsì ẹ̀ka àwọn ajàfẹ́tọ̀ọ́ ènìyàn lábẹ́ United Nations tí wọ́n sì sọ pé àwọn kò nílòo wọn mọ́.
A kò gbà pé kí wọ́n pa wọ́n, oró ni kí wọ́n dá wọn fún oṣù marun-un, kí wọ́n dá wọn lóró bí ìgbà tí àkeekèé bá ta eniyan.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Barrakat Bello: Sábàbí ire ní ikú Barakat padà já sí fún wa- Ẹ̀bí fẹ̀mí ìmoore hàn sí àwọn ọmọ Nàíjíríà 12 Òkùdu 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 28 Agẹmo 2020 Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Barrakat Bello: Iya rẹ̀ ní báwọn èèyàn ṣe ń fún òun lówó, làwọn míì ń tún ilé ṣe Arabinrin Kafayat Bello, Iya Barakat Bello, ti dupẹ lọwọ awọn ẹlẹyinju aanu ti o dide iranlọwọ lẹyin iku ọmọ rẹ.
Àwọn Jebusi yìí sì tún wà láàrin àwọn eniyan Juda ní Jerusalẹmu títí di òní olónìí.
àwọn tí ó wí pé,“Ẹ jẹ́ kí á mú lára ilẹ̀ Ọlọrunkí á sọ ọ́ di tiwa.
Wọ́n pàṣẹ fún ẹni tí ó ń ṣọ́ àwọn ẹlẹ́wọ̀n pé kí ó ṣọ́ wọn dáradára.
Nípasẹ̀ ìrìnàjò afẹ́ náà, a fẹ́ mọ bí ayé àti ìgbé ayé ṣe rí ní Hong Kong.
Ọmọ ẹgbẹ́ òsèlú APC tako Oshiomole Ìrẹ́pọ̀ tó sọnù ló ń fa aáwọ̀ APC - Oshiomole Saraki, má gbé adé wa lọ sí ilé onílé - Oshiomole Ọbasanjo kọ́ ni yóò fi ààrẹ jẹ nínú ìdìbò 2019 - Oshiomole Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
kí ẹ má baà gbé ògo yín fún ẹlòmíràn,kí ẹ sì fi ìgbé ayé yín lé aláìláàánú lọ́wọ́.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Man United vs Chelsea: Chelsea fún Man U lóújẹ àbùkù jè, Cuppy bínú yí jọ̀lọ́ọ̀fù dànù 19 Agẹmo 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 20 Agẹmo 2020 Àkọlé àwòrán, DJ Cuppy binu fi Arsenal silẹ, o gba Man U lọ laimọ pe, ohun to n bẹ lẹyin Efa.
Lẹ́yìn olóògbé Barrister àti Kollington, èmi làgbà kàn nínú iṣẹ́ orin Fuji- Obesere yarí Ohun méje tí Jimoh Aliu fi yàtọ̀ lágbo tíátà Wo bí ìfigagbágbá tani yòó di gómìnà Edo láàrin Obaseki àti Ize-Iyamu yóò ṣe lọ Ninu fidio naa lo ti wọ aṣọ funfun igbeyawo ti ọkọ rẹ naa wọ kootu to si jẹ wipe awọn mejeeji nikan sọ́ọ́ lo wa ninu fidio naa.
Bayii, Cindy ti di gbajugbaja ọdọbinrin to jà to si ti n di ilumọọka sii.
Ronke Odusanya Lọjọ kọkandinlogun oṣu kẹjọ ọdun 2019 ni Ronke Odusanya kede loju opo Intsagram rẹ pe Ọlọrun fi ọmọ jojolo ta oun ati ọkọ oun lọrẹ.
Satchet Alcohol ban: Ìjọba àpapọ̀ yóò fòfin de títà àti rírà ọtí inú ọ̀rá bíi 'pẹlẹbẹ', 'pàrágà'
Oríṣun àwòrán, Getty Images Njẹ awọn ileeṣẹ tẹlifiṣọn Amẹrika lagbara lati kede esi ibo lalẹ ọjọ kan naa?
Yiya igbẹ ju bo ṣe yẹ lọ lai dawọ duro, ti yoo si tun jẹ eyi to ṣan Ẹjẹ yoo ma wa ninu igbẹ lai ni idi kankan Inu rirun ni gbogbo igba, inira ninu ikun, tabi ki ikun o wu - eyi le waye lẹyin ounjẹ jijẹ, o si le mu ki ounjẹ kankan o ma wu eeyan jẹ Ẹni naa yoo ma a ru.
 o je a tele gun-duro egbe ti asofin fun awon gichu constituency ati awon eya alagbawi ti awon ga ejo ti orile-ede kenya.
Ṣé ẹ lè gbà kí ẹnikẹ́ni dúró tì mí, tí ẹ kò bá gbà kini ìdí?
Owo naa to jẹ biliọnu marundinlọgọrin lowa fun awọn ọdọ to ba fẹ ẹ da iṣẹ ti ara wọn silẹ.
Joṣua wí fún Akani pé, “Ọmọ mi, fi ògo fún OLUWA Ọlọrun Israẹli, kí o sì yìn ín.
Ọmọdekunrin naa, tii se ọmọ ọdun meje ni awọn obi rẹ kofiri pe agbọn isalẹ rẹ n wu, eyi to mu ki wọn gbe lọ sile iwosan.
Ó rọ ìjọba àpapọ̀ àti àwọn gómìnà ìpínlẹ̀ Yoruba la'ti gbé ìgbẹ́sẹ nítorí ààrẹ ọ̀nà kò lé ṣe ńkan kan ti ìjọba kò bá lọ́wọ́ síí Iba Gani Adams mẹnu ba ọ̀rọ̀ MURIC ti wọ́n fẹ̀sùn kan pé ó gbowó lọ́wọ́ ISWAP láti gba awọn Fúlani fún ìgbésùmọmi, sùgbọ́n ó ṣeni laáànu pé, ìjọba kọ̀ láti ṣe ìwádìí nípa pípe adari MURIC, ọjọgbọ́n IShiaq Akintola.
Eyi lohun to wa ninu atẹjade ti Gomina Akeredolu fi sita lati ọwọ akọwe rẹ nipa iroyin, Segun Ajiboye, pe awọn gbọ iroyin pe, iṣẹlẹ jiji ẹru ijọba ko fẹ waye kan ni ọfiisi igbakeji gomina, ṣugbọn ti awọn ẹṣọ ọfiisi naa ṣiṣẹ gidi lati ma jẹ ki wọn ri nkankan ji lọ.
Ẹrí rè é, Sanwo-Olu ṣèlérí lóòtó lórí súnkẹrẹ-fàkẹrẹ Apapa Ìgbìmọ̀ ìgbẹ́jọ́ wọ́gilé ẹ́jọ tó takò iyansipo Sanwo Olu Ọwọ́ tẹ ayédèrú agbẹjọ́rò ní Eko Atiku ni kò tíì dópin fún Adeleke, PDP ni àwọn gba idájọ́ wọlé Ninu ifọrọwanilẹnuwo pẹlu igbakeji agbẹnusọ rẹ, ọgbẹni Gboyega Akosile, o ni Gomina Sanwo Olu lọ si Egypt lootọ amọ ko ṣadehun tabi fun awọn Super Eagles lowo kankan.
Ẹ le ka nipa rẹ si nibi Ngozi Onwumere Ọjọ ori: Mẹridinlọgbọn Orilẹẹde: Nigeria Ere idaraya: Kẹkẹ ori yiyin ‘Bobsleigh’ Ngozi Onwumere je elere ori papa to ti soju orilẹẹde Nigeria ninu idije ere idaraya ilẹ Afrika lọdun 2015   Ẹ le ka nipa rẹ si nibi Simidele Adeagbo Ọjọ ori: Mẹridinlogoji Orilẹẹde: Nigeria Ere idaraya: Skeleton Lẹyin isinmi ọdun mẹsan fun ere idaraya,Simidele Adeagbo ni iwuri latari aseyori  ikọ kẹkẹ ori yiyin ‘Bobsleigh team’ orilẹẹde Nigeria.
Tako iroyin ti awọn ileeṣẹ iroyin kan gbe jade, iwadii ti BBC ṣe fihan pe lootọ ni iyawo aarẹ pada si ilu Dubai, ṣugbọn kii ṣe lati ma a gbe ibẹ.
oludije miiran to tun lee wa ni ipo abenugan ju Gbajabiamila lọ.
Awọn meje ti wọn lọ naa ni: Akara oogun, Kako Oni kumọ ẹkun, Olohun Iyọ, Elegbeje Ado, Aramanda Olotutu, Imadoye ati Efo Iyẹ.
Dokita Adan ni oun ti ri iranlọwọ moto meji gba lati ọdọ ajọ ilera agbaye ti WHO.
Pẹlu bi gbogbo nnkan wọnyi ṣe n ṣẹlẹ, awọn nọọsi ati dokita naa tun n gunle iyanṣẹlodi.
Gabola Church: Ẹnu gbẹ ní Ṣọ́ọ̀ṣì wa torí òfin ìséde Covid-19
Ṣugbọn ki lo jẹ ki Umar jẹ ogbologbo afẹsunkan?
Naijiria fi ìgbájú mẹ́ta lé Cameroon kúrò ní AFCON Ìdí tí mo fi fẹ́ di Gómìnà Kogi - Dino Melaye Kí ló mú ọmọ Nàìjíríà mẹ́sàn án forí la ikú nínú ìkọlù Libya?
Mahrez dá Super Eagles dùbúlẹ̀ lórí pápá oko tútù Ṣé o rántí itú tí Bright Omokharo fi Algeria pa ní MAROC '88?
” Baba rẹ̀ dá a lóhùn pé, “Kí ni, ọmọ mi?
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Akomolede ati asa Yoruba: Ẹ wá kọ́ nípa àpòtí ìṣura èdè wa lórí BBC Yorùbá Nigba to n ba awọn akọroyin sọrọ, o ni ohun to wu oun lọkan lati ṣe ni lati kọ ileegbe fun awọn opo ti ọkọ wọn ti ba ogun lọ.
N kò bá kọ jù báyìí lọ, àmọ́ kíní ọ̀hún ò tiẹ̀ wúni lórí lọ títí o jàre.
[ [ wiwaye ( ẹko nipa ajakalẹ arun ) | wiwaye ] ] anafilasisi jẹ 4-5 ninu awọn eniyan 100,000 l ' ọdun , pẹlu [ [ cumulative incidence | ewu fun igbe-aiye ] ] ti 0.
eleyii jẹ ojuse ti a gbodo se, ti o ba jẹ pe lootọ ni a n sin Ọlọrun.
Nibayii, ọjọ kẹtalelogun oṣu keji ni eto idido naa yoo waye.
Awọn ti iṣẹlẹ naa ṣoju wọn ni n ṣe ni awọn agbebọn naa dana sun awọn eeyan naa laaye.
Wó̩n ní è̩bùn ti làákàyè àti ti è̩rí‐o̩kàn, ó sì ye̩ kí wo̩n ó máa hùwà sí ara wo̩n gé̩gé̩ bí o̩mo̩ ìyá.
Awọn eniyan yoo nilo lati ma a yago fun ara ju tẹlẹ lọ paapaa ni awọn ile igbafẹ, ile ounjẹ ati ọkọ igboro lati dena itankalẹ arun naa.
 Ẹgbẹ ́ upn jogún ìmọ ̀ wọn láti ẹgbẹ ́ òṣèlú àtijọ ́ tẹ ́ lẹ ̀ tí action group tí ó sì jẹ ́ kí ó di ẹgbẹ ́ òṣèlú fún gbogbo àwùjọ ́ .
Ikede yii si ni ko ba awọn ọmọ Naijiria kan lara mu loju opo Twitter.
Joseph Smith fi àṣẹ sí àtúntẹ̀ míràn ti Ẹ̀kọ́ àti àwọn Májẹ̀mú, èyítí ó jẹ́ títẹ̀jáde ní oṣù díẹ̀ péré lẹhìn ikú ajẹ́rìíkú ti Wòlíì ní 1844.
Bẹẹ ni ọrọ ri pẹlu iwaasu ti gbajumọ oṣere tiata lobinrin, Toyin Abraham ṣe loju opo Instagram rẹ, eyi to fi n pa asamọ lowe lowe nipa awọn iṣẹlẹ agbọsọgbanu to n waye lawujọ wa lẹnu ọjọ mẹta yii.
Ìpànìyàn mìíràn wáyé ní ilé ìtaja-ohun-èlò-inú-ilé.
Oriṣi mẹfa lo wa: Igbẹ to ri bi okuta marble tumọ si pe inu kun.
” Àwọn ìgbìmọ̀ rí sí ọ̀rọ̀ rẹ̀.
Mimiko ti kọkọ ṣalaye ninu ifọrọwerọ pẹlu BBC Yoruba laipẹ yii pe ohun ti ṣeto igbaradi gbogbo to yẹ lati di aarẹ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Odebiyi: ìgbà gbogbo ni Bàbá mi ń polówó iṣẹ́ mi fáráyé Saa isejọba gomina Rochas Okorocha ni ipinlẹ Imo, to bẹbẹ fun isiju aanu wo baba naa ti kogba wọle, ti ijọba tuntun si ti wa nijọba, a ko si mọ boya o seese ki wọn seto iranwọ fun baba naa.
Àwọn ni: Ṣelemaya, alufaa, Sadoku, akọ̀wé, ati Pedaaya, ọmọ Lefi.
Ọjọ ti ofin ọlọsẹ meji naa yẹ ko parí, ni Aarẹ tun kede afikun ọsẹ meji.
Mo gbagbọ pe amuwa Ọlọrun ni eyi nitori mi o ṣẹ ẹnikankan, mi o dẹ ba ẹnikankan ja.
Olori ile igbimọ asofin agba ati asoju-sofin l'Abuja Bukola Saraki ati Yakubu Dogara wa lara awọn eekan ẹgbẹ oṣelu PDP to wa nibi ifẹhonu han naa.
Mourinho sọ pe Liverpool ni igboya lati koju Man U nitori wọn jawe olubori ninu ifẹsẹwọnsẹ mẹta ti wọn gba sẹyin.
Kí ìjọ mi ní Sagamu le gbòòrò ni mo fi ń ṣiṣẹ́ ajínigbé pawó - Pásítọ̀ Bí ọlọ́pàá bá mú ọ, kí ló yẹ kí o ṣe?
Aarun naa ti pa awon eniyan to le ni egberun
“Ní ọjọ́ náà, bí ẹnìkan bá wà lórí ilé, tí àwọn nǹkan rẹ̀ wà ninu ilé, kí ó má sọ̀kalẹ̀ lọ kó o.
 Olukolu tun salaye pe ojoojumọ ni ilu n gbooro si ti ọrọ aje naa si n gberu sii, eleyii lo faa ti awọn janduku ati ọdaran naa fi n gbilẹ ni ipinle Oyo sugbon o fi da oga agba fun ile –ise olopaa loju pe awon osise oun to gbangba sun lọyẹ.
Bala Mohammed, Bauchi Ọjọ kẹrinlelogun oṣu Kẹta ọdun 2020 ni iroyin gbode kan pe Bala Mohammed, to jẹ gomina ipinlẹ Bauchi ti ni arun Coronavirus.
" Ṣe ọsẹ yii ma a pa gbogbo kokoro aifojuri?
Ẹkẹsan-an mú Matanaya, òun ati àwọn ọmọ rẹ̀ ọkunrin, ati àwọn arakunrin rẹ̀ jẹ́ mejila.
Àìsí àwọn iléèwé olùkọ́ni (Grade ) mọ́ bi i tàtijọ́ nàá n kó bá ètò ẹ̀kọ́ ló fi jẹ́ wí pé iléèwé NCE ni ọ̀pọ̀ ṣábà nlọ.
Ní ọjọ́ náà, ẹ gbẹ́kẹ̀lé àwọn ohun ìjà tí ó wà ninu Ilé-Igbó, 
O salaye pe, awon omode ni awon igberiko maa n lo opolopo wakati lati wa omi pipon kiri, eyi ti o n dena won lati lo si ile-iwe lasiko.
Ero ti @ChinnyPillz ni pe, kii se oogun ikọ olomi Codine nikan ni ile iṣẹ Emzor ati awọn ile iṣẹ oogun meji yoku nse.
Kí àwọn olódodo máa yọ̀ ninu OLUWA,kí wọ́n sì máa wá ààbò lọ́dọ̀ rẹ̀!
Idunnu subu layo nigba ti awon omode-binrin naa pada sile, ti awon obi won n jo kiri oju opopona ile naa.
Nibayii, awọn alaṣẹ fasiti Ibadan ti wa kede ofin isede lọgba faisiti naa laarin agogo mejila oru si agogo marun idaji.
Ọlọ́pàá ilẹ̀ Yorùbá 'Àmọ̀tẹ́kùn' ṣetán láti bẹ̀rẹ̀ iṣẹ́ káàkiri ilẹ̀ káàrọ́ọ̀ oò jíire Ògo tuntun yóò sọ ní ọdún 2020!
Peteru bá fà á lọ́wọ́ dìde.
Idi ti onibara wa ṣe pe Fatoyinbo lẹjọ ni ki ile ẹjọ le e ṣe idajọ ti o tọ, ati lati ran awọn elomiran ti o lee wa niru ipo yii lọwọ."
#BBCNigeria2019 America àti Ilẹ̀ Gẹ̀ẹ́sì ní àwọn kò ní ààyò olùdíje ní Naijria #BBCNigeria2019 Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, ìpàdé ìtagbangba ìfọ̀rọ̀wánilẹ́nuwò pẹ̀lú àwọn olùdíje sípò gomina ní ìpínlẹ̀ Eko.
O tesiwaju pe “Ninu iwadii  ti oun se pelu awon adari elesin ati oloselu lojo kéjìdínlógún si ojo kọ́kànlélógún nipa eto idibo 2019 ti yoo waye lorile ede Naijiria .
Nibayii, ajọ eto ilera lagbaye, WHO ko fẹ da ijọba orilẹede Naijiria da eto gbigbogun ti arun Coronavirus pẹlu bi ajọ naa ti ṣe n funrarẹ wa awọn eeyan to ba arinrinajo ọmọ orilẹede Italy to ko arun Coronavirus wọ Naijiria ni ọsẹ to kọja.
Ẹ mú ìdì ewé hisopu, kí ẹ tì í bọ ẹ̀jẹ̀ tí ẹ bá gbè sinu àwo kòtò kan, kí ẹ fi ẹ̀jẹ̀ náà kun àtẹ́rígbà ati òpó ìlẹ̀kùn mejeeji.
Akure Explosion: Bọ́mbù ni, bọ́mbù kọ̀ ọ́!
Aare Buhari tun tesiwaju pe ,
Asafu yìí jẹ́ ọmọ Berekaya, ọmọ Ṣimea; 
Woods pari lọna aramọda lati gba ife ẹyẹ Masters ti ọdun 2019.
Wọ́n ń kùn pé: “Ìbá sàn fún wa bí ó bá jẹ́ pé a ti kú nígbà tí àwọn arakunrin wa kú níwájú OLUWA.
Oríṣun àwòrán, Twitter/gboyega akosile Wo àwọn ìpínlẹ̀ tó ti dẹwọ́ ìséde lẹ́yìn ìwọ́de #EndSars Awọn ipinlẹ meji ni o ti paṣẹ ki ofin konile o- gbele rọlẹ lagbegbe wọn lẹyin ti wọn paṣẹ ofin naa lasiko ti rogbodiyan gbode kan nitori ifẹhọnuhan EndSars to gbode kan ni awon ipinle Naijiria.
Amọ, ọjọ keji ti wọn bẹrẹ iwe kikọ pada ni ijọba tun kede ki olukuluku akẹkọọ ati olukọ o fi idi mọle wọn nitori gbọnmọgbọnmọ wahala awọn janduku to ti ja iwọde #EndSARS gba ti wọn si ti fi n da ilu laamu bayii.
Bakan naa ni Shehu sọ pe Aarẹ Muhammadu Buhari ti bu ẹnu atẹ lu iṣẹlẹ naa, o si paṣẹ pe ki eto abo to nipan wa ni gbogbo ileewe.
Ó ṣe fun yín, ayé, ati fún òkun!
Ọ̀la ni Arafat, wo iṣẹ́ tó ṣe kókó láti ṣe ní Hajj lásìkò Àràfá àti lẹ́yìn rẹ̀ Ìpànìyàn, ìjínigbé ti gbàkóso ilẹ̀ Yorùbá, Buhari, tètè kéde pé ètò ààbò kò fararọ - Soyinka Àlàyé rèé lóríi ìdí tí wọ́n fi ń pe aya ní ìyàwó Àwọn ọmọ Nàìjíríà kan ń dá ẹ̀bi, òmíràn ń dárò, lórí bí ológun ṣe pa ọlọ́pàá mẹ́ta Ọjọ kejidinlogun, Osu yii ni aarẹ yoo pade si ile aarẹ ni ilu Abuja saaju iburawọle fun awọn minisita tuntun ti wọn sẹsẹ yan.
Bi o tile je pe, Iko agbaboolu Guinea kopa ribiribi ni saa kinni ifesewonse ohun, sugbon omi poju oka lo, leyin ti won fowo pa ida Super Eagles loju ni saa keji, ti ida ohun o si ko lati ge won yana-yana.
”Nibi ipade awon toro kan gbogbon ninu ẹgbẹ oṣelu APC to waye
Ṣaaju ni iroyin tẹ BBC Yoruba lọwọ pe ileeṣẹ ọlọpaa orilẹede Naijiria ti ofiisi Adajọ Agba Walter Onnoghen pa, ti wọ́n si tun le awọn oṣiṣẹ́ to n ṣiṣẹ pẹlu rẹ jade.
Bí bàbá mi tún ti wo iwájú báyìí, ṣánṣán ni ẹ̀dá yìí dúró tí ó ń rẹ́rìn-ín tí ó sì ń wo bàbá mi bí ẹni pé ìjà ṣẹ̀ṣẹ̀ bẹ̀rẹ̀ ni.
Ṣugbọn ni orilẹede Naijiria, awọn adari ijọ olokiki bii meloo kan ti fi ara ko imi ẹsun agbere, eyi ti iroyin rẹ yani lẹnu pupọ.
Olufẹmi Lanlẹhin kan sara si ile iṣ BBC fun agbekalẹ eto.
Igba ti mo wa ni ọmọ ọdun mẹtadinlogun ni mo ri i pe mo ni ailera ni ẹsẹ mi i, nitori pe gbogbo igba lo maa n wu.
Nítorí náà, wọ́n gbé e kúrò ninu kẹ̀kẹ́ ogun tí ó wà tẹ́lẹ̀ sinu òmíràn, wọ́n sì gbé e lọ sí Jerusalẹmu.
Nígbà tí àwọn ọkunrin náà dé ọ̀dọ̀ Jesu, wọ́n ní, “Johanu Onítẹ̀bọmi ni ó rán wa sí ọ láti bi ọ́ pé, ‘Ṣé ìwọ ni ẹni tí ń bọ̀ ni, tabi kí á máa retí ẹlòmíràn?
A gbọ pe ọpọ lara awọn ti wọn ko si ahamọ nilu Ibadan lori isẹlẹ ọhun ni ko pada mọ silu Ogbomoso, ti awọn ẹbi rẹ ko si mọ boya o ku ni tabi o sọnu.
Èmi náà fèsì ìwè ọ̀rẹ̀ mi.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù APC àti PDP takora wọn lórí Olùsirò owó àgba Ọsun tó fisẹ́ sílẹ̀ 22 Sẹ́rẹ́ 2018 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 17 Owewe 2018 Oríṣun àwòrán, Sola Fasure Àkọlé àwòrán, Aregbesola yan elòmíràn dípò Oyetola Ní báyìí tí ìdìbò gómìnà ní ìpínlẹ̀ Ọ̀sun kù sáátá, ọ̀pọ̀ awuyewuye ló gba ilẹ̀ kan nítorí bí Olùsirò owó àgba, Alaba Akintayọ se kúrò lẹ́nu isẹ́.
Orile ede  India ti fun orile ede
"Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Iya awọn ọmọ naa fi ọwọ si igbeyawo wọn Ohun to tun jẹ kayeefi ninu iṣẹlẹ naa ni wipe, niṣe ni iya awọn ọmọ naa sọ fawọn akọroyin pe igbesẹ awọn ọmọ ohun ba Bibeli mu, pẹlu afikun wipe: ""ọmọ mi san owo ori boṣetọ ati boṣeyẹ."
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Chloroquine for coronavirus: Njẹ Chloroquine nipa kankan láti kojú Coronavirus?
aare orile ede Naijiria niwaju igbimo to n ri si awuye-wuye lori eto idibo
"Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Bolaji Faleke ni Olùkọ́ tó ń kọ́ wa ní àṣà oge ṣiṣe lórí BBC Yorùbá ""Ko pẹ diẹ si asiko yii ni awọn adigunjalẹ bẹrẹ si ni koju ija si mi, nitori wọn rọ wi pe emi ni mọ ni ile ti mo n gbe ati awọn ẹru ti wọn n ko wa lati oke okun to jẹ ti onile ti a n gbe naa."
Ọkọ kọọkan yoo ma a gbe to eniyan ọgọrun, ti yoo si ma a lọ si Ogbomoso, Oyo, Ibarapa ati bẹẹ bẹẹ lọ''.
Èmi kò fẹ́ Aàrẹ Buhari o- Sadiya Umar Farouq Lati bii ọjọ mẹta kan ni iroyin ti gba ori ayelujara kan pe Aarẹ Muhammadu Buhari to n tukọ Naijiria fẹ gbe iyawo miran le Ayisha aya rẹ.
Ẹ̀yin náà ti wà lára irú àwọn eniyan wọnyi nígbà kan rí, nígbà tí ẹ̀yin náà ń ṣe nǹkan wọnyi.
Ẹni tí ó bá ń wá ọ̀nà láti gba ẹ̀mí rẹ̀ là, yóo pàdánù rẹ̀.
Wọ́n ti rí ìbejì Taofeeq Akeugbagold tí wọ́n jígbé nílùú Ibadan Ọ̀pọ̀ ìgbà ni àwọn jàǹdùkú ká mi mọ́lé nítórí ìròyìn tí mo kà - Folake Otuyelu Coronavirus ti gbẹ̀mí èèyàn mìí ní ìpínlẹ̀ Osun 'Kò sí ààyè fún àwọn tó n gbé nípìnlẹ̀ Ogun, ṣùgbọ́n tó ń ṣiṣẹ́ l'Eko láti jáde tàbí wọlé' O ṣalaye fún BBC Yorùbá pé lẹ́yìn to wọle ọkọ lọdun mẹrin ti ko bimọ ni wọn ni ki oun wa ṣe iṣẹ abẹ latii yọ oyun ìju ti o n yọ oun lẹnu.
Ẹni ọdun mọkandinlaadọta ara Italy naa yoo wa lori alefa titi di ọdun 2023 lai ni alatako kankan.
Kí o wá sọ fún àwọn tí ń gbé ilẹ̀ náà pé, ‘OLUWA Ọlọrun sọ nípa àwọn ará Jerusalẹmu ati àwọn tí ń gbé ilẹ̀ Israẹli pé: Pẹlu ìpayà ni wọn óo máa fi jẹun, tí wọn óo sì máa fi mu omi, nítorí pé ilẹ̀ wọn yóo di ahoro nítorí ìwà ipá tí àwọn tí ń gbé inú rẹ̀ ń hù.
BBC Yoruba ti wa wọnu itan lọ lati lọ wu awọn ọrọ to jọra, ti awọn awọn olori Naijiria ti sọ ṣeyin lasiko ibo.
Kò sí ará ìlú kan tí yóo sọ pé,“Ara mi kò yá.
Oríṣun àwòrán, @HeyLagos Ile ẹjọ sọ pe ki alajọgbelepọ Ọdẹniyi san miliọnu meji Naira fun ipalara, aisan, idinilọwọ pẹlu ariwo, ti ẹrọ amunawa rẹ ọhun fa fun ẹnikeji, to jẹ alabagbele rẹ.
Wọ́n kó ọpọlọpọ eniyan jọ, wọ́n dí àwọn orísun omi ati àwọn odò tí ń ṣàn ní ilẹ̀ náà.
A ko le fidi ọrọ mulẹ boya o gba owo ifẹyinti yii lasiko to jẹ Senetọ ṣugbọn ipinlẹ Akwa Ibom ko ti mu ayipada tabi ki o pa ofin yii rẹ, di baa ti ṣe n sọrọ yii.
Oríṣun àwòrán, Dele Momodu Àkọlé àwòrán, Ọrọ atunto eto iṣejọba jẹ ohun ti o ti gba iwaju ọrọ oṣelu lorilẹede Naijiria Oloye Ayọ Adebanjọ nibi ipade naa sọ pe awọn kan sara sii Atiku Abubakar pe eeyan ti awọn lee fi ọwọ rẹ sọya pe yoo ṣe ifẹ awọn Yoruba lori atunto eto iṣejọba lorilẹede Naijiria.
Oludari Agba fun ijọ irapada, Redeemed Christian Church of God (RCCG), Pasito Enoch Adeboye ti ni ọpọlọpọ iṣẹlẹ ni yoo waye kaakiri agbaye ni ọdun 2020.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Sunday Igboho: Fulani kò leè dúró, táa bá lo ohun ta jogún lọ́dọ̀ àwọ̀n bàbá wa Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Ìṣeọ ̀ rọ ̀ awùjọ ni àgbéwòkà onísáyẹ ́ nsì àwùjọ .
i pe gbogbo iwe to yẹ ki won gbe lọ siwaju ipade igbimo ijoba apapo ni ki won
Ìpínlẹ̀ Oyo kéde àdínkù owó orí nítorí Covid 19 Ìjọba àpapọ̀ kéde ọjọ́ tí ìdánwò NECO, NABTEB àti BECE yóò bẹ̀rẹ̀ Keisha sàlàyé ìdí tó fi sunkún ní ìyàrá ìrántí nílé ẹlẹ́gbọ̀n ọ́n àgbà, ayé pariwo Ìjọba Èkó yóò fi òfin dè títà afẹ́fẹ́ gáàsì létílé láti dènà ìbúgbàmú láwùjọ Ìkúnlẹ̀ abiyamọ, ìkókó mẹ́jọ kú nílé ìwòsàn lálẹ́ ọjọ́ kàn Fásítì Babcock lé akẹ́kọ̀ọ́bìnrin tó hàn nínú fídíò ìbálòpọ̀ lọ sílé Saaju la ti mu iroyin wa fun yin pe fasiti Babcock ti fọwọ oṣi juwe ile fun akẹkọọbinrin to wa ninu fọnran to lu ayelujara pa, nibi ti ọkunrin ati obinrin kan ti ni ibalopọ.
Ikú, ìwọ ẹ̀dá aláìlàánú, mo fi ọ sílẹ̀ fún Ọlọ́run ọba.
Ibi tí mo ti ń gbọ́ orin dídùn yìí ni mo ti rí ilẹ̀kùn kan tí ó déédéé sí ní ẹ̀gbẹ́ ògiri ni ẹ̀bá ọ̀dọ̀ mi bẹ́ẹ̀ kò sí ilẹ̀kùn ní ibẹ̀ nígbà tí mo kọ́ dé, nígbà tí mo sì wo ojú ọ̀nà ibẹ̀ mo rí kìnnìún kan ti ó ba ni lẹ́rù púpọ̀, ó ń bọ̀ lọ́dọ̀ mi.
Wọ́n gba gbogbo ìbú ilẹ̀ ayé, wọ́n wá yí àwọn eniyan Ọlọrun ká ati ìlú tí Ọlọrun fẹ́ràn.
Ile aṣofin orilẹ-ede UK sọ pe, ominu nkọ oun lori rogbodiyan to waye lasiko iwọde ENDSARS, ati pe awọn ṣi n duro de iwadii ti ijọba Naijiria yoo ṣe lori ẹsun ifiyajẹni ti araalu fi kan awọn ọlọpaa.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ifẹhonuhan Lẹkki lori ẹkun owo irinnọ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Ifẹhonuhan Lẹkki lori ẹkun owo irinnọ 9 Èrèlè 2018 Ifẹhonuhan Lẹkki lori ẹkun owo irinnọ waye loni lagbegbe eti ọsa Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí kan sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
Àkọlé àwòrán, Ilorin Adajọ agba ti yoo bura wọle fun gomina tuntun ni ipinlẹ Kwara, Alhaji Durosinlohun Kawu ti wa nikalẹ.
Wọ́n dàbí òkúta kọ̀bìtì sí ojú ọ̀nà àwọn èrò ẹ̀yìn.
 Inu wa si dun pupo fun atileyin ati ifowosowopo ti a ri gba lowo ajo mejeeji ati awon toro kan miiran.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Kano Woman who killed son: Obìnrin kan dèrò ilé ẹjọ́ lórí ẹ̀sùn pé ó fi ọ̀bẹ rẹ́ ọmọ rẹ̀ lọ́rùn 19 Ògún 2020 Oríṣun àwòrán, Other Obinrin ẹni ọdun mẹtadinlọgbọn kan ti di ẹni to n kawọ pọn rojọ niwaju Adajọ lori ẹsun pe o ṣeku pa ọmọ rẹ ẹni ọdun marun un.
Oríṣun àwòrán, Others Bakan naa ni wọn rọ awọn eniyan lati sọra nipa kikọ ile si oju omi nipinlẹ naa, eleyii ti wọn ni o sokunfa bi afara naa ṣe ja.
"Saka ati Kelvin Ikeduba ṣe ọjọ Ibi Ṣe ẹ ranti agba oṣere ""Saka I don port"" alawada ninu ọpọ ere agbelewo ṣe ọjọ ibi ni Ọjọbọ, Ogunjọ osu kẹjọ ọdun yii."
Ẹwẹ, iroyin ti kọkọ gbode pe ọkan lara awọn oludije ọhun, Nathaniel Adojutelegan ti yọwọ lawo lati dije ninu idibo abẹle naa, ṣugbọn o sọ fun BBC pe irọ pọmbele ni.
Ta ni ẹ̀ ń fi ṣe ẹlẹ́yà?
Abiola Ajimobi: Iku Ajimọbi jẹ́ ǹkan ìjayà nítori kò só sí ẹnìkan tó ń reti irúẹ̀ lásìkò yii
Bawo ni Lamidi Adeyemi ati Abibat se pade?
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ondo Election 2020: Olùdíje ẹgbẹ́ òṣèlú PDP, Eyitayo Jegede ti yan Gboluga Ikengboju gẹ́gẹ́ bí ìgbákejì 7 Ògún 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 17 Ògún 2020 Oríṣun àwòrán, other Jegede kéde Gboluga Ikengboju gẹ́gẹ́ bí igbákejì rẹ̀ nínú ètò ìdìbò tó ń bọ́ l'Ondo losu kẹwaa, ọdun yii.
nítorí náà an yóò kọ́kọ́ gbọ́ ti ará ìlú kí wọ́n tó r'aàyé ti àwọn alejò.
Dangote, Fayemi pari ìjà láàrin Gomina Ganduje àti Emir Kano Sanusi II
Ayo meji ọtọtọ ni Ronaldo gba wọle bi Juventus ṣe fagba han Sassuolo pẹlu ami ayo meji sẹyọkan.
Ìdìbò ẹgbẹ APC láti kéde Buhari ni Eagle Square Àkọlé àwòrán, Awọn ẹgbẹrun meje aṣoju ni yoo yan Aarẹ Buhari Àago mọ́kànlá alẹ́ ni ìdìbò abẹ́lé ti ẹgbẹ oṣelu APC ti o n waye ni Eagle Square, ni ilu Abuja yoo bẹ̀rẹ̀ nibi ti fi ontẹ lu Aarẹ Muhammadu Buhari gẹgẹbii ẹni ti yoo dije du'po aarẹ labẹ aṣia ẹgbẹ oselu naa ni ọdun 2019.
Ìdí ti àwọn kọmísọna ṣe to láti kí ìyáwó gómìnà tuntun káàbọ̀ Gomina Seyi Makinde, to n gbalejo ipade ọhun, ninu ọrọ rẹ, tun sisọ loju rẹ pe awọn gomina ẹkun iwọ oorun guusu Naijiria ti setan lati tun se amulo awọn irinsẹ igbalode feto aabo lati mu ki aifararọ aabo ọhun tẹriba.
Gẹgẹ bi itan nipa igbesi aye Bande ti Àjọ Isọkan Agbaye(UN) fi lede, Ọjọgbọn Bande jẹ ẹni ti o nimọ pupo nipa eto oselu lagbaye ati ibasepo laaarin awọn orilẹede.
 A ti pinnu lati ri aridaju pe awon irinse to n wole ati eyi ti a n se nile ba ofin amuye mu ki okan gbogbo awon to n lo irinse naa le bale pe ko ni si ewu ti won ba n loo ti won yoo si mo pe ere pupo n bo fun won nitori pe awon ohun eelo naa yoo maa sise bi o ti ye”.
 wọ ́ n bíi sí ìdíilé olókìkí oníṣòwò calcutta tí apá kan obí rẹ ̀ jẹ ́ gẹ ̀ ẹ ́ sì tí ìkan tókù jẹ ́ Índíà , harper kàwé ní orílẹ ̀ èdè Índíà àti ilẹ ̀ gẹ ̀ ẹ ́ sì àti pé ó darapọ ̀ mọ ́ rfa ní ọdún 1937 .
Ó bá kígbe tòò, ó ní, 
Àwọn ọmọ Jafẹti ni: Gomeri, Magogu, Madai, Jafani, Tubali, Meṣeki ati Tirasi.
Gomina sọ pe lati ibẹrẹ ijọba oun, awọn ẹka ọrọ aje mẹsan kan ni awọn
Ó bá fún Jakọbu ní Biliha, iranṣẹbinrin rẹ̀ kí ó fi ṣe aya, Jakọbu sì bá a lòpọ̀.
Wọn yóo jẹ àwọn ọmọ ẹran yín ati èso ilẹ̀ yín títí tí ẹ óo fi parun patapata.
"BBC Africa Eye: ìwádìí ìkọ̀kọ̀ BBC fihàn pé àwọn kan ń jí ohun eèlò ìdáàbòbò ìjọba tà nígboro ""Àwọn èèyàn ìlú Okeho ló kó gbogbo owó tí wọn rí gbà lọ́wọ́ àwọn adigunjalè tí wọ́n mú"" Olùrànlọ́wọ́ pàtàkì fún ọ̀rọ̀ ibojì òkú, àti àwọn ipò òṣèlú mìíràn tó jẹ́ kàyééfì ní Nàìjíríà Buruji Kashamu jẹ́ ènìyàn tó nífẹ̀ aráàlú- Gómínà Dapo Abiodun Amọ awọn ọmọ Naijiria to fesi si fidio naa lori Twitter ni iru ọrọ bẹẹ ko tọ si ẹnu Madueke nitori oun jẹjọ iwa ibajẹ lọwọ lorilẹ-ede Naijiria."
Tẹẹ ba gbagbe, Osu Kefa ọdun to kọja ni eniyan marun fara gba arun iba ọrẹrẹ, sugbọn ti awọn onimọ ijinlẹ tete ka ọwọja arun naa ko lẹkunrẹrẹ.
Ẹni to bori: Tunisia Algeria vs Cameroon.
Ifidirẹmi fun eyikeyi ẹgbẹ le se akoba fun wọn ninu idibo gbogbogbo to n ba lọdun 2019.
Ẹwẹ, agbẹnusọ fun ile iṣẹ Ọlọpaa, Ebere Amaraizu ti wa fi ọrọ ranṣẹ fun awọn araalu pe ki wọn ma foya o.
@Lucasscot_101 ṣalaye ni tiẹ wi pe ẹgbẹ oṣelu APC lo kọkọ bẹrẹ iwa aṣiwere tawọn eeyan si ro pe ko si were to le ju iyẹn lọ.
ipo kinni, Ni bayii, Uganda ati Tanzania ti
Iwe ẹri imọ ijinlẹ kejì lati Fasiti Pennsylvania.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Cancer: Àṣe ara mi ni iso ti n run gbogbo bí mo ṣe n ṣèrànwọ́ lórí jẹjẹrẹ Amọ, sẹnatọ Sani ni eleyii ti wọn ti ya tẹlẹ ri, ki ni wọn ti fi ṣe?
O ti lé ní ènìyàn mẹ́wàá tí ina jó gúrúgúrú nínú ìjàmbá tó wáyé ní Delta Ilé Aṣòfin yóò pe Godswill Akpabio l'ẹ́jọ́ fún ìbanilórúkọ jẹ́ Èmi Ọba tí wọ́n ń kó jẹ nígboro- Oluwo ti ilú Iwo Wo bí ètò ìsìnkú Tolulope Arotile ṣe lọ nílùú Abuja Alabojuto ẹka itọju ọmọniyan ni ajọ isọkan agbaye, UN lorilẹede Naijiria, Edward Kallon ni ohun to ṣẹlẹ yii ko tọna pe awọn to n gbiyanju ati ṣeranwọ gan ni wọn n ṣe ikọlu si ti wọn si n pa.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Khadijat Oluboyo: Ilé ẹjọ́ sọ ọ̀rẹ́kùnrin rẹ̀ sí gbaga 16 Agẹmo 2018 Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Khadijat Oluboyo: Ilé ẹjọ́ sọ ọ̀rẹ́kùnrin rẹ̀ sí gbaga Olólùfẹ́ ti wọ́n ló pa ọ̀rẹ́bìnrin rẹ̀ fi ṣòògùn ní Akurẹ fojú ba ilé ẹjọ́.
Yatọ si ile itaja Shoprite ti wọn kọlu, awọn janduku yii tun lọ ṣọsẹ ladugbo Taiwo, nibi ti wọn ti yabo ile itaja Fonemart.
Ṣugbọn awọn kan gbagbọ pe ipaniyan ati ija ẹsin peleke si ni asiko eto iṣakoso Buhari.
Ọjọ́ kẹwàá oṣù kọkànlá ọdún 2019 ní Gold Kolawole di àwáti ni sọ́ọ̀sì ọmọde inú ìjọ náà, lẹ́yin náà ni wọ́n si ti fi ẹsùn ìjínígbé kan pásítọ̀ yii.
Ṣugbọn, aisan jẹjẹrẹ inu ẹjẹ 'leukaemia' ti ṣeku pa lọmọ ọdun mẹtadinlogun.
O pe àwọn mẹ́tẹ́ẹ̀ta, o fún ẹnìkọ̀ọ̀kan wọn ni àpò owó mẹ́ta, o ní kí wọ́n kúrò ní ìlú kí wọ́n lọ lo owó tí òun ffún wọn fi ra nǹkan tí ó bá jẹ́ ìyanu wá àti pe ẹni tí nǹkan tiẹ̀ bá ya ni lẹ́nu jù ni yóò fẹ́ Ẹwadapọ, ìwọ̀ntunwọ̀nsì lobìnrin.
Naijiria pegede fun idije agbaye FIBA fun igba akoko lodun 2006, sugbon won ko jawe olubori ninu ifigagbaga kankan ti won fi ja kuro ninu idije ohun.
Shannon-Ogbani Abeda Ọjọ ori: 21 Orilẹẹde: Eritrea Ere idaraya: Alpine skiing Abeda to dagba silẹ Canada gbero lati jẹ agbaboolu afigi gba lori yiyin ‘ice hockey’ sugbọn awọn obi rẹ ni ere yiyo lori yiyin pẹlu opa onirin(skiing) ni yoo je ere idaraya to ye.
Dokita, ójọgbọn, akọroyin, ayaworan ati ọpọlọpọ akọṣẹmọṣẹ miran bẹẹ, koda ẹni ti ko niṣẹ lọwọ paapaa.
Ẹnìkọ̀ọ̀kan láti ẹ̀gbẹ́ kinni, dojú kọ ẹnìkọ̀ọ̀kan láti ẹ̀gbẹ́ keji, wọ́n sì gbá ara wọn lórí mú.
Wò ó, n óo tẹ̀ yín ní àtẹ̀rẹ́ ní ibùgbé yín, bí ìgbà tí ọkọ̀ kọjá lórí eniyan.
Ǹ jẹ́ o mọ ọ̀rọ̀ tí Ààrẹ Buhari sọ fún Ọọ̀ni níbi ọdún Ọlọ́jọ́?
koi ti kopa fun iko Super Eagles lati igba ti won ti pari idije boolu agbaye FIFA
Ọ̀rọ̀ rẹ ni àtùpà fún ẹsẹ̀ mi,òun ni ìmọ́lẹ̀ sí ọ̀nà mi.
Ó dára kí eniyan fetí sí ìbáwí ọlọ́gbọ́n, ju láti máa gbọ́ orin ìyìn àwọn òmùgọ̀ lọ.
Pa Adebanjo ni 'emi lawọn mejeeji tẹ papaa julọ Obasanjo pẹlu bi wọn ṣe tun n sọrọ si ara wọn.
Ẹ dúpẹ́ lọ́wọ́ OLUWA, nítorí pé ó ṣeun,nítorí ìfẹ́ rẹ̀ tí kì í yẹ̀ wà títí lae.
" Oríṣun àwòrán, Dino Melaye Bakan naa, sẹnetọ Dino Melaye ti fi igbe bọnu loju opo Twitter rẹ pe awọn janduku kan ti n dunkoko mọ ẹmi oun ati tawọn mọlẹbi oun.
Bakan naa ni awọn onigbọwọ owo nabi yi nfi ipa gba gbese tawọn ọmọbinrin naa ba jẹ wọn eyi to nii se pẹlu owo ti wọn fi gbe wọn lati Naijiria lọ silẹ okeere .
Internet: Ìpínlẹ̀ Oyo ni yóò kọ́kọ́ jànfàní òpó ìtàkùn àgbáyé
awon ona ti won yoo se maa sagbakale esi egbe oselu kookan.
Tí epo bá ti wà, wọ́n á yáa rọ gbogbo ọkọ̀ àti garawa wọn kún dẹ́mú-dẹ́mú.
Ni nnkan bi ọdun diẹ sẹyin ni George ṣipo pada lọ si Minneapolis lati lọ ṣiṣẹ, nibẹ naa lo ti ṣe kongẹ iku lọwọ awọn ọlọpaa to fun un lọrun.
Oríṣun àwòrán, Others Ọdun 1974 ni Baba Legba dara pọ mọ ikọ osere tiata Awada kerikeri labẹ akoso Moses Olaiya, taa mọ si Baba Sala.
0 34 Erekusu Falkland Island 0 0.
Ọgbọ́n ni adé àwọn ọlọ́gbọ́n,ṣugbọn ìwà aláìgbọ́n jẹ́ yẹ̀yẹ́ àwọn òmùgọ̀.
Èmi OLUWA ni ó sọ bẹ́ẹ̀.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Pneumonia: Dókítà ní kòkòrò àìfojúrí ló ń fàá òtútù àyà Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Pneumonia: Dókítà ní kòkòrò àìfojúrí ló ń fàá òtútù àyà 21 Bélú 2019 Ọpọ asọdun lo maa n waye nipa aisan kan ta n pe ni otutu aya eyi ti oloyinbo n pe ni Pneumonia.
fun osise kọọkan gege bi owo itanran.
Ọlọ́pàá gbé àwọn tó yìnbọn lu olólùfẹ́ ní Ajegunle Ọ̀wọ́ngógó epo bẹntirò: NNPC ni 'ìròyìn ẹlẹ́jẹ̀' ni Oladejo Okediji àti ìgbé ayé ìtàn kíkọ rẹ̀ 'Ọdún méjì sẹ́yìn ni òbí àwọn ọmọbinrin Chibok gbọ́ láti ọ̀dọ́ ìjọba kẹ́yìn' Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ọ̀dọ́kùnrin tó kọ́kọ́ ṣe ẹ̀rọ tó ń tu ìyẹ́ lára adìyẹ Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Ó bẹ̀rẹ̀ sí gbadura, ó ní, “OLUWA Ọlọrun Israẹli, kò sí Ọlọrun kan tí ó dàbí rẹ̀ lókè ọ̀run tabi ní ayé yìí, tíí máa pa majẹmu rẹ̀ mọ́, tíí sì máa fi ìfẹ́ rẹ̀ tí kì í yẹ̀ hàn sí àwọn iranṣẹ rẹ̀, tí ń fi tọkàntọkàn gbọ́ràn sí i lẹ́nu.
' Gbajugbaja olorin Reggae naa wa kesi ajọ EFCC lati jẹ ki aanu ijọba lori idajọ lori ọrọ Naira Mailey.
Má jẹ́ kí n bá àwọn oníṣẹ́ ẹ̀ṣẹ̀ rìn pọ̀,má sì jẹ́ kí n jẹ ninu oúnjẹ àdídùn wọn.
Wọn ni ni kete ti awọn ọmọkunrin naa ri awọn ọlọpaa ni wọn sa gba ọna ọtọọtọ, amọ ọwọ ọlọpaa tẹ mẹtadinlọgọta lara wọn.
Conference Centre, ogba ile eko giga Fafiti, Ibadan ni ipinle Oyo ,to je keun
Aare so pe: “lati odun kejidinlogun(18 years) ni awon omo orile ede Naijiria ti n sayeye odun eto ijoba tiwa-n-tiwa ni ojo kokandinlogbon.
Kò ṣe mí ní nǹkankan bí ẹ bá ń dá mi lẹ́jọ́ tabi bí ẹnikẹ́ni bá ń dá mi lẹ́jọ́.
bí ó ti ń ṣẹ́jú, bẹ́ẹ̀ ni ó ń jansẹ̀ mọ́lẹ̀,tí ó sì ń fi ìka ṣe àpèjúwe.
Ènìyàn 653 míràn tún kún iye àwọn tó ní COVID-19 ní Nàìjíríà Wo àwọn olorì àgbà mẹ́rin tí Aláàfin ń wárí fún Atẹjade kan ti igbimọ naa fi sita, eyi ti agbẹnusọ fun gomina ipinlẹ Kwara fi ọwọ si lo yọju ọrọ yii sita.
Idi ni pe se ni awọn asofin naa n kọ ofin yii silẹ, ti ọpọ awọn ọmọ ile asofin ti wọn jẹ ọkunrin si n fi ẹnu abuku kun aba naa nigbakuugba ti wọn ba tun gbe wa siwaju ile.
Ìyá Alájé: Ṣùgbọ́ ṣá o, kòsí ẹ̀wà múrí kan àbọ̀.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ilorin illegal Rehab: Bàbá ẹni ọdún 77 ni alákòóso ibùdó 25 Ọ̀wàrà 2019 Oríṣun àwòrán, OTHER Ile iṣẹ Ọlọpaa ipinlẹ Kwara ni igbesẹ tawọn n gbe lọwọ ni lati wa ọna ati mọ awọn obi awọn eeyan ọgọrun o le mẹjọ ti wọn ko si ayederu ibudo atunwaṣe ni Ilorin.
Egbe alatako orile-ede Ethiopia ti fi esun kan ijoba orile-ede Ethiopia pe, o n tapa si eto omo eniyan, won si ni igbagbo pe, yiyan omowe Tedros si ipo naa yoo je ki orile-ede naa tun ni idagbasoke laarin orile-ede yoku lagbaye.
Iwa fifi ẹgbẹ kan silẹ lati lọ darapọ mọ ẹgbẹ mii jẹ eleyi tawọn oloṣelu Naijiria fẹran lati maa ṣe.
biliọọnu lọna ọọdunrunlemọkandinlaadọrun ati miliọọnu lọna
Awọn onimọ-ẹrọ to gbe ẹrọ apọwo naa ri awọn owo beba ẹ́gbẹrun meji alapapọ ati ẹẹdẹgbẹta alapapọ ti wọn jẹ owo Rupee, tawọn eku ọhun ti bajẹ.
Ẹ wá ná, kí ló ń ṣẹlẹ̀ pẹ̀lú APC àti Kayode Fayemi ní Ekiti gan an?
Múra gírí, jẹ́ kí á fi gbogbo agbára wa jà fún àwọn eniyan wa ati fún ìlú Ọlọrun wa.
Oríṣun àwòrán, NICHOLAS KAMM Àkọlé àwòrán, Iṣẹ ori ran mi ni mo n ṣe Oun ni olorin gboogi to kọrin nigba ti wwọn bura fun Barack Obama gẹgẹ bii aarẹ orilẹ-ede Amerika.
Oríṣun àwòrán, @thenff Àkọlé àwòrán, NFF fun awọn agbabọọlu ni ami ẹyẹ Awọn ami ẹyẹ miran ti wọn tun fi sita nibi eayẹyẹ ami ẹyẹ Aiteo NFF to waye naa ni ami ẹyẹ fun ọjẹwẹwẹ agbabọọlu to gbamuse julọ fun ọdun2018.
Akinlaja sọ pe, iwa ọdaran ko ni nnkan ṣe pẹlu iye siimu ti eeyan n lo.
Ìtàn ilu naa Nkan akọkọ ti Daura gbajumọ fun ni ìtàn iṣẹdalẹ ilu naa.
Amọ o ni, o yẹ ki Saraki ṣe ohun to yẹ, nipa fi fi ipo rẹ silẹ gẹgẹ bi aarẹ ile aṣofin.
 O tẹsiwaju pe ""a ko ri ami kankan pe Aarẹ n gbe igbesẹ lati yẹ́ ibura rẹ lati daabo bo awọn ọmọ Naijiria si."
Ọpọlọpọ iṣẹlẹ ijinigbe lo ṣẹlẹ kaakiri orilẹ-ede Naijiria lasiko yii ni eyi to n kọ ọpọ olori lominu.
" Oríṣun àwòrán, others Ninu ọrọ tiẹ, alaga ẹgbẹ CAN ni Ondo salaye pe, ijọba kan n fi ẹtẹ silẹ, maa pa lapalapa ni nitori awọn onimọ isegun ti kede saaju pe, awọn arugbo ni ko sa fun Covid-19, kii ṣe ọmọde.
Ni ipari, won tun ro awon osise oniroyin lati mase figba kan bo kan ninu, ninu awon iroyin won kookan ti won gbejade.
Ọwọ́ yín kò tẹ ohun tí ẹ fẹ́ nítorí pé ẹ kò bèèrè lọ́dọ̀ Ọlọrun.
Dájúdájú, OLUWA, tìrẹ ni ààbò wa;ìwọ, Ẹni Mímọ́ Israẹli ni ọba wa.
Ẹ̀yin òpùrọ́ ati ẹlẹ́tàn wọnyi,ẹ̀yin oníṣègùn tí ẹ kò lè wonisàn.
Ó tún sọ fún mi, pé, “Ọmọ eniyan, fi etí sí gbogbo ọ̀rọ̀ tí n óo bá ọ sọ, kí o sì fi wọ́n sọ́kàn.
Alakoso ohun so pe, o je ohun edun okan pe, awon agbe ohun ko le pada sile won, tori pe, awon daran-daran ti gbakoso ile won.
Ankara ti kuro ni aso lasan ni orile ede Naijiria, o ti di ami idanimo lagbaye ti won fi n pon awon eniyan ile Adulawo le nibi gbogbo.
OLUWA ti fún un ní ọpọlọpọ mààlúù ati agbo ẹran, ọpọlọpọ fadaka ati wúrà, ọpọlọpọ iranṣẹkunrin ati iranṣẹbinrin, ati ọpọlọpọ ràkúnmí ati kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́.
Ó sọ omi odò di líle bí òkúta,ojú ibú sì dì bíi yìnyín.
Aisha Buhari sàtìlẹyìn fáwọn ọ̀dọ́ tó fọnmú lórí ìyànsípò àwọn alátakò sínú ìjọba APC Mà á fún àwọn ọba alayé ní ojúṣe nínú ìjọba mi - Seyi Makinde Lẹ́yìn ọlọ́pàá, VIO nìkan ló láṣẹ láti dá ọkọ dúró láìṣẹ̀ - Ọ̀gá VIO Eko Àwọn àṣà àti ìse tó yọ obìnrin sílẹ̀ nílẹ̀ Yorùbá Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Florida: Ọ̀ọ̀nì àléègbà dé ba Mary lálejò lọ́gànjọ́ òru Inú fu, àyà fu ni Naijiria wà tẹ́lẹ̀ Ikọ super Falcons, tii se agbabọọlu obinrin fun orilẹ-ede Naijiria atawọn ọmọ Naijiria, yoo kun fun adura lati gba idajọ rere nipa ati tẹ siwaju ninu idije ife ẹyẹ agbaye to n lọ lọwọ lorilẹ-ede France.
A wà nínú igbó tí a ti ń wá àwọn arinrìnàjò mẹ́jọ láti Abuja sí Eko tí wọ́n jígbé lọ- Ọlọ́pàá Ondo Wo odò tí wọ́n ti rí Aishat tí àgbárá òjò gbé lọ ní Eko Oshiomhole ní, òun kò kábàmọ́ gbogbo ìgbésẹ̀ ti òun ti gbé sẹyin.
Ni kete ti igbakeji Fayose,Olusọla Eleka ti fidirẹmi ninu idibo Gomina ipinlẹ Ekiti ajọ EFCC kede pe 'awọn ti gbọn awọn iwe to wa lọwọ awọn lori magomago to waye lori awọn ile adiyẹ ti wọn dá sílẹ̀ l'Ekiti.
    “Ohun gbogbo ti ń bẹ ní òde ayé ni ó ni ìdí wọn: gbongbo ni ìdí igi; orísun ni ìdí omí; ẹyin ni ìdì àkùkọ- bí o ti ṣe déédéé rí mi lákòókò yìí kò sàìní ìdí pàtàkì kan.
Ileeṣẹ ọlọpaa Dubai lo fi ikede ọrọ yii sita ninu atẹjade kan to fi si oju opo Twitter rẹ.
Àwọn ọmọ ogun Babiloni ti ṣíwọ́ ogun jíjà,wọ́n wà ní ibi ààbò wọn;àárẹ̀ ti mú wọn, wọ́n sì ti di obinrin.
Nígbà ti Nengi jẹ́ olórí ilé.
Wọn pada f'oju fo ẹsun ole jija naa, ṣugbọn o gba idajọ ẹwọn ọdun mẹta ataabọ fun ẹsun jibiti.
Ọpọlọpọ ìgbà ni ó gbà wọ́n sílẹ̀,ṣugbọn wọ́n ti pinnu láti máa tàpá sí i,OLUWA sì rẹ̀ wọ́n sílẹ̀ nítorí ẹ̀ṣẹ̀ wọn.
PDP: APC fi bàálù dẹ́rùbà wa láti dìpò, tó sì fi ọlọ́pàá gbé ọ̀pọ̀ ọmọ ẹgbẹ́ wa Ẹgbẹ oselu PDP ti ni, oun ko gba esi idibo ti Ajọ Eleto idibo lorilẹede Naijiria, INEC gbe jade, lẹyin ti wọn kede Raheem Olawuyi ti ẹgbẹ oselu APC, gẹgẹbi ẹni to jawe olubori ninu atundi ibo si ile asojusofin lẹkun idibo Ekiti/Irepodun/Isin/Oke-Ero ni ipinlẹ Kwara.
Ǹjẹ́ nisinsinyii gbogbo àwọn tí ó bá ti paniyan tabi tí ó ti fọwọ́ kan òkú láàrin yín yóo dúró lẹ́yìn ibùdó fún ọjọ́ meje.
Nígbà tí ó sọ báyìí tán, ó kúnlẹ̀ pẹlu gbogbo wọn, ó sì gbadura.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Olusegun Obasanjo: Ọmú ìyá mi ti mo fi ń mùkọ ni kekere ló jẹ ki ń lókun Ṣugbọn nigba ti ijọba alagbada yoo fi pada si Naijiria lẹyin iku Sanni Abacha lọdun 1999, Soyinka pada wa sile.
Ayẹyẹ ti wọn maa n ṣe fawọn ologun ni wọn yoo ṣe fun oloogbe Tolulọpe ẹni ọdun mẹrinlelogun.
Coronavirus in Lagos: Sanwo-Olu ti ilé ẹ̀kọ́ pa, fòfin de ayẹyẹ àdúgbò àti òde fàájì torí ọwọ́jà àrùn
Bibẹ kọ, ọtọ lohun taa baa maa sọ.
Ni ọdọọdun ni ija awọn ọmọ ẹgbẹ NURTW maa n mu ẹmi dani ni Ipinlẹ Eko.
Tìrẹ nìkan ṣoṣo ni kí ó jẹ́,má jẹ́ kí àjèjì bá ọ pín ninu rẹ̀.
Ẹkẹrinla mú Matitaya, òun ati àwọn ọmọ rẹ̀ ọkunrin, ati àwọn arakunrin rẹ̀ jẹ́ mejila.
Olóṣèlú alátakò Azer Gasimli sọ pé ìfọ̀rọ̀-wáni-lẹ́nuwò ọ̀hún fi hàn pé “ìfoyà ti dé bá” ìjọba láàárín bí àwọn ará ìlú ò ṣe gba ti wọn àti ọ̀rọ̀ ajé ìlú tí ó ń ṣ'òjòjò.
Òtítọ́ ni ọ̀rọ̀ yìí: ó dájú, ó sì yẹ ní gbígbà tọkàntọkàn, pé Kristi Jesu wá sinu ayé láti gba ẹlẹ́ṣẹ̀ là.
òun nìkan ni n óo fi kọ arọmọdọmọ Jakọbu ati Dafidi, iranṣẹ mi sílẹ̀, tí n kò fi ní máa yan ọ̀kan ninu àwọn ọmọ rẹ̀ láti jọba lórí ìran Abrahamu, Isaaki ati Jakọbu.
Naijiria yoo maa koju iko Australia, Argentina ati Turkey nniu ipele keji iyikoto ifigagbaga idije agbaye 2018 FIBA Women’s Basketball ti yoo bere lojo kejilelogun osu kesan an titi di ogbon ojo odun ti a wa yii, nilu Tenerife, lorile-ede Spain.
Nínú àwọràn náà ni obinrin kan dojubolẹ ninu àgbàrá ẹjẹ̀ rẹ̀ pẹ́lú àpá to lágbára ni apá rẹ̀, eyí ni wọ́n ni o jẹ ọkan lára àworan to wà ninu iṣẹ̀lẹ̀ náà.
Wọn ni kii jẹ ki eniyan wuwo lalẹ.
Nitori òwe Yorùbá ti ó sọ pé “Bi a bá tori Ẹni burúkú fọ́jú, a kò ni ri ojú ri ẹni rere”, ó yẹ ki a farabalẹ̀ wo iwà ẹni ti a bá pàdé ju ki itàn tàbi iwà awọn diẹ ba gbogbo ẹni ti ó bá ti ẹbi, ilú tàbi ẹ̀yà kan jẹ́, ki á lè ri ojú ri ẹni rere.
Kete ti wọn ba ti so ijokoo ile rọ ko ni si ijiroro tabi idibo kankan.
Apọju ṣuga mu ki eeyan ni arun jẹjẹrẹ.
Kini awọn eeyan n sọ lori afara yii?
Ko to di akoko yii ni awọn oniroyin ti n sọ pe ko daju boya ẹmi kankan ba iṣẹlẹ naa rin ṣugbọn pe awọn ọkọ naa bajẹ yanna yanna.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Àrà méèrírí , ẹ wo ọkùnrin tí eegun rẹ̀ rọ̀ bíi rọ́bà, tó ń ká bíi ẹja Igbó mímu lè ṣe kóríyá, kò lé fi kún orín ẹnu òṣèré - 9ice Jesu Oyingbo rèé, pásítọ̀ tó láṣẹ ìbálòpọ̀ lóri ọmọ ìjọ obìnrin O ni iya oun maa n sunkun pe oun ko pe lọmọ tabi pe oun ko lee ta putu, ni oun ko se ni ifẹ abo, sugbọn o ni eyi ko ri bẹẹ, bi Ọlọrun se se isẹda ti oun ni.
Ile-ise olopaa so pe, o farahan pe ero igbalode latona ti a mo si (remote control), ni awon dari ado oloro naa.
A múra a kí ara wa; kò sì dàgbà ju ti àtijọ́ lójú mi, ṣùgbọ́n ìbọn ọkùnrin náà túbọ̀ dúdú sí i, ó da bí aṣọ kíjìpá àgbàlagbà obìnrin, tí wọ́n ti rà kí ìyá mi tó wọ ile ọkọ, ti wọ́n sì ti pa ní aró ní oríṣiríṣí ìgbà, ti kíjìpá eléyìínì dúdú kẹlẹkẹlẹ, bẹ́ẹ̀ ni fìlà àkàrà – oògùn a máa wù mí, nítorí ìgbà tí òun bá kó ìṣáná àti ewé tábà sí inú rẹ̀ tán, tí òun bá si tẹ fìlà náà sí ìpàkọ́, eléyìínì a da bi èèso orí igi.
 Ṣùgbọ ́ n ẹbọ to jade ṣí nip é ki o lọ ni eja abori ńlá kan , obi àbàtà , àti iyàn ìlèkẹ ̀ ko fi bọ ẹlẹda rẹ .
Ọ̀rọ̀ ẹlẹ́rìí èké yóo di asán,ṣugbọn ọ̀rọ̀ ẹni tí ó fetí sílẹ̀ ni a óo gbàgbọ́.
- Aregbesola Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí 3 sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 2:23 Fídíò, Water Generator: Ó leè ṣiṣẹ fún wákàtí mẹfà, kó tó sinmi, Duration 2,2310 Òkùdu 2020 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
Ẹwẹ, ẹgbẹ oṣelu PDP naa ba awọn eniyan kẹdun, ti wọn si gbadura fun awọn eniyan to sọ ẹbi ati ara nu ninu iṣẹlẹ naa, ki Olọrun tẹ wọn si afẹfẹ rere PDP si fikun wi pe awọn yoo ṣe ohun gbogbo to wa ni ikawọ awọn lati ri wi pe ajọ lorilẹede lagbaye dide si iṣẹlẹ Naijiria, ki alaafia ati oṣelu tiwantiwa le pada sipo ni Naijiria.
Lẹyin iṣẹju diẹ to jọwọ ara rẹ fun awọn agbofinro tan lo dede ṣubu lulẹ, ti ko si le rin mọ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù 8th Assembly: Saraki pín owó ìyọ̀nda rẹ̀ fún ẹbí Leah Sharibu àtàwọn míì 9 Òkùdu 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 10 Òkùdu 2019 Oríṣun àwòrán, Twitter/Dr Abubakar Bukola Saraki Adari ile igbimọ aṣofin agba ikẹjọ to ṣeṣẹ kogba sile, Sẹnẹtọ Bukola Saraki ti fi owo iyọnda rẹ ranṣẹ si awọn ẹbi akẹkọọbinrin Leah Sharibu to wa lakata Boko Haram atawọn oṣiṣẹ oluranlọwọ ti Boko Haram sẹkupa.
Ṣugbọn opó tí ó bá ń gbádùn ara rẹ̀ káàkiri ti kú sáyé.
Tún dá ọwọ́ pada sẹ́yìn, kí o fi wọ́ ara àwọn ẹ̀ka,bí ẹni tí ń ká èso àjàrà.
OLUWA ní, “Ẹ ti fi ẹnu yín sọ ọ̀rọ̀ burúkú sí mi.
Onimọ nipa oju-opo ayelujara kan, Zainab Sule, sọ pe ''iroyin to ti pẹ maa n saaba wa lori oju-opo ayelujara ijọba nitori ''kii saaba ni ẹnikan gbogi ti o maa n bojuto o.
Macaroni sọ lori awọn fọto naa ti Lateef si sita.
Nítorí náà, Jehoramu kó gbogbo àwọn kẹ̀kẹ́ ogun rẹ̀, wọ́n lọ sí Sairi láti bá Edomu jagun.
Ko si ologun kankan ni ilu Dapchi tabi Buniyadi nibi ti wọn ni awọn ko ọmọogun si ni iwọn ibusọ ọgbọn si ilu Dapchi."
Agbarijọpọ ẹgbẹ awọn ọmọ bibi ilẹ Yoruba, YWA si lo se agbatẹru ipade eto aabo naa.
Ó jẹ́ òfin tí ó jẹmọ́ àrùn ẹ̀tẹ̀ tí ó bá wà lára ẹ̀wù tabi aṣọ, láti fi mọ̀ bóyá ó mọ́ tabi kò mọ́, kì báà jẹ́ aṣọ onírun tabi olówùú, tabi ohun èlò aláwọ.
Wọn yóo ṣe nǹkan wọnyi nítorí wọn kò mọ Baba, wọn kò sì mọ̀ mí.
Ó mú mi lọ sí ilẹ̀ Israẹli ninu ìran, ó gbé mi sí orí òkè gíga kan.
Nítorí OLUWA ti fi ìlú yìí le yín lọ́wọ́.
Dino Melaye: Mò ń bọ wá yojú sí yin lágọ́ọ̀ ọlọ́pàá
Wọn ṣalaye pe bi a ba sunmọ Olọrun ninu isin wa paapaa nipa kikọ orin iyin si I ninu ẹmi pẹlu iwa otitọ, ko ṣoro fun Ọlọrun lati mu igba ọtun alailẹgbẹ  ba orilẹ-ede Naijiria.
Ọlọpa kan yinbọn mọ ọga rẹ nitori obinrin Àwọn arẹwà obinrin Yollywood, tá ló mọ iṣẹ́ rẹ̀ jù?
Itara abiyamọ n mu iya Sujith bayii de ibi pe wọn kiyesi pe o lọ n ran apo to ro pe oun a lo fi yọ ọmọ oun sita ninu kanga to ko si.
Ọmọ Josẹfu ni àwọn eniyan mọ̀ ọ́n sí.
Iyì àti ẹ̀yẹ níbi àjọ̀dún Dubar nílú Ilọrin Ẹ fójú lóúnjẹ lórí àbẹwò igbákejì ààrẹ si Ilorin Àbúrò Saraki ní APC ló ni Kwara lọ́jọ́ Abamẹta tó m bọ̀ Ó tó gẹ́, Atikulated àti àwọn àṣà ìpolongo tó gbòde lásìkò ìbò 2019 Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ondo: Dejí sun ọmọ méje àtagbalagba meji mọ́lé nítorí pé ó ń bínú Lẹyin ti wọn kirun Ishai tan lalẹ ọjọ aje oṣu kẹfa ọdun 2019 ni Mama Nma jade laye.
Sọ àsọtẹ́lẹ̀ nípa ikọ̀ tí yóò gba ife ẹ̀yẹ àgbáyé 2018 pẹ̀lú eré ìdárayá tuntun ti BBC Ṣé orílẹ̀èdè rẹ ti gba ife ẹ̀yẹ àgbáyé rí?
"Gbajúgbajà òṣèré tíátà, ""Ijẹwuru"" ti jáde láyé Ayélujára ló ń dá ìjà òsèré sílẹ̀ - Ọ̀gá Bello Àwọn òsèré Nollywood se ìdárò BURGER to jáde láyé Ẹ yàgò fún ìwà adìẹ dàmí lóògùn nù, màá fọ lẹ́yin lásìkò ìjà - Buhari O sọrọ lori afojusun rẹ lati di alafo to wa laarin awọn oṣiṣẹ ọlọwọ idan ninu sinima ilu oyinbo ati ti ilẹ Adulawọ."
Eyi fihan pe, alekun ba eto irina oko lati N171.
Wọ́n jẹ́ ẹlẹ́gbin ati aláìgbọràn, wọn kò yẹ fún iṣẹ́ rere kan.
“Okoowo bebi je ohun to n gboro si lojoojumo, paapajulo ni China, France ati awon orile-ede kankan, eyi ti a si ni ebun ti o po ni Naijiria lati darapo mo awon orile-ede yii.
OLUWA, má jẹ́ kí ojú ó ti ẹnikẹ́ni tí ó bá gbẹ́kẹ̀lé ọ;àwọn ọ̀dàlẹ̀ eniyan ni kí ojú ó tì.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Tani tíkẹ̀ẹ̀tì Gómìnà Kwara yóò já mọ́ lọ́wọ́?
Ọrọ owo ori sisan si lo fa ogun naa, bi o tilẹ jẹ pe awọn eeyan kan lero pe o tun lọwọ ọrọ oselu diẹ ninu.
Ninu idije Champions League,iru itu bayi sọwọn ti awọn eeyan si n kan sara si Liverpool.
O ni 'ẹni to ba jale ti pari iṣẹ rẹ pẹlu wa niyẹn'.
Ayade ati iyawo rẹ Linda ti dibo won ni agbegbe  Kakum ni ijọba ibilẹ Obudu , ni ipinlẹ Cross
Ajakale àrùn yìí náà jẹ mafarakanmi tàbí masunmọmi, tí àwọn èèyàn sì ń ṣe ara wọn mọle, gẹgẹ ba ti n se láyé ajakale àrùn Coronavirus yìí, kí wọn máa bàa kò àrùn náà.
O sọ pe lootọ iriri se pataki sugbọn o yẹ ki awọn ọdọ ni anfaani lati se ijọba nitori lawọn orileede to ti gun oke agba, awọn ọdọ lo n dari eto.
Nibẹ bayii, labẹ igbele ni olukuluku wa, lara awọn to s wa labẹ igbele yii ni awọn ọmọ orilẹede Naijiria wa pẹlu.
Ó lé àwọn ọ̀tá rẹ̀ sẹ́yìn;ó dójú tì wọ́n títí ayé.
"Àìmọ̀kan ló mú mi hu ìwà tí mo hù kọjá sẹ́yìn, Jonathan dárí jì mí - Dino Melaye Ìjọba ìpínlẹ̀ Kano pàṣẹ pé kí gbogbo ilé ẹ̀kọ́ ètò ìlera di títì pa Wo àwọn ìṣesí ojoojúmọ́ mẹ́wàá tó le ṣàkóbá fún ọpọlọ rẹ Wọ́n ní kí ọ̀gá àgbà ""Ede Poly"" lọ rọ́kún nílé lórí ẹ̀sùn pé ó kan bẹ́ẹ̀dì sí ọ́fíìsì Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsèjẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọ Ó pe ẹgbẹ́ lẹ́jọ́ fún irú ìlànà ti ó tẹ̀lé láti dìbò yan olùdíje dupò gómìnà lábẹ́ àsíà ẹgbẹ́ òṣèlú APC nípìnlẹ̀ Ondo."
Agbẹnusọ igbakeji, Laolu Akande, ni iwadii ti bẹrẹ ni pẹrẹwu.
Lati igba naa ni awọn ọmọ Naijiria ti n fi ọrọ ikẹdun ati erongba wọn lori igbesẹ yii ranṣẹ.
alfred adler je onisegun omo ile austria .
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Tinubu 2023: Àwọn èèkàn ilẹ̀ Yorùbá ń ṣèpàdé ṣáájú dídìbò fún Tinubu ní 2023 15 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Oríṣun àwòrán, Others Àkọlé àwòrán, Asiwaju Tinubu Ilẹkẹ ma ja sile, ilẹkẹ ma ja sode, ibi kan ni yoo kuku pada jasi nipa ẹya ti yoo jẹ aarẹ orilẹede Naijiria to mbọ.
6 Jumada Al Akhirah- Idakeji oṣu Jumada-Al Ula ni oṣu yi jẹ.
mule pe o seese ki awon to fara kaasa isele ibi ohun tun po si ju yen lo.
Ọdún náà gbọdọ̀ jẹ́ ọdún ìsinmi fún ilẹ̀.
Eyi ni mo n pariwo, ti mo si tun maa n  be awon  awon gomina lati maa se idanilekoo fun awon eniyan won, ki won si mu  kaadi idibo won lokunkundun, ki won si toju re daadaa.
” Wọ́n bá wọn ọgbọ̀n owó fadaka fún mi gẹ́gẹ́ bí owó iṣẹ́ mi.
awọn ọmọ orilẹ ede Naijiria to le ni mẹ́rìndínlọ́gbọ̀nlelọ́ọ̀dúnrún lati orile ede Libya.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Alaafin: Olori Aanu Adeyemi ṣàlàyé ìdí tó ṣe gẹ́ Oba Lamidi Adeyemi ti ìlú Oyo O ni ASUU ko ni sinmi iyanṣẹlodi ti ijọba ko ba ṣe amuṣẹ adehun rẹ ọdun 2019 pẹlu ASUU.
Bi o tilẹ jẹ wi pe awọn ọmọlẹyin rẹ n lọọgun pe ohun to n sẹ́lẹ yii ni ọwọ ijọba Naijiria ninu amọ ijọba paapaa n pariwo.
Ẹwẹ, ile igbimọ aṣofin agba ti fi abadofin naa ṣọwọ si igbimọ to tun duro ire lori ọrọ idajọ, ẹtọ ọmọniyan ati ọrọ ofin.
Maria Magidaleni ati Maria ìyá Josẹfu ń wo ibi tí wọ́n tẹ́ ẹ sí.
O ni eeyan to feran iselu awa ara wa ni Walter jẹ, O ni o sin oun ni gbere ipakọ pe wọn fẹ mu oun ti oun ba pada de si Naijiria.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ẹré bọ́ọ̀lù: Arsenal bọ́ mọ́ Dangote lọ́wọ́ láti rà 7 Ògún 2018 Oríṣun àwòrán, Facebook/Dangote and Kroenke Àkọlé àwòrán, Aliko Dangoke jẹ́ ọ̀kan lára àwọn olólùfẹ́ ikọ̀ Arsenal lorílẹ́èdè Nàìjírìa Gbajugbaja oniṣowo ọmọ Naijiria Aliko Dangote le maa ni anfani lati ra ẹgbẹ agbabọọlu Arsenal mọ lẹyin ti ọmọ ilẹ Amẹrika, Stan Kroenke, kede pe oun fẹ ra ikọ agbabọọlu naa pa.
"O ni ""mo dupẹ lọwọ gbogbo yin fun adura ati atilẹyin yin."
 méjìdínlógún  ti won n san fun awon osise ko tọ rara, o
Laide, to jẹ ọkan lara awọn ọmọbinrin mejidinlaadọfa ti wọn ri idande gba kuro nile ọmọ alaigbọran naa sọ pe awọn ọmọ ati ibatan oludasilẹ ile ọmọ alaigbọran naa, lo ti sọ ohun di ẹrọ ibanilopọ, ti wọn si n sun ti oun bo se wu wọn.
5 119,640 Dominican Republic 2,432 22.
Àródan jẹ́ ọ̀rọ̀ Yorùbá tí ìtúmọ̀ rẹ̀ fara sin
Awọn eeyan ìdíkọ̀ naa gba pe iṣẹ́ burúkú ni oògùn olóró n ṣe lara wọn.
OLUWA ní, “Wò ó, níwòyí ọ̀la, n óo da yìnyín bo ilẹ̀, irú èyí tí kò sí ní ilẹ̀ Ijipti rí, láti ọjọ́ tí wọ́n ti tẹ̀ ẹ́ dó títí di òní yìí.
Olúdíje ẹgbẹ òṣèlú PDP nikan ni kò yọjú síbi ìpàde ìta gbángba ninu gbogbo awọn oludije ti wọn kọwe pe.
EFCC fẹsun jiji owo ilu kan Gomina Abia tẹlẹ Orji Uzor Kalu Ẹjọ miiran ti ajọ EFCC ṣe agbatẹru rẹ lasiko ti Magu fi jẹ alaga ajọ naa ni ẹsun kiko owo bii N7.
Owo to wole si apo isuna orile ede yii lati odun 1999 si 2014 wa ninu akosile sugbon won ko lo owo yii dara-dara lati fi pese ohun amayederun.
Nítorí náà, OLUWA, fún èmi iranṣẹ rẹ ní ọgbọ́n láti darí àwọn eniyan rẹ, kí n lè mọ ìyàtọ̀ láàrin ire ati ibi, nítorí pé, bí kò bá jẹ́ bẹ́ẹ̀, ta ni lè ṣe àkóso àwọn eniyan rẹ tí wọ́n pọ̀ báyìí?
Oòrùn yóo ṣókùnkùn,òṣùpá yóo pọ́n rẹ̀bẹ̀tẹ̀ bí ẹ̀jẹ̀,kí ọjọ́ OLUWA tí ó lẹ́rù tó dé.
Ere kẹkẹ: Awọn ọmọde fẹran lati ma a yii kẹkẹ, wọn si ma n se lati ẹnikan si ekeji ni, titi yoo fi kari awọn toku.
igba ti a ba kaaramasiki ọrọ aabo awọn ara ilu ati awọn nnkan ini wọn,
Oríṣun àwòrán, Ben Burce Koda, o ṣe alaga igbimọ tẹẹkoto fun gbogbo ẹgbẹ oṣelu PDP ni Guusu iwọ oorun Naijiria patapata nigba kan.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Coronavirus: Ṣẹ́ lóòtọ́ ní ginger àti garlic lè pa àrun Coronavirus?
Ibẹ̀ ni n óo ti máa bá àwọn eniyan Israẹli pàdé, ògo mi yóo sì máa ya ibẹ̀ sí mímọ́.
Àmọ́ gbígbé pẹ̀lú ẹbí tàbí ọ̀rẹ́ kò kan ti ìtìlẹyìn.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ìdẹ̀ra dé, Gẹnẹrátọ̀ tó ń lo omi dé, a bọ́ lọ́wọ́ òkùnkùn Bí mo ṣe dúró ti Toyin nílé ìgbẹ̀bí jẹ́ kí ń mọ̀ pé ó yẹ kí ọkùnrin máa bọ aya wọn - ọkọ Toyin Abraham Iṣẹ́ ọpọlọ ló yẹ ká ṣe nínú tíátà, kìí ṣe àfihàn ara bíbó àbí ìhòòhò wa - Binta Mọgaji Ìjọba, ẹ yé fi ọlọ́pàá àtàwọn ológun dúnkokò máwọn èèyàn- Ṣoyinka Irọ́ ló pa, a kò mọ̀ ọ́ rí tàbí fún ọ ní ₦13m - APC tako afurasí ajínigbéAṣírí ìdí ti El-Zakzaky fi padà si Nàìjíríà láti India Khafi ni wọn lo sọrọ iwuri nipa Naijiria julọ, lẹyin naa ni wọn kede rẹ gẹgẹ bi ẹni to jawe olubori ninu idije naa.
Fun idi eyi, o gboriyin fun ijoba to ṣetan lati gbe igbese naa, ti o si ki won ku iṣe takuntakun.
Ó súre fún ẹ̀yà Bẹnjamini pé:“Bẹnjamini, ẹ̀yà tí OLUWA fẹ́ràn tí ó sì ń dáàbò bò,OLUWA ń ṣọ́ wọn nígbà gbogbo,ó sì ń gbé ààrin wọn.
Òun fúnrarẹ̀ sọ pé, “N óo sá tẹ̀lé àwọn olólùfẹ́ mi, àwọn tí wọn ń fún mi ní oúnjẹ ati omi, ati aṣọ òtútù, ati aṣọ fẹ́lẹ́fẹ́lẹ́ funfun, ati òróró olifi ati ọtí.
  Adari eto nile igbimo asoju sofin agba, Orji
Tabi o kò mọ̀ pé mo lè ké pe Baba mi, kí ó fún mi ní ẹgbaagbeje angẹli nisinsinyii?
Lizzy Anjorin Oríṣun àwòrán, Lizzyanjorin/instagram Tí ẹ o bá gbàgbé Lizzy Anjonrin ṣe ìgbéyawó laipẹ yìí, to sí fí àwọn fóto ìgbéyàwó náà síta lórí àtẹjíṣẹ rẹ̀ ni ọṣẹ̀ tó kójá òdé yìí.
Ilé ẹjọ́ rán ọjọ̀gbọ́n fasiti OAU lọ sẹ́wọ̀n ọdún méjì Mo gbàgbé sùnlọ sìnú ọkọ̀ òfurufú, ẹ̀rù ikú bà mí -Tiff Ọlọ́pàá ìpínlẹ̀ kọ́ ní ojútùú ìṣòro ìjínigbé ilẹ̀ Yoruba - Onímọ̀ ọ̀rọ̀ ààbò Kyari ṣalaye fun BBC pe iwadii miran maa n gba to oṣu mẹta si mẹfa ki ọwọ IRT to tẹ awọn ọdaran naa.
Bakan naa lo fikun pe ọmọkunrin to n ba obinrin naa sun ni fasiti ọhun ti le lori ẹsun oogun oloro, to si tun fikun pe oun ti juwe ọna ile fun akẹkọbinrin ti wọn n ba lopọ naa nitori idojuti to ko ba ile ẹkọ ọhun.
Yoruba Films: Lizzy Anjorin yẹ́ iyabo Ojo sí kí ọjọ́ ìbí rẹ̀ tó pé
Bi a ko ba gbagbe awọn alatilẹyin Saraki to wa si ile arugbo naa ti wọn si ba akọroyin wa sọrọ sọ pe ijọba keti ikun si aṣẹ ile ẹjọ to ni ki wọn ma fọwọ kan ile arugbo Olusola Saraki Wíwó Ilé Arúgbó kò lè yọ ìfẹ Saraki kúrò lọkàn aráàlú- Alága PDP Ẹgbẹ oṣelu PDP ti sọrọ lori bi ijọba ipinlẹ Kwara ṣe wo Ile Arugbo lulẹ.
Kí ló wá dé tí o fi ń wo àwọn ọ̀dàlẹ̀, tí o sì dákẹ́, tí ò ń wo àwọn ẹni ibi níran tí wọn ń run àwọn tí wọ́n ṣe olódodo jù wọ́n lọ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, AAUA; Ọ̀pọ̀ ìgbà ni SARS ma ń lu àwọn akẹ́kọ̀ọ́ fásitì wa Iṣẹlẹ naa lo mu awọn ọdọ kan binu di oju ọna marosẹ Eko si Abeokuta ti eleyi si fa sunkẹrẹ fakẹrẹ loju popo lọjọ Aiku.
2019 Guber election: Mi ò fara mọ èsi ìdìbò Ọyọ́ Ayédèrú òògùn ààrùn onígbáméjì tó wà ní ta rèé Ààrẹ Algeria kò ní pẹ́ kọ̀wẹ́ fipò sílẹ̀ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Okùnrin SARS náà sọ pé òun máa pa èèyàn síbi ni- Aladugbo Lasiko to n da ẹjọ naa, Adajọ Agba Oathman Musa sọ wi pe iwadii fihan pe ọdun 1976 ni Adeleke wọ ile iwe girama, amọ ti ko si iwe ẹri to fihan pe o jade iwe mẹwa ni ọdun 1980.
fun awon ara ilu lati gbogun ti iko Boko Haram ti won si pa meta ninu won , ti
Oluwatoye ni ohun to n kọnilominu ni wi pe awọn obinrin ti o jẹ wi pe lati ara wọn ni gbogbo eniyan ti jade naa lotun wa n koju iru wahala bayii.
Ọjọgbọn Ọṣinabajo to jẹ igbakeji aarẹ Muhammadu Buhari sọ pe ''kii ṣe pe oṣi ti tan patapata o.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Good luck fish: Ààrẹ Zambia ṣ'èdárò Ẹja akóredé tó papòdà 8 Owewe 2020 Oríṣun àwòrán, Facebook/Edgar Lungu Aarẹ orile-ede Zambia, Edgar Lungu ti darapọ mọ ogunlọgọ ọmọ ilẹ naa ti wọn n ṣe idaro ẹja nla kan to ku ni fasiti Copperbelt to tobi sikeji lorilẹ ede naa.
Toun ti pe ẹrọ alagbeka ni awọn eeyan mọ Huawei fun,wọn a tun ma pese awọn irinṣẹ fawọn to n ṣeto ibanisọrọ.
Ko ba dara ti ijọba tabi ajọ alaanu ba tun ile Fagunwa se di ibi apewawo.
 alárẹ ̀ fi ọmọbìnrin rẹ ̀ kan gbórowó , fún odùduwà láti fi ṣe aya .
Ta ni yóo ya ọ̀dọ̀ yín, láti bèèrè alaafia yín?
Ogagun Emuekpere ,so pe “opolopo aseyori ni won ti se nipa gbigbokun ti awon to n ji epo robi wa, awon agbesunmomi, awon to n dana,awon to n fomo sowo eru ati awon to n ji epo lori omi,paapaa julo ni ipinle  Akwa Ibom, Cross River ati Rivers.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ọsun Decides: Charlie Boy ni ọ̀pọ̀ àìda ló wáyé lásìkò ìbò Ọ̀sun 23 Agẹmo 2018 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 27 Bélú 2018 Oríṣun àwòrán, Funmi Sodiq Gbajugbaja onkọrin takasufe nni, Charles Oputa ti ọpọ mọ si Charly Boy ti pe fun iwadii to jinlẹ lori bi eto idibo gomina ipinlẹ Ọsun to kọja ṣe lọ.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: PDP bu ẹnu àtẹ́ lú ìpàdé àpàpo APC Àsọtẹ́lẹ̀ tó ṣẹ nípa ìfẹsẹ̀wónsẹ̀ Naijiria Oju àwọn tó gbẹ̀mí awọn olólùfẹ́ OOU rèé Sùgbọ́n nílẹ̀ yìí, o léè f'ẹ̀wọ̀n ọdún mẹ́ẹ̀dógún gbára bí wọ́n bá ká igbó mọ́ ọ lọ́wọ́.
4 4973 Orilẹede South Sudan 63 0.
Ilé Ìwé Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ààrẹ Muhammadu Buhari Ni ọmọ ọdun mọkandinlogun, Buhari dara pọ mọ ile iwe girama fun ẹkọ nipa ijagun, Nigerian Military Training College (NMTC) ni odun 1962.
nígbà tí ilé-ẹ ̀ kọ ́ náà bẹ ̀ rẹ ̀ ní ọdún 1935 , àqọn tí wọ ́ n pọ ̀ jù lọ nínú àwọn akẹ ́ kọ ̀ ọ ́ ilé-ẹ ̀ kọ ́ náà jẹ ́ ìran hausa , tí aláṣẹ ètò-ẹ ̀ kọ ́ ìgbà náà ìyẹn morris , ṣe da lábà ní ọdún 1939 wípé kì ilé-ẹ ̀ kọ ́ yábàá bí láti kọ ́ ẹgbẹ ̀ lẹ ́ gbẹ ̀ àwọ ́ n tí wọ ́ n wá láti gúsù ilẹ ̀ nàìjíríà í wọ ́ n sì di olùkọ ́ fún ìgbaradì ètò-ẹ ̀ kọ ́ tó yanrantí nílé-ẹ ̀ kọ ́ girama ní agbègbè gúsù orílẹ ̀ -èdè nàìjíríà lọ ́ jọ ́ iwájú .
Aare orile ede Naijiria Muhammadu Buhari ti dupẹ lọwọ  ọkẹ aimọye ọmọ orilẹ ede Naijiria fun ipa Pataki ti won ko ninu eto idibo aare lati tun yan an gege bi aare ti yoo maa tukọ orile ede yii fun saa mẹrin miiran.
Ìṣesí Kunle Ọlasọpe ni mo ṣe yan iṣẹ́ akọ̀ròyìn láàyò - Lekan Alabi Àwọn ọmọ Nàìjíríà faraya lórí Boniface tó fẹ́ bá àkẹ́kọ̀ọ̀ sùn Akọsilẹ fihan pe ẹgbẹlẹgbẹ ọmọ Naijiria ni kori ile gbe, awọn eeyan yii si ni ireti pe awọn naa yoo rile gbe lọjọ kan.
Àwọn tí ó kórìíra OLUWA yóo fi ìbẹ̀rùbojo tẹríba fún un,ìyà óo sì jẹ wọ́n títí lae.
Ile iṣẹ ogun fi kun un wi pe saare ti iroyin naa n sọ nipa rẹ iyẹn to wa ni bareke ologun Maimalari jẹ ti ile iṣ ogun sọ́ọ́ to si wa apa Ila Oorun- Ariwa Naijiria.
Ọjọ kẹta ọdun ileya ni ọdun Ojude Ọba maa n waye, ọdun 1892 si lo bẹrẹ lasiko ti Ọba Adesunmbọ Tunwase fun awọn musulumi nilẹ lati kọ mọsalasi si.
Bariga / Oworonshoki Bridge Ijọba ibilẹ Ikeja Somolu / Kosofe Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Wo àwọn àdúgbò tí ìpínlẹ̀ Eko ti fòfin de ọ̀kadà àti Marwa 33.
Trump Impeachment: Aṣòfin 232 ló dìbò yọ ààrẹ nígbà tí 197 tako ìgbésẹ̀ náà
Ó kọjá l’ókè ọ̀dàn, òórùn gba ‘jù.
Ìran èké ati ti ẹ̀tàn ni àwọn wolii rẹ ń rí sí ọ;wọn kò fi ẹ̀ṣẹ̀ rẹ hàn ọ́,kí wọ́n lè dá ire rẹ pada,ṣugbọn wọ́n ń ríran èké ati ìran ẹ̀tàn sí ọ.
Wọ́n ti ba iwájú jẹ́, àwọn tí ó bá ti bá wọn pàdé lẹ́ẹ̀kan kò níí fẹ́ ran àwọn ẹlòmíràn lọ́wọ́ mọ́.
"Aikoju oṣuwọn ileesẹ NIPOST lo mu ki awọn ileesẹ abani fi nkan ránṣẹ kee kee ke bẹrẹ ni Naijiria.
’“Bí ẹ bá mú àjàgà kúrò láàrin yín,tí ẹ kò fi ìka gún ara yín nímú mọ́,tí ẹ kò sì sọ ọ̀rọ̀ ibi mọ́.
Mùsùlùmí ni mí ṣùgbọ́n ìrírí àkọ́kọ́ mi rèé nípa ọdún Kérésìmesì ní Canada, Muhammad Hussain ṣàlàyé
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù #UEFAawards: Van Dijk gbadé UEFA mọ́ Messi àti Ronaldo lọ́wọ́ 29 Ògún 2019 Oríṣun àwòrán, Twitter/UEFA Adẹyinmu fun ẹgbẹ agbabọọlu Liverpool, Virgil Van Dijk lo gbami ẹyẹ agbabọọlu UEFA to pegede julọ ni saa bọọlu to lọ.
Moshood Adeoti ADP Moshood Adeoti ni oludije labẹ ẹgbẹ oṣelu ADP, o ni oun a ṣagbekalẹ igbimọ elétí gbáròyé kalẹ̀ ti yoo wa fun ijọba àti ẹlẹgbẹjẹgbẹ.
” Wọn kò sì lè jẹ ẹ́ mọ́.
Ọmọdebinrin kan wá rí i, ó tẹjú mọ́ ọn, ó ní, “Ọkunrin yìí wà pẹlu Jesu.
Oríṣun àwòrán, AFP Àkọlé àwòrán, Aubameyang ati Mkhitaryan Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Ikọlu yii waye lẹyin oṣe meji ti ọ̀kan ti kọkọ waye nibi ti ko fi bẹ jina si Tajoure.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Man City vs Chelsea: Wọn ṣe ìyà fún Chelsea pẹ̀lú àmì ayo 6-0 10 Èrèlè 2019 Oríṣun àwòrán, Reuters Àkọlé àwòrán, Ẹgbẹ́ agbábọ́ọ́lù Manchester City ló ń se ipò kíní lórí tábìlì Premier League pẹ̀lú àmì ayò 65 lórí àtẹ.
Ninu iwadii ati iroyin ti CNN gbe jade wọn lawọn kan si awọn akọsẹmọsẹ to salaye pe asẹku ọta ibọn tawọn fi han jẹ iru eyi tawọn ọmọ ileesẹ ologun Naijiria n lo.
Èyí ni àròpọ̀ ibi mímọ́ ati ilẹ̀ ti gbogbo ìlú náà.
Tambuwal, Sokoto; Abdulaziz Yari, Zamfara; Badaru Abubakar, Jigawa ati Nasir El-Rufai,
Tshepo Ikaneng lo firoyin naa lede nigba ti o n jabọ iroyin yajoyajo nibi ti ko jina si bi ti awọn ọmọ African National Congress ti n ṣepade ọjọ iwaju Aarẹ Zuma.
Gbajabiamila to n soju fun ipinle Eko(APC-Lagos),naa ti darapọ mọ awọn akẹgbẹ rẹ
Agbegbe ikire si apomu ni opopona marosẹ Ifẹ si Ibadan ni wọn ti ji ojọgbọn naa gbe.
Ìpínlẹ̀ Èkó jẹ ikan ninú ipinle mẹ́fà Yorùbá.
Lára àwọn àkàrà tí ẹ bá kọ́kọ́ ṣe ni ẹ óo máa mú wá fi ṣe ọrẹ fún OLUWA ní ìrandíran yín.
Best Supporting Actress Best Supporting Actor Best short film or online video Best actor in a comedy Best actress in a comedy Best actor in a drama Best actress in a drama Best Indeginous Language Movies/TV Series- Yoruba Ní ti àwọn òṣèré Nollywood yoruba ti wọ́n yàn fún àmì ẹ̀yẹ náà ni Wumi Olabintan - Intent Oyebade Adebimpe - Adebimpe Omo Oba Yewande Famakin- Alukbarika Ronke Odusanya- Ajoji Godogbo Àwọn to kù ni Funke Akindele Àkọlé àwòrán, MVCA Award: Ronke Odusanya, Oyebade Adebimpe, Funke Akindele àti Toyin Abrham tani ami ẹyẹ yoo já mọ lọ́wọ́?
jawe olubori ninu ifigagbaga ti o waye pelu iko Valencia, esi ifesewonse naa ko
Ìdààmú bá wọn, wọ́n sì túká pẹlu ìpayà.
Bẹẹ lo tun da ẹgbẹ Oduduwa Group"" silẹ lọdun kan naa."
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ìbejì Oníbẹ̀mbẹ́ Òru tí kò yara wọn lẹ́yìn ọgọ́ta ọdún Ohùn ìjálá lásán ni mo fi ń pa ẹran nínú igbó - Ọdẹ Oníjàálá Mo fẹ́ ọkọ mi torí bó se ń kọrin, kìí se torí owó - Ìyàwó Aràrá Mo fẹ́ kí àyẹyẹ ìgbeyàwó mi dùn ni mo se bú sẹ́kún - Ọkọ ìyàwó ẹlẹ́kún Samuel Ladoke Akintọla jẹ́ Agbẹjọ́rò àti Akọ̀ròyìn tí ọ̀rọ̀ dá lẹ́nu rẹ̀ Hubert Ogunde rèé, baba àwọn òsèré tíátà Ìyàtọ̀ wà nínú ìlépa àwọn òṣèré tíátà ayé àtijọ́ àti ìsisìnyí-Papalolo O ni olukọ ati osere ni baba oun, inu ẹjẹ oun si ni isẹ apanilẹrin wa, eyi ti oun ti bẹrẹ lati kekere.
17 Bélú 2020 Lady Peller: Ọjọ́ ni ọjọ́ tí idán yíwọ́ fún ọkọ mi lẹ́yìn tó gé mi sí méjì, mo kú tán15 Bélú 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Àwọn ọ̀dọ́ ilẹ̀ Yoruba kò gbọdọ̀ gbàgbé àṣà ati ohun àdàyébá wọn - Ooni Ile Ife Ṣé ojúlówó ni Oogùn apakòkòrò 'Sanitizer' tó ń lò?
Ẹwẹ, nigba to da si ọrọ naa, ajọ to n ri si agbekalẹ ikọ Amotekun, Dawn Commission ti sọ pe, idi ti wọn ṣe gbe ikọ Amotekun kalẹ ni lati pana iwa ọdaran lawujọ, kii ṣẹ lati da si ọrọ miran ti ko jọ mọ iwa ọdaran.
Amọ ipenija akọkọ ti Pence yoo koju ki o to le yan Trump sipo igbakeji ni pe awọn ọmọ ile aṣojuṣofin yoo ni lati buwọlu iyansipo yi.
Pẹlu iye awọn eeyan tuntun yii, o ti pe 86,576 eeyan to ti ni arun naa ni orilẹede Naijiria bayii.
Harry Akande: Makinde, Dele Momodu ń ṣèdárò Àgbà Oyè Ilẹ̀ Ibadan, Harry Akande tó jáde láyé
Bakan naa ni wọn tun ba ọpọlọpọ nkan jẹ nile aṣofin ọhun.
N kò ní fọwọ́ mi kan ohunkohun àfi ohun tí àwọn ọmọkunrin tí wọ́n bá mi lọ ti jẹ, ati ìpín tiwọn tí ó kàn wọ́n, ṣugbọn jẹ́ kí Aneri, Eṣikolu ati Mamure kó ìpín tiwọn.
Aṣoju orileede Amẹrika pataki si Iran sọ pe otubantẹ ni ọrọ ti Iran n sọ yi ati pe ko si ẹni ti yoo ka wọn kun.
Link Ohùn márùn ún tó yẹ kí o mọ́ nípa àyájọ́ èdè abínibí EFCC ń wá owó Atiku bọ̀ wálé mi- Fayoṣe Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, #NigeriaDecides: BBC ti wa ni gbogbo ìpínlẹ̀ Naijiria láti firoyin gbogbo tóo yin létí Bakan naa, ajọ FIFA ni ki ajọ to n ri si ere bọọlu nilẹ Gẹẹsi, FA san owo to din dẹ ni ẹgbẹrun lọna irinwo pọn-un gẹgẹ bi owo itanran.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Tithing: Daddy Freeze àtàwọn ọmọ Nàìjíríà míì ta gbá òjíṣẹ́ Ọlọ́run torí ègún ìdá mẹ́wàá 31 Sẹ́rẹ́ 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 17 Agẹmo 2020 Oríṣun àwòrán, @DavidOyedepoMin Ṣe ni ori ayelujara tun n gbona tori ọrọ ida mẹwaa ti olori ìjọ Living Faith, Bisọọbu David Oyedepo sọ ni ọjọ Ẹti.
Iwe tawọn akọroyin n lo lati fi kin ọrọ lẹyin nipa alekun yi ni wọn sọ pe o wa lati ọdọ arakunrin kan ti o n ṣiṣẹ pẹlu PPMC ọgbẹni D.
Orile-ede Botswana ti yegi fun arakunrin kan ti o seku pa orebinrin ati omo re okunrin, eyi ti o je idajo iyegi fun alakoko iru re lati bi odun meji lorile-ede naa ti o ko lati fagile idajo iku.
ṣugbọn ẹ̀jẹ̀ ara wọn ni irú àwọn eniyan bẹ́ẹ̀ lúgọ dè,ìparun ẹ̀mí ara wọn ni wọ́n lúgọ tí wọn ń retí.
Ẹ kò gbọdọ̀ jẹ ẹyẹ tabi ẹranko kankan tabi àwọn ẹ̀dá alààyè tí ń káàkiri lórí ilẹ̀, tí mo ti yà sọ́tọ̀ fun yín pé wọ́n jẹ́ aláìmọ́.
Ọdún 1944 ni wọ́n bẹ̀rẹ̀ sí ní jẹ oyè Báálẹ̀ ní Abúlé Ọja, Olóyè Sèídù Bánkọ́lé ló kọ́kọ́ jẹ ẹ́, Elétǔ Òdìbò (Olóyè) AbduLlahi Bámgbọ́pàá ni ó sì fi wọ́n jẹ.
Lọwọlọwọ bayi, awọn akẹkọọ ile ẹkọ naa n san owo to to ẹgbẹrun lọna aadọta dọla lọdun kan.
Toyin tun ti wa gbe sinima tuntun kan sita eyi to pe akọle rẹ ni Elevator Baby, asiko ti oyun rẹ si pe osu mẹfa lo ya sinima naa.
 Lẹyin to ko sọwọ ajọ EFCC, o jẹwọ pe lootọ ni oun lu awọn obinrin ni jibiti gẹgẹ bi ẹsun ti wọn fi ka oun.
Eyi ni awọn amuyẹ ti ileeṣẹ ọlọpaa ni yoo wa fun awọn ọlọpaa ti yoo darapọ mọ ikọ naa.
''Ogbẹle to sẹlẹ lọdun yẹn lo ran itankalẹ awọn kòkòrò naa lowo'' Nípasẹ ṣíṣe àkóso ètò nnkan ọgbin, Olugbenga sọ wi pé awọn kòkòrò wọnyi ti n jẹ ọ̀pọ̀ oúnjẹ tó yẹ ki àgbẹ̀ kò lérè.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Kloe: Èmi kìí mu òògùn olóró, àmọ́ mo fẹ́ràn láti máa wà lẹ́bà omi Gomina to n bọ naa tun ni, Ajimọbi tun fun ajọ to n tun opopona ṣe ni ipinlẹ Ọyọ, ni bii biliọnu marun-un naira.
Nigbà to ń ba akòròyìn BBC s'ọ̀rọ̀, Oba Àkanbi sọ wipe áàwọ to wa láàárin àwọn oba ipinlẹ Ọ̀ṣun lo faà ti wọn ko tíi ṣe ìpade fun ọdún meji.
Kò sí ẹni to ọ̀rọ̀ náà yé ìdí ti Gomina Ganduje fi karabọ ọ̀rọ̀ mọ́salási ti kìí ṣe àwọn ní wọ́n kọ́ọ Àkọlé àwòrán, Imaamu àgbà mọsálási Trans-Amadi yìí ń rọ ìjọba ìpiínlẹ̀ Rivers láti fí ilẹ̀ náa sílẹ̀ fún àwọn Gbọ́n misi omi o tó láàrin gómìnà alágbára méèjèjì tí wọ́n wà ni ẹgbẹ́ òṣèlú ọtọ̀ọ̀tọ yìi jẹ́ ǹkan to lè da ìjà ẹsin silẹ̀ lórilẹ̀-ède Naijiria.
Góòlù pọ̀ ní ìlú Madaka ṣùgbọ́n wọn kò ní ọ̀nà fún ọgọ́rùn ún ọdún Kò sí ẹnikẹ́ni tó kú níbi rògbòdìyàn tó wáyé lánàá - Deji ilu Akure Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Cancer: Àṣe ara mi ni iso ti n run gbogbo bí mo ṣe n ṣèrànwọ́ lórí jẹjẹrẹ Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
OLUWA bá yí ìpinnu rẹ̀ pada, ó ní, “Ohun tí o rí kò ní ṣẹlẹ̀.
Ọ̀rọ̀ tí a sọ lákòókò tí ó yẹdàbí ohun ọ̀ṣọ́ wúrà tí a gbé sinu àwo fadaka.
Wọn kò sì ní dó tì í.
Àwọn ọmọ Naìjíríà yarí, wọn ni àfì dandan ki ìjọba gbé ìgbésẹ̀ lórí ọ̀rọ̀ àwọn ọlọ́pàá SARS tó n fi ojoójómọ́ pa àwọn ọdọ́ ni orílẹ̀èdè yìí.
Ni bi nkan ti ṣe ri yi, oun ati ọmọ orileede South Korea Yoo Myung- he ni wọn yoo fi orukọ wọn ṣọwọ ninu awọn marun un to ṣẹku tẹlẹ.
Jẹ́ kí Alákọ̀wé ráàyè gbé ẹ̀wù kànkà yìí pamọ́ o jàre.
Rewane tẹsiwaju ninu àlàyé naa pe, ilana ti igbimọ gba ni lati sọ owo oṣu gbogbo awọn ti ko to ẹgbẹrun lọna ọgbọn Naira si ẹgbẹrun lọna ọgbọn Naira.
O ni, opurọ gbaa ni Toyin, ile alagbo ọmọ lo bimọ si.
Nigba ti o ba BBC Yoruba sọrọ, Ọgbẹni Balogun ṣalaye wi pe fidihẹ lasan ni awọn gomina ipinlẹ lori ohun ti wọn le ṣe lori ọrọ eto aabo nipinlẹ wọn.
Ni ilẹ Yoruba lapapọ, ko si ẹnikan to je oye yi, sugbọn ni ilu Ilorin, akọsile wa pe, Oloye Olusola Saraki to ti di oloogbe jẹ oye naa, eleyi ti Oba Ilu Ilorin nigbakanri, Oba Zulu Gambari, fi daa lọla.
com/6IO64wolBc— 🇳🇬 Super Eagles (@NGSuperEagles) June 26, 2018Ewe, eyi ni bi igbaradi iko Super Eagles ohun se n lo lowo ni Essentuki ki won o to teko leti lo si papa isere St.
Ẹgbẹlẹgbẹ owo to to biliọnu mejilelọgọrin naira (£211m) to jẹ ti olori tẹlẹ fun orilẹede Naijiria, oloogbe Ọgagun Sani Abacha, ni wọn ti ri nile ifowopamọ Jersey bank nilẹ okeere.
Akọsilẹ ajọ to n ṣewadi nipa eto ilera ni Cameroon, Cameroon Health and Demographic Survey, DHS, fihan pe ìdá mọkanlelogun obirin to wa ni Cameroon lo ni ibalopọ akọkọ nipa ifipabanilopọ.
Ayaba láti ilẹ̀ gúsù yóo dìde dúró ní ọjọ́ ìdájọ́ láti ko ìran yìí lójú, yóo sì dá wọn lẹ́bi.
Ọ̀kan nínú àwọn amúgbálẹ́gbẹ̀ gómìnà tó bá BBC sọ̀rọ̀ sàlàyé pé àwọn òun gan wà nílé ìwé lọ́wọ́ ko si sí èròngbá láti ti ilé ìwé bí àwọn ìpínlẹ̀ ti wọ́n múle ti ṣe n ṣe.
Won n lo lati ti fi ohun ranṣẹ si ara ilu lasiko ogun, wọn fi n se ayẹsi, wọn si fi n parako ogun.
Jharkhand ti ṣe àkọsílẹ̀ iye ẹṣẹ̀ àwọn ènìyán ṣẹ̀ tí ó pọ̀ jù lọ tí ó tan mọ́ ìṣọdẹ-àjẹ́ àmọ́ kì í ṣe ìpínlẹ̀ náà nìkan.
Tinubu Colloquium: Ìṣẹ́gun APC ní ìdìbò 2019 ni ẹ̀bùn pàtàkì tí mo rí gbà fún ọjọ́ ìbí mi
Loni ojó kẹtadinlọgbọn, oṣù keje yii ni ijoba apapọ ati awọn Kọmiṣọnna ipinle merindinlọgbọn Naijiria ati aṣoju ẹgbẹ awọn Olukọ ati ẹgbẹ awọn Onile iwe Aladani kaakiri ipinlẹ Naijiria fẹnuko lori igbesẹ yii lẹyin ti wọn se ipade papọ lori ayelujara.
Ẹni tí ó pè ọ́ yóo wá tọ̀ ọ́ wá, yóo sọ fún ọ pé, ‘Fi ààyè fún ọkunrin yìí,’ Ìwọ yóo wá fi ìtìjú bẹ̀rẹ̀ sí máa wá ààyè lẹ́yìn.
Àbẹ̀tẹ́lẹ̀ dàbí òògùn ajẹ́-bí-idán lójú ẹni tí ń fúnni,ibi gbogbo tí olúwarẹ̀ bá lọ ni ó ti ń ṣe àṣeyege.
Ẹ dá àpò fún ara yín tí kò ní gbó laelae; ẹ to ìṣúra tí ó dájú jọ sí ọ̀run, níbi tí olè kò lè súnmọ́, tí kòkòrò kò sì lè ba nǹkan jẹ́.
Idaduro ti ko ni gbedeke yii da lori pe wọn ko tẹle ohun ti ile fẹnuko le lori nipa ipo ti kiko awọn irinṣẹ kọọkan lati sakani wọn pada lọ sile aṣofin.
Ẹwẹ, lọpọ igba ti awọn miran ba bẹrẹ si n lo awọn oogun tabi agbo to le mu ki wọn jo, ni wọn ki n fẹran bi wọn ṣe maa n ri mọ, nitori wọn maa n jo ju bi wọn ṣe fẹ lọ.
mo sì bèèrè ìtumọ̀ ohun tí mo rí lọ́wọ́ angẹli tí ń bá mi sọ̀rọ̀.
Àti àwọn ìbéèrè míràn Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí kan sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Aeroplane House: Látọdún 1999 ni mo ti bẹ̀rẹ̀ kíkọ́ ilé yìí fún ìyàwó mi ọ̀wọ́n Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Iya oloogbe Barakat, Arabinrin Kafayat Bello ba ikọ BBC Yoruba sọrọ lasiko ti a ṣe abẹwo si ile wọn lowurọ Ọjọru.
”Aare tun tesiwaju pe ekun Niger/Delta ti bere si ni jegbadun eto alaafia bayii nipa ifowosowopo pelu awon agbalagba ati awon eniyan rere  to wa ni ekun naa.
Obinrin naa ẹni ọdun mọkandinlọgbọn to fẹ onisowo kan ni Delhi to jẹ ọmọ ọdunn mẹtalelọgbọn lo ṣegbeyawo ni ogunjọ oṣu kẹsan ọdun 2020 ni Delhi Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Oba Adedokun Abolarin ti Oke Ila: Ó ya ọ̀pọ̀ tó súnmọ́ mi lẹ́nu bí mo ṣe ń kọ́ Ipinnu wọn ni lati ṣe igbeyawo igbalode ni ilẹ Amerika ninu osu kẹsan an, ọdun.
" Àwọn ni "" idán ńlọ "" , "" owó idán "" àti "" agbára "" ."
Awọn ọmọ ẹgbẹ Republican ni igbẹjọ yi jẹ anfaani fawọn lati le gbaruku ti aarẹ to si tun jẹ kawọn pawọpọ da owo jọ fun ipolongo aarẹ Trump .
 omo àdúgbò imojì ni àwon ará òkè-Ìdèra jé .
Ẹ óo máa jọba lórí ọpọlọpọ orílẹ̀-èdè, ṣugbọn wọn kò ní jọba lórí yín.
Bakan naa ni o fi to wa leti pe lọna ati lee dẹkun ọwọja ebi ati inira lasiko aṣẹ konileogbele naa, ijọba oun ti gbe awọn igbesẹ ti yoo bu omi tu araalu lara bii sisanwo oṣu fun awọn oṣiṣẹ ki wọn to gbe aṣẹ naa kalẹ ati idasilẹ igbims majẹobajẹ kan lori ọna ati gbogun ti arun naa ati lati mu irọrun ba araalu lasiko ti wọn ba fi n baa wọ iyaaja.
''Donald Trump kii ṣe aarẹ to yẹ fun orileede yii'' ni ọrọ ti Michelle sọ ninu fọnran kan to fi ṣọwọ sawọn to n kopa nibi apero ẹgbẹ Democrat.
O maa n lefo lori omi.
Nígbà tí ó bá gbó tán, lẹsẹkẹsẹ ọkunrin náà yóo yọ dòjé jáde nítorí pé àkókò ìkórè ti dé.
Day 25: Àwọn àkànlò èdè lásìkò ìdìbò #BBCNigeria2019 ‘Ó yẹ kí Obasanjo ti jẹ asaájú Yorùbá, àmọ́ kò leè jẹ́’ Ilé ẹjọ́ fún Elzakzaky àti ìyàwó ní ẹ̀tọ́ sí ètò ìwòsàn Ẹgbẹ́ òsìsẹ́ NLC ti kọ #27,000 owó osù òsìsẹ́ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Murphy Elégungun Rọba: Mo fẹ́ di ẹnití egungun rẹ rọ jùlọ ní àgbáyé Ẹsun ajẹbanu ati lilo owo ile iwe basubasu, ni wọn fi kan awọn adari ile iwe giga.
Oríṣun àwòrán, Reuters Àkọlé àwòrán, Olori orilẹede naa tuntun, Abiy Ahmed ṣẹṣẹ ba awọn ero sọrọ tan nibi iwọde naa, ni ado oloro naa dun Ko ju bii wakati melo kan lọ ti ori ko aarẹ orilẹede Zimbabwe Emmerson Mnangagwa yọ lọwọ ado oloro ti ti Ethiopa naa ṣẹlẹ.
Bakan naa ni wọn dupẹ lọwọ ijọba orilẹede Naijiria fun ifọwọsowọpọ wọn to jẹ ki idoola ẹmi naa ṣeeṣe.
Alaafin of Oyo: Olori Anu dúpẹ́ lọ́wọ́ kábíyèsí Ọba Adeyemi fún ipa ribiribi to kó láyé òun
Minisita to n ri si ere-idaraya ati idagbasoke awon odo ni Naijiria, ogbeni Solomon Dalung, ti ro iko Naijiria ti yoo lo soju ninu oniruuru idije ere-idaraya Commonwealth Games ti yoo waye lorile-ede Australia lati kopa daradara.
maa n sokunfa lojuna ati dena irowo-rose eto idibo, a ri wi pe ise takun-takun
Mo fojú sọ́nà títí, agara dá mi,níbi tí mo tí ń retí ìgbàlà rẹ,ati ìmúṣẹ ìlérí òdodo rẹ.
Bí ó ti gbé e mì tán Èṣù dáhùn ó ní, ‘o fi èrú gba ìbùkún, kò dúró gbádùn ìbùkún’.
Nítorí pé, Solomoni ti kọ òun sílẹ̀, ó sì ń bọ Aṣitoreti, oriṣa àwọn ará Sidoni; ati Kemoṣi, oriṣa àwọn ará Moabu; ati Milikomu oriṣa àwọn ará Amoni.
Fruits and Vegetables: Ǹ jẹ́ o mọ̀ pé ó yẹ ko se Carrot rẹ, ko tó jẹ ẹ́
Ilu ile ifẹ ati ileewe giga fasiti OAU ti n gbe pọ fun ọjọ pipẹ to le ni aadọta ọdun paapaa, nitori naa ko si si igba kan ti iru nnkan bayii waye.
Kódà ó mú ìrìnàjò inú igbó náà dùn dáadáa ni.
 wọ ́ n dá mamser kalẹ ̀ ní ọjọ ́ kejìdínlọ ́ gbọ ̀ n oṣù kẹ ́ fà , ọdún 1987 .
Nollywood: Funmilayo Ogunsola mí kanlẹ̀ lásìkò àìsàn ráńpẹ́
Nígbà tí wọ́n gbọ́ ọ̀rọ̀ yìí, wọn kò tún ní ìkọminú mọ́ nípa ohun tí ó ṣẹlẹ̀.
Ẹni ìyìn ni OLUWA títí lae!
O so di mimo pe, ile-ise oun yoo se agbekale iko ise-akanse awon akose-mose, pelu awon ti o muse naa lokunkun-dun lati se amulo awon ohun elo mimo awon onibara won.
O ma ni o se oun laanu fun ọmọbibi ilẹ Yoruba ti ko ba lee sọ ede rẹ doju ami nitori eyi ko bojumu to.
’ Chichi Igbo: Ọ̀pọ̀ máa ń rò pé mo ní nǹkan ọkùnrin lábẹ́ torí ìrísí mi jọ ti ọkùnrin Ààrùn Coronavirus tún ti ran ènìyàn 575 l'órílẹ̀-èdè Nàìjíríà FBI jí Hushpuppi gbé ní Dubai ni- Agbẹ́jọ́rọ̀ Ramọni Igbalode Ó di gbéré!
" Nigba taa beere pe se o tun seese ki wọn pada maa se papọ lẹyin ti wọn ba tileẹjọ de, Agbowu ni laelae awọn ko lee se ọrẹ mọ.
Wọn kò bẹ̀rù OLUWA, bẹ́ẹ̀ ni wọn kò tẹ̀lé ìlànà rẹ̀, tabi àṣẹ tí ó pa, tabi òfin tí ó ṣe fún àwọn ọmọ Jakọbu, tí ó sọ ní Israẹli.
Ṣugbọn nígbà tí ẹ bá gbọ́ nípa oríṣìíríṣìí ogun nítòsí ati ní ọ̀nà jíjìn, ẹ má ṣe dààmú, bẹ́ẹ̀ ni ó níláti rí, ṣugbọn òpin ayé kò tíì dé.
Gege bi ajo to n mojuto boolu afesegba lorile-ede Brazil, CBF “Iroyin ayo lo je fun wa lana nigbati a gbo pe, Douglas Costa yoo lanfaani lati gbaradi pelu awon akegbe re ti o ku,”Ewe, eekan soso ni Costa ti lanfaani lati kopa ninu ifesewonse iko naa pelu orile-ede Costa Rica lati igbati idije ohun ti bere.
Aṣoju ajọ ọhun to ba BBC sọrọ ṣugbọn ti ko fẹ fi orukọ rẹ lede ni, ko si otitọ ninu iroyin kan to sọ pe ẹnikẹni ti ko ba forukọ silẹ fun numba idanimọ ọhun yoo ṣewọn oṣu mẹta.
Bi esi ayẹwo naa ṣe lọ niyii: Lagos - 62 FCT - 52 Kaduna 31 Sokoto 13 Kebbi - 10 Yobe - 9 Borno - 6 Edo - 5 Bauchi - 5 Gombe - 4 Enugu - 4 Oyo - 4 Zamfara - 3 Nasarawa - 2 Osun - 2 Ebonyi - 2- Kwara - 2 Kano -2 Plateau - 2 Lọwọlọwọ, o ti pe ẹgbẹrun meji ati irnwo din mejila (2388) eniyan to ti ni aarun naa ni Naijiria.
Lẹ́yìn ìgbà tí wọ́n tí wọ́n ti ṣè àlàyé pé ọ̀rọ́ Ọ̀sanyìnnínbí tí wọ́n mú ni ó gbé àwọn wa ni wọ́n ṣe àlàye pé tí ó bá jẹ́ pé òun ni ó jí owó Orímóògùnjẹ́, yóò ti ná tó ẹgbẹ̀jọ náírà (N1,600.
Seyi: Ọmọ ọgbọn ọdun ni Seyi.
Aarẹ Ali Bongo naa wa lara awọn to da owo fun wọn.
Ìyíde náà tún tẹnu mọ́ ìlọsíwájú àti ìbáṣepọ̀ rere láàárín ẹgbẹ́ abódiakọ-akọ́diabo; bákan náà ni ó tẹnu mọ́ ìyàsọ́tọ̀ àti rògbòdìyàn.
Ọlọrun yóo gbọn olúwarẹ̀ dànù lọ́wọ́ òfo.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Tani Ibrahim Oloriegbe tó gbà ipò aṣòfin lọwọ Saraki?
Nǹkan ayọ̀ ni ọ̀rọ̀ rẹ jẹ́ fún mi, ó sì jẹ́ ìdùnnú ọkàn mi.
Kò sí ibi ti jìgá ko lè wọ lara àwọn Èdìdàrẹ́, jìgá kọ́ pẹ̀tẹ́ è si sí wọn ni àtẹ́lẹsẹ̀, o kọ ilé ilẹ̀ sí wọn ni ìbàdi, ṣùgbọ́n ori ni aafin àwọn ina wa.
Oríṣun àwòrán, Others Awọn mejeeje to fo bọ silẹ naa lo ku, ti ooru ina si tun pa eniyan meji nigba ti eefin ina rubo ile itura ọhun.
Wo àwọn oúnjẹ tí àṣẹ Buhari leè mú kó gbówó lórí Àjẹ́ àti Aṣẹ́wó ní ìyá Rainbow - Òjòpagogo Ẹ̀yin obìnrin, ẹ lọ kọ́ iṣẹ́ káfíńtà torí ó lówó lórí ju iṣẹ́ aránṣọ lọ"" Àwọn ọmọbíbí ìpínlẹ̀ Ọyọ nìkan ni yóò rí iṣẹ́ àgbàṣe gbà lábẹ́ ìjọba mi - Seyi Makinde Bí Khafi ṣe ní ìbálòpọ̀ ojútáyé tako àṣà Yorùbá - Ìjọba Ekiti Akọroyin BBC to wa nibi iwọde naa salaye pe, o to ọkọ nla mẹwaa to ko awọn agbofinro naa wa si ibi ti iwọde ọhun ti waye, ko to di pe awọn oluwọde de sibẹ, lati ri daju pe alaafia jọba ni agbegbe naa."
"- Amẹ́ríkà fọnmú Èmi àti Kolington kò fẹ́ra padà o, ọba Wákà kò fẹ́ ọba Fuji mọ́ - Salawa Abeni Èmi sì ní Oluwo tilẹ̀ Iwo, kò sí ìgbìmọ̀ ọba kankan tó lè ní kí ń rọ́ọ́kún nílé - Oluwo Toyin Abraham ọkọ rẹ̀ àti Ire ní London, Odunlade 'kòlábò' pẹ̀lú Mercy Aigbe Èlé owó iná ọba kọ́ ló kàn, ẹ kọ́ ṣàtúnṣe sí ìlànà àdánú tẹ́ ń ṣe fún wa - Iléeṣẹ́ apínná sọ fún ìjọba ""A ni ki Oluwo naa ba wa sọrọ amọ ohun ta ri dimu ninu ọrọ rẹ ni pe, oun ko na Agbowu, oun kan kilọ fun pe ko ma na ọpa ọwọ rẹ si oun mọ ni."
" Olori Anu wa kere pe ẹnu ya oun lati sawari rẹ pe wọn n yaju sawọn mọlẹbi oun nitori pe alaafin ko mọ ibi ti oun wa.
Angẹli tí ó ń bá mi sọ̀rọ̀ tún pada wá, ó jí mi bí ẹni pé mo sùn.
Koda o fẹran ko maa da nikan fi ọkọ sare ije.
N óo máa sọ wọ́n lu ara wọn.
Nígbà tí ó bá dé, yóo fi ohun gbogbo hàn wá.
Ọkọ yìí sọkún gbígbóná, ó mí ìmí ẹ̀dùn, ó bẹ̀bẹ̀ títí, síbẹ̀ obìnrin náà kò dá ọwọ́ nínà dúró, ó gbnàgbé Ọlọ́run Ọba.
A ti ń sin òkú méjì sínú ibójì kan náà nítorí ọ̀wọ́ngógó ibojì ìsìnkú"" Wo díẹ̀ nípa ohun tí Walter Carrington gbé ṣe nígbà ayé rẹ̀ Ẹgbẹgbẹ̀rún ọmọ Nàìjíríà ní yóò má a kú lójoojúmọ́ tí wọn bá gbà wọ́n láàyè láti gbébọn dání- Amofin Ilé ẹjọ́ ju ọmọ ìjọ tó fi ìpá bá ọmọ pásítọ̀ rẹ̀ sùn ní ìpínlẹ̀ Ondo sí ẹ̀wọ̀n gbére Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Olusegun Obasanjo sọ̀rọ̀ síta pé ọpẹ́lọpẹ́ Walter Carrington láyé òun nígbà tí Sani Abacha ń lé òun kíri18 Ògún 2020 Kano lack of burial ground: Àìtó ibójì ti ń fa awuyewuye ní ìpínlẹ̀ Kano- Àwọn òṣìṣẹ́ ibojí13 Ògún 2020 Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí kan sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn."
Àwọn mọ̀lẹ́bí ajínigbé tó pàdánù ẹ̀mí l'Ondo kò tí ì yọjú Ẹ̀sun olè ní a fi kan Akoroyin Samuel Ulrich ba BBC Yoruba sọrọ lori ìrírí rẹ̀ láti igba to ti de paapaa lori odo naa, ojubọ Obatala to ti de ati alaafia ati idunnu ti oun woye rẹ lara gbogbo awọn to ti de fun ọdun.
Wọn óo tú aṣọ rẹ, wọn óo gba àwọn ohun ọ̀ṣọ́ rẹ, wọn yóo sì fi ọ́ sílẹ̀ ní ìhòòhò.
" Lizzy Anjorin wa gboriyin fun Aláàfin pe abiyamo rere ní, to si tun ṣe apejuwe rẹ bii apọnmọ mawẹyin.
yóo nu gbogbo omijé nù ní ojú wọn.
Ṣugbọn lójú kan náà ó fọhùn sí wọn, ó ní, “Ẹ fi ọkàn balẹ̀.
Ǹjẹ́ jìbìtì ti lù ọ́ lórí àṣùwọ̀n báǹkì rẹ rí?
Lẹyin ti aṣiri rẹ tu tan lo fẹsẹ lọ si afin ọba ilu Akure ki wọn to faa le ajọ NSCDC lọwọ.
Àlábàápàdé àwọn ẹ̀mí àti òjìjíi wọn 
Lálẹ́ ọjọ́ náà ni wọ́n mú ìyàwó mi wá bá mi.
Real Madrid j'áwé olúborí nínú ìpele àkọ́kọ́ ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ náà pẹ̀lú àmìn ayò méjì ṣ'ẹ́yọọ̀kan lọ́sẹ̀ tó kọjá.
Bawo wa a ni awọn eniyan ṣe wa n di odi igbagbọ mú?
Oluja omo bibi ile biritiko, eni ti ami-eye beliti igbadi WBA ati IBF wa lowo re bayii, Anthony Joshua so pe ifigagbaga oun pelu Joseph Parker  ti yoo waye ni gbagede Principality Stadium  ni Cardiff lojo abameta(Saturday) yoo lagbara gan.
Ṣugbọn ó sọ fún mi pé, ‘OLUWA náà tí òun ń fi gbogbo ayé òun sìn yóo rán angẹli rẹ̀ sí mi, yóo sì ṣe ọ̀nà mi ní rere.
Alukoro ileeṣẹ EKDC, ṣalaye pe ayipada ẹrọ igbalode wọn lati ba odiwọn owo tuntun ti wọn ṣẹṣẹ kede naa mu lo fa eyi.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Shiite: Kò ní sí ìwọ́de mọ́ yíká Nàíjíríà láti bu ọ̀wọ̀ fáwọ̀n èèyàn tó dá sí wa 31 Agẹmo 2019 Oríṣun àwòrán, Empics Ẹgbẹ Shiite ti kede pe oun ti wọgile awọn iwọde gbogbo loju popo ilu Abuja, eyi to ni se pẹlu itusilẹ olori wọn, Ibrahim El-ZakZaky.
Àwọn amòfin kan ń rò ninu ara wọn pé, “Ọkunrin yìí ń sọ̀rọ̀ àfojúdi sí Ọlọrun.
Bẹnaya ará Piratoni ati Hidai ará ẹ̀bá àwọn odò Gaaṣi; 
ti o sun mo wa gbogbo, ti o si tun fi da won loju pe aabo to peye wa fun won
Ẹni tó jí ọ̀pá aṣẹ ń bọ̀ wá túbá fúnrarẹ̀, mo fi dáa yín lójú gẹ́gẹ́ bí ìyá - Erelu Kuti Ojú àwọn tọ́wọ́ ti tẹ̀ lára àwọn tó jí 'tíá rọ̀bà ọ̀kadà', fíriìjì, ẹ̀rọ ata kó nílée Sẹ́nétọ̀ Teslim Folarin rèé Àwọn ìbéèrè tí Tinubu bi gómìnà Sanwo-Olu àtàwọn olùwọ́de tó faragbọta ní Lekki Tollgate rèé Bakan naa ni Ọjọgbọn Wole Soyinka ti bu ẹnu atẹ lu fidio tuntun ti Grandson fi sita, to si rọ awọn eeyan ẹya Igbo to n gbe nilẹ Yoruba, lati ma fi eti si nkan to sọ.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ẹ pèsè ẹlẹ́rìí púpọ̀ bí bẹ́ẹ̀ kọ́, Sotitobire yóò jẹ́rìí fúnrarẹ̀ o!
Irú ẹ̀mí wo sì ní ń gba ẹnu yín sọ̀rọ̀?
Ninu ifọrọwerọ pẹlu ileeṣẹ BBC, Alaga ẹgbẹ oṣelu PDP,Ọgbẹni Kola Shittu ṣalaye pe wiwo ti ijọba wo Ile Arugbo ko le mu ifẹ awọn arugbo kuro lọkan Saraki.
Wọn si ni ki ẹ dibo yin fun itẹsiwaju.
Ajọ Caf ṣalaye pe ayipada naa waye nitori pe Cameroon beere fun un.
Ó sọ wípé, eléyìí ló fàá tí wọ́n fi pinnu pé kìí ṣe nítorí Ọlọ́run ni wọ́n ń fi ń ṣe nǹkan yìí, tí wọ́n sì pinnu láti jáde kúrò nínú ẹgbẹ́ náà.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, International Day Against Drug Abuse and Trafficking: ìdí ti mo fi ń mu oògùn olóró Bakan naa ni iroyin to n tẹ wa lọwọ nsiyi sọ pe awọn oṣiṣẹ ni ijọ COZA ni Abuja ti duro lati ma fi aaye gba awọn oluwọde lati wọle rara.
Jíjáde tí a jáde, ojú ọ̀nà òkè Ìrònú ni a jáde sí, ní ibi tí a ti kọ ri i .
Odò kan báyìí ni ó pín ibẹ̀ níyà pẹ̀lú ọ̀run, gbangba sì nì àwọn ti ń gbé ibẹ̀ máa ń wo ohun tí àwọn ará ọ̀run bá ń ṣe.
Ibadan, sugbon ti Olubadan gbawon sẹgbẹẹ ti o si n seto ilu Ibadan pelu ero a-da-ni-kanpa.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Champions League: Ṣé Liverpool ò wọ gàu lọ́wọ́ Messi báyìí?
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi Oludari kan ninu ajọ naa, Funmi Opesanwo sọ pe oriṣiriṣi eto ayipada tabi atunse ni ajọ naa ma n ṣe, sugbọn kii ṣe ọ̀fẹ́.
Bákan náà ni gbogbo wọn ṣe sùn ninu erùpẹ̀,tí ìdin sì bò wọ́n.
 Ó wà ní ẹ ̀ gbẹ ́ king ' s college , lagos , st.
Nitori òṣiṣẹ́ Ìjọba ti gba àbẹ̀tẹ́lẹ̀, àwọn ti ó gba iṣẹ́ lè ma ṣe iṣẹ́ tàbi ki wọn ṣe iṣẹ́ ti kò dára.
ri si bi awon ile igbimo asoju ati ile eto idajo ni ipinle  yoo se da duro lori eto inawo, Ita Enang,fi
Ìdí rèé ti Nàìjíríà fí ń gbé inú òkùnkùn South Africa gbọ́dọ̀ dá owó ìtanràn padà kí wọ́n si fìyà jẹ àwọn ti ọ̀rọ̀ kàn -Sen Basiru Omíyalé àgbàrà ti ya ṣọ́ọ̀bù ní Niger Bianca júwe ilé fún Serena Williams nínú ìdíje l'America Igbimọ ajọ awọn gomina ti Fayemi soju wa rọ awọn Musulumi lati kọ eti ikun si ọrọ naa pe Wike wo Mọṣalaṣi ni ilu Port Harcourt.
Kayode Fayemi: Kìí ṣe torí àti di ààrẹ ni mo ṣe sapá mi fún Àmọ̀tẹ́kùn ṣùgbọ́n tó bá yá, máa sọ̀rọ̀ lórí bóyá a ó jẹ ààrẹ tàbí rárá
Ní ọdún yìí, owó ìfèróngbà hàn nínú ẹgbẹ́ òṣèlú APC kò dín ní mílíọ̀nù márùndínláàdọ́ta nígbà ti ẹgbẹ́ òṣèlú PDP tún rọjú díẹ̀ pẹ̀lú mílíọ̀nù méjìlá náìrà.
Ó mú tóbẹ́ẹ̀ tí ó fi lè gé ẹ̀mí kúrò lára ọkàn, ó sì lè rẹ́ mùdùnmúdùn kúrò lára àwọn oríkèé ara.
Ó ṣẹgun Hadadeseri, ọba Siria ní Soba, ní agbègbè ilẹ̀ Hamati, bí Hadadeseri tí ń lọ fìdí ìjọba rẹ̀ múlẹ̀ létí odò Yufurate.
“O fún mi ní àpáta ìgbàlà rẹ,ìrànlọ́wọ́ rẹ ni ó sọ mí di ẹni ńlá.
 Bee si ni, O ti korin ni opolopo awon orile ede lagbaaye, lara won ni ile aare orile –ede Amerika(white house).
Sugbọn iwadi BBC Yoruba fihan pe, ni aafin Ọyọ, awọn ayaba orekelẹwa yii le ni mẹjọ to jẹ afẹfẹ ti alaafin fi n mi, ta a si tun le pe wọn ni Ẹlẹ Daddy, gẹgẹ bi wọn se n pe ara wọn.
Iru eniyan wo ni Ogun Majek to jade laye?
Fídíò rèé nípa bí Aláké tuntun ṣe ń gba ìwúre lábẹ́ Olúmọ kó tó gba adé Sanusi Adebisi Idikan rèé, olówó tó ń san owó orí fún gbogbo ọkunrin ilẹ̀ Ibadan Alabi ni ipinnu oun lati fopin si eyi lo mu ki oun se agbejade ere alaworan Orompoto ninu eyi ti awọn alawọ dudu ti kopa, ti wọn si sọ ede wa.
Ninu ile ijọsin St Paul's Anglican Church, Ayegbaju, Ile-Ife ni Ọọni ti lọ fi ẹmi imore rẹ han si Oluwa.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Oyenusi ló mú mi wọ ẹgbẹ́ adigunjalè kó tó di pé mo b'Ólúwa pàdé' Awọn oṣere igbalode ko pe wa si iṣẹ mọ , wọn ti gbagbe wa Agbaọjẹ oṣere lorilẹede Naijiria, Olusẹgun Akinrẹmi ti ni awọn oṣere ode oni ti gbagbe awọn agbaojẹ oloṣere, ti wọn ko si naani wọn mọ.
Ọlọ́pàá ní àwọn ṣì ń ṣèwádìí ẹni tó bẹ́rí ní Alasiya l'Eko Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, JAMB 2019: A ó fagi lé ìdànwò ẹni tó bá ṣe aṣemáṣe Fun akoko melo kan, dipo lilo ibọn, awọn ohun elo imọ ẹrọ bii ẹda ibọn mii ti oloyinbo n pe ni electro-muscular disruption technology, Taser tabi Stun gun""."
Oríṣun àwòrán, AFP Àkọlé àwòrán, Orilẹede Libiya ti jẹ ọnọ pataki awọn aṣikiri ti n gbiyanju lati de okun gusu ilẹ Yuroopu lati ori okun.
sipo nigba akọkọ to wa lori aleefa  lodun
Nígbà tí wọn óo gbé e, ó ti kú.
Bọ̀dá Màjídì tún gbé tuntun dé óò.
Akowe agba eka ifọrọtoni-leti  fun ajọ Niger Delta, Ogbeni Marshall Gundu lo soro yii niluu Abuja pe, lara ohun ti igbimo naa yoo maa jiroro le lori ni idagbasoke ohun amayedẹrùn, ayika to dara, ipese isẹ, eto aabo ati isẹ agbẹ.
Ibẹ̀ ni ìdíje Olympics ti ṣẹlẹ̀ ní ìdun-ùnta, ìyẹn l’ọ́dún mẹ́ta sẹ́yìn.
Ayédèrú ‘Sim Card’ ló jẹ́ kí ìjínigbé pọ̀si ní Naijiria - NCC Ọmọ ọdún márùn-ún wọ gàú ajínigbé ní Warri, ọlọ́pàá ri he ní Lafia Buhari fi ọ̀kadà, ọkọ̀ àti $500,000 ta orílẹ̀èdè Guinea Bissau l'ọ́rẹ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Unko Museum yìí n ran àwọn ènìyàn lọ́wọ́ láti rí ìgbọ̀nsẹ̀ bí nkan tó rẹwà Igba akọkọ kọ niyi ti awọn ajinigbe yoo ji awọn ọmọ ilẹ okeere ni Naijiria.
Isẹ lilu bẹmbẹ fi ji wéré loru ni wọn yan laayo lati ọjọ pipẹ nilu Ibadan.
Mo sọkún, inú mi sì bàjẹ́ lọ́pọ̀lọpọ̀.
Ẹ ye ri mi tabi fi mi we Oluwa rara nitori eniyan ẹlẹran ara ni mi, ẹ ye fi aworan mi ati ti aya mi sara awọn eroja kankan.
Ọlọrun fúnra rẹ̀ ni ó fi ìka ara rẹ̀ kọ ohun tí ó wà lára àwọn wàláà náà.
Ikọ̀ agbábọ́ọ́lù wo ni yóò la ìsọ̀rí àkọ́kọ́ kọjá?
Ìjọba ìpínlẹ̀ Eko tí kéde ìlànà ìséde tuntun fún ará ìlú Ojú àwọn tọ́wọ́ ti tẹ̀ lára àwọn tó jí 'tíá rọ̀bà ọ̀kadà', fíriìjì, ẹ̀rọ ata kó nílée Sẹ́nétọ̀ Teslim Folarin rèé Òkú ọ̀dọ́ 15 ni mo kà ní Lekki amọ́ mo kábàámọ̀ pé a gbà kí ológun gbé okù wọn lọ - DJ Switch A o ranti pe ọpọ awọn gbajumọ osere tiata atawọn ilumọọka ọmọ Naijiria miran, ni wọn ṣe ìpolongo ibo fawọn oloselu lọdun 2015 pẹlu orin ati ijo lati ipinlẹ kan si omiran ati nijọba apapọ pẹlu.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Fatma ti Senegal gboye tuntun ni FIFA Fatma to jẹ ọmọ ilẹ Senegal ni wọn ni ko maa ṣakoso CAF foṣu mẹfa lati ọjọ kinni, oṣu kẹjọ ọdun yii lọ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Bola Tinubu: Àwọn màlúù dà níbí tí wọ́n ti pa ọmọ Fasoranti?
Seun kuti ni lootọ loun n gbe ni agbegbe kan ti wọn pe ni Akin Oshiyẹmi lagbegbe Ikẹja ti oun si ti wa nibẹ fun bi ọdun mọkanla bayii.
Egbọn iya Baraka ti o ba wa sọrọ, Arakunrin Ọlalẹyẹ Daud ni, sababi ire ni iku Baraka pada jasi.
Ní àkókó náà, ẹlẹ́wọ̀n olókìkí kan wà tí ó ń jẹ́ Jesu Baraba.
"O ni ""mo lo akoko yii lati fi fi oju itan ibi mi dan faraye nitori mo fi oye ile iwe giga ti mo gba yii ji iya mi"" Aláàfin Ọyọ: Pọ́ńbélé Yorùbá ni mí Ṣé ó ṣeéṣe kò jẹ́ àṣírí ìbejì Aláàfin nìyíì?"
Eewọ, mo kọ lati jawọ ninu idije yii - Dino Bi awọn eniyan ṣe n foju sọna fun eto idibo lati mọ ẹni ti yoo jade dupo gomina ipinlẹ Kogi labẹ asia PDP ṣe n sunmọ ni iroyin kan jade pe Dino ti kuro ninu awọn oludije.
Nigba ti wọn n ka ni agọ ọlọpaa, awọn ole naa ni ara ọmọ ẹgbẹ ikọ adigunjale kan ti wọn n da agbegbe Lekki laamu ni awọn.
Aare Muhammadu Buhari to n tuko Naijiria ti kedun iku alaga banki ariwa nigbakanri, iyen, Alhaji Muhammad Lugga to ku leyin aisan ranpe.
" Ọjọgbọn Maurice Iwu Ọjọgbọn kan nilẹ Nàìjíríà, Maurice Iwu tí kéde ni osu kejì ọdún pé òun ti ṣe àwárí òògùn tó lè wo àrùn Coronavirus.
Ìyá Ìṣẹ̀dá ń kérora fún ìwàláàyè
Oríṣun àwòrán, Babajide sanwo-olu Gomina Sanwo-Olu ṣalaye loju opo Twitter rẹ pe mẹta ninu awọn eeyan wọnyii lo jẹ obinrin ti meje yooku si jẹ Ọkunrin.
Oríṣun àwòrán, The Nigeria Lawyers Ó rẹ ẹni ọdún 49 tó ri ẹ̀wọ̀n ọgọ́ta ọdún he lẹ̀yìn tó bá ọmọ ọdún méjì lòpọ̀ Mo pàṣẹ pé kí ọ̀gá owó ìfẹ̀yìntì tẹ́lẹ̀, Maina sì wà látìmọ́lé- Adájọ́ Oríṣìíríṣìí ẹ̀bùn tí àwọn olọṣèlú ń pín #BBCNigeria2019 Ṣé irúfẹ́ oúnjẹ tí ò ń jẹ́ lè jẹ́ kí o gbádùn ìbálòpọ̀ rẹ síi?
À ń retí àkókò ìwòsàn, ṣugbọn ìpayà ni a rí.
Awọn ọmọbinrin Dapchi de s'Abuja, funpade pẹlu Aarẹ Buhari
Àwọn ọ̀pọ̀lọ́ àti akèrè ti wọn jẹ ọ̀kan nínú àwọn ti ń jà fún ẹja pàápàá tún ddà wa láàmú, níto’ri pé igbe wọn lásán họ ọ, họ ọ, họ ọ, tí gba gbogbo àgbègbè tó bẹ́ẹ̀ tí a ko lè sọ̀rọ̀ sí ara wa, nígbà tí mo ba sì pàṣẹ fún àwọn ọdẹ igbe àwọn wọ̀nyí kò jẹ́ kí ẹnikẹ́ni gbọ́ ohun tí mo ṣo.
Alábàárù ni mò ń ṣe lọ́jà Ketu àti Mile 12, kí ń tó bẹ̀rẹ̀ Fuji - Atawẹ́wẹ́ Àìle è ka kéú ló sọ mí di Krìstíẹ̀nì - Adewale Ayuba Barrister ló sọ mí di èèyàn ńlá - Ayinla Kollington Ọ̀pọ̀ ló ṣì n ṣelédè lẹ́yìn Barrywonder!
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Offa Bank Robbery: Àwọn afunrasi ní àwọn kò fí t'inu fẹdo jẹwo fún ọlọ́pàá 16 Ẹrẹ̀nà 2019 Ọwọ ti tẹ Oríṣun àwòrán, NIGERIA POLICE Àkọlé àwòrán, Ọjo Kerin Oṣun Kẹrin ọdun 2018 lawọn afunrasi naa yabo ile ifowopamọ nilu Offa ti wọn si pa eeyan mẹtalelọgbọn Mẹta ninu awọn afunrasi to n jẹjọ lori ẹsun ipaniyan ati idigunjale to waye nilu Offa lọdun to kọja ti sọ fun ile ẹjọ pe iya lawọn ọlọpaa fi gba ọrọ ijẹwọ lẹnu awọn.
pọ̀lọpọ̀ nǹkan ni a fi ojú rí nígbà tí a kúrò ní ìlú yìí tán ṣùgbọ́n kò sí ààyè nísisí yìí láti sọ gbogbo wọn.
Lẹyin ti awọn dokita bẹrẹ iyanṣẹlodi wọn lọjọ Aje, ti ọpọ ọmọ orilẹede Naijiria si ti n pariwo, awọn oṣiṣẹ eto ilera yoku naa ti gbe ikilọ sita pe awọn pẹlu yoo gunle iyanselodi bẹrẹ bi ijọba apapọ ba kuna lati sise lori ẹdun wọn.
Awọn ti ọrọ na ṣoju wọn ni ọkọ meji kan ja si odo lẹyin igba ti ọkọ oju omi naa kọlu opo to di afara naa mu.
Wọ́n bá bẹ̀ ẹ́ pé, “Jọ̀wọ́, bá wa wádìí lọ́dọ̀ Ọlọrun, kí á lè mọ̀ bóyá ìrìn àjò tí à ń lọ yìí yóo yọrí sí rere.
Ìdajì àwọn ará ìlú náà yóo lọ sóko ẹrú, ṣugbọn ìdajì yòókù ninu wọn yóo wà láàrin ìlú.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Temitope Akinnusi: Ọ̀pọ̀ iléeṣẹ́ ló takú láti gbà mí síṣẹ́ torí mo ní ojú kan Magun Mafogọta: Gọta ni yoo ma wu ọkunrin to ba lu Magun yii lati fo, ni kete ti o ba si ti fo o bayii, yoo jade laye ni.
Liverpool fí ogun ẹ̀yìn ja Barcelona Kcee fí ọwọ́ Jóná lóri Liverpool Vs Barcelona Arsenal tun fidirẹmi Ọlọ́pàá fi páńpẹ́ ọba mú ọmọ ogun ilẹ̀ Naijiria Pierre Emerick Aubameyang ti saaju gba bọọlu sawọn fun Arsenal ni abala ikini ṣugbọn eleyi ko ja mọ nkankan nigba ti ifẹsẹwọnsẹ naa yoo fi wa si opin.
Eto ipolongo eto idibo ohun ni ajo eleto idibo orile-ede Sierra Leone kede re ni ojo karun osu kejiodun ti a wa yii.
Ọ̀kan ninu àwọn Farisi ọ̀hún ni Nikodemu, ẹni tí ó lọ sọ́dọ̀ Jesu nígbà kan.
OLUWA àwọn ọmọ ogun wà pẹlu wa,Ọlọrun Jakọbu ni ààbò wa.
Ojú ń pọ́n mi lọpọlọpọ,sọ mí di alààyè, OLUWA, gẹ́gẹ́ bí ìlérí rẹ.
‘Ọ̀rọ ẹnu lásán ni wàhálà tí Nnamdi Kanu ní òun lè dásílẹ̀ ní Nàíjíríà’ Ààrẹ Algeria kò ní pẹ́ kọ̀wẹ́ fipò sílẹ̀ Àwọn olùgbé Fiditi pé fún ìrànlọ́wọ́ lórí àwọn òrùlé tí atẹ́gùn ojó ṣí lọ Ẹ̀ wo bí àwọn ẹ̀ṣọ́ ojú etí òkun ṣe ń ṣiṣẹ́ l'Eko Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí kan sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
Inú ibojì kan náà pẹ̀lú aya rẹ̀ ní wọ́n a sin Bàbá Fasanmi sí lọ́jọ́ kẹrin, osù kẹjọ!
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Cech Nitori naa, oun ti yiyan sipo eniyan kan bii Cech yoo ṣe ni lati mu aawọ to le wa laarin awọn to ni ẹgbẹ agbabọọlu ati akọnimọọgba kuro.
Oríṣun àwòrán, Alhaji Kareem Adepoju/Facebook Àkọlé àwòrán, Agba oṣere ni Alhaji Kareem Adepoju ti ọpọ mọ si Baba Wande.
Olori Badirat Adeyẹmi kii ṣe ajeji si ori itakun ayelujara nitori naa nṣe ni iroyin ọhun lalẹ gaaraga.
ṣugbọn nígbà tí ó rí i pé mo pariwo, ó ju ẹ̀wù rẹ̀ sílẹ̀ sí mi lọ́wọ́, ó sá jáde.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Musa: Igi owo Onwoye Jacob Davidson kọ nipa Musa lọdun 2015 pe, Musa lọrọ ju ohun tẹni kankan le ṣalaye lọ.
₦80m la fi rán ogún ìyàwó asòfin lọ Dubai - Obasa Olori ile asofin nipinlẹ Eko, Mudasiru Obasa, ti salaye niwaju igbimọ oluwadii lori bi ile asofin naa ṣe na awọn owo kan.
O ni danwo lo bi iya ọkẹrẹ, ti Olubadan ba sọ pe oun fẹ le awọn Ọba mọkalelogun, a jẹ wi pe o fẹ pin Ibadan si meji niyẹn, oun si lo maa jọba lori eyi to kere ju, ti ilẹ Ibadan ba fi pe meji."
Arauna dá a lóhùn pé, “Máa mú un, kí o sì mú ohunkohun tí o bá fẹ́ fi rúbọ sí OLUWA.
Aare Muhammadu Buhari ti gbosuba kare-lai fun iko agbaboolu Chan Super Eagles fun pipegede sinu asekagba idije Championship of African Nations (CHAN) to n lo lowo lorile-ede Morocco.
Okoowo Bitcoin ni Naijiria Lati bi ọdun diẹ sẹyin ni Bitcoin ti di gbajúmọ laarin awọn ọmọ Naijiria kan.
O kawe lawọn ile iwe miran ni Naijiria ati loke okun.
Osinbajo: Nasir El-Rufai ní igbákejì ààrẹ, Yemi Osinbajo ni alága àwọn 'kògajùgò' lórílẹ̀èdè Nàìjíríà
"Oríṣun àwòrán, TWITTER/BUKKY SHONIBARE Àkọlé àwòrán, Shonibarẹ ni nigba ti wọn gbe Darlington de agọ ọlọpaa, wọn bọ aṣọ rẹ, wọn ko ri àpá eyin kankan O ni, ""Lẹyin ti wọn fi awakọ mi silẹ ni ọga ọlọpaa kan ni agọ naa sọ pe oun ti ri arakunrin kan ti o ni irùgbọ̀n bii ti awakọ mi."
Akowe ẹgbẹ Yoruba Council of Elders (YCE), Kunle Olajide lo ṣe apejuwe Baba Obasanjọ bẹẹ lasiko ayẹyẹ ọjọ ibi pe wọn pe ẹni ọdun mẹtalelọgọrin.
"Ghebreyesus sọrọ yii nilu Geneva, nibi to ti ni aarin ọdun meji pere ni ajakalẹ arun ""Spanish flu"" fi ja, ko to kasẹ nilẹ lọdun 1918."
Awon arinrinajo lona aibofin mu n wo orile-ede Israel ni awon enu ibode orile-ede Egypt to pin yele-yele ni odun 2007, amo won ti gbiyanju ati mu atunse baa won enu ibode naa, sugbon awon eniyan si n gba ibe wole lona aibofin mu.
Ireti ọpọ ni pe ki wọn kede eyi lori ileeṣẹ iroyin ijọba orilẹede naa pẹlu bi iwọde ṣe n tẹsiwaju kikankikan fun ọjọ kẹfa laiduro bayii ninu eyi ti awọn eeyan ti n ke si aarẹ naa pe ko fi ipo silẹ.
Pásítọ̀ Fatoyinbo fi ipò sílẹ̀ fún ìgbà díẹ̀ nítorí ẹ̀sùn ìfipábánilòpọ̀ Ọkọ mi kò le f'ipá bá ẹnikẹ́ni lò pọ̀ láíláí - Modele Fatoyinbo A kò fipá mú ẹnikẹ́ni láti dá Ruga, aàgọ́ Fulani sílẹ̀ -Iléeṣẹ́ aàrẹ Ogedengbe Agbógun Gbórò, Akọni tó ń dẹ́rù ba ikú.
Àríyànjiyàn Osinbajo àti PDP Buhari ba osinbajo sayẹyẹ igbeyawo ọmọ rẹ Osinbajo: Ẹ dìbò fún Buhari, kí ẹ̀yà Yorùbá lé gbàjọba ní 2023 Nàìjíríà bá RCCG, ìyá Folu Adeboye yọ ayọ̀ 70 Kíni iyatọ tó wà láàrin FSARS àti SARS?
Kété ti ijọ̀ba ba ṣàtúnṣe sójú òpópónà ni ìjínigbé á dínkù -Awakọ̀ Àṣà ìbálé lálẹ́ ìgbeyàwó ń dọdẹ àwọn obìnrin òde òní Ṣé ìnàkí tún gbé owó tó lé ní mílíọ̀nu mẹ̀fà Náírà mì ni?
Donald Trump: Àwọn obìnrin ilé ìgbìmọ̀ aṣòfin Amẹrika fọnmú sí ọ̀rọ̀ Trump
Lẹ́yìn tí ó gbadura, ó gbé ọwọ́ lé e, ó sì wò ó sàn.
Ẹ̀yin ará, àwa kò fẹ́ kí ẹ má ní òye nípa àwọn tí wọ́n ti sùn, kí ẹ má baà banújẹ́ bí àwọn tí kò nírètí.
N óo sì bèèrè ọrẹ àdájọ lọ́wọ́ yín ati ọrẹ àtinúwá tí ó dára jùlọ pẹlu ẹbọ mímọ́ yín.
O ni iwa ti won hu yii, ti je ki orile ede Naijiria je ore pataki pelu orile ede Russia.
Shotunde ni oun kii se igi iwe nitori wakati kan pere ni oun fi n kawe lojumọ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù 2019 Elections: Àwọn olùdíje ipò Gómìnà ní Kwara yóò sọ ààtò wọn Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ 2019 Elections: Àwọn olùdíje ipò Gómìnà ní Kwara yóò sọ ààtò wọn 3 Sẹ́rẹ́ 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 10 Sẹ́rẹ́ 2019 Gẹgẹ bi akitiyan ile iṣẹ iroyin BBC Yoruba lati mu iroyin nipa idibo orilẹede Naijiria lọdun 2019 wa fun gbogbo eniyan nile ati lẹyin odi, ipade itagbangba yoo waye lawọn ipinlẹ kọọkan nilẹ Yoruba.
mo si n fi oju sọna fun igbesẹ gbigba alejoipade ajọ Ecowas miran ni ilu Abuja losu kejila ọdun 2018.
 Ènìyàn maa ń ṣàkóràn rẹ ̀ bí ó bá mu omi tí ó ní eṣinṣin omi àkóràn aràn sòbìà ọmọ kòkòrò .
Bàbá mi hùwwà ọlọ́gbọ́n ní àkókò yí, órọra kó àwọn ǹkan ọwọ́ rẹ̀ sílẹ̀ ó lọ sí abẹ́ ọ̀kan nínú àwọn ibi wọ̀n-ọnnìó dọ̀bálẹ̀ gbalaja níwájú Ọlọ́run ó si wí pé:
Maria ti yan ipò tí ó dára tí a kò ní gbà kúrò lọ́wọ́ rẹ̀.
Ó ní kí ẹ má ṣe jẹ́ kí ó mú ki ẹ gbẹ́kẹ̀lé OLUWA kí ó máa sọ pé OLUWA yóo gbà yín sílẹ̀, ati pé kò ní jẹ́ kí ogun Asiria kó ìlú yín.
Eyi ni esi ifesewonse idije English Premier League(EPL), ti o waye lopin ose:Leicester City 1 – 1 Stoke CityAFC Bournemouth 2 – 2 Newcastle UnitedBrighton & Hove Albion 4 – 1 Swansea CityBurnley 1 – 1 SouthamptonLiverpool 4 – 1 West Ham UnitedWest Bromwich Albion 1 – 2 Huddersfield TownWatford 1 – 0 EvertonCrystal Palace 0 – 1 Tottenham HotspurManchester United 2 – 1 ChelseaBakan naa, esi ifesewonse asekagba idije EFL Iko agbaboolu Manchester City fagbahan Arsenal FC pelu ami ayo meta sodo(3-0).
” láti fihàn pé ọmọ ni ẹ jẹ́.
Àsìkò tí wan sàbẹ̀wò ní ọ̀ga àgbà FAAN ní pápákọ̀ òfurufú náà sàlàyé pé, ọkọ̀furufú kan láti Middle Belt yoo maa bẹ̀rẹ̀ iṣẹ́ fún ìgbà àkakọ́ lónìí.
EndSars Protest slang: Kíní ìtumọ̀ Sọ̀rọ̀ Sókè tí àwọn afẹ̀họ́núhàn EndSars ń lò káàkiri
Ẹni tí ó bá ṣe nǹkan wọnyi,ẹsẹ̀ rẹ̀ kò ní yẹ̀ laelae.
Ṣebí ọ̀kan ninu yín ni ó ń gbìmọ̀ burúkú sí OLUWA, tí ó sì ń fúnni ní ìmọ̀ràn burúkú?
Sedekaya ọba bá pàṣẹ, wọ́n sì fi Jeremaya sinu gbọ̀ngàn ọgbà àwọn tí ń ṣọ́ ààfin.
Baby abandoned on dunmpsite: Mo ti bímọ mẹ́rin tẹ́lẹ̀ fún bàbá méjì nínú òṣí- Dupe Ogbomọṣọ
Iyawo meji (Olubunmi àti Motẹniọla) ati ọmọ ati ọmọ ọmọ lo gbẹyin Baba Adebayo Faleti.
 nínú káà yìí ni Ògògó tí ó jẹ ́ ọkọ ato , ti ń wo ọmọ náà nígbàkúùgbà .
BIAFRA at 50: Ìhàlẹ̀ ológun ni Gowon ni ká kọ́kọ́ fi bẹ̀rẹ̀- Aladejẹbi Wo ohun tó yẹ kó mọ̀ nípa Gomina Imo ti ilé ẹjọ́ giga ye àga mọ́ nídí Èyí ni bí ogun abẹ́lé Biafra ṣe bẹ̀rẹ̀ ní Nàìjíríà Wo ipa tí Mayegun yóò ma kó ní ilẹ̀ Yoruba!
àwọn ọkunrin ati àwọn obinrin, àwọn ọmọde, àwọn ìjòyè, ati gbogbo àwọn tí Nebusaradani, olórí àwọn ẹ̀ṣọ́ ọba Babiloni, fi sábẹ́ àkóso Gedalaya ọmọ Ahikamu, ọmọ Ṣafani, ati Jeremaya wolii ati Baruku ọmọ Neraya.
Wọn fẹnukò pé Kelly kò jẹbi ẹsùn kankan.
Igbimọ oluwadii ni yoo sọ boya wọn o gbẹsẹ le esi akẹkọọ to ṣe mago-mago, tabi wọn yoo gbe esi awọn ti ko jẹbi jade.
Ki lawọn apẹrẹ ti a fi n da mọ Eyi to jẹ ojulowo apẹrẹ arun yi ta mọ ni ara gbigbona ati ikọ Lawọn ibi kan apẹr bi ki ọna fun ma dun eeyan, ori fifọ tabi yiya igbẹ gburu naa a ma farahan ti awọn kan a si ma ni eeyan ko ni le gborun nnkan daada.
Ninu gbogbo ìgbé-ayé asán mi, mo ti rí àwọn nǹkan wọnyi: Mo ti rí olódodo tí ó ṣègbé ninu òdodo rẹ̀, mo sì ti rí eniyan burúkú tí ẹ̀mí rẹ̀ gùn, pẹlu bí ó ti ń ṣe ibi.
Ikede ẹni ti yoo gbalejo idije naa yoo waye lolu ilu Senegal ti ṣe Dakar.
Àwọn tí ó gbọ́ ní, “Ta wá ni a óo gbà là?
 Mo bẹrẹ si gbe lọdọ iya mi, to si jẹ ki n mọ nipa ise awọn obinrin pupọ.
Nítorí náà, ohun tí èmi OLUWA níí sọ nípa rẹ̀ ni pé, ẹyọ ọmọ rẹ̀ kan kò ní jọba lórí ìtẹ́ Dafidi.
”Siba dá a lóhùn pé, “Bẹ́ẹ̀ ni, oluwa mi, èmi ni.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Trump picture: ọjọ́ tí Trump kí mi kú iṣẹ́ lórí 'twitter' ní inú mi dùn jù- Oyedele Ile iṣẹ iroyin Reuters ni ina ṣi n jo ninu ọkọ ofurufu naa ṣugbọn ko tii si akọsilẹ ẹni to laa ja titi di asiko yii.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Minimum wage: NLC ló ń fa ọwọ àfikún owó òṣìṣẹ́ sẹ́yìn!
Ó kọ àgọ́ àwọn ọmọ Josẹfu sílẹ̀;kò sì yan ẹ̀yà Efuraimu;
Ajọdun ilu nilẹ Afrika to maa n waye ni ipinlẹ Ogun l'orilẹede Naijria jẹ afihan ati ṣiṣe ajọyọ ipa ti ilu n ko nilẹ Afrika.
Kini eero rẹ lori ki awọn ọdọ o ṣe ijọba?
Nípa ti ìyàwó mi, mo lè wí fún ọ pé ìyàwó mi ń bẹ; nípa ti àwọn ènìyàn mi, mo lè wí fún ọ pé alàáfíà ni àwọn ènìyàn mi wà; bí ó sì tilẹ̀ jẹ́ pé, ọjọ́ pẹ́ tí mo ti fi àwọn ènìyàn mi wọ̀nyí sílẹ̀, síbẹ̀ àdúrà tí ọmọ èn[[iyàn bá gbà fún ara rẹ̀ ni Olódùmarè ń bá a gbà, ọkàn ẹni ni àlúfáà ẹni.
Odumakin ni awọn obinrin nilo ati pe fun idasilẹ asuwọn alajọni kan ti awọn obinrin lee maa ti inu rẹ mu owo lati ja fun ipo oṣelu.
odun 2019 ti a wa yii, o je ki o di mimo pe opolopo ipenija lo n dojukọ eto  oro aje to n jo ina ajoreyin lorile-ede yii.
ó sì to àwọn burẹdi náà létòlétò sórí rẹ̀ níwájú OLUWA, gẹ́gẹ́ bí OLUWA ti pàṣẹ fún un.
NIMC registration portal: Ìjọba Nàìjíríà fọjọ́ mọ́kànlélógún gbako kun ọjọ́ láti so NIN rẹ̀ mọ́ síìmù
Ọ̀rọ̀ǹpọ̀tọ̀niyùn, Aláàfin obìnrin àkọ́kọ́ rèé, tó ní nǹkan ọkùnrin Ẹ yàgò fún ìwà adìẹ dàmí lóògùn nù, màá fọ lẹ́yin lásìkò ìjà - Buhari Dókítà yọ oyin mẹ́rin tó n gbé nínú ẹyinjú arábìnrin kán Beckham, àgbábọ́ọ́lù tẹ́lẹ̀ rèé tó ń sọ èdè Yorùbá Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Hakeem: Mo lè sọ arúgbó dí ọmọge nígbà tó bá wù mí Amofin Balogun fikun ọrọ rẹ pe kọmisọnan fun ilẹ iṣẹ ọlọpaa nipinlẹ le kọ eti ikun si aṣẹ ti gomina ba pa ayafi ti o ba gbasẹ lati ọdọ ọga ọlọpaa ni Naijiria.
ALL WOMEN MPs walk out of Budget speech sitting of Parliament to protest the assault of Wajir Woman Representative.
Fasiti Kaduna ni ki olùkọ́ lọ rọọ́kún nílé látààrí ẹ̀sùn pé ó ń dúnkookò mọ́ akẹ́kọ̀ọ́ Ìlé ẹjọ́ ti pàṣẹ pé kí ilé iṣẹ́ ọ̀lọ́pàá dá ìgbaniwolé dúró Iṣẹlẹ ki ara maa san pa maalu kò ṣẹṣẹ maa ṣẹlẹ ni ipinlẹ Ondo.
Lopo igba ni Rakhmat Akilov to je omo ogoji odun , maa n kaanu fun awon omo ogun olote(IS)  , ki o to di pe ikolu yii waye.
“Ni bayii awon ti o farapa ti n gba itoju lowo,”  Ateny Wek Ateny soro naa di mimo nile-ise aare lojoAje(Monday).
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, 'Mo Salah ni agbabọọlu to fakọyọ julọ lagbaye bayii' 'Ẹ dée ládé e ọba bọ́ọ̀lù' Bi o tilẹ jẹ wi pe, llati inu ikọ Roma ni Salah ti ko ẹru rẹ wa si Liverpool, ṣugbọn ko fi eyi ṣe, pẹlu bo ṣe tan bii irawọ ọsan, ti n ba agba lẹru ni gbogbo asiko ti ifẹsẹwọnsẹ naa fi waye.
Premier League: Ọ̀mì ayò kan ni Man U àti Liverpool gbá!
Ìgbà tí gbogbo àwa ọdẹ dọ̀bálẹ̀ tí a kí iwin pàtàkì yìí, ó dáhùn ó ni,
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Sunday Igboho: Ẹ fi Ògún búra fún wa láti jà fún ilẹ̀ Yorùbá láì gbé Amotekun sábẹ́ ìjọba Ipinlẹ Ọṣun nikan ni wọn ti n kede ọjọ isinmi lẹnu iṣẹ lati fi ṣe ajọyọ ajọdun naa.
Buhari, o kò ṣe bẹbẹ kankan láì jẹ́ pé o gba Leah Sharibu náà sílẹ̀ Oríṣun àwòrán, Getty Images Ariwo ààrẹ Buhari ṣe bẹbẹ ni ọ̀pọ̀ ọmọ Nàìjíríà ń pa láti ọjọ tí ìròyìn ti tàn pé, ìjọba ti rí àwọn ọmọ ilé ẹ̀kọ́ Kankara nípìnlẹ̀ Katsina gbà lọ́wọ́ àwọn ajínigbé.
 O gbaa ami-ayo mejo wole ninu ifesewonse marunlelogbon ti o gba fun orile-ede Spain.
Primate Ayodele: Àwọn pásítọ̀ tó ń lo bàálù pẹ̀lú èrò rẹpẹtẹ ń tan aráàlú jẹ ni
Gbogbo ìyà tí ẹ ti jẹ á wá jẹ́ lásán?
O sọ ninu atẹjade naa pe o ti gbangba pe igbimọ PFN yoo ṣegbe lẹyin ẹnikan ni ko jẹ ki oun lọ siwaju wọn.
Oríṣun àwòrán, Facebook/Nigeria Airforce Bí ẹgbẹ́ One Million Boys ṣe bẹ̀rẹ̀ rèé àti ọṣẹ́ tó ṣe n'Ibadan Sotitobire: Ẹlẹ́rìí mẹ́rìn ló tẹ̀lé Alfa Babatunde wá síwájú ilé ẹjọ́ lonìí Wọ́n ṣe iburawọle fun un gẹgẹ bi Ajagun oju ofurufu ninu oṣu kẹsan ọdun 2017 oun si lo jẹ Obìnrin àkọ́kọ́ tò wa ẹlikọpita Iléesẹ́ ọmọogun òfúrufú Naijiria.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, World Press Day: Ọ̀pọ̀ ìgbà ni àwọn jàǹdùkú ká mi mọ́lé nítórí ìròyìn tí mo kà O ni lẹyin toun ṣalaye ohun to ṣẹlẹ fun ọga oun, wọn ni ki oun ma foya ti wọn ko si kọkọ gbe iroyin iṣẹlẹ naa sita.
Eyi kọ ni igba akọkọ ti ijọba orilẹ-ede Saudi Arabia ko ni faye gba ọpọ eeyan lati wa ṣiṣẹ Hajj ni Saudi.
A kò ní dá ẹni tí ó bá gbà á gbọ́ lẹ́bi.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ofin Naijiria ko tako ibalopọ laarin ọkunrin s'ọkunrin Ibi ti oun ti n gbiyanju lati ṣalaye ara rẹ fun awọn ọlọpa ni wọn ti gbe gbogbo wọn ju sinu ọkọ ọlọpaa.
 Ofin yii yoo le jẹ ki wọn le ṣawari iru awọn oṣiṣẹ bayii to ba huwa ibajẹ”.
to jẹ mọ ilẹ okeere  naa tun sọ pe.
Eyi n tọka si iwa ika ti ọpọ awọn ọlọpaa ilẹ Amerika n hu si awọn alawọ dudu ilẹ Amerika, lara rẹ ni eyi to waye laipẹ yii ni bi ti ọlọpaa Maryland kan ti yin ọkunrin kan nibọn ninu ọkọ ọlọpaa.
A ó máa mú ẹbọ àkàrà ojoojumọ lọ sibẹ, a ó sì máa rú ẹbọ sísun níbẹ̀ láàárọ̀ ati lálẹ́; ati ní ọjọọjọ́ ìsinmi, ati ní ìbẹ̀rẹ̀ oṣooṣù, ati ní gbogbo ọjọ́ àjọ̀dún OLUWA Ọlọrun wa, gẹ́gẹ́ bí ó ti pa á láṣẹ fún Israẹli títí lae.
Ẹyìn èyí ni ikú ssì tọrọ àyè lọ́wọ́ Ọlọ́run kí ó jẹ́ kí òun fẹ́ ẹ kí obìnrin náà baà lè jẹ́ olùrànlọ́wọ́ fún òun ni ibi iṣẹ́ òun.
Oyo NURTW: Tokyo ló kọ́kọ́ bá Auxillary sọ̀rọ̀ lẹ́yìn ọdún gbọọrọ
Ifesewonse ohun waye ni papa isere Modibo Keita ni Bamako, leyin ti iko agbaboolu  Djoliba  ti fagbahan MFC tele ninu ifesewonse akoko pelu ami ayo kan sodo(1-0).
"Olorì àgbà mẹ́rin tó jẹ́ igi lẹ́yìn ọgbà fún Aláàfin Adeyemi Nigeria Police recruitment 2020: Bí ó bá fẹ́ dara pọ̀ mọ́ ìṣẹ́ ọlọ́pàá, forúkọ́ sílẹ̀ níbí Wo ilé ìwòsàn kan ti tọmọ-tìyà ti ń kú lẹ̀yìn tí Covid-19 búrẹ́kẹ ""Olúwá ó ṣeun tí ó tún fún mi lánfàni láti ṣe ohun àrà ọ̀tọ̀ lọ́dún tuntun."
6bn ohun ìní Nàìjíríà 2 Owewe 2019 Oríṣun àwòrán, Twitter/UK High Commission Naijiria ko ni owo ti orilẹ-ede kankan le gba lasiko yii - Awọn oluwọde.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ṣẹ gbọ́ nípa Alájọ Ṣómólú, tó ta mọ́tò ra kẹ̀kẹ́?
Jekolaya, ará Jerusalẹmu ni ìyá rẹ̀.
Èmi yóo ṣe ohunkohun tí ẹ bá bèèrè ní orúkọ mi, kí ògo Baba lè yọ lára Ọmọ.
Ọkùnrin kan tó yasó nínú ọkọ̀ Uber rí ẹ̀wọn he Àṣé àṣírí wà nínú Hijabu tí Aisha Yesufu ń wọ̀ lọ ìwọ́de Ninu atẹjade ti ajọ FCTA fi sita lonii Ọjọbọ, ajọ naa ṣalaye pe lootọọ ni awọn ọmọ orilẹede Naijiria lẹtọ labẹ ofin lati ṣe iwọde wọọrọwọ lori ohun ti ko ba tẹ wọn lọrun.
Bi gbogbo ọrọ naa ba se jẹ, BBC Yoruba wa ni sẹpẹ lati mu ẹkunrẹrẹ iroyin wa fun yin.
Shina Rambo ni Alhaja yii ni awakọ oun, to si le sare asapajude pẹlu mọto laisi ewu, laarin iṣẹju diẹ, yoo si wa ọkọ lati Naijiria de Cotonou.
Ti tẹlẹ Eyi to tẹlẹ Ọdún mọ́kànlélọ́gọ́rin ni Winne Mandela lò lókè èèpẹ̀, kí ọlọ́jọ́ tó dé lọ́jọ́ ajé, ọjọ́ kejì, osù kẹrin ọdún 2018 lásìkò àìsàn ọlọ́jọ́ gbọọrọ.
Owo orile ede South Afrika si duro sojukan ninu eto okoowo  agbaye yato si ti owo orile ede Amerika lojo Eti, bo tile je pe eto okoowo ma –dami-dofo si tun ti goke si i.
Mo rọ àwọn asòfin Ekiti láti súgbá Fayẹmi - Fayose Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ṣọla Allyson: Obìnrin tí kò bá rẹwà ni yóò máa ṣí ara sílẹ̀ Gẹ́gẹ́ bí ofin Sharia tí ìpínlẹ̀ náà gùnlé, wọn ní gbogbo obìnrin tí ọlọ́pàá Hisbah bá ti mú ní ojú pópó pé ó ń dá rìn ní ààgo mẹ́jọ alẹ́ kìí ṣe ọmọ, yóò sì fí ojú ba àgọ́ ọlọ́pàá.
Mo láyọ̀ ninu ọ̀rọ̀ rẹ,bí ẹni pé mo ní ọpọlọpọ ìkógun.
àwọn alufaa: Eliakimu, Maaseaya ati Miniamini Mikaya, Elioenai, Sakaraya ati Hananaya, ń fun fèrè.
0 8834 Orilẹede Cote d‘ivoire 140 0.
Ọgbẹni Adegbie sọwipe awọn ara ilu kereje yoo san ẹgbẹrun ( 1000) si ẹgbẹwa(2000) naira lọdọọdun gẹgẹbi owo ori ilẹ wọn, nigba ti awon to ba n gbe agbegbe to laju bii Akure to je olu ilu naa, yoo san egbeedogbon(5000) si egbaarun( 10,000) naira, lẹyin ti Gomina Rotimi Akeredolu ba buwọlu atunto ofin naa to ti wa latọdun 2014, ki ọdun yii to pari.
Awọn iroyin ti ẹ lee nifẹẹ si: Ọmọ to n ko ọmọ alainile kuro lori titi Tinubu ti bẹrẹ isẹ ti Buhari gbe le lọwọ Kini 'pen' lede Yoruba?
Ni ẹṣin mìíràn bá yọ jáde, òun pupa.
Ni ọdun 2000, wọn fun un ni ẹyẹ National Merit ati Ẹlẹgbẹ ti Ẹkọ Ile-ẹkọ giga ti Naijiria.
Iko agbaboolu Real Madrid ti yan akonimoogba agba iko agbaboolu orile-ede Spain, Julen Lopetegui gege akonimoogba ti yoo maa tuko iko ohun bere lati saa to n bo.
Ọpọlọpọ akẹkọọ ti ko lo ibomu si ni wọn da pada sile lẹnu iloro lasiko ti ikọ BBC Yoruba ṣe abẹwo si awọn ile ẹkọ kan niluu Ibadan lọwurọ ọjọ Aje.
Ọlọrun tí ó ń gbẹ̀san fún mi,tí ó sì ń tẹ orí àwọn eniyan ba fún mi;
Ohun ti wọn ko si bẹ ni pe ki o fi owo ṣeranwọ fun Bitcoin.
2020 Events: Àwọn ìròyìn tó yẹ kẹ máa fojú sọ́nà fún rèé lọ́dún yìí
OLUWA níí gbani,kí ibukun rẹ̀ kí ó wà lórí àwọn eniyan rẹ̀.
"Tí ẹ bá lọ sínú àwọn ọjà wa, kò sí ẹni tọ n tèlé ìlàna òfin Covid-19, ko si si ẹni tó mú wọ́n si.
Nítorí náà, jẹ́ kí wọ́n fi sí ẹ̀yìn ibùdó fún ọ̀sẹ̀ kan, lẹ́yìn náà, kí wọ́n mú un pada.
Jada tẹsiwaju pe oun pade akọrin naa, eyiun August ni ọdun mẹrin aabọ sẹyin, tawọn si di ọrẹ korikosun.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Oyo Schools: Akẹ́kọ̀ọ́ Fásitì, Poly wà nílé, kí ló mú ti alákọ̀ọ́bẹ̀rẹ̀, girama wà níta?
Ọjọ kẹedọgbọn oṣu karun un ni wọn pe ọlọpaa si i pe o fẹ fi owo ayederu ra siga.
Oríṣun àwòrán, @MBuhari Koda, ọkan lara wọn ni Abba Ahmed, ẹni to kede pe oun setan lati pa ara oun ti ọmọ aarẹ ba fi se igbeyawo lẹyin oun.
World theatre Day: Kosọkọ ní ètò adójútòfò wà fọ́jọ́ alẹ́ àwọn onítíátà
 botilejepe ile naijiria ni eya awon eniyan pupo , awon meta ni won tobijulo , ti won si pojulo .
Oun ni alatilẹyin mi to tobi julọ.
Iroyin to n tẹwa lọwọ si tun fi idi rẹ mulẹ pe bi a ṣe n sọrọ yii, Eduwa ti fi ọmọ ta wọn lọrẹ.
Alagba Lamidi wa lara awọn eeyan ilu Ifọn-Orolu nipinlẹ Ọṣun to wa fun iwosan ọfẹ fun aisan oju wọn.
Wọ́n fi pákó fẹ́lẹ́fẹ́lẹ́ bo ara ògiri Tẹmpili náà yíká láti ilẹ̀ títí kan ibi fèrèsé, títí kọjá ìloro.
 Ó tún rumọ ̀ lọ ́ run ní orin tí wọn fi ń yìn ín .
O ṣalaye pe awọn ileewe to fara gba aṣẹ yii pa aala pọ pẹlu ipinlẹ Katsina ti wọn ti ṣẹṣẹ ji awọn akẹkọọto le lọọdunrun gbe, ipinlẹ Kaduna ati Sokoto.
Infantino wa so pe, ti igbimo naa ba bowolu lilo ero VAR, won yoo samulo re ninu idije agbaye lorile-ede Russia.
Kọmiṣọnna fun iṣẹ ṣiṣe Amoju ẹrọ Rotimi Suleiman ni kọmiṣọnna fun ile iṣẹ to n ri si ọrọ iṣẹ ṣisẹ ni ipinlẹ Kwara.
Ẹgbẹrun lọna ogún Naira si ni owo oṣu wọn.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Gbogbo kika ibo ko tii le pe tan lalẹ ọjọ idibo ṣugbọn dede ibo to to lati mọ ajaweolubori lo wa nibẹ.
Oniruuru iroyin lo si ti waye lori rẹ ti ọpọ awọn eekan si ti n ke sawọn agbofinro lati tete fi oju awọn aṣebi to ṣiṣẹ naa sita.
Yala ko jẹ wi pe awọn obirin atọmọde ko lee saba ko arun yii tabi ko jẹ wi pe awọn ẹya ara wọn lagbara lati koju kokoro arun coronavirus ọhun.
N kò ni nkan kan sọ lórí fídíò to gba ayélujára kan pé mo ń we igbó, ẹ mú ẹnu kúrò nibẹ - Oluwo Ẹ wo àwọn gbajúmọ̀ òṣèré tíátà tó jogún eré ṣíṣe lọ́dọ̀ òbí wọn Owó gọbọi wá nídìí oko-owo igbó gbingbin, Ìpínlẹ̀ Ondo kò ní pẹ gba àṣẹ láti gbin - Akeredolu Gómìnà Ṣèyí Mákindé ó ní ìdí tí òun kò fi leè ti ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́ pa nítorí COVID-19 Oluwo ni, Arun Coronavirus kii ṣe arun ti eeyan n fi ṣere rara."
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù SERAP: Ọjọ́ méje la fún UI, AAUA lati dá owó iléẹ̀kọ́ padà 12 Ìgbé 2018 Oríṣun àwòrán, AAUN News Forum Àkọlé àwòrán, Akitiyan BBC láti bá iléeṣẹ́ ọlọ́pàá ní ìpínlẹ̀ Òndó jásí pàbó Àjọ ajàfẹ́tọ́ ọmọnìyàn kan lórílẹ̀èdè Nàìjíríà, SERAP ti ń lérí léka pé àwọn yóò gbé àwọn aláṣẹ fásitì Ìbàdàn, UI àti fásitì ìpínlẹ̀ Oǹdó lọ sí ilé ẹjọ́ bí wọn kò bá tètè tún èrò wọn pa lórí àfikún owó ilé ìwé tí wọ́n ṣẹ̀ṣẹ̀ gbé kalẹ̀.
ate ajo FIFA ti o jade lojoBo(Thursday), eleyi ti o je ipo ate keyin ti yoo
Oko eleru yii lo gbera lati ilu Eko ti o si n lo si ilu
Ọba ni ojiji Ọlọrun Ọba lórilẹ̀ ayé nítori náà ko yẹ ki Ọba maa bọ oriṣà Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Kò sí ǹkan tó ń jẹ́ ọ̀rọ̀ ìgbàgbọ́ tàbí ìmọ̀le nínú àgbékalẹ̀ Amotekun - Alake ti Egba Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Orúkọ ọmọ ni Yorùbá gbà pé ó máa ń ro ọmọ nílẹ̀ Oodua Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
a wa n fi akoko yii bẹ awon baba wa, awon iya wa ,ni oja yii ati ara adugbo yii
Bakan naa ni Alhaji Smith, ti oun pẹlu ti fi igbakan ri jẹ ọga agba ọlọpaa lorilẹede Naijiria tun ni ko si aaye fun ọlọpaa lati gba igbega lẹnu iṣẹ lai jẹ pe o ṣe awọn idanwo gbogbo to ba yẹ.
Ohun tí ó dára ni pé kí o dúró ní ìlú, kí o sì máa fi nǹkan ranṣẹ sí wa láti fi ràn wá lọ́wọ́.
Omo orile-ede CanadaO safihan pe, ilu Dubai lo n lo.
ọkunrin tí ó bá obinrin yìí lòpọ̀ níláti fún baba ọmọbinrin náà ní aadọta ìwọ̀n ṣekeli fadaka.
Ẹsun ti wọn fi kan Gomina Fayemi ni wi pe oun ṣiṣẹ tako ẹgbẹ oṣelu APC,eleyii to tako ofin ẹgbẹ.
Ilé iṣẹ́ to n ri sí ìgbokegbodo ọkọ̀ ni ìpínlẹ̀ Ogun (TRACE) tí gba àwọn awakọ àti gbogbo àwọn tó n sàmúlò ojú pópó náà láti lo àwọn ọ̀nà yìí.
" Oríṣun àwòrán, Nigeria Defence HQ/ twitter.
Ẹ woo bọdẹ ba roṣẹ to ro iya to jẹ ninu igbo bo ba pẹran ko ni fun ẹnikẹni jẹ lọrọ yii o Àwọn jàǹdùkú ṣe ikú pa ẹnìkan n'ílùú Eko Gómìnà Makinde, pe Sunday Igboho àti Auxilliary kóo parí ìjà wọn, àwọn ọmọ Nàìjíríà sọ̀rọ̀ jáde 'Màálù tó bá tàsẹ̀ àgẹ̀rẹ̀ níwájú ilé mi, ó dẹran àsun!
Lẹyin ẹkọsẹ yii wọn tun ni ki a san awọn owo pẹpẹpẹ bẹrẹ lati igba naira si ẹgbẹrun meji naira."
Awọn eeyan miran to tun sọrọ nibi ayẹyẹ ọjọ ibi naa ni Oloye Olusẹgun Ọṣọba, tii se gomina nipinlẹ Ogun nigba kan ri.
Akọwe ẹgbẹ YCE naa ni igbeṣẹ ti awọn yoo gbe yoo waye lẹyin ti awọn ba ṣẹ iwadii finifini lori boya ijọba n takọ ikọ Amọtẹkun patapata ti wọn si n lero pe ki wọn tu wọn ka.
Orilẹede Italy ma n jẹ burẹdi ati iyẹfun ti wọn fi idin se Oríṣun àwòrán, Anja Barte Telin Àkọlé àwòrán, Jijẹ burẹdi onidin jẹ eewọ nilẹ Europe nitori ipa rẹ lara awọn eniyan.
O tun mẹnu ba idagbasoke ti ijọba Buhari ti mu ba Naijiria nipa pipese ayika to faye gba karakata ati idunadura pẹlu awọn ilẹ okeere.
Egbe to n sejoba lowo ,( All Progressives Congress, APC) ti so pe awon ko ni pẹ bẹrẹ lati seto idibo egbe won, ni eyi ti won yoo fi mo awon oludije ti yoo dije nibi eto idibo ti yoo waye lọdun 2019.
Ẹ̀wẹ̀ Kọmísọ́nà fún ètò ẹ̀kọ́ ni Ìpínlẹ̀ Kano Muhammad Sansi Sa'ad sọ fún BBC pé kò tíì sí ìfojúsùn ọjọ́ tí àwọn yóò ṣí ilé ẹ̀kọ́ tó ti wà ní títì pa láti oṣù méjì sẹ́yìn.
“Ṣugbọn fún ẹ̀yin tí ẹ̀ ń gbọ́ ọ̀rọ̀ mi, mo sọ fun yín pé: ẹ fẹ́ràn àwọn ọ̀tá yín: ẹ máa ṣoore fún àwọn tí ó kórìíra yín.
Wọn ni Isiaka fi omobinrin kan ati iyawo to wa ninu oyun silẹ lọ.
Àwọn ìròyìn mìíràn tí ẹ lè nífẹ̀ẹ́ si: Owó wọgbó!
'Obinrin lo mu mi fẹran orin kikọ' Ọmọlóòkú d'èrò ọ̀run níbi ìsìnkú ìyá rẹ̀ Wọ́n fipá bá ọmọbìnrin ogún ọdún lò pọ̀, wọ́n sì pa á 'Ọọ̀nì ńlá méjì ní wọ́n jọ ń gbé nínú iyàrá' Kanya gbà pé àìlera kò yẹ́ kó sọ eeyan di alagbe rárá ati pé iyẹn kò ni ki eeyan má gbe igbe aye alaafia.
Ni ipari wọn gba pe afi ki ijọba fi ofin de awọn oniṣe ibi yii kawọn ọdọ wa yee ko si ọwọ wọn lataari ifẹ ere bọọlu ni gbigba.
Fẹstu wá sọ pé, “Agiripa aláyélúwà ati gbogbo ẹ̀yin eniyan tí ẹ bá wa péjọ níbí.
Bawo ni wọn yoo ṣe ṣee to ba jẹ wi pe eto ti wọn n ṣe jẹ eto ẹya Ibo tabi Hausa tabi ede miran ni ṣugbọn ti wọn wa ni ipinlẹ naa.
Adájọ àgbà Dipak Misra ní ''kò b'ofin mú kí èèyàn fojú ìwà òdaran wo ìbálòpọ̀.
Gbogbo wọn ni wọn kan oro mi sinu, o si dabi ẹni pe ọta pọ, Ọlọrun yoo si gbe mi jẹri wọn.
Kìí ṣe sinimá ni mò ń ṣe, ìṣẹ̀lẹ̀ ojú ayé gangan ní sùgbọ́n.
Nítorí náà, ẹ bẹ Oluwa ìkórè kí ó rán àwọn alágbàṣe sí ibi ìkórè rẹ̀.
Ọdún meji ni Absalomu fi gbé Jerusalẹmu láì fi ojú kan ọba.
“opolopo igbese ni ilu Eko ti n gbe lati mu ohun iwuri de ba awon onisowo lati da okoowo sile.
1 2178 Orilẹede Martinique 42 11.
Mide Martins: Oríṣun àwòrán, others Mide Martins ni ọmọbìnrin gbajumọ osere olóògbé Funmi Martins jẹ, ní kete tí Funmi si fi ilẹ ṣe aṣọ bora, ní Mide, ọmọ rẹ gbé igba ere tíátà tó fi silẹ, to si ti di ilumọọka.
Ní orí òkè tí ó wà lọ́hùn-ún yìí ni àwọn baba wa ń sin Ọlọrun, ṣugbọn ẹ̀yin wí pé Jerusalẹmu ni ibi tí a níláti máa sìn ín.
Ojo jẹ ko di mimọ siwaju sii pe N156 miliọnu ni wọn ya sọtọ fun awọn to n ṣiṣẹ iyọnda Pẹlu N15,000 ajẹmonu owo pe wọn n fẹmi ara wọn wewu ti wọn ti n jẹ wọn latinu oṣu kẹta.
Bo tile je pe irinwo wakati lo gba awon lati fi se atunse ati ayewo oko ofurufu yii.
“N óo na ọwọ́ ibinu mi sí ilẹ̀ Juda, ati sí àwọn tí ń gbé Jerusalẹmu.
"Ọgbẹni Olaniyi sọ pe ""abẹ ibusun, ati awọn ibomiran bi kọnbọọdu, ni awọn janduku naa sa pamọ si, ki ọwọ to o tẹ wọn."
Ó dé, ó ń wá èso lórí rẹ̀, ṣugbọn kò rí.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Wole Soyinka Ṣé o ti gbọ́ ohun ti Ọọni Ifẹ́ àti Soyinka parí ọ̀rọ̀ Yorùbá sí?
Ẹni tí ó bá kó eérú náà jọ gbọdọ̀ fọ aṣọ rẹ̀, òun náà yóo jẹ́ aláìmọ́ títí di ìrọ̀lẹ́ ọjọ́ náà.
Lẹyin ti Big Brother ki awọn olukopa marun to kẹhin si ori eto naa, ni Ebuka kede pe Vee ti ja kuro lori eto naa.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ayédèrú agbẹjọ́rò tó ṣiṣẹ́ fún ọdún mẹ́ta láì ní'wé ẹ̀rí 3 Òkùdu 2018 Oríṣun àwòrán, LAGOS STATE POLICE COMMAND Àkọlé àwòrán, Uche Julian Nwajiakwu bẹ̀rẹ̀ iṣẹ́ agbẹjọ́rò ni 2015 Ọwọ́ ọlọ́pàá ti tẹ arákùnrín kan ní ilé ẹjọ́ ìbílẹ̀ tí ó wà ní Ọ̀jọ́ ni Ìpínlẹ̀ Eko lórí ẹ̀sùn pé ayédèrú agbẹjarò ni.
 gẹ ́ gẹ ́ bí alóre láwùjọ , ọ ̀ kọrin tàbí òṣèré lè fi orin gbé ẹ ̀ dùn ọkàn èrò àwùjọ síta , èyí tí ìba máa fún ni ni ìnira tàbí ìtẹ ̀ mọ ́ lẹ ̀ tàbí ìbánujẹ ́ abẹ ́ nu , yálà láti ọwọ ́ ìjọba tàbí àwọn aláṣẹ kan .
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Gbogbo àgbáyé ẹ gbà wá lọ́wọ́ àsẹ oníkùmọ̀ Buhari - PDP Ìdààmú Dino Melaye kò tíì tán, àwọn ọlọ́pàá tún ya bo ilé rẹ̀ Kí lo fẹ́ mọ̀ nípa D.
Onimọ iṣegun Adeola to jẹ akọṣẹmọṣẹ nipa ọrọ oju ni ile iwosan ijọba ni Idi Araba mẹnuba igbesẹ to yẹ ni gbigbe fun itọju oju.
 kò mọ ̀ ṣéni tó le ríre tí ò ni ribi gín-ń-ginní rẹ ̀ tọ ̀ ọ ́ .
Bakannaa ni wọn tun ya owo sọtọ fun kikọ papa isire si Igbogbo, Epe, Badagry Ajeromi Ifelodun (Ajegunle) pẹlu owo lati pari awọn akanse isẹ to n lọ lọwọ ni Epe ati Badagry Marina.
Olùdíje fún ipò igbákejì gómìnà fẹ́gbẹ́ òsèlú ADC l‘Ọ́sun náà wá fọwọ́ gbáyà pé ẹgbẹ́ òsèlú ADC yóò pèsè isẹ́ lọ́pọ̀ yanturu fáwọn èèyàn ìpínlẹ̀ Ọ̀sun.
Wọ́n pé ọdún méjìlá báyìí Ganiyat tó fi irin gbígbóná àti àdá ya ara ọmọ àbúrò ọkọ rẹ ti dèrò àgọ́ ọlọ́pàá l' Ogun Ohun mẹ́wàá pàtàkì nípa Maradona àti ìbáṣepọ̀ rẹ̀ pẹ̀lú ẹlẹ́sẹ̀ ayò Diego Costa rèé Nàìjíríà fohùn ránṣẹ́ padà sílé aṣofin UK pé ọ̀rọ̀ EndSars kò sí lẹ́nú wọn láìgbọ́ ìwádìí tán!
Ìpínlẹ̀ Zamfara Ní ọjọ́ ìṣẹ́gun, ìjọba ìpińlẹ̀ Zamfara náà kéde pé ki wọ́n ti àwọn ilé iwé mẹ́wàá kan to sún mọ́ ààlà ìpínlẹ̀ Katsina, nítori ǹkan tó ṣẹlẹ̀.
Olùṣọ́-aguntan mi tí kò bá níláárí gbé!
Ìrìn Àjò láti Ijipti sí Moabu.
Ìyẹn ni pé gbogbo àwọn eléré ìdárayá tí wọ́n máa kópa nínú ìdíje náà a jẹ́ àkàndá àti abarapa ẹ̀dá bákan.
Iroyin Isẹju Kan BBC lawọn ede wọnyi jẹ iroyin ni soki ti a se akojọpọ rẹ fun awọn ololufẹ wa lai fi ti ọjọ ori se.
Osu kejila odun to koja ni wọn ṣẹṣẹ faaye gba obinrin lati maa wa ọkọ.
Èyí ni ìdí tí Cameroon fi yí àkókò tó yẹ kí AFCON 2021 wáyé padà Màá ra Arsenal ní 2021 tí mo bá kọ́ iléeṣẹ́ ìfọ́po rọ̀bì tán - Dangote PDP yóò wọ́de nítorí ìdájọ́ ìdìbò gómìnà ìpínlẹ̀ Imo Ẹ má mu gaarí mọ́ nítorí ìbà Lassa- Dókítà Boniface Ìgbéyàwó ọkùnrin s'ọ́kùnrin, obìnrin s'óbìnrin ti di òfin ní Northern Ireland Bi o tilẹ jẹ wi pe Liverpool gba bọọlu si awọn manchester United ni igba meji miran lasiko ifẹsẹwọnsẹ naa, wọn ko kaa nitori awọn aṣemaṣe ti wọn ṣe ṣaaju rẹ.
All 23 invited players are now in and will be part of training today.
Eyi si le mu ki ọpọlọpọ wọn sọ ole jija, tabi awọn ọna alumọkọrọyi mi i di orisun ọrọ aje wọn.
Ijọba Ondo n wa ọdẹ aperin O dèèwọ̀ lati ti ojú pópó pa nipinlẹ Ondo 'Èèwọ̀' gààrí fún àwọn èèyàn ipínlẹ̀ Ondo Awọn ọmọ ogun wa fi da gbogbo awọn arinrinajo loju pe ko nii sewu mọ lopopona lati isinyii lọ.
Mú wa bọ̀ sípò, Ọlọrun àwọn ọmọ ogun;fi ojurere wò wá,kí á lè là.
O ni ''gbogbo awọn ọmọ ẹgbẹ NURTW to wa ni ipo kan tabi omiiran ni Auxiliary ti yọ nipo tan ti o si fawọn eeyan tiẹ sibẹ.
Gbajumọ oṣere yii, ti ede Yoruba yọ lẹnu rẹ lo wa lati ilu Eku ni ẹkun guusu Delta, to si n fi ede Yoruba sisọ jẹun.
Ileeṣẹ ọlọpaa ipinlẹ Eko ko gbe ago nigba ti BBc Yoruba pe wọn lati mọ ohun to ṣokunfa iku awọn eeyan naa.
O salaye pe, igbimo ohun ro pe “bi won ba kede ofin ilu-o-fara ro, eyi yoo mu alaafia joba lorile-ede naa”Minisita fun eto abo ni o kede oro naa lojo-Abameta, eyi ti o sokunfa laasigbo eleyameaya tuntun, eyi ti won nilo lati daabobo ara-ilu.
Lara awon ti o tun wa ninu ipade ohun ni, gomina ipinle Kebbi, ti oun je okan lara asoju awon gomina, ati minisita to n ri si oro awon osise, Chris Ngige.
Àwọn ọmọ Iyabọ Ojo rí Bàbá lẹ́yìn ọdún mẹ́fà 'Àwọn akọni mẹ́rin gun ọ̀kadà láti Germany wá sí Nàìjíríà' Ọrọ ki ololufẹ maa fibinu gun ara wọn pa ti to apero ọmọ eriwo ni Naijiria bayii.
O dabi ẹni pe eero pe ooru le fi opin si Itankalẹ coronavirus ti dawọ duro, bi aarun naa ṣe n tan kaakiri agbaye.
A ó gbé'gbésẹ̀ lẹ́yìn ìwádìí fídíò tí Dino ti ń náwó lójú agbo- Ọlọ́pàá Ajọ CAN ti kede pe awọn n reti abọ iwadii ajọ PFN ki awọn to mọ igbesẹ to kan lati gbe lori ọrọ ẹsun ifipabanilopọ naa.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, #EndSARS : Àwọn ọ̀dọ́ dáná sun tírélà akẹ́rù tẹrùtẹrù ní Ekiti Wo ohun tó yẹ kí o mọ̀ nípa akíkanjú obìrin tó kópa nínú ìwọ́de End SARS?
Oba Folagbade Olateru-Olagbegi wàjà lẹ́ni ọdún 77 Wo ibi tí ayédèrú ìròyìn bá Áfíríkà dé láàrin ọdún kan Kò sí àjòjì darandaran kankan ní Nàìjíríà -NIS 'Ọkọ mi yọ kindinrin mi lati rọpo owo ori' Mẹrinla ninu awọn afọbajẹ marundinlogun to wa ni ilu Ọwọ ni wọn dibo fun Ọmọọba Ajibade Ogunoye.
 mílíònù mẹ ́ sàn-án ènìyàn ló ń sọ èdè zulu .
Lasiko ti a fi n ko iroyin yii jọ, awọn omuwẹ ṣi n wa eeyan kan to ku ninu ọkọ oju omi naa.
Ó kórìíra àwọn ọmọ Israẹli, òun sì ni ọba ilẹ̀ Siria.
Ajafẹtọ ọmọniyan naa fi awọn oloselu naa we onisowo ti o seese ki o fi okoowo kan silẹ fun omiran nitori ko pe wọn mọ.
Kí ọkunrin kọ̀ọ̀kan, láti inú ẹ̀yà kọ̀ọ̀kan wà pẹlu yín láti máa ràn yín lọ́wọ́.
Olubadamọran pataki fun gomina Seyi Makinde, Fatai Owoseni lo kede ọrọ naa nibi ipade ita gbangba to waye ni Akinyele, eyi ti ileeṣẹ agbohunsafẹfẹ kan gbe kalẹ.
Iroyin fi mule pe, awako ofurufu ohun, ti o je enikan soso ti o wa ninu oko ofurufu naa, ni ori koyo, leyin ti awon osise to n ri si isele pajawiri sawari re.
Eyii lo mu ki ijọba ipinlẹ Ọyọ kan sii nipasẹ alamọran pataki fun gomina Ṣeyi Makinde lori ọrọ awọn ọdọ.
Adeniran, tun so pe iko omo ogun oju omi yoo tun tepele mo ifowosowopo pelu awon ajo eleto aabo lati  dekun awon iwa ibajẹ lorile ede Naijria.
Latori afihan sinima, de ori ọjọ ibi kan oku arugbo lo waye laarin awọn oṣere tiata Yoruba ti a mọ si Yollywood lọsẹ yii.
Tẹle ilana ofin girama ede Pidgin bi o ti yẹ.
 Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ìgbẹ́jọ́ aṣaájú ìjọ Sotitobire kúrò nílé ẹjọ́ Mágísíréètì lọ sílé ẹjọ́ gíga l‘Akure Ibùdó amúnáwá kan bú gbàmù n‘Ibadan, ni iná bá ṣẹ́yọ Saheed àti Fathia Balogun dìjọ ń ṣe ọjọ́ ìbí lónìí, ẹ wo àjọṣepọ̀ tó wà láàrin wọn Wo àtúpalẹ̀ ìlànà tuntun nípa gbígba físà Nàíjíríà tí Buhari gbé jáde Ọ̀pọ̀ nǹkan tí kò yé èmi àti Bàbá Wande, ló fa ìjà lórí sinimá Tolúwa Nilẹ̀ - Tunde Kelani Gbogbo awọn egboogi bi cocaine, heroine, ati bẹẹbẹ lọ lo ni iwulo ninu ipese awọn oogun oyinbo, ṣugbọn ilokulo wọn ni ko dara.
Ohunkohun tí aláìmọ́ bá fọwọ́ kàn yóo di aláìmọ́, ẹnikẹ́ni tí ó bá sì fọwọ́ kan ohun tí aláìmọ́ náà bá fọwọ́ kàn yóo di aláìmọ́ títí di ìrọ̀lẹ́.
naa  asofin Rose oko n soro nipa iyaafin
Wọn kò tilẹ̀ lé àwa ọmọdé sí ẹ̀hìnkùlé.
Ọọni, Aláàfin, Ojisẹ Ọlọ́run àti oniṣẹ ìwádìí fi Ògún gbari pé òògùn ìbílẹ̀ le wo Covid-19 Madagascar herbal cure: Ọọni, Aláàfin, Ojisẹ Ọlọ́run àti oniṣẹ ìwádìí fi Ògún gbari pé òògùn ìbílẹ̀ le wo Covid-19 Oríṣun àwòrán, ooni adeyeye ogunwusi Laipẹ yìí ni Minisita fún ètò ìlera ní Nàìjíríà, Dókítà Osagie Ehanire kéde pé, ìjọba kò tako àmúlò òògùn ìbílẹ̀ fún ìwòsàn àrùn Coronavirus.
Àwọn aṣòfin Naijiria ṣọ̀rọ̀ ìwúrí nípa Ajimobi Bẹẹ ba gbagbe, ọjọ kẹẹdọgbọn, oṣu Kẹfa, ọdun 2020 ni opo nla nipinlẹ Oyo naa yẹ, ti erin Ajimobi subu lai le e dide.
Kúrò ní ṣóńṣó òkè Amana,kúrò lórí òkè Seniri ati òkè Herimoni,kúrò ninu ihò kinniun, ati ibi tí àwọn ẹkùn ń gbé.
Àkọlé àwòrán, Ìtàn Manigbagbe: Ẹ fokan balẹ, àwọn ajakale àrùn kan rèé to burú ju Coronavirus lọ Wọn yóò fi aṣọ bo imú àti ẹnu wọn, gẹ́gẹ́ bá ti ń ṣe lásìkò ajakale àrùn Coronavirus yìí.
Oríṣun àwòrán, University of Ibadan Ọladẹjọ wa mu da awọn akẹkọ to wa lọgba fasiti Ibadan, awọn obi wọn ati gbogbo awujọ lapapọ pe, ko si ewu kankan loko nipa eto aabo ile ẹkọ naa, nitori awọn alasẹ ileekọ ọhun ti setan lati mu agbega ba eto aabo rẹ, ki iru isẹlẹ yii ma baa waye mọ.
igbakeji aarẹ́ si tun kede awọn ipin idokoowo to ni.
Àwọn yàrá náà ń fẹ̀ sí i láti àgbékà dé àgbékà, bí òpó tí wọ́n mọ sí ara ògiri Tẹmpili ṣe ń tóbi sí i.
ede Naijiria ti fimọ sọkan lati sepade apero  lori eto aabo ni  ẹkun Gusu orile ede yii.
Ó wá jẹ́ pé ikú ní ń ṣiṣẹ́ ninu wa, nígbà tí ìyè ń ṣiṣẹ́ ninu yín.
Oríṣun àwòrán, @misspetitenaija Awọn koko to wa ninu ọrọ ti aarẹ Buhari bawọn ọmọ Naijiria sọ ree: Afojusun ijọba mi ni lati ri pe abo wa lori ẹmi ati dukia awọn ọmọ Naijiria, ṣugbọn ijọba ko lee da iṣẹ naa ṣe, lai si atilẹyin awọn ara ilu.
Esi yii ti sọ apapọ awon to ti ko arun naa ni Naijiria lapapọ di 100,087, awọn 80,030 ti ri iwosan nigba ti awọn 1,358 ti dero ọrun.
Agbẹjọro Abiade parọwa naa lasiko to n ba BBC Yoruba sọrọ ni Ọjọ Ayajọ ifopinsi ifiyajẹ obinrin ni agbaye.
Bukata owo Sukuk Se ẹ ranti owo Sukuk ti ijọba apapo ya laipe yi lati fi pari awọn oju ọna kan kakiri orileede Naijiria?
Awọn ladelade, loyeloye, aṣoju ijọba, ẹlẹgbẹjẹgbẹ awujọ, ajọ awọn ẹṣọ alabo, to fi mọ awọn akoṣẹmọṣẹ nipa aabo ẹmi ati dukia lo kora jọpọ sibi akanṣe eto naa.
Àwọn ọmọ Naijiria ṣèdárò gbajúgbajù agbábọ́ọ̀lù Super Eagles tó dolóògbè Ẹ̀rọ CCTV tú àsírí ọkùnrin ẹni ọgbọ̀n ọdún tó fi ipá bá ọmọ ọdún mọ́kànlá lòpọ̀ Bí mo bá wọlé padà, mí ò lè yàn Ize Iyamu tàbí Osagiobare sípò olùbádámọ́ràn- Obaseki Facebook mú àyípadà bá àtẹ̀jíṣẹ́ síra ẹni lórí òpó Instagram, wo àwọn ǹkan tó kàn ọ níbẹ̀ Iléeṣẹ́ ọlọ́pàá ní Kano tí ṣe àyẹ̀wò àwọn 13, 048 tó fẹ́ darapọ̀ mọ́ wọn Ọṣẹ yii ninu aye Odunlade Adekọla: Gbogbo ọsẹ yii ni ilumọọka oṣere, Odunlade Adekola fi n polowo ipadabọọ sinima rẹ, Saamu Alajọ eyi ti gbogbo eeyan n wari fun Loju opo instagram rẹ, lo ti n fun awọn eeyan ni itọwo kekeke ninu ẹkunrẹrẹ fiimu Saaamu Alajọ to jẹ sinima apanilẹrin.
Ni ọjọ Iṣẹgun ni ọga ọlọpaa lorilẹede Naijiria ṣe ipade ori ayelujara pẹlu awọn lọgalọga lẹnu iṣẹ ọlọpaa lorilẹ€de Naijiria nibi to ti paṣẹ fun wọn lati tubọ rii pe aṣẹ konile o gbele naa fẹsẹmulẹ sii ti wọn si ni o paṣẹ pe ki wọn maa fi panpẹ ofin mu ẹnikẹni ti irinkerindo rẹ ba ti kọja agogo mẹjọ alẹ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Okunrounmu: Ijọba Buhari jẹ ijiya Ọlọrun fun Naijiria Lati igba naa si lawọn ọmọ Naijiria ti n reti reti koda lẹyin ti aarẹ ile igbimọ aṣofin agba gan, Ahmed Lawal kede pe yoo jade ki ọsẹ yii to kanlẹ.
11 Ọ̀wàrà 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 16 Ọ̀wàrà 2020 Oríṣun àwòrán, Police Oga Agba ọlọpaa, Muhammed Adamu ti kede pe ijọba ti tu ikọ ọlọpaa SARS ka lẹyin ti awọn eniyan ko dawọ duro lori ifẹhọnu han ti wọn n ṣe pẹlu asia #EndSARS.
ìlú Eko kọ́ ló léwu jùlọ láti gbé lágbàáyé- Ìjọba Eko Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Aaroni bí ọmọkunrin mẹrin: Nadabu, Abihu, Eleasari ati Itamari.
Sotitobire: Pásìtọ̀ Alfa Babatunde padà s'ẹ́wọ̀n, Iléẹjọ́ sún ìgbẹ́jọ́ sí ọjọ́ Ajé tó ń bọ̀ Ileẹjọ giga ipinlẹ Ondo to wa niluu Akure ti sun igbẹjọ Pasitọ ijọ Sotitobire, Alfa Babatunde si ọjọ Aje to n bọ tii ṣe ọjọ kẹẹdogun oṣu kẹfa ọdun 2020.
Ìtìjú ti bá Moabu, nítorí pé ó ti wó lulẹ̀; ẹ kígbe, ẹ máa sọkún.
ADC, ADP, APC, SDP fakọyọ níbi ìpàdé ìtagbangba l'Ọṣun Ará Kwara soríre bí mo se jáwé olúborí - Ọlawuyi Deede agogo mẹsan owurọ ni eto yoo bẹrẹ pẹlu bi awọn akopa yoo ṣe ti ṣaaju fi orukọ silẹ loju opo https://bit.
Wọ́n bá gbogbo nǹkan bí àwọn obinrin ti wí, ṣugbọn wọn kò rí òun alára.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Oman ń ṣelédè lẹ́yìn Sultan Qaboos bin Said 11 Sẹ́rẹ́ 2020 Oríṣun àwòrán, Reuters Sultan Qaboos ni adari ilẹ Arab to pẹ ju lagbaye, o si ti wọ kaa ilẹ sun bayii lẹni ọdun mọkandinlọgọrin.
Nigba to n sọrọ nipa ọfọ nla to ja lu orilẹede Ivory Coast yii, aarẹ Quattara ni lootọ ni ara Coulibaly ko ya lasiko ipade igbimọ alaṣẹ ijọba ti wọn se.
Síbẹ̀, ọ̀gọ̀rọ̀ ènìyàn ni ó ní ìgbàgbọ́ wípé àyípadà ọ̀tún ń bọ̀ fún àwọn ènìyàn wọ̀nyí láti gbé ìgbé ayé ìfọkànbalẹ̀ nígbà tí ẹ̀tọ́ ọmọnìyàn gbogbo ní ìlú á wà ní ọ̀gbọọgba ní ojú àwọn ènìyàn àti ní abẹ́ òfin.
 ati wò lápapọ ̀ pé wọ ́ n lè dẹ ́ kun ìdá 70 ti kòkòrò jẹjẹrẹ abẹ ́ obìnrin , ìdá 80 ti kòkòrò jẹjẹrẹ ihò-ìdí , ìdá 60 ti kòkòrò ojú ara obìnrin , ìdá 40 ti kòkòrò jẹjẹrẹ ojú ìta ara obìnrin , àti bóyá kòkòrò jẹjẹrẹ ẹnu .
Gbogbo orílẹ̀-èdè kò tó nǹkan níwájú rẹ̀,wọn kò jámọ́ nǹkan lójú rẹ̀, òfo ni wọ́n.
Lẹ́yìn náà, ó wá gun orí òkè lọ, ó pe àwọn tí ó wù ú sọ́dọ̀, wọ́n sì tọ̀ ọ́ lọ.
Oríṣun àwòrán, iyaboojofespris Àkọlé àwòrán, Inu ẹni kii dun, ka pa a mọ̀ra ni ihuwasi ati irinsi Iyabo lọjọ isile Oríṣun àwòrán, iyaboojofespris Àkọlé àwòrán, Iya rẹ naa ba yọ ayọ ile tuntun.
Eyi ni ó jẹ́ ki Yorùbá ma ki ẹni ti ó bá ntọ ọmọ lọ́wọ́ pé “Ẹ kú ọwọ lómi nitori ọwọ́ ki kúrò ni omi aṣọ fí fọ̀.
" Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Rape cases in Nigeria: Ọmọ ọdun 5 àti 14 ni Kalu wà nígbà tí obìnrin fipá ba lòpọ̀ Lọwọlọwọ bayii, o ni ọkunrin naa ti wa nile iwosan ijọba to wa nilu Rodo, nibi to ti n gba itọju, tawọn ọlọpaa si n fi ọrọ wa awọn aburo rẹ lẹnu wo.
Sugbọn, ọwọ yẹpẹrẹ ni Aarẹ Lukashenko fi mu ọrọ rẹ, to si fi ṣe awada pé àwọn kan lo n dari rẹ lati ilẹ okeere.
Àwọn ọmọ Nàìjíríà la ohùn Èèyàn mẹ́tàlá dèrò ọ̀run nínú ìjàmbá ọkọ̀ lópòpónà Ìbàdàn s'ÈKó Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Aeroplane House: Látọdún 1999 ni mo ti bẹ̀rẹ̀ kíkọ́ ilé yìí fún ìyàwó mi ọ̀wọ́n Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Kògbérèégbè mẹ́ta nínú òṣèré Yorùbá Àṣìta ìbọn pa èèyàn kan lásìkò tí SARS ń kojú adigunjalè l'Eko Ọlọ́pàá Bayelsa ní àwọn ti kán lugbó láti wá ìyá Siasia 'Kò sí ǹkan tó jọ tòmátò tó ní májèlé ní Nàìjíríà' Ile alaja mẹta yii ni awọn iyara aladagbe to pọ ati ọpọlọpọ ile itaja ti wọn kọ papaọ ni aarin gbungbun Jos.
Idin Gano ni orukọ alaga ẹgbẹ Gano, oun si lo lewaju idunadura pẹlu akọnimọọgba Aston Villa Abba Alasan Super Stars ti wọn fi gba lati san owo naa fun Salisu.
Ṣugbọn ọba Ijipti dá wọn lóhùn pé, “Ìwọ Mose ati ìwọ Aaroni, kí ló dé tí ẹ fi kó àwọn eniyan wọnyi kúrò lẹ́nu iṣẹ́ wọn?
Wò ó, ṣebí ìkáwọ́ OLUWA àwọn ọmọ ogun ni ó wà, pé kí orílẹ̀-èdè kan ṣe làálàá tán, kí iná sì jó gbogbo rẹ̀ ní àjórun, kí wahala orílẹ̀-èdè náà sì já sí asán.
nítorí pé ẹ jèrè igbagbọ yín nípa ìgbàlà ọkàn yín.
Ìyìnbọn mọ ́ ọ ̀ pọ ̀ ènìyàn ní ṣọ ́ ọ ̀ sì ní charleston ( tí a tún mọ ̀ bi Ìfikúparun ṣọ ́ ọ ̀ sì ní charleston ) jẹ ́ ìṣẹ ́ lẹ ̀ ìfìbọn pa ọ ̀ pọ ̀ èníyàn tó ṣẹlẹ ̀ nígbàtí dylann roof , tó jẹ ́ oníṣègbéraga àwọn aláwọ ̀ funfun ọmọ ọdún 21 fìbọn pa àwọn aláwọ ̀ dúdú ará amẹ ́ ríkà mẹ ́ sàn ( tí olùṣọ ́ -àgùtàn àgbà àti , alàgbà ilé aṣòfin clementa c.
A rí àkọlé yìí, ó tọ́ka sí ọ̀nà náà: ‘Eléyìí ní ìlú àwọn Aláṣejù nibi tí ọba Aláyélúwà Aláṣetẹ́ ti ń ṣe ọba wọn.
Kete ti iwe yii jade, ni awọn eniyan tun ti ṣiwe iranti kan ile ijọsin naa.
Abrahamu sọ fún àwọn ará Gerari pé arabinrin òun ni Sara aya rẹ̀, Abimeleki, ọba Gerari bá ranṣẹ lọ mú Sara.
Ọwurọ̀ Ọjọ́rú ni Linda Igwetu to jẹ agunbanirọ ti ọlọpaa pa ati awọn akẹgbẹ rẹ jade lọ ṣe àjọyọ pipari ìsìnrú'lú ọdun kan wọn.
Ṣugbọn bí ẹnìkan bá láyà láti fi ohun kan ṣe ìgbéraga, ẹ jẹ́ kí n sọ̀rọ̀ bí aṣiwèrè, èmi náà láyà láti ṣe ìgbéraga.
Àkọlé àwòrán, Ipade itagbangba BBC Yoruba Ẹni to ba duro lori oke Mapo, kedere ni yoo maa ri gbogbo ilu Ibadan ninu ogo rẹ.
Awọn ilumọ̀ọ́ká ti wọn ba BBC Yoruba sọrọ fi ohun dá meji lori ọrọ naa ni.
 yunus tí ní irú bánkì yìí nínú abúlé tó tó 35,000 nínú abúlé 68,000 tí ó wà ní bangladesh .
” Saulu sì bẹ̀rẹ̀ sí sọkún.
N óo mú kí àwọn tó ń ni ọ́ lára máa pa ara wọn jẹ:wọn óo máa mu ẹ̀jẹ̀ ara wọn, bí ẹni mu ọtí,gbogbo ayé yóo sì mọ̀ nígbà náà pé,èmi ni OLUWA, Olùgbàlà rẹ,Olùràpadà rẹ, Ọlọrun alágbára Jakọbu.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Lagos APC Rally: MC Oluọmọ fara gb'ọ̀bẹ níbi ìpolongo ìbò 9 Sẹ́rẹ́ 2019 Nibi ipolongo ibo APC to waye nipinlẹ Eko, wahala bẹ silẹ, Musiliu Akinsanya ti gbogbo eniyan mọ si MC Oluọmọ si fara gbọgbẹ.
Iyabọ ni iwa irẹnijẹ nijọba n se fawọn arinrinajo silẹ okeere tabi to de lati ilẹ okeere nidi ayẹwo arun Coronavirus.
Nítorí náà, gbọ́ tiwọn, ṣugbọn kìlọ̀ fún wọn gidigidi, kí o sì ṣe àlàyé gbogbo ohun tí ọba náà yóo máa ṣe sí wọn fún wọn dáradára.
Nítorí pé ẹnu àwọn eniyan burúkú ati tiàwọn ẹlẹ́tàn kò dákẹ́,wọ́n ń sọ̀rọ̀ èké nípa mi.
Sotitobire àti àwọn wòlíì ọmọ Nàìjíríà míràn tó ti lọ sẹ́wọ̀n nítorí ẹ̀sùn ìwà ọ̀daràn Ìdájọ́ ẹ̀wòn gbére kò ní kí Wòlíì Sotitobire má lọ sí ilèẹjọ́ kòtẹ́milọ́rùn - Agbẹjọ́rò Pásítọ̀ Alfa Babatunde Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ìdájọ́ òdòdò ló fẹsẹ̀ múlẹ̀ lórí ọ̀rọ̀ Pásítọ̀ Sotitobire - Agbẹjọ́rò fún ìjọba Ààrẹ ilẹ̀ Amẹríkà, Donald Trump tún yẹrẹpẹ ààrùn Coronavirus bó ṣe n kúrò nílé ìwòsàn Bí ìgbà tí ènìyàn ń ṣe eré orí ìtàgé ni ààrẹ Donald Trump ń fi ọ̀rọ̀ coronavirus ṣe gẹgẹ bi yóò ṣe padà si ilé ijọba lónìí, lẹ́yìn ọjọ́ mẹ́ta nílé ìwòsàn.
 nípa tíátà ni a ti mọ ̀ pàápàá ni ilẹ ̀ yorùbá àwọn àṣà ati iṣe wa , tí ó ti sọnù nítorí àṣà àti ìwà àwọn òyìnbó ti gba àṣà àti ìṣe wa lọ ́ wọ ́ wa .
'Àgbàrá òjò wọ́ ọmọ méjì lọ ní Ketu l'Eko lálẹ́, a ṣì ń wá wọn di òní' Ajọ NAFDAC ni ijọba apapọ fẹ gbe igbesẹ yii nitori ipa ti mimu ọti lọna ti ko tọ n mu ba ilera ilu pẹlu igbayegbadun araalu.
Nígbà náà ni àwọn Juu sọ pé, “Ẹ ò rí i bí ó ti fẹ́ràn rẹ̀ tó!
Ìgbà tí mo tún padà mo wa rí igi Ìfẹ̀yìntì-Olódùmarè yìí, ṣùgbọ́n ṣe ni ara rẹ̀ ń yọ̀ bí ilá ọ̀ọ̀meje ni mo sì já lulẹ̀ nibi tí mo ti ń gùn ún, nígbẹ̀yìn ṣá mo fi erùpẹ̀ ra inú, mo bẹ̀rẹ̀ sí í pọn ọn títí mo di dé òkè tí mo ká èso náà, góòlù ni gbogbo ara rẹ̀, ṣe ni o n pupa dẹ̀dẹ̀.
ìjì líle kan fẹ́ la àṣálẹ̀ kọjá, ó fẹ́ lu ilé náà, ó wó, ó sì pa gbogbo wọn, èmi nìkan ni mo sá àsálà láti wá ròyìn fún ọ.
Kí OLUWA ṣàánú fun yín, bí ẹ ti ṣàánú fún èmi ati àwọn òkú ọ̀run.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Rape: Norma Ka Mbele ní ayé òun kò rí bákàn náà mọ́ lẹ́yìn ìfipábálòpọ̀ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Rape: Norma Ka Mbele ní ayé òun kò rí bákàn náà mọ́ lẹ́yìn ìfipábálòpọ̀ 14 Ọ̀wàrà 2019 Iwadii fihan pe Orilẹede South Africa lo ni iye obinrin ti wọn ti fipabalopọ, ti wọn si tun sekupa julọ lagbaye.
tẹẹkotọ lati maa gba esun  naa wole
Gege bi awon ti o sagbekale ipade ohun, ipade naa nireti wa pe yoo da lori adehun ile Paris lori iyipada oju ojo labe eto idanileko Paris ti a mo si(Paris Agreement Work Programme,PAWP).
Kò fẹ́ kí ẹnikẹ́ni ṣègbé ṣugbọn ó fi ààyè sílẹ̀ kí gbogbo eniyan lè ronupiwada.
cynthia ann mckinney ( ojoibi march 17 , 1955 ) je alakitiyan ati oloselu are amerika .
Bakan náà ni DanMallam fi ọkàn ará ìlú balẹ̀ pé ìdájọ ododo ní yóò wáye lori ọ̀rọ̀ náà nítori pé kò si ẹnikẹ́ni tó kọjá òfin.
Chris ni itara fun itọju ara rẹ lati kekere sugbọn lẹnu lọọlọ yii, ọna ara ọtọ lo gba tọju awọ ara rẹ.
Bakan naa ni inu wọn ko dun pẹlu bi Trump ṣe di ọrẹ awọn olori apaṣẹ waa bii Vladimir Putin.
Ó bá sọ fún àwọn iranṣẹ rẹ̀ pé, “Ǹjẹ́ a lè rí irú ọkunrin yìí, ẹni tí ẹ̀mí Ọlọrun ń gbé inú rẹ̀?
Ile ọti kan to wa nijọba ibilẹ Madagali si ni isẹlẹ naa ti waye.
Bii awọn ipinlẹ naa ṣe lọ ni yii; Eko-102 Ogun-34 FCT-29 Borno-26 Kaduna-23 Rivers-21 Ebonyi-17 Kwara -16 Katsina-14 Edo-10 Delta-10 Kano-10 Bauchi-10 Bayelsa-9 Imo-8 Plateau-4 Ondo-3 Nasarawa-2 Gombe-1 Oyo-1 Ní Ọjọ́ọ̀rú nìkan, ènìyàn 348 ló lùgbàdì àrùn Coronavirus ní Naijiria Ajọ NCDC ti kede eniyan 348 gẹgẹ bi apapọ eniyan to ni arun Coronavirus lorilẹede Naijiria ni Ọjọọru nikan lorilẹede Naijiria.
Ṣugbọn iroyin fihan pe aarẹ ko ti i gba iṣẹ́ lọ́wọ́ Yusuf bo ti lẹ ni pe ko lọ simi diẹ nigba ti wọn gbe igbimọ naa kalẹ ni oṣu kẹwaa, ọdun 2019.
Pẹlu ẹ̀tàn, ọba yìí yóo mú àwọn tí wọ́n kọ majẹmu náà sílẹ̀ lọ́rẹ̀ẹ́; ṣugbọn àwọn tí wọ́n mọ Ọlọrun yóo dúró ṣinṣin, wọn óo sì ṣe ẹ̀tọ́.
Àwọn ará Babiloni gbé, nítorí ọjọ́ wọn ti pé,àní ọjọ́ ìjìyà wọn.
Ìwọ tí ń panirun,tí ẹnìkan kò parun,ìwọ tí ò ń hùwà ọ̀dàlẹ̀nígbà tí ẹnìkan kò dà ọ́.
Ẹrin ẹnu rẹ ati iduro rẹ jẹ eyi ti o lee mu ki abo fi akọ ti o n tẹle silẹ.
ọmọ Elikana, ọmọ Joẹli, ọmọ Asaraya, ọmọ Sefanaya, 
Emi gan kabamọ sugbọn ko wulo mọ ni baba sọ.
Bakan naa ni Osu Kẹwa, ọdun 2019 ni arakunrin kan fo sanlẹ to si ku, nibi to ti n sare ni agbeegbe WEMCO, ni Ogba, nipinlẹ Eko.
“Bí mo bá ṣe gbogbo èyí, tí ẹ kò sì gbọ́ tèmi, ṣugbọn tí ẹ tún kẹ̀yìn sí mi, 
Òkú ọmọ ọdún mẹ́ta tó kó sí kàǹga ní Ipaja ni wọ́n yọ' Rara o, wọn so yigi o, ile wa ni mo wa."
O tesiwaju pe ki i se iye awon eso eleto aabo lo se pataki ju  , bi ko se bi won se lee se ise si lati ri I pe eto aabo to peye wa fun awon oludibo ati apoti idibo.
Ọba naa ni oriade ilu Iketewi, to wa ni ijọba ibilẹ Obokun, nipinlẹ Osun.
Ọpọlọpọ awọn eniyan jankan-jankan lo wa lati orisirisi ipinlẹ ni orilẹede yii ati ni awọn orilẹede miran lagbaye, lati kopa ninu ọdun naa, eyi ti ko yọ awọn oyinbo alawọ funfun sẹyin.
Gege bi alaga igbimo asofin to n mojuto abewo ohun, Gbenga Ashafa,”leyin abewo leni, Mo le so gbangba-gbangba pe, ise akanse yii ko le wa sipari lopin odun yii.
2m dọlà ni obìnrin yìí ń gbà tó bá kọ ǹkan sí ojú òpó Instagram rẹ̀ Wo ohun tó yẹ kí o mọ̀ nípa àwọn obìnrin méje ti Buhari forúkọ wọn ránṣẹ Ijọba lawọn ti rẹyin Boko Haram ṣugbọn bi wọn ti ṣe n da oro loore-koore ko jẹ ki ara ilu le sọ boya opin ti de ba Boko Haram.
O tun wa yi biri ni nkan bi ọdun mẹta sẹyin nigba ti awọn ologun fi tipa tipa gba ijọba lọwọ aarẹ Robert Mugabe ati ẹni to gbe ọpa aṣẹ le lọwọ, Emmerson Mnangagwa eyi to mu atunto ba ọrọ aje wọn ati ijọba to ni ọwọ mimọ lasiko ẹgbẹ oṣelu Zanu-PF wa ni ijọba.
Ni ipari o ni ki awọn awakọ maa fọwọsowọpọ pẹlu awọn oṣiṣẹ ẹṣṣo aabo oju popo FRSC ki alaafia le jọba loju popo Naijiria.
Báàlẹ́ yìí lo sáà wọn títí ọdún 1952 nígbà tí ẹlẹ́mìí gbà á.
OLUWA pa á láṣẹ fún wa pé kí á máa tẹ̀lé gbogbo àwọn ìlànà wọnyi, kí á bẹ̀rù òun OLUWA Ọlọrun wa fún ire ara wa nígbà gbogbo, kí ó lè dá wa sí, kí á sì wà láàyè bí a ti wà lónìí yìí.
Òsìsẹ́ Custom tó déédé sọ ara rẹ̀ di Ọ̀gá Àgbà CG ní ìdàmú ọpọlọ - Attah Ilé ẹjọ́ sún ẹjọ́ Sẹ́nétọ̀ Abbo síwájú pẹ̀lú béèlì mílíọ̀nù márùn-ún O fẹ́ yọ́ wọ ààyè ibùsùn àwọn obìnrin lọwọ́ ọlọ́pàá bá tẹ̀ ẹ!
Pẹ̀lú òfin àwọn ìpínlẹ̀ India tí ó ka ìṣọdẹ-àjẹ́ sí ohun tí ó lòdì sófin, àwọn akópa ọ̀ràn wọ̀nyí rí i gẹ́gẹ́ bí ọ̀nà ìdáààbò-ara-ẹni.
Adamu Adamu, Minista ètò ẹ̀kọ́ ti fi òfin àátẹ̀lẹ́ síta kí àwọn ilé ìwé lè wọlé Ikú Williams Aanuoluwa lágbo òṣèré hú ọ̀pọ̀ ọ̀rọ̀ síta Ilé ẹjọ́ yá lórí òfin CAMA tó fẹ́ gba àkóso ilé ìjọsìn, tẹ ẹ̀tọ́ aráàlú mọ́lẹ̀ - SERAP Kí ló ń ṣẹlẹ̀ lọ́wọ́ sí Mamman Daura àti ìlera rẹ̀?
Buhari ni awọn asaaju to jẹ lẹrin saa ijọba alagbada akọkọ lo ba ofin naa jẹ, ti wọn si gba isẹ awọn darandaran se.
A máa mú kí gbogbo ara wá gbóná, iná ọ̀run àpáàdì ni ó túbọ̀ ń fún un ní agbára.
LuisCarlos wà ní orí kẹ̀kẹ́ẹ rẹ̀, ṣùgbọ́n láti aago 5:30 ni mi kò ti gbúròó rẹ̀ mọ́, bẹ́ẹ̀:
5: E Sa Ma Mi Lengbe Vol.
O fi kun pe awọn to jẹ ẹni ọdun mejidinlogunn si aadọrin ọdun nikan lo lọ gba fọọmu ọhun.
 Bakannaa ni aarẹ orilẹede yi ati oludari agba fun ileesẹ ologun orilẹede yi n ki yin ku oriire lori bi ẹ se gba igbo Sambisa.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Kainji dam Bi awọn eniyan ṣe n kọ ile si oju omi naa jẹ ọkan lara awọn ohun to n fa ijamba omiyale nitori oju omi ko fẹ to lati jẹ ki omi raye kọja.
Watford lu Chelsea la'lubolẹ Chelsea wọyaja pẹlu Barcelona Chelsea lu West Brom lalubomi Chelsea fún okùn mó Tottenham.
Ewe, ipade oni bonkole ohun ni o waye lojuna lati wa ojutu si awon idojuko to n koju eto aabo lorile-ede yii, bee si ni lati gbe igbese ti yoo dena wahala ninu ayeye odun Eid-el Kabir to n bo lona yii.
Lọpọ awọn ipinlẹ Naijiria ni ofin to bu owo tabua fawọn Gomina ati igbakeji wọn ti wa nilẹ lẹyin ti wọn ba pari saa wọn yala ọdun mẹrin tabi mẹjọ.
Àwọn ẹja royìn ìwà ìkà yín sí wọn, bí ó ti jẹ́ pé àti kékeré àti ńlá nínú àwọn ni ẹ̀ ń fi àwọn kò kúrò nínú omi, ti ẹ kò tilẹ̀ dákẹ́ bẹ́ẹ̀, ti ẹ̀ ń jẹ ẹyín tí àwọn bá yé tí ẹ kò fẹ́ kí ìran àwọn sí nínú odò mọ́.
"Oun ati ikeji rẹ, Mountain Black ni wọn jọ kọ orin ""Danfo Driver"" to gba gbogbo igboro kan lọdun 1998 ati ọpọlọpọ orin mii."
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Àṣà Yorùbá: Èèwọ̀ ni kí obìnrin wọ igbó orò 3 Sẹ́rẹ́ 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 14 Èbibi 2020 Oríṣun àwòrán, @Khemeticchurch Àkọlé àwòrán, Àwọn àṣà àti ìse tó yọ obìnrin sílẹ̀ nílẹ̀ Yorùbá Ni ilẹ́ Yoruba, oniruuru asa, ise ati igbagbọ lo wa, eyi ti o de awọn obinrin lati mase kopa ninu rẹ.
Ìlú náà kò nílò ìmọ́lẹ̀ oòrùn tabi ti òṣùpá, nítorí pé ògo Ọlọrun ni ó ń tan ìmọ́lẹ̀ sí i; Ọ̀dọ́ Aguntan ni àtùpà ibẹ̀.
"Máṣe jẹ́ kí ibà Lassa pa ọ́, wo ọ̀nà láti dènà rẹ̀ ""Ẹ́ sinmi àìmọ̀kan, àìsàn òtútù àyà kò ní nǹkan ṣe pẹ̀lú òtútù"" ‘Wo ohun tó yẹ kóo mọ̀ nípa àrùn onígbá-méjì’ Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí 3 sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 2:23 Fídíò, Water Generator: Ó leè ṣiṣẹ fún wákàtí mẹfà, kó tó sinmi, Duration 2,2310 Òkùdu 2020 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn."
Abọ iwadi ti oluyẹ́we owo wo agba gbe wa siwaju igbimọ ile lo sisọ loju rẹ pe miliọnu mẹrindinlọgọfa Naira (₦116m), ni ileeṣẹ to n mojuto epo rọbi na lati fi ra bairo, iwe ati ohun elo itẹwe laarin ọdun kan.
O wa n beere pe kí ni ìdí ti wọ́n kò fi ti gba Leah Sharibu kalẹ̀ títí di àsìkò yìí?
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ìfẹ́ Yorùbá ló mú mi fi ẹ̀mí wéwu láti kojú ajínigbé ní Kishi - Sunday Igboho Kò bójúmu kí owó epo ní Nàíjíríà dínwó ju ti Saudi lọ - Buhari Wo ìṣẹ̀lẹ̀ márùn-ún tí kò bá pín Nàíjíríà sí yẹ́lẹ-yẹ̀lẹ Bọ́ síta láti ṣe ìwọ́de mọ́ ìjọba Nàìjíríà lónìí, ko rugi oyin - Iléeṣẹ́ ọlọ́pàá Ẹ̀yin ọlọ́pàá 10,000 tí ọ̀gá ọlọ́pàá gbà ṣíṣẹ́ ní 2019, ẹ padà sílé - Iléẹjọ́ pàṣẹ Odeh ninu atejisẹ rẹ soju opo Twitter ni, ki aarẹ ranti pe ko si nkan iwuri kankan ninu ayẹyẹ ominira ọgọta ọdun ti Naijiria.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Abike Dabiri vs Pantami: Èrò ọmọ Nàìjíríà sọ̀tọ̀tọ̀ lórí fàákájáa láàrin Abike Dabiri-Erewa àti mínísítà ètò ìbárẹ̀nisọrọ̀ 25 Èbibi 2020 Oríṣun àwòrán, Twitter/Signal Ọ̀rọ̀ sọ̀tọ̀tọ̀ lọ́dọ̀ àwọn ọmọ Nàìjíríà lórí igbésẹ̀ àwọn òṣìṣẹ́ ìjọba àpapọ̀ méjèèjì ti wọ́n léra síta lórí ayélujára lórí ọ̀rọ̀ tó yẹ kí wọ́n yanjú láì jẹ kí etí míràn gbọ́ síi tí wọ́n tahùn síra wọn lórí àtẹ̀jísẹ́ Twitter Fọ́nrán kan ló kọ́kọ́ jẹ yọ níbi tí ile ișẹ́ ìròyìn Sahara ti ṣe ìfọ̀rọ̀wánilẹ́nuwò lórí bí ilé iṣẹ́ to rí sí ọ̀rọ̀ ilẹ̀ òkèèrè ṣe n sojúṣe wọn àti pé àwọn ìpèníjà wo ni wọ́n n kojú lásìkò yìí Nínú èsì rẹ̀ alága àjọ tó n rí sí ọ̀rọ̀ ilẹ̀ òkèèrè Abike Dabiri-Erewa ṣàlàyé pé mínísítà fún ẹ̀rọ ìbárẹ̀nisọrọ̀, Isa Ali Pantami fi ìbọn le òun àti àwọn òṣìṣẹ́ rẹ̀ síta nínú ọ́fíìsì ìjọba, lásìkò tó n rin ìrìn àjò lọ si ilẹ̀ òkèrè.
Ìwà tí ó dùn mọ́ni ti “playing mas'” àti jíjó sí orin ni wípé ní bákan, àwọn èèyàn máa ń ju ọwọ́ sí òkè, pẹ̀lú ohunkóhun tí wọ́n bá mú ní ọwọ́, títì kan ohun-mímu àti aṣọ inujú.
Ṣùgbọ́n ìbànújẹ́ ni ó jẹ́ fún ni pé onibodè tuntun náà kò pẹ́ ní ibẹ̀ jù bẹ́ẹ̀ lọ, nítorí gẹ́gẹ́ bí ó ti ríní àárin àwọn ènìyàn ni ó rí nì ààrin àwọn ẹbọra, nítorí oníbodè yìí kò lo àwọn ẹ̀dá wọnọnnì ni ìlò ẹrù, tí kò fi wọ́n sí ipò ìwọ̀fà, tí ó pè wọ́n ní ọmọlúwàbí, tí ó sì bẹ̀rẹ̀ sí bá wọn ṣiré, wọ́n fi ọwọ́ pa idà rẹ̀ lójú, nítorí bí ó ti wà ní àárin ènìyàn náà nì ó rí ní ààrin àwọn ẹbọra, àwọn ẹni ìwọ̀sí kan wà lórí ilẹ̀ ayé tí wọn kò jẹ́ lo àǹfààní tí Ọlọ́run Ọba fún wọn,  àwọn wọ̀nyí ni àwọn afooresúniíṣe, bi o bá yẹ́ wọn sí, tí o lò wọ́n bí ènìyàn, dípò kí wọ́n máa fẹ́ ọ tọkànktọkàn, ìwà àrífín ni wọn yóò maa hù sí ọ: àwọn wọ̀nyí dàbí igi ńlá tí ó wó si ojú ọ̀nà mọ́tò, tí kò jẹ́ kí mọ́tò kọjá mọ́, nítorí ẹni tí ó bá bá wọn lò lẹ́ẹ̀kan ṣoṣo, wọn kò ní jẹ́ kí olúwaarẹ̀ fẹ́ẹ́ máa hu ìwà rere sí àwọn tí ń bọ̀ lẹ́hìn mọ́.
George Ayisi to jẹ alukoro ajọ naa ṣalaye pe, oku eniyan mejilelogun ni wọn ti ri bayii ni eyi ti awọn ogoje eeyan dẹ ti di alainile lori.
Arabinrin Moromoke tẹsiwaju pe lati igba ti wahala yii ti bẹrẹ ni ọkọ oun ko ti fi owo silẹ fun ounjẹ tabi itọju ile silẹ mọ.
Se ni wsn n lo isẹlẹ ikọlu ni South Africa lati boju fi sisẹ ibi.
” Jẹtiro dá Mose lóhùn pé, “Máa lọ ní alaafia.
Ó gbé èdè Yorùbá lárugẹ nipa ṣi ṣe iṣẹ́ ìtumọ̀ èdè Gẹ̀ẹ́sì si èdè Yorùbá, ó kọ ìwé itumọ̀ ọ̀rọ̀ nipa li lo orúkọ Yorùbá.
Abiodun Koya: Láti ọmọ ọdún mẹ́ta ni mo ti ń kọrin bi ẹyẹ
 Ó gba àmì ẹ ̀ yẹ Úbádì ní ọdún 1907 láti ọwọ àwọn Ẹgbẹ arin ìrìn àjò aláwárí fún eni àkókó tí ó ṣe àwárí agbègbè Àríwá ìlà oòrùn .
omi naa, nitori awon irinse naa ti won ko tete ri ra.
Asiko ko si fun oun miiran.
Iyabode Ogunsola Iyabode Ogunsola ni ọpọ eeyan mọ si Efunsetan Aniwura, to si jẹ gbajumọ oṣere lobinrin lasiko ti ọkọ rẹ wa laye.
66m lọ gẹ́gẹ́ bi ọkùnrin nígbà ti obinrin gbọdọ jẹ́ 1.
Ni Hagai, òjíṣẹ́ OLUWA, bá jẹ́ iṣẹ́ tí OLUWA rán an sí àwọn eniyan náà pé òun OLUWA ní òun wà pẹlu wọn.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ilé iṣẹ́ ọkọ̀ òfúrufú tuntun 'Nigeria Air' ṣíwọ́ iṣẹ́ Ọmọ Yorùbá ni onímọ̀ ẹ̀rọ ‘Rọ́bọ́tì’ tó ń gbowó jùlọ ní UK Àgbárá òjò bà'lú jẹ́ n'Ípínlẹ̀ Ogun Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, OsunDecides: Adeleke kò jáwọn olólùfẹ́ tó fẹ́ wòran ijó rẹ̀ kulẹ̀ Ṣaaju ipo tuntun yii, Mallam Kyari ni ọga agba fun ẹka to n ri si karakata epo rọbi ni ajọ NNPC.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Sisọ ede Yoruba di ofin nipinlẹ Eko 9 Èrèlè 2018 Oríṣun àwòrán, @AkinwunmiAmbode Gomina ipinle Eko, Ogbeni Akinwunmi Ambọde ti buwọlu ofin to f'agbara fun ede Yoruba gẹgẹbi ede t'awọn ara ilu yoo maa sọ nibi ise ati fun karakata.
Ohun ti awọn eeyan kan n sọ lagbegbe naa ni pe boya oloogbe naa da awọn kan lara awọn ọlọṣa naa mọ ni wọn ṣe pa.
abiye lati fi lee ran awon ti wahala le kuro ni ibugbe won lọwọ ati lati fi lee
Ni ipari, Germany wa ni ipo kinni, Brazil ipo keji ti Portugal si sepo keta lagbaye.
Ibojì wọn ni ilé wọn títí lae,ibẹ̀ ni ibùgbé wọn títí ayérayé,wọn ìbáà tilẹ̀ ní ilẹ̀ ti ara wọn.
'Ìbọn dún láàfin Ọ̀ọ̀ni ilé ifẹ̀ lóòtọ́, ṣùgbọ́n kò séwù' Aláàfin Ọyọ: Ọba tó bá n mú ọtí ní ìta kò yẹ ní ẹni tàá bọ̀wọ̀ fún Yorùbá rẹwà, kọ́ nípa àwọn ọ̀rọ̀ tí ìró ẹnu wọn jọra àmọ́ tí ìtumọ̀ wọn yàtọ̀ Ilẹ̀ ifẹ̀ ní ìran Ìgbò tí ṣẹ wá kìí ṣe ilẹ̀ Juu - Ọọni N kò ni nkan kan sọ lórí fídíò to gba ayélujára kan pé mo ń we igbó, ẹ mú ẹnu kúrò nibẹ - Oluwo Iya-iya Ọọni Ogunwusi, ti ọpọ mọ si 'Mama Agba'nigba aye rẹ ni wọn ṣalaye pe o jẹ gbajums oniṣowo ti wọn bi ni ọdun 1907 si idile Oloye Aina Akinyẹmi ni agboole Ajigbayin ni ilu Ile Ifẹ.
Agunbiade ṣalaye awọn ilana ti o maa n waye ki Gomina to ṣe agbekalẹ abadofin iṣuna-owo ilu ninu
Ọpọ ro tẹlẹ pe orukọ Ronaldo le maa wa lara awọn orukọ agbabọọlu ti wọn yoo kede fun ami ẹyẹ naa nitori iwadi to n lọ lọwọ lori ẹsun ti arabinrin ilẹ Amẹrika kan fi kan an pe o fipa ba oun lo pọ lọdun 2009.
Ṣugbọn Kalebu pa àwọn eniyan náà lẹ́nu mọ́ níwájú Mose, ó ní, “Ẹ jẹ́ kí á lọ nisinsinyii láti gba ilẹ̀ náà, nítorí a lágbára tó láti borí àwọn eniyan náà.
Ọjọ n gun ori ọjọ, osu n gori osu, Adegbọrọ lo ọdun mẹjọ ni sja Oyingbo, to si di gbajumọ nidi isẹ wiwa ọmọlanke.
O tun so pe”Rogbodiyan lori eto ibo maa n je ki  ifaseyin de ba  idagbasoke ijoba tiwa-n-tiwa lorile ede Naijiria ati nile Afirika.
Ni àsikò yi, Bàbá kan wa ti ó ni Iyawo púpọ̀, Oko rẹpẹtẹ, ogún-lọ́gọ̀ ohun ọsin, ọ̀pọ̀lọpọ̀ Ẹrú tàbi Alágbàṣe, Ọmọ púpọ̀, ṣùgbọ́n ninú gbogbo ọmọ wọnyi, ikan ṣoṣo ni ọkùnrin.
    Ìgbà tí ó tilẹ̀ ṣe o ní kí àwọn onílù máa ki òun àwọn bá bẹ̀rẹ̀ wọ́n ni, ‘Wèrédìran, ti ń gbe ilé Òmùgọ̀parapọ̀, Òmùgọ̀parapọ̀, Omùgọ̀parapọ̀, bí ó bá burú tán, ìwọ nìkan ni ó kù, ìwọ nìkan ni ó kù, ìwọ nìkan ní ó kù, Wèrédìran, Wèrédìran, Wèrédìran ọwọ́ epo ni aráyé ń bá ní í la, ọwọ́ epo ni aráyé n ba nii la, ọwọ́ epo ni aráyé níí la, wọn ko n bá ni láwọ́ ẹ̀jẹ̀, wọn ko n bá ni láwọ́ ẹ̀jẹ̀, wọn ko n bá ni láwọ́ ẹ̀jẹ̀ rá rá rá rá rá (ìlù tún sọọ́)
A fẹ ki awọn obinrin mii lọ kọ imọ nipa ofin Sharia Adajọ Shushaidah fi kun un wi pe awọn iyawo mi a maa faramọ ki ọkọ wọn fẹ iyawo keji.
Gẹgẹ bii iroyin ti o tẹ BBC News Yoruba lọwọ ṣe sọ, ni ọjọ aiku ni wọn yoo sin oku Iyalode Ilẹ Ibadan, Aminat Abiọdun ni ilana ẹsin Musulumi Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Papalolo ní ìlépa owó ni ìyàtọ̀ tó wà láàárín àwọn òṣèré tíátà àtijọ́ àti ìsisìnyí Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
 O ni egbe oselu APC nikan lo le mu idagbasoke to monyan lori ba eto ọrọ aje ni ipinle Osun ati lorile ede Naijiria.
 a sọ ni gbogbo india , paapa ni awọn ipinle andhra pradesh , delhi , bihar ati uttar pradesh .
Nígbà tí a jí ní òwúrọ̀ ọjọ́a tí á ń lọ sí ìlú àwọn ejò yìí tí a bẹ̀rẹ̀ sí mu oògùn aporó tí Baba-onírùngbọ̀n fún wa Àgùntàn-ìnàkí wí pé oògùn náà korò jù kò sì bá wa mú un lọ́jọ́ náà.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Arabic on Naira: CBN ní owó gọbọi ní yóò ná Nàíjíríà láti tẹ owó tuntun jáde 10 Bélú 2020 Oríṣun àwòrán, Twitter/Nairametrics Ileẹjọ giga apapọ nilu Eko ti ṣetan lati gbẹjọ lori ẹsun t'agbẹjọro kan gbe wa siwaju rẹ pe, ki ile ifowopamọ apapọ Naijira, CBN, yọ Keu ti wọn kọ si ara Naira kuro.
Kí wọ́n ṣáà tètè dé ibiṣẹ́, kí wọ́n tètè parí iṣẹ́, kí wọ́n sì tètè padà dé’lé ló jẹ wọ́n lógún.
Fẹmi Adebayọ: Òsèré tíátà Yorùbá kò leè gba owó ju òsèré olóyìnbó lọ
Ṣugbọn pẹlu bi ọrọ ṣe ri bayii, adiyẹ balokun lọrọ oye Babalọja gẹneral ni ipinlẹ Ọyọ bayii nitori omi alaafia aarin awọn ọlọja naa ko fẹ gun.
Lẹ́yìn náà, Abidoni ọmọ Hileli ará Piratoni ṣaláìsí, wọ́n sì sin ín sí Piratoni, ní ilẹ̀ Efuraimu, ní agbègbè olókè àwọn ará Amaleki.
Ṣugbọn àwọn mìíràn ń ṣe ẹlẹ́yà; wọ́n ní, “Wọ́n ti mu ọtí yó ni!
Oríṣun àwòrán, @Ps/io/sta Àkọlé àwòrán, Adebayo Faleti Ajayi ni olu ẹda itan to jẹ ọmọ Oloye Olokun Esin.
“ko si ona miiran fun wa ju pe, ki a gbaradi ni kikun sile fun idije boolu agbaye naa to ti n sunmo etile.
Oun lo rọpo Thomas Tuchel to padanu iṣẹ rẹ lọjọ kọkandinlọgbọn oṣu kejila ọdun 2020 lẹyin to ti tukọ ẹgbẹ agbabọọlu naa fun ọdun meji ati aabọ.
"Olukoya to pe ọdun 2020 ni ""ọdun isọji ati ogo tuntun"", rọ awọn ọmọ Naijiria lati gbadura ki ohun gbogbo ma dojuru ni 2020."
"O yẹ kẹ mọ isẹ yin bii isẹ, nitori pe awọn ọlọpaa n hu iwa yii, ko sọ pe ki awa naa se bẹẹ ninu ere tiata wa.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Increased DSTV tariff: MultiChoice ní àfikún owó epo, owó iná pẹ̀lú owó orí VAT ló jẹ́ káwọn fowó kún tàríìfù DSTV 13 Ọ̀wàrà 2020 Oríṣun àwòrán, Twitter/Super Sport Ti ko ba nidi, obinrin kii jẹ ikumolu.
Ogun iphone theft: Ọkùnrin kan dèrò ẹ̀wọ̀n lẹ́yìn tó jí ẹ̀rọ ìbáraẹnsọ̀rọ̀ tí iye owó rẹ̀ tó ₦950,000
O wa ro awon omo orile ede Naijiria ki won tubo maa je asoju rere nipa bibowo fun ofin orile ede ti koowa won n gbe, ki won si maa sedajo lati owo ara won.
Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
“Iyọ̀ níí sọ ẹbọ di mímọ́, bẹ́ẹ̀ gan-an ni ó jẹ́ pé iná ni a óo fi sọ gbogbo eniyan di mímọ́.
Ta ló tó kò ó lójú?
Awọn eeyan naa, El Shafee Elsheikh ati Alexanda Kotey, ni wọn fi ẹsun kan pe wọn darapọ mọ ẹgbẹ egbesumọmi IS, ti wọn si n ṣeku pa awọn eeyan ni Syria.
Amọ ibinu lọna ti ko dara le ba nkan jẹ, o si lee fa ogun jija, ti awọn agbaagba ni orilẹede kan ba binu sodi lai fi ti awọn ara ilu se.
Kódà gbọingbọin la wà lẹ́yìn Akintoye gẹ́gẹ́ bíi adarí YWC nílé, lẹ́yìn odi Àwọn ìjọba ìpínlẹ̀ kéde ìwọlé fásitì, ASUU àti ìjọba àpapọ̀ ní kí wọ́n ṣọ́ra!
Ọmọ Ààrẹ lẹ́tọ̀ọ́ láti ṣe ìgbéyàwó yálà àwọn ará ìlú fẹ́ràn ìjọba bàbá rẹ̀ tàbí bẹ́ẹ̀ kọ́ - Aisha Buhari Ọkùnrin tí wọ́n fẹ̀sùn kàn pé ó jí ǹkan nílé ìjọsìn rí ẹ̀wọ̀n he!
2023 Presidency: Adelé alága APC l'Eko ní àdéhùn wà láàrín Buhari àti Tinubu lórí ìdíje ipò ààrẹ lọ́dún 2023
Gbogbo ìlú wọn tí wọ́n rí ni wọ́n sì sun níná.
Ni Ọjọbọ, ọsẹ to kọja ni Baba Obasanjo sọ wipe orilẹede Naijiria ti n lọ sokun igbagbe nitori oun gbogbo ti n dẹnukọlẹ lasiko iṣejọba Aarẹ Muhammadu Buhari.
Ẹ óo mú burẹdi meji tí wọ́n fi ìdámárùn-ún ìwọ̀n efa ìyẹ̀fun kíkúnná dáradára ṣe wá fún ẹbọ fífì; àwọn àkàrà náà yóo ní ìwúkàrà ninu, ẹ óo mú wọn tọ OLUWA wá gẹ́gẹ́ bí àkọ́so oko yín.
Awọn Agbẹjọro fun ọkunrin naa ni ile isẹ ipoogun naa ko mu ilera awọn eniyan ni ọkunkundun, amọ wọn n lepa ere ti wọn yoo jẹ lori oogun naa.
Ìwádìí ìjìnlẹ̀ ni ó ti bẹ̀rẹ̀ báyìí láti rí kíló lè fa kí ọkùnrin apààyàn náà kọjú ìbọn sí àwọn ọmọdé tí wọ́n kéré báyìí.
Oríṣun àwòrán, Ajimobi lives on Bello ni ọpọ awọn fọnran aworan ti Ajimobi ti sọrọ silẹ nigba aye rẹ fihan pe, oloogbe naa kii se eeyan lasan, wolii Ọlọrun ni."
A padà san owó ìtanràn fáwọn ajínigbé kí wọ́n to fi àwọn mẹ́tẹ̀ẹ̀ta sílẹ̀- Ẹbí Spaghetti, mílíìkì, Chivita àti Àǹkàrá sọ Rabiu dèrò ẹ̀wọn ni Eko Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Domestic Violence: Ìjà láàrin lọkọlaya sọ aya dèrò ọ̀run Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Dájúdájú, yóo jà fún wọn, kí ó lè fún ayé ní ìsinmi, ṣugbọn kí ìdààmú lè bá àwọn ará Babiloni.
A si pinnu lati fi ọrọ naa to awọn ọlọpa leti.
O gbọ̀dọ ni èrò okoòwò ti o ṣee kówó lé lóró, ti o ṣe fòye gbé ti ó sì ṣee ṣe.
”Jese dáhùn, ó ní, “Ó ku èyí tí ó kéré jù, ṣugbọn ó ń tọ́jú agbo ẹran.
Wọ́n to ẹgba sí mi lẹ́yìn,gbogbo ẹ̀yìn mi lé bíi poro oko.
Ẹ mú un wá sí ilẹ̀ yín ẹ fá irun orí rẹ̀, kí ẹ sì gé èékánná ọwọ́ rẹ̀.
Wọn gbe Bode Thomas lọ silu Ijẹbu Igbo fun itọju, sugbọn nibẹ lo ti tẹri gbasọ lọjọ Kẹtalelogun, osu Kọkanla, ọdun 1953 Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Bakare Mubarak: ọ̀pọ̀ èèyàn ló máa ń fẹ́ dúró sí ẹgbẹ́ mí tójú si máa n tì mí Bode Thomas fẹ iyawo, ti orukọ rẹ n jẹ Lucretia Sobola Odunsi, to si bi ọpọ ọmọ.
Mo wí fún wọn pé kòsí oúnjẹ kankan nílẹ̀ wọn tó láta to tiwa.
N óo rán ogun tẹ̀lé wọn, títí n óo fi pa wọ́n tán.
Oríṣun àwòrán, Diane Reeve Mo sọ fun ọkan lara awọn obinrin naa to ni aarun yii, o si sọ fun mi pe nise ni Philippe pariwo mọ oun nigba to n bi i pe o fun oun ni aarun HIV.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Kurunmi: Akọni Ààrẹ Ọ̀nà Kakanfo tó pàdánù ọmọ márùn-ún to bí sínú ogun Ìjàyè 27 Ìgbé 2020 Oríṣun àwòrán, Other Ní ayé àtijọ́, onírúurú ogún lo tí wáyé láàárín ẹ̀yà Yoruba sì àwọn ẹ̀yà miran àti ní àárín ara wọn pẹlu.
Gomina ipinlẹ Ọyọ, Seyi Makinde ti ni, ijọba oun yoo lo awọn ọba alaye ni agbeegbe kọọkan lati mu ibugbooro ba eto aabo ni ipinlẹ naa.
O sọ fun iya wọn pe, ko pa odidi ẹran kan, ko si ko gbogbo ifun ati ẹjẹ rẹ fi ṣe etutu, ko si gbe e lọ si orita awọn ẹlẹyẹ, ti ko ba fẹ ki ọmọ kẹta naa o ku.
Gbogbo àwọn nǹkan yòókù tí Jehoramu ṣe ni a kọ sinu Ìwé Ìtàn Àwọn Ọba Juda.
Wọ́n ń jẹ àjẹrun lósì,sibẹ wọn kò yó,àwọn eniyan sì ń pa ara wọn jẹ.
Àwọn eniyan Juda sì fi òróró yan Jehoahasi ọmọ rẹ̀ ní ọba.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ọmọ onílẹ̀ wọ gàù, ó kó sí gbaga ọlọ́pàá Ayinla Ọmọwura, orin èébú àti oríyìn lo fi di ọ̀rẹ́ àwọ̀n obìnrin Wo àwòrán ńkan tó ń ṣẹlẹ̀ ní ìpádé ìran Yorùbá ní Ibadan báyìí Àǹfàní wà láti fí ìwé ìrìnnà ránṣẹ́ ṣùgbọ́n àwọn èèyàn kò lòó ni -NIS Alhaji Ọlajide tun salaye pe awọn ọmọ ẹgbẹ ọlọkọ ero ko fa ijangbọn kankan lẹsẹ, tawọn si n gba alaafia laaye lai naani pe ijọba fi ofin de wọn, to si tun fi ọwọ sọya pe alaafia ipinlẹ Ọyọ ko ni yinjẹ.
" Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Tomomewo Favour: olóṣèlú kìí ṣe ọ̀daràn tàbí alágbèrè Pasitọ yii ni: Ọ̀pọ̀ ẹ̀mi ló n rìn kiri ti yóò ma tan àwọn ènìyàn jẹ ká ti ènìyàn kò bá kíyèsára gẹ́gẹ́ bi irú èyí"" Ononogbu tún tẹnpẹlẹ mọ́ọ pé bi asọtẹ́lẹ̀ nípa Super Falcons tilẹ kùna òun túbọ dúro lóri ipò ti France yóò kangun sí Ó rọ àwọn ọmọ Nàìjíríà láti ma dá oun lẹ́jọ nitori ọ̀rọ̀ yìí nítori pé òun ti sọ asọtẹ́lẹ̀ mẹ́jọ ọtọ̀ọ̀tọ tó ti jási òòtọ́."
Oríṣun àwòrán, Twitter/@nigeria customs Àkọlé àwòrán, Awọn oṣiṣẹ aṣọbode n ṣafihan awọn ounjẹ ati nkan mii ti wọn gba lọwọ awọn onifayawọ Ohun ti Aarẹ Muhammadu Buhari sọ lọsẹ to kọja ni pe awọn orilẹ-ede to paala pẹlu Naijiria ti ni òye nkan ti igbesẹ titi ẹnu ibode pa da le lori.
 Ó díje sípò Ààrẹ orílẹ ̀ -èdè nàìjíríà ní ọdún 1993 , òun náà sì ni gbogbo ènìyàn gbàgbọ ́ tí wọ ́ n sì fẹnukò sí jákè-jádò orílẹ-èdè nàìjíríà wípé ó jáwé olúborí nígbà tí olóri ìjọba ológun ìgbà náà ibrahim babangida kò kéde rẹ ̀ gẹ ́ gẹ ́ bí olúborí ètò ìdìbò náà tí ó sì fi ẹ ̀ sùn àìṣòtítọ ́ àti àìṣòdodo ètò ìdìbò yàn náà .
Àárọ̀ ni òkùnkùn biribiri jẹ́ fún gbogbo wọn,ọ̀rẹ́ wọn ni òkùnkùn biribiri tí ó bani lẹ́rù.
Ikú Barakat Bello ní Akinyele kó oríire bá mọ̀lẹ́bí rẹ̀ Ìpolongo ìbò Obaseki mú làásìgbò lọ́wọ́ láàfin Ọba Benin, èèyàn mẹ́wàá farapa Wo àwọn nǹkan tí o kò mọ̀ nípa 'Church of Satan' Lizzy Anjọnrin fẹ̀si fáwọn agbọ́yì-sọ̀yí lórí ìgbéyàwó rẹ̀, Madam Sajẹ dasójú ilé iṣẹ́, àti àwọn ǹkan míràn tó ṣẹlẹ̀ lágbo tíátà lọ́sẹ̀ yìí Oríṣun àwòrán, Twitter/ Barr Bisi Adegbuyi Kí ló dé tí wọ́n ṣe fi owó kún NIPOST?
Ṣugbọn ní tèmi, n óo máa wo ojú OLUWA, n óo dúró de Ọlọrun ìgbàlà mi; Ọlọrun mi yóo sì gbọ́ tèmi.
Ahasaya sì kú gẹ́gẹ́ bí ọ̀rọ̀ OLUWA tí Elija sọ.
Awọn oluwọde naa, laarọ ọjọ Aje, si ni wọn n kọ oniruuru orin to n tabuku ijọba Buhari.
January 20, 2017 Pẹlu bi ijọba ṣe kọ lati tẹle aṣẹ náà, ile ẹjọ giga sọ pe Ọga agba Ọlọ́paa, Ibrahim Idris, Adajọ agba Naijiria tẹlẹ ri, Abubakar Malami ati adari agba ajọ DSS, Lawal Daura ni yoo jẹbi ẹsun yii ti wọn yoo si fi ẹwọn gbara bi wọ ba tẹsiwaju lati maa kọ si ile ẹjọ lẹnu ọjọ keji oṣu kejila ọdun 2016.
O ṣeeṣe ko jẹ pe eniyan perete ni yoo le ri abẹrẹ ajẹsara yii gba ninu ọdun yii.
ASUU Strike: Òtítọ́ wo ló wà nínú pé ASUU tún fẹ́ yanṣẹ́lódì?
Sugbọn eyi ko rii bẹẹ rara taa ba n sọrọ awọn osere ori itage.
Èdè àìyedè láàrin Seyi Makinde àtàwọn aṣòfin yanjú, àbá ọdún 2021 dòhun O jẹ ko di mimọ pe wọn ko lee sọ awọn ajinigbe naa di alailagbara patpapata toripe ṣe ni wọn n fi awọn akẹkọọ daabo bo ara wọn awọn ko si fẹ pa awọn ọmọ na lara.
 Ẹgbẹ ́ òṣèlú náà ló dá lórí ipò aṣáájú ológbèé Ọbáfẹ ́ mi awólọ ́ wọ ̀ , ẹni tí ó ti fìgbà kan jẹ ́ ìlú-mọ ̀ ọ ́ ka olóṣèlú ilẹ ̀ nàìjíríà tí ó sì ti dípò ìṣèjọba mú rí lásìkò rẹ ̀ .
kí ó tó já Gómìnà mẹ́rin yóò jẹ́jọ́ lẹ́yìn sáà wọn - EFCC Abẹ̀sẹ́kù bí òjò wọ gàù lẹ́yìn tó fẹnu ko ''Jennifer'' lẹ́nu Ẹwẹ, ẹlẹsẹ-ayo fun ikọ Liverpool Mohamed Salah kuna lati gba bọọlu sawọn ninu ifẹsẹwọnsẹ meje to gba sẹyin.
Ọrọ Ruga ti ijọba si fi sọri aagọ to fẹ da silẹ fawọn darandaran yii, jẹ ọrọ kan ninu ede Fulani, eyi to tumọ si aaye tabi ibudo fawọn darandaran.
Ẹ má ṣe kanra mọ́ wọn.
Pẹlu ipá sì ni olukuluku fi ń wọ̀ ọ́.
    Ẹwadapọ dára ni ọmo, ẹ̀gàn ló kù.
Ọga rẹ, Temidayo Adeleke, ṣẹṣẹ de pada sorilẹ-ede Naijiria ni lati ilẹ okeere to ti lọ kawe, to si n mura silẹ fun igbeyawo rẹ lasiko ti ọmọ ọdọ rẹ pa a.
 Oríṣun àwòrán, others Elebuibon ni Ọjọbọ ni awọn ma n ṣe ipade ni aago mejila ọsan si lawọn ma n bẹrẹ ipade Nibi ipade naa, a ma n gba awọn adura to gbona gidigidi.
Kí ó pa akọ mààlúù náà níbẹ̀, kí àwọn ọmọ Aaroni, alufaa, gbé ẹ̀jẹ̀ rẹ̀ wá siwaju OLUWA, kí wọn da ẹ̀jẹ̀ náà yíká ara pẹpẹ tí ó wà ní ẹnu ọ̀nà Àgọ́ Àjọ.
Sanyeri ni ọdun mẹta ṣe, ki oun to kuro lọdọ ọga oun, tí oju oun si ri mabo nigba ti oun ati Kamilu de Eko, ọdọ ẹgbọn Kamilu Compo si ni awọn n gbe.
"Ààrùn Coronavirus ti wọ Nàìjíríà Ẹ jókòó sí ilẹ̀ yín gbogbo ẹ̀yín tó fẹ́ lọ sí Mecca Igbákejì mínísíta fún ìlera ní Iran ti kó Coronavirus Ìjọba fi páńpẹ́ ọba mú àwọn àkàndá tó fẹ̀họ́nú hàn ní Eko Atẹjade kan lati ọdọ minisita feto ilera, Dokita Osagie Ehanire, eyi tawọn ileeṣẹ iroyin abẹle gbe sita ṣalaye pe, ""Ọmọ orilẹede Italy kan to n ṣiṣẹ lorilẹede Naijiria lo ko aarun naa wọle nigba to pada de si Naijiria lati ilu Milan ni ọjọ karundinlọgbọn oṣu keji ọdun."
Èyi tùmọ́ si pé, ìṣòro yi á ré kọjá bi enia bá lè rọ́jú.
iPhone 12 tuntun yii yoo ni oju gilaasi fifẹ ti yoo ju ti tẹlẹ lọ.
Lọ́sàn-án gangan ijọ́sí, nígbà ti mo jẹun ẹ̀ẹ̀kejì tán, mo kúrò ní ilé mi, mo bọ́ si ẹ̀yìn odi, mo gun orí àpáta ńlá kan lọ; nígbà ti mo si dé òkè lọ́hùn-ún tán, mo bọ́ sí abẹ́ igi kan tí ó hù sí orí àpáta, mo jókòó mo lé góngó; bẹ́ẹ̀ ni òòrùn náà mú gidigidi, ara ọmọ aráyé gbóná bí ìkòkò èlùbọ́, òógùn bo ara gbogbo ènìyàn, àfi bí ẹni pé wọ́n bu pmi sí ara ni.
Àwọn akọni Nàìjíríà padà sílé pẹ̀lú àmì ẹ̀yẹ 121 láti Morocco Dino, Wada àti àwọn olùdíje 11 míràn n dù àsíá PDP fún gómìnà ìpínlẹ̀ Kogi Wike kìí ṣe dọ́là tí Ganduje leè kó sápò- Agbẹ́nuso ìjọba ìpínlẹ Rivers Kìí ṣe gbájúẹ̀ nìkan lọmọ Nàìjá ń ṣe lókè òkun!
Halifu ni ede larubawa tumọ si ẹgbẹrun kan, olukọ to si duro bii eeyan ẹgbẹrun kan ni wọn n pe ni Alfa.
Dokita oṣiṣẹ ijọba ipinlẹ ti a pe sọ pe tori gbogbo nkan ni koko ti awọn dokita fi maa n sa lọ soke okun latori owo oṣu titi dori gbogbo owo ajẹmọnu to yẹ ki wọn maa san fun wọn.
Ará, ẹ̀yin fúnra yín mọ̀ pé wíwá tí a wá sọ́dọ̀ yín kì í ṣe lásán.
Sinimá àwòdamiẹnu, Ẹ̀fáńjẹ́líìsì jìyà àjẹmumi nílé aṣẹ́wó l'Ejigbo ní ìlú Eko Ìjàmbá ọkọ̀ tó ṣẹlẹ̀ sí Adams Oshiomole kìí ṣe ojú lásan, àwọn kan ló fẹ́ pa á- APC Ọba Saudi Arabia yọ ọmọ rẹ̀ àti àbúrò rẹ̀ kúrò nípò nítorí ìwà àjẹbánu lórí owó tó yẹ fún ààbò ìlú Èèyàn 239 míràn ṣẹ̀ṣẹ̀ kó COVID-19 ní Nàìjíríà Ibeere yii mu ki Fani Kayode gbana jẹ, to si bẹrẹ si ni sọrọ kubakungbe si akọroyin ileeṣẹ Daily Trust to bere ibeere naa lọwọ rẹ.
Àwọn ìṣẹ̀lẹ̀ kàyéfì àti mánigbàgbé tó wáyé lásìkò ìpolongo ìbò #NigeriaDecides 'Kò s'ówó oṣù, kò s'íbò ni 2019'-JOHESU Ṣé ìgbé ayé rẹ dára ju bó ṣe wà lọdún mẹ́rin sẹ́yìn?
"O kọ akọle tirẹ pe ""bi a ba wa papọ, a ni okun""."
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, FUTA: Àwọn mẹ́jọ ló ṣíná ìyà fún Bolu ní FUTA Wọn fi ẹsun ipaniyan kan Austine ati ẹsun ole jija lọna mẹta.
Jakọbu bá sọ fún gbogbo àwọn ará ilé rẹ̀ ati àwọn alábàágbé rẹ̀, pé, “Ẹ kó gbogbo ère oriṣa tí ń bẹ lọ́dọ̀ yín dànù, kí ẹ ya ara yín sí mímọ́, kí ẹ sì pààrọ̀ aṣọ yín.
Àwọn ìràwọ̀ yóo máa já bọ́ láti ojú ọ̀run, a óo wá mi gbogbo àwọn ogun ọ̀run.
Naira Marley ti tèṣù mọ́lẹ̀ nílé ẹjọ́ májísíréètì lórí ẹ̀sùn ìjọ́kọ̀gbé Aláàfin Ọyọ: Ọba tó bá n mú ọtí ní ìta kò yẹ ní ẹni tàá bọ̀wọ̀ fún Àwọn omidan Naijiria ni wọ́n fi ń ṣerú ní Lebanon- Ọmọlọla Bí ìtàn ayé Toyosi Arigbabuwo ṣe lọ rèé láti ẹnu Musiliu Dasofunjo àti Ogun Majek Rogbodiyan yii lo jẹ ki olootu ijọba Naijiria nigba naa, Sir Abubakar Tafawa Balewa kede ko nile o gbele nilẹ Yoruba.
 Ẹ jẹ ́ kí á ṣe àkíyèsí àwọn nǹkan wọ ̀ nyí tí wọ ́ n mẹ ́ nu bà ní orí yìí .
Èmi tí ìwọ ń wó yìí jẹ́ apá kan ènìyàn àti apá kan iwin.
 Awon eniyan ti won feran lati maa jeun lale tabi loru je ohun to ku die kaa to.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Kò sí oúnjẹ Nàìjá tí a ò sè ní Kenya' Ṣugbọn awọn kan gbagbọ pe awọn ounjẹ pẹẹpẹpẹ naa jẹ ọna lati ṣọ owo na, tabi ṣe nkan to yatọ si ti atijọ.
" Komla jẹ oniroyin to moye to si mohun ohun to n ṣe, botilẹ jẹ pe apaṣẹ waa ni, sibẹ o jẹ alaanu, ati ẹni to maa n ru ọmọlakeji soke.
Láìjẹ́ pé wọ́n rí ohunkohun tí ó fi jẹ̀bi ikú, wọ́n ní kí Pilatu pa á.
Ewe, ninu oro okan lara awon olukopa naa, Kenny Aliu pe, idokowo ni ipinle naa yoo pese ise lopo yanturu, ni paapaa julo, awon ti ko nise lowo.
7 6501 Orilẹede Somalia 121 0.
Ó kó gbogbo wọn wá fún OLUWA, ó là wọ́n sí meji meji, ó sì tẹ́ wọn sí ẹ̀gbẹ́ ara wọn lọ, ṣugbọn kò la àdàbà ati ẹyẹlé náà.
Gbogbo agbaye lo si ti n gbe igbesẹ lori ọna ti yoo fi pari lọdọ wọn.
 Ọba a máa dájọ ́ ikú .
Oríṣun àwòrán, AFP Àkọlé àwòrán, Ni Nairobi bakan náà a rí ọmọdékúnrin yiìí ni bi tí ó fi gbogbo ọkan gbàdúrà ní pápá yídi Oríṣun àwòrán, AFP Àkọlé àwòrán, O ní dá ounjẹ jẹ"" èyí jẹ ohun ti wọn kọ si àra apoti ounjé ní ]ilú Cairo ní ọjọ jimọ sáájú aṣekaágbá Liigi Uefa."
Itele-Ijebu ni Old-gate ni iṣẹlẹ naa ti ṣẹlẹ ni Ọjọru.
    Nígbà tí ilẹ̀ ọjọ́ kejì mọ́ tí a jẹun a lọ sí ilé ọba.
Ṣugbọn lóòótọ́ ni, Ọlọrun fi àwọn ẹ̀yà ara kọ̀ọ̀kan sí ipò wọn bí ó ti wù ú.
“Ẹ gé irun orí yín dànù,ẹ lọ sọkún tẹ̀dùntẹ̀dùn lórí òkè,nítorí OLUWA ti kọ ìran yín sílẹ̀,ó ti fi ibinu ta ìran yín nù.
Nítorí náà, mú akọ mààlúù meje ati àgbò meje lọ sí ọ̀dọ̀ Jobu kí o rú ẹbọ sísun fún ara rẹ; Jobu iranṣẹ mi yóo sì gbadura fún ọ, n óo gbọ́ adura rẹ̀, n kò sì ní ṣe sí ọ gẹ́gẹ́ bí ìwà òmùgọ̀ rẹ.
idibo yoo ti waye , ni eyi ti awon ti ko awon agbofinro lọ sibẹ.
À ń táràrà lára ògiri bí afọ́jú,à ń táràrà bí ẹni tí kò lójú.
Àwọn ọ̀tá kó gbogbo ẹrù ati oúnjẹ àwọn ará Sodomu ati Gomora, wọ́n bá tiwọn lọ.
Àwọn tí ń jẹ eniyan mi bí ẹni jẹun,àwọn tí kì í ké pe OLUWA.
Mo ṣakiyesi pe kii ṣe ẹrọ ibaraẹnisọrọ ile rẹ lo fi pe mi, eyi si mu ki ara fu mi.
Jesu bá fi okùn kan ṣe ẹgba, ó bẹ̀rẹ̀ sí lé gbogbo wọn jáde kúrò ninu àgbàlá Ilé Ìrúbọ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Nigeria Independence Day: Wo ohun tó ṣẹlẹ̀ níbi ayẹyẹ àyájọ́ ọdún òmìnira ní ìpínlẹ̀ Oyo 1 Ọ̀wàrà 2019 Àwọn èèkàn ìpínlẹ̀ Oyo ṣàjọyọ̀ ọdún òmìnira ìkọkàndínlọ́gọta Naijiria pẹlu àwọn ènìyan rẹ.
 Bakan naa ni mo tun bẹ ijọba lati ro awọn ọdọ lagbara sii, nitori ọwọ to ba dilẹ ni eṣu n bẹ lọwẹ”.
won ti  bura fun aare Muhammadu Buhari bayi gege bi aare orile ede Naijiria fun saa keji fun odun merin.
Nígbà tí ilẹ̀ ṣú, àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ wà ninu ọkọ̀ ní ààrin òkun, òun nìkan ni ó kù lórí ilẹ̀.
Wo àwọn èèkàn, ìlúmọ̀ọ́ka olórin tó ṣàbẹ̀wò sí ijọ Celestial Church ti Genesis Global Tí mi ò bá fẹ́ ìyàwó mi, n ó tí di àgbégbìn- Ayodele Fayose Wo bi wọ́n ṣe n ṣe àmójútó ilé ìjọsìn Prophet Israel Oladele, CCC Genesis Global Ẹ jọwọ, ẹ ba mi bẹ ìyàwó mi kí ìgbéyàwó mi ma baà túká - 9ice A kò tíì lè sọ pé ọmọ Ọba tuntun ni yóò jẹ Ooni lọ́jọ́ iwájú - Elebuibọn Èyí ni bí wọ́n ṣe pín fásitì LAUTECH láàrín ìpínlẹ̀ Oyo àti Osun Ọkùnrin tó pe ìyàwó rẹ̀ lájẹ̀ẹ́ tì í mọ́lé fọ́dún mẹ́rin, fún un lóyún nígbà mẹ́ta!
Ṣugbọn èmi ó kọrin ìyìn agbára rẹ;n óo kọrin sókè lówùúrọ̀, nípa ìfẹ́ rẹ tíkì í yẹ̀.
Adajọ to dari igbẹjọ naa, Nicholas Owibo ni lati sun igbẹjọ rẹ siwaju di ọjọ ikọkanla ati ikejila oṣu ikejila ọdun 2019 tori aawọ to waye laarin agbẹjọro.
Ààrùn Coronavirus rápálá wọ ilẹ̀ olóoru Áfíríkà Kí ni ìjọba ń ṣe lórí ààrùn Coronavirus tó wọ Nàìjíríà?
OLUWA bá dá àkókò kan, ó ní, “Ní ọ̀la ni èmi OLUWA, yóo ṣe ohun tí mo wí yìí ní ilẹ̀ Ijipti.
“Ajo INEC nikan ko lee dawọ ibo rira duro.
Bo tilẹ jẹ pe ko ni owo naa lọwọ, o ni Ọlọrun pese owo ọhun lọna iyanu.
Ewé li lo fún pi pọ́n àwọn oúnjẹ kò léwu rárá bi ọ̀rá igbàlódé.
Ẹ̀ṣẹ̀ àwọn wolii rẹ̀ ló fa èyí,ati àìdára àwọn alufaa rẹ̀,tí wọ́n pa olódodo láàrin ìlú.
Aago mẹ́fà àbọ̀ ìrọ̀lẹ́ ni mo ya àwòrán yìí lónìí, àmọ́ ẹ wo bí oòrùn ti mún.
Obinrin Akansẹ: Ẹsẹ kiku bi ojo kọ mi lati di alagbara
Ẹni ti ko wọle si ile ẹkọ giga lọdun yii, ti o ba di ọdun to n bọ yoo wọle'' #Segun lori ayelujara #Segun ti gbode loju ayelujara Twitter ti awọn iriwisi ọtọọtọ si ti n ba iṣẹlẹ yii wa.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Osun: Àwọn ọ̀daràn tó ń d'àlú Ikire rú wọ gàù Ọlọ́pàá 27 Òkùdu 2019 Oríṣun àwòrán, Oodua Peoples Congress Àkọlé àwòrán, OPC Adari ẹgbẹ Oodua Peoples Congress ni ipinlẹ Osun ṣalaye bi awọn eeyan wọn ni ilu Ikire ṣe koju igara ọdaran mẹrin kan to n damuu awọn olugbe ilu naa atawọn arinrinajo opopona Ife si Ibadan.
Oríṣun àwòrán, Ayodele Fayose/Facebook Àkọlé àwòrán, Ayọdele Fayoṣe ti máa ń tako ìjọba Ààrẹ Muhammadu Buhari Ni ọdun 2016 ni àjọ EFCC gbẹ́sẹ̀ lé àṣùwọ̀n ìfówópamọ́sí Gómìnà ìpínlẹ̀ Èkìtì, Ayọ̀délé Fáyóṣe.
Di ekinni mú ṣinṣin, má sì jẹ́ kí ekeji bọ́ lọ́wọ́ rẹ; nítorí ẹni tí ó bá bẹ̀rù Ọlọrun yóo ní ìlọsíwájú.
Atúnṣe ti wọ́n ṣe si òfin orílẹ̀-èdè náà fún ààrẹ Faure Gnassingbé wà lórí oye titi di ọdun 2030, èyí ti ó túmọ sí pé tó ba di àsìkò náà ìdíle Gnassingbé ti wà ní ìjọba fún ọdún mẹ́tà lé láàdọ́ta.
Ẹ pa gbogbo akọ mààlúù rẹ̀,ẹ fà wọ́n lọ sí ibi tí wọ́n ti ń pa ẹran.
#7000 sí #10000 ni owó àbẹ̀tẹ́lẹ̀ fún bẹẹdi ní ilé àwọn aláìsàn ọpọlọ Máṣe jẹ́ kí ibà Lassa pa ọ́, wo ọ̀nà láti dènà rẹ̀ Yàtọ̀ sí eku gọ́tà tàbí èku inú ilé, kò sí eku téèyàn ò lè jẹ - Òǹtajà Eléwé ọmọ Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Eyi lo faa ti atundi ibo se
Ipo Keji: Ẹka eto ẹkọ Ẹka eto ẹkọ lo ko ida to tobi julọ sikeji ninu eto isuna ọdun 2020 nipinlẹ Ọyọ pẹlu ida mejilelogun ati diẹ, 22.
O sapejuwe aseyori yii gege bi ireti nla fun
Ọrẹ timọ timọ ni olori Memunat ati olori Badirat, ki wọn to wọ aafin Ọyọ, ati lẹyin ti awọn mejeeji di ayaba tan.
Ó tọ́, kí ó bọ̀wọ̀ fún àgbà ọlọ́jọ́ orí
Ẹnu òmùgọ̀ a máa dá ìjà sílẹ̀,ọ̀rọ̀ ẹnu rẹ̀ a sì máa bá a wá pàṣán.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Alaafin: Olori Aanu Adeyemi ṣàlàyé ìdí tó ṣe gẹ́ Oba Lamidi Adeyemi ti ìlú Oyo Bi onirese Alphaeus Taiwo Olunaike, taa mọ si Alajọ Ṣomolu ko ba fin igba mọ, eyi to ti fin silẹ ninu isẹ to yan laayo, tii se ajọ gbigba ko ni parun lailai.
fa orile ede yii fun awon jẹgudu-jẹra oloselu.
" 'Ko si ẹni to ni lati yan ọ' Loju kan naa, Okina pinnu ninu ọkan rẹ lati ṣe ju t'atẹyin wa lọ fun awọn ọmọ naa.
Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Military Bruitality: Sójà obìnrin lù mí lálù bami nílùú Ibadan4 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Adolf Hitler: Kíni ẹ̀yin rántí tàbí mọ̀ nípa Adolf Hitler yìí?
Dokita Igbekele sọ pe SS ko gbudọ daba rara lati fẹ AS.
Ahi, ọmọ Abidieli, ọmọ Guni ni olórí ìdílé baba wọn; 
Nítorí pé ninu gbogbo ìrìn àjò wọn, ìkùukùu OLUWA wà lórí àgọ́ náà lọ́sàn-án, iná sì máa ń jó ninu rẹ̀ lóru ní ìṣojú gbogbo àwọn eniyan Israẹli.
Nígbà tí àwọn tí Dafidi rán dé ibẹ̀, wọ́n jíṣẹ́ fún Nabali, ní orúkọ Dafidi, wọ́n sì dúró.
Bí ènìyàn bá já ewé igi yìí kìí bàjẹ́ láéláé, yóò máa dúdú ni, ojoojumọ ti olúwarẹ̀ bá sì tí lọ sí ibi tí ó fi ewé náà sí, owó góòlò ńlá kan ni yóò máa bá lábẹ́ rẹ̀.
awọn musulumi fun ibẹrẹ aawẹ Ramadan ti ọdun 2019 yii.
Abala karun eto naa leyi to wa sopin yii, ta mọ si Season 5 Lockdown.
Oríṣun àwòrán, BB Naija Ó sàlàyé pé, ọmọ to ṣe e mú yangan ní Erica, tó si lè dúró tí ni lásìkò ìṣòro àti pé, gbogbo nǹkan tó ṣẹlẹ̀ si nínú ilé ẹlẹ́gbọ̀n àgbà, ọ̀pọ̀ wa nítorí Kiddwaya ni.
Ó fi wúrà, aṣọ aláwọ̀ aró, ti elése àlùkò ati aṣọ pupa ati aṣọ funfun onílà tẹ́ẹ́rẹ́tẹ́ẹ́rẹ́ rán efodu.
 Ìnáwó àbàadì pàápàá yóò sì máa gbẹ ́ nú ìgbẹ ́ wo wá láwùjọ wa .
Amọ ara ọtọ ni goolu meji ti Giroud ẹni ọdun mẹtalelọgbọn gba wọle ninu rẹ jẹ.
Nígbà náà ni Ẹ̀mí Mímọ́ wá fún Peteru ní agbára lẹ́kùn-únrẹ́rẹ́, ó bá sọ fún wọn pé, “Ẹ̀yin ìjòyè láàrin àwọn eniyan ati ẹyin àgbààgbà, 
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Muhammadu Buhari: Femi Adesina tọ́ka sáwọn ẹ̀rí pé kìí ṣe ẹ̀dà ààrẹ ló ń darí Nàíjíríà 17 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Oríṣun àwòrán, @MBuhari Kii se ohun tun mọ pe ki asaaju ikọ IPOB, Nnamdi Kanu ati awọn ọmọ Naijiria kan maa pe aarẹ orilẹede yii, Muhammadu Buhari ni ẹda eniyan.
Yar'adua fẹ Hauwa Umar Radda ni iyawo keji lọdun 1992 ti wọn si ni ọmọ meji.
Ọọni kọ́lé fàwọn ọmọ òrukàn ní Ibadan ‘Ọọni pè fún ìfè òtító láàárín àwọn olósèlú’ Ọdún Ọlọ́jọ́ nile Ifẹ bẹ̀rẹ̀ Eto n lọ ni pẹruwu bẹẹni imurasilẹ ti lọ loriṣii fun ọdun Ọlọjọ eleyi ti Ọọ̀ni ti ilé Ifẹ, Ọba Adeyẹye Ogunwusi, Ọjájá kejì yoo ṣe agbatẹru rẹ.
Nítorí pé ìbànújẹ́ ni mo fi ń lo ayé mi;ìmí ẹ̀dùn ni mo sì fi ń lo ọdún kan dé ekeji.
com/XHQIwcy6nB— 🇳🇬 Super Eagles (@NGSuperEagles) June 24, 2018 Tobi Sangotola.
Bẹẹ ba si gbagbe, irufẹ iṣẹlẹ ifipabanilopọ yii ti waye laarin ọsẹ kan sira wọn fun ọmọbìnrin meji miran eyi to n mu ki awọn araalu figbe bọnu.
Buhari, o kò ṣe bẹbẹ kankan láì jẹ́ pé o gba Leah Sharibu náà sílẹ̀"" Wo àwọn nǹkan to tún nílò NIN fún yàtọ̀ fún ìforúkọsílẹ̀ síìmù Ilé aṣòfin àgbà yọ gómìnà nípò, ẹni tó fi owó ìlú rán ọmọ lọ sí Amẹ́ríkà Amẹ́ríkà yarí pé àwọn agbégbọn tó jí akẹ́kọ̀ọ́ 344 gbọ́dọ̀ fojú winá òfin Sanwo-Olu lo sọ ọrọ naa ninu atẹjade kan to wa loju opo ijọba ipinlẹ Eko."
" @Sunnyyon ni ti s pe boti lẹ jẹ pe oun kii ṣe ololufẹ ajọ Hisbah, oun naa ko fẹran àṣà 'Black Friday'.
Ninu oṣu Kẹwaa ni Olori Anu naa fi aafin naa silẹ.
ni ipinle Adamawa, ni ekun ila oorun Ariwa, Audu Madaki so pe awon ti ko awon
Olùfẹ́ mi ní ọgbà àjàrà kanní orí òkè kan tí ilẹ̀ ibẹ̀ lọ́ràá.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Oshiomole: Asaajú, àtẹ̀lé yẹ kó fìmọ̀ sọ̀kan nínú APC 23 Òkùdu 2018 Oríṣun àwòrán, Jubril A.
Ẹnikẹ́ni tí a bá kà ní àkókò ìkànìyàn náà, tí ó bá tó ọmọ ogún ọdún tabi jù bẹ́ẹ̀ lọ, ó gbọdọ̀ san owó náà gẹ́gẹ́ bí ọrẹ fún OLUWA.
Àwọn ọbá aláye ilẹ̀ Yorùbá márùn-ún pẹ̀lú ọ̀pá àṣẹ wọn Wo ohun tí Fashola rí níbi ìṣẹ̀lẹ̀ Lekki Tollgate tó ń fa ariwo lórí ayélujara Èèyàn 229 ló ti wà ní gbaga òfin fún wàhálà tó wáyé l'Eko Buhari kò láànú ọmọ Nàìjíríà lójú - Aisha Yesufu Orukọ awọn meji ti wọn yan yi ni Rinu Oduala ati Majekodunmi Oluwaseun.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù EFCC: Akẹ́kọ̀ọ́ mẹ́rin tó ń kọ́ iṣẹ́ Yahoo l‘Eko lọwọ́ EFCC tẹ̀ 28 Èbibi 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 29 Èbibi 2019 Oríṣun àwòrán, EFCC Ajọ to n gbogun ti iwa ọdaran nidi owona lorilẹede Naijiria, EFCC, ti kede loju opo ikansira ẹni Facebook rẹ pe, ọwọ palaba oludasilẹ ileẹkọ kan ti wọn ti n kọ nipa iwa lilu jibiti lori ayelujara, taa mọ si Yahoo ti segi.
Eyín akọ̀ròyìn fò yọ lásìkò tó n ka ìròyìn lọ́wọ́ lórí tẹlifísàn Ohun mẹ́fà tí ọ̀pọ̀ kò mọ̀ nípa ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ Arsenal àti Machester City Ènìyàn 653 míràn tún kún iye àwọn tó ní COVID-19 ní Nàìjíríà Gina Best to jẹ Iya India Kager ti wọn ni awọn agbofinro ṣeeṣi yinbọn pa ni ọdun 2015 naa ti ke gbajare sita.
Bakan naa ni ti ibo awọn aṣofin.
    Ọkùnrin yìí rọra díde kò fọhùn, nítorí ọ̀rọ̀ ti pa èsì jẹ.
Lẹ́yìn èyí mo tún rí ìran mìíran.
Ìwọ alákọrí yìí, tí o ṣse ikùn bí àpò èkùrọ́.
Wọ́n ní kí eniyan má ṣe jẹ àwọn oríṣìí oúnjẹ kan, bẹ́ẹ̀ sì ni Ọlọrun ni ó dá a pé kí àwọn onigbagbọ ati àwọn tí wọ́n mọ òtítọ́ máa jẹ ẹ́ pẹlu ọpẹ́.
Báyìí ni mo bẹ̀rẹ̀ sí wí, àṣé bí mo ti ń sọ̀rọ̀ nì, ọ̀kan nínú àwọn ọlọ́pàá wọn-ọnnì ń gbọ́ ohun tí mo ń sọ bẹ́ẹ̀ ni ọlọ́pàá yìí jẹ́ ọ̀kan nínú àwọn ìrànńṣẹ́ tí ọmọ ènìyàn máa ń bá pádè ní òde ayé tí wọ́n jẹ́ ọ̀lẹ àti àgbàgebè tí í máa fi òfófó wá ojúrere lọ́dọ̀ ọ̀gá wọn kí onítọ̀hún máa baà rí àṣírí wọn.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Oluwo ní Aso Rock: Ààrẹ gbàléjò Ọọ̀ni, Oluwo, àtàwọn ọba Yorùbá mìí 1 Ògún 2019 Oríṣun àwòrán, emperortelu1 Àkọlé àwòrán, Aarẹ Buhari ati Oluwo ti Iwo Lẹyin ti Oluwo ti ilu Iwo Oba Abdulrasheed Akanbi kọ lẹta si aarẹ Muhammadu Buhari lori ibi ti abo de duro ni Naijiria, aarẹ ti gbalejo Ọọni atawọn ọba alade mii nilẹ Yoruba ati ẹya miiran.
  Leyin ipade wakati merin ti awon adari
Ẹ̀kíní, tí wọ́n bá pèsè ètò-ìtanná to péye ni, àwọn èèyàn ò ní nílò àti máa gbé epo sílé rárá.
Báyìí ni Àrẹ̀mọ Ooni Adeyeye Ogunwusi ṣe wọ ṣọ́ọ̀ṣì fún ìgbà àkọ́kọ́ láti bá bàbá rẹ̀ ṣe ìdúpẹ́ ìwúyè Ọdún mọ́kànlá rèé témi àti ọkọ mi bẹ̀rẹ̀ ìfẹ́ láti ilé ẹ̀kọ́ girama - Bukunmi Oluwasina Kíni ẹ mọ̀ nípa àwọn gbajúgbaja Yollywood?
Má jẹ́ kí ẹ̀rù wọn ó bà ọ́, bí bẹ́ẹ̀ kọ́, n óo dẹ́rù bà ọ́ níwájú wọn.
Amọ sa, Dogara ti wa sẹ lori ahesọ ọrọ kan to n ja ranin-ranin nilẹ pe, oun fẹ du ipo gomina ipinlẹ Bauchi tabi pada sile asoju-sofin, lo mu ki oun pada sinu ẹgbẹ oselu APC.
Wọ́n na ìyẹ́ wọn sókè, ọ̀kọ̀ọ̀kan na ìyẹ́ meji meji kan ìyẹ́ ẹni tí ó kángun sí i, wọ́n sì fi ìyẹ́ meji meji bora.
 akòleè sọ pàtó ibi ti ìkóni ti bẹ ̀ rẹ ̀ , nítorí pé orílẹ ̀ èdè kọ ̀ ọ ̀ kàn àti àkójọpọ ̀ àwọn ènìyàn níbikíbi lóní ìlànà ti wọ ́ n ń gbá kọ ́ àwọn ènìyàn tiwọn .
Lẹ́yìn ìgbà díẹ̀, ní àkókò ìkórè ọkà, Samsoni mú ọmọ ewúrẹ́ kan, ó lọ bẹ iyawo rẹ̀ wò.
Ìkádìí Wọ́n bí Iyiọla Ajani Omisore sí ìdílé ọba ní ọjọ́ kẹẹ̀dógún, oṣù Kẹsàn án, ọdún 1957 ní ìlú Ilé-Ifẹ̀.
Ninu ifọrọwerọ pẹlu BBC Yoruba lori isẹlẹ yii, agbẹnusọ fun gomina ipinlẹ Ọyọ, Ọgbẹni Taiwo Adisa sọ pe lootọ ni ijọba ko ṣẹṣẹ ma a gbọ iru iroyin bẹ ẹ.
Bí nǹkan oṣù rẹ bá dáwọ́ dúró, àwọn ohun tí yóò ṣẹlẹ̀ sí ọ rèé Tọpẹ Alabi to ni oun n kọ ile iwe kan lọwọ fun iṣẹ orin, wa gba awọn eeyan nimọran lati mase lo ẹbun ẹlẹbun, tori o dara ki onikaluku mọ ẹbun ti Ọlọrun ba fun.
Gẹ́gẹ́ bí o ti rán mi sí ayé, bẹ́ẹ̀ ni mo rán wọn lọ sinu ayé.
Omowe Enelamah so pe, won yoo fowo siwe adehun ifenuko naa nilu Kagali lorile-ede Rwanda lojokokanlelogun osu keta odun ti a wa yii, nibi ipade apero ajo-isokan ile Afrika naa.
kò rí bẹ́ẹ̀ fún ipò kékeré, o siṣẹ́ títí o fi dé ipò gíga.
Bi o tilẹ jẹ wi pe agbẹnusọ fun aafin Oodua ko ṣalaye awọn oloye to lọ ni pato, iroyin ti a gbọ fi idi rẹ mulẹ pe alamojuto abo ibilẹ fun Ọọni, Saarun Oodua, Oloye Oriowo Oriyọmi lo lewaju awọn agba oloye Ile Ifẹ bii Akọgun Waasin, Lowaatẹ ati Ẹrẹbẹsẹ lọ ki Arẹmọ tuntun kaabọ sile aye.
 Iku Coulibaly si ni yoo mu ki ominu wa lori eto idibo to n bọ lọna ni orilẹede naa."
Nigba to dele, ni iya ọmọ tuntun ba pe aladugbo rẹ pe ko wa wo ọmọ oun, ko si sọ boya ọkunrin abi obinrin, sugbọn dipo ki aladugbo yii fọhun, n se lo gba Catherine ni imọran lati lọ sile iwosan.
Ninu iwoye rẹ, bi awọn ipenija wọnyii ṣe pọ si lo n ṣe afihan pe awọn akẹkọgboye tuntun lawọn ileewe giga gbọdọ ji giri.
"Ẹkeji, Alaafin gba adura fun mutumuwa pe ""ìkoko ọbẹ"" wọn o ni gbẹ, bẹẹni aka wọn ko ni ṣofo ati pe awọn ọmọ ilẹyii yoo ṣe rere ninu alaafia tii ṣe baalẹ ọrọ."
Vaginismus: Nígbà tí ara rẹ bá kọ ìbálòpọ̀, kí ló ṣẹlẹ̀?
Ó rán ọ̀wọ́ eṣinṣin sí wọn tí ó jẹ wọ́n,ati ọ̀pọ̀lọ́ tí ó pa wọ́n run.
Bo tilẹ jẹ pe ọpọ awọn to lugbadi arun naa lo ri iwaosan gba pada, ṣugbọn ninu wọn lo maa n lo ọpọ ọsẹ ninle iwosan, ti awọn miran si maa n wa ni ẹsẹ kan aye, ẹsẹ kan ọrun.
fun ajo  INEC  , ọjọgbọn Bello Shehun kede abajade esi idibo
" Oríṣun àwòrán, Marta Moreiras Gẹgẹ bi Marta Moreiras ti wi, ọdun 2008 ni ero yii wa si oun lọkan lasiko ti oun n wo ọkan ninu awọn aworan to wa ninu ile oun, to si ya aworan naa, ti wọn ti ya sọtọ fun ami ẹyẹ ayaworan to dantọ ti ileesẹ Sony fẹ se.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Alaafin: Ó wu àwọn ìyàwó mi ni wọ́n fẹ́ mi, èmi kọ́ ni mo dẹnu ìfẹ́ kọ wọ́n 9 Ọ̀pẹ̀̀ 2018 Oríṣun àwòrán, alaafin_oyo/Instagram Alaafin ilu Ọyọ, Ọba Lamidi Adeyẹmi, sọ pe oun ko kọnu ifẹ kọ obinrin kankan ri.
Juda, àwọn arakunrin rẹ yóo máa yìn ọ́,apá rẹ yóo sì ká àwọn ọ̀tá rẹ;àwọn ọmọ baba rẹ yóo máa tẹríba fún ọ.
O fikun-un pe, igbe aye alafia sekoko ninu idagbasoke ilu, besini sise ifilole ofin tuntun lati fayegba didaran nipinle naa ni,  lati mu alafia joba laarin awon agbe ati awon darandaran patapata.
Ilẹ̀ Ẹ̀yà Manase ní Apá Ìwọ̀ Oòrùn.
Wiskid: Oríṣun àwòrán, Instagram/hushpuppi Ilumọọka olorin, Wiskid naa ti ṣe faaji pẹlu Hushpuppi ri, koda awọn mejeeji ti jọ ṣe faaji lori omi ri nilu Dubai.
Ẹni tí ilé rẹ̀ rì sinu ìparun,tí ọ̀nà rẹ̀ sì wà ninu ọ̀fìn isà òkú.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Pius Adesanmi: Awọn ọmọ Nàìjíríà ń ṣelédè lẹ́yìn akọni tó lọ 11 Ẹrẹ̀nà 2019 Oríṣun àwòrán, Adesanmi Àkọlé àwòrán, Pius Adesanmi: Awọn ọmọ Nàìjíríà ń ṣelédè lẹ́yìn akọni Gbógbo ọmọ Nàìjíríà nílé àti lẹ̀yìn odi tó jẹ́ ọ̀rẹ́ àti alábaṣiṣẹ́pọ̀ ọ̀jọ̀gbọ́n Pius Adebola Adesanmi tó jẹ́ Ọlọ́run nípe, lásìkò ti bàálù boeing 737 X8 tó ń lọ si Narobi lọ́jọ́ àikú, ọjọ Kẹ́wàá oṣù Kẹ́ta ọdun 2019 já, lẹ̀yìn ìṣẹ́jú mẹ́fà to gbera.
Oo nifẹ lati maa mu tabi jẹ nkan didun ni gbogbo igba: Ti omi o ba to ni ara, ara ko ni le lo okun to nilo lasiko too nilo rẹ nitori naa yoo maa wa ohun amuṣagbara kiakia eyi ti o le ri ninu ṣuga ati awọn nkan didun miran.
Gbà wá sílẹ̀ nítorí ìfẹ́ rẹ tí kì í yẹ̀.
Awon omo egbe wa ti n sakitiyan lori eto oro aje ni eyi ti won yoo fi maa seto iranwo fun awon to nilo re,nitori naa awon omo egbe wa yoo tubo maa mu ohun iwuri ba ona ti orile ede China yoo se maa da ile-ise sile.
Awọn to wa nibẹ ni, Adebayo Alao Akala ADP, Adebayo Adelabu APC, Olufemi Lanlẹhin ADC ati Bolanle Sarumi Aliyu NIP.
Dafidi yà wọ́n sí mímọ́ fún OLUWA, fún iṣẹ́ ìsìn pẹlu àwọn fadaka ati wúrà tí ó gbà lọ́wọ́ àwọn orílẹ̀-èdè tí ó ti ṣẹgun: àwọn bíi Edomu ati Moabu, Amoni, Filistini ati Amaleki.
Àkọlé àwòrán, Awọn asofin ipinlẹ Ogun naa wa lara awọn ti wọn yoo ma burawọle fun ni Ọjọru Ipinlẹ Kwara: Bi o tilẹ jẹ pe awọn ipinlẹ kan ko mu ayẹyẹ ibura awọn gomina tuntun ni kekere, ti wọn si fẹ ṣe ayẹyẹ ibura naa tilu-tifọn, amọ eyi ko ri bẹẹ rara ni ipinlẹ Kwara.
O sọrọ lori aṣeyọri iṣejọba rẹ akọkọ nigba to jẹ gomina ipinlẹ Ọyọ.
Ọjọ́ mẹ́fà ni mo lò lọ́dọ̀ àwọn Fulani Ajinigbe - Hamzat Òsìsẹ́ Custom tó déédé sọ ara rẹ̀ di Ọ̀gá Àgbà CG ní ìdàmú ọpọlọ - Attah Maleebu ni ki awọn ọmọde ma ṣe ri talẹnti wọn mọlẹ ki wọn gbe ogo ti Olorun fun wọn sita.
 Èdè kankan ló sì ní ìlànà tirẹ ̀ to ń tèlé  ."
Òùngbẹ Ọlọrun ń gbẹ ọkàn mi,àní, òùngbẹ Ọlọrun alààyè.
Ibi tí ó dé bá Lẹbanoni yóo bò yín mọ́lẹ̀; ìparun àwọn ẹranko yóo dẹ́rùbà yín, nítorí ìpànìyàn ati ibi tí ẹ ṣe sí ayé, sí àwọn ìlú ati àwọn tí wọn ń gbé inú wọn.
Ògo Ọlọrun ninu àwọn ohun tí Ó dá.
Alaga ajọ to n ri si awọn ọmọ Naijiria ti wọn wa nilẹ okeere, Abike Dabiri-Erewa lo fidi ọrọ yii mulẹ loju opo Twitter rẹ.
Nítorí pé jíjí ni wọ́n jí mi gbé kúrò ní ilẹ̀ Heberu, ati pé níhìn-ín gan-an, kò sí ẹ̀ṣẹ̀ tí mo ṣẹ̀ tí wọ́n fi gbé mi jù sẹ́wọ̀n yìí.
Gẹgẹ bi iroyin ti il iṣẹ New York Times ati Washignton Post gbe jade, awọn meji yii ni wọn le kuro ni ẹwọn ti awọn ọmọ ogun Kurd n ṣakoso rẹ ni Ariwa orilẹ-ede Syria.
Four Square Church tí ní kí olùkọ́ fásitì Eko, Pasitọ̀ Boniface, lọ fìdímọ́lé.
Ati pe diẹ lara awọn agbegbe tutu to ti ni itankalẹ aarun naa ni abẹle, bi Malaysia ati Democratic Republic of Congo, sunmọ agbedemeji, nitorina o le maa fun wa ni ẹri to daju nípa bi nkan yoo ṣe ri nibo miran.
Nibayii, ọpọ eeyan lo ti kọminu pẹlu ikede ijọba apapọ pe ki awọn ileewe wọle pada lọjọ Aje, ọjọ kejidinlogun oṣu kinni ọdun 2021.
Òun ni Ọlọrun fi ṣe ọgbọ́n wa ati òdodo wa.
Oríṣun àwòrán, @KingTblackhoc/twitter Nigba to fidi iṣẹlẹ naa mulẹ fun BBC Yoruba, Araba ilu Osogbo, to tun jẹ ọkan lara awọn alamojuto ẹsin ibilẹ nilẹ Yoruba, Oloye Ifayemi Elebuibon, sọ pe niṣe ni ọmọkunrin naa fi kele ati ọpẹlẹ kọrun, to si lọ ba awọn obinrin ṣe aṣemọṣe.
Oríṣun àwòrán, @NGRSenate Àkọlé àwòrán, Laipẹ yii ni Godswill Akpabio kuro ninu ẹgbẹ oṣelu PDP, to si lọ darapọ mọ ẹgbẹ oṣelu All Progressives Congress, APC.
Victor Osimhen lo ti n siwaju ẹgbẹ agbabọọlu Super Eagles lati igba ti Ighalo ti fẹyinti.
Emir Ilorin fẹ́ parí ìjà Risikat olójú búlúù àti ọkọ rẹ̀ Wo ọmọ Nàíjíríà tí wọn fi pósí ‘₦34m’ sin Yéèpà, òfin ìtakété síra ẹni forí ṣánpọ́n lásìkò ọdún Osun Osogbo Ẹ fura, iyọ̀ onímájèlé tó dóde ti gbẹ̀mí èèyàn méje!
Awọn to se idanwo WAEC naa ti ko si jẹ WAEC ni owo le ri esi idanwo naa ni oju opo ayelujara ti WAEC : www.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Lagos-Ibadan: Ìjọba àpapọ̀ pàṣẹ pé kí gbogbo ọkọ̀ agbépo kúrò ní òpòpónà márosẹ̀ Eko si Ibadan- Fasola 22 Bélú 2020 Oríṣun àwòrán, @2020pics Babatunde Raji Fasola to jẹ minista fun ọrọ iṣẹ ati ile gbigbe ni Naijiria ati gomina ipinlẹ Ogun, Dapọ Abiodun ni wọn jọ kọwọrin lọ si opopona marosẹ Eko si Ibadan.
Ijoba orile ede Naijiria ti bu
Gbogbo awọn ọlọpaa to ms si iku arakunrin naa ni wọn ti n fi jofin bayii lẹyin ti awọn alalṣẹ ileeṣẹ ọlọpaa nibẹ fi kọkọ tẹti lori fifi wọn jofin.
Akọtun iwadi, eyi ti ile igbimọ asofin agba nilẹ Naijiria gunle, ko sẹyin bi ọwọn gogo epo rọbi se nfojojumọ waye eleyi to ti nmu ara kan awọn araalu.
Ẹjẹ́ ká gbé ìbéèrè méjì yìí 
idunnu re han bi ise se n tesiwaju si, o wa ro awon osise kongila ohun lati tun
Ajọ PANDEF fikun wi pe awọn ẹgbẹ ni Naijiria bi IPOB ati awọn miran to n bere fun ominira ẹya wọn fihan pe ina wa lori orule orilẹede Naijiria.
O ni eyi lo mu ki awọn ọga ọlọpaa ni agbegbe Shasha ati Idimu nipa asẹ kọmisọna, yabo ile igbafẹ naa lati ṣe iwadii lori eto igbaniwọle naa.
Ìgbà tí mi ò kọhùn Ọlọ́run
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Bakare Mubarak: ọ̀pọ̀ èèyàn ló máa ń fẹ́ dúró sí ẹgbẹ́ mí tójú si máa n tì mí Bi awọn miran ṣe n sọ wi pe ko lẹtọ ki wọn ma a lo owo araalu lati fi tọju wọn ti wọn ba ti kurọ ni Ilẹ Gẹẹsi lọ gbe ni orilẹede Canada.
Orile ede Naijiria ti fi ẹ̀gbẹ̀rún lona ẹ̀ẹ́dẹ́gbẹ̀ta
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù ANC pahunpọ pe ki Zuma f'ipo s'ilẹ 13 Èrèlè 2018 Oríṣun àwòrán, AFP Àkọlé àwòrán, ANC kọ'we si aarẹ Jacob Zuma lati kọ'we f'ipo rẹ silẹ Ẹgbẹ oselu to wa lori oye lorilẹede South Africa, ANC ti kọ'we si aarẹ Jacob Zuma lati kọ'we f'ipo rẹ silẹ, awọn oniroyin lo sọ bẹẹ.
 Wọn gbe ipolongo wọn naa lọ si awọn gbagede itaja igbalode ni ipinlẹ Eko lati tubọ la awọn ara ilu loyẹ nipa ewu to wa ninu awọn idọti onike yii.
Oríṣun àwòrán, AFP Àkọlé àwòrán, Abdul Aziz ni ohun ri nnkan ti ounṣe gẹgẹ bi ohun nla Iyawo to sare pada lati doola ọkọ rẹ Hosne Ara gbọ iro ibọn, to si sare lati doola ẹmi awọn obinrin ati awọn ọmọde to wa ni ile ijọsin naa.
Igbesẹ yii mu ki ọpọlọpọ eeyan lorilẹ-ede Naijiria ati loke okun o bẹrẹ si ni kun lori aṣa rin siwaju yọdi-sẹyin ti ijọba yii ti gbe lori awọn iyannisipo awọn eeyan kan lati igba to ti de aleefa.
Ganduje fi ọwọ́ òsì da ìdájọ́ ilé ẹjọ̀ nù lórí Emir tuntun mẹ́rin!
Ẹ̀yin náà ẹ ro ọ̀rọ̀ ọ̀hún wò láàrin ara yín.
Van Dijk fẹyin Cristiano Ronaldo ti Juventus ati Lionel Messi ikọ Barcelona gba lẹ gba ami ẹyẹ naa.
"O ṣalaye pe ""o ti lẹ ni ọpọlọpọ ọdun ti ijọba Naijiria kii le fi awọn to ba pa oluwọde jofin, eyii to ti wa di aṣa bayii."
Ẹ̀kọ́ itàn yi ni pé, bi èniyàn bá mbá ọ̀rẹ́ ọlọ́gbọ́n burúkú rin, ki ó mã funra tàbi ki ó yẹra, ki o ma ba ri àkóbá.
da lori bi eto aabo yoo se ri ni awon ipinle apa Ariwa nibi ti atundi eto idibo
- Aarin gbungbun kọọrọ tabi ọna to jẹ kọ́nà - Ori oke tente nibi to ga soke ju ọna to ku lọ nitori pe o ṣeeṣe ki irufẹ ọkọ bẹẹ pada si ẹyin.
Lara ohun ti wọn ba lọwọ wọn bi ẹri ni miliọnu meji ati ẹgbẹrun lọna ọtalerugba o din mẹwa Naira ti wọn ba ninu ọkọ DSP ọlọpaa naa.
64 Ọ̀kọ̀ọ̀kan àlùfáà, olùkọ́ni, tàbí díakonì, ẹnití a yàn láti ọwọ́ àlùfáà, lè gba ìwé ẹ̀rí lọ́wọ́ rẹ̀ ní àkókò náà, ìwé ẹ̀rí èyítí ó jẹ́ pé, bí a bá fún alàgbà kan, yíò kà òun yẹ fún ìwé àṣẹ, tí yíò fi àṣẹ fún un láti ṣe àwọn iṣẹ́ tí ó rọ̀ mọ́ ìpè rẹ̀, tàbí òun lè gbà á nínú ìpádé àpéjọpọ̀ kan.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Osun: Ìjọba kédeìsinmi fáwọn òṣìṣẹ́ láti ṣe àjọ̀dún àyájọ́ ọdún Ìṣẹ̀ṣe 19 Ògún 2019 Oríṣun àwòrán, Alaafin Oba Adeyemi III Gbogbo wa la mọ pe gbogbo ọdun Kiristẹni ati musulumi lorilẹede yii ni ijọba apapọ maa n kede isinmi lẹnu iṣẹ fun.
“Ohun tí ó tọ́ ni OLUWA ṣe,nítorí mo ti ṣe àìgbọràn sí ọ̀rọ̀ rẹ̀;ṣugbọn, ẹ gbọ́, ẹ̀yin eniyan,ẹ kíyèsí ìjìyà mi;wọ́n ti kó àwọn ọdọmọbinrin ati ọdọmọkunrin milọ sí ìgbèkùn.
Obinrin tí kò tíì mọ ọkunrin rí ni kí ó fẹ́ láàrin àwọn eniyan rẹ̀.
Idije naa ni yoo duro gẹgẹ bi idanwo fun igbimọ to ṣeto idije naa lori bi igbalejo idije African Nations Cup yoo ṣe ri l'ọdun 2021.
Ìdí sì rèé tí wọn ṣe fi orúkọ Emperor Justinian 1, to ń darí ìjọba ilẹ̀ Rome nígbà náà sọri ajakale àrùn naa.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Coronavirus in Nigeria: Wọ́n ti fi ọmọ orílẹ̀-èdè Italy tó kó coronavirus sílẹ̀ nílèéwòsàn 21 Ẹrẹ̀nà 2020 Oríṣun àwòrán, Twitter/babajide sanwo-olu Àkọlé àwòrán, Ọmọ Italy naa ni wọn fi nkan bo l'oju ninu aworan to ya pẹlu awọn oṣiṣẹ ijọba Wọn ti fi ọmọ orilẹ-ede Italy to ko arun coronavirus wọle si Naijiria silẹ nileewosan.
Orilẹede China China ni tirẹ̀ ni awọn kò faramọ́ ikọlu naa nitori pe ó lòdì si òfin ìbásepọ̀ laarin awọn orilẹede lágbàáyé.
Àwọn baba wa jẹ mana ní aṣálẹ̀, gẹ́gẹ́ bí a ti kọ ọ́ pé, ‘Ó fún wọn ní oúnjẹ láti ọ̀run wá jẹ.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Arẹgbẹsọla fowó lé isẹ́ àgbàse ní ìlọ́po márùn-ún - Omisore Ọ̀rọ̀ LAUTECH gba àpérò f'áwọn Olúdíje Ọṣun Ijó Ademọla Adeleke rèé níbi ìpolongo ìbò PDP l‘Ọ́sun Àtúnse Nàíjíríà gbọdọ̀ bẹ̀rẹ̀ láti ìdìbò Ọ̀sun - Saraki Ìpínlẹ̀ Oṣun kò nílò Gómìnà oníjó - Oshiomole Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí kan sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
Ẹ̀wẹ̀, àìmọye ìgbà ni Sẹnatọ Ndume ko ti ri Maina mu wá si ilé ẹjọ́.
Wọ́n tún di ìbò bákannáà láti gba wọlé ati lati ṣe àtìlẹhìn Joseph Smith Kekeré àti Oliver Cowder gẹ́gẹ́bí àwon olórí òṣìṣẹ́ ti ìjọ.
Wo bí o ṣe lè ṣe eré ìdárayá tí yóò fún ọ ní adùn àti okun fún ìbálòpọ̀ Àjọ ọlọpàá Eko kédé pé ìbalòpọ̀ nítà kò bójúmu Lóòtọ́ ni ọkọ mi lù mí bí àṣọ òfì, àmọ́ gómìnà ti bá wa parí ẹ̀, ẹ máa gbàdúrà fún ìdílé mi- Dokita Ifeyinwa Mi ò kí n ṣe afẹfẹ-yẹ̀yẹ̀ lórí ayélujára nítorí pé mí ò ní dúkìá tí mó le fihàn- Ronke Oshodi-Oke Ìgbìmọ̀ aláṣẹ APC jáwe lọ gbéle rẹ fún ìgbákejì alága: Hilliard Eta!
Rehoboamu ọba bá lọ jíròrò pẹlu àwọn àgbààgbà tí wọ́n jẹ́ olùdámọ̀ràn Solomoni baba rẹ̀ nígbà ayé rẹ̀, ó bi wọ́n léèrè pé, “Irú ìdáhùn wo ni ó yẹ kí n fún àwọn eniyan wọnyi?
Nítorí náà, ẹ ṣọ́ra yín, kí ẹ má ṣe hùwà aiṣootọ sí aya tí ẹ fẹ́ nígbà èwe yín.
Oríṣun àwòrán, Twitter/Prof Yemi Osinbajo Àkọlé àwòrán, Yemi Osinbajo: Ẹgbẹ́ àwọn àgbààgbà Yorùbá ní Osinbajo kò gbọdọ̀ kọ̀wé fipò sílẹ̀ O rọ igbakeji aarẹ pe ko tẹsiwaju lati maa ba aarẹ Buhari ṣiṣẹ pọ pẹlu inu kan.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Oshisko twins: Ojú wa rí, ṣùgbọ́nÌgbọ́raẹniyé ló ń ràn wá lọ́wọ́ Oju gbogbo yoo tun wa lori ipinlẹ Kano nibi ti gomina Abdullahi Ganduje yoo ti maa waako pẹlu Abba Kabir Yusuf ti ẹgbẹ oṣelu PDP.
Sugbọn ki igbesẹ yii to lee waye, ofin wa ti awọn asofin naa gbọdọ tẹle, nitori wọn ko le dede yọ Igbakeji Gomina ni ipo.
ti o kopa ninu ipade naa ni: Minisita fun eto iṣuna ati aato ilẹ wa, Minisita
O ṣe apejuwe iya gẹgẹ bi akikanju obinrin ti ki i fi iṣẹ ṣere.
Ọjọ Aje ni esi idibo naa jade lẹyin ti ile ẹjo gbesẹ kuro lori esi idibo naa.
A fi agbára fún ẹni tí ó gùn ún láti mú alaafia kúrò ní ayé, kí àwọn eniyan máa pa ara wọn.
Nígbà tí ẹ̀ṣẹ̀ rí ohun dìrọ̀ mọ́ ninu òfin, ó tàn mí jẹ, ó sì pa mí kú.
"Okan ni "" imu rẹ ti n ṣẹjẹ"" nigba ti omiran n kigbe pé"" dide kuro lọrun rẹ"" Loju ẹsẹ o jọ bi ẹni pe ọkunrin naa ko mira mọ ki wọn to gbe sinu ọkọ ambulansi."
"Akeredolu ṣalaye pe ọrọ bibẹrẹ iṣẹ awọn Amotekun yii ti di rangbọndọn lẹnu awọn eeyan torinaa awọn gbudọ gbe igbesẹ ati wipe ""gẹgẹ bii Yoruba, a o ki n ṣe ọmọ lọle lọ gb'esi wa, nigba ti awọn aṣaaju wa o tilẹ ṣe bẹẹ loju ọta""."
yoo tun ran orile ede Naijiria lọwọ ,nitori pe awon ni o ni owo to pọ julọ ninu
Awon akoroyin ti won kopa ninu idanilekoo naa ni won wa lati ile-ise iroyin atewe-ta, ile-ise iroyin radio, ero amohun-maworan ati awon akoroyin ori ero ayelujara.
 O ni o yẹ ki wọn ri Ile Igbimọ Aṣofin Apapọ gẹgẹ bi ibi ọwọ to yẹ ki wọn pese aabo to peye fun.
Ogagun Pius Oahimire to je adari iko omo oogun ti eka 131, to tun je onimo ero dupe  lowo oga agba patapata fun iko omo oogun ofurufu naa, Sadique Abubakar, pe aseyori yii waye nipa eto iranwo ati imoriya ti oga agba patapata naa se fun won lati le se ise naa ni aseyori .
Eyi ni ifẹsẹwọnsẹ bọọlu akọkọ laarin awọn ikọ odu ẹgbẹ agbabọọlu lorilẹede naa ti wọn yoo maa wọgile nitori arun naa.
Seyi Awolowo wa lara awọn ọmọ Naijiria to nkopa ninu eto idaraya ilumọọka nii, BB Naija.
Ẹ máa bẹ̀rù OLUWA, kí ẹ sì máa sìn ín pẹlu gbogbo ọkàn yín.
Nítorí ààfin náà dára púpọ̀, ó dára ju nǹkan tí ẹnu máa sọ.
Mo sọ fun yín, yóo sàn fún Tire ati fún Sidoni ní ọjọ́ ìdájọ́ jù fun yín lọ.
Nítorí pé OLUWA yóo rú ẹbọ ní Bosira,yóo sì pa ọpọlọpọ eniyan ní ilẹ̀ Edomu.
Oun si ni sẹnatọ to n ṣoju ẹkun idibo ila-oorun ipinlẹ Eko nile igbimọ aṣọfin agba to wa ni ilu Abuja.
 ) ( he felt dulled and stupid with sleep .
Ogun Àgbẹ́kọ̀yà, ìjà òmìnira fáwọn àgbẹ̀ ni àbí ìfẹ̀míṣòfò?
Eyi n mu ọpọlọpọ ewu wa fun wọn lati ko arun yii eleyii to ti mu eeyan to le ni ẹgbẹrun mẹrindinlogoji bi a ṣe n sọrọ yii.
Nígbẹ̀hìn, ogun bẹ́ sílẹ̀ ní òde ọ̀run, àwọn tí ó fẹ́ràn obìnrin náà dá rúdurùdu sílẹ̀ tó bẹ́ẹ̀ tí ọ̀ rọ̀ náà dé etí Ọlọ́run Ọba.
Sùgbọ́n ki ènìyàn to jẹ irú ounjẹ yìí, àwọn ìgbẹ́sẹ̀ kan se pàtàkì.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Àwẹ̀ Ramadan wákàtí 22 lóòjọ́, ṣé ẹ̀mí rẹ gbà á?
n kò ní já ọmọ Nàíjíríà kulẹ̀ - Buhari Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fọ́nrán ohùn, Akala lè ṣàtìlẹ́yìn fẹ́ni tó bá wù ú Wahala yii waye lagbegbe Adabata si Kuntu nigbati awọn olugbe ibẹ ni awọn janduku agbebọn kan ti wọn funra si pe wọn jẹ oniṣẹ iku awọn oloṣelu kan ya bo adugbo naa ti wọn si ba ọpọlọpọ dukia jẹ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, What causes coronavirus: Akeugbagold sọ àṣírí ohun ti àrùn coronavirus ń dá lárá f 'Ewu nla ti awọn alasẹ kọti ikun si' Iwadii awọn akọroyin BBC fihan pe bi awọn ọmọ wọ yi ti se n pada si ipinlẹ wọn, ni awọn alasẹ n se ayẹwo ti wọn si n ya wọn sọtọ.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Champions League: Messi yóò kojú Man U nínú ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ tí yóò ta lẹ́nu Akọnimọọgba Solskjaer ni Messi nikan kọ ni Man U yoo koju nitori awọn agbabọọlu mii bii Luis Suarez, Philippe Coutinho, Ivan Rakitic ati Arturo Vidal wa ni Barca.
Onimọ ẹlẹsin Islam kan ni ilu Numan nipinlẹ Adamawa, Malam Aminu Yakubu, sọ fun BBC pe iwa aimọkan nipa ẹkọ ẹsin Islam lo n da awọn ẹlẹsin Hakika laamu.
”Ami-eye(NNMA, Nigerian National Order of Merit Award), je ami-eye ti o wa fun awon onimo ijnle, akeko gboye yala nile eko tabi sise agbekale awon eto oniruuru ti o le sanfaani fun idagbasoke orile-ede Naijiria, ti o si tun le buyi kun aworan orile-ede Naijiria lawujo ati nile okere.
Ó ń pẹ̀gàn ìdàrúdàpọ̀ inú ìlú ńlá,kò gbọ́ ariwo àwọn tí wọn ń fi kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ ṣiṣẹ́.
8TH Assembly: FRSC kò yan Saraki sọjú pé kó dá nọ́mbà ọkọ̀ tó lò padà
Ṣé nítorí mo ti dákẹ́ fún ìgbà pípẹ́,ni o kò fi bẹ̀rù mi?
Oríṣun àwòrán, Fatima Muhammad Oniruuru ibudo igbafẹ to jẹ oju ni gbese lo wa yika orilẹede Naijiria amọ̀ ni ibudo ẹwa atọwọda naa, ẹka mẹta ọtọọtọ lo mu ko wu oju ri.
Nígbà náà ni ọba Sodomu, ati ọba Gomora jáde lọ, pẹlu ọba Adima, ọba Seboimu, ati ọba Bela, (tí ó tún ń jẹ́, Soari).
pe aseyọri ti egbe oselu APC se, ninu eto idibo to waye lorile ede Naijiria lọdun
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Àwọn ìgbà tí àwọn ọmọ Ọbasanjọ ti takò ó ní gbangba 2 Bélú 2018 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 3 Bélú 2018 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Gbenga Ọbasanjọ fi ẹsun kan pe o n ba iyawo oun ni ibalopọ O jẹ ohun ti ko wọpọ ki ọmọ tako baba tabi iya rẹ nilẹ Yoruba, nitori pe aṣa ati iṣe Yoruba gbagbọ pe obi ẹni jẹ ọlọrun kekere fun ni, ati pe ọmọ to ba gboju soke wo awọn obi rẹ n tapa si ọrun ara rẹ ni.
Èyí jẹ́ ìrántí ohun tí ojú àwọn ọmọ Mozambique rí ní ìparí ọdún-un 2018, nígbàtí ìjọba pinnu láti fi owó kún ìwé àṣẹ gbogbo, bẹ́ẹ̀ náà ni ó bá ìwé àṣẹ ọkọ̀ wíwà, tí ìdíyelée rẹ̀ fi ìdá 500 gbéwó lórí.
Adeleke yóò borí nílé ẹjọ́ tó gajù lọ- Dele Adeleke Bí ọlọ́pàá bá mú ọ, kí ló yẹ kí o ṣe?
Owurọ Ọjọ Iṣẹgun ni iroyin sọ pe wọn ri oku Toke ninu igbo kan ni agbegbe Onikoko, loju ọna Ibadan silu Oyo.
Lẹyìn naa lo wa lọ gba iwe ẹri pe o ti kọja ìpele yi.
Oríṣun àwòrán, Other Hugo Ifeanyi Odiogor Lana ode yii niti Odiogor to jẹ ọga agba oniroyin ati alaga nile iṣẹ iroyin Vanguard tẹlẹ ri.
 Orilẹ-ede France nife ẹyẹ agbaye n tẹle lọ sile nigba ti wọn fagbahan Croatia pẹlu ami ayo mẹrin si meji.
Sex workers strike: Àwọn aṣẹ́wó kílọ̀ fún Buhari kó dá'wó epo padà, bíbẹ́ẹ̀kọ̀, ìyanṣẹ́lódì ló kù
Mo ranti ìgbà àtijọ́,mo ṣe àṣàrò lórí gbogbo ohun tí o ti ṣe,mo sì ronú lórí àwọn iṣẹ́ ọwọ́ rẹ.
Nígbà náà ni àwọn ọkunrin marun-un tí wọ́n lọ ṣe amí ilẹ̀ Laiṣi sọ fún àwọn arakunrin wọn pé, “Ǹjẹ́ ẹ mọ̀ pé ẹ̀wù efodu kan wà ninu àwọn ilé wọnyi ati àwọn ère kéékèèké, ati ère tí wọ́n gbẹ́ tí wọ́n sì yọ́ fadaka bò lórí, nítorí náà, kí ni ẹ rò pé ó yẹ kí á ṣe?
Ó bá tún pẹpẹ OLUWA tí ó ti wó ṣe.
"Oríṣun àwòrán, yinkaayefele ""Mo dupẹ lọwọ gbogbo yin pe ẹ ro ire ro emi ati ẹbi mi, mo si gbadura pe yoo ri bẹ ti wi ni orukọ Jesu."
Naijiria fi ìgbájú mẹ́ta lé Cameroon kúrò ní AFCON Wo àwọn ẹ̀ṣọ́ ara tó tó $40m Diezani Madueke tí ilé ẹjọ́ gbẹ́sẹ̀ lé Kí ló mú kí àwọn èèyàn máa jẹ ọ̀rọ̀ Adeboye lẹ́nu lórí Twitter Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, CAN: Samson ni ọrọ awọn ajinigbe ti gba àpérò ní Naijiria Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Ìròyìn sọ pé, awakọ̀ kan ló fún ọkan nínú àwọn ọmọogun náà ni owó àbẹ̀tẹ́lẹ̀ ọgọ́rùn náìrà nígbà tí ó fẹ́ wọ inú ọjà, sùgbọ́n tí ó kọ̀ láti sa òmíràn nígba tó fẹ́ jáde kúrò nínú ọjà náà.
Ekun Gusu– alaga egbe ,igbakeji alaga egbe,igbakeji akowe agba, igbakeji  alakoso fun eto ofin, igbakeji alukoro agba.
Ajọ to n ri si iṣẹlẹ pajawiri lorilẹede Naijiria, NEMA ni awọn janduku to maa n bẹ ọpa epo bẹntiroo lati ji epo wa lo fa katakata to ṣẹlẹ lọjọbọ ni agbegbe Ijegun ti ọpa epo ti gbina.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Kanu Nwakwo: Òní ni ọjọ́ ìbí Kanu, àwọn ǹkan tó ti gbé ṣe rèé Yemisi Oyedepo Broadcast Journalist 1 Ògún 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Kanu lásiko tó ńgba fún orilẹ̀-èdè Naijiria Oní ni ọjọ́ ìbí Kanu Nnwankwo, gbajúgbajà agbábọ́ọ̀lù orilẹ̀èdè Nàìjíríà, Super Eagles tẹ́lẹ̀ rí.
Ọba kó wọn sí ààfin Igbó Lẹbanoni.
O ni paapaa lori awọn oloṣelu ti ko fẹ ilọsiwaju eto oṣelu ni wọn ṣe fẹ gbe e.
N óo fi nǹkan ìríra ńlá mìíràn hàn ọ́.
Awọn nkan mii to tun wa ninu ilana tuntun naa Bakan na ni irinajo ọkọ oju'rin naa yoo bẹrẹ pada.
Ìwọ́de #RevolutionNow forí ṣánpọ́n ní Ibadan, àgbófinró gbàkóso ojú pópó Ọlọ́pàá àti àwọn olùfẹ̀hónúhàn gbéná wojú ara wọn níbi ìwọ́de Revolution Now Soworẹ ń déte láti dìtẹ̀ gba ìjọba Nàíjíríà lá ṣe gbé e - DSS Dangote, jọ̀ọ́ nawọ́ ìrànwọ́ láti dá iléeṣé sílẹ̀ fún wa ní Ọyọ - Aláàfin rawọ́ ẹ̀bẹ̀ Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Bẹẹ ba gbagbe, ọjọ Kẹrindinlọgbọn osu Kọkanla ọdun 2020 ni Makinde gbe aba isuna ọdun to n bọ kalẹ siwaju awsn asofin lati yiiri wo, ki wọn si fontẹ lu.
Ẹwẹ, koko to wa nibẹ ni pe ijọba wọgile ipẹjọ lodi si Woodberry lai ni ẹta inu, tumọ si pe, ijọba ni ẹsun tuntun ti wọn yoo fi kan an, eyi ni alaye Eribake.
O fi kun un pe ijọba ko lẹbọ kankan lẹru lori ọrọ yii.
Bí ẹnìkan bá sì gbé obinrin tí a ti kọ̀ sílẹ̀ ní iyawo òun náà ṣe àgbèrè.
Lọjọ Aiku ni aarẹ awọn oṣere tiata Yoruba Naijiria, Bolaji Amusan Mr Latin fidi ọrọ naa mulẹ fun ileeṣẹ BBC Yoruba.
Gbogbo awọn to ba n kopa ni eto ibilẹ gbọdọ maa sọ ede Ekiti tabi ede Yoruba.
Nkan oníkanòjọ̀kan àti onírúirú ló wà níbẹ̀ fún ìgbádùn tọmọdé tàgbà.
Gẹgẹ bi Oyeyemi ti ṣe sọ, baalẹ abule naa lo fi iwe ranṣẹ si awọn ọlọpaa lati wa ba wọn koju awọn kan ti wọn ni nkan ija lọwọ, ''Ọga ọlọpaa agọ to wa ni Ijebu Igbo lo lewaju pẹlu awọn fijilante lati koju awọn obilẹjẹ yi.
Ẹbi awọn to ba iṣẹlẹ ọkọ oju omi to da nu ni agbegbe Ijede ni ilu Eko sọ ipo ti gbogbo agbegbe omi ti wọ n gba kọja yii wa.
Aare Muhammadu Buhari ki iko agbaboolu Super Eagles ku ori-ire pipegede fun idije boolu afesegba ile Afrika, AFCON (2019 Africa Cup of Nations) ti yoo waye lorile-ede Cameroon.
Ẹwẹ, nigbati adajọ si ti da ẹjọ ẹwọn gbere fun un tan, agbẹjọro rẹ nigbati BBC Yorba fi ọrọ wa a lẹnu wo jẹ ko di mimọ pe, ìdájọ́ ẹ̀wòn gbére kò ní kí Wòlíì Sotitobire má lọ sí ilèẹjọ́ kòtẹ́milọ́rùn.
Ìtàn ti Joseph Smith dáa lábàá pé a gba ìfihàn yìí lẹ́hìn ìmúpadàbọ̀sípò Oyè Àlufáà ti Aaronì.
44 Àti láti darí gbogbo àwọn ìpàdé.
Aláàánú ati olóore ni OLUWA,kì í tètè bínú, ìfẹ́ rẹ̀ tí kì í yẹ̀ sì pọ̀.
Wọn ti kọlu awọn oniruuru ile itaja ati ọfiisi ti wọn si ji ọpọ nkan ko ti wọn ba nkan jẹ.
Ilé Aṣòfin Àgbà fòǹtẹ̀ lu N30,000 owó oṣù òṣìṣẹ́ Ileeṣẹ to n gbogun ti awọn to koba ọrọ aje Naijiria (EFCC) ati eyi to n gbogun ti iwa ibajẹ ( ICPC) wọn ṣe alaye pe ibo rira lodi si ofin ajẹbanu.
Wayii o, minisita to n ri si eto iroyin lorile-ede naa Dora Siliya so lori ero ayelujara re pe, kosi ooto bi o se le wu ko mo ninu esun naa.
Àmọ́ ṣáá o, alukoro àjọ olopaa ní ìpínlè náà, Williams Aya, sọ wí pé, kò tí ì sí eni tí ó mú ẹ̀sùn íjini gbé bẹ́ẹ̀ tó wọn létí.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Wọ́n ti ṣí ilé oúńjẹ ọgbọ̀n náírà (N30) lẹ́yìn tí mínísítà Nanono sọ pé oúńjẹ N30 le yó èèyàn 25 Ọ̀wàrà 2019 Ọ̀rọ̀ tí mínísítà ètò ọ̀gbìn àti ìdàgbàsóké igbèríko sọ pé oúńjẹ N30 le yó èèyàn ní Kano bí ọ̀pọ̀ àwọn ọmọ Nàìjíríà nínú.
Aya gómìnà Kwara fẹ́ ran tìyá- tọmọ olójú búlúù lọ́wọ́ Wo àwọn àìsàn ti ìwọ́ ọmọ tuntun le wòsàn A ó fún ẹbí akẹ́kọ̀ọ́ Fásitì Ibadan tó dolóògbé ní owóo gbà mábìnú - Ìjọba Oyo Ìtàn ayé Shina Rambo, adigunjale tó fi oyún 27 gún ọṣẹ Alfred fi ẹsun kan adari ile iwe Bright SHS pe o ṣegbe lẹyin awọn ọmọ ile iwe naa lati ṣakọlu si awọn oṣiṣẹ WAEC to wa mojuto idanwo nibẹ.
”Elija dá a lóhùn pé, “Pada lọ, àbí, kí ni mo ṣe fún ọ?
Igbakeji ni asiko ti LaVey ṣe iribọmi fun ọmọ rẹ obinrin ni ilana Satani.
Dafidi fún ẹgbaa mejila (24,000) ninu wọn ní iṣẹ́ ninu tẹmpili; ó ní kí ẹgbaata (6,000) máa ṣe àkọsílẹ̀ ati ìdájọ́ àwọn eniyan, 
Nítorí ìfẹ́ ati àánú rẹ̀, ó rà wọ́n pada.
Eyikeyi iwe ti Fayose ba ni to ṣafihan pe a jijọ ta a ni, irọ pọnbele ni'' Laipẹ yii ni Gomina Fayose sọ pe ohun gba iyọnda awọn igbimọ amuṣẹya ẹgbẹ ki ohun to ta olu ileeṣẹ ẹgbẹ PDP Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Dafidi mú òkúta kan jáde láti inú àpò rẹ̀, ó fi kànnàkànnà rẹ̀ ta òkúta náà, òkúta náà wọ agbárí Goliati lọ, ó sì ṣubú lulẹ̀.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Mama Rainbow: iṣẹ́ tíátà kò ta sánsán mọ́ bíi ti ayé àtijọ́ Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Ilé ẹjọ́ sún ẹjọ́ Sẹ́nétọ̀ Abbo síwájú pẹ̀lú béèlì mílíọ̀nù márùn-ún Iya Wolii ni ọdun kẹta rẹ ree ti oun ti n ṣe iṣẹ awada to n dẹrin pa awọn eniyan Naijiria.
Amọ ẹnikan nileesẹ ologun fidi rẹ mulẹ fun BBC pe, owo nla kan ti sadeede poora, ati wi pe, wọn ti fi iṣede se ọgagun kan mọle rẹ, ko gbọdọ fi ile rẹ silẹ nilu Abuja.
Awọn adari ile ijọsin ati imaamu naa si sọ wi pe awọn ni igbagbọ ninu aṣẹ ijọba ati wi pe wiwa ni alaafia awọn eniyan jọ wọn loju.
Oríṣun àwòrán, Others Wo oye owó ti ìjọba fẹ́ fi lé owó ináa ìlẹ́tírìkì Iroyin ti o tẹwa lọwọ ti fi han pe, lati ọdun ti n bọ, awọn ọmọ Naijaria yoo maa san ju iye owo ti wọn n san tẹlẹ lọ fun ina ijọba.
Oríṣun àwòrán, Bukky raji Àkọlé àwòrán, Lukman Raji ati Bukky Adekongbe (Aminatu papapa) Lukman Raji ati Bukky Adekongbe (Aminatu papapa) Njẹ ẹ mọ Ọkọ Aminatu papapa Lukman Raji ati Bukky Adekongbe ti ọpọlọpọ mọ si Aminatu papapa pẹlu naa n ṣe lọkọlaya lagbo ere tiata Yoruba.
“Pàṣẹ fún àwọn ọmọ Israẹli pé, ‘Nígbà tí ẹ bá dé ilẹ̀ Kenaani tí mo fun yín, gbogbo ilẹ̀ náà ni yóo jẹ́ tiyín.
O ni wọn ti n lọ si ile ẹjọ tẹlẹ sugbọn nitori ọrọ Coronavirus lo faa, ti ile ẹjọ fi ni ki wọn lọ fi wọn pamọ si ahamọ ọlọpaa nitori awọn ẹwọn ti kun.
Kriangsak Thanompun to jẹ oludari ọgba naa sọ fun BBC News Thai pe ''A ni igbagbọ pe o ti pẹ to ti n jẹ awọn nkan wọn yi ki o to ku'' O ṣalaye pe awọn ro pe awọn nnkan to jẹ lo di ifun rẹ ṣugbọn awọn yoo ṣe iwadii ẹkunrẹrẹ .
Pabanbari ni wi pe bi ọrọ yi ba lee fa ogun, yoo ba okun ajọṣepọ katakara jẹ laarin awọn orilẹ-ede agbaye eyi ti Afirika fi so wọn pọ gẹgẹ bi ileewe giga Washington Institute ṣe sọ ọ.
Ní Naija, ọkọ̀ òfurufú kò yéé jábọ́.
IRÚ ÈNÌYÀN WO NI À N PÈ NÍ OLÈ?
Oloye Bakare ni ọ̀nà abayọ kan soso to wà ni pé ki ẹ̀yà Yoruba pada si ìdí ìṣèṣe nítori pé ninú ìṣẹ̀ṣe a ní adehun, ìbúra, ilérí, ìmùlẹ̀ àti majẹ̀mú Awọn ǹkan wọ̀nyi ni kìí jẹ́ ki ìgbéyawó aye atijọ́ tú, ẹrù wà nínú àwọn ǹkan ìbúra bi wọ́n se n na Kurani àti Bibeli soke lai si iberu nibẹ, sùgbọ́n ninu iṣẹ̀ṣe ti wọ́n ti n fi omi àti ẹ̀jẹ̀ Bura kíàkíà si ni àwọn ọlọrun ǹkan wọ̀nyi ń pa ènìyàn nítori náà kò sí ẹni ti yóò fẹ́ taṣẹ̀ àgẹ̀rẹ̀ Láye òde oni kò si ẹni to lé ba ọkunrin tabi obinrin kankan mulẹ̀ mọ Ó pé mi kí n kú jù kí n darapọ̀ mọ́ ẹgbẹ́ APC - Fani-Kayode Arsenal vs Man City: Arsenal rìn lọ́jọ́ ebi ń pọ̀nà bọ́ sọ́wọ́ kìníhún Manchester City Iná tó ṣẹ́yọ nílú Ibadan mú kí àwọn oníṣòwò pàdánù ogọ́rùn ún mílíọ́nù náírà Ìyàwó igbákejì ààrẹ Zimbabwe dèrò àgọ ọọ́pàá lórí ẹ̀sùn jẹgúdújẹrá Yatọ si eyi, ẹkọ ile, ifarada, amojukuro, ifẹ tootọ, ibọwọfun ara ẹni ati awọn iwa ọmọluwabi gbogbo laiyọ igbagbọ ninu iṣootọ nipasẹ oriṣa ti onikaluku n sin tun n jẹ ki igbeyawo awọn baba nla wa ko tọjọ ki wọn si jọ maa gbe ni alaafia.
Oríṣun àwòrán, Inec Ajọ naa kede agbekalẹ oju opo ọhun lẹyin ipade ajọ naa to waye l'Ọjọbọ gẹgẹ bi ara ọna lati tubs mu ki okun akoso ibo lorilẹede Naijiria o gbopọn sii ki o ma si ni bojuboju kan ninu rara.
Alukoro ile iṣẹ́ ọlọ́pàá, Bala Elkana nínú àtẹjade kan to fọwọ́si sàlàyé pe àwọn ajínígbe fi àwọn ènìyàn ọ̀hun silẹ̀ láì farapa.
Amọ, Ajọ awọn oniburẹdi ni ipinlẹ Eko ti ni awọn yoo bẹrẹ iṣẹ pada loni, amọ o lera fun awọn lati ta burẹdi ni iye ti wọn n ta a tẹlẹ nitori ọpọlọpọ wọn ti jẹ gbese lori iṣẹ burẹdi tita naa.
Ohun tí ó kọ sórí rẹ̀ ni pé, “Jesu ará Nasarẹti, ọba àwọn Juu.
Ni bayii, ajọ ọlọpaa ipinlẹ naa ti pe fun iwadii to loorin lati fi panpẹ ọba mu ẹni ti ade ọrọ naa ba ṣi mọ lori.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Thanksgiving Trump: Aàrẹ Trump kọ̀ láti jẹ Tọkí ìsìn ìdúpẹ́ 2019 nílé, ó gba Afghanista lọ!
" Dokita Obinnaadigo sọ pe ti wọn ko ba tete ṣe ayẹwo lati mọ nkan to n fa inu dídùn, o le yọrí si ki appendix ko lu iho jade, eyi si lewu pupọ""."
Ó sì fi wúrà tí wọ́n fi òòlù lù ṣe àwọn Kerubu meji, ó jó wọn mọ́ igun kinni keji ìtẹ́ àánú náà, 
Bí nǹkan ọkùnrin bá há sójú ara obìnrin, kìí ṣe Mágùn, ẹ má páyà Oríṣun àwòrán, Getty Images Ni ọpọ igba la ti gbọ iroyin kaakiri nipa bi nnkan awọn ọkunrin kan se ha soju ara awọn obinrin ti wọn n ba sere ifẹ.
''Ìséde káàkiri Nàìjíríà lọ̀nà àbayọ sí ìtànkálẹ̀ coronavirus, bí bẹ́ẹ̀ kọ́ àpá kò ní ká covid-19 mọ́''- Onímọ̀ Ikú Dagrin pé ọdún mẹ́wàá, wo àwọn nǹkan mánigbàgbé nípa rẹ̀ Nàìjíríà tún ní àkọsílẹ̀ ènìyàn 108 tó ní ààrùn coronavirus Wo àwọn nkan tí o le ṣe gẹ́gẹ́ bi aláboyún lásìkò àjàkálẹ̀ ààrùn Covid-19 ‘Pussypedia’ rèé, ojú òpó tó ń mú àdínkù bá ìṣòro ìmọ̀ nípa ẹ̀yà ara obìnrin Ọjọ kẹrindinlogun, oṣu Kẹrin, ọdun 2020 si ni ileeṣẹ ọlọpaa kede pe, ọwọ titẹ afurasi mẹẹrin lori ipaniyan naa.
Ẹ jẹ́ kí á gbọ́ ohun tí Mose kọ́kọ́ sọ; ó ní,“N óo jẹ́ kí àwọn tí kì í ṣe orílẹ̀-èdè mu yín jowú,N óo sì jẹ́ kí orílẹ̀-èdè tí kò lóye mú kí ara ta yín.
Ìkejì bọ́sí ìgbà ìwọ́wé tí ojúmọ́ nkuru síi.
Olori ẹka to n risi imusẹ ofin Ajọ NCC, Efosa Idehen ni oju opo ibaraẹnisọrọ Facebook ajọ naa sọ wi pe, ọpọlọpọ awọn jandugu lo n lo awọn 'Sim Card' ẹbu fun ijinigbe lati gba owo ẹmi.
ng Àkọlé àwòrán, Ọwọ tẹ awọn afunrasi meji ni Delta to ji pata eniyan mewaa Isẹlẹ jiji pata awọn obinrin lo ti di iroyin to n gbalẹ bii ọwara ojo lawujọ wa bayii.
L’áíyé òde òní, ìmọ̀-ẹ̀rọ yìí ti gbòòrò gidigidi, ó sì ti dàgbà sókè dé ibi pé kò fẹ́ẹ másìí nkan ẹ̀rọ ìgbàlódé kankan tí kò ní ẹ̀rọ yìí nínú.
Kó bá mi béèrè lọwọ Àsàráílù oun mo fi ṣé
ìta gbangba láàrin ìlú ni a fẹ́ sùn.
Mo ka Silifanu yìí sí arakunrin tí ó ṣe é gbẹ́kẹ̀lé.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Abọde awọn akẹ́kọbinrin Chibok Oni lo pe ọdun kẹrin ti awọn agbebọn Boko Haram ji awọn akẹkọbinrin naa gbe, mejilelọgọfa wọn lo ṣi wa lahamọ awọn agbebọn yii.
Ọmọ ènìyàn wo kiní ọ̀hún títí ó ní “Ṣúgà la ó máa pè ọ́”
Mimiko wa gbadura pe ogun ti oloogbe Bamidele Olumilua fi silẹ ko ni bajẹ, ti Ọlọrun yoo si tẹ si afẹfẹ rere.
Nítorí, ẹ ti di aláfarawé àwọn ìjọ Ọlọrun tí ó wà ninu Kristi Jesu ní ilẹ̀ Judia, nítorí irú ìyà tí wọ́n jẹ lọ́wọ́ àwọn Juu ni ẹ̀yin náà jẹ lọ́wọ́ àwọn ẹ̀yà tiyín.
Wo ohun tó yẹ kí o mọ̀ nípa àwọn obìnrin méje ti Buhari forúkọ wọn ránṣẹ Kò lè ṣééṣe kí Ruga wà lápá gúúsù Nàìjíríà fáwọn Fulani- Ganduje Èmi kò ní kí Shiite má ṣe ẹ̀sìn won o -Muhammadu Buhari Aarẹ Buhari pàṣẹ pé kí wọ́n ṣàwárí àwọn oníṣẹ́ ibi tó pa èèyàn 65 ni Borno Wo àwọn ìgbá ti Abubakar Shekau ti ku ni Naijiria: Ọpọlọpọ igba ni wọn ti kede pe ijọba Naijiria ti rẹyin Abubakar Shekau lati ọdun 2009 ti Naijiria ti n ja ogun ikọlu awọn alakatakiti ẹsin Islam naa.
Ta ló lè mú ohun mímọ́ jádeláti inú ohun tí kò mọ́?
Ṣugbọn nígbà tí ó rí i tí afẹ́fẹ́ ń fẹ́, ẹ̀rù bà á, ó bá bẹ̀rẹ̀ sí rì.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Sotitobire n jẹjọ nipa Gold Kolawole ọmọ ọdun kan to di awati nile ijọsin rẹ ni ilu Akure.
Abajade iwadi kan ti sọ pe, owo ti awọn eeyan marun un to lowo ju ni Naijiria ni, le dẹkun oṣi oun iṣẹ lorileede naa.
Ìwé àtẹ̀jáde mìí, Telegram channel Mash sọ pé ọmọ Nàíjíríà ọ̀ún ra ọ̀pọ̀lọpọ̀ ọtí láti mu tó sì mu ú yó kẹrí, ó bọ́ sí ẹnu ọ̀nà rẹ̀ ó sì bẹ̀rẹ̀ sí ní kọrin sókè tantan pẹ̀lú ijó níwájú ilé tirẹ̀ tó wà ní àjà kejì.
Ẹ bá mi kálọ ẹ̀yin ọ̀rẹ́-ẹ̀ mi.
Laipẹ yii ni awọn alaṣẹ MMM kéde lójú òpó ayélujára pé ètò nàá ti gbe aṣọ ìlànà tuntun wọ̀.
Oríṣun àwòrán, Reuters Àkọlé àwòrán, l'ọjọ Abamẹta, awọn eeyan ṣe iwọde l'awọn oju opoponaa igboro Floreence ni orilẹede Italy lati fi ẹhonu han lori pipa ọmọ orilẹede Senegal kan to n taja, Idy Diene.
Pásítọ̀ gún ìyàwó rẹ̀ lọ́bẹ nínú ṣọ́ọ̀ṣì, ló bá tì í bọ ara rẹ̀ náà níkùn Òbí àwọn ọmọ tó j'óná mọ́lé n'Ibadan leè dáràn ìjọba o!
Awọn ti iṣẹlẹ naa ṣe oju wọn ṣalaye pe ni kete ti ọkunrin akọkọ jabọ sinu omi ni ẹnikeji rẹ gbiyanju lati yọọ jade ni oun pẹlu jabọ sinu kọnga naa to si ku.
Ọgá àgbà ilé ẹkọ kan ni iporuuru dé bi pé o ró pé òṣìṣẹ́ òhun ni àìsàn kan ti o ń mú kí o maa sùn lẹ́nú iṣẹ́.
" wọ ́ n ní ó rọ ̀ láti orí òkè kan pẹ ̀ lú ẹ ̀ wọ ̀ n , ní èyí tó mú kí wọ ́ n ma kìí wípé : "" oòduà ayẹ ̀ wọ ̀ nrọ ̀ "" tí ó túmọ ̀ sí ( ' one who descends on a chain ' ) ."
Amọ aarẹ ẹgbẹ, Mr Latin, ninu alaye to ṣe si oju opo Instagram rẹ ti ni, eyi ko lee ṣee ṣe nitori awọn idi kan to mẹnuba.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìtàn Mánigbàgbé: Oyenusi ní òun kò bá tí digunjalè, táwọn òbí òun bá lágbára láti rán òun níléèwé 18 Òkùdu 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 23 Èrèlè 2020 Oríṣun àwòrán, AFP Yoruba ni ẹni ba jale lo ba ọmọ jẹ, ati pe, bi ole ba da aran bori, asọ ole lo da bora, bi ẹni to ba si jale ba ni ọla laye, ko lee ri ọrun wọ bi ọlọjọ ba de.
Ẹ ṣọ́ ẹnu yín, ẹ má sọ̀rọ̀ burúkú,ẹ má sì jẹ́ kí ọ̀rọ̀ ẹ̀tàn ti ẹnu yín jáde.
Pásítọ̀: Jésù kò ní gun kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ tó bà wá láyé
Iná ni wọ́n ń fi í dá, nígbà tí iná bá jó o lórí, tí ó jó o nídìí, tí ó sì sọ ààrin rẹ̀ di èédú, ṣé ó tún ṣe é fi ṣe ohunkohun?
Losu kini ọdun yi ni ilẹ Amẹrika fi ado oloro pa Soleimani ni Iraq.
O wa ro awon eniyan  ati awon akoroyin lati maa kede esi idibo ,nitori pe ajo eleto idibo nikan lo ni ase lati kede esi idibo naa.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Òbí ọmọ Chibok kú nínú ìjàmbá ọkọ̀ Sé agbésùmọ̀mí ní àwọn darandaran Àjọ tó ń rí si ìṣẹ̀lẹ̀ pajawiri (NEMA) lo fìdí ọ̀rọ̀ náà múlẹ̀, ó fi kún un pé ènìyàn tó lé láàdọ́ta lo fara káasa nínú ìṣẹ̀lẹ̀ náà.
Àwọn èèyàn fi ìtara ba ilé ìjọsìn jẹ́ Mo ní àwọn ẹ́rì pé Ààrẹ Buhari fẹ́ dupò fún sáà kẹta - Femi Falana Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Oluwo of Iwo, Oba Abdulrasheed Akanbi tun ti sọ oko ọrọ lori iyapa to waye laarin rẹ ati Olori rẹ tẹlẹ, Chanel Chin.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ojojúmọ ní mọ ń kẹ́kọ̀ọ́ lára ọmọ mi to jẹ akanda Baba ọmọ ti iṣẹlẹ yii sẹlẹ si, Ọgbẹni Ade ṣalaye pe oun ṣakiyesi pe ibaṣepọ to wa laarin olukọ ti wọn da duro ati awakọ yii mu ifura dani.
Ó pàṣẹ pé kí gbogbo àwọn baálẹ̀ agbègbè, àwọn olórí ati àwọn gomina, àwọn ìgbìmọ̀ ati àwọn akápò, àwọn onídàájọ́ ati àwọn alákòóso ati gbogbo àwọn òṣìṣẹ́ ọba tí wọ́n wà ní àwọn agbègbè Babiloni wá sí ibi ìyàsímímọ́ ère tí òun gbé kalẹ̀.
Bí aláṣẹ bá ń fetí sí irọ́,gbogbo àwọn ìgbìmọ̀ rẹ̀ yóo di eniyankeniyan.
Lagos-66 Plateau-63 FCT-48 Kaduna-21 Bayelsa-19 Rivers-12 Niger-9 Ogun-4 Ekiti-2 Bauchi-1 Osun-1 Eyi tumọ si pe awọn to ti ni Covid-19 ni Naijiria ti pe 66,228, nigba ti eeyan 61,884, ti ri iwosan, awọn 1,166 si ti ku.
Ogagun Daramola se lalaye pe, won koju ija si agbegbe igbo Sububu lataari sise awari awon ibi ti awon omo ogun olote naa n fori pamo si.
wọn fọwọ si biliọnu lọna irinwo din milionu meje ati milionu mẹjọ naira
Leyin ti won dibo yan Ahmed
kí ó sì sọ wí pé, “Báyìí ni yóo rí fún Babiloni, kò sì ní gbérí mọ́, nítorí ibi tí OLUWA yóo mú kí ó dé bá a.
Gbogbo ọ̀nà eniyan ni ó dára lójú ara rẹ̀,ṣugbọn ọkàn ni OLUWA ń wò.
Ọgbẹni Ibrahim Abubakar lo ṣe ipo keji pẹlu mẹwaa le ni ẹẹdẹgbẹrin.
Gẹ̀gẹ̀ bí ìjábọ̀ ìròyìn, àwọn àgbàlagbà wọ̀nyí ṣe ikú pa ọkùnrin kan, ni ìgbìmọ̀ abúlée Panchayat ṣe dá wọn lẹ́bi.
34 Nítorínáà, ẹ má bẹ̀rù, agbo kékeré, ẹ ṣe rere; ẹ jẹ́ kí ayé àti ọ̀run àpáàdì parapọ̀ ṣe òdì sí yín, nítorí bí a bá kọ́ọ yín lé orí àpáta mi, wọn kì yíò lè borí.
O gbagbọ pe obinrin to ba n yan aale le fa iku fun ọkọ rẹ.
- Ẹgbẹ́ àgbẹ̀ kìlọ̀ Iléèwé Chrisland yóò wọlé padà lọ́jọ́ Ajé, wọ́n ní òfin ìgbélé coronavirus kò mú ìgbẹ̀kọ́ orí ayélujára Nàìjíríà yóò wo tí aráàlú bá bínú lórí àfikún igbele Covid-19 - Dele Momoodu O rọ awọn ọmọ Naijiria lati fi ara daa fun ọsẹ meji nitori anfaani gbogbo ọmọ Naijiria naa ni.
Yomi Fabiyi tọrọ idariji lọwọ Toyin Abraham lori ẹrọ ikansiraẹni Instagram rẹ, ki Toyin si fọwọ wọnu ninu ọdun tuntun.
Pius Adesanmi: Òní ni ẹ̀bí akọni Pius Adesanmi n ṣètò ìkẹyìn fún ogbontarigi náà
Ọrọ to sọ yi n fa ariyanjiyan, pẹlu bi awọn kan ṣe n sọ pe o ṣeeṣe ki aarẹ Muhammadu Buhari ma a koju igbelewọn ninu ile gẹgẹ bi ọkọ, bi ko ṣe koju oṣuwọn gẹgẹ bi aarẹ.
Ìrètí ń bẹ fún òmùgọ̀ju ẹni tí ó gbọ́n lójú ara rẹ̀ lọ.
Àwọn rèé19 Agẹmo 2020 Aláàfin ní tí kìí bá ṣe òṣèlú ni, Ìwó ló yẹ kó jẹ́ olú ìlú ìpínlẹ̀ Osun2 Bélú 2020 Alaafin Oyo: Àwọn onílù mí ló ń tú àṣírí ìkà èèyàn tó bá wọ ààfin mi - Aláàfin18 Ògún 2020 Alaafin: Tí kò bá sí ìbàlẹ̀ ọkàn fún mi láàfin Oba Oyo, mi ò ní dúró síbẹ̀- ayaba Aanu Adenike Adeyemi14 Bélú 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù UN: Nàíjíríà, ẹ sọ ìlò igbó fún ìwòsàn di òfin 27 Ẹrẹ̀nà 2018 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, UN sọ̀ fún Nàíjíríà, pé kí ó sọ lìlò igbó fún ìwòsàn di òfin Ní ọjọ́ ajé ni àjọ ìsọ̀kan orílẹ̀èdè àgbáyé (United Nations) ní, òun ti fòǹtẹ̀ lu ìlò èròjà igbó fún ìwòsàn, tó sì rọ orílẹ̀èdè Nàíjíríà láti dẹ ọwọ́ lóríi òfin tó de fífi ọwọ́ sí ìlò igbó bíi òògùn fún ìwòsàn àwọn èèyàn.
Bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé díẹ̀ ni àwọn ọmọ ogun Siria tí wọ́n wá, sibẹsibẹ OLUWA fi ọpọlọpọ ninu àwọn ọmọ ogun Juda lé wọn lọ́wọ́ nítorí pé wọ́n ti kọ OLUWA Ọlọrun baba wọn sílẹ̀.
Ṣugbọn nígbà tí mo bá ń retí ohun rere,ibi ní ń bá mi.
Pregnancy cravings: Ìgbésẹ̀ wo ní aláboyún lé gbé láti dẹ́kun ìjẹkújẹ nínú oyún?
Donald Trump ti gbà pé Coronavirus yóò burú jáì kí ǹkan tó dára fún Amẹ́ríkà Coronavirus yóò burú jáì kí nkan tó dára fún Amẹ́ríkà- Donald Trump Aarẹ ilẹ Amerika Donald Trump ti fi ikilọ sita pe ajakalẹ aarun Coronavirus ni ilẹ Amẹrika yoo buru ju bo se wa yii lọ ki nkan to dára.
Igbakeji aare orile ede Naijiria ,ojogbon Yemi Osinbajo ti rọ awọn ọmọ
A gbọ pe ifa lo maa n fa ọmọge ti yoo ru igba Ọṣun kalẹ laarin awọn ọmọbinrin ti Ataoja to wa lori oye ba bi.
Èmi ni ìmọ́lẹ̀ tí ó ńtan nínú òkùnkùn, tí òkùnkùn náà kò sì borí rẹ̀.
“Kọ ìwé yìí sí angẹli ìjọ Sadi:“Ẹni tí ó ní Ẹ̀mí Ọlọrun meje ati ìràwọ̀ meje ní: Mo mọ iṣẹ́ rẹ.
À ń dúró de òṣìṣẹ́ tó bá ṣèwọ́de, ẹ finmú káta òfin - Iléeṣẹ́ ọlọ́pàá Yoruba bọ, wọn ni ka wi fun ni ka to da ni, agba ijankadi.
Fun idi eyi, aarẹ Buhari ti ni ki wọn jẹ ki ofin ṣe iṣẹ rẹ lẹkunrẹrẹ.
 Ẹtan ti pọju ninu iṣẹ tiata, o ti bajẹ , o si ti pin yinkin, ko si le e to ogun ọdun mọ ti ẹka iṣẹ tiata yoo fi dojude.
Awọn iroyin miran ti ẹ le nifẹ si: Ero ara ilu lori owo awọn sẹnatọ Naijiria Amusa Dayo so wipe ko si eni ti ko ni baba isalẹ Igboro da paroparo lasiko abẹwo Buhari si Benue Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Àwọn arakunrin rẹ̀ bá bi í pé, “Ṣé o rò pé ìwọ ni yóo jọba lórí wa ni?
5m péré wá, ko kópa nínú ìbò abẹ́nú fún ipò gómìnà ní Ondo àti Edo - APC kéde Àwọn ìbejì mi kò le rìn dáadáa nítorí ọgbẹ́ tí wọ́n dá sí wọn lára ní ìgbèkùn - Akeugbagold Àfi ìgbà tí mo bọ́ sọ́wọ́ ọ̀tá mí nínú ìrìnàjò ìfẹ́- Roshan Àwọn dókítà ìpínlẹ̀ Eko tó ń yanṣẹ́lódì ti padà s'ẹ́nu iṣẹ́ Nigba ti gbogbo rẹ yoo fi rọlẹ ni iroyin jade pe awọn eeyan mẹta kan gbiyanju lati fi ipa wọ aafin ninu ọkọ ayọkẹlẹ kan.
Lẹ́yìn tí Lọti ti kúrò lọ́dọ̀ Abramu, OLUWA sọ fún Abramu pé, “Gbé ojú rẹ sókè, kí o wò ó láti ibi tí o wà yìí, títí lọ sí ìhà àríwá ati sí ìhà gúsù, tún wò ó lọ sí ìhà ìlà oòrùn títí dé ìhà ìwọ̀ oòrùn.
Bí ó bá jẹ́ pé a gbàgbé orúkọ Ọlọrun wa,tabi tí a bá bọ oriṣa,
Àlàáfíà ni àwa náà wà níhìn-ín,
Ìjọ̀ba Saudi ti tú Zainab tí wọ́n fẹ̀sùn òògùn olóró kàn sílẹ̀ Champions League: Ajax f'imú Tottenham fọn fèrè Kẹrẹ kẹrẹ, o ba bẹrẹ plu owo perete ẹgbẹrun lọna ogun naira to fi ṣe awọn nkan to kọkọ ṣe koko lati ni fun iṣẹ yii.
Eji Gbadero, ọmọ Ibadan àti jayé-jayé ọmọ ónílẹ̀ ti wọn yẹgi fun l'Eko Ẹbí Abiola Ajimobi kéde bí ètò ìsìnkú rẹ̀ yóò ṣe rí pé.
Iṣẹlẹ naa mu ẹmi awọn eniyan to niye lọ.
(Ẹ̀kọ́ àti àwọn Májẹ̀mú ti Ìjọ Àwọn Ènìyàn Mímọ́ Ọjọ́ Ìkẹhìn).
Oríṣun àwòrán, Instagram/theliberianinfluence Àkọlé àwòrán, Ààrẹ George Weah fìdí rẹmi pẹ̀lú ẹgbẹ́ agbábọ́ọ̀lù Liberia Henry Onyekuru ati Simeon Nwankwo lo gba ayo meji sawọn fun Nigeria ki agbabọọlu Kpah Sherman to d'ayo kan pada pẹlu pẹnariti.
Nígbà tí ó tó àkókò fún Ẹsita, ọmọ Abihaili ẹ̀gbọ́n Modekai, láti lọ rí ọba, Ẹsita kò bèèrè nǹkankan ju ohun tí Hegai, ìwẹ̀fà ọba tí ń tọ́jú àwọn ayaba, sọ fún un pé kí ó mú lọ.
Ni ọdún 2012 ó jẹ̀bi ẹsun ti wọn fi kan ni DR Congo nítori pe ó ṣe ẹni to ń ba gbé àwọn orin rẹ̀ síta lọ́nà ti kò tọ́, wọn si wọn ẹwọn oṣù mẹ́tà fún.
”Obinrin náà dáhùn pé, “Mo rí ẹbọra kan, tí ń jáde bọ̀ láti inú ilẹ̀.
Àwọn jàndùkú jí agbábọ́ọ̀lù Nàìjíríà méjì gbé lópòpónà Owo sí Benin Agbábọ́ọ̀lù Manchester United tẹ́lẹ̀, Marouane Fellaini lùgbàdì àrun coronavirus Nítorí coronavirus, Mikel Obi sá kúrò ní ikọ̀ Trabzonspor Ààrẹ Buhari sún eré ìdárayá àpapọ̀ Edo 2020 síwájú Paul Pogba gbé ètò owó dídá kalẹ̀ fún ààrùn Coronavirus Wọn sun idije agbaye naa to yẹ ko waye lọdun yii tẹlẹ siwaju nitori ajakalẹ arun Coronavirus to n da agbaye laamu lọwọlọwọ.
 bàbá amòye tún ń bá ọ ̀ rọ ̀ rẹ lọ pé : méjì là á wònìyàn ; bí ò jẹ ́ ti yínyìn , a jẹ ́ ti èébú .
 gbogbo atótónù àti awuyewuye to ń lọ lórí ọ ̀ rọ ̀ jìjì ni àwọn ará ìlú Ògìrììyàndá mọ ̀ .
Bẹ́ẹ̀ ni ẹ óo ṣe mú ọrẹ yín wá fún OLUWA ninu ìdámẹ́wàá tí àwọn ọmọ Israẹli bá san fun yín.
Hagari ni òkè Sinai ní Arabia tíí ṣe àpẹẹrẹ Jerusalẹmu ti òní.
Hotamu, arakunrin rẹ̀, bí ọmọkunrin mẹrin: Sofa, Imina, Ṣeleṣi ati Amali.
" Ẹfunroye Tinubu - Ògbóǹtagí oníṣòwò, olówò ẹrú àti afọbajẹ Samuel Ajayi Crowther, òjíṣẹ́ Ọlọ́run tó gbé èdè Yoruba lárugẹ Mọrèmi Àjàṣorò, akọni obìnrin tó gba Ilé Ifẹ̀ sílẹ̀ lóko ẹrú Asiko yii si ni irufẹ iyalọmọ bayii yoo wa fi ika hanu pe ko ba san, ki oun ti mọ awọn ẹkọ kan nipa ti a se n fun ọmọ lọyan, ti yoo fi mu amuyo.
Awọn adajọ to n da oju ẹjọ ru Baṣọ̀run Gáà: Ó yan ọba mẹ́rin, tó sì pa ọba mẹ́rẹ̀ẹ̀rin àmọ́ ọba karùn-ún ló pa á Irọ́ ni pé a fẹ́ fowó kún owó iná mọ̀nàmọ̀nà- NERC Al Shabab ṣe ìkọlù sí ibùdó ogun America ní Kenya, ẹ̀mí mẹ́ta lọ síi Ó ṣeésẹ kí ọkùnrin tó n mu àmujù ọtí ó maa lo ìwà ipá pẹ̀lú ìyàwó rẹ̀ 3.
Àwọn ọmọ ìgbìmọ̀ ìdìbò abẹ́lé ìpińlẹ̀ Ondo"" 1."
Amọ, ohun ti awọn eniyan sọ ni pe, bi Tinubu ṣẹ na ọwọ rẹ soke ni idibo sipo gomina lọdun 2016 lasiko ti ko si ẹni to mọ ọ rara, ti ko tilẹ di ipo ọṣelu kankan mu tẹlẹ ki o to di igba naa.
Awọn agbabọọlu Tottenham naa ba tun da ẹsẹ ru fun Mancity ni Lucas Moura ba tun da ekeji naa pada.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù ÀJọ UN bu ẹnu àtẹ́ lu bí Nigeria se kó àwọn ọmọ Cameroon pada silu wọn 2 Èrèlè 2018 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, ÀJọ UN bu ẹnu àtẹ́ lu bí Nigeria se kó àwọn ọmọ Cameroon pada silu wọn Ajọ isọkan agbaye, United Nations sọ wipe tipa tipa ni orilẹede Naijiria fi ko ẹgbẹ awọn ọmọ orilẹede Cameroon kan to ngbe lorilẹede Naijiria pada si ilu wọn.
" Awọn ara adugbo olusosun ke gbajare si ijoba Ewe, Igbakeji alaga fun ibudo atọkọse naa, Ọlaniyi Adeoti, ti sọ saaju fun akọroyin BBC pe awọn asoju wọn ti kọkọ lọ ri awọn osisẹ ileesẹ ọrọ ayika ni Alausa nigba to ku wakati diẹ ki wọn wa le awọn kuro ni ibudo naa.
Ó ní, “Ẹ wò ó, eniyan mẹrin ni mo rí yìí, wọ́n wà ní títú sílẹ̀, wọ́n ń rìn káàkiri láàrin iná, iná kò sì jó wọn, Ìrísí ẹni kẹrin dàbí ti ẹ̀dá ọ̀run.
 Bakan naa ni, igbakeji aare yoo tun maa
Ẹ jẹ ki eyi jẹ ara ijijagbara tako iwa ibajẹ, ati ipe si ijọba lati sin wa lotitọ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Angel Gomes: Angel Gomes, agbábọ́ọ̀lù Manchester United ṣàlàyé ohun gan tó gbé e dé ṣọ́ọ̀ṣì T.
Alaafia ni, alaafia ni fún àwọn tí ó wà ní òkèèrè, ati àwọn tí ó wà nítòsí;n óo sì wò wọ́n sàn.
- Ẹ tún wá mi d’;e ìhín!
Dókítà Baka sọ pé, ẹni tó bá sọ fún ọ pé, ayé ti sú òun, lé fi ẹrin sọ ọ́ tàbi kí o léjú, sùgbọ́n àmi ńla ni pé, ó ṣeeṣe ki irú ẹni bẹ́ẹ̀ maa rònú láti pa ara rẹ̀.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Pẹlu ija yii, Adesanya ti ja ija mọkandinlogun, o si ti bori gbogbo rẹ.
Anfaani ni èyí yóo jẹ́ fun yín láti jẹ́rìí.
Inú bí Kaini, ó sì fa ojú ro.
Bẹ́ẹ̀ ni OLUWA ṣe fún àwọn ọmọ Israẹli ní ilẹ̀ tí ó ti búra fún àwọn baba wọn.
Daniẹli bá lọ sí ọ̀dọ̀ Arioku, tí ọba pàṣẹ fún pé kí ó pa àwọn ọlọ́gbọ́n Babiloni; ó fi ọgbọ́n ati ìrẹ̀lẹ̀ bá a sọ̀rọ̀, 
O ṣá ti mọ̀ mí, èmi iranṣẹ rẹ, OLUWA Ọlọrun!
Lẹyin igba yẹn, a ti ri iyatọ lara gbogbo ile, awọn ọmọ Naijiria dide iranlọwọ inu mi ti ẹ dun.
O ṣójú mí kóró bí wọ́n ṣé fí àdó olóró pa Dele Giwa lọdún 1986- Soyinka Nigba ti ikọ BBC n ba Kabiyesi sọrọ lori boya awọn maalu naa wọ ilẹ Ooṣa, Ọba alaye naa ni, wọn ko le sọ boya arinfẹsẹsi lo jẹ fun awọn maaluu naa ṣugbọn gbogbo rẹ yoo ni yanju.
Ọwọ tẹ akẹkọ to fowo ileewe rẹ ta MMM Àwọn olùdókòwò MMM ń fi apá jánú Àìsan ọkàn pa olùdásílẹ̀ sogúndogójì MMM Wọ́n ni gbogbo ìgbìyanju atí tẹ̀siwaju pẹ̀lú sogúndogójì ọ́hun kò ní ṣeéṣé.
Alukoro ọlọpaa ni ẹbi awọn ti wọn ji gbe kankan ko tii kan si ile iṣẹ ọlọpaa lati fun wọn ni iroyin kankan ṣugbọn awọn n ṣe iṣẹ awọn lọwọ lọwọ.
Akowe agba fun ile ise to n ri
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Onínúfùfù ni Saheed Oṣupa, ṣùgbọ́n èèyàn dáradára ni-Taye Currency Inú mi kìí dùn torí ẹ̀ẹ̀kan lọ́dún mẹ́rin ni ọjọ́ ìbí mi máa ń wáyé"" Èmi àti Kolington kò fẹ́ra padà o, ọba Wákà kò fẹ́ ọba Fuji mọ́ - Salawa Abeni Kàyééfì ńla!"
‘Ọ̀run ni ìtẹ́ mi, ayé ni tìmùtìmù ìtìsẹ̀ mi.
" Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ó dìgbà!
Àwọn nǹkan tí a kò lè fi ojú rí ni yóo wà títí laelae.
Bí àwọn ẹlòmíràn bá ní ẹ̀tọ́ láti jẹ lára yín, ṣé ẹ̀tọ́ tiwa kò ju tiwọn lọ?
Amọṣa gẹgẹ bi ọpọlọpọ ṣe mọ nipa awọn oloṣelu Naijiria, ko ṣeeṣe ko gba f'Ọlọrun bẹẹ.
“Ìwọ ọmọ eniyan, kọ orin arò nítorí ohun tí ń bọ̀ wá ṣẹlẹ̀ sí ọba Tire.
Ijọba lee pawo wọle lati ara ọdun egungun - OluwoNinu ọrọ rẹ pẹlu ikọ BBC Yoruba, Oluwo ti ilu Iwo, Ọba Abdulrasheed Adewale Akanbi, Telu kinni, ṣe alaye wipe akanṣe ọdun egungun naa jẹ nnkan iṣẹnbaye, ti o si tun jẹ nnkan ti wọn fi n da ọba lara ya.
Ojúkòkòrò ni ọmọ ìyá ìlara, àti ìlara àti owú jíjẹ ọ̀kan náà ní.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ilupeju Killing: Àṣìta ìbọn pa ẹnìkan lásìkò t'ọ́lọ́pàá kojú adigunjalè 15 Agẹmo 2019 Oríṣun àwòrán, POLICENG_PCRRU/TWITTER Ileeṣẹ ọlọpaa ipinlẹ Eko ti fidi rẹ mulẹ pe lootọ ni ibọn pa arakunrin kan lasiko ti awọn oṣiṣẹ ajọ ọlọpaa SARS ati awọn janduku kan koju ara wọn lagbegbe Ilupeju nipinlẹ naa.
Libya shipwreck: Aṣàtìpó lọ sí Yuropu 45 kú sínú òkun ní Libya, 37 m'órí bọ́
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Operation Amotekun: Amotekun dé!
Àwọn Farisi sọ fún un pé, “Ò ń jẹ́rìí ara rẹ, ẹ̀rí rẹ kò jámọ́ nǹkankan.
Bi nkan ti ṣe ri bayi, ko si ẹni to le sọ ibi ti Maina ati ọmọ rẹ salọ lati igba ti igbẹjọ wọn ti bẹrẹ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Blacksmith: èmí ni ìran keje tó jogún iṣẹ́ àgbẹ̀dẹ yii- Alatiṣe Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Ọkàn wa ní ìrètí lọ́dọ̀ OLUWA;òun ni olùrànlọ́wọ́ ati ààbò wa.
Wò ó bí Alaafin àti aya àkọ́fẹ́ rẹ̀, Olorì Abibat ṣe pàdé ní èwe Coronavirus ti fa ọ̀wọ́ngógó oúnjẹ ní ìpínlẹ̀ Eko, Kano, Rivers àti Abuja- NBS Àwọn èrò yarí lórí sísan owó àyẹwò covid-19 bí bàálù ilẹ̀ òkèèrè ti ba s'Abuja lẹyìn oṣù márùn ún Ẹ wo ààrẹ orílẹ̀-èdè tó ń ṣèdárò Ẹja akóredé tó d'olóògbé Nibayii, eeyan 1,075 lo ti ba ajakalẹ arun naa lọ ni Naijiria.
Ní ọjọ keedogun oṣu kẹfa, wọn yinbọn pa ọmọ Naijiria kan Eniola Aluko ni Plumstead.
Liverpool 17:30February 12 21:00 Chelsea ?
Awọn eeyan naa ni wọn ṣawari orisun omi orioke olumirin.
Oríṣun àwòrán, others Awijare agbẹjọro Hushpuppi, Pissetzky: Bi o tilẹ jẹ pe agbẹjọro Hushpuppi, Gal Pissetzky si n tẹnumọ pe ki wọn gba oniduro Hushpuppi, sibẹ ẹbẹ rẹ ko wọle leti adajọ.
Èrò mi lórí ọ̀rọ̀ yìí ni pé ohun tí ó dára jùlọ fun yín ni.
Iroyin ti kọkọ sọ pé aarẹ Muhammadu Buhari ti pasẹ pe ki aarẹ NFF naa lọ foju winna igbẹjọ, lori awọn ẹsun ti wọn fi kan ọhun.
Bí kò bá sì ní ọmọbinrin, ilẹ̀ ìní rẹ̀ yóo jẹ́ ti àwọn arakunrin rẹ̀.
Tokunbo-Awolowo Dosumu; igbakeji gomina Ipinle Oyo, Onimo ero Rauf Olaniyan ati
si ofin yii yoo jẹ ki iṣẹ awon aṣagbeyẹwo owo ilu tona sii.
3 egbegberunketa ( idamerin gio oloruko lagbaye ati idamarun gio agbaye fun ipin agbara iraja ) .
Oloogbe Worlu je iyaafin oludari agba ile-ise oniroyin Voice of Nigeria tele ri, Sam Worlu.
 ulcerans  a má a pọ oró tí a mọ ̀ sí mycolactonejáde , èyí tí ó má a ndín ìlànà iṣẹ ́ àtako àrùn kù , tó sì má a nfa ikú ."
Ìbà pọ ́ njú-pọ ́ ntọ ̀ , tí a mọ ̀ láti ìṣẹ ̀ wá sí yẹ ́ lò jaki tàbí àjálù pupa , jẹ líle Àkóràn àrùn .
Seun Adigun, Ngozi Onwumere, Akuoma Omeoga ati Simidele Adeagbo lati orilẹede Naijiria ni yoo maa kopa ninu idije kẹkẹ ori yinyin.
Kò sí ohun ìjà tí a ṣe láti fi bá ọ jàtí yóo lágbára lórí rẹ.
Ìwọ ló ni òkú ọmọ, ààyè ọmọ ni tèmi.
Garba sọ pe ijọba ipinlẹ ti ṣetan lati gba ẹnikẹni pẹlu ẹran-ọsin wọn ni ipinlẹ naa.
Mo fẹ́ kí ẹ mọ̀ dájúdájú pé, ẹni tí kò bá gba ìjọba Ọlọrun bí ọmọde, kò ní wọ inú rẹ̀.
Ẹnikẹni to ba ba mi ri i ko ba mi sọ fun un pe mo tọrọ aforiji.
Gege bi oro minisita oun, mimo awon onibara won je koko kan gboogi si ayipada lilo awon ero igbalode, mimu igberu ba ile-ise amohun-maworan ati awon ohun elo fun ile-ise naa.
PFN: Fatoyinbo kọ̀ láti yọjú ni ìwádìí wa kò ṣe parí Biodun Fatoyinbo fi ipò sílẹ̀ lorí ẹ̀sùn ìfipábánilòpọ̀ Ìjọ Satani dá MI lóhùn lórí ọ̀rọ̀ Fatoyinbo Ọlọ́pàá Germany ń wádìí àfurasí mẹ́rin nínú àwọn tó kọlu Ekweremadu ni Germany Gẹgẹ bi iroyin ti o tẹwa lọwọ, bi Leon ṣe n tu odi naa se, ti o si kọ ẹyin si awọn kiniun ti oun se itoju fun, ni ọkan lara wón bu u jẹ ni ọrun.
Alex Akinyele jade laye loni ọjọ kẹẹdogun, oṣu kọkanla, ọdun 2019.
Oríṣun àwòrán, Odun Adekola Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Dino Melaye kan sárá sí ààrẹ àná, Jonathan, ó ní irú olóṣèlù rẹ̀ ṣọ̀wọ́n láwújọ16 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Regent female kings: Wo àwọn Adelé-Ọba aládé méje tó jẹ́ obìnrin nílẹ̀ Yorùbá15 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Tinubu 2023: Àwọn èèkàn ilẹ̀ Yorùbá ń ṣèpàdé ṣáájú dídìbò fún Tinubu ní 202315 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Adeleke lo jáwé olúborí nínú ìdìbò abẹnu ẹgbẹ náà, eyi tó waye losu keje odun yii, pẹlú ìbò 1,569, nigbati Akin Ogunbiyi n pọn lẹyin rẹ pẹlu ìbò 1,562.
kí gbogbo àwọn tí kò gba òtítọ́ gbọ́ lè gba ìdálẹ́bi, àní, àwọn tí wọ́n ní inú dídùn sí ìwà ibi.
Ijọba ko ti i sọ ọjọ ti awọn eeyan wọn yii yoo pada bẹrẹ iṣẹ wọn, lẹyin ayẹwo naa, ṣugbọn o sọ pe ki awọn to ni ileeṣẹ naa mura silẹ lati tẹle ilana tuntun naa, nitori pe coronavirus ti mu ayipada ba ayika wa.
Eyi kun ara awọn afẹnuko awọn asofin agba orilẹede Naijiria nibi ijoko wọn ni ọjọ isẹgun.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Joke Silva: Olu, ó tó gẹ́ pẹ̀lú obìnrin yìí níkan tó ń ba ẹ ṣeré ìfẹ́ nínú sinimá!
Aláboyún oṣù mẹ́jọ kú lẹ́yìn tí ejò bù ú jẹ nílé ìyàgbẹ́ ilé rẹ̀
Atiku banújẹ́ sí ìròyìn pé Amẹ́ríkà dínà mọ́ àwọn ọmọ Nàìjíríà Wo ìdí tí orílẹ̀-èdè America ṣe tako ìyànsípò Okonjo-Iweala gẹ́gẹ́ bi olórí ajọ WTO Wo àwọn Ṣọ́ọ̀ṣì Nàìjíríà àti l'Áfíríkà tó ń wólẹ̀ àdúrà kí Trump lè wọlé ìbò ààrẹ America Ẹ wo Daniel tí wọ́n fẹ́ yẹgi fún lẹ́yìn tí US kò ṣe irú ẹ̀ fún odidi ọdún 17 7) April Ademiluyi: Ngozi Akubuike, ati Benjamin Osamenam, naa n dije.
Lara awon ti yoo lo soju igbimo asofin lorile ede Russia ni, adari egbe  to kere julo nile igbimo asofin , asofin  Godswill Akpabio,oludari eto nile igbimo asofin ,Senator Olusola Adeyeye, alaga igbimo asofin fun oro ile okeere Monsurat Sunmonu,alaga igbimo fun omo-ogun ofurufu Duro Faseyi, alaga igbimo fun ere idaraya ati oro to je mo awon odo, Obinna Ogba ati igbakeji alaga  igbimo fun omo-ogun, Ibrahim A.
Ǹ báà ní ẹ̀bùn wolii, kí n ní gbogbo ìmọ̀, kí n mọ gbogbo àṣírí ayé, kí n ní igbagbọ tí ó gbóná tóbẹ́ẹ̀ tí ó lè ṣí òkè ní ìdí, tí n kò bá ní ìfẹ́, n kò já mọ́ nǹkankan.
Oríṣun àwòrán, Lateef Ọkọ̀ bààlú tó gbéro àádọ́ta pòórá lẹyìn tó gbéra láti Jakarta Njẹ́ o mọ̀ pé àṣírí rẹ kò bò mọ́ lórí Whatsapp nítorí ìlànà tuntun tí wọ́n gbé síta?
25 Agẹmo 2020 BBNaija: Terry Waya sọ oun tó fojú Kiddwaya rí nílé nígbà tó ń bẹ̀bẹ̀ láti lọ BBNaija28 Ògún 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Absalomu ati gbogbo àwọn ọmọ Israẹli tí wọ́n wà pẹlu rẹ̀ wọ Jerusalẹmu lọ, Ahitofeli sì wà pẹlu wọn.
ohun di mimo lasiko to n dahun si iroyin eleje kan lori ero kalekaako ti o so
Ṣugbọn kò pe èmi iranṣẹ rẹ sí ibi àsè náà, kò sì pe Sadoku alufaa, tabi Bẹnaya, ọmọ Jehoiada, tabi Solomoni iranṣẹ rẹ.
’ Mo sọ fun yín, ẹ gbé ojú yín sókè kí ẹ sì rí i bí oko ti pọ́n fun ìkórè.
Biden la oludije ẹgbẹ Republican Donald Trump mọlẹ ninu eto idibo tawọn ọmọ ilẹ Amẹrika ti tu yaya tu yaya jade.
Ṣugbọn ẹni tí ó bá ń hùwà òtítọ́ á máa wá sí ibi ìmọ́lẹ̀, kí iṣẹ́ rẹ̀ lè hàn pé agbára Ọlọrun ni ó fi ń ṣe wọ́n.
Àwọn afọ́jú meji kan jókòó lẹ́bàá ọ̀nà.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 2020: Ọdun 2020 yii ko nìí nira fún àwọn tó bá bẹ̀rù Olorun O ni o na olori abule nitori pe ko baa gbe ẹru rẹ lọ sile to to maili mẹwaa sira wọn.
Asoju ẹgbẹ́ náà to ba akoroyin sọ̀rọ̀ ni Port Harcourt, Ogbeni Enafaa Georgewill ni ki ile iṣẹ́ ọlọpaa san owo ilé iwosan awọn to kù.
kí á má ṣẹ̀ṣẹ̀ sọ ti eniyan tí ó dàbí ìdin,tabi ọmọ eniyan tí ó dàbí ekòló lásánlàsàn!
Ẹnìkan lè bi baba rẹ̀ pé:‘Irú kí ni o bí?
"Ẹ jẹ ka sọra se nipa arun naa, ka si sisẹ tọ idaabo bo ara wa nitori ojuse wa ni lati maa fi oju sọri bii alakan.
Olè gbé òrùka ìgbéyàwó mì ní Eko Bíbéèrè fún ìbálòpọ̀ gbogbo ìgbà sọ ìyàwó ilé dèrò ilé ìwòsàn Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Kayeefi: Facebook ni Wolii Arole Jesu fi tàn an wọ agbo, orí rẹ̀ ni wọ́n fi s'owó Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Amọ o ni sibẹ aarẹ Muhammadu Buhari ṣi n lepa lati yọ orukọ igbimọ naa kuro lara awọn ẹgbẹjẹgbẹ to forukọ silẹ labẹ ijọba.
Kini wọn n pe ni uterus didelphys?
Oyebode ni awọn ti wọn yọ kuro lẹgbẹ lo ko ara wọn jọ lati kede pe awọn naa yọ Gomina Fayemi nipo.
Ninu iṣẹ́ yìí ni mo ti ń jìyà títí mo fi di ẹlẹ́wọ̀n bí ọ̀daràn.
Lára Ìjọba Ológun àkọ́kọ ti Ọ̀gágun Aguiyi Ironsi ti jẹ́ Olóri Ìjọba ni wọn ti fi Ọ̀gágun Adékúnlé Fájuyi  jẹ Olóri ni ipinlẹ̀ Yorùbá dipò Òṣèlú Ládòkè Akintọ́lá ti àwọn Ológun pa.
Find out more I have a TV Licence.
Absalomu á wí fún un pé, “Wò ó, ẹjọ́ rẹ tọ́, o sì jàre, ṣugbọn ọba kò yan ẹnikẹ́ni gẹ́gẹ́ bí aṣojú rẹ̀, láti máa gbọ́ irú ẹjọ́ báyìí.
Ẹnikẹ́ni tí ó bá sì ní ohunkohun láti bèèrè lọ́dọ̀ OLUWA yóo lọ sí ibi àgọ́ àjọ náà, tí ó wà lẹ́yìn ibùdó àwọn ọmọ Israẹli.
Kò sí ìdánwò kan tí ó dé ba yín bíkòṣe irú èyí tí ó wọ́pọ̀ láàrin eniyan.
Iroyin ti a gbọ ṣalaye pe, o ti pe ọsẹ meji bayii ti kọmiṣọna naa ti dubulẹ aisan ki o to jade laye loni.
Toyin Abraham Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Báwo ni ọ̀rọ̀ yín ti ṣe lè dára nígbà tí ẹ̀yin fúnra yín kò dára?
Ọba pàápàá fi ọwọ́ gbọn erùpẹ̀ tí ó lè mọ́ ọ lára àti ní ìdí tí o mú kí ìdí rẹ di pupa.
Ọ̀pọ̀ àwọn alába ṣiṣẹ́ pọ̀ gómònà ló bẹnu ẹ̀tẹ́ lu ìwà ti Ayiloge wu yìí to fi mọ olurànlọ́wọ́ pàtàkì si gomina lóri ìrìnnà, Tobi Ogunleye.
Lẹ́yìn èyí, Jesu tún fara han àwọn ọmọ-ẹ̀yìn ní òkun Tiberiasi.
Fi nǹkan ẹ̀jẹ́ kan lélẹ̀ fún mi lọ́dọ̀ rẹ;ta ló wà níbẹ̀ tí yóo ṣe onídùúró fún mi?
Òkú ọmọ tuntun pòórá nílé ìgbókúpamọ́sí nílùú Akurẹ Kayeefi: Deji pa èèyàn mẹ́sàn án nítorí ìfẹ́ Kayefi: Dókítà ló ṣe iṣẹ́ abẹ tó pa ìyàwó mi láì gba àṣẹ lọ́wọ́ mi Tani Deji Adenuga to dáná sun ènìyàn mẹ́jọ?
 erò yìí hàn nínú òwe yorùbá kan pé  ẹni mojú ọwá là ń bẹ ̀ sọ ́ wá , olójú ọwá kan kò sí bíkòṣe ayaba "" ."
 Ewe, awon to n wa isokan, ilosiwaju ati alafia orile-ede yii po ju awon alatako re lo, leyi ti o si farahan gbangba-gbangba pe, won ko le e bori.
Da ẹ̀jẹ̀ wọn sí ara pẹpẹ kí o sì fi ọ̀rá wọn rú ẹbọ sísun olóòórùn dídùn sí mi.
''Gbogbo igba ti wọn ba wa sile lati Abuja ni wọn ma n sere pẹlu awọn onisẹ ọwọ mẹkaniki wọn, ni aaye igbafe to wa ladugbo Ajitadundun.
Ó kọ́ ibùdó àwọn ọmọ ogun káàkiri ilẹ̀ Edomu, gbogbo àwọn ará Edomu sì ń sin Dafidi.
Banki Nàìjíríà, CBN ṣàlàyé nípa àwọn tó máa rí gbà nínú owó ìrànwọ́ N75b tíjọba gbé kalẹ̀ Ilé aṣòfin ìpínlẹ̀ Oyo jáwée lọ sinmi nílé fún alága ìgbìmọ̀ mẹ́tàlá káàkiri ìjọba ìpínlẹ̀ Wo ọ̀nà àbáyọ fún àwọn akẹ́kọ̀ọ́ tí àjọ WAEC gbẹ́sẹ̀ lé èsì ìdánwò wọn Wo ǹkan tó yẹ kí o mọ̀ nípa Joe Biden, tó ń kojú Trump nínú ìbò America 'Ìdí tí kámẹ́rà táa rí ní Lekki Tollgate kò fi ká gbogbo ìṣẹ̀lẹ̀ tó wáyé rè é' Ni ana ode yii ni ẹgbẹ ASUU ni iyansẹlodi awọn olukọ to n lọ lọwọ yii nikan lọna abayọ lati ri daju pe ijọba ko doju awọn ile ẹkọ fasiti Naijiria bọlẹ patapata.
Akoba to n se ni pe o le ko irẹwẹsi ọkàn bá onitohun tabi ko máa tètè gbagbe nkan tabi ko sí ma le kẹkọọ bo ti ṣe yẹ.
Alukoro ile isẹ ọlọpaa, Moshood Jimoh lo lede ọrọ naa ninu atẹjade kan.
“Ìran tí mo rí yìí bà mí lẹ́rù pupọ, ọkàn mi sì dààmú.
Ọkan lara awọn ọmọ naa, Usman, n mura fun igbeyawo rẹ, ti ikeji, Musa, si ti ni idile ti ẹ.
"O ni o wu oun ki oun wa lori eto naa di ọjọ ikọkandinlọgọrun ṣugbọn ""ẹlẹran ara ni mi, mo ja kulẹ, mo si tun jakulẹ lọpọ igba""."
Àwọn ọmọ ogun Elamu gbé ọfà wọn kọ́ èjìká,pẹlu kẹ̀kẹ́-ogun ati àwọn ẹlẹ́ṣin,àwọn ọmọ ogun Kiri sì tọ́jú asà wọn.
Agbẹnusọ fun Ileeṣẹ ọlọpaa ni ipinlẹ Eko, Bala Elkana sọ wi pe ko si idigunjale ni ipinlẹ Eko ati Ogun bi awọn eniyan se n polongo rẹ.
Wọ́n bá sọ fún mi pé, “O níláti tún kéde fún ọ̀pọ̀ àwọn eniyan ati oríṣìíríṣìí ẹ̀yà ati àwọn orílẹ̀-èdè, ati ọpọlọpọ ìjọba.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ṣé o mọ̀ pé àwọn kan ń fi onídùúró ṣe òwò?
OLUWA dá a lóhùn pé, “Pada lọ sinu aṣálẹ̀ ẹ̀bá Damasku.
Ìwé eré oníṣe orì ìtàgé ni ìwé yìí .
Nibi ipade Commonwealth to pari laipẹ yii, anfani idokowo ogoje miliọnu poun jẹ yọ fun Naijiria ati orilẹede Pakistan.
" Ẹ̀ṣọ́ Amotekun ní láti ṣiṣẹ́ pọ̀ pẹ̀lú ọlọ́pàá agbègbè- Ọ̀gá ọlọ́pàá Naijiria Ìpínlẹ̀ Oyo, Ogun, Ondo buwọ́lu àbádòfin Àmọ̀tẹ́kùn Ẹ̀yin obìnrin, ẹ fi òdòdó ṣe ẹ̀bùn ọjọ́ olólùfẹ́ fún ọkùnrin dípò kẹ gbà kó já òdòdó ara yín"" Ẹgbẹ́ alátakò ló sanwó fáwọn èèyàn kan láti pariwo lé ààrẹ Buhari lori - Iléeṣẹ́ ààrẹ Arisekola ló fún mi ní ilẹ̀ tí ìjọba Ọyọ gbẹ́sẹ̀ lé, ń kò ní gbà - Ajimobi ""Ipinlẹ Eko ti ni nnkan to jọ mọ nnkan ti wọn sọ yẹn tipẹtipẹ, ko to di akoko yii."
Ẹ ya ara yín sí mímọ́, ẹ̀yin ati àwọn eniyan yín, kí ẹ baà lè gbé Àpótí Majẹmu OLUWA Ọlọrun Israẹli wá síbi tí mo ti tọ́jú sílẹ̀ fún un.
ẹni tí ó wá ní àwòrán Ọlọrun, sibẹ kò ka ipò jíjẹ́ ọ̀kan pẹlu Ọlọrun sí ohun tí ìbá gbé léjú.
Òun ń rìn bọ̀, bàbá mi náà ń rìn lọ, ìgbà tí ó si kù díẹ̀ kí wọn pàdé, àwọn méjéèjì tún dúró wọ́n ń wo ara wọn – gọngọ máa sọ.
Sugbọn sa orukọ titun wọn yii ko fi bẹ yẹn dara.
Eyi lo bi ọrọ ki ẹ kọkọ maa gba aṣẹ lọwọ obi ọmọde ki ẹ to fi abẹrẹ tabi oogun kankan dan ara wọn wo.
Yóo dojú rẹ̀ rú,yóo sì fọ́n àwọn eniyan inú rẹ̀ ká.
"Ọpọlọpọ igba ipọnju ni mo la kọja ṣugbọn mi o ni gbagbe bi o ṣe ka mi lara gan nigba ti mo fi de ipele ẹkọ kẹjọ ati ikẹwa atii lọdun ti mo wọ ile iwe fasiti.
Nínú ọgbà àwọn ológun ní Inal àti àgbègbè rẹ̀, wọ́n pín àwọn ológun yẹ́lẹyẹ̀lẹ, wọ́n rì wọ́n mọ́lẹ̀ ní òòyẹ̀,  wọ́n yìnbọn lù wọ́n, wọ́n sì yẹgi fún wọn ní ìrántí òmìnira orílẹ̀-èdè náà lọ́dún 1990.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Àwọn ọba Yorùbá kan rèé tí wọ́n rọ̀ lóyè, tí ọba míràn jẹ lójú ayé wọn Kí ló fà ogun Ìjàyè àti ìṣubú Kurunmi, ìfẹ́ ìlú ni àbí orí kunkun?
Petrol price in Nigeria: Ìjọba àpapọ̀ ti kéde àdínkù owó epo bẹntiróòlù sí N162.
Eleyele-Dugbe ANCE Road bayii ti di Oba Saliu Adetunji road.
Bákan náà ni fọ́nran kan jẹyọ lójú òpó twitter níbi ti àwn ará ìlú ti ń pe fún ìrànwọ́ láti pa iná náà.
Oríṣun àwòrán, @seyimakinde Àkọlé àwòrán, Oluwaseyi Makinde Lọdun 2017, amoju ẹrọ Makinde pada si ẹgbẹ oṣelu rẹ tẹlẹ, PDP; o ni kii ṣe tori anfani ti oun yoo jẹ loun ṣe dara pọ mo egbe PDP, bi ko se fun idagbasoke ipinle Oyo nipa wiwa ojutu si opolopo isoro to n doju ko ipinle naa.
Amọ, awọn ẹya Yoruba lo gba iwe Ireke Onibudo bii igba ọtin, ti o si pọn dandan fun ẹnikẹni to ba ko Ede Yoruba.
Child Labour: Òbí mi kú nígbà ti mo wà lọ́mọ́ ọdún kan'
Jakọbu bá fún Esau ní àkàrà ati ẹ̀bẹ ati ẹ̀fọ́.
“Ní ọjọ́ náà, eniyan yóo máa sin ẹyọ mààlúù kékeré kan ati aguntan meji péré, 
Ọwọ́ tẹ ọkùnrin tó ya 'Blue film' nínú igbó Osun Osogbo, tó tún fi sorí ayélujára Èèyàn kan kú nígbà tí Reluwé kọ̀lu ọkọ̀ mẹ́ta nílú Eko Ó yẹ kí Sotitobire gbọ́ ìdájọ́ lónìí ṣùgbọ́n ẹ wo bí ilé ẹjọ́ ṣe tún ṣe é Ọsán jáá!
Ta ni jẹ́ aláìlera tí n kò ní ìpín ninu àìlera rẹ̀?
Sola Allyson, olorin Ẹmi ni orin àìmọ ààlà ìfẹ́ àti àṣejù ń mú àwọn olólùfẹ́ kóbá àye àwọn olórin
Ko si awọn to n beere lati ra epo rọbi lagbaye bayii nitori aṣẹ konileogbele kaakiri agbaye eleyi to ti ti ọpọlọpọ awọn eeyan mọle jakejado agbaye.
    Nígbà tí ó ti sọ báyìí, mo mọ̀ pé ó rí mi, mo rọra dide láàrin ẹka igi tí mo fò tagbáratagbára mo balẹ̀ síwájú ibi ti iwin náà wà, wéré ó ti fò tì mí ṣùgbọ́n kí ó tó kàn mi lára, mo ti dide mo fi iré síi, èyin ọ̀rẹ́ mi nnǹkan dé, Ẹlẹ́gbára náà gbé eré dà sílẹ̀ o, ó ń sáré oúnjẹ, èmi ń sáré ikú, ọ̀r[sn di gburururururu!
Bakan naa ni wọn fi panpẹ ofin gbe laye ọgagun Sani Abacha to si lo oṣu mẹsan an latimọle ki wọn tu silẹ lẹyin iku ọgagun naa.
Ọpọlọpọ àwọn ẹlẹ́tàn ti dé inú ayé, àwọn tí kò jẹ́wọ́ pé Jesu Kristi wá ninu ara eniyan.
“Jobu, ṣé o rò pé ó tọ̀nà,kí o máa sọ pé, ‘Ọ̀nà mi tọ́ níwájú Ọlọrun?
Ẹ yọ mí látìmọ́lé DSS, ó lòdì s'ẹ́tọ̀ọ́ mi- Ṣowore Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Yollywood: Sinimá Ajé Ọjà tún so Fathia àti Saheed Balogun pọ̀ nínú Sinimá Ààrẹ sọ èyí di mímọ lọ́sàn òní lórí àtẹjíṣẹ́ Twitter rẹ̀, ó fi kún pé bi ìjọba ṣe ń rọkun sápa àwọn ọmọ ogun rẹ̀ tí wọ́n sí ń fún wọn ìdánilẹ́kọ̀ọ́ tó yẹ, tí ìjọba kò si ṣe à[rẹ lóri mímú ìwúri ba àwọn ọmọ ologun, o ti di dandan ki wọn ṣe àṣeyọri.
Àṣà fi fẹ́ iyàwó púpọ̀ ṣe kókó nitori bibi ọmọ púpọ̀ pàtàki ọmọ ọkùnrin fún irànlọ́wọ́ iṣẹ́-oko.
Ni nkan bi ọdun 1960, yatọ si awọn ọrọ to ma n kọ nipa ara rẹ sinu iwe iroyin, o kọ lẹta lati bu ẹnu ẹtẹ lu bi ijọba ṣe n ṣe awọn olukọ, lẹyin to ri ọkan lara awọn olukọ to kọ nileewe, to wọ akisa aṣọ.
Arabinrin Svetlana Tikhanovskaya lo dije dipo ọkọ rẹ to wa ni atimọle, ti o si dari ifẹhọnuhan ọlọgọọrọ.
Ṣugbọn láti òní lọ, n óo bukun yín.
Makinde fẹ́ san ₦30,000 fáwọn òṣìṣẹ́ l’Oyo, yóò tún kọ́ ọjà ìgbàlódé sí Akẹ̀sán Fayẹmi tẹsiwaju wi pe, eyii lo ta awọn gomina ilẹ Yoruba nidi kan lati pe ipade pajawiri lori eto aabo ilẹ Yoruba ni bii oṣu mẹfa sẹyin, abajade apero naa si ni Amọtẹkun ti wọn n ṣiṣọ loju ẹ lonii.
3M lórí ayélujára Mo bọ́ lọ́wọ́ igbó mímu ṣùgbọ́n ìnira ilé Aafa Ọlọrẹ ti pọ̀jù- ọ̀dọ́ kan Ọlọ́pàá kan jáde láyé, èèyàn méjì fara gbọta lásìkò ìdigunjalè ní Falomo l‘Eko Ọdunrun un naira o le diẹ lawọn elewọn n gba lọdun bayii lorilẹede naa, ọdun 1979 tii ṣe ogoji ọdun sẹyin nijọba ti ṣe agbeyẹwo owo oṣu awọn ẹlẹwọn kẹyin.
Àwọn ọ̀rẹ́ àti ojúlùmọ̀ tó n ṣelédè lẹ́yìn rẹ̀ Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Adari ile tun ṣalaye wipe awọn aṣofin o ribi dawọle awọn iṣẹ akanṣe to ṣe gboogi pẹlu bi ọdun yii ṣe n lọ sopin tori owo ti ko jade.
n óo yọ si yín bí ẹranko beari tí wọ́n kó lọ́mọ lọ, n óo sì fa àyà yín ya pẹ́rẹpẹ̀rẹ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Europe: Yúrópùù ní ọmọ Nàìjíríà àti orílẹ̀-èdè Áfíríkà 43 míì kò ni wọ ilẹ̀ òun 1 Agẹmo 2020 Oríṣun àwòrán, others Àwọn ọmọ orílẹ̀-èdè Naìjíríà àti àwọn orílẹ̀-èdè mẹtalelogoji míràn nílẹ̀ Afirika, ni kò ni lé wọ ilẹ̀ Yuroopu, EU láti Ọjọ́ Kíní, Oṣù Keje, ọdún 2020.
Orúkọ ọkunrin náà ni Nabali, iyawo rẹ̀ sì ń jẹ́ Abigaili.
Ẹni tí ó bá ń gbé inú mi, tí èmi náà sì ń gbé inú rẹ̀, yóo máa so èso pupọ.
Sanwo-Olu fẹ́ fojú-rinjú pẹ̀lú ọmọ tó ní kí ìyá òun ‘Calm down’ Keisha sàlàyé ìdí tó fi sunkún ní ìyàrá ìrántí nílé ẹlẹ́gbọ̀n ọ́n àgbà, ayé pariwo Ìjọba Èkó yóò fi òfin dè títà afẹ́fẹ́ gáàsì létílé láti dènà ìbúgbàmú láwùjọ Bakan naa ni Ogbeni Akinola Ojo tun salaye idi ti ijọba fi sun ọjọ fifopin si owo ori sisan sẹyin fun awọn eeyan ati onile isẹ nlanla ati keekeeke.
Kwara - Àwọn agbébọn kọlu olùdíje APC Aṣòfin 18 sá àsálà kúrò nípínlẹ̀ Ondo Laipẹ yii naa ni Aarẹ Naijiria nigba kan, Oluṣẹgun Ọbasanjọ parọwa fun awọn oloṣelu lati maa lo awọn ọmọ bibi inu wọn fun jagidijagan oṣelu.
n kò ní sùn,bẹ́ẹ̀ ni n kò ní tòògbé,
”Rutu dáhùn, ó ní, “Èmi Rutu, iranṣẹbinrin rẹ ni.
Àwọn eniyan ń ṣe inúnibíni sí wa, ṣugbọn Ọlọrun kò fi wá sílẹ̀.
Scheme Fund (Amendment), FCT Primary Healthcare Board.
Ẹ pín ninu ìkógun tí ẹ kó lọ́dọ̀ àwọn ọ̀tá yín fún àwọn arakunrin yín.
Nítorí ó mọ ẹ̀dá wa;ó ranti pé erùpẹ̀ ni wá.
O ṣalaye pe o digba ti esi iwadii ba jade lori ohun to ṣ'okunfa iku awọn eniyan naa ki awọn to le mọ bo ya aarun coronavirus lo pa wọn.
 Ki idibo naa to le je itewogba, won nilo ibo eniyan mesan an.
Ní ọjọ́ kan níbi tí ó ti ń bọ oriṣa ninu ilé Nisiroku, oriṣa rẹ̀, ni Adirameleki ati Ṣareseri, àwọn ọmọ rẹ̀ bá fi idà pa á, wọ́n sì sá lọ sí ilẹ̀ Ararati.
Ó san ki wọn wọ aṣọ Òkè-Òkun, ju ki wọn kó owó rẹpẹtẹ ti wọn ji kó lọ si Òkè-Òkun.
Ó sọ orúkọ rẹ̀ ní Noba tíí ṣe orúkọ ara rẹ̀.
Lọwọ yii, oun ni alaṣẹ ati oludari ileeṣẹ Persianas Nigeria Limited to maa n kọ ilegbe, ile itaja, ile itura atawọn ile miran lati ọdun 1990.
Ẹ wo ohun tí baba Adeboye sọ lórí ọ̀rọ̀ Coronavirus Oríṣun àwòrán, @PastorEAAdeboye Baba Adeboye, gẹgẹ bi ọpọlọpọ ṣe maa n pe iranṣẹ Ọlọrun naa ṣalaye ninu fidio to gbe jade pe ko si buburu kan ti yoo kan awọn to ba gbagbọ ninu Ọlọrun.
Ondo election 2020: Gómìnà Akeredolu la Jegede mọ́lẹ̀ wọlé ìbò gómìnà Ondo fún sáà kejì
olódùmarè náà ni Ọba àìrí , àwámárìdí yorùbá tún gbà pé ó jẹ Ọba mímọ ́ tí kò léèérí , alálà funfun òkè .
Ààrẹ Donald Trump ti padà sí ilé ìjọba lẹ́yìn ọjọ díẹ̀ tó lùgbàdì ààrùn coronavirus Ẹ̀yin olùkọ́, ìlànà àkànṣe owó oṣù tuntun dé fún yín Ẹ̀wọ̀n ni wàá gbẹ̀yìn sí, kò sí bóo ṣe dọ́gbọ́n tó - Seyi Makinde wa ègúná ọ̀rọ̀ lé Fayose Partey to jẹ ọmọbibi orilẹede Ghana gba ife ẹyẹ Europa League ati Super Cup ọdun 2018 pẹlu Atletico nigba to wa nibẹ.
Bo tilẹ jẹ pe ọpọ eeyan ni yoo joko ti ẹrọ amohunmaworan lalẹ ọjọ idibo ti a n sọrọ rẹ yii, o ku sọwọ suura awọn ileeṣẹ amohunmaworan lati ṣe iṣẹ wọn bo ṣe yẹ.
Wo bí agbábọ́ọ̀lù Super Eagles tẹ́lẹ̀, Christian Obodo tí wọ́n jígbé lẹ́ẹ̀kejì ṣe móríbọ́ Ààrẹ ti kọ̀wé fipò sílẹ̀ torí èèyàn méjì t'ọ́lọ́pàá pa níbi ìfẹ̀hónúhàn lòdì sí ìjọba Wo ọkùnrin tó dáná sun ọ̀rẹ́bìnrin rẹ̀ torípé kó gbà látí jẹ́ aya rẹ̀ Taiwo ni ẹgbẹ awọn Yoruba to ku ti kuna lati ṣe ohun to tọ, eleyii to jẹ ki ifaṣẹyin wa fun ilẹ Yoruba.
Ẹ fún wa lówó oṣù wa tàbí kí a gùnlé ìyanṣẹ́lódì ọlọ́jọ́ gbọọrọ- Àwọn dokita ìpínlẹ̀ Ondo Ọkùnrin kan rí ẹ̀wọ̀n ọdún mẹ́rin he lẹ́yìn tó jí ẹ̀rọ ìléwọ́ iPhone ní ìpínlẹ̀ Ogun ₦50 bílíọ́nù ni a pín fún gbogbo ìpínlẹ̀ ní Naijiria láti kojú àrùn Covid-19- Ìjọba àpapọ̀ Àwọn ọ̀dọ́ dáná sun ọkọ̀ akérò tó ṣekúpa ọlọ́kadà ní Ibadan Oṣú mẹ́fà ni òṣìṣẹ́ ìjọba tó bá bímọ yóò máa lò nílé kó tó wọṣẹ́ padà- Seyi Makinde Iru ẹkọ igbaradi wo gan an ni wọn n ṣe?
Johanu fi wọ́n sílẹ̀ níbẹ̀, ó pada lọ sí Jerusalẹmu.
Ati pe, igbimọ naa yoo beere fun afikun saa rẹ pẹlu oṣu mẹfa, nitori asiko ti ko fi bẹ ẹ si fun mọ.
 Ajọ NiBUCAA ti ran awon ipinle wonyi lowo.
Apẹẹja tẹlẹri yii ni o ri isẹ lẹyin to o gba awọn oluwẹ mẹta lati ilẹ Indian la.
awon odaran naa ti wa nitosi lati hu iwa odaran ni Kirsa ati Sunke ti o wa ni
Sùúrù ni àwọn olórí mú kí wọ́n tóó dé ipò oórí, sùúrù ni àwọn aṣáájú mú tí wọn kó fi kò àwọn èrò ẹ̀hìn ṣìnà, sùúrù ni Ọlọ́run Ọba mú tí kò fi run àwọn ọmọ aráyé ṣuṣu.
Iwe/Rẹkọọdu iwaasu Baba Adeboye ati orin Kristẹni Ẹ o le ṣe kẹẹ ma ri awọn iwe ti Pasitọ Adeboye atawọn ojiṣẹ Ọlọrun miiran to fi mọ rẹkọọdu iwaasu tabi awn orin ẹmi ati ere agbelewo ẹsin Kristẹni lori igba kaakiri ayika ipagọ naa.
Bẹ́ẹ̀ ni ó sì wáá jẹ́ pé, ní ìgbà náà tí Òjòlà-ìbínú sọ̀rọ̀ òdì sí Ọlọ́run Ọba, ìfun jáde, ẹ̀dọ̀ jáde, àpòkókú yọ sí ìta gbangba.
Mama Adeoye, gẹgẹ bi ọpọ ṣe n pee nigba aye rẹ jẹ aburo Alaafin ilu Ọyọ.
Ni ba ti se n sọrọ yi, ile ẹjọ giga ti yẹ aga nidi rẹ tawọn miran si ti n ja witiwiti lati wa ni ipo alaga.
Ṣugbọn ẹ kò gbọdọ̀ jẹ ẹran ti òun ti ẹ̀jẹ̀, nítorí pé, ninu ẹ̀jẹ̀ ni ìyè wà.
pàápàá nítorí ẹ mọ gbogbo àṣà àwọn Juu dáradára, ẹ sì mọ àríyànjiyàn tí ó wà láàrin wọn.
da lat fi kọ mọṣalaṣi naa.
Iṣoro to n doju kọ awọn obinrin to ti yọ ile ọmọ wọn kuro Iwadii akọroyin BBC to ṣe abẹwo si abule Vanjarwadi to wa ni agbegbe Beed, fihan pe ilaji awọn obinrin to wa ni abule naa lo ti yọ ile ọmọ wọn kuro.
Akoṣile sọ fun akọroyin BBC to ba a sọrọ lọjọ kẹjọ, oṣu Keje, pe irọ patapata ni iroyin naa.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù No reception wedding: Adewale ni àpèjẹ kò ṣe pàtàkì sí òun Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ No reception wedding: Adewale ni àpèjẹ kò ṣe pàtàkì sí òun 11 Owewe 2019 Kìí ṣe dandan ni ki eeyan pe apejẹ lẹyin igbeyawo -Adewale Laipẹ ni iroyin iwe ipe si ibi ase igbeyawo laarin arakunrin Adewale Olamilekan Yussuf ati omidan Blessing Ijeoma Oghota gba ayelujara kan.
Jesu bá ní, “Kí n lè ṣe ìdájọ́ ni mo ṣe wá sí ayé yìí, kí àwọn tí kò ríran lè ríran, kí àwọn tí ó ríran lè di afọ́jú.
O ni bi kii se pe ijọba la oju ọna fun omi lati gba, akoba to sẹlẹ yii ko ba ju bẹẹ lọ.
Nítorí pé ìwọ ni ibi ìsádi fún talaka,ibi ìsápamọ́sí fún aláìní lákòókò ìṣòro.
Bí Peteru tí ń lọ káàkiri láti ibìkan dé ibi keji, ó dé ọ̀dọ̀ àwọn eniyan Ọlọrun tí wọn ń gbé ìlú Lida.
 lẹ ́ yìn tí ó kúrò ní Òṣogbo , ó gbéra lọ sí Ìbàdàn , ní bi tí ó ti ń ṣiṣẹ ́ olùkọ ́ .
Ọmọ ijọ Sotitobire kan, to wa nile ẹjọ lọjọ Aje, lasiko ti igbẹjọ asaaju ijọ naa n lọ lọwọ lori ẹsun ijọmọgbe ti ba BBC Yoruba sọrọ.
”Ewe, Berhalter je agbaboolu iko yii teleri lọdun 2002 si odun 2006.
Funkẹ sọ pe asiko ẹkọ kikọ ni ọsẹ bi i melo sẹyin jẹ fun oun, ṣugbọn ko gbọdọ da itẹsiwaju duro."
Olootu ijọba ọhun nigbagbọ pe ofin atijọ orilẹede Canada to fi ofin de igbo ko ṣiṣẹ, nitori Canada ṣi wa lara awọn orilẹede ti wọn ti n lo igbó julọ pẹlu gbogbo ofin rẹ.
Election 2019 Updates: Atiku pe ẹjọ́ tako Buhari pẹ̀lú 20 àgbà amòfin
ko lẹsẹ nilẹ ni pe awon janduku ti dana sun  ile-ise ajọ eleto idbo to wa ni ipinle Osun.
Lasiko ti awọn oluwọde naa n pariwo ẹ fi opin si SARS, ati awọn nkan miran, ni awọn janduku naa ya de, ti wọn si bẹrẹ si ni kọlu wọn pẹlu àdá ati igi.
EPL: Chelsea, Man Utd f'idi rẹ'mi Man United bori Chelsea ni Old Trafford Ìsẹ́jú kọkànlá ni góòlù àkọ́kọ́ ninu ìdíje ọ̀ún wọle sinu àwọ̀n Manchester United lati ọ̀dọ̀ Tottenham, sùgbọ́n ìyàlẹ́nu ló jẹ́ nigba ti Sanchez yí ìpinu Tottenham pada ni ìsẹ́jú kẹrìnlelógún, ti Herrera sì fọba lée ni abala kejì ìdíje.
Ohun tí ẹ bá sọ ninu yàrá, lórí òrùlé ni a óo ti pariwo rẹ̀.
Ebila: Ọ̀pọ̀ ẹ̀mí àti dúkìá ni ẹgbẹ́ One Million Boys ṣe lọ́ṣẹ́ ni Ibadan
Ìdi rẹ̀ ti n kò si tíìi fi fẹ́ pé kí o bá àwọn ẹgbọ́ rẹ lọ sí òkò Láńngbódó yìí pin sí ọ̀nà méjì: lọ́nà kín-ín-ní, ọ̀ràn àbúrò rẹ yìí wà lọ́kàn mi, n kò fẹ́ kí ọmọ náà lọ ṣe báyìí sọ orí ara rẹ̀ nù sí ìlú onílùú, lọ́nà kejì, mo fẹ́ kí ojú ìwọ pàápàá là sii: nítorí ẹni ti ń gbé aabà oko ọgbọ́n abà oko nìkan ni yóò ni; ẹni ti ń gbé ìletò, ọgbọ́n ìletò ni yóò ni, ṣùgbọ́n ẹni tí o bá ń là kàkà láti dé ibi púpọ̀ ní ilé ayé yìí, ojú olúwarẹ̀ yóò là ju ti ọ̀pọ̀lọpọ̀ lọ.
Bakan naa ni ilu naa ni awọn ilẹkun abalaye ati ilu olodi, to wọpọ ni ọpọlọpọ ilu to wa ni ilẹ Hausa.
Salah nírètí pé òun yóò gbògo fún Egypt lónìí Kí lo mọ̀ nípa Eniọla Badmus?
Gẹgẹ bi aṣa ati iṣe ati ede Yoruba ṣe ṣe pataki pupọ fọmọ Oodua, ẹ jẹ ki gbogbo wa kọ awọn ọmọ wa nipa wọn fun idagbasoke rẹ̀.
Mo bì ọ́ lulẹ̀, mo sọ ọ́ di ìran wíwò fún àwọn ọba.
Idi si ree ti aburo Chidozie, Emmanuel se fi awọn aworan omi naa, to fi mọ ile iyagbẹ ileewosan ọhun soju opo Twitter.
Ó rí ọkunrin kan ará Masedonia tí ó dúró, tí ó ń bẹ̀ ẹ́ pé, “Sọdá sí Masedonia níbí kí o wá ràn wá lọ́wọ́.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Buhari Foreign Trips: Ìrìnàjò ààrẹ Buhari sílẹ̀ òkèèrè kò nípa kankan lórí ọrọ̀-ajé Nàijíríà 28 Ọ̀wàrà 2019 Oríṣun àwòrán, Instagram/Bashir Ahmad Lẹyin ọjọ meji to de lati irinajo rẹ si orilẹ-ede Russia, Aarẹ Muhammadu Buhari tun ti mori le ilẹ Saudi Arabia bayii.
'Alífábẹ́ẹ́tì Ohùn Oduduwa di ìtẹ́wọ́gbà ni Ajaṣẹ' Ṣẹ gbọ́ nípa Alájọ Ṣómólú, tó ta mọ́tò ra kẹ̀kẹ́?
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Mobolaji Johnson: Yàtọ̀ sí Onikan stadium, wo àwọn dúkìá ìlú tí a fi sọ orí àwọn akọni 4 Ọ̀pẹ̀̀ 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 5 Ọ̀pẹ̀̀ 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Yàtọ̀ sí Onikan stadium, wo àwọn dúkìá ìlú tí a fi sọ orí àwọn akọni Gẹgẹ bii ara eto ati ṣe iranti iṣẹ ribiribi ati ipa manigbagbe ti oloogbe Mobọlaji Johnson ko nigba aye rẹ, gomina ipinlẹ Eko Sanwo-Olu ti fi orukọ rẹ sọ papa iṣire Onikan nilu Eko.
Ẹnu ti kun Ka3na lopin ọsẹ to kọja, lẹyin ti iroyin jade pe oun ati Praise jọ ni ibalopọ.
"'"" Alhaji Usman rọ gbogbo òbi ti o ni irú ọmọ bẹ́ẹ̀ láti wádìí ǹkan ti wọ́n fẹ́ràn nítori ó ṣe pàtàkì láti fi ọjọ iwáju wọ́n léwọn lọ́wọ́ Kò sẹ́ni tó wù láti jẹ́ àkàndá, ẹ má dẹ́yẹ sí wọn mọ́- Fola 'Mo ti gbà pé lóòtọ́ ni ọmọ mi ní àárùn ọpọlọ ‘Ọ̀rẹ́ mi ní kí n fi ‘acid’ sí oúnjẹ ọmọ mi’ Èyí tí a wò jùlọ 5:03 Fídíò, Omolola Arohunmolase Welder: Mo ti fí iṣẹ́ 'Welder' gbayì láwùjọ, tó mo fi tọ́ ọmọ yanjú, Duration 5,039 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 5:39 Fídíò, Akomolede ati Asa lori BBC: Olùkọ́ Kikelomo Ogunboye tan ìmọ́lẹ̀ sí ìwà olè ọ̀gá ọlọ́pàá Audu gẹ́gẹ́ bí àwòkọ́ṣe àsìkò yìí, Duration 5,398 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 4:11 Fídíò, Oba Adeyeye Ogunwusi: Ojú mi ti rí lọ́pọ̀ lọpọ̀, ọ̀pọ̀ èèyàn ni kò tilẹ̀ gbàgbọ́ pé mo lè jọba- Ooni, Duration 4,117 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 4:43 Fídíò, Promise Akinlade: ọmọ ọdún mọ́kànlá tó ń fi ìlù dárà bíi àgbàlagbà sọ̀rọ̀ nípa tálẹ́ǹtì rẹ̀, Duration 4,437 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 0:59 Gbọ́, Ìsẹ̀lẹ̀ jákèjádò orílẹ̀èdè àgbáyé láàárín ìṣẹ́jú kan, Duration 0,59wákàtí 6 sẹ́yìn 4:45 Fídíò, Yoruba Films: Ẹ̀ẹ́ bẹ̀ mi kúrò láyé ni, mi ò lè kú - Fadeyi Oloro, Duration 4,4526 Èrèlè 2020 7:03 Fídíò, Olumuyiwa Bolade Adedeji Military Bruitality: Bí arákùnrin onípèníjà ara tí sọ́jà lù ṣe dé, Duration 7,035 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 2:48 Fídíò, Esther Ajayi: Èmi náà ti borí ìṣòro rí ló ń mu mi ṣojú àánú, Duration 2,481 Ògún 2019 6:08 Fídíò, Adebola Ademilua: Àìrísẹ́ ṣè lẹ́yìn ìwé kíkà ló sọ mi dí ìyá onírú, mo dúpẹ́ tèmi, Duration 6,0827 Bélú 2020 5:55 Fídíò, Soyinka Cancer: Àṣe ara mi ni iso ti n run gbogbo bí mo ṣe n ṣèrànwọ́ lórí jẹjẹrẹ, Duration 5,5527 Bélú 2019 BBC News, Yorùbá Ìdí tí ẹ fi le è nígbàagbọ́ nínú ìròyìn BBC Ìlànà Lílò Nípa BBC Òfin Àṣírí Cookies Kàn sí."
Wọ́n jọ ń jẹun láti ilé dé ilé.
Bákan náà ni wọ́n ń wí àwáwí fún gbígba ohun ìní àwọn obìnrin, fi agbára gbẹ̀san tàbí fi ipá bá obìnrin lò pọ̀.
" Ṣùgbọ ́ n arábìnrin kan Ọlájùmọkẹ ́ Òrìságunà tí ó jẹ ́ onípolówó ló tún fan rere ọ ̀ rọ sàláwà wípé : ' lábẹ ́ òfin ilẹ ̀ nàìjíríà tí ó sì tún dá lórí òfin ilẹ ̀ bríténì wípé "" "" ìbálòpọ ̀ akọsákọ jẹ ́ ìwà ọ ̀ daràn tí ó sì tọ ́ sí ìjìyà lábẹ ́ òfin ilẹ ̀ nàìjíríà láti ọmọ ọdún mẹ ́ rìnlá lọ sókè yálà kí wọ ́ n t ̀ i wọ ́ n mọ ́ lé tàbí kí wọ ́ n yẹjú wọn "" "" ."
Mí o lè gbà iṣẹ́ Tottenham torí pé mò nífẹ Chelsea púpọ jù-Mourinho Aláìṣẹ̀ ṣì ni Onyema Air Peace títí America afí fìdí ẹ̀sùn jìbìtì $20b múlẹ̀- America A jọ ṣe ìyàwó pọ̀, a jọ bímọ ní ọjọ́ kan náà, a tún jọ máa ń ṣàìsàn pọ̀ ni Mo bọ́ lọ́wọ́ igbó mímu ṣùgbọ́n ìnira ilé Aafa Ọlọrẹ ti pọ̀jù- ọ̀dọ́ kan Ẹwẹ, Frank Lampard to jẹ akọnimọọgba Chelsea funra rẹ ti figba kan gba bọọlu fun Man City lẹyin to kuro ni Chelsea.
Eyi lo tubọ mu ki ọpọ eeyan sun mọ, nitori wọn gbagbọ pe, o ti ni aṣẹ Agbara Okunkun Aye.
Labour Partylo si egbe oselu ,All Progressive Congress, APC ni  ojo keje ,osu keta ,odun 2017.
Oluranlọwọ pataki fun Aarẹ Buhari lori ibaraẹnisọrọ igbalode, Bashir Ahmed loju opo Twitter rẹ fidi iroyin naa mulẹ.
O fí kún pé Atiku ò fi ìgbà kankan janpata pé ìrọ ni obasanjo pa mọ oun àbi pé òun yóò gbe lọ sí ilé Ejọ Àkọlé àwòrán, Obasanjo fi kún pé Atiku kò ṣe gbara lé àti pé ajinilẹ́sẹ̀ ni Atiku lásiko ti àwọn jọ ṣe ijoba.
Awon olori agba egbe APC, All
Kí Oluwa jẹ́ kí ó lè rí àánú rẹ̀ gbà ní ọjọ́ ńlá náà.
Nítorí pé mo mọ èrò tí mò ń gbà si yín, èrò alaafia ni, kì í ṣe èrò ibi.
Nítoí Ọmọ-Eniyan dé láti wá àwọn tí wọ́n sọnù kiri, ati láti gbà wọ́n là.
Atẹjade náà fikùn pé, ilé ìwòsàn UCH sì ń dúró de èsì ayẹwo náà láti ibùdó ayẹwo níta, táwọn yóò si maa fi ìṣẹ̀lẹ̀ náà tó aráyé létí bo ba ṣe ń lọ.
Nigeria-Ghana trade war: Ààrẹ Ghana pàṣẹ kò sáàyè òwò fọ́mọ China tàbí Nàìjíríà mọ́ ní Ghana
Anfani to po ni awon osere ati gbogbo osise Nollywood ni ni Naijiria.
Òtítọ́ làwọn sọ́jà gbé ìbọn tó lọ́ta gidi nínú lọ sí Lekki Toll Gate lásìkò ìwọ́de EndSARS- Ọ̀gágun Taiwo DSS ti fi ẹ̀sọ́ àbò abẹnugan ilé ìgbìmọ̀ asofin tó pa fẹ́ndọ̀ l'Abuja sátìmọ́lé Wọ́n ti rí òkú Alága ẹgbẹ́ APC ní Nasarawa tí àwọn agbébọn jí gbé lọ́jọ́ Satide Wo nkan tó sọ Woli ìjọ Genesis Global di ọmọ ìjọ Cele lẹ́yìn tó kúró nínú ìjọ C.
Ó ní àwọn onímọ̀ nípa ìṣègún ń ṣiṣẹ́ takuntakun láti le sọ pàtó irú àbẹ́rẹ́ ti yóò dára fún àwọn ọmọ Nàìjíríà, pàápàá jùlọ nítorí orílẹ̀-èdè Nàìjíríà kò ni amú omítutu tó tuntùn tó ìwọ̀n ọgọ́rin.
Awọn aṣofin to fẹran Brexit ninu ijọga May ni adehun naa ti jẹ ki Ilẹ Gẹẹsi sun mọ EU just ṣugbọn awọn alatako wọn ni alaye adehun naa ko ye ara ilu daradara.
Ni Amẹrika ti ọja Apple ti n ta ju, itakun 5G ọhun fẹ lọra nibẹ.
Idi ni pe awọn afọbajẹ yii lo n kesi ijọba ipinlẹ Osun pe ko yọ Ọba Akanbi kuro nipo ọba nitori awọn ohun kan to tọkasi bii asemase rẹ.
Eyi ti akosile iyato re je 308.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Afihan ọkọ ayọkẹle ita gbangba to yẹ ko waye ni New York, lorilẹ-ede Amẹrika lọṣu Kẹrin ọdun 2020 naa ni wọn tun ti sun siwaju.
"Ilana ta n gba ṣíṣẹ yatọ pupọ, to fi mọ owo osu ati ajẹmonu wa, bakan naa ni ipese irinsẹ fun iṣẹ wa ni Naijiria yatọ si ti oke okun, ti itọju nla si wa fun Nọọsi loke okun.
Ẹni to so ado iku mọra yii wọ aṣọ ileewe yii lọjọọ naa.
 Àwọn wọ ̀ nyí níí ṣe pẹ ̀ lú ijó .
“Nígbà tí òjò bá kọ̀ tí kò rọ̀, nítorí pé àwọn eniyan rẹ ṣẹ̀, bí wọ́n bá kọjú sí ilé yìí, tí wọ́n sì gbadura, tí wọ́n jẹ́wọ́ orúkọ rẹ, tí wọ́n yipada kúrò ninu ẹ̀ṣẹ̀ wọn, nítorí pé o ti jẹ wọ́n níyà, 
Insecurity: Agbẹkọya ní òògùn abẹnugọ̀ǹgọ̀ ní ọ̀nà àbáyọ fún ìjínigbé!
Police Ondo: Láìpẹ́ ni ọwọ́ yóò tẹ àwọn agbébọn tó wa òṣìṣẹ́ wa
Ọna naa gun de ipinlẹ Kogi.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Lagos Lockdown: Wo ìlànà tuntun ṣáájú ṣíṣí ilé ìtura, sinimá, gbọ̀ngàn ayẹyẹ ní Eko 1 Ògún 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 24 Ògún 2020 Oríṣun àwòrán, @followlasg Ijọba ipinlẹ Eko ti gbe ilana tuntun jade fun awọn olokoowo to n fi irinajo afẹ, ati faaji ṣiṣẹ nipinlẹ naa.
” OLUWA, tí orúkọ rẹ̀ ń jẹ́ Ọlọrun àwọn Ọmọ Ogun, ni ó sọ bẹ́ẹ̀.
Ìgbá tí ó sá jáde yìí ni Ẹlẹ́gbára pàápàá tó ri i, wéré ó sì ti dì í mú, bí ó sì ti fẹ́ pa á, Ayédèrú-ẹ̀dá kígba ó nu, ‘Jọ̀wọ́ ṣe mi jẹ́jẹ́ ki n bà fi ibi tí àwọn yòókù wà hàn ọ, nítorí a pọ̀ jù báyìí lọ.
N kò jẹ ẹrankẹ́ran tabi ẹran àìmọ́ kan rí.
Kí á lọ sinu ọgbà àjàrà láàárọ̀ kutukutu,kí á wò ó bóyá àjàrà ti ń rúwé,bóyá ó ti ń tanná;kí á wò ó bóyá igi Pomegiranate ti ń tanná,níbẹ̀ ni n óo ti fi ìfẹ́ mi fún ọ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Mo n wa'yawo - Falz Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Yemi Alade Promo Davido, Wizkid, Falz kogoja gẹgẹbi ọ̀dọ́ tó pegedé l'Áfíríkà Ninu ọrọ rẹ o ni oun fẹ ki awọn obinrin gbogbo mọ iyi ara wọn ati wi pe ko si ẹni ti ko rẹwa laaye tirẹ ''ati ẹni tirin,ati ẹni sanra,bo ni idi nla,bo ni,gbogbo wa la rẹwa'' Tiwa Savage ko ti fẹsi si ọrọ yi sugbọn awọn obinrin miran ti gbosuba kare fun Yemi Alade fun pe o wu iwa yi Ija bum bum,ere lasan abi ootọ Lọjọ ẹti lawọn olorin mejeeji naa Tiwa Savage ati Yemi Alade bẹrẹ ija lori ẹni ti idi rẹ tobi julọ laarin wọn.
Ènìyàn 26,000 ni àìsàn jẹjẹrẹ ń pa lóòjọ́ Wo àwọn ọtí ẹlẹ́rìndòdò tó ń fa àrùn jẹjẹrẹ.
Eto igbẹjọ ati idajọ ileẹjọ nipa awọn eeyan ti wọn fẹsun kan pe o huwa ibalopọ lọna aitọ lee fori sọgi nigba ti awọn eeyan to yẹ ko jade bii ẹlẹri ba n fa sẹyin lati jade sita wa jẹri tako awọn eeyan naa.
oloogbe MKO Abiola ni won yoo tun maa fun ni oye adari awon iko omo-ologun ti orile ede Naijria (the Grand Commander of the Federal Republic, GCFR), eyi ni oye to ga julo ti awon to ba je aare orile ede maa n gba.
Lori asia yii ni arakunrin yii kọ ọ̀pọlọpọ̀ ọ̀rọ̀ sori rẹ.
Lẹ́yìn ìwádìí ti ọjọ́ yìí, Akin Ọlọ́fìn-íntótó àti ilésanmí padà sí Ìbàdàn.
Kí oore-ọ̀fẹ́ ati alaafia láti ọ̀dọ̀ Ọlọrun Baba wa kí ó wà pẹlu yín.
Òmùgọ̀ ọmọ ni wọ́n;wọn kò ní òye.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù WASSCE time table 2020: Àwọn akẹ́kọ̀ọ́ da ìdánwò WAEC rú ni Ghana, wọn gún infijilátọ̀ 5 Ògún 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 9 Ògún 2020 Oríṣun àwòrán, Other Ajọ to n ri si idanwo aṣekagba ileewe girama lẹkun Iwọ Oorun Afirika, WAEC, lorilẹ-ede Ghana ti bẹrẹ iwadii lori ohun to mu ki awọn akẹkọọ Bright Senior High, SHS, kọlu awọn to wa ṣakoso idanwo naa nile iwe wọn.
Nítorí pé àwọn agbẹ̀bí náà bẹ̀rù Ọlọrun, ìdílé tiwọn náà pọ̀ síi.
Eti mi ti kun nipa ọpọ iwa aidaa awọn agbébọn naa ti wọn farasin si agbegbe Oke Ogun ati bi wọn ṣe n dunkooko mọ eto aabo ilẹ Yoruba lapapọ.
Èkíní nínú àwọn ẹ ̀ yà Ẹ ̀ gbà yìí ni Ẹ ̀ gbá aké .
Face app: Àwọn òṣèré tíátà kan ṣàfihàn fọ́tò ọjọ́ ogbó wọn
Àjọ ọlọpàá Eko kédé pé ìbalòpọ̀ nítà kò bójúmu Ǹjẹ́ o mọ̀ pé ẹgbẹ̀run kan náírà ní obì ní Brazil?
Abẹrẹ ajẹrẹsara lo n daabo bo ẹgbẹlẹgbẹ awọn eeyan kaakiri agbaye.
apapo  ati igbimo alase lori eto ọrọ aje
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Bolaji Faleke ni Olùkọ́ tó ń kọ́ wa ní àṣà oge ṣiṣe lórí BBC Yorùbá Ki lo ti ṣẹlẹ sẹyin lori ọrọ yii: Máa gbé kẹ̀kẹ́ rẹ lọ, àwọn akọròyìn kọ̀ ìpàkọ́ sí Femi Fani Kayọde Awọn akọroyin ni ipinlẹ Ọyọ naa ti kọ ipakọ si ipade awọn akọroyin ti minisita tẹlẹ lorilẹ-ede Naijiria, Fẹmi Fani Kayọde nilu Ibadan.
Ambode ní kò sí gìrì, eré ọwọ́ lásán ni EFCC ń ṣe 'Ẹ má ṣi Fayemi túmọ̀ lórí àṣẹ tó pa nípa sísọ èdè Yorùbá' Kòsí àṣà tó faramọ́ fífi èmí ènìyàn ṣe ìrúbọ - Olúwó Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Ní'lùú Ilọrin, èèyàn méjì fara gbọta ìbọn INEC: Kò sí ìká tí o kò lè fí dìbò, ṣáà tí tẹ̀ ẹ́ sójú ẹ dáadáa Kí ló mú àwọn obìririn meji yìí pa bàbá wọ́n?
Awọn ajafẹtọ ati ọpọ eeyan ni wọn ti tako aba ọhun, wọn ni ọna lati maa dunkoko mọ awọn eeyan ni, eleyi to lodi si ẹtọ lati maa sọrọ tawọn ọmọ Naijiria ni.
- Mike Bamiloye Wò ó bí Alaafin àti aya àkọ́fẹ́ rẹ̀, Olorì Abibat ṣe pàdé ní èwe Ọsinbajo se‘dana ọmọbinrin rẹ nile ijọba Adekunle Gold, Simi tú àṣírí ètò ìgbéyàwó wọn Àwòrán ìgbeyàwó ọmọ Fayose dùn, ó lárinrin Wo bí ìgbéyàwó ọmọ bàbá olówó, Adama Indimi àti Prince Malik Ado ọmọ Ọba Ohinoyi ilẹ̀ Ebira ṣe lárinrin tó Ikede yi ti mọlẹbi Mike-Bamiloye kan fidi rẹ mulẹ fun BBC ti n da awọn eeyan lọrun ti awọn ọmọ Naijiria si ti n da si ọrọ ifẹ wọn.
Ipo ti o ga ju fun awon obinrin nile-ise olopaa naa, ni Jesca Orodriyo ati  Elizabeth Muwanga ti won je igbakeji giwa ile-ise olopaa naa.
 leyin eyi , o tesiwaju lo si ile eko girama ti awon ologun ti o wa ni ìpínle Èkó .
4+4= Next Level Aarẹ Muhammadu Buhari lo fun ara rẹ jan aṣa ipolongo yi lontẹ nigba ti o lọ si iwaju ile asofin Naijiria lati gbe aba isuna ọdun 2019 kalẹ.
Níbi mímọ́ ni ẹ ti gbọdọ̀ jẹ wọ́n.
atejade kan ti o fi ranse lati  fi ki
Kano Emirs: Ilé ẹjọ́ wọ́gilé ìyànsípò àwọn Emir mẹ́rin tí Ganduje yan
Àwọn wọ̀nyí ni wọ́n ngbé ní abúlé kan tí wọ́n tẹ̀dó sórí omi ọ̀sà ní Èbúté Mẹ́ta.
''O maa n lu mu lalubami nigba kuu gba ti o ba beere owo mi wi pe mo fẹ fi i silẹ,'' Oshonaike lo sọ bẹẹ.
Nítorí náà OLUWA, èmi bẹ̀ Ọ́, fi agbára ńlá rẹ hàn gẹ́gẹ́ bí ìlérí rẹ pé, 
Igba nla kan si lee wa laarin ayaba meji tabi ju bẹẹ lọ, ti wọn yoo maa gba a bi wọn ṣe n kọrin, tawọn miran laarin wọn yoo si maa gbe orin naa.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ilé aṣòfin Ondo bẹ̀rẹ̀ ìgbésẹ̀ láti yọ igbákejì gómìnà nípò Kò ní sí ayẹyẹ ọdún Ojúde Oba lọ́dún yìí- Awujale ilẹ̀ Ijebu Bí àwọn adarí ìjọba ṣe ń kó Coronavirus, ń kọ wá lóminú - Ìjọba àpapọ̀ Àkójọ́pọ̀ àwòrán rèé lórí bí ìwọlé akẹ́kọ̀ọ́ ṣe lọ sí ní Oyo Iroyin sọ pe igbimọ ti Aarẹ yan yii lo pe Magu fun iwadii ninu ile ijọba Aso Rock.
Bẹ́ẹ̀ náà ni àwọn angẹli tí wọn kọjá ààyè wọn àkọ́kọ́, tí wọ́n kúrò ní ipò tí Ọlọrun kọ́ fi wọ́n sí.
Ìlé ọ̀hún wá dúró gẹ́gẹ́ bí ilé ìwòsàn àti ìgbafẹ́ ọlọ́kanòjọ̀kan fún àwọn arawọn, àti àwọn ọmọ onílẹ̀ tí wọ́n jẹ́ ọlọ́lá.
Oríṣun àwòrán, Matt Vikers Àwọn orílẹ̀-èdè tó tí ń ṣe amúlò òfin yii tẹ́lẹ̀ Belgium Canada Colombia Luxembourg Switzerland àti Netherlands Àwọn ìpińlẹ̀ kan náà ni Amẹrika ń ṣee bẹ́ẹ̀ náà ni àwọn ènìyàn Australia ni ìpińlẹ̀ Victoria naa ti sọ di òfin.
Ọọni ile Ifẹ ati Aarẹ ana kakanfo ilẹ Yoruba ni asiko to fun ilẹ Yoruba lati kilọ fun awọn agbenipa darandaran lati maṣe ta ẹsẹ agẹẹrẹ ni aala ilẹ Yoruba mọ.
com/n8BePcDHfYGbegede tun ti gbina bayii leyin ti iko agbaboolu Liverpool di  keregbe iya merin otooto  sori agbaboolu Barcelona kookan pelu ami ayo merin sodo(4-0) lati pegede si asekagba idije UEFA Champions  League.
Lẹ́yìn èyí, Jesu ń lọ káàkiri ní ilẹ̀ Galili nítorí kò fẹ́ máa káàkiri ilẹ̀ Judia mọ́, nítorí àwọn Juu ń wá ọ̀nà láti pa á.
dìgbòlugi ńfa ikú lágbayé lọ ́ dọọdún bi 26,000 sí 55,000 .
Nípasẹ̀ rẹ̀ ni a ti dá gbogbo nǹkan, nítorí tirẹ̀ ni a sì ṣe dá wọn.
Abiyamọ mẹjọ lo wa si ile iwosan lọjọ taa n wi yii, ti wọn si ni lati se iṣẹ abẹ ki wọn ba le bi ọmọ wọn.
ISIS in Oyo: Ó ń bọ̀ ó ń bọ̀ àwọ̀n làá ń dẹ dè é, ISIS ti wọ ìpińlẹ̀ Oyo o -Gani Adams Aarẹ Ọna Kakanfo ilẹ Yoruba Iba Gani Adams ti ke gbàjarè pé awọn ọmọ ẹgbẹ agbesumọmi Islamic State, (IS) wa wọ ipinlẹ Oyo.
Mo wu ìwà títí: mo wu ìwà tí kò gbeni; ìwà tó mú ni şìnà, mo rin ọ̀nà tí kò pé; ọ̀nà tó mú ni jẹ̀bi.
Ẹ mú ìwúkàrà àtijọ́ kúrò, kí ẹ lè dàbí burẹdi titun, ẹ óo wá di burẹdi titun ti kò ní ìwúkàrà ninu.
 Kalu to n soju fun ila Ariwa Abia ni ti
Tí àwọn ẹ̀yà ara wọ̀nyí bá kófìrí àwọn kòkòrò aṣekúpani nínú àgọ́ ara, kíákíá ni wọ́n máa da àwọn ọmọ-gun síta kí wọn lọ dojú ìjà ko wọ́n.
Orin rẹ si ma n da lori aṣa, ikilọ iwa, ibọwọ f'agba, oṣelu ati igbokegbodo eeyan laye.
Ọmọ rẹ̀ yìí ni Ọlọrun fi agbára Ẹ̀mí Mímọ́ yàn nígbà tí ó jí i dìde kúrò ninu òkú.
Lock down: Akojọpọ nkan amayedẹrun ti ijọba ti fun awọn ọmọ Naijiria nitori aarun coronavirus Oríṣun àwòrán, @MBuhari Ṣaaju àsìkò yìí, ni aarẹ Buhari ti kọkọ ti awọn ẹnubodè to wọ Naijiria pa pẹlu igble ọlọjọ mẹrinla akọkọ ni Abuja, ipinlẹ Ogun ati Eko.
Nígbà tí a kúrò lọ́dọ̀ Baba-onírùngbọ̀n-yẹ́úkẹ́ ẹni tí ń gbé ibi gegele òkúta, ojú wa rí nǹkan púpọ̀ lójú ọ̀nà, àti eyí tí ẹnu lè sọ àti èyí tí ẹnu kò lè sọ ni a fi ojú wa rí tí a sì ṣe alábàápàdé, bí kò bá sí wí pé Ọlọ́run tóbi lọ́ba, èmi pàápàá kò bá tí tó ẹni tí ń sọ̀rọ̀ lónìí.
Awọn kan tilẹ n wa ibi ti wọn ti lee ri abẹrẹ ajẹsara ọhun naa lori itakun agbaye.
Oríṣun àwòrán, @NewsOfNigeria Awọn oṣiṣẹ panapana tete de sibi iṣẹlẹ ọhun lati bu omi pa ina naa eleyii to ti bẹrẹ si ni jo inu agolo ikẹrususi kọntena ti wọn ko awọn ẹrọ ayẹwo kaadi oludibo naa si Bi o tilẹ jẹ wipe ko si ẹni lee sọ ni pato bi ina naa ṣe bẹrẹ ati ohun to ṣokunfa rẹ, Amofin Okoye ti fi da araalu loju pe iwadii yoo waye lati tu mọ ohun to ṣokunfa ijamba ina ọhun.
Amọṣa awọn ims tuntun ti fihan bayii pe ko si idi fun wa lati maa sọ iwọ ati olubi awọn ọmọ tuntun ti a ba ṣẹṣẹ bi mọ nitori agbara iwosan ọpọlọpọ arun gbẹmigbẹmi lo wa ninu wọn.
Oríṣun àwòrán, Others Amọ o ni oun fun Trump lesi pada lai jẹ ko mọ ero ọkan oun, toun si ni ija agbẹ atawọn darandaran ju ọjọ ori oun gan lọ, ka to wa sọ ti Trump, tori mo si fi ọdun diẹ ju lọ.
Ọbasanjọ ni ọmọ òrùkàn tó di olóri orílẹ̀èdè lẹ́ẹ̀mẹ́ta ọ̀tọ̀ọ̀tọ̀ Gómìnà ìpínlẹ̀ Ondo, Akeredolu sọ Amotẹkun di òfin!
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Wunmi Toriola: Ọ̀pọ̀ olólùfẹ́ rẹ̀ kò fẹ́ kó bá Seyi Edun ṣe ọ̀rẹ́ mọ́.
Isele igbona ti di nla bayii nile Euroopu lati odun 2017.
Iṣẹ́ àwọn ọmọ Merari ninu Àgọ́ Àjọ nìyí.
Mo mọ̀ pé mo ti ṣẹ̀; Ìdí nìyí, tí ó fi jẹ́ pé èmi ni ẹni àkọ́kọ́ tí ó kọ́ wá pàdé rẹ lónìí, ninu gbogbo ìdílé Josẹfu.
Ṣe awọn alasẹ to fọwọ si idapada awọn ọmọ wọnyi si ipinlẹ ti wọn ti wa mọ wipe awọn n dakun itankalẹ arun Covid 19 ni?
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ọpọlọpọ kayefi lo wáyé ni ipele to ṣaaju eyi to kangun si aṣekagba Ọpọlọpọ kayefi lo wáyé ni ipele to ṣaaju eyi to kangun si aṣekagba pẹlu bi esi ti awọn eeyan ko nireti ṣe n jade.
Ẹ̀tàn ni àríyá tí wọn ń ṣe nígbà tí ẹ bá jọ jókòó láti jẹun.
Ọlọ́pàá ìpínlẹ̀ kọ́ ní ojútùú ìṣòro ìjínigbé ilẹ̀ Yoruba - Onímọ̀ ọ̀rọ̀ ààbò Seyi Awolowo, ọmọ-ọmọ Awolowo, kí ló ń wà lórí ètò BB Naija?
n óo fi ìdí ìjọba rẹ múlẹ̀, bí mo ti bá Dafidi, baba rẹ, dá majẹmu pé, ìran rẹ̀ ni yóo máa jọba lórí Israẹli.
Ọpọ wọn ni kii kuro lojukan ti wọn wa ki wọn to ṣeto karakata oojọ wọn ni Estonia ṣugbọn eku ti ṣe akoba nla fun eto ọrọ aje wọn bayii.
 Àìsàn ńlá kan se tó béè gè tí won fi kó ilé ohílèkùn ńlá kan fún un gégé bí ifá se wí .
Oṣu diẹ lẹyin to bori yii, o ni aarẹ nigba kan ri naa ṣe bi baba fun oun nigba ti awọn pade.
Marina / Ikoyi Bridge Ijọba ibilẹ Ikeja Lagos Island / Eti-Osa41.
Trump: FBI ko mọ isẹ wọn bi isẹ
Ede aiyede naa ko ju pe tani o yẹ ki wọn kọkọ ta a fun, eyi to di ija laarin wọn, eyi si ni afunrasi naa fi binu ko sinu ọkọ rẹ to si lọ fa ibọn yọ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìdìbò Kano kò fararọ, bẹ́ẹ̀ láwọn ìpínlẹ̀ to kù náà kò ní ìfọ̀kanbalẹ̀ 23 Ẹrẹ̀nà 2019 Àkọlé àwòrán, Ìdìbò Kano kò fararọ, bẹ́ẹ̀ láwọn ìpínlẹ̀ to kù náà kò sí ní ìfọ̀kanbalẹ̀ Oludije dupò ààrẹ lábẹ́ ẹgbk òṣèlú People's Democratic Party (PDP) sọ pe pẹ̀lú ọlọkan-òjọkan ìròyìn jákejádò Nàìjíríà tó tẹ òun lọ́wọ́ lórí àtúndi ìdìbò tó wáye lónìí, kò si ibi ti ìdìbò náà ti lọ ni irọwọ́rọsẹ̀.
Mo ti ṣe àkíyèsí nígbà tí mo wà lọ́hùn-ún pé inú rẹ funfun ó ju ẹ̀gbọ̀n òwú lọ, ṣùgbọ́n mo fẹ́ kí o mọ̀ pé kì í ṣe bẹ́ẹ̀ ni inú gbogbo aráyé rí.
O rọ eeyan lati pin fidio naa nitori pe o da oun loju pe ibo diẹ ni Trump yoo fi la Biden mọlẹ ninu ibo aarẹ Amẹrika.
Ara n ni araalu - Bode George 'Ìbànújẹ́ kò ni wọ́n nílé àwọn tó pa ọkọ mi' Aarẹ Ọna Kakanfo yoo dena idunkoko ajeji nilẹ Yoruba Day 8: Bode George dá sí aawọ̀ Buhari, Obasanjo #BBCNigeria2019 Nigba ti Bode George n dahun ibeere lori ayajọ iṣẹjọba Alagbada ti Democracy Day tọdun 2019, o ni iran Yoruba ni lati kọgbọn sii fun itẹsiwaju to yẹ.
 Ǹjẹ́ ìwọ ṣe irú èyí sí gègé rẹ
Irọ́ ni pé a fẹ́ fowó kún owó iná mọ̀nàmọ̀nà- NERC Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Aadota odun ree ti e ti n paro atunse ise yin fawon omo Naijiria lero awon kan Jìbìti ni àfikún owó iná mọ̀nàmọ́ná tí ìjọba kéde rẹ̀- Egbẹ oṣiṣẹ Ẹgbẹ oṣiṣẹ lapaapọ atawọn ẹgbẹ ajafẹtọ ti koro oju si afikun owo ina mọnmọna ti ijọba apapọ kede rẹ.
O ni lootọ lawọn yinbọn nibi yanpọnyanrin naa ṣugbọn awọn to ti ika bọ oun lẹnu lo mu ki oun faraya.
Wọn kò ní rú ẹbọ ohun mímu sí OLUWA, bẹ́ẹ̀ ni ẹbọ wọn kò ní tẹ́ ẹ lọ́rùn.
Mo ti bọ́ra sílẹ̀,báwo ni mo ṣe lè tún múra?
Bi iṣẹ perfume tita ti ṣe yí ìgbésí ayé Adéwálé Aladejana padà
Yoruba-Hausa clash: Ọlọ́pàá mú èèyàn márùn ún lórí ìjà tó bẹ́ sílẹ̀ láàrin Hausa àti Yorùbá l'Eko
Makinde ni gómìnà, èmi ni igbákejì rẹ̀; kò sí ìjà láàrin wa-Rauf Adeniyan, igbákejì gómìnà ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́ Ṣé lóòtọ́ ni Kayode Fayemi, gómìnà ìpínlẹ̀ Ekiti fẹ́ du ipò ààrẹ orílẹ̀èdè Nàìjíríà?
The Lost Café – Kenneth Gyang
An ti wọn buwọlu ofin yii sọ wi pe ẹsin musulumi ko sọ iye ọjọ ori to yẹ ki obinrin jẹ ko to le ṣe igbeyawo.
O ni lati igba ti adari tẹlẹ ti tẹri gbaṣọ ni iran Yoruba ko ti ki n fẹnuko mọ lati 2008.
Ẹni tí kì í bá na ọmọ rẹ̀ kò fẹ́ràn rẹ̀,ṣugbọn ẹni tí ó fẹ́ràn ọmọ rẹ̀ yóo máa bá a wí.
À ń lọ nítorí egbẹ̀rún ìran ti ń bọ̀ lẹ́yìn, à ń lọ nítorí gbogbo yín.
Àwọn ọmọ Senaa jẹ́ egbejidinlogun ó lé ọgbọ̀n (3,630)
Dafidi bèèrè lọ́wọ́ Ọlọrun, ó ní: “Ṣé kí n lọ bá àwọn ará Filistia jà?
Ninu ọrọ to ba BBC sọ, baba rẹ, Ọjọgbọn Felix Chukwuneke, ṣalaye nipa bi ọmọ rẹ ṣe ja fafa, to si nifẹ awọn ọmọ bi i tirẹ.
A ko mọ idi ti wọn fi fẹ ẹ ṣe ijamba fun wa.
O tẹnumọ pe ipinu yii ni idahun si ibeere tawọn akọroyin bi i nipa ọrọ Gomina El Rufai to sọ.
Ati pe ida mẹsan an pere ninu ọgọrun un si wa fun rira ohun eelo ijagun ati awọn iṣẹ akanṣe.
Ìyàtọ̀ wà láàrin bí wọ́n ṣe nkọ ọ́ ní ìlànà Amẹ́ríkà àti ti àwọn Oríẹ̀èdè ìyókù.
 jesse king tí wọ ́ n bí ní ìlú auchi ṣùgbọ ́ n tí ó gbé ní ìlú Èkó , kẹ ́ ẹnintì orin rẹ ̀ gbajúmọ ̀ láàrín àwọn ẹ ̀ yà yorùbá pàápàá ní ìpínlẹ ̀ Òndó .
Aarẹ Buhari to sọrọ ninu atẹjade kan to fi ki awọn musulumi ki ọdun Ileya, sọ pe ifaraẹnijin to ṣe pataki julọ fawọn musulumi ododo ni pe ki wọn fi idajọ otitọ ati ododo ṣe atọna wọn lọjoojumọ.
Kò sí ọ̀kan ninu àwọn aláṣẹ ayé yìí tí ó mọ àṣírí yìí, nítorí tí ó bá jẹ́ pé wọ́n mọ̀ ọ́n ni, wọn kì bá tí kan Oluwa tí ó lógo mọ́ agbelebu.
Kabíyesi ni eyi jẹ́ iṣẹ́ ti Olodumare ran òun ni pe àwọ́n ti wọ́n gbé ade Oodua sori kò gbọ̀dọ bọ orisa kankan.
ṣe aìlè bá obìnrin lò pọ̀
kí o lọ sọ́dọ̀ ọba, kí o sì sọ ohun tí n óo sọ fún ọ yìí fún un.
Aisha ni kò dara to pe kí ènìyàn tó le ni mílíọ̀nù mẹ́ẹ̀dogún dibo yan ọkọ òun wọle ki àwọn ènìyàn meji dondo si gba ìjọba láti keyin awọn naa si ààrẹ.
O so pe “lotito,lo ye ki n wa nipo di igba ti ijoba wa yoo fi pari, sugbon eri okan mi ati irewesi ti mo n ri lenu ise ko lee je ki n tesiwaju lati je olotito si iwo egbon mi ati asiwaju mi”.
Wo àbọ̀ tí ọmọba kan, obìnrin àkọ́kọ́ tó ṣe ìwádìí nípa rẹ̀ gbé jáde A kò lè gbà kí ìjọba àpapọ̀ ṣ'agbátẹrù Amotekun, ìjọba ilẹ̀ Yorùbá yarí Lẹyin ti Ronald Koeman di akọnimọọgba tuntun fun Barcelona, ẹgbẹ agbabọọlu naa ti bẹrẹ awọn atunto kan lati tẹ ikọ naa siwaju.
O ni ọjọ ti awọn mu naa ni wọn gbe e lọ sile ìwosan, to si wa nibẹ fun ọjọ mẹsan.
Oríṣun àwòrán, @BBNaija/Twitter Òní lòní ńjẹ́ nílé ẹlẹ́gbọ̀n-ọ́n àgbà BBNaija fún Dorathy, Prince, Kiddwaya, Ozo!
Nígbà tí oòrùn wọ̀, gbogbo àwọn tí wọ́n ní oríṣìíríṣìí àrùn ni wọ́n mú wá sọ́dọ̀ Jesu.
Ṣùgbọ́n bí orúkọ rere bá sàn jù wọ́n lọ, dájúdájú àwọn Yorùbá ka orúkọ rere sí nǹkan iyebíye tí a kò lè fi owó rà rárá.
Ó pé ọdún mẹ́rìnlélàádọ̀ta tí Akintola kú, ìdí abájọ ìja rẹ̀ pẹ̀lú Awolowo rè é Ìtàn Gbọnka àti Timi, akọni méjì tó borí Aláàfin Ṣango ''Nigba ti maa fi de ileeṣẹ rẹkọọdi Decca, wọn ko fẹ ki n ri ọga ileeṣẹ naa, ṣugbọn mi o sọ ireti nu, ti mo si sọ fun wọn pe, irawọ ọjọ ọla ni mi.
Ó ṣì ku ẹ̀ẹ́dégbẹ̀ta ọmọ Nàíjíríà tó kù sí South Africa - Alákoso Airpeace Irú ètùtù wo ni ìlú Ijare fẹ́ ṣe kí wọ́n tó lè yanjú màálù 36 tí àrá sán pa?
Awon agbaboolu Super Eagles miran ti won jo maa sise papo bayii ni: Bryan Idowu, Shehu Abdulahi, Henry Onyekuru, Oghenekaro Etebo, ati Mikel Agu.
Awọn iroyin miran ti ẹ le nifẹ si: Ọ̀mùtí ọmọ Nàìjíríà kábàmọ̀ ní Russia Nàìjíríà ń wá ẹlẹ́dẹ̀ aríran 'Gbogbo Nàìjíríà kó ló wà nínú òkùnkùn' Adó olóró méjì to bu gbamu yìí ti pa eniyan mọkanlelọgbọn ni ìlú Damboa, ìpínlẹ̀ Borno, ní apá ìlà oòrùn àríwá Nàìjíríà.
mu awon odaran, agbodegba won,ati awon to n ran won lọwọ lati se ise ibi ohun,
“Bí Farao bá wí pé kí ẹ ṣe iṣẹ́ ìyanu kan fún òun kí òun lè mọ̀ pé òtítọ́ ni ọ̀rọ̀ yín, kí ìwọ Mose sọ fún Aaroni pé kí ó ju ọ̀pá rẹ̀ sílẹ̀ níwájú Farao ọba, kí ọ̀pá náà lè di ejò.
Bongo gba ipo lowo baba re Omar Bongo,ti o ti fi igba kan dari orile ede naa fun odun mọ́kànlélógójì, ki o to ku ni odun 2009.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Saraki: Ilana gbigbogun ti iwa ijẹkujẹ ṣi n mẹhẹ lorilẹede Naijiria 8 Ẹrẹ̀nà 2018 Oríṣun àwòrán, @NGRSenate Àkọlé àwòrán, Ko to ida mẹwa awọn ileesẹ ijọba lorilẹ̀ede Naijiria to tẹle ofin isuna Ileegbimọ aṣofin agba lorilẹede Naijiria ti pinnu bayii lati gbẹsẹ le iṣuna fun ileeṣẹ ati lajọlajọ ijọba apapọ bii oji lerinwo ati mẹrin fun kikuna lati tẹle ilana ti ofin orilẹede Naijiria gbe kalẹ fun ayẹwo iwe owo wọn ṣaaju ọjọ kejidinlogun ọdun 2018.
Olu ilu Naijiria Abuja lo leke pẹlu iye awọn to ṣẹṣẹ lugbadi arun naa pẹlu eeyan 90.
Àwọn òṣìṣẹ́ tẹmpili nìwọ̀nyí:àwọn ọmọ Siha, àwọn ọmọ Hasufa ati àwọn ọmọ Tabaoti;
Àjọ tó n jàfún àkóyawọ́ lẹ́ka ètò ọrọ̀ ajé ní Nàìjíríà, (SERAP), lọ́dún 2017 nínú àbọ̀ ìwádìí kan fi ẹ̀sùn kan ìṣèjọba Olusẹgun Ọbasanjọ, olóògbé Umar Yaradua, tó fi mọ́ Goodluck Jonathan, pé wọ́n ná bílíọ́nù mọ́kànlá Naira básu-bàṣù lórí iná ọba.
Bẹẹ ba gbagbe, ọjọ kinni osu keje ọdun 2017 ni osere tiata padanu ọmọbìnrin kan, ẹni to jẹ alaisi lati ipasẹ arun foniku fọlande.
Donald Trump ti gbà pé Coronavirus yóò burú jáì kí ǹkan tó dára fún Amẹ́ríkà Awọn oṣerẹ bii Toyin Adewale ati Bose alao ati awọn miran ni wọn n ṣe ilede lẹyin rẹ ti wọn si banujẹ nigba ti wọn gbọ iroyin iku Satia Yusuf Oríṣun àwòrán, Kunle Afod/instagram Ikú ti yọ́wọ́ òṣèré Nollywood Yorùbá, Yusuf Satia l'áwo Oṣere Nollywood Yoruba, Yusuf Satia, ti ku.
Ko si ofin kankan to sọrọ nipa igbeyawo ori ayelujara lorilẹede Naijiria.
Ẹwẹ, laarin oṣu kẹsan ọdun 2020 yii ni ileeṣẹ ọkọ ojuurin sọ tẹlẹ pe ọkọ reluwe yoo bẹrẹ si ni ṣiṣẹ lati ilu Eko si Ibadan.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Blind DJ: Etu Omotayo kò ríran àmọ́ ó le to irinṣẹ́ eléré pọ̀ láti kọrin láì sí ìrànwọ́ Sugbọn bi idanwo naa ba se n lọ ni BBC Yoruba yoo maa mu iroyin nipa rẹ wa fun yin.
Kàyééfì, oyún inú nínú ilé ìgbọ̀nsẹ ọkọ̀ òfurufú Lẹ́yìn ò rẹyìn Seyi Makinde búra fún ìgbìmọ̀ olùgbaninímọ̀ràn Oko òkú rèé, níbití òkú ti ń jẹrà mọ́lẹ̀ fún àyẹ̀wò Ìgbà Marún-un ti Aisha Buhari ti tako ìjọba Buhari Alexandra yoo gba bọọlu fun igba ọgọrun un ti Germany ba koju Naijiria loni.
Wọ́n dájọ́ ikú nípa yíyẹgi fún David West tó ń pa àwọn obìnrin ní PortHarcourt lónìí Ẹ gbà mí o!
Harris ti baba rẹ jẹ ara Orilẹ-ede Jamaica ti iya rẹ si wa lati India lo di obinrin ẹya alawọdudu Asia akọkọ lati wa lorii tikẹẹti ẹgbẹ oṣelu pataki fun aarẹ.
Asiri ni baba Tahati, Tahati ló bí Urieli, Urieli bí Usaya, Usaya sì bí Saulu.
” Mo tún pè é lẹ́ẹ̀kẹta pẹ̀lú mo wí pé, Àkàrà-oògùn, òun náà sí ẹ̀rín, ó fi ọwọ́ sọ àyá, ó wí tìgbéragatìgbéraga, ó ní, ‘Àkàrà-oògùn ni orúkọ mi, orúkọ ńlá ni mo ń jẹ́, oríkì ti ó rọ̀ mí lọ́rùn ni mo gbà, ìrìn ẹsẹ̀ tí ó yẹ mi ni mo ń rìn kiri, èmi ni ọ̀rẹ́ rẹ àtijọ́, bẹ́ẹ̀ ni agbára mi kò dínkù, egungun ń bẹ lára okùnrin; ki ọwọ́ bọ àpò rẹ, bóyá ohun ìkọ̀wé le wà níbẹ̀, gọngọ á sọ lónìí; mo ní iṣẹ́ láti rán ọ si àwọn ọmọ aráyé, nítorí ọ̀rọ̀ pàtàkì ń bẹ ní agbárí, bẹ́ẹ̀ ni ìmọ̀ràn tí ó níláárí ń bẹ ní àtàrí mi, nítorí náà mo fi orúkọ àwọnn ènìyàn dúdú bẹ̀ ọ́, jọ́wọ́ dọ̀bálẹ̀ lórí àpáta, kí á fi àpáta ṣe tábìlì wa, kí èmi dúró gẹ́gẹ́ bí alága, kí ìwọ dúró gẹ́gẹ́ bí akọ́wé, kí ewéko igbó sì dúró gẹ́gẹ́ bí ọmọ ẹgbẹ́ fún wa.
Ọpọlọpọ igba ni orukọ alufa yii ti sun soke lori ayelujara to si tun jẹ ọkan lara awọn gbajugbaja ojiṣẹ Ọlọrun lagbaye amọ ọrọ tirẹ a maa fa ọpọlọpọ ọrọ jade lori ayelujara paapaa lẹnu awọn ọmọ Naijiria.
 yaléyalé ( architect ) ni .
Wolii OLUWA kan tí ń jẹ́ Odedi wà ní ìlú Samaria; ó lọ pàdé àwọn ọmọ ogun Israẹli nígbà tí wọ́n ń pada bọ̀.
Ìmúra málegbàgbé ti Sẹnatọ Dino Melaye ti mú níle aṣòfin àgbà l'Abuja
Lara awọn igbesẹ naa ni pe awọn ọlọkada ko gbọdọ siṣẹ kaakairi ipinlẹ Eko; ti awọn oni kẹkẹ marwa ko si gbọdọ gbe ju ero meji lọ.
Nítorí ẹ̀mí ṣe pataki ju oúnjẹ lọ, ara sì ṣe pataki ju aṣọ lọ.
Owó ilé ẹ̀kọ́ Fáṣítì Ìpínlẹ̀ Ondo ló kéré jùlọ ní Nàìjíríà Gomina Rotimi Akeredolu ti kede pe owo ile ẹkọ fasiti ipinlẹ Ondo lo kere julọ ni Naijiria.
Ọ̀gunbodede ní, èrí tún fi hàn pé, Monica ko féèlì ìdánwò náà, nítoripe èsì ìdánwò fi han pe ó gba maaki márùndíláàdọ́ta, tí ọmọ binrin náà ko si mọ̀ pe òun páàsì ìdánwò náà.
Ògiri tó gbé Nàíjíríà ró ń mì tìtì, ó sì le wó - Osinbajo figbe ta Laycon, kú oríire àmọ́ bá ń kó owó orí nínú ẹ̀bùn rẹ nílé BB Naija - Ìjọba Eko Ninu fidio kan to gba ori ayelujara kan bayii, ni Sẹnatọ Abbo ti kede pe, nitori oun se agbatẹru fun Leycon, o di dandan ko jawe olubori ninu idije naa.
Oríṣun àwòrán, @iam_Davido Àkọlé àwòrán, Ẹgbẹ oṣelu PDP wa ke si aarẹ lati wa nnkan ṣe si ọrọ naa Amọṣa ẹgbẹ oṣelu PDP ti pariwo sita pe ki aarẹ Muhammadu Buhari o tete ke si ajọ EFCC pe ko da gbe ẹsẹ kuro lori aṣuwọn owo Adeleke ninu eyi ti Sẹnetọ Ademọla Adeleke to n dije gẹgẹ bii oludije ẹgbẹ oṣelu naa nibi idibo gomina ti yoo waye lọjọ kejilelogun oṣu kẹsan.
Òun ni mo fi yà á l'áwòrán kí n tó mu ú o jàre.
O ni kete ti iṣẹ akanṣẹ to n lọwọ nibẹ ba ti pari ni ohun gbogbo ti wa si ipari nibẹ.
kí o sì sọ fún un pé, OLUWA Ọlọrun sọ nípa Jerusalẹmu pé:“Ilẹ̀ Kenaani ni a bí ọ sí; ibẹ̀ ni orísun rẹ.
O fẹ́ yọ́ wọ ààyè ibùsùn àwọn obìnrin lọwọ́ ọlọ́pàá bá tẹ̀ ẹ!
Oríṣun àwòrán, @olafare Àkọlé àwòrán, Oro to ba gba aaro ni siso a kii fi ale soo nile Yoruba Wọn ni o yẹ ki ijọba maa gbiyanju lati gbọ ohun tawọn eniyan wọn ba n sọ ki onikaluku le maa fẹdọ lori oronro sun.
Idowu ni ọpọlọpọ eeyan ko fi bẹẹ ni igbagbọ ninu iṣegun ibilẹ lati ọjọ pipẹ wa, pẹlu alaye wi pe iṣẹ iwadi ti awọn Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ṣé o láyà: Ẹ wo àkójọpọ̀ àwọn ǹkan ti o máa n wáyé lẹyin kámẹra lásiko iṣẹ́ Onimọ sayẹnsi yoo ṣe ni yara ayewo ni yoo mu ki o rọrun lati fi ọwọ awọn ogun ibilẹ naa sọya.
BB Naija 2019: Ọlọ́pàá Gẹ̀ẹ́sì bẹ̀rẹ̀ ìwádìí lórí Khafi lórí ẹ̀sùn ṣíṣe ìbálòpọ̀
Ìjàmbá ṣàwọn ajínigbé tó fẹ́ fipá gba akẹgbẹ́ wọn lákàtà àwọn ọlọ́pàá Nitootọ ni ìdìbò míràn á wáyé ní Kogi, mo máa di gómínà ni -Dino Ta ni Ọjọgbọn Adebanji Akintoye tó borí Tinubu láti di olórí àwọn Yoruba?
Nítorí OLUWA ló ni ìjọba,òun ní ń jọba lórí gbogbo orílẹ̀-èdè.
Ìyàlẹ́nu ló jọ́ fún ọ̀pọ̀ ọmọ Lebanon pé ìjọba kó àwọn èròjà olóró sí ìgboro Beruit, bótilẹ̀ jẹ́ pé, o ti pẹ́ ti àwọn ọmọ orílẹ̀-èdè náà ti ń nànka àláebù sí àwọn olóṣèlú, fún ìwà àjẹbánu, àìbìkítà àti síṣẹ́ ǹkan ìlú báṣubàṣu tí wọ́n tí ń ṣe látẹ̀yìn wá.
Avocado pear: Eso pear wulo pupọ fun agọ ara wa, nitori o tun maa n mu adinku ba awọn ọra ara taa mọ si Cholesterol.
Sugbọn to ba ti di aago kan ọsan si mejila oru, awọn to n bọ lati Lagos Island nìkan ni yoo le lo ori afara, ti iyatọ diẹ si wa nibẹ.
Fífi èké kó ìṣúra jọdàbí lílé ìkùukùu, ó sì jẹ́ tàkúté ikú.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: ‘Buhari ti gbàbọ̀dè fún Nàìjíríà’ ‘Èmi kò leè gbà kí Ọba Ìbàdàn di 48 Oyinlọlá kúrò ní APC, PDP ní kó padà wálé Ó ní, ó ṣeéṣe kí àwọn irinṣẹ́ ètò ààbò tó jẹ́ ojúlówó wà níbẹ̀, tó fi mọ́ àwọn nkan mìi tí wọ́n kó síbẹ̀, ṣùgbọ́n kò yẹ kí iye tí wọ́n nàá láti fi kọ́ ìlé nàá tó bẹ́ẹ̀.
 Ẹnìkan lè dá a kọ fún gbogbo ènìyàn tàbí kí gbogbo ènìyàn kópa níní kíkọ rẹ ̀ .
Iṣẹlẹ yii waye lẹyin oṣu diẹ ti awọn ọlọpaa tẹ George Floyd to jẹ alawọ dudu lọrun pa l'Amẹrika yii kan naa.
 Ayokunle Sulaiman ati aya rẹ, Reme Olotun ti n ka ọjọ ka oṣu si ọjọ ayẹyẹ wọn eyi to yẹ ko waye ni ile itura Sheraton ni ipinlẹ Eko, orilẹede Naijiria, lọjọ ti wọn da, ọjọ kejidinlogun oṣu kẹrin ọdun 2020."
Ṣugbọn bí o bá tí ṣe alaiṣootọ sí ọkọ rẹ (níwọ̀n ìgbà tí o wà ní ilé rẹ̀), tí o sì ti sọ ara rẹ di aláìmọ́ nípa pé ọkunrin mìíràn bá ọ lòpọ̀, 
 murtala tún se àtúnyèwò òye ise ìtójú ìlú tó ní se pèlú ìlú mìíràn tí àwon egbé ìlú tí ó n sèdá epo ròbì lágbàáyé ( opec ) .
Omotola loju opo Twitter rẹ pe, orilẹede Naijiria dabi ọrun apaadi labẹ iṣejọba Aarẹ Buhari ati igbakeji rẹ, Ọjọgbọn Yemi Osinbajo.
Keshi lo gba ife ẹyẹ AFCON ti ikọ Naijiria gba kẹyin lọdun 2013 lorilẹede South Africa.
Lẹsẹkẹsẹ, ó bẹ àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ pé kí wọn wọ ọkọ̀ ojú omi ṣáájú òun lọ sí òdìkejì, nígbà tí ó ń tú àwọn eniyan ká.
Oríṣun àwòrán, @APCNigeria Àkọlé àwòrán, Aáwọ̀ abẹ́nú lóríṣiiríṣìí ló ń ṣẹlẹ̀ ninu ẹgbẹ APC lorilẹ-ede Naijiria O tẹsiwaju wi pe awọn ti ''gbe igbimọ ti yoo pẹtu saawọ laarin awọn ọmọ ẹgbẹ kalẹ.
Ìgbésẹ̀ ìgbìmọ̀ amúṣẹ́yá ẹgbẹ̀ nàá kò ṣẹ̀yìn àbájáde ìwádìí tí ìgbìmọ̀ tí wọ́n gbékalẹ̀ láti ṣàyẹ̀wò àwọn tó fẹ́ díje fún ipò gómìnà nínú ẹgbẹ́ nàá, bẹẹ, iwe èri agunbanirọ jẹ ọkan lara àwọn àmúyẹ lati lè dije fún ipo gomina ni Naijiria.
President @MBuhari addressing the #UNGA #NigeriaAtUNGA https://t.
Banky W: ojoojúmọ́ ayé mi ni mo ti fi lá àlá kó lè wá sí ìmúṣẹ
Ẹni tí ó fi kọ́kọ́rọ́ dán séèfù wò tí a ń sọ̀rọ̀ rẹ̀ lókè ni Àṣàkẹ́ ìyá Bándélé.
Yàtọ̀ sí eku gọ́tà tàbí èku inú ilé, kò sí eku téèyàn ò lè jẹ - Òǹtajà Eléwé ọmọ Lẹ́yìn ọdún mẹ́ta l'ẹ̀wọ̀n akọrin ẹ̀mi gbẹ̀mí ará rẹ̀ látìmọ́lé Iku Mọkaliki: Àgbáríjọ àwọn ajàfẹ́tọ̀ọ́ pè fún ìdádúró kọmísánà ọlọ́pàá Ibrahim Magu ni lati ọdun 2015 ni awọn ti bẹrẹ igbogunti naa ni ọkunkundun, ti awọn si ti fi panpẹ ọba mu eniyan mẹtalelọgọrun ni 2015, marundin-nigba ni ọdun 2016 ati ọọrundunrun le mẹrinla ni ọdun 2018, nigba ti awọn si mu eniyan to le ni ẹgbẹrun lọdun 2019 nikan.
2019 Guber Polls: Ẹ wo àwọn baba ìsàlẹ̀ òṣèlú tí wọ́n bá ìtìjú bọ̀ nínú ìbò gómìnà
Ohun kan ni kí ẹ ṣe: ẹ fi àwọn ohun tí ó wà ninu kọ́ọ̀bù ati àwo ṣe ìtọrẹ àánú; bí ẹ bá ṣe bẹ́ẹ̀, gbogbo nǹkan di mímọ́ fun yín.
Kini awọn ọna eto abo miran ti wọn fi lelẹ lẹyin ti wọn ko awọn ologun kuro nibẹlati maa da abo bo awọn eeyan to wa nibẹ?
"South Africa: Wọ́n jó ọmọ Nàíjììrà nína láàyè Àwọn ọmọ Naijiria kóju ija sí àwọn South Africa wọ́n ní ""Ó tó gẹ́"" Ìjọba South Africa pèpàdé lórí ìkórìíra àlejò Oluwateru ni o ṣeni laanu pe orileede South Afrka ti Naijiria ti ṣe loore to pọ, ni yoo ma wa fi ẹ̀yin ọbẹ jẹ Naijiria niṣu."
"Oríṣun àwòrán, Natalia Ojewska Àkọlé àwòrán, Ipinu wa ni ki a da awon odanran pada si aarin awujọ "" Wọn wọ sọọsi ti wọn bẹrẹ si ni sa wa ni ada ti wọn si n pa awọn eniyan, eri ọgbẹni Kayitera ti oun naa bọ lọwọ ogun naa ree nítori o sa pamọ saarin awọn oku."
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Olusegun Obasanjo: Ọmú ìyá mi ti mo fi ń mùkọ ni kekere ló jẹ ki ń lókun Ibikunle Amosun Lootọ ni Gomina Ipinlẹ Ogun Ibikunle Amosun jawe olubori ninu ibo ile igbimọ aṣofin agba l'Abuja, ṣugbọn o ni ijakulẹ ninu ibo gomina lẹyin ti Adekunle Akinlade oludije ẹgbẹ APM to ṣatilẹyin fun fidi rẹmi.
Àwọn òṣìṣẹ́ iléeṣẹ́ tó ń mójútó àyípadà àwọn ti wón ń mu oògùn ikọ́ olómi Codeine bíi egbògi olóró máa ń so wọn mọ́lẹ̀ ni.
O tun wa ro awon omo orile ede Naijiria lati yago fun iwa jagidi-jagan, oro to le da wahala sile, “ Ki won si maa wa idagbasoke orile ede Naijiria ati awon omo to n bo lojo iwaju.
Gomina ipinlẹ Ọyọ, Seyi Makinde ti ni awọn gomina ni ẹkun Iwo-oorun guusu Naijiria ti mura lati se ifilọlẹ eto aabo to gbooro ni osu to n bọ.
” Gbogbo wọn bá yin OLUWA Ọlọrun àwọn baba wọn.
Ẹsun ti wọn tun fi kan ileeṣẹ naa ni wi pe, wọn ko pese ohun elo aabo bii PPE fun Richard lo ṣe ku.
Ìdílé gbajúgbajà ajàfúnẹ̀tọ́ ọmọnìyàn ni ó ti wà, adájọ́ ajàfúnẹ̀tọ́ ọmọnìyàn Ahmed Seif El Islam, ni bàbáa Alaa, ẹni tí a ti rán lọ ní ẹ̀wọ̀n láì mọye ìgbà ní abẹ́ àṣẹ Hosni Mubarak.
Bawo ni Coronavirus ṣe kan awọn ọmọde?
Lootọ ni BBC Yoruba ko ti i le sọ pato otitọ to wa ninu iroyin yii, amọ awọn akiyesi kan ti a ri lori ayelujara Instagram Olori Anu re e: Iyatọ to ba oju opo Instagram olori Anu lẹyin iroyin pe o kọ Alaafin: Ayẹwo si oju opo naa fihan pe, ko si aworan kankan to ya pẹlu Ọba Adeyẹmi, tabi ti kabiesi nikan, mọ loju opo naa (Gbogbo awọn olori lo ni aworan Alaafin si oju opo ayelujara wọn).
“Ìbá ti dára tó, kí Ọlọrun mú ìbéèrè mi ṣẹ,kí ó fún mi ní ohun tí ọkàn mi ń fẹ́.
Koko ohun to f'arahan ninu ọrọ yii paapaa ti a ba n sọrọ eto ọgbin ni wi pe o yẹ ki a pese aye ti yoo le gba awọn to n sisẹ ni ẹka naa duro daadaa.
 tí ó sì wà láàárin ọ ̀ pọ ̀ àwọn ènìyàn .
Laipẹ yii si ni Pasitọ kan, Pasitọ Paul Enenche sọrọ lori bi Freeze ṣe sọrs abuku si Oyedepo.
Ìdí rẹ̀ ni ẹ fi ń gbọ́ ariwo.
Ṣugbọn lẹ́yìn tí ẹ bá ti jìyà díẹ̀, Ọlọrun tí ó ní gbogbo oore-ọ̀fẹ́, òun tí ó pè yín sinu ògo rẹ̀ ayérayé nípasẹ̀ Kristi, yóo mu yín bọ̀ sípò, yóo fi ẹsẹ̀ yín múlẹ̀, yóo fun yín ní agbára, yóo sì tún fi ẹsẹ̀ ìgbé-ayé yín múlẹ̀.
Wayii o ajo to n mojuto isele pajawiri lorile-ede Mozambique
Nàìjíríà wà ní ìsọ̀rí kejì pẹ̀lú Burundi, Madagascar àti Guinea Ọ̀dọ́kùnrin tó kọ́kọ́ ṣe ẹ̀rọ tó ń tu ìyẹ́ lára adìyẹ Bí o ṣe lè fí òǹkà, ọ̀mọ̀ ìka tàbí ìkúùkù wọn oúnjẹ́ Oga agba ajọ yii gba pé ọpọlọpọ ile iwe giga ni awọn ti ko ba yege to ninu idanwo UTME ṣi le wọ bii ilẹ ẹkọ nipa iṣẹ itọju alaisan, ilẹ ẹkọ nipa ọsin ẹja ati bẹẹ bẹẹ lọ.
Lasiko abẹwo rẹ, Macron yoo tun se abẹwo si ibi igbafẹ, ‘Afrika Shrine’ ni ipinlẹ Eko nibi ti olorin afro- juju, Fela Anikulapo Kuti da si lẹ, ti ọmọ rẹ, Femi Kuti si se atunse si, to si pe orukọ rẹ ni ‘New Afrika Shrine’.
22 Bélú 2020 Ọwọ́ ọlọ́pàá tẹ àwọn méji tó jẹ ẹran ara ọlọ́pàá tí wọ́n pa n'Ibadan24 Bélú 2020 Kegel: Eré ìdárayá tí àwọn onímọ̀ sọ pé ó n fikún adùn ìbálòpọ̀ fún obìnrin, tó tún n fún ọkùnrin ní agbára24 Bélú 2020 Fídíò, Oba Adedokun Abolarin ti Oke Ila: Ó ya ọ̀pọ̀ tó súnmọ́ mi lẹ́nu bí mo ṣe ń kọ́ àwọn akẹ́kọ̀ọ́ pẹ̀lú ipò Ọba23 Bélú 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Ebola: Nàìjíríà ń ṣọ́ pápákọ̀ òfurufú tórí Ebola
’’Adesina so pe awon ti akoroyin so nipa re yii ko kọ iyan aare Buhari kere rara .
Ohun tí ó ń fa ikú ni ìbàjẹ́ ọkàn tí a ò wò sàn.
Aaron Ramsey: £400k lọ́sẹ̀ ni Ramsey yóò maa gbà ní Juventus
Amọ, o sọ pe ijọba apapọ fi ẹtẹ silẹ, o n pa lapalapa nitori o kọ eti ikun si ọrọ eto ati maa pin owo tuntun fawọn ipinlẹ ṣugbọn o kede akanṣe owu oṣu tuntun fawọn olukọ.
Ẹ kò rí ‘rùngbọ̀n rẹ̀ bí ó ti ń gbálẹ̀ guruguru.
 Àwọn ẹgbẹ ̀ rún méjì ènìyàn ló wá sí ibi ayẹyẹ náà .
"Oò lè pa owó púpọ̀ gẹ́gẹ́ bí obìnrin níbí""."
Ẹkẹẹdogun mú Jeremotu, òun ati àwọn ọmọ rẹ̀ ọkunrin, ati àwọn arakunrin rẹ̀ jẹ́ mejila.
Ó ní, mo ṣá gbọdọ̀ fẹ́ aya fún ọmọ òun láàrin àwọn eniyan òun ati ní ilé baba òun.
Chief Kanran wa rọ awọn ọmọ Yoruba lati fi ọwọ sọwọpọ, ki wọn sọra fun gbogbo iwa ibajẹ ki wọn le de ibi aṣeyọri.
O ni: Mi ko ri awọn eniyan Sinhalese ri tabi ba wọn sọrọ ri.
Oríṣun àwòrán, NNPC/Twitter Àkọlé àwòrán, Iye owo ti awọn alagbata epo n ra awọn epo ni ibudo igbepo (depot) nikan ni adinku yii ba.
oludije to ti wa ni ipo tẹlẹ ba jawe olubori, ti Ajọ INEC wa fun ni iwe lati da
Oríṣun àwòrán, @itz_chibuisky Àkọlé àwòrán, Abeokuta Yatọ si eyii, awọn oluwọde tun gbọna ọfiisi gomina ipinlẹ Ogun, Dapọ Abiodun lọ lati sẹ ifẹhonuhan nibẹ.
mo sì ti sọ̀kalẹ̀ wá láti wá gbà wọ́n sílẹ̀ lọ́wọ́ àwọn ará Ijipti, ati láti kó wọn jáde kúrò ní ilẹ̀ náà lọ sí ilẹ̀ kan tí ó dára, tí ó sì tẹ́jú, ilẹ̀ tí ó lẹ́tù lójú tí ó kún fún wàrà ati oyin, àní, ilẹ̀ àwọn ará Kenaani, ati ti àwọn ará Hiti, ati ti àwọn ará Perisi, ati ti àwọn ará Hifi ati ti àwọn ará Jebusi.
Ofin to de lilo ẹrọ ayelujara ni Naijiria fun ijọba Naijiria laaye lati ṣe ọfintoto awọn iroyin ti ileeṣẹ iroyin lati oke okun ba n gbe jade ni Naijiria, lati ri wi pe wọn ko gbe iroyin to le e da wahala silẹ ni Naijiria.
Ìjà sì ń ṣẹlẹ̀ láàrin àwọn darandaran Abramu ati àwọn ti Lọti.
 Laipe ni a maa siso loju eegun awon eto ti a ti la kale fun irinajo afe nipinle Eko”.
Àṣẹ yìí ni mo rí gbà láti ọ̀dọ̀ Baba mi.
Germany lo gbalejo idije ife ẹyẹ agbaye lọdun 2011.
"Àpá àdá ṣi ǹ bẹ lara mi.
Ko si si ẹnikẹni ninu wọn ti yoo bọ si jade bọ si gbangba titi eto idibo naa yoo fi pari, ti wọn si fẹnuko lori Poopu tuntun.
Oríṣun àwòrán, Others Tinubu sọ pe iwa aimore ni lati maa mọ riri ipa ti Oshiomole ko ninu ẹgbẹ oṣelu APC papaajulọ lasiko ibo to ja.
Bakan naa, O tun sise gege bi minisita to n mojuto eto isuna lorile-ede Naijiria, lati odun 2003 si odun 2006.
Amọṣa iyatọ ti o ṣeeṣe ko de baa ni pe aarẹ Buhari lee fẹ aṣẹ naa loju ko ka gbogbo orilẹede Naijiria lai da ipinlẹ kọkan si.
O gbadura pe Olorun a te oloogbe si afefe rere yoo sit u awon ebi, ara ati iran Yoruba ninu lapapo.
Lati ṣe atunse si akọsilẹ nipa ọjọ ìbí rẹ, ẹgbẹrun mẹẹdogun Naira ni wa a san.
Imaamu àgbà mọsálásí Tran-Amadi Haroon Mohammed sọ pé láti ọdún 2007 ní àwọn ti ra ilẹ̀ náà lọ́wọ́ ọkunrin Kan.
Mẹ́rin nínú àwọn to fipá bálòpọ̀ náà ló lóyún, tó sì jẹ́ pé, ìyàwó rẹ̀ Juliana ló máa n ṣọ̀nà bi wọ́n ṣe ń ṣẹ́ oyún náà, kódà ọkan nínú àwọn ọmọbinrin náà ló ni òun ti ṣẹ́ oyún tó ìgbà mẹ́fà láti ìgbà ti òun ti wà nílé ìwé girama Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'N500 dé fún gbogbo ọmọ tuntun lóṣooṣù bí mo bá di gómìnà Ondo - Adeleye AAC Timothy Omotosho Oríṣun àwòrán, Sowetan/Getty Images Nínú oṣù kẹwàá ọdún 2018, ajíhìnrere kan Timothy Omotosho ti ìjọ Dominion International Church ni South Africa náà dèrò ẹ̀wọn nítori ẹsùn ifípábánilòpọ̀ to ṣe si ọmọ ìjọ rẹ̀ Cheryl Zondi láti ìgbà tí ó ti wà ni ọmọ ọdún mẹ́rìnlá títí tó fi pé, ọmọ ọdún méjìlélógún.
Olukọ rẹ lo fi iwe kan ransẹ si mi pe Tanitoluwa nifẹ lati maa ta ayo Chess, yoo si dara ti mo ba lee ba olukọni wọn sọrọ.
Lẹyin ọ̀rọ̀ olorin takasufe, Jude Abaga ti gbogbo eniyan mọ si MI sọ lẹyin awuyewuye to waye nigba ti Busola Dakolo fi ẹsun ifipabanilopọ kan adari ijọ COZA, Biodun Fatoyinbo, ijọ Satani ti ni ki wọn ma pa orukọ Satani pọ mọ awọn to ba ṣe iṣẹ ibi.
Ọ̀gbẹ́ni Hazzan sọ fún wa, pẹ̀lú àlàyé bó se máa ń sá fáwọn alásẹ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Oba Adedokun Abolarin ti Oke Ila: Ó ya ọ̀pọ̀ tó súnmọ́ mi lẹ́nu bí mo ṣe ń kọ́ Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Femi Gbajabiamila: DSS ti fi ẹ̀sọ́ àbò Gbajabiamila tó pa fẹ́ndọ̀ l'Abuja sátìmọ́lé23 Bélú 2020 Covid 19 update: Wo ǹkan mẹ́wàá tó yẹ kí o mọ̀ tí o bá fẹ́ lọ fún ìsinmi lẹ́yìn Covid 1923 Bélú 2020 Fídíò, The New Pandemic: Kíni àwọn onímọ̀ sáyẹ́ńsì ń sọ nípa rẹ̀?
Yekini fikun pe nigba ti wọn pada de lati Alimoso, Gbadero fa ìbọn yọ lati abẹ sokoto rẹ, to sì sọ fun oun pe oun Eji Gbadero ti pa ọkùnrin ti Kehinde kọ lati pa.
Pásítọ̀ gún ìyàwó rẹ̀ lọ́bẹ nínú ṣọ́ọ̀ṣì, ló bá tì í bọ ara rẹ̀ náà níkùn Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Ṣugbọn bí ọkọ rẹ̀ bá kú, ó ní òmìnira láti tún ní ọkọ mìíràn tí ó bá fẹ́.
irinse ati ohun elo idibo naa.
Ni afikun, Koeman ti tuko agbaboolu Vitesse Arnhem, Benfica, Valencia, AZ Alkmaar, Feyenoord ati Southampton.
” Mo dáhùn pé, “Rárá, oluwa mi, n kò mọ̀ ọ́n.
ofin orile ede yii  ati pe o tun jẹ
Wàyì ó, àtẹ̀jáde kan tí ilé asòfin àgbà ilẹ̀ wa fi síta lórí ìsẹ̀lẹ̀ náà sàlàyé pé àwọn jàǹdùkú kan yabo àwọn níbi jókòó ilé, tí asòfin kan tí wọ́n ti ní kó lọ rọọ́kún nílé ná, Ovie Omo-Agege sì ló kó sòdí, tí wọn sì gbé lọ Oríṣun àwòrán, @SenateNG Àkọlé àwòrán, Lásíkò tí ìjókòó ilé ń lọ lọ́wọ́, lawọn jàǹdùkùú ya wọnú ilé, tí wọn sì gbé ọ̀pá àsẹ ilé.
“Awon iko agbaboolu miiran ohun ni: Kada Football Club, Malumfashi FC, Bimo FC, Real Stars FC, Stores FC ati Rovers FC,”O fikun un pe, igbimo to n sakoso idije naa gba lati je ki awon iko agbaboolu tuntun darapo mo idije ohun, ni paapaa julo lati mu ofin miiran, eyi ti yoo da idije ohun duro gbara ti idije boolu agbaye ba bere.
Solomoni jọba lórí gbogbo ilẹ̀ tí ó wà ní apá ìwọ̀ oòrùn odò Yufurate, láti ìlú Tifisa, títí dé ìlú Gasa, ati lórí gbogbo àwọn ọba tí wọ́n wà ní apá ìwọ̀ oòrùn odò Yufurate; alaafia sì wà láàrin òun ati àwọn agbègbè tí ó wà ní àyíká rẹ̀.
adari  omo egbe oselu to poju, ti  asofin Asinmiyu Alarape je olori omo egbe
''Mo si rọ ọ ko lọ fun iwosan, amọ o kọ, mi o si fẹ ko ko arun ran mi.
Bẹ́ẹ̀ ló ṣe ya Aaroni ati àwọn aṣọ rẹ̀ sí mímọ́, ati àwọn ọmọ rẹ̀, tàwọn taṣọ wọn.
Lẹyin naa lo tun gboye keji ni ati ikẹta ni fasiti Columbia niluu New York l'Amẹrika lọdun 1970 ati 1974 ninu ẹkọ nipa sayẹnsi osẹlu ati ibara-ẹni-ṣepọ laarin awọn orilẹede agbaye.
Ní ọjọ́ iwájúJakọbu yóo ta gbòǹgbò,Israẹli yóo tanná, yóo rúwé,yóo so, èso rẹ̀ yóo sì kún gbogbo ayé.
Ọlọ́pàá ń wa Baale Apese d'àwátì, ó bọ́ sọ́wọ́ ajínigbé!
Josẹfu tún sọ fún wọn pé, “N kò gbà, ibi tí àìlera ilẹ̀ yìí wà ni ẹ wá yọ́ wò.
Èèyàn méjì gbẹ́mìí mì nínú ìjàmbá ọ̀kọ̀ tó ṣẹlẹ̀ lórí afárá Otedola Bi wọn ṣe pa a yii ti ru ọpọlọpọ ibinu soke laarin orilẹede Iran ati orilẹede Amẹrika.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Wilder ni oriṣiiriṣii ounjẹ loun n jẹ lọwọ yii pẹlu afẹsọna atawọn ọmọde to rọgba yi oun ka.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìjọba Ọyọ: Igba náírà péré làwọn ọlọ́kadà yóò máa san lójúmọ́ fáwọn adarí ibùdókọ̀ tuntun 15 Èrèlè 2020 Oríṣun àwòrán, @transports_NG Ijọba ipilẹ Ọyọ ti kede pe oun ti yan awọn alakoso ibudokọ lati maa se akoso awọn ibudokọ to wa lawọn gbogbo ijọba ibilẹ to wa jake jado ipinlẹ naa.
Ata rodo ní ń jẹ́ Chilli.
Wọn fẹ ki ọba naa wa lai ni àṣẹ, ọ̀wọ̀ ati agbara.
Nítorí náà Esau lọ sọ́dọ̀ Iṣimaeli ọmọ Abrahamu, ó sì fẹ́ Mahalati ọmọ rẹ̀, tíí ṣe arabinrin Nebaiotu, ó fi kún àwọn aya tí ó ti ní.
Digbí ni mo wà lẹ́yìn Amotekun, máà ṣèrànwọ́ mílíọ̀nú èèyàn fun - Nnamdi Kanu Irọ̀ ni ìjọba ń pa, Ikọ Amọtẹkun ba ofin Naijiria mu- Ìgbìmọ̀ Yoruba Amotekun: Kí ni iṣẹ́ tí Amotekun yóò máa ṣe gangan?
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù COZA: Ìlú tí ọdaràn ba tí dẹṣẹ ló yẹ kí wọn tí gbẹ́jọ́ rẹ̀ -Agbẹjọ́rò 9 Agẹmo 2019 Oríṣun àwòrán, @BIODUNFATOYINBO/@BUSOLADAKOLO Àkọlé àwòrán, Pasitọ Biodun Fatoyinbo àti Busola Dakolo Ọrọ ibi ti wọn yoo ti gbẹjọ ẹsun ifipabanilopo ti wọn fi kan Pasito Biodun Fatoyinbo ti ijọ COZA ko yẹ ki o mu awuyewuye wa.
Ṣugbọn Eleasari kú láì ní ọmọkunrin kankan; kìkì ọmọbinrin ni ó bí.
Ọpọ ẹnu lo ti n kun Davido lẹyin ti iroyin jade pe ọpọ awọn eeyan to sun mọọ lo ti n ni arun yi lara.
Èmi náà sì tún fèsì, mo ní, ‘Hin-in, bí ẹnu mi bá ń le koko ńkọ́?
Son Heung-min lo kkọ fi bọọlu sinu awọn, lẹyin ti Dele Alli gba bọọlu fun un, ti o si wọ inu awọn.
 Ó ti tó ọdún mẹ ́ fà kí akin Ọlọ ́ fín-íntótó ọmọ olúṣínà àti Ọmọ ́ tọ ́ ṣọ ̀ ọ ́ ti rí ara wọn mọ kí wọn tún tó rí ara wọn yìí .
Ìyẹn bẹ́ẹ̀, àwọn ọmọ ẹgbẹ́ẹ ajótà Ìran Ọ̀kín Thangya márùn-ún di èrò ẹ̀wọ̀n tí ó wà ní Insein títí di ìgbà tí wọn yóò lọ sí ilé ẹjọ́ fún ẹ̀fẹ̀ tí wọ́n fi ológun ṣe.
Onome Ebi, ọkan lara awọn agbabọọlu ti oju wa lara rẹ ni awọn sa ipa awọn ninu idije pẹlu France ko to di pe wọn gba ami ayo kan sile Naijiria ninu kọju si mi koo gbaa sile.
Nítorí náà, OLUWA ní, òun óo mú kí ibi ó dé bá wọn, ibi tí wọn kò ní lè bọ́ ninu rẹ̀.
Eko ni o kun fun ero julọ nilẹ Adulawọ.
Lọwọlọwọ yii, igbo mimu ṣi lodi sofin ni Naijiria, ati wipe ẹnikẹni ti ọwọ ba ba le lọ ẹwọn.
A ṣe é lọ́ṣọ̀ọ́ bí ìgbà tí a bá ṣe iyawo lọ́ṣọ̀ọ́ fún ọkọ rẹ̀.
Mo si ba sisẹ papọ gẹgẹ bi Gomina ati bii baba si ọmọ.
A bi Adebanji Akintoye sile alade lọdun 1935.
Níwọ̀n ìgbà tí ìkùukùu náà bá ti wà ní orí Àgọ́ Àjọ, àwọn ọmọ Israẹli yóo dúró ninu àgọ́ wọn.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ṣọla Allyson: Obìnrin tí kò bá rẹwà ni yóò máa ṣí ara sílẹ̀ Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Bí Jesu ti ń lọ àwọn eniyan ń bì lù ú níhìn-ín lọ́hùn-ún.
Àwọn ẹranko pàtàkì gbogbo tí wọn ń gbé etí ìbodè ni wọ́n jáde nítorí ọ̀ràn yìí, nítorí kìnnìún dúró gẹ́gẹ́ bí alága, àjànàkú sì dúró bí igbákejì, bẹ́ẹ̀ ni ẹkùn wà nínú ẹni tí ń wòran.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Bullmastiff German Shepherd: Aja yii ma n pa awọn aja kekeke to ba sun mọ.
Bí ile asofin àgbà, a yà idà mẹwa ọ̀rọ̀ aje wá ṣílẹ̀ fún idagbasoke eto ìlera, ìdènà ajakalẹ àrùn àti ìmọ̀ ẹ̀rọ, tá sì tún ń ṣe agbeyẹwo àwọn òfin wá ti ọjọ́ tí lọ lórí wọn."
O si tun da ISIL silẹ l'oṣu Kẹrin, ọdun 2013.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ọmọ Yahoo tú àṣírí ara rẹ̀ fún, bí wọ́n ṣe ń ṣe é BBC Yorùbá Ewu ń bẹ lóko lóńgẹ́!
FBI List: Ìwádìí EFCC àti FBI ti ń so èso rere
kí ó sọ fún Aaroni ati àwọn ọmọ rẹ̀ pé, “Báyìí ni ẹ óo máa súre fún àwọn ọmọ Israẹli.
Wọn yóo máa sọ pé, ‘Wò ó níhìn-ín’ tabi, ‘Wò ó lọ́hùn-ún’.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ṣé o láyà: Ẹ wo àkójọpọ̀ àwọn ǹkan ti o máa n wáyé lẹyin kámẹra lásiko iṣẹ́ Lásìkò to n ba BBC sọ̀rọ̀ Ọmọlabakẹ sàlàye pé ìdá ààdọrun nínú àwọn arìnrìn ajo ló jẹ́ olugbé ìlú Eko sùgbọ́n ìjọb a ni ilú Abuja ni àwọn yóò ti lọ já wọ́n silẹ̀.
Adari ile isẹ to n risi eto ẹkọ ni ipinlẹ Ọyọ, Idowu Adeosun lo fi ọrọ naa lede ninu atẹjade to fi sita.
N óo mú kí ahọ́n rẹ lẹ̀ mọ́ ọ lẹ́nu kí o sì ya odi, kí o má baà lè kìlọ̀ fún wọn, nítorí pé ìdílé ọlọ̀tẹ̀ ni ìdílé wọn.
N óo fọ́n àwọn tí wọn ń gé ẹsẹ̀ irun wọn ká sí igun mẹrẹẹrin ayé,n óo sì mú kí ibi bá wọn láti gbogbo àyíká wọn.
"Oríṣun àwòrán, Twitter ""Alaye to ṣe fun mi ni pe ija lo waye laarin ọmọbìnrin naa ati awọn kan ninu sọọsi."
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Constituency office: Kí ni pàtàkì ọ́fíìsì agbègbè fún aṣòfin?
Wọ́n ṣe ère kinniun mejila sí ẹ̀gbẹ́ àtẹ̀gùn náà, ọ̀kọ̀ọ̀kan ní ẹ̀gbẹ́ kinni keji ìṣísẹ̀ kọ̀ọ̀kan.
Oun ni olori awọn obinrin ninu ẹgbẹ oṣelu ANPP ti Buhari ba dije tẹlẹ.
Ìyàsímímọ́ Aaroni ati Àwọn Ọmọ Rẹ̀.
Orisirisi isele ni o n waye laarin awon alatileyin  Samura Kamara ati Julius Maada Bio, ti won je oludije meji gboogi, ti won yoo figa-gbaga ninu atundi eto idibo ti yoo waye lojo ketadinlogbon osu keta odun ti a wa yii.
"Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Farms to You: Irú ajílẹ̀ wo ló yẹ fún lílò lásìkò yìí- Aisha Issa ni: ""A pade lẹyin ti mo bẹrẹ si ni 'tẹle e' lori Instagram, to ba si fi aworan kankan si oju opo naa, maa fi ifẹ han si."
Ẹni tí ó bá jẹ́ ti Ọlọrun yóo gbọ́ ọ̀rọ̀ Ọlọrun.
Koda, baba naa fi igi kan hanu to dabi ikoko taba, to si joko dabu ẹsẹ rẹ sori ara wọn.
Wọn ji eeyan mẹfa gbe lọjọ Aje ti iṣẹlẹ naa waye.
Lekki free toll: Àwọn ará ìpínlẹ̀ Eko kan sárá sí Sanwoolu
Ẹnikẹ́ni ní inú ilé ni ó lè mú un ní ibẹ̀ kí ó sì fi sí ilẹ̀kùn Yéwándé ni ó máa ń tọ́jú Orímóògùnjẹ́ lóru nígbà tí ó ń ṣe àìsàn.
Lara awọn ohun ti wọn da pada ni ilu Adamawa ni ẹrọ ilọta, ẹya ara ọkọ, irẹsi, ikoko ọbẹ ati bẹẹ bẹẹ lọ.
Nígbà tí ìkún omi dé, tí àgbàrá bì lu ilé náà, kò lè mì ín, nítorí wọ́n kọ́ ọ dáradára.
•Gbogbo ilẹkun awọn ibudo igbafẹ bii ibudo isenkan isẹnbaye lọjọ si, to fi mọ ibudo itọju ẹranko lorilẹede Amẹrika, ni yoo wa ni titipa.
Amọ Akitoye ko sinmi, o bẹ awọn oyinbo lọwẹ lati gbogun ti Kosoko, ti wọn si le e kuro lori oye lọ silu Epe pẹlu Oshodi, ni ọjọ kẹtala, oṣu Kẹjọ, ọdun 1853.
Ati a kọlà ni, ati a kò kọlà ni, kò sí èyí tí ó ṣe pataki.
Ọ̀pọ̀lọpọ̀ ìlú lagbaye ni ko mọ pe apa ibi kan ṣi wa lorilẹ aye ti wọn ti n ta eku gbigbẹ iyẹn ni Naijiria Awọn olutaja kan wa to jẹ pe loju paali, ni beeli, beeli, dọsiini dọsiini ni wọn ko ekute to ti ku sori igba wọn.
Àwọn eniyan Ninefe yóo dìde dúró ní ọjọ́ ìdájọ́ láti ko ìran yìí lójú, wọn yóo sì dá wọn lẹ́bi.
“Ọjọ́ kẹrinla oṣù kinni ni Àjọ̀dún Ìrékọjá OLUWA.
Ipinlẹ wo ni yoo sọ ibi ti ọpa ẹbiti ibo yoo re si ?
wọ ́ n bí leventis ní abúlé lemythou , ní ìletò limassol district , ní ìlú troodos mountains .
láti inú ẹ̀yà Gadi, ó rán Geueli ọmọ Maki.
Oríṣun àwòrán, @BrianKarem Awọn onímọ̀ ẹ̀rọ, àwọn ti kò ní ohun ṣe pẹ̀lú iṣẹ́ ọ̀gbìn àti àwọn ti wọ́n máa ń ràn ẹbi lọ́wọ́ fun ìtọ́jú ọmọ tàbi ìtọ́jú ilé, tó fí mọ́ àwọn ọ̀gá ilé iṣẹ́ ńlańlá ni ọ̀rọ̀ náà yóò kan.
Dokita Olajide ni labẹ ofin, ohun ti ijọba sọ ko bojumu nitori ijọba tiwantiwa la n ṣẹ, ti onikaluku si ni ẹt lati da aabo bo ara wọn, igbimọ kọọkan ni ẹtọ lati da abo bo ara wọn.
dije du ipo gomina nigb ati egbe oselu merindinlaadota (659) fa oludije mejilelogbon
Nítorí náà, gẹ́gẹ́ bẹ́ẹ̀ ni, ẹnikẹ́ni ninu yín tí kò bá kọ gbogbo ohun tí ó ní sílẹ̀, kò lè jẹ́ ọmọ-ẹ̀yìn mi.
Àwọn tí wọ́n jẹ́ aṣiwaju ninu àwọn ọmọ Lefi nìwọ̀nyí: Haṣabaya, Ṣerebaya, ati Joṣua ọmọ Kadimieli pẹlu àwọn ẹlẹgbẹ́ wọn dúró kọjú sí ara wọn, àwọn ìhà mejeeji yin Ọlọrun lógo wọ́n sì dúpẹ́ ní ṣísẹ̀-n-tẹ̀lé, gẹ́gẹ́ bí ìlànà tí Dafidi, eniyan Ọlọrun fi lélẹ̀.
Máa lọ; láti ìsinsìnyìí lọ, má ṣe dẹ́ṣẹ̀ mọ́.
Àkọlé àwòrán, Se lawọn akẹkọ fasiti Ibadan duro gogogo lai mọ ohun ti wọn yoo se Alaye wọn ni wipe, igbesẹ naa le dina atijẹ mọ wọn, nitori wipe nipasẹ ọja ti wọn ta fun awọn akẹkọ ni wọn fi n ri ọwọ mu lọ sẹnu, gẹgẹ bi wọn ṣe n l'anfani lati tọ awọn ọmọ ti wọn naa pẹlu.
Èmi nìyí níwájú yín yìí, bí mo bá ti ṣe nǹkankan tí kò tọ́, ẹ fi ẹ̀sùn kàn mí níwájú OLUWA ati ọba, ẹni àmì òróró rẹ̀.
Lásìkò ti yóò lọ síbẹ̀, àkọlé aṣọ to wọ lọ ni EFCC I'M HERE, tó túmọ̀ sí EFCC mo dé.
Àwọn eniyan tí ó jẹun tó ẹgbẹẹdọgbọn (5,000) ọkunrin láì ka àwọn obinrin ati àwọn ọmọde.
Bí ẹ bá dán ọ̀rọ̀ kòbákùngbé wò - Lai Mohammed Mo kan wàhálà lálẹ ọjọ ìgbeyàwó torí ìbálé mi kò ṣe ẹjẹ - Ìyàwó ọ̀sìngín Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Pẹlu akọle lọwọ ni awọn dokita naa fi wọde kaakiri agbegbe Idi Araba nibi ti LUTH tẹdo si ni Idi-Araba ni Ipinlẹ Eko.
Orile-ede Gambia dara po mo ajo commonwealth ni odun 1965, nigba ti orile-ede ohun gba ominira lowo ijoba ile-Geesi, eyi ti o je ki won je omo-egbe metaleladota.
Amasaya kó oriṣa àwọn ará Edomu tí ó ṣẹgun wá sílé.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 67 year old mother: Mo kojú ọ̀pọ̀lọpọ̀ àìsàn fún ọdún 35 lẹ̀yín ìgbéyàwò Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Adetoun Ogunṣẹyẹ: ìrìnàjò ẹ̀kọ́ mi títí dé òkè kò rọrùn rárá 'Àwa kò lè san ju #22,500 lọ fún Minimum wage' O fi kun ọrọ rẹ pe aye yii yoo dara ju bayiii lọ ti onikaluku ba n fifẹ han si ọmọlakeju wọn.
“Inu wa dun  si eyi , ajo to n mojuto oro to je mo wiwa ekusa ati irin, banki  to n ri si oro to je mo ile-ise ati egbe wa yoo fowosowopo lati se ipinnu lori ona ti awon omo egbe wa yoo se maa je anfaani eto eyawo naa.
Eyi jẹ ọkan lara awọn anfaani to ti jẹyọ lati ibi apero TICAD7 lorilẹde Japan.
Wọn fi kun un pe ki won gbe awọn akọṣẹmọṣẹ oniwadii wa lati UN ati AU ki ọrọ naa ba le yanju.
OLUWA ti san án fún mi gẹ́gẹ́ bí òdodo mi,bí ọwọ́ mi ṣe mọ́ ni ó ṣe pín mi lérè.
eto idibo ni ale ojoBo ni ilu Daura, ni ipinle Katsina.
Níbẹ̀ ni ẹkún ati ìpayínkeke yóo wà.
"Boya mo fẹ iyawo mii tabi mi o fẹ, Regina mọ pe o le ṣẹlẹ.
Amọṣa, ariyanjiyan naa n dabi eyi ti wọn ti wa ojutu si bayii lẹyin ti alase ọmọ ọdun mẹrinlelogun kan lati orilẹede Ghana, Sika Mortoo, fi ajulọ han akẹgbẹ rẹ lati orilẹede Naijiria, nibi idije ase kan to waye.
Olódodo yóo yọ̀ nígbà tí ẹ̀san bá ń ké,yóo fi ẹsẹ̀ wọ́ àgbàrá ẹ̀jẹ̀ àwọn eniyan burúkú.
9 74664 Orilẹede Yemen 606 2.
Batiṣeba bá lọ sọ́dọ̀ ọba láti jíṣẹ́ Adonija fún un.
Ìbúrawọlé Nàìjíríà ṣojú àgbáyé 29 Èbibi 2019 Àkọlé àwòrán, Ogun Latori ilu Abuja titi de gbogbo awọn ipinlẹ ti wọn ti dibo yan awọn adari ti yoo ṣoju awn ọm Naijiria ni saa iṣejọba tuntun yii ni eto ibura wọle yoo ti waye lonii.
Gagara tun mẹnuba pe aisi ọkọ ayọkẹlẹ lati rin pẹlu owona wa lara isoro to n koju ajọ naa lati sisẹ rẹ deede.
Chelsea teleri Juan Mata ati agbaboolu owo eyin iko Chelsea Marcos Alonso eleyi
 ní bíi nkàn an ọdún bíi mewa séyìn ìye àwon tí ó n sẹ ẹ ̀ sìn ìgbàgbọ ní àgbáye fẹ ́ rẹ ̀ tó bílìònù méjì ènìyàn bíì àwọn ẹ ̀ sìn míràn èsìn ìgbàgbọ ́ ní àwọn òpó igbagbọ àti àsà tì ó dìrò mó .
O gbé òróró ati turari mi kalẹ̀ níwájú wọn.
Ekeje mú Jeṣarela, òun ati àwọn ọmọ rẹ̀ ọkunrin, ati àwọn arakunrin rẹ̀ jẹ́ mejila.
Àkọlé àwòrán, Ẹni to ba kan ẹgbẹ awọn obinrin nibi ijoko wọn, yoo ki aje ku ikalẹ pẹlu asọ olowo iyebiye ti wọn ko si Àkọlé àwòrán, Onírúuru ẹgbẹ́jọda àṣọ làwọn ènìyàn wọ fún ayẹyẹ tó wọlé dé Àkọlé àwòrán, Ere òòdua rèé o tí tọka si ibi ti ọmọ Yorùba ti ṣẹ̀ wá Àkọlé àwòrán, Àwọn Isòrò ń dúró de Oònirìsà lati kìí fún ayẹyẹ ọdun Ọlọ́jọ Àkọlé àwòrán, Awọn awo lóbìnrin náà rèé láàyè wọn lati júba Ọ̀òni Àkọlé àwòrán, Gbàgede àyẹyẹ náà rèé oo, gbogbo ènìyàn ló ti wà ní ṣẹpẹ́ Àkọlé àwòrán, Aafin Ọọni naa n sọkutu wọwọ fun ọdun Ọlọjọ Àkọlé àwòrán, Awọn ẹni bi ẹni, eeyan bii eeyan ko gbẹyin nibi ayẹyẹ ọdun Ọlọjọ Àkọlé àwòrán, Awọn Oloye naa joko sẹpẹ Àkọlé àwòrán, Asọ funfun ree to duro wawa lara awọn oloye Àkọlé àwòrán, Ẹ kore Yeye o Àkọlé àwòrán, Oju pe, ẹsẹ pele ni ọdun Ọlọjọ Àkọlé àwòrán, Awọn irun ibilẹ yii rẹwa, wọn jẹ oju ni gbese.
Ilé ìṣọ́ àwọn eniyan burúkú yóo di òkítì àlàpà,ṣugbọn gbòǹgbò eniyan rere a máa fìdí múlẹ̀ sí i.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Kid boxer: Ọmọọba 'The Buzz' Larbie rèé, ọmọ ọdún méje tó ń fi ẹ̀ṣẹ́ dá bírà Awọn ara abule yii mọ pe Gbadero yoo pada wa, kiakia ni wọn si lọ fi ẹjọ rẹ sun ni agọ ọlọpaa to wa ni Agege.
O ṣi tún kẹkọo síwájú sii nípa ìmò ilé kíkó ni Fáṣítì kan náà.
Eyi maa n jẹ batiri pupọ bo ṣe n gbọn yẹn.
”Abramu bá fún Mẹlikisẹdẹki ní ìdámẹ́wàá gbogbo ìkógun tí ó kó bọ̀.
OLUWA ní, “N óo sọ Jerusalẹmu di àlàpà ati ibùgbé ajáko.
Lẹyin ti wọn ba ti lo ọdun mei ninu eto naa, ijọba yoo tun gba isọri awọn ọdọ miran siṣẹ labẹ asia eto ọhun.
Lẹ́yìn ogoji ọjọ́, OLUWA kó àwọn tabili òkúta náà, tíí ṣe tabili majẹmu, fún mi.
Ajọ PPPRA to n ṣamojuto owo epo rọbi lo ṣe ikede naa ninu atẹjade kan to fi sita lọ́sàn Ọjọrun.
Idije naa yoo ko gbogbo orilẹede ilẹ Yuroopu pọ lati gba bọọlu.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Oyo Politics: Ilé aṣòfin ìpínlẹ̀ Oyo jáwée lọ sinmi nílé fún alága ìgbìmọ̀ mẹ́tàlá káàkiri ìjọba ìpínlẹ̀ 31 Ọ̀wàrà 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 3 Bélú 2020 Oríṣun àwòrán, Seyi Makinde Ile igbimọ aṣofin ipinlẹ Oyo ti kede lọjọ Iṣẹgun pe wọn jawe lọ sinmi nile diẹ fun awọn alaga fidihẹ mẹtala lawọn ijọba ibilẹ kaakiri ipinlẹ Oyo.
O tẹsiwaju pe ohun to fa iṣẹlẹ omiyale to n waye lagbegbe idi Oro, Mushin atawọn agbegbe miran nilu Eko ko ṣẹyin bi awọn eeyan ṣe ma n da idọti soju gọta.
Wọ́n ṣe ìrúbọ pataki ní ọjọ́ náà, wọ́n sì yọ̀, nítorí Ọlọrun jẹ́ kí wọ́n yọ ayọ̀ ńlá, àwọn obinrin wọn, ati àwọn ọmọ wọn náà yọ̀ pẹlu.
Mo ké pe OLUWA, ẹni tí ìyìn yẹ,Ó sì gbà mí lọ́wọ́ àwọn ọ̀tá mi.
Ṣé àwọn òkú lè dìde kí wọ́n máa yìn ọ́?
”Lara awon ti o ba aare  Buhari se ipade ni  Sheikh Ahmed Al Maktoum,okan lara ẹbi  ti won n se alakoso  Dubai , ti won si tun ni ile-ise to pọ ni  Dubai, eyi ni o jẹ ti ipinle ati ile-ise
Àwọn ẹgbẹ́ ọlọ́ṣà, mẹta ninu ọmọ ogun Filistini jáde láti inú àgọ́ wọn, àwọn kan lọ sí apá ọ̀nà Ofira ní agbègbè Ṣuali, 
Ọmọ́ Yorùbá korò ojú sí Buhari bí kò ṣe fi orúkọ Obasanjo sọ ibùdókọ̀ ojú'rin Ìjọba Nàìjíríà kéde ìsinmi ọlọ́jọ́ méjì f'ọdún Iléyá Ìyá Barakat fi ẹ̀mí ìmoore hàn sí gbogbo àwọn tó nawọ́ síi lẹ́yìn ikú ọmọ rẹ̀ Òtítọ́ lékè!
Olùdìbò gé ìka ara rẹ̀ torí ó ṣèṣì dìbò fún ẹgbẹ́ mìíràn Ninu atẹjade kan ti ile iṣẹ ọlọpaa fi sita, ọga wọn patapata nibẹ, Usman Belel sọ pe nkan bii ọgọrun ọdọ lati ilu Atali lo fọ igana agọ ọlọpaa Elimgbu ti wọn si jo ile ọkan ninu awọn sagẹnti, Isreal Sunday ti wọn si ba gbogbo dukia to wa ninu rẹ jẹ.
Akeredolu n sọ eyi gẹgẹ bi ikọ alaabo ẹya Yoruba nipinlẹ naa Amotekun ṣe bẹrẹ iṣẹ ni pẹrẹwu.
Ìdí ọ̀rọ̀ mi rèé: ìwọ olówó-ayé, o dìde ni kùtùkùtù, nínú òtútù yìí, ó wá sí ilé mi, o jókòó, o bẹ̀rẹ̀ si yẹ́ mi sí, o kò wò mi bi ẹrú, o kò wò mí bí ìwọ̀fà, o kò wí pé kí ni arúgbó kùjọ̀ù yìí máa ṣe: ṣùgbọ́n kàkà bẹ́ẹ̀, o bẹ̀rẹ̀ sí sọ̀rọ̀ rere nípa mi: o ṣe é púpọ̀; ẹni tì ó máa moore ni ọ́.
Gege bi Koeman se so“Inu mi dun pupo lati je akonimoogba tuntun iko yii, besini mo ti setan lati bere ise kiakia lai fi nkan-nkan faale,.
 orúkọ oyè rè ni Ògbóni .
Oluranlọwọ pataki fun Buhari lori eto iroyin ati ipolongo, Garba Shehu sọ pe ààrẹ ti pasẹ fun awọn alaṣẹ lati pese iranlọwọ fun awọn ti ọrọ kan.
O jẹ ẹni to kun fun ọrọ ọgbọn, awada, to si maa n ṣetan lati sọ okodoro nipa iṣẹlẹ yoowu ni gbogbo igba."
Mose sì wí pé: “Jọ̀wọ́ má fi wá sílẹ̀, nítorí pé o mọ aṣálẹ̀ yìí dáradára, o sì lè máa darí wa sí ibi tí ó yẹ kí á pa àgọ́ wa sí.
Bí iye eniyan tí ó wà ninu ẹ̀yà kọ̀ọ̀kan bá ti pọ̀ sí ni kí ẹ fi pín ilẹ̀ náà fún wọn.
Bí ó ti ṣe akọ mààlúù tí wọ́n fi rú ẹbọ ìmúkúrò ẹ̀ṣẹ̀ ni yóo ṣe akọ mààlúù yìí pẹlu.
Amotekun: Miyetti Allah ní òun yóò péjú síbi ìpàdé ìta gbangba lọ́jọ́ Ajé láti sọ tẹnu òun
Lẹ́yìn tí wọ́n tún halẹ̀ mọ́ wọn, wọ́n dá wọn sílẹ̀, nítorí wọn kò rí ọ̀nà tí wọn ìbá fi jẹ wọ́n níyà, nítorí àwọn eniyan.
Mo wá ẹnìkan láàrin wọn tí ìbá tún odi náà mọ, kí ó sì dúró níbi tí odi ti ya níwájú mi láti bẹ̀bẹ̀ fún ilẹ̀ náà, kí n má baà pa á run, ṣugbọn n kò rí ẹnìkan.
Arẹwa oṣere naa ki ara rẹ ku ọjọ ibi loju opo Instagram rẹ.
Gbogbo awọn to n gbe ẹru owo ori to wuwo le awọn ọmọ orilẹ-ede yii lori.
Wọn yóo sì máa pe ìdílé rẹ̀ ní ìdílé ẹni tí wọ́n bọ́ bàtà lẹ́sẹ̀ rẹ̀.
Wumi ṣalaye pe o ṣe pataki fawọn ọdọmọbinrin lati ni aṣọ to juju n gbese eyi to yoo maa mu wọn ri bi ọmọ kekere ni gbogbo igba.
Òmíràn á ní, ‘ Ẹsẹ̀ rẹ̀ ni o máa fi rin padà wálé o, Olúwa kò ní jẹ́ kí á gbọ́ o.
Orile ede Naijiria ati Angola yoo fọwọsowọpọ lati jọ mojuto eto alaafia, isejọba ati eto aabo ni ekun ilẹ Afirika.
Ṣugbọn irú ìmọ̀ yìí a máa mú kí eniyan gbéraga, ṣugbọn ìfẹ́ ní ń mú kí eniyan dàgbà.
Gege bi akonimoogba iko agbaboolu Juventus, Massimiliano Allegri“Iko agbaboolu mi kopa ribiribi lopolopo, bee si ni won leto lati jawe olubori ninu ifigagbaga yii,”Gege bi Akonimoogba iko agbaboolu Ac Milan, Gatuso,“O bami ninu je pupo pe ẹ̀gbẹ̀rún lona Márùndínlógójì ololufe wa lowa wo asekagba idije yii pelu bi a tun se padanu ifesewonse ohun.
Ọpọ eeyan mii naa lo fariga lori ayelujara pe Amọtẹkun ti fẹ maa ṣe ju ara rẹ lọ.
Arabinrin ẹni aadọrun ọdun naa ṣalaye pe, kii ṣe nitori nkankan bi kii ṣe pe agba ti de.
Ti eeyan ko ba ko ipa tirẹ, Ọlọrun naa ko ni ṣe ohun kan.
Nǹkan ṣe sí ọ̀nà Igbó Elégbèjè, nǹkan ṣe.
Durkwa, naa tun gbosuba fun iko omo ogun naa fun aseyori won lori gbigbogun ti
Iṣẹ́ ọnà aláràbarà ti orí òrùlé ibi ìbojúwòta gígùn.
Lagos-Ibadan road: Ọkọ̀ agbépo tó gbiná ní Ibafo dá súnkẹrẹ fàkẹrẹ sílẹ̀
Aare orile-ede Naijiria, Muhammadu Buhari  pada silu Abuja lojoBo(Thursday), leyin irin ajo re si orile-ede Amerika .
O ni o yẹ ka dẹkun iwa lile akẹkọ kuro nile iwe lọna aitọ.
Obaseki salaye pe, ipinnu lori eto-ogbin ohun se pataki fun ijoba, ni eyi ti o n pe awon eniyan lati satileyin fun ijoba lati le se aseyori ninu erongba naa, eyi ti yoo sanfaani fun opo eniyan.
Kí ló dé tí o kò bá Jeremaya ará Anatoti tí ń sọ àsọtẹ́lẹ̀ fun yín wí.
Ẹwẹ, Ologbondiyan ni awọn ilana kan wa ti eeyan ni lati tẹle ki o to le darapọ mọ ẹgbẹ oṣelu PDP.
Ṣugbọn ó dá wọn lóhùn pé, ‘Rárá o!
Ẹ ranti àwọn ọ̀rọ̀ tí àwọn wolii ti sọ ati òfin Oluwa wa ati Olùgbàlà tí ẹ gbà lọ́wọ́ aposteli yín.
Abel Wabella, alákòóso Ohùn Àgbáyé ní ‘ Èdè  Amharic , kò fi etí ẹ̀gbẹ́ẹ rẹ̀ kan gbọ́ràn já geere mọ́n láti ara ìjìyà oró tí ó jẹ́ nítorí pé ó kọ̀ láti ti ọwọ́ bọ ìwé ìjẹ́wọ́.
Kò sí rògbòdìyàn tó lè sẹlẹ̀ ju wákàtí 24 lọ láì ní ọwọ́ ìjọba níbẹ̀- Ogagun Ibrahim Babangida ''Ohun ti a kọkọ gbọ ni iro ibọn, ti wọn si jawọ ile igbohunsi naa, lẹyin naa ni wọn pe awọn ara adugbo lati wa ma a ko awọn ounjẹ naa lọ́fẹ̀ẹ́ ''Awọn ohun eelo ounjẹ ti awọn eniyan n ko naa jẹ eleyii ti wọn kọ orukọ Covid-19 si lara.
Kò si ìfẹ́ ilú, nitori eyi, àwọn oniwà ibàjẹ́ ni àwọn ará ilú nyin bi wọn bá ti ẹ fi èrú kó owó jọ pàtàki ni ilé ìjọ́sìn, wọn kò ri ẹni ba wọn wi.
Ọlọrun, o ò bá àwọn ọmọ ogun wa lọ sójú ogun mọ́.
Oyo ni papa isere Obafemi Awolowo ti a mo si (Liberty Stadium) ni agbegbe
Mo bi gbogbo yín lónìí, ènìyàn lè rí nǹkan pàtàkì láìjẹ́ pé ó bá ìṣòro pàtàkì pàdé?
”Ni ipari apapo ile igbimo asofin panupo lati so gbogbo ojo kejila osu kefaa di ayeye ayajo odun eto ise ijoba tiwa-n-tiwa lorile-ede Naijiria.
Níbi ìpàdé ọ̀hún tí yòó wáyé ní Rabat, nìrètí wà pé , àwọn olórí méjéèjì yòó ti jíròrò lórí ọ̀nà láti ró àdéhùn tó wà láàrin orílẹ̀-èdè méjéèjì, lórí ẹ̀ka tó n pèsè ajílẹ̀, lágbára.
Nígbà náà ni Eliakimu ati Ṣebina ati Joa sọ fún Rabuṣake pé, “Jọ̀wọ́, èdè Aramaiki ni kí o fi bá wa sọ̀rọ̀, nítorí pé àwa náà gbọ́ Aramaiki.
Eyi wa tun ṣe gẹgẹ iha ti awọn eniyan maa n kọ si didi eniyan nla laye ari itanjẹ ti wọn maa n gbagbọ gẹgẹ bi Arole ṣe ṣalaye ẹ ninu ọrọ rẹ.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Bàbá mi, ẹ yé fi mí gba ìràwọ̀, ọmọbìnrin Charly Boy, Dewy Oputa fárígá fún bàbá rẹ̀ DSS ṣèlérí iwadìí tí kò rújú lórí bí òṣìṣẹ́ rẹ̀ kan ṣe yìnbọn pa fẹ́ńdọ̀ lẹ̀yìn Gbajabiamila Èyí ni bí wọ́n ṣe pín fásitì LAUTECH láàrín ìpínlẹ̀ Oyo àti Osun Saka ń wá ọ̀rẹ́ rẹ̀ kan nítorí aṣọ kóòtù ọdún 34 sẹ́yìn Wo àwọn tó kàgbákò Covid-19 ní White House lẹ́yin Ààrẹ Trump Aarun Covid-19 tubọ n pọ sii ni ile ijọba orilẹede Amẹrika, paapa laarin awọn to sunmọ Aarẹ Donald Trump.
 Akinrinlola je ki o di mimo pe lotito ni won gbe Hon Olatoye wa si ile
national democratic coalition ( nadeco ) ni wọ ́ n dá sílẹ ̀ ní ọjọ ́ kẹẹ ̀ dógún oṣù karùún ọdún 1994 ( may 15 , 1994 ) láti ọwọ ́ ( broad coalition of nigerian democrats ) , tí ó pè ìjọba ológun tí sani abacha láti kúrò lórí àléfà fún ẹni adìbòyàn june 12 , 1993 , ìyẹn m.
Igba kẹta ree ti Nana Akufo-Addo ati John Mahama maa jọ figagbaga ninu idije dupo aarẹ Ghana.
Àwọn ọmọ wọn ti parun,pẹlu àwọn arakunrin wọn ati àwọn aládùúgbò wọn;àwọn pàápàá sì ti di àwátì.
Ìdí tí Gúúsù Akure, Owo àti ìwọ̀orun Ondo yóò fi sọ ẹni tí yóò jáwé olúborí nínú ìbò gómìnà Ondo Ìpalẹ̀mọ́ aráàlú àti agbófinró fétò ìdìbò dójú ọ̀gbagadè ní Ondo Gómìnà Seyi Makinde bá ẹbí Isiaq Jimoh tó kàgbákò ikú òjijì dárò Ṣaaju, ninu ọrọ ikinni kaabọ rẹ, Kọmiṣọnna fajọ eleto idibo nipinlẹ Ondo, Oluwatoyin Akeju dupẹ lọwọ gbogbo awọn eeyan to wa nikalẹ fun atilẹyin wọn, lati ri daju pe eto idibo naa kẹsẹ jari.
Ẹgba ni ó fi nà yín, ṣugbọn àkeekèé ni n óo máa fi ta yín.
 Àwọn èèyàn tí ìdáhun agbóguntàìsàn wọn bá ń ṣíṣe báyìí má ń gba ohun tí ó má fún agbóguntàìsàn yìí lágbára láìsí ìdí fún àyẹ ̀ wò ẹ ́ jẹ ́ .
Oye naa ti kọkọ da ariyanjiyan silẹ lẹyin ti Alaafin sọ pe Wasiu ti ọpọ mọ si KWAM 1 ko ni dọbalẹ f'awọn ọba kan mọ lati oni lọ.
ṣugbọn bí o kò bá jẹ́ kí ó bá wa lọ, a kò ní lọ, nítorí pé ọkunrin náà tẹnumọ́ ọn fún wa pé a kò ní fi ojú kan òun láìjẹ́ pé arakunrin wa bá wa wá.
"O dara ká máa jíròrò, ká sì dá ọpọlọ láàmú, ká tó ṣe eré.
 ti àwọn Ìsáájú dúró fún aramaic ní àṣìkò ìgbà ayé àtijọ ́ ati tí ode òní orisiirisi aramaic ni wọ ́ n ń ṣọ lati nǹkan bí centiuri mẹwa bc .
Nítorí náà, ẹ ronupiwada, kí ẹ yipada sọ́dọ̀ Ọlọrun bí ẹ bá fẹ́ kí á pa ẹ̀ṣẹ̀ yín rẹ́.
NCDC: Àlàyé bí a ó ṣe gbé òkú àwọn tó bá Covid 19 lọ látòkè òkun wálé rèé Kí ni ìdí tí ilé ẹjọ́ tún ti sún ìgbẹ́jọ́ Alfa Babatunde Sotitobire síwájú Àwọn ọmọogun mẹ́wàá tọ́rọ̀ náà kàn kò yọjú silé ẹjọ́ lónìí, bákan náà ni wọ́n ò yọjú silé ẹjọ́ nínú oṣu kẹta ọdun.
Lọ́jọ́ karun-un oṣù náà, tíí ṣe ọdún karun-un tí wọ́n ti mú ọba Jehoiakini lọ sí ìgbèkùn, 
Adetayo Adeleke-Adedoyin, ninu ifọrọwanilẹnu latọdọ awọn akọroyin salaye pe, ko si ẹnikẹni to fofin de tabi dawọ isẹ Amotekun duro, amọ ipalẹmọ fun ilana ti wọn yoo gba sisẹ lo mu ki idaduro ranpẹ wa, ki ikọ naa to bọ sita lati sisẹ.
Bi ọkùnrin bá fẹ́ ọkùnrin, wọn ò lè bi ọmọ lai si pé wọn gba ọmọ tọ́ tàbi ki wọn wa obinrin ti yio bá wọn bi ọmọ tàbi bi ó bá jẹ laarin obinrin meji ti ó fẹ́ ara, ikan ninú obinrin yi ti lè bimọ tẹ́lẹ̀ tàbi ki ó wá ọkùnrin ti yio fún ohun lóyún ki wọn lè ni ọmọ ni irú igbéyàwó yi.
    Ìgbà tí o ka ìwé náà, o dì ìwé tí ìyàwó mi kọ sí mi, o ni òun ti ń wo ìyà gbogbo tí mo ti jẹ láti ìgbà tí òun ti lọ, ìforítì mi jọ òun lójú gidigidi, òun kò le fi mi sílẹ̀ mọ́, òun dari gbogbo ohun ti mo ti ṣe jì mi, nítorí náà, ki n yà sí ọ̀dọ̀ òun nígbà tí a ba ń pada bọ̀.
Ọpọ ọdọ lo n wo Chadwick gẹgẹ bii awokọṣẹ rere ni gbogbo agbaye nitori pe o fi ifẹ han si awọn alarun jẹjẹrẹ pupọ lai naani pe oun naa n ba aisan naa finra de gongon lọdun mẹrin gbako.
dupo alaga ijoba ibilẹ ninu   eto idibo ohun .
 ) je ti cauchy sugbon won ko foriko si nomba oniipin .
O ni idasile eka ileese lati maa mojuto oro omiyale yoo wa.
”Ṣugbọn àwọn Juu sọ fún un pé, “A kò ní àṣẹ láti ṣe ìdájọ́ ikú fún ẹnikẹ́ni.
Orí pápá ló ti subu ti oun náà si gba ibẹ̀ lọ, ọmọ ọdun mọkandinlọgbọ̀n ni lásìkò náà.
 Fun apeere;wahala to dojuko orile Libya nipase omo-ogun  Boko Haram, awon ohun ti o ye ki a foju lameeeto wo niyi, nitori iru isele bayii lo maa n fa owo idagbasoke orile ede wale.
Iṣẹ́ náà tẹ̀síwájú títí tí wọ́n fi tún ilé OLUWA náà ṣe tán, tí ó sì rí bíi ti iṣaaju tí ó sì tún lágbára sí i.
kejila odun 2018, lagogo mefa aabo(6.
Nítorí náà kò sí ìwà tí àwọn ọmọ ilé-ìwé lè hù tí ó tayọ ìwà ìrẹ̀lẹ̀ níwájú àgbàlagbà, ọ̀wọ̀ fún àwọn òbí, àti itẹríba fún ìlànà Ọlọ́run Ọba.
Ile itaja Shoprite lo tobi julọ ni Africa, ẹka rẹ si to ẹgbẹrun mẹta o din igba jakejado ilẹ Afirika.
Bí ẹ̀yin ẹ̀yà Reubẹni ati ẹ̀yà Gadi bá pada lẹ́yìn OLUWA, yóo kọ àwọn eniyan wọnyi sílẹ̀ sinu aṣálẹ̀.
Iyawo ni Ajani n wa lataari pe iya rẹ n yọọ lẹnu nigba gbogbo pe ohun to kan fun un naa ni ki obinrin wa ni ẹẹdẹ rẹ.
Ẹ̀kọ́ ìtàn yi ni pe àṣejù ohunkóhun kò dára pàtàki ki enia gbójúlé ọrọ̀ ilé ayé bi ẹni pé àwọn ti ó kù kò mọ̀ ọ́ ṣe, nitori Yorùbá sọ wi pé “kìtà kìtà kò mọ́là, Ká ṣiṣẹ́ bi ẹrú kò da nkan, Ọlọrun ló ngbé ni ga”.
Àṣìṣe ló ṣẹlẹ̀ níbi ètò ìsìnkú Abba Kyari- FCTA Yewande bí'mọ tuntun jòjòló, Mercy Aigbe pàdánù èèyàn rẹ̀, Toyin Abraham fèsì lórí aṣoju NCDC Ìtàn Manigbagbe: Àwọn àjakalẹ-àrun to ti wáyé rí ṣáájú Coronavirus ''Aisan yii le ti ara oku ti wọn sin bọ si ara awọn eeyan to gbe posi tabi awọn eeyan to wa leti iboji,'' Dokita Faduyile lo woye bẹẹ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Baby abandoned on dunmpsite: Mo ti bímọ mẹ́rin tẹ́lẹ̀ fún bàbá méjì nínú òṣí- Dupe Ogbomos Akeredolu fikun pe, ni 2018, awọn ri owo to to N1.
Ìwọ̀nba ọrọ̀ pẹlu òdodo, sàn ju ọ̀pọ̀ ọrọ̀ tí a kójọ lọ́nà èrú lọ.
Lekan Kingkong: Níbikíbi tí mo bá wà, màá gbé àṣà Yorùbá ga
 augustine ) , austin enimimo ( st.
N óo pín wọn káàkiri ilẹ̀ Jakọbu,n óo sì fọ́n wọn ká ààrin àwọn eniyan Israẹli.
O salaye pe, awon alase orile-ede naa fofin de eto iwode ohun lale lojo-Ru, ni nnkan bi agogo mefa irole.
Amọṣa, awọn ileeṣẹ elepo rọbi mejeeji yii ni wọn ti ṣ'alaye wi pe awọn ko jẹbi ẹsun ti wọn n fi kan wọn yii.
Wo díẹ lára ẹkọ tí àwọn Mùsùlùmí leè kọ lásìkò Ramadan tó ń wáyé nínú àrùn Coronavirus Oríṣun àwòrán, Getty Images Bi oṣu Ramadan ṣe bẹrẹ lọjọ kẹrinlelogun, oṣu Kẹrin, ọdun 2020, Ramadan ọdun yii yoo yatọ nitori ajakalẹ arun Coronavirus.
Elikana, Iṣaya, ati Asareli, Joeseri, ati Jaṣobeamu, láti inú ìdílé Kora, 
Hungary lè di àlá làsàn fún Pẹlumi tí kò bá rì N1 mílíọ́nù láti kòpa nínú ìdíje Olympiad ní orílẹ̀èdè náà
O tun orin naa sè pọ pẹlu onkọrinayara bi àṣá Naijiria, Ice Prince.
Koda, eto aabo to gbopọn, pẹlu osisẹ agbofinro to to ẹgbẹrun lọna ọgọrun ni wọn mu lati oniruuru ẹka to wa labẹ ileesẹ eto abẹle, ti wọn si pin wọn si awọn ibudo awn alalaji naa kaakirifun ipese eto aabo to peye Àkọlé àwòrán, Ìléyá ti dé, èran ọdún di jíjẹ!
Jakọbu ranṣẹ pe àwọn ọmọ rẹ̀, ó wí fún wọn pé, “Ẹ kó ara yín jọ kí n lè sọ ohun tí yóo ṣẹlẹ̀ si yín ní ọjọ́ iwájú fún yín.
Àwọn ọmọ ogun yóo bo gbogbo òkè ńlá,bí ìgbà tí òkùnkùn bá ń ṣú bọ̀.
Bẹẹ ni wọn ni ki wọn tẹsiwaju pẹlu ṣiṣe afihan esi idbo loju opo ayelujara eyi ti yoo jẹ ki onikaluku ri okodoro bi idibo ti ṣe lọ lagbegbe wọn.
Lọwọ ẹgbẹ Aston Villa Gano ni Super Stars ti ra Salisu Iriyos lati ipele liigi keji ni iye owo ẹgbẹrun marun un.
Nítorí èmi ni OLUWA tí ó ko yín jáde láti ilẹ̀ Ijipti wá, láti jẹ́ Ọlọrun yín; nítorí náà, ẹ níláti jẹ́ mímọ́, nítorí pé, mímọ́ ni èmi Ọlọrun.
Ẹ̀yin rí aláǹtakùn kí ó wí pé òun kò ran òwú mọ́?
Gbogbo bo ṣe n lọ lo ye mi daadaa.
Nítorí wọ́n ń sọ bí ẹ ti ṣe gbà wá nígbà tí a dé ọ̀dọ̀ yín, ati bí ẹ ti ṣe yipada kúrò ninu ìbọ̀rìṣà, láti máa sin Ọlọrun tòótọ́ tíí ṣe Ọlọrun alààyè; 
Orilẹede Burkina Faso lapa iwọ oorun Afirika ni ifipagbajọba ti ṣẹlẹ julọ, ẹmeeje ọtọọtọ ni ifipagbajọba ti ṣẹlẹ ni orilẹede naa.
” Ṣugbọn nígbà tí ó sọ pé, “Gbogbo nǹkan ni ó fi sí ìkáwọ́ rẹ̀,” ó dájú pé ẹnìkan ni kò sí ní ìkáwọ́ rẹ̀: ẹni náà sì ni Ọlọrun tí ó fi gbogbo nǹkan sí ìkáwọ́ Kristi.
Nígbà tí wọ́n dé agbègbè odò Jọdani, tí ó wà ní ilẹ̀ Kenaani, àwọn ẹ̀yà Reubẹni, ẹ̀yà Gadi, ati ìdajì ẹ̀yà Manase tẹ́ pẹpẹ kan lẹ́bàá Jọdani, pẹpẹ náà tóbi pupọ.
Ikede naa ni konileogbele ohun bere lati ago mọkanla ọjọ ẹti tii ṣe ọjọ kerindinlọgbọn Oṣu Kewa.
Latin to n beere ohun gan to kan ileeṣẹ BBC lori ọhun ni ko sohun to buru nibẹ bi ileeṣẹ BBC naa ba da si ọrọ ọhun.
OLUWA, Ọlọrun Israẹli ní, kí n lọ sọ fún Sedekaya, ọba Juda pé òun OLUWA ní, “Mo ṣetán tí n óo fi ìlú yìí lé ọba Babiloni lọ́wọ́; yóo sì dáná sun ún.
Ni kutu owurọ ọjọ abamẹta lawọn oludibo ti tu sita lawọn agbegbe bii ijọba ibilẹ Yalwa ni ipinlẹ Kano lati dibo wọn Oríṣun àwòrán, @AWTambuwal Àkọlé àwòrán, INEC, awọn agbofinro ni eto gbogbo ti to fun ikẹsẹjari atundi ibo naa.
Jesu bá dáhùn pé, “Àkókò díẹ̀ ni ó kù tí n óo lò pẹlu yín, lẹ́yìn náà n óo lọ sọ́dọ̀ ẹni tí ó rán mi níṣẹ́.
ó ní, “Bí ẹ bá lè ba majẹmu tí mo bá ọ̀sán ati òru dá jẹ́, tí wọn kò fi ní wà ní àkókò tí mo yàn fún wọn mọ́, 
Ẹlẹ́wọ̀n náà ní isẹ́ onímọ̀ ẹ̀rọ ni òun fẹ́ se, tó sì bẹ̀bẹ̀ fún ìsíjú àánú woni.
Àwọn eléyìí ni ẹni ègún, tí wọ́n ṣẹ̀ sí Olódùmarè wọ́n sì ṣẹ̀ sí ènìyàn pẹ̀lú, bí ẹnìkan bá rẹ ara rẹ̀ sílẹ̀, dípò kí wọn túbọ̀ máa gbé e ga, gẹ́gẹ́ bí àṣẹ ọmọ Olódùmarè ní ijọ́sí, wọn a fi olúwarẹ̀ sí abẹ́ àtẹ́lẹsẹ̀ wọn, wọ́n á gbé ẹsẹ̀ wọn sókè, wọ́n a gbé lọ̀ ọ́.
Ní ọdún-un 2015, Orílẹ̀èdè Olómìnira Ìṣọ̀kan Tanzania kéde Ìgbésẹ̀ Ìrúfin Orí Ẹ̀rọ Ayélujára.
Ile itura kan lorile-ede Kenya, ti bere fun milionu kan Shillings owo Kenya, eleyi ti o je ẹ̀gbẹ̀rún mẹ́wàá owo dollar($10, 000 ), ti apapo re ni Naira si tun je, milionu meta le ni ẹ̀gbẹ̀rún lona ẹ̀ẹ́dẹ́gbẹ̀ta (3.
Lati ra ipapanu Pizza ni oke okun, iyẹn ni ilu London, iye rẹ wa laaarin pọun mẹsan an (£9) si ogun pọoun (£20).
Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Fídíò, Risikat Azeez: Ilé wa ni mo ṣì wà, èmi kò tíì padà sọ́dọ̀ Bàbá Kaosara22 Ògún 2020 2:49 Fídíò, Risikat Moromoke Azeez: Mínísítà tí fi ẹ̀bùn owó ránṣẹ́ si ìyá Kausara, ó tún jẹ́jẹ̀ẹ́ ẹ̀kọ́ ọ̀fẹ́ f'áwọn ọmọ rẹ̀, Duration 2,4910 Ògún 2020 6:44 Fídíò, Risikat Moromoke Azeez: Inú èmí àti Òbí mi dùn nígbà ti Risi bí ọmọ olójú búlù- Wasiu, Duration 6,4420 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Risikat Azeez: Aya gómìnà tún fẹ́ gba sọ́ọ́bù, ra ọjà fún obìnrin olójú búlúù8 Owewe 2020 Risikat Azeez: Ìyàwó Gómìnà ìpínlẹ̀ Kwara mú ìlérí rẹ̀ ṣẹ, Risikat tí bẹ̀rẹ̀ sí ní kọ́sẹ́ aṣojú lóge19 Ògún 2020 2:08 Fídíò, Risikat Azeez: Ìyá àti bàbá ọmọ olójú búlù tí parí ìjà- wọ́n fẹ́ tún yìgì so, Duration 2,0820 Ògún 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
 Eto naa je akanse fun itaniji lori idojuko oro ohun jije ni eyi ti SBN se pelu ajosepo GAIN ati FATE Foundation.
eyi ti iwe eto isuna ti odun 2019 wa ninu rẹ.
Iwadi naa, gẹgẹ bi iroyin ṣe sọ, lo da lori owo ti ajọ elere bọọlu lagbaye FIFA, gbe fun ajọ elere bọọlu ilẹ wa, NFF, laarin ọdun 2014 si 2016.
Ileesẹ Ọlọpaa: Aarẹ ni awọn ti bẹrẹ iyipada ni ẹka ileesẹ ọlọpaa, lati pese fun awọn ọlopaa, ati ohun gbogbo ti wọn nilo lati mu eto aabo labẹle gbooro si.
Wo àwọn àwòràn tó làmìlaaka nílẹ̀ Adúláwọ̀ lọ́sẹ̀ yìí Kíkọ́ ẹ̀kọ́ gboyè nínú iṣẹ́ ìṣègùn ìbílẹ̀ yóò pèsè ìtọ́jú tó péye fọ́mọ Nàìjíríà- Ẹgbẹ́ àwọn dókítà Olubadamọran aarẹ ni iroyin ofege lo pọ ju ninu nkan ti awọn eniyan n sọ nipa Leah Sharibu.
Bí wọ́n ṣe ń ti àwọn ènìyàn mọ'lé ní Naijiria tí jẹ́ ọ̀rọ̀ àfẹnubà fún ọjọ́ tó ti pẹ́.
Ìgbáyé-gbádùn ọmọ Nàìjíríà ní South Afrika ló jẹwá lógún- Buhari Díẹ̀ lára àwọn òṣèré Nollywood ti wọ́n ti ṣe ìgbéyàwó lẹ́ẹ̀kejì Oga agba agbofinro ni Mozambique ni awọn ti mu eniyan ogun ti awọn furasi si gbaga nitori ọrọ yii.
Kí àwọn ọmọ Israẹli yòókù pa àgọ́ wọn ní ìsọ̀rí-ìsọ̀rí, olukuluku ní ibùdó rẹ̀, lábẹ́ àsíá ẹ̀yà rẹ̀.
 gẹ ́ gẹ ́ bí ìkan nínú ẹgbẹ ́ 14 lórí tábìlì ìdásìkò àwọn ẹ ́ límẹ ̀ ntì , ó jẹ ́ aláìjẹ ́ -mẹ ́ tàlì àti afagbáramẹ ́ rindìmú - èyí jẹ ́ pé ẹ ̀ lẹ ́ ktrọ ́ nù mẹ ́ rin wà láti dá ìsopọ ̀ kẹ ́ míkà àjọfagbáradìmú .
Solomoni dáhùn gbogbo àwọn ìbéèrè rẹ̀, kò sì sí ohunkohun tí ó le fún Solomoni láti ṣàlàyé.
’ Bẹ́ẹ̀ sì ni OLUWA kò rán wọn níṣẹ́ kankan; sibẹ wọ́n ń retí pé kí OLUWA mú ọ̀rọ̀ wọn ṣẹ.
Dogara wa ni ile igbimo asoju yoo gbiyanju lati tete se atunse to ba ye lori
Pantami sọ pe igbesẹ NIPOST tako ọrọ ajọ sọ to wa laarin oun ati awọn oludari NIPOST.
Ronke Oshodi Oke: Katakara eroja ipara ati ọsẹ ibora ati atọkun eto lo mu mọ isẹ tiata Ronke Ojo Anthony ti a tun mọ si Ronke Oshodi Oke ko fi okoowo to n se lẹyin isẹ tiata se asiri rara nitori ojoojumọ lo n polowo ohun to n ta lori ayelujara.
O ni ayẹwo awọn dokita ni ileewosan General Hospital to wa ni ilu Ọwọ ti wọn gbe e lọ jẹ ki awọn mọ pe oogun naa ti se isẹ buruku lara rẹ.
Nígbàtí Prem Chand àti àwọn ẹlẹgbẹ́ẹ rẹ̀ ṣe ìbẹ̀wò sí àwọn ẹlẹ́ṣẹ̀ wọ̀nyí nínúu túbú, wọ́n bá ìpèníjà:
Ogbeni Garba salaye pe, ifehonu han awon alaise lataari bi won
Ekeji ti Aisha tun fisita ṣafihanbi Sẹnetọ Ben Bruce ṣe n sọ pe orilẹede Naijiria jẹ ilu ti ko ni ofin ati ilana.
Dafidi tún bi í pé, “Báwo ni ẹ̀rù kò ṣe bà ọ́ láti pa ọba, ẹni tí OLUWA fi àmì òróró yàn?
Ó ṣeéṣe ki n ma ti ọkọ mi lẹ́yìn nínú ìdìbò tó n bọ"" Ṣáájú ìdìbò ọdun 2019 ní aya ààrẹ orilẹ̀-èdè Naijíríà sọ pé ó ṣeese láti má fọ̀wọ̀sowọpọ lóri ìdìbò 2019."
Kí ó fa apá rẹ̀ mejeeji ya, ṣugbọn kí ó má fà wọ́n já.
Ìjọba Nàìjíríà ti rí obìnrin tó wà l'óko ẹrú ní Lebanon gbà Imam tó fẹ́ ọkùnrin míì níyàwó forí kó ìjìyà òfin Amotekun: Kí ni iṣẹ́ tí Amotekun yóò máa ṣe gangan?
Ohun to han gbangba ni si awọn eniyan pe Udom di gomina ipinlẹ Akwa Ibom nitori ibaṣepọ rẹ pẹlu Baba isalẹ Akpabio ti o gbe le ejika lati dije dupo gomina ni ọdun 2015 to si yege.
Yewande bí'mọ tuntun jòjòló, Mercy Aigbe pàdánù èèyàn rẹ̀, Toyin Abraham fèsì lórí aṣoju NCDC Ìtàn Manigbagbe: Àwọn àjakalẹ-àrun to ti wáyé rí ṣáájú Coronavirus Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí kan sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
Lẹyin to ni irọ ni wọn pa mọ oun ni fasiti OAU ṣe iwadii to fi han wipe ootọ ni pe ohun ọjọgbọn naa ni o wa lori igbohunsilẹ naa.
Ẹlòmíràn á sọkún kíkorò, á sì kí àwọn ènìyàn wa báyìí pé:
Secret Cults in Nigeria: Ọwọ́ ọlọ́pàá tẹ àwọn ọmọ ẹgbẹ́ òkùnkùn tó yìnbọn
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Nigeria Immigration Service: kò sí àjòjì darandaran kankan ní Nàìjíríà 17 Òkùdu 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Kò sí àjòjì darandaran kankan ní Nàìjíríà ni ọrọ alukoro Nigeria Immigration Service Àlejò tí kò bá ni ìwé ìgbélùú Naijiria n padà sílé ni -Babandede.
Inú odò ni wọ́n ti rí òkú ọmọ ọdún méjì tó sọnù l'ọ́jọ́ ọdún Eid nílùú Ibadan Ọkọ kọ àwọn ọmọ méjì lé ìyàwó lọ́wọ́ nítorí ìrísí ojú wọn ní Ilorin Abuja lékè bì Coronavirus ṣe já padà sókè, èèyàn 304 ló kó o lọ́jọ́ ìṣẹgun Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Beirut blast leaves extensive damage Igbimọ olugbejọ kan labẹ ajọ isọkan agbaye ni yoo gbe idajọ kalẹ laipẹ ninu igbẹjọ afurasi mẹrin ti wọn lo lọwọ ninu iwa isekupani lati ipasẹ Ado oloro naa.
Tunde Kelani: Èmi ò jẹ́ Baba Wande lówó lórí fíìmù Ti Olúwa nilẹ̀ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Tunde Kelani; Èmi ò jẹ́ Baba Wande ní owó lórí fíímù Tolúwanilẹ̀ Gbajugbaja olosere Tunde Kelani ti sọ wi pe irọ ni ọrọ ti Baba Wande sọ, wi pe o yan oun jẹ, lori owo to san fun un lorii fiimu ‘Ti Olúwa nilẹ̀’.
O óo rìn kọjá lórí kinniun ati paramọ́lẹ̀;ẹgbọ̀rọ̀ kinniun ati ejò ńlá ni o óo fi ẹsẹ̀ tẹ̀ mọ́lẹ̀.
"Ẹ le wo fidio ọrọ ti aarẹ ba awọn ọmọ Naijiria sọ ni: Coronavirus lockdown: Inú ìbèrù bojo ni àn gbé báyìí nítori àwọn jàndàkú- Olùgbé ilú Eko Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Inú ìbèrù bojo ni àn gbé báyìí- Awọn ènìyàn àdúgbo, Ogba, Agbado Ijaye àti Agege Láti bi ojọ mẹ́ta sẹyin ni gbogbo ènìyàn ti n nagùn #LagosUnres àti #AgegeUnrest lori àtẹjisẹ twitter sùgbọn ni òru moju òní, o dàbi ẹni pe ọrọ náà ti fẹ kọja afarada.
Fayose ni fifi iru ẹsun bẹẹ kan oun ko yatọ si ki oun maa ba awọn adigunjale ṣe ọrẹ.
Ogunje lasiko to n ba BBC sọrọ ni wi pe Asofin Ikengboju ni asẹ labẹ ofin orilẹede Naijiria lati dije dupo bi o ti le jẹ ọmọ orilẹede meji, amọ to jẹ orilẹede Naijiria ni wọn ti bi oun ati awọn obi rẹ.
'Outside' ni awo na ba jade.
Mínísítà abẹ́lé fétò ìsúná ní Uganda, David Bahati sọ fáwọn asòfin náà pé ìjọba nílò owó orí náà, láti fi san díẹ̀ lára gbèsè tí orílẹ̀èdè náà jẹ, èyí tó ń rú gọ́gọ́ síi.
Irọ pọnbele ni pe iyawo mi n gba miliọnu mẹwa ni osoosu lati inu owo ile asofin, ẹni to ba si ni ẹri to daju, ko mu wa."
Sugbọn Troy Deeney gba bọọlu na s'ọwọ Petr Cech to n ba Arsenal sọ le ni.
Kannywood Kidnapping: 'Mọ́ngòrò nìkan ni wọ́n fún mi jẹ ní àhámọ́ ajínigbé'
Adari ana lorile ede Niajiria ogagun fehinti, Abdulsalami Abubakar ti ro
"Akọroyin BBC kan si i lojukoroju, o si baa ni gbolohun ninu eyi ti Amina Zakari ti sọ wi pe ""Mi o kii ṣe ọmọ ẹgbọn tabi aburo aarẹ."
Bẹẹ si ree Azikiwe, ileeṣẹ Azikiwe at'awọnẹbi rẹ ni wọn ni ipin idokoowo to pọ julọ ni banki naa nigba naa.
OLUWA ní kí Mose sọ fún àwọn eniyan Israẹli pé, “Ẹ ti rí i fúnra yín pé mo ba yín sọ̀rọ̀ láti ọ̀run wá.
Ọpọ ninu wọn lo n sọ pe Oba AbdulRasheed Akanbi ti ṣe iranwọ nla fun awọn araalu.
Àwọn ará Filistia sì ti kó ara wọn jọ ní Mikimaṣi.
Eeyan 260 tuntun mii lo ṣẹṣẹ lugbadi aarun Coronavirus ni Naijiria.
N óo ṣẹ́ ẹ ní apá mejeeji: ati èyí tó ṣì lágbára, ati èyí tí ó ti ṣẹ́ tẹ́lẹ̀; n óo sì gbọn idà bọ́ lọ́wọ́ rẹ̀.
Eyi to wa lati ti awọn ileewe pa, o si di igba ti ijọba apapọ ba tun gbe aṣẹ miran jade to tako eyi ki awọn to lee ṣi ileewe pada.
Duro Ladipọ, ìlúmọ̀ọ́ká òṣèré tíátà àti ọmọ àlúfà tí kò gbàgbé àṣà ìbílẹ̀ Onimọ nipa ounjẹ tun tẹnu mọọ pe kii ṣe awn eso ti wn ti da kẹmika pọ mọ lo yẹ bi ko ṣe eyi to ṣẹ wa lati oko.
Kò sí nǹkan tí yóò ṣe Goodluck Jonathan lábẹ́ ìṣèjọba mi-Buhari Sambo Dasuki gbòmìnira lẹ́yìn ọdún mẹ́rin Kò tíì pẹ́ jù bí ìjọba bá leè sọ ẹni tó pa olóògbé Bola Ige- Gani Adams Olè yabo báńkì.
Ti a ko ba gbagbe, Ambọde lọsẹ to kọja, bu'wọlu abadofin to f'agbara fun ede Yoruba.
Yatọ si ipo ọga agba fasiti Ibadan, Oloye Adeyemi sọ pe o wu awọn bakan naa ki aarẹ yan ọmọ Ibadan si ipo ọga agba ile ikọṣẹ iṣegun fasiti Ibadan,UCH.
Ṣaaju asiko yi, Gomina Nyesom Wike ti kede ọgbọn miliọnu naira gẹgẹ bi ẹbun fẹnikẹni to ba ri Digbara mu.
Lẹ́hìn èyí, a di ẹrù wa silẹ̀ olúkúlùkù sì mú ohun ìjà rẹ̀ lọ́wọ́ ṣùgbọ́n púpọ̀ nínú àwọn oògùn wa ń bẹ lọ́wọ́ Ewédayépọ̀.
Nítorí náà ni ó ṣe rán oníṣẹ́ lọ bèèrè lọ́wọ́ Baalisebubu, oriṣa Ekironi, bóyá òun yóo sàn ninu àìsàn náà tabi òun kò ní sàn.
Ní wàrànṣesà tí ọ̀rẹ́ yìí ṣán kú ni àwọn ará ilérẹ̀ ti bẹ̀rẹ̀ òpò ṣíṣe.
Ẹ kó àwọn kókó ọlọ́yún ati àwọn èkúté tí ẹ fi wúrà ṣe, tí ẹ fẹ́ fi ranṣẹ gẹ́gẹ́ bí nǹkan ètùtù sinu àpótí kan, kí ẹ wá gbé e sí ẹ̀gbẹ́ àpótí OLUWA.
Ọ̀rọ̀ jẹ́ẹ́jẹ́ tí ọlọ́gbọ́n bá sọ, ó dára ju igbe aláṣẹ láàrin àwọn òmùgọ̀ lọ.
Onitsha market fire: Ilé tó lé ni 100 ló bá ìṣẹ̀lẹ̀ ìjàmbá iná lọ ní Onitsha
Oun ni igbakeji ẹgbẹ Boko Haram ti Mohammed Yusuf da silẹ lati tako imọ nipa iwe kika lọna igbalode.
O salaye siwaju sii pe, ohun ti gomina Makinde gbiyanju ati sọ ninu ifọrọwanilẹnuwo to ṣe ni pe awsn ohun ti oun sọ ninu ifọrọwanilẹnuwo naa jẹ awọn nnkan ti oun maa n jẹ ti ọrọ oun to jẹ dokita tun gba oun nimọran lati maa jẹ siwaju ati siwaju sii.
" Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Laipẹ yii ni iroyin kan kaakiri orilẹede Naijiria wipe awọn ọmọde ti ọjọ ori wọn ko to ọdun mejidinlogun fi orukọ silẹ lati dibo ni ipinlẹ Kano Amọsa o, alaga ajọ eleto idibo ipinlẹ Kano naa si n fi ọwọ sọya wipe ko si ọmọde kankan to dibo ninu eto idibo si ijọba ibilẹ to waye ni ipinlẹ naa laipẹ yii.
nípa ọ̀nà titun ati ọ̀nà ààyè tí ó ti yà sọ́tọ̀ fún wa tíí ṣe ẹran-ara rẹ̀.
pe, iwọsi ati abuku ni awon adari ile-ise eleto aabo naa hu si ile igbimo
Iyawo aarẹ Buhari se eyi nipa fi fi ara awo orin ti oṣere tiata kan lede Hausa, Adam Zango gbe jade soju opo Twitter rẹ.
Ìtàn ìgbé ayé VictorOmololu Olunloyo: Ìlú Ibadan, tíì ṣe olú ìlú Ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́ ni wọn ti bi Omololu Olunloyo ni ọjọ́ Kẹrìnlá, oṣù kẹrin, ọdún 1935 èyí tó pé fi ọdún marunlelọgọrin báyìí.
Ni ọjọ Kẹjọ osu kaarun ọdun 2010 ni wọn jawe oye fun ọba Mufutau ti Gomina igba naa nipinlẹ Kwara Bukola Saraki si gbe ọpa asẹ fun un ni ọjọ Kẹsan osu kaarun ọdun 2010.
Akinwumi Isola: Wo ohun tí Abeni fi ojú ọkọ rẹ rí tórí iṣẹ́ bọ́ lọ́wọ́ rẹ̀ nínú ìwé Nitori Owo"""
Wọ́n pe ìpolongo wọn ní “Ẹ Yé é Dà Wá”, wọ́n gbà pé ìwà ọ̀dàlẹ̀ jẹ́ ìdí tí ó tọ́ láti máa fìyà jẹ obìnrin.
O ni ibi ti ajọ NDDC de lonii, tori aisi abojuto to peye ni.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Calabar Killing: Àwọn ará ilú dáná sún èèyàn méji tí wọ́n furasí bíi olè 7 Sẹ́rẹ́ 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 8 Sẹ́rẹ́ 2020 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Calabar Killing: Àwọn ará ilú dáná sú èèyàn méji Àwọn ènìyàn méjì kan ti wọ́n fura si gẹ́gẹ́ bi olè, ni wọ́n ti dáná sun nilu Calabar, tii ṣe olú ilú Cross River.
Amọ, ẹyẹle kan ree ti orukọ rẹ n jẹ New Kim, miliọnu ₦893,000,000 ni wọn ta ẹyẹle naa.
Ọga ọlọpaa DPO naa sọ ninu ẹjọ to pe telọ Adeniyi pe iwa ọdaran gbaa ni aranṣọ ọhun hu.
Bakan naa ni irufẹ awọn oniduro bẹẹ gbọdọ fi ẹri silẹ pe wọn ni ilẹ ni aarin ilu Kaduna Ijọba ilẹ Naijiria gbọdọ gba iwe idaniloju lati ọdọ ijọba orilẹede India pe oun ko ni gba awọn olujẹjọ naa laaye lati se atipo ni orilẹede wọn, tabi ki ẹnikẹni beere lorukọ wọn lati se atipo ni ilẹ India, yatọ si pe wọn lọ se itọju ara wọn nibẹ Ikọọkan awọn olujẹjọ ọhun lo gbọdọ kọ iwe adehun, ti agbẹjọro wọn yoo si fọwọsi pe, lasiko tawọn ba lọ gba itọju ni India, awọn ko ni se ohunkohun to lee pagidina igbẹjọ to n lọ lọwọ, tabi alaafia ati eto aabo orilẹede Naijiria ati ofin ilẹ India lọna kọna Ileesẹ asoju ijọba ilẹ wa to wa ni India yoo kọkọ se ayẹwo, ti yoo si fọwọsi pe alejo kankan to ni anfaani lati ri awọn olujẹjọ mejeeji lasiko ti wọn ba wa ni orilẹede India.
Ismail tó jẹ́ ọmọ Palestine sùgbọ́n to n gbé Lẹbanon, sọ pé àwọn aláṣẹ US bere àwọn ibeere lórísírisi lọ́wọ́ oun ni pápákọ̀ ofurufu Boston lọ́ja Jimọ.
Ọ̀kan kò jọ̀kan ni àwọn mẹrẹẹrin.
“Ẹ kò gbọdọ̀ dí mààlúù lẹ́nu nígbà tí ẹ bá ń lò ó láti fi pa ọkà.
Ọba bá sọ fún Hamani pé, “Yára lọ mú aṣọ ìgúnwà, ati ẹṣin náà, kí o sì ṣe bí o ti wí sí Modekai, Juu, tí ó máa ń jókòó sí ẹnu ọ̀nà ààfin.
Ninu ifọrọwanilẹnuwo ninu fọnran naa to wa loju opo YouTube,Ọbasanjọ sọ pe pẹlu ''ohun ti oun mọ nipa Atiku, Ọlọrun ko ni forijin oun ti oun ba segbe lẹyin Atiku'' Ṣe Ọlọrun yoo fori ji Ọbasanjọ?
Bo tilẹ jẹ pè oun funra rẹ ko ti i sọrọ lori Twitter tabi Instagram lati sọ wipe ootọ ni oun bimọ lorilẹede Amerika, awọn ọrẹ rẹ ti n ki oun ati ọkọ rẹ Abdul Rasheed Bello ti aye mọ si JJC Skillz pe wọn ku ori ire.
Mo dáríjì àwọn IPOB tó nà mí ní Germany nítorí wọn o m'ohun tí wọ́n ń ṣe- Ekweremadu Ọlọ́pàá Ogun gb'ọmọ Ìmáàmù lọ́wọ́ ajínigbé, ṣùgbọ́n wọ́n gbé ọkọ̀ ojú omi ọlọ́pàá lọ Wilfred Ndidi, ọmọ Nàìjíríà pa iná ògo Chelsea ní Stamford bridge Ọlọ́pàá Ogun gb'ọmọ Ìmáàmù lọ́wọ́ ajínigbé, ṣùgbọ́n wọ́n gbé ọkọ̀ ojú omi ọlọ́pàá lọ Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Oríṣun àwòrán, Getty Images Amọ Ajọ Eto Ilera ni Agbaye, WHO ti ni, Ọjọ Kejilelogun, Osu Kini, ọdun 2020 ni awọn yoo ṣe ipade lori boya awọn yoo ka aisan naa si arun bii Ebola ati aisan ẹlẹdẹ ' Swine flu '.
tí gbogbo nǹkan tí ó ń sọ sì ń rí bẹ́ẹ̀; bí ó bá wí pé kí ẹ wá lọ bọ oriṣa mìíràn tí ẹ kò mọ̀ rí, 
"O wipe ""Ninu ọrọ rẹ, oluṣọ-aguntan yi jẹwọ pe oun pa arabinrin naa ati pe oun sin oku rẹ sinu ijo oun lẹhin ti o ti bẹ ori rẹ ati ọwọ rẹ mejeeji fun awọn idi ti o kọ lati sọ fun awọn ọlọpaa."
N óo ti òkèèrè wá gbà yín là,N óo gba àwọn ọmọ yín tí wọ́n wà ní ìgbèkùn là pẹlu.
Oríṣun àwòrán, @seyiamakinde Ki ọlọjọ to de, Ajimobi ti jẹ sẹnatọ nile igbimọ aṣofin lọdun 2003 ko to de ipo gomina lọdun 2011 labẹ asia ẹgbẹ oṣelu Action Congress of Nigeria, ACN, lọdun naa lọhun.
" Ọ̀bẹ naa lo fi kọkọ gun Adekunle ni ẹsẹ̀.
Won ni o ku lásìkò to lọ fun itọju fún ìgbà pípẹ ni ilẹ Gẹ́ẹ̀sí, wọ́n tún fi kùn un pé ayéderu Buhari lo wá si Naijira eyí ti wọ́n n pe ni ará Sudan.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Mo fi iṣẹ́ Banki silẹ̀ lọ bẹ̀rẹ̀ alápatà - Derin Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
O ni apero naa pọn dandan, nipasẹ odiwọn awọn ipenija to nii ṣe pẹlu eto aabo lorilẹede yii.
 ní ojó kan wón ro oko yí ìdi igi ìto yìí ká , wón gbá pàǹtí sí abé igí ìto yìí , wón fi iná sí i .
Ẹ wo iye ọmọ Yorùbá tó bá Coronavirus lọ lókè òkun Èèyàn 17 mííràn tún ti lùgbàdì ààrùn Coronavirus ní Naijiria Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Funke Akindele jẹ àkàndá ẹ̀dá - Adaku Àwọn alákòóso gareji náà ló yà wá sí Soka bíi eṣu, láti wá kọlu àwọn ọlọkada nítorí pé wọ́n kùnà láti sanwó tó yẹ."
'Ilé làbọ̀ ìsinmi oko fọ́mọ Yorùbá lórí Brexit' Ipa tí ìyànsípò Olóòtú ìjọba Gẹ̀ẹ́sì tuntun yóò mú bá ‘Brexit’ Oríṣun àwòrán, EPA Àkọlé àwòrán, Bi ko si ẹwa ko le si gbẹgiri, bi ile ko jokoo ko si imuṣẹ ofin Ohun to n kọnilominu lori isinmi awọn ọmọ ile igbimọ aṣofiin yii ni pe Ogbẹni Johnson n din odiwọn akoko ijokoo ile ku ni.
Aare Trump ni oun ti so fun awon asoju NRA pe asiko ti to lati wagbo dekun fun oro asilo ibon to fe maa gbebo lowo ile Amerika bayii.
Moses Olaiya dagbere faye lẹyin to ti ṣe awọn iṣẹ to lamilaaka ninu ere oniṣe ati fiimu agbelewo.
Awọn onwoye oselu ipinlẹ Ekiti ni ohun to n sẹlẹ yi le se akoba fẹgbẹ APC bi wọn ko ba tete wa wọrọkọ fi sada yanju aawọ ojojumọ laarin awọn eekan ẹgbẹ ni ipinlẹ naa.
Nígbà náà, o óo gbadura sí i, yóo sì gbọ́,o óo sì san ẹ̀jẹ́ rẹ.
Lati ilu Oyo, Ibadan, Abeokuta, Osogbo ati bẹẹ bẹẹ lọ, ni wọn ti n ko ẹru wa fun idile ọba Mobee, Ti ọja Belekete naa si wa nilu Badagry, ti wọn ti n ta ẹru fun awọn oyinbo ati adulawọ.
Lẹyin idupẹ yii lo wa bẹrẹ si ni sọ oko ọrọ si ẹni to n bu awọn osere tiata naa, to si ni sebi oke okun ni onitọun fidi kalẹ si, to ti n ri owo na, o wa gba nimọran pe ko lee mọ oun ti ọmọ Naijiria kọọkan n koju lati jẹun ayafi to ba wa gbe ni Naijiria.
Ohun to mu ọrọ yii wa ko ju ibeere ti eeyan kan beere loju opo Twitter ajọ to n ṣeto kaadi idanimọ ni Nigeria NIMC nipa gbigba kaadi mi ti eleyi toun ni ba sọnu.
Kii si ṣe ọba nikan ni eekan ilu ti ẹmi rẹ bọ sinu laasigbo ọhun, koda ẹmi awọn ijoye kan gan lọ si, ti ẹjẹ nla si san nilu Ogbomoso lọjọ naa.
Awọn oludasilẹ ile ọmọ alaini kan ni orilẹede India lo gbe e ti wọn si n tọju rẹ.
Ìyá rẹ̀ ló dúro gẹ́gẹ́ bí olùdàrí iṣẹ́ orin to yàn láàyò.
Lẹ́yìn náà, ọba ranṣẹ pe Ṣimei, ó wí fún un pé, “Kọ́ ilé kan sí Jerusalẹmu níhìn-ín kí o sì máa gbé ibẹ̀.
O maa lọ ra ohun ija oloro to fẹ lo, tabi ko maa ronu awọn anfani to fi le ka ololufẹ rẹ mọ.
 Àwọn ìpìlẹ ̀ mẹ ́ rẹ ̀ ẹ ̀ rin yìí ni wọ ́ n so pọ ̀ mọ ́ ṣúgà / oníyọ ̀ fósfórù láti dá odidi núkléótídì , bó ṣe hàn fún adenosínì oníyọ ̀ fósfórùkan .
2bn fún Obanikoro Ta ni awàdà rẹ̀ wú u yín lórí jù ní Yollywood?
Aṣoju Joshua, Eddie Hearn ti sọ pe oun yoo gbiyanju lati jẹ ki ija mii o waye laarin awọn mejeeji nilu London, ninu oṣu Kọkanla tabi Ikejila.
Arakunrin naa ti orukọ rẹ n jẹ, David Charo sọ wi pe oun ṣeeṣi gbe burọọsi ifọyin naa mi nigba t'oun fọ ẹyin rẹ.
“Mo bá àwọn wolii sọ̀rọ̀; èmi ni mo fi ọpọlọpọ ìran hàn wọ́n, tí mo sì tipasẹ̀ wọn pa ọpọlọpọ òwe.
Dave Downy to je oludari ile ise panapana ti ekun Miame-Dade  ni won salaisi bi won se ja soju opopona marose olopo oko to je okan lara awon opopona marose ti ero po si julo ni guusu Florida.
 olówu yìí ni ó gbé àkọ ́ bí ọmọ rẹ ̀ ọkùnrin wá kí odùduwà .
Makinde ko jẹ ki ijakulẹ rẹ fun igba akọkọ da omi tutu si i
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ipaniyan nilu ṣọọṣi Iroyin ti a ri gbọ lati ọdọ ile iṣẹ iroyin AFP kọkọ sọ pe o kere tan eeyan igba lo n gba itọju lọwọ lawọn ile iwosan sugbọn o ṣeeṣe ki o ju bẹ lọ.
 Ogbeni Dolapo Badru ti sise gege  bi a-gbani-moon-ko fun ere boolu alafesegba ni fafiti Gloucestershire ,ni UK”.
Nǹkan bí agogo mẹ́fà òwúrọ̀ ni ó máa ń lọ wẹ̀ lójoojúmọ́, ìmọ̀ràn Ènìyàn-ṣe-pẹ̀lẹ́ ni èyí pé kí á lọ wá ọ̀pọ̀lọpọ̀ àdá kí a pọ́n wọn kí wọ́n mú dáadáa, nígbà tí ó bá di alẹ́ kí á lọ ri àwọn àdá náà mọ́ ilẹ̀ kí á kọjú wọn sí ìta, ìgbà Òjòlà-ìbínú bá ń lọ wẹ̀ tí ó bá gbé ẹnu lé àdá, tí àdá náà bá gé e kò ní ṣáì fẹ́ẹ́ tètè sàre kúrò ní ibẹ̀, bí ó bá sì ti ń sáré sí iwájú ni àwọn àdá náà yóó ma là á ní àyà lọ.
Ogagun Benson tun yanana awon idojuko ti iko omo ogun n koju, o sapejuwe ogun
(Independent) O dabi ẹni pe ko si bi agbabọọlu iwaju fun Juventus ati Portugal, Cristiano Ronaldo ṣe mọ idunna-dura a ṣe to, ko ni le fi ọrọ yi atamatase Paris St-Germain, Neyman lọkan pada lati darapọ mọ idije Serie A, nitori o da bi ẹni pe Neyman ti pinnu lati pada si Barcelona.
Odiwọn iye owo irufẹ ẹrọ ibanisọrọ ti wọn n lo yii kọ sisọ.
Wọ́n bá lé òun ati àwọn angẹli rẹ̀ kúrò ní ọ̀run.
 johnson ( 1921 : 8 ) jẹ ́ rì í sí èyí pé ;.
" Folaranmi ni àwọn fi ìṣẹ̀lẹ̀ náà tó ileesẹ ọlọ́pàá tó wà ládùúgbò Sanyo létí, tí wọn sì pe igun méjèèjì sí ìpàdé àlàáfíà ni iléesẹ ọlọ́pàá tó wà ní Iyaganku.
Bẹ́ẹ̀ ni ó ṣe parí iṣẹ́ tí ó bá Solomoni ọba ṣe ninu ilé OLUWA.
Ò ń jẹ burẹdi tí ó dùn, tí wọ́n fi ìyẹ̀fun tí ó kúnná ṣe, ò ń lá oyin ati òróró; o dàgbà, o sì di arẹwà, o dàbí Ọbabinrin.
Àwọn ọmọ Kiriati Jearimu; Kefira ati Beeroti jẹ́ ẹẹdẹgbẹrin ó lé mẹtalelogoji (743)
Ṣe aadọta ojóbó sí awẹ́ tí ó parí àránpọ̀ aṣọ kinni, kí o sì ṣe aadọta ojóbó sí etí awẹ́ tí ó parí aṣọ àránpọ̀ keji.
Wọ́n bi wọ́n pé, “Ọmọ yín nìyí, tí ẹ sọ pé ẹ bí ní afọ́jú?
Bakan naa ni wọn daṣa ''sọrọ soke'' to lu oju ayelujara pa bayii.
Àwọn ẹ̀gbọ́n Ọ̀ọ̀ni nàá péjú síbi ayẹyẹ ọjọ́ ìbí rẹ̀ Ọjájá kejì máa ń jòkó gẹ́gẹ́ bíi adári ìgbìmọ̀ ilé ìfowópamọ Imperial Homes Mortgage, tó jẹ́ ẹka ilé ìfowópamọ Guarantee Trust Bank, bákan náà ló jẹ́ olùdarí Howard Roark Garden.
Ọlọrun dá a lóhùn lójú àlá, ó ní, “Bẹ́ẹ̀ ni, mo mọ̀ pé òtítọ́ inú ni o fi ṣe ohun tí o ṣe, èmi ni mo sì pa ọ́ mọ́ tí n kò jẹ́ kí o ṣẹ̀ mí, ìdí sì nìyí tí n kò fi jẹ́ kí o fọwọ́ kàn án.
Àbí ẹnìkan lè sọ̀rọ̀ òtítọ́ rẹ ninu ìparun?
Ọkàn mi ń ṣe àfẹ́rí rẹ lálẹ́,mo sì ń fi tọkàntọkàn wá ọnítorí nígbà tí ìlànà rẹ bá wà láyéni àwọn ọmọ aráyé yóo kọ́ òdodo.
Oríṣun àwòrán, Twitter/Seyi Makinde Yatọ si Jimoh, Makinde tun ba awọn mọlẹbi Abdulrasaq Olawale, Oluwadamilare Gbohunmi ati awọn marun un mii ti wọn farapa kẹdun.
Ipade tọdun yii ni ẹleẹkejila rẹ ni eyi ti yoo mu ki erongba Agreement Establishing the African Continental Free Trade Area nilẹ Adulawọ ṣẹ.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Àwọn agbégbọn ní kí awakọ̀ mi dúró àmọ́ ó ń sálọ ni wọ́n ṣe yìnbọn fún wa - Toyosi Adesanya Bí Amẹrika bá dínà mọ́ Nàíjíríà láti wá sílẹ̀ wọn, ewu ń bẹ fún wa - Lai Muhammed Tìpá-tìkúúkùù, àwọn Alága Káńṣù l‘Ọyọ, tí Makinde fòfin dè yọjú síjọba ìbílẹ̀ wọn Àgádágodo ní wọ́n fi ti ẹnú ọ̀nà káńṣù l‘Ọyọ, ọlọ́pàá gbàródan síbẹ̀ Okada Ban: ọjọ kini oṣù keji ni òfin tuńtun yóò bẹ̀rẹ̀ Nigba to n sọrọ lori isẹlẹ yii, aarẹ fun ẹgbẹ awọn osere ori itage TANPAN, Bolaji Amusan, ti gbogbo eeyan mọ si Mr Latin sọ fun BBC Yoruba pe oun ti ba Toyosi Adesanya sọrọ ni kete ti isẹlẹ naa waye laarọ ọjọ Aje, ti inu oun si dun pe ara rẹ le.
Àgbo Covid-19 Madagascar kò ṣiṣẹ́, àwọn ènìyàn tí bẹ̀rẹ̀ sí ní kú níbẹ̀ Ọ̀rọ̀ ìtàjẹ̀sílẹ̀ ní Nàìjíríà yìí tí ń kọ àwa Oṣo àti Àjẹ́ lóminú, a fẹ́ wa ǹkan ṣe síi Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ìdílé tí ọkọ da ọmọ síta tóríi ojú Búlùú tí wọ́n ní bá BBC sọ̀rọ̀ Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí The Church of Beer: Ìnira nlá ni òfin tó dé kátà-kárà ọtí líle lásìkò Covid-19 jẹ́ fún ilé ìjọsìn wà5 Ògún 2020 WASSCE time table 2020: Àwọn akẹ́kọ̀ọ́ da ìdánwò WAEC rú ni Ghana, wọn gún infijilátọ̀9 Ògún 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Oludasilẹ ile ẹkọ adani kan naa fidi rẹ mulẹ pe, awọn ọga agba ileewe ni ipinlẹ Oyo, ti ṣe ipade lori eto ti wọn gbọdọ ti ṣe kalẹ fun awọn akẹkọọ, ki arun Coronavirus ma ba tan kalẹ si laarin awọn akẹkọọ.
Ara kò wà fún ṣíṣe àgbèrè bíkòṣe pé kí á lò ó fún Oluwa.
Awọn alaṣẹ ile ijo naa ṣalaye pe awọn gbe igbesẹ ọhun lati dena itankalẹ arun ọhun ni nitori pe agbo ti ọpọlọpọ eeyan lati origun mẹrẹẹrin agbaye ti n pade ni.
Ìjọba: Zakzaky ń kó èrò jọ lọ́nà tó lòdì sófin
Awọn ọlọpaa ni olu ilu Belarus, iyẹn Minsk ti fẹ afẹfẹ gaasi tajutaju fun awọn to n fẹhọnu han pe idibo aarẹ naa ni magomago ninu.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ekiti Election: Ẹ́gbẹ̀rún mẹ́rin nàirà ni ẹnikọ̀ọ̀kan ń gbà 13 Agẹmo 2018 Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ekiti Election: Ẹ́gbẹ̀rún mẹ́rin nàirà ni ẹnikọ̀ọ̀kan ń gbà Fidio to wa loke yii lo n salaye bi awọn eeyan iluEkiti se n gba ẹgbẹrun mẹrin naira saaju ididbo gomina.
Ó wá wí fún Tomasi pé, “Mú ìka rẹ wá, wo ọwọ́ mi, mú ọwọ́ rẹ wá kí o fi kan ẹ̀gbẹ́ mi.
Ṣugbọn Lampard ni awọn ṣetan fun ipenija idije Super Cup pẹlu Liverpool.
Tunwẹ, Razak Ọlayiwọla, tawọn eeyan mọ si Ojopagogo naa salaye pe asẹwo ati ajẹ ni iya naa nitori pe gbogbo ọkunrin lo maa n pe ni ọkọ oun, to si tun maa n gba eeyan nimọran, bii ẹni to mọ ohun ti yoo sẹlẹ lọjọ ọla.
Gẹ́gẹ́ bi àkọwé àgbà fún ìpínlẹ̀ Katsina Alhaji Mustapha Inuwa ṣe sọ, àwọn ọmọ náà ti wà ni Tsafe, ní ìpínlẹ̀ Zamfara to pa ààlà pẹ̀lú Katsina.
Ọdun 2019 ni Real Madrid na owo to le ni aadọjọ miliọnu poun lati ra Eden Hazard lọdọ Chelsea.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù BBC: Ìrọ́ ní, a kò ṣètò owó ẹ̀kọ́ òfẹ fún akẹ́kọ̀ọ́ gboyè fásítì 12 Ọ̀wàrà 2018 Àkọlé àwòrán, BBC: Ìrọ́ ní a kò ṣé ètò owó ẹ̀kọ́ òfẹ fún akẹ́kọ̀ọ́ gboyè fásítì Àtẹ̀jíṣẹ́ kan ti ń jà ràin-ràin ká orí ẹ̀rọ ayélujara bayii pé, BBC ń ṣètò owó ẹ̀kọ́ ọ̀fẹ́ fún àwọn akẹ̀kọ̀ọ́ gboyé àkọ́kọ̀ ní fásítì lórílẹ̀-èdè Nàìjíríà atawọn to nílò ẹ̀yáwó láti tẹ̀síwájú nílùú òyìnbó.
 O tẹsiwaju lati gba gomina Akeredolu ni imọran pe, nkan to yẹ ko kọkọ ṣe ni lati da ileeṣẹ ti wọn yoo ti maa lo o silẹ."
Saraki tẹsiwaju pe gbogbo nkan to ba gba lohun yoo fi ba ijọba Kwara fa lori ilẹ to sọ pe Baba oun gba iwe aṣẹ ki o to kọ ile si ori rẹ.
Ó bá òkun pupa wí, òkun pupa gbẹ,ó sì mú wọn la ibú já bí ẹni rìn ninu aṣálẹ̀.
Pàlàpálá òkúta wọnyi ni Jonatani gbà lọ sí ibùdó ogun àwọn Filistini.
Ikanni Twitter ọun ni àmì ìdánilóju pe ẹgbẹ APC lo nií lọ́ọ̀tọ́, kó tó di pe wọn bẹ̀rẹ̀ si ni fi ikanni naa polówó òwò ẹ̀rọ ayelujara ti a mọ̀ sí Bitcoin lálẹ́ ọjọ́ àbámẹ́ta.
Bakan naa ni agbẹnusọ fun ijọ ẹsin Shia lorilẹ-ede Naijiria, Ibrahim Musa sọ fun BBC News Yoruba pe ẹni ti wọn ba n na obitibiti owo bẹ fun ounjẹ rẹ yẹ ki o mọọ li ara.
Wayi, oju opo Twitter lo ti n gbona jainjain pe ki lo de ti Alaafin ko darkọ̀ Ọba tilu Eko gẹgẹ bii awọn oriade to kọ iwe naa lorukọ wọn.
Nígbà tí ó yá àwọn ọmọ-ẹ̀yìn wá sọ́dọ̀ Jesu níkọ̀kọ̀, wọn bi í pé, “Kí ló dé tí àwa kò fi lè lé ẹ̀mí èṣù náà jáde?
Ó mú mi la ààrin wọn kọjá; àwọn egungun náà pọ̀ gan-an ninu àfonífojì náà; wọ́n sì ti gbẹ.
Akoko kii se ọrẹ wa mọ, isẹ ati osi si n jinlẹ laarin ilu si lojoojumọ ni.
Àwọn ológun ti yọ Omar al-Bashir, olórí ìjọba Sudan nípò Ọmọ atàpátadìde ni mí, télọ̀ ni bàbá mi- Abiola Ajimobi Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, JAMB 2019: A ó fagi lé ìdànwò ẹni tó bá ṣe aṣemáṣe Ninu Iwe Iroyin Astrophysical Journal Letters ni wọn ti gbe e jade.
Lakotan, ti aba ọhun ba di ofin tan, o ti di eewọ patapata fun ẹnikẹni lati gbe ilẹ fun awọn ọlọsin ẹran lati maa fi sin ẹran tabi fi haya, tabi ta fun wọn, ti eyi ba si ti waye, gomina ipinlẹ Ọyọ ni asẹ lati gbẹsẹ le iru iwe asẹ ilẹ bẹẹ.
Arábìnrin lẹ̀dì àpò pọ̀ pẹ̀lú ọ̀rẹ́kùnrin rẹ̀ pé kó ó jí òun gbe, ọ̀rẹ́kùnrin gba 700k tán ló bá sálọ Èsì ìdìbò tí yóò gbé aàrẹ tuntun wọlẹ́ ní Ghana rèé.
Awọn mii ni awon ko ri laarinja iṣẹ to ṣe yanju Nàìjíríà fẹ́ yá $100m lọ́wọ́ India fún ìtàkùn àgbáyéni ẹka ile iṣẹ ijọba apapo to moujto naa.
Ni ọjọ kan naa ni ẹgbẹ miran to ya kuro labẹ ẹgbẹ ASUU ni fasiti naa ti wọn pe orukọ rẹ ni CONUA pẹlu yan awọn adari rẹ.
Wọ́n pé ọdún méjìlá báyìí Boti lẹ jẹ pe ao ti mọ koko bi ọrọ ṣe jẹ, iroyin sọ pe awọn ajinigbe naa bẹrẹ si ni yinbọn ọkọ rẹ, lati da a duro.
Ṣé ẹ ti mọ̀n tẹ́lẹ̀ pé ọkùrin mẹ́ta ni mí?
Oloye Afọlabi ti ọpọ mọ si SM ni minisita f'ọrọabẹle labẹ isejọba Olusẹgun Obasanjọ nipasẹ bẹẹ oun ni alakoso eto kaadi idanimọ orilẹede Naijiria akọkọ nigba naa eyi ti owo agbase rẹ jẹ igba o le mẹrinla miliọn dola ($214million).
Wọn ni àwọn maraarun fipa kọlu obinrin alawọ funfun kan to n sare idaraya ni agbegbe Central Park.
Kí o da òrùka wúrà meji sí etí kinni keji ìgbàyà náà.
Pence, ati awon eniyan jankan-jankan lorile ede naa.
Lasiko to n ba BBC Yoruba sọrọ, Grandma Maruwa ni, bo se n pẹ pupọ ki ijọba to san owo osu awọn olukọ, eyi to n mu ebi pa oun, lo ta oun ni idi kan lati dara pọ mọ ẹgbẹ awọn awakọ, ẹka ti Maruwa.
Èmi Alákọ̀wé yín àtàtà, mo fi ẹsẹ̀ mi méjéèjì tí Elédùà fún mi rin àwọn òkè  náà.
ó ní, “Ohun tí yóo ṣẹlẹ̀ kẹ́yìn ibinu Ọlọrun sí àwọn eniyan lẹ́yìn ọ̀la ni ìran tí o rí.
O ni oun mọ riri iṣẹ ribiribi ti wọn n ṣe lasiko yii.
Ọ̀rọ̀ gbina, ó ti ń ràn nítori àwọn ọmọ Yahoo Oṣó ni mí, àjẹ̀ ni mí - Brymo Gbogbo orin kọ́ ló yẹ kó ní ìtumọ̀ Wọ́n fi orin wọn ṣe ìgbélárugẹ fún iṣẹ́ ìlu-ni ní jìbìtì yìí, táwọn ọmọ Nàìjíríà nàá a sì maa jó sí àwọn orin nàá, bí ẹni pé jíjẹ́ 'ọmọ yahoo-yahoo' jẹ nkan tó dára.
Nigba ti ilẹ yoo fi mọ, ọpọ eniyan ti gba adugbo Ẹlẹyo-wo to wa ni ẹyin odi ilu Akurẹ ni oju ọna Akurẹ si Ọwọ, nibi ti ariwo nla naa ti wa.
Gomina Makinde, ẹni to woye ọrọ yii lasiko to n side ipade apero lori eto aabo to waye nilu Ibadan lọjọ Aje, wa kan saara, to si se sadankata si Olubadan ati awọn agba ijoye nilẹ Ibadanlori bi wọn se jẹ ki ogun sinmi, ti wọn si gba alaafia laaye.
Samuẹli bá sọ fún un pé, “Dákẹ́!
awon omo ipinle Zamfara kedun nipa awon eniyan to padanu ẹmi won, ninu isele buruku
EFCC gbé Mompha afurasí ọmọ Yahoo lọ ilé ẹjọ́ lònìí 'Yahoo ni mí ṣùgbọ́n mo lójú àánú' Lẹyin ifẹsẹwọnsẹ naa lawọn ẹgbẹ alatilẹyin Arsenal kan sọ fun awọn alaṣẹ ikọ Arsenal pe ki wọm fọwọ osi juwe ile fun Emery.
O ti ní àníkún ọrọ̀ nítorí ọgbọ́n rẹ ninu òwò ṣíṣe, ìgbéraga sì ti kún ọkàn rẹ nítorí ọrọ̀ rẹ.
Oríṣun àwòrán, AfricanDrumFestival Àkọlé àwòrán, Awọn ọbalaye kan sara si awọn agbaṣaga Ni tirẹ, gbajugbaja onkọwe ni, ọjọgbọn Wọle Soyinka rọ awọn ọba alaye lati maṣe kaarẹ lori awọn oloṣelu to n ṣakoso ijọba bayii nipa gbigbawọn lamọran latigba de igba paapaa julọ lori idagbasoke aṣa ati iṣe ilẹ Yoruba.
Ẹ wo fidio naa: Ọga ọlọpaa lorilẹede Naijiria tun ṣalaye siwaju sii pe nigba ti wọn tun ranṣẹ pe arabinrin yii ni ọjọ keji pe ko wa wi tẹnu rẹ lori bi o ṣe kọlu ọga ọlọpaa naa, nṣe lo tun mu awọn ọlọpaa obinrin mejeeji Ripẹtọ Ojola Abiola ati Queen Eguaje ti wọn ran sii lu, koda o tun ge ọkan ninu wọn jẹ pẹlu.
Ní ọjọ́ kẹta, Ẹsita wọ aṣọ oyè rẹ̀, ó dúró ní àgbàlá ààfin ọba, ó kọjú sí gbọ̀ngàn ọba.
Brexit: Ibò mọ́kàndínlógun péré ni Theresa May fi bọ́ lọ́wọ́ àwọn aṣòfin
Nígbà tí wọ́n dé ọ̀dọ̀ Jesu, wọ́n rí ọkunrin tí àwọn ẹ̀mí èṣù jáde ninu rẹ̀, tí ó jókòó lẹ́bàá ẹsẹ̀ Jesu, ó wọ aṣọ, ojú rẹ̀ sì wálẹ̀.
Agbẹnusọ fun ileeṣẹ aarẹ, Femi Adesina sọ fun BBC pe, awọn ni akọsilẹ ibi tawọn Gomina kan ti fọwọ si kikọ ọgba fun dida ẹran, lati fi dẹkun wahala to n waye laarin awọn agbẹ ati darandaran.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Àwọn ọmọ Yorùbá wo ni mínísítà ní ìjọba Buhari?
Ẹni tó wípé Alákọ̀wé ìwọ dà láti’jọ́ yìí?
Lẹ́yìn náà, Israẹli dé sí Ijipti,Jakọbu ṣe àtìpó ní ilẹ̀ Hamu.
Ó kìlọ̀ fún wọn, ó ní “Ohun tí ẹ gbọdọ̀ máa fi tọkàntọkàn ṣe, pẹlu ìbẹ̀rù OLUWA ati òtítọ́ nìyí: 
O menuba akosile ajo isokan agbaye, UN pe lowolowo, ibon lorisiirisii to to eedegberun milionu lo ti wo iwo oorun ile Adulawo ni eyi ti oodunrun milionu ati aadota ti wo orile-ede Naijiria bayii ni eyi to tumo si pe ida aadorin ninu ogorun ibon ilewo naa wa ni Naijiria.
APC, PDP di ẹgbẹ́ aládúrà nítorí ìdájọ́ èsì ìdìbò Ọṣun Ìbò 1.
Ẹni tí ó bá ní ìmọ̀ a máa kó ahọ́n rẹ̀ ní ìjánu,ẹni tí ó bá jẹ́ olóye eniyan a máa ṣe jẹ́ẹ́.
Ọmọdekunrin naa ti orukọ rẹ n jẹ Oreoluwa di gbajumọ lẹyin ti fidio ibi to ti n bẹ iya rẹ pe ko fara balẹ nigba to fẹ na an lẹyin to ṣe aṣiṣe kan ti ko mẹnuba jade sori ayelujara.
"O ni ""Ilẹ Yoruba ko ni gba ki ajeji kankan wa gba ilẹ rẹ kankan lati fi di owo rara nitori asise ijọba kankan to kundun ko maa ya owo kiri."
Ó sọ fún Maria ìyá rẹ̀ pé, “A gbé ọmọ yìí dìde fún ìṣubú ati ìdìde ọpọlọpọ ní Israẹli ati bí àmì tí àwọn eniyan yóo kọ̀.
Wá irin pẹlẹbẹ kan tí ó fẹ̀, kí o gbé e sí ààrin ìwọ ati ìlú náà, kí ó dàbí ògiri onírin.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ọba Olutayọ: ìgbésẹ̀ Ọọni àti Alaafin ti ń mú ìṣọ̀kàn dé sáàrin àwọn Ọba Yorùbá 3.
"O ni ""ọmọ ijọ Anglica ni mi, ọpọ Kristiẹni lo si n fẹ Musulumi lasiko naa."
Awon orile-ede lagbaye ati awon elegbe-jegbe ti pe fun ipade ijiroro naa fun igba pipe, amo won ko mu lokunkundun, pupo awon adari awon to yapa naa ni won ti fi owo sinkun mu, ti won si da pada lati orile-ede Naijiria ninu osu kinni odun, amo won koi ti yoju silw-ejo.
A kò fòfin de owó naira tó ti pẹ́ ní Naijiria -CBN Ẹ yé gba owó orí níbi ìdána ìyàwó mọ́, sísọmọbìnrin s'óko ẹrú ni- Daddy Freeze Ọwọ́ ọlọ́pàá ti tẹ ọkùnrin kan tó pa ọ̀rẹ́ rẹ̀ nítorí N40 ní Kano Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, VAT: Kò sí àǹfàní kankan tí ìjọba ti ṣe fún mi sẹ́yìn Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Mo bá sọ fún ọba pé, “Bí ó bá tẹ́ kabiyesi lọ́rùn, tí èmi iranṣẹ rẹ bá sì rí ojurere rẹ, rán mi lọ sí Juda, ní ìlú tí ibojì àwọn baba mi wà, kí n lọ tún ìlú náà kọ́.
Eyi ni koko to jẹyọ lyin abajade ipade aarẹ Buhari pẹlu igbimọ yi lọjọ Iṣẹgun nile ijọba lAbuja.
Awọn ẹṣọ aabo igberiko ati diẹ lara awọn alejo ti wọn fi iwe pe nikan lo wa nikalẹ, ti wọn si ti gbe awọn ọkọ isẹ ti wọn fẹ pin fun awọn osisẹ alaabo kalẹ.
Yóo wá wí nígbà náà pé, “N óo pada sọ́dọ̀ ọkọ mi àárọ̀, nítorí ó dára fún mi lọ́dọ̀ rẹ̀ ju ti ìsinsìnyìí lọ.
" Lọwọ-lọwọ bayii, o le ni ọgọrun-un abẹrẹ ajẹsara ti wọn n dabaa pe yoo wo arun naa san, eyi ti wọn n ṣe lọwọ - sugbọn Dokita Ryan tọka si pe, awọn arun miran bii Ẹyi, ni ko kuro ni ayika wa patapata lai naani pe, aimọye abẹrẹ ajẹsara lo wa fun iwosan rẹ.
 awon jews naa gbe ni ibe , won ni ile ta eran ati ile eko fun oj isinmi.
Àwọn ọmọ tí Makiri ọmọ Manase bí, ọwọ́ Josẹfu ni ó bí wọn sí pẹlu.
Agbẹnusọ rẹ, Muktar Gidado sọ ọ ninu atẹjade kan lẹyin ti ajọ NCDC ṣe ayẹwo mẹfa lara Ọgbẹni Mohammed to si fihan pe o ni arun naa.
Josẹfu sọ fún Farao, ó ní, “Ọ̀kan náà ni àlá mejeeji, Ọlọrun fi ohun tí ó fẹ́ ṣe han kabiyesi ni.
Kí ló dé tí o fi kọ̀ mí sílẹ̀?
Baba mi ra iru rẹ nigba naa, tayọtayọ la fi maa n fi aṣọ ankara ati omi ati adinagbọn nu ẹṣe ati pako ara rẹ!
3 % n gbe ni ilu ati iye eniyan 167.
Samuẹli tún sọ fún wọn pé, “OLUWA tí ó yan Mose ati Aaroni, tí ó kó àwọn baba ńlá yín jáde wá láti ilẹ̀ Ijipti ni ẹlẹ́rìí.
Ní tèmi, kì í ṣe pé mo gbọ́n ju àwọn yòókù lọ ni a ṣe fi ọ̀rọ̀ ìjìnlẹ̀ yìí hàn mí, bíkòṣe pé kí ọba lè mọ ìtumọ̀ rẹ̀, kí òye ohun tí ó ń rò sì lè yé e.
Ṣugbọn kí ẹ jẹ igẹ̀ tí ẹ bá fi rú ẹbọ fífì ati itan ẹran tí wọ́n fi rú ẹbọ ní ibi mímọ́, ìwọ ati àwọn ọmọkunrin rẹ ati àwọn ọmọbinrin rẹ, nítorí pé ìpín tìrẹ ni, ati ti àwọn ọmọkunrin rẹ, ninu ẹbọ alaafia, tí àwọn eniyan Israẹli rú.
Dafidi ní kí wọ́n sọ fún Amasa pé, ẹbí òun ni Amasa; ati pé, láti ìgbà náà lọ, Amasa ni òun yóo fi ṣe balogun òun, dípò Joabu.
Kí omi kíkorò tí ń mú ègún wá yìí wọ inú rẹ, kí ó mú kí inú rẹ wú, kí ó sì mú kí abẹ́ rẹ rà.
Ìdámẹ́ta ayé bá jóná, ati ìdámẹ́ta àwọn igi ati gbogbo koríko tútù.
Àwọn kan tilẹ̀ gbàgbọ́ pé, ara ọ̀nà àtijẹ ni, kìí ṣe ìwà ọ̀daran.
Bi ọpọlọpọ awọn lọkọ laya ode oni ṣe n ṣe, leyi ti ọkọ le e wọ inu iyara igbẹbi pẹlu iyawo rẹ lasiko ibimọ kii ṣe ti Ọba alaye nilẹ Yoruba.
 Asiwaju Tinubu sọ pe oun ko kuro ni ilu Eko."
Minisita fun ètò irinna, Rotimi Amaechi lọ sọ bẹẹ ni ilu Abuja, lasiko to n sọrọ lori ibi ti wọn ba iṣẹ de.
"Oríṣun àwòrán, @djxgee ""Iyatọ yoo ba ọna tawọn eeyan fi maa n se ẹyẹ ikẹyin fun ololufẹ wọn to ba rekọja lọ."
Fasiti Ọbafẹmi Awolọwọ, (Obafemi Awolowo University) OAU, Ile Ifẹ Oríṣun àwòrán, oau Orukọ fasiti yii nigba ti wọn daa silẹ ni fasiti Ile Ifẹ, iyẹn University of Ife, nigba ti ijọba ẹkun iwọ oorun Naijiria nigba naa ni ọdun 1961 daa silẹ.
Oṣu Karun, ọdun 2015, ni ẹgbẹ naa ṣe ikọlu akọkọ ni Pakistan.
" Ẹ bá mi dúpẹ́ lọ́wọ́ Sunday Igboho, Ajimobi, Seyi Makinde àti àwọn ọlọ́pàá fún iranwọ wọn láti rí ìbejì gbà padà Àwọn àràmọ̀ndà ìbomú-bẹnu tó gbòde lásìkò Coronavirus yìí Obìnrin pa olólùfẹ́ rẹ̀, ó fi se ìrẹsì Wo ohun tó yẹ kí o mọ̀ nípa òfin NCDC tó ń dá rògbòdìyàn sílẹ̀ Nígbà tó ń ṣe afiwe orin ẹ̀mí lásìkò yìí sí ìgbà tó bẹ̀rẹ̀ orin kíkọ, Tope Alabi ni àwọn tó ń kọrin ẹ̀mí kò pọ nígbà tí òun bẹ̀rẹ̀ orin kíkọ yàtọ̀ sí bí àwọn olórin ẹ̀mí ṣe pọ ni asiko yii.
 “Yoo sefilole ofin ati ilana ti yoo tete mu
Nítorí náà, ó pe Jehoiada ati àwọn alufaa yòókù, ó bèèrè pé, “Kí ló dé tí ẹ kò fi tún ilé OLUWA ṣe?
Nígbà tí ó pẹ́ díẹ̀ tí mo ronu títí tí n kò mọ nǹkan tí mo lè ṣe, mo gbé àpò mi, mo gbé ìbọn mi, mo fi orí lé inú igbó, mo ń lọ.
Ó jẹ́ ẹni tí ó gbọ́n púpọ̀, bí àwọn wúndíá sì ti ń wọlé rẹ̀ lọ́sàn-án tí wọn ń wọ̀ ọ́ lóru kò fẹ́ wọn lẹ̀hìn ìgbà tí ó fẹ́ ọmọ ẹ̀gbọ̀n mi tí mo ń sọ̀rọ̀ rẹ̀ yìí.
Newcastle run Manchester United mọ́lẹ̀ jégéjégé Israel Adesanya fi ẹ̀ṣẹ́ mú ẹ̀jẹ̀ jáde nímú Whittaker láti gba àmì ẹ̀yẹ UFC Èmi kò sí nílé, ọkọ́ mi ló leè sọ bóyá lóòtọ́ọ́ ló fẹ́ gbéyàwó àbí bẹ́ẹ̀ kọ́ - Aisha fèsì Ẹ jọ̀ọ́, òógùn ojú mi kò gbọdọ̀ já sásán lórí sinimá tí mo yà pẹ̀lú oyún oṣù mẹ́fà - Toyin Abraham Sugbọn lẹyin ọpọlọ akitiyan ninu abala keji idije ọhun ni ikọ Brazil da bọọlu naa pada si awọn ikọ Naijiria, ni igba ti Casemiro to n gba bọọlu fun ikọ Real Madrid sọ ayo tiẹ wọle.
Àkọlé àwòrán, Ariwo No to Rape"" ni wọn n pa ni iwọde ipinlẹ Eko Ariwo "" No to Rape"" ni àwọn olùwọ́de ń pa nipinlẹ Eko nínú òjò."
Lẹ́yìn náà, Dafidi jọba ní Jerusalẹmu fún ọdún mẹtalelọgbọn.
eniyan ti won je anfaani yii.
"’Awọn sọja Cameroun tu mi sihoho' Amẹ́ríkà ń béèrè ìròyìn facebook, email arìnrìnàjò tó f'ẹ́ gbà'wé àṣẹ ""Ojú ń tì mí láti rí àwọn ọmọbìnrin Nàìjíríà tó ń ṣe aṣẹ́wó ní Italy"" Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, African Migrants: Awọn arinrinajo sọ iriri wọn lọ si ilẹ Amerika Lẹyin ọpọlọpọ ikun sinu latọdọ awn ara adugbo, awọn alaṣẹ gba pe awọn ti fun arakunrin naa ni ijiya to pọ ju."
"Owọ ofin tẹ ẹ gẹgẹ bi ajọ EFCC ṣe gbe e lọ si ile ẹjọ lori ẹsun pe o n jale lori ẹrọ ayelujara eyi ti gbogbo eniyan mọ si ""Yahoo Yahoo""."
Ilé alájà mẹ́ta wó pa èèyan méje, èèyàn 20 farapa ní Obalende, Eko A máa ná N10.
Nígbà tí wọ́n dé, ọba sọ fún wọn pé, “Ẹnikẹ́ni tí ó bá lè ka ohun tí wọ́n kọ sára ògiri yìí, tí ó sì sọ ìtumọ̀ rẹ̀, n óo fi aṣọ elése àlùkò dá a lọ́lá, n óo ní kí wọ́n fi ẹ̀gbà wúrà sí i lọ́rùn, yóo sì wà ní ipò kẹta sí ọba ninu ìjọba mi.
 bakanna hammarskjöld nikan na tun ni akowe agba u.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Lampard Ni Derby, o tun ba akẹgbẹ rẹ nigba kan ri Jody Morris pade.
Yatọ si awọn wọnyii, awọn ọgagun mii to wa jẹri niwaju igbimọ naa ni ọgagun to n dari 81 Military Intelligence Brigade to wa ni Victoria Island, ọgagun Ahmed Taiwo, olori oṣiṣẹ ọmọ ogun 81 Division V.
ile- ise ọlọpaa yoo tesiwaju  nipa sise  ipolongo ifilole ọlọpaa agbegbe, eleyii ti yoo
je omo ile igbimo asoju tẹlẹri ti o tun je agbenuso fun egbe oselu APC ni
Abiy di olori orilẹede naa lẹyin ti olori ti tẹlẹ Hailemariam Desalegn, kọ'we f'iṣe silẹ ni oṣu keji ọdun yii.
Ofin tuntun yii kan awọn arinrinajo to fẹ gba iwe aṣẹ irina 'B' eleyi ti wọn maa n fun awọn awọn arinrinajo.
“Àwọn ràkúnmí ati agbo ẹran wọn yóo di ìkógun.
Wọn kò sì ranti majẹmu tí wọ́n bá àwọn arakunrin wọn dá.
O Fagunwa kọ wa pe ohun ta ba gbe ile aye se lo ja ju, kii se ọrọ̀ ta ba ko jọ.
Saraki: Ìwà àrékérekè ni ilé mi tí EFCC tì pa Bí ọlọ́pàá bá mú ọ, kí ló yẹ kí o ṣe?
Àdó okoró búrẹ́kẹ' Ọpọ lo ṣi n daro ti wọn si n sọrọ lori bi awọn agbebọn ikọ Boko Haram naa ṣe dumbu awọn agbẹ naa loko irẹsi ti wọn ti n ṣiṣẹ.
Gbajumọ osere tiata lobinrin, Foluke Daramola lo fi idi ọ̀rọ̀ yii mulẹ lójú opo Instagram rẹ pẹlu àfikún pe, Ogun Majek nílò owó láti fi ṣe itọju ara rẹ.
Ilẹ n jeeyan, ko si awaye-ma-lọ.
Wọ́n jí ọmọ yìí gbé láti máa fi tọrọ bárà l'Eko ‘Bi Gomina Ajimobi se yan adarí òsìsẹ́ tuntun ní Oyo kò dí wa lọ́wọ́’ Kí ló yẹ kí Àyájọ́ ọjọ́ àwọn èwe Nàìjíríà lọ́dún yìí dá lé lórí?
Bakan naa, orisirisi aseyori ni isakoso ijoba aare Buhari ti se lati igba ti o ti gori aleefa, eleyi ti o han gbangba-gbangba si awon omo orile-ede Naijiria.
Ìyàwó mẹ́rin ni Àkàndé Orímóògùnjẹ́ tí ó jẹ́ ìyá Dúró ti kú, ó ku mẹ́ta.
Amọ akọwe iroyin fun Gomina Seyi Makinde, Ọgbẹni Taiwo Adisa lasiko to ba BBC Yoruba sọrọ ṣalaye pe, ijọba ṣeranwọ fun UCH pẹlu awọn irinṣẹ atawọn eroja itọju awọn alaarun Covid-19.
Gbogbo àwọn ọmọ wẹ́wẹ́ tó tẹ̀ɔẹ yóò dáhùn .
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Èdè Yorùbá: Àjọ̀dún àádọ́ta ọdún Ẹgbẹ́ Akọ́mọlédè àti Àṣà Yorùbá Nàìjíríà 5 Ògún 2019 Ayẹyẹ lati dawọọ Ẹgbẹ Akọmọlede ati Aṣa Yoruba Naijiria ti wọn da ẹgbẹ ọhun silẹ.
Grandma Maruwa: Ó yẹ kí obìnrin sisẹ́ láì wojú ọkọ kó tó jẹun
Minisita feto irinajo ni Naijiria Rotimi Amaechi lo fi ikede yi soju opo Twitter rẹ ti o si ni fun oṣu mẹrin gbako lawọn eeyan yoo fi wọ reluwe ọfẹ.
36 Àti pé Olúwa Ọlọ́run ti sọ ọ́; àti ọlá, agbára àti ògo ni ó yẹ orúkọ mímọ́ rẹ̀, nísisìyí àti títí láe.
Àwọn ọ̀tá ń lépa mi tọ̀sán-tòru,ọpọlọpọ ní ń bá mi jà tìgbéraga-tìgbéraga.
Ẹjẹ ma a wa ni imu ati ẹnu wọn.
Bí àwọn kan ti ń kígbe bákan, bẹ́ẹ̀ ni àwọn mìíràn ń kígbe bá mìíràn.
Ọmọ ni a gbàdúrà kí a fi oyún bí.
Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Somalia rape death sentence: Ìdájọ́ ikú ló bá dé fáwọn méjì tó fipá bá ọmọ ọdún mẹ́rìnlá lò pọ̀5 Bélú 2020 Ẹkún àti ìbànújẹ́ láwọn mọ̀lẹ́bí fi sìnkú ọmọ méje ní Kumba, Cameroon lónìí5 Bélú 2020 Ibadan Tailor: Ilé-ẹjọ́ dá ẹjọ́ lòdì sí ìwà ọ̀gá ọlọ́pàá sí télọ̀ rẹ̀18 Bélú 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 3 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 5 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
óyá dára wò pẹ̀lú àwọn òwe Yorùbá 15 Òkùdu 2019 Gbiyanju òwe yii nípa fifi èyí to jẹ idahun ipari rẹ̀ kan ara wọn Fi igun ibẹrẹ òwe naa kan igun ipari òwe naa papọ Wo iye máákì mi Ṣe afihan esi rẹ Omi tó tán lẹ́yìn ẹja ló sọọ́ di èrò ìṣaasùn A kì í fi ọjọ́ kan bọ́ ọmọ tó rù.
A tún kúrò ni ibi èyí o di ilé mìíràn, ìgbà tí a dé ọ̀hún, a rí àwọn ọkùnrin méjì lórí àkàsọ̀ kan, nígbà tí Èṣù dé ibẹ̀ ó wí fún èyí tí ó wà ni ìsàlẹ̀ àkàsọ̀ kí ó fa ẹsẹ̀ èyí tí ó wà lókè, lóòótọ́ èyí tí ó wà ní ìsàlẹ̀ ṣe bí ó ti wí, ó fà á lulẹ̀ wéréwéré, ó gba ipò rẹ.
Bayelsa Electiions : Ile ẹjọ́ gíga jùlọ kọ ìpẹ̀jọ́ David Lyon àti ẹgbẹ́ òṣèlú APC
N óo ya yín jẹ bíi kinniun, bí ẹranko burúkú ṣe ń fa ẹran ya.
Ogunye sọ eyi lasiko ti o n fesi si bi ijọba Aarẹ Muhammadu Buhari ṣe gbe ẹsẹ le iwọde lati ọdọ awọn ẹgbẹ Shia (IMN) to n se alatilẹyin fun adari wọn, El-Zakzakky to wa ni atimọle ijọba.
Apapa gridlock: Ìjọba àpapọ̀ ní òun kò ní gbà kí wọ́n ba ọrọ̀ ajé ilẹ̀ yìí jẹ́
Oríṣun àwòrán, Olusegun Obasanjo Presidential Library Mo fẹran akọmọna ileewe kan to ni sisẹ ko si gbadura, sugbọn fun awọn eeyan miran, gbadura ko to sisẹ ni, bi o tilẹ jẹ pe ọna tẹ gba gbe ọrọ yii kalẹ kọ ni koko.
"Wọn n fi ẹmi wọn lelẹ fun gbogbo wa eyi si ba ni lọkan jẹ pe ọpọlọpọ wọn lo ti pa jijagun ti""."
Ó jẹ́ ẹnìkan tí ó ń sin Ọlọrun.
Magu ni awọn ọmọ Naijiria n sa ipa wọn lati fi oju awọn ọbayejẹ han, o ni ki wọn tubọ tẹra mọ iṣesi naa, ki awujọ lee dara si.
Lágbo tíátà lọ́sẹ̀ yìí, Femi Adebayo di àgbà àáfà òníláwàní, Iyabo Ojo fi sìgá dárà, Allwell Ademola di ọmọdé padà, tí Wazo si bímọ tuntun.
2 513576 Orilẹede Netherlands 9690 56.
Kí ni ayé ọmọ ènìyàn já mọ́?
Ogbó ti dé sí Ahija ní àkókò yìí, kò sì ríran mọ́, 
98 fun osu keji lodun 2028 , amosa ida ogoru un 12.
Ni àsikò yi, ọmọ ọkùnrin ni ó n jogún Bàbá, pàtàki àkọ́bí ọkùnrin nitori ohun ni Àrólé.
 ní Ìjọba ìbílẹ ̀ irẹpọ ̀ dun , lára àwọn Ìlú tí wọ ́ n ti ń sọ ẹ ̀ kà-èdè igbómìnà ni Àjàṣẹ ́ , Òró , Òmù-Àrán , Àrán-Ọ ̀ rin .
O ni ki awon abiyamo fopin si fifun omi oyan soju awon omo tuntun won nitori pe ko dara sugbon ki won tete gbe omo ti won ba fura si pe oju n yo lenu lo sile iwosan fun ayewo kikun.
Àwọ̀n ọlọ́kadà 123 láti Jigawa kìí se àwọn agbésùnmọ̀mì-Ọlọ́pàá Adari eto to n bojuto ayika ni ipinlẹ Eko, Yinka Egbeyemi ti ni awọn ọlọkada to le ni ọgọfa to wa lati ipinlẹ Jigawa wa si ipinlẹ Eko kii ṣe agbesunmọmi tabi ọdaran.
naa wa ni ihamọ  awọn ọlọpaa , ni eyi ti
Bayii ni o ṣe le wo esi idanwo rẹ lori foonu Awọn nọmba kan wa ti o nilo lati fi wo esi idanwo rẹ.
A ti ń sin òkú méjì sínú ibójì kan náà nítorí ọ̀wọ́ngógó ibojì ìsìnkú Wo díẹ̀ nípa ohun tí Walter Carrington gbé ṣe nígbà ayé rẹ̀ Ẹgbẹgbẹ̀rún ọmọ Nàìjíríà ní yóò má a kú lójoojúmọ́ tí wọn bá gbà wọ́n láàyè láti gbébọn dání- Amofin Ilé ẹjọ́ ju ọmọ ìjọ tó fi ìpá bá ọmọ pásítọ̀ rẹ̀ sùn ní ìpínlẹ̀ Ondo sí ẹ̀wọ̀n gbére Ooni Ifẹ bu ẹnu ẹ̀tẹ́ lú ètò BBNaija nítorí ó tàbùkù àsà Yoruba Obadiah Mailafia lo sọ lori redio pe gomina ni ẹkun ariwa Naijiria gan an ni ọkan gboogi lara awọn adari ikọ agbesunmọmi Boko Haram ni Naijiria.
Àwọn ẹranko tí pátákò ẹsẹ̀ wọn là sí meji, tabi tí wọ́n bá ní ìka ẹsẹ̀, tí wọ́n sì ń jẹ àpọ̀jẹ, irú wọn ni kí ẹ máa jẹ.
Gbogbo wọn bá pada lọ sí Giligali, wọ́n sì fi Saulu jọba níwájú OLUWA.
Opọ awọn eniyan ni wọn ti n woye ibi ti ọrọ naa yoo jasi.
FC Astana ni wọn ba pade ninu ifẹsẹwọnsẹ wọn akọkọ ti wọn si bori.
Mi o joye lati buga, ṣugbọn oye yii wa lati ṣi awọn eeyan leti.
Mo ní ọ̀rọ̀ fún àwọn tí ó ti gbeyawo: ọ̀rọ̀ tèmi fúnra mi kọ́, bíkòṣe ti Oluwa wa.
Ọmọdekunrin naa ti orukọ rẹ n jẹ Bamfo, ni akẹkọ ti ọjọ ori rẹ kere julọ laarin awọn bi ẹgbẹrun mẹta din ọgọrun, to n gbele kawe ti wọn gba wọle si fasiti naa lọdun yii.
Ni nkan bi ago mẹfa abọ kọja iṣẹju kan ni o gba abẹrẹ yi, akọkọ abẹrẹ ẹgbẹrun lọna ẹgbẹrin ti ile iṣẹ Pfizer/BioNTech gbe jade.
Bẹẹ lo tun kede pe idanwo ti ajọ NABTEB n ṣakoso rẹ yoo waye laarin ọjọ kọkanlelogun, oṣu kẹsan an si ọjọ karundinlogun, oṣu kẹwaa, ọdun 2020.
Ẹni tí ó ń ṣọ́ ẹnu rẹ̀, ẹ̀mí ara rẹ̀ ni ó ń ṣọ́, ẹni tí ń sọ̀rọ̀ àsọjù yóo parun.
Mikilotu bí Ṣimea; àwọn náà ń gbé lọ́dọ̀ àwọn eniyan wọn ni òdìkejì ibùgbé àwọn arakunrin wọn ní Jerusalẹmu.
BBC ṣewadìí àwọn ewu to rọ̀ mọ kí àwọn Ọba alade maa kọ ìyàwó silẹ̀ ni aafin.
17 Bélú 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Ọrọ yi lo fẹ ṣe rẹgi pẹlu awọn ti wọn gba oriyin fun iwa akin ti wọn wu, lasiko iṣẹlẹ iyinbọn paniyan to waye ni Mọṣalasi meji lorileede New Zealand.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù NHIS: Lẹyin ọpọlọpọ àbájáde ìwádìí, Buhari ni ki ọjọgbọn Yusuf máa lọ 2 Agẹmo 2019 Oríṣun àwòrán, others Àkọlé àwòrán, Ta ni Mohammad Sambo, olùdarí NHIS tuntun?
Tẹlẹ lọjọ Abamẹta ni fidio ọlọpaa SARS to joko silẹ ti ọpọ eeyan si rọgba yii ka lu ayelujara pa.
Kìí ṣe torí ìbèérè ni mo ṣe bẹ́ Fani-Kayode, àwọn akẹẹgbẹ́ mi ló kó mi láyà jẹ - Eyo Charles Àwọn òṣèré Nollywood tí wọn ò sí lóri amóhùmáwòrán mọ́ Ohun tó ṣẹlẹ̀ láàrin Ozo àti Nengi lálé àná nílé BBNaija rèé Gẹgẹ bi aarẹ ṣe sọ, ijọba apapọ ti n ṣiṣẹ lati rii daju pe ileeṣẹ to n pin ina, DisCos, fi ara jin si ṣise afikun si iye wakati ti ina yoo fi ma wa ni oojọ.
Ìtàn bí bàbá mi ti ṣe fẹ́ ìyá mi yẹ ní sísọ, nítorí n kò tí ì sọ eléyìínì fún ọ rí, bẹ́ẹ̀ ni ìtàn dídùn náà ni, kò sí nǹkankan nípa ìgbásí-ayé bàbá mi tí n kò mọ̀, nítorí òun náà pàápàá kò jáfàra nígbà tí ó ń bẹ lórí ilẹ̀ ayé, bí bàbá mi ti sun iṣu sí iná bẹ́ẹ̀ bi o ń fi ojú w;a ọ̀bẹ, bí ó ti wà ní ayé nígbà náà a máa tẹ ọ̀rọ̀ yìí mọ́ wa létí nígbàkúùgbà pé, ‘Ọkùnrin tí ó jí ní kùtùkùtù ọjọ́ ayé rẹ̀ tí ó gbé ọ̀ràn obìnrin lé ibi pàtàkì oókan àyà rrẹ̀ kò ní í di pàtàkì láéláé; obìnrin tí ó jí ni kùtùkùtù tí ó gbé ọ̀ràn ọkùnrin le ibi pàtàkì oókan àyà rẹ̀ kò ní í di pàtàkì láéláé; ọkùnrin tí o tó àkókò àti ní obìnrin ti ó gbé ọ̀ràn obìnrin rẹ̀ ti ó ní lé ibi pàttàkì oókan àyà rẹ̀ yóó di pàtàkì láéláé; obìnrin tí ó tó àkókò àti ni ọkọ tí ó gbé ọ̀ràn ọkọ rẹ̀ tí ó ni lé ibi pàtàkì oókan àyà rẹ̀ yóó di pàtàkì láéláé; ọkùnrin alábòsí tí ó fẹ alábòsí obǹirin tí ó gbé ọ̀ràn alábòsí náà lé ibi pàtàkì oókan àyà rẹ̀ kò ní í di pàtàkì láéláé; obìnrin alábòsí tí ó fẹ́ alábòsí ọkùnrin tí ó gbé ọ̀ràn alábòsí náà lé ibi pàtàkì oókan àyà rẹ̀ kò ni í di pàtàkì láéláé; ọkùnrin pàtàkì tí ó fẹ́ alábòsí obìnrin tí kò gbé ọ̀ràn alábòsí náà lé ibi pàtàkì oókan àyà rẹ̀ yóó di pàtàkì láéláé; obìnrin pàtàkì tí ó fẹ́ alábòsí ọkùnrin tí kò gbé ọ̀ràn aláòsí náà lé ibi pàtàkì oókan àyà rẹ̀ yóó di pàtàkì láéláé, ẹnikẹ́ni pàtàkì ti ó gbe ọ̀ràn ẹlòmíràn pàtàkì lé ibi pàtàkì oókan àyà rẹ̀ yóó di pàtàkì láéláé.
"Mo rọ yin lati ro arojinlẹ lori awọn ẹkọ bii ifaraẹnijin, idariji, ijọsin fun Ọlọrun ati ikoraẹni-ni- ijanu pẹlu ifẹ tootọ fun ọmọlakeji, eyi to suyọ lasiko Ramadan.
igbakuugba ti mo ba si fẹ rẹwẹsi pe n ko se mọ, ti mo ba ranti awọn osisẹ mẹtalelogun ti wọn n sisẹ labẹ mi, ti wọn yoo padanu isẹ wọn, ma tun joko jẹẹ.
Ọ̀rọ̀ Aisha Buhari sí Ramaphosa wú ọ̀rọ̀ síta lẹ́nu àwọn ọmọ Nàìjíríà Kí ló ṣe ikú pa Adediwura Lateefat Bello lẹ́yìn ọ̀sẹ̀ méjì tí wọ́n ń wá a?
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Pogba: Ikọ̀ Real Madrid ń gbáradì láti kó £70m lé Paul Pogba lórí 26 Ìgbé 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 3 Èbibi 2020 Oríṣun àwòrán, Getty Images Ẹgbẹ agbabọọlu Real Madrid ti n gbaradi lati ko aadọrin miliọnu pọun le atamatase ikọ Machester United, Paul Pogba lori.
Afẹ́fẹ́ líle yìí bá bẹ̀rẹ̀ sí taari ọkọ̀.
“Ohun ti mo ri nipa ile naa ni  pe
Ṣe loju maa n ti i ti ko si fẹran lati maa foju han tori naa, ọmọ rẹ ọkunrin to gbẹnu rẹ sọrọ Mohammed Jammal ti o gbajugbaja pẹlu orukọ rẹ, White Nigerian"" sọ bi wọn ṣe bẹrẹ ile naa."
Apero naa ni ireti wa wi pe yoo waye fun ọjọ mẹta gbako, gẹgẹ bi awọn gomina naa ṣe pinnu lati tẹlẹ awọn amọran ti o ba ti ibi apero naa jade.
N óo wó ògiri tí ẹ kùn lẹ́fun, n óo wó o lulẹ̀ débi pé ìpìlẹ̀ rẹ̀ yóo hàn síta.
 ( he taught us about prose diction .
Davido àti Chioma aya rẹ̀ ti d'ọ̀rẹ́ padà ní Instagram O fi kun pe Olamide yoo f'oju ba ile ẹjọ lori orin naa.
Nígbà tí àwọn iranṣẹ Saulu jíṣẹ́ fún Dafidi, inú rẹ̀ dùn, ó sì gbà láti di àna ọba.
Bí eniyan bá ń bá ọlọ́gbọ́n rìn yóo gbọ́n, ṣugbọn ẹni tí ó bá ń bá òmùgọ̀ kẹ́gbẹ́ yóo ṣìnà.
 ní ojọ ́ ọkàndínlógún oṣù kẹsán Ọdún 2015 , ó jẹ ́ olọ ́ run nípè lẹ ̀ yìn tí ó lo ọdún ọ ̀ kàndínlọgọrún láyé , oṣù mẹ ́ jì kí ó ṣe ọjọ ́ ìbí ọgọ ́ rún ọdún .
Ẹ̀ẹ̀kejì, láti bẹ̀rẹ̀ ìgbésẹ̀ fún jíjẹ ànfàní àti síse ìtọ́jú àwọn èwe lágbayé.
 báyìí , àwọn akẹ ́ kọ náà maa ń bá àwọn ẹlẹgbẹ ́ wọn ṣe ìdánwò west african school-leaving certificate àti national examinations council .
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ọmọ ẹgbẹ Boko Haram ogun gba'dajọ ẹwọn 13 Èrèlè 2018 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Boko Haram ti se iku pa ogunlọgọ eniyan lati ọdun 2013 Ko din ni eeyan ogun ti wọn ti ju s'ẹwọn l'orilẹede Naijiria nitori wipe wọn jẹ ọmọ ẹgbẹ agbesunmmi, Boko Haram.
idagbasoke eto oro aje ati ipese ise ni Europe ati Afirika.
Ṣírò iṣẹ́ rẹ bí ọmọ-ọ̀dọ̀, nítorí n óo dá ọ dúró lẹ́nu iṣẹ́.
egbe PDP gbe jade jẹ ayederu ati pe  ko
Nígbà tí ó wí báyìí tán, ọba tí ó wà nínú ihò dá a lóhùn, ó ní, Ọ̀rẹ́ mi ayé, ọ̀rẹ́ mi ọ̀run, mo ń bẹ ní ibodè ọ̀run o.
Olorin fuji naa n mu gari naa tidunnu-tidunnu.
Son lo kọkọ gba kaadi alawọ pupa nigba ti ifẹsẹwọnsẹ naa wọ iṣẹju kẹtalelogoji ti Foyth si gba tirẹ ni iṣẹju kejidinlaadọta.
Ó bá dá wọn lóhùn pé, “Bí ẹ ti wí gan-an, bẹ́ẹ̀ ni yóo rí.
Dákun má ṣe fara wé wọn
Ẹ san án fún un gẹ́gẹ́ bí iṣẹ́ ọwọ́ rẹ̀, ẹ ṣe sí i bí ó ti ṣe sí àwọn ẹlòmíràn; nítorí pé ó ṣe àfojúdi sí OLUWA, Ẹni Mímọ́ Israẹli.
O ni 'a gbagbọ ninu ijọba awaarawa, sugbọn awọn to wa l'oju kan ni igbagbọ nilu iṣejọba pipin owo ilu laarin awọn kan, to fi mọ jiji owo orilẹede Naijiria ko sapo ara wọn.
Lójijì yóo kígbe tòò, ara rẹ̀ óo le gbandi.
Lọdun 2012, ọpọlọpọ ọmọ Naijiria jade lati fi ẹhonu han lori ipinnu ijọba aarẹ Goodluck Jonathan nigba naa lati yọ owo iranwọ epo (subsidy).
23 Kíyèsíi ìwọ ni Hyrum, ọmọ mi; lépa ìjọba Ọlọ́run, ohun gbogbo ni a ó sì fi kún un gẹ́gẹ́bí èyĩnì tí ó tọ́.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Òṣìṣẹ́ Bánkì ni mí l'Amẹ́ríkà kí n tó bẹ̀rẹ̀ Tíátà' O gba awọn eniyan Naijiria niyanju lati pese iranlọwọ nipa ipese ohun eelo, awọn oṣiṣẹ eleto ilera lati maa ra awọn ikoko pada lọwọ iku ojiji.
Ilé ẹjọ́ ju ọmọ ìjọ tó fi ìpá bá ọmọ pásítọ̀ rẹ̀ sùn ní ìpínlẹ̀ Ondo sí ẹ̀wọ̀n gbére Ooni Ifẹ bu ẹnu ẹ̀tẹ́ lú ètò BBNaija nítorí ó tàbùkù àsà Yoruba Ogun Àgbẹ́kọ̀yà, ẹ̀kọ́ wo ló yẹ́ kí àwá ọ̀dọ́ kọ́ níbẹ̀?
boolu afesegba ile Afrika(Africa Cup of Nations (AFCON) ti yoo waye lorile-ede Egypt.
 ní ọdún 1999 ni àìsàn kan ń bá a jà ní kíndìnrín .
Ni Ọjọ Kọkandilọgbọn, Oṣu Kẹjọ, ọdun 2020 ni ileẹjọ yoo da ẹjọ fun awọn soja marun un ti wọn jẹbi iṣekupani naa.
Igbimọ PTF to n ri si ari dena ajakalẹ aarun covid-19 lo gba ijọba nbi imọran tẹlẹ jẹki awọn oṣiṣẹ ijọba lati ipele kejila pada sẹnu iṣẹ.
Àwọn ẹrú ati àwọn ẹ̀ṣọ́ jọ dúró ní àgbàlá, wọ́n ń yáná tí wọ́n fi èédú dá, nítorí òtútù mú.
ko gbọdọ gba wọn laaye lati maa fi ẹrọ ayelujara da wahala ija ẹsin, ija ẹlẹyamẹya,
Abacha: Al Mustapha ní ète ìdìtẹ̀ gbàjọba méjọ ni Sani Abacha borí
Orileede Cameroon to yẹ́ ko gbalejo rẹẹ̀ padanu anfaani naa latari ipalẹmọ wọn ti ko munadoko to.
Ọrọ yi jẹyọ lẹyin ti adari ajọ to n gbogun ti ilokulo oogun Mustapha Abdallah ati gomina Ipinlẹ Ondo Rotimi Akeredolu, Ọgá NDLEA lọ kọ nípa gbíngbin igbó ní Thailand fun lilo gẹgẹ bi oogun.
Páńpẹ́ EFCC ti mú Mínísítà ètò ìdájọ Nàìjíríà tẹlẹ lórí ẹsùn ajẹbanu $1.
Amuneke fipò sílẹ̀ gẹ́gẹ́ bí akọ́nimọ̀ọ́gbá Tanzania
Ibadan Traditional worshippers: Àwọn ẹlẹ́sìn ìbílẹ̀ ń bèèrè ọludé lọ́dọọdún fún àyájọ́ ìṣẹ̀ẹ̀ṣe
Awọn olupese: Isọri awọn eeyan yii ni awon to n fun awọn olufẹhonuhan ni ounjẹ ki wọn baa le ni okun lati tẹsiwaju ninun iwọde ọhun.
Ìdí ni pé, nígbà míràn, ó máa n nira láti bori àsìkò yìí tí ìṣk náà yóò tún ran àwọn ọmọ.
Wọ́n wá fetí sílẹ̀ sí ohun tí Banaba ati Paulu níí sọ nípa iṣẹ́ abàmì ati iṣẹ́ ìyanu tí Ọlọrun tọwọ́ wọn ṣe láàrin àwọn tí kì í ṣe Juu.
Wọ́n ṣe àkànpọ̀ igi mẹfa fún ẹ̀yìn àgọ́ náà ní apá ìwọ̀ oòrùn.
''Amọ, yatọ si orilẹede South-Afrika ni ilẹ Afrika, arun yii ko ni ipa lara wa bi akọsilẹ ṣe kọkọ sọ wi pe yoo ri.
Akọroyin BBC to wa niluu Nairobi sọ pe ṣiṣe igbeyawo tipatipa fawọn ọmọde eyi to wọ pọ laarin awọn ẹya Massai lẹkun Narok n kọ ọpọ lominu lorilẹede Kenya Ẹwẹ, ileeṣẹ ọlọpaa ti wa awọn baba ọmọdebinrin naa atawọn ọkun mejeeji to fẹ ni tipatipa laarin oṣu kan.
Sheffield faṣọ iyì ya mọ́ Chelsea lára lọ́nà ìrìnàjò sí Champions League Akanbi mi, má fọ̀ ọ́, mo wà pẹ̀lú ẹ; Ẹni tó ṣe ìgbéyàwó olórùka ló l'ọkọ- Lizzy Anjorin Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Nítorí ìkùukùu ni yín, tí ó wà fún àkókò díẹ̀, lẹ́yìn náà tí kò ní sí mọ́.
Bàbá arúgbó kan pa ara rẹ̀  nígbà tí ó bẹ́ láti ojúu fèrèsé ilé alájà-mẹ́rin pẹ̀lú okùn tí ó so mọ́ ọrùn.
Ara rẹ maa n sinmi lasiko ti o ba n sùn, ko si pe oun ronu ohunkohun, ọkan rẹ si le ronu oriṣiriṣi nipa ibalopọ.
Idije ife ẹyẹ tilẹ Adulawọ laarin awọn agbabọọlu alafẹsẹgba ti bẹrẹ ni ọjọ kọkanlelogun, oṣu Kẹfa.
Nítorí náà, pàṣẹ fún àwọn iranṣẹ rẹ, kí wọ́n bá mi gé igi kedari ní Lẹbanoni.
Ṣugbọn à ń waasu pẹlu ọkàn kan bí eniyan Kristi, ati gẹ́gẹ́ bí ẹni tí Ọlọrun rán níṣẹ́, tí ó ń ṣiṣẹ́ níwájú Ọlọrun.
Aaroni ati Mose ni OLUWA pè, tí ó sì wí fún pé kí wọ́n kó àwọn eniyan Israẹli jáde kúrò ní ilẹ̀ Ijipti.
Titi di akoko yii, eeyan bii ẹẹdẹgbẹta lo wa nibudo awọn eeyan ti ko nile lori, a si nrawọ ẹbẹ si awujọ agbaye lati wa seranwọ fun wa.
 Àdán ẹlẹ ́ nu gígùn pẹ ̀ lú ojú nlánlá náà ni a gbàgbọ ́ pé ó má a ngbé àrùn náà káàkiri , tí ó sì má a ntàn-án káàkiri láì jẹ ́ pé àrùn náà pa òun fúnraararẹ ̀ lára .
Nígbà tí wọ́n jẹun tán, Jesu bi Simoni Peteru pé, “Simoni ọmọ Johanu, ǹjẹ́ o fẹ́ràn mi ju àwọn wọnyi lọ?
Ní ìgbẹ̀yìn-gbẹ́yín, ìfọ̀rọ̀-wáni-lẹ́nuwò ọ̀hún jẹ́ àkọ́ṣe tí ó kọyọyọ.
" Láìpẹ́ yii, ni àjọ EFCC ké gbàjarè pé àìsí owó tótó n ṣe ìdíwọ́ fún iṣẹ́ òhun.
Ìtura lati oju ara tabi G-Spot G-spot ni orukọ ti wọn n pe aaye kekere kan to wa ni oke tente iwaju oju ara obinrin, eyi si le fun awọn obinrin ni itura ti wọn ba fi ọwọ́ tabi nkan ọkunrin rìn wọ́n níbẹ̀.
Ati pé, arabinrin mi ni nítòótọ́, bí ó ṣe jẹ́ nìyí, bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé kì í ṣe ìyá kan náà ni ó bí wa, ọmọ baba kan ni wá kí ó tó di aya mi.
Ṣugbọn, ṣe ẹyin naa mọ pe eniyan ẹlẹran ara naa ni eniyan yoo ma a jẹ.
aare tabi ipo ti ijoba yan si fi lu awon ara ilu ni jibiti sun ijoba.
Amọ ile aṣofin tako ti wọn si dibo pe ki o waye lowurọ ọjọ Aje.
Ṣá máa jẹ́ ọkọ wa, kí á máa jẹ́ orúkọ rẹ; kí o mú ìtìjú kúrò lọ́rọ̀ wa.
Adeboye lo sọ ọrọ naa laarọ ọjọ Abamẹta nibi ipade adura Holy Ghost Congress to maa n waye lọdọdun ni Olu ijọ naa to wa lọna marosẹ Eko si Ibadan.
Ṣugbọn yóo jẹ ẹ̀yin ará Edomu níyà fún ẹ̀ṣẹ̀ yín,yóo tú àṣírí ẹ̀ṣẹ̀ yín.
Ó ní bí àwọn tilẹ̀ bá àwọn ará Kalidea jagun, àwọn kò ní borí.
Olúbàdàn, ẹ bá wa bẹ́ Seyi Makinde kó tú wa sílẹ̀ - Oyo NURTW Lẹ́yìn ọdún mẹ́wàá, Tokyo àti Auxillary ṣèpàdé bòńkẹ́lẹ́ NURTW yóò fikùnlukùn pẹ̀lú Gómìnà Makinde láìpẹ́ NURTW l‘Abuja yóò kàn sí Makinde láìpẹ́ lórí bó ṣe fòfin dè wá l‘Ọyọ - Ejiogbe Ṣeyi Makinde ṣé ìfilọ́lẹ̀ àwọn olùdarí ìbùdókọ́, ó yan Auxilliary lálaga ìgbìmọ̀ Òfin ṣì gbẹ́sẹ̀lé Ẹgbẹ́ awakọ̀ èrò NURTW ní ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́ Ijọba Ọyọ ni lọdọ awọn, ko sẹni to mọ okolo awọn ẹgbẹ NURTW lẹkun iwọ oorun guusu Naijiria lọyọ, tori wọn ko fi orukọ silẹ lọdọ awọn, oye ohun to si n waye nipinlẹ naa ko ye wọn to.
Ṣé òótọ́ ni pé ìgbẹ́ erin le è wo aarùn Coronavirus sàn?
Nigeria 2 - 1 South Africa Ere pari Alaye kikun lori ere Awọn agbabọọlu ti wọn yan Alaye ni soki lori ere bọọlu Ẹkunrẹrẹ Ilana ere bọọlu Nigeria (4-2-3-1) South Africa (4-3-3) Ẹkunrẹrẹ 14 - Mothiba 0 - 0 27 - Chukwueze football 1 - 0 35 - Musa 1 - 0 49 - Hlatshwayo 1 - 0 58 - Lorch                                                                          down Zwane                                                                      up 1 - 0 62 - Tau 1 - 0 71 - Zungu football 1 - 1 75 - Mkhize 1 - 1 81 - Musa                                                                          down Simon                                                                      up 1 - 1 86 - Mothiba                                                                          down Veldwijk                                                                      up 1 - 1 89 - Troost-Ekong football 2 - 1 91 - Iwobi                                                                          down Balogun                                                                      up 2 - 1 Alaye ni soki lori ere bọọlu Nigeria South Africa Bọọlu wa nikawọ mi 39.
Anthony Joshua: Ta ni yóò borí nínú abala kejì ìjà Ruiz pẹ̀lú AJ?
Yatọ si eyi, o fikun pe ibudo ti wa fun ẹnikẹni ti wọn ba fi ipa balopọ nipinlẹ Ekiti, lati lọ fun itọju, idanilẹkọọ ati imọran.
Ayò Bánkólé ni bi ẹ ba tilẹ korira Atiku, ẹ o gbudọ ma fẹran iru esi to fọ yii.
Ó ń bọ̀ nígbà tí ó bá yá.
Awa naa yoo pe ẹjọ miran lati tako igbesẹ yii ni kiakia.
Lara ẹkọ ti wọn lọ kọ yii, wọn ṣe ibẹwo si ibudo iṣewadii lori igbo ni fasiti orilẹede naa nibi ti gomina Akeredolu ti ni oun fẹ ki wọn ṣiṣẹ pọ pẹlu ipinlẹ Ondo.
Ó kígbe sókè, ó ní, “Ibukun Ọlọrun wà lórí rẹ pupọ láàrin àwọn obinrin.
A o lee ri iru awon eroja ti won fi kọ
Wọ́n bá sọ ọ̀rọ̀ Oluwa fún òun ati gbogbo ìdílé rẹ̀.
Ó mú Dafidi wá siwaju ọba, ó sì bẹ̀rẹ̀ sí ṣiṣẹ́ iranṣẹ fún ọba bíi ti àtẹ̀yìnwá.
Ǹjẹ́ yóo ní inú dídùn sí Olodumare?
Jonadabu bá sọ fún ọba pé, “Àwọn ọmọ oluwa mi ni wọ́n ń bọ̀ yìí, gẹ́gẹ́ bí mo ti wí.
Cardi B ti pín yà pẹ̀lú ọkọ rẹ̀ Offset lẹ́yìn ọdún kan Simí, Davido gba àmì ẹ̀yẹ 'Headies' Oríṣun àwòrán, @mrchidozie Wakati kan abọ lẹyin ti ifẹsẹwọnsẹ naa bẹrẹ, ọrọ ni iyanju ti Liverpool si pegede ti Kcee si padanu miliọnu Naira kan.
O wa gbosuba kare fun ajo eleto idibo, INEC fun ise ribi -ribi ti won  nse, paapaa julo, lori  atunse  awon kudie-kudie to waye ninu idibo to waye ni
Ọba Ahasu-erusi pàṣẹ pé kí àwọn orílẹ̀-èdè tí wọ́n jìnnà ati àwọn tí wọn ń gbé etíkun máa san owó orí.
Ebola: Àwọn aláìsàn mẹ́ta sá kúrò níléwòsàn ní DR Congo
Ẹgbẹ n fẹhonu han nitori olori wọn to wa latimọle, Ibrahim Zakzaky, ohun ti wọn n beere fun ni pe ki ijọba fun un lominira.
Àwọn agbébọn pa ọ̀gá àjọ tó ń rí sí ọ̀rọ̀ ìjọba ìbílẹ̀ Ó yẹ kí Sotitobire gbọ́ ìdájọ́ lónìí ṣùgbọ́n ẹ wo bí ilé ẹjọ́ ṣe tún ṣe é Lai Mohammed, Ayo Fayose, Afẹnifẹre, Ndigbo, Arewa dá sí ọ̀rọ̀ Buhari àti Obasanjo Nibayii, iroyin sọ pe o ti wa ni ahamọ awọn ọlọpaa nibi ti wọn ti n fi ọrọ wa a lẹnu wo.
Pẹlu idà rẹ ni o óo fi wà láàyè, arakunrin rẹ ni o óo sì máa sìn,ṣugbọn nígbà tí ó bá yá, o óo já ara rẹ gbà,o óo sì bọ́ àjàgà rẹ̀ kúrò lọ́rùn rẹ.
Agbébọ́n tún ṣoro ní márosẹ̀ Ibadan sí Eko, wọ́n jí èèyàn mẹ́ta gbé Ẹni orí yọ, ó dilé!
 Ilorin gbàlejò Wizkid, àwọn olólùfẹ́ rẹ̀ fẹ́ ẹ̀ gbée lójú agbo Bi àwọn kan ṣé n jẹ àsun ní àwọn míì n ṣeré lórí omí láti gbádùn Kérésì àná Ìjọba Buhari kò tíì fi akọ̀ròyìn kankan sátìmọ́lé láti ọdún 2015 - Garba Shehu Èyí ni ìdí tí Bàbá Kérésì fi máa n wọ aṣọ pupa àti funfun nígbà gbogbo Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Larisa: Má jẹ́ kí ọjọ́ orí rẹ dí ẹ lọ́wọ́ láti bẹ̀rẹ̀ ohunkóhun to wù ọ Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?"
ti awon se gbọdọ da ile-ifowopamo imo ero igbalode silẹ.
Àwọn ọmọ Delaaya, àwọn ọmọ Tobaya, ati àwọn ọmọ Nekoda.
Ìléyá ni wọ́n ń pè é ní èdè Yorùbá nítorí pé nígbàtí àgùntàn ti rọ́pò ènìà lójúbọ, Ibrahim wí fún Ishmael pé iléyá!
1 90579 Orilẹede Kazakhstan 2550 13.
Wo oríṣiríṣi ìgbádun ibálòpọ̀ láwọn orílẹ̀èdè mìíràn 'Ǹkan ìṣeré ìbálòpọ̀ mi ńpaná iṣẹ́ mọ́ mi lára' Ǹjẹ́ ara rẹ ń kọ ìbálòpọ̀ bí?
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, SS3 ní mo wà báyìí, mo sì ti gba àmì ẹ̀yẹ̀ púpò nílé-lóko gẹ́gẹ́ bí onílù - Ayansike Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Ondo State Election result 2020: Bí èsì ìdìbò gómìnà ìpínlẹ̀ Ondo ṣe ń jáde rèé.
Ẹsẹ́ púpọ̀ fún isẹ takuntakun yín lórí wa.
Ewu to wa ninu fa ki n fa yii ni pe i awọn mejeji ba kọ lati pari ọrọ naa ni itubi inubi, o le da ogun silẹ lagbegbe ọhun.
Àmọ́, kòkòrò àwọn ológun tó gba ijọba ilẹ̀ wá nígbà náà, kò jẹ ki Omololu gbádùn òbí ipò gomina tó gbó kaka.
MSME free business registration: Oníṣẹ́ alàdáni, ẹ wo ọ̀nà láti jẹ ànfàní ìforúkọsílẹ ọ̀fẹ́ tí ìjọba gbékalẹ̀
O ṣalaye pe, ifẹ lati ni idi to tobi bii ti ojulowo ọmọbinrin lo jẹ ki oun diju ṣe iṣẹ abẹ naa ni ọdun marun un sẹyinsun ohun o.
Oríṣun àwòrán, Instagram/K1 the ultimate Ọpọ olorin atawọn eeyan jankan jankan lo ti n ki K1 ku oriire oye Mayegun to ṣẹṣẹ jẹ.
Anatoti ati Alimoni, gbogbo wọn jẹ́ ìlú mẹrin.
Bẹẹni ko tilẹ sun mọ ida kan ninu ọgọrun (0.
 ) so àsiá wón so asía won sí gbogbo àwon ònà náà lati sàjoyò igbá oróke tí awon egbe agbábóòlu náà gbé.
" Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Mother Language Day: Bàbá míì ní àìkọ́ ọmọ òun ní Yorùbá ló mú kò pàdánù iṣẹ́ olówó ńlá Oluwo ni oun si ni Ọba alade nilẹ Iwo, Oluwo ti Iwo, Alase lori orisa, ọba miran ko si lee ni ki oun lọ rọọkun nile na, wọn kan le ni ki oun ma wa si ipade wọn mọ ni.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ẹ bá mi wá nọ́ńbà ìpè òbí ọmọ Mummy Calm Down jáde - Yinka Ayefele Ọlọ́pàá sálọ fún aráàlú l‘Okeho, nígbà tí wọn yari láti ṣun olè méjì tó kù Kí ìjọ mi ní Sagamu le gbòòrò ni mo fi ń ṣiṣẹ́ ajínigbé pawó - Pásítọ̀ Àwa àti fijilanté pẹ̀lú ọdẹ́ ìbílẹ̀ ló dojú kọ adigunjalè ní First Bank Okeho - Iléeṣẹ́ ọlọ́pàá Ìtàn ọba Yorùbá tí wọn yẹgi fún torí ó jí ọmọ gbé ṣe ètùtù Ẹ káàbọ̀ sọ́jọ́ Arafat, tí Ọlọ́run yóò fi ààwẹ̀ Mùsùlùmí pa ẹ̀ṣẹ̀ wọn rẹ́ Boko Haram da ìbọn bo ọkọ̀ gómìnà Borno, ẹ̀ṣọ́ àláàbò rẹ̀ farapa Nigba to n salaye idi to fi yan iru iwa naa laayo, Bobrisky ni awọn iwa bii were lo n jẹ awọn ọmọ Naijiria, ẹni to ba si nhuwa to tọ, ko le e riba ti se.
Oun ni ọmọ Naijiria akọkọ ninu iwe itan ti yoo di ipo yii mu ni agbegbe Colombia.
 O tun so pe “iye awon olopaa to ba wu ki won lo, lati pese aabo fun awon eniyan to fe dibo  fun oludije to ba wu won.
O ni koda, aarẹ le lo to ọjọ mọkanlelogun ni ẹyin odi lai fi to awọn aṣofin leti.
Aṣofin naa tun woye pe ofin yoo dipo iru ofin yii to wa fun awọn alarun ọpọlọ to ti wa tẹlẹ ni ipinlẹ Eko ati pe yoo le jẹ ki awọn alarun ọpọlọ ni alekun itọju si i pẹlu abadofin yii, ti yoo si le gegi dina iwa idẹyẹsi si awọn eniyan bayii lawujọ.
Àwọn ajínigbé jí adarí ìlú Daura gbé Ọlọ́pàá tó n gba rìbá sọ pé 'Ọlọ́run gan fara mọ́ olè jíjà' Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Oluwo: Mo lè jẹ Ọba ní Ile Ife Iṣẹ̀lẹ̀ ọhun to wáye lásìkò ti àwọn ènìyàn ń wo ifẹsẹwọnsẹ to wáye láàrin Barcelona àti Liverpool.
36 Kúrò ní ilé àti ibùgbé rẹ, bíkòṣe nígbàtí ìwọ bá fẹ́ láti rí àwọn ẹbí rẹ.
Àwọn ni wọ́n sọ fún ọba Ijipti pé kí ó dá àwọn eniyan Israẹli sílẹ̀.
Bakan naa ni ẹgbẹ agbesunmọmi Boko Haram naa n ṣọsẹ l'awọn ipinlẹ kan.
Ati pé kì í ṣe ẹ̀yin ni ẹ ni ara yín?
Ikede yii jẹ iyipada ikede ti wọn ti saaju fi sita pe awọn oju ọna kan yoo wa ni titi pa nigba ti Aarẹ Buhari ba wa fun ipolongo idibo ni papa iṣere agbegbe Surulere lọjọ ti.
Ilé ẹjọ́ yẹ àga mọ́ Ọba Ìkirè nìdí lẹ́yìn ọdún 27 lórí ìtẹ́ Ayédèrú Lọ́yà tó ń díbọ̀n gbowó lọ́wọ́ aráàlú bọ́ sí gbaga ọlọ́pàá Adari ikọ ọtẹlẹmuyẹ Dubai, ọgagun Jamal Salem Al Jallaf ni, awọn ri ẹri pe awọn ọdaran yii n gbimọran ọtẹ lati lu awọn eeyan ni gbajuẹ, ti iye owo rẹ to miliọnu lọna irinwo le marundinlogoji dọla.
Leyin ti Cobain kọ orin Nirvana lọdun 1987 lo di ojulumọ ninu orin takWo aṣasufe.
'Ilé orin wa tí Ajimobi tun kọ́ dára púpọ̀, ṣùgbọ́n a kò ní dẹ́kun òtítọ́'
Oríṣun àwòrán, STATE HOUSE Àkọlé àwòrán, Ọgbẹni Rex Tillerson ti de ni Ethiopia, Kenya ati Chad Minisita fun ọrọ ilẹ okeere lorilẹede Amẹrika, Rex Tillerson ti wa lẹnu abẹwo si ilẹ Afirika lati bi ọsẹ kan sẹyin.
Pupọ awọn to padanu ẹmi wọn jẹ ọmọ ileeṣẹ ọlọpaa ati ọmọ ogun Naijiria.
Gbogbo wa ni ọrọ yi kan.
Ṣugbọn ní tiwa, nípasẹ̀ Ẹ̀mí ni à ń retí ìdáláre nípa igbagbọ.
Ṣugbọn Jakọbu dáhùn, ó ní, “Ọmọ tèmi kò ní bá yín lọ, nítorí pé ẹ̀gbọ́n rẹ̀ ti kú, òun nìkan ni ó kù.
Ṣugbọn bí ẹrú Kristi, ẹ máa ṣe ìfẹ́ Ọlọrun láti ọkàn wá.
Oríṣun àwòrán, @sumner_sambo Ni oṣu Kẹrin, ọdun 2018 ni Melaye dede fo kuro ninu ọkọ to wa lori ere, eyii ti wọn fi n gbe lọ lati koju ẹsun kan ti wọn fi kan.
A sì níláti kọ́kọ́ dán wọn wò ná; bí wọ́n bá jẹ́ aláìlẹ́gàn, kí á wá fi wọ́n sí ipò diakoni.
N óo ṣàánú yín, n óo jẹ́ kí ó ṣàánú yín, kí ó sì jẹ́ kí ẹ máa gbé orí ilẹ̀ yín.
Lọdọ awọn agbabọọlu Tottenham, iwa yi ṣakoba fun aṣọle wọn ati Heung -min Son to gba kaadi pupa fun bi o ti ṣe gba Rudiger nipa.
ní ọjọ ́ tó Òòrẹ ́ fẹ ́ gbé ohun tí jìjì fẹ ́ ràn jù fún jìjì , gọngọ sọ lọ ́ jọ ́ náà .
Oríṣun àwòrán, Others Erebọọlu lo pọ ju laarin awọn ọmọkunrin gẹgẹ bi ere ṣiṣe, amọ awọn ere ọmọde wọnyiii wa ti wọn tun kundun lati ma a ṣe, paapaa ti wọn ba de lati ile iwe ati labẹ osupa lalẹ ti wọn ba de ile.
Nínú gbèsè Nàíjíríà, ₦121,000 ló kàn ẹnìkọ̀ọ̀kan, ṣó o ṣetán láti san tìẹ?
Wọn a máa fi àwọn ọba ṣe ẹlẹ́yà, wọn a sì sọ àwọn ìjòyè di àmúṣèranwò.
Free Pad: Scotland ti di orílẹ̀-èdè àkọ́kọ́ tó bẹ́rẹ̀ pínpín páàdì ǹkan osu fún gbogbo obìnrin lọ́fẹ̀ẹ́
Ninu atẹjade kan ti oluranlọwọ lori ọrọ iroyin si Atiku, Paul Ibe buwọlu, wọn ni ko si ohun to jọ bẹẹ.
Ẹwẹ, ni ipinlẹ Ogun, eeyan meje lo tun ko aarun naa bayii, mẹfa lati ipinlẹ Ekiti, marun un lati ipinlẹ Plateau, mẹrin lati ipinlẹ Rivers, Kano ni mẹta, Nasarawa ni mẹta ti Niger si ni meji.
Awọn ounjẹ to n ṣafikun síǹkì lara ni ẹja onipẹ, ara ẹran, eso, kaṣuu, eréè, miliki ati wara.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Akomolede ati asa Yoruba: Ẹ wá kọ́ nípa àpòtí ìṣura èdè wa lórí BBC Yorùbá Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Access Bank: Babaláwo ní òun yóò t'ọwọ́ Ifá bọ̀ọ́, tí Access Bank kò bá dá owó ìyá òun pádà21 Ògún 2020 5:58 Fídíò, Akomolede ati asa Yoruba: Ẹ wá kọ́ nípa àpòtí ìṣura èdè wa lórí BBC Yorùbá, Duration 5,5820 Ògún 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Sójà obìnrin lù mí lálù bami nílùú Ibadan Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ìgbátí ìgbámú àná látọwọ́ sọ́jà obìnrin ti bá arákùnrin náà dé iléèwòsàn Makinde sọ pe, bo tilẹ jẹ oun kii ṣe akọbi iya naa, awọn eeyan maa n pe ni mama Ṣeyi.
”Aare wa dupe lowo gbogbo omo egbe APC fun atileyin won fun egbe naa, lai wo esi idibo egbe ti o waye.
Ẹgbẹ́ Àwọn Àjọ tí ó ń ṣe Àmójútó ìwàlálàáfíà Àwọn ọmọdé ní Burundi jábọ̀ pé wọ́n ti fi akẹ́kọ̀ọ́ kan tí ó jẹ́ ọmọ ọdún mẹ́tàlá sílẹ̀ lẹ́sẹkẹsẹ̀ nítorí pé ó ṣì kéré, kò sì tí ì tó ọdún mẹ́ẹ̀dógún.
Wọ́n búra pé àwọn kò ní jẹun, bẹ́ẹ̀ ni àwọn kò ní mu omi títí àwọn yóo fi pa Paulu.
Nigeria ti rọ ijọba apapọ atawọn ti ipinlẹ lati dẹkun fifi ipa le awọn eeyan kuro nibi kan tabi ominiran.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ondo state: Bàbá ọlọ́mọ méjì kú sínú àgbàrà òjò nílùú Akure 28 Owewe 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Omi ti gbe baba ọlọmọ meji kan lọ nilu Akurẹ lẹyin ti ojo arọọrọda kan rọ lalẹ ọjọ Ẹti.
Ajọ̀ NBC ni ileesẹ igbohunsafẹfẹ Ekiti yoo si wa ni titi pa fun igba diẹ na.
Ó dáhùn ó ní ikú ni o ń lé òun, o sì tọka sí igi ìrókò kan, ó ní abẹ́ igi náà ni ik;u wà, bí wọ́n bá fẹ́ mọ ikú kí wọ́n lọ sí ìdí ìrókò náà.
Ó lè rí ìrànwọ́ fún àwọn tí ó ń bá ìparaẹni fà á àti àwọn tí ó wà nínú ìbàjẹ́ ọkàn.
Aseyọri yi waye lẹyin ti Bournemouth ati Watford f'oju Chelsea gbo'lẹ ninu ifẹsẹwọnsẹ meji ti wọn gba sẹyin, eleyi ti o fi jẹ ọran-an yan fun wọn lati jawe olubori ninu ifẹsẹwọnsẹ naa.
 láyọ ̀ ọ ́ nú tó jẹ ́ olórí wọn náà ti bọ ́ sórí àga rẹ ̀ .
Wọn á máa bi wọ́n pé “Kí ló dé tí bíríkì tí ẹ mọ lónìí kò fi tó iye tí ó yẹ kí ẹ mọ?
, ni eyi ti yoo se je ki ipinnu rere ti oun ni lokan wa si imusẹ.
Abacha pé ogún ọdún ní sàréè Small Doctor, Afolayan bá Buhari ṣínu ààwẹ̀ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Fídíò BBC yọ àwọn èèyàn FIFA níṣẹ́ ṣááju Russia 2018 Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Agbẹnusọ ileeṣẹ ọlọpaa ipinle Eko, Muyiwa Adejobi ṣalaye pe awọn ti da ọlọpaa to ṣiṣẹ ibi náà mọ ṣugbọn ko si labẹ ileeṣẹ ọlọpaa ipinlẹ Eko.
Dapọ Abiọdun tun tirakalọdun 2015, to si tun pada dije sile aṣofin agba fun saa keji ni ẹkun ila oorun Ogun labẹ ẹgbẹ oṣelu APC, amọ to fidi rẹmi.
Awọn afẹhonuhan ni ko si idi kankan to fi yẹ kaa ni awọn ofin wọnyii.
Àtíkù: Ọbásanjọ́ kìí se Ọlọ́run tó leè ní kí ń má di ààrẹ
Lẹ́yìn ìgbà díẹ̀, Josẹfu wu aya ọ̀gá rẹ̀, ó sì bẹ̀rẹ̀ sí rọ̀ ọ́ pé kí ó wá bá òun lòpọ̀.
Lati oṣu kẹta ọdun 2020 ni ijọba ti ni ki wọn sọ agadagodo sawọn Mọṣalaṣi ati Ṣọọṣi nitori ajakalẹ arun Covid-19.
Ẹ múra, kí ẹ sì ṣe ọkàn gírí, nítorí pé bẹ́ẹ̀ ni OLUWA yóo ṣe sí gbogbo àwọn ọ̀tá yín, tí ẹ̀ ń bá jà.
Ó sọ fún Solomoni ọba pé, “Kò sí irọ́ ninu gbogbo ohun tí mo ti gbọ́ nípa rẹ ati nípa ọgbọ́n rẹ.
Awọn aworan tuntun ti wọn ya lati ori itakun agbaye laarin ọjọ kẹtadinlọgbọn osu kẹfa si ọjọ Kejila osu keje ọdun 2020, lo ṣe afihan bi agbega ṣe n ba odiwọn omi ti adagun odo naa n fa ọwọ rẹ sẹyin.
O fikun wi pe nitori otutu, ẹfọri ati ara riro wa lara awọn apẹrẹ to ma n fi aisan iba han lo jẹ ki awọn eniyan ti ojo ba pa, ti aisan iba si ti wa lara wọn sọ wi pe ojo ma n fa aisan iba.
Ẹ wo fidio yii lati mọ iru ara ti Chinonso n fi bọọlu da nidi ege gige.
Alimi sọ loju opo Instagram rẹ pe, ko si ọna mii lati ṣayẹyẹ ọdun kẹrin igbeyawo oun ati Davis, ju bi awọn ṣe ṣẹṣẹ ra ile keji niluu London.
Terry Waya tó jẹ́ ìlúmọ̀ọ́ká olówó, lásìkò tó n sọ̀rọ̀ lórí ayélujára instagram pẹlú olóyè Dele Momodu, sàlàyé nipa ètó tó ni nílẹ̀ fún Erica, tiwọ́n le kúrò nílé lọ́lọ́ ọjọ Aiku.
Àjọ tó ń mójútó àyíká l'Eko mú 123 ọlọ́kadà tó ń bọ̀ láti Jigawa Ọwọ́ EFCC tẹ ọ̀kan lára àwọn ti FBI fi èsún jìbìtì kàn!
Bákan náà ló tún ké sí à\\won ajọ kan tii ṣe ti ìjọba bí Islamic Human Right Commission (IHRC) àti àwọn ọmọ ẹgbẹ́ Shia míràn pẹ̀lú èròngbà láti dúrò sibẹ fún ààbọ tí yóò si mórí lé orílẹ̀-èdè míràn tó ba yá.
Peter Fatomilola ní àìsí ẹ̀kọ́ ń mú káwọn òṣèré tíátà ó máá ṣe oun tí kò tọ́.
Ajọ Iṣọkan Agbaye, UN ti fi lede pe ida aadọrun iye awọn eniyan lagbaye ni wọn ṣi n ṣe idẹyẹsi fun awọn obinrin lagbaye.
NLC: A ó gbé ìpínlẹ̀ tí kò bá san ₦30,000 owó osù tuntun lọ sílé ẹjọ́
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Iyalode Ibadan: Olubadan jáwé oyè lé Ìyálóde tuntun lórí 12 Agẹmo 2019 Oríṣun àwòrán, Olubadan Palace Olubadan ilẹ Ibadan, Ọba Saliu Adetunji, Aje Ogungunniso ti jawe oye fun Iyalode tuntun fun ilẹ Ibadan, Agba oye Theresa Laduntan Oyekanmi.
A gbọ́ ariwo ogun ati ìparun ńlá, ní ilẹ̀ náà.
Àwọn ọ̀tọ̀kùlú sì ńṣe fàájì bí agbára-a wọ́n ti mọ.
Ìbeèrè ti wọ́n bèrè ni pé, Ah!
Nítorí Johanu dé, kò jẹ, kò mu.
Gẹ́gẹ́ bí ìwádìí náà ṣe sọ, àwọn onímọ̀ tí kọ́kọ́ gbé ọ̀rọ̀ náà yẹ̀wò nínú yàrá àyẹ̀wò, kí wọn to lọ ṣe ìwádìí láàrín àwọn àdàn náà.
Ǹ jẹ́ o mọ àwọn èèyaǹ wọ̀nyí tó jà fún òmìnira Nàìjíríà?
Ṣugbọn, mo ma n sọ fun pe ko ṣe e ṣe.
Saulu tọ Samuẹli lọ, lẹ́nu ibodè, ó bèèrè lọ́wọ́ rẹ̀ pé, “Jọ̀wọ́, níbo ni ilé aríran?
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ibadan Murder: Oyún oṣù méje ló ń bẹ nínú Azeezat, kí wọ́n tó f'òkúta fọ́ ọ lórí Bakan naa lo gbiyanju ati pa Adeọla Azeez ati ọmọ rẹ obinrin Dọlapọ Oyeyẹmi ti ori ko yọ.
” Ìyapa bá bẹ́ sáàrin wọn.
òun nìkan ṣoṣo ni ó dá ojú ọ̀run tẹ́ bí aṣọ,tí ó sì tẹ ìgbì omi òkun mọ́lẹ̀.
Nígbà náà ni mo ké pe OLUWA,mo ní, “OLUWA, mo bẹ̀ ọ́, gbà mí!
 Ẹ jẹ ka ranti pe idibo ṣe pataki, ninu ti awọn ondibo ti n fi ẹtọ wọn han gẹgẹ bi alẹnulọrọ pataki ninu iṣakoso ijọba tiwa-n-tiwa”.
Taiwo níṣk ni Lekki Toll gate Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Mo ní àṣírí ìyá tó fẹ́ ọmọ rẹ̀ láya fún Boko Haram torí ẹbí rẹ̀' Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Fashola EndSARS Protest: Fashola rí kámẹ́rà he ní ibùdó ìṣẹ̀lẹ̀ Lekki Tollgate, àwọn ọmọ Nàìjíríà bá figbe ta26 Ọ̀wàrà 2020 2:15 Fídíò, The New Pandemic: Kíni àwọn onímọ̀ sáyẹ́ńsì ń sọ nípa rẹ̀?
Ìyàtọ ̀ maa ń wà fún àwọn ènìyàn bíi 95 % lẹ ́ yìn ọjọ ́ mẹ ́ wá tí wọ ́ n bágba ìtọ ́ jú .
Kedere la ri arakunrin kan to wọ aṣọ ọlọpaa ti o fẹ gba owo ti a fura si pe o jẹ abẹtẹlẹ lọwọ awakọ kan ti a ko ri oju rẹ.
Lọ se oúnjẹ tí o fẹ́ sè, ṣugbọn kọ́kọ́ tọ́jú díẹ̀ lára rẹ̀, kí o sì gbé e wá fún mi.
Ero awọn ikọ osisẹ BBC Yoruba Adedayo Owolabi: Mo ri ileesẹ agbounsafẹfẹ BBC gẹgẹ bii ibudo atọnisọna taa ba n sọrọ nipa eto igbohunsafẹfẹ lode oni."
eto ilera to pe ati ogbon, imo ati oye lati fi mu idagbasoke ba orile ede
"O ni ""mo n bẹbẹ nitori awọn ọrọ ti mo sọ nigba naa ati fun ọrọ abuku to ta ba Biṣọpu David Oyedepo ninu fidio naa""."
“Bi a se n sajodun Maulud, Nabiyy, mo ro awon musulumi lati lo anfaani yii lati fimo sokan, ki won si tun fi emi ife han si ara won ,bi a se n sunmo eto idibo odun to n bo ni 2019.
 A o maa fito yin leti bi ioade
Afurasí ikú ọ̀wọọ̀wọ́ l'Akinyele jápa mọ́ ọlọ́pàá lọ́wọ́ Wo ọmọ Nàíjíríà tí wọn fi pósí ‘₦34m’ sin Yéèpà, òfin ìtakété síra ẹni forí ṣánpọ́n lásìkò ọdún Osun Osogbo Ẹ fura, iyọ̀ onímájèlé tó dóde ti gbẹ̀mí èèyàn méje!
O ni ọjọ Aiku ni ọkọ oloogbe naa atawọn mọlẹbi gbe oku rẹ Nigba ti ikọ BBC News de ile oloogbe naa lagbagbe Bourdilourn ni ilu Eko lowurọ Ọjọ Aje nibi ti awọn eeyan leni ejeeji ti n wọle ba wọn daro.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ààrẹ Akufo-Addo la Mahama mọ́lẹ̀ wọlé ìbò ààrẹ Ghana fún sáà kejì Ẹ̀yin tí ẹ máa ń bú àwon tó sanra ni ẹ ń jẹ́ kí wọ́n ronú pa ara wọn - Eniola Badmus Ilé aṣòfin kò láṣẹ kankan láti pe ààrẹ Buhari wá rojọ́ lórí ọ̀rọ̀ ètò àbò - Malami Ṣé lóòtọ́ ni tírélà ti gba ààrín Ronke Odusanya àti bàbá ọmọ rẹ̀, Jago?
Ijọba Oyo ni awọn gbe igbesẹ yii fun irọrun awọn akẹkọọ lo mu ki awọn ṣe gbe igbese naa, ki saa naa le lọ ni irọwọ-rọsẹ.
Òótọ́ ni mo sọ, nítorí irọ́ kò yẹ ọmọ ènìyàn, irọ́ kò yẹ ọmọ ẹbọra.
Agbenuso fun ile-ifowopamo CBN, Isaac Okoroafor so ninu atejade kan lojo-Aiku pe, alekun ti ba owo to wa ni ipamo naa  bi bilionu meta o le meji owo dollars3.
Agbabọọlu iwaju Richalison to jẹ omọ orilẹede Brazil lo gbayo akọkọ wọ le ni bi iṣẹju kan din laadọta.
Africa in Pictures: Àwọn àwòràn tó ṣàrà ọ̀tọ̀ láti ilẹ̀ Afirika
” Pẹpẹ náà wà ní Ofira ti ìdílé Abieseri títí di òní olónìí.
Ọmọ ọba yìí kò jà á ní iyàn rárá ó bá a gbé e-wọ́n  jọ ń lọ.
May 29: Àwọn ọmọ Nàìjíríà sọ irú àwọn adarí tí wọ́n ń fẹ́
Eléyìí mú ìrònú bá mi mo sì bẹ̀rẹ̀ sí kábàámọ̀ ara tí ó ré mi tí mo fi hu irú ìwà òmùgọ̀ bẹ́l.
O tún fi kúun pe, awọn ò ni ìdí kankan lati gbàgbọ́ pe lara awọn ọmọ náà ti jáláìsí.
Wọ́n yí orúkọ ìlú náà pada kúrò ní Laiṣi tí ó ń jẹ́ tẹ́lẹ̀, wọ́n sọ ọ́ ní Dani gẹ́gẹ́ bí orúkọ baba ńlá wọn tí ó jẹ́ ọmọ bíbí Israẹli.
Wọ́n múra, wọ́n gbọ̀nà Ijiptiláì bèèrè ìmọ̀ràn lọ́dọ̀ mi.
Goroyo ní, bíi ìdá mẹ́sàń nínú mẹ́wáà ìrẹsì tí ọmọ Naijira ń jẹ ní àwọn àgbẹ̀ orilẹ̀èdè yí ń gbìn fúnra wọn.
Ewe, ninu ipo ate FIBA, Naijiria ni o kere julo laarin awon akegbe won ti won yoo maa koju.
Iṣẹ́ àgbẹ̀ ni iṣẹ́ pàtàkì jùlọ tí àwọn ènìyàn ìlú Ìjẹ̀bú - Jẹ̀ṣà ń ṣe.
Bí wọn bá jẹ́ wolii nítòótọ́, bí ó bá jẹ́ pé èmi OLUWA ni mo fi ọ̀rọ̀ sí wọn lẹ́nu, ẹ ní kí wọn gbadura sí èmi, OLUWA àwọn ọmọ ogun, kí n má jẹ́ kí wọ́n kó àwọn ohun èlò tí ó kù ní ilé OLUWA ati ní ààfin ọba Juda ati ní Jerusalẹmu lọ sí Babiloni.
Mo rò pé yóo pada tọ̀ mí wá, lẹ́yìn tí ó bá ṣe àgbèrè rẹ̀ tán ni; ṣugbọn kò pada; Juda arabinrin rẹ̀, alaiṣootọ sì rí i, 
Mo gbà á lọ́wọ́ wọn pẹlu àwọn ọmọ-ogun mi nítorí mo gbọ́ pé ọmọ-ìbílẹ̀ Romu ni.
apapo lorile ede yii ,a jẹ pe oruko omo lo n romọ ,Ọlọrun bori (Godwin ) , iyen tun ja si pe ogbeni
South West Security: Ọlọ́pàá Ogun àti Ọ̀ṣun ni àwọn kò lọ́wọ́ nínú àjọṣepọ̀ ọ̀hún
Obinrin kan ti ẹnikẹni ko i ti mọ orukọ rẹ lo ti fẹsẹ fẹ bayii nigba ti wọn ri oku okunrin kan ti orukọ rẹ n jẹ Raji.
Búrẹ́dì Brazil: Èròjà protein tó wà lára Aáyán dára fún ènìyàn
22 Kí májẹ̀mú mi ti ayérayé lè fi ẹsẹ̀ múlẹ̀.
Alufa naa ni daju daju Ọlọrun lo gba ẹnu Obasanjo sọ ọrọ yii tori ohun ti awọn alufa ti n tẹnu mọ lati ọjọ yii gan ni Obasanjo ṣẹṣẹ sọ jade yii.
Wọn óo mọ òkítì sí ara odi rẹ, wọn yóo ru erùpẹ̀ jọ, wọn óo fi la ọ̀nà lẹ́yìn odi rẹ, wọn óo sì fi asà borí nígbà tí wọ́n bá ń gun orí odi rẹ bọ̀.
Àkọlé àwòrán, Ni Asokoro ni tokunrin tobinrin ti jade wa fun iwode lodi si pasito COZAyii Awọn ikọ #Churchtoo ni wọn n ṣeto iwọde ti Abuja ti wọn fi ni ki pasitọ Fatoyinbo fipo rẹ silẹ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Kwara: Fọ́fọ́fọ́ ni mọ́ṣáláṣí kún tí ìlànà ìjìnàsíraẹni sí forí ṣánpọ́n lẹ́yìn tí ìrun Jímọ̀ bẹ̀rẹ̀ padà ni Ilorin 15 Òkùdu 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 19 Òkùdu 2020 Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Kwara: Fọ́fọ́fọ́ ni mọ́ṣáláṣí kún tí ìlànà ìjìnàsíraẹni 'social distancing' sí forí Witiwiti lawọn olujosin ẹlẹsin Musulumi ṣi bo awọn Mosalasi nilu Ilorin pẹlu bi ijọba ti ṣe faaye gba ijọsin lawọn Mọsalasi ati ile ijọsin Kristẹni pada.
Eto ẹkọ lorilẹede Nigeria ni a o kọkọ ma a gbeyẹwo.
Inú pẹ̀gànpẹ̀gàn kì í dùn sí ìbáwí,kì í bèèrè ìmọ̀ràn lọ́wọ́ ọlọ́gbọ́n.
Gbọ́ tèmi OLUWA, àre ni ẹjọ́ mi; fi ìtara gbọ́ igbe mi.
Latigba to ti di ọmọ ọdun mẹrin loti bẹrẹ sini kopa ninu fiimu ni ede Tamil, Telugu, Malayalam, Kannada ati Hindi .
Aarẹ ọna Kakanfo naa dupẹ lọwọ Ambọde fun ipa rẹ lori gbigbe aṣa ati iṣe Yoruba larugẹ nipa ede Yoruba.
Ó ní ìwa yíì ti wọ́pọ̀ jù tí àwọ́n olùkọ́ wọn sì ńbá wọn lò pọ̀.
Basilai ti darúgbó gan-an, ẹni ọgọrin ọdún ni.
Ẹgbọn rẹ obinrin yii, Firdausi Okezie, wa nileewe giga fasiti lasiko ti iṣẹlẹ yii waye.
 Ìlosíwájú ti dé bá imọ ̀ ẹ ̀ rọ láwùjọ wa .
Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 3 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 5 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Awọn elewe ọmọ yii ni ìrírí to pọ̀ lori oyun ninu, ọmọ bibi, ati ọmọ titọ ninu igbagbọ awọn alaboyun kan.
Nilẹ kaarọ o jiire, paapa nilu Ibadan, n se ni iku n pa awọn eeyan jankanjankan bi ẹni pa adiẹ.
Kii kuku ṣe arosọ ileeṣẹ iroyin BBC News Yoruba lọrọ yii; gomina Seyi Makinde funra rẹ lo sọ ọrọ yii lasiko to fi n ba awọn eeyan sọrọ nibi ifarahan rẹ akọkọ ni itagbangba lẹyin to bọ lọwọ arun Coronavirus.
Àwọn ẹnìk jejì mi jẹ́ oúnjẹ náà ṣùgbọ́n èmi jẹ lára àkàrà tí ìyá mi mú láti isà òkú wá fún mi.
"Oríṣun àwòrán, @juwon2017 ""Ni ilana asa ibilẹ wa, Ọlọwọ tuntun gbọdọ mu ida kan ni Oke Mapo, ida to ba si mu, ni igbagbọ wa pe yoo sọ bi akoko rẹ lori itẹ yoo se ri."
Àwọn mejeeji ni yóo jóná pọ̀,kò sì ní sí ẹni tí yóo lè pa iná náà.
Orisirisi alaye si ni awọn eeyan ti fi sita lati na ika si awọn ti wọn lero pe o lọwọ ninu iku rẹ.
Oríṣun àwòrán, Reuters Olori ijọba orilẹede Germany, Angela Merkel naa ki Johnson ku oriire, bakan naa lo sọ pe ilẹ Germany ati ilẹ Geẹṣi yoo tubọ jọ ni Narendra Modi Olootu ijọba India, Narendra Modi naa gboṣuba fun Ọgbẹni Johnson, bakan naa lo ni oun yoo maa foju sọna fun ajọṣepọ tuntun laarin laarin ilẹ Gẹeṣi ati orilẹede India.
Mẹsan an mẹwaa ni akọnimọọgba Arsenal, Mikel Arteta n ki ẹlẹsẹ ayo, Aubameyang fun ipa ribiribi to ko ninu ifẹsẹwọnsẹ Community Shield.
OLUWA Ọlọrun ti fi ìwà mímọ́ rẹ̀ búra pé, “Ọjọ́ ń bọ̀, tí wọn óo fi ìwọ̀ fà yín lọ, gbogbo yín pátá ni wọn óo fi ìwọ̀ ẹja fà lọ, láì ku ẹnìkan.
Orisun: Speedtest Global Index latọwọ Ookla.
; Koda, o ṣeniyan daadaa ninu itan naa nibẹrẹ, nitori ori ti ko ba jẹ eeyan takuntakun, ko ni de ibi giga to ku si.
APCOjogbon Osinbajo ni idagbasoke ti de ba eto oro aje yii,
"A si ti n ṣe ayẹwo mẹẹrin lara wọn fun igbesẹ ti o kan""."
Eyi lo mu ko darapọ mọ ijọ Cele kan ti ko jinna si ile wọn.
N óo dúró de OLUWA ẹni tí ó fojú pamọ́ fún ilé Jakọbu, n óo sì ní ìrètí ninu rẹ̀.
Gbogbo awọn iroyin ti kii ba se ojulowo ti eeyan kan ba gbe jade, ni Facebook yoo maa sun si isalẹ patapata loju opo ẹni to kọọ, ti ko si ni lee maa se alabapin iroyin naa bo se yẹ.
50k), ni wọn yoo fun ni paali tikẹẹti lati maa mu lọ fi jẹun ni buka oúnjẹ ile ẹkọ wọn.
"Fun awọn ileewe girama, awọn akẹkọọ wọn le pada sileewe, lati le pari idanwo wọn, ki wọn o si tun pada lọ ọ joko sile.
Manchester City pàdí ọrẹ dà f'ogun ẹ̀yìn ja Chelsea Jose Mourihno fakọ yọ pẹ̀lú bí Tottenham se na West Ham!
Oluwo woju Ọọni niwaju awọn lọba-lọba
Ohun tó ṣe pàtàkì ni pé ẹni tó bá ṣẹ̀, a níláti tọ ìlànà àátẹ̀ẹ́lé lábẹ́ òfin."
ṣugbọn ko le si afikun owo fun orile ede naa nitori gbese to si wa lọrun won.
O ni ko pẹ pupọ ni ikan lara awọn oṣiṣẹ wa ri wi pe obinrin naa sa sita lojiji lọna ti o mu ifunra dani.
Ará ìlú fárígá, wọ́n wọ́ alàkóso ìlú nilẹ́ pẹ̀lú ọkọ̀ UNILAG ní kí olùkọ́ míì, Samuel Oladipo to ń bèèrè ìbálòpọ̀ lọ́wọ́ akẹ́kọ̀ọ́ lọ fìdí mọ́lé Òpópónà àti afárá 19 níjọba fẹ́ ṣe nínú àbá ìṣúná ọdún 2020 Ǹkan mẹ́jọ tó máa kọ́kọ́ ṣẹlẹ̀ kí olólùfẹ́ méjì tó pa ara wọn 4.
Idi ree ti aarẹ tẹlẹ ni Naijiria, Oloye Olusegun Obasanjo fi gunle ọsin ẹja bii ẹgbẹrun lọna aadọta lati dena iyan to le waye lẹyin arun Coronavirus.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Niyi Akinmolayan tó ṣe fíìmu àwòrán-dèèyàn Cartoon nípa COVID-19 tó la ayé já ní N Lara awọn eeyan ọhun to ba BBC sọrọ ni ti Coronavirus ko ba pa wọn, ebi lo ma pa wọn sile, nitrori naa ko si ohun miran ti wọn le ṣe ju ki wọn jade.
Lọwọlọwọ ni ẹnu wọn kò kò lori sisan owo sapo awọn alaga ijọba ibilẹ bi o ti yẹ ni eyi tijọba apapọ ṣẹṣẹ fẹ mojuto lasiko yii.
“Nítorí náà, ẹ níláti tẹ̀lé ìlànà mi, kí ẹ sì pa òfin mi mọ́, kí ẹ lè máa gbé inú ilẹ̀ náà láìséwu.
15 Òkùdu 2020 Kaakiri agbaye ni wahala awọn ọlọpaa ti n waye koda eyi ko ys awọn orilẹ€de ti aye n fi oju wo pe wọn ti goke agba silẹ.
O sọ siwaju si pe, ti ijọba ba ṣe bẹ, iru ijiya naa yoo sọ iṣoro ọhun di abala meji ni.
Ní tèmi, gbogbo ọ̀ràn yìí pátá yóò jẹ́ yíyẹ̀ lulẹ̀ bí a bá le è ṣe iṣẹ́ àkọ́bẹ̀rẹ̀ ti àtúnṣe sí ìwé òfin.
Èèyàn mẹrin láti ọdọ Adeleke ati Ogunbiyi ni ìrètí wa wipe wọn yóò yan láti jo fọrọ jomitoro ọrọ lórí aawọ òhun.
Wo ìtàn ayé gbajúmọ̀ adigunjalè méje nílẹ̀ Yorùbá Gbajabiamila balẹ̀ sí Ghana láti pẹ̀tù sááwọ̀ láàrin Nàìjíríà àti Ghana Ẹgbẹ́ òṣìṣẹ́ NLC, PDP, MAN fọnmú lórí epo bẹntiró tó dí N162 Kí ló wá nínú àbádòfin pínpín omi àti àwọn ǹkan inú omi tó ń mú awuyewuye wa?
Oríṣun àwòrán, Others Ọmọ bibi ipinlẹ Imo ni Osadebe, eyi si lo mu ki o tẹsẹ ile bọ ọrọ aisan ti o si gba ilu wọn Isiala Mbano lọ fun itọju.
Agbenusoro fun ile igbimo asoju-sofin, ogbeni Yakubu Dogara ti ro ile-ise alaabo lorile-ede yii lati ri daju pe aabo ti o peye wa fun asofin Dino Melaye to n soju eka iwo-oorun ipinle Kogi ki o to di igba ti o lo ile ejo.
gbogbo  Ipinleto wa lorile ede Niajiria
Ó dàbí àwọ̀n tí a dà sinu òkun, tí ó kó oríṣìíríṣìí ẹja.
N óo mú hílàhílo bá ọmọ eniyan, kí wọ́n baà lè rìn bí afọ́jú.
Ikọ agbabọọlu Super Eagles ti orilẹede
Lọsẹ to kọja ni awọn ọmọ Naijiria figbe ta pe awọn ko lee gba bi orilẹede Ghana ṣe n wọ awọn nilẹ ti wọn si n foju keree wọn.
Kí a tó sanwó ajínigbé ní àwọn agbófinró dóòlà ọmọ Ọffa mẹ́fà -ODU Gbàgbé ẹ̀sọ́ ara $40m rẹ pátápátá - Ilé ẹjọ́ sí Dienzani Ohabunwa sọ fun ile ẹjọ pe, INEC yọ awọn ibo kan ṣeyin nigba ti wọn fẹ ka ibo naa, ati pe, ọpọlọpọ eeyan to yẹ ki wọn dibo ni ajọ INEC ko gba laaye lati dibo.
Oríṣun àwòrán, Facebook/Femi Adesina Buhari rọ awọn ọmọ ẹgbẹ APC lati ṣa ipa wọn, ki wọn si rii pe APC lẹgbẹ to siwaju ninu awọn ẹgbẹ oṣelu to wa lẹkun wọn.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Nigeria Pensioners: Wàhálà àyẹ̀wò iwé ìfẹyinti yì ti pọ̀jù Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Nigeria Pensioners: Wàhálà àyẹ̀wò iwé ìfẹyinti yì ti pọ̀jù 28 Agẹmo 2019 Ara pupọ ninu wọn lo ti di ara agba ti nkan ko rọrun fun mọ.
“Ṣe ìgbàyà ìdájọ́, èyí tí wọ́n ṣe iṣẹ́ ọnà dáradára sí lára, gẹ́gẹ́ bí iṣẹ́ ọnà ara efodu náà: wúrà, aṣọ aláwọ̀ aró, aláwọ̀ elése àlùkò, aláwọ̀ pupa ati aṣọ ọ̀gbọ̀ tí ó ní ìlà tẹ́ẹ́rẹ́tẹ́ẹ́rẹ́, ni kí o fi ṣe é.
Amọ ṣa, ni ọjọ Iṣẹgun, ọjọ kọkanla oṣu kẹjọ ni afurasi naa sa lọ kuro ninu ahamọ ọlọpaa, ti awọn ọlọpaa si ni awọn ṣi n wa a.
Lati kekere ni aisedede ti o n waye lawujọ ti jẹ nnkan to n kan ni ominu.
A Fi Ijipti Wé Igi Kedari.
Ẹni Ọgọrin ọdun ni alagba naa ki o to dagbere laye.
"A ń fikunlukun pẹ̀lú FBI láti mú àwọn ""Yahoo Boys"" tó kù- EFCC Nínú gbèsè Nàíjíríà, ₦121,000 ló kàn ẹnìkọ̀ọ̀kan, ṣó o ṣetán láti san tìẹ?"
Sri Lanka attack: Orílẹ̀èdè mẹjọ, yàtọ̀ sí Sri lanka ló pàdánù èèyàn wọn nínú ìṣẹ̀lẹ̀ náà
Buhari, Makinde, Sanwo-Olu kẹ́dùn pẹ̀lú ẹbí Tola Oyediran, àkọ́bí lóbìnrin tí Obafemi Awolowo bí tó papòdà Wo àfiwé owó oṣù Ọlọ́pàá Nàìjíríà pẹ̀lú akẹgbẹ́ wọn lókè òkun Ọkọ̀ akẹ́rù tí ìjánu rẹ̀ já ló kọlù ọkọ̀ agbépo tó fa ìjàmbá iná ní Otedola- LASEMA Ẹ foríjìn wá ọmọ Nàìjíríà, mó mọ̀ pé ẹ̀ ń bínú tórí a kò tètè gbé ìgbésẹ̀ lórí ọ̀rọ̀ EndSARS- Osinbajo O fi kun un pe ifẹhonu han alaafia ni oun fẹ eleyi to ni ko ṣajeji si ilana ijọba awarawa.
Aarẹ tuntun naa naa lo fi ẹyin aarẹ Donald Trump janlẹ ninu eto idibo aarẹ to waye lọjọ Isẹgun amọ Trump ni oun yoo tako esi ibo naa.
Ẹ ma se sa garri sita gbangba.
Abba Kyari: Ta a ni yóò rọ́pò Abba Kyari gẹ́gẹ́ bi olórí òṣìṣẹ́ Buhari?
Ogun abẹ́lé tó ń ja Akeredolu l'Ondo, òní la ó mọ̀ bóyá yó borí rẹ̀ Àwọn tó jí àwọn akẹ́kọ̀ọ́ GSSS gbé ní Kankara ti kàn sí wa - Masari Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ọgbà ẹ̀wọ̀n ni wọ́n ti já àbálé Esra lábẹ́ àwáwí àyẹ̀wò wúndíá Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Coronavirus in Lagos: Sanwo-Olu ti ilé ẹ̀kọ́ pa, fòfin de ayẹyẹ àdúgbò àti òde fàájì torí ọwọ́jà àrùn19 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Ondo politics: Ilé ẹjọ́ da ìpèjọ́ pé Akeredolu kọ ló wọlé ìdìbò ìpińlẹ̀ Ondo nù16 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Sudan removed from terrorist list: America yọ Sudan kúrò nínú ìwé orílẹ̀-èdè tó ń ṣagbátẹrù ẹgbẹ́ agbésùnmọ̀mí lágbàyé14 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Kankara Abduction: Àwọn ológun ṣàlàyé ìdí tí wọ́n fi yọ̀nda àwọn tó jí àwọn akẹ́kọ̀ọ́ gbé.
 Coronavirus Cases in Africa:Ẹ wo ọ̀nà tí àwọn èniyàn ń gbà rí oúnjẹ̀ jẹ lásìkò àrùn Coronavirus Coronavirus: Opó afọ́jú kan sọ̀rọ̀ lórí ìnira tó ń kojú pẹ̀lúu coronavirus Dokita oníṣègùn oyinbo gan lo wu mi ki n ṣe lati kekere, nigba to ya ni ẹbun orin kíkọ jẹ jade lara mi, mo dara pọ mọ ẹgbẹ akọrin, lẹyin naa ni mo wa bẹrẹ ere apanilẹrin.
N kò fẹ́ kí ẹ rò pé mò ń fi àwọn ìwé tí mò ń kọ dẹ́rù bà yín.
Oniwasu ni Baba rẹ, o si wu ki ọmọ rẹ naa tẹle ipasẹ rẹ.
Aarẹ Buhari sọ pe iwa irẹlẹ ti Jonathan ni jẹ ohun manigbagbe eleyi ti yoo mu ilọsiwaju ati idagbasoke ba awọn iran to n bọ.
Fayemi je, koi se aimo foloko, oun le e fowosoya lori re wipe yoo sise bi ise,
Eyi lo mu ki a ṣe akọsilẹ diẹ lara ipenija to ṣeeṣe ki igbimọ tuntun yii koju.
“Bí ẹnìkan bá dẹ́ṣẹ̀ kan, tí ó jẹ́ pé ikú ni ìjìyà irú ẹ̀ṣẹ̀ tí ó dá, tí ẹ bá so ó kọ́ sórí igi, 
Igba akọkọ niyii ti yoo yọju si gbangba lati dun 2017 ti ileeṣẹ ologun Naijiria ti kọlu ilu abinibi rẹ, Afaraukwu, to wa ni ipinlẹ Abia.
Ifesewonse naa yoo bere gbara laago mejo aabo (8.
Àwọn iwin wá ní onírúúrú tiwọn.
FBI sọ pe Abbas jẹ ọkan lara awọn olori ẹgbẹ onijibi ori ayelujara, to pa ẹka kaakiri agbaye, ati kiko owo pamọ lọna aitọ.
Tí atẹ́gùn bá fẹ́, àwọn ewé wọ̀nyí á wá máa wọ́, wọ́n á máa rẹ̀ sílẹ̀ bí ẹni pé ó nrọ̀jò ewé ni.
Wọn ṣe ìdájọ́ ẹ̀wọ̀n ọdún marun fún.
Oríṣun àwòrán, Twitter Àkọlé àwòrán, Akojọpọ esi ayẹwo aarun Covid-19 ni orilẹ-ede Naijiria gẹgẹ bi ajọ NCDC ṣe n kede rẹ.
Bẹ́ẹ̀ ni Ẹ̀mí Mímọ́ sì kún inú wọn.
Ṣugbọn nígbà tí ìṣòro dé ba yín,ẹ bẹ̀rẹ̀ sí kígbe pè mí pé kí n dìde, kí n gbà yín là.
Aaroni dá Mose lóhùn pé, “Wò ó!
Irin ni wọ́n fí kọ́ ilé náà.
ogbon atinuda, awon to se onigbonwo eto naa tun so pe ’’ Anfaani ti eniyan yoo je nipa
Wọ́n rí mi lójú ọ̀nà, wọ́n ní kí n lọ pe bàbá àti ìyá mi wá.
Oríṣun àwòrán, Hujjaj in Masjid al Namirah, Arafat Ọjọ Arafa ni ọjọ kẹsan oṣu Zul-Hijjah, ni onka oṣù ojú ọrun.
 wọ ́ n gbàá ní ọ ̀ gá ní yiya ìhòhò ní gbogbo ilẹ ̀ yúróòpù .
Iroyin safihan pe, iyanselodi lati bi ojo meta ohun ti so ilu naa di asale, awon ile itaja wa ni titi pa, ko si irina oko loju popo bakan naa ni awon ile-ise ijoba naa wa ni titi pa.
Wakati meji meji ni wọn n jẹ ki awọn akẹkọọ lọ fọ ọwọ wọn nigba gbogbo.
Ọlọrun n fẹ Digbolugi Ololufẹ Ọgbẹni Trump kan lo n ṣe eto adura lọsọọsẹ fun atunyan rẹ to si ṣe ayẹyẹ ọjọ ibi Trump pẹlu ọpọlọpọ ọrọ iwuri loju opo Facebook.
Ọbasanjọ: PDP bẹ̀bẹ̀ lórí ìwà àìda wọn sí mi
Ìjọ Àgùdà dìbò pé kí àwọn baálé ilé tó ní ìyàwó má a jẹ àlùfáà ìjọ Olólùfẹ́ méjì jábọ́ láti àjà kẹsàn án lásìkò tí wọ́n n ṣe kerewà Ilé aṣọ̀fin Nàìjíríà ń gbèrò ẹ̀wọ̀n f'áwọn olùkọ̀ tó bá dẹnu ìfẹ́ kọ akẹ́kọ̀bìnrin Pápà mímọ́ gbarata lóríi ìpànìyàn Benue Loṣu keji ọdun ni awọn olori ijọ Aguda pe fun iyipada ofin yi lasiko ipade apero wọn.
Ọ̀rọ̀ Aisha Buhari sí Ramaphosa wú ọ̀rọ̀ síta lẹ́nu àwọn ọmọ Nàìjíríà Wọ́n jí ọmọ yìí gbé láti máa fi tọrọ bárà l'Eko Demilade Adepegba( NAIJIRIA) Ọmọ ọdún mẹ́wàá ni Damilola Adepegba, tó ń fi fèrè dá bí ẹdun, rọ̀ bí òwè!
Bí Hushpuppi ṣe tiraka rèé l‘Eko, kí ọlà ‘òjijì’ tó dé Àjọ NCDC kéde èsì àyẹ̀wò ènìyàn 575 tó tún ti ní ààrùn Coronavirus ní Nàìjíríà Magu lọ farahàn níwájú ìgbìmọ̀ tó ń ṣ'àyẹ̀wò EFCC, DSS kò mú un- EFCC Ọjọ́ Kẹrin oṣu Kẹ́jọ ni ìdánwò WAEC yóò bẹ̀rẹ̀ - Ìjọba àpapọ̀ Ki lo kọkọ ṣẹlẹ ki ọrọ yii to di ofin lónìí?
Yemi Osinbajo: Ènìyàn 108 lò kú ní ìsẹ̀lẹ̀ omíyalé ní Kogi
Kabiesi parọwa fun awọn eeyan pe ki onikaluku ṣe ohun to yẹ fun awọn alaini to wa nitosi rẹ.
” Ó tún fi kún un pé, “Wọ́n ń wa kẹ̀kẹ́ ogun wọn bíi Jehu, ọmọ Nimṣi, nítorí wọ́n ń wà á pẹlu ibinu.
Ìwọ tí o gbé ayé kalẹ̀ lórí ìpìlẹ̀ rẹ̀,tí kò sì le yẹ̀ laelae.
”OLUWA àwọn ọmọ ogun ló sọ bẹ́ẹ̀.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ọwọ́ tẹ ọkùnrin kan ní pápákọ̀ òfurufú l‘Eko tó ń kó ike ATM 2,886 lọ si Dubai Ọ̀kẹ àìmọye ẹ̀rọ àyẹ̀wò káàdì olùdìbò jóná mọ́lé l' Ondo Wo iye àwọn tó ti gbẹ̀mí ara wọn ní Nàìjíríà láàrin ọdún mẹ́rin ìjọba Buhari Gbèsè Nàìjíríà ti lé ní 18 tírílíọ́ọ́nù lábẹ́ ìṣèjọba Ààrẹ Buhari- DMO Wo bí iṣẹ́ abẹ wákàtí mẹ́fà, tí wọ́n fi dóòlà ẹ̀mí ìjàpá tí ọkọ̀ tẹ̀, ṣe lọ Kò sóhun tó ń jẹ́ ‘Captivus’ nílẹ̀ Oodua, mágùn ni mágùn ńjẹ́ - Babaláwo Wo àwọn obìnrin abúlé kan tó dáwó ra ọkọ̀ láti máa gbé aláboyún lọ ilé ìwòsàn Ìtàn rèé nípa bí Ogbomoso ṣe pa ọba, yọ nǹkan ọkùnrin rẹ jó kiri ìlú O ni ijọba oun yoo fi abadofin ti yoo yi orukọ papa iṣere naa pada si orukọ Yekini, ranṣẹ si Ile Igbimọ Asọfin ni ipinlẹ naa.
Ìyìn ni fún Ọlọrun, ẹni tíí ṣe olùdarí ohun gbogbo, lae ati laelae.
(CJTF) naa tun darapo mo won, eleyi ti won ko awon ohun ija oloro bi, ibon,
Ẹ má hùwà burúkú níwájú mi mọ́.
Nígbà tí ẹ bá kórè, ẹ óo pín gbogbo ohun tí ẹ bá kórè sí ọ̀nà marun-un, ìpín kan jẹ́ ti Farao, ìpín mẹrin yòókù yóo jẹ́ tiyín.
Ariwo ọkan-o-jọkan orin lo gba ẹnu gbogbo awọn alatilẹyin Sẹnetọ Kọla Balogun kan lẹyin idajọ naa.
Wọn gbe igbesẹ yii latari pe wọn ni ijọba ko ṣe ohun to yẹ fun awọn lẹyin ti wọn fun ijọba ni gbedeke ọjọ meje ki wn to gun le iyanṣẹlodi naa.
Lati igba naa ni Kalu ti kuro ni ọgba ẹwọn, to si ti bẹrẹ iṣẹ rẹ pada ni ile aṣofin orilẹede Naijiria.
Ẹni tí à ń wò ní áwòsọkun tí ń wo ara rẹ̀ ní àwò- rẹ́riǹ-ín ni Bádérù.
Gómìnà Keje – Ọ̀gá Adarioko Ojúomi Mike Akhigbe – Gómìnà fún ọdún meji – ọdú́n mọ́kànlélọ́gbọ̀n di ọdún mọ́kàndinlọ́gbọ̀n sẹhin
Ọwọ́ ọlọ́pàá tẹ ọmọ Britain tó ń ta kẹ́míkà gẹ́gẹ́ bi omi ìyanu LÀàrẹ Ilé Ẹjọ́ kòtẹ́milọ́rùn yọra rẹ̀ nínú ìgbẹ́jọ́ èsì ìdìbò ààrẹ Kò sí ààbò, kò síṣẹ́; Àwọn dókítà LUTH bínú tán Wọ́n jí ọmọ yìí gbé láti máa fi tọrọ bárà l'Eko Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Abdulfatah Ahmed: Àwọn Kwara fẹ́ dán ilé ọkọ kejì wo ni lásìkò yí Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
 gbọ ̀ gán lisabi jásí àyíká okobaba àti ọ ̀ sà .
Bùhárí: Gaddafi ló kọ́ darandaran ní ìwà ipá
Ọgbà òdòdó ni mo máa ń pè é.
Àwọn ọmọ Nàìjíríà ṣe ìwọ́de l'Osogbo lórí àfikún owó epo bẹntiróò Wo ohun tí ilé ẹjọ́ ní kí wọ́n ṣe fún Sunday Shodipe, afurasí ìṣekúpani l'Akinyele Ọwọ́ ọlọ́pàá tẹ afurasí olóògùn owó tó fẹ́ gé ọmú obìnrin kan nílé ìtura Awọn arinrinajo to m bọ ni Naijiria gbọdọ lọ soju opo lati forukọ silẹ: https://nitp.
Wọ́n rú àwọn eniyan ati àwọn àgbààgbà ati àwọn amòfin nídìí, ni wọ́n bá mú un, wọ́n fà á lọ siwaju àwọn ìgbìmọ̀.
”Tesiwaju si, gege bi gomina, maa ri daju lati gbe ijoba mi sile fun enikeni ti o ba jawe olubori ninu idibo gbogbogbo lọdun 2019 lai fa wahala kankan.
Wá kẹ́kọ̀ọ́ nípa ègé ọ̀rọ̀ ohùn Yorùbá tí a mọ̀ sí Sílébù Àwọn Olúkọ ìpínlẹ̀ Oyo fakọyọ lórí ètò Akọ́mọlédè àti Àṣà púpọ̀ Àwọn Olùkọ́ ìpínlẹ̀ Eko dárà lórí Akọ́mọlédè àti Àṣà lórí BBC Àṣà Oge Ṣíṣe ní Akọ́mọlédè BBC Yorùbá ń gbé yẹ̀wò lónìí, Ó yá, iṣẹ́ ti bẹ̀rẹ̀.
Ara mi yóo rọlẹ̀, inú kò sì ní bí mi mọ́.
Lọwọlọwọ awọn ọmọ ileewe girama to wa ni kilaasi aṣekagba nikan lo n lọ ileewe kaakiri gbogbo ipinlẹ mẹrindinlogoji Naijiria lati ọjọ kẹrin oṣu kẹjọ ọdun 2020 lati le kọ idanwo wọn bii WAEC ati NECO.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ore Helicopter: Iléeṣẹ́ ọkọ̀ òfurufú ní wọn fi ẹlikọ́pútà tó dá àríyànjiyàn sílẹ̀ dóòlà ẹmí ni 26 Òkùdu 2019 Àkọlé àwòrán, Elikoputa naa da wahala silẹ lẹyin to balẹ si aarin popo naa lati gbe eniyan kan Ileeṣẹ ọkọ ofururu kan ti sọ fun BBC wipe, aisan to ṣadede mu ọkunrin ti ọkọ ofuruf ẹlikoputa gbe ni aarin sunkẹrẹ-gba-kẹrẹ to waye loju ọna Benin-Ore laipẹ yii.
Lady Gaga ṣubú yakata níbi tó tí ń kọrin Wumi Toriola di iya ikoko: Oṣere sinima to ṣẹṣẹ n gbori soke ni Wumi Toriola, sugbọn tọmọde tagba lo mọ ọ Àwọn ojú oge Yollywood t'ọ́jà wọ́n ṣì ń tà wàràwàrà .
Nígbà tí obìnrin náà wí báyìí tán kìnnìún náà bìlà sẹ́hìn.
Ìbá jẹ́ pé mo mọ ibi tí mo ti lè rí i ni,ǹ bá lọ siwaju ìtẹ́ rẹ̀!
Gbogbo eniyan tí ó ti ìdílé Jakọbu jáde lọ sí Ijipti patapata wá jẹ́ aadọrin.
L'Ọjọru ni wọn fi ọwọ osi juwe ile fun Trump, ṣugbọn ẹgbẹ oṣelu Democrat kọ lati bẹrẹ igbẹjọ rẹ nile aṣofin agba.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ayinla Kollington: ọ̀rẹ́ ni èmí àti Barrister kó tó jáde láyé Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Àìsàn jẹ́ kí àwọ̀ ara Amida dàbí ara ẹja Ẹwẹ, ile iṣẹ ọtẹlẹmuyẹ ti ṣalaye pe Sowore n gbero lati fi ifẹhonu han da Naijiria ru pẹlu awọn kan nilẹ okere lati ṣe mu.
Lara awon ohun ti ajo EFCC ri gba lowo awon afurasi
Yóo ṣe ohun tí ó níí ṣe,ohun tí yóo ṣe yóo jọni lójú;yóo ṣe iṣẹ́ rẹ̀iṣẹ́ rẹ̀ yóo ṣe àjèjì.
Mose sì sọ fún OLUWA pé, “Àwọn tí wọn tó ogun jà nìkan ninu àwọn eniyan tí mò ń ṣe àkóso wọn yìí jẹ́ ọgbọ̀n ọ̀kẹ́ (600,000) o sì wí pé o óo fún wọn ní ẹran jẹ fún oṣù kan.
Zamfara INEC ti kéde pé àwọn ọmọ ẹgbẹ́ òṣèlú PDP ló jáwé olúbori nínú ìdìbò 2019
A gbá wọn dànù, kí àkókò wọn tó tó,a ti gbá ìpìlẹ̀ wọn lọ.
Minisita to n ri si eto irinna ọkọ ofurufu, Hadi Sirika lo kéde bẹẹ nigba ti igbimọ ti ìjọba àpapọ gbe kalẹ lori ọrọ Covid-19 n jabọ ni ilu Abuja.
Frank Lampard ni yoo jẹ akọnimọọgba fun igba akọkọ nigba ti o yoo ko awọn ẹgbẹ agbabọọlu Chelsea sọdi wa si idije naa.
Ọgbọn atinuda ni obinrin yii fi ṣe ibomu-bẹnu pẹlu ankara ati gilaasi.
Minisita fun eto ilera lorilẹede Naijiria, Ọjọgbọn Isaac Adewọle lo sọ eleyi ninu ifọrọwerọ kan pẹlu BBC Yoruba.
7 Ó sì fún un ní àwọn òfin èyítí ó mísí i;
Solomoni dá OLUWA lóhùn, ó ní: “O ti fi ìfẹ́ ńlá rẹ, tí kìí yẹ̀ hàn sí Dafidi, baba mi, iranṣẹ rẹ, nítorí pé ó bá ọ lò pẹlu òtítọ́, òdodo ati ọkàn dídúró ṣinṣin.
Gbogbo ile itaja kọmu lorilẹede Naijiria lo ti kan si ti wọn o ni iwọn ọmu rẹ lori igba ti wọn a si ṣeleri fun un pe awn a kan si ti awọn ba ti ni.
Nigba ti wọn de Côte d'Ivoire, ni wọn mu Adeola lọ si ile obinrin ti o sọ wi pe ki oun bura pe oun ko ni salọ, to si gbe omi silẹ́ lati bura lẹyin to kede pe isẹ asẹwo ni oun yoo maa se fun oun.
okoowo won sile lorile ede Naijiria tun ti pọ si bayii laarin odun 2017 si odun
Àwọn ará Dedani náà ń bá ọ ṣòwò, wọ́n ń kó aṣọ gàárì tí wọ́n fi ń gun ẹṣin wá.
Àkókò tó; ọjọ́ náà sì ti dé tán, kí ẹni tí ń ra nǹkan má ṣe yọ̀; bẹ́ẹ̀ ni kí ẹni tí ń tà má sì banújẹ́, nítorí ibinu ti dé sórí gbogbo wọn.
2018, eleyii to tako ọna ti o tọ lati fi aba iṣuna-owo ilu ranṣẹ sile.
Wọ́n máa ń fún ìṣẹ̀mí lágbárá Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Olú (mushroom) gáa ní agogo nínú ara rẹ Agogo ínú ara (Circadian rhythms) máa ń fún àwọn àsìkọ̀ bíi alẹ́ àti ọ̀sán, àsìkọ̀ ooru àti òtútú ànfàní àti mọ̀ ìgbà tí ǹkan yóò ṣẹlẹ̀, nítorí náà wọ́n máa ń gbaradì fún wọn.
Ogun abẹ́lé tó ń ja Akeredolu l'Ondo, òní la ó mọ̀ bóyá yó borí rẹ̀ Ìjọba Amẹrika yọ orúkọ Sudan kúrò nínú ìwé orílẹ̀-èdè tó ń ṣagbátẹrù ẹgbẹ́ agbésùnmọ̀mí Coronavirus: ''Ìjọba kò tíì pàṣẹ ìlànà ìtakété-síra-ẹni padà nínú BRT la ò ṣe máa tẹ̀le'' Wo àwọn Adelé-Ọba aládé méje tó jẹ́ obìnrin nílẹ̀ Yorùbá Èyí ni bí èèyàn 538 ṣe ń yan ààrẹ lé èèyàn mílíọ̀nù 331 ní Amẹ́ríkà Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Africa Eye: Wo ìtàn ìyá kan ìyá kan àtàwọn olè ajọ́mọgbé tó n ta ọmọ ní Kenya Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Ede Poly Rector suspension: Wọ́n ní kí ọ̀gá àgbà Pólì Ede lọ rọ́kún ńlé lórí ẹ̀sùn pé 'ó kan bẹ́ẹ̀dì sí ọ́fíìsì'15 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 New Covid 19 update: Ẹ̀yà kòkòrò Covid-19 míràn jáde ní ọgọ́ta agbègbè nílẹ̀ Gẹẹsi, àjọ elétò ìlera fọkàn ará ìlú balẹ̀15 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Fídíò, Fuji Music: Kollington Ayinla sọ ẹni tó dá orin Fuji sílẹ̀ gan an ní Nàiìjíríà16 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 New Covid-19 Strain UK : Atiku ní kí ìjọba dì ìrìnnà ọkọ̀ òfurufú láàrin ilẹ̀ Gẹ̀ẹ́sì sí Nàìjíríà kú nítorí Covid-1921 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Obinrin rẹ̀ kan tí ń gbè Ṣekemu náà bí ọmọkunrin kan fún un, orúkọ ọmọ yìí ń jẹ́ Abimeleki.
Iye awọn eniyan to ti lugbadi arun Coronavirus ni Naijiria bayii ti le ni ẹgbẹrun lọna mẹtadinlọgọta.
Aisha Buhari: Àwọn alágbára ti já ìjọba gbà mọ́ ọkọ mi lọ́wọ́
Nigeria 2019: INEC ìpínlẹ̀ Rivers ṣetán láti kéde èsì ìdìbò Rivers
Nítorí bí àwọn ará Masedonia bá bá mi wá sọ́dọ̀ yín, tí wọ́n wá rí i pé ẹ kò tíì múra sílẹ̀, ìtìjú ni yóo jẹ́ fún wa, kí á má wá sọ tiyín, nígbà tí a ti fi ọkàn tan yín lórí ọ̀rọ̀ yìí.
Jonatani ṣẹgun ọ̀wọ́ ọmọ ogun Filistini tí wọ́n wà ní Geba; gbogbo àwọn ará Filistia sì gbọ́ nípa rẹ̀.
Wọn ni ifaṣeyin ọdun 2020 yii lo buru ni Naijiria lati ọdun 1987.
Ọba tí ń lọ sí ìgbèkùn ni kí ẹ sọkún fún,nítorí pé yóo lọ, kò sì ní pada wá mọ́láti fojú kan ilẹ̀ tí a bí i sí.
laisi ani, ani , mo ba awọn eniyan kẹdun pupo lori ijamba ina to sẹlẹ yii.
Gomina sọ fún wọn pé wọn kò gbọdọ̀ fẹnu kan oúnjẹ mímọ́ jùlọ títí tí alufaa kan tí ó lè lo Urimu ati Tumimu yóo fi dé.
raye lati mojuto idibo naa daadaa.
Oríṣun àwòrán, @LASG Bello ni koda, niṣe ni inu awọn oluwọde naa dun nigba ti wọn ri awọn ati pe, oun paapaa fun awọn oluwọde ni omi ati ati ọti ẹlẹrindodo pẹlu imọran pe, ki wọn pada sile.
Noa kú nígbà tí ó di ẹni ẹgbẹrun ọdún ó dín aadọta (950).
Asiko ijọba oyinbo amunisin ni o bẹrẹ.
Ogagun Nwachukwu fikun oro re pe, kosi ohun ti o je be, bee si ni awon oko, keke ati ohun irinse miiran n gba opopona naa koja lai si idaduro bi o se le wu ko mo.
Ni ẹnu ọjọ mẹta yii, oniruuru iroyin iwa kotọ nipa awọn ọmọ orilẹ-ede Naijiria to wa loke okun lo n fọn kalekako lori ayelujara.
Wọn óo parẹ́ ṣugbọn ìwọ yóo wà títí lae;gbogbo wọn yóo gbó bí aṣọ,o óo pààrọ̀ wọn bí aṣọ;wọn yóo sì di ohun ìpatì.
Olówó-ayè, dìgbò lù ú, kọlù ú, dìgbò lù ú, kọlù úu, ọmọ Akọ̀wédìran, ọmọ Akọ̀wédìran, Olówó-ayé, Olówó-ayé, o kò lè ṣe bí bàbá rẹ ńdan?
Aya rẹ naa sọ pe awọn ounjẹ ti wọn maa n jẹ lasiko yii ni ẹwa, ẹfọ, igbin, ẹja, ati bẹebẹe lọ dipo ẹran ẹlẹjẹ.
 wọ ́ n tún máa ń pe èdè yìí ni azeri .
 Ó ṣe aláìsí lójijì lójú ọ ̀ run nítorí wárápá tó gbée ní ọdún 1998 nígbà tó jẹ ́ ọmọ-ọdún 38 .
"Kíni ìdí ti wọn fi ń lọ ọmú obinrin Ìpanu ‘Cheese ball’ ni wọ́n fi jí Ikimot gbé, àmọ́ ó padà sílé lẹ́yìn ọdún márùn-ún World TB Day: ""Ó dùn mí jù pé ń kò rí ọmọ mi fún ọdún kan"" ìfipábánilòpọ̀: Má dákẹ́ - Oluwaseun Tinubu kìlọ̀ fún Buhari lórí ohun tó leè ṣàkóbá fún sáà kejì rẹ̀ Mìmì kan kò mì wá, Ẹlẹka yóò jíǹde bí i Lasaru inú Bíbélì -PDP Ekiti 'Fashọla, o ò dẹ̀ bẹ̀rù Ọlọ́run!"
Oun ati ọkọ rẹ, JJC Bello si ni wọn jọ lọ sibi ayẹyẹ awuni lori naa.
Bunmi Ojo: Ó ń wòran bọ́ọ́lù lọ́wọ́ ni àgbébọn sekú pàá
Ohun to mu ọrọ yii jade gan ni bi ajọ NCDC ko ṣe tii jabọ boya eeyan lugbadi COVID -19 ni ipinlẹ Cross River lọsan ọjọ aje yẹn.
Ẹjọ naa ṣi wa nile ẹjọ.
Ìfẹ́ akọ sákọ àti abo sábo tó wọ́pọ̀ ní Àríwá Nàíjíríà ló fa ìbínú Ọlọ́run Ọ̀pá àṣẹ Ọba Akiolu tẹ gbé, a kò ní fọwọ́ yẹpẹrẹ mu - Ìgbìmọ̀ Ọba l‘Eko yarí Olori Badra sọ̀rọ̀ nípa ayé rẹ̀, ó ní ẹ́ bá òun sọkún ''A ti kọkọ fun ijọba ni gbedeke ọlọjọ meje akọkọ, lẹyin naa la fun wọn lọjọ meje si, ṣugbọn ko so eso rere kankan'' O ni ijọba lẹtọ lati ṣagbekalẹ eto to ba wu lati maa fi san owo osu oṣiṣẹ rẹ ṣugbọn eto yii ni gbọdọ faye gba awọn owo ajẹmọnu kan tawọn ọmọ ẹgbẹ awọn gba.
Ìgnà tí wọ́n sì ti yọ ni a ti tú sí igbo tí olúkúlùkù sá pamọ́ bẹ̀rẹ̀bẹ̀rẹ̀, kẹkẹ kò gbọdọ gbin.
Obinrin ọhun ni ewe ati omi ni oun ati ati ọmọ oun n jẹ ninu igbo fun odidi aadọrun ọjọ, eyiun osu mẹta, ki awọn ologun to ri oun ati ọmọ rẹ he ni abẹ oke kan lẹba ipinlẹ Gombe.
Oyo: Inú òbí dùn sí ìgbẹ́sẹ̀ ìpínlẹ̀ Ọyọ láti bẹ̀rẹ̀ ilé-ìwé tí àwọn akẹkọ̀ọ́ ń gbé
Gbọ́ ti baba tí ó bí ọ,má sì ṣe pẹ̀gàn ìyá rẹ nígbà tí àgbà bá dé sí i.
 “Mo mo ise takun-takun ti orile-ede Naijiria gbese lati ri daju pe eto aabo ati igbe-aye alaafia tun pada bo sipo nile Afrika ati ninu ajo  ECOWAS.
Yatọ si ede abinibi rẹ ti a mọ si Akan, ti wọn n sọ ni orilẹede Ghana, o tun gbọ awọn ede Kru ti wọn n sọ ni awọn ẹya Ivory Coast ati Liberia.
Agbẹjọro awọn olujẹjọ naa Mathias Emeribe lo pe igbẹjọ laarin igbẹjọ to n waye lọwọlọwọ lati fi salaye bi awọn to n soju ko ti ṣe finu fẹdọ jẹwọ fun awọn ọlọpaa.
Nínú ìwàdìí míràn ni ìwádìí ti fihan pé àwọn ẹrànko míràn a maa ya ara wọn sọ́tọ̀ fúnra wọ́n, sùgbọ́n nígbà míràn ẹ̀wẹ̀ àwọn ni wọ́n yóò pa èyíkéyìí tó bá ni àìsàn náà kí o ma ba ko ran ẹlòmíràn.
Igbimọ alamojuto (minisita ati awọn Ọga Agba ileeọẹ ibaraẹnisọrọ) yoo mojuto lati ri i pe awọn ileeṣẹ ibaraẹnisọrọ tẹle aṣẹ yii.
Atejade kan lati ile-ise iko alaanu labe ajo isokan agbaye ( United Nations humanitarian office), ti o wa ni ilu Kinsasa so pe, awon agbebon kan ti won ko mo ni won dode won lojo-Abameta.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ọ̀ṣun Oṣogbo 2018: Ulrich Salazar wálé ọdún láti New York Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Ajo eleto idibo ohun ko ni alaga kan gboogi latigba ti Rita Makarau kowe fise sile ninu osu kejila.
Oríṣun àwòrán, Instagram/ronkeoshodioke Lakotan ọrọ rẹ, Gbajugbaja oṣere tiata naa ni oun ṣetan lati mu atunṣe ba gbogbo bi ohun ṣe n ṣe nkan tẹlẹ, nipa afikun imọ nipa lilo ẹrọ ayelujara, eleyii to pe ni 'Rebranding.
Sedekaya ọba bá búra fún Jeremaya ní ìkọ̀kọ̀ pé, “Mo fi OLUWA alààyè ẹni tí ó dá ẹ̀mí wa búra, pé n kò ní pa ọ́, n kò sì ní fi ọ́ lé àwọn tí wọn ń wá ọ̀nà láti pa ọ́ lọ́wọ́.
Bẹ́ẹ̀ náà ni, nígbà tí ẹ bá rí i, tí gbogbo nǹkan wọnyi ń ṣẹlẹ̀, ẹ mọ̀ pé ìjọba Ọlọrun súnmọ́ tòsí.
Nígbà tí ó ń ṣe àgbèrè ní gbangba, tí ó sì tú ara rẹ̀ sí ìhòòhò, mo yipada kúrò lọ́dọ̀ rẹ̀ pẹlu ìríra, bí mo ti yipada kúrò lọ́dọ̀ ẹ̀gbọ́n rẹ̀.
Afojusun Aarẹ Nana Akufo-Addo ni pe orilẹede Ghana yoo de ipo giga ni 2020.
Àwọn nǹkan yòókù tí Usaya ṣe, láti ìbẹ̀rẹ̀ dé òpin, wà ninu àkọsílẹ̀ wolii Aisaya, ọmọ Amosi.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Nigeria movie industry: Àgbà òṣèré, Lere Paimo ní àìgbọràn ló ń da ọ̀pọ̀lọpọ̀ àwọn Arun jẹjẹrẹ oju: Dokita Ramatu Hassan to jẹ olulanilọyẹ nipa arun jẹjẹrẹ oju ni Naijiria tẹlẹ ṣalaye fun BBC pe, igbeyawo laarin ẹbi maa n fa arun jẹjẹrẹ oju.
Nítorí náà, ará, a kì í ṣe ọmọ ẹrubinrin, ọmọ obinrin tí ó ní òmìnira ni wá.
" Alaye ni kikun nipa eto naa ni ileeṣẹ BBC yoo fi lede ti asiko ba to.
Erùpẹ̀ ni ọ́,o óo sì pada di erùpẹ̀.
Nígbà tí OLUWA bá Abrahamu sọ̀rọ̀ tán, ó bá tirẹ̀ lọ, Abrahamu náà bá pada sí ilé rẹ̀.
Ẹni tí ó ń fọn fèrè sì wà ní ẹ̀gbẹ́ ọ̀dọ̀ mi.
Ọjọ́ Abamẹta nidije ipò kẹta ti waye nigba ti ife ẹyẹ yóò doríkọ orilẹ-ede tó fẹ́ loni.
Ọmọ Nàìjíríà kan ti ní àrùn Coronavirus nípìnlẹ̀ Eko Kí ni àwọn ayédèrú ìmọ̀ràn ìwòsàn tó rọ̀ mọ́ àrùn coronavirus?
Ninu idajọ naa ti adajọ agba lorilẹ-ede yii, Tanko Muhammad kọ, ti adajọ John Okoro ka sọ pe, ẹjọ ti oludije sipo Aarẹ ninu ẹgbẹ PDP, Atiku Abubakar pe ko lẹsẹ nilẹ.
Wọn sì jẹ́wọ́ pé àwọn jí ǹkan tí a bá lára wọn ni, àti pé àwọn máa n jalè lágbègbè Iwo Road, Inalende ati gbogbo agbegbe rẹ̀.
Club/ RD Congo), Arsène Zola (TP Mazembe/ RD Congo), Glody Ngonda Muzinga (AS V.
 yemọja ló ń fomi ojú ṣògbéré ojú látàrí àìrọ ́ mọ bí rẹ ̀ , tí ó sì lọ bá ifá fún ọ ̀ nà àbáyọ .
N óo fi ìdí àwọn eniyan mi múlẹ̀ ní ilẹ̀ náà,wọn yóo sì máa bí sí i.
Nigba to n sọ ọna abayọ si asa hihu iwa ipa ninu idile, oludasilẹ ẹgbẹ obinrin FIN wa rọ gbogbo awọn eeyan to ba n koju iru iwa aidaa yii lati sọrọ sita, nitori iru iwa bayii kii se eyi ti a n de mọ abẹ asọ.
Visa: Àwọn ọmọ Naijiria yóò má a san àfikun owó láti wọ Amẹrika
“Ìlànà tí èmi OLUWA fi lélẹ̀ nìyí: Ẹ sọ fún àwọn ọmọ Israẹli kí wọ́n mú ẹgbọ̀rọ̀ abo mààlúù pupa kan wá.
Nisinsinyii, n óo fojú sílẹ̀, etí mi yóo sì ṣí sí adura tí wọ́n bá gbà níbí yìí.
Jesireeli ni à ń lọ láti lọ kí àwọn ọmọ ọba ati àwọn ìdílé ọba.
Ọmọbìnrin ọdún 25 gún ọ̀rẹ́kùnrin rẹ̀ pa nítorí ó ní ko lọ ṣẹ́ oyún Sinimá àwòdamiẹnu, Ẹ̀fáńjẹ́líìsì jìyà àjẹmumi nílé aṣẹ́wó l'Ejigbo ní ìlú Eko Ìjàmbá ọkọ̀ tó ṣẹlẹ̀ sí Adams Oshiomole kìí ṣe ojú lásan, àwọn kan ló fẹ́ pa á- APC Ọkùnrin kan da ṣọ́ọ̀ṣì rú lásìkò ìgbéyàwó, Ó ní òun lọkọ àárọ̀ ìyàwó tuntun E wo ọmọ Yorùbá àkọ́kọ́ tó jà fún ẹ̀tọ́ àwọn aláwọ̀dúdú ní America!
Wọn ko ni abawọn lẹnu iṣẹ wọn 5.
Ṣugbọn ajọ FA ti ni ohun yoo pe ẹjọ ko tẹmi lọrun lori ọrọ naa.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù FA Cup: Man City pòkọ ìyà fún Swansea pẹ̀lú àmì ayò 3-2 nínu FA Cup 16 Ẹrẹ̀nà 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Idije FA Cup Ẹgbẹ agbabọọlu Manchester City ti pgede fun ipele to kangun si aṣekagba ninu idije FA lẹyin ti wọn fagba han Swansea City pẹlu ami ayp 3-2.
 Njẹ Neymar ti ṣe tan fun Copa América?"
Ẹya Ijẹbu ni ipinlẹ Ogun ni guusu Naijiria kii sọ ọmọkunrin wọn ni Ojo.
Ati pe iduunu lo jẹ fun oun lati ri i pe awọn ọdọ n ja fun ọjọ iwájú wọn, nigba ti oun wa laaye.
ipo losu to kọja,yoo maa kawọ sẹyin ro ẹjọ 
Ṣugbọn ẹni tí ó bá jẹ́wọ́ Ọmọ ní Baba pẹlu.
"Oríṣun àwòrán, @globalextra Momoh tẹsiwaju pe: ""Fun apẹrẹ, epo wa ni ileeṣẹ MRS, ṣugbọn a ko lee ko epo nibẹ nitori awọn 'container' to di ọna mọ ọkọ wa, ṣe kii ṣe ijọba Eko lo yẹ ko wa ojutuu si iru iṣoro bayẹn, abi ileeṣẹ LASTMA kọ lo n risi ọrọ oju popo ni ipinlẹ Eko?"
Ijọba apapọ ni idi fi awọn fi ti afara third mainland naa ni lati ṣe atunṣe oni igba de igba ti wọn ma n sẹ ki afara naa ma ba a da ijamba silẹ fun awọn eniyan to n gba ibẹ .
Ó yẹ kí àwọn àgbà tí wọ́n bá ṣe iṣẹ́ aṣiwaju dáradára gba ìdálọ́lá ọ̀nà meji, pataki jùlọ àwọn tí wọn ń ṣe iṣẹ́ oníwàásù ati olùkọ́ni.
Nigba to ba BBC Yoruba sọrọ, Faduyile sọ pe lootọ ni awọn eniyan le lo igbo fun iwosan aisan kan tabi omiran, ṣugbọn asa lilo igbo lọna ti ko tọ ni a fi n sọ pe, ko yẹ ko wa ni awujọ.
Kí àká wa kún fún oniruuru oúnjẹ,kí àwọn aguntan wa bí ẹgbẹẹgbẹrun,àní, ẹgbẹẹgbaarun ninu pápá oko wa.
Ará ilú ki ronú wi pé “Alaaru tó njẹ́ búrẹ́dì, awọ ori ẹ̀ ló njẹ ti kò mọ̀”.
Gege bi aare se so:”okan mi bale pe ti iko agbaboolu wa ba ni igbagbo ninu ara won, o di dandan ki won pegede nibi ipele ti o fe  le fun won,ki won si tun tesiwaju nibi ifese-wonse yii.
Jakọbu bá dáhùn pé, “Kọ́kọ́ gbé ipò àgbà rẹ fún mi ná.
Ẹnikan to mọ ẹkunrẹrẹ to jẹ oṣiṣẹ ileeṣẹ gaasi naa sọ fun BBC pe o ti le ni wakati kan ti ina yii ti n jo.
Ẹ óo wá mọ̀ pé èmi OLUWA ni mo sọ̀rọ̀ pẹlu owú nígbà tí mo bá bínú si yín tẹ́rùn.
Kọmisọna ọlọpa nipinlẹ Ọsun, Fimihan Adeoye ni irọ patapata ni gbogbo ohun ti Ọlayẹmi sọ fun awọn mọlẹbii rẹ atipe oun gan-an lo mọọmọ gbe ara rẹ pamọ.
Ṣaaju asiko yii ni ọkunrin kan, Muhammad Zubair ati ẹgbẹ kan ti wọn pe ni Lawyers for Sustainable Democratization of Nigeria, gbe ọrọ lọ sile ẹjọ pe awọn aṣofin ọhun ko gbọdọ ṣewadi Ganduje.
Ọ̀kan ninu àwọn Serafu náà bá fi ẹ̀mú mú ẹ̀yinná kan lórí pẹpẹ, ó mú un lọ́wọ́, ó bá fò wá sọ́dọ̀ mi.
Ọwọ́ kan bá dì mí mú, ó gbé mi nílẹ̀, mo da ọwọ́ ati orúnkún mi délẹ̀.
Xenophobic Attack: Báwo ni ìkọlù sáwọn àjèjì ṣe pọ̀ tó ní South Africa?
Eeyan 1,420 lo ti ba arun coronavirus lọ ni Naijiria.
Obong Roviel ni ọrọ Peter Okoye ko ya oun lẹnu nitori Peteru ninu Bibeli gan da Jesu.
Ayé kún fún àwọn ẹ̀dá rẹ.
Igbesẹ Ilẹ Gẹẹsi yii farapẹ igbesẹ awọn orilẹ-ede miran ni ilẹ Europe ti o ti pinnu lati da awọn ohun abalaye to jẹ ti ilẹ Afrika amọ ti wọn jigbe pada si ibi to yẹ.
Kíní àwọn ọmọ Nàìjíríà ń sọ?
Eyi si maa n mu ki ọpọ ọkọ ninu ile yẹra fun iyawo rẹ to ba n ṣe nnkan osu, yatọ si ero ti wọn tun ni pe iru obinrin bẹẹ ko mọ.
Ẹgbẹrun mejilelọgọta o le ẹgbẹrin ati mọkandinlogun (62,819) lawọn ti ara wọn ti ya nigbati aarun naa si ti gbẹmi awọn ẹgbẹrun kan ati mọkanlelaadọjọ (1171) eeyan.
Ti ẹ ko ba gbagbe, ọdun Ojude Oba maa n waye lọdọọdun ni ọjọ kẹta ọdun Ileya ti awọn Musulumi maa n ṣe.
Ọ̀rá ni àwọn dókítà fi ń dáàbò bo ara wọn nílẹ̀ẹ Gẹ̀ẹ́sì Iṣẹ́ abẹ tí mo ṣe láti fi kún ìkébé mi ṣàkóbá fún mi- Omotola Taiwo Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ogundiya: Àṣìṣe Dókítà ló sọ mi di aláàbọ̀ ara lórí kẹ̀kẹ́ Bakan naa, dokita ni kii ṣe pe ijọba Naijiria ko lee san ju bayii lọ ṣugbọn wọn ko kan fi ọrọ eto ilera ṣe pataki ni.
Imam tó fẹ́ ọkùnrin míì níyàwó forí kó ìjìyà òfin Wo ipa tí Mayegun yóò ma kó ní ilẹ̀ Yoruba!
igbagbo pe agbaboolu owo eyin iko Gor Mahia naa, yoo se iranwo pupo fun iko yii
Aarẹ orilẹede Naijria tẹlẹri naa ni, bi o tilẹ jẹ wi pe Aarẹ Buhari wọle fun saa keji, ko seese ki ọrọ aje Naijiria gbooro si, nitori nkan ko sẹnu ire lọwọlọwọ.
Kò si ipèsè ohun amáyédẹrùn pàtàki omi mi mun ni àwọn agbègbè tuntun lai yọ àdúgbò ọlọ́rọ̀ silẹ̀.
Amọ, o ṣeeṣe ki Adeyeye gbe ẹjọ naa lọ si ile-ẹjọ kotẹmilọrun laaarin ọjọ mẹrinla.
Mose sì rán wọn lọ sójú ogun lábẹ́ àṣẹ Finehasi ọmọ Eleasari alufaa, pẹlu àwọn ohun èlò mímọ́ ati fèrè fún ìdágìrì lọ́wọ́ rẹ̀.
Mose mú igẹ̀ àyà àgbò náà, ó fì í gẹ́gẹ́ bí ẹbọ fífì níwájú OLUWA.
O gba nǹkan ìdógò lọ́wọ́ àwọn arakunrin rẹ láìnídìí,O bọ́ wọn sí ìhòòhò goloto.
“Ayé mì, ó sì wárìrì;ìpìlẹ̀ àwọn ọ̀run sì wárìrì,ó mì tìtì, nítorí ibinu Ọlọrun.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Oúnjẹ ibìkan jẹ́ èèwọ̀ ibòmíì ni ọ̀rọ̀ ọmú ńlá' Gbogbo igba si ni Dokita Anu ma n sẹ lori awọn ẹsun naa.
Ikede yi wa lasiko igba ti awọn eeyan n faraya lẹyin ti akara tu sepo nipa iye owo osu ti awọn asofin n gba eleyi ti aṣofin Sheu Sani lati ipinlẹ Kaduna bẹ sita.
Ọjọgbọn ninu imọ itan ni fasiti California lorilẹede Amẹrika, Rudolph Butch Ware sọ pe, ko rọrun lati sọ iye owo ti Musa ni ni pato, nibi ti o lowo to si lọrọ de laye igba yẹn.
osise  lẹbi lori abajade to ba waye lẹyin
Nisinsinyii, sọ fún wọn pé, ‘Bí mo tì wà láàyè, n óo ṣe yín gẹ́gẹ́ bí ẹ ti wí.
Coronavirus kò lè tán lórí ilẹ̀ ayé pátápátá- Bàbá Adeboye Ọ̀nà mi dàrú nígbà tí wọ́n lé mi ní Fáṣitì Ilorin, ọpẹ́ ádúrótì ìyá mí - Agba Inaki Wo báwọn mùsùlùmí ti ṣe ọdun ìtúnu ààwẹ̀ káàkiri ilẹ̀ Afirika lásìkò covid-19 yìí Ṣọ́ọ́ṣì kan sí ìlẹ̀kùn rẹ̀ fún àwọn mùsùlùmí láti kírun Jímọ̀ ní Germany Ológun mú àwọn sọ́jà tó kọ́wọ̀ọ́ fipá bá akẹ́kọ̀ọ́ fásitì AAUA lò pọ̀ Ile iṣẹ olgun Naijiria ni ilu Akure, ipinlẹ Ondo ni awọn ti mu àwọn sọja kan ti wọn fi ẹsun kan pe wọn pawọ pọ fipa ba akẹkọ onipele ikẹta ni fasiti Adekunle Ajasin, Akungba Akoko.
Ṣugbọn ọmọ arabinrin Paulu kan gbọ́ nípa ète yìí.
Aleekun ọun ni wọn sọ pe, yato si siga, yoo de ba ọti beer, waini ati awọn ọti mii laarin ọdun 2018 ati ọdun 2020.
Ọpọ awọn ibeere wọnyii lo n beere fun idahun.
Koda, osere tiata kan, Kemi Korede kede pe osere tiata lobinrin miran Funke Akindele ti fun Ajirebi ni ile ti yoo maa gbe.
O jẹ ọmọ ẹgbẹ okunkun kan to n gbimọ lati ko awọn janduku wọ adugbo nitori ọmọ ẹgbẹ wọn kan to padanu ẹmi rẹ.
Akeem Olatunji to jẹ agbẹnusọ fun ẹgbẹ oselu PDP ni gomina Ajimobi lo si wa lori oye, bẹẹ lo si ni anfaani lati se ohun to wu u.
Lasiko abewo olojo meji re nilu Nairobi ti n se olu ilu orile-ede Kenya, akowe agba Scotland yoo sepade pelu Aare Uhuru Kenyatta awon minisita ijoba ati olori ijoba teleri, Raila Odinga,Akowe agba ohun so pe, “ orile-ede Kenya je omo egbe kan pataki ninu ajo naa, anfaani abewo ohun ni lati fi idunnu han lori awon idagbasoke ati alaafia to joba, nipa ifenuko to waye laarin Aare Kenyatta ati Odinga.
Inu mi dun lati buwọlu ẹkunwo oṣu naa pẹlu ireti pe yoo mu ki ijafafa awọn ọlọpaa o lọ siwaju sii.
Pilatu ti mọ̀ pé nítorí ìlara ni wọ́n fi mú un wá sọ́dọ̀ òun.
Bí ọ̀ṣẹ̀ kan ṣẹ́yìn ni ìlúmọ̀ọ́ká pásìtọ̀ ìjọ The Citadel Global Community Church, Tunde Bakare ké sí àwọn ọmọ Nàìjíríà láti wá ǹkan ti yóò ràn ìtẹ̀síwájú orílé-èdè Nàíjíríà lọ́wọ́ O ní èyí yá jú kí wọ́n máa gbi egbìrìn ọ̀tẹ̀ lórí ìpinu Tinubu láti di ààrẹ lọ́dún 2023 lọ.
O sọ ọ debi pe ọkọ ọga rẹ maa n fi ibalopọ lọ ọ.
Ọ̀rọ̀ inú ìwé yìí kún fún ọgbọ́n o sì dùn bí oyin.
ọmọ Abiṣua, ọmọ Finehasi, ọmọ Eleasari, ọmọ Aaroni, olórí alufaa.
Awọn alaṣẹ ileeṣẹ naa wa rawọ ẹbẹ si ileeṣẹ to n ri si ọrọ awọ́n oṣiṣ ni ipinlẹ Oyo lati jọwọ tun ero wọn pa lori titi ileeṣẹ wọn pa tori pe yoo kan tun da kun iṣoro ọrọ aje eyi ti Covid-19 ti da silẹ tẹlẹ ni.
5m, N8bn tí wọ́n kó pamọ́’ Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Wakati kan gbako ni ikọ panapana mẹrin fi wọ'ya ija pelu ina ọhun ki wọn to rẹyin rẹ ni agbegbe Kangaroo Point.
Abrahamu gbà bí Efuroni ti wí, ó bá wọn irinwo (400) ìwọ̀n ṣekeli fadaka tí Efuroni dárúkọ fún un lójú gbogbo wọn, ó lo ìwọ̀n tí àwọn oníṣòwò ìgbà náà ń lò.
O tesiwaju pe  “Kaadi idibo wa ni agbara wa lati fi se aseyori ninu eto idibo 2019, nitori naa , e rii pe ẹ daabo bo daadaa nitori ife okan yin.
Bakan naa ni EFCC sọ pe, miliọnu mẹtala Naira l'ọdun ni ile ti ọkọọkan wọn n gbe.
orile ede Afirika yoo se maa na owo kan naa jade ni osu kefa fun awon aare  orile ede 
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, John Amanam: Ìfẹ́ tí mo ní sí àbúrò mi ló sọ mi dí ẹni tó ń ṣe 'Prosthetic' báyìí Ṣugbọn lati Ọjọru ọsẹ to lọ ni ọpọ araalu ti n kuro ni Oyigbo lẹyin tawọn agbofinro bẹrẹ si ni kaakiri lati rii pe ofin konle-o-gbele to wa lode mulẹ.
Níbo ni mo lè sá gbà tí ojú rẹ kò ní tó mi?
Ni oju oja Bureau De Change (BDC) pasipaaro re je ọ́ọ̀dúnrún le lọgọ́ta(N360), ti owo Pound Sterling ati Euro si je ẹ̀ẹ́dẹ́gbẹ̀ta din mọ́kàndínlógún(N481) ati irinwó le mẹ́rìndínlógún(N416) ni n tele n tele.
Mose bá wí fún wọn pé, “Lónìí ni ẹ yan ara yín fún iṣẹ́ OLUWA, olukuluku yín sì ti fi ẹ̀mí ọmọ rẹ̀, ati ti arakunrin rẹ̀ yan ara rẹ̀, kí ó lè tú ibukun rẹ̀ sí orí yín lónìí yìí.
ọwọ igbimo ijoba aare to n ri si bi ile igbimo asoju ati ile –ise eto idajo yoo
"A si ti mu eniyan mẹta fun ẹsun igbiyanju lati sekupani to fi mọ ifiyajẹni.
”Alaga egbe oselu PDP, Uche Secondus, wa ro awon alatileyin egbe won lati daabo bo kaadi idibo won , ni eyi ti yoo lee je ki won dibo lọdun to n bo.
ọmọ Metusela, ọmọ Enọku, ọmọ Jaredi, ọmọ Mahalaleli, ọmọ Kenani, 
Ó fi idẹ ṣe gbogbo àwọn ohun èlò tí ó jẹ mọ́ ti pẹpẹ náà: àwọn bíi ìkòkò, ọ̀kọ̀, agbada, ọ̀kọ̀ tí wọ́n fi ń mú ẹran ati àwo ìfọnná; idẹ ni ó fi ṣe gbogbo wọn.
Ẹ̀ṣọ́ NSCDC ṣèèṣì yìnbọ̀n pa ọlapàá ọ̀tẹlẹ̀múyẹ́ DSS l'Osun MC Murphy ko sọ òótọ́ ọ̀rọ̀ to wà níbẹ̀, tó ba wùú kó sọ òótọ- Adebayọ Sunday Igboho kàn ń gbé ‘Camera’ lẹ́yìn kiri, kí wọ̀n lè rò pé ó ń jà fún Yorùbá - Gani Adams Ikú tó ń pa ojúgbà ẹni.
Nígbà tí àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rí i tí ó ń rìn lójú omi, ẹ̀rù bà wọ́n gan-an, wọ́n ń sọ pé, “Iwin ni!
Eleyi to jẹ ki Algeria fi Naijiria ṣatẹgun si ipele aṣekagba pẹlu ami ayo meji sẹyọ kan.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Offa Robbery: Àwọn aráàlú ṣi n gbé nínú ìpaya lẹ́yìn ọdún kan Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Èmi OLUWA àwọn ọmọ ogun, Ọlọrun Israẹli ni mo sọ bẹ́ẹ̀.
Nigba ti o wa ni Benue, Gomina Fayọṣe kẹdun pẹlu awọn ara ipinlẹ naa lori ipaniyan to gbalẹ nibẹ.
fidio ifọrọwanilẹnuwo naa ree Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, PVC: Ṣé a ṣẹ̀ 'jọba la ṣe ń jìyà lóri káádì ìdìbò ni?
Oríṣun àwòrán, Other Iwadii awọn ọlọpaa fihan pe laago mẹrin oru ni ọkunrin naa wọle tọ iyawo rẹ lọ, ṣugbọn obinrin naa ko gba lati jọ ni ajọṣepọ pẹlu ọkọ rẹ nitori oun kọ lo wu u lati fẹ.
Esaradoni ọmọ rẹ̀ sì jọba ní ipò rẹ̀.
Ìrẹ̀wẹ̀sì bá ọkàn mi nítorí ìbànújẹ́,mú mi lọ́kàn le gẹ́gẹ́ bí ọ̀rọ̀ rẹ.
Nígbà tí gbogbo àwọn ọmọ Israẹli gbọ́ pé Jeroboamu ti pada dé láti ilẹ̀ Ijipti, wọ́n pè é sí ibi ìpàdé kan tí wọ́n ṣe, wọ́n sì fi jọba Israẹli.
O ni ija, asọ ati ipaniyan yoo pọsi lorilẹede Naijiria, bẹẹ ni rogbodiyan yoo peleke si kaakiri agbaye.
O wa pari ọrọ rẹ pe ọrọ pe, kesekese ni Toyin si ri, kasakasa si n bọ lọna.
Orisirisi awọn eniyan lọmọde lagba ni wọn kopa ninu idije ọun.
Oyeyemi sọ wipe, Afurasi naa tẹle wọn lọ Ifo, wọn si gbe akẹgbẹ rẹ naa, ti wọn si gba awọn ibọn ati ọta lọwọ rẹ."
Gbogbo ará ayé ni yóo kórìíra yín nítorí orúkọ mi.
Máa lépa òdodo, ati ìfọkànsìn Ọlọrun, igbagbọ, ìfẹ́, ìfaradà, ati ìwà pẹ̀lẹ́.
Akira ni iyalẹnu lo jẹ nigba ti iṣẹ iwadii naa n di nla ti o fi di itẹwọgba ni gbogbo agbaye bayii.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Buhari: Mo gbọdọ̀ lọ́ra kàwé, kí ń tó buwọ́ lùú 12 Agẹmo 2018 Oríṣun àwòrán, Muhammadu Buhari/Facebook Àkọlé àwòrán, lBuhari ní òun lọ́ra láti buwọ́ lu ìwe kankan nítorí èèyàn kìí kánjú lá ọbẹ̀ gbóná.
Dájúdájú kò ní ṣàì yà ọ́ lẹ́nu pé eléyìínì náà ni wọ́n ṣe fún bàbá mi mọ, òótọ́ ni, wọn ṣe jù bẹ́ẹ̀ lọ.
Ọ̀gá NIMASA tẹ́lẹ̀ fi ẹ̀wọ̀n ọdún 42 jura Ọpọlọpọ ẹ̀mí ati dukia lo dẹ ti sọnu sinu irufẹ ija ẹsin yii.
O ṣe pàtàkì láti máa dágunla si ìkéde àjọ tó n ri sí bí ojú ọjọ́ yóò ṣe rí: Ní ọ̀pọ̀ ìgbà ní àwọn àjọ yìí máa ń kéde bí ojú ojọ́ yóò ṣe ri, òjò ti yóò fa ọmí yale, nígbà ti irú ìpè yìí bá wáye kò yẹ ki ará ìlú keti ọ̀gbọ́in síi, ó ṣe pàtàkì láti maa gbọ rẹdíò, tẹlẹfisọn àti kika ìwé ìròyìn ní gbogbo ìgbà láti mọ nípa àwọn apá ibi ti amíyale yóò ti wáye.
Wọ́n lè di ẹrú yín, ṣugbọn ẹ̀yin ọmọ Israẹli tí ẹ jẹ́ arakunrin ara yín, ẹ kò gbọdọ̀ mú ara yín sìn, ẹ kò sì gbọdọ̀ fi ọwọ́ líle mú ara yín.
Ọ̀nà kan kò wọ ọjà ni ọrọ Osuolale nítorí bo ti ń ṣe agbẹjọro lọ tún mú oselu mọ isẹ rẹ, tó sì jẹ minisita feto ẹ̀kọ́ ni ṣáá eto ìṣèlú àkọ́kọ́, ni ayé ijọba Tafawa Balewa Bákan náà lọ tún jẹ́ minisita feto ìdájọ́ ni ṣáá eto iselu alágbada kejì, nígbà tí Alhaji Shehu Shagari jẹ aarẹ Naijiria.
Eleyi jẹ ki Yorùbá ri ohun mu yangàn.
Baba Sala wọ káà ilẹ̀ lọ ní Ilesa Wọn ti n ṣe fakinfa lori ọjọ ati asiko ti iburawọle yi yo waye.
Ọ̀jọ̀gbọ́n fásitì OAU pàdánù ẹ̀mí rẹ̀ lópoópónà Benin sí Auchi.
Nípasẹ̀ rẹ̀ ni gbogbo nǹkan sì fi wà létò.
Nígbà náà ni yóo dára fún ọ, gbogbo ohun tí o bá dáwọ́ lé yóo sì máa yọrí sí rere.
" Ọ̀pọ̀ biliọnu náírà ni idokowo náà yóò gbà, gbogbo agbaye sì ti ní èwe igbó tí wọn gbìn ni Ìpínlẹ̀ Ondo lo dára julọ lagbaye, kò sì yẹ ká máa sún wọn ni iná.
Wọn óo fi tipátipá mú kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ rẹ lọ lójú rẹ, wọn kò sì ní dá a pada fún ọ mọ́.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù FIFA 2019: Ọdún 1991 làkọ́kọ́ irú rẹ̀ ní àgbáyé Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ FIFA 2019: Ọdún 1991 làkọ́kọ́ irú rẹ̀ ní àgbáyé 8 Òkùdu 2019 Orilẹ-ede Amerika, Japan, Norway àti Germany nìkan ló tíì gba ife ẹyẹ àgbáyé àwọn obìnrin rí.
ati gbogbo awon ti oro imototo agbegbe kan lati dena aisan ati ajakale arun
Idaji awọn to lugbadi arun wọn yi wa lati ilẹ South Afrika.
tun je ki idagbasoke de ba eto oro aje lorile ede yii.
Ri i pe o tu iṣu de isalẹ ikoko nipa ibi ti iroyin naa ti wa ki o to o pin - tabi ki o ma ti ẹ pin rara.
Bíi wákati kan gbáko ni Arsenal fui n dàmú lóri pápá lái kó èrè oko déle, bí wọn ṣe ràn Ainsley Maitland niṣẹ́ láti ló gbá èwé jọkó jẹ́jẹ́ wá.
Àní, eniyan meji péré ṣe lè lé ẹgbaarun eniyan sá?
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù NYSC: Àwọn àgùnbánirọ̀ gbọ́dọ̀ gba àṣẹ kí wọ́n tó ṣètò ìgbafẹ́ 6 Ògún 2018 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 8 Ògún 2018 Oríṣun àwòrán, Nysc/twitter Àkọlé àwòrán, Ibi ìgbáfẹ́ já sí ibi ikú fún àwọn agànbánirọ̀ mẹ́san an Ọga agba ajọ agunbanirọ, Ọgagun Suleiman Kazaure kilọ fawọn agunbanirọ lati ṣọra fun irede oru.
Nígbàtí akọ̀ròyìn BBC sèbẹ̀wò sí agbo ilé wọn, àti D'Banj, àti ìyàwó rẹ̀, wọn kò kó fìrí ẹnikẹ́ni nínú wọn.
 Ọkan ní pé ni ìlú Ìlọrin ní sákárà tí bẹ ̀ rẹ ̀ láti ọwọ ́ àwọn mùsúlùmí kan , kí a to mú un wá sí Ìbàdàn lásìkò baálẹ ̀ sítú tí ó jẹ ́ olúbàdàn láàrin ọdún 1914 sí 1925 .
Oun ati awọn mẹtadinlogun miran, ni awọn ọlọpaa mu nitori ija igboro to waye ni Ebem Ohafia.
O ti wa fun adajọ Ayenakin ni gaafara lati bọ ẹwu rẹ ko si kuro nile ẹjọ niwọn igba ti ọrọ ko ti wọ.
Ilé laawo ki a to sọ ọmọ ni orukọ ni igbagbọ awọn Baba nla iran Yoruba.
O ti rí nǹkan burúkú tí wọ́n ṣe sí mi,OLUWA, dá mi láre.
Ẹ óo wá mọ̀ pé èmi ni OLUWA nígbà tí mo bá ko yín dé ilẹ̀ Israẹli, ilẹ̀ tí mo búra láti fún àwọn baba ńlá yín.
 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ijọba ti seleri ati sawari awọn akẹkọ naa O ni ọjọ kan naa ti awọn alasẹ ologun ko awọn ọmọogun kuro nilẹ nilu Buniyadi nipinlẹ Yobe lawọn apanijaye yii sọsẹ."
Ẹwẹ, awọn olorin mii atawọn oṣere mii naa ti fi ọrọ sita lodi si iwa yii to fi mọ awọn mii naa ti wọn fifẹ han lati darapọ mọ iwọde ọhun.
Lefi ní ọmọkunrin mẹta: Geriṣoni, Kohati ati Merari, wọ́n sì jẹ́ olórí àwọn ìdílé wọn.
Lasiko ti won n jiroro yii ni awon asofin kan dabaa pe , ki won yo awon olori eso eleto aabo  ati adari oga olopaa orile ede yii, pe won kunna lati daabo bo emi ati dukia awon omo orile ede yii, ni eyi to je  ojuse won to wa labe ofin.
Wọ́n rékọjá odò sí òdìkejì, láti dara pọ̀ mọ́ àwọn tí wọn yóo sin ìdílé ọba kọjá odò, ati láti ṣe ohunkohun tí ọba bá fẹ́.
Amọṣa o ni ijsba yoo joko lati wadi ọna abayọ nibẹ.
Ọmi ni ayo naa gangan pari sí ki wọn to lọ abala wòmí-n-gba-sí-ọ, eyi ti Chelsea ti wa fi agba han.
Kidnapped Turkish Nationals: Iléèṣẹ́ ọlọ́pàá Kwara dóòlà ọmọ Turkey mẹ́rin tí wọ́n jígbé
"Idunu ati ayọ ni Arteta fi gba iṣẹ naa to si sọ pe ""O jẹ iyi nla fun mi lati dara pọ mọ ikọ Arsenal."
Oloogbe Bush je iyawo aare mọ́kànlélógójì orile-ede Amerika, George H.
Àbí ẹ lè dá olódodo ati alágbára lẹ́bi?
Ọgbẹ́ni Salkida tún sọ pe ìsèjọba ààrẹ àná Goodluck Jonathan rọ oun lati dúnàá dúrà lori dídá awọn ọmọ ọun sílẹ̀ lẹ́yìn ọ̀sẹ̀ meji ti wọ́n ko wọn lọ.
Amọ baba naa, ẹni to ti n se aisan atọgbẹ, ti ko si riran daada, ni ijọba tu silẹ lọgba ẹwọn to wa nilu Enugu, ti ọmọbinrin rẹ, Chisom Celestine ati awọn asoju ẹgbẹ GSAC, si lọ pade rẹ ni kede ti wọn tu silẹ lọgba ẹwọn ọhun.
3rd Mainland Bridge, Ijọba ibilẹ Lagos Island / Mainland / Somolu 23.
nítorí wọ́n fẹ́ràn ìyìn eniyan ju ìyìn Ọlọrun lọ.
Wọ́n dáhùn pé, “Ọkunrin kan pàdé wa lọ́nà, ó sì sọ fún wa pé, ‘Ẹ pada sọ́dọ̀ ọba tí ó ran yín, kí ẹ sì sọ fún un pé, “OLUWA ní, ṣé nítorí pé kò sí Ọlọrun ní Israẹli ni o fi rán oníṣẹ́ lọ wádìí ọ̀rọ̀ lọ́dọ̀ Baalisebubu, oriṣa Ekironi?
Kíkọ ìmọ̀ ìṣìrò ti jẹ̀ ìṣòrò fun ọ̀pọ̀ láti ìgbà to ti pẹ́ láti ilé ìwé alákọbẹ̀rẹ̀ jákèjádò gbogbo àgbàyé, ǹkan to si fa irú iṣòro yii ni pé ìmọ ẹkọ náà ni ọ̀pọ̀ àwọn ofin ti a ko le foju ri ṣùgbọ́n ti a gbọ̀dọ fi pamọ sinu ọpọlọ ní.
Miyetti Allah ní kí wọn wọ́gilé Amotekun, Sunday Igboho yarí Sunday Igboho yarí, ó fohùn ránsẹ́ sáwọn èèyàn tó ń pẹ̀gàn rẹ̀ Opral Benson, ẹni ti oge ṣíṣe sọ di gbajúmọ̀ àti Yeye Oge ìlú Eko Ọjọ́ orí wo ló yẹ kí ikùn ẹ̀dá bẹ̀rẹ̀ sí tóbi?
Ni kete ti iroyin naa de afẹfẹ ni Pinnick ke gbajare lori Twitter pe ko si ootọ kan nibẹ.
Omotola Jalade ní Nàìjíríà dàbí ọ̀run àpáàdì lábẹ́ ìjọba Buhari Ọmọogun ilẹ̀ Amẹ́ríkà ni mí tẹ́lẹ̀ kí n tó di aláwàdà - Oluwakaponeski Duro Ladipọ, ìlúmọ̀ọ́ká òṣèré tíátà àti ọmọ àlúfà tí kò gbàgbé àṣà ìbílẹ̀ Ọ̀pọ̀ òṣèré tíátà tó ń sàìsàn ni kò ṣe dáadáa f'ẹ́gbẹ́ - Jide Kosọkọ Deji àti Charly Boy tako ara wọn lórí fọ́nrán tó jáde Ìyá àgbà Ọlayinka, arúgbó tó ń ṣoge bí omidan Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí kan sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
Oríṣun àwòrán, Instagram/Lisahannamp Ni ọdun 2007ni Hanna du ipo to si wọle gẹgẹ bi aṣoju ẹkun idibo rẹ.
teleri  ati alaga igbimo naa, Abubakar
Àwọn àṣà àti ìse tó yọ obìnrin sílẹ̀ nílẹ̀ Yorùbá Iṣẹ́ tíátà tí bájẹ́, ẹni ẹlẹ́ni ló ń jẹ iṣẹ́ wa - Yomi Fabiyi Gomina Makinde gbàlejò àwọn Imam lásìkò àjàkálẹ̀ àrùn Coronavirus Nigba to n fi idi rẹ mulẹ boya baba rẹ ti ri owo naa gba lọwọ Ileesẹ aṣọbode, Olusola ni Ileesẹ aṣọbode nilẹ wa ko fun baba oun ni kọbọ ninu owo tile ẹjọ ni ki wọn san fun baba oun, lori iya ti wọn fi jẹ ẹ ní ahamọ.
Ibéérè márùn ún tí Chelsea ní láti dáhùn lẹ́yin Sarri Ojú tirọ́ wọn!
Dupẹ ni oun duro nitosi lati mọ ẹni ti yoo gbe ọmọ naa lẹyin ti oun bii lẹgbẹ ṣalanga to fi gbe ọmọ naa sori akitan ni Ogbomọsọ ni ipinlẹ Oyo.
Njẹ o tun ni awọn ibeere miran?
Ẹ wo àbájáde ìwádìí wa Donald Trump ti gbà pé Coronavirus yóò burú jáì kí ǹkan tó dára fún Amẹ́ríkà Wo bí ètò ìsìnkú Tolulope Arotile ṣe lọ nílùú Abuja Ìjọba ìpínlẹ̀ Kano tí wọ́gilé ayẹyẹ lẹ́yìn ìrun ọdún Iléyá!
Ẹ̀yin ará, ipòkípò tí olukuluku bá wà tí a bá fi pè é, níbẹ̀ ni kí ó máa wà níwájú Ọlọrun.
Ẹ̀wù rẹ̀ ń dán, ó funfun láúláú, kò sí alágbàfọ̀ kan ní ayé tí ó lè fọ aṣọ kí ó funfun tóbẹ́ẹ̀.
Kii ṣe ahesọ ọrọ mọ pe oniruuru awuyewuye lo ti wọ tọ ọrọ tani yoo dije ipo gomina ni ipinlẹ Ondo.
Inú bí OLUWA sí Aaroni tóbẹ́ẹ̀ tí OLUWA fi ṣetán láti pa á run, ṣugbọn mo gbadura fún Aaroni nígbà náà.
Generator Ban: Àbá ọ̀hún wá yọ àwọn ilé ìwòsàn, pápákọ̀ òfurufú àti àkànṣe iṣẹ́ míì sílẹ̀
Ajọ naa ni awọn mọ nipa jibiti owo ati 419 to ṣe ni Niajiria, ti awọn amugbalẹgbẹ rẹ si ti wa ni panpẹ awọn bayii lorilẹede Naijiria.
"Nigba to n salaye bo se mọ pe awọn ti oun n pe ni obi oun kọ lo bi oun, Jọkẹ ni, ""Mo jade pẹlu ibatan mi kan, la ba pade ẹbi wa miran ti wọn jẹ agbalagba, ibatan mi taa dijọ jade wa n fi mi han baba naa pe, emi ni ọmọ Dokita Silva."
Bẹẹ ni ọrọ aawọ to n waye laarin gomina Seyi Makinde ti ipinlẹ Ọyọ ati awọn alaga ijọba ibilẹ mẹtalelọgbọn to wa nipinlẹ naa wa bayii.
̀ Fún àpẹrẹ: a lérò wípé àwọn ti a kọ si ojú ìwé yi,  àti bi a ti le pe ìkíni kankan a wúlò  fún yin.
Gov Ganduje Vs Sanusi: Ganduje kò lẹ́tọ̀ọ́ láti yan Emir mẹ́rin
Lọwọlọwọ, apapọ awọn to ti ni aarun naa ti pe 56,177.
Aare ana orile-ede South Africa teleri ,ti o si tun je eni ti o gba ami idanilola teleri, FW de Klerk ,ni  o n gba itoju ni  ile-iwosan latari aisan okan ,Lowolowo , iroyin roo wi pe ,Aare ana naa  n dahun si itoju , o si seese ki won da a sile ni ose to n bo.
Ó bi ekeji pé, ‘Ìwọ ńkọ́?
Yóo fẹ́ràn yín, yóo bukun yín, yóo sọ yín di pupọ, yóo bukun àwọn ọmọ yín, ati èso ilẹ̀ yín, ati ọkà yín, ọtí waini yín, ati òróró yín; yóo bukun àwọn mààlúù yín, yóo sì mú kí àwọn ẹran ọ̀sìn yín kéékèèké pọ̀ sí i, ní ilẹ̀ tí ó ti búra láti fún àwọn baba yín.
Ó tún fi kún un fún Sadoku pé, “Wò ó!
Mo fẹ́ di obinrin to dára júlọ lágbàyé-Bobrisky Kí ni ó gbé ọlọ́pàá dé ibi àjọ̀dún ọjọ́ ìbí i Bobrisky?
Ọjọgbọn Akinyẹmi ni lootọ ọpọ awọn eeyan lo ni ireti to ga nipa isejọba to n bọ lọna eleyi ti yoo wa labẹ isakoso ọgbẹni Cyril Ramaphosasugbọn awọn ọgbun mẹta kan wa lọna rẹ ti o gbọdọ sọra fun.
Bakan naa lo gbadura ki Ọlọrun tẹ ẹ si afẹfẹ rere.
Bee ilu Mexico ko tii bo lowo ile riri to sele losu kesan an ni eyi to se ku pa eniyan to din die ni eedegbeta.
Wọ́n ṣe iṣẹ́ àmì rẹ̀ ní ilẹ̀ náà,wọ́n sì ṣe iṣẹ́ ìyanu rẹ̀ ní ilẹ̀ Hamu,
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Iran:: Ẹ má fi taratara dúró níbì kan nítorí àwọn tó fẹ́ gbẹ̀san ikú Soleimani 6 Sẹ́rẹ́ 2020 Àkọlé àwòrán, Ẹ má fi taratara dúró níbì kan nítorí àwọn tó fẹ́ gbẹ̀san ikú Soleimani Oju ni alakan fi n ṣọri lọrọ eto aabo gba bayii lorilẹ-ede Naijiria- Olatunbosun Abolarinwa.
” Wọ́n rí i pé ẹnikẹ́ni kò wá ninu àwọn ará Jabeṣi Gileadi sí àjọ náà.
Ki iru eyi ma baa ṣẹlẹ ms ni ọkan lara awọn oṣere tiata Yoruba, Folukẹ Daramọla fi dide lati gbe eto kan kalẹ eleyii ti yoo maa ri si bi alaafia ati ilera yoo ṣe maa de ba awọn oṣere nigba ti ọjọ alẹ ba de.
Oluwo Ìwo ṣ'àlàye lori oye Emir
wọn óo rúwé bíi koríko inú omi àní, bíi igi wilo lẹ́bàá odò tí ń ṣàn.
Fasiti Usman Dan Fodio, (Usmanu dan Fodio university) Sokoto Oríṣun àwòrán, usman dan fodio university Ni ọdun 1975 ni wọn da fasiti yii silẹ gẹgẹ bii fasiti ilu Sokoto.
 irúkèrúdò ti wà nínú ìgbésí ayé ọmọ ènìyàn .
Fídíò náà sì ni àwọn ènìyàn tó lè ní ẹgbẹ̀rún lọ́nà àádọ́ta wò, tí àwọn bíi ẹgbẹjọ si ṣe alábàápín rẹ.
OLUWA wà pẹlu wa, ẹ má bẹ̀rù.
Ọja mẹta ọtọọtọ si ni Ọsinbajo ti pin owoya naa, tii se ẹgbẹrun mẹwa fun ontaja kọọkan.
Wo àwọn ayédèrú ìròyìn tó gbà'gboro kan lásìkò ìwọ́de #EndSARS Ìwọ́de EndSARS kìí ṣe ọ̀rọ̀ ẹlẹ́yàmẹ̀yà, ara ti kan àwọn èèyàn ni - Afenifere A ti gbé ìwádìí dìde lórí ìpànìyàn tó wáyé lásìkò ìwọ́de EndSARS- Ilé ẹjọ́ àgbáyé, ICC Ẹ wo ọ̀rọ̀ àwọn Wòlíì tó ti sọ àsọtẹ́lẹ̀ saájú nípa làásìgbò EndSARS Ẹni ọdun mẹtadinlọgbọn naa too jẹ olorin ati oluṣe ẹyinju aanu farahan nile ẹjọ lẹyin ọjọ mẹsan ti wọn fi ẹsun kan an pe o da omi alafia ilu ru.
Ó kó gbogbo fadaka ati wúrà tí ó rí ati gbogbo àwọn ohun èlò ilé OLUWA ati gbogbo ohun tí ó níye lórí ní ààfin, ó sì pada sí Samaria.
 Ẹni tí ó jẹ ́ bí asíwájú ogun pàtàkì yìí ni okùnrin alajagun Ìjẹ ̀ sà kan ti orúkọ rẹ ń jẹ ́ Ògèdèngbé .
23 Bélú 2020 Prophet Israel Oladele: Ẹ̀tanú pé Olùṣọ́ CCC Genesis Global kò fẹ́ Laide Williams-Oni ló ṣe rán an lọ́ sí ẹ̀wọ̀n ọdún kan20 Bélú 2020 EndSARS Protest: Wo bí olùwọ́de EndSARS, Eremosele Adene ṣe gba òmìnira lọ́wọ́ ọlọ́pàá20 Bélú 2020 Paul Okoye fàbínú yọ lórí ọ̀rọ̀ìkíni tí ìyàwó ìbejì rẹ̀ Lola Omotayọ kọ, ẹ wo ohun tó sọ19 Bélú 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Gẹgẹ bi iwoye rẹ, o ni ko si bi iye awọn to forukọsilẹ lati dibo lọdun 1983 to jasi 65,304,818 yoo ṣe ju iye eeyan (57 million) ti ajọ eleto ikaniyan fi sita gẹgẹ bi iye eeyan to wa ni Naijiria lọdun 1963.
"Oyeyemi fi kun un pé Olùfisùn ni Alhaji Fagbemi lo wa ayédèrú iwé ẹri náà láti dupò k bi ọmọ oye àti lati láti bọ sori àpèrè Oluwoye ti ilú Iwoye"" Ẹjọ náà si ti wà ni ẹka àwọn to n moju to ọ̀rọ̀ ajínigbe ti wà láti ṣe ìwádìí ọ̀rọ̀ náà."
Bẹ́ẹ̀ gẹ́gẹ́ náà ni àwọn akẹgbẹ́ rẹ̀ tó yẹ̀ kí wọ́n jọ lọ sùgbọ́n tí ìsẹ̀lẹ̀ Kaduna ti dí wọ́n lọ́wọ́.
Ẹwẹ, awọn eniyan ko jẹ ki wọn ri ekuru ọrọ yii jẹ tan lawo o, ọpọ gbajugbaja naa lo ti n darapọ mọ ifẹhonuhan yii ti awọn mii naa si ti n gbero lati bẹrẹ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 2020: Oloye Awurela Ifaleke ti wúré ọdún ìgbéga fún kóówá Oludasilẹ ijo INRI tun fikun un wi pe ọrọ aje yoo tubọ dẹnukọlẹ si nii.
Femi Okunronmu: Parliamentary pé wa ju ìṣèjọba presidential lọ
Oríṣun àwòrán, Reuters Mayor Lightfoot n ṣalaye pe aisan itọ ṣuga, aisan ọkan ati aisan to niiṣe pẹlu eroja eemi pọ laarinawọn ileto awọn alawọ dudu nibẹ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Iléesẹ̀ Ọlọ́pàá: Ọlọ́pàá 22 farapa nínú ìkọlù Shiite 17 Ìgbé 2018 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, O ti to ọjọ mejidinlogorun ti awọn ọmọ ẹgbẹ́ Shiite ti'n fẹ̀hónú hàn fún ìtúsílẹ̀ olori wọn Sheikh Ibrahim Zakzaky.
Nítorí oore-ọ̀fẹ́ ni a fi gbà yín là nípa igbagbọ.
Nítorí náà, OLUWA yóo fi ìyà jẹ Israẹli.
" Ó bẹ ̀ rẹ ̀ iṣẹ ́ eré ṣíṣe bí ọmọdé òṣèré ní ọdún 1964 ní eré "" makanjuola "" tí wọ ́ n máa ṣàfihàn rẹ ̀ ní amóhùnmáwòran ."
A ṣe tán láti yọ ìjìyà ikú kúrò nínú àbá ọ̀rọ̀ ìkórìra- Sẹ́nẹ́tọ̀ Sabi Darandaran Fúlàní kankan kò ṣí kúrò l'Ọ́ṣun - olórí Fulani Ènìyàn 27 lo ti bá iṣẹ̀lẹ̀ ọkọ̀ ofúrufú tó já rìnrìn ajò Àmúwá Ọlọ́run lásán ní ìṣẹ̀lẹ̀ tó wáyé ní Iba-Eburu Iba Oba Okunoye Ṣé ẹ mọ̀ pé Ẹ̀wà Sóyà, Ẹja Puffer, àti ewébẹ̀ yìí lè ṣekú pa'ni kíákíá?
m ni ojú mi déédé fọ́ níbi tí mo ti ń darí ọkọ̀ ni Ọrẹgun Ikẹja -LASTMA Yesufa Mamora, Lai Mohammed, Gbemi Saraki wà lára minista Buhari tuntun Òkìtì iyanrìn wó pa èèyàn méjí nílùú Ibadan Àgùnbánirọ̀ akọ̀ròyìn Channels náà ti dágbére fáyé látààrí ìkọlù Shiite l'Abuja Ni kete ti wọn kede esi ibo naa ni Johnson ti yonbo alatako rẹ ti wọn dijọ fa ipo naa mọ ara wọn lọwọ, eyiun Jeremy Hunt, to si se apejuwe rẹ bii ẹni to kun fun ọpọ ọgbọn to dara.
Ìyàwó Ọ̀ọ̀ni Ogunwusi kò bímọ tuntun A gbọ pe Mayegun se agbohunsafẹfẹ yii, bii ọsẹ tii se oju, to si fi se ẹlẹya lori ọrọ ti ko to nnkan.
    Mo rò pe ẹ o fẹ́ láti mọ bí a ti ṣe ọba wọn sí, yálà a fi ọba mìíràn jẹ ni tàbí a kò fi jẹ.
APC mókè nínú ìbò gómìnà níjọba ìbílẹ̀ mẹ́sàn-án l‘Ondo, PDP gba mẹ́ta Gómìnà Seyi Makinde bá ẹbí Isiaq Jimoh tó kàgbákò ikú òjijì dárò Àjọ elétò ìdìbò INEC ti lọ sinmi ní Ondo, ó tún di aago mẹ́sàn án kí wọ́n tó tẹ́síwájú Amọṣa, ohun kan wa to n ks agba oṣere yii lominu nipa ipo ti agbo ere sinima ati tiata lorilẹede Naijiria, paapaa julọ ilẹ Yoruba wa bayii.
Afurasi ọhun to n gbe labule Sabon Birni, to wa ni ijọba ibilẹ Gwarzo ni ipinlẹ Kano n jẹjọ ẹsun kan ṣoṣo, eyii to ni ṣe pẹlu ipaniyan.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Máákì fún ìbálópọ̀: Ọ̀jọ̀gbọ́n Richard Akindele rẹ́wọ̀n ọdún méjì he 17 Ọ̀pẹ̀̀ 2018 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 18 Ọ̀pẹ̀̀ 2018 Oríṣun àwòrán, ICPC Ile ẹjọ giga kan nilu Oṣogbo ti ran ọjọgbọn Richard Akindele ti ẹka iṣiro owo fasiti Obafemi Awolowo, Ile-Ife lọ ẹwọn ọdun meji lẹyin ti o ni oun jẹbi ẹsun ti wọn fi kan an.
Nigba to n gbara ta lori isẹlẹ naa loju opo Twitter rẹ, Anthony Joshua ni nnkan ti wa buru gan bayii.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Domestic Violence: Ìjà láàrin lọkọlaya sọ aya dèrò ọ̀run Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Domestic Violence: Ìjà láàrin lọkọlaya sọ aya dèrò ọ̀run 30 Ògún 2019 Ìja ojoojumọ laarin awọn mejeeji sú ara ilé, o sú ẹ̀bí àti iyekan paapaa.
 lákọkọ ́ , àwọn àkóràn kòní àwọn aamì wọ ́ n sì wà báyì fún ọdún 5 lọsí 20 ọdún .
Toyin fikun ọrọ rẹ pe igba marun un ni oun lọ mu omi bakan naa laarin iṣẹju mẹẹdogun lori itage.
Àgbàọ̀jẹ̀ agbábọ́ọ̀lu n nì Lionel Messi ló gbá àmìn ayò mẹ́ta wọle, tí ikọ̀ ẹgbẹ́ agbábọ́ọ̀lu náà fi jáwé olúborí nínú ìdíje náà.
Oko òkú rèé, níbití òkú ti ń jẹrà mọ́lẹ̀ fún àyẹ̀wò Ìgbà Marún-un ti Aisha Buhari ti tako ìjọba Buhari Wo àwọn ẹranko tí wọ́n máa figagbaga ni Egypt Àwọn àṣà àti ìse tó yọ obìnrin sílẹ̀ nílẹ̀ Yorùbá Ta ni awàdà rẹ̀ wúu yín lórí jù ní Yollywood?
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Kòkòrò oyin lé ọ̀pọ̀ èèyàn kúrò nílé l'órílẹ̀-èdè Cameroon 30 Bélú 2020 Oríṣun àwòrán, @BBOWT Inu ibẹru ni awọn eeyan to n gbe ni awọn agbegbe kan nilu Maroua, lorilẹ-ede Cameroon wa bayii, nitori bi kokoro oyin ṣe yabo wọn.
Alfa:Orúkọ miran ta tun n pe Malam ni Alfa, eyi tii ṣe olukọ to mọ keu, to si n kọ ni lẹkọọ rẹ.
Wákàtí mẹ́rìnlélógún ni ilé-aiyé fi nyí biri  lẹ́ẹ̀kan ṣoṣo, èyí tí nṣe ọjọ́ kan.
Akomolede àti Aṣa: Ọ̀rọ̀ Ẹ̀yán ni Bunmi Femi Amao ń kọ́ wa lórí ètò Akọ́mọlédè àti Àṣà lórí BBC Yorùbá
Ijoba apapo fi mule pe, awon ko san owo abetele tabi gba mabinu Kankan bi o ti le wu ko mo lati fi gba awon omo obinrin Dapchi ti o wa nipo ahamo awon omo ogun olote nigba kan ri sile.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Akomolede ati asa Yoruba: Ẹ wá kọ́ nípa àpòtí ìṣura èdè wa lórí BBC Yorùbá Ninu atẹjade ti Obasanjo fi sita lati kẹdun pẹlu aya oloogbe Walter Carrington, Arese Carrington ni eyi ti OgbeniKehinde Akinyemi to je olubadamoran Obasanjo fi sita ni Abeokuta.
Mo wá láti dínà fún ọ nítorí pé kò yẹ kí o rin ìrìn àjò yìí.
sepade pẹlu akẹgbẹ  rẹ ti o je igbakeji
Bakan naa ni ọrọ ri lọdọ ẹgbẹ awọn awakọ naa.
“Nígbà tí OLUWA Ọlọrun yín bá pa àwọn orílẹ̀-èdè run níbi gbogbo tí ẹ bá lọ, tí ẹ bá bá wọn jagun tí ẹ gba ilẹ̀ wọn, tí ẹ sì ń gbé ibẹ̀; 
idagbasoke ohun amayederun , atunse lori eto oro aje.
Ìgbẹ̀yìn ọkùnrin tó pa obìnrin 93 ni America Odunlade fijó bẹ́ẹ, Lizzy padà sọ́dún 2012, Toyin Abraham tọ̀ lẹ́ẹ̀mẹwàá Aisha ni Fatima ya fọnran naa lati le doju ti oun ni, ati pe ihuwasi ẹbi Daura ko ṣẹyin bi aarẹ Buhari ṣe ni ki wọn kẹru wọn kuro nile ijọba.
 Ṣùgb ́ ọn , ìgbìm ̀ ọ yí k ̀ unọ ̀ láti ṣe àseyọrí nínu gb ́ igba ìjọba fún ara wọn , b ́ i ́ o ti l ̀ ẹ j ́ ẹ wípé , ìyànjú wọn ṣe ikú pa Ọgágun murtala ramat mohammed .
Ọ̀wọ̀n ìkùukùu tí ó ń tọ́ wọn sọ́nà kò fìgbà kan kúrò lọ́dọ̀ wọn lọ́sàn-án, bẹ́ẹ̀ ni ọ̀wọ̀n iná kò sì fi wọ́n sílẹ̀ lóru.
ogbeni Muraina Ajibola lati ipinle  Oyo.
Igbakeji Gomina Banki Apapọ Naijiria (CBN) tẹlẹri, Obadiah Mailafia ni ajọ DSS ko kan an nipa fun oun lati sọ ohun ti oju oun kori.
Nínú ẹgbẹ́ ológun, aláwọ̀ dúdú kan ṣoṣo ni ó máa ń wà láàárín ológun mẹ́wàá.
"Amọ nigba to ya ni awọn ọdọ kan ja ẹgbẹ ọhun gba, ti wọn si bẹrẹ si ni lo fun iwa ipa, idigunjale, ati ipaniyan, bẹẹ ni wọn n da alaafia ilu ru Ohun tí o kò mọ̀ nípa Ebila ""One Million Boys"" àti Ekugbemi, olórí ẹgbẹ́ òkùnkùn méjì tó da ìlú Ibadan rú."
Makinde ni ṣe ni Ajimọba fẹ da ijọba oun to n bọ loro, ko ma baa ṣeeṣe ki oun ri nkan ṣe.
Wọn ti ka abadofin yii ti Sẹnetọ Muhammed Musa mu aba rẹ wa ni ipele kika meji bayii.
Lọjọ kinni, oṣu kẹta, ọdun 2003 ni wọn muu.
Padeborn 07, Germany); Semi Ajayi (Rotherham United, England)Awon agbaboolu Aarin(Midfielders):
Àwọn olódodo yóo gbilẹ̀ bí igi ọ̀pẹ,wọn óo dàgbà bí igi kedari ti Lẹbanoni.
Tinubu tun sọrọ lori bi awọn kan ninu ẹgbẹ oṣelu APC ṣe n sọ pe ki wọn yọ alaga ẹgbẹ oṣelu naa Adams Oshiomole nipo, o ni kosi ohun to jọ bẹ rara.
Immigration: Bàyìí ni iṣẹ́ ajé ṣe sọ àwọn ọmọ Nàìjíríà nù sí London
Wọn ni ọba yii parada di orisirisi nnkan bii ologbo, okuta ,titi de ori ọmọ tuntun, ti ọkan lara awọn ayaba gbe pọn, nigba tawọn oluwọde yii wọnu iyẹwu rẹ.
Àjọ NCDC tún ti kéde ènìyàn 245 míràn tó ní ààrùn Covid-19 l'órílẹ̀-èdè Nàìjíríà Duro Ladipọ, ìlúmọ̀ọ́ká òṣèré tíátà àti ọmọ àlúfà tí kò gbàgbé àṣà ìbílẹ̀ Ọwọ́ tẹ báàlẹ̀, Ṣinkó mẹ́tàdínlógún tó ń jí kùsà wà ní ìpínlẹ̀ Ọ̀ṣun Akinlade ni èyí lo jẹ́ ki àwọn òṣìṣẹ́ ilera pa ọkan pọ láti lọ fún ìyanṣẹ́lódì yìí, O fi kun un pé láti bii ọdún díẹ̀ sẹyin ni àwọn oṣìṣẹ́ náà ti s ọfun ìjọba nipa owo oṣù ti ko dọgba láàrin awọn ilé iwosan ikọni miran láwọn ìpínlẹ̀ to kù àti ilé iwosan ìkọ́ni ti ìjọba àpapọ̀.
Ohun tí à ń sọ kì í ṣe ohun tí eniyan fi ọ̀rọ̀ ọgbọ́n kọ́ wa.
Mo rọ̀ yín, ẹ̀yin ọmọbinrin Jerusalẹmu,bí ẹ bá rí olùfẹ́ mi,ẹ bá mi sọ fún un pé:Àìsàn ìfẹ́ ń ṣe mí.
Dokita ọmọ Naijiria jàjàbọ́ nílẹ̀ Ọba Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Abdulrafiu Adeniji sọrọ lori isorogun Dokita ati osìsẹ́ ilera Koko miran ti awọn eeyan tun fi n tasi minista yii lori ayelujara ni pé Aarẹ Buhari lọ si London fun ọpọlọpọ ọsẹ fun itọju ni eyi ti o fihan pe eto ilera Naijiria ko ti i goke agab tó.
Igbimo tuntun ohun ni yoo maa mojuto pipese eto ilera to peye jake-jado awon agbegbe nipinle Benue.
Ọ̀gá iléeṣẹ́ LASEPA tó ń mojútó àyíká ní ìpínlẹ̀ Eko, Dolapo Fasawe, sọ wí pé wọ́n ti fi àwọn afurasí náà sọwọ́ sí àwọn ọlọ́pàá, lẹ́yìn tí wan ti ìbùdọ ìgbáfẹ́ náà pa.
Awon olukopa ti won to aadojo ni won fun ni awon ohun elo lati bere ise ti won ko,nigbati  obirin kan omo –odun mejilelogorin ati eni ti o tayo julo laarin awon elegbe re si gba ebun iye owo ti o to ogorun naira lati apo alamojuto agba naa.
Jehoaṣi ọba Israẹli ranṣẹ sí ọba Juda pé, “Ní àkókò kan, ẹ̀gún ẹ̀wọ̀n kan ní Lẹbanoni ranṣẹ sí igi kedari ní Lẹbanoni pé, ‘Mo fẹ́ fẹ́ ọmọbinrin rẹ fún ọmọkunrin mi.
Ẹni tí ó pa ẹnu rẹ̀ mọ́pa ara rẹ̀ mọ́ kúrò ninu ìyọnu.
Ọmọ ọdọ kan lo tun pa ọga rẹ, Oloye Opeyemi Bademosi, ni ọjọ kọkanlelọgbọn, oṣu Kẹwaa, ọdun 2018.
Àwọn ọ̀tá rẹ bú ramúramù ninu ilé ìsìn rẹ;wọ́n ta àsíá wọn gẹ́gẹ́ bí àmì ìṣẹ́gun.
Lagos gas explosion: Ènìyàn 5, ilé 25 ilé ìtajà 16 àti àwọn ǹkan mírà lo bá ìṣẹ̀lẹ̀ iná naa rìn.
Ijoba orile ede Naijiria ti so pe inu ohun dun pe ohun ti
Nehemaya tí ó jẹ́ gomina, ati Ẹsira, alufaa ati akọ̀wé, ati àwọn ọmọ Lefi tí wọ́n kọ́ àwọn eniyan náà sọ fún gbogbo wọn pé, “Ọjọ́ mímọ́ ni ọjọ́ òní jẹ́ fún OLUWA Ọlọrun yín.
Yoòbá ò purọ́ nígbà tó wípé “a kìí fi oyin sẹ́nu ká tutọ́”.
O ni ipinlẹ Eko jẹ ipinlẹ gbogbo eniyan Naijiria ati pe ko si ẹni ti awọn eeyan n fẹ ti wọn ti ko le di ipo mu nipinlẹ Eko.
A kò lòdì sí kí àwọn mùsùlùmí ṣé ìwọ́de àyájọ́ Ashura-Ọlọ́pàá Nàìjíríà Ìdí rè é tí mo ṣe lọ sí South Africa fún àpérò ọrọ̀ ajé - Ezekwesili ṣàlàyé Ajímọ̀bí lè pe Ọlọ́run lẹ́jọ́ bí ìdájó kò bá tẹ́ ẹ lọ́rùn -Kọla Balogun Àwọn ọmọ Nàìjíríà 320 yóò padà wálé láti South Africa lọ́jọ́rú - Adama Abike Dabiri Erewa ni ijọba ti pese owo to to ogoji ẹgbẹrun sori ẹrọ ibanisọrọ ẹni kọọkan ki wọn fi kọkọ pe ẹbi ara ati ọrẹ wọn.
Ijọba buhari kun fun iwa ijẹkujẹ Awọn kan gbagbọ pe Aarẹ Buhari kuna ninu ẹ̀jẹ́ to jẹ lasiko ipolongo ibo pe iṣejọba oun yoo gbogun ti iwa ibajẹ ni Naijiria, ti oun yoo si fi ofin fiyajẹ awọn to ti ko owo ilu jẹ.
Wọn kò sì ní máa panirun lórí òkè mímọ́ mi mọ́.
Ṣùgbọ́n kí ni ìgbẹ̀hìn ìjà yìí jẹ́ fún bàbá mi?
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Mọ̀ síi nípa Oyedele Adedokun tó ya àwòràn Donald Trump tó lu ayélujára pa 3 Ọ̀pẹ̀̀ 2019 Oríṣun àwòrán, @Dok Àkọlé àwòrán, Oriṣii nkan daadaa ni a le fi ayelujara ṣe ni rere, kii ṣe fun iwa ibajẹ nikan.
 Won mo o mo ife to ni fun oti waini ati ounje aladun, o feran ko maa ko ewi ati awon ise ona miran.
Ayọ̀ ń bẹ fún ẹni tí ń ro ti àwọn aláìní:OLUWA yóo gbà á ní ọjọ́ ìpọ́njú.
Lataari gbogbo oro abele to romo akonimoogba agba iko Super Eagles Gernot Rohr pe yoo fiko Super Eagles sile lo tuko agbaboolu orile-ede Algeria.
Bí ẹnìkan bá sọ irú ọ̀rọ̀ yìí, kò sí òye ìmọ́lẹ̀ níbẹ̀.
Ní ọjọ́ kan, Beṣasari ọba, se àsè ńlá kan fún ẹgbẹrun (1,000) ninu àwọn ìjòyè rẹ̀, ó sì ń mu ọtí níwájú wọn.
mo rí i tí àwọn mààlúù meje kan tí wọ́n sanra rọ̀pọ̀tọ̀ rọ̀pọ̀tọ̀, tí ara wọn sì ń dán, ti inú odò náà jáde wá, wọ́n sì bẹ̀rẹ̀ sí jẹ koríko létí odò.
Dafidi lọ sọ́dọ̀ Ahimeleki alufaa, ní Nobu.
Iko agbaboolu Juventus lo soro ohun di mimo lori ero ayelujara iko ohun lojo Aje(Monday).
Ẹwẹ̀ lọjọ Iṣegun to jẹ pe lẹyin ọjọ mẹta lera ti iye awọn to ko Covid-19 ni Naijiria ṣẹṣẹ ja wa silẹ, o tun ti gbera sọ pada lọjọ Iṣẹgun.
Mide Martins Ọmọbibi inu gbajugbaja osere, Funmi Martins ni Mide Funmi Martins Abiodun.
 wọn ò kọ ́ kọ ́ mú un lọ ́ kùn-ún-kúndùn rárá .
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Iwa-ipa Fulani darandaran: ọlọpa fi panpẹ ọba mu eniyan meji 13 Èrèlè 2018 Oríṣun àwòrán, AFP Àkọlé àwòrán, Opolopo ijamba loti sele latari aigboraeniye laarin awon Fulani darandaran ati agbe Ile ise ọlọpa ni wọn ti mu Fulani darandaran kan ati agbẹ oloko kan ninu isẹlẹ to waye lagbegbe guusu Akure, agbẹnusọ ajọ ọlọpa ipinlẹ Ondo fi idi rẹ mulẹ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù PDP vs Tinubu: Aṣíwájú Tinubu lọ́ra láti fi wá kọ́ èébú 22 Èbibi 2019 Oríṣun àwòrán, Twitter Àkọlé àwòrán, Asiwaju Ahmed Tinubu fẹ̀sùn kan PDP pé wọ́n fẹ́ fi tipátipá mú Atiku Abubakar jẹ ààrẹ orílẹ̀èdè Naijiria.
Bí ó bá fẹ́ ẹ sọ́nà fún ọmọ rẹ̀ ọkunrin, ó gbọdọ̀ ṣe ojúṣe rẹ̀ gẹ́gẹ́ bí baba rẹ̀ gan-an.
igbalode ayara bi asa(Computers) lo ti baje patapata, awon oogun ati irinse
Dambazau wa fikun un oro re pe, aare Muhammadu Buhari kedun pelu ebi ati ara
Agbẹjọro wọn tiẹ ṣapejuwe igbesẹ ijọba naa lati fi wọn si ahamọ iwa ta ni yoo mu mi eleyi to lodi si ofin.
Ìjọba Èkó figbé ìkìlọ̀ ta JAMB yóò má gbé èsì ìdánwò jáde látòní Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, '500 level'' ni mo wà nígbà tí mo di adélé Ọba' Amọ, Ireke Onibudo to jẹ iwe kika Yoruba, ni wọn fi se fiimu ni ọdun 2009, sọ nipa itan igbesi aye ọkunrin akinkanju ati bi o ṣe kuro nipo alaini di ọba.
”Lójú kan náà, ìkùukùu dúdú dà bò ó.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Peters Ijagbemi dá àrá lórí ètò 'Ṣé o láyà' ti BBC Yorùbá lọ̀sẹ̀ yìí Akinsanya ṣalaye pe ọkan ninu wọn (Beidu) lo ranṣẹ pe awọn meji to ku ki wọn to jọ fọwọsowọpọ ji Maalu naa.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Nigeria 2019 Elections: Ọkọ àti ìyàwó sọ àsọtẹ́lẹ̀ tani yóò wọlé nínú PDP tàbí APC Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Nigeria 2019 Elections: Ọkọ àti ìyàwó sọ àsọtẹ́lẹ̀ tani yóò wọlé nínú PDP tàbí APC 11 Èrèlè 2019 BBC Yoruba ba idile kan sọ̀rọ̀ to jẹ́ wi pe alatako ni ọkọ ati iyawo lori ọrọ oṣelu.
O ni awọn meji miiran lo fara pa nibi iṣẹlẹ naa, ti wọn si n gba itọju ni awọn ni ile iwosan kan ni Ajah.
Wọn ma n jẹ Egbo pẹlu ata dindin to ni alubọsa, epo pupa, ẹja yiyan ati tomati ninu.
'Obinrin jẹ amuludun' Fọlọrunṣọ Alakija: Obinrin nilo imọ 'Awọn obinrin nilo ajọ iranwọ fun oṣelu' Angelique kidjo pe fun anfani f'awọn obinrin Tani otutu ma n mu ju laarin Ọkunrin ati Obinrin?
Ẹnìkan ninu wọn bá dá a lóhùn pé, “Olùkọ́ni, ọmọ mi tí ẹ̀mí èṣù ti sọ di odi ni mo mú wá sí ọ̀dọ̀ rẹ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Mo máa n forin mi kìlọ̀ ìwà ìbàjẹ́ láwùjọ ni -Hameen Ejiogbe wa gbe osuba kare fun aarẹ ẹgbẹ ọlọkọ ero nilẹ wa, Alhaji Najeem Yaasin fun aayan rẹ lati ri daju pe alaafia jsba pada ninu ẹgbẹ awakọ ero nipinlẹ Ọyọ.
 Awọn ọmọogun wa n ja fitafita lati sẹ eegun ẹyin awọn adunkoko mọni, bẹẹ si la tun n sisẹ kara lati se agbekalẹ ibasepọ okoowo to jẹ ọfẹ ati eyi ti ko ni magomago ninu.
bí mo bá pe isà òkú ní baba,tí mo sì pe ìdin ní ìyá tabi arabinrin mi,
Lọ́wọ́lọ́wọ́ bi a ṣe n kó ìròyìn yìí jọ àwọn ènìyàn ti ṣe àgbékalẹ̀ mílíọ̀nù mẹ́fà náírà.
"Oluwatoyin, pẹlu iwuri ni ""ọmọ daada ni Tani, o si ni ọpọlọ pipe, sugbọn boya nitori emi ko ta ayo chess ri, mo kan ro pe ere ayo ti wọn n ta nile iwe ni, n ko lero pe o lee ta ọmọ mi yọ si gbangba bi eyi."
Wọ́n bẹ̀rẹ̀ sí sọ pé, “Ṣebí Jesu ọmọ Josẹfu ni; ẹni tí a mọ baba ati ìyá rẹ̀?
Ó sì ní àwọn akọni ọmọ ogun ní Jerusalẹmu.
Ọwọ ologun tẹ afurasi ọdaran ni Nasarrawa Wahala Benue: 'Operation Cat Race' ko lee yanju ikọlu darandaran Oríṣun àwòrán, Getty Images Igbimọ ICRC lo se alarina ijiroro laarin ileese ọtẹlẹmuyẹ Naijiri ati ẹgbẹ Boko Haram naa.
'Ọ̀rẹ́kùnrin ọmọ Yahoo ló fi Khadijat ṣe ògùn owó' Wo Ọ̀jọ̀gbọ́n Ẹlẹka tó ń díje fún ipò gómìnà Ile isẹ ibaraẹnisọrọ naa fikun wipe awọn to se ifẹhọnu han naa ba ọpọlọpọ nkan jẹ, ti awọn osisẹ wọn naa si farapa.
Orilẹede Liberia ati Sierra Leone tun lo kan tawọn oṣiṣẹ eleto ilera tun ti ko aarun covid-19 ju.
OLUWA ní,“Ẹ gbógun ti ilẹ̀ Merataimu, ati àwọn ará Pekodi.
Fún ọjọ́ meje ni ẹ óo fi máa rú ẹbọ ìwẹ̀nùmọ́ fún pẹpẹ náà tí ẹ óo sì máa yà á sí mímọ́; bẹ́ẹ̀ ni ẹ óo ṣe yà á sọ́tọ̀ fún lílò.
Ẹ̀ ń sọ pé ojú ń tì yín nítorí pé wọ́n kẹ́gàn yín;ẹ ní ìtìjú dà bò yín,nítorí pé àwọn àjèjì ti wọ ibi mímọ́ ilé OLUWA.
BBC Yorùba bá Ọlọ́fà tì ìlú Ọ̀ffà, Ọba Muftau Gbadamosi, Esuwoye kejì sọ̀rọ̀ pe ko kí Ọọniriṣa kú ọdún, àṣèyí sẹ̀míì.
Kidnapped Girl: Iyá Ikimot ní lẹ́yìn ọ̀pọ̀ ìdààmú àti owó láti wá ọmọ náà, òun sọ ìrètí nù
 láti Ìkàrẹ ́ , ìlú Ọ ̀ gbàgì wà ní apá ìwọ ̀ oòrùn tí ó sì jẹ ́ pé títì tí a yọ ́ ọ ̀ dà sí ló so ó pọ ̀ mọ ́ ìlú Ìkàrẹ ́ tó jẹ ́ ibùjókòó ìjọba ìbílẹ ̀ àríwá Àkókó .
Lọwọ lọwọ bayii, Oluwo ti gbe awọn afọbajẹ naa lọ sile ẹjọ, ti awọn afọbajẹ naa si ti gbe Oluwo lọ sile ẹjọ miran.
Èyí làwọn ohun tí a mọ̀ nípa ìṣẹ̀lẹ̀ ikú Barakat Bello, táwọn kan fipá bálòpọ̀ ní Ibadan Àkọlé àwòrán, Eyín ọ̀ọ́kán mi ni Barakat tí wọ́n pa lẹ́yìn tí wọ́n fipá bá a lòpọ̀- Ìyá Barakat Ni ọjọ Iṣẹgun ni okiki iroyin kan kaakiri igun mẹrẹẹrin orilẹede Naijiria nipa iku omọdebinrin kan tawọn kan gba ẹmi ẹ lẹyin ti wsn fi ipa baa lo pọ.
Lọpọ igba, wọn ni wọn a maa kọ ile alamọ sibẹ, ti ijọba a si maa mu awọn ohun amayederun miran ba wọn nibẹ, bii ile iwe ati ile iwosan.
Àwa náà wá wọkọ̀ ojú omi ní Filipi lẹ́yìn Àjọ̀dún Àìwúkàrà, a bá wọn ní Tiroasi lọ́jọ́ karun-un.
won jẹbi la ti yọ kuro lẹnu nisẹ, ti awon olopaa  mẹ́rìnlélógún yooku si gbọdọ foju
Àwa di òmùgọ̀ nítorí ti Kristi, ẹ̀yin wá jẹ́ ọlọ́gbọ́n ninu Kristi!
Jehu pa gbogbo àwọn ìbátan Ahabu tí wọn ń gbé Jesireeli ati àwọn iranṣẹ rẹ̀, ati àwọn ọ̀rẹ́ rẹ̀ ati àwọn alufaa; kò dá ọ̀kan ninu wọn sí.
''Tí a bá ní káwọn èèyàn jókòó sílé nítorí coronavirus, ebi àti olè jíjà ma pọ̀'' Mò ti ya ara mi sọ́tọ̀ bí mo ṣe dé láti America nítorí coronavirus- Soyinka Ìjọba ìpínlẹ̀ Eko ti ni ki gbogbo ọjà wà ni títì pa, sùgbọ́n.
O kilọ pe oun yoo gba biliọnu mẹwaa owo naira ti ajọ naaba tun di oun lọwọ iṣẹ.
Lati kekere ni Bianca ti n gba bọọlu ẹlẹyin ori tabili ni eyi to si ti gba ami ẹyẹ bii WTA Premier ni Indian Wells ati Toronto to si gba ẹbun owo rẹpẹte si.
Ní ti Jesebẹli, OLUWA ní, ajá ni yóo jẹ òkú rẹ̀ láàrin ìlú Jesireeli.
Ọgbẹni Omotosho ni idi ni yii tawọn oludokowo ati awọn arinrinajo fi n ṣafẹri ilu Eko.
Ọgagun Buratai parọwa yi nibudo Camp Zero, tii se ibujoko ibuba tẹlẹ f'awọn adunkoko mọni naa ninu igbo Sambisa lasiko abẹwo to se sawọn ọmọogun naa.
Bí a bá wí pé iṣu ń wù wa jẹ, wéré ni iṣu a bọ́ sílẹ̀ níwájú wa tí yóò maa hooru nínú àwo, bí a bá wí pé ìrẹsì ń wù wá jẹ òun ọbẹ̀ adìẹ̀, kí á wo iwájú kí a rí ìrẹsì àti adìẹ tí wọn ti dín tí ó gbẹ tẹ́kítẹ́kí ni.
Wọ́n fi ranṣẹ sí àwọn baálẹ̀ agbègbè, àwọn gomina, ati àwọn olórí àwọn agbègbè, láti India títí dé Etiopia, gbogbo wọn jẹ́ agbègbè mẹtadinlaadoje (127).
“Àwọn aláìní a máa ṣe làálàá káàkiri,bíi kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ inú aṣálẹ̀,wọn a máa wá oúnjẹ fún àwọn ọmọ wọn ninu aṣálẹ̀.
Awon to wa ninu egbe JOHESU ni awon osise eleto ilera , yato si awon dokita ati olutoju eyin, ni won ti  gunle iyanselodi alailojo lati fehonu han lori eto inawo ati ise akanse nile iwosan ti ijoba apapo .
” Esau bá dá a lóhùn pé, “Èmi ọmọ rẹ ni.
Aṣofin naa tun ki Kabiyesi Aromọlaran ku oriire, o ṣapejuwe irinajo wọn wa si ilu Eko ati Ile Igbimọ Aṣofin naa gẹgẹ bi eyi to ni aami pataki nitori igba naa bọ si asiko ti awọn ọmọ ẹgbẹ ati awọn olugbe Ipinlẹ Eko lapapọ n ṣayẹyẹ ọdun mẹẹdogun ti Ọba Eko, Ọba Rilwan Babatunde Akiolu gun apere baba-nla wọn.
DC, so pe oun ko nigbagbo pe ogbeni Kabila yoo fi eto iselu sile tabi pe ko ni
’ OLUWA bá dáhùn pé, ‘Lọ tàn án jẹ, o óo ṣe àṣeyọrí.
Oko yii jabo lataari ile riri to sele lasiko naa.
Nígbà tí wọ́n rí ìwé Jehu gbà, àwọn olórí Samaria pa gbogbo àwọn ọmọ Ahabu, wọ́n sì kó orí wọn sinu apẹ̀rẹ̀ lọ fún Jehu ní Jesireeli.
Risikat ni igba toun ti kuro lọdọ baba Kausara, ile awọn obi oun loun ko lọ ti wọn si n gbọ jijẹ mimu.
Awọn oniroyin ti ọrọ ṣe oju wọn ni, ṣe ni awọn ọlọpaa de ofiisi naa ti wọn si sọ fun awọn oṣiṣẹ to wa ninu awọn ofiisi to yii ka ki wọn fi ijoko wọn silẹ lẹyin ti wọn si tii pa.
Tí ó bá yíwọ, ère náà kò leè dára, àwọn tí yóò sì kopa ninu rẹ, ara wọn kò leè dá saka láti ṣeé.
Dìde, olùfẹ́ mi, arẹwà mi,jẹ́ kí á máa lọ.
” Ehanire fikun pe iye eeyan to ni arun Coronavirus ni Naijiria ti le ni ẹgbẹrun lọna aadọrin, 70,000, ti awọn eeyan to le ni ẹgbẹrun marundinlaadọrin, 65,242 si ti ri iwosan gba.
Itẹ oku Vault Garden, to wa ni Awoyaya lẹba Mayfair Garden ni adugbo Lekki nilu Eko ni wọn sin asofin Braimoh si.
Kí OLUWA fi ìfẹ́ ńlá ati òdodo rẹ̀ hàn fun yín.
Àkọlé àwòrán, Pelu ojo to n ro naa ni awon eniyan si duro si fun iwode naa Gbogbo awon to jade ninu ojo ni Eko n pariwo 'No to Rape' ni.
Ifilọlẹ ẹgbẹ alajumọse n waye n'ipinlẹ Ogun
OLUWA yóo ṣírò rẹ̀ mọ́ wọnnígbà tí ó bá ń ṣe àkọsílẹ̀ àwọn eniyan rẹ̀ pé,“Ní Sioni ni a ti bí eléyìí.
Alagba Fasanmi, nigba aye rẹ, jẹ agba oselu to de ipo Sẹnatọ, oun si ni asaaju fun ẹgbẹ ọmọ bibi ilẹ Yoruba kan, Ilosiwaju Yoruba.
Bí ojú ṣe ro ẹnìkan ni ẹ̀rù ba ẹlòmíì.
" Ọpọ ni ara n ni lori isẹ aanu ti Foluke Daramola n ṣe, ọpẹ iru wa to wa lẹyin rẹ, awọn kan ro pe o n wa okiki, lo ṣe n ṣaanu.
Máa jẹ ẹ́, ìwọ ni a fi pamọ́ dè, pé kí o jẹ ẹ́ ní àkókò yìí pẹlu àwọn tí mo pè.
Ṣugbọn ègún ni fun yín bí ẹ kò bá tẹ̀lé òfin OLUWA Ọlọrun yín, tí ẹ bá yà kúrò lójú ọ̀nà tí mo pa láṣẹ fun yín lónìí, tí ẹ bá ń sin àwọn oriṣa tí ẹ kò mọ̀ rí.
A wo saàkun bí ǹkan ṣe ń lọ ni gbogbo àgbáyé, a sì wò o pé orílẹ̀-èdè wo lọ̀rọ̀ náà kan jù?
Ni bayii, akọroyin BBc Yoruba mu iroyin wa latọdọ akọnimọọgba Super Eagles, Gernort Rohr.
Seyi, Frodd àti Omashola dèrò ilé lórí ètò BBNaija Ko si ohun to ba ni ibẹrẹ, ti kii lopin, bẹẹ si lọrọ ri pẹlu eto Big Brother Nigeria to ti n waye lati osu mẹta sẹyin.
 wọ ́ n yí orúkọ iké-ẹ ̀ kọ ́ yí padà ondo state polytechnic ní ọdún 1990 .
Tí àwọn bá si fẹ́ ara wọn kò léèwọ̀; owó wọn yόò má-a ṣubú lόrí owó, ọlá lόrí ọlá, ìgbéga wọn yόò sì má-a wà lόrí ìgbéga.
fafiti naa paapaa julo lati se atunse si awon popo oju ona ogba Fafiti  ati yara ikawe-yawe fun awon akekoo.
Mose ya ìlú mẹta sọ́tọ̀ ní ìhà ìlà oòrùn odò Jọdani, gẹ́gẹ́ bí ìlú ààbò, 
Àwọn ọmọ Israẹli dàbí àjàrà dáradára tí ń so èso pupọ.
” Ó bá bi wọ́n léèrè pé, “Àwòrán ati àkọlé ta ni ti ara rẹ̀ yìí?
Pupo awon ile-ise iroyin ni won so pe, awon oludibo ti wa  lori ila lati nnkan bi agogo marun-un owuro ni awon ipago idibo, latari ati dibo ni kete ti eto idibo ba ti bere ni agogo meje.
Flaco naa jẹ ajijangbara ayika ni Panama.
Yakubu ṣalaye pe awọn tun doola ẹmi awọn eeyan mẹta miran ti wọn jigbe loju ọna naa ni ọjọ kẹrindinlọgbọn, oṣu Kẹjọ.
Àwọn tí à ń pè ní Refaimu yìí pọ̀, wọ́n lágbára, wọ́n sì ṣígbọnlẹ̀ bí àwọn ọmọ Anaki, àwọn òmìrán.
Kí ẹ mọ̀ lónìí, kí ó sì da yín lójú pé, OLUWA ni Ọlọrun; kò sí ọlọrun mìíràn mọ́ ní ọ̀run ati ní ayé.
Joṣua bá pe àwọn ọkunrin mejila tí ó ti yàn tẹ́lẹ̀ ninu àwọn ọmọ Israẹli, ẹnìkọ̀ọ̀kan láti inú ẹ̀yà kọ̀ọ̀kan; 
ti o se Pataki ti ijoko naa yoo maa jiroro le lori ni bi won yoo se wa ojutu si
Ìwọ Babiloni, tí odò yí ká, tí ìṣúra rẹ pọ̀ lọpọlọpọ,òpin ti dé bá ọ,okùn tí ó so ayé rẹ rọ̀ ti já.
Ẹ dẹkun ere sísá lójú pópó láti dẹkun ìjàmbá- FRSC Ààrẹ Buhari wọ́gilé kí àwọn òṣìṣẹ́ ìjọba máa wọ ọkọ̀ bàálù olówó gọbọi A ti gbé kọ́kọ́rọ́ sẹ́nu ibodè Nàìjíríà kí ọrọ̀ ajé wa leè gbé pẹ́lí- ìjọba àpapọ̀ Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Gbogbo ìlú ló sì mọ̀ wọ́n papọ̀ pé ọ̀rẹ́ gidi ni wọ́n ń ṣe.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Mo ti gba kádàrá lórí bí Ọlọrun ṣe dá mi' Oludari ajọ NNPC naa ṣalaye pe ko si idi fun araalu lati ko aya soke lori boya ijamba ina naa yoo ṣokunfa ọwọngogo epo rọbi nitori, gẹgẹ bi Ọmọwe Baru ṣe sọ, ajọ NNPC ni epo bẹntiro atawọn ẹya epo miran ninu aka rẹ, eleyi ti yoo to orilẹede Naijiria lo fun ọjọ marundinlaadọta bi omiran ko ba tilẹ wọle.
Al-Shabaab gbẹsẹ le bọọlu gbigba lorilẹede Somalia
Iwadii BBC fihan pe, ile iwosan naa ni awọn iyara ti awọn alaisan to ba lowo lọwọ le e wọ si pẹlu ẹbi wọn.
Bí mo bá ní kí wọn túká lọ sí ilé wọn ní ebi, yóo rẹ̀ wọ́n lọ́nà, nítorí àwọn mìíràn ninu wọn ti ọ̀nà jíjìn wá.
Bi eeyan ko ba mọ awọn agbabọọlu Arsenal tẹlẹ ri yoo ro wi pe ikọ mi ni Mikel Arteta ko si ori papa pẹlu bi wọn ti ṣe n ṣigun ba awọn alatako wọn.
Bi ẹ ba fi ọkan si iye odo to wa lẹyin biliọnu 116,100,000,000.
Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Gun control in Nigeria: Wo ọ̀nà márùn ún tí o lè gbà dábòbò ara rẹ lọ́wọ́ ìjàmbá!
A óo gbá gbogbo wọn jọ pọ̀ sinu kòtò bí ẹlẹ́wọ̀n,wọn óo wà ní àtìmọ́lé ninu ẹ̀wọ̀n.
 Aare wa gbadura pe, Olorun yoo te oloogbe naa safefe rere.
 Ọpọlọpọ aṣa lo n polongo pe ibale obinrin ṣe pataki ṣaaju igbeyawo, eyi si lo maa n mu ki awọn obinrin kan o tun awọ fẹlẹfẹlẹ to bo ẹnu iho oju ara wọn ṣe."
osise ipinle naa lati lee wa ọna ti won yoo maa gba lati fi san ekunwo naa.
Ó wọ inú ọgbà náà, òun ati àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀.
Bakan naa ni awọn eniyan kesi awọn ara Surulere lati dibo yọ ọ kuro ni ipo, nitori ko ṣe ifẹ awọn araalu mọ.
Ó lè gbìyànjú láti fi ẹ̀tàn pa àrankàn rẹ̀ mọ́,ṣugbọn ìwà burúkú rẹ̀ yóo hàn ní àwùjọ gbogbo eniyan.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ishaq Oloyede ní àjọ JAMB ń gbé ènìyàn ọgọ́rùn ún lọ ilé ẹjọ́ nítorí màgòmágó ìdánwò 4 Èbibi 2019 Oríṣun àwòrán, Pulse Adari ajọ JAMB, Ọjọgbọn Ishaq Oloyede, ni ajọ naa ti ṣetan lati gbe ọgọrun eniyan to kopa ninu idanwo aṣewọle lọ awọn ile iwe giga (UTME) lọ ile ẹjọ lori ẹsun magomago idanwo.
Adari Ajọ NAN, Danielson Akpan lasiko to ba BBC Yoruba sọrọ ni ijọba ti ile iwe fasiti Adekunle Ajasin (AAUA) ati Osustech pa ni ilu Okitipupa nitori awọn akẹẹkọ fẹhọnu han lori bi wọn se fi owo kun owo ileewe wọn.
Jide Sanwo-OluCleared - O yege Ipinlẹ Ọyọ: 1.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ìtàn ayé Ọba Seriki Abass ti Badagry, tó ní aya 128, ọmọ 144 Ilé ẹjọ́ yá lórí òfin CAMA tó fẹ́ gba àkóso ilé ìjọsìn, tẹ ẹ̀tọ́ aráàlú mọ́lẹ̀ - SERAP Wo bí o ṣe le fi orúkọ sílẹ̀ fún ìgbani ṣíṣẹ́ ológun Nàìjíríà tó bẹ̀rẹ̀ Ọmọdé 5 àti àgbà 40 bómi òkun lọ, 37 mórí bọ́ lásìkò tí ẹ́ńgínì ọkọ̀ ojú omi gbiná Kò sí ọ̀nà láti jáde tàbí wọlé sí Mali, ikọ̀ ológun ọlọ́tẹ̀ kéde ìṣédeWo ibùdó arẹwà tí ọ̀pọ̀ èrò ń ya lọ ní Abuja Obìnrin kan dèrò ilé ẹjọ́ lórí ẹ̀sùn pé ó fi ọ̀bẹ rẹ́ ọmọ rẹ̀ lọ́rùn Makinde ti sọ̀rọ̀ lẹ́yìn tí asekúpani Akinyele sálo mọ́ àwọn ọlọ́pàá lọ́wọ́ ní àhámọ́ Olólùfẹ́ mi ṣèèsì fi ọkọ́ gbá mi sí gọ́tà, mo rò pé ọlọ́jọ́ dé ni - Iya Osogbo Babalawo Adewole ni fifi Ogun bura wa lara awọn ilana ti awọn to ba fẹ darapọ mọ ikọ Amọtẹkun gbọdọ tẹle gẹgẹ bi Sunday ṣe sọ.
Titi di bi a ti ṣe n sọrọ yii, owo tabua ati ajẹmọnu lofin bu fawọn to dipo mu tẹlẹ yii.
Ikede iyalẹnu yi jẹyọ pẹlu bi ayẹyẹ iwuye alaragbayida ti wọn yoo ṣe ti ṣe ku ọsẹ kan.
Nígbà náà ni Tomasi tí wọn ń pè ní Didimu (tí ìtumọ̀ rẹ̀ jẹ́ “Ìbejì”) sọ fún àwọn ẹlẹgbẹ́ rẹ̀ pé, “Ẹ jẹ́ kí á lọ kí àwa náà lè bá a kú.
"Ko si ẹni fẹ ṣe jagidijagan to ba ri iṣẹ ṣe.
Bí a bá wo inú Ìwé Mímọ́, a óo rí i pé àwọn wolii ti kéde ìyìn rere náà tẹ́lẹ̀ rí.
Ṣáájú ní igbákejì ààrẹ Yemi Osinbajo ti ṣe àbẹwò sí ìpínlè náà.
Síbẹ̀, ohun tí ó ń fa àdánù ní agbègbè kan náà lè mú wọn pọ̀ ní agbègbè mìíràn.
Ṣe ni gbogbo ogiri kun fun idọti ẹjẹ ati igbẹ.
“Ẹ̀yin ará, dandan ni pé kí ohun tí Ẹ̀mí Mímọ́ sọ ninu Ìwé Mímọ́ láti ẹnu Dafidi ṣẹ, nípa ọ̀rọ̀ Judasi tí ó ṣe amọ̀nà àwọn tí ó mú Jesu.
Aare ile igbimo asofin Naijiria, dokita Bukola Saraki ti seleri pe won yoo lo sagbekale iwe eto isuna odun 2018 fun aare Muhammadu Buhari lojo Eti(Friday).
Ṣugbọn bí kò bá sí ohun kan tí a lè rí dìmú ninu ẹ̀sùn tí wọ́n fi kàn mí, ẹnikẹ́ni kò lè fi mí wá ojurere wọn.
Owo to to biliọnu mejilelọgọrin o dín diẹ ni awọn igbimọ oluwadii ile igbimọ Aṣofin n ṣe iwadii rẹ.
Ọlọrun tún mú kí Resoni ọmọ Eliada dojú ọ̀tá kọ Solomoni, sísá ni Resoni yìí sá kúrò lọ́dọ̀ Hadadeseri, ọba Soba, tí ó jẹ́ ọ̀gá rẹ̀.
Oríṣun àwòrán, Instagram/ajimobi Wọn ni Ajimobi ti a mọ si ẹni to kọ Oyo ode oni ṣe iṣẹ ribiribi, o si tun sin ipinlẹ rẹ fun odidi ọdun mẹjọ, ko si wa yẹ ki wọn ro iku ro o, paapaa lasiko yii ti o ti gba igbega lati tukọ ẹgbẹ oṣelu APC ni gbogbo Naijiria."
O dàbi ẹni pé mo nilò Dokita, o yẹ ki ọmọ mi gboye imọ iṣegun oyinbo, ti o ba si kùna nínu imọ isiro, o túmọ si pé ẹkọ imọ isìro owó ni ẹni náà yóò kangun sí.
Ṣugbọn nígbà tí wọ́n kígbe pé OLUWA, OLUWA gbé olùdáǹdè kan dìde fún wọn tí orúkọ rẹ̀ ń jẹ́ Otinieli, ọmọ Kenasi, àbúrò Kalebu, òun ni ó gbà wọ́n kalẹ̀.
Ohun tí ẹ óo ṣe nìyí: nígbà tí àwọn alufaa ati àwọn ọmọ Lefi bá kúrò lẹ́nu iṣẹ́ wọn ní ọjọ́ ìsinmi, ìdámẹ́ta ninu wọn yóo máa ṣọ́ ẹnu ọ̀nà ilé OLUWA, 
Ọjọ́ ìsinmi náà yóo bẹ̀rẹ̀ láti ìrọ̀lẹ́ ọjọ́ kẹsan-an títí di ìrọ̀lẹ́ ọjọ́ kẹwaa.
Àwọn eniyan bá wá fi ojú ara wọn rí ohun tí ó ṣẹlẹ̀.
Ìròyìn Yàjóyàjó - Ààrẹ Buhari yan Ibrahim Gambari gẹ́gẹ́ bíi olórí àwọn òṣìṣẹ́ lọ́fíìsì Ààrẹ Damilọla Ajayi: Ọ̀dá owó ló ṣún mi dé ìdí lílo ìyarun bíi fèrè Wọn ni eleyii ti ajọ to n sakoso oogun ati ounjẹ lorilẹede Naijria, NAFDAC n ṣe ayẹwo rẹ lọwọlọwọ jẹ oogun to n to n koju ikọ, eleyii to jẹ ọkan ninu awọn ami to ma n fihan pe eniyan ni arun Coronavirus.
Àwọ́n oúnjẹ márùn-ún tí ẹ gbọdọ yẹwò dáradára ki ẹ tó jẹ 1.
Ìdí tí mo fi ń ṣe ayẹyẹ ọjọ́ ìbí 35 lọ́dọọdún rèé- Allwell Ademola Iléẹjọ gíga jùlọ da ẹjọ́ SDP àti PDP nù, wọ́n ní Yahaya Bello ló wọlé ìbò gómìnà Kogi Ìjà d'ópin, fún ìgbà àkọ́kọ́, bàálù gbéra láti Israel lọ sí UAE Wọ́n ti sún ìdájọ́ àwọn sójà tó pa ìyá àti ọmọ ní ọdun 2018 sí oṣù tó m bọ̀ Máa gbé kẹ̀kẹ́ rẹ lọ, àwọn akọròyìn kọ̀ ìpàkọ́ sí Femi Fani Kayọde Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Wo bí Sunday Orimola ṣe gba ikú ẹranko kú ní Ifon ni Ondo lórí ọ̀nà àtijẹ Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí 6:18 Fídíò, Akomolede: Bolaji Faleke ni Olùkọ́ tó ń kọ́ wa ní àṣà oge ṣiṣe lórí BBC Yorùbá, Duration 6,181 Owewe 2020 6:10 Fídíò, Yoruba Language: Akomolede ati Asa Yoruba tọ̀sẹ̀ yí rèé lẹ́nu olùkọ́ wa, Duration 6,1030 Ògún 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
OLUWA ní, “Sọ fún wọn pé, èmi OLUWA Ọlọrun Israẹli ní, ‘Gbogbo ìkòkò ni a óo rọ ọtí waini kún.
8 547 Orilẹede Papua New Guinea 9 0.
Eyi ni Sadiya Umar Faruk lati (Zamfara) a maa moju to ati ilé iṣẹ́ akanṣe iṣẹ ati ọrọ okeere, ti George Akume láti (Benue) ń soju fún.
Abẹwo BBC Yoruba sile oloogbe ṣafihan awọn ololufẹ rẹ, to n sọrọ tẹdun-tẹdun pe alaanu kan ṣoṣo to ku fun awọn ni wọn fi da wọn loro.
Ó pín ilẹ̀ wọn fún àwọn eniyan rẹ̀;ó pín in fún Israẹli bí ohun ìní wọn.
Ẹnikẹ́ni tó bá ṣáájú láti jì àpótí ìbò, ẹ̀mí rẹ̀ ló fi ń ṣeré - Buhari APC, PDP, CUPP kọ etí ikún sí òfin INEC Lọjọ Aje kanna ni ẹgbẹ PDP ṣe ipade pajawiri lasiko igba ti ipade APC naa n waye.
" Igbakeji gomina ipinlẹ Oyo ni awọn to n gbe irufẹ iroyin bayii mọ ohun ti wọn ni lọkàn fun ra wọn .
Ó ní, “Adájọ́ kan wà ní ìlú kan tí kò bẹ̀rù Ọlọrun, tí kò sì ka ẹnikẹ́ni sí.
Ẹwẹ, bi ko ba tilẹ ro o pe ile ijọsin wulo fun aye rẹ, o ni i ṣe pẹlu ọjọ iwaju oṣelu rẹ.
Sugbọn bi awọn kan ṣe ti wa lẹyin Trump, gbogbo orilẹ-ede ọhun ti pinya bayii ti awọn kan n sọ pe awọn lodi si bi aarẹ Trump ṣe n ṣe tirẹ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, George Floyd: Àwọn ọlọ́pàá darapọ̀ mọ́ àwọn olùwọ́de lórílẹ̀èdè Amẹ́ríkà Nítorí George Floyd, Àwọn ọlọ́pàá darapọ̀ mọ́ àwọn olùwọ́de lórílẹ̀èdè Amẹ́ríkà George Floyd protests: Àwọn ọlọ́pàá darapọ̀ mọ́ àwọn olùwọ́de lórílẹ̀èdè Amẹ́ríkà láti wọ́de lórí adúláwọ̀ t'ọ́lọ́pàá ṣekúpa Ayẹwo aladani ti wọn ṣe fun oku ọmọkunrin alawọdudu tawọn ọlọpaa ṣekupa lorilẹede Amẹrika, George Floyd ti fihan pe ọkunrin naa ku lẹyin ti ko ri afẹfẹ mi sinu mọ.
Oríṣun àwòrán, Twitter/Man U O ni oun atawọn ẹgbọn ati aburo oun maa n ya owo sọtọ ninu owo ounjẹ lati le lanfaani wo Manchester United.
Ṣaaju ọjọ naa ni ikọ Coalition for Revolution ti Sowore da silẹ, ke si awọn ọmọ Naijiria kaakiri orilẹede yii lati jade si igboro, ki wọn si beere fun opin si aisi aabo ni Naijiria.
Ṣé mo lè jẹ́ kí eniyan máa rọbí,kí n má jẹ́ kí ó bímọ bí?
 orí-ọ ̀ rọ ̀ ṣegbàjá láti orí-pele oníkékeré ìṣàgbéṣe ẹnìkọ ̀ kan àti ìbáṣepọ ̀ dé orí-pele onígbàngbà àwọn sístẹ ́ mù àti ìpele àwùjọ .
Ifẹsẹwọnṣẹ yii ni ẹlẹkeeji ti wọn yoo gba ninu idije Afcon 2019, lẹyin ti wọn jawe olubori ninu ifẹsẹwọnsẹ wọn akọkọ pẹlu Burundi.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, India: Ẹ wo bí àwọn ènìyàn ṣe dóòlà èmí erin tó jálulẹ̀ Ninu lẹta kan ti igbakeji adari ajọ naa, Kolawole Oluwadare fi sita lọjọ Aiku o ni ''fifi aaye gba awọn Gomina lati ya ninu owo yi yoo ṣe akoba fawọn to ni owo naa'' O tẹsiwaju pe ''bi eeyan ba wo bi wọn ti ṣe n lu owo ifẹyinti ni ponpo ni Naijiria ati bawọn ipinlẹ kọọkan kii ṣe sootọ, ko yẹ ki wọn jẹ ki wọn ya ninu owo yi'' Ìjọba Nàìjíríà gbọdọ̀ ṣàlàyé ìdí tí 13.
Wò ó, n óo mú kí ibi bá gbogbo eniyan, èmi OLUWA ni mo sọ bẹ́ẹ̀; ṣugbọn n óo jẹ́ kí o máa sá àsálà ní gbogbo ibi tí o bá ń lọ.
Àwọn ọ̀dọ́ ilẹ̀ Yoruba kò gbọdọ̀ gbàgbé àṣà ati ohun àdàyébá wọn - Ooni Ile Ife Àwọn àádọ́ta ọ̀dọ́ wọ gàù nítorí ilé ijó ní Ilorin Ǹjẹ o yẹ kí èèyàn máa sùn lẹ́nu iṣẹ́?
Nígbà tí Dafidi dé Mahanaimu, Ṣobi, ọmọ Nahaṣi, wá pàdé rẹ̀, láti ìlú Raba, ní ilẹ̀ Amoni.
Yatọ si owo itanran, adajọ to gbọ ẹsun ti wọn fi kan Marley, Idayat Akanni, tun sọ pe o gbọdọ kọ iwe lati bẹ ijọba ni gbangba, to si gbọdọ tẹ lẹta ẹ̀bẹ̀ naa sinu iwe iroyin gbogboogbo kan.
1 Agẹmo 2019 Oríṣun àwòrán, @Ooduavoice1 Àkọlé àwòrán, Ogedengbe Agbogungboro Akinkanju Balogun ni Saraibi Ogedengbe to tun jẹ Obanla ilu Ijesha (Oba-Ala Ogedengbe ti Ileṣa Kinni).
eleekerinla iru re , ni yoo waye lojo Eti (Friday)ojokokandinlogbon , osu karun
Eyi ni oye ṣẹṣẹ yee pe bi bẹẹ kọ ni o ṣeeṣẹ ki oju oun ti fọ lataari omi ara oyin naa ka ni oun fọwọ gbo oju ṣaaju ile iwosan ni.
Ṣugbọn o ti dá ọpọlọpọ ẹ̀ṣẹ̀ burúkú ju ti àwọn tí wọ́n jọba ṣáájú rẹ lọ.
Tafàtafà kò ní lè dúró, ẹni tí ó lè sáré kò ní lè sá àsálà; bẹ́ẹ̀ ni àwọn ẹlẹ́ṣin kò ní lè gba ara wọn kalẹ̀.
Àwọn ni wọn yóo jẹ́ ìpín kẹta tí àwọn ọmọ Israẹli bá fẹ́ ṣí láti ibùdó kan sí òmíràn.
Wo àwọn tó ń jí owó Covid-19 tí Ìjọba ní wọ́n yóò káwọ́ pọ̀nyìn rojọ́ Ìjọba ìpínlẹ̀ Eko ti bẹ̀rẹ̀ àtúnkọ́ ilé tí ẹlikọ́pútà tó jábọ́ bàjẹ́ ní ìlú Eko Lasiko igbe aye rẹ, Oba Adegbite ni aarẹ ẹgbẹ awọn lọbalọba aadoje kan ni ipinlẹ Ondo to si tun jẹ ọmọ ẹgbẹ igbimọ lọbalọba ipinlẹ Ondo.
Ibi mímọ́ kan ninu àgbàlá Àgọ́ Àjọ ni wọ́n ti gbọdọ̀ jẹ ẹ́.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Helen Paul sọ idi tó fi gba orúkọ ní kékere Igbagbọ John ni pe ayipada yoo wa nigba to l'oyun.
Àwọn ẹ̀dá alààyè mẹrin náà bá dáhùn pé, “Amin!
Awọn ọmọkunrinkan wà ni ile iwe mi nígbà ti mọ pé ọdún mẹ́tàdínlogun, wọ́n dá ẹgbẹ́ kan silẹ loju opo Facebook ní wọ́n so pe àkọle rẹ́ ni Nugmanova jẹ́ àjẹ́ apári"" ""Wọn rò pé yóò bimi nínú sùgbọ́n kò dun mi to bẹ́ẹ̀."
4) Olupoti ìlú Ipoti- Ekiti - Ọba Oladele Ayeni: Lẹyin ọdun mẹẹdọgbọn ti Ọba Isaiah Oladele Ayé I ti wa nipo ni wọn to o rọ loye.
Jesu dáhùn pé, “Ẹ̀yin ìran oníbàjẹ́ ati alaigbagbọ yìí!
Aare Buhari sapajuwe gbigba ife-eye AWCON fun igba keta lori ara won, bee si ni nigba kokanla lapapo gege bi ohun ti o mu ori oun wu, ti o si tun gbe orile-ede Naijiria laruge lagbaye.
Iwe Iroyin Wall Street Journal gbe jade wi pe ọkan lara awọn awakọ naa pariwo ki awakọ baalu naa lọ soke, ko lọ soke, ki o ma ba a da ẹnu kọlẹ bi ose n se mọ.
Ọ̀dọ̀ fásitì jànkàn Oxford ló ti jáde Coronavirus cases in Africa- Ó tí lé ni mílíọ̀nù kan ènìyàn to ti lùgbàdì ààrùn Covid-19 Wọn fikun pe, gbogbo ẹkun to wa ni Naijiria ni wọn gbọdọ ma a pa owo wọle, paapaa awọn agbegbe to ni ohun alumọni to le mu ibugbooro ba bi owo ṣe n wọle ni abẹle.
Ó ní bí òun ti ṣe sí ìdílé Ahabu ati àwọn ọmọ rẹ̀, bẹ́ẹ̀ ni òun óo gbá àwọn eniyan náà kúrò ní Jerusalẹmu, bí àwo tí a nù tí a sì da ojú rẹ̀ bolẹ̀.
"Ṣèyi Law ni olùdásílẹ̀ ètò apanilẹ́rìín ""I must laugh""."
Akẹkọọ naa ti inagijẹ rẹ̀ ń jẹ 'Ẹja' ni wọn sọ pe o n kẹkọọ imọ nipa ile kikọ nileewe gbogboniṣe Polytechnic to wa nilu Ẹdẹ.
"Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Àwọn kànga ìṣẹ̀ǹbáyé rèé ní Badagry tó ń pa ẹrú níyè Ìyàwò lárìnlọọ̀dù mi pè mí ní akálòlò ni mo ṣe paa - Afurasí ""Ambode, wá jẹ́jọ́ lórí ọkọ̀ BRT 5000 to ló fi ₦45b rà, àmọ́ 820 péré ló kó wá"" Buhari, pe ìpàdé àpérò ọmọ Nàíjíríà fún àgbékalẹ̀ òfin tuntun - Afe Babalola ‘Kò sí ohun tó lè yẹ ìfèhọnú ọjọ karun un Oṣu Kẹsan lórí àtìmọ́lé Omoyele Sowore’ Buhari, pe ìpàdé àpérò ọmọ Nàíjíríà fún àgbékalẹ̀ òfin tuntun - Afe Babalola Lero ti agbẹjọro Kanmi Ajibola, ipe yii jẹ eyi to tọ ṣugbọn ko daju pe yoo jẹ ọna abayọ si awọn ipenija to n koju Naijiria lọwọ."
Nigba to n sọrọ loju opo Twitter rẹ, Abiodun fi kun pe aṣeyọri naa ti fi han pe gbogbo owo ti ijọba ipinlẹ Ogun ati akitiyan rẹ lori ere idaraya ko lọ lasan.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ọkọ̀ akérò BRT gbiná lórí afárá 3rd Mainland 22 Èbibi 2019 Oríṣun àwòrán, @AlliAdekola @chuachebe @StockmanNigerian Àkọlé àwòrán, Ọkọ̀ BRT Ìròyìn tó ń tẹ̀ wa lọ́wọ́lọ́wọ́ ní wí pé ọkọ̀ akérò ńla kan tí wọ́n mọ̀ sí BRT nípinlẹ̀ Eko ń jóná lórí afárá 3rd Mainland.
 Oríṣun àwòrán, Instagram/sanyeri2 Asiko ijade ounjẹ nile iwe ni ọrẹ mi kan mu mi lọ sibi isẹ tiata lọdọ oga mi tó di oloogbe, mo bẹrẹ tiata ni pẹrẹu nigba ti mo jade ile ẹkọ girama lọdun 1992.
Mushin / Isolo Link Bridge, Ijọba ibilẹ Mushin Oshodi Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Wo àwọn àdúgbò tí ìpínlẹ̀ Eko ti fòfin de ọ̀kadà àti Marwa 6.
bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé a wà ní ipò láti gba ìyìn gẹ́gẹ́ bí òjíṣẹ́ Kristi.
Ó gba ara rẹ̀ lọ́wọ́ ọba Asiria, ó di òmìnira, ó kọ̀ kò sìn ín mọ́.
Wo bí agbábọ́ọ̀lù Super Eagles tẹ́lẹ̀, Christian Obodo tí wọ́n jígbé lẹ́ẹ̀kejì ṣe móríbọ́ Ààrẹ ti kọ̀wé fipò sílẹ̀ torí èèyàn méjì t'ọ́lọ́pàá pa níbi ìfẹ̀hónúhàn lòdì sí ìjọba Wo ọkùnrin tó dáná sun ọ̀rẹ́bìnrin rẹ̀ torípé kó gbà látí jẹ́ aya rẹ̀ Lara awọn to ba BBC Yoruba sọrọ sọ pe ko si idi miran ti wọn fi n ti apo wọn ni banki ọhun bi ko ṣẹyin bo sẹ tẹ ẹtọ awọn onibara rẹ loju mọle nitori wọn ṣe iwọde.
Ẹwẹ, mo fẹ fi da a yin loju laipẹ, a o bẹrẹ si ni jere ijọba yii paapaa ni ẹka ọrọ-aje ilu ti atunto ati atunṣe ti n de ba bayii.
Ẹwẹ, iye owo ti wọn fi n san owo osu yii fẹrẹ dọgba pẹlu owo isuna fun eto abo ati wi pe owo perete (12.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Energy Drink: Ìjọba fi òfin de èyí tó ń mú ǹkan ọmọkùnrin le 21 Ẹrẹ̀nà 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Energy Drink: Ìjọba fi òfin de èyí tó ń mú ǹkan ọmọkùnrin le Ijọba ìbílẹ̀ Zambia ti fòfin de àwọn ohun mímu tó n fun àwọn ọkunrin ní àgbára (Energy Drink) láti ba àwọn obinrin lòpọ̀ lẹ́yìn ti wọn se awari pe ó ni èròja kan ninu Viagra èyi ti won ń pe ni melcine gẹ́gẹ́ bi ǹkan to ń mu ǹkan ọmọkunrin duro ṣàsàn Ní ọdun to kọja, ọkunrin kan ni Uganda sọ pe ǹkan ọmọkunrin òun kò wálè lẹ́yìn to mu SX ti wọn ń ṣe la'ti Zambia Olórin Makossa, Koffi Olomidé rẹ́wọ̀n he lórí ẹ̀ṣùn ìfipábánilòpọ̀ U.
"Òṣùká kékeré kò rẹrùn àgbà, orílẹ́èdè Nàìjíríà ṣòro púpọ̀ láti darí - Ibrahim Babangida Pàtàkì June 12 fún Nàíjíríà O ṣójú mí kóró bí wọ́n ṣé fí àdó olóró pa Dele Giwa lọdún 1986- Soyinka Agbẹnusọ IBB ni oun ko jẹbi kankan O ni gbigbọ iroyin naa pa awọn lẹrin gidi gan, ""o ya ni lẹnu ko si si ibọwọ fun ni kankan ninu iroyin naa""."
 ní ilẹ ̀ amẹ ́ ríkà iye owó rẹ ̀ jẹ ́ 100 sí 200 fún ìdá kan .
Ta ba wa ni ka beere, ki lo de tawọn eeyan fi n se agbako iku ojiji bayii, paapa lasiko ere idaraya atawọn ọna ta lee gba dena rẹ.
Àwọn eniyan inú rẹ ń parọ́ láti paniyan.
Atamatase iko agbaboolu Real-madrid, Cristiano Ronaldo di agbaboolu akoko ti yoo gba ogorun-un ami-ayo wole ninu itan idije Uefa Champions League fun iko kan-naa, leyin ti o gba ami-ayo meji wole ninu ifagagbaga pelu iko agbaboolu Paris Saint-German lojo-Ru(Wednesday).
Ẹgbẹrun un lọna ẹẹdẹgbẹta eeyan lo n tẹle Vee loju opo Instagram rẹ.
Ẹgbẹ agbabọọlu Manchester United lo fọrọ naa lede loju opo Twitter wọn.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Coronavirus in Nigeria: Ìjọba àpapọ̀ kéde pé káwọn òṣìṣẹ́ ìpele 12 àti 13 padà s'ẹ́nu iṣẹ́ 27 Èbibi 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 10 Ògún 2020 Oríṣun àwòrán, Twitter/Tolu Ogunlesi Ijọba apapọ ti kede pe ki awọn oṣiṣẹ rẹ to wa ni ipele kejila ati ẹkẹtala pada si ẹnu iṣẹ.
“Ẹ kò gbọdọ̀ se ọmọ ewúrẹ́ ninu wàrà ọmú ìyá rẹ̀.
Fun idi eyi, a fẹ fi eto Ọgọrun obinrin 2018 lati fi ta awọn obinrin ji ki wọn si le sọ nipa iriri wọn.
Lọjọ abamẹta ni igbimọ ipolongo Sẹnẹtọ Adeleke fi atẹjade sita nipa idajọ yi eleyi ti wọn ni o fihan pe lootọ ni pe Sẹnetọ Adeleke kaju iwọn lati du ipo Gomina.
Wọn yoo tan fita to ni oju mẹrindinlogun titi di opin ajọdun naa.
Ó fi í lé àwọn ọ̀wọ́ ọmọ-ogun mẹrin lọ́wọ́ láti máa ṣọ́ ọ; (ọmọ-ogun mẹrin ni ó wà ní ọ̀wọ́ kọ̀ọ̀kan).
7 58004 Orilẹede Senegal 506 3.
Aarẹ Yemi Osinbajo ati alaga ẹgbẹ
O sọrọ nipa awọn ipenija iṣẹ rẹ ati pataki gbigba kadara lori bi Olorun ṣe dani.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Oluwo Jogbodo Series: Ìmẹ́lẹ́ jẹ́ orísun àìnílárí, Ifá ṣe ìkìlọ̀ rẹ̀ fáwọn ará Ibadan kí Itan bi Ilẹ ṣe di ẹni ti ko le sọrọ mọ nitori Akufa: Elebuibon wa lo itan bi Ilẹ ṣe di ẹni ti ko le sọrọ mọ, eyi to da lori awọn ọmọ iya mẹta to pa ẹranko agbọnrin, ti wọn si fi nkan di i bi oku wọ aarin ilu, nitori ki wọn o ma ba fun ẹnikẹni jẹ lara ẹran naa.
Ohun tí a ti rí, tí a sì ti gbọ́ ni à ń kéde fun yín, kí ẹ lè ní ìrẹ́pọ̀ pẹlu wa.
Ajọ to n risi ọrọ oju popo lorilẹ-ede Naijiria, FRSC ti ni ẹgbẹrun mẹta Naira ni awakọ yoo maa san ni gbogbo igba ti awọn ba ti mu wọn fun ijanu ọkọ (Speed Limiter) lójú pópó.
Ṣugbọn nígbà tí ọmọ rẹ yìí dé, àpà ara rẹ̀, tí ó ti run ogún rẹ̀ sọ́dọ̀ àwọn aṣẹ́wó, o wá pa mààlúù tí ó sanra fún un.
Ko din ni ọgọrun eeyan to ti dero ọrun nipasẹ iru akọlu bẹ ni ipinlẹ ọhun laarin oṣu Kẹrin si oṣu Kẹfa ọdun yii.
Chatta sọ eyi lasiko to n ba BBC Yoruba sọ̀rọ lori ẹsun wi pe o ma n na iyawo rẹ.
Eji Gbadero, ọmọ Ibadan àti jayé-jayé ọmọ ónílẹ̀ ti wọn yẹgi fun l'Eko O jẹ ara awọn eeyan to kọkọ laju, o kọ ẹkọ iwe, o lowo, o lọla, o gbajumọ, o si jẹ asaaju ilu.
Iru awọn iroyin ti ẹ le nifẹ si: Igbakeji gomina Eko sọrọ nipa obinrin Obi awọn akẹkọ Dapchi nbeere ọmọ wọn Fọlọrunṣọ Alakija: Imọ ṣe koko 'Ara sisan kii ṣe arun' Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí kan sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
Ija ti a sọ wẹrẹ yii le ni ọdun kan to fi waye, ti iroyin atẹnu-dẹnu kan si ni ọgbọn ẹwẹ ni ọlọpaa obinrin kan fi mu Tafa Adeoye.
Mí o lè gbà iṣẹ́ Tottenham torí pé mò nífẹ Chelsea púpọ jù-Mourinho Ẹ wo ìpínlẹ̀ táwọn gómìnà tẹ́lẹ̀ àti igbákejì wọn ń gba dúkìá ìfẹ̀yìntì tabua Lẹnu lọọlọ yi, ẹnu ti n kun Unai Emery ti ọpọ si ti n reti igba ti wọn yoo fọwọ osi juwe ile fun un.
"O ni ""Oju mi ti ri ọpọ nnkan lọdun yii, Mo ja aimọye ija, wọn ja mi kulẹ, ọkan mi rẹwẹsi, wọn parọ mọ mi, ti mo la ipo ibanujẹ kọja."
Aṣa Yoruba, lo ni ilana tirẹ nipa ọkọ fifẹ tabi iyawo nini, eyi ti a daye ba.
Ta òróró yìí sí Aaroni ati àwọn ọmọ rẹ̀ lórí, kí o fi yà wọ́n sí mímọ́; kí wọ́n lè máa ṣe alufaa fún mi.
Àwọn àmì mẹ́fà tó ń sàfihàn ọkùnrin tó ń hùwà ipá!
ó fún Nàìjíríà l'èsì àwọn ẹ̀sùn tó fi kàn-án Wo nkan tó yẹ kí o mọ̀ nípa Tolanibaj, Wathoni àti Brighto ni wọ́n lé kúrò ni BBNaija l'ọ́sẹ̀ yìí Allwell ni oun kan n se oun to n mu oun dabi ọdọ sii lọdọọdun ni ati pe iyẹn ko sọ pe ẹni ọdun marundinlogoji ṣi ni oun rara.
Besini, awon miran ti won yoo jo sise papo ninu yiyikoto naa ni: Mikael Silvestre, Camille Abily, Damien Seguin ati Aela Mocaer.
Mọ àwọn òǹdíje sí ipò ààrẹ Nàìjíríà ọdún 2019
Linda ní òun àti bàbá ọmọ òun ti túká 'Ọdún 35 ni ọmọbìnrin gbọdọ̀ ti bímọ tán' Dokita Stella Adadevoh kò bá pé ọdún 62 Tani otutu ma n mu ju laarin Ọkunrin ati Obinrin?
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Alaafin: Yóò dára kí Fayemi máṣe fọwọ́ yẹpẹrẹ àwọn oríadé nílẹ̀ Yorùbá 14 Ẹrẹ̀nà 2020 Oríṣun àwòrán, Alaafin of Oyo Alaafin tilu Ọyọ, Ọba Lamidi Ọlayiwọla Adeyẹmi kẹta, ti kọ lẹta ransẹ si gomina ipinlẹ Ekiti, Kayode Fayemi lorukọ awọn ọba alaye ilẹ Yoruba.
idibo to n waye nilẹ Afirika jẹ apẹẹrẹ rere pe eto ijoba tiwa-n-tiwa ti fẹsẹ
Gbogbo àwọn ìmọ́lẹ̀ tí ó ń tàn lójú ọ̀run ni n óo jẹ́ kí ó di òkùnkùn lórí rẹ̀, n óo jẹ́ kí òkùnkùn bo ilẹ̀ rẹ̀.
"Àwọn àmì tó fi mọ̀ pé wọn ń fipá bá ọmọdébìnrin rẹ lòpọ̀ Ó rẹ ẹni ọdún 49 tó ri ẹ̀wọ̀n ọgọ́ta ọdún he lẹ̀yìn tó bá ọmọ ọdún méjì lòpọ̀ ""Grandpa àti Uncle mi, ń fipá bá mi lòpọ̀ láti ọmọ ọdún mẹ́rin"" Gbajue ń lọ orúkọ mi láti gba owó- Mama Rainbow Bakan naa ni Poopu sọ pe ''pe awọn ọmọ igbimọ ijọ naa gbọdọ tẹle ofin ilu, wọn si gbọdọ ran awọn oṣiṣẹ ile ẹjọ lọwọ lati ṣe iwadii ti iṣẹlẹ yii ba waye."
Aare wa gbosuba fun ipa rere ti oloogbe naa ti ko ni igbese aye awon omo re, ni eyi ti o n ran won lowo lati ko ipa pataki ninu ipo adari lagbaaye.
3 % , larin omo odun 15-65 je 54.
Ó wólẹ̀ níwájú Jesu, ó bẹ̀ ẹ́ pé kí ó bá òun kálọ sí ilé, 
“O kò gbọdọ̀ bá obinrin lòpọ̀, nígbà tí ó bá ń ṣe nǹkan oṣù rẹ̀ lọ́wọ́.
Ẹgbẹ agbabọọlu Super Eagles ti Naijiria ti pari ifẹsẹwọnsẹ wọn ninu idije ilẹ Afirka, lẹyin ti wọn pari pẹlu ipo kẹta ninu idije Afcon 2019.
Olaiya ni Aarẹ Buhari ko ni gba jẹgudujẹra laaye, eleyii ti oun sọ pe o fa ifasẹhin fun orilẹ-ede Naijiria lati bi ọdun mẹrindinlogun sẹyin, ti Aarẹ Buhari n gbiyanju lati wa ọna abayọ si.
Ọrọ alubọsa ayuu ati awọn ẹtalẹ funfun ati pupa yii naa jẹ ọkan nibẹ.
Ọ ̀ pọ ̀ lọpọ ̀ àkẹ ́ kọ ̀ ọ ́ ilé-ẹ ̀ kọ ́ ilé-ẹ ̀ kọ ́ sẹ ́ kọ ́ ńdírì àti ti olùkọ ́ ni , láì-mẹ ́ nu-ba àwọn olùkọ ́ ní àwọn ilé-ẹ ̀ kọ ́ bẹ ́ ẹ ̀ , ni wọ ́ n ti ń lo ìwé Èdè Ìperí yorùbá tí n.
theodor wiesengrund adorno ( september 11 , 1903 - august 6 , 1969 ) je omo ile jemani to je onimo oro-awujo , amoye , ati onimo oro-orin .
Nígbà tí ó ti sọ báyìí tán, bí wọ́n ti ń wò ó, a gbé e sókè, ìkùukùu bò ó, wọn kò sì rí i mọ́.
Ìwọ̀nyí jẹ́ ìlànà àwọn nǹkan tí a lè fojú rí, tí yóo sì máa wà títí di àkókò àtúnṣe.
Ẹ óo ṣe máa fi ará Ṣulamu ṣe ìran wòbí ẹni wo ẹni tí ó ń jóníwájú ọ̀wọ́ ọmọ ogun meji?
Iyalode Ibadan: Olubadan jáwé oyè lé Ìyálóde tuntun lórí
Ó bá sọ fún wọn pé, “Ẹ ti ṣe lójo bẹ́ẹ̀, ẹ̀yin onigbagbọ kékeré wọnyi?
Ẹ kún fún àdúrà nítorí ìdájọ́ kóòtù àgbà lórí gómìnà l'Ọ́ṣun-APC Ọṣun Ìdí rèé táwọn ọmọ Nàíjíríà kan ṣe ń tako ìdásílẹ̀ ‘Ruga Settlement’ Nigba to n kede ipinnu rẹ naa ni owurọ ọjọ Isẹgun, Lanlẹyin salaye pe, oun gbe igbesẹ naa nitori pe o ti n foju han bayi pe gomina Makinde ti n yẹsẹ lori iwe adehun ti wọn fẹnu ko le lori.
OLUWA, kí ló dé tí o fi ta mí nù?
Awọn ọmọ ati ọmọ oloogbe to ba wa sọrọ ni, Iyalode to di oloogbe naa ni aajo ọmọ, o nibẹru Ọlọrun, ti ko si si isoro ti ko lee ba eeyan yanju rẹ.
O ni awọn ọmọbinrin bii mẹta ọtọọtọ to padanu ẹmi wọn nitori ifipabanilopọ ati iwa ipa laarin ọsẹ kan ti fa aibalẹ ọkan fun gbogbo abiyamọ pata.
Nígbà tí owó bá pọ̀ ninu àpótí náà, akọ̀wé ọba ati olórí Alufaa yóo ka owó náà, wọn yóo sì dì í sinu àpò.
Atẹjade ti Agbẹnusọ fun ileeṣẹ Amerika, Morgan Ortagus fi sita ni Washington lorilẹ-ede Amerika ni lati ọjọ kẹrinlelogun, oṣu kinni ọdun ni Amerika ti n gbiyannju lati gbe igbesẹ yii.
Fayemi ni lati bii oṣu melo kan sẹyin, ni ọkanọjọkan ipade ti n waye laarin aarẹ orilẹede yii, Mohammadu Buhari ati gbogbo awọn gomina lori eto aabo.
Nítorí anfaani kí ni ó jẹ́ fún eniyan kí ó jèrè gbogbo dúkìá ayé yìí, ṣugbọn kí ó pàdánù ẹ̀mí rẹ̀?
Ijiya to to fun iru awon eniyan bayii ni ki ijoba gbese le awon dukia ti won ti fi ona eeru yii ko jo, ki ijoba si tun gba awon owo ti won ji lowo won.
’’Ko ni si seku-sẹyẹJoshak tun so pe ẹsọ eleto aabo to ba segbe lẹyin oludije Kankan yoo jẹ iyan rẹ nisu.
Èyí mú kí ó di dandan fún àwọn eniyan Ọlọrun, tí wọn ń pa àṣẹ Ọlọrun mọ́, tí wọ́n sì dúró ninu igbagbọ Jesu láti ní ìfaradà.
Khafi to jẹ ọlọpaa nilẹ Gẹẹsi sọrọ loju opo Instagram rẹ pe, oun lẹni to ṣẹṣẹ ni ọkọ tuntun nigboro bayii.
Ó sọ̀rọ̀ bí òun ti jẹ́ tálákà tẹ́lẹ̀ rí, tí tálákà òun pọ̀ tó bẹ́ẹ̀ tí òun kò ní ju ìbàǹtẹ́ nínú ayé, tí ìyàwó òun kò ní ju yẹ̀rì lọ, tí owó ọwọ́ òun kò ju tọ́rọ́ lẹ́ẹ̀kan ṣosọ, tí òun kì í sùn lóru nítorí ìrònú, tí ọkàn òun kì í balẹ̀, tí oúnjẹ òun kò níláári, tí ara òun gbẹ bíi igi.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù World Breastfeeding Week: Fífún ọmọ lọ̀yan kìí wá lásán, ó nílò ìdánilẹ́kọ̀ọ́ 1 Ògún 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ẹ mase feti si awọn apọnpo nipa ifọmọ lọyan, gbogbo igba naa kọ lo rọrun lati fun ọmọ lọyan Ọjọ Kinni osu Kẹjọ ọdọọdun ni ọsẹ fifun ọmọ lọyan maa n bẹrẹ, o si yẹ ka mọ pe fifun ọmọ lọyan ni ọpọ anfaani fun ọmọ ati iya.
Oríṣun àwòrán, Rotimi Obende Àkọlé àwòrán, Ilu okere nikan ni ofin to munodoko wa lati dẹkun idokowo sogúndogójì Nigba ti o'n ba BBC Yoruba sọrọ, o ni ainitẹlọrun lo maa n sun ọpọ eeyan debi ilana sogundogoji yii.
Amọṣa, nigba ti yoo fi yẹ owo naa wo pada, gbogbo miliọnu mẹtalelogun owo ilẹ Burundi (ti yoo ja si miliọnu meji naira o le diẹ) to wa nibẹ ti poora pẹlu owo ti arakunrin yii mu wa.
itesiwaju nikan lee waye nipa emi isokan ati ife ni orile ede Naijiria.
Koda, awọn akẹkọọ naa ko tilẹ si nile iwe lasiko Covid 19 naa rara, leyin o reyin ni a rii pe apo awọn kan ni owo naa wọ lọ.
20 Kíyèsíi, mo sọ àwọn nkan wọ̀nyí fun yín, àní bí mo ṣe sọ fún àwọn ènìyàn bákannáà nípa ìparun Jerusalẹmu; àti pé ọ̀rọ̀ mi ni a ó fi ìdí rẹ̀ múlẹ̀ ní àkókò yìí bí a ṣe fi ìdí rẹ̀ múlẹ̀ ní ìgbà ìṣaájú.
" Gomina ipinlẹ Ekiti naa sọ wipe asiko to fun Aarẹ Buhari lati pakiti mọra se afọmọ ijọba rẹ ki o si yọ gbogbo awọn to n fi wahala Boko Haram jẹun ninu ijọba danu bi ẹni yọ jiga iyẹn to ba jẹ lootọ lo n fẹ ki gulegule awọn Boko Haram o dopin.
Ara rẹ yoo ma sẹ giri bi ẹyẹ to bo kuro ninu okun.
Eyi ko sẹyin iroyin kan to jade pe, ajọ to ma n ba ni sin gbèsè ni Naijiria, AMCON, ti gbẹsẹ le ile rẹ to wa ni Banana Island nipinlẹ Eko.
Kini ‘ǹfààní ẹni tóní ọwọ́ ayé ò le tẹ òun
Jesu dá wọn lóhùn pé, “Èmi kò ní ẹ̀mí èṣù rárá!
Awọn dokita naa ti kọkọ lọ fun iyanṣẹlodi onikilọ ọlọjọ mẹkanlelogun lati fi fa ijọba leti ṣugbọn ti ko si ọrọ kankan latọdọ ijọba titi di bi a ṣe n sọrọ yii.
Ó rí ọ̀pọ̀ eniyan tí ó ti péjọ.
Human trafficking in Libya: Ẹsẹ̀ bàtà àti èso kukumba ni wọ́n fi ń já àbálé àwọn ọmọ Nàìjíríà ní Libya-Yetunde, arìnrìnàjò sí Libya
Bá mi wí fún Ọlọ́run Ọba pé ìlú tí Ó jẹ́ kí wọ́n ti bí mi kò tẹ́ mi lọ́rùn, mo ń fẹ́ kí ọmọ aráyé máa pè mí ní ọmọ ìlú mìíràn, n kò fẹ́ kí ẹikẹ́ni mọ ìlú náà pẹ̀lú mi.
Ǹjẹ́ òògùn vitamin C lè pa coronavirus?
 Sẹ́ láyà lètò, ètò ni sẹ́ láyà"
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Xenophobia: Naijiria á kọ́kọ́ pèsè ọ̀nà láti bá ẹbí sọ̀rọ̀ fún wọn Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
ilu Ibadan ko ni maa foju wina sunkere- fakere oko gege bi ti Apapa sugbon yoo
Eyín mi ló lágbára jù ní Afíríkà, mò ń fi eyín gbé àpò ìrẹsì, símẹ́ńtì àti jẹnẹrátọ̀ - Taju eléyín idán Àgbẹdọ̀, ẹ yé wí pé wàhálà abẹ́lé wà lẹ́gbẹ́ òṣèlú APC mọ́-Issa Onilu, alukoro àpapọ̀ fún APC O ní ìdá àadọrùn nínú àwọn olówó orilẹ̀-èdè Naijiria lo máa nlọ si ilé Baba Alawo, nítori pe àrà àṣà abíni bi ni lórilẹ̀-èdè Naijiria àti pe tí ọ̀pọ̀ bá bẹ̀rẹ̀ si ni wo fíímu, wọ́n kii biki ta láti wòó pari ti wọ́n maa sọ pe àwọn ti mọ ibi ti yóò pari si èyi si maa n mú wọ̀n pàdánù láti mọ ẹkọ ti o wà níbẹ̀, ni ọ̀pọ̀ ìgbà àwọn fíímu náà maa n naka àbùkù si àwọn to hu irú ìwà síse oògun owo ni.
Wọ́n ka òfin Ọlọrun ninu ìwé náà ketekete, wọ́n túmọ̀ rẹ̀, wọ́n sì ṣe àlàyé rẹ̀ fún àwọn eniyan, ó sì yé wọn.
Ohun tí ó wá burú ju gbogbo rẹ̀ lọ ni pé, a rí àwọn òmìrán ọmọ Anaki níbẹ̀.
Àwọn oríṣi àjẹsára náà ti òde-òní kò léwu láti lò rárá .
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Sogidi Lake: Kòṣẹja-kòṣèèyàn lá bá nínú adágún odò náà -Ojedele Ẹ́kọ́ wo la ri kọ́ nipa isẹ̀lẹ̀ yii?
Ọpọlọpọ lara awọn ti BBC ba sọrọ ni àwọn ti sẹ okowo loriṣii pẹlu owo ti kò to ẹgbẹrun mewaa naira sẹyin.
Igbákejì mínísíta fún ìlera ní Iran ti kó Coronavirus Ẹ jọ̀ọ́, ẹ má jẹ́ kí ikú ọmọ mi lọ lásán - Ìyá Tiamiyu tí ọlọ́páà pa Ààrẹ Buhari ṣí ilé iṣẹ́ àti afára ní ìpínlẹ̀ Ondo Ìjọba Germany mú afurasi ọmọ Boko Haram Eni to kọ iwé ẹsùn náà ni fẹ̀sùn kan pe Waheed sọ pe oun gba iwé ẹri WAEC ni ọdun 1988 sugbọn irọ ni nitori pé ayédèrú ni.
Koda, ọrọ naa kanlẹ, o kan baale, to si tun kan jẹjẹ ni mo joko mi, nitori ọkọ bọọsi agbero kan to ko ero mejidinlogun, to fi aake kọri pe oun yoo tiraka gba ibi ti epo naa ti n da silẹ kọja, ni ina mu mọlẹ, to si pa gbogbo ero to wa ninu rẹ.
Jakande pé 90 láì gba àmì ẹ̀yẹ kankan ní Nàíjíríà -Osoba Ni nkan bii ẹgbẹrun ọdun pupọ sẹyin ni Hernán Cortés to jẹ onimọ ọmọ Spain gbajọba ẹkun ti a n pe ni Mexico nsiyi lọwọ Maya Ati Aztec.
Barrister ló sọ mí di èèyàn ńlá - Ayinla Kollington Ìlú ò rẹ́rìn ín rárá, Alaafin Adeyemi III fárígá fún Buhari nínú lẹ́tà tuntun Ọrọ̀ ajé Nàíjíríà tún leè dagun tí Buhari bá fi ìyànsípò àwọn mínísítà falẹ̀ si - Onímọ̀ Ìjọba Nàìjíríà gbọdọ̀ ṣàlàyé ìdí tí 13.
Apá ọ̀tá ko ní ka yín, ọmọ aráyé kò ní lè fi yín ṣe nǹkan, àwọn ẹyẹ kìí ṣàìri ounjẹ òòjọ́ jẹ, ẹ kò ní ṣàì rí oúnjẹ jẹ laelae, ẹjá kìí tan nínú omi, ọmọ kò ní tan nínú ilé yín láéláé.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Coronavirus tips: Ìdí nìyí tí ààrùn coronavirus ṣe n ṣekú pa àwọn tó pa 3 Ìgbé 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 5 Ìgbé 2020 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àwọn onimọ nípa ètò ìlera sọ pé kò rújú rárá- bí o bá ṣe ń dàgbà sì í, ni ó ṣe ní ewu fún ọ sí láti ní ààrùn Coronavirus.
Koda awọn awujọ agbaye gbogbo ni wọn kan sara si fun iṣẹ takuntakun ti o ṣe nigba naa.
O ní lọ́pọ̀ ìgbà ti a wọn ba pe ìpàde, àwọn ti ko mọ bi ẹgbẹ́ YWC ṣe wa sáye, ni Akintoye maa n pè láti maa jẹ̀gàba lórí àwọn àgbà ẹgbẹ́.
”Akonimooja Parker, Kevin Barry naa ti fowo-soya pe, oun naa nigboya pe Parker yoo fagbahan Joshua ninu ifigagbaga naa.
Igi olifi meji wà lẹ́gbẹ̀ẹ́ fìtílà náà, ọ̀kan ní apá ọ̀tún àwo náà, ọ̀kan ní apá òsì.
Ó rọ awọn obinrin lati ni suuru pẹ̀lú ẹbí wọn lai faaye gba iwa ipá ninu ile ati lawujọ pẹlu afiwe Iya Adeboye.
2003 Wọn dajọ ẹwọn fun nitori ẹsun jibiti ati ole jija lori owo to ya nile ifowopamọ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Burna Boy Twice as Tall: Ǹkan tí ó yẹ ki o mọ̀ nípa Damini Ebunoluwa Ogulu Rex (Burna Boy) ti orin rẹ̀ lu ìgboro pa báyìí 14 Ògún 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 25 Bélú 2020 Oríṣun àwòrán, Burna Boygram Bí ilẹ̀ ṣe mọ́ lónì ni òkìkí kan lórí ayélujára pé Burna Boy bi ọmọ tuntun.
Alagba Ojedele sọrọ lori bi adura awọn eeyan ṣe n gba ti wọn ba tọrọ nkan ninu odo yii.
24 Bẹ́ẹ̀ni, òun ti rú ọ̀kàn wọ́n sókè láti bínú tako iṣẹ́ yìí.
 A n dupe lowo ijoba ipinle Ogun fun ipinnu won lati fowosowopo pelu wa ki eto naa le yori sir ere”.
Òtítọ́ ọ̀rọ̀ gan-an ni mò ń sọ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Kwara Politics: Ayo Adedoyin ti ẹgbẹ Accord Kwara sọ̀rọ̀ lórí níní bàbá ìsàlẹ̀ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Kwara Politics: Ayo Adedoyin ti ẹgbẹ Accord Kwara sọ̀rọ̀ lórí níní bàbá ìsàlẹ̀ 28 Èrèlè 2019 Ayo Adedoyin to jẹ oludije sipo gomina ni ipinlẹ Kwara labẹ asia ẹgbẹ oṣelu ACcord bu ẹnu atẹ lu ọrọ baba isalẹ ninu oṣelu.
Olukuluku ọkunrin yóo mú ọrẹ wá gẹ́gẹ́ bí ó bá ti fẹ́ ati gẹ́gẹ́ bí OLUWA Ọlọrun yín bá ti bukun un.
pẹlu àwọn ọba ati àwọn ìgbìmọ̀ àgbáyé, tí wọ́n ti sùn,àwọn tí wọ́n tún àlàpà kọ́ fún ara wọn;
Àkọlé àwòrán, Isin oni ti pari ni COZA nigba ti Pasitọ Biodun Fatoyinbo ba awọn ọmọ ijọ sọrọ.
Pásítọ̀ Adeboye kéde ààwẹ̀ ọjọ́ 63 fọ́mọ ìjọ rẹ̀, ariwo sọ lórí ayélujára Ìgbákejì ààrẹ, tètè yọ Trump nípò, bí bẹ́ẹ̀ kọ́.
Èṣù sọ fún un pé, “Bí ó bá jẹ́ pé Ọmọ Ọlọrun ni ọ́ nítòótọ́, sọ fún òkúta yìí pé kí ó di àkàrà.
Bí mo bá tìtorí iyì eniyan bá ẹranko jà ní Efesu, anfaani wo ni ó ṣe fún mi?
Àwọn ọmọ Israẹli bẹ̀rẹ̀ sí kọlu Jabini, ọba Kenaani lemọ́lemọ́ títí wọ́n fi pa á run.
22 Ẹrẹ̀nà 2018 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 12 Èbibi 2020 Oríṣun àwòrán, Thisday Laipẹ yii ni ẹgbẹ awọn oṣiṣẹ ti kii ṣe olukọ lawọn ile ẹkọ fasiti nilẹ wa, (NASU) ati awọn ẹgbẹ miran to so mọ figbe ta pe, ijọba apapọ ti n gbe igbesẹ lati ṣe amulo abọ iwadii igbimọ Stephen Orosanye nipa isẹ ọba.
Osù tó ń bọ̀ la ó gbé ètò ààbò ilẹ̀ Yoruba jáde!
E say sabi pipo don check am see say Cannabis na one of di drugs wey fit cause serious mental palaa for pesin.
O ni ohun nikan lọna kan to ku, tawọn ko fi ni di ẹni yẹyẹ ni saa bọọlu ọdun yi.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù RAMADAN: Onímọ̀ ẹ̀sin sọ nípa isẹ́ láádá àti làádà nínú oṣù mímọ́ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ RAMADAN: Onímọ̀ ẹ̀sin sọ nípa isẹ́ láádá àti làádà nínú oṣù mímọ́ 17 Èbibi 2018 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 6 Èbibi 2019 Oṣù Ramadan jẹ pàtàkì oṣù fún àwọn mùsùlùmí jakejado àgbáyé.
Ogbeni Abdullahi Aremu to je akosemose lori ewu idoti lawujo to tun je adari ile ise arannilowo ti kii se tijoba to wa fun imototo ayika lo parowa yii nilu Abuja.
Seleki, ará Amoni, Naharai, ará Beeroti, tí ó máa ń ru ihamọra Joabu, ọmọ Seruaya.
Ìyá dú ọmọ rẹ̀, o yíi láta, ó sì tún jòkó jẹ ẹ́ Lisabi Agbongbo Akala rèé, ẹni tó fi ìfẹ́, ìṣọ̀kan àti ìrẹ́pọ̀ gba ilẹ̀ Ẹ̀gbá lọ́wọ́ ìmúnisìn Pasuma kìí ṣe ọkọ mi o!
Aare wa pe fun awon onimo ijinle ninu ise miiran lati to ipase ogbeni Williams fun aforiti, ise takuntakun ati ifokansin re ninu ise yii, ni ona lati mu ise won naa de ibi ti io lapere lawujo.
" Láti orí 'Our Mumu don do' sí 'Revolution Now' Bí ọdún Ọ̀ṣun Oṣogbo ṣe bẹ̀rẹ̀ rèé àti pàtàkì rẹ̀ fún Nàíjíríà Saudi ṣàtúnṣe lílẹ òkò mọ́ Asitani láti dẹ́kun títẹra-ẹni-pa Ẹgbẹ́ Akọ́mọlédè àti Àṣà Yorùbá Nàìjíríà pé àádọ́ta ọdún Joseph salaye pe, o ti le ọdun kan ti awọn ọlọpa naa ti wa loju popo lati pese eto aabo si agbegbe naa, amọ o se ni laanu pe awọn olubi ẹda naa tun lori laya lati wa kọlu awọn ọlọpa gan.
Botilẹjẹ pe iya Samuel ati baba rẹ ti kọ ara wọn silẹ, Samuel ni ẹgbọn obinrin kan, ti awọn mejeeji jọ fẹran ara wọn daada nigba naa.
Lẹyin ominira lọdun 1962, Aarẹ Ahmed Ben Bella fi Bouteflika jẹ minisita fun ọrọ awọn ọdọ ati ere idaraya.
Àwọn òṣìṣẹ́ ilé aṣòfin Nàìjíríà bẹ̀rẹ̀ iyànṣẹ́lódì
Irúgbìn nìyí, ẹ lọ gbìn ín sinu oko yín.
'Èèyàn mi mẹ́ta ló wà nínú ọkọ̀ ojú omi tó dà nù l'Eko!
Mo wá sinu ayé bí ìmọ́lẹ̀, kí ẹni tí ó bá gbà mí gbọ́ má baà wà ninu òkùnkùn.
Ẹ̀yin ọ̀rẹ́ẹ̀ mi ọ̀wọ́n, ìṣẹ̀lẹ̀ tí kò dùn mọ́ni nínú kan ṣẹlẹ̀ ní ọjọ́ mélòó kan sẹ́yìn, ṣùgbọ́n mo nírètí pé irú ìṣẹ̀lẹ̀ náà á pín pẹ̀lú ọdun 2018 àti pé irú ìṣẹ̀lẹ̀ bẹ́ẹ̀ ò ní wáyé mọ́.
Lasiko naa, wọn pe e ni Big Brother Nigeria.
Ijọba ipinlẹ Oyo ni, idi ti awọn fi gbe igbesẹ naa ni pe, awọn akẹkọọ ti duro nile nitori iyansẹlodi ọlọjọ gbọọrọ ti awọn osisẹ gule, awọn ọjọ isinmi ti ijọba fun awọn eniyan lati se ọdun tabi ayajọ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìjàmbá iná: Sitofu tó gbaná pàdé ike pẹtiró, ni iná bá sọ 25 Ẹrẹ̀nà 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Ijamba ina to waye ni agbegbe Mile 12, nijọba ibilẹ Kosọfẹ nipinlẹ Eko, ti sọ eeyan di alainile lori, tawọn eeyan miran si padanu sọọbu ọja wọn.
láì tíì ka igba ó lé ogún (220) àwọn òṣìṣẹ́ tẹmpili, tí Dafidi ati àwọn ẹmẹ̀wà rẹ̀ ti yà sọ́tọ̀ láti máa ran àwọn ọmọ Lefi lọ́wọ́.
Adajọ, ẹ jọwọ, ẹ tu wa ka.
 Wọn beere fun pipese ina mọnamọna si adugbo Awolesi; pipese ẹrọ amunawa ti yoo le maa tan awọn ina adugbo deedee ni agbegbe Magodo-Iṣẹri.
Ni ọjọ Iṣẹgun ni ile ẹjọ naa ti kọkọ gbe aṣẹ kalẹ pe ẹgbẹ oṣelu PDP ko gbọdọ f'aye gba Obaseki lati dije labẹ aṣia rẹ.
Fun igba diẹ bayii ni ariyanjiyan ti wa lori ẹni to ni fiimu ‘Ti Olúwa nilẹ̀’ ti ‘Mainframe’ gbe jade lọdun 1993, pẹlu Kareem Adepoju ti gbogbo eniyan mo si ‘Baba Wande’, ti Tunde Kelani si se olootu rẹ.
Nígbà tí ó bá ṣẹlẹ̀, ọkàn gbogbo eniyan yóo dàrú, ọwọ́ wọn yóo rọ ìrẹ̀wẹ̀sì yóo dé bá wọn, ẹsẹ̀ wọn kò ní ranlẹ̀ mọ́.
Oriṣiriṣi òwe ni Yorùbá ni lati fihàn pé iwà rere ló ni ayé.
Ẹ kò gbọdọ̀ jẹ ajá mọ́' Àdó olóró parí ọdún ìtúnu ààwẹ̀ Ramadan Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Ẹlẹ́dẹ̀ wa ti tó kó jáde síta' Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Nígbà tí oòrùn ń lọ wọ̀, Joṣua pàṣẹ pé kí wọ́n já òkú wọn lulẹ̀ kí wọ́n sì sọ wọ́n sinu ihò tí wọ́n sápamọ́ sí, wọ́n sì yí òkúta ńlá dí ẹnu ihò náà.
Ọlọrun Allah han, ki wọn si fi ifẹ bara wọn lo pẹlu iwa ikora-ẹni-nijanu
ile igbimọ aṣofin ẹkun Iwọ Oorun Gusu orilẹ-ede Naijiria lati gbogun ti ipenija eto aabo ni
Jehu bẹ̀rẹ̀ sí lépa rẹ̀, ó pàṣẹ fún àwọn ọkunrin rẹ̀ pé kí wọ́n ta á lọ́fà!
Awọn onwoye nipa eto oṣelu ti bẹrẹ si ni woye ẹni ti yoo rọpo olori oṣiṣẹ Aarẹ Buhari, Abba Kyari to d'oloogbe.
Wọ́n sọ fún mi pé, “Inú wahala ńlá ati ìtìjú ni àwọn tí wọ́n ṣẹ́kù, tí wọn kò kó lẹ́rú wà, ati pé odi Jerusalẹmu ti wó lulẹ̀, iná sì ti jó gbogbo ẹnu ọ̀nà rẹ̀.
N óo wó odi tí mo mọ yí i ká,wọn yóo sì tẹ̀ ẹ́ mọ́lẹ̀.
Oríṣun àwòrán, authenticmuy Agbẹnusọ rẹ, Wuraola sọ ninu ifọrọwanilẹnuwo kan pe lootọ ni Muyiwa wa ni ile iwosan to si jẹ wipe wahala iṣẹ ti wọ ọ lara ni.
O ti foju han gbangba pe Russia wa digbi, to si fẹsẹ rinlẹ lati mu ki okun ajọsepọ rẹ lati aye Soviet Union nilẹ Afirika tubọ le si.
Kanran sọ iriri rẹ bi oun ṣe di ẹni ti ko ri ile gbe mọ ati bi ohun gbogbo ṣe daru fun oun ni nkan bi ọdun melo ṣẹyin.
Wọ́n tọ Eleasari, alufaa, ati Joṣua ọmọ Nuni, ati àwọn àgbààgbà lọ, wọ́n wí fún wọn pé, “OLUWA ti pàṣẹ fún Mose pé kí ó pín ilẹ̀ fún àwa náà, gẹ́gẹ́ bí ó ti pín fún àwọn ìbátan wa, tí wọ́n jẹ́ ọkunrin.
” wọ́n sì ń bèèrè bí Simoni tí àpèlé rẹ̀ ń jẹ́ Peteru bá dé sibẹ.
O tun ti jẹ alaga Bank of Commerce and Industry eyi ti ko ṣiṣẹ mọ bayii.
àwọn tí ọwọ́ wọn kún fún iṣẹ́ ibi,tí ọwọ́ ọ̀tún wọn sì kún fún àbẹ̀tẹ́lẹ̀.
Koda o rinrinajo kaakiri ati kọja ilu rẹ, mo tun wa iṣẹ lai lo iwe ẹri fasiti rẹ ṣugbọn ọpọlọpọ igba ni wọn n kọ iwe iwaṣẹ mi."
Gbogbo ẹ̀ wá nfẹsẹ̀ falẹ̀ bí ìjàpá.
Ó sọ fún un pé, “Josẹfu, ọmọ Dafidi, má bẹ̀rù láti mú Maria aya rẹ sọ́dọ̀, nítorí láti ọ̀dọ̀ Ẹ̀mí Mímọ́ ni oyún tí ó ní.
 ) tí ó tan imólè , tí ó mole , tí o dán , oòrùn náà mole dáadáa .
 síbẹ ̀ aáwọ ́ tí ó wà láàárín lúwà àti alárẹ ̀ nípa óyè jíjẹ kò í tán láàárín àwọ ́ n ẹbí méjèèjì .
Wọ́n sì tún gbàgbọ́ wípé bí ẹ̀jẹ̀ẹ ẹni tí a pè ní àjẹ́ bá kan ilẹ̀ ọ̀gẹ́rẹ́, yóò pàdánù agbára ẹlẹyẹ rẹ̀.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù US presidential election 2020: Iye owó tí ìjọba Amẹrika ń ná sí ìdìbò Ààrẹ rèé 2 Bélú 2020 Ara ọtọ ni idibo Aarẹ orilẹ-ede Amẹrika ọdun yii yoo gba nitori ajakalẹ arun Coronavirus, ṣugbọn orilẹ-ede naa naa yoo na obitibiti owo si eto idibo ti yoo waye lọjọ kẹta, oṣu Kẹwaa, ọdun 2020.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Amb.
Pa àwọn aapu bii afihan ibudo ti o wa ati maapu lasiko ti o ko ba lo wọn.
Orúkọ àwọn orílẹ̀èdè tí yóò kópa ní AFCON 2019 rèé Idije ti AFCON tọdun yii lo tobi ju lati ọdun 1957 to ti bẹrẹ.
Nibi asale apeje ti gomina ipinle Jiagawa se fun aare lojo Aje , lati fi yẹ aare si fun abewo olojo meji ti o se si ipinle Jigawa.
"Ọ̀rọ̀ yìí dá ọ̀pọ̀lọpọ̀ aríyanjiyan sílẹ̀ lórí ẹ̀rọ twitter Àkọlé àwòrán, Aisha ni tí ènìyàn tó le ni mílíọ̀nù mẹ́ẹ̀dogún ba le dibo yan ọkọ òun wọle ti àwọn ènìyàn meji dondo si gba ìjọba láti keyin wọn si ààrẹ ""Àwọn obinrin Kano kò jànfàní owó amúlúdùn fún àwọn toosi jùlọ"" Láìpẹ yìí ni ìyàwó ààrẹ tún bu ẹnu ẹ̀tẹ́ lú èto ìjọba Muhammadu Buhari lóri pínpín owó ẹdẹ́gbẹ̀ta bílíọ̀nú náírà tó wà fún àwọn tó tòsì jùlọ pàápàá jùlọ ni ìhà Arewa."
Ìsàlẹ̀ òkun di gbangba, ìpìlẹ̀ ayé sì ṣí sílẹ̀,nígbà tí OLUWA bá wọn wí,tí ó sì fi ibinu jágbe mọ́ wọn.
Wọ́n lọ káàkiri gbogbo ilẹ̀ Juda, wọ́n lọ kó àwọn Lefi ati àwọn baálé baálé gbogbo ní Israẹli wá sí Jerusalẹmu.
Ko si idi meji fun eyi ju pe agbabọọlu ọmọ ilẹ Afirika mẹfa ọtọọtọ ni yoo kopa ninu ifẹsẹwọnsẹ naa.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Àwọn gómìnà nílẹ̀ Yorùbá ti kùnà láti pèsè ààbò tó péye fún aráàlú - Ẹgbẹ́ Majeobaje Ọ̀fẹ́ ló bá dé, Boko Haram kọ́ ló jí akẹ́kọ̀ọ́ gbé, a kò san kọ́bọ̀ fún ìdáǹdè wọn - Masari Ṣé lóòtọ́ ni Bimpe Oyebade lóyún fún Lateef Oladimeji?
Bakan naa, ni won  tun n du emi awon
gbọ́ adura wọn lọ́run lọ́hùn-ún, dárí ẹ̀ṣẹ̀ wọn jì wọ́n, kí o sì mú wọn pada wá sórí ilẹ̀ tí o fún àwọn baba ńlá wọn.
Ẹni ti iṣẹlẹ naa ṣoju rẹ ni awọn onijagidijagan naa ṣekọlu si awọn ileeṣẹ naa, ti wọn si ba awọn ohun ini wọn jẹ.
bí àwọn eniyan mi, tí à ń fi orúkọ mi pè, bá rẹ ara wọn sílẹ̀, tí wọ́n bá gbadura, tí wọ́n sì wá ojurere mi, tí wọ́n bá yipada kúrò ní ọ̀nà burúkú wọnyi; n óo gbọ́ láti ọ̀run, n óo dárí ẹ̀ṣẹ̀ wọn jì wọ́n, n óo sì wo ilẹ̀ wọn sàn.
Ó ti sọ àwọn ọmọkunrin yín di ẹni tí ń sálọ fún ààbò;ó sì sọ àwọn ọmọbinrin yín di ìkógunfún Sihoni ọba àwọn ará Amori.
Ní àkókò náà, àwọn olùṣọ́-aguntan wà ní pápá, níbi tí wọn ń ṣọ́ aguntan wọn ní òru.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Àwọn èèyàn sọ́rọ́: Ẹ máà ṣi Fayemi túmọ̀ lórí àṣẹ tó pa nípa sísọ Yorùbá 20 Ògún 2019 Oríṣun àwòrán, facebook/Government of Ekiti State, Nigeria.
N kò gba owó rí lọ́wọ́ olùdíje kó tó dé ipò - Oyedepo Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Iwode fun Ochanya ti won ba lopo waye nilu Eko Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 3 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 5 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
 O le ni pogun odun seyin ti won ti koko ko ona yii ni eyi to ti n wu bayii.
Nkan tí a mọ̀ nìyíì Mo ti kúrò ní ààfin Oyo, kí ìròyìn tó ò jáde pé èmi àti Wasiu Ayinde n fẹ́ ara wa - Olori Badirat Lara awọn adugbo ta gbọ pe ọrọ naa kan ni Gareeji Epe, Ejinrin Road, Adefisan, Gareeji Ibadan, Onirugba, Tatina ati oju ọna Benin si Ondo.
Ọmọ Uganda gba àmi ẹ̀yẹ Komla Dumor BBC tọdun yii Orí kó aboyún 19 yọ lọ́wọ́ àwọn tó ń tá ọmọ ní gbàǹjo ₦300,000 Ọpẹ́ o!
Èmi àti Saheed kìí ṣe ọmọdé, a ti jọ ṣe Sinimá papọ̀, èyí túmọ̀ sí pé ìjà ti parí - Fathia Balogun Iṣẹ́ tí Ọlọ́run kọ mọ́ mi ni mò ń ṣe -Ṣọla Ṣobọwale 'Ìyá Tíṣà lòdì sí kí n mutí, fagbó tàbí sìgá' Bakan naa ni wọn jọ mẹnuba inawo inu gbigbe fiimu tuntun sita.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Nigeria: Ọwọ tẹ afurasi mẹrin lori iku ọga SARS 8 Èrèlè 2018 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ileesẹ ọlọọpa Naijiria ko sinmi lati gbogun tiwa ọdaran Olu ilese ọlọpa nipinle Ọyọ ti sọpe ọwọ ti te afurasi merin ninu awọn eeyan to sekupa Seu Magu, ọga ọlọpa SARS, to n gbogun tawọn adigunjale, ti wọn pa ni ijeta.
Ìjọba Zamfara wọ́gilé owó ìfẹ̀yìntì tàbùà tabua fawọ̀n Gómìnà
Third mainland bridge: Afárá Third mainland gùn, ṣùgbọ́n afárá Hong Kong-Zhuhai tó gùn jùú lọ ti di ṣíṣí
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù 'A máa ń bẹ́ orí ẹni tó bá gbé imọlẹ̀ ọdún ìjẹṣu tó bá ṣubú ni' Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ 'A máa ń bẹ́ orí ẹni tó bá gbé imọlẹ̀ ọdún ìjẹṣu tó bá ṣubú ni' 17 Owewe 2018 Ìrọ̀rùn ni ẹgba jíjẹ ba dé ni ọdún ijẹṣu Ilara-mọkin nipinlẹ Ondo.
University of Education Kano) didasilẹ Fafiti ile-eko awon oluko ti  ijoba apapo Alvan Ikoku Federal University of
O ni ijọba ti kọkọ fofin silẹ fun awọn to n pọn ọti inu ọra pelebe ati igo kekeke ni ibẹrẹ ọdun 2020 pe ki wọn din iwọn ti wọn n ṣe jade ku pẹlu ida aadọta ninu ọgọrun, (50%) gẹgẹ bi igbesẹ akọkọ lati dẹkun awọn ọti inu ọra naa.
Oríṣun àwòrán, @anaedoonline Lero ti Asofin Sada Soli lati ipinlẹ Katsina, o ni asẹ ti ileesẹ asọbode pa ọhun kọja agbara ti ofin gbe le wọn lọwọ, to si kesi ile alti pasẹ fun ileesẹ assbode pe ko wọgile ofin to se naa.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù World Sàngó Festival 2019: Ìyàtọ̀ tó wà láàrín arugbá Ọ̀ṣun Òṣogbo arugbá Ṣàǹgó lóde Ọ̀yọ̀ 19 Ògún 2019 Oríṣun àwòrán, Alaafin Oba Adeyemi III Ko si tabi ṣugbọn pe bi a ba n sọrọ nipa arugba ninu iṣẹṣe ati Aṣa Yoruba, ajọdun Ọṣun Oṣogbo ni ọkan ọpọ maa n lọ.
“Mo bá fi igi akasia kan àpótí kan, mo sì gbẹ́ tabili òkúta meji bíi ti àkọ́kọ́, mo gun orí òkè lọ pẹlu àwọn tabili náà lọ́wọ́ mi.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Alaafin: Olori Aanu Adeyemi ṣàlàyé ìdí tó ṣe gẹ́ Oba Lamidi Adeyemi ti ìlú Oyo Èsì MURIC yìí wà nínú àtẹ̀jáde to adári ẹgbẹ́ náà ọjọ̀gbọ́n Ishiaq Akintola fọwọ́ sí lọ́nìí ọjọ́ Isẹgun, ọjọ kọkànlá, osú kẹjọ, 2020.
Oshiomole ni kikuro ti awọn eniyan naa kuro ninu ẹgbẹ awọn ko ba awọn ni ojiji, nitori pe awọn ti n foju sọna fun un.
Seyi Makinde ni gbogbo ẹni ti yóò ba pada sẹnu iṣẹ́ gbọdọ maa gba ẹnú ọ̀nọ́ kan ṣoṣo ti wọ́n o ṣí sílẹ̀ láti wọ sẹkitríàtì nígba ti gbogbo ìloro to kù yóò wà ni títì pa, eyi ni la'ti dẹ́kun ìtànkalẹ̀ ààrun Corornavirus.
Iye ibo ti wọn di jẹ – 599,
Yóo máa ṣe ibi ní ilẹ̀ àwọn olódodo,kò sì ní rí ọlá ńlá OLUWA.
Amọ ṣa, akọrin naa sọ pe iṣẹlẹ naa ko waye rara.
Lẹyin naa lo lọ ọ ṣaluwala, to si kirun.
Ko din ni irinwo o le mẹsan eeyan ti wọn ti mu ni ipinlẹ Kwara, Plateau, Benue ati Abuja.
Ipinlẹ Eko lo ṣi le tente pẹlu eeyan marundinlaadọsan,165 ti Abuja si tẹle pẹlu eeyan mẹtadinlogun,17.
bàbá rẹ ̀ jẹ ́ yor ̀ ubá ọmọ orílẹ ̀ èdè nàìjíríà tí ìyá rẹ ̀ sì jẹ ́ ọmọ ilẹ ̀ german .
** Àwọn iyé akọsilẹ̀ to ti wà fún àwọn ti o ṣẹ́ṣẹ̀ ni ààrun náà jẹ́ àkójọpọ̀ ọjọ́ mẹ́ta.
Bí ó ṣe ta rọ́bà rẹ̀ pàrà, ilé agbọ́n ló lọ bà.
Lara awon gomina to wa nibi
E wo awọn ile awosifila ti olola Akin-Olagbade ko to jade laye: Oríṣun àwòrán, Bolu Akin-Olugbade Ile nla alaja mẹta ni Aarẹ Onakakanfo ti ilu Owu, Bolu Akin Olugbade kọ si aafin rẹ ni Abeokuta, nitosi odo ogun Ile nla awosifila naa ni yara ibusun mọkanla, chandeliers mẹrinla, ile igbafẹ mẹrin lo wa nibẹ Bakan naa ni aafin ọhun dabi ti afin Ilẹ Gẹẹsi, Burkingham Palace, to si ni yara iwo sinima Bẹẹ ni Gbagede 'Amphitheatre' ko gbẹyin nibẹ pẹlu ibi ti ọkọ ofururu rẹ ma n balẹ si Akin Olugbade tun ni ile si ilu Eko, Ilu Ọba ni Ilẹ Gẹẹsi, Ilu Los Angeles ni Ilẹ Amẹrika ati ni Dubai pẹlu.
Ni ọjọ keji oṣu kẹrin ọdun 2019 ni Bouteflika kọwe fi ipo silẹ lẹyin iwọde ọpọ ero fun ọpọlọpọ oṣu.
Àdínkù bá owó ojúmọ́ ọlọ́kadà l‘Ọyọ láti ₦200 si ₦100, owó gbígbà bẹ̀rẹ̀ lónìí Maryam Sanda pe ẹjọ́ kòtẹ́milọ́rùn lóri ìdàjọ́ ikú Ìjàmbá ọkọ̀ tó ṣẹlẹ̀ sí Adams Oshiomole kìí ṣe ojú lásan, àwọn kan ló fẹ́ pa á- APC Wo ìtàn ayé gbajúmọ̀ adigunjalè méje nílẹ̀ Yorùbá Alhaji Mukaila ni ọwọ to ba ṣẹ ẹkusi lo maa n jẹ ẹ, o ni iyẹn tumọ si pe oun ti ṣiṣẹ silẹ de ongbẹ lasiko yii nitori ẹgbẹ oṣelu PDP loun tẹ le lasiko ibo gbogbogbo to lọ.
Bo ṣe n na orilẹede Naijiria, lo n pada si ilu Cotonou ni Republic of Benin, ti yoo si fi tipa gba ọkọ ayọ́kẹ́lẹ́ bíi ogoji ni ọjọ kan ṣoṣo, bẹẹ lo di olowo ati ọlọrọ rẹpẹtẹ.
Atiku ni kò tíì dópin fún Adeleke, PDP ni àwọn gba idájọ́ wọlé Àlàyé rèé lórí ìdí tí ìyá mi fi sọ fáráyé pé mo ti kú Wo àwọn ẹ̀ṣọ́ ara tó tó $40m Diezani Madueke tí ilé ẹjọ́ gbẹ́sẹ̀ lé Bi agbegbe naa ṣe dọti maa n fa aarun oriṣiriṣi fun awọn obinrin.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìjọba Kaduna: Gbogbo àwọn tó wà nídìí ìṣẹ̀lẹ̀ ìpànìyàn yóò gé ìka jẹ 15 Èrèlè 2019 Oríṣun àwòrán, @elrufai Gomina ipinlẹ Kaduna, Mallam Nasil El-Rufai ti figbe ta pe eeyan mẹrindinlaadọrin ni awọn gende agbebọn sekuta nijọba ibilẹ Kajuru.
Wọ́n fi agídí sé ọmọ Naijiria mọ́lé ní China nítorí àrùn Coronavirus
Champions League: Tottenham fìyà jẹ Man City
O ni wọn fi ọrọ to awọn gomina ipinlẹ gbogbo leti nibi ipade naa lori bi nnkan ṣe n fojojumọ yii sii lori ija gbigbogun tarun COVID-19 pẹlu ipa ti awọn ẹka aladani nko pẹlu idasilẹ eto CACOVID ti wọn gbe kalẹ lati ṣe iranwọ to ba yẹ.
Sanusi ko gbe ọrọ oṣelu ti sẹgbẹ kan nitori ọpọ igba lo ti bu ẹnu atẹ lu awọn adari ni iha Ariwa Naijira fun aibikita wọn lori awọn eeyan ti wọn n ṣejọba le lori.
 O soro lo si ise ti PEBEC n se pelu awon minista mewaa ati gomina banki Naijiria pelu awon olori eka ijoba kookan.
"Iku rẹ ba mi lojiji, jinni-jinni n mu mi lọwọ lori iku Ajimobi, n ko le sọ ohunkohun.
Ey na wa ni ọpọlọpọ wahala, nitori pe obinrin ọtọọtọ lo n gbe wa sile lojoojumọ.
    Mo gba ìmọ̀ràn wọn mo tẹ̀lé e dáadáa.
isoro to n dojuko awon omo orile ede Naijiria.
”Baalu ofurufu naa ti lo ọgbọn odun,aarẹ George H W Bush, ni wọn koko fi gbe.
Orílẹ̀-èdè Chad pé ọgọ́ta ọdún, àwọn ara ìlú ń pariwo lábẹ́ Aàrẹ Deby tó gba 'Field Marshal' Africa Field Marshal: Ṣé ìwọ mọ ìtumọ̀ kí wọ́n fún adarí ní oyè Field Marshal?"
Loni ni wọn yoo koju Super Eagles Naijiria lati mọ ẹni ti agbara wa lọwọ rẹ.
Asa gé oriṣa náà lulẹ̀, ó sì dáná sun ún ní àfonífojì Kidironi.
Ìfihàn tí a fúnni nípasẹ̀ Wòlíì Joseph Smith sí arákùnrin rẹ̀ Hyrum Smith, ní Harmony, Pennsylvania, Oṣù Karũn 1829.
Oríṣun àwòrán, David Ajiboye Àkọlé àwòrán, Ijọba ipinlẹ Ọyọ ni 'aigbọran Yinka Ayefẹlẹ lo mu ki awọn wo ileeṣẹ rẹ.
Ọtunba Adams s'ọrọ yii nigba ti o n fi ẹhonu rẹ han lori bi awọn Fulani darandaran se n sekupa awọn eniyan ati bi wọn se fẹsun kan darandaran kan wipe ohun lo sekupa olori awọn eleto aabo ni ipinlẹ Ọyọ.
Esi ayẹwo lati ipinlẹ mọkandinlogun ni wọn gbe jade lọjọ Abamẹta.
EndSARS protest Update: Afẹnifẹre ní ara ti kan àwọn èèyàn, ìjọba sì ló fà á
Alaga igbimọ ile lori eto iroyin, aṣofin Fatai olotu ṣalaye fun awọn oniroyin lẹyin ijoko ile pe ẹsun ṣise owo baṣubaṣu, aikun oju iwsn lẹnu iṣẹ ati ẹsun miran ni wọn tun fi kan Bamidele Oloyelogun ati igbakeji rẹ, Iroju Ogundeji ki wọn to yọọ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Tenancy: Njẹ́ o mọ ẹ̀tọ́ rẹ̀ gẹ́gẹ́ bi ayálégbé?
Nítorí náà, mo wí pé,“Ògo mi ti tán,ati gbogbo ohun tí mò ń retí lọ́dọ̀ OLUWA.
" Lukman fikun pe o se ni laanu pe igbimọ alakoso ẹgbẹ to yẹ ko wa ojutu sawọn isoro yii lo fẹ dabi eyi ti wọn ti so rọ.
UK ko tun ni maa da owo sinu eto isuna ajọ isọkan ilẹ Yuroopu mọ - eyi to jẹ biliọnu mẹsan pọun, eyiun biliọnu mọkanla ati miliọnu lọna ẹgbẹrun meji dọla ($11.
Eyi si jẹ anfaani nla lati kan si ọpọ eeyan ni ede abinibi wọn.
Ọba bá pàṣẹ fún àwọn ọmọ ogun tí wọ́n wà lọ́dọ̀ rẹ̀ pé, “Ẹ pa àwọn alufaa OLUWA nítorí pé wọ́n wà lẹ́yìn Dafidi, wọ́n mọ̀ pé ó ń sá lọ, wọn kò sì sọ fún mi.
Pẹlu abajade ifẹsẹwọnsẹ naa, Liverpool lo ṣi n lewaju atẹ igbelewọn liigi ilẹ gẹẹsi bayii pẹlu ami ayo mẹrinlelọgọta ninu ifẹsẹwọnsẹ mejilelogun nigba ti Manchester United ṣi di ipo karun un rẹ mu pẹlu ami ayo mẹrinlelọgbọn ninu ifẹsẹwọnsẹ mẹtalelogun.
kí ẹ wá mú àbíkẹ́yìn yín tí ẹ̀ ń wí wá, kí n rí i, kí á lè mọ̀ pé òtítọ́ ni ọ̀rọ̀ yín, ẹ óo sì wà láàyè.
Kò sì sí èyíkéyìí ninu àwọn ọ̀tá wọn tí ó lè ṣẹgun wọn, nítorí pé OLUWA ti fi gbogbo àwọn ọ̀tá wọn lé wọn lọ́wọ́.
gbọ́ adura ati ẹ̀bẹ̀ wọn láti ibùgbé rẹ lọ́run, kí o sì tì wọ́n lẹ́yìn.
“Àwọn ni wọ́n lè sọ yín di aláìmọ́; ẹnikẹ́ni tí ó bá fi ọwọ́ kan òkú wọn yóo di aláìmọ́ títí di ìrọ̀lẹ́.
Àwọn àwòrán ìrántí tó ń sàmì ogójì ọdún tí Ọba Adesoji Aderemi jáde láyé Ẹ wo bí ìsìnkú Adegbenro, Kọmíṣọ́nnà l‘Ondo ṣe lọ.
n ko lori eto idagbasoke  eto ọrọ aje ko
Igbákejì gómìnà Ondo ti gbawọn òṣiṣẹ́ rẹ̀ mẹ́jọ tí Akeredolu dá dúró ṣíṣẹ́ padà Igbakeji Gomina ipinlẹ Ondo to fi ẹgbẹ oṣelu APC silẹ lọ si PDP, Agboola Ajayi ti gbawọn amugbalẹgbẹ rẹ mẹjọ ti Gomina Rotimi Akeredolu da duro lẹnu iṣẹ.
8 wọlé lójúmọ́ lẹ́yìn tíjọba ti ẹnu bodè -Ali Ìjọba ní ọmọ Naijiria yóò padà sí ní san owó ‘tollgate' Hall ni oun mọ pe o ṣoro fun awọn akanda ẹda lati gbori soke ninu isẹ akọroyin.
8 146317 Orilẹede Croatia 2420 58.
Ogun gbóná ní ọjọ́ náà, Ahabu ọba bá rá pálá dìde dúró, wọ́n fi ọwọ́ mú un ninu kẹ̀kẹ́ ogun rẹ̀, ó kọjú sí ogun Siria.
“Ẹ̀yin ni ẹ̀ ń ṣe àkóso àwọn ọmọ ọba, ẹ sì ní àwọn kẹ̀kẹ́ ogun, ẹṣin, ati àwọn ohun ìjà ati àwọn ìlú olódi ní ìkáwọ́ yín.
Coronavirus Pandemic: Màmá Guardiola d'olóògbé lẹ́yìn tó lùgbàdì Coronavirus
Àsìkò tó láti fi ìwọ́de gba ara wa sílẹ̀ lọ́wọ́ ebi àti oko ẹrú - Sowore Saaju ni Alaafin ti mẹnuba ipenija aisiṣẹ fawọn ọdọ lagbegbe rẹ ati jakejado Naijiria.
Ijamba baalu mu ẹmi mejilelọgbọn lọ Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Olóòtú ìjọba ilẹ̀ Gẹ̀ẹ̀sì, Theresa May sọ pé ó dá òun lójú ọwọ́ àwọn tẹ oun tí wọ́n fẹ́ Látàrí ìkọlù tó wáyé lórí orílẹ̀èdè Syria, olóòtú ìjọba ilẹ̀ Gẹ̀ẹ̀sì, Theresa May sọ pé ìgbésẹ̀ orílẹ̀èdè Amẹ́ríkà àti Faransé tí ilẹ̀ Gẹ̀ẹ́sí dara pọ̀ mọ́ dá òun lójú wípé ti jíjáwé olúborí ni.
Gbogbo nakn naa lo gbe wa de ibi ti a de l'oni.
Ṣugbọn Aroloye sọ pe o lodi si iṣẹṣe ilu Idanre ki obinrin jẹ Adele Ọba.
Salawu Street Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ondo disability: Kò sí ẹni tí àkàndá kò lè ya ilé rẹ̀- Ayọdele Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
'Títẹ àwọn afipábánilopọ̀ lọ́dàá kọ́ ni ọ̀nà àbáyọ sí ìwà ìfipábánilopọ̀' Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Claudiah: ìrẹ̀wẹ̀sì ọkàn bá mi fínra fún ọpọlọpọ ọdún Iwa ifipabanilopọ kii ṣe ohun to bojumu, ṣugbọn o dabi pe iwa yi n burẹkẹ si ni Naijiria lẹnu ọjọ mẹta yii.
 nẹ ́ ọ ̀ nù ni ó jẹ ́ èkejì nínú àwọn ẹ ̀ fúùfù àṣọ ̀ wọ ́ n mẹ ́ tẹ ̀ ẹ ̀ ta tó jẹ ́ wíwárí , ó sí jẹ ́ dídámọ ̀ kíákíá bíi ẹ ́ límẹ ̀ ntì tuntun nítorí ìgbàjá-àwọ ̀ ìtúsíta pupa rẹ ̀ .
Ó ni bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé, irinṣẹ́ tó wà nínú ilé ìwòsan náà ko kójú òsùwọn tó síbẹ̀ wọ́n ṣe aṣeyọri.
 bì ó tilẹ ̀ jẹ ́ wípé àwọn ológun ilẹ ̀ nàìjíríà , kìíbfipá múni láti dara pọ ̀ mọ ́ iṣẹ ́ kgun .
21 Èrèlè 2018 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 28 Ìgbé 2020 BBC Yoruba ko fẹ ki ede Yoruba parun ni iran yii ni a ṣe maa n ran ara wa leti awọn ọrọ kan ki a le tumọ rẹ fun ara wa.
Àwọn olórí tí wọ́n wà nílùú dàbí kinniun tí ń bú, tí ó sì ń fa ẹran ya.
Báńkì ìdàgbàsókè Áfríkà yóò bẹ̀rẹ̀ àkọ̀tun ìwadìí lórí Olùdarí báńkì náà, Akinwumi Adesina Banki to wa fun idagbasoke ilẹ Afrika, The African Development Bank, sọ pe oun ti ṣe agbekalẹ igbimọ oluwadii aladani lati wadii awọn ẹsun iwa ibajẹ ti wọn fi kan Oludari banki naa, Akinwumi Adesina.
Gbogbo àwọn ọ̀sanyìn ọba náà ni wọ́n lọ tí àwọn náà sì kú sí oko.
Ko si ija laarin wa ti a ba si ri ede aiyede kan ao pari rẹ ni tubi n nibi ni, gẹgẹ bi baba ati ọmọ."
nítorí ẹ̀ṣẹ̀ tí ó dá, tí ó ṣe nǹkan burúkú lójú OLUWA, tí ó tọ ọ̀nà tí Jeroboamu tọ̀, ati fún ẹ̀ṣẹ̀ tí ó dá: tí ó mú kí àwọn ọmọ Israẹli náà dẹ́ṣẹ̀.
egbe oselu APC ti won yoo tun maa satileyin fun Ahmad ni awon gomina ipinle teleri,
Ẹni tí ń gbé abẹ́ ààbò Ọ̀gá Ògo,tí ó wà lábẹ́ òjìji Olodumare,
"O ni ""Itakurọsọ laarin ọmọ naa ati iya rẹ panilẹrin, ṣugbọn o sọ nipa akitiyan awọn obi lati kọ awọn ọmọ wọn lẹkọọ ile to ye kooro."
Oluwatobiloba Ipense jẹ oluṣọ ni ileejọsin Holy Gathering Evangelical Church ti o wa ni Papalanto, ni agbegbe ijba ibilẹ Ewekoro.
" Awọn iroyin ti ẹ le nifẹ̀ si: Charles Okah gba'dajọ ẹwọn gbere 'Naijiria ko laṣeyọri lori gbigbogun t'iwa ijẹkujẹ' Rufai Imam di adajọ agba ile ẹjọ Sharia ‘A ko mọ ibi ti Nnamdi Kanu wa’ Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Àjànàkú sùn bí òkè, erin wó kò le dìdi.
 agbára ni ó fi ń darí ilẹ ̀ náà ( a dictator ) .
Ọpọ ni wọn ti jigbe, ge lapa tabi lẹsẹ, fipa ba lopọ ti awọn miran si ti ku.
tuntun ki o to di pe adehun to wa laarin wọn yii yoo tan lọdun to n bọ.
Bẹẹ gẹgẹ ni igbakeji adari ile igbimọ aṣofin agba l'Abuja tẹlẹ, Sẹnẹtọ Ike Ekweremadu ti fesi si bawọn ẹya Igbo to ni ọmọ ẹgbẹ IPOB ni wọn ṣe fiya jẹẹ lọjọ abamẹta ni ilu Nuremberg lorilẹede Germany.
Ewé igi inú igbó ni wọ́n ń já jẹ,àní, àwọn igi ọwọ̀ tí kò ládùn kankan.
Egbẹ ọdọ Yoruba naa fọnmu lori ihuwasi Oluwoo Alakoso ẹ́gbẹ́ YYSA, Ọlalekan Hammed ni, ti wọn ko ba tete wa nkan se lori ọrọ yii, o seese ko di wahala nla lọjọ iwaju.
Ó bẹ̀rẹ̀ láti ibi àkọsílẹ̀ yìí, ó waasu ìyìn rere Jesu fún un.
Ni apapo, O gba ife-eye mẹ́rìndínlógún, ami-eye agbaboolu ti o gba boolu sagbon julo igba merin otooto ati awon olokan-o-jokan ami-eye ti ko lo n ka.
Bakan naa, lo tun sọ nipa bo ṣe pada gbe ọmọ naa lọ si yara awọn ọmọ wẹwẹ ati bo se wa di ohun to n kọ ni lẹnu lati sọ bi ọmọ ọdun kan ti ko tii le rin tabi sọrọ ṣe poora.
Amosa, ki odun yii to pari ni wọn  yoo se ifilole re niluu Abuja.
Ẹ máa hùwà bí ẹni tí ó ní òmìnira, ṣugbọn kì í ṣe òmìnira láti bo ìwà burúkú mọ́lẹ̀.
Èrò rere kan ń gbé mi lọ́kàn,mò ń kọ orin mi fún ọbaahọ́n mi dàbí gègé akọ̀wé tó mọṣẹ́.
Nibẹ naa lawọn miran a si ti ma dọta ti ija wọn ko ni pari.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, NISE NI OJO TO RO LEKO KUN OJU TITI Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
3 2444 Orilẹede Lesotho 44 2.
Nítorí náà, Ìyábọ̀, ṣọ́ra rẹ o.
Gẹgẹ bi ọ̀rọ̀ Yorùbá ti ó sọ pé “Igba” ó yẹ ki enia kọ lati lo àsikò dáradára, nitori igbà kò dúró de ẹni kan.
Lẹyin ọ rẹyin, ami ayo mẹta sẹyọkan ni Everton fi gbo ewuro soju Chelsea Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
“Bí ẹ bá fẹ́ràn mi, ẹ óo pa òfin mi mọ́.
Ẹni tí ọ̀nà rẹ̀ bá tọ́, tí ó sì ń sọ ọ̀rọ̀ òtítọ́,ẹni tí ó kórìíra èrè àjẹjù,tí ó kọ̀, tí kò gba àbẹ̀tẹ́lẹ̀,tí ó di etí sí ọ̀rọ̀ àwọn tí ń gbèrò ati paniyan,tí ó sì di ojú rẹ̀ kí ó má baà rí nǹkan ibi.
N kò yapa kúrò ninu òfin rẹ,nítorí pé o ti kọ́ mi.
O jẹ́ ǹkan to ya ni lẹ́nu lati maa gbọ ìròyìn òfége pe adiyẹ broiler lo n fa COVID19, oṣiṣẹ kan ni NCDC, Chukwuemka Oguanuo lo sọ fún BBC.
 Ibanujẹ ni nkan to ṣẹlẹ jẹ fun ẹbi wa, nkan ti a si fẹ ni pe ki awọn to ṣe nkan yii ko má lọ lai jiya."
Oludari agba eka iforotonileto ati igbodegba ile-ise omo ogun naa, ogagun Ibikunke Daramola ati oga agba eka iwosan, ogagun Sale Shinkafi soro ohun di mimo fun awon akoroyin pe, erongba sise agbekale eto idanileko naa ni lati ro awon osise naa lagbara si labe ise akanse Operation LAFIYA DOLE ti o fi mo awon eka miiran lorile-ede yii.
gbogbo ìran àwọn tí ó kù ní ilẹ̀ náà, tí àwọn ọmọ Israẹli kò parun, ni Solomoni ń fi tipátipá kó ṣiṣẹ́ títí di òní olónìí.
Kò sí èyí tí kò tóbi tó géńdé ọkùnrin nínú àwọn ọlọ́pàá wọn-ọnnì, wọ́n ba ni lẹ́ru gidigidi.
Ṣugbọn kò ba àwọn pẹpẹ ìrúbọ jẹ́, àwọn eniyan ń rú ẹbọ níbẹ̀, wọ́n sì ń jó turari.
Àwọn òpó ọ̀run mì tìtì,wọ́n sì wárìrì nítorí ìbáwí rẹ̀.
Mercy Aigbe bu èpè jó àwọn tó ní gómìnà kan ló ra ilé fún-un Funke Adesiyan, òṣèré Yollywood tó di olùrànlọ́wọ́ aya ààrẹ, Aisha Buhari Àwọn òṣèré tíátà kan rèé, tí wọn fẹ́ ara wọn, tí ìgbeyàwó wọn sì pẹ́ Toyin Abraham rèé, ọmọ ìpínlẹ̀ Edo tó di àràbà nínú tíátà Yorùbá Mr Latin, Jide Kosọkọ àti Mama Rainbow sọ̀rọ̀ lórí ìjà Toyin ati Lizzy Liz Da Silva Oríṣun àwòrán, @lizdasilva Elizabeth Tekovi Da Silva ni apeja orukọ Liz to jẹ ọmọ Naijiria ṣugbọn ti awọn obi rẹ ara orilẹ-ede Togo bi i ni Lagos Island, ipinlẹ Eko to si dagba ni agbegbe Obalende l'Eko.
Èyí ni pé Ọlọrun kì í ṣe Ọlọrun àwọn òkú bíkòṣe ti àwọn alààyè.
Tinubu se'pade pẹlu gomina ipinlẹ Sokoto, Aminu Tambuwal ati sinetọ Aliyu Wamakko lori bi ija to wa laarin awọn ọmọ ẹgbẹ naa ni iwọ-orun ariwa Naijiria yoo ti pari.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Coronavirus vaccine: Kí ló wà nínú àbá àkóso ajakalẹ àrùn tó fi ní àtakò?
A kò tí ẹnu Bodè pa rárá- iléeṣẹ́ Aṣọ́bodè Ikú dóró!
Igbesẹ Kinni: Ohun akọkọ ni lati fi iwe ẹsun wiwu iwa aitọ ranṣẹ si Igbakeji Gomina Ida mẹta awọn aṣofin lo gbọdọ bu ọwọ lu iwe ẹsun yii, ti olori Ile Aṣofin si gbọdọ fi ọwọ si.
itan àtenudénu fìdí rè múlè pé àwon ènìyàn yaka pèlú suku jé ara àwon tí ó kógun ja ìlú ńlá kongo ni egbèrún odún kerìndínlógún .
Iko agbaboolu MFM FC tilu Eko, lorile-ede Naijiria ti jade kuro ninu idije CAF Confederation Cup (CAFCC), bi o ti le je pa, esi ifigagbaga ese keii naa pari si omi ayo(0-0) pelu iko agbaboolu Djoliba torile-ede Mali.
Àwọn náà ni Vee, Neo Nengi Laycon Dorothy Àwọn mẹ́ẹ̀dógun lo tí kó ẹrù wọ́n kúrò níle ẹlẹ́gbọ̀n àgbà láti ìgbà ti ètò náà ti bẹ̀rẹ̀ Lilo, Ka3na, Eric, Tochi, Kaisha, Praise, Wathoni, Tolanibaj, Bighto, Lucy, Prince Kiddwaya, Trickytee àti Ozo,wọ́n lé Erica lọ nírori o rú òfin Bigbrother.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Lagos State: Ìjọba ìpínlẹ̀ Eko ní irọ́ ni àjọ EIU ń pa pé ìlú Eko ló léwu jùlọ láti gbé lágbàáyé 2 Owewe 2019 Àkọlé àwòrán, Lagos State: Ìjọba ìpínlẹ̀ Eko ní irọ́ ni àjọ EIU ń pa pé ìlú Eko ló léwu jùlọ láti gbé lágbàáyé Ilu Eko kọ lo lewu julọ lati gbe lagbaye, koda ilu Eko wa lara awọn ilu ti eeyan le gbe pẹlu ifọkanbalẹ nilẹ Afirika.
Ọmọ Eko ni baba rẹ amọ ọmọ ipinlẹ Edo ni iya rẹ.
Nitori emi kọ ni ọba, Ọlọrun ni ọba.
"O sọ fun mi pe oun n sinmi lọwọ, ṣugbọn iyalẹnu lo jẹ fun mi pe o ti di eero mọsuari nigba ti yoo fi di aago marun irọlẹ.
Ọjọ karundinlọgbọn, oṣu karun un, ọdun 2020 ni awọn akẹkọọ pada sẹnu ẹkọ wọn.
Obi ti ko ba mọ iru awọn ilana bayii, lati so ẹmi wọn rọ, wahala nla ni wọn ma n koju.
Èyí náà wá já sí àádọ́wà mílíọ́nù àpò ìrẹsì (190).
 "" Mo ni Akeredolu nikan kọ lo bori eto idibo naa, mo ni awa taa jẹ akọni oselu, awọn asoju ẹgbẹ ati araalu la dijọ sisẹ taa fi bori ibo naa."
Ìyàn tí ó mú ní ìlú Samaria pọ̀ pupọ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Anthony Joshua: Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Ẹ̀yin ọmọ Israẹli ẹ má yọ̀, ẹ sì má dá ara yín ninu dùn, bí àwọn orílẹ̀-èdè mìíràn, nítorí ẹ ti kọ Ọlọrun yín sílẹ̀, ẹ ti ṣe àgbèrè ẹ̀sìn lọ sọ́dọ̀ oriṣa.
Amọ ajọ DSS ko sọ boya wọn yoo mu ẹnikẹni to ba yọju fun iwọde naa l'ọjọ Aje.
O f'ojuhan pe, aarẹ n binu simi.
"138 tolosa ( latin "" tolōsa "" , / toʊˈloʊsə / or / toʊˈloʊzə / ; [ toˈloː."
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Èyí ni bí àwọn ọmọ̀dé 20 ṣe kú sínú kànga ní Kano 30 Èbibi 2018 Àkọlé àwòrán, Kànga ni orísun omi fún ọ̀pọ̀lọpọ̀ ìdílé ní ìpínlẹ̀ Kano Máni gbàgbé ni ọjọ́ kọkàndínlógún, oṣù Kẹrin ọdún 2018 jẹ́ fún ìdílé Bashir Hotoro.
Alukoro fun ile-ise olopaa, Moshood se lalaye lekunrere pe, gbogbo ẹka SARS to n sise labe asia eka to n mojuto iwa odaran ati ise iwadii (Force Criminal Intelligence and Investigations Department (FCIID).
Fífò ni odi náà tí ènìà máa fi bọ́ sí inú oko nlá náà.
Ninu àwọn ọmọ Finehasi, Geriṣomu ni olórí.
Ètò sogúndogójì 'MMM' tún ti padà dé, rọ́bọ́ọ̀tì ni yóò maa ṣàkóso Ọ̀rọ̀ ti yanjú dé ibì kan lórí owó àjẹmọ́nú àwọn Super Falcons Ọmọ ogun Nàìjíríà bẹ̀rẹ̀ lílo 'Drone' láti gbógun tàwọn ajínigbé ni Ondo àti Ekiti Jẹ́ kí a jọ sọ àǹfàní US fún Nàìjíríà -Osinbajo Tiffani ni ẹ̀rù ba ọkunrin yii to di jinijini sii lara pé bawo leeyan a ṣe wa ninu ọkọ ofurufu di asiko naa.
Ó ṣe àlàyé pé, ohun fẹ́ràn Olóri Ẹrú gidigidi nitori o fi tọkàn-tọkàn sin ohun, nitori na a, ki wọn kó gbogbo ohun ini ohun fún Ẹrú yi.
O ni erongba Obasanjo ni ọrọ to wa ni ninu atẹjade naa, ati pe gẹgẹ bi ọmọ Naijiria, Baba Iyabo lẹtọọ lati sọrọ labẹ ofin.
Orí kí ni a gbé ìpìlẹ̀ rẹ̀ lé,àbí ta ló fi òkúta igun rẹ̀ sọlẹ̀;
''Ohun to ṣẹlẹ ni pe ijọba Kwara da ninu owo ti wọn fi kọ ile naa ni ibamu pẹlu ofin to de sisan owo ifẹyinti fawọn Gomina ati igbakeji wọn ti Saraki si fi owo ara rẹ pari eleyi to ku'' Olaniyonu sọ pe iṣẹ ko bẹrẹ lori ile yi titi di asiko ti Saraki fẹ pari saa rẹ gẹgẹ bi Gomina ti o si fi iwe sọwedowo san owo kikọ ile naa Ojú alábaṣiṣẹ́pọ̀ Mompha rèé, EFCC ṣí i síta A ò tì ilé Saraki pa ní'lú Eko - EFCC EFCC: Àwọn ọba aládé àti olóṣèlú ṣé àpapín owó ìrànwọ́ N2bn ní Kwara Dino ní ìyàwó ni Adeyemi jẹ́ f'óun lágbo òṣèlú, Adeyemi l'ọ́mọ ọ̀dọ̀ ni Dino jẹ́ O wa tẹnumọ pe Saraki yoo tako igbesẹ yi ni ile ẹjọ lati le fi igbagbọ rẹ ninu titẹle ofin ilẹ yi rinlẹ .
    Nígbà tí ó wí báyìí tán mo tọrọ ààyè lọ́wọ́ rẹ̀, kí ó fún mi ní ààyè díẹ̀ kí èmi àti àwọn ẹlẹgbẹ́ mi lọ ronú nípa ọ̀ràn náà, ó sì gbà bẹ́ẹ̀ fún mi.
Ni osu kini ọdun yi, itanna Facebook ni awọn yoo satunse bi awọn eniyan yoo se maa ri iroyin lori itakun naa, ati wipe awọn yoo jẹ ki awọn eniyan o maa ri nnkan ti ẹbi ati ọrẹ ba fi s'oju opo lọlọpọ ju ipongo awọn onisowo, ile-isẹ iroyin ati awọn ile-isẹ nlanla miran lọ.
Ologbondiyan ní ìjọba apápọ̀ àti ẹgbẹ́ APC fẹ́ ẹ̀ mọ̀ọ́mọ̀ da ètò ìṣèjọba àwaarawa Nàìjíríà jẹ́ ni.
Wọn le ni ipa bi i : Ara yiyun ati wiwu Ara tita tabi jijajẹ Ati ki àwọ ara o maa bo (Orisun -NHS UK) Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
N όò jόkòό sí ipò-o bàbá-à mi, ẹ̀yin ọ̀rẹ́-ẹ̀ mi náà yόò sì jόkòό sí ipò mi bí mo bá ṣe ńsọ ìtàn náà fún fún-un yín.
", mo si n dupẹ fun itọni ati isinileti wọn, ade yoo pẹ lori, bata yoo si pẹ lẹsẹ.
Àwọn ọkunrin mẹtẹẹta náà kò dá Jobu lóhùn mọ́, nítorí pé ó jẹ́ olódodo lójú ara rẹ̀.
Balaamu dáhùn pé, “Nítorí tí ò ń fi mí ṣẹ̀sín, bí ó bá jẹ́ pé idà wà lọ́wọ́ mi ni, ǹ bá ti pa ọ́.
Gbajúgbajà ife ẹ̀yẹ mẹtalelogun ọ̀tọ̀ọ̀tọ̀ ni Serena Williams ti gba, ninu ìdíje tẹniisi lágbáyé.
O ni agbaboolu ọhun ti setan lati da ogo orile ede yii pada ninu ere ifesewonse U-17 to n lọ lọwọ.
 Ó tẹ ̀ síwájú nínu ẹ ̀ kọ ́ rẹ ̀ ní yunifásitì ti ìlú Ìbàdàn níbi tí ó ti gba oyè kejì ( m.
Oun wuwa si ni gẹgẹ bi ọmọ lai fasẹyin fun ẹnikẹni to ba tọ ọ wa.
Ogbeni  Raphael Biu, tun ro ijoba apapo lati wa woroko fi sada, lori owon-gogo epo-robi ti n waye ni gbogbo igba, latari ati mu irorun ba awon ara-ilu.
Naijiria ni ipa rere lori oun, bakan naa ni oun tun  gbiyanju lati 
O ni oju ẹni to kọ ọkọ rẹ silẹ n ri to!
Amọ ṣa, ojisẹ Ọlọrun naa ni oun ti forijin awọn ajọmọgbe naa patapata gẹgẹ bi Pope mimọ ṣe darijin awọn agbenipa to fẹ gba ẹmi rẹ nijooni.
Akanse eto naa, to jẹ akọkọ tileese ologun kan yoo ṣe nilẹ Afirika, lo wa lati ṣe awari awọn eeyan to n kede iroyin aṣọdun lori ayelujara.
Olόyè Ògbójú ti wό ilé aláìsàn rí nítorí onitọ̀un jẹ-ẹ́ ní kọ́bọ̀.
8 3182 Orilẹede Central African Republic 63 1.
“Ohun tí a kọ náà nìyí: ‘MENE, MENE, TEKELI, PERESINI.
Awọn ọmọde ẹfalelaadọruunlelẹgbẹriin (894) ti ẹrindinlaadọfa (106) lara wọn je obinrin ni wọn gba itusilẹ lọwọ awọn ọlọde to n koju awọn agbesunmọmi pelu awọn ologun(CJTF) ni Maiduguri, ariwa-oorun Naijiria loni, gẹgẹ bi ipa lati dẹkun lilo awọn ọmọde fun ikọ agbesunmọmi.
Ẹ kú atijọ o, kí ni ṣe tí ó pẹ tó bẹ́ẹ̀ kí ẹ tó kúrò ni ìlú àwọn Èdìdàrẹ́ .
Nígbà tí àwọn Olófìn-íntótó dé ilé Orímóògùnjẹ́ láti bẹ̀rẹ̀ ìwádìí.
Naijriia sekupa, ti olopaa kan miiran si farapa yananaIsele buruku naa waye ni
ra irinse oko ogun oju omi naa.
Jesu fi ohùn líle kìlọ̀ fún un, lẹsẹkẹsẹ ó bá ní kí ó máa lọ.
MC Oluomo: Ẹgbé Awakọ lpińlẹ Èko yan Musiliu Ayìndé Akínsànyà bíi Adarí.
BBC sọ̀rọ̀ lórí òfin tí Burundi fi dè é
 Awọn ọdẹ ilu Ipao Ekiti ti fariga."
Aba naa, ti Sẹnatọ Bima Enagi to n soju ẹkun idibo guusu ipinlẹ Niger gbe wa siwaju ile, ti wọn si ti ka fun igba akọkọ, lo tun n daba ijiya ẹwọn ọdun mẹwa fun ẹni to ba gbe jẹnẹratọ wọ Naijiria wa tabi to ba n ta a.
Lasiko to n kede igbesẹ naa, Alaga ẹgbẹ NLC nipinlẹ Ọyọ, Comrade Bayọ Titilọla-Sodo, sọ pe awọn bẹrẹ iyanṣẹlodi pẹlu ireti pe ọjọ diẹ to ku ninu iṣejọba to wa nita lọwọlọwọ nipinlẹ Ọyọ yoo so eso rere fun awọn oṣiṣẹ.
Nígbà náà ni Pilatu sọ fún un pé, “O kò gbọ́ irú ẹ̀sùn tí wọn ń fi kàn ọ́ ni?
Oríṣun àwòrán, Olawale Abolade Jẹgẹde ni ki lo de ti ile iṣẹ INEC ko jona saaju asiko yii.
"Báyìí lo ṣe kọ sójú òpó Twitter rẹ, ""Mo ti lùgbàdì ààrùn Covid-19"", mo ti lọ si ilé ìwòsàn."
2 146 Orilẹede Monaco 3 7.
 ile eko igbalode ti Oba Akinbiyi ni
Nítorí náà, OLUWA àwọn ọmọ ogun ní òun óo jẹ wọ́n níyà; àwọn ọdọmọkunrin wọn yóo kú lójú ogun, ìyàn ni yóo sì pa àwọn ọmọkunrin ati ọmọbinrin wọn.
Jọ̀wọ́, dáríjì èmi iranṣẹ rẹ, ìwà òmùgọ̀ gbáà ni mo hù.
Mose ṣe gbogbo ohun tí OLUWA pa láṣẹ fún un.
Halima Sani to jẹ ọkan lara awọn obinrin ilu naa to ba BBC sọrọ wi pe awọn obinrin ilu naa yoo fẹdọ lori oronro sun bayi ti ọwọ ti tẹ ọdaran yi.
Wọ́n sì ta á lọ́fà ninu kẹ̀kẹ́ ogun rẹ̀ ní ọ̀nà Guri lẹ́bàá Ibileamu, ó sá lọ sí Megido, níbẹ̀ ni ó sì kú sí.
Òmùgọ̀ ọmọ á kẹ́gàn ìtọ́sọ́nà baba rẹ̀,ṣugbọn ọmọ tí ó gbọ́ ìkìlọ̀, ọlọ́gbọ́n ni.
Saraki pè fún ìwádìí ikú olórí ikọ̀ adigunjalè tó ṣọsẹ́ ní Offa Obìnrin pa olólùfẹ́ rẹ̀, ó fi se ìrẹsì 'Ààrùn sickle cell ti lóògùn báyìí' Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ọba Olutayọ: ìgbésẹ̀ Ọọni àti Alaafin ti ń mú ìṣọ̀kàn dé sáàrin àwọn Ọba Yorùbá Ìwé ìlànà ìṣèjọba ọlọdún méje tí Atiku gbé jáde lọjọ Àìkú tún sọ wí pé, àwọn eeyan to padanu isẹ wọn lati 2014 ti to miliọnu meje bayii.
Ṣugbọn Ọlọrun ranti Noa, ati gbogbo ẹranko, ati ẹran ọ̀sìn tí ó wà pẹlu rẹ̀ ninu ọkọ̀.
 Wọn ni ayẹyẹ naa ni Ikọ Ẹgbẹ Akọrin Ijọ Methodist, ẹka ti Ipinlẹ Eko lapapọ (Lagos Diocese of Methodist Musical Society) gbe kalẹ lọdọọdun bayii lakọtun lati jẹ ki awọn ijọ ati awọn eniyan maa lanfani si  awọn ojulowo orin imisi ẹmi mimọ aladun loriṣiriṣi ti wọn mọ mọ Ijọ Methodist.
Jesu bá wò ó sàn; ọkunrin náà bá bẹ̀rẹ̀ sí sọ̀rọ̀, ó sì ríran.
- Àjọ ajàfẹ́tọ̀ọ́ ọmọdé Al Shabab ṣe ìkọlù sí ibùdó ogun America ní Kenya, ẹ̀mí mẹ́ta lọ síi Buhari, Osinbajo, ẹ̀yin gómìnà, ẹ kéde dúkìá yín kọ́jọ́ méje tó pé-SERAP Pẹsẹ́ ní Ọlọ́pàá Nàìjíríà wà látàrí ìṣekúpani Ọ̀gágun Iran- Ọ̀gá Ọlọ́pàá Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Inu mi bàjẹ́ nígbà tí mo bí i, odidi oṣù mẹ́ta, mi ò lè gbàdúrà s'Ọ́lọ́run' Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Iditẹ gbajọba naa si lo yẹ aga akoso mọ aarẹ ana, Boubacar Keita ati olootu ijọba rẹ nidi lọjọ Isẹgun.
Bí Jesu ti ṣe ìrìbọmi tán, tí ó gòkè jáde kúrò ninu omi, ọ̀run pínyà lẹsẹkẹsẹ.
Nítorí náà, ẹ máa gbadura láì sùn, láì wo, fún gbogbo àwọn eniyan Ọlọrun.
Agbada náà nípọn ní ìwọ̀n ìbú àtẹ́lẹwọ́ kan.
Àlàyé rèé lóríi ìdí tí wọ́n fi ń pe aya ní ìyàwó Itan igbe aye Basọrun Gaa: Basọrun Gaa ni olori ogun Ọyọ ile ati gbajumọ ilu ni saa onka ẹgbẹrun ọdun kẹtadinlogun si ikejidnlogun, 17th / 18th century Basọrun Gaa se gudugudu meje ati ya a ya mẹfa lati rii daju pe Ọyọ ile akọkọ di ilu nla, o lagbara, to si fẹ de ọpọ ilu ati orilẹ-ede lode oni Lọdun 1750 ni Alaafin Labisi yan Gaa gẹgẹ bii Basọrun, olootu ijọba ati olori igbimọ lọbalọba ẹlẹni meje fun Alaafin nilu Ọyọ ile, ti agbara si n pa Gaa bi ọti Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Wo itan omi gbigbona ati tutu ni Ikọgosi Ekiti Ilu Ọyọ ile roju, o tuba, o tusẹ lasiko ti Basọrun Gaa joye, ti Ọyọ si maa n gba isakọlẹ lati ọpọ ilu àmọ́nà to wa labẹ rẹ Tọmọde-tagba nilu Ọyọ lo n bẹru, ti wọn si n bọwọ fun Basọrun Gaa, tori pe o ni oogun abẹnu gọngọ, ti asẹ rẹ si mulẹ ni aarin ilu ju Alaafin Labisi to yan an sipo lọ Itan sọ pe Basọrun Gaa ni oogun pupọ, to si maa n parada di ẹranko to ba wu u, to fi mọ Ẹkun, Kiniun, Igala, Ọya ati bẹẹ bẹẹ lọ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Awọn Obinrin Dahomey: Awọn obinrin ilẹ Afirika ti wọn yii itan pada re e Ni kete ti Gaa di Basọrun ni Ọyọ ile lo pa meji ninu awọn ọrẹ imulẹ Alaafin Labisi, eyi to dun ọba naa de egungun, to si gba ẹmi ara rẹ lọdun 1750 naa Alaafin Awọnbioju lo jẹ Alaafin lẹyin Labisi, sugbọn niwọn igba toun naa kọ lati gba itọni lọdọ Basọrun Gaa, aadoje ọjọ pere lo lo lori itẹ ti Gaa fi ni ki wọn yẹju rẹ Alaafin Agboluaje to jẹ lẹyin Awọnbioju tiẹ ri ijọba se n tiẹ, tori o n gbọrọ si Basọrun Gaa lẹnu, sugbọn ọwọ Basọrun Gaa naa ni ẹmi rẹ papa bọ si.
owo ti a n ṣagbekalẹ rẹ lonii yii jẹ akojọpọ ati afihan awọn owo ati
Àwọn wọnyi ni ẹ̀mí àwọn ẹni tí kò gbàgbọ́ nígbà kan rí, nígbà ayé Noa, nígbà tí Ọlọrun ninu àánú rẹ̀ mú sùúrù tí Noa fi kan ọkọ̀ tán.
sisan ẹkunwo  ọgbọ̀n egberun naira ti o je owo
org Àkọlé àwòrán, Lati ilẹ ni Atiku ti tẹnumọ ipese iṣẹ ni adisọkan rẹ Bakannaa ni iwe eto iṣejọba naa ni ti awọn ọmọ Naijiria ba dibọ fun Atiku,yoo sọ ajọ to wa nidi ọrọ epo rọbi lorilẹede Naijiria, NNPC di aladani ti yoo si ta awọn ile iṣe ifọpo epo mẹrẹrin to wa ni Naijiria.
Soyinka wa n beere pe ki wọn fi iya to pọ jẹ awọn eeyan to wa nidii ṣíṣe iyansipo oselu naa ninu ijọba Buhari nitori iwa ọdaran ni wọn hu.
1403 au , ati essentriki re je 1172 , iyipo re je 4.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Awọn onimọ nipa eto ayika ti sọ wi pe ijamba ti lilo nylon tabi rọba n se si ayika pọju anfaani to n se lo.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Coronavirus tips: Kí ni a ń pè ní fẹntilétọ̀ àtipé kí ni pàtàkì rẹ̀?
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Lagos Lockdown: Ìgbésẹ̀ ìjọba lórí Twitter tì mí lójú- Jimi Disu 10 Ìgbé 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 13 Èbibi 2020 Oríṣun àwòrán, OTHERS Àkọlé àwòrán, Lagos Lockdown: Ìgbésẹ̀ ìjọba lórí twitter gbà mí lójú tì- Jimi Disu Ọ̀pọ̀ àwọn ọmọ orílẹ̀-èdè Nàìjíríà nípìnlẹ̀ Eko tí bu ẹnu àtẹ́ lu ìjọba ìpínlẹ̀ Eko fún ìgbésẹ̀ rẹ̀ bí ó ṣe gbé sorí àtẹ̀jísẹ twitter pé kí àwọn ènìyàn dìbò bóyá kí ijọba kéde ìgbélé míràn tàbí kí wọ́n ma kéde.
Bi o ti le je pe, James Rodriguez gba ami ayo miiran wole, sugbon omi poju oka lo.
 O ni:“Ọrọ to wa niwaju wa yii ki i ṣe boya ẹnikan fẹ
 lára èyí ni : síse ẹran ẹlẹ ́ dẹ ̀ dáradára , àwọn ilé ìyàgbẹ ́ tí ó tọ ́ àti níní ànfàní sí omi tí ó mọ ́ lásìkò tó yẹ .
Olóri Aṣòfin-Àgbà fẹ ra ọkọ̀ mẹsan fún ara rẹ nikan.
Coronavirus in Nigeria: Ìwádìí fihàn pé ọ̀pọ̀ aráàlú ni kò gbà pé àrùn Covid-19 wà
Ọ̀pọ̀lọpọ̀ wọn ni ó jẹ́ àgbẹ̀ alárojẹ, bẹ́ẹ̀ ni a tún rí àwọn tó mú àgbẹ̀ àrojẹ mọ́ àgbẹ̀ agbinrúgbìn tó ń mówó wọlé lọ́dọ́ọdún àti láti ìgbàdégbà.
Omoni ṣalaye pe awọn agbofinro to n wọde ni ijọba ibilẹ naa lo jẹ ki alaafia maa jọba diẹdiẹ nibẹ bayii.
Judity Bakira - Agbẹ lati Uganda Inu oko kan lorilẹede Uganda ni wọn ti wo Judity Bakira dagba, to si di ẹni akọkọ laarin awọn akẹẹgbẹ rẹ ti yoo janfaani ẹkọ ọfẹ lọ sile ẹkọ awọn obinrin to gbajugbaja, to si ti ibẹ ls silẹ UK lati gba oye imọ ijinlẹ keji, to si tun n sisẹ nibẹ.
Awọn kan faake kọri lori ayelujara pe Peter n parọ ni, wọn ni o ṣẹ ẹ nitori wọn ti le Tacha kuro ni BBNaija.
Ṣugbọn bi ọrọ gangan an lọrọ ọhun, nitori alaga awọn awakọ nipinlẹ Eko, Musiliu Ayinde Akinsanya ti ọpọ mọ si MC Oluọmọ ni tirẹ ni Mike loun dibo fun un.
Kí á má ṣe jẹ́ kí ó sú wa láti ṣe rere, nítorí nígbà tí ó bá yá, a óo kórè rẹ̀, bí a kò bá jẹ́ kí ó rẹ̀ wá.
ti won ti ko nile-ise ologun ofurufu naa.
Wí fún àwọn òkè ńláńlá ati àwọn òkè kéékèèké, ati àwọn ipa odò ati àwọn àfonífojì, pé èmi OLUWA Ọlọrun ní ìtara ati ìgbónára ni mo fi ń sọ̀rọ̀ nítorí pé ẹ ti jìyà pupọ, ẹ sì ti di ẹni ẹ̀gàn lọ́wọ́ àwọn orílẹ̀-èdè yòókù.
Oríṣun àwòrán, Trace Sugbọn ijamba naa se okunfa sunkẹrẹ-fakẹrẹ ọkọ lopopona marosẹ Ibadan si ilu Eko ni ọjọru.
Ṣùgbọ́n, ìwà kìí fi oníwà sílẹ̀, agódóńgbó inú ẹtu ń bá ẹtu lọ.
Igba akọkọ ree ti ẹgbẹ agbabọọlu Tunisia yoo de ipele to kangun si aṣekagba lati igba ti wọn ti gba ife ẹyẹ AFCON lọdun 2004 ti wọn gbalejo idije ọhun.
Bẹ́ẹ̀ gan-an ni ó rí pẹlu yín.
ọmọ Enọṣi, ọmọ Seti, ọmọ Adamu, ọmọ Ọlọrun.
Ó ti ná gbogbo ohun tí ó ní fún àwọn oníṣègùn ṣugbọn ẹnikẹ́ni kò lè wò ó sàn.
Kí á lè gbé wọn yẹ̀wò;kí á lè mọ àyọrísí wọn,tabi kí ẹ sọ àwọn ohun tí ń bọ̀ wá ṣẹlẹ̀ fún wa.
Oríṣun àwòrán, @goji1986 Ohun to ṣẹlẹ ni pe awọn mẹsan an to wa ninu ile naa ni anfaani lati fi orukọ ẹni meji silẹ ti wọn fẹ ko maa lọ sile.
Gomina Godwin Obaseki so eyi lasiko ifilole ile-ise iwadii kan lojo-aje, ti a mo si Paxherbal Biogas and Mushroom Spawn ni Ewu ni agbegbe ijoba ibinle Esan, nipinle naa.
"Òṣìṣẹ́ alarina Toyin Abraham náà ni, ẹ̀rọ ibaraẹnisọrọ ti osere-binrin náà mú lọ́wọ́ lọ́jọ́ naa sì ku ẹgbẹ̀rún lọ́nà àádọ́jọ náírà, tí yóò fi sanwó fóònù náà tán.
Ṣugbọn awọn eeyan Naijiria ko tilẹ jẹ ki iroyin naa balẹ ki wọn to ma lọgun pe ẹkunwo yi yoo mu inira ba ara ilu.
Oyo Òkò atijọ ni ibudo itan iwe naa, O safihan iṣoro ijẹgaba ati imunilẹru ti awọn ọdọ koju nigba naa ni ilẹ Yoruba.
Omíyalé àgbàrà ti ya ṣọ́ọ̀bù ní Niger Ìjọba Ondo kéde ìsimi ọ́sẹ̀ mẹ́ta fún àwọn ilé ìwé to lùgbàdì omíyalé!
Nítorí náà, Saulu ní kí wọ́n gbé ẹbọ sísun ati ẹbọ alaafia wá fún òun, ó sì rú ẹbọ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Premier League: Arsenal àti Man U dèrò Europa League 5 Èbibi 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 6 Èbibi 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Idije Premier League Aṣe tẹni to de laari, a ko mọ tẹni to n bọ.
Khalifa ni yoo fi Mukadam jẹ.
Ireti wa tele wipe, oga agba Ja’afaru
Nígbà tí ó dé, obinrin yìí sọ ohun kan náà fún un, ó ní, “Ẹrú ará Heberu tí o mú wá sí ààrin wa, ni ó déédé wọlé tọ̀ mí wá láti fi ẹ̀gbin lọ̀ mí, 
Ile America ti fi erongba aawo piparii re han fun awon mejeji ki alaafia le joba lasiko idije Olympics sugbon won ni won ko ni ba  Pyongyang soro laise pe o gba lati fi awon ado oloro re sile.
Kò pẹ́ púpọ̀ tí àgbọ̀nrin lọ tán tí mo rí ehoro ti ń kọjá lọ mo sì tún gbìyànjú mo ké sí i mo ní, ‘Ehoro ò!
Wo àgbáríjọpọ̀ àwọn Arugbá Ọ̀ṣun Òṣogbo látìgbà tó ti bẹ̀rẹ̀ Ẹ̀yin obìnrin, ẹ lọ kọ́ iṣẹ́ káfíńtà torí ó lówó lórí ju iṣẹ́ aránṣọ lọ"" El-Zakzaky: Arúfin ni ijọba Muhammadu Buhari gan-an - Ladoja Èmi àti Saheed kìí ṣe ọmọdé, a ti jọ ṣe Sinimá papọ̀, èyí túmọ̀ sí pé ìjà ti parí - Fathia Balogun ""Mo fẹ́ pa ara mi torí ojú àbùkù tí wọn ń fi wò mí pé mo fi iṣẹ́ abẹ bímọ"" Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí kan sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn."
Ọ̀nà yìí náà ni a ń lọ títí a fi de ilé náà.
Àkọlé àwòrán, Ile miran tun wo ni Ibadan Ni agbegbe Ṣogoye lẹgbẹ Molete ni iṣẹlẹ naa ti ṣẹlẹ.
Russia Boxer: Abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò dágbére fáyé lásìkó ìjà rẹ
Brazil (1970) Lootọ lo jọ ọpọ jẹsi ti Brazil ti maa n lo, sugbọn eyi tun peleke.
"Oluomo wa n beere pe ""ta lo lee ro pe iru eeyan bii ti emi to wa lati idile mẹkunnu lee de iru ipo giga bayii, abi ta lo lee gbagbọ pe iru eyi lee farahan?"
Oríṣun àwòrán, iamcertified_eyinjueledumare/Instagram Ọrọ naa lo ni o dara lootọ ki awọn eeyan daro iku ẹni to ba di oloogbe amọ irufẹ idaro bayii gbọdọ ni odiwọn.
Ibudo itaja ShopRite naa ti wa sọ agadagodo sẹnu ọna rẹ, to si ti kede pe yoo wa ni titipa fun igba diẹ naa lati dẹkun ikọlu.
Odusanya gboye gẹgẹ bi agbẹjọro ni Naijiria lọdun 1990 ko to kawe siwaju sii.
Wọ́n sọ fún un pé, “Ní Bẹtilẹhẹmu ti ilẹ̀ Judia ni.
Aṣa naa lalẹ ti awọn olorin kọọkan naa tun sọ di akọmọna ti awọn ọmọ gbẹ PDP n kọ kaakiri.
aṣọ aláró, aṣọ elése àlùkò, aṣọ pupa, aṣọ funfun, ati irun ewúrẹ́; 
Awọn to wa ni Iwọ oorun Gusu yoo gba idanilẹkọ ni Police Force Training College, Ila-Orangun, nipinlẹ Ọṣun.
Atundi ibo jẹ idibo tajọ eleto idibo ṣeto lati fi aṣoju mi rọpo tabi di awọn aaye to ṣofo lẹyin idibo apapọ lorilẹede.
Ilumọka ajihinrere naa jẹ afọju lootọ sugbọn lọdọ awọn to jẹ ọmọ ijọ rẹ, kii ṣe afọju lasan.
Gbogbo wọn jẹ́ ọgọta ìlú ńláńlá tí wọn mọ odi yíká, bàbà ni wọ́n sì fi ṣe ọ̀pá ìdábùú ìlẹ̀kùn ẹnubodè wọn.
Aare de si papa ofurufu Diori
Ó fẹ̀ ní ọ̀pá ọwọ́ rẹ̀ kan, ó sì ga ní ọ̀pá kan, (mita 3).
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Pásítọ̀: Jésù kò ní gun kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ tó bà wá láyé 30 Èbibi 2018 Oríṣun àwòrán, @jesse_duplants Àkọlé àwòrán, Ọrọ náà ko ba ma di awuyewuy,e bi kíì ṣe pé bàálù kẹrin lo n beere fún Oníwàásù orí amóunmáwòrán kan lorílè-èdè Amẹrika, ti ke gbajare sí àwọn ọmọlẹyìn rẹ pé kí wọn ra bàálù fún òun.
o tun wa rọ wọn lati tubọ maa tu asiri awon iwa ibi to ba n sẹlẹ lorile ede
" 110 ni ìyè àwọn àgbẹ̀ tí Boko haram dúmbú ní Borno tí dì báyìí-UN Níbo ni Ọ̀gbẹ́ni 'Emma', tíṣà tí wọ́n ní ó lu ọmọ pa ní Ikorodu wà bayìí?
 Wabara wa kadii oro re pe “ijiroro nikan lo le tan awon ipenija  to n dojuko wa , koda ,o tun je ona lati fese eto aabo mule lorile ede.
Ninu ifọrọwerọ rẹ pẹlu BBC news Yoruba, alukoro fun ajọ JAMB, Ọjọgbọn Benjamin Fabian ṣalaye pe, loots ni ajọ naa ti bẹẹrẹ gbogbo igbesẹ ti o yẹ ko ṣaaju ijade awọn esi idanwo awọn akẹkọ naa ṣugbọn ko tii lee sọ ni pato ọjọ ti esi naa yoo jade.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù SERAP si Buhari: Pàṣẹ fún amòfin àgbà, EFCC láti ṣèwáàdí Ganduje 15 Ọ̀wàrà 2018 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 4 Bélú 2018 Oríṣun àwòrán, @GovUmarGanduje Ajọ kan to n ja fun ẹtọ araalu ati ijọba rere, SERAP ti ke si aarẹ Muhammadu Buhari pe ko tete wa n kan ṣekan lori ẹsun gbigba owo riba ti wọn fi kan gomina ganduje tipinlẹ Kano.
Òun ní Olówó-ayé, tí ó wá sí Igbó Olódùmarèwáá ṣe ọdẹ.
Ikopa ninu rogbodiyan yii ti nipa buburu fun agọ ara wọn ati ironu wọn.
Kano Sharia Police: Ènìyàn Kano ọgọ́rin lo ti wà látìmọ́lé nítorí wọn jẹun nínú ààwẹ̀.
O salaye pe, “iroyin ti won gbo  fihan pe, die lara apapo awon olopaa naa FPU (Formed Police Unit)ni won n ba awon obinrin ti o wa ni agbegbe naa ni ajosepo, eyi ti o lodi si ofin ati ilana ajo UN ati UNMISS lati ni ibalopo pelu awon eniyan ti won n daabobo.
Gege bi Ikechukwu, ti o je akonimoogba agba iko MFM FC, O gboriyin bantabanta fun iko re fun akitiyan ati ise takun-takun ti won se ninu ifesewonse naa.
” Ó dáhùn pé, “Bẹ́ẹ̀ ni, n óo lọ.
O woye pe nigba ti yoo ba fi to oṣu kan si asiko yii, ooru yoo dinku, ti òjò yoo si bẹrẹ si i rọ̀.
 lowolowo ohun ni igbakeji olori eko fun awon eto iparieko ni ile-eko iseero ati sayensi alamulo ti university of virginia .
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ìpàdé ASUU àti ìjọba àpapọ̀ yóò tẹ̀síwájú lọ́sẹ̀ tó mbọ̀ Kwara - Àwọn agbébọn kọlu olùdíje APC Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ìgbé ayé Instagram fún ọ́sẹ̀ kan Gomina Ajimọbi ni, ni iwoye ti oun, ibi ti ileeṣẹ Ayefẹlẹ wa ko ba ofin mu ati pe, awawi ni ohun ti awọn kan n sọ kiri pe akanda ẹda ni, to si n gba ọpọlọpọ eeyan siṣẹ.
Won ti gbe oku re fun awon ebi re ki won fi pamo bi o ti ye ki won to gbe e lo si India lo sin.
Bí àwọn ọmọ-ẹ̀yìn mejila ti ń lọ, wọ́n ń waasu pé kí gbogbo eniyan ronupiwada.
Ṣugbọn ohun tí ó sọ kò yé wọn.
Ìròyìn nípa ìyàwó túntún fún ọkọ mi kò mì mí lọ́kàn rárá-Aisha Buhari Èrò yapa ní mọ́ṣáláṣí Jimọ̀h láti wá fójú lóúnjẹ lórí ìgbéyàwó òfegè Buhari.
 Èyí kò sẹ ̀ yìn ìgbìyànjú serbia láti gba àwọn ẹ ̀ yà tí austria-hungary ti kó sínú ìgbèkùn nínú ogun tí wọ ́ n ti jà tẹ ́ lẹ ̀ .
O tẹsiwaju pe, pupọ ninu awọn ijamba yii lo n ṣẹlẹ lataari aini suuru awọn awakọ.
Ẹnikẹ́ni tí ó bá ṣépè lé ọ, òun ni èpè yóo mọ́,ẹnikẹ́ni tí ó bá sì súre fún ọ, ìre yóo mọ́ ọn.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, BBC Africa Eye tú àṣírí ìfìyàjẹni àwọn òṣìṣẹ́ aláàbò Ohun ti awọn oluwọde naa n beere fun ni pe, ki ijọba apapọ fopin si SARS, ki wọn si tun fi oju gbogbo awọn ọlọpaa to fi iya jẹ ara ilu lọna aitọ wina ofin.
Lẹ́hìn tí ó wí báyìí tán Ènìyàn-ṣe-pẹ̀lẹ́ tún ṣe ìbéèrè lọ́wọ́ rẹ̀, ó ní kí ó sọ àwọn ohun tí ó lè jẹ́ ìṣóro lójú ọ̀nà fún wa, ọkùnrin náà sí ka àwọn ìṣòro ojú ọ̀nà sílẹ̀ ó ní a ó kọjá ìlú àwọn ejò níbi tí Òjàláìbínú ti ń ṣe ọba wọn àti pé bí a kò bá ṣọ́ra a lè sọ ẹ̀mí wa nù sí ibẹ̀, lẹ́hìn èyí ó tún sọ fún wa pé a óò dé ibi tí àwọn ọmọbìnrin méje kan wwà tí wọ́n máa ń lé ara wọn kiri títí ọjọ́ ayé wọn àti wí pé bí a bá wo apá ọ̀dọ̀ wọn tí a rí tí wọ́n ń ṣe, bí a fẹ́ bí a kọ̀ a óò máa bá wọn ṣiré náà a kò sì ní í lè kúrò níbẹ̀ láéláé.
’’Aare Buharitun so pe “Ami eye ti won fun Ribadu je imoore fun awon ipa pataki ti a ko nipa gbigbogun ti iwa ibajẹ , ni eyi ti o je okan lara ipinnu meta ti ijoba yii gunle.
10 Agẹmo 2020 Oríṣun àwòrán, Others Mohammed Umar ni ijọba Naijiria yan gẹgẹ bi oludari ti yoo ma ṣakoso gbogbo eto ajọ to n gbogun ti iwa ajẹbanu,EFCC ni Naijiria.
Bi awọn ọlọpaa naa ko ba si tun ṣe afihan ara wọn, beere fun idanimọ wọn ati ibi ti wọn ti wa.
Gomina Ipinlẹ Ekiti Ayodele Fayose ni Aarẹ Muhammadu Buhari n ṣe bii Hitler, olori ijọba Nazi ni Germany to fa ogun agbaye keji ninu eyi ti ọgọrọ eniyan lagbaye ti parun.
Ojú yóo ti Efuraimu, ojú yóo sì ti Israẹli nítorí ère oriṣa rẹ̀.
 Bakan naa ni Fabiyi tọka si pe, iya n jẹ awọn eeyan ninu iṣẹ tiata ni oun ṣe n pariwo sita, ẹni to ba si wu, ko fẹran oun, tabi korira oun, osere tiata ti ojuṣe rẹ ba si tọ si sinima kan, lo yẹ ki wọn maa pe sibẹ, lai fi ọrọ ẹbi abi ti ọrẹ ṣe."
Ìgbésẹ ̀ àjọ agùnbábirọ ̀ yí ti bá ọ ̀ pọ ̀ lọpọ ̀ ìfẹnu ṣátá pàdé láti ọ ̀ dọ ̀ àwọn ọ ̀ dọ ́ agùnbánirọ ̀ náà nípa ọowó ọ ̀ yà tí kò tó ǹkan tí ìjọba ń san fún àwọn ọ ̀ dọ ́ agùnbánirọ ̀ náà .
Pẹlupẹlu àwọn ni wọ́n ń ki èmi iranṣẹ rẹ, nílọ̀,èrè pupọ sì ń bẹ ninu pípa wọ́n mọ́.
Orisabunmi ti jáde láyé, ohun tí a mọ̀ nípa ayé àti ikú rẹ̀ nìyí Wo ọ̀nà tí Yoruba ń gbà dá ọmọ àlè mọ̀ nínú ìdílé- Elebuibon Bakan naa, awọn eeyan miran lero pe arun idile le sokunfa iku tẹle n tẹle, idi si ree ta tun fi tọ dokita oloyinbo lọ lati mọ boya ootọ ni, ka le se ọtun ati osi lai ba ibikan kan jẹ.
N óo fún àwọn eniyan mi ní alaafia ati ibukun ninu rẹ̀.
Mo wọn fadaka, wúrà ati àwọn ohun èlò tí ọba, ati àwọn ìgbìmọ̀ rẹ̀, ati àwọn ẹmẹ̀wà rẹ̀ mú wá, ati èyí tí gbogbo àwọn ọmọ Israẹli tí wọ́n wà níbẹ̀ náà mú wá fún ìlò ilé Ọlọrun.
Wọ́n dá a lóhùn pé, “A kò rí ìwé gbà nípa rẹ láti Judia; bẹ́ẹ̀ ni ẹnikẹ́ni ninu àwọn ará wa kò débí láti ròyìn rẹ tabi láti sọ̀rọ̀ rẹ ní ibi.
Lẹ́yìn tí wọ́n kọ orin tán, wọ́n jáde lọ sí Òkè Olifi.
Lẹhin ọdún, wọn a fi ọdún tuntun bẹ̀rẹ̀ si san igbèsè, nitori eyi Ìyá àti Bàbá a ma a ti ibi iṣẹ́ kan lọ si ekeji lai ni ìsimi tàbi ri àyè àti bójú tó àwọn ọmọ.
Ni owurọ ọjọ Ẹti, ni Gomina Makinde se ifilọlẹ igbimọ ẹlẹnu mẹwa naa to kede laipẹ yii, ryi ti Sẹnetọ Hosea Ayọọla Agboọla ko sodi.
Wọn kò ní jẹ́ orílẹ̀-èdè meji mọ́; wọn kò ní pín ara wọn sí ìjọba meji mọ́.
" Ọpọlọpọ igba ni mo ti kuna, nipa ai fi aaye silẹ lati wa pẹlu rẹ bose yẹ.
Ka to ṣẹju pẹ, adari ija ti fọn feere poo!
Ikọ̀ ẹlẹ́sìn Hàkíkà rèé, níbití wọn ti ń pààrọ̀ ìyàwó láàrín ara wọn Alárùn ọpọlọ lu àwọn nọ́ọ̀sì àti dókítà agba níléèwòsàn ní àlùdákú Irú ẹ̀dá wo ni aṣòfin Bukola Saraki jẹ́?
Ṣugbọn nígbà náà, n óo ní ìmọ̀ lẹ́kùn-únrẹ́rẹ́ gẹ́gẹ́ bí Ọlọrun ti mọ̀ mí.
lati igba ti awon eniyan ti bẹrẹ ifẹhonuhan ti o le aare orile ede
Ẹ̀yin olólùfẹ́ mi àti ẹbí ni mo bẹ̀ Ẹ lọ́ jáwé gbé jẹ́ẹ́ sọ́wọ́ bí bẹ́ẹ̀ kọ́.
Yahoo Yahoo: Ọkùnrin kan rí ẹ̀wọn ọdún kan àbọ̀ he lẹ́yìn tó lu obìrin ní jìbìtì ìfẹ́ lórí ayélujára
Ará, ẹ ranti ìṣòro ati làálàá wa, pé tọ̀sán-tòru ni à ń ṣiṣẹ́ láti gbọ́ bùkátà ara wa, kí á má baà ni ẹnikẹ́ni ninu yín lára nígbà tí à ń waasu ìyìn rere Ọlọrun fun yín.
Gbogbo ẹni tí ó bá gbàgbọ́ pé Jesu ni Mesaya, a bí i láti ọ̀dọ̀ Ọlọrun.
Lẹyin igba naa ni wọn ṣe idakẹrọrọ iṣeju meji.
Denis Mukwege to ti figba kan je eni to gba ife eye fun
Ẹwẹ, ninu ifọrọwanilẹnuwo BBC Yoruba pẹlu agbnu sọ rẹ, o fi aridaju han pe wn ti daa silẹ sugbọn ohun ko ni le sọrọ pupọ fun oniroyin lasiko ti a ko iroyin yii jọ.
Ẹ kúkú ti mọ ọ̀nà ibi tí mò ń lọ.
0 17473 Orilẹede Quatar 240 8.
NUJ ní báwọn ọlọ́pàá ṣe ń ti akọ̀ròyìn mọ́lé láìtọ́ sàfihàn ìwà taniómúni wọn Oríṣun àwòrán, @MBuhari Ẹgbẹ awọn akọroyin nilẹ wa, NUJ, ti kesi aarẹ Muhammadu Buhari lati ba awọn ọmọ Naijiria sọrọ nipa iwọde EndSARS to n lọ lọwọ.
Ẹ gbọ awọn ọrọ to n sọ lẹnu; wọn ti Saudi Arabia pa.
Oríṣun àwòrán, @BashirAhmaad Àkọlé àwòrán, Aarẹ Buhari ṣ'eleri pipese iṣẹ fun ọpọlọpọ Gomina Simon Lalong ninu ọrọ tirẹ, sọ fun Aarẹ Buhari pe iṣakoso rẹ n lepa lati pese aabo ati iranlọwọ ti o peye fun awọn ara ilu.
Lẹ́yìn náà, ó dáhùn ó ní, ‘Ayé rẹ ni ìwọ ń wò o ni, ìyà yóò jẹ ọ́ ní ìsáájú, ayọ̀ jẹ́ tìrẹ nígbẹ̀yìn, ṣùgbọ́n bí ìwọ bá ba ara rẹ jẹ́ lákòókòo ìyà, yóò ṣòro kí ayọ̀ pigbẹ̀yìn tó dé ọwọ́ rẹ.
Ọga agba ile isẹ panapana ni ipinlẹ Eko ti ni awọn ara ilu gbọdọ ni agolo ilewọ iyẹfun panapana bii meji si inu ile lati tete dawọ ijamba ina duro Ẹ ma a pa gbogbo oju opo ti ina ijọba n gba wọ inu ile, ti a ba n jade kuro ninu ile Gbigbe ẹrọ amunawa ati epo bẹntiroolu kuro ni inu ile Ẹ ma se mu siga ni inu ile Ẹ sun igbo ati koriko ni gbangba pẹlu omi ni tosi lati tete pa ina to ba pọju lasiko ti a ba n jo oko Ẹ lo awọn ẹrọ igbalode to n mu ina wa bii ‘rechargeable lamps’ dipo titan abẹla ninu ile.
ile yii ti dagba pupo , ni eyi ti awon ebi naa si n toju re, lati fi pa itan
Iroyin iku rẹ to kaakiri laipẹ yii fihan bi agba olorin Juju naa ṣe lokiki si, nitoripe kaakiri agbaye ni awọn eeyan ti n beere pe ṣe lootọ ni tabi irọ.
Ni pataki julọ, o ni lati gbiyanju ipa rẹ lati kọ ara rẹ lati igba diẹ sẹyin, ti o ba ti fi ọkan si i pe, wọn o ni fun ọ laaye lati jẹ iru awọn ounjẹ kan, o nira lati ko ara rẹ ni ijanu ni igbakuugba ti o ba ri iru ounjẹ bẹẹ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Omololu Olunloyo: Ọdọmọde Kọmiṣọnnà tí kò pé ẹni ọgbọ̀n ọdún tó tún jé Gómìnà oṣù mẹ́ta 15 Ìgbé 2020 Oríṣun àwòrán, others Ta bá ń sọ̀rọ̀ ojúlówó àwọn ọmọ Yorùbá tó dantọ, àwọn ọmọ ilẹ̀ Kaaro óò jiire tí kìí ṣe asadanu, ọkàn ni Victor Omololu Olunloyo jẹ́.
    Nígbà tí o ṣe, a ri ẹnu ọ̀nà kan báyìí níwájú wa, wọn ri òpó irrin lápá ọ̀tún àti lápá òsì, wọ́n sí ṣe ìlẹ̀kùn sii, lóri òpó irin méjì yìí lókè ni wọ́n gbe igi gbi gbòòrò tí ó rí pẹlẹbẹ báyìí kà, lára igi yìí ni wọ́n sì kọ àkọlé yìí sí:
 Àjèjì yìí kò fèsì lọ báa bóyá ijà ni ó bá wá ní tòótọ ́ .
Omi kan náà ni Ọlọrun fi pa ayé tí ó ti wà rí run.
Agígírí fẹ́ràn Ajíbógun ọwá Obòkun púpọ̀ nítorí pé ọmọ ìyá rẹ̀ ni.
Oreoluwa lo di ilumọọka bayii lẹyin ti fidio kan lu awọn oju opo ayelujara pa ninu eyi to ti n sọ fun iya rẹ pe ko 'Calm Down' lasiko to fẹ na a.
Boasi pe àwọn mẹ́wàá ninu àwọn àgbààgbà ìlú, ó ní, “Ẹ wá jókòó sí ibí.
    Ìgbà tí a dé ọ̀dọ̀ èyí iwájú, tí o rí èmi ti mo wá ní iwájú pátápátá ó dáhùn, ó ni, ‘Jẹ́wọ́ ẹ̀sẹ̀ rẹ́ ki n má ba pa ọ.
Ojuse awọn ọba si ni lati pa ina aawọ to ba fẹ suyọ laarin ilu, ko to di rogbodiyan.
Ìgbà tí mo ri i pé ó jẹ odidi kan tán mo pè é ni èèkejì: ‘Ìbẹ̀ǹbẹ́-olókùnrùn kú iṣẹ́ o- Òun náà wá wo apá ọ̀dọ̀ mi o fi imú dá mi lóhùn ó ni ; hòo, ó tún bẹ̀rẹ̀ síi jẹ àgbọ̀nrín kejì lọ.
Ṣugbọn ẹni tí ó bá pinnu ninu ọkàn rẹ̀, tí kò sí ìdí tí ó fi gbọdọ̀ ṣe igbeyawo, bí ó bá lè kó ara rẹ̀ ní ìjánu, tí ó sì ti pinnu ní ọkàn ara rẹ̀ pé òun yóo jẹ́ kí wundia òun wà bí ó ti wà, nǹkan dáradára ni ó ṣe.
Ọdun to kọja ni ọmọkunrin gomina ipinlẹ Ọyọ, Ajimobi fẹ Ọmọbinrin gomina ipinlẹ Kano ti wọn si di ana ara wọn.
Ìwé ti wọ́n yóò fọ́wọ́sí láti ìjọba ìbílẹ̀ gbọdọ wá pẹ̀lú fótò pélébé ẹni ti ó tọwọ́ bọ̀wé, ẹ̀dà fọ́tò iwé ìrìnà ọ̀kọ̀, káàdì ìdánimọ̀ ìjọba àpapọ̀ tàbí ìwé ìrìnà lọ si ilẹ̀ òkèrè.
Ọgbẹ́ni Bolaji Amusan ní ọ̀rọ̀ náà ko ribẹ̀ rara, nítori gbogbo orilẹ̀-ède aye ní ènìyàn máa ń mọ iṣe àti àsà wọn láti ara awọn òṣèré wọ́n, Amusan sàlaye àwọn àmúyẹ to wà lára àwọn orilẹ̀-èdè àti àwọn eré ti wọ́n máa ń ṣe bi àpẹrẹ Amẹrika fiimu, India fíimu, to fi mọ fíìmù àwọn korea .
Ẹ fi òrùka sí i lọ́wọ́, ẹ fún un ní bàtà kí ó wọ̀.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Coronavirus in Nigeria: Seyi Makinde fojú hàn n'íta fún ìgbà àkọ́kọ́ lẹ́yìn tó ṣẹ́gun Coronavirus 6 Ìgbé 2020 Gomina ipinlẹ Oyo, Ṣeyi Makinde foju han n'ita gbangba fun igba akọkọ lẹyin ti o jaja ṣẹgun aarun Coronavirus.
Àkọlé àwòrán, AMVCA Award: Tani yóò gbà ami ẹyẹ́ yìí?
Bí ọwọ́ rẹ bá mú ọ kọsẹ̀, gé e sọnù, ó sàn fún ọ kí o wọ inú ìyè pẹlu àléébù ara, jù pé kí o ní ọwọ́ mejeeji kí o wọ iná àjóòkú, [ 
Nígbà tí o mọ̀ bẹ́ẹ̀, kí ni kò jẹ́ kí o fi owó mi fún àwọn agbowó-pamọ́ pé nígbà tí mo bá dé, kí n lè gba owó mi pada pẹlu èlé?
Mo lé fi òjò dá àrà tò wù mi f'áwọn oníbárà mi lásìkò tó wù mí Ogun Anglo àti Francophones Cameroon mú ẹ̀mí 23 lọ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Wọ́n rò pé mo ya wèrè ni Saudi lẹ́yìn ikú ọkọ mi Ọjọ keje, Oṣu Kẹjọ, 2018, lo yẹ ki awọn aṣofin naa kọkọ ṣe ipade pajawiri ti Aarẹ ile aṣofin agba, Bukọla Saraki pe, lori owo eto iṣuna ajọ INEC ati 'ilọsiwaju Naijiria'.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Osogbo Photographer: Bakan naa ni Igboho ni o ti to ẹẹmẹfa ti awọn ọmọ onilẹ naa ti ya bo awọ̀n eeyan adugbo naa, ti wọn si n yinbọn ti wọn n pa awọn mẹkunnu, ti ọpọ wọn si ti ku lai jale, to si n beere pe se gbogbo mẹkunnu lo ni owo lọwọ lati tun ilẹ ra.
tí yóo sì gba ilẹ̀ náà, lẹ́yìn náà, ẹ lè pada nítorí pé ẹ ti ṣe ẹ̀tọ́ yín sí OLUWA ati sí àwọn arakunrin yín.
Arabinrin naa tilẹ sọ fun awọn ọlọpaa pe nigba ti onibaara naa n ja oun l'ole, oun gee jẹ.
Àwọn ọmọ-ogun náà bá gba owó tí wọ́n fún wọn, wọ́n ṣe bí wọ́n ti kọ́ wọn.
Koda, O fi Alkurani bura pe oun n ṣe ẹtọ to yẹ lori wọn.
Oya,ẹ jẹ ki a wo awọn orileede to la ijiya kalẹ fẹni kni to ba bu aarẹ Netherlands Losu Kẹrin ọdun 2018, ile aṣofin Netherlands fi ofin lelẹ pe bo nba bu ọba, o le lo to ọdun marun un lẹwọn.
Ìjọba ìpínlẹ̀ Eko ti ni ki gbogbo ọjà wà ni títì pa, sùgbọ́n.
(Àgbá mẹrẹẹrin ní irin tẹẹrẹtẹẹrẹ tí ó so ọ̀kọ̀ọ̀kan wọn pọ̀).
Wọ́n ti sún ọjọ́ ìjà Mike Tyson pẹ̀lú Roy Jones Jr síwájú Èèyàn 290 míràn ló ṣẹ̀ṣẹ̀ fara káásá àrùn Covid-19 ní Nàìjíríà, 160 gbàwòsàn Àjọ JAMB kéde ìlànà ìgbà ni wọlé tuntun fún àwọn ilé ẹ̀kọ́ gíga Dẹ́rẹ́bà kẹ̀kẹ́ Maruwa rí ẹ̀wọ̀n gbére he lẹ̀yìn tó fi ipá bá ọmọ ọdún mẹ́rìnlá lòpọ̀ Ni ti Amotekun, a ti fẹnuko wi pe ohun to ba gba la o fun un a o si ni jẹ ki ẹnikẹni ti wa gbọọn gbọọn""."
Bi ẹ ko bá kúkú ní gbàgbé, ẹgbẹ ADP yii kan naa ni Alaaji Moshood Adeoti tó jẹ akọwe ijọba labẹ ijọba gomina Rauf Aregbesola to jẹ ti ẹgbẹ APC darapọ mọ lẹyin to kuro laipẹ yìí.
Ewe, ami-eye ohun lo je okan lara ami-eye meta ti ipinle naa gba ninu ayeye ohun.
Laarin ọdun mẹewa sẹyin,ida mẹrin le diẹ 4.
Daniẹli Gbadura fún Àwọn Eniyan Rẹ̀.
Owolewa ni ibo 164,026, nigba ti Robinson-Paul ni ibo 18,600, ti Syed si ni 15,372.
Ṣugbọn Dafidi dá Abiṣai ati Joabu ẹ̀gbọ́n rẹ̀ lóhùn pé, “Kí ló kàn yín ninu ọ̀rọ̀ yìí?
Gbajumọ oṣere tiata kan Muka Ray Eyiwunmi lo sisọ loju ọrọ yii lasiko to n kopa lori eto kan loju opo ikanni BBC Yoruba.
Koda, ọpọ eeyan lo ṣe iwọde lọ si awọn ẹka ile ijọsin COZA nilu Abuja, Eko, ati Port Harcourt.
Gbogbo àrìnrìn àjò tó n bọ̀ ni Naijiria gbọdọ̀ forúkọ̀ silẹ̀ nibi https://nitp.
Ṣugbọn Adajọ ti sun ọjọ idajọ rẹ di ọjọ kọkanlelogun, oṣu kẹsan an, ọdun 2020 yii.
Ẹ kò gbọdọ̀ kó wọn fún ara yín, kí wọn má baà di ohun ìkọsẹ̀ fun yín, nítorí ohun ìríra ni wọ́n lójú OLUWA Ọlọrun yín.
Awọn odije naa ni wọn yan  sipo nipasẹ eto idibo pẹlu ohun enu, ti wọn si gba wọn wọle bẹẹ.
Ẹgbẹ TAMPAN jẹ ẹgbẹ́ to ya kuro lara, Association of Nigeria Theatre Arts Practitioners, ANTP l'ọdun 2014.
Ajọ eleto ilera lagbaye ṣalaye pe kokoro arun lee lugọ si ara beba owo fun ọpọlọpọ ọjọ eleyi ti wọn ni o mu ki o ṣe pataki fun awọn eeyan lati yẹra fun lilo owo beba fun karakata wọn bi o ti wulẹ o mọ.
Ìyè ainipẹkun náà ni pé, kí wọ́n mọ̀ ọ́, ìwọ Ọlọrun tòótọ́ kanṣoṣo, kí wọ́n sì mọ Jesu Kristi ẹni tí o rán níṣẹ́.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Wọ́n dájọ́ ẹ̀wọ̀n ọgbọ̀n ọdún fún ọmọbìnrin kan ní El Salvador nítorí pé ó bí àbíkú Darren Julien to jẹ aarẹ awọn agbatẹru eto tita aṣọ otutu onkọrin Kurt yii ni aṣọ yii jẹ ọkan pataki julọ lara aṣọ ti awọn gbajugbaja onkọrin lagbaye tii wọ ri.
6 Ẹ rántí ìgbàgbọ́, ìwà rere, ìmọ̀, àìrékọjá, sùúrù, inú rere sí ọmọnìkejì, ìwà-bí-Ọlọ́run, ìfẹ́ àìlẹ́gbẹ́, ìrẹ̀lẹ̀, aápọn.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Coronavirus Updates: Àì gba ìwé àṣẹ ìjọba ṣàkóbá fún sinima orítá ọmọkùnrin yìí Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Coronavirus Updates: Àì gba ìwé àṣẹ ìjọba ṣàkóbá fún sinima orítá ọmọkùnrin yìí 14 Òkùdu 2020 Ẹgbẹlẹgbe owo ni Arakunrin Rotimi Ojo-Abegunde fi ṣofo lasiko to se eto sinima fun awọn eniyan lati wa wo ninu ọkọ wọn.
awon idojuko to n koju eto aabo lorile-ede Naijiria.
"Kò to di pé mo dara pọ mọ iṣẹ́ tíátà, láàrin odidi ọdún méjì tí mo fi ṣiṣẹ́ amofin, mo ń gba ẹgbẹ̀rún mẹẹdogun náírà losu, nígbà tí mo sì ń rí ẹgbẹ̀rún marundinlaadọta laarin ọjọ́ mẹ́rin nínú isẹ tíátà.
Akọrọyin BBC to wa labuja sọwipe, awọn obi n ran awọn ọmọ wọn lọ si ile-iwe nitoriwipe wọn gbagbọ ninu ijọba aarẹ Buhari ati gbogbo ipolongo awọn ọmọgun ilẹ Naijiria wipe awọn ti bori ikọ Boko Haram.
Akonimoogba iko Super Eagles, Gernot Rohr ti pase fun awon agbaboolu re lati maa wo ewu igbalode, ki won o to bere igbaradi, ti a mo si (GPS trackers), eyi ti yoo maa safihan bi agbaboolu kookan se n kopa si ninu igbaradi olokan-o-jokan won.
Ti ààrin igi ẹlẹ́gùn-ún ni ẹni tí ó gbọ́ ọ̀rọ̀ náà, tí àníyàn ayé yìí ati ìtànjẹ ọrọ̀ fún ọ̀rọ̀ náà pa, tí kò fi so èso.
Kano Torture: Inúu gáréèjì ni àwọn ẹlẹ́yinjú àánú ti rí Ahmed tú sílẹ̀
BBC Africa Eye: ìwádìí ìkọ̀kọ̀ BBC fihàn pé àwọn kan ń jí ohun eèlò ìdáàbòbò ìjọba tà nígboro Àwọn èèyàn ìlú Okeho ló kó gbogbo owó tí wọn rí gbà lọ́wọ́ àwọn adigunjalè tí wọ́n mú"" Olùrànlọ́wọ́ pàtàkì fún ọ̀rọ̀ ibojì òkú, àti àwọn ipò òṣèlú mìíràn tó jẹ́ kàyééfì ní Nàìjíríà Buruji Kashamu jẹ́ ènìyàn tó nífẹ̀ aráàlú- Gómínà Dapo Abiodun Amọ, Fadeyii ni awọn ko i tii le fi idi ọrọ naa mulẹ, amọ awọn n fi ọrọ wa awọn adigunjale marun un to wa ni panpẹ awọn lẹnu wo lori bi owo naa ṣe rin."
Aare Muhammadu Buhari ti sapejuwe awon ogo weere pe awon ni ojo ola fun orile-ede Naijiria.
 Kremlin ni :Gege bi ohun ti a gbo, ko si eni to la ninu ijamba naa rara”.
Sibẹsibẹ, n kò bèèrè owó oúnjẹ tí ó jẹ́ ẹ̀tọ́ gomina, nítorí pé ara tí ń ni àwọn eniyan pupọ jù.
Sugbọn o pada ku ni ọjọ Aje, ọjọ kẹtala, oṣu Kẹjọ, lẹyin ọjọ mẹsan.
Ọgbẹ́ ọkàn láéláé ni fún ọmọbìnrin ọdún mẹ́wàá, tí bàbá rẹ̀ dáná sí lábẹ́ - Amòfin Maryam Sanda, ìyàwó tó pa ọkọ rẹ, ri ìdájọ ikú he Ẹ ta kété sí àjọṣepọ̀ tí kò bá fún yín láyọ̀ torí ẹ̀mí kò ní ààrọ̀ - Àwọn òṣèré tíátà gbarata lórí ìdájọ́ ikú Ẹ wo bí Amotekun ṣe gba ilẹ̀ Yoruba silẹ̀ lọ́wọ́ agbéṣùnmọ̀ní ní igba ọdún sẹ́yìn Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 3 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 5 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Kọmiṣọna ipinlẹ Edo, Ọgbẹni Johnson Kokumo lo fi oju awọn afurasi mẹfa naa han lọjọru ọsẹ.
Simon Msuwa, Erasto Nyoni ati Aggrey Morris lo gba bọọlu sawọn ti Tanzania fi dero AFCON 2019.
Kọmiṣọna ọhun rọ awọn agba adugbo atawọn olori ẹlẹsin lati tu aṣiri gbogbo awọn ti wọn ba fura si pe o lẹbọ lẹru.
Dokita Chris salaye pe, oun nigbagbo pe egbe ASUU yoo fopin si iyanselodi ohun lataariadehun ipade naa, papaa julo fun anfaani awon omo ile-iwe ti o ye ki won bereidanwo, eleyi ti iyanselodi o je.
Nitori idi eyi si ni Arakunrin Jago ṣe ta ọkọ ayọkẹlẹ kan ti owo rẹ to miliọnu mejila, ṣugbọn to ta ni miliọnu mẹrin Naira.
 Ó jẹ ́ ọ ̀ rọ ̀ tí ìtumọ ̀ rẹ ̀ kò dá geere .
Wọ́n ń ṣe èyí kí wọ́n lè gba adé tí yóo bàjẹ́.
Ẹnikẹ́ni tí ó bá bẹ̀rù rẹ̀, tí ó sì ń ṣe rere ni yóo fà mọ́ra láì bèèrè orílẹ̀-èdè tí ó jẹ́.
Ẹ má bínú, mo kábàmọ́ pé mo na obìnrin -Elisha Abbo Ilé iṣẹ́ ọlọ́pàá ti bẹ̀rẹ̀ ìwádìí sí ọ̀rọ̀ Sẹ́nétọ̀ Abbo Elisha Abbo ṣàlàyé ìdí tó fi lu obìnrin fún BBC Ṣugbọn Anjuguri ko fẹ ṣafihan orukọ ile ẹjọ ti wọn gbe e lọ.
Nitorinaa, a ko ti le sọ ni pato pe akojọ ero oludibo kankan le ṣe atọhan to daju ibi ti idibo ọdun yi yoo ja si.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fọ́nrán ohùn, Joe Igbokwe kò yẹ́ fún ipò ti wọ́n fún nípìnlẹ̀ Eko - Babatunde Gbadamosi O ṣiṣẹ olukọni nipa Itan eniyan ilẹ Adulawọ ni Fasiti guusu Florida iyẹn South Florida University ni Tampa ni Florida ni orilẹ-ede America.
Salimoni, ará Ahohi, ati Maharai, ará Netofa; 
Ẹ ma sọrọ alufansa si i lori ayelujara, Facebook, iwe iroyin tabi Twitter.
Àjọ ìṣọ̀kan àgbáyé (UN) lo kéde ọ̀rọ̀ òhún lónìí, pẹlu alaye pé, tí àwọn orílẹ̀ èdè ó bá wà ojútùú sí ìṣòro náà afaimo ni kí nkan má bajẹ.
Bayii lọrọ ṣe ri fun ẹgbẹ agbabọọlu Barcelona ti Bayern Munich lu lalubami.
Kọmiṣọna fikun ọrọ rẹ pe ''ilu Eko jẹ ilu kan tawọn alejo fẹran lati maa wa nitori awọn eti okun to rẹwa atawọn oriṣiiriṣii iṣẹ to wa l'Eko.
"’ rèé Iṣu ló wà nínú mọ́tò mi, kìí ṣe èèyàn ni mo sọ di iṣu - Afurasí Ajínigbé figbe ta Afọnja, ẹni tó finú wénú ní Ilọrin, àmọ́ tó jẹ iwọ Poly Ibadan: Ọjọ́ iwájú la rò táa fí dáná sún fóònù àwọn akẹ́kọ̀ọ́ Gomina Oyetọla ni oun ti "" ranṣẹ si awọn aṣiwaju ẹgbẹ oṣelu APC lati ṣawari awọn ti yoo kopa ninu igbimọ iṣejọba oun."
Mo dé ìhà ìlà-oòrùn àgbáyé níbi tí ọjọ́ ti ń kọ́kọ́ mọ́n.
Bi itan Aláàfin Ọ̀rọ̀ǹpọ̀tọ̀niyùn se lọ ree.
Ẹgbẹ oṣelu PDP ni ṣe ni ijọba apapọ n gbaradi ati gbogun ti Sẹnetọ naa ni lati lee gbagbe ilepa rẹ.
O ni ori ti ọdọ naa fi sese lo sokunfa iku to paa Gomina Sanwo-Olu wa kẹdun lori isẹlẹ naa, to si ni o ba oun lọkan jẹ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Philip Shekwo: Aága ẹgbẹ́ APC ní ìpínlẹ̀ Nasarawa tí àwọn agbébọn jí gbé ti kú 23 Bélú 2020 Oríṣun àwòrán, Other Alaga ẹgbẹ oṣelu All Progressive Congress, APC, nipinlẹ Nasarawa, Philip Shekwo ti ku.
Ó ti tó ọdún mẹ́fà kí Akin Ọlọ́fín-íntótó ọmọ Olúṣínà àti Ọmọ́tọ́ṣọ̀ọ́ ti rí ara wọn mọ kí wọn tún tó rí ara wọn yìí.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Eid-el Kabir: Aisha Buhari lọ Hajj pẹ̀lú ìyàwó Ààrẹ Niger, Senegal, Gambia 9 Ògún 2019 Oríṣun àwòrán, Twitter/Presidency Àkọlé àwòrán, Ààrẹ Muhammadu Buhari má a padà sí ìlú Abuja ní Ọjọ Kejidinlogun, Osù yìí lẹ́yìn Ìsinmi ọdún ilẹ́yá.
Ìrora pọ̀ fún àwọn eniyan burúkú,ṣugbọn ìfẹ́ tí kì í yẹ̀ ni ó yí àwọn tí ó gbẹ́kẹ̀lé OLUWA ká.
Nígbà tí àwọn tí kì í ṣe Juu tí kò mọ Òfin bá ń ṣe ohun tí Òfin sọ bí nǹkan àmútọ̀runwá, bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé wọn kò mọ Òfin, wọ́n di òfin fún ara wọn.
Koda, wọn fi atẹjiṣẹ ṣọwọ sori foonu kọmisana eto ilera ipinlẹ Ọyọ.
Ó tún bá a wí fún gbogbo nǹkan burúkú mìíràn tí ó ṣe.
Ó wá sọ fún olùtọ́jú ọgbà pé, ‘Ṣé o rí i!
“Bí mo ti ń wò mo tún rí ẹranko mìíràn tí ó dàbí ẹkùn, òun náà ní ìyẹ́ mẹrin lẹ́yìn.
”Daware gba awon eniyan niyanju lati maa je awon eso ati ewebe to dudu ti ise won lara san ju oogun lo.
Unuoghara (07) ni deede aago mefa owuro yii, ti won si n yin ibọn soke
Ni kiakia lawọn oloju kogberegbe ti sare tọka si asikọ yii.
Wọ́n ń kọrin titun kan níwájú ìtẹ́ náà ati níwájú àwọn ẹ̀dá alààyè mẹrin ati àwọn àgbààgbà mẹrinlelogun.
Nigba to n ba BBC Yoruba sọrọ, Kemi Dairo ni ariwo nla kan lo jade lati inu speaker nibi inawo naa, ti eti oun si ho, lai mọ pe ijamba ti se oun.
ó sọ pé, “Ọpẹ́ ni fún ọ OLUWA Ọlọrun Abrahamu, oluwa mi, tí kò gbàgbé ìfẹ́ rẹ̀ tí kì í yẹ̀ ati òdodo rẹ̀ sí oluwa mi.
“Mo fi da a yin loju pe a ko nii dakẹ, bẹẹ ni a ko ni kawọ ko ki wọn maa tẹ ẹtọ wa loju mọlẹ, bo ti lẹ jẹ pe a ko ni fi ṣe ọrọ ija, sibẹ a o ni ṣai maa ja fun ẹtọ wa”.
3 lẹ ́ yìn ikú lámurúdu ni odùduwà gba ipò .
Dafidi ọba sọ fún àpéjọpọ̀ àwọn eniyan pé, “Solomoni ọmọ mi, ẹnìkan ṣoṣo tí Ọlọrun yàn, ó kéré, kò tíì ní ìrírí, iṣẹ́ náà sì tóbi pupọ, nítorí ààfin náà kò ní wà fún eniyan, bíkòṣe fún OLUWA Ọlọrun.
Ẹ̀rù bà wọ́n nígbà tí wọ́n gbọ́ pé ọmọ-ìbílẹ̀ Romu ni wọ́n jẹ́.
Ṣugbọn ẹni tí ó ń yọ yín lẹ́nu yóo gba ìdájọ́ Ọlọrun, ẹni yòówù kí ó jẹ́.
Adajọ fẹyinti Oloyede naa fikun wi pe, lẹyin igbesẹ wọnyii nikan ni aarẹ le yọ Adajo Agba kuro ni ipo.
"Ibẹru si ti n lọ lara awọn oṣiṣẹ eto ilera naa.
Idà tí yóo pa ọ̀pọ̀ eniyan ní ìpakúpa, tí ó sì súnmọ́ tòsí wọn pẹ́kípẹ́kí.
Gbogbo nǹkan èlò tí wọ́n fi wúrà ati fadaka ṣe ni Nebusaradani, olórí àwọn tí wọn ń ṣọ́ ọba Babiloni kó lọ.
Mú wọn, kí o lọ bá wọn wẹ ẹ̀jẹ́ náà kúrò.
A fogun kó wọn, láìsí ẹni tí yóo gbà wọ́n sílẹ̀,a kó wọn lẹ́rú, láìsí ẹnikẹ́ni tí yóo sọ pé:“Ẹ dá wọn pada.
Ni ọdun 2019 ni iroyin jade sita pe ko si oriṣa ọṣun ni ojubọ rẹ mọ atipe awọn kan ti taa fun ẹgbẹlẹgbẹ owo dọla ilẹ Amẹrika.
miiran bẹẹ ni awọn o pari  Ninu ọrọ rẹ,
Ní ọjọ́ náà, a óo sọ fún Jerusalẹmu pé:“Ẹ má ṣe fòyà;ẹ má sì ṣe jẹ́ kí agbára yín dínkù.
Ọpọlọpọ eniyan ni ó péjọ sibẹ tí wọn ń gbadura.
NCDC lo kede bẹẹ loju opo Twitter rẹ, nibi to ti sọ pe ọrọ naa ti di oju lalakan fi n ṣọri bayii.
Bẹ́ẹ̀ ni ìyàwó yìí kò sí lọ́dọ̀ ọkọ nígbà tí onítọ̀hún kò ní aṣọ oókan.
Ayé ò tún fẹ́ kí a d’ọlọ́rọ̀
Ṣugbọn kò pe Natani wolii, tabi Bẹnaya, tabi àwọn akọni ninu àwọn jagunjagun ọba, tabi Solomoni, arakunrin rẹ̀.
Ọkunrin náà bá mú mi pada wá sí ẹnu ọ̀nà Tẹmpili, mo sì rí i tí omi kan ń sun láti abẹ́ ìlẹ̀kùn àbájáde ó ń ṣàn lọ sí ìhà ìlà oòrùn, ìhà ìlà oòrùn ni tẹmpili kọjú sí.
L'ọdun 2017, awọn eniyan to to okoolerugba din ẹyọkan lo ni ibà ni orilẹede mẹtadinlaadọrun (Akọsilẹ ajọ WHO) Eniyan to to ojilenirinwo din maarun, 435,000, ni ibà pa l'ọdun 2017 Ilẹ Afirika ni aisan ibà pọ si ju - l'ọdun 2017 nikan, ìdá mejilelaadọrun ni awọ̀n to tni ibà ni Afirika, ìdá mẹtalelaadọrun si lo pa.
 ibà , àárẹ ̀ , àti ìrora kékèké nínú iṣan-ara a má a wáyé lára àwọn ènìyàn tó kéré sí ìwọ ̀ n kan nínú ọgọ ́ ọ ̀ rún lára àwọn tó gba àjẹsára náà .
Adaba tiwa ko nọnni a n kungbẹ, ina n jo ẹyẹ oko n lọ.
Nipa ti irinajo si okeere, adari ajọ irinna ofurufu ni Naijiria, Sam Adurogboye salaye pe, awọn si n duro de abọ awọn eleto ilera ati ajọ amuṣẹya, ti aarẹ Buhari gbekalẹ, lati koju arun Coronavirus.
Kiniun pa olusọ ọgba ẹranko Ọ̀bọ lé àwọn ènìyàn kúrò nílè Asiri ibudo igbafẹ ẹranko ni Naijiria Erin wọ̀lú, ó pa ènìyàn méjì Kìnìhún joko jẹ ẹran ara afurásí ọdẹ tí kò gbààyè kó tó ṣọdẹ Ijọba Ondo n wa ọdẹ aperin Gẹgẹ bi iroyin to tẹ wa lọwọ, awọn to n pa ẹran lọna aitọ lo yinbọn lu erin naa ninu igbo Gbarpolu.
Africa Free Trade Zone: Kò sí ìdènà láti kó ọjà láti orílẹ̀èdè kan sí òmíràn
jẹjẹ pẹlu ifẹhonu han wọn ki wọn ma tun fi ba nnkan jẹ nitori okun ko ni
    Ṣùgbọ́n ọ̀ràn iwin yìí di ìjà láàrin àwa pàápàá bàyìí ni: ṣe ni a fi àwọn iwin náà sílẹ̀ tán tí ọkùnrin kan báyìí tì à ń pé ni Gọ̀ǹgọ̀ṣú-tàkìtì àti ẹ̀gbọ́n rẹ̀ ti ń jẹ́ Ìnàkí-gorí-ìtẹ́ bẹ̀rẹ̀ gbé mi tí wọ́n ń bá mi pé n kò sọ̀®ọ̀ fún àwọn iwin náà tó bí ó ti yẹ.
Gẹgẹ bi akọroyin BBC Yoruba ti se akojọpọ rẹ, awọn eeyan to n se iwọde naa ni wọn ti fi ipade si oni ọjọ Isẹgun pe awọn yoo tẹsiwaju pẹlu iwọde awọn, lẹyin ti awọn ọlọpaa fi afẹfẹ alata ati tajutaju tu wọn ka lọjọ Aje.
Ẹ kanlẹ̀kùn, a óo sì ṣí i fun yín.
O kere tan awọn ọmọ Naijiria a gba isinmi fun ọjọ mẹwaa ti a ya sọtọ fun sisami ayẹyẹ ati iranti lọdun 2020.
Bí ẹnikẹ́ni kò bá ra ẹni náà pada lọ́nà tí a ti là sílẹ̀ wọnyi, wọ́n gbọdọ̀ dá òun ati àwọn ọmọ rẹ̀ sílẹ̀ nígbà tí ó bá di ọdún jubili.
Eyi ni o jẹyọ ninu atẹjade ti ile iṣẹ naa fi sita ti igbakeji adari ile iṣẹ naa Rhoda Ishaku Iliya si buwọlu lọjọbọ.
Sibẹsibẹ wọn ò dẹ́kun ẹ̀ṣẹ̀ dídá;wọ́n ṣọ̀tẹ̀ sí Ọ̀gá Ògo ninu aṣálẹ̀.
Mo bá yan àwọn kan tí yóo máa mójútó ètò ìsúná owó ní àwọn ilé ìṣúra.
Ohun ti ọpọ awọn abọde ilẹ Gẹẹsi naa n sọ ni pe lati nnkan wakati mẹta ti wọn ti de si papakọ ofurufu naa ni awọn ko ti ri ẹnikẹni ti yoo yọju siwọn lati sọ igbesẹ to kan.
Lara awọn eeyan naa to ba BBC sọrọ ti ko fẹ ki a darukọ oun sọ pe, kii ṣe ohun to mu ọgbọn wa ni ijọba fẹ ṣe nitori alekun owo ori naa yoo tumọ si afikun owo ọkọ Uber tabi Bolt ọhun.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Àwọn wo ló kó oníkẹ̀ẹ̀kẹ́ 'Napep' wọ ìgboro ìlú Liverpool?
Kí inú àwọn orílẹ̀-èdè ó dùn,kí wọn ó máa kọrin ayọ̀,nítorí pé ò ń ṣe ìdájọ́ àwọn eniyan láìṣe ojuṣaaju;o sì ń tọ́ gbogbo àwọn orílẹ̀-èdè ayé.
tuntun ile-ise NNPC, Mallam Mele Kyari, soro naa di mimo lasiko ti o sabewo si
O sọ wipe ni kete ti wọn ba ti pari iwadi wọn naa, lawọn afurasi ti ọlọpa mu, yoo fi oju ba ile ẹjọ.
O ni, “n jẹ ẹ mọ ewu nlanla ti idọti onike yii n koba awujọ ati awọn ẹda inu omi?
Àfiwé orúkọ rẹ̀ ni Sodomu ati Ijipti.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ìtàn ọba Yorùbá tí wọn yẹgi fún torí ó jí ọmọ gbé ṣe ètùtù Ẹ káàbọ̀ sọ́jọ́ Arafat, tí Ọlọ́run yóò fi ààwẹ̀ Mùsùlùmí pa ẹ̀ṣẹ̀ wọn rẹ́ Akẹ́kọ̀ọ́ Babcock tí wọn bá lòpọ̀ nínú fídíò rí ẹ̀kọ́ ọ̀fẹ́ ní fásitì òkè òkun Aláwàdà ni ọmọ mi láti kékeré, kò ṣẹ̀ṣẹ̀ máa gbé mi mọ́ra- ìyá ‘Mummy calm down’ (Toluige Olokoobi Babalola) Wo ìyàtọ̀ tó wà láàrin Bíbélì Yorùbá tí Kumuyi kọ sí èyí tó wà ńlẹ̀ Ìkúnlẹ̀ abiyamọ, ìkókó mẹ́jọ kú nílé ìwòsàn lálẹ́ ọjọ́ kàn Dayo Amusa gbarata lórí bí agbófinró ṣe ń pa ọ̀dọ́ láì nídìí Amọṣa o fi kun un pe, awọn olopaa kogberegbe atawọn fijilante pẹlu ọdẹ jumọ kọ oju oro s'awọn Adigunjale naa ti wọn si ṣe aṣeyọri.
Yato si eyi, o fi kun oro re pe, ilana ohun tun ti mu igberu ba oja abele, pipese ise fun awon ara-ilu, ati sise alekun owo ti o n wole sowo awon agbe ati awon onile-ise lorile-ede Nigeria.
Ó gùn ní ogoji igbọnwọ (mita 20), ó sì fẹ̀ ní ọgbọ̀n igbọnwọ (mita 15) àwọn mẹrẹẹrin sì rí bákan náà.
Àròsọ àti ìgbàgbọ́ àwọn ènìyàn lórí gbígba ẹ̀jẹ̀ Ta ni yóò borí láàrin Aisha Buhari àti ọkọ rẹ̀ lórí ọ̀rọ̀ ‘First Lady’?
Gbogbo wọn jẹ́ baálé baálé ní ìdílé wọn.
Ohun ti wọn ṣe ko mu ọgbọn wa rara.
Nigba ti eyi pari ni aarẹ ba tun kede konile-o-gbele ọlọjọ mẹrinla miran eleyi tii yoo pari ni agogo mọkanla ọjọ Aje, ọjọ kẹtadinlọgbọn oṣu kẹrin ọdun 2020 lati dena itankalẹ arun yii.
 ojú ibi àkóràn yìí maa ń dun ènìyàn lọ ́ pọ ̀ lọpọ ̀ .
Bakan naa ni Ọjọ Aiku, awọn ọdọ ni aimoye wọn jade lati sẹwọde pẹlu adura fun odidi wakati mẹta, ti wọn si n bẹbẹ si Olorun pe ki ayipada ba orilẹede Naijira.
Ẹni ọdun mejidinlaadọrin ọhun gbadura pe ki Ọlọrun da si eto iṣuna Naijiria, ko si tun yi ọkan awọn alaṣẹ to n mọọmọ ṣe awọn eto to n pa owo Naira lara pada.
Ó lawọ́ sí àwọn talaka,a sì máa ran àwọn aláìní lọ́wọ́.
Lati ọjọ abamẹta ni ileesẹ ọlọọpa ni Sanusi ti wa ni ahamọ lọdọ awọn.
Nisinsinyii, o wá sọ fún mi pé kí n lọ sọ fún oluwa mi pé o wà níhìn-ín.
Bakan naa ni ao mu adinku ba iye akẹkọọ ti yoo wa ni kilaasi kọọkan."
Ó wá tún lọ siwaju díẹ̀ síi, ó dojúbolẹ̀, ó bẹ̀rẹ̀ sí gbadura pé, “Baba mi, bí ó bá ṣeéṣe, mú kí ife kíkorò yìí fò mí ru.
Ọjọ kọkanlelọgbọ́n oṣu kejila ọdun 1953 ni wọn bi adajọ Ibrahim Tanko Muhammed ni ilu Doguwa, ijọba ibilẹ Giade ni ipinlẹ Bauchi.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Iniesta: Mò ṣetán láti fi Barcelona sílẹ̀ Messi di aláṣẹ lórí ohun eèlò tó gbé orúkọ rẹ̀ Salah gba àmì ẹ̀yẹ PFA Ẹgbẹ́ agbábọ́ọ̀lu alátakò Real Madrid ní wọ́n ti gba àmin ẹ̀yẹ náà lẹ́ẹ̀mẹtàlélọ́gbọ̀n.
orile ede Naijiria mọ riri odun merin ti mo lo lori aleefa lati dari won,
Wọ́n wá bi í pé, “Iṣẹ́ ìyanu wo ni ìwọ óo ṣe, tí a óo rí i, kí á lè gbà ọ́ gbọ́?
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Coronavirus in Nigeria: Ìtànkálẹ̀ coronavirus ṣe ìdíwọ́ fún ìrun Jimọ 24 Ẹrẹ̀nà 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 27 Ẹrẹ̀nà 2020 Àkọlé àwòrán, Mọṣalaaṣi An-nur nilu Abuja niyii, gbajugbaja ni, ṣugbọn itankalẹ aarun coronavirus sọ ọ di ofo.
Ẹ tún ranti àwọn tí à ń ni lára pẹlu, nítorí pé inú ayé ni ẹ wà sibẹ, irú nǹkan wọnyi lè ṣẹlẹ̀ sí ẹ̀yin náà.
Eyi lo mu ki Saurduna igba naa le e kuro niluu lọ si agbegbe kan laarin ilu Ogbomọṣọ ati ipinlẹ Kogi.
Ọsẹ tó nira julọ fún mi rèé- Neil Warnock Ìyá lu ọmọ rẹ̀ pa nítorí 21,000 Naira Aṣòfin ọmọ Naijiria ní Ilẹ̀ Gẹ̀ẹ́sì rẹ́wọ̀n oṣù mẹ́ta he Bakan naa ni Hazard fun ra rẹ ti sọ pe o wu oun lati darapọ mọ ikọ Real Madrid to jẹ pe awọn ni ife ẹyẹ UEFA Champions League wa lọwọ wọn bayii.
Ṣùgbọ́n Fìlásayépọ̀ kúrò ni ọ̀run Àpáàdì ó wá sínú ayé o ń ṣíṣẹ́ ọdẹ, ibi tí wọ́n di ọ̀rẹ́ ara wọn ipa kùmọ́dirpan ni o sì tọ̀ dé ìrìnàjò sí Òkè Ìrònú yìí.
Wamu wamu lawọn ẹṣọ ologun duro bi awọn alabasiṣẹ pọ Aarẹ ti n kii kaabọ ni papapapakọ-ofurufu l'Abuja.
Àṣírí ìdánwò tú síta lóòtọ́ọ́, ọwọ́ tẹ alákòóso ìdánwò nípínlẹ̀ mẹ́ta - WAEC Oríṣun àwòrán, @hadd1nzarewa Olori ileesẹ to n seto idanwo asejade nile ẹkọ girama lẹkun iwọ oorun Afirika, WAEC, Ọgbẹni Patrick Areghan ti kede pe ọwọ ajọ ọhun ti tẹ awọn alakoso idanwo kan, to tu asiri idanwo ajọ naa sita.
80% wọn fi apẹrẹ diẹ han - wọn ni iba ati ikọ.
N óo fọ́n wọn ká sí ààrin àwọn orílẹ̀-èdè tí àwọn ati àwọn baba ńlá wọn kò mọ̀, n óo sì jẹ́ kí àwọn ọ̀tá yọ idà tẹ̀lé wọn títí tí n óo fi pa wọ́n run.
Ìgbà tí ó ba ń lọ a máa yí ara padà sí bí ó bá ti fẹ́ ni, ìgbà mìíràn a wá bí ọmọ kékeré ìgbà mìíràn a wá bí àgbàlagbà.
Iroyin kan lati orile-ede kan so pe, awon eniyan mejila ti padanu-emi  won, nigba ti oko oju-irin akero meji kolu ara won ni ekun Beheira ti o wa ni apa ariwa ilu Cairo, ti n se olu ilu orile-ede naa, nigba ti awon medogun miiran si fara pa ninu ijamba naa.
ibi ti gbogbo awon igbimo ile ifowopamo ti ijoba orile ede ati igbimo aare lori
Ko din ni ogun lara awọn ọmọ ogun ilẹ India to jẹ Ọlọrun nipe ninu ikọlu to waye ni erekusu Galwan, ni agbegbe Ladakh.
"Irinwó lé méje èèyàn ló gbàwòsàn lọ́wọ́ Covid-19 lọ́jọ́ Àbámẹ́ta, 453 míì tún lùgbàdì rẹ̀ Wo ǹkan méjìlá nípa Buruji Kasamu tí Covid 19 mú lọ Wo iye àwọn ilé ìjọsin ìlú Eko ti wọ ko ni ṣí ìlẹ̀kùn ilé ìjọisin wọ́n lẹ́yìn ti ìjọba ti ni wọ́n le máa jọ́sìn Ipa tí Fathia Balogun kó nínú bí mo ṣe dèèyàn lágbo òṣèré fíìmù Yorùba rèé - Baba Ijesha Jerry ṣlaaye pe: ""Ọkan lara awọn infijilatọ naa ka ọkan lara awọn akẹkọọ ọhun to gbiyanju lati gbe iwe wọle, o si fi ẹrọ ibanisọrọ rẹ ka a silẹ, ni wahala ba bẹrẹ."
Fun ikọ Tottenham ni tirẹ, agbabọọlu orilẹ-ede Ivory Coast, Serge Aurier yoo wa n kalẹ lati darapọ mọ awọn ọmọ ilu rẹ bii Didier Drogba, Yayah Toure ati Solomon Kalou ti wọn ti f'igba kan ri gba ife ẹyẹ UEFA Champions League.
Ìjà láàrin Jeremaya ati Paṣuri Alufaa.
Ileẹkọ fasiti Howard lo ko akẹkọjade mẹrindinlọgọrun silẹ, ti mẹrindinlaadọta ninu wọn si jẹ ọmọ Naijiria.
Agbara ojo kii ṣe oun afojudi rara: Awọn onimọ ni agbara ojo to ga to iwọn bata ẹsẹ kan le wọ ọkọ lọ loju popo.
Ko ti si alaye nipa ohun ti o fa ijamba naa.
yoo se  lee maa sun, tun fa lala, pelu
Lonii ni Oludije fun ipo gomina ipinlẹ Oṣun labẹ asia ẹgbẹ oṣelu PDP ninu idibo ọdun 2018, Sẹnetọ Ademọla Adeleke ti foju ba ile ẹjọ Majisireti to wa ni Mpape l'Abuja.
gbogbo àwọn akọni ọkunrin tí wọ́n gbóyà gidigidi gbéra, wọ́n lọ gbé òkú Saulu ati òkú àwọn ọmọ rẹ̀ wá sí Jabeṣi, wọ́n sì sin egungun wọn sí abẹ́ igi oaku ní Jabeṣi, wọ́n sì gbààwẹ̀ fún ọjọ́ meje.
Awọn agbesunmọmi Boko Haram tẹlẹ gba idande Ologun Nigeria gbakoso ibuba Boko Haram ‘Itusilẹ yoo wa fawọn onde Boko Haram’ Boko Haram tu awọn olukọni UNIMAID silẹ Kete ti awọn alakatakiti ẹsin Islam Boko Haram kede orilẹ-ede ara wọn ni ero awọn eniyan nipa wọn yipada.
Wọ́n ṣe ọpọ́n orí òpó inú yàrá àbáwọlé náà bí ìtànná lílì, ó ga ní igbọnwọ mẹrin.
Wọ́n bá fi tayọ̀tayọ̀ gbà á sinu ọkọ̀.
Ọlọrun, ra Israẹli pada,kúrò ninu gbogbo ìyọnu rẹ̀.
Ọkùnrin náà lè kọrin púpọ̀ ó sì lè sọ̀rọ̀ púpọ̀; òun ni wọn ìbá máa pé ni Olóhùn-un-dùùrù ní ìlú wa.
Èsí ìdánwò WAEC: Ìdá 53 nínú ọgọ́rún akẹ́ẹ̀kọ́bìnrin fakọyọ
Ìyá rẹ̀ sì ni Abigaili, ọmọbinrin Nahaṣi, arabinrin Seruaya, ìyá Joabu.
Iroyin naa ni lati osu kejila ọdun to kọja, paapa lati ọjọ aisun ọdun Keresi ni awọn ologun ti ya bo agbegbe naa, ti wọn si n le awsn eeyan naa tipa tikuuku.
Àwọn ohun tuntun tí a mọ̀ nípa ìgbẹ́jọ́ Wòlíì Sotitobire Ṣé lóòtọ́ ni Sẹ́netọ̀ Bayo Osinowo ní ìfura ikú ara rẹ̀?
Aremu ni omi lo ni ida aadorin ninu idas ogorun un ile ti o si je ida ogota ninu ida ogorun un ninu eya ara eniyan fun idi eyi, o ye ki a maa mojuto irufe orisun omi ti an lo ati eyi ti an mu.
Ayo Fasanmi Afenifere: Ta ni Bàbá Fasanmi tí wọ́n ń gbé lọ sí Iye Ekiti padà lẹ́yìn tó papòdà?
Gbogbo awọn eniyan jankanjankan ati awọn ẹlẹgbẹjẹgbẹ yii ni wọn dide ninu ipade naa lati fa ọwọ Aṣofin Tunde Braimoh soke gẹgẹ bi ondijedupo ti wọn fọwọ si lati pada ṣoju fun ẹkun idibo Koṣọfẹ keji ninu Ile Igbimọ Aṣofin Ipinlẹ Eko.
Oríṣun àwòrán, Bolu Akin-Olugbade Titi di ọjọ iku rẹ ni ẹni ọdun mẹrinlelọgọta, oun ni oloye Aarẹ ọna kankanfo ti ilu Owu.
Jonatani bá pe ọdọmọkunrin tí ń ru ihamọra rẹ̀, ó ní, “Jẹ́ kí á rékọjá lọ sí ọ̀dọ̀ àwọn ará Filistia, àwọn aláìkọlà wọnyi, bóyá OLUWA a jẹ́ ràn wá lọ́wọ́.
Kí o sì gbé àpótí ẹ̀rí tí òfin mẹ́wàá wà ninu rẹ̀ sinu àgọ́ náà, kí o sì ta aṣọ ìbòjú dí i.
Àkọlé àwòrán, Ogunlọgọ awọn eeyan to ti de sibi ipolongo ibo naa ni wọn wọ asọ ẹgbẹjọda ti wọn tẹ́ẹ ami idamọ ẹgbẹ oselu PDP si lara.
Ìwọ tí o ti di ahoro,kí ni èrò rẹ tí o fi wọ aṣọ elése àlùkò?
Ẹ̀mí ní ń wádìí ohun gbogbo títí fi kan àwọn ohun ìjìnlẹ̀ Ọlọrun.
Akinbinu pari ọrọ rẹ pe ohun to ṣe pataki ni ki awọn eeyan mọ ohun ti wọn n fẹ ki ọjọ idibo to de ki wọn lee mọ ẹni ti wọn yoo dibo fun.
Eyi si maa n lagbara debi pe o ma n fa iṣoro airọmọbi.
Colorado ni Amẹrika àti Adò Awaye ní Naijiria nìkan ni àdágún órí àpáta ní gbogbo àgbáyé!
OLUWA sọ fún Mose pé, “Ka gbogbo àkọ́bí lọkunrin láàrin àwọn ọmọ Israẹli láti ọmọ oṣù kan sókè, kí o sì kọ orúkọ wọn sílẹ̀.
Ẹrí rè é, Sanwo-Olu ṣèlérí lóòtó lórí súnkẹrẹ-fàkẹrẹ Apapa Ènìyàn 721 fi ayédèrú ìwé ẹ̀rí gba iṣẹ́ ìjọba àpapọ̀ - ICPC Kò sí ǹkan tó ń ṣe Idris agbébọn ní Kano - Ará ilé Buhari yan Kyari ní olùdarí tuntun fún àjọ NNPC Èyí jẹ alébu sí ìjọba ààrẹ Muhammadu Buhari ti ọ̀pọ̀ àwọ̀n eníyan bẹ̀rẹ̀ si ni gbàá bí ẹni gab igba oti.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ife Àgbáyé 2026: Ọjọ́ 13, Osù Kẹfà la o mọ olùgbàlèjò 26 Ẹrẹ̀nà 2018 Oríṣun àwòrán, Reuters Àkọlé àwòrán, Ọdún 2016 ni wọ́n yan Gianni Infantino gẹ́gẹ́ bíí àarẹ Fifa Àjọ tó ń rí sí erébóòlù lágbàáyé, Fifa ti sọ wí pé ó ku ọ̀la kí Ìdíje Àgbáyé 2018 ó bẹ̀rẹ̀ ni àwọn yóò se ìpolongo orílẹ̀èdè tí yóò gbàlejò Ife Àgbáyé 2026.
Èmi OLUWA, Ọlọrun àwọn ọmọ ogun ni mo sọ bẹ́ẹ̀.
Ni gomina ba mu u lọ si ibi tabili rẹ to si gbe e joko sori aga gomina.
" A jọ rọ lu koto ṣugbọn mo di i mu gba gba.
Bawo ni Dele Giwa ṣe ku?
O darapo mo Odunayo Adekuoroye ti o ni osuwon kilogramu mẹ́tàdínllọ́gọ́ta (57kg) ati Aminat Adeniyi ti o ni osuwon kilogramu méjílélọ́gọ́ta  (62kg), fun ifigagbaga ti yoo waye ni gbagede Times Square, nilu New York.
Lẹ́yìn náà, yóo sọ̀rọ̀ sí wọn ninu ibinu rẹ̀,yóo dẹ́rùbà wọ́n gidigidi ninu ìrúnú rẹ̀,
Bẹnaya, ọmọ Jehoiada ni olórí àwọn Kereti ati àwọn Peleti (tí ń ṣọ́ ààfin), àwọn ọmọ Dafidi ọkunrin ni wọ́n sì jẹ́ alufaa.
“Ṣugbọn ṣá o, ẹni tí yóo fi mí fún àwọn ọ̀tá ń bá mi tọwọ́ bọwọ́ níbi oúnjẹ yìí.
Tí ó wá bẹ̀rẹ̀ sí lu àwọn ẹrú, ẹlẹgbẹ́ rẹ̀, tí ó ń jẹ, tí ó ń mu pẹlu àwọn ọ̀mùtí, 
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ẹ̀rọ CCTV tú àsírí ọkùnrin ẹni ọgbọ̀n ọdún tó fi ipá bá ọmọ ọdún mọ́kànlá lòpọ̀ 5 Owewe 2020 Oríṣun àwòrán, others Ọkunrin ẹni ọgbọn ọdun kan ti dero atimọle lẹyin ti ẹrọ ayaworan CCTV tu aṣiri rẹ lẹyin to fi ipa ba ọmọdebinrin ẹni ọdun mọkanla lopọ.
Atamatase iko ohun, Ayobami Junior  lo gba ami-ayo kan soso naa wole niseju merin saa kinni ifesewonse naa.
Ohun to yẹ ki o mọ nipa aarẹ ilẹ Faransẹ, Emmanuel Macron Lopin ọsẹ to kọja ni Aarẹ ilẹ Faranse naa, Emmanuel Macron darapọ mọ awọn adari awọn orilẹede to wa ni ilẹ Afirika, ni ipade ‘Ajọ Africa Union’ to waye ni olu ilu orilẹede Mauritania, Nouakchott.
K Odukoya 'ń gun orí òkè àdúrà nítorí COVID-19'-Wò báwọn èèyàn fi wò wọ́n Gómìnà Ṣèyí Mákindé ṣàlàyé ìdí tí òun kò fi leè ti ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́ pa nítorí COVID-19 Ọwọ́ tẹ̀ èèyàn 65 tó tàpá sí òfin gbéléẹ níbi ayaẹyẹ ọjọ́ ìbí Orúkọ Abiku ni Okunnu tí mo ń jẹ nínú eré, inú orin Barrister ni mo sì ti ri - Wale Akorede O ni ṣáájú ni òun ti kọ ìwé sì ileesẹ Aṣọbode náà pé, àwọn fẹ́ kó ẹgbẹsan irẹsi tí kò dára, tí wọ́n fún Ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́ bíi èròjà iranwọ fún igbele Covid-19 padà, àmọ́ wọn kò gba àwọn láàyè láti rí ọ̀nà wọlé sínú ileesẹ wọn láti ja irẹsi ọhun silẹ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ẹgbẹ́ Dókítà: A yóò máa kẹ́yin s'awọ̀n alárùn lassa 5 Ìgbé 2018 Àkọlé àwòrán, Dokita mẹjọ lo ti ba arun lassa lọ ni Naijiria Àjọ tó ń gbógunti àjàkálẹ̀ ààrùn àti ìdènà rẹ̀ lórílẹ̀èdè Nàìjíríà, ti kéde wí pé ìpínlẹ̀ tótó ogún ni àrun ibà Lassa ti wọ bayii lorilẹede Naijiria.
Eeyan to din diẹ ni miliọnu kan (948,000) lo n tẹle e loju opo Instagram rẹ, ti wọn si wa lara awọn ti wọn n dibo fun un ni gbogbo igba.
Lẹyin o rẹyin ọwọ tẹ mẹta ninu awọn ọlọṣa naa nigba ti ọkọ bọọsi ti wọn n gbe salọ gb'okiti taraalu si da ina sii nigba ti wọn fẹ salọ."
Títí OLUWA yóo fi bojú wo ilẹ̀ láti ọ̀run wá,tí yóo sì rí wa.
Ọsẹ to kọja ni kọmiṣọna ileeṣẹ ọlọpaa ipinlẹ Ondo yọ awọn ẹṣọ alabo Agboola Ajayi, to jẹ igbakeji gomina ipinlẹ Ondo.
Asiko ti wọn n se ọdun yii ni Ọba Adeyemi ke si awọn olori rẹ lati wa fara kinra pẹlu oun ni gbọngan igbẹjọ.
Okuta posi kan ree ti wọ̀n ya aworan si lara eyi ti wọn se awari rẹ nilu Cairo lorilẹede Egypt lọjọ Satide Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Nítorí Ẹni Gíga, tí ó ga jùlọ,ẹni tí ń gbé ninu ayérayé, tí orúkọ rẹ̀ ń jẹ́ Mímọ́:òun ni ó ní, “Ibi gíga ati mímọ́ ni mò ń gbé lóòótọ́,ṣugbọn mo wà pẹlu àwọn oníròbìnújẹ́ ọkàn ati àwọn onírẹ̀lẹ̀.
Aare Buhari yoo tun maa lọ si Amman ni Dubai, United Arab Emirates (UAE) lọjọ  Aiku lati darapọ mọ awon akẹgbẹ  rẹ nibi ipade eto okoowo to maa n waye lọdọọdun
awon eso agbofinro, awon eniyan to n ta ibo ati awon oloselu to n ra ibo gbodo fowosowopo lati dekun iwa ibajẹ yii.
Lọjọ Iṣẹgun ni ile ẹjọ paṣẹ ki awọn ọtẹlẹmuyẹ tu agbatẹru iwọde Revolution Now ti wọn fi si ahamọ lori ẹsun pe o fẹ fiditẹgbajọba silẹ.
Awọn alaga kan ni digbi lawọn wa lẹyin Oshiomole Bi awọn kan ti ṣe ni awọn ko fẹ ri imi Oshiomole lakitan mọ lawọn agbarijọpọ alaga ijọba ibilẹ kan sọ pe gbọingbọin lawọn wa lẹyin rẹ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù FaceApp: Ǹjẹ́ ẹwu wà nínú lílò ẹ̀rọ yìí?
Ko si ṣẹyin bawọn Gomina ti ṣe sọ ipinu yi lẹyin ipade wọn to waye laipẹ yi pe awọn buwọlu aba meji ọkan ti wọn, ikeji ti banki apapọ CBN to fẹ ya ninu owo ifẹyinti oṣiṣẹ.
Yóo sọ àwọn ohun tí yóo ṣẹlẹ̀ fun yín.
Bí kì í bá ṣe òun Ọlọrun,ta ló tún tó bẹ́ẹ̀?
Ajọ to n gbogun tiwa jẹgudujẹra ni Naijiria, EFFC ati akẹgbẹ wọn FBI lati ilẹ Amerika ti kede aṣeyọri ajumọṣepọ wọn ti wọn pe ni 'Operation Rewire'.
Fun apẹẹrẹ, o le ni ọdun kan ti awọn akẹkọọ fasiti imọ ẹrọ Ladoke Akintola, LAUTECH fi joko sile.
won lowo nipa gbigbogun ti airise lorile ede yii .
Ọmọ náà wá dàbí ẹni tí ó kú, tóbẹ́ẹ̀ tí ọpọlọpọ ninu àwọn eniyan náà ń sọ pé ó ti kú.
Oríṣun àwòrán, Bobrisky Lẹyin ti ariwo sọ nile loko lori ohun ti ọlọpaa n wa ni ibi ayẹyẹ ọjọ ibi rẹ; agbẹnusọ awọn ọlọpaa ni ipinlẹ Eko, Bala Elkana ṣalaye pe awo iroyin kan to lu si awọn lọwọ lo gbe awọn lọ sibi ayẹyẹ naa.
Ìdí rèé táwọn àkàndá ẹ̀dá fi dí iwájú iléeṣẹ́ ìjọba ìpínlẹ̀ Oyo pa l'Agodi n'Ibadan Ọlọ́pàá, sójà yabo Lekki Toll Plaza láti dènà ìfẹ̀hónúhàn míràn Lóòtọ́ ni ọkọ mi lù mí bí àṣọ òfì, àmọ́ gómìnà ti bá wa parí ẹ̀, ẹ máa gbàdúrà fún ìdílé mi- Dokita Ifeyinwa Mi ò kí n ṣe afẹfẹ-yẹ̀yẹ̀ lórí ayélujára nítorí pé mí ò ní dúkìá tí mó le fihàn- Ronke Oshodi-Oke Àwọn èèyàn tí bẹ̀rẹ̀ sì ní gba abẹ́rẹ́ àjẹsára fún ìdènà àrùn Coronavirus ni ilẹ̀ Gẹ̀ẹ́sì Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Death During Sex: Àwọn nǹkan mẹ́ta tó le ṣekú pa ọkùnrin lásìkò ìbálòpọ̀ rèé9 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Overweight and pot belly: Wo oríṣìí oúnjẹ márùn ún tó lè dẹ́kun ikùn yíyọ àti ara àsanjù8 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Fake Kidnap: Ọlọ́pàá Eko ń wá arákùnrin tó parọ́ gba owó ìjínigbé 700k lọ́wọ́ mọ̀lẹ́bí ọ̀rẹ́bìnrin rẹ̀8 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Male Fertility: Wo àwọn oúnjẹ márùn ún tó ń mú kí àtọ̀ ọkùnrin dára sí i7 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Orílẹ̀-èdè kan ń pa ekeji run, ìlú kan sì ń pa ekeji rẹ́, nítorí Ọlọrun mú oniruuru ìpọ́njú bá wọn.
Nítorí pé OLUWA sọ̀rọ̀, ayé wà;ó pàṣẹ, ayé sì dúró.
O ni ọ̀rọ̀ ọkunrin naa da bi ọrọ̀ Yoruba kan to sọ pe 'ko si ẹni to fẹ ẹ fi ọbẹ to nu j'ẹsu.
Ẹwẹ, ọjọ Abamẹta ni akọnimọọgba Liverpool, Jurgen Klopp gba ami ẹyẹ akọnimọọgba to pegede julọ ni saa bọọlu 2019/2020.
Momodu ni Oloye Akande fi imura bi ẹni n rode pawọn ku nilẹ Amẹrika.
“Kó àwọn ọmọ rẹ̀ wá, kí o sì wọ̀ wọ́n lẹ́wù, 
Bi Arogundade ṣe gbọ idajọ rẹ ni o ṣubu wọọ ninu koto ijẹjọ ti ariwo ẹkun si sọ lati ẹnu awọn mọlẹbi rẹ ninu ile ẹjọ.
Ni ọjọ kẹta, oṣu kẹsan ni wọn kede pe wọn n wa ọgagun naa lẹyin ti o poora lasiko ti o fi n rinrinajo lati Abuja lọ si ipinlẹ Bauchi.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Wo bí Sunday Orimola ṣe gba ikú ẹranko kú ní Ifon ni Ondo lórí ọ̀nà àtijẹ Ẹyin ọmọ Yoruba, ẹ ran mi lọwọ lati ra irinṣẹ mi to jona patapata Chief Kanran lasiko to n bere iranwọ lọwọ awọn ọmọ Naijiria sọ wi pe gbogbo ohun ini oun ni awọn ti oun ya owo ni ọwọ wọn lati ṣe sinima gba pada, ti oun si da ẹni ti ko ni ọkọ ayọkẹlẹ mọ.
Iroyin ni odomode omo odun kan naa ri somi ninu ile onkorin yii ni Ikoyi nilu Eko ni ojo Aiku.
Ẹni to bori: Algeria Ghana vs Kenya.
5 miliọnu ni awọn fi ra awọn nkan iranwọ, ounjẹ ati irugbin fun araalu.
A ó gbé'gbésẹ̀ lẹ́yìn ìwádìí fídíò tí Dino ti ń náwó lójú agbo- Ọlọ́pàá Ninu iwe adehun igbanisiṣẹ ti Seedorf ati Kluivert tọwọ bọ, ara ohun ti yoo mu iṣẹ wọn duro ni ki wọn gba ife ẹyẹ naa eleyii ti wọn gba ni ọdun 2017.
Akeredolu, Ọgá NDLEA lọ kọ nípa gbíngbin igbo ní Thailand Bí ọlọ́pàá bá mú ọ, kí ló yẹ kí o ṣe?
O sọ pe ti owo ba da ọkọ ati iyawo pọ nigba miran, ija le lagbara ju aale yiyan lọ.
Ọmọ Yoruba ọhun to jẹ ọmọ orilẹede Gẹẹsi, ẹni ọdun mejidinlọgbọn (28), lo ọwọ osi rẹ dara-dara nigba ija ti Parker to jẹ ọmọ orilẹede New Zealand naa ti lo iyawọ rẹ ati amumọra rẹ bo ti yẹ Sugbọn o da bi ẹni pe igbanu ẹyẹ WBO rẹ yoo pada si idi Joshua nigba to ri awọn ami ayo pataki nibi ẹṣẹ isalẹ agbọn to gba Parker ni ẹsẹ kejọ ati bo ti fi ẹṣẹ ta bi agbọn ni ẹsẹ kewa idije ija naa.
Àwọn ọkunrin wọnyi gbìmọ̀, wọ́n sọ fún ọba pé, “Kabiyesi, o mọ̀ pé òfin Mede ati ti Pasia ni pé òfin tí ọba bá ṣe kò gbọdọ̀ yipada.
Funke Akindele Nollywood: Mi ò gbẹ́kẹ̀lé ènìyàn!
Oríṣun àwòrán, Others Ìgbìmọ̀ amúṣẹ́ṣe ìjọba àpapọ̀ lórí Covid-19 ti fẹdun ọkan wọn han lori bi itankalẹ aarun Coronavirus ṣe n pọ si laarin awọn to n bẹ nì'jọba.
Ẹ le ka nipa rẹ si nibi Mialitiana Clerc Ọjọ ori: Mẹrindinlogun Orilẹẹde: Madagascar Ere idaraya: Alpine Skiing Mialitiana Clerc  bẹrẹ sini  kọ nipa ere ori yinyin nigba ti o jẹ ọmọ ọdun mẹta ni ilẹ France.
OLUWA ní: “Bí olùṣọ́-aguntan tií rí àjẹkù ẹsẹ̀ meji péré, tabi etí kan gbà kalẹ̀ lẹ́nu kinniun, ninu odidi àgbò, bẹ́ẹ̀ ni yóo rí fún àwọn ọmọ Israẹli, tí ń gbé Samaria: díẹ̀ ninu wọn ni yóo là, àwọn tí wọn ń sùn lórí ibùsùn olówó iyebíye.
O tun jẹ owo Bitcoin to to ẹẹdẹgblta Dọla, ati aṣoju ileeṣẹ.
Loju awọn ọmọ Naijiria bii Ime- Albert, wọn senetọ yii kan bẹbẹ lori ahọn ni ati pe o yẹ ko gba ẹbi rẹ ni ẹbi ni o.
"Tems ti gba ìtúsílẹ̀ lọ́gbà ẹ̀wọ̀n Uganda Wọ́n ní kí ọ̀gá àgbà ""Ede Poly"" lọ rọ́kún nílé lórí ẹ̀sùn pé ó kan bẹ́ẹ̀dì sí ọ́fíìsì Wo ohun tí yóò ṣẹlẹ̀ ní ìpàdé àwọn èèkàn Yorùbá láti mú kẹ́ẹ dìbò fún Tinubu ní 2023 Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Kollington ṣàlàyé bí orin Fuji ṣe bẹ̀rẹ̀ gan an ní Nàiìjíríà O fi kun un wipe igbesẹ ọhun gan ṣe pataki nitori iṣoro aabo to wa lorilẹede yii ati lati dena iru nkan to ṣẹlẹ nileewe Girama Government Science Secondary School ni ilu Kankara, ipinlẹ Katsina."
Àwọn wọnyi ti ń tẹ̀lé e láti ìgbà tí ó ti wà ní Galili, tí wọn ń ṣe iranṣẹ fún un.
Lẹyin igbeyawo ọdun mejidinlogoji, tọkọ-taya naa tuka.
Wo àwọn oúnjẹ márùn ún tó ń mú kí àtọ̀ ọkùnrin dára síi Rògbòdìyàn bẹ́ sílẹ̀ láàrin àwọn ọlọ́kadà àti àwọn òṣìṣẹ́ ọgbà ẹ̀wọ̀n ní Ibadan Ọdun 2012, 2016 àti 2020 ni John Mahama àti Nana Akufo-Addo ti jọ ń figagbága dupò aàrẹ Ghana Amẹrika ti yọ àfikún owó Físà kúrò fún arìnrìnàjò Nàìjíríà Ẹwẹ, agbẹnusọ Deji ti ilu Akure, Oloye Micheal Adeyeye ti sọ fun awọn akọroyin pe ẹni ti wọn gun lọbe ko ku.
Ẹ̀yin ni ògo wa ati ayọ̀ wa.
nile igbimo asofin ipinle eko,so pe atunse si iwe ofin naa yoo ran ibasepọ to
Ẹ óo mú akọ mààlúù ẹbọ ìmúkúrò ẹ̀ṣẹ̀; ẹ óo sun ún ní ibi tí a yàn lára ilẹ̀ Tẹmpili ní ìta ibi mímọ́.
Oríṣun àwòrán, others Bẹẹ ba gbagbe, oṣu kẹta ọdun 2020 ni aarẹ Muhammad Buhari pasẹ pe, ki wọn ti awọn papakọ ofurufu ilẹ wa pa, eyi to wa gẹgẹ bii ara ọna lati dẹkun ọwọja itankalẹ arun Coronavirus ni Naijiria.
Inu awọn kan dun si ,wọn si ti ni ki o tete ma pada bọ wa si Manchester United to fi silẹ Emir Borno lé àwọn aṣẹ́wó léré, ó ní kò sáyè fún wọn nípìnlẹ̀ òun Òjò ló lè mú kí ìtànkálẹ̀ àrun ìgbẹ́ ọ̀rìn má tètè dópin ni Eko- Iléeṣẹ́ ìlera Ta ni Ken Saro-Wiwa tí ìjọba ológun sekúpa?
"Shogunlẹ tun jẹ ko di mimọ pe, ""igbesẹ yoo bẹrẹ ni kiakia lati mu adinku ba awọn to wa ni ihamọ FSARS jake-jado Naijiria."
Igba akọkọ ni yii ti awọn maraarun maa foju han nile ẹjọ lẹyin iṣẹlẹ New York, Washington ati Pennsylvania.
Ní àkókò yìí Abija, ọmọ Jeroboamu ọba ṣàìsàn, 
Bákan náà nígbà tí ẹ bá rí àwọn ìṣẹ̀lẹ̀ wọnyi, kí ẹ mọ̀ pé Ọmọ-Eniyan wà nítòsí, ó fẹ́rẹ̀ dé.
Bakan naa ni wọn kilọ fun awọn eniyan lati ri pe wọn ko ju ogun eniyan lọ ni ibi ti wọn ba wa, ki eniyan ma pọju bo ṣẹ yẹ lọ ni ibikan.
Ọkunrin náà lọ sí ilẹ̀ àwọn ará Hiti, ó tẹ ìlú kan dó, ó sì sọ ọ́ ní Lusi.
 Ó jẹ ́ olùgbèjà fún àwọn aláìlẹ ́ nìkan , ó sì jẹ ́ olùdásílẹ ̀ nigeria union of teachers àti nigerian union of students .
ni ọjọ Aiku ni ijọba ipinlẹ naa gbe atẹjade kan jade lori eyi.
Fun ile ẹjọ, ofin tuntun yii yoo mu ki ile ẹjọ tete ma a gbọ ẹsun ifipabanilopọ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Christmas: Ẹ ronúpìwàdà lásíkò ọdún, àti àwọn ìkíni mìrán tó jẹ yọ fún Kérésì 25 Ọ̀pẹ̀̀ 2019 Àkọlé àwòrán, A ku ọdun Keresi ni koowa n kira wn lonii Aarẹ Muhammadu Buhari ti ki awọn ọmọlẹyin Kristi to wa ni orilẹ-ede Naijiria ku oriire ọdun Keresimesi.
Adigunjalè gégé bí orúko rè ni eni tí ó di ìhámóra Ogun lo sí oko olè.
olopaa naa tun ro awon iko re lati ri i pe won tele asẹ ti oga agba fun ile-ise
Ọ̀pọ̀lọ́ ń tú jáde ní ilẹ̀ wọn,títí kan ìyẹ̀wù àwọn ọba wọn.
O fikun pe o se pataki kawọn ki ijọba oun ni awọn eeyan to ni ọgbọn, oye ati iriri ni gbogbo ẹka igbe aye ọmọniyan, ti wọn yoo maa kopa ninu eto akoso ipinlẹ Ọyọ.
Awon egbe oselu alatako ni won dajo fun lojo kerindinlogun osu kini odun ti a wa yii, ni eyi ti awon agbejoro pese awon olujeri marun-un pelu kaseti igbohun sile, eyi ti o safihan eleri karun ti o gba sile.
Fún irúgbìn ní àárọ̀, má sì ṣe dáwọ́ dúró ní ìrọ̀lẹ́, nítorí o kò mọ èyí tí yóo dàgbà, bóyá ti òwúrọ̀ ni tabi ti ìrọ̀lẹ́, tabi àwọn mejeeji.
Aare wa dupe lowo awon omo
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ojú mi ti rí lọ́pọ̀ lọpọ̀, àmọ́ mo dúpẹ́ pé mo ti pé ọdún márùn ún lórí oyé- Ooni Ṣugbọn Ogunyemi ni ẹgbẹ naa ṣi n ṣe ipade lọwọ, wọn si n reti ki ijọba mu ileri rẹ ṣe nipa sisan owo to jẹ wọn.
Emir ti Gusau, Alhaji Ibrahim Bello,akowe agba fun ipinle naa,
Ọ̀run Àpáàdì ni Filásayépọ̀ dàgbà sí nítorí bàbá rẹ ti fi i fún Èṣù tii ṣe ọba ìbẹ̀ ní kékeré kí ọmọ náà má ba à bàjẹ́, Èṣù sì fi ìyà jẹ ẹ́ gidigidi, ibi  iná ìléra ńlá ni Èṣù fi sí kí ó máa fẹ́ iná ní ọ̀run Àpáàdì, eléyìí sì mú kí ojú ọkùnrin náà yípadà kí ó di pupa, bẹ́ẹ̀ náà sì ni ara rẹ̀ yípadà tí ó di dúdú mọ̀nàmọna.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Iléeṣẹ́ ọlọ́pàá tún ti ṣèlérí àtúntò ikọ̀ ọlọ́pàá kògbérégbè FSARS 13 Òkùdu 2018 Oríṣun àwòrán, @OfficialSARS Àkọlé àwòrán, Àwọn aláṣẹ Iléeṣẹ́ ọlọ́pàá ní ìlànà iṣẹ́ ikọ̀ ọlọ́pàá kògbérégbè FSARS kò fi ààyè ìrégbè sílẹ̀ fún wọn Ileeṣẹ ọlọpa ti ni ko si ofin kan to fun awọn oṣiṣẹ ọlọpa FSARS lati da ọkọ duro fun ayẹwo loju popo.
Yóo tilẹ̀ dúró ni, nítorí Oluwa lè gbé e ró.
Ẹgbẹ́ Boko Haram pa àwọn òṣìṣẹ́ UN márùn ún tó wá ṣiṣẹ́ ìrànwọ́ ní Nàìjíríà Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Working religious women: Ẹ̀lẹ́hàá kìí ṣe ọ̀lẹ- Aminat Adegoke Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 3 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 5 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Ní ọdún kẹtalelogun tí Nebukadinesari jọba, Nebusaradani, olórí àwọn tí wọn ń ṣọ́ ọba, kó ojilelẹẹdẹgbẹrin ó lé marun-un (745) eniyan lára àwọn Juu.
Ajọ NCDC kede pe awọn to tọwọ arun naa dero ọrun lapapọ ni Naijiria lọjọ Aje ti di ẹẹwalelẹẹdẹgbẹrun.
Ṣugbọn wọ́n gbèrò láti pa á.
Àwọn ìlú wọn tóbi, tí odi tí wọ́n mọ yí wọn ká sì ga kan ojú ọ̀run.
orile-ede Italy, ki o to teko leti lo sorile-ede Germany lo jiroro pelu aare
Ekiti rape: Ẹni ọdún 51 fipá bá ọmọ ọdún 12 lòpọ̀, ìjọba ìpínlẹ Ekiti lẹ awòrán rẹ̀ gbangba sí àárín ìlú
Ó sì dáhùn pé, “Ohun tí OLUWA bá sọ fún mi ni mo gbọdọ̀ sọ.
Ileeṣẹ aarẹ orileede Naijiria ni ohun iyalẹnu lo jẹ fawọn bi awọn Gomina ipinlẹ kan ti ṣe n tapa si idasilẹ agọ Fulani, eyi ti wọn pe ni ''Ruga Settlement.
Ẹni to tako ilana Nigba iṣejọba rẹ gẹgẹ bi Emir ilu Kano, ọpọ awọn awọn eeyan oke Ọya lo n wo Sanusi bi ẹni to n tako ilana aṣa awọn eeyan rẹ.
Ẹsun pe Abba Kyari ni olori awọn igbimọ apaṣẹ wa (Cabal) ni ileeṣẹ aarẹ.
Pabanbari ibẹ ni pe ibalopọ yanturu ni gbangba ati kọọrọ naa yoo waye nibẹ.
Bakan naa ni won ti seku pa aimoye awon elesin kristeni ninu ikolu ado-oloro ati ibon yiyin, bakan naa ni won tun ju ado-oloro si oko ofurufu orile-ede Russia kan, ti o ko awon arinrin-ajo afe.
Ẹ̀ ń fi bẹ́ẹ̀ dẹ́ṣẹ̀ sí àwọn arakunrin yín tí ó jẹ́ aláìlera, ẹ̀ ń dá ọgbẹ́ sí ọkàn wọn, ẹ sì ń fi bẹ́ẹ̀ dẹ́ṣẹ̀ sí Kristi.
Oríṣun àwòrán, @odunomoadekola Àkọlé àwòrán, Òsèré Tíátà Odunlade Adekola Odunlade Adekola A bí i ní ọjọ́ kọkànlélọ́gbọ̀n osù kejìlá ọdún 1978.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ife Ẹyẹ Agbaye ti Russia 2018 balẹ bagẹ si BBC 9 Ẹrẹ̀nà 2018 Lara awọn aworan nibi isafihan Ife Ẹyẹ agbaye ti Russia 2018 ni Ile-isẹ BBC.
Ondo Election 2020:Lóòtọ́ làwọn tọ́ọ̀gì APC kọlu PDP ní Oba Akoko, ìwádìí ti bẹ̀rẹ̀
Ìdí rèé tí mi ò fi yọjú sí ìgbìmọ̀ àjọ PFN- Fatoyinbo Ọ̀rọ̀ ìfipábánilòpọ̀ di kàyééfì lásìkò yìí; ọwọ́ tẹ àwọn kan ní Ekiti Obìnrin kan rèé tó sọ ìrírí rẹ̀ lẹ́yìn tí ọkùnrin mẹ́ta fipá báa lòpọ̀ Iyabo Ojo, Toyin Abraham, Mercy Aigbe, ta làwọn òṣèrébìnrin yìí gbè lẹ́yìn lórí ọ̀rọ̀ ìfipábánilòpọ̀?
7 696830 Orilẹede Chile 17369 92.
Bakan naa ni ẹni ti o jẹ Olugbani siṣẹ ajọ agbaye tẹlẹ ki arabinrin yii lori ẹro ayelujara fun iwa akọni rẹ lati rin iru irin ajo naa.
Olu ilu orilẹede Kenya, Nairobi ni ipade yii ti n waye.
Èyí ẹ ṣe tó, England àti VAR júwe ilé fún Cameroon Ọ̀rọ̀ ti yanjú dé ibì kan lórí owó àjẹmọ́nú àwọn Super Falcons Ọmọ ogun Nàìjíríà bẹ̀rẹ̀ lílo 'Drone' láti gbógun tàwọn ajínigbé ni Ondo àti Ekiti Jẹ́ kí a jọ sọ àǹfàní US fún Nàìjíríà -Osinbajo Bakan naa ni Favour sọrọ lori awọn ipenija ti oun koju lagbo iṣelu nitori aiko owo silẹ.
” Nítorí ó wí pé, “Ṣé nítòótọ́ ni mo rí Ọlọrun, tí mo sì tún wà láàyè?
Èdè àti Àṣà Yorùbá kò ni parẹ́.
"Jatta sọ siwaju si pe, ""Aarẹ nigba kan ri naa ko ni asiko lati maa sọrọ lori awọn iroyin ti kii ṣe otitọ."
T Asua wọgile ẹjọ naa tori pe awọn olupẹjọ kuna lati fi iwe ranṣẹ saaju gbendeke ọjọ meje ti ofin la kalẹ.
BBC: Igbesẹ wo lẹ n gbé lati ri i pe awọn nkan ti Baba Awoo ṣe silẹ ko parun?
A kò tíì lè sọ pé ọmọ Ọba tuntun ni yóò jẹ Ooni lọ́jọ́ iwájú - Elebuibọn Àwọn ìgbésẹ̀ tí SERAP ń fẹ́ kí ìjọba gbé lórí ọrọ̀ ajé Nàìjíríà tó dẹnukọlẹ̀ Ìjọba orílẹ́-èdè Nàìjíríà tí kéde lójọ́ sátidé pé ọrọ̀ ajé rẹ̀ ti dẹnukọlẹ̀ pátápáta báyìí láti inú oṣù mẹ́ta àkọ́kọ́ ọdún 2020.
O ni Leah ni wolii obinrin ni inu tubu ti Boko Haram fi awọn pamọ si, oun lo maa n gbadura fawọn eeyan yoku, to si tun n sisẹ iwosan lati ipasẹ adura rẹ naa.
Fafiti ilu Ibadan , ni ekun Gusu ni ipinle Oyo n fi amin eye da Gomina
Kí lo mọ̀ nípa fẹntilétọ̀, ohun èlò aṣèrànwọ́ èémí Ìlànà ojúlówó márùn ún tó dènà àrùn Coronavirus Àwọn jàǹdùkú ṣe ikú pa ẹnìkan n'ílùú Eko Akojọpọ ǹkan amáyedẹrùn tí ijọba ti fun awọn ọmọ Naijiria nitori aarun coronavirus Afeez ṣalaye fun Akoroyin Ayaworan BBC, Joshua Akinyemi pe gigun ti oun gun ju awọn eniyan lọ yii ti fun oun ni anfaani lati lọ silẹ okeere bii Amerika.
"6bn ohun ìní Nàìjíríà Àwọn ọmọ Naijiria kóju ija sí àwọn South Africa wọ́n ní ""Ó tó gẹ́"" Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?"
1) Pa ibi to n sọ ibudo ti o wa ninu foonu rẹ.
Nítorí OLUWA ti ru ẹ̀mí àwọn ọba Media sókè,nítorí pé ó ti pinnu láti pa Babiloni run.
Amọ, ẹgbẹ oṣiṣẹ NLC fikun pe awọn yoo gunle iyanṣelodi ti ijọba ba kọ lati gba ero wọn ro, abi ti wọn ni dandan awọn yoo tẹsiwaju pẹlu owongogo owo epo bẹntirol ati ina mọnamọna naa.
”Ó sọ bẹ́ẹ̀ bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé ó ti parí iṣẹ́ rẹ̀ láti ìpìlẹ̀ ayé.
Labani ati Betueli dáhùn pé, “Ati ọ̀dọ̀ OLUWA ni nǹkan yìí ti wá, àwa kò sì ní sọ pé bẹ́ẹ̀ ni tabi bẹ́ẹ̀ kọ́.
O lede ọrọ naa nigba ti o'n ṣe ipade pẹlu awọn alẹnulọrọ ni ipinlẹ Taraba lọjọ aje.
Kò ṣẹ̀ṣẹ̀ di ìgbà tí ẹnikẹ́ni bá sọ fún un nípa ọmọ aráyé nítorí ó mọ ohun tí ó wà ninu wọn.
    Aafin ọba Òmùgọ̀diméjì kò dara tó aba oko rara, ogiri ti wọ́n mọ yíí ká, ẹsẹ̀ méjì ni gíga rẹ̀.
Gómìnà Kejilá – Ọ̀gbẹ́ni Bọla Ahmed Tinubu – Gómìnà Ìjọba Alágbádá fún ọdún mẹjọ – ọdún mejidinlógún titi di ọdún mẹwa sẹhin
Ni kete ti eto kika naa bẹrẹ si ni awọn ijọba ibilẹ miran n wọle, yatọ si ti mẹrin to wa nilẹ saaju.
Wọ́n gbe kiri titi fún itọ́jú ṣùgbọ́n asán ló já si.
Ẹgbẹ naa ti wọn pe ni ‘Blossom Africa Initiative (BAI)’ ni wọn ní ilepa fun aṣeyọri ‘Erongba Ifẹsẹmulẹ Idagbasoke Agbaye (Sustainable Development Goals (SDGs) onipele mẹtadinlogun’.
"Èyí ló fàá ti àwọn ọmọ ẹgbẹ́ awakọ̀ tọ kù fi tẹ̀lé awakọ̀ náà láti lọ bá àwọn sójà ọ̀hún sọ̀rọ̀, ""ibi tí a ti ń tí sọ ọ́ ni gbọmísí omí-òtó ti bẹ̀rẹ̀, ọmọogun kan sì yin àwọn awakọ níbọ̀n, ènìyàn mẹ́ta ló kú lójú ẹsẹ̀, tí àwọn méjì sì padà kú nílé ìwòsàn."
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ethiopian Airlines crash: Awakọ̀ òrúrufú pariwo 'lọ sókè!
Awon akosemose eto oro-aje ti kinlo pe, erongba orile-ede America lati gbe ofin dandan le owo ori-oja kiko irin wole, le sokunfa laasigbo kara-kata, eyi ti o le sakoba fun eto oro-aje lagbaye ti  iye owo re n lo bi egbederun 470 biloinu dollars, bi o ba fi maa di odun 2020.
O ni niṣe ninu oun maa n dun nigba kugba ti Man U ati Arsenal ba fẹ waako nitori oun mọ pe Man U yoo bori.
Nigba ti wọn juu sẹwọn lọdun 2009 ko si ẹbi rẹ kan to bẹẹ wo bakan naa ko ṣẹni to ba tọ awọn ọmọ rẹ mararun.
Ìdí nìyí tí ẹ̀rù fi bà mí níwájú rẹ̀,tí mo bá ro nǹkan wọnyi, jìnnìjìnnì rẹ̀ a bò mí.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Kayode Fayemi fi iwe eri moyege han Aare Buhari Ohun to yẹ koo mọ nipa ajọ gpmina Naijiria Ọdun 1999 ni wọn da ajọ awọn gomina ipinlẹ mẹrindinlogoji to wa ni Naijiria silẹ.
Nígbà tí ó kú a sin ín pẹlu àwọn eniyan rẹ̀.
”Ó dá wọn lóhùn pé, “Níbi tí òkú ẹran bá wà, níbẹ̀ ni àwọn igún ń péjọ sí.
Elija sọ fún un pé, “Tún lọ ní ìgbà meje.
Àjọ INEC ti kéde pé PDP ló jáwé olúbori ni Zamfara Ajimobi figbe ta, ó ní 'èmi kọ́ ló pa Ṣugar o!
Lẹyin o rẹyin baba kan ba so Ojelade ni agadagodo lẹyin to di ọọni tan eyi ti ko si le yipada di eeyan mọ.
Coronavirus ti di ara wa, kò le è kúrò mọ láéláé - WHO Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí 2 sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
Oko àgbẹ̀ tí mo dé tì ni mo já sí lágá.
Nítorí n óo ṣe iṣẹ́ kan ní àkókò yín,tí ẹ kò ní gbàgbọ́ bí ẹnìkan bá ròyìn rẹ̀ fun yín.
O ni wọ́n kọ́kọ́ bẹ̀rẹ̀ si ni lẹ okúta láti le àwọn ènìyàn sá ti wọ́n o si já sọọbu tábi ilé ti wọ́n ba ri wọ láti lọ kó gbogbo ǹkan ti wọ́n ba rí nibẹ.
Àwọn afurasí ṣá ìgbákejì kọmísọ́nà ọ̀gá ọlọ́pàá láàké dójú ikú Ọ̀dọ́bìnrin, ẹ ṣọ́ra!
Oríṣun àwòrán, AFP Àkọlé àwòrán, Ìpòrúuru bá ìyàwó mi bó ṣe gbọ ohun ọmọ wa - Baba Leah Ìroyìn tó jáde láti ile ìròyìn Cable lalẹ́ ọjọ́ Ajé gbé ohun Leah to ti wà ni àhámọ Boko Haram láti inú oṣù kejì pèlú àwọn ọmọ Dapchi tó lé ni ọgọ́rùn tí wọn ti tú sílẹ̀.
Ẹ̀mí Èṣù ni àwọn ẹ̀mí náà, wọ́n sì lè ṣe ohun abàmì.
Agbebọn pa ọmọ ogun mejila Afunrasi afipajinigbe k'agbako ni Ogun Ifilọlẹ ẹgbẹ alajumọse nipinlẹ Ogun Amnesty: Ọmọ ogun Nigeria ko naani ẹmi Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Gbogbo olùdíje Ogun fi dá àwọn ènìyàn lójú pé.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Apollo 11: Àgbáyé sayẹyẹ ọdún 50 tí ènìyàn kọ́kọ́ wọ inú Osupa 21 Agẹmo 2019 Oríṣun àwòrán, AFP Ẹgbẹgbẹrun eniyan kaakiri agbaye lo n se ayajọ aadọta ọdun ti eniyan kọkọ wọ inu Osupa.
Awọn ti agbẹjọro yii ṣaba maa n ṣoju ni awọn ti wọn ba fi ẹsun jibiti owo, jibiti ori ayelujara ati iwa ibajẹ nidi oṣelu.
Lẹyin wakati kan ti wọn ti ṣe ifẹhonu han ni wọn fun oṣiṣẹ olu ileeṣẹ ilẹ Gẹẹsi kan ni lẹta ti wọn mu dani.
Gómìnà Seyi Makinde bá ẹbí Isiaq Jimoh tó kàgbákò ikú òjijì dárò Bí èsì ìdìbò gómìnà ìpínlẹ̀ Ondo se ń jáde rèé.
 bíbófinmu níí se pèlú ìmò èdè ; ìlò èdè ni jíjé ítéwógbà níí se pèlú .
NCAA: A fún àwọn adarí ní ọ̀sẹ̀ méjì si láti dá wọn lóhùn
Ṣugbọn n óo wí fún wọn pé, ‘Èmi kò mọ̀ yín rí.
" Eniyan Ọlọrun lasan ni mi, emi kii se Ọlọrun, Ọlọrun ko ni ba eniyan kankan pin ninu ogo rẹ, emi ko si setan lati ku, Esu, emi ko setan lati ku o"" Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 3 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 5 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!"
Nígbà tí ó n sọ̀rọ̀ ninú àseyẹ kan tí íjọba Ìpínlẹ̀ Bauchi gbé kalẹ̀ láti yẹ́ẹ sí ní Ojọ́bọ, ààrẹ ní òun ti kọ́kọ́ sọ fún àwọn agbẹnusọ òun pé wọn kò gbọ́dọ̀ fèsì, ṣugbọn Mohammed ni ó sọ pé ìjọba gbọ́dọ̀ dá Obasanjo lóhùn.
Ipò tí àwọn èròjà tó ń jà fún ara bá wà ṣe pàtàkì lori oro aarun a Coronavirus, tí ó bá seese fún wọn láti gbógun ti aarun náà ti wọn si se àṣeyọrí, bákan náà ni ó nise pelu ara ẹni tí ènìyàn tí jáde, tí òye yìí bá yẹ àwọn ènìyàn, yóò ṣe iranwo láti mọ àwọn tí wọn dabo bo ara wọn láti má lè yọjú sì ipele tí ó lágbára nílé ìwòsàn.
Láti ìhà àríwá ni Ọlọrun ti yọ,ó fi ọlá ńlá, tí ó bani lẹ́rù, bora bí aṣọ.
Justice for Richard: Òbí àkẹ́kọ̀ọ́ tó kú síléeṣẹ́ ọṣẹ ń bèèrè fún ìdájọ́ lórí ikú ọmọ wọn
Dafidi ní, “N óo fi ìfẹ́ hàn sí Hanuni bí baba rẹ̀ ti fi ìfẹ́ hàn sí mi.
Ọpọ igba ni igbesẹ ijọba lo ti ba oniruru iha araalu pade.
 Mo fe ki e wa si Afrika wa wo aso wa, ki e wa gbadun a awon ounje aladun wa.
kéjìlá, osu kẹ́fà fun ojo isinmi lorile ede , ni eyi ti ayajo ayeye eto ijoba
Ẹgbẹ́ ajàfẹ́tọ̀ọ́ ẹni yóò bẹ túbú ọlọ́pàá wò Shogunlẹ ti ipo rẹ gẹgẹ bii ọlọpaa jẹ igbakeji kọmiṣọna (ACP), fesi lọna to bi awọn ara ilu ninu nigba ti iroyin jade nipa awọn obinrin ti awọn ọlọpaa kan mu lori ẹsun ṣiṣẹ owo nọbi ni Abuja ti wọn si fipa bawọn lọ po.
Ṣé lóòtọ́ ni Sẹ́netọ̀ Bayo Osinowo ní ìfura ikú ara rẹ̀?
Jummai sọ pe ninu ọmọ mẹtadinlogun ti oun bi, meje ti ku lara wọn, to si ku mẹwaa; ọkunrin marun un, ati obinrin marun un.
Engine oil) 560, ti iye owo re to ogoji milioni naira ni agbegbe Akinyele niluu
Òtítọ́ ni ìran náà, ó ṣòro láti túmọ̀, ṣugbọn a la ìran náà ati ìtumọ̀ rẹ̀ yé Daniẹli.
Wayii o, idije 2019 AFCON yoo
Ekiti: Ìtumọ̀ Pelúpelú nínú òyè ọba jíjẹ ní ìpínlẹ̀ Ekiti àti ìpele tí àwọn ọba pín sí
Ó sì tún ra ọsàn, ìrèké àti ọ̀gẹ̀dẹ̀.
O kò gbọdọ̀ fi ọwọ́ líle mú un, ṣugbọn bẹ̀rù Ọlọrun rẹ.
Ǹjẹ́ ọ̀rọ̀ asán tí ẹ̀ ń sọ yìí tilẹ̀ lópin?
Nigba to n sedaro Dagunro, Adebayọ Salami, ti a mọ si ọga Bello, se apejuwe Dagunro bii ẹni to gbe asa Yoruba ga ni nigba aye re.
nigba meta pere, lataari awon atamatase bi Neymar, Kylian Mbappe ati Edinson
Kábíyèsí, mo dúpẹ́ lọ́wọ́ yín, mo dúpẹ́ gidigidi, mo dúpẹ́ fún ìtọ́jú yín lórí mi, bí mo bá ti rí yín kò sí ẹni tí ó tún dára lójú mi nínú ayé yìí mọ́, ẹ̀yin ni òrìṣà mi, kí Olódùmarè sì jẹ́ kí á jèrè ara wa.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, John Ogu bá BBC Yorúbá sọ̀rọ̀ lórí ìgbáradì Nigeria vs Madagascar Rohr ṣalaye fawọn oniroyin pe Collins ati Shehu ti n gba itoju to yẹ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Segalink:ìkùnsínú pọ̀ láàrin àwọn agbófinró bẹ́ẹ̀ wọn kò ni agbẹnusọ O ni oun maa n fun wọn ni owọ ti wọn ba na fi ra ohun eelo nigba mii ni.
Ọpọlọpọ awọn akẹgbẹ Mama Rainbow ninu iṣẹ tiata ni wọn yẹ ẹ si nibi ayẹyẹ ọjọ ibi ọhun, nigba to n ṣe ayẹyẹ ẹni odun mẹtadinlọgọrin loke eepẹ.
Iṣẹ wọn ni lati wadii iṣẹ ati iṣe Magu gẹgẹ bi alaga ajọ EFCC ati ajọ EFCC gan an pẹlu.
Oríṣun àwòrán, AFP Àkọlé àwòrán, Lọjọ kan naa, iya kan n bimọ tuntun jojolo ni olu-ilu South-Sudan, Juba.
Kò sí ọba tí ó dàbí rẹ̀ láàrin àwọn ọba àwọn orílẹ̀-èdè mìíràn, Ọlọrun sì fẹ́ràn rẹ̀, Ọlọrun sì fi jọba lórí gbogbo Israẹli, sibẹsibẹ, àwọn obinrin àjèjì ni wọ́n mú un dẹ́ṣẹ̀.
Ọgbẹni Uzoma ṣalaye pe ẹni ọdun mẹtadinlọgọta ni Majek Fashek ki o to dagbere faye.
Wọn a ma tẹle ilana ipasẹ eleyi to fara jọ t'awọn ologun.
Oga agba eka egbe ajafeto omo eniyan ninu ajo UN, Zeid Al Hussein so pe, “won n fi eto awon omo orile-ede South Sudan dun won, bi: eto fun igbe aye alaafia, eto fun eto idajo ati eto lati fi erongba ati ehonu-eni han.
Ẹdinwo naa ti Aarẹ Muhammadu ti buwọ lu yoo bẹrẹ ninu oṣu kinni ọdun 2019 gẹgẹ bi minisita eto ẹkọ ti sọ.
egbe  oselu APC  Comrade Adams OshiomoleAlhaji 
Eyi si wa lara ẹsun tawọn oyinbo amunisin ka si Oba Kosoko lọrun, ki wọn to rọ ọ loye, to si sa lọ silu Badagry pẹlu Balogun rẹ, Oshodi Tapa, níbi ti owo ẹru rẹ tun ti buyaari.
Aare Muhammadu Buhari so pe, ijoba ti n yanana awon isoro to n dojuko eto abo lorile-ede Naijiria.
iru rẹ ti o waye lorile ede Naijiria niluu Abuja.
Ajọ to n mojuto ọrọ ẹṣẹ kikan ni orilẹ-ede Russia ni awọn ti bẹrẹ iṣẹ iwadii kikun lori iṣẹlẹ yii.
Bẹẹ ni o tun ke pe awọn olori ẹgbẹ oṣẹlu, lati ba oun ṣe ipade pọ ki wọn baa le fi ero inu wọn han nipa ọna to tọ nipa Brexit.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ilé ẹjọ́ tó ń gbọ́ ẹ̀sùn ìwà ọ̀daràn l'àgbáyé, ICC bẹ̀rẹ̀ ìwádìí lórí ìpànìyàn tó wáyé lásìkò ìwọ́de EndSARS 4 Bélú 2020 Ile ẹjọ agbaye to n gbọ ẹsun iwa ọdaran, ICC, ti sọ fun BBC pe oun ti gbe iwadii dide lori ohun to ṣẹlẹ lasiko iwọde #EndSARS ni Naijiria.
Ṣugbọn nisinsinyii, èmi OLUWA náà ni mo sì tún ń sọ pé, kò rí bẹ́ẹ̀ mọ́, nítorí pé àwọn tí wọ́n bá bu ọlá fún mi ni n óo máa bu ọlá fún, àwọn tí wọn kò bá kà mí sí, n kò ní ka àwọn náà sí.
Ganduje pe awọn darandaran si Kano Èèwọ̀!
Yala o ti pọn loju tabi ko tii pọn, ọpọlọpọ kii le mọ boya eyi to ti jade ṣi kan tabi o ti ni adidun.
Bi a ko ba gbagbe pe, awon omo ogun olote naa sekupa awon omo ogun ati awon agbe lasiko ikolu ohun ti o waye fojo meta nipinle naa lose ti o koja.
after ( prep ) ; lẹ ́ yìn , tẹ ̀ lé : tomorrow is the day after today .
OLUWA ní, “Bẹ́ẹ̀ gan-an ni n kò ní ṣàánú àwọn eniyan ilẹ̀ yìí mọ́.
Ó kó àwọn tabili òkúta mejeeji sinu àpótí ẹ̀rí náà, ó ti àwọn ọ̀pá àpótí náà bọ inú àwọn òrùka rẹ̀, ó sì fi ìdérí rẹ̀ dé e lórí.
Wọ́n mọ̀ pé nígbà tí wọ́n pa Stefanu, ẹlẹ́rìí rẹ, bí mo ti dúró nìyí, tí mò ń kan sáárá sí àwọn tí ó pa á tí mò ń ṣọ́ aṣọ wọn.
Oṣere ẹgbẹ rẹ, Adeniyi Johnson to pade lọdun 2012 lo fẹ.
Alawẹ ni Alaafin ko lee wa jẹ gaba lori awọn ọba Ekiti nitori Ekiti ko si labẹ isejọba Ọyọ ri, bẹẹ ni ko lee si labẹ Alaafin laelae.
Adamu ṣalaye fun Charles, akọroyin BBC pe: Ọmọ rẹ, ọdun mẹjọ lo sun lai si nkan to ṣe e, ki o to wa dii wi pe ko le e gbe apa gbe ẹsẹ ati apa rẹ, ki o to di wi pe wọn gbe e lọ si ile iwosan.
mi dun fun ogbon ati iriri rẹ.
òkú méjìlá jóná mọ inú mọ́ṣúárì Fásítì OAU Àwọn jàndùkú dáná sun Aṣáájú obìnrìn ẹgbẹ́ òṣèlú PDP mọlé ní Kogi Kìnìhún tí wọ́n mú l'Eko kìí ṣe ti orílẹ́èdè Nàíjíríà Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Lóṣù mẹ́ta sẹ́yìn, mò ń wa ọkọ̀ taasín, ṣùgbọ́n wọ́n sọ mí di afọ́jú lọ́san gangan' Bawo ní Aroke ṣe tún le hùwà ọdaran láti inú ọgbà Ẹwọn Ajọ EFCC sàlàyé pé ìwádìí fi han pé lòdi si òfin to gbe ọgbà ẹwọn ró o ní ànfani sí ẹ̀rọ ayelujara àti ẹrọ iléwọ nínú ọgbà ẹwọn to yẹ ti maa ṣẹwọn rẹ.
Wọn ya aworan (scan), iyẹn si fihan pe mi ko ni ile ọmọ tabi oju ara obinrin.
Wonyii ni bi awon Esi ifesewonse naa se lo: What a day in the #PL… pic.
, Duration 4,2617 Bélú 2020 Èyí tí a wò jùlọ 5:03 Fídíò, Omolola Arohunmolase Welder: Mo ti fí iṣẹ́ 'Welder' gbayì láwùjọ, tó mo fi tọ́ ọmọ yanjú, Duration 5,039 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 5:39 Fídíò, Akomolede ati Asa lori BBC: Olùkọ́ Kikelomo Ogunboye tan ìmọ́lẹ̀ sí ìwà olè ọ̀gá ọlọ́pàá Audu gẹ́gẹ́ bí àwòkọ́ṣe àsìkò yìí, Duration 5,398 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 4:11 Fídíò, Oba Adeyeye Ogunwusi: Ojú mi ti rí lọ́pọ̀ lọpọ̀, ọ̀pọ̀ èèyàn ni kò tilẹ̀ gbàgbọ́ pé mo lè jọba- Ooni, Duration 4,117 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 4:43 Fídíò, Promise Akinlade: ọmọ ọdún mọ́kànlá tó ń fi ìlù dárà bíi àgbàlagbà sọ̀rọ̀ nípa tálẹ́ǹtì rẹ̀, Duration 4,437 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 0:59 Gbọ́, Ìsẹ̀lẹ̀ jákèjádò orílẹ̀èdè àgbáyé láàárín ìṣẹ́jú kan, Duration 0,59wákàtí 5 sẹ́yìn 7:03 Fídíò, Olumuyiwa Bolade Adedeji Military Bruitality: Bí arákùnrin onípèníjà ara tí sọ́jà lù ṣe dé, Duration 7,035 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 4:45 Fídíò, Yoruba Films: Ẹ̀ẹ́ bẹ̀ mi kúrò láyé ni, mi ò lè kú - Fadeyi Oloro, Duration 4,4526 Èrèlè 2020 2:48 Fídíò, Esther Ajayi: Èmi náà ti borí ìṣòro rí ló ń mu mi ṣojú àánú, Duration 2,481 Ògún 2019 6:08 Fídíò, Adebola Ademilua: Àìrísẹ́ ṣè lẹ́yìn ìwé kíkà ló sọ mi dí ìyá onírú, mo dúpẹ́ tèmi, Duration 6,0827 Bélú 2020 2:36 Fídíò, Sotitobire: Ìdájọ́ òdòdò ló fẹsẹ̀ múlẹ̀ lórí ọ̀rọ̀ Pásítọ̀ Sotitobire - Agbẹjọ́rò fún ìjọba, Duration 2,367 Ọ̀wàrà 2020 BBC News, Yorùbá Ìdí tí ẹ fi le è nígbàagbọ́ nínú ìròyìn BBC Ìlànà Lílò Nípa BBC Òfin Àṣírí Cookies Kàn sí.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Naira Marley: Pásítọ̀ Omatsola tún kìlọ̀ fáwọn ọ̀dọ́ láti yé pe ara wọn ní Marlians 7 Sẹ́rẹ́ 2020 Gbajugbaja olorin takasufe, Afeez Fashola ti ọpọ eeyan mọ si Naira Marley, ti fesi si ọrọ Pasitọ Chris Omashola to pe ni ẹlẹmi Eṣu.
Oluwa wá sọ fún un pé, “Ẹ̀yin Farisi a máa fọ òde kọ́ọ̀bù ati àwo oúnjẹ, ṣugbọn inú yín kún fún ìwà ipá ati nǹkan burúkú!
ng Sun si oju ikansiraeni ìkíni káàbọ̀ ki o si tẹ ami afihan 'e-ID Card Status Portal' lati mọ ti kaadi rẹ ba ti wa nilẹ fún gbígba.
Isinmi naa maa n jẹ ki onikaluku fi ri aaye sami rẹ ni ọna ti o ba gbagbọ ninu rẹ ni.
N óo bá àwọn ọ̀tá yín jà; wọn yóo sì di ẹrú àwọn tí ń sìn wọ́n.
Ẹẹdẹgbẹjọ miliọnu araalu ati Sọja ẹgbẹta miliọnu lo ku ni Belarus lasiko ogun naa to fi mọ o fẹrẹẹ to iye gbogbo awọn ẹya Juu.
Ìfẹ́ dà bí ẹmu orí ọ̀pẹ ti ọkùnrin kan mu yó, tí ó bẹ̀rẹ̀ si pa á, tí ó sì sọ ọ́ di aṣiwèrè tí kò jẹ́ kí ó mọ èyí tí òun ṣe mọ́.
Nigba ti o n fesi, alaga egbe awon akoroyin ni Ipinle
Ọgbọ́n àrékérekè ní ìjọba ń dá lórí àfikún owó oṣù òṣìṣẹ́, a o sí ní gbà- NLC Ẹ̀kọ́ ńlá ni ọ̀nà tí Ghana fi paná ìdìtẹ̀gbàjọba tó yẹ kó wáyé níbẹ̀ Atiku gba ilé ejọ́ tó ga jùlọ, ó ní òun ló jáwé olúborí nínú ìbò ààrẹ Ọkùnrin kan kú si ìyárá ìtura Aarẹ ẹgbẹ TUC, Quadri Olaleye ṣalaye pe iwa ajẹbanu, awọn ologun to sọ ara wọn di oloṣelu, ija ẹlẹyemẹya ati ẹleṣinmẹsin wa lara awọn ohun to n gbogun ti idasoke Naijiria.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Àwọ̀tẹ́lẹ̀: Èwo lo ní ìfẹ́ sí nínú orísirísi kọ́mú yìí?
 lẹ ́ yìn ikú rẹ ̀ , Ọ ̀ rànmíyàn lò yẹ kí ó jẹ ọba ní ilé-ifẹ ̀ ṣùgbọ ́ n ó ti lọ sílùú àwọn ọmọ rẹ ̀ , eweka ni eìní ati aláàfin ni Ọ ̀ yọ ́ .
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ekiti Sack: Kí ló dé tí àwọn ìjọba ń yọ òṣìṣẹ́ bíi ẹní yọ jìgá ní gbogbo ìgbà?
Lati osu Kẹsan ọdun 2018, o le ni ẹgbẹrin eeyan to ti jalaisi lati ipasẹ arun Ẹyi ni orilẹede Madagascar nikan.
Ẹgbẹ Shiite tun sọ ninu atẹjade ti wọn fi sita pe, bi wọn ti fi El-Zakzaky ati iyawo rẹ mọle nile iṣẹ ọlọpaa ọtẹlẹmuyẹ lodi si ẹtọ ọmọniyan.
Onimọ naa sọ pe awọn iṣesi yii lo ti ṣe akotan gbogbo opo ẹsin musulumi.
loju pe orile-ede Naijiria wa leyin re ni digbi.
Bí ó ti wọ ilé Ọlọrun lọ ní àkókò Abiatari Olórí Alufaa, tí ó jẹ burẹdi tí ó wà lórí tabili níwájú Oluwa, tí kò yẹ kí ẹnikẹ́ni jẹ, àfi alufaa nìkan, tí ó tún fún àwọn tí ó wà pẹlu rẹ̀ jẹ?
"Gẹgẹ bi ọrọ rẹ, ""ẹnu mi ko gba ọrọ bayii bi ko ṣe lati ba baba daro."
Lose ti o koja ni ero amohun-maworan safihan Nyantakyi ti o n gba owo abetele ti o to ẹ̀gbẹ̀rún lona márùndínláàdọ́rin owo dola($65,000), lowo akoroyin to n sise labele fun aare orile-ede Ghana, Nana Akufo-Addo fun oju rere ajo ohun ti o tun fi mo awon osise ijoba miiran.
Wọn ni ahesọ lasan ni ọrọ tó n ja ranyinranyin nilẹ pe igbakeji alaga ẹgbe oṣelu APC naa ti jade laye nipasẹ ajakalẹ arun coronavrus.
Umar Yar'adua fi ori jin àwọn agbebọn náà, ó ní kí wọn jọ̀wọ́ ohun ijagun wọn, tó sì ń ṣàn owó iranwọ fún wọn.
'Títẹ àwọn afipábánilopọ̀ lọ́dàá kọ́ ni ọ̀nà àbáyọ sí ìwà ìfipábánilopọ̀' Ọpẹ́ o!
Mo ti rí i pé kò sí ohun tí ó lè pé tán,àfi òfin rẹ nìkan ni kò lópin.
6 246376 Orilẹede Zimbabwe 636 4.
Ìgbàlà ati ògo ati agbára ni ti Ọlọrun wa.
Awọn ti iṣẹlẹ naa tun ṣoju wọn sọ pe, awọn oṣisẹ eleto aabo ko le doju jọ awọn janduku ọhun.
Alábàárù ni mò ń ṣe lọ́jà Ketu àti Mile 12, kí ń tó bẹ̀rẹ̀ Fuji - Atawẹ́wẹ́ Ó tó gẹ́ẹ́!
onibara won ki won lee jegbadun ipe ati lilo ero ayelujara laisi iyọnu.
Kí igi ìdábùú tí ó wà ní ààrin gbùngbùn àkànpọ̀ igi náà gùn láti ẹ̀gbẹ́ kinni dé ẹ̀gbẹ́ keji àgọ́ náà.
Ile ẹjọ kotẹmilọrun lo yi idajọ ile ẹjọ kekere to da pipa Lee duro, danu.
ti o de Goma lojo Aiku, ni o lọ sile iwosan fun ayẹwo, nibi ti won ti rii pe ,
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Yinka Ayefele: Oṣù àwọn ìbẹ́ta mi kò pé ní kò jẹ́ kí n kọ́kọ́ kéde ìbí wọn Amoṣa ki ni Sẹnetọ Ademola Adeleke to jẹ oludije ẹgbẹ oṣelu PDP lasiko idibo naa gbọ eyi si, o ni wọn ko gbe ẹnu toun naa fun alagbafọ.
O ni ọdun 1982 gan an ni ijọbakọ ile iwosan sori ilẹ naa pẹlu erongba lati fi ilẹ to ku kọ ile iwosan nla lọjọ iwaju.
NLC pẹ̀lú ẹ̀bùn ọ̀dún tuntun fún Nàìjíríà Ìpàdé NLC àti ìjọ̀ba àpapọ̀ lórí owó osù tuntun forí ṣánpọ́n Ìdẹ̀ra dé l'Eko!
Keyamo lo soro yii pe awon kan n gbero lati da awon ile –ikabo ru, ki won si da
Ṣugbọn Ọlọrun tíí dáríjì ni ni Ọ́, olóore ọ̀fẹ́ ati aláàánú sì ni ọ́, o kì í tètè bínú, o sì kún fún ìfẹ́ tí kìí yẹ̀, nítorí náà o kò kọ̀ wọ́n sílẹ̀.
awon eniyan lati tubo fọwọsowọpọ , ni eyi ti won yoo se gbogun ti aarun iba.
Ohun ti mo kan sọ ni pe mo ni iriri ifipabanilopọ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Azeezat Shomuyiwa : Oyún oṣù méje ló wà nínú Azeezat, kí wọ́n tó f'òkúta fọ́ ọ lórí pa Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Azeezat Shomuyiwa : Oyún oṣù méje ló wà nínú Azeezat, kí wọ́n tó f'òkúta fọ́ ọ lórí pa 9 Òkùdu 2020 Lẹyin igbeyawo nilana Musulumi ti wọn n pe ni Nikkah, ireti Alfa Ridwan ati Iyawo rẹ Azeezat ni pe lẹyin oṣu mẹsan ki wọn wa ba wọn ṣe isọmọlorukọ, iyẹn 'suna'.
Ní ọjọ́ kan, Mose ń ṣọ́ agbo ẹran Jẹtiro, baba iyawo rẹ̀, tíí ṣe alufaa ìlú Midiani.
Nítorí pé mo gba ẹ̀há kò ní kí ń ṣọlẹ̀ tàbí ṣagbe- Ẹ̀lẹ́hàá Amina Afárá Third mainland gba ẹ̀gbọ́n Wo ohun tí Adájọ́ ṣe sí àṣùwọ̀n ìfowópamọ́sí Wòlíì Sotitobire Báwo ni ìlù gángan se bẹ̀rẹ̀?
Ohun to yẹ ko mọ nipa Hubert Ogunde: Ọjọ Kẹwaa, osu Keje, ọdun 1916, eyiun ọdun mejilelọgọrun (102) sẹyin ni Hubert Ogunde fi ori sọlẹ si ilu Ọ̀sọsà, nipinlẹ Ogun Jeremiah Deinbọ ati Eunice Owotusan Ogunde lo se ọkọ rẹ wa sile aye, Olusọagutan si ni baba rẹ.
Sibẹsibẹ, nítorí ti Dafidi, OLUWA Ọlọrun fún Abijamu ní ọmọkunrin kan tí ó gorí oyè lẹ́yìn rẹ̀, ní Jerusalẹmu, tí ó sì dáàbò bo Jerusalẹmu.
Kí ìjọba rẹ̀ ó lọ láti òkun dé òkun,ati láti odò ńlá títí dé òpin ayé.
bẹrẹ si n yan ibọn soke lera-lera , ni eyi ti won yin ibon si arakunrin naa ni
Ní àkókò yìí ẹ wá dìtẹ̀ sí i, ẹ ṣe ikú pa á.
Lara awọn eto to waye nibi ayẹyẹ naa ni orin idaraya, idije lọlọkanojọkan laarin awọn ibeji, yiyanfanda bi ologun, ifamiẹyẹdanilọla ati bẹẹbẹẹ lọ.
Nítori náà, wàhálà tó ṣẹlẹ̀ lówùrọ̀ yìí wáyé nítori pé àwọn afẹhónúhàn náà jẹ́ ẹbí àwọn aláìsàn ti àwọn aláṣẹ́ ilé ìwòsàn FMC kọ̀ láti tójú.
Sibẹsibẹ, ó wu OLUWA láti pa á lára,ó sì fi í sinu ìbànújẹ́,nígbà tí ó fi ara rẹ̀ rú ẹbọ ẹ̀ṣẹ̀;yóo fojú rí ọmọ rẹ̀,ọjọ́ rẹ̀ yóo sì gùn.
Ṣugbọn, ẹgbẹrun meji ati ọrinlelọọdunrun le maarun (2385) eeyan lo ti ri iwosan.
"ng/nin Tẹ ààyè tó ni àwọ ewé, níbi ti wọ́n kọ ""Verify and link your NIN Now"" si Tẹ nọ́mba rẹ àti gbogbo ǹkan tí wan ba bèrè síbẹ̀ Ilé iṣẹ́ tó n mójú tó ọ̀rọ̀ ìbáraẹnisọ̀rọ̀ àtí ọ̀rọ̀ orí ayélujára ti pàsẹ fún gbogbo àwọn ilé iṣk ibáraẹnisọ̀rọ̀ gbogbo láti wọ́gile ogún náírà tí wan yọ tí àwọn ará ìlú bá fk mọ nọ́mbà NIN wọ́n ni kíá."
Bí ẹnìkan bá mú nǹkan yín, ẹ má bèèrè rẹ̀ pada.
Gẹ́gẹ́ bí àṣẹ Solomoni ọba, wọ́n fọ́ òkúta ńláńlá, wọ́n sì gbẹ́ wọn fún mímọ ìpìlẹ̀ ilé OLUWA náà.
Dájúdájú n óo gbẹ̀san lára ẹnikẹ́ni tí ó bá paniyan, kì báà jẹ́ ẹranko ni ó paniyan tabi eniyan ni ó pa ẹlẹgbẹ́ rẹ̀, pípa ni a óo pa olúwarẹ̀.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Igboho, Ajimobi, Makinde àti àwọn ọlọ́pàá ṣe bẹbẹ kí n tó rí ìbejì mi gbà padà Adajọ Emmanuel Idowu kọ lati gba oniduro fun gbogbo wọn.
Èwo ninu wọn ni ó fetí sí ọ̀rọ̀ rẹ̀ tí ó sì gbà á gbọ́?
Ọlọ́run ló yàn mí ti Arsenal, mi ò lè fi wọ́n sílẹ̀ láéláé- Mama Arsenal yarí West Ham fi omi àbùkù wẹ Chelsea láwọlé sùn, Arsenal yìnbọn pa Norwich Mo jọ ọkùnrin pẹ̀lú iṣan, ìdí àti egungun líle, síbẹ̀ obìnrin ni mi - Àgbábọ́ọ́lù obìnrin tẹ́lẹ̀ Wo agbábọ́ọ̀lù Super Eagles Nàìjíríà àkọ́kọ́ tó lùgbàdì coronavirus Ọ̀rọ̀ǹpọ̀tọ̀niyùn, Aláàfin obìnrin àkọ́kọ́ rèé, tó ní nǹkan ọkùnrin Funke Akindele fún mi lówó tí mo fi gba ilé, kò ra ilé fún mi o - Ajirebi Aṣe ẹgbẹ agbabọọlu Sheffield n ṣẹṣẹ mu ẹyẹ bọ lapo ni, ni wọn ba tun gbayo kẹta sinu awọn Chelsea.
Rivers,  ti won yoo si tun kede
Olori ajọ WAEC ni ko bojumu rara ki awọn akẹkọọ maa wa orijo kiri lasiko idanwo, ohun itiju gbaa ni, idi si ree ti oun fi bọ sita lati tọpinpin bi idanwo naa se n lọ si.
Jameel ni gomina ipinle Nasarrawa,Umaru Tank ko kaare lati
Kì í tètè bínú, bẹ́ẹ̀ ni kì í ka ẹ̀ṣẹ̀ sí eniyan lọ́rùn.
Ṣáàjú ni àjọ nàá tí gbé ilẹ̀kùn àwọn iléeṣẹ́ nàá, Peace Standard, Emzor àti Bioraj, táwọn méjéèjì wà ní ìpínlẹ̀ Èkó àti Kwara tì pa fún ipa tí wọ́n kó lórí ìtànkálẹ̀ ògùn ikọ́ olómi tó ní èròjà codeine nínú, èyí tí àwọn ọ̀dọ́ Nàìjíríà ti sọ di egbòogi, tí wọ́n n lò ní ìlòkulò.
Nítorí Ọlọrun sọ ninu àkọsílẹ̀ pé, “Tèmi ni ẹ̀san, Èmi yóo sì gbẹ̀san.
Ó kó ọpọlọpọ iranṣẹ lẹ́yìn, ó sì di turari olóòórùn dídùn, pẹlu òkúta olówó iyebíye ati ọpọlọpọ wúrà ru ọpọlọpọ ràkúnmí; ó wá sí Jerusalẹmu.
Akonimoogba agba fun iko egbe Nasarawa Flickers, Zainab Suleiman, so pe, oun dupe lowo Olorun ati ipinle naa fun esi boolu ohun.
Yasin fikun pe, wọn ti gbe awọn eeyan to farapa naa lọ sile iwosan fun itọju.
Nígbà tí ó di ọjọ́ tíí àjọ̀dún yóo parí, tíí ṣe ọjọ́ tí ó ṣe pataki jùlọ, Jesu dìde dúró, ó kígbe pé, “Bí òùngbẹ bá ń gbẹ ẹnikẹ́ni, kí ó wá sọ́dọ̀ mi kí ó mu omi.
Lara awọn aseyọri rẹ bii gomina ni lila ọpọlọpọ opopona tuntun ati atunse awọn oju popo ti ko dara jakejado ipinlẹ Oyo eyi to to igba, Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ladoja Atunse ati bibu ẹwa kun ayika ipinlẹ Oyo, Kíkọ afara abẹyẹfo to wa ni Mokola nilu Ibadan, gbigba awọn ọdọ ti ko niṣẹ lọwọ bii osisẹ Yes-O, rira ọkọ pẹlu kẹkẹ Ajumọse ati bẹẹ bẹẹ lọ.
Ọ̀rọ̀ ẹkún, ati ọ̀rọ̀ ọ̀fọ̀, ati ègún ni wọ́n kọ sinu rẹ̀.
#Revolution Now: Ara ló ń ta ìjọba àpapọ lórí ìfèhọnú hàn ní Naijiria
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Say no to rape: Àwọn òṣèré tíátà Yorùbá pariwo síta lórí wàhálà ìfipábánilòpọ̀ Oludasilẹ ileewe naa fi kun ọrọ rẹ ni agọ ọlọpaa pe, akẹkọọbinrin naa sọ fun oun pe, olukọ ti wọn fi ẹsun kan, ni oun yoo fidirẹmi ninu idanwo WAEC, ti oun ba fi kọ ko ba a ni ibalopọ.
Paulu Sọ Bí Ó Ṣe Di Onigbagbọ.
Ohùn Bolarinwa tó jẹ́ àbúrò Sẹnatọ Dino Melaye rèé: Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fọ́nrán ohùn, Ẹ̀rù ń bá wá lóri ilera sẹnatọ Dino Melaye Bákàn náà ló tun sọ fún BBC yoruba pé, ẹgbọ́n òun ni àìsàn ikọ́ sémìí-semìí ( Asthma) àti pé, kò lè dúró pẹ́ nínú ilé tí wọn ti já iná rẹ, tí wọn sì tún ti gbogbo rẹ̀ pa.
Oríṣun àwòrán, AFP Ki o to di pe awọn oloogun orilẹede Sudan yọ Al-Bashir nipo, ọpọlọpọ ọmọ orilẹede naa lo ti ku ninu ifẹhonuhan ti wọn ti n ke si i wi pe ko fi ipo silẹ lati oṣu kejila ọdun 2018.
O da iwe iroyin Africann Pilot silẹ lọdun 1937, lẹyin naa lo tun da awọn iwe iroyin miran silẹ.
Ó ti pa èèyàn 172 ni Nàìjíríà - WHO Adolf Hitler gbé àpótí ìbò, aráàlú yàn án sípò gẹ́gẹ́ bíi Káńsílọ̀ A ó korò ojú sí Amotekun tó bá tẹ ẹ̀tọ́ aráàlú lójú mọ́lẹ̀ - DAWN tó ṣàgbékalẹ̀ Amotekun Oríṣun àwòrán, FACEBOOK Bayelsa Atundi ibo meji ni yoo waye si ẹkun idibo aarin gbungbun ati Iwọ Oorun ipinlẹ Bayelsa.
Ní ìrọ̀lẹ́ ọjọ́ kan, nígbà tí Dafidi jí lójú oorun, ó gun orí òrùlé ààfin rẹ̀.
Ọmọbìnrin ọdún 25 gún ọ̀rẹ́kùnrin rẹ̀ pa nítorí ó ní ko lọ ṣẹ́ oyún Gẹgẹ bi ohun ti ileeṣẹ ilera fi soju opo Twiter wọn, ''Naijiria n wa gbogbo imọ nipa itọju ati abẹrẹ ajesara lati koju arun yii'' Ileeṣẹ naa tun sọ pe awọn nifẹ si ibaṣepọ pẹlu Russia eyi ti yoo mu ajọsepo to gunrege wa.
Oríṣun àwòrán, @TheICIR Ọga agba tuntun fun fasiti Eko yii lo ti jẹ oniwadii agba lori kokoro arun HIV, to si tun jẹ alaga igbimọ to n ka ọwọja arun to n ran ko.
Ọ̀pọ̀ lo si n dáro Okwaraji titi di àsìkò yìí nítori o jẹ olókìkí to si mọ ere orí pápá náà gbá dáadaa.
A wá dàbí àwọn tí o kò jọba lórí wọn rí,àní, bí àwọn tí a kò fi orúkọ rẹ pè.
Amẹ́ríkà yarí pé àwọn agbégbọn tó jí akẹ́kọ̀ọ́ 344 gbọ́dọ̀ fojú winá òfin Ẹ̀ẹ̀kan láàrin ọjọ́ méjì là ń jẹun ní ìgbèkùn, ìyà jẹ wá - Akẹ́kọ̀ọ́ Kankara ṣàlàyé Sé Boko Haram ń pẹ̀ka kiri Nàíjíríà ní ìjínigbé ṣe burú báyìí?
Akojọpọ awọn akọṣẹmọṣẹ bii adari ere bọọlu, awọn agbabọọlu, awọn alabojuto ere bọọlu atawọn oniroyin lo yan awọn oludije marun un ti ile iṣẹ BBC yoo gbade fun.
Balaki sọ fún Balaamu pé, “Jẹ́ kí á lọ sí ibòmíràn tí o ti lè rí wọn.
Ilé ìjọsìn, mọ́sálásí àti ọkọ òfurufú ṣí, Ẹ wo àwọn ìlànà tuntun tí ìjọba là sílẹ̀ Ènìyàn 416 ló ti lùgbàdì àrùn Coronavirus ní Ọjọ́ Ajé ní Naijiria Gómínà Kogi pàṣẹ kóníléógbélé ní ìjọba ìbílẹ̀ kan ní Kogi Amọ, ileeṣẹ ọlọpaa ni ipinlẹ Edo ti fi panpẹ ọba mu awọn afurasi lori iṣẹlẹ naa.
Nígbà ìṣẹ̀lẹ̀ kan ní 2014, Debjani Bora, ẹlẹ́sẹ̀ ehoro ọmọ bíbíi orílẹ̀-èdèe India ti fi ara kááṣá rí.
Ajọ EFCC fikun pe adajọ tun faye gba oun lati gbẹsẹ le awọn ile kan to jẹ ti babalawo naa ati akoto owo ti wọn lawọn fura si pe o fi n ṣe gbajuẹ.
" won pe ara won ni kel tamasheq tabi kel tamajaq ( "" awon to unso tamasheq "" ) , "" imuhagh "" , "" imazaghan "" tabi "" imashaghen "" ( "" eniyan olominira "" ) , tabi "" kel tagelmust "" , i."
Àwọn ni wọ́n ń ṣe ètò àtikó oúnjẹ jọ ní agbègbè wọn, fún ìtọ́jú ọba ati gbogbo àwọn tí ń gbé ààfin ọba.
Opọlọpọ awọn eniyan ti kii ṣe iran Igbo ni iṣu ẹni lo ti ọwọ ẹni bọ epo ni ọrọ yii nitori ile kan naa ni gbogbo wọn ti wa ni ila oorun guusu Naijiria Wo àwọn eléré ìdárayá mẹ́ta tí àjọ FIFA ti fòfin dè títí ayé Fowler kò sí lábẹ́ ìwádìí kankan-Garba Sheu Ìjìyà ń bẹ fún àwọn ti adé ọ̀rọ̀ náà bá ṣí mọ́ lóri -Ọga àgbà FRSC Ambode ní kò sí gìrì, eré ọwọ́ lásán ni EFCC ń ṣe Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Nítorí èyí, kì í ṣe ẹni tí ń gbin nǹkan, tabi ẹni tí ń bomi rin ín ni ó ṣe pataki, bíkòṣe Ọlọrun tí ó ń mú un dàgbà.
    Bí a ti jẹun tán ni mo kó àwọn ohun ìkọ̀wé jáde tí mo bẹ̀rẹ̀ iṣẹ́, òun náà sì bẹ̀rẹ̀ ọ̀rọ̀ i sọ ó ni:
Ni ọjọ kẹwaa oṣu kẹfa ti ẹjọ naa waye kẹyin niwaju Onidajọ Oluṣẹgun Oduṣọla ni awọn ileeṣẹ Agbofinro DSS n ṣe alaye idi to fi jẹ awọn lo n ṣe iwadii ẹsun naa dipo awọn ọlọpaa to kọkọ bẹrẹ iwadii rẹ.
Gbogbo àwọn ọ̀rọ̀ yìí yóo ṣẹ nígbà tí ó bá yá.
Ohun ni asiko ti ọgbẹlẹ ba wa si opin.
fikun un oro re wipe, “Ko si ohun kan tabi keji to n fa awon
Oríṣun àwòrán, Adamu adamu/twitter Adamu Adamu Lati ibẹẹrẹ iṣejọba Aarẹ Muhammadu Buhari ni ọdun 2015 ni Arakunrin Adamu Adamu ti jẹ minisita fun eto ẹkọ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Oyo state: 615, nọ́mbà tuntun fún ìdáàbòbò àwọn èèyàn ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ̀ 30 Owewe 2019 Oríṣun àwòrán, @seyiamakinde Bi ẹ ba n gbọ ariwo Ẹfa, ookan, aarun, 615 ni ipinlẹ Ọyọ, kii ṣe nọmba tẹtẹ tita tabi ti baba ijẹbu o.
Láíyé òde òní ọ̀pọ̀lọpọ̀ ló ndá gbé, tàbí kí wọ́n pé ẹyọ méjì péré nínú ilé kan.
Nitori pe iye ti a ra pọ ju iye eniyan to wa si ipade.
"mo ṣi bọwọ fun Toyin ati ọgbọn ori to fi n ṣiṣẹ rẹ""."
Ọ̀rọ̀ ti yanjú dé ibì kan lórí owó àjẹmọ́nú àwọn Super Falcons Ọmọ ogun Nàìjíríà bẹ̀rẹ̀ lílo 'Drone' láti gbógun tàwọn ajínigbé ni Ondo àti Ekiti Jẹ́ kí a jọ sọ àǹfàní US fún Nàìjíríà -Osinbajo Ta ni olórí ogun Ethiopia, Saere Mekonnen to kú sínú ìdìtẹ̀-gbàjọba?
Audu Ogbeh ṣalaye ọrọ yii lasiko to n dahun ibeere niwaju igbimọ tẹẹkoto kan niile aṣofin apapọ.
Akala ni ohun ti o ku f'oun lati ṣe bayii ni lati rii pe oludije to kun oju oṣuwọn jade ninu ibo abẹle lati ṣoju ẹgbẹ oṣelu APC ninu ibo gomina ọdun 2023 to n bọ.
”Ko so eso rere pupoNigba ti Okechukwu n ba awon oniroyin soro leyin ipade naa, o so pe”o se mi laaanu pe ipade ti awon eniyan pataki  wa bi I  aare egbe Ohaneze oloye  John Nnia Nwodo, ojogbon Charles Soludo ati bee bee lo , wa ni won ko menuba anfaani ti Ohaneze yoo je nibi ipade ti yoo waye laarin ila oorun ati iwo oorun .
Awọn alaṣẹ ilẹ Naijiria ko ti i fidi ọrọ yi mulẹ.
Ọpọlọpọ awọn ileeṣẹ lo ti ko igba wọle lorilẹede Naijiria tabi ko igba wọn lọ si awọn orilẹede miran lnilẹ Afirika nitori idakureku ina manamana lorilẹede Naijiria.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ìdájọ́ ọmọ mi tó gbé àdó ìkú wọ bàálù le púpọ̀, ẹ bá mi wòó ṣe - Bàbá Mutallab Ọ̀dọ́mọdé Onímọ̀ ẹ̀rọ rèé tó ń ṣe bàálù, ọkọ̀, ilé àti ọkọ̀ ojú omi Wada la Dino mọ́lẹ̀ nínú ìbò abẹ́lé PDP fún ìpò gómìnà ní Kogi Ìjọba Nàìjíríà ti ránsẹ pé àsoju ijọba ni South Africa láti dari wálé Èèmọ̀ rèé o!
Ẹni tí nǹkan ọkunrin dà lára rẹ̀ yìí gbọdọ̀ fọ ọwọ́ rẹ̀, ẹnikẹ́ni tí ẹni náà bá fi ọwọ́ kàn, kí ó tó fọ ọwọ́ rẹ̀, olúwarẹ̀ gbọdọ̀ fọ aṣọ rẹ̀, kí ó sì wẹ̀ yóo jẹ́ aláìmọ́ títí di ìrọ̀lẹ́.
Ó bí ọmọbinrin kan tí orúkọ rẹ̀ ń jẹ́ Tamari.
Aṣọ Yorùbá kò pé, lai si Gèlè.
Wọ́n ti àwọn ẹ̀wọ̀n wúrà mejeeji náà bọ àwọn òrùka mejeeji tí wọ́n wà ní etí kinni keji ìgbàyà náà.
O ni o ku diẹ kaato bi Inec ti ṣe sun ibo naa siwaju o si ni o di dandan ki awọn wadi ọfintoto lẹyin ibo idi ti Inec ṣe sun ibo naa siwaju.
Ìdí nìyí tí mo fi mú un wá siwaju yín, pàápàá siwaju Agiripa aláyélúwà, kí n lè rí ohun tí n óo kọ nípa rẹ̀ lẹ́yìn tí a bá ti yẹ ọ̀rọ̀ náà wò.
Ohun ni aadọta Ọba Ilé Ifẹ̀.
"O ro pe Okikiola ti oun pẹlu rẹ ni gbolohun asọ ni ṣugbọn o ṣeni laanu pe ọtọ ni ẹni ti ibọn ba.
Ọ̀pá àṣẹ rẹ, ọ̀pá àṣẹ ẹ̀tọ́ ni.
Orọ awọn ọdaran Fulani darandaran, ọrọ awọn adigunjale, ọrọ awọn ajinigbe ni wọn jọ n wa ojutu sii.
Nígbà tí ilẹ̀ ọjọ́ kejì fi maa mọ́ gbogbo àwọn ti a jọ wà ti yípadà, wọ́n tóbi wọ́n sì sanra.
ogbeni Makama Danjuma ati ogbeni  Patrick
Ẹ máa ṣe ohun gbogbo létòlétò, ní ọ̀nà tí ó dára.
”Wọ́n dá a lóhùn pé, “Ọmọ Dafidi ni.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Diego Maradona: Àgbàọ̀jẹ̀ agbábọ́ọ̀lù Argentina ṣiṣẹ́ abẹ lórí ẹ̀jẹ̀ tó dì sí i lọ́pọlọ lẹ́yìn ọjọ́ ìbí ọgọ́ta ọdún 4 Bélú 2020 Oríṣun àwòrán, Getty Images Agbaọjẹ agbabọọlu orilẹede Argentina nigba kan ri, Diego Maradona ti ṣiṣẹ abẹ lori ọpọlọ rẹ, iṣẹ abẹ naa si kẹsẹ jari.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Blind DJ: Etu Omotayo kò ríran àmọ́ ó le to irinṣẹ́ eléré pọ̀ láti kọrin láì sí ìrànwọ́ Ẹ jọwọ, ẹ tun oju opo iroyin yi yẹwo, ki ẹ lee ri ẹkunrẹrẹ iroyin ọtun laipẹ.
OLUWA bá fi wọ́n lé Jabini ọba Kenaani, tí ó jọba ní Hasori lọ́wọ́; Sisera, tí ń gbé Haroṣeti-ha-goimu ni olórí ogun rẹ̀.
Àwọn ọ̀dọ́langba náà gbé kẹ̀kẹ́ wọn sí ipò pàtàkì.
Iru awọn iroyin ti ẹ le nifẹ si: Ọna wo ni Wenger ati Mugabe gba jọra?
Sùgbọ́n, ààrẹ Soludẹrọ̀ sọ pé, lóòtọ́ ni sùgbọ́n àwọn jọ fi ọwọ́ sọwọ́pọ̀ ni ti àwọn fi ri ọmọkùnrin náà mú.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ètò ìsìnkú Abba Kyari tako ìlànà ìjìnàsíraẹni lórí ààrùn covid-19- Àwọn ọmọ Nàìjíríà yarí Nigba tó ń ṣàlàyé ìdí tí wọn ṣe kó àwọn ọkọ wọn kúrò ní gareji gbogbo, igbakeji akọ̀wé ẹgbẹ́ awakọ NURTW ni wọn ń bá àwọn ọkọ wa jẹ, ohun tó kú ní ká kò dúkìá wá kúrò nibẹ, a sì ti sá ipa wá kí gomina leè gbé ẹsẹ kúrò lórí òfin ti wọn si de ẹgbẹ́ wá, tí aarẹ ẹgbẹ́ lapapọ gan tí wá rí gomina bíi ìgbà méjọ àmọ́ gomina kan ń tàn ni""."
Àwọn afọ́jú ati arọ yóo wà láàrin wọn,ati aboyún ati àwọn tí wọn ń rọbí lọ́wọ́.
Dorathy Oríṣun àwòrán, BIG BROTHER NAIJA Dorathy, to jẹ gbaju-gbaja lori eto naa, ti ọpọ si sọ pe o konimọra, ti jẹ ẹbun owo to to miliọnu mẹrin Naira, N3,926,000.
Nítorí ó ti di ọdún keji tí ìyàn yìí ti bẹ̀rẹ̀ ní ilẹ̀ yìí, ó sì ku ọdún marun-un gbáko tí kò fi ní sí ìfúrúgbìn tabi ìkórè.
Ṣugbọn nítorí àwọn àyànfẹ́, Ọlọrun yóo dín àwọn ọjọ́ náà kù.
Ẹ wá di àpẹẹrẹ fún gbogbo àwọn onigbagbọ tí ó wà ní Masedonia ati Akaya.
Ọmowé Olugbenga ni ''bi èèyàn bá ní pé òun yóò dúró títí tí kòkòrò náà bá wọ inú okò tán kí òun tó ná owó sí ìtànkálẹ̀ rẹ̀, ẹpa kò ní boro mọ.
Aare Buhari si wa ni Maiduguri,
Ikede yi la gbo pe o waye lọjọru nibi ipade awọn alẹnulọrọ ẹkun arin gbungbun ipinlẹ Oyo ni papa isere Durbar ni Oyo.
” Mo rí ẹṣin dúdú kan.
Ni bi a ṣe n sọrọ yii, o ti le ni miliọnu mẹta eeyan to ti ko aarun yii lagbaye.
- Aráàlú ń bèèrè Ẹ fura, làásìgbò le wáyé ní ìjọba ìbílẹ̀ mẹ́fà yìí lásìkò ìbò gómìnà Ondo - YIAGA Wo ìṣẹ̀lẹ̀ márùn-ún tí kò bá pín Nàíjíríà sí yẹ́lẹ-yẹ̀lẹ Bọ́ síta láti ṣe ìwọ́de mọ́ ìjọba Nàìjíríà lónìí, ko rugi oyin - Iléeṣẹ́ ọlọ́pàá Ẹ̀yin ọlọ́pàá 10,000 tí ọ̀gá ọlọ́pàá gbà ṣíṣẹ́ ní 2019, ẹ padà sílé - Iléẹjọ́ pàṣẹ Nibi ipade ori ayelujara ọhun, ni wọn ti pe gomina tẹlẹ fun ile ifowopamọ apapọ Naijiria naa, lati wa sọrọ lori ọrọ ija ẹlẹyamẹya ati ẹlẹsin to n fojoojumọ peleke si ni Naijiria.
Awọn omi ati ounjẹ ti ko mọ, pẹlu ayika ti o kun fun ẹgbin kun ara awọn ohun ti wọn ni o n ṣokunfa ọwọja aarun onigbameji.
Mo pọ́n ọn fún odidi ọjọ́ kan, ẹnu rẹ̀ sì mú dáradára.
” Àwọn ọkunrin náà bá lọ, 
"Fuji (Barry Black, 1998) ""Millennium Stanza"" (Fuji Chambers, 2000) ""Controversy"" (2005) ' REALITY ' ( 2008)."
Ọdun 1940 ni wọn bi Bamidele silu Ikere Ekiti, o kawe, o gboye rẹpẹtẹ ni Naijiria ati loke okun, ko to dara pọ mọ eto iselu.
Minisita fun eto irinna ofurufu nigba kan ri, Femi Fani-Kayode ni ọrọ Kumuyi yii jẹ ibanujẹ fun awọn akọni to ti ja fun ẹsin Kristẹni ni atijọ.
ÒGÚN: Ògún (do mi) ni orukọ ti wọn fun orisa kan nilẹ Yoruba.
"Ọpọ ṣẹṣẹ gbagbọ nipa imọsilara rẹ pẹlu ajọṣepọ akọ si akọ ati abo si abo nigba ti o kigbe pé "" Go Gays"" - Akọ si akọ; abo si abo, ẹ tẹsiwaju."
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ẹ jẹ́ ká dá ìbọn kọjá, tó bá jẹ́ pé Oluwo kò fìyà jẹ́ mí - Agbowu Nǹkan yan, kò sí àmì ìfẹ́ mọ́!
Labẹ́ asia ẹgbẹ́ òṣèlú National Party of Nigeria, NPN, táwọn èèyàn tún mọ si ẹgbẹ́ Onílé ni Omololu Olunlọyọ fi dije dupo wọle lati tukọ ipinlẹ Oyo.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Oluwo ti Iwo: N kò ni nkan kan sọ lórí fídíò to gba ayélujára kan pé mo ń we igbó, ẹ mú ẹnu kúrò nibẹ 20 Ẹrẹ̀nà 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 9 Èbibi 2020 Oríṣun àwòrán, oluwo of iwo Oluwo tilu Iwo, Oba Abdul Rasheed Adewale Akanbi, Telu Kínní, tí kéde pé ẹẹmẹta laarin ọ̀sẹ̀ kan ni òun ń fún àwọn ará ìlú Iwo tí ebi ń pá ni oúnjẹ èyí tó bẹ̀rẹ̀ ni ọdún mẹrin sẹ́yìn.
Wọ́n ń kọ́ àwọn eniyan ní àṣà tí kò tọ́ fún wa láti gbà tabi láti ṣe nítorí ará Romu ni wá.
Bakan naa arẹmọ yii ni ifẹẹ ọkọ pupọ to si ti n ṣe katakara ọkọ lati ọdun 1990.
Sin òkú aya rẹ síbikíbi tí ó bá wù ọ́ jùlọ ninu àwọn itẹ́ òkú wa, kò sí ẹnikẹ́ni ninu wa tí kò ní fún ọ ní itẹ́ òkú rẹ̀, tabi tí yóo dí ọ lọ́wọ́, pé kí o má ṣe ohun tí o fẹ́ ṣe.
 o gbà pé nǹkan tí ó bá ṣẹlẹ ̀ ní ẹgbẹ ̀ rún méjì ọdún kan ni yóò tún ṣẹlẹ ̀ ní ẹgbẹrún méjì ọdún tí ó bá tún tẹ ̀ lé é .
A kò tíì lè sọ pé ọmọ Ọba tuntun ni yóò jẹ Ooni lọ́jọ́ iwájú - Elebuibọn Ọjọ kejidinlogun, oṣu kọkanla, ọdun 2020 ni Ooni Ile Ife, Adeyeye Enitan Ogunwusi, kede lori ayelujara pe Olori oun, Naomi Ogunwusi, ti bi ọmọ ọmọkunrin tuntun.
Nígbà tó yá a kúkú dé iwájú ilé gígá roro náà.
"'Àlàyé rèé lórí ìdí ti mo fi na ọmọ òrukàn, tí mo sì tì í mọ́ ilé ajá' Ọdẹ ìbílẹ̀, OPC àti agbófinró ń pèèlò tí yóò se ọbẹ̀ ààbò jinná nílẹ̀ Yorùbá Ariwo ""Allahu Akbar"" kò tọ́ sawọn Agbébọn àti Boko Haram - Buhari Facebook fi kọ́kọ́rọ́ ti àwọn ojú òpó ayédèrú ìròyìn léde Yorùbá àti Igbo Ọjọgbọn naa wa rọ ijọba apapọ lati mojuto awọn kudiẹkudiẹ to wa ni ileesẹ to n samojuto ọgba ẹwọn nilẹ wa, ki ayipada ti ijọba n se lori ileesẹ naa lee yọri si rere."
“Ìgbà mẹta ni o níláti máa ṣe àjọ̀dún fún mi ní ọdọọdún.
Kò pẹ́ sí àsìkò yìí ni àtẹ̀jáde míràn tún jẹ̀yọ láti ọ̀dọ̀ àwọn ẹgbẹ́ YWC pé kò ṣeeṣe kí ènìyàn mẹ́rin yọ ààré YWC kúrò lẹ́gbẹ́.
Ṣugbọn èmi a máa fi ìfẹ́ mi, tí kì í yẹ̀, hàn sí ẹgbẹẹgbẹrun àwọn tí wọ́n fẹ́ràn mi, tí wọ́n sì ń tẹ̀lé òfin mi.
Iye àwọn ọmọ àwọn aṣọ́nà:àwọn ọmọ Ṣalumu ati àwọn ọmọ Ateri, àwọn ọmọ Talimoni ati àwọn ọmọ Akubu; àwọn ọmọ Hatita ati àwọn ọmọ Ṣobai jẹ́ mọkandínlogoje (139)
Ekinni gbé iyawo, láìpẹ́ ó kú.
ile akede Naijiria (VON) ti olu-ilu won  gunlẹ si Abuja.
Ìjòyè náà bẹ̀ ẹ́ pé, “Alàgbà, tètè wá kí ọmọ mi tó kú.
” Inú ọba dùn láti rán mi lọ, èmi náà sì dá ìgbà fún un.
O jọ bi ẹni pe o ti rẹ wọn.
O fi àwọn oniṣẹ ọwọ́ lọkan balẹ pe gbogbo wọn loun maa gbe iṣẹ àgbàṣe fun lati tun gbogbo ọna Awolowọ atijọ ṣe.
Idi ni pe bi ọpọ eeyan ṣe n pariwo pe ilu le, ko si owo lode lasiko Coronavirus yii, ti ọpọ awọn oṣere tiata ko si ri iṣẹ ṣe, eyi ko kan Aigbe nitori o ṣẹṣẹ ra ọkọ ayọkẹlẹ tuntun kan ni.
NCDC loju opo wọn sọ pe eeyan 896 lo ti baarun naa lọ.
Olatunbosun fikun pe, awọn yoo se ipade lati se ayẹwo ohun to wa nilẹ, ki awọn to le e sọ pe awọn yoo san gbedeke owo osu osisẹ ni ipinlẹ Oyo.
Agbẹnusọ fun aarẹ, Garba Shehu salaye loju opo Twitter rẹ pe ita ẹnu ibode ile aarẹ gan ni ọrọ yii ti ṣẹlẹ.
Bakan naa ni Fada Ejike Mbaka to ti ijọ Adoration Ministry ti ni iyipada yoo deba ijọba Naijiria ni ipinlẹ ati ni ijọba apapọ.
EFCC gbé ọmọ ilẹ̀ Britain sẹ́wọ̀n lórí ẹ̀sùn ìkówójẹ
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Pásítọ̀ Bakare kéde orúkọ àwọn ọ̀tá tó ń da Nàìjíríà láàmú 6 Sẹ́rẹ́ 2020 Oríṣun àwòrán, Tunde Bakare/twitter Pasitọ ijọ Latter Rain Assembly to tun ti figba kan ri du ipo igbakeji aarẹ lorilẹ-ede Naijiria, Tunde Bakare ti pariwo sita pe ọta mọkanla ni orilẹ-ede Naijiria ni.
Má jẹ́ kí nǹkan burúkú borí rẹ, ṣugbọn fi ohun rere ṣẹgun nǹkan burúkú.
Nígbà tí wọ́n jẹun tan, wolii àgbàlagbà yìí di kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ kan ní gàárì fún wolii ará Juda.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Lady Peller: Ọjọ́ ni ọjọ́ tí idán yíwọ́ fún ọkọ mi lẹ́yìn tó gé mi sí méjì, mo kú tán 14 Bélú 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 15 Bélú 2020 Alhaji Silifat Peller jẹ ọ̀kan lára àwọn ìyàwó ìlúmọọka Alhaji Moshood Abiola Peller, ti gbogbo ènìyàn mọ̀ sí prof Peller.
Akpan sọ fun awọn ọlọpaa pe Bright lo paṣẹ pe ki wọn o pa wọn.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Risikat Moromoke Azeez: Inú èmí àti Òbí mi dùn nígbà ti Risi bí ọmọ olójú búlù- Wasiu ''Lọjọbọ ọṣẹ to kọja ni a bẹrẹ ikọṣẹ yi ti a o si pari lọṣẹ to n bọ.
Dájúdájú, ìwà ìrẹ́jẹ a máa mú kí ọlọ́gbọ́n eniyan dàbí òmùgọ̀, àbẹ̀tẹ́lẹ̀ a sì máa ra eniyan níyè.
Nigba miran, awọn agbalagba ilu tabi ẹbi le da si iru ọrọ bẹ l, ki wọn o si parọwa fun obinrin naa.
Ọpọlọpọ eniyan ń tọ̀ ọ́ lẹ́yìn láti Galili ati Ìlú Mẹ́wàá ati Jerusalẹmu ati Judia, ati láti òdìkejì Jọdani.
Mo si le ro pe ọrọ rẹ jọju botilẹjẹ wi pe mi o mọ ibi to ti wa.
Abija lé Jeroboamu, ó sì gba ìlú Bẹtẹli, ati Jeṣana, ati Efuroni ati àwọn ìletò tí ó yí wọn ká lọ́wọ́ rẹ̀.
Bí ẹnìkan bá fọ́ ọ̀kan ninu ẹyin yín, ejò paramọ́lẹ̀ ni yóo jáde sí i.
Obinrin ti ọkọ rẹ̀ bá kú wọn yio fi jogún gẹ́gẹ́ bi iyàwó fún ọmọ ọkọ ọkùnrin tàbi ẹbi ọkọ ọkùnrin.
" Ile asofin Amẹrika wa n rọ ijọba Naijiria lati ri daju pe o bọwọ fun ẹtọ ọmọniyan gẹgẹ bo se wa ninu ofin ilẹ wọn fun araalu kọọkan, ki wọn si gbe igbesẹ lati di alaafo to wa laarin wọn ati awọn akọroyin, awọn ọmọ ẹgbẹ oselu alatako, atawọn ọmọ ẹgbẹ ajafẹtọẹni.
Ki a ma deena pẹnu rara, diẹ re lara awọn iṣẹlẹ to jẹyọ nigbesi aye awọn oṣere tiata Yoruba loṣu yii ree.
Newcastle run Manchester United mọ́lẹ̀ jégéjégé Ẹ lọ sìmẹ̀dọ, ẹ jẹ́ ki a kóju mọ iṣẹ́ ìlú- Agbẹnusọ APC Ewé súnko!
Kíyèsíi, ẹnikẹ́ni tí ó bá ní ìyè ayérayé ni ọlọ́rọ̀.
5 tirilionu lodun 2017, iye yii je ohun iyalenu ninu itan orile ede Naijiria.
 Àwọn bí i mílíọ ̀ nù ni wọ ́ n ń lo èdè yìí gẹ ́ gẹ ́ bí èdè méjì .
Ọwọ awọn ọmọogun to n saayan eto abo 'Operation Ayem Akpatuma' tẹ awọn afurasi naa nileto Tse-Tigir ati Tse-Ndugh.
O mọ ilé gíga fún ara rẹ ní gbogbo gbàgede, o tẹ́ ìtẹ́ gíga fún ara rẹ ní ìta gbangba.
Àwọn ọmọ bàbá méjì, tí wọn jẹ́ ọkùnrin àti obìnrin, ló jogún ilé náà.
Obinrin náà ní, “Bẹ́ẹ̀ ni, Oluwa.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, World Diabetes Day: Ọdún kọkandinlogun ti mo ti wà lẹ́nu itọ ṣúgà nìyí Dickson jẹ ọmọ ọdun mẹtadinlogoji agbabọọlu agba to ti fi ẹgbẹ AlK Solna silẹ naa ni oun yoo tun ẹjọ naa gbe lọ sile ẹjọ to ga julọ.
Wọn gbe oṣiṣẹ to farapa naa lọ si ile-iwosan to sunmọ ju lọ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Victor Agunbiade ni ojú àlá ni Ọlọrun ti yan iṣẹ́ ọmọ ogun ojú omi fún òun ní America Ṣugbọn ibeere ọpọ eeyan lẹyin ogun Agbekoya naa ni pe, ṣe ominira wa de fun awọn agbẹ naa titi di akoko ta wa yii abi wọn kan fi ẹmi ọpọ eeyan sofo lasan?
ọdun oro jẹ ọkan lara ọdun iṣẹṣẹ ilẹ Yoruba Oríṣun àwòrán, EPA Àkọlé àwòrán, Diẹ lara awọn oluranlọwọ ti wọn de si Floriana ni Malta lasiko ti awọn ọmọ ogun ilẹ Italy n sin wọn lọ.
 o si tun je alase ati oludari yinka folawiyo group .
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Mo ń ṣa ike jọ láti san owó ilé iwé ọmọ mẹ́ta' Ehuriah sọrọ lori ifarada ki idagbasoke le de ba Naijiria lasiko iṣejọba aarẹ Buhari tuntun yii.
Alimọṣọ keji ninu Ile-Igbimọ Aṣofin naa bẹnu atẹ lu ikọlu naa ati pe o
Minisita to n ri si oro ile okere, Geoffrey Onyeama, lo sagbekale iwe iyansise tuntun naa fun asoju tuntun ohun.
Baba ọkọ ni yoo fi iyawo fun ọkọ Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, O ṣeeṣe ki orukọ ọkọ iyawo ati iyawo rẹ o yi pada lẹyin igbeyawo yii Bẹẹni, ẹ maa jẹ ko ya yin lẹnu pe baba ọkọ ni yoo fi iyawo fun ọmọ rẹ dipo baba iyawo.
Ó wò yíká, ó sì rí ìṣù àkàrà kan, ati ìkòkò omi kan lẹ́bàá ìgbèrí rẹ̀.
Iṣelẹ yii ti mu ki gomina ipinlẹ naa, AbdulRahman AbdulRazaq kede ọfọ ọjọ meje lati fi ṣedaro oloogbe ọhun.
O óo wà nílẹ̀ láàrin àwọn aláìkọlà, pẹlu àwọn tí a fi idà pa.
Ó farati ilé rẹ̀,ṣugbọn kò le gbà á dúró.
2 40165 Orilẹede Syria 476 2.
Èmi ṣì ni Gómìnà ìpínlẹ̀ Ọṣun-Oyetọla Ilé ẹjọ́ kéde Ademọla Adeleke gẹ́gẹ́ bíi gómìnà ìpínlẹ̀ Ọṣun Ademọla Adeleke, Fayoṣe, Atiku sọ̀rọ̀ lórí ìdájọ́ ilé ẹjọ́ Ilé ẹjọ́ yọ ìbò 2,029 nínú ìbò APC, 1,246 nínú ibò PDP l'Ọṣun Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí 3 sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 2:23 Fídíò, Water Generator: Ó leè ṣiṣẹ fún wákàtí mẹfà, kó tó sinmi, Duration 2,2310 Òkùdu 2020 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
Kíni ìjọba ń ṣe lórí ewu ẹkọ Almajiri àti covid 19 ní Nàìjíríà?
Àwa tí a gbàgbọ́ ni a wọ inú ìsinmi náà.
: Ìdí tí gbígbé ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́ tì pa nítorí àrùn COVID-19 ṣe ṣòro fún mi-Seyi Makinde Oríṣun àwòrán, Seyi makinde Gomina Makinde ti ni wiwa ọna lati mu idọgba ba ilera ara ati ilera ọrọ aje ipinlẹ Ọyọ atawọn eeyan rẹ lo ṣokunfa bi oun ko ṣe paṣẹ konile-o-gbele ọlọjọyipo ni ipinlẹ Ọyọ latigba ti ajakalẹ arun Coronavirus ti bẹ silẹ nibẹ.
Ó gba ìgboyà láti fẹ́ràn ìlú ẹni pàápàá lẹ́yìn ìjìyà nítorí wípé a sọ̀rọ̀ síta.
Ẹ ̀ mí fúnra wọn gbàgbọ ́ láti gbé nínú igi ẹ ̀ yà òwú sílíìkì .
Nígbà tí aya Jeroboamu dé, ó ṣe bí ẹni pé ẹlòmíràn ni.
Ilana lilọ wọn naa lo sọ pe yoo nira pupọ - amọ ile asofin apapọ ilẹ Gẹẹsi lo si wa lẹnu isinmi lọwọ lọwọ bayii.
Lẹ́yìn náà yóo mú hisopu, yóo tì í bọ omi náà, yóo sì fi wọ́n àgọ́ náà ati àwọn ohun èlò tí wọ́n wà ninu rẹ̀ ati àwọn eniyan tí wọ́n wà ninu rẹ̀.
Ó kó gbogbo àwọn àgbààgbà ìlú náà, ó sì mú ẹ̀gún ọ̀gàn ati òṣùṣú, ó fi kọ́ wọn lọ́gbọ́n.
Arẹwa oṣere naa, to kẹkọọ gboye akọkọ ninu ede Gẹẹsi sọ pe, sababi ni bi oun se di osere tiata.
oloro , paapaa julọ lasiko Umrah ati  Hajj odun 2019 yii.
Erica gungi rékọjá ewé pẹ̀lú ìwà tó hù lálẹ́ ọjọ Satide - Ọmọ Nàíjíríà faraya Ọlọ́pàá wú òkú obìrin tó ń múra ìgbéyàwó lọ́wọ́ tí 'gate-man' rẹ̀ ṣekúpa A fẹ́ yọ ààrẹ ẹgbẹ́ Yorùbá YCE nípò torí àwọn ìwà tí kò bójúmu"" Wo àànfàní ‘Masturbation’, fífún ara rẹ̀ ní adùn ìbálòpọ̀ Ṣaaju ni ija kan ti kọkọ waye larin Erica ati Laycon, nibi ti Erica ti sọ awọn ọrọ kobakungbe kan."
O si bẹrẹ si ni fi nkan lu mi ni ori.
ẹ kò gbọdọ̀ dá wolii tabi alálàá náà lóhùn, nítorí pé OLUWA Ọlọrun yín ń dán yín wò ni, láti mọ̀ bóyá ẹ fẹ́ràn òun tọkàntọkàn.
O ni ṣiṣe ipade pẹlu ọbasanjọ se koko fun awọn lati gba imọran ati itọni lori imurasilẹ PDP fun idibo 2019.
Ise Akanse ti Abuja ati agbegbe eMinista fun Abuja ati agbegbe re, Mohammed Bello so fun awon akoroyin pe igbimo naa fowosi rira kemikaa fun fifo opa omi ati sise ona papako ofurufu nilu Abuja.
Oríṣun àwòrán, @Oladapo Awọn iwe miran ti Lawuyi Ogunniran kọ ni: Ìbàdàn Mesì Ọ̀gọ̀.
A mo iko agbaboolu Manchester United seyin gege bi, iko ti o nife lati maa gba ife eye lopolopo, o dami loju pe, lai pe a tun gba ife-eye.
A óo sì ṣe é fún ọ.
"Marley gbajugbaja fun orin rẹ, to n milẹ titi nigboro ""Issa Goal""."
Adele ọwọ ọtun ni Ọmọkharo, idije ife ẹyẹ ilẹ Afirika, Maroc 88 ni o si ti gba inagijẹ yii ninu ifẹsẹwọnsẹ laarin orilẹ-ede wa Naijiria ati orilẹ-ede Algeria.
Bakan naa lo fi kun ọrọ rẹ pe oun ti n gba itọju to peye, nibi ti oun ti ya ara oun sọtọ.
Ó ń gbọ́ gbogbo ohun tí àwọn ọmọ rẹ̀ ń ṣe sí àwọn ọmọ Israẹli, ati bí wọ́n ti ṣe ń bá àwọn obinrin tí wọn ń ṣiṣẹ́ ní ẹnu ọ̀nà àgọ́ àjọ lòpọ̀.
Ṣugbọn ninu esi rẹ si atẹjade ọhun, Ọjọgbọn Ogundipe sọ pe Ọgbẹni Azeez lo mọ ibi ti o ti ri iroyin to n gbe kaakiri.
Igi yìí hù, ó dàbí àjàrà tí kò ga, ṣugbọn tí ó tàn kálẹ̀.
Igbagbọ wọn ni pe obinrin ko lee dabira lawujọ bii awọn ọkunrin, wọn ro pe ọkunrin nikan lo lee jẹ eeyan takuntakun, ti yoo si sọ orukọ wọn di manigbagbe lọjọ ọla.
Bakan naa ni wọn n jiyin isẹ iriju wọn laarin ara wọn, ti wsn si n se ojuse to yẹ, eyi to n paroko fun ijọba nipa bawọn ọdọ ilẹ yii ti dangajia to.
Nígbà tí ó di alẹ́ kẹrinla tí afẹ́fẹ́ ti ń ti ọkọ̀ wa kiri ninu òkun Adiria, àwọn atukọ̀ fura ní òru pé a kò jìnnà sí ilẹ̀.
Ni ọjọ kẹrindinlogun, oṣu kẹjọ ọdun 1942 ni wọn bi Oloogbe Jubril Martins Kuye ki Aarẹ ana, Goodluck Jonathan to yan an gẹgẹ bii minisita lọjọ kẹfa, oṣu kẹrin, ọdun 2010.
Àkọlé àwòrán, Awọn eeyan adugbo naa ni owo lawọn janduku naa n ja si Ninu ọrọ tawọn olugbe adugbo naa ba BBC News Yoruba sọ, ija lori owo lo ṣokunfa rogbodiyan ọhun.
Gẹ́gẹ́ bi àtẹjáde ti Nwaboachi fi síta ṣe sọ, ó ní kí mínísítà kọ́kọ́ sàlàyé àwọn owó bílíọ̀nù to ná nínàkúnà náà lásìkò ti àwọ ìgbìmọ̀ IMC san fún ara wọ́n pẹlu ibuwọ́lù Godswill Akpabio.
Itapasi iwa eto-omoniyanAyipada yii waye nipa esun ti awon omo orile ede Niajiria fi n kan eka yii “nipa titapa si eto omoniyan.
Fi ààmì sórí 'Bobajiroro Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
2bn fún Obanikoro Sọ àsọtẹ́lẹ̀ orílẹ̀èdè tí yóò borí ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ t'òní Presidential Election Tribunal: Láyé, a ò lè gba ẹ̀bẹ̀ PDP láti yẹ ojú òpó ayélujára INEC wò Ta ni awàdà rẹ̀ wú u yín lórí jù ní Yollywood?
Baba-onírùngbọ̀n-yẹ́úkẹ́ ṣe wọ́n ní àlejò púpọ̀ lálẹ́ ọjọ́ náà, gbogbo wọn ló sì jẹun tí wọn yó bámúbámú.
pe ilekun ile -ise oun si sile nigbakuugba ti won ba nilo alaye lati to won
Ẹ̀ṣùn tó fi kàn wọ́n dá lórí ipa ti wọ́n kó nínú ìwọ́de ìfẹ̀hónúhàn #Endsars tó wáye ni oṣù tó kọjá.
Aarẹ orilẹede Amerika, Donald Trump ti sọ wi pe oun yoo fopin si bi awọn asatipo se n bimọ si ilẹ Amerika lati gba iwe igbele.
OLUWA wà ní ọwọ́ ọ̀tún rẹ,yóo rún àwọn ọba wómúwómú ní ọjọ́ ibinu rẹ̀.
Ipinlẹ Eko ati Ekiti gba lati san 30,000 owo osu osisẹ Amọ ijọba ipinlẹ Eko ati Ekiti ti sọ wi pe, awọn yoo san gbedeke owo osu osisẹ.
Jakọbu dá a lóhùn pé, “Ọjọ́ orí mi jẹ́ aadoje (130) ọdún.
Lorilẹede Naijiria, gẹgẹ bi iroyin lati ọdọ ẹgbẹ awọn dokita iṣegun lorilẹede Naijiria, NMA, ọtalelugba o le mẹrin awọn dokita iṣegun oyinbo lo ti fara kan awọn eeyan to laarun coronavirus lorilẹede Naijiria ninu eyi ti ogun dokita ti ni arun yii.
Ìjọba àpapọ̀ fẹ́ f'òfin dé irina ọkọ̀ akero jakejado Nàìjíríà Coronavirus wọ ìpínlẹ̀ Rivers, èèyàn méjì míì tún ni l'Eko, ó di èèyàn 51 tó níi ní Nàìjíríà Ìjọba ìpínlẹ̀ Kano tilẹ̀kùn ibodè rẹ̀ nítorí aàrùn coronavirus Awọn ọmọ orileede mìíràn tí wọn mú fún ẹsun ṣiṣe owó ẹrú àti àwọn tí wọn ń ṣe fayawo náà wá lára àwọn tí wọn yóò gbà itusile ti wọn yóò sì dá olúkúlùkù padà sí ìlú abinibi wọn.
Femi kuti ni akọbi gbajugbaja akọrin kan ni ilẹ Afirika, Fela Anikulapo Kuti, ẹni to ja fun ẹtọ awọn ọmọ Naijiria ni ipasẹ orin kikọ nigba aye rẹ Ọjọ Kẹrindinlogun, Osu Kẹfa, ọdun 1962 ni wọn bi Femi Kuti, ti wọn pe orukọ rẹ ni Olufela Olufẹmi Anikulapo Kuti Ọdun 1977 ni Femi ti bẹrẹ si ni tẹlẹ baba rẹ kọrin, lẹyin ti iya rẹ kọ baba rẹ silẹ lati kekere Bí i baba rẹ, Femi ma n lo orin lati fi se moriwu fun awọn eniyan, ki atunse le deba ilẹ Afirika Moriya ti orin rẹ sẹ fun awọn eniyan lo se mu ki wọn fi orukọ silẹ fun Grammy Awards lọdun 2003, 2010,2012 ati 2013 Ni ọdun 2017, ni Femi Kuti lamilaaka julọ ni agbaye lẹyin to fun fere fun isẹju mọkanlelaadọta o le Femi Kuti lo ni gbagede orin ti wọn n pe ni ‘the Shrine’, ti o wa ni ilu Eko, ni Naijiria.
Diẹ lara awọn iroyin naa ni a fẹ gbe yẹwo lati mọ awọn to jẹ ayederu ninu wọn atawọn to jẹ otitọ.
Okan lara awọn iṣẹlẹ ifẹhonuhan ọdọ to waye tipẹ tipẹ, to si jẹ Manigbagbe, ta maa ranti laelae ni ẹhonu awọn akẹkọọ to waye ni odun mejilelogoji sẹyin ti wọn pe ni 'Ali Must Go'.
Ẹ wo bí ọ̀rọ̀ òṣèlú, ẹ̀sìn àti ẹ̀yà ṣe fa ogun abẹ́lé Biafra Kàkà k‘éwé àgbọn dẹ̀ lágbo òṣèlú l‘Ondo, akọ̀wé ìjọba tún kọ̀wé fipò sílẹ̀ Ẹ̀kún omi ṣọṣẹ́ ní Ogun, ìjọba yarí láti wó ilé ojú odò Mà á gbẹ̀san bàálù àjọ UN tó já ní Borno - Buhari yarí Lọwọ yii, irinwo le mẹrindinlọgọta eeyan lo ti ni arun naa ni ipinlẹ Ondo.
Alukoro Ọlọpaa ni loore koore ni àwọn òṣìṣẹ́ Ọlọpaa ń wá ní agbègbè yìí àti àwọn àgbègbè miran nigboro Ibadan àti ní àwọn ìlú miran lọsan àti ní òru.
Gẹgẹ bii aṣa iran Yoruba, Iyalufa n tọ Ọmọyẹ sọna lori awọn ọna ti yoo gba se abiamọ, ti yoo fi tọju ọmọ rẹ bo se yẹ ati awọn eewọ to rọ mọ itọju ọmọ.
ede Naijiria, ogagun TY Buratai ti ni awon ti pasọ ana da nipa ona ti won n lo
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Wo àwọn ọ̀nà tí o lè gbà láti di ọjọ́ ogbó pẹ̀lú olólùfẹ́ rẹ Oriṣiriṣi awọn gbajumọ ni Naijiria ati lawọn orilẹ-ede miran lagbaye lo ti n ṣegbe lẹyin iwọde ọhun.
Alaga ana  wa fun alaga tuntun ni ami idanimọ gege bi alaga tuntun.
6 Nísìsìyí èyí kìí ṣe gbogbo ẹ̀bùn rẹ; nítorí ìwọ tún ní ẹ̀bùn míràn, èyí tíí ṣe ẹ̀bùn Áárónì; kíyèsíi, èyí ti sọ ọ̀pọ̀lọpọ̀ àwọn nkan fún ọ.
Òun ni ó pàdé Abrahamu nígbà tí Abrahamu ń pada bọ̀ láti ojú-ogun lẹ́yìn tí ó bá ọba mẹrin jà, tí ó sì pa wọ́n ní ìpakúpa.
Melaye to n bẹ nileewosan gbogboogbo l'Abuja lọwọlọwọ, sọ ninu atẹjade kan ti oluranlọwọ rẹ, Gideon Ayọdele, fi sita pe irọ ni ẹsun ti awọn kan fi n kan oun pe awọn jọ bu Aarẹ Buhari.
'A ti pa Boko Haram run pataoata'
Nítorí ète wa dára lójú Oluwa, ó sì dára lójú àwọn eniyan pẹlu.
Awọn ẹsun miran to tun maa n soju fun ni lilu jibiti l'ẹka eto ilera, iditẹ, ipaniyan, rira ati tita oogun oloro, ifipabanilopọ, ati awọn ẹsun miran to l'agbara.
 leyin ilominira orile-ede tuntun yi koju iyan , ajalu eda ati aini togbale , ati wahala oselu ati igbajoba ologun .
"Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Risikat Moromoke Azeez: Inú èmí àti Òbí mi dùn nígbà ti Risi bí ọmọ olójú búlù- Wasiu Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Risikat Moromoke Azeez: Inú èmí àti Òbí mi dùn nígbà ti Risi bí ọmọ olójú búlù- Wasiu 14 Ògún 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 20 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Mo fẹ ki Risikat pada sile ọdọ mi ni- Wasiu ọkọ Risikat ""Mo fi Àlìkùrání búra pé mò ń tọ́jú Risikat àti àwọn ọmọ mi- Bàbá àwọn ọmọ olójú búlúù Ọmọ Risikat olójú búlúù méjèéjì jẹ̀bùn oríire àti ìfà ńlá Mínísítà fún ọ̀dọ́ àti eré ìdárayá tí fi ẹ̀bùn owó ránṣẹ́ si ìyá Kausara, ó tún jẹ́jẹ̀ẹ́ ẹ̀kọ́ ọ̀fẹ́ f'áwọn ọmọ rẹ̀ Òṣèré tíátà Yorùbá yìí la orí mọ́lẹ̀ nígbà tó ń ṣe sinimá lọ́wọ́ Lẹ́yìn ò rẹyìn, Wasiu Ayinde sọ̀rọ̀ nípa Ayinde Barrister Wo ìdí tí ọmọ ọdún mẹ́wàá ṣe ti àbúrò rẹ̀ ọmọ ọdun kan àbọ̀ sínú kàǹga Wasiu to jẹ ọkọ Risikat oloju buluu ba BBC Yoruba sọrọ ni kikun lori ohun to ṣẹlẹ ki Risikat to ko lọ ati lẹyin to kuro nile rẹ."
Àkọlé àwòrán, Buhari fi orukọ awọn minista rẹ ranṣẹ si ile igbimọ aṣofin Ile igbimọ aṣofin agba Naijiria ti kede orukọ awọn ti Aarẹ Buhari forukọ wọn ranṣẹ fun ipo Minisita lorile-ede Naijiria.
2019 Elections: Ṣé òṣì n pọ̀ si tàbí o n dínkù láwùjọ?
Bẹ́ẹ̀ ni ọjọ́ ńlá ni ọjọ́ náà, ti ìgbéyàwó da ara òde ọ̀run pọ̀ mọ́ ara ayé, ẹbọra ń gún iyán, ẹbọra ń ro ọkà, ẹbọra ń ṣe alága, ẹbọra ń ṣe olórí ẹgbẹ́, àwọn ará òkè àti ti ìsàlẹ̀ n jùmọ̀ ṣe àríyá pọ̀, nǹkan ṣe ní òde ọ̀run.
Lẹ́yìn ikú Ahitofeli, Jehoiada, ọmọ Bẹnaya ati Abiatari di olùdámọ̀ràn ọba.
"Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Mercy Aigbe: Èmi ni ìyá onílé tuntun Pásítọ̀ àti Ìmàámù yóò gba owó osù lọ́wọ́ ìjọba Buhari, ó yá, tètè kọ̀wé fipò sílẹ̀ - Oyedepo Wọ́n n gbógun tì mí kí ń leè dúró sínú APC - Saraki Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Mo ni baba isalẹ' Loju opo ikansira ẹni Instagram, Festus Oladunjoye Ojo, fedel x, to jẹ ọmọkunrin Iyabọ Ojo ni ""Baba mi ree, fun ẹyin ti ẹ fẹ mọ bi baba ti ri."
Amọṣa, ọpọ igbeyawo laaarin awọn oṣere tiata lo n duro digbi lai yẹ gẹrẹ ṣugbọn ti ọpọ ko mọ.
Ogagun-agba Enobong Udoh, ti o je adari eka ile-ise ologun,ti a mo si General Officer Commanding (GOC), 81 Division ile-ise ologun, ni o soju fun oga-agba naaOga-agba ohun so pe, ise-akanse ati awon ojuse miiran, eyi ti o wa lara idanileko ti awon omo-ogun naa ti gba ni odun 2017, seranlowo bi won se segun iwa laabi ti o n waye ni awon agbegbe naa.
Kò sí àjòjì darandaran kankan ní Nàìjíríà -NIS Ò ń lọ s'Amẹrika bí?
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Àjọ ajàfẹ́tọ̀ọ́: Ènìyàn 2000 ti kú nínú ìṣẹ̀lẹ̀ darandaran 10 Ìgbé 2018 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, 'Ìkọlù darandaran pa èèyàn 2000' Ajọ ajafẹtọ kan lorilẹede Naijiria ti sọwipe o le ni ẹgbẹrun meji (2000) eniyan to ti ku ninu rogbodiyan laarin awọn darandaran ati awọn agbẹ lati bi Osu Mejidinlogun lorilẹede Naijiria.
Àwọn kan tí wọ́n yàn bá dìde, wọ́n kó àwọn tí àwọn ọmọ ogun kó lẹ́rú ati ẹrù wọn, wọ́n wọ àwọn tí wọ́n wà ní ìhòòhò láṣọ; wọ́n fún wọn ní bàtà, wọ́n pèsè oúnjẹ ati nǹkan mímu fún wọn, wọ́n sì fi òróró sí ọgbẹ́ wọn.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Pásítọ̀ ló sọ fún mi pé Ọlọ́run pè mí láti di Olokun tó ń bọ omi' Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Kankara Abduction: Ohun ìbànújẹ́ ni bí wọ́n ṣe jí akẹ̀kọ̀ọ́ t'o le ni 300 gbé - Tinubu20 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 EndSars in Portharcourt: Ọjọ́ méjì sẹ́yìn ni aya awakọ̀ Márúwá tí ọlọ́pàá pa bímọ tuntun10 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Coronavirus in Nigeria: Èèyàn mẹ́jọ kú, 1,024 míràn tún lùgbàdì ààrùn náà ní Nàìjíria11 Sẹ́rẹ́ 2021 US visa fee for Nigeria: Amẹrika ti yọ àfikún owó Físà kúro fún arìnrìnàjò Nàìjíríà6 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 3 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 5 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
ó ń kígbe lóhùn rara lẹ́nu ibodè àtiwọ ìlú,ó ń ké ní ẹnu ọ̀nà àbáwọlé pẹlu,ó ń wí pé:
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù NNPC pàṣẹ fáwọn òǹtàjà epo pé owó epo bẹntiróòlù kò gbọdọ̀ lé ní N145 12 Agẹmo 2019 Oríṣun àwòrán, @Bolarinwaiyanu Ileeṣẹ epo rọbi lorilẹede Naijiria, NNPC ti kede pe, oun ko ni erongba lati fi owo kun owo ori epo lorilẹede Naijiria.
Wọn yóo sọ ìgbéraga Ijipti di asán, ogunlọ́gọ̀ àwọn eniyan rẹ yóo sì parun.
O ni Sunday Dare to jẹ minista ọrọ ọdọ naa wa si aafin fun ipade lori ọrọ iwọde yii naa ni.
Ṣugbọn àwọn eniyan Dafidi ti pa ọtalelọọdunrun (360) ninu àwọn eniyan Abineri.
Lọwọlọwọ bayii, ijoko ile asofin si n tẹsiwaju, a o ma a mu iroyin wa fun yin lẹkunrẹrẹ.
Ní ọ̀la ìwọ ati àwọn ẹgbẹ́ rẹ, ẹ mú àwo turari, 
 wọ ́ n si máa ń ṣe àpọ ́ nlé àwọn bàbá ńlá wọn tí wọ ́ n ti kú .
Nítorí náà, wọ́n yan àwọn akóniṣiṣẹ́ láti ni wọ́n lára pẹlu iṣẹ́ àṣekára.
” Ipese iseOnimo ero fun ise akanse naa tun so fun minisita pe awon ti pese  ise  to le ni egberun merin fun awon eniyan lasiko ti awon bere ise oju opopona yii.
Ṣùgbọ́n ọ̀ppọ̀lọpọ̀ ló kú sínú odò Ẹ̀jẹ̀ nínú àwọn ti a jọ̀ n bọ̀, àti pàápàá àwọn tí wọ́n dára pọ̀ mọ́ wa láti ìlú àwọn aláṣejù.
Yinka Ayefele di bàbá ìbẹta Owó dé!
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fọ́nrán ohùn, Charly Boy l'óun kò gbowó O ni o dun oun pe nigba ti oun wa lẹwọn, awọn ti awọn jọ n ja fẹtọ ọmọniyan le laya lati lọ gbowo lọwọ ijọba Charly Boy fikun ọrọ rẹ pe oun ko ṣegbe lẹyin ọkankan ninu ẹgbẹ oṣelu APC tabi PDP nitori, ọkan ko gbekan bi owu jango lawọn mejeeji.
Awọn agbofinro parapọ ṣiṣẹ lati pese eto aabo to peye fawọn eeyan lasiko idibo to kọja ni Tunisia Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Awa ara wa la rira wa, ologinni lo rọmọ ẹkun!
A súré tete tọ ilé ọ̀hún lọ pé bóyá a lè rí ibìkan gọ sí kí gbogbo aṣọ wa má baà tutù tán.
Wọ́n bá mú un lọ sí kóòtù níwájú Galio.
nípaṣe ìṣe àwọn baba ńlá baba àwọ ́ n yorùbá , eọ ́ n ń fún ọmọ wọn lórúkọ níbi ayẹyẹ tí ó máa ń wáyé ní ọjọ ́ kẹẹ ̀ jọ lẹ ́ yìn ìbímọ.
Won ti rọ gbogbo awon omo
Iná jó àwọn ènìyàn 10 tó ń gbà ìwòsàn arùn Coronavirus níbùdó ìtọ́jú Mo ti buwọ́lu àdínkù owó orí nítorí ìrọ̀rùn àwọn èèyàn ìpínlẹ̀ Ogun lásìkò Covid 19- Dapo Abiodun Àwọn adarí lágbàyé ṣèpàdé láti ṣèrànwọ́ fún Lebanon lẹ́yìn ìbúgbàmù tó pa ènìyàn 158 Wo ohun tí Adájọ́ ṣe sí àṣùwọ̀n ìfowópamọ́sí Wòlíì Sotitobire Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Teach your children Yoruba: Wo àwọn òyìnbó tó ń kẹ́kọ̀ọ́ èdè Yorùbá ní Michigan, America Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Brexit: Ibò mọ́kàndínlógun péré ni Theresa May fi bọ́ lọ́wọ́ àwọn aṣòfin 16 Sẹ́rẹ́ 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àwọn ọmọ ile aṣofin Ilẹ Geẹsi dibo a ko ni igbékélé ninu rẹ mọ ni Ọjọru lati yọ adari ijọba Theresa May nipo, ṣugbọn o jajaboọ pẹlu ibọ mọkandinlogun.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Lagos City Marathon: Ipò wo ni Gómìnà Sanwo-Olu gbà?
Ọ̀rọ̀ LAUTECH gba àpérò f'áwọn Olúdíje Ọṣun Ìpínlẹ̀ méjìlá nínú ewu àgbárá òjò ní Nàìjíríà Aago méjìlá ọjọ́ Ẹti ni ìséde yóò bẹ̀rẹ̀ ṣáájú ìdìbò náà Kíni ẹ mọ̀ nípa àwọn gbajúgbaja Yollywood?
Ninu eyi ni ikọlu ti waye fawọn ajeji ni South Africa ki awọn ọmọ ogun ilẹ̀ tó yanju ẹ.
O ni ofin tuntun yii ko yọ awọn ti wọn gbiyanju lati da idibo Naijiria tọdun 2019 to kọja yii rú silẹ.
”Ogagun  Nwachukwu tun ni “Adari iko omo ogun orile ede Naijiria,Tukur
Ẹ̀rù ńlá sì ba gbogbo àwọn tí wọ́n gbọ́.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Sotitobire: Iléẹjọ́ ṣún ìgbẹ́jọ́ síwájú di ọjọ́ kẹrìndínlógún oṣù Kẹta ọdún 2020 6 Èrèlè 2020 Ile ẹjọ giga tilu Akurẹ ti sun igbẹjọ siwaju lori ẹsun ijọmọgbe ti wọn fi kan olori ijọ Sotitobi rẹ, Alfa Babatunde.
“Kí ló dé tí o fi ń wo ẹ̀ẹ́rún igi tí ó wà lójú arakunrin rẹ, nígbà tí o kò ṣe akiyesi ìtì igi ńlá tí ó wà lójú ìwọ alára?
Lọjọ kẹsan osu kẹta, Naijiria kede ẹni keji iyẹn ọmọ Naijiria to ṣalabapade ọmọ Italy to gbe arun naa wọle.
Kò sí ìfòyà ninu ilé wọn,bẹ́ẹ̀ ni Ọlọrun kò jẹ wọ́n níyà.
Ṣugbọn Asafu, Jedutuni, ati Hemani wà lábẹ́ àkóso ọba.
Igbakeji adari ile-ise Aiteo, Francis Peters, Ninu oro re lasiko ipade igbami-eye eyi ti o waye nilu Eko lojo Aje (Monday), O ni inu ile-ise Aiteo dun lopolopo fun awon eto ajo NFF ti won sese kede fun ipalemo idije nla yii.
 Ọbàlùfọ ̀ n aláyémọrẹ rìn títí ó fi dé orí òkè kan .
Orí rẹ ni Olódùmarè tẹ́ ilé-ayé lé
Ara wọn nìkan ni wọn yóo lè fi òdodo wọn gbàlà.
Àkókò ogun jíjà ni àkókò náà , gbogbo wọn sì máa ń pa ra pọ ̀ jagún ni Àwọn-jagunjagun pọ ̀ nínú wọn .
Ogunlọ́gọ̀ àwọn eniyan láti Ẹnu Ọ̀nà Hamati títí dé odò kékeré Ijipti ni wọ́n péjọ níwájú OLUWA fún ọjọ́ meje.
Aare orile ede Niajiria Muhammadu Buhari ni, ohun ti oju oun ri ni ẹẹmẹta ti o dije fun ipo aarẹ lorile ede Naijria ko se fẹnusọ,Idi niyi ti oun se pinnu lati wa ojutuu si isoro to n dojukọ eto isejọba lorile ede yii, paapaa julo nipa eto inawo ti igbimo asoju ati ile-ise eto idajo to wa ni  ipinle orile ede Naijiria.
Dafidi ati àwọn olórí ogun ya àwọn kan sọ́tọ̀ ninu àwọn ọmọ Asafu, Hemani ati ti Jedutuni láti máa sọ àsọtẹ́lẹ̀ nígbà tí wọ́n bá ń fi dùùrù, ati hapu ati aro kọrin.
Àwọn kerubu na àwọn ìyẹ́ wọn sórí ibi tí àpótí náà wà tóbẹ́ẹ̀ tí wọ́n bo àpótí náà ati àwọn òpó rẹ̀.
Wọ́n dàbí ẹni tí ó gbé àáké sókè,tí ó fi gé igi ìṣẹ́pẹ́.
“Bí mo bá ṣe gbogbo èyí, sibẹ tí ẹ kò gbọ́ tèmi, n óo jẹ yín níyà ní ìlọ́po meje, fún àwọn ẹ̀ṣẹ̀ yín.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù LASEMA: Àwa àti panápaná ń ṣiṣẹ́ kára láti dènà ìjàmbá iná 25 Owewe 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 6 Ọ̀wàrà 2020 Ajọ oṣiṣẹ pajawiri nipinlẹ Eko, LASEMA ni awọn ti le awọn eniyan kuro nibi ti iṣẹlẹ ọkọ agbepo to danu ti waye ni ilu Eko.
Ṣugbọn n óo máa ṣọ́ àwọn ará Juda, n óo sì fọ́ ojú ẹṣin àwọn ọ̀tá wọn.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Àwa obìnrin tó ń lépa afòjúsùn máa n ba ọkùnrin lẹ́rù ni -Toyin Lawani Orilẹ-ede Brazil lo ti lọ ṣe iṣe abẹ naa ni eyi ti àwọn dokita gba imọran pe ki wọn ṣọra fún iṣẹ abẹ lọwọ awọn ti kò koju oṣuwọn tó.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Male Fertility: Wo àwọn oúnjẹ márùn ún tó ń mú kí àtọ̀ ọkùnrin dára sí i 6 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 7 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Ọmọ bibi jẹ ohun to ṣe pataki ni igbe aye awọn ẹda paapaa ọkunrin ati obinrin.
Koda, awọn osisẹ ati onibara to fẹ wọle sibudo itaja naa ni jẹbẹtẹ gbe ọmọ le lọwọ nigba ti wọn foju kan awọn agbofinro naa, ti ẹnikẹni ko si lee wọle tabi jade latinu ibudo itaja naa.
Wọn ni o seese ko jẹ pe ọta ibọn lo seese ba ọkunrin naa lasiko tawọn ọlọpaa n le awọn janduku sẹyin, ki wọn maa ba sisẹ ibi wọn.
Ìró ìlù ayọ̀ ti dákẹ́,ariwo àwọn alárìíyá ti dópin.
kí o lè la ojú àwọn afọ́jú,kí o lè yọ àwọn ẹlẹ́wọ̀n kúrò ni àhámọ́,kí o lè yọ àwọn tí ó jókòó ninu òkùnkùn kúrò ní ọgbà ẹ̀wọ̀n.
Opolopo egbe oselu APC  ni won  ro lo si ibi ipolongo egbe oselu APC to waye ni papa isere Oluyemi Kayode, sugbon ki o to di aago mejila osan ni papa isere naa ti kun fọfọ .
Eto isuna odun 2019 ti o ye ki won
Igbakeji adari ajọ SERAP, Kolawole Oluwadare lo sọ ọrọ yii ninu ifọrọwerọ pẹlu ileeṣẹ BBC.
Amọ nse ni wọn fi tipa gba awọn ohun eelo isẹ osisẹ akọroyin agba fun ileesẹ BBC, Joshua Ajayi to wa nibudo naa lati sisẹ tiẹ lasiko ti awọn osisẹ ọhun wa nibẹ, to si fẹ seto ifọrọwanilẹnuwo fawọn osisẹ atọkọse ati ontaja ti wọn wa ni agbegbe yii, ti ọrọ naa kan.
Wọn ji Kọmisana naa ati eeyan kan ti wọn jọ wa ninu ọkọ gbe ti wọn si tun yinbọn pa Kansilọ nijọba ibilẹ Ilejemeje kan ti wọn jọ wa ninu ọkọ naa.
Ṣugbọn Jehu, aríran, ọmọ Hanani lọ pàdé rẹ̀, ó sọ fún un pé, “Ṣé ó dára kí o máa ran eniyan burúkú lọ́wọ́, kí o fẹ́ràn àwọn tí wọ́n kórìíra OLUWA?
Nígbà tí ìpìlẹ̀ bá bàjẹ́,kí ni olódodo lè ṣe?
Ẹ wo ìṣẹ̀lẹ̀ nípa ẹ̀sùn ìfipábánilòpọ̀ tí wọ́n fi kan D'banj ní sísẹ̀-n-tẹ̀lé Ó ṣeéṣe kó jẹ́ pé àwọn alágbara ló ń fi agbára hàn lórí arábìnrin tó fẹ̀sùn ìfipábánilòpọ̀ kan kọmíṣọ́nà Kogi -Agbẹjọ́rò Ta ló fipá bá Jennifer lò pọ̀?
Coronavirus in Nigeria: Ààrùn Covid-19 ti ran ènìyàn 454 míràn ní Nàìjíríà
Lẹyin igbeṣẹ ọkọ iyawo ati ẹbi rẹ ni iyawo yoo dagbere fun mọlẹbi rẹ ti yoo si gba ile ọkọ lọ.
Yipada kuro ni lilo ero aye atijo si ti igbalode ni gomina ipinle Enugu, Ifeanyi Ugwuanyi ati minisita ohun se ifilole re.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù TCN, ní kò s'óhun tí yóò ṣe iná mànàmáná ní Nàìjíríà lóní 13 Èbibi 2019 Àkọlé àwòrán, Ẹgbẹ oṣiṣẹ TUC lo faake kọri pe oun yoo da iṣẹ ru nileeṣẹ to n pin ina ọba lorilẹede Naijiria, TCN Ajọ to n pin ina ọba lorilẹede Naijiria, TCN ti ṣalaye fun BBC News pe iroyin ti awọn kan n gbe kiri pe ina ọba yoo lọ kaakiri orilẹede Naijiria lọjọ aje, ọjọ kẹtala oṣu karun ko lee waye.
Idasẹsile náà mú ìnira ba opo aláìsàn ṣugbọn lójó keje idasẹsile náà, wọn yanjú òrò ọ̀hún ní tunbi n nubi pẹlu ijọba.
Ó tọ Pilatu lọ láti bèèrè òkú Jesu.
Ẹni a wí fún, Ọba jẹ́ ó gbọ́.
"Ọ ̀ kọ ̀ ọ ̀ kan àwọn kílíìkì wọ ̀ nyí ló lè ní kíkùnyùn-ùn , ( voicing ) ríránmú ( nasality ) , "" aspiration "" ati "" ejection "" ."
Oluwo jọgbọdọ Orunmila àti àwọn eeyan rẹ nibi iwọde #End Sars ati #Sarsmustend to n lọ lọwọ ni ilu Ibadan.
Bi ọmọ ko ba ba itan, yoo ba arọba: Lọdun 2016, ida mọkanlelọgọrin awọn ijọ onihinrere lo dibo fun Trump ti ida ọgọta awọn ọmọ ijọ Katoliki si yan an dipoo alatako rẹ, Hillary Clinton ti ida mẹtadinlogoji ijọ Katoliki pere dibo fun.
" Nígbà tó ń sọ̀rọ̀ lórí igbesẹ riro àwọn obìnrin lágbára àti ìwòsàn àrùn jẹjẹrẹ, Akeredolu gbé oriyin fun aya rẹ, Betty, fún isẹ takuntakun tó ń ṣe, pẹ̀lú àfikún pe ó tún ń kọ àwọn ọmọdébìnrin ni onírúurú isẹ ọwọ, kí wọ́n leè dá dúró fúnra wọn.
Esi yi jẹ ohun to mu irẹwẹsi ọkan ba pupọ alatilẹyin ẹgbẹ naa.
Ọ ̀ pọ ̀ àọn ọmọ orílẹ ̀ -èdè nàìjíríàtí wọ ́ n jẹ ́ ọ ́ mọ ̀ wé ni wọ ́ n sọ ̀ rọ ̀ nípa ilé-ẹ ̀ kọ ́ náà , pààpàá jùlọ ìwé ìròyìn olóhoojúmọ ́ ilẹ ̀ nàìjíríà tí a mọ ̀ sí nigerian daily times ni ó sọ àgvọ ́ ọ ̀ gbẹ ọ ̀ rọ ̀ wípé :  ó jẹ ́ èrò tó dára àti ọ ̀ nà tí ó tọ ́ kí a má ṣe kọ ́ ilé alárà sórí ìpìlẹ ̀ tí ó mẹ ́ hẹ "" ."
Ó bèèrè lọ́wọ́ wọn pé, “Ṣé ọmọ ti kú ni?
Ìdàpapọ ̀ ṣiṣẹ ́ elbs n jẹ ́ kí a lè ṣètò aromatic tí kò lómi .
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Awọn ọmọ ogun aladani to n pese aabo lorilẹede Central African Republic Yatọ si orilẹede Central Africa Republic ti ifarahan Russia ti fẹsẹ mulẹ, bakan naa la tun gbọ pe lorilẹede Sudan ati Libya atawọn orilẹede miran, ileesẹ ologun aladani kan, Wagner, ti wọn lo ni ajọsepọ to gunmọ pẹlu Russia, wa nibẹ.
Alaafia ńláńlá ń bẹ fún àwọn tí ó fẹ́ràn òfin rẹ,kò sí ohun tí ó lè mú wọn kọsẹ̀.
Ẹni to bori: Egypt South Africa vs Mauritania.
Lọjọru ni àwọn afurasi Janduku kan lọ dana sun awọn iṣẹ akanṣe ti Senetọ Dino Melaye fẹ ṣí.
Yóo rí i pé ikú a máa pa ọlọ́gbọ́n,òmùgọ̀ ati òpè a sì máa rọ̀run;wọn a sì fi ọrọ̀ wọn sílẹ̀ fún ẹlòmíràn.
Aarẹ ẹgbẹ MOSOP, Legbosi Pyagbara to pe ipe yii ninu ọrọ ayajọ idaabo bo ayika ti ọdun 2018.
Ann Grace Aguti, Obìnrin kan to fẹ́ ọkọ mẹ́ta lẹ́ẹkàn ṣoṣo A kò tíì rí ọmọ ọdún méjì tó kó sí kànga- Olootu India Fọ́tò ló ṣàfihàn ibi tí ọmọ ti Nọọsi jígbé lódún 1997 wà Ebi ló ń pami ti mo fi já sọọbu láti jí bisikitì- Afurasi Asuquo Èyí tí a wò jùlọ 5:03 Fídíò, Omolola Arohunmolase Welder: Mo ti fí iṣẹ́ 'Welder' gbayì láwùjọ, tó mo fi tọ́ ọmọ yanjú, Duration 5,039 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 5:39 Fídíò, Akomolede ati Asa lori BBC: Olùkọ́ Kikelomo Ogunboye tan ìmọ́lẹ̀ sí ìwà olè ọ̀gá ọlọ́pàá Audu gẹ́gẹ́ bí àwòkọ́ṣe àsìkò yìí, Duration 5,398 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 4:11 Fídíò, Oba Adeyeye Ogunwusi: Ojú mi ti rí lọ́pọ̀ lọpọ̀, ọ̀pọ̀ èèyàn ni kò tilẹ̀ gbàgbọ́ pé mo lè jọba- Ooni, Duration 4,117 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 4:43 Fídíò, Promise Akinlade: ọmọ ọdún mọ́kànlá tó ń fi ìlù dárà bíi àgbàlagbà sọ̀rọ̀ nípa tálẹ́ǹtì rẹ̀, Duration 4,437 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 0:59 Gbọ́, Ìsẹ̀lẹ̀ jákèjádò orílẹ̀èdè àgbáyé láàárín ìṣẹ́jú kan, Duration 0,59wákàtí 6 sẹ́yìn 4:45 Fídíò, Yoruba Films: Ẹ̀ẹ́ bẹ̀ mi kúrò láyé ni, mi ò lè kú - Fadeyi Oloro, Duration 4,4526 Èrèlè 2020 7:03 Fídíò, Olumuyiwa Bolade Adedeji Military Bruitality: Bí arákùnrin onípèníjà ara tí sọ́jà lù ṣe dé, Duration 7,035 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 2:48 Fídíò, Esther Ajayi: Èmi náà ti borí ìṣòro rí ló ń mu mi ṣojú àánú, Duration 2,481 Ògún 2019 6:08 Fídíò, Adebola Ademilua: Àìrísẹ́ ṣè lẹ́yìn ìwé kíkà ló sọ mi dí ìyá onírú, mo dúpẹ́ tèmi, Duration 6,0827 Bélú 2020 5:55 Fídíò, Soyinka Cancer: Àṣe ara mi ni iso ti n run gbogbo bí mo ṣe n ṣèrànwọ́ lórí jẹjẹrẹ, Duration 5,5527 Bélú 2019 BBC News, Yorùbá Ìdí tí ẹ fi le è nígbàagbọ́ nínú ìròyìn BBC Ìlànà Lílò Nípa BBC Òfin Àṣírí Cookies Kàn sí.
Nígbà tí Jesu wọ Jerusalẹmu, gbogbo ìlú mì tìtì.
Níbo ni wọ́n ti ń sinmi,nígbà tí oòrùn bá mú?
Ṣugbọn Ọlọrun wí fún un pé, ‘Ìwọ aṣiwèrè yìí!
Nigba to n salaye ohun ti oṣere tiata naa n la kọja faraye, gbajugbaja oṣere tiata miran, Murphy Afolabi sọ loju opo Instagram rẹ pe, ọkunrin naa nilo iranwọ araalu kiakia.
Wọn yoo si fi aworan oku wọn sori Facebook bakan naa.
 Wọn ni ifarada ni igba iṣoro eleyii to jẹyọ ni asiko ti wọn pinnu lati fi ọmọ wọn kan ṣoṣo rubọ.
Bakan naa, orisirisi anfaani ni Oumar Kida, Siaka Bagayoko ati Mohammed Cisse padanu lati tun gba ami ayo wole.
    Ìdí rẹ̀ nì yí, ẹ̀yin ènìyàn wa, tí o fi di pé ẹ rí gbogbo wa tí a pinnu lọ́kàn wa pé àfi dandan bí a ti ayé lọ sí ẹnu odi ọ̀run, sí òkè Ìrònú ti ń bẹ nínú Igbó Elégbèjè, ìlú ni Òkè Ìrònú, ó eà lẹ́nu odi ọ̀run, ṣùgbọ́n inú rẹ̀ ni Igi Ìrònú wà èso èyí tí ó le ṣe ìlẹ̀ yìí loore.
Ile ẹkọṣẹ ọlọpaa to wa ni Ikẹja nilu Eko ni Ẹgbẹdokun wa gẹgẹ bii igbakeji ọga agba nibẹ ki wọn to yan an si ipo adele Kọmiṣọna nipinlẹ Eko.
Yatọ si ifẹsẹwọnsẹ Totteham ati Ajax, Loucas Moura ti fakọyọ ninu ifẹsẹwọnsẹ miran to ti jẹ awọn goolu to ṣokunfa itẹsiwaju ẹgbẹ agbabọọlu Tottenham ninu awọn idije ti wọn ti kopa ninu rẹ.
Wo fọ́tò àrà MC Oluomo, Pasuma àtàwọn òṣèré tíátà míì níbi ìṣílé Iyabo Ojo Ẹ má jẹ́ kí ayélujára tàn yín jẹ́, mẹ̀kúnnù lọ̀pọ̀ àwa òṣèré tíátà - Iyabo Ojo Èmí kò leè bá obìnrin kankan jà lórí ọkùnrin, kò leè ye yín - Iyabo Ojo Àwọn òṣèré, olórin Yorùbá gbàdúrà fún MC Oluomo Àwọn ojú oge Yollywood t'ọ́jà wọ́n ṣì ń tà wàràwàrà Iyabọ ni aarọ ọjọ Aiku ana si ni oun se ayẹwo arun Coronavirus, ki oun to kuro ni papakọ ofurufu Instabul, lorilẹede Turkey.
Akpan ni bi aarẹ se fi iyansipo awọn minisita naa falẹ yoo se akoba fun eto ayẹwo ati fifi ontẹ lu wọn, eyi ti ile asofin agba fẹ se fun wọn.
Ṣelumieli ọmọ Suriṣadai ni yóo jẹ́ olórí láti inú ẹ̀yà Simeoni.
Ẹnikẹta niyii ti wọn yoo kede pe o ni arun naa ni Naijiria.
Won ti fun aare Zuma ni gbedeke lati fi alefa sile, leyin ti igbimo egbe oselu naa se ipade lori oro naa.
yii waye lati fi lwe pese aabo to peye fun eniyan ati duki awon.
Mo sì bẹ̀rẹ̀ sí gbọ̀n fún ìbẹ̀rù.
Ẹ kó gbogbo àwọn nǹkan ẹ̀gbin kúrò ninu ibi mímọ́, 
Ọrọ akọnilẹnu jẹ gbolohun ọrọ ti a to papọ ti a maa n sare sọọ ki eeyan le ṣe aṣiṣe tabi fihan pe o dangajia mimu ede Yoruba.
Àgbárá òjò bà'lú jẹ́ n'Ípínlẹ̀ Ogun Fayose kọ̀ láti yọjú sí EFCC l'Ọjọ́bọ̀ Olórí ilé asòfin l‘Ọ́sun pàdánù N38m sọ́wọ́ gbájúẹ̀ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, OsunDecides: Omisore ní ẹni tó bá fẹ́ ra ìbò, àwọn yóò lọ lásọ mú ni Lẹyin ti Adekunle pari eto ẹkọ girama rẹ nilu Eko, lo tẹ ọ̀kọ leti lọ soke okun fun eto ẹkọ fasiti rẹ, ni University of West England Adekunle kẹkọjade nile ẹkọ fasit naa, to si jade pẹlu iwe ẹri isọri akẹkọ kinni to yege, taa mọ si First Class ni ẹka imọ nipa sise ẹrọ deniyan rọbọti, lẹyin eyi lo wa da ileesẹ tara rẹ silẹ, eyi to n se ẹrọ Rọbọti.
 A ni lati fun un ni nkan ti yoo maa jẹ ko ṣi diẹ diẹ to jẹ wi pe a tun ṣe awọn eroja ara lokun pada titi ara yoo ṣe le gba awọn.
Ó ní lórí wàhálà àgbẹ̀ àti darandaran, òṣèlú ẹ̀tánú ló wà nì ìpìlẹ̀ rẹ̀.
 fólúkẹ ́ , omówùmí àti oládípọ ̀ jẹ ́ ọmọ yẹ ́ wándé .
"Afurasi naa, Collins Uligbe, sọ lasiko ti ọlọpaa fi oju wọn han ni gbangba pe ""Iya onile oun, Mary Ade, lo fun oun ati awọn isọmọgbe rẹ ni miliọnu kan Naira, lati pa ọmọbinrin naa."
Dino Melaye nánwó fún Ayefẹlẹ lójú agbo
Eyi lo si mu ki BBC kan si iya awọn ọmọ naa, Arabinrin Risiqot Moromoke.
Laipẹ yi ni awọn kan bnu atẹ lu minisita ọrọ abo Britain tori pe o fẹ lo awọn irinṣẹ Huawei kan faabo wọn.
Crystal Palace vs Manchester United: Crystal Palace pàkúta sí gaàrí Manchester United ní Old Trafford
Ní ọjọ́ 13, oṣù Ògún ọdún-un 2018, Ilé-ẹjọ́ Gíga Dhaka pàṣẹ fún àjọ ìjọba tí ó ń rí sí ètò ìdàgbàsókè ìlú ní ìlànà tìgbàlódé ní Dhaka láti máà wó tàbí tún àwọn ilé àjogúnbá tí ó wà ní olú-ìlú náà tó bíi 2,200 kọ́.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Nigeria 2019 Elections: Ṣé ọwọ́ ti ká Boko Haram ní Nàìjíríà 20 Èrèlè 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 22 Èrèlè 2019 O ti le ni ọdun mẹwa ti ẹgbẹ agbebọn Boko Haram ti n da wahala silẹ lẹkun ila oorun ariwa orilẹede Naijiria.
Oyewọ tun ni aayan tun ti n lọ lati ri daju pe pepele kan wa fun atunse awọn ẹlẹwọn, ti ayipada yoo si tun ba ero araalu ti wọn gba pe awọn olowo ati ọlọrọ nikan ni idajọ ileejọ n gbe.
Ọgbẹni Salman sọ siwaju sii ninu atẹjade naa pe lojiji ni ile iṣẹ Asa Investment ṣaa deedee bu ninu ilẹ ilẹ naa lati lo fun okowo lọna aitọ.
Johanani ọmọ Karea ati gbogbo àwọn olórí ogun tí wọ́n wà ní ìgbèríko wá sọ́dọ̀ Gedalaya ní Misipa.
Lotani ní arabinrin kan tí ń jẹ́ Timna.
Nígbà tí ó rí Dafidi dáradára, ó wò ó pé ọmọ kékeré kan lásán, tí ó tóbi tí ó sì lẹ́wà ni, nítorí náà, ó fojú tẹmbẹlu rẹ̀.
Igbese yii waye leyin ipade ti aare Muhammadu Buhari ati aare orile ede  Benin, Patrice Talon, se lojoRu,nile aare to wa niluu Abuja .
'Ẹnikẹ́ni ò lè tì mí gbọ̀ngbọ̀n láti gbé orúkọ mínísítà jáde' EFCC ń wádìí iléeṣẹ́ Bola Tinubu,' Alpha Beta Consulting Ltd' Àríyá ò lópin láti ìgbà tí Nàìjíríà ti júwe ilé fún South Africa Ìgbárùn ni ètò BB Naija kíì ṣe ìgbádùn rárá- MURIC Ki a to wi ka to fọ, wọn ti ja arabinrin yi si ihoho pẹlu ọpọlọpọ lilu.
Lẹ́yìn náà, Ẹ̀mí gbé Jesu lọ sí aṣálẹ̀ kí Èṣù lè dán an wò.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Olofa ina: ẹ parí òwe yìí pé ìgbà tí ara bá tu ìgbẹ́ láà ri eṣú.
"Lasiko ijọba Ọgagun Sanni Abacha laarin ọdun 1993 si 1998, Soyinka fi Okada Alupupu fẹsẹ fẹẹ kuro lorilẹ-ede Naijiria, o gba ọna ""NADECO"" iyẹn ibode Benin jade."
O ni ojiji aye lasan ni gbogbo wa n le kiri, ta si n jẹ gaba lori awọn eeyan miran lai mọ ohun ti yoo sẹlẹ ni isẹju meji si asiko yii.
Bakan naa ni wọn ni olori ile naa tẹlẹ, Pasitọ Kọla Oluwawọle pẹlu gbọdọ yọju o.
Nígbà tí wọ́n bá ké pe OLUWA nítorí àwọn aninilára, OLUWA yóo rán olùgbàlà tí yóo gbà wọ́n sí wọn.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi 4 Sẹ́rẹ́ 2021 Titi di oni, sisọ iwọ ati olubi smọ nu ti di aṣa eyi ti o maa n waye ni kete ti ibi smọ tuntun ba ti waye.
Bakan naa si ni awọn oṣiṣẹ ajọ EFCC ti gbe e pada si ọgba ẹwọn ikoyi titi di igba ti yoo fi lee pari eto gbogbo lori beeli ọhun.
Fayẹmi la gbọ wi pe o sọ ọrọ yii lasiko eto oloṣooṣu kan to ti maa n ba awọn araalu sọrọ lori amohunmaworan.
Balogun Super Eagles, Mikel to fọrọ naa lede loju opo Instagram rẹ, sọ pe, asiko ti to fun oun lati fi ikọ agbabọọlu Naijiria silẹ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Bórípẹ́ nílẹ̀, á dire; ẹlẹ́wọ̀n méjì yóò di dókítà ọ̀mọ̀wé 15 Ògún 2018 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 16 Ògún 2018 Oríṣun àwòrán, Rumourspro/Facebook Ìbẹ̀rẹ̀ kìí ṣe oníṣẹ́, àforitì ni iìpilẹ̀ṣẹ̀ ilọsiwaju ẹ̀dá Ọga agba to n dari ileeṣẹ ijọba to n mojuto awọn ẹwọn ni Ipinlẹ Eko, Ọgbẹni Tunde Ladipo, ni bii mẹtadinlọgọjọ (157) ẹlẹwọn ni yoo kọ idanwo aṣekagba ile iwe girama (WASSCE) to n bọ ni ipinlẹ naa.
Ó ga ju ọ̀run lọ, kí lo lè ṣe sí i?
 fífarahàn àìsàn náà máa n sáábà gbà tó ọ ̀ ṣẹ ̀ mẹ ́ jọ , tí ó sì máa n wá pẹ ̀ lú ọkàn-rínrìn , èèbì , ìgbẹ ̀ -gbuuru , awọ-ara bí-àyìnrín , ibà àti inú rírun .
"A gbé ìlànà kan kalẹ, a kesi àwọn akọroyin, a mú àyípadà bá ibasepọ rẹ, mo sì dúpẹ́ lọ́wọ́ Ọlọ́run pé làálàá mi lórí rẹ kò já sí asán.
Wayi o, ọga agba ọlọpa ti wa kesi awọn obi lati maa mojuto awọn ọmọ wọn bo se yẹ nitori awọn eeyan to sun mọ awọn ọmọde yii, lo maa n pa wọn lara.
Bẹẹ si ni o ni oun maa n da fila bo oju ki ẹnikẹni ma baa da a mọ.
Koda, ajọ EFCC tun gbẹsẹ le ile awo dami ẹnikan to jẹ ti Alison-Madueke to wa niluu Eko.
nítorí ọgbọ́n níye lórí ju ohun ọ̀ṣọ́ olówó iyebíye lọ,kò sí ohun tí o fẹ́, tí a lè fi wé e.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Mutiu Agboke: Ìbanilórúkọjẹ́, ìjínigbé, àti ìdúnkookò mọ́ni la kojú lásìkò ìbò 26 Ẹrẹ̀nà 2019 Oríṣun àwòrán, INEC Àkọlé àwòrán, Kọmisana fun ajọ INEC nipinlẹ Ọyọ tun kede pe, Ọjọru ni gomina ti wọn dibo yan ati igbakeji rẹ yoo gba iwe mo yege ibo.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Paystack Shola Akinlade: Ìgbésẹ̀ 5 yìí ni mo gbé tíléeṣẹ́ Stripe fi dókòwò $200m pẹ̀lú mi Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Paystack Shola Akinlade: Ìgbésẹ̀ 5 yìí ni mo gbé tíléeṣẹ́ Stripe fi dókòwò $200m pẹ̀lú mi 16 Sẹ́rẹ́ 2021 Lasiko ajakalẹ arun Coronavirus ta wa yii, ọpọ ọrọ aje orilẹede ati tawọn idile lo ti dẹnukọlẹ, ti airisẹse si gbode.
Ó sọ fún àwọn ọmọ Israẹli pé, “Nígbà tí àwọn ọmọ yín bá bèèrè lọ́wọ́ àwọn baba wọn ní ọjọ́ iwájú pé báwo ni ti àwọn òkúta wọnyi ti jẹ́ rí?
Bótilẹ̀ jẹ́ pé ààrun coronavirus ń ṣe àwọn ènìyàn mọ́lé síbẹ̀ kò di àwọn òṣèré tíátà dúro láti ṣe tíwọn.
Mohammed ni Naijiria ko ri owo pa wọle mọ bii ti tẹlẹ, nitori naa awọn ko ni le san owo iranwọ lori epo bẹntirol ati mọnamọna mọ.
Lẹ́yìn èyí ni Òmùgọ̀diméjì bẹ̀rẹ̀ ọ̀rọ̀ i sọ tí ó ni:
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Divorce in Ibadan: Iléẹjọ́ tú ìgbéyàwó ọdún méjé ká nítorí àìnáání ara ẹni 6 Bélú 2020 Oríṣun àwòrán, Nigerian Observer Ilẹejọ Mapo Customary Court ni ilu Ibadan ti tu igbeyawo ọdun meje ka laarin Abiola Giwa ati ọkọ rẹ lori ẹsun pe ko naani iyawo rẹ.
ara ẹ ̀ yà ilẹ ̀ yorùbá náà ní ilú Ìrè-Èkìtì wà .
13bn síwájú Ilé Aṣòfin Gómìnà mẹ́rin yóò jẹ́jọ́ lẹ́yìn sáà wọn - EFCC EFCC ń wádìí iléeṣẹ́ 'Bola Tinubu,' Alpha Beta Consulting Ltd' O ṣọ ninu ọrọ rẹ pe, ko si ẹtanu kankan ti wón ni si Ambọde, ẹni ti o ṣe ijọba ni ipinlẹ Eko laarin ọdun 2015 si 2019.
wọn, nitori naa“Ti won ko ba tete se ayẹwo fun awon
 Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó Kini ọna abayọ kuro ninu Akufa?"
"Oríṣun àwòrán, Google O sọ fun ileesẹ iroyin ABC pe "" sadede ni mo gbọ ariwo kan ti ayekootọ mi, Eric, si bẹrẹ si ni pariwo."
Wọn ni bakannaa ni wọn n bere Hamza Idris ti orukọ rẹ wa lori iroyin naa.
Ọlọ́gbọ́n a máa ṣọ́ra, a sì máa sá fún ibi,ṣugbọn òmùgọ̀ kì í rọra ṣe, kì í sì í bìkítà.
ati Ifipabanilopọ ati awọn iwa aiṣedede miiran to n sẹlẹ lorile ede Naijiria.
"san juan ( , , láti "" san juan bautista "" "" jòhánnù onítèbomi mímó "" ) ní olúìlútitóbijùlo ní puerto rico ."
Abdulrazaq ni ijiroro awọn da lori ọna ati mu idagbasoke ba awọn ọdọ lawujọ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù BBC: A fẹ mọ idi tijọba Eko fi kọlu akọroyin wa 21 Ẹrẹ̀nà 2018 Àkọlé àwòrán, BBC nfẹ kijọba ipinlẹ Eko fun awọn akọroyin lominira alti sisẹ wọn laisi atako Ileesẹ agbohunsafẹfẹ BBC ti bu ẹnu atẹ lu iwa abuku ti awọn osisẹ ijọba ipinlẹ Eko se si akọroyin wọn kan nigbati wọn fi tipa-tipa gba ẹrọ agbohunsilẹ akọroyin naa, ti wọn si pa aworan to ka silẹ nibẹ rẹ.
Awọn alatako rẹ si ti koju rẹ pe, eyi jinna si ootọ nitori, gẹgẹ bi wọn ṣe sọ, ọwọja awọn agbebọn naa tun ti gberu sii.
Ondo: Iya lu ọmọ pa nítori ẹgbẹ̀rún mọkànlélógun Naira
Ijinigbe ile ẹko Dapchi: Oun ta mọ nipa rẹ
 ní Ọjọ ́ kẹta oṣù kẹrin , richmond , virginia , Ìpínlẹ ̀ Ìṣọ ̀ kan , bọ ́ sọ ́ wọ ́ àwọn ológun àpapọ ̀ .
Oríṣun àwòrán, LASEMA Ninu atẹjade ti ileeṣẹ to n risi iṣẹlẹ pajawiri nipinlẹ Eko, LASEMA fi lede ni wọn ti sọ wi pe ọkọ to n gbe oti lọ lo yidanu sọri ọkọ meji, ti ohun to wa ninu rẹ si danu.
O ni akọsilẹ wa pe lasiko awọn asaaju Fayemi, awọn ọba safihan ẹmi ifọwọsowọpọ ati igboya, ti wọn si koju awọn alagbara ogun lati Ibadan fun odidi ọdun mẹrindinlogun, Fayemi si jẹ ọkan lara awọn to n janfaani ogun rere tawọn ọba Yoruba fisilẹ, itan ti wa fẹ maa fi oju awọn alalẹ rẹ gbolẹ bayii.
Ó fi àwọn ọmọ ogun yòókù sí abẹ́ Abiṣai, arakunrin rẹ̀, wọ́n sì dojú kọ àwọn ọmọ ogun Amoni.
Falling Containers: Ilé ẹrù náà ló já bọ́ lé ọkọ̀ akérù lórí
Ìdí rèé tí a fi ni kí a tan ìmọlẹ̀ sí àwọn ǹkan ti o yẹ kí ẹ mọ̀ nípa òfín Sharia.
Wọ́n wá àwọn ẹlẹ́rìí èké tí wọ́n sọ pé, “Ọkunrin yìí kò yé sọ̀rọ̀ lòdì sí Tẹmpili mímọ́ yìí ati sí òfin Mose.
Fidio bi wọn se gbe Fayose lọ sile iwosan si lo wa nisalẹ yii.
Opọ awọn eniyan ni wọn n woye pe Ta ni Sadiya Umar Farouq tí ìròyìn ń gbé pé òun ló fẹ́ dí ìyàwó tuntun Buhari?
A kò ní kó egungun wọn jọ, bẹ́ẹ̀ ni a kò ní sin wọ́n.
Jesu sọ fún un pé, “Ǹjẹ́, ríran.
Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Commonwealth scholarship 2020/2021: Wo ìlànà ìforúkọsílẹ̀ fún ẹ̀kọ́ ọ̀fẹ́ Ph.
won, orile-ede Croatia si wa nipo karun un.
Coronavirus: Ọmọ ilẹ̀ Amẹrika kú sí Ekiti Èyí ni ipa tí àdínkù owó epo bẹtiró yóò mú bá ọ̀rọ̀ ajé Nàìjíríà Ireti wa pe iya ati baba Gold Kọlawọle ni yoo ṣiwaju awọn ẹlẹri marun tawọn agbẹjọro ijọba yoo pe jade loni nile ẹjọ.
Ọwọ tẹ afẹsunkan naa lẹyin igba ti Ọba Benin, Ọba Ewuare keji, kilọ̀ fun awọn ọdọ ki wọn ye ti ọwọ bọ sise oogun owo, ti yoo jẹ ki wọn maa ji pata kiri.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Biodun Fatoyinbo: Mò ń gbé Busola Dakolo lọ ilé ẹjọ́ 28 Òkùdu 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 29 Òkùdu 2019 Lẹyin awuyewuye tó tẹle ifòròwanilẹnuwo kan, ninu eyi ti Busola to jẹ iyawo olorin takasufe Timi Dakolo, ti fẹsun ifipabanilopọ kan Alufaa ijọ COZA ni Abuja, Biodun Fatoyinbo, pasitọ naa ti ni oun yoo gba ile ẹjọ lọ lori ọrọ naa.
Osere tiata lapa oke ọya, Rabi Ismaila: Oṣere tiata lapa ariwa ilẹ Naijiria ni Rabi Ismaila, to si fi ilu Kano ṣe ibudo.
 iṣẹ ́ arọ ́ túmọ ̀ sí kí a rọ nǹkan tuntun jáde fún ìwúlò ara wa.
Nkan to waye yii kii ṣe ajoji ni ilẹ Amẹrika labẹ ofin iwa ọdaran, ilana 48 maa n faaye gba ijọba da ipẹjọ ti wọn ti kọkọ pe fun eniyan tẹlẹ nu.
ko si nkan ti oju awọn to n wo wa nile ko le ri o, a kan maa n f'oju kere akiyesi awọn onworan ni.
Èmi yìí kan náà ni ó wá sí ọ̀dọ̀ àwọn tèmi, àwọn tèmi kò sì gbà mí.
Pilatu bá pàṣẹ pé kí wọ́n fún un.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù #LIVBAR:Oróò!
Ruga Settlement: Ààrẹ Muhammadu Buhari ti dá èròǹgbà láti dá àgọ́ daran-daran sílẹ̀ dúró
“Mo ṣebí a pàṣẹ fun yín pé kí ẹ má fi orúkọ yìí kọ́ ẹnikẹ́ni mọ́?
Ekeji náà kú, ati ẹkẹta, títí tí àwọn mejeeje fi kú.
Fun ẹkunrẹrẹ lẹsẹlẹsẹ lori bi ere idaraya Winter Olympics naa se n lọ, ẹ le kan si ẹka iroyin BBCTV, Redio, gbogbo ẹrọ ayelujara ti BBC ati ti oju opo BBC Sports.
"Saraki sọ pé ""O kú oríire Dókítà Kayode Fayemi, Gómìnà tí ìpínlẹ̀ Ekiti ṣẹ̀ yàn lórí àṣeyọrí rẹ nínú ìdìbò gómìnà lánàá."
A gbọ pe ni igba ti ẹgbẹ naa ṣẹṣẹ n bẹrẹ, niṣe ni awọn ọmọ ẹgbẹ naa yoo ko ara wọn jọ lọ si ibi ayẹyẹ ti wọn ko pe wọn si.
Ijoba apapo lorile-ede Naijriia so pe awon ti ni adehun alagbada, eleyi ti o tun mo siadehun ti o fese mule pelu egbe awon osise ile eko giga fafiti(Academic StaffUnion of University, ASUU), lati fopin si iyanselodi ose marun un ti egbe ohungbenu le lati ojo karun un osu kokanla odun ti a wayii.
Olubadan: Ìpàdé àláàfíà wáyé láàrin Olubadan àti àwọn àgbà ìjòyè tí Ajimobi sọ di ọba.
Wọn ti kọkọ gbe ọmọ yii lọ si ileewosan Dalhatu Arab ni Nasarawa, ṣugbọn nigba ti ko lee gbera, wọn ba tun gbe e lọ sile iwosan ijọba to wa ni fasiti ilu Jos, nibi ti ireti wa pe yoo ṣe iṣẹ abẹ bii mẹsan.
Gusu nile igbimo asofin lowo-lowo bayii.
Ẹwẹ, a gbọ pe lati inu oṣu keji ọdun ni ileeṣẹ ti gba ile ṣugbọn arakunrin naa kii fibẹẹ gbe ile ọhun titi di asiko yii.
Oṣere sinma ibalopọ, ti awọn elede Gẹẹsi n pe ni porn tabi blue film, ni Jolaosho, ti inagijẹ rẹ n jẹ King Tblak HOC.
Àwọn olùgbàlà yóo lọ láti Sioni,wọn yóo jọba lórí òkè Edomu;ìjọba náà yóo sì jẹ́ ti OLUWA.
Toma Unu: Ọmọbìnrin tó ń fi ẹsẹ̀ rẹ̀ ya àwọran nítori pe ó ni ìpènija ọpọlọ
Ọjọ́ ìdààmú Moabu fẹ́rẹ̀ dé, ìpọ́njú rẹ̀ sì ń bọ̀ kánkán.
    Mo rò pé ọ̀rọ̀ tí mo sọ yìí kò ní bí yín nínú.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Sex Offenders: NAPTIP ní àwọn aráàlú tó jẹ́ ẹ̀jẹ̀ kannáà kìí fẹ́ kí ẹbí wọn ṣẹ̀wọ̀n ìfipábánilòpọ̀ 26 Bélú 2019 Oríṣun àwòrán, Others Ọjọ Aje ni igbakeji aarẹ, Ọjọgbọn Yemi Osinbajo sefilọlẹ iwe akọsilẹ ti yoo maa gbe orukọ awọn eeyan to ba jẹbi ẹsun ibalopọ lọna aitọ sita.
Lonii ni won se ibura fun gomina Kayode Fayemi gege bi gomina tuntun fun ipinle Ekiti.
Ó rí àwọn mààlúù meje kan tí wọ́n sanra rọ̀pọ̀tọ̀ rọ̀pọ̀tọ̀, tí ara wọ́n sì ń dán, wọ́n ti inú odò náà jáde wá, wọ́n sì bẹ̀rẹ̀ sí jẹ koríko létí odò.
Nígbà tí wọn kò rí wọn, wọ́n fa Jasoni ati díẹ̀ ninu àwọn onigbagbọ lọ siwaju àwọn aláṣẹ ìlú.
"Ki gomina le ri orukọ wọn kọ silẹ ninu iwe itan to daa ni ipinlẹ Oyo, agbọgbọn'ti ni ki wọn maa gbọ orin maa jo lọ mo n wo ẹyin rẹ tawọn araalu kan n kọ fun wọn""."
" Àkọ ́ bí ọmọ rẹ ̀ jéọkùnrí tí orúkọ rẹ ̀ ń jẹ ́ "" Ẹ ̀ fẹ ̀ "" ( the humorist ) ; Ẹ ̀ fẹ ̀ ma ń dàwọ ̀ n bojú láti fi àwọn ènìyàn ṣe yẹ ̀ yẹ ́ àti àwàdà nítorí orúkọ rẹ ̀ ."
 Ó di igbákejì apàṣẹ ti i corps lábẹ ́ nguyễn khánh , tí ó sì bá ọ ̀ gá rẹ ̀ gbàjọba lẹ ́ yìn oṣù mẹ ́ ta .
 won fun ni ebun lasker ni 2009 .
“Bí ó bá ṣeéṣe láti wọn ìbànújẹ́ mi,tí a bá sì le gbé ìdààmú mi lé orí ìwọ̀n,
Ọjọ Kọkanla, oṣu kọkanla, ọdun 2020 yii ni Adele naa pe ẹni ọdun marundinlọgbọn laye.
Bakan naa lo ni bi wọn se n gba awọn osisẹ sẹnu isẹ gbọdọ di atungbeyẹwo ati bi wọn se n se iwuri fun awọn ti o jafafa lẹnu isẹ.
Osinbajo yoo tun maa soro lori eto oro aje.
ní ọjọ́ tí Ọlọrun yóo rán Jesu láti ṣe ìdájọ́ ohun ìkọ̀kọ̀ gbogbo tí ó wà ninu eniyan gẹ́gẹ́ bí ìyìn rere tí mò ń waasu.
" "" Àjèjé ọwọ ́ kan kò gbẹ ́ rù dóri "" àjùmọ ̀ ṣè wọn yìí mú ìlọsíwájú wá fún ìlú náà lọ ́ pọ ̀ lọ ́ pọ ̀ "" abiyamọ kì í gbọ ́ ẹkún ọmọ rẹ ̀ kò má tatí were "" ni ti àwọn ọmọ Ìjẹ ̀ bù - jẹ ̀ ṣà sí ohunkóhun tí wọ ́ n bá gbọ ́ nípa ìlú wọn ."
Eko: A ti din lara owo-ori ilẹ ati ile ku
Lojoojumọ ni àwọn eniyan ń wá sọ́dọ̀ Dafidi láti ràn án lọ́wọ́; títí tí wọ́n fi pọ̀ tóbẹ́ẹ̀ tí wọ́n dàbí ogun ọ̀run.
Ìríwísí àwọn aráàlú bí EFCC ṣe kó afurasí ọmọ yahoo 49 ní Ibadan Àwa ò ri lẹ́ta kankan gbà láti ọ̀dọ̀ Malami lóri ọ̀rọ̀ àwọn alága Kansu - Makinde Mí ò le nífẹ̀ẹ́ obìnrin Nàìjíríà kankan mọ lẹ́yìn ti mo ti tọ́ obìnrin òyìnbó wò- Issa Kini akiyesi ti awọn eniyan gbọdọ mojuto?
 Ìmìtìtì àpàlà gbòòrò si pẹ ̀ lú àsìkò , ó fi orin kúbànì ṣe àtẹ ̀ gùn tí ó sì di gbajú-gbajù ní kánádà .
Nígbà tí o bá wọn wí, wọ́n sá,nígbà tí o sán ààrá, wọ́n sá sẹ́yìn.
Àwọn olùdarí wọn pàápàá kò mọ nǹkankan.
Òun yìí ni òjíṣẹ́ ní ilé ìsìn tí ó mọ́ jùlọ tíí ṣe àgọ́ tòótọ́, tí Oluwa fúnrarẹ̀ kọ́, kì í ṣe èyí tí eniyan kọ́.
 Àlàá , Àkin àti ilésanmí fi kọ ́ kọ ́ rọ ́ náà dán séèfù wò , kò sí i .
Ọmọlójú ìyá rẹ̀,ẹni tí kò ní àbààwọ́n lójú ẹni tí ó bí i.
Oriṣiriṣi fidio ni wọn ti fi sita lati fi ṣafihan awọn iṣẹ ibi ti wọn n ni awọn n ṣe fawọn ara ilu ni agbegbe yii.
Ọjọ Aiku tii ṣe ọjọ kẹtadinlọgbọn oṣu kẹsan an ọdun 2020 ni ajijakandi ọmọbibi orilẹede Naijiria to jẹ aṣaaju ninu ija UFC, Israel Adesanya to yoo koju Paulo Costa ọmọ ilẹ Brazil.
Àwọn ọlọ́pàá ti gbé Emia ìlú Kano, Lamido Sanusi kúrò ní ààfin rẹ̀ lẹ́yìn tí ìjọba rọ̀ ọ́ l'óyè Ìdí mẹ́ẹ́rin tí sísùn ní ìhòhò lé gbà ṣe ara a rẹ l'óore Ìròyìn Yàjóyàjó - Nàìjíríà kéde èèyàn míràn pẹ̀lúu àrùn Coronavirus Buhari, ìjọba rẹ ń jọ bí ègún f'órílẹ̀èdè Nàìjíríà-Oyedepo Àwọn ọmọ Naijiria to ti kú lóri pápá lásìkò ìfẹsẹwọ́nsẹ Sowore fikun ọrọ rẹ pe abadofin naa ko nibii re, koda o ni abadofin naa ti ku patapata.
Oríṣun àwòrán, CAF Naijiria fi Cameroon paa ni ipele ẹlẹni mẹrindinlogun pẹlu ami ayo mẹta si meji ki wọn to ṣeya fun South Africa ni ipele ẹlẹni mẹjọ.
Bí Jehu ti gba ẹnu ọ̀nà wọlé, Jesebẹli kígbe pé, “Ṣé alaafia ni, Simiri?
O ni oun naa n fẹ ẹsan pe ki wọn gba pe ohun ti awọn ọlọpaa ṣe ko dara si ọmọ oun naa.
Bẹ́ẹ̀ ni wọ́n bẹ̀rẹ̀ sí pa wá ní ọ̀kọ̀ọ̀kan tí mo ń réti ọjọ́ tí ikú yóó kàn mí, ṣùgbọ́n bí wọ́n ti ń gbé oúnjẹ fun wa tóó nì, b kò jẹ oúnjẹ wọn, àkàrà tí ìyá mi fún mi ni mo ń jẹ òun náà sì ni àwọn ìyókù ẹgbẹ́ mi, àwa tí a jọ kúrò nínú ilé Baba-onírùngbọ̀n ń jẹ, eeléyìí sì ṣe wá ní oore púpọ̀ nítorí kò jẹ́ kí a sanra sí i àti pàápàá a bẹ̀rẹ̀ sí rù níbi tí a ti ń ronú ohun tí a o ṣe.
Opo ni ikolu iji lile ohun ba loju orun, ti o si wo ile ohun mo won lori, ti awon miiran si padanu emi won latari ikolu ina monamona.
oko ayokele Toyota Highlander kan; ati awon oko ti ko din ni mejidinlogoji ti
Ẹnu yóo ya àwọn ará ìwọ̀ oòrùn,ìwárìrì yóo sì mú àwọn ará ìlà oòrùn,nítorí ohun tí yóo ṣẹlẹ̀ sí i.
Jesu bá pàṣẹ fún ẹ̀mí èṣù náà kí ó jáde kúrò ninu rẹ̀, ara ọmọ náà sì dá láti ìgbà náà.
Ìtàn sọ wí pé eku ni àdán tẹ́lẹ̀ ki ìjà nla tó bẹ́ sílẹ̀ laarin eku àti ẹyẹ.
Adetunji wa fi kun un  pe, ko si ofin kankan
RAMADAN: Onímọ̀ ẹ̀sin sọ nípa isẹ́ láádá àti làádà nínú oṣù mímọ́
Bí àwọn ẹlòmíràn kò bá tilẹ̀ gbà mí bí aposteli, ẹ̀yin gbọdọ̀ gbà mí ni, nítorí èdìdì iṣẹ́ òjíṣẹ́ mi ninu Kristi ni ẹ jẹ́.
O tun so pe’’lasiko eto idibo awon oloselu maa lo awon odo fun iwa janduku, dida wahala sile, jiji ibo  gbe lati da wahala sile lawujo ati awon iwa ipanle miiran.
Are buhari ro iko agbaboolu Super Eagles lati gbe asia orile ede yii ga, nipa
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Oba Adedokun Abolarin ti Oke Ila: Ó ya ọ̀pọ̀ tó súnmọ́ mi lẹ́nu bí mo ṣe ń kọ́ Atẹjade naa fi kun un pe ọga ọlọpaa to wa lagọ ọlọpaa Adatan lo ko awọn ọtẹlẹmuyẹ lọ si ile obinrin naa ti wọn si fi panpẹ ọba mu.
Ijọba ilẹ Gabon ti ni alaafia ti pada si eto oṣelu orilẹede naa lẹyin ti awọn ologun gbiyanju lati gba ijọba orilẹede naa.
Wọ́n gbé ère wọn kalẹ̀ ninu ilé tí à ń fi orúkọ mi pè, wọ́n sì ti sọ ọ́ di aláìmọ́.
Lẹyin iṣẹju mẹta pere ti wọn bẹrẹ ere bọọlu ọhun ni ẹlẹsẹ ayo, Odion Ighalo gba bọọlu sawọn eyi to fun Naijiria lanfani lati siwaju ninu ifẹsẹwọnsẹ to kangun si aṣekagba.
9 181016 Orilẹede Switzerland 8641 101.
”Aare tesiwaju pe, osi ati aini
O ni iyi nla lo jẹ fun oun layyi farapọ mọ awọn ọdọ yii lọna ati fi erongba wọn han ati pe oun yoo rii daju pe James Nwafor jẹjọ lẹyin to gba iṣẹ lọwọ rẹ.
Ẹ mọ̀ bí mo ti fi ìrẹ̀lẹ̀ ati omi ojú sin Oluwa ní ọ̀nà gbogbo ninu àwọn ìṣòro tí mo fara dà nítorí ọ̀tẹ̀ tí àwọn Juu dì sí mi.
"Èyí ni ohun tí Ọọ̀ni sọ nípa Àrẹ̀mọ rẹ àti ètùtù tó ń ṣe lọ́wọ́ Àwọn ohun tó yẹ kí o mọ̀ nípa Ọ̀ọ̀ni Ilẹ̀ ifẹ̀ Àwọn ọbá aláye ilẹ̀ Yorùbá márùn-ún pẹ̀lú ọ̀pá àṣẹ wọn ""Àsìkò yí ló yẹ kí Yorùbá fi ìmọ̀ ṣọ̀kan"" Ilé ẹjọ́ dájọ́ ẹgba mẹ́ẹ̀dóògún fún ọ̀daràn tó jí Iphone ní Kaduna Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ìgbátí ìgbámú àná látọwọ́ sọ́jà obìnrin ti bá arákùnrin náà dé iléèwòsàn Ki wa ni igbesẹ ti Ọba fi le ri ọmọ tuntun nilẹ Yoruba?"
Ọ̀pọ̀ àwọn aboyún ni ẹ̀rù ń bà láti láti lọ sí ilé ìwòsàn fún àyẹ̀wò ìgbàdédéìgbà tí ó yẹ kí wọn máa lọ fún nítorí wọn fẹ máa tẹ́lẹ̀ àṣà sún - fúnmi - ń - sún fún ọ.
Àwọn àwòrán àwòmáleèlọ ní ìpàdé ìfọ̀rọ̀wérọ̀ BBC Yorùba ti Ogun Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Gbogbo olùdíje Ogun fi dá àwọn ènìyàn lójú pé.
Ṣaaju ni banki apapọ Naijiria, CBN, ti kọkọ gba aṣẹ lọwọ ile ẹjọ lati kan an nipa fun awọn ile ifowopamọ pe ki wọn gbẹsẹle apo gbogbo awọn eeyan to ṣagbatẹru iwọde ọhun.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Sleeping naked: Ìdí mẹ́ẹ́rin tí sísùn ní ìhòhò lé gbà ṣe ara a rẹ l'óore 8 Ẹrẹ̀nà 2020 Oríṣun àwòrán, Getty Images Ọpọlọpọ eniyan lo maa n wọ kaba, ṣokoto atẹwu, ẹwu nla, awọtẹlẹ ati oriṣiriṣi aṣọ miran lati sun ni alẹ nitori pe o tẹ wọn lọrun lati ṣe bẹ.
Absalomu bá bi í pé, “Kí ló dé, tí o kò fi ṣe olótìítọ́ sí Dafidi ọ̀rẹ́ rẹ mọ́?
Nígbà tí mo fi tọkàntọkàn pinnu láti wá ọgbọ́n ati láti wo iṣẹ́ tí wọn ń ṣe ní ayé, bí eniyan kì í tíí fi ojú ba oorun tọ̀sán-tòru, 
Mo gbọ́ ohùn ńlá kan lẹ́yìn mi bí ìgbà tí fèrè bá ń dún, 
Àlàyé rèé lórí ááwọ̀ Femi Fani-Kayode àti Tunde Bakare Àwọn àjàkálẹ-àrùn tó ti wáyé rí ṣáájú Coronavirus Ta ni Ọ̀jọ̀gbọ́n àkọ́kọ́ nípa ìmọ̀ ọ̀daràn ní Nàíjíríà, Femi Odekunle tí Covid-19 pa?
 ni february 2008 , awon adugbo miran tun je didasile lati mu iye apapo de 170 ni ghana .
Ọkan lara wọn alaabo ilu to wa ni adugbo naa to mọ nipa ọrọ naa, Ishola Agbodemu ni awọn ọmọ ẹgbẹ okunkun n ṣoṣẹ ni agbegbe naa lọpọlọpọ.
37 Ẹ ṣe àyẹ̀wò àwọn òfin wọnyí, nítorí wọn jẹ́ òtítọ̀ àti òdodo, àti pé àwọn àsọtẹ́lẹ̀ àti àwọn ìlérí tí ó wà nínú wọn gbogbo ni yíò wá sí ìmúṣẹ.
Ẹ̀yin eniyan mi, ẹ ranti ète tí Balaki, ọba Moabu pa si yín, ati ìdáhùn tí Balaamu, ọmọ Beori, fún un.
Òkìkí Jesu wá kan ká gbogbo ìgbèríko Galili.
Naijiria ku ajọdun keresimesi ati odun to n bọ lọna.
Die lara awon oludibo ti won baa won oniroyin soro so pe, awon ti ji kuro nile lati le tete dibo ki won si pada sile lasiko.
Ọbadaya jẹ́ ẹni tí ó bẹ̀rù OLUWA gan-an.
Wo bí bàbá ẹni ọdún 67 yóò ṣe tún lo ọdún 25 ayé rẹ̀ lẹ́wọ̀n Gbogbo ohun tí ènìyàn nílò láti dári ni Tinubu ní - APC Ìpínlẹ̀ Osun yóò mú àyípadà bá àwọn ilànà ìṣèjọba Rauf Aregbesola Awọn lọbalọba ni ipinlẹ naa ko gbẹyin nibi ayẹyẹ ifilọlẹ iṣẹ akanṣe naa.
gege bi aare orile ede yii, nitori ise gudu gudu meje ti o ti gbe se ni ipinle
Amọ awọn miran sọ wi pe, Tinubu sọrọ gẹgẹ bi adari ẹgbẹ oselu ni, kii se wi pe o se atilẹyin fun ẹya kan yato si omiran.
Wolii Ayodele, ẹni to n sọ asọtẹlẹ nipa awọn isẹlẹ ti yoo waye ninu ọdun tuntun 2021 wa sekilọ fun gbogbo awọn eeyan to n foju sọna pe ipo aarẹ yoo wa si guusu Naijiria lati gbagbe ero naa.
Ṣugbọn, kò lọ ní gbangba, yíyọ́ ni ó yọ́ lọ.
Wọn óo gé àwọn tí wọn dára jùlọ ninu àwọn igi Kedari yín,wọn óo sì sun wọ́n níná.
Ìjà ni ó dé pẹ̀lú èmi àti ẹnìkan ni òde-ọ̀run ni wọ́n wí pé mo ṣe àbòsí s’’i Ọlọ́run Ọba, èyìínì ni àwọn ẹ̀dá abàmì wọ̀n-ọnnì bá fi pinnu wí pé àfi dandan bí mo bá kúrò ni òde ọ̀run.
 wọ ́ n ṣẹ ́ gun ọmọ ogun ilẹ ̀ faransé ní ogun nile ní 1798 .
Wọ́n ń sọ fún àwọn òkè ati àpáta pé, “Ẹ wó lù wá, kí ẹ pa wá mọ́ kúrò lójú ẹni tí ó jókòó lórí ìtẹ́ ati ibinu Ọ̀dọ́ Aguntan.
Awọn yoku ni Rafiu Mutiu ẹni ọdun marundinlogoji, Fatai Akanji ẹni ọdun mọkandinlaadọta ati Rafiu Modinat ẹni ọdun mọkandinlọgbọn.
Atejade ohun tun so pe, “o je edun okan lati ri bi awon eniyan se n padanu-emi ati dukia ninu laasigbo, amo, a ni igbagbo ninu ominira ati eto omo eniyan”.
Ṣugbọn OLUWA ń bẹ ninu tẹmpili mímọ́ rẹ̀, kí gbogbo ayé parọ́rọ́ níwájú rẹ̀.
Gomina ipinlẹ Eko ni asiko to to yẹ ki wọn faaye gba awọn ipnilẹ lati ni ọlọpa tiwọn, koda, o ni ọrọ naa ti pẹ ju.
A óo fọ́ àwọn ère oriṣa yín, a óo pa wọ́n run, a óo wó pẹpẹ turari yín, iṣẹ́ yín yóo sì parẹ́.
Ẹ gbé àwọn tí ipò wọn rẹlẹ̀ ga, kí ẹ sì rẹ àwọn tí ipò wọn wà lókè sílẹ̀.
Ẹ ò ranti wipe ọrọ ogun ikọ olomi Codeine di ọrọ ti gbogbo awọn eniyan orilẹede Naijiria n da si nigba ti BBC gbe iwadii kan jade to ṣafihan bi ogun na sẹ n ṣọṣẹ lara awọn ọdọ.
Ojú gbogbo eniyan ń wò ọ́,o sì fún wọn ní oúnjẹ wọn ní àsìkò.
Yóo kó àwọn oriṣa wọn, ati àwọn ère wọn lọ sí ilẹ̀ Ijipti, pẹlu àwọn ohun èlò olówó iyebíye wọn tí wọ́n fi wúrà ati fadaka ṣe; kò sì ní bá ọba Siria jagun mọ́ fún ọdún bíi mélòó kan.
Nígbà tí ọkùnrin yìí parí ọ̀rọ̀ rẹ̀ inú bí àwọn èranko púpọ̀ sí ẹ̀dá burúkú náà tí ó ń fọ ọkùnrin yìí ní akèǹgbè ẹmu.
Kalebu, ọmọ Jefune, bí ọmọ mẹta: Iru, Ela, ati Naamu.
 ní ìjọba ìbílẹ ̀ Òkè-Ẹ ̀ rọ ̀ ẹ ̀ wẹ ̀ , wọn a máa sọ Ìgbómìnà ni Ìdọ ̀ fin .
Lẹ́yìn tí Jesu ti fi gbogbo ìlànà wọnyi lélẹ̀ fún àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ mejila tán, ó kúrò níbẹ̀ lọ sí àwọn ìlú wọn, ó ń kọ àwọn eniyan ó sì ń waasu.
Eeyan mẹta lati Kaduna, meji ni Niger, Ondo ati Plateau lo ni covid-19 lọjọ Aje.
Iko agbaboolu ori tabili Naijiria ti bere ifigagbaga won ninu idije Commonwealth Games to n lo lowo lorile-ede Australia.
Àkọlé àwòrán, Ikolu ojoojumọ yẹ ko dopin ni South Africa O le ni ida mẹtdinlọgbọn ninu ogorun un awọn eniyan ti wọn padanu iṣẹ oojọ wọn.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ìṣẹlẹ iyinbon APC Ekiti : Ki gaan lo ṣẹlẹ?
Bí mo bá sọ fún ọ̀kan pé, ‘Lọ!
Oun lo ni idagbasoke awọn ileeṣẹ julọ ni Afrika - ṣugbọn otun jẹ ọ̀kan lara awọn orilẹede ti aidọgba pọ si ju ni agbaye.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ọmọ Nàìjíríà fárígá lórí olú iléeṣẹ́ Nàìjíríà tí wọ́n wó ní Ghana Ṣugbọn awọn alaṣẹ Ghana ni bẹẹ kọ ni ọrọ ṣe ri nigba ti ijọba Naijiria naa fọrọ ikilọ ranṣẹ pe ki wọn ṣọra gidi gan.
Oloye Ọlajide ni oniruuru ẹlẹgbẹjẹgbẹ to jẹ ti ọdọ nilẹ Yoruba ni Oloye Adams yoo ko jọ, kii si se ẹgbẹ OPC nikan, to fi mọ ọpọ ẹgbẹ awọn agbaagba pẹlu, to fi mọ YCE, awọn ọba alaye, ati oloselu lati ri daju pe a le awọn eeyan to ba fẹ dunkoko mọ wa jinna tefetefe.
Ohun ti o n ba spọ lẹru ni bi awọn agbebọn Boko Haram ṣe n lo awọn smọde gẹgẹ bi irinsẹ iku pẹlu ado oloro.
Oṣiṣẹ yii wa lara awọn to ṣiṣẹ lasiko idibo gomina ati ti aarẹ tọdun 2019.
Wo àwọn òṣìṣẹ́ kólẹ̀-kódọ̀tí tó ń fi ẹ̀mí wọn wéwu kí Abuja leè mọ́ tónítóní Ènìyàn 653 míràn tún kún iye àwọn tó ní COVID-19 ní Nàìjíríà Mo ti bẹ̀rẹ̀ sí ń bá àwọn tí a jọ díje nínú ìdìbó abẹ́lé sọ̀rọ̀ kí àláàfíà léè jọba - Akeredolu Èèyàn 576 míràn tún kún àwọn tó ní àrùn COVID-19 ní Nàìjíríà Wo àwọn nkan tó yẹ́ kí o mọ̀ nípa 'Awawa Boys', ọ̀kan lára ẹgbẹ́ òkùnkùn tó n dá Eko rú Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Olofa ina: ẹ parí òwe yìí pé ìgbà tí ara bá tu ìgbẹ́ láà ri eṣú.
Obinrin yìí bá sálọ sí aṣálẹ̀, níbìkan tí Ọlọrun ti pèsè sílẹ̀.
Tí ẹ o ba gbàgbé ètò ìgbaniwọlé ọlọpàá náà bẹ̀rẹ̀ ní òpin ọdún to koja.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Nkechi Blessing: Àgbo tí yóò mú mi tíírín ti jẹ́ kí ìbàdí mi lọ sílẹ̀ 10 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Oríṣun àwòrán, nkechiblessingsunday Pupọ ninu awọn eeyan to sanra lo maa n wa ọna lati jo, yala nitori ilera ara wọn tabi nitori oju ti awọn eeyan fi n wo wọn lawujọ.
Lara awọn mẹtala ti wọn mu naa jẹ awọn ẹlẹgbẹ okunkun Aiye, ti wọn si wọn si ti gbe wọn lọ si atimọle.
Wọ́n mọ iṣẹ́ ibi í ṣe dáradára; àwọn ìjòyè ati àwọn onídàájọ́ wọn ń bèèrè àbẹ̀tẹ́lẹ̀, àwọn eniyan ńlá ń sọ èrò burúkú tí ó wà lọ́kàn wọn jáde; wọ́n sì ń pa ìmọ̀ wọn pọ̀.
Minisita fikun un oro re pe, ijoba yoo wa ona lati san awon owo won ohun lojuna ati fi opin siiyanselodi naa patapata.
Àlàó tí ó tọ́jú Akin àti Ilésanmí nígbà tí wọ́n dé Ifẹ̀ kò fẹ́ran oògùn ìbílẹ̀ Ọ̀sanyìnnínbí sọ pé Orímóògùnjẹ́ kì í finú tan Àlàó yìí Àwọn ohun tí ó tún yẹ kí á ṣe àkíyèsí ní orí yìí ni ìwọ̀nyí: Awódélé wá kí Ọ̀sanyìnnínbí Àkànbí, àbúrò Aríyìíbí, tí Ọ̀sanyìnnínbí nígbà tí ó ń ṣàìṣàn ní ó dúró fún Ọ̀sanyìnnínbí ní àgọ́ ọlọ́pàá (Ìyẹn ni pé Àkàbí tí Ọ̀sanyìnnínbí wòsàn ni ó dúró fún òun náà) Ní ọjọ́ tí àwọn Ọ̀fíntótó wá sí ilé Ọ̀sanyìnnínbí, nnkan bí agogo mókànlá ni ó wọlé àwọn Òfíntótó sì dé ilé rẹ̀ ní aago méjì kọjá ìṣẹ́jú mẹ́wàá.
"’' ""Wọn sọ fun wa pe ninu àgbàrá ẹ̀jẹ̀ ni wọn ti ba aburo mi, ti wọn ti ya pátá rẹ, sikẹẹti rẹ naa wa ni kika soke, ẹwu rẹ si ti kun fun ẹ̀jẹ̀."
Ami ayo mẹrin si meji yii ni wọn jọ gba de opin ti idije ife ẹyẹ agbye 2018 fi wa sopin ti gbogbo e tun di 2022.
Awọn agbebọn naa pa awọn oṣiṣẹ alaabo ọhun, ti ọ̀kan lara wọn jẹ awakọ ọkọ̀ to gbe wọn, ki wọn to o gbe awọn oṣiṣẹ meji naa.
04 million, nigba ti ile-ifowopamo FBN ni oja ti o ti to 21.
ó wí fún wọn pé, “Ẹ kọjá lọ níwájú Àpótí Majẹmu OLUWA Ọlọrun yín, sí ààrin odò Jọdani, kí ẹnìkọ̀ọ̀kan sì gbé òkúta kọ̀ọ̀kan lé èjìká rẹ̀.
Ẹkún sisun Dókìtà Kadiri ni ẹkún wọn kìí ṣe eyi ti eniyan ń sun, ti yóò simi, ẹkun asu-un-dakẹ ni.
" Èrè ti Nàìjíríà yóò jẹ nínú Báwo ni ọ̀rọ̀ Iran àti US yìí ṣe kan ilẹ̀ adúláwọ̀ gan Njẹ́ ẹ mọ̀ pé orílẹ̀-èdè Nàìjíríà ló n wo 'Blue film' jù?
Ẹ níláti fi ìyá wọn sílẹ̀ kí ó máa lọ ṣugbọn ẹ lè kó àwọn ọmọ rẹ̀, kí ó lè dára fun yín, kí ẹ sì lè pẹ́ láyé.
Ó wípé ọ̀dọ̀ wọn lòun ti kọ́kọ́ tọọrọ owó, ṣùgbọ́n wọn kò fún òun ní nkankan rara.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Coronavirus: Fífi nkan bó ìmu nìkan kò le dènà kíkó coronavirus Ìjọba ìpínlẹ̀ Eko ti ni ki gbogbo ọjà wà ni títì pa, sùgbọ́n.
Ninu ẹ̀kọ́ tí ò ń kọ́ àwọn eniyan, kí wọn rí òtítọ́ ninu rẹ, kí wọn sì rí ìwà àgbà lọ́wọ́ rẹ.
Itiju ni oyun ọmọ naa jẹ fun mi, nitori ipo ti mo wa.
Kidnapping in Nigeria: Arìnrìnàjò kan ṣàlàyé bí orí ṣe ko yọ lọ́wọ́ ajínigbé
Ẹgbẹẹgbẹrun èrò a tẹ̀lé e lọ sí ibojì,àìmọye eniyan a sì sin òkú rẹ̀;kódà, ilẹ̀ á dẹ̀ fún un ní ibojì rẹ̀.
Bí ẹnikẹ́ni bá dá irú ẹ̀ṣẹ̀ yìí, kí ó dá ohun tí ó jí pada, tabi ohun tí ó fi ìrẹ́jẹ gbà, tabi ohun tí wọ́n fi dógò lọ́dọ̀ rẹ̀, tabi ohun tí ó sọnù tí ó rí he, 
N kò ní yìn yín fún èyí.
“Bí ẹnìkan ninu yín bá ní iranṣẹ kan tí ó lọ roko tabi tí ó lọ tọ́jú àwọn aguntan, tí ó bá wọlé dé láti inú oko, ǹjẹ́ ohun tí yóo sọ fún un ni pé kí ó tètè wá jókòó kí ó jẹun?
Ó kọ́ ilé tí òun alára óo máa gbé sí àgbàlá tí ó wà lẹ́yìn gbọ̀ngàn bí ó ti kọ́ àwọn ilé yòókù; ó sì kọ́ irú gbọ̀ngàn yìí gan-an fún ọmọ ọba Farao tí ó gbé ní iyawo.
Òfin àtijọ́ náà ni ọ̀rọ̀ tí ẹ ti gbọ́.
 Ifowosowopo wa  laarin orile-ede Nigeria ati ijoba orile-ede miran lagbaye lori eto irinajo loju ofurufu.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Àwọn òṣìṣẹ́ ilé iṣẹ́ ìròyìn NAN wọ́de lórí ìlànà iṣẹ́ tó mẹ́hẹ 26 Agẹmo 2018 Oríṣun àwòrán, Abdulwahab Àkọlé àwòrán, Awọn oṣiṣẹ NAN ke si'jọba apapọ lati tete wa wọrọkọ fi ṣada lori amojuto igbayegbadun awọn oṣiṣẹ.
Ondo election: Rotimi Akeredolu ti yan Lucky Orimisan Aiyedetiwa gẹ́gẹ́ bíi igbákejì tí wọ́n yóò jọ díje ní Ondo
OLUWA, o ti yẹ̀ mí wò, o sì mọ̀ mí.
Ṣugbọn nitori isede, agbẹjọro kan, Abisola Ogunbadejọ sọ pe awọn to ṣe inawo yii ti bere ibeere fun iwadii boya aye gba wọn labẹ ofin fun ohun ti wọn ṣe tori naa wọn ni atilẹyin onimọ ofin ni Naijira.
Gẹgẹ bi ileesẹ ologun ilẹ wa ti kede bayii, se ni awọn ọmọ ẹgbẹ Boko Haram n da ọgbọn lati maa se okoowo ẹja gbigbẹ, eyi ti wọn n ko wọle lati awọn orilẹede to mule ti orilẹede Naijiria.
Ìgbà tí o sì ti kí wa dáadáa tí ìyá rẹ̀ náà ti sure fún wa tán ni o ṣí ìlẹ̀kùn kan báyìí fún wa.
Nígbà tí ẹ bá rékọjá sí òdìkejì odò Jọdani, ẹ to àwọn òkúta tí mo paláṣẹ fun yín lónìí jọ lórí òkè Ebali, kí ẹ sì fi ohun tí wọ́n fi ń rẹ́ ilé rẹ́ ẹ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Nigeria Elections 2019:Ìbò la ní kí ẹ dì, àwa kò bá tìjà wá Bakan naa ni SEC tun paṣẹ pé ki gbogbo awọn ọmọ igbimọ alaṣẹ to n ṣakoso ileeṣẹ ọhun tọrọ kan kọwe fipo wọn silẹ.
Fásitì OAU ní ohùn ọ̀jọ̀gbọ́n Richard Akindele ni wọ́n ká sílẹ̀
Aliyu,, to jẹ akekoo, ti awon odaran kan ko sinu wahala  nipa gbigbe oogun oloro sinu ẹru rẹ, ti o si
Ọwọ́ ikọ̀ aláàbò STF tẹ afurasí mẹ́jọ tó lọ́wọ́ nínú ìpànìyàn lemọ́-lemọ́ọ Gúúsù Kaduna A ti bẹ̀rẹ̀ ìwádìí lórí ibì tí owó tí àwọn adigunjalẹ̀ gbé ní banki Okeho wọ̀lẹ̀ sí- Ọlọ́pàá Awọn iyawo baba rẹ sọ pe nitori o ni arun ọpọlọ ati warapa, ni wọn ṣe fi sibẹ.
“Nígbà tí ẹ bá jáde lọ láti bá àwọn ọ̀tá yín jà, tí ẹ bá rí ọpọlọpọ ẹṣin ati kẹ̀kẹ́ ogun ati àwọn ọmọ ogun tí wọ́n pọ̀ jù yín lọ, ẹ kò gbọdọ̀ bẹ̀rù wọn, nítorí OLUWA Ọlọrun yín, tí ó kó yín jáde láti ilẹ̀ Ijipti wà pẹlu yín.
Nítorí náà, Elifasi ará Temani, Bilidadi ará Ṣuha, ati Sofari ará Naama lọ ṣe ohun tí OLUWA sọ fún wọn, OLUWA sì gbọ́ adura Jobu.
Ogun Police: Bàbá fìdí ọmọ ọdún márùn ún jó sítóòfù gbígbònà, ó di aláàbọ̀ara torí ó jí ẹja
Mo wí fún wọn pé kí olukuluku kọ àwọn nǹkan ẹ̀gbin tí ó gbójú lé sílẹ̀, kí ẹ má sì fi àwọn oriṣa ilẹ̀ Ijipti, ba ara yín jẹ́; nítorí pé èmi ni OLUWA Ọlọrun yín.
Balogun ẹgbẹ́ agbábọ̀ọ̀lù Belgium Eden Harzard lo ran ikọ̀ rẹ̀ lọ́wọ́ látim gbégbá orókè, pẹlu bi ìfẹsẹ̀wọ́sẹ̀ náà se parí pẹ̀lú àmi àyò méjì si òdò Super Eagles ngbaradi fun Russia 2018 France wọ ìpele àṣekágbá Russia 2018 Ṣé £99m kò pọ̀jù láti ra Ronaldo?
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Soyinka: Háà, ó ṣe.
Wúrà ni wọ́n fi ṣe àwọn ìkọ́ wọn pẹlu, wọ́n sì fi fadaka ṣe ìtẹ́lẹ̀ mẹrin fún àwọn òpó náà.
Idi niyi ti Yorùbá ṣe ma npa a lowe pe “Ẹni tó ni Ẹrú ló ni Ẹrù.
Nítorí náà, ẹ fi èké ṣíṣe sílẹ̀.
Wọ́n diidi fura si i pe o jẹ́ ọmọ ẹgbẹ́ adunkokomọ́ni, Boko Haram.
Kò tún ní pada lọ rí ọba mọ́, àfi bí inú ọba bá dùn sí i tí ó sì ranṣẹ pè é.
Pákó igi sipirẹsi ni wọ́n sì fi tẹ́ gbogbo ilẹ̀ rẹ̀.
xxxxxxxxxxxxxxxxxxxxxxxxxxxxxxxxxxxxxxxxxxxxxxxx Ọlọ́pàá Sars bíi ọgọ́fà fẹ́ sá kúrò ní Èkó Ninu iroyin mi i ẹwẹ, n se lawọn osisẹ ọlọpaa to wa ni ẹka to n gbogun tiwa idigunjale, SARS, ti wọn to ọgọfa niye, ti n kọwe beere pe ki isẹ gbe awọn kuro ni ipinlẹ Eko lọ si ipinlẹ miran, nitori ofiin tuntun kan ti ijọba se.
“Mú alikama ati ọkà baali, ẹ̀wà ati lẹntili, jéró ati ọkà sipẹliti, kí o kó wọn sinu ìkòkò kan, kí o sì fi wọ́n ṣe burẹdi fún ara rẹ.
Koda wọn ti ṣe gbogbo eto bi Abiola yoo ṣe ko lọ si Aso Rock ni Abuja ti eeyan kan dedee wa sọ fun Oloye Abiola pe ko ma lọ sibẹ lọjọ to gbero lati lọ o.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ṣé òótọ ni pé èèyàn leè kó Coronavirus láti ara aṣọ tàbí bàtà?
Ile ẹjọ da a silẹ pẹlu beeli wọn si tun sun ẹjọ rẹ siwaju di ọjọ kẹtadinlogun, oṣu keje.
Ṣugbọn bí ẹ bá kọ̀ ọ́ sílẹ̀, òun náà yóo kọ̀ yín sílẹ̀.
 Oríṣun àwòrán, lasema Gẹgẹ bi ajọ Lasema ṣe sọ, ọkọ agbepo kan to gbe epo bẹtiro ẹgbẹrun lọna mẹtalelọgbọn lita lo kọlu ọkọ agbepo miran loju ọna naa."
Kékeré ni mo ti nífẹ̀ẹ́ Òrìṣà - Ọmọ ilẹ̀ Brazil Wo àgbáríjọpọ̀ àwọn Arugbá Ọ̀ṣun Òṣogbo látìgbà tó ti bẹ̀rẹ̀ Owó, ọmọ, àlááfíà àti àìkú á bá gbogbo wa gbé ni 2020- Oloye Ifaleke Ọba tèmi ò ba lórí ohun gbogbo!
wo awọn ohun ti SARS fi n ṣe ami idanimọ ọdọ ti wọn ba ni o n ṣe yahho yahoo.
ọrọ alaga Igbimọ Tẹẹkoto naa Rotimi Abiru, o gboriyin fun iṣẹ takuntakun
Ìpànìyàn orí ayélujára lásán lẹ̀ ń pariwo, ìbọn òfifo làwọn sọ́jà yìn sínú afẹ́fẹ́ - Lai Muhammed Minisita eto ibanisọrọ ati iroyin lorilẹede Naijiria, Lai Mohammed ti sọ pe, awọn ọmọ ologun ko yinbọn lu oluwọde kankan nibi iṣẹlẹ Lekki Toll gate to waye loṣu kẹwaa, ọdun 2020.
Ipinlẹ Borno lo ko eyi to ju ninu awọn iku wọn yii nibi ti ẹ̀mí eniyan to ju ẹgbẹrun mẹsan an (9,303) ti lọ, Zamfara (1,963) ati Adamawa (1,529) lo tẹ lee.
 Àwọn èyà ìlù tó kù ni dùndún tàbí ángan , bàtá , àtibìlùgbẹ ̀ du .
Bí ẹnikẹ́ni bá rìn ní ọ̀sán kò ní kọsẹ̀, nítorí ó ń fi ìmọ́lẹ̀ ayé yìí ríran.
O tẹsiwaju pe nibayii ti wọn ti ri i mu pada lẹyin ti o salọ mọ wọn lọwọ, o ti di dandan ki wọn sọ ọ si ọgba ẹwọn nibi ti eto aabo ti fi ẹsẹ mulẹ daadaa.
Ọgbẹni Salman ṣalaye pe ijọba yi ero rẹ pada lori ilẹ naa lọdun 1980 pẹlu erongba lati kọ ile iwosan fawọn oṣiṣẹ ijọba sori ilẹ naa.
Justice For Uwaila: Ọlọ́pàá ìpínlẹ̀ Edo fojú àwọn aṣebi tó pa Uwaila Omozuwa hàn
O ni iku jẹ nnkan ti a ko gbọdọ fi ọwọ yẹpẹrẹ mu nipa titu ọfọ tori naa ''aṣamọ ọrọ, owe ati afiwe iṣẹlẹ ni a gbọdọ lo lati fi tufọ'' Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, EkitiRapeCastration: ìgbésẹ̀ míì lè dẹ́kun ìwà ìfipábánilòpọ̀ Oloye Adegbenga ni ko ba oju mu ki a maa tufọ fun eeyan lori foonu rara.
Babaláwo rèé pẹ̀lú afurasí adigunjalè mẹ́rin láhàmọ́ọ́ ọlọ́pàá Lara ẹsun ti wọn fi kan Adesina, to jẹ minisita fun eto ọrọ aje lorilẹede Naijiria ni lilo ipo rẹ lọna aitọ, lilu owo banki ni ponpo ati ṣiṣe oju-saaju.
Saheed Balogun sìnkú ìyá rẹ̀, Ogogo ní ẹgbẹ́ agbábọ́ọ̀lù!
Nigba ti wọn pa Grace Oshiagwu ni ọjọ kẹtala, oṣu kẹfa, ti wọn si tun pa ọmọ ọdun marun un kan, Mojeed Tirimisiyu ni ọjọ kejilelogun, oṣu kẹfa ni agbegbe akinyẹle.
" Wo ojú àwọn tó na ìka máa lọ ilé sí Praise nilé ẹlẹ́gbọ́n àgbà BBNaija Owó dé!
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ṣé ẹ rántí orin - Má ṣe jẹ́jẹ́ ma wà mi lọ?
Ẹ wo adúrú ẹnu tí mó n bọ́ - Jaiye Kuti Wo orílẹ́èdè tí wọ́n tí ń dáwó ìsìnkú ara wọn pámọ́ Ayédèrú Ọ̀ṣun ni wọ́n ń bọ lónìí, kìí ṣe ojúlówó - Bàbá Ọlọ́ṣun tún figbe ta ''Àwọn ọmọ wa ma ń wọ ọkọ̀ ojú omi láìsí ẹ̀wù ìdàábòbò nítorí àti kàwé'' Tinubu ní kò jẹ́ kí àwọn ọmọ bíbí Eko gbérí nínú òṣèlú Nínú ìfọ̀rọ̀wánilẹ́nuwò ti Punch fún ààrẹ gbogbo-gboo ẹgbẹ́ ALGON, ọgbẹ́ni Alabi David sàlàyé pé, o ti wá di dandan bayìí láti gba iyé owó yìí, nítori ìṣẹ́ ribiribi tí ó ti wà lọ́rùn àwọn alága ìjọba ìbílẹ̀ báyìí kii se kekere.
Lóòtọ́ ni ọkọ mi lù mí bí àṣọ òfì, àmọ́ gómìnà ti bá wa parí ẹ̀, ẹ máa gbàdúrà fún ìdílé mi- Dokita Ifeyinwa Ìgbín, iṣu, epo, àádùn, obì, iyọ àti oyin wa lára ohun ti a fi sọ ọmọ tuntun Ọọni Ifẹ lórúkọ!
 ohun kan ṣoṣo tí kò wá jẹ ́ kí fíìmù yìí dí ìtẹwọ ́ gbà káàkiri ni pé , ó fi àwọn yorùbá hàn gẹ ́ gẹ ́ bí ènìyàn burúkú tí wọ ́ n máa ń ṣe oríṣìíríṣìí ẹgbẹ ́ tí ó ń bànìyàn lẹ ́ rù .
India: Idán yíwọ, Chanchal Lahiri kú sómi gbe
 o ku nigba odo sugbon nigba igbesiaye soki re o se abewo lo si europe , amerika ati seychelles .
Itan nipa Arọgidigba jẹ ki n ro pe baba mi n yan Yemọja ni ale ni"" Awọn itan ti Fagunwa kọ nipa awọn orisa yoo mu kii eeyan ro pe oun gan ni olulaja wọn ninu igbo."
Nítorí wọn kò lè kú mọ́, nítorí bákan náà ni wọ́n rí pẹlu àwọn angẹli.
Wọn kò fi ara gbún ara wọn,olukuluku ń lọ ní ọ̀nà tirẹ̀;wọ́n kọlu àwọn nǹkan ààbò láìní ìdádúró.
Ajo to n mojuto boolu afesegba lorile-ede, Nigeria Football
Olúkúlùkù àwọn ẹnìkejì mi tí wọn ti mọ bí ọ̀ràn ìfẹ́ wa ti ń lọ sì ni wọ́n bẹ̀rẹ̀ síí yín ìn.
Eyi ko ruju rara, ni bo ṣe jẹ pe ni laatrin iṣẹju mọkanla ti ifẹsẹwọnsẹ naa bẹrẹ ni Kevin Gameiro ti gba bọọlu sawọn Arsenal, lati fun Valencia ni ayo akọkọ.
Èṣù-kékeré ni ó kọ́ sọ̀rọ̀ ó la ẹnu rẹ̀ ńlá nì ó sì wí pé:
Ẹ kó ọpọlọpọ igi jọ; ẹ ṣáná sí i.
Gbogbo nǹkan wọnyi ni ó kọ sílẹ̀ fínnífínní gẹ́gẹ́ bí ìlànà láti ọ̀dọ̀ OLUWA nípa iṣẹ́ inú tẹmpili; ó ní gbogbo rẹ̀ ni wọ́n sì gbọdọ̀ ṣe gẹ́gẹ́ bí àkọsílẹ̀ náà.
‘Ọ̀rẹ́ mi ní kí n fi ‘acid’ sí oúnjẹ ọmọ mi’ World Autism Day: Ẹ̀bùn ni ọmọ mi jẹ - ìyá ọmọ àkanda Ohun márùn ún tí o kò mọ̀ nípa òfin tó dáàbò bo àwọn àkàndá Ojú mi gún régé àmọ́ wọ́n ń sá fún mi - Arẹwà Àkàndá Abiyamọ ju abiyamọ lọ ni ọ̀rọ̀ Sima Sarkar Arun 'Cerebral Palsy' ti Stpeh ni jẹ ki awọn oniṣegun oyinbo sọ pe ko ni le sọrọ, rin, kọwe tabi ka iwe ni aye rẹ.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ọmọ to n ko ọmọ alainile kuro lori titi Child Engineer: Olamide Odukọya ní òun fẹ́ ṣe ohun kan tí yóò wúlò fún gbogbo àgbáyé A kò tíì rí ọmọ ọdún méjì tó kó sí kànga- Olootu India Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Ọdọmọde to n seranwọ fun awọn ọmọ ita ni Calabar19 Èrèlè 2018 Joshua Beckford: Ọmọ ọdún mẹ́rìnlá kàwé gboye jáde ni Fasiti Oxford30 Ògún 2019 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
"O ni ""A yọ ọ nipo gẹgẹ bi Aarẹ nitori a ri pe ko le e dari wa lọ ibi kankan pẹlu iru igbe aye to n gbe."
Restructuring: Obasanjo gbóṣùbà fáwọn gómìnà ilẹ̀ Yorùbá lórí àgbékalẹ̀ Amotekun
Bi atupalẹ awọn ipinlẹ yooku ti awọn eeyan to kun iye awọn to laarun COVID-19 ṣe lọ niyi: Bi ẹ ko ba gbagbe, ni Ọjọbọ, marundinlaadọrun lawọn to ni aarun naa lati ipinlẹ Plateau.
Bakan naa ni wọn fi orukọ wọn silẹ fun ami ẹyẹ ọdọmọde agbabọọlu to tayọ (Young Player of the Season).
Ajo to n mojuto boolu afesegba lorile-ede China kede iyansipo Hiddink lori ero ayelujara won.
Katsina mẹwaa, Sokoto mẹjọ, Ẹdo meje, Borno mẹfa, Yobe, Ebọnyi ati Adamawa si ni ẹyọ kọọkan Coronavirus cases in Africa: Èèyàn 195 míràn tún ti ní àrùn Coronavirus ní Nàíjírìa Eeyan marundinigba miran ni ayẹwo tun ti fihan pe o ni arun Coronavirus bayii lorilẹede Naijiria.
Nígbà tó ń fìdí ọ̀rọ̀ yìí múlẹ̀, ìyálọ́jà kan, arábìnrin Ọmọlọlá Adéoyè ní lọ́ọ̀tọ́ọ́ ni owó àwọn ọjà ń dínwó díẹ̀díẹ̀ láwọn orí ọjà kọ̀ọ̀kan.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Facebook sọ wipe awọn eniya lo beere fun atunto opo ayelujara naa Zukerberg to pe ọdun 2017 ni ọdun to lagbara julo ati eyi to tun le julọ, fikun un wi pe iye owo to wọle fun facebook lọdun to kọja ru gẹgẹ soke pẹlu ida mẹtadinlaadọta ninu ida ọgọrun ju tatẹyin wa pẹlu ere toto ida mẹrindinlọgọta.
Iwe ìpéjọ naa pada sọ pe Ọgbẹni Ahmadu ati ileesẹ Drexel Tech Nigeria Ltd, ná lara owo naa lati ra dukia ni ilu Abuja.
Aare ni bi awon odaran kan, ti won ko ni iberu Olorun se n pa awon eniyan kaakiri orile ede yii, paapaa julo ni  ipinle  Benue, Zamfara ati Taraba je ohun to ba eniyan ninu je.
Àmọ́ lai naani àṣeyọrí ọba yìí, ìgbà yípadà, wàhálà de, gbẹgẹdẹ gbiná, ruke rudo wọlu, èyí tó yọ ọba Olateru-Olagbegi kejì nípò ni ọdún 1966, lẹ́yìn ọdún kẹẹdọgbọn to jọba, aṣọtẹlẹ àkọ́kọ́ tí ifá sọ ṣáájú, si wá si ìmúṣẹ.
O ti dán àwọn tí wọn ń pe ara wọn ní aposteli, tí wọn kì í ṣe aposteli wò, o ti rí i pé òpùrọ́ ni wọ́n.
Ọgbẹni Toby ni ile iṣẹ to n ri si ọrọ ilẹ okeere ni ọfiisi naa ti n fin ogun ti o lee pa ẹranko.
Ó ń waasu ní gbogbo àwọn ìlú tí ó gbà kọjá títí ó fi dé Kesaria.
títí tí ọfà fi wọ̀ ọ́ ninubí ẹyẹ tí ń yára bọ́ sinu okùn,láì mọ̀ pé ó lè ṣe ikú pa òun.
Àkókò tí àárò rẹ sí ń sọ mi gan-an ni ìwé rẹ yìí tẹ̀ mí lọ́wọ́.
Àgbàrá òjò gbé alága àdúgbò àti èèyàn méjì mìí lọ nílùú Ibadan Ngozi Okonjo-Iweala ló borí gẹ́gẹ́ bí obìnrin àkọ́kọ́ tó di olórí ajọ okoòwò l'ágbàáyé, WTO Ẹ má à gbìyànjú láti bo àṣírí ìpànìyàn tó wáyé ní Lekki, á ní ẹ̀rí tó dájú - Amnesty International Fun awọn to fẹ gba iwe ẹri keji ati PHD, wọn le lọ si Russia (iyẹn to ba jẹ nibẹ lo ti gba iwe ẹri akọkọ), China, Hungary, Serbia, ati Mexico.
 omo ládèkàn , omo Àmúlé lámùlé orí kò rerù , orí dada ponponran .
lati pese eto aabo ni awon ekun to wa lorile ede Naijiria.
Ọkan lara awọn ọmọ ẹgbẹ APC to n fapa janu, Sẹnetọ Kabiru Marafa ni awọn ọmọ igbimọ fidihẹ APC ti kọja aaye wọn pupọ.
Bẹ́ẹ̀ ni èéfin ń rú jáde láti agbárí ẹbọra yìí tí ẹ̀rù rẹ̀ sì ba ènìyàn gidigidi.
Ni Osu kejila , odun 2016 ni oba morocco ti koko wa si orile ede Naijiria, lati je ki  ibasepo to wa laarin  awon  orile ede mejeeji naa tun tubo mule si i.
”Siba dá a lóhùn pé, “Ọ̀kan ninu àwọn ọmọ Jonatani wà láàyè, ṣugbọn arọ ni.
Ọgbẹni Sanni Azeez lati kọwe si gbogbo ibi to yẹ gẹgẹ bi wọn ṣe fẹnu
Amọ ṣa, ọsẹ kan ti pe bayii, ti ẹnikẹni ninu wọn ko si ti i ri 'kọbọ' gba.
asofin, ni eyi ti o ran won lowo lati bori lasiko  ti won gbe abadofin naa wa sile igbimo asofin.
Bí wọ́n ti ń bá ara wọn jíròrò, tí wọn ń bá ara wọn jiyàn, Jesu alára bá súnmọ́ wọn, ó ń bá wọn rìn lọ.
Lopez Iyke ni gomina ọhun àti pe ipinlẹ Kogi ko ni ilọsiwaju kankan labẹ iṣakoso gomina naa.
9m kalẹ̀ fún owó oṣù òṣìṣẹ́ ní Kwara Gomina Abdulfatah ba BBC Yoruba sọrọ pé ohun to kuku n tan lọdun eegun ni ọrọ oṣelu.
O ni yíyan àwọn ọlọpaa lọ si agbegbe náà kò ṣẹyìn àbẹwo igbákeji ọgá ọlọpàá Anthony Micheal sí agbegbe náà.
Kóńgò èso kan ni ẹni tí ó gbin kóńgò marun-un yóo rí ká.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Human Calculator: N kò lo idán àbí àlùpàyídà fún ìṣirò ọpọlọ tí mò ń ṣe 14 Ẹrẹ̀nà 2020 Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Human Calculator: N kò lo idán àbí àlùpàyídà fún ìṣirò ọpọlọ tí mò ń ṣe Imọ isiro jẹ ohun ti ko wọpọ, o si maa n le fun ọpọ akẹkọ lati mọ, eyi to n mu ki wọn maa gbe ẹrọ isiro, taa mọ si Calculator kiri.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, June 12:Àwọn tó wà ní ìjọba Baba mi ní kò lu owó ìlú ní póńpó- Ọmọ Abacha Bi wọn ṣe wa gbe oloye Abiola lọ si atimọle niyẹn ti Abacha bẹrẹ si ni ṣejọba lọ.
Apẹrẹ arun ọhun le fara jọ aisan to wọn pọ bi otutu ati ọfinki, leyi to le ma mu ki eeyan tete fura pe Coronavirus lo n ba oun ja.
‘Kò tọ́sí Adeleke láti díje dupò gomina Ọṣun’ Ààrẹ Abdulaziz Bouteflika ti kowe fipo silẹ Magu,'estimated billing' àti àwọn ohun míràn tí ilé aṣòfin Nàìjíríà kò rí yanjú Ayédèrú òògùn ààrùn onígbáméjì tó wà ní ta rèé Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Àyà mi kọ́kọ́ máa ń já nígbà ti mo ṣẹ̀ṣẹ̀ bẹ̀rẹ̀ -Alaga iduro ọkùnrin Njẹ ẹka idajọ Naijiria ni ominira ni tootọ?
Ìjọba ìpínlẹ̀ Èkó -Àbẹ̀wò Buhari kò mú ìdìwọ́ bá lílọ bíbọ̀ ará ìlú
OLUWA sọ fún Mose pé, “Nígbà tí o bá pada dé Ijipti, o gbọdọ̀ ṣe gbogbo iṣẹ́ ìyanu tí mo fún ọ lágbára láti ṣe níwájú Farao, ṣugbọn n ó mú kí ọkàn rẹ̀ le, kò sì ní jẹ́ kí àwọn eniyan Israẹli lọ.
Ṣugbọn wọ́n tún ń sin àwọn ẹ̀mí burúkú, ati oriṣa wúrà, ti fadaka, ti idẹ, ti òkúta, ati ti igi.
Olúfẹ̀ mi, olùfẹ́ mi, olùfẹ́ mi ọ̀wọ́n jùlọ - lọ́jọ́ ìbànújẹ́ ìwọ fún mi láyọ̀; lọ́jọ́ ẹkùn ìwọ pa mí lẹ́rìn-ín; lọ́jọ́ ìbínú ìwọ lo tù mi nínú; lọ́jọ́ ìjà ìwọ lo fún mi ní sùúrù; lọ́jọ́ ìrẹ̀sílẹ̀ ìwọ lo gbé mi ga; nígbà tí àwọn ọmọ aráyé kọ̀ mí sílẹ̀ ìwọ kò kọ̀ mí; nígbà tí wọ́n ń bú mi ìwọ kò búu mi; nígbà tí wọ́n ń di rìkíṣí mọ́ mi ìwọ kò dì mọ́ mi – ìwọ ni mo fi ń ṣe iyì fún àwọn ọ̀rẹ́, ìwọ ni mo fi ṣe fọ́rífọ́rí fún àwọn ojúlùmọ̀, ìwọ ni mo fi ń ṣe ìlérí láàárin àwọn gbajúmọ̀ gbogbo.
N óo ṣe ìdílé Ahabu bí mo ti ṣe àwọn ìdílé Jeroboamu ọmọ Nebati, ati ìdílé Baaṣa ọba, ọmọ Ahija.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Calabar Prison: Ẹlẹ́wọ̀n bí ìbejì làǹtì lànti!
Àìsàn náà pọ̀ tóbẹ́ẹ̀ tí ọmọ náà ṣàìsí.
O sọrọ nipa awọn owo ti ohun ti na lori oju iyawo rẹ ati awọn ọmọ rẹ mejeeji.
Ijọ naa da si ọrọ Jude ninu eyi to ti sọ wi pe alufaa to ba ṣe ohun buruku, ki i ṣe eniyan Ọlọrun bi ko ṣe eniyan Eṣu.
"A gbe igbesẹ yii lati le mu ki Hajj o waye ni ayika to ba ilana eto ilera mu, ati lati daabo bo awọn eeyan lọwọ ewu to rọ mọ aarun naa, to si jẹ ọkan lara awọn ilana ẹsin Islam pe lati da ẹmi eniyan si i.
Ṣugbọn otitọ to wa ninu ọrọ igbesi aye rẹ ni pe ibatan Emperor orilẹ-ede France, Napoleon I, to si tun jẹ anti fun Ọmọọba Philip, Duke ilu Edinburgh, jẹ ẹni kan ti itan ko le gbagbe rẹ lailai.
Boko Haram: Ọmọ 37,000 yóò jànfani ẹkọ́ ọ̀fẹ́ ní ìjọba ìbílẹ̀ mẹ́ta ní ìpínlẹ̀ Borno
 Ó kẹ ́ kọ ̀ ọ ́ gboyè ní ilé ẹ ̀ kọ ́ gbogbo-nìṣe adékúnlé ajáṣin ní ìpínlẹ ̀ Òndó ní ọdún 1999 .
Rehoboamu bá dáhùn pé, “Ẹ pada wá gbọ́ èsì lẹ́yìn ọjọ́ mẹta.
Wo orúkọ àwọn ẹ̀yà ara rẹ̀ ní èdé Yorùbá Ẹ wo àwọn ọ̀dọ́mọdé Naijiria tó ń ṣe bẹbẹ nínú isẹ́ aládaní nílé Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ẹ wo fídíò Kìnìhún ní ibùgbé rẹ̀ tuntun ní Bogije, Lekki Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Gege bi ojogbon Obafemi,”Eko je ipile kan ti o se pataki fun idagbasoke orile-ede, eleyi ti aseyege ninu re pe fun akiyesi ijoba.
Bo tilẹ jẹ wi pe ileeṣẹ ọlọpaa nipinlẹ Ọyọ ṣe afihan awọn ọdaran ti wọn mu lorii iku Barakat ninu oṣu keje ọdun yii, awọn olugbe agbegbe Akinyẹle ti o ba wa sọrọ labẹ aṣọ, fi idi ọrọ mulẹ wi pe, awọn to n ṣiṣẹ ibi ni agbegbe naa kọ ni ọlọpaa ri mu.
Bakan naa ni wọn fẹ gba owo osu kinni ọdun 2017 fun gbogbo osisẹ pata ati owo ajẹmọnu isinmi lẹnu isẹ.
A máa ń lo èdè láti fi pèṣẹ̀
n óo tẹ̀lé e lọ, n óo lù ú, n óo sì gba aguntan náà kúrò lẹ́nu rẹ̀.
OLUWA tún rán Mose pé kí ó 
Lóṣooṣù ni wọn yóo máa so èso tuntun nítorí pé láti inú tẹmpili ni omi rẹ̀ yóo ti máa sun jáde wá.
Awọn ọlọpaa ni ẹni ọdun mejidinlọgbọn naa ni awọn fi silẹ lọdun naa lọhun pẹlu ẹjẹ pe ko ni wuwa buruku lawujọ.
Kìnìún mẹ́rìnlá bọ́ sígboro Àwà gómìnà PDP ṣetán láti san #30,000 owó oṣù fáwọn òṣìṣẹ́- Dickson Ẹ dákẹ́ àhesọ ọ̀rọ̀, n kò bí ìbẹta - Yinka Ayefẹlẹ Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Okan lara osise ajo FIFA, ti o tun je omo orile-ede Ghana, Kwesi Nyantakyi leni ti o wa labe iwadii lowo lorile-ede Ghana, lo ti kowe fipo re sile bayii ninu ajo FIFA, lataari esun iwa ibaje ti won fi kan.
Àwọn onílẹ̀ yìí sì ti gba ènìà láàyè àti rìn lórí ilẹ̀ẹ wọn láì ṣẹ̀ṣẹ̀ tú máà tọọrọ àyè lọ́wọ́ọ wọn.
Adajọ Okuwobi to jẹ alaga igbimọ naa sọrọ lorukọ ijọba pe didun lọsan yoo sọ fun idajọ ododo lori awọn ti ọpọ n ṣe iwode nitori wọn.
Kelubu, arakunrin Ṣuha, ni baba Mehiri, Mehiri ni baba Eṣitoni.
Ó lọ sí ilé ẹ ̀ kọ ́ gíga ti obáfẹ ́ mi awólọ ́ wọ ̀ yunifásitì níbi tí ó ti gba ìwé ẹ ̀ rí nínu ìmo eré ìtàgé kí ó tó gba oyè kínín ( b.
OLUWA sọ fún Mose pé, “Na ọwọ́ rẹ sójú ọ̀run, kí yìnyín lè bọ́ kí ó sì bo ilẹ̀ Ijipti, ati eniyan, ati ẹranko, ati gbogbo ewéko inú ìgbẹ́.
Bi a ba tun wo awon ise akanse lolokan–o-jokan ti  ijoba aare Buhari ti gbese eleyi ti o n sanfaani pupo fun eto oro aje orile-ede Naijiria ko lonka.
N kò ní í lè sọ gbogbo nǹkan tí ojú mi rí kí ó tóó di pé mo dé ibib tí mo ti kọ́ ṣìnà sí inú Igbó Olódùmarè nígbà tí mo kọ́ kúrò ní ìlú mi.
Joiada, ọmọ Pasea, ati Meṣulamu, ọmọ Besodeaya, ni wọ́n ṣe àtúnṣe Ẹnubodè Àtijọ́.
 Goomina ipinlẹ Eko naa salaye pe oun wa n bi ara oun leere pe ""Bawo la se rin, ta fi ba ara wa niru ipo yii?"
Nigeria ti fi ọwọ́ sí àdéhùn okòwò kan náà ní Afrika, AfCFTA Egypt dá akọ́nimọ̀ọ́gbá Aguirre dúró lẹ̀yìn ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ Èyí ni ọ̀nà tí àwọn obìnrin n gbà kó ara wọn sí wàhálà nítorí ara bíbó Ìdí tí mo fi fẹ́ di Gómìnà Kogi - Dino Melaye Lọdọọdun, ọpọlọpọ awọn idile to talika lati agbegbe Beed, Osmanabad, Sangli ati Solapur maa n rinrinajo lọ si awọn agbegbe awọn olowo lati ṣiṣẹ ni oko ireke fun oṣu mẹfa.
Boya eyi lo mu ki aya aarẹ Naijiria, Aisha Buhari fi n ke tantan loju opo Twitter rẹ pe, ko dara ki awọn eeyan ti ko ba awọn ọmọ ẹgbẹ APC jiya ka to dibo, maa wa jẹ igbadun ijọba lẹyin eto idibo.
 Ètò abúlé wọ ́ pọ ̀ , ó sì gún régé , baálẹ ̀ tàbí olóróko ( olórí oko ) ni o wà ní ipò ọ ̀ wọ ̀ jùlọ .
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Okonjo-Iweala WTO DG nomination: Kíni ìdí tí orílẹ̀-èdè America ṣe tako ìyànsípò Okonjo-Iweala gẹ́gẹ́ bi olórí ajọ WTO 8 Ọ̀wàrà 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 28 Ọ̀wàrà 2020 Oríṣun àwòrán, TEAMNGOZI Lootọ ni wọn ti fi orukọ ọmọ orilẹ-ede Naijiria, Ngozi Okonjo-Iweala silẹ lati di oludari agba fun ajọ okoowo l'agbaye, World Tradr Organisation (WTO).
Mo sì tún dúpẹ́ lọ́wọ́ rẹ fún ìmọ̀ràn gbogbo tí o fún mi, n kò gbàgbè wọn rárá, wọ́n ń bẹ ní àtẹ́lẹwọ́ òsì mì n kò sì ní í fi ọwọ́ náà jẹun.
Gẹgẹ bi ẹni tọrọ tun ṣoju oun naa, o ni ere lawọn pe e nigba tawọn naa gbọ iroyin nkan tawọn ologun n sọ nigba naa toun wa nileewe loke okun afi ti wọn ni Abiola ko ni wọle.
Fọnran aworan yii, lo je ifinmu finlẹ ikọ ọfintoto BBC Africa Eye ni fasiti meji lẹkun iwọ oorun Afirika, eyiun fasiti Eko taa mọ si UNILAG ati fasiti Ghana.
Ijọba ni kikọlu awọn ileeṣẹ orilẹede South Africa ni Naijiria yoo ni ipa ti ko dara lara ọmọ Naijiria ju South Africa lọ.
Joṣua bá gbadura, ó ní, “Yéè!
Ìdí rẹ̀ nìyí tí ó fi ní agbára láti lè ṣe iṣẹ́ ìyanu.
Oloogbe Tudun Wada se ojuse rẹ gege bi akinkanju eniyan.
Atẹjade naa ni ọwọ awọn ọlọpaa ti ba ogoji ọmọ ẹgbẹ Shiite ti wọn kopa ninu iwọde naa, ti iwadi si ti n lọ lọwọ.
Ìgbà tí o sì ń tẹnumọ́ ọ pé kí a sọ fún òun, inú bí wa a ṣebí o ń fẹ́ gba àbẹ̀tẹ́lẹ̀ lọwọ wa kí ó tó wọlé lọ sọ ni.
3) Boya wọn n ṣe iṣẹ aṣekara fun ọgbọn iṣẹju?
Ọpọ awọn ọdọ to jẹ janduku bẹrẹ si darapọ mọ, ti wọn si n lo ada, ìbọn ati ọbẹ lati da ilu ru.
0 1217126 Ilu Ọba 63082 94.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Coronavirus: Ǹjẹ́ fífi omi àti iyọ̀ yọnu leè dènà àrùn Coronavirus?
Wolii Gẹ́gẹ́ Bí Ẹni Tí Ó sá fógun.
Ọgbẹni Bunmi Ojo, tó ti figba kàn jẹ olùrànlọwọ fun Gómìnà ìpínlẹ̀ Èkìtì tẹlẹri, Segun Ọni pàdé ikú rè nibudo igbafẹ to wa ni Ajitadundun ladugbo Adebayo nilu Ado Ekiti nibi ti o ti n wò ifẹsẹwọnsẹ Premiership láàrin Manchester United ati Leicester City.
Nadal fagba han akegbe re omo orile-ede Argentina, Leonardo Mayer lasiko
ede Czech Republic, Andrej Babis;adari ijoba ti orile ede Finland, H.
Ile ejo kotẹmilọrun orile ede Senegal  ti ni ki alatako oloselu to n dije fun ipo aare  lọ fi ẹwọn odun márùn ún  gbara.
Abidoni ni àkọ́bí rẹ̀, lẹ́yìn rẹ̀ ni ó bí: Suri, Kiṣi, Baali, ati Nadabu; 
A wà lẹ́bàá odò Kebari, mo bá rí i tí ojú ọ̀run ṣí sílẹ̀; mo sì rí ìran Ọlọrun.
Bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé ó fi omijé wá ọ̀nà àtúnṣe, kò sí ààyè mọ́ fún ìrònúpìwàdà.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Ẹlẹ́ẹ̀kẹjọ t'óyún máà bàjẹ́ lára mi ni mo tó rí àànú gbà' Koda, ninu ifọrọwerọ kan ti Wunmi Toriola ṣe pẹlu BBC Yoruba nigba kan, o sisọ loju rẹ pe, ọrẹ minu oun ni Seyi Edun, tii ṣe iyawo osere tiata miran, Adeniyi Johnson, tii ṣe ọkọ Toyin Abraham tẹlẹ.
Tí àwọn olórí rẹ̀ ń ṣe àríyá ní àsìkò tí ó tọ́;tí wọn ń jẹ tí wọn ń mu kí wọn lè lágbára,ṣugbọn tí kì í ṣe fún ìmutípara.
Ìròyìn sọ pé, ó lé ni mílíọ̀nù mẹ́fà imọ-ilẹ to wà ni ìlà-oòrùn- Gúúsù àwọn orílẹ̀-èdè Asia.
O tun je ki awon afeyinti ninu
 orin ìgbàfẹ ́ ni orin àpàlà .
Àkókò kan ń bọ̀, tí n óo gbé Ẹ̀ka olódodo kan dìde ninu ìdílé Dafidi.
odùduwà jẹ ́ kìí ṣe aláṣeẹ àtolùdarí ìran yorùbá òun tún ni gbòngbò kan pàtàkì tí ó so ilẹ ̀ yorùbá ró láti ilé ife , tí tí dé ibi kíbi tí wọ ́ n bá ti ń jẹ Ọba káàkàkiri ilẹ ̀ káàrọ ̀ -oò -jíire pátá .
Ẹ gbọ́ ìtọ́ni, kí ẹ sì kọ́gbọ́n,ẹ má sì ṣe àìnáání rẹ̀.
14 Òkùdu 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Blood donation: Kíni àwọn èrò àti ìgbàgbọ́ tí kò tọ̀nà lórí ẹjẹ́?
Ó ní òun ti fún Nebukadinesari, ọba Babiloni iranṣẹ òun, ní gbogbo àwọn ilẹ̀ wọnyi, òun sì ti fún un ni àwọn ẹranko inú igbó kí wọn máa ṣe iranṣẹ rẹ̀.
Wọn si ti yan gomina ipinlẹ Yobe, Mai Mala Buni gẹgẹ bi Alaga ẹ́gbẹ́ oṣelu APC fidiẹ ni Naijiria.
Ẹwẹ, aarẹ ni gbigbe ofin yii wálẹ ko tunmọ si pe ki awọn eniyan pa ofin ọwọ fifọ ti, pàápàá jùlọ láti tẹle gbogbo ofin ti àjọ to n gbogun ti àjakalẹ ààrun lórílẹ̀-èdè Naijiria.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù France Attack: Ọga Ọlọpaa ìlú Nice ní adúnkookòmọ́ni ló gún àwọn èèyàn náà pa 29 Ọ̀wàrà 2020 Oríṣun àwòrán, EPA Eeyan mẹta ni Agunbẹ kan kọlu ninu sọọsi kan nilu Nice, lorile-ede Faranse l'ọjọbọ.
Obaseki ni igbesẹ naa pọndandan nitori awọn janduku to n ba nkan jẹ lasiko ifẹhọnuhan to n waye ni ipinlẹ naa.
Twitter ko fẹ ki ọrọ a n ka ohun silẹ tabi gbọ ohun ti a ka silẹ di eyi ti ko ni jẹ kawọn onibara wọn o ma lee ṣe awsn nnkan miran to ba yẹ ki wọn ṣe.
Yatọ si eyi, pear tun maa n se iranwọ fun tọkunrin-tobinrin to ba n wa ọmọ, eyi ti ko yẹ ki wọn maa fi sere rara.
CCC Genesis Global: Ǹkan mẹ́wàá tí ẹ ò gbọ́ rí nípa Israel Oladele, Woli ìjọ Genesis Global Ẹ̀tanú pé Olùṣọ́ Genesis kò fẹ́ Laide Williams-Oni ló ṣe rán an lọ́ sí ẹ̀wọ̀n ọdún kan - CCC Genesis Global Irọ́ ni CNN ń pa, àwọn ọmọ ogun Naijiria kò pa ẹnikẹ́ni ní Lekki Toll Gate - Lai Mohammed Àjọ AMCON gbẹ́sẹ̀lé gbogbo ǹkan ìní Jimoh Ibrahim tó lé ní N69 bíliọ̀nù Ìtàn ayé Abiola Peller, ọlọ́wọ́ idán tó fi ọ̀bẹ gé ìyàwó rẹ̀ sí méjì Iroyin fi idi rẹ mulẹ pe, ni kete ti iroyin ibi arẹmọ wọle ni Kabiyesi Ọlọwọ ti ilu Ọwọ, Ọba Ajibade Ogunoye ati Olori rẹ, Adenikẹ ti n dawọ idunnu.
0 184 Agbegbe St Vincent and the Grenadines 0 0.
Joshua ti gba oriṣiiriṣii ami ẹyẹ ninu ẹṣẹ kikan lagbaaye, to fi mọ ami ẹyẹ wura ninu idije ''Olympics'' ọdun 2012.
Oríṣun àwòrán, OFFICIALRASKIMONO/INSTAGRAM Àkọlé àwòrán, Ras Kimono dágbére f'aye pé o dìgbóṣe lọjọ Aiku Ras Kimono tí ó jẹ́ ọmo Ìpínlẹ̀ Delta ṣe àwo orin rẹ̀ àkọ̀kọ̀ 'Under Pressure' ní ọdún 1989.
Ninu atẹjade kàn ti Anjuguri Manzah fi ṣòwò sí àwọn akọ̀ròyìn, o ní àwọn afurasi naa yóò fojú bá ile ejo ní kété ti àwọn ba parí ìwádìí.
“Ẹ bèèrè, a óo sì fi fun yín.
Ikọ BBC lọ ṣawari Baba SARS, Alagba Fulani Kwajafa to da ikọ naa silẹ.
“Níhìn-ín ni Aaroni yóo kú sí, kò ní dé ilẹ̀ tí mo ti ṣe ìlérí pé n óo fún àwọn ọmọ Israẹli, nítorí pé ẹ̀yin mejeeji lòdì sí àṣẹ mi ní Meriba.
Ó bá súre fún wọn ní ọjọ́ náà, ó ní, “Orúkọ yín ni Israẹli yóo fi máa súre fún eniyan,wọn yóo máa súre pé,‘Kí Ọlọrun kẹ́ ọ bí ó ti kẹ́ Efuraimu ati Manase.
Tí orúkọ ìyá rẹ̀ ń jẹ́ Maria, tí àwọn arakunrin rẹ̀ ń jẹ́ Jakọbu ati Josẹfu ati Simoni ati Judasi?
feminine : adj ; ( that dress makes you look.
Ninu ìhámọ́ ni wọ́n wà, tí wọ́n ń gbé bí opó, títí tí wọ́n fi kú.
Nígbà tí àwọn eniyan gbọ́ ìròyìn burúkú náà, ọkàn wọn bàjẹ́, kò sì sí ẹni tí ó fi ohun ọ̀ṣọ́ sí ara rárá.
Ede Poly Rector suspension: Wọ́n ní kí ọ̀gá àgbà Pólì Ede lọ rọ́kún ńlé lórí ẹ̀sùn pé 'ó kan bẹ́ẹ̀dì sí ọ́fíìsì'
Ofin si ti wa nilẹ lorilẹede South Afrika nigba naa pe, alawọ funfun kankan ko gbọdọ ni ibalopọ pẹlu alawọ dudu, ti ẹlẹya mẹya si wọpọ pupọ lorilẹede naa nigba naa Nigba to bimọ tan, ọmọ naa funfun lawọ, ti wọn si ro pe alawọ funfun ni, wọn sọ orukọ rẹ ni Karoline, amọ nigba ti yoo fi pe osu mẹta, akara tu sepo pe adulawọ ni ọmọ naa, to si jẹwọ fun ọkọ rẹ pe oun se asemase ni.
"Ọkùnrin tí kò ríran kan rèé tó ń lọ ẹ̀rọ ata Afọ́jú akẹ́kọ̀ọ́gboyè sọ̀rọ̀ nípa ìrírí rẹ̀ 'Dokita ilé ìwòsàn ló gba ẹsẹ̀ lọ́wọ́ mi' Nigba to dagba tan lawọn dokita sọ fun un pe oju rẹ ti fọ tan patapata ko le riran mọ Ọdọ baba rẹ lo ti bẹrẹ si ni lo irinṣẹ bii ""Spanner"" lati tun kẹkẹ ṣe."
O sọrọ lori iriri rẹ pe oun ko fi iwe ẹri giga oun ṣiṣẹ ri bi ko ṣe ilu 'Drum Set' lilu.
Bo tile je pe omo orile ede Naijiria ni, sibe o ko ipa ipataki ninu idagbasoke ipinle Kwara.
Ó mú àwo turari tí wọ́n fi wúrà ṣe lọ́wọ́.
Bí wọ́n bá sápamọ́ sórí òkè Kamẹli, n óo wá wọn kàn níbẹ̀; n óo sì mú wọn.
Wọ́n ti dáwọ́ ìdánwò àbẹ́rẹ̀ àjẹsára Oxford dúró lẹ́yìn ti olùkopa kan ṣàìsàn Coronavirus bí èso rere nílẹ̀ Adúláwọ̀, wo díẹ̀ lára èso náà.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Barcelona vs Osasuna: Real Madrid gbadé ògo La Liga, Messi ní Barcelona ò lè ta pútú mọ́ 17 Agẹmo 2020 Oríṣun àwòrán, Getty Images Nibi ti ẹlẹkun ti n sunkun lalayọ ti n yọ.
Afi bi ala ni ọrọ naa ri nigba tawọn ẹgbẹ agbabọọlu olorogun mejeeji ti wọn fi apa ariwa ilu London ṣe ibujoko kọju ija si ara wọn.
Àwọ onímọ̀ fi kún un pé, àwọn tó bá ni ié tàbi ill lé maa tàa.
Ó gbé ara rẹ̀ ga, títí dé ọ̀dọ̀ olórí àwọn ogun ọ̀run.
A bi Ọjọgbọn Ibrahim Agbaoola Gambari niluu Ilorin ipinlẹ Kwara lọjọ kẹrinlelogun, oṣu kọkanla, ọdun 1944.
Fun idi eyi, o ṣeeṣe ki araalu tun fara gba ọwọn gogo epo bẹntiroo, bi ijọba ko ba tete da awọn oṣiṣẹ yi lohun.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ó dára kí obìnrin níṣẹ́ lọ́wọ́ - Toyin Lawani Nigba to n salaye nipa ajọṣepọ to wa laarin rẹ ati Lizzy Jay ọmọ Ibadan, ti wọn dìjọ maa n ṣe awada lori ayelujara, Lawyer Kunle ni ọrẹ lasan ni awọn mejeeji.
"'Ààrùn HIV kò lè ràn pẹ̀lú itọ́ tàbí òógùn' 'Ǹkan ìṣeré ìbálòpọ̀ mi ńpaná iṣẹ́ mọ́ mi lára' Ofin ti f'àyè gba ìbálòpọ̀ Akọs'akọ, Abos'abo ní Botswana Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Africa Eye: Olùkọ́ méjì ní fásitì Eko àti Ghana lùgbàdì ọ̀fíntótó BBC lórí ìwà ìbàjẹ́ ""Awọn ile itaja kan tilẹ n ta a ni ẹgbẹrun mẹta (3,000) ṣile iye owo ilẹ Tanzania eyi to jẹ bii $1; N351, o lee jẹ 5,000 tabi 10,000 ṣile ni iye owo ilẹ Tanzania iyẹn da lori iru ẹya rọba to ba jẹ."
Njẹ awọn mọlẹbi rẹ ti wa a gbe oku rẹ?
“Kọ ìwé yìí sí angẹli ìjọ Pẹgamu pé:“Ẹni tí ó ní idà olójú meji tí ó mú ní: 
O ni nilẹ Afrika eeyan ko le darukọ Naijiria ko ma pe Ghana pẹlu rẹ.
won tan nipa iyaafin Abike  Dabiri –Erewa
Ki wọn si to beere ọja awin lọwọ rẹ, ni wọn ti mọ esi ti yoo fi da wọn lohun.
Èmi Paulu ati Timoti, àwa iranṣẹ Kristi Jesu.
“ ‘O kò gbọdọ̀ ṣe panṣaga.
tàánú-tàánu tí ológbò ń rìn sọdẹ eku ni à ń rìn ni Ìkọ ̀ lé ọ ̀ run .
Lẹ́yìn náà, bù díẹ̀ ninu lúbúlúbú yìí, kí o fi siwaju àpótí ẹ̀rí ninu àgọ́ àjọ, níbi tí n óo ti bá ọ pàdé, yóo jẹ́ mímọ́ fún yín.
Ara rẹ̀ la ti rí màrìwò tí a fi ń ṣe ọwọ̀ ìgbálẹ̀ at ọjọ̀ ewédú.
Lasiko yii, South Africa ni osise bii milionu kan ati irinwo pelu eeyan milionu mejilelaadota.
Greece gba imọran awọn onimọ ni ti o si fi ilana itakete-siara-ẹni lelẹ saaju ki wọn to ni ẹni akọkọ to dero ọrun nipasẹ arun naa.
Esi ayẹwo coronavirsu fun 20/06/2020 Diẹ lo ku ki awọn to ni aarun Covid-19 o pe ẹgbẹrun lọna ogun bayii, lẹyin ti ajọ to n mojuto aarun ni Naijiria, NCDC tun kede eniyan 661 lọjọ Abamẹta.
”Naamani mú ìwọ̀n talẹnti fadaka mẹ́wàá ati ẹgbaata (6,000) ìwọ̀n ṣekeli wúrà ati ìpààrọ̀ aṣọ mẹ́wàá, 
Wọn ni awọn ṣe eyi nitori pe ó parọ́ nígbà tó fẹ̀sùn kan Arakunrin Rotimi Akeredolu to n tukọ ipinlẹ Ondo bayii.
Kíni 'Òkú ewúrẹ́ tí í fọhùn bí ènìyàn'
Alaga ikọ Amọtẹkun ni ipinlẹ Ọyọ tun ṣalaye pe awọn ọmọ ikọ Amọtẹkun ni ipinlẹ Õyọ yoo gba owo oṣu.
Ẹ kò mú mi nígbà náà!
O ní wọn yóò pín bílíọ̀nù mọárùndínláàdọ́jọ náà si ọ̀nà mẹ́ta ni ti yóò sì jẹ́ bílíọ̀nù márùdínlọ́gbọ̀n fún ọdún kọ̀ọ̀kan.
Ijoba ipinlẹ Koji so siwaju wipe, awọn yoo koju aisan naa nipa siseto ilanilọye fun awọn araailu, lati ri wipe aisan naa ko tan ka ibugbe kankan.
Mú lára ẹ̀jẹ̀ tí ó wà lára pẹpẹ, sì mú ninu òróró tí wọ́n máa ń ta sí ni lórí, kí o wọ́n ọn sí Aaroni lórí ati sí ara ẹ̀wù rẹ̀, ati sí orí àwọn ọmọ rẹ̀, ati sí ara ẹ̀wù wọn.
“Nígbà tí àwọn eniyan rẹ bá lọ dojú kọ àwọn ọ̀tá wọn lójú ogun, níbikíbi tí o bá rán wọn lọ, tí wọ́n bá kọjú sí ìlú tí o yàn yìí, ati ilé ìsìn tí mo kọ́ fún ọ, tí wọ́n sì gbadura, 
Buni soro ohun di mimo lasiko to n ba awon akoroyin soro lojo isegun(Tuesday), niluu Abuja.
Ayefẹlẹ: Orí ìkúnlẹ̀ ni ìyàwó mi wà, tó ń bẹ gómìnà, láti 11pm si 4am Nigba ti wahala wiwo ile iṣẹ redio gbajugbaja akọrin ni, Yinka Ayefẹlẹ waye ni Ibadan, BBC News Yoruba lo lewaju iroyin ohun gbogbo to n lọ nigba naa, lai jẹ ki eti araalu di si bi ọrọ naa ṣe lọ.
Akọroyin BBC nilu Nairobi, Ferdinard Omondi sọ pe, awọn ọmọ Kenya n binu lori bi wọn ko se lanfaani lati wo awọn iroyin ati awọn eto to wọn lori awọn ẹrọ amohunmaworan fun ọjọ kẹta ti wọn ti wa ni titipa.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù The Church of Beer: Ìnira nlá ni òfin tó dé kátà-kárà ọtí líle lásìkò Covid-19 jẹ́ fún ilé ìjọsìn wà 22 Ìgbé 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 5 Ògún 2020 Oríṣun àwòrán, Twitter Orileede South Africa ti bẹrẹ ifilọlẹ ofin to de ọti tita lasiko Covid -19 fun igba ẹlẹẹkeeji.
“Ireti ko sonu gege bi awon eniyan se n so aheso oro kiri; a si lee maa gba ara wa  niyanju.
Alaye rẹ ni pe, ati olowo ati ọlọrọ, ati ọmọde ati agba lo n foju wina ijinigbe nilẹ Yoruba.
Ọkunrin tí ó ti ojú ogun wá bẹ̀rẹ̀ sí ròyìn fún àwọn ará ìlú, ẹ̀rù ba olukuluku, àwọn eniyan bẹ̀rẹ̀ sí ké.
Hunt to ba ajọ to n pese ounjẹ ati ile gbigbe fun awọn ogunlende to n gbe lagbeegbe Maiduguri lẹyin ti ikọ Boko Haram se ikọlu si agbeegbe wọn.
Ayọ̀ ń bẹ fún ẹ̀yin tí ebi ń pa nisinsinyii,nítorí ẹ óo yó.
12 Ìjìyà àìlópin jẹ́ ìjìyà ti Ọlọ́run.
Aarẹ ọna kakanfo ni olori awọn ologun ilẹ Yoruba nigba iwasẹ.
Oju rẹ bẹrẹ si ni di gbajugbaja lọdun 2006.
O ni ọpọlọpọ awọn aṣoju onile lo ṣo fun oun pe, ki oun mu ọrẹkunrin oun wa lati duro gẹgẹ bi ọkọ fun oun, ki oun lee ri ile gba.
Ó kí wọn pé, “Alaafia fun yín!
”Ọba bèèrè pé, “Kí ni, ìyá mi?
"Jẹ́ kí ó mọ̀ ibi ti ó dúro si, ko si àpọ́nle kankan nínú ìgbé ayé àgàbàgebè"" Lẹ́yìn náà lo fi ọ̀rọ̀ míràn gba lẹ́yìn pé gbogbo ǹkan ni òun le gbà sùgbọ́n ti ọ̀rọ̀ bá ti kan ti ọmọ òun pàápàá jùlọ to ba ti di ọ̀rọ̀ ìjà òun ko le fara dàá, ""Bí ẹ ba ri ẹnikẹ́nì tí ó ní ìkóròrí sí ọmọdé, apànìyàn ni irú ẹni bẹ́ẹ̀, wọ́n le fún ènìyàn ni iwọ jẹ"" Oríṣun àwòrán, Wumi Toriola/Instagram Bótilẹ̀ jẹ́ pé, bí àwọn kan ṣe n yín Wumi Toriola bí o ṣe sọ́rọ́ síta, bẹ́ẹ̀ ni àwọn olólùfẹ́ rẹ̀ míràn sọ fún pé, kò bá ojúmu tó láti má a pé ọmọlakeji rẹ̀ ni àgàn."
Ṣugbọn atẹjade kan ti ileeṣẹ ọlọpaa fi sita yatọ si iṣẹlẹ to ṣẹlẹ yii.
Ẹ wo iye ọmọ Yorùbá tó bá Coronavirus lọ lókè òkun Bí ẹni forí ọká họmú ni ti ìjọba bá dẹ́kun òfin koníléógbélé báyìí-WHO O ni saaju ki wọn ti fidi ọrọ itankalẹ lati ara ẹni kan si omiran ni aarin osu kini ọdun ni Taiwan ti bẹrẹ si ni se ayẹwo awọn arinrinajo to n wọ ilẹ wọn lati ilu Wuhan ti arun yi ti kọkọ sẹyọ.
Buhari ń bọ̀ l'Eko: Àwọn ọ̀nà láti yàgò fún àyàfi tí ẹ ba gbé ibùsùn dání Ǹjẹ́ irú irun ti ò ń ṣe ń fa orí pípá fún ọ?
O ni ijoba oun yoo lo de gbogbo esekuku ati igberiko oun ko si ni ye kuro lori oun ti oun so.
Ijọba apapọ ni ohun gbe igbesẹ yii nitori awọn eeyan to ti lugbadi arun Coronavirus ti ju ẹgbẹrun kan lọ lawọn ilẹ naa.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Akanbi Oluwasegun: Mo yá owó ni kí ẹ̀rọ tó ń tu ìyẹ́ adìyẹ yìí tó di odidi Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Akanbi Oluwasegun: Mo yá owó ni kí ẹ̀rọ tó ń tu ìyẹ́ adìyẹ yìí tó di odidi 12 Ìgbé 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 13 Ìgbé 2019 Ìrọ̀rùn dé!
Ṣugbọn agbẹjọro tirẹ naa n ba wọn fa a pe wn n tẹ ẹtọ rẹ loju mọlẹ ni wipe ohun to tọ ni ki wọn yaa gba beeli rẹ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Àwa obìnrin tó ń lépa afòjúsùn máa n ba ọkùnrin lẹ́rù ni -Toyin Lawani Ko rọrun lati dariji, nitori o ti jẹ ko ṣoro fun mi lati fi inu tan ẹnikẹni.
"Ẹ ̀ tẹ ̀ , tí a tún mọ ̀ sí Àrùn hansen ( hd ) , jẹ ́ ́ bárakú àkóràn ti kòkòrò àrùn "" mycobacterium leprae "" àti "" mycobacterium lepromatosis "" ."
Onilù àdúgbò lè lùlù ki wọn jó, ṣùgbọ́n kò kan dandan ki wọn lu ilu tàbi ki wọn jó.
Jehoiada fẹ́ iyawo meji fún un, wọ́n sì bímọ fún un lọkunrin ati lobinrin.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Electricity new tariff: ''Àjọ NERC ti fún Disco láṣẹ láti padà sí owó tàríìfù tuntun iná mọ̀nàmọ́ná'' 2 Bélú 2020 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Aadota odun ree ti e ti n paro atunse ise yin fawon omo Naijiria lero awon kan Otitọ ni wi pe ileeṣẹ ina mọnamọna Disco ti pada si owo ina tuntun ti wọn ni ki awọn araalu maa san.
Oríṣun àwòrán, Dolapo Badmos/Twitter Àkọlé àwòrán, Dolapo Badmos àwọn ole ajipata lo jẹ́jọ́ ipaniyan Bi ọ̀rọ̀ oogun owo ṣe n wọ́pọ̀ si, ni ọwọ n tẹ awọn afunrasi tí wọn ní o ń jí awọ̀tẹ́lẹ̀ awọn obinrin, nibi ti wọ́n ba sá wọn sí.
lori ofin ti yoo je ki awon ile igbimo asoju ati ile- idajo da duro .
Eto okoowo ti orile ede Russia nifee si ni, ina mona-mona, irin,afefe gaasi ati epo robi.
Àwọn lÒdùdù tí í du orí ìlemèrè.
Kiakia ni awọn ijọba ilẹ Adulawọ gbe igbesẹ ilanilọyẹ lori ọna lati tako itankalẹ bii ọwọ fifọ nigba gbogbo, itakete sira ẹni lawujọ, ati wiwọ ibomu.
Ṣé ọlọrun àwọn orílẹ̀-èdè mìíràn gbà wọ́n lọ́wọ́ ọba Asiria?
Ewe, ile-ise olopaa ti so tele pe, ohun ko ni fi owo sinkun ofin mu Zuma latari isele to niise pelu molebi GuptaLowuro yii, ni awon olopaa gbese le awon dukia kan ti won ti molebi Gupta, ti won si tun fi owo sinkun mu awon molebi Gupta meta.
Ipilẹ ti ko lagbara Owo gọbọi ni ipilẹ ile to dantọ maa n jẹ, onimọ nipa ile kikọ kan, Ọjọgbọn Anthony Ede ti fasiti Covenant niluu Ota, ipinlẹ Ogun sọ pe ipilẹ ile to lagbara le gba idaji owo ti eeyan maa na sori gbogbo ile.
Ohun tẹ́ẹ gbúdọ mọ nípa kókó orí ọyàn yín lásìkò fífọ́mọlọ́yàn Ọkọ kọ àwọn ọmọ méjì lé ìyàwó lọ́wọ́ nítorí ìrísí ojú wọn ní Ilorin Wo ìdí tóó fi san 5 Mílíọ̀nù bóo bá sọ̀rọ̀ kòbákùngbé ní Nàìjíríà 'Ọkọ mi mú ọ̀bẹ jáde lápò, ó sì gé imú mi jábọ́.
K’ó yí ni lárá nìkan lèèwọ̀.
 Ọ̀rọ̀ náà wa lábẹ́ ìwádìí, mí ò ṣetán láti sọ̀rọ̀ le lóri, ọ̀pọ̀ àwọn oníròyìn ló ti wá bá mi lórí ọ̀rọ̀ náà, ǹkan ti mo kàn le sọ ni pé owó sọnu èyí ní ọ̀rọ̀ Kashekobo.
Iru ẹranko wo ni Yoruba n pe ni imado?
Àkọlé àwòrán, Titipa ni ilẹkun Mọṣalaaṣi apapọ Naijiria nilu Abuja wa.
Ni temi, mi o ni ni akọwe obinrin kankan ritori pe ti obinrin ba fi ẹsun kan ẹ, ko si ẹni ti yoo gba ọ gbọ koda ki o jare.
Awọn nnkan marun-un to se koko nipa lọjọ Arafa: Oríṣun àwòrán, @YasirQadhi Ọlọrun sọ ofin ẹsin Islam kalẹ: Ní irú ayajọ ọjọ yìí lasiko hajj ìdágbére láyé Anabi Muhmmad (S.
Akẹ́kọ̀ọ́ Ilaro Poly tó pegedé jù jẹ ẹ̀bùn iṣẹ́ ọ̀fẹ́ lọ́wọ́ Gómìnà Abiodun Kíni ẹ mọ̀ nípa Mama Rainbow tó jẹ́ àgbà òṣẹ̀ré tíátà Yoruba?
ede Naijiria ati awon orile ede Afirika miiran gbe  yoo tun jẹ ki idagbasoke ba eto ọrọ aje.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Kí ni Yorùbá ń pe ọmọ tí wọ́n bí lẹ́yìn Àlàbá?
“Moses wa lara iko akoko lasiko saa akonimoogba teleri fun Chelsea, Antonio Conte, sugbon lataari ara oto akonimogba tuntun Sarri, ti o gbe wonu iko naa, eyi ni o sokunfa idi ti Moses ko fi le kopa ninu iko re.
Oríṣun àwòrán, Yemi Osinbajo Awọn koko ohun to si mẹnuba ree pe o jẹ igbesẹ lati gbe ta ba fẹ lo iwe akọsilẹ naa, ti a si kọ̀ orukọ awọn afipabanilopọ sibẹ.
Pẹlu ìrànlọ́wọ́ Sadoku ọmọ Eleasari ati Ahimeleki ọmọ Itamari, Dafidi pín àwọn ọmọ Aaroni sí ẹgbẹẹgbẹ́ gẹ́gẹ́ bí iṣẹ́ tí wọn ń ṣe ninu iṣẹ́ ìsìn.
 Àwọn ẹranko tó ti ní àkóràn àrùn náà lè máṣe ní àmì àìsàn kankan rárá , wọ ́ n lè ní àmì àìsàn níwọ ̀ nba , tàbí kí wọ ́ n ní àmì àìsàn tó burú púpọ ̀ .
Jediaeli ni baba Bilihani; Bilihani bí ọmọ meje: Jeuṣi, Bẹnjamini, Ehudu, Kenaana, Setani, Taṣiṣi ati Ahiṣahari.
Kerubu tí ń ṣọ́ ọ sì lé ọ jáde kúrò láàrin àwọn òkúta olówó iyebíye tí ń tàn yinrinyinrin.
“Sibẹsibẹ, àwọn eniyan rẹ ń wí pé, ‘Ọ̀nà OLUWA kò tọ́,’ bẹ́ẹ̀ sì ni ọ̀nà tiwọn gan-an ni kò tọ́.
Ọ̀rọ̀ náà sì ń ṣiṣẹ́ ninu ẹ̀yin tí ẹ gbàgbọ́.
Alaga ẹgbẹ awọn oṣiṣẹ ni ile ẹkọ fasiti Abeokuta, Adebayo oti sọ fun ile iṣẹ iroyin Punch pe awọn ti fi aṣẹ naa ranṣẹ si awọn ọmọ ẹgbẹ naa.
 Awon osise alaabo wa ti n
ẹṣin funfun ń fa ẹkẹta, àwọn tí wọn ń fa ẹkẹrin sì jẹ́ kàláńkìnní.
Oríṣun àwòrán, Twitter Àkọlé àwòrán, Ajọ awọn oṣiṣẹ olukọ ile ẹkọ giga Ẹgbẹ ASUU n fẹ ki ijọba mu suuru titi di igba ti wọn ba lee ri ọna gboogi lati dinwọ aranka aarun Coronavirus ku.
Ojú yóo ti àwọn ọ̀tá rẹ,ilé àwọn eniyan burúkú yóo sì parẹ́.
awon osise ijoba ti osu keji yii fale ki won o to o san lojuna ati din wahala
Bí ilẹ̀ bá ti mọ́, tí oòrùn sì bẹ̀rẹ̀ sí yọ, gbéra, kí o sì gbógun ti ìlú náà.
Nigba ti o n menuba lara awon ipenija to n mu ifaseyin
Awọn to ṣe iwadi naa sọ pe, bi awọn ọmọde se n fa eefin siga simu ṣeeṣe 'ko fi kun iye awọn eeyan ti ki i mu siga, ṣe n ku l'ọdọọdun.
"Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Bí ẹ ṣe mọ̀wé tó, ẹ wá dánrawò níbí pẹ̀lú ""Àpólà Ọ̀rọ̀ Orúkọ - Noun Phrase Gbogbo asiko yii ko si nkankan laarin oun ati ọkọ rẹ, nigba ti o si de pe oun ri ẹni ti o fẹ fẹ, oun mọ pe bukata rẹ yoo kuro lọrun ijọ."
Kò l’áàńsí lórí Ayélujára láti ṣiṣẹ́
A bẹrẹ igbesẹ yii nipa ṣiṣe moriya fun awọn idile naa fun adanu wọn a si tun ṣeleri lati ṣe ju bẹẹ lọ fun wọn.
"Ọmọ, mo wọ mọ wọn lọwọ ni o, emi to jẹ pe wọn ti kan mi ni eewo tẹlẹ, ti wọn ti ja mi kulẹ, fine kọ, fanta ni.
Da òrùka wúrà meji, sì dè wọ́n mọ́ etí kinni keji ìgbàyà náà lọ́wọ́ inú, ní ẹ̀gbẹ́ tí ó kan ara efodu.
Iroyin kan tiẹ sọ pe ọmọ ọdun mẹtadinlogun lo wa nigba ti o ṣiṣẹ ni miliọnu kan naira lọwọ.
Mò ń fọ èdè tí ó lè yé eniyan, nítorí ọgbọ́n yín kò ì tíì kọjá ohun tí a lè fi ojú rí.
Ó bá wọ yàrá rẹ̀, ó lọ sọkún níbẹ̀.
Iṣẹ abẹ ni wọn fi gbẹbi ẹni ọdun mọkandinlọgbọn naa, bẹẹ ni awọn ọmọ ọhun ko gbo, eyii to mu ki awọn nọọsi gbe wọn sinu igo.
Lẹsẹkẹsẹ ni ẹ̀yìn rẹ̀ bá nà, ó bá ń fi ògo fún Ọlọrun.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Election 2019 Updates: Makinde ní Ajimọbi fẹ́ ná owó Ọyọ tán, láti dá ìjọba òun lóró 19 Ẹrẹ̀nà 2019 Àkọlé àwòrán, Ọga, ẹ fẹ na owo ilu tan ni?
Àwọn tí wọn ń ṣiṣẹ́ ń fi ọwọ́ kan ṣiṣẹ́, wọ́n sì mú ohun ìjà ní ọwọ́ keji.
Ni oṣu keje ọdun 2013 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Lara awọn ọmọbinrin chibok ti wọn ji gbe ti pada wale Awọn agbebọn kan ti awọn eeyan gbagbọ pe wọn wa lara ikọ Boko Haram pa awọn eeyan mejilelogoji, pupọ ninu wọn si jẹ akẹkọ ni ilu Mamudo.
OLUWA ti jẹ Nabali níyà fún ìwà burúkú rẹ̀.
Ọ̀rọ̀ tí OLUWA bá Jeremaya wolii sọ nípa àwọn orílẹ̀-èdè nìyí.
Efunsetan si ni gbogbo aye mọ julọ ninu awọn aya oloogbe Isola Ogunsola sugbọn lọwọ lọwọ bayii, o ti dagbere fun iṣẹ tiata, to si di oniwaasu ọrọ Ọlọrun.
Atileyin AkotunAjo EU, ti o tun fi edun okan re han fun awon ebi ati ore awon omodebinrin ti won padanu-emi won, bakan naa ni won seleri atileyin akotun fun awon omodebinrin ti won si wa nigbekun awon ajini-gbe naa, ni eyi ti won n pe fun itusile won ni kiakia.
Kódà èèyàn lè lòó fi darí iPhone/iPod – fi jẹ́ ìpè ago, fi yín orin sókè tàbí sílè, fi yan orin míràn, àti bẹ́ẹ̀ bẹ́ẹ̀ lọ.
Nibayii, Dokita naa ni saka ni ara rẹ da, ti o si tun ṣe daadaa ninu gbogbo idanwo ti o ṣe.
Ṣugbọn Sihoni kò ní igbẹkẹle ninu àwọn ọmọ Israẹli pé kí wọn kọjá láàrin ilẹ̀ rẹ̀.
Kò sí ìgbà kan tí ẹ kì í ronú nípa mi ṣugbọn ẹ kò rí ààyè láti ṣe àwọn ohun tí ẹ̀ ń gbèrò.
Bí amọ̀ ti rí lọ́wọ́ amọ̀kòkò ni ẹ rí lọ́wọ́ mi, ẹ̀yin ilé Israẹli.
BBC Yoruba wa ń gba ni àdúrà pé Ọlọ́run Ọba yóò gbà àbọ̀ olóògbé náà, yóò si fi ikú ṣe ìsinmi fún un.
Nígbà tí mo sì ronú díẹ̀ nípa ọ̀rọ̀ wọ̀nyí mo fẹ́rẹ́ lè sọkùn fún àwọn ọmọdé ìwòyí nítorí wọn kò bẹ̀rù àgbàlagbà mọ́, wọ́n jẹ́ ọlọgbọ́n lójú ara wọn.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Working religious women: Ẹ̀lẹ́hàá kìí ṣe ọ̀lẹ- Aminat Adegoke Ni oju opo ikansiraẹni Twitter ni Olotu Ijọba orilẹ-ede India, Narendra Modi ni o ti fi ọrọ naa lede, ti awọn si ti bẹrẹ iwadii lori iṣẹlẹ naa.
Nítorí náà, n óo dá a pada fún ọ.
Ninu eyi ẹgbẹrunlọna igba (200,000) nikan ni ọlọpa to n sisẹ fun araalu ti ẹgbẹrun lọna aadọjọ (150,000) yooku n sisẹ aduro gboin lẹyin oloselu tabi awọn eniyan ti wọn nifọn leekannaa lawujọ eleyi ti kii se isẹ sin araalu.
Bi o tile je pe, opo eyan so pe, kikuna Serena lati jawe olubori o ni se pelu omo ti o sese bi, sugbon ifigagbaga ohun lo di igba mokandinlogbon ti awon omo-iya mejeeji maa pade, ti Venus si jawe olubori igba marundinlogbon.
“Ó wà lára àwọn ohun àkọ́kọ́ tí èmi Ọlọrun dá,sibẹ ẹlẹ́dàá rẹ̀ nìkan ló lè pa á.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Akomolede ati asa Yoruba: Ẹ wá kọ́ nípa àpòtí ìṣura èdè wa lórí BBC Yorùbá 2.
”“idide ati atewo ti awon ololufe Juventus fi ye misi je ohun iwuri fun mi pupo.
Yóo ṣẹgun àwọn ọ̀tá rẹ̀ ní Edomu,yóo sì gba ilẹ̀ wọn.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Alaafin Oyo: Kíni 'Ẹ̀lẹ̀ daddy' Olorì Abbey Adeyemi ṣe tí ojú òpó ayélujára rẹ̀ fi ń yeruku lálá?
 Ṣùgbọ ́ n nítorí pé ó tin í ìyàwó nílé nígbà náà wọ ́ n gbé e padà sí Ìbàdàn .
Àwọn akọni Nàìjíríà padà sílé pẹ̀lú àmì ẹ̀yẹ 121 láti Morocco Dino Melaye tó ń díje dupò gómínà Kogi ni irọ́ ni pé òun ti ju awà sílẹ̀ Àwọn akọni Nàìjíríà padà sílé pẹ̀lú àmì ẹ̀yẹ 121 láti Morocco A fẹ́ bẹ̀rẹ̀ òfin má lo fóònù mọ́ fàwọn ọmọ wa -Òbí Òní nilé ẹjọ́ tó ga jùlọ yóò gbẹ́jọ́ ẹ̀sùn ayédèrú sabuké tí wọ́n fi kan Buhari Ta ni Binaca Andreescu?
Iṣẹlẹ yi ni ṣe pẹlu Kọmisana eto ilera ipinlẹ Kogi to ṣaadede bu sẹkun lasiko to n ṣe ayẹwo bi awọn janduku ṣe ba ẹrọ ayẹwo olowo iyebiye jẹ nile iwosan Kogi.
yan awon adari miran lọdun tuntun, ohun to ye ki awon eniyan mo ni pe, idibo kii
Omi náà pọ̀ tóbẹ́ẹ̀ tí ọkọ̀ fi léfòó lójú omi.
Ẹ kọ gbogbo àwọn òfin wọnyi sára òkúta náà, ẹ kọ wọ́n kí wọ́n hàn ketekete.
Iroyin ni ẹgbẹlẹgbẹ miliọnu eniyan to n gbe lorilẹede India ni ko ni yara igbọn se si agbeegbe wọn.
Wọ́n bá fi àwọn eniyan sílẹ̀, wọ́n mú un lọ pẹlu wọn ninu ọkọ̀ tí ó wà.
Igba akọkọ Igba akọkọ ti wọn kede iku Shekau ni lọdun 2009.
Ni mo bá wí fún wọn pé, ‘Ẹnikẹ́ni tí ó bá ní wúrà, kí ó bọ́ ọ wá.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Àwọn ọ̀dọ́ lu 'Ẹja' tó fi mọ́tò pa ọ̀dọ́kùnrin kan pa 28 Ògún 2018 Oríṣun àwòrán, florbabs Àkọlé àwòrán, Wọn ni o ti kọkọ fi ọkọ rẹ kọlu obinrin ẹlẹha kan lagbegbe Olowo-Bida nilu Ẹdẹ kan naa Awọn eeyan ilu Ẹdẹ nipinlẹ Ọṣun tu lu ọmọ ileewe onipele kẹrin ileewe giga gbogbońṣe apapọ to wa ni ilu naa pa.
Awon adari meji yooku ni Aare teleri lorile-ede Ghana John Mahama, yoo soju fun ajo Commonwealth, nigba ti Aare teleri lorile-ede Nigeria, omowe Goodluck Jonathan yoo soju fun ile-eko ti o n moju to isakoso ijoba tiwa-n-tiwa nile Africa.
Jesu dá a lóhùn pé, “Ìjọba mi kì í ṣe ti ayé yìí.
Ekiti: Àyọjúràn ni Fayoṣe tó yọjú sí Ilé Igbìmọ̀ Aṣòfin l'Ekiti
Láti orí àwọn ti kò mọ obinrin sí àwọn tí wọn ń ní àjoṣepọ̀ pẹ̀lú oríṣiríṣi obinrin, èyí ní oníruuru ọná tí àwọn ènìyàn fí má ń ni ìbálòpọ̀ jákèjádò àgbáyé.
Awon miran ni Lydia Forson to gba amugbalegbe oserebinrin apanilerin to dara julo ati Bisola Ariola ti Big Brother Naija 2017 to gba ami eye miran.
Agbenusọ fun gomina ipinlẹ Eko, Gboyega Akosile to fidi iṣẹlẹ naa mulẹ fun BBC, sọ pe awọn kan lo kọlu ọgbà ẹ̀wọ̀n naa.
Wo ohun mẹ́wàá tó yẹ kí o mọ̀ tí o bá fẹ́ lọ fún ìsinmi lẹ́yìn Covid 19 Wo bi wọ́n ṣe n ṣe àmójútó ilé ìjọsìn Prophet Israel Oladele, CCC Genesis Global Seyi Makinde fún olórin Fuji Taye Currency lẹ́bùn ọkọ̀ bọ̀kìnnì Toyota Prado 2020 Ìjọba àpapọ̀ pàṣẹ pé kí gbogbo ọkọ̀ agbépo kúrò ní márosẹ̀ Lagos-Ibadan Adeola Stella Oluwafeyisola ati Tijani Yusuuf salaye bi awọn ṣe jẹ omo orukan ṣugbọn ti Kabiesi ti fun wọn ni ireti tuntun.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Champions League Final: Liverpool dín dòdò ìyà ṣínu ààwẹ̀ fún Tottenham 1 Òkùdu 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 2 Òkùdu 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images A kii ṣẹgbẹ yin!
Gbogbo eniyan ni yóo mọ̀,àwọn ará Efuraimu ati àwọn ará Samaria,àwọn tí wọn ń fọ́nnu pẹlu ìgbéraga pé:
 Mo n fi asiko yii ro gbogbo awa iko osise yii lati ri ara wa lokan, ki a gbo ohun ti awon to fe wa dokowopo pelu wa n fe ati awon aladani ki a le mo ona ti a ti maa pese iranwo to ye fun erongba wa.
Ọlọ́pàá ìpínlẹ̀ Ogun dóòlà Díákónì ìjọ Redeem tí wọ́n jí gbé n'Ijebu Ode #FreeSowore: Àwọn ọmọ Naijiria fi gbe ta lórí Sowore ti DSS mú!
Ooni: EFCC, ẹ se àtúnse sí ìgbé ayé àwọn ọdaràn tẹ bá mú
81 Yíò jẹ́ ojúṣe onírúurú awọn ìjọ, tí àpapọ̀ wọ́n jẹ́ ìjọ ti Krístì, láti rán ọ̀kan tàbí jù bẹ́ẹ̀ lọ nínú àwọn olùkọ́ wọn láti wà ní ibi onírúurú àwọn àpéjọpọ̀ síṣe lati ọwọ́ àwọn alàgbà ìjọ,
Mo ní ẹ gbọdọ̀ dá ẹrú náà sílẹ̀ kí ẹ sì jẹ́ kí ó máa lọ ní òmìnira, ṣugbọn àwọn baba ńlá yín kò gbọ́ràn sí mi lẹ́nu.
Buhari ní ìdìbò 2019 kìí ṣe tikú-tìyè Kí ló fà 'pàsán ojú' tí Buhari na aṣòfin?
Orilẹede Ghana, Naijiria ati South Africa ni awọn adajs nibi idije naa ti wa.
Kí ló dé tí o kò fi pa àṣẹ OLUWA mọ?
”Ijamba ina ohun bere laago kan owuro ojoRu(Thursday) ni isale ile naa ki o to gba gbogbo eka miran ninu ile ohun ka.
ó sì rán Natani wolii pé kí ó sọ ọmọ náà ní Jedidaya, nítorí pé, OLUWA fẹ́ràn rẹ̀.
Ọ̀gá ọlọ́pàá Adamu Pàṣẹ́ iṣẹ́ àkànṣe nílẹ̀ Yorùbá Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Gọngọ sọ, ẹlẹ́há pàdé àwọn tó lùú ní jìbìtì nílùú Eko lọ́jà Ibadan Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, International Day Against Drug Abuse and Trafficking: ìdí ti mo fi ń mu oògùn olóró Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Network of Niger Delta Republic Fighters: Àwọn ajìjàgbara Niger Delta fẹ́ yapa kúrò ní Nàíjíríà
Mercy, sọ fun BBC pe oun ti ọkọ oun ṣe ko ya oun lẹnu, nitori ọkọ oun maa n fi gbogbo igba ran ọmọnikeji lọwọ ni.
Ẹ dúró lórí òkè Baṣani, kí ẹ pariwo gidigidi,ẹ kígbe láti orí òkè Abarimu,nítorí pé a ti pa gbogbo àwọn alájọṣe yín run.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù BBC 100 Women: Obìnrin tí o lasẹ lórí kí ọkùnrin fẹ ìyàwó kejì Lati ọwọ Heather Chen BBC News, Shah Alam, Selangor, Malaysia 20 Bélú 2018 Oríṣun àwòrán, Joshua Paul for the BBC Àkọlé àwòrán, Agbára mi lè fún ọkunrin Malaysia laaye lati fẹ iyawo keji Ti wọn ba n sọrọ Sharia leti ọpọ eeyan, ohun to maa n wa si ọkan wọn ni ẹgba tabi ijiya to lagbara.
Wọ́n ti ọlọ́pàá mọ́lé nítorí ìbúgbàmù Abiy Ahmed di olóòtú ìjọba Ethiopia 'Awakọ̀ bàálù Ethiopia Airline tó já kò jẹ̀bi' Iroyin tilẹ sọ pe oju opo ayelujara ti dẹnu kọlẹ ni Ethiopia, ti awọn araalu ni Bahir Dar si n gbọ iro ibọn ni kikan-kikan.
Ọpọlọpọ nǹkan ati iṣẹ́ abàmì mìíràn ni Jesu ṣe lójú àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ tí a kò kọ sinu ìwé yìí.
 ""Oṣelu lo ti ba nkan jẹ, oun naa lo si mu ki iru Alaafin Ọyọ maa dasi nkan to n lọ l'Ekiti."
 Ìlú Ọ ̀ ra-Ìgbómìnà ló dúró bí afárá tí a lè gùn kọjá sí ìpínlẹ ̀ Ọ ̀ yọ ́ , ípínlẹ ̀ ondó , àti ìpínlẹ ́ kwara .
Nígbà tí ó bá wó, ẹ óo ṣègbé ninu rẹ̀.
Kò sí, àti ẹni tí ó bá máa pe àgùntàn ni màálù, tí o pe mọ́tò ní kẹ̀kẹ́, tí o pe ọmọtúndé ní Akíntúndé, tí ó pe ará ayé ní ará ọ̀run.
Mo ti rí eniyan burúkú tí ń halẹ̀ mọ́ni,tí ó ga bí igi kedari ti Lẹbanoni.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Tinubu s'abẹwo si iwọ orun ariwa Naijiria lati yanju aawọ APC 18 Èrèlè 2018 Oríṣun àwòrán, Twitter/@Imamimam Adari agba fun ẹgbẹ ọselu APC lorilẹede Naijiria, Bola Tinubu, ti bẹrẹ igbesẹ lati pari ija laarin awọn ọmọ ẹgbẹ naa pẹlu sise abẹwo si iwọ orun ariwa Naijiria.
Babatunde Olatunji: E wo ọmọ Yorùbá tó kọ́kọ́ jà fún ẹ̀tọ́ àwọn aláwọ̀dúdú ní America!
Nítorí ìwà burúkú yìí, inú bí OLUWA sí Juda ati Jerusalẹmu.
Iyawo rẹ̀ sì ti ṣe ara rẹ̀ lọ́ṣọ̀ọ́ dè é.
Egbe naa so pe won ti fun ijoba ni opolopo akoko lati le yanju aawo to sele yii.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù BIAFRA at 50: Ìhàlẹ̀ ológun ni Gowon ni ká kọ́kọ́ fi bẹ̀rẹ̀- Aladejẹbi Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ BIAFRA at 50: Ìhàlẹ̀ ológun ni Gowon ni ká kọ́kọ́ fi bẹ̀rẹ̀- Aladejẹbi 15 Sẹ́rẹ́ 2020 Awolowo lo jawe olubori ninu idibo ọdun 1966- Aladejẹbi Ogun Biafra jẹ ogun abẹle ti Naijiria ja pẹlu awọn iran Igbo lọdun 1967 si ọdun 1970.
Buhari kò lọ́wọ́ sí ìyọnípọ̀ Sanusi, e yé parọ́ kiri.
Wọn so ohun gbogbo to ni ṣe pẹlu iwe irina nileeṣẹ orileede Amerika leko ati Abuja rọ titi di igba ti wọn ba yanju idẹnukọlẹ ìṣèjọba to n ja rain lamẹrika.
Abubakar ki oludije naa lori atẹ Twitter rẹ, ti o si rọ ọ pe ki o sọp fun awọn alatilẹyin rẹ ki wọn so ewe agbejẹ mọ ọwọ.
Wọn ni ọkunrin naa ti ilẹkun mọ oku iyawo rẹ pẹlu awọn ọmọ meji ko to di wi pe ọmọ ọdọ wọn wa lọ fi ẹjọ sun ni agọ ọlọpaa.
Bí eniyan burúkú bá yá owó, kò ní san;ṣugbọn ẹni rere ní ojú àánú, ó sì lawọ́.
Nọmba ti LASEMA fi sita lati maa pe fun ifitonileti iṣẹlẹ pajawiri ni 767 / 112.
Awon janduku dana sun ile –eko
Irú irun tí o bá n ṣe ni yóò sọ bí orí rẹ yóò ṣe rí
À ì sí Iná Mọ̀nà-mọ́ná àti Epo Ọkọ̀ bá Onílé pẹ̀lú Àlejò.
Onimọ nipa ọrọ aabo ayika kan, Ọgbẹni Ehi Iden sọ fun BBC wi pe, ọrọ agbara ojo lagbara ju bi awọn eniyan ṣe ro o lọ.
K’á rúbọ àgùtàn, k’á tún m’ádìẹ ọ̀ṣọ́rí,
Bo tilẹ jẹ pe Chelsea ṣe bi okunrin, to si gbiyanju lati ri ẹyin awọn Southampton, ṣugbọn ko lee ta putu.
Ile Igbimo asofin ipinle Benue ti fiwe a o yoo nipo ranse si gomina Samuel Orthom lojo Aje.
Anthony Joshua darapọ̀ mọ́ Mohammed Alli, Lenox Lewis ati Holyfield 'Bàbá mi' fi ipá bá mi lájọṣepọ̀ fún ọdún mẹ́sàn án Òkété ti bórù!
”Jesu ń bá wọn wí, kò jẹ́ kí wọ́n sọ̀rọ̀, nítorí wọ́n mọ̀ pé Jesu ni Mesaya.
Ibadan robbery: Àgbègbè Secretariat ni adigunjalè ti gba ₦446,000 lọ́wọ́ oníbàárà báńki tí wọ́n pa
Ọbasanjọ: N kò ní dẹ́kun láti máa tako Buhari
Ọwọ́ ọlọ́pàá ti tẹ ọkùnrin kan tó pa ọ̀rẹ́ rẹ̀ nítorí N40 ní Kano Ẹ yé gba owó orí níbi ìdána ìyàwó mọ́, sísọmọbìnrin s'óko ẹrú ni- Daddy Freeze A kò fòfin de owó naira tó ti pẹ́ ní Naijiria -CBN Ọkọ̀ òfúrufú ọlọ́pàá yóò bẹ̀rẹ̀ sí ní káàkiri Naijiria - Ọgá Ọlọ́pàá Laarin ọdun 2002 si 2003 ni ọwọ tẹ awọn mẹrin to ku.
''Ẹhn ẹhn, àwọn da ẹni to mu ọti yoo mọ?
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Shiite: Tinúbú, bá Buhari sọ̀rọ̀ kó tú ZakZaky sílẹ̀ kó tó pẹ́ jù Oga agba awọn ọlọpaa ni ko si ẹni to n sọ pe ki awọn olujọsin Shiite ma sọ ohun ti wọn n fẹ lọwọ ijọba ṣugbọn wọn ko gbọdọ fa ijọngbọn.
O ṣalaye pe wọn ko fọwọ kan awọn ọmọ ilẹ Yuroopu ati Amẹrika to wa lọhun, ṣugbọn awọn alawọ dudu nikan ni wọn n dojukọ.
Titi di asiko ti a n ko iroyin yii jọ, Ọjọgbọn Banji Akintoye ko tii fesi si igbesẹ ti awọn to fi ẹgbẹ yii lọọlẹ gbe.
Seyi Adeyemi to muu ri fun ọdun mẹtalelogun kaakiri ipinlẹ Eko royin bi oun ṣe maa n dibọn tọrọ owo fi ra oogun oloro.
Fọ́kùnrin tó ba fẹ́ dupò lọdún 2019 nínú ẹgbẹ́ òṣelú All Progressives Congress (APC) àti Peoples Democractic Party (PDP).
abacavir di ifihàn nígbangba ní ọdún 1988 tí wọ ́ n sì fi oùntẹ ̀ tẹ ̀ ẹ ́ fún lílò ní orílè ède Àmẹ ́ ríkà ní ọdùn 1998 .
Germany bale si Moscow lojo isegun(Tuesday), ni erongba lati wa figagbaga daabobo ife-eye agbaye ti o wa lowo won, ti won si n gbero lati mu okan kuro ninu gbogbo ariyanjiyan oselu ti o ro mo Mesut Ozil ati Ilkay Gundogan sile.
Mo wọ ilé rẹ, o kò fún mi ní omi kí n fi fọ ẹsẹ̀.
 yorùbá máa ń ná owó àti ara sí ìsìnkú àgbà , pàápàá bí olóògbé bá jẹ ́ ẹni tí ó ní ipò àti ọlá nígbà tí ó wà láyé , tí ó sì tún bí ọmọ .
"Bàbá ẹni ọdún 61 bá ọmọ rẹ̀ lopọ̀, ó fún un lóyún l'Eko Florence Ajimobi tahùn sí igbákeji gómìnà Oyo lórí ikú ọkọ rẹ̀, ""Gbogbo wa làó kú"" Wolii Babatunde Sotitobire tun de ile ẹjọ giga ipinlẹ Ondo lonii lati jẹjọ nipa Gold Kolawole ọmọ ọdun kan to di awati nile ijọsin rẹ l'Akure."
Lati igba to ti de si ẹgbẹ agbabọọlu naa igba mẹtadinlọgbọn pere lo ṣeṣe gba bọọlu fun ikọ Zinedine Zidane.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ibadan: Bode Akindele, Richard Akinjide àti àwọn èèkàn míì tó kú lọdún 2020 29 Òkùdu 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 30 Òkùdu 2020 Lẹnu lọọlọ yi, iku awọn eekan ilu, paapa julọ awọn to ti gun oke agba ṣebi ẹni fẹ wọpọ.
Igbákejì gómìnà ìpínlẹ̀ Ondo Agboola Ajayi ti fẹgbẹ́ APC sílẹ̀ lọ PDP Wo àwọn àsọtẹ́lẹ̀ ìgbà tó yẹ kí ayé parẹ́ àtàwọn tó sọ àsọtẹ́lẹ̀ náà Ọ̀rọ̀ ńlá, àwọn adigunjalè ja àgọ́ ọ́lọ́pàá lólè Wo àwọn oníròyìn méje tó kú láàrin ọjọ́ méje ní Nàìjíríà Arabinrin naa ni oun ti ṣalaye pe awọn ko mọ pe awọn ti kọja ala ilẹ ipinlẹ Eko wọ ipinlẹ Ogun lasiko naa eleyii to ni awọn oṣiṣẹ kansu naa faake kọri, wọn ko gbọ.
Níbẹ̀ ni ó kú sí, òun ati àwọn baba wa náà.
Bẹẹ si ni, Tọba Joseph sọ wipe ki ‘Aarẹ Buhari o ranti wipe awọn ọdọ kii se ọlẹ’, lẹyin ti Aarẹ Buhari sọ laipe yii wipe, ọgọọrọ awọn ọdọ lorilẹede Naijiria ni ko fẹ isẹ se, ti wọn si n gbẹkẹle owo rọọbi.
Akurẹ Kidnap: Èmí kò ṣetán láti gbọ́ ẹ̀jọ yín lónìí, ó di 2020- Adájọ́ Adeyanju
Elòmìràn ngba ọdún mẹta fún owó à san silẹ̀.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù London Bridge: ọlọpàá kí àwọn aráàlú tó kojú agbésùnmọ̀mí náà kú akitiyan 29 Bélú 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 30 Bélú 2019 Oríṣun àwòrán, @GeorgeBarden_ Àkọlé àwòrán, Wọ́n ti fi ọkunrin kan si àhámọ́ lori bi wọ́n ṣe gún ènìkàn lọ́bẹ pa lóri afárá London.
odun 2019 , ajo INEC fẹnuko pe ilana eto idibo to waye ni ipinle Rivres ti tako
Kí lẹ tíì rí nípa Amotekun?
Ọkàn mi bàjẹ́ nítorí àwọn wolii,gbogbo ara mi ń gbọ̀n.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Akomolede ati Aṣa lori BBC: Mọ̀ si nípa oríṣìí ẹ̀ka ìsọ̀rí ọ̀rọ̀ àti ìwúlò wọn Afenifere ni igbesẹ lati ṣe atunṣe iwe ofin Naijiria ti di ohun ti ijọba n kede lọdun mẹrin mẹrin lai si iyipada kankan to ba ofin ọhun.
Eyi ni agba adura ti akẹgbẹ rẹ, Rasaq Olasunkanmi Olayiwola ti ẹ mọ si Ojopagogo ṣe fun un.
Habits that damage brain: Wo àwọn ìṣesí ojoojúmọ́ mẹ́wàá tó le ṣàkóbá fún ọpọlọ rẹ
ni awon orile-ede asa;e meweewa yii.
Igbimọ Aṣofin naa fọwọ si biliọnu lọna ẹẹdẹgbẹta din miliọnu mẹta ati
Rutu bá gbéra, ó lọ sí oko ọkà, ó sì bẹ̀rẹ̀ sí ṣa ọkà tí àwọn tí wọn ń kórè ọkà gbàgbé sílẹ̀.
 kí o wá padà si Ìkọ ̀ lé ayé .
Ọta ìbọn ogun Biafra ṣì wà lọ́rùn mi lẹ́yìn àádọ́ta ọdún tí ogun parí - Umar Awọn ẹkọ ti itan igbe aye Bode Thomas kọ wa: Ẹkọ akọkọ ni pe a gbọdọ se amulo ọpọlọ ti Ọlọrun fun wa lati fi mu idagbasoke ba awujọ ati iran wa Ẹkọ miran ti itan igbe aye Bode Thomas kọ wa tun ni lati mase fi aaye gba ibinu tabi sọrọ odi, paapaa si awọn eeyan to ju wa lọ.
Aare Muhammadu Buhari  ti pada de si ilu Abuja lorile ede Naijiria lojo Aje, leyin  irinajo olojo-meji si orile ede Morocco.
" Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Madrid-Bayern, Arsenal-Athletico yóò wàákò Aláwàdà ni Buhari - Fáyóṣé Ọọ̀ni : Oluwo lorukọ oyè tí ọba Ìwó ń jẹ́ Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Agbenusoro fun ile-ise olopaa Afghan, Mohebullah Moheb lo jabo oro naa sugbon ti salaye bi oro ohun se lo lekunrere.
Akọkọ rẹ ree ti iru anfaani bayii yoo wa ni ilẹ Naijiria ati ni ilẹ Afirika lapapọ.
Nebusaradani, olórí àwọn ẹ̀ṣọ́ ọba Babiloni, sọ fún Jeremaya pé, “OLUWA Ọlọrun rẹ ti pinnu láti ṣe ilẹ̀ yìí ní ibi; 
Paulu dáhùn pé, “Ará, n kò mọ̀ pé Olórí Alufaa ni.
Ó ní,“Àgbàlagbà ni yín, ọmọde sì ni mí,nítorí náà ni ojú fi ń tì mí,tí ẹ̀rù sì ń bà mí láti sọ èrò ọkàn mi.
“Ẹ ranti ìgbà àtijọ́,ẹ ṣe akiyesi ọpọlọpọ ọdún tí ó ti kọjá.
 Ọkan lara awọn oṣiṣẹ Osun United ti ko fẹ ki orukọ oun jade, sọ fun ile iṣẹ iroyin Punch pe, ẹgbẹrun mẹwaa pọun wọle sinu akanti banki Access Osun United, ninu oṣu kaarun ọdun."
Ṣé lóòtọ́ ni PDP fẹ́ kẹ̀yìn sí Gómìnà Seyi Makinde nípínlẹ̀ Oyo?
Ọpọ iṣe wa lọwọ obi ati alagbatọ awọn eniyan to n mu oogun oloro.
lori ọrọ naa, ki won si wa jabọ fun ile igbimo asoju lẹyin ọsẹ meji to n bọ
Àwọn ẹgbẹ́ náà ní gbogbo iṣẹ́ tó ń wáyé ní MMA2 ní àwọn yóò bẹ́gi dínà rẹ̀ láti ọjọ́ kẹ́wàá oṣù kẹ́wàá àyàfi bí wọ́n bá dá gbogbo àwọn òṣìṣẹ́ tí dá dúró padà láì pàdánù owó oṣù tàbí ipò gíga wọn.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Àṣìlò òògùn burú, ṣùgbọ́n ṣé ẹ̀bi ará ìlú nìkan ni?
Ètò ìdìbò abẹ́lé kò tìí dábì pé yóò wáyé ní ìpínlẹ̀ Ogun.
Oríṣun àwòrán, AFP Falana ni iwe ofin orilẹede Naijiria sọ wipe ti aarẹ ba fẹ rin irinajọ lọ ẹyin odi, ọ gbọdọ fi to awọn aṣofin leti.
Ko si ifoya fun awọn onisowo ti ọpọ ninu wọ́n a si ma rin lalai ni ẹsọ.
Ìyá mi ni mo jọ, n kò sì fi ibi kan jọ bàbá mi ni o sì mú u lójú ogun, lákòókò tí ìjà dé láàrin àwọn ara òde ọ̀run àti Èṣù, tí Èṣì dúrò gẹ́gẹ́ bí olórí ogun láti da ojú ìjà kọ Ọlọ́run ọba.
Ko si ti i ju oṣu mẹta lọ ti iroyin jade pe awọn kan fi ipa ba ọmọde mẹta lopọ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ipinlẹ Ọyọ yoo da papa ijẹko silẹ fawọn darandaran 25 Èrèlè 2018 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Wahala darandaran fulani ati agbẹ oloko ti di gbẹmigbẹmi lorilẹede Naijiria Igba akeji gomina ipinlẹ Ọyọ, Ọtunba Moses Alake-Adeyemo ti sọ wipe ijọba ipinlẹ naa ti setan lati da awọn papa ijẹko silẹ lati wojuutu si gulegule wahala laarin awọn darandaran Fulani ati agbẹ olohun ọgbin nibẹ.
Ra òtítọ́, má sì tà á,ra ọgbọ́n, ẹ̀kọ́ ati òye pẹlu.
Nígbà tí Ibisani ṣaláìsí, wọ́n sin ín sí Bẹtilẹhẹmu.
Wo àwòrán bí ọdún Keresimesi ṣe ń lọ káàkiri àgbàyé Canada sọ igbó mímu àti títà rẹ̀ di ìrọ̀rùn Olè yabo báńkì,fọ́n owó ká fáwọn èrò lẹ́yìn tó pariwo 'Merry Christmas' Ni bayi ẹni ọdun marundinlọgbọn naa sọ pe oun n foju sọna de owurọ ọjọ Keresi akọkọ ti oun yoo ba wọn ṣe.
Aṣọ ọ̀hún ní àmi àwọ ewé àti funfun, èyí tó fi àwọ àsíá orílẹ̀èdè Nàìjírìá hàn.
Oriṣiriṣi iwulo ni ammonium nitrate ni, ṣugbọn meji to wọpọ julọ ni pe, wọn ma n lo o lati fi ṣe eroja Ajilẹ fun iṣẹ agbẹ, ati bii eroja abugbamu.
Mo rí òkú àwọn ọlọ́lá ati ti àwọn mẹ̀kúnnù, tí wọ́n dúró níwájú ìtẹ́ náà.
A fẹ́ bẹ̀rẹ̀ òfin má lo fóònù mọ́ fàwọn ọmọ wa -Òbí Dino, Wada àti àwọn olùdíje 11 míràn n dù àsíá PDP fún gómìnà ìpínlẹ̀ Kogi Àwọn akọni Nàìjíríà padà sílé pẹ̀lú àmì ẹ̀yẹ 121 láti Morocco Ǹkan mẹ́jọ tó máa kọ́kọ́ ṣẹlẹ̀ kí olólùfẹ́ méjì tó pa ara wọn Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Gomina ana ni ipinlẹ Ekiti, Ayọdele Fayoṣe ni 'boya ki wọn kuku yan ọmọ aarẹ gẹgẹ bii alaga ajọ eleto idibo INEC?
Ni oju oja Bureau De Change (BDC) pasipaaro re je ọ́ọ̀dúnrún le lọgọ́ta(N360), ti owo Pound Sterling ati Euro si je ẹ̀ẹ́dẹ́gbẹ̀ta din lọgọ́rin N480) ati irinwó le méjìdínlógún (N416) ni n tele n tele.
Ìdí nìyí tí orúkọ ìlú náà fi ń jẹ́ Beeriṣeba títí di òní yìí.
3 8946 Orilẹede Equatorial Guinea 86 6.
Ọlọ́pàá Germany ti mú àfurasí mẹ́rin nínú àwọn tó kọlu Ekweremadu ni Germany Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Àwọn ọ̀dọ́ Naijiria ti sọ̀rọ̀ síta lórí ohun ti wọ́n ń retí lọ́dọ̀ minista tuntun Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
 Branda je omo odun méjídínláàdọ́rin, o  fi orile ede re sile lodun 2014, nigba ti o kuna nibi idije fun ipo aare.
Nítorí náà ó silẹ̀ bí gẹ̀dẹ̀gẹ́dẹ̀ ọtí.
Bi awọn esi naa ṣe lọ niyii: Eko-136 Kano-4 Niger-3 Ekiti-2 Kaduna-2 Ogun-2 Taraba-2 FCT-1 Èèyàn 112 míràn ló tún lùgbàdìi Coronavirus ní Nàìjíríà Apapọ awọn to ni coronavirus ni Naijiria ti pe 64,996 bayii.
Josẹfu dá Farao lóhùn, ó ní, “Kò sí ní ìkáwọ́ mi, Ọlọrun ni yóo fún kabiyesi ní ìdáhùn rere.
Awọn nọmba miran wa lara kaadi idanimọ E-Card lootọ amọ ko si NIN lara wọn.
Èyí èkeje wà nínú ipò tí ó ba ni lẹ́rù gidigidi.
"m newscast ) , èyí tí ó fẹsẹ ̀ múlẹ ̀ lẹ ́ yìn tí "" the oprah winfrey show "" kásẹ ̀ kúrò nílẹ ̀ tán tí bádérìnwá sì tẹ ̀ síwájú láti ma bá ètò ìròyìn alágo márùn ún 5 p."
Ọkunrin yìí tún rán ẹrú mìíràn.
Kasira ni: “Nitooto, ajo NOA n sise daadaa nipinle Kwara sugbon o ku nibon n ro, mo fe ki e tubo seto ilaniloye fawon eniyan lainifise odiwon ipele eto eko won ki imo won le kun daadaa saaju eto idibo odun 2019.
Laaarin ariwo ayò ati idunnu ni Hon.
0 6051 Orilẹede Belize 173 45.
Eyi lo mu ki wọn gba ile ijọsin T.
A Sabo ni Wuse Zone 3 Abuja, ni asiri ọrọ naa ti tu sita.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù ASUU ní ìjọba àpapọ̀ ni kò fẹ́ kí ìyanṣẹ́lódì àwọn o pari 2 Sẹ́rẹ́ 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Àwọn olùkọ́ fásitì lórílẹ̀èdè Nàìjíríà bẹ̀rẹ̀ ìyanṣẹ́lódì nítorí àwọn àdéhun tí ìjọba àpapọ̀ kùnà láti mú ṣẹ Iyanṣẹlodi ẹgbẹ olukọ fasiti lorilẹ-ede Naijiria ti wọ oṣu meji bayii.
O ni Ọbamakin Ọsangangan to jẹ Ọọni akọkọ ni iran baba nla oun ati pe ileto mẹtala ni baba oun ti ni ni ile iIfẹ ki Oduduwa to de.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Siasia: Ọlọ́pàá Bayelsa ṣalàye ibi tí wọ́n bá ìyá Siasia tó bọ́ sọ́wọ́ ajínigbé 15 Agẹmo 2019 Oríṣun àwòrán, Other Iroyin to tẹwa lọwọ latọdọ ile iṣẹ Ọlọpaa Bayelsa ni peawọn agbebọn ya wọ ile arabinrin Beauty Siasia wọn si ji i gbe lọ.
ologun tun so pe “iko omo ogun  192 orile
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: NUPENG ti ìyanṣẹ́lódì NLC lẹ́yìn Buhari ló kòwé bèrè ìwé ẹrí rẹ̀ lọ́wọ́ àjọ wa- WAEC Kí ló fà á tí àwọn ọmọ Obasanjo ń ta kò ó ní gbangba?
Sugbọn a dupẹ lọwọ Ọlọrun pe, a ti n bọ ninu rẹ diẹdiẹ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Wo imọran Fọlọrunṣọ Alakija fun awọn ọdọ adulawọ Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Ọlọrun gbọ́ adura Manoa, angẹli Ọlọrun náà tún pada tọ obinrin yìí wá níbi tí ó jókòó sí ninu oko; ṣugbọn Manoa, ọkọ rẹ̀, kò sí lọ́dọ̀ rẹ̀.
Allwell Ademola di ọmọde pada: Oríṣun àwòrán, others Ara ọwọ awọn oṣere tiata to dilẹ, ti sọ awọn gbajugbaja oṣere tiata kan, ninu eyi taa ti ri Allwell Ademola di ọmọde pada.
Ẹ̀yin èèyàn mi nkan ńbẹ o!
Akinyele lọ ile ẹkọ alakọbẹrẹ All Saints School ni ilu Ondo, lẹyin naa lo tẹsiwaju ninu ẹkọ girama ni Gboluji Grammar School, ni Ilẹ Oluji, lẹba ilu Ondo.
Àwọn ire inú ilé rẹ yóo tẹ́ wa lọ́rùn,àní, àwọn ire inú tẹmpili mímọ́ rẹ!
bíótilẹ ̀ jẹ ́ pé rògbòdìyàn yìí kò dáwọ ́ dúró .
Bakan naa ni gomina ipinlẹ naa, Aminu Masari sọ fun awọn oniroyin pe o to eniyan mẹrinlelogoji to padanu ẹmi wọn sinu iṣẹlẹ naa.
OLUWA gbọ́ adura Hesekaya, ó sì wo àwọn eniyan náà sàn.
Yatọ si ile yi,Ile mẹta miran ni awọn ọdọ naa tun dana sun.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Adebisi Idikan: Òun ló gba Ìbàdàn sílẹ̀ lọ́wọ́ ìyà owó orí sísan Atẹjade naa ni ile Fẹlẹ to wa ni adugbo Ẹlẹbu nilu Ibadan ni wọn yoo sin oloogbe naa si ni aago mẹsan si mẹwa oorọ yii.
Odunlade Adekola, Femi Adebayo, Jenifa ṣi aṣọ lójú àwọn fíìmù tuntun tẹ́ẹ ti ń retí Ìdí ti mo fi da sọ́ọ̀sì rú lásìkò ìgbéyàwó ìyáwó mi tó ló fẹ́ ọkọ míran- Osadebe Gani Adams ni ikọ̀ asẹrubani ISIS ti ni ibùdó si agbègbè Oke Ogun ní ìpińlẹ̀ Oyo, o si yẹ kawọn ọmọ Yoruba fura.
Oríṣun àwòrán, RAUF AREGBESOLA/FACEBOOK Àkọlé àwòrán, Gomina ipinlẹ Ọsun, Ọgbẹni Rauf Arẹgbẹsọla nlọgun pe ki awọn ọmọ Naijiria sọra O yẹ kawọn ọmọ jawọ ninu iwa ipaniyan, ọrọ ikorira ati iwa ika.
Abẹwo aarẹ Trump ṣe kongẹ pẹlu iranti ikariudinlọgọrin D -Day Landings ti Obabinrin Elizabeth àti aarẹ Trump atawọn olori orilẹ-ede miran a jọ ṣe ni ọjọru.
”Ọgbẹni Muṣowo bu ẹnu atẹ lu lilo ohun eelo onike lẹẹkan ṣoṣo, ki a si ju u nu, pe eleyii n ko iko aadọta awọn idọti ti a n sọrọ rẹ yii.
Ṣaaju ni iroyin kan ti gbode pe Ajimobi ti di oloogbe ṣugbọn ti awọn ẹbi atawọn eeyan miran to sun mọ sọ pe ọrọ ko ri bẹ.
Aṣa ati iṣe ilu ni wọ́n tẹlé ti wọn fi yan an gẹgẹ bii adele nitori oun ni akọbi baba rẹ.
Bakan naa ni wọn rọ awọn eeyan to ba sanra ni ipinlẹ kọọkan, lati ko ara wọn jọ, bẹrẹ lati eeyan mẹwa, wa dara pọ mọ ẹgbẹ Lush Beauties.
Ninu iwadi ti ajọ naa gbe jadẹ, wọn ni iwadi naa dalori ikọlu awọn agbe ati darandaran to waye lagbegbe ariwa ati gbungbun Naijiria laarin oṣu kini 2016 ati oṣu kẹwa ọdun 2018.
Ọ̀gá àgbà ninú Olórin ilẹ̀ aláwọ̀-dúdú (Olóyè, Olùdarí Ebenezer Obey) kọ ninú orin ni èdè Yorùbá pé “ki lẹni kan ṣe, tẹni kan ò ṣe ri?
Wọ́n fi ọ̀nà títọ́ sílẹ̀, wọ́n ń ṣe ránun-rànun kiri.
Mose ṣe olóòótọ́ ninu gbogbo ìdílé Ọlọrun gẹ́gẹ́ bí iranṣẹ.
Bakan naa ni asofin Buraimoh ti se alaga ijọba ibilẹ Kosofe ri, to si tun jẹ aṣoju ṣofin fagbegbe Ketu.
"Oríṣun àwòrán, topealabi Ohun tí o kò mọ̀ nípa Ebila ""One Million Boys"" àti Ekugbemi, olórí ẹgbẹ́ òkùnkùn méjì tó da ìlú Ibadan rú Nigeria Police recruitment 2020: Bí ó bá fẹ́ dara pọ̀ mọ́ ìṣẹ́ ọlọ́pàá, forúkọ́ sílẹ̀ níbí Ǹjẹ́ o mọ àwọn olorì àkọ́fẹ́ Aláàfin Adeyẹmi?"
Ó ń sọ̀rọ̀ àfojúdi sí Ọlọrun.
Àwọn meji yóo wà ní oko, a óo mú ọ̀kan, a óo fi ekeji sílẹ̀.
Ijiroro pẹlu awọn alẹnulọrọ lori iwe orukọ awọn oludibo naa.
Bakan naa ni onimọ kan nipa ile ọmọ obinrin l'orilẹede Singapore, sọ pe ile ọmọ meji ni obinrin naa ni - eyi ti awọn onimọ iṣegun oyinbo n pe ni 'uterus didelphys'.
Gomina Makinde sọrọ yii nigba to n ṣe idupẹ agbole ni ijọ Aguda Dafidi Mimọ, ti o wa ni Ijọmu, ni ilu Akurẹ, ni ipinlẹ Ondo.
Awọn tọkọ taya naa fikun wipe igbagbọ awọn to daju ati ibẹru Ọlọrun lo se koko lati duro ninu igbeyawo.
Ó ń tan ìmọ́lẹ̀ fún wọn lálẹ́, láti máa tọ́ wọn sí ọ̀nà tí wọn yóo máa rìn.
Ó rọ̀ ọ́ pẹlu ọpọlọpọ ọ̀rọ̀ ẹ̀tàn,ó fi ọ̀rọ̀ dídùn mú un.
 Àwọn ni o n lọ gba isakọlẹ fọ ́ ba .
"Gbogbo igbesẹ bi a ṣe maa mú ni a n ṣe lọsan lorun, ti ẹnikẹni ba gbọ nnkan nipa rẹ ati ibi to n rin si, ki wọn tete fi to wa leti "" Ìtàn ayé Alájọ Ṣómólú rèé, tó ta mọ́tò ra kẹ̀kẹ́?"
Idi si niyii ti awọn eleto ilera ṣe ma n sọ pe o ṣe pataki fun alaboyun ti inu ba n run lati lọ ri dokita.
Ìgbà mélòó ní wọn fẹ kéde ikú ẹṣọ tó pá Ọ̀gágun Lorílè-èdè Ethiopia ?
"Inu mi bajẹ gidigidi nipa rogbodiyan to n waye lọwọ bayii lorilẹede Naijiria; mo si n fi eyi rọ ijọba atawọn eeyan orilẹede Naijiria lati yago fun wahala ki wọn si gba alaafia laaye.
Wọ́n sọ wá sẹ́wọ̀n, wọ́n wá fẹ́ tì wá jáde níkọ̀kọ̀.
INEC ń pe àwọn èèyàn lórí fóònù láti wá gba káàdì ìdìbò wọn
Bakan naa, o tun ṣe iru ẹ si iya ẹni ọgọrin ọdun.
Iru awọn iroyin ti ẹ le nifẹ si: 'Akonimu BBC' Jamb padanu owo s'ikun ejo Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí 2 sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
Nítorí ó dá mi lójú pé, kò sí ohunkohun–ìbáà ṣe ikú tabi ìyè, ìbáà ṣe àwọn angẹli tabi àwọn irúnmọlẹ̀, tabi àwọn ohun ayé òde òní tabi àwọn ti ayé tí ó ń bọ̀, 
Bí ẹ kò mọ nǹkan ẹ ko mọ iyì ìbàǹtẹ́ mi?
Bakan naa ni o n ro ijoba apapo ni gbogbo ona lati satileyin fun ise-akanse yii.
Nígbà tí ó yá, àwọn eniyan a máa gbé àwọn aláìsàn wá sí títì lórí ẹní ati lórí ibùsùn, pé kí òjìji Peteru lè ṣíji bò wọ́n nígbà tí ó bá ń kọjá.
Ṣugbọn Jesu sọ fún wọn pé, “Ẹ̀yin ni kí ẹ fún wọn ní oúnjẹ.
Wọn óo kó eérú kúrò lórí pẹpẹ, wọn óo fi aṣọ elése àlùkò bò ó.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Aràrá bíi tèmi, kó má rò pé kò sì ǹkan tó lè ṣe láyé ju iṣẹ́ agbe lọ' Ẹni mọ́kànléláàdọ́fà 111 ló lùgbàdì àrùn covid-19 ní Nàìjíríà lọ́jọ́ Àìkú Eeyan mọkanlelaadọfa lo ko aarun coronavirus kaakiri orilẹede Naijiria lanaa ọjọ Aiku tii ṣe ọjọ kinni oṣu kọkanla ọdun 2020 yii.
Àwọn rèé19 Agẹmo 2020 Fídíò, Alaafin: Olori Aanu Adeyemi aya Oba Lamidi Adeyemi ti ìlú Oyo ní ohun tó bá kúkú wu ọmọ láti jẹ kìí.
ọmọniyan nilẹ Afirika yoo wa si ile- ẹjọ ECOWAS to wa ni  orile ede Niajiria, ni eyi ti won yoo si lo ọsẹ
Nítorí a gbọ́ ohùn kan láti ilẹ̀ Dani,tí ń kéde ibi láti òkè Efuraimu.
Ní ti ìwọ Paṣuri, ati gbogbo àwọn ará ilé rẹ, wọn óo ko yín ní ìgbèkùn lọ sí Babiloni.
pupọ lori abajade ti ile-ise asoju orile ede Britain ko nipa ija to maa n waye
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Lateef Adedimeji and Adebimpe Oyebade: Ohun tí BBC mọ̀ nìyí nípa àjọṣepọ̀ òṣèré tíátà méjéèjì 17 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 25 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Oríṣun àwòrán, Instagram/@adefits Laipẹ yii ni iroyin jade pe, gbajugbaja oṣerebinrin, Adebimpe Oyebade ti loyun, ti ọpọ eeyan si n sọ pe akẹẹgbẹ rẹ, Lateef Adedimeji ni ọkọ rẹ to loyun fun.
Bí ó bá jẹ́ pé mo ti fẹ́ ní ọkọ ni, mo rò pé n ba tilẹ̀ ti di ẹni ti ń bímọ nísisì yìí, nítorí ọ̀pọ̀lọpọ̀ okùnrin ló ti yọ mi lẹ́nu sẹ́yìn pée ki n fẹ́ àwọn tí mo kọ̀ fún wọn.
Ninu ìpọ́njú, mo ké pe OLUWA,ó dá mi lóhùn, ó sì tú mi sílẹ̀.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Jemila dáná sún ilé ọ̀rẹ́kùnrin rẹ̀ àti ọ̀rẹ́bìnrin tó bá nílé 24 Bélú 2020 Oríṣun àwòrán, Lagos Police Command Ilé iṣẹ́ ọlọ́pàá ìpińlẹ̀ Eko tí mú obìnrin ẹni ọdún mọ́kàndílógún kan tó dána sun ilé ọ̀rẹ́kùnrin tó n fẹ́ tẹ́lẹ̀ àti ọ̀rẹ́bìnrin rẹ̀ tó bá nílé.
’inú a sì máa bí Ewédayépọ̀, a wí pé: N kò mà fẹ́ o, Olówó-ayé, n kò mà fẹ́ o.
Ẹnikẹ́ni kò gbọdọ̀ bá ọ wá, ẹnikẹ́ni kò sì gbọdọ̀ sí níbikíbi lẹ́gbẹ̀ẹ́ òkè náà, àwọn mààlúù, tabi àwọn aguntan kò gbọdọ̀ jẹ káàkiri níbikíbi lẹ́gbẹ̀ẹ́ òkè náà.
Nípa agbára rẹ̀ ó ń jọba títí lae.
Ṣé ọ̀nà àbáyọ sí ìṣòro Nàìjíríà ní ẹgbẹ́ òṣèlú tuntun ti Falana, Ezekwesili àtàwọn 28 mìí dá sílẹ̀ yìí?
Bakan naa ni aarẹ ana orilẹede Naijiria, Gooluck Jonathan ṣe ṣadankata IBB, bi o ti pe ọdun mọkadinlọgọrin loke eepẹ.
Àwọn ọmọ ogun rẹ̀ tí a kà jẹ́ ọ̀kẹ́ meji ó lé ẹẹdẹgbaaje ati irinwo (53,400).
Ewe, iko agbaboolu Enyimba FC tilu Aba, nikan lo ku ti yoo maa soju orile-ede Naijiria ninu idije naa, leyin ti iko agbaboolu Plateau United ati Akwa United ti ja kuro saaju.
Àwọn Minisita agbègbè Lake Chad se ìpàdé Ìpalẹ̀mọ́ ọdún Ileya kò rọgbọ ní Maiduguri, ojo ado oloro n rọ leralera Ìkọlù agbébọn tó ṣékú pá ọmọ ogún Niger 89, iṣẹ́ bọ lọ́wọ́ Ọgágun àgbà O ni Al Qaeda n gbe igbesẹ lati pẹka sii paapa julọ sawọn agbegbe mii ni ila oorun ilẹ Afrika.
Bi awọn kan ṣe n sọ pe olowo ṣe ohun gbogbo tan, wọ́n ni imura rẹ dara pupọ, o si ba igba mu.
 ati lati lo awọn  ohun alumọọni orile ede yii fun idagbasoke awọn
” Ó bá dìde, ó jẹun, ó dárayá, kò sì banújẹ́ mọ́.
Àwọn tí wọ́n jẹ̀bi ọ̀rọ̀ náà jù ni àwọn olórí ati àwọn eniyan pataki ní Israẹli.
Iwa nabi tu igbeyawo ọgbọn ọdun ka Kí ló le fà á kí ìyàwó pa ọkọ rẹ̀?
Ìdí nìyí tí a fi gba Titu níyànjú pé, nígbà tí ó jẹ́ pé òun ni ó bẹ̀rẹ̀ iṣẹ́ oore-ọ̀fẹ́ yìí láàrin yín, kí ó kúkú ṣe é parí.
N11trn subsidy: Ǹjẹ́ ẹ mọ̀ pé owó ìrànwọ́ epo lè kọ Second Niger Bridge méjìléláàdọ́ta?
Ann Grace Aguti, Obìnrin kan to fẹ́ ọkọ mẹ́ta lẹ́ẹkàn ṣoṣo Èèyàn 667 ló lùgbàdì àrùn Coronavirus ní Naijiria ní Ọjọ́ Ẹtì Ìlànà ìjìnàsíraẹni 'social distancing' forí ṣánpọ́n bí ìrun Jímọ̀ ṣe bẹ̀rẹ̀ padà ni Ilorin Ètò ìsìnkú Ibidunni Ighodalo yóò wáyé lórí ẹ̀rọ amóhùnmáwòrán bó bá ṣe ń lọ Ọrọ yi ko jẹ tuntun sawọn to ba mọ isesi awọn oloselu Naijiria.
Ó yí ìṣe rẹ̀ pada níwájú wọn, ó bẹ̀rẹ̀ sí ṣe bíi wèrè.
Ile-ise Cement ti o wa ni apa ariwa orile-ede Nigeria ni akinkanju lopo-lopo, nipa tita oja idokowo ,ti iye owo re je 134.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Kankara Abduction: Àwọn ológun ṣàlàyé ìdí tí wọ́n fi yọ̀nda àwọn tó jí àwọn akẹ́kọ̀ọ́ gbé.
Amọ awọn to fẹ ki ofin konile o gbele o tẹsiwaju ko po to awọn to fẹ ki ofin naa di ohun ana.
Ni bayi, o ni Federal Special Anti Robbery Squad(FSARS) ni SARS yoo maa jẹ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Alaafin: Olori Aanu Adeyemi aya Oba Lamidi Adeyemi ti ìlú Oyo ní ohun tó bá kúkú wu ọmọ láti jẹ kìí.
mawjoudin queer film festival jẹ ajọyọyọyọ ọdun kan ni orilẹ-ede tunisia nṣe ayẹyẹ agbegbe lgbt .
eye naa , pe ki won tun maa se rẹwẹsi lati sa ipa won lona ti won yoo fi gba ami
Awọn to ba ninu ẹgbẹ naa rọ yika wọn, wọn si fi orin, ilu, ijo ati egba to le ki oun ati awọn ọmọ ẹgbẹ tuntun miiran kaabọ bẹrẹ lati oru titi di afẹmọjumọ.
Ẹwẹ EFCC tun darukọ awọn oludari ileifowopamọ kan pe wọn mọ nipa apapin owo yi.
Wọn kede lọjọ kejilelogun, oṣu kẹfa ọdun loju opo ayelujara wọn pe ilana tuntun ti awọn n ṣiṣẹ le lori lati igba ti ti tẹlẹ dẹnu kọlẹ, ti pari fun lilo.
Femi Adebayo Ilu Eko ni wọn ti bi gbajugbaja olosere yii.
Ileesẹ ologun ṣalaye pe ọwọ ti tẹ awọn ajinigbe ọhun, ati pe awọn tun ti gba oriṣiiriṣii ohun ija lọwọ wọn.
mo tún ti dé pẹ ̀ lú ohùn ẹnu mi , mo tún fẹ ́ sọ ̀ rọ ̀ lórí àṣà àti ìṣe ilẹ ̀ yorùbá .
Loju opo Twitter ati kaakiri ẹrọ ayelujara lawọn ọmọ Naijiria ti n daro rẹ Ọmọ bibi ilu Ilesha ni alagba Moses Olaiya ti a si bi ni ọdun 1936.
Ṣugbọn ọrọ Giroud ti di okuta tawọn ọmọle kọ silẹ to ti wa di pataki igun ile bayii pẹlu ara to fi bọọlu da nigba ti orilẹede Faranse waako pẹlu Ukraine.
Iye bíríkì tí wọn ń ṣe tẹ́lẹ̀ kò sì gbọdọ̀ dín; nítorí pé nígbà tí iṣẹ́ kò ká wọn lára ni wọ́n ṣe ń rí ààyè pariwo pé, ‘Ẹ jẹ́ kí á lọ rúbọ sí Ọlọrun wa.
Ajọ to n bojuto idanwo asewọle si ile iwe giga, JAMB ti ni akẹẹkọ ọdọmọkunrin ọdun mẹẹdọgun, Elene Franklin lo gba maaki to pọju lọ ninu esi idanwo JAMB.
Iroyin ohun to safihan awon ewu ti o n koju eto ogbin, lara eyi ti a ti ri laasigbo lori ounje, eti ti o sokunfa owon-gogo owo ori ounje.
41 Àti láti fì ẹsẹ̀ àwọn wọ̃nnì múlẹ̀ tí a rìbọmi sínú ìjọ, nípa gbígbé ọwọ́ lé wọn lórí fún ìrìbọmi ti iná àti ti Ẹ̀mí Mímọ́, ní ìbámu sí àwọn ìwé mímọ́;
Inú àwọn ẹbí, ọ̀rẹ́ àti ojúlùmọ tó péjọ yóò dùn fún igbe ayọ̀ tí ọmọ náà ké.
 Gomina ipinle Eko , Akinwumi Ambode, naa tun
Iná míràn tún fẹ́ ràn lẹ́ka ilera Nàìjíríà A n jekuru ọrọ l'agboeto ilera lorilẹede Naijiria ko tan lawo, ṣe ni wọn tun n gbọn ọwọ rẹ sinu awo.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Insecurity: Monguno ní àsìkò ti tó láti f'òpin sí Almajiri ní Nàìjíríà 4 Ọ̀pẹ̀̀ 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Oludamọran fun ijọba lori ọrọ aabo, Babagana Monguno ti kepe ijọba lati fopin si eto ẹkọ Almajiri to wọpọ lapa ariwa orilẹede Naijiria.
Gbogbo àwọn obìrin náà wà ní ìhòòhò, wọn ń wọlé wọ́n ń jáde.
wọ́n parapọ̀ pẹlu àwọn arakunrin wọn ati àwọn ọlọ́lá wọn; wọ́n gégùn-ún, wọ́n sì búra pé àwọn ó máa pa òfin Ọlọrun mọ́, àwọn óo sì máa tẹ̀lé e, bí Mose iranṣẹ rẹ̀ ti fún wọn.
13 Bélú 2020 Coronavirus: Bóo ṣe lè sọ iṣẹ́ láti ilé lásìkò Coro” di ìgbádùn fún ara rẹ9 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 3 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 5 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!"
), tí ó jẹ́ pé, ní báyìí, ni àkọlé tí ó gbajúmọ̀  ní orí ìkànnì ayélujára Twitter ti Orílẹ̀ Èdè Venezuela.
Oun lo gba onkọrin obinrin to dara julọ ni aarin gbungbun Afrika lọdun 2018 ninu eto ifami ẹyẹ danilọla fun orin to pegede lọdun 2018.
Ajo to n koju arun Coronavirus ni Naijiria, NCDC to fi lede ni Ọjọọru, ni iye awọn to ti ni arun naa ti le ni ẹgbaata ati ọrinlelẹgbẹtadinmẹta (6677).
rẹ ti o ba n dupo  lati maa ba awon
"O ni ""o ti su wa ni Naijiria, ta si n sisẹ laagun lati jẹ eeyan, ọpọ ninu awa gbajumọ si lo jẹ mẹkunnu ti ko ni owo lọwọ, bẹẹ ni inu wa ko dun rara, ẹ ma si jẹ ki ohun meremere tẹ n ri lori ayelujara nipa wa tan yin jẹ."
#EkitiDecides: Kayọde Fayẹmi ní wíwọ ẹ̀wù agbọta kò lòdì sí òfin
Wọn fẹsun kan pe o gbe oogun oloro.
Ènìyàn ẹgbẹ́rún lọ́nà ààdójọ ni olùdìbò tó ti fórúkọ sílẹ̀.
    Báyìí ni a pari ìjàkadì ọjọ́ náà.
O sọ fún àwa iranṣẹ rẹ pé kí á mú un tọ̀ ọ́ wá, kí o lè fi ojú rí i.
Bákan náà ni ọ̀pọ̀ àwọn àgbáríjọ onímò sáyẹ́nsì àti onímọ̀ ẹ̀rọ láti ilé ìwé Oxford àti King's College London náà tí ṣe àfılọ́lẹ̀ Fẹntílàtọ̀ olówó pọ́ọ́kú tiwọn, èyí tí wọn ní àwọn lè bẹ̀rẹ̀ ṣíṣe rẹ̀ ni kíákíá.
Arabinrin Modupe Kolawole ni àwọn aṣọna to wa lẹ́nu iṣẹ́ lọ́jọ́ náà àti igbakeji oludari lo lọ sibẹ ṣùgbọ́n oludasilẹ ijọ ko dasi ọ̀rọ̀ náà.
Ẹ̀mí OLUWA bà lé e, ó sì fún un ní agbára ńlá, ó bá fa kinniun náà ya pẹ́rẹpẹ̀rẹ bí ìgbà tí eniyan ya ọmọ ewúrẹ́.
Ọlọrun yín óo wá pẹlu ẹ̀san,ó ń bọ̀ wá gbẹ̀san gẹ́gẹ́ bí Ọlọrun;ó ń bọ̀ wá gbà yín là.
tí mo bá sì pada dé ilé baba mi ní alaafia, OLUWA ni yóo máa jẹ́ Ọlọrun mi.
Mose bá rọ ejò idẹ kan, ó gbé e kọ́ sórí ọ̀pá gígùn kan, ẹnikẹ́ni tí ejò bá bù jẹ, tí ó bá ti wò ó, a sì yè.
PFN: Fatoyinbo kọ̀ láti yọjú ni ìwádìí wa kò ṣe parí Ọ̀pọ̀ èèyàn bẹnu ẹ̀tẹ́ lu Mercy Aigbe lórí bó ṣe ki Adeniyi Johnson Fayemi fojú Alufa to fipa bá ọmọde lòpọ̀ síta l'Ekiti Ayọ̀ abara bíńtín!
Ẹ mọ̀ pé ìdílé Stefana ni àwọn kinni tí ó kọ́kọ́ gbàgbọ́ ní ilẹ̀ Akaya; ati pé wọ́n ti yan ara wọn láti máa ṣe iṣẹ́ iranṣẹ fún àwọn eniyan Ọlọrun.
Ní ti èrò yín yìí, àwọn ọmọ yín ni yóo ṣe onídàájọ́ yín.
"O ṣalaye pe nibi ifọrọwanilẹnuwo fun irina wọn loju ọpọ ti maa n ja a ti ile iṣẹ afọrọwanilẹnuwo ""embassy"" ko ni gba eyi ti wọn mu wa iyẹn ti abẹle ni Naijiria eyi ti wọn n pe ni ""form E""."
Manchester city kọ lẹ́tà ìyà, Arsenal ló tẹ́wọ́ gbàá ní Etihad Èèyàn 587 ló lùgbàdì àrùn Coronavirus ní Naijiria ní Ọjọ́rú Gómìnà márùn ún tó fojú winá ìbínú bàbá ìsàlẹ̀ wọ̀n Báyìí ni orin ìsìn ìkẹyin olóògbé Ibiduni Ighodalo ṣe lọ Diẹ lara bi oju ọjọ ṣe ri kaakiri ree pẹlu aworan.
Ajafẹtọ ọmọniyan yii gba pé awọn ipinlẹ pupọ ti ijọba ologun da silẹ lo faaye gba oloṣelu lati maa jẹ ìlú lasiko yii.
Ànfààní ńlá wà nínú ètò Amọtẹkun, àwọn agbẹjọ́rò ló lè sọ bó yá kò bá òfin mu- Olu Falae Ó pé ọdún mẹ́rìnlélàádọ̀ta tí Akintola kú, ìdí abájọ ìja rẹ̀ pẹ̀lú Awolowo rè é Ilé ẹjọ́ rán ọmọ ìjọ lẹ́wọ̀n ọdún 18 lórí ẹ̀sùn pé ó jí ₦15m owo ìjọ Kéere o!
Amọ, ounjẹ ajẹju o dara lasiko aawẹ Ramadan, ati wi pe sise ohun gbogbo ni iwon tuwon si lasiko Ramadan yoo jẹ ki ara ati ọkan eniyan o ji pepe.
Ọrọ to jọ mọ iru eleyi lo gba ẹnu awọn eeyan kan loju opo ayelujara lẹyin ti aworan awọn oloṣelu mejeeji lu sita nibi ti wọn ti n dọwẹkẹ nibi igbeyawo ọmọ Ayodele Fayose.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù IRememberWhen: Àràmànda ni ǹkan ti ẹlọmiran ń ránti 10 Ọ̀wàrà 2019 Igbàkan o lọ bi òréré, àkisà náà ti lògbà rí, gbogbo èniyàn lo ti ni àsìkò kan tàbi omíràn ti wọ́n ko le gbàgbé láilái.
Ejò lọ́wọ́ nínú lórí ìdájọ́ ẹ̀wọ̀n gbére tí wọ́n dá fún Wòlíì Sotitobire, àwọn ọmọ ìjọ rẹ̀ yarí Ejò lọ́wọ́ nínú lórí ìdájọ́ ẹ̀wọ̀n gbére tí wọ́n dá fún Wòlíì Sotitobire, àwọn ọmọ ìjọ rẹ̀ yarí Oríṣun àwòrán, Mike bamiloye/facebook Àkọlé àwòrán, Ọkọ iyawo, Lawrence, ati awọn ọrẹ rẹ re e to n dọbalẹ niwaju awọn obi iyawo rẹ.
Wọn gba pé Ijọba yẹ ki wọn ṣagbekalẹ ibudo idanipada-sipo lawujọ fawọn to n mu oogun oloro yatọ si fif ofin de e nikan.
Irú igbagbọ bẹ́ẹ̀ yóo gba ìyìn, ògo, ati ọlá nígbà tí Jesu Kristi bá dé.
“Ṣugbọn bí ẹ̀sùn tí wọ́n fi kan obinrin náà bá jẹ́ òtítọ́, pé wọn kò bá a nílé, 
Ṣáájú iyànsípò rẹ̀ gẹ́gẹ́ bíi olórí ilé aṣòfin ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́, òhun ni igbákejì akójánu ilé náà.
Agbára ti ẹran ara ni àwọn ọmọ ogun tirẹ̀ ní, ṣugbọn OLUWA Ọlọrun ni ó wà pẹlu wa láti ràn wá lọ́wọ́ ati láti jà fún wa.
Okoye soro yii nibi ifilole fiimu agbelewo “Anyanwu Ututu” nile ijoba nipinle Anambra ni Awka to je olu ilu ipinle naa.
Oga agba Idris gboriyin fun ise takun-takun igbakeji oga agba ile-ise olopaa ti o sese gba igbega lenu ise, o ro lati tun bo tepa mose re si.
"Awọn jàndúkù yabo ilé Sẹ́nétọ̀ Teslim Folarin, wọ́n kó ẹ̀rọ ata, ọ̀kadà, fírìíjì àti àwọn nkan tí owó rẹ̀ tó N200m ""Apena fẹ́gbẹ́ Oṣugbo, Opa, Akala àtẹ̀yin awo, ẹ wa ọ̀pá àṣẹ Ọ́ba Akiolu jáde"" Èmi ṣì ni Jagaban, aṣíwájú Eko gangan, èmi ò lè sá kúrò l'Eko- Ahmed Tinubu Àwọn ọ̀nà láti dẹ́kun ìwọ́de ọ̀dọ́ lọ́jọ́ iwájú nìyí Èèyàn 229 ló ti wà ní gbaga òfin fún wàhálà tó wáyé l'Eko Fun idi eyi, ọgbẹni Adamu paṣẹ pe ki awọn ọga ọlọpaa ko awọn ikọ́ wọn sita ki wọn ja alafia ilu gba pada lọwọ awọn ọdaran to n fi aṣọ oluwọde bora ti wọn si n da omi alafia ilu ru."
Mo ti jáwọ́ lápọ̀n tí ò yọ̀ wàyí, mo ti gbómi ilá kaná.
"Awọn ọlọpaa maa n yọ mi lẹnu nibi iṣẹ oogun tita ni ilu Emure ti mo n gbe nipinlẹ Ondo nigba naa, eyi gan an lo jẹ ki n fi iṣẹ oogun tita silẹ, ti mo fi bẹrẹ ere tiata ṣiṣe.
Bi Aarẹ Buhari ṣe bẹrẹ iwadii lori bi awọn eniyan ṣe na owo ijọba ni ajọ NDDC lati ọdun 2001 titi di asiko yii yoo ja si aṣeyori ni abẹ isakoso Ọjọgbọn Pondei.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ìtàn ìgbé ayé Abdulrahman Abdulrazak, gómìnà Kwara Ìtàn ayé Seyi Makinde, gómìnà tuntun ní Ọ̀yọ́ Ta ni Babajide Sanwo Olu, gomina tuntun l‘Eko?
Wọn ti da ẹjọ naa nu fun igba diẹ, ṣugbọn o ṣeeṣe ki wọn tun pada bẹrẹ igbẹjọ ọhun bi ẹri tuntun ba fi f'ojuhan.
wọ́n rí í pé inú àìsàn ní Ẹwadapọ̀ wà, àìsàn náà le, bí ó bá sì tó ìṣẹ́jú mẹ́wàá si i, dandan ni kí ọmọ náà kú.
Lẹyin ọpọ atotonu, awọn mọlẹbi Ujunwa san ẹgbẹrun lọna ẹẹdẹgbẹrin Naira fun Ifesinachi.
 a lè lo oríṣi àjẹsára méjèèjì náà láìséwu bí ènìyàn bá ní oyún àti bí ènìyàn bá ní àrùn kògbóògùn hiv / aids ṣùgbọ ́ n tí ara rẹ ̀ ṣì dá ṣáká .
Ọlọ́pàá Ogun ti dá àwọn olùwọ́de #ENDSARS tí wọ́n mú lánàá sílẹ̀- Gómìnà Dapo Abiodun Ìfẹ́ tí mo ní sí aráàlú ló gbé mi wọlé lẹ́ẹ̀kejì - Gomina Akeredolu Ẹni méjì kú, ọ̀pọ̀ dèrò ilé ìwòsàn níbi ìjàmbá ọkọ̀ tó ṣẹlẹ̀ ní Okokomaiko nípínlẹ̀ Eko Lẹyin ọpọlọpọ igba ti awọn ọmọ Naijiria ti n fọnmu lori pe ki ijọba gbe igbesẹ lori bi awọn ikọ agbofinro SARS ṣe n ṣe awọn araalu lọṣẹ ni aṣeyọri yi to waye.
Iko agbaboolu Liverpool bo si ipo keta, leyin ti iko ohun gba ami dogba-dogba pelu iko agbaboolu Arsenal.
Atẹjade naa sọ wipe aarẹ Muhammadu Buhari lo pasẹ pẹ ki ileesẹ ọtẹlẹmuyẹ Naijiria ko kansi Boko Haram naa.
“OLUWA sọ fún mi pé, ‘Gbẹ́ tabili òkúta meji bíi ti àkọ́kọ́, fi igi kan àpótí kan kí o sì gun orí òkè tọ̀ mí wá.
Ọlọrun ti fojú fo àkókò tí eniyan kò ní ìmọ̀ dá.
Ṣé ẹ̀yin alára náà kò ti dẹ́ṣẹ̀ sí OLUWA Ọlọrun yín?
Bẹẹni Aṣofin Dogara to jẹ olori ile aṣoju-ṣofin ni ẹfọn to ba le eeyan ni furọ lọrọ naa, o n fẹ suuru.
Ọmọde yóo nàró mọ́ àgbàlagbà,àwọn mẹ̀kúnnù yóo máa dìde sí àwọn ọlọ́lá.
Lẹ́yìn náà, ọdún mejilelọgọta lọ́nà meje ni a óo sì fi tún un kọ́, yóo ní òpópónà, omi yóo sì yí i po; ṣugbọn yóo jẹ́ àkókò ìyọnu.
Jehoṣafati bèèrè pé, “Ọ̀nà wo ni a óo gbà lọ?
O sọ eyi nitori ọkọ ofurufu awọn ọlọpaa yoo bẹrẹ si ni kaakiri awọn ipinlẹ lorilẹ-ede Naijiria.
Jonathan, iyawo rẹ  ati iya rẹ ti dibo
Àwọn ọmọ ìyá mi lọkunrin bínú sí mi,wọ́n fi mí ṣe olùtọ́jú ọgbà àjàrà,ṣugbọn n kò tọ́jú ọgbà àjàrà tèmi alára.
Ipaniyan Zamfara: Ile isẹ ọlọpaa kede mimu afurasi meta
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Pete Edoche: Elebuibon ní tá bá ṣọ́ra, àṣà àjèjì yóò sọ wá dẹrú òyìnbó 21 Èrèlè 2020 Oríṣun àwòrán, @theknot Araba awo ilu Oshogbo, Oloye Ifayemi Elebuibon ti sọ pe, ki ọkunrin maa kunlẹ lati beere lọwọ ọrẹbinrin rẹ pe ko fẹ oun, kii ṣe aṣa ilẹ Yoruba,o ni iwa ajeji naa ni asa ọhun.
Laipẹ ni iroyin jade nipa baba ẹni ọdun mọkanlelọgọrin kan to fipa ba ọmọdebinrin kan lo pọ ni ipinlẹ Eko Koda, iroyin sọ pe ọmọ naa ti loyun.
Ni bayii, Real Madrid yoo koju iko agbaboolu ti o ba jawe olubori ninu iko agbaboolu AS Roma ati Liverpool, eyi ti yoo waye ni papa isere Stadio Olympico nilu Rome ni asale ojoru(Wednesday).
Ṣugbọn nígbà tí Nebukadinesari, ọba Babiloni gbógun ti ilẹ̀ yìí, a wí fún ara wa pé kí á wá sí Jerusalẹmu nítorí ìbẹ̀rù àwọn ọmọ ogun, àwọn ará Kalidea ati ti àwọn ará Siria.
Oyedepo kede ọrọ yii lasiko iwaasu to se nibi isin ọjọ isinmi to waye ninu olu ijọ Winners to wa ni Ọta, nipinlẹ Ogun.
Lẹ́yìn náà ó sọ fún wọn pé, Mesaya yìí náà ni Jesu tí òun ń sọ̀rọ̀ rẹ̀ fún wọn.
Ó wọlé síbi tí òkú ọmọ náà wà, ó ti ìlẹ̀kùn, ó sì gbadura sí OLUWA.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Sotitobire: Ọkọ mi kò mọ̀ Jegede PDP rí, kódà kò fa ẹnikẹ́ni kalẹ̀ dípò Akeredolu- Bisola Wahala bẹ silẹ ni Toll Gate naa lẹyin wakati diẹ ti ijọba ipinlẹ Eko kede ofin konile-o-gbele, ṣugbọn ti awọn oluwọde ọhun kọ lati fi agbegbe naasilẹ.
Kini ojuṣe ikọ PMS nipinlẹ Oyo?
Àkọlé àwòrán, Amọ, ijọba ipinlẹ Ọṣun ti ni awọn ko tii gbọ nipa iyanṣẹlodi kankan.
Saraki to ti jẹ Ṣẹneto tẹlẹ ri to si tun jẹ obinrin ko tilẹ dahun ibeere kankan ti ile fi gba a laaye lati maa lọ.
Ìwà ìbàjẹ̀ bíi olé jíjà, ìjínigbé àti rìbá gbígbà ní Okediji fi ṣàpèjúwe ǹkan tó ń ṣẹlẹ̀ ní Nàìjíríà Kìí ṣe gbogbo ohun tí dókìtà ni kí n má jẹ torí àìsàn jẹjẹrẹ ni mo tẹ̀lé- Soyinka Èsì ìdìbò tí yóò gbé aàrẹ tuntun wọlẹ́ ní Ghana rèé.
Ninu àwọn ọmọ Joabu, Ọbadaya, ọmọ Jehieli, ni olórí;orúkọ igba eniyan ó lé mejidinlogun (218) ni wọ́n kọ sílẹ̀ pẹlu rẹ̀.
Nigba to n fi ẹmi imoore rẹ han si Hajia Ramatu, Ẹni-ọwọ Hayap mọriri ọwọ ọrẹ naa, to si se apejuwe obinrin musulumi ọhun bii ẹlẹyinju aanu.
Gbogbo àwọn Juu tí wọ́n pada láti oko ẹrú ati àwọn tí wọ́n kọ ẹ̀sìn ìbọ̀rìṣà sílẹ̀ láti sin OLUWA Ọlọrun Israẹli, tí wọn ń bá wọn gbé ní ilẹ̀ náà, tí wọ́n sì wá síbi ayẹyẹ náà pẹlu wọn, ni wọ́n jọ jẹ àsè náà.
Bukola Saraki, ti rọ gbogbo awon musulumi lorile ede Niajiria lati maa gbadura
Ṣugbọn gbogbo ilé Israẹli, àwọn eniyan yín, lè ṣọ̀fọ̀ iná tí OLUWA fi jó yín.
Ìdí tí àwọn ìpińlẹ̀ se ń ti ilé ẹ̀kọ́ ní ìhà ìwọ̀ Oòrun-Àríwá Nàìjíríà rèé Lọdun 2014, Boko Haram ji awọn akẹkọọbinrin gbe nile ẹkọ Chibok, nipinlẹ Borno.
Àwọn èèyàn àti ọkọ̀ tó há sínú súnkẹrẹ-fàkẹrẹ tó ń wáyé lásìkò tí ọkọ̀ epo náà gbinná, ló forí sọta àjálù náà.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Akomolede ati asa Yoruba: Ẹ wá kọ́ nípa àpòtí ìṣura èdè wa lórí BBC Yorùbá Ṣugbọn ninu atẹjade kan to fi ṣọwọ si awọn akọroyin, alukoro ileeṣẹ ọlọpaa ipinlẹ Oyo, Olugbenga Fadeyi sọ pe ẹgbẹrun lọna ẹẹdẹgbẹta naira ni ileeṣẹ naa yoo fun ẹnikẹni to ba le e ranwọn lọwọ lati ri Shodipe mu nigba keji.
Àwọn tí Wọ́n Dé láti Oko Ẹrú Babiloni.
Awọn eroja yii pe oriṣiriṣi; ọṣẹ, ipara, ororo, tabilẹti oogun ati abẹrẹ, ti wọn ṣe lati le da iṣẹ eroja melanin, to n sọ iru awọ ti eniyan yoo ni, duro.
Nisinsinyii, ninu yín, ta ló fẹ́ fi tinútinú ṣe ìtọrẹ, tí yóo sì ya ara rẹ̀ sọ́tọ̀ lónìí fún OLUWA?
Ohun to ṣajeji ninu iwe ipe sibi ase igbeyawo naa ni pe wọn ni ko ni si apejẹ lẹyin isin igbeyawo ni eyi to ya awọn eeyan lẹnu.
O ni, Ipinnu mi ni wipe ki a ri ibi ti a le pe ni tiwa."
Ẹni to bori: Senegal Benin vs Algeria.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù APC: Mí ò tíí ní ìpinnu lóri ìdíje ààrẹ ọdún 2023-Tinubu 17 Òkùdu 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 27 Òkùdu 2020 Oríṣun àwòrán, Tinubu instagram Asáájú ẹgbẹ́ òṣelú ẹgbẹ́ APC, Sẹnatọ Bola Ahmed Tinubu ní òun kò ti ṣe ìpinnu láti díje dupò ààrẹ orílẹ̀-èdè Naijiria lọ́dun 2023 Èyí lòdì sí àwọn oníruuru ọ̀rọ̀ tó ti n lọ nígboro tẹ́lẹ̀, yálà Asiwáju ní ǹkan to jẹ òun lógun jùlọ ni bi ọrọ ajé tó n dẹnu kọle yìí yóò ṣe gbéra sọ pada àti bi eto iléra yóò ṣe pada bọ̀ sípò ní Naijiria.
Kò si ẹ̀rọ ifọṣọ igbàlódé nitori na a, ó di dandan ki wọ́n fọ aṣọ ọmọ àti ẹni ti ó gbé ọmọ ni igbà gbogbo ni ilé ọlọ́mọ tuntun.
Olùkọ́ àgbà tó fipá bá ọmọ ọdún 13 lò yóò fojú ba ilé ẹjọ́ ni Benue Uganda ti bẹrẹ ìgbésè láti fi ikú ṣefàjẹ fún ẹní bá ṣe ìgbéyàwó akọ si akọ ati abo si abo Lẹyin to gboryin fun Baba Ibeji olowo ori Funkẹ pe o ku atilẹyin oun.
Ṣugbọn n kò ní ohun kan pàtó láti kọ sí oluwa mi nípa rẹ̀.
Lẹ́yìn náà ẹ jẹ́ kí á lọ sí Bẹtẹli, kí n lè tẹ́ pẹpẹ kan sibẹ fún Ọlọrun, ẹni tí ó dá mi lóhùn ní ọjọ́ ìpọ́njú, tí ó sì wà pẹlu mi ní gbogbo ibi tí mo ti lọ.
Ajọ to n ri si ere bọọlu afẹsẹgba ni Naijiria, NFF naa ko gbẹyin, niṣe ni NFF gboṣuba rabandẹ fun ẹni ire to lọ.
Harry àti Megan: Ọbabinrin rọ àwọn òṣìṣẹ́ láàfin láti wá ojútú si ìpinu wọ́n Nigba to n bawọn akọroyin sọrọ, Alaga fun igbimọ to wa feto iroyin labẹ ẹgbẹ awọn dokita, ẹka tile iwosan naa, Taiwo Olagbe salaye pe, wọn jẹ awọn dokita naa ni owo to to osu mẹfa, marun, mẹrin ati mẹta, eyi to wa lọwọ igba ti onitọun ba wọ isẹ.
‘Ọ̀rọ ẹnu lásán ni wàhálà tí Nnamdi Kanu ní òun lè dásílẹ̀ ní Nàíjíríà’ #EndSARS lu ayélujára pa lórí ikú Kolade Johnson Ìjọba South Africa pèpàdé lórí ìkórìíra àlejò Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
A bi ọmọọba Jide Kosọkọ ni ọjọ kejila, oṣu kinni, ọdun 1954 ni erekuṣu Eko nipinlẹ Eko ni guusu Naijiria.
Ogun yóo kó àgọ́ wọn ati àwọn ẹran ọ̀sìn wọn lọ,ati àwọn aṣọ àgọ́, ati ohun ìní wọn;Ọ̀tá yóo kó ràkúnmí wọn lọ,àwọn eniyan yóo máa kígbe sí wọn pé,‘Ìpayà wà ní gbogbo àyíká.
Oríṣun àwòrán, FRSC/Facebook Àkọlé àwòrán, Bi eeyan ba wa ọkọ lalai ni iwe aṣẹ awakọ, o ti tapa sofin Ohun taa si fi jẹri si ni pe yoo ti gba iwe aṣẹ awakọ lọdọ awọn alaṣẹ.
Ní ọjọ́ keji, afẹ́fẹ́ kan láti gúsù fẹ́ wá, ni a bá tún ṣíkọ̀.
Ìwo ńlá mẹrin mìíràn sì hù dípò rẹ̀.
com Àkọlé àwòrán, Otis Hugbley sọ fun awọn agbabọọlu naa pe, dandan ni, wọn gbudọ fagba han Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Gbogbo wọn jẹ́ olórí ní ìdílé wọn, ìdílé àwọn baba wọn sì pọ̀ lọpọlọpọ.
Alaga ile lori eto ibanisoro, Benjamin Kalu naa sọ wi pe, ipeleke ti ba iṣekupani ni agbeegbe Ila-oorun apa ariwa Niajiria, to si n beere ohun ti ileeṣẹ ọlọpaa n ṣe lati gbogun ti eto aabo to dẹnukọlẹ naa.
Pẹ̀lú ìdájọ yìí, ìlú Eruwa, ní ìpínlẹ̀ Oyo ko lọ́ba báyìí.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Pásítọ̀ bẹ́'rí ọmọ ìjọ ní ìpínlẹ̀ Ògùn Afẹ́fẹ́ òjò líle ṣọṣẹ́ nípinlẹ Kwara Ẹmi mẹrin sọnu sinu ijamba afara Kara Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Lafikun o ni ko dara keeyan maa foju kere ẹnikẹni laye koda ko ṣe ẹni to n nu bata ẹsẹ rẹ tori ko sẹni to mọ ọla.
Nàìjíríà wà ní ìsọ̀rí kejì pẹ̀lú Burundi, Madagascar àti Guinea Egypt ni yóò gbàlejò Afcon 2019 Orúkọ Amuneke wọ ìwé ìtàn pẹ̀lú ikọ̀ agbábọ́ọ̀lù Tanzania Àáyá bẹ sílẹ o bẹ sáré,wábiwọ́sí ìyá ni Flying Eagles fi bẹrẹ fún Qatar Akọnimọọgba ikọ Black Stars,Kwasi Appiah ni awọn fi Gyan jẹ Balogun kaafata tori pe oun ni o dagba ju lọ laarin ikọ naa.
Oyedepo sọ pe digbi ni oun wa lẹyin awọn oluwọde naa nitori gbogbo eeyan lo ni aṣẹ labẹ ofin lati fi erongba wọn sita nipa ifẹhonuhan.
Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Kaduna, Zamfara àti àwọn ìpínlẹ̀ tó ti ilé ìwé nítorií wahala Boko Haram àti ìdí míràn.
 o ko ipa ti o se koko ninu ijagbara ile cuba .
Lori eyi, Merkel ni oun ati Aarẹ Buhari fi ẹnu ko pe ipese iṣẹ nikan ni kan lo le fi opin si ṣiṣe fayawọ ọmọniyan ati irinajo si ilẹ okeere lọna aitọ.
Oríṣun àwòrán, others Fídíò bí Bester ṣe ń fà ìbínú yọ lórí ijakulẹ ọmọ rẹ ọhun, sì lo gba ojú òpó ìkan síra ẹni Twitter kan ni àárọ̀ Ọjọ́bọ, nibiti ọ̀pọ̀ èèyàn ti ń sọ èrò wọn lórí ìṣẹ̀lẹ̀ naa.
Barea to ṣafihan agbara Madagascar ni orukọ inagijẹ ẹgbẹ agbabọọlu Madagascar ti Naijiria n koju loni.
Kò sí èèyàn kánkan tó kù nílé tó wó ní Ibadan- NEMA Iyanrìn làwọn ẹbí olóògbé bàálù Ethiopia rí gbà dípò òkú Àkọlé àwòrán, Ile miran tun wo l'Eko Àkọlé àwòrán, Ile miran ta lu lẹ Àkọlé àwòrán, Ki ile naa to ya lu lẹ Àkọlé àwòrán, Ile miran wo L'Eko Àwọn tọrọ soju wọn ṣàlàyé pé, wọn tí yọ àwọn méjì tó farapa nínú àwọn merin tó wà níbè wọn sì ti kó wọn lọ sí ilé ìwòsàn Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
World Isese Day: Àwọn oníṣẹ̀ṣe ṣàlàyé pàtàkì ọdún ìṣẹ̀ṣe àti ìdí tí ìjọba fi gbọdọ̀ kéde ìsinmi lẹ́nu iṣẹ́ bí àwọn ọdún ẹ̀sìn míràn
Ìdùnú ṣubú l'ayọ̀ ní Ishan Ekiti, ìlú olùdíje fún ẹgbẹ́ òṣèlú APC John Kayode Fayemi nínú ìbò Gómìnà ipínlẹ̀ Ekiti.
Aláriwo ni obinrin tí kò gbọ́n,oníwọ̀ra ni, kò sì ní ìtìjú.
ti mu gbogbo ileri ti o se fun awon omo orile ede Najijiria sẹ, bi odun yii se
Watford da iyanrìn sínúu gaàrí Arsenal Òfò ṣ'ẹ̀dá: Ẹ̀fọn Norwich já bàálùu Man City Chelsea sáré kọjá kádàrá, góòlù kan ṣoṣo ní Vanlencia fi lù wọ́n Tammy Abraham dáná sun Wolves, ni Twitter bá ń lọgun rẹ̀ tan-tan Iṣẹju kẹrinla ati ikẹtalelọgbọn ifẹsẹwọnsẹ naa ni Di Maria gba bọọlu sawọn ki Meunier to fsba lee nigba ti idije naa wọ aadọrin iṣẹju.
Akẹẹgbẹ rẹ Nicholas Paul naa kọkọ bẹrẹ gẹgẹ bi apẹẹja, ko to di wi pe o beere isẹ ẹso eti okun lati bi ọdun meje sẹyin.
Ìròyìn nípa àjàkálẹ̀ àìsàn yìí ń gba gbogbo orí ẹrọ-alátagbà kan tí ó sì ń mú àìbalẹ̀ara àti ọkàn bá ọ̀pọ̀lọpọ̀ àwọn òǹlo ẹ̀rọ-alátagbà.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Sergio Aguero: Ẹ̀rù n ba àwọn agbabọọlu láti padà sí ìdíje Premier League tó fẹ́ bẹ̀rẹ̀ padà 2 Èbibi 2020 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ọjọ kẹjọ, oṣu Kẹfa, ọdun 2020, ni ireti wa pe idije Premier League yoo tẹsiwaju Atamatase fun ẹgbẹ́ agbabọọlu Manchester City, Sergio Aguero ti sọ pe ẹru a ti pada sori papa n ba awọn agbabọọlu pẹlu bi aarun coronavirus ṣe n tankalẹ.
waye lati kun awon orile-ede ohun lowo, paapaa julo fun igbepo alaafia, igberu
A pa á ní ti ara, ṣugbọn ó wà láàyè ní ti ẹ̀mí.
Agbẹjọro yii tun fẹ ki wọn fi ede abinibi Yoruba, Igbo, tabi Hausa parọ ọrọ kewu tabi ede gẹẹsi to ba wa lara owo Naijiria.
Ẹni to bori: Egypt Aṣekagba Nigeria Egypt Nigeria vs Egypt.
Tirẹ̀ ni ògo lae ati laelae.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Àṣìṣe ọlọ́pàá àti Adájọ́ sọ mí di ẹni tí wọ́n dájọ́ ikú fún, ọpẹ́lọpẹ́ Fayoṣe tí ko buwọlu Ki lo tin ṣẹlẹ sẹyin?
Ó já àwọn ohun tí ó wù ú gbà,ta ló lè dá a dúró?
pé, ‘Mo rí i bí o ti pa Naboti ati àwọn ọmọ rẹ̀ lánàá, dájúdájú n óo jẹ ọ́ níyà ninu oko kan náà.
"Wọn ni orukọ ti adugbo awọn njẹ tẹlẹ gan ni ""Five Junction tori pe ọna naa pin si marun un"" ṣugbọn wọn ni iṣẹlẹ ki ina maa jo ni gbogbo igba lo mu awọn sọ ọ lorukọ ""Fire Junction"" bayii."
Ninu wọn ni awọn to jẹ aṣaaju ẹsin.
Ẹ̀yin ará, ó yẹ kí á máa dúpẹ́ lọ́wọ́ Ọlọrun nígbà gbogbo nítorí yín.
lo ti ṣe ipinnu lati ṣi lọ dibo dipo isunsiwaju ti ajọ INEC ṣe.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Teach your children Yoruba: Wo àwọn òyìnbó tó ń kẹ́kọ̀ọ́ èdè Yorùbá ní Michigan, America Kini ero rẹ lori awọn to n bẹnu atẹ lu ọrọ Obasanjọ lori ayelujara?
’’Dogara tun so pe “awa yoo gbiyanju lati pese eto iranwo lati odo wa fun awon ti ajalu buruku yii kolu.
Ọjọru ni Gomina Seyi Makinde gbe aba ọhun lọ siwaju ile igbimọ aṣofin lati ṣiṣẹ lori rẹ.
Olódodo a máa rìn ní ọ̀nà òtítọ́,ibukun ni fún àwọn ọmọ rẹ̀ tí wọ́n tẹ̀lé e.
Jesu wí fún un pé, “Arabinrin, igbagbọ rẹ ti mú ọ lára dá.
Ekiti: Fayemi gbẹ́sẹ̀ lé èdè òyìnbó sísọ fáwọn òṣìṣẹ́ nípinlẹ̀ Ekiti
Ibi tí mo ti ń wo Ìbànújẹ́-ìsàlẹ̀ ni mo ti rí ẹnì kan tí ó jẹ́ ẹnì tí mo ti mọ̀ dáadáa.
awọ àgbò tí wọ́n ṣe ní àwọ̀ pupa ati awọ ewúrẹ́, igi akasia, 
Ajọ NNPC wa rọ awọn ọmọ Naijiria lati fi ọkan wọn balẹ o nitori ko si ohun to jọ fifowo kun epo bayii.
Ọfà Olodumare wọ̀ mí lára,oró rẹ̀ sì mú mi.
Kemi Olunloyo ń làjà láàrin Toyin àti Lizzy lọ́wọ́ Ọkọ Toyin Abraham pẹ́ ọ̀rọ̀ sọ lórí aáwọ̀ láàrin ìyàwó rẹ̀ àti Lizzy Anjorin Lizzy Anjorin: Mi ò bẹ Toyin o!
Afunrasi ọdaran naa ti wọn f'orukọ bo laṣiri ṣa dede wọ ileewe alakọbẹrẹ St.
Jọ̀wọ́, bá ọba sọ̀rọ̀, mo mọ̀ dájúdájú pé yóo fi mí fún ọ.
lori ni gbogbo awon osise orile ede yii yoo maa gba”.
Bakan naa ni wọn yan Họnọrebu Abiodun Muhammed Fadeyi to n ṣoju ẹkun idibo Ona Ara ni igbakeji adari ile aṣofin ipinlẹ Oyo.
Ìtàn Mánigbàgbé: Kí lo fẹ́ mọ̀ nípa ‘Ajala Travels’?
Khafi wọ gàu lẹ́nu iṣẹ́ lórí ẹ̀sùn ìbálòpọ̀ ní BB Naija O tó gẹ́; A kò fẹ́ ìwòkuwò mọ́ ní Nàijíríà- Runsewe (NCAC) Oludije tawọn akẹgbẹ rẹ ba di ibo to pọju lọ fun ni yoo kẹru rẹ kuro lọsẹ naa.
Pardew ni iko ohun gba ninu osu merin seyin, ni ireti pe yoo mu ayipada otun de ba iko naa lori tabili idije, sugbon omi poju oka lo.
Nítorí a rí i nígbà tí ó gba ọlá ati ògo lọ́dọ̀ Ọlọrun Baba, nígbà tí ó gbọ́ ohùn láti ọ̀dọ̀ ẹni tí ọlá ati ògo yẹ fún, tí ó wí pé,“Ìwọ ni àyànfẹ́ ọmọ mi,inú mi dùn sí ọ.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ijọba apapọ orileede se ajoyo awọn akekọbinrin Chibok to kọkọ pada de Sibẹ́sibẹ́, bi awọn ọ̀dọmọbinrin to ku ko se tii ri itusilẹ gba lọwọ awọn ẹsinokọku Boko Haram, gbogbo igba ni ianti wọn ngba onije loju awọn obi wọn Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Obi awon akekobinrin Chibok ko tii dake riranti awon omo won Nigba ti isi kinni awọn akẹkọbinrin Chibok pada de, se ni inu ijọba ati gbogbo ara ilu dun bi o tilẹ jẹ wipe ọpọlọpọ aidaa lo ti sẹlẹ̀ si wọn ninu ahamọ Boko Haram Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Igbakeji Aarẹ, Yẹmi Ọsinbajo nigba to nki awọn akẹkọbinrin Chibok to ti de sile ku abọ Awọn ọdọmọbinrin naa ti wọn ko sai ranti ile nibi ti iko Boko Haram gbe wọn lọ sun ẹkun ayọ Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Iyawo igbakeji Aarẹ, Dolapọ Ọsinbajo yọ̀ pẹlu awọn ọmọ naa Lati ọdun ,ẹrin sẹyin ti wọn ti ko awọn ọdọmọbinrin yii sigbekun ni ọpọlọpọ ọr ti njẹyọ kaakiri agbaye.
Nígbà tí a bá kéde òfin yìí jákèjádò agbègbè rẹ, àwọn obinrin yóo máa bu ọlá fún àwọn ọkọ wọn; ọkọ wọn kì báà jẹ́ talaka tabi olówó.
Nilu Oakland California ni wọn ti bi lọdun 1964.
Àṣírí ìràwọ̀ meje tí o rí ní ọwọ́ ọ̀tún mi, ati ti ọ̀pá fìtílà wúrà meje nìyí: ìràwọ̀ meje ni àwọn angẹli ìjọ meje.
Awọn orilẹede Asia ni wọn n ta irẹsi naa fun Guinea.
Àwọn ọmọ alufaa yòókù ni wọ́n ń po turari, 
Salinṣile ni bi oju ọrọ ti ṣe ri bayii, ko si idi fun ijọba ipinlẹ Ọṣun lati san aabọ owo oṣu mọ lẹyin eyi nitori ayipada rere to de ba eto iṣuna orilẹede Naijiria lapapọ ati paapaa julọ ipinlẹ Ọṣun.
Iṣẹlẹ naa lo ṣẹlẹ lẹba abule Gidan Busa to wa laarin Jere ati Kateri lopopona ọhun.
4 legbegberun iyearabudo to n so ede fon , yoruba tele won pelu 1.
Ọjọ kẹtadinlọgbọn, oṣu Kọkanla, si ni Black Friday ti ọdun 2020.
Sergei Skripal, ti o je omo ogun Russia GRU  teleri, ati omo re Yulia, ti o je omo odun metalelogbon ti aisan apaniyan ohun gbesanle, ni awon minisita ti n  se ipade lori re lati mo iru aisan buburu yii, tio gbemi baba ati omo.
Àwọn oluwadii ti ni awọn yoo ran ọkọ to n ṣe iwadii abẹ omi lọ sibi ti wọn ti ri ajaku baalu naa ni ọjọ Aje.
Bi iwadii ṣe bẹrẹ ni pe, akẹkọọ to wa ni ipele SS1 lo ṣe aisan ni Ọjọ Kẹta, Oṣu Kẹwaa, ọdun yii, ti wọn si ran an lọ sile lẹyin ti wọn kọkọ fun un ni itọju ni ileewe naa.
Oun lo pada di minista fun inawo ni Naijiria lọdun 2018 nigba ti o gba iṣẹ lọwọ Kẹmi Adeọṣun.
5m péré wá, ko kópa nínú ìbò abẹ́nú fún ipò gómìnà ní Ondo àti Edo - APC kéde Oríṣun àwòrán, @newsacrosscom Ẹgbẹ oṣelu APC ni Ipinlẹ Edo ti kede pe Ọjọ Aje, ọjọ kejilelogun oṣu kẹfa ọdun 2020 gẹgẹ bii ọjọ ti eto idibo abẹnu fun awọn oludije gomina ninu ẹgbẹ oselu naa ni Ipinlẹ Edo yoo waye.
"Gbajugbaja oṣere Yoruba mii, Iyabo Ojo ni ""ẹ bori ninu eyi na!"
David gba awọn ọdọ niyanju lati kọ iṣẹ ọwọ kan mọ iwe ti wọn ba n ka nitori pe atẹlẹwọ ẹni kii tan ẹni jẹ.
Nígbà tí ó ti sọ báyìí tán, òun náà mú burẹdi, ó dúpẹ́ lọ́wọ́ Ọlọrun níwájú gbogbo wọn, ó bù ú, ó bá bẹ̀rẹ̀ sí jẹ ẹ́.
Kò sí ohun tí kò tọ̀nà fún mi láti ṣe, ṣugbọn n kò ní jẹ́ kí ohunkohun jọba lé mi lórí.
Ọmọ ìlú kan náà nì òun àti Akin Olúṣínà.
" Gẹgẹ bi Lai ṣe sọ, ọpọlọpọ eniyan ko mọ nipa oloogbe pe o fi tọkantọkan ṣiṣẹ fun ilu wa lati ri pe iṣẹ agbẹ lọ soke, ni pataki julọ, ọrọ irẹsi gbingbin, ati ajilẹ (fertilizer) wa lara awọn nkan to mu lọkunkun dun.
agbofinro ti tẹ awon odaran kan , ni eyi ti won si n wa awon yooku.
O wa gba awọn obinrin nimọran lati ta giri si ala wọn lojuna ati maṣe bẹru ninu mimu ero wọn wa si imuṣẹ lai wo iru ẹya tabi aawọ ibi ti wọn ti wa.
Emir ilu Awe, Umar Isa Abubakar; Kabir Musa Ibrahim ati alaga ijọba ibilẹ ti ilu naa wa, Umar Da-Akanio atawọn eeyan mii ni wọn tun ṣabẹwo si Emir tẹlẹ ri ọhun.
O fikun pe, saaju eto idibo gbogbo gboo to kọja ni awọn asaaju ẹgbẹ PDP ti sọ Dubai di ibiti wọn n lọ loore koore, bẹẹ si ni bi Hushpuppi se sunmọ awọn oloselu naa kii se oju lasan.
Ọrọ yii ki ṣ'oun to pamọ fun mi, mo mọ nipa ohun ti mo ri ati nkan ti El-Zakzaky sọ fun mi, fun ra rẹ lo n ra ounjẹ to n jẹ lati igba to ti wa ni ahamọ Ààwẹ Ramandan àti irú ouńjẹ tí o lè jẹ."
Àlùbolẹ̀ ni Chelsea lu Southampton mọ́lé Ẹgbẹ agbabọọlu Chelsea ti bẹrẹ si ni yọ eruku lala bayii o, alubolẹ ni wọn lu Southampton mọle ninu idije Premier League lọjọ Aiku.
Oríṣun àwòrán, Reuters Àkọlé àwòrán, Agbo kan wọ ami ẹyẹ to jẹ nigba ti wọn n lu gbanjo ọlọjọ mẹta ni Misrata, Libya.
Ìgbà tí mo bá dé ni n óò tóó tún máa bá ìtàn bàbá mi lọ.
Gbogbo àwọn tí wọ́n bá ọ dá majẹmu ti tàn ọ́ jẹ,wọ́n sì ti lé ọ títí dé ààlà ilẹ̀ rẹ;àwọn tí ẹ jọ ń gbé ní alaafia tẹ́lẹ̀ ti di ọ̀tá rẹ;àwọn ọ̀rẹ́ tí o gbẹ́kẹ̀lé ti dẹ tàkúté sílẹ̀ dè ọ́,o kò sì mọ̀.
Jesu wí fún un pé, “Nítorí mo wí fún ọ pé mo rí ọ ní abẹ́ igi ọ̀pọ̀tọ́ ni o ṣe gbàgbọ́?
Nítorí náà Abimeleki kìlọ̀ fún gbogbo àwọn eniyan rẹ̀ pé, “Ẹnikẹ́ni tí ó bá fi ọwọ́ kan ọkunrin yìí tabi aya rẹ̀, pípa ni wọn yóo pa á.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Àwọn aṣòfin àpapọ̀ ń dí mi lọ́wọ́ iṣẹ́-Buhari Fọ́tò àǹkóò oyún ọmọ ìyá mẹ́ta gbòde kan Pasuma: Ìdí tí mi ò fi lè kọrin ní Saudi Arabia Ninu idanilẹkọ kan ti o ṣe ni ilu Eko ni ibẹrẹ ọdun 2018, aarẹ ana Oluṣẹgun Ọbasanjọ ni, eeyan kan to gburo iwa olootọ Dora lasiko to fi wa ni ileewe kan ni ilẹ Gẹẹsi lo fi ọrọ rẹ to oun leti ti oun fi yan an.
"Duro Ladipọ, ìlúmọ̀ọ́ká òṣèré tíátà àti ọmọ àlúfà tí kò gbàgbé àṣà ìbílẹ̀ Ibi tí orí dá èmi Razak Olayiwola sí ni mò ń gbé- Ojopagogo ""Mo fẹ́ pa ara mi torí ojú àbùkù tí wọn ń fi wò mí pé mo fi iṣẹ́ abẹ bímọ"" Ṣé ẹ̀yin mọ orúkọ tí Yorùbá ń pé 'Necklace'?"
Mo ti rù láàrin ọ̀sẹ̀ kan, iṣẹ́ Eko kò dẹ́rùn - Sanwo-Olu Dangote, Fayemi pari ìjà láàrin Ganduje àti Emir Sanusi Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ladoja: Àwọn èèyàn Oyo fì ìbò sọ̀rọ̀ pé ìjọba Ajimobi kò dára Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Iba Gani Adams: Bẹ́ẹ gbé màláíkà kan lọ sí Aso Rock, kò lè ṣàṣeyọrí Amọ, John Dyegh to n ṣoju ẹkun Gboko/Tarka nipinlẹ Benue to si tun jẹ ọmọ ẹgbẹ osẹlu APC loun si wa maa dije fun ipo adari ile igbimọ aṣoju ṣofin.
Ninu atẹjade ti wọn fi sita ni wọn ti ṣalaye pe ko wa fun awọn Fulani nikan bikoṣe fun gbogbo awọn ti wọn n ṣiṣẹ ẹran ọsin.
goke agba ninu imo ero igbalode ati asa.
iyé èèyàn túntun to lùgbàdì àrùn náà ni àwọn ìpińlẹ̀ makànlá tókù kò tó márùn-márùn.
Ọ̀kan ninu wọn ní, “Kabiyesi inú ilé kan náà ni èmi ati obinrin yìí ń gbé, ibẹ̀ ló sì wà nígbà tí mo fi bí ọmọkunrin kan.
Ìjọba Amẹrika fi ojú àwọn ọmọ Yahoo mẹ́fà léde, wọ́n gbẹ́sẹ̀ lé dúkìá wọn Ìwadìí ti bẹ̀rẹ̀ lórí àrá tó sán pa òṣìṣẹ́ FRSC mẹ́ta nípínlẹ̀ Ogun- Ọ̀gá àjọ FRSC Ohun tí a mọ̀ nìyí nípa ìròyìn Ajimobi kú, kò kú, táyé ń gbé kiri Invictus Obi, Hushpuppi, àwọn ọ̀dọ́ Nàìjíríà méjì tí ẹ̀sùn gbájúẹ̀ wà lọ́rùn wọn Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Bákan náà, àwọn yàrá kan wà ní ìhà gúsù, lára ògiri òòró àgbàlá ti ìta, wọ́n fara kan àgbàlá tẹmpili, 
Bakannaa lo ṣẹlẹ ni Ghana Egypt,Cameroon ati Mozambique Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
"O ni ""Bi a ṣe n lọ si ibiṣẹ, ko si awọn ohun ti a nilo lati fi dabo bo ara wa; bi ibomu atawọn nnkan mii to yẹ ki ijọba pese, ijọba kọ lati pese rẹ."
Lori awuyewuye oun ti Gomina ipinlẹ Eko, Babajide Sanwoolu sọ nipa didẹkun sunkẹrẹ fakẹrẹ Apapa, ile iṣẹ BBC ṣewadi, a si ri ẹri pe o sọ bẹẹ.
Ewe, akonimoogba ohun soro naa ko Moses loju pe, o le kuro ninu iko naa ti asiko iduna-dura ba to ninu osu kinni odun to n bo.
Nítorí kò sí ẹni tí yóo ranti rẹ lẹ́yìn tí ó bá ti kú.
Awọn ọdọ to n se iwọde naa, ti oju wọn ko rẹrin rara, ni wọn gbarodan jọ siwaju ẹnu ọna abawọle fasiti Benin, to wa lopopona marosẹ Benin si Ore.
Prince Lawal Onikeke Quassim YWC yọ Ààrẹ Banji Akintoye nípò àbi Akintoye tú ìgbìmọ̀ aláṣẹ YWC ká?
ose yii, nigba ti o gbe iwe eto isuna odun 2019 lo siwaju ile igbimo
Pauline Tallen (Plateau) - Minisita fun ọrọ awọn obinrin Ramatu Tijani (Kogi)- Minisita abẹle fun olu ilu orilẹede Naijiria, FCT Zainab Shamsuna Ahmed (Kaduna) - Minisita feto iṣuna ati aato ilẹẹwa Ọpọ ọmọ Naijiria lo ti fi aidunu wọn han lati igba ti oruks awọn minisita tuntun naa ti bs sita nibi ti wọn ti ni aarẹ Buhari kuna ati mu adehun to ṣe fun awọn ọmọ orilẹede Naijiria ṣẹ.
Èyí ni à ń pè ní Ibi Mímọ́.
Mo si fi anfani yii rọ oun ati ikọ iṣejọba rẹ lati ṣiṣẹ takuntakun ki wọn lee mu ileri ti wọn ṣe fun gbogbo agbaye ṣẹ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Clean Water; Àwọn ara Ezeukwu ma ń rin ìrìn wakati méjì torí omi mímu Agbẹnusọ Ileesẹ Ọlọpaa ni ipinlẹ Ondo ni ko si ẹmi to sọnu ninu iṣẹlẹ naa, sugbọn awakọ naa farapa to si n gba itọju lọwọ ni ile iwosan ni ipinlẹ naa.
Ẹlòmíì nínú wọn kò tilẹ̀ le kọ lẹ́tà tàbí kàwé dáàda.
Awon mejeji gba pe ki alaafia le joba ki Jerusalem si wa ni ilu mimo fun awon musulumi, jew ati kristiani agbaye.
#Adetutu Alabi OJ: Mo ti gba kámú lórí ilà ojú mi Lori awọn aṣa to ti fẹ parun, BBC News Yoruba gbe iroyin kan jade nipa ọmọbinrin awẹlẹwa kan ti o kọ ila ati iriri rẹ lori ila naa.
Agbẹnusọ fun Agboola Ajayi, Allen Sowore lo sọ bẹẹ fun BBC Yoruba.
Oríṣun àwòrán, @lshaofficial Adajọ si ti ni ki Ambọde o fi iwe ipẹjọ atawọn iwe miran gbogbo to rọ mọ ẹjọ naa naa, wa awọn aṣofin naa lọ.
Bi aarẹ tuntun naa ṣe fi ẹyin aarẹ to wa nipo, Peter Mutharika janlẹ, jẹ iyalẹnu.
Alade si ni oṣere, oludari ati Olootu ere tiata akọkọ to ṣe ifilọlẹ ere sinima agbelewo.
''O ti pẹ ti mo ti n gbiyanju lati gba ile ki n le maa gbe pẹlu pọ pẹlu ẹbi mi, ṣugbọn ko si agbara.
”“A ni igbagbo pe irinajo aare lo si ipinle Plateau yoo pese eto iranwo fun awon ti ijamba  yii sele si  .
Ẹgbẹ naa si yan an lọdun 1979 lati dije fun ipo aarẹ orilẹede Naijiria.
"harold george "" harry "" belafonte , jr ."
Nígbà tí afẹ́fẹ́ bẹ̀rẹ̀ sí fẹ́ jẹ́jẹ́ láti apá gúsù, wọ́n rò pé ó ti bọ́ sí i fún wọn láti ṣe ohun tí wọ́n fẹ́ ṣe.
Eto aabo Ileri: Riri daju pe 'ipa tabi agbara kankan labẹle tabi llyin odi ridi joko ni Naijiria.
Amẹ́ríkà ń béèrè ìròyìn facebook, email arìnrìnàjò tó f'ẹ́ gbà'wé àṣẹ SEC: Tinubu kò gbọdọ̀ ṣe olúdarí iléeṣẹ kankan fódùn márùn ún Liverpool da ata gúngún sójú Tottenham gba ife ẹ̀yẹ Champions League Ìròyìn ìbúrawọlé jákèjádò orílẹ̀èdè Nàìjíríà ní ẹ̀kúnrẹ́rẹ́.
Ọwọ́ ọlọ́pàá ti tẹ ọkùnrin kan tó pa ọ̀rẹ́ rẹ̀ nítorí N40 ní Kano
Nígbà tí ọjọ́ rọ̀, àwọn ọmọ-ẹ̀yìn mejila sọ fún un pé, “Tú àwọn eniyan wọnyi ká kí wọ́n lè lọ sí àwọn abúlé káàkiri ati àwọn ìletò láti wọ̀ sí ati láti wá oúnjẹ, nítorí aṣálẹ̀ ni ibi tí a wà yìí.
Ní báyìí, wọ́n tún ti kéde pé kí àwọn ènìyàn jáde láti ní ọ̀sán òní ọjọ́ Ajé lásìkò ti aṣojú ìjọba ilọ̀ Lebanon, Hassan Diab yóò máá pe ìpàdè ìgbìmọ̀ aláṣẹ ìjọba Lebanon.
Oríṣun àwòrán, AFP Ninu ọrọ tirẹ, Olotu Ijọba orilẹ-ede Lebanon, Hassan Diab ti ni oun yoo pe fun eto idibo ni kiakia, gẹgẹ bi ọna abayọ si rogbodiyan ti ibugbamu naa da silẹ.
Bí ẹ kò bá ṣe é gbẹ́kẹ̀lé nípa ohun tí ó jẹ́ ti ẹlòmíràn, ta ni yóo fun yín ní ohun tí ó jẹ́ ti ẹ̀yin fúnra yín?
Nígbà tí alufaa bá yẹ̀ ẹ́ wò, kí ó pè é ní aláìmọ́.
Samuel Olasehinde Ọmọ kekere ọjọ́ si ti wá dàgbà báyìí, ǹjẹ ẹ ránti, ọmọdékùnrin tó ṣe fíìmù ìrù ẹṣín lọ́dún náà lọ́ùn, hẹn, ó ti ṣe ọjọ́bi lọ́sẹ̀ yìí.
Adajọ fi kun un pe ko si ile ẹjọ kankan laye to lee tu idajọ yii wo mọ.
n kò ní fi ẹnu mi purọ́,ahọ́n mi kò sì ní sọ̀rọ̀ ẹ̀tàn.
"Fulani darandaran méjì fojú balé ẹjọ́ Gani Adams kilọ f'awọn darandaran ""Afẹnuko gbogbo awọn gomina ni, paapaajulọ ijọba apapọ, lati rii daju pe a wa egbo dẹkun si wahala awọn darandaran Fulani ati agbẹ oloko eyi to ti di gbẹmigbẹmi lojoojumọ bayii."
Iroyin sọ pe Salami tẹle awakọ rẹ lọ sibẹ lati yanju ọrọ ṣugbọn airi ọkọ naa gba lo mu ki Salami da oogun apakokoro mu.
"Inú sinima 'Iwọkuwọ' ni mo ti ń jẹ Okunnu, àmọ́ inu sinima 'Afúnrúgbìn' si ní Okunnu tí wá jáde dáadáa.
Afárá Third mainland gba ẹ̀gbọ́n Wo ohun tí Adájọ́ ṣe sí àṣùwọ̀n ìfowópamọ́sí Wòlíì Sotitobire Irinwó lé méje èèyàn ló gbàwòsàn lọ́wọ́ Covid-19 lọ́jọ́ Àbámẹ́ta, 453 míì tún lùgbàdì rẹ̀ Ta ló ń lọ sílé lónìí nílé ẹlẹ́gbọ̀n ọ́n àgbà?
O le ni miliọnu mẹrindinlaadọta ọmọ Naijiria to n ṣe igbọnsẹ si ita gbangba gẹgẹ bi ilana atọka idagbasoke ti banki agbaye gbe kalẹ ṣe sọ.
 Ìgbà mẹ́ta ọ̀tọ̀ọ̀tọ̀ tí ìjọba Nàìjíríà ti gbẹsan lára orilẹ-ède mí tó dẹ́yẹsí i Ṣé o fẹ́ ṣiṣẹ́ ológun?"
Pẹ̀lú abẹ̀rẹ̀ àjẹsára yìí, ẹ̀fọn kankan kò lè mú àìsàn ibà wá 'N50,400 là ń gbà fún àyẹ̀wò Covid-19 láwọn láàbù aládàáni l'Eko' Níbo lọ̀rọ̀ dé dúró nípa iṣẹ́ àwọn tó n wa iṣẹ́ N-Power?
Ó ṣeéṣe kí ilé ìjọsìn, mọ́sálásí àti ọkọ òfurufú ṣí, Ẹ wo àwọn ìlànà tuntun tí ìjọba là sílẹ̀ Ọwọ́ bàtá Auxiliary tó ń ró ní àrójù, leè ya láìpẹ́ - Ìjọba Oyo dúnkookò Pásítọ̀ Adeboye ṣelérí àti fojú aṣebi hàn lórí ikú Omozuwa, Amnesty International pẹ̀lú kọminú Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Nigeria movie industry: Àgbà òṣèré, Lere Paimo ní àìgbọràn ló ń da ọ̀pọ̀lọpọ̀ àwọn Kóníléógbélé náà yóò bẹ̀rẹ̀ láti aago mẹ́jìlá ọjọ kejì oṣù kẹfa títí di ọjọ kẹẹdógún ọṣù kéfa, bákàn náà ni wọ́n kò gbọdọ rí ẹnikẹni rìn ládùgbọ́n wọn.
ní àsìkò ogun yìí , ilẹ ̀ faransé ní Ọ ̀ gágun kan tí orúkọ rẹ ̀ ń jẹ ́ napoleon bonaparte .
Bóò ṣe lè yẹra fún ikú nígbà òjò - Onímọ̀ Ehi Iden Amọ ṣa, Minisita fun eto iṣuna ati aato ilu, Udoma Udo-Udoma kede pe gbogbo akọsilẹ to wa ninu owo iṣuna ti aarẹ buwọlu ọhun yoo jẹ fifi si ita gbangba fun ara ilu nibi eto kan ti yoo waye lọjọ Iṣẹgun.
Ohun gbogbo tí ó bá hàn kedere di ìmọ́lẹ̀.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fọ́nrán ohùn, Ẹ lọ mú ẹ̀rí ibi tí a ti gba owó wá- NLC/TUC Gẹgẹ bi ọgbẹni Egbule ti ṣe sọ, ọjọ kejidinlogun, oṣu kẹrin ọdun 2019 ni sisan owo oṣu naa bẹrẹ ifidimulẹ; afẹfẹ rẹ yoo si kan awọn onipele owo oṣu marun un.
'Penis Fish,', ẹ̀ja tuntun lúwẹ̀ẹ́ jáde nínú òkun ní Carlifornia
1936, 1943, 1972, ati 1975 Herbert Armstrong to jẹ ọkan lara awọn ajihinrere to kọkọ bẹrẹ si ni waasu lori tẹlifisan sọ wi pe igbasoke awọn ayanfẹ yoo waye lọdun 1936, Sugbọn o ya a lẹnu pe ko ṣẹlẹ bẹẹ lasiko to da.
Bakan naa ni awọn to fẹ sinku gbọdọ kọ lẹta igbayọnda ti wsn gbọdọ fi iwe ẹri oku lati ileewosan ijọba tabi lẹta lati ọdọ ileeṣẹ ijọba feto ilera nipinlẹ naa, ti amugbalẹgbẹ fun gomina lori ọrọ ilera gbọdọ buwọlu.
Nígbà tí oòrùn bá sì wọ̀, ó lè wọ inú àgọ́ wá.
Bí arakunrin rẹ bá di aláìní tí ó bá sì tà ninu ilẹ̀ rẹ̀, ọ̀kan ninu àwọn ẹbí rẹ̀ yóo dìde láti ra ohun tí ìbátan rẹ̀ tà pada.
Ní ìbẹ̀rẹ̀, kí á tó dá ayé, ni Ọ̀rọ̀ ti wà, Ọ̀rọ̀ wà pẹlu Ọlọrun, Ọlọrun sì ni Ọ̀rọ̀ náà.
Abọ̀ iwadii naa daba onikoko mẹwa eyi to da lori igbesẹ pinpin ipo agbara fawọn ijọba ipinlẹ, lọna ati se atunto ilẹ Naijiria.
Àwọn ọmọ Bẹnjamini ní ìdílé-ìdílé nìwọ̀nyí: ìdílé Bela, ìdílé Aṣibeli, ìdílé Ahiramu; 
Sugbọn wọn ni pupọ ninu awọn ohun elo naa ni ina ọmọ ọrara ti sọ di eeru, ki awọn aladugbo to gbe omi ati awọn ohun elo mii ti wọn fẹ fi pa ina to de.
A wo bi a ṣe n se agbekale isẹ to da le girama, iwe atumọ, ọ̀rọ̀ àpilẹ̀kọ, àbọ̀ ìpàdé, ìjábọ̀ ìwádìí, ìwé ìkéde pélébé àti eyí ti a fi n se ìpolongo ti a máa ń tẹ̀ mọ́ ara ògiri.
Ó ní, ‘N óo mójú kúrò lára wọn,n óo sì máa wò bí ìgbẹ̀yìn wọn yóo ti rí.
Oba naa wa seleri lati se ise pelu aare lona ti
Ajọ Agbaye to ni akọri ti ọdun yii ni 'I am and I will', fikun wi pe ẹgbẹrun mẹrinlelọgbọn eniyan lo n ku lojoojumọ nitori aisan jẹjẹrẹ.
” Kò sì bá a lòpọ̀ mọ́.
Àwọn ìgba mẹ́rin t'áwọn èèkàn tí dùbúlẹ̀ àìsàn lásìkò tí wọ́n ń jẹ́jọ́ níwájú adájọ́
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ikoyi Ile Farmers Herders Clash: Àwọn àgbẹ̀ Ikoyi Ile kérora síjọba ìpínlẹ̀ Oyo!
Nítorí pé ìwọ ni mò ń yìn.
Abilekọ Ọlayẹmi James Adeṣemọwọ gba pe òun kò ni wo telemundo ati Zee world ti òun fẹran julọ lasiko ìdíje ife ẹyẹ agbaye.
Aarẹ ni pe Yusuf a ko lọ si Glass House bi o ṣe pada de yii ki wọn le pese itọju to yẹ fun un nitori o sunmọ ibugbe iya rẹ, Aisha.
Mo mọ̀ nisinsinyii pé OLUWA ju gbogbo àwọn oriṣa lọ, nítorí pé ó ti gba àwọn eniyan náà lọ́wọ́ àwọn ará Ijipti, nígbà tí àwọn ará Ijipti ń lò wọ́n ní ìlò àbùkù ati ẹ̀gàn.
Gẹ́gẹ́ bí ìṣe rẹ̀, ó tún ń kọ́ wọn.
Aláàfin tó rí ìbẹ̀rẹ̀ àti opin sáà gómìnà mọ́kànlélógún l‘Oyo Njẹ́ ẹ ti gbọ́ nípa àríyá oníhòhò àti ìbálòpọ̀ tó fẹ́ wáyé ní Kaduna lásìkò ọdún?
Koda, a tiẹ gbọ pe awọn eeyan kan ti n dunkoko lati gbe ajọ IBDEC lọ sile ẹjọ lori isẹlẹ yii.
Aare Muhammadu Buhari ki Osile ti Oke Ona ti ile Egba lapapo ku oriire ayeye ojo ibi ogorin odun lori oke eepe.
Julius Malema lo da ẹgbẹ awọn osisẹ awakusa silẹ lọdun 1982 ki o to di ọmọ ileegbimọ asofin lorilẹede South Africa, laipẹ lo si di alaga igbimọ to se aayan atunto iwe ofin orilẹede naa lọdun 1994.
Lẹsẹkẹsẹ bí gbogbo àwọn eniyan ti rí i, ẹnu yà wọ́n, wọ́n bá sáré lọ sí ọ̀dọ̀ rẹ̀, wọ́n ń kí i.
Àwọn yìí ni Ẹ̀mí Ọlọrun meje.
Koda aw'on Baba nla wa ninu ise orin gan an korin bu ara won ki onikaluku le ta oja tire.
Nítorí èmi ni mo kéré jùlọ ninu àwọn aposteli.
Bí wọ́n ti ń jẹun, ó wí fún wọn pé, “Mo fẹ́ kí ẹ mọ̀ dájúdájú pé ọ̀kan ninu yín yóo fi mí fún àwọn ọ̀tá.
Iwe igbadegba kan lori ilera ti ẹgbẹ awọn onimọ ilera Amẹrika gbe jade sọ pe aseyọri Taiwan nipa kikoju Coronavirus ko sẹyin pe wọn ti n mura kalẹ lati igba ti ajakalẹ SARS ti kọkọ bẹ silẹ nibẹ.
Awọn asofin yoku to da si ọrọ naa ni o yẹ ki wọn maa fi oju aanu sisẹ wọn, ti wọn si sapejuwe ofin to de epo gbigbe lọ sẹnu bode bii ofin onikumọ.
níwọ̀n ìgbà tí àwọn ọmọ yín bá ń ranti àwọn pẹpẹ yín, ati àwọn oriṣa Aṣera yín, tí ẹ rì mọ́ ẹ̀gbẹ́ gbogbo igi tútù, ati lórí àwọn òkè gíga; 
Níṣe ni àwọn ènìyàn tún gba èyí bí ẹni gba igbá ọtí.
Epo ti a ba gba lori ina Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Epo pupa Iru efin epo ti a ba gba lori ina ni aye idana ti efin rẹ si gbalẹ kan le ṣe akoba fun ẹmi.
Kò séwu nínú ìdìbò tó ń bọ̀ l'Ondo àfi gìrì àparò- Akeredolu Oríṣun àwòrán, others Ṣaaju ni wọn ti fun Aarẹ Deby ni oye Field Marshal lasiko isami ọgọta ọdun ominira Chad.
” Ṣugbọn àwọn eniyan náà kò sọ ohunkohun.
 Àdìmú àwọn krómósómù àti kromatínì yàtọ ̀ pẹ ̀ lú ìpínyà àhámọ ́ .
Laarin osu Karun un, nkan bi orile-ede ọgọrun un ni ko tii kede igba tawọn akẹkọọ yoo wọle pada.
Wo bí o ṣe lè rí nọ́mbà ìdánimọ́ NIN rẹ gbà lónìí ní Nàìjíríà Ṣé lóòtọ́ ni pé Aisha Buhari ti kó lọ sí Dubai?
Ẹ tọ́jú àwọn ẹṣin tí Paulu yóo gùn, kí ẹ sìn ín dé ọ̀dọ̀ Fẹliksi gomina ní alaafia.
Ara gbigbona Ki ooru o ma a mu wọn lati inu Ki egungun o ma a dun eniyan Ki wọn ni isoro pẹlu aya ati ọkan wọn.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Kissing: Orílẹ̀-èdè Morocco, Egypt, Zimbabwe, UAE àti China tako títage níta 14 Sẹ́rẹ́ 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 15 Sẹ́rẹ́ 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Awọn akẹẹkọ ofin de awọn akẹẹkọ lati maa di mọ ara wọn Kayeefi nla, ile ẹkọ giga fasiti Al-Azhar, lorilẹ-ede Egypt, le akẹkọọbinrin kan kuro nile iwe lẹyin ti awọn alaṣẹ ile ẹkọ naa rii nibi ti o ti n di mọ ọrẹkunrin rẹ ninu fidio kan.
"Ìdá márùn-ún nínú àwọn ọmọ ẹgbẹ́ SAICE tó tó ẹgbẹ̀rùn mẹ́fà ló jẹ́ obìnrin Àjọ tó ń sègbè fábo ní orílẹ̀-èdè South Africa náà ní àwọn fọ́wọ́ sí ìgbése ẹgbẹ́ náà Aarẹ Cyril Ramaphosa s'adehun igba ọtun fun South Africa Oríṣun àwòrán, Reuters Àkọlé àwòrán, Cyril Ramaphosa, ẹni ọdun 65, jẹ okan lara awọn oselu ti wọn ni owo ju ni orilẹede South Africa Aarẹ orilẹede South African tuntun, Cyril Ramaphosa, ti s'ọrọ nipa ""igba ọtun"" ninu ọrọ rẹ akọkọ nipa bi orilẹede naa ti wa ni ile igbimọ asofin orilẹede naa."
”Ajo naa wa kilo fun awon to se
Ó kó gbogbo ère kúrò ní gbogbo ilẹ̀ Juda ati gbogbo ilẹ̀ Bẹnjamini ati ní gbogbo àwọn ìlú tí wọ́n gbà ní agbègbè olókè Efuraimu.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Nàìjíríà ń wá ẹlẹ́dẹ̀ aríran Wọn ò gbà kí Nàíjiríà gbé adìyẹ wọ Russia Elẹ́dẹ̀ àràmàǹdà ríran sí Nàíjíríà Ìròyìn tó tẹ̀ wá lọ́wọ́ sọ pé àwọn alábágbé rẹ̀ rọ̀ ọ́ pé kó fara balẹ̀ sùgbọ́n ó kọ etí ikún sí wọn.
Oríṣun àwòrán, FACEBOOK Àkọlé àwòrán, Láìpẹ́ yìí ni BBC Yoruba se àfihàn bí ìgboro ìpínlẹ̀ Oyo se dòtí, àmọ tí ìjọba ní àwọn yóò wá ǹ kan se sí.
Lójijì, Absalomu já sí ààrin àwọn ọmọ ogun Dafidi.
Gege bi aare Buhari,“Iru akoko bayii, pe fun igbese komon-komon lai fi oro fale rara,”  “A gbodo tete wa woroko ka fi sada.
Wo ohun mẹ́wàá tó yẹ kí o mọ̀ tí o bá fẹ́ lọ fún ìsinmi lẹ́yìn Covid 19 Kíni àjọ ọlọ́pàá ń ṣe lórí bí agbófinró ṣe ń ṣèèṣì pànìyan lójoojúmọ́?
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Oluwo: Ọ̀ràngún ní táwọn kò bá ní kí Oluwo sinmi nílé, kò ní ṣíwọ́ ìwà àbùkù tó ń ṣe 22 Èrèlè 2020 Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Orangun ṣàlàyé ìdádúró Oluwo ní ìgbìmọ̀ lọ́balọ́ba Ọrọ ti n foju han bayii lori idi ti igbimọ lọbalọba nipinlẹ Ọsun fi pasẹ fun Oluwo ti Iwo, Ọba Abdulroshid Adewale Akanbi, Telu Kinni, lati lọ sinmi nile fun osu mẹfa gbako.
Oríṣun àwòrán, Babajide sanwo-olu Boss Mustapha akọwe ijọba apapọ to tun jẹ alaga igbimọ naa ṣalaye pe awọn ijọba ibilẹ bii ogun naa ni wọn ko ida bii ọgọta ninu ọgọrun iye arun coronavirus lorilẹede Naijiria.
 Orin “Under Pressure” to gbe jade nibẹrẹ ọdun 1980.
Ajọ ilera agbaye ti ṣekilọ ṣaaju asiko yii pe awọn to ba ni aisan kan lagọ ara ti wọn n wo wa ninu ewu gidigidi pẹlu arun Coronavirus yii-eyi tums si peo rọrun fun iku lati mu wọn nipasẹ arun COVID-19 yii 21k USD: Ọlọ́pàá ké sí bàbá tó na ọmọ rẹ̀ tó kùnà nínú ìdánwò, láti wá sọ ìdí tó fi tẹ ẹ̀tọ́ ọmọ náà lójú mọ́lẹ̀ Oríṣun àwòrán, others Ọkùnrin kan, George Bester, lo tí faraya lórí bí ọmọkùnrin rẹ ṣe fi idi rẹmi nínú esi idanwo tó ṣe nile ẹ̀kọ́.
Ọba bá pàṣẹ pé kí wọ́n lọ mú gbogbo àwọn tí wọ́n fi ẹ̀sùn kan Daniẹli, ati àwọn ọmọ wọn, ati àwọn aya wọn, wọ́n bá dà wọ́n sinu ihò kinniun.
Oríṣun àwòrán, AFP Keita gbadura pe ki Eleduwa ko fi iṣọ rẹ ṣọ gbogbo awọn ọmọ orilẹede Mali.
MFM FC ilu Eko, ninu ifigagbaga ifesewonse ti o waye lojo-Ru(Wednesday), iko ohun pegede sinu ipele keji idije CAF Champions League,  leyin ti won fagbahan iko agbaboolu AS Bamako orile-ede Mali pelu ami-ayo kan sodo(1-0).
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Àwọn ọkùnrin tó wà nínú ayé wa gbúdọ̀ bọ̀wọ̀ fún wa - Adarí FIN Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Mori ara mi to funfun, mi o mọ pe ẹtẹ ni Agbabọọlu ọmọ ilẹ Amẹrika naa fi kun ọrọ rẹ pe aṣọ naa tun ran oun lọwọ lati dena ẹjẹ didi eleyi to ti da oun laamu tẹlẹ.
Èyí ekinni wà ní apá àríwá ọ̀nà náà, ó dojú kọ Mikimaṣi.
Iroyin ni ija bẹ silẹ laarin baba naa, Taiwo Olagesin ati ọmọ rẹ nigba ti Babatunde ni oun fẹ lọ ṣiṣẹ owo ni Oshodi, Ipinlẹ Eko.
Àwọn òbí rẹ̀ tọ́ ọ fún oṣù mẹta ninu ilé baba rẹ̀ 
N óo máa pa òfin rẹ mọ́ nígbà gbogbo, lae ati laelae.
Wo bí o ṣe lè di aṣojú tó ṣe pàtàkì nínú àjọ ìṣọ̀kan àgbáyé 'UN Goodwill Ambassador' A kò ní fara mọ́ fífi àkókò ṣòfò lórí ẹjọ́ Sotitobire - Ìjọba Ondo Ìpínlẹ̀ Oyo sọ àsìá Nàìjíríà kalẹ̀ láti dárò Abiola Ajimobi Òtítọ́ ọ̀rọ̀ rè é lórí ilẹ̀ tó fa awuyewuye láàrin Ghana àti Nàìjíríà Ọpọ ọmọ Naijiria lo ri Kyari bi alagbara eeyan ninu iṣẹjọba Buhari, ti ko si ṣeyin bi aarẹ ṣe ma n tẹkọ leti lọ si ilu Ọba nitori ilera ara rẹ.
Gege bi akowe agba ajo FIFA, fatma_Samoura se so lori ero ayelujara re“Si awon omo orile-ede Naijiria, e yin ara yin, e mokan ro, ki e esi pa okan po, ke mu inu ara yin dun.
O ni o ṣeni laanu pe gbogbo bi awọn ṣe n gbiyanju lati koju awọn agbesunmọmi yi, niṣe ni wọn gbooro sii.
29 Owewe 2020 Fídíò, Wole Soyinka sọ ìdí tó fi ni òun a fi màálù Fulani ṣe súyà fáwọn èèyàn abúlé23 Owewe 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Bawo ni aarun naa ṣe buru to?
Theresa May  soro yii ni owurọ ọjọ Eti ni Downing street  niluu London.
“O kò gbọdọ̀ pe orúkọ OLUWA Ọlọrun rẹ lásán, nítorí pé, èmi OLUWA yóo dá ẹnikẹ́ni tí ó bá pe orúkọ mi lásán lẹ́bi.
Alukoro Ọlọpaa naa fikun wi pe awọn ti fi panpẹ ọlọpaa mu olori awọn eleegun naa ni ipinlẹ Ondo.
Nítorí bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé ọmọ aládé àwọn ẹbọra ni mi, síbẹ̀, ọkàn wọn kò fà mí, n kò ní ìfẹ́ wọn.
Ọkan lara wọn ti oruko rẹ n jẹ Benjamin Peters doju ibọn kọ ọ ninu ọkọ ti wọn wa.
Amọ Femi Fani-Kayode lasiko to n fesi lori ikanni Twitter sọ wi pe isọkusọ ni ọrọ ti Asiwaju sọ, a ti pe ọrọ oselu ni Tinubu sọ.
'Kaduna ni àjọ NYSC pín mi sí sùgbọ́n.
Nítorí Ọmọ-Eniyan kò wá pé kí eniyan ṣe iranṣẹ fún un; ó wá láti ṣe iranṣẹ ni, ati láti fi ẹ̀mí rẹ̀ ṣe ìràpadà fún ọpọlọpọ eniyan.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ayinla Ọmọwura, orin èébú àti oríyìn lo fi di ọ̀rẹ́ àwọ̀n obìnrin Iṣọla Oyenusi rèé, ẹnití ìfẹ́ obìnrin ṣun dé ìwà ìdigunjalè Ọwọ́ ọlọ́pàá Ọyọ tẹ́ afurasí mẹ́ta lórí ìjinigbé ọmọ mínísítà Gani Adams: Iléèṣẹ́ ọlọ́pàá ti kàn sí OPC lórí ètò ààbò Ọpọlọpọ awọn to fesi pẹlu oju opo #sackFestusAdedayo sọ wi pe, arakunrin naa ko ni ẹtọ si ipo naa, nitori o pẹlu awọn alariwisi to ma n kọ iroyin buburu nipa Aarẹ Muhammadu Buhari ati isejọba rẹ, paapa saaju ati lẹyin ibo to kọja.
Odidi oṣù mẹ́ta ni a tilẹ̀ lo ní ìlú kan báyìí tí orúkọ rẹ̀ ń jẹ́ Ìsinmi – àlàáfíà.
Bawo ni igbe aye ṣe ri lẹyin ti Joe ku?
Ọkan lara awọn osisẹ iranwọ pajawiri so fun ileesẹ iroyin Interfax wipe baalu naa jabọ ni, kosi si aye fun ẹnikẹni lati jade laaye lati inurẹ.
Ẹnikẹ́ni kò sì ní mọ̀ pé oúnjẹ ti fi ìgbà kan pọ̀ rí, nítorí ìyàn ńlá tí yóo tẹ̀lé e yóo burú jáì.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Fadele: Dán an wò, lóbí ìyá ọ̀kẹ́rẹ́ ni a fi ọ̀rọ̀ ọ̀kadà náà ṣe 4.
 wọ ́ n ti fi ìgbà kan kári ilẹ ̀ yorùbá rí .
"Ìhà ti Fatai yara kọ sí eyi ni pe o bẹ̀rẹ̀ si kọ ara rẹ bí wọn ṣe ń lu ohun eèlò orin ""gìtá"" eyi to bẹ̀rẹ̀ lọdun 1955 pẹlu gita tí kii lo batiri tabi iná ayafi afẹ́fẹ́."
"Òṣèré méjì yìí ń fi ẹ̀wọ̀n runmú tóríi fíìmù ""Ife"" táwọn obìnrin ń bá ara wọn lòpọ̀ Ilé ìtajà kan ni àwọn afurasí ọmọ Yahoo ti n bọ̀, kí ọlapàá SARS tó lé wọn sí ẹnu ikú l'Osogbo Àwọn ọmọ Nàìjíríà gbarata lóríi fọ́nrán tí Tinubu fi síta lóríi dídìbò f'ún Obaseki ti Edo Lanlehin kéde ìparí gbogbo ètò láti darapọ̀ mọ́ ẹgbẹ́ òṣèlú APC Oyo Ninu ọrọ to ba BBC sọ, akọwe agba ẹgbẹ awọn oṣiṣẹ TUC lorilẹede Naijiria, Comrade Musa Lawal ṣalaye pe ijọba apapọ labẹ iṣejọba Muhammadu Buhari ko ṣe bi ẹni to mọ pe ara n ro araalu rara paapaa pẹlu atunbọtan ajakalẹ arun COVID-19 to da ọrọ aje ọpọlọpọ eeyan ati orilẹede ru, ninu eyi ti ọpọ di alainiṣẹ lọwọ."
Ni kete lẹyin ikede akọkọ yii ni awọn ijọba orilẹ-ede ilẹ Adulawọ gbe igbesẹ akin lati gbogun ti itankalẹ ajakalẹ arun Covid 19.
OLUWA ranti wa, yóo bukun wa,yóo bukun ilé Israẹli,yóo bukun ìdílé Aaroni.
O fidiẹ mulẹ pe nkan bi aago mẹfa ku iṣẹju mẹẹdọgbọn ni wọn de nidaji aarọ yii.
Mo lero pe ko ni ju bẹẹ lọ'' Ọrọ ti akọnimọọgba Madrid Zinedine Zidane sọ re lẹyin ifẹsẹwọnsẹ wọn.
Grandpa àti Uncle mi, ń fipá bá mi lòpọ̀ láti ọmọ ọdún mẹ́rin Ẹ má bínú, mo kábàmọ́ pé mo na obìnrin -Elisha Abbo Ààrẹ Buhari jámi lórí ètò RUGA ná Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Àjẹ́, eégún, kí ni wọn ò pè mí tán tórí Vitiligo lára mi' Ṣugbọn ohun ti fidio naa ṣe afihan rẹ yatọ si ohun to sọ.
Eyi kun ara ohun to n fa idiwọ naa nitori ọpọ onibara ni ko mọ bo ṣe jẹ.
"Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Wo bí Sunday Orimola ṣe gba ikú ẹranko kú ní Ifon ni Ondo lórí ọ̀nà àtijẹ Ọpọ awọn aladugbo lo sọ pe ni iwoye ti wọn, ẹfanjẹliisi yii kọja aye rẹ nitori pe ""oun funra rẹ mọ pe ibi aimọ ni agbegbe naa"" ni Ejigbo."
Nígbà tí Israẹli jáde kúrò ní ilẹ̀ Ijipti,tí àwọn ọmọ Jakọbu jáde kúrò láàrin àwọn tí ń sọ èdè àjèjì,
(Ẹni tí ọ̀rọ̀ yìí ṣe ojú rẹ̀ ni ó jẹ́rìí, òtítọ́ ni ẹ̀rí rẹ̀, ó mọ̀ pé òtítọ́ ni òun sọ, kí ẹ̀yin lè gbàgbọ́.
Emmanuel sọ wipe oun ko mọ nipe aawọ abẹlẹ kankan laarin Oluwo ati Ọọni tẹlẹ.
Bákàn náà sì ni lọ́dọ̀ àwọn ẹyẹ, Ògòǹgò baba ẹyẹ tí wọ́n pè láti Igbó Irúnmọlẹ̀ pé kí ó wáá ṣe alágá kò rí àyè wá nítorí ìdíwọ́ ilé.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Segalink: ìkùnsínú pọ̀ láàrin àwọn agbófinró; bẹ́ẹ̀, wọn kò ni agbẹnusọ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Segalink: ìkùnsínú pọ̀ láàrin àwọn agbófinró; bẹ́ẹ̀, wọn kò ni agbẹnusọ 15 Ìgbé 2019 Gbajugbaja amofin Segun Awosanya wa ojútùú siṣoro ki awọn agbofinro maa yinbọn pa alaiṣẹ ara ilu'Àwọn SARS ló yìnbọn pa ìyá mi'.
Àwọn angẹli bá wá sọ́dọ̀ rẹ̀, wọ́n ń ṣe iranṣẹ fún un.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Fulani Ilorin l'ọkọ mi' Amofin Kayọde Ajulọ ti kọkọ ṣalaye pe lopin ọsẹ to kọja ni oun ṣe alabapade awọn darndaran fulani kan ti wọn ṣe apejuwe ara wọn gẹgẹ bii ọmọ ẹgbẹ fijilante fulani ni agbegbe naa.
Mo ti fi ojú mi rí ìṣubú àwọn ọ̀tá mi,mo sì ti fi etí mi gbọ́ ìparun àwọn ẹni ibi tí ó gbé ìjà kò mí.
Muhammadu Buhari ti fi aidunnu ati ibanujẹ okan  rẹ han  lori
“Ìwọ ọmọ eniyan, sọ fún àwọn ọmọ Israẹli pé ilẹ̀ tí kò mọ́ ni ilẹ̀ wọn, ilẹ̀ tí òjò kò rọ̀ sí lákòókò ibinu èmi OLUWA.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Owó fọ́ọ̀mù APC fún ipò Ààrẹ gọbọi- olùdíje Oun nikan kọ.
Ajọ NCDC ṣalaye pe Ipinlẹ Ondo ati Edo ni aarun naa tun ti jẹyọ.
Wọn dá núdúlù sílẹ̀ lati ṣẹ́gun ebi lágbàyé Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Kan bu omi síi Lẹ́yin ti Japan ṣegun nígbà ògun àgbáyé elékejì, à ti rí ounjẹ jẹ le koko, ọ̀pọ̀ ènìyàn ló ń gbákàn lé ìrànwọ́ ilẹ̀ Amẹ́rikà.
Gbogbo ipade ati ijiroro gbọdọ maa waye lori ayelujara.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ní ìmọ̀ nípa bi BBC ṣe n ṣiṣẹ́ ìròyìn ayélujara nínú òtítọ́ àti láì ti igbá kan bọ̀ ọ̀kan nínú BBC jẹ́ ìlúmọ̀ọ́ka láàrín àwọ́n olólùfẹ́ rẹ̀ lórìlẹ̀-èdè UK àti jákèjádò àgbáyé, à ń ṣe àgbékalẹ̀ ìròyìn tí ẹ le fọkàn tán.
Minisita to n ri si iforotonileti ati Asa, Alhaji Lai Mohammed, ti kẹdun pelu ebi, ara, ore ati awon ojulumo gbajugbaja osere ori ero amohunmaworan,  Moses Olaiya, ti awon eniyan mo si ‘Baba Sala ti o di oloogbe ni omo odun méjílélọ́gọ́rin.
Igbimọ naa to bẹrẹ iṣẹ wọn ni ọjọ kẹrinlelogun oṣu kaarun yoo wa fi esi iwadi wọn ṣọwọ si ijọba lọjọ kerinlelogunoṣu Kẹfa bayii.
Láti Kadeṣi wọ́n lọ sí Òkè Hori, lẹ́bàá ilẹ̀ Edomu.
2 Ọ̀pẹ̀̀ 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 3 Ọ̀pẹ̀̀ 2019 Oríṣun àwòrán, Nigeria senate Njẹ o mọ ẹni ti o n ṣoju fun ẹkun idibo agbegbe rẹ ni ile aṣofin apapọ bi?
Bello ni láàrin oṣu kini ọdun si oṣù kẹjọ ọdun yìí ni àwọn ti mú àwọn gbájuẹ̀ orí ayelujara mẹ́tàle ni ààdọfà ní ìpínlẹ̀ Edo, Delta, àti Ondo tí mẹ́tàlélaàdọ́ta sì ti fọ́ju bale ẹjọ.
Fayemi tesiwaju pe :” Eyi ni ireti ti a n reti lati gba ara wa sile lowo ijoba amunisin ti won ti n dari ijoba ipinle Ekiti lati ojo pipe.
Eyi ni ọkan lara awọn idi onimọ ẹrọ nipa ikọle Henry Mwanaki Alinaitwe ati Stephen Ekolu sọ pe o jẹ kile to wo ni orilẹede Uganda lọdun 2004 wo.
Ìwọ ṣá darapọ̀ mọ́ wa,kí á sì jọ lẹ̀dí àpò pọ̀.
Balaamu dá àwọn oníṣẹ́ Balaki lóhùn pé, “Balaki ìbáà fún mi ní ààfin rẹ̀, kí ààfin náà sì kún fún fadaka ati wúrà, n kò ní lòdì sí àṣẹ OLUWA Ọlọrun mi, ninu nǹkan kékeré tabi nǹkan ńlá.
Awon ebi Gupta ti o je,  Ajay, Atul ati Rajesh, ni won fesun iwa ibajẹ kan leyin ti won n lo anfaani ibasepo ti won ni pelu aare orile-ede naa teleri, Zuma lati fi maa kowo ilu je.
Bakan naa ni wọn yoo pin iboju-bomu ti ijọba ipinlẹ naa ṣe funra rẹ ni ọ̀fẹ́ nigba ti yoo ba fi di opin ọsẹ yii.
Ṣugbọn ti obinrin oyinbo ba sọ fun ọ pe oun nifẹ rẹ, ṣe ki n ma tan yin, ati isalẹ ọkan rẹ lo ti wa.
Onígbèsè bá gbéra ó di ilé Yeyemoja Olókun Seniade, Nígbàtí ó dé ọ̀dẹ̀dẹ̀ Yeyemoja, ó wípé, nígbàkúgbà tí ó bá fẹ́ rán oníṣé sí òhun kò dákun má ṣe rán Ọmọ rẹ̀ Ẹja sí òhun mó, Wípé ọmọ rẹ̀ Alákàn ni òhun fẹ́.
Wọle Ṣoyinka: Ẹ máṣe gba gbogbo ohun tẹ bá rí lórí ayélujára gbọ́ nípa mi
“Sọ fún àwọn ọmọ Israẹli, àwọn olóríkunkun, pé OLUWA Ọlọrun ní, ‘Ẹ̀yin ọmọ Israẹli, ẹ dáwọ́ àwọn nǹkan ìríra tí ẹ̀ ń ṣe dúró.
Saulu bá dìde nílẹ̀, ó la ojú sílẹ̀ ṣugbọn kò ríran.
Oríṣun àwòrán, AFP Ọjọ ti pẹ ti orukọ ajọ Hisbah ti n jẹyọ ninu iroyin, paapaa ni awọn ipinlẹ to wa ni Ariwa Naijiria.
Ọlọ́pàá, a fún yín ní gbèdéke ọjọ́ 21 láti mú àwọn tó pa ọmọ Fasoranti - OPC Ẹgbẹ Oodua Peoples Congress (OPC), New Era, ti fun ileeṣẹ ọlọpaa ati awọn ileeṣẹ eto aabo mi i l'orilẹede Naijiria ni gbedeke ọjọ mọkanlelogun lati tu aṣiri awọn to pa Abilekọ Funke Olakunrin, ọmọ olori ẹgbẹ Afẹnifẹre, Alagba Reuben Fasoranti.
Rehoboamu bá lọ jíròrò pẹlu àwọn àgbààgbà Israẹli tí wọ́n bá baba rẹ̀ ṣiṣẹ́ nígbà ayé rẹ̀, ó ní, “Ẹ fún mi ní ìmọ̀ràn, irú èsì wo ni ó yẹ kí n fún àwọn eniyan wọnyi?
Latin lórí àìsàn Ogun Majek Ewu ń bẹ!
O ni àseyege gbaa ni ni ìkọlù naa jẹ́, ti ó sì tún dúpẹ́ lọ̀wọ̀ awọn orilẹede to fọwọ́sowọ́pọ̀ pẹlu rẹ̀.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ààwẹ Ramandan àti irú ouńjẹ tí o lè jẹ Zakzaky yọjú sílé ẹjọ́ lórí ẹ̀sùn ìpànìyàn Ó yẹ kí àwọn asòfin yọ Buhari - Shiite Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí 2 sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
Wo bí o ṣe lè di aṣojú tó ṣe pàtàkì nínú àjọ ìṣọ̀kan àgbáyé 'UN Goodwill Ambassador' Àwọn èèyàn ìpínlẹ́ Ondo kò gbàgbọ́ pé Coronavirus wà lọ jẹ́ kó máa pọ̀ síi - ìjọba Wo bí ọwọ́ orílẹ̀-èdè Dubai ṣe tẹ Ramoni Igbalode tí gbogbo ayé ń pè ní Hushpuppi Wo àwọn èèyaǹ jàǹkàn mérin tí àrùn Coronavirus ti sọ dèrò ọ̀run ní Naijiria Oríṣun àwòrán, Others Àkọlé àwòrán, Ilé ẹjọ́ kòtẹ́mílọ́rùn yọ alága ẹgbẹ́ òṣèlú APC Adams Oshiomhole nípò Adams Oshiomhole: Ilé ẹjọ́ kòtẹ́mílọ́rùn yọ alága ẹgbẹ́ òṣèlú APC Adams Oshiomhole nípò Ilé ẹjọ́ kòtẹ́milọ́rùn ti ilú Abuja ti yẹ àga mọ alága ẹgbẹ́ òṣèlú APC, Adams Oshiomhole nídìí Ìgbìmọ̀ ẹlẹ́ni mẹ́tà ti adájọ́ Eunice Onyemanam sójú fún ni wọ́n fẹnu kò láti jan idájọ́ tí ilé ẹjọ́ ti kọ́kọ́ dá tẹ́lẹ̀ lóntẹ̀.
Wo ipò tí Buhari fún Faṣọla, Lai Mohammed, Saraki àti bẹ́ẹ̀ bẹ́ẹ̀ lọ Leon van Biljon dí èrò ọrun nípasẹ̀ Kìnìún rẹ̀ PFN: Fatoyinbo kọ̀ láti yọjú ni ìwádìí wa kò ṣe parí Tani Tolani Alli?
Amẹrika: Ipa ti idẹnukọlẹ isejọba ni lori araalu
Lagos Cane Village: Lórí iṣẹ́ ikàn yìí, a ti kọ́ ilé, ọmọ ti lọ ilé ìwé
ẹlẹ́rìí èké tí ẹnu rẹ̀ kún fún irọ́,ati ẹni tí ń dá ìjà sílẹ̀ láàrin eniyan.
Àjọṣepọ̀ tí ó dán mọ́nrán ń bẹ ní àárín-in Ohùn Àgbáyé àti Irrawaddy.
A máa wà ní ojú òpópónà ní olú ìlú fún oṣù Èrèlé, ní àwọn ọjọ́ kọ̀ọ̀kan tí a yàn, ọjọ́ kẹrin oṣù Èrèlé ni ìwọ́de náà bẹ̀rẹ̀, àmọ́ ní ọjọ́ kéje ni a máa padà sí ojú òpópónà, tí a óò tún wà ní ọjọ́ kankànlá, tí a ó sì jábọ̀ ní ọjọ́ kẹtàlá, bí ìjọba kò bá yí ohùn padà.
Kogi Prison: Kò sí ẹ̀mí kankan tó nù, a sì tí rí lára àwọn tó fẹsẹ̀ fẹ́ ẹ
Oríṣun àwòrán, @ganiadams01 Àkọlé àwòrán, Aarẹ Marundinlogun lo ti jẹ ninu itan Yoruba Ni oṣu kini ọdun 2018 ni Gani Adams bọ si ipo aarẹ Ọna kakanfo.
Ọlọ́pàá ti mú ẹni márùn ún lórí ìjà láàrin Hausa àti Yorùbá l'Eko Ìjìyà ń bẹ fún àwọn ti adé ọ̀rọ̀ náà bá ṣí mọ́ lóri -Ọga àgbà FRSC Ike Ekweremadu, igbákejì ààrẹ ilé aṣòfin àgbà tẹ́lẹ́ rí èèmọ̀ he nilùú Germany!
Boko Haram: Ọlọ́pàá mú afẹ̀sùnkàn olójú kan tó ti pa ju igba ènìyàn
Leah Sharibu ni akẹkọbinrin ile iwe giram Dapchi ti awọn oniṣẹ ibi boko haram kọ̀ lati tu silẹ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Health workers Strike: Àwọn òṣìṣẹ́ elétò ìlera lábẹ́ àsìá JOHESU fagilé ìyanṣẹ́lódì káàkiri Nàìjíríà 4 Owewe 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 21 Owewe 2020 Oríṣun àwòrán, others Ẹgbẹ oṣiṣẹ eleto ilẹra lapapọ labẹ ẹgbẹ JOHESU ti kesi awọn oṣiṣẹ wọn lati pada si ẹnu iṣẹ.
Ó bá sọ fún mi pé, “Sọ àsọtẹ́lẹ̀ fún àwọn egungun wọnyi, kí o wí fún wọn pé, ‘Ẹ̀yin egungun gbígbẹ wọnyi, ẹ gbọ́ ohun tí OLUWA wí’.
Amọṣa gẹgẹ bi Dokita MacDermott ṣe sọ, eyi kii waye pẹlu arun Coronavirus lara awọn ọmọde o, ko si si ẹni to mọ ohun ti arun naa n ṣe lara awọn ọmọde ti eyi fi ri bẹẹ.
Sheu loju opo Twitter sọ pe, irọ ni pe ijọba apapọ Naijiria lo paṣẹ pe ki EFCC ṣayẹwo ile awọn ọmọ Atiku Abubakar.
Àwọn olólùfẹ̀ Ààrẹ Buhari kan ra fọ́ọ̀mù 45m naira fún un lati díje dupò ààrẹ lọ́dun 2019.
won ko tii fọwọ kan lati bi ogun odun seyin.
O pari rẹ bayii pe ko si ẹni ti ori rẹ pe ninu awọn ẹgbẹ mejeeji.
Àwọn aguntan mi fọ́n káàkiri sórí gbogbo ilẹ̀ ayé.
Ni kete ti ifẹsẹwọnsẹ naa pari si ni awọn ololufẹ awọn mejeeji ti n waako lori ikanni ayelujara gbogbo.
Ewe, yatosi aare orile-ede Naijiria ti o dari ipade ohun, ni a tun ti ri aare orile-ede Chad, Idris Deby, aare orile-ede Niger Republic, Mahamadou Issoufou ati oludari orile-ede Cameroon, Philemon Yang ti o lo soju aare Paul Biya.
" Nibayii, wọn rọ ijọba lati ran wọn lọwọ nitori ẹkun omi to ma n waye ni gbogbo igba ti wọn ba ti ṣi daamu naa.
Alága NLC ati TUC sọ́ òhun tó fa ìdì abájọ ìbani lórúkọ jẹ́ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fọ́nrán ohùn, Ẹ lọ mú ẹ̀rí ibi tí a ti gba owó wá- NLC/TUC Ekiti Workers: Ìbásepọ̀ àìtọ́ láàárín Fayose àtàwọn olórí wa ló fìyà jẹ wá Àkọlé àwòrán, ‘Ẹ wádìí ₦264m táwọn asaájú òsìsẹ́ gba lásìkò Fayose’ Àwọn òṣìṣẹ̀ ìpínlẹ̀ Ekiti tí kọ̀wé ẹ̀hónú sí ilé ìgbìmọ̀ aṣofin ìpínlẹ̀ Ekìtì, láti ṣe ìwádìí lórí mílíọ̀nù mẹ́fà tí gomina ana nipinlẹ naa, Ayọdele Fayose ń san fáwọn olórí òṣìṣẹ́ lósoosù, tó fi di mílíọ̀nù lọna ọtalerugba o le mẹfa náírà ( ₦264m).
Èyí ni àwọn arẹwà ‘ẹ̀lẹ̀ Daddy’, àfẹ́fẹ́ tí Aláàfin fi ń mí Wo ọ̀nà tí àwọn ‘ẹ̀lẹ̀ Daddy’ gbà dé ààfin Ọyọ Wo àwọn olorì àgbà mẹ́rin tí Aláàfin ń wárí fún Kí ló pa Bobrisky àti Olorì Aláàfin Oyo pọ̀?
Ó bá wí tẹ̀dùntẹ̀dùn pé, “Mo fẹ́ kí ẹ mọ̀ dájúdájú pé, ọ̀kan ninu yín ni yóo fi mí lé àwọn ọ̀tá lọ́wọ́.
Bo se wulo fun itọju oju, taa ge wẹwẹ fi bo ẹyinju wa mejeeji, naa lo tun wulo fun irun ori obinrin.
Bẹ́ẹ̀ ni ọ̀rọ̀ ẹni tí ó lọ bá aya aládùúgbò rẹ̀ lòpọ̀ rí,kò sí ẹni tí yóo ṣe bẹ́ẹ̀ tí yóo lọ láìjìyà.
Bí ilẹ̀ kan bá wọ̀ wọ́n lójú, wọn á gbà á lọ́wọ́ onílẹ̀; bí ilé kan ló bá sì wù wọ́n, wọn á fi ipá gbà á lọ́wọ́ onílé; wọ́n ń fìyà jẹ eniyan ati ilé rẹ̀, àní eniyan ati ohun ìní rẹ̀.
Luis Moreno-Ocampo, to jẹ olupẹjọ ile ẹjọ agbaye nigba kan ri sọ ni ọdun 2009 wipe Omar al-Bashir ko owo to to biliọnu mẹsan dọla (triliọnu mẹta aabọ naira) pamọ si awọn ile ifowopamọ to wa ni Ilẹ Gẹẹsi.
46 Ojúṣe àlùfáà ni láti wàásù, kọ́ni, sọ àsọyé, gbani níyànjú, àti ṣe ìrìbọmi, àti ṣe àkóso ouńjẹ àlẹ́ Olúwa,
Wọ́n mú ẹgbaarun (10,000) mìíràn láàyè, wọ́n kó wọn lọ sí góńgó orí òkè kan, wọ́n jù wọ́n sí ìsàlẹ̀, gbogbo wọn sì ṣègbé.
 Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Mo ni baba isalẹ' Ọwọ́ tẹ̀ èèyàn 65 tó tàpá sí òfin gbéléẹ níbi ayaẹyẹ ọjọ́ ìbí Ọmọbìnrin Gbenga Adeboye náà fikùn pé, Baba òun ni ifẹ gbogbo ènìyàn bíi ọmọ àti àbúrò rẹ ni, ó sì tẹ bàbá òun lọrun pé ki awọn ẹbi rẹ mu gàárì kí àwọn ará ìta leè rí oúnjẹ jẹ, tàbí rí owó fún àwọn èèyàn."
Shekau ni Boko Haram lo ja ọkọ ofurufu ologun ilẹ wa,kii se pe o bajẹ.
Ni bayii, awon omo naa wa nile iwosan iko omo ogun lati gba itoju ti o peye, bi awon omo ogun naa se n tesiwaju lati mu ileri won se, lati gba gbogbo awon ti o wa nipo ahamo sile lowo awon onise ibi yii Tobi Sangotola.
Ẹni to bori: South Africa Nigeria vs Mali.
Orúkọ rẹ ti kun àwọn agbabọọlu Premiership miran to tí tapa sí òfin konile o gbele lasiko yìí Kyle Walker tí Man City n duro dè abajade iwadii eléyi tó n tọ pinpin bi o ti ṣe pé apejẹ nínú ilé rẹ pẹlu awọn obinrin oníṣẹ́ nàbì méjì kàn.
báyìí ni wọ ́ n ṣe di ọ ̀ rẹ ́ tímọ ́ tímọ ́ .
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Seyi Makinde: Akọ̀wé ìjba tuntun ni Olubamiwo Adeọsun.
197 Awọn to ni arun ọpọlọ nibi iwọde naa - N6,121,678.
Atiku ni ko fẹẹ ma si ipinlẹ kan lorilẹ-ede Naijiria ti ko ni idojukọ tabi ipenija kan tabi omiran lori ọrọ aabo.
Mamman Daura ko kan ki n ṣe korikosun aarẹ Naijiria, ọmọ ẹgbọn Muhammadu Buhari lo jẹ bi o tilẹ jẹ pe o gba ọdun mẹta lọwọ aarẹ tori ọmọ ẹgbọn rẹ ọkunrin ni.
Bi wọn ba n pa awọn to n ṣe ọmọde baṣubaṣu pẹlu iwa nọbi, iṣoro yii yoo dinku.
Super Eagles lati rii pe won gba ife ẹyẹ AFCON 
Wọ́n bi í pé, “Ṣé ó bá òfin mu láti ṣe ìwòsàn ní Ọjọ́ Ìsinmi?
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, SS3 ní mo wà báyìí, mo sì ti gba àmì ẹ̀yẹ̀ púpò nílé-lóko gẹ́gẹ́ bí onílù - Ayansike Ọjọ kejila oṣu keje ọdun 2020 ni ija to kopa ninu rẹ kẹyin waye, ninu eyi to ti lu Jorge Masvidal niluu Abu Dhabi.
Ó gbé ìgbésí ayé rere nipa ìtọ́jú àwọn ọmọ àti ìyàwó, ó si fún àwọn ọmọ ni ẹ̀kọ́ ilé àti ti ilé-ìwé.
Bakan naa lo sọ pe awọn ti kowe wa salaye tẹnu rẹ si ẹka igbẹjọ ọlọpaa t'awọn si ti ni ki adari ẹka naa wa sọ ohun to mọ nipa iwe ipẹjọ yi.
ninu ọ̀rọ̀ rẹ̀, Gbenga Adeyinka to jẹ gbajugbaja adẹrinpoṣonu lorilẹ̀ede Naijiria ni lilọ Arsene Wenger kọ̀ ni opin iṣoro ikọ Arsenal nitori, ni iwoye tirẹ, 'Wenger kọ ni i'soro Arsenal.
" Oríṣun àwòrán, OLUWO ILU IWO Àkọlé àwòrán, Àkọ́kọ́ ìpàdé tí Olúwó ti ìlú Iwò Oba Abdulrasheed Akanbi yóò bá àwọn lọ́balọ́ba ṣe lati ìgbà tó ti gun orí oyé ni ọdún 2015.
Coronavirus: Ẹ tilẹ̀kùn ṣọ́ọ̀ṣì àti mọ́ṣáláṣí yín tí èrò bá ju 50 lọ láti dẹ́kun Coronavirus
Nisinsinyii a ti waasu nǹkan wọnyi fun yín nípa ìyìn rere tí ó ti ọwọ́ Ẹ̀mí Mímọ́ wá, tí a rán láti ọ̀run wá fun yín.
- Àjọ ajàfẹ́tọ̀ọ́ ọmọdé Al Shabab ṣe ìkọlù sí ibùdó ogun America ní Kenya, ẹ̀mí mẹ́ta lọ síi Góminà Bauchi, Bala Muhammed wá ṣe àgbékalẹ̀ ìgbìmọ̀ ẹlẹni mẹ́tàdinlógun láti tú iṣu dé ìsàlẹ ìkòkò lóri bi ọ̀rọ̀ náà ṣe jẹ́.
Tramadol tó ń polówó ikú tantan-tan Akọroyin Tom Odula bọ si gbogbo adugbo ilu ṣewadii boya lootọ, ẹmi okunkun lo n gbenu awọn to n ṣe iṣẹ abami yii loru ọganjọ.
Victor Giadom gbàṣẹ iléẹjọ́ gíga láti jẹ adelé alága APC Gómìnà márùn ún tó fojú winá ìbínú bàbá ìsàlẹ̀ wọ̀n Ṣé lóòtọ́ ni Sẹ́netọ̀ Bayo Osinowo ní ìfura ikú ara rẹ̀?
Ẹ̀yin fúnra yín náà, ẹ gba ohun tí mò ń sọ rò.
Tí o bá ṣe bẹ́ẹ̀, yóo jẹ́ ìwòsàn fún ara rẹ,ati ìtura fún egungun rẹ.
Eyi lo jẹ ki Tottenham bori Juventus pẹlu ami ayo mẹta si meji ninu ere bọọlu naa.
Manoa bá gbadura sí OLUWA, ó ní, “OLUWA, jọ̀wọ́ jẹ́ kí iranṣẹ rẹ tí o rán sí wa tún pada wá, kí ó wá kọ́ wa bí a óo ṣe máa tọ́jú ọmọkunrin tí a óo bí.
Lori eto igbokegbodo ọkọ ati karakata pẹlu iṣẹ gbogbo.
Omo Aare ana lorile-ede South Africa Duduzane  Jacob  Zuma  yoo fojuba ile-ejo lori esun ipaniyan nipa oko – ayokele.
“O gbé ibinu wọ̀ bí ẹ̀wù,ò ń lépa wa,o sì ń pa wá láì ṣàánú wa.
Nítorí ó ti yan ọjọ́ tí yóo fi òdodo ṣe ìdájọ́ gbogbo ayé nípa ọkunrin tí ó ti yàn.
Ẹnikẹni to ba si ra ọja mi, to wọ ọ, yoo duro re nilẹ, ti yoo si dun wo.
Wọn kò ní tẹ́ pẹpẹ wọn sí ẹ̀gbẹ́ tèmi mọ́, tabi kí wọn gbé òpó ìlẹ̀kùn wọn sí ẹ̀gbẹ́ tèmi; tí ó fi jẹ́ pé ògiri kan ni yóo wà láàrin èmi pẹlu wọn.
Ìgbéraga pinu lati padà si ilú rẹ lati gba ogún ti ó tọ́ si lára oko kòkó rẹpẹtẹ ti bàbá rẹ fi silẹ̀.
Apá rẹ̀ wà lókè títí tí oòrùn fi ń lọ wọ̀.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù AFCON 2019: Idíje Egypt ati Zimbabwe, ọ̀rọ̀ kọ sísọ 22 Òkùdu 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Egypt ṣíná fún Zimbabwe, ẹ̀kọ́ mẹ́rin tó yẹ ní kí kọ́ Idije AFCON fawọn agbabọọlu ilẹ̀ Adulawọ lo bẹrẹ ni ana ni orilẹ-ede Egypt.
À máa ń yin eniyan gẹ́gẹ́ bí ó bá ṣe gbọ́n tó,ṣugbọn ọlọ́kàn àgàbàgebè yóo di ẹni ẹ̀gàn.
Adeleye AAC - BBC News Yorùbá BBC News, YorùbáFò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ondo Election 2020: Mo ṣèlérí N500 lóṣooṣù fún gbogbo ọmọ tuntun - Adeleye AAC Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Ondo Election 2020: Mo ṣèlérí N500 lóṣooṣù fún gbogbo ọmọ tuntun - Adeleye AAC 6 Ọ̀wàrà 2020 Bo tilẹ jẹ pe o ti to ẹgbẹ oṣelu mọkanla taa gbọ pe o ti darapọ mọ ẹgbẹ oṣelu Peoples Democratic Party ni ipinlẹ Ondo fun idibo gomina to n bọ, awọ oludije ṣi sọ afojusun wọn fun BBC Yoruba.
 ) ( international problems must be solved by diplomacy , not war .
Odunlade, Toyin, Ijebu dásí ìwọ́de #EndSARS, Mercy Aigbe gbébọn Ìdí táwọn olùwọ́de EndSARS fi kọ oúnjẹ àti ọtí ẹlẹ́rìndòdò tí MC Oluomo gbé wá rèé Ọkọ̀ akẹ́rù tí ìjánu rẹ̀ já ló kọlù ọkọ̀ agbépo tó fa ìjàmbá iná ní Otedola- LASEMA Ẹ foríjìn wá ọmọ Nàìjíríà, mó mọ̀ pé ẹ̀ ń bínú tórí a kò tètè gbé ìgbésẹ̀ lórí ọ̀rọ̀ EndSARS- Osinbajo Omijé fẹ́ bọ́ lójú mi tí mo bá ṣàfiwé SARS tí mo dá sílẹ̀ àti SARS tó wà níta báyìí- Fulani Kwajafa Ninu atẹjade ti oludamọran Aarẹ Buhari lori ọrọ iroyin, Garba Shehu fi sita, Buhari ni ki wọn dupẹ lọwọ Eledua fun igbe aye to daara ti mama gbe nigba to wa laye.
    Ìgbà tí Adéforítì bá a sọ̀rọ̀ nípa lébìrà tí ó bá lọ fún un tán, Èṣù ṣe ìlérí àti fún un ní léebìrà ṣùgbọ́n ó wí fún adéforítì pé òun fẹ́ fi díẹ̀ hàn án ní ọ̀run àpáàdì kí ó tó lọ.
O tẹnu mọ ọ pe ko si ipinlẹ kankan ti yoo san owo to kere ju deede iye owo oṣu oṣiṣẹ to kere julọ gẹgẹ bi ilana ijọba.
Nítorí pé ẹ ní ọpọlọpọ ẹ̀bùn ninu Kristi: ẹ ní ẹ̀bùn ọ̀rọ̀ sísọ, ẹ sì tún ní ẹ̀bùn ìmọ̀.
Ẹ kọ orin titun sí OLUWA;gbogbo ayé, ẹ kọ orin sí OLUWA.
Cadée gba àwọn aboyún níyànjú láti wádìí lọ́dọ̀ àwọn olùtọ́jú wọn ọ̀nà tí ó dára jù lásìkò yìí láti ṣe ètò àyẹ̀wò ìgbàdédéìgbà tí alaboyun máa ń ṣe Bi mo bá láàrùn COVID-19, ṣé mo leè ko ran ọmọ láti inú oyún ?
Ogbeni Adekunle Adebiyi to je oga agba ile ise ibanisoro MTN lo siso loju eegun eto akanse naa pe MTN n satileyin fun ayeye odun asa ibile metadinlogoji lodun 2018 yii nikan.
Wọ́n fi ẹ̀gún hun adé, wọ́n fi dé e lórí.
Ni bayii, Barcelona ti pegede sipele keta si asekagba idije ohun.
Ọmọ mẹrindinlogun ati iyawo mẹrin ni Ọjọgbọn naa fi silẹ saye lọ.
Ohun to damiloju ni pe iwa ibajẹ lo n ja takuntakun bayii."
O ni ijọba oun yoo rii daju pe wọn fa ẹgbẹ naa danu kuro ẹkun Ila Oorun Ariwa Naijiria.
Ìran wolii náà nípa Olórí Alufaa.
Egbe oselu SLPP ti o je eyi ti o da gbaju , ni o si je ilumoka ni apa ila oorun ati guusu orile-=ede naa.
Ni ilu Eko, Badagry ati Ẹgba, okiki arabinrin Ẹfunroye Tinubu tan kaakiri nitori pe ọlọla ni, o gbajumọ, to si tun jẹ gbajumọ onisowo ẹru, ọti oyinbo ati awọn ohun ija oloro.
" Lizzy Anjorin, ti dáhùn ìbéérè yín lórí ìdí tó fi ṣe ìgbéyàwó lẹ́yìn ọdún mẹ́rìnlá tó ti pàdé ọkọ rẹ̀.
Eredi to fi n ṣe iru iṣẹ ọna yii ni lati gba ilu Eko mọ kuro ninu idọti isẹ r yii si ti n gbajugbaja bayii lorilẹede Naijiria.
Amọṣa, iwadii ti ajọ Armed Conflict Location & Event Data Project (ACLED) ṣe, ayẹwo awọn iroyin to n jade ninu awọn ileeṣẹ iroyin abẹle atawọn iroyin miran.
Wo orúkọ àwọn ẹ̀yà ara rẹ̀ ní èdé Yorùbá Ẹ wo àwọn ọ̀dọ́mọdé Naijiria tó ń ṣe bẹbẹ nínú isẹ́ aládaní nílé Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ẹ wo fídíò Kìnìhún ní ibùgbé rẹ̀ tuntun ní Bogije, Lekki Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Òṣìṣẹ́ inú ọkọ̀ òfuurufú olóbìrin nìkan wọ ìwé ìtàn ní Mozambique
 “Bi awon daran-daran se fẹran lati maa ko ẹran
Arioku bá mú Daniẹli lọ sí ọ̀dọ̀ ọba kíákíá.
Awọn Mallam to ba n dako a maa fi awọn ọmọ yi sisẹ ninu oko wọn.
Bí ẹnìkan bá fi agbára mú ọ pé kí o ru ẹrù òun dé ibùsọ̀ kan, bá a rù ú dé ibùsọ̀ keji.
Niṣe ni mo fi ibinu kuro ninu yara ibusun wa, ti mo si lọ si yara igbalejo.
Ọkan lara awọn eroja to ni ni zinc, folic acid ati selenium to n mu ki ato okunrin dara si.
A kò ní gbọ́ ohùn ẹran ọ̀sìn níbẹ̀.
Awọn onimọ nipa itakun agbaye ninu ọrọ wọn sọ wipe igbesẹ to dara ni Facebook gbe ati wipe yoo lapẹẹrẹ lọjọ iwaju.
Fidio yii se afihan bi Dokita lati orilẹede Amerika se kọkọ se awari kokoro HIV lẹyin to sekupa eniyan kan.
IdajoOshiomhole, wa fokan igbimo naa bale pe .
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Èmi àti Saheed kìí ṣe ọmọdé, a ti jọ ṣe Sinimá papọ̀, èyí túmọ̀ sí pé ìjà ti parí - Fathia Balogun Mo fẹ́ pa ara mi torí ojú àbùkù tí wọn ń fi wò mí pé mo fi iṣẹ́ abẹ bímọ"" Fulani kò leè dúró, táa bá lo ohun ta jogún lọ́dọ̀ àwọn bàbá wa - Sunday Igboho Ọjà Àgbáláta ní Badagry rèé, níbití ẹran ejò ti dùn ju ẹran adìẹ lọ Ọlọ́run yóò ṣe ìdájọ́ nkan tó wà láàrin èmi àti Ireti Ajanaku - Tope Alabi ""Asiko ti awọn ọmọ ogun n le wọn yii ni awọn afurasi naa bẹrẹ si ni yinbọn si awọn ọmọ ogun, eyi to mu ki awọn naa da a pada fun wọn."
Ṣùgbọ́n ọkan nínú àwọn ọlọ́gbọ̀n tí wọ́n péjọ sí ilé mi tí wọ́n gbọ́ ìtàn náà wí fún mi pé rírí tí a kò rí ọkùnrin náàmọ́ kò ya òun lẹ́nu, nítorí kò yàtọ̀ sí Àkàrà-oògùn jú bẹ́ẹ̀ lọ, òun àti Òmúlẹ̀mófo ọ̀kan náà ni.
Ijọba ni oun n gbe igbesẹ naa ki iṣẹ ipese ilera ati itọju awọn alaisan ma baa dawọ duro nibẹ.
Oríṣun àwòrán, LASEMA Bẹ́ẹ̀ àwọn ìrònú àròròtán lóri ètò ọ̀rọ̀ ajé àti ìgbéyàwó ló maa n ti ẹlòmíràn láti pa ara rẹ̀.
Benhadadi pàápàá sá wọ inú ìlú lọ, ó sì sá pamọ́ sinu yàrá ní ilé kan.
Ile ise ọlọpaa ti saaju gba asọ lọrun inspektọ Ogunyẹmi Olalekan lori ipa to ko ninu iyinbọn pa Kolade Johnson.
Pẹlu ayọ̀ ni ẹ fi gbà kí wọ́n fi agbára kó àwọn dúkìá yín lọ, nítorí ẹ mọ̀ pé ẹ ní dúkìá tí ó tún dára ju èyí tí wọn kó lọ, tí yóo sì pẹ́ jù wọ́n lọ.
Ajọ eto ilera lagbaye, WHO sọ pe iwadii si n lọ lọwọ lori ati wa oogun tabi abẹrẹ to le wo coronovirus ṣugbọn ko sii oogun rẹ bayii.
Gadi bá lọ sọ ohun tí OLUWA wí fún Dafidi.
Oríṣun àwòrán, Twitter/Gboyega Akosile Bakan naa lo ba awọn ẹbi ati ara ti ajalu naa ṣẹlẹ si kẹdun, pẹlu adura wi pe wọn ko ni rogun ibanujẹ mọ, ati wi pe Olorun yoo tu wọn ninu.
Oogun iba to wọpọ nilẹ Afirika, papaa julọ lorilẹede Naijiria ni bi ogun ọdun si ọgbọn sẹyin, Chloroquine phosphate ni awọn onimọ iṣegun ti sọ pe, oogun naa ṣiṣẹ fun itọju aarun Coronavirus to n tan kalẹ kaakiri.
Ken Praxton to jẹ adajọ agba fun Texas sọ ninu atẹjade to fi sita pe o bani ninujẹ lati ri iru iṣẹlẹ bayii.
Ikú á mú àwọn alágbára lọ láì jẹ́ pé eniyan fi ọwọ́ kàn wọ́n.
Ó ṣe nǹkan tí ó tọ́ níwájú OLUWA, bí Amasaya baba rẹ̀.
Awọn Akọròyìn tó mòye Ìròyìn BBC tí ó ba jẹ pe BBC ló ṣe ìwádìí rẹ̀ máa ń ni orúkọ àkọròyín àti àwọn akọroyin tó tí wọ́n ní ojúṣe kan pàtó.
Má rìn láìwọ bàtà, Israẹli,má sì jẹ́ kí òùngbẹ gbẹ ọ́.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Koko iroyin: Awuyewuye Dapchi, alaboyun tan’gbaloju nibi irọbi 22 Ẹrẹ̀nà 2018 Eyi ni awọn akojọpọ iroyin ti toni.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: A kò ní fara mọ́ fífi àkókò ṣòfò lórí ẹjọ́ Sotitobire - Ìjọba Ondo Tinubu, ojú tì ẹ́, o ta Yorùbá fún ọ̀tá torí àdánìkànjẹ - Fani-Kayode Omijé bọ́ níbi ìsìnkú Ogun Majek Ìbánújẹ́ gbọkàn àwọn èèyàn nílé abílékọ ọlọ́mọ mẹ́ta tí wọ́n ṣẹ̀ṣẹ̀ pa ní Ibadan Gagara fikun pe ọwọ tẹ awọn aadọjọ agboogun oloro naa laarin osu kinni si osu kẹfa ọdun 2020.
to n samojuto eto aabo lorile  yii fun
 fun eto ipolongo fun egbe APC ,Festus
Nítorí náà, ẹ ya ara yín sí mímọ́, kí ẹ sì jẹ́ mímọ́, nítorí pé, èmi ni OLUWA Ọlọrun yín.
’ rèé Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí 2 sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 2:23 Fídíò, Water Generator: Ó leè ṣiṣẹ fún wákàtí mẹfà, kó tó sinmi, Duration 2,2310 Òkùdu 2020 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
Tabi ki wọn ṣafihan awọn ilana aatẹle ti wọn fẹ fi ṣawari awọn ti wọn ṣe magomago lasiko idibo ọhun.
Lati da okoowo sile ni awon eka ile
Afenifere: Ọlọ́pàá kò le sọ bóyá Fulani darandaran ló pa Funke Olakunrin
Akọ̀wé ìgbìmọ̀ ìlú ló mú kí wọ́n dákẹ́.
Isele ohun je eyi ti o buru julo ninu ijamba oko oju-irin ti o ti n waye lorile-ede Egypt latinu osu kokanla odun 2013, bakan naa ijamba oko oju-irin ati oko akero kan kolu ra won ni apa gusu ilu Cairo ninu eyi ti awon eniyan metadinlogbon ti gbemi mi.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Healthy lifestyle: Wo irú ìgbé ayé tó lè mú ẹ̀mí rẹ gùn 11 Bélú 2020 Oríṣun àwòrán, Getty Images Gbigbe igbe aye to dara le fi ọdun mẹwaa kun ọjọ aye awọn obinrin, bakan naa lo le fi ọdun meje kun t'awọn ọkunrin.
Awọn arinrin ajo igbafẹ ko lo ṣabẹwo sawọn itura to wa nibẹ lati oṣu kẹta ti wọn ti gbe ibode ti pa.
Nigba ti Lionel Messi ti gba a lẹẹmeji lọdun 2011 ati 2015.
Ọ ̀ pọ ̀ lọpọ ̀ iṣẹ ́ ló ti wà lórí ìtàn ìṣẹ ̀ dálẹ ̀ ìlú ilè-ifẹ ̀ bẹ ́ ẹ ̀ ọ ̀ pọ ̀ lọpọ àwọn òǹkọ ̀ wé àti òǹpìtàn ló ti fi èrò wọn hàn lórí ìtan ìṣẹ ̀ dálẹ ̀ ìlú ilé-ifẹ ̀ .
42 Nítorí gbogbo ènìyàn ni wọ́n gbọ́dọ̀ ronúpìwàdà kí wọ́n sì sì rì wọ́n bọmi, kìí sìí ṣe ọkùnrin nìkan, ṣùgbọ́n àti àwọn obìnrin, àti àwọn ọmọdé tí wọ́n ti dé awọn ọdún ìjíhìn.
Láti ọdún 1998 tí olórí ìjọba ológun tẹ́lẹ̀, ọgagun Sani Abacha tí dagbere faye, ọ̀pọ̀ ìgbà ni orílẹ̀ èdè Nàìjíríà tí rí owó tó ko pamọ sókè òkun gbà padà.
Ìdí rèé tí ilẹ̀ Afirika fi gbọdọ̀ kópa nínú dídán abẹ́rẹ́ coronavirus wò Ọpọ iroyin to mu ibẹru dani lo ti jade lori didan abẹrẹ aarun coronavirus wo lara awọn ọmọ ilẹ Adulawọ.
Ọga agba GRIDCo, Jonathan Amoako Baah ṣalaye pe niṣe ni aisina yi waye nigba ti ina ti wọn fi ranṣẹ si orileede Côte d'Ivoire pada si ori opo ina ti ilẹ Ghana.
 Àwọn ìdin náà yóò sì gba inú ikùn kọjá fún ìgbà kejì sínú ìfun níbití wọn yóò ti dàgbà sí aràn nlá .
Ṣé Makinde kò wá rugi oyin báyìí lórí ìpàdé ìtagbangba PDP tó ṣe níbàdàn Láì náání àjàkálẹ̀ àrùn coronavirus?
''Ṣugbọn nigba ti owo bẹrẹ si ni wọlẹ, niṣe ni wọn gbaruku ti mi,'' Victoria lo sọ bẹẹ.
O ṣeeṣe ki ajakalẹ aarun coronavirus bẹ silẹ lorilẹede Naijiria fun igba keji- Ọjọgbọn Faduyile Ìwọ́de 'End SARS' lè tan àjàkálẹ̀ arùn coronavirus lẹ́ẹ̀kejì ní Nàìjíríà- Ọjọ̀gbọ́n Faduyile Alaga ajọ ẹgbẹ awọn dokita oniṣegun oyinbo tẹlẹ, Ọjọgbọn Francis Faduyile lo fidi ọrọ yii mulẹ fun BBC Yoruba.
ẹgbẹ̀ta megawati ina mona-mona lo ye ki a maa lo sugbon tipa-tipa ni won se maa n fun wa ni ọ́ọ̀dúnrún , ni eyi to si je pe ohun la n pin kaakiri”.
Wọ́n mú àwọn tó jẹ́rìí pẹ̀lú rẹ̀, wọ́n so wọ́n, wọ́n sì fi ìyà oró jẹ wọ́n pẹ̀lú rẹ̀.
Àwọn agbébọn pa Ọlọ́pàá 7 l'Abuja Àwọn Ọ̀tẹlẹ̀múyẹ́ ya wọ ilé ìwé girama l'Ekiti 'Àwọn SARS ló yìnbọn pa ìyá mi' Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Ipinlẹ Eko kọ ninu gbagede Ile Igbimọ Aṣofin naa.
" erékùṣù kọ ̀ ọ ̀ kan ní ọ ̀ nà ìsọ èdè ti wọn ọ ̀ tọ ̀ ọ ̀ tọ ̀ ; ti anjouan únjẹ ́ "" shindzuani "" , ti mohéli "" shimwali "" , ti mayotte "" shimaore "" , ati ti grande comore "" shingazija "" ."
Lebaotu, Ṣilihimu, Aini ati Rimoni; gbogbo ìlú ati ìletò wọn jẹ́ mọkandinlọgbọn.
Arsenal náà laná bí Manchester United Ayé le, ìbòsí ò!
O ni ere asapjude lo ṣokunfa eyi to pọju ninu ijamba ọkọ to ṣẹlẹ naa.
Amọṣa, ẹgbẹ oṣelu PDP ti ni ko si nnkan to jọọ rara ni nitori pe ọmọ ẹnii kii ṣe idi bẹbẹrẹ ka fi ilẹẹkẹ sidi ọmọ ẹlomiran.
O ni: ''Ẹtọ awọn ọmọ Naijiria ni lati beere fun nkan ti wọn fẹ lọwọ ijọba, ki wọn si ṣe fun wọn.
Ilupeju Killing: Àṣìta ìbọn pa ẹnìkan lásìkò t'ọ́lọ́pàá kojú adigunjalè
"Ẹ̀gbọ́n àdúgbò ni Asiwaju Tinubu jẹ si mi.
Lagos City Marathon: Sintayehu Legese láti Ethiopia ló jáwé olúborí
Marie Stopes ti ko awọn rọba to le ni miliọnu kan ti wọn ti kọkọ pin fawọn eeyan Uganda kuro nilẹ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù NYSC: Ọ̀gágun S.
Wo àwọn nkan tí ó yẹ kí o mọ̀ nípa Bitcoin, kí o tó ó dáwọ́ le e Tolulope Arotile: Ẹ wo ọgbọ́n tí wọ́n tò pọ̀ láti túfọ̀ ikú Tolu fún bàbá àti ìyá rẹ̀ Taa ni Ebila One Million Boys"" àti Ekugbemi, olórí ẹgbẹ́ òkùnkùn míì tó da ìlú Ibadan rú?"
O ni oun ko mọ ohun ti Garba Shehu n sọ pẹlu pe ọga agba ọlọpaa ni yoo ṣagbatẹru bi Amotekun yoo ti maa ṣiṣẹ, ayafi to ba jẹ pe ofin ọga ọlọpaa gaju ofin awọn ipinlẹ Yoruba lọ loku.
Ìyá Barakat fi ẹ̀mí ìmoore hàn sí gbogbo àwọn tó nawọ́ síi lẹ́yìn ikú ọmọ rẹ̀ Afurasí tí Ọlọ́pàá ní ó pa Barakat, Grace àtàwọn míì l'Akinyele ti sọ̀rọ̀ pé.
 indonésíà jẹ ́ orílẹ ̀ -èdè olómìnira , pẹ ̀ lú aṣòfin àti ààrẹ adìbòyàn .
Ẹni to bori: Tanzania Côte d'Ivoire vs Benin.
3 150353 Orilẹede Myanmar 2110 3.
ìwọ tí o ṣe iṣẹ́ abàmì, ati iṣẹ́ ìyanu ní ilẹ̀ Ijipti, o sì tún ń ṣe iṣẹ́ náà títí di òní ní Israẹli ati láàrin gbogbo eniyan; o sì ti fìdí orúkọ rẹ múlẹ̀ gẹ́gẹ́ bí ó ti rí lónìí.
Victoria ni baba oun fẹ ki oun kawe di dokita tabi agbẹjọro ni.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Atali Elimgbu community: Ọ̀lọ́pàá ní àbò ara ẹni ló mú ọlọ́páà pa ọdọ́ kan ní Port Harcourt 19 Ìgbé 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 20 Ìgbé 2019 Oríṣun àwòrán, YASUYOSHI CHIBA Àkọlé àwòrán, Ọlọpaa Naijiria Ohun gbogbo ko rọgbọ ni ilu Atali, ijọba ibilẹ Elimgbu ni ipinlẹ Rivers nibi ti awọn ara ilu fi ẹsun kan pe awọn ọlọpaa pa ọdọ kan ni ọjọbọ ọsẹ.
Bí o bá sì ń ṣubú ní ilẹ̀ tí ó tẹ́jú,báwo ni o óo ti ṣe nígbà tí o bá dé aṣálẹ̀ Jọdani?
Wawaye ni Ede Hausa ti awọn eniyan yii n sọ tumọ si pe omugọ ni wọn, awọn olugbe agbegbe naa ti wọn ba BBC sọrọ ni wi pe awọn eniyan maa n fi orukọ ilu naa bu awọn nigbakigba ti awọn ba jade.
 A o sa gbogbo ipa wa lati maa ri daju pe Ipinlẹ Eko n tẹ siwaju gẹgẹ bi ọrọ iwuri yin, ṣe yinyinni kẹni ṣe mii”.
Àwọn tí mo bá fẹ́ràn ni mò ń bá wí, àwọn ni mò ń tọ́ sọ́nà.
Michael Yemetu, mejeeji ni ilu Ibadan.
Ogbẹni Prince Wiro to jẹ alaga ajọ awọn ajijangbara nipinlẹ Rivers ni wọn ko gbọdọ fiya aitọ jẹ afurasi naa rara.
 a má a ńṣe ìtọ ́ jú ipele èkíní pẹ ̀ lú àwọn egbògi tí a ńpè ní pentamidine tàbí suramin .
Ṣugbọn lọjọ aiku ni Fayẹmi lọ si ọdọ Alaafin lati ni ijiroro pẹlu rẹ, eyi to ṣeeṣe ko jẹ lori ọrọ lẹta naa.
Nigeria, TCN ) lati pese ina mona-mona deede lorile ede yii.
Amọ orilẹede South Africa jẹ ọkan lara awọn orilẹede ti nkan o ti bara dọgba julọ lagbaye.
Nípa ìbáwí rẹ, Ọlọrun Jakọbu,ati ẹṣin, ati ẹni tó gun ẹṣin,gbogbo wọn ló ṣubú lulẹ̀, tí wọn kò sì lè mira.
Èyí ọkùnrin tí o jẹ́ àkọ́bí ni orúkọ rẹ̀ ń jẹ́ Ìṣubú.
Gẹgẹ bi alakalẹ ṣiṣi ile iwe ọhun ṣe lọ, awọn ọmọ ile iwe alakọbẹrẹ lati ipele kini si ikẹta yoo lọ ile iwe lati aago mẹjọ owurọ si mọkanla, nigba ti awọn to wa ni ipele kẹrin si ikẹfa yoo lọ lati aago mejila ọsan si aago mẹta.
Ṣaaju asiko yii lawọn ologun ti n sọ fun gomina naa pe awọn ti gba ilu Baga pada lọwọ awọn Boko haram ati pe awọn ti gba akoso ibẹ.
Gbogbo owo yii ni wọn fẹ ẹ kopọ lati yanju awọn gbese to wa lọrun ijọba.
Josẹfu bá dìde, ó gbé ọmọ náà ati ìyá rẹ̀ pada sí ilẹ̀ Israẹli.
Ṣugbọn ọba àwọn ará Amoni kò tilẹ̀ fetí sí iṣẹ́ tí Jẹfuta rán sí i rárá.
Awọn ohun to niiṣe pẹlu bi awọn araalu ṣe n pọ si, to fi mọ idagbasoke to n de ba awọn ileesẹ lasiko igba naa lo fa a lo ṣe atọkun fun idasilẹ rẹ.
À ń fẹ́ epo ọ̀fẹ́ tàbí gbà má bínú lọ́wọ́ ìjọba' 'À ń fẹ́ epo ọ̀fẹ́ tàbí gbà má bínú lọ́wọ́ ìjọba' Èyí ni àwọn ìdí tí INEC fi sún ìdìbò aarẹ síwájú O ṣafikun pe adinku naa yoo bẹrẹ lati ọjọ Aje ti ṣe ọjọ kejidinlogun Oṣu keji titi di ọjọ kejila Oṣu kẹta ọdun 2019.
"Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ẹ ṣetò ìbò gómìnà míràn ní Bayelsa kó tó di Nov - Adájọ́ pàṣẹ Ọlọ́pàá dóòlà ọkùnrin kan tí wọn so mọ́lẹ̀ fún ọdún mẹ́ẹ̀dógún Oríṣi ẹbu ìwé ìdánwò ìṣìrò mẹ́ta ló dọ́wọ́ wa, àmọ́ wọn fi ń lu jìbìtì ni - WAEC ""Àwa Emèrè Onítẹ̀síwájú la ṣèpàdé nílé Elebuibon, kìí ṣe Oṣó àti Àjẹ́"" Nǹkan wọ̀lú!"
O fi kun pe, aworan bi oun se ba ẹnu jẹ lọjọ igbeyawo, ti BBC Yoruba lo lori Facebook rẹ, ti ọpọ eeyan si n sọ ero ọkan wọn lori rẹ, ni oun ko mọ pe yoo rin jinna to bayii.
Awọn mejeeji tun jiroro lori ọrọ to nii se pẹlu eto ọrọ aje ati eto abo to kan awọn orile-ede mejeeji.
 wọ ́ n tún ń sọ èdè yìí ní turkey , syria àti afgloanistan .
“Wọ́n gbọdọ̀ kọ́ àwọn eniyan mi láti mọ ìyàtọ̀ láàrin àwọn nǹkan mímọ́ tí a yà sọ́tọ̀ ati àwọn nǹkan lásán.
Ọkọ̀ akẹ́rù gbàngbà kan sáré kọjá lẹ́gbẹ̀ẹ́ rẹ̀.
Hushpuppi: Ìròyìn sọ pé ó ṣiṣẹ́ olórin rí, ta àlòkù àṣọ àti Kọ̀ńpútà
Wọ́n kà á ninu àkọsílẹ̀ pé Modekai tú àṣírí Bigitana ati Tereṣi, àwọn ìwẹ̀fà meji tí wọn ń ṣọ́ ẹnu ọ̀nà ilé ọba, tí wọ́n dìtẹ̀ láti pa Ahasu-erusi ọba.
Oríṣun àwòrán, @Tallen Àkọlé àwòrán, Pauline ni obinrin akọkọ to jẹ igbakeji gomina ni ariwa Naijiria Pauline lo ṣe minista abẹle fun ileeṣẹ ijọba to n ri si imọ sayẹnsi ati imọ ẹrọ lọdun 2007.
Asunfọnfọn ni Anton Nguyen n sun lọwọ nile alaja-meji rẹ ni Brisbane, Queensland lasiko ti ina sadede ṣeyọ loru Ọjọru.
 Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fọ́nrán ohùn, iyonipo Sugbọn sibẹ Agbowu ni Oluwo na oun lalubolẹ, koda o ni igbakeji ọga agba ọlọpa lo wa gbe Oluwo dide lori oun, nigba ta si bi AIG, o ni oun ko fi ọwọ kan wọn, amọ ẹri to daju han pe lootọ ni Oluwo na Agbowu.
Ohun ti o mu ẹni ọgọta ọdun naa di ẹsọ ẹti okun ni wi pe, ti o ba lọ pa ẹja lodo, wọn ma n ri oku awọn eniyan ti yoo wa si eti okun.
ó sọ fún wọn pé, “Ẹ̀yin ni olórí ìdílé yín ninu ẹ̀yà Lefi.
Inú mi dùn fún bi ẹ ṣe gbàmi laaye láti sin ilẹ baba mi.
"Wọ́n fi kún ọ̀rọ̀ wọn pé ọ̀pọ̀lọpọ̀ ìpèníjà ni àwọn òṣìṣẹ́ ń kojú lórí àtijẹ-àtimu bó tilẹ̀ jẹ́ pé ""àwọn ọmọ ilé ìgbìmọ̀ aṣọ̀fin orílẹ̀-ede Nàìjíríà ló ń gbówó jùlọ l'ágbáyé."
Lara awon ti yoo wa nibi ajodun ayeye naa ni awon oludari ile-ise ijoba apapo, awon aare ana lorile ede yii, awon oba, awon asoju orile ede ile-okeere, minisita ati awon omo orile ede Naijiria.
Franklin tó jẹ́ ààrẹ ẹgbẹ́ tó n gbógun ti ìwà ìbàjẹ́, Global Society for Anti-Corruption (GSAC) sọ pé àwọn ti fi ọ̀rọ̀ Alàgbà Egbuchune tó ìjọba àti agbẹjọ́rò àgbà fún ìpínlẹ̀ Imo, Miletus Nlemedim létí, pé kí ìjọba f'oríji bàbá nàá, ṣùgbọ́n gómìnà Rochas Okorocha kò tìí buwọ́ lùú.
Ado oloro to bu gbamu ni agbegbe Howladag ni awọn osisẹ ijọba lagbegbe naa sọ fun BBC pe o se iku pa ọmọ ogun mẹta ti eeyan mẹrinla si farapa.
Koda, awọn ọmọ orilẹede Naijiria, paapaa julọ awọn ọdọ, ti n lo anfani naa lati ṣalaye akitiyan ati iyanju ti wọn n gba lati gbọ jijẹ mimu ara wọn.
Bakan naa ni ko le sọ igba ti ijọba yoo bẹrẹ si ni san owo naa, nitori pe eto ṣi n lọ.
Africa Eye: Coronavirus di adákẹ́jà ní Somalia, ikú ọ̀wọ́ọ̀wọ́ ń peléke si Èèyàn 555 míràn tún kó COVID-19 ní Nàìjíríà l'Ọ́jọ́ Aiku Ikú Barakat Bello ní Akinyele gbé aláàánú pàdé ẹ́bí rẹ̀ Wo ọ̀nà àbáyọ lọ́wọ́ súkẹrẹ fàkẹrẹ ọkọ̀ bí ìjọba ṣe ti afára 3rd Mainland Aafin ọba Edomwonyi Iduozee Ogiegbean, Enigie ti ilu Egbaen ni ipolongo idibo naa ti waye.
Ìran burúkú ati oníbọkúbọ ń wá àmì; ṣugbọn a kò ní fi àmì kan fún un, àfi àmì Jona.
Lizzy Anjorin gbàgbé ọ̀rọ̀ àná, ó kí Iyabo Ojo kú ọjọ́ ìbí, Femi Adebayo kọ ọmọ l'áṣà Kò sí ìjà láàrín èmi àti gómìnà Ọ̀ṣun - Aregbesola Wo bí àwọn obìnrin kan ṣe n sọ ara wọn di 'fágìn' lẹ́ẹ̀kejì Ẹ má gbàbọ̀de kankan láti tú Wolii ìjọ Sotitobire sílẹ̀ o!
Gomina naa tun kesi awọn ti o farakasa ijamba ina yi lati wa si ipade kan lọjọ Aje to n bọ lati le mọ bi ijọba yoo ti ṣe ṣe iranwọ fun wọn.
Heburoni bí ọmọ mẹrin: Kora, Tapua, Rekemu ati Ṣema.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, World Radio Day: Àwọn òṣìṣẹ́ rédíò ní àwọn ń pa ìsòro àwọn mọ́ra ni láti mú inú aráàlú dùn Ọdun mẹtala ni Okunnu fi gbe orilẹede Saudi Arabia, amọ o ni isẹ tiata ko gba oun laye lati wọ eyin Mecca, ati pe ọṣọ lasan ni eyin Mecca.
Ileeṣẹ redio kan, Cadena Ser lorilẹede Spain ti sọ pe adehun ọdun meji ni Manchester City fẹ ṣe pẹlu Messi ti wọn ba ti ra a tan lati Barcelona.
Gernot Rohr ni o kuna lati kopa ninu ipade apero naa latari ipade igbaradi idije boolu agbaye ti o lofun lorile-ede Russia.
Wo àwọn òṣìṣẹ́ kólẹ̀-kódọ̀tí tó ń fi ẹ̀mí wọn wéwu kí Abuja leè mọ́ tónítóní Mo ti bẹ̀rẹ̀ sí ń bá àwọn tí a jọ díje nínú ìdìbó abẹ́lé sọ̀rọ̀ kí àláàfíà léè jọba - Akeredolu Bayii, o ti ṣeeṣe fun ọ lati ba dokita rẹ sọrọ lori aisan rẹ lai de ile iwosan rara.
Ìdènà àrùn náà níí ṣe pẹ ̀ lú ìmọ ́ tótó , èyítí ó kan mímú ìlọsíwájú bá níní ànfàní sí ilé-ìyàgbẹ ́ àti dída ìgbẹ ́ nù ní ọ ̀ nà tí ó tọ ́ .
 ni 2006 , awon adugbo 28 tuntun je didasile eyi mu apapo iye awon adugbo de 138 .
O sọ siwaju pe awọn eeyan ilu naa n binu si ijọba lọwọ, paapaa julọ awọn oṣiṣẹ ileeṣẹ panapana latari bi wọn ṣe kuna lati tete pa ina ọhun.
Alakoṣo ijọ Redeem, alufa Enoch Adeboye lo sọ bẹẹ ninu iwaasu rẹ ninu isin ọjọ Aiku to pe akori rẹ ni ''ọna meje lati doju kọ oke.
Nígbà tí ó di ìrọ̀lẹ́, ó pa ọkà tí ó ṣà, ohun tí ó rí tó ìwọ̀n efa ọkà baali kan.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Wo àwọn ọ̀nà tí o lè gbà láti di ọjọ́ ogbó pẹ̀lú olólùfẹ́ rẹ Lara awọn ohun ti orin naa sọ ni pe: ''Ni orukọ Olorun, a bẹyin ki ẹ tẹti silẹ si awọn eniyan yin, a nilo iranlọwọ, Ariwa orilẹede Naijiria n sunkun/ Ẹjẹ ti wọn ta silẹ, awọn eniyan n ku/dukia si n bajẹ.
Ṣugbọn ọ̀nà ìyè há, ẹnu ọ̀nà rẹ̀ sì fún.
eleyi ti ajọ eleto idibo Naijiria kede.
Inu aṣọ yii ni Ajax wa to fi na Panathinaikos ni Wembley pẹlu ami meji soodo.
“Ṣé o óo ṣe ìdájọ́ wọn?
” (Ìdí nìyí tí wọ́n fi ń wí pé, “Àwọn afọ́jú ati àwọn arọ kò ní lè wọ ilé OLUWA.
Nígbà tí Pilatu gbọ́ bẹ́ẹ̀, ó mú Jesu jáde, ó wá jókòó lórí pèpéle ìdájọ́ níbìkan tí wọn ń pè ní “Pèpéle olókùúta,” tí ń jẹ́ “Gabata” ní èdè Heberu.
Obasanjo salaye pe, bi eto isinku ọhun ṣe bẹrẹ ni agogo mẹwa owurọ ni ijọ Saint Peters Anglican Church to wa ni Isara-Remo, ni ipinlẹ Ogun, ni oun funra oun ti ilẹkun ile ijọsin ọhun, ki awọn eniyan ma ba raye wọle.
Amọ, wọn fi gba kan sọ fun BBC wipe wọn ti fẹrẹ mu olori ikọ Boko Haram ki oto di wipe wọn se ikọlu tuntun yii.
Oríṣun àwòrán, others Bo tile je pe wọn ko ribi gba àmì ẹ̀yẹ láwọn ìdíje agbaye ti won ti kopa, orukọ wọn kò ní parẹ nínú ìtàn ilẹ wọn.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Awọn ọmọ Nàìjíríà bá aarẹ Buhari sọ̀rọ̀ lójú òpó BBC lórí ètò ààbò ìlú 1 Sẹ́rẹ́ 2020 Àkọlé àwòrán, Awọn ọmọ Nàìjíríà bá aarẹ Buhari sọ̀rọ̀ lójú òpó BBC lórí ètò ààbò ìlú Ẹ̀kọ́ ọ̀fẹ́, ètò ìlera ọ̀fẹ́, ọ̀pọ̀ ounjẹ, ìpèsè iṣẹ́, ìná ọba to duro déédé, àabò ẹmi àti dukia ní o jẹ́ orí nínú lẹ́ta ti àwọn ọmọ Naijira kọ sí àarẹ Muhammadu Buhari.
omo ti ko si nile iwe lorile ede yii.
pelu iko olote boko haram gege bi ogun ti o tonka.
Ẹwẹ, lara awọn idahun ti Kemi gba lori ọrọ to fi sita ni ti obinrin kan to ṣalaye pe Kemi kan n dibọn bii pe ọwọ rẹ mọ ni.
Oríṣun àwòrán, Sylvester Ofori/Facebook Lọsu to kọja ni iroyin gbode pe Pasitọ yi yinbọn lu iyawo rẹ niwaju ọfisi arabinrin naa ni ilu Orlando Florida gẹgẹ bi awọn ọlọpaa Amẹrika ti ṣe wi pe Kí ìjọ mi ní Sagamu le gbòòrò ni mo fi ń ṣiṣẹ́ ajínigbé pawó - Pásítọ̀ Ọlọ́pàá fẹ̀sùn ìpànìyàn kan ìyawo olóòtú ilẹ̀ Lesotho pé ó pa ìyáálé rẹ̀ Ọkùnrin tó pa ìyàwó rẹ̀ tí gba ìdájọ́ ikú Obìnrin bíi Ruth Bader ni yóò gba ipò rẹ́ ní iléẹjọ́ tó gajùlọ nílẹ̀ Amerika- Donald Trump Sophia Tommey, to jẹ ọmọ iya oloogbe naa ṣalaye pe Sylvester binu pa iyawo rẹ nitori pe o bẹrẹ eto lati kọ silẹ.
Child Mortality in Nigeria: Ìyanṣẹ́lódì àwọn Nọ́ọ̀sì ṣé àkóbá, ìkókó mẹ́jọ kù níléèwòsàn lalẹ ọjọ́ kàn
Ninu ọrọ idagbere rẹ lo ti sọ eyi nibi eto idagbere ti ile aṣofin saa kẹjọ ṣe ni ọjọbọ.
Wọn ko awọn kaadi ti wọn kọ oririṣiriṣi akọle si, eyii ti wọn fi n bu ẹnu atẹ lu ele ori owo naa.
A Aderinto kọ ranṣẹ si awọn obi saaju iwọlẹ naa, o dupẹ lọwọ wọn fun ọgbọn, oye ati suuru ti wọn mu lo lasiko ti aawọ naa waye.
Nibayii, ilumọọka osere tiata mii, Iyabo Ojo, naa tun ti bọ soju opo ayelujara rẹ pẹlu ileri tuntun.
Oríṣun àwòrán, Getty Images O ni kaka ki wọn gbọ imọran Obasanjo, radarada ni ijọba aarẹ Buhari n ba kaakiri.
lowo  rẹ pe , se yoo ki eni to ba jawe  olubori ku ori-ire ti ko ba yege ninu idibo
O salaye pe, “Gege bi a se n reti lati fi iroyin kan mule lori awon omode-binrin marun ti won ti gbemi mi,  ajo UNICEF ba awon ebi ti won padanu awon omo won kedun gidi-gidi,  bakan naa ni a gboriyin fun akitiyan awon ti won gbiyanju ati ri pe, awon omode-binrin yii pada sodo awon molebi won layo ati alaafia”.
Olori naa ni oun pinnu lati rọra kuro ninu aafin lai pariwo, ki oun le wa nile aye lati ṣe iya awọn ọmọ oun ni.
12) Ma ṣe lo batiri rẹ de ibi pe o maa ku patapata to jẹ ida odo ninu ọgọrun un tabi koo maa fi sina si ida ọgọrun un nigba gbogbo.
Nítorí ikú ni òfin tí a kọ sílẹ̀ ń mú wá, ṣugbọn majẹmu ti Ẹ̀mí ń sọ eniyan di alààyè.
" Ìdẹ̀ra dé, Gẹnẹrátọ̀ tó ń lo omi dé, a bọ́ lọ́wọ́ òkùnkùn Ìkúnlẹ̀ àbiyamọ o!
Mo ní àwọn ọmọ-ogun lábẹ́ mi.
 Bakan naa ni Lizzy fẹ ki araye mọ pe oun si ni obinrin osere tiata to lowo julọ ni Naijiria nitori pe kii fi bo rara pe ko si akẹẹgbẹ oun kankan ti o ni dukia ti oun ni, tabi ti Ọba oke kẹ ju oun lọ."
Nígbà tí ó pada sókè, ó gé burẹdi, ó jẹun.
ki igbesẹ wa ni kiakia lati dẹkun iwa ikọlu ajoji
"Ọkùnrin kan tó yasó nínú ọkọ̀ Uber rí ẹ̀wọn he Ẹ wo èrò bìbà níbi ìwọ́de #EndSARS ní ìlú Ibadan Mọ̀ nípa iPhone 12, fóònù ológo 5G tí kìí lo ""Charger” tó ṣẹ̀ṣẹ̀ jáde Wo diẹ lara awọn to fi adun ati aṣeyọri si iwọde End SARS naa to n lọ lọwọ: 1."
OLUWA ní, “Mo fẹ́ràn yín pupọ.
 Adele aare, Ojogbon Yemi Osinbajo lo soro yii lasiko ti o n jiroro pelu awon eniyan orile-ede yii pelu awon osise ijoba loni ojo Ru ni gbongan Conference Centre, nilu Abuja to je olu-ilu Naijiria.
Ajọ to n ṣeto idanwo WAEC sọ pe esi idanwo akẹkọọ to le ni ẹgbẹrun lọna igba (215, 149) to ṣe idanwo ọdun 2020, ni oun gbẹsẹ le.
yan awọn ọmọ igbimọ yii, lẹyi ti Ile Igbimọ Aṣofin Ipinlẹ Eko ba ti fọwọ
Aare wa pe akiyesi awon ile-ise to n
Àṣírí ńlá tó ń bẹ láàrín Alaafin àtàwọn onílù rẹ̀ rèé Trump kò yẹ láti jẹ́ ààrẹ lásìkò yìí, èèyàn kò le fi mọ̀kàrúrù ṣe ààrẹ - Michelle Obama Oyedepo àti ìjọba ń tahùn síra lórí bí ìjọba ṣe ń gba àkóso àwọn ilé ìjọsìn EFCC tún gbé Mompha lórí ẹ̀ṣùn lílu jìbìtì lórí ayélujára Agbẹnusọ fun ijọba orilẹede Malli, Yaya Sangaré ṣalaye fun BBC pe aarẹ Keita, olotu ijọba orilẹede naa, Boubou Cissé, ọmọ rẹ, ati igbakeji rẹ ni wọn mu.
Fehmi Lassoued aati Anabel Salipada ni awon olopaa mu losu ti o koja nile re ti ko jina si embassy Amerika ni Manila, ti awon olopaa si so pe, won ba orisirisi ohun ija oloro nikawo awon mejeeji.
Àjakalẹ-àrun kejì to tún gbaju gbaja ni ibà Maáwú-maáwú, tí wọn ń pè ní Plague of Justinian àbí Black death: Iba yìí ló máa ń mú àwọn èèyàn ni otútù, tí abiya, koropọn ati ẹyin etí wọn yóò sì máa wù.
Iroyin ni igbesẹ naa waye lati ri pe Onnoghen ko ri aye wọ ofiisi naa nigbakugba.
Kò tọ́ sí Ọlọ́pàá láti ti ọmọ mi mọ́lé tórí ore tó ṣe lásìkò ìwọ́de EndSARS!
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Cancer: Àṣe ara mi ni iso ti n run gbogbo bí mo ṣe n ṣèrànwọ́ lórí jẹjẹrẹ Yemi Osinbajọ ti ya ara rẹ̀ sọ́tọ̀ fún àyẹ̀wò àrùn Coronavirus Igbesẹ yi lo n waye lẹyin ti amugbalẹgbẹ aarẹ Muhammadu Buhari, Abba Kyari fara kaasa arun naa.
Oríṣun àwòrán, Twitter Igba to wa ni ọmọ ọdun merinlelogun lọdun 1962, lo darapọ mọ ajọ isọkan agbaye, UN, gẹgẹbi oṣiṣe ajọ agbaye to n ri si eto ilera (WHO).
“Bí arakunrin rẹ, tí ń gbé tòsí rẹ bá di aláìní, tí ó sì ta ara rẹ̀ fún ọ, o kò gbọdọ̀ mú un sìn bí ẹrú.
Wọ́n dàbí ìgbà tí atẹ́gùn gbígbóná ìlà oòrùnbá fẹ́ lu koríko tabi ewéko tí ó hù ní orí òrùlé.
Kò sí ẹni tí ó lè fi agbára mú un kí ó fi ara balẹ̀.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Kò sí oúnjẹ Nàìjá tí a ò sè ní Kenya' Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Yinka Ayefẹlẹ, lasiko to n sọrọ lori redio ọhun, Fresh FM, to bẹrẹ isẹ pada lẹyin wakatai meji ti ijọba wo ile naa, rọ awọn araalu to n se atilẹyin fun-un, lati mase da rogbodiyan kankan silẹ lori isẹlẹ naa.
Wọn óo rí ayọ̀ ati ìdùnnú gbàìbànújẹ́ ati òṣé yóo sá kúrò níbẹ̀.
Ó tún sọ pé,“Èmi ní tèmi, èmi óo gbẹ́kẹ̀lé e.
Ẹyin ero, e dẹkun ẹjọ rirọ ninu mọto pẹlu dirẹba awakọ ni imọran ti ajọ FRSC n ke tantan Iru awọn iroyin ti ẹ le nifẹ si: 'Mo kan sara sawọn ayasọlo' Ẹ wo ọdọmọde olorin, Megabyte Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí 2 sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 2:23 Fídíò, Water Generator: Ó leè ṣiṣẹ fún wákàtí mẹfà, kó tó sinmi, Duration 2,2310 Òkùdu 2020 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
Nítorí náà, ẹ gbọdọ̀ ṣọ́ra kí ẹ sì máa pa òfin rẹ̀ mọ́, kí ẹ sì tẹ̀lé ìlànà ati ìdájọ́ rẹ̀ tí mo fun yín lónìí.
Ni asiko ti a n ri ọpọlọpọ awọn arugbo ni igboro ti wọn n ṣagbe, a ri iya ti ọkan lara awọn ọmọ rẹ woo pe ẹwa rẹ ṣi lee ṣe anfani fun awujọ ati iwuri fun ọpọ awọn obinrin lode oni.
Ẹ má ṣe bá àwọn tí ó ń ṣiṣẹ́ òkùnkùn tí kò léso rere kẹ́gbẹ́.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Shiloh 2020: Oyedepo ní òun kò le tòṣì láéláé!
Ọlọ́pàá gbé àwọn tó yìnbọn lu olólùfẹ́ ní Ajegunle Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Segalink:ìkùnsínú pọ̀ láàrin àwọn agbófinró bẹ́ẹ̀ wọn kò ni agbẹnusọ Adari Ajọ 'Climate and Sustainable Development Network' ni ọpọlọpọ awọn orilẹ-ede ni ilẹ Afirika bii Côte d'Ivoire, Cameroon, Mauritania, Tunisia, Kenya, Uganda, Rwanda, Tanzania, Morocco ati South Africa lo ti gba lati f'opin si lilo ike rọba ati ipenija rẹ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ode/Isinigbo land Crisis: Ìjọba ìpínlẹ̀ Ondo kéde òfin konile-o-gbele ní Ode ati Ishinigbo 11 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Oríṣun àwòrán, Paradisenews Ijọba ipinlẹ Ondo ti kede ofin konile-o-gbele oni wakati mẹrinlelogun ni ilu Ode ati Ishinigbo, to wa ni ijọba ibilẹ Ariwa Akure.
Mahili ati Muṣi láti inú ìdílé Merari.
Gomina ipinlẹ Oyo ni ijọba n ṣiṣẹ lati rii pe ajọṣepọ to dan mọran wa si laarin ile iwosan UCH ati ile iwosan ajakalẹ arun to wa ni Olodo n'Ibadan.
Ìyá dú ọmọ rẹ̀, o yíi láta, ó sì tún jòkó jẹ ẹ́ Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
14 Agẹmo 2020 Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ondo 2020: Tani ìgbìmọ̀ tó ń sàyẹ̀wò olùdíjẹ lábẹ́ APC nípínlẹ̀ Ondo yọ kúro gan-an?
” Wọ́n bá ṣe bí ó ti wí.
Ajọ LASEMA naa ṣalaye pe ojo arọọrọda naa wa lara afojusun ẹka to n risi ọrọ oju ọjọ ni Naijiria, NIMET to fi lede pe ojo to to 240 si 270 ni yoo rọ nipinlẹ Eko ti yoo si fa omiyale agbara ya sọọbu.
Àkọlé àwòrán, Ọkan lara amuyẹ ẹgbẹ okunkun Buccaneers ni pe wọn maa n ṣe faaji rẹpẹtẹ Ọpọ igba si ni ija orogún ma n waye laarin awọn ẹgbẹ okunkun, eyi to ma n mu itajẹ silẹ dani nigba miran.
''A dupẹ fun ipadabọ ọmọ wa Yusuf loni lẹyin itọju nilẹ okeere, Minista fun eto ilera lo pade rẹ ni papakọ ofurufu'' Ikede na ko darukọ ibi ti Yusuf ti lọ gba itọju.
Ẹnikẹ́ni tí ó bá jẹ́wọ́ pé Ọmọ Ọlọrun ni Jesu, Ọlọrun ń gbé inú rẹ̀, òun náà sì ń gbé inú Ọlọrun.
O so eyi di mimo fawon oniroyin ni Maiduguri nipinle Borno to je okan lara awon ipinle ti ogun boko haram ba finra julo lati opo odun seyin.
“Ẹ̀yin ará Hasori, ẹ sá,ẹ lọ jìnnà réré, kí ẹ sì máa gbé inú ọ̀gbun.
Elisuri ọmọ Ṣedeuri ni olórí wọn.
Mo fẹ́ di obinrin to dára júlọ lágbàyé-Bobrisky ’Awọn sọja Cameroun tu mi sihoho' Wo ìdí tí Tẹni, ọ̀dọ́mọdé olórin obìnrin kìí fi ń ṣí ìhòhò rẹ silẹ̀ Iriri yii lo mu ki arabinrin Mumbi di agbẹnusọ ati ajafẹtọ fawọn obinrin, ti wọn ko foju jọ obinrin tabi ti wọn ni aleebu lara.
 Ó gba ilẹ ̀ tí wọ ́ n pín fún un , ó sì sọ ọ ́ di dandan fún àwọn ẹ ̀ gbọ ́ n rẹ ̀ láti máa san ìsákọ ́ lẹ ̀ lórí ilẹ ̀ náà .
''Mo ti fi orukọ mi lelẹ ṣaaju ki ere Eran Iya Oṣogbo to jade.
"Bakan naa lo tun ṣafihan èsì wọn lori ibeere marun un to ṣafihan ""igbagbọ wọn ninu sayẹnsi"" si kekere, giga ati eyi to wa laarin Giga O wa laarin Kekere Mi kò ni èrò kankan Giga O wa laarin Kekere Mi kò ni èrò kankan Orisun: Wellcome Global Monitor, Gallup World Poll 2018 Ma binu, ko si akọsilẹ fun ibi yii Gbiyanju ẹ lẹẹkan sii."
” Oludari ohun, Dokita Abari salaye ipa pataki awon osise ijoba ni ibamu pelu erongba aare Muhammadu Buhari.
Bakan naa ni minisita fọrọ ilẹ okeere ni Iran, Javad Zarif pẹlu ti ṣalaye loju opo Twitter pe awọn fi ikọlu naa daabo bo ara awọn ni o kii ṣe pe awọn fẹ fi fẹ wahala naa loju sii.
Ibadan: Oluwapọ̀nmile sọ ìrírí rẹ̀ lọ́wọ́ àwọn sójà tó fìyàjẹ́ ní Ibadan
Ṣé pẹ̀lẹ́-pẹ̀lẹ́ ni ìṣe àgbà, òun ni ijó ọba.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Wo àṣírí tó gbé ìgbéyàwó Remi àti Bola Tinubu dúró bó tilẹ̀ jẹ́ pé ẹ̀sìn wọn yàtọ̀ 28 Owewe 2020 Oríṣun àwòrán, MOtherhood-in-style Iyawo Aṣiwaju ẹgbẹ oṣelu APC, Bola Tinubu, Oluremi Tinubu ti sọ pe iṣoro iyandaagbe lo sọ oun di ẹlẹsin Kristiẹni tootọ.
Ṣùgbọ́n ìrírí mi bí wọ́n ṣe ń rí mi bíi atọ̀húnrìnwá ti jẹ́ kí n ní ìmọ̀ nípa àṣà àwọn èèyàn mi: àṣà Tibet.
Bakan naa, lara awon eyan jankanjankan ti o kopa ninu ipade ohun, ni Gomina ipinle Eko, ogbeni Akinwunmi Ambode, ti o si tun jeje pe ijoba oun yoo tun mu igberu ba ere-idaraya ati paapajulo boolu afesegba lapapo.
Gbogbo wa ló ti mú aporó tí Baba-Onírùngbọ̀n yẹukẹ ti fi fún wa.
Ẹka igbani nimọran Awọn to wa ninu ẹgbẹ yii lo ma n gba awọn ọmọ ni imọran lori lori ohunkohun ti wọn ba n la kọja.
Ọpọlọpọ àwọn obinrin àjèjì ni Solomoni fẹ́, lẹ́yìn ọmọ Farao, ọba Ijipti, tí ó kọ́kọ́ fẹ́, ó tún fẹ́ ará Moabu ati ará Amoni, ará Edomu ati ará Sidoni, ati ará Hiti.
Ṣugbọn kí ó fihàn pé ọmọ obinrin tí òun kò fẹ́ràn yìí ni àkọ́bí òun, kí ó sì fún un ní ogún tí ó tọ́ sí i ninu ohun ìní rẹ̀.
Ọlọ́pàá gbé Samuel Ogundipe lọ ilé ẹjọ́ O fi ẹsun kan kọmisana naa pe o sọ̀ fun ileeṣẹ redio naa lati da awọn eto kan 'to n tọka si awọn nkan ti ko dara ninu eto iṣakoso ijọba Gomina Abiola Ajimọbi.
Bẹẹ naa ni ikọlu awọn agbesunmọmi, ajinigbe ati ija awọn ẹkun Naija-Delta n ṣẹlẹ.
Ó bá tẹ̀lé wọn wọ inú Tẹmpili; ó ń rìn, ó ń fò sókè, ó sì ń yin Ọlọrun.
Lati igba ti iṣẹlẹ naa ti waye ni ijọba ati ikọ alatako ti Khalifa Haftar n dari ti n di ẹbi ru ara wọn.
Oríṣun àwòrán, @odolz Bi o tilẹ jẹ pe ko si ẹni to tii le sọ ẹkunrẹrẹ iroyin nipa iku rẹ lori ayelujara, amọ awọn kan ni asita ibọn lo lọ ya ba Oke ninu ile, ẹni to si wa loju opo Twitter titi di aago meji ku isẹju mẹfa lọsan Ọjọru.
"Ko si ohun to kan awa Afenifere nibẹ"" A ti kọkọ mu iroyin naa wa wi pe, ẹgbẹ Afẹnifẹre beere nibi ipade naa idi ti Buhari ṣe yọ Adajọ agba ana ni Naijiria, Walter Onnoghen niṣẹ."
 Àìsàn náà sì máa n lọ pátápátá láì ṣe àkóbá fún ẹ ̀ dọ ̀ .
Akinyele: Ẹ wo àwọn ọ̀rọ̀ ìkẹyìn tí Alexander Akinyele ṣo kọ́lọ́jọ́ tó dé
Ó ní bí Hesekaya bá ní OLUWA Ọlọrun wọn yóo gbà wọ́n lọ́wọ́ òun ọba Asiria, ó ń ṣì wọ́n lọ́nà ni, ó fẹ́ kí òùngbẹ ati ebi pa wọ́n kú ni.
Èké àti irọ́ wọn ti sú àwọn èèyàn.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Gbajugbaja osere, Yemi Elesho ti sọ iriri reki o to di ilumọọka ni ẹka amuludun Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Gbajugbaja osere, Yemi Elesho ti sọ iriri reki o to di ilumọọka ni ẹka amuludun 25 Ìgbé 2020 Gbajugbaja osere, Yemi Elesho ti ni baba oun ko ṣe faramọ pe ki oun ṣe ere cinema ki oun to lọ si ile iwe giga.
Bí ayé ti rí ni èyí, ìwọ ọ̀rẹ́ mi.
ki a daabo bo oArabinrin .
Ijọba naa si fi aṣẹ si i.
Ó pẹ́ níbi tí ó lọ.
Bakan naa lo rọ awọn araalu lati mọ daju wi pe isẹde naa kii ṣe lati fi aye ni awọn eniyan lara, amọ ki alaafia le jọba ni.
Oríṣun àwòrán, Allwell Ene Onikẹkẹ Maruwa naa ni wọn sọ pe iyawo rẹ bimọ ni ọjọ meji sẹyin, ti wọn si ti gbe oku ọkunrin naa lọ sagọ ọlọpaa to wa ni Rumuokoro.
Oríṣun àwòrán, other Àkọlé àwòrán, O tun ni wọn maa n ṣafihan awọn nkan to le fa wahala lawujọ ninu eto araarọ wọn ti wọn pe ni Kakaki Social.
Ẹnu mi yóo sọ̀rọ̀ ọgbọ́n;àṣàrò ọkàn mi yóo sì jẹ́ ti òye.
Funke Akindele fún mi lówó tí mo fi gba ilé, kò ra ilé fún mi o - Ajirebi Mínísítà fún ọ̀dọ́ àti eré ìdárayá tí fi ẹ̀bùn owó ránṣẹ́ si ìyá Kausara, ó tún jẹ́jẹ̀ẹ́ ẹ̀kọ́ ọ̀fẹ́ f'áwọn ọmọ rẹ̀ Nigba to n ki awọn alaṣẹ ẹgbẹ oṣelu PDP fun atilẹyin niwọn igba ranpẹ ti o fi jẹ ọmọ ẹgbẹ naa, Ajayi ni oun gbe igbesẹ lati fi ẹgbẹ naa silẹ nitori awọn eeyan ipinlẹ Ondo fẹ ki oun dije fun ipo gomina ninu ibo to n bọ.
Revolution Protest: Wámú-wámú ni àwọn òsìsẹ́ aláàbò dúró nibí tí ìwọ́de Revolution Now ti fẹ́ wáyé
Ọwọ mi mọ, mi o si bẹru ẹsun kankan bi o ti wu ki o ri.
Afẹsunkan naa sọ fun awọn ọlọpaa wipe oun ko mọọmọ pa baba oun.
Ijọba orilẹ-ede Mali ti ke gbajare fun gbogbo agbaye lori ikọlu to n ṣẹlẹ ni ẹkun Mpoti.
Bi isẹlẹ yii ba si se n tẹsiwaju, nileesẹ BBC Yoruba yoo maa mu wa fun yin.
Ọga agba ajọ FRSC Ọmọwe Boboye Oyeyẹmi lo fọrọ naa lede lọjọ Satide nigba to ṣabẹwo silu Ibadan lati rii pe ko si idiwọ kankan fun lilọ-bibọ ọkọ kaakiri orilẹede Naijira.
Wo bóo ṣe lè mọ̀ ayédèrú Wo bí ètò ìsìnkú Tolulope Arotilẹ yóò ṣe lọ nílùú Abuja lọ́sẹ̀ tó ń bọ̀ Lizzy Anjori ṣèyàwó, àwọn òṣèré púpọ̀ ṣọjọ́ ìbí f'ọ́mọ lọ́sẹ̀ yìí Ni ọjọ Ẹti nileeṣẹ ọlọpaa fi oju awọn afurasi kan han lolu ileeṣẹ ọlọpaa ni ipinlẹ Ọyọ to wa lagbegbe Ẹlẹyẹle.
Ó na mọ ́ lúbí àkọ ́ kọ ́ si mi .
Ọwọ́ ọlọ́pàá ti tẹ àwọn ọmọbìrin méjì tó pa b[pabá wọn
Ní ọjọ́ keji, Mose jókòó, ó bẹ̀rẹ̀ sí ṣe ìdájọ́ fún àwọn ọmọ Israẹli, àwọn eniyan wà lọ́dọ̀ rẹ̀ láti òwúrọ̀ títí di àṣáálẹ́.
Obasanjọ kò kábáàmọ̀ ọ̀rọ̀ rẹ̀ lẹ́yìn ikú Kashamu- Kehinde Akinyemi 53712017Ìwà Bashorun Gaa ni Obaseki hù ní ipínlẹ̀ Edo -Tinubu Òwò mẹ́wàá tí yóò pàdánù àìsí ìpéjọpọ̀ ńlá RCCG lọ́dún yìí Wo iye àwọn ilé ìjọsin ìlú Eko ti wọ ko ni ṣí ìlẹ̀kùn ilé ìjọisin wọ́n lẹ́yìn ti ìjọba ti ni wọ́n le máa jọ́sìn Iru igbesẹ yii wo ni ipinlẹ Eko gbe ṣaaju asiko yii?
Ṣugbọn bí o bá gbeyawo, kì í ṣe ẹ̀ṣẹ̀.
” Juda bá kó wọn fún un, ó sì bá a lòpọ̀, Tamari sì lóyún.
Ẹni tí yóo bá jẹ́ ẹni tí ó ṣe pataki jùlọ ninu yín níláti dàbí ọmọ tí ó kéré jùlọ.
Ijọba Naijiria fidiẹ mulẹ pé Ogagun Tukur Buratai ṣi ni o n ṣiṣẹ adari awọn ọmọ ogun Naijiria lọ ati pe Ogagun Lamidi Adeosun yoo ṣi tẹsiwaju ninu ṣiṣe adari ẹka ikọni awọn ọmọ ogun ilẹ̀.
pe oun lo n fi ara rẹ han gẹgẹ bi Chri Dan ẹni ogoji ọdun (40) lati ilu Britain
“Bí mo ti ń wò ó, mo rí i ti ìwo yìí ń bá àwọn eniyan mímọ́ jà, tí ó sì ń ṣẹgun wọn, 
Ọkunrin náà fọwọ́ lẹ́rán, ó ń wò pé bóyá lóòótọ́ ni OLUWA ti ṣe ọ̀nà òun ní rere ni tabi bẹ́ẹ̀ kọ́.
" Ileesẹ naa se afikun wi pe awọn onimọ-ẹrọ ati ajọ to n se amojuto lilọ-bibọ awọn ọkọ-ofuurufu ni Naijiria se ayẹwo fini-fini lori baalu naa ki o to o gbera, wọn ko si ri ami iyọnu kan-kan.
Boko Haram kọlu abule Kofa ni Maiduguri O kere tan eniyan kan ti padanu ẹmi ti ọpọlọpọ miran si ti f'arapa ninu ibugbamu ikọlu Boko Haram n'ipinlẹ Borno.
A kò tíì gbọ́ nípa ikú aṣòfin Ayeọla -INEC US Shut down: Embassy Nàìjíríà kógbá nílé Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Alapinni Oosa ṣàdúrà fún gogbo ọmọ kúoótù, oò jíire bí?
Tí ó mú ọmọ ẹnìkejì rẹ̀ sìn lọ́fẹ̀ẹ́,láìsan owó iṣẹ́ rẹ̀ fún un.
Ọgbẹni Peter Njonjo to jẹ aarẹ ileeṣẹ Coca cola lẹkun iwọ oorun ilẹ Afirika, lo ko ikọ FIFA sodi lọ si ilu Eko.
- iléeṣẹ́ ológun kìlọ̀ Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí #ENDSARS: Àṣìta ìbọn ọlọ́pàá ló sọ mọ̀lẹ́bí mi, Adenike di báyìí, wọn ò bí i bẹ́ẹ̀, EndSARS ni dandan o- Toyin Abraham16 Ọ̀wàrà 2020 Alaafin Oyo: Kí ló ń ṣẹlẹ̀ láàfin Oyo táwọn èèyàn fi ń ki Alaafin ní mẹ́sàn án mẹ́wàá?
Oríṣun àwòrán, @ahmedMusa718 Àkọlé àwòrán, iya ni wura iyebiye Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, ìpàdé ìtagbangba ìfọ̀rọ̀wánilẹ́nuwò pẹ̀lú àwọn olùdíje sípò gomina ní ìpínlẹ̀ Eko.
Lẹ́yìn náà, Jehu pe gbogbo àwọn ará Samaria jọ, ó sọ fún wọn pé, “Ahabu sin oriṣa Baali díẹ̀, ṣugbọn n óo sìn ín lọpọlọpọ.
O ni awọn agbofinro ti bẹrẹ iwadii ni kikun lori ohun to fa iṣẹlẹ naa ati idi ti wọn ṣe gba ẹmi ẹni ọdun mẹtadinlogun ọhun.
Bẹ́ẹ̀ náà ló rí ní àkókò yìí, àwọn kan kù tí Ọlọrun yàn nítorí oore-ọ̀fẹ́ rẹ̀.
 Oríṣun àwòrán, The park Management Oyo State Auxiliary tun ni oun ko ni faramọ iwakiwa to le ta epo si aṣọ aala awọn, tabi ba iṣẹ rere tawọn ti n tiraka lati ṣe jẹ lati ipasẹ iwa idaluru."
Nítorí náà, Hanuni mú àwọn oníṣẹ́ Dafidi, ó fá irùngbọ̀n wọn, ó gé ẹ̀wù wọn ní ìbàdí, ó sì lé wọn jáde.
 gírámà yìí sàlàyé gbólóhùn oónna , gbólóhùn ti ó jé àdàpè ara won abbl .
ìwọ tí ooru mú nígbà tí ayé dákẹ́ rọ́rọ́nítorí pé afẹ́fẹ́ ìhà gúsù kò fẹ́?
Awọn ohun jijẹ ni ilu mọ iya naa fun nigba ṣango ode rẹ ti ko si si ẹni ti ko fẹrẹ maa mọọ ni ọja Itaakọgun, Ọja titun atawọn ọja miran ni ilu Ile Ifẹ ati agbegbe rẹ.
Ìwọ̀n wúrà tí Solomoni ń rí ní ọdọọdún jẹ́ ọtalelẹgbẹta ó lé mẹfa (666) talẹnti (kilogiramu 23,000), 
paapaa ti wọn koju iwa ikọlu
"Ileesẹ naa maa n sapejuwe ara rẹ gẹgẹ bi ""akọṣẹmọṣẹ ninu ka bani seto iwe irinna ati pasipọọti ilẹ okeere ni Naijiria"", pẹlu ajọsepọ awọn ileesẹ aṣoju orilẹ-ede l'agbaye, lati seto irinna silẹ okeere lai mu inira dani rara."
Ẹnìkan tí ó ní àrùn ẹ̀tẹ̀ wá sí ọ̀dọ̀ rẹ̀, ó kúnlẹ̀ níwájú rẹ̀, ó ń bẹ̀ ẹ́ pé, “Bí o bá fẹ́, o lè sọ ara mi di mímọ́.
Oludari agba nile-iwosan ijọba apapọ to wa nipinlẹ Kogi, Dokita Olatunde Alabi sọ pe gbogbo awọn to wa labe itọju ni wọn ti ya sọtọ fun itọju, nitori wọn ni ifarakanra pẹlu Dokita to dologbe naa.
Wo ohun tó yẹ kí o mọ̀ nípa akínkanjú obìnrin alága àjọ elétò ìdìbò Ghana 2020 4.
Buhari wa fi ẹmi imoore rẹ han si awọn akẹẹgbẹ rẹ ninu ajọ Ecowas, ti wọn kọ lati faramọ bi oun se faake kọri lati gba ipo naa nigba ti wọn kọkọ fi ipinnu wọn ọhun to oun leti.
O salaye pe, asa ati ise wa ni pipolongo ounje, eyi ti o je nipase eto ogbin, a n fe awon ologbon ati oloye eniyan jake-jado awon orile-ede nile Afrika.
“Gbogbo àwọn Juu ni wọ́n mọ̀ bí mo ti lo ìgbésí ayé mi láti ìbẹ̀rẹ̀ ní ìgbà èwe mi nígbà tí mò ń gbé Jerusalẹmu láàrin àwọn ọmọ orílẹ̀-èdè wa.
Chelsea: Sarri ní Eden Hazard lè lọ tó bá fẹ́ lọ
Ilẹ̀ dáradára tí wọ́n fi sílẹ̀ di ahoro, tóbẹ́ẹ̀ tí kò sí ẹnikẹ́ni níbẹ̀ mọ́.
7 Ògún 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
O tun gbosuba fun aare nipa awon ise ribi ribi ti o se paapaa julo lori ise akanse ti oju popo lati  Abuja-Keffi-Lafia-Makurdi o wa ro aare ,lati tobe se ise akanse oju popo ti  Makurdi-Otukpo  ati lati tun mojuto omi ero igbalode fun awon to n gbe ni Gboko ati Otukpo.
Eyi gaan ni ibẹrẹ bi ohun gbogbo ṣe doju ru.
Lati le kẹsẹjari lori ipinu yi,Naijiria gbọdọ na ilọpo mẹta iye to ya sọtọ fun eto ilera si 1.
Oríṣun àwòrán, Getty Images RUSSIA: Bi o tilẹ jepe aarẹ Donald Trump fẹran aarẹ orilẹede Russia, Vladmir Putin, to si ṣetan lati dariji i.
Bi ko ba maa ba awọn ọlọpaa woya ija, oun ati Gomina ipinlẹ rẹ ko ni ma salai ni aawọ.
Èèyàn 91 míràn tún ti ní àrùn Coronavirus ní Nàíjírìa Èèyàn mẹ́rin péré ló ní àrùn Coronavirus ni Ọjọ́ Satidé Ọ̀pọ̀ òjò lo ti rọ láàrin emi àti Olúwòó- Olorì chanel Ijọba ipinlẹ Kano ni pẹlu iwadii ranpẹ ti awọn ti ṣe, ohun to n fa iku ọwọọwọ yii ni aisan iba, itọ ṣuga, ẹjẹ ruru ati yinrunyinrun ati pe kii ṣe coronavirus gẹgẹ bi awọn kan ṣe n pariwo kiri.
Kalebu bá fi Akisa ọmọ rẹ̀ fún un láti fi ṣe aya.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù UN Plane Crash: Èèyàn méjì, tó fi mọ́ ọmọ ọdún márùn-ún ló kú nínú bàálù tó já ní Borno 25 Sẹ́rẹ́ 2018 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 6 Agẹmo 2020 Oríṣun àwòrán, @MBuhari Aarẹ orilẹede Naijiria, Muhammadu Buhari ti leri leka pe ijọba oun yoo gbẹsan ikọlu si baalu ajọ isọkan agbaye ti wọn ja lulẹ, eyi to mu ẹmi eeyan meji lọ.
Arun naa ti ran awọn to din diẹ ni miliọnu mejila (11.
Nítorí ọ̀pọ̀ ni yóo wá ní orúkọ mi, tí wọn yóo máa sọ pé, ‘Èmi gan-an ni Mesaya náà,’ wọn yóo sì tan ọpọlọpọ jẹ.
Yóo ti pẹ́ tó tí ibinu rẹ yóo máa jò bí iná?
Ẹni tí ó dá ayé ti ó tóbi bàǹtà banta bí irú èyí, tí ó fi ènìyàn jọba lórí gbogbo rẹ̀, eléyìí nì ti parí oore.
Kán eyín mọ́ wọn lẹ́nu, Ọlọrun;OLUWA!
Oríṣun àwòrán, Reuters Beirut Port Explosion: Àwọn adarí lágbàyé ṣèpàdé láti ṣèrànwọ́ fún Lebanon lẹ́yìn ìbúgbàmù tó pa ènìyàn 158 Awọn adari lagbaye yoo ṣe ipade loni lati jiroro lori bi wọn yoo ṣe da owo jọ fun orilẹ-ede Lẹbanon ti ibugbamu ba ọpọlọpọ nkan jẹ nibẹ.
Wọn ṣe abiyamọ fun un ki ọlọjọ to de.
Orúkọ àwọn ọmọ Aaroni lọkunrin nìwọ̀nyí: Nadabu ni àkọ́bí, lẹ́yìn rẹ̀ ni Abihu, Eleasari ati Itamari.
Kii se pe o lọ sile onigbajamọ lati lọ ge irun rẹ sugbọn o seese ko jẹ pe arun kan lo fa a, ki o pa lori - irun didi lọpọ igba lo ṣakoba fun bi ori rẹ pa.
Láti Gudigoda, wọ́n lọ sí Jotibata, ilẹ̀ tí ó kún fún ọpọlọpọ odò tí ń ṣàn.
Bakan naa lo ni iku oloogbe naa ti fi opin si saa igbe aye kan nilẹ Yoruba.
(Ẹ gbọ́ ariwo bí àwọn eniyan tí ń sá àsálà kúrò ní ilẹ̀ Babiloni, wá sí Sioni, láti wá ròyìn ìgbẹ̀san Ọlọrun wa, ẹ̀san tẹmpili rẹ̀ tí wọ́n wó lulẹ̀.
Oríṣun àwòrán, @Masjid Àkọlé àwòrán, Aworan Mọṣalaṣi Median laarin agbegbe to wa lalẹ, ina orisirisi lo fi kun ẹwa yii!
Lati igba ti aare Pierre Nkurunziza ti bo lowo ogun idite igbajoba , ni eyi to waye lasiko igba to fe tun tesiwaju isejoba re ni eleeketa lori aleefa.
Ará, ẹ má máa ṣe bí ọmọde ninu èrò yín.
Ronke Oshodi-Oke: Ọkọ mi kò mọ̀ pé òṣèré ni mi nígbà tí a pàdé- Ojo
 Bẹẹ ni a ko ni kẹrẹ lati tubọ
Bẹ́ẹ̀ ni n óo ṣe sí ọ, ìwọ náà óo di ahoro.
 Awon idoti bii agolo, roba, ora, atawon miran maa n pa awon eranko inu omi ni.
Bákan náà, ìloro náà ní àwọn fèrèsé yíká, àwòrán ọ̀pẹ sì wà lára àtẹ́rígbà rẹ̀.
Ẹya Kanuri lati ipinlẹ Borno ni olori oṣiṣẹ fun Aarẹ Muhammadu Buhari, Abba Kyari, ti aarun Covid-19 pa.
"Iwo yii rabata, bẹẹ na lo si jin, ti a ko si ri iru rẹ ri.
Ko si ninu awọn ẹgbẹ oṣelu mejejeji to lamilaaka l'Amẹrika to tii yan obinrin alawọ dudu lati dije du ipo Aarẹ.
Iṣẹlẹ naa mu ki igbakeji gomina ọhun fẹsun kan kọmiṣọna ọlọpaa naa pe o n ṣiṣẹ lodi si oun nitori họwuhọwu to wa laarin rẹ ati gomina Rotimi Akeredolu.
 Èyí ló mú kí ilẹ ̀ germany kéde ogun lé ilẹ ̀ russia lórí ní ọjọ ́ kìíní osù kejọ ọdún 1914 [ 1 / 8 / 1914 ] .
Lilo oogun oloro tabi oti mimu Dokita Henry King ni ẹnikẹni to ba n mu oti amupara ṣeeṣe ki o tọ sile.
Wò ohun mẹ́ta tí a mọ̀ tí yóò mú ìjọba pàṣẹ kónílé-ó-gbélé lẹ́ẹ̀kejì ní ìpínlẹ̀ Èkó Is there a lockdown extension in Lagos: Ìdí mẹ́ta tí ó fi ṣeéṣe kí ìjọba pàṣẹ kónílé-ó-gbélé lẹ́ẹ̀ejì ní ìpínlẹ̀ Èkó Oríṣun àwòrán, Muhammadu Buhari Lasiko ti a fi n ko iroyin yii jọ, ẹgbẹrun mẹrin o le mọkandinniirinwo eeyan lo ti ni arun COVID-19 lorilẹede Naijiria, ẹgbẹrun kan o le ẹgbẹrin ati marundinlaadọta ninu awọn wọnyii lo wa lati ipinlẹ Eko.
Kò ní jẹ́ kí ẹsẹ̀ rẹ ó yẹ̀,ẹni tí ń pa ọ́ mọ́ kò ní tòògbé.
Shittu ni a ń tẹnu mọ pé, awuyewuye lori ọ̀rọ̀ oju opo ayelujara INEC kò ni ìtùmọ kankan, nítori pé, nínú gbogbo ìpàdé ti a se ki ètò ìdìbò tó dé, kò si ìgbà ti a jọ sọ̀rọ̀ lóri lílo oju opo ayélujára láti fí èsì ìdìbò ránṣẹ́, ọ̀nà láti yẹ̀yẹ́ àjọ elétò ìdìbò lásán ni."
Kí ló dé tí o kò fi bá a lọ?
Ile –ẹjọ kotẹmilọrun to wa ni ipinle Sokoto, ti adajọ Tom Yakubu, n dari rẹ ti fagile ẹjọ ti ile- ẹjọ to wa ni ipinle  Zamfara  da pe eto idibo ti egbe oselu ( All Progressives Congress ,APC) se lati yan awon oludije ninu egbe won lati dupo gomina, ile igbimo asofin agba , ile igbimo asofin kekere ati igbimo asoju ti ipinlẹ.
soya pe, laipe orile-ede Naijiria yoo di ohun amuyangan lagbaye laipe.
Didarapo mo igbimo ohun, ni yoo di agbaboolu Super Eagles meje ti yoo maa sise papo pelu DW sports.
Lẹ́yìn èyí mo gbọ́ ohùn kan bí igbe ọ̀pọ̀ eniyan ní ọ̀run, tí ń sọ pé, “Haleluya!
Abileko Juliana Audu to je alaga ijob aibile Makurdi to je okan lara awon oluseto idanilekoo naa ni won gbe idanilekoo naa kale lati fi rogun sawon obinrin lapa lati tubo nife si ise agbe.
O ni ko yẹ ki a maa wo ti ẹya, ede tabi ohunkohun miran lo le mu ki orilẹ-ede Naijiria o ga de ibi ti o yẹ ko de.
Lẹyin eyi o lo tun lọ lọ si St.
Bi ọjọ ṣe ń ka ọjọ latimọle fun oludasilẹ ẹgbẹ ajafẹtọ Revolution Now, Omoyele Sowore, ijọba apapọ Naijiria ti fi ẹsun meje kan an.
O ni ko ṣeeṣe fun ọlọpọlọ pipe lati gba pe wọn le tilẹkun mọ odindin aya Aarẹ orilẹ-ede ninu ile ara rẹ.
Saaju la ti kede fun yin pe Agbowu ti ilu Ọgbaagba, Oba Dhikirullahi Akinropo ti wọ Oluwo ti Iwo, ba Abdulrasheed Adewale Akanbi, Telu Kinni, lọ si iwaju ile ẹjọ giga ipinlẹ Osun, to si n beere fun owo gba, ma binu tii se ọgọrun miliọnu Naira fun bi Oluwo ṣe fi iya jẹ ẹ.
Aàrẹ Trump kọ̀ láti jẹ Tòlótòló ìsìn ìdúpẹ́ 2019 nílé, ó gba Afghanista lọ!
Wọn kò ká ohunkohun mọ́ ọn lọ́wọ́ nítorí olóòótọ́ eniyan ni.
’’Ojo kẹ́sán án osu yii ni awon igbimo ijoba apapo fi ipade
Ìdí èyí ni àwọn akọrin òwe ṣe ń kọrin pé:“Wá sí Heṣiboni!
Gbogbo rẹ̀ ò wá ní bójúmu rárá.
Lẹyin to ti jẹ olori ẹka ọdọ fun ẹgbẹ oṣelu PDP ni ẹkun idibo apapọ aringbungbun ipinlẹ Ogun, lo wa lọ du ipo alaga ijọba ibilẹ Lagelu ni ipinlẹ Ọyọ ni ọdun 2007.
56k Ọkọ̀ tírélà 3 kọlu ọkọ̀ ìgboro, obìrin 2 kú, 6 farapa yánnayànna Iléeṣẹ́ ìròyìn Daily Trust gbọdọ̀ san N6 bilion nítorí ìbanilórúkọjẹ́- Femi Fani Kayode Kí ló wá nínú àbádòfin pínpín omi àti àwọn ǹkan inú omi tó ń mú awuyewuye wa?
nítorí pé, OLUWA Ọlọrun yín tí ó wà láàrin yín, Ọlọrun tíí máa ń jowú ni; kí inú má baà bí OLUWA Ọlọrun yín sí yín, kí ó sì pa yín run kúrò lórí ilẹ̀ ayé.
Ó wá pa òwe yìí fún àwọn tí wọ́n gbójú lé ara wọn bí olódodo, tí wọn ń kẹ́gàn gbogbo àwọn eniyan yòókù.
Ileẹjọ ni ki wọn yẹgi fun gbogbo wọn, titi ti ẹmi yoo fi bọ lara wọn, ọdun 1949 si ni awọn ọdaran naa dagbere faye.
Ní ọdun 2011, wan le kuro nílu pèlú ìfẹ̀honu han, èyi lo si far rogbodiyan lorisirisi ni ààrin àwọn ẹya Arab.
Lonii, iwadii sọ pe awọn to jẹ ẹlẹsin Coptic lagbaye wa laarin miliọnu mẹwa si ọgọta miliọnu.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ìpínlẹ̀ Oyo àti Eko kò nífẹ̀ẹ́ láti gba 'Ruga Settlement' láyè Ogedengbe Agbógun Gbórò, Akọni tó ń dẹ́rù ba ikú.
Biṣọọbu Oyedepo sọrọ yii nigba ti o n waasu nibi akanṣe eto ọlọdọọdun ijọ Winners, Shiloh 2020 niluu Ota, ipinlẹ Ogun.
Gbogbo àwọn ọkunrin Israẹli bá kó ara wọn jọ, wọ́n gbógun ti ìlú náà.
Omijé bọ́ níbi ìsìnkú Ogun Majek Ejò wo ló mi ₦118m láàrin UCH àti ìjọba Oyo?
Nígbà tí ó rí i pé Josẹfu fi ẹ̀wù rẹ̀ sílẹ̀ sí òun lọ́wọ́, ati pé ó sá jáde kúrò ninu ilé, 
Ó ṣe àwọn àgbá kẹ̀kẹ́ yìí bíi ti kẹ̀kẹ́ ogun, dídà ni wọ́n dà á ati irin tí àgbá náà fi ń yí, ati riimu wọn, ati sipoku ati họọbu wọn.
Lalong sọ pe eyi ri bẹ nitori wipe oun ati iyawo oun fẹran ẹranko pupọ, awọn si ti yan awọn ẹranko kan laayo ninu ọgba ẹranko to wa ni ilu Jos lati maa tọju.
Aarẹ wa dupẹ lọwọ awọn to ti i lẹyin fun ifọkansin wọn o si ṣeleri lati ṣe gbogbo daadaa to ba le ṣe ni saa tuntun yii.
Ikọ̀ Arsenal ti pegede fún aṣekagba Europa league bayìí.
Ariwo ati ayọ ni awọn ara Ekiti fi pade Gomina ti wọn sẹsẹ dibo yan naa ni ipinlẹ Ekiti nigba ti o jade si gbangba lẹyin ti Ajọ INEC kede ẹgbẹ oselu APC gẹgẹ bi ẹyi to jawe olubori ninu idibo naa.
Dafidi yipada kúrò lọ́dọ̀ rẹ̀ sí ọ̀dọ̀ ẹlòmíràn, ó tún bèèrè ìbéèrè kan náà.
A wa gbadura pe Ọlọrun yoo tubọ lọra ẹmi Alaafin ati Olori rẹ agba, ki wọn le lo ara wọn gbo si.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Google Map: Ànfààní wo ló wà nínú lílo ẹ̀rọ̀ ajuwe ọnà pẹ̀l'óhùn Nàìjíríà?
20 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Coronavirus in Lagos: Sanwo-Olu ti ilé ẹ̀kọ́ pa, fòfin de ayẹyẹ àdúgbò àti òde fàájì torí ọwọ́jà àrùn19 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 3 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 5 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
 ilé-ẹ ̀ kọ ́ yábàá yí ni agbegbe ìkọ ́ ni lẹ ́ kọ ̀ ọ ́ fún fásitì ilẹ ̀ lọ ́ ndọ ̀ nù .
Adele oga agba ile-ise omo ogun naa, ogagun Abdulmalik Bulama Biu, soro naa di mimo lojo keyin ti won kase idanileko olojo meji ti o waye laarin awon omo ogun ohun ati awon osise ajo isokan agbaye lojo abameta(Saturday), niluu Maiduguri.
Yatọ si awọn ipinlẹ wọn yii, awọn ijọba ibilẹ kan lawọn ipinlẹ miran bi Osun, Ondo, Kogi, Jigawa, Enugu, Ekiti ati Kebbi naa wa ninu ewu omiyale lọdun yii.
Ní ọjọ́ náà, OLUWA yóo fi idà rẹ̀ tí ó mú, tí ó tóbi, tí ó sì lágbára,pa Lefiatani, ejò tí ó ń fò,Lefiatani, ejò tí ń lọ́ wérékéké,yóo sì pa ejò ńlá tí ń bẹ ninu òkun.
Oríṣun àwòrán, Others Ninu lẹta naa ni Mehitabelle ti ni abọ ti oun ati awọn obi oun nikan ba fi jẹun ni oun yoo maa fọ, koda, oun ko ni fọ ikoko ti wọn ba fi se ọbẹ abi ounjẹ rara.
Iroyin fi mule pe, eniyan mefa lo padanu emi won sinu isele ohun, ti o si ba ile ti o to ẹ̀ẹ́dẹ́gbẹ̀ta o le ni ogbon je nipinle ohun.
 báyìí nì won se kúkú so agbégbè yìí ni idí àbà .
Gẹ́gẹ́ bí àwọn ẹgbẹ́ ònwoye àládani ṣe sàlàyé nínú àbájadé ohun ti wọn ri nínú ìdìbò tó kọja, ó jẹ òhun ìjákulẹ̀ pé ìròyìn kan pé àwọn ènìyàn kọ láti jade díbò, ìdúnkòko mọ́ àwọn olùdibò, ìbò rírà, kíkó àwọn ológun síta lọ́jọ́ ìdìbò àti rògbodiyàn láwọn agbègbè kan.
Ìwọ ọmọ eniyan, ṣé o óo ṣe ìdájọ́ wọn?
Nígbà tí Solomoni ọba parí gbogbo iṣẹ́ ilé OLUWA, ó kó gbogbo nǹkan tí Dafidi baba rẹ̀ ti yà sí mímọ́ wá sinu ilé Ọlọrun: àwọn nǹkan bíi fadaka, wúrà, ati gbogbo ohun èlò, ó pa wọ́n mọ́ ninu àwọn ilé ìṣúra tí wọ́n wà níbẹ̀.
Ẹni ti o jẹ alaga agba fun ẹgbẹ NURTW, Alhaji Tajudeen Ibikunle Baruwa ni o yan an ti o si fa a kalẹ.
Bákan náà, àtẹjáde kan tí kọmíṣọnà ọlọpàá ní ìpínlẹ Borno, ọgbẹni Damian Chukwu fi síta fi ìdí rẹ múlẹ pé àwọn agbébọn náà kọlu ìletò mẹrin kan; Bale, Shuwari, Alikaramti àti Jimine tí gbogbo wọn wa ní ìjọba ìbílẹ Jere.
Ọna ati gbogun ti arun naa ni ki eniyan sun daadaa, ki eniyan mu omi daadaa ati lilo oogun ara riro tabi ori fifọ bii paracetamol.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Human trafficking: Ààrẹ Buhari, ẹ̀yin gómìnà ìpínlẹ̀ Yorùbá, ẹ rántí wa ní Oman, àwọn ọmọ Wo ǹkan mẹ́fà tó lágbára nípa Ebuka Obi-Uchendu tó ń gbàlejò Big Brother Naija season 5 Igba kérin ree ti Ebuka Obi-Uchendu yoo gbalejo eto Big Brother Naija.
Nigba to n ba BBC Yoruba sọrọ, Princess ni ohun ko to ọmọ ọdun mejidinlogun, ti oun ti n da gbe pẹlu aburo oun ọkunrin, ti ọpọ bukata si wa niwaju oun.
Kọmisana fun ileeṣẹ ọlọpaa nipinlẹ naa, Joseph Mukan sọ pe ki awọn ẹbi awọn oloogbe o ma bẹru, nitori pe awọn yoo ri pe idajọ ododo fẹsẹmulẹ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Wòlíì Kasali sọrọ nípa awuyewuye pé o lè ìyàwó rẹ̀ jáde nílé Nipasẹ ajọ naa ni mo fi ni anfaani lati ma a rinrinajo kaakiri agbaye.
Nípa ṣíṣe báyìí wọn pa ara wọn tán, bẹ́ẹ̀ ni a sì ṣe tí a sẹgun wọn.
Owurọ ọjọ Aiku ni BBC gbọ iroyin pe awọn agbebọn kan ji alaga ẹgbẹ osẹlu APC gbe.
Wọ́n mú OLUWA bínú lẹ́bàá omi Meriba,wọ́n sì fi tiwọn kó bá Mose,
Oúnjẹ yìí ni àwọn eniyan yóo máa jẹ láàrin ọdún meje tí ìyàn yóo mú ní ilẹ̀ Ijipti, kí ilẹ̀ náà má baà parun ní àkókò ìyàn náà.
O ni Sholaye dẹkun fifi atẹjiṣẹ ọrọ ifẹ ranṣẹ si oun, bẹẹ ni ko si pe oun mọ lori ago.
 a ṣe àgbéjáde àwọn àjẹsára náà nípasẹ ̀ kòkòrò àìlèfojúrí afàìsàn rotavirus tí a ti sọ di aláìlágbára .
Ó tún ranṣẹ bákan náà sí ẹ̀yà Aṣeri, ẹ̀yà Sebuluni, ati ẹ̀yà Nafutali, àwọn náà sì lọ pàdé rẹ̀.
Kò sí ìwé ìrìnnà 'VISA' fáwọn ọmọ Naijiria tó hùwà àìtọ́ nígbà ìdìbò 1.
OLUWA bínú sí Balaamu nítorí pé ó bá wọn lọ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Funmi Adewara: Tele Medicine' ní a fi ń ṣàyẹ̀wò èèyàn ìdá ọgọtá láti dènà ìtànkálẹ̀ Covid Ṣaaju idibo naa lawọn kan lara awọn oludije naa ti fi ẹsun kan igbakeji gomina ipinlẹ naa, Agboọla Ajayi pe o ti ọwọ bọ iwe awọn aṣoju ọmọ ẹgbẹ ti yoo dibo ti o si ti rọpo rẹ pẹlu awọn ayederu aṣoju.
Ìdí míràn ní pé ìpolongo ìdìbò Atíkú ń tọka si pé ìjọba oun yóò wà fún awọn olówó níkàn nígba ti ẹni ti ó sì ń ba dije timfi han gbangba pé ìjọba oun wà fún àwọn mẹkunu, pàápàá jùlọ lóri ọ̀rọ̀ kan to sọ pé àwọn ọ̀rẹ́ òun ní ẹ̀tọ́ láti jẹ ànfani òun ti òun bá di ààrẹ.
Àwọn ará Juda mọ Ọlọrun,orúkọ rẹ̀ sì lọ́wọ̀ ní Israẹli.
00 ni ijọba yoo na lọdun.
Arákùnrin tó 'jíǹde' ní mọ́ṣúárì tí kú Àwọn tó ń ṣagbátẹrù ọ̀rọ̀ náà sàlàyé pé, kí ìjọba dá àwọn tí wọ́n mú si àhámọ́ ọlọ́pàá nítori ipa ti wọ́n kó lásìkò ìwọ́de àkọ́kọ́ Wọ́n fẹ́ kí bánkì apapọ̀ Nàìjíríà tú àkántì àwọn ti wọ́n tì pa nítori ìwọ́de àkọ́kọ́.
Inú bí Saulu gidigidi sí Jonatani, ó ní, “Ìwọ ọmọ ọlọ̀tẹ̀ ati aláìgbọràn obinrin yìí, mo mọ̀ wí pé ò ń gbè lẹ́yìn Dafidi, o sì ń ta àbùkù ara rẹ ati ìhòòhò ìyá rẹ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Omo Ibadan coaching center bá iléeṣẹ BBC lálejò, ẹrín ń pé èrín rán níṣẹ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Omo Ibadan coaching center bá iléeṣẹ BBC lálejò, ẹrín ń pé èrín rán níṣẹ 26 Èrèlè 2018 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 15 Òkùdu 2020 Itumọ BBC ti a mọ ko ba ti ọmọ Ibadan mu.
lorile ede Naijiria , NLC ti rọ awon osise lati mu suuru , pe bi owo ori  se jẹ dandan ,bakan naa ni o se jẹ dandan fun
Raji Razaq ní wọ́n kan yọ awakọ̀ náà kúrò lára àwọn to n mójútó àwọn alárùn coronavirus ni, nítorí pé ó kùna láti pa àwọn ilànà tóyẹ ki o tẹ̀lé mọ́.
Nígbà tí wọ́n sọ fún un pé lábẹ́ àṣẹ Hẹrọdu ni ó wà, ó rán an sí Hẹrọdu, nítorí pé Hẹrọdu náà kúkú wà ní Jerusalẹmu ní àkókò náà.
Mo bá ẹ̀yin ati atọmọdọmọ yín dá majẹmu, ati gbogbo ẹ̀dá alààyè tí wọ́n wà pẹlu yín: 
Peter Awonuga so bi o ṣe n wa igboya lati ka bibeli ati bi awọn ọrẹ oun to jẹ ọmọ Pasitọ ṣe fa oun wọle atawọn nkan to sun oun de idi oogun oloro.
Oríṣun àwòrán, @AAAjimobi Àkọlé àwòrán, Abiola Ajimobi Bẹẹ naa ni wọn ni Arch Waziri Bulama ni yoo jẹ akọwe ẹgbẹ ti Paul Chukwuma yoo si jẹ oluyẹweowowo ẹgbẹ.
Tí a fiṣọwọ́ ní 10:4810:48 Ẹ ṣọ́ra, ọwọ́jà Corovirus ń peléke si ní Nàíjíríà, a ń wọ abala kejì àjàkálẹ̀ àrùn lọ - Ìjọba àpàpọ̀ Coronavirus in Nigeria: Ìjọba ní Covid-19 ba ọ̀rọ̀ ajé ìdílé jẹ́, ó fa àrùn ọpọlọ fọ́pọ̀ aráàlú Ijọba apapọ Naijiria ti kede pe o seese ki orilẹede yii tun wọ abala keji ọwọja arun Coronavirus.
Baalu ere idaraya ni, o ti sun mọ papakọ ofurufu Danbury Municipal to fẹ balẹ si ni Connecticut, USA.
Ènìyàn 27 lo ti bá iṣẹ̀lẹ̀ ọkọ̀ ofúrufú tó já rìnrìn ajò Ẹ yé parọ́ kiri!
Ile ẹjọ giga nilu Abuja sọ pe ki Nyame, to ti jẹ gomina ipinlẹ Taraba ri jẹbi ẹsun debi pe ko lọ ṣe ẹwọn ọdun mẹrinla fun jija awọn eniyan ipinlẹ rẹ to ni igbagbọ ninu rẹ kulẹ.
BBC Debates: Àwòrán tí ẹ kò rò níbi ìpàdé ìfọ̀rọ̀wérọ̀ BBC Yorùbá l'Eko
Ọmọdekunrin kan ti ko ju ọmọ ọdun mẹwa lọ, to wa lẹyin ọkọ rẹ, ni wọn ni afurasi naa ji gbe.
Àwọn eniyan ń retí, gbogbo wọn ń rò ninu ọkàn wọn bí Johanu bá ni Mesaya.
”Ẹnu yà wọ́n pupọ sí ìdáhùn rẹ̀.
Ọjọ kọkandinlogun, oṣu Kẹsan-an, ni idibo yoo waye ni ipinlẹ Edo, ti ipinlẹ Ondo, yoo si waye ni ọjọ kẹwa, oṣu Kẹwaa.
"A ko mọ iru iṣẹṣe ti wọn ti ṣe fun awọn naa nigba yẹn""."
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Election Update 2019: Onímọ̀ kan ní Obasanjọ ni ko jẹ ki Atiku wọlé ààrẹ 27 Èrèlè 2019 Àkọlé àwòrán, Obasanjọ ni ko jẹ ki Atiku wolé ààrẹ Ìdíbò orílẹ̀-èdè Naijíríà tí wá, ó sì ti lọ sùgbọ́n àwọn ọmọ Nàijíríà sì ń sọ èrò ọkan wọn lóri ìdìbò náà.
 Ó ti fìgbà kan rí jẹ ́ òṣìṣẹ ́ ilé iṣẹ ́ asọ ̀ rọ ̀ -mágbè sì ti ìpínlẹ ̀ Òndó àti ti d Ìpínlẹ ̀ Èkìtì .
Àwọn ọmọ Aaroni, alufaa, ni wọ́n fún ní ìlú Heburoni, tíí ṣe ìlú ààbò fún àwọn tí wọ́n bá ṣèèṣì pa eniyan, pẹlu àwọn pápá ìdaran tí ó wà ní àyíká rẹ̀, ati ìlú Libina pẹlu àwọn pápá ìdaran tí wọ́n wà ní àyíká rẹ̀.
Nígbà tí mo kọ ìwé tí mo kọ́ kọ, kì í ṣe nítorí ti ẹni tí ó ṣe àìdára, bẹ́ẹ̀ ni kì í ṣe nítorí ti ẹni tí wọ́n ṣe àìdára sí.
Fayose ni oun o jẹbi ẹsun naa ti wọn si ni beeli rẹ ni aadọta miliọnu naira pẹlu oniduro kan.
A si sọ fun-un wipe ile iṣẹ olominira le yi.
ẹkun idibo Agege kinni ni ẹgberun mẹtadinlogun-le-ni-ọtalelẹgbẹta ati
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Shagari pada dariji Buhari ko to kú Ohun to kọju si ẹnikan, ẹyin lo kọ si ẹlomii bi ilu gangan, awọn miran gba pe igbesẹ to dara ni Buhari gbe nipa diditẹ gbajọba ni 1983 Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Alapinni Oosa ṣàdúrà fún gogbo ọmọ kúoótù, oò jíire bí?
Ìdí nìyí tí ó fi jẹ́ pé pẹlu ẹ̀jẹ̀ ni a fi ṣe majẹmu àkọ́kọ́.
Mo kìlọ̀ fún àwọn ọmọ Lefi pé kí wọ́n ya ara wọn sí mímọ́, kí wọ́n wá láti ṣọ́ àwọn ẹnubodè, kí wọn lè pa ọjọ́ ìsinmi mọ́.
Nàìjíríà á bí ọmọ 25, 685 lọjọ́ kínni, oṣù kinni, ọdún 2019.
Coronavirus, pẹlu àfikún pé, ki wọn maa lo ọ̀sẹ̀ ifọwọ àti aṣọ ibomu, tí wọn ba jáde nínú ilé.
Akẹgbẹ rẹ, Ike Shorunmu ni ileewosan akọkọ ti wọn gbe e lọ kọ ọ, ko to di wi pe wọn gbe lọ si ileewọsan ẹkọni ti ilu Ibadan, tii o si dakẹ ki wọn to wọle sinu ileewosan naa.
 O ni: Öpolopo eniyan ni won sese mo nipa pataki lilo adin-agbon fun ohun jije ati ohun eelo ipara ati lorisirisii iwulo lasiko yii.
i sinu atimole ko bojumu rara.
Aarẹ Ile Igbimọ Aṣofin Agba Bukola Saraki ati àjọ ti o n pè fun atunṣe ileeṣẹ ọlọpaa (NOPRIN) ti pe fun iwadi si bi Michael Adikwu, to jẹ olori awọn afunrasi ọlọṣa ti wọn ja ọpọ banki lole ni ilu Ọffa ni oṣu kẹrin, ọdun 2018, ṣe ku si ihamọ.
Gbogbo àwọn ọmọ ogun, ará Siria tí wọ́n wá láti Soba ati Rehobu, ati àwọn ará Tobu ati ti Maaka, àwọn dá dúró ninu pápá.
Gbogbo orin egúngún bìkiafù tí wọ́n kọ sí mi l'étí nípa Ajayi tí mi o gbọ̀ ló bu mí lọ́wọ́- Akeredolu Báwó ni òògùn dexamethasone ṣe ń ṣiṣẹ́ lára Àwọn àádọ́ta ọ̀dọ́ wọ gàù nítorí ilé ijó ní Ilorin Ta ni Ebuka Obi-Uchendu tó ń gbàlejò BBNaija 2020?
O ni idi niyii t'oun ko le fi fun ẹnikankan ninu owo ti oun gba lori iṣẹ ọhun.
Àwọn Olúkọ ìpínlẹ̀ Oyo fakọyọ lórí ètò Akọ́mọlédè àti Àṣà púpọ̀ Wo ibi mẹ́rìnlá tí o kò gbọdọ̀ gbé ọkọ̀ rẹ sí lásìkò yìí.
lee daabo bo ẹtọ awon onibara ati fifopin si ọna ẹburu ti awon to n pese ina
Opọ̀lọpọ̀ àwọn ènìyàn ni wọ́n ń pe Marylove ní orúkọ ìnagijẹ 'Serena Nàìjíríà'.
 Ìbà ń wáyé níbití oṣì wà ó sì ní ipa odì lórí ìdàgbà ọ ̀ rọ ̀ ajé .
Oríṣun àwòrán, Others Àkọlé àwòrán, Ijọba ipinlẹ Ọyọ ti bẹ awọn oniṣegun ibilẹ lọwẹ lori aarun Corona Ìjọba ìpínlẹ̀ Oyo tí bẹ àwọn oníṣẹ̀gùn lọ́wẹ̀ lórí ààrùn Coronavirus Coronavirus: Ìjọba ìpínlẹ̀ Oyo tí bẹ àwọn oníṣẹ̀gùn lọ́wẹ̀ lórí ààrùn Coronavirus Edotimi ni NAFDAC ti ṣetan lati ṣe iforukọsilẹ fun awọn ibudo ti ipesẹ awọn ogun ibilẹ naa yoo ti maa waye.
"Àtíkù wá ń bèèrè pé sé ""òfin kankan wà tó ní dandan ẹni tó bá fẹ́ jẹ ààrẹ orílẹ̀èdè Nàíjíríà gbọdọ̀ kàn sí Amẹ́ríkà ná, kí onítọ̀ún tó leè di ààrẹ?"
Nítorí náà, mo bẹ̀rẹ̀ sí ronú nípa ìwà ọlọ́gbọ́n, ìwà wèrè ati ìwà òmùgọ̀.
Obasanjo ti ṣaaju jẹ ologun ko to ṣe ijọba gẹgẹ bi olori orilẹede lẹẹmeji .
Ìdí rèé táwọn àkàndá ẹ̀dá fi dí iwájú iléeṣẹ́ ìjọba ìpínlẹ̀ Oyo pa l'Agodi n'Ibadan Kò sí ẹnikẹ́ni tó kú níbi rògbòdìyàn tó wáyé lánàá - Deji ilu Akure Ọlọ́pàá, sójà yabo Lekki Toll Plaza láti dènà ìfẹ̀hónúhàn míràn Idi ti Odili fi gba ibi ìbálòpọ̀ lọ sí ọ̀run alákeji nílùú Port Harcourt Makinde, Dele Momodu ń ṣèdárò Àgbà Oyè Ilẹ̀ Ibadan, Harry Akande tó jáde láyé Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Ghana elections result 2020: Èsì ìdìbò tó gbé aàrẹ tuntun wọlẹ́ ní Ghana rèé.
Ó ti tán fún mí lọ́dún 2023- Ààrẹ Muhammadu Buhari Nàìjíríà bí ìkókó 26, 039 lónìí ọjọ́ kíní, oṣù kínií, ọdún 2020- UNICEF Ẹ̀kọ́ ọ̀fẹ́, ètò ilera ọ̀fẹ́ àti iná ọba ló jẹ wá lógún- ọmọ Nàìjíríà Oríṣun àwòrán, Lanko ọmọba Dubai Kudirat Shoremi (No Network) ati Adeola Shoremi (Lanko ọmọ Dubai) Gbogbo awọn onworan ere tiata Yoruba ko lee gbagbe obinrin adẹrinpoṣonu kan to jẹ pe ilana aditi ni awọn gbe ipa idẹrin pẹẹkẹ araalu gba ni tiwọn.
"Lafikun, SERAP ni ""Ẹsun pe wọn ko nkan iranwọ pamọ kaakiri ipinlẹ to fi mọ ikuna idọgba ninu pinpin awn nkan naa fawọn to ku diẹ kaato fun atawọn tiya n jẹ nilu ti di eyi ti wọn n fi ẹtọ wọn dun wọn to yẹ ki wọn ran wọn lọwọ""."
Àwọn òṣèlú tí wọ́n ndu ipò yìí pọ̀ ṣùgbọ́n àwọn méjì péré ni wọ́n jẹ́ asíwájú.
Ohun ti ofin naa n gbero ni lati jẹ ki awọn ọba to ba waja ni anfaani isinku ni ilana ẹsin to wu wọn yala ti Kristẹni tabi ti Islam.
Botilẹjẹ wi pe ọlaju ti de, awọn obinrin kan si n ṣe e, nitori pe awọn ọkunrin kan maa n fẹ ki iyawo ti wọn yoo fẹ ẹ jẹ omidan ti ko ni ibalopọ ri.
Àwọn Ará Ijipti Gbógun ti Juda.
igba ti awon igbimo Olubadan ba ti setan lati bọ ‘ade ti ko ba ofin mu’ to
Bẹ́ẹ̀ ni Maku, ati Arisitakọsi, ati Demasi ati Luku, àwọn alábàáṣiṣẹ́ mi.
South Africa gbọ́dọ̀ dá owó ìtanràn padà kí wọ́n si fìyà jẹ àwọn ti ọ̀rọ̀ kàn -Sen Basiru Akeredolu ò ṣe ǹkan àrítọ́kasi ni Ondo- Komísọnà ọ̀rọ̀ to n lọ tẹ́lẹ̀rí Ṣé lóòtọ́ ni àdó olóró bú níléeṣẹ́ ìjọba South Africa tó wà nílùú Abuja?
Josẹfu sì lọ káàkiri ilẹ̀ Ijipti.
Dandan kọ́ ni kí Buhari ó bá ayín sọ̀rọ̀ lórí coronavirus, ó ti ṣe gbogbo nkan tó yẹ kó ṣe - Iléèṣẹ́ ààrẹ Ṣé òògùn Chloroquine lè dènà ààrùn Coronavirus bí?
Ilé a sì máa ṣe àyẹwò ìwé náà pẹ̀lú ìbéèrè lọwọ ẹni to bá fẹ jẹ́ ipò Mínísítà láti mo bóyá o kún ojú oṣuwọn.
Lawọn ibomiran wọn a ma fi ileri anfaani ipo tabi siso awọn ọmọ ẹgbẹ yi mo awọn ti yoo ran wọn lọwọ tan wọn jẹ.
Gbe lọ si Ẹ̀rọ fún li lọ̀ tàbi gun pẹ̀lú odó lati lọ ọ.
Ni bayi, papa iṣere ti idije naa yoo ti waye ti wa ni ṣiṣi fun igbaradi, sugbọn awọn elere idaraya lati orilẹede Botswana n fi ẹsun kan pe, awọn ko ri ounjẹ to dara fun ilera awọn jẹ.
Onimọ kan, Abdulazeez Musa tilẹ sọ pe ọjọ ti pẹ ti inakuna, iwa ibajẹ ati aibọwọ fun ilana ti wa ni Naijiria, eyi naa si lọwọ si bi ọpọ eniyan ṣe n gbe ninu oṣi.
’Eléyìí ya àwọn ọddẹ yìí lẹ́nu, wọ́n sì dá iwin náà dáuró, wọ́n bèèrè ohun tí o ń lé e.
Awọn ọmọ orilẹede Argentina ati gbogbo agbaye si n ṣe idaro gbajugbaja agbabọọlu elege ara, Diego Maradona ti filẹ ṣaṣọ bora lẹni ọgọta ọdun l'Ọjọru.
ifehonu han awon egbe oselu alatako eyi ti won gbero lati se, eleyi ti ijoba
Amọ, MTN nigba to n fesi si ifẹhọnu han ni oju opo ikansiraẹni, Twitter wọn bu ẹnu atẹ lu ifẹhọnu han naa.
Wo arẹwà tí àwọn ọmọ Nàìjíríà fẹ́ kó di àárẹ wọn 22 Ògún 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 23 Ògún 2020 Oríṣun àwòrán, Lisa Hanna Oju awọn ọmọ Naijiria ti ri arẹwa, wọn si ti ni awọn o kọ lati yan sipo aarẹ.
o di apoti iya ru Daria Kasatkina ninu ifigagbaga re kinni pelu ami ayo mefa
Arakunrin naa kọkọ sọ wi pe oun kọ lo pa ọga oun, wi pe awọn adigunjale lo se ikọlu si wọn.
Hassan, Iyabo Ojo, Ronke Ojo, and Doris Simon, atawọn mii.
Ọ̀pọ̀ ni ó ń dìde sí mi!
Governor's Pension: Kwara fẹ́ ṣé bí Èkó, ó dẹ́kun sísan owó ìfẹ̀yìntì fáwọ̀n Gọ́mìnà àná àti igbákejì wọn
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù 2019 Election Update: Ìgbìmọ̀ ìgbẹ́jọ́ fún Atiku láyè láti ṣàyẹ̀wò ohun èlò ìdìbò ààrẹ 6 Ẹrẹ̀nà 2019 Oríṣun àwòrán, Facebook/Atiku Ababakar Àkọlé àwòrán, Ibo aarẹ orilẹede Naijiria Igbimọ igbẹjọ kotẹmilọrun lori ibo ti fun oludije si ipo aarẹ fẹgbẹ oṣelu PDP Atiku Abubakar lanfani lati ṣayẹwo ohun elo idibo ti ajọ INEC lo lasiko ibo aarẹ ọjọ kẹtalelogun oṣu keji.
Nítorí ní ọpọlọpọ ìgbà ni wọ́n kó ṣẹ́kẹ́ṣẹkẹ̀ sí i lẹ́sẹ̀, tí wọ́n tún fi ẹ̀wọ̀n dè é lọ́wọ́.
Òun pẹlu Samuẹli sì lọ ń gbé Naioti.
Solomoni ọba fẹ́ wọn bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé OLUWA ti pàṣẹ fún àwọn ọmọ Israẹli tẹ́lẹ̀, pé wọn kò gbọdọ̀ fẹ́ aya láàrin àwọn orílẹ̀-èdè náà, bẹ́ẹ̀ ni wọn kò gbọdọ̀ fi ọmọ fún wọn; kí àwọn orílẹ̀-èdè náà má baà mú kí ọkàn àwọn ọmọ Israẹli ṣí sọ́dọ̀ àwọn oriṣa wọn.
Ọkàn rẹ̀ bá yipada, ó pinnu pé òun kò ní gbé e lọ sí Jerusalẹmu, ìlú Dafidi mọ́.
Ẹ gbọdọ̀ mú àwọn ohun ìyàsímímọ́ tí ẹ ní, ati àwọn ẹ̀jẹ́ yín lọ sí ibi tí OLUWA ti yàn fún ìrúbọ.
lee fa ofo emi ati dukia.
Àwọn ènìyàn sì bẹ̀rẹ̀ sí bèérè pé ọdún mélòó gan ló yẹ́ kí ẹni tó bá ti gba ìdájọ́ ikú lò l'ẹ́wọ̀n.
n mojuto ere idaraya nipinle Eko, Kweku Tandoh ti o fi mo awon komisona kookan
O kopa ninu ogun ilẹ Egypt fun nnkan bii aadọta ọdun, papa lọdun 1967 ati 1973 nibi to ti gba oye 'Field Marshal'.
Kabiyesi ṣe afikun ọrọ wipe, ayipada ọtun ti de ba ọdun eegun naa, nitori ko si anfani fun egungun kankan lati wọ aṣọ idoti wa si aafin Ọba.
Lẹ́yìn ikú Ahabu ọba, àwọn ará Moabu ṣọ̀tẹ̀ sí Israẹli, wọ́n fẹ́ fi tipátipá gba òmìnira.
Ọkunrin lara awọn eeyan naa tilẹ ti di gbajumọ nitori bo ṣe maa n gbe asia naa to si ma n ju sọtun ati si osi.
Èmi Olódùmarè ma sì rọ òjò lé e, ma fẹ́ ẹ̀fúùfùlẹ̀lẹ̀ lé e, ma fi ìkúùkù òjò bò ó mọ́nlẹ̀, ma ṣán an ní àrá ṣààràrà, bẹ́ẹ̀ náà ma sì fa òṣùmàrè pálapàla sí iwájú rẹ̀.
 Fun idi eyi, mo fe ki a gba won laaye lati se ise won.
ìwọ̀n àwo fadaka kọ̀ọ̀kan jẹ́ aadoje (130) ṣekeli; ìwọ̀n gbogbo àwọn abọ́ fadaka náà jẹ́ ẹgbaa ṣekeli ó lé irinwo (2,400).
Lára ilẹ̀ ẹ̀yà Gadi, wọ́n fún wọn ní Ramoti ní ilẹ̀ Gileadi ati Mahanaimu, 
Dan Foster: Gbajúgbajà sọ̀rọ̀sọ̀rọ̀ orí rédíò Dan Foster ti dágbére fáyé
Gbajugbaja oṣere ''Blue Film'' Ron Jeremy tun ti wọ wahala sii lẹyin ti wọn fẹsun kan an pe o ti fipa ba awọn obinrin to le ni mẹtala lọpọ, ti ọmọ ọdun marundinlogun si wa lara wọn.
Oríṣun àwòrán, AFP Àkọlé àwòrán, Alufa orilẹede South Sudan kan n dari ijọsin ni ibudo atipo kan to wa ni ilu Obo l'orilẹede Central African Republic l'ọjọ Ẹti.
"Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Messis vs Ronaldo: Jurgen Klopp ní àràmọ̀ndà agbábọ́ọ̀lù tó ń jẹ Messi, ó ju Ronaldo lọ lórí pápá 14 Èbibi 2020 Oríṣun àwòrán, Getty Images Akọnimọọgba ẹgbẹ agbabọọlu Liverpool, Jurgen Klopp naa ti da si arayinjiyan ""ta lo dara ju"" laarin Lionel Messi ati Cristiano Ronaldo."
Ìpínlẹ̀ Oyo àti Eko kò nífẹ̀ẹ́ láti gba 'Ruga Settlement' láyè 'Kí ni alága NFF, Amaju Pinnick ń wá ní Egypt fún AFCON?
agba ile-ise to n mojuto isele pajawiri ati ṣiṣe awari ohun ti o ba sonu loju
Nítorí ìṣẹ̀lẹ̀ náà ni wọ́n ṣe ń pe òkè náà ní Àpáta Àsálà.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ilé ẹjọ́ wọ́gilé ìgbẹ́jọ́ Olalekan 'Woodberry' Pọnle 10 Agẹmo 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 24 Agẹmo 2020 Oríṣun àwòrán, @Woodberry Woodberry: Ile ẹjọ wogile igbẹjọ Olalekan 'Woodberry' Ponle.
Nígbà tí mo dé inú igbó yìí n kò rí nǹkankan rárá, n kò rí ẹranko bẹ́ẹ̀ n kò sì rí ẹyẹ, ọ̀kẹ́rẹ́ kò tilẹ̀ gun igi kọjá lójú mi.
Oríṣun àwòrán, Other Funmilayo ni iyawo kẹta Isho Pepper, toun naa si ko ipa ti ko kere si idagbasoke iṣẹ tiata.
Ìparun ati ikú jẹ́wọ́ pé,‘Àhesọ ni ohun tí a gbọ́ nípa rẹ̀.
Di àpẹẹrẹ ẹ̀kọ́ tí ó yẹ, tí o ti gbà láti ọ̀dọ̀ mi mú, pẹlu igbagbọ ati ìfẹ́ tí ó wà ninu Kristi Jesu.
Coronavirus lè tara òkú Abba Kyari ran àwọn tó péjú síbi ìsìnkú rẹ̀- Ààrẹ ẹgbẹ́ dókítà ní Nàìjíríà Auxiliary lo ń jà káàkiri ìlú Ibadan lọ́jọ́ Aje, ẹgbẹ́ ọlọkọ èrò NURTW kọ - Ejiogbe Ìyàn ń bọ̀ ní Nàìjíríà lẹ́yìn coronavirus àyàfi.
Èèyàn kan kú, ẹni mẹ́ta farapa nínú àkàsọ̀ ìgbàlódé(lift) tó já ní Cocoa House n'Ibadan
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Bọde George: Àwọn èèyàn mọ ẹni to yìnbọn pa Adeniyi Aboriṣade Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Bọde George: Àwọn èèyàn mọ ẹni to yìnbọn pa Adeniyi Aboriṣade 28 Ògún 2018 Mo mọ ẹni tó pa ọkọ mi nitori pe ó ti sọ àsọtẹ́lẹ̀ pé òun a pa á.
Ọ̀dọ́ aguntan mẹfa tí kò lábàwọ́n ati àgbò kan tí kò lábàwọ́n ni ọba yóo fi rú ẹbọ ọrẹ sísun sí OLUWA ní ọjọ́ ìsinmi.
Èmi tí mo bá Àǹjànnú-ìbẹ̀rù tí í ṣe oníbodè Igbó Olódùmarè jà tí ó sì dàbí ẹni pé tèmi parí láyé, mo tún bá ara mi nínú kẹ̀kẹ́ lẹ́hìn náà pẹ̀lú ìyàwó mi àfẹ́sọ́nà, mo tún di ẹni tí n gbé ilé pẹ̀tẹ́ẹ̀sì, mo di ẹni tí ń gbé ìyàwó tí ayé ń gbọ́ tí ọ̀run ń mọ̀; n ó kọ ìtàn ìyókù ìgbésí-ayé mi sílẹ̀ nítorí n kò mọ ohun tí ń bọ̀ níwájú.
"Toyin Abraham àtàwọn ọ̀dọ́ sọ̀kò èèbú síra wọn torí ìwọ́de #EndSARS ""Ẹ dariji mi, mi o mọ tẹlẹ ni."
Ilẹ ẹjọ fagilé ìbò ọmọ ẹgbẹ́ APC nípinlẹ̀ Ogun pè kí àtúndì ìbò wà Gẹgẹ bi ohun ti akọroyin wa jabọ lati ẹnu aṣoju FBI ni Naijiria, ọgbẹni Uche Amdi ni ọwọ tẹ awọn eeyan wọn yi lẹyin ti wọn ti ṣaaju fẹsun kan awọn eeyan ọgọrin kan.
Oríṣun àwòrán, OTHERS Oniṣowo ni Tayo Amusan, ẹni ọgọta ọdun ni, biliọnia si ni pẹlu.
Asofin Abdulrasak Atunwa, ti ẹgbẹ oṣelu PDP ko fojuhan nibi ipade naa.
Jesu yìí ni ‘Òkúta tí àwọn ọ̀mọ̀lé kọ̀ sílẹ̀,tí ó wá di òkúta pataki igun-ilé.
Aarẹ laelae bẹrẹ ni China Oríṣun àwòrán, Reuters Àkọlé àwòrán, Ọgbẹni Xi patẹwọ lẹyin igba ti igbimọ asofin f'ọwọ si atunṣe naa China ti f'ọwọ si fif'opin si iye saa ti aarẹ orilẹede le ṣe, nibi igbese kan to le je ki Aarẹ Xi Jinping maa se ijọba lọ karin.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Wọn kọ lati tẹle imọran ajọ isọkan agbaye pe ki wọn ti orile-ede wọn pa.
EFCC gbé agbẹjọ́rò àti àna Atiku lọ iléẹjọ́ lórí ẹ̀sùn gbígbé owó tùùlù rìn Ọ́kọ̀ mẹ́wàá tó kún fún àwọn agbófinró gba ìbùdó ìwọ́de kan ní Abuja Ni ọjọ Ẹti ni ajọ FIFA kede pe awọn ti gbẹsẹ le kikopa Sisasia ninu ohunkohun to nii ṣe pẹlu ere bọọlu lagbaye nitori ẹsun gbigbimọ lati gba owo riba ti wọn fi kan an.
igbimo asoju naa ku ori-ire .
Idi ni pe oju ọna Ibadan silu Eko ti ọkan balẹ le lori tẹlẹ, ni ipaya tun ti n waye lori rẹ bayii nitori awọn gende agbebọn ti wọn se ọsẹ nla ni irọlẹ ọjọ Isẹgun.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Wakanda Forever : Aubameyang fi 'Black Panther' dáwọ̀ọ́ ìdùnnú lórí pápá 15 Ẹrẹ̀nà 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Wakanda Forever,Aubameyang fi ifẹ rẹ han si ilẹ Afrika Ẹgbẹ agbabọọlu Arsenal bori ifidirẹmi goolu mẹta lọwọ Rennes ti wọn si pegede lati kopa ninu abala komẹsẹoyo idije Europa League.
Eyi ko si ṣẹyin bi ile iṣẹ ọlọpaa ṣe sọ pe o ṣeeṣe ki awọn ọlọlufẹ ọgagun orilẹ-ede Iran, Qassem Soleimani ti ilẹ Amẹrika ṣekupa fẹ da rogbodiyan silẹ ni Naijiria.
Asiko to níra jù- àwọn ọjọ akọkọ ti ààwẹ ba bẹ̀rẹ̀ Ìmọ̀ fi yeni pe ara kìí wọ inu ààwẹ ti kò ba ti pe w;akàti mẹ́jọ lẹ́yìn ounjẹ ti ènìyàn ba jẹ kẹ́yìn.
Gbadero pe ẹjọ kotẹmilọrun, ti awọn adajọ mẹta to gbọ ẹjọ naa si gba pe ko jẹbi ẹsun iditẹ lati pa eeyan amọ o jẹbi ẹsun ipaniyan.
Ẹ̀ ń rẹ́ talaka jẹ, ẹ sì ń fi ipá gba ọkà wọn.
 iru ijoba re je jijuwe pe o je bi ' quasi-federal ' pelu gbongan to lagbara ati awon ipinle ti won ko lagbara , sugbon o ti di apapo diedie lati opin awon odun 1990 nitori awon iyipada oloselu , olokowo ati alawujo .
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Tayọ̀tayọ̀ ni mó fẹ́ ṣiṣẹ́ pẹ̀lú INEC ki ìdìbò 2019 lé dára' Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Bí o bá wá OLUWA, o óo rí i, ṣugbọn bí o bá kọ̀ ọ́ sílẹ̀, yóo ta ọ́ nù títí lae.
Ti a ba woye pelu atimaaṣebọ rẹ̀ tẹlẹ ati awọn ipolongo ti awọn ololufe re nse lori ẹro ayelujara, o ṣe ṣe kí o du ipo Aarẹ pẹlu Buhari.
Ọlọ́kàn líle ẹ̀dá ni ikiú jẹ́, kò ní àánú ẹnikẹ́ni, bẹ́ẹ̀ ni kìí pinnu kó bojú eẹ̀yìn lẹ́ẹ̀kan.
Wọ́n dá a lóhùn pé, “Bí ọkunrin yìí kò bá ṣe nǹkan burúkú ni, a kì bá tí fà á lé ọ lọ́wọ́ fún ìdájọ́.
 Èyí ti lámurúdu ìbá fi gbà , ó fi ìlú mẹ ́ kà sílẹ ̀ , ó sì tẹ ifẹ ̀ dó.
 Ó jẹ ́ ọ ̀ kan lára ìjọba ìbílẹ ̀ tí wọ ́ n pín ìpínlẹ ̀ Èkó sí ( lagos division ) .
“ ‘Àwọn ará Etiopia, ati Puti, ati Ludi, ati gbogbo ilẹ̀ Arabia ati Libia, ati gbogbo àwọn eniyan wa tí wọ́n jọ gbìmọ̀ pọ̀, ni ogun yóo pa.
Coronavirus: Ọjoọ́ mélòó ni Coronavirus ń lò lára kí ènìyàn tó gba ìwòsàn?
Eyi si ti jẹ ki awọn oloṣelu kan lori ariyanjiyan lori igbesẹ Brexit ni eyi to lọwọ kan ejo ninu.
Ijọ naa maa n ṣe ipagọ ọlọdọọdun l'oṣu Kejila ọdun.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ìfàsẹ́yìn díẹ̀ tí yóò ní àtúnse ni àdánù ìbò gómìnà mi - Adeleke Wo àwọn tó ń du ipò gómìnà lábẹ́ APC nílẹ̀ Oòduà Nkàn ti bàjẹ́ púpọ̀ láàrin àwa lọ́balọ́ba - Ọọ̀ni Kíni ìwọ mọ̀ nípa Funmilayọ Ransome-Kuti?
Ìwọ tí o dá ọ̀run ati ayé pẹlu agbára ńlá ati ipá rẹ!
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Irinajo Hajj jẹ ọkan lara opo marun to wa ninu ẹsin Islam Ni ipinlẹ Sokoto ni Mukhtar, ẹni ti Abdullahi Sale, alamojuto isẹ sisẹ ninu ajọ to n mojuto ọrọ awọn arinrinajo Hajj soju fun ti sọrọ ọun.
Àwọn ẹ̀mí èṣù náà jáde lọ, wọ́n wọ inú àwọn ẹlẹ́dẹ̀ náà.
Oríṣun àwòrán, @jenneric Ni kete ti Ọrunmila si gunlẹ si aafin Iwo, ose, oju mimọ ati eebu ni Wuraọla fi pade rẹ, sugbọn Ọrunmila kan rẹrin musẹ lai sọ ohunkohun pada.
Nítorí níbi tí ẹni meji tabi mẹta bá péjọ ní orúkọ mi, mo wà níbẹ̀ láàrin wọn.
Gettleman lọjọ Iṣẹgun paṣẹ pe ki wọn wọgile igbẹjọ naa.
Dókìtà Steven Fagbemi to jẹ́ olúdari dídá ajàkálẹ̀ ààrùn duro sàlàye lọ́jọ́ Iṣẹgun lásìkò to n jábọ fún gómìnà Rotimi Akeredolu àti alága ìjọba ìbílẹ̀ Ondo North àti Central pe ọrọ yii ti n n to apero ọmọ eriwo.
WÈRÈ dùn wò, kò ṣeé bí 
Laarin oṣu kan, iwadii fihan pe iye awọn to ti lugbadi arun naa ti peleke si ni lorilẹ-ede naa.
Adedimeji tẹsiwaju pe, lootọ ni oun ni afẹsọna, ati pe laipẹ yii ni ayẹyẹ igbeyawo oun yoo waye.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Idije Premier League Ẹlẹsẹ ayo Pierre-Emerick Aubameyang lo kọkọ gba pẹnariti sawọn fun Arsenal lẹyin iṣẹju mẹsan an ti ere bọọlu naa bẹrẹ.
Bí o bá fojú pamọ́,ẹ̀rù á bà wọ́n,bí o bá gba ẹ̀mí wọn, wọn á kú,wọn á sì pada di erùpẹ̀.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù UK Election 2019: Boris Johnson kéde pé January ni UK yóò fi EU sílẹ̀ 13 Ọ̀pẹ̀̀ 2019 Oríṣun àwòrán, Boris Johnson Olootu ijọba ilẹ Gẹẹsi, Boris Johnson ati ẹgbẹ osẹlu rẹ, Conservatives lo jawe olubori ninu idibo gbogbogbo to waye lọjọbọ nilẹ naa.
Ẹnikẹ́ni kò ní gbé ibẹ̀ láti ìran dé ìran,àwọn ará Arabia kankan kò ní pa àgọ́ sibẹ,bẹ́ẹ̀ ni àwọn darandaran kankan kò ní jẹ́ kí agbo aguntan wọn sinmi níbẹ̀.
Akeredolu fidirẹmi lori ibo rẹ nileẹjọ Bill Gates tako ilana ọrọ aje Buhari Atẹjade kan lati ọwọ oludari ajọ naa ni ẹka ti ipinlẹ Eko, ọgbẹni Yakubu Suleiman sọ wipe awọn ọkunrin mẹ́tàdínláàdọ́fà ati awọn obinrin méjílélógójì lo pada wa sile.
Ìpè orí fóònù tó mú kí America fẹ́ yọ ààrẹ Trump rèé Ọkùnrin kan kú si ìyárá ìtura Àwọn ọmọ Naijiria fèsì sí Osinbajo tó ṣetán láti wàákò pẹ̀lú Timi Frank Arabinrin naa wa parọwa si awọn obinrin lati ye fẹ ọkọ ọlọkọ, ki idile lee gboro sii, nitori ewu ti o n fa ninu idile ko kere rara.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Mo fọ kọ́mú, pátá, ògiri ilé lórí 200,000 láìlèfọhùn lórílẹ̀èdè Oman' Bakan naa, wọn ti ṣe ibura wọle fun minisita orilede Oman fun ọrọ aṣa, Haitham bin Tariq lati tẹsiwaju ni ipo rẹ.
Ìwà burúkú ni fún obìnrin náà, tí baálé rẹ̀ fún ni owó oúnjẹ, tí kó ṣe oúnjẹ, tí ó bá ọ̀nà tirẹ̀ lọ.
Ó ní, “Tẹ̀lé mi, kí o wá wo ìtara mi fún OLUWA.
Ooni ile Ife: Iná sọ láàfín Ọọ̀ni Ilé Ifẹ̀, Ọọ̀ni ilé ifẹ̀ ní kò sí ẹ̀mí tó báa lọ
O ni oun yoo koju si Oke Ogun fun nnkan ọgbin jijẹ ati tita.
Ẹ má ṣe dá eniyan lẹ́bi.
O fikùn un pé nígbà tí òun tún ń kọjá ní irọlẹ ládùúgbò náà, àwọn ọmọlẹ́yìn Remi Soka yìí tún kọlu òun, wọn ń lẹ òkúta mọ òun, èyí tó mú kí ọkọ òun dúró ṣùgbọ́n wọn kò dúró de òun rárá.
Johnson & Johnson san biliọnu 8 dọ́là fún ẹni tóògùn gbòdì lára rẹ̀!
Otunba Oyewole Fasawe àti Ayọ Osuntokun ni wọn jọ kọ́wọ̀ọ́ rìn lọ síbẹ̀ Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Ẹwẹ, Kọmiṣọna ọlọpaa ipinlẹ Kano ti ni ki wọn gbe ọrọ naa lọ si ọfiisi awọn ọtẹlẹmuyẹ ipinlẹ (SCID) fun itẹsiwaju iwadii.
Alufaa tí ó ṣe ètò ìwẹ̀nùmọ́ ẹni náà yóo mú adẹ́tẹ̀ náà ati àwọn nǹkan ìwẹ̀nùmọ́ wá siwaju OLUWA lẹ́nu ọ̀nà Àgọ́ Àjọ.
Ó ju ọ̀kọ̀ náà nígbà meji, ṣugbọn Dafidi yẹ̀ ẹ́ lẹẹmejeeji.
Oríṣun àwòrán, Lere Olayinka Àkọlé àwòrán, Wahala ikọlu ati ipaniyan n fojojumọ peleke nipinle Benue Lasiko abẹwo naa, Gomina Fayọṣe yọju si aye ti wọn sin awọn eniyan mẹtalelaadọrin ti o padanu ẹmi wọn nigba ti awọn afurasi darandaran se ikọlu pẹlu wọn.
Ajo idagbasoke ona ibanisoro DEVCOMS pelu ajosepo ile ise ilaniloye lori ifetosomobibi tigbalode ti a mo si Nigerian Urban Reproductive Health Initiatives, NURHI, ti se ifilole igbimo elenu meedogbon fun ipolongo igba gbogbo ifetosomibibi ni Naijiria.
Ẹni ọdun mẹtadinlaadọrun ni wọn jẹ.
Oríṣun àwòrán, Ogun State Governor's office Àkọlé àwòrán, Ọjọgbọn lawujọ, awọn eniyan jankan jankan naa pẹjọ sibi ọdun ilu ti 2019.
 “alakoso egbe ti yan igbimo alabe sekele ti yoo gba egbe niyanju lori oro naa, nipa bayii ,a o tii gbe igbese Kankan lori oro naa.
 kòkòrò àkóràn yíì yóò rìn kiri lọ inú ẹ ̀ dọ ̀ níbi tí wọn a ti dàgbà láti pọ ̀ si .
Amọ akọtun oore to tun wọle tọ idile naa bayii ni ti ẹbun ẹkọ ọfẹ ti oludasilẹ ile iwe wọn fun awọn ọmọbinrin meji ti tọkọtaya Dada bi.
" Ni bayii, alaafia ti n pada jọ̀ba nilu naa, ti awọn agbofinro si ti n sa ipa wọn lati dena isẹlẹ ibugbamu awọn ado oloro naa.
Ìgbáradì yóò gbérasọ ní ìpínlẹ̀ Ekiti lọ́jọ́ Àìkú tó ń bọ̀ Neo n fọ pátá Vee nílé ẹlẹ́gbọ́n àgbà BB Naija, wo ohun táwọn olólùfẹ́ ètò náà n sọ Afẹ́fẹ́ gáàsì ṣe ìjàmba fún èèyàn 30, ilé 23,ọkọ 15 ní ìpínlẹ̀ Eko Adegoke ni àwọn afọbajẹ náà ń fẹ́ ki Oluwo, Oba Abdulrasheed Akanbi maa ta ilẹ̀ mọ́ àwọn ènìyàn Iwo lórí nítorí wọ́n ni owó kò tó .
pe ipade naa jẹ nipa isẹ ilu ati ona lati je ki ilosiwaju ba orile ede
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ sí: Fayoṣe: Mi ò jẹ̀bi ẹ̀sùn kankan Ìjà ẹ̀sìn Kaduna dènà ètò àgùnbánirọ̀ Olorì Ìlé-Ifẹ tẹlẹ̀ rí bá Ọọ̀ni Ogunwusi yọ̀ O sọ nkan pupọ fun mi nipa ara rẹ.
Ẹwẹ, ninu atẹjade kan ti Aroloye fi lede, o ni irọ pọnbele ni gbogbo ohun ti Adele ọhun sọ, nitori oun ko ran janduku kankan lati fi iya jẹ.
Ẹ ṣe àyẹ̀wò wi wé gèlè ni ojú iwé yi.
A n se akojọpọ ẹkunrẹrẹ iroyin yajoyajo lọwọ, a o maa gbe ẹkunrẹrẹ iroyin naa sori atẹ iroyin wa laipẹ.
Mò ń tọ̀ s'ára ni mo fi gba ara à mi l'óko ẹrú ní Oman Obìnrin tó ń ṣiṣẹ́ ẹrú ní orílẹ̀èdè Oman tó bá fẹ́ ní òmìnira, gbọdọ̀ bá ọ̀gá rẹ̀ ṣùn - Obìnrin méjì tó ti Oman dé Kò dín ní ọkùnrin márùndínlógún tó ń bá mi lò lójúmọ́ Ẹyin ni wọ́n fi n gba ìbále ẹlòmiran lára wa ki a to lọ pàde àwọn oníbara Ẹtọ awọn obinrin pẹlu idọgba pẹlawọn ọkunrin lo gbode gẹgẹ bii ohun ojutaye lasiko ajọyọ ayajọ obinrin lagbaye ti ọdun yii.
Ẹni to bori: Senegal Nigeria vs Uganda.
Aare orilẹede naa, John Magufuli sọ loju opo ayelujara rẹ wipe inu oun bajẹ nipa iku awọn ibeji naa.
Ile marun un pẹlu ṣọọbu ti ko din ni marundinlọgbọn lo jona lasiko ijamba ina naa.
Ẹ̀wẹ́, àgbẹnusọ ilé iṣẹ́ aṣọ́bodè Joseph Attah sọ pé, òun kò mọ ẹni to fún wọ́n ni àwọn aṣírí yìí, sùgbọ́n ìwádìí ń lọ lọ́wọ́.
Ó bi wọ́n pé, “Kí ni ẹ óo fún mi bí mo bá fi Jesu le yín lọ́wọ́?
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Ti o bá dá ara ẹ lójú, ki ẹni tó n ṣe irun kí n gbọ́?
EU: Òfo ni ètò ìdìbò 2019 ní Naijiria
Pilatu bá dá Baraba sílẹ̀ fún wọn kí ó lè baà tẹ́ wọn lọ́rùn.
Asọ oloyinbo ni mama Juwọn kọkọ n ta, to si si sọọbu kaakiri to fi mọ ilu Eko ati Ibadan.
 Òfin ati ìlànà ọba nyimu wọn ń tẹ ̀ ̀ lé oba shyaam ni ọba àkọ ́ kọ ́ .
Alágbèrè pàápàá ń ṣọ́ kí ilẹ̀ ṣú,ó ń wí pé, ‘Kò sí ẹni tí yóo rí mi’;ó fi ìbòjú bo ojú rẹ̀.
Oríṣun àwòrán, @raufaregbesola Àkọlé àwòrán, 'A kan sara si awọn obinrin, awọn iyaa wa, iyawo wa, ẹgbọn ati aburo wa lobinrin fun itọju, ifẹ, iwa aforiti, ifarada, okun ati isedeede wọn' A kan sara si awọn obinrin, awọn iya wa, iyawo wa, ẹgbọn ati aburo wa lobinrin fun itọju, ifẹ, iwa aforiti, ifarada, okun ati isedeede wọn."
San owo iye odiwọn ina ọba ti o fẹ lori awọon oju opo ayelujara ti wọn ya sọtọ fun owo sisan.
 Àwọn ẹgbẹ ́ nigerian youth movement , tí wọ ́ n jẹ ́ alátakò ìdásílẹ ̀ ilé-ẹ ̀ kọ ́ náà ni wọ ́ n tún padà di ẹgbẹ ́ òṣèlú nílẹ ̀ nàìjíríà .
Pẹlu iru nkan bayi, anfaani wa, bẹẹ si ni ipenija wa pẹlu ṣugbọn gbogbo rẹ ku si ọwọ awọn to n ṣe ijọba.
”Akapo egbe APC, oloye George Moghalu  naa tun gbosuba fun egbe win  bi eto idibo naa se waye ni irowo-irose ni ipinle naa.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ọwọ́ ọlọ́pàá tẹ àwọn tó lọ kó ọjà ọlajà ní Shoprite Ilorin Amọ ikọ ọlọpaa kogberegbe ati awọn ẹṣọ oju lalakan fi n ṣọri n gbiyanju lati ri pe wọn ko tun ji nnkan kò níbẹ.
eto aabo ilu, paapaa nipa riro ikọ ẹṣọ LNSC yii lagbara.
Arábìnrin lẹ̀dì àpò pọ̀ pẹ̀lú ọ̀rẹ́kùnrin rẹ̀ pé kó ó jí òun gbe, ọ̀rẹ́kùnrin gba 700k tán ló bá sálọ Wo oríṣìí oúnjẹ márùn ún tó lè dẹ́kun ikùn yíyọ àti ara àsanjù Nibi ti ijiroro ti waye lori ṣiṣi awọn ẹnubode naa lati bẹrẹ owo pẹlu awọn orilẹede Afirika yoku.
Wọn n gboriyin fun wọn nitori iṣe ribiribi wọn, sugbọn wọn ko mọ iru ewu ti wọn n doju kọ lojoojumọ.
Gẹ́gẹ́ bí àjọ ìsọ̀kan àgbáyé ṣe sọ ọ́, orólẹ̀èdè Nàìjíríà ni orílẹ̀èdè kẹta tó m'ókè jù nínú àwọn tó ń m'ugbó ní gbogbo àgbáyé.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Aisan jẹjẹrẹ asẹtọ Ọkunrin n paniyan ju tatẹyin wa lọ nitori iye eniyan to n pọ si lagbaye Ajọ to n gbogun ti aisan jẹjẹrẹ nile Geesi (Prostate Cancer UK), ti ni igbega to n ba iwadi ati iwosan arun jẹjẹrẹ oyan ti n so eso rere, eyi to mu ki alekun ba owo ti wọn n na, to si le se anfani fun awọn to ni aisan jẹjẹrẹ asẹtọ.
Ibadan/Oyo Express/Iseyin-Owode to lọ si Akesan-Palace ati Old Ibadan-Oyo road yoo yipada si Alaafin Lamidi Adeyemi III road.
DSP Abimbola Oyeyemi to jẹ alukoro ọlọpaa ni ipinlẹ Ogun, lo fidi ọrọ yii mulẹ ninu atẹjade kan to fi sita fawọn akọroyin.
Ṣé o rò pé n kò lè sọ ọ́ di ẹni pataki ni?
"Àwọn ajínigbé jí adarí ìlú Daura gbé Agbébọn tún ya bo abule Moriki ní ìpínlẹ̀ Zamfara ""Mi o fi igba kankan sọ fun ẹnikẹni pe a ti mu awọn ajinigbe naa ."
Olusola wa gba ẹnikẹni to ba nifẹ si ere tiata nimọran pe onitọhun gbọdọ kawe bo ṣe yẹ, ko ni suuru, ko ma si tori owo se iṣẹ ọhun, nitori iṣẹ tiata ko ni owo gidi lori.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Afẹ́nifẹ́re: A kò tíì ní ẹnìkankan táá gbè lẹ́yìn rẹ̀ fún ipò Ààrẹ 22 Èbibi 2018 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 10 Ọ̀wàrà 2018 Oríṣun àwòrán, @SenatorAdesanya Àkọlé àwòrán, Lẹyin ipade naa Afẹ́nifére kọ lati sọ ẹni ti wọn yoo mu laarin Buhari ati Atiku Ori la fi n mẹran lawo sugbọn to ba kan ọrọ yiyan ẹni ti awọn Yoruba yoo gbe lẹyin rẹ́ fun ipo Aarẹ Naijiria lọdun 2019, ọrọ naa yoo gba isiro ati apero daadaa.
O jẹ ọkan lara awọn obinrin to nimọ ti wọn n danilẹkọ nipa Islam ni ilu Kano.
O ni oun ti buwọlu awọn igbesẹ kan lori ọrọ owo ori ni eyi ti yoo mu irọrun de sii fun awọn ti oun n dari.
Ṣugbọn, ọpọlọpọ awọn obinrin lo maa n ra awọn eroja ibora lai gba itọni tabi ilana lọwọ onimọ nipa eto ilera.
Iroyin sọ pe Ọgbẹni D'Angelo ko owo ti wọn ko jọ lori ipolongo ori ayelujara fun Ọgbẹni Monday lati fi di iya ti awọn ọlọpaa fi jẹ ẹ.
Ohun tí a sọ ni pé, “Ọlọrun ka igbagbọ sí iṣẹ́ rere fún Abrahamu.
NBC ní kí àwọn ilésẹ to tẹ ofin lóju san #500,000
Okiki iṣẹlẹ yii kan kaakiri agbaye ti ọpọ si rii gẹgẹ bii itiju fun odindi aarẹ orilẹede Amẹrika.
Ileẹjọ fun Ibrahim El-Zakzaky ati iyawo rẹ ni beeli lati lọ tọju ara wọn lorilẹede India, bo tilẹ jẹ pe ileẹjọ naa paṣẹ pe kawọn to n ṣeto igbẹjọ tẹ wọn lọ.
Iroyin to tẹ wa lọwọ ni pe o ṣeeṣe ki wọn gbe MC Oluọmọ lọ si oke okun lati lọ tẹsiwaju itọju rẹ ṣugbọn lẹyin rẹ ni omii jade pe o n peleke sii ni.
TTactile Ballot Paper (Iwe idibo awọn akanda ẹda) : Iwe idibo
Ọgbẹni Abdullahi Binuyọ to jẹ igbakeji adari awọn oṣiṣẹ lọfiisi gomina ipinlẹ Ọṣun ṣalaye pe ko si ijọba ti yoo kawọgbera maa woran nigba ti awọn eeyan kan yoo maa ba ọrs ajumọni rẹ jẹ tabi jii ko.
Amọṣa o fi kun un o pe lootọ oninufufu ni Oṣupa Saheed sibẹ o dara si oun ko si si idi kan fun aawọ lati wa laarin oun ati Oṣupa.
Ami ayo meji sodo ni wọn fi gbe ifẹ ẹyẹ lọ ti wọn fi na Netherland.
Ètò OLUWA wà títí lae,èrò ọkàn rẹ̀ sì wà láti ìran dé ìran.
Owo oṣù Ọba Olagbegi nígbà náà jẹ ẹgbẹ̀rún kan àti pọn-un mẹrindinlọgọfa (£1,116) fún ọ́dún kan, èyí tí ọba náà kò gbé gbogbo ara le rárá, àmọ́ ó mú isẹ ọ̀gbìn nibaada, tó sì ṣe ọ̀gbìn koko, kọfi ati ọpẹ lọpọ yanturu, èyí tó fi ń tọju ẹbi àti ìlú rẹ.
”O tesiwaju pe, eyi ni yoo je ki ijoba apapo feti si igbe awon osise.
Gomina ipinle Edo, Godwin Obaseki ti so pe, erongba ijoba ipinle ni lati mu igberu ba eto-ogbin ni agbegbe Esan, ni iyanju ati pese ise lopo yanturu, mimu igberu ba eto ohun osin ati ounje ni ipinle naa.
Oríṣun àwòrán, Iyabo Ojo Àkọlé àwòrán, Pasuma, MC Oluomo ati awọn eekan ilu miran fi ijoko yẹ Iyabo Ojo si lọjọ isile rẹ BBC News, Yorùbá Ìdí tí ẹ fi le è nígbàagbọ́ nínú ìròyìn BBC Ìlànà Lílò Nípa BBC Òfin Àṣírí Cookies Kàn sí.
N óo yan ibìkan fún Israẹli, àwọn eniyan mi, n óo fìdí wọn múlẹ̀, wọn óo máa gbé ilẹ̀ wọn, ẹnikẹ́ni kò ní yọ wọ́n lẹ́nu mọ́, àwọn ìkà kò tún ní ṣe wọ́n lófò mọ́ bíi ti àtijọ́, 
sé bọ ́ ká bá síwájú , tí pamọ ́ lẹ ̀ tẹ le e , tí baba wọn òjòlá wá ń wọ ́ ruru bọ ̀ lẹ ́ yìn , kò sí baba ẹni tó jẹ dúró .
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ẹsẹ̀ bàtà, èso kukumba ni wọ́n fi ń já àbálé àwọn ọmọ Nàìjíríà ní Libya Coronavirus symptoms and treatment: Bí Eko ati Abuja ṣe rí rèé lọ́jọ́ àkọ́kọ́ tí wọ́n dẹ ọwọ́ igbele Coronavirus Ní báyìí tí ìjọba àpapọ̀ tí dẹ okun lọrun àṣẹ kònílé ó gbélé, ó dàbí ẹni pé àwọn aráàlú Èkó àti Abuja tí gbàgbé òfin títa kété síra ẹni.
Àtúnbọ ̀ tán kíkankíkan kò fi bẹ ́ ẹ ̀ wọ ́ pọ ̀ .
Ohun to sọ ni wipe, ejo kan wọ ọọfisi, to si gbe miliọnu mẹrindinlogoji ti wọn pa mi.
"Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Trump yọ Tillerson kuro nipo Trump tọrọ aforiji lori asise rẹ Trump bu ẹnu atẹ lu FBI ""Èmi kò gbà pé Trump kò ní ìlera tó dápé láti jẹ ààrẹ, sùgbọ́n kò ní àwọn àbùdá tó yẹ gẹ́gẹ́ bíi ààrẹ Amẹ́ríkà."
Aare Muhammadu Buhari ti ro awon loba-loba, nijoye-nijoye ati awon oludari akoso ijoba ibile pata-pata lati mojuto awon ekun ti won dari, paapaa julo fifi ese alaafia ati aabo mule sinsin saaju idije gbogbogbo-o to n bo lona.
" Shina ni oun ge ori ọgọrun eeyan, ti oun gbe fun awọn Babalawo naa, wọn si ṣe oogun afẹẹri fun oun, ko si si iru ọta ibọn ti wọn yin mọ oun, bii igba ti wọn sọ ọra omi lu oun ni, ko si si oun ti oun ko le ṣe lati wa agbara.
”Má jẹ́ kí wọn wí pé,“A rẹ́yìn ọ̀tá wa.
Wo bí wọ́n ṣe ṣe ọjọ́ ìbí Anọbi ní Abuja ati ní Ghana Ta ni Ken Saro-Wiwa tí ìjọba ológun sekúpa?
Àwọn ohun tí mo sọ kò yé mi,ìyanu ńlá ni wọ́n jẹ́ fún mi,n kò sì mọ̀ wọ́n.
Nigeria SWAT team, EndSars, End SWAT: Àfiwé owó oṣù ọlọ́oàá Nàìjíríà pẹ̀lú akẹgbẹ́ wọn lókè òkun
Ní ọjọ́ náà,OLUWA àwọn ọmọ ogun yóo jẹ́ adé ògo ati adé ẹwà,fún àwọn tí ó kù ninu àwọn eniyan rẹ̀.
Àwọn olùṣọ́ ẹnubodè nìwọ̀nyí: àwọn ọmọ Ṣalumu, àwọn ọmọ Ateri, àwọn ọmọ Talimoni, àwọn ọmọ Akubu, àwọn ọmọ Hatita, ati àwọn ọmọ Ṣobai.
A báni dámọ̀ràn bí ìyekàn ẹni
O fi kun ọrọ rẹ wi pe, Bi o ba ṣe pe ooṣa kan ni awọn ọdaran naa n fi ẹjẹ bọ ni, wọn ni lati waa jade""."
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Baba Sala: Ẹbí, ọ̀rẹ́, ojúlùmọ̀ péjú láti ṣ'ẹ̀yẹ ìkẹyìn fún Baba Sala nílùú Ilesa 7 Ọ̀pẹ̀̀ 2018 Àkọlé àwòrán, Ayẹyẹ ikẹyin fun Baba Sala Awọn ebi, ara, ọrẹ ati ojulumọ lo korajọpọ nilu Ileṣa lati ṣe ẹyẹ ikẹhin fun alagba Moses Ọlaiya Adejumọ ti ọpọlọpọ awọn eeyan mọ si Baba Sala.
O seleri lati pari ise naa ni odun 2020.
Nítorí pé OLUWA àwọn ọmọ ogun, Ọlọrun Israẹli sọ pé: wọn yóo tún máa ra ilẹ̀ ati oko ati ọgbà àjàrà ní ilẹ̀ yìí.
Ó mu wa yí ilé náà po ṣùgbọ́n èyí tí ó yà wá lẹnu jù níbi tí o ti n mu wa ká ni pe ìgbà tí a wọ inu iyààrá kan, kò sí nǹkan tí ó kù níbẹ̀ tí kò ni fi han ni.
Minisita tẹlẹ ri fun ọrọ katakara ati idokoowo, Okechukwu Enelamah ṣi oju BBC Yoruba si bi Naijiria ṣe pa a ti wọn kun un ti wọn fi ṣe daadaa loju tirẹ pe wọn kọkọ wale wa ronu si i ki wọn to tọwọ bọ ọ.
Ohun ti eleyii tunmọ si ni pe ko ni laanfaani lati gba bọọlu mọ ni saa ọdun yii.
Obìnrin náà dáhùn, ó ní, N óò fẹ́ ọ ìwọ ọlọgbọ́n ọkùnrin nítorí ìfẹ́ tí ó pé jùlọ ni ìfẹ́ tí ènìyàn kò lè sọ ìdí rẹ̀, bí ènìyàn bá fẹ́ràn ẹnì kan nítorí ojú rẹ̀ dára, bí ó fẹ́ ẹ nítorí ipò tí olúwaarẹ̀ ní, bí ó fẹ́ ẹ níttorí ìdílé rẹ̀ tí ó dára, bí ó fẹ́ ẹ nítorí ọgbọ́n orí rẹ̀, bí ó fẹ́ ẹ nítorí fáàrí rẹ̀, bí ó fẹ́ ẹ nítorí ọ̀rọ̀ ẹnu rẹ̀, bí ó bá sì fẹ́ ẹ nítorí ìrìn ẹsẹ̀ rẹ̀, ìfẹ́ náà kò jámọ́ nǹkan kan.
Obinrin ará Ṣunemu nì ni ó ń bọ̀ yìí!
Nítorí náà, ẹ̀yin àyànfẹ́ mi, gẹ́gẹ́ bí ẹ ti ń gbọ́ràn nígbà gbogbo, tí kì í ṣe nígbà tí mo bá wà lọ́dọ̀ yín nìkan, ṣugbọn pàápàá jùlọ ní àkókò yìí tí n kò sí lọ́dọ̀ yín, ẹ máa ṣe iṣẹ́ ìgbàlà yín pẹlu ìbẹ̀rù ati ìwárìrì.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Social Media Slay: Onílé kan bínú fi àwòrán iyàrá ayálágbé ré hàn lórí ayélujéra 1 Ọ̀wàrà 2019 Oríṣun àwòrán, @The Paper Àkọlé àwòrán, Awọn ololufẹ Weibo lanu silẹ lori bi iyara Lisa Li ṣe ri bii.
Eyi to fihan pe ko ji titi baalu fi balẹ ti gbogbo ero si sọkalẹ tawọn oṣiṣẹ ọkọ ofurufu naa ti lọ.
 Ó fi iṣẹ ́ yìí sílẹ ̀ láti máa kọ ìwé .
Ọgbẹni Garba Shehu sọ wipe awọn eeyan mẹtala ti won tusilẹ naa wa lọwọ ileesẹ ọtẹlẹmuyẹ Naijiria, ati wipe awọn ọmọogun Naijiria tin gbe awọn eniyan naa losi Abuja.
Ìbọn àti afẹ́fẹ́ aláta ní DSS fi tú wa ká lásìkò ìwọ́de fún ìdásílẹ̀ Sowore Ká máa sọ òyìnbó nínú eré Yorùbá ń ba àṣà wa jẹ́ - Damola Olatunji Ìjọba Ọyọ yàtọ̀ sí ti Ọṣun àbí Ekiti tí APC leè fi àṣẹ iléẹjọ́ lé dànù - Seyi Makinde Jálà epo bẹntiróò di N600 nítorí ibodè títìpa Nigba to n gbarata lori isẹlẹ yii, Alaga ajọ to wa fun akoso eto ibaraẹnisọrọ ni Naijiria, NCC, Umar Danbatta kede pe ofin naa ti n ni ipa ti ko dara lori awọn ọmọ Naijiria to n gbe lawọn ẹnu bode.
Oríṣun àwòrán, Kenechukwu/twitter Oríṣun àwòrán, Kenechukwu/twitter Ọjọ́ Ajé ló gbé ọ̀rọ̀ náà lọ sí ilé ẹjọ́, pé àwọn ènìyàn náà kó ipa ribiribi nínú ìfẹ̀hónúhàn EndSars, èyí tó padà yìí sí rògbòdìyàn Nínú ìwé ẹ̀sùn tó fi pẹjọ́ lo ti sàlàyé pé, gbogbo nkan ìní òun ló bàjẹ́ poo.
orin ìgbàlódé ni orin fújì .
Ìwọ tí ò ń kọ́ ẹlòmíràn, ṣé o kò ní kọ́ ara rẹ?
Nítorí náà, mo búra fún wọn ninu aṣálẹ̀ pé n kò ní mú wọn dé ilẹ̀ tí mo ti ṣèlérí pé n óo fún wọn, ilẹ̀ tí ó kún fún wàrà ati oyin, ilẹ̀ tí ó lógo jù ní gbogbo ilẹ̀ ayé.
Mo bá tún sọ̀rọ̀ mo ní, ki ni ìdí rẹ̀ ti ẹ fi ń sọkún nínú aṣọ jìngìnnì irú èyí?
Eeyan meji ọtọọtọ l'awọn ero dana sun lagbegbe ASAS ni Molete ati Oke Ado ni ilu Ibadan lọjọ Aje.
 Ó ń kọ opera , choral music , orchestral music àti chamber music .
Igba ti Buhari lọ China ni gbogbo won naa sẹlẹ Ṣé Atiku leè mú ìlérí àtúntò ìlànà ìṣèjọba ṣẹ?
Ninu ìjàkadì yín ẹ kò ì tíì tako ẹ̀ṣẹ̀ dé ojú ikú.
Goolu akọkọ Granit Xhaka ni saa bọọlu ọdun yi ni Arsenal fi ṣe Ade lori goolu meji ni abala kini idije naa.
NIS: Ẹgbẹ́ dókítà làwọn kò mọ sí ìrìnàjò dókítà 58 tí NIS dènà mọ́ láti lọ sí London
Ijọba apapọ si ti sọ saaju pe agbekalẹ abule Ruga yoo jẹ ki imọtoto to yẹ wa fawọn ẹran ta n jẹ nilẹ Naijiria.
Ijoba apaapo orile-ede Naijiria ti pa ase fun awon eleto abo lati se iwadi  ohun ti o sokunfa laasigbo to be sile ni ile igbimo asofin agba lorile-ede Naijiria ati jiji opa – ase gbe ,eyi ti o waye ni ojo “Ru Wednesday.
Oríṣun àwòrán, @zakzakky Àkọlé àwòrán, Awọn Shiite ni awọn ṣetan lati fi ẹmi wọn dii Aṣẹ ti wa lati ọdọ ijọba pe ki wọn kede IMN ni ẹgbẹ agbesunmọmi bayii.
Tí ó bá ti eniyan mọ́lé,ta ló lè tú u sílẹ̀?
Bo tilẹ jẹ wi pe ọpọlọpọ igbeyawo laarin awọn oṣere ni ki i fi bẹ tọjọ ni Naijiria, igbeyawo tọkọ-taya Olu Jacobs ati Joke Silva, jẹ apẹẹrẹ rere.
Ṣé wọ́n rò pé n óo dá wọn lóhùn tí wọ́n bá wádìí ọ̀rọ̀ lọ́wọ́ mi?
Aworan yiya ko jẹ tuntun sii nitori lati igba ewe rẹ ni o ti'n ya aworan ni ilu rẹ, Maputo tii se olu ilu Mozambique.
Nítorí náà àwọn tí wọn ń lépa mi yóo kọsẹ̀,apá wọn kò ní ká mi.
Ẹ̀yin òpè, ẹ kọ́ ọgbọ́n,ẹ̀yin òmùgọ̀, ẹ fetí sí òye.
NYCS sọ èyí di mímọ nínú àtẹjáde kan tí adari èto ìfọ̀rọ̀léde Adeyemi Adenike fí síta, sàla[yé pé nínú akọsílẹ̀ àwọn, o fi han pe Adeosun kọ̀wé ránṣẹ́ láti gbààyè, sugbọn ìwádìí yóò wáyé lóri ọ̀rọ̀ náà.
Bí ó ti ń lọ, bẹ́ẹ̀ ni ó ń ké pé, “Ha!
 O tun menu ba abewo re si orile-ede Naijiria nigba mewa otooto lasiko to  n sise lati ko apapo iko omo ogun jo lojuna ati koju awon omo ogun olote Boko Haram.
Ọkunrin kan wá láti Baaliṣaliṣa, ó mú burẹdi àkọ́so èso wá fún eniyan Ọlọrun, ati ogún burẹdi tí a fi ọkà-baali ṣe ati ṣiiri ọkà tuntun ninu àpò rẹ̀.
Oríṣun àwòrán, AFP Àkọlé àwòrán, Ọwọn epo bẹtiro wọpọ ni orilẹede Naijiria, eyi si maa n waye latari ẹkunwo epo tabi ikunsinu latọdọ awọn oṣiṣẹ elepo rọ̀bì Owo epo to le si ni awọn kan gbagbọ pe o n mu inira ba awọn to n gbe ni orilẹede Naijiria, nitori bi owo ounjẹ, ile, owo ọkọ, ati awọn nkan mi i ṣe lewo si.
Ninu atẹjade kan to fi sita lọjọ Aje o ni ileeṣẹ ọlọpaa ṣi n ṣe iwadii ọrọ naa.
Awọ eweko naa duro fun ọrọ aje Naijiria tii se eto ọgbin lasiko igba naa, eyiun ilẹ ti eto ọgbin ti n gbooro, ilẹ to lọra fun ohun ọgbin nigba ti awọ funfun tumọ si alaafia Ọjọ Kinni, osu Kẹwa ọdun 1960 ti Naijiria gba ominira si ni wọn fi asia Naijiria naa lọlẹ fun lilo, tijọba si san ọgọrun pọun (£100) fun Taiwo Akinkunmi, eyi tii se ọrinlerugba ati ẹyọ kan dọla, ($281), ta ba si sọ di Naira, o jẹ ẹgbẹrun lọna mejilelogoji ati aadọjọ naira, (₦ 42,150) Taiwo Akinkunmi pada si orilẹede Naijiria lẹyin ẹkọ rẹ lọdun 1963, to si pada si ẹka isẹ ọgbin to ti kuro tẹlẹ lati maa sisẹ titi di ọdun 1994 to fẹyinti Ọjọ Kọkandinlọgbọn osu Kẹsan ọdun 2014 ni ijọba apapọ fun Taiwo Akinkunmi ni ami ẹyẹ OFR nilu Abuja, lati mọriri ọgbọn inu ati ẹbun atinuda to lo fi gbe asia Naijiria, to jẹ oju ni gbese kalẹ Gẹgẹ bii ẹni ti isẹ ọwọ rẹ wu lori, Taiwo Akinkunmi maa n wọ asọ agbada toke tilẹ to jẹ awọ asia ilẹ Naijiria, eyi to tun ba asa Yoruba to ti wa mu Agbo ile baba Taiwo Akinkunmi to wa ni adugbo Ekotẹdo nilu Ibadan ni baba naa n gbe lẹyin to fẹyin ti lẹnu isẹ ọba tan, ti atijẹun si di ọtọtọ ọran Amọ pẹlu igbe awọn akọroyin, ijọba ipinlẹ Ọyọ, lasiko isejọba Ọtunba Christopher Adebayọ Alao Akala, kọ ile kan fun ni adugbo Ayepe, Academy loju ọna Iwo Road nilu Ibadan Koda, awọ eweko ati funfun, tii se asia ilẹ wa ni wọn fi kun ile ọhun Taiwo Akinkunmi ni iyawo, to si bi ọmọ, ilu abinibi rẹ, Ibadan si lo tẹdo si lọjọ ogbo rẹ titi di oni oloni.
Ẹ mọ iṣẹ́ tí ó rán sí àwọn ọmọ Israẹli, ọ̀rọ̀ ìyìn rere alaafia nípasẹ̀ Jesu Kristi, ẹni tíí ṣe Oluwa gbogbo eniyan.
Eyi ko yẹ ko ri bẹẹ rara.
Ṣugbọn àwọn mìíràn ń wí pé, “Elija ni.
Ileẹjọ fidi rẹ mulẹ pe iwe iforukọ silẹ awọn ọmọde eyi ti orukọ Gold wa nibẹ fihan pe lootọọ lọmọ naa wa ni ṣọọṣi lọjọ to di awati.
Bí wọ́n ti ń lọ tí wọ́n sì ń sọ̀rọ̀, lójijì kẹ̀kẹ́-ogun iná ati ẹṣin iná gba ààrin wọn kọjá, Elija sì bá ààjà gòkè lọ sí ọ̀run.
Lara awọn ọtọkulu to ti Alaafin ku ayẹyẹ ọjọ ibi ni oludije fun ipo gomina ipinlẹ Oyo fẹgbẹ oṣelu ZLP ninu idibo gbogbo ọdun 2019, Oloye Sharafadeen Alli.
Ìwọ ni mo gbé ojú sókè sí,ìwọ tí o gúnwà ní ọ̀run.
Èmi nìkan ni mo kù tí mo sì rí ìran ńlá yìí.
"ni gbogbo àwon tí wón gbó òrò òhún se pé; ""ènìyàn ti seé féràn erú ju omo bíbí inú rè lo?"
Akẹkọọ to ba si san owo oúnjẹ yii fun saa eto ẹkọ kan, tii ṣe naira kan ati aadọta kọbọ (N1.
Bi awọn miran si ṣe n gba ẹdinwo oṣu ni awọn kan n gbadura kiṣẹ maa bọ lọwọ wọn.
Ikán yóo jẹ wọ́n bí aṣọ,kòkòrò yóo jẹ wọ́n bí òwú;ṣugbọn ìdáǹdè mi yóo wà títí lae,ìgbàlà mi yóo sì wà láti ìran dé ìran.
O tilẹ ni igba mẹfa ni awọn ti ṣe bẹẹ ni ọdun to kọja.
A gbọ pe tilu-tifọn ni Olubadan fi ki awọn ijoye rẹ ọhun kaabọ pada s'aafin, ti Olubadan si sọ fun awọn ijoye naa pe, oun fi aaye gba ipade ipẹtu saawọ ọhun nitori alaafia, iṣọkan ati ilọsiwaju ilu Ibadan.
Ṣugbọn Gbajugbaja atọkun eto ori redio, Ifedayo Olarinde ti ọpọ mọ si Daddy Freeze sọ pe owo ẹru ni owo ori sisan lori obinrin tumọ si.
Nígbà tí ó rí i, àánú ṣe é.
Àwọn èèyàn t'ókùú fi sílẹ̀ lọ nikú nà l'ẹ́gba ìpayínkeke
- Ààrẹ Akufo-Addo Fídíò Number 12: Ghana yóò yan ìgbìmọ̀ fìdíhẹẹ́ Inú àwọn ọmọ Nàìjíríà dùn báyìí ju ti tẹ́lẹ̀ lọ - WHR Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Asa Trokosi nibi ti ọmọde ti n jiyan ẹsẹ mọlẹbi rẹ , wọpọ ni Ghana, Togo ati Benin.
Mo sọdá àwọn odò tí wọn kò jìn púpọ̀jù, mo sì rìn nínú àwọn igbó wọnnì pẹ̀lú.
Kete lẹyin ibura yii ni awọn eniyan gba pe aarẹ Buhari yoo kede ipo ti onikaluku a dimu gẹgẹ bi minista.
Bio ti le jepe, Netherland ko ni kopa ninu idije boolu agbaye ti yoo waye lorile-ede Russia lodun ti a wayi, sugbon ni bayi won yoo maa gbaradi lati kopa lodun 2022.
Ṣé kò yẹ kí orílẹ̀-èdè wádìí ọ̀rọ̀ lọ́dọ̀ Ọlọrun wọn?
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, EndSars, EndSwat Protest: Òbí agbábọ̀ọ̀lù Gbenga Tiamiyu Kaka àtàwọn míì tí ọlapàá pa sọ̀r Ẹwẹ, ikede jade pe wọn ti gba itusilẹ lọjọ Ẹti, ọgbọnjọ Oṣu kẹwaa.
Van Dijk ti kopa ninu idije mọkandinlọgọta to si ti gba ọpọlọpọ goolu sawọn.
Láti ọjọ́ tí mo ti ń rìn kiri n kò í tí ì rí ẹ̀dá tí ó ba ni lẹ́rù bí Òjòlá-ìbínú tí í ṣe olórrí ejjò ayé gbogbo.
Ohun kan ló dájú: Síṣe ní núdùlù, wọn a sèé, wọn sì ń jẹẹ́, ounjẹ yìí jẹ́ ìlúmọ̀ọ́ká àti ìtẹ́wọ́gbà lágbàyé gẹ́gẹ́ bi ounjẹ ti àwọn ènìyàn nífẹ̀ẹ́ sí.
Iṣẹ́ àkànṣe tí kò parí ni Buhari ń bọ̀ wá ṣí l‘Eko - Aráàlú figbe ta ‘Alẹ́ làwọn ọkùnrin fẹ́ bá mi jáde, torí mo kọ ilà’ Sunkẹrẹ Fakẹrẹ loju popo Awọn iwe iroyin oke okun kan tilẹ jabọ iroyin pe lọdun 2012, ninu gbogbo ilu ti sunkẹrẹ fakẹrẹ ọ̀kọ̀ wa lagbaye, ti ilu Eko lo gbegba oroke.
eleto idibo (Independent National Electoral Commission, INEC), ile-ise Ologun ati
Osun tribunal: Ta ni ilé ẹjọ́ yóò gbẹ́ adé ìdìbò gómìnà ìpínlẹ̀ Ọṣun fún?
Itan igbesi aye Wooli Oladele Ogundipe sọ pe idile rẹ ko fẹran ijọ alaṣọ funfun, nigba to wa ni kekere.
Nítorí pé wọ́n ti jẹ Jakọbu run;wọ́n sì ti sọ ibùgbé rẹ di ahoro.
Ọrọ naa jẹ eleyi to fẹ le diẹ nitori pe awọn musulumi lo pọju lariwa Naijiria ti awọn to gbe lẹyin eto ẹkọ yi si ni ọna ati pa ẹkọ Islamu lara ni ijọba fẹ da.
Àkọlé àwòrán, Oorun mu, ti oju ọjọ si dara laisi ifarahan ojo wẹli-wẹli kankan to lee ba eto ipolongo ibo naa jẹ.
Ọgbọ́n kún inú ẹni tí ó mòye,ṣugbọn kò sí ohun tí ó jọ ọgbọ́n lọ́kàn òmùgọ̀.
Àwọn ọ̀jọ̀gbọ́n onímọ̀jìnlẹ̀ ti fi yé wa pé ọ̀bìrìkìtì ni ilé-aiyé nṣe, kìí ṣe pẹlẹbẹ.
Nígbà tí ojó ìpíngún pé,Basòrun sàlàyé ohun tí Oba so sílè kí elémìí ó tó gbàá, ó sì ro Adéláyò Omo Oba láti tóka òkan péré nínú dúkìá bàbá rè tí yóò jogún kí àwon ó tó fa gbogbo dúkìá yóòkú fún Àyìnlá olórí erú Oba.
Ìpínlẹ̀ Kaduna tún ti dá olùkọ́ 4,562 tuntun dúró
Ipa tí a fẹ́ kó nínú ẹgbẹ́ yìí rọ̀ mọ́ gbígbé èdè Yorùbá lárugẹ, kí ó ma bàà di èdè tí kò ní ní alábòójútó ní ọjọ́ iwájú.
"Lootọ la fẹ ẹ ranwọn lọwọ, ṣugbọn a ṣi gbọdọ gba ọrọ ti yoo ran ijọba lọwọ lati le mura silẹ fun ọjọ iwaju, ati lati mọ igbesẹ to yẹ.
idoti to ti di oju odo agbegbe naa.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Coronavirus in Nigeria: Ààrùn Covid-19 ti ran ènìyàn 454 míràn ní Nàìjíríà 28 Ẹrẹ̀nà 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 5 Agẹmo 2020 Oríṣun àwòrán, Getty Images Awọn eeyan mẹrinlelaadọta o le ni irinwo tuntun ni ajọ NCDC to n mojuto itankalẹ ajakalẹ arun ni Naijiria fi sita lalẹ ana ọjọ Ẹti, Ọjọ kẹta, Oṣu keje, ọdun 2020 pe wọn ṣẹṣe lugbadi Covid 19.
Lóòótọ́ bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé ẹni tí ó ní ọ̀rọ̀ pàtàkì nínú tí kò rí ènìyàn láti sọ̀rọ̀ náà fún dàbí ẹni tí ebi ń pa tí ó rí oúnjẹ tí kò gbọdọ̀ jẹ, síbẹ̀ kì í ṣe ohun gbogbo tí àgbàlagbà bá rí ni àgbàlagbà lè sọ.
Ẹ máa pa ọjọ́ ìsinmi mọ́ nítorí pé ọjọ́ mímọ́ ni fún yín, ẹnikẹ́ni tí ó bá sọ ọ́ di aláìmọ́, pípa ni kí wọ́n pa á; ẹnikẹ́ni tí ó bá ṣe iṣẹ́kíṣẹ́ kan ní ọjọ́ náà, a óo yọ ọ́ kúrò lára àwọn eniyan rẹ̀.
a jẹ́ pé àrùn ẹ̀tẹ̀ gan-an ni ó wà ní ara ẹni náà.
Ohun tó bá wù yín ni kẹ sọ, iṣẹ́ ló ká mi lára - Ighalo Coronavirus ṣe bẹbẹ!
Naijiria , paapaa julo nipa iwa ipaniyan.
Àyẹ̀wò mélòó ní Afíríkà ti ṣe ?
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Banki agbaye se ẹyawo milionu 486 fun ina ọba ni Naijiria 16 Èrèlè 2018 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ipenija nla ni aisina ọba ni orilẹẹde Naijiria Banki agbaye ti kede ibuwọlu ẹyawo milliọnu ọrinlẹniwo ati mẹfa fun agbega ipese ina ọba ni orilẹede Naijiria.
Peller gbé 'gbá ìbò fún 2019 Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí kan sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
Ẹ má jẹ́ kí wọ́n tàn yín jẹ.
Sugbọn ẹni to mu omele lọwọ lo mọ ohun ti oun n fi omele sọ, Buhari ni àyàn to n lu ilu yii pe ki Olorun tẹ oloogbe si afẹfẹ rere ati pe oun ti ṣe abewo si ẹbi rẹ bi o ṣe yẹ.
Ó ní kí Josẹfu pàṣẹ fún wọn pẹlu kí wọ́n kó kẹ̀kẹ́ ẹlẹ́ṣin láti ilẹ̀ Ijipti, láti fi kó àwọn ọmọde ati àwọn obinrin, kí baba wọn náà sì máa bá wọn bọ̀.
Má bẹ̀rù, ọmọ mi, gbogbo ohun tí o bèèrè ni n óo ṣe fún ọ, nítorí pé gbogbo àwọn ọkunrin ẹlẹgbẹ́ mi ní ilẹ̀ yìí ni wọ́n mọ̀ pé obinrin gidi ni ọ́.
Nígbà tí Dafidi rí i pé wọ́n ń bá ara wọn sọ̀rọ̀ kẹ́lẹ́kẹ́lẹ́, ó fura pé ọmọ ti kú.
Se àlàáfíà ni gbogbo wa wà
Arsenal ko ba fidirẹmi lẹlẹẹkarun ni tẹlentẹle nigba akọkọ lati ọdun 1977 ki wọn o to f'akọyọ ni San Siro.
Bi o tilẹ jepe ‘Game of Thrones’ se afihan ihoho awọn eniyan, Ireke Onibudo se igbelarugẹ bibo ihoho ẹda ati igbeyawo laarin iyawo kan ati ọkọ kan.
awon asoju orile ede agbaye  soro nibi
Paṣan ti a fi na iyale.
Ṣugbọn ti obinrin naa bẹ ẹ pe ko mu suuru fun oun di ọjọ keji, ki oun fi ṣẹ owo ilẹ okeere to wa lọwọ oun si Naira.
Wọ́n jẹ́ ojilelẹgbẹta ó lé meji (642).
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Opo òunjé ilẹ̀ Gẹẹsi lo ni ewé yìí nínú Enìyàn ni lati sọ́ra nítori pé èyí to jẹ aláwọ ewé rẹ̀ léwu gidigidi o sì ni májèlé nínú.
eyi waye lẹyin ti ajọ to n ṣamojuto ajakalẹ arun, NCDC, kede esi ayẹwo ọgọsan eeyan to tun ṣẹṣẹ ni i.
Nígbà tí mo fi tọkàntọkàn pinnu láti ṣàkíyèsí ohun tí ó ń ṣẹlẹ̀ nílé ayé, mo rí i pé ọpọlọpọ eniyan ní ń lo agbára wọn lórí àwọn ẹlòmíràn sí ìpalára ara wọn.
Òtútù ò dára fún arúgbó, a fi ti onilé nã bá lówó lati san owó iná ti o gun òkè nitori àti tan ẹ̀rọ-amúlé gbónọ́.
Akowe ajọ naa lorilẹede Naijiria, Dudu Emeka wa fikun pe awọn ti ṣe oogun labẹle to koju aisan ẹjẹ, Sickle cell Anaemia, oogun ikọ ati bẹẹ bẹẹ lọ.
Kí Ọlọ́run má ṣe fi ni lé ọ̀tá lọ́wọ́, ìmọ̀ràn ọ̀tá dà bí ọbẹ̀ ìtàdógún ṣùgbọ́n ìmọ̀ràn ọ̀rẹ́ dùn ju oyin ìgàn lọ, ìdí rẹ̀ sì nìyí tí ó fi yẹ kí ọmọlúwàbí máa ronú kí  ó tóó gba ìmọ̀ràn tàbí kí ó tóó tàpá sí i, ṣùgbọ́n ọ̀rẹ́ mi ni ìwọ í ṣe, ìwọ Baba-onírùngbọ̀n-yẹ́úkẹ́, ìmọ̀ràn rẹ sì ti wọ̀ mí ní ibi kọ́lọ́fín agbárí lọ.
ẹnikẹni)Tendered ballot paper (Idibo to ni bosejẹ) : Eyi ni iwe idibo
Ọdún ayọ̀ laa ṣe láṣẹ Èdùmàrè
Bawo ni ijamba naa ṣe ṣẹlẹ?
Olùkọ́ tó fọmọọ tiẹ̀ sílẹ̀; Tó wá ń tọ́jú ọmọ ọlọ́mọ.
Ó pàṣẹ pé kí yìnyín rọ̀ sórí ilẹ̀,bẹ́ẹ̀ náà ni òjò wẹliwẹli,ati ọ̀wààrà òjò.
Orin ọpẹ́ yóo máa ti ibẹ̀ jáde wá,a óo sì máa gbọ́ ohùn àwọn tí ń ṣe àríyá pẹlu.
Asiko ojo naa si ni Ajirebi maa n lọgun fun araye pe omi tun ti ya wọnu ile oun, to si ba awọn dukia oun jẹ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Africa Eye: Ohun tí ọ̀rẹ́ mi fí sórí 'Social Media'ló wọ̀ mí lójú- Grace Ọ̀pọ̀ ló ṣì n ṣelédè lẹ́yìn Barrywonder!
Ìjọbá ti dóòlà àwọn akẹ́kọ̀ọ́ 340 ti wọ́n jí gbé ni GSSS Kankara, ìpińlẹ̀ Katsina Oríṣun àwòrán, Boko Haram Ìròyìn tó tẹ ilé iṣẹ́ BBC lọ́wọ́ sọ pé, àwọn ọmọ tó lé ni ọ̀ọ́dúnrún ni ilé ìwé GSSS Kankara ti wọ́n jí gbé tí gba òmìnir báyìí.
Ìdí tí mo ṣe fẹ́ yọ ayédèrú ìdí ńlá tí mo ní- Sophie Ìlú kò mọ ohunkóhun nípa iṣẹlẹ màálù tó kú nilu Ikarẹ- Oba Olukarẹ Ìgbà tí òògùn ẹ̀jẹ̀ ríru lè ṣiṣẹ́ jù rèé- Onímọ̀ Ó rẹ ẹni ọdún 49 tó ri ẹ̀wọ̀n ọgọ́ta ọdún he lẹ̀yìn tó bá ọmọ ọdún méjì lòpọ̀ Itedo-Ijowa ni Agbegbe Isanlu, nijọba ibilẹ Ila oorun Yagba ni a ti bi Pius nipinlẹ Kogi.
Dafidi Ṣẹgun Àwọn Ará Amoni ati Àwọn Ará Siria.
Laipẹ yii ni ọrọ ''Association of Stingy Men'' gba ori ayelujara pa ti awọn eeyan si n gba ọrọ naa bi ẹni n gba igba ọti.
Èrò àwọn ọmọ Naijiria ṣọ̀tọ̀ọ̀tọ̀ lórí Tinubu àti Abbo A ti mọ òbí 40 nínú 108 t'ọ́mọ wọn bọ́ ní ayédèrú ibùdó atúnwàṣe Ilorin - Ọlọ́pàá Kwara Ta ni Funmilayọ Ransome-Kuti?
 wón da lónà nínú mótò rè , nígbà tí òun ti mósálásí bò nínú ìfipá-gbà-joba tí ó jé ìjákulè nígbèyìn .
Nígbà tí ó yá, ọkunrin arúgbó kan ń ti oko bọ̀ ní alẹ́; ará agbègbè olókè Efuraimu ni, ṣugbọn Gibea ni ó ń gbé.
Ile igbimo asoju –sofin ti ro aare orile ede Naijiria muhammadu Buhari lati fi  iwe adehun ti awon igbimo fenuko le, lori ekunwo owo osu awon osise orile ede yii, ki won lee jiroro lori re, ki o lee dena iyanselodi ti awon osise ijoba tun fe gunle.
Nígbà tí wọ́n wádìí ọ̀rọ̀ lẹ́nu mi, wọ́n fẹ́ dá mi sílẹ̀ nítorí wọn kò rí ohunkohun tí mo ṣe tí wọ́n fi lè dá mi lẹ́bi ikú.
Ìsòrí kọkànlá yìí ni ó ti hàn gbangba pé Fọláṣadé, ọ̀kan nínú àwọn ìyàwó Orímóògùn ni ó jí owó rẹ̀ gbé.
yoo se dojude, pelu igbese ti won gbe wonyi.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Funke Adesiyan: Gbajúgbajà òṣèré Yollywood di olùrànlọ́wọ́ aya ààrẹ, Aisha Buhari 17 Ọ̀wàrà 2019 Oríṣun àwòrán, Facebook/Funke Adesiyan Àkọlé àwòrán, Funke Adesiyan, òṣèré Yollywood tó di olùrànlọ́wọ́ aya ààrẹ, Aisha Buhari Oṣere Yollywood, Funke Adesiyan ti di oluranlọwọ aya Aarẹ orilẹ-ede Naijiria, Aisha Buhari lori ọrọ abẹle ati awujọ.
ọkan lara awọn eto ti awọn ẹgbẹ oselu fi n se eto lati gbe oludije jade lẹgbẹ
oju popo,ise agbe ati ironilagbara fun awon ọdọ.
Ẹ wo òtítọ́ ọ̀rọ̀ nàá 16 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Oríṣun àwòrán, Instagram/@Aishambuhari Ọpọlọpọ eeyan lo ti n ṣe ariyanjiyan lori ayelujara Twitter ati awọn oju opo ayelujara ibaraẹnidọrẹ mii lori pe ṣe lootọ ni aya aarẹ, Aisha Buhari ko gbe ni Naijiria mọ?
Ki ọna ọfun o maa dun eniyan, igbẹ gbuuru, ara gbigbona, otutu, ati ori fifọ wa lara ami ti awọn eniyan tun ti sọ pe awọn n ri.
Nígbà tí wọ́n súnmọ́ etí ìlú, ó wo ìlú náà, ó bá bú sẹ́kún lórí rẹ̀.
“Ẹ gbọdọ̀ máa ṣe àjọ̀dún ọ̀sẹ̀ ìkórè àkọ́so alikama ọkà yín, ati àjọ̀dún ìkójọ nígbà tí ẹ bá ń kórè nǹkan oko sinu abà ní òpin ọdún.
Funke Akindele: Ajirebi ní Funke Akindele f'óun lówó t'óun fi gba ilé ni, kò ra ilé f'óun
Àwọn Ọmọ Israẹli Ṣẹgun Ogu Ọba.
Minisita soro idaniloju yii ,lojo Aiku,nigba to wa kedun pelu oba Mufutau Gbadamosi ti ilu Offa ni ipinle Kwara, lori ikolu awon adingunjale to waye niluu naa, ti awon eniyan metadinlogun , olopaa mesan an ati awon ara ilu mejo jepe olorun.
Akọṣemọṣẹ oniṣegun kan to mọ nipa iṣẹlẹ pajawiri Dokita Anthony Mgbolu sọ pe ti afẹfẹ buruki ba file wọ inu ọna ọfun lọ ,yoo sẹ akoba fun ọpọlọ ti eleyii yoo si mu ki ẹni naa ma le mi mọ.
Xenophobia: South Africa gbọ́dọ̀ dá owó ìtanràn padà kí wọ́n si fìyà jẹ àwọn ti ọ̀rọ̀ kàn -Sen Basiru
Lára wa tí à ń tẹnumọ́ ọn pé ó pọ̀jù [láti sọ̀rọ̀ síta tako ìjìyà Abẹ́lé] náà ni ẹni tí ó ń gba àwọn ọmọbìnrin, arábìnrin àti ìbátan lóbìnrin níyànjú láti máa fi ara da ìbáṣepọ̀ tí ó ń pani lára pẹ̀lú ọ̀rọ̀-ẹ̀tàn pé ọ̀rọ̀ tọkọtaya ò ṣe é dá sí, àwọn mìíràn á ní kí o tẹ̀síwajú bẹ́ẹ̀, bí ọ̀rọ̀ lọ́kọláya ṣe rí nìyẹn… Àwọn kan tilẹ̀ rò pé obìnrin lè ṣe gbogbo nǹkan, ṣùgbọ́n wọn ò gbọdọ̀ gbàgbé ‘ojúṣe’ wọn.
Àwa ní olú ilé iṣẹ́ẹ SEBIN headquarters àti pé wọ́n ní àwọn kò ní í [ní àhámọ́ àwọn] .
Ó ní, “Èmi ni OLUWA, tí mo dá ohun gbogbo.
 O ni; gbogbo ọna to yẹ ni ijọba ni gbogbo ipele n gba lati mu igbesi aye rọrun fun yin.
Gomina ni ijọba oun gba awọn olounjẹ to le ni ẹgbẹrun un meji lati maa gbe ounjẹ kaakiri ile iwe alakọbẹrẹ kaakiri ipinlẹ ọhun, fun eto ounjẹ ti ijọba n fawọn akẹkọọ.
Oríṣun àwòrán, eniola_badmus Ijọba pasẹ fun ileesẹ to n pin ina ọba ni Eko, EKEDC, lati pa ina ladugbo Lekki: Ori ayelujara gbona pẹlu iroyin tawọn eeyan kan n pin kiri pe ijsba Eko lo pasẹ pe ki ileesẹ amunawa mase fun adugbo Lekki ni ina ọba.
Tawọn alasẹ lorilẹede Naijiria ba lee gba abajade iwadi naa wọle, eyi yoo fun ọpọ awọn ileto ati ilu to ti fara kaasa ọwọja wahala ifọnka epo rọbi lanfaani lati gbe awọn ileesẹ mejeeji lọ sileẹjọ fun biba agbegbe wọn jẹ lai san owo gba-maa binu.
Kí a tó wí, kí a tó fọ ni àwọn ẹgbẹ ọdọ kan ti ko owo kalẹ ra fọọmu ìfèrongbà hàn láti kópa nínú ìdìbò Ààrẹ fún Buhari.
Oríṣun àwòrán, @NGRPresident Àkọlé àwòrán, Awọn agunbanirọ padanu ẹmi wọn lasiko awọ̀n eto idibo kan to ti waye ni Naijiria, ati ninu awọn iṣẹlẹ mi i.
Sunday Igboho wá ṣẹ lórí ahesọ ọ̀rọ̀ kan tó ní àwọn ọmọlẹ́yìn òun kọlu àwọn èèyàn Auxiliary ládùúgbò Soka nílùú Ibadan.
’ Ẹranko ìgbẹ́ kan ń kọjá lọ, ó sì tẹ ẹ̀gún náà mọ́lẹ̀.
Ṣugbọn àwọn ọmọ ìjọba ọ̀run ni a óo tì jáde sinu òkùnkùn biribiri, níbi tí ẹkún ati ìpayínkeke yóo wà.
Oríṣun àwòrán, Others Nkan ti wọn ṣe yẹn ko dara, paapa fun ẹni to ti jẹ aarẹ Naijiria lẹẹmeji."
Oríṣun àwòrán, others Irinajo oselu Omololu kò tán si ipo Kọmiṣọnna rárá nítorí ó tún díbo wọlé sípò gomina ní Ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́ lọ́dún 1983.
Amoṣun: Mo gba àṣẹ lọ́wọ́ Jonathan láti dá iléeṣẹ́ aláàbò sílẹ̀ àti ríra ohun ìjà olóró
yóo kú bí àwọn baba ńlá rẹ̀ ti kú,kò sì ní fojú kan ìmọ́lẹ̀ mọ́.
Pataki atẹjade naa ni lati pe akiyesi ijọba Naijiria si koko pe awọn oṣiṣẹ eleto aabo Naijiria n fiya jẹ awọn eniyan lọna aitọ.
 Busayọ Akọgun: Ibẹrẹ ọtun fun isẹ akọroyin ti mo yan laayo ni bi mo se darapọ mọ ileesẹ agbohunsafẹfẹ BBC jẹ.
Ẹni tí ó yó lè wo oyin ní àwòmọ́jú,ṣugbọn bí nǹkan tilẹ̀ korò a máa dùn,lẹ́nu ẹni tí ebi ń pa.
Biṣọọbu Oyedepo ni majẹmu ti Ọlọrun ti la kalẹ ninu iwe mimọ ti oun n tẹle ko le jẹ ki oṣi mọ ile oun laelae.
Ninu fọnran fidio ti o tẹ BBC lọwọ lati ile ẹjọ naa,a ri ti Pasitọ Babatunde sọkalẹ ninu ọkọ akero pẹlu awọn afunrasi mẹfa miran.
Nigba ti akọroyin wa fi ọrọ wa agbẹjọro rẹ lẹnu wo, o ṣalaye pe bi onibara oun ko ba ṣ si ofin, wọn yoo fi silẹ.
Bí o bá ti gbé iyawo, má ṣe wá ọ̀nà láti kọ aya rẹ.
 ajẹ ̀ bú àti olóde jẹ ́ lára àwọn àtẹ ̀ lé alárẹ ̀ .
Ojúkòkòrò àti olè ji jà Ìjọba Ológun àti Òṣèlú lábẹ́ Ìjọba-àpapọ̀ ti fa ebi, òùngbẹ àti àìsàn fún ará ilú.
Ninu àwọn ẹ̀yà ara wa, ahọ́n ni ó ń kó nǹkan ibi bá gbogbo ara.
Iroyin naa ni ko din ni eeyan mẹẹdogun to jẹpe Ọlọrun nigba ti awọn gende agbebọn to wọ asọ ologun ya bo awọn ilegbe kan lopopona Rukuba, to wa nijọba ibilẹ ariwa Jos, eyi ti ko jinna si ileesẹ ọwọ kẹta awọn ologun orilẹ-ede yii.
Bichi sọ èyí di mímọ̀ lásìkò tó pe àwọn oníròyìn jọ lati sàlàyé pé ti wọn ò bá wọ́gilé ìdìbò náà à jẹ́ wípe ilé ẹjọ ni wọn yóò fipàdé sí nítori gbogbo àwọn ènìyàn Kano ló ti fi han pé ẹgbẹ́ òṣèlú PDP ni àwọn fẹ́ dìbò fún.
Naomi Osaka lorukọ ọdọmọbirin naa oun si ni o se adinagboku fun Serena Williams lati ma gba ife ẹyẹ ẹlẹkẹrinle logun rẹ ninu idije Us Open Grand Slam.
Fún ọjọ́ kéjì léra, ìpínlẹ̀ Plateau gbé ipò kíní lórí àtẹ COVID-19!
Agbẹnusọ Ile naa wa pa a laṣẹ fun Akọwe agba Ile, Ọgbẹni Azeez Sanni lati kọwe iṣatilẹyin-fun, ranṣẹ si Ile Igbimọ Aṣofin-agba yii, lati fi kẹdun pẹlu wọn.
” Níbi ìpakà Arauna ará Jebusi kan ni angẹli náà wà nígbà náà.
kí gbogbo eniyan lè bu ọlá fún Ọmọ bí wọ́n ti ń bu ọlá fún Baba.
Super Eagles gba iṣẹ́ lọ́wọ́ Seedorf olùkọ́ni Indomitable Lions Cameroun CAN kò rán ẹnikẹ́ni lọ ṣọ́ọ̀ṣì COZA, iṣẹ́ ara wọn ní wọ́n lọ jẹ́ -Samson Ayokunle Yinka Ayefele di bàbá ìbẹta Wá gbọ́ ìmọ̀ràn tí Jonathan fún Buhari lórí ọmọ Fasoranti tó kú!
Ẹwẹ bi ẹ ko ba tii gbojusoke wo aworan to wa ninu fidio yii, ohun ti ẹ n gbọ lasan a jẹ ki ẹ ro pe Adewale Ayuba lo n kọrin ni.
Ọpọ ọmọ Naijiria lo tako igbesẹ fasiti Babcock nigba naa, lori bi wọn ṣe fi ọwọ osi juwe ile fun akẹkọbinrin naa ti wọn n ba lopọ ninu fidio to lu ori ayelujara pa.
Lóníì ipinlẹ Imo ni ìlú mẹ́tàdinlogojiléẹgbẹ̀ta pẹlu ọba wọn lọ́tọ̀ọ̀tọ ti o si jẹ gómìnà Okorochanáà lo yan wọn IPINLẸ OYO Ní ìhà Gúúsù-Iwọ̀-òòrun Nàìjíríà Ìpinlẹ̀ Oyo, àwọn ti koju ǹkan to farapẹ irú ǹkan bayiìí laipẹ yìí nígbà ti Gomina Ajimobi àti Oba Saliu Adetunji to jẹ Olubadan ti ìlú Ibadan Oríṣun àwòrán, @AAAJIMOBI Àkọlé àwòrán, Governor Ajimobi fìdírẹmi nínú ìpo ṣẹnatọ to dije fún lọdun 2019 lẹ́yìn to ti ṣe Gomina Oyo léèmèjì Ní inú oṣù kẹ́jọ ọdun 2017 Ajimobi sún àwọn mogaji mọkanlélógun sí ipò ọba èyi to mu wọn duro ni ipò kan náà pẹ̀lú Olubadan.
Ère wọn dàbí aṣọ́komásùn ninu oko ẹ̀gúsí,wọn kò lè sọ̀rọ̀,gbígbé ni wọ́n máa ń gbé wọnnítorí pé wọn kò lè dá rìn.
Agba awo naa ni ohun to dara ju ni ki awọn eeyan maa duro ti nnkan won, ki wọn maa si ṣe ojukokoro si obinrin olobinrin.
Wọn yóo run èso ọgbà àjàrà yín, ati igi ọ̀pọ̀tọ́ yín.
Ojú yóo ti gbogbo àwọn tí ó kórìíra Sioni,a óo lé wọn pada sẹ́yìn.
18 Ọ̀pẹ̀̀ 2018 Hridoy Sarkar tó jẹ ọmọ ọdún mejidinlogun ni ọmọ gende náà ti iya rẹ pọn ti aworan wọn jade lori ayelujara kaakiri.
" Ẹwẹ wọn ti gbe awọn to fara pa lọ si ile iwosan fun itọju kanmọkanmọ.
Ẹni tí ó jẹ́ olórí láàrin wọn yóo gbé ẹrù rẹ̀ lé èjìká ní alẹ́, yóo sì jáde kúrò nílùú.
Ìdí nìyí tí mo fi ń fi ìtara sọ̀rọ̀.
Mò ń ba yín sọ̀rọ̀ bí ọlọ́gbọ́n.
Àwọn iranṣẹ Benhadadi ti ń ṣọ́ Ahabu fún àmì rere kan tẹ́lẹ̀.
eyi,ninu ọrọ agbenusọ Ile Igbimọ Aṣofin Ipinlẹ Eko, Aṣofin Mudashiru
Awon asoju igbimo naa yoo pada wa sorile ede Naijiria ni ojo kejilelogun , osu kefa , 2018 , lojo ti iko agbaboolu orile ede Naijiria Super Eagles yoo maa koju iko agbaboolu ti orile ede Iceland nibi ipele keji ,boolu agbaye to n lo lowo lorile ede Russia.
Getty Iye adùn suga Giraamu 35Odiwọn suga to wa ninu agolo 330ml Coca-cola kan MejeIye to jẹ ni odiwọn ṣibi ṣuga 12.
”Gomina Ortom ni ijoba ko ni pẹ
A ṣe sùúrù tó, ọmọ wa ló gbọ́dọ̀ jẹ́ ọ̀gá fásitì UI lọ́tẹ̀ yìí - àkóríjọ́ ẹgbẹ́ ọmọ Ibadan Kí ni ìjọba Ogun sọ nípa N25, 000 owó àyẹ̀wò COVID-19 fáwọn akẹ́kọ̀ọ́ tí yóò wọlé padà?
Lẹ́yìn náà, Solomoni pe gbogbo àwọn àgbààgbà Israẹli jọ, àwọn olórí ẹ̀yà, ati àwọn baálé baálé ní ìdílé Israẹli ati ti Jerusalẹmu, láti gbé àpótí majẹmu OLUWA láti Sioni, ìlú Dafidi, wá sinu tẹmpili.
Eyi waye laatari ipade ti o ye ko waye leni ojo isegun(Tuesday)laarin awon toro kan gbongbon nile igbimo ohun.
Adura mi ni pé kí ìfẹ́ yín máa gbòòrò sí i, kí ìmọ̀ yín máa pọ̀ sí i, kí ẹ túbọ̀ máa ní làákàyè sí i, 
Laarin Olori ana ni aafin Iwo, Olori Chanel Chin Ninu ifọrọwerọ kan to ṣe eleyi to n ja ranyinranyin lori afẹfẹ bayii, olori ana naa ni oun ti ba oluwo lori obinrin ọmọ ọdun mẹtala kan ri ti wọn n lajọṣepọ lori ibusun toun ati Oluwo n sun.
Awon asoju ajo EU so pe, ajo isokan ile Europe ti setan lati se alekun ilopo meji owo ti won n na lori apapo awon omo-ogun, ti won n se ise-akanse  igbogun ti awon omo-ogun olote ti won wa ni ekun  Sahel, lapa iwo-orun ile Africa.
Piri lologo n ji, a kii bokurun eye lori ite.
Kí ni kí n tún wí?
Fayose: Awọn to wa nijọba Buhari ko lee jẹ ki Boko Haram dẹkun
Ninu ọrọ awọn to sọrọ nibi ipade naa to waye ninu gbọgan Kayode Jakande ni gbagede Ile Igbimọ Aṣofin naa sọ pe ijọba ipinlẹ yii ko lẹtọọ lati ṣalekun owo-ori ilẹ naa bẹẹ.
Ninu atẹjade ti wọn fi sita, Ile itaja nla to wa lati ilu Cape Town lorilẹede South Africa yii sọ pe esi ere ti awọn ri lọdun yii ko fiṣẹ yin awọn rara latọdun ti wọn ti n taja ni Naijiria.
”O tun so pe “awon iresi ti won fi oko epo robi ko naa, lewu fun ilera awon eniyan.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Idibo yii yoo fidi mulẹ bi awọn aṣofin agba ba dibo sapa kan naa lori rẹ.
O wa ń para poro pé irú àwọn ìwà ọ̀daràn báyìí kò yẹ kó máa wáyé làwọn Ìpínlẹ̀ àti orílẹ̀ èdè tí ìjọba ti ń ná owó gọbọi lórí ìpèsè eto ààbò àti mímú adinku bá àwọn ìwà ọ̀daràn loniran ń rán.
Mo kó àrùn Coronavirus lẹ́yìn tí mo ṣalábapàdé ẹni tó ní àrùn náà lára - Idris Elba Èèyan 35 ló ti ru àrùn Coronavirus la ní Naijiria Wo àwọn irọ́ ti ọ̀pọ̀ ń pa nípa Coronavirus!
Iniesta dágbére fun Barcelona Fàyàwọ́ ọmọnìyàn kó ọmọ ilé ìwé ọgọ́rùn ún Ìwádìí bẹ̀rẹ̀ lórí ilé alájà tó jó ní Grenfell Gbọ iroyin iṣẹju kan BBC Fidio wa fun toni Àsá Trokosi tó ń fi ọmo jìyà ẹ̀sẹ̀ mọ̀lẹ́bi rẹ̀, wọ́pọ̀ ní Ghana, Togo àti Benin.
Mohammed Umar di alákòóso tuntun fún àjọ EFCC Ẹ wo ọ̀gọ̀ọ̀rọ̀ èèyàn nílé Tunde Braimoh tó jáde láyé Ìdùnnú ṣubú layọ̀!
Nígbà tí Isley Lynn rántí ìgbà àkọ́kọ́ tó ní ìbálòpọ̀ gẹ́gẹ́ bí amúgbálẹ́gbẹ̀ẹ́ ọ̀dọ́, ó ṣàpèjúwe rẹ̀ gẹ́gẹ́ bí èyì tí kò jọ ìgbà àkọ́kọ́.
Angẹli OLUWA kan wá, ó jókòó lábẹ́ igi Oaku tí ó wà ní Ofira, igi Oaku yìí jẹ́ ti Joaṣi, ará Abieseri.
 cordellia ( 2006 : 33-36 ) , sọ fún wa nínú ìtàn àkọ ́ kọ ́ pé odùduwà fi ẹ ̀ wọ ̀ n rò kalẹ ̀ pẹ ̀ lú àwọn igba irúnmọlẹ ̀ ( 200 deties ) láti ọ ̀ run láti wá tẹ ilé-ifẹ ̀ dó .
Ọkọ agbepo nla ni ijanu ọkọ rẹ da iṣẹ silẹ to si yi danu le ori ọkọ meji ti awọn ọkọ naa si jona raurau lẹsẹkẹsẹ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Sara-Jayne King: Ọ̀nà ayé mi dàrú torí òbí mi ta mí nù fún alágbàtọ́ 5 Agẹmo 2019 Ọdun 1980 ni wọn bi Sara-Jayne King silẹ South Afrika, lasiko ti awọn eebo amunisin n dari orilẹede South Afrika, awọ rẹ si jẹ amulu-mọla dudu ati funfun bi o tilẹ jẹ pe iya rẹ jẹ alawọ funfun, idi si ree to fi lọ faa kalẹ fawọn obi alagbatọ ti wọn jẹ alawọ funfun, pe ki wọn fi se ọmọ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, FFK: Buhari ló ń fún àwọn Fulani láàyè láti máa pa ènìyàn' Ogun ẹlẹyamẹya ti maa n figba gbogbo ṣẹlẹ laarin awọn Fulani ati awọn eniyan ẹya Dongon ni aarin gbungbun Mali tipẹ.
Wo ǹkan tó yẹ kí o mọ̀ nípa Joe Biden, tó ń kojú Trump nínú ìbò America Ibú-owó Bloomberg fẹ́ ta kànùngbọ̀n pẹ̀lú Trump nínú ìbò ààrẹ Amẹrika Jẹ́ kí a jọ sọ àǹfàní US fún Nàìjíríà -Osinbajo US election 2020: Bi kò tilẹ̀ wọlé, ẹ wo ayípadà tí Ààrẹ Trump mú bá awọn orilẹede ní àgbáyé Gbogbo aadọta ipinlẹ to wa lorilẹ-ede Amẹrika lo ti buwọlu abajade ibo naa.
Ninu atẹjade kan ti Adari Iroyin fun ikọ ọmọogun Naijiria, Ọgagun Aminu Iliyasu fi lede ni, awọn agbesunmọmi Boko Haram meje lo ku ninu ado oloro to bu gbamu naa, leti ẹba ọna ti wọn fi dẹkun si, ti mẹjọ si farapa.
Muiz ni pe opin ọsẹ ni awọn maa n ya fidio naa ko ma lè pa ẹkọ awọn lara.
Atẹjade naa ni ọkunrin kan ti wọ̀n n pe orukọ rẹ ni Kazeem Agbabiaka Ajetunmọ̀bi, to n gbe nilu Oke-mẹsi Ekiti, lo ransẹ pe asofin Timothy Owoẹyẹ, to si fi han awọn eeyan kan to ni wọn yoo se iwẹnumọ fun-un.
Arun Alzheimer wa lara arun ti ounjẹ ajẹju le ko ba ọpọlọ wa nitori na ki a jẹun ni ìwọnba ni imọran awọn oniṣegun fun itọju ara.
Chelsea kéde Frank Lampard gẹ́gẹ́ bíi olùkọ́ni tuntun
”Ewe, Super Eagles yoo maa gbaradi lati gba ifsewonse olorejore pelu orile-ede Czech Republic, England ati DR Congo fun ipalemo idije agbaye naa.
Ìpele ikọ̀ mẹrindinlogun Zimbabwe vs Kenya.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ọ̀pọ̀ ẹ̀mí sọnù sínú ìjàmbá iná l'órílẹ̀èdè Ghana 22 Ẹrẹ̀nà 2019 Oríṣun àwòrán, TV3 GHANA Ogunlọgọ eniyan lo ti padanu ẹmi wọn lẹyin ti ọkọ bọọsi meji kọlura wọn laarin gbungbun Ghana.
“Nítorí náà, sọ fún un pé, èmi OLUWA àwọn ọmọ ogun ní ‘mo mú un wá láti inú pápá, níbi tí ó ti ń da ẹran, pé kí ó wá jọba lórí, àwọn eniyan mi, Israẹli.
Bí ẹnikẹ́ni bá rí arakunrin rẹ̀ tí ó ń dẹ́ṣẹ̀ kan, tí kì í ṣe ẹ̀ṣẹ̀ tí ó jẹ mọ́ ti ikú, kí ó gbadura fún un, Ọlọrun yóo fún un ní ìyè.
” Ó bá sọ orúkọ rẹ̀ ní Peresi.
Oríṣun àwòrán, Facebook/Nigeria Presidency Àkọlé àwòrán, Àrẹ̀mọ olóògbé MKO Abiọ̀la, Kọla, gba àmì ẹ̀yẹ ní orúkọ gbogbo ẹbí Abiọla Oríṣun àwòrán, Twitter Àkọlé àwòrán, Abiọla kú ní ọjọ kèje osù keje, ọdún 1998 lẹ́yìn ìdìbò sípò ààrẹ ti gbogbo ènìyàn gbàgbọ́ pé òun ló jáwé olúbori Oríṣun àwòrán, Facebook/Nigeria Presidency Àkọlé àwòrán, M.
OLUWA ní: “Gbogbo eniyan ni yóo máa pa òwe yìí mọ́ ìwọ Jerusalẹmu pé: ‘Òwú ìyá gbọ̀n ni ọmọ óo ran, bí ìyá bá ti rí ni ọmọ rẹ̀ obinrin yóo rí.
Nígbà tí Dafidi gbọ́ pé àwọn ará Filistia ń gbógun ti àwọn ará Keila, wọ́n sì ń jí ọkà wọn kó ní ibi ìpakà, 
ti o n soro lati enu ogbufọ, ni o ti ju ọgọ́rùn
Fidio bi awọn ajafẹtọ ọmọniyan ati awọn ọlọpaa ṣe doola ọmọ naa wa lori ayelujara.
O ni ki obi ati alagbatọ fi ibẹru Olorun tọ awọn ọmọ wọn ki wọn si jẹ ki wọn mọ nipa iṣẹ ati ere awọn akikanju.
 Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ohun tẹ́ẹ gbúdọ mọ nípa kókó orí ọyàn yín lásìkò fífọ́mọlọ́yàn Èèyàn 16 kú lẹ́yìn tí bàálù Air India já lulẹ̀ , tó sì kán sí méjì ní Kerala Àgbáríjọ àwọn nọ́ọ̀sì fẹ́ gbé Olamide Baddo lọ sílé ẹjọ́ fún ìbanilórúkọjẹ́ Inú odò ni wọ́n ti rí òkú ọmọ ọdún méjì tó sọnù l'ọ́jọ́ ọdún Eid nílùú Ibadan Iléeṣẹ́ ìjọba méjì NIPOST àti FIRS, fẹ̀dí ara wọn síta lórí Twitter O tẹ̀siwaju lati sọ pe akọbi ọmọ oun, Kaosara jẹ ọmọ ọdun mẹjọ, ti eyi aburo, Hassanat si jẹ ọmọ ọdun mẹrin aabọ."
Aarẹ Buhari fi kun un pe ijọba oun ti dari ajọ to n ri si eto owo oṣu fawọn oṣiṣẹ ọba lorilẹede Naijiria lati tete ṣe iṣẹ lori afikun owo oṣu awọn ọlọpaa atawọn oṣiṣẹ ajọ alaabo yoku lorilẹede NAijiria ki o lee kun oju iwọn.
lo dibo yan enikeni ti won ba nifee si  lojuna ati tun fese isejoba tiwa-n-tiwa
Òun ló fìmọ̀ mọ ẹni tí ò mọ̀ lọ́jọ́sí.
Ọmọ meji ni baba rẹ bi, to si ko ẹbi mọra Omuwẹ to dantọ ni Fagunwa, to si maa n doola ẹmi awọn eeyan ati ẹru to ba fẹ ba omi lọ amọ iku odo lo papa pa omuwẹ rẹ.
Dino Melaye ni oun lo maa rẹrin igbẹyin lori gbogbo iṣẹlẹ yii.
Wọ́n jọ kan àwọn ọkọ̀ ojú omi tí yóo lọ sí ìlú Taṣiṣi.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Osun Osogbo: Àtáója ní káwọn èèyàn má a bọ̀ wá bọ Ọ̀ṣun lónìí, torí kò ṣe é jígbé, Ki lo fa 'Blue film' lojubọ Ọṣun?
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Akomolede ati Asa lori BBC: Olùkọ́ Kikelomo Ogunboye tan ìmalẹ̀ sí ìwà olè ọ̀gá ọlọ́pàá Eyi to tumọ si pe, ki eeyan to lee di aarẹ lorilẹ-ede Amẹrika, o kere pin, igba o le aadọrin lara awọn ọmọ igbimọ yii lo gbọdọ dibo fun un.
“Ọmọ-ẹ̀yìn kò ju olùkọ́ rẹ̀ lọ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Bí rere ni àbí búburú, wo ohun tí Covid-19 leè ṣe sí àgọ́ ara rẹ Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 3 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 5 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Wọ́n bá ka àwọn ọmọ ogun, wọ́n sì rí i pé Jonatani ati ọdọmọkunrin tí ń ru ihamọra rẹ̀ kò sí láàrin wọn.
“Bí ẹnikẹ́ni bá lu eniyan pa, pípa ni a óo pa òun náà.
Igba akọkọ ni yii ti wọn maa yege lati dije ninu ife ẹfẹ ẹyẹ Afrika.
Olówó-ayé, Olówó-ayé, ara kò le bí?
Ilé Aṣòfin Àgbà fòǹtẹ̀ lu N30,000 owó oṣù òṣìṣẹ́ Ẹlẹ́rìí 400 ni yóò tako Buhari lórí èsì ìbò - Atiku Ìlànà àjọ LASBCA rèé lórí ilé wíwó ní ìpínlẹ̀ Eko A gba ìwé ìpẹ̀jọ́ ₦200m lọdọ mọlẹbi Sugar - UCH Seyi Makinde figbe ta lórí bí Ajimobi ṣe ń ná owó ìlú Ṣugbọn Atiku ati ẹgbẹ PDP, ti wọn jẹ olupẹjọ ni, magomago wa ninu esi idibo ti ajọ INEC kede naa.
8 wọlé lójúmọ́ lẹ́yìn tíjọba ti ẹnu bodè -Ali.
O ni Buhari fun ra rẹ lo nigba to gori aleefa gẹgẹ bi ọgagun olori orilẹede Naijiria lọjọ kọkanlelọgbọn oṣu kejila ọdun 1983 pe awọn ile iwosan ni Naijiria ti di ibi ti awọn eeyan ti n ri awọn dokita lasan an.
O sọ fun BBC Yoruba pe Dating , Construction, awọn tó ń ṣe credit card, wire-wire, ati oniruuru orukọ ni iṣẹ awọn n jẹ.
Alukoro ileeṣẹ ọlọpaa sọ pe wọn ti gbe oku rẹ lọ si ile igbokupamọ si bayii fun ayẹwo.
Solomoni ati àwọn ọmọ Israẹli ṣe Àjọ̀dún Àgọ́ Àjọ níbẹ̀.
Ayẹyẹ yiyan awọn minisita naa ti n waye lẹyin ti aarẹ ti fi orukọ awọn mẹtalelogoji ransẹ si ile igbimọ asofin nilu Abuja fun ifọwọsi.
Ọmọ-ẹ̀yìn Jesu kan wà ní Damasku tí ń jẹ́ Anania.
Nítorí pé wọ́n bo gbogbo ilẹ̀ patapata, tóbẹ́ẹ̀ tí gbogbo ojú ọ̀run ṣókùnkùn dudu, wọ́n sì jẹ gbogbo ewé, ati gbogbo èso tí ń bẹ lórí igi, ati koríko tí ó ṣẹ́kù tí yìnyín kò pa.
" Mi ò to iṣẹ́ Regina Daniels rárá kí n tó fẹ́ ẹ láàrin ọ̀sẹ̀ mẹ́ta, mo sì tún le fẹ́ ìyàwó míì - Ned Nwoko Àwọn Ọba alayé ní Naijiria ṣàbẹ̀wò sí Ọba Eko, Gómìnà Eko àti Bola Tinubu Lẹyin ìwọ́de EndSARS Ohun tó yẹ kẹ́ẹ mọ nípà olùdíje mèjì tó lágbára nínú ìdìbò Ghana rèé Àyà mi já nígbà tí Ganduje rọ Sanusi lóyè Emir Kano tó fi Bayero síi, ṣùgbọ́n.
Lọdọọdun ni omiyale agbara ya ṣọọbu ma n ṣe akoba ni ipinlẹ Ogun.
ati àwọn ìlú tí ó ń kó àwọn ohun èlò rẹ̀ pamọ́ sí, ati àwọn ìlú tí ó ń kó kẹ̀kẹ́ ogun rẹ̀ sí, ati àwọn ìlú tí àwọn ẹlẹ́ṣin rẹ̀ ń gbé, ati gbogbo ilé yòókù tí ó wu Solomoni láti kọ́ ní Jerusalẹmu, ní Lẹbanoni, ati ní àwọn ibòmíràn ninu ìjọba rẹ̀.
Orukọ rẹ lori itage rẹ ni ''G-Fresh''.
Ìgbà tí o sì pẹ́ tí a ti jókòó ni obìnrin kan pe ọ̀kan nínú àwọn ìránṣẹ́ ilé náà pé kí ó pe ọba wá wí pe iṣu tí òun ṣe ti jiná kí ọba wá gún iyán ní ẹ̀yìnkùnlé.
Atẹjade naa sọ pe aarẹ yoo sọrọ lori iṣepataki ki awọn orilẹ-ede to jẹ ọmọ ẹgbẹ OIC wa ni iṣọkan lati le jọ koju ipenija bi awọn agbesumọmi ti wọn n da rogbodiyan kalẹ kaakiri.
 Ìwé tí ó lè ṣe èyí ni ìwé tuntun yìí .
- Yinka TNT Bawo ni idibo ijuwe ile fawọn oludije yoo ṣe lọ ni ti ọdun yii?
pẹlu ìdámẹ́ta òṣùnwọ̀n hini ọtí fún ẹbọ ohun mímu; yóo jẹ́ òórùn dídùn sí OLUWA.
Kí ẹ̀yin ọkọ náà máa fi ọgbọ́n bá àwọn aya yín gbé.
Ṣugbọn wọn pada gba ominira lẹyin ọjọ perete.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Afeez Agoro: O ṣòro fún mi láti wọ Danfo jáde Netherlands (1988) Aṣọ naa jẹ ọkan lara eyi ti awọn eniyan n wárí fún ni gbogbo igba.
Abiodun sọ eleyii lasiko to lọ ṣabẹwo si awọn ẹbi Kashamu lẹyin to doloogbe.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ijinigbe: BBC ṣe ìwádìí bí ikọ̀ IRT ṣe ń gbéjà ko awọn ajinigbe lójú Ijọba ni iṣẹ yoo bẹrẹ ni awọn ipinlẹ ti wọn ti faramọ kikọ aàgọ́ Fulani ni ipinlẹ wọn.
Buhari, Obasanjo ṣe'pade nilu Abuja Ni ipade AU Buhari ati Obasanjo d'ọrẹ apapandodo Ọbasanjọ ni to ba jẹ pe lootọ lawọn oku maa nriran ri awọn alaaye, ‘awọn obi mi yoo maa fi ẹmi imoore wọn han si awọn eeyan to sisẹ pọ pẹlu mi lati ri pe mo se awọn aseyọri yii’."
Sugbọn losu kẹta ọdun 2019, olori Mariam naa bi ọmọkunrin kan lẹyin ọsẹ mẹta ti olori Mojisola bimọ Olori Anuoluwapo Adeyemi: Oríṣun àwòrán, queenmoji_gloo Instagram Ẹgan ni hẹẹ, olori Anuoluwapo naa rẹwa lobinrin, ti ko si se fi ọwọ rọ sẹyin laarin awọn ẹlẹ Daddy to wa ni aafin Ọyọ.
Lootọọ ni pe ko si ẹni to laarun covid-19 nibẹ, ṣugbọn ajakalẹ aarun coronavirus si ṣakoba fun wọn lọpọlọpọ.
Nígbà tí ó wo ọ̀tún, tí ó wo òsì, tí kò rí ẹnìkankan, ó lu ará Ijipti náà pa, ó sì bò ó mọ́ inú yanrìn.
Ní àkókò tí mo ṣìnà yìí, n kò lè fi ẹnu mi sọ fún àwọn ènìyàn, ó sì ṣòro fún ọwọ́ mi láti kọ fún àwọn aráyé, gbogbo àwọn nǹkan àjèjì àti nǹkan ìjìnlẹ̀ tí mo rí, tí mo gbọ́, tí mo bá lò, tí ó sì ṣe alábàápàdé mi.
Ọkùnrin yìí wí fún un pé kì í ṣe òun ṣùgbọ́n kòo gbọ́, ó ní àfi bí ó bá sọ nǹkan tí ó ń pa á lẹ́rìn-ín fún òun.
Iye awọn eekan to ti lọ baa kẹdun tun le ọkan sii ni owurọ ọjọ Aiku nigba ti igbakeji aarẹ orilẹ-ede Naijiria, Ọjọgbọn Yẹmi Oṣinbajọ pẹlu fi ẹsẹ kan de ile rẹ ni ilu Akurẹ.
" Simi èré ṣíṣé, simi eré ṣíṣe, "" bó se sọ èyí ló búsẹkún, ""Kìí ṣe èmi ní èyí'' Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, R Kelly ń sukun lóri TV bó ṣe kọ ẹ̀sun ìfipábáni lòpọ̀ ""Gbogbo yín ń gbìyànjú lati pa mí?"
Lassa Fever: Ṣe ẹ rí eku tí ẹ̀ ń pè yẹn, oúnjẹ tó dára ni
Mohammed ni awọn ọkunrin mẹta to ni ipenija ilera lawọn ti ko lọ si ile iwosan ni kete ti wọn balẹ.
Ó tún fi kún un fún wọn pé, “Bí ẹnìkan ninu yín bá ní ọ̀rẹ́ kan, tí ó wá lọ sọ́dọ̀ ọ̀rẹ́ yìí ní ọ̀gànjọ́ òru, tí ó sọ fún un pé, ‘Ọ̀rẹ́ mi, yá mi ní burẹdi mẹta, 
Kọmiṣọnna ohun elo omi Arinola Lawal lo jẹ kọmiṣọnna fun ile iṣẹ ijọba to n ṣamojuto ohun elo omi mimu nipinlẹ Kwara.
“Gbọ́, ìwọ adití,sì wò ó, ìwọ afọ́jú, kí o lè ríran.
Dafidi sì rú ẹbọ sísun ati ẹbọ alaafia sí OLUWA.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ẹ dín agbára ìjọba àpapọ̀ kù, kẹ ṣì ṣe àgbékalẹ̀ ọlọ́pàá ìpínlẹ̀ - Tinubu bẹ̀bẹ̀ Wo eyi to súnmọ́ ọ nínú àwọn ibùdó 203 fún ìforúkọsílẹ̀ fún NIN rẹ Adigunjalè méjì ko ìjàmbá ọ̀kadà lẹ́yìn ìṣẹ́ ibi n‘Ibadan, ọ̀kan kú lójijì, aráàlú dáná sun èkejì Àwọn ohun kàyéèfì tó le mú kí ọmọbìnrin ní oyún ìju Ìrẹ̀sì kò gbọdọ̀ wọlé níbáyìí ta ṣí ẹnu bodè padà - Ìjọba àpapọ̀ Jide Kosoko forin sẹ́nu pé òun ni igi lẹ́yìn ọgbà Mr Latin lórí ipò ààrẹ TAMPAN tó wà Ó pé ọdún mẹ́wàá tí Barrister kú; wo ǹkan tó yẹ láti mọ̀ nípa rẹ̀ gẹ́gẹ́ bíi olórin, tẹ̀wé-tẹ̀wé, akọ̀wé àti sọ́jà Àìmọ̀kan ló mú mi hu ìwà tí mo hù kọjá sẹ́yìn, Jonathan dárí jì mí - Dino Melaye Koda Kanu fi ọwọ sọya pe, oun ni awọn ẹri aworan to daju lọwọ lati fidi rẹ mulẹ pe, ẹlomiran lo n dari ijọba Naijiria, kii se Buhari.
Lara awọ̀n adugbo ti wọn ti pa ni opopona Allen si oba Akran, koda paro paro ni awọn agbegbe naa da.
’ Ìdí rẹ̀ tí mo fi dúpẹ́ lọ́wọ́ rẹ fún ọ̀rọ̀ tí o sọ ni èyí, afooresúníiṣe kún inú ayé, wọ́n dàbí paramọ́lẹ̀ láàrin àwọn ọmọ ènìyàn.
Ẹ̀rín náà ni mò ń rín tí mo fi tọ igbó náà já sí pápá kan.
Àwọn kan bẹ̀rẹ̀ sí tutọ́ sí i lára.
Minisita naa sọ pe ọwọ Aarẹ Buhari lo wa lati kede konile-o-gbele miran, lẹyin ti wọn ba ṣe agbeyẹwo gbigbẹsẹ kuro lori ofin naa lẹyin ọsẹ meji, ki wọn tun to mọ nkan to ku lati sẹ.
Eṣitoni yìí ni ó bí Betirafa, Pasea ati Tẹhina.
” Nítorí ọwọ́ Oluwa wà lára rẹ̀.
Wọn ni o yẹ ki o mu oju to wahala to wa nile ki o to sọ gbera lọ si ipade nita.
Bí o bá ti rìnrìn àjò lọ sí Hong Kong, o ṣe é ṣe kí o dé Yau Ma Tei, agbègbè ọjà alẹ́ tí ó jẹ́ ìlúmọ̀nánká níbi tí àwọn ènìyàn ti máa ń lọ ra ọjà àti oúnjẹ ẹ̀gbẹ́ẹ títì.
Gẹgẹ bi oludari agba ajọ LASEMA ṣe fi sita, nibayii, wọn ti di ọpa naa wọn si ti dena igbokegbodo ọkọ lagbegbe naa torii iṣẹ to n lọ lọwọ nibẹ.
OLUWA ní: “Ọ̀run ni ìtẹ́ mi,ayé ni àpótí ìtìsẹ̀ mi.
Ẹ fara mọ́ àwọn nǹkan rere.
Lẹ́yìn tí àwọn ará Filistia gba àpótí Ọlọrun lọ́wọ́ àwọn ọmọ Israẹli, wọ́n gbé e láti Ebeneseri lọ sí Aṣidodu.
Ọ̀kan lára àwọn òṣèré yìí ni Toyin Afolayan ti ọ̀pọ̀ èèyàn mọ̀ sí Lọla Idije.
15 Agẹmo 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 21 Owewe 2020 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ọdun 2011 ni wọm bẹrẹ si ni kọ adagun odo yii, bayii lo ṣe ri lọdun 2019 Ohun to n fa sababii gbọnmi si i omi o to o laarin awọn orilẹ-ede Afirika kan lorii odo Nile ni ẹni ti yoo maa ṣakoso lori odo yii to gun ju ni gbogbo ilẹ Afirika.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Oba Adedokun Abolarin ti Oke Ila: Ó ya ọ̀pọ̀ tó súnmọ́ mi lẹ́nu bí mo ṣe ń kọ́ Yatọ si eyi, ijọba Naijiria tun sọ pe awọn fidio to wa lori ayelujara idọrẹpọ 'social media', ni CNN ṣa jọ, eyi to lewu.
Bakan naa o siṣẹ gẹgẹ oludari agba ile iṣẹ naa.
Ọlọrun jọba lórí gbogbo àwọn orílẹ̀-èdè;Ó gúnwà lórí ìtẹ́ mímọ́ rẹ̀.
Aláìníláárí ẹ̀dá kan wà ní ààrin àwọn ará Giligali tí orúkọ rẹ̀ ń jẹ́ Ṣeba, ọmọ Bikiri, láti inú ẹ̀yà Bẹnjamini.
Dafidi bèèrè lọ́wọ́ rẹ̀ pé, “Níbo ni o ti ń bọ̀?
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Kannywood Kidnapping: 'Mọ́ngòrò nìkan ni wọ́n fún mi jẹ ní àhámọ́ ajínigbé' 27 Èbibi 2019 Oríṣun àwòrán, Salisu Muazu/Facebook Àkọlé àwòrán, Aworan akọkọ ti Muazu ya re e, lẹyin ti wọn tu u silẹ lọsan ọjọ Aiku Gbaju-gbaja oludari ere Kannywood ti awọn ajinigbe tusilẹ lọjọ Abamẹta, Salisu Muazu ti sọ fun BBC pe mọngoro nikan ni awọn ajinigbe naa fun oun ati ọrẹ mẹta ti wọn jigbe jẹ fun ọjọ mẹta.
Ko tan sibẹ o, Aarẹ Buhari tun buwọlu u pe ki wọn mase gba owo ori lọwọ awọn to n ko mita wọle lati ilẹ okeere fun ọdun kan, ki awọn ọmọ Naijiria ti ko ni ẹrọ naa le tete ri gba lowo ti ko nira.
OLUWA yóo jà fún yín, ẹ̀yin ẹ ṣá dúró jẹ́.
Orukọ ọlọpaa mẹta yoku ni - Thomas Lane, J Alexander Kueng ati Tou Thao - wọn fẹsun kan wọn pe, wọn ṣe iranwọ fun ẹni ti wọn fẹsun ipaniyan kan.
 Ri dájú pe o wà ni ìgbéle fun ọjọ mẹrinla ti o ba ṣẹsẹ tirin ajo dé si Naijiria.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ààrẹ ní kí wọ́n wádìí oun tó ti bààlú Osinbajo fi já lulẹ̀ 3 Èrèlè 2019 Oríṣun àwòrán, Laolu Akande/Twitter Àkọlé àwòrán, Ọjọ Abamẹta ni ọkọ naa, Augusta AW139 Ileeṣẹ Aarẹ ti paṣẹ pé kí wọ́n wádìí oun to fa ijàmba ọkọ ojufurufu ti o gbe Igbakeji Aarẹ Yemi Osinbajo to ja lule ni Kabba, Ipinlẹ KogI nibi to ti lọ ṣe ipolongo ibo.
Nínú ayé, o lè borí, o sì lè kùnà nínú àwọn kan.
Kíló ṣe ti kò le dáhun ibéèrè ti mo bíi?
Emi ati iya mi saayan lati gbe ẹgbọn mi lọ siwaju agọ ọlọpaa lati wa iranwọ amọ awọn janduku si n soro lọwọ.
Nígbà tí ọkunrin náà fẹnu kan àpótí Ọlọ́run, Eli ṣubú sẹ́yìn lórí àpótí tí ó jókòó lé ní ẹnu ọ̀nà, ọrùn rẹ̀ ṣẹ́, ó sì kú, nítorí pé ó ti di arúgbó, ó sì sanra.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Fun gbogbo iroyin labẹle ati lẹyin odi Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Fun gbogbo iroyin labẹle ati lẹyin odi 19 Èrèlè 2018 Iroyin labẹle ati lẹyin odi lede Yoruba.
Asa ati àwọn ogun rẹ̀ lé wọn títí dé Gerari.
Nígbà tí àwọn eniyan náà rí i, wọ́n mú ọgbọ̀n ninu àwọn ẹlẹgbẹ́ rẹ̀ wá láti wà pẹlu rẹ̀.
Aarẹ Buhari lasiko idibo sipo aarẹ ni ọdun 2015 ati 2019 sọ wi pe ọkan googi ninu ohun ti iṣejọba oun yoo ṣe ni gbigbogun ti iwa ibajẹ.
Nígbà tí ó yá, Gideoni, tí àdàpè rẹ̀ ń jẹ́ Jerubaali, ati àwọn eniyan tí wọ́n wà lọ́dọ̀ rẹ̀ gbéra ní òwúrọ̀ kutukutu ọjọ́ kan, wọ́n lọ pàgọ́ sí ẹ̀gbẹ́ odò Harodu.
Lara awọn to wa nibi ikede esi idibo naa ni Gomina ipinlẹ Osun, Rauf Aregbesola, Gomina ipinlẹ Oyo, Abiola Ajimobi ati Gomina ipinlẹ Zamfara, Abdul'aziz Abubakar Yari to tun jẹ Alaga eto idibo abẹlẹ ohun.
Ò ni àwọn n gbaradi fún ètò yiyan-bí-ologun won, ni àwọn ọmọ ẹgbẹ́ ọlọ́kọ̀-èrò náà bá ṣíná ìyà fún àwọn.
ni eyi ti won fonte lu N8,558,529,755  lati fi ran awon ipinle yii lowo, ipinle  Adamawa, Benue, Borno, Plateau, Taraba, Yobe
Kete ti wọn kede Boris Johnson ni ẹni to jawe olubori ninu ibo naa ni Jeremy Hunt ti kii ku oriire pe: Jeremy sọrọ lori iṣẹ ipolongo takuntakun ti awọn mejeeji jó ṣe ni eyi to yẹ ko jẹ awokọṣe fawọn oludije miran.
Àìdára yín ti yí ìgbà wọnyi pada,ẹ̀ṣẹ̀ yín ti dínà ohun rere fun yín.
Oríṣun àwòrán, Wellcome Collection Àkọlé àwòrán, Nigba kan awọn dokita oniṣegun n fi oorun taba bo awọn oku ti wọn fi n kọsẹ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Njẹ ọ mọ̀ pé mímí afẹ́fẹ́ tí kò dára lè fa àìsàn?
Hajiya Sadiya ti ẹnu n kun yii wa ninu awọn obinrin meje ti wọn jẹ minista tuntun ti Buhari yanWo ohun tó yẹ kí o mọ̀ nípa àwọn obìnrin méje ti Buhari fẹ́ yàn sípò minista Lori ayelujara ni awọn eniyan Naijiria ti ṣeto igbeyawo fun wọn lana Bó tilẹ̀ jẹ́ pé ìròyìn òfegè ni pé Buhari fẹ fẹ́ Sadiya, síbẹ̀ àwọn ọmọ Nàìjíríà ń ṣètò ìyàwò náà lórí ayélujára Ẹto aabo Naijiria: aṣẹ gun ori aṣẹ f'ọga ọlọpaa Magu ati Keyamo ri‘binu ijọba Àwọn akọni Nàìjíríà padà sílé pẹ̀lú àmì ẹ̀yẹ 121 láti Morocco Ìran Yorùbá: Àṣà ju àṣà lọ!
 lẹ ́ yìn tí ogun náà parí ní ọdún 1845 yìí kan náà , Ọlọ ́ gbẹ ́ ńlá kò padà sí ifẹ ̀ mọ ́ , ó kúkú fi Òkè-igbó ṣe ibùjókòó rẹ ̀ .
iwo-oorun orile-ede Sudan, ni ekun Bahr el Ghazal, ti sekupa eniyan mẹ́tàlélọ́gbọ̀n,, ti ọgọ́ta eniyan miiran si
Eeyan 10,801 lo ti ri iwosan gba, nigba ti awọn 616 ti dero ọrun nitori arun ọhun.
Hiramu ọba Tire rán àwọn oníṣẹ́ sí Dafidi.
Ìdámẹ́ta gbogbo ohun ẹlẹ́mìí tí ó wà ninu òkun ni wọ́n kú.
Kò sí ẹni tí ó lè wí pé kì í ṣe bẹ́ẹ̀.
Fifi ife han si ara wa, ki a si tun se ara wa bi osusu owo
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Libya Returnees: Àtìpó 161 míì dari dé padà láti Libya layajọ́ ominira Naijiria 1 Ọ̀wàrà 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ó lé l'ẹ́gbẹ̀rún mẹ́jọ àwọn ọmọ orílẹ̀èdè Nàíjíríà tí wọ́n ti kó padà dé láti orílẹ̀èdè Libya Awọn atipo mọkanlelọgọjọ miran tun ti dari de si orile-ede Naijiria lati orile-ede Libya.
    Nígbà ti a ti dé aarin ọjà wọn tí a wo ìwà wọn tí ó burú bi mo ti ròyìn yìí ni a ti pinnu pé ó yẹ ki á pa àgọ́ sí etí ibẹ̀ kí a wò wọ́n fún ọjọ́ mélòó kan.
Lónìí, òun ni Alága ìpàdé àwọn alákòóso ẹ̀kọ́ tí wọ́n jẹ́ ènìyàn pàtàkì gbogbo ní ilẹ̀ Yorùbá, bẹ́ẹ̀ ni ìgbésí ayé obìnrin náà fi hàn ni pé nǹkan mìíràn wà tí o lágbára jú owó lọ.
Ni ipinlẹ Eko, Gomina Akinwumi Ambode ati agbaọjẹ oloselu ipinlẹ naa Ahmed Bola Tinubu to fa a kalẹ gẹgẹ bi Gomina, pada gbena woju ara wọn.
Àwọn tí ń fọn fèrè ogun ń fọn ọ́n lemọ́lemọ́.
“Iru iwa bayii tun je ki won gborinyin fun ijọba yii lorile ede Naijria ati loke okun.
Kaduna kidnap: Akẹ́kọ̀ọ́ mẹ́fà mórí bọ́ lọ́wọ́ àwọn ajínigbé
Ẹgbẹẹgbẹrun yóo ṣubú, ṣugbọn a óo gba Edomu ati Moabu lọ́wọ́ rẹ̀, ati ibi tí ó ṣe pataki jùlọ ninu ilẹ̀ àwọn ará Amoni.
Naijria, pe ko sewu loko , ki won fọkan balẹ pe aabo to peye wa fun won ati pe
Ọrọ oṣelu lo fa rogbodiyan to waye nilu Ọwọ nigba naa.
Jehoada sì ni baba: Alemeti, Asimafeti, ati Simiri.
Ìwọ ni ò ń fún àwọn ọba ní ìṣẹ́gun,tí o sì gba Dafidi, iranṣẹ rẹ, là.
1 17365 Orilẹede Thailand 69 0.
Ko pẹ lo tun bẹrẹ orin apala kikọ, to si wa ni sawawu awọn ilumọọka akọrin bii Haruna Iṣọla, Ligali Mukaiba, Fatai Ayilara, Ojubanirẹ Tẹwọgbade, Kasumu Adio ati Yusuff Ọlatunji.
Ojogbon Patami so pe, igbese naa yoo tun mu ibasepo ti o donmonron jeyo laarin ile-ise NITDA ati VON lati mu idagbasoke ba orile-ede yiiOjogbon Patami tun salaye pe “Ile-ise akoroyin Voice of Nigeria se pataki papaa julo fun erongba ati afojusun re lati mu igberu ba aworan orile-ede Naijiria lagbaye,”Oriyin 
Anthony Joshua gba nọ́mbà ìdánimọ̀ NIN, àwọn ọmọ Nàìjíríà kan kérora lórí ètò náà Coronavirus: Ó dá mi lójú pé ìwá ìbàjẹ́ ló fa àrùn yìí - Ọ̀gá àgbá EFCC Ibà Lassa wọ ìpínlẹ̀ Èkó!
O ni ominu n kọ oun pe awọn ọlọpaa lọpọ yanturu lo n di oloogbe lẹnu iṣẹ a n daabo bo ilu.
Milionu ogun awon maalu, ko le maa jeko kiri, ko si ani-ani, a gbodo wa ona abayo, bi o se wa ni orile-ede India, eyi ti won ni bi odunrun maalu ati awon daran-daran, ni orile-ede Brazil, o le nigba awon daran-daran ati maalu, bakan naa ni orile-ede America , ko si oro gbomi si omi o to, a gbogbo se amulo bi awon orile-ede lagbaye se n sin eran osin won laisi wahala ninu”.
Ó bá tún bi wọ́n pé, “Bí ó bá jẹ́ bẹ́ẹ̀, báwo ni Ẹ̀mí Mímọ́ ṣe darí Dafidi tí Dafidi fi pe Mesaya ní ‘Oluwa’?
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Trump picture: ọjọ́ tí Trump kí mi kú iṣẹ́ lórí 'twitter' ní inú mi dùn jù- Oyedele Ohun to ṣeesẹ ko jẹ iyanilẹnu fun awọn eniyan kan ni pe orilẹ-ede Naijiria to jẹ ibi ti ẹsin ti fi ẹsẹ mulẹ daadaa le jẹ orilẹ-ede ti wọn yoo darukọ rẹ gẹgẹ bi orilẹ-ede to n wo fidio ibalopọ julọ lori ayelujara.
Ìwà ati ìṣe wọn ni mo fi dá wọn lẹ́jọ́.
Dafidi ṣí adé wúrà orí ọba wọn, adé náà wọ̀n tó ìwọ̀n talẹnti wúrà kan, ó sì ní òkúta olówó iyebíye kan lára, ó sì fi dé orí ara rẹ̀.
Celestine àti ọmọ rẹ̀ ọkùnrin, Paul Egbunuche, tó jẹ́ ẹni ọdún mọ́kànlélógójì, ni wọ́n jọ wà nínú ọgbà ẹ̀wọ̀n Enugu Maximum Security Prison, ní ẹkùn Ìlà Oorùn Gúsù, fún ẹ̀sùn kan nàá.
Ogbẹni Oladele Olugbemi to jé alaga ẹgbẹ SDP ni Ondo salaye fun BBC pe ko si ohun ti ẹgbẹ naa le ṣe lẹyin awọn eeyan ipinlẹ Ondo.
Tofeti ni wọn yóo sì máa sin òkú sí nígbà tí kò bá sí ààyè ní ibòmíràn mọ́.
Ẹ gbọ́ ohun tí Desmond Elliot sọ lórí ayélujára tó bí àwọn ọmọ Nàìjíríà nínú Ṣé o mọ̀ pé o leè forúkọ̀ iléeṣẹ́ rẹ̀ sílẹ̀ lọ́fẹ̀ẹ́?
Koda, iwadii abẹle ti wọn kọkọ ṣe lori rẹ sọ pe ko jẹbi.
Ẹni tí ẹ̀rù bá bà tí ó sá,yóo já sinu kòtò,ẹni tí ó bá rá pálá jáde ninu kòtòyóo kó sinu tàkúté.
Kókó ohun tí à ń sọ nìyí, pé a ní irú Olórí Alufaa báyìí, ẹni tí ó jókòó ní ọwọ́ ọ̀tún ìtẹ́ ọlá ńlá ní ọ̀run.
Jesu bi wọ́n pé, “Eniyan a máa gbé fìtílà wọlé kí ó fi igbá bò ó, tabi kí ó gbé e sí abẹ́ ibùsùn?
Ẹwẹ, akọnimọọgba Man U Jose Mourinho sọ pe nnkan n ṣẹnu 're fun Liverpool lọwọ bayii nitori oke ti wọn wa ninu idije Premier League.
Oríṣun àwòrán, Instagram/africanmagic Bawo ni ile BBNaija saa karun un yoo ṣe ri?
Peter Whitmer Kekere di ọ̀kan nínú Àwọn Ẹlérìí Mẹ́jọ fún ìwé Ti Mọ́mọ́nì lẹ́hìn náà.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ajimobi coronavirus: Àwọn èèyaǹ jàǹkàn mérin tó ti jẹ́ Ọlọrun nípè nítorí àrùn Coronavirus ní Naijiria 27 Òkùdu 2020 Oríṣun àwòrán, others Lati igba ti arun Coronavirus ti ṣẹyọ ni ilu Wuhan lorilẹ-ede China lọdun 2019, ọpọ ẹmi lo ti sọnu kaakiri agbaye.
Dillon Ripley ṣe nípa ẹyẹ náà nínú ìwée rẹ̀ Ìṣàwárí ẹyẹ Spiny Babbler
O Fagunwa, Adebayo Faleti, Akinwumi Iṣọla, Lawuyi Ogunniran àti Oladejo Okediji ṣiṣẹ silẹ ki wọn to lọ 3 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Awọn Onkọwe ju onkọwe lọ gẹgẹ bi ọmọ ṣe ju ọmọ lọ.
Ó bá sọ fún Paulu pé, “Ó tó gẹ́ẹ́ lónìí.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: INEC: Èsì ìdìbò Ekiti lẹ́kùnrẹ́rẹ́ 'Ẹnu lásán kò lè sàn owó oṣu oṣiṣẹ l'Ekiti' Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ekiti Decides: Abiọdun Aluko ní báwọn se kàwé tó l‘Ekiti, ìyà sì ń jẹ àwọn Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Ohun tí OLUWA sọ nípa Senakeribu ni pé,‘Sioni yóo fi ojú tẹmbẹlu rẹ,yóo sì fi ọ́ ṣe ẹlẹ́yà;Jerusalẹmu yóo fi ọ́ rẹ́rìn-ín.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìkíni kú oríire ti ya bo Funke Akindele àti ọkọ rẹ̀ JJC Skillz 22 Ọ̀pẹ̀̀ 2018 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 23 Ọ̀pẹ̀̀ 2018 Oríṣun àwòrán, funke akindele Gbajugbaja oṣere tiata Funke Akindele ti ọpọlọpọ n pe ni Jenifa ti di iya ibeji bayi, to ba jẹ pe ootọ ni awọn ikinni oriṣiriṣi to gba ori afẹfẹ lati aarọ ọjọ Abamẹta.
isere Stamford Bridge, ami ayo mẹta sodo lai labula ni wọn fi sagba Dynamo.
Lagos-116 Anambra-20 FCT-9 Oyo-9 Rivers-9 Delta-3 Nasarawa-3 Edo-2 Kaduna-2 Ogun-2 Plateau-2 Ekiti-1 Osun-1 Pẹlu iye awọn eeyan tuntun yii, o ti pe 60,834 eeyan to ti ni arun naa l'orilẹede Naijiria bayii.
wọ́n ní, ‘OLUWA Ọlọrun wa ti fi títóbi ati ògo rẹ̀ hàn wá, a sì ti gbọ́ ohùn rẹ̀ láàrin iná.
Nigba ti o n ba BBC Yoruba sọrọ lori ago, Kọmiṣọnna eto ẹkọ nipinlẹ Osun, Folorunso Oladoyin ṣalaye pe ọrọ ṣiṣi ileewe lasiko yii gba ero nitori ajakalẹ aarun covid-19.
Wo bí ọkùnrin ọmọ òrukàn yìí ṣe ń ran àwọn opó tí ọkọ wọn kú sójú ogun lọ́wọ́ Deji Akure pàṣẹ kí wọ́n ti gbogbo ọjà pa fún ọjọ́ méjì, ohun tó fàá nìyí Coronavirus bí èso rere nílẹ̀ Adúláwọ̀, wo díẹ̀ lára èso náà.
Ọdun 1982 ni aarẹ Paul Biya gba ọpa asẹ lati maa dari orilẹ-ede Cameroon, o si jẹ ọkan lara awọn aarẹ to dagba julọ lori oye ni ilẹ Afrika.
Lai pe yi ni ileeṣẹ́ ologun fẹsun kan ajọ to n risi itọju ọmọde kaakiri agbaye Unicef pe wọn n ṣe iranwọ fun ikọ Boko Haram.
Ó mú wọn la ibú omi kọjá, bí ẹṣin ninu aṣálẹ̀;wọ́n rìn, wọn kò fẹsẹ̀ kọ.
Ọ̀ré rẹ ńkọ́, ṣé ó ń bẹ lá làáfíà ara?
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Oyo Politics: Onímọ̀ nípa òṣèlú ní kí 'Gomina Makinde má polongo ọ̀rọ̀ àwọn aráàlù 17 Ọ̀wàrà 2019 Oríṣun àwòrán, Seyi Makinde/Twitter Laipẹ yii ni iroyin kan jade pe gomina ipinlẹ Oyo, Seyi Makinde ni àwọn araalu n ke si oun lati lọ fun saa keji.
Ó lọ fi ọ̀pá Eliṣa lé ọmọ náà lójú, ṣugbọn ọmọ náà kò jí.
Àwọn kan ninu àwọn Farisi ń sọ pé, “Ọkunrin yìí kò ti ọ̀dọ̀ Ọlọrun wá, nítorí kò pa òfin Ọjọ́ Ìsinmi mọ́.
Mustapha sọ pe erongba lati fi Adoke si ihamọ yoo fun wsn ni asiko lati pari iwadii wọn lori ẹsun ti wọn fi kan an.
Ẹni to bori: South Africa Côte d'Ivoire vs Mali.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Àwọn obìnrin yarí, wọ́n kò fẹ́ àwọn ọkùnrin ní òde ijó wọn Pàtàkì ọdún Ojúde Ọba fún ìran Yorùbá Lórí ìmọ̀ràn Sunday Igboho, Ẹlẹbubọn ní yóò dára kí Yorùbá padà sí àmúlò èròjà ìbílẹ̀ fún ààbò Àlàyé rèé lóríi ìdí tí wọ́n fi ń pe aya ní ìyàwó Khafi wọ gàu lẹ́nu iṣẹ́ lórí ẹ̀sùn ìbálòpọ̀ ní BB Naija Àlàyé rèé lóríi ìdí tí wọ́n fi ń pe aya ní ìyàwó Nigba to n sọrọ pẹlu BBC, Oludari ajọ naa Ọmọwe Bukọla Aluko Kpotie salaye pe, awọn isẹ ti awọn obinrin pa ti fun awọn ọkunrin yii lo ni owo lori, ti oun si gba lati maa kọ awọn akẹkọọ lati ile ẹkọ girama lọna ti wọn fi lee mọ awọn isẹ wọnyii.
Adesanya UFC253: Wo ìlúmọ̀ọ́ká akànṣẹ́ mẹ́ta ọmọ Nàìjíríà tó ń ṣe bẹbẹ lágbàáyé
Alaga ẹgbẹ naa, Alagba Gboyega Oguntuase lo sọ ọrọ yi ninu ifọrọwanilẹnuwo pẹlu akọroyin ile iṣẹ BBC.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Sotitobire: Adájọ́ sọ̀rọ̀ nípa ọjọ́ ìdájọ́ fún Wòlíì Sotitobire Alfa Babatunde 12 Owewe 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 18 Owewe 2020 Adajọ to n gbọ ẹjọ ẹsun ijọmọgbe ti wọn fi kan gbajugbaja wolii ijọ Sọtitobirẹ Praising Chapel ni ilu Akurẹ, Alfa Babatunde ti ọpọ mọ si sọtitobirẹ atawọn mẹfa miran ti sọ ọjọ ti yoo gbe idajọ kalẹ.
Eto isinku ọhun ni wọn ṣe pẹlu ilana ijinasiraẹni ti ajọ NDCD gbe kalẹ nitori ajakalẹ arun Coronavirus to wa lode.
Mo ti wí fún bàbá mi, o sì ti gbà bẹ́ẹ̀, ṣùgbọ́n ó ní kí o ránṣẹ́ wá kí àwọn ará ilé rẹ wá tọrọ mi lọ́wọ́ òun, nígbà tí ó wí báyìí, mo sọ fún un pé ọ̀nà ìrìnàjò sí ÒKè Ìrònù ni o wà àti wí pé àwọn ara ilé rẹ kò ní lè wá, kò kọ́ gbà, ṣùgbọ́n, mo lọ bá ẹ̀gbọ́n mi àgbà, àbúrò rẹ̀, ó sì ti báa sọ ọ́ pe kí wọ́n má wá mọ́, ṣùgbọ́n dípò bẹ́ẹ̀ pé kí o kọ̀wé sí bàbá mi, Nítorí náà, ọwọ́ rẹ ló kù sí nísisì yìí, kí o tètè kọ̀wé sí bàbá mi o.
Ti awọn ọmọ ogun Naijiria si kọlu ilu abinibi rẹ ninu eto akanṣe kan ti wọn pe ni 'Operation Python Dance', eyi to mi ko ṣoro lati mọ ibi to wa titi di asiko yii.
Bayi yoo jẹ aarẹ akọkọ ti wọn yọ ni ile aṣoju-sofin, ti yoo kopa ninu idibo to n bọ lọna loṣu Kọkanla ọdun yii.
Ninu iwadi naa ni wọn ti beere lọwọ awọn ti wọn fi ọrọ wa l'ẹnu wo, lori ibaṣepọ ti wọn ni pẹlu awọn to n fa siga lati kekere wọn, wọn si lo idahun awọn eniyan naa lati tọpinpin bi eto ilera wọn yoo ṣe ri ni ọdun mejilelogun si asiko yii.
''O fi ọrọ ranṣẹ si mi pe ki n ko jade kuro nibẹ lọ si ile awọn obi oun nitori oun ti loyun'' ''Fun ọdun mẹrin, mi o gbọ nkankan lati ọdọ rẹ, mo tọju ọmọ mi lai ri iranwọ kankan lati ọdọ rẹ'' ''Ko si alaafia fun mi lati ọdun meje ti mo ti mọ ọ'' Ninu ọrọ rẹ, ọkọ iyawo Adebimpe ni oun fi ọwọ si ituka igbeyawo naa, amọ ohun ko jẹbi ẹsun ti o fi kan oun.
Ṣugbọn ẹ máa gba ara yín níyànjú lojoojumọ níwọ̀n ìgbà tí ọ̀rọ̀ “Òní” tí Ìwé Mímọ́ sọ bá ti bá àwa náà wí, kí ẹ̀ṣẹ̀ má baà tan ẹnikẹ́ni lọ, kí ó sì mú kí ó ṣe agídí sí Ọlọrun.
Ṣé èmi Paulu ni wọ́n kàn mọ́ agbelebu fun yín?
jẹ́ ẹgbaa mẹtadinlọgbọn ó lé irinwo (54,400).
Ìgbà tí mo bá wí pé n kò lọ, ta ni ki n wí pé o bí mi!
Bí Hazard bá fẹ́ lọ kó máa lọ - Sarri Èwo nínú ìlérí tí Buhari ṣe ní 2015 ló ti mú ṣẹ?
Kí àwọn Kerubu náà na ìyẹ́ wọn bo ìtẹ́ àánú, kí wọ́n kọjú sí ara wọn, kí àwọn mejeeji sì máa wo ìtẹ́ àánú náà.
 Fun idi eyi, inu mi dun si iṣẹ Ile Igbimọ Aṣofin Ipinlẹ Eko, eleyii ti ko lẹgbẹ kaakiri awọn Ile Igbimọ Aṣofin ti mo ti de kaakiri orilẹ-ede Naijiria ati awọn orilẹ-ede miiran paapaa julọ fun ọwọ ti wọn ni fun aṣa ati iṣe wa”.
Igi aligumu yìí ni ọba fi ṣe àtẹ̀gùn láti máa gòkè ati láti máa sọ̀kalẹ̀ ninu tẹmpili OLUWA ati ninu ààfin ọba.
Oyetọla ṣalaye siwaju sii pe,ijọba oun yoo maa san ẹkunrẹrẹ owo oṣu awọn oṣiṣẹ deede.
Tí a fiṣọwọ́ ní 5:47 16 Sẹ́rẹ́ 20215:47 16 Sẹ́rẹ́ 2021 Ọ̀nà márùn-ún rèé to lè gbà lo ayélujára fún èrè gọbọi lórí okoòwò Video content Video caption: Paystack Shola Akinlade: Ìgbésẹ̀ 5 yìí ni mo gbé tíléeṣẹ́ Stripe fi dókòwò $200m pẹ̀lú miPaystack Shola Akinlade: Ìgbésẹ̀ 5 yìí ni mo gbé tíléeṣẹ́ Stripe fi dókòwò $200m pẹ̀lú mi Onimọ nipa eto idokowo lori ayelujara, to tun jẹ oludari ileesẹ Paystack Shola Akinlade salaye bo se lu aluyo lori ayelujara nidi okoowo fun BBC.
Ilé ẹjọ́ kéde Ademọla Adeleke gẹ́gẹ́ bíi gómìnà ìpínlẹ̀ Ọṣun
Kíní ìdí tí àbádòfin yìí fi pọ̀ dàndàn fáwọn ọmọ ilé ìgbìmọ̀ asofin lásìkò yìí Ọ̀pọ̀ àwọn ọmọ ilé aṣòfin to dá si ọ̀rọ̀ náà sàlàyé pé, kí ìlọsíwájú to lè wáyé, tólórí tẹ̀lẹ́mù gbọdọ wà ní ìṣọ̀kan sùgbọ́n, àwọn ènìyàn ń lò ayélujára láti gbé àwọn ìròyìn òfégè síta láti ṣátá ètò àti ìpínnú ìjọba.
Ẹwẹ, àwọn oṣere tiata naa ko simi ẹnu lori ohun ti awọn ọmọ Naijiria la kọja lakoko yii, paapaa awọn agunbanirọ atawọn mii to jẹ oṣiṣẹ sarenbaja fun ajọ INEC.
Akọwe agba nileeṣẹ ijọba to wa fun ọ̀rọ̀ ilẹ okeere, Mustapha Suleiman lo kede iroyin naa sita nilu Abuja.
"Bẹẹni tọkọtaya Harry ati Meghan ti dupẹ lọwọ gbogbo mutumuwa ninu atẹjade kan loju opo instagram wọn dun ""atilẹyin wọn ati aanu ti wọn fi han wọn"" Atẹjade naa ni 'akoko ayọ nla lo jẹ ninu igbesi aye wọn bi wọn ṣe n ki akọbi wọn kaabọ."
" Àkọlé àwòrán, Ọrọ aje orilẹede Liberia nla akoko to le kọja Bakanaa ni Weah seleri lati gbogun ti iwa ajẹbanu eyi to dun mọ awọn ọmọ orilẹede naa ninu.
Lẹ́yìn náà gbogbo àwọn tí ọ̀rọ̀ náà wọ̀ lọ́kàn, tí ó sì jẹ lógún bẹ̀rẹ̀ sí pada wá ní ọ̀kọ̀ọ̀kan, wọn ń mú ọrẹ wá fún kíkọ́ àgọ́ àjọ náà, ati gbogbo ohun tí wọn nílò fún àgọ́ náà, ati fún ẹ̀wù mímọ́ àwọn alufaa.
England); Oghenekaro Etebo (Stoke City FC, England); John Ogu (Hapoel Be’er
Bótilẹ̀jẹ́pé ojú-ọjọ́ ṣe bí ẹní fẹ́ rọ̀'jò, nkan táa lọ ṣe níbẹ̀ náà ni àrìnká káàkiri inú igbó àti pákáko ẹ̀bá ìgbèríko ọ̀hún, gẹ́gẹ́ bí ìṣe wa bí onírìnàjò.
Yatọ si wahala to de ba ọga Huawei yi pe ki wọn ma lọ ṣẹjọ rẹ l'Amẹrika,arabirin Meng n koju awọn ẹsun miran to fi mọ pe ile iṣẹ Huawei lẹdiapopọ pẹlu Iran.
ASUU lo se agbekalẹ UTAS lati duro gẹgẹ bii IPPIS tiẹ, eyi to da gbọmisi-omi-oto silẹ laarin ASUU ati ijọba apapọ.
isẹju Ajo eleto idibo INEC to wa
Amofin Abiade gba awọn eniyan Naijiria nimọran pe kaka ti ẹmi a fi maa sọnu lọdun tuntun, ko buru ki onikaluku ni imọ lori igbesẹ to yẹ ni gbigbe labẹ ofin Naijiria.
Diẹ lara awọn eto ti Mosobolaje Akande Faleti bẹrẹ ni: Ẹ dide, ẹ mu saari jẹ; Baba Keresi ati bẹẹ bẹẹ lọ.
Àjàgà rẹ̀ yóo bọ́ kúrò lọ́rùn àwọn eniyan mi,ati ẹrù tí ó dì lé wọn lórí.
 ) ( could you entertain the childern for an hour .
Wole Soyinka: Pańpẹ́ ọba lọ̀nà àbáyọ sí ìwà ìbàjẹ́
Wọn gbagbọ pe ẹbi isẹlẹ naa le e ma wa lati ọdọ ọmọbinrin to jẹ akọwe ti baba ni ki ọmọ rẹ le danu, nitori o jẹ moriwu fun un lojoojumọ lati lọ si ibi iṣẹ.
Aṣọ naa dùn ún wo lọrun wọn pẹlu bi wọn ṣe bori ninu idije European Championship fun igba akọkọ.
 Àṣá dara pọ ̀ mọ ́ ilé iṣẹ ́ ́ ( naïve records ) .
Igbesẹ naa i ba dara pupọ.
Mo ké bòòsí tòò bí mo ṣe bí ìbejì, ti ọ̀kan jẹ́ àfín, ìkejì jẹ́ dúdú-Màmá Ọlátẹ́jú
”Aare tun ba ijọba ati gbogbo omo  ipinle Plateau kedun lori” isele buruku yii.
Oríṣun àwòrán, Instagram/currentalhaja Ni ipari ọrọ rẹ ni Olori Abbey ki ara rẹ ku ayẹyẹ ọjọ ibi, o gbadura pe ki Eleduwa fi ẹmi gigun ati ayọ jinki oun.
Ọkọ̀ aképo gbiná ní òpópónà Eko sí Badagry Sanwo-Olu ló jáwé olúbórí ní APC l'Eko Àrá sán pa màálù 23 l'Ekiti Oṣu kẹrin ọdun 2018 ni ile ẹjọ da Onyeri lẹbi fun gbogbo awọn ẹsun rẹ.
Babafemi, tíì ṣe òṣìṣẹ́ fẹyinti kan nileesẹ àjọ ẹsọ ojú pópó FRSC ṣàlàyé pé, òun ti sọ fún ọmọ òun láti dúró sí Eko, àmọ́ tí kò gbọ .
Àwọn ni ọkàn àwọn tí wọ́n ti bẹ́ lórí nítorí ẹ̀rí tí wọ́n jẹ́ nípa Jesu ati nítorí ọ̀rọ̀ Ọlọrun.
Ninu oro agbeleko re, eyi ti amugbalegbe Pataki si Aare ni eka iroyin ati itaniji Malam Garba Shehu ko, Aare  so wi pe oloogbe Winnie Mandela ja fitafita gbogun ti eleyameya Pataki julo lakoko ti won fi oko re Aare Nelson Mandela sinu ihamo.
Nítorí náà ni a ṣe kọ ọ́ sinu Ìwé Ogun OLUWA pé:“Ìlú Wahebu ní agbègbè Sufa,ati àwọn àfonífojì Arinoni,
Jim Mattis wo awoyanu ọmọogun Indonesia to nmu ẹjẹ ejo
Ninu ọrọ ti wọn, ẹgbẹ awọn ọmọ Igbo, Ohanaeze Ndigbo sọ wi pe otitọ ọrọ ni Obasanjo sọ nitori o mọ ibi ti bata ti n ta orilẹede Naijiria lẹsẹ, amọ o ṣeni laanu wipe ijọba to wa lode yii ko gbọ ọrọ si awọn eniyan lẹnu.
Èèyàn 12 ló ti kú báyìí nínú ìjàmbá iná Eko Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Obìnrin tí kó ba fẹ́ òṣìṣẹ́ Mọ́ṣúárì, ìpinu rẹ̀ mẹ́hẹ' Ọkan lara awọn oṣiṣẹ sọ fun BBC pe obinrin naa ti wọn ko darukọ ti n gba itọju ni ile Iwosan kan to wa ni ilu Johannesburg, lẹyin ti awọn onimọ nipa ẹya ara fi ti ọwọ si i.
Aarẹ Kagame pe fun irẹpọ laarin awọn orilẹede ọmọ ẹgbẹ lati le se aseye ti alakan n s'epo nipa atunto ninu ajọ AU ati ni awọn orilẹede to parapọ di ajọ yii.
Eyi ni iriri Arakunrin Adamu Misa lati ipinlẹ Yola, ni ẹkun Ariwa orilẹ-ede Naijiria.
Kò wo ìwà wọn tí ó fi ń fẹ́ wọn, ẹwà ara àti títóbi ìdílé ni ó ń wò tí ó fi ń fẹ́ wọn, ṣùgbọ́n ní àkókò tí Aṣojú-Olódùmarè fi máa padà dé, ọkàn ọkùnrin náà kò balẹ̀ nínú ilé, ilé rẹ̀ kún fún ariwo, ìjà, ìbànújẹ́ àwọn ará ilé náà kò fi ara wọn ṣe ọ̀rẹ́, wọ́n jẹ́ ọ̀tá pàtàkì fún ara wọn.
Èyí ni pé Mesaya níláti jìyà; àtipé òun ni yóo kọ́ jí dìde kúrò ninu òkú tí yóo sì kéde iṣẹ́ ìmọ́lẹ̀ fún àwọn eniyan Ọlọrun ati fún àwọn tí kì í ṣe Juu.
A o maa mu ẹkunrẹrẹ wa fun yin laipẹ.
Lati rii daju pe ko wa si ẹjẹ lọwọ, o ni lati rii daju pe ko saaye fun ina yii lagbegbe rẹ."
Ó ní ọmọ náà ni yóo kọ́ ilé fún òun.
5 Lẹ́hìn tí a ti fi hàn fún alàgbà àkọ́kọ́ yìí lõtọ́ pe òun ti gba ìmúkúrò àwọn ẹṣẹ̀ rẹ̀, a tún gbé òun dè nínú àwọn ohun asán ayé.
Ile isẹ iroyin BBC lo ni awọn aworan yii.
Orilẹede to kun fun ẹya ati ẹsin pupọ ni orilẹede wa, a si n ke si Aarẹ Muhammadu Buhari wipe ko gbọran si ohun ti ofin to de pinpin ipo lorilẹede Naijria, Federal character commission act sọ pẹlu gbogbo awọn iyansipo ati eto rẹ gbogbo.
rẹ ni won tun ri ni Tipaza, ti o je olu-ilu naa, nibi ti iwadii yoo gbe maa
Bakan naa ni ẹgbẹ alafọwọsowọpọ fawọn agbẹ wa, to maa n duna-dura laarin agbẹ ati ìjọba lori iye owo koko.
Eyi ri bẹẹ nitori awọn iwa kan to se ajeji ti awọn ẹlẹsin Hakika maa n hu bii pi paarọ iyawo laarin ara wọn ti wọn ba ti de ipo giga kan ninu ẹsin, kikọ irun kiki silẹ ati kikọ ẹyin si aawẹ gbigba lasiko Ramadan, eyi to jẹ ara opo ẹsin Islam.
Nígbàkúùgbà tí àwọn arakunrin yín bá mú ẹjọ́ wá siwaju yín láti ìlú kan, kì báà ṣe ti ìtàjẹ̀sílẹ̀, tabi ti nǹkan tí ó jẹ mọ́ òfin, tabi àṣẹ, tabi ìlànà, ẹ níláti ṣe àlàyé fún wọn kí wọ́n má baà jẹ̀bi níwájú OLUWA, kí ibinu OLUWA má baà wá sórí ẹ̀yin náà ati àwọn arakunrin yín.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù UEFA Champions League: Ó di gbéré!
Mo dúpẹ́ mo tún ọpẹ́ dá, kí Olódùmarà ṣe wa ni ọ̀rẹ́ ara wa di alẹ́ o.
Bi ẹyin naa ba wa pẹlu rẹ bi a ṣe n sọrọ yii, yoo ya yin lẹnu bi ara rẹ ṣe le ko ko ko.
Kí a ṣe àjọyọ̀ àbí kí á máà ṣe é, ìbéèrè ni ìyẹn.
Ọjọ Aje ni agbẹjọro ijọba, Shogunle Adenekan sọ nile ẹjọ wipe gbogbo awọn ti ọrọ naa kan ni o ti fẹnu ko lori ọrọ naa, eyi to faa ti Akindele ṣe ni oun jẹbi ni tootọ.
aare so pe, ofin tuntun yii ko yo ile-ise kankan sile jake-jado orile-ede
Àwọn àjèjì darandaran ń wọ ìpínlẹ̀ Oyo àti Ogun lọ́gọ́ọ̀rọ̀ - Amotekun Sunday Igboho kàn ń gbé ‘Camera’ lẹ́yìn kiri, kí wọ̀n lè rò pé ó ń jà fún Yorùbá - Gani Adams Àgbáríjọpọ ẹgbẹ OPC, fijiláńté VGC, Agbẹkọyà ti bẹrẹ ètò aàbò ní ilẹ Yorùbá Àṣẹ àwọn gómìnà là ń retí, àwa ti ṣetán láti dáàbò bo ilè Yorùbá- Gani Adams O ni ijọba ibilẹ Saki east, Saki West ati Atisbo, ni wọn n gba wọle.
Òní ní ó pé ọjọ mẹ́jọ tí ìdíje AFCON ẹlẹ́ẹ̀kẹtàlá irú rẹ̀ bẹ̀rẹ̀ ní orílẹ̀-èdè Egypt.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Bọla Tinubu: Ìpínlẹ̀ Ọ̀ṣun kò ní owó mi lọ́wọ́ NOMBAẸGBẸ OṢELUORUKỌ OLUDIJE ATI IGBAKEJI WỌN LABẸ 01AJulius Olapade Okunola - Azeez Kayode Jimoh 02AAOgunmodede Adeloye - Adepoju Timothy Adetunji 03ABPOludare Timothy Akinola - Halimat Bunmi Ibrahim 04ACDGbenga Afeni - Oni Esther Oluwatoyin 05ACPNRufai Adebisi Mujidat - Agboola Peter Oluremi 06ADJames Olugbenga Akintola - Abdulhakeem Oyeniyi Bello 07ADCFatai Akinade Akinbade - Arowolo Oladele 08ADPAdeoti Moshood Olalekan -Durotoye Adeolu Akinbola 09AGAKehinde Olufemi Lawrence - Lawal Oluseyi Afusat 10AGAPAdejola Adebayo Rufus - Adebayo Adewale Olaolu 11ANRPAlarape Babatunde A.
”Jesu sọ fún un pé, “Ìwọ náà lọ ṣe bẹ́ẹ̀ gan-an.
Oba Adeyeye Ogunwusi: Ojú mi ti rí lọ́pọ̀ lọpọ̀, ọ̀pọ̀ èèyàn ni kò tilẹ̀ gbàgbọ́ pé mo lè jọba- Ooni
Awọn mejilelaadọrun un ninu wọn lo jẹ ọkunrin nigba ti ọgọta jẹ obinrin, ọmọde lawọn mẹjọ to ku.
”O wa ro awon eniyan paapaa julọ
Lara awọn ere naa ni Fere bi Ekun, Alaafin Aganju, Agbalowomeri, Efunsetan Aniwura, Ibu Olokun, Koseegbe, Ajaloleru, Iyawo Alalubosa ati bẹẹ bẹẹ lọ, ko si fẹ ẹ si ilu kan ni Naijiria ti Isho pepper ko gbe ere tiata de.
Ọlọrun wí fún un pé, “Jakọbu ni orúkọ rẹ, ṣugbọn wọn kò ní pè ọ́ ní Jakọbu mọ́, Israẹli ni orúkọ rẹ yóo máa jẹ́.
'Kò si ẹ̀ri fún ìbò ọmọ kékèké ni Kano' Buhari gbọ́dọ̀ bẹ̀rẹ̀ ìwádìí Ganduje láàrín ọjọ́ mẹ́rìnlá-SERAP Ọsẹ yii lo yẹ ki iṣẹ iwadii ti igbimọ naa n ṣe wa s'opin, ki ile aṣofin to wa sọ eero rẹ lorii boya Gomina Ganduje jẹbi tabi ko jẹbi.
Ekiti: Ìjọba ti iléeṣẹ́ rẹ́díò Fayose pa nipinlẹ Ekiti
Obìnrin burúkú náà tàn mí jẹ fún ọ̀pọ̀lọpọ̀ ìgbà kí ó tóó di pé Olódùmarè tú àṣírí rẹ̀ sí ìta, báyìí ni:
 O tun je komisona to n mojuto eto oro aje ati eto isuna lasiko saa akoko gomina Fayemi.
Oríṣun àwòrán, AsoRockVilla Àkọlé àwòrán, Ibrahim Tanko Muhammed Adajọ Tanko Muhammed di adajọ agba ile ẹjọ giga ilu Abuja ni ọdun 1989 titi di 1991 ti iṣẹ tun gbe e lọ si ipinlẹ Bauchi.
Pinnick fikun oro re pe,“Aare ajo FIFA, Gianni Infantino yoo gunle si Naijria lojo-Aje (Monday) fun ipade olojo meta ohun, besini yoo mu awon akoroyin lagbaye wa sorile-ede Naijria,”Ni ipari, Infantino yannana oro ohun pe, awon asoju marundinlogbon leto ti wa nile pe yoo kopa ninu ipade naa, eyi ti yoo waye nile itura Eko Hotel and Suites, nibiti won yoo ti jo jiroro lori bi idagbasoke yoo tun se de ba ere boolu afesegba lagbaye.
Ṣé kò ní sí ìyàtọ̀ láàrin ìpín àwọn eniyan burúkú ati ti àwọn olódodo ni?
Christopher Alao Akala - O yege3.
Yóo ṣe ohun tí ó ti pinnu láti ṣe fún mi ní àṣeyọrí,ati ọpọlọpọ nǹkan bẹ́ẹ̀ yòókùtí ó tún ní lọ́kàn láti ṣe fún mi.
Ọmọwe ni ẹni to ba mọ nkan to n ṣe gbudọ ṣọra fun apọnju latọdọ araalu.
Ẹgbẹ oselu PDP ti fa ọwọ sẹnetọ Buruji Kashamu soke gẹgẹ bi ẹni ti yoo dije dupo gomina ni ipinlẹ Ogun ni idibo gbogboogbo ọdun 2019.
Iwin kan ṣoṣo ní ń bẹ ní inú igbó yìí, ò gbóna ju àpáàrà ojú ọ̀run.
Ọlọrun pàṣẹ pé kí ilẹ̀ mú oríṣìíríṣìí ẹ̀dá alààyè jáde: oríṣìíríṣìí ẹran ọ̀sìn, oríṣìíríṣìí ohun tí ń fàyà fà lórí ilẹ̀ ati oríṣìíríṣìí ẹranko ìgbẹ́, ó sì rí bẹ́ẹ̀.
 Ni owuro yii ni alaga ajo
ni lati ṣeto iṣuna owo ọdun kan ki o si ṣagbekalẹ rẹ niwaju Ile Igbimọ
Atiku lo wọ aarẹ Muhammadu Buhari lọ sile ẹjọ lati tako idibo to gbe wọle fun saa keji gẹgẹ bii aarẹ Naijiria.
Alaye sọ́kí lórí ìlú àti àwọn ènìyàn ìjẹ̀bù-jẹ̀ṣà
“ ohun ti a se ni kl a wa ojutuu si wahala to n sele laarin egbe wa , paapaa julo laaarin awon agba egbe, ti a si tun mo pe ,a ko ri ojo mu so lokun, nipa eto idibo to n bo lona , nitori naa, o se dandan  lati fi osu mejila kun odun to ye ki awon alakoso egbe naa lo lati kogba sile .
Awa yoo se ise lori gbogbo abajade ti igbimo ba fun wa.
Ẹ fi owó yín sí ibi tí ẹnu yín wà.
 awọn òbíi rè máa n fún un ní ìwúrí nínú èkóo rẹ ̀ mú pò si ; mú gbòòrò sí má se mú ìwà búbúru omo pò sí omodé .
Ṣugbọn bí ẹlòmíràn bá wá ní orúkọ ara rẹ̀, ẹ óo gbà á.
"O jẹ ọkan lara awọn ti wọn ṣe adari eto ""Idol West Africa"" nigba kan ri."
Gẹgẹ baa se gbọ, awọn adigunjale naa ni wọn ya lọ sile ifowopamọ ati agọ ọlọpa to wa niwaju ile ifowopamọ naa.
A rán arakunrin tí ó lókìkí ninu gbogbo àwọn ìjọ nítorí iṣẹ́ rẹ̀ nípa ìyìn rere pé kí ó bá a wá.
"Oríṣun àwòrán, Ijọba ipinlẹ Yobe Àkọlé àwòrán, Ijọba Naijiria sọ wipe ẹrindinlọgọrin ṣi ni akọsilẹ wa fun Alhaji Lai Mohammed ni, ""Ki itusilẹ naa le fidimulẹ, ijọba loye pe, iwa ipa ati igboju agan sira ẹni ko le jẹ ọna abayọ nitori pe o le fi ẹmi awọn ọmọbinrin naa sinu ewu."
Igbésẹ̀ ti SERAP ń gbe láti ṣe àdínku ba ìwá jegudujẹra Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fọ́nrán ohùn, SERAP ni ẹ̀ka ìdájọ ló gbégba oróke sìkeji Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí 5:38 Fídíò, Kidnapped Girl: Iyá Ikimot ní lẹ́yìn ọ̀pọ̀ ìdààmú àti owó láti wá ọmọ náà, òun sọ ìrètí nù, Duration 5,3827 Ẹrẹ̀nà 2019 Fídíò, Rape: Oluwaseun Osowobi ní Commonwealth fún lámì ẹ̀yẹ ọ̀dọ́ tó pegedé jùlọ ní 201826 Ẹrẹ̀nà 2019 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Komla Dumor: Victoria Rubadir ọmọ Kenya ló gba àmì ẹ̀yẹ Komla Dumor BBC World News 1 Owewe 2020 Victoria Rubadiri to jẹ akọroyin ati aṣewadi abẹlẹ to tun jẹ olootu eto lori ẹrọ amohunmaworan lo gba ami ẹyẹ Komla Dumor BBC World News ọdun 2020.
Ewe, Petr Cech darapo mo iko agbaboolu Chelsea lọdun 2004 lati
Àìṣọ̀kan ọmọ Oòduà kó wọn lẹ́rù fún Fúlàni.
ni ọna ti won yoo fi mu idagbasoke ba orile ede Naijiria.
Ṣaaju ni wọn ko ti le kọkọ fidi ohun to n fa ajakalẹ arun to n gbẹmi ọpọ eeyan ni Kano mulẹ.
Lẹsẹkẹsẹ ni Ẹ̀mí bá gbé mi.
Bakan naa ni awọn onwoye se akiyesi pe ijakulẹ nla lee waye fun ẹgbẹ oselu naa lọdun 2023 fẹgbẹ APC, ti aarẹ Muhammadu Buhari ba pari saa rẹ.
Ijọba ilẹ Mali ni iṣẹlẹ ibi yii ko ṣeyin awọn agbesunmọmi ṣugbọn awọn ara agbegbe naa n kigbe pe awọn Fulani lo wa nidi ọrọ naa.
Usa ati Ahio sì ń wa kẹ̀kẹ́ náà.
Anasi ati Kayafa sì jẹ́ olórí alufaa.
Ọgbẹni Abutu wa rọ awọn araalu lati mase foya, nitori iwadii ti bẹrẹ lati rii pe ọwọ tẹ awọn aṣebi naa.
Bí àpẹ̀rẹ ni ọdún 2009, ọ̀pọ̀ àwọn ọmọ ilẹ̀ Gẹ̀ẹ́sì tí wọ́n ni ilé ara wọ́n, ti wọ́n si tún ni iṣẹ́ lọ́wọ́ pada gbádùn nígbà ti ǹkan pada bọ̀ sípò.
Oríṣun àwòrán, Ayobami Agboola Àkọlé àwòrán, Guaranty Trust Bank Offa, Kwara state Agbẹnusọ fún olú iléeṣé ọlọ́pàá, Jimoh Moshood sọ pé wọ́n gba àwọn ǹkan bíi ẹ̀rọ alágbeká, ẹ̀rọ àtẹ́léwọ́ ipad àti káàdì ẹ̀rọ ìbánisọ̀rọ̀ àwọn tí wọ́n fara gbá padà lọ́wọ́ wọn.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Trump tẹsiwaju pe ajọ isọkan ilẹ Yuroopu, EU ti kuna lati gbe awọn igbesẹ iru eleyi tawọn gbe, lati fi koju aisan naa.
Awọn mi i to tun ti wa ni Penny Wise, Swiss Golden, Twinkas, Plan well, Nopecsto ati bẹẹbẹ lọ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Mama Rainbow: Toyin Adegbola àti Razak Olayiwola ní ìyá rere àti àwòkọ́ṣe gidi ní Mama Rainbow Idowu Philps ti ọpọ eeyan mọ si Mama Rainbow, Iya Oṣumare naa ṣe ọjọ ibi rẹ ninu ọsẹ yii.
Gas Explosion: Ẹ̀mí kan bọ́, èèyàn mẹ́ta fara pa nínú ìṣẹ̀lẹ̀ ìbúgbàmù gáàsì tó wáyé l‘Eko
Gẹgẹ bi awọn onimọ nipa eto ọrọ aje ṣe sọ, ti ọrọ aje orilẹ-ede ba ti ja walẹ lere-lera laarin abala meji ọdun kan, o n tumọ si pe ifasẹyin ti de ba ọrọ aje irufẹ orilẹ-ede beẹ niyẹn.
Ni kete ti Iyadunni bi Ojelade ni akọsẹjaye rẹ ti fihan pe o maa ni laari nidi isẹ eegun ju Ojelarinaka, baba rẹ lọ ni eyi ti mọlẹbi fi fa a le Dasofunjo lọwọ lati kọ ọ ni ise ọ̀jẹ̀.
Makinde, Sharafadeen yọ ra wọn níbi ìpàdé ìfọ̀rọ̀wérọ̀ BBC l'Ọyọ Ìpàdé ìfọ̀rọ̀wérọ̀ BBC Yorùbá l'Ọyọ fakọyọ Ẹwẹ, nigba ti Ọtunba Alao Akala da nikan sọ pe ohun iwuri ni oṣelu Naijiria latyin wa, idakeji ni awọn oludije mẹta to ku fnu ko le lori pe oṣelu Naijiria ko ṣee mu yangan.
Oríṣun àwòrán, EPA Àkọlé àwòrán, Ọgbẹni Lukashenko lasiko to lọ dibo nilu Minsk Nise ni Aarẹ gba awọn ara ilu ni imọran pe ki wọn o ma a mu ọtí lile vodka, ati ìwẹ̀ saunas, fi gbogun ti aarun naa.
Ajọ oluranlọwọ Action Against Hunger, ṣalaye pe awọn da awọn oṣiṣẹ oluranlọwọ mẹfa to wa ninu fidio naa mọ.
Báyìí ni kí ẹnìkọ̀ọ̀kan máa wí fún ẹnìkejì rẹ, ati fún arakunrin rẹ̀, “Kí ni ìdáhùn OLUWA?
Kí ni yóo jẹ́ èrè wa?
Àwọn ìròyìn mìírànm tí ẹ lè nífẹ̀ẹ́ sí: Ọwọ ọlọpa tẹ adigunjale ajọkọgbe nipinlẹ Ọsun Ilé ẹjọ́ pàṣẹ ki wọ́n sọ́ afurasí 5 sì àhámọ́ lórí ìdigunjalè Ido-Ani Ìjàmbá ọkọ̀ ojú'rin ní Agege, Eko Bi wọn se pa ọga SARS Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Ọlọrun, ìwọ ni a bẹ̀rù ninu ìgbìmọ̀ àwọn eniyan mímọ́,o tóbi, o sì lẹ́rù ju gbogbo àwọn tí ó yí ọ ká lọ?
OLUWA bá Jeremaya sọ̀rọ̀, ó ní: 
“ ‘Ṣé ẹ wá rí i nisinsinyii pé,èmi nìkan ṣoṣo ni Ọlọrun,kò sí ọlọrun mìíràn mọ, lẹ́yìn mi.
Ko tan sibẹ o, a gbọ pe alẹ ni olukọ naa ma n pe akẹkọọbinrin naa jade ni yara ibusun awọn akẹkọọ, ti yoo si lọ ọ ba lopọ ninu kilaasi.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ǹjẹ́ àrùn Coronavirus leè wà lára èèyàn títí lái?
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Bàbá ọmọ náà ní ó jí ẹja ní òun ṣe fi ọmọ naa jókòó ní orí sítóòfù ẹ̀lẹ́tíríkì, tí ìdí àti apá ọmọ náà sì bó fálafàlá.
Àwọn ọkunrin tí ó wà lọ́dọ̀ Dafidi sì sọ fún un pé, “Ní Juda tí a wà níhìn-ín, inú ewu ni a wà, báwo ni yóo ti rí nígbà tí a bá tún lọ gbógun ti àwọn ará Filistia ní Keila?
Nítorí láti ìgbà tí àwọn baba wa ninu igbagbọ ti lọ tán, bákan náà ni gbogbo nǹkan rí láti ìṣẹ̀dálẹ̀ ayé!
O ni yatọ si pe o le jẹ aarun Covid-19 to wa nita, o ni iwadii yoo da lori iru aisan tabi awọn ami aisan ti gbogbo wọn fihan ṣaaju iku wọn.
Oríṣun àwòrán, Reuters Àkọlé àwòrán, Agbébọn kọlu àwọn ènìyàn níbi ìdíje eré sísá ẹṣin Ọkunrin naa ni iroyin ni o kọkọ kilọ fawọn to n fẹṣin sare naa ki wọn má gba oju titi adugbo oun kọja.
O fikun wi pe nitori epo bẹntiroolu ti lọ silẹ lagbaye bayii, ijọba ti pada si ohun alumọni ati agbẹ to lere gẹgẹbi ọna lati mu ki ibugboro ba ọrọ aje Naijiria.
"Oríṣun àwòrán, Lagos state Mi ò ṣẹ̀ máa pín ǹkan lọ́wọ́ ara mi fún aráàlù, ilé mi gangan kọ́ ni wọ́n ti jí ""Palliative"" kó - Họ́nọ́rébù Agunbiade Báyìí ni 50 Kobo ṣe dá ìfẹ̀hónú ""Ali Must go"" sílẹ̀ tó mú ọ̀pọ̀ ẹ̀mí akẹ́kọ̀ọ́ lọ Amy Coney Barrett di adajọ́ àgbà nílé ẹjọ́ tó ga jùlọ l'Amẹrika Àsìá tó ní àbàwọ́n ẹ̀jẹ̀ ọmọ wa la fẹ́ fún ìran tó ń bọ̀ - Tunde Bakare Ẹ̀kọ́ ọ̀fẹ́ déé fáwọn ọmọ Ọlọ́pàá tó kú lásìkò EndSARS, Gómìnà Sanwo-Olu kéde Ìjọba ìpínlẹ̀ Eko ti iléèwé pa nítorí ìwọ́de #EndSARS Oríṣun àwòrán, @Sanwo Olu Ijọba ipinlẹ Eko ti ti ileewe pa ti o si ti paṣẹ ki gbogbo awọn akẹkọọ ileewe ijọba ati ti aladani o fi idi mọle nitori wahala iwọde #ENDSARS to n lọ lọwọ."
Ó bẹ̀rẹ̀ eré síse ní ọdún 2003 nígba tí òsèré Tíátà Bukky Wright lọ se fíìmù kan ní ìlu Ibadan.
Iroyin ni, apapọ ikọlu ti Boko Haram se jẹ aadọjọ (150) lọdun 2017, eyi si fihan pe ọwọ ikọ adunkoko mọni naa mulẹ pupọ lọdun 2017 ju tọdun 2016 lọ, nitori ikọlu mẹtadinlaadoje (127) lo se lọdun 2016.
Ọwọ àwọn ọlọ́pàá ọtẹlẹmuyẹ lorílè-èdè Ghana ti tẹ alága àjọ tó n mójú tó bọọlu lorílè-èdè náà.
Ọga agba ajọ NDLEA, Alfred Adewumi lo saaju bi won se fi katakata hu oko na ni ilu Oketepe, Okula, afunrasi naa ni o san ki oun ku ju ki oun ri bi wọn ṣe n ba oko ti oun ti n jiṣẹ jiya le lori lati bi ọdun kan sẹyin jẹ lọ.
“Nítorí pé ẹ gbẹ́kẹ̀lé kẹ̀kẹ́ ogun ati ọpọlọpọ ọmọ ogun yín, 
Nigba naa ọhun ni olotu ijọba ẹkun iwọ oorun orilẹede Naijiria.
Nipari Odumosu soro lori pataki ise akanse yii fawon olugbe agbegbe Ikenne ati Ijebu ode nipa ipese awon ohun amayederun sii fun won bi opopona to ja geere.
UNO bẹnu àtẹ́ lu ìdàdúró Onnoghen Àjọ NJC fún Onnoghen àti Mohammed ní gbèdéke ọjọ́ méje ‘Adájọ́ Àgbà Nàíjíríà, Walter Onnoghen ní ẹjọ́ láti rò’ Igbimọ ẹlẹni mẹta naa tun sọ pe, Onnoghen ko gbọdọ di ipo ilu kankan mu fun ọdun mẹwaa, ati pe ko gbagbe gbogbo owo to ni si apo aṣunwọn maarun nileefowopamọ.
Pasitọ Adeboye kan n sọ ododo ọrọ ni lati fi imoore han fun iyawo rẹ fun itẹriba to ni, nitori naa iwa oponu patapata gbaa ni lati maa fi ẹnu tẹmbẹlu rẹ, nitoripe ootọ ọrọ lo sọ.
"Ko si awọn ohun elo lawọn ileewosan alabọde, bẹẹni isẹ wọn gan ko rinlẹ laawujọ.
Ọlọrun ṣe èyí kí á lè tẹ̀lé ìlànà Òfin ní ẹ̀kúnrẹ́rẹ́, àní àwa tí ìhùwàsí wa kì í ṣe bíi tí ẹni tí ẹran-ara ń lò ṣugbọn bí àwọn ẹni tí Ẹ̀mí ń darí.
Wọn ni iro ibọn nikan lawọn gbọ bi awọn ṣe n kọja ti Linda si paruwo pe ibọn ti ba oun o.
Pẹlu bi o ṣe jẹ pe eka ere ori itage lorilẹ-ede Naijiria, ti a mọ si Nollywood ni awọn onwoye ti kede gẹgẹ bii ileeṣẹ tiata ti o n goke ju lọ lorilẹ-ede agbaye, ẹka ere tiata ilẹ Yoruba, Yollywood si jẹ ọkan lara awọn ti o gbe e soke.
Nítorí kò sí ohun tí a fi pamọ́ tí a kò ní gbé jáde, bẹ́ẹ̀ ni kò sí ohun ìkọ̀kọ̀ kan tí a kò ní yọ sí gbangba.
Udoma salaye ipinnu ijoba nipele meta lati fi mojuto afojusun eto ERGP pe:  “A n bere pelu eto ogbin ati eto irinna, eto ipese ohun eelo pelu ipese afefe gaasi atina monamona ti abala akoko ti bere lojo keedogun osu kinni si ojo kerin osu keta odun yii.
Ninu atẹjade kan to fi sita l'Ọjọru lati ọwọ agbẹnusọ rẹ, Yusuph Olaniyonu, Saraki ni EFCC lọ sile ẹjọ giga nipinlẹ Eko l'Ọjọru nibi ti wọn ti beere fun aṣẹ lati gbẹsẹ le ile rẹ to wa ni Ilorin.
Wọ́n gbàgbé Ọlọrun, Olùgbàlà wọn,tí ó ṣe iṣẹ́ ribiribi ní Ijipti,
dollars), ti o fi mo ise akanse irinna oju omi ti o wa niluu Warri.
Aṣiwaju ere awọn ẹyẹle tẹlẹ, ayara bi aṣa, Armando ti wọn sọ ni orúkọ agbaọjẹ F1, Lewis Hamilton ti fẹyin ti ki wọn to ta a lọdun 2019.
Ninu esi rẹ, Aṣofin Eṣinlokun sọ pe gbogbo ero ati aba awọn ara ilu naa ni wọn yoo ṣiṣẹ le lori ninu ijiriroro ile naa, ki wọn to sọ abadofin naa di ofin.
Ninu ọrọ kan to fi si oju opo Instagram rẹ pẹlu fidio diẹ lara bi nnkan ṣe lọ nibi ode ijo lọjọ naa, Naira Marley naa ṣe apejuwe ileeṣẹ baluu naa gẹgẹ bii 'ileeṣẹ baluu elebi' Naira Marley ni awọn oṣiṣẹ rẹ gbogbo gan ninu baluu naa titi kan awakọ baluu ọhun ni wọn jẹ Marlian, iyẹn apejuwe awọn ololufẹ Naira Marley.
15 Nítorí ìwọ ti fi ààyè gba ìmọ̀ràn olùdarí rẹ lati di ìtẹ̀mọ́lẹ̀ láti àtètèkọ́ṣe.
 Ìyọkúrò àwọn wíwú inú ara lábẹ àwọ ̀ ara nípa iṣẹ ́ abẹ ni a tún lèṣe .
Nítorí pé wọ́n ń sun turari lórí àwọn òkè ńlá,wọ́n sì ń fi mí ṣẹ̀sín lórí àwọn òkè kéékèèké.
Ìyàwó mi ṣẹ̀ṣẹ̀ bímọ tuntun, kò si oúnjẹ fún wa torí ìgbélé Coronavirus- Yakubu Auxiliary lo ń jà káàkiri ìlú Ibadan lọ́jọ́ Aje, ẹgbẹ́ ọlọkọ èrò NURTW kọ - Ejiogbe Coronavirus ló lé mi kúrò níléèwòsàn UCH n'Íbàdàn- Ogun Majek Ta a ni yóò rọ́pò Abba Kyari gẹ́gẹ́ bi olórí òṣìṣẹ́ Buhari?
Amọ ṣa, Oloye Adegbenga ni ti a ko ba fi oye tufọ, o ṣeeṣe ki oku di meji tori a ko mọ iru ipo ti ẹni ti a ba fẹ tufọ fun le wa.
Iwadi naa ni ''ẹyinkule lọta wa, ile ni aṣeni to n pa ọpọ awọn obinrin wọn yi n gbe.
Jakande pé 90 láì gba àmì ẹ̀yẹ kankan ní Nàíjíríà -Osoba Jeremy Hunt ni òun gbà pé Boris Johnson á ṣiṣẹ́ dáadáa Eyi ja si pe ida mẹrindinlogun naa ni o tun n tun fẹ lo lasiko yii.
Moloka ni wọn n pe orukọ ounjẹ naa.
Lẹ́yìn náà lòun fí àtẹ̀jíṣẹ́ ránṣẹ́ sí gbajúgbajà olórin náà lẹ́yìn ti òun fi àwọn fótò díẹ̀ sọwọ́ síi.
Tọwọ́ tẹsẹ̀ laá fi gba ìrànwọ́ owó ẹ̀kọ́ Almajiri ní ìpinlẹ̀ Oyo- Alága Subeb Buhari kàn ń kọwọ́ bọ̀wé nílẹ̀ òkèèrè kiri ni, a ò rí ipa ní Nàijíríà- Onímọ̀ ọrọ̀-ajé Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 3 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 5 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
 Mo n rọ awọn eeyan wa lati mọ riri ohun ti awọn ara oke okun ba fi ransẹ si wọn nile nitori ko rọrun rara fun ara oke okun naa lati to tu owo jọ, to si rọ awọn to wa loke okun pẹlu lati fi ẹsọ ṣe."
Ó ranti rẹ̀, ó dojúbolẹ̀, ó kí i tọ̀wọ̀tọ̀wọ̀, ó sì bi í léèrè pé, “Àbí ìwọ kọ́ ni, Elija, oluwa mi?
com/mBObC8e1noIle-ise omo ogun oju ofurufu fikun oro re pe, awon yoo ri daju lati
Ati pe ki wọn ko awọn ohun to jẹ ti ilu ati tile igbimọ aṣofin gbogbo to ba wa lọwọ wọn sile.
com/IyywFX4Wuc— Nigerian Air Force (@NigAirForce) 6 September 2018Oga agba Daramola tesiwaju pe, “Ni ojo keji ikolu naa, ti n se ojo kerin osu kesan odun ti a wayii, ikolu si ibudo otooto meta awon ogun olote naa lagbegbe Tumbun Rego, Sabon Tumbun ati Tumbun Allura, seku pa ogunlogo awon omo ogun olote ohun.
Ẹnikẹ́ni tí ó bá wá sọ́dọ̀ mi, n kò ní ta á nù; 
Wo imọran Fọlọrunṣọ Alakija fun awọn ọdọ adulawọ
Ilé aṣòfin Amẹ́ríkà yarí Ìwádìí BBC rèé lórí ìjà APC tó fẹ́ gbẹ̀mí Sẹ́nátọ̀ l‘Osun Ìlú tuntun tó kún fún ohun àdáyébá láìsí ọkọ̀ tàbí òpópónà ń bọ̀ ní Saudi Arabia Mo ti gba ọmọ Igbo tó ń wá bàbá rẹ̀ bí ọmọ, kó má ba à pa ara rẹ̀ - Iba Oluyole Lẹ́yìn ọgọ́rùn ún ọjọ́ tí wọn ti Lekki Toll Gate pa, ẹ wo owó gọbọi tíjọba Eko ń pàdánù Ẹ́ ràgà bo ìṣọ̀kan Nàíjíríà, ìyàpà le mú ìṣẹ́ àwọn akọni wa já sásán - Osinbajo August Agboola Brownie, ọmọ Yorùbá tí wọ́n n wárí fún ní Poland Gẹgẹbi iransẹ Ọlọrun naa ṣe sọ, ọpẹ ni ọjọ mọkanlelogun akọkọ ti wọn ba aawẹ naa yoo da le lori, ọjọ mọkanlelogun keji yoo da lori adura fun idile and bibeere fun aanu.
Igbimọ iṣakoso ijọba ipinlẹ Kano lo rọ Emir Sanusi loye ni ọjọ Aje, ọjọkẹsan oṣu kẹta ọdun 2020.
Mo bá gbé ère ọmọ mààlúù tí ẹ yá, tí ó jẹ́ ohun ẹ̀ṣẹ̀, mo dáná sun ún, mo lọ̀ ọ́ lúbúlúbú, mo sì dà á sinu odò tí ń ṣàn wá láti orí òkè.
" Akọroyin BBC naa tẹsiwaju pe Mbaka ati Obiekezie jade wa latinu ile nigba ti wọn gbọ ariwo ija to n lọ nita, ti Fada Mbaka si kọju si oun naa, bẹẹ lo n fi awọn ika ọwọ rẹ gun oun loju, to si n pe oun ni 'Elesu'.
Afọnja, ẹni tó finú wénú ní Ilọrin, àmọ́ tó jẹ iwọ 5:30 p.
1964 Wọn ran ọgbẹni Mandela lọ si ẹwọn gbere.
Àwọn aposteli ń fi ẹ̀rí wọn hàn pẹlu agbára ńlá nípa ajinde Jesu Oluwa.
Iranṣẹ rẹ ni mí,fún mi lóye, kí n lè mọ ìlànà rẹ.
Èsì àyẹ̀wò òkú George Floyd tí ẹbí rẹ̀ ṣe fihàn pé ó kú lẹ́yìn tí kò lè mí mọ́ Ìdí tí a ṣe fikún owó okọ̀ BRT l'Eko rèé - Fola Tinubu Ọmọ pupa làwọn olólùfẹ́ wa fẹ́ wò nínú fíìmù làwọn òṣèré tíátà fi ń bóra- Muka Ray Ẹ wo ọmọ Yorùbá kan tó ru àrùn coronavirus là nílẹ̀ Gẹ̀ẹ́sì Olorì Anu Adeyemi ń ṣe ọjọ ìbí, ẹ gbọ́ ǹkan tò sọ sí Kábíyésì Oríṣun àwòrán, Getty Images Esi ayẹwo ti ijọba ṣe tun sọ pe Ọgbẹni Floyd ku nitori awọn ailera kan to wa lara rẹ tẹlẹ ni.
Oríṣun àwòrán, Instagram/queen_Dami Olori akọkọ to kuro ni aafin Oyo lọdun 2020: Ṣe ẹ o gbagbe pe ninu ọdun 2020 yii kan naa, ni iroyin sọ pe, wọn ti le ọkan lara awọn olori alaafin to gbajumọ julọ lori ayelujara, Olori Badirat, kuro ni aafin.
Naomi sàlàyé pé nínú àhámọ Boko Haram, wọ́n pin ìwé kíkà fún àwọn láti máa fi kọ ẹkọ́ ìmọ̀ Kuran.
Ìwọ ati Abiatari, ẹ pada sí ìlú ní alaafia, mú Ahimaasi, ọmọ rẹ, ati Jonatani ọmọ Abiatari lọ́wọ́.
NCDC lo kede bẹẹ loju opo Twitter rẹ ni Ọjọ Ìṣẹ́gun.
Gbajumọ olootu, oṣere ati akọtan ere tiata ni Ẹniọla Afeez, Esther, iyawo rẹ naa kopa ni ọpọlọpọ awọn ere, paapaa julọ, ninu ere Jenifa.
Eyi loun naa fi de ibi ti oun wa de lonii, bi o ba ti pa ara rẹ, ẹ o ba ma til gb pe ẹnikan wa to n jẹ Seyi.
Ìjọba ń gbèrò láti fẹ̀sùn ìgbésúnmọ̀mí kan Sowore bíi Nnamdi Kanu- Falana Obasanjo, Gowon, Muhammed- wo àwọn olóri Nàìjíríà lọ́dọ̀ọ́ Àgbékalẹ̀ ètò tó ń ṣàmójútó ìnáwó ìjọba á gbógunti ìwà àjẹbánu- APC Ọ̀pọ̀ èèyàn ló sá fún mi nígbà tí mo dùbúlẹ̀ àìsàn- Ògògó Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Silas Robotic Engineer: Kò sí ǹkan rere tí ọmọ Nàìjíríà kò lè ṣe Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 3 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 5 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
7 to forukọ silẹ lọdun to kọja, 2018.
Aare wa soro nipa wahala to ku die ko waye lasiko ipolongo ibo aare to
9 Ma ṣe sọ ohunkohun ṣùgbọ́n ironúpìwàdà fún ìran yìí; pa àwọn òfin mi mọ́, kí o sì ṣe àtìlẹ́hìn lati mú iṣẹ́ mi jáde wá; ní ìbámu pẹ̀lú àwọn òfin mi, ìwọ yíò sì di alábùkúnfún.
Nígbà tí wọn dé ibi tí omi tí ń ṣàn wọ ìlú láti orí òkè tí ó wà ní ọ̀nà pápá alágbàfọ̀, wọ́n dúró níbẹ̀.
Nítorí náà a o rí pé ko dájú láti kó ààrùn Coronavirus látàrí pé ènìyàn wà nínú ilé kan náà pẹ̀lú ẹni tó ní ààrùn Coronavirus ṣùgbọ́n tí kò fàmì hàn bí ikọ́ àbí kàtá kò na ṣeé.
É sìí bó ṣe a rí
Awọn ọba mẹfa miran lati ijọba ibilẹ mẹta ti wọn sọ pe ọrọ naa ṣoju awọn naa, kọ ọrọ ẹri wọn lati ṣatilẹyin fun ẹsun ti Agbowu fi kan Oluwo.
Ni deedee aago kan aabọ oru ni a gbọ pe obinrin yii lọ ṣiṣẹ laabi ọhun.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Naira Marley: Àwọn agbẹjọ́rò ń jà sí àga ìjókòó níbi ìgbẹ́jọ́ Naira Marley 24 Ọ̀wàrà 2019 Oríṣun àwòrán, nairamarley Ile ẹjọ giga kan ni ipinlẹ Eko ti sun igbẹjọ gbajugbaja olorin Afeez Fashola ti gbogbo eniyan mọ si Naira Marley.
Oríṣun àwòrán, Femi Adesina Agbẹnusọ Aarẹ kan sọ fun BBC pe, Aarẹ fidi rẹ mulẹ fun awọn Aarẹ tẹlẹ naa pe, eeyan mọkandinlọgọrin lo ku nitori iṣẹlẹ naa, ṣugbọn ko ṣalaye boya awọn eeyan to gbẹmi mi ni Lekki wa lara awọn ti Buhari darukọ.
Mo ti yan àwọn eniyan rẹ, àwọn ọmọ Lefi, láàrin àwọn ọmọ Israẹli gẹ́gẹ́ bí ẹ̀bùn fún ọ.
Ó bá kígbe sókè, ó ní, “Dìde, kí o dúró lórí ẹsẹ̀ rẹ bí eniyan.
Olóòótọ́ a máa kórìíra èké,ṣugbọn eniyan burúkú a máa hùwà ìtìjú ati àbùkù.
Lórí iyansipo rẹ bíi agbenuso fún ilé, Ajibola ni yiyan tí wọn yàn òun, tòun ṣẹ̀ṣẹ̀ wá sílè asofin àgbà fún ìgbà àkọ́kọ́, lo ṣe àfihàn ìgbẹ́kẹ̀lé tí àwọn asofin náà ni nínú òun ni.
Kii ṣe Badirat Ajoke nikan ni olori to kuro ni aafin Oyo.
Man U tún ṣubú dàánù lẹ́ẹ̀kan síi Top 4 ta pàù!
Ṣugbọn, ori ko o yọ nigba ti oṣiṣẹ mọṣuari kan pada lọ yẹ ẹ wo nibi ti wọn gbe e si.
Akinyemi ni Ọjọ Keje, Oṣu Kẹjọ, ọdun 2020 ni baba ṣe ayẹwo fun arun Coronavirus ni ile rẹ to wa ni Olusegun Obasanjo Presidential Library (OOPL) Pent House residence, Okemosan, Abeokuta, ni ipinlẹ Ogun.
O ṣalaye pe abala keje ofin orilẹede Naijiria to sọrọ nipa awọn ijọba ibilẹ pe, bi a ṣe n dibo yan awọn aṣofin tabi gomina naa ni awọn alaga ijọba ibilẹ ni ẹtọ lati jẹ yiyan si ipo.
Bí wọ́n tilẹ̀ gbé ogun wá bá mi,sibẹ, ọkàn mi kò ní mì.
Awọn ipinlẹ ni Naijiria to woo julọ ni: Ọlọ́pàá Eko ní kí olùkọ́ UNILAG Boniface wá sọ tẹnu rẹ̀ lórí ẹ̀sùn ìfipábánilòpọ̀ Àjọ ọlọpàá Eko kédé pé ìbalòpọ̀ nítà kò bójúmu Àwọn ọ̀nà tí obìnrin fi le gbádùn ìbálòpọ̀ Sisitá ìjọ Kátólíkì méjì wá ṣe iṣẹ́ ìhìnrere l‘Afirika, lóyún bá dé Ẹ̀mi arákùnrin yìí kò gbé e, ó bá aláṣẹ́wò lò dórí ìgbà ìkéje ló bá ré sálákeji Porn Hub fikun pe orilẹ-ede Ghana, Kenya ati Egypt n tọ Naijiria lẹyin ni.
Tabili, pẹlu àwọn ọ̀pá rẹ̀ ati gbogbo àwọn ohun èlò rẹ̀ pẹlu burẹdi ìfihàn orí rẹ̀.
Jerusalẹmu ni Jehoṣafati ń gbé, ṣugbọn a máa lọ jákèjádò ilẹ̀ náà láàrin àwọn ọmọ Israẹli, láti Beeriṣeba títí dé agbègbè olókè Efuraimu, a máa káàkiri láti yí wọn lọ́kàn pada sí OLUWA Ọlọrun baba wọn.
Gbogbo alejo ti ọjọ ori wọn ba ju ọdun mejidinlogun lọ gbọdọ fi ọwọ si iwe Covid-19 ni ẹnu ọna, ki wọn si kọ orukọ wọn, adirẹsi ati numba ẹrọ ibanisọrọ wọn.
Rape: Norma Ka Mbele ní ayé òun kò rí bákàn náà mọ́ lẹ́yìn ìfipábálòpọ̀ Ọlọ́pàá ti bẹ̀rẹ̀ ìwádìí láti mọ òkodoro bí wọ́n ṣe gbé ọmọ tuntun náà sin láàyè ní India Ìdùnnú ni yóò jẹ fún wa ti wọn bá ṣe àwọn ọnà tí kò dára wọnyíì- Bosun Aguda Ajọ Amnesty International ní kò dín ní 119 ọmọ Nàìjíríà ti wọ́n ti gba ìdájọ́ ikú ní Malaysia Fatima Daura fi kun un wi pe kete ti Yusuf de pada ni Aarẹ ni ki Baba mi ko kuro ni Glass House lọ si ibo mii to tun tobi ni Aso Rock.
Bákàn náà ni May yóò jíròrò nípa ètò ààbò, fífí ènìyàn ṣòwò, lẹ́yìn náà ní yóò lọ si Èkó láti sàbẹ̀wò sí àwọn to ti bọ́ sọ́wọ́ ìmúnisìnru lọ́nà ìgbàlódé.
Ni ọjọ kinni, oṣu karun ọdun 2016 ni agbegbe Oke-Odan ipinlẹ Ogun, eyi to jẹ iwọn bii kilomita mẹwaa lati Idiroko tii ṣe ilu ibode laarin orilẹede Naijiria ati Benin Reepublic, ṣaadede ni wọn ni awọn ẹṣọ aṣọbode naa ya wọ ilu bi aguntan ti ko loluṣọ ti wọn si bẹrẹ si ni da ibọn bo ẹnikẹni ti wọn ba pade.
”Ṣugbọn àwọn mìíràn ń sọ pé, “Báwo ni Mesaya ti ṣe lè wá láti Galili?
Awọn Iroyin tẹẹ le nifẹ si Apapọ awọn to ko Covid-19 tuntun ni Naijiria si jẹ 304 Lapapọ awọn to ti ni Naijiria bayi jẹ 44,433 Awọn tara wọn ti ya lẹyin itọju si jẹ 31,851.
Lọtẹ yii, arabinrin kan, Adeola Bamidele ati ọmọ rẹ obinrin, Dolapo, ni awọn agbebọn kan kọlu ninu ile wọn.
ile-ise aladaani lati tubo da ile ise won sile lorile ede yii, sugbon awon
 Ọjọ ́ yìí ni ọ ̀ pọ ̀ lọpọ ̀ ìdílé wá sí ààrin ìlú láti oko tí wọ ́ n ń gbé yálà láti wá ṣo ìpàdé e mọ ̀ lẹ ́ bí tàbí láti wá ṣe ohun pàtàkì míràn .
Iṣẹ́ ẹ̀ṣẹ̀ ni iṣẹ́ yín,ìwà ipá sì ń bẹ lọ́wọ́ yín.
Lẹ́yìn tí Jesu ti tú àwọn eniyan ká, ó wọ inú ọkọ̀ ojú omi, ó bá lọ sí agbègbè Magadani.
Wọ́n fẹ́ràn láti máa fí fọ́nran síta Àwọn Boko Haram maá ń sáabà sẹ fídíò nígbà míran kété ti wọ́n ba ti wo ìròyìn tán.
Ìjọba Èkó figbé ìkìlọ̀ ta Lara awọn ti wọn tun so pọ mọ ẹjọ naa ni ọga agba ọlọpaa lẹkun kọkanla, AIG Zone XI, ajọ ileeṣẹ ọlọpaa ati amofin agba orilẹede Naijiria, Abubakar Malami lori ifidimulẹ ẹtọ wọn labẹ ofin.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: ''Ìdí tí mo fi rin ìrìn 800 metres'' 'Ayélujára la fi rí ọmọ wa tó sọnù!
Solomoni rú ẹbọ sísun sí OLUWA lórí pẹpẹ OLUWA tí ó kọ́ siwaju yàrá àbáwọlé ní tẹmpili.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù #EkitiDecides: Wọn gbe Fayoṣe digba digba wọ inu ọkọ alaarẹ 11 Agẹmo 2018 Àkọlé àwòrán, Fayose ní àwọn oṣiṣẹ aláàbò n dun koko mọ awọn ọmọ ẹgbẹ PDP nipinlẹ naa.
Amọ bi Ile Ifẹ se lagbara, to si gbajumọ to yii gẹgẹ bii ilu olokiki, asiko kan wa to la awọn ohun to lagbara kọja ninu itan, ti ilu naa si fẹ parun, gẹgẹ baa ti gbọ.
Iru eyi gan an lo ṣẹlẹ l'Ọjọru ni Ita-Faji lagbegbe Lagos Island niluu Eko Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Ni Ipinlẹ Delta, iroyin fẹsun kan gomina Ipinlẹ naa Ifeanyi Okowa wipe, gomina Ipinlẹ naa nigba kan ri, James Ibori ni baba isalẹ rẹ.
Cardi B ṣàlàyé ohun tó gbé fọ́tò ìhòhò rẹ̀ d'órí ayélujára Instagram Ẹ ṣọ́ra ní òpópónà AIT, ọkọ̀ agbépo kan ti yí dánù lọ́nà agbègbè Alagbado Wo àwọn ojúṣe àti èèwọ̀ fún ikọ̀ ọlọ́pàá SWAT tó gba iṣẹ́ lọ́wọ́ SARS Ìjọba ìpínlẹ̀ Eko ti kéde orúkọ àwọn ọlọ́pàá tó fi ìyà jẹ àwọn olùwọ́de #EndSARS Wo ìsọ̀rí àwọn tó jẹ́ kí ìwọ́de End SARS / end SWAT lárinrin àti ìtumọ̀ Falz ni irọ ni wọn fi bẹrẹ ijiroro lori ipade naa lati ibẹrẹ lori ohun ti wọn sọ fun oun.
O ni ''ẹnikẹni to ba ro wi pe ohun lee ko awọn janduku sẹyin lati ji apoti ibo tabi da ibo ru n fi ẹmi ara rẹ ṣere ni.
Ile ẹjọ ni o lodi si ofin ki oloselu to jẹ ọmọ orilẹede miiran yatọ si Naijiria, ki o dije dupo si Ile Igbimọ Asofin, gẹgẹ bi ẹsẹ ofin Section 66 (1) ti iwe ofin orilẹede Naijiria.
Ilé iṣẹ́ ọlọpàá náà si ti gbé àtẹ̀jáde kan síta pé, ìwà ti òṣìṣẹ́ wọ́n yìí hù kò bá ìlànà òfin tó dé iṣẹ́ náà mu, nítori ìdí èyí, àwọn ti bẹ̀rẹ̀ ìwádìí, ó sì ṣeeṣe kí Khapilat Kareem pàdánù iṣẹ́ rẹ̀.
o si se iranwo ayo kan ninu apapo ifesewonse marundinlogbon re ni saa ti a
Ní Ọjọ́bọ̀ ni àwọn ọlọ́pàá gbé Sẹ́nétọ̀ Dino Melaye lọ sí ilé ẹjọ́ lórí kẹ̀kẹ́ tí adájọ́ sì kọ̀ láti gba onídúró rẹ̀.
Ṣe awọn adigunjale naa ko gba eeyan siṣẹ ni ?"
5 ° fún ìṣẹ ́ jú kan .
Oríṣun àwòrán, Islamic Propaganda Àkọlé àwòrán, Ikọlu ti IS n ṣe ti sọ ọpọlọpọ orilẹ-ede di ahoro Awọn orilẹ-ede ti Islamic State ti n sisẹ niyii: Iraq: Orilẹ-ede Iraq ni orísun ẹgbẹ alakatakiti Islamic State, ati awọn isọmọgbe rẹ.
Àkúntúnkú, ìgbà márùn ún rè é tí Shekau kú tí wọ́n ní kò kú mọ Mohammed Yusuf: Irú èèyàn wo ní olùdásílẹ̀ Boko Haram?
Lati daabo bo ẹtọ awọn to ni idamu ọpọlọ.
Day 22: Ṣé o lè dìbò fún olùdíje obìnrin?
Awon miiran ti won tun yan
"Ọ̀rọ̀ ajé dẹnu kọ̀lẹ̀ yíká Nàíjíríà, àkẹ́kọ̀ọ́, olókoòwò àti òṣìṣẹ́ ọba jókòó sílé Ẹlẹ́wọ̀n 200 sálọ lọ́gbà ẹ̀wọ̀n Benin lásìkò ìwọ́de EndSars SERAP pe Buhari, igbákejì rẹ̀ lẹ́jọ́ lórí àfikún owó iná àti epo bẹntiró ""Buhari, ìwọ́de yóò yíwọ́, tó ba jẹ́ ki ológun bẹ̀rẹ̀ ‘Operation Crocodile Smile’ "" Ondo Ninu atẹjade ti ijọba ipinlẹ Ondo fi lede, igbimọ naa ni oṣu mẹfa pere lati ṣiṣẹ, ko si fi esi iwadii rẹ ṣowọ si ijọba."
Nítorí náà, a pọ́n idà náà, a sì fi epo pa á,kí á lè fi lé ẹni tí yóo fi paniyan lọ́wọ́.
 nítorí àjàkálẹ ̀ tó bẹ ̀ rẹ ̀ ní bùràsílì ní ọdún 2015 , Àjọ Ìgbìmọ ̀ Àgbayé kéde rẹ ̀ bíi Ìlera Àwujọ pàjawírì tí ó kan gbogbo Àgbayé ní oṣù kejì ọdún 2016 .
Ṣùgbọ́n ìbá tilẹ̀ gbẹ́ o, bí kò ṣe ti ẹ̀gbọ́n rẹ̀ Ìnàkí-gorí-ìtẹ́ tí ó wí pé àfi bí ó padà dandan.
Owo naa ni wọn ni o jẹ eyi ti wọn pa lati ara tita kaadi ẹrọ ayelujara lawọn ileesẹ ajọ naa to n bẹ lawọn ipinlẹ to fi mọ awọn alagbata rẹ.
"O ni: ""Gbogbo Emir Kano Maraarun ni yoo lọ yidi ni agbegbe wọn ninu mọtọ."
Òkúta emeradi, aṣọ àlàárì, aṣọ funfun onílà tẹ́ẹ́rẹ́ tẹ́ẹ́rẹ́, iyùn ati òkúta agate ni wọ́n fi ń ṣe pàṣípààrọ̀ fún ọ.
tí ó kú nítorí tiwa, ni ó pè wá sí, pé bí à ń ṣọ́nà ni, tabi a sùn ni, kí á jọ wà láàyè pẹlu rẹ̀.
Aaroni ati àwọn ọmọ rẹ̀ ni wọ́n ni àwọn burẹdi náà, ibi mímọ́ ni wọn yóo sì ti máa jẹ wọ́n, nítorí pé òun ni ó mọ́ jùlọ ninu ìpín wọn, ninu ọrẹ ẹbọ sísun sí OLUWA.
“Eto idibo ku osu meji ti yoo waye lọdun 2019, ni eyi ti a o yan awon ti yoo
Arole Oodua, tii tun se Ọọni ti Ile Ifẹ, Ọba Adeyẹye Ẹnitan Ogunwusi, Ọjaja Keji, lo fọwọ idaniloju yii sọya, lasikoto n ki Emir ti Borgu, Alhaji Muhammed Haliru Dantoro, Kitoro Kẹrin, kaabọ̀ si aafin rẹ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Akinyele local government: Iléeṣẹ́ ọlọ́pàá ìpínlẹ̀ Oyo ti mú àwọn afurasí lórí ìpànìyàn tó wáyé 3 Òkùdu 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 8 Agẹmo 2020 Oríṣun àwòrán, @NSEupdate Ileeṣẹ ọlọpaa ipinlẹ Ọyo ti fi ṣikun ofin mu awọn afurasi kan ni Ibadan lori iṣekupani Akinyele.
Lara awọn dukia ti awọn adigunjale naa ko ni ags ọlọpaa Nima to wa ni aringbungbun ilu Accra ni ẹrọ kọmputa alagbeka, tẹlifiṣan, awọn iwe atohun elo ikọwe to fi mọ ẹwu awọn ọlọpaa kan.
Oríṣun àwòrán, Others Ayanyemi ni orisirisi ilu lo si wa laye ode oni, paapa julọ, ni aafin ọba.
Jesu bá na ọwọ́, ó fi kàn án, ó ní, “Mo fẹ́ kí ara rẹ di mímọ́.
Ẹ má lọ sinu oko,ẹ má sì ṣe rìn lójú ọ̀nà náà,nítorí ọ̀tá mú idà lọ́wọ́,ìdágìrì sì wà káàkiri.
Ọmọlufa yan iṣẹ agbẹ laayo, to si di agbẹ paraku, to ni oko nla, ti kii si ṣe imẹlẹ, ọwọ rẹ ji sowo, iṣu rẹ n ta, agbado rẹ n yọ ọmọ bọkua-bọkua, to si n fi owo, ounjẹ ati aṣọ kẹ iya wọn.
 O ni eleyii yoo le ṣe iranlọwọ fun awọn to ku diẹ kaato fun lawujọ, yoo si le mu inu awọn ara ilu dun lapapọ.
Ẹ wo fidio ifọrọwerọ BBC Yoruba pẹlu Laycon naa ni oju opo wa ni Facebook wa: Bakan naa lo sisọ loju rẹ pe, ọrẹ oun ni Vee, bẹẹ ni ko si ọjọ kankan to jẹ ọjọ ibanujẹ fun oun lasiko ti oun wa nile BB Naija.
Lẹyin ti Titi ko sinu ilé Deji tan lo gbọ pe Deji ti pa iyawo akọkọ rẹ nitori #450, 000 tẹlẹ.
What did Buhari say about the lockdown: Awọn ọmọ Nàìjíríà káàkiri àgbáyé sọ ìrírí lábẹ́ àṣẹ kónílé-ó-gbélé
Ibeere yii lo gba ori ayelujara kan, to si nii se pẹlu iku ọmọ ogun orilẹ kan, Lẹfutanaati Borgi, ti wọn pa ni agbegbe Bama ni ipinlẹ Borno.
Oríṣun àwòrán, Biodun Fatoyinbo Àkọlé àwòrán, Iyawo gbaju-gbaja akọrin, Timi Dakolo, Busola Dakolo, fi ẹsun kan Fatoyinbo pe o fi ipa ba oun lo pọ lẹẹmeji ọtọọtọ ki oun to o pe ẹni ogun ọdun.
Ṣebí àwọn ọmọ Hamori, baba Ṣekemu, ni Gideoni ati Sebulu, iranṣẹ rẹ̀ máa ń sìn?
Lizzy Anjorin: Mi ò bẹ Toyin o!
Iroyin sọ wi pe awọn agbebọn naa ti wọn jẹ ole agbe-maluu, gun alupupu ṣigun kọlu ileto naa ti wọn si ṣi ina ibọn bolẹ, bẹẹni wọn n ti ina bọ ile gbogbo nibẹ.
Nibi ifọrọwanilẹnuwo naa ni ko ba ti raaye sọ bi yoo ṣe ṣe e.
Wo ìdí to fi gbọdọ̀ yàgò fún Bobrisky, akọ tó ń ṣe bíi abo Sanusi Adebisi Idikan rèé, olówó tó ń san owó orí fún gbogbo ọkunrin ilẹ̀ Ibadan Àkọlé àwòrán, #IRememberWhen: Kíni ẹyin rànti nínú àkna ti ẹ n ṣe tẹ́lẹ̀ Ọpọ awọn ọdọ asiko yii ni wọn ko jẹgba ri tori pe wọn fọ́ ẹyin lantani oke yii; ṣugbọn awa kan jẹ ẹgba ati igbaju olooyi tori pe ẹyin lantaani oke yii jabọ lọwọ wa.
Ijoba ipinle Jigawa ti kede pe aare Buhari ti o fe wa si ipinle Jigawa lojo Aje ose yii ti sun irinajo re siwaju .
Kọmisọnna naa wa fikun wipe ijọba ipinlẹ Eko mu ede Yoruba lọkunkundun ati wipe ohun iyi lo jẹ fun wọn lati gbe ede Yoruba larugẹ.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Germany na Nàìjíríà ni 2018 FIFA U-20 Osinbajo fi Seiyifa rọpo Daura gẹgẹ bí ọgá DSS 'Mímu ọyàn àyà ìyàwó rẹ̀ ní àǹfàní tó pọ̀' Usmanov ti gbiyanju lọpọ igba lati ra ikọ Arsenal ṣugbọn Kroenke to lowo to pọ ju ninu ikọ agbabọọlu naa kọ jalẹ pe oun ko ni ta ẹgbẹ agbabọọlu naa.
 Ó ń gbá fún wọn gẹ ́ gẹ ́ bí onígun ( winger ) .
mu igberu ba egbe NUJ lawujo.
Ile ẹjọ naa ni awọn ẹri to kun to ṣafihan ohun ti awọn agbabọọlu mejeeji fun Stamatopoulos fihan pe wọn jẹbi ẹsun naa.
Oloogbe naa si lo se oju opo ti wọn ti lee fi ẹjẹ silẹ fun idoola ẹmi lori ayelujara.
Iwe iroyin The Seattle Times sapejuwe okunrin naa gege bi eni ti ko naani nkankan to ti fi opolopo fonran fidio sori ayelujara nibi to ti n fi oko ofurufu Q400 kan to je ti Alaska Airlines dara lorisiirisi.
Ìròyìn Kàyééfì BBC Yorùbá: Ẹ̀kúnrẹ́rẹ́ àlàyé lórí ááwọ̀ tó wáyé láárin Oluwo ati Agbowu
Ọ̀kẹ́ Meje Ó Lé Ẹgbaaji (144,000) Eniyan Israẹli.
Eko ti fọwọ si abadofin ṣiṣe agbekalẹ Igbimọ Aṣakoso Ijọba ibilẹ Ati
Ta ni kò jẹ́ kí ẹ gba òtítọ́ mọ́?
Bí ẹ bá gba Mose gbọ́, ẹ̀ bá gbà mí gbọ́, nítorí èmi ni ọ̀rọ̀ ìwé tí ó kọ bá wí.
"O to awọn janduku mẹwa ti wọn ya bo aafin mi pẹlu awọn ohun ija oloro, ti wsn si n beere pe nibo ni Kabiyesi wa?
Dá mi lóhùn, OLUWA, nítorí ìfẹ́ rẹtí kì í yẹ̀ dára;fojú rere wò mí, gẹ́gẹ́ bí ọpọlọpọ àánú rẹ.
 Àwọn obìnrin kan wà tí wọn ti sá kúrò ní ibùba Boko Haram, àmọ́ tí òògùn olóró ti di bárakú fún nítorí ń se làwọn àdúnkookò-mọ́ni náà máa ń lo òògùn fáwọn ọmọdebìnrin náà tí wọn bá ti ń sunkún."
Iye awọn eeyan to ṣẹṣẹ ko arun naa ni ipinlẹ kọọkan ree: Eko -121 FCT-70 Bauchi-25 Rivers-18 Oyo-16 Kaduna-15 Gombe-14 Edo-13 Ogun-13 Jigawa-8 Enugu-6 Kano-5 Osun-2 Ondo-2 Ènìyàn 350 ló ní àrùn Coronavirus ní Naijiria ní Ọjọ́bọ̀ Oríṣun àwòrán, Twitter Eeyan 350 miran ni ayẹwo tun ti fihan pe o laarun Coronavirus lorilẹede Naijiria bayii.
Bí Jeremaya wolii ti dé bodè Bẹnjamini ọ̀kan ninu àwọn oníbodè tí orúkọ rẹ̀ ń jẹ́ Irija ọmọ Ṣelemaya ọmọ Hananaya mú un, ó ní, “O fẹ́ sálọ bá àwọn ará Kalidea ni.
Ti o ba ri bẹẹ, nigba wo ni awọn ologun yoo fi iwe ẹri ti aarẹ sọ pe o wa lọdọ wọn sita?
3 Èbibi 2019 Àkọlé àwòrán, Akọ̀ròyìn kan farapa nígba ifẹhonuhan awọn ara ilu ni Venezuela.
Ninu ọrọ rẹ, Alaga Igbimọ Tẹẹkoto fun ọrọ Ilera ninu  Ile Ìgbìmọ Aṣofin Ipinlẹ Eko, Asọfin Ṣẹgun Olulade sọ pe Ipade Itagbangba awon Alẹnulọrọ naa ṣe pataki lati fun gbogbo olugbe Ipinlẹ Eko ni anfaani lati le gba itọju to peye ni ile-iwosan ni ibikibi ti wọn ba wa ni ipinlẹ yii.
" ibi tí wọ ́ n kọ sí yìí maa ń jẹ ́ kí àwọn ènìyàn ní ààǹfàní láti wo òkun àti àyìká tí ó jẹ ́ kí wọ ́ n maa ń pèé ní "" environment of aquatic splendour "" ."
Yóo fún ọ ní ohun tí o fẹ́ ninu ọkàn rẹ,yóo sì mú gbogbo èrò rẹ ṣẹ.
”Ṣugbọn àwọn ọmọ Israẹli wí pé, “Ẹ jẹ́ kí á sá, kí á sì tàn wọ́n kúrò ninu ìlú wọn, kí wọ́n bọ́ sí ojú òpópó.
re ati igbimo alakoso iko naa, eleyi ti o si n fa ifaseyin fun iko Roma.
Titi di asiko yii, a ko tii le só ohun to ṣokunfa iṣẹlẹ naa ati iye awọn ti iṣẹlẹ naa kan.
Ẹ̀yin ọmọde, mò ń kọ ìwé si yín, nítorí pé a ti dárí ẹ̀ṣẹ̀ yín jì yín nítorí orúkọ Jesu.
"Alagba Markle ṣe adura pe ""ọmọ naa yoo dagba, yoo si sin ori ade atawọn eeyan ilẹ Gẹẹsi pẹlu ayọ, ati iwa rere."
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Alaafin: Ọmọ ọdún 17 ní Ayaba Abibat Adeyemi nígbà tó fẹ́ ọkọ rẹ̀ 8 Owewe 2020 Oríṣun àwòrán, Others Ọba alade nilẹ Yoruba jẹ ẹni ọwọ ati ẹni apọnle, ti awọn araalu si maa n bu ọla to pọ fun wọn.
“Olùkọ́ni, Mose pàṣẹ fún wa pé bí eniyan bá ní iyawo, bí ó bá kú láìní ọmọ, kí àbúrò rẹ̀ ṣú iyawo rẹ̀ lópó, kí ó ní ọmọ lórúkọ ẹ̀gbọ́n rẹ̀.
Ẹyẹ meji kii jẹ aṣa ni ọrọ Ọpẹbẹ ninu sinima nitori oun naa ni oṣere apanilẹrin ti o maa n gbe iwa akanda ẹda ti ọwọ n dun wọ, ninu sinima Yoruba.
Ọsẹ mẹta gbako ni ẹkọ igbaradi wọn lẹyin rẹ si ni wọn o pin wọn kaakiri sẹnu iṣẹ wọn.
Ìbátan mi ni òun í ṣe ni ìdí ìyá mi.
ẹ̀yin ọdọmọkunrin ati ọlọ́mọge,ẹ̀yin ọmọde ati ẹ̀yin àgbààgbà.
Wọ́n dán Ọlọrun wò ninu ọkàn wọn,wọ́n ń wá oúnjẹ tí yóo tẹ́ ìfẹ́ ọkàn wọn lọ́rùn.
BBC Yorùbá ní gbólóhùn pẹ̀lú àwọn agbábọ́ọ̀lù Super Eagles ní Egypt NGA VS GUI: Super Eagles fi Guinea ṣe ẹṣin lọ sí ìpele 'Round of 16' Bí eṣinṣin bá kọ́já, wíwọ́n ní, lásìkò ìṣíde AFCON 2019 Sọ àsọtẹ́lẹ̀ orílẹ̀èdè tí yóò borí ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ t'òní O ranti bi wọn ṣe ṣe e pẹlu ikọ Burundi ti wọn fi da sẹria fun wọn pe ik Burundi ba awọn wọ ọ gan ni ṣùgbọ́n Naijiria pada borí.
  Àyàfi tí ẹyẹ tàbí ọ̀kẹ́rẹ́ bá fi jẹ.
George AkumeIgbakeji alaga fun ila GusuAsofin
Ìdáhùn nìyíì Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí 3 sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
Adoniramu ọmọ Abida ni olórí àwọn tí ń kó àwọn eniyan ṣiṣẹ́ tipátipá.
Ohun ti o da Ẹlẹsọ yatọ si awọn adẹrinpoṣonu yoku ni ọrọ kabiti ẹnu rẹ ti ko lee ṣai dẹrin pẹrẹkẹ eniyan to ba wo sinima ti o ba wa.
a bí ògágun murtala ramat muhammed ni ojó kéjo , osù kejì odún 1938 ( 8 / 2 / 1938 ) .
Bakan naa Ilorin Express Junction-Ikoyi - Takie - Palace - Ogbomoso Grammar School road yoo maa jẹ Soun Oyewumi Ajagungbade.
“Mú Aaroni ati àwọn ọmọ rẹ̀ wá sí ẹnu ọ̀nà àgọ́ àjọ, kí o sì fi omi wẹ̀ wọ́n.
Nkan ti a n ja fun lori baba isale ni eto oṣelu pada wa sẹlẹ ninu eto idibo Edo Oludije ẹgbẹ oselu YPP ti sọ pe ọgbọn ti INEC lo lati fi saseyọri ninu eto idibo Edo jẹ eleyi to bọgbọn mu.
Nígbà tí kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ náà rí angẹli náà, ó wó lulẹ̀ lábẹ́ Balaamu.
OLUWA ni agbára ati orin mi,ó ti di olùgbàlà mi.
Agbára OLUWA sọ̀kalẹ̀ sára mi, ẹ̀mí rẹ̀ sì gbé mi wá sinu àfonífojì tí ó kún fún egungun.
Ajọ eleto ilera lagbaye, WHO lo fi ontẹ jan lilo oogun apakokoro lati le maa pa awọn kokoro to ba wa lọwọ lasiko ti ko ba si ọṣẹ ati omi larọwọto.
Ó wo ara rẹ̀ dáradára, ó kúrò níbẹ̀, kíá ó ti gbàgbé bí ojú rẹ̀ ti rí.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Egypt rán ènìyàn 700 lọ ẹ̀wọ̀n lórí ìfẹ̀hónúhàn 2013 8 Owewe 2018 Oríṣun àwòrán, Reuters Àkọlé àwòrán, Awọn márùndínlọ́gọ́rin ni wọn dajọ iku fun lara awọn to fi ẹhonuhan ni 2013 Orílẹede Egypt ti ran awọn eniyan bii has ẹẹdẹgbẹrin (700) lọri ifẹhonuhan awọn alatilẹyin ẹgbẹ Muslim Brotherhood lẹyin ti wọn le aarẹ orilẹede naa ana Mohammed Morsi kuro lori aleefa ni ọdun 2013.
3 biliọnu, owo iranwọ ti ijọba kede lọsẹ to kọja.
Ó jó àwọn ọmọ Jakọbu bí iná,ó sì pa gbogbo ohun tí wọn ní run.
Ohun tí a mọ̀ nìyí nípa ìdí tí Victor Giadom fi gbà'jọba ẹgbẹ́ òṣèlú APC Victor Giadom ti kede pe oun ko dede darukọ ara oun gẹgẹ bi Alaga ẹgbẹ oselu APC, amọ ile ẹjọ lo na ọwọ soke gẹgẹ bi adele Alaga ẹgbẹ oselu APC.
Tí ó sì dàbí ọmọ ọba obinrinláàrin àwọn ìlú yòókù.
Ajọ to n risi ọrọ oju popo lorilẹ-ede Naijiria, FRSC ni awọn awakọ igboro ni awọn kọkọ bẹrẹ si ni kan an ni dandan fun.
64 fun obinrin to ba fẹ kopa.
Won fagile awon esi ibo ni
Ti awon eniyan ba n gbo iroyin otito ati gbigbe igbe aye tooto, adinku yoo ba itankale aarun, awon eniyan yoo si maa gbe igbe aye alaafia.
Igbesẹ ti ijọba gbe yii tubọ mu ki ina ija laarin gomina ati Emir Sanusi o jo si.
”Aare ana ti koko ko iwe oju metala lati fi tako isejoba aare Buhari , ni eyi to si n pe fun igbese miiran lati fi gba orile ede yii sile lowo ipenija to n la koja.
Amọṣa, gomina ipinlẹ Kogi ni oun ko mọ nipa ohun ti oju igbakeji oun n ri lọwọlọwọ.
Ní ọjọ́ kinni oṣù keji, ní ọdún keji tí àwọn ọmọ Israẹli jáde kúrò ní ilẹ̀ Ijipti, OLUWA sọ fún Mose ninu Àgọ́ Àjọ, tí ó wà ninu aṣálẹ̀ Sinai, pé, 
Kí o ti àwọn ọ̀pá náà bọ àwọn òrùka tí wọ́n wà lẹ́gbẹ̀ẹ́ kinni keji àpótí náà láti máa fi gbé e.
Fẹstu wá fi ọ̀rọ̀ Paulu siwaju ọba.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ibrahim Gambari: Olórí àwọn òṣìṣẹ́ lọ́fíìsì Ààrẹ ní oun tí ààrẹ Buhari nílò ni ìjólóòtọ́, ìfọkànsìn pẹ̀lú àtìlẹ́yìn òun 13 Èbibi 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 14 Èbibi 2020 Oríṣun àwòrán, Getty Images Olori tuntun fun awọn oṣiṣẹ lọfiisi aarẹ, Ọjọgbọn Ibrahim Gambari ti sọ ọ laifọtape pe oun ati ọmọ Naijiria kii ṣe ọlọrọ o, oun ati aarẹ Buhari lọlọrọ ninu iṣejọba yii.
Ta ni yóo gbà mí lọ́wọ́ ara tí ó fẹ́ ṣekú pa mí yìí?
Fásitì Ghana lé olùkọ́ méjì tí àṣírí wọ́n tú lórí ẹ̀sùn ìbálòpọ̀ lọlé Ẹkún omí yalé, ó ṣekú pa ọmọ fásitì Akungba Mi ò gbọ́ pé Akeredolu ti yọ mí nípò gẹ́gẹ́ bíi Olùbádámọraǹ rẹ̀ - Pelemo Òótọ́ ni Iyabo Ojo ń sọ́!
Nigerians in Oman: Ààrẹ Buhari, ẹ̀yin gómìnà ìpínlẹ̀ Yorùbá, ẹ rántí wa ní Oman, àwọn ọmọ Nàìjíríà
Awọn akẹgbẹ rẹ ni bi o ṣe fi oogun apakokoro Snipper sinu irun ori rẹ lo de e pe ki o le pa awọn kokoro ina inu irun naa.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù AfroBasketWomen: Buhari kí D'Tigress lẹ́yìn tí wọ́n ṣíná ìyà fún Senegal gba ife 19 Ògún 2019 Oríṣun àwòrán, Twitter/FIBA Àkọlé àwòrán, La ba gbe ife ẹyẹ lọ kuro ni Senegal!
"Èèyàn 403 ló lùgbàdì àrùn Coronavirus ní Naijiria ní Ọjọ́ Isinmi Àjọ ọlọ́pàá, Ìjọba ìpínlẹ̀ Ọyọ jẹ́jẹ̀ẹ́ láti ṣàwárí òòsà tó ń mu ẹ̀jẹ̀ nílùú Ìbàdàn O ni ""Ki n ṣe pe o wu awa dokita lati gunle iyanṣẹlodi, ṣugbọn ijọba ko kọbi ara si gbogbo awọn ohun ti a n bere lọwọ wọn."
Bakan naa ni Adebimpe naa sọrọ nipa ajọsepọ oun ati Lateef ninu ifọrọwanilẹnuwo kan to ṣe pẹlu BBC Yoruba laipẹ yii.
Bóyá kí ìwọ Sergey ó ṣe ìfọ̀rọ̀wọ́rọ̀ náà?
Yoruba Culture: Ìran Yorùbá: Àṣà ju àṣà lọ!
O tun dupẹ lọwọ gbogbo agbaye fun atilẹyin wọn pẹlu afikun pe ibi to ba le, la n ba ọmọkunrin.
O ni gbogbo awọn ohun abẹmi inu odo naa lasiko ti wọn da majele naa sii lo fara gba ninu rẹ.
Joabu, ọmọ Seruaya, bẹ̀rẹ̀ sí ka àwọn eniyan, ṣugbọn kò parí rẹ̀.
''Ko si wahala kankan to jọ mọ iru eleyi ti a n koju ni Naijiria nipa aabo ni ilu ti mo wa.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Offa robbery: Saraki, NOPRIN ní ọlọ́pàá gbọ́dọ̀ ṣàlàyé bí Adikwu ṣe kú 21 Èbibi 2018 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 24 Bélú 2018 Oríṣun àwòrán, NIGERIAP POLICE FORCE Àkọlé àwòrán, Awọn marun un ni awọn afurasi ti o farahan ni iwaju ile ẹjọ nilu Ilọrin ni ọjọru.
Grace Osadebe ni yii to n ta bọọli, ẹja ati iṣu sisun ni Pọta to dẹ ti fi ṣe ohun rere gbogbo ti eeyan le fi iṣẹ ọwọ ẹni sẹ.
Awọn meji yii ni wọn yọ ninu ile naa bi ẹni yọ jiga lọjọ Isinmi.
Ẹ̀yin ọmọ, ẹ gbọ́ ẹ̀kọ́ baba yín,ẹ tẹ́tí sílẹ̀, kí ẹ lè ní ìmọ̀,
Wọ́n ti búra wọlé fún Akinwunmi Adesina gẹ́gẹ́ bí ààrẹ Banki ilẹ̀ Afrika, AfDB Àwọn ọba Yorùbá kan rèé tí wọ́n rọ̀ lóyè, tí ọba míràn jẹ lójú ayé wọn Bàbá ìsàlè ilé ìwé fásitì Nàìjíríà ni Ọba Enitan Ogunwusi!
O ni tọkọtaya ni wọn gbọdọ dijọ tẹriba fun ara wọn, ti ile yoo ba toro.
Agbẹnusọ fun Baba Obasanjọ, Kehinde Akinyemi lo fi lede bẹẹ ninu atẹjade ni Ọjọ Isinmi pe ayẹwo fihan pe ko ni arun Coronavirus.
Bí o ti jókòó ní ipò tọ̀ún tán àfi riri tí a rí ejò ńlá kan tí o ń yọ orí bọ̀, tí ó lọ mọ́ ọkùnrin yìí, wéré ó pa á wéré ó gbé e mì.
Mo wá wòye pé èyí pàápàá jẹ́ ìmúlẹ̀mófo.
Àwọn orin tí ó dùn jùlọ tí Solomoni kọ nìwọ̀nyí: 
Olùdíje mẹ́rin ti Gbajabiamila lẹ́yìn ṣáájú ìbò ilé aṣojú ṣòfin Gómìnà ìpínlẹ̀ Osun wọ́gilé ìrìnàjò àwọn alága sí Dubai Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Iba Gani Adams: Bẹ́ẹ gbé màláíkà kan lọ sí Aso Rock, kò lè ṣàṣeyọrí Ẹwẹ, bo ṣe n waye nipinlẹ Oyo naa lo n ri bakan naa ni Oke-Mosan, Abeokuta ipinlẹ Ogun nibi ti Họnọrebu Olakunle Taiwo Oluomo jawe olubori gẹgẹ bii adari ile igbimọ aṣofin ipinlẹ Ogun.
Iṣẹ aabo ilu kii ṣe ti ijọba nikan, bi kii ṣe ti gbogbo wa.
Àwọn ìlú mímọ́ rẹ ti di aṣálẹ̀,Sioni ti di aṣálẹ̀, Jerusalẹmu sì ti di ahoro.
Òdodo ni ìlànà rẹ títí lae,fún mi ní òye kí n lè wà láàyè.
Ọjọgbọ̀n to mọ̀ nípa ààbo àti itan iṣẹ̀nbaye, Adam Okene Ahmed sàlayé pé bi ìjà yìí ba ju bi óṣe wà yii lọláàrin àwọn orílẹ̀-èdè mééjèèjì o túmọ si pé Naijiria, Ghana, Chad, Gabon àti àwọn míràn yóò jẹ ànfani to pọ̀.
Sugbọn ti ẹkun omi yii si ti sọọ di ayalegbe bayii.
Ṣugbọn nisinsinyii, Timoti ti ti ọ̀dọ̀ yín dé, ó ti fún wa ní ìròyìn rere nípa igbagbọ ati ìfẹ́ yín.
Ijipti ń ru bí odò Naili,bí odò tí ó kún bo bèbè rẹ̀.
Fun apẹẹrẹ, ti eroja folic acid ko ba to nkan ni agọ ara obinrin to loyu, ọmọ inu rẹ wa ninu ewu lati ni aisan spinal bifida - ki ọpọlọ ati ọpa ẹyin ko ma dagba daada.
Victor Agunbiade ni ojú àlá ni Ọlọrun ti yan iṣẹ́ ọmọ ogun ojú omi fún òun ní America Ilé ayé mi ti d'ojú bolẹ̀ pẹ̀lú ikú àfẹ́sọ́nà mi- àfẹ́sọ́nà Immaculate Okochu Àgbo Covid-19 Madagascar kò ṣiṣẹ́, àwọn ènìyàn tí bẹ̀rẹ̀ sí ní kú níbẹ̀ Ilé ẹjọ́ ju ọmọ ìjọ tó fi ìpá bá ọmọ pásítọ̀ rẹ̀ sùn ní ìpínlẹ̀ Ondo sí ẹ̀wọ̀n gbére Ninu atẹjade ti Ogundipe kọ si Ozekhome, O ni wọn yọ oun lai tẹlẹ ilana otitọ ati ododo to yẹ ki wọn tẹle lati yọ oun kuro ni ipo.
O kere tan eniyan mejilelọgọtalelelọọdunrun lo n gba owo oṣu lai ṣiṣẹ ni ijọba ibilẹ to wa ni ipinlẹ Ekiti.
Wọn ni Makanjuọla sẹsẹ ri isẹ pẹlu Ile-Isẹ Dangote Cement Company , ti o si yẹ ko lọ bẹrẹ isẹ ni Ọjọ Aje, ọsẹ yii.
Yorùbá dùn lédè, ẹ máa sọọ́ Ajayi lo tumọ bibeli ni ede oyinbo si Yoruba, eyi to pe ni Iwe Mimọ Bibeli, to si tun se akojọpọ iwe atumọ ede (Dictionary) ni Yoruba O si tun kọ oniruuru iwe sita, to fi mọ akojọpọ awọn owe ilẹ Kaarọ oo jire to gbe jade lọdun 1852 Ajayi gbe ile kan ti Henry Townsend kọ silu Badagry lọdun 1845 fun ọpọlọpọ ọdun, to si tun gbe iwe jade lede Igbo ati Nupe lọdun 1864 Aisan rọlapa-rọlẹsẹ, ta mọ si stroke, lo gbẹmi Samuel Ajayi Crowther lọjọ kọkanlelọgbọn, osu Kejila, ọdun 1891, ti wọn si sin in si itẹ oku Ajẹlẹ nilu Eko.
Toyin Abraham Bi ọmọde o ku, agba ni i da.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Makinde: Ẹgbẹ́ òṣìṣẹ́ faramọ́ wíwọ́gilé ₦3000 táwọn akẹ́kọ̀ọ́ girama ń san Awọn alaga naa ṣapejuwe igbesẹ Makinde gẹgẹ bi aṣẹ onikumọ.
Nígbà tí Joabu rí i pé àwọn ọ̀tá ti gbógun ti òun níwájú ati lẹ́yìn, ó yan àwọn akọni ninu àwọn ọmọ ogun Israẹli láti dojú kọ àwọn ará Siria.
oni jẹ anfaani lati safihan ipa Pataki ti ile-isẹ omo ologun ko lati pese
Army: Ọkọ mẹ́sàn-án tó kún fún àpò ẹja la gbà lọ́wọ́ Boko Haram
Ẹjọ́ ọdún méje parí, àmì ìdánimọ̀ Messi di òótọ́.
 Lojo Eti yii ni ajo to n ri si bi won se n n ta epo robi lagbaaye iyen OPEC fenuko lori bi adinku yoo se de ba iwon epo robi ti awon orile ede kan, n ta epo robi si orile ede miiran.
Àwọn kan bá gbé arọ kan wá, ó dùbúlẹ̀ lórí ibùsùn.
” Àwọn ará Gileadi á bi í pé, “Ǹjẹ́ ará Efuraimu ni ọ́?
Àwọn ẹyẹ ìwò ń gbé oúnjẹ ati ẹran wá fún un ní ojoojumọ, ní àràárọ̀ ati ní ìrọ̀lẹ́ ìrọ̀lẹ́, ó sì ń mu omi odò náà.
    Ọjọ́ kejì ni a kúrò ní ìlú àwọn Aláṣjù.
Ijọba Naijiria ti kede pe wọn yoo pese ẹgbẹrun mẹwaa owo iranwọ fawọn oniṣowo keekeeke jakejado Naijiria.
Ṣugbọn Ọlọrun jí i dìde ní ọjọ́ kẹta, ó sì jẹ́ kí eniyan rí i.
A mọ̀ pé níwọ̀n ìgbà tí a bá fi ara yìí ṣe ilé, a dàbí ẹni tí ó jáde kúrò lọ́dọ̀ Oluwa.
Wọn ma n din, ti wọn si ma n gbadun rẹ lọpọ igba.
Ikú ti yọ́wọ́ òṣèré Nollywood Yorùbá, Yusuf Satia l'áwo Kí ló pa Bobrisky àti Olorì Aláàfin Oyo pọ̀?
Mallam Lanre Issa-Onilulo  lo soro yii ninu
FIFAWWCUP: Wo ohun mẹ́rin tó jẹ́ ki America tún gbá ife ẹ̀yẹ àgbáyé
“Ẹ gbọ́, ẹ̀yin ọmọ Israẹli, ẹ óo la odò Jọdani kọjá sí òdìkejì lónìí, ẹ óo sì gba ilẹ̀ àwọn orílẹ̀-èdè tí wọ́n pọ̀ jù yín lọ, tí wọ́n sì lágbára jù yín lọ.
Ìfẹ́ a máa mú sùúrù, a máa ṣe oore.
Kissing: Orílẹ̀-èdè Morocco, Egypt, Zimbabwe, UAE àti China tako títage níta
Owó díẹ̀ ni àwọn Filistia máa ń gbà, láti bá wọn pọ́n ohun ìtúlẹ̀ ati ọkọ́, wọ́n ń gba ìdámẹ́ta owó ṣekeli láti pọ́n àáké ati láti tún irin tí ó wà lára ohun ìtúlẹ̀ ṣe.
''Mi o mọ Van Persie ri, oun naa ko si mọ mi, nitorinaa Van Persie ko lẹtọọ lati ma tako ọna ti mo n gba dari ikọ Man U,'' Solskjaer lo sọ bẹẹ.
O ni inu oun dun pe arabinrin yii ko ba iṣẹlẹ naa rin nitori pe ori koo yọ pe ko fi ọwọ gbo oju rẹ nigba ti awọn kokoro naa wa ninu ẹyinju rẹ.
Nígbà náà ni mo dáhùn pé: “OLUWA Ọlọrun, jọ̀wọ́, dáwọ́ dúró.
O tọka si pe miliọnu kan aabọ ni gomina fun ijọba ibilẹ kọọkan, ti gbogbo wọn jẹ metalelọgbọn to wa ni ipinlẹ naa, lati fi ṣe awọn iṣẹ amuṣe kan.
Jẹ́ kí olukuluku máa lọ sí ilé rẹ̀ ní alaafia.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Èmi kìí ṣe ọmọ ẹgbẹ́ ASUU' Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, ASUU Strike: Bí àwọn kan se dunnú, làwọn kan fajúro Ogunyemi ni triliọnu kan naira le diẹ lawọn ati ijọba ṣadehun pe o yẹ ki wọn fi mu idagbasoke ba awọn fasiti Naijiria laarin ọdun 2013 si 2018.
Ṣaaju ni Oyetola ti kọkọ darapọ mọ awọn oluwọde naa lagbegbe Alekuwodo to si n ba awọn eeyan naa kọrin, pẹlu ileri pe gbogbo ẹdun wọn ni oun yoo gbe yẹwo ki awọn janduku to da iwọde ọhun ru.
Eeyan mọkandinlọgọta si lo ni i.
Nígbà tí ó sì sọ èyí fún mi tán, inú èmi náà dùn, mo jókòó dáadáa mo wí fún ọ̀rẹ́ mi tuntun yìí pé mo tẹ́tí sílẹ̀, kí ó máa bá ọ̀rọ̀ lọ.
Ohun tó sọ Okorocha di olóròróó ọ̀sán gangan
 nígbà mìíràn , Èṣù sì jẹ ́ olùdánwò fún ifá .
Ewe, omo odun mẹ́tàdínlọ́gbọ̀n ohun, Mahrez ran iko agbaboolu Leicester lowo lati gba ife-eye idije EPL ti saa idije 2016.
Ṣé ìgbé ayé rẹ dára ju bó ṣe wà lọdún mẹ́rin sẹ́yìn?
Aare tun tesiwaju pe :“iwa fifi emi ati dukia sofo to waye ni ipinle Plateau, je ohun to ba ni lokanje pupo.
Nigba ti Neymar de si ile igbafẹ naa ni ọjọ ikẹẹdogun oṣu kẹta, o daju pe o ti mọti yo gẹgẹ bi obinrin naa ṣe sọ.
ija oloro metalelogun (23); oniruru oko mejo (8); keke alupupu ti a mo si okada
1 Agẹmo 2019 Ọ̀pọ̀ ìgbà ni a maa n ri awọn agbabọọlu ti a nifẹ si ṣugbọn ti wọn yoo wa ninu awọn ẹgbẹ agbabọọlu oriṣiriṣi.
Gẹgẹ bi akọroyin BBC Yoruba to wa nibẹ ṣe sọ ọ, gba gba gba lawọn ọlọpaa duro sẹnu ọna ti awọn eeyan kan wa nita.
Ìlú mejila ni wọ́n fún àwọn ìdílé yòókù ninu ẹ̀yà Lefi tí à ń pè ní Merari gẹ́gẹ́ bí iye ìdílé wọn.
Wọn kò lè rí ohunkohun wí tí ẹ lè rí dìmú ninu ẹjọ́ tí wọn wá ń rò mọ́ mi lẹ́sẹ̀ nisinsinyii.
Àwọn agbésùmọ̀mí méjì ló ṣíṣe ńlá ibi òhún nínú mọsalasi kan, nígbà tí ikejì wáyé ní ìgboro Mubi tó jẹ́ ààlà orile-ede Naijiria àti Cameroon.
Ẹ kó gbogbo oriṣa tí àwọn baba yín ń bọ ní òdìkejì odò ati ní Ijipti dànù, kí ẹ sì máa sin OLUWA.
Adari Ikọ Ajọ Irinna popo ni ipinlẹ Eko, Hyginius Omejie to ba BBC Yoruba sọrọ lasiko to n fesi si igbesẹ wọn lati rii wi pe awọn awakọ lo ẹrọ ti yoo fopin si ere asapajude loju popo lasiko ọdun yii.
Cardi B ti pín yà pẹ̀lú ọkọ rẹ̀ Offset lẹ́yìn ọdún kan
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ẹgbẹrun meji o le lawọn to n reti iku lọgba ẹwọn Naijiria 16 Èrèlè 2018 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ọpọ awọn ti wọn da ẹjọ iku fun ni awọn gomina kuna lati buwọlu iwe iku wọn Ẹgbẹrun meji ati ọrinlelugba o le ẹyọkan awọn ẹlẹwọn ti wọn ti gba idajọ iku ni wọn kaakiri awọn ọgba ẹwọn lorilẹede Naijiria lọwọ yii sugbọn ti awọn gomina kọ lati fi ọwọ si iwe iku wọn.
"Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Toríi ""Coro"", ẹ wo bí ètò ìsìn ìgbéyàwó orí ayélujára Zoom ṣe lọ Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!"
Soyinka sọ eyi ni Abuja nibi ipade ẹlẹẹkẹjọ Ajọ Commonwealth fun awọn adari ile-isẹ to n gbogun ti iwa ajẹbanu ni ilẹ Afirika.
Atipe, lọwọlọwọ bayi, Ileesẹ BBC Yoruba ni aye mi.
Nigba to jẹ pe ko si ẹni ti ko ni ku, Balogun Landuji Oshodi Tapa dagbere faye ni ọjọ Keji, oṣu Keje ọdun 1868 lẹyin ọdun mẹfa to pada de silu Eko lati Epe.
Ibidun Ighodalo: Ǹkan ti amọ̀ nípa ilúmọ̀ọ́ká arẹwà obìnrin nígbà kan rí tó d'olóògbé Ọpọlọpọ awuye lo n lọ lori iku to pa Ibidun Ighodalo to jẹ́ ọbinrin tó rẹ̀wà jùlọ nígbàkan rí, tó sì tún jẹ́ ìyàwó adarí àti olùdásílẹ̀ ìjọ Trinity House.
Iroyin ti n gbe e jade tipẹ pe ikọ Real Madrid fẹ ki Hazard darapọ mọ ikọ ọhun lorilẹede Spain.
Ọmọ orilẹ-ede Naijiria ni ti wọn bi ni ọjọ kejidinlọgbọn, ọdun 1985.
1000 x Assorted rounds of different calibre ammunition.
High Profile Corruption Cases in Nigeria: EFCC fọwọ́ òfin mú èèyàn 865 lọ́dún 2020
ede Naijiria ,naa tun so nipa oju ona oko to lo si  Ilorin-Jebba ti won ti se lati mu igba aye
Aare Muhammadu Buhari ti bale siluu Krakow, lorile-ede Poland, saaju ipade apero kẹ́rìnlélógún egbe(COP24) ti o wa labe isokan agbaye, igbimo to n mojuto ipa iyipada oju ojo.
 Awon kan tile n so pe aare ko se
Alaafin of Oyo: Wo olorì Aláàfin tí àwọn èèyàn ń pariwo pé ó jọ Bobrisky
O pe àwọn okunrin Nàìjíríà nija láti dide ki wọ́n ba wọn ja.
Wọ́n tú àṣírí ìfiyàjẹni àwọn Ológun àti SARS káàkiri Nàìjíríà Ìgbìmọ̀ ọ̀tẹ̀ ní ọ̀rọ̀ àwọn àgbààgbà ẹkùn àríwá pé ìjọba Buhari ti kùnà- Femi Adesina Àṣírí èèyàn kan tó dìbò ní ìgbà 89 tú, Ọlọ́pàá gbé e jàǹtò!
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Emmanuel Macron: Maà á kọ́ ìjọ Àgùdà tó jóná láàárín ọdún máàrún ún 15 Ìgbé 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 17 Ìgbé 2019 Oríṣun àwòrán, @macron Àkọlé àwòrán, Gbogbo wa la jọ maa fọwọsowopọ Lẹyin ti ina jo ijọ Aguda nla ti orilẹ-ede Faranse ni aarẹ Emmanuel MAcron ti ni oun ṣetan lati tun un kọ.
Lẹ́yìn ọjọ́ díẹ̀, Jesu tún lọ sí Kapanaumu, àwọn eniyan gbọ́ pé ó wà ninu ilé kan.
Tinubu ní kò jẹ́ kí àwọn ọmọ bíbí Eko gbérí nínú òṣèlú Wo ipò tí Buhari fún Faṣọla, Lai Mohammed, Saraki àti bẹ́ẹ̀ bẹ́ẹ̀ lọ Ọ̀lẹ, aṣẹ́wó àti oníranù ni àwọn oní tíátà -Ìyá Rainbow Èrò àwọn ọmọ Naijiria ṣọ̀tọ̀ọ̀tọ̀ lórí àwọn ti Sanwo Olu yàn sípò Kíni àwọn ọ̀dọ́ Naijiria ń fẹ́ lọ́wọ́ àwọn mínísta tuntun?
Gbogbo àwọn orílẹ̀-èdè yóo péjọ níwájú rẹ̀, yóo wá yà wọ́n sọ́tọ̀ọ̀tọ̀, bí olùṣọ́-aguntan tíí ya àwọn aguntan sọ́tọ̀ kúrò lára àwọn ewúrẹ́.
Kọmiṣọna ọlọpaa ni ipinlẹ Edo, Haliru Gwandu lo ṣalaye ọrọ yii lasiko ifọrọwerọ lori ikanni ayelujara twitter kan to waye lori ọrọ awọn ọlọpa SARS.
Ẹ gba ẹnubodè kọjá,ẹ tún ọ̀nà ṣe fún àwọn eniyan.
Ọpọ awọn ọdọ ti wọn lara awọn to n ṣe iwọde ni wọn fesi pe alaafia lawọn n lepa, ati pe iwọde wọọrọwọ lawọn n ṣe.
" Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Alao Akala:Èmi àti Ajimọbi kò ṣe ìlérí kankan fún ara wa Agbarijọpọ ẹgbẹ oṣiṣẹ labẹ, NLC, TUC ati ULC n fi ẹhonu han lori bi ijọba apapọ ṣe kuna lati fi aba ofin nipa sisan ẹkunwo oṣu tuntun ranṣẹ si ile aṣofin apapọ fun lati fọwọsi.
Mo nigbagbo pe awon agbegbe yoo  fowosowopo pelu awon ile -ise ijoba lati lee
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ohun mẹ́fà tí kò yẹ́ kí o gbàgbé nípa Gómìnà Ambode Ẹ pé Sheuuuu fún ọmọ China tí wọ́n wé láwàní oyè fún nílu Kano Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Wo bí obìnrin ṣe lè kun ojú pá pà pá Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Eleyii to fa a ti wọn wọgile idibo to waye ni agọ idibo mẹtalelaadọta ni ẹkun Iwọ-Oorun Kogi ati mejilelogun ni ẹkun idibo Ajaokuta.
Ọkùnrin kan tó yasó nínú ọkọ̀ Uber rí ẹ̀wọn he Àṣé àṣírí wà nínú Hijabu tí Aisha Yesufu ń wọ̀ lọ ìwọ́de Ọgbẹni Dare fi kun ọrọ rẹ pe ijọba yoo ri wi pe gbogbo ilana idaabobo Covid-19 ni wọn tẹle lawọn ibudo yi.
Lumumuba Okugbawa lo fidi ọrọ yi mulẹ ninu ifọrọwanilẹnuwo pẹlu BBC Yoruba.
Olórí ẹ̀ṣọ́ Adarí ẹgbẹ́ òṣèlú APC, Bola Ahmed Tinubu ti kú lẹ́yìn tó lùgbàdì àrùn Coronavirus Gbogbo ìgbésẹ́ to yẹ ni a gbé nígbà ti àwọn ọ̀daràn dé ọgbà wa- Agbẹnusọ ọgbà ẹ̀wọ̀n Èèyàn 64 míràn tún ti ní àrùn Coronavirus ní Nàíjírìa Kókó mẹ́jọ tó jẹyọ nínú ọ̀rọ̀ Ààrẹ Buhari fáwọn ọmọ Nàìjíríà Ninu ohun ta ri gbọ ninu awọn iwe iroyin ilẹ Naijiria,eeyan kan ninu mọlẹbi Kọmisana sọ fun awọn akọroyin ni iAdo Ekiti lọjọ Aje pe awọn ajinigbe naa ti pe awọn lori ago ti wọn si ti beere owo ẹmi ọgbọn miliọnu naira.
Lọjọ ti iṣẹlẹ naa waye, Tolulope n lọ si ọja Mammy ninu ọgba ileeṣẹ naa to wa ni Kaduna ni nkan bi aago mẹrin abọ irọlẹ ko to pade awọn akẹgbẹ tẹlẹ nile ileeṣẹ ologun, Air Force Comprehensive School.
“Ẹ̀yin ni iyọ̀ ayé; ṣugbọn bí iyọ̀ bá di òbu, kí ni yóo tún sọ ọ́ di iyọ̀ gidi mọ́?
Joseph Olasunkanmi Tegbe - O yege4.
 Ìdí nìyí tí ó fi jẹ pé bí a bá fẹ ́ kí Ọba ṣe ohun kan fún ni a ó bẹ ayaba sí i , ipò alágbàwí láàárin àwọn abòòṣà àti olódùmarè ni àwọn òòṣà wà .
Lori gbogbo awọn to ku ti ile iṣẹ ọlọpaa foju wọn han pẹlu Sunday nigba naa, alukoro ọlọpaa salaye pe, gbogbo wọn si wa ni ahamọ.
Gege bi okan gbogi lara osise NFF se so,“Rohr ti pinnu lati mu Ezenwa ati Eze lati kopa ninu awon iko re ti yoo ko lo fun idije boolu agbayeO fikun oro re pe, o wa ku sowo awon mejeeji lati ja fun aye won ninu iko naa.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Wò ó bí Alaafin àti aya àkọ́fẹ́ rẹ̀, Olorì Abibat ṣe pàdé ní èwe Ìjà ẹgbẹ́ òṣèré TAMPAN àti ANTP ni kò jẹ́ kí wọ́n pe Baba Legba sínú eré mọ́, kó tó kú - Owolabi Ajasa Tí mo bá kú lónìí, Pásítọ̀ Ibiyeomie ló pa mi - Daddy Freeze kébòòsí Àwọn afurasí lórí ẹ̀ṣùn jíjí ìbejì Akeugbagold gbé yọnú sílé ẹjọ́ láì ní agbẹjọ́rò Aṣòfin méje yarí mọ́ Akeredolu lọ́wọ́ torí ọkọ̀ ayọ́kẹ́lẹ́ tí kò pín fún wọn Aya gómìnà Kwara gba ilé fún Risikat olójú búlúù àti ọkọ rẹ̀ Risikat, ìyá àwọn ọmọ olójú búlù tí bẹ̀rẹ̀ sí ní kọ́sẹ́ aṣojú lóge Lai Mohammed ni, bi o tilẹ jẹpe awọn yọ owo iranwọ to wa lori epo, iye ti awọn n ta lo kere julọ ni iwọ oorun ilẹ Afrika.
Ondo State: Àwọn aláṣẹ Poly Rufus Giwa di ítì pa di ọjọ́ iwájú
Àlejò àpàndodo ni Fayoṣe, a kò fìwé pèé - Afuye Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Lábẹ́ igi kan, ilẹ̀ ṣe bí orí ènìyàn kan tó lanu bí ẹní kọrin.
Àwọn òǹtàjà náà ń pin kiri àwọn ilé ijó lálẹ́, tó fi mọ́ ojú pópó.
Kí ló dé tí ẹ fi fi ojú tẹmbẹlu wa?
4 Agẹmo 2020 Alaafin Oyo: Níbo ni Olorí Anu àti Dami wà?
Bi omi ṣe gbe lọ ọ pẹlu ọmọ mẹrin ni yii.
Kí ló wà ní ìdí igbá tí àwọn olorì Aláàfin máa ń tí lóde Ọ̀yọ̀ Wo ipa tí ìlànà tuntun tí ìjọba Eko gbé jáde lórí Covid-19 yóò nìí ní ìgbésí ayé rẹ Ààrẹ Buhari kò ní bá àwọn ọmọ Naijiria sọ̀rọ̀ lónìí - Ìjọba àpapọ̀ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Coronavirus symptoms in Nigeria: Pẹ̀lú èròjà olùgbèjà ara 'Antibodies' Ohun iyalẹnu ni wi pe meji ninu awọn ọdaran naa lo sun mọ Baba ibeji pẹkipẹki gẹgẹ bi oṣiṣẹ, milliọnu mẹrin naira sini wọn gba ki wọn to jọwọ awọn ọmọ naa.
Bi o tilẹ jẹ pe ko tii si idahun sawọn ibeere naa bayii, sugbọn a mọ pe laipẹ ni idahun yoo maa ba awọn ibeere yii bi ọjọ ba se n gun ori ọjọ ni agbo oselu Naijiria.
Oladejo Okediji àti ìgbé ayé ìtàn kíkọ rẹ̀ Ọ̀wọ́ngógó epo bẹntirò: NNPC ni 'ìròyìn ẹlẹ́jẹ̀' ni Ọlọ́pàá gbé àwọn tó yìnbọn lu olólùfẹ́ ní Ajegunle Kínni ife ẹ̀yẹ ti Tiger Woods gbà ní Augusta fi yàtọ́?
Ṣugbọn ileeṣẹ to ni ẹlikoputa naa ni ko si oun to buru ninu wipe, ki awọn lọ doola ẹmi ẹni ti aisan mu ni ọna to jina.
Ariwo gbajare yii ni wọn ni o de eti Alaafin ti iku baba yeye fi paṣẹ ki wọn wa nnkan ṣe si ilẹ naa.
Àwọn ọmọ Israẹli tún wádìí lọ́dọ̀ OLUWA, nítorí pé àpótí majẹmu Ọlọrun wà ní Bẹtẹli ní àkókò náà.
O tun salaye iru obinrin ti oun n wa.
Ó sì lè gbin igi kedari kan, omi òjò a sì mú kí ó dàgbà.
 Ajafẹtọ naa ṣ'alaye fun BBC Yoruba lórí wahala ti oun ṣe ki o to di pe Darlington jade ni ahamọ ọlọpaa nigba ti ko si ẹri kankan pe o jẹbi."
Yorùbá ni “Bi a ti nṣe ni ilé wa, èèwọ̀ ibòmíràn” òfin Àmẹ́ríkà yi jẹ́ èèmọ̀ ni ilẹ̀ Yorùbá nitori a kò gbọ tàbi ka a ninú itàn àṣà Yoruba  .
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ojú mi ti rí lọ́pọ̀ lọpọ̀, àmọ́ mo dúpẹ́ pé mo ti pé ọdún márùn ún lórí oyé- Ooni Kinni Ronke Odusanya 'Flakky Ididowo' sọ?
"Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Oronpoto Animation: Akin Alabi ní kò dára bí eré aláwòrán fáwọn ọmọdé ṣe jẹ́ aláwọ̀ funfun Shina, lasiko to n sọ irinajo rẹ fawọn akọroyin lẹyin ti ọwọ ba a tan, salaye pe ""ọpọ etutu ni mo ti ṣe, ti n ko si le e ka tán."
Owo yii ni ajọ EFCC ni o wa lara owo kan ti ko bofinmu.
Gbogbo wọn ti yapa kúrò lójú ọ̀nà,gbogbo wọn kò níláárí mọ́,kò sí ẹni tí ó ń ṣe rere,kò sí ẹnìkan.
Oríṣun àwòrán, Instagram/odunomoadekola Ni nkan bi ọjọ meloo kan sẹyin lawọn kan ni awọn afọbajẹ ti kan sipe ko wa jẹ ọba ilu rẹ ṣugbọn oṣere naa ko ti sọ nipa rẹ.
Pẹlu ohun to n ṣẹlẹ si wa ni ilẹ Yoruba bayii, bi ijọba ko ba tete wa nnkan ṣe si, afaimọ ki awọn eeyan wa maa bẹrẹ si ni da ọgbọn ati daabo bo ara wọn o, eleyii ti ko ni so eso rere fun iṣọkan orilẹ-ede yii.
Awọn wọ̀nyí wà láàrin àwọn ènìyàn pàtàkì tí mo rò pé ó yẹ kí ọmọ Yorùbá máa rántí látí ìran dé ìran.
Mo si tun n sọ ni gbangba bayii.
OLUWA sọ fún Joṣua pé, “Wò ó!
Muhammadu Buhari ti ni ohun yoo tepele mo eto idaabo bo ẹtọ awon omo orile ede
Àwọn olórí ninu àwọn ọmọ Lefi: Konanaya pẹlu Ṣemaaya ati Netaneli, àwọn arakunrin rẹ̀; ati Haṣabaya, Jeieli, ati Josabadi, àwọn olóyè ninu ọmọ Lefi dá ẹẹdẹgbaata (5,000) ọ̀dọ́ aguntan, ati ọmọ ewúrẹ́, ati ẹẹdẹgbẹta (500) mààlúù fún àwọn ọmọ Lefi kí wọn fi rú ẹbọ Ìrékọjá.
Ayẹyẹ Hawan Sallah jẹ eto pataki, ninu eyi ti Emir ti ma n gun ẹṣin yipo ilu Kano, ti awọn eeyan yoo si ma a kan saara si.
Ile ise  to n ri si tita ati rira epo robi ni ekun Texas(WTI)yoo tun se agbekale ere ti won yoo ri lori epo lose yii.
Bakan naa lo tun lewaju ẹgb kan to n ja fun ilana iṣejọba rere, 'Red Card' Lara awọn ipo ti o ti di mu ninu iṣejọba orilẹede Naijiria lati igba ti saa iṣejọba tiwantiwa yii ti bẹrẹ ni amugbalẹgbẹ pataki fun aarẹ Ọbasanjọ lori amojuto iwe eto iṣuna, minisita fun ohun alumọni ati minisita feto ẹkọ.
Awọn ọmọde maa lọ yan bi ologun ni awọn papa iṣere kaakiri awọn ipinlẹ ni Naijiria ni ọpọ igba.
Oríṣun àwòrán, @NLCHQ_ABUJA O ni ifẹhọnu ti awọn fẹ ṣe ni Ọjọ Iṣẹgun ni lati dẹkun ifiyajẹni to n waye ni ipinlẹ Rivers.
Ọ̀rẹ́ mi, iṣẹ́ tí Olódùmarè bá rán ọ, jẹ́ ẹ fún àwọn ọmọ aráyé; má ṣe jẹ́ kí ó rẹ̀ ọ́.
fún àwọn ọba, ati fún gbogbo àwọn tí wọ́n wà ní ipò gíga, pé kí á máa ṣe pẹ̀lẹ́pẹ̀lẹ́, kí á máa gbé ìgbé-ayé bí olùfọkànsìn ati bí ọmọlúwàbí.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Àwọn agbófinró tún ti'mú Dino Melaye Kenya rí akẹ́kọ̀ọ́ tó há sí Ṣáláńgá yọ Èmi kò leè kú láéláé Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
bi oorun si ti yọ, lawọn omilẹgbẹ eeyan naa ti wọn da bii omi ninu asọ funfun, n gun oke Arafa yii, eyi to to kilomita mẹẹdogun si ila oorun ilu Mekkah, lẹyin ti wọn lo alẹ ọjọ kan lati sasaro ati ẹbẹ adura labẹ agọ ti wọn kọ fun wọn.
Wọ́n gbé asà wọn kọ́ káàkiri ara ògiri rẹ, àwọn ni wọ́n mú kí ẹwà rẹ pé.
" Inú ìbànújẹ́ ni mo wà lórí ikú alága CAN tí àwọn Boko Haram pa- Buhari Ààrùn ‘Coronavirus’: Ẹ yé rìnrìn àjò lọ sí ìlú Wuhan mọ́ Olanrewaju Bamidele fi 'Screw driver' gún ìyáwo rẹ̀ pa Mí ò le nífẹ̀ẹ́ obìnrin Nàìjíríà kankan mọ lẹ́yìn ti mo ti tọ́ obìnrin òyìnbó wò- Issa Bakan naa lo fikun pe, o yẹ ki awọn eeyan ilẹ Yoruba to tẹwọgba eto naa mọ nipa ofin to gbe Amotekun royats si awsn eeyan to n tako.
Dorathy: Oríṣun àwòrán, Instagram/Dorathy Dorathy Bachor, to jẹ gbaju-gbaja lori eto naa, ti ọpọ si sọ pe o konimọra, lo ṣeeṣe ko gba ipo keji nitori bi awọn eeyan ṣe n dibo fun un.
Ohun tí Jesu ń sọ̀rọ̀ bá ni ikú Lasaru, ṣugbọn wọ́n rò pé nípa oorun sísùn ni ó ń sọ.
Mo ké pe OLUWA, ẹni tí ìyìn yẹ,ó sì gbà mí lọ́wọ́ àwọn ọ̀tá mi.
Oríṣun àwòrán, @OfficialPDPNig O ni O yẹ ki n rinrin ajo kan, ṣugbọn mi o ni lọ titi di ọjọ Jimọ ti mo maa lanfani ati gbadura papọ ni Mọṣalaṣi kan pẹlu Sanusi."
pé, “Jẹ́ kí a ní àjọṣepọ̀, gẹ́gẹ́ bí àwọn baba wa ti ṣe; gba wúrà ati fadaka tí mo fi ranṣẹ sí ọ yìí, kí o dẹ́kun àjọṣepọ̀ rẹ pẹlu Baaṣa ọba Israẹli, kí ó lè kó àwọn ọmọ ogun rẹ̀ kúrò lórí ilẹ̀ mi.
    Àṣé bí ó ti lọ tán, ṣe lo lọ yí aṣọ padà.
Gomina Akeredolu ti wá rọ àwọn ara ilú láti lọ fi ọkàn wọ́n balẹ̀ ati pe ìjọba ti ṣe awọnn èto láti koju àjàkálẹ̀ ààrun náà.
Awọn to tun wa ninu ewu to l'agbara ni awọn alaboyun, ati awọn ti agọ-ara wọn ko l'agbara to lati gbogun ti aisan.
Vice Presidential Debate: Osinbajo,Peter Obi ko yọju ‘ASUU da ìyanṣẹ́lódì dúró' Lẹyìn tí mo figbe ta, INEC mú PVC mi wá bá mi nílé - Gani Adams Obasanjo, Osinbajo, Shonekan àtàwọn èèkàn ọmọ Ogun nínú ìṣèjọba Nàìjíríà.
Awon alase ni baalu naa gbera lojo Eti laigba ase lati gbera kuro ni papako ofurufu ni eyi to je ki ijoba ti papako Seattle-Tacoma pa.
Ṣugbọn o, awọn ẹbi tun le pe ẹjọ kotẹmilọrun si ile ẹjọ to gaju lọ, lati da pipa awọn ọ̀daràn naa duro, ti wọn ba le ṣe bẹẹ ki o to di aago mẹrin irọlẹ.
Ènìyàn tó lé ni ẹgbẹ̀rún kan (1,247) ló ti ba corovirus rin lọ́dun 2020.
Ìtàn tó wà nídi òwe ‘Sebótimọ Ẹlẹ́wà Sàpọ́n’ Irú ọmọ wo ni Yorùbá ń pè ní Àjàyí?
Bakare Olumide sàlàyé fún BBC News Yoruba pé, lọ́sàn ọjọ́ ìṣẹ́gun ni àwọn ọlọ́pàá mú ọkọ̀ Uber ti ó gbé àwọn ti wọ́n sì darí àwọn láti lọ si àgọ́ ọlọ́pàá tó wà ni Ogudu l'Eko.
A ti so obinrin pọ̀ mọ́ ọkọ rẹ̀ níwọ̀n ìgbà tí ọkọ rẹ̀ bá wà láàyè.
Ọba Abdulrasheed Akanbi rọ àwọn Ọba aláde yoruba láti dẹ́kun ẹgbẹ́ òkùnkùn síṣe
Lara awon to peju sibi ipade ohun ni Alaafin ilu Oyo,
Gbogbo eniyan ri i gẹgẹ bii onirẹlẹ eniyan ati olusin Ọlọrun.
Wọn tun sàlàye pé lasìkò ti ìgbẹ́jọ rẹ̀ ń lọ lọdun 2015 ni Aroke ra ilé oni yàra mẹrin ni Plot 12, Deji Fadoju òpópònà, Megamounds Estate Lekki County Homes , Lekki ní mílíọnù N48.
Nitorina ipese ma n wa fun awọn obinrin lati le wọ ile iwe ki iye wọn ba le dọgba pẹlu awọn ọkunrin wọn.
Eyi to daju ni pe, ati ẹlẹsin Kristẹni ati ẹlẹsin musulumi lo wa ninu awọn eeyan to le ni miliọnu meji to n tẹle loju opo Instagram.
Ọjọ keji, oṣu kẹfa ni Aarẹ Buhari yoo pada si orilẹ-ede Naijiria.
Wan kan n gbé òfin kalẹ̀ ni.
Mo wo apá ọ̀tún, n kò rí i,mo wo apá òsì, kò sí níbẹ̀.
Ahabu ọba sọ gbogbo ohun tí Elija ṣe fún Jesebẹli, aya rẹ̀, ati bí ó ti pa gbogbo wolii oriṣa Baali.
Bí mo tún ti gbé ojú sókè, mo rí ọkunrin kan tí ó mú okùn ìwọ̀n lọ́wọ́.
Bí àwọn ọmọ ogun Baraki ti ń fi idà pa wọ́n, Sisera sọ̀kalẹ̀ ninu kẹ̀kẹ́ ogun rẹ̀, ó bẹ̀rẹ̀ sí sá lọ.
Ìdí tí ASUU kò fi d'ópin ìyanṣẹ́lódì lẹ́yìn tí ìjọba sọ pé òun ti dá wọn l'óhùn NLC, TUC, ULC yóò ṣe ìwọ́de l'ónìí Ìpàdé NLC àti ìjọ̀ba àpapọ̀ lórí owó osù tuntun forí ṣánpọ́n Buhari kò leè ṣàtìlẹyìn fún olùdíje Amosun l'Ogun Alaga ijọba ibilẹ Irẹpọdun, Muyiwa Ọladipọ lo kede rẹ ni ilu Omu aran.
Nígbà tí obinrin náà rí i pé kò ṣe é fi pamọ́, ó bá jáde, ó ń gbọ̀n.
Bó ọmọdé bá ṣubú a wo iwájú, bí àgbàlagbà bá ṣubú, á wo ẹ̀yìn.
Josẹfu bá kó wọn súnmọ́ baba rẹ̀, baba rẹ̀ dì mọ́ wọn, ó sì fi ẹnu kò wọ́n lẹ́nu.
"Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Àrà méèrírí , ẹ wo ọkùnrin tí eegun rẹ̀ rọ̀ bíi rọ́bà, tó ń ká bíi ẹja Ọbasanjọ sọ àsírí sàgbàdèwe rẹ̀ Lẹ́yìn ìfẹ̀yìntì ọdún márùn-ún, báágì àti bàtà ló kàn Kloe tó lọ sí BB Naija rèé, ó ní òun fẹ́ràn ọkùnrin tó bá dúdú Àlàyé rèé lórí bí ilé mííràn ti wó l'Eko ""Ìlú mímọ́ nibí, wọn kò gbọdọ̀ bímọ, sin òkú àbí ẹran síbẹ̀"" O fikun pe fere fifọn ko di iwe oun lọwọ nitori pe, oun kii ranti fere fifọn rara lasiko ti oun ba n kẹkọ lọwọ."
" Ó dá agbo súúfí tirẹ ̀ náà sílẹ ̀ tí ó pe orúkọ rẹ ̀ ní "" zawiyyah daru salam "" ní ajélógo kétu mile2 ní 1980s , àti láborà ní ọdún 1999 ní ìpínlẹ ̀ Èkó , tí ó sì tún fi lọ ́ lẹ ̀ ní modinatu daru salam okolówó níbọdún 2006 ."
awon kan maa so fun ọ pe iyanu kan lee sẹlẹ.
Ǹjẹ́ eniyan a máa fi kùmọ̀ lọ ọkà alikama tí wọ́n fi ń ṣe burẹdi?
Bo tilẹ jẹ pe eto aabo nijọba sọ pe o fa igbesẹ naa, o foju han pe nitori ija to wa laarin igbimọ lọbalọba ati ijọba lo fa a.
Lanre Kuti ni mo fẹ́ - Jaiye Kuti Ninu oṣu keji dun ni wọn le ọmọkunrin to wa ninu fidio naa danu tefe tefe lẹyin ti iwadi fi han wọn pe o lọwọ ninu awọn iwa wuru wuru ti ile iwe ko fọwọ si.
O ni awn yoo ṣe ojuṣe awọn si Naijiria bo ṣe tọ ati bo ṣe yẹ.
Àwọn àjẹsára àrùn rọpárọsẹ ̀ , jẹ ́ àwọn àjẹsára tí à ń lò láti dènà àrùn rọpárọsẹ ̀ ( ) .
Ode/Isinigbo land Crisis: Ìjọba ìpínlẹ̀ Ondo kéde òfin konile-o-gbele ní Ode ati Ishinigbo
Pierre-Emerick Aubameyang lo gba bọọlu wọle fun Arsenal, niṣe lo fi bọọlu ju goli si ibi ti ẹgbẹ kan.
Èyí yóo jẹ́ kí ẹ wòye, kí ẹ wá mọ̀ pé Baba wà ninu mi, ati pé èmi náà wà ninu Baba.
Tẹẹ ba gbagbe, Ojilelẹẹdegbẹta ọmọ Naijiria, to jẹ isi kinni awọn ọmọ Naijiria to rinrin ajo lọ silẹ Libya, lo pada de si ilu Port Harcourt lọse to kọja.
Nítorí náà, wọ́n sán aṣọ ọ̀fọ̀ mọ́dìí, wọ́n sì wé okùn mọ́ ara wọn lórí.
Ṣugbọn títí di ọjọ́ òní, nígbàkúùgbà tí wọn bá ń ka Òfin Mose, aṣọ a máa bo ọkàn wọn.
Aare Buhari wa rọ  ajọ eleto aabo lorile ede Naijiria  lati jẹ oju ni alakan fi n sọri,ki won si  wa ojutuu si isoro eto aabo lorile ede
 Ni ṣọọṣi tiwa, ago mọkanla alẹ la o pari isin adura opin ọdun wa, ki awọn eeyan le lanfaani lati pada si ile wọn ki iṣede to bẹrẹ laago mejila.
Bí bẹ́ẹ̀ bá ni, ọpọlọpọ ìgbà ni ìbá ti máa jìyà láti ìgbà tí a ti fi ìdí ayé sọlẹ̀.
Wọ́n ti fa Ààrẹ Amẹrika, Donald Trump kalẹ̀ fún àmì ẹ̀yẹ Nobel Peace Prize Ọkùnrin tí wọ́n fẹ̀sùn kàn pé ó jí ǹkan nílé ìjọsìn rí ẹ̀wọ̀n he!
 Awọn ọmọ onilẹ naa ko ọlọpaa lẹyin, t'oun ti aṣẹ ile ẹjọ gẹgẹ bi iṣe wọn lọsẹ yii.
Ìjọba tún paá láṣẹ pé kí ilé ìwòsàn náà má dari àwọn ènìyàn sí ilé ìwòsàn Abuja mọ́ láì gba àṣẹ láti ọ̀dọ̀ ìjọba ìpínlẹ̀ Kogi, Lẹ́yìn èyí ọ̀pọ̀ àwọn ti FMC fi sọ́wọ́ si Abuja ló ní ààrùn náà.
Ẹwẹ, alaga igbimọ alaṣẹ ẹgbẹ oṣelu PDP, Sẹnatọ Walid Jibrin ti sọ pe ibukun nla ni igbesẹ ijọba Buhari lati gbe agadagodo sẹnu ibode Naijiria.
Minista fun oro ile okeere ni Jordan, ti se ikilo pe o lewu ti Amerika ba fopin si iranlowow yii nitori pe ajo to n risi oro awon asatipo Palestine UNRWA ko ni agbara lati pese ohun to ye fun won lasiko yii.
" Ọmọkunrin kan fẹ́ jána mọ́ móto mi lẹ́nu lójú pópó, mo sọ̀kalẹ̀ nínú mótò mi láti ba ọmọ náà wi pé kí ó m a ṣe bẹ́ẹ̀ mọ́""."
minisita lo se abewo si oju ona oko oju-irin ti o wa ni opopona Eko si Ibadan,
Kii wọpọ ki awọn obinrin maa yọra sibi iru nkan bayii ṣugbọn wọn pọ ti wọn patẹ iṣẹ ọwọ wọn lọtẹ yii.
Dipo iyanṣẹlodi, eyi ti ọpọ ọmọ orilẹede Naijiria n fọkan si tẹlẹ, ẹgbẹ oṣiṣẹ ni iwọde nikan ni yoo waye bayii.
s ' akiyesi pe awon nomba onipin ko lo tan o .
Chelsea ṣetán láti gb'ẹ̀san 4-0 lára Manchester United Davido lẹjọ ro lórí àwọn obìnrin tó sọ panpẹ sí lọ́wọ́ - Ọlọ́pàá Misago ni ọjọ Iṣẹgun l'oun sin ọmọ naa, ọjọ kan naa ti ọmọ yii ku.
Batiṣeba sì ṣẹ̀ṣẹ̀ parí ètò ìwẹ̀nùmọ́ rẹ̀ lẹ́yìn tí ó parí nǹkan oṣù rẹ̀ ni.
"APC ṣe afikun saa Oyegun gẹgẹbii alaga Ọwọ ologun tẹ darandaran mẹwa ni Benue ""A si ti gbe igbesẹ ki wahala naa maa baa tan ka de awọn agbegbe miran ni ipinle yi."
Ara awọn ti wọn ran l'ẹwọn ni gbajugbaja oniroyin alaworan kan ti orukọ rẹ njẹ Mahmoud Abu Zeid.
Bí wọ́n ṣe pín wọn kò sì fì sí ibìkan nítorí pé 
Gẹgẹ bi awọn alaṣẹ ilu Chicago ṣe sọ, titi di ọjọ karun un oṣu kẹrin, ẹgbẹrun mẹrin ati ọrinlelẹgbẹta eeyan ni arun coronavirus ti mu, okoo le lẹgbẹsan ati mẹrin ni iye awọn eeyan to jẹ alawọ dudu laarin wọn.
Ní kété to bá sì ti rí im'\\o-ill yiìí yóò gbẹ́lẹ̀, bákan náà ni yóò pe ènìyàn ti wọ́n jọ ń ṣiṣẹ́ láti ṣe èyí tó kù ni àṣeyọri.
Ijọba lo gba awọn ọmọ ikọ PMS si iṣẹ lati di gbogbo ibi ti owo n gba poora, ki wọn si tun ri i daju pe owo to n wọle fun ijọba pọ si.
Ikilọ ree lati ẹnu Igbakeji aarẹ Naijiria tẹlẹ ri Atiku Abubakar lori ọna ati dena itankalẹ arun Covid-19 lẹẹkeeji ni Naijiria.
nigba ti o ni iye ibo 11,262,978 .
Coronavirus: Wo èròjà tó wà lára àwọn èèyàn kan, tí Covid-19 fi di èèwọ̀ fún wọn
Loju opo Adetayo Adeseyi, @ade_tayos, o ni oun lero pe ojo yoo rọ loni lati ba abẹwo Buhari jẹ ni Eko.
“Kò sí ẹni mímọ́ bíi OLUWA,kò sí ẹlòmíràn,àfi òun nìkan ṣoṣo.
kò sí bí a óò ti perí ajá tí a kò ní perí ìkòkò tí a fi ṣè é .
Eyi ti yoo si tan de inu ẹjẹ ni yoo ba fa ẹjẹ riru.
Ìfẹ́ rẹ tí kì í yẹ̀ níye lórí pupọ, Ọlọrun!
Koda awọn oṣiṣẹ ipinlẹ Eko yo rẹrin lọ ile nipari oṣu kọkanla yii, nitori oṣu gan an ni ijọba yoo bẹrẹ si ni san ẹkunwo owo oṣu oṣiṣẹ tuntun.
Agbenusoro fun awon omo ile igbimo mẹ́jọ  naa, so fun awon akoroyin pe igbimo asofin ti bere igbese lati yo gomina Orhtom nipo gege bi gomina nipa iwa sise owo ilu kumọ-kumọ.
Ni bàbá fi igbe ta, àwọn àwòdì kò rí ẹran gbe, ọ̀bẹ bàbá ni wọ́n kì mọ́lẹ̀.
pe digbi ni ile ise ọlọpaa ipinle Oyo wa, lati ri daju pe ayeye ati eto
Ǹkan mẹ́jọ tó máa kọ́kọ́ ṣẹlẹ̀ kí olólùfẹ́ méjì tó pa ara wọn Wo àwọn orílẹ̀-èdè márùn ún tó fún àwọn obìnrin làńfàní tuntun sí ẹ̀tọ́ wọn Nàìjíríà kò nílò sénétọ̀ kankan- Fayemi Jessica Nabongo ni obìnrin àkọkọ nílẹ Adúláwọ tó rin gbogbo àgbáyé.
Adesọji Aderẹmi ti pe ogoji ọdun ti ọba naa papoda bayii, ko si ni dara ki iran asiko yii ma mọ ẹni ti Ọba Adesọji Aderẹmi se O si tun yẹ ki wọn mọ awọn ipa ribiribi to ti ko si igbega iran rẹ, bi o tilẹ jẹ pe onirese rẹ ko fin igba mọ, amọ ko yẹ ka jẹ ki eyi to fin silẹ parun.
Àwọn ọmọ Israẹli ṣe bí ọba ti wí, Josẹfu fún wọn ní kẹ̀kẹ́ ẹlẹ́ṣin gẹ́gẹ́ bí àṣẹ Farao, ó sì fún wọn ní oúnjẹ tí wọn yóo máa jẹ lọ́nà.
Awọn kan ti iṣẹlẹ naa ṣoju wọn sọ lori ayelujara Twitter, pẹlu fidio kan pe eefin ina ati iro ìbọn ni wọn kọkọ n gbọ lati ọna ibi ti ọgbà ẹ̀wọ̀n naa wa ni adugbo Alagbon ni Lagos Island.
Nígbà tí Juda rí Tamari tí ó fi aṣọ bojú, ó rò pé aṣẹ́wó ni.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Gas Explosion: Ẹ̀mí kan bọ́, èèyàn mẹ́ta fara pa nínú ìṣẹ̀lẹ̀ ìbúgbàmù gáàsì tó wáyé l‘Eko 4 Sẹ́rẹ́ 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 28 Agẹmo 2020 Oríṣun àwòrán, @followlasema Ọkunrin kan ti wọn ko ti dárúkọ rẹ ti padanu ẹmi rẹ lasiko ti ibugbamu afẹfẹ gaasi to waye ni agbegbe Palmgrove nilu Eko.
(International Monetary Fund ,IMF) ti ni awon yoo tun maa tẹsiwaju lati pese  iranlọwọ imọ-ẹrọ ati eto ilan fun orile ede Sudan,
Ọrọ ti ẹgbẹ agbabọọlu Liverpool sọ fun Tottenham niyii lẹyin ti wọn fimu wọn fọn feere ninu aṣekagba idije UEFA Champions League niluu Madrid lorilẹede Spain.
Loju opo Twitter wọn, alukoro ọlọpaa Frank Mba ṣalaye koko marun un ti iyipada yi yoo tẹle.
"Wọn o jẹ ki a sun mọ ibi to wa, wọn o jẹ ka fun un ni ounjẹ, koda inu iporuru ọkan lo wa bayi, ti a ko si mọ nkan ti wọn n ṣe fun wọn ni agọ ọlọpaa.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Làásìgbò ọ̀tun súyọ nínú ẹgbẹ́ òṣèlú APC Báwo ni Joe Biden yóò ṣe mú ìyípadà bá òfin tí Trump fi de orílẹ̀èdè àgbáyé?
Ọlọ́pàá Eko: A ti fi Tekno sílẹ̀ àmọ́ ìwádìí sì ń lọ lọ́wọ́
Aare soro idaniloju yii nibi ipade ita gbangba ni Jos to je olu ilu ipinle Plateau lasiko to n sabewo sawon ipinle ti won ti n ni ikolu lorisiirisii.
Atẹjade kan lati ọdọ Kabiesi Deji ti ilu Akurẹ, eyi ti agbẹnusọ rẹ, Adeyẹye Michael fi sita fi idi rẹ mulẹ pe ni ọjọ kẹrinlelogun, oṣu kẹjọ ọdun yii ti ṣe ọjọ Aje to n bọ, ko ni si tita rira ni gbogbo ọja to wa ni ilu Akurẹ.
Òun gan-an ni yóo kọ́ ọ, tí yóo sì gba ògo ati ẹ̀yẹ tí ó yẹ fún ọba, yóo sì jọba lórí ìtẹ́ rẹ̀.
Osinbajo, ti akọwe ijọba, Boss Mustapha soju fun, sọ eyi lasiko isin ayẹyẹ ọgọta ọdun ti Naijiria gba ominira, eyi to waye nilu Abuja.
Ní nkan bíi 1940 sí 1945 ni wọ́n ṣẹ̀dá Computer àkọ́kọ́ ní ìlẹ Gẹ̀ẹ́sì àti ilẹ̀ Amẹ́ríkà.
Ni nkan bi ọdun 1990 awọn kan bẹ ori olori ẹgbẹ okunkun ti won si gbe kọ si ori opo lati fi ṣe afihan pe awọn pegede.
Charles Okah gba'dajọ ẹwọn gbere Lush beauties: Ara sisan kii n ṣe arun Nibi ipade ọhun ni iroyin sọ wi pe ẹgbẹ alakatakiti naa ti tẹẹ mọ awọn to wa nibẹ leti wi pe ki gbogbo awọn papa isire aladani nibẹ lọ ti papa isire wọn pa ni kiakia.
Ni bayii, ikọ agbaboolu Chelsea fẹ ki Hazard bọwọ lu iwe adehun
Oloye Ademola Odunade lasiko to n sọ idajọ rẹ ni oun tu igbeyawo naa ka ki alaafia le jọba.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Abdullahi Olatoyan: Iṣẹ́ fífọ gíláàsì ọkọ̀ ń tì mí lójú láti dẹnu ìfẹ́ kọ obìnrin N kò lóyún, bẹ́ẹ̀ ni ń kò ní ọkọ, ẹ fi mí lọ́rùn sílẹ̀ - Dayo Amusa OPC, Miyetti Allah, agbófinró yóò wà nínú ìgbìmọ̀ aláàbò nílẹ̀ Yorùbá A fẹ́ gba ₦1bn lọ́wọ́ ìjọba Eko pé ó dẹ́yẹ sí wa - 123 Ọlọ́kadà Jigawa Bí ẹ̀bẹ̀ kò bá dẹ́kun ìkọlù South Africa, ẹ gbé iléeṣẹ́ aṣojú rẹ̀ ní Nàíjíríà tìpa"" Wọn wa rọ wọn lati mu oludije kan gboogi ti yoo le soju won ninu idibo si ipo gomina naa."
Akeugbagold Twins: Ilé ẹjọ́ fi afurasí méje pamọ́ sọ́gbà ẹ̀wọ̀n lórí ẹ̀ṣún ìjọmọ́gbe
Akọwe agba fun ajọ to n mojuto iṣẹlẹ pajawiri nipinlẹ Katsina, Dokita Aminu Waziri, ni awọn ti bẹrẹ si ni san gbogbo ọna lati ṣawari awọn to di awati.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Mo fa Fayoṣe sí kóòtù Ọlọ́run lórí gbèsè Èkìtì - Fayẹmi Ènìyàn 700 r'ẹ́wọ̀n he lórí ìfẹ̀hónúhàn Ìbálòpọ̀ ọkùnrin sí ọkùnrin kò lòdì s'ofin Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Adebisi Idikan: Òun ló gba Ìbàdàn sílẹ̀ lọ́wọ́ ìyà owó orí sísan Nigba to n tan imọlẹ́ si ibeere yii, Kọmisọna feto iroyin nipinlẹ Ọsun, Ọgbẹni Lanny Baderinwa ni irọ to jinna sootọ ni pe Akintayọ kọwe fi isẹ silẹ laipe ọjọ, to si rọ awọn eeyan lati kẹyin si iru ahesọ ọrọ bii eyi.
Ojúlówó wúrà ni kí o fi ṣe ẹnu rẹ̀ ati àwo pẹrẹsẹ rẹ̀, 
Bẹẹ ba gbagbe, Pasito ijọ alaṣọ funfun kan, Segun Philip ati Adeeko Owolabi to jẹ ọrẹkunrin Favour pẹlu iya rẹ, Bola Oladele ni akara tu sepo pe wọn fi ọmọbinrin naa se oogun owo.
South Africa gbọ́dọ̀ dá owó ìtanràn padà kí wọ́n si fìyà jẹ àwọn ti ọ̀rọ̀ kàn -Sen Basiru Ìdí rèé ti Nàìjíríà fí ń gbé inú òkùnkùn Wọ́n gbé Akọ̀ròyìn ní Morocco lọ sílé ẹjọ́ lórí ẹ̀sùn àgbèrè àti oyún ṣíṣẹ́ Bianca júwe ilé fún Serena Williams nínú ìdíje l'America O ni gbagbagba lawọn aṣiwaju ati gbogbo ọmọ ẹgbẹ oṣelu PDP wa lẹyin Gomina Makinde atipe iṣọkan to jina denu lo wa laarin ẹgbẹ oṣelu naa.
Bakan naa ni a ri olugba aare nimoran kan pataki lori oro ile-igbimo asofin ohun, asofin Ita Enang ati ojogbon Hakeem Baba Ahmed, ti o je oga agba iko ologun fun Aare ile-igbimo asofin naa.
Oríṣun àwòrán, olatoye sugar Àkọlé àwòrán, Ile iwosan nla UCH ni ilu Ibadan lo ku Ni ọdun 2011, ni wọn fi ibo yan an si ile aṣofin ipinlẹ Ọyọ labẹ aṣia ẹgbẹ oṣelu Accord, ki o to wọle gẹgẹ bii ọmọ ile igbimọ aṣoju-ṣofin to n soju ẹkun idibo Lagelu/Akinyele, labẹ aṣia ẹgbẹ oṣelu APC.
O ni oun tun jẹ gbese ẹyawo owo ile ati ọkọ'' Nigba ti BBC Yoruba ba alukoro ọlọpa ni ipinlẹ Ekiti Caleb Ikechukwu sọrọ, o fidi ọrọ naa mulẹ pe lootọ ni wọn si ti gbe oku rẹ lọ si ile igbokupamọ si.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Àwọn aránṣọ yarí pé gbogbo ẹ̀bi kìí ṣe tàwọn, díẹ̀ wà lọ́wọ́ àwọn oníìbárà náà Fifi ẹnu ko Nini ilana idibo naa, oludije gbọdọ ni ida meji ninu ida mẹta ibo ki wọn o to kede rẹ pe o wọle (ida meji naa yoo le ẹnikan, ti iye awọn cardinal to dibo ko ba ṣe e pin si mẹta).
Dókítà ọmuti ṣe iṣẹ́ abẹ tó pa olóyún àti ọmọ rẹ̀ Ẹ wo àwọn ẹlẹ́sìn Hindu tó ń jẹ ènìyàn Ṣé o mọ̀ pé láàrín ìṣẹ́jú méjì, ọmọdé kan ń kú?
 Omi ń bẹ láàmù fún wa lórí ètò àbò, ètò ọ̀gbìn, ọrọ̀ ajé, gbígbógun ti ìwà ìbàjẹ́ àti bẹ́ẹ̀bẹ́ẹ̀ lọ.
Ki wa ni Drogba ṣe tó mú dì ilumọọka agbabọọlu n'ilẹ rẹ?
Ìyẹ̀fun yòókù yóo di ti alufaa, gẹ́gẹ́ bí ti ẹbọ ohun jíjẹ.
Bi o tilẹ jẹ pe ẹkun ariwa ni ọwọja ikọ afẹjẹwẹ Boko Haram naa pọ si, sibẹ, awọn eeyan ẹkun iwọ oorun ati ila oorun guusu Naijiria naa n mọ ipa rẹ lara.
Awọn ẹgbẹ okunkun Naijiria ko ri bayi lati ipilẹ.
Ó kẹ́ ọfà rẹ̀ bí ọ̀tá,ó múra bí aninilára.
Ní Ọjọ́ Ìsinmi a jáde lọ sẹ́yìn odi ìlú lẹ́bàá odò, níbi tí a rò pé a óo ti rí ibi tí wọn máa ń gbadura.
Ibùsùn yìí kò ní àfiwé; gbogbo ọ̀pá ibùsùn yìí la fi gόòlù ṣe ọnà sí lára.
Ohun taa gbọ ni wi pe awọn to ṣe ọṣẹ yii fẹ fi obinrin naa ṣe ogun owo ni.
 Emi ko ni simi, ayafi igba ti mo ba mu ipnnu mi se “ Nipa  omowe TedrosOmowe Tedros je minisita fun eto ilera ati oro ile okeere, alaga fun igbimo to n sakoso eto owo iranwo fun igbokun ti aarun eedi, iko ife ati aarun iba.
Ọkunrin kan tí orúkọ rẹ̀ ń jẹ́ Naboti, ará Jesireeli, ní ọgbà àjàrà kan.
Eyi yoo jẹ ida ọọdunrun owo osu re laarin ọdun meji-meji Ida mẹwa ninu ọgọrun owo osu rẹ gẹgẹbii ajẹmonu owo itọju ile Ọlọpa mẹjọ, osisẹ ọtẹlẹmuyẹ SSS meji, ti ọkan ninu wọn si gbọdọ jẹ obinrin Igba keji gomina yoo gba Ọlọpa meji, osisẹ ọtẹlẹmuyẹ SSS kan.
Ise-akanse ajo isokan agbaye lorile-ede South Sudan  so pe, ohun ti so fun iko eleni merindinladota lati pada si iluJuba ti n se olu ilu orile-ede naa nibi ti won ti n sise idaabobo awon ara-ilu ti won kii se ologun ni agbegbe Wau, ti o wa ni apa ariwa iwo-orun ilu Juba, leyin iwadii kan ti won se lori esun pe, awon omo-ogun naa n ni ibasepo pelu awon obinrin ti won wa ni ipago naa.
Ile Igbimọ Aṣofin Ipinlẹ Eko ti pe ijọba
Kola Olongbodiyan to jẹ agbodegba ẹgbẹ naa lẹyin ipade wọn ni awọn lero wi pe ihalẹ Aarẹ Buhari ki ṣe wi pe o fẹ fi ṣe boju boju ki awọn ọmọogun baa le yinbọn lu awọn eeyan ki wọn si jin apoti ibo gbe.
AWỌN IROYIN TẸẸ LE NIFẸ SI NIPA RẸ Taló ya fídíò ibi tí Aisha Buhari ti ń bínú ní Aso Rock?
“Nítorí pé ìpànìyàn kún ilẹ̀ náà, ìlú wọn sì kún fún ìwà ipá.
Ó gbé talaka dìde láti inú erùpẹ̀,ó sì gbé aláìní sókè láti orí eérú,
Kunama III’  ti se aseyori pupo lati mu awon obayejẹ ati
Awọn mẹjọ yii ni wọn gba pé wọn nii ṣe pẹlu awọn ọmọ ilẹ Canada meji to di awati lọjọ Iṣegun to kọja ni Ghana.
Ibi tì abàmì ẹ̀dá náà ti ń ṣe èyí ni ọkùnrin yìí ti kígba ńlá, igbì tí ó sì kigbe, ẹ̀dá yìí gbé akèǹgbè ẹmu ńlá tirẹ̀ ó ń sáré lọ.
66% awọn to ba ni aarun naa ni yoo kú.
Bawo ni ilana tuntun naa yoo ṣe lọ?
Wọ́n ti kọsẹ̀ ní ojú ọ̀nà àtijọ́ tí wọn ń tọ̀,wọ́n ti yà sí ọ̀nà ojúgbó tí kì í ṣe ojú ọ̀nà tààrà.
Nígbà tí Johanu fẹ́rẹ̀ dópin iṣẹ́ rẹ̀, ó ní, ‘Ta ni ẹ rò pé mo jẹ́?
 aare tun pase fun oga agba ile-ise olopaa ati awon ile ise eleto aabo to ku lati wa ojutu si rukerudo gbonmisi omi o to to n waye laarin awon ara Tiv ati Jukun ni ekun ipinle Benue ati Taraba lojuna ati da igbe-aye alafia pada si awon ekun ohun gbogbo.
3 3579 Orilẹede Togo 66 0.
Usman Umar to jẹ kọmisọna ajọ ọlọpàá FCT sọ pe àwọn ko ni jọkọ fọwọleran lóri ọ̀rọ̀ náà àti pé àwọn yoo tusu de isalẹ ikoko pẹlu'ajo tó n dabo bo ayika nilu Abuja láti mọ idi ti wọn fi ń mu àwọn olbinrin satimọle.
Nígbà tí wọn ń ka ìgbàgbọ́ yìí ẹníkẹ́ni kò sọ̀rọ̀ kan ṣoṣo ṣùgbọ́n wéré tí wọn kà á tán ni wọ́n ti tún bẹ̀rẹ̀ ariwo.
Nígbà tí àwọn ọmọ ogun Filistini rí i pé akikanju àwọn ti kú, wọ́n bá bẹ̀rẹ̀ sí sá lọ.
Ó ń pe ara rẹ̀ ní aríran, ó ń tan àwọn iranṣẹ mi jẹ, ó ń kọ́ wọn láti ṣe àgbèrè ati láti jẹ oúnjẹ ìbọ̀rìṣà.
Ìgbàkúùgbà tí ẹ bá fẹ́ tẹ̀síwájú ni kí ẹ máa fọn fèrè ìdágìrì.
Àwọn mẹta ti ó gbé àpóti ibò fún ipò olóri òṣèlú ni, Hillary Clinton, obinrin àkọ́kọ́ lati dé irú ipò bẹ́ ẹ̀ fún ẹgbẹ́ (Democrat), Donald J.
Ogbeni Muhammed Haruna to jẹ kọmiṣọna fun ajọ eleto idibo ni ẹkun Kogi, Kwara, ati Niger lo fun wọn ni iwe ẹri naa loni ni Lokoja.
Eeyan yoo maa da wa lọpọ igba lasiko to ba n fun ọmọ lọyan: Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Awọn ọmọ tuntun kii le ba ni sere bii agbalagba.
Ọgagun agba patapata lorilẹede Naijiria, Ọgagunagba Abayọmi Olonisakin, olori ileesẹ ọmọogun oju omi, Ibok-Ete Ekwe Ibas, Ọgagun ileesẹ ọmọogun orilẹ, Tukur Buratai ati oludari agba fun ileesẹ ọtẹlẹmuyẹ ni Naijiria, (SSS) Alhaji Lawal Daura ni ijọba apapọ ti pasẹ fun pe ki wọn kọri si ẹkun naa.
Ìbánújẹ́ gbọkàn àwọn èèyàn nílé abílékọ ọlọ́mọ mẹ́ta tí wọ́n ṣẹ̀ṣẹ̀ pa ní Ibadan Àkọlé àwòrán, Iléeṣẹ́ ọlọ́pàá ní aago márùn-ún ìdájí ni wọ́n pa obìnrin náà níwájú ilé rẹ̀ BBC ṣe abẹwo si ile arabinrin Oluṣayọ Fagbemi, abilekọ ẹni ọdun mejilelogoji ti awọn amokunṣeka kan tun ṣekupa l'owurọ Ọjọru ni agbegbe Ṣaṣa, ijọba ibilẹ Akinyẹle niluu Ibadan.
Wọn kìí dá ẹjọ́ ẹ̀tọ́ fún aláìníbaba,kí ó lè rí ẹ̀tọ́ rẹ̀ gbà;wọn kò sì jẹ́ gbèjà aláìní,kí wọ́n bá a dáàbò bo ẹ̀tọ́ rẹ̀ nílé ẹjọ́.
Nitori ohun ti gomina so yii, ni gbogbo ile-ise ijọba se wa ni titi-pa lojo isegun.
Ẹ kú dédé àsìkò yìí gbogbo olólùfẹ́ ojú ìwé yìí, ẹ fojú sọ́nà fún ẹ̀tò pàtàkì tó ń bọ̀ láìpẹ́ láti ọwọ́ àwọn olùdarí Èdè Yorùbá Rewà.
"Gbajúgbajà òṣèré tíátà, ""Ijẹwuru"" ti jáde láyé Àwọn ohun to yẹ ko mọ nipa Aisha Abimbọla Èèmọ̀ rèé!"
Awọn oun to le ṣẹlẹ rèé: pada si EU lati jẹ ki awọn adehun to sẹ pẹlu ajọ naa jẹ oun ti awọn aṣofin fẹ, ko sọ fun awọn aṣofin ki wọn ba oun wa ọna miiran to yatọ si adehun oun, tabi ko tilẹ halẹ mọ wọn.
Èèyàn 22 mííràn tún ti lùgbàdì ààrùn Coronavirus ní Naijiria Ajọ to n risi idẹkun itankalẹ arun lorilẹede Naijiria, NCDC ti kede pe eniyan mejilelogun miran tun ti ni arun Coronavirus lorilẹede Naijiria.
’’ orile ede NaijiriaAlaga egbe  WIC, Prof.
Ẹkunrẹrẹ lori iroyin yii wa ni: Tí kìí bá ṣe ti Barrister, iṣẹ́ ‘Gateman’ ni ń bá máa ṣe - Ayinla Kollington Ikọ̀ Super Eagles padà wálé lẹ́yìn tí wọ́n tún gba Bronze lẹ́ẹ̀kẹjọ Àkọlé àwòrán, Super Eagles Diẹ to ninu nnkan oni nnkan, eyi lo difa fun ẹgbẹ agbabọọlu Naijiria, Super Eagles ti wọn ipo kẹta tawọn nnkan n pe ni golden bronze ninu idije AFCON 2019.
Àjápọ̀ sí dátà àjápọ̀mọ́ra ẹyọ ìnú ìkọ́pamọ́
Igbesẹ AS Roma naa ya ni lẹnu pupọ, ṣugbọn awọn akopa ninu idibo naa fi han pe jọlọfu Naijiria ni awọn fẹran ju nitori orilẹ-ede naa ko ida mọkanlelaadọrin gbogbo ibo awọn akopa.
Òkè mímọ́ rẹ̀, tí ó ga, tí ó sì lẹ́wà,ni ayọ̀ gbogbo ayé.
Ninu ẹ̀yà Nafutali àwọn tí wọ́n tó ẹni ogún ọdún, tí wọ́n tó lọ sójú ogun, gẹ́gẹ́ bí àkọsílẹ̀ wọn ní ìdílé-ìdílé 
    Èmi ni tiyín títí mo fi máa kú
Ègbé soca tí ó dùn ní etí, pẹ̀lú ọ̀rọ̀ orin dancehall díẹ̀díẹ̀, ti ń da orí àwọn ènìyàn rú ní ìtaja Ijó ìta-gbangba.
Nítorí Jakọbu, iranṣẹ mi,ati Israẹli, àyànfẹ́ mi,mo pè ọ́ ní orúkọ rẹ.
Ni aafin Awujale tile Ijebu ni alaga igbimo to n se todun 2018, Wahab Osinusi ti soro yii nibi iside eto ipalemo odun naa.
Nítorí àjàkálẹ̀ àrùn kan náà ni ó kọlu gbogbo yín ati àwọn ọba yín maraarun.
Ìnú ẹ̀rọ yìí ní mo máa ń kọ gbogbo ètò sí, òun sì ni í ṣe atọ́kasọ́nà tí mo bá wà ní agbègbè ibi tí n kò mọ̀, kí n má baà sọnù.
“Kí ló dé tí eléyìí fi ń sọ̀rọ̀ bẹ́ẹ̀?
Tipẹ tipẹ lawọn ololufẹ Arsenal ti n sọ pe ki Ọgbẹni Kroenke ta ikọ agbabọọlu naa fun ẹlomiiran nitori wọn ko fẹran bi o ṣe n dari rẹ.
Wọ́n pa àṣẹ náà ní Susa tíí ṣe olú-ìlú, àwọn òjíṣẹ́ sì yára mú un lọ gẹ́gẹ́ bí àṣẹ ọba.
O kere ju awọn agbegbe mẹwa ni ayika Ojota, Ketu, Magodo, Mile 12, Olusosun ati awọn ẹya ara Alausa-Oregun lọwọlọwọ ni o wa ninu eefin ti o n jade lati inu Olusosun nibiti iná ti yọ ni ọjọru ọsẹ to kọja.
Àwòrán bí ìlú Ìwó se rọ̀sọ̀mù f’ọ́dún eégún Njẹ́ ọlọ́pàá Naijiria lé jẹ ounjẹ N6bn tán?
Ó mú akọ mààlúù meji, ó gé wọn sí wẹ́wẹ́, ó fi wọ́n ranṣẹ jákèjádò ilẹ̀ Israẹli, pẹlu ìkìlọ̀ pé, “Ẹnikẹ́ni tí kò bá tẹ̀lé Saulu ati Samuẹli lọ sójú ogun, bí a óo ti ṣe àwọn akọ mààlúù rẹ̀ nìyí.
Asofin naa so pe, iyalenu ati ibanuje okan ni iku oloogbe Jonathan je fun egbe akoryin  ati orile ede Naijiria.
Idunnu lo fi maa n gba bọọlu, ni eyi ti ko wọpọ rara.
Ni oṣu kejila, ọdun 2018 lawọn aṣofin ipinlẹ Ekiti kọkọ gbegile awọn alaga kansu ọhun ki wọn to da mẹjọ ninu wọn pada ni oṣu keje, ọdun 2019.
“Ẹ mú ìyẹ̀fun tí ó kúnná dáradára, kí ẹ sì fi ṣe burẹdi mejila, ìdámárùn-ún ìwọ̀n ìyẹ̀fun efa kan ni kí ẹ fi ṣe burẹdi kọ̀ọ̀kan.
Oluwo kéde ọdún tí yóò gbé adé Iwo sílẹ̀ Oríṣun àwòrán, Gistube Kabiyesi Oluwo ti ilu Iwo, Ọba Rasheed Akanbi ti jẹ ko di mimọ fun awọn to n pe fun irọloye rẹ pe ọdun mẹtadinlaadọrin lo ku fun oun lati lo lori oye gẹgẹ bi Oluwo.
26, Igbese lati duro gege –bi omiran ni gbogbo ona, ni isakoso yi ti se akosile re latari mimu idagbasoke deba ojuna oko ni gbogbo ekun Kankan lorile-ede Naijiria lati odun meta sehin.
Covid-19 pa Ọlọ́lá Akin Olugbade, ẹ wo dúkìá jaburata tó fisílẹ̀ NCDC àti NYSC bẹ̀rẹ̀ ìpàdé lórí ṣíṣí ìpàgọ́ àwọn àgùnbánirọ̀ Ìjọba ìpińlẹ̀ Kwara dá owó tí àwọn obìrin 25 fi kọ́ ilé Ẹ̀kọ́ fún àwọn ọmọ wọ́n pada Ìjọba àpapọ̀ pàṣẹ kí ilé-ẹ̀kọ́ wọlé ní ọjọ́ 18, oṣù kíní ọdún.
Olùfẹ́ mi gbọ́wọ́ lé ìlẹ̀kùn,ọkàn mi sì kún fún ayọ̀.
ẹ̀wù àwọ̀tẹ́lẹ̀ ati ẹ̀wù àwọ̀lékè ati aṣọ wọn, ati àpò 
Nigba ti o n ba BBC Yoruba sọrọ, Bode George ni ipinlẹ Eko lo jẹ gbese ju lẹyin ijọba apapọ lorilẹede Naijiria Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí 2 sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
Lẹ́yìn tí gbogbo wọn bá ti mu tiwọn tán, ọba Babiloni yóo wá mu tirẹ̀.
Odò yìí kkún fún ogunlọ́gọ̀ ènìyàn tí wọ́n ti já síbẹ̀ láti orí afá, èyí tí o sì ya ni lẹ́nu níbẹ̀ jù nipé wọn kò kú, bẹ́ẹ̀ ni wọ́n n mu omi odò Ẹ̀jẹ̀ báyìí lémọléemọ, ṣùgbọ́n wọ́n pọ̀ tó bẹ́ẹ̀ púpọ̀, ìgbà tí àwọn tí ó bá yọjú sí ìta bá fi ara hàn fún ìgbà pípẹ́ wọ́n a tún rì sí ìsàlẹ̀ kí wọ́n bá fún àwọn tí ó wà ní ìsàlẹ̀ odò ni ààyè kí àwọn náà tún wa sí òkè kí wọ́n fi ara hàn díẹ̀ kkí  àwọn náà tún mu omi ẹ̀jẹ̀ lójú gbogbo aráyé.
Oludari igbimọ naa, Dokita Sani Aliyu to n ba awọn akọroyin sọrọ ni, ninu ayẹwo tawọn ṣe fun eeyan ẹgbẹrun meji ati irinwo le mẹta arinrin ajo si Naijiria, ọgọrin ninu wọn lo ko Covid-19.
Jesu wí fún wọn pé, “Ní tèmi, oúnjẹ mi ni láti ṣe ìfẹ́ ẹni tí ó rán mi níṣẹ́ ati láti parí iṣẹ́ tí ó fún mi ṣe.
Adajo Oladipo Abimbola ni ọ̀nà alùmọkọ́rọ́yí ni Ọba yii gbà dé orí ipò náà.
Àjèjì ti da omi síwájú rẹpẹtẹ fúnrarẹ̀.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fọ́nrán ohùn, Aabo to peye gbọdọ wa fawọn olutọju alaisan Laarin oṣu kẹfa, ọdun 2015 si oṣu karun un, ọdun 2019 ni wọn fi ṣe afojusun iṣẹ iwadii naa.
Ọba kan yóo jẹ pẹlu òdodo,àwọn ìjòyè yóo sì máa ṣe àkóso pẹlu ẹ̀tọ́.
Boko Haram: Ọlọ́pàá ní aràrá wà láàárín àwọn afurasí
 Ìdí rèé tí Òòrẹ ́ fi kúrò ní agbègbè ìlú rẹ ̀ , tó fi kọrí sí agbègbè akilápá níbi tí igbó ńlá wà .
Ẹwẹ, awọn gbajugbaja olorin ti pọ rẹpẹtẹ ti yoo ṣe isin orin nibi ọjọ ibi aṣẹyinde oloogbe naa lonii lati ago mẹjọ alẹ wọ mejila oru ti yoo ti bọ si ọjọ ibi rẹ.
a “ọmọ rẹrẹ”, wọn  tun jẹwọ pe ọpọlọpọ ibọn , owo ati ọkọ ni Bukola Saraki ati Alhaji Abdulfatah Ahmed maa n ko fun  wọn  lati fi sisẹ.
" Ileeṣẹ Channels fi atẹjade sita lori iṣẹlẹẹ naa pe awọn ko fọwọ si tabi faramọ iwa ipa si awọn obinrin, tabi ẹnikẹni.
ipenija to n dojukọ orile ede yii.
Ní ọjọ́ kan ni Yeyemoja pe ọmọ rẹ̀ Ẹja (fish) pé kí ó lo bá òhun sin gbèsè.
Di ẹ̀kọ́ mú ṣinṣin,má jẹ́ kí ó bọ́,pa á mọ́, nítorí òun ni ìyè rẹ.
 Àkóràn wáyé láti ara guillain-barré syndrome .
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Nígbà tí kò ṣeéṣe fún wa láti fò, a ó lọ́ wọkọ̀' Ṣáájú, ẹgbẹ́ náà nínú ìkìlọ̀ tí wọ́n ṣe lọ́jọ́ ìṣẹ́gun ti sọ wí pé àwọn yóò dí iṣẹ́ lọ́wọ́ ní ibùdókọ̀ eléyìí tí ilé iṣẹ́ Bi-Courtney Aviation Services Limited (BASL) ń ṣe àkóso rẹ̀.
Oríṣun àwòrán, Facebook Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ajá kìí rorò kó ṣọ́ ojú'lé méjì, kò tọ́ ọ́ sí Alaafin láti dásí ọ̀rọ̀ ọba l‘Ekiti - Peter Fatomilọla Coronavirus dá wàhálà sílẹ̀ ní Ghana, ìjọba gbé ìlẹ̀kùn gbogbo iléẹ̀kọ́ tìpa Iṣẹ́ akin ni ọ̀gá iléẹ̀kọ́ tó kú nínú ìbúgbàmù Eko ṣe, ẹ fàmì ẹ̀yẹ da lọ́lá - PDP késí ìjọba Rẹ́rẹ́ rún níbi ìbúgbàmù l'Eko, ọ̀pọ̀ àwòrán rèé Gbogbo ẹ̀yin tẹ fẹ́ yọ Oshiomole nípò, ẹ kò moore, ìwà yín ń kóbá APC - Tinubu Eyi lo mu ki ijọba ipinlẹ Ondo fi gbe asaaju ijọ naa ls sile ẹjọ lẹyin ti gbogbo aayan lati ri ọmọdekunrin naa ja si pabo.
Mo pe orúkọ rẹ ní àpèjá, bẹ́ẹ̀ ni o kò mọ̀ mí.
Laarin ọjọ meji pere, awọn ọlọpaa to dantọ naa fidi rẹ mulẹ pe awọn afọmọ setutu lo gbe ọmọde yii lọ.
Bakan naa lo sọ pe awọn ile ti, ile faaji, ati ile ijo yoo ṣi wa ni titi pa.
ojo ketadinlogun osu keje odun yi.
Ó ní èyí máa n nípa lórí àwọn ará ilú gidigidi ni Nàìjíríà Bákan áà ló tún sàlàyé ìṣẹ̀lẹ̀ tó ṣẹ̀lẹ̀ lásìkò kan ti ẹnikan kú sí ilé iṣẹ́ Clarence Peters tó jẹ́ ọmọ Clarion Chukwura tó bi fún Shina Peters.
N óo fi í ṣe alákòóso ilé Dafidi.
Bi o tilẹ́ jẹ pe aye ti laju, ti ọpọ awọn asa ati ise yii si ti n lọ sokun igbagbe, sibẹ ọpọ wọn lo ni anfaani, iwulo ati awọn aleebu kọọkan ninu rẹ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Gómìnà Oyetọla tí yi ìlànà ètò ẹ̀kọ Rauf Aregbesola pada 2 Ẹrẹ̀nà 2020 Oríṣun àwòrán, Others Àkọlé àwòrán, Gómìnà Oyetọla tí yi ìlànà ètò ẹ̀kọ Rauf Aregbesola pada Lọ́sẹ to kọja ni àwọn ọmọ igbimọ ti gomina ìpinlẹ̀ Osun Gboyega Oyetola gbékalẹ̀ láti ṣe àyẹwo àwọn ìlànà èto ẹkọ gomina àná Rauf Aregbẹsọla, gbé àbájade ìwádìí wọ́n wá.
Ogunyemi ni ninu adehun awọn pẹlu ijọba o yẹ ki wọn san ''200 biliọnu naira lọdun 2013,ninu 1.
Ọrẹ ẹbọ rẹ̀ ni: àwo fadaka kan tí ìwọ̀n rẹ̀ jẹ́ aadoje (130) ṣekeli, abọ́ fadaka kan tí ìwọ̀n rẹ̀ jẹ́ aadọrin ṣekeli, ìwọ̀n tí wọn ń lò ní ibi mímọ́ ni wọ́n fi wọ̀n ọ́n.
OLUWA yóo fi wọ́n lé yín lọ́wọ́, ẹ óo sì ṣe wọ́n bí mo ti pa á láṣẹ fun yín ninu òfin tí mo fun yín.
Ṣugbọn gbogbo èyí ṣẹlẹ̀ kí ọ̀rọ̀ àwọn wolii lè ṣẹ ni.
Ọlọ́pàá Ogun gb'ọmọ Ìmáàmù lọ́wọ́ ajínigbé, ṣùgbọ́n wọ́n gbé ọkọ̀ ojú omi ọlọ́pàá lọ Ọ̀pọ̀ èèyàn bẹnu ẹ̀tẹ́ lu Mercy Aigbe lórí bó ṣe ki Adeniyi Johnson Mo dáríjì àwọn IPOB tó nà mí ní Germany nítorí wọn o m'ohun tí wọ́n ń ṣe- Ekweremadu Àwọn òṣìṣẹ́ fásitì yóò fi ìyanṣẹ́lódì ṣẹ Nàìjíríà lọ́wọ́ lọ́jọ́ Ajé Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Iroyin naa so pe  Mursi ni o ti n kọkọ dakẹ-daji nile ẹjọ lasiko
    Báyìí ni a sọ ọkan pàtàkì nù nínú wa, a sì gbẹ́ ihò, a sin ín síi, a sì sọkún a káànú rẹ̀ bí ó ti yẹ.
ko reti rẹ ba imọ ati erongba  buruku wọn
NHIS: Lẹyin ọpọlọpọ àbájáde ìwádìí, Buhari ni ki ọjọgbọn Yusuf máa lọ
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Trump impeachment: Trump kò fìdí janlẹ̀ tán, àmọ́ níbo ni yóò jásì?
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Hospital Wedding: Oṣù kan péré ni Tash fi ṣe ìgbéyàwó pẹ̀lú Simon kó tó kú Lẹyin ti wọn pari ọṣẹ ti wọn fẹ se ni abule naa ni wọn tun morile abule Ungwan Masara ati Maraban Kagoro.
Ìwọ́de, ìkọ̀wéfipò sílẹ̀, gbode lori ìdìbò abẹ́lé l‘Ọsun Ìdìbò abẹnu ipinle Osun to waye lopin ọse, kángun kángun kángun,o kọ, ko ríbi kángun sí Bi àwọn alatilẹyin ọgbẹni Akin Ogunbiyi tó fidi rẹmi nínú ìdìbò abẹnu ẹgbẹ òṣèlú PDP nipinlẹ Osun ṣé n wọde ni Olú ilé ẹgbẹ wọn nílu Òṣogbo lakowe osise ijọba ipinle Osun,Moshood Adeoti kowe fi APC sile.
Àwọn iroyin yi bi àwọn èrò ninú,  nitori èyi, aláwọ̀ dúdú àti funfun tú jáde lati fi ẹ̀dùn hàn pé “Ìgbésí Ayé Aláwọ̀-dúdú ṣe pàtàki” pé àwọ lè yàtọ̀, ṣùgbọ́n ẹ̀jẹ̀ kò yàtọ̀.
    Èmi Ìrinkèrindò, ọmọ Ìfẹ́dayépọ̀, ọmọ ènìyàn, ti n gbé Ilé- Alárìnkiri, ti ń lọ sí òkè Ìrònù, nínú igbó Elegbeje, gba Ìfẹ́pàtàkì, ọmọ Ajédùbúlẹ̀, ti ń gbé odó Ìrántí, àbúrò Olókun tí í ṣe alákòóso omi.
Nibayii, wọn ti gbe oku ọmọ naa fun awọn mọlẹbi rẹ ati ikọ ọlọpaa to wa lati agọ ọlọpaa Alagolo eyi ti insipẹkitọ Abumere dari.
Ṣugbọn, o padanu afojusun rẹ, eyi ti o ṣe iku pa oluranlọwọ ti Lawal, Ayinla.
”Aare wa fi n da awon omo orile
Ọgbẹni Wabba fi kun ọrọ rẹ pe igbesẹ ẹgbẹ oṣiṣẹ lapapọ nibi ipade ti wọn ṣe papọ loni ni lati gun le iyanṣẹlodi miran lọjọ Iṣẹgun.
Lasiko idibo na ni awọn ọlọpaa Ghana mu awọn oṣiṣẹ eleto ididbo meji pe wọn n ṣe magomago ni agbegbe Awutu Senya West ati ni Bawku Central.
Ṣugbọn adé tí kò lè bàjẹ́ ni tiwa.
Àwọn òṣìṣẹ́ Solomoni ati ti Hiramu, ati àwọn ọkunrin mìíràn láti ìlú Gebali ni wọ́n gbẹ́ òkúta, tí wọ́n sì la igi fún kíkọ́ ilé OLUWA.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Àwọn oúnjẹ tó n gbayì níbi ayẹyẹ báyìí Ọ̀jọ̀gbọ́n onímọ̀ ẹrọ tí o ní kí wọ́n wọgi lè ìbò Ààrẹ Nàìjíríà Tinubu kìlọ̀ fún Buhari lórí ohun tó leè ṣàkóbá fún sáà kejì rẹ̀ 'Iléèṣẹ́ ọlọ́pàá ló gbégbà orókè nínú ìwà jẹgudujẹra ní Nàìjíríà' Ta ni ipò ààrẹ ilé aṣòfin àpapọ̀ tọ́ sí?
Àrùn Coronavirus ti tàn dé orílẹ̀-èdè míràn nílẹ̀ Afrika Àǹkóò àrùn coronavirus dé orílẹ̀èdè Togo Ààrùn coronavirus ti ràn dé ilẹ̀ Afirika, Egypt ló kọ́kọ́ yà A n ṣé àyẹwò ẹni tá fúnra sí pé o ní Coronavirus l'Eko-Kọmísánà ìlera Minisita Nadine ni oun ti n gbe gbogbo igbesẹ to yẹ ati pe oun ko jade sita ni bamu pẹlu imọran awọn eleto ilera.
6 243286 Orilẹede Kenya 1726 3.
bí ó bá ṣe nǹkan burúkú lójú mi, tí kò gbọ́ràn sí mi lẹ́nu, n óo dá nǹkan rere tí mo ti fẹ́ ṣe fún un dúró.
Awa mejeeji fura pe oun lo ko aarun naa ran wa.
Àti ẹni burúkú àti ẹni rere ló wà ninú ẹbi, ilú, àti gbogbo ẹ̀yà àgbáyé ninú èniyàn dúdú àti funfun, ọkùnrin, obinrin, ọmọdé àti àgbà.
Awọn iriri mi lo sọ mi di alaanu, ati ẹni to n polongo fun awọn to tun ni aisan yii lati ni igboya lati koju gbogbo ipenija wọn.
Ṣugbọn obinrin náà lóyún ó sì bí ọmọkunrin ní akoko náà ní ọdún tí ó tẹ̀lé e gẹ́gẹ́ bí ọ̀rọ̀ Eliṣa.
Bẹ́ẹ̀ náà ni ohun tí Ọlọrun ṣe rí.
Ó kó àwọn eniyan bí irinwo (400) jọ.
Iku awọn alufa ijọ meji kan ni ipinlẹ Benue lọwọ awọn afunrasi darandaran lo ṣe okunfa igbesẹ yi.
ko ni kaarẹ lati ri i pe eto aabo to peye wa ni jake-jajo orile ede Naijiria,
Pé ète búburú yìí ti di rírò sínú fún ènìyàn ibi náà ti ó sì jẹ́ mímọ̀ sí Olúwa àní nígbàtí Mọ́mọ́nì, ará Néfì olùpìtàn ìgbàanì, nṣe àkekúrú àwọn àwo tí a ti kójọ sílẹ̀, ni ó fara hàn nínú Ìwé Ti Mọ́mọ́nì (wo Àwọn Ọ̀rọ̀ ti Mọ́mọ́nì 1:3–7).
Ayuba Wabba: Ẹ̀yin gómìnà kò lẹ́tọ̀ọ́ sí owó ìfẹ̀yìntì òṣìṣẹ́, ẹ rìn jìnnà si
Wọ́n dá a lóhùn pé, “Oluwa, a fẹ́ kí ojú wa là ni.
Ondo politics: Ọ̀gá àgbà iléeṣẹ́ ọlọ́pàá pàṣẹ kí wọn dá àwọn ẹ̀ṣọ́ aláàbò igbákejì gómìnà ìpínlẹ̀ Ondo padà
Aare so pe  orile ede Naijiria ko ni gbagbe ise  rere ti oloogbe Akanbi ti se lorile ede Najiria lati je ki iwa otito ati ibowo fun ofin ni ajo idajo lorile ede Naijria.
Ati pe nigba ti wọn beere ọrọ lọwọ rẹ, o ju apo naa silẹ, o si sa wọ inu igbo lọ.
Shearer tenumo-on pe, “gbogbo awon ti won wa nidi laasigbo naa gbodo bowo fun eto omo eniyan, laifi ti eleya-meya, igbagbo, esin tabi ti oloselu se”.
Ní kété lẹyin ti ọlọpaa rii pe ololufẹ mejeeji ti re ọrun àrèmábọ̀ ni ìwádìí fojú àwọn méji tí wọ́n ní o pa àwọn olólùfẹ́ mejéèji han, tí ẹ̀ka IRT si gbé wọn lẹyẹ o sọka.
Nígbà tí mo wà ní ọmọde, èmi a máa sọ̀rọ̀ bí ọmọde, èmi a máa gbèrò bí ọmọde, ṣugbọn nisinsinyii tí mo ti dàgbà, mo ti pa ìwà ọmọde tì.
N óo mú kí arọmọdọmọ jáde lára Jakọbu,àwọn tí yóo jogún òkè ńlá mi yóo sì jáde láti ara Juda.
Iya ọmọ naa ni ọmọ awọn, ọdun mẹtadinlọgbọn kii si ṣe yahoo yahoo.
Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Owó làwọn olóṣèlú mọ̀ ni wọ́n ṣe fẹ́ kí dókítà lọ sókè òkun - NMA24 Ìgbé 2019 Àbẹ̀wò Buhari: Mo fẹ́ kí òjò rọ̀ ní Eko, kó sì ba àbẹ̀wò Buhari jẹ́24 Ìgbé 2019 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Wọn ni o maa n waye nigba ti oju ọrun ba ran afẹfẹ to tutu gan si ile aye to si fa ọpọlọpọ iṣlẹ to mu otutu dani.
Iroyin to tẹ wa lọwọ ṣọ pe, ẹgbẹ oṣiṣẹ naa ṣe ipade pẹlu awọn alaṣẹ ile iṣẹ naa lalẹ Ọjọbọ nibi ti wọn ti gba lati fagi le iyanṣẹlodi naa.
Oríṣun àwòrán, Bashir Ahmed Nipinlẹ Ondo, igun meji lo wa ninu ẹgbẹ APC.
Koda, adugbo Ikeja ni adirẹsi sọọbu asọ tuntun ti olori naa sẹsẹ fẹ si bayii, osu Kẹwa to n bọ si lo ni sọọbu naa yoo di sisi.
Aare Muhammadu Buhari ti orile-ede Naijiria ti fagile erongba re lati rinirinajo lo si ilu Kigali lorile-ede Rwanda, latari ati lo se ifilole anfaani idokowo ti ko lowo-ori ninu ni ile Afrika, African Continental Free Trade Area (AfCFTA), eyi ti o ye ko waye ni ojo kokanlelogun osu keta odun 2018.
4 5717 Orilẹede Thailand 60 0.
seleri pe oun yoo sapa oun lati mu igbe aye  irorun ba awon eniyan Ipinle Oyo.
''Emi fun ra mi ni alaga ipade pẹlu awọn gomina ipinlẹ mẹrindinlọgbọn ati minisita olu ilu Naijiria, Abuja nibi ti a ti gbe igbimọ ti yoo ṣe iwadii iwa ika tawọn ọlọpaa #SARS ti hu.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù EndSARS: Fayemi ní ọlọ́pàá ti fìyà jẹ òun náà rí, gbọin-gbọin lòun wà lẹ́yìn àwọn ọ̀dọ́ lórí ìwọde EndSARS 15 Bélú 2020 Oríṣun àwòrán, facebook/Kayode Fayemi Gomina ipinlẹ Ekiti, Ọmọwe Kayode Fayemi ti sọ pe oun ṣetan lati darapọ mawọn ọmọ Naijiria ti wọn to n beere fun atunṣe awọn ọlọpaa Naijiria nitori ọlọpaa ti fiya jẹ oun ri.
Bẹ́ẹ̀ ni Babiloni náà gbọdọ̀ ṣubú,nítorí àwọn tí wọ́n pa ní Israẹli.
Nítorí pé ò ń bá mi bínú,mo sì ti gbọ́ nípa ìwà ìgbéraga rẹ,n óo sì fi ìwọ̀ kọ́ ọ ní imú,n óo fi ìjánu bọ̀ ọ́ ni ẹnu,n óo sì dá ọ pada sí ọ̀nà tí o gbà wá.
Ṣibẹsibẹ, awọn onimọ nipa ilera sọ pe omi mimu dara fun ara rẹ.
Láti inú ẹ̀yà Lefi, wọ́n jẹ́ ẹẹdẹgbaata ó dín irinwo (4,600); 
Ẹ̀yin ọmọde, ẹ má bá wọn bọ oriṣa.
iroyin Alaroye, Alao Adedayo je ko di mimo pe aifimosokan omo Yoruba lo faa ti
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Africa in Pictures: Àwọn àwòràn tó ṣàrà ọ̀tọ̀ láti ilẹ̀ Afirika 19 Agẹmo 2019 Oríṣun àwòrán, Reuters Àkọlé àwòrán, Awọn ọmọbinrin akẹkọ mẹta ni orilẹede Sierria Leone to n ti ile iwe bọ, sa si abẹ́ aburada kansoso lasiko ti ojo n rọ.
Nígbà náà ni Maria sọ pé,“Ọkàn mi gbé Oluwa ga,
”Won yan an fun idije gbigba ami eye OSCAR lodun 1967 ko to gba ami eye CBE lodun 1997 to tun gba iranwo ni 2001 lowo ile ise ile Geesi British Film Institute.
Ondo accident: Tírélà méjì tẹ ìyá àti ọmọ pẹ̀lú èèyàn méjì míì pa ní Ikare-Akoko, awakọ̀ sá lọ
“iko omo ogun oju omi ko ni kaare lati tepele mo gbigbokun ti iwa ibajẹ .
, ojú rèé ìran rèé lọ́dún 2018.
Policeman smoking shisha: Iléeṣẹ́ ọlọ́pàá ti bẹ̀rẹ̀ ìwádìí lórí fídíò ọkùnrin kan tó ń mu shisha"""
Aṣẹ ti Adajọ yi gbe kalẹ n waye lẹyin nkan bi ọjọ mẹta ti ile ẹjọ yi kan naa gbe aṣẹ iru rẹ kalẹ ki wọn mu Abdulrasheed Maina ti o sa mọ ile ẹjọ lọwọ.
Ó pe àkọ́bí obinrin ni Jemima, ekeji ni Kesaya, ẹkẹta ni Kereni Hapuki.
Gẹgẹ bii awọn alaṣẹ ileeṣẹ naa ṣe sọ, awọn ibudo ti ifa yii gunlẹ si naa ni The Palms shopping mall, Lekki Landmark events centre, Victoria Island University of Lagos, Akoka MMA2 (Domestic Airport) Ikeja City Mall, Alausa, Ikeja Computer Village, Ikeja Oríṣun àwòrán, @googleafrica Àkọlé àwòrán, Igbakeji aarẹ Yẹmi Osibajọ ni ara igbesẹ ti ijọba apapọ n gbe niyi lati darapọ mọ awọn orilẹede ti o n fi imọ ẹrọ ṣọrọ Ninu ọrọ rẹ nibẹ, igbakeji aarẹ orilẹede Naijiria, Ọjọgbọn Yẹmi Osibajọ to ṣi eto ọhun ni ara ohun to lee mu eto ẹkọ ati mọọkọ-mọọka gbẹrẹgẹjigẹ sii lagbaye ni amulo ẹrọ ayelujara.
Rwanda Ọdun 2018 ni Rwanda fofin lelẹ pe o le lọ ẹwọn ọdun marun un tabi meje to ba bu aarẹ nitori ipo pataki to dimu.
Dìde nisinsinyii, kí o wọ inú ìlú lọ.
Ó ṣe ohun tí ó burú lójú OLUWA; ó sì tẹ̀lé ìwà ẹ̀ṣẹ̀ Jeroboamu, ọmọ Nebati, tí ó mú Israẹli dẹ́ṣẹ̀.
Kí OLUWA bojúwò yín,kí ó sì fún yín ní alaafia.
Ìjọba Kano fi páńpẹ́ òfin mú Ọba àwọn Oṣó lórí ẹ̀sùn jìbìtì Awakọ̀ Maruwa tó bá gbé okùnrin àti obìnrin papọ ní Kano yóò jẹ búlálà mẹ́wàá- Hisbah Òṣèrébìnrin tí wọ́n bá fi ìbálòpọ̀ lọ̀ 'torí ìṣẹ́, kó bọ́ síta láti sọ̀rọ̀ - Kunle Afod Naira Marley, Burna Boy àti Rema ló kó àmì ẹ̀yẹ tó pọ̀jù ló ni MVP Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Àwọn aránṣọ yarí pé gbogbo ẹ̀bi kìí ṣe tàwọn, díẹ̀ wà lọ́wọ́ àwọn oníìbárà náà Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
''Ọpọ idile ni ebi n pa lasiko yii, ati pe maalu meji si mẹta ti wọn yoo gba gẹgẹ bi owo ori lo n mu ọpọ ṣe igbeyawo tulaasi fawọn ọmọde,'' Kaputah lo woye bẹẹ.
Ewe, iko ti o n ri si oro awon arinrinajo lona aibofin-mu ninu  ajo isokan agbaye, ti gba pea won yoo pese owo ti won yoo fi da awon abala yii pade, bakan naa ni won yoo pese ounje ati eto ilera fun awon omo orile-ede Ethiopia naa.
"Gbogbo ọjọ́ kérésì ni ìyá Leah Sharibu ń sàìsàn, ó tún ti wà nílé ìwòsàn Àwọn àjàkálẹ-àrùn tó ti wáyé rí ṣáájú Coronavirus Ọkọ mi kìí bọ òkun, ""Elder"" ni ní ṣọ́ọ̀ṣì àmọ́ ìdí nìyí tó fi bọ̀wọ̀ fún ìpè mi - Olokun Omolara Ojúṣe òbí ní láti sọ fọ́mọ rẹ̀ kó má ṣe ‘Yahoo’, ń kò lè báwọn ọ̀dọ́ wí - Zlatan Ibile Ìtàn ìgbé ayé Isola Ogunsola, akọni mánigbàgbé òṣèré tíátà, olórin àti onílù 'Ààrùn sickle cell ti lóògùn báyìí' ""N kò mọ̀ pé alárùn ‘Sickle Cell’ ni mí títí mo fi pé ọdún méjìdínlógún"" Ohun méje tí o kò gbọ́ rí nípa aláìsàn arunmọ-léegun- Dókítà Igbekele World Autism Day: Ẹ̀bùn ni ọmọ mi jẹ - ìyá ọmọ àkanda Mo sọ Dókítà dí òpùrọ́ lórí ayé mi - Steph Ilé-isẹ́ ìpòogùn Johnson & Johnson san biliọnu 8 dọ́là fún ẹni tóògùn gbòdì lára rẹ̀!"
Ninu ikede olojoojumọ to maa n gbe sita lori bi nnkan ṣe n lọ si pẹlu ajakalẹ arun COVID-19 lorilẹ-ede Naijiria, ajọ to n gbogunti ajakalẹ aarun lorilẹ-ede Naijiria, NCDC ṣalaye pe gẹgẹ bi iṣe rẹ, ipinlẹ Eko lo moke ninu ipinlẹ ogun ti arun naa tun ti ko awọn eeyan mọra ni Naijiria.
“Ìwọ ọmọ eniyan, sọ àsọtẹ́lẹ̀ pé èmi: OLUWA Ọlọrun ní:Ẹ wo idà, àní idà tí a ti pọ́n, tí a sì ti fi epo pa.
Ní ọjọ́ kẹwaa oṣù kẹwaa ọdún kẹsan-an ìjọba rẹ̀, Nebukadinesari, ọba Babiloni, òun ati àwọn ọmọ ogun rẹ̀ gbógun ti Jerusalẹmu, wọ́n dó tì í, wọ́n sì mọ odi yí i ká.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ejo abami to n mu owo ni ajọ Jambu Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Yorùbá dùn lédè, ẹ máa sọọ́ Ẹfunroye Tinubu - Ògbóǹtagí oníṣòwò, olówò ẹrú àti afọbajẹ Samuel Ajayi Crowther, òjíṣẹ́ Ọlọ́run tó gbé èdè Yoruba lárugẹ Mọrèmi Àjàṣorò, akọni obìnrin tó gba Ilé Ifẹ̀ sílẹ̀ lóko ẹrú Ọwọ́ pálábá ségi fún gbajúgbajà olè méjì tó ń ṣọṣẹ́ lọ́wọ́ l‘Eko Lẹ́yìn ọdún mẹ́wàá, Tokyo àti Auxillary ṣèpàdé bòńkẹ́lẹ́ Ọbasanjọ sọ àsírí sàgbàdèwe rẹ̀ Nigba to n salaye awọn ohun to nifẹ si, Kloe ni oun fẹran lati maa se ounjẹ, oun kii mu oogun oloro, dipo ti oun yoo ba fi mu, yoo dara ki Ọlọrun kuku pe oun sọdọ.
Lónìí òpin ọdún 2012, tí a bá bojú wẹ̀hìn, a ó rí i pé ọ̀pọ̀  òjò ló ti rọ̀ lọ́dúnnìí, tí ilẹ̀ sì fi mu.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Lẹkki: Araalu gbanajẹ lori afikun owo ibode 9 Èrèlè 2018 Àkọlé àwòrán, Ọpọlọpọ fẹhonuhan lagbegbe eti ọsa lori ifinku Ọpọlọpọ eniyan tu s'ita lagbegbe Lẹkki nibilẹ eti ọsa lati fẹhonuhan lori afinku owo irinna ẹnu ibode (Toll gate) ninpinlẹ Eko lọjọ ẹti.
Ikede iku Fẹlẹ Ni ọsan ọjọ Iṣẹgun ni Alhaji Fẹlẹ jade laye nileewosan Zenith Kidney Hospital nilu Abuja.
Nile ni Chelsea kuku wa ti Man City ko igbaju igbamu bo wọn bi ole to ji ike owo.
"Ìdájọ́ ẹ̀wòn gbére kò ní kí Wòlíì Sotitobire má lọ sí ilèẹjọ́ kòtẹ́milọ́rùn - Agbẹjọ́rò Pásítọ̀ Alfa Babatunde Afurasí darandaran jí èèyàn mẹ́rìnlá gbé ní Ọ̀ṣun Àwọn mẹ́wàá tí wọ́n jígbé ní Ọ̀ṣun gba ìtúsílẹ̀ O ni ""Inu oko ni mo wa pẹlu ọrẹ mi, ti awọn ẹni a wi yii de lori alupupu, ti wọn si di ibọn mọra."
"Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Àwọn oṣiṣẹ feyinti ni Osun ṣé iwọde ""Bi wọn ba kọ lati san owo naa laarin asiko yii si ọjọ ẹti, o ṣeeṣe ki a pada si ẹnu gbedeke ọlọjọ meje ti a fẹ gunle o."
Ajọ NERC sọ pe gbogbo awọn to lo ina ọba ni alekun ti ba owo ti wọn n san ayafi awọn ti ko ba ki n lo ina fun wakati mejila lojumọ loku.
Ní pẹ̀tẹ́lẹ̀ Jọdani tí ó jẹ́ ilẹ̀ amọ̀, láàrin Sukotu ati Saretani, ni ọba ti ṣe wọ́n.
Aisha Buhari pariwo sita nigba naa pe pe awọn eeyan kan n ko aarẹ Buhari ni papa mọra ti wọn si sọ ara wọn di apaṣẹ waa ni ileeṣẹ aarẹ.
Awọn miran ti lẹ sọ wi pe ki aarẹ jẹ ki ileewe ṣi, ki awọn olukọ le pada si ẹnu iṣẹ, ki awọn ti wọn ti kuna iṣẹ wọn nitori arun Coronavirus naa le ri iṣẹ.
Odidi ọdun mẹta gbako ni ogun abẹle naa fi waye, ko to pari lọdun 1970 sugbọ ogun naa mi isọkan ominira orilẹede Naijiria logbologbo.
Sùgbọ́n ní ti Naomi àti olólùfẹ́ rẹ̀ tí wọ́n maa ń wà papọ, Sarah Samuel tó jẹ ẹni ogún ọdún gbìyànjú láti fi ìwé tiwọn pamọ àti ìwé àwọn ọmọbinrin mẹ́ta míràn tí wọ́n máa ń kọ àwọn ìrírí wọ́n sí.
Bí ọ̀kan ninu àwọn eniyan wọnyi, tabi wolii kan, tabi alufaa kan, bá bi ọ́ léèrè pé, “Kí ni iṣẹ́ tí OLUWA rán?
Ó yẹ kí á ṣe àríyá, kí á sì máa yọ̀, nítorí àbúrò rẹ yìí ti kú, ó sì tún yè, ó ti sọnù, a sì tún rí i.
Corruption: Ìwádìí àjọ aṣèṣirò òde, NBS gbé e jáde pé àwọn ọlọ́pàá, adájọ́ àtàwọn aṣọ́bodè ló gba rìbá jùlọ ní Nàìjíríà
Gbogbo àwọn baálẹ̀ ìgbèríko, àwọn olórí, àwọn gomina, ati àwọn ìgbìmọ̀ ọba, kó ara wọn jọ, wọ́n sì rí i pé iná kò jó àwọn ọkunrin wọnyi, irun orí wọn kò rùn, ẹ̀wù wọn kò yipada, bẹ́ẹ̀ ni wọn kò tilẹ̀ gbóòórùn iná lára wọn.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Buhari kò leè ṣàtìlẹyìn fún olùdíje Amosun l'Ogun Àwọn ológun gba ìjọba ilẹ̀ Gabon Ìpàdé NLC àti ìjọ̀ba àpapọ̀ lórí owó osù tuntun forí ṣánpọ́n Gẹgẹ bii iwe onka ọjọ ti atijọ, ti a mọ si Orthodox Calendar ti ṣe fi lelẹ, ọjọ keje oṣu kini ni a bi Jesu Kristi.
Ìpínlẹ̀ Ekiti ló bàjẹ́ jùlọ ní Naijiria- Afe Babalola Awakọ̀ 700 kò sí páńpẹ́ òfin, 191 ṣẹ̀wọ̀n lórí ẹsùn wíwakọ̀ lẹ́yìn tí wọ́n mu ọtí Ǹ jẹ́ o mọ àwọn èèyaǹ wọ̀nyí tó jà fún òmìnira Nàìjíríà?
"Florence Ajimobi tahùn sí igbákeji gómìnà Oyo lórí ikú ọkọ rẹ̀, ""Gbogbo wa làó kú"" Arúfin ni Seyi Makinde pẹ̀lú bó ṣe gbà kí wọ́n sin Ajimobi sí GRA - Amòfin Àwọn ògo Ibadan márùn ún tí ikú mú lọ lọ́dún 2020 O ni Makinde n fi ọrọ iku ọkọ oun ṣe ọrọ ati ija oṣelu."
Nígbà tí Filipi sáré, tí ó súnmọ́ ọn, ó gbọ́ tí ó ń ka ìwé wolii Aisaya.
Dokita Kwajafa sọ pe isẹ awọn ni igbiyanju lati doola ẹmi gẹgẹ oniṣegun, ati wipe o ṣe pataki fun awọn lati fifẹ han si awọn eniyan.
' Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Nígbà tí mò ń wà Awolowo, Gowon, Babangida, mo fi ara mi sípo ọ̀wọ̀ tóri .
Babachir Lawal bọ lọwọ EFCC Bukola Saraki kò kọjá òfin - EFCC EFCC tun gbe Akala yọju sile ẹjọ ‘Patience Jonathan yoo yọju sileẹjọ’ Igbẹjọ iwa ajẹbanu yii jẹ ọkan lara awọn ẹsun igbogun ti iwa ibajẹ tijọba Buhari ri ṣe lati ọdun 2015 to ti gori aleefa.
N óo ti Sisera olórí ogun Jabini jáde láti pàdé rẹ lẹ́bàá odò Kiṣoni pẹlu àwọn ọmọ ogun rẹ̀ ati àwọn kẹ̀kẹ́ ogun rẹ̀, n óo sì fà á lé ọ lọ́wọ́.
Kóda láì ni ìdí ni ààrẹ ilẹ̀ Amẹrika ti sọ pé abẹ́rẹ́ ajẹsara nii ṣe pẹlu ohun to n fa ti àwọn ọmọ tí ọpọlọ wọ́n ko jí pépé to.
Ilẹ̀ ṣú, ilẹ̀ sì tún mọ́, ó di ọjọ́ keji.
    Wọ́n kò da ẹjọ́ púpọ̀ lọ̀jọ̀ tí mo ń sọ̀rọ̀ yìí, ṣùgbọ́n èyí tí wọ́n sì dá, ẹjọ ọba pàápàá ni.
Ninu esi rẹ, Aṣofin Braimoh fi han pe gbogbo ipa ni ijọba ti sa lati mu igberu ba ẹkun naa ati pe gbogbo awọn nnkan ti wọn beere fun naa ni awọn yoo ko pọ sinu abajade ipade apero naa ti wọn yoo gbe siwaju Ile Igbimọ Aṣofin Ipinlẹ Eko, ti wọn yoo jiroro le e lori, ti wọn yoo si ṣiṣẹ le wọn lori.
Ìtàn ayé Shina Rambo, adigunjale tó fi oyún 27 gún ọṣẹ Ẹ wo ìrírí aláboyún tó ń rọbí lọ́wọ́ lásìkò ìbúgbàmù tó wáyé ní Lebanon Al-Qaeda ń gbèrò láti kógun wọ Ìwọ̀ Oòrùn àríwá Nàìjíríà - Amẹ́ríkà ké gbàjarè Kí ló fa iná ńlá tó ṣẹ́yọ lọ́jà Ajman ní Dubai?
Hazard to darapọ mọ Chelsea lọdun 2012 ti gba ayo mẹwaa sawọn fun Chelsea ninu idije Premier League ti saa yii.
 Ó jẹ ́ ọ ̀ kan lára àwọn àrùn àwọn orílẹ ̀ -èdè ipa ọ ̀ nà oòrùn tí a kò bìkítà fún .
Ijọba si ti ṣetan lati ma a san owo iranwọ ẹgbẹrun lọna ogun Naira fun wọn ni oṣooṣu, ti wọn yoo si pese irinṣẹ fun wọn.
ati awọn omo orile ede Mozambique, Zimbabwe ati Malawi nipa atileyin adura ati
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù WAEC Result: Olùdíje kò nílò ìwé ẹ̀rí WAEC fún ìpò ààrẹ tàbí gómìnà 15 Ìgbé 2019 Oríṣun àwòrán, Faceboo/Kenyamo Àkọlé àwòrán, Ọrọ iwe ẹri girama Oludari ipolongo ibo aarẹ fun Aarẹ Muhammadu Buhari, amofin agba Festus Keyamo ni oludije ko nilo iwe ẹri WAEC lati dije fun ipo aarẹ tabi gomina lorilẹede Naijiria.
Beautiful Nubia - Orin mi kìí ṣe orin lásán 'Obinrin lo mu mi fẹran orin kikọ' Kèǹgbè lílù ní Ilọrin rèé, orin ìgbéyàwó, àwàdà àti ẹ̀ẹ̀kẹ́ èébú 'Mò ń fi Orin mi kọ́ àwọn èwe ní ẹ̀kọ́ ìwà rere' Ọkùnrin tó pe ìyàwó rẹ̀ lájẹ̀ẹ́ tì í mọ́lé fọ́dún mẹ́rin, fún un lóyún nígbà mẹ́ta!
 Ṣùgbọ ́ n ó jẹ ́ ẹní tí ìyá rẹ ̀ fi ìfẹ ́ hàn sí láti kékeré .
Idajọ ẹgbẹ awọn ọkunrin to lahun ni pe ki ọkunrin naa lọ fi ẹwọn aadọta ọdun jura.
Gbaju-gbaja oludari ere, Adebayo Tijani naa ṣe ayẹyẹ ọjọ ibi.
oloogbe  Tudun Wada gege bi, onirẹlẹ ati
Minisita fun eto abo lorilẹede Naijiria, Mansur Dan Ali to salaye ọrọ yii ni, ọwọ ti awọn ọrọ ikorira n ba jade bayii lori awọn ikanni ayelujara (social media) n fẹ amojuto.
siluu Daura, nipinle Katsina lojoBo(Thursday) saaju idibo gomina ati ile-igbimo
O tun le ṣe akọsilẹ àwọn nọ́mbà mii ti o ba n lo nibẹ.
igbinmo asofin naa, asofin Mudashiru Obasa so ninu oro ti e pe, o pon dandan ki
Duro Ladipọ, ìlúmọ̀ọ́ká òṣèré tíátà àti ọmọ àlúfà tí kò gbàgbé àṣà ìbílẹ̀ Gómìnà Seyi Makinde bá ẹbí Isiaq Jimoh tó kàgbákò ikú òjijì dárò Ìdí márùn ún tí agbára Covid 19 ní ilẹ̀ Adúláwọ̀ kò fi tó tí àwọn ilẹ̀ àgbáyé míràn APC mókè nínú ìbò gómìnà níjọba ìbílẹ̀ mẹ́sàn-án l‘Ondo, PDP gba mẹ́ta Blessing ni aṣiṣe nla lawọn to n sọ pe oun ju idi kiri ki awọn aye le maa sọrọ ṣe nitori iṣu Ọlọrun ti ko ṣe fọwọ bo ni ikebe naa jẹ foun.
Ẹran-ara mi ni oúnjẹ gidi, ẹ̀jẹ̀ mi sì ni ohun mímu iyebíye.
Ṣe awọn agba bọ wọn ni ko si iku ti yoo pa agba ti ko ni ṣee loju firi.
"PDP: Jẹgudu jẹra ni ijọba ẹgbẹ APC Buhari bẹrẹ abẹwo si ipinlẹ Benue ""A nilo ofin tuntun lati koju ọwọja iwa yii lawujọ."
Ìdílé kọ̀ọ̀kan gbọdọ̀ ní àwọn ọmọ Lefi tí wọn yóo wà pẹlu wọn.
Kí lo mọ̀ nípa fẹntilétọ̀, ohun èlò aṣèrànwọ́ èémí Ǹjẹ́ àwọn arúgbó nìkan ni ààrùn coronavirus ń mú?
Bakan naa, aare yoo tun se abewo ikedun si Emir ipinle Katsina, Alhaji Abdulmumuni Usman, nibi ti yoo ti ba awon adari ati agbaagba ilu naa soro lori oro ilu.
Ẹni mímọ́ kan sọ̀rọ̀; mo tún gbọ́ tí ẹni mímọ́ mìíràn dá ẹni tí ó kọ́ sọ̀rọ̀ lóhùn pé, “Ìran nípa ẹbọ sísun ojoojumọ yóo ti pẹ́ tó; ati ti ẹ̀ṣẹ̀ tí ó ń sọ nǹkan di ahoro; ati ìran nípa pípa ibi mímọ́ tì, ati ti àwọn ọmọ ogun tí wọ́n di ìtẹ̀mọ́lẹ̀?
Nìgbà tí a pé ọmọ-ọ̀dọ̀ yìí tí mo bu àkàrà díẹ̀ fún un tán, a bẹ̀ ẹ́ kí ó lọ bá wa kó àwọn nǹkan wa jáde láti inú ilé ìṣúra wá òun náà sì gbà bẹ́ẹ̀ fún wa ṣùgbọ́n ó wí pé ó di ìgbà tí àwọn tí ń sọ ilé ibẹ̀ bá ṣíṣẹ́ ọjọ́ náà parí tí wọ́n kúròi ní áàfin kí òun tóó lè lọ bá wa kó àwọn nǹkan wa.
Ilé aṣòfin àgbà Nàìjíríà dàbí ọjà bí Saraki ṣe pa Akpabio lẹ́nu mọ́
O menuba pataki ki awon eniyan maa lo fun ayewo kikun ni o keere tan eekan lodun lati mo ipo ti eya ara won kookan wa paapaa oju won.
Àwọn tí wọ́n gba Oluwa gbọ́ túbọ̀ ń darapọ̀ mọ́ wọn, lọkunrin ati lobinrin.
Nígbà tí mo wò yíká, ilẹ̀ ti ṣú bámúbámú.
Ipade kẹsan niyii ti ẹgbẹ olukọ fasiti ASUU n se pẹlu Minisita fun ọrọ osisẹ ati igbanisisẹ, Chris Ngige lati bii oṣu mẹta.
Dafidi ṣẹgun Filistini náà láìní idà lọ́wọ́; kànnàkànnà ati òkúta ni ó fi pa á.
Ọjọ ori Gbigbe igbe aye inira Fifi taba lile ati oti mimu Aisan inu ara Sisanra lasanju le fa aisan jẹjẹre ọmu, ikun ati isalẹ inu pẹlu aisan jẹjẹrẹ ile ọmọ.
Nígbà tí wọ́n dé Kapanaumu, tí wọ́n wọ inú ilé, ó bi wọ́n pé, “Kí ni ẹ̀ ń bá ara yín sọ lọ́nà?
OLUWA Ọlọrun yín yóo tún da yín pada sí ilẹ̀ àwọn baba yín, ilẹ̀ náà yóo tún pada di tiyín, OLUWA yóo mú kí ó dára fun yín, yóo mú kí ẹ pọ̀ ju àwọn baba yín lọ.
Àwọn eniyan yóo máa wá láti gbogbo ìlú Juda ati àwọn agbègbè Jerusalẹmu, láti ilẹ̀ Bẹnjamini ati pẹ̀tẹ́lẹ̀ Ṣefela, láti àwọn agbègbè olókè ati ilẹ̀ Nẹgẹbu, wọn yóo máa mú ẹbọ sísun ati ẹbọ ọrẹ wá, pẹlu ẹbọ ohun jíjẹ ati turari; wọn yóo máa mú ẹbọ ọpẹ́ wá sí ilé OLUWA.
Ó ní, “Wọ́n fún Dafidi ní ẹgbẹẹgbaarun ṣugbọn wọ́n fún mi ní ẹgbẹẹgbẹrun, kí ló kù tí wọn óo fún un ju ìjọba mi lọ.
ho ruru, ka wa a ruru.
ìwọ̀n pẹpẹ turari tí a fi wúrà yíyọ́ ṣe ati ohun tí ó ní lọ́kàn nípa àwọn kẹ̀kẹ́ wúrà àwọn Kerubu tí wọ́n na ìyẹ́ wọn bo Àpótí Majẹmu OLUWA.
Ninu atẹjade kan ti ẹgbẹ oṣelu PDP fi sita ni ọjọ abamẹta, ẹgbẹ oṣelu naa ni o ti lu si awọn lọwọ pe ijọba apapọ ti n gbero ati fi oru boju gbe Kẹmi Adeọṣun kuro lorilẹede Naijiria lọ si oke okun.
tí yìnyín bo odò náà tóbẹ́ẹ̀ tí ó fi ṣókùnkùn,tí yìnyín ńláńlá sì farapamọ́ sibẹ,
Loju opo Twitter, eeyan kán kan sara si Moura bi o ti ṣe fakọyọ laaarin awọn akẹgbẹ rẹ ninu ifẹsẹwọnsẹ pẹlu Ajax.
Kòṣẹlẹ̀rí ni Hajj ọdún 2020, wo ìyàtọ̀ tó wà nínú rẹ̀ sí ti tẹ́lẹ̀ Ẹ̀yin ẹlẹ́gbẹ́ òkùnkùn tẹ fẹ́ ṣe àjọ̀dún lónìí, lákọ la ń dúró dè yín - Iléeṣẹ́ ọlọ́pàá Ìjọba Akeredolu kò ní omi àánú lójú, a kò tọ́jú alárùn Coronavirus mọ́ - Dókítá Ondo Bí àwọn adarí ìjọba ṣe ń kó Coronavirus, ń kọ wá lóminú - Ìjọba àpapọ̀ Ọrọ iyọnipo igbakeji gomina naa si lo lewaju ijiroro ile asofin naa, to pada wọle lẹyin isisnmi ranpẹ ti wọn lọ fun.
Àwọn ojú oge Yollywood t'ọ́jà wọ́n ṣì ń tà wàràwàrà Awọn ọmọ Naijiria miran wo ni iku wọn mu ibeere dani?
Abileko Sally Mbanefo, to je komisona fun ise ona, asa, irinajo afe ati oro awon eniyan won nile okeere ti kede pe ijoba ipinle Anambra yoo tun iboji alufaa Tansi se ki o le di ibi iworan ti awon eniyan a maa wa wo nipinle naa.
Ajọ naa fi sita loju opo twitter rẹ pe pẹlu bo ṣe ri yii, o ti di aadọwa eeyan ti wọn ti ṣawari pe o ni arun naa bayii lorilẹede Naijiria.
Wọn bi i lọjọ kẹtala, oṣu keje, ọdun 1934.
Awọn ọdẹ lo maa n pa awọn eku yii wa fun awọn to n ta a.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Coronavirus Update: Báwo lo ṣe leè mọ Oogùn apakòkòrò 'Sanitizer' tó jẹ́ ayédèrú?
O tun ni o yẹ ki ofin ipinlẹ jọju, iṣejọba oun yoo si fi ontẹ luu nipa biba awọn lọba lọba ṣiṣẹ.
Joy Chioma tun sọ pe lati bii osu meta kan seyin ni oga
Kìí ṣe ẹ̀ẹ̀kan ṣoṣo ni ẹ óo pa gbogbo wọn run, kí àwọn ẹranko burúkú má baà pọ̀ ní ilẹ̀ náà, kí wọ́n sì ju agbára yín lọ.
Igbẹjọ naa ti bẹrẹ nile ẹjọ bayii, bo ba si se n lọ, la maa mu iroyin naa wa fun yin.
” Lara awon osise ti yoo maa kopa lori eto ohun naa ni iyaafin Aderonke Osundiya,Tobi Sangotola ati Maryam Yusuf .
Coronavirus in Africa: Wo àwọn ẹ̀rọ mẹ́wàá tí àwọn onímọ̀ ẹ̀rọ ṣe nítorí àrùn Covid-19 Ni bayii ti arun Covid-19 ti kọlu miliọnu kan eeyan le diẹ nilẹ Afrika, ọpọ awọn onimọ ẹrọ lo ti bẹrẹ si n ṣe awọn ẹrọ igbalode ni idahun si ajakalẹ arun naa.
Atẹjade kan lati ọdọ alukoro ileesẹ naa, AC Njoku lo fidi ọrọ yii mu'lẹ.
Bẹ́ẹ̀ ni kí ọlọ́rọ̀ kí ó yọ̀ nígbà tí Ọlọrun bá rẹ̀ ẹ́ sílẹ̀, nítorí bí òdòdó koríko ìgbẹ́ ni ọlọ́rọ̀ kò ní sí mọ́.
Mo ti rí bí ó ti ń ṣe,ṣugbọn n óo ṣì wò ó sàn;n óo máa darí rẹ̀, n óo tù ú ninu,n óo sì fún àwọn tí ó bá ń ṣọ̀fọ̀ ní Israẹli ní orin ayọ̀.
Ọọni Ile Ifẹ wa gbadura fun awọn ti o ti padanu ẹmi wọn kaakiri Naijiria nitori iwọde naa ati imularada awọn to fara gbọgbẹ gbogbo.
" Bakan naa ni Ọba Akanbi tun pe fun eto pipa owo wọle labẹle lna to se ara ọtọ , paapa ni ẹka awọn aladani, ko lee rọrun fun ijọba lati ri owo lo.
0 183242 Orilẹede Lithuania 2376 84.
Ayé sú mi,n kò ní wà láàyè títí lae.
Sanwoolu ṣe é dáa fún wa níbodè Lekki, Ikoyi - Awakọ̀ ní Lekki Kí ni Bode 'Thomas' ní ṣe pẹ̀lú ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ Nàìjíríà àti South Africa?
Agbẹnusọ fun ile iṣẹ ọlọpaa to fọrọ naa lede sọ pe awọn eeyan ti ọjọ ori wọn bẹrẹ lati ọmọ ọdun mọkanlelogun si aadọta ọdun ni ile iṣẹ ọlọpaa fẹ gba fun iṣẹ ọhun.
Kíyèsíi, èmi kò mú un wá láti pa èyíinì run tí wọ́n ti gbà, ṣùgbọ́n láti gbé e ró.
Ìdí tí mo ṣe fi ọ́ sílẹ̀ ní Kirete ni pé kí o ṣe àtúnṣe àwọn ohun tí ó kù tí kò dára tó, kí o sì yan àwọn àgbà lórí ìjọ ní gbogbo ìlú, gẹ́gẹ́ bí mo ti ṣe ìlànà fún ọ.
AMAA 2018 Ami eye fun eyi to dara ju ti won ya loke okun
 Awon miiran tun ni ,Rotimi Oshinbajo, omo odun merindinlogbon, Fola Odubiyi, omo odun mejidinlogun, Niyi Shode,omo odun merinlelogun , Kelvin Odunuyi, omo odun ookandinlogun, Abraham Badru,omo odun merindinlogbon,  Israel Ogunsola,omo odun mejidinlogun,ati awon isele miiran to ti sele sugbon ti ko ni akosile.
Oríṣun àwòrán, Instagram/ajimobi Iku Abiola Ajimobi: Amọ o ṣeni laanu pe asiko yii ni agba oselu naa ti wa lori aisan, ti ẹnu si n kun un pe arun Coronavirus lo n ba a finra, bẹẹ ni ko lo ipo naa fun ọjọ kan ṣoṣo, ko to pa ipo da.
Àwọn tí kò lọ sí Hajj naa má a n gbà awẹ lati pa ọkan mọ pẹlú àwọn tó wà ní Hajj.
O ni ọkọ Ajagbe naa pẹlu nọmba ọkọ XC 791 LSR, ti o n lọ si Ipinlẹ Eko lati Abeokuta ni o deede padanu ijanu ọkọ rẹ, ti o si ṣeku pa ọmọbinrin naa.
Wo itan iya kan ati awọn ole ti wọn n ji ọmọ gbe ta.
Ṣugbọn àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ ń jẹ, wọ́n ń mu ní tiwọn ni.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Flooding in Lagos: Ojú àwọn ará Èkó rí màbo pẹ̀lú òjò àrọ̀ọ̀rọ̀dá dá wàhálà sílẹ̀ ní Eko 18 Òkùdu 2020 Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Lagos: Ojú àwọn ará Èkó rí màbo pẹ̀lú òjò àrọ̀ọ̀rọ̀dá dá wàhálà sílẹ̀ ní Eko Ko si ẹni ti kii gbadura fun ojo paapaajulọ fun itura bi oju ọjọ ba ṣe bi ẹni mooru.
Awọn to n ta sinima wa lo n pa owo sapo ara wọn lai fun ẹni to ni iṣẹ ninu ere ti wọn ba jẹ.
Kò tán síbẹ̀ óò, nígbà ti Erica tún de yàrá ti wọ́n ti yà sọ́tọ̀ fún àwọn olórí ilé, ó tún kọjú mọ́ Prince, nítorí pé ó ń gbìyànjú láti pẹ̀tù síi lọ́kàn.
” Gege bi Garba Lawal naa tun se so, “O sapejuwe ipa awon agbaboolu ohun pe, ai ki farajin to tabi kopa daradara to ni ibere saa akoko ifesewonse won gbogbo, o wa lara ohun ti o n sokunfa pipadanu awon ifesewonse won, eleyi ti won si gbodo mojuto ki idije agbaye naa o to bere,”Tijani Babangida naa tenumo pe, “Bi iko ohun se kopa lasiko ifesewonse won pelu England naa ni yen, leyin ti won padanu ami-ayo meji siwaju ni saa kinni ifigagbaga naa, kii won to maa sare lati da ami ayo ohun pada ni saa keji.
 Ìtàn náà sọ fún wa pé odùduwà sọ ̀ kalẹ ̀ sí ilé-ifẹ ̀ láti ọ ̀ run pẹ ̀ lú àwọn ẹmẹ ̀ wà rẹ ̀ .
 A ti pe awon bii Seriake Dickson to je gomina Bayelsa seyin atawon miran”.
Má gbàgbé, má sì kọ ọ̀rọ̀ sí mi lẹ́nu.
Òun ati Elija ati gbogbo ará ilé rẹ̀ sì ń jẹ àjẹyó fún ọpọlọpọ ọjọ́.
Ọba bá ranṣẹ pé kí wọ́n mú idà kan wá.
Lákòókò náà gan-an ni àwọn ọkunrin mẹta tí a rán sí mi láti Kesaria dé ilé tí mo wà.
N óo sọ ilẹ̀ Ijipti di ahoro patapata, n óo jẹ́ kí àwọn ìlú rẹ̀ di ahoro fún ogoji ọdún.
Buhari: Èsì mi lórí orúkọ àwọn mínísítà
, omowe Ogbonnaya Onu lo soro yii nibi ayeye ti o kadi ipate oja imo ero
Elégbèdè mọtí yό ό lu igi mẹ̀fa ya, bẹ́ẹ̀ ni ẹ̀lírí ńgbádùn ayé-e rẹ̀ lẹ́bà-á àsun fún odidi oṣù mẹ́jọ láì fara pa.
Bí kò bá jẹ́ pé Oluwa dín àkókò náà kù, ẹ̀dá kankan kì bá tí kù láàyè.
Ìgbà mélòó ni iṣẹ́ ibi wọn ń dà lé wọn lórí?
Gbé mi ró gẹ́gẹ́ bí ìlérí rẹ, kí n lè wà láàyè,má sì dójú ìrètí mi tì mí.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Bolaji Faleke ni Olùkọ́ tó ń kọ́ wa ní àṣà oge ṣiṣe lórí BBC Yorùbá Ọpọ lo ti di ẹbi aṣọ iwọkuwọ ṣọọṣi ru awọn obinrin nikan, ṣugbọn awọn mii sọ pe ki lawọn ọkunrin naa n wo lara obinrin ti wọn kko kọ oju mọ isin ni ṣọọṣi.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ilé ẹjọ́ pàṣẹ kí EFCC gbẹ̀sẹ̀ lé àpò àsùwọ̀n kan tó ní nkan ṣe pẹ̀lú Akinwumi Ambode 6 Ògún 2019 Oríṣun àwòrán, Google Ile ẹjọ giga ijọba apapọ to wa ni adugbo Ikoyi nilu Eko ti paṣẹ pe ki owo kan to to biliọnu mẹwa Naira, N9.
Ewe, awon oludije miiran ti o
Ó níláti máa wá alaafia,kí ó sì máa lépa rẹ̀.
Nígbà tí oúnjẹ kò sí mọ́ ní gbogbo ilẹ̀ Ijipti, àwọn eniyan náà kígbe tọ Farao lọ fún oúnjẹ.
Ijamba ina naa sele leyin ti awon elewon dana sun ibusun won, nigba ti won fe sa jade kuro latimole lojoru.
0 720 Saint Barthélemy 1 10.
Iwọ ti o ba fẹ gba oniduro gbọdọ mọ ki o si ni oye irufẹ ẹsun ti wọn fi kan ẹni to fẹ ṣe oniduro fun.
Gege bi oludari  iroyin ati ikede fun ile-ise omo –oogun ofurufu,  Ibikunle Daramola,se so “awon omo –oogun naa yoo maa darapo mo awon akegbe won ni ipinle Kaduna lati dawo ipaniyan to n sele ni awon agbegbe kan duro, ki won si pese eto alaafia nibẹ.
Awọn apẹẹrẹ yii le jẹ ti aisan miran, yatọ si colon cancer.
Ọ̀ràn náà dùn mí dé inú egungun, nítorí bàbá mi kì rí bẹ́ẹ̀ nínú àwọn ọkùnrin.
Ṣugbọn kí wọn jẹ́ olóòótọ́ ati ẹni tí ó ṣe é gbẹ́kẹ̀lé ní ọ̀nà gbogbo.
Oga agba iko omo ogun oju ofurufu naa, ogagun Sadique Abubakar, wa gboriyin fun iko omo ogun naa fun ipa akinkanju won loju ogun.
Oríṣun àwòrán, Twitter/@IsaacIfeoluwa9 Nigba ti awọn ọdọ yi de aafin, wọn ko ba nkan jẹ ṣugbọn ko pẹ si igba ti wọn kuro lawọn janduku kan yabo aafin lasiko ti Minsisita ati Soun n ṣe ipade.
Oríṣun àwòrán, others Gẹgẹ bi iroyin nigba naa,ko si ẹnikẹni to lee ṣe ohunkohun nigba naa bi awọn igbimọ alagbara yii ko ba fọwọ sii.
Sowore ṣèpàdé pẹ̀lú Nnamdi Kanu láti dojú ìjọba Nàíjíríà bolẹ̀ - Àjọ DSS Ìjọba Buhari ń wùwà bíi ìjọba Abacha lórí ọ̀rọ̀ Ṣoworẹ- Ṣoyinka Ààrẹ Buhari ti lọ sí ìlú Daura fún ọdún Sallah Lórí ìmọ̀ràn Sunday Igboho, Ẹlẹbubọn ní yóò dára kí Yorùbá padà sí àmúlò èròjà ìbílẹ̀ fún ààbò Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Sunday Igboho: Fulani kò leè dúró, táa bá lo ohun ta jogún lọ́dọ̀ àwọ̀n bàbá wa Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, ''Ọjà ẹran àgbò kò yá bí ti ọdún tó lọ'' Ṣowore ni idajọ ileẹjọ to fun ile iṣẹ DSS laṣẹ lati ti oun mọ le fun ọjọ marundinlaadọta tumọ si pe ki eeyan sọ ohun to lodi sofin di ohun to tọna labẹ ofin.
Oríṣun àwòrán, The Protected Area Regional office 13 (Phrae) Àkọlé àwòrán, Kilo meje pantiri ni wọn ba ninu Igala naa Loju opo ayeluja ni awọn eeyan ti n bẹnu atẹ awọn to n ju idọti silẹ ninu ọgba ọhun.
Yatọ si eyi, gbogbo nkan to yẹ ki ẹni ti wọn ba dibo yan yẹ ko ni ni iriri ati eto ẹkọ to yaranti, naa lo yẹ ki ẹni to ba fẹ gba ipo kọmiṣọna ni ki ato buwọ lu iyansipo wọn.
O wa ro, apapo iko ohun ati awon toro kan ninu iko naa pe, ki won ri daju lati kopa daradara ninu olokan-o-jokan ifesewonse olorejore won ti won yoo gba fun igbaradi ni kikun saaju idije nla naa.
- MC Oluomo 'Èèwọ̀' gààrí fún àwọn èèyàn ipínlẹ̀ Ondo Ọkùnrin kan sálọ lẹ́yìn tó gbẹ̀mi ènìyàn mẹ́ta Olóri ẹgbẹ́ ìjọba ìbílẹ̀ àti kọmísọnà fún ètò ìlera Wahab Adegbenro ló ni kò tọ̀nà fún Ayiloge láti parọ mọ gomina nitori pe ó fẹ́ ṣe ìbàjẹ́ rẹ̀.
Ọmọ orukan ni ọmọbinrin naa, to jẹ ọkan lara awọn alejo wa lori eto wa taa pe ni 'Nibo laye kọju si' eyi to waye lori ikanni BBC News Yoruba lori Facebook.
Jesu yìí ni ẹ fi lé àwọn ọ̀tá lọ́wọ́, òun ni ẹ sẹ́ níwájú Pilatu nígbà tí ó fi dá a sílẹ̀.
Àkọlé àwòrán, Arulogun sọ wi pe akanṣe eto naa duro gẹgẹ bi ipilẹ fun ilepa lati ṣe akojọpọ awọn ibẹji l'agbaye.
Àwọn mẹjẹẹjọ yìí ni Milika bí fún Nahori, arakunrin Abrahamu.
com/Y4Z25wwgiYGege bi iwe ateranse naa: “O ti fi gbogbo aye re, lati ipo odo di akoko yii sin orile-ede Naijiria, o ti figba kan je ajagun, gomina, minisita to n mojuto oro epo robi, adari ilu, iwo tun re bayii ti o tun je aare orile-ede Naijiria.
Sani Ahmed Daura: Gomina akọkọ to jẹ ni ipinlẹ Yobe lọdun 1991 si 1998.
 gẹ ́ gẹ ́ bí ọ ̀ jẹ ̀ -wẹ ́ wẹ ́ olórin ó kọ ́ kọ ́ jẹ it wọ ́ gbà àwọn ènìyàn ní ọdún 2004 nígbà tí ó kópa nínú ìṣíde ijó-jíjó kan pẹ ̀ lúu gbajúgbajà akọrin reggae tí ń jẹ ́ Ṣean paul nílùú hamburg .
Ìdílé tí ó ṣẹ́kù ninu ẹ̀yà Lefi ni ìdílé Merari.
Kí Ọlọrun alaafia kí ó yà yín sí mímọ́ patapata; kí ó pa gbogbo ẹ̀mí yín mọ́ ati ọkàn, ati ara yín.
Kabiesi ni ìwásáye àwọn Ọba òde oni láti ṣe atúnṣe ǹkan ti àwọn baba nla to lọ ti ṣe, lati ṣe àtunṣe àwọn ǹkan mìíran ti wọ́n ti ṣe sẹ́yìn.
Níwọ̀n ìgbà tí a ti dá mi lẹ́bi,kí ni mo tún ń ṣe wahala lásán fún?
Ọba dọwọ́ bojú, ó ń sọkún, ó sì ń kígbe sókè pé, “Ọmọ mi!
Ta ni ó mọ ohun tí ó dára fún eniyan láàrin ìgbà kúkúrú, tí kò ní ìtumọ̀, tí ó níí gbé láyé, àkókò tí ó dàbí òjìji tí ó ń kọjá lọ.
Ọ̀nà tó fi le è mọ gbájúẹ̀ babaláwo - Ẹlẹ́buìbọn Ọwọ àjọ NYSC tẹ ayédèrú àgùnbánirọ̀ 65 Nàìjíríà náà dá a padà!
Àwọn olórí ogun Joaṣi ọba dìtẹ̀ mọ́ ọn, wọ́n sì pa á ní ilẹ̀ Milo ní ọ̀nà tí ó lọ sí Sila.
O ṣàlàyé pé Baba yí tí òun pade ni Yewá lè ma je Bàbá to bi òun ṣùgbọ́n òun mo iyì àgbà.
Ó ní òun yóò ṣe èyí bí ìgbìmọ̀ amúṣẹ́yá ẹgbẹ́ náà bá kọ̀ láti kéde olùdíje tí òun fà sílẹ̀, Abdul-Kabir Adekunle Akinlade.
Awon to wa ninu igbimo naa ni awon eniyan pataki lawujo bi i awon olori elesin,awon obinrin pataki, awon oba , lara won  tun ni a ti ri aare ana ogagun Abdulsalam Abubakar, Bisobu Mathew Kukah, ati Alhaji Sa’ad Abubakar III, Sultan tiSokoto.
Paul sọ pé àwọn ẹlẹ́wọ̀n yóòkù maa n ran òun lọ́wọ́ láti tọ́jú bàbá rẹ̀ nígbà mi i.
OLUWA yóo ṣe ìdájọ́ gbogbo ayé,yóo fún ọba rẹ̀ lágbára,yóo sì fún ẹni tí ó yàn ní ìṣẹ́gun.
Ó tún wí fún wọn pé òun ni Josẹfu arakunrin wọn, tí wọ́n tà sí Ijipti.
Ọrọ yii si lo bii ninu to bẹẹ, to fi ni oun lee pa Leycon, nitori isẹlẹ to n ja nilẹ naa.
O ni ibọn yii lo kọ si oun ni ọna abajade si popona ila Oorun Ọmọbabinrin ilẹ naa.
o dara julo sikeji lagbaye(World number 2), ti pegede sipele ti o kan ninu
” Bí o kò bá ṣe àgbèrè ṣugbọn o paniyan, o ti di arúfin.
Nigba ti yoo fi di ipari osu Kini ọdun yi, Hong Kong gẹgẹ bi apẹrẹ ti ni ki wọn ti gbogbo ile iwe ti wọnsi ti wọgile gbogbo ayẹyẹ eleyi ti yoo u ki awọn eeyan ma darapọ mọ ara wọn.
Ẹgbẹ alatako Iye awọn to ti si wi pe awọn fe du Aarẹ to je alatako ti pọ̀ diẹ̀.
Tammy ta Norwich pa mọ́ lé, bí Chelsea ti gbéra Lẹyin ọ rẹyin, ẹrin gba ẹkẹ akọnimọọgba Chelsea, Frank Lampard lẹyin ti ẹgbẹ agbabọọlu Chelsea gbegba oroke fun igba akọkọ lati igba to ti gori aleefa gẹgẹ bi akọnimọọgba tuntun ni papa iṣere Stamford Bridge.
Ẹ óo sì mọ̀ pé èmi ni OLUWA nígbà tí òkú wọn bá sùn lọ káàkiri láàrin àwọn ère oriṣa wọn yíká pẹpẹ ìrúbọ wọn, ní gbogbo ibi ìrúbọ ati lórí gbogbo òkè ńlá, lábẹ́ gbogbo igi tútù ati gbogbo igi oaku eléwé tútù; ní gbogbo ibi tí wọ́n ti ń rú ẹbọ olóòórùn dídùn sí àwọn oriṣa wọn.
Iléeṣẹ́ Ọmọogun ní òun yóò bẹ́ ‘speaker’ lórí ìṣẹ̀lẹ̀ Lekki ṣùgbọ́n.
Lekki Shooting: UN, Biden, Clinton àtàwọn gbajúmọ̀ lágbááyé tó korò ojú sí ípànìyàn Lekki
Buhari ba osinbajo sayẹyẹ igbeyawo ọmọ rẹ Ayẹyẹ igbeyawo melo ni Aarẹ Buhari lọ?
N óo láyọ̀ ninu Jerusalẹmu,inú mi óo sì máa dùn sí àwọn eniyan mi.
’’ Aare  Muhammadu Buhari soro yii lojo Isegun lasiko
Iko agbaboolu orile-ede France fagbahan Uruguay pelu ami-ayo meji sodo, ti Belgium si fagbahan orile-ede Brazil pelu ami-ayo meji sookan ninu ifigagbaga ipele keta lati pegede sinu ipele keji.
 O ni:”A ti foju wina ewu seyin ti opolopo agbe si ti gbemi mi lataari ogun boko haram to so awon miran di asatipo nile baba nla won.
Ìwọ ọmọ mi, má ṣe gbàgbé òótọ́-inú, ó lágbára ju òògùn lọ, òun ni àáké tí ènìyàn fi ń bẹ́ rìkíṣí , òun ni pàṣán tí ènìyàn fi ń so ìlara kọ́ sí orí igi.
Saulu jẹ́ bíi ọmọ ọgbọ̀n ọdún.
O ni gbogbo ahesọ ọrọ bẹẹ lo wa ki awọn eeyan lee maa bẹru ọba ati paapaa ki wọn le maa wo o pe hee, Ipalara to wa fun ilu ti ọba ba gba ẹsin to yatọ si ilana iṣẹmbaye Oríṣun àwòrán, Alaafin Oyo Oba Adeyemi Lamidi III Gẹgẹ bi baba Ifayẹmi ẹlẹbuibọn ṣe sọ, ipalara wa fun ilu ati Ọba gan to jẹ laifi ti ilana ijọba ni ilẹ Yoruba ṣe.
Gomina Makinde tu awọn igbimọ iṣejọba ibilẹ ni ipinlẹ naa ka lori ẹsun pe ilana ti wọn fi de ipo tako ofin.
Àwọn aláìní ń rìn kiri ní ìhòòhò láìrí aṣọ wọ̀;ebi ń pa wọ́n, bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé ìtí ọkà ni wọ́n rù.
Awọn nnkan amunudun yii gaan ni gbogbo eniyan ti nduro de gẹgẹ bi awọn akopa ti wọn ti yan laarin ọpọlọpọ awọn ti wọn jọ forukọ silẹ ti awọn kan si ti ja yoo tun maa figagbaga ninu ile kan naa pẹlu oniruuru idanwo bii ere ojukoroju ti wọn gbe ka iwaju wọn.
Gẹgẹ bi agbẹnusọ fun ajọ EFCC, Tony Orilade, to gbẹnu Magu sọrọ ti wi, ajọ naa ti n se afikun aayan ri lati ri daju pe oun sọiye eeyan ti yoo lọ swọn ni 2019 di ilọpo meji awọn eeyan ti ajọ naa ran lẹwọn lọdun to kọja.
lodun 2015 ṣugbọn nigbẹyin, ko bọ sii fun un.
Ki lo ba ti iroyin o ku, ko ku jade.
Ní òru ọjọ́ náà, Ọlọrun tọ Balaamu wá, ó ní, “Bí ó bá jẹ́ pé àwọn ọkunrin wọnyi wá bẹ̀ ọ́ pé kí o bá wọn lọ, máa bá wọn lọ, ṣugbọn ohun tí mo bá sọ fún ọ ni o gbọdọ̀ ṣe.
Nítorí náà, nígbà tí a ti jí i dìde kúrò ninu òkú, àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ ranti pé ó ti sọ èyí fún wọn, wọ́n wá gba Ìwé Mímọ́ gbọ́ ati ọ̀rọ̀ tí Jesu ti sọ.
Oríṣun àwòrán, @Mr__Calox Àkọlé àwòrán, Ajọdun Dubar nilu Ilọrin Oríṣun àwòrán, @bukolasaraki Àkọlé àwòrán, Ajọdun Dubar nilu Ilọrin Gẹgẹ bi ẹ ti ṣe mọ pe ohun kan ti kii gbẹyin nibi ajọdun durba ni ẹṣin gigun; eyi naa ko si gbẹyin nibi ajọdun Dubar ilu Ilọrin.
Lọ̀dun 2015 ní wọn mú Zakzaky nínú ikọlu kan ti ọ̀ọ́dúnrún àwọn ọmọ ẹgbẹ́ rẹ ti pàdánù ẹ́mi wọn.
Gbogbo awọn to pa Ọlayẹmi Tunde ni Ipao Ekiti lana, yala wọn jẹ darandaran tabi ohun yoo wu ti wọn lee jẹ, ọwọ ofin yoo tẹ wọn wọn o si jiya to tọ niwaju ofin.
31 Àti pé nípa àwọn ìjìnlẹ̀ ẹ̀kọ́ ni ìwọ kí yíò sọ̀rọ̀, ṣùgbọ́n ìwọ yío kéde ironúpìwàdà àti ìgbàgbọ́ nínú Olùgbàlà, àti ìdárìjì ẹ̀ṣẹ̀ nípa ìrìbọmi, àti nípa iná, bẹ́ẹ̀ni, àní Ẹ̀mí Mímọ́.
OLUWA fẹ́ràn òdodo ati ẹ̀tọ́;ayé kún fún ìfẹ́ rẹ̀ tí kì í yẹ̀.
Ajo WHO ni ko si ipolongo to peye fun gbigba abere ajesara mo ni agbegbe yii ni eyi to n di nla moa won osise eleto ilera lowo.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Bisi Alimi: Ìyà mi rò pé n kò leè ṣe ni àmọ́ n kò ní ìfẹ́ abo ni mo ṣe fẹ́ akọ 'Nibayi, eniyan mẹjọ ti ku ninu ẹbi naa, nitori bi ina ṣe jo wọn.
O óo sọ fún wọn pé, ‘Ẹ̀yin ni orílẹ̀-èdè tí kò gbọ́ ohùn OLUWA Ọlọrun rẹ̀, tí kò sì gbọ́ ìbáwí.
Ki lawọn eeyan sọ loju opo Twitter Iriwisi ṣe ọtọọtọ lori ọrọ rẹ ti a mọ pupọ lo kan sara si i pe o ṣe iwaasu to m'ọgbọn wa.
Nígbà tí o bá dé ibẹ̀, bèèrè Jehu, ọmọ Jehoṣafati, ọmọ Nimṣi; mú un wọ yàrá kan lọ kúrò láàrin àwọn ẹgbẹ́ rẹ̀.
Amọ, ko si ẹni to di wọn lọwọ lati ka iwe tabi jẹ olowo ati ọlọrọ ni awujọ.
Bi o tilẹ jẹ wi pe ko si ẹni to ms ibi ti iroyin naa ti ṣẹ wa nitori pe lẹyin o rẹyin igbeyawo naa ko waye, Aisha ni ko si eyikeyi ninu oun ati ọkọ oun to mọ ohunkohun nipa iroyin naa.
Nǹkankan kù díẹ̀ kí ó tó nípa igbagbọ yín.
Ibeere kan ti dokita rẹ bi i nipa nkan oṣu lo jẹ ki Julian Peter to ti pe ẹni ọdun mọkandinlọgbọn o mọ pe wọn ko bi oun pẹlu ile ọmọ, ẹnu ọna ile ọmọ, ati oju ara obinrin.
Awọn alejo mẹtẹẹta to wa lori eto jẹ awọn ti iṣẹlẹ June 12 ṣoju wọn koro.
Ninu oro adari iko EFF naa, Julius Malema pe akiyesi oro ile naa nigba ti Jan van Riebeeck de si ilu Cape ni odun1652 , nipase ijakule egbe oselu ANC lati  tun  awon eniyan ti won wa lewon sile ni ilu naa.
“Mú hapu, kí o máa káàkiri ààrin ìlú,ìwọ aṣẹ́wó, ẹni ìgbàgbé.
Olatunji da ilumọọka lẹyin to ṣe awo orin mẹtadinlogun pẹlu awo orin to kọkọ ṣe lọdun 1959, eyi to pe akọle rẹ ni Drums of Passion""."
7 358713 Orilẹede Switzerland 5349 62.
Yatọ si orileede Naijiria,pupọ awọn orileede nilẹ Asia bi India,Bangladesh ati Singapore lawọn eeyan ti ma n wọ kẹẹkẹ ẹlẹsẹmẹta yii.
Abenugan ile igbimo asofin, Bukola Saraki lo siso loju eegun pelu adura lati fi bere ipade naa laago mokanla owurọ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Koko iroyin: Lai Mohammed fèsì sí ọrọ Obasanjo, Ìjọ́ba ìpínlẹ̀ Ògùn kéde ìsinmi ní June 12 9 Òkùdu 2018 Èyí ni àkójọpọ̀ àwọn ìròyìn tí tòní Lai Mohammed: Ọbasanjọ, bí ìwo bá ṣé réré, Ara kì yóò yà ọ?
Sise agbekale Ile-iwe giga fafiti naa yoo wa ni ibamu pelu ofin ati ilana  agbekale ile-iwe giga todun 2010, ni eyi ti akeko yoo ni eto si iwe-eri leyin gbogbo saa re ti o ba lo lati fi keeko.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Swearing in 2019: Àga, àsìá, àtìbàbà àti ẹní àtẹ́ẹ̀ká ti wà nílẹ̀ fún ìbúra 28 Èbibi 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 29 Èbibi 2019 Ọjọru ọjọ Kọkandinlọgbọn o'su Karun ọdun 2019 ni ayẹyẹ ibura yoo waye Fun aarẹ Muhammadu Buhari ni ilu Abuja.
10) Osemawe ti ìlú Ondo - Ọba Adekolurejo Jimosun Keji: Ọba naa jẹ laarin ọdun 1918 si 1925 ti wọn le e kuro nilu lọ si Ilé-Ifẹ̀.
 Ìwádìí fi hàn pé ó tilè bi òkan nínú àwon omo rè tí ń je tòkunbò si ìlú oba , a gbó wí pé isé èsé kíkàn ni òdómokùnrin òhún ń se .
O salaye pe, orile-ede Nigeria ti fowo si olokan-o-jokan iew adehun lati bi odun pipe seyin, idi niyii ti o fi se Pataki lati se atunse si awon iwe adehun naa lati le je ki orile-ede Nigeria ni ibasepo to yanranti.
Ilu Goma ti n gbaradi fun
OLUWA sì sọ fún un pé, 
Ọga ọlọpa nipinlẹ Ọsun tun fi kun-un wipe, ileesẹ ọlọpa ti n se eto ilana tuntun fun igbogunti iwa ọdaran nipinlẹ naa, eyi to ni yoo wa egbo dẹkun fun gbogbo iwa awọn kọlọransi lawujọ nibẹ.
Dele Momoodu, lásìkò to ń bá BBC Yoruba sọ̀rọ̀ ṣàlàyé pé, kí ìjọba tí àwọn èèyàn mọle kọ ní ọ̀nà àbáyọ kan ṣoṣo tó wà láti dènà àrùn Coronavirus.
Oríṣun àwòrán, Twitter/gboyega akosile Àkọlé àwòrán, Gomina Sanwo-Olu mu wọn lọ si diẹ lara awọn dukia ijọba ati aladani ti awọn janduku dana sun.
" O ni ara awọn ohun rere to farahan lasiko eto idibo apapọ naa ni omilẹgbẹ awọn ọdọ to jade dije ti wọn si gbiyanju kọja bi awọn eeyan ati onwoye ṣe lero ṣaaju idibo naa lọ.
Oríṣun àwòrán, AfricanDrumFestival Àkọlé àwòrán, Aṣa lo n siwaju ẹsin nitori aṣa lagbara ju ẹsin lọ Aṣa lo n siwaju ẹsin nitori aṣa lagbara ju ẹsin lọ.
Awọn ololufẹ naa ti wọn ko ju ọmọ ọgbọn ọdun lọ wa lati ilu Okija ni ipinlẹ Anambra, nibi ti Ilẹ Gẹẹsi ti fofin de owo ẹru ni ọdun 1900s.
Láì tíì ṣe ibura wolẹ́ sí ilé ìjọba, o ti n pinnu láti sàn owó oṣù oṣiṣẹ láàrín oṣù mẹfa.
 Bakan naa o tun fi anfaani sile fun osise lati pe ile-ise re lejo, bi
Ẹ̀yin ni kí ẹ mójútó ọ̀ràn náà.
 Àwọn ará ìlú Àkúrẹ ́ wá gba Àjàpadà gẹ ́ gẹ ́ bí akíkanjú ọdẹ tí yóò lè ní agbára láti gba ará ìlú rẹ ̀ ní ọjọ ́ mìíràn tí ogun tàbí ọ ̀ tẹ ̀ bá dé .
Amotekun: Ìjọba ìpínlẹ̀ Oyo, Ogun, Ondo ní ìyókù kù sí ọwọ́ asòfin ìpínlẹ̀
Ìjọba ìpínlẹ̀ Oyo tí bẹ àwọn oníṣẹ̀gùn lọ́wẹ̀ lórí ààrùn Coronavirus Ọọni, Aláàfin, Ojisẹ Ọlọ́run àti oniṣẹ ìwádìí fi Ògún gbari pé òògùn ìbílẹ̀ le wo Covid-19 Iṣẹ́ amòfin tí mo kọ́ ni Fáṣítì kò mú owó wọlé fún mi bíi iṣẹ́ tíátà - Femi Adebayo Coronavirus: Kíni àwọn àmì tuntun tó n fihàn?
Oro abuku ti o so si awon omo ile igbimo asofin naa, ni won fi mule pe oro ohun ti gbode kan bayii.
Bẹẹ si ni bii ọgọrun lo ti bajẹ ninu wọn.
A sì fẹ́ mọ ìtumọ̀ rẹ̀.
Kokoro arun HIV ko tii kuro nilẹ - a tun ti n ba ajakalẹ arun Coronavirus yi."
Kojo oni to pari ni, aare Buhari yoo maa se ipade po pelu awon egbe to ni i se pelu ohun ogbin,ise agbe , ohun osin abiye ati  eranko.
ti apapo ibo egbe oselu PDP si je(337,377).
Aṣofin Bisi Yusuf, to n ṣoju ẹkun idibo Alimọṣọ kinni yii ninu Ile Igbimọ Aṣofin Ipinlẹ fi mulẹ pe Ile Igbimọ Aṣofin naa ti n gbe igbesẹ lori ọrọ yii;“Inu awa aṣofin ni Ipinlẹ Eko naa ko dun si bi idọti ṣe gbalẹ kan-an kaakiri ilu bayii.
Ṣugbọn awọn mii a gba mi niyanju wọn a si fun mi lowo.
@iam_damayor, nibẹ lo ti ni awọn ọkunrin n duro de awọn obinrin lati mọ bi wọn yoo ti se ayajọ Ma lo kọmu.
Mo tún bá wọn dá majẹmu pé n óo fi ilẹ̀ Kenaani fún wọn, ilẹ̀ tí wọ́n ti jẹ́ àlejò.
 Ó jẹ ́ olórí gbogbo ẹlẹ ́ sìn ìbílẹ ̀ tí a fún lágbạra láti ṣe ìrúbo sí olódùmarè àti àwọn orìṣà lórúko gbogbo ìran yorùbá ní àgbaye ní ìgbà Ọdún olójó .
 Ó lọ sí ilé-ẹ ̀ kọ ́ pọ ́ ọ ̀ lù mímọ ́ ní ayétòrò .
Mohammed Fawehinmi ni iyi ni to fi mu ki Aarẹ Buhari sọrọ pe oun mọ riri June 12, o tun yẹ Abiola si pẹlu oye GCFR lẹyin to ti doloogbe.
4) Burna Boy - Ye Àrà ọ̀tọ̀ inú orin tó jáde 'Ye' ti Burna gbé sita lọ́dún 2018 ní Nàìjíríà.
 ara káúntì ( county ) aberdeenshire ni ó wà tẹ ́ lẹ ̀ .
Nígbà tí a óo sì fi ṣíkọ̀, wọ́n fún wa ní àwọn nǹkan tí a lè nílò lọ́nà.
Ẹgbẹ Orange Movement ti bẹrẹ si ni pariwo ''O to gẹ'' iru orin ti wọn kọ abẹnugan ile aṣofin agba l'Abuja, Bukola Saraki ko to fidi rẹmi ninu ibo ile aṣofin agba ọjọ kẹtalelogun oṣu Keji.
Tí a fiṣọwọ́ ní 10:1910:19 Covid-19: Ilé aṣojú-ṣòfin l'Abuja dábàá kí ìjọba sún ìwọlé àwọn akẹ́kọ̀ọ́ síwájú pẹ̀lú oṣù mẹ́ta Alaga ile lori eto ẹkọ, Ọjọgbọn Julius Ihonvbere lo ṣi aṣọ loju eegun ọrọ yii ninu atẹjade kan to fi sita lorukọ igbimọ rẹ.
Makurdi Church theft: Àga oníke mẹ́wàá ní wọ́n kọ́kọ́ ni Joseph jí tó fi di èrò ẹ̀wọ̀n ní NASME Barracks ní Benue
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Osinbajo: Ààrẹ Buhari rán mi láti wá àbáyọ sí ààbò tó mẹ́hẹ 21 Agẹmo 2019 Oríṣun àwòrán, Google Àkọlé àwòrán, Ọ̀pọ̀lọ̀pọ̀ ènìyàn ló ń jíròrò láti wá ọ̀nà àbáyọ sí ètò ààbò tó mẹ́hẹ ní Naijiria, pàápàá ní Ìwọ-òòrùn Naijiria.
Google bẹ̀rẹ̀ sí lo ohùn Nàìjíríà lórí ẹ̀rọ̀ ajúwe ọ̀nà Ààrẹ orílẹ̀èdè Tunisia dágbére fáyé Lẹyin oṣu diẹ ni gomina wa ran awọn oluranlọwọ rẹ lati tun lọ bẹ Daniel wo nile iwe ki wọn si mu u wa si ọfiisi oun.
ọ̀tọ̀ ni àwọn ẹranko jókòó sí tí wọ́n ti ń jẹun nítoiríìdí wọn gongo gongo kò lè jókòó lé orí àga.
Unai Emery: Àwọn olólùfẹ́ Arsenal ní Emery gbọdọ̀ fipò rẹ̀ sílẹ̀ dandan
Asofin Albert Akpan ninu oro afikun tire figbagbo re han pe ida ogorin ninu ogorun-un awon to n gbe nigberiko nilo owo wewe yii ki won le maa ri karakata won se pelu irorun, o fi aidunnu re han lori owongogo owo woniyii lasiko yii.
Amọ, Minisita fọrọ abele orilẹede naa wipe, isẹ awọn ile-isẹ amohunmaworan naa tapa si ofin to de aabo orilẹede naa.
Ọlọrun jẹ́rìí sí ìwà rẹ̀ nígbà tí ó sọ pé, ‘Mo rí i pé Dafidi ọmọ Jese jẹ́ ẹni tí ọkàn mi ń fẹ́, ẹni tí yóo ṣe ohun gbogbo bí mo ti fẹ́.
Jẹ́ kí ìwà èké ati irọ́ pípa jìnnà sí mi,má jẹ́ kí n talaka, má sì jẹ́ kí n di ọlọ́rọ̀,fún mi ní ìwọ̀nba oúnjẹ tí ó tó mi jẹ,
Sugbọn iyawo oloogbe naa Lovina salaye fun ile isẹ iroyin Channels pe lọjọru pe ti se ayewo aarun covid -19 ti esi ayẹwo naa si jade lọjọru sugbọn ọsan ọjọ naa lo dagbere f'aye.
17 Sẹ́rẹ́ 2019 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Gomina Abdullahi Umar Ganduje to je gomina ipinle Kano to gbalejo apero todun yii ninu oro iside tire soro kikun lori ilana ofin ominira lati soro nibikibi to wa ninu abadofin ile Naijiria.
Àwọn ìròyìn mìíràn tí ẹ lè nífẹ̀ẹ́ si: Bàálù to gbe Yẹmi Oṣinbajo já lulẹ̀ ní Kabba nípìnlẹ̀ Kogi Àríyànjiyàn Osinbajo àti PDP Ọsinbajo sàbẹ̀wò sílé tó dàwó ní Abuja Kíni iyatọ tó wà láàrin FSARS àti SARS?
Gege bi akonimoogba iko Valencia,“Esi yii dara pupo, sugbon ifigagbaga ese keji seese ko gba ona mi yo, a gbodo gbaradi lopolopo, nitori atileyin awon ololufe Arsenal ma tun ran  won lowo.
A ṣì ń ṣèwádìí lọ́wọ́ lórí àwọn t'ọ́ta ìbọn pa lọ́jọ́ ọdún Eid n'Ibadan - Ọlọ́pàá Coronavirus kò rí ju èèyàn 304 tó forí kó o lọ lọ́jọ́ àìkú Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Oyo Schools: Akẹ́kọ̀ọ́ Fásitì, Poly wà nílé, kí ló mú ti alákọ̀ọ́bẹ̀rẹ̀, girama wà níta?
Ẹ óo máa pa ọkà títí tí èso àjàrà yóo fi tó ká, ẹ óo sì máa ká èso àjàrà lọ́wọ́, títí àwọn nǹkan oko yóo fi tó gbìn.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ìpanu ‘Cheese ball’ ni wọ́n fi jí Ikimot gbé, àmọ́ ó padà sílé lẹ́yìn ọdún márùn-ún ìfipábánilòpọ̀: Má dákẹ́ - Oluwaseun Wọ́n ta ère Ọ̀ṣun Osogbo sí Togo - Bàbá Ọṣun figbe ta Dangote: Mo ti gbà $10m ri ní bánkì kí n lè mọ bí o tí ṣé rí lójú Iroyin ko to afojuba ninu fidio yii, nibi ti ẹrin yoo ti pa yin nipa oniruuru ami tawọn araalu fun ọrọ naa.
Àkọlé àwòrán, Àwòrán láti ìpàdé ìtagbangba BBC Yorùba ní ìpínlẹ̀ Ọṣun Àkọlé àwòrán, Akinbade: ''Due Process'' ni awa yoo fi se ijọba Àkọlé àwòrán, Awọn ọdọ se pataki fun isejoba wa Àwọn Olùdíje sípò gómìnà l'Osun naa tun se fọ̀rọ̀wérọ̀ lórí àlàkalẹ̀ ètò tí wọ́n ní fún ará ìlù ati nnkan miiran.
Nitori èyi èrò pọ̀ jù ilẹ̀ lọ nitori omi ló yi Èkó ká.
Wo inú ihò tí Adewura kó sí nínú òjò l'Eko Kí ló ṣe ikú pa Adewura Latifat Bello lẹ́yìn ọ̀sẹ̀ méjì tí wọ́n ń wá a?
Nítorí mo wí fun yín pé ohun gbogbo tí a ti kọ sílẹ̀ nípa mi níláti ṣẹ, pé, ‘A kà á kún àwọn arúfin.
Alaga naa ni ise yii ti di ajose nitori pea won loba loba paapaa fowosiwe ki agbe kookan to ri owo yiya naa gba lowo ijoba ni eyi to fihan pea won oniduro agbe naa yoo ba won mojuto lilo owo naa daadaa ati aown ohun eelo bii opa omi irinle, afonko, kemikaa lorisiirisii ati ajile pelu odiwon bi oko onikaluku ba se tobi to pelu eto dida owo naa pada pelu iresi lojo iwaju.
I was sad because we will miss his contribution to the building of a new world of his dream and an Africa of our joint dream but I am grateful to God for his life well spent in the service of God and humanity.
Èyí jẹyọ nínú àtẹ̀jáde kan tí akọ̀wé fún ìjọba ìpínlẹ̀ nàá, Taiwo Adeoluwa fọwọ́ sí.
Eto idibo naa to yẹ ko waye l'ọjọ keji, oṣu Kọkanla, ọdun 2019, ni yoo waye bayii lọjọ kẹrindinlogun, oṣu Kọkanla, 2019.
Titi di asiko yii, a ko tii gbọ ọrọ lẹnu Toyosi Adesanya, ti oun ati Juwọn dijọ rinrinajo , ti a ko si lee sọ iru ipo ti oun gan wa bayii, amọ bo ba se jẹ, a mu ẹkunrẹrẹ iroyin naa wa fun yin.
Mo ṣaa fẹ mọ ẹni to n jẹ Michelle Damsen yii, mo tun wadii kiri .
Ọmọ ile gbọdọ figba gbogbo maa ṣe ohun to yẹ nigboro ki awọn ara ilu le tubọ nigbagbọ ninu igbimọ ile aṣofin sii.
Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Yollywood: Lágbo tíátà lọ́sẹ̀ yìí, Toyin Abraham fi orin yẹ́ Iyabo Ojo sí níbi ìsìnkú ìyá rẹ̀, Òṣùpá fíi ìkíni ọjọ́ ìbí ránṣẹ́ sí Pasuma28 Bélú 2020 Fatai Rolling Dollar: Baba 70 jayé kọjá 70 kó tó dágbére fáyé pé ó dìgbóṣe!
9 266816 Orilẹede Lebanon 1825 26.
Àti pé ó yẹ kí àjọ INEC dá dúró láì gba àṣẹ lọ́wọ́ ẹnikẹ́ni.
Adájọ́ Salman sún ìgbẹ́jọ́ sí ọjọ́ kẹẹdọgbọn osùn kẹrin ọdún fún tí tẹ sìwájú ẹjọ́ náà.
Eto ọhun ti wọn da pe ni Project Libra eleyi ti facebook n gbero rẹ yii yoo wa bọ si gbangba ni oṣu kejila ọdun.
Wunmi Toriola Ijafara lewu lawọn Yoruba ma n wi.
”Obinrin náà ní, “Gbọ́ ọ̀rọ̀ tí èmi, iranṣẹbinrin rẹ fẹ́ sọ.
 aláàfin dada tí òpìtàn fẹnu bà pé ó jẹ ọba ní Ọ ̀ yọ ́ da ìtàn rú .
Bakan naa lo sisọ loju rẹ pe awọn asofin mẹrinla lo fi ọwọ siwe pe ki wọn rọ igbakeji gomina naa loye, ninu asofin mẹrindinlọgbọn to wa nibẹ.
Àwọn tí wọ́n wà lọ́dọ̀ Dafidi sọ fún un pé, “Òní gan-an ni ọjọ́ tí OLUWA ti sọ fún ọ nípa rẹ̀, pé òun yóo fi ọ̀tá rẹ lé ọ lọ́wọ́, kí o lè ṣe é bí ó ti wù ọ́.
Zimbabwe: Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ọkunrin ati obinrin ko le fa ara wọn lọwọ lawọn ilu kan Ni ile iwe giga fasiti lorilẹ-ede Zimbabwe, o ṣeeṣe ki wọn le awọn akẹkọọ ti wọn ba n fẹnu kora wọn lẹnu tabi ti wọn ba jọ ni ajọṣepọ.
Lizzy, ẹni to n dupẹ lọwọ Ọlọrun fun ile awodamiẹnu naa tun fikun un pe, bi ile naa ko tilẹ to ile idana ẹlomiran, sibẹ oun ki iya oun to ti jade laye ku oriire, pe oun kọ ile naa.
Oríṣun àwòrán, Wumi Toriola Ẹ̀wẹ̀, Seyi Edun nítirẹ sọ lójú òpó tirẹ̀ pé, nínú ohun gbogbo kí a ṣáà maa dúpẹ́ ni, nítrori idí èyí ni ọ̀ps àwọn olúlufẹ́ tirẹ̀ bẹ̀rẹ̀ ni ni pẹ̀tu síi lọ́kàn láti kí eti ikún si ohun gbogbo ti Wumi Toriola ń ṣọ Oríṣun àwòrán, i-am-shai/Instagram Báyìí ni ọ̀rọ̀ ìyànjú tí àwọn olúlùfẹ́ Seyi náà ṣe lọ Títí di àsìkò yìí, àwọn ọ̀rẹ́ méjì yiìí kò tí sàlàyé ǹkan to fa ìdí ìjà wọn Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Wọn mẹnuba ewu to rọ mọ irinajo yii nitori ko si ẹwu idaabobo rara ṣugbọn pataki ẹkọ fawọn ọmọ wọn lo mu wọn moju kuro.
O ni awọ okuta pẹlu bọtiini olododo goolu gẹgẹ bi o ṣe ṣalaye.
Iná orí àti iná aṣọ pẹ̀lú ogunlọ́gọ̀ idun ti ṣe ọ̀nà sí ara wọn.
Bakanaa Aarẹ Naijiria sọ wi pe yiyan ti wọn yan Aarẹ Xi s'afihan igbagbọ t'awọ eeyan orilẹede naa ni si.
Ikọ SARS bẹrẹ ni ọdun 1984 lati gbogun ti gulegule awọn adigunjale lorilẹ-ede Naijiria.
oro to so keyin lori ero ayelujara Twitter rẹ re e.
Bí Buhari kò bá múra, ẹsẹ̀ ìjọba rẹ̀ ń mì- Àsọtẹ́lẹ̀ Mbaka Ṣé lóòtọ́ọ́ ni Ọba Rilwan Akiolu padà sí ààfin lọ́jọ́ ọdún?
Isley ti pe ọgbọ̀n ọdún báyìí sùgbọ́n ara rẹ̀ kò fẹ́ gáánní ǹkan ọmọ ọkùnrin rárá, ìrírí yìí ń fa ọkàn rẹ̀ ya pẹ́rẹpẹ̀rẹ.
Kí ló ń ṣẹlẹ̀ n'ílé Aṣòfin Edo táwọn Ọlọ́pàá gba ìsàkóso ibẹ̀?
O ni lawọn orilẹede miran, oludije fun oṣelu le kuna, to ba kọ lati yọju sibi ijiroro iru eyi ti Buahri ati Atiku ko lọ.
Iye awọn eeyan to ṣẹṣẹ ko arun naa ni ipinlẹ kọọkan ree: Eko-118 Delta-84 Ebonyi-68 FCT-56 Plateau-39 Edo-29 Katsina-21 Imo-13 Ondo-12 Adamawa-11 Osun-8 Ogun-8 Rivers-6 Kano-5 Enugu-3 Bauchi-3 Akwa Ibom-3 Kogi-1 Oyo-1 Bayelsa-1 Oríṣun àwòrán, Getty Images Eeyan 779 tuntun mii lo ṣẹṣẹ lugbadi arun Coronavirus ni Naijiria.
 ilé-ẹ ̀ kọ ́ girama ni ó wà .
“Ilú-Oyinbo dára, ọ̀rẹ́ mi òtútù pọ̀”
Èyí ni àsìkò ti ifun ba ti ṣe àmúlò àswọn ounjẹ to kù ni àra.
Ṣé a lè rí iṣẹ́ ìyanu rẹ ninu òkùnkùn ikú?
"Ti a ba wo o daadaa, iwọnba perete ibo ni Cyril Ramaphosa fi bori nibi idibo si ipo alaga ẹgbẹ oselu naa to waye ni ọdun 2017.
Ọ̀pọ̀lọpọ̀ ẹni jàṅkàn jàṅkàn ló wá sí àṣeyẹ yìí; àwọn ẹ̀mí ọ̀run olόkìkí sì wá pẹ̀lú.
Bí mo ti gbé ojú sókè ni mo rí àwọn obinrin meji tí wọn ń fi tagbára tagbára fò bọ̀, ìyẹ́ apá wọn dàbí ìyẹ́ ẹyẹ àkọ̀.
Orilẹede Egypt lo gbalejo idije naa bayii fun igba karun un.
Ẹlẹsẹ ayo Tammy Abraham lo gba mii wọ le fun Chelsea eleyi to jẹ ẹlẹẹkeji rẹ ninu ifẹsẹwọnsẹ naa.
Primate Ayodele gẹgẹ bi gbogbo eeyan ṣe maa n pe ni awọn iran mii ti ojiṣẹ Ọlọrun ba sọ, bo ṣe ri kọ ni ẹlomiran ṣe ma n tumọ rẹ lo fi ma n da bii pe ko wa si imuṣẹ.
Ẹ gbọdọ̀ dá a pada fún un ní alẹ́, kí ó lè rí aṣọ fi bora sùn, kí ó lè súre fun yín.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Irokotọla: Báwo ló ṣe rọrùn láti fi àmì sí ọ̀rọ̀ yìí, ‘Irokotọla’ *Oṣu kẹsan an, ọdun 2007: Minisita feto isuna lọ́dún 2007, Nenadi Usman náà tún kéde pé, Nàìjíríà tún ti rí bílíọ̀nù méjì àti àbọ̀ dọla ($2.
Wọ́n gbé Àpótí Majẹmu náà jáde láti ilé Abinadabu, wọ́n gbé e lé orí kẹ̀kẹ́ titun.
Ohun ti wa fi ranṣẹ si ''32327'' ni ''WAEC*ExamNo*PIN*ExamYear.
Ibukun ni ìjọba tí ń bọ̀,ìjọba Dafidi baba ńlá wa.
'Ìbí kò ju ìbí, Èèyàn bíi tiyín ni àfín, ẹ dẹ́kun dídẹ́yẹsí àfín'
Ẹ ké pè mí ní ọjọ́ ìṣòro;n óo gbà yín, ẹ óo sì yìn mí lógo.
Ọmọ mi, gbọ́n, kí o sì mú inú mi dùn,kí n lè rí ẹnu dá àwọn tí wọn ń pẹ̀gàn mi lóhùn.
Wọ́n yóò sì maa san mílíọ̀nù mẹ́jọ náírà lati sọ ìwé àṣẹ̀ wọ́n dọ̀tun lọ́dọọdún.
Itan yii tun kọ wa pe ka ni ipinnu ọkan ati ọkan akin lati gbe orilẹede wa goke agba lai naani isoro yowu to le fẹ doju kọ wa.
gege bii akojanu fun igbimo ohun , ti won si yan asofin Adebisi Yusuff gege bii
 sùgbọ ́ n nínu ya , ọ ̀ nà méjì ni a lè gbà ṣe ìyísódì fọ ́ nrán ìhun tí a pẹ àkíyèsí sí .
Àwọn tí wọn ń sá fún ogun dúró ní ibi ààbò Heṣiboni,wọn kò lágbára mọ́,nítorí iná ṣẹ́ jáde láti Heṣiboniahọ́n iná sì yọ láàrin ilé Sihoni ọba;iná ti jó Moabu tíí ṣe adé àwọn ọmọ onídàrúdàpọ̀ ní àjórun,
N óo máa wà láàrin àwọn eniyan Israẹli, n óo sì máa jẹ́ Ọlọrun wọn.
 Asiko iyipada sir ere ti de ni Naijiria ti awon to beru Olorun ba jade wa dije fun ipo adari rere lawujo.
Akonimoogba agba iko Super Eagles, Gernot Rohr  fowo soya pe, asole tuntun fun iko Super Eagles Francis Uzoho yoo kopa daradara ninu idije boolu agbaye to n bo lona lorile-ede Russia.
Eyi gan-an lo ma n mu ki ọpọ wọn o ta ọja gbanjo, ki o ma ba bajẹ mọ wọn lọwọ.
6 4058 Orilẹede Rwanda 133 1.
Gideoni tún wí fún Ọlọrun pé, “Jọ̀wọ́, má jẹ́ kí inú bí ọ sí mi, ẹ̀ẹ̀kan ṣoṣo yìí ni ó kù tí mo fẹ́ sọ̀rọ̀; jọ̀wọ́ jẹ́ kí n tún dán kinní kan wò pẹlu irun aguntan yìí lẹ́ẹ̀kan sí i, jẹ́ kí gbogbo irun yìí gbẹ ṣugbọn kí ìrì sẹ̀ sí gbogbo ilẹ̀, kí ó sì tutù.
Oríṣun àwòrán, others Àkọlé àwòrán, léeṣẹ́ Ọlọ́pàá ṣetán láti bẹ̀rẹ̀ ètò ìgbanisíṣẹ́ lákọ̀tun Ìjọba ilẹ̀ Turkey yí ilé Ìṣẹ̀mbáyé tó ti lo ọdún 1,500 padà sí Mọ́ṣáláṣí Ìdí rèé tí a fí dá àwọn dókítà Nàìjíríà 58 tó fẹ́ lọ sí London padà- NIS Ó di gbéré!
A sì máa gbé e jókòó lórí ẹsẹ̀, bí ẹni pé ọmọ rẹ̀ gan-an ni.
Ó rò ninu ara rẹ̀ pé bí Esau bá dé ọ̀dọ̀ ìpín tí ó wà níwájú, tí ó bá sì pa wọ́n run, ìpín kan tí ó kù yóo sá àsálà.
  Àwòrán náà dàbíi orí abàmì ènìà kan tí ó ranjú kalẹ̀.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Aàrẹ Buhari buwọlu yíyí orùkó àwọn ibùdókọ ọkọ ojú ìrìn bíi ti Apapa padà fi sọrí àwọn èèkàn ìlú 'kò sí ẹ̀rí àrídájú níńu ọ̀rọ̀ Akpabio' Ìyá òòṣà fẹ̀sùn àjẹ́ kan ìyá ẹni ọdún 90, aráàlú bá sọ ọ́ lókò pa Nàìjíríà ṣí àwọn ilé ìwé padà; Ìdánwò WAEC á bẹrẹ lẹyìn ọdún Iléyá!
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ẹ̀mí sòfò nínú ìjàǹbá ọkọ̀ ní Ìlasamàjà ‘Kò tọ́ s'Ọbásanjọ́ láti tọ́ka sí oníjẹkújẹ’ ‘Jí foonu ọkọ rẹ̀ wò, kóo fi ẹ̀wọ̀n jura’ Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Wọn bimọ meji funra wọn ninu igbeyawo ọdun meji.
Ó kó àwọn ọkunrin tí wọ́n wà pẹlu rẹ̀, ó pín wọn sí ìsọ̀rí mẹta, wọ́n sì ba níbùba ninu pápá.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, SS3 ní mo wà báyìí, mo sì ti gba àmì ẹ̀yẹ̀ púpò nílé-lóko gẹ́gẹ́ bí onílù - Ayansike O fikun pe ọtalerugba o din mẹwa 250TL owo Turkey ni oun san lati fi se ayẹwo Coronavirus ọhun, eyi to to ẹgbẹrun mẹẹdogun naira wa ni Naijiria.
OLUWA kọjá níwájú rẹ̀, ó sì kéde orúkọ ara rẹ̀ báyìí pé, “OLUWA Ọlọrun aláàánú ati olóore, ẹni tí ó lọ́ra láti bínú, tí ó sì pọ̀ ní àánú ati òtítọ́.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Jude Chukwuka: Wọ́n yóò fi ojú ọlọgbọ́n wo akúrí tó bá sọ ojúlówó èdè Yorùbá Mo ti pe wọn nija loju aye,gbogbo wọn kan n lo anfaani pe ọkọ mi jẹ eeyan gidi ni, mo n pe wọn lati ko smọ wọn wa fun ayẹwo DNA.
CBN lori ẹrọ ikansiraẹni Twitter wọn bu ẹnu atẹ lu fọnran naa wi pe ko si owo to sọnu ni apo banki apapọ Naijiria.
PTF Nigeria Covid-19: Ààrẹ Buhari ní iṣẹ́ sí wà nílẹ̀ tí ìgbìmọ̀ yóò ṣé kí wọ́n sì wá níbẹ̀ dì 2021
Nítorí tí ìwọ ti fi OLUWA ṣe ààbò rẹ,o sì ti fi Ọ̀gá Ògo ṣe ibùgbé rẹ,
Ó ṣe ìwòsàn fún ọpọlọpọ àwọn tí ó ní oríṣìíríṣìí àìsàn, ó tún lé ẹ̀mí èṣù jáde.
Àwọn ọmọ mi sì ń bẹ lọ́dọ̀ yín.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ìhòhò ọmọlúàbí ni mo má a ń bá àwọn ọmọkùnrin mi wí - Elesho Onyeama, jọ̀ọ́ má bínú ìdẹ́yẹsí tá a ṣe torí pé o jẹ́ adúláwọ̀ - Ilé ẹ̀kọ́ Eton Abiola Ajimobi kò gbọdọ̀ kú, ẹ lọ wọlé àdúrà - APC Oyo pariwo Àlààyé rèé lórí ìdí ta fi gbé ìlẹ̀kùn olú iléeṣẹ́ APC tì pa l‘Abuja Ohun tí ọlọ́pàá ń ṣe rèé láti sàwárí àwọn ‘mùjẹ̀-mùjẹ̀’ ní Akinyele Wo bí ìpinu Amẹ́ríkà lórí gbígba físà ṣe kan ọ́ Diẹ nipa iroyin ọkọọkan wọn ree: Olori Rukayat Abiodun Ajoke Adeyemi: Oríṣun àwòrán, Abbey Adeyemi Facebook Olori Abiodun yii la lee pe ni iya awọn ewe ni aafin Ọyọ, eyi tums si alakoso awọn ayaba kekere to wa lẹyin rẹ.
nigba ti awọn aijinigbe ji gbe.
Ajọ WHO la awọn ọna abayọ to n ṣiṣẹ silẹ fun gbogbo eniyan to wa ninu ewu nini aisan iba.
Simiri, ọ̀kan ninu àwọn ọ̀gágun rẹ̀, alabojuto ìdajì àwọn kẹ̀kẹ́ ogun rẹ̀, ṣọ̀tẹ̀ sí i.
Ìgbéyàwó èmi àti Aláàfin kò pé, ṣùgbọ́n.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Alao Akala:Èmi àti Ajimọbi kò ṣe ìlérí kankan fún ara wa Awọn ologun naa ti gba ile isẹ redio ti ijọba ni aago mẹrin owurọ oni ti wọn si polongo ‘Ajọ National Restoration Council’ to ti gba ijọba.
 O ṣalaye pe akọsilẹ ni banki le ṣafihan ẹni to n gba owo lọwọ ara wọn, ati nkan to fi ṣe."
Super Eagles f'ìyẹ́ bo Carthage Eagles Tunisia mọ́ 'lẹ̀ Ta ni agbábọ́ọ̀lù tó fakọyọ jù lọ ní Afcon 2019?
Ṣugbọn bí olùṣọ́ bá rí i pé ogun ń bọ̀, tí kò bá fọn fèrè kí ó kìlọ̀ fún àwọn eniyan; bí ogun bá pa ẹnikẹ́ni ninu wọn, ẹni tí ogun pa yóo kú ninu ẹ̀ṣẹ̀ rẹ̀, ṣugbọn èmi OLUWA óo bèèrè ẹ̀jẹ̀ rẹ̀ lọ́wọ́ olùṣọ́ náà.
Ọwọ́ Ọlọrun ni ìgbàlà ati ògo mi wà;òun ni àpáta agbára mi ati ààbò mi.
ó wo ìhà ibi tí Sodomu ati Gomora wà, ati gbogbo àfonífojì náà, ó rí i pé gbogbo rẹ̀ ń yọ èéfín bí iná ìléru ńlá.
Ẹ fi ojú ọ̀nà sílẹ̀, ẹ yà kúrò lójú ọ̀nà,ẹ má sọ nípa Ẹni Mímọ́ Israẹli fún wa mọ́.
Ori ade yi ni niṣe ni iwọde naa mu idunnu ati ayọ wa si ọkan oun nitori awọn ọdọ ti taju pẹlu ohun kan ati afojusun kan naa.
Mercy Aigbe ṣègbéyàwó pẹ̀lú Lanre Gentry ní ọdún 2013 wọ́n sì ní ọmọ̀ méjì.
Lagos-48 Rivers-8 Kwara-6 Yobe-6 Katsina-5 FCT-3 Nasarawa-2 Plateau-1 Ogun-1 Kano-1 Osun-1 Pẹlu bi nnkan ṣe ri yii, ẹgbẹrun mẹtadinlaadọrin o le irinwo ati mejila (67,412) eeyan lo ti ko aarun naa lorilẹede Naijiria lati igba ti wọn ti kẹẹfin ẹni akọkọ to laarun naa ni Naijiria ni oṣu keji ọdun 2020.
Ogunjọbi ṣe akọwe ajọ NFF laarin ọdun 2002 si ọdun 2005, bẹẹ o jẹ ọmọ igbimọ alaṣẹ ajọ NFF laari ọdun 2006 ati 2010.
NUJ: Kò yẹ kí akọ̀ròyìn fi ìròyìn tú àsírí ológun fún Boko Haram
Ijọba ilẹ Gẹeṣi maa n gbẹsẹ le owo kowo ti wọn ba ri ni ilu Jersey, ijọba maa n ri owo bẹe bi owo ti awọn ọdaran ji ko.
Eeyan kan ree to n dẹgbẹ lori okun lai si lori ọkọ oju omi, Huu, nkan n bẹ Oríṣun àwòrán, AFP Àkọlé àwòrán, Ọlọrun ma jẹ ki itan yii fa ya, ki lo le to eyi.
Ẹni tó tún ga ju àwọn náà lọ tún ń ṣọ́ gbogbo wọn.
Fún àpẹẹrẹ; “Yàrá kékeré gba ogún ọ̀rẹ́, tí ÌFẸ́ bá wà láàárín wọn.
Ẹgbẹ oṣelu Minnesota Democratic Farmer-Labour Party, to jẹ isọmọgbe ẹgbẹ Democrat, lo ti fẹ ẹ dupo.
Igba gbogbo ni awon alase Turkey maa n mu awon omo ogun olote Islaamu satimole ti won ba fura si won ninu ise iwadii bayii won ko mo boya awon afurasi yii nii se pelu isele to sele nile ise ijoba embasi ile Amerika.
George Floyd: Àwọn ọlọ́pàá darapọ̀ mọ́ àwọn olùwọ́de lórílẹ̀èdè Amẹ́ríkà
Ni ọgba ileeṣẹ ijọba apapọ to n mojuto eto ẹkọ, nilu Abuja ni ipade naa yẹ kó ti waye.
    Èyí tí o tilẹ̀ wa bú wa yìí kò pa rárá, ó dàbí kùkùté, nígbà tí mo sì wo ẹnu rẹ̀ báyìí, ó dàbí ẹnu ọbọ, eyín méjì kan tí ó ká báyìí nínú eyin rẹ̀ mú kí eyín rẹ̀ rí kafuru àfi bí ẹni pé wọ́n ṣe ìlẹ̀kùn sí ẹnu abàmì ẹ̀dá náà.
“Ohunkohun tí ń fi àyà fà lórí ilẹ̀ ayé jẹ́ ìríra, ẹnikẹ́ni kò sì gbọdọ̀ jẹ ẹ́.
 baker bẹ ̀ rẹ ̀ ẹ ̀ kọ ́ rẹ ̀ ní ọdún 1876 ní national academy of design , níbi tí ó ti kọ ́ ẹ ̀ kó pẹ ̀ lú bierstadt àti de haas .
Nigeria 1 - 0 Burundi Ere pari Nigeria Burundi Bọọlu wa nikawọ mi 64.
Nígbà tí Dafidi ọba lọ bẹ̀ ẹ́ wò, Amnoni wí fún un pé, “Jọ̀wọ́, jẹ́ kí Tamari, arabinrin mi, wá ṣe àkàrà díẹ̀ lọ́dọ̀ mi níhìn-ín, níbi tí mo ti lè máa rí i, kí ó sì gbé e wá fún mi.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Covid-19 in Ondo: Dókítá mìí dágbére fáyé lẹ́yìn tó lùgbàdì àrùn Covid-19 ní Ondo 10 Sẹ́rẹ́ 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 9 Agẹmo 2020 Oríṣun àwòrán, Others Arun Covid-19 tun ti mu Dokita miran lọ nilu Akure.
’ rèé Afọnja, ẹni tó finú wénú ní Ilọrin, àmọ́ tó jẹ iwọ Ẹfunsetan Aniwura, obìnrin tó ju ọkùnrin lọ Ọ̀rọ̀ǹpọ̀tọ̀niyùn, Aláàfin obìnrin àkọ́kọ́ rèé, tó ní nǹkan ọkùnrin Èyí tí a wò jùlọ 5:03 Fídíò, Omolola Arohunmolase Welder: Mo ti fí iṣẹ́ 'Welder' gbayì láwùjọ, tó mo fi tọ́ ọmọ yanjú, Duration 5,039 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 5:39 Fídíò, Akomolede ati Asa lori BBC: Olùkọ́ Kikelomo Ogunboye tan ìmọ́lẹ̀ sí ìwà olè ọ̀gá ọlọ́pàá Audu gẹ́gẹ́ bí àwòkọ́ṣe àsìkò yìí, Duration 5,398 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 4:11 Fídíò, Oba Adeyeye Ogunwusi: Ojú mi ti rí lọ́pọ̀ lọpọ̀, ọ̀pọ̀ èèyàn ni kò tilẹ̀ gbàgbọ́ pé mo lè jọba- Ooni, Duration 4,117 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 4:43 Fídíò, Promise Akinlade: ọmọ ọdún mọ́kànlá tó ń fi ìlù dárà bíi àgbàlagbà sọ̀rọ̀ nípa tálẹ́ǹtì rẹ̀, Duration 4,437 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 0:59 Gbọ́, Ìsẹ̀lẹ̀ jákèjádò orílẹ̀èdè àgbáyé láàárín ìṣẹ́jú kan, Duration 0,59wákàtí 5 sẹ́yìn 7:03 Fídíò, Olumuyiwa Bolade Adedeji Military Bruitality: Bí arákùnrin onípèníjà ara tí sọ́jà lù ṣe dé, Duration 7,035 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 4:45 Fídíò, Yoruba Films: Ẹ̀ẹ́ bẹ̀ mi kúrò láyé ni, mi ò lè kú - Fadeyi Oloro, Duration 4,4526 Èrèlè 2020 2:48 Fídíò, Esther Ajayi: Èmi náà ti borí ìṣòro rí ló ń mu mi ṣojú àánú, Duration 2,481 Ògún 2019 6:08 Fídíò, Adebola Ademilua: Àìrísẹ́ ṣè lẹ́yìn ìwé kíkà ló sọ mi dí ìyá onírú, mo dúpẹ́ tèmi, Duration 6,0827 Bélú 2020 2:36 Fídíò, Sotitobire: Ìdájọ́ òdòdò ló fẹsẹ̀ múlẹ̀ lórí ọ̀rọ̀ Pásítọ̀ Sotitobire - Agbẹjọ́rò fún ìjọba, Duration 2,367 Ọ̀wàrà 2020 BBC News, Yorùbá Ìdí tí ẹ fi le è nígbàagbọ́ nínú ìròyìn BBC Ìlànà Lílò Nípa BBC Òfin Àṣírí Cookies Kàn sí.
Nítorí náà lákòókò yìí, ìyá mi mú bàbá mi lọ sí inú òkúta ní ilé wọn wọ́n sí dán an wò.
Jí pátá obìnrin ko jẹ́jọ́ ìpànìyàn - Dolapo Badmos Ìpàdé NLC àti ìjọ̀ba àpapọ̀ lórí owó osù tuntun forí ṣánpọ́n Mi ò tan mọ́ ààrẹ Buhari rárá o!
Ẹ dárúkọ àwọn tí ó wà nínú àwòrán yìí
Ní òwúrọ̀ kutukutu, nígbà tí iranṣẹ Eliṣa jáde sí ìta, ó rí i pé àwọn ọmọ ogun Siria ti yí ìlú náà po pẹlu ẹṣin ati àwọn kẹ̀kẹ́-ogun.
 Lati ọdun 2009 ni wọn ti wa ki wọn to ṣe igbeyawo losu keje ọdun.
Minisita fun imo sayensi ati ero lorile ede Naijiria Ogbonnaya Onu  lo so eleyii lasiko ti awon asofin to n mojuto imo sayensi ati ero  wa si ajo naa fun ayewo lori owo isuna ti ajo naa gba lori ise akanse.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ẹ wo àwọn ọmọ orílẹ̀-èdè Brazil tó wá síilẹ̀ Yorùbá láti mọ orisun wọn Orukọ awọn mẹrin naa ni Ndasule Moses lati aarin gbungbun ariwa, Lawan Mamman lati ila oorun ariwa, Gladanci Imam Najip lati iwọ oorun ariwa ati Adeleke Adebayo lati iwọ oorun guusu.
"O ni ""akókò yìí tó jẹ akoko ijiya ati iku Jesu Kristi kọ ni pe lai si ajinde Jesu kuro ninu oku, asan ni igbagbọ jẹ."
Oju ọna olobiripo (roundabout) Berger to wa ni iṣẹlẹ naa ti waye, nibi ti awọn eeyan ti n wọde lati owurọ kutu.
Akanbi mi, má fọ̀ ọ́, mo wà pẹ̀lú ẹ; ẹni tó ṣe ìgbéyàwó olórùka ló l'ọkọ- Lizzy Anjorin Kini ofin sọ lori iṣẹlẹ yii?
Aṣiri to tun ọhun lo mu ki wọn o yọju si ọọfisi orilẹede Saudi to wa ni ilu Abuja lati bẹrẹ igbesẹ lori bi Zainab yoo ṣe gba ominira.
Nítorí Jesu Kristi, Ọmọ Ọlọrun, tí èmi, Silifanu ati Timoti, ń waasu rẹ̀ fun yín, kì í ṣe “bẹ́ẹ̀ ni” ati “bẹ́ẹ̀ kọ́”.
A tún kọ nínú ìtàn yìí pé, kò yẹ ká máa jẹ gàba le ara wa lori, tàbí fi tipa wá ipò aṣáájú nítorí ọmọ iya kan náà ni wa nilẹ Yoruba.
Bi eeyan jẹ ori ahun, yoo sunkun lọ Oríṣun àwòrán, Empics Àkọlé àwòrán, Bi ọdẹ ba ku, ọdẹ lo n soro lẹyin ọdẹ.
“Ṣugbọn àwọn baba wa kò fẹ́ gba ọ̀rọ̀ rẹ̀ gbọ́.
Ukah ni ajọ to n risi ọrọ idanwo, Examination Ethics Disciplinary Committee ni ipinlẹ naa ti bẹrẹ igbesẹ lati fi iya tọtọ jẹ awọn olukọ to wu iwa magomago.
Iya Woli: Ẹ̀mí ìjókíjó, Wòó, Ṣọ̀kí, Wojú, Ṣàkùṣákù, One Corner.
Ṣugbọn awọn ọmọkunrin ti ọwọ ọlọpaa tẹ ọhun ni irọ ni wọn pa mọ wọn, pe awọn ki i ṣe ibalopọ ọkunrin s'ọkunrin.
"' Waziri lo n gbọ jijẹ mimu ninu ile ṣùgbọ́n ""igba ti iṣẹlẹ yii ti ṣẹlẹ ko si nkan to le da ṣe funra rẹ""."
Eli pè é, ó ní, “Samuẹli, ọmọ mi!
Bakan naa o ti di gbajugbaja lori ayelujara fun oniruuru ọrọ to ma n suyọ latari awọn asọtẹlẹ rẹ.
Oríṣun àwòrán, Abdurasheed Adeoye/Facebook Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Aràrá bíi tèmi, kó má rò pé kò sì ǹkan tó lè ṣe láyé ju iṣẹ́ agbe lọ' Gẹgẹ bi oludari agba ẹka iṣẹ ọna fasiti Ilorin to gba eku ida ẹka yii kan naa lọwọ Ọjọgbọn Akinwale, Ọjọgbọn Rasheed Adeoye ṣe fi atẹjade sita, gbajugbaja oṣere yii to tun jẹ igi nla lagbo imọ ẹkọ Tiata, Ayo Akinwale jade laye lọjọ kẹtala oṣu kẹsan ọdun 2020 ni ile iwosan fasiti Ilorin.
Joramu mú ọpọlọpọ ẹ̀bùn tí wọ́n fi wúrà ṣe, ati ti fadaka, ati ti idẹ lọ́wọ́ fún Dafidi.
Bíi kinniun ni n óo rí sí Efuraimu, n óo sì fò mọ́ Juda bí ọ̀dọ́ kinniun.
 Ódá lórí baṣọ ̀ run gáà tìlú Ìbàdàn , ẹni tí ó jẹ ́ afọbajẹ àti ayọba lóyè .
Bakan náà BBC bá ilumọọka agbohunsafẹfẹ naa ti wọn pe ni Wole Sorunke, ti ọpọ eeyan mọ si MC Murphy, ẹni tii se oludari eto gbogbo nileesẹ radio Fresh FM to wa nilu Abeokuta náà sọ̀rọ̀.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Eyi ni àwo ti wọn maa n ko iwe idibo si ninu Ni kia ti wọn ba si ti wọleni wsn yoo bura lati pa aṣiri gbogbo mọ.
ni owe awọn agba n wi ati pe lowe lowe ni a n lu ìlù ogidigbo.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Kano: Ìlú àwọn ‘òmùgò’ gba orúkọ tuntun lẹ́yìn àádọ́rin ọdún 25 Bélú 2019 Àkọlé àwòrán, Orúkọ ìlú náà Wawaye ní ìpínlẹ̀ Kano ló túmọ̀ sí ìlú àwọn òmùgò, tí àwọn ènìyàn sì maa ń fi bú wọn.
 o ni bode mo poland ni ariwailaorun , jemani ni iwoorun ati ariwaiwoorun , austria ni guusu ati slovakia ni ilaorun .
ninu awon omo orile ede Naijiria ti fun mi ni anfaani odun mẹ́rin miiran .
O ni inu oun dun wipe wọn yẹ oun si gẹgẹ bii akọnimọọgba.
Tabi o lè fìdí wọn múlẹ̀ lórí ilẹ̀ ayé?
Mark Henry, Booker T ati The Rock ni wọn ti gba iru ami ẹyẹ bẹẹ tẹlẹ.
Ẹnu yà á nítorí aigbagbọ wọn.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Idanre Kingship tussle:Adelé Ọba Idanre ní Ọba Aroloye wà lórí ìtẹ́ nígbà tí àwọn jàndùkú lù ú 1 Bélú 2020 Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fọ́nrán ohùn, Idanre Kinship: Owa Idanre o rán ẹnikẹ́ni si Temilolu, awọn ọ̀dọ́ ìlú ló ń bínú Adele Ọba Alade Idanre, Temilolu Akinboola ti ṣalaye fun BBC bi awọn janduku kan ṣe ya bo aafin rẹ ti wọn si lu u ni ilu bara.
Ọkùnrin tí kò ríran kan rèé tó ń lọ ẹ̀rọ ata ‘Ò dà bí àlá bí mọ ṣe da ìlúmọ̀ọ́ka nítorí bí a ṣe ń gbé òkú jó ní Ghana’ Ọwọ́ ọlọ́pàá tẹ 'ọba alayé' àti ọmọ rẹ̀ tó fi ipá bá ọmọ ọdún mẹ́rìnlá lòpọ̀ l'Ọ́ṣun Alífábẹ́ẹ́tì Ohùn Oduduwa di ìtẹ́wọ́gbà ni Ajaṣẹ Ṣé lóòtọ́ọ́ nipé irọ́ n'ìjọba Nàìjíríà ń pa lórí ìtànkálẹ̀ ààrùn coronavirus?
Zamfara Bandits: Kò sí ẹni tó mọ iye ènìyàn tí àwọn adigunjalè gbé lọ
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Sotitobire: Àwọn ọmọ ìjọ yarí, wọ́n ní ejò lọ́wọ́ nínú lórí ìdájọ́ tí wọ́n dá fún Alfa Babatunde 5 Ọ̀wàrà 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 8 Ọ̀wàrà 2020 Ọrọ ko tii tan lori idajọ ẹwọn gbere ti ileẹjọ giga niluu Akure da fun pasitọ ijọ Sotitobire Praising Chapel, Alfa Babatunde lẹyin tawọn ọmọ ijọ rẹ tako idajọ naa.
Ṣebí jamba a máa bá àwọn alaiṣododo,àjálù a sì máa dé bá àwọn oníṣẹ́-ẹ̀ṣẹ̀.
Ọmọbinrin ọhun ni wọn fẹsun kan pe, o tapa sofin ile iṣẹ ọlọpaa Metropolitan Police nitori fọnran to lu ayelujara pa ṣafihan rẹ pe, o n ni ibalopọ pẹlu akẹgbẹ rẹ lori eto ọhun.
Ogun ti Ekiti-parapọ gan an waye lẹyin ti wọn jagun ṣẹgun ogun Kiriji miran laarin ọdun 1877 - 1892.
Àwọn ará Filistia bá bẹ̀rẹ̀ sí bèèrè pé, “Ta ni ó dán irú èyí wò?
Operation Puff Adder: Ọwọ́ ọlọ́pàá tẹ afurasí ajínigbé 93, ọ̀pọ̀lọpọ̀ ìbọn 'AK47' àti aṣọ ṣọ́jà
Àṣe àwọn iwin náà kò jìnà rárá àfi wéré tí wọn padà tí a bẹ̀rẹ̀ sí í gbọ́ igbe Gọ̀ǹgọ̀ṣútàkìtì tí ó ń ké, ‘Ẹ gbà mi o, ẹ wá gbà mi o, ó pa mi o, ó yọ mí lójú o abbl.
Bẹẹ gan-an ni ọrọ ri fun ọmọ aarẹ Biya, nitori pe bi awọn kan ṣe n ki kú oriire, ni awọn miran n bu ẹnu ẹtẹ lu u pe ko tọ ọ bo ṣe ṣi sọọbu irun si Amẹrika.
"Ẹ wo ìdí tí El Rufai kò fi leè fi Sanusi sílẹ̀ ""N kò kọ̀ kí ń kú, ìfẹ́ tí mo ní sí Buhari ni mo ṣe sáré dì mọ"" Eré apanilẹ́rìn ké kè ké lórí ayélujára ti ṣí ọ̀pọ̀ ìlẹ̀kùn fún mi - Mr Macaroni Amọ titi di akoko yii, ijọba ipinlẹ Ekiti ko tii sọrọ lori lẹta ti Alaafin kọ si naa."
Ọmọ Naijiiria ni mí, ọ̀rọ APC kò lésì -Atiku Ọ̀wọ́ngógó epo bẹntirò: NNPC ni ìròyìn ẹlẹ́jẹ̀' ni Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, JAMB 2019: A ó fagi lé ìdànwò ẹni tó bá ṣe aṣemáṣe Iroyin ni awọn ololufẹ mejeeji naa n bọ lati ibi igbafẹ ni ki wọn to koju awọn ọlọpaa ninu eyi ti ẹmi ọmọbinrin naa ti bọ́ si.
20 Ẹrẹ̀nà 2020 Laye ọjọsi, ere itage jẹ gbajugbaja lawujọ awọn onitiata lorilẹede Naijiria.
Nígbà tí o sì mú mi, o fi okùn sí mi ni ẹsẹ̀ o sì so mi mọ igi rẹ̀gẹ̀jì kan ti ń bẹ ní ìta rẹ̀, mo kọ orí sí odò mo ń fi dírọ̀dírọ̀, o sì gbé ẹrù pàsán jáde, ó bẹ̀rẹ̀ sí í fà wọ́n yọ lọ́kọ́ọ̀kan o sì ń nà mi.
Eko eeyan mejilelogoji (42), Ilu Abuja eeyan marundinlọgbọn (25), ipinlẹ Katsina eeyan mẹrinla (14), ipinlẹ Kaduna eeyan mọkanla (11), ipinlẹ Kwara eeyan mẹjọ (8), ipinlẹ Ondo eeyan meje (7), ipinlẹ Delta eeyan mẹrin (4), ipinlẹ Anambra eeyan mẹta (3), ipinlẹ Oyo eeyan mẹta (3) ti ipinlẹ Edo, Ogun ati ṣun si ni meji meji.
Anfaani afikun ọsẹ mẹta lawọn to ba ti ni NIN tẹlẹ yoo jẹ bayi ti awọn ti yoo si ṣẹṣẹ forukọsilẹ ni ọsẹ mẹfa.
Babatunde Fashola ló ṣe atọ́nà bí Naira Marley ṣe rí bàlùú wọ̀ dé Abuja Ohun tí a mọ̀ nípa Ṣẹnetọ Adebayo Osinowo tó dágbére fáyé Ẹ̀kọ́ mẹ́jọ tó yẹ kí ilẹ̀ Afirika kọ́ lára àjàkálẹ̀ aàrùn coronavirus Oríṣun àwòrán, Others Ti ijọba ipinlẹ Cross River ko ba yi ẹnu pada, awọn ni ko ba jẹ ipinlẹ akọkọ ti yoo ṣi ileewe pada lorilẹede Naijiria.
"Ẹ̀wẹ̀, lẹ́yìn ti ọlọpàá gba àṣẹ́ láti tú ilé rẹ̀ wò, wọ́n ní ""a ri pé iwé ẹ̀ri ti o ni nọmba ti Waheed náà ni lori ìwé ẹrí rẹ̀ jẹ́ ti Raimot Omotola Adebayo"" Ní àsìkò ìfọ̀rọ̀wánilẹnu wò ni o jẹ́wọ pe òun gba iwe ẹ̀rí náà lọ́wọ́ ẹni ti o ní lábẹ ẹ̀tàn pe òun fẹ́ ba a wa iṣẹ́, sùgbọ́n oun mú lọ si ọdọ àwọn to n tẹ iwé láti gbé orukọ oun lee ki o le da bi pé ti oun ni."
 bv jẹ ́ àrùn tó wọ ́ pọ ̀ ní africa pẹ ̀ lú díẹ ̀ ní asia àti europe .
Wọ́n sì ti bẹ̀rẹ̀ sí í léwé kọ̀ọ̀kan lára, bíótilẹ̀jẹ́pé irúfẹ́ igi kannáà ni àwọn pẹ̀lú àwọn funfun ti iwájú igbó náà.
Wọ́n kúrò ní Dofika, wọ́n lọ pàgọ́ sí Aluṣi.
Oríṣun àwòrán, Olusegun Obasanjo Presidential library Wọn yinbọn lu ọkọ rẹ, wọn si pa Murtala Muhammed ninu iditẹ-gbajọba to waye ọhun, bi Bajọwa ṣe gba mi la lọwọ awọn aṣekupani niyẹn.
"O sọ pe "" ipa ti iru ajakalẹ aarun bayii yoo ni lara awọn ọmọde to jẹ talaka ati alaini oluranlọwọ le l'agbara pupọ""."
FIFAWWC -Ọ̀rọ̀ ti yanjú dé ibì kan lórí owó àjẹmọ́nú àwọn Super Falcons
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Say no to rape: Àwọn òṣèrébìrin Yollywood sọ tiwọn lórí ìfipábánilòpọ̀ tó gbòde 8 Òkùdu 2020 Oríṣun àwòrán, Instagram Awọn obinrin to jẹ oṣere ni Naijiria ko lee pa ero ti wọn mọra rara pẹlu iwa aburu ifipabanilopọ to gbode kan to si n waye kaakiri orilẹede Naijiria.
Abass lọ ṣe ẹrú ni Brazil, nibi to ti gbọ ede oyinbo, to si tun mọọ kọ, mọọ ka, ki wọn to da a pada sile lati wa maa ṣe Alakoso owo ẹrú fun ọga rẹ, Williams nilu Badagry.
Igba naa si ni igba akọkọ ti wọn ko gbogbo awọn ọba ni Naijiria papọ si oju'kan.
Agbẹnusọ fun aarẹ orilẹede Naijiria lori ọrọ gbogbo to jọmọ iroyin lori ẹrọ igbalode ati ayelujara, Bashir Ahmad salaye wipe inu aarẹ dun lori bi orilẹede Naijiria se n kopa fun igba akọkọ nibi idije Winter Olympics ọhun.
Laipẹ yii ni aarẹ Buhari sọ nibi eto ipolongo ibo to ṣe ni ipinlẹ Imo ati Abia fun saa keji nipo sọ pe oun ti mu gbogbo ileri t'oun ṣe lọdun 2015 ṣẹ fun awọn ọmọ Naijiria.
 Ọ ́ jọ pé orílẹ ̀ èdè sundan ni wọ ́ n ti sẹ ̀ wá ; àgbẹ ̀ , ọdẹ àti apẹja sì ni wọ ́ n .
Oríṣun àwòrán, @EKEDP A ṣe agbekalẹ ina ọba to yatọ fun wọn ni.
Gbogbo rẹ dé òtéńté nigba ti Funmilayọ kò san owó orí ara rẹ, ti wọn fi gbee lọ sile ẹjọ́ ti ọpọlọpọ awọn obinrin sì tẹle lọ lọdun 1947.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù End SARS, End SWAT: Ó pé mi bí SARS kò ṣe sọ mí dolówọ́- Fulani Kwajafa Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ End SARS, End SWAT: Ó pé mi bí SARS kò ṣe sọ mí dolówọ́- Fulani Kwajafa 16 Ọ̀wàrà 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 17 Ọ̀wàrà 2020 Òfin àkọ́kọ́ ti SARS ti mo dá sílẹ̀ ni pé wọn kò gbọdọ̀ yìnbọn fún ẹnikẹ́ni- Fulani Kwajafa Fulani Kwajafa to jẹ kọmiṣọnna ọlọpaa ti aarẹ Buhari paṣẹ fun pe ko da SARS silẹ lọdun 1884 gba BBC lalejo, o sọrọ ilẹ kun lori ọrọ SARS.
Oríṣun àwòrán, Biodun Abdu-Raheem Isẹlẹ naa la gbọ pe o waye ni deede aago mẹjọ alẹ ana nigba ti wọn n ja Kọmiṣọ́nna naa sinu ile rẹ, ti wọn si yin awakọ rẹ, Lukman Adebayo ni ibọn eyi to mu ko jade laye loju ẹsẹ, nigba ti wọn tun yin osisẹ ọlọpaa to n sọ ọ ni ibọn lapa.
Ọkunrin kan, Ọgbẹni Ibukun Mike lo fi fidio bi awọn oṣiṣẹ ajọ naa ṣe gba owo lọwọ rẹ ati awọn awakọ miran, nitori pe wọn ṣẹ si ofin.
Àwọn ìṣẹ̀lẹ̀ mánigbàgbé tó wáyé nínú oṣù Kẹ́wàá ọdún 2020 Àwọn ọmọ Nàìjíríà yarí lórí èròngbà ilé aṣòfin pé kí àjọ FRSC má a lo nkan ìjagun Àwọn ìwàásù akọnilẹ́nu hàà tí Prophet Israel Oladele CCC Genesis Global ti ṣe rèé Báàgì Ghana Must Go pàwọ̀dà, ó di ohun táwọn ránsọ ránsọ fi ń dárà orísirísi Oríṣun àwòrán, Genesis Global Wòlíì Genesis kan yẹra díẹ̀ ni, ó máa tó wọlé padà bí olè lóru- Adelé pásítọ̀ Oladele Adelé pásítò Oladele ní wòlíì Genesis kan yẹra díẹ̀ ni, ó máa tó wọlé padà bí olè lóru Adaba o naa ni a n kungbẹ, ina n jo ẹyẹ oko n lọ ni ijọ Celestial Church of Christ Genesis Global fi ṣe lẹyin ti ileẹjọ dajọ ẹwọn ọdun meji fun alakoso ijọ naa, Woli Israel Oladele lori ẹsun gbajuẹ.
nifẹẹ lati da ile-itura ati ibi igbafe sile lorile ede Naijiria.
Àwọn Juu wá bẹ̀rẹ̀ sí kùn sí i nítorí ó wí pé, “Èmi gan-an ni oúnjẹ tí ó sọ̀kalẹ̀ láti ọ̀run wá.
Yoo kọ mejidinlogoji ile iwosan igbalode iru eyi to wà ni Texas yii Ile iwosan yii ni Ile Iwosan Southwestern to wa ni fasiti Texas ni orilẹ-ede Amerika.
OLUWA bá yín sọ̀rọ̀ lojukooju lórí òkè ní ààrin iná.
Aisha Buhari tọrọ ìdáríjì lórí fídìo tó jáde Ọkọ̀ agbépo tó gba iná ṣe àkóbá ní ọjà Onitsha BBC 100 Women 2019: Wo ọmọ Nàíjíríà kan tó wà nínú wọn Njẹ́ o mọ pé N3000 ló o sàn láti gbà kaadi ìdánimọ̀ míì bí tí tẹ́lẹ̀ bá sọnù?
O ni oun tọrọ aforijin lati kọkọ gbe gbogbo oriyin fun awọn agbofinro Naijiria tẹlẹ.
Oríṣun àwòrán, others Àkọlé àwòrán, Mùsùlùmí tó ń gbèrò láti lọ hajj ni Alhaji, Alhaja - Onímọ̀ Ki ni itumọ ati pataki oye ẹṣin Islam:Malam:Sheikh Isola ni ede Hausa ni Malam.
Biafra at 50: Ó tó mílíọ̀nù mẹ́ta èèyàn tó bá ogun náà lọ
Àwọn èèyàn sọ́rọ́: Ẹ máà ṣi Fayemi túmọ̀ lórí àṣẹ tó pa nípa sísọ Yorùbá
Mose ati Aaroni bá sọ fún gbogbo àwọn eniyan Israẹli pé, “Ní ìrọ̀lẹ́ òní ni ẹ óo mọ̀ pé OLUWA ló mú yín jáde láti ilẹ̀ Ijipti.
Ẹ má jẹ́ kí ó sinmi,títí yóo fi fi ìdí Jerusalẹmu múlẹ̀,títí yóo fi sọ ọ́ di ìlú ìyìn láàrin gbogbo ayé.
Idi si niyi ti ẹgbẹ oselu PDP naa fi n nahun kesi gomina ipinlẹ Ọyọ, Onimọ ẹrọ Seyi Makinde pe ni kia mọsa, ko yara tete tanna wadi bi ijọba Ajimọbi se lọ, ki awọn ohun ikọkọ lee foju han ni gbangba.
Eeyan meji to n ṣiṣẹ ni ibudo iwayanrin kan nilu Ibadan ti di oloogbe bayii.
kí ó gbé ọwọ́ rẹ̀ lé e lórí, kí ó sì pa á níwájú Àgọ́ Àjọ náà; kí àwọn ọmọ Aaroni da ẹ̀jẹ̀ rẹ̀ sí ara pẹpẹ náà yípo.
Fẹmi Kuti wa lara awọn akọrin ti yoo side AFCON 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Idije AFCON tọdun 2019 ni igba kejilelọgbọn ti idije naa yoo waye.
Marwan Abboud sọ pé ọ̀pọ̀ ènìyàn ni wọ́n ko tilẹ̀ rí mọ́ títí di àsìkò yìí, ti ọ̀pọ̀ sì jẹ́ àwọn àjòjì tó wá ṣiṣẹ́ ni Lebanon.
O jẹ igbakeji gomina ipinlẹ Bayelsa lọdun 1999 ni wọn bura wọle fun un gẹgẹ bi igbakeji gomina si gomina Diepreye Alamieyeseigha labẹ asia ẹgbẹ oṣelu PDP.
Eid-el Kabir: Saudi ṣàtúnṣe lílẹ òkò mọ́ Asitani láti dẹ́kun títẹra-ẹni-pa
Oríṣun àwòrán, Getty Images Asise nidi ayẹwo DNA: Gẹgẹ ba se mọ pe ko si ẹnikẹni tabi ohunkohun to pe ayafi ọlọrun ọba.
"Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Kà nípa ìròyìn mánigbàgbé tí BBC News Yorùbá ṣe láàárín ọdún kan ""Aṣọ́bodè tó yìnbọn pààyàn ti mutí yó"" Àwọn ìgbà tí ẹ̀ṣọ́ aṣọ́bodè ti pànìyàn lọ́nà àìtọ́ 'À ń fẹ́ epo ọ̀fẹ́ tàbí gbà má bínú lọ́wọ́ ìjọba' Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Arsene Wenger gbọdọ lọ' Ṣugbọn, Mourinho ti Manchester United le lọ ile ni oṣu Kejila ọdun 2018, ti buyi kun Wenger ninu fidio kan."
"Arabinrin Cheney sọ pe ""Aarẹ Trump ti da ilẹ Amerika, o si tun ti tapa si iwe ofin orileede naa pẹlu ihuwasi rẹ lọfiisi "" O ni Trump lo ko awọn ero to ṣe ikọlu sí ile aṣofin ni Capitol jọ."
O ni awọn 'alagbara eeyan' kan naa n ṣiṣẹ tako igbesẹ ijọba ipinlẹ naa lati fi opin si ifipabanilopọ.
Ẹ ṣọ́ra kí àwọn eniyan burúkú wọnyi má baà tàn yín sí inú ìṣìnà wọn, kí ẹ má baà ṣubú lórí ìpìlẹ̀ tí ẹ dúró sí.
FFK sọrọ lori ọ̀fọ̀ to ṣẹ̀ ni Benue, Adamawa, Taraba, Plateau, Zamfara ati bẹẹ bẹẹ lọ.
Nípa àwọn wọnyi ni Enọku tí ó jẹ́ ìran keje sí Adamu sọ àsọtẹ́lẹ̀ pé, “Mo rí Oluwa tí ó dé pẹlu ẹgbẹẹgbẹrun lọ́nà ẹgbẹrun àwọn angẹli rẹ̀ mímọ́, 
Awọn onimọ nipa eto idibo naa ti sọ pe o ṣeṣe ki esi ibo waye lalẹ ọjọ idibo, ki awọn eeyan si mọ ẹni to jaweolubori lọjọ kan naa.
Mínísítà Adamu Adamu, tó kọminú lórí bí àwọn agbébọn ṣe ń dojúkọ ètò ẹ̀kọ́, ṣàlàyé pé ẹgbẹ̀rún méjì ó lé márún dín lọ́ọ̀dúnrún olùkọ́ ní àwọn agbébọn Boko haram ti pa, tí ẹgbẹ̀rún mọ́kàndínlógún míràn sì ti fọ́n káàkiri àwọn ìpínlẹ̀ Yobe, Borno àti Adamawa láàárín ọdún mẹ́sán sẹ́yìn.
Eniyan meji tun ku loju ọna naa ninu ijamba miiran ni ọdun 2017.
O le ni miliọnu eniyan ti wọn ti ko kuro ni agbeegbe Orissa naa, ti wọn si ti ko wọn lo si awọn ilu miran ti iji lile naa ko de.
nǹkankan a sì máa dún lókè awọsanma tí ó wà lórí wọn.
Àgbo tí mò ń lò láti jò kó bá mi, ìdí mi ti yọ́ tán - Nkechi Blessing figbe ta Ọ̀pọ̀ ọkùnrin ló máa ń wò mí ní àwòyànu pé obìnrin ń ṣe 'Welder'- Omolola Èyí ni àwọn aṣíwájú ìjọba tí ajé ìwà ìjẹkújẹ ti ṣí mọ́ lórí láàrin ọdún 1960 sí àsìkò yí Ṣé lóòtọ́ ni tírélà ti gba ààrín Ronke Odusanya àti bàbá ọmọ rẹ̀, Jago?
Sibẹ mo rí i pé ọwọ́ Ọlọrun ni èyí tún ti ń wá.
Orísun omi ni ọkàn ọba lọ́wọ́ OLUWA,ibi tí ó bá wu Oluwa ni ó ń darí rẹ̀ sí.
Sadiq Ango, ọkan lara mọlẹbi wọn ṣalaye pe niṣe ni awọn mọlẹbi mẹtẹẹta pawọpọ lati da owo san owo itanran ki awọn oniṣẹ ibi naa to fi wọn silẹ.
 sugbon , o pinsoto lati egbe apaiworun pelu ile india .
Magu,'estimated billing' àti àwọn ohun míràn tí ilé aṣòfin Nàìjíríà kò rí yanjú Ààrẹ Abdulaziz Bouteflika ti kowe fipo silẹ Ilé ẹjọ́ kòtẹ́milọ́rùn yá lórí ọ̀rọ̀ Adeleke- PDP Ìpànìyàn Zamfara: Kò gbọdọ̀ sí ìwakùsà ní Zamfara Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ojojúmọ ní mọ ń kẹ́kọ̀ọ́ lára ọmọ mi to jẹ akanda Ṣugbọn The Rock fun ra rẹ ti sọ pe apa kan eeyan dudu loun ti apa keji si jẹ ọmọ ilẹ Samoa ni erekuṣu nitrori awọn alaṣẹ WWE ko ka kun alawọdudu.
Ní ogún ọdún tí Jotamu, ọmọ Usaya jọba Juda, ni Hoṣea, ọmọ Ela, dìtẹ̀ mọ́ Peka ọba, ó pa á, ó sì jọba dípò rẹ̀.
Èrò àwọn ọmọ Naijiria ṣọ̀tọ̀ọ́tọ̀ lórí ohun tó n wáyé l'ágbo òṣèlú
Ọmọ márùn-un ni Àkàńgbé Orímóògùnjé bí Dúró sì ni àgbà gbogbo wọn.
nile idibo to wa ni , Ayi unit 39, Ward 13 ni papa isere ti  Otazi , Otuoke ,ni ijoba ibile Ogbiani , ni ipinle
Oríṣun àwòrán, @NigAirforce Ileeṣẹ ọmọ ogun ofurufu ti fa awọn mẹta to wa ninu ọkọ to pa Tolulọpẹ Arotile le awọn agbofinro lọwọ bayii.
Ọrẹ oloogbe Davy to ba awọn akọroyin sọ̀rọ̀ lori ipo ti o wa fi hande pe ọ̀rọ̀ yii bẹrẹ nigba ti oloogbe ti leri to fọwọ sọya niwaju awọn ọrẹ rẹ pe oun le lo wakati meji lori obinrin lai simi.
Ìfẹ̀hónúhàn l'Abuja lórí ìdájọ́ ilẹ̀ Gẹ̀ẹ́sì tó gbẹ́sẹ̀ lé $9.
Aare wa gbadura pe, Ọlọrun yoo fun alaga
igbimo yii yoo ma lọ lati oja kan si ikeji ti won yoo si maa ba awon onimoto
Saraki sọ èyí di mímọ nínú àtéjáde kan ti àgbẹnusọ rẹ̀, Yusuph Olaniyonu gbe jade, o wa rọ àwọn ọmọ Nàìjíríà kí wọn máse káàrẹ̀ láti máà ṣiṣẹ́ ìtọrẹ àànú, pẹ̀lú adúrà ẹ̀bẹ̀ fún orilẹ̀-èdè Nàìjíríà.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Àfi bí mo bá sunkún mọ́ títọrọ̀ owó, tórí gbobo wa ni ìyà ń jẹ níbí' Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
"Oríṣun àwòrán, STREET PRIESTS Àkọlé àwòrán, James bẹrẹ si ni ran awọn ọmọde lọwọ nigbati o wa l'ọmọ ọdun mẹẹdogun Nitori ibanujẹ ọkan rẹ, o bẹrẹ si ni lo akoko rẹ l'ode , o si n darapọ mọ awọn ti o ṣe apejuwe wọn gẹgẹbi ""ọrẹkọrẹ""."
Kò sì ní sí ẹnikẹ́ni tí yóo fẹ́ gba ilẹ̀ yín nígbà tí ẹ bá lọ sin OLUWA Ọlọrun yín, lẹẹmẹtẹẹta lọdọọdun.
Àwọn Kerubu bá na ìyẹ́ apá wọn, wọ́n gbéra nílẹ̀ lójú mi, bí wọ́n ti ń lọ, àwọn àgbá náà wà lẹ́gbẹ̀ẹ́ wọn.
Oríṣun àwòrán, Twitter/Govt of Nigeria Nkan miran tun ni pe ẹsẹ ni awọn eeyan kan fi n rin lati Iyana Oworo ni irọlẹ ti akọroyin BBC kọja.
Lẹyin ọdun meje ti Morohunfolu dara ilẹ, Oyinkan tun ba ifẹ pade, to si di aya Dokita kan, Kofoworola, ti wọn ni orúkọ baba tiẹ naa jẹ orúkọ baba ọkọ aarọ Oyinkan, eyiun Abayomi.
Ọlọ́pàá Adamawa ni #30,000 ni wọ́n fi bọ́ igún látìmọ́lé Ẹ̀rù ogun n bà mí fún ìran Yorùbá -Bode George Ìjọba Buhari kìí ṣe ọ̀nà àbáyọ síṣòro Naijiria -Jiti Ogunye Wo àwọn míniístà mẹ́fà tí ẹnu ń kùn jùlọ Ọpọ maa n gba pé ọdaju ọmọ ni wọn nitori ìbí wọn ṣeeṣe lati já si ikú fun iya wọn ti ko ba tete ri itọju to peye lasiko irọbi.
Ó wá gbàgbé pé ọba lókè Arínúríta, Olùmọ̀ràn ọkàn kọ ìwà mànáfìkí.
Nígbà tí ó gbọ́ ohùn Peteru, inú rẹ̀ dùn tóbẹ́ẹ̀ tí kò fi dúró ṣí ìlẹ̀kùn; ṣugbọn ó sáré lọ sinu ilé, ó lọ sọ pé Peteru wà lóde lẹ́nu ọ̀nà.
Ẹni to ba si ti dagba ju ọgọrin ọdun lọ laarin wọn ko le dibo.
Nobu, Ananaya ati Hasori, ní Rama ati Gitaimu, 
Mò ń jowú nítorí yín, bí Ọlọrun tií jowú.
‘Wà á ṣe obìnrin kalẹ́ o.
nitori awon isoro kekere to doju kọ wọn.
Ilẹ naa ti iwọn rẹ to ọgbọn sare ni wọn sọ pe Alaafin Lamidi Adeyẹmi fun eekan oludaleeṣẹsilẹ kan lati fi kọ ileewe girama ti wọn pe oruks rẹ ni Abiọdun Atiba Grammar School ki wọn lee lo iyoku rẹ fun idagbasoke lọjọ iwaju.
Ó tẹ́ pẹpẹ kan níbẹ̀, ó sì sọ pẹpẹ náà ní Eli-Ọlọrun-Israẹli.
“Ẹ̀yin ilé Israẹli, ṣé n kò lè ṣe yín bí amọ̀kòkò yìí ti ṣe ìkòkò tí ó mọ ni?
Àwọn ará Filistia sì kó ara wọn jọ, wọ́n pa ibùdó sí Ṣunemu.
Bakan naa ni aṣa sọ pe ki wọn o sin oku ẹnikẹni to ba ku sinu odo si eti odo naa.
Báyìí ni Àrẹ̀mọ Ooni Adeyeye Ogunwusi ṣe wọ ṣọ́ọ̀ṣì fún ìgbà àkọ́kọ́ láti bá bàbá rẹ̀ ṣe ìdúpẹ́ ìwúyè Mo gbóríyìn fún Buhari bó ṣe dóòlà ẹ̀mí àwọn akẹ́kọ̀ọ́ tí wọ́n jí gbé ní Kankara Ọsẹ́ tí ọkọ̀ aképo tó gbiná lẹ́bàá Otedola Estate l'Eko ṣe rèé 'Ìdí tí a ò fi pa àwọn ajínigbé tó gbé àwọn akẹ́kọ̀ọ́ Kankara nìyìí' Òṣèré tíátà Yorùbá yìí la orí mọ́lẹ̀ nígbà tó ń ṣe sinimá lọ́wọ́ Àwọn ìgbésẹ̀ tóo lè fi so NIN rẹ̀ pọ mọ́ síìmù MTN, Glo, Airtel ati 9Mobile rẹ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Pásítọ̀ ló sọ fún mi pé Ọlọ́run pè mí láti di Olokun tó ń bọ omi' Iroyin ni lẹyin to ti ọmọ ọdun kan ati oṣu mẹjọ naa sinu kanga tan lo sọ fun baba rẹ pe wọn ti ji ọmọ ọhun gbe.
Emir Sulu Gambari kú ara fẹ́rakù
" A ṣetán láti ran àjọ aláàbò alájùmọ̀ṣe lọwọ fún ààbò tó péye nílẹ Yorùbá - Ọlọ́pàá Ogun Ìpàdé àpérò kọ́ ló kàn, àdánìkànjẹ ẹ̀yà kan ni ká dẹ́kun ní Nàíjíríà - Òǹwòye Nínú gbèsè Nàíjíríà, ₦121,000 ló kàn ẹnìkọ̀ọ̀kan, ṣó o ṣetán láti san tìẹ?
Bẹ́ẹ̀ ni mo fi wúrà ati fadaka ṣe ọ̀ṣọ́ sí ọ lára.
'Ẹ má ṣi Fayemi túmọ̀ lórí àṣẹ tó pa nípa sísọ èdè Yorùbá' Kò sí àṣà tó faramọ́ fífi èmí ènìyàn ṣe ìrúbọ - Olúwó Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Owé Yorùbá ti ó sọ wi pé “Ránti ọmọ Ẹni ti iwọ nṣe ” pin si ọ̀nà méji.
 Amọṣa awọn alaṣẹ ileewe fasiti OAU ni ọrọ ilẹ ti awọn eeyan kan fẹ gba mọ ileewe naa lọwọ lo n fa igbesẹ yii."
tayọ akẹgbẹ rẹ lati ẹgbẹ oṣelu PDP ti o ni ẹgbẹrun
A wa n gbadura pe ajinde ara yoo maa jẹ fun Baba Suwe, ko si ni wolẹ aisan mọ titi aye.
Wọn fi ẹsun kan Adam Thomas, ẹni ọdun mejilelogun, ati Claudia Patatas, ẹni ọdun mejidinlogoji, to fi mọ Daniel Bogunovic, ẹni ọdun mẹtadinlọgbọn, pe wọn jẹ ọmọ ẹgbẹ́ ọlọtẹ National Action.
Eleyii to tako abala keje ofin ti o n gbogun ti iwa ọdaran ori ayelujara tọdun 2015 (the Cybercrime Prohibition, Prevention etc Act 2015 ) Bi agbẹjọro fun olupẹjọ ṣe n rọ adajọ ile ẹjọ naa lati fun wọn ni ọjọ ti igbẹjọ gan an yoo bẹrẹ ni agbẹjọro Naira Marley n beere fun ọjọ lati gbọ ẹjọ lori ẹbẹ rẹ fun gbigba oniduro rẹ.
Amọ Bamiloye ni iṣẹ iranṣẹ ijere ẹmi Kristẹni ti Ọlọrun pe oun si, nikan ni oun gbajumọ.
Illegal Orphanage: Ìjọba ti ayédèrú ilé ọmọ aláìlóbìí pa, ọmọdé mẹ́tàdínlọ́gbọ̀n gbòmìnira
Ijọba Naijiria n sọ pe awọn n wa alaafia ni.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Yoruba to ti fẹ Fulani l'ọkọ fun ọdun metala Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Yoruba to ti fẹ Fulani l'ọkọ fun ọdun metala 7 Ẹrẹ̀nà 2018 Ọmọbinrin kan ni ilu Isẹyin, ti o ti fẹ Fulani lọkọ fun ọdun mẹtala so iri rẹ.
Ọba Siria ti pàṣẹ fún àwọn ọ̀gágun tí wọn ń ṣàkóso àwọn kẹ̀kẹ́ ogun rẹ̀ pé kí wọ́n má ṣe bá ẹnikẹ́ni jà bíkòṣe ọba Israẹli nìkan.
Aisaya sọ nǹkan wọnyi nítorí ó rí ògo Jesu, ó wá sọ àsọtẹ́lẹ̀ nípa rẹ̀.
Ẹ ṣọ́ra yín, ẹ sì ṣọ́ agbo tí Ẹ̀mí Mímọ́ fi yín ṣe alabojuto lórí rẹ̀, kí ẹ máa bọ́ ìjọ Ọlọrun tí ó fi ẹ̀jẹ̀ Ọmọ rẹ̀ ṣe ní tirẹ̀.
" Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, A gbúdọ̀ wẹ̀ ọmọ tuntun pẹ̀lú epo pupa, kàìnkàìn ìbílẹ̀ àti ọṣẹ dúdú' Wiro ni: ""Ṣugbọn ti oyun ba de, a maa n sọ fun wọn ki ẉon kan si Welfare, ileeṣẹ FIDA, tabi ile awọn ọmọ alaini iya to wa ni Port Harcourt kaka ki wọn sọ odidi ọmọ nu sori aatan."
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Temitope Akinnusi: Ọ̀pọ̀ iléeṣẹ́ ló takú láti gbà mí síṣẹ́ torí mo ní ojú kan Gbogbo ẹbẹ dokita naa sawọn ọlọpaa ọhun pe oun fẹ sare lọ dahun ipe pajawiri to le la ẹmi lọ nile iwosan lo ja si pabo.
Idi ni pe awọn ilu mejeeji lo n doju ija kọ ara wọn nitori aawọ ilẹ, ti ọrọ naa si ti dogun dọdẹ, koda, wọn ti gbe ara wọn lọ sile ẹjọ pẹlu.
Adari ile igbimọ aṣofin agba l'Abuja, Bukọla Saraki naa ko gbẹyin ninu awọn to n ṣe iranti aarẹ to lọ.
Ṣugbọn Gbẹdu ni ilẹ Yoruba ti pẹ ti won ti n lo, ọwọja iṣẹ rẹ si ti tan kọja ilẹ Yoruba nikan, lati bi Senturi kẹtadinlogun ni Benin ti mu Gbẹdu gẹgẹ bi ami ọmọ alade.
Ọpọlọpọ nǹkan mìíràn ni Jesu ṣe, bí a bá kọ wọ́n ní ọ̀kọ̀ọ̀kan, mo rò pé kò ní sí ààyè tó ní gbogbo ayé tí yóo gba ìwé tí a bá kọ wọ́n sí.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù APC caretaker committee: Nkan márùn ún tí àwọn adarí ẹgbẹ́ gbọdọ́ ṣe kíákíá kí nkan ó má lọ yíwọ́ 7 Èrèlè 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 27 Òkùdu 2020 Oríṣun àwòrán, Bashir Ahmed Ọjọ kẹẹdọgbọn, oṣu Kẹfa, ọdun 2020, ni igbimọ oludari ẹgbẹ oṣelu All Progressives Congress, APC, ṣe ipade lati fi opin si wahala to ṣẹlẹ ninu ẹgbẹ wọn.
Awọn onimọ nipa oju ọjọ sọ pe o jẹ iṣẹlẹ to maa n sẹlẹ lẹẹkan laarin iran kan.
Wọn tun sọ pe awọn ti wọn ti fi ẹsun jibiti ati iwa ibajẹ kàn ni Adesina n gbega l'ẹnu isẹ.
Ilẹ̀ tí ọba rẹ̀ jẹ́ ọmọde gbé!
" Oniwaasi agbaye naa, to ni oun maa n ṣe alarena laarin ọkùnrin to n wa aya, tabi obinrin to n wa ọkọ tun ni, o ti to ẹgbẹrun marun-un lọkọ laya ti oun ti so pọ lati ọdun 2017 ti oun ti bẹrẹ eto naa.
Ọlọrun alaafia yóo sì wà pẹlu yín.
Wo iléeṣẹ́ ìjọba tí Kọmísánà tuntun kọ̀ọ̀kan ní Ọyọ yóò dìmú Ìjọba mi ṣetán láti mú àgbéga bá ètò ààbò l‘Ọyọ - Seyi Makinde Gba owó lọ́wọ́ àkẹ́kọ̀ọ́ ìjọba, ko rugi oyin - Seyi Makinde Adebo Ogundoyin, ẹni ti o jẹ agbẹnusọ ile igbimọ asofin ipinlẹ Ọyọ lo fi ọrọ naa lede loju opo Facebook rẹ ni ọjọ Aje.
 tíátà ṣíṣe ti wá da iṣẹ ́ òòjọ ́ àwọn kan lóde òní .
Kí àwọn tí ó kórìíra rẹ̀ sá níwájú rẹ̀.
Oníwọ̀ra ati alaiṣootọ eniyan ni àwọn wolii rẹ̀, àwọn alufaa rẹ̀ sì ti sọ ohun mímọ́ di aláìmọ́, wọ́n yí òfin Ọlọrun po fún anfaani ara wọn.
Ẹbí Buhari lásán ni Mamman Daura kò nípò òṣèlú kankan Ìdìbò gómìnà ku oṣù kan, Buhari ń béèrè N10b fún ìjọba Kogi láti sàn gbèsè rẹ̀ Èrò yapa ní mọ́ṣáláṣí Jimọ̀h láti wá fójú lóúnjẹ lórí ìgbéyàwó òfegè Buhari.
Nígbà tí ó bá di ọjọ́ kẹwaa oṣù keje tíí ṣe ọjọ́ ètùtù, ẹ óo rán ọkunrin kan kí ó lọ fọn fèrè jákèjádò gbogbo ilẹ̀ yín.
Oríṣun àwòrán, Seyi Makinde Baderinwa, nigba to n fesi ni Ijọba ipinlẹ Ọsun ko kuna ri rara ninu awọn ojuse rẹ lati ọdun mọkandinlọgbọn ti wọn ti da silẹ, to si n se ojuse to tọ si gẹgẹ bii ipinlẹ alajọni fasiti Lautech lai naani pe ijọba ipinlẹ Ọyọ n yan awọn jẹ."
“Ẹnikẹ́ni tí ó bá bá ẹranko lòpọ̀, pípa ni kí wọ́n pa á.
”Samsoni bá bẹ baba rẹ̀, ó ní, “Ẹ ṣá fẹ́ ẹ fún mi nítorí ó wù mí pupọ.
Bí ó ti ń lọ, ó rí Lefi ọmọ Alfeu tí ó jókòó níbi tí ó ti ń gba owó-odè.
Amugo tenumo pe, ko seni to mo ibere tabi orisun odowo kara-kata owo takada ohun, eyi ti o le je ki awon odaran maa lo lati fi kowo pamo si ile-okere tabi maa fi satileyin fawon eni ibi adunkooko-moni.
Igbesẹ ti ilẹ gbe yii, lo mu ki awọn ẹlẹyẹ gba ohùn lẹnu rẹ ti ko fi le sọrọ mọ.
 itọ ́ láti ara ẹranko tí ó ní àkóràn náà léṣòkùnfà dìgbòlugi nígbà tí itọ ́ bá kan ibi itọ ́ ẹranko tàbí ènìyàn míìràn .
 Gbogbo awon to bo si abe isori yii je awon metadinlogbon le ni egbeta ni eyi ti owo won ti to lati san gege bi o se wa ninu iwe isuna todun 2016.
Àìsàn Muyiwa kò lè la ẹ̀mí lọ - Agbẹnusọ Òṣèré, Muyiwa Ademola Joe Biden náà ti gba abẹ́rẹ́ àjẹsara Covid-19 Kóníléógbélé ọlọ́sẹ̀ márùn ún gbáko ni ìjọba Nàíjíríà gbé kalẹ̀ fàwọn oṣìṣẹ́ lábẹ́ ìlànà Covid-19 tuntun Àwọn tó jí wa gbé fi tìpá-tìkúùkù bọ́ Hijab mi, wọ́n lù mí ní ìlù bàrà - ọmọ ọdún mẹ́rìndínlógún Amọṣa, awọn onimọ iwadi ijinlẹ nibudo iwadi ijinlẹ nipa awọn ajakalẹ arun nilẹ Afrika, African Center of Excellence for Genomics of Infectious Diseases, ACEGID ni fasiti Redemmers University to wa nilu Ẹdẹ ṣalaye pe ninu iwadi wọn, o fihan pe ṣaaju akoko yii ni ẹya kokoro arun COVID-19 to wa ni orilẹede Naijiria ti yatọ si COVID-19 to wa nilẹ tẹlẹ.
Orí pẹpẹ náà ga ní igbọnwọ mẹrin (mita meji).
O ni ipade apero tẹẹkoto ti gomina PDP tẹlẹ n ṣe ni Gombe ti dopin bayii nitori pe omi tuntun ti ru, ẹja tuntun ti wọ inu iṣejọba ipinlẹ Gombe bayii.
Ètò yìí ni a fi ń gbé àwọn ìṣẹ̀lẹ̀ tó gbẹnu tán, tó ka ni láyà, tó yanílẹnú wo káàkiri àgbáyé bẹ̀rẹ̀ láti orílẹ̀èdè Nàìjíríà.
OLUWA ní,“Mo ṣetán láti dá ire ilé Jakọbu pada,n óo fi ojurere wo ibùgbé rẹ̀.
“Nítorí pé, ní òru ọjọ́ náà ni n óo la gbogbo ilẹ̀ Ijipti kọjá, n óo pa gbogbo àkọ́bí ilẹ̀ náà, ati ti eniyan ati ti ẹranko, n óo sì jẹ gbogbo àwọn oriṣa ilẹ̀ Ijipti níyà.
Kete ti Fani Kayode sọrọ yii naa ni awọn ọmọ ijọ church of Satan ti bẹrẹ sini fun un ni esi pe ki o má fi ọrọ ti awọn sii: Ni ọrọ ba di dámi lohun ki emi naa fún é lesi pada.
bí a ṣe lè dènà àrùn náà ni dídin ìtànkáàkiri rẹ ̀ kù láti ara àwọn ọ ̀ bọ àti ẹlẹ ́ dẹ ̀ tó ti kó àrùn náà sí ara àwọn ènìyàn .
" 27 : 54 ] ihinrere ti luku kọ ọ pe , "" dajudaju ọkunrin yi jẹ alailẹṣẹ !"
Ekiti Election: Joe Odumakin ni ko si ìdí fun 30, 000 ọlọpaa
Bakan naa, ijọba Buhari-Idiagbon ni ki wọn yẹgi fun awọn gbajumọ marun nidi gbigbe oogun oloro, eyi to jẹ ara ọna tawọn eeyan n gba wa owo ojiji lasiko naa.
Nípa igbagbọ ni ó fi yé wa pé ọ̀rọ̀ ni Ọlọrun fi dá ayé, tí ó fi jẹ́ pé ohun tí a kò rí ni ó fi ṣẹ̀dá ohun tí a rí.
Ẹni tí ó bá fẹ́ràn ẹ̀mí rẹ̀ yóo pàdánù rẹ̀, ṣugbọn ẹni tí ó bá kórìíra ẹ̀mí rẹ̀ ní ayé yìí yóo pa á mọ́ títí di ìyè ainipẹkun.
Botilẹ jẹ wipe 'ilu awọn alfa' ni ọpọlọpọ eeyan mọ ilu Iwo si, sibẹ lọdọọdun ni ajọdun egungun n gbilẹ sii.
Bẹ́ẹ̀ ni ẹ bá àwọn ẹlẹ́wọ̀n jìyà.
“Aseyọri isẹ ni ikọ omo -ogun
Kí ni kò jẹ́ kí ẹ máa gba ìrẹ́jẹ?
Ẹjẹ Igbeyawo: Oríṣun àwòrán, Istagram/malivelihood Nigba ti wọn wa nile ijọsin, bo se wu ọkọ iyawo lo sọ ẹjẹ igbeyawo rẹ, ti ko si tẹle ilana ẹjẹ ti ile ijọsin maa n ka fun tọkọtaya.
Amuneke fipò sílẹ̀ gẹ́gẹ́ bí akọ́nimọ̀ọ́gbá Tanzania Ẹ yé irọ́ pa, mí o fún Super Eagles ní ẹbùn owó kánkan -Sanwo Olu Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Ṣe iroyin naa mu inu rẹ dun, bi ọ ninu tabi mu ipaya ba ọ?
Sí ìjọ Ọlọrun ti ó wà ní Kọrinti, àwọn tí a yà sí mímọ́ nípa ìṣọ̀kan pẹlu Kristi Jesu, tí a pè láti jẹ́ eniyan ọ̀tọ̀, ati gbogbo àwọn tí ń pe orúkọ Oluwa wa Jesu Kristi níbi gbogbo, Jesu tíí ṣe Oluwa tiwọn ati tiwa.
Nítorí wọn kò ní ẹ̀rí ọkàn tí ó lágbára, jíjẹ oúnjẹ bẹ́ẹ̀ jẹ́ àbùkù fún wọn.
Oríṣun àwòrán, AFP Àkọlé àwòrán, Ọpọ̀ àwọn tó ní sọọbu lẹ̀rù ń ba láti pada sí ibùṣọ wọn nítori rògbòdìyan míràn tún lèè bk silẹ̀.
S Embassy Kíni ẹ mọ̀ nípa Ọmọ́táyọ̀ Olútóyè, Ọ̀jọ̀gbọ́n obìnrin àkọ́kọ́ nínú ẹkọ́ èdè Yorùbá lágbàyé Kìí ṣe gbájúẹ̀ nìkan lọmọ Nàìjá ń ṣe lókè òkun!
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù ÌP&ID: Ẹgbẹ́ àgbáríjọpọ̀ ajàfẹ́tọ̀ọ́ fẹ̀hónú hàn l'Abuja lórí ìdájọ́ tó gbẹ́sẹ̀ lé $9.
Igbimo ijoba apapo ti bọwọlu owo to le ni bilionu meji naira fun ise akanse ni
Ibrahim Musa to jẹ agbẹnusọ fun IMN ṣalaye fun BBC pe ootọ ni pe ọmọ ẹyin awọn mẹta ti ku ni Kaduna bayii.
Ààrẹ àti oníròyìn ọ̀hún rán mi l'étí nípa “ọkọ̀ tó léfòó lórí irọ́”.
n óo sì pa ọba ati àwọn ìjòyè rẹ̀ run.
Ohun ti igbeṣẹ́ yi tunmọ si fun awọn to ba fẹ gba pali irina ni wi pe wọn yoo ni lati ṣe suuru titi di igba ti wọn ba bẹrẹ iṣẹ.
Bí odò tí ó kún bo bèbè rẹ̀ni yóo ṣe mú ìparun bá àwọn ọ̀tá rẹ̀;yóo sì lépa àwọn ọ̀tá rẹ̀ bọ́ sí inú òkùnkùn.
Wọ́n fẹ́ ṣe màgòmágó ìbò tó ń bọ̀ - Danjuma figbe bọnu Nibi ijoko ile asofin to waye lojọ Aje, ni wọn ti ka awọn ẹsun sise owo ilu basubasu si gomina Ambọde lọrun, ti wọn si ransẹ pe ko wa sọ tẹnu rẹ.
Àwọn aṣojú ẹgbẹ́ PDP àti APC gúnlẹ̀ sí ilé ẹjọ́ fún ìdájọ́ Oyetola àti Adeleke Alaga PDP ni Osun, Soji Adagunodo sọ fun awọn akọroyin wipe, ile ẹjọ ti sọ tirẹ, ko si si ohun ti awọn le ṣe si.
lo gba bọọlu sawọn lo ba di ọmi 2-2.
Ó fún Nàìjíríà l'èsì àwọn ẹ̀sùn tó fi kàn-án Ìdí tí mo fi ń ṣe ayẹyẹ ọjọ́ ìbí 35 lọ́dọọdún rèé- Allwell Ademola Wo ojú Akeem t'Ọlọ́pàá mú pé ó fipá bá ọ̀dọ́mọbìnrin kan sùn létí odò l'Oṣun Iléẹjọ gíga jùlọ da ẹjọ́ SDP àti PDP nù, wọ́n ní Yahaya Bello ló wọlé ìbò gómìnà Kogi Ibeere wo gan-an lo fa ibinu yọ lapo Fani-Kayode?
Bí ó ṣe n ṣe ayẹyẹ ọjọ́ ibi ló n ṣe ajọdun igbéyawo bákan náà lo tún fi yé àwọn ọlólùfẹ́ rẹ pe wọn kú afojusọ́nà, sinima agbélewo rẹ̀ túntun to n bọ.
Àwọn ọkunrin wọnyi ni wọ́n lọ bá Dafidi ní Sikilagi, nígbà tí ó ń farapamọ́ fún Saulu, ọmọ Kiṣi; wọ́n wà lára àwọn akọni tí wọ́n ń ran Dafidi lọ́wọ́ lójú ogun.
Minisita fun ọrọ ile-isẹ,okoowo ati idokoowo, ọmọwe Okechukwu Enalemah sọ fun awọn asọju nibi ipade naa pe orilẹ ede Naijiria ko tọwọbọ adehun okoowo ọfẹ nitori pe , awọn ti ọrọ naa kan , ko mọ nipa ọrọ naa.
Nígbàkúùgbà tí wọ́n bá bí mí léèrè pé : ‘Ibo lo ti wá?
N óo da ìdá kan yòókù yìí sinu iná, n óo fọ̀ wọ́n mọ́, bí a tíí fi iná fọ fadaka.
Bí ayé bá dẹ, lúlu l’ayé ń lu
O fikun un pe ọmọbinrin naa kabamọ iwa to hu.
 Àkọtọ ́ yìí ní kóńsónáǹtì mẹ ́ tàlélọ ́ gbọ ̀ n ọ ̀ kọ ̀ ọ ̀ kan wọn sì ní ẹ ̀ dà méjeméje .
Ṣugbọn oore-ọ̀fẹ́ tí Ọlọrun fi fúnni tóbi ju èyí lọ.
Oluwo: Èmi ni atọ́nà oyè Wàzírì nílẹ̀ Yorùbá
"Oloye Ẹlẹbuibọn ni ohun to mu ki ọba yatọ si awọn eeyan yoku naa ni ""oro ti ọba nṣe, ẹkọ ti wọn kọ ọba, awọn nnkan ibilẹ bii ifoju ba odu ati mimu wọn tẹ ifa pẹlu ṣiṣe oro idile gbogbo ti wọn jọba le lori fun wọn."
Ṣugbọn ẹ ma lọ, lai fi ami si ori ọrọ naa, Ayekofẹnifọrọ.
Ṣugbọn ẹ lọ, ẹ sọ fún àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ ati Peteru pé ó ti lọ ṣáájú yín sí Galili, níbẹ̀ ni ẹ óo gbé rí i, gẹ́gẹ́ bí ó ti sọ fun yín.
Aare orile ede Naijiria , Muhammadu Buhari lo foruko yii ranse si ile   igbimọ  asofin lati fonte lu u.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Lẹ́yìn ti South Africa fìdí rẹmi nínú ìfigagbága wọn pẹ̀lú Bangladesh lọjọ àìkú, èyí ti àwọn onímọ pè ni ìdíje to mú ìrunu báni jùlọ nínú eré ìdáya ife ẹyẹ agbaye Krikẹti ìmúra ọkan lára àwọn olólùfẹ ereidaraya ni Bangladesh.
Àbí ẹni tí ń fún eniyan ní ìmọ̀, ni kò ní ní ìmọ̀?
“Ní ojúran, lórí ibùsùn mi, mo rí olùṣọ́ kan, Ẹni Mímọ́, 
Ọjọ Ẹti ni ariwo ta yika agbaye pe aarẹ ilẹ Amẹrika ati aya rẹ naa ni kokoro arun shun n ba finra.
àyọrísí ìfaradà ni ìyege ìdánwò; àyọrísí ìyege ìdánwò ni ìrètí.
Nígbà tí wọ́n gbá a mú, 
Ó tún bi wọ́n pé, “Ṣé alaafia ni ó wà?
sibẹ, baba yín rẹ́ mi jẹ, ó sì yí owó ọ̀yà mi pada nígbà mẹ́wàá, ṣugbọn Ọlọrun kò gbà fún un láti pa mí lára.
Oríṣun àwòrán, @Jokeofficial Àkọlé àwòrán, Joke Silva: Modupe lọ́wọ́ àwọn algbatọ mi fún itóju wọn Gẹgẹ bi a ti gbọ, awọn alagbatọ lo gba Joke Silva tọ ni ile ọmọ alainiya kan ni àdúgbò Yaba nilu Eko.
atimọle, di igba ti iwadii yoo fi pari.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Temitope Akinnusi: Ọ̀pọ̀ iléeṣẹ́ ló takú láti gbà mí síṣẹ́ torí mo ní ojú kan Sugbọn o ni lọpọ igba, alawada ni oloogbe naa ati baba Sala saba maa n se ninu ere.
Ọna/Ina ilu Eko Lara akanṣe iṣẹ nla ti gomina Akinwumi Ambode gbe ṣe lọdun 2016 ni iṣẹ na.
Fayoṣe: Mo rọ àwọn asòfin Ekiti láti súgbá Fayẹmi
Wọn ni ohun to n dun awọn ni pe ijọba Naijiria ko gbe igbese lati mojuto awọn iṣẹlẹ wọnyii.
Ni ọjọ Isegun ni agbẹnusọ fún ileeṣẹ ọlọpaa ni Eko Chike Oti sọ fun akoroyin BBC Yoruba wipe, oun kò tíì mọ ọjọ́ tí olorin naa yoo foju ba ile ẹjọ.
Ọjọ Kẹwaa osu Kẹsan ọdun 2020 si ni ijọba apapọ sefilọlẹ eto mejeeji naa, labẹ ileesẹ to wa fun ifẹsẹmulẹ ọrọ aje nilẹ Naijiria.
“Ọrọ yii naa lo ṣokunfa akori ipade apero ti saa yii ti wọn pe ni “Nigbaradi fun Eto Idibo ti yoo waye ni irọwọ Irosẹ, ti yoo si jẹ Ojulowo”.
orísi àwọn arùn dálé iye irúfẹ ́ kòkòrò tí ó wà níbẹ ̀ : paucibacillary àti multibacillary .
Ẹ kò ní lè dé ibi tí mò ń lọ.
wa tele lo, nipa lila ona oju’rin lati mu adinku de ba igboke-gbodo oko loju
”Pilatu sọ fún wọn pé, “Ẹ̀yin fúnra yín ẹ mú un, kí ẹ kàn án mọ́ agbelebu, nítorí ní tèmi, n kò rí ẹ̀bi kankan tí ó jẹ.
O ni gbogbo dukia tí oun fi aarọ ọjọ aye oun ko jọ ni oun ti ta tan lori aisan naa, to si n rọ ọmọ Naijiria lati ran lọwọ.
Nígbà tí ó di ìrọ̀lẹ́, ó jókòó láti jẹun pẹlu àwọn mejila.
Ile-ejo to ga ju lorile-ede Libya gbegi dina gbogbo ipenija ofin ti a fi le se akosile ofin lojo-Ru, eyi ti yoo faye gba ipinnu awon ara-ilu.
Ọ̀kan ninu àwọn angẹli meje tí ó mú àwo meje lọ́wọ́, tí ìparun ìkẹyìn meje wà ninu wọn, ó wá bá mi sọ̀rọ̀.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù #justiceforDonDavis: Orí ayélujára n gbóná janjan fún ariwo ìdájọ́ fún akẹ́kọ̀ọ́ kan níléèwé Kumuyi 28 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Oríṣun àwòrán, /Deeper Life High SchoolDeborah Okezie Ori ayelujara n gbona janjan lọwọlọwọ ni Naijiria, nitori bi awọn ọmọ orilẹ-ede yii kan se n polongo fun idajọ ododo fun ọmọdekunrin kan ti awọn akẹkọọ to julọ kan se fi ipa ba lopọ.
27 Ògún 2019 Oríṣun àwòrán, @EarlJoey_.
Amọ ohun to tun pa wọn pọ ni igbesẹ ti ijọba ipinlẹ Kano gbe lati yan Emir mẹrin kun Emir Sanusi lati ma a se isakoso ilu kan.
Agbẹnusọ ileeṣẹ ọlọpaa ipinlẹ naa, Tee-Leo Ikoro lo fidi ọrọ naa mulẹ fun BBC.
Ó bẹ̀rẹ̀ sí sọ̀rọ̀ pẹlu ìgboyà ninu ilé ìpàdé àwọn Juu.
Amofin Lawal ṣalaye pe bi ijọba ba wa kuna lori awọn agbekalẹ rẹ wọnyii ko si ohun to n di awọn lọwọ iwọde awọn niyẹn.
Kí ìtìjú bo àwọn ọ̀tá mi bi aṣọ,àní, kí wọn gbé ìtìjú wọ̀ bí ẹ̀wù.
Gbọ́ ọ̀rọ̀ lẹ́nu afurasí tí Ọlọ́pàá ní ó pa Barakat Bello, Grace Oshiagwu àtàwọn míì l'Akinyele Ibadan Èèmọ̀!
Ikoyi Prison: Wáyà iná já lu ẹlẹ́wọ̀n márùn ún lọ́gbà ẹ̀wọ̀n l'Eko, ọ̀pọ̀ w'à níléèwòsàn
Ninu ilẹ̀ ìdajì ẹ̀yà Manase, wọ́n fún wọn ní àwọn ìlú wọnyi pẹlu àwọn pápá ìdaran tí ó wà ní àyíká wọn: Taanaki, ati Gati Rimoni, wọ́n jẹ́ ìlú meji.
Ìjọba ìpínlẹ̀ Eko rọ àwọn tó bá ọmọ Nàìjíríà tó k'árùn COVID-19 wọ bàlúù láti jókó sílé fún ọjọ́ mẹ́rìnlá Ẹni ti wọn ṣẹṣẹ kede yii ko ni nkankan se pẹlu ọmọ orilẹ-ede Italy to ko arun naa wọ Naijiria.
Ọ̀pọ̀ ló ṣì n ṣelédè lẹ́yìn Barrywonder!
Ajọ naa fikun pe, gbogbo igbesẹ to ba tọ ni oun yoo gbe, lọna ati tẹle ofin ti ijọba apapọ pa laṣẹ fun wọn.
Ohun ti a gbọ ni pe Kembi, ọmọ ogun ọdun ṣabẹwo si ọrẹkunrin rẹ ni Ikorodu eyi to sọ pe miliọnu meji owo naira loun gba lati fi ọmọdebinrin naa joogun.
Kí ọlá ati ògo jẹ́ ti Ọba ayérayé, Ọba àìkú, Ọba àìrí, Ọlọrun kan ṣoṣo, lae ati laelae.
Àwọn ọmọ ogun Siria bá sá.
Àtúntẹ̀ ti lọ́wọ́lọ́wọ́ yìí tún àwọn ònkà ọjọ́ ṣe síi àti àwọn orúkọ ibìkan ó sì ṣe àwọn àtúnṣe mìíràn.
Èrò ọmọdé gbáà ni èyí, à ṣé ikú kò mọ ọmọdé, bẹ́ẹ̀ ni kò mọ àgbà, ẹni ikú bá rí ni ikú ú mú lọ.
Ao sọ agbara lati tun awọn sẹẹli wa ṣe nu Ara wa ni agbara lati dena ki awọn ẹya to ti bajẹ pọ ninu sẹẹli wa.
Awọn mii ni Raab, Boris Johnson ti Donald Trump, aarẹ ilẹ̀ Amerika ni oun faramọ atwaọn miran.
Gege bi egbe PDP se sọ pe, ninu atẹ ayelujara ti won n lo lasiko eto
    Ní ìtọ́jú ẹbọra olójú kan, àgbègbè ilé Ikú,
Mo bá bẹ̀rẹ̀ sí gbààwẹ̀, mo sì ń gbadura sí Ọlọrun ọ̀run pé, 
Jesu tún wí fún wọn pé, “Nígbà tí ẹ bá gbé Ọmọ-Eniyan sókè, nígbà náà ni ẹ óo mọ̀ pé èmi ni, ati pé èmi kò dá ohunkohun ṣe fúnra mi, ṣugbọn bí Baba ti kọ́ mi ni mò ń sọ̀rọ̀ yìí.
"Oríṣun àwòrán, Bolu Akin-Olugbade Gbogbo awọn to sunmọ lo mọ wipe o fẹran Rolls Royce Limonsine ko to jade laye,to si jẹ pe mẹwaa iru rẹ lo lo nigba aye rẹ Ọdun 1984, nigba ti Akin-Olugbade wa ni ẹni ọdun mọkanlelogun, lo kọkọ ra ọkọ bọgini Rolls Royce (Luxury) rẹ Rolls Royce Cullinan - RR Cullinan ($500,000) ni ikẹwa to ra ni ọdun 2019 Awọn ọkọ Rolls Royce yoku ni o kọ orukọ rẹ si lara bii ""BOLU 1, 2, 3, 4, 5…"" Ọkọ bọgini Phantom Convertible Drophead Ọkọ bọgini Ghost, 2018 Phantom V111."
’’Lasiko irinajo re lo si Vienna , ojogbon Osinbajo yoo maa
Eleyi je eekeji otooto ni odun meje ti awon agbesunmomi yoo tun ji Pa Michael Obi gbe  sa lo.
Igbakeji aare orile ede Naijiria, Yemi osinbajo ti salaye pe orile ede yii gbodo mojuto eto oro aje lona ti yoo fi lee satileyin bi  iye awon eniyan se n po si lorile ede yii.
O ni ile iwe girama ni oun wa nigba toun ṣakiyesi wi pe irun oun n ja.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ondo: Dejí sun ọmọ méje àtagbalagba meji mọ́lé nítorí pé ó ń bínú Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Barister lo bi gbogbo oníṣẹ́ fújì -Oṣupa Àìle è ka kéú ló sọ mí di Krìstíẹ̀nì - Adewale Ayuba Èèmọ̀ wọ̀lú!
mamser jẹ ́ gbólóhùn ìgé-kúrú fún ( mass mobilization for self reliance , social justice , and economic recovery ) Ó jẹ ́ ìgbésẹ ̀ òṣèlú láti dáni lẹ ́ kọ ̀ ọ ́ ní orílẹ ̀ èdẹ nàìjíríà , tí Ààrẹ babángídá buwọ ́ lù gẹ ́ gẹ ́ bí ìlànà kan pàtàkì tí ẹ ̀ ka ètò ìṣèlú lábẹ ́ ììjọba tí dr.
Ninu eyi ni Kudirat n ba Abiola jiya.
“A dupe pupo fun atileyin ati akitiyan ijoba orile-ede China fun ibasepo won lati mu idagbasoke ba eto oro aje orile-ede Naijriia.
Pẹpẹ ẹbọ sísun tòun ti ojú ààrò onídẹ rẹ̀, pẹlu àwọn ọ̀pá rẹ̀ ati àwọn ohun èlò tí ó jẹ mọ́ ti pẹpẹ ẹbọ, agbada omi ati ìtẹ́lẹ̀ rẹ̀.
Ní òru ni wọ́n dé ìlú náà, wọ́n sì yí i po.
"Àlàyé rèé lórí bí wọ́n ṣe pa Ebila, olórí àwọn ""One million boys"" n'Ibadan Tolulope Arotile: Ọ̀rẹ́ Tolu ṣàlàyé bí ìjàmbá ọkọ̀ tó ṣekúpa á ní Kaduna ti ṣẹlẹ̀ Yahaya Bello ni alága ìgbìmọ ìdìbò abẹ́lé gómìnà ìpińlẹ̀ Ondo Funke Akindele fún mi lówó tí mo fi gba ilé, kò ra ilé fún mi o - Ajirebi Amọ nigba ti wọn n tara lori iku ọmọbinrin naa, akọwe fun ẹgbẹ Afenifere, Yinka Odumakin pẹlu Aarẹ ọna Kakanfo ilẹ Yoruba, Gani Adams ati ẹgbẹ onkọwe to jẹ ajafẹtọ ẹni, Huriwa ni ọrọ iku Tolulope naa mu ifura lọwọ."
Ṣugbọn ó dàbí ẹni pé a dì wọ́n lójú, wọn kò mọ̀ pé òun ni.
Ọ̀tọ̀ lọ̀rọ̀ táa ń pè yín sí - Aráa Ketu Ẹgbẹ naa ni eyi fihan pe bi ijọba ba ti kuna lati ṣe ohun meji yii, ko si ijiroro kankan to lee waye nitori pe o yẹ ki ijọba fi ọrọ naa lọ araalu ki wọn to da iru aṣọ bẹẹ ṣoro.
Kano Emirate: Ṣé àwọn gómìnà ò máa tọwọ́ bọ àṣà lójú báyìi?
Ojogbon Conde ni pe oun ni
Oríṣun àwòrán, @AfricaCeleb Bakan naa lo fikun pe, ẹgbẹ NANS yoo tun se abẹwo ibanikẹdun sawọn ẹbi oloogbe, awọn alasẹ fasiti Fuoye, awọn ọba alaye lagbegbe naa ati awọn akẹkọọ to farapa ninu laasigbo naa.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Tunde Bakare: Ìjà àgbà méjì!
Àwọn alálẹ̀ kò ní forí jìn mí tí ń kò bá ṣe ọdún Ṣàngó - Alaafin Buhari, ṣí ìwé àkọsílẹ̀ orúkọ àwọn gómìnà tó jẹ̀bi ìkówójẹ, káráyé mọ̀ wọ́n - SERAP Ibùdó Amúnáwá kọsẹ́ lẹ́ẹ̀mejì lọ́jọ́ márùn ùn SERAP gbé Fashola lọ sílé ẹjọ́ nítorí owó iná Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Ó ti di ènìyàn ogójìlénígba ti ìjọba tí sèdájọ fún láti oṣù kẹ̀wá ọdún tó kọjá lóri ìwà ìgbésùmọ̀mí.
Afunrasi afipajinigbe k'agbako ni Ogun Aajo SARS ti ijọba apapọ ti pa afurasi ọmọ ẹgbẹ afipajinigbe kan, ti wọn n s'ọsẹ ni agbegbe Ilaro ni ijọba ibilẹ guusu Yewa ni ipinlẹ Ogun, ajọ ọlọpa ti sọ eyi di mimọ.
“Ohun tí ẹ óo máa fi rúbọ sí OLUWA nìwọ̀nyí: ìdámẹ́fà òṣùnwọ̀n eefa kan ninu òṣùnwọ̀n homeri ọkà yín kọ̀ọ̀kan, ati ìdámẹ́fà òṣùnwọ̀n eefa kan ninu òṣùnwọ̀n homeri alikama yín kọ̀ọ̀kan.
Ẹlẹ́rìí èké a máa kẹ́gàn ìdájọ́ òtítọ́,eniyan burúkú a máa jẹ ẹ̀ṣẹ̀ bí ẹni jẹun.
Ọ̀pọ̀ àwọn alábàáṣiṣẹ́pọ̀ Trump ló ti ni ààrun náà láti bi ọjọ́ díẹ̀ sẹ́yìn.
Ṣé ó mọ Age mi ni
Ẹ wò ó, wọ́n ti gbó, wọ́n sì ti ya.
idibo naa yoo lọ ni irọwọ-irọsẹ.
Mo fẹ́rẹ̀ dákú, nígbà tí ó sọ̀rọ̀,mo wá a, ṣugbọn n kò rí i,mo pè é, ṣugbọn kò dáhùn.
Pẹlu ipá ati ọwọ́ líle ni ó fi kó wọn jáde,nítorí pé ìfẹ́ rẹ̀ tí kì í yẹ̀ wà títí lae.
Nígbà náà ni wọ́n tó gba ọ̀rọ̀ rẹ̀ gbọ́,wọ́n sì kọrin yìn ín.
Èmi kò ní kí Shiite má ṣe ẹ̀sìn won o -Muhammadu Buhari Mo ṣe tán láti kú tọmọ taya bí wọn kò bá fi El-Zakzaky sílẹ̀ - ọmọ ẹgbẹ́ Shiite Etí ìjọba Buhari di sí ìmọ̀ràn àwọn ará ìlú -Jiti Ogunye Fulani nìkan kọ́ ló ń pa ènìyàn ní Naijiria -Tinubu Ganduje ijọba apapọ kọ lo yẹ ko ṣagbatẹru ọrọ ruga fawọn Fulani ẹlẹran ọsin, o ni awọn ipinlẹ to ba nifẹ sii lo yẹ ko ṣagbatẹru eto naa.
"Aideloje sọ loju opo Facebook BBC Yoruba pe ''Kilode ti won o fi pada tunsọ ni ""Nigeria Airways"" eyi ti n se orukọ ti wọn n jẹ tẹlẹ tẹlẹ?"
    Ìgbà tí o wí báyìí tan, ó kọjù sí ẹru rẹ̀ tí o dì sílẹ̀, ó ni, Ẹ máa kó èyí lọ sílé mo ń bọ̀.
OLUWA Ọlọrun ní, “Ẹnu ọ̀nà àgbàlá inú tí ó kọjú sí ìlà oòrùn gbọdọ̀ wà ní títì fún ọjọ́ mẹfa tí a fi ń ṣiṣẹ́.
Gbogbo àwọn alufaa tí àwọn ọba Juda ti yàn láti máa rúbọ lórí pẹpẹ oriṣa ní àwọn ìlú Juda ati ní agbègbè Jerusalẹmu ni Josaya dá dúró, ati gbogbo àwọn tí wọn ń rúbọ sí oriṣa Baali, sí oòrùn, òṣùpá, àwọn ìràwọ̀, ati àwọn nǹkan tí wọ́n wà ní òfuurufú.
Lẹ́yìn wákàtí díẹ̀ tí ọ̀rọ̀ yìí jáde ní mínísítà náà ba fèsì pé irọ́ pọ́nbélé tó jìnà sóòtọ́ ni ọ̀rọ̀ Abike Dabiri.
Ìbọn ti kò lo ọ̀ta làwọn ọlọ́pàá a máa kọ́kọ́ yìn- IG Omíyalé gbẹ̀mí èèyàn méje, o tún ba dúkìá púpọ̀ jẹ́ Wo aláànú tó n wa ọkọ̀ tí wọ́n fi n gbé aláìsàn lọ́fẹ̀ẹ́ Awọn akọṣẹmọṣẹ bii Jeremy Melvin to jẹ ayaworan ile ni o to ọdun mejilelaadọsan ki wọn to kọ Notre-Dame tan tẹlẹ.
Aare ati iyawo re ni eni akọkọ ti won kọkọ dibo ni wodu Sarkin Yara.
Hanna ṣalaye pe awọn ọmọ orilẹede Naijiria ọun gbimọ pọ pẹlu awọn aṣoju ijọba apapọ ati ijọba ipinlẹ lati lu awọn kan ni jibiti.
 Ìkóríta ìpínlẹ ̀ mẹ ́ tẹ ̀ ẹ ̀ ta ni Ọ ̀ ra-ìgbómìnà wà , ṣùgbọ ́ n ìpínlẹ ̀ Ọ ̀ yọ ́ ní wọ ́ ṣírò rẹ ̀ mọ ́ .
Wọ́n a máa jẹ ilé àwọn opó run.
Sugbọn, Adekunle pada ja ọ̀bẹ gba mọ ọ lọwọ, o fi gun Stanley ni aya, o si tẹ ẹ mọ́lẹ̀ titi to fi ku.
Amọṣa, ẹtọ rẹ ni lati kọ jalẹ paapaa ti o ba ri pe kikọ iru iwe bẹẹ lee ko ọ sinu wahala.
Sowore, AAC ti yọ Leonard Ezenwa tó kéde ìyọnípò Ṣòwòrẹ́ Ìbọ̀wọ̀ fófin ni bí wọ́n se fi Sowore sílẹ̀ Sowore takú, kò jẹun ní àgọ́ ọlọ́pàá torí májèlé - Deji Adeyanju Adájọ tí so ìjòkò igbẹ́jọ́ Omoyele Sowore rọ dì ago mọ̀kànlá Ẹsun meje ni awọn ajọ DSS fi kan Sowore bayii bii eyi ti wọn ni o bu aarẹ Buhari lori itakun agbaye, kiko owo jade lọna aitọ ati iditẹgbajọba.
Iroyin sọ wi pe ẹkun ariwa ni ọkọ naa n ri irinajo lọ ki o to di wi pe o padanu ijanu ọkọ lasiko to n sa fun awọn ẹṣọ aabo oju popo niluu Ogbọmọṣọ, ṣugbọn adari ẹṣọ aabo oju popo to n bẹ ni agbegbe naa, Bọlade Olugbẹsan sọ wi pe irọ to jina si ọọtọ ni ẹsun naa.
 bí ó tilẹ ̀ jẹ ́ pé ọpọ ́ lọpọ ́ onígbàgbọ ́ ló gbàgbọ ́ pe ènìyàn ìyanu ni jésù , àti pé ìṣẹ ̀ dá rẹ ̀ yàtọ sí ti ẹ ̀ dá alàyè yókù wọn a ( àwọn onígbàgbọ ) si tún máa kóni láti tẹ ̀ le àwọn ìkọ ̣ ́ ni jésù , síbẹ ̀ síbẹ ̀ , imọ awọn onígbàgbọ ́ nipa ohun tí jésù jẹ ́ nítòótọ ́ kò jọra wọn .
Ṣọ́ra rẹ, kí á má baà dán ìwọ náà wò.
Ṣugbọn Mose tún ní, “OLUWA mi, mo bẹ̀ ọ́, rán ẹlòmíràn.
Rinu Oduala Bi ẹ ba ti n fọkan ba iwọde ENDSARS bọ, yoo ṣoro ki ẹ to ma da arabinrin yi mọ ninu awọn oluwọde ni ipinlẹ Eko.
Micheal Obafemi lo kọkọ dana sile Chelsea ninu abala kini ifẹsẹwọnsẹ naa.
Usa kú sẹ́gbẹ̀ẹ́ àpótí ẹ̀rí náà.
Mo sọ fún ọ pé: Peteru ni ọ́, ní orí àpáta yìí ni n óo kọ́ ìjọ mi lé; agbára ikú kò ní lè ká a.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Nigeria Security Tracker: Ọ̀pọ̀ ọmọ Naijiria ti kú sí rògbòdìyàn ó n ṣẹlẹ̀ 6 Òkùdu 2019 Oríṣun àwòrán, AFP/Getty Images Àkọlé àwòrán, Ipaniyan kaakiri Naijiria ti sọ ọpọ sinu ibanujẹ Iwadii ajọ orilẹ-ede Amerika kan ló fidi ẹ mulẹ pé ọpọ ẹ̀mí ti sọnu ni Naijiria.
Ko da alaga ajọ to n ri si ọrọ ọlọpaa, Ọgbẹni Musiliu Smith ati akọwe agba ajọ naa, Ọgbẹni Mbaeri Maurice Nnamdi naa ko gbẹyin nibi ipade ọhun.
Ni kete ti abẹrẹ naa ba ti jade, mo rọ yin lati lọ gba a.
Ọkan lara awọn oluṣakoso idanwo ọhun to ba BBC sọrọ, Jerry Alfred sọ pe awọn ọmọ ile iwe naa ṣe mẹrin leṣe ninu awọn mẹfa to lọ ṣakoso idanwo ọhun nile iwe naa.
Onírúurú ǹkan ní ń bẹ ní aginjù.
Bi orilẹede naa tilẹ jẹ wi pe ibẹ ni awọn to lowo ju nilẹ Afirika pọju si, sibẹ, ni saa kẹrin ọdun 2018, ida mẹtadinlọgbọn ninu ọgọrun awọn eeyan orilẹede naa ni ko niṣẹ lọwọ.
Abi ki gbogbo oṣiṣẹ darapọ mọ Ibrahim El-Zakzaky lahamọ ni ki wọn lee maa gba ẹgbẹrun lọna mẹrindinlọgọfa (N116,000) lojumọ.
Ẹni to bori: South Africa Nigeria vs Cameroon.
Ohun márùn-ún tí Atiku ń bèrè lọ́wọ́ Buhari níbi ìpàdé rẹ̀ pẹlú Abdulsalam, Kukah APC pàṣẹ lọ rọ́ọ́kún nílé fún Amosun, Okorocha Ìpàdé ẹgbẹ́ alátakò l'Oyo yóò tẹ̀síwájú lórí bí wọn ṣe fẹ́ fẹ̀yìn APC gbá lẹ̀ Akala darapọ̀ mọ́ APC fún ìbò gómìnà Yinka Ajia ni oun ko ni owo pupọ tabi baba isalẹ kankan ṣugbọn ọkan oun balẹ pé ti wọn ba dibo fun oun erongba oun a san awọn eniyan Kwara si daadaa.
Lẹ́hìn èyí ọba yìí wáá lo ọgbọ́n kan, ó mú ìbọn rẹ̀ kékeré ó fi i sínú àpò ṣòkòkò rẹ̀ ó lọ sí inú ibojì olùfẹ́ obìnrin náà tí ń bẹ nínú ààfin.
Oga agba naa wa ro awon omo orile-ede yii nile loko ati leyin odi pe,”E je ki a lo asiko yii lati fi ife otito han sira wa, ki a si se ara wa bi osusu owo, papajulo fun isokan ati idagbasoke orile-ede Naijiria.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, SARS ti bẹ̀rẹ̀ ìgbésẹ̀ láti yọ àwọn ọ̀bàyéjẹ́ kúro Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Olaoluwa Aina (Torino FC, Italy); Abdullahi Shehu (Bursaspor FC, Turkey);
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Russia2018: àwọn àsìkò mọ́legbàgbé nínú ìdíje ife ẹ̀yẹ àgbáyé 16 Agẹmo 2018 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Rẹfirí Nestor Pitana ló darí ifẹsẹ̀wọnsẹ̀ àṣekágbá láàrin France àti Croatia Idije ife ẹyẹ agbaye 2018 World Cup ti orilẹ-ede Russia gbalejo rẹ ti pari, ṣugbọn o kun fun awọn asiko mọlegbagbe.
Ǹjẹ́ ẹ mọ̀ pé Cameroon ni wọ́n ti ru Kìnìhún VI wá?
Ko si olukopa kankan ti yoo san owo fun fọọmu naa tabi lati jẹ anfaani yii.
Ifeoma Thelma ati Onyemaechi ni wọn ṣe igbeyawo lọdun 2014 ti wọn si bẹrẹ si ni woju Oluwa fun ẹbun ọmọ rere to jẹ ìní Oluwa.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Pneumonia: Dókítà ní kòkòrò àìfojúrí ló ń fàá Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Atẹjade kan ti ajọ naa fisita lori Twitter fihan pe, igbesẹ tuntun naa waye lẹyin ti INEC ṣe ipade pẹlu awọn ẹgbẹ oṣelu.
Ileesẹ ọlọpaa ipnnlẹ Ogun lo fi ọrọ naa sita pe ọwọ ti tẹ baba agba naa, Hunsu Sunday, ẹni aadọrin ọdun, to fun ọmọ ọmọ rẹ, ọmọ ọdun mẹẹdogun loyun.
BBC 100 Women 2019: Wo ọmọ Nàíjíríà kan tó wà nínú wọn Njẹ́ o mọ pé N3000 ló o sàn láti gbà kaadi ìdánimọ̀ míì bí tí tẹ́lẹ̀ bá sọnù?
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Mò máa ń fọ àwọ̀tẹ́lẹ̀ ìyá mi, ni ìṣe àwọn obìnrin fi wù mí - Bobrisky Ẹ bá mi wá nọ́ńbà ìpè òbí ọmọ Mummy Calm Down jáde - Yinka Ayefele Ọlọ́pàá sálọ fún aráàlú l‘Okeho, nígbà tí wọn yari láti ṣun olè méjì tó kù Ìpalẹ̀mọ́ ọdún Ileya kò rọgbọ ní Maiduguri, ojo ado oloro n rọ leralera Kí ìjọ mi ní Sagamu le gbòòrò ni mo fi ń ṣiṣẹ́ ajínigbé pawó - Pásítọ̀ O ni idi ti igbeyawo oun ṣe wa titi di isinyii ni wi pe, oun kii ṣe mọnamọna pupọ, nitori niwọntun wọnsi ni ọrọ toun, bẹẹ si ni Olorun lo gbe ẹbi oun ro.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'N500 dé fún gbogbo ọmọ tuntun lóṣooṣù bí mo bá di gómìnà Ondo - Adeleye AAC Iroyin to wa n tẹ BBC Yoruba lọwọ ni yajoyajo ni pe, ọjọ Kẹfa osu Kẹwaa ọdun 2020, ni wolii naa yoo mọ ibi ti ori n ba ẹsẹ rẹ ree.
Ṣugbọn bí o kò bá fi ara rẹ le àwọn ìjòyè ọba Babiloni lọ́wọ́, ìlú yìí yóo bọ́ sọ́wọ́ àwọn ará Kalidea, wọn yóo sì dáná sun ún, ìwọ pàápàá kò sì ní bọ́ lọ́wọ́ wọn.
Ẹlẹ́rìí èké kò ní lọ láìjìyà,bẹ́ẹ̀ ni òpùrọ́ kò ní bọ́ lọ́wọ́ ẹ̀san ibi.
Awọn onimọ sayẹnsi ti fihan pe Itakun ayelujara tuntun ti ileeṣẹ yii ṣe yoo mu ọja wọn gbooro sii tayọ bo ṣe wa lọdun 2014 lẹyin ti ileeṣẹ na ṣe iPhone 6 jade.
Opeyemi tun salaye pe, akoko ti okiki oun n lọ soke gidi, ti ohun gbogbo n ṣe deede, ni oun fi iṣẹ tiata silẹ lati ṣe igbeyawo nigba to ku diẹ, ki oun pe ẹni ọgbọn ọdun.
Ìtàn Àrọ̀gìdìgbà jẹ́ kí ń rò pé bàbá mi yan Yemọ̀ja ní àlè - Ọmọ Fagunwa Ẹfunsetan Aniwura, ọmọ Ẹ̀gbá tó di akíkanjú obìnrin nílẹ̀ Ibadan Ọọ̀ni obìnrin, Lúwòó Gbàgídà rèé, akọni tó ń gun ọkùnrin ní ẹṣin rìn Sanusi Adebisi Idikan rèé, olówó tó ń san owó orí fún gbogbo ọkunrin ilẹ̀ Ibadan Aarẹ ọna kakanfo Yoruba Itan igbe aye Basọrun Gaa yii ni ọpọ ẹkọ to kọ wa, paapa awọn alagbara lode aye, o si kọ wọn pe ki wọn rọra se.
O salaye pe, arowa yii pon dandan, toripe asiko ipolongo eto idibo yoo bere jake-jado orile-ede yii laipe ojo.
"Omotosho ni ""ọrọ naa ko kọ Sanwo-Olu lominu, nitori kii ṣee igba akọkọ ree ti alabaṣiṣẹpọ pẹlu rẹ yoo kaarun coronavirus."
Ọkọ̀ ojú omi ''fẹri'' kọlu afárá, ọkọ̀ méjì já sódò Adájọ́ pàṣẹ kí wọ́n fi ọlọ́pàá tó lọ́wọ́ nínú ikú Kolade Johnson sí àhámọ́ “Kò sí àgbègbè Nàìjíríà kánkan tó wà lábẹ́ àkóso Boko haram” Kí ló kàn olórí ọmọ ilé aṣòfin Osun pẹlú ìdájọ kòtẹ́milọ́rùn Sẹnẹtọ Adeleke?
Gege-bi oro re ,orile-ede Naijiria kun fun awon alumooni inu ile ti o le mu igbeeru deba eto oro-aje orile-ede Naiiria.
Iko agbaboolu orile-ede Iran je iko akoko ti yoo bale si orile-ede Russia lojo isegun(Tuesday), saaju idije boolu agbaye  ti yoo bere ni papa isere Luzhniki lojo kerinla osu kefa odun ti a wayii.
Ni Abuja, awọn ọmọ ẹgbẹ amofin kan ti bẹrẹ si ni ṣe iwọde ni oriko ẹgbẹ awọn amofin Naijiria (NBA) ni Abuja bayii.
Ọpọ lo si ti fẹẹ gbagbe pe awọn ṣe ọdun keresimesi ti ọdun 2018, ṣugbọn ọjọ keje oṣu Kini ni awọn ẹya Kristẹni kan ti a mọ si Coptic Christians n ṣe ti wọn.
EFCC: Irọ́ ni Fayoṣe ń pa, àwọn ilé rẹ̀ gangan la tì pa
Ẹni ti kò bá pa òfin mọ, á wọ ijọ̀ngbọ̀n ti ó lè fa ikú tàbi ẹ̀wọ̀n.
a lè pín wọn gẹ ́ gẹ ́ bi ìrísi àti àyè tí àwọn ẹgbẹ ́ oníṣé wọn wà , bíi alpha- ( α- ) , beta- ( β- ) , gamma- ( γ- ) or delta- ( δ- ) amino acid ; àwọn ẹ ̀ ka tókù ní lati ṣe pẹ ̀ lú òpó , ìwọn ph àti oníṣé irú ìsomọ ́ ẹ ́ gbẹ ́ ( aliphatic , acyclic , aromatic , tí ó ní hydroxyl àti sulfur , àti bẹ ́ ẹ ̀ bẹ ́ ẹ ̀ lọ .
awon irinsẹ oko naa ti o ti nilo atunse.
Ijọba ipinlẹ Ekiti naa wa rọ awọn eniyan lati maṣe ru ofin konile-o-gbele ki wọn ba le kapa arun naa ni ipinlẹ ohun.
Ṣugbọn ojú Oluwa kan síàwọn tí ó ń ṣe burúkú.
Fi ọwọ́ ara rẹ jà fún wọn,sì ràn wọ́n lọ́wọ́ láti borí àwọn ọ̀tá wọn.
Ninu ilé ìṣọ́ ìlú náà, Ọlọrun ti fi ara rẹ̀ hàn bí ibi ìsádi.
Lẹ́yìn náà, ọkọ rẹ̀ dìde, ó lọ bẹ̀ ẹ́ pé kí ó pada.
 Mohammad Mahmoud – Kaduna, Minisita fun ọrọ ayika(Environment) mẹ́tàlélógún) Mohammed Sabo Nanono – Kano, Minisita fun eto Ọgbin ati idagbasoke igberiko( Agriculture) mẹ́rìnlélógún ) Maj.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Wyclef Police Ibadan: Kí ni Ọ̀gá Ọlọ́pàá yóò ṣe fàwọn Ọlọ́pàá Ibadan tó ṣe obìnrin bó ṣe wù wọ́n nínúu fídíò?
Ó wá bi wọ́n pé, “Àwòrán ati àkọlé ta ni èyí?
Solomoni ọba mú kí fadaka pọ̀ ní Jerusalẹmu bí òkúta, igi Kedari sì pọ̀ bí igi Sikamore tí ó wà káàkiri ní Ṣefela ní ẹsẹ̀ òkè Juda.
Oríṣun àwòrán, Karen Charmaine Chanakira Ọrọ naa da ipaya ati iporuru ọkan si mi lara.
O jẹ alaga igbimọ awọn agba agbaye (The Elders) eyi ti aarẹ South Africa nigba kan ri, Nelson Mandela gbe kalẹ.
O soro yii nibi eto apero ti koko re da lori ‘Nigeria: A ko ni yee gbagbo ninu orile ede wa” ti o sagbateru re.
Wọn yóo wí pé, ‘Ilẹ̀ yìí, tí ó ti jẹ́ igbó nígbà kan rí, ti dàbí ọgbà Edẹni, àwọn eniyan sì ti ń gbé àwọn ìlú tí wọ́n ti wó lulẹ̀, tí wọ́n ti di ahoro, tí wọ́n sì ti run tẹ́lẹ̀; a sì ti mọ odi wọn pada.
Eyi ti ọpọ eeyan ko le gbagbe laelae ni idije ife ẹyẹ agbaye eyi ti Maradona gba pẹlu orilẹede rẹ lọdun 1986.
O si tun yọju sita pe mẹrin ninu ija marun to ja sẹyin ni ṣisẹ-n-tẹle lo ti padanu bayii.
Fọ́tò tó ṣàlàyé àwọn ayò àràmọ̀ndà Ronaldo Èèkàn agbábọ́ọ̀lù sọ̀rọ̀ nípa góòlù Ronaldo Transfer Window: Pogba, Maguire, Bale, Neyman, báwo ni nkan ṣe ń lọ?
 Àwọn ènìyàn inú ilé a sì máa pe Ògògó ní alàgbọ ̀ ọ ́ -wá1 .
Ọgbẹni Adamu to sọ ọrọ naa lasiko to n ṣi ipade ijiroro kan to waye laarin awọn ọga lawọn ileewosan ileeṣẹ ọlọpaa ni olu ileeṣẹ naa sọ pe ki adinku de ba a lati wakati mejila di mẹjọ.
Ẹ gbọ ọrọ rẹ siwaju si: Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fọ́nrán ohùn, Lagos Chinese restaurant: Ayorinde ní Ìpínlẹ̀ Eko ń gbé ìgbésẹ̀ nípa ilé oúnjẹ elẹ́yàmẹ̀yà Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
 Eyi lo sokunfa bi a se panupo lati pese igbimo alaabo ti yoo se ise akanse ohun, ni erongba lati ri daju pe aabo ti o peye wa fun won nipinle naa,”Bakan naa, asofin ti o soju fun arin gungun ipinle Zamfara, Kabiru Marafa dupe pupo lowo aare Muhammadu Buhari fun awon ise akanse re ti o n gbese lati ri daju pe, oun pese aabo fun emi ati dukia awon ara ilu jakejade orile-ede yii.
 Ìṣẹ ̀ lẹ ̀ àrùn náà ti wáyé ní àwọn orílẹ ̀ -èdè tó ju 32 lọ .
A kò ní fi pamọ́ fún àwọn ọmọ wọn;a óo máa sọ ọ́ fún àwọn ìran tí ń bọ̀ lẹ́yìn–iṣẹ́ ńlá OLUWA ati ìṣe akọni rẹ̀,ati iṣẹ́ ìyanu tí ó ṣe.
N óo dá ìdàrúdàpọ̀ sílẹ̀ láàrin àwọn ará Ijipti,olukuluku yóo máa bá arakunrin rẹ̀ jà,àwọn aládùúgbò yóo máa bá ara wọn jà,ìlú kan yóo gbógun ti ìlú keji,ìjọba yóo máa dìde sí ara wọn.
World Environment Day: Atẹ́gùn burúkú ń pa mílíọ̀nù 8.
ki  idagbasoke ba ise  ati igbe aye awon obinrin naa .
Awon yooku ni:  Ugochi Emenayo (Nasarawa Amazons),  Joy Jegede (Bayelsa Queens),  Mariam Ibrahim (Nasarawa Amazons) and  Maureen Okpalla (Confluence Queens).
Ọpọlọpọ awọn eeyan ti pa epo ti lati maa fi jẹ iṣu bayii, ti wọn si ti n lo ẹyin dindin, ṣugbọn iṣu ati epo ma n dun laye atijọ ninu oko.
Kò ní kùnà, bẹ́ẹ̀ ni ọkàn rẹ̀ kò ní rẹ̀wẹ̀sì, títí yóo fi fìdí ìdájọ́ òdodo múlẹ̀ láyé.
Iṣẹ alufaa lo wu u lati ṣe ṣaaju ki awọn obi rẹ to parọwa si i pe ko darapọ mọ isẹ ologun.
Ooni Ile Ife: Àwọn ohun tó yẹ kí o mọ̀ nípa Ọ̀ọ̀ni Ilẹ̀ ifẹ̀ to pe Ọdún mẹ́ta lórí ìtẹ́ Òdùduwà
Eeyan 39,977 ni apapọ ni arun naa ti fara kan labẹ ayẹwo lorilẹede Naijiria.
Aláàfin yẹ́ Lizzy Anjọrin sí níbi ayẹyẹ ìwúyè rẹ̀ Ìgbín ní èmi àti ìyá mi máa ń he kiri, ká tó lee jẹun - Lizzy Anjọrin Mercy Aigbe bu èpè jó àwọn tó ní gómìnà kan ló ra ilé fún-un Ibeere yii lo bi Lizzy ati awọn ololufẹ rẹ ninu, ti wọn si n beere pada pe igba melo gan ni Toyin funra rẹ yọ pẹlu Lizzy lasiko to ba kede loju opo Instagram rẹ pe oun n se nkan ayọ abi oriire.
Ṣugbọn àwọn olódodo eniyan ni yóo dá àwọn obinrin náà lẹ́jọ́ panṣaga, ati ti apànìyàn, nítorí pé panṣaga eniyan ni wọ́n, wọ́n sì ti paniyan.
"Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: ""7000 Jàǹdùkú ló fọ́ ọgbà ẹ̀wọ̀n Okitipupa, jó mọ́tò, tí wọn si se òṣìṣẹ́ léṣe"" Buhari kọ́ ni ìṣòro wa, bó ṣe wà láti láéláé rèé - Fr Mbaka Àwọn ọ̀dọ́ fi ọ̀nà àrífín pe Tinubu lórí aago àmọ́ ó ní òun kò mọwọ́-mẹsẹ̀ nípa ìpànìyàn Lekki Wo díẹ̀ lára dúkìá tí jàǹdùkú sun níná l‘Eko torí ìwọ́de EndSARS Á ràgà bo CCTV Lekki bí i ẹ̀rí tó dájú fún ìwádìí ìpànìyàn - Sanwo-Olu SERAP gbé ìjọba àpapọ̀ lọ ilé ẹjọ́ àgbáyé ICC lọrí ẹ̀sùn ìpànìyàn ""Jàǹdùkú gún ẹ̀gbọ́n mi lọ́rùn, jó ilé àti mọ́tò wa méjì, kòròfò la wà"" Olùwọ́de 12 kú ni Lekki, 38 lapapọ kú lọ́jọ́ Isẹ́gun, 56 ni àròpọ̀ àwọn tó bá ìwọ́de lọ - Amnesty International Osinbajo gbarata lórí ìṣẹ̀lẹ̀ Lekki, ó ní ìdájọ́ òdodo yóò wà Iroyin ti a gbọ ni pe, awọn janduku kan fẹ yawọ agọ ọlọpaa to wa ni Testing Ground ni opopona Iwo road, lẹyin ti wọn dana sun ọkọ Operation Burst kan ni agbegbe naa."
N óo gbé àwọn ará Kalidea dìde, orílẹ̀-èdè tí ó yára, tí kò sì ní àánú; àwọn tí wọ́n la ìbú ayé já, tí wọn ń gba ilẹ̀ onílẹ̀ káàkiri.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Internet Fraud: Iléẹjọ́ ní kí ''Yahoo boy'' lọ darí ọkọ̀ f'óṣù mẹ́ta lẹ́yìn tó tan obìnrin òyìnbó jẹ 15 Ògún 2020 Oríṣun àwòrán, Facebook/EFCC Ileẹjọ giga kan niluu Ilorin nipinlẹ Kwara ti dajọ wi pe ki ọkunrin kan, ọmọ ọdun mẹtalelogun lọ dari igboke-gbodo ọkọ fun oṣu mẹta, lẹyin to jẹ ẹsun ilujibi ori ayelujara.
Ẹ wa kọ nipa itumọ Litireṣọ, isọri rẹ, abuda rẹ to fi mọ apoti isura ede Yoruba, ẹẹkan lọsẹ si ni eto yii yoo maa gun ori afẹfẹ.
Lẹ́yìn náà ni alufaa yóo fi àwọn ẹbọ náà níwájú OLUWA.
Lootọ orukọ Olabode Thomas lee ma jẹ ki awọn eeyan ranti adugbo kan ti wọn fi sọri rẹ ni agbegbe Surulere nipinlẹ Eko, amọ ohun ribiribi to se nile aye ko gbọdọ parẹ.
Máa bá a ǹṣó, ó ń dùn mọ́ mi, ọ̀rọ̀ rẹ ń wọ̀ mí létí, mo ń gbádùn ọ̀rọ̀ rẹ, ọ̀rẹ́ mi, Baba-onírùngbọ̀n-yẹ́úkẹ́ ọkùnrin.
’ Ṣugbọn ẹ̀yin ti sọ ọ́ di ibi tí àwọn ọlọ́ṣà ń sápamọ́ sí!
Mi o mọ nkan ti wọn ri ṣugban wọn ni ki n pada si ahamọ'' O ṣalaye pe, n ṣe ni oun maa n ranti iṣẹlẹ naa to waye ni ọdun 2018 lori pe wọn fẹ ri iwe ẹri oun.
Nítori àwọn àtúgbẹ́yẹ̀wò, o níra láti ṣe àkójọpọ fún àwọn ọkọ́ naa Orisun: Johns Hopkins University atawọn ajọ eto ilera ilu Iye akọsilẹ to waye gbẹyin 15 Oṣù Ṣẹ́rẹ́ 2021 20:44 WAT+3 ''A ko mọ si pe awọn ajinigbe naa n beere owo ki wọn to tusilẹ.
Kí á lè gba àyànfẹ́ rẹ là,fi ọwọ́ agbára rẹ gbà wá, kí o sì dá mi lóhùn.
Orisirisi ọkunrin ni mo ba sun lọna ati jẹ.
3 trillion ni CBN gbé jáde fún ọdun 2020 Àwọn iròyin ẹlẹ́jẹ̀ márùn ún tó fẹ́ẹ̀ tú Nàìjíríà ká Ki lo ti ṣẹlẹ tẹlẹ?
ọkàn rẹ̀ yóo pín sí meji.
Nígbà tí Maria dé ibi tí Jesu wà, bí ó ti rí i, ó kúnlẹ̀ níwájú rẹ̀, ó ní, “Oluwa, ìbá jẹ́ pé o wà níhìn-ín, arakunrin mi kì bá tí kú.
com/N4rFebqZpLBi a ko ba gbagbe pe, iko agbaboolu Barcelona gbo ewuro iya soju Liverpool ninu ipele kinni ifesewonse ohun pelu ami ayo meta sodo(3-0), ti opo eniyan si ti gbokan kuro lori Liverpool pe won sile e jawe olubori.
Ọjọ mẹẹrin ni awọn ọmọ naa fi wa ni akata rẹ, ki oun ati ikọ ajinigbe rẹ to gba miliọnu meji Naira, owo itusilẹ.
Ó ní bí òun ti ṣe ìdílé Jeroboamu, ọmọ Nebati, ati ti Baaṣa, ọmọ Ahija, bẹ́ẹ̀ ni òun óo ṣe ìdílé rẹ; nítorí o ti jẹ́ kí àwọn ọmọ Israẹli dẹ́ṣẹ̀, o sì ti mú òun OLUWA bínú.
Àsẹ̀hìnwá-àsẹ̀hìnbọ̀ bàbá mi yípadà ó di ènìyàn, ṣùgbọ́n a kò gbúròó Àǹjànnú-ìbẹ̀rù mọ́, ó ti kú pátápátá.
Bí Simiri ti gorí oyè, tí ó bẹ̀rẹ̀ sí jọba ni ó pa gbogbo àwọn ìdílé Baaṣa patapata.
Eyi fa irora fun ọpọlọpọ mẹkunnu.
Ǹjẹ́ ó jẹ́ nǹkankan lójú yín?
12: BURUNDI: O wa ni ila Oorun Adulawọ ti o si fun ọmọ Naijiria ni anfani ọgbọn ọjọ lati gbelu laisi iwe aṣẹ.
“Àwọn eniyan ń kígbe nítorí ọpọlọpọ ìnira,wọ́n ń bẹ̀bẹ̀ fún ìrànlọ́wọ́,nítorí àwọn alágbára ń tẹ̀ wọ́n mọ́lẹ̀.
Ohun ti gbajugbaja olorin Fuji, K1 si sọ̀ nigba naa ni pe, 'ko si idi fun mi lati ni ajọ̀ṣepọ̀ kankan pẹlu awọn ayaba laafin.
Sẹnetọ Ọlọrunnibẹ Mamoora Abii ni ọjọ kẹrindinlogun, osu keji, odun 1953 ni ipinlẹ Eko.
Agbẹkọya ilẹ Oodua ti ni ko si ọrọ nibẹ rara nitori ko si ijọba to le sọ pe ki onikaluku ma pese abbo fawọn eniyan rẹ bi o ṣe yẹ.
"O ni, ""Ninu iṣọkan, pẹlu iṣana ati ẹgba ọrun wa, ao sọ orilẹede yii di ominira."
Minisita kekere fun eto ilera ni Naijiria, Senetọ Olorunninbe Mamora ti sọ pe agbo aarun coronavirus ti orilẹ-ede Madagascar ko ran ṣe si Naijiria ko ba ọ̀fẹ́ de.
Ni bayii, awọn ọmọ naa ti wa ni ileeṣẹ ijọba ipinlẹ Ondo to n ri si ọrọ awọn obinrin, kọmiṣọna ileeṣẹ naa, Titilayo Adeyemi si ti ṣeleri pe oun yoo tu iṣu de isalẹ ikoko iṣelẹ ọhun.
A jọ ṣe ìyàwó pọ̀, a jọ bímọ ní ọjọ́ kan náà, a tún jọ máa ń ṣàìsàn pọ̀ ni Ọ̀yẹ̀ yóò là fún abẹ́rẹ́ ìfètòsọ́mọbíbí fáwọn ọkùnrin láìpẹ́ Andrew Haruna: So-bàtà tó di ọ̀jọ̀gbọ́n fásitì tó tún jẹ́ ọ̀gá àgbà pátá (V.
Malema ko fe gba pe, ki I se Zuma nikan ni o da yanpon-yanrin oloselu yii sile bikose egbe oselu ANC lapapo.
'Nigeria Air' ni orúkọ ti wọn yan fún un.
“Àwọn wọnyi ni kí o pín ilẹ̀ náà fún gẹ́gẹ́ bí iye wọn.
Nígbà tí ó ti sọ báyìí tán, ó kígbe sókè pé, “Lasaru, jáde wá!
 darandaran tààrà ni wọ ́ n.
Èyí ni ìṣe mi:Èmi a máa pa òfin rẹ mọ́.
Wọ́n máa lè jẹ ogún àti ẹ̀tọ́ láti di ìbò.
Oríṣun àwòrán, Other Junior Senaya to jẹ ọkan lara awọn agbabọọlu fikun ọrọ Adebayor pe, ninu ọkọ lawọn wa tawọn n gbọ orin, ṣadeedee lawọn bẹrẹ si ni gbọ iro ibọn ninu igbo.
Eyi to tumọ si pe awọn obinrin ti ko niye ni yoo ti ko aarun naa lara rẹ.
OLUWA yóo bi odi gíga rẹ̀ wó, yóo wó o palẹ̀, yóo sì sọ ọ́ di erùpẹ̀ ilẹ̀.
Awọn orilẹede to ni akọroyin to pọju ni agbaye ree ni ọdun 2018: Turkey - 68 China - 47 Egypt - 25 Saudi Arabia and Eritrea - 16 Iṣẹ iroyin ati ijọba awa-arawa Ajọ Iṣọkan agbaye (UN) ti tan ina soju ọrọ ipa nla ti awọn oniroyin n ko ninu ijọba awa-arawa, paapaa nigba idibo.
Àwọn sẹnatọ nínú atẹjade ti wọn fi sita kìlọ̀ pé, àwọn aṣofin ẹgbẹ́ oṣèlú PDP kò ní gba ki ará ìta lọ́wọ́ nínú bi àwọn yóò se yan adari tuntun.
Àwọn kan bá lọ sọ fún àwọn ará Gasa pé Samsoni wà níbẹ̀.
Ọlọrun náà ni ó tún ń mú kí ìmọ̀ rẹ̀ tí ń jáde láti ara wa máa gba gbogbo ilẹ̀ káàkiri bí òórùn dídùn níbi gbogbo.
Dájúdájú Ọlọrun àwọn Juu ati ti àwọn orílẹ̀-èdè yòókù ni.
Ilana isegun oyinbo fi ye wa pe, ti ololufẹ meji ba ha sinu ara wọn lasiko ere ifẹ, wọn ko nilo lati paya rara, ifarabalẹ nikan ni wọn nilo.
Dipo eyi, jẹ ki a fẹ oju awọn eeyan to n san owo ori.
Amọṣa o, wọn ni ajọdun naa ko ni di lils bibọ ọkọ ati ẹsẹ lọwọ.
Agbẹnusọ fun ile iṣẹ ọlọpaa Folasade Odoro lo fidi ọrọ mulẹ ninu atẹjade kan.
Mo duro digbi lati siṣẹ sin awọn ọmọ Naijiria labẹ iṣakoso Aarẹ Muhammadu Buhari.
Lẹ́yìn náà, kí o wí níwájú OLUWA Ọlọrun rẹ pé, ‘Gbogbo ìdámẹ́wàá tíí ṣe ohun ìyàsímímọ́ ni mo ti mú kúrò ninu ilé mi, mo sì ti fi fún àwọn ọmọ Lefi ati àwọn àlejò, ati àwọn aláìní baba, ati àwọn opó, gẹ́gẹ́ bíi gbogbo àṣẹ tí o pa fún mi.
Nígbà tí ó bá yá, ẹ̀yin gan-an ni ẹ óo tún máa pariwo ọba yín tí ẹ yàn fún ara yín, ṣugbọn OLUWA kò ní da yín lóhùn.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Pistachio Green Puppy: Àwọn ẹgbẹ́ rẹ̀ jẹ́ aláwọ̀ funfun, tí òun sì jẹ́ aláwọ̀ ewé Ọgbẹni Adewuyi sọ pe awọn ẹṣọ Operation Burst to koju awọn janduku naa ri pe alaafia jọba pada lagbegbe ọhun.
Nígbà tí ó di alẹ̀ ọjọ́ tí wọ́n dá, èyí obìnrin ló kọ́ dé etí odò yìí tíó ń dúró de olùfẹ́ rẹ̀.
A tún rí ẹ̀rí tí ó dájú ninu àsọtẹ́lẹ̀ àwọn wolii, pé, kí ẹ ṣe akiyesi ọ̀rọ̀ yìí, nítorí ó dàbí fìtílà tí ń tàn ninu òkùnkùn, títí ilẹ̀ yóo fi mọ̀, títí ìràwọ̀ òwúrọ̀ yóo fi tan ìmọ́lẹ̀ rẹ̀ sinu ọkàn yín.
Igbesẹ ijọba naa bọ si apo ibinu awọn agbẹ, ti wọn si n ba dukia ijọba jẹ, bẹẹni wọn pa ọpọ oṣiṣẹ ijọba, ti ohun gbogbo si tun dojude ni ẹkun ìwọ oorun guusu Naijiria lasiko ti ogun abẹle n lọ lọwọ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Osun: Gboyega Oyetola, Adeleke ń ṣe àríyànjiyàn lórí èyí tó dárajù nínú 'oníjó' àti 'akówójẹ' 20 Agẹmo 2019 Oríṣun àwòrán, dailypost Ọrọ naa bẹrẹ pẹlu gomina Gboyega Oyetola to ni inu oun bajẹ gidigidi wi pe onijo lo ba oun du ipo gomina ipinlẹ Oṣun lasiko idibo gomina to waye lọdun 2018.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Awọn oloyinbo maa n pe ipenija yii ni Catatonic, eleyii ti o dabi ki eniyan pada si kekere.
Bíótilẹ̀jẹ́pé kòì tíì wá sí gbangba kí ó ṣàlàyé ohun tí ó ṣẹlẹ̀, àwọn ẹlòmíràn ń sọ pé fúnra rẹ̀ ni ó yọ ọ́ kí ọ̀ràn tó wà nílẹ̀ lè tán bọ̀rọ̀.
Airinjinna ni airi abuke ọkẹrẹ, Yoruba gbà pé ti eeyan ba rin jinna, o di dandan kó ri ekute onidodo.
tun rọ ileẹjọ lati fofin fe Oluwo lori awọn nnkan miiran.
“A ti lo si awon ile-itaja nlanla ati awon ile-itaja kekeke, lati sayewo boya won n ko awon eran won wole, amo, a ri pe, won sin awon osin won pelu ounje latorile-ede Naijiria.
Oṣere tiata, Onkọrin, onijo oludari ati Olootu sinima ni Ade Love, to si jẹ ẹni akọkọ to ṣe fiimu jade ni Naijiria yatọ si ere itage to wọpọ nigba naa.
Ojo ireti nla kọkọ rọ fun awọn ololufẹ Chelsea nigba ti ọkan lara awọn ọjẹ wẹwẹ ti wọn gbe goke agba si ikọ naa, Mount kọkọ gba goolu wọle nigba ti ifẹsẹwọnsẹ naa wọ iṣẹju meje lẹyin aṣiṣe ti Ndidi, agbabọọlu Naijiria to n gba bọọlu jẹun ni Leicester city ṣe.
nítorí ẹ̀ṣẹ̀ tí Baaṣa ati Ela ọmọ rẹ̀ dá ati èyí tí wọ́n mú kí Israẹli dá, tí wọ́n mú kí OLUWA Ọlọrun Israẹli bínú nítorí oriṣa wọn.
“Ọrẹ tí wọn óo máa mú wá fún ẹbọ sísun tí ẹ óo máa rú sí OLUWA nìwọ̀nyí: ọ̀dọ́ aguntan meji ọlọ́dún kan tí kò ní àbààwọ́n fún ẹbọ sísun ojoojumọ: 
Ibe Kachikwu: Ọ̀nà àbáyọ sí èlé owó epo ni àtúnṣeàwọn ibùdó ìfọpo wa
Omay Lay fúnra rẹ sọ pe otitọ ni iroyin naa, loju opo ayelujara Twitter rẹ.
Oba Yoruba jẹ igbakeji oriṣa to jẹ aṣegbe ni ohun ti wọn ba ṣe pẹlu ibẹru Olorun.
Ile iwosan IDH yii si ni wọn ti n tọju awọn alarun Coronavirus, ti wsn si ni igbesẹ awọn naa ko sẹyin bi ọwọja itankalẹ arun Covid-19 se n gbilẹ si nipinlẹ naa.
Oríṣun àwòrán, @Eleruwa Àkọlé àwòrán, Àkójọpọ̀ mẹ́wàá lára àwọn Ọba Ilẹ̀ Yorùbá tí wọ́n lé kúrò ní ipò Ọba.
Aare muhammadu Buhari ti sọ pe awon to n se owo orile ede Naijiria kumọ-kuma latari owo ti wọn ya sọtọ fun isẹ akanse lori ina mọna-mọna ati owo ti wọn ri lori epo robi, ko ni ifẹ orilẹ ede yii lọkan rara.
Iye omi ti o yẹ ki eniyan maa mu loojọ niṣe pẹlu ilera ara.
"O bu mi gbangba lori ẹrọ amohunmaworan ṣugbọn emi o ka a si, mo ṣi n bá a ṣọrẹ.
'' Ti a ba ni orilẹede bii 'United States of Nigeria', o ṣeeṣe ki Niajiria dara ju bi o ṣe wa yii lọ'' ''Bakan naa ni a nilo Ile Igbimọ awọn lọbalọba, House of Chiefs nitori awọn ni wọn mọ ibi ti bata ti n ta awọn eniyan wọn lẹsẹ julọ'' ₦750m ni Akeredolu ń gbà lóṣù fún ‘Security Vote’ àti ₦150m owó oṣù - Agboola Ajayi fèsì INEC kéde agbègbè ẹsẹ̀ odò 270 ti èrú ìbò ti le wáyé ní ìpínlẹ̀ Ondo Ọ̀pọ̀ aráàlú Owo wà nílé ìwòsàn, síbẹ̀ APC àti PDP kò gba ẹ̀bi Ọgọ́rin arìnrìnàjò tó padà wá sí Nàìjíríà ló ní Coronavirus - PTF ''Amọ lorilẹede Niajiria ti gbagbe awọn lọbalọba, ohun lo jẹ ki a wa ni ipo ti a wa loni'' Adari ijọ Redeemed Christian Church of God, Pasitọ Enoch Adeboye naa wa fikun wi pe atuntọ Naijiria gbọdọ waye ni kiakia, ki nkan ma ba a bajẹ.
Igbe ẹkún ńlá sì sọ ní gbogbo ilẹ̀ Ijipti, nítorí pé kò sí ẹyọ ilé kan tí eniyan kò ti kú.
Ìpele tuntun ló kàn nínú ìrìnàjò ayé mi, ń kò pe ẹjọ́ lóri ìrọ̀lóyé - Sanusi Kò sẹ́ni tó fẹ́ pa Buhari o, ọkùnrin tó pakuru mọ́ ààrẹ kàn fẹ́ bọ̀ọ́ lọ́wọ́ ni - Femi Adesina Ọmọ ti lọ kí baba, Fayemi bẹ Aláàfin wo l‘Ọyọ, wọ́n jírórò lórí lẹ́tà Ẹ́ gbaradì, to bá lo jẹnẹrátọ̀ àbí tà á, ò ń fi ẹ̀wọ̀n ọdún mẹ́wàá ṣeré - Sẹ́nétọ̀ ń dábàá Láì lo Kakulétọ̀, mo ní ọpọlọ ìṣirò, tábìlì ìṣirò wà lórí mi - Human Calculator Ẹgbẹ PDP, ninu ikede kan ti wọn fi sita loju opo Twitter rẹ sọ pe, oun mọ riri iṣẹ akọni ti arabinrin naa ṣe, ti oun si rọ ijọba apapọ lati fi ami ẹyẹ da a lọla lẹyin iku rẹ.
Wọn ni epo rọbi ti wọn n ri ni Chad to agba epo biliọnu ẹgbẹrun kan ati aabọ ni eyi ti wọn fi jẹ ọkan lara awọn orilẹ-ede ilẹ Adulawọ to ni epo rọbi julọ.
Mo mọ̀ pé kí ṣe ọ̀rọ̀ májèlé oúnjẹ, bíkò ṣe èèfi gẹnẹrátọ̀ ló pá wọ́n , èèfi náà ń kì mọ́ èèyàn láyà, àwọn obi ìyawó wà láàyé sùgbọ́n enìkeji tó jẹ ìbejì fún ìyàwó àti àwọn abúrò rẹ̀ ló bá ìṣẹ̀lẹ̀ náà lọ."
Ọpọlọpọ kẹ̀kẹ́ ogun ati ẹlẹ́ṣin ni Solomoni ọba kó jọ, kẹ̀kẹ́ ogun rẹ̀ jẹ́ egbeje (1,400), àwọn ẹlẹ́ṣin rẹ̀ sì jẹ́ ẹgbaafa (1,200).
Bi ọbẹ̀ bá dànù, kò ṣe kó padà, à fi ki enia se ọbẹ̀ tuntun, bi ó bá fẹ jẹ ọbẹ̀.
Oríṣun àwòrán, toyin_abraham Sugbọn ara aje n ta Toyin Abraham lọwọ-lọwọ bayii, ti ko si tii sinmi lori bi wọn se n wo sinima naa si paapa nigba ti ibudo sinima kan kọ lati se afihan sinima Elevator Baby ọhun.
Ìjọba, ẹ yé fi ẹ̀tọ́ ọmọnìyàn dun ọmọ Nàìjíríà mọ́- SERAP Wọ́n ti ṣí ilé oúńjẹ oní ọgbọ̀n náírà (N30) ní Kano Ìdí tí mo ṣe fẹ́ yọ ayédèrú ìdí ńlá tí mo ní- Sophie Ìlú kò mọ ohunkóhun nípa iṣẹlẹ màálù tó kú nilu Ikarẹ- Oba Olukarẹ Irinajo si orilẹ-ede Amẹrika Ninu oṣu kẹsan an ni aarẹ Buhari lọ si ilu New York fun apejọ ajọ iṣọkan agbaye to jẹ ẹlẹẹkẹrinlaadọrin iru rẹ.
Oríṣun àwòrán, Temilolu Akinboola Gbogbo akitiyan lati kan si Ọba Frederick Aroloye lati sọ bi ọrọ naa ṣe jẹ lo ja si pabo.
Ọwọ́ ọlọ́pàá ti tẹ ọkùnrin kan tó pa ọ̀rẹ́ rẹ̀ nítorí N40 ní Kano Wọ́n mú ọjọ́ ìgbẹ́jọ́ agbésúnmọ́mí 9/11 tó ṣẹlẹ̀ l'Amẹrika Kíkọ́ ẹ̀kọ́ gboyè nínú iṣẹ́ ìṣègùn ìbílẹ̀ yóò pèsè ìtọ́jú tó péye fọ́mọ Nàìjíríà- Ẹgbẹ́ àwọn dókítà Orilẹ-ede Egypt to gba idije naa kẹyin naa lo tun bori ni tọdun yii ni eyi ti Naijiria ti gbe ipo keji lapapọ.
Ní oṣù Ẹrẹ́nà ọdún tó kọjá, Nkurunziza gba orúkọ tuntun lọ́dọ̀ àwọn ẹgbẹ́ òṣèlúu rẹ̀, Àjọ Agbèjà Òmìnira Àwọn Ológun – Fún Ìgbéga Ìjọba Oníbò (CNDD-FDD).
 Shehu tun wa rọ awọn adari
Aare Buhari bu ẹnu atẹ lu iwa
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Nigeria 2019 Elections: Alága INEC, Mahmood Yakubu ní àṣẹ Ààrẹ Buhari lórí pípa ẹni tó bá jí ìbò gbé tako ohun tí òfin sọ 19 Èrèlè 2019 Oríṣun àwòrán, @inecnigeria Alaga ajọ INEC ti tako aarẹ Buhari lori aṣẹ to pa pe ki awọn ologun o maa yinbọn fun ẹnikẹni to ba ji apoti ibo gbe lasiko idibo apapọ to n bọ.
Báyìí ni ọba Igbó Olódùmarè náwó fún bàbá mi lajọ́ ìgbéyàwó yìí kò sì tí ì sí irú rẹ̀ ní ibẹ̀ láti ọjọ́ tí ọba náà ti gún orí oyè.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Yorùbá tone mark: Fífi àmì ohùn sí orí ọ̀rọ̀ Yorùbá ṣe pàtàkì Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Yorùbá tone mark: Fífi àmì ohùn sí orí ọ̀rọ̀ Yorùbá ṣe pàtàkì 28 Bélú 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 18 Èbibi 2020 Ede olóhùn ni èdè Yoruba jẹ.
Ipade apapo awon minisita elekefa iru re ni yoo waye lorile-ede Tunisia ni saa kinni odun 2019.
Bi wọn ṣe pari kika ibo lawọn ibudo idibo ti wọn si ti ilẹkun gbọngan ibudo pa to jẹ wi pe awọn oluwoye nikan lo wọle, ṣe lawọn alatilẹyin ẹgbẹ duro sita ti wọn n wo lojuu ferese.
Yàtọ̀ sí coronavirus, wo ìgbà mẹ́wàá míì táwọn mùsùlùmí kò lè ṣiṣẹ́ Hajj Awọn arinrinajo Hajj yoo bẹrẹ si sanwo ori Ẹ̀yin mùsùlùmí, ẹ yàgò fún ìwà ipá- Buhari Lọpọ igba awọn ayẹyẹ maa n tẹle ọdun ileya ṣugbọn nitori ajakalẹ arun Covid 19, ko ni fi bẹ si pọpọṣinṣin lasiko Ileya tọdun yi.
Nítorí wọ́n pa ọ́,o sì ti fi ẹ̀jẹ̀ rẹ bá Ọlọrun ṣe ìràpadà eniyan,láti inú gbogbo ẹ̀yà,ati gbogbo eniyan ní gbogbo orílẹ̀-èdè.
OLUWA dá a lóhùn, ó ní, “N óo wà pẹlu rẹ, o óo sì run àwọn ará Midiani bí ẹni pé, ẹyọ ẹnìkan péré ni wọ́n.
A kò gbo̩dò̩ s̩àdédé fi òfin mú ènìyàn tàbí kí a kàn gbé ènìyàn tì mó̩lé, tàbí kí a lé ènìyàn jáde ní ìlú láìnídìí.
Ipinlẹ Eko, Aṣofin Mudashiru Ọbasa ti pe fun ifọwọsowọ awọn
Ọgagun to ba tayọ, to tun fakọyọ julọ ninu iṣe tabi ninu iṣẹlẹ manigbagbe laelae ti ko wọpọ lo n gbaa.
gbọdọ kojú mọ iṣẹ ti wọn gbe kale fun un ti ṣe didẹkun iwa adigunjale àti ìwà ajinigbe tó fí mọ mímú àwọn tí wọn hù ìwà tó jẹ mọ àwọn ẹṣẹ wọn yí.
Arabinri Adepeju daa pada pe bi obinrin ba tilẹ ran ọkọ rẹ lọwọ lati san owo ile iwe, o yẹ ki ọkọ daa pada nitori ọp ọkunrin lo maa n sọ ọ di oju ọwọ.
Ko pẹ si igba naa ni EFCC kowe ransẹ ki Fayose yọ́ju si ile isẹ ajọ naa ti o si kọ lati yọju.
O fi kun un pe irẹpọ orilẹede yii wa lọ́wọ́ iru atilẹyin ti awọn ọlọpa ba ri latọdọ araalu toripe bi eyi ba n bajẹ, o ma n faaye gba awọn janduku lati bẹrẹ iwa ipa wọn laarin ilu.
Ọ̀FỌ̀ ṢẸ̀ WÁ NÍNÚ ẸBÍ WA
O tun ṣalaye pe awọn mọto 4, 494.
Ibi ti wọn kọ ile naa si ko ba ofin mu.
Ìbẹ̀rùbojo gba ọkàn àwọn olùgbé Eko àti Ogun nítorí adágún omi Ọ̀yan tí yóò di ṣíṣí láìpẹ́ Ṣé ó leè jẹ́ ilẹ̀ tí Makinde kò jẹ́ kí Florence Ajimobi gbà ló ń bi nínú?
Ikede ayipada ninu iye awọn to n ko arun yi ni Naijiria n waye lasiko ti awọn orileede mii ni Afirika bi South Afrika n ga si.
Orúkọ ìyá rẹ̀ ni Sebida, ọmọ Pedaaya, láti ìlú Ruma.
Nigbẹyin, o ṣalaye bi awọn eniyan kan ṣe pada ṣe apejẹ ranpẹ fun tọkọtaya fi ya wọn lẹnu lẹyin isin igbeyawo wọn to waye lọjọ kẹtadinlogun, oṣu kẹjọ, ọdun 2019 yii.
Ninu ọrọ to ba ileese iroyin Naijiria (NAN) sọ, Ọgbẹni Benjamin sọ wi pe awọn esi idanwo kan yoo jade titi ọjọ kọkandinlogun oṣu keta yii.
Kano: Gomina Kano yan Emir mẹ́rin bíi Ajimobi tó jẹ́ àna rẹ̀
Má lúgọ bí eniyan burúkú láti kó ilé olódodo,má fọ́ ilé rẹ̀.
Minisita ti pasẹ pe ki won ti
Nínú àtẹ̀jáde tó tọwọ́, tó jẹ́ adari alukoro fún ilé iṣẹ́ ọmọogun orílẹ̀, Texas Chukwu jáde sàlàyé pé lóòtọ́ ní àwọn ọmọogun ní ìdojúkọ Haram ní ìlú Chingori ní àgbègbè Bámá nípìnlẹ̀ Borno, tí wọn sì gbìyanjú láti gba mọ́tò sùgbọ́n àwọn ọmọogun ṣì dóju ìjà kọ wọn pẹ̀lú àṣeyọrí àti ìrànlọ́wọ́ àwọn ọmọogun ojú ofurufu Nàìjíríà.
Nítorí náà, wọ́n sáré sí ìkógun, wọ́n pa àwọn aguntan ati mààlúù ati ọmọ mààlúù, wọ́n sì ń jẹ wọ́n tẹ̀jẹ̀tẹ̀jẹ̀.
 Ni kete ti a ba ti gbo ohunkohun nipa awon omodebinrin naa ni a maa fi too yin leti”.
 O salaye pe, “erongba ijoba apapo ni lati mu igberu ba ilera awon ara-ilu, ni eyi ti yoo tunbo maa wa iyanju si awon ipenija ti o n sakoba fuitoju awon alarun HIV, eyi ti o je idena lati ri oogun fun aarun yii, lara awon ipenija ohun ni:  aisi awon ohun elo itoju to peye, aisi akosile to peye, ati aisi owo fun itoju, erongba wa lati salekun itoju awon alarun HIV ni ibamu pelu agbekale ilana ajo-isokan ile Afrika ati ajo-isokan agbaye, ni iyanju ati waa ojutu si ipenija aarun HIV/AIDS, aisan iba ati iko jedo-jedo, bakan naa lati so awon aarun wonyii di afiseyin teegun n fiso bi o ba fi maa di odun 2030”.
naa, awon to n dije fun ile igbimo asofin ipinle tun jẹ márùndínlọ́gbọ̀n (25) ninu ẹgbẹ oselu ti iye wọn jẹ ọ̀tàlénígbalemẹjo (268) ti awon oludije si jẹ mẹ́rìndínlọ́gbọ̀n (26)ninu egbe oselu orisirisi bi i; DPM, YPP, Accord, KOWA,
 O ni Wọn ma n bẹrẹ pẹlu awọn ọrọ kobakungbe to maa mu inu bi eeyan, eyi tyo jẹ ọna ti wọn ma n gba lati fa ijọgbọn lẹsẹ.
Ikowefiposile rẹ ko ya ọpọ eeyan lẹnu nitori awọn ara ilu ti n farata lati igba ti iroyin lu jade pe iwe ẹri ayederu ni o n lo.
Gbogbo wọn tún pinnu láti pa àjọ náà mọ́ fún ọjọ́ meje sí i, wọ́n sì fi tayọ̀tayọ̀ ṣe é.
Eyi ni igbesẹ ti o nilo lati maa wo esi naa bi o ba ṣe n jade loju opo INEC naa: Igbesẹ akọkọ: Ẹ lọ soju opo https://inecelectionresults.
ede Niajiria, lojo ti eto idibo ku ọla.
Irọ́ ni, abẹ́rẹ́ àjẹsára Covid-19 kò lè ṣàyípadà DNA rẹ Àyẹ̀wò DNA ti fẹ́ bẹ̀rẹ̀ fún àwọn àlùfá Kátólíìkì tó bímọ Ìnàkí bímọ lẹ́yìn tí ìfẹ̀tòsọ́mọbíbí pòfo!
Àkọlé àwòrán, Mo ṣetan lati mojuto ọrọ airiṣẹṣe awọn ọ̀dọ́ Kwara.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Mo fẹ́ kí Ọlọ́run fún wa ní ọmọ olójú búlúù si lẹ́yìn yìgì - Ọkọ olójú búlúù Adamu Adamu, Minista ètò ẹ̀kọ́ ti fi òfin àátẹ̀lẹ́ síta kí àwọn ilé ìwé lè wọlé Makinde ti sọ̀rọ̀ lẹ́yìn tí asekúpani Akinyele sálo mọ́ àwọn ọlọ́pàá lọ́wọ́ ní àhámọ́ Olólùfẹ́ mi ṣèèsì fi ọkọ́ gbá mi sí gọ́tà, mo rò pé ọlọ́jọ́ dé ni - Iya Osogbo Ẹ̀yin gómìnà, Ifá nìkan ló le tọ yín sọ́nà láì kùnà lórí Amotekun - Babaláwo Afurasí lórí ikú Tolulope Arotile ti dé ilé ẹjọ́, èyí ni ẹ̀sùn tí wọ́n fi kàn án Ọgbẹni Agba ṣalaye pe ti ọrọ aje orilẹede yii ko pa gbe pẹẹli diẹ sii ni oṣu mẹta si asiko yii, o ni ewu n bẹ loko longẹ fun ọrọ aje Naijiria.
Oríṣun àwòrán, AFP Àkọlé àwòrán, Ojojumọ kọ la ma n ri erin to n fo loke-sugbọn bọrọ ọhun se ri niyi lọjọru lagbeegbe Nyeri,lorilẹede Kenya.
 Bó ṣe bá mi ti móto yẹn tan, mo wa ni ó jọ bi ẹni pé mọ́tò náà kò ni ṣiṣẹ́ pé o ṣeun àti pé mó fẹ́ lọ pe ẹni ti yoo ba mi tún ṣe.
Ọtí tí wọ́n fi Sanitáísà àti Methanol pò pọ̀ ṣekú pá èèyàn 86 Bí a bá gbáa yín mú tí ẹ́ ju Ààdọ́ta olùjọ́sìn lọ pẹ́rẹ́ ní ṣọ́ọ̀ṣì.
2 mílíọ́nù owó ìtanràn Awọn ileeṣẹ mii to pawọpọ pẹlu ajọ LASEMA fun aṣeyọri iṣẹ naa ko ma baa pa awọn olugbe agbegbe naa lara ni ileeṣẹ panapana ipinlẹ Eko atawọn ọlọpaa.
Ó kọ́ ẹnu ọ̀nà òkè ilé OLUWA, ó sì tún ògiri Ofeli mọ.
" Nínú ọ̀rọ̀ tirẹ̀, Olúwó ti ìlú Iwò Oba Abdulrasheed Akanbi ní àlááfíà wa láàárín àwọn ọba alaye ní ìpínlẹ̀ naa.
Àwọn ohun mẹ́rin tó yẹ kí ẹ ko mọ nípa Ramoni Igbalode tí gbogbo ayé ń pè ní Hushpuppi Ikọ̀ ìjọba Ọ̀yọ́ dé lásìkò tí kò yẹ ni wọn kò ṣe wọlé - Ẹ̀bí Ajimobi fèsì Ọ̀pọ̀ èèyàn tí kò yin Ajimobi lojú ayé, tó ń yìn-ín lẹ́yìn ikú, yóò jẹ ìyà - Oníwáàsí Mo ti bá ọmọ ọwọ́ mẹ́ta lòpọ̀ sẹ́yìn, ọmọ oṣù mẹ́ta ló ṣìkẹrin - Afurasí jẹ́wọ́ Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Di American rapper bin visit Trump Tower shortly after Mr Trump win election O ṣe diẹ ti ọkan Kanye West ti wa nipo aarẹ ilẹ Amẹrika Ṣaaju ni West ti sọ lọdun 2015 pe o wu oun lati du ipo aarẹ ilẹ Amẹrika.
Èsì àyẹ̀wò tí àjọ NCDC gbé síta fihàn pé ènìyàn 265 ló tún ti ní ààrùn Covid-19 ní Nàìjíríà Ṣọ́ọ́ṣì kan sí ìlẹ̀kùn rẹ̀ fún àwọn mùsùlùmí láti kírun Jímọ̀ ní Germany Àwọn ìbejì Akeugbagold kò le rìn dáadáa mọ́ lẹ́yìn tí wọ́n dáwọn padà Ọọni, Aláàfin, Ojisẹ Ọlọ́run àti oniṣẹ ìwádìí fi Ògún gbari pé òògùn ìbílẹ̀ le wo Covid-19 Mo kábàámọ̀ pé n kò kàwé, kí n tó bẹ̀rẹ̀ iṣẹ́ tíátà - Sanyeri Ẹ wo àwọn gbajúmọ̀ òṣèré tíátà tó jogún eré ṣíṣe lọ́dọ̀ òbí wọn Awuyewuye loriṣiriṣi lo n waye lori ewu to wa nibi ki awọn akẹkọọ pada si ileewe lai se pe wọn ri abẹrẹ ajẹsara atabi oogun to le koju arun Covid-19.
Ọpọlọ eniyan ṣe pataki pupọ ninu ẹyà ara eniyan ni eyi to jẹ pe ti o ba ni iyọnu kankan, yoo fa wahala nla fun irufẹ eeyan bẹẹ.
Awọn akoonu gbolohun kọọkan ati koṣeemani ninu ọrọ Yoruba ni Olukọ wa ṣlaye fun wa.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Florida: Ọ̀ọ̀nì àléègbà dé ba Mary lálejò lọ́gànjọ́ òru Ọkẹrẹ ni ti Benin nigba ti Ivory Caost yan Erin lakatabu laayo.
Nígbà gbogbo ni ẹ̀ ń tako Ẹ̀mí Mímọ́.
Ẹ jẹ́ kí gomina Juda ati àwọn àgbààgbà Juu tún ilé Ọlọrun náà kọ́ síbi tí ó wà tẹ́lẹ̀.
Bẹ́ẹ̀ ni yóo rí fún Moabu.
Igbeyawo akọkọ ti Toyin Abraham ṣe pẹlu oṣere tiata miiran, Ọgbẹni Adeniyi Johnson fori ṣanpọn.
Ajọ naa si tun ti rọ awọn olugbe Ipinlẹ Eko ki wọn yago fun awọn ọna wọnyii.
Nígbà tí a pàdé ẹ̀kejì; o mi ìmí ẹ̀dùn kanlẹ̀, ó wò wá láti òkè dé ìsàlẹ̀, ó ṣe bí ẹni pé ó ń pẹ̀gàn w,a nígba tí a pàdé ẹ̀kẹta ó mọ́ wa lójú, ó pòṣé, ó sì sọ̀rọ̀, ó ni, ‘Àwọn alákọrí gbogbo’
Duro Ladipọ, ìlúmọ̀ọ́ká òṣèré tíátà àti ọmọ àlúfà tí kò gbàgbé àṣà ìbílẹ̀ Ọ̀rọ̀ǹpọ̀tọ̀niyùn, Aláàfin obìnrin àkọ́kọ́ rèé, tó ní nǹkan ọkùnrin Ṣaaju eyi ni aarẹ Buhari rinrinajo lọ si oke okun fun eto ilera ara rẹ.
O jẹ wọn lowo oṣu bẹẹ ni ko pese ohun idabo bo araẹni fun wọn lasiko ajakalẹ arun Coronavirus.
Lootọ awọn ikọlu kọọkan ti waye ti ijinigbe awọn oloselu kan si waye laipe yi,eyi ni igba akọkọ ti wọn yoo ji onisowo gbe ni Tanzania paapa julọeleyi ti o lorukọ bi ọgbẹni Dewji.
Àwọn Ọba Yorùbá kan rèé tí wọ́n rọ̀ lóyè, tí ọba míràn jẹ lójú ayé wọn Ìpalẹ̀mọ́ aráàlú àti agbófinró fétò ìdìbò dójú ọ̀gbagadè ní Ondo Wo bí ìwọ́de #ENDSARS tí Toyin Abraham ṣe nípínlẹ̀ Oyo ṣe lọ Ọlọ́pàá f'ẹsẹ̀ fẹ́ẹ l'Eko lẹ́yìn tó ki ìbọn bọ ọ̀rẹ́bìnrin rẹ̀ lẹ́nu tó sì yìn ín Ìbò aráàlú pẹ̀lú ẹ̀yà yókù lá fi yanjú àtúntò Nàíjíríà - YCE Ìdí tí Gúúsù Akure, Owo àti ìwọ̀orun Ondo yóò fi sọ ẹni tí yóò jáwé olúborí nínú ìbò gómìnà Ondo Níbayìí Afolabi ni ǹkan ẹyọ kan ti àwọn ń bèrè fún ni pé kí ilé iṣẹ́ ọlọ́pàá mú ẹni tó ṣe irú iṣẹ́ ibi náà jáde Hussein Afolabi ní kìí ṣe Isiaq nìkan ko ni ọlọ́pàá yìn níbọ̀n, àwọn méjì míràn wà ní ilé ìwòsàn níbi ti wọ́n ti n gba ìtọ́jú Ó fi kun un pé gbogbo ìgbésẹ̀ tó yẹ ni ò ń gbé lọ́wọ́ láti túṣu désàlẹ̀ ìkòkò ọ̀rọ̀ náà.
Alufaa yóo mú òróró tí ó kù ní ọwọ́ rẹ̀ yóo sì fi ra orí ẹni tí wọ́n fẹ́ wẹ̀ mọ́, láti fi ṣe ètùtù fún un níwájú OLUWA.
Resources) pelu ajosepo ile ise Iroyin, Asa ati Igbafe ti sejilo fun gbogbo
Oniruuru ọna lawọn eeyan ti n gba da si ọrọ naa ti wọn si n ke si ijọba lori igbesẹ to yẹ ki wọn gbe.
Lara wọn ni awọn ọkọ ijagun oloro, oniruru ibọn, ọta ibọn, awọn iwe ẹsin lorisirisi, agolo, afẹfẹ idana gaasi pẹlu ajilẹ to ni wọn fi n se ado oloro alatọwọda, IEDs.
Agbẹnusọ fun ajọ EFCC, Wilson Uwujaren lo fọrọ yii lede loju opo ayelujara Twitter ati Facebook ajọ naa.
Swilson ni oun ko kaanu kankan fún Trump, bo ba tilẹ ni aarun naa nitori pe iya oun wa nile iwosan níbi ti o ti n ja fun ẹmi ẹ.
“Ẹnikẹ́ni tí ó bá jẹ́ aláìmọ́ tí kò sì ṣe ìwẹ̀nùmọ́, yóo jẹ́ aláìmọ́ sibẹ nítorí pé a kò tíì da omi ìwẹ̀nùmọ́ sí i lára.
Wọ́n Kọ Ilà Abẹ́ ní Giligali.
- Ìjọba àpapọ̀ Wo ohun tí ìrìnàjò ààrẹ Buhari fún ìgbà àkọ́kọ́ lásìkò Coronavirus lọ sí Mali yóò bá bọ̀ Ọmọ Yorùbá mẹ́wàá tó jẹ́ àmúlùúdùn ní Amẹ́ríkà àti Yúróòpù Èèyàn 38,344 ló ti ní COVID-19 ní Nàìjíríà lẹ́yìn tí 543 kún un lọ́jọ̀rú Apapọ iye awọn to laarun coronavirus lorilẹede Naijiria bayii ti di ẹgbẹrun mejidinlogoji ati ojilelọọdunrun o le mẹrin, 38,344 lẹyin ti eeyan ojilelẹẹdẹgbẹta ati mẹta, 543 kun wọn l'Ọjọru Ajs to n gbogun ti ajakalẹ arun lorilẹede Naijiria, NCDC lo kede eyi loju opo twitter rẹ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Brighton vs Arsenal: Ọmọ Otedola bú sẹ́kún lẹ́yìn tí Brighton tún d'ẹrù ìyà lé Arsenal lórí 18 Òkùdu 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 20 Òkùdu 2020 Oríṣun àwòrán, Instagram/cuppymusic Ẹgbẹ agbabọọlu Arsenal ti ba ọpọlọpọ ololufẹ wọn ninu jẹ lẹyin ti Brighton ti ẹyin gbe ru wọn ninu idije liigi Premier League ti wọn gba lọjọ Abamẹta.
Gun orí òkè Nebo lọ, kí o sì wo gbogbo ilẹ̀ Kenaani tí mo fún àwọn eniyan Israẹli.
Egbe Rotary international ti maa n fun awon adari orile ede ati ile ise ti o ba fakọyọ ninu igbiyanju won lati dena aarun romo lapa, romo lese lorile ede won.
Obinrin náà dáhùn pé, “Èmi kò ní ọkọ.
Tani awọn ti yoo figa gbaga pẹlu Ambode naa?
 Àfi bí akọ òkúta ni ọkàn rẹ ̀ ṣele .
OLUWA àwọn ọmọ ogun ti fi tó mi létí pé:“A kò ní dárí ẹ̀ṣẹ̀ yìí jì yíntítí tí ẹ óo fi kú.
A tẹrí mi ba kí n má baà gbọ́ nǹkankan,wọ́n dẹ́rù bà mí kí n má baà ríran.
Wọ́n bá gbé agbelebu rù ú, wọ́n ní kí ó máa rù ú tẹ̀lé Jesu lẹ́yìn.
Samuel Okwaraji gbá bọ́ọ̀lù ní Summer Olympics to wáye ni Seoul, South Korea, pẹ̀lú awọn bíi Samson Siasia, Rashidi Yekeni, Bright Omokaro, Wole Odegbami, Christain Obi, Jude Agada àti Henry Nwosu.
Aworan: Gomina ipinle Zamafara, Abdul’aziz Abubakar Yari, sabewo sile egbe naa nilu Abuja lojoRu(Wednesday).
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Independence Day Nigeria: Ogun abẹ́lé, Ikọ̀ Boko Haram, ìbò June 12 wà lára ìṣẹ̀lẹ̀ tó fẹ́ pín wa sí yẹ́lẹ-yẹ̀lẹ 1 Ọ̀wàrà 2020 Ọjọ kinni osu Kẹwa ọdun 1960, eyiun ọgọta ọdun sẹyin ni orilẹede Naijiria gba ominira.
Arabinrin Akinbile-Yussuf sọ pe miliọnu kan Naira ni ẹnikẹni to ba ru ofin yii yoo san gẹgẹ bi owo itanran.
Ọ̀rọ̀ nípa àtúnṣe láti àdírẹ́ẹ̀sì IP yìí.
Àwọn eniyan burúkú ti dẹ okùn sílẹ̀ dè mí,ṣugbọn n kò kọ ìlànà rẹ sílẹ̀.
S nítorí wọ́n bí ọ síbẹ̀ mọ́’ Gbajue ń lọ orúkọ mi láti gba owó- Mama Rainbow Èyí ni àwọn ìdí tí wọ́n fi fẹ́ ẹ̀ fi 37 Billion Naira tún ilé aṣòfin Nàìjíríà ṣe Trump Impeachment: Báyìí ni wọ́n ṣe ń yọ ààrẹ nípò lórílẹ̀-èdè Amẹrika Wọn ti yọ Donhald Trump nipo gẹgẹ bi aarẹ orilẹ-ede Amẹrika ṣugbọn, ọrọ ko tii tan sibẹ.
 orin lè mú ní sapá ṣe ohun tí ó dàbí ẹní ṣòroó ṣe fún ní nígbà mìíràn .
Lionel Messi ti pegede bayi ju ẹnikini lọ ni La liga pẹlu iye ifẹsẹwọnsẹ ti o ti ti fakọyọ.
Ṣugbọn àwọn oníwà pẹ̀lẹ́ ni yóo jogún ilẹ̀ náà:wọn óo máa gbádùn ara wọn;wọn óo sì ní alaafia lọpọlọpọ.
OLUWA àwọn ọmọ ogun ní, “Ẹ ṣara gírí, gbogbo ẹ̀yin tí ẹ̀ ń gbọ́ ọ̀rọ̀ tí àwọn wolii tí ń sọ láti ìgbà tí a ti fi ìpìlẹ̀ ilé OLUWA àwọn ọmọ ogun lélẹ̀, kí ẹ baà lè kọ́ ilé náà parí.
Atẹjade ti ẹka eto idajọ ilẹ Amẹrika fi sita ṣalaye pe lati ọjọ kọkandinlogun, oṣu kọkanla ni ẹka naa ti fẹsun kan wọn pe wọn jọ gbimọ pọ lati lu jibiti pẹlu ile ifowopamọ l'Amẹrika.
Wọn yóo máa wí pé, ‘Ọkunrin yìí bẹ̀rẹ̀ ilé, kò lè parí rẹ̀!
Awakọ̀ òfúrufú Ethiopian Airlines pariwo 'lọ sókè!
SERAP: SERAP gbé ìjọba Nàìjíríà lọ iléẹjọ́ ọ̀daràn lágbàáyé, ICC
Àwọn Eniyan Tí Wọn Ń Gbé Jerusalẹmu.
Kò sí àyè fún fíìmù eré ìfẹ ṣíṣe ni Kannywood mọ́ Tó o bá ṣàdéhùn ìfẹ́ tó ò mú u ṣẹ, ẹ̀wọ̀n lo fi ń ṣeré Ọlọ́wọ́ idán Houdini kò yè é o, ó bómi lọ!
Lẹyin eyi ni Calum Chambers ati Aubameyang wa gba ayo kọọkan wọle lati bọ ẹwu itiju ti aston villa fẹ da ro Arsenal ni ibuba rẹ kuro.
Ṣugbọn olórí alufaa tí a yàn nípa ọ̀rọ̀ ìbúra tí ó dé lẹ́yìn òfin ni Ọmọ Ọlọrun tí a ṣe ní àṣepé títí lae.
”Won ko so oro lori eleyii mo.
Arun ọpọlọ: Arun mii ti igbeyawo laarin ẹbi maa n fa ni arun ọpọlọ, gẹgẹ bi iwadii awọn onimọ sayẹnsi ṣe sọ.
Ṣé ẹ fẹ́ kí n dá ‘Ọba àwọn Juu’ sílẹ̀ fun yín?
edwin muir ( 15 may 1887 - 3 january , 1959 ) a bí muir ní 1887 .
Emir of Kano: Soyinka ní ó dun òun pé Ganduje kò ní alámọ̀ran rere
Wo ọjọ́ tí wòlíì Sotitobire yóò gba ìdájọ́ Ìdájọ́ òdòdò ló fẹsẹ̀ múlẹ̀ lórí ọ̀rọ̀ Pásítọ̀ Sotitobire - Agbẹjọ́rò fún ìjọba Akure:Àwọn ọ̀dọ́ ilu dáná sun ilé ìjọsìn Sotitobire Iléẹjọ́ gíga Akure kọ̀ láti gba onídùróó olórí ìjọ Sotitobire Ejò lọ́wọ́ nínú lórí ìdájọ́ ẹ̀wọ̀n gbére tí wọ́n dá fún Wòlíì Sotitobire, àwọn ọmọ ìjọ rẹ̀ yarí Ọwọ́ ọlọ́pàá tẹ afurasí tó ní òun ló jí ọmọ gbé láti parọ́ mọ́ pásítọ̀ ìjọ Sotitobire Bisola alfa sọ bi Woli se sanwo ikede ni gbogbo radio kaakiri ipinlẹ Ondo lati fi ṣawari ọmọ to sọnu, iyẹn Kolawole Gold.
Orilẹ-ede France fi agba han orilẹ-ede Belgium pẹlu ami ayo kan si odo.
Nígbà tí Bela kú, Jobabu, ọmọ Sera, ará Bosira gorí oyè.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Sudan Protest: Àwọn òṣìṣẹ́ aláàbò kọlu àwọn tó n ṣe ìwọ́de ní Sudan 3 Òkùdu 2019 Oríṣun àwòrán, AFP/Getty Images Àkọlé àwòrán, Ija Sudan Awọn ikọ alaabo l'orilẹede Sudan fi tipa-tipa wọ aarin awọn to n ṣe iwọde ifẹhonuhan ni ilu Khartoum to jẹ olu ilu orilẹeede naa ni owurọ kutu-kutu ọjọ Aje.
nítorí ọ̀rọ̀ Ọlọrun ati adura ti sọ ọ́ di mímọ́.
Àtìpó 161 míì dé padà láti Libya layajọ́ ominira Naijiria A ti ní mílíọ̀nù 11 Naira láti se ẹjọ́ pẹlú ilé-isẹ́ ọlopaa Naijiria!
Kidnapping: Aago méje alẹ́ ọjọ́ Ìṣẹ́gun làwọn agbégbọn dí ọ̀nà márosẹ̀ Ibadan
Ọrọ naa yanju lẹyin ipade alaafia kan to waye tawọn mejeeji si ni awọn ti pana ohunkohun to n da wahala silẹ.
Wí fún wọn pé, OLUWA Ọlọrun ní idì ńlá kan wá sí Lẹbanoni, apá rẹ̀ tóbi, ìrù rẹ̀ sì gùn, ó sì ní ìyẹ́ aláràbarà.
Rọ ọlọpaa naa lati gba ọ laye ki o pe ẹbi tabi ọrẹ rẹ kan tabi agbẹjọro rẹ ni kete lẹyin ti wọn ba mu ọ lati lee dena kiko ẹbi rẹ laya soke.
O ni oun mọ idi ti wọn se n se idajọ oun, nitori pe wọn ko ri oun ni ojoojumọ ni lati ni oye iru ẹni ti oun jẹ, ki wọn si tẹwọgba oun.
Àwọn Eniyan Mú Ọpọlọpọ Ẹ̀bùn Wá.
Ile ẹkọ Oluyole High School ni olukọ yii wa.
Nínú ọ̀rọ̀ tí mọ̀lúmọ̀ọ́ká olórin náà fi síta lọ́jọ́ ajé ni Ayefẹlẹ dúpẹ́ lọ́wọ́ gómìnà Ajimọbi fún ìgbésẹ̀ yìí.
Afikun ti wọn kede ọhun yoo wa jẹ lati naira márùndínláàdọ́jọ (N145) lita kan ti o wa tẹlẹ si iye tuntun yi.
Gege ile-ise akoroyin Amaq, O ni, awon omo ogun olote elesin islam ni awon lawon wa nidi isele ohun.
Awọn oniburẹdi gunle iyanṣẹlodi lẹyin ti iye owo iyẹfun, suga ati awọn awọn ohun elo miran wọn si.
Kọmisana fun eto ilera ni ipinlẹ naa, Inyang Asibong ni ọjọbọ ọsẹ ni o bi ibeji naa ninu ọgba ẹwọn ilu Calabar.
Ààrẹ orílẹ̀-èdè Nàìjíríà Muhammadu Buhari ti buwọ́lu àbádofin láti sọ June 12 di àyájọ ọjọ́ ìjọba àwa ara wa lórilẹ̀-èdè Nàìjíríà.
Gbogbo Israẹli, ati onílé, ati àlejò, gbogbo àwọn àgbààgbà, ati àwọn olórí, ati àwọn aṣiwaju dúró ní òdìkejì Àpótí Majẹmu OLUWA, níwájú àwọn alufaa, ọmọ Lefi, tí wọ́n ru Àpótí Majẹmu náà.
Ni Uganda ni ogun ọdun sẹyin ni oluṣe iwadii Catherine Kyoubutungi ni o di dandan lati ṣafihan gbogbo igbesẹ inu abẹrẹ tabi oogun ti eeyan ba fẹ dan iṣẹ rẹ wo ki ohun gbogbo si wa letoleto bi o ti yẹ.
Bẹ́ẹ̀ ni a óo sì ṣe, bí Ọlọrun bá fẹ́.
N óo dè ọ́ lókùn mọ́lẹ̀, tí o kò fi ní lè yí ẹ̀gbẹ́ pada títí tí o óo fi parí iye ọjọ́ tí o níláti fi gbé ogun tì í.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Spanish flu and other pandemic: Ẹ fọkàn balẹ̀, àwọn àjàkálẹ̀ àrùn kan rèé to burú ju Coronavirus lọ 17 Ìgbé 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 30 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Àkọlé àwòrán, Ìtàn Manigbagbe: Àwọn àjakalẹ-àrun to ti wáyé rí ṣáájú Coronavirus Wọn ní ìgbà kan ń lọ, ìgbà kan ń bọ̀, ayé kò dúró soju kan torí ẹṣin ta ta ta, ó kú, ènìyàn rìn, rìn rìn, ó sọnu.
Oluranlowo aare lori iroyin Bahir Ahmed naa tun fi sori ero Twitter re pe :”Aare Muhammadu Buhari yoo maa dari ipade igbimo ijoba lojo Eti , ni eyi ti won yoo ti maa jiroro lori iwe isuna ati bi iwe isuna naa  yoo se lo si ile-igbimo asofin , ki won lee tete bowolu iwe isuna naa.
Ko si ayẹyẹ igbeyawo, isinku tabi apejọ kankan mọ lasiko konile o gbele.
Kò sí hóró òótọ́ kán nínú ìtàkùrọsọ ọ̀hún.
Ọpọ awọn ọdọ lo gbe kaadi ilewọ dani nibi ti wọn kọ oriṣiiriṣii nnkan to nii ṣe pẹlu ẹtọ ọmọniyan si.
Ilé aṣòfin Oyo àti Ogun buwọ́lu àbádòfin ikọ̀ aláàbò Amotekun Strongest Teeth: Tajudeen ní èèyàn ló kù tí òun fẹ́ máa fi eyín gbé Ẹ̀bí àti ọ̀rẹ̀ ní mo kó lọ sí Dubai fún ayẹyẹ ọjọ́ ìbí ọlọ́sẹ̀ kan fún màmá mi - Gbajabiamila N kò jalè rí, ọtí àmuyó ló jẹ́ kí ń jí káàdì ìpè àti ẹ̀rọ ìbánisọ̀rọ̀"" Ogundoyin ni ikọ amọtẹkun naa yóò wá fún ìṣàkóso ètò ààbò ní àwọn ìpínlẹ̀ kọ́ọ̀kan tó wà ní ìlẹ̀ Yoruba ti ètò ààbò ti dẹnukọlẹ̀."
wa ni lati kopa daradara ninu idije NWPL ti a sese gba igbega si yii.
Bo tilẹ jẹ pe ko ni i si igbele, titi pa ni awọn ile oúnjẹ, ile igbafẹ, ile ọtí, ati sinima yoo wa.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Kogi Election: Kí ló mú àwọn jàndùkú dáná sun Aṣáájú obìnrìn ẹgbẹ́ òṣèlú PDP mọlé ?
Jakọbu dáhùn pé, “Kọ́kọ́ búra fún mi ná.
Wọ́n bẹ̀ ẹ́ kí ó dúró lọ́dọ̀ wọn fún àkókò díẹ̀ sí i, ṣugbọn kò gbà.
Yorùbá bò wọn ní; Ọ̀rọ̀ tútù ní ń mú obì jáde lápò, Ọ̀rọ̀ burúkú idà ni ń yọ.
Oríṣun àwòrán, others Dr Stella Immanuel: Facebook yọ fídíò òògùn ìwòsàn Coronavirus Oju opo ayelujara Facebook, Periscope atawọn oju opo ayelujara miran ti fa fidio obinrin alawọ dudu kan, Dokita Stella Immanuel yọ, eyi to se lati salaye idi ti oogun iba Hydroxychloroquine fi pegede lati wo arun Coronavirus san.
Orile-ede ohun ti setan lati ni olori tuntun, ni eyi ti Aare Ernest Bai-koroma yoo fi alefa sile, leyin saa meji re.
Ikọ Boko Haram yii lo n beere pe oun n fẹ amulo ofin Sharia lorilẹede Naijiria, ti ko si gbọdọ si ohunkohun to jọ mọ ẹkọ iwe tabi ọlaju igbalode.
"Ara gbigbona ni nọọsi to wa lẹnu iṣẹ ro pe o n ṣe mi, lo ba fun mi ni abẹrẹ laimọ pe aarun rọmọ lapa, rọmọ lẹsẹ lo wa nidi aisan yẹn (polio) ni.
Lẹ́hìn èyí obìnrin náà tún dáhùn o ní, Ìwọ dé Igbó Olódùmarè rí ńdan?
Bi a baa gbagbe, apapo egbe awon osise, Nigeria Labour Congress (NLC), Trade Union Congress (TUC) ati United Labour Congress (ULC), fopin si iyanselodi re nipari osu kesan ti o koja, eleyi ti o bere lojo kerindinlogbon osu kesan an odun ti a wayii.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Eleruwa: Ilé ẹjọ lé Ọba Èrúwà kúrò lórí Àpèrè lẹ́yìn ọdun 21 29 Bélú 2019 Oríṣun àwòrán, Eruwa/facebook Àkọlé àwòrán, Ilé ẹjọ lé Ọba Èrúwà kúrò lórí Àpèrè lẹ́yìn ọdun 21 Adájọ Ladipo Abimbola ti ilé ẹjọ́ kòtẹ́milọ́rùn ti ní ìdájọ tó gbé Ọba Adegbola wolé lọdun 2011 kìí ṣe èyí to tọ̀nà rárá nítori náà ìmúlẹ̀ múfo ni.
Won ni eni to ba dan eleyii wo, yoo foju ba ile-ejo.
Bí mo bá sì wí fún eniyan burúkú pé dandan ni pé kí ó kú, bí ó bá yipada kúrò ninu ẹ̀ṣẹ̀ rẹ̀, tí ó bẹ̀rẹ̀ sí ṣe ohun tí ó dára, tí ó sì tọ́, 
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Mama Arsenal: Màmá àgbà yìí máa ń lọ sí ìbùdó tí wọ́n ti ń wo bọ́ọ́lù láti wòran Lọjọ naa ni Manchester City to sun mọ wọn julọ lori atẹ igbelewọn liigi premiership ilẹ Gẹẹsi lọ fidirẹmi ni ile Chelsea lọjọ naa lọhun.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Nínú irú ìṣẹ̀lẹ̀ tó lágbára bayii kòkòrò aifojuri yìí le ba ẹ̀dọ̀ fòòró jẹ́.
 luiz gama tún mú ọ ̀ rọ ̀ yìí lọ sí ilé ìgbìmọ ̀ aṣòfin níbi tí wọn kò ti fi ara mọ ́ ìdáǹdè ẹsẹ ̀ kẹsẹ ̀ fún gbogbo ẹrú .
O lọ ilé iwé alakọbẹrẹ Islamia ni ipinlẹ Eko àti Osogbo ki o to lọ si ilé ẸKỌ Adekanbi Commercial High School, ni agbegbe Mile12 ni ìlú Eko sùgbọ́n ilú Osogbo lo ti gba iwé ẹri WAEC.
O ni lẹyin ti ipolongo idibo ati idibo gangan ti pari bayii, igbesẹ fun itẹsiwaju ọrọ aje orilẹede Naijiria lo yẹ ki ijọba aarẹ Buhari ati igbakeji rẹ, Yẹmi Ọṣinbajọ o gbe yẹwo bayii.
Abaribe pe akiyesi ile si oro naa pe sise oko oju irinna ni ekun yii yoo je ki irinna rorun lati guusu orile-ede yii si ariwa ati si iwo oorun.
Ẹ̀sìn ìṣẹ̀ṣe ṣún síwájú, wo orin aládùn lẹ́nu ẹgbẹ́ akọrin àti ìjèrè ọkàn tí wọn ń ṣe Ojúlówó Shina Rambo yọjú sígboro lọ́jọ́ Àìkú, ó fi ìka hánu lórí ìpànìyàn tó ti ṣe Àwọn ọ̀dọ́ Benue pa pásítọ̀ ti wọ́n fẹ̀sùn kan pé ó ń mú ǹkan ọmọkunrin Iléẹjọ́ mú ọjọ́ kejìdínlógún, oṣù kọkànlá fún ìgbẹ́jọ́ àwọn tó jí ìbejì Àáfà Akeugbagold ní Ibadan Àgọ́ ọlọ́pàá Sanyo ni wọ́n darí ọkọ̀ akérò tó kó àwọn Fulani wọ ìlú Ibadan lọ - Oyo OPC Ṣugbọn ṣa, awọn kan tun n sọ pe, ko jọ pe ipagọ naa yoo waye titi di ọdun 2021.
ewon osu merin gbako pelu ise asekara.
Bẹẹ ni ọrọ igbe aye gbajumọ oṣere tiata lobinrin, Remilekun Oshodi, ti ọpọ eeyan mọ si Remi Surutu ri.
Ọgbẹni Nsengimana tiẹ tun sọ pe ọpọ awọn agbaṣẹṣẹ maa n mọnmọn lo ohun elo ti ko lagbara nitori ki wọn le ri owo to pọ.
Kòsí iṣẹ́, kò sí owó"" ni ìjọba sọ fún àwọn òṣìṣẹ́ tó ń gbèrò láti dá iṣẹ́ sílẹ̀ tẹ́lẹ̀rí, sùgbọ́n níbáyìí, wọ́n ti dá ìjọba lóhùn wípé, ""kò sí owó oṣù, kò sí ìbò""."
Ohùn kan wá fọ̀ láti ọ̀run pé, “Ìwọ ni àyànfẹ́ Ọmọ mi; inú mi dùn sí ọ gidigidi.
Ó nà gbalaja lé ọmọ náà lórí, ó fẹnu kò ó lẹ́nu, ó fojú kò ó lójú, ó sì gbé ọwọ́ lé ọwọ́ rẹ̀.
Tí ìjọbá bá kọ̀ láti san owó oṣù wa, a o da iṣẹ́ sílẹ̀ - ASUU Ẹgbẹ awọn oṣiṣẹ lorilẹede Naijiria, ASUU ti paṣẹ fun awọn olukọ fasiti lati da iṣẹ silẹ ni igbakugba ti ijọba ba ti kọ, lati san owo oṣu wọn.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ọgbà ẹ̀wọ̀n ni wọ́n ti já àbálé Esra lábẹ́ àwáwí àyẹ̀wò wúndíá Lọjọ kinni ,oṣu kejila, ọdun 2020 yii lawọn ọlọpaa mu ọkunrin mẹẹdọgbọn ni ihoho niluu Brussels nibi ti oloṣelu aṣofin ilẹ Hungary ti n saa lọ.
Kyari si ni oṣiṣẹ ijọba to wa ni ipo to ga, ti Covid-19 kọkọ pa ni Naijiria.
Online Slave Market: Wo ìlú tí wọ́n tí ta ọmọdé àti obìnrin ṣe káràtátà lórí ayélujára
Oríṣun àwòrán, Getty Images Ikọ agbabọọlu Norway to gba Ife Ẹyẹ naa ni ọdun 1995 lo jawe olubori pẹlu bi ko se si gbajugbaja elere bọọlu wọn, Ada Hegerberg ni ifẹsẹwọnsẹ naa.
Siwaju si i, igbakeji gomina tun ran gomina leti nipa ipade ti won se ni ojo kọ́kàndínlógún, osu kẹ́rin pe oun, n ronu lati fise sile.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Brexit: Bí orílẹ̀-èdè Gẹẹsi ṣe fi àjọ ìṣọ̀kan ilẹ̀ Europe sílẹ̀ rèé 1 Èrèlè 2020 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Adari ilẹ Gẹẹsi, Boris Johnson ni inu awọn kan ko dun si iyapa yii.
Amọ, orilẹede Mexico ati Canada naa maa n fun ọmọ ni iwe igbelu nitori wọn bii si orilẹede naa.
Bakan naa wọn jẹ ko di mimọ pe o maa n tọ agọ ara sọna nipa ohun to yẹ ko ṣe ki ara lee ji pepe.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Akomolede ati Asa lori BBC: Olùkọ́ Kikelomo Ogunboye tan ìmọ́lẹ̀ sí ìwà olè ọ̀gá ọlọ́pàá Audu gẹ́gẹ́ bí àwòkọ́ṣe àsìkò yìí Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Akomolede ati Asa lori BBC: Olùkọ́ Kikelomo Ogunboye tan ìmọ́lẹ̀ sí ìwà olè ọ̀gá ọlọ́pàá Audu gẹ́gẹ́ bí àwòkọ́ṣe àsìkò yìí 8 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Iwa ibajẹ to sọdo ni Naijiria ni Oladejo Okediji fi sakawe itan inu iwe arosọ litireṣọ toni.
Ileeṣẹ ọlọpaa naa fi kun pe, ọpọ eeyan lo dagbere faye nitori ikọlu awọn janduku naa, ti awọn mẹrin kan si farapa yanayana.
Gbogbo awọn eeyan to si dibọn bii ẹni pe wọn n ran wa lọwọ lati ko awọn ẹru wa jade ki ina maa baa jo wọn, ni wọn tun ja wa lole.
Ṣugbọn ti Kristi ni yín, Kristi sì jẹ́ ti Ọlọrun.
" Ìdí nìyí tí a fí ń pe "" ilé-ifẹ ̀ ní ìlú ibi tí o júmọ ́ ti ń mọ ́ wá ""."
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Obateru Akinruntan: Wíwá ohun tá jẹ títí láé ló gbé wa kúrò nílé Ife Koda, o ni oun tun paarọ tikẹti oun ati akoko ti oun yoo rinrin ajo, ki oun le gba esi ayẹwo covid 19 naa, eyi ti yoo jẹ ki wsn jẹ ki oun wọ baalu wa sile.
Bí ẹnikẹ́ni bá ní etí láti fi gbọ́ràn, kí ó gbọ́.
lati ṣatunṣe si oju ti awọn ara ilu fi n wo ọrọ naa”O ṣalaye pe gẹgẹ bi o ṣe
OLUWA Ọlọrun yín yóo bukun yín ní ilẹ̀ tí ẹ̀ ń lọ gbà tí yóo sì di tiyín.
Ina ọkọ rẹ gbọdọ mọlẹ kedere Yoruba a ma ni oju ni baba ara.
Bakan naa, ọkunrin ọmọ Cambodia kan to de lati France, ati awọn eniyan meji miran to de, lẹyin ti wọn lọ fun ayẹyẹ ẹsin Islam kan ni orilẹ-ede Malaysia naa ni arun asekupani yii Eyi mu ki apapọ awọn to ti ni arun naa l'orilẹ-ede Cambodia jẹ mejila bayii.
Ọ̀pọ̀ a máa pe ni ọkúnrin pẹ̀lú igbàgbọ́ pé o kan n fi ìmúra rẹ̀ ran ọ̀rọ̀ ajé rẹ̀ lọ́wọ́ lásan ní àti pé orúkọ rẹ̀ ọkùnrin ní.
Wọ́n bi í pé, “Kí ni ó ṣe sí ọ?
Seyi Makinde ṣe ìbúra fún kọmísánà tuntun mẹ́rìnlá
"Banki Nàìjíríà, CBN ṣàlàyé nípa àwọn tó máa rí gbà nínú owó ìrànwọ́ N75b tíjọba gbé kalẹ̀ Wo ọ̀nà àbáyọ fún àwọn akẹ́kọ̀ọ́ tí àjọ WAEC gbẹ́sẹ̀ lé èsì ìdánwò wọn Ẹ dẹ̀kun lílo Sniper àti Dichlorvos fún ìtọ́jú oúnjẹ- NAFDAC kìlọ̀ ''Àjọ NERC ti fún Disco láṣẹ láti padà sí owó tàríìfù tuntun iná mọ̀nàmọ́ná'' EFCC bẹ̀rẹ̀ ìwádìí lórí ẹ̀sùn ìwà jẹgúdújẹrá tí wọ́n fi kan Fowler tó jẹ́ Alága iléeṣẹ́ FIRS tẹ́lẹ̀ Ìgbónára ló máa ń mú àwọn èèyàn ṣe ""Jungle justice"" tí ìjàmbá ọkọ̀ bá ṣẹlẹ̀- Dokita Dokita to n ṣetọju arun ọpọlọ kan, Dare Omowumi, ti sọ pe idi ti awọn eeyan ṣe maa n ṣedajọ gbigbona latọwọ ara wọn ni ara gbibona ati ai lee ni suuru."
Fayemi balẹ biba sibi ayẹyẹ iburawole Àkọlé àwòrán, Awọn Imamuu wa nibẹ lati fi adura ran ijọba tuntun yi lọwọ Àkọlé àwòrán, Ko si ayẹyẹ iburawọle ti ko ba si adajọ ti yoo bura fun Gomina tuntun Àkọlé àwòrán, Ogbeni Kayode Fayemi ati iyawo rẹ ni wọn jijọ kọwọrin wa ibi ayẹyẹ naa Àkọlé àwòrán, Ki lẹ lero wi pẹ alagba Bisi Akande n sọ fun alaga ẹgbẹ APC teleri alagba John Odigie-Oyegun?
4 Agẹmo 2020 Alaafin Ọyọ Queens: Ǹjẹ́ o mọ àwọn olorì àkọ́fẹ́ Aláàfin Adeyẹmi?
Ni agbegbe Apake lopopona marosẹ Ogbomọṣọ si Ilọrin atijọ ni ọkọ akẹru kan ti sa wọ ibi ti awọn ero ọkọ ati ọlọkada korajọpọ si.
Ninu ọrọ tiẹ, aarẹ ana to tun figba kan jẹ igbakeji fun Aarẹ Yar'adua, Goodluck Jonathan ṣapejuwe Yar'Adua bi ọrẹ, iyekan ati ọga.
O ni: ''Gbogbo awọn olè naa kọ ni awọn araalu Okeho sun ni ina, marun un si wa ni agọ ọlọpaa wa A n ṣewadii lori ibi ti awọn adigunjale naa ti wa, ki lo de ti wọn se fọ banki naa ati owo ti wọn jigbe nibo lo wa?
Ẹ gbọdọ̀ pa ìlànà yìí mọ́ láti ìrandíran.
Oloṣelu ma n ba awọn ọba wi bi ọmọ ọdọ, awọn ọba ti sọ ara wọn di yẹ̀bù-yẹ́bù, awọn oloṣelu naa si ti ba àṣà wa jẹ.
"Oríṣun àwòrán, Twitter/real_mercyeke Oun ati ololufẹ rẹ lasiko ti wọn wa nile ẹlẹgbọn agba Ike ti lọ da eto tiwọn naa kalẹ ti wọn n pe ni ""Mercy & Ike ""."
Ẹ jáde kí ẹ máa lọ ní alaafia.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Àwọn òṣìṣẹ́ BBC News Yorùbá sọ̀rọ̀ ìdùnnú lórí ayẹyẹ ọdún kan iléeṣẹ́ náà Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Damilọla Ajayi: Ọ̀dá owó ló ṣún mi dé ìdí lílo ìyarun bíi fèrè Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
"Ẹyìn tí Hydroxychloroquine, Zinc ati Zithromax da lára yá,ẹ bọ síta wà jẹrìí mí-Dr Stella Emmanuel Ọ̀pọ̀ òkú ṣùn, dúkìá jóná nínú àkọ̀tun ìṣẹ̀lẹ̀ ìbúgbàmù gáàsì l‘Eko Tí ìjọba kó bá dẹ́kun ìpànìyàn ní Gúúṣù Kaduna, aráàlú yóò jà fúnra wọn - CAN Ayẹyẹ ìgbaniwọlé sínú ẹgbẹ́ òkùnkùn bẹ́yìn yọ, wọ́n lu ọmọ ẹgbẹ́ tuntun pa Ninu fidio naa, iya rẹ gbiyanju lati na a lẹgba, ṣugbọn ni ṣe lo n pariwo ""Mummy calm down, mummy calm down"" lọna ati bọ lọwọ ijiya ọhun."
Lọ́dọ̀ mi ni èso rẹ̀ ti ń wá.
Kò sí àbẹ̀tẹ́lẹ̀ nínú Igbó Olódùmarè, nítorí wíwọ́ ni ọ̀nà àbẹ̀tẹ́lẹ̀ jẹ́, ṣùgbọ́n ọ̀nà òótọ́ gbòòrò ó ń dán kooro – ó dígbà o.
"Bo tilẹ jẹ pe ijọba ipinlẹ naa ""yoo bọwọ fun aṣa ati iṣe ilu naa, ti ko si ni sọ nkankan nipa orukọ àràbà nla to wo nipinlẹ naa"", iroyin to n lọ nipe Olufon ti Ifon, Ọba Isreal Adewusi ni awọn afurasi ajinigbe pa."
 doni , ohun nikan ni he alakoso agba britani to ba ebun nobel ninu litireso , ati eni keji ti o je niyi bi araalu oniyi isodokan awon ipinle amerika .
OLUWA ṣèlérí fún Jehu pé, “Àwọn ọmọ rẹ títí dé ìran kẹrin yóo jọba ní Israẹli.
"Crystal Palace pàkúta sí gaàrí Manchester United ní Old Trafford Wilfred Ndidi, ọmọ Nàìjíríà pa iná ògo Chelsea ní Stamford bridge Manchester United dáná sun Chelsea bi ẹràn àgbò iléyá ""Ojú wa rí tó ní Egypt, bí wọ́n ṣe ń tẹ̀ wá lọ́mú, ni wọ́n ń gbá wa ní ìdí"" Toyin Abraham kìí bá èmi náà yọ̀, ni kò jẹ́ kí ń gbé e lárugẹ fún ayọ̀ ọmọ - Lizzy Anjorin Ọ̀pọ̀ èèyàn bẹnu ẹ̀tẹ́ lu Mercy Aigbe lórí bó ṣe ki Adeniyi Johnson Ìdí rèé tí mi ò fi yọjú sí ìgbìmọ̀ àjọ PFN- Fatoyinbo Shehu Sani lootọ ni ko ni boju mu ki aarẹ Naijiria tun wa lati apa ariwa orilẹede yii ninu idibo ọdun 2023, amọ o le ṣẹlẹ bẹẹ ti awọn eeyan to wa lapa ila oorun ati iwọ oorun guusu ko ba fimọ sọkan."
Awon to n gbe agbegbe yii ni ijọba ko tii mu ìlérí to ṣe fún wọn lori ìpèsè ààbò ṣẹ́ rara Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Wọ́n ti sin òkú àwọn tó kú ni Kaduna Wọ́n ti sin ológun Naìjíríà 11 ní Kaduna Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 3 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 5 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìpànìyàn Benue: Ìsìnkú Fada àtàwọ́n ọmọ ìjọ yóò wáyé l'ọ́jọ́ Ìṣégun 20 Èbibi 2018 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Àìmọye ìgbà ni darandaran ti rán ọ̀gọ̀ọ̀rọ̀ èèyàn ìpínlẹ̀ Benue sí ọ̀run ọ̀sán gangan Ikọ aṣoju Poopu ati aadọta bisọbu ni yoo wa nibi isinku àwọn Fada méjì pẹ̀lú ọmọ ìjọ mẹ́tàlá ti Ìjọ Aguda, ipinlẹ Benue.
Ọ̀kọ̀ọ̀kan ninu wọn ní ojú mẹrin mẹrin ati ìyẹ́ mẹrin mẹrin.
eni to le salaye ipa eto ounje fun awon akekoo, ju awon akekoo ti iye won le ni
ààbò jẹ ́ ohun tó dará púpọ .
Bianca júwe ilé fún Serena Williams nínú ìdíje l'America Ìròyin sọ pé nínú ìwé ìròyìn tó ti tí fẹ̀sun kan ìjọba Akeredolu pé ko gbìyànjú rárá nínú ìdàgbàsoke ohun èlò amúlùdún àti pípa owó lábẹ́lé.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Osun Election Results 2018: Adeleke sọ pé PDP yóò gba ipò gómìnà rẹ̀ padà nílé ẹjọ́ Ẹgbẹ oṣelu APC ni awọn ko lee gba idajs naa wọle ati pe ile ẹjọ kotẹmilọrun ni awọn n gba lọ bayii.
” Nígbà tí Simoni Peteru gbọ́ pé Oluwa ni, ó wọ ẹ̀wù rẹ̀, nítorí ó ti bọ́ra sílẹ̀ fún iṣẹ́, ó bá bẹ́ sinu òkun, ó ń lúwẹ̀ẹ́ lọ sébùúté.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ìdẹ̀ra dé, Gẹnẹrátọ̀ tó ń lo omi dé, a bọ́ lọ́wọ́ òkùnkùn Khafi jẹ̀bùn ọkọ̀ ₦7.
Sibẹsibẹ inú OLUWA kò ní rọ̀,bẹ́ẹ̀ ni kò ní dá ọwọ́ ìjà rẹ̀ dúró.
Ibẹ̀ ni wọ́n sì ti pínyà, ṣùgbọ́n wọ́n ṣe àdéhùn pé ẹnikẹ́ni tí ó bá kọ́ dé oríta yìi’nígbà tí ó bá ń padà bọ̀ níláti dúró síbẹ̀ de àwọn méjì tí ó kù.
ipinle Cross River  ni ẹkun Gusu orile
Eto aabo fẹsẹ mulẹ ni gbagede Eagle Square naa, nibi ti
Muhammadu Buhari: Falana ní ilé ìwòsàn ti di mọ́ṣúárì ní Nàìjíríà nígbà tí Buhari ń gbàtọ́jú nílẹ̀ òkèrè
Olateru-Olagbegi II: Ìtàn ayé Ọba Olateru-Olagbegi Kejì, àkàndá ẹ̀dá tí kò ṣe fi ara wé
Ikú ti yọ́wọ́ òṣèré Nollywood Yorùbá, Yusuf Satia l'áwo Gómìnà ìpínlẹ̀ Ekiti, Kayode Fayemi nàá ti ni aàrùn Coronavirus Kí ló dé tí ìjọba ìpínlẹ̀ Oyo kéde fífagilé Sáà ètò ẹ̀kọ́ kẹta fún àwọn akẹ́kọ̀ọ́?
A pa wọ́n títí tí kò fi ku ẹnikẹ́ni ninu àwọn eniyan rẹ̀.
Omowe Onu , ni idasile awon ile-ise tuntun naa yoo ran awon omo orile ede Naijiria lọwọ lati lee  ni imọ nipa isẹ iwadii ati  lati lee mu idagbasoke ba ohun amayederun ati eto oro aje lorile ede Naijiria.
Ipaniyan naa ko yọ awọn ọdọ to n sinru ilu silẹ.
Ogboìya onísòwò níí jèrè, hílàhílo ni oníyèméjìí máa bá kiri – kí Ọlọ́run má ṣe wá ni oníhìlàhìlo ènìyàn.
Dokita Abimbola Bowale to gba ẹnu ileewosan naa sọrọ sọ diẹ lara nkan to yẹ lati mọ nipa ọkunrin naa fun BBC: Ẹni ọdun mẹrinlelogoji ni ọkunrin naa jẹ Gbogbo awọn ayẹwo bi ifunpa, ara gbigbona ati bẹẹbẹ lọ wa ni ipo to dara bayii Itọju ti wọn n fun n wọ ọ lara dara-dara O wa si orilẹ-ede Naijiria lati ṣe iṣẹ fun awọn ileeṣẹ kan ni Ọjọ keji to de Naijiria lo dubulẹ aisan, wọn si ṣayẹwo rẹ ni ileewosan ileeṣẹ naa Dokita to yẹ ẹ wo fura pe o ṣeese ko jẹ aarun Coronavirus lo ni nitori pe bi o ṣe ṣẹṣẹ de lati Italy, eyi lo si mu ki wọn o gbe lọ si ileewosan Mainland Hospital ni Yaba ni aarọ ana Nibẹ ni wọn si ti fidirẹmulẹ pe o ni i Kìí ṣe ìpínlẹ̀ Eko nìkan ni ọkùnrin nàá dé, ó lọ sí Ogun nàá Ọmọ orilẹ-ede Italy to kọkọ gbe aarun Coronavirus wọ ipinlẹ Eko, l'orilẹ-ede Naijiria tun lọ si ipinlẹ Ogun ni kete to de lati ilu Milan to jẹ olu ilu Italy ko to o di pe wọn fidirẹmulẹ pe o ni aarun naa.
’ rèé Iṣu ló wà nínú mọ́tò mi, kìí ṣe èèyàn ni mo sọ di iṣu - Afurasí Ajínigbé figbe ta Adeleke ló ní ọmọ ẹgbẹ́ tó pọ̀jù l‘Ọṣun, nipò gómìnà ṣe tọ́ si ní 2022 - PDP Ọṣun Poly Ibadan: Ọjọ́ iwájú la rò táa fí dáná sún fóònù àwọn akẹ́kọ̀ọ́ Ipinlẹ Kano jẹ ọkan lara awọn ipinlẹ mejila ni ẹkùn Ariwa Naijiria to n lo ofin ẹsin Islam, ti a tun mọ si Sharia.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù NDLEA: Ó sàn kí ẹ pa mí ju kí ẹ ba oko tí mo gbin igbó sí jẹ́ lọ- Afurasi Clement Akor ní Kogi 3 Owewe 2020 Oríṣun àwòrán, Others O san ki ẹ pa mi ju ki a ẹ ba oko ti mo gbin igbo si jẹ lọ- Afunrasi kan lo rọ NDLEA bẹẹ.
Abrahamu retí títí, ó gbàgbọ́ pé òun yóo di baba fún ọpọlọpọ orílẹ̀-èdè gẹ́gẹ́ bí Ọlọrun ti wí, pé, “Bẹ́ẹ̀ ni àwọn ọmọ rẹ yóo rí.
Eyi waye lẹyin ti Taifa Stars ti wọn ṣẹṣẹ kopa ninu idije ife ẹyẹ Nations Cup lati ọdun 1980 ko lee tẹsiwaju mọ ninu idije to n waye ni Egypt tori wọn ja kulẹ lẹẹmẹta.
 a má a ń ṣe àgbéjáde ẹ ̀ yà àjẹsára náà titun lẹ ́ ẹ ̀ mejì lọ ́ dún nítorí tí kòkòrò àrùn àìlèfojúrí afàìsàn ọ ̀ fìnkì a má a paradà kíákíá .
Awọn kan lara wọn si ti jẹ to ẹbun owo miliọnu marun Naira.
O ni wi pe Oshiomole kò ni asẹ lati sọ pe ki Saraki fi ipo rẹ silẹ.
N óo já wọn kúrò lápá yín, n óo sì tú àwọn ẹ̀mí tí ẹ dè sílẹ̀ bí ẹyẹ.
"O jẹ́ ǹkan tó nira láti le bọ́ sita gbangba pé ènìyàn ni ààrùn Covid-19"" Peter Okoye ni ""mó rò pé àwàdà ni ọ̀rọ̀ ààrun Covid-19 tẹ́lẹ̀ ni, mí ò sì kọbi ara si"" Lẹ́yìn náà ni ìyàwọ mi àti ọmọ mi ni ààrùn náà ti fi mọ́ ẹni to n ba wa dána àti alágbàta ọmọ mi náà."
Ẹ lọ nisinsinyii kí ẹ sì tún ṣe ìwádìí dáradára nípa ibi tí ó wà, ati ẹni tí ó rí i níbẹ̀; nítorí mo gbọ́ pé alárèékérekè ẹ̀dá ni Dafidi.
Egiloni yìí jẹ́ ẹni tí ó sanra rọ̀pọ̀tọ̀.
Wọ́n bi í pé, “Àbí àwa náà fọ́jú?
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Ọ̀lọ́pàá shátà mi láti Mowe dé Magboro dé Shagamu, wọ́n ní ṣé mi ò mọ̀ pé ìjọ́ba ni mo ṣiṣẹ́ fún' Ṣé lóòtọ́ ni ẹ̀yà kòkòrò àrùn COVID-19 ti wọ ìpínlẹ̀ Osun?
Modric ti orilẹ-ede Croatia lo gba ami ẹyẹ ẹlẹsẹ ayo (Golden Boot) fun todun 2018.
Ẹ óo dààmú ṣugbọn ìdààmú yín yóo di ayọ̀.
O ni o jẹ nnkan ibanujẹ wi pe awọn olubi ẹda naa ko jẹ ki Sukura wọn aṣọ ọdun rẹ.
Wọn óo rí i lojukooju, orúkọ rẹ̀ yóo sì wà níwájú wọn.
Àwọn mejeeji sì fi ẹnu ko ara wọn lẹ́nu, wọn sọkún títí tí ara Dafidi fi wálẹ̀.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Jim Mattis wo awoyanu ọmọogun Indonesia to nmu ẹjẹ ejo 24 Sẹ́rẹ́ 2018 Oríṣun àwòrán, Reuters Àkọlé àwòrán, Awọn ọmọogun Indonesia nfi ejo sere gẹgẹbii ara igbaradi wọn.
Lẹyin naa ni ẹnikan yoo paṣẹ fun gbogbo awọn ti ko ni i kopa ninu idibo lati jade sita ki wọn o to o ti ilẹkun.
Ninu eyi ti o gbọdọ ronu ibi ti oo maa gbe awọn ọkọ naa si.
aforijin lọwọ awon eniyan bi won se pẹ lati bẹrẹ eto idibo.
Ju gbogbo rẹ̀ lọ, anfaani ni ilẹ̀ tí à ń dáko sí jẹ́ fún ọba.
A mú ẹranko náà lẹ́rú, pẹlu wolii èké tí ó ń ṣe iṣẹ́ abàmì níwájú rẹ̀, tí ó ti tan àwọn tí wọ́n gba àmì ẹranko náà jẹ, ati àwọn tí wọ́n júbà ère rẹ̀.
Nibẹ ni wọn ti kọlu ara wọn.
À ní ọmọ Àmọ́dù, ọmọ Ẹjalónibú
 wọ ́ n ń sún láyé ; wọ ́ n ń sùn lọ ́ run .
Bí ọmolúwàbí bá lọ síibi kan bí àlejò ó yẹ kí ó mọ ìgbà tí ó tó àkókò kí ó fi ibẹ̀ sílẹ̀, àwọn aláìmòye ènìyàn kò mọ ìwà wọ̀bìa sí àìdára.
Eleyi lo jẹ ki ijọba naa tu, ki awọn oyinbo to wa ko ilẹ Afirika lẹru.
Igbagbọ awọn obi ati alagbatọ to ran akẹkọọ lọ sile iwe ni ki wọn lọ kawe, ki wọn si di eeyan lọjọ ola.
Nàìjíríà kéde orúkọ àwọn agbábọ́ọ̀lù Falconets fún ìdíje àgbáyé
OLUWA Ọlọrun fi ara rẹ̀ búra ó ní, ‘Àwọn aguntan mi di ìjẹ, fún gbogbo ẹranko nítorí pé wọn kò ní olùṣọ́; nítorí pé àwọn tí ń ṣọ́ wọn kò wá wọn, kàkà bẹ́ẹ̀ oúnjẹ ni wọ́n ń wá sẹ́nu ara wọn, wọn kò bọ́ àwọn aguntan mi.
Gbogbo orin egúngún bìkiafù tí wọ́n kọ sí mi l'étí nípa Ajayi tí mi o gbọ̀ ló bu mí lọ́wọ́- Akeredolu Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí kan sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
Ìlànà tí ìjọba Eko gbé kalẹ̀ fún ìjọsìn lásìkò Covid-19 kò bá wa lára mu - Chris Okotie Ìjọba Ìpínlẹ Ọyọ yọ̀ǹda pé kílé Ìjósìn má san owó orí mọ́ - Makinde Ìjọba Nàìjíríà fi ọ̀sẹ̀ mẹ́rin kún ìséde ààrùn Coronavirus Aarẹ Muhammadu Buhari ti fi ọwọ si afikun ọsẹ mẹrin si abala keji didẹwọ isede coronavirus.
Nígbà tí Jesu dìde kúrò ní ilé ìpàdé, ó wọ ilé Simoni lọ.
Grace Adejoh nikan ni oludije obinrin to wa lara wọn.
Àwọn ti ọ̀rọ̀ náà sojú wọ́n ni to sì pe ara rẹ̀ ni Taiwo a.
Kalebu ṣe ìlérí pé, ẹnikẹ́ni tí ó bá ṣẹgun Kiriati Seferi tí ó sì gba ìlú náà ni òun yóo fún ní Akisa ọmọ òun, láti fi ṣe aya.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ondo:O d‘èèwọ̀ láti tí ojú pópó pa fún ayẹyẹ 29 Sẹ́rẹ́ 2018 Oríṣun àwòrán, Twitter Àkọlé àwòrán, O ti di eewọ bayi lati da oju irn reluwe kọja ladugbo Ọja Ọba Ijọba ipinlẹ Ondo ti kede pe lati akoko yi lọ, o ti di eewọ fun ẹnikẹni lati di oju popo pa fun ayẹyẹ kayẹyẹ tabi fun eto okoowo yika tibu tooro ipinlẹ naa.
Gẹ́gẹ́ bí ó ti wà ní àkọsílẹ̀ pé, “Ẹnìkan lawọ́, ó ń ta àwọn talaka lọ́rẹ, iṣẹ́ àánú rẹ̀ wà títí.
Nibi ti wọn ti n ṣe ipade apero kan nipa ilana ti wọn fi n ṣe igbeyawo lọna ofin lorilẹede yii ni akọwe agba ile iṣ to n ri si ọrọ abẹnu, Georgina Ehuriah ti lede ọrọ naa.
"O ni ""bi awọn agbebọn ṣe ya bo ile iwe lọsan gangan ti wọn si ji awọn akẹkọọ to le ni ọọdunrun gbe jẹ ohun ibanujẹ ati eyii ti ko yẹ ka fi ọwọ yẹpẹrẹ mu""."
Pẹlu iye awọn eeyan tuntun yii, o ti le ni ẹgbẹrun mẹrinlelaadọta eeyan to ti larun naa lorilẹede Naijiria bayii.
Mo fi Ọlọrun jẹ́rìí ohun tí n óo sọ yìí.
Idahun yii n waye nitori bi ẹka ẹgbẹ naa nilu Benin ṣe ni oun ko ni igbagbọ mọ ninu alaga ẹgbẹ nipinlẹ ati alaga apapọ ẹgbẹ naa.
Students kidnap: Garba Shehu ní iléeṣẹ́ ológun ti yabo ibùdó àwọn jàndùkú tó jí àwọn akẹ́kọ̀ọ́ lọ nílé ìwé katsina
Ẹ kò gbọdọ̀ bẹ̀rù eniyan, nítorí Ọlọrun ni onídàájọ́.
Àjọ WAEC fún Buhari ní ìwé ẹ̀rí Oríṣun àwòrán, @BashirAhmaad Àkọlé àwòrán, Àjọ WAEC ṣàfihàn ìwé ẹ̀rí girama Ààrẹ Muhammadu Buhari Ẹ sinmi ariwo ni orin to da bi ẹni pe Aarẹ orilẹede Naijiria, Muhammadu Buhari n kọ bayi lẹyin ti ajọ to n ri si idanwo ile iwe girama lapa iwọ-oorun ilẹ Afirika WAEC fun un ni iwe ẹri.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Alaafin of Oyo: Olori Anu dúpẹ́ lọ́wọ́ kábíyèsí Ọba Adeyemi fún ipa ribiribi to kó láyé òun 9 Ìgbé 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 31 Èbibi 2020 Oríṣun àwòrán, Olori Anu/ Instagram Àkọlé àwòrán, Olorì Anu Adeyemi ń ṣe ọjọ ìbí, ẹgbẹ́ ǹkan tò sọ sí Kábíyésì Ọkan nínú olori lááfìn ọba Oyo, Ọba Lamidi Olayiwole Atanda Adeyemi III Iku baba yeye, olori Anu.
Bakan naa ni a gbọ pe awọn ara Baghdad ko le ṣe ṣiṣẹ Hajj fun ọpọlọpọ ọdun.
Gẹgẹ bi akọsilẹ to wa ni itakun agbaye ṣọọṣi naa, oun ni ipejọpọ akọkọ to n gbe igbe aye rẹ gẹgẹ bi ẹlẹran ara.
- Ọọ̀ni Ife Ìgbẹ́jọ́ aṣaájú ìjọ Sotitobire kúrò nílé ẹjọ́ Mágísíréètì lọ sílé ẹjọ́ gíga l‘Akure Bayìí ni àwọn ọlọpàá Akure ṣe ko àwọn ará ìlú ti o ji ẹrù ni sọọsi Sotitobirẹ Yetunde ni lootọ ni isin n waye nile ijọsin Sotitobire amọ awọn ko lee lu ilu rara nitori gbogbo rẹ ni awọn oluwọde kan ti sun nina, lasiko ti wọn se iwọde wa sile ijọsin naa.
 kò yẹ kí mọ ́ gbè tún máa pọngbá .
Burẹdi ìfihàn sì gbọdọ̀ wà lórí rẹ̀ nígbà gbogbo.
Ajọyọ yii b silẹ nigba ti olori ẹgbẹ ọmọ ogun to boju to gbigbe ijọba le ẹlomiiran lọ́wọ́ lẹyin ọjọ kan pere ti wọn bura wọle fun un.
3 317867 Orilẹede Jordan 4121 41.
Orin Fela Kuti ló pọ̀ nínú àkojọpọ̀ orin Burna Boy tí wọ́n si dibo pé ki o gba àmì ẹ̀yẹ lọ́dun 2014 Ti se akójọpọ̀ awo orin to le ni mẹ́jọ, yàtọ̀ sí àwọn orín ẹlẹ́yọ kọ̀ọ̀kan, àti àwọn eyi to darapọ̀ mọ́ àwọn ènìyàn láti kọ.
kí àwọn ará ilẹ̀ tí o ti kó wa wá má baà wí pé, ‘OLUWA kò lè mú wọn lọ sí ilẹ̀ tí ó ṣèlérí fún wọn ati pé ó kórìíra wọn, ni ó ṣe kó wọn wá sinu aṣálẹ̀ láti pa wọ́n.
Kini ofin tuntun ti ijọba ṣẹṣẹ fikun sisọrọ kubakugbe lawujọ Minisita fun eto iroyin ni Naijiria, Lai Muhammed ni ofin tuntun naa ti wọn pe ni 'Edition of the Broadcasting Code' ti mu ayipada pa iroyin to niiṣe pẹlu oṣelu, iroyin abẹle, iroyin yajoyajo ati iroyin karakata ni Naijiria.
Kabiyesi Akanbi ni ohun ko jọba tori ati kowo jẹ, oun fẹ fara sin ilu ni.
"A ko lee tọ awọn ọdọ orilẹede yii ti iye wọn yoo ti wọ igba miliọnu ti a o ba fi de ọdun 2045 ni yara ikẹkọ kilaasi nikan"" Oríṣun àwòrán, @googleafrica Àkọlé àwòrán, ""Ko si ohun ti o ko lee fi wo, kii tan bẹẹni anfani yii yoo kan awọn agbegbe miran laipẹ"" O ni ara igbesẹ ti ijọba apapọ n gbe niyi lati darapọ mọ awọn orilẹede ti o n fi imọ ẹrọ ṣọrọ."
ndugu m ' hali tabi kalulu ( c.
Ọgbẹni Mohammed jẹ igbakeji ọga ọlọpaa lorilẹede Naijiria, o si jẹ ọmọ ilu Lafia to jẹ olu ilu Ipinlẹ Nasarawa.
Olugbani nimọran pataki fun aarẹ Naijiria lori ọrọ ilẹ okere atawọn ọmọ Naijiria to wa loke okun, Abike Dabiri-Erewa ti ṣapejuwe idajọ iku yii bi eyi to ṣe ni laanu jọjọ.
Biden yan Adewale Adeyemo ẹ́gẹ́ bíi igbákejì mínísítà ìṣúná ní ilẹ̀ Amẹrika Èèyàn 145 tún ti ní COVID-19 ní Nàìjíríà Kàyééfì!
Nígbà tí wọ́n dé agbègbè Sufu, Saulu sọ fún iranṣẹ tí ó wà pẹlu rẹ̀ pé, “Jẹ́ kí á pada sílé, bí bẹ́ẹ̀ kọ́, baba mi lè má ronú nípa àwọn kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ mọ́, kí ó máa páyà nítorí tiwa.
Ẹwẹ ni ipele yii nigba ti wọn ba ti fẹẹ ka gbogbo ibo tan, iwoye ṣi ni ko tii di abajade esi gangan.
Nítorí ó níláti dá ẹlẹ́wọ̀n kan sílẹ̀ fún wọn ní àkókò àjọ̀dún.
Ẹnìkẹta ninu àwọn akọni náà ni Ṣama, ọmọ Agee, ará Harari.
Ẹ gbójú sókè, ẹ wo ojú ọ̀run,kí ẹ sì wo ayé ní ìsàlẹ̀.
Idahun: Isọri mẹta to wa ninu N-power ọdun 2020 ni N-Power Knowledge, N-Power Volunteer ati N-Power build.
Lẹyin ikọlu wọn naa, obìnrin kan fara gba ọta, to si ku.
Ẹ má ṣe jẹ́ kí oòrùn wọ̀ ba yín ninu ibinu.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Jiti Ogunye: Ìjọba àkóbá lológun gbé kalẹ̀ ni 1999 Gomina tuntun naa wa dupẹ lọwọ awọn lẹgbẹlẹgbẹ, loyeloye to fimọ awọn adari ẹgbẹ oṣẹlu to ṣe atilẹhin fun un lasiko ipolongo idibo.
Afrurasi ọhun lọwọ awọn osisẹ asọbode tẹ ni papakọ ofurufu Muritala Muhammed nilu Eko, lasiko to fẹ wọ ọkọ ofurufu lọ si Dubai.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Èyí ni àwọn ìdí tí INEC fi sún ìdìbò aarẹ síwájú Ẹnikẹ́ni tó bá ṣáájú láti jì àpótí ìbò, ẹ̀mí rẹ̀ ló fi ń ṣeré - Buhari Ihalẹ Buhari: PDP na ìká àbuku sí Buhari lẹyìn ìpàdé wọn O ṣeéṣe ki iṣẹ́ bọ́ lọ́wọ́ ọlọ́pàá inú àwòrán 4+4 APC, PDP, CUPP kọ etí ikún sí òfin INEC Àwọn ìgbà tí ẹ̀ṣọ́ aṣọ́bodè ti pànìyàn lọ́nà àìtọ́ Àjọ aṣọ́bodè gba Codeine N200m Iléeṣẹ́ aṣọ́bodè gba nǹkan ìjagun àìtọ́ Ẹ́ wo iye ààrẹ Nàíjíríà tó sọ̀rọ̀ ìjayà lásìkò ìbò INEC tako àṣẹ Buhari lórí pípa ẹni tó bá jí ìbò gbé Ṣugbọn, agbẹnusọ fun ileeṣẹ aṣọbode, Joseph Attah, to ti kọkọ fi atẹjade sita, sọ pe irọ ni ileeṣẹ Iyare Motors n pa.
Ọba yóo wá dá wọn lóhùn pé, ‘Mo fẹ́ kí ẹ mọ̀ dájúdájú pé, níwọ̀n ìgbà tí ẹ ti ṣe é fún ọ̀kan ninu àwọn arakunrin mi tí ó kéré jùlọ, èmi ni ẹ ṣe é fún.
Opolopo awon eniyan lo ti wa ni ahamo bayii, ti olori ileto Dura si di eni ti won n wa kaakiri.
Igbesẹ yii ko sẹyin bii ijọba orilẹ-ede Amerika se polongo afikun owo irinna fun awọn ọmọ Naijiria ti o ba fẹ wa si Amerika nitori owo goboi ni awọn ọmọ ilẹ Amerika n san lati wọ Naijiria.
"Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Passover Night: Òjíṣẹ́ Ọlọ́run ní o lè gbàdúrà ìparí ọdún nílé rẹ láì lọ sí ṣọ́ọ̀ṣì 29 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 31 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Oríṣun àwòrán, CAC worldwide Lílọ ""Cross-over night"" kò ní kí ọdún ó yabo láì ní ìpinnu tàbí ètò f'ọ́dún tuntun- Pásítọ̀ Ajifowowe Cross-over night: Pásítọ̀ Ajifowowe ní ""o lè gbàdúrà ìparí ọdún nílé rẹ láì lọ sí ṣọ́ọ̀ṣì"" A ko gbọdọ tapa si ofin ijọba lori adura ipari ọdun 2020 si 2021 nitori ajakalẹ arun coronavirus."
Ohun tí ẹ ó ṣe nìyí: gbogbo ọkunrin wọn ati gbogbo obinrin tí ó bá ti mọ ọkunrin, pípa ni kí ẹ pa wọ́n.
Àwọn kan ninu àwọn Sadusi bá lọ sọ́dọ̀ rẹ̀.
ẹgbẹ oselu kọọkan lati yan ẹni ti yoo gbe asia ẹgbẹ lati dije dupo ni ọjọ
Ogbeni Agboke tun se alaye pe eniyan mejilelogoji lo
  Àwọn òṣìṣẹ́ ìjọba nìkan ní wọ́n ní àṣẹ láti wọ ibẹ̀ .
Ipinle Oyo ,nigba ti Minisita fun igbokegbodo oko, Rotimi Amaechi naa bu owo lu
Gẹgẹ bi atẹjade kan ti olori ile aṣofin naa Mustapha Jafaru fi sita lọjọ Iṣẹgun, awọn aṣofin naa sọ pe lati wakati yii lọ ko ni si owo ifẹyinti ati awọn ajẹmọnu miiran mọ fun Gomina ati igbakeji rẹ.
Eliṣa bá wí pé, “Ẹ kó wọn fún àwọn ọmọkunrin, kí wọ́n jẹ ẹ́.
Oríṣun àwòrán, Ogun State Governor's office Àkọlé àwòrán, Ẹlẹẹkẹrin si ni ti ọdun 2019 to n waye nilu Abẹokuta, tii ṣe olu ilu ipinlẹ Ogun.
OLUWA bá fi ìtara rẹ̀ sí ọkàn Serubabeli, ọmọ Ṣealitieli, gomina ilẹ̀ Juda, ati sí ọkàn Joṣua ọmọ Jehosadaki, olórí alufaa ati ọkàn gbogbo àwọn tí wọ́n pada dé láti oko ẹrú.
OLUWA ni èmi óo máa fi yangàn;kí inú àwọn olùpọ́njú máa dùn nígbà tí wọ́n bá gbọ́.
Ninu ọrọ rẹ pẹlu BBC news Yoruba ni ileeṣẹ rẹ nilu Eko ni Pasuma ti sọ ọrọ yii.
Laipẹ yii ni awọn kansilọ mẹrin ninu mẹwa to wa ni ijọba ibilẹ naa, dibo yọ Ọlamiju lẹyin to kede pe oun n fi ẹgbẹ oṣelu APC silẹ lọ si ẹgbẹ oṣelu ADP, nibi ti baba rẹ ti n gbe igba dije fun ipo gomina ipinlẹ Ọyọ.
 ní ìgbà tí ó pé ọmọ ọdún mérin-dí-láàdóta , ní ọdún 1982 , ó sọ èmí rè nù nínú àgbákò ọkò .
Ṣe bí ẹni tí ó ti wà ninu ọ̀fọ̀ fún ọjọ́ pípẹ́; 
Ẹwẹ, eeyan 17,374 lo ti ri iwosan gba ti wọn si ti ja ajabọ lọwọ ajakalẹ arun naa.
Ni wọ́n bá lọ jí Jesu, wọ́n ní, “Ọ̀gá!
Ìmọ́lẹ̀ rẹ ti di òkùnkùn, o kò ríran,ìgbì omi sì bò ọ́ mọ́lẹ̀.
’ Bí ó ti wí bàyìí tí ọkùnrin yìí fi ẹnu kò ó ní ẹnu, kò jẹ́ kí ọkùnrin náà gbé orí kúrò lẹ́nu mọ́, o dì mọ́ ọ, o ń fà á lọ ó sì fà á dé ibi odò jíjìn kan, o fàá jù sínú odò, odò gbé onitọ́hùn lọ.
" Yemi sọ pe lẹyin naa loun bẹrẹ si wa Maruwa nitori oun ti sa kuro nile.
Ọgbẹni Ilesanmi ni ''Inu mi dun pe ọlọpaa mọ pe awọ́n ko lẹtọ lati mumi tori pe mo n fi bibeli ṣe iwaasu.
Gege bi olugbani-nimoran pataki fun aare lori oro igbohun-safefe, ogbeni Femi Adesina seso nilu Abuja,” Aare Buhari panupo pelu ogoro milionu awon ololufe iko agbaboolu Super-Eagles lati sajoyo pipegede sinu asekagba idije CHAN, eyi ti yoo waye lojo aiku (Sunday) pelu iko agbaboolu Morocco ti o sagbateru idije naa, ti won si tun se gudu-gudu meje ohun yaya mefa lati pegede si asekagba idije ohun.
Otitọ ọrọ ti ko ni abawọn irọ ninu.
Bákan náà ni FFK tún fi kún pé Bakare ń ti Tinubu mọ́ àwọn ènìyàn ti kò fẹ́ lọ́run ni gẹgẹ bii oludije aarẹ lọdun 2023.
Ǹjẹ́ ẹ mọ ohun tí igbákejì ààrẹ Yemi Osinbajo sọ nílé bàbá Fasoranti Ọ̀gá ọlọ́pàá Adamu Pàṣẹ́ iṣẹ́ àkànṣe nílẹ̀ Yorùbá EFCC ń wádìí iléeṣẹ́ 'Bola Tinubu,' Alpha Beta Consulting Ltd' Wole Soyinka rèé láti kékeré Àwọn agbébọn jí ìyàwó bàbá Sẹ́nétọ̀ Abbo tó lu obìnrin nílùú Abuja gbé Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Fasoranti: Dẹ́rẹ́bà tó wa ọmọ Fasoranti ṣàlàyé bí wọ́n ṣe pa Funke Olakunrin Orukọ awọn marun un ti iwe iroyin Forbes gbe jade pe wọn ni owo julọ ni orilẹ-ede Naijiria ni: Aliko Dangote Mike Adenuga Abdul Samad Rabiu Folorunsho Alakija Femi Otedola Amọ iwadii naa ni ida ọgọta awọn ọmọ Naijiria ni ko ni to miliọnu dọla kan lati na loojọ, eleyii to fi han gbangba iru iya ati isẹ to n jẹ ọpọlọpọ awọn ara orilẹ-ede Naijiria Bakan naa ni iwadii Oxfam gbe jade ni ọpọlọpọ awọn eniyan ni orilẹ-ede Naijiria ni isẹ ati iya n ba finra.
Ṣọra fun fifi ọwọ kan oju, imu ati ẹnu rẹ Oríṣun àwòrán, Getty Images Ọwọ rẹ ti o ti fi kan oniruuru nnkan lee ti kan kokoro arun yii.
Laipẹ yii ni Ile Igbimọ Asofin ipinlẹ naa gbe igbesẹ lati yọ Gomina Ambode kuro nipo, amọ Adari Ẹgbẹ Oselu APC, Asiwaju Bola Ahmed Tinubu lo pẹẹtu saawọ awọn mejeeji.
Igbakeji aare orile ede Naijiria, ojogbon Yemi Osinbajo ti salaye ipa pataki ti awon agbejoro n ko lori eto ijoba tiwa-n-tiwa ati eto idajo lorile ede Naijiria.
ẹ ṣọ́ra kí ẹ má baà dẹ́ṣẹ̀ nípa yíyá ère fún ara yín, irú ère yòówù tí ó lè jẹ́; kì báà ṣe akọ tabi abo, 
Laipẹ yii, nijọba apapọ fofin de ẹgbẹ Ipob, to npe fun idasilẹ orilẹede Biafra, tijọba si pe wọn ni ẹgbẹ adunkokomọni, pẹlu ileri wipe ẹnikẹni to ba darapọ mọ wọn, yoo ri ibinu ijọba.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Oluwakaponeski ní ọmọogun ilẹ̀ Amẹ́ríkà ni òun tẹ́lẹ̀ kí òun tó di aláwàdà Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Oluwakaponeski ní ọmọogun ilẹ̀ Amẹ́ríkà ni òun tẹ́lẹ̀ kí òun tó di aláwàdà 28 Ẹrẹ̀nà 2019 Oluwatobi Ọbatẹdo ni orukọ ti obi sọ ọ, oluwakaponeski lawọn ololufẹ rẹ loju opo Instagram mọ ọ si, 'Mama Tobi'si ni ere alawada rẹ.
Bí wọ́n bá sá kúrò níwájú mi, tí wọ́n sápamọ́ sí ìsàlẹ̀ òkun, n óo pàṣẹ fún ejò níbẹ̀, yóo sì bù wọ́n jẹ.
Chris Ngige fun ipinlẹ Anambra ‘Buhari ti wọnu ẹmi lọ’ Buhari gbasẹ lọwọ adajọ meji.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ọrọ lori Ballon D'or Awọn wo ni wọn fi orukọ wọn silẹ fun ami ẹyẹ ọhun lọdun yii?
 iye owó rẹ ̀ lójú pálí jẹ ́ 44 sí 78 usd fún ètò ìtọ ́ jú lẹ ́ ẹ ̀ kanṣoṣo ní ọdún 2014 .
Ni ọdun 2016 mẹsan lo waye gẹgẹ bii ajọ UNICEF ṣe sọ.
OLUWA, ìwọ ni Ọlọrun, o ti ṣe ìlérí ohun rere yìí fún èmi iranṣẹ rẹ.
Onimọ nipa ibaṣepọ laarin irugbin ṣe iṣe iwadii yii ni aadọrin orilẹ-ede kaakiri agbaye ni.
Ṣèbí ìlọsíwájú ìran àti ẹ̀yà tirẹ̀ ló nwá kiiri.
Àwọn dọkítà ní bó tilẹ̀ jẹ́ pe àṣìlò òògùn kìí ṣe ẹ̀bi awọn ará ìlú, ó mú ewu púpọ̀ dání
Àsìkò tó láti dóòlà Nàíjíríà, a ti gbé ẹ̀ṣùn ìbò lọ sílé ẹjọ́ tó ga jùlọ - PDP Sola Sobowale gbàmì ẹ̀yẹ òṣèré tíátà obìnrin tó dáńtọ́ jùlọ Wo àwòdamiẹnu àwòrán Mọ́ṣáláṣí Ànọ́bì ní Medina!
Oríṣun àwòrán, George Okoro Àkọlé àwòrán, Aisha Buhari ko ṣẹsẹ ma f'ọ̀rọ̀ da ìgboro rú lórí ìjọba ọkọ rẹ̀ Bẹẹ ba gbagbe, Aarẹ Buhari sọ fun awọn akọroyin saaju ko to di aarẹ pe, iwe ofin ko faye gba ipo First Lady, fun idi eyi, oun ko ni fi aaye gba.
Nítorí náà, mo rà á ní ṣekeli fadaka mẹẹdogun ati ìwọ̀n ọkà baali kan.
Oríṣun àwòrán, julian peter Àkọlé àwòrán, Julian Peter da ẹgbẹ kan silẹ fun awọn to ni aarun yii, wọn si maa n gba ara wọn ni imọran Ẹlomiran sọ pe aye mi ri bẹ nitori ibi ti mo ti wa, Ukambani (agbegbe kan ti wọn sọ pe awọn ajẹ wa).
Aadọta ojóbó ni wọ́n rán mọ́ àránpọ̀ aṣọ títa kinni, aadọta ojóbó náà ni wọ́n sì rán mọ́ etí àránpọ̀ aṣọ títa keji, àwọn ojóbó náà dojú kọ ara wọn.
A díá fún àgbò tó di ẹran Iléyá.
Kirusi ọba fún Mitiredati, akápò ìjọba rẹ̀ ní àṣẹ láti kó wọn síta, ó sì kà wọ́n ní ọ̀kọ̀ọ̀kan fún Ṣeṣibasari, olórí ẹ̀yà Juda.
Ó ní “Ẹ̀yin ará mi ati ẹ̀yin baba wa, ẹ fetí sí ẹjọ́ tí mo ní í rò fun yín nisinsinyii.
O fún wọn ní oúnjẹ láti ọ̀run wá nígbà tí ebi ń pa wọ́n, o sì ń fún wọn ní omi mu láti inú àpáta nígbà tí òùngbẹ ń gbẹ wọ́n.
Nítorí kì í ṣe lásán ni idà tí ó wà lọ́wọ́ wọn.
Apere ata-rodo ti di egberun mejo N8,000 lati egberun merin abo N4,500 tele, nigba ti apere tatase ti di egberun mejo N8,000 lati egberun merin N4,000 ti o wa tele.
Gómìnà ní ìjọba ò ti gbé iṣẹ́ kankan jáde láti ìgbà ti o ti dé, àti pé kí àwọn ara ilú lọ mú ọkàn wọ́n kúrò nibi pé bóya àwọn ti gbé iṣẹ́ fún àwọn ará ìta Oríṣun àwòrán, SeyiMakinde Àkọlé àwòrán, Seyi Makinde, lásìkò tó ń dúpk lọ́wọ́ àwọn Ogbomoṣọ Dípò bẹ́ẹ̀ a ó gbé iṣẹ́ fún kọngilá tó jẹ ará ìlú láti mú ìdàgbàsókè bá ètò ọ̀rọ̀ ajé ìpiínlẹ̀ Oyo àti láti jẹ́ kí wọ́n ni ipa nínú ìjọba"" O rọ gbogbo àwọn ti wọ́n ń retí ìpò kàn tàbí òmíràn nínú ìjọba rẹ̀ láti lọ fí ọkàn balẹ̀ nítorií yóò kàn wọ́n láìpẹ́."
Ajọ WAEC naa kede pe awọn akẹẹkọ to le ni miliọnu kan aabọ lo joko ṣe idanwo naa, ti awọn akẹẹkọ to to 786, 016 (ida 49.
Gbogbo ẹbọ ohun jíjẹ rẹ ni o gbọdọ̀ fi iyọ̀ sí, o kò gbọdọ̀ jẹ́ kí iyọ̀ wọ́n ninu ọrẹ ohun jíjẹ rẹ; nítorí pé iyọ̀ ni ẹ̀rí majẹmu láàrin ìwọ pẹlu Ọlọrun rẹ, o níláti máa fi iyọ̀ sí gbogbo ẹbọ rẹ.
ó gbé ọwọ́ rẹ̀ lé e lórí, ó sì fún un ní àṣẹ.
ba idagbasoke eto oro aje ohun, omowe Nwani je ko di mimo pe yiya owo lati maa
Ikú ọmọ ní í pá yindin yindin
O rọ ijọba lati ṣe agbekalẹ ọja tawọn agbẹ ti le maa ta ọja oko wọn lasiko yii, tabi ki ijọba gan an maa ra lọwọ wọn.
"A ti sọ fún gbogbo àwọn tọ́rọ̀ kan, gbogbo àwọn ẹbi tó kù àti àwọn òṣìṣẹ̀ ti sàyẹwọ̀ pẹ̀lú.
Ati pé kí Ọlọrun fun yín ní agbára gẹ́gẹ́ bí ọ̀pọ̀ ògo rẹ̀, kí ó fun yín ní ìfaradà ninu ohun gbogbo, pẹlu sùúrù ati ayọ̀.
Bi o til jẹ pe o ni ko rọrun rara rara lati ṣe iru ipinu yii, Bimbo ni oun kuro tori pe oun ko fẹ ku ni."
 o gun ori oye ni 7 february 1999 leyin iku baba re oba hussein .
Agbejero fun Walter Onnoghen , iyen Adegboyega Awolowo, wa rọ Ile–ẹjo
Ileeṣẹ Tẹlifiṣan apapọ orilẹ-ede Iran ṣalaye pe igbesẹ naa waye lati fi gbẹsan bi Amẹrika, labẹ aṣẹ aarẹ Trump, ṣe pa olori ikọ ogun Iran, Ọgagun Qasem Soleimani ni Baghdad.
Ọga Bello tún woye pe, nínú sinima ti orin bá ti ń bo ere mọlẹ, a jẹ pé Olootu ere náà kii ṣe akọsẹ-mọṣẹ osere tíátà ni.
Ìkérora ati ìpohùnréré ẹkún yóo wà ninu rẹ̀,bíi Arieli ni yóo sì rí sí mi.
Ọkàn Eli dàrú gidigidi nítorí àpótí ẹ̀rí náà, ó sì jókòó lórí àga rẹ̀ lẹ́bàá ọ̀nà, ó ń wo òréré.
Eyi ni atupalẹ iye owo ti wọn n ta awọn ọunjẹ kan ki ijọba to ti bọda ati lasiko yii ti wọn ti ṣi ibode.
Bákan náà, e̩nì kò̩ò̩kan ló tún ní ààbò nígbà àìnís̩é̩ló̩wó̩, nígbà àìsà n, nígbà tó bá di aláàbò̩‐ara, ní ipò opó, nígbà ogbó rè̩ tàbí ìgbà mìíràn tí ènìyàn kò ní ò̩nà láti rí oúnje̩ òò jó̩, tí eléyìí kì í sì í s̩e è̩bi olúwa rè̩.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Bauchi State: Okú 596 ló ṣì ń gba owó oṣù 6 Sẹ́rẹ́ 2020 Oríṣun àwòrán, @SituationRoomNg Àkọlé àwòrán, Okú 596 ló ṣì ń gba owó oṣù O kéré tán ènìyàn mẹrindinlẹ́gbẹ̀ta ló ṣi n wà lórí ìwé ti wọ́n fi n san owó oṣù òṣìṣẹ́ ìjọba ti wọ́n si n gba gbogbo àjẹmọnú wọ́n ni ìpínlẹ̀ Bauchi, gẹ́gẹ́ bi ìgbìmọ̀ ìwádìí ṣe sọ.
Bi o ṣe kede sisọ asia kalẹ si idaji naa ni awọn ọmọ Naijria ti n fi ero wọn han lori ayelujara.
Ó gbadura pé, “OLUWA Ọlọrun Israẹli, tí ń gbé láàrin àwọn Kerubu, ìwọ nìkan ni Ọlọrun tí ń jọba lórí gbogbo ilẹ̀ ayé, ìwọ ni o dá ayé ati ọ̀run.
Àkọlé àwòrán, Àjọ NCDC kéde èèyàn 239 míràn tó ni ààrùn Covid-19 lórílẹ̀-èdè Naijíríà Ìpínlẹ̀ Borno ni mẹ́tàdínlógun (17), Abuja ènìyàn méje (7), Kwara mẹ́fà (6), Oyo márùn-ún (5) nígbà tí Sokoto àti Adamawa ni ènìyàn mẹ́ta-mẹ́ta.
“N óo sọ gbogbo òkè mi di ojú ọ̀nà,n óo kún gbogbo òpópó ọ̀nà mi.
Zyrech, omo orile-ede Germany lo ti fagba han Djokovic pelu ami ayo 6-4, 6-3, lati gba ife eye ohun fun igba akoko ni ilu Rome.
Koda iroyin ni wọn tun yinbọn pa awakọ rẹ pẹlu.
Ó fi tìpá tìkúùkù gbé ọmọ náà láì san owó ori-i rẹ̀ ni.
Iranṣẹ Oluwa kò sì gbọdọ̀ jà.
Èrò àwọn ọmọ Naijiria ṣọ̀tọ̀ọ̀tọ̀ lórí Tinubu àti Abbo Dúkìá àti ọkọ̀ jóná, ọlọ́pàá mẹ́sàn-án fara gbọta lásìkò ìwọ́de Shiite Gba owó lọ́wọ́ àkẹ́kọ̀ọ́ ìjọba, ko rugi oyin - Seyi Makinde Iṣu ló wà nínú mọ́tò mi, kìí ṣe èèyàn ni mo sọ di iṣu - Afurasí Ajínigbé figbe ta Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Gómìnà Sanwo Olu ní òun kò sanwó ẹbùn N41.
Bakan naa ni ọmọ sori nilẹ Ekiti, Ondo, Ẹgba ati bẹẹ bẹẹ lọ amọ ti Ibadan nikan lo yatọ nilẹ Yoruba.
Ẹ̀yin ilé Juda ati ilé Israẹli, bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé orúkọ yín ni àwọn eniyan fi ń ṣépè lé àwọn mìíràn tẹ́lẹ̀, ṣugbọn nisinsinyii, n óo gbà yín, ẹ óo sì di orísun ibukun.
N óo da yín lẹ́jọ́ gẹ́gẹ́ bí ìwà yín, n óo sì jẹ yín níyà nítorí gbogbo ìwà ìríra yín.
Oríṣun àwòrán, NTDC TWITTER Ṣugbọn ṣa, eyi kọ ni igba akọkọ ti wọn fi ofin de adura agbapọ, nitori awọn idi l'oriṣiriṣi.
O fi kun ọrọ rẹ pe nigba ti Tinubu kede atilẹyin rẹ fun Buhari lọdun naa, lo to o fojuhan pe oun ni yoo gba tikẹẹti ẹgbẹ lati dije.
Lẹyẹ o sọka si ni o yan Mike Pompeo to jẹ ọgaagba ileeṣẹ alami ilẹ Amẹrika, CIA lati rọpo rẹ.
Bakan naa ni Aṣofin Ọbasa tun benu abuku lu iwa kikọlu awọn aṣofin.
Aṣofin Ṣolaja-Saka ti o n ṣoju ẹkun Ikorodu keji ninu Ile Igbimọ Aṣofin Ipinlẹ Eko, ti o tun jẹ Adele Alaga Igbimọ to n ri si ẹka Imọ Ijinlẹ Sayẹnsi ati Imọ Ẹrọ ninu Ile naa, ni o sẹto ironilagbara yii labẹ akoonu oṣelu rẹ, ti o pe ni ’Bibire Mega Empowerment Programme’.
Lẹ́yìn náà, gbogbo wọn lọ sí ilé oriṣa Baali, wọ́n wó o palẹ̀, wọ́n wó pẹpẹ ati àwọn ère túútúú, wọ́n sì pa Matani, tí ó jẹ́ alufaa Baali, níwájú pẹpẹ.
Ajo to n mojuto boolu afesegba lorile-ede Spain ti kede ikowe fise sile akonimoogba agba iko agbaboolu orile-ede naa, Fernando Hierro lana, leni ti o gbase lowo Julen Lopetegui ti ajo ohun fopin si ise re gbara ti idije agbaye ohun fe bere.
Sáájú ní ọjọ́ ajé ni gómìnà ìpínlẹ̀ Eko Babajide Sawnwo-Olu ti kéde pé èròjà èlò ti wọ́n fi n ṣe àyẹwò ààrùn Coronavirus ko si ni ìkáwọ́ àwọn mọ́ àti pé, o tó ènìyàn ẹgbẹ̀run mẹ́ta tó wà nilẹ̀ bayìí ti kò si bi wọ́n a ṣe ṣe àyẹ̀wò fún wọ́n Auxiliary ń ní wá lára pẹ̀lú gbígba owó aitọ, a ń ko ọkọ̀ wa kúrò lójú pópó - Awakọ èrò Ọwọ́jà coronavirus yóò ṣì wà pẹ̀lú àgbáyé fún ìgbà pípẹ́- Ngozi Okonjo-Iweala Ìjọba àpapọ̀, ẹ so ifilọlẹ ẹ̀rọ alatagba 5G rọ na - ilé asofin àgbà Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Wo bí o ṣe leè ṣe ìjìnàsíraẹni ní ibiṣẹ́ lásìkò Coronavirus yìí Ìdí nìyí ti BBC ṣe wádìí lọ́wọ́ kọmísọna, lórí ìgbésẹ̀ ti ìjọba n gbé ti ọ̀rọ̀ ààrùn Coronavirus kò ṣe ni bẹ́yìn yọ ni ìpínlẹ̀ Eko.
Koko ipade naa si lo da lori ọna lati wa ojutu si isoro akoso ẹgbin to n ba ilu Ibadan finra, ti Makinde si fọwọ sọya pe oun yoo ri daju pe wọn ko gbogbo awọn ẹgbin to dabi oke nilu Ibadan kuro laipẹ.
Ọgbẹni ṣalaye pe ijọba Eko naa ti n wo ṣaakun ọwọja covid-19 lẹẹkeji lati mọ iru ilana ti wọn tun fẹ gbe kalẹ.
Laipe mo lo si ipinle Kaduna lati lo si okan lara awon ise akanse ti a jo se papo ni eyi to n mu inu mi dun pe ajosepo naa n bi eso rere ti a ti fi n siju kuro lara epo robi nikan gege bi orisun owo Naijiria.
alufaa yóo pàṣẹ pé kí wọ́n fọ ohun èlò tí àrùn wà lára rẹ̀ yìí, yóo sì tún tì í mọ́lé fún ọjọ́ meje sí i.
Lé pẹ̀gànpẹ̀gàn síta, ìjà yóo rọlẹ̀,asọ̀ ati èébú yóo sì dópin.
Ni asiko ogun agbaye keji ni wọn kọ papakọ ofurufu yii.
Ṣugbọn bí ẹ bá tilẹ̀ jìyà nítorí òdodo, ẹ ṣe oríire.
Àwọn eniyan yóo kígbe: gbogbo àwọn ará ìlú yóo sọkún tẹ̀dùntẹ̀dùn.
Nigba ti wọn kọọ nibi to salọ,o wa fẹ pada si ẹgbẹ wa, Ko jọ rara'' Lọ́jọ́bọ̀ ni Mimiko kede pé òun yóò gbé àpótí ìbò láti di Ààrẹ orílẹ̀èdè Nàìjíríà lọ́dún 2019 labẹ asia ẹgbẹ Labour Party.
Nítorí ọjọ́ ẹ̀san ló wà lọ́kàn mi,ọdún ìràpadà mi sì ti dé.
Awọn ọlọpa mu awọn eniyan kan lẹhin iṣẹlẹ naa ṣugbọn fi wọn silẹ nitoripe wọn se akiyesi pe awọn kọ ni wọn se ikọlu naa.
kí ni àwọn ìdánudúró fún gbólóhùn ?
Ile-ise omo-oogun ofurufu orile ede Naijiria ti fi omo-oogun ranse si ipinle Kaduna lati satileyin  fun awon agbofinro to n pese eto aabo ni ipinle naa.
 Òun náà ni ọmọ nàìjíríà kìíní tí yoo di adájọ ́ ilé-ẹjọ ́ kóòtù gíga ( high court of judge ) .
Ile-ise olopaa lorile-ede Rwanda ti fowo sinkun mu awon adari ile-ijosin mefa, lara eyi ti a ti ri busobu Innocent Rugagi, okan lara awon gbaju-gbaja alufaa lorile-ede naa, latari erongba igbese ijoba nipa titele kiko ile-ijosin  ati  fifi ariwo di awon ara-ilu lowo.
”Nítorí náà, mo gbadura sí Ọlọrun ọ̀run.
Ìgbà tí a tún máa ń sun rárà ni ibi ìnáwó ìsọmọ lórúkọ .
Rutu bá dá Naomi lóhùn, ó ní, “Gbogbo ohun tí o sọ fún mi ni n óo ṣe.
Wọ́n fi ẹsun kan pé Osinbajo àti àwọn ọmọ ijọ náà pe wọn ń gbadúra pé ki ààrẹ Buhari ku.
yii lasiko ti o n dahun si ibeere awọn igbimo naa.
ibi akọkọ ti wọn ti kọkọ kirun laye  ni Kabbah, ekeji ni ti
Oríṣun àwòrán, Facebook/Adenitan Akinola Àkọlé àwòrán, Ikini ikẹdun loju opo Facebook Bunmi Ojo Oríṣun àwòrán, FACEBOOK/AKOLAWOLE GBENGA Àkọlé àwòrán, Ikini ikẹdun loju opo Facebook Bunmi Ojo Ko ti daju idi ti awọn agbebon naa fi pa Bunmi Ojo.
'Ọjọ́ tí Inec sún ìbò ààrẹ sí ni ìgbéyàwó wa' Ìyálé àti ìyàwó bínú di omi gbígbóná àti tútù Wọn kédé Narendra, oludije ẹgbẹ́ BJP ni India pẹ̀lú ariwo ńla Mohammed Adamu ti di Ọ̀gá ọlọ́pàá Nàìjíríà tuntun Bẹẹ gbogbo obi ati alagbatọ lo n wa ọna atijẹ fawọn ọmọ wọn ati igbe aye to dara.
Ile iṣẹ ọlọpaa ilẹ Gẹẹsi to ṣalaye ninu atẹjade kan ti wọn fi ṣọwọ si BBC salaye pe, ọlọpaa naa beere fun aaye iyọnda lati lọ kopa ninu eto naa ṣugbọn ileeṣẹ ọlọpaa ko fun un laaye naa.
Ó wá Ahasaya káàkiri títí; ní Samaria níbi tí ó sá pamọ́ sí ni wọ́n ti rí i mú, wọ́n bá mú un tọ Jehu wá, ó sì pa á.
Igbesẹ kan naa lo ni lati kọkọ gbv'é, koda ki igbesẹ naa kere.
Se awọn ipinlẹ mi yoo tele igbese yi Kwara nikan kọ ni awọn gomina wọn ti kuro ni ipo kan bọ si omi.
Bi onirese ko ba fingba mọ, awọn to ti fin silẹ ko le bajẹ.
Nígbà tí Jesu parí àwọn ọ̀rọ̀ wọnyi, ó kúrò ní Galili, ó dé ìgbèríko Judia ní òdìkejì odò Jọdani.
"Rishi ni iṣẹju ti oun ti pinnu lati ṣe igbeyawo naa ni oun ti mọ nkan ti oun yoo gbọ Oríṣun àwòrán, Sanjana Rishi O ni: ""Mo mọ pe oun yo wọ sokoto ati kootu igbalode, iru eyi ti mo wọ gan an ni pato"" Eya ti Italian Gianfranco Ferré vintage ti ọdun 1990."
Gbemi jẹ ọmọ bibi inu agba ọjẹ oloṣelu Oluṣọla Saraki to n dari iṣelu ipinlẹ Kwara fun ọpọlọpọ ọdun ko to di oloogbe.
Ṣugbọn wọn kò gbọ́rọ̀ sí Mose lẹ́nu; àwọn mìíràn ṣẹ́ ẹ kù di òwúrọ̀ ọjọ́ keji, nígbà tí ilẹ̀ ọjọ́ keji mọ́, ohun tí wọ́n ṣẹ́kù ti bẹ̀rẹ̀ sí yọ ìdin, ó sì ń rùn, Mose bá bínú sí wọn.
" Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Fídíò, Boko Haram: Oluwatobi Adeigba, Ọkọ mi ń lọ siṣẹ́ fún àjọ INEC ló kàgbákò ikú - Opó Adeigba2 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Assistant Commissioner of Police: Àwọn afurasí ṣá ìgbákejì kọmísọ́nà ọ̀gá ọlọ́pàá láàké dójú ikú2 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Alaafin Oyo: Olorì Anuoluwapo Adeyemi gba àmì ẹ̀yẹ lórí oge ṣíṣe1 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Borno Zabarmani Rice Farmer Massacre: Àwọn àgbàgbà Òkè Ọya ní ẹ̀mí èèyàn kò níyì mọ́ lábẹ́ ìṣèjọba Buhari5 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Serena Williams: Mo fẹ́ àkókò si láti díje lorí amọ̀ 9 Èbibi 2018 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Gbajúgbajà ife ẹ̀yẹ mẹtalelogun ọ̀tọ̀ọ̀tọ̀ ni Serena Williams ti gba ninu ìdíje tẹniisi lágbáyé.
Mo tẹ́tí sílẹ̀ kí n gbọ́ tiwọn,ṣugbọn wọn kò sọ̀rọ̀ rere.
Eyi lo mu ki obinrin kan tete fi mọto sẹburu ọkọ afurasi ajinigbe naa, ti wọn si da duro pẹlu atilẹyin awọn ọlọpa to wa nitosi ibẹ.
Datani ati Abiramu pẹlu aya ati àwọn ọmọ wọn jáde wá sí ẹnu ọ̀nà àgọ́ wọn.
Aṣọ títa kan yóo wà ní ẹ̀gbẹ́ keji ẹnu ọ̀nà náà, òun náà yóo gùn ní igbọnwọ mẹẹdogun, yóo sì ní òpó mẹta ati ìtẹ́lẹ̀ mẹta bákan náà.
 Ìmúlò rẹ ̀ ní àwọn orílẹ ̀ -èdè tí àrùn náà ti wọ ́ pọ ̀ a má a mú àbájáde tí a lérò wáyé .
Ṣugbọn lẹyin ti Kyari jade laye, Aisha sọ loju opo Twitter rẹ pe oun gbadura Ki Ọlọrun dari ẹṣẹ rẹ jii."
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: ''Bí mo ṣe borí àrùn asétọ̀ rèé'' Seyi Makinde palẹ̀ ẹ̀gbin Ibadan mọ́ lóru mọ́jú, ó ṣèlérí ọ̀sẹ̀ mẹ́rin fún ìmọ́tòtó àyíká Sanwo-Olu kéde ìgbésẹ̀ rẹ̀ lórí ìrìnnà ọkọ̀ àjàgbé l'Eko Tí o bá rí àpẹrẹ mẹ́fà yìí, sá àsálà fún ẹ̀mí rẹ̀!
Awọn ọmọdekunrin ni wọn maa n lo fun igba Sango wọn si maa n ju ẹyọkan lọ pẹlu.
Oríṣun àwòrán, @TaoheedLawal Aginju Idakẹrọrọ: Aginju Idakẹrọrọ yii ni Fagunwa se apejuwe rẹ pe o dakẹ mini-mini, eku ati ẹyẹ kii ke nibẹ, bi abẹrẹ si bọ silẹ, eeyan yoo gbọ iro rẹ.
Amọ ṣa, ko si eyi to wọ ipele ami ẹyẹ goolu to dara ju ni saa yii ninu awọn mejeeji.
Wọn yóo mú díẹ̀ ninu ẹ̀jẹ̀ ẹran náà, wọn yóo fi kun àtẹ́rígbà ati ara òpó ìlẹ̀kùn mejeeji ilé tí wọn yóo ti jẹ ẹran náà.
Lara awon eniyan jankanjankan ti o tun ye ayeye idije ohun si lati ri asoju Naijiria sorile-ede Australia, ogbeni Bello Husseini , beesini aare teleri ati aare ti o wa lori alefa bayii ti igbimo to n ri si idije Olympic ni Naiijiria Nigeria Olympic Committee (NOC), naa ko gbeyin, Sani Ndanusa ati Habu Gumel.
gba ipinle Oyo , sugbon igi kan ko lee dagbo se,  wa rọ gbogbo omo ipinle Oyo lati fọwọsowọpọ pẹlu
Akanṣe iwadii yii boju wo ibẹrẹpẹpẹ aṣa ifiyajẹni awọn agbofinro yii, o foju awọn tọwọ wọn wa ninu rẹ ju han, o si wadii idi ti wọn ko fi fi wọn jofin.
eyi ti awon ti mu awon osise ile –ise naa mẹ́wàá ati  awon ẹsọ  to n sọ enu ọna ile-ise naa lasiko ti isele naa sẹlẹ.
Èyí ló fa gbọ́nmisi-omi o to lẹ̀yìn ti ìdìbò pari ti gómínà Ganduje si wolé fún sáà keji, Gomina Ganduje buwọ lu abádofin láti ṣe ìdásilẹ̀ àwọn ààfin tuntun míràn ni Gaya, Rano àti Karaye ti wọn ó si jọ ni agbára àti àṣẹ kan náà bi ti Emir Kano gẹ́gk bi ọba onipo kíní Ní ọjọ́bọ ni ìjọba tún fi ìwé wá wi tẹnu rẹ ránsẹ si Emir Sanusi láti sàlàye bí ọ ṣe ná bílíoọnù mẹ́ta o lé ọwọ́ mẹ́rìn ti Emir ṣe mọ́umọ̀ku Olubadamọran gómìnà Saliu Tanko sọ fún BBC pé ìpàdé láti pẹtu sí ààwọ náà ló wáye fún ìgbà aàkọkọ ní alẹ́ ọjọ Jimọ Emir Sanusi kìí ṣe akápò tàbí akọ̀wé ìgbìmọ ẹ́míréètì- Abba Yusuf àgbẹnusọ Emir Kano Oríṣun àwòrán, Kano Emirate Council Àkọlé àwòrán, Àjàku akáta ní ọ̀rọ̀ gómìnà ìpínlẹ̀ Kano àti Emir kano láti ìgbà ti ìdìbò gbogboogbò ọdún 2019 ti pari.
8 4579 Orilẹede Suriname 117 20.
’Ile igbimo asofin tun ro ijoba apapo lati
OLUWA Ọlọrun ní, “N óo ti ọwọ́ Nebukadinesari, ọba Babiloni, fi òpin sí ọrọ̀ Ijipti.
Eeyan 79,417 lo ti pada sile lẹyin tara wọn ya ti apapọ awọn to ti ku si jẹ 1,350.
Ninu ìyìn rere yìí ni a ti ń fi ọ̀nà tí Ọlọrun fi ń dá eniyan láre hàn wá: nípa igbagbọ ni, láti ìbẹ̀rẹ̀ dé òpin.
Ààbò Naijiria tó dojúrú, ẹ gbé ọ̀rọ̀ ọlọ́pàá abẹ́lé wò bóyá yóò san wá - Ilé aṣojú-ṣòfin Maryam Sanda, ìyàwó tó pa ọkọ rẹ, ri ìdájọ ikú he Ẹ̀mí 15 bọ́, èèyàn 38 farapa nígbà tí ọkọ̀ akẹ́rù kan bọ́ sínú odò Ogun O ni nigba ti atijẹ atimu fẹ ma nira loun ba bẹrẹ si ni ṣe iṣẹ kọndọ.
Ogungunniso1 de ipo to wa lonii.
Ẹgbẹ one million boys bẹrẹ si gbilẹ nilu Ibadan, lati adugbo Beere, Mapo, Idi Aro, Odinjo, Eleta, Modina de Born Photo ni awọn ọmọ ẹgbẹ okunkun yii ti n ṣe ọṣẹ, wọn n jale, wọn si n pa eeyan.
Coronavirus lockdown Kayeefi: Àkójọpọ̀ ìṣẹ̀lẹ̀ tó yanilẹ́nu lásìkò àjàkálẹ̀ ààrùn Covid-19
Emi ni mo n san owo sori ẹrọ ibanisọrọ rẹ, nitorina mo lo anfaani naa lati yẹ awọn to n pe e wo.
Bakan naa, awọn ipinlẹ mii ti atundi ibo yoo ti waye ni Kogi, Borno, Plateau, Zamfara ati Imo.
ọrẹ ati awọn ololufẹ rẹ ni wọn n ṣeranti Barrister lonii.
Ẹṣin ati kẹ̀kẹ́ ogun wọn kò lóǹkà.
Gẹ́gẹ́ bí ọ̀dọ́mọkùrin náà ṣe sọ, nígbà tí wọ́n fi wà nínú ìlú, iṣẹ́ tí wọ́n kọ́kọ́ ṣe ni íjínigbé nítorí owó ìtúsílẹ̀.
Crystal Palace lo kọkọ lu wọn lalubolẹ mọle tẹlẹ.
Onírúurú ilé iṣẹ́ ìròyìn ló jábọ̀ láti pápákọ̀ òfurufú wí pé o ti tẹkọ̀ òfurufú létílọ sí London.
2 2378 Orilẹede Benin 46 0.
com/yoruba/afrika-45028252 Ẹ tun lee wo awọn iroyin miran to jẹ mọ idagbasoke obinrin ni ibi: Ìran kan si ìkejì ló n gbèrò láti ṣe ìgbéyàwo àjùmọ̀ṣe 'Shao' fọ́mọ wọn https://www.
Angẹli OLUWA náà tún wí fún un pé, “N óo sọ atọmọdọmọ rẹ di pupọ tóbẹ́ẹ̀ tí ẹnikẹ́ni kì yóo le kà wọ́n tán.
Bi a ko ba gbagbe laipe yi ni iriwisi waye lori fidio orin Falz to pe akọle rẹ ni 'This is Nigeria' Fidio orin naa to ṣe afihan awọn ọmọ obinrin to n jo Shaku Shaku pẹlu Hijab mu inu bi awọn ẹgbẹ Musulumi kan ti wọn ni orin naa tabuku ba ẹsin awọn.
Pataki julọ, o ni orukọ rere ti oun ti ni lati igba ti oun ti ṣe Sẹnetọ ko ni bajẹ.
Ẹgbẹ agbabọọlu Man City ti gba ọkan ninu ami ẹyẹ mẹrin ọhun, lẹyin ti wọn gba ife ẹyẹ Carabao Cup lai pẹ yii.
Ile iṣẹ naa gba ami ẹyẹ ara ọtọ kan ni ilodi si ijọba Naijiria latari akanṣe iṣẹ afẹfẹ gaasi kan to pa ile iṣẹ naa ati ijọba Naijiria pọ eyi to to iye owo dollar biliọnu mẹsan.
Ohun ti iṣẹ iwadii fi mulẹ ni wi pe mẹta ninu awọn ọlọpaa to wa lati gbegbe Mapo lo le awọn ọdaran wa si agbegbe Oke-Arẹ ti ọrọ si di bamii.
Yorùbá bọ̀ wọ́n ní àjòjì ọwọ́ kan ò gbẹ́rù dórí.
Wo iye máákì mi Ṣe afihan esi rẹ Ààbò ọ̀rọ̀ làá sọ f'ọ́mọlúàbí tó bá dé núẹ̀ á di odidi Bíná bá kú á fi eérú b'ojú Àì tètè m'ólè olè ń m'olóko Alágẹmọ ti bímo rẹ̀ ná àìmọ̀ọ́jó kù sí ọwọẹ̀ B'ígbín bá fà ìkarahun a tẹ̀le Ẹni a sùn tì là ń jarunpá lù B'ọ́mọ́dé bá kọ iyán alé àgbà a f'ìtàn balẹ̀ Ààbò ọ̀rọ̀ làá sọ f'ọ́mọlúàbí tó bá dé núẹ̀ á di odidi Bíná bá kú á fi eérú b'ojú Àì tètè m'ólè olè ń m'olóko Alágẹmọ ti bímo rẹ̀ ná àìmọ̀ọ́jó kù sí ọwọẹ̀ B'ígbín bá fà ìkarahun a tẹ̀le Ẹni a sùn tì là ń jarunpá lù B'ọ́mọ́dé bá kọ iyán alé àgbà a f'ìtàn balẹ̀ Naijiria ń ṣe ìrántí àwọn ọmọ ógun tó ṣègbé Ẹ wá ná, kí ló ń ṣẹlẹ̀ pẹ̀lú Brexit?
Ó ti fi ibinu wó ibi ààbò Juda lulẹ̀.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Olórí l‘Afirika, ẹ dìde tako òṣèlú ẹ̀tanú ní Benin - Obasanjo àti Kufuor Dagunro ní ìtẹríba, tó sì ń gbé àṣà lárugẹ - Ọ̀gá Bello Àìle è ka kéú ló sọ mí di Krìstíẹ̀nì - Adewale Ayuba Ìdààmú ńlá ńbọ̀ fún Nàíjíríà lábẹ́ ìjọba Buhari - Ọbasanjọ O fikun pe orukọ awọn afurasi ọdaran naa ti wa ni akssilẹ awọn lati ọjọ pipẹ fun oniruuru ẹsun iwa ọdaran, tọwọ sinkun awọn osisẹ SARS naa si tẹ wọn lọjọ Kẹfa osu Kẹfa ladugbo Arojẹ, nilu Ogbomosọ ni deede aago meje abọ alẹ.
Ọmọ ilu Ibadan ni Sikiru Ayinde to lọ sile iwe alakọbẹrẹ Muslim Mission ati Ile Iwe Model ni Mushin.
gbe Sugar digba-digba lo sile iwosan UCH, amo aso o bo omoye mo, nitori omoye
Khalifa Sall, to je alaga(Major) ijoba ibilẹ Sakar to je olu-ilu Senegal ni won fesun iwa ibajẹ sise owo ilu kumo-kumo kan, ni ibere odun yii.
Ni ọpọ igba lawọn obinrin ti n se awawi pe awọn kii ri imọ nipa ohun to jẹ mọ oju ara wọn, to si jẹ pe ti wsn ba lọ sori ayelujara lati se awari imọ nipa oju ara wọn, 'iregbe' ni wọn sọ pe awọn maa n ri nibẹ.
Ilé kan lá mà rí o.
Láti ìsinsìnyìí lọ, ẹ gbọdọ̀ máa kó owó tí ẹ bá gbà sílẹ̀ fún àtúnṣe ilé OLUWA.
Ẹgbẹ̀rún 150 àwọn ènìyàn wọ̀nyí ni ó ń dá gbé.
- arìnrìn oge Lẹ́yìn ìgbeyàwó ọdún mọ́kànlá àti ọ̀pọ̀ ìjà, Bọsẹ di èrò ọ̀run nílé Saidi Ni bayii, osisẹ kan nile itaja naa ti n gbarata loju opo Twitter rẹ pe isẹlẹ naa ti kọja igbẹsan sawọn ọmọ orilẹede South Africa, amọ awa ara wa ni Naijiria la n doju kọ ara wa.
Akọkọ ni pe ta lo ju fidio naa sita to fi de oju opo Twitter, ati pe nitori ki lo mu ko se bẹẹ, awọn eeyan wo si lo n ba pin fọnran aworan naa kiri?
“Bí mo bá jẹ́ kí àwọn ẹranko burúkú já wọ orílẹ̀-èdè náà, kí wọ́n pa wọ́n lọ́mọ jẹ, tí wọ́n sọ ilẹ̀ náà di ahoro, tí ẹnikẹ́ni kò lè gba ibẹ̀ kọjá mọ́, nítorí àwọn ẹranko tí wọ́n wà níbẹ̀, 
Awọn obinrin náà tún fẹ̀sùn kàn pé ó fi àwọn pamọ sinnu ile kan ní agbegbe paris lòdi sí ìfẹ́ inu àwọn sùgbọ́n àwọn sá kúrò ni oru ọjọ́ kan lọdun 2006 ti àwọn ò si le pada si DR Congo ki ó ma ba tun mú àwọn.
Olori ijoba titun naa , Abiy Ahmed so eyi lori ero agbohunsafefe  ati amohunmaworan wi pe ,oun da mefa pada lara igbimo amusese teleri ,nigba ti oun si yan awon titun mewa.
Ìdí tí ààrẹ Buhari ṣe padà gbà láti yọjú si ilé ìgbìmọ̀ aṣójú-ṣòfin tórí ọ̀sẹ́ Boko Haram Adari ile igbimọ aṣojuṣofin ilẹ Naijiria, Femi gbajabiamila ti fi lede pe aarẹ Muhammadu Buhari ti gba lati wa siwaju ile aṣojuṣofin bayii.
" Oríṣun àwòrán, @Sanwoolu Rahman ni lai naani ọna arifin tawọn ọdọ naa gba ba Tinubu sọrọ, sibẹ o tiraka lati salaye awọn ọrọ naa fun wọn.
a Pa Kasumu, Peter Fatomilola, Lanre Hassan (Iya Awero), Idowu Phillips (Iya Rainbow), Lere Paimo a.
Ìgbẹ́jọ́ Fu, Zhang àti Luo's wáyé ní ibìkan ní Ilé-ẹjọ́ Àwọn Ènìyàn Agbedeméjì Chengdu nínú oṣù Igbe.
 Masters, eleyi ti o je ifarahan re akoko ninu idije ti o se pataki lati odun 2015.
OLUWA óo dẹ́rùbà wọ́n, yóo sọ gbogbo oriṣa ilé ayé di òfo, olukuluku eniyan yóo sì máa sin OLUWA ní ààyè rẹ̀ ní gbogbo orílẹ̀-èdè.
Ìtàn ìgbé ayé Isola Ogunsola 'I-sho Pepper', ògbóǹtagí òṣèré tíátà tó s'eré Yorùbá yíká Nàìjíríà Wo aláànú tó n wa ọkọ̀ tí wọ́n fi n gbé aláìsàn lọ́fẹ̀ẹ́ Ǹjẹ́ o mọ̀ pé o le gba owó lára 'ATM' láì lo káàdì?
Àjọ tó ń mójútó àyíká l'Eko mú 123 ọlọ́kadà tó ń bọ̀ láti Jigawa Van Dijk gbadé UEFA mọ́ Messi àti Ronaldo lọ́wọ́ N650,000 péré ni mò ń gbà gẹ́gẹ́ bíi owó oṣù -Gomina Ọyọ Ṣe ẹ ti gbọ́ ri?
Tosyn Bucknor, gbajugbaja sọrọsọrọ ori afẹfẹ dẹni ilẹ̀ loṣu kọkanla lẹyin to ba arun arunmọleegun pòó.
ilu kumọ-kumọ ati sise atilẹyin fun awọn ọlọtẹ.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Àwọn akẹ́kọ̀ọ́ Kankara tí wọ́n jígbé ti gúnlẹ̀ sí Katsina Ọla Adedibu ní Ladoja jẹ̀ tó fi wọlé Gómìnà l‘Oyo labẹ ẹgbẹ́ PDP - Obasanjo Ẹ̀sìn kò fàjà!
”Ogbeni Gbenga Alabi tun tesiwaju pe ajọ NiBUCAA tun n fọwọsowọpọ pelu ile-ise NACA lorile ede Naijiria lati gbokun ti aarun kogboogun, bẹẹ si ni opolopo awon aseyori ni won ti se nipa ifọwọsowọpọ yii.
Nígbà náà ni ilẹ̀ lanu, tí ó gbé wọn mì pẹlu Kora, wọ́n sì kú, òun ati àwọn ẹlẹgbẹ́ rẹ̀.
wole gbara niseju merin ti ifesewonse ohun bere lataari asemase asole iko
Mo gbọn ire bí ẹni gbọn òwú, iwin náà sì ń lé mi, a sáre títí a fi de ibi ihò títóbi kan báyìí, nígbà tí mo sì dé ibbẹ̀ mo kó sii, àṣé ihò kìnìhín ni, ìgbà tí kìnìhún sì rí mi tí mo ń sá bọ̀ ó ṣebí Ẹlẹ́gbára ni mi, dípò kí ó bá mi jà, ó sá jáde, ìgbà tí ó máa jáde, ó pàdé Ẹlẹ́gbára, ó sebí ènìyàn ni, ó bá bẹ̀rẹ̀ ìjà pẹ̀lú Ẹlẹ́gbára, wọ́n bẹ̀rẹ̀ ìjà, ibi tí wọ́n ti ń jà, mo sá jáde.
Ènìyàn 284 ló ní àrùn Coronavirus ní Ọjọ́òrú ní Nàíjíríà Eniyan ọrinlenigbalenimẹrin lo tun ṣẹṣẹ ni arun Coronavirus ni Naijiria ni Ọjọọru.
Ṣeba, Ofiri, Hafila, ati Jobabu, àwọn ni ọmọ Jokitani.
Bẹ́ẹ̀ ni yóo rí ní ìgbẹ̀yìn ayé.
Kò ní sí kinniun níbẹ̀,bẹ́ẹ̀ ni ẹranko burúkú kankan kò ní gba ibẹ̀.
Lọjọ kejilelogun, oṣu kẹsan an, ọdun yii ni idibo naa waye nibi ti ẹgbẹ oṣelu PDP ti ni 254, 698 nigba ti APC ni 254, 345.
Ẹni ọdun mẹtelogun ọhun ni Ninu iwoye mi, o dabi ẹni pe mo jẹ ki ifẹ ọkan mi bori idi Pataki ti mo fi lọ sori eto naa mọlẹ."
Ko si alaye kankan lori iye ọmọ ogun to ku ninu isẹlẹ naa.
5 16521 Orilẹede Cuba 136 1.
" Aarẹ Gani Adams, ninu atẹjade kan to fisita lati ba mọlẹbi Arotile kẹdun, wa kesi gbogbo awujọ agbaye lati tanna wadi ohun to ṣe okunfa iku ojiji fun obinrin naa nitori o mu ifura lọwọ.
Ẹ jẹ́ kí a fẹ́ àlàáfíà.
Kylie Jenner ń pa $360m lọ́dún kan, tó sì ta adarí Facebook yọ
Ninu ọrọ ti ẹgbẹ OPC sọ, o kilọ fun awọn janduku to n lo anfaani rogbodiyan to waye ọhun lati ma a fi ja ole, to si tun n ba dukia ijọba jẹ, lati mase ṣọ Iwọ-oorun Gusu Naijiria di ibudo ogun.
 Ìmọ àrùn yíì lè wáyé nìkan nípa àwọn àpẹẹrẹ àti ààmì .
Ẹni to bori: Ghana Angola vs Morocco.
Ni oni tọun pariwo, to si sọ fun pe ẹsẹ ni!"
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù N30,000 minimum wage: Ṣé N30,000 mú ìyàtọ̀ gorí N18,000 owó oṣù òṣìṣẹ́?
Awọn akọroyin BBC ṣi n duro wòye boya idibo naa a tẹsiwaju tabi bẹẹ kọ́.
Ondo deputy governor: Akeredolu ti géètì mọ́ igbákejì rẹ̀, ó fẹ̀sùn olè kàn án, kò tún jẹ́ kó lo ọkọ̀ ìjọba' Ọrọ di ero ya waa wo, idan orita ni ile ijọba ipinlẹ Ondo to wa ni agbegbe Alagbaka, Akure ni alẹ ọjọ Abamẹta lasiko ti awọn oṣiṣẹ alaabo kọ lati jẹ ki igbakeji gomina ipinlẹ naa, Agboola Ajayi o jade kuro nile ijọba.
Oríṣun àwòrán, others Àkọlé àwòrán, Shehu àti Collins kò ní kópa nínú ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ Naijiria àti Madagascar Ta ni Madagascar n Naijiria ti gbena woju nirọlẹ yii?
Ọkan lara awọn eeyan naa, Ọgbẹni Tope Okeowo lo fidi ọrọ yii mulẹ fun BBC Yoruba.
Ǹjẹ́ o mọ ìdí ti n kò ṣe dìbò gómìnà ìpínlẹ́ Ekiti?
Dafidi pàṣẹ pé kí gbogbo àwọn àjèjì tí wọn ń gbé ilẹ̀ Israẹli péjọ, ó bẹ̀rẹ̀ sí kó wọn ṣiṣẹ́, ara wọn ni wọ́n gbẹ́ òkúta fún kíkọ́ tẹmpili.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù AFCON 2019: Debola olólùfẹ́ Super Eagles mú BBC Yorùbá dé ibùdó Bọ́ọ̀lù wíwò Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ AFCON 2019: Debola olólùfẹ́ Super Eagles mú BBC Yorùbá dé ibùdó Bọ́ọ̀lù wíwò 5 Agẹmo 2019 Ere Bọọlu jẹ ere idaraya kan ti awọn ọmọ Naijiria kii fi ṣere rara yala labẹle tabi lẹyin odi.
Obinrin kan rèé tó borí ogun Gẹ̀ẹ́sì Bakan naa lo gba awọn obi ati alagbatọ nimọran lati maa ṣatilẹyin to ba yẹ fawọn ọmọ wọn nitori pe ko sẹni to mọ ọjọ ọla awọn ọdọ yii.
Tí èèyàn bá ní àrùn Covid-19, ajẹsara to wá lára wọn yóò pèsè àwọn èròjà tó ń gbógun ti àrùn, tí yóò sì kọjú oro sì kòkòrò àrùn Coronavirus.
Bí aboyún tí ó fẹ́ bímọ,tí ó ń yí, tí ó sì ń ké ìrora,nígbà tí àkókò àtibímọ rẹ̀ súnmọ́ tòsíbẹ́ẹ̀ ni a rí nítorí rẹ, OLUWA.
O ni ki ile ẹjọ ko awọn ọmọ mejeeji ti awọn bi fun oun, ti wọn ba tiẹ fẹ tu igbeyawo ka, nitori pe Basirat ko le mojuto wọn.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Bí Sanwo-Olu bá fún Super Eagles lówó ń kọ̀; Ṣebí kìí ṣ'owó ìjọba 10 Agẹmo 2019 Oríṣun àwòrán, @:Sanwo-olu Àkọlé àwòrán, To ba wú Sanwo Olu o lè fún Super Eagles lowo to ju eyi lọ Iye tó ba wu Sanwo Olu ló lè fún ẹnikẹni - Akoṣile Laipẹ yii ni awọn iwe iroyin kan gbe e pe Gomina ipinlẹ Eko, Babajide Sanwo-Olu fun awọn ọmọ ẹgbẹ agbabọọlu Super Eagles ni miliọnu mọkanlelogoji o le diẹ lasiko to lọ fun idije AFCON 2019 to n lọ lọwọ ni Egypt.
Irú ilé wo ni ẹ̀ báà kọ́ fún mi?
Ó sọ fún wọn pé, “Ṣé ẹ rí gbogbo ilé yìí, mo fẹ́ kí ẹ mọ̀ dájúdájú pé kò ní ku òkúta kan lórí ekeji tí wọn kò ní wó palẹ̀.
Iyabọ sapejuwe baba rẹ ninu lẹta naa to kọ l'ọjọ kẹrindinlogun, oṣu Kejila, ọdun 2013, sọ pe opurọ, ọlọgbọn ẹwẹ, ati alagabangebe, to fẹ wa ni iṣakoso titi lai.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Buhari, Saraki, Dangote, abẹ́ mi ni wọ́n wà' Iṣẹlẹ miran ti awọn alaṣẹ mọṣalaṣi yii mẹnuba ni ti ọkunrin kan to fẹ gun Aafa Sheik Sudais lọbẹ nigba ti o n pe irun ni mọṣalaṣi Ka'bah ni Mecca.
Bákan náà, ni wọ́n ń késí àwọn asòfin Nàíjíríà láti tètè yọ ààrẹ Muhammadu Buhari nítorí kò tẹ̀lé òfin orílẹ̀èdè yìí.
Sowore wa pe fun atunto eto oṣelu ki o ba le jẹ ki awọn ọmọ Naijiria laanfaani lati kopa daada.
“Ta ni ó ń kọrin níbẹ̀ yẹn” jẹ́ eré Yugoslavia ayé ìgbà 1980 tí ó sì di ipò ẹgbẹ́-ìmùlẹ̀ láàárín àwọn Balkan.
Ọọni rọ awọn ọmọ Naijiria lati gbaruku ti ijọba ki wọn balẹ bori arun Coronavirus to n ja tan kaakiri agbaye.
 wọn tún un se , wọn sì jẹ ́ kí o wúlò tóbẹ ́ ẹ ̀ tí ilé-ifẹ ̀ pàápàá ń gáárùn wo ògbóni Ẹ ̀ gbá .
Adamasingba niluu Ibadan ni Ipinle Oyo.
Bakan náà ni o fi kún un pé ni ti owó, àwọn ti gba ní dọla àti naira owó to lé ni bilọnù mẹta báyìí.
Wolii Jeremaya bá bá ọ̀nà tirẹ̀ lọ.
O nilabẹ ijọba awọn,awọn yoo pawọpọ plu ilẹ Gẹẹsi ati Amerika lati koju ipenija aabo to n ba Nijiria finra Khadijah Abdullahi Aabo to peye jẹ ọna kan gbogi ti Khadijah Abdullahi da laba lati koju ipenija aabo.
"Àkọlé àwòrán, Eto naa yoo ṣe awọn akanda ẹda lanfani Hall ni ""Iroyin BBC to n wa lati ilẹ Afirika n de ọdọ awọn eeyan ti ko din ni ọgọrun un miliọnu kan."
Nitori naa ko si idi kan fun ikayasoke.
O daa o, iru iba wo ni iba to n ṣafihan coronavirus?
Sibẹ, wọn sọ fun un pe wọn ko ti i ri ọkọ rẹ.
O din diẹ ni miliọnu mẹrin eniyan lo ti ni aarun Covid-19 ti eniyan to le ni ogoje si ti ku ni ilẹ Amẹrika, eyi lo ga julọ lagbaye.
Adedayo Shittu lo soro yii nibi eto ti ile-ise to n la awon eniyan  lọyẹ lorilẹ ede Naijiria, lasiko to n se ifilole
Minisita to n ri si ere idaraya ati idagbasoke awon odo lorile-ede Naijjria, Solomon Dalung, ti fi mule pe, ifesewonse olorejore ti yoo waye laarin iko agbaboolu Super Eagles ati Congo DR yoo waye ni papa isere miiran, ti atunse to n lo lowo ni papa isere ilu Abuja ko ba ti wa si ipari ki o to di asiko ifesewonse naa.
Wọ́n bẹ̀rẹ̀ sí yọ̀ nígbà tí ilẹ̀ rọ̀,ó sì mú kí wọ́n gúnlẹ̀ sí èbúté ìfẹ́ wọn.
98% awọn to ṣe idanwo ni ọrọ yii kan.
Oun ti a mọ nipa bi Miller ṣe ko coronavirus Oludamọran Aarẹ Trump ọhun sọ pe oun ti wa ni iyasọtọ lati ọjọ Iṣẹgun to ti mọ pe aarun naa ti wọ lara.
Bi ikọ ẹgbẹ agbabọọlu Enyimba ba ti n waako pẹlu Energie FC naa ni ẹgbẹ agbabọọlu miran lati orilẹede Naijiria, Akwa United FC pẹlu yoo maa koju Al-Ittihad ti orilẹede Libya ni Tunisia.
Kí ẹ máa fi gbogbo ọgbọ́n kọ́ ara yín, kí ẹ máa fún ara yín ní ìwúrí nípa kíkọ Orin Dafidi, ati orin ìyìn ati orin àtọkànwá.
O ni oun to dunni ju ni pe bi gbogbo eyi ṣe n ṣẹlẹ bọọ lawọn agbofinro n wo lai lee ṣe ohunkohun Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Ayé ò fẹ́ kí á yó
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fọ́nrán ohùn, Dókítà Òbílàdé: Ẹni tó bá lo Tramadol lálòjù leè sùn, kó má jí mọ́ Ọmọde naa, Jack, ni aisan Down syndrome nigba ti wọn gbe e digbagba wa si ile iwosan ti Hadiza ti n sisẹ.
9 756 Orilẹede Gilbraltar 5 14.
 Gbogbo ebi wa lo faramo yiyan ti baba wa yan an sipo pataki yii.
Bakan naa ni wọn fi lede wi pe, ijọba Aarẹ Buhari nilo ifọwọsowọpọ awọn araalu, ẹgbẹ oṣiṣẹ lorilẹede Naijiria ati awọn ẹgbẹ oṣelu to ku ni Naijiria lati le mu Niajiria de ilẹ ileri.
Operation Amotekun: Ẹgbẹ́ kan rọ Tinubu, láti sọ èrò rẹ lórí ọ̀rọ̀ Amọtẹkun
oko ayokele Toyota Corolla kan; Aloku oko ayokele Toyota Sequodia kan; Aloku
mewaa ni yoo de si orile ede Naijiria ni osu kefa lati din wahala  ti awon ero ti o n lọ fun irirnajo lati Abuja
Èmi ni mo ṣẹ̀, tí mo sì ṣe nǹkan burúkú.
Irú ọrọ̀ bẹ́ ẹ̀  kò bá wọn kalẹ́ bẹni ìrántí wọn kò dára.
Má bá oníbìínú eniyan kẹ́gbẹ́,má sì bá onínúfùfù da nǹkan pọ̀.
Oríṣun àwòrán, Instagram/Hushpuppi Ninu awọn ọrọ kan to fi sioju opo Instagram rẹ, o sọ pe oore ti Allah ṣe fun ohun to ga ju lọ ni pe, oun jẹ musulumi.
"Oluwo ṣalaye pe inu igbo rere nile Fulani koda, wọn mọ igbo wa ju wa lọ""."
Ambode, tí Kọmíṣọ́nà fun ètò ìròyìn, Kehinde Bamigbẹ́tàn ṣojú rẹ̀, níbi àyájọ ọjọ́ akọsilẹ ìsẹ̀lẹ̀ tó ti kọjá lọ, èyí tó wáyé ní àdúgbò Ìkeja, sọ pé, ó yẹ kí ìjọba àpapọ̀ gbe fọ́nrán ohùn àti àwòrán ìgbà ìkẹ̀yìn Abiola síta, kí gbogbo ayé leè ríi.
Láìpẹ́ ni NDLEA gbẹ́sẹ̀lé ìgò oògùn ikọ́ olómi Codeine ẹgbẹ̀rún mérìnlélógún nínu ọkọ̀ agbégi kan ní ìpílẹ́ Katsina.
Lẹyin ti akọnimọọgba Arsenal, Mikel Arteta fẹyinti gẹgẹ bii agbabọọlu, ọdọ akọnimọọgba Manchester city, Pep Guardiola lo ti kọṣẹ akọnimọọgba ki o to wa gba iṣẹ akọnimọọgba Arsenal.
Oríṣun àwòrán, The Protected Area Regional office 13 (Phrae) Àkọlé àwòrán, Rọba ati awọn idọti miran ti Igala naa jẹ lo ṣeku pa Ajọ to n mojuto ayika ẹni, Greenpeace sọ pe o to biliọnu márùndínlọ́gọ́rin rọba ti awọn eeyan n ju silẹ lọdọọdun.
Eyi ṣẹlẹ lẹyin to fi mọto pa akẹkọọ kan ti o n wa ọna ati wọ ileewe naa.
Nígbà tí ó kú, wọ́n sin ín sí ìlú Dafidi, baba rẹ̀, Rehoboamu, ọmọ rẹ̀ sì jọba lẹ́yìn rẹ̀.
Nígbà tí ẹ̀rù bá ń bà mí,èmi yóo gbẹ́kẹ̀lé ọ.
Ogun Suicide: Ẹ̀lẹ́sìn Islam àti tìbílẹ̀ fìjà pẹ́ẹ́ta lórí ìsìnkú ẹni tó pokùnso
Oríṣun àwòrán, @OlugbengaAyo Àkọlé àwòrán, Oṣu to kọja ni ọmọdekunrin jojolo kan di awati nile ijọsin ọhun Lẹyin naa ni iya ọmọ ọhun ke gbajari sita, ti awọn agbofinro si pe oluṣọagutan ijọ naa, woli Alfa Babatunde, fun ifọrọwanilẹnuwo.
Sẹ mọ pe ọpọlọpọ awọn ọmọ naa ni ki i le sọ fun ẹnikẹni nipa isẹlẹ adojutini naa, nitori pe nigba mi, ẹni to n fi ipa ba wọn lopọ yoo ti kilọ tabi halẹ mọ wọn pe, oun yoo pa wọn tabi fi iya jẹ wọn ti aṣiri naa ba fi tu sita.
Èmi kò forí ṣọta ìjàmbá ọkọ̀ òfúrufú kankan - Obasanjo Mà á ṣiṣẹ́ bí i gómìnà tó ní èrò aráàlú lọ́kàn - Seyi Makinde Aṣọ ń pe aṣọ ránṣẹ́ ni lásìkò ìbúra gómìnà àti ààrẹ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Nigeria Population: Báwọn ọmọ Nàíjíríà ṣe ń pọ̀ si jẹ́ ìpèníjà fún Buhari Kinni erongba OIC?
" Nigba to n salaye lori ohun tawọn eeyan kan fisita pe awọn gende agbebọn to sọsẹ naa jẹ Fulani, Ajayi ni ohun ti awọn gbọ niyẹn, ko si ọlọpa kankan nibi isẹlẹ naa nigba to waye, amọ iwadi ti n lọ lọwọ lati mọ iru awọn eeyan to sisẹ naa.
Nígbà tí wọ́n sọ fún Farao, ọba Ijipti, pé àwọn ọmọ Israẹli ti sálọ, èrò òun ati àwọn ẹmẹ̀wà rẹ̀ nípa àwọn eniyan náà yipada.
- iléeṣẹ́ ológun kìlọ̀ Irọ́ ni pé wọ́n hú òkú Kolawole Gold lórí pẹpẹ ìjọ ọkọ mi- Bisola aya Sotitobire Ẹ wo èrò bìbà níbi ìwọ́de #EndSARS ní ìlú Ibadan Wo bí àwọn jàndùkú ṣe yabò àwọn olùwọ́de #ENDSARS ní Alausa l'Eko àti Abuja Kí ló ń ṣẹlẹ̀ láàfin Oyo táwọn èèyàn fi ń ki Alaafin ní mẹ́sàn án mẹ́wàá?
Ìyá àwọn ìbejì - BBC News Yorùbá BBC News, YorùbáFò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Conjoined Twins: Wọ́n fi mí ṣe yẹ̀yẹ́ ládùúgbò, ojú tì mì - Ìyá àwọn ìbejì 31 Ògún 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 1 Owewe 2020 Ileewosan ijọba to wa ni Yola, ipinlẹ Adamawa tun ti ṣiṣẹ alaṣeyọri kan gẹgẹ bi wọn ṣe fi aṣẹ abẹ ya awọn ọmọ ibeji to lẹpọ.
Nítorí èyí ni Ìwé Mímọ́ ṣe sọ pé, “Ọlọrun lòdì sí àwọn onigbeeraga, ṣugbọn ó fi oore-ọ̀fẹ́ fún àwọn onírẹ̀lẹ̀.
O ni ko si ohun ti ẹni pupa le da lara ti ẹni dudu naa ko le fi yangan.
Sunmọbi ki o ba wa fi aami sori ọrọ yii to ba jẹ ojulowo ọmọ Yoruba.
Lagos Kidnap: Wo ohun tí ọlọ́pàá ti ṣe nípa àwọn méje tí wọ́n jí gbé l'Eko
BUSA 2019: Èrò yapa ní mọ́ṣáláṣí Jimọ̀h láti wá fójú lóúnjẹ lórí ìgbéyàwó Buhari
Auxiliary sọ pe gbogbo awọn ọbayejẹ ẹda to ba fẹ ma ja ijọba lole nipa gbigba owo lọna aitọ ni yoo foju wina ofin nipinlẹ Oyo.
Bí ọmọbinrin àfẹ́sọ́nà yìí tilẹ̀ ké: ‘Gbà mí!
Ẹni tó bá ń bínú kàn ń bínú lásán ni- Oyedepo Owó Naira yóò sì tún padà níyì láwùjọ àwọn owó orílẹ̀-èdè tó gbé pẹ́ẹ́lí jùlọ lágbàáyé- Adeboye Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
 bákan náà ni Ọdúnjọ tún ṣe olùkọ ́ àti olùkọ ́ àgbà fún àwọn ilé-ìwé ìjọ ́ sìn kátólííkì oríṣiríṣi káà kiri láti ọdún 1940 tí tí di 1950 .
” Jona dáhùn, ó ní: “Ó tọ́ kí n bínú títí dé ojú ikú.
Kí nǹkan tí eniyan ṣe, wí nípa ẹni tí ó ṣe é pé:“Kìí ṣe òun ló ṣe mí.
Kò sí ẹyọ alágbẹ̀dẹ kan ní gbogbo ilẹ̀ Israẹli, nítorí pé àwọn ará Filistia ti pinnu pé, àwọn kò ní gba àwọn ọmọ Israẹli láyè láti rọ idà ati ọ̀kọ̀ fúnra wọn.
Awọn eniyan yii ni wọn ni ẹri to pọ to n ṣafihan bi awọn agbofinro Naijiria ṣe maa n huwa aitọ si awọn eniyan nibikibi.
ede lati tun fi kun un.
Mo mọ̀ pé àwọn obìnrin mìíràn, kà á sí ẹ̀tẹ́ pé, kí àwọn tọrọ àforíjì lọ́wọ́ ọkọ àwọn bí àwọnn bá ṣẹ̀ ẹ́, mo sì mọ̀ dájú pé, ara ni irú àwọn bẹ́ẹ̀ fi yàtọ̀ sí ìnàkí, agbárí wọn ti ìnàkí ni.
nítorí pé ẹ̀wù yìí ni àwọ̀lékè kan ṣoṣo tí ó ní, òun kan náà sì ni aṣọ ìbora rẹ̀.
Lẹyin naa lo gba awọn ara ilu niyanju lati dẹkun ṣiṣe idajọ ọwọ ara ẹni nitori o lodi si ofin.
ede Naijiria se sọ ,pe iko omo ogun  LAFIYA
 Nigba ti abala ise gangan yoo waye lati ojo karun un osu keta si ojo keedogun osu kerin odun.
Aarẹ Ọna Kakanfo kilọ fun awọn darandaran fulani Ikọlu darandaran: Fayọṣe ṣe abẹwo si Ortom ni Benue Ijọba ipinlẹ Edo pinnu lati gbe awon igbesẹ wonyi lẹyin igba ti gomina Godwin Obaseki se ipade pẹlu awọn asoju Hausa ati Fulani lati ijọba ibilẹ mejidinlogun to wa ni ipinlẹ naa.
Ṣugbọn iyawo Gileadi gan-an bí àwọn ọmọkunrin mìíràn.
gẹ ́ gẹ ́ bí a ti rí i àti bí a ṣe gbọ ́ láti ẹnu àwọn asunrárà tí a wádìí lọ ́ dọ ̀ ọ wọ ́ n , àwọn àsìkò tí a máa ń sun rárà jẹ àsìkò ti a bá ń ṣe àríyá tàbí àjọyọ ̀ .
Ethiopia Airlines ET302: Obìnrin yìí ṣì ń ṣèdárò àwọn tó kú nínú ìjàmbá bàálù Ethiopia
Bí mo ba di ààrẹ ní ọdun 2019, mo ti fi ohùn sílẹ̀ láti ṣe sáà kan ṣoṣo' Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ọsẹ́ tí òògùn Tramadol ń se nínú ara Wo oríṣiríṣi ìgbádun ibálòpọ̀ láwọn orílẹ̀èdè mìíràn Pákáleke lórí ìdìbò àti ọrọ̀ ajé Nàíjíríà ń já wa láyà - UN Àwòrán bí ìlú Ìwó se rọ̀sọ̀mù f’ọ́dún eégún N kò fẹ́ eégún onídọ̀tí ní ààfin mi - Oluwo Oshiomọlẹ ń se bi adìẹ tí ojò pa, tó ń sunkún kiri- Saraki Ikọ̀ ẹlẹ́sìn Hàkíkà rèé, níbití wọn ti ń pààrọ̀ ìyàwó láàrín ara wọn Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ìyá Darasimi: Ọlọ́run fi ìbejì rẹ̀ mí lẹ́kún, lẹ́yìn ikú Darasimi tó mu sódà Ó ní bótilẹ̀ jẹ́ pé Buhari náà jẹ́ irú ẹ̀jẹ́ bẹ́ẹ̀ lọdun 2011 tí kò sì tèlée, ọ̀rọ̀ tohun kò ni rí bẹ́ẹ̀ rárá àti pé, òhun ti ṣetán láti tọwọbọ ìwé àdéhun."
Olori ijoba ile Biriko naa gboriyin fun ipinnu Aare Trump naa.
Ninu atẹjade kan ti a ri lati ọwọ oluranlọwọ rẹ lori ọrọ iroyin,Ikechukwu Eze,Aarẹ Jonathan ni awọn ko ṣẹṣẹ ma gbo iru irọ bẹ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ile asofin agba buwọlu aba to fofin de tita siga leyọ ẹyọ 8 Èrèlè 2018 Oríṣun àwòrán, National Assembly/Website Àkọlé àwòrán, Ile igbimọ Asofin agba ni ẹka asofin to ga julọ lorilẹede Naijiria Idunnu subu layọ fawọn ajọ to n ja fun imọtoto ati alaafia agbegbe lorilẹede Naijiria (Environmental Rights Action ati Friends of the Earth Nigeria (ERA/FoEN) , nigbati ile igbimọ asofin agba buwọlu aba to fofin de asa siga tita lawọn agbegbe ile-ẹko alakọbẹrẹ ati ti girama.
Amọṣa o ni aṣẹ ti awọn ile ẹjọ kọọkan pa lori eto idibo naa lawọn n tẹle fi gbe igbesẹ ọhun.
Má fi ìwàǹwára gbé ọwọ́ lé ẹnikẹ́ni lórí láti fi jẹ oyè ninu ìjọ, má sì di alábàápín ninu ẹ̀ṣẹ̀ ẹlòmíràn.
Nítorí náà, OLUWA mú kí ọ̀gágun ilẹ̀ Asiria wá ṣẹgun Juda, wọ́n fi ṣẹ́kẹ́ṣẹkẹ̀ bàbà de Manase, wọ́n fi ìwọ̀ mú un, wọ́n sì fà á lọ sí Babiloni.
Eyi ti ko ṣẹyin awọn ẹsun kan ti ajọ ọlọpaa ọtẹlẹmuyẹ DSS fi kan an niwaju awọn aṣofin.
Tóun tí bí ẹnu ti ṣe n kun wọn,ilé iṣẹ ọlọpa lorílè-èdè Nàìjíríà ni awon kò ri ìdí tí wọn yóò fi kagba Sars wọlé Bo tilẹ jẹ pe awọn yoo gbe igbeṣẹ lati ri pe wọn ṣe atunto ẹka SARS naa.
Bi o ti le je pe, orisirisi rogbodiyan lo ti n waye ni ibode ti o so orile-ede mejeeji po, eleyi ti o si n sokunfa wahala lopolopo.
12 Àti nísisìyí, lõtọ́, lõtọ́, ni mo wí fún ọ, fi ìgbẹ́kẹ̀lé rẹ sínú Ẹ̀mì náà èyí tí ó ndarí lati ṣe rere—bẹ́ẹ̀ni, láti ṣe títọ́, láti rìn ní ìtẹríba, láti dájọ́ ní òdodo; èyí sì ni Ẹ̀mí mi.
Ọpọ awọn oluwoye lo n beere pe ṣe erongba ibudo okoowo ilẹ Afrika ọhun ko ni foriṣanpọn, nigba ti orilẹ-ede Naijiria to ni eto ọrọ aje rẹ tobi ju lọ ni Afrika, to tun jẹ olori ẹkun Afrika yọwọ kuro ninu rẹ.
Nítorí pé n óo fún àwọn tí àárẹ̀ mú ní agbára; n óo sì tu gbogbo ọkàn tí ń kérora lára.
44 fún lítà kan Àwọn èèyàn tí bẹ̀rẹ̀ sì ní gba abẹ́rẹ́ àjẹsára fún ìdènà àrùn Coronavirus ni ilẹ̀ Gẹ̀ẹ́sì Ìdí rèé táwọn àkàndá ẹ̀dá fi dí iwájú iléeṣẹ́ ìjọba ìpínlẹ̀ Oyo pa l'Agodi n'Ibadan Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Ibadan clash: Rògbòdìyàn bẹ́ sílẹ̀ láàrin àwọn ọlọ́kadà àti àwọn òṣìṣẹ́ ọgbà ẹ̀wọ̀n ní Ibadan24 Bélú 2020 ASUU strike: Mi ò tíì lè sọ ní pàtó ìgbà tí a ó fòpin sí ìyanṣẹ́lódì wa - Aarẹ ASUU7 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Overweight and pot belly: Wo oríṣìí oúnjẹ márùn ún tó lè dẹ́kun ikùn yíyọ àti ara àsanjù8 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Ondo 2020 Tribunal: Ìgbìmọ̀ olùgbẹ̀jọ́ ìbò gómìnà yóò gbérasọ lọ́jọ́ Iṣẹgun7 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Mikali sì mú ère kan, ó tẹ́ ẹ sórí ibùsùn, ó gbé ìrọ̀rí onírun ewúrẹ́ sibẹ, ó fi ṣe ìrọ̀rí rẹ̀, ó sì fi aṣọ bò ó.
daa  yin loju pe, odun merin yii yoo lọ
" Oríṣun àwòrán, Seyi Makinde Lara awọn eeyan miran to tun tẹle gomina Makinde ni lati oludamọ̀ran rẹ feto aabo, Fatai Owoseni, ti gbogbo wọn si sisẹ loru mju lati ri daju pe ọrọ ẹgbin to fọn kaakiri ilu di afiẹyin, ti eegun fi asọ.
Akeredolu lo sọ bẹẹ ninu atẹjade ti oluranlọwọ pataki rẹ lori ọrọ to n lọ, Ojo Oyewamide fi lede.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Olupẹjọ nilẹ Amẹrika, Nick Hanna, sọ pe, ọwọ ṣikun ijọba ti tẹ awọn mẹrinla O wa rọ awọn ti ọrọ naa kan ti o wa lorilẹ-ede Naijiria lati yọju si ajọ FBI bi o ba dawọn loju pe, wọn ko lu ẹnikẹni ni jibiti.
Àwọn mejeeji bá bẹ̀rẹ̀ sí lọ títí wọ́n fi dé Bẹtilẹhẹmu.
Ko ti si ẹnikakan to jade lkati sọ pe awọn lawọn wa nidi iṣẹlẹ naa sugbọn erekusu Jolo la gbọ pe awọn alakatakiti pọ si to fi mọ ikọ kan ti orukọ wọn jẹ Abu Sayyaf Kini a mọ nipa ikọlu naa?
Àwọn ọmọ Beria ni: ìdílé Heberi ati ìdílé Malikieli.
kí àwọn eniyan lè ní ọgbọ́n ati ẹ̀kọ́,kí òye ọ̀rọ̀ ìjìnlẹ̀ lè yé wọn,
Sugbọn nitori pe o ti pẹ ti mo ti gbọ pe o sọrọ nipa Pasuma, iṣẹ ti pọ lọwọ rẹ bayii, ko s'aye.
Ojú ọ̀run ń sọ̀rọ̀ ògo Ọlọrun,òfuurufú sì ń kéde iṣẹ́ ọwọ́ rẹ̀.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Manfe-Dove: Àgbà ìlú kan ní ohùn kan ló fọ̀ sáwọn baba ńlá àwọn láti ṣe bẹ́ẹ̀ Koffi Olomidé jẹ ìlúmọ̀ọ́ká olórin Rumba àti Soukous, ti gbogbo ènìyàn mọ ní ọ̀pọ̀ àwọn ilẹ̀ aduláwọ̀ Sáájú ni wọn ti pe Olomidé lẹ́jọ́ lọ́dun 2012, fún ẹ̀sùn ìbálòpọ̀ sùgbọ́n nígbà tó yá ni wọn ṣe àdínkù ẹ̀sùn náà.
Ìdí ree ti a fi gbọdọ kiyesara nipa awọn ìṣesí to lè ṣakoba fún ọpọlọ wa.
Ekiti state: Nítoríi fóònù ìbánisọ̀rọ̀, géńdé méjì kú sínú u kọ̀ǹga l'Ékìtì
 Àǹfàní àti ní àwọn àrùn ìbálòpọ ̀ míràn bíi hiv / aids maa ń pọ ̀ bí ènìyàn bá ní àrùn bv .
Oríṣun àwòrán, Getty Images Ṣugbọn ṣa, eniyan 13,447 ti ri iwosan, awọn 740 si ti ku.
Nuhu Gidado to je gomina ipinle Bauchi ti kowe fise sile.
Oríṣun àwòrán, @EKITISTATEGOV Ta ni wọn yóò búra fún bíi gómínà Bayelsa lónìí, olùdíje PDP ni àbí olórí ilé aṣòfin?
Com Kim Doyeon lo bun Naijiria ni goolu akọkọ lẹyin to gba bọọlu sinu awọn ile rẹ.
 nítorí náà orúkọ jẹ mọ ́ ìhun ọ ̀ rọ ̀ -orúkọ nínú èdè adúláwọ ̀ kọ ̀ ọ ̀ kan ; ó jẹ mọ ́ ìmọ ̀ lára ènìyàn , ó jẹ mọ ́ ìgbàgbọ ́ , ìfẹ ́ , àníyan àti ìrètí ènìyàn pẹ ̀ lú .
Nigba miran, wọn ko ki n fẹ sọ ẹya ẹjẹ (genotype) wọn tori bi ẹlomii to ti yo ifẹ wọn.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ìtàn ayé Henry Fajemirokun, olówó tó fi owó mọ Olúwa àti ènìyàn N kò gba ₦4bn lọ́wọ́ Magu, ẹ má ró àjẹbánu mọ́ mi láṣọ - Osinbajo pariwo Àṣírí tú!
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Buns ni ọmọ mi jẹ tán ní ṣọ́ọ̀ṣì, ló bá di àwátì' Tani ó ni oré-ọ̀fẹ́ Mo jẹbi ẹ̀sùn ẹ jẹ́ kí a ṣe adéhùn: Ní ọ̀pọ̀ ìgbà, àsìkò ìgbẹ́jọ ni olùjẹ́jọ le bẹbẹ mo jẹbi ẹsùn Olùjẹ́jọ yóò jọ́wọ̀ àwọn ǹkan ti wọ́n ba ni o jí fún ìjọba Agbẹ́jọ́rò àgbà náà ni aṣẹ̀ láti gbé ẹ̀sẹ̀ lé ẹjọ to ba wùú Àjọ EFCC kò ní agbára láti pinu irú ìjìyà ti o tọ́ si ọ̀dáràn àyàfi ti agbẹjọ́rò àgbà ba gbà láti ṣe bẹ́ẹ̀ Àdéhùn gbọ̀dọ wà láàrin àwọn agbẹjọ́rò àgbà àti ẹnikẹni tó ba ń bá ọdaran ṣẹjọ Tí ìjọba ba ri pé ìgbésẹ̀ náà dín ináwó kù, o dí àsìkò ti yóò sòfò kù, nítori pé kò rọrùn láti ṣe ẹjọ o si maa n gba àsìkò púpọ.
Igbimo asewadii ohun ni ireti wa pe, won yoo sewadii fini-fini lori awon ohun ti o sokunfa jiji awon akekoo naa gbe, sise ayewo lori iko agbemila ti won n sise akanse lori isele ohun, ati ona abayo lati dekun iru isele laabi yii lojo iwaju.
Gẹgẹ bi baba onifa yii ṣe sọ ọ, wọn gbudọ tọwọ iwa ipaniyan lemọ lemọ to n waye ni iha Ariwa orilẹ-ede yii bọlẹ.
Ọ̀rọ yìí e débi à ń yọ orùka
Ijó ni iná fi i jó
Nigba to n sọrọ lori aisan to n ṣe Baba rẹ, Olusola ni nkan ko fi bẹẹ dabi mọ fun baba mi nitori oju apa ko jọ oju ara fun un, bi aisan naa si ṣe n lọ, lo tun n pada, ti ọrọ naa ko si ye mi mọ rara."
Mo ti rù láàrin ọ̀sẹ̀ kan, iṣẹ́ Eko kò dẹ́rùn - Sanwo-Olu Èèmọ̀ wọ̀lú!
Atiku Abubakar to jẹ oludije labẹ asia ẹgbẹ PDP ni oun ṣi n mu ẹyẹ bọ lapo.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ẹlẹ́tàn ni ọkùnrin, tó bá rí nkan tó n wa lára obìnrin, yóò yí ìwà padà - Bimpe Oyebade Wo àwọn ẹ̀ṣẹ̀ Trump tó mú kí alátakò ilé darapọ̀ mọ́ tìta láti yọ nípò A kò le gbà kí ASUU gba ₦30bn nínú ₦40bn tíjọba gbé kalẹ̀ - NASU yarí Ẹ̀yin adarí Nàíjíríà, ẹ dẹ́kun àwáwí asán lórí ètò ààbò tó mẹ́hẹ - Ààrẹ àṣòfin àgbà Ẹ dákẹ́ àhesọ ọ̀rọ̀, ohun tó pa ẹ̀gbọ́n àti àbúrò Orisabunmi rèé - Mọ̀lẹ́bí gbarata Wo àdánù tó wà nínú gbígba ayédèrú áápù fún ìforúkọsílẹ̀ NIN lórí ayélujára Àmúlò ẹ̀rọ POS fun òwò ṣíṣe, ṣé ó tọ̀nà nínú Islam àbí bẹ́ẹ̀ kọ́?
Agbaboolu owo eyin iko Juventus ati orile-ede Italy, Giorgio Chiellini ko ni kopa ninu ifesewonse olorejore ti iko agbaboolu Italy yoo gba latari ifarapa eyi ti o ni.
    Nígbà tí Kùmọ́dìran bẹ̀rẹ̀ síí sọ̀rọ̀, àyà mi já, ó sọ̀rọ̀ yánna yànna ó ni:
Ile-ise akowe agba fun orile ede Naijiria ni yoo maa salaye fun awon igbimo lori ibi ti ise ti duro lose to koja, bakan naa  ni yoo tun maa salaye fun igbimo lori ohun ti won fe jiroro nibi ipade toni.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Omiyalé Àkútè: N50 si N100 làwọn èèyàn fi ń kọjá lórí ẹ̀kún omi Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Omiyalé Àkútè: N50 si N100 làwọn èèyàn fi ń kọjá lórí ẹ̀kún omi 20 Owewe 2018 Awọn olugbe agbegbe Akute nipinlẹ Ogun ni oju wọn n ri mabo lọwọ isẹlẹ ẹkun omi to n da wọn laamu.
ni: “ohun ti mo n sọ ni pe niwọn ti ofin faaye gba pe mo le beere lati gba
Òkè kékeré kan ń bẹ láàrin ilẹ̀ ọ̀dàn náà.
Ìdí rèé tí Aisha Buhari kò tíì padà sí Nàìjíríà- Iléeṣẹ́ ààrẹ Adigunjalè kó ẹrọ amọhùnmáwòrán méjì lọ níle ọga Ọlọpaa Ile ẹkọ agba yii ni awọn igbiyanju bii ti Diaz yii lo n jẹ iwuri lati tẹsiwaju fun awọn ninui ẹkọ awọn agbalagba.
 Òun ni ó darí italy ní 1922 sí 1943 .
Ṣugbọn a le ṣe agbeyẹwo itankalẹ rẹ ni orisirisi orilẹ-ede ti oju ọjọ wọn yatọ si ara wọn fun àmì.
Iroyin naa sọ wi pe awọn ọlọpaa mu u lọ si agọ wọn pẹlu panpẹ lọwọ.
Jehoramu ọmọ rẹ̀ sì gorí oyè dípò rẹ̀.
Irẹwẹsi ọkan ba Sara pe iya to bi oun mọọmọ kọ oun silẹ ni, to si jẹ ibanujẹ nla fun, amọ ko pẹ lo wọ ile ẹkọ fasiti Greenwich, lati kẹkọ gboye akọkọ lẹka imọ nipa ofin, Law.
"O ni, ""Iyalẹnu lo jẹ pe Ogbẹni Oshiomhole n ṣe bi adiyẹ ti ojo pa, to si n su ẹkun kakakiri ilẹ bi ẹni pe olori ile igbimọ aṣofin agba ni oku to n le e kiri."
” Mo ṣì ní ìgbàgbọ́ wípé [àtúnṣe ìjọba àwa-arawa] ni ìdáhùn kan ṣoṣo.
" Joke Jacobs wa fi ọkan awọn ololufẹ wọn balẹ pe ko si ewu rara fun ọkọ oun.
Títí ayérayé ni ìjọba rẹ̀,àtìrandíran rẹ̀ ni yóo sì máa jọba.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Africa Drum Festival 2019: Eruku sọ níbi àjọ̀dún ìlù l'Abẹokuta Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Africa Drum Festival 2019: Eruku sọ níbi àjọ̀dún ìlù l'Abẹokuta 26 Ìgbé 2019 Ọdọọdun ni ajdun ilu ilẹ Afirika yii maa n waye.
OLUWA ní, “Mo dá ọ̀run tuntun, ati ayé tuntun;a kò ní ranti àwọn ohun àtijọ́ mọ́,tabi kí wọn sọ sí eniyan lọ́kàn.
Kí ló dé tí Ọlọrun fi ṣe bẹ́ẹ̀?
Ìdáhùn Ọbasanjọ Sáájú àbẹ̀wò Gbenga sí oko Olóyè Ọbasanjọ to n jẹ Otta Farm, ọfiisi Aarẹ ti y ara wọn kuro ninu oun ti Gbenga sọ eleyi to jẹ ki ọplọp ro wi pe lati ile iṣẹ Aarẹ lawn ọrọ rẹ ti ṣẹ wá.
won , opo eniyan lo wa lati wa gbo wa ti  inu mu si dun pe awon eniyan ti setan lati yan
Garba so pe“ Inu ijoba orile ede Naijiria dun
Apapọ owo ti wọn naa lati fi gbogun ti ibà le biliọnu mẹta Dọla ( $3.
Zakzaky ati iyawo rẹ lo ti wa ni ahamọ lati bii ọdun marun sẹyin, ti ileẹjọ ko si gba oniduro rẹ.
Iye ọdún tí ó bá kù ni wọn yóo fi ṣírò owó ìràpadà rẹ̀.
Lo ba kọri si ile ẹgbọn baba rẹ lati maa ṣe aṣọ́ ẹran ọ̀sìn.
Lionel Messi Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Sáájú ni gómìnà ìpińlẹ̀ Ondo Arákùnrin Rotimi Akeredolu ti Ọwọ́ àwọn alásẹ ọgbà ẹ̀wọn ní ọ̀daràn to ni Corornavirus wà báyìí-Kọmísọ́nà ìlera Ondo Corornavirus: Ọwọ́ àwọn alásẹ ọgbà ẹ̀wọn ní ọ̀daràn to ni Corornavirus wà báyìí-Kọmísọ́nà ìlera Ondo Ijọba ipinlẹ Ondo ni ọgba ẹwọn ilu Ọwọ ni afunrasi ọdaran to ni arun Coronavirus ṣi wa.
Aseyori nla si leyi fun ijọba Muhammadu Buhari nidi gbigbe ogun ti itankalẹ arun Coronavirus.
Kí ló dé tí o fi rán mi sí wọn?
Eyi jẹ aiṣedeede inu ara nibi ti obinrin ti maa n ni apo ile ọmọ meji.
Nigba to wa laye, orisi aworan lo safihan igbe aye gbajugbaja agbabọọlu to tun pada ṣe akọnimọọgba fun Lionel Messi.
Pupọ awọn ilẹ Asia lo ti kẹkọ lara ajakalẹ arun SARS ni ọdun 2003.
Ibi yìí ni Super Tuesday ti jẹ yọ.
Leyin Iseju márùndínláàdọ́rin ti iko mejeeji ti n bara won po, balogun iko agbaboolu Belgium, Eden Hazard sawari Thomas Meunier ni igun keji ori papa isere naa, ki agbaboolu iko Paris Saint-Germain ohun o to tun sawari Batshuayi lati gba boolu naa sagbon.
Progressives Congress (APC) ti n gba awon osise eleto idibo ti won yoo lo lati
A fẹ́ kí a máa tẹ àwọn afipábánilòpọ̀ lọ́dàá ni báyìí - Ìjọba Ekiti Fasiti Eko ti Cold Room"" ni Staff Club wọn pa látàri ìwádìí BBC lórí àwọn olùkọ́ kan UNILAG ní kí olùkọ́ míì, Samuel Oladipo to ń bèèrè ìbálòpọ̀ lọ́wọ́ akẹ́kọ̀ọ́ lọ fìdí mọ́lé Buhari ti fòfin de àwọn mínísítà láti rìnrìn àjò lọ sí ilẹ̀ òkèrè Ohene ti le ọdun mẹrinlelaadọrin ọdun bayii, ko to ṣẹṣẹ gbe igbesẹ lati sọ ohun to ṣẹlẹ sii ni ọgọta ọdun o le diẹ sẹyin."
Hagari bí ọmọkunrin kan fún Abramu, Abramu sì sọ ọmọ náà ní Iṣimaeli.
Ẹ̀yin àgbà, ẹ ṣe bí àgbà
 alákùnrẹ ́ tẹ ̀ síwójú láti dá ibùgbé tirẹ ̀ ní .
Mo n salaye fun gbogbo aye pe Funke Akindele ko fun mi ni ile gẹgẹ bi awọn eeyan kan se maa n sọ.
Loju opo Twitter ati Facebook ile ijọsin naa ni wọn fi atẹjade si eleyi ti Rev.
Wọn ba gbogbo aafin mi jẹ patapata, ta si ti ko wa si aafin tuntun bayii amọ alẹ ọjọ Aje tun ni wọn tun ya wa ba wa lẹẹkan si.
- Trump Cisse bẹ́ sí Kàǹga nítori fóònù N3,000 Ẹyin ni wọ́n fi n gba ìbále ẹlòmiran lára wa ki a to lọ pàde àwọn oníbara Ìjọba Canada kò gbó nípa ìgbéṣẹ̀ Harry àti Meghan láti wá sí ilẹ̀ wọn Ọpọ ọmọ orilẹede Naijiria papaajulọ awọn oṣere ere ori itage lo ti bi ọmọ si ilẹ Amẹrika eleyi to si ti sọ awọn naa ọmọ ilẹ Amẹrika.
Ìpínlẹ̀ Ogun náà ti ilé ìwé títí dí ọjọ́ Ajé tó m bọ̀, kò ní sí lílọ bíbọ̀ ọ̀kádà fún wákàtí 24 Laipẹ yii ni ipinle bii Eko, Ondo, Ekiti, Edo, Delta ati Plateau paṣẹ ki ofin konile o-gbele gberasọ nibẹ nitori jagidijangan to bẹẹsilẹ kaakiri, ti wọn si bẹrẹ si ni pa awọn eniyan pẹlu awọn dukia ti wọn bajẹ kaakiri ipinlẹ naa.
Òun yìí ni ó wà nípa omi ati ẹ̀jẹ̀, àní Jesu Kristi.
Bí ó ti gbójú sókè, ó rí kànga kan ninu pápá, ati agbo aguntan mẹta tí wọ́n dùbúlẹ̀ lẹ́gbẹ̀ẹ́ rẹ̀, nítorí pé láti inú kànga yìí ni wọ́n ti ń fún àwọn aguntan náà ní omi mu.
Oríṣun àwòrán, AFP Àkọlé àwòrán, Buhari kede June 12 lọjọ iṣejọba alagbada Bakan naa ni aarẹ Muhammed Buhari kede pe orukọ Basọrun Moshod Kashimaawoo Olawale Abiola ni a o maa fi pe papa iṣere Abuja lati isinyi lọ.
Koda, o le tun pa ọmọ, ẹbi, ara ati ẹnikẹni to ba fẹ kẹfin ipaniyan yii ki aṣiri rẹ ma baa tu lọjọ iwaju.
co/7HeJTukexI— Chelsea FC (@ChelseaFC) 19 April 2018Ewe,” ji jawe olubori ninu ifesewonse otooto meji lera yoo se iranwo n la fun wa lati kopa daradara ninu awon ifesewonse wa miran to n bo lona.
Wò ó, ète burúkú wà ní ọkàn yín.
Nítorí pé ọjọ́ kan péré ninu àgbàlá rẹ,ṣe anfaani ju ẹgbẹrun ọjọ́ níbòmíràn lọ.
Igba akọkọ kọ ree tawọn kiniun naa yoo sa kuro ni ahamọ wọn.
Nítorí mo rò pé Ọlọrun ti fi àwa òjíṣẹ́ hàn ní ìkẹyìn bí àwọn tí a dá lẹ́bi ikú, nítorí a ti di ẹni tí gbogbo ayé fi ń ṣe ìran wò: ati àwọn angẹli, ati àwọn eniyan.
Sibẹ, àwọn ará Juda kò pa òfin OLUWA Ọlọrun wọn mọ́, wọ́n tẹ̀lé ìwà tí àwọn ọmọ Israẹli ń hù.
 Àwọn fọ ́ nrán ìhun tí a lè ṣe bẹ ́ ẹ ̀ gbé sí iwájú ni : òlùwà , àbọ ̀ , kókó gbólóhùn , ẹ ̀ yán , àpólà-atọ ́ kùn .
Èmi àti Oladipupo Owomoyela jọ lọ ẹ̀wọ̀n Alágbọn- Caroline Owoh, aya Orlando Owoh Aàbò tó péye yóò wà fún àwọn tí yóò kópa nínú ìfẹsẹwọ̀nsẹ̀ Naijiria àti Sierra Leone ní Benin - Obaseki DPO ọlọ́pàá ju télọ̀ sátìmọ́lé, gbé e lọ sílé ẹjọ́ n'Ibadan torí ''ó ba aṣọ rẹ̀ jẹ́'' Inú mi máa ń bàjẹ́ ni tí mo bá ti rí SARS- Fasasi Tiamiyu Dokita Luque sọ pe Maradona si wa labẹ ayẹwo bi ara rẹ ti n ya bọ diẹdiẹ lẹyin to ṣiṣẹ abẹ tan.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Ajafẹtọ ọmọniyan ati onimọ ijinlẹ nipa ik Boko Haram, Bulama Bukarti sọ fun BBC pe awọn ọmọogun miran tilẹ wa ni ibẹ ti wọn fẹ fi oju ogun silẹ, amọ ti wọn ko tii gba fun wọn.
Nọmba mọkanla ni nọmba yii, ti o si wa lapa oke iwe pelebe yii.
Ààlà náà kọjá lọ sí apá ìhà àríwá òkè Betaraba; láti ibẹ̀ ó lọ sí Araba.
Ọ̀pọ̀ aráàlú Owo wà nílé ìwòsàn, síbẹ̀ APC àti PDP kò gba ẹ̀bi Makinde gba àwọn òṣìṣẹ́ LAUTECH 41 tí ìjọba Ajimobi dá dúró lẹ́nu iṣẹ́ padà Obabinrin Elizabeth kejì kí Nàìjíríà kú oríire òmìnira ọgọ́ta ọdún Gbajugbaja akoroyin ni Naijiria, Fisayo Soyombo ni ibanujẹ ni ọjọ oni nitori ọrẹ oun ti awọn ajinigbe jigbe ti pe ọjọ meji ni akamọ wọn.
School re-opening: Àwọn orílẹ-èdè tó ti ṣilẹkùn ilé ìwé padà
nítorí náà, ojú ara mi tì mí,fún ohun tí mo ti sọ,mo sì ronupiwada ninu erùpẹ̀ ati eérú.
Jẹ́ kí wọ́n wà lára àwọn tí yóo máa bá ọ jẹun pọ̀, nítorí pé òótọ́ inú ni wọ́n fi wá pàdé mi ní àkókò tí mò ń sá lọ fún Absalomu, arakunrin rẹ.
Nigba to n kede aseyọri rẹ tuntun naa, olori Badra kọ soju opo Instagram rẹ pe ọjọ ti pẹ ti oun ti n gbaa lero lati si ibudo asọ tita, ti inu oun si dun pe ala oun naa papa wa si imusẹ.
Oríṣun àwòrán, Facebook/Rotimi Akeredolu Ninu ọrọ tirẹ, Gomina ipinlẹ Eko, Babajide Sanwo-Olu ni ibi giga ni ipinlẹ Ondo n lọ, nitori naa ki wọn ma a gbadura fun un lati mu gbogbo ileri rẹ ṣẹ.
Àkọlé àwòrán, Ọpọlọpọ eeyan ni awọn ọlọpaa mu lasiko iwọde to waye lọjọ Aiku Bakan naa, ikunsinu ti n waye nitori bi wọn ko ṣe pe awọn oluwoye lati tọ pinpin idibo naa, ìdá bi ogoji ibo si ni wọn ti di saaju ọjọ idibo.
Obinrin náà bá lọ sọ fún ọkọ rẹ̀, ó ní, “Eniyan Ọlọrun kan tọ̀ mí wá, ìrísí rẹ̀ jọ ìrísí angẹli Ọlọrun.
Nítorí ìdààmú pupọ yóo wà ní ayé, ibinu Ọlọrun yóo wà lórí àwọn eniyan yìí.
Nítorí náà, nígbà tí wọ́n rí Jehoṣafati, wọ́n rò pé ọba Israẹli ni, wọ́n bá yíjú sí i láti bá a jà.
Ni ipari, ile-ise BSEMA ati ajo NEMA wa ro gbogbo awon to n gbe layika ojuna odo lati tete wa woroko fi sada lai fi oro ohun fale rara.
Ó da òjò dídì bo ilẹ̀ bí ẹ̀gbọ̀n òwú,ó sì fọ́n ìrì dídì ká bí eérú.
"Wọn ni ""isẹ wa lara ni."
Nígbà tí ó hù, ó bá gbẹ nítorí kò sí omi.
Ní ọjọ́ náà, OLUWA yóo na ọwọ́ rẹ̀ lẹẹkeji, yóo ra àwọn eniyan rẹ̀ yòókù pada ní oko ẹrú, láti Asiria, ati Ijipti, láti Patosi ati Etiopia, láti Elamu ati Ṣinari, láti Amati ati àwọn erékùṣù òkun.
Ó sọ fún wọn pé, “Ẹ jọ̀wọ́, ẹ gbọ́ àlá kan tí mo lá.
Iṣẹlẹ ẹnu ọjọ mẹta yi nipa ibaṣepọ laarin ẹka alaṣẹ ni Naijiria ati ka idajọ n tọka si pe ohun gbogbo ko lọ deede laarin awọn mejeeji.
Amọ nigba to n ba awọn akọroyin sọrọ, Pa Kasumu ni oun ko nilo owo lati ọdọ awọn ololufẹ oun bi ko ṣe adura nitori aisan to n da agọ ara oun laamu ti kọja ọrọ oogun oyinbo lilo.
CAN: Ó pọn dandan kí wọn fágile ìdánwò ọlọ́pàá
" Oríṣun àwòrán, other Babafemi ni kí òun to gba ọmọ òun sínú ilé, yóò kọ́kọ́ lo ọjọ́ mẹ́rìnlá na ni ibùdó iyasọtọ nítorí òun kò leè fi ẹbí òun sínú ewu àrùn Covid-19.
OLUWA ni Olùṣọ́-aguntan mi,n kò ní ṣe àìní ohunkohun.
“Tí ẹ bá kọ́ ilé titun, ẹ níláti ṣe ìgbátí sí òrùlé rẹ̀ yípo, kí ẹ má baà wá di ẹlẹ́bi bí ẹnikẹ́ni bá jábọ́ láti orí òrùlé yín, tí ó sì kú.
 Bakannaa ni ẹgbẹ CAN tun bu ẹnu atẹ lu bi awọn ọmọde ti ko tii to ibo o di se n forukọsilẹ lati dibo pẹlu ipe si ajọ eleto idibo orilẹede Naijiria, INEC lati tete wa wọrọkọ fi sada lori ọrọ naa eleyi ti wọn ni o n waye kaakiri bayii ti eto iforukọsilẹ awọn oludibo tuntun n lọ lọwọ."
Emir Kano Muhammedu Sanusi II tí fèsì sí ìwé ẹ̀sùn ti Gómìnà ìpínlẹ̀ Kano kọ síi ni ọjọ́ pé kó wá wi tẹ́nu rẹ̀ lóri bí ó ṣe na bílíọ̀nu mẹ́ta lé ọwọ́ mẹ́rin náírà owó igbìmọ ẹmireeetì.
"Mi ò mọ ohunkóhun nípa ""Aketi Whyski"" - Akeredolu ké gbàjarì Báyìí ni o ṣe lè fi orúkọ oògùn tàbí àgbo rẹ sílẹ̀ lábẹ́ àjọ NAFDAC Bàbá Aláàfin ìlú Ọ̀yọ́, Elérúwà àti àwọn Ọba Ilẹ̀ Yorùbá míràn tí wọ́n rọ̀ lóyè Ṣugbọn aṣiri tu nigba ti ọmọ ọhun figbe ta, ki awọn eeyan to lọ gba silẹ."
Àkọlé àwòrán, Gbogbo àwọn oba aláde ti kò lè yọjú síbi ayẹyẹ náà fi ọ̀pá àṣẹ wan ránṣẹ́ Àkọlé àwòrán, Awọn aláwọ̀ funfun náà wá láti ṣe ọdún Osun Osogbo Àkọlé àwòrán, Tarúgbó tomidan lo peju ni bi ayẹyẹ ti wọ́n sì ń reti iwúre àtàọjà Àkọlé àwòrán, Awọn àgbààgbà obinrin náà rèé oo, ninu aṣọ òfì àti leesi ẹgbẹ́jọdá Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
fasiti ti ijọba apapọ niluu Ilorin, ipinlẹ Kwara nibi to ti gboye ninu ẹkọ ede
Yinka Ayefele: Aláàánú kan fi kẹ̀kẹ́ tuntun ta akọrin Tungba lọ́rẹ
Ere yii saba maa n waye lalẹ labẹ osupa, ki awọn ọmọde to lọ sun, o n mu ki ifẹ gbilẹ laarin wọn, ifarakinra maa n wa, to si tun n da wọn laraya.
Àkọlé àwòrán, ìfọ̀rọ̀wérọ̀ BBC Yorùbá Adebayo Adelabu ti ẹgbẹ oṣelu APC ni wn bi pe bawo lo ṣe fẹ ṣee lai ni iriri kankan ri to fi fẹ bẹrẹ pẹlu jijẹ gomina.
Awọn ile isẹ naa lodi si asẹ ijoba pẹ ki wọn ma se afihan iburasipo olori alatako, Raila Odinga.
Wo ojú Akeem t'Ọlọ́pàá mú pé ó fipá bá ọ̀dọ́mọbìnrin kan sùn létí odò l'Oṣun Iléẹjọ́ tó ga jùlọ fòǹtẹ̀ lu Yahaya Bello gẹ́gẹ́ bí Gómìnà ìpínlẹ̀ Kogi Ìjọba Ghana ṣí iléeṣẹ́ àwọn ọmọ Nàìjíríà padà.
Àkọlé àwòrán, BBC Fake News Conference Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Ó to àwọn fìtílà rẹ̀ sórí rẹ̀ níwájú OLUWA gẹ́gẹ́ bí OLUWA ti pàṣẹ fún un.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Eletricity Tarriff: IKEDC ní sísan owó iná ọba tayọ èèyàn yókù kò lòdì sófin 26 Ògún 2019 Oríṣun àwòrán, Instagram/ikejaelectric Bi wọn ba ni ko san owo ina ọba to le si eyi to n san lati le gbadun ina ọba, bi elo lo lero pe o le san?
Ni ọjọ kẹkandinlogun oṣu kẹsan ni idibo sipo gomina yoo waye ni ipinlẹ Edo gẹgẹ bi ajọ eleto idibo, INEC ṣe ti laa kalẹ.
Ewe, ile-ise olopaa safihan awon afurasi mejeeji fun awon oniroyin lojo kokandinlogun osu keji odun yii, won si so pe, “Leyin gbogbo iwadii” lati fi otito oro ohun mule.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Beer Belly: Wo ohun tó yẹ ko mọ̀ nípa ikun rẹ tó ń to tobi 15 Èrèlè 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 17 Sẹ́rẹ́ 2021 Njẹ o jẹ eeyan to maa n mu ọti bia (Beer), abi o mọ ọti bia funra rẹ?
Gege bi oludari agba iko omo ogun naa to n mojuto oro ifitonileti ati igbodegba, ogagun Texas Chukwu se so, O ni ikolu naa waye leyin ti iko omo ogun olote ohun sekolu si iko omo ogun ni agbegbe Amdaga niluu Pulka, ti won si da ina sun oko akero kan, bee si ni won tun mu awon arinrin ajo sinu ahamo won lojo Isegun(Tuesday).
Aare  Muhammadu Buhari ti  ki Alaafin  ti ilu  Oyo, Oba Lamidi Adeyemi III, Iku Baba Yeye  fun ayeye  ojo ibi ọgọ́rin odun ti won pe.
Tennis Tournament, ti o waye lana ojoRu(Wednesday), niluu Barcelona, lorile-ede
"Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Gomina Ortom ti Benue fi APC sílẹ̀ lọ PDP Olùdíje ìbò abẹ́nú PDP, APC fárígá l‘Ọ́sun Àwọn ajínigbé tó pa fadá gba ìdájọ́ ikú ""Lẹyin ti mo ti rii pe o dabi ẹni pe awọn adari ẹgbẹ oṣelu yii ko fẹ mi mọ tabi pe wiwa ti mo wa lẹgbẹ yii n dooru mu wọn ni mo fi gbe igbesẹ yii."
Eyi jẹ lati fi kun iye awọn adajọ to wa ki wọn le pe mọkanlelogun gẹgẹ bi o ṣe wa ninu ofin.
” Tamari bá gbé àkàrà náà, ó sì tọ Amnoni lọ láti gbé e kalẹ̀ níwájú rẹ̀ ninu yàrá.
Bo ṣe mu ọgbọ́n yii jade kii ṣe bíi ti gbogbo oṣere Tiata bo tilẹ jẹ pe imọ ẹkọ yii lo kọ ni fasiti, Seun sọ pe iṣẹ ti oun n ṣe yii gba ọpọlọpọ ọgbọn ati akoko.
Jẹ́ kí wọ́n là á sí meji.
Amọ ṣa ti ọrọ ba kan awọn nnkan elo kan ninu ile, ọpọ lo ti fi nnkan to ju ọrun yin lọ.
Jakọbu bá gbé òkúta kan, ó fi sọlẹ̀ gẹ́gẹ́ bí ọ̀wọ̀n.
Ẹni tí ó jẹ́rìí èké nípa aládùúgbò rẹ̀dàbí kùmọ̀ ọmọ ogun, tabi idà, tabi ọfà tí ó mú.
Bẹ́ẹ̀ gan-an ni ó rí pẹlu gbogbo ẹni tí a bí ní bíbí ti Ẹ̀mí.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 2020: Oloye Awurela Ifaleke ti wúré ọdún ìgbéga fún kóówá Eyi lo jẹ ki oun pinnu lati di ọmọ ogun nitori aṣaaju ijóba labule wọn ni ko si nkan ti ẹnikéni le ṣe fun sọja naa nitori pe aye ajẹrọrun ni awọn ọmọ ogun n jẹ nigba naa.
 Orisirisi ipenija ni orile-ede Naijiria n
Nitori naa awọn adari ni Ilẹ Afrika gbọdọ ṣe ayẹwo awọn nkan wọnyii finifini, ki wọn fi opin si iwa ẹlẹyamẹya ati idẹyẹsi ni laarin awujọ wọn.
Wọ́n ń gbọ́ ohun tí ò ń wí, ṣugbọn wọn kò ní ṣe é; nítorí pé ẹnu lásán ni wọ́n fi ń sọ pé wọ́n ní ìfẹ́ pupọ, ṣugbọn níbi èrè tí wọn ó jẹ ni ọkàn wọn wà.
Nehemaya Borí Ìṣòro Tí ó Dojú Kọ Iṣẹ́ Rẹ̀.
Eto ilera alabọde ni Adelabu ni awọn yoo kọ si awọn igberiko.
ti ipinle naa, iyẹn Obo Effanga ati awon agbofinro , ti kọmisọna awon ọlọpaa, Usman
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: APC pàdánù aṣòfin míràn ní'pínlẹ̀ Osun 'Ààrẹ Buhari kò náání àwọn ọmọ Nàìjíríà tó fọkàn tán an' Ìjọba àpapọ̀ buwọ́lu $1.
 Ó di pè wọn ń yan ọba kan gẹ ́ gẹ ́ bí olórí gbogbo gbò .
Funke Akindele, oníròyìn, agbẹjọrò àti òṣèré; ohun tí ẹ kò lérò nípa rẹ̀ 'Èmi àti Toyin Abraham ṣẹ̀ sọ̀rọ̀ fún ìgbà àkọ́kọ́ láti ọdún méjì torí ìjà òun àti Lizzy' Jesu Oyingbo rèé, pásítọ̀ tó láṣẹ ìbálòpọ̀ lóri ọmọ ìjọ obìnrin D.
N óo fún wọn ní koríko tí ó dára jẹ, orí òkè Israẹli sì ni wọn óo ti máa jẹ koríko.
" Ẹ yé gba owó orí níbi ìdána ìyàwó mọ́, sísọmọbìnrin s'óko ẹrú ni- Daddy Freeze Tí mo bá kú lónìí, Pásítọ̀ Ibiyeomie ló pa mi - Daddy Freeze kébòòsí Kí la tún gbọ́ nípa ìdámẹ́wàá?
Gbogbo Alalaaji ló gbódò sọ òkúta yií lọjọ Kejì ti wọn ba gun Arafat ati ọjọ kẹta Arafat.
Alaafia wà láàrin àwọn ọmọ Israẹli ati àwọn ará Amori.
Ẹni kan lara awọn to n woye yoo maa pe orukọ cardinal kọọkan ti wọn dibo fun bi wọn ba ṣe n ka awọn iwe pelebe naa.
Oríṣun àwòrán, Omotosho/Paul Bi Oyebode ti ṣe n sọ tiẹ, bẹẹ naa ni arakunrin Omotosho Paul n darukọ Babafemi Ojudu ati awọn mii ninu atẹjade lati yọju sọ boya lootọ ni wọn ni awọn yọ Fayemi kuro lẹgbẹ.
Ko si pẹ ti orin naa jade lo ku.
 Ọkan lara awọn obi awọn ọmọ naa, Adamu Muhammed, sọ wipe ""Lotitọ ti wọn ba se iru nkan bai si yan inu rẹ ko ni dun, sugbọ gẹgẹ bi Musulumi, gbogbo nkan to ba sẹlẹ si mi, maa kan ti si Ọlọrun mi ni."
O óo di nǹkan ìdáná, lórí ilẹ̀ yín ni a óo pa yín sí, ẹ óo sì di ẹni ìgbàgbé, èmi OLUWA ni mo sọ bẹ́ẹ̀.
Ó ní kí àwọn ènìyàn gbìyànjú láti má súmọ́ ẹni tí ó bá ní oyún, tí ó bá sì ṣeé ṣe kí wọn pèsè yàrá ìgbọ̀nsẹ̀ tí ó yàtọ̀ fún aláboyún Bákan náà lọ fi kún pé ó ṣe pàtàkì kí a máa fí omi àti ọṣẹ fọ ọwọ ni gbogbo ìgbà.
Irú ọgbọ́n wo ni ọgbọ́n tirẹ̀ yìí, tí iṣẹ́ ìyanu ń ti ọwọ́ rẹ̀ ṣe?
"Mide Martins Oríṣun àwòrán, Mymidemartins Laarin ọsẹ yii kan naa ni Mide Funmi Martins tẹsiwaju ninu fiimu kan ti wọn ya lọwọ, ""Enu mi."
Odunlade Adekola, Femi Adebayo, Jenifa ṣi aṣọ lójú àwọn fíìmù tuntun tẹ́ẹ ti ń retí Ìdí ti mo fi da sọ́ọ̀sì rú lásìkò ìgbéyàwó ìyáwó mi tó ló fẹ́ ọkọ míran- Osadebe Niwaju gbogbo awọn olugbe BB Naijia si ni Neo, ẹni ti ifẹ Vee n pa bii ọti, ti kede pe o di dandan ki oun fun ọmọbinrin naa loyun, ki awọn to setan ninu ile naa.
Nígbà tí ó ti sọ báyìí tán, ó fi ọwọ́ rẹ̀ ati ẹ̀gbẹ́ rẹ̀ hàn wọ́n.
Iyawo Aarẹ Orilẹede Naijiria, Aisha Buhari ti ni ọkọ oun yoo lo saa keji yii lati mu gbogbo ileri to ṣe lasiko ipolongo idibo lorilẹede Naijiria wa si imuṣẹ.
Ofin to rọ mọ gbendeke fifi ẹjẹ silẹ lẹyin itọju aisan kan yatọ sira wọn lati orilẹ-ede kan si ikeji lagbaye.
Àkọlé àwòrán, Arabinrin Modupe Kolawole ni àwọn asọna to wa lẹ́nu iṣẹ́ lọ́jọ́ náà àti igbakeji oludari lo lọ sibl sùgbọ́n oludasilẹ o dasi ọ̀rọ̀ náà.
Ẹ óo tún fi òbúkọ mìíràn rú ẹbọ ìmúkúrò ẹ̀ṣẹ̀ fún ètùtù, ẹ óo sì rú ẹbọ sísun ati ẹbọ ohun jíjẹ ati ẹbọ ohun mímu ojoojumọ pẹlu.
Akọroyin ere bọọlu ọmọ orilẹede France kan, Gabriel Hanot lo kọkọ gbe ero nipa Ballon d'Or kalẹ lọdun 1956.
Ọkan lara iru eto bẹẹ ni ipade adura nla ti ijọ Irapada, RCCG to maa n waye ni ipagọ nla wọn to wa mi Kilomita 36, opopona Eko si Ibadan lorilẹede Naijiria.
Ni ọjọ naa, awọn afunrasi mẹta toku ni awọn ko jẹbi ọrọ ẹsun naa.
Adari ajọ ọhun, dokita Chikwe Ihekweazu lo fi ọrọ naa lede ninu awọn atẹjade kan loju opo Twitter rẹ nigba to n sọrọ lori bi arun naa ṣe n peleke si ni Naijiria lati nnkan bi oṣu kan sẹyin.
Ninu idajọ rẹ, adajọ to n gbọ ẹjọ naa ni ki Fayose san owo iduro aadọta miliọnu naira ki o si jọwọ iwe irinna rẹ soke okun si akoso ile ẹjọ naa.
Àwọn ọlọ́jà ń sèdárò Ìyálọ́jà ìpínlẹ̀ Oyo tó dolóògbé, wọ́n yan asojú míràn Yíyọ́ ẹkùn mi, tojo kọ́ o, ẹ jámí lórí ìwọ́de yín lẹ́yẹ́ ò ṣọkà, mo tí gbọ́ ohun tí ẹ ń sọ yékéyéké-Buhari Tani Oke Obi-Enadhuze: tí orúkọ rẹ̀ gba orí ayélujára kàn lẹ́yìn wàhálà #Lekki tollgate?
Ní ìgbà àtijọ́, oríṣìíríṣìí ọ̀nà ni Ọlọrun fi ń bá àwọn baba wa sọ̀rọ̀ láti ẹnu àwọn wolii rẹ̀.
Lagos-712 FCT-145 Plateau-117 Kwara-81 Kaduna-54 Sokoto-39 Oyo-38 Rivers-37 Gombe-21 Enugu-20 Akwa Ibom-16 Bauchi-14 Delta-14 Ebonyi-13 Anambra-9 Taraba-8 Edo-8 Kano-3 Osun-2 Ekiti-2 Ogun-1 Ènìyàn 576 míràn ló tún ṣẹ̀ṣẹ̀ lùgbàdì ààrùn Covid-19 ní Nàìjíria Ajọ to n gbogun ti ajakalẹ aarun lorilẹ-ede Naijiria, NCDC ti kede pe eeyan 576 miran ti kun iye awọn to ti ni aarun COVID-19 ni Naijiria.
A ò ní gbà kẹ́ẹ buwọ́lu ofin tí yó máa dí wa lẹ́nu lórí ayélujára Nínú àbá ìṣúná 2020, ìjọba Ọyọ fẹ́ gba 500 òṣìṣẹ́ ìlera pẹ̀lú ọ̀pọ̀ olùkọ́ O ni lootọ ni pe, ọwọngogo ounjẹ ti mu ki owo ọja gbe owo lori kaakiri orilẹede Naijiria.
Aare soro yii lasiko to n ba awon
Owo to ti jẹ ti le ni miliọnu marun-un Naira, N5,031,000.
Ọgbẹni Mumuni wa rọ awọn ọmọ Naijiria lati ke gbajari si ijọba pe ko ṣe atunṣe si ofin to jẹ mọ bi idibo ṣe n waye, ko ma ba di pe olowo nikan ni yoo ma kopa ninu eto oṣẹlu.
Nítorí pé nígbà tí mo pè wọ́n, ẹnikẹ́ni wọn kò dáhùn;nígbà tí mo sọ̀rọ̀ fún wọn, wọn kò gbọ́,wọ́n ṣe ohun tí ó burú lójú mi,wọ́n yan ohun tí inú mi kò dùn sí.
Wọn ni orúkọ oye tuntun yii jẹ nkan ti awọn ko gbọ ri ninu itan ilu Iwo.
Coronavirus and OCD: 'Mo fi ogún ọdún gbáradì fún àjàkálẹ̀ ààrùn yìí' Coronavirus: Kíni àwọn àmì tuntun tó n fihàn?
Ṣugbọn Lọti wí fún wọn pé, “Áà!
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Àwọn olùgbọ́ BBC Yoruba fi èrò han lẹ́yìn #BBCGovDebate Eko Amọ, ẹgbẹ oselu PDP ni anfaani lati lọ si ile ẹjọ kotẹmilọrun ti wọn ko ba faramọ idajọ naa.
Ni ọdọọdun, ajọ to n ja fun aabo awọn akọroyin ni agbaye maa n ya aworan awọn akọroyin to wa ni ahamọ ni ipari ọdọọdun.
Àwọn ọmọ Lefi ní ìdílé-ìdílé nìwọ̀nyí: ìdílé Geriṣoni, ìdílé Kohati ati ìdílé Merari, 
Jesu bá dúró, ó pè wọ́n, ó ní, “Kí ni ẹ fẹ́ kí n ṣe fun yín?
Igbimo torokan gbangban, FEC ti bowolu sise agbekale ile-iwe giga fafiti awon omo ogun (Nigerian Army University)  nilu Biu ti o kogun si ariwa ipinle Borno, Naijiria.
Igba wo ni Bola Tinubu, to ko awọn eniyan lọ iwaju Buhari di aṣoju Afẹnifẹre?
Olówó-ayé, ọmọlúwàbí ni ọ́, bí ó sì ti wù tí ọ̀ràn náà burú tó mo fẹ́ kí o ṣe gẹ́gẹ́ bí ìlérí rẹ.
Fidio ibi to ti daku re e: Lẹyin naa ni wọn gbe e digba-digba jade kuro ninu yaara ti wọn ti n fi ọrọ wa a l'ẹnu wo.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Osun elections: APC pè fún àdúrà lórí ìdájọ́ kóòtù àgbà tó ń bọ̀ lórí gómìnà l'Ọ́ṣun 2 Agẹmo 2019 Oríṣun àwòrán, @OSUN_APC Àkọlé àwòrán, Ọjọ́ Ẹtì ni ilé ẹjọ́ tó ga jùlọ lórílẹ̀-èdè Nàìjíríà yóò kéde gómìnà tòótọ́ fún ìpínlẹ̀ Ọ̀ṣun Ọjọ Ẹti ọsẹ yii ni ile ẹjọ to ga julọ lorilẹ-ede Naijiria yoo gbe idajọ kalẹ lori ẹni gan an ni pato ti awọn eeyan ipinlẹ Ọṣun dibo yan an gẹgẹ bii gomina wọn.
Lady Gaga ṣubú yakata níbi tó tí ń kọrin BBC 100 Women 2019: ọ̀pọ̀ obìnrin ilẹ̀ Afirika ń gbàràdá!
Láti ìgbà tí mo ti kúrò lọ́hùn-ún kò sí ọjọ́ kan tí n kò rántí rrẹ, àárò rẹ sọ mi púpọ̀, ìgbà púpọ̀ ni mo sì ń lá àlá rí ọ.
Kíni ẹ mọ̀ nípa Ọmọ́táyọ̀ Olútóyè, Ọ̀jọ̀gbọ́n obìnrin àkọ́kọ́ nínú ẹkọ́ èdè Yorùbá lágbàyé A kò tí ì gbọ́ ǹkankan lórí owó ìwé ìrìnnà sí Naijiria - U.
Àadọrun biliọnu Naira ni ijọba yoo na lori abẹrẹ ajẹsara fun awọn ọmọ ikoko lalai fi owo ti awọn oṣiṣẹ ilera ti yopo fun wọn labẹrẹ ati oogun naa yoo gba tabi owo ọkọ ti wọn yoo fi gbe wọn lọsi awọn ileeṣẹ ilera.
Yoruba Culture: Kò sí nínú àṣà Yorùbá kí wọ́n tú ọfọ fèèyàn lórí fóònù-Gbenga Adeoye
Sẹ́ Ògì pẹ̀lú asẹ́ aláṣọ tàbi asẹ́ igbàlódé
Ninu lẹta kan ti ọga agba ọlọpaa naa kọ si Saraki lo ti ni ko yọju lọjọ isẹgun ni deede aago mẹjọ aarọ, ko lee wa tanna si ibasepọ rẹ pẹlu awọn afurasi adigunjale marun-un to wa ni ahamọ.
Ọkọ mẹ́sàn-án tó forí-gbárí lórí afárá Otedola mú ẹ̀mí méjì lọ Bobrisky dárò pé EFCC gbé Mompha, ọ̀dọ́mọdé olówó tó ń lo aago ₦20m Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ẹgbẹ agbábọ́ọ̀lù Chelsea ya àgbàdo hà sí ikọ́ Ajax lẹnu lẹ́yìn tí wọ́n lù wọ́n mòlé Eyi mu ki akọnimọgba ikọ Ajax Erik ten Hag, parọ awọn ọmọ rẹ meji ni wara wara, ṣugbọn ẹpa ko boro mọ.
Fun awọn kan, iwa ipá ninu igbeyawo ni nkan ti wọn ro pe o buru ju.
Láti ìgbà náà, Kiriati Jearimu ni wọ́n gbé àpótí OLUWA sí fún nǹkan bíi ogún ọdún, gbogbo àwọn ọmọ Israẹli sì ń ké pe OLUWA fún ìrànlọ́wọ́.
Adari egbe oselu to n se ijọba
Nítorí pé, bí ẹ bá yipada, tí ẹ sì darapọ̀ mọ́ àwọn orílẹ̀ èdè tí wọ́n ṣẹ́kù láàrin yín, tí ẹ̀ ń fẹ́ ọmọ lọ́wọ́ wọn, tí àwọn náà sì ń fẹ́ ọmọ lọ́wọ́ yín, 
“Nígbà tí gbogbo àwọn ibukun tabi ègún tí mo gbé kalẹ̀ níwájú yín lónìí bá ṣẹ mọ́ yín lára, tí ẹ bá dé ààrin àwọn orílẹ̀-èdè tí OLUWA yóo fọn yín ká sí, tí ẹ bá ranti anfaani tí ẹ ti sọnù, 
Kò ní sí ayẹyẹ ọdún Ojúde Oba lọ́dún yìí- Awujale ilẹ̀ Ijebu Wo ìgbẹ́sẹ̀ méjọ tí ilé aṣòfin ìpínlẹ̀ gbọdọ̀ tẹ̀lé láti yọ igbákejì gómìnà Kòṣẹlẹ̀rí ni Hajj ọdún 2020, wo ìyàtọ̀ tó wà nínú rẹ̀ sí ti tẹ́lẹ̀ Àkójọ́pọ̀ àwòrán rèé lórí bí ìwọlé akẹ́kọ̀ọ́ ṣe lọ sí ní Oyo Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Kemi Dairo: Iṣẹ́ abẹ nínú ọpọlọ àti ẹ̀rọ ni mo fi ń gbọ́ ọ̀rọ̀ báyìí Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
APC: A kò ní takò ìdájọ ilé ẹjọ lórí àṣẹ lọ rọọ́kún nílé Oshiomole
Kí ẹ dá baba mi ati ìyá mi sí, ati àwọn arakunrin mi, ati àwọn arabinrin mi, ati gbogbo àwọn eniyan wọn; ẹ má jẹ́ kí á kú.
Ẹ kò fetí sílẹ̀ bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò gbọ́, bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé nígbà gbogbo ni OLUWA ń rán àwọn wolii, iranṣẹ rẹ̀, si yín, tí wọn ń sọ fun yín pé 
Awọn mọlẹbi awọn to wa ninu ọkọ ofurufu naa ti n paraaye ibi ti ijọba ṣi silẹ fun iwaadi.
Aare orile ede Naijiria Muhammadu Buhari ti bowolu yiyan  awon adajo tuntun mọ́kàndínlọ́gbọ̀n fun ile-ejo kotemilorun,ile-ejo ijoba apapo to ga julo, ati ile-ejo ijoba to wa niluu AbujaAwon adajo méjìlá   ti won yanfun ile-ejo kotemilorun naa ni:Aare tun fowosi yiyan awon adajo tuntun mẹ́sán án    fun ile-ejo to ga julo ti ijoba apapo.
Minisita ranṣẹ ibanikẹdun si ẹbi agbabọọlu Martins to di oloogbe.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Kaduna kidnap: Akẹ́kọ̀ọ́ mẹ́fà mórí bọ́ lọ́wọ́ àwọn ajínigbé 11 Ọ̀wàrà 2019 Oríṣun àwòrán, Nigerian Army Àkọlé àwòrán, Kaduna kidnap: Akẹ́kọ̀ọ́ mẹ́fà mórí bọ́ lọ́wọ́ àwọn ajínigbé Ọpẹ o!
Agbẹnusọ fun ile iṣẹ aarẹ ni ọrọ eto aabo, okowo, imọ ijinlẹ ati ipese gaasi afẹfẹ idana lo gbe Buhari lọ si Russia.
Ẹni tí ó bá ń ṣe ìfẹ́ Ọlọrun kò ní bọ́ sọ́wọ́ rẹ̀, ṣugbọn ẹlẹ́ṣẹ̀ yóo kó sinu tàkúté rẹ̀.
kí wọn má dàbí àwọn baba ńlá wọn,ìran àwọn olóríkunkun ati ọlọ̀tẹ̀,àwọn tí ọkàn wọn kò dúró ṣinṣin,tí ẹ̀mí wọn kò sì dúró gbọningbọnin ti Olodumare.
Nígbà tí àwọn Farisi rí i, wọ́n wí fún un pé, “Wò ó!
Bayii ni ẹgbẹ agbabọọlu Arsenal ṣe ya ọpọ ololufẹ ere bọọlu lẹnu lẹyin ti wọn fiya jẹ Liverpool mọle.
nítorí pé ó pẹ̀gàn ọ̀rọ̀ OLUWA, kò sì pa òfin rẹ̀ mọ́, a óo yọ ọ́ kúrò patapata, ẹ̀bi ẹ̀ṣẹ̀ rẹ̀ yóo sì wà lórí rẹ̀.
Láti ìgbà náà ni ẹ̀rù sì ti ń ba àwọn ará Siria láti ran àwọn ará Amoni lọ́wọ́.
Fi ojúlówó wúrà bo òkè, ati gbogbo ẹ̀gbẹ́ rẹ̀ yíká, ati ìwo rẹ̀ pẹlu.
Ninu àwọn ọmọ Bigifai, Utai ati Sakuri ni olórí,orúkọ aadọrin eniyan ni wọ́n kọ sílẹ̀ pẹlu wọn.
    Ìgbà tí mo rí yín ní ìjọ́sí, àánú yín ṣe mi irú ipò tí ẹ wà, òun ni mo ssì fi ṣe aájò yín, àti pàápàá kìí pẹ́ ki n tó mọ̀ bí ìwà ènìyàn bá ti rí, rírí tí mo ti ri yín ni mo ti mọ̀ pé ènìyàn dáadáa ni yín.
Ni kete to gbe ọrọ rẹ yii jade ni awsn ọmọ Naijiria kan ti fọn sori ayelujara lati fi ero wọn han lori ọrọ naa.
" Atiku Abubakar, igbakeji aarẹ orilẹede Naijiria nigbakanri.
Ẹgbẹ naa lo fi idaniloju han pe, awọn lo se eyi to poju ninu ikolu si awọn eroja ipese epo robi ni orilẹede Naijiria lọdun 2016, eyi to se okunfa adinku to ba ipese epo robi nilẹ Naijiria, pẹlu afikun pe, o le ni milionu kan si meji agba epo rọbi tilẹ wa padanu.
Lo ba di ookan soodo nigba ti idije wọ iṣẹju mẹrinla.
Nítorí náà ni Ọlọrun ṣe gbé e ga ju ẹnikẹ́ni lọ; ó sì fún un ní orúkọ tí ó ga ju gbogbo orúkọ yòókù lọ, 
 o jẹ ́ arẹwà okùnrin ti ènìyàn púpọ ̀ fẹ ́ ràn rẹ ̀ pàápàá àwọn babaláwo tó ń wá sí ààfin .
Ó bá lọ sí ọ̀dọ̀ àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀, ó bá wọn tí wọn ń sùn.
Àkọlé àwòrán, Inec wa n rọ awọn araalu lati kẹyin si ayederu esi ibo to gba oju opo ayelujara kan.
Akọwe feto iroyin fun Sẹnetọ Ladoja, Lanre Latinwo sọ lọjọru pe Rashidi Ladoja lọ sile Tinubu lati ba kẹdun lori ọpọ dukia to padanu lasiko rogbodiyan EndSARS nilu Eko ni.
Buhari o, pèsè ohun tó yẹ sí ọgbà ẹ̀wọ̀n, kí àyípadà orúkọ wọn léè pegedé El-Zakzaky fẹ́ jayé ọlọ́ba ní India, kò sígbà tí kò ní padà wálé - Ìjọba àpapọ̀ Ariwo Allahu Akbar"" kò tọ́ sawọn Agbébọn àti Boko Haram - Buhari Àjẹ́ àti Aṣẹ́wó ní ìyá Rainbow - Òjòpagogo Òṣèré tíátà Toyin Abraham daya Kolawole Ajeyemi Amofin Adeniyi John Farinto ni kọmiṣọna fun ileeṣẹ Eto Iṣuna ati aato Ọgbẹni Adeniyi Adebisi ni kọmiṣọna fun ileeṣẹ to wa feto okoowo Ọgbẹni Muyiwa Jacob Ojekunle di kọmiṣọna fun eto ọgbin Ọjọgbọn Oyelowo Oyewo lo jẹ Kọmiṣọna fun eto idajọ Amofin Olasunkanmi Olaleye ni kọmiṣọna fun ileeṣẹ idasilẹ Agbẹjọro Seun Asamu ni kọmiṣọna tuntun fun ileeṣẹ ohun amusagbara Ọgbẹni Rahman Abiodun AbdulRaheem ni kọmiṣọna fun ọrọ ilẹ Oloye Bayo Lawal ni Kọmiṣọna fun fawọn akanse isẹ Asofin Funmilayo Orisadeyi lo jẹ kọmiṣọna fun ọrọ ijọba ibilẹ ati oye jijẹ Dokita Bashir Bello lo jẹ kọmiṣọna fun eto ilera."
Ìpínlẹ̀ Èkó ṣe Àjọyọ̀ Ìdásílẹ̀ Àádọ́ta Ọdún
A gba àwọn ìlú ńláńlá rẹ̀ nígbà náà, a sì run wọ́n, ati ọkunrin, ati obinrin, ati àwọn ọmọ wọn.
Kó àwọn nǹkan tí wọ́n fi ń dóti ìlú tì í.
Vedio Producer: Ajoke Ulohtse Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí kan sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
Dambazau  wa ro awon osise  lati tubọ maa satileyin fun ijoba orile ede
Coronavirus: Oluwo ké sáwọn ọmọ Nàìjíríà láti mú ètò ìmọ́tótó lọ́kúnkúndùn lásìkò coronavirus yìí Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Coronavirus: Oluwo ní kò sí ẹ̀bùn òkè òkun tó lée mú òun gbàlejò láàfin Pẹlu bi ọwọja arun Coronavirus ṣe n gbilẹ kaakiri agbaye bayii, Oluwo ti ilẹ Iwo, Ọba Abdulrasheed Akanbi Telu I ti ke sawọn ọmọ Naijiria lati rii pe wọn tẹle gbogbo ilana to yẹ lati daabo bo ara wọn lọwọ itankalẹ arun naa.
69 Àti pé àwọn ọmọ ìjọ yíò fihàn ní iwájú ìjọ, àti bákannáà níwájú àwọn alàgbà, nípa ìrìn bí Ọlọ́run àti ìsọ̀rọ̀, pé wọ́n yẹ fún un, pé kí àwọn iṣẹ́ àti ìgbàgbọ́ lè wà ní ìbámu sí àwọn ìwé mímọ́—rírìn ní mímọ́ níwájú Olúwa.
kí ẹ má jẹ ẹran tí a fi rúbọ sí oriṣa; kí ẹ má jẹ ẹ̀jẹ̀; kí ẹ má jẹ ẹran tí a lọ́ lọ́rùn pa; kí ẹ má ṣe àgbèrè.
Iléẹjọ́ tó ga jùlọ fòǹtẹ̀ lu Yahaya Bello gẹ́gẹ́ bí Gómìnà ìpínlẹ̀ Kogi Ìjọba Ghana ṣí iléeṣẹ́ àwọn ọmọ Nàìjíríà padà.
Oríṣun àwòrán, Instagram/currentalhaja ''Kabiesi, lai si iranwọ yin ati ifẹ ti ko lẹgbẹ ti ẹ fihan si mi, ko ba ti si ẹni to n jẹ emi,'' Olori Abbey lo sọ bẹẹ.
Àkọlé àwòrán, Fadeyi Oloro Aliasi Sukee wa nibẹ Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ọ̀rọ̀ LAUTECH gba àpérò f'áwọn Olúdíje Ọṣun Aago méjìlá ọjọ́ Ẹti ni ìséde yóò bẹ̀rẹ̀ ṣáájú ìdìbò náà Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Osun Decides: Adegoke ni òun kò ni lo kọngilá n Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'A máa ń bẹ́ orí ẹni tó bá gbé imọlẹ̀ ọdún ìjẹṣu tó bá ṣubú ni' Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Ọpọlọpọ ọmọ Naijria lo si bu ẹnu atẹ lu igbesẹ naa, pẹlu alaye pe ilu ti ẹni to ni Covid-19 ba n gbe naa ni ki wọn o ti ma a tọju wọn.
O ma n wuwa ipa, o si ma n tobi, awọn ọlọpaa ma n lọ wọn fun isẹ wọn.
Ohun mẹ́wàá pàtàkì nípa Maradona àti ìbáṣepọ̀ rẹ̀ pẹ̀lú ẹlẹ́sẹ̀ ayò Diego Costa rèé Àwòrán rèé nípa bí 'Hand of God' ṣé dí inagijẹ Diego Maradona Taa ni Ọọni àná tí Ọba Ogunwusi forúkọ ọmọ rẹ̀ sọ?
Orile-ede Czech Republic ti satileyin orisirisi ohun elo ija fun iko omo Naijiria lati koju idojuko to n koju eto aabo lorile-ede yii, papaajulo iko omo ogun olote boko haram ti won n sekolu si ariwa gusu ila oorun orile-ede yii.
O tun parọ fun Hayatou pe baba oun ṣetan lati yan an si ipo adari ni ẹka ileeṣẹ naa to wa ni ilu Eko ni Naijiria.
Èèyàn 562 tuntun ló tún ti lùgbàdì COVID-19 ní Nàìjíríà ní àná Mo ti bẹ̀rẹ̀ sí ń bá àwọn tí a jọ díje nínú ìdìbó abẹ́lé sọ̀rọ̀ kí àláàfíà léè jọba - Akeredolu Kanye West ti bẹ̀rẹ̀ ìpolongo àti díje dupò aàrẹ ilẹ̀ Amẹrika Wo àwọn nkan tó yẹ́ kí o mọ̀ nípa 'Awawa Boys', ọ̀kan lára ẹgbẹ́ òkùnkùn tó n dá Eko rú Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí kan sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
Mose sọ fún wọn pé, “Ohun tí OLUWA paláṣẹ fun yín láti ṣe nìyí, ògo OLUWA yóo hàn sí yín.
Magawa kò tóbi jù o si fúyẹ daadaa, eyi ló fún ni ànfani lati le rin lórí imọ-ilẹ láì jẹ́ ki o bú gbàmù.
Awọn agbẹjọro ti ji de ile ẹjọ bẹẹ si ni ile ẹjọ ti kun fọfọ.
Lara alaye ti Iya Oṣogbo ṣe lori eto naa tun ni ere sinima ti akọle rẹ jẹ Eran Iya Oṣogbo, eyi to fi gba orukọ.
Adajọ Olusegun Odusola to n gbọ ẹjọ ẹsun ijọmọgbe ti wọn fi kan wolii ijọ Sotitobire naa, lo woye bẹẹ lasiko igbẹjọ to waye lọjọ Isẹgun.
Eleyi lo fun un ni igboya lati lọ si ilu naa, irin-ajo yii si gba a ni ọdun mẹjọ gbako ki o to de bẹ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Alaafin: Olori Aanu Adeyemi ṣàlàyé ìdí tó ṣe gẹ́ Oba Lamidi Adeyemi ti ìlú Oyo Ìdí rèé tí igbákejì Gómìnà Ondo Agboola Ajayi tún ṣe fi ẹgbẹ́ òṣèlú PDP sílẹ̀ Ti iwaju ko ba ṣe lọ, ẹyi a ṣe e pada si.
Bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé eniyan inú rẹ̀ pọ̀, àwọn díẹ̀ ni yóo ṣẹ́kù, àárẹ̀ yóo sì ti mú wọn.
Èèyàn 125 ní àrùn Coronavirus tún ṣẹ̀ṣẹ̀ ràn ní Nàìjíríà ní Ọjọ́bọ̀ Oluwo kọ̀ láti sọ̀rọ̀ lórí àwọn afọbajẹ tó fẹ́ yọ ọ́ nípò, aráàlú fọ́n síta láti fẹ̀hónú hàn APC Ekiti pàṣẹ lọ rọ́ọ́kún nílẹ̀ fún àna Tinubu àti Babafemi Ojudu Ọ̀wọ́ngógó oúnjẹ, epò, iná ọ̀ba ti sọ owó oṣù N30,000 da N9 nitórí náà kò ní sí ọjà, epo, iléèwòsàn láti Ọjọ́ Ajé - NLC Ẹgbẹ awọn oṣiṣẹ lorilẹede Naijiria,NLC ti kede wi pe awọn yoo bẹrẹ iyanṣẹlodi ati ifẹhọnuhan kaakiri orilẹede Naijiria bẹrẹ lati Ọjọ Ajẹ, ọsẹ to n bọ.
Baba Adeboye fi eyi lede lori ẹrọ ikansiraẹni Facebook rẹ̀, lẹyin ti Iwe Iroyin kan sọ wi pe Alaga ẹgbẹ oselu APC, Bola Tinubu sọ fun Baba Adeboye wi pe ko si ohun ti oun le sẹ si saa ẹlẹẹkeji Gomina Akinwunmi Ambode ti ilu Eko.
Ọmọ Nàìjíríà, àfikún owó iná tuntun bẹ̀rẹ̀ lónìí: ọjọ́ kínní, oṣù kẹsàn án, ọdún 2020- NERC, Disco Lọjọ kejidinlọgbọn, oṣu kẹjọ ni ajọ NERC ti atẹjade kan sita pe awọn onibara ileeṣẹ mọna-mọna yoo bẹrẹ si i maa san owo to ju ohun ti wọn n san tẹlẹ lọ.
3 Kí ló ma n fa Àkúfà nílẹ̀ Yorùbá, àti ọ̀nà àbáyọ?
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Akomolede ati Aṣa: Mọ̀ síi nípa ìró afárànma àti agbárànmọ́ fáwẹ́ẹ̀lì Yorùbá Ṣaaju ni eto ọrọ aje Indonesia ti dẹnu kọlẹ nitori ajakalẹ arun Covid-19 to n ba gbogbo agbeye finra.
O fi kun pe awọn ileeṣẹ naa ati ijọba ni lati jokoo fun ijiroro lori ọna abayọ, bi bẹẹ kọ, o ṣeeṣe ki awọn ileeṣẹ ọhun fi ipinlẹ Eko silẹ lọ awọn ipinlẹ miran, tabi ki wọn tilẹ orilẹ-ede Naijiria sile gan paapaa.
Opolopo ninu awon agbaboolu ohun ni o gboriyin fun adele akonimoogba iko Man U, Ole Gunnar Solskjaer fun ise takun-takun ati ipa re lati igba ti o ti ropo akonimoogba iko naa tele, Jose Mourinho.
O wa pasẹ pe ki wọn ri wi pe wọn pese ẹda eto isuna naa fun ile asofin ni kia kia.
Bó ṣe ni anfaani tiẹ̀, sì lo ní àléébù pẹ̀lú.
Ìdíje yii wà fún àwọn akẹ́kọ̀ọ́ ti wọn ti pé tàbí ju ọmọ ọdún mejidinlogun lọ.
"Fidio naa ṣafihan wọn ti wọn jẹ, ti wọn mu, koda, Freeze sọ ninu fidio naa pe ki ""awọn ọdọ to n sọrọ Hushpuppi laida lori ayelujara o bẹ Hushpuppi lati gba baba wọn siṣẹ awakọ rẹ."
Àyà mi ń lù pì pì pì, ó rẹ̀ mí láti inú wá;ojú mi sì ti di bàìbàì.
Bakanaa ni agbarijọpọ ẹgbẹ ọdọ nilẹ Yoruba ti sọrọ kobakungbe si Ọba Adewale Akanbi lorii bo se tẹwọgba oye Emir, to si pa oye Oluwo ti.
Akọwe agba Amẹrika Mike Pompeo ni ''bi orileede kankan ba gba 5G to si fi si ẹrọ alatagba wọn,a ko ni ba wọn aṣepọ mọ.
Nigba to ya ni Elesho pada de ọdọ oloogbe Adeyemi Afolayan, ti ọpọ mọ si Ade Love.
Ẹ bámi dé agbègbè àyíká Lọndọn Bridge – ìgbádùn ń bẹ níbẹ̀.
Abdullahi Shehu, Wilfred Ndidi, Chidozie Awaziem, Moses Simon ati Jamilu
Wọ́n pinnu láti kó lọ sí ilẹ̀ Ijipti nítorí ẹ̀rù àwọn ará Kalidea ń bà wọ́n; 
Mò ń lọ dán an wò, dákun, yọ̀ǹda mi.
Buruji kú lẹ́ni ọdún méjìlélọ́gọta Ní kété ti òkìkí ikú Kasamu kan, ọ̀pọ̀ àwọn ọmọ Naijiria lo ti n ṣelédè lẹ́yin rẹ̀.
Oríṣun àwòrán, Twitter screenshot Mílíọ́nù mẹ́wàá Náírà ni ilé ẹjọ́ ni kí Kábíyèsí san gẹ́gẹ́ bí owó ìtaran ilẹ̀ tí ó gbà lọ́nà àìtọ́ Wo ọ̀nà tí ọrọ̀ ajé Naijiria tó dẹnu kọlẹ̀ gba kàn ọ Ẹran ara ọlọ́pàá di èkìrí ẹran súyà, wo àwọn tó jẹ́ níbẹ́.
Nibi igbẹjọ naa ni ajọ DSS ti se afihan awọn fidio gẹgẹ bii ẹri to n se afihan pe Sowore lọ se ipade pẹlu olori ikọ Biafra tijọba ti fofin de, Nnamdi Kanu, ati eyi to fi n parọwa si awọn ọmọ ẹgbẹ Shiite lati dara pọ mọ ikọ Revolution Now, ki wọn le doju ijọba ilẹ wa bolẹ.
"Drone àti CCTV ni yóò máa ṣọ́ ọ̀pọ̀ igbó tó wà nílẹ̀ Yorùbá - Ooni Òwò ẹrú pé irinwó ọdún tó bẹ̀rẹ̀, àwọn Amẹrika tó jẹ́ dúdú wá sí Afirika láti bẹ ilé wò A kò ní ṣe ìwọ́de mọ́ torí a ti gbé ìjọba lọ sílé ẹjọ́ - Shiite kéde fáráyé Ìjọba Buhari ń lo agbára láti jà ìjà ẹsìn- Jiti Ogunye ""Awọn eeyan maa n san idamẹwaa to wuwo gan fun mi, iyẹn lemi naa ṣe n ribi ṣ'oore""."
Tantra: Ìlànà yìí ló ń kọ́ wa láti fi èémí àti ìṣẹ́po ara gbádùn ìbálòpọ̀
Ignatius Longjan, sẹnẹtọ ẹkun guusu Plateau Sẹnẹtọ to n ṣoju ẹkun guusu ipinlẹ Plateau, Ignatius Longjan jade laye lalẹ ọjọ Aje, ọjọ kẹsan an oṣu keji, ọdun 2020.
Wọ́n ti rí òkú Alága ẹgbẹ́ APC ní Nasarawa tí àwọn agbébọn jí gbé lọ́jọ́ Satide Oríṣun àwòrán, Getty Images Ogbeni Ahmad ni FIFA kede fifi ofin ọlọdun marun un de yii ni wọn tun ni ko san owo itanran $200, 000 to jẹ ẹgbẹrun lọna igba owo dọla ilẹ okeere.
"Ẹsun ni ẹsun n jẹ niwọn igba ti ile ẹjọ ko ba tii fi aridaju han.
Irinke-rindo ikọ BBC làwọn ojú pópó n'ilu Eko lónìí ọjọ́ Ajé, ṣàkíyèsí pé, ní agbègbè Ojodu-Berger, ṣe ni àwọn aráàlú ń du ọkọ wọ, tí wọ́n ko si bọ̀wọ̀ fún òfin ìtakété síra ẹni, bẹ́ẹ̀ ni àwọn ọlọkọ èrò ń gbé èrò kún inú mọto wọn dẹnu.
Bakan naa o fidi ọrọ naa mulẹ fun BBC Yoruba latẹnu agbẹnusọ rẹ, Yusuf Olaniyi pe oun ti fiṣẹ silẹ fawọn to ṣẹṣẹ n dide ninu oṣelu.
Ṣugbọn awuyewuye po lori owo naa paapa julo lori iye ti awọn agbẹjoro fẹ gba gẹgẹ bi owo ise fun pe wọn se atọna dida owo naa pada.
 ní ọdún 2010 , àìsàn hepataitisi a tó kanpá yọrí sí ikú àwọn 102,000 ènìyàn .
Ninu ọrọ rẹ agbẹnujsọ ọgba ẹwọn ipinlẹ Ondo Amofin Babatunde Ogundare, salaye pé ilé iṣẹ́ ọgba ẹwọn gan lo rọ ìjọba ipnilẹ Ondo láti lọ se ayẹwo fun awọn ọdaran naa ni ilana pẹlu ofin ti ajọ naa gbekalẹ láti igba ti aarun Covid-19 ti bẹrẹ Babatunde ni bi wọn ṣe de ki esi ayẹwo to jade ni wọn ti wa ni aaye ọtọti (isolation Cell) wọn o si darapọ mọ awọn to ti wa lọgba ẹwọn tẹlẹ.
 apohùn ìṣẹ ̀ nbáyé àti àwọn abínà-ìmọ ̀ .
Oríṣun àwòrán, Samir Hussein Awọn iwe iroyin kan sọ pe o ṣeeṣe ki Ọmọ ọba Harry ati aya rẹ maa bimọ sibẹ nitori ailefarapamọ nile iwosan ọhun.
Lati ka si nipa iṣẹ iwadi yii , lọ si opo ayelujara yii www.
Ṣaaju, awọn ọmọ ijọ rẹ ti ba BBC Yoruba sọrọ pe: Ẹ̀tanú pé Olùṣọ́ Genesis kò fẹ́ Laide Williams-Oni ló ṣe rán an lọ́ sí ẹ̀wọ̀n ọdún kan - CCC Genesis Global Ìpànìyàn orí ayélujára lásán lẹ̀ ń pariwo, ìbọn òfifo làwọn sọ́jà yìn sínú afẹ́fẹ́ - Lai Muhammed Adájọ́ ní Seun Egbegbe ṣì lẹ́jọ́ láti jẹ́ lórí ẹ̀sùn gbájúẹ̀ Ǹkan mẹ́wàá tí ó yẹ kí ó mọ̀ nípá Woli Genesis Wasiu ni orukọ abisọ rẹ nitori idile Musulumi ni a ti bi i, o fi aye rẹ fun Jesu Kristi o si n lọ ijọ Christ Gospel Apostolic Church nibi to ṣi n lọ di asiko yii, Diakoni ni baba ati iya rẹ ninu ijọ CGAC.
Ọgbọ́n ni Jakọbu lò fún Labani ará Aramea, nítorí pé Jakọbu kò sọ fún un pé òun fẹ́ sálọ.
 eliot won gba bi akoewi daada iseodeoni lede geesi .
Àwọn mẹta wọnyi ni àwọn ọgọfa (120) gomina náà yóo máa jábọ̀ fún.
“Ìjọba ayérayé ni ìjọba rẹ̀láti ìrandíran ni ìjọba rẹ̀,àní, láti ìrandíran ni ìjọba rẹ̀.
Ẹgan ni hẹẹ pẹlu ẹwa ti Ọlọrun fun Muyiwa Ademọla.
ó gbọdọ̀ ṣe bí ó ti wí, àfi bí baba rẹ̀ bá lòdì sí ẹ̀jẹ́ náà ati ìlérí tí ó ṣe.
 Ó tún rántí bí àwọn ènìyàn kan ní u.
Michy Batshuayi tun gba ami ayo miiran sagbon pelu boolu atungba, leyin ti asole iko Iceland mu boolu Hans Vanaken jabo sile.
Ẹ ò gbọdọ̀ wo o, ojú ò gbọdọ̀ ri
 ilé ejilolá : enìtó pèsè ilé yìí jé alágbède .
Fún oṣù mẹta ni ó fi ń sọ̀rọ̀ pẹlu ìgboyà; ó ń fi ọ̀rọ̀ yé àwọn eniyan nípa ìjọba Ọlọrun, ó ń gbìyànjú láti yí wọn lọ́kàn pada.
Igbimọ alaṣẹ ile iwe naa sọ pe iwadii fihan wi pe olukọ naa maa n fi awọn akẹkọọ ṣọ Ọgbẹni Matthew nitori ibaṣepọ to wa laarin awọn mejeeji.
Àjọ to n gbógun ti àjàkálẹ̀ ààrùn lọ́rílẹ̀-èdè Nàìjíríà (NCDC) kéde lórí àtẹjísẹ́ wọ́n lálẹ́ ọjọ́ sátide lo fi ìkéde náà síta.
Minisita fun ọrs oṣiṣẹ ati igbanisiṣẹ, Chris Ngige, lo kede aṣẹ naa lẹyin ipade to ṣe pẹlu awọn olori ẹgbẹ oṣiṣẹ loru ọọ Iṣẹgun.
 Lootọ ni a le maa tẹle gbogbo ilana ti wọn ni ki a maa tẹle lasiko yii, lati daabo bo ara wa."
idibo gomina laarin gomina ipinle Osun ,Adegboyega Oyetola ati Ademola Adeleke
Ẹ tẹ́tí sílẹ̀, kí ẹ gbọ́ ẹkún àwọn darandaran,nítorí ògo wọn ti díbàjẹ́.
Miliọnu lọna mẹrindinlogoji ni wọn ni pé o gbe nigba naa ti wọn si ni o sọ pé ejo lo gbe owo naa mi.
"Ọgbẹni Hancock ni ""awọn ko ri aridaju pe o n fa arun yi lagbara ju èyí to wa nilẹ lọ tabi pe abẹrẹ ajẹsara ko ni ṣiṣe mo."
Boya aisan kan n ṣe - dajudaju, o nilo iranlọwọ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Texas Walmart shooting: Èèyàn ogún pàdánù èmi wọn ninu ìyibọ́npanìyàn El Paso 4 Ògún 2019 Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Police were filmed responding to the shootings Eeyan ọgun ti dero ọrun lọwọ agbebọn ti eeyan mẹrindinlọgbọn si farapa ninu iyinbọnpaniyan kan to waye nilu El Paso Texas.
Masturbation: Ire ni àbí ibi fún ìlera ẹ̀dá?
Ni Wuhan ti aarun coronavirus ti bẹrẹ, igbokegbodo ko ti i pada bọ sipo rara ti a ba fi we bọ ṣe ri lọdun to kọja.
Olùdìbò gé ìka ara rẹ̀ torí ó ṣèṣì dìbò fún ẹgbẹ́ mìíràn Eku jẹ $17,600 nínú ẹ̀ro apọwó ATM Wọ́n jí ọmọ yìí gbé láti máa fi tọrọ bárà l'Eko Lẹ́yìn ọdun mẹ́ta tó kú, ilé ẹjọ́ dájọ́ ikú fún alásè tó pa Temidayo Adeleke Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Contortionist: Mo lè gbé ìfun mi pamọ́ ki n tún se èémí!
Wọn ni Odion Ighalo, atamatase fún ìkọ Super Eagles to ko lati jẹ goolu naa fara ko ninu ẹbi ọrọ́ yii.
Ilé-iṣẹ́ náà fi kún un pé àwọn á ṣe ìdánilẹ́kọ̀ọ́ fún àwọn òṣìṣẹ́ wọn lórí bí a ṣe ń hùwà bí wọ́n bá fura sí olè jíjà.
Nítorí pé ìtara ilé rẹ ni ó jẹ mí lógún,ìwọ̀sí àwọn tí ó ń pẹ̀gàn rẹ sì bò mí mọ́lẹ̀.
Wọn ni kii jẹ ki awọn raye lọ sẹnu isẹ oojọ awọn, koda awọn ko ni lee lọ se idanwo tabi se ohunkohun.
Sugbọn ninu ọrọ rẹ, Thomas sọ pe aṣọ ẹgbẹ́ okunkun ti oun fi ya aworan jẹ eré lasan, ṣugbọn o gba pe lootọ ni oun n dẹ́yẹ si awọn ẹ̀yà to ku.
18 Ẹrẹ̀nà 2018 Oríṣun àwòrán, NIGERIAN GOVERNMENT Aarẹ Muhammadu Buhari ti de ibi ayẹyẹ igbeyawo to to marun latigba to ti jawe olubori nibi ibo aarẹ ọdun 2015.
Gbogbo wọn ń ṣe ohun tí ó lòdì sí àṣẹ Kesari.
18 Ẹ béèrè ní ọwọ́ Bàbá ní orúkọ mi pẹ̀lú ìgbàgbọ́, ní gbígbàgbọ́ pé ẹ̀yin yío rí gbà, ẹ̀yin yíò sì ní Ẹ̀mí Mímọ́, èyítí ó nfi ohun gbogbo hàn tí ó wúlò fún àwọn ọmọ ènìyàn.
Kò pẹ tí mo dé inú ihò yìí tí àgbàra òjò fi lé mi j’de tí mo sì tún sá sí ihò míràn.
Ó kú, wọ́n sì sin ín sí ibojì àwọn baba rẹ̀.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Bode George: òòtọ́ ni ìkìlọ̀ Obasanjọ ati Soyinka Mo wọgile #3,000 tawọn akẹkọọ ipinlẹ Oyo n san - Makinde Seyi Makinde to jawe olubori labẹ ẹgbẹ oṣelu PDP ni yoo tukọ ipinlẹ Oyo titi di ọdun 2023.
Àwọn ọmọ Ṣefataya jẹ́ ọọdunrun ó lé mejilelaadọrin (372)
Ọ fí kún un pé ní ọjọ́ ìṣẹ́gun, ọjọ́ kẹfa oṣu yìí, àwọn ṣetan láti ṣe ìpàdé pọ̀ pẹ̀lú Naira Marley láti dáhun gbogbo àwọn ìbéèrè tó bá ni láti sọ lórúkọ àwọn ọ̀dọ́ Naìjíríà lórí ọ̀rọ̀ SARS àti àwọn ǹkan míràn tó jẹ wọ́n lógún.
o dibo rẹ laarin ogunlọgọ awon eniyan ti won jade lati wa dibo ni agbegbe naa.
Ẹwẹ̀, kọmísọna ọlọpàá, Zubairu Muazu ti pá a láṣẹ pé kí wọ́n ṣe ìwàdìí tó péye.
Fun gbogbo iroyin labẹle ati lẹyin odi
"Adams nigba to n sọrọ nipa abadofin ti Gomina Ambode bu'wọlu lori gbigbe ede Yoruba larugẹ, fikun un wi pe ""orilẹede tabi agbegbe ti o ba gbagbe ede rẹ, yoo gbagbe aṣa ati ise rẹ, eleyi to sọ wipe yoo pa iru agbegbe bẹẹ run."
Ǹjẹ́ nisinsinyii, dá obinrin náà pada fún ọkọ rẹ̀, nítorí pé wolii ni ọkunrin náà yóo gbadura fún ọ, o óo sì yè.
Evander Holyfield: Holyfield padanu igbanu ẹyẹ WBA, IBF ati Lineal sọwọ Micheal Moorer eleyii to ya ọpọ ololufẹ ẹṣẹ kikan lẹnu.
“Bí ó bá jẹ́ pé ohun jíjẹ tí a yan lórí ààrò ni ẹbọ náà, kò gbọdọ̀ sí ìwúkàrà ninu rẹ̀.
Ajafẹtọmọniyan naa tun tẹsiwaju pe, ko yẹ ki orileede South Africa sa si abẹ ika pe o n gbalejo apero agbaye lai ṣe pe wọn fi ijiya to tọ jẹ.
Ẹ̀yin aṣòfin túntun, ẹ má gbàgbé ẹni gbé'ṣẹ́ fún ni o - Saraki Ìdààmú ńlá ńbọ̀ fún Nàíjíríà lábẹ́ ìjọba Buhari - Ọbasanjọ Àìle è ka kéú ló sọ mí di Krìstíẹ̀nì - Adewale Ayuba Sẹnẹtọ mọkandinlaadọrin pẹlu aṣoju ṣofin mọkanlelaadọjọ ni FRSC n beere pe ki wọn dá awọn nọmba ọkọ yii pada.
Odugbemi ka eko nipa sise fiimu ati ere amohunmaworan ni Fasiti Montana State University.
Yóo máa dára fún ẹni tí ó bá lójú àánú, tí ó sì ń yáni ní nǹkan,tí ó ń ṣe ẹ̀tọ́ ní gbogbo ọ̀nà.
Àkọlé àwòrán, EFCC kìlọ̀ EFCC: Ẹ yàgò fún MMM, àwa ké fún un yín tó o!
Premier League yóò bẹ̀rẹ̀ padà lóṣù kẹfà Ẹ̀rù n ba àwọn agbábọ́ọ̀lù Premier League láti padà sórí pápá nítorí coronavirus Àwọn jẹsí tó gbajúmọ̀ nínú ìtàn ìdíje bọ́ọ́lù Oríṣun àwòrán, @AFTVMedia Patrick Vieira ni balogun ẹgbẹ agbabọọlu ikọ naa ninu eyi tawọn agbaọjẹ agbabọọlu bi Thierry Henry, Robert Pires, Dennis Beckamp, Sol Campbell, Arshley Cole ati Kanu Nwankwo wa.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Mo fẹ́ gbé ògo ìdílé ìyá àti bàbá mi ga pẹ̀lú iṣẹ́ Mọkálìíkì' Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Nibi ti awọn ololufẹ ffimu Yoruba ati awọn ololufẹ Jaiye Kuti gan funra rẹ fẹ mọ ohun to wa nidi ọrọ yii de, ṣe ni gbogbo wọn bẹrẹ si ni tẹnu bọ ọrọ ọpẹ.
Awon orile ede ti ajo naa ti
Eyi tumọ si pe ko maṣe fi foonu rẹ sinu ina di oru mọju rara.
Batiṣeba wólẹ̀ níwájú ọba, ó sì kí i tọ̀wọ̀tọ̀wọ̀.
Àwọn ọmọ Ṣilo ni Asaaya, àkọ́bí rẹ̀, ati àwọn ọmọ rẹ̀.
 a tún ní àwọn onífá , babaláwo àti bẹ ́ ẹ ̀ bẹ ́ ẹ ̀ lọ .
Ránti Ọmọ Ẹni ti Iwọ Nṣe: Olè ki ṣe Orúkọ Rere lati fi Jogún
Lasiko ti wọn n gbaradi fun idije naa, orilẹede South ati North Korea fọwọsowọpọ fun igba akọkọ, ti wọn si parapọ yan awọn obinrin ti yoo soju wọn fun ere idaraya Hockey, ninu idije naa.
Òun ni ó kọ́ ẹnu ọ̀nà apá ìhà àríwá ilé OLUWA.
- Agbẹnusọ Kassim Ṣe ni awọn aran maa n ri ara wọn bọ abẹ ilẹ ṣugbọn laip yii ni iji wu wọn jade si ori okun Drakes ni nkan bii aadọta maili si ilu San Francisco ti wọn si kun gbogbo ilẹ.
Ṣé o mọ ìgbésẹ̀ ìkọ̀sílẹ̀ lábẹ́ òfin Naijiria?
Ajọ to n risi idena ati amojuto ajakalẹ aarun ni Naijiria, NCDC lo fi ikede naa sita lalẹ ọjọ Ẹti loju opo Twitter rẹ.
Orile-ede South Africa lo sokunfa ai-pegede orile-ede Naijiria fun idije boolu awon Adulawo todun 2015 ni orile-ede Equitorial Guinea lataari esi ifesewonse awon iko mejeeji ti won gba ami ayo meji meji(2-2), ti o waye ni ipinle Akwa ibom, Uyo, lodun 2014.
Wọn óo wọ aṣọ ọ̀fọ̀, ìpayà óo sì bá wọn.
Ìdí sì rèé tí BBC Yoruba fi wọnú ìtàn lọ, láti jẹ ki awon eeyan mọ nipa ọpọ ìṣẹ̀lẹ̀ àjakalẹ-àrun tó ti wáyé ṣáájú kàakíri àgbáyé, kódà, wọn fẹẹ ju ogún lọ, gẹ́gẹ́ bàa ṣe kaa lójú òpó itakun agbaye.
Awọn iroyin miiran ni bii bilọnu kan dọla ni gbogbo ọrọ̀ Al-Bashir.
Àwọn ọ̀pọ̀lọ́ náà yóo kúrò lọ́dọ̀ rẹ, ati ninu àwọn ilé rẹ, ati lọ́dọ̀ àwọn ẹmẹ̀wà rẹ, ati lọ́dọ̀ àwọn eniyan rẹ; kìkì odò Naili nìkan ni ọ̀pọ̀lọ́ yóo kù sí.
Bẹẹ ni ọrọ ri pẹlu owo ti adari ijọba ologun tẹlẹ lorilẹede Naijiria, Oloogbe Sani Abacha n fi ransẹ lati ajule ọrun ri bayii.
Shodipe jẹ afurasi ti wọn ti kọkọ mu lori iṣẹlẹ iṣekupaniyan to n waye lẹnu lọọlọ yi lagbegbe Akinyele ni ilu Ibadan.
Ohun lo mu ki gomina Oyetola wa paṣẹ ofin konile-o gbele ọlọjọyipo oni wakati mejilelaadorin, ki ohun gbogbo fi le pada sipo.
Ẹni to bori: Senegal Aṣekagba Namibia Senegal Namibia vs Senegal.
Bidemi tun ni ẹgbọn, Sola Kosoko, ti oun naa jẹ oṣere ati ẹgbọn ọkunrin, Tunji Kosoko.
Nigba to n ki awọn alẹnulọrọ ninu eto idibo naa kaabọ, Ọjọgbọn Olayinka ti ka esi idibo ijọba ibilẹ mẹẹdogun ninu mejidinlogun to wa ni ipinlẹ Ondo.
Umahi so pe “ A gbọ pe aare ti  yi ipinnu  rẹ  pada
Ni kete ti a ba ti ri esi tirẹ gba lori ọrọ yi la o fi to yin leti.
Nígbà tí Jakọbu rí Rakẹli, ọmọ Labani, tíí ṣe arakunrin ìyá rẹ̀, ati agbo aguntan Labani, ó yí òkúta náà kúrò lẹ́nu kànga, ó sì pọn omi fún wọn.
Nígba ti ọ̀rọ̀ náà bẹ̀rẹ̀, àwọn kan ni Alfa ọhun ni ìbásṣepọ pẹlú gomina ìpínlẹ̀ Ondo, èyi si ló ṣe okùnfa ti Gomina ipínlẹ̀ kò fi dá si ọ̀rọ̀ náà.
Eeyan mejeeje to wa ninu ọkọ naa ku loju ẹsẹ, ti mọto meji miran si tun rọ lu tirela naa, eyi to tun mu ẹmi eeyan mọkanla miran lọ.
50 Ṣùgbọ́n nígbàtí alàgbà kan bá wá níbẹ̀, òun ó kàn wàásù, kọ́ni, sọ àsọyé, gbani níyànjú, àti ṣe ìrìbọmi.
Wọn ni awọn ti gbe ọrọ naa le ẹka ileesẹ ọlọpaa to n sewadi awọn iwa ọdaran to le lọwọ.
2019 Elections: INEC fún àwọn èèyàn ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́ ní ìdánilójú ṣáájú ìdìbò ọjọ́ àbámẹ́ta
Ṣugbọn ìròyìn kan yóo dé láti ìlà oòrùn ati àríwá tí yóo bà á lẹ́rù, yóo sì fi ibinu jáde lọ kọlu ọpọlọpọ, yóo sì pa wọ́n run.
O sọ lori Twitter ni Ọjọru pe igbimọ apapọ orilẹede Naijiria lo ṣe ipinnu naa lati so ileeṣẹ naa rọ.
‘PDP yóò padà sí ìjọ̀ba Nàìjíríà ni 2019’ Oyinlọlá kúrò ní APC, PDP ní kó padà wálé Àríyànjiyàn Osinbajo àti PDP Agbẹnusọ fun ileesẹ ọlọpaa Ipinlẹ Eko, Chike Oti, ni wọn gbe Aborisade digbadigba lọ ile iwosan First Consultant to wa ni Obalende, sugbọn wọn ko le doola ẹmi rẹ.
Kàkà bẹ́ẹ̀ ẹ̀ ń fi ẹ̀ṣẹ̀ yín yọ mí lẹ́nu,ẹ sì ń dààmú mi pẹlu àìdára yín.
Lẹyin naa ni olori ẹgbẹ APC, Bola Tinubu tun yan gẹgẹ bii oluranlọwọ pataki nigba to jẹ gomina.
Ìbéèrè àti ìdáhùn pẹ̀lú Seyi Awolowo ti BBNaija lórí BBC Yorùbá Àwọn èrò nígboro Eko fẹ́ lu obìnrin kan pa, pé ó mú nǹkan ọmọkùnrin pòórá Jessica Nabongo ni obìnrin àkọkọ nílẹ Adúláwọ tó rin gbogbo àgbáyé.
Ṣugbọn Josaya ṣe oríkunkun, ó paradà kí wọ́n má baà dá a mọ̀, ó lọ bá a jà.
Oríṣun àwòrán, others Abba ti ṣiṣẹ gẹgẹ bii ọkan lara awọn ọmọ igbimọ adari ile ifowopamọ First Bank, Merchant Bank of Commerce ati ile iṣẹ Adojutofo Standard Alliance Insurance ri.
Public safety drones – Saving the world from above https://t.
Nígbà tí mo gbọ́ bẹ́ẹ̀, mo fa aṣọ ati agbádá mi ya, láti fi ìbànújẹ́ mi hàn, mo sì fa irun orí ati irùngbọ̀n mi tu; mo sì jókòó pẹlu ìbànújẹ́.
ti won si  tun n korin pe : “Elo ni won n ta  ẹjẹ a-ji-ja-gbara’’?
Kí ni kò jẹ́ kí o lọ fi owó mi pamọ́ sí banki, tí ó fi jẹ́ pé bí mo ti dé yìí, ǹ bá gbà á pẹlu èlé?
Ó rí ọkunrin kan níbẹ̀ tí orúkọ rẹ̀ ń jẹ́ Iniasi tí ó ti wà ní ìdùbúlẹ̀ àìsàn fún ọdún mẹjọ; kò lè dá ara gbé nílẹ̀.
Wo orin l'édè Yoruba àti Zulu tí Burna Boy fi fa ayélujára ya Kí ló dé tí Aàrẹ Buhari kìí fí í dá sí aáwò àwọn ọmọ ẹgbé APC?
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ooni Adeyeye ti Ile Ife fẹ sèrànwọ́ owó iléèwè fún akẹ́kọ̀ọ́ 5 mílíọ̀nù ní Nàìjíríà Ọkùnrin kan rí ẹ̀wọn he lẹ́yìn tó lu obìnrin ní jìbitì ìfẹ́ tí iye rẹ̀ tó $15,000 lórí ayélujára Àwọn jàndùkú ṣọṣẹ́ nílé aṣòfin ìpínlẹ̀ Ogun, wọ́n jí ọ̀pá àṣẹ gbé!
Àwọn kan láti inú ẹgbẹ́ àwọn Farisi tí wọ́n jẹ́ onigbagbọ wá dìde.
Wọn yóo dàbí ìgbẹ́ lórí ilẹ̀.
Ó fún Nàìjíríà l'èsì àwọn ẹ̀sùn tó fi kàn-án Ìdí tí mo fi ń ṣe ayẹyẹ ọjọ́ ìbí 35 lọ́dọọdún rèé- Allwell Ademola Wo ojú Akeem t'Ọlọ́pàá mú pé ó fipá bá ọ̀dọ́mọbìnrin kan sùn létí odò l'Oṣun Yàtọ̀ sí Eko, wo ohun t'áwọn ìpínlẹ̀ meje míràn ń sọ nípa ìwọlé àwọn akẹ́kọ̀ọ́ Lara anfani ti awọn akẹkọ yoo jẹ ni pe wọn yoo maa fun ẹka awọn ọmọ wẹwẹ ileewe girama onipele keji ni ounjẹ gbigbona ni ọọkan lojoojumọ.
Ó ti pinnu tẹ́lẹ̀ láti fi wá ṣe ọmọ rẹ̀ nípasẹ̀ Jesu Kristi, ohun tí ó fẹ́ tí inú rẹ̀ sì dùn sí nìyí; 
” Àwọn ẹlòmíràn ń sọ pé, “Angẹli ló bá a sọ̀rọ̀.
Aare Muhammadu Buhari ti ro apapo omo egbe ile-igbimo asoju-sofin ti o jawe olubori labe asia egbe oselu APC ninu idibo gbogbogbo to se e pari yii, lati duro sinsin saaju saa kesan ile igbimo asofin to n bo yii.
Ninu oro re, Kayode Fayemi gbosuba fun awon asiwaju ati awon akoni eniyan to je omo bibi ipinle Ekiti fun gudugudu meje , yaya mefa ti won se lati da ipinle Ekiti sile.
’ Kí ẹ sọ fún un pé, ‘Oluwa nílò rẹ̀ ni.
Pasitọ Adeboye ni iyipada yoo deba isejoba lagbaye, eleyii ti yoo mu irọun dani ni awọn agbegbe kan, nigba ti ti awọn miran yoo mu rogbodiyan lọwọ.
Wole Soyinka rèé láti kékeré Ajibade Ogunoye di Ọlọ́wọ̀ tuntun fún ìlú Ọwọ Ìtàn tó rọ̀ mọ́ òwe ‘aṣọ kò bá Ọ́mọ́yẹ mọ́.
Ó kígbe sí angẹli tí ó ní dòjé mímú pé, “Iṣẹ́ bẹ̀rẹ̀ fún dòjé mímú rẹ.
Ẹnu ẹ̀ lá wà báyìí-báyìí  tí aṣeni fi ṣílẹ̀kùn ẹ̀hìnkùlé fún ọ̀tá!
Àdúgbò márùnún pàtàkì ni wọ́n pín ìlú yìí sí kí bà lè rọrùn fún ètò ìjọ̀ba síṣe àti fúniṣẹ́ Ìlọ́rọ̀, Ọ̀kènísà àti Òdògo.
Ilẹ̀ fúnra ara rẹ̀ ni ó ń mú kí ohun ọ̀gbìn so èso: yóo kọ́ rú ewé, lẹ́yìn náà èso rẹ̀ yóo gbó.
Nàìjiríà si wà ni ipò keje ní ilẹ̀ Afíríkà, Cameroon ló wà ni ipò kẹrin nígbà tí Ghana kò si ni ipò méjìlá àkọ́kọ́, nínú orílẹ̀-èdè ti àwọn ènìyàn ti n gba ẹ̀mi ara ẹni.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Naming of Railway stations in Nigeria: Afenifere, YCE, Akitoye, Fani-Kayode ní ẹ̀tanú Obasanjo ni Buhari ṣe 20 Bélú 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 28 Agẹmo 2020 Yatọ si awuyewuye to n waye lori ayelujara, awọn ọmọ bibi ilẹ Yoruba kan ti fi èrò wọn han lori bi orúkọ aarẹ Naijiria nigba kan, Olusegun Obasanjo, ko ṣe sí lara orukọ ti ijọba apapọ kede lọjọ Aje fun awọn ibudokọ oju'rin ni Naijiria.
Ọ̀rọ̀ OLUWA ń rùn létí wọn,wọn kò fẹ́ gbọ́ mọ́.
Nitori eyi, ọpọ lo ti n wadii irufẹ jẹjẹrẹ ti wọn n pe ni colon cancer, ati awọn nkan to le fa a.
Irinajo Gbajabiamila jẹ ọkan lara ọna ati lọ wa ojutuu si ọrọ owo miliọnu kan dọla ti orilẹ-ede Ghana ni ki awọn ọmọ Naijiria to n taja lọhun maa san.
Crump ni titi laelae ni iṣẹlẹ yii yoo maa ṣe iyọnu fawọn ọmọ naa.
Gbogbo nkan tí wọ́n nsọ ni gbogbo aráyé ngbọ́ pátápátá.
Ami kan ninu ile awọn ti Olorun gba fun ni telifiṣọn yii jẹ lasiko yii Oríṣun àwòrán, @others Àkọlé àwòrán, Nọ́mbà 16: Telifiṣọn eyi kọja bẹẹ, aworan inu rẹ maa n jade bii fọto igbalode ni, ohun inu rẹ a ja geere bi ti awoko, eeyan inu rẹ a dabi pe ẹ jọ wa ninu ile, o tun le yipo si ibi ti eeyan ba fẹ ko doju kọ ninu ile nigbakigba.
Mose gbadura fún wọn, iná náà sì kú.
Wo àwọn tó ń jí owó Covid-19 tí Ìjọba ní wọ́n yóò káwọ́ pọ̀nyìn rojọ́ Ọkùnrin kan di èrò ọ̀run nítorí pé o fi ẹ̀sùn kan alájọgbélé rẹ̀ pé o n yan ìyàwó ẹnìkan lálè Ọmọ ọba Mohammed bin Salman, to jẹ ọmọ rẹ ni awọn eniyan maa n fi sọrọ nipa ọba Saudi nitori oun lo n se agbatẹru igbogun ti iwa ibajẹninu ijoba baba rẹ.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Àlá àwọn òjíṣẹ́ Olúwa tó fẹ́ jẹ ààrẹ Nàíjíríà leè má ṣẹ lógún ọdún - Abiara Ọba Lamidi Adeyẹmi, òṣìṣẹ́ adójútòfò àti Abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò kó tó jọba Kíni ìwọ mọ̀ nípa Funmilayọ Ransome-Kuti?
N kò mọ ẹni tó fẹ́ gba ìyàwó mi, àmọ́ wọn máa ń sọ pé ó rẹwà - Mike Bamiloye Wo bí ìtàkurọ̀sọ láàrin Donald trump àti Joe Biden yóò ṣe wáyé Àríyá yá!
Ijọba ni bio tilẹ jẹpe awọn ọmọde ti ọjọ ori wọn koju ọdun marun lọ naa n ku nitori aisan iba, ohun to ba ni lẹru ni wi pe aisan otutu-aya ṣi n pa awọn ọmọde ju aisan iba lọ nitori itọju tete wa fun aisan iba ju aisan otutu aya lọ.
Àwọn nkan tó yẹ kí o mọ̀ nípa ṣíṣe ìṣirò àsìkò tí o bá n yé ẹyin Agbára Oṣó àti Àjẹ́ yóò mú àgbéga bá ìmọ̀ ẹ̀rọ Nàíjíríà - Elebuibon Ilé ẹjọ́ ní kí ''Yahoo boy'' lọ darí ọkọ̀ f'óṣù mẹ́ta pẹ̀lú N50,000 owó ìtanràn Mọ̀ síi nípa Shina Rambo tó pàdé Jesu lọ́gbà ẹ̀wọn lẹ́yìn tó ti jalè Lai pari ọrọ rẹ pe minisita eto irina mu ori oun wu pẹlu aayan to fi n ṣe iṣẹ opopona oju irin naa.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Mnangagwa ni o tu keke ọrọ aarẹ Mugabe silẹ Lai pẹ yi ni Ilé ìgbìmọ̀ asòfin orílẹ̀èdè Zimbabwe pe ààrẹ̀ àná, Robert Mugabe láti wá fi àrídájú hàn nípa ohun tí ó sọ lórí jíjí òkúta iyebiye.
O ye ki ará ilú para pọ̀ pẹ̀lú Ìjọba lọ́wọ́lọ́wọ́, lati gbé ogun ti iwà ibàjẹ́ àti àwọn aṣèbàjẹ́, ju pé ki wọn fi ara gbi gbóná kọ ìyà ọgbọ̀n ọdún laarin ọdún kan tàbi meji.
 A se agbekale agbegbe Lekki fun eto oro-aje igbalode, ti yoo je etikun ati lati je ona ibasepo pelu awon eka aladani, latari ati mu idagbasoke be eto oro-aje.
Lati ọjọ kinni oṣu keje, awọn eeyan to n lo Microsoft store ko ri WhatsApp gba lori ayelujara mọ.
May  n ki  Aare orile ede Naijiria  kaabo si 10 Downing StreetVIDEO: Alakoso Ijoba orile ede Britain @theresa_may n ki Aare  Buhari kaabo  si 10 Downing Street.
BBC Yoruba lọ si ilu Ifọn nibi ti iya Orlando Owoh n gbe lati kan si ẹbi rẹ.
Oríṣun àwòrán, Instagram/abiolaajimobi Awọn yoku ni Gomina Abdulahi Ganduje ti Kano, Gomina Kayode Fayemi ti Ekiti, Gomina Rotim Akeredolu ti Ondo ati Oloye Bisi Akande.
tí wọn ń sin òkú àwọn àkọ́bí wọn tí OLUWA pa, OLUWA fihàn pé òun ní agbára ju oriṣa àwọn ará Ijipti lọ.
Kí ẹ mọ̀ pé ìdánwò igbagbọ yín ń mú kí ẹ ní ìfaradà.
Oríṣun àwòrán, Getty Images A gbọ pe Kerala ni odo mọkanlelogoji to n domi sinu okun Arabia, ọgọrin adagun odo to wa leti awọn odo naa lo ti ṣi bayii, nitori pe agbara wọn ko ka awọn odo naa mọ.
"O ni, ""Bi o ti lẹ jẹ pe mo ti n ṣiṣẹ lori ọrọ yii lati bii oṣu melo kan sẹyin, fidio BBC naa jẹ ki ọrọ naa wa ye mi daradara sii."
Ó lè dàbí ẹni pé ọgbọ́n wà ninu àwọn nǹkan wọnyi fún ìsìn ti òde ara ati fún ìjẹra-ẹni-níyà ati fún ìkóra-ẹni-níjàánu.
Border closure: Ẹ wo iye t'óúnjẹ dà báyìí lọ́jà lẹ́yìn tí ìjọba ti ibodè
Wọ́n jábọ̀ pé wọ́n ṣe ìdásílẹ̀ àwọn akẹ́kọ̀ọ́ mẹ́ta lọ́jọ́ Ẹtì, 15 oṣù Ẹrẹ́nà ṣùgbọ́n àwọn mẹ́ta yòókù ṣì wà ní àtìmọ́lé.
Ayajọ ọjọ Ajinde: ọjọ Ajé, ọjọ kẹtala, oṣu kẹrin: Eyi ni ọjọ ti awọn onigbagbọ maa n lọ si Galili nibi ti wọn gbagbọ pe Jesu ti kọkọ farahan to fi dagbere fawọn ọmọ ẹyin rẹ pe oun n padabọ wa lẹẹkeji lati wa ko awọn ayanfẹ.
Aarẹ Trump ti ẹgbẹ Republican n koju atako lọdọ Joe Biden to ṣe igbakeji Barack Obama.
Oríṣun àwòrán, others Àkọlé àwòrán, Àkójọpọ̀ mẹ́wàá lára àwọn Ọba Ilẹ̀ Yorùbá tí wọ́n lé kúrò ní ipò Ọba.
O ṣalaye pe awọn ọlọpaa fẹ kọkọ wa awọn ajinigbe ri ki wọn to wa ọkọ oju omi.
''Igba ti wọn ṣe ayẹwo fun mi ni wọn ri i pe aarun HIV ni mo ni.
Ní apá ìlà oòrùn ibẹ̀, ààlà ilẹ̀ wọn yípo lọ sí apá Taanati Ṣilo, ó sì kọjá ibẹ̀ lọ ní ìhà ìlà oòrùn lọ sí Janoa.
Láti ile ìwòsàn yìí ni o ti maa ń ló si ilé ìtura nibi tí o ti n ri ìyàwọ àti àwọn ọmọ rẹ̀ méjí, nígba miran a tún maa lọ fún awọn ayẹyẹ to ba ni.
" Ọ ̀ pọ ̀ lọpọ ̀ ìgbà ni wọn má n pe e ni "" sakayamuni "" , itumọ ̀ èyí tí ń jẹ ́ amòye nínú "" sakyas "" ."
"Ni saa yii ko ni si aye fun akoko iwẹ apapọ, ti wọn da pe ni ""Shower hour"" Oríṣun àwòrán, Bigbrother naija/africa magic Bakan naa ni wọn tun wọgile eto apejọpọ awọn araalu fun iworan ati ifọrọwerọ pẹlawọn olukopa ti wọn ba fẹ gbọn ys kuro lori eto naa."
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: A ṣe ọdún Ọ̀ṣun lásìkò yìí láti kó Coronavirus lọ ni - Ooni ṣàlàyé Wo àwọn nǹkan tí o kò mọ̀ nípa 'Church of Satan' Àwọn afurasí ajínigbé tó tan oníṣòwò jáde ní ṣọ́ọ́sì wọ gàù Ọlọpaa Eré ìtàgé lórí ayélujára, àbíkẹ́yìn faraya pé iṣẹ́ ilé ń pá òun lórí, ó gbé òfin kalẹ̀ fún ẹbí Boko Haram 601 parí iléẹ̀kọ́, ìjọba yóò san ₦20,000 lóṣù fún ẹnì ìkọ̀ọ̀kan Aráàlú faraya torí èèyàn 63 tó dèrò ọ̀run ní Gúúṣù Kàdúná láàrin ọ̀sẹ̀ kan Bẹẹ ba gbagbe, lasiko ti iya Barrakat, Kafayat Bello n ba BBC Yoruba sọrọ lori bi isẹlẹ naa se waye, o ni ko ba nira fun awọn onisẹ ibi naa lati raye wọnu ile wọn, to ba jẹ pe wọn ni ferese ati ilẹkun gidi ninu ile naa ni.
Nítorí a ti gbọ́ bí OLUWA ti mú kí Òkun Pupa gbẹ níwájú yín nígbà tí ẹ jáde ní Ijipti, a sì ti gbọ́ ohun tí ẹ ṣe sí Sihoni ati Ogu, àwọn ọba ará Amori mejeeji tí wọ́n wà ní òkè odò Jọdani, bí ẹ ṣe pa wọ́n run patapata.
O ti fi mí ṣe ẹlẹ́yà nígbà mẹta, o kò sì sọ àṣírí agbára ńlá rẹ fún mi.
9th Assembly: Dogara kìlọ̀ fáwọn ẹgbẹ́ òṣèlú láti má dásí yìyan olórí ilé
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Gbajúgbajà òsèré tó tún mọ́ ọbẹ̀ sè 4.
Lara awọn kọ orin nibẹ ni ọmọ rẹ obinrin, ọkọ rẹ, pasitọ Ituah Ighodalo ati gbajugbaja olorin ẹmi, Tope Alabi.
" Oríṣun àwòrán, Seyi Makinde Bakan naa tun ni Makinde fikun pe, aba ti oun gbe kalẹ lati gba akoso ileẹkọ fasiti LAUTECH labẹ akoso ipinlẹ Ọyọ nikan ni ọna abayọ si ọpọ ohun ti fasiti naa n poungbẹ rẹ.
com/gGkHnacUYg📸 A memorable day on the south coast for @ManCity#BHAMCI pic.
Ọmọ ọdún mẹ́wàá ń fọn fèrè lágbo àríyá Ìlú mímọ́ nibí, wọn kò gbọdọ̀ bímọ, sin òkú àbí ẹran síbẹ̀"" Lẹ́yìn ìfẹ̀yìntì ọdún márùn-ún, báágì àti bàtà ló kàn Ọbasanjọ sọ àsírí sàgbàdèwe rẹ̀ Baba Ọsun ni Ataoja fẹ kawọn maa lu jibiti, ki awọn lee maa ri owo ni, bẹẹ si ni ojulowo ere Ọsun ko si ni Osogbo mọ."
Kinní kan ni mo wá fẹ́ tọrọ, jọ̀wọ́, má fi kinní ọ̀hún dù mí.
Ori ayelujara ni ọpọ ọmọ Naijria ti n sọ erongba wọn lori ṣiṣe ofin konile-o-gbele miran, paapa ni ipinlẹ Eko ti aarun naa pọ si julọ.
Nítorí náà ṣe èmi iranṣẹ rẹ ní oore kan, nítorí o ti mú mi dá majẹmu mímọ́ pẹlu rẹ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Mayowa Omoniyi: Kò sí orin Obey, Sunny Ade abí tàkasúfèé tí ń kò le ta gìtá sí Obìnrin kan ti iṣẹlẹ ọhun ṣoju rẹ sọ pe oun si n gbọn di akoko yii.
Ni idahun si wi pe ṣe ofin sọ pe asiko kan pato leeyan le kan sara si iṣẹ gomina ati lati sọ pe ko lọ fun saa kan sii, Yagboyaju fesi pe ohun gbogbo lo lasiko tirẹ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Fáyóṣé fèsì lórí bí Buhari se ńdá Gaddafi lẹ́bi wàhálà darandaran 13 Ìgbé 2018 Oríṣun àwòrán, Nigeria presidency Àkọlé àwòrán, Fayoṣe ni awọn darandaran ti ko pa awọn ọmọ ilẹ̀ Libya ni wọn ń wá pa àwọn èèyàn ní Nàìjíríà.
Nígbà tí ó tó àkókò tí Josẹfu yóo kú, nípa igbagbọ ni ó fi ranti pé àwọn ọmọ Israẹli yóo jáde kúrò ní ilẹ̀ Ijipti, tí ó sì sọ bí òun ti fẹ́ kí wọ́n ṣe egungun òun.
Nígbà tí ó dà á sinu omi, ẹja tí ó kó pọ̀ tóbẹ́ẹ̀ tí àwọ̀n fẹ́ ya.
Dájúdájú, ǹ bá gbé e lé èjìká mi,ǹ bá fi dé orí bí adé;
Agbẹnusọ Ile Igbimọ Aṣofin Ipinlẹ Eko, Aṣofin Mudashiru Ọbasa ti rọ awọn ọmọ orilẹ-ede Naijiria, paapaa awọn musulumi lati ma ṣe fa sẹyin ninu ojuṣe fifi ifẹ han sira ẹni, bo ti lẹ ṣe pe aawẹ Ramadan ti pari.
Àwón Oníbúrẹ́dì ń gbé ìgbésẹ̀ láti fi kún owó Búrẹ̀dí ní Nàìjírià Adájọ́ ní kí Ahmed Danladi, tó jẹ́ awakọ̀ tó jalè gbálẹ̀ kóòtù f'ọ́jọ́ méjì ní Abuja Wo àmì márùn-un tí o fi le mọ ẹni tó fẹ́ gbẹ̀mí ara rẹ̀ Àjọ Elétò ìdìbò INEC ti sọ̀rọ̀ lórí iná tó jó àwọn káàdì ìdìbò ní Ondo Wo fọ́tò àrà MC Oluomo, Pasuma àtàwọn òṣèré tíátà míì níbi ìṣílé Iyabo Ojo Wo ìyá ọlọ́mọ mẹ́ta tó ti pé ọdún 48 tó ń ṣe ìdánwò WAEC, kó le di nọ́ọ́sí Ọmọ ogun ọdun ni Ibrahim, ara awọn kolẹ-kodọti ni oun naa.
Awọn Gomina f'aramọ ọlọpaa ipinlẹ Wọn ni ajọ to n ri si ọrọ akosọ ileeṣẹ ọlọpaa, Police Service Commission, lo laṣẹ lati ṣeto igbaniwọle siṣẹ.
Ìyá rẹ̀ dá a lóhùn pé, “Kí ègún náà wá sí orí mi, ọmọ mi, ṣá gba ohun tí mo wí, kí o sì lọ mú àwọn ewúrẹ́ náà wá.
” Ṣugbọn ẹnikẹ́ni kò dá a lóhùn ninu wọn.
yoo waye losu to n bo lọ ni irowo-irose.
O wa tun gbara ta lori bi awọn agbẹ to jẹ iran Yoruba se n fi oko wọn silẹ fun awọn afurasi ọdaran to n ba wọn lalejo, ti wọn si n sa asala fun ẹmi wọn.
Àwọn alufaa meje tí wọ́n mú fèrè ogun tí wọ́n fi ìwo àgbò ṣe lọ́wọ́ níwájú Àpótí Majẹmu OLUWA kọjá siwaju, wọ́n sì ń fọn fèrè ogun wọn lemọ́lemọ́.
Wọle Soyinka: Ti mo ba dara pọ m'ẹgbẹ Obasanjọ, wọn gbọdọ yẹ mi lọpọlọ wo
””Inu wa dun lati se ayeye ajodun orile ede wa niluu Abuja, lorile ede Naijiria.
" Maha lọ fun iṣẹ abẹ naa nigbati o ku oṣu meji ti yoo ṣe igbeyawo pẹlu ọkunrin to ju u lọ diẹ.
ti ajo eleto idibo INEC ti kede rẹ gege bi eni ti o jawe olubori ninu eto idibo
Àjọ ọlọpàá Eko kédé pé ìbalòpọ̀ nítà kò bójúmu Ṣé irúfẹ́ oúnjẹ tí ò ń jẹ́ lè jẹ́ kí o gbádùn ìbálòpọ̀ rẹ síi?
Ti o ba fi rorun fun awon orile ede ti won ko to orile ede Naijiria,fun
Nítorí èyí, mo sọ fún ọ, a dárí ẹ̀ṣẹ̀ rẹ̀ tí ó pọ̀ jì í, nítorí ó ní ìfẹ́ pupọ.
Seyi: Mo ti ṣe agbekalẹ eto kan fun awọn to ni ẹbun pataki lori ẹrọ ayelujara lati jọ pade fun iwulo ara wọn.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù PDP South West: Ọ̀rọ̀ ọkọ̀ ayọ́kẹ́lẹ́ ìjọba tó pòórá kìí ṣe ìṣẹ̀lẹ̀ àfojúfò 14 Ògún 2019 Oríṣun àwòrán, @OfficialPDPNig Ẹgbẹ oselu PDP lẹkun iwọ oorun guusu Naijiria ti faraya lori gbolohun kan ti gomina ana nipinlẹ Ọyọ, Abiọla Ajimọbi sọ pe, ọrọ ọkọ ayọkẹlẹ ti wọn lo poora jẹ isẹlẹ kekere ti ko lowura rara.
Ìnàkí-gorí-ìtẹ́ mú aṣọ dúdú kékeré, ó sánan mọ́ aṣọ rẹ̀, gẹ́gẹ́ bí àmì ọ̀fọ̀ Gọ̀ǹgọ̀ṣútàkìtì tii ṣe àbúrò rẹ̀.
Ẹwẹ, gomina Oyetola sọ pe asiko ko tii to fun iru irinajo yii bo tilẹ je pe ohun ti wọn fẹ ṣe lorilẹede UAE ṣe pataki.
BBC Yoruba ba ọkàn nínú àwọn alábasiṣẹ́ pọ rẹ lẹ́nu iṣẹ́ ìròyìn sọ̀rọ̀, tii tun se Agba oye kan nilẹ Ibadan, Lekan Alabi sàlàye pé òun mọ baba náà fún ìgbà àkọkọ ní ọdún 1964, nígbà ti òun wà ní ọmọ ọdún mẹrinla.
Ipade ohun ti o n waye ni gbonga kan nile-igbimo asofin ohun, ni Aare ile-igbimo asofin agba omowe Bukola Saraki, asofin Ahmed Lawan ati awon asofin miiran ti won je omo egbe oselu APC peju-pese si.
Ṣugbọn OLUWA ń fi eniyan burúkú rẹ́rìn-ín,nítorí ó mọ̀ pé ọjọ́ ìparun rẹ̀ ń bọ̀.
lo wa si ibi ipate naa.
Kọngadẹrọ ni ida kan ninu mẹta awọn ọmọ Naijiria ti n ri anfani omi to mọ fun mimu.
Ẹ bèèrè lọ́wọ́ baba yín, yóo fihàn yín,Ẹ bi àwọn àgbààgbà yín,wọn yóo sì sọ fun yín.
Loju opo yii naa ni awọn arinrinajo ni oore ọfẹ lati sọrọ lori eto ilera wọn ati ayẹwo ti wọn ṣe Bakan naa ni wọn le sọ ibi ti wọn ti fẹ ṣe ayẹwo ati ibi ti wọn ti fẹ gab esi ayẹwo wọn Nigba gbogbo ni wọn a maa yẹ bi ara wọn ṣe gbona to wo ni papakọ ofurufu E wo ọmọ Yorùbá àkọ́kọ́ tó jà fún ẹ̀tọ́ àwọn aláwọ̀dúdú ní America!
Eniyan bi ẹgbẹrun marun lo ti ni Coronavirus ni Germany.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Kàkà kílẹ̀ ó kú.
Àwọn ogun Amoni tò lẹ́sẹẹsẹ siwaju ẹnubodè ìlú wọn, ṣugbọn àwọn ọba tí wọ́n bẹ̀ lọ́wẹ̀ wà lọ́tọ̀ ninu pápá.
Kí ló fa ìjà láàrin Wunmi Toriola àti Seyi Edun?
Àwọn ìlú tí wọ́n wà ní aṣálẹ̀ ni, Betaraba, Midini, Sekaka; 
Nkan ti gomina ipinlẹ Katsina tẹnumọ ni pe, awọn ajinigbe lo gbe awọn ọmọ naa.
Àgbéyẹ̀wò àṣà: Ìdí tí Yorùbá kìí fí tufọ ikú òjìji fún èèyàn Mú N22.
Ohun tí ẹ̀yin ará Efuraimu ṣe, tí ẹ rò pé ohun kékeré ni yìí, ó ju gbogbo ohun tí àwọn ará Abieseri ṣe, tí ẹ kà kún nǹkan bàbàrà lọ.
Ẹlòmíràn kú pẹlu ìbànújẹ́ ọkàn,láìtọ́ ohun rere kankan wò rí.
O kò gbọdọ̀ mú ọmọ mi pada sibẹ.
Ta ni í mú kí eniyan ya odi, tabi kí ó ya adití, tabi kí ó ríran, tabi kí ó ya afọ́jú?
Kambale Musavuli , to je okan ara awon to n polongo fun
 eré yìí sábà máa ń ní olórí tí yíò máa dá orin , tí àwọn yòókù yíò máa gbè ti ìlù bá ń lọ lọ ́ wọ ́ .
Ẹ bá Moabu wá ìyẹ́, nítorí yóo fò bí ẹyẹ;àwọn ìlú rẹ̀ yóo di ahoro, kò ní ku ẹnikẹ́ni ninu wọn.
Ramsey to jẹ ọmọ ọdun mejidinlọgbọn buwọ lu iwe adehun ọlọdun mẹrin lẹyin to ti lo ọdun mọkanla gbako pẹlu Arsenal.
Wọn tun sọ ninu fidio naa wi pe awọn ko ni nnkan ija to koju oṣunwọn.
Ìjọba ìpínlẹ̀ Kaduna ló gbée lọ si ilé ẹjọ́ July 11, 2018 Ilé ẹjọ́ sún ìgbẹ́ja náà sí ọjọ́ kejì oṣù kẹjọ́, ọdún 2018 August 2, 2018 Ilé ẹjọ́ sún ìgbẹ́jọ ìtúsilẹ̀ El-Zakzaky sí ọjọ́ kẹrin, osù kẹ́wàá, ọdun 2018 October 4, 2018 Ilé ẹjọ tún sún ìgbẹ́jọ ìtúsílẹ̀ rẹ̀ sí ọjọ́ kẹ́tadínlógun ọdún 2018 October 27, 2018 Àwọn ọmọ ẹ̀yin El-Zakzaky, dí ojú pópó ní agbègbè afárá Zuba, Abuja.
’ Ẹ̀mí náà dáhùn pé, ‘N óo mú kí gbogbo àwọn wolii Ahabu purọ́ fún un.
Bakan naa ni awọn ti yoo maa pin abẹrẹ naa fun awọn eeyan ilu ni lati jẹ awọn oṣiṣẹ eto ilera to kọṣẹ mọṣẹ.
“Kí ni ẹ rò nípa Mesaya, ọmọ ta ni?
Hasaeli dáhùn pé, “O óo yè ninu àìsàn rẹ.
Emmanuel Macro to jẹ aarẹ ile Faranse ti ṣeleri lati tun ile ijọsin naa kọ pẹlu iranlọwọ awọn eeyan.
OLUWA ní, “Ẹ kọrin ayọ̀, kí ẹ sì jẹ́ kí inú yín máa dùn, ẹ̀yin ará Jerusalẹmu, nítorí pé mò ń bọ̀ wá máa ba yín gbé.
Gani Adams kilọ f'awọn darandaran Iṣẹ́ bọ́ lọ́wọ́ ọ̀gá ilé iṣẹ́ ológun lórí ikú Fulani 134 A kò lè gba àwọn jandùkú Fulani láàyé nílẹ̀ Yoruba -Awọn gómínà Afurasí Fulani ṣekú pa ọmọ olórí ẹgbẹ́ Afẹ́nifẹ́re, Fasoranti Kọmiṣọna ọlọpaa, Bashir Makam ni wọn ko san owo itanran kanakna lati fi doola ẹmi awọn eniyan yii ṣugbọn mọlẹbi wọn ni pe irọ ni.
Wo àwárí akọ́ṣẹ́mọṣẹ́ yìí Akeredolu kilọ fawọn to n fi oju ẹlẹyamẹya wo Amọtẹkun pe eto aabo to munadoko lo jẹ awọn logun, eyi lo fa sababi ifilọlẹ Amọtẹkun.
Alex Badeh: Ọwọ́ ba afunrasí mejì 'Irọ́ ni o, Ọlọ́pàá 167 tó fẹ́ koju Boko Haram kò sá lọ' Buhari pàṣẹ pé kí àsíá Nàìjíríà wálẹ̀ fọ́jọ́ meta Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Tsunami: Lẹ́yìn ọ̀sẹ̀ kan ti Jumasil ti sọnù ni wọ́n rii padà Diẹ lara awọn ipaniyan to milẹ bi ọwara ojo lorilẹ-ede Naijiria lọdun 2018 niwọnyii: Ọgagun agba, Alex Badeh, Ọgagun agba ileeṣẹ ọmọogun apapọ Naijiria tẹlẹ Oríṣun àwòrán, NAF Àkọlé àwòrán, Ìpèníjà ọ̀rọ̀ àbò lórílẹ̀èdè Nàìjíríà fa ọ̀pọ̀lọ́pọ̀ ariwo lọọ́dún 2018 Alex Badeh ni Ọgagun agba ileeṣẹ ọmọogun apapọ Naijiria labẹ iṣejọba aarẹ ana, Goodluck Jonathan lẹyin to ti jẹ ọgagun agba ileeṣẹ ọmọogun ofurufu lorilẹede Naijiria laaarin oṣu kẹwa, ọdun 2012 si ọdun 2014.
ÌWÀ Ẹ̀̀DÁ Ẹ̀̀dá nimí, mo sì ń fi ìgbà gbogbo dárà.
Ẹgbẹ́ òṣèlú PDP sún ìdìbò abẹ́nú Edo síwájú síi Ìdílé márùn-ún tó gbajúmọ̀ fún òwò ẹrú nílẹ̀ Yorùbá 11.
Ọpọ awọn ero lo n sare lọ ra ohun jijẹ ati ohun eelo ile ni awọn ile itaja nla nla.
“Bí ẹnìkan bá dẹ́ṣẹ̀, nípa pé ó gbọ́ tí wọn ń kéde láàrin àwùjọ pé, kí ẹnikẹ́ni tí ó bá mọ̀ nípa ọ̀ràn kan jáde wá láti jẹ́rìí, bí ó bá mọ ohunkohun nípa ọ̀ràn náà, kì báà jẹ́ pé ó rí i ni, tabi wọ́n sọ ohunkohun fún un nípa rẹ̀ ni, tí ó bá dákẹ́, tí kò sọ ohunkohun, yóo jẹ̀bi.
Àwọn ọmọ Naijiria kóju ija sí àwọn South Africa wọ́n ní Ó tó gẹ́"" Ìjọba South Africa pèpàdé lórí ìkórìíra àlejò Kíló fa ìpànìyàn tó tún ń wáyé ní South Africa Pásítọ̀ tí wọ́n ní ó fi irọ́ jí òkú dìdé rí ẹjọ́ he Kí ni Bode 'Thomas' ní ṣe pẹ̀lú ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ Nàìjíríà àti South Africa?"
Senetọ Nurudeen Ademola Adeleke, ni oludije ipo Gomina labe asia ẹgbẹ oselu Peoples Democratic Party, PDP, ninu idibo Gomina ipinlẹ Osun .
Lẹ́yìn náà, ó kọjá lọ sí òkè Baala títí dé Jabineeli, ó wá lọ parí sí Òkun Mẹditarenia.
Koko iroyin fun t'oni: Ikọlu BBC l'Eko, wahala Facebook Osisẹ ijọba Eko gba irinsẹ akọroyin agba BBC Nise ni ikọ ẹlẹni mẹfa naa, ti igbakeji oludari nileesẹ ọrọ ayika, Awoniyi Joshua ko sodi, so wi pe awon yoo fi akọroyin BBC si ahamọ.
Bawo ni mom ṣe le ṣayẹwo arun naa?
Wọ́n ti búra pé àwọn kò ní jẹun, bẹ́ẹ̀ ni àwọn kò ní mu omi títí àwọn yóo fi pa Paulu.
A óo kó àwọn eniyan Israẹli ati ti Juda papọ̀, wọn óo yan olórí kanṣoṣo fún ara wọn; wọn óo sì máa ti ibẹ̀ jáde wá.
Koda, awọn aṣoju ijọba duro si oju ọna, ti wọn si n da awọn eniyan duro.
Bakan naa lọdun 2018, wọn tun ji awọn akẹkọọbinrin gbe nipinlẹ Yobe.
Taiwo sọ pe nitori awọn janduku to wa laarin awọn olufẹhonuhan lo jẹ kawọn ologun gbe ibọn to ni ọta gidi ninu lọ sibẹ.
Awon amoye n se iyemeji lori ojo iwaju egbe oselu MDC ohun, ni eyi ti awon miiran gbagbo pe laisi Tsvangirai, o seese ki egbe naa fo.
Ẹ wo isọri awọn pataki iṣẹ ti eso kekere yii n ṣe.
Alẹ ọjọ Aje ni alaga ajọ naa, Ọjọgbọn Mahmood Yakubu kede asẹ tuntun naa.
Ipa ọ̀nà rẹ̀ wà ninu ìjì ati ẹ̀fúùfù líle,awọsanma sì ni eruku ẹsẹ̀ rẹ̀.
awon apa ibikan ni awon ipinle to wa lorile ede Naijiria lati segbe fun awon
rírọ ́ nǹkan ntun jáde ni èrọ ìmọ ̀ sáyéǹsì gẹ ́ gẹ ́ bí ń ṣe sọ ṣáájú ló bí ìmọ ̀ ẹ ̀ rọ .
2023 Elections: Shehu Sani ní àfàìmọ̀ kí Yorùbá àti Igbo má kùnà nínú ìbò ààrẹ ọdún 2023
Asán ni kí á jí ní òwúrọ̀ kutukutu,kí á tún pẹ́ títí kí á tó sùn.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Oyedepo: Ẹni tó bá ń sàánú àwọn apànìyàn, kò ní mú 2018 jẹ 24 Agẹmo 2018 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 14 Ọ̀wàrà 2018 Àkọlé àwòrán, Oyedepo ni ọdun yii ko ni lọ lai jẹ pe Ọlọrun bẹ awọn eeyan to n gbẹmi awọn ọmọ orilẹ-ede yii wo Olori ijọ Living Faith, ti wọn n pe ni Winners Chapel, Bisọọ́bu David Oyedepo ti fewe ọmọ mọ gbogbo awọn to n gbẹmi alaisẹ ni orilẹ-ede yii leti pe, ọjọ ẹsan wọn sunmọ etile, ti ilẹ yoo mọ ba osika wọn.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, nnnnnn Ṣaaju ikọlu naa lo ti jẹ ko di mimọ fun awọn ọdọ to n wọde naa pe gbogbo awọn to ba fara ṣeṣe lasiko ikọlu awọn janduku sawọn to ba n ṣewọde ENDSARS ni ipinlẹ naa ni ijọba yoo gbọ bukata owo itọju wọn.
Nítorí nígbà kan rí, àwa náà ń ṣe wérewère, à ń ṣe àìgbọràn, ayé ń tàn wá jẹ, a jẹ́ ẹrú ìfẹ́kúfẹ̀ẹ́, a sì ń jẹ ayé ìjẹkújẹ ní oríṣìíríṣìí ọ̀nà.
Ṣé kí n wá mú oúnjẹ mi ati omi mi ati ẹran tí mo pa fún àwọn tí wọn ń gé irun aguntan mi, kí n sì gbé e fún àwọn tí n kò mọ ibi tí wọ́n ti wá?
Moses gba ami-eye naa latari ipa re ti ko se ye sile ninu iko Super-Eagles, fun riran iko naa lowo lati pipegede fun idje boolu agbaye ti yoo waye lorile-ede Russia lodun ti a wayi.
Ayé mi wà ninu ewu nígbà gbogbo,ṣugbọn n kò gbàgbé òfin rẹ.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Everton pòkọ ìbànújẹ́ fún Chelsea pẹ̀lú 2-0 Man City pòkọ ìyà fún Swansea pẹ̀lú àmì ayò 3-2 nínu FA Cup Barcelona yóò kojú Man U nínú ìdíje Champions League Bi o tilẹ jẹ pe abajade ifẹsẹwọnsẹ naa ko lee ni ipa lara ilepa eyikeyi ikọ mejeeji ninu bi nnkan ṣe ri ṣaaju ninu idije naa, ireti wa pe awọn ikọ mejeeji yoo ta biọbiọ lati ṣe bi ọkunrin.
ti bere si n fehonuna han ni  oju popo
Ó sán ìbàǹtẹ́ mọ́ ìdí o sì pọ́n ìbàǹtẹ́ náà ni ìkólóbo.
Asaraya, ọmọ Natani, ni olórí gbogbo àwọn òṣìṣẹ́.
1 104487 Orilẹede Serbia 2172 31.
Ọ̀pá tírín kanlẹ̀ ó kan ọ̀run.
"Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Afurasí afipábánilópọ̀ kàgbákò, obìnrin tó jà lólè fi eyín gé nǹkan ọkùnrin rẹ̀ jábọ́ lásìkò ‘Blow Job’ Àwọn ọba alayé, Mínísítà àti gómìnà nílẹ̀ Yorùbá ṣèpàdé pẹ̀lú ìjọba àpapọ̀, àbọ̀ rèé ""Ìyá mi sì wà ní páńpẹ́ ajínigbé, ọlọ́pàá, irọ́ lẹ̀ ń pa pé ó ti gba ìdáǹdè"" Iná ṣẹ́yọ nílé ìtajà aya Ajimobi lẹ́yìn ọjọ́ mẹ́ta tó jáde opó Ìjọba Eko fẹ́ tú olùwọ́de EndSARs 253 sílẹ̀ lọ́jọ́ Ajé nínú 361 tó wà láhàámọ́ ""Ìfẹ́ akọ sákọ àti abo sábo tó wọ́pọ̀ ní Àríwá Nàíjíríà ló fa ìbínú Ọlọ́run"" Ọ̀pá àṣẹ Ọba Akiolu tẹ gbé, a kò ní fọwọ́ yẹpẹrẹ mu - Ìgbìmọ̀ Ọba l‘Eko yarí Olori Badra sọ̀rọ̀ nípa ayé rẹ̀, ó ní ẹ́ bá òun sọkún Aarẹ orilẹede yii, Muhammadu Buhari lo kọkọ saaju igbesẹ lati doola awọ to suyọ ninu ẹgbẹ APC nitori bi ile ẹjọ se yẹgi mọ alaga rẹ, Adams Oshiomole nidi."
tabi aṣojú ọba gẹ́gẹ́ bí ẹni tí ó rán láti jẹ àwọn tí ó bá ń ṣe burúkú níyà, ati láti yin àwọn tí ó bá ń ṣe rere.
Ẹni to ba bori ninu awọn mejeeji ninu ifẹsẹwọnsẹ toni yoo lanfani lati kopa ninu idije ere bọọlu awọn obinrin lagbaye lọdun 2019 lorilẹede Faranse nibi ti awọn ẹgbẹ agbabọlu mẹta yoo ti ṣoju ilẹ Afirika.
Ìdí tí Ọlọrun fi ṣe báyìí ni pé kí ẹnikẹ́ni má baà lè gbéraga níwájú òun.
fidio kan jade, ni eyi ti o gbe bi asofin Abbo ati olopaa se fi iya lọna
Awọn orin aṣa ati itan Yoruba, ijo ati gbigbe Egungun, Eyo ati Gelede kii gbẹyin.
Lasiko ti wọn ṣe ifilolẹ igbimọ ile aṣojuṣofin lori agbeyewo iwe ofin Naijiria, Mahmood kesi awọn aṣofin ọhun lati yara ṣiṣẹ yi ki idibo to wọle.
Awọn nkan ti Laycon to jawe olubori yoo ko lọ sile •Dubai trip for 2 Irinajo silu Dubai fun eeyan meji •Ile fulaati oni yaara ibusun meji •Ọgbọn miliọnu Naira •Irinajo lati lọ wo aṣekagba idije Champions League, ohun mimu Pepesi fun ọdun kan, ati firiiji Pepsi kan •Foonu OPPO RENO •Ọkọ jiipu Innoson G40 •Irinajo si ilu Dublin •Tẹlifisan ati firiji nla •Ati awọn nkan miran bi i indomie ati ipanu 'chinchin' Wo bi àṣekágbá ètò Big Brother Naija Lockdown ṣe lọ Ni deede aago meje alẹ ni eto naa, ti Ebuka Obi-Uchendu, ṣe atọkun rẹ.
Èso ilẹ̀ náà yóo jẹ́ oúnjẹ fún àwọn tí wọn ń ṣiṣẹ́ ninu ìlú.
Ìkùukùu kan bá ṣíji bò wọ́n, ohùn kan bá wá láti inú ìkùukùu náà tí ó wí pé, “Èyí ni àyànfẹ́ ọmọ mi, ẹ máa gbọ́ tirẹ̀.
Àkọlé àwòrán, Igbakeji Aarẹ Yemi Osinbajo dupẹ lọwọ Emir Ibrahim Zulu Gambari fun bi wọn ti ṣe n gba gbogbo ẹgbẹ lalejo lalai ṣegbe lẹyin ẹgbẹ kankan Àkọlé àwòrán, Awọn alatilẹyin ẹgbẹ APC meji yi n fi ifẹ han si igbakeji Aarẹladugbo Adeta nilu Ilorin Àkọlé àwòrán, Niwaju Mosalasi nla ilu Ilorin,awọn alatilẹyin ẹgbẹ APC n juwọ si Igbakeji Aarẹ Àkọlé àwòrán, Emir ilu Ilorin, Maimartaba Ibrahim Zulu Gambari gbalejo Igbakeji Aarẹ Yemi Osinbajo Àkọlé àwòrán, Igbakeji Aarẹ kọwọrin pẹlu awọn ọmọ ẹgbẹ APC lasiko abẹwo naa Àkọlé àwòrán, Abdulrahaman Abdulrazaq to n du ipo Gomina labẹ asia APC lo joko si apa ọtun Emir Ilorin Àkọlé àwòrán, Awọn ọmọ ẹgbẹ APC ladugbo Gaa Arẹmu nilu Ilorin tuyaya lati pade Igbakeji Aarẹ BBC News, Yorùbá Ìdí tí ẹ fi le è nígbàagbọ́ nínú ìròyìn BBC Ìlànà Lílò Nípa BBC Òfin Àṣírí Cookies Kàn sí.
" Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Tunde Kelani: Àwa ọmọ Nàíjíríà kò le è bá òyìnbó mọ́ láéláé nínú sinimá ṣíṣe Ara ilana ileeẹjọ ni bi wọn se gbe ẹjọ naa lọ sile ẹjọ giga nitori oun nikan lo lẹtọ lati gbọ ẹjọ onikoko meji ti wọn fi kan olujẹjọ ọhun, ti igbẹjọ yoo si bẹrẹ ni sansan.
Ṣugbọn a gbadura sí Ọlọrun wa, a sì yan àwọn olùṣọ́ láti máa ṣọ́ ibẹ̀ tọ̀sán-tòru.
A ti kọwé sí ìjọba àpapò làti pe agbaṣèṣe odò Asa padà- Gomina Kwara Bo ti lẹ jẹ pe, ẹgbẹ agbaboolu Frankurt ni ọpọlọpọ anfaani lati gba bọọlu wọ inu awọn ile Arsenal sugbọn ti nkan ko sẹnu u re fun wọn.
Gbogbo iye owo naa ti wọn fọwọ si naa wa jẹ biliọnu
Nítorí ó dára kí eniyan farada ìyà tí kò tọ́ sí i tí ó bá ronú ti Ọlọrun.
 Agbẹnusọ fún ìjọ ẹ̀sìn Islam naa, ni kò sí ẹni tó kú gẹ́gẹ́ bí àwọn èèyàn kan ṣe ń sọ káàkiri."
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Wo bí Sunday Orimola ṣe gba ikú ẹranko kú ní Ifon ni Ondo lórí ọ̀nà àtijẹ Bakan naa, awọn ọmọ naa wa daadaa ti wọn si ti bẹrẹ si nii ṣere lẹyin ọjọ mẹta ti wọn ti pari iṣẹ abẹ naa.
IbrahinBoyi so pe, eto ohun ti so ogoro awon agbe di oloro, ni eyi ti o seleri pe, awon agbe oniresi yoo tunbo maa satileyin fun akitiyan ijoba, lati le je ki orile-ede Naijiria ni ani-to ati ajese-ku ounje.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Wò ó bí Alaafin àti aya àkọ́fẹ́ rẹ̀, Olorì Abibat ṣe pàdé ní èwe Coronavirus ti fa ọ̀wọ́ngógó oúnjẹ ní ìpínlẹ̀ Eko, Kano, Rivers àti Abuja- NBS Àwọn èrò yarí lórí sísan owó àyẹwò covid-19 bí bàálù ilẹ̀ òkèèrè ti ba s'Abuja lẹyìn oṣù márùn ún Ẹ wo ààrẹ orílẹ̀-èdè tó ń ṣèdárò Ẹja akóredé tó d'olóògbé Àbá àpérò 2014 CONFAB lojútùú sí àtúnṣe ìwé òfin Nàìjíríà- Afenifere sáwọn sẹ́nẹ́tọ̀ Ìjọba ìpínlẹ̀ Ogun fún àwọn ọmọ ilé ìwé ní ìgbéga sí kílààsì tó kàn láì ṣe ìdánwó nítori Covid-19 Ninu atẹjade kan ti akọwe eto iroyin rẹ, Laolu Akande fisiti lo ti jẹyọ pe Osinbajo ke gbajare yii nibi agbeyẹwo isẹ iriju ọdun kinni awọn to dipo ilu mu.
Àjọ EFCC ní sáájú òhún ti mú onisiro owo ìpínlẹ̀ Imo Uzoho Casmir fún ríràn Okorocha lọ́wa láti jí owó tó to bílíọnù kan Naira kó lásiko ìdìbò gómìnà àti ilé ìgbìmọ asofin.
Kí ló wá nínú àbádòfin pínpín omi àti àwọn ǹkan inú omi tó ń mú awuyewuye wa?
Aregbesola wa gbosuba fun Salaam ti o fidi rẹmi ninu eto idibo egbe to waye sugbon ti o fiwa akọni han lati tele ipinnu egbe.
Ni ọjọ kọkandinlogun ni Keita pe awọn ọmọ igbimọ ijọba rẹ lati tun igbimọ ka nitori pe o ni oun ko nilo itajẹ silẹ, ki oun to gbe ijoba silẹ.
Ile-ise iroyin North Korea lojo Aiku(Sunday), fi esun kan orile-ede Amerika pe, ikilo o ni kaan-pa ohun, fun awon lati jawo lori sise-to ohun ija oloro naa, ni lati dojuko awon orile-ede Korea.
Kì í ṣe eniyan ni o ṣèké sí, Ọlọrun ni.
Nígbàmíràn àwọn ọmọdé á máa ṣeré lóríi yìnyín náà.
Ó dá mi lóhùn, ó ní: “Ẹ̀bi ẹ̀ṣẹ̀ ilé Israẹli ati ti Juda pọ̀jù.
Jamaica ati awọn orilẹede to wa ni agbegbe Caribbean: Awọn orilẹede bii Antigua, Saint Lucia ati agbegbe U.
Mo rí àwòrán oríṣìíríṣìí kòkòrò ati ti ẹranko, tí ń rí ni lára, ati gbogbo oriṣa àwọn ọmọ Israẹli tí wọ́n yà sí ara ògiri yíká.
Ṣugbọn ninu idaji esi ibo ti wọn ka, Oloye MKO Abiọla lo n leke, ti awọn eeyan si gba pe oun lo jawe olubori ninu ibo naa, nitori oun lo ni ibo to pọ julọ.
Bakan naa ni wọn sọ wi pe awọn yoo gbe tẹsiwaju lati fofin ọrọ aje ilẹ Russia, Joe Biden ni o dun mọ oun ninu bi o ṣe waye bẹẹ labẹ aarẹ Donald Trump, ti yoo si tẹsiwaju ni abẹ iṣejọba oun.
Àkọlé àwòrán, Awọn ọdọ naa pa ẹnu pọ sọ pe ohun kan ṣoṣo tawọn ọmọ Naijiria ni lati sọrọ fun ara wọn ni ori ayelujara ati pe ki wọn fi ẹtọ wọn silẹ jẹjẹ ki wọn si ma ṣe ofin yẹn mọ rara.
Iwadii ti ile-isẹ ajafẹtọ ọmọniyan, Oxfam gbe jade lo fihan wi pe owo awọn olowo yii le ni biliọnu mọkanlelọgbọn owo ilẹ okeere dọla.
Ohun tí mò ń wí fun yín ni mò ń wí fún gbogbo eniyan: ẹ máa ṣọ́nà.
Ni idahun si oro aare, gomina ipinle Kano,  Abdullahi Ganduje wa fi da aare loju pe oun yoo gba awon eniyan ohun ni towo-tese wonu egbe APC pada lai fi akoko sofo lojuna ati bere ise papo saaju idibo odun 2019 to n bo lona.
Ọpọ ọmọ Naijiria lo ti n fesi si ikede ileesẹ ologun lati bẹrẹ akanse eto igbogun tiwa ọdaran ti wọn pe ni Operation Crocodile Smile.
Awọn oluwọde yii ni wọn n kọ orin ibilẹ wa ati tipinlẹ Ekiti, ti wọn si gbe oniruuru akọle to n tabuku aarẹ Buhari ati ijọba rẹ lọwọ.
Bi o ṣe mọ wipe gbigbe ọrọ naa wa ọna ti o tọ yoo ran an lọwọ lati ri iranlọwọ gba si, lo mu ki o da Street Priests Inc (awọn alufa to n gbe loju popona) silẹ.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Boko Haram tún ṣọṣẹ́ ní Adamawa, ọ̀pọ̀ òkú ṣùn, àìmọye dúkìá jóná Ọjọ́ burúkú, èṣù gbomi mu ní Ṣagamu nígbà tí agbábọ́ọ́lù kan dèrò ọ̀run Oluwo kò gbọdọ̀ kọrin òwe tàbí bá àkọ̀ròyìn sọ̀rọ̀, kó má baà ba ẹjọ́ ara rẹ̀ jẹ́ - Ọ̀ràngún ṣàlàyé BBC Yorùbá gba àmì ẹ̀yẹ akọni nídìí àgbéga àṣà àti èdè abínibí Ẹ má sọ Amotekun di ẹgbẹ́ OPC, ẹ fi wá sínú ẹ̀ṣọ́ aláàbò - Miyetti Allah Buhari, kí ló dé tó fẹ́ dá $100m owó Abacha padà fún gómìnà Kebbi?
" Obinrin naa fikun ọrọ rẹ pe awon eeyan le ṣe isin ipari ọdun nile wọn lai lọ si ṣọọṣi.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Ní Tanzania, Aàrẹ John Magufuli fi èrò ọkan rẹ̀ han pé kò dáju pe àwọn akósilẹ̀ èsì àyẹ̀wò ti wọ́n ń gbé síta ni ilé ibùdó àyẹwò peye.
Ojude Oba 2019: Ọba Adetọna ní bí òun bá papòdà, ẹni tó bá dáńtọ́ ni kí wọ́n fi jẹ Awùjalẹ̀
8 118415 Orilẹede Kuwait 947 22.
Bi ọjọ ti n gori ọjọ, ti oṣu n gori oṣu, awọn ọmọbinrin mejeeji yii n dagba, wọn n to oju bọ, ti wọn si to ẹni to n yan isẹ ati okoowo ti wọn yoo se laayo.
yii nile ijosin irapada( Redeemed Christian Church of God,) City of Grace,niluu
Igbakeji Agbẹnusọ fun gomina ipinlẹ Eko, Gboyega Akosile lo sọ eyi lasiko to n ba BBC Yoruba sọro lori igbese ijọba lati ri wi pe ko si ẹkun omi ni ipinlẹ Eko.
Wọn kò lè mú ọ̀rọ̀ mọ́ ọn lẹ́nu lójú gbogbo eniyan.
Agbẹnusọ fun Ajọ EFCC, Wilson Uwujaren lo fi idi ọrọ naa mulẹ pe Fowler wa ni ileeṣẹ wọn lọwọlọwọ nibi ti wọn ti n fi ọrọ wa lẹnu wo.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ọmọ Sudan kan n ju asia orilẹede Sundan.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Àwọn ọ̀dọ́ ló mọ ìtumọ̀ 'Problem' Mo n wa'yawo - Falz 'Kékeré ni mo ti mọ̀ pé iṣẹ́ apanilẹ́ẹ̀rín l'ọ̀nà mi' Ìyá àwọn ọmọ mi lò mí láti gbé ẹbí tiẹ̀ ga - Ninalowo Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí 2 sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
Ó di ọdún mẹta tí mo ti ń wá èso lórí igi ọ̀pọ̀tọ́ yìí tí n kò rí.
 ""Ṣe ni wọn kò Ada àti ìbọn wá, tí wọn sì ń yinbọn sókè tako-tako, bẹ́ẹ̀ ni wọn sá ọpọ ọlọkada ni ada, tí wọn sì fara gba ọgbẹ lorisirisi, ọpọ wọn sì wà nílé ìwòsàn."
Èyí nìkan kọ́ ni wọ́n ṣe sí mi, wọ́n sọ ibi mímọ́ mi di eléèérí, wọ́n sì ba àwọn ọjọ́ ìsinmi mi jẹ́.
Maaka, Iyawo Makiri, bí ọmọ meji: Pereṣi ati Ṣereṣi.
"Syinka lo sọ èyí Soyinka fí kún pé ìjọba ilẹ̀ Gẹẹsì ń fi àpẹrẹ ""ti kò dára lélẹ̀"" Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!"
Ìgbà mẹ́rin ọ̀tọ̀ọ̀tọ̀ ní àjọ WHO tí ló ìrú ìkéde yìí tó fi mọ àsìkò ti Ebola gba gbogbo ìhà Ìwọ̀-òòrun Afirika láàrin 2014 -2016 tó pa ènìyàn tó lé ni ẹgbẹ̀rún mọkànlá.
Ninu atẹjade kan ti oludari eto iroyin ni ile iṣẹ eto ilera Adeola Salako fi sita,lorukọ Komisana fun eto ilera, Jide Idris, o sọ pe oku eeyan ogun ni wọn gbe lo si awọn ile igbokupamọ nipinlẹ Eko.
- Amina Zakari Ọmọ Nàíjíríà fèsì lórí ààrẹ NANS tó ń sèlérí ìbò fún Buhari Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Mọrèmi: Ọọ̀ni ní láìsi Mọrèmi, kò leè sí ilẹ̀ Yorùbá Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ronke Oṣodi: òótọ́ ọ̀rọ̀ máa ń korò gan ni f'áwa èèyàn Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
AMAA 2018 Ami eye fun asotan tile okere to dara ju
Nítorí gbogbo wa níláti lọ siwaju Kristi bí a ti rí, láti lọ jẹ́ ẹjọ́.
Ẹjẹ Amẹ́rika,ti Japan, ati Haiti lo wa lara rẹ Alawọdudu ni Baba Naomi Osaka,Leonard Francois ti o si jẹ ọmọ orileede Haiti.
Ní ìrọ̀lẹ́ ọjọ́ 11, oṣù Ẹrẹ́nà olùfèsì sí ọ̀rọ̀ ìṣèlú Naky Soto tí ó tún jẹ́ aya akọ̀ròyìn àti ajììjàǹgbara iṣẹ́ ìròyìn tí ó jẹ́ ọmọ orílẹ̀ Venezuela, Luis Carlos Díaz túwíìtì pé òun ti ń wá ọkọ òun fún wákàtí márùn-ún.
Iwadi naa ni ajọ FIFA se pelu ifọwọsọwọpọ awọn ẹka miran ninu ajọ bọọlu alafẹsẹgba.
Ẹbẹ yii ko sẹyin bi ajọ onidanwo NECO ṣe sun ọjọ idanwo to n lọ lọwọ siwaju nitori iwọde ENDSARS.
"SERAP pe Buhari, igbákejì rẹ̀ lẹ́jọ́ lórí àfikún owó iná àti epo bẹntiró Ìjọba Eko pàdánù ₦234m láàrín ọ̀sẹ̀ kan torí ìwọ́de End SARS Wo àwọn Ṣọ́ọ̀ṣì Nàìjíríà àti l'Áfíríkà tó ń wólẹ̀ àdúrà kí Trump lè wọlé ìbò ààrẹ America ""Buhari, ìwọ́de yóò yíwọ́, tó ba jẹ́ ki ológun bẹ̀rẹ̀ ‘Operation Crocodile Smile’ "" Bakan naa ni awọn ọlọkada naa fi ọkada wọn di oju ọna, ti wọn ko si jẹ ki ẹnikẹni kọja."
Ki     Ọlọrun tẹ awon to padanu ẹmi won si afẹfẹ
Ọbasanjọ, ninu atẹjade kan ti oluranlọwọ rẹ lori eto iroyin, Kẹhinde Akinyẹmi fi sita sọ pe, Ọbasanjọ sọ ọrọ naa nibi ipatẹ ọja ilẹ Afrika to waye fun igba akọkọ nilu Cairo l'orilẹede Egypt,.
Àwọn ìròyìn mìíràn tí ẹ lè nífẹ̀ẹ́ sí: Olè gbé òrùka ìgbéyàwó mì ní Eko 'Orí ló kó ọmọ mi yọ' Ọlọ́pàá tún ọ̀daràn mú lẹ́yìn ọjọ́ karún tó kurò lẹ́wọ̀n Agolo akẹ́rù Apapa kò pa ènìyàn ṣùgbọ́n ó ba ọ̀pọ̀ ọkọ̀ jẹ́- Ọ̀ga RRS Ṣugbọn nigba ti wọn pe ẹni to sọ pe o ran oun niṣẹ, Abubakar bẹrẹ si ni ka bi ẹyẹ.
Saulu wí fún Ahija, alufaa pé, “Gbé àpótí Ọlọrun wá níhìn-ín.
Idris, tí o ṣe lòdì sí ìpànìyàn ní ìpínlẹ̀ náà wí pé àwọn ọlọ́pàá ti jáde si'ta láti bẹrẹ ìwádìí fínífíní sí ìṣẹ̀lẹ̀ tí o là ẹ̀mí ọ̀pọ̀ èèyàn lọ yìí.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Real Madrid: Kí ni ká ti pe ìfarapa gbogbo ìgbàa Eden Hazard lórí pápá?
Àwọn àgbààgbà Israẹli kan tọ̀ mí wá, wọ́n jókòó siwaju mi.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù World theatre Day: Kosọkọ ní ètò adójútòfò wà fọ́jọ́ alẹ́ àwọn onítíátà 27 Ẹrẹ̀nà 2019 Oríṣun àwòrán, Jide Kosoko Isẹ tiata abi ere sise kii se isẹ to see fi ọwọ rọ sẹyin ni awujọ wa nitori pataki rẹ.
Joseph Hanlon: Ogójì tọ́ọ́nù heroin ló ń gba Mozambique kọjá
Man City fi ìkanra na Watford bolẹ̀ Ọmọ iná làá rán síná, Angel Maria fojú ọlá Real Madrid gbolẹ̀ Athletico bu omi la ìgara Christiano Ronaldo, ní Madrid Ẹgbé agbabóòlù Arsenal ṣe Frankurt báṣubaṣu pèlu ayò mẹta si odo.
Ati pe bi wọn ko ba wa ayipada si iṣakoso to wa lasiko yii, ohun ti yoo ṣẹlẹ si Naijiria si lẹyin rẹ yoo buru ju boṣe wa lọ.
Seba ati Salimuna bá dáhùn pé, “Ìwọ alára ni kí o dìde kí o pa wá?
Àwòrán rèé nípa àwọn gbajúmọ̀ tó ti bá Hushpuppi ṣe Oríṣun àwòrán, Others Lati igba ti awọn ọlọpaa ti mu gbajumọ ori ayelujara Instagram, Ramoni Abbas Igbalode, a.
" O ni gbogbo irinṣẹ ti wọn nilo lati tun afara naa ṣe lo ti wọle si orilẹ-ede Najiria, nitori naa ijọba yoo bẹrẹ iṣẹ ọhun ni kankan.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Àwọn olólùfẹ́ Bayern Munich ya wọ orí pápá lẹ́yìn ìdíje 26 Ìgbé 2018 Oríṣun àwòrán, AFP Àkọlé àwòrán, Àwọn olólùfẹ́ Bayern Munich yarí fún ọmọ egbẹ́ agbábọ́ọ̀lù náà Àjọ tó ń rí sí eré bọ́ọ̀lù nílẹ̀ aláwọ̀ funfun-UEFA ti fi ẹ̀sùn kan ikọ̀ agbábọ́ọ̀lù Bayern Munich lẹ́yìn tí àwọn olólùfẹ́ wọn ya wọ orí pápá.
Lakoko to n ba awon akoroyin soro ni ipari ipade awon amusese ijoba apaapo  ti o waye ni Ojo Ru Wednesday ,eyi ti igbakeji Aare Orile-ede Naijiria Ojogbon Yemi Osinbajo dari.
Nosa Okunbo, to n gbẹnusọ fun LASEMA sọ fun awọn oniroyin pe igbugbamu miran to waye lẹyin ti ina naa bẹrẹ, lo ba awọn ile to wa layika jẹ, bi ile ijọsin kan ati ibugbe awọn ọmọ ile iwe St Margaret, to wa lagbegbe ọhun.
Atejade latodo egbe oselu naa so pe, akikanju kan  ti o ja fun ominira orile-ede Zimbabwe ni odun 1970, Ambrose Mutinhiri fi egbe oselu ZANU-PF to wa lori alefa sile, bakan naa ni o fi ijokoo omo ile-igbimo asofin sile lojo-Eti, ni eyi ti o lo se ipade pelu  Mugabe  lojo-Aiku, lori igbese re tuntun.
Ẹsun yii lo n waye lẹyin ti fidio kan jade lori ayelujara, eyii to n ṣafihan bi awọn ẹbi awọn alaisan to wa nile iwosan ọhun ṣe n sun ita gbangba.
Àkọlé àwòrán, Alaafin Ọyọ nikan lo lee fi aarẹ Kakanfo Iyanda Ọbadoke Aṣubiaro Latooṣa Ni ọjọ kẹta oṣu kẹwa ọdun 1871 ni wọn fi Iyanda Aṣubiaro Latoosa jẹ aarẹ ọna kakanfo.
Àwọn Gómìnà ti ó ti jẹ lati ìgbà ti wọn ti dá ìpínlẹ̀ Èkó silẹ̀ ni wọnyi:
Ẹ rántí wípé ẹni ti o bá laanu ló lè ronú lati ran ẹlòmíràn lọ́wọ́.
Bakan naa ni iyalode tilu Osogbo, Oloye Awawu asindẹmade naa kin ọba lẹyin pe, wọn ko ta ere Ọsun amọ bi ọba ṣe le ọmọ iya Ọsun ni aafin lori asemase kan, lo mu ki iya Ọsun naa ko jade laafin.
 Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Bí ẹ ṣe mọ̀wé tó, ẹ wá dánrawò níbí pẹ̀lú ""Àpólà Ọ̀rọ̀ Orúkọ - Noun Phrase Makinde ni "" Bi awọn eniyan ba wa fẹ wọn o dibo fun, bi wọn o ba si fẹ, sugbọn ni ti Ọba, ọjọ to ba ti gori oye, o di igba to ba wọ aja lọ ba awọn baba rẹ, nitori naa, ko si nkan to le maa fa ija laarin oun ati Kabiyesi"" ""Mo tun fẹ fi da a yin loju lẹẹkan si pe, a o se gbogbo nkan ti o yẹ ka ṣe bi ijọba, kii se fun Olubadan nikan bikose se gbogbo awọn lọbalọba to ku nipinlẹ Oyo."
"Oríṣun àwòrán, Reuters Nibi awọn iwọde ṣe lo br si nii bọ: ""awọn baba nla baba mi ṣiṣẹ ni ile iṣẹ eedu north-east Pennsylvania"" ati pe inu tun bi i pe wọn ko ri iru anfani to wu wọn jẹ laye."
Bakaanna ni Gomina Ayo Fayose ti saaju sọ lori opo Twitter rẹ pe awọn ọlọpaa n yinbọn niwaju ile iṣẹ ijọba Ekiti.
O óo kó àwọn eniyan rẹ wọlé,o óo sì fi ìdí wọn múlẹ̀ lórí òkè mímọ́ rẹ,níbi tí ìwọ OLUWA ti pèsè fún ibùgbé rẹ,ibi mímọ́ rẹ tí ìwọ OLUWA ti fi ọwọ́ ara rẹ pèsè sílẹ̀.
OLUWA Ọlọrun mi, gbọ́ igbe èmi iranṣẹ rẹ, ati adura tí mò ń gbà níwájú rẹ.
Wọ́n lọ láti ibẹ̀ sí agbègbè olókè ti Efuraimu, wọ́n dé ilé Mika.
Ti wn ko ba ri oṣu lọjọ kọkandinlọgbọn, a jẹ wi pe ọgbọn ọjọ ni oṣu naa de.
Aare Buhari ni: “Asiko ti a n na anadanu owo ile okeere fi ko ohun jije wo Naijiria ti koja paapaa lori eto ogbin.
Abubakar wa salaye  fun awon osise olopaa ohun pe awon janduku to sa kuro ni ekun ariwa iwo oorun orile ede yii naa lo n da omi alaafia ekun Gusu  yii ru sugbon o fi da won loju pe ile-ise olopaa naa ti mura lati si won lowo ise ibi won, eleyii to je idi pataki ti oun fi pe ipade apero pelu gbogbo gomina ekun Gusu, awon  adari gbogbo pelu igbimo loba-loba lati wa ojutuu si ipenija yii.
Ọps àwọn to ní sọọbu ló fẹ́sẹ̀ fẹe lẹ́yìn ti wọn kó erù ti wọn lé kó dání.
Toyin sọ ninu iwọde naa pe ijọba gbọdọ tẹti si ohun tawọn oluwọde n beere fun.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Facebook: Gbogbo ojú òpó ìròyìn èké ní èdé Afirika pátá ló ń lọ 15 Ògún 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Gbogbo ẹyin tẹ n gbe iroyin eke ni ede abinibi lori ikanni Facebook, ẹ sunmọ bi, tori ọrọ yii kan yin.
 Awon ohun asaraloore yii maa n daabo bo oju paapaa ti eniyan ba ti darugbo.
Ki aarẹ Muhammadu Buhari to pada wa buwọlu u, o ti gba iwaju ile aṣofin kọja nigba mẹrin.
Nígbà tí wọ́n tají, wọ́n rí ògo rẹ̀ ati àwọn ọkunrin meji tí wọ́n dúró tì í.
Si eyi, ọpọlọpọ awọn to n tẹle Marley lo da si ọrọ naa ti wọn si n ṣe afikun tabi idi ti ọrọ rẹ ko fi ta leti wọn.
Ipo Akọwe Ijọba Apapọ lo n dije fun.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ìtàn tó rọ̀ mọ́ òwe ‘aṣọ kò bá Ọ́mọ́yẹ mọ́.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù BBC Yorùbá: Temidayọ Ọlọfinsawo ní kò rọrùn láti darí òṣìṣẹ́ ọlọ́pọlọ pípé Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ BBC Yorùbá: Temidayọ Ọlọfinsawo ní kò rọrùn láti darí òṣìṣẹ́ ọlọ́pọlọ pípé 19 Èrèlè 2019 Nigba to n sọrọ lori ajọdun ọdun kan BBC Yoruba, Temidayọ Ọlọfinsawo, tii se olootu ileesẹ iroyin naa ni ileesẹ ọhun ti se bẹbẹ laarin ọdun kan ti wọn da silẹ.
Ó bá mi rìn ní alaafia ati ìdúróṣinṣin, ó sì yí ọkàn ọpọlọpọ eniyan pada kúrò ninu ẹ̀ṣẹ̀.
Bakan naa, aare tun gbosuba kare lai fun gbogbo awon akonimoogba iko naa, ajo NFF ati awon ololufe lataari akitiyan ati ise takun-takun won eyi ti o n farahan ninu olokan-o-jokan esi ifesewonse ti iko Super-Eagles n gba.
Ní ọjọ́ kan náà, Jesu jáde kúrò nílé, ó lọ jókòó létí òkun.
Ẹwẹ, ijọba Aarẹ Muhammadu Buhari ti ni lootọ ni pe ibode ti awọn ti lo fa ki owo ọja o gbe pẹẹli soke si Ibodè tí a tì ló fa ọ̀wọ́ngógó owó ọjà- Ìjọba Naijiria.
Wọn tún ti ji ọ̀pọ̀ èrò kó ni Birnin Gwari Ìdigunjale Offa: Ọlọ́pàá gbé N5m sílẹ̀ Àwọn agbébọn fọ́ ọgbà ẹ̀wọ̀n ni Minna Irọ funfun báláwú ni, Boko Haram kò dawa lọnà rárá -Ọmọ ogun Naijiria ''Gbogbo igbiyanju to wa ni ikapa wa la n gba, ti a si ti sọ fun awọn mọlẹbi awọn ti wọn jigbe pe ki wọn pa ọkan pọ.
yoo so fun gbogbo wa patapata.
Ogun Flood: Ọ̀pọ́ Dúkìá ló sọnù ní 2019 lásìkò tí ìjọba ṣí dáàmù Ọyan Ṣáájú áti lẹ́yìn ìforúkọsílẹ̀ N-Power, ohun tó yẹ kóo mọ̀ rèé o!
Èkúté tó sàwárí bọ́mbù ilẹ̀ gbàmi ẹ̀ye wúrà fún iṣẹ́ takuntakun Wo ọ̀nà tí o fi lè dáàbò bo ọmọ rẹ lọ́wọ́ COVID-19 níléèwé Kò sí iléẹjọ́ tó le dá wa dúró, ìyanṣẹ́lódì yóò bẹ̀rẹ̀ ní Ọjọ́ Ajé - NLC Wo iye ìgbà tí ẹgbẹ́ òṣìṣẹ́ àtàwọn ọmọ Nàìjíríà ti ṣèwọ́de lórí àfikún owó epo bẹntírò Kọ́ sí i nípa àwọn oúnjẹ aṣaralóore tó yẹ kí Aláboyún máa jẹ Ẹ gbọ́ òhun tí àwọn olùdíjé sípò gómìnà nípínlẹ̀ Ondo sọ nípa bàbá ìsàlẹ̀.
Owo orilẹede tirẹ ki wọn to yọ owo ori, elo lowo osu rẹ jẹ lọdun?
Hesekaya sọ fún Aisaya pé, “Ọ̀rọ̀ OLUWA tí o sọ dára.
O ni agbara ofin lati pin awon fiimu ati fidio wonyi si isori isori lorisiirisii yala eyi ti a se nile tabi eyi to wa lati ile okeereOfin wa fun un lati se iforukosile awon fiimu ati fidio to n jade kaakiri Naijiria ati bee bee lo.
Ṣùgbọ́n ni àsìkò yìí ìjọba ìbílẹ̀ yìí ni Olusegun Mimiko ti wá tí ó sì wà lẹ́yìn ọkàn lára àwọn olùdíjẹ lábẹ́ Zenith Labour Party (ZLP) Agboola Ajayi.
Àwọn eniyan náà sì yọ̀ǹda fún wọn.
O ni igbese yii yoo da wahala sile laarin egbe awon osise ati ile-ise
Ìba ohun tí mo lè sọ fún ọ ni èyí, ọmọ mi’.
Ẹ yin OLUWA ní Sioni,ẹni tí ń gbé Jerusalẹmu!
Mo tún ní àwọn aguntan mìíràn tí kò sí ninu agbo yìí.
Ta ni Wolii Olapade Agoro tó re ibi àgbà ń rè tí ayé ń pariwo rẹ̀ yìí?
Ni Idi Aba, ni Abẹokuta nipinlẹ Ogun ni Akinlatun ti ilẹ̀ Egba ti gba alejo Arole Oodua nile rẹ fun ọrọ apero omọ eriwo naa.
Báyìí ní ìwé tí ìyàwó Wèrédìran kọ sii ri, ìgbà tí mo sì ti jókòó díẹ̀ nínú ilé náà lẹ́yìn èyí ni mo ti múra ti mo n lọ.
N kò tíì kọ́ ọgbọ́n,n kò sì ní ìmọ̀ Ẹni Mímọ́.
Saulu ranṣẹ ìkìlọ̀ kan sí àwọn ará Keni pé, “Ẹ jáde kúrò láàrin àwọn ará Amaleki, kí n má baà pa yín run, nítorí pé ẹ̀yin ṣàánú àwọn ọmọ Israẹli nígbà tí wọn ń bọ̀ láti Ijipti.
Òògùn aporó tí kò wọ́n rara yìí wà láti wo ara ríro níwọ̀n ba.
Adult Bedwetting: Kí ló ń fa kí àgbàlagbà má a tọ̀ sí ilé?
Gege bi ile-ise akoroyin TASS news agency lojo Aje(Monday) pe, ni bayii won ko ti mo idi pataki ti minisita naa se fe lo sabewo si Russia.
Benny Fortune Akinyemi wa fi ibeere le fun olori Aanu pe ''Nigba ti nkan n rọsọmu laarin olori ati Alaafin, ta lo gbọ si?
Ọ̀rọ̀ rere ṣe àjèjì sí ẹnu òmùgọ̀,bẹ́ẹ̀ ni irọ́ pípa kò yẹ àwọn olórí.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Yetunde Bakare dárà lórí ètò Ṣé o láyà, ẹ ràn án lọ́wọ́ nínú ìbéèrè tó ṣì Ọmọ meje lo wu Kanye West lati bi Lọwọ yii, West ti bi ọmọ mẹrin, ṣugbọn o sọ ninu ifọrọwerọ kan lọdun 2019 pe ọmọ meje pere lo wu oun lati bi.
Sugbọn wọn ko gbe Alfa Babatunde yọju sile ẹjọ rara nitori bi wọn se sun ẹjọ naa siwaju amọ agbẹjọro rẹ, wa nile ẹjọ .
Tamọtiye ti wọn n pe ni Tammy Abraham lo kọkọ ṣide iya lẹyin to gba goolu akọkọ sawọn fun Chelsea nigba ti ere bọọlu ọhun de iṣẹju mẹtadinlogun.
Ẹ̀ṣẹ̀ ìbọ̀rìṣà wà ní Gileadi, dájúdájú yóo parun; bí wọ́n bá fi akọ mààlúù rúbọ ní Giligali, pẹpẹ wọn yóo dàbí òkúta tí a kójọ ní poro oko.
Wọ́n ní àkókò kò dúró de ẹnìkan.
Adajọ agba ati minisita fun eto idajo lorile ede Naijiria ,Abubakar Malami tun wa gbosuba fun ile-ise to n seto iranwo owo fun ijamba pajawiri fun eto iranwo ti won se lati pari ise akanse yii.
 awon data spektroskopi unsaba je fifihan pelu spektrumu .
Àyàfi tí irúfẹ́ oge kan bá gbòde tójẹ́pé ṣòkòtò-ò-balẹ̀ l’olúwarẹ̀ nkúkú wá ká.
Àwọn Juu kò gbàgbọ́ pé ó ti fọ́jú rí kí ó tó ríran títí wọ́n fi pe àwọn òbí ọkunrin náà.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Atagitá Fẹ́mi Aníkúlápó-Kútì bá obìnrin lọ l‘Amẹ́rika Saraki, Dogara korò ojú sí ìgbésẹ̀ àti yọ Ortom Ẹ̀kún omi kò yọ àwọn akẹ́kọ̀ọ́ fásitì OAU sílẹ̀ Ìjọba gbẹ́sẹ̀ lé 2.
Mo gbé ẹrù mi lé èjìká níṣojú wọn.
O ni lẹyin naa loun ṣẹṣẹ lọ si ile iwe eyi ti baba oun fẹ, ki oun tiẹ to le ṣe ohun kohun.
Bi o tilẹ jẹ pe ko ri owo naa gba titi di oni, sibẹ lẹyin iriri yii si tun ni aisan de ba ilumọọka osere tiata naa, to si dubulẹ aisan.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ọba Thailand Vajiralongkorn sọ ẹ̀ṣọ́ rẹ̀ di olorí láàfin 2 Èbibi 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 8 Èbibi 2020 Oríṣun àwòrán, Reuters Ọba orile-ede Thailand ti jẹwọ ipo rẹ gẹgẹ bi alaṣẹ aṣeyiowu pẹlu bi o ti ṣe sọ ẹsọ rẹ di olori ti o si sọ di ayaba laafin.
Amọ eyi ko ri bẹẹ fun akanda ẹda kan, Jolaade Tella, tii se ẹni ọdun mẹtadinlọgbọn, ti ọba oke fi imọ isiro da lọla.
Ohun to ba ọpọ ninu jẹ julọ ni pe kani ko sa mọ ọlọpaa lọwọ ni, Funmilayọ to pa kẹyin i ba ṣi wa laye.
Babalola ni ''ọrọ owo ile ati awọn gbese ti o jẹ lo n ran lẹnu nigba ti o wa si ọdọ mi ni ago mẹrin ọjọ iṣẹgun.
Nafutali dàbí àgbọ̀nrín tí ń sáré káàkiri,tí ó sì ní àwọn ọmọ tí ó lẹ́wà.
Ahọ́n wọn dàbí ọfà apanirun,wọ́n ń sọ̀rọ̀ ẹ̀tàn.
Iyẹn ti a bá ṣe àfiwé rẹ pẹ̀lú àwọn orílẹ̀-èdè àgbáye tọ kù, bó tilẹ̀ jẹ́ pé ẹka ètò ìlera ọ̀pọ̀ ilẹ̀ Afirika kò kójú òṣùwọ́n.
Lẹ́yìn tí ẹ ti ṣe àgbèrè pẹlu ọpọlọpọ olólùfẹ́;ẹ wá fẹ́ pada sọ́dọ̀ mi?
A óo máa mú àwọn àkọ́bí ọmọ wa, ati ti àwọn mààlúù wa lọ sí ilé Ọlọrun wa, fún àwọn alufaa tí wọn ń ṣiṣẹ́ níbẹ̀, gẹ́gẹ́ bí a ti kọ ọ́ sinu ìwé òfin.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ramadan, wakati ṣọ̀tọ̀ọ̀tọ̀, kini ẹ mọ̀ nipa àwọn Yollywood?
"m ni ojú mi déédé fọ́ níbi tí mo ti ń darí ọkọ̀ ni Ọrẹgun Ikẹja -LASTMA Yesufa Mo ti kó kúrò nílé Olu Jacobs rí lẹ́ẹ̀mejì- Joke Silva ""Mo fẹ́ pa ara mi torí ojú àbùkù tí wọn ń fi wò mí pé mo fi iṣẹ́ abẹ bímọ"" Èmi àti Saheed kìí ṣe ọmọdé, a ti jọ ṣe Sinimá papọ̀, èyí túmọ̀ sí pé ìjà ti parí - Fathia Balogun Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí 2 sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn."
Ezekwesili: Irọ́ gbáà ni ẹgbẹ́ òṣèlú ACPN ń pa Fela Durotoye, olùdíje ipò ààrẹ ẹgbẹ́ òṣèlù ANN #BBCNigeria2019 Bakan naa, o fi hande wi pe aarẹ Buhari ti yan ẹlomiran, Ibrahim Tanko Muhammed gẹgẹ bi adele ni ipo adajọ Onnoghen.
mẹrinlelaadọta ninu ida ọgọrun lo duro fun inawo iṣẹ akanṣe nigba ti
Òṣìṣẹ́ ẹka arinrinajo ọkọ̀ òfúrufú Nàìjíríà fẹ́ gún lè iyanṣẹlodi 'Òkú bí àádọ́ta ni iná jó gúrú-gúrú ní mọ́ṣúárì l'Anambra' O ni ko si idi fun obinrin kankan ni ipinlẹ Ekiti lati bi ọmọ sile tabi awọn ile agbẹbi ibilẹ.
Nítorí náà, ẹnikẹ́ni tí ó bá ń jẹ burẹdi, tabi tí ó ń mu ninu ife Oluwa láìyẹ jẹ̀bi ìlòkulò ara ati ẹ̀jẹ̀ Oluwa.
Iṣẹlẹ yi waye lasiko ti Real Madrid n koju Alaves eyi ti wọn ti fidi rẹmi pẹlu goolu meji sookan.
Kí Aaroni ati àwọn ọmọ rẹ̀ máa wọ ṣòkòtò náà, nígbà tí wọ́n bá wọ inú àgọ́ àjọ lọ, tabi nígbà tí wọ́n bá súnmọ́ ibi pẹpẹ láti ṣe iṣẹ́ alufaa ni ibi mímọ́, kí wọ́n má baà dẹ́ṣẹ̀, kí wọ́n sì kú.
Ìwọ̀n tí wọn ń lò ní ibi mímọ́, èyí tíí ṣe ogún ìwọ̀n gera ni kí wọ́n fi wọ̀n ọ́n.
Orílẹ̀èdé Naijiria ti gba Àgbo Coronavirus ti ilẹ̀ Madagascar ṣe tọwọ́tẹsẹ̀!
Wúrà ni orí rẹ̀, àyà ati apá rẹ̀ jẹ́ fadaka, ikùn rẹ̀ títí dé itan sì jẹ́ idẹ.
Jakọbu kúrò ní Beeriṣeba, ó ń lọ sí Harani.
Oluwo ti ilu Iwo, Oba Abdulrasheed Akanbi ti kọ lẹta si Aarẹ orilẹede Naijiria, Muhammadu Buhari, fun igba akọkọ lori ipaniyan awọn Fulani darandaran ni orilẹede Naijiria.
Ẹni tí ó farada agbelebu, kò sì ka ìtìjú ikú lórí agbelebu sí nǹkankan nítorí ayọ̀ tí ó wà níwájú rẹ̀.
Asofin Ita gbagbo pe ohun ti awon se lowo bayii se pataki lati ri daju pe igbimo kookan se ojuse won lati sakojo iwa isuna naa.
Ilé-ìwé ti gbé ẹsẹ̀ lé ìṣẹ̀ṣọ́ọ Kérésìmesì nínú ọgbà ó sì ti sọ pàṣìpàrọ̀ ẹ̀bùn di èèwọ̀ ní ìpolongo ìtako àjọ̀dún Òyìnbó.
Ni ọjọ kejidinlogun oṣu kejila ọdun 1963 ni wọn bi aarẹ Burundi tẹlẹ to jade laye, Pierre Nkurunziza.
Ẹwẹ, ajọ ọtẹlẹmuyẹ DSS naa ti sọ tẹlẹ irọ ni iroyin to tan kalẹ kaakiri pe, ajọ naa ti fi ọwọ ofin adele alaga ajọ EFCC, Ibrahim Magu.
"Káńsélọ̀ Sajid Javid kọ̀wé fipò sílẹ̀ lẹ́yìn tí Boris Johnson ṣàtúntò ìjọba rẹ̀ Ẹ̀yin òṣèrè tíátà, ẹ ní ṣùúrù de àsìkò Ọlọ́run, ẹ máṣe kánjú kọjá kádàrá - Madam Ṣajẹ Lẹ́yìn ọdún 44 tó jáde láyé, igbá tí onírèsé Murtala Muhammed fín sílẹ̀, kò parun ""Iṣẹ́ ìgbóhùnsáfẹ́fẹ́ lórí rédíò máa ń mú ẹ̀wà àti àpọ́nlé ba ni àmọ́ kò lówó lórí"" Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 3 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 5 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!"
" Lati igba naa si ni wọn ti n pe ni ni Constituted Authority"" di oni."
Ni oju opo Facebook BBC News Yoruba, awọn eeyan kan lu minisita naa lọgọ ẹnu, wọn si tun kin ọrọ rẹ lẹyin bẹẹ ni awọn miran tun bu ẹnu atẹ lu rọ yii.
Nígbà tí Aaroni, ati àwọn ọmọ Israẹli rí Mose, wọ́n ṣe akiyesi pé ojú rẹ̀ ń kọ mànàmànà, ẹ̀rù sì ń bà wọ́n láti súnmọ́ ọn.
Lẹ́yìn náà, rán àwọn òkúta mejeeji mọ́ àwọn èjìká efodu náà, gẹ́gẹ́ bí òkúta ìrántí fún àwọn ọmọ Israẹli.
Àwọn tí ọ̀rọ̀ náà sóju wọ́n sàlàyé pé, àwọn tó n tẹ̀lé eégún náà kó onírúurú ǹkan ìjà tó léwu lọ́wọ́, ìdí nìyìí tí wọ́n fi mú ẹjọ́ náà lọ sọ́dọ ọlọ́pàá.
“Sọ fún wọn pé, èmi OLUWA Ọlọrun ní kí o bèèrè lọ́wọ́ wọn pé, ‘Ṣé àjàrà yìí yóo ṣe dáradára?
Àgbẹ̀nusọ fún gomina Bauchi Bala Mohammed Mukhtar Gidado, sọ fún BBC pé kò sí ǹkan to buru ninu ki àwọn alába siṣẹ gomina lọ pade ìyàwó rẹ̀ ni pápákọ ofurufu àti pé àṣà ní Agbẹnusọ lori ọ̀rọ̀ ìròyìn, ń fèsi lóri fọto kan to gba ayelujara opo twitter kan nípa bi àwọn kọmisona ṣe ń duro de ìyàwọ tuntun ti gomina Bala Muhammed ṣẹsẹ fẹ Ayẹyẹ igbeyawo melo ni Aarẹ Buhari lọ?
Ẹ fi ìlù ati ijó yìn ín;ẹ fi gòjé ati dùùrù yìn ín.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Kété tí wọ́n bá ti báa yín sùn tàn torí pé ẹ tóbi, ẹ gbà pé ìfẹ́ yẹn ti parí - Auntie Remi Ọlọ́yàn ńlá Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Federal Government scholarship 2021/2022: Wo bi o ṣe le fi orúkọ̀ sílẹ̀ fún ètò ẹ̀kọ́ ọ̀fẹ́ ìjọba Nàìjíríà28 Ọ̀wàrà 2020 Fídíò, Soyinka Cancer: Àṣe ara mi ni iso ti n run gbogbo bí mo ṣe n ṣèrànwọ́ lórí jẹjẹrẹ27 Bélú 2019 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Abajade ati adehun ti wọn fẹnuko le ni ipade alaafia naa f'oriṣanpọn, ogun si bẹrẹ.
Ṣugbọn Ọgbẹni Ade sọ pe iṣẹlẹ naa ṣẹlẹ si ọmọ oun nitori wọn kẹ eti ikun si ikilọ ohun.
Ẹlòmíràn yóo kọ ‘Ti OLUWA ni’ sí apá rẹ̀yóo máa fi orúkọ Israẹli ṣe àpèjá orúkọ rẹ̀.
NAFDAC, ninu atẹjade lati ọwọ adari ẹka naa, Arabinrin Mojisola Adeyeye fi lede, wi pe awọn eniyan n lo awọ ẹran maalu ti awọn ile-isẹ to n ṣe baata tabi baagi ra lati fi se pọnmọ ti awọn eniyan n jẹ.
Ilana idibo gbangba laṣa n ta yii jẹ ki eto ibo naa lọ geerege, ti awọn eeyan si dibo fun oludije to wọn lai fi ti ẹya, ẹsin ati ede ṣe.
Gbogbo èbúté yóo mì tìtìnígbà tí àwọn tí wọn ń tọ́ ọkọ̀ rẹ bá kígbe.
Joaṣi ọba kò ranti oore tí Jehoiada, baba Sakaraya ṣe fún un, ṣugbọn ó pa ọmọ rẹ̀.
Máṣe jẹ́ kí ibà Lassa pa ọ́, wo ọ̀nà láti dènà rẹ̀ Báwo ni Coronavirus ṣe n tànkálẹ̀ l'Afrika?
Ọgbeni Damian Opara, tó jẹ̀ alukoro ẹgbẹ́ náà fún ipínlẹ̀ Imo, fi àtẹ̀jáde síta pé kí àwọn ọmọ ẹgbẹ́ rẹ fà sẹ́yìn nínú ètò ìdìbò náà O ní ìgbésẹ̀ ìdìbò náà ti ń ni ǹkan míràn nínú, àfi ti àjọ elétò idìbò INEC bá gba àṣẹ ilé ẹjọ́ tó ga jùlọ pé kí wọn sún un síwájú.
Mo rò pé ohun tí ó dára ni pé kí eniyan má ṣe kúrò ní ipò tí ó wà, nítorí àkókò ìpọ́njú ni àkókò yìí.
E yí wà ní ìbámu pè̩lú ò̩nà tó ye̩, tó sì tó̩ láti fi báni lò nínú àwùjo̩ fún ire àti àlàáfíà àwùjo̩ náà nínú èyí tí ìjo̩ba yóò wà ló̩wó̩ gbogbo ènìyàn.
Tsige ko ṣẹṣẹ ma gbiyanju lati ditẹgbajọba.
Bo tilẹ jẹ wi pe awọn alakoso ti o yẹ ki o ba oniroyin sọrọ ko si ni ofiisi lasiko ti a ṣe abẹwo sibẹ, oṣiṣẹ kan ti o ni ki a fi orukọ bo oun lasiri lo tu iṣu de isalẹ ikoko lori papakọ ofurufu naa.
(LUC Charges) O si tun yọ ida mẹẹdọ́gbọn ninu ọgọrun un kuro fun awọn to ba tete san ti won lasiko yii.
Kó gbogbo ìṣòro rẹ lé OLUWA lọ́wọ́,yóo sì gbé ọ ró;kò ní jẹ́ kí á ṣí olódodo ní ipò pada.
Aare orile ede Naijiria Muhammadu Buhari ti so pe adari to ba lowo ninu iwa ibajẹ ,lati maa ji owo ilu ko si apo ara re, ti o si kuna lati san eto awon osise fun won , yoo foju ba ile-ejo.
Mo gbé ẹrù mi jáde lọ́sàn-án gangan bí ẹrù ẹni tí ń lọ sí ìgbèkùn.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Orúkọ ọmọ ni Yorùbá gbà pé ó máa ń ro ọmọ nílẹ̀ Oodua Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Orúkọ ọmọ ni Yorùbá gbà pé ó máa ń ro ọmọ nílẹ̀ Oodua 20 Òkùdu 2019 Kí ede ati àṣà Yoruba ma baa parun ni a ṣe da BBC Yoruba silẹ ni Naijiria.
Ninu ohun taa mu tọ yin wa naa tun ni iroyin itakoọrọ to waye laarin Seyi Edun ati eeyan kan to ranṣẹ eebu si loju opo Instagram.
'Mo ti gbà pé lóòtọ́ ni ọmọ mi ní àárùn ọpọlọ Pẹ̀lú ìròyìn tó ń tẹ̀ wá lọ́wọ́, kò sọ́nà fún àwọ́n arìnrìn àjò káàkiri oríllèdè Nàìjíríà láti wọ ọkọ̀ bàálù lọ ibikíbi.
Ajọ eleto pajawiri ni ipinlẹ Eko, Lasema ni, gomina Sanwo-Olu gbe igbeṣẹ yii lẹyin ti awọn Alaga ijọba ibilẹ naa ke gbajare si fun ipese eto iranwọ.
Ta ni Nana Akufo- Addo to wọle ibo aarẹ Ghana lẹẹkeji?
Olori Macerata, (Mayor) Romano Carancini sọ wipe ida mẹsan ninu ọgọrun ninu awọn olugbe ilu naa jẹ awọn aṣikiri tabi arinrinajo.
N óo mú ìlera ati ìwòsàn wá bá wọn; n óo wò wọ́n sàn, n óo sì fún wọn ní ọpọlọpọ ibukun ati ìfọ̀kànbalẹ̀.
Minisita ni o ṣeni laanu pe pe awọn mejeeji ṣagbako iku ojiji lai le jẹ ohun ti wọn fẹ jẹ laye.
N óo láyọ̀ ninu ọkàn minígbà tí o bá ń sọ òtítọ́.
Oríṣun àwòrán, dailypost Ọjọru ni ajọ SERAP ke pe awọn ọmọ Naijiria ti ọrọ naa ba bi ninu lati fi orukọ wọn ranṣẹ ki awọn le fi orukọ wọn sara awọn to n pe ijọba lẹjọ lori ọrọ naa.
Oríṣun àwòrán, Facebook/Bolaji Abdullahi Àkọlé àwòrán, Bolaji Abdullahi nibi ikede iferongba lati dije Gomina Ni ọjọru ni o kede erongba rẹ ni Ilu Ilorin niwaju awọn alatilẹyin rẹ.
25 Bélú 2020 Adeyeye Ile Ife: Kílódé tí Ọọni Ife, Oba Ogunwusi kò fi gbọdọ̀ rí ọmọ rẹ̀ tuntun títí di ẹ̀yìn oṣù mẹ́fà?
Ni mànàmáná bá bẹ̀rẹ̀ sí kọ, ààrá ń sán, ilẹ̀ ń mì tìtì, tóbẹ́ẹ̀ tí kò sí irú rẹ̀ rí láti ìgbà tí eniyan ti dé orí ilẹ̀ ayé.
Ninu atẹjade kan ti wọn fi ṣọwọ lori Facebook,wọn ni awọn ko kọ lati wọ ẹni ti o ba n pin iru iroyin ayederu bẹẹ lọ si ile ẹjọ.
11 Béèrè kí ìwọ lè mọ̀ àwọn ohun ìjìnlẹ̀ Ọlọ́run, àti kí ìwọ baà lè túmọ̀ àti lati gba ìmọ̀ nínú gbogbo àwọn àkọsílẹ̀ àtijọ́ wọ̃nnì èyítí a ti fi pamọ́, tí wọn jẹ́ mímọ́; àti gẹ́gẹ́bí ìgbàgbọ́ rẹ ni a ó ṣe fún ọ.
Tí a fiṣọwọ́ ní 12:46 11 Òkùdu 201912:46 11 Òkùdu 2019 Ovie Omo-Agege borí gẹ́gẹ́ bí ìgbákejì ààrẹ ilé aṣòfin àgbà Ovie Omo-Agege jawe olubori pẹlu ibo mejidinlaadọrin eyi to fi la Ike Ekweremadu mọlẹ to ni ibo mẹtadinlogoji.
Ọkùnrin kọ́ ló ra jeep fún Iyabo Ojo, òógùn ojú mi ni mo fi rà á fun Àwọn ọ̀dọ́ l‘Eko yarí, ìwọ́de tó tako ọlọ́pàá SARS gbòde Ohun méjì yìí ní Buhari gbọ́dọ̀ ṣe ká tó wọlé padà - ASUU Adìyẹ́ jẹ̀fun ara wọn!
Yan àwọn tí o fẹ̀ fún ẹgbẹ agbábọ́ọ́lù ààyò rẹ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ijinigbe: BBC ṣe ìwádìí bí ikọ̀ IRT ṣe ń gbéjà ko awọn ajinigbe lójú Adajọ agba, Mojisola Olatoregun tẹ pẹlẹ mọ ọ pe wọn funra pe owo naa jade latari iwa magomago.
Jehoṣafati ọmọ Ahiludi ni olùtọ́jú àwọn àkọsílẹ̀ ní ààfin ọba.
Buhari fi àmì ẹ̀yẹ dá olóògbé Adadevoh tó dènà Ebola l'ọ́lá Awọn ọmọ ìjọ sàtánì ń bínú sí Nàìjíríà COZA: Mi ò fípá bá obìrin lò pọ̀ rí láyé mi - Pásítọ̀ Fatoyinbo Omotola Ekehinde, Ezekwesili, Funmi Iyanda dá sí ẹ̀sùn ìfipábánilòpọ̀ Fatoyinbo Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
O tun jẹ agbabọọlu ọmọ Argentina tó gbà ife ẹyẹ agbaye gẹgẹ bi Balogun ikọ ọmọ agbabọọlu Argentina.
Fun apẹẹrẹ, dida ileesẹ ajọ ẹṣọ oju popo, FRSC, papọ mọ ileesẹ Ọlọpaa.
" Okun ati imisi naa si lo fẹ ẹ lo fi dari orilẹ-ede bayii.
Apapo osuwon akosile oro aje, odiwon ati awon akosile miiran ti won fi se iwadii bi alekun tabi adinku se n ba eto oro ajo lorile-ede Nigeria.
Iko agbaboolu Roma fagbahan Liverpool pelu ami-ayo merin si meji (4-2), sugbon apapo ami-ayo ohun ni o ran iko agbaboolu Liverpool lowo lati jawe olubori, leyin ti ifigagbaga naa pari si ami-ayo mefa si meje (6-7).
Nítorí pé bí olódodo bá ṣubú léra léra nígbà meje, yóo tún dìde,ṣugbọn àjálù máa ń bi ẹni ibi ṣubú.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Teni entertainer: Idi ti mí kìí fi ṣí ìhòhò mi bi àwọn olórin obinrin míran Yemisi Oyedepo Broadcast Journalist 18 Ọ̀pẹ̀̀ 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 13 Ọ̀wàrà 2020 Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Tẹniọla: Pè mí láago tí o bá mọ iyán gún pẹ̀lú ọbẹ̀ ilá tó dùn Yoruba bọ wọ́n ni bí fingbáfingbá kò bá fingbá mọ, èyi to tí fin silẹ̀ kò ni parún.
Ó jagun gẹ́gẹ́ bí akikanju, ó ṣẹgun àwọn ará Amaleki.
’Kó àwọn ọmọ mi ọkunrin wá láti òkèèrè,sì kó àwọn ọmọ mi obinrin wá láti òpin ayé,
Ìrìbọmi ni èmi fi ń wẹ̀ yín mọ́ nítorí ìrònúpìwàdà.
“N óo jẹ́ kí ọkàn ọpọlọpọ eniyan dààmú nígbà tí mo bá ko yín ní ìgbèkùn lọ sí ilẹ̀ tí ẹ kò dé rí, láàrin àwọn orílẹ̀-èdè ayé.
Èrò àwọn ènìyàn lórí ẹ̀rọ àyélujára nípa ìdámẹ́wàá sísan
lọkọ ̀ bá ṣí , Ó dòkè lójú sán mọ ̀ eré burúkú kí ọkọ ̀ máa sáré ẹgbẹ ̀ rún mẹ ́ wàá kìlómítà láàrín wákàtí kan .
Orile-ede South Africa ko tete fesi lori idi ti ko se fowo siwe adehun naa lose to koja, awon miiran duro si abala ti orile-ede  Botswana, South Africa, Nambia, Burundi, Eritrea, Benin, Sierra Leone ati orile-ede Guinea Bissau duro si.
Wọn yóo bọ́ aṣọ lára rẹ; wọn yóo kó gbogbo nǹkan ọ̀ṣọ́ rẹ lọ.
Paulu wá sọ fún balogun ọ̀rún ati àwọn ọmọ-ogun náà pé, “Bí àwọn ará ibí yìí kò bá dúró ninu ọkọ̀, kò sí bí ẹ ti ṣe lè là.
Fun idi eyi, wọn ni ina awọn ko lee wọ mọ lorilẹede yii.
Kollington ni ko le se ki ija ma wa laarin awon eniyan laye.
 O pari ọọ rẹ pe ko le si idagbasoke lawujọ ibi ti ibẹrubojo ati abo ti ko peye wa."
Ní ọdún kejilelaadọta tí Asaraya jọba ní Juda, ni Peka, ọmọ Remalaya, jọba lórí Israẹli ní Samaria, ó sì wà lórí oyè fún ogún ọdún.
Ninu òfin yín a kọ ọ́ pé òtítọ́ ni ẹ̀rí ẹni meji.
(N140) bere lati ojo kọ́kànlélógún di ojo kárùndínlọ́gbọ̀n osu keji odun ti a
Oorun ti gbé obinrin tí ó wà ní ẹnu ọ̀nà, tí ń fẹ́ ọkà lọ́wọ́ lọ, ó sùn lọ fọnfọn.
Ó di omi papọ̀ ninu ìkùukùu rẹ̀ tí ó nípọn,sibẹ ìkùukùu kò fà ya.
Nítorí pẹlu ọpọlọpọ ìdààmú ati ọkàn wúwo ni mo fi kọ ọ́, kì í ṣe pé kí ó lè bà yín lọ́kàn jẹ́ ṣugbọn kí ẹ lè mọ̀ pé ìfẹ́ tí mo ní si yín pọ̀ pupọ.
Wo àwọn ìlérí tàwọn Gómìnà tuntun ṣe nínú ìbúra wọn Ará ìlú dájọ́ oró fún ọkùnrin to bẹ́ orí ẹ̀gbọ́n rẹ̀ ní Cross River Kíni N11trn owó ìrànwọ́ epo tí ìjọba àpapọ̀ san fún àwọn agbépo lè rà?
ogbeni Mdude Nyagali pupo , ni eyi to je ki o rẹẹ, ti o si soro fun un lati sọrọ;
Ẹgbẹgbẹrun awọn oṣisẹ eleto aabo lo n wa ẹkun to n kaakiri orilẹ-ede India, lẹyin to ti pa eniyan marun un.
Ghana fagbahan Gabon ti won n gbalejo idije naa pelu ami ayo marun un si odo ni papa isere Stade de Port Gentil.
Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Sex For Marks: Ọwọ́ ọlọ́pàá tẹ olùkọ́ tó n fipa bá akẹ́kọ̀ọ́ tó n ṣe ìdánwò WAEC sùn' l'Ogun12 Owewe 2020 Fídíò, Ifipabanilopọ ma n fa ọgbẹ ọkan11 Ẹrẹ̀nà 2018 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Àwọn mejeeji dá majẹmu níwájú OLUWA; Dafidi dúró ní Horeṣi, Jonatani sì pada sílé.
O ni, egbe to n mojuto kara-kata
Ó mi ọfà, ó bá oriṣa sọ̀rọ̀, ó sì woṣẹ́ lára ẹ̀dọ̀ ẹran.
Irú ẹni bẹ́ẹ̀ ń ṣe ìgbéraga nípa ìran tí ó ti rí, ó ń gbéraga lásán nípa nǹkan ti ara rẹ̀; 
Basiru ni o ṣeni laanu pe ajọ iṣọkan ilẹ Adulawọ ko ri ohun kanakn to ṣe gboogi ṣe lori ọrọ yii.
Ìdálẹ́bi náà ni pé ìmọ́lẹ̀ ti dé sinu ayé, ṣugbọn aráyé fẹ́ràn òkùnkùn ju ìmọ́lẹ̀ lọ, nítorí iṣẹ́ wọn burú.
wa laarin oun ati aare Julius Maada Bio gboro si fun idagbasoke orile-ede
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Assistant Commissioner of Police: Àwọn afurasí ṣá ìgbákejì kọmísọ́nà ọ̀gá ọlọ́pàá láàké dójú ikú 2 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Oríṣun àwòrán, Nigerian Police force Iroyin ti jade awọn afurasi kan ti fi aake ṣa igbakeji kọmisọna ọlọpaa, ACP.
Kí aadọtalenirinwo (450) àwọn wolii oriṣa Baali ati àwọn irinwo (400) wolii oriṣa Aṣera, tí ayaba Jesebẹli ń bọ náà bá wọn wá.
O tesiwaju pe, eto isuna owo ohun se pata ki, ati anfaani nla lati le pese awon ohun ti o ye ni sise ni ipinle naa, bakan naa ni isuna owo odun 2018 yoo se adinku owo yiya, eyi ti o le ko ipinle naa sinu gbese airotele.
 O ni, o maa n gba owo ati asiko lati jana awon onibara won.
Ṣugbọn kí ni mo lè sọ?
Suliya ní òun kò si lára àwọn tó lọ já ilé ìtàjà ńla náà sùgbọ́n agbègbè náà ni òun wà nígbà ti rògbòdìyàn náà ṣẹlẹ̀.
Awọn olugbe agbegbe ọhun ni ileesẹ ologun lorile-ede Naijiria ati awọn baluu ogun ko ipa takuntakun lati le awọn agbebọn naa jinna.
Tope Alabi, Ron Kenolly àtàwọn míì yóò kọrin níbi ọjọ́ ìbí àṣẹ̀yìndè fún olóògbé Ighodalo lónìí
martha karua ( bi ni odun 1957 ) je oloselu ni ilu kenya.
kí o mú un wá siwaju Eleasari alufaa ati gbogbo àwọn eniyan, kí o sì fún un ní àṣẹ lójú wọn.
'Mo ṣẹṣẹ gba ipe naa tan ni, koda mi o le sọ bi inu mi ṣe dun to.
" Ipinlẹ Ọyọ wa lara awọn ipinlẹ to n fara kaasa wahala yii paapaajulẹ lawọn agbegbe okeogun, Ọgbomọsọ ati Saki.
Nígbà míì a fi ẹni ibi sílẹ̀, a mú ẹni ire lọ.
 Chris wa fi idi rẹ mulẹ pe to ba jẹ pe lootọ ni oun huwa ọdaran, ko lee pẹ rara ti ẹnikan yoo fi da oun mọ."
Adele alase fun ajo to n mojuto ilera alabode ni Abuja, Onisegun oyinbo Mathew Ashikeni lo so eyi di mimo lasiko to n ba awon oniroyin soro ni Abuja.
Nígbà tí Saulu gbọ́ pé Dafidi wà ní Keila, ó sọ pé, “Ọlọ́run ti fi Dafidi lé mi lọ́wọ́, nítorí ó ti ti ara rẹ̀ mọ́ inú ìlú olódi tí ó ní ìlẹ̀kùn, tí ó sì lágbára.
Nígbà tí Ẹja dé ọ̀dọ̀ onígbèsè, ni ó bá barajé, Ó ṣòrọ̀ àbùkù òhun ẹ̀tẹ́ sí onígbèsè.
Ikú wá, òun àti ìyàwó-o rẹ̀ Àrùn.
Akonimoogba agba iko agbaboolu Zenit St Petersburg naa, se ipade po pelu asoju ajo FA orile-ede Italy, Alessandro Costacurta ati oludari agba iko agbaboolu naa, Gabriele Oriali fun wakati meji gbako niluu Rome nirole ojo Aje(Monday).
Bẹ́ẹ̀ ni kí ẹ ṣe, kí OLUWA Ọlọrun yín lè bukun ohun gbogbo tí ẹ bá ń ṣe.
Eyi to ba si le pupọ, wọn yoo da ẹni naa duro sileewosan, ni ẹka ti wsn ti n ṣe iranlọwọ fun eemi.
Coronavirus protest: Àwọn Dókítà fáríga nípìnlẹ̀ Ondo,wọn ní kí Gomina san owó oṣù mẹ́ta tó jẹ wọ́n!
NUT ní àìsí àbò ń ṣàkóbá fún àwọn olùkọ́ ní Nàìjíríà
Gomina Godwin Obaseki se afikun rẹ wipe, irufẹ igbimọ yi, ti oun yoo lewaju rẹ nipinlẹ naa, ni ọga ọlọpa ipinlẹ Edo, oludari ileesẹ ọtẹlẹmuyẹ ipinlẹ naa, olori ileesẹ ologun ati awọn eeyan lati ẹkun idibo mẹta to wa nipinlẹ Edo yoo jẹ ọmọ igbimọ.
A gbìn ín pẹlu ara ti ẹ̀dá, a jí i dìde ní ara ti ẹ̀mí.
Ninu igbẹjọ naa, adajọ Adedayo Akintoye ni Joel jẹbi ẹsun pe o pa Adeleke ni ile rẹ to wa ni Parkview Estate, Ikoyi, lẹyin ti arabinrin naa ran an lọwọ lati fun ni iṣẹ.
Ṣe ni awọn ara abule yii la ẹnu sílẹ lai lee pa de mọ, nitori o han daju pe irọ ni Gbadero n pa.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù 'Sẹ́ríkí Fúlàní ní ìpínlẹ̀ Ọṣun ní kò sí ìdí fún àwọn darandaran láti kúrò l'Ọ́ṣun 25 Bélú 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Ni opin ọsẹ to kọja ni okiki kan nipa iṣẹlẹ kan eyi to ṣẹ ninu eyi ti ara ti san pa maluu ti ko din ni mẹtadinlogun ninu agbo ẹran darandaran fulani kan ni ilu Iba ni ipinlẹ Ọṣun.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, CAN: Samson ni ọrọ awọn ajinigbe ti gba àpérò ní Naijiria Eyi si yatọ patapata si agbekalẹ gaa Fulani ti Ruga ti ijọba Buhari n gbero yii.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ìdìbò Ekiti; àáyá bẹ́ sílẹ̀, ó bẹ́ áré Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ekiti Election: Ará Èkìtì ń fẹ́ gómìnà tí yòò tù wọ́n lára Chibok Girls: ilé ejọ́ ju ajínigbe sẹ́wọ̀n Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, #EkitiDecides: Fayose sùn lórí ibùsùn aláìsàn Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
-Big Brother sọ fún Dorathy Ìwé èsì àyẹ̀wò arùn Covid-19 lè di kòṣeémàní fáwọn tí o bá fẹ́ rìnrìn àjò sí ilẹ̀ òkèèrè Wo oríṣìí ìlù Yorùbá, ìwúlò wọn àti ba ṣe ń lò wọ́n Àwọn òṣèré tíátà Yorùbá kọjú ìjà síra wọn lórí ìdárò akẹẹgbẹ́ wọn tó kú Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Olusegun Obasanjo sọ̀rọ̀ síta pé ọpẹ́lọpẹ́ Walter Carrington láyé òun nígbà tí Sani Abacha ń lé òun kíri18 Ògún 2020 BBNaija: Terry Waya sọ oun tó fojú Kiddwaya rí nílé nígbà tó ń bẹ̀bẹ̀ láti lọ BBNaija28 Ògún 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Láyé àtijọ́, iṣẹ́ Ọdẹ jẹ ikan ninú iṣẹ gidi ni ile Yorùbá.
Fake News; Àwọn iròyin ẹlẹ́jẹ̀ márùn ún tó fẹ́ẹ̀ tú Nàìjíríà ká
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Waste to Wealth: Ẹ̀gbin tìrẹ ni èròjà táwọn èèyàn míràn fi n ṣiṣẹ́ ajé, okoòwò ńlá ni Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 3 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 5 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Ifẹ Oyedele ni oun gbe igbesẹ naa lati lee ṣe atilẹyin fun gomina Rotimi Akeredolu.
Mo ké pè ọ́; gbà mí,n óo sì máa mú àṣẹ rẹ ṣẹ.
"Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: ""Àwọn ajínigbé yìí dájú o, wọ́n fipá bá obìnrin mẹ́rin ló pọ̀ níwájú mi"" Ìgbeyàwó túka nígbà tí afipábánilópọ̀ fi fídíò aya àfẹ́sọ́nà sórí ayélujára Sotitobire: Ojú àwọn Wòlí tó tí lọ sẹ́wọ̀n lórí ẹ̀sùn ọdaràn tẹ́lẹ̀ rèé Tí wọ́n bá kó owó wá fun yín lásìkò ìdìbò, owó tí wọ́n jí ni o, ẹ gbà á àmọ́."
Ọjọ Iṣẹgun ni aba naa de ipele keji nile eleyi to mu ki ọpọ tako o lori ayelujara.
Ṣugbọn sibẹ inú Ọlọrun kò dùn sí ọpọlọpọ ninu wọn, nítorí ọpọlọpọ wọn ni wọ́n kú dànù káàkiri ninu aṣálẹ̀.
4 Àti pé èyí ni ẹ̀yin yíò ṣe kí ìránṣẹ́ mi Joseph Smith, Kékeré, má baà di píparun, kí èmi baà lè mú àwọn èrò òdodo mi ṣẹ sí àwọn ọmọ ènìyàn nínú iṣẹ́ yìí.
 ilagbaralori ati isiseabinimoju ) , pelu ogun latodo obi si omo , ati pelu ipinkari , iyasoto ati iyipada larin awon olugbe .
EndSARS Protest Update: DJ Switch ṣàlàyé ohun tójú rẹ̀ rí níbi ìfẹ̀míṣòfò àwọn olùwọde EndSARS ní Lekki
Ẹwẹ, lẹyin ipade naa, aarẹ dupẹ lọwọ awọn ọmọ ile igbimọ aṣofin fun bi wọn ṣe n ṣe iṣẹ wọn ti wọn si n hu iwa ire.
Ayẹwo ti wọn ṣe fun eku fihan pe yiyọ awọn sẹẹli naa le mu adinku ba ipa ti didarugbo n ni lara.
Aare ti ya owo pupo soto lati fi Satunse awon ibi to baje wonyi.
Mose bá dá wọn lóhùn pé, “Ẹ dúró di ìgbà tí mo bá gbọ́ àṣẹ tí OLUWA yóo pa nípa yín.
àwọn ni wọ́n ń kọ orin ninu Àgọ́ Àjọ títí tí Solomoni fi kọ́ ilé OLUWA parí ní Jerusalẹmu; àṣegbà ni wọ́n ń ṣiṣẹ́ wọn.
Igba akọkọ kọ niyii ti iṣẹlẹ yii n waye.
N óo múra láti hu ìwà pípé pẹlu ọgbọ́n;nígbà wo ni o óo wá sọ́dọ̀ mi?
Àwọn eniyan yóo máa gbé inú ìlú Jerusalẹmu, kò ní sí ègún mọ́, ìlú Jerusalẹmu yóo sì wà ní alaafia.
" Àkiyèsí àti ìwádìí yìí ni àwọn eléde gẹ ̀ ẹ ́ sì ń gọ ́ ka sí nígbà tí àwọ ́ n ba sọ pé "" language is culturally transmitted "" ."
Iṣẹ́ bọ́ lọ́wọ́ ọ̀gá ilé iṣẹ́ tó bẹ́nu àtẹ̀ lu Obinrin Àwọn olùdíje Ọṣun jẹ́wọ́ ara wọ́n Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'A máa ń bẹ́ orí ẹni tó bá gbé imọlẹ̀ ọdún ìjẹṣu tó bá ṣubú ni' Linda kọ̀ láti jẹ̀ kí àwọn olólùfẹ́ rẹ mọ orúkọ ọmọ tuntun náà bó ṣe pe orúkọ rẹ̀ ní baby J láti osẹ̀ tó kọjá Ikeji tó jẹ olówó jùlọ nínú àwọn àkọroyìn ori àtagbà tí ṣe ìkíni kààbọ fún ọmọ tuntun náà ní orílẹ-èdè Amẹrikà láti osẹ̀ tó kọjá nígbà ti wọn ń reti ọmọ jòjòló.
Ǹ bá fò lọ, ǹ bá lọ sinmi.
"Tems ti gba ìtúsílẹ̀ lọ́gbà ẹ̀wọ̀n Uganda Wọ́n ní kí ọ̀gá àgbà ""Ede Poly"" lọ rọ́kún nílé lórí ẹ̀sùn pé ó kan bẹ́ẹ̀dì sí ọ́fíìsì Adajọ́ Àgbà Naijiria, Tanko Muhammad ti ní Covid-19 Wo àwọn Adelé-Ọba aládé méje tó jẹ́ obìnrin nílẹ̀ Yorùbá Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Kollington ṣàlàyé bí orin Fuji ṣe bẹ̀rẹ̀ gan an ní Nàiìjíríà Olugbenga ni ko si ọlọpaa kankan ni ipinlẹ Oyo to farapa tabi ti wọn jigbe nitori iṣẹlẹ yii."
Nítorí mo mọ ẹni tí mo gbẹ́kẹ̀lé.
 o gbo ede geesi ati ede fransi daada .
Àwọn ará Bẹnjamini bá tún jáde láti Gibea ní ọjọ́ keji, wọ́n pa ọ̀kẹ́ kan ó dín ẹgbaa (18,000) eniyan ninu àwọn ọmọ Israẹli, gbogbo wọn jẹ́ jagunjagun tí ń fi idà jà.
A gbo pe oun lo pegede laarin awọn oludije ti wn le ni mewa to n du ipọ naa.
Àpapọ̀ wọn pẹlu àwọn arakunrin wọn, tí a ti kọ́ ní orin kíkọ sí OLUWA, ati lílo ohun èlò orin, jẹ́ ọọdunrun ó dín mejila (288).
lẹ ́ yìn tí àwọn ọmọm méjèjì náà deni tí ń láya òun ọkọ , wọ ́ n níi .
“Jẹ́ kí á wá àwọn wundia tí wọ́n lẹ́wà fún ọba, kí á yan àwọn eniyan ní gbogbo ìgbèríko ìjọba rẹ̀ láti ṣa àwọn wundia tí wọ́n lẹ́wà wá sí ibi tí àwọn ayaba ń gbé ní ààfin, ní Susa, tíí ṣe olú ìlú, kí wọ́n wà lábẹ́ ìtọ́jú Hegai, ìwẹ̀fà ọba, tíí ṣe olùtọ́jú àwọn ayaba, kí á sì fún wọn ní àwọn ohun ìpara, 
Lásìkò to ń bá BBC Yoruba sọ̀rọ̀ lọjọru, Akeugbagold kọ láti sọ iye owó tí àwọn ajọmọgbe náà ń béèrè fún aráyé, ó ní wón ti dunkooko mọ òun láti má ṣe tú àṣírí náà síta.
Nana Ama McBrown, Lydia Forson and Sika Osei – Sidechic Gang
Ṣugbọn n óo fìdí majẹmu mi múlẹ̀ pẹlu Isaaki, tí Sara yóo bí fún ọ ní ìwòyí ọdún tí ń bọ̀.
O s'afikun wipe awọn agbe ti din gbigbin irẹsi ku nitori ikolu awọn eku ati kokoro naa.
2 mílíọ́nù owó ìtanràn Wọnyii lawọn oṣere ori itage Yoruba tawọn naa n kopa ninu ifẹhonuhan #EndSARS to n lọ lọwọ: Odunlade Adekola Gbajugbaja oṣere tiata Yoruba, Odunlade Adekola palẹ awọn akẹgbẹ rẹ naa bọ soju popo lati ṣe iwọde #EndSARS ati SWAT.
Koda, o ni ti Ọlọrun ba fi ọwọ tọ lọkan pe ko se ounjẹ fun awọn ni ẹkọọkan, bii igba ti eeyan jẹ majele ni nitori apọju ata.
OLUWA yóo dojú kọ òun nìkan, láti ṣe é ní ibi láàrin gbogbo ẹ̀yà Israẹli, gẹ́gẹ́ bí ègún tí ó wà ninu majẹmu, tí a kọ sinu ìwé òfin yìí.
 bándélé jẹ ́ ọmọ odún méje .
Bukola Saraki figbe ta pé iléẹjọ́ ń fá orí òun lẹ́yìn òun Lẹ́yìn ọdún kan, ìgbẹ́jọ́ Fayose lórí ẹ̀ṣùn àjẹbánu ₦2bn gbérasọ Adájọ́ àgbà ní Kogi búra fún igbákejì gómìnà tuntun Ètò àbò, epo bẹntiró àti ọrọ̀ ajé ló gbé Buhari lọ sí Russia Ẹ̀wẹ̀ nínú ọ̀rọ̀ tirẹ̀ lóju òpó Instgram rẹ ni Bobrisky ti fèsì lẹ́yìn ti ọkunrin náà bẹ̀rẹ̀ si ni bẹẹ pe èdè aiyede kékere ló bẹ́sílẹ̀ láàrin awọn, sùgbọ́n Bobriksky ni ko ri bẹ́ẹ̀ oo, kìí ssi ṣe ọ̀rs ti àwọn yóò foju fò.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Amotekun: Ìjọba Eko kéde pé òun ní ẹ̀ṣọ́ aláàbò tẹ́lẹ̀, òun kò sí ní yí orúkọ rẹ̀ padá sí Amotekun 14 Èrèlè 2020 Oríṣun àwòrán, facebook/Amotekun Kọmiṣọna feto iroyin ni ipinlẹ Eko, Gbenga Omotoso ti sọ pe ipinlẹ naa ko fa sẹyin ninu eto aabo rara, ki awọn gomina ilẹ Yoruba to daba agbekalẹ ikọ alabo Amotekun.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Floyd dagbere faye lẹyin ti Derek Chavin to jẹ agbofinro nigba naa tẹẹ lọrun mọlẹ titi ti ẹmi fi bọ lara rẹ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù TUNNGR: Ta ló ṣe móríyá fún ọ jù lọ ní Super Eagles?
Awọn ayaba maa n tigba lati da ọba laraya ninu aafin rẹ lasiko idunnu tabi lati tu ninu.
Ki wa lawọn igbesẹ ti wọn gbe.
 hardy , pe o wa niduro kanna bi ti awon olusemathimatiki bi euler , gauss , newton ati archimedes .
Oluwo fi ọrọ yii sita loju opo ayelujara Instagram rẹ, lẹyin ti oun ati awọn ọba alaye to le ni ogun, ṣe abẹwo ikinni ku oriire si Gomina Gboyega Oyetọla ti ipinlẹ Ọṣun, lọọfisi rẹ.
Nígbà náà ni Sedekaya, ọmọ Kenaana súnmọ́ Mikaya, ó gbá a létí, ó wí pé, “Nígbà wo ni ẹ̀mí OLUWA fi mí sílẹ̀ tí ó wá ń bá ọ sọ̀rọ̀?
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Aràrá bíi tèmi, kó má rò pé kò sì ǹkan tó lè ṣe láyé ju iṣẹ́ agbe lọ' Gbogbo agbaye ni Ayo Akinwale ti rin kaakiri lati lọ ṣiṣẹ.
Yatọ si Drogba awọn ilumọọka agbabọọlu miran bi Yahya Touré, Kolo Touré ati Emmanueli Eboue wa lori papa ti ireti sí wa pé wọn yóò jáwé oluborí.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Risikat Moromoke Azeez: Inú èmí àti Òbí mi dùn nígbà ti Risi bí ọmọ olójú búlù- Wasiu Emi naa jẹri fun ọmọbinrin mi nile ẹjọ Baba kan naa sọ fun BBC pe wọn fipa ba ọmọ ohun to jẹ ọmọ ọdun mejila lopọ ni ọdun meji sẹyin ti ọrọ naa ko si tii kuro nile ẹjọ latigba naa di bayii.
Botilẹjẹ pe agbẹjọro awọn afurasi naa ko yọju sile ẹjọ, Onidajọ Bob Manuel bẹrẹ igbẹjọ naa.
Laada ni baba Mareṣa, ati ìdílé àwọn tí wọ́n ń hun aṣọ fẹ́lẹ́fẹ́lẹ́ funfun ní Beti Aṣibea 
O wa gbadura pe ki Ọlọrun tẹ oloogbe naa safẹfẹ rere.
Orúkọ àwọn alufaa tí wọ́n fẹ́ àwọn obinrin àjèjì nìwọ̀nyí:Ninu ìdílé Jeṣua ọmọ Josadaki ati àwọn arakunrin rẹ̀: Maaseaya ati Elieseri, Jaribu, ati Gedalaya.
Oríṣun àwòrán, Channels tv Àkọlé àwòrán, Ìbéèrè tó ń jẹyọ báyìí ni bóyá adájọ́ àgbà orílẹ̀-èdè Nàìjíríà, Walter Onnoghen yóò yọjú sílé ẹjọ́ Ni kete ti iroyin yii ti jade sita ni awọn gomina to wa lati ẹkun aringbungbun guusu orilẹ-ede Naijiria ti wọ inu ipade lọ.
"De Gea y'ẹ́yin, Man United k'àbùkù lọ́wọ́ Chelsea, Cuppy já pa Akanbi mi, má fọ̀ ọ́, mo wà pẹ̀lú ẹ; Ẹni tó ṣe ìgbéyàwó olórùka ló l'ọkọ- Lizzy Anjorin Wo díẹ̀ lára àwọn tí yóò kópa nínú ìdíje BBNaija ọdún yìí Iléeṣẹ́ ológun òfúrufú ti dárúkọ ẹni tó fi ọkọ̀ pa Tolulope Arotilẹ Victoria ""Vee"" Adeyele Olorin ni Vee, ipinlẹ Eko lo si fi n ṣebugbe ko to darapọ ile BBNaijia ọdun 2020."
Oríṣun àwòrán, Kayode Fayemi/Facebook Fayemi sọ pe ọjọ Iṣẹgun ni oun ṣe ayẹwo ilera kẹta, ti esi rẹ fihan pe oun ti ni coronavirus.
O pa ejo yii, o bẹ ẹ lori, o si pọn omi jade ninu kanga.
, Duration 8,0016 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 6:56 Fídíò, Wòlíì Kasali sọ̀rọ̀ nípa awuyewuye pé ó lé ìyàwó rẹ̀ jáde nílé, Duration 6,5628 Ọ̀pẹ̀̀ 2018 8:23 Fídíò, Deborah Adebola Fasoyin: Èmi kọ́ ló gbé orin ọdún ń lọ sópin kalẹ̀, CAC ló ni í ni mó n ṣe àkójọ orin- Fasoyin, Duration 8,2331 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 2:59 Fídíò, Paystack Shola Akinlade: Ìgbésẹ̀ 5 yìí ni mo gbé tíléeṣẹ́ Stripe fi dókòwò $200m pẹ̀lú mi, Duration 2,5916 Sẹ́rẹ́ 2021 BBC News, Yorùbá Ìdí tí ẹ fi le è nígbàagbọ́ nínú ìròyìn BBC Ìlànà Lílò Nípa BBC Òfin Àṣírí Cookies Kàn sí.
Bẹẹ naa ni wọn ni wọn ti fofin de awọn eeyan lati ba wọn dowo pọ.
Sowore ń gbìmọ̀dìtẹ̀ láti gba ìjọba lọ́wọ́ Ààrẹ Buhari
O ni, “a o tẹ siwaju lati maa ṣatilẹyin fun nnkan tiwantiwa, a o si maa gbe aṣa wa larugẹ.
Mo bá sọ àsọtẹ́lẹ̀ bí OLUWA ti pàṣẹ fún mi.
Dafidi kò dá ẹnìkankan sí yálà ọkunrin tabi obinrin kí wọ́n má baà mú ìròyìn ohun tí ó ṣẹlẹ̀ lọ sí Gati, bẹ́ẹ̀ ni Dafidi ń ṣe ní gbogbo ìgbà tí ó ń gbé ààrin àwọn ará Filistia.
Djibouti: Ni Iwọ Oorun ilẹ Afirika, ọkan pataki ibi ti o yẹ lati bẹwo lati orilẹ-ede Naijiria ni Ilu yii.
Museveni, eni ti o ti wa lori alefa lati odun 1986 so pe, isakoso ijoba oun ti ja fun ideye si awon obinrin, nipa sise ofin ti o ro awon obinrin naa lagbara.
Àkọlé àwòrán, Oludari BBC ni orilẹede Naijiria, Aliyu Tanko n ki Ọmọọbabinrin Adebisi Ogunsanya (YPP) ku abọ sibi eto Àkọlé àwòrán, Àwòrán àwọn oṣiṣẹ alaabo ti o ti de sibi ipade ṣaaju eto Àkọlé àwòrán, Gbọngan ipade ṣaaju ifọrọwerọ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Nollywood Round up: Lizzy Anjọnrin fẹ̀si fáwọn agbọ́yì-sọ̀yí lórí ìgbéyàwó rẹ̀, Madam Sajẹ dasójú ilé iṣẹ́ àti àwọn ǹkan míràn tó ṣẹlẹ̀ lágbo tíátà lọ́sẹ̀ yìí 25 Agẹmo 2020 Oríṣun àwòrán, others Lara awọn iroyin to migboro titi lagbo oṣere tiata Yoruba lọsẹ yii ni bi awọn kan ṣe n ṣe ọjọ ibi lawọn mii n ṣe igbeyawo.
EFCC: Ìwádìí lórí ẹ̀sùn ìwà jẹgúdújẹrá tí wọ́n fi kan Babatunde Fowler tó jẹ́ àdàrí iléeṣẹ́ FIRS tẹ́lẹ̀
Arun yoo le peleke si fun awọn miran, eleyii to le jẹ bi ọjọ mẹwa lẹyin ti wọn ba ti ni arun naa lara.
Awọn kan gbà pé agbára òṣèlú ni Àwọn mìíràn ní bóyá ó ti sọ ara rẹ̀ di wòlíì ni o.
"Eeyan meji si lo ku, kii ṣe mẹjọ tabi mẹwaa ti wọn n pariwo.
Gómìnà Sanwo Olu ní òun kò sanwó ẹbùn N41.
Àwọn kwere ò ni ìjọba àpapọ ̀ ijọba ìletò , ijọba abúlé àti ìjọba ìlú-síluń ní wọ ́ n ní Àgbà àdúgbò ló ń fi olórí jẹ .
Oríṣun àwòrán, EPA Àkọlé àwòrán, Awọn alakoso igbimọ pe ipade pajawiri fun ọjọ aje lati jiroro lori Aarẹ Zuma Amọ, ko i ti di mimọ fun awọn oniroyin bi aarẹ Zuma yoo se fesi si iwe ti wọn kọ sii lati kọwe fipo silẹ.
Rántí  wí pé Olódùmarè fẹ́ràn àwọn ọmọ ènìyàn púpọ̀-púpọ̀ tó bẹ́ẹ̀ tí Ó fi ohun gbogbo tí ń bẹ lóde ayé, bí ayé ti kún fún oríṣiríṣi nǹkan tó wọn-ọnnì, Ó fi àwọn nǹkan wọn-ọnnì jìǹkí ọmọ ará ayyé.
Leah Sharibu ti lo irínwó ọjọ́ ní àhámọ́ Boko Haram
Ajagunfẹyin, Ọgagunagba ati oloṣelu to dantọ ti gbogbo agbaye ko lee fọwọ rọ sẹyin ni Ọbasanjọ jẹ.
Ègbé ni fún àwọn eniyan burúkú,kò ní dára fún wọn.
O ni pé ẹni to moju ogun lo yẹ ki wọn yan ko pabì nire lainii fi ṣe iran ẹni naa.
Ìwọ Sioni, n óo lo àwọn ọmọ rẹ bí idà,láti pa àwọn ará Giriki run,n óo sì fi tagbára tagbára lò yínbí idà àwọn jagunjagun.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Lagos Cane Village: Lórí iṣẹ́ ikàn yìí, a ti kọ́ ilé, ọmọ ti lọ ilé ìwé Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Lagos Cane Village: Lórí iṣẹ́ ikàn yìí, a ti kọ́ ilé, ọmọ ti lọ ilé ìwé 13 Èbibi 2019 Abule ikan yii jẹ ọkan lara awọn ibudo ti wọn ti n fi ikan ṣe oriṣiriṣi nkan amulo oun si lo tobi ju laarin awọn iru ẹ ni ipinlẹ Eko.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, AbdulQudus Bello ṣàlàyé bí òun ṣe dí aláàbọ̀ ara nítorí pọpọ́ọ̀fù àti ìbínú jàǹdùkù àdúgbò Minista fun ọrọ iṣẹ tun tẹpẹlẹ mo pe ẹnikẹni to ba fẹ ṣiṣẹ awakọ gbọdọ ronu ibi ti yoo maa gbe ọkọ rẹ si ko to bẹrẹ.
Adéle gíwá ti wọ́n ṣẹ̀ṣẹ̀ yàn ko ti i bẹ̀rẹ̀ iṣẹ́.
1 9819 Orilẹede San Marino 65 192.
Ọọ̀ni Ilé Ifẹ̀, Ọba Okùnadé Alade Sijúwadé, Olúbùṣe Keji Wàjà 
Àwọn Non Tradesmen/Women kò gbọdọ ju ọmọ ọdún méjìdinlógun si ọmọ ọdún méjìlélógún lọ, ní ọgbọ̀n ọjọ ọsù kẹfa ọdún 2021 O gbọdọ ni o kéré tan ami kare marun to fi mọ ìṣirò àti gẹẹsi níjoko ẹ̀ẹ̀meji nínú SSCE/NECO/ GCE/NABTEB Fún ti Tradesmen/Wome: (a) Olùforukọsilẹ̀ gbọdọ̀ wà láàrin ọdun méjidílógún sí márùndínlọ́gbọ̀n àfi àwọn to bá fẹ́ gbá oye Chaplain/ Imaams àti Awakọ.
Elisabẹti iyawo rẹ yóo bí ọmọkunrin kan fún ọ, o óo pe orúkọ rẹ̀ ní Johanu.
Rain: Ìgbà òjò léwu, ohun tó o ní láti mọ̀ rèé
Seyi Makinde: PMS kò ní ohun ṣe pẹ̀lú NURTW, ìṣẹ́ rẹ̀ ni láti pawó wọlé fún ìjọba
pe o jẹ ohun itiju fun eto ijoba orile ede Naijiria.
Kí ni olùfẹ́ rẹ fi dára ju ti àwọn yòókù lọ?
Eleyii lo maa n faa tawọn ọmọde maa fi n saba n ni aisan iba.
''Ṣugbọn ayipada yii ko le waye bi wọn ko ba ṣe n kankan, ti wọn si gba ki awọn ọta Naijiria maa tan wọn.
Bakan náà ni ọ̀pọ̀ àwọn ọmọ Naijira lórí àtẹjíṣẹ́ twitter sọ pé àwọn yóò ṣe àkójọpọ̀ ọgọ́rùn mílíọ̀nù náírà láti fi ràn lọ́wọ́.
Ojú rẹ ni gbogbo wọn ń wò,fún ìpèsè oúnjẹ ní àkókò.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Buhari kọ́ ni ìṣòro wa, bó ṣe wà láti láéláé rèé - Fr Mbaka Àwọn ọ̀dọ́ fi ọ̀nà àrífín pe Tinubu lórí aago àmọ́ ó ní òun kò mọwọ́-mẹsẹ̀ nípa ìpànìyàn Lekki Wo díẹ̀ lára dúkìá tí jàǹdùkú sun níná l‘Eko torí ìwọ́de EndSARS Á ràgà bo CCTV Lekki bí i ẹ̀rí tó dájú fún ìwádìí ìpànìyàn - Sanwo-Olu SERAP gbé ìjọba àpapọ̀ lọ ilé ẹjọ́ àgbáyé ICC lọrí ẹ̀sùn ìpànìyàn Jàǹdùkú gún ẹ̀gbọ́n mi lọ́rùn, jó ilé àti mọ́tò wa méjì, kòròfò la wà"" Olùwọ́de 12 kú ni Lekki, 38 lapapọ kú lọ́jọ́ Isẹ́gun, 56 ni àròpọ̀ àwọn tó bá ìwọ́de lọ - Amnesty International Osinbajo gbarata lórí ìṣẹ̀lẹ̀ Lekki, ó ní ìdájọ́ òdodo yóò wà ""A ba wọn sọrọ, a bẹ wọn ki wọn ja ọgba ẹwọn naa, awọn ẹyin eti wọn ni gbogbo ẹbẹ wa n bọ si."
Isẹlẹ yii bẹrẹ ko tii to ọsẹ meji rara bẹẹ si ni laarin ọsẹ meji yii nikan, yatọ fun iye awọn obinrin ti wọn ti fipabalopọ lawọn ipinlẹ kọọkan, kayefi ni iroyin to yi awọn iṣẹlẹ ọhun ka eyi to n kọ awọn araalu lominu.
Mílíọ́nù mẹ́wàá Náírà ni ilé ẹjọ́ ni kí Kábíyèsí san gẹ́gẹ́ bí owó ìtaran ilẹ̀ tí ó gbà lọ́nà àìtọ́ Kíni àjọ ọlọ́pàá ń ṣe lórí bí agbófinró ṣe ń ṣèèṣì pànìyan lójoojúmọ́?
O pada wa si ilu Eko lọjọ Eti to ku ọla ọjọ igbeyawo to si ti kọkọ lọ agọ ọlọpaa Agbado Station lati fi to wọn leti pe oun yoo da igbeyawo naa ru Bi o ṣe de ọgba ile ijosin naa ni deede aago mọkanla awọn adari ijọ to mọọ ti bẹẹ pe ko gbagbe ọrọ naa ti osi fariga Máa gbé kẹ̀kẹ́ rẹ lọ, àwọn akọròyìn kọ̀ ìpàkọ́ sí Femi Fani Kayọde Ọkùnrin kan di èrò ọ̀run nítorí pé o fi ẹ̀sùn kan alájọgbélé rẹ̀ pé o n yan ìyàwó ẹnìkan lálè Wo àwọn orílẹ́-èdè mẹ́wàá tí kò ní coronavirus lágbàáyé, bá wo ni wọ́n ṣe ṣe é?
Nítorí náà, wọn á kó ìgbéraga bọ ọrùn bí ẹ̀gbà,wọn á fi ìwà ipá bora bí aṣọ.
Oríṣun àwòrán, others Àkọlé àwòrán, A ti ṣetán láti kojú Germany -Super Falcons Nigba ti wọn gbe ipo keji ni ọdun 1995.
lati ri I pee to idagbasoke ati ilosiwaju wa ni  Ipinle Oyo, nitori naa won gbodo ri I daju pe
5 Èbibi 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 8 Èbibi 2020 Oríṣun àwòrán, Getty Images Bi ọsẹ akọkọ ti ijọba dẹ ofin konile o gbele ṣe n wa sopin, ni ọpọ araalu, paapa lori ayelujara ti n sọ pe ki ijọba o tun gbe ofin konile o gble jade pada.
inu mi dun nitori pe wọn ma n padawa lati wa dupe.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Wilder gbe $50m kalẹ̀ láti bá Joshua jà Anthony Joshua na Joseph Parker Ìjọba pàṣán ni ìjọba Buhari yóò jẹ́ fún Nàìjíríà ní sáà kejì- Ṣoworẹ Ogun: Amosun, ẹgbẹ́ òṣìṣẹ́ NLC fẹ́ forígbárí l'Ógùn Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Sekinat Quadri ọmọ ọdun meje ajẹsẹ to fẹ dabi Anthony Joshua Eyi si tun mu ko di ọmọ orilẹ-ede Naijiria akọkọ ti yoo gba igbanu ẹyẹ Welterweight.
"Ẹ darapọ̀ mọ́ BBC Yorùbá lásìkò ìbò fún ìròyìn yàjóyàjó Oúnjẹ wọ́n l‘Eko, gómìnà tó ń bọ̀, ẹ wá nǹkan ṣe si - Ará Eko ń kígbe ""Kashamu ṣì ni olùdíje PDP fún ipò gómìnà l'Ogun"" Báwọn olóṣèlú ṣe ń darapọ̀ kò leè ṣàkóbá fún ìdìbò - INEC Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí kan sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn."
Ere sinima kii se eremọde, oju taye fi n wo wa se pataki, ohun to tọ si lo yẹ ki awa osere maa gbe jade.
 “Boya ifesewonse Super Eagles ohun temilorun tabi ko temilorun, temi nip e, mo ni igboya fun iko naa.
 Ìjọba ìbílẹ ̀ Ìsàlẹ ̀ Èkó ló kó ìlàjì nínú apá ìwò oòrùn lagos island , nígbà tí apá ìlà oòrùn Ìsàlẹ ̀ Èkó tókù wà ní abẹ ́ àkóso ìjọba ìbílẹ ̀ etí-Ọ ̀ sà .
O si maa n to miliọnu meji eeyan to maa n kopa ninu eto ẹ̀sìn naa.
Gígùn ati ìbú rẹ̀ jẹ́ igbọnwọ marun-un (mita 2¼), gíga rẹ̀ sì jẹ́ igbọnwọ mẹta (1.
 Èyí jásí wípé , Ó tún jẹ ́ ìlú alálà nàìjíría àti orílẹ ̣ ̀ -èdè olómìnira benin ni sèmè .
Wọn yóo sì sọkún tẹ̀dùntẹ̀dùn bí ẹni tí àkọ́bí rẹ̀ ṣàìsí.
Aare  Buhari tun seleri lati se atunse to monyan
Ẹni tí ó bá pa òfin mọ́, ẹ̀mí ara rẹ̀ ni ó pamọ́,ẹni tí ó kọ ọ̀nà Ọlọrun sílẹ̀ yóo kú.
Ǹjẹ́ ènìyàn tó ní àrùn coronavirus rí lè níi lẹ́ẹ̀kejì?
Ìkánjú ni òun pàápàá tilẹ̀ bá jáde, nítorí pé OLUWA ti jẹ ẹ́ níyà.
Bẹ́ẹ̀ ni òun ati àwọn ọmọ Israẹli ṣe ya ilé OLUWA náà sí mímọ́.
O si ni ṣugbọn ọmọde gbọn agba gbọn la fi da Ile Ifẹ.
O fikun pe iwuwasi ọmọ oun ati bi o ṣe n pegede si ni ileewe fihan pe ọlọpọlọ pipe ni ọmọ oun.
Orile ede Naijiria  ti seleri lati pese eto iranwo lori ise akanse fun orile ede Sao Tome  ati Principe lasiko eto idibo ile igbimo asoju-sofin orile ede naa, ti yoo waye ni ojo keje osu kẹwaa ,ọdun  yii.
 Ìsó ; ààbò : ìdáàbòbò Àwon ológun náà lóri ìsó ní gbogbo oru .
Lati igba ti iroyin yii si ti jade ni awọn eeyan ti n pariwo ki awọn alaṣẹ fasiti OAU o gbe igbesẹ to yẹ lori rẹ.
Mẹ́fà nínú àwọn ogún náà ló péjú si ilé ẹjọ tó fi mọ́ Wadume lónìí ọjọ́rú.
Mo sọ fun yín, bẹ́ẹ̀ gan-an ni àwọn angẹli Ọlọrun yóo máa yọ̀ nítorí ẹlẹ́ṣẹ̀ kan tí ó ronupiwada.
’’Aare Buhari tun  wa gbosuba fun alaga ana , aare orile ede Togo ,Faure Gnassingbe lori aseyori re lati se ipade pataki meji to je mo ti igbimo aarin gbungbu orile ede Afirika ati ajo ECOWAS ni eyi ti o je ikẹ́tàléláàdọ́ta iru re ti yoo waye .
akoroyin ile aare  soro lojo Isegun  pe, igbimo ipinle ti fenuko lori ọgbọ̀n egberun naira fun
Bi won se ra awon irinse naa, ni a ti loo lati
Yóo fìdí rẹ̀ múlẹ̀,yóo sì gbé e ró pẹlu ẹ̀tọ́ ati òdodo,láti ìgbà yìí lọ, títí ayérayé.
Adamu ni ijoba ti yan yanju aawo
World Heavyweight mu digbi digbi lowo re.
Oríṣun àwòrán, Anadolu Agency Àkọlé àwòrán, Awọn irinse bayi ni wọn ma fi n wa oṣu Ni Naijiria ati ni awọn orileede miran ti musulumi wa to fi d'ori Saudi, awọn olori musulumi a ma gbe eto oṣu wiwa le awọn igbimọ kan lọwọ.
Nebukadinesari fi kìkì wúrà yá ère kan tí ó ga ní ọgọta igbọnwọ (mita 27), ìbú rẹ̀ sì jẹ́ igbọnwọ mẹfa (mita 2.
Èmi OLUWA ni èmi máa ń wádìí èrò eniyan, tí èmi sì máa ń yẹ ọkàn eniyan wò,láti san án fún olukuluku gẹ́gẹ́ bí ìṣe rẹ̀,ati gẹ́gẹ́ bí iṣẹ́ ọwọ́ rẹ̀.
 lokanna mo oko re , joliot-curie gba ebun nobel fun kemistri ni 1935 fun iwari won iranna afowose .
Èmi OLUWA ni ẹlẹ́san, n óo sì gbẹ̀san, nítorí ọjọ́ ń bọ̀, tí àwọn pàápàá yóo yọ̀ ṣubú.
O nigbogbo awọn ẹhonu marun un ti wọn fi kalẹ ni ijọba oun tẹwọgba ti oun si ti bẹrẹ igbesẹ lori rẹ.
Ilẹ̀ náà ti di ti olùpẹjọ sílé ẹjọ́ kòtẹ́milọ́rùn, bótilẹ il òun ti wa lọ́wọ́ olóye Etim àti awọn ará ìlú Ibiaku Ishiet níjọba ìbílẹ̀ Uruan yóò san mílíọ̀nù mẹ́wàá Naíra.
Ọla ọjọ Satide, ọjọ Kẹtadinlọgbọn osu Kẹfa ọdun 2020 ni eto isinku naa yoo waye .
Oríṣun àwòrán, others Ikú Williams Aanuoluwa lágbo òṣèré hú ọ̀pọ̀ ọ̀rọ̀ síta Àwọn òṣèré tíátà Yorùbá kọjú ìjà síra wọn lórí ìdárò akẹẹgbẹ́ wọn tó kú Awaye ku ko si, Ọba oke mase jẹ ka fi ọjọ ọlọjọ lọ ni.
Àwọn tó wà níbi ìpàdé náà ni Oloye Olusegun Obasanjo, Goodluck Ebele Jonathan, Yakubu Gowon, Abdusalam Abubakar àti Ernest Shonekan.
O ni ijọba ipinlẹ Eko ti n le awọn ọkọ ajagbe kuro lagbegbe Iganmu bayii ki oju ọna lee la fun awọn to fẹ rinrinajo lọ si Apapa.
Ìṣẹ̀lẹ̀ yìí jẹ́ ara àwọn nǹkan ìgboyà tí àwọn akọni ọmọ ogun mẹta náà ṣe.
Bí ó ti bọ́ sí èbúté, ọkunrin kan tí ó ní ẹ̀mí èṣù jáde láti inú ìlú wá pàdé rẹ̀.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù #Adewura Latifa Bello: Ọlọ́pàá ní àwọn kò tíì lè fídí rẹ̀ múlẹ̀ pé òun ni 27 Èbibi 2019 Oríṣun àwòrán, Adediwura Àkọlé àwòrán, Akọ́ṣẹ́mọṣẹ́ onímọ̀ ìṣirò owó ni Lateefat, ẹni ọmọ ọdún mẹ́rìndinlọgbọ̀n Adewura Latifat Bello, ẹni ọdún mẹ́rìndínlọ́gbọ̀n ti wọ́n ń wá láti ọjọ́ kẹẹ̀dógún, oṣu karùn ún ọdún 2019 lásìkò tó ń padà lọ sílé láti ibiṣẹ́ lágbègbè Gowon Estate ní wọ́n ti rí báyìí.
Àti ṣòkòtò, àti ẹ̀wù, àti fìlà iwin yìí rí jìngbìnnì kanlẹ̀, bí o ba sí ti ń rìn, wọn ń dún jinwinjinwin bí ìgbà tí àwọn abọ̀rìsà ba n lu ìlù agogo ijó òríṣà wọn.
Mo mọọmọ fi ẹmi ara mi lelẹ, fun isọkan ati alaafia Yoruba ni, ti Ọlọrun si lo awọn eeyan lati ti mi lẹyin.
Ọ̀rọ̀ yìí pada tàn de ọ̀dọ̀ ààrẹ to si ni láti fi dá àwọn ara ìlú lóju ni ìgbà ti ìdìbò ọdun 2019 súnmọ, to si jade láti wá fi dá awọn ènìyàn lójú pé oun ni Buhari tààrà, bakán náà ni ilé iṣẹ́ ààrẹ tún fi àtẹjáde síta lórí ọ̀rọ̀ náà.
Somalia: 'Wọ́n pàṣẹ fún mi láti dá Ramla dúró ká tò lè ṣe igbeyàwó'
"Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Abule Ado explosion: Irọ́ ńlá ní NNPC pa lórí ìbúghbàmù Abule Ado níbí tí ẹ̀mí èèyàn 23 Ṣé Nàìjíríà lẹ́mìí nkan tí Ghana ń ṣe fáwọn akẹ́kọ̀ọ́ ""Secondary"" tí yóò wọlé ní October yìí?"
Igbesẹ Keje: Ti Igbimọ naa ba kede pe Igbakeji Gomina ko jẹbi ẹsun ti wọn fi kan an, iwadii naa pin si bẹ niyẹn Amọ ti Igbimọ naa ba ni Igbakeji Gomina jẹbi ẹsun ti wọn fi kan an, awọn aṣofin yoo gbeyẹwo, ti wọn yoo si dibo lori boya ki wọn gba abajade Igbimọ naa wọle.
"Royin ni: ""mi o fi bo mọ."
 mílíọ ̀ nù méjì lé lẹ ́ gbẹ ̀ rún lọ ́ nà ọ ̀ ọ ́ dúnrún ni barreteau àti monino ( 1978 ) tọ ́ ka sí gẹ ́ gẹ ́ bí àwọn tó ń sọ èdè ubangi .
Ẹ ti ní ọkọ mìíràn, àní, ẹni tí a ti jí dìde kúrò ninu òkú, kí á lè sin Ọlọrun lọ́nà tí yóo yọrí sí rere.
"Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Day 13: Àwọn ńkan méje tí ẹ lè má mọ̀ nípa Igbákejì Ààrẹ Osinbajo #BBCNigeria2019 Ààrẹ ní kí wọ́n wádìí oun tó fa ìjàmbá bààlú Osinbajo Ìyansẹ́lódì ẹgbẹ́ olùkọ́ fásitì ASUU ń tẹ̀síwájú Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ọ̀nà tí àwọn olùdíje ipò gómínà ní Ìpínlẹ̀ Ọyọ fẹ̀ gbà yànjú ọ̀rọ̀ ààbò rèé Ninu ọrọ to ba BBC News Yoruba sọ, Iba Gani Adams ni oun ko lee sọ pe oloṣelu bayii ni yoo ṣe daradara tabi omiran ṣugbọn ""ohun kan ti mo lee sọ ni pe eyikeyi ninu wọn to ba daju pe yoo ṣe atunto ilana iṣejsba ni ki Yoruba dibo fun."
Nítorí pé láti orí àwọn mẹ̀kúnnù,títí dé orí àwọn eniyan pataki pataki,gbogbo wọn ni wọ́n ń lépa èrè àjẹjù.
Gbajugbaja ni agbẹjọro rẹ yii, nitori pe o ti ṣoju gbajugbaja akọrin to ti di oloogbe, Michael Jackson ri ninu igbẹjọ kan.
Tacha: Mo mọ̀ pé ìwà burúkú ló pa mi bí ọtí, ẹ dárí jì mí Ariwo sọ, wọ́n fọwọ́ òsì júwe ilé fún Tacha lórí ètò àgbéléwò BBNaija Èèmọ̀ rèé!
 àwọn ará ilé Ọ ̀ rúntọ ́ ni ó gba lámurúdu àti odùduwà ní àlejò4 .
OLUWA bá sọ fún Jeremaya pé, 
Oríṣun àwòrán, Nigerian Navy Lara awọn ohun ti wọn rigba pada lọwọ awọn adigunjale naa ni epo rọọbi to le ni lita ẹgbẹrun lọna igba(150 drums of 250 litres), ohun ifa epo, ati awọn engine nlanla.
Awọn oluwọde n hó lé awọn ọmọ ijọ COZa lori ni Eko bi wọn ṣe n tu jade.
kan ti ko rorun rara, ti o si nilo suuru, ifarada, ibale okan, ogbon ori, imo lati
àwọn tí ń fi ọ̀rọ̀ ẹnu sọ eniyan di ẹlẹ́ṣẹ̀,tí ń dẹ tàkúté sílẹ̀ fún ẹni tí ń tọ́ni sọ́nà,tí wọ́n sì ń fi àbòsí tí kò nídìí ti olódodo sí apá kan.
Lẹyin ọsẹ meji, gbogbo siimu ti ko ba ni nọmba NIN ko ni i ṣiṣẹ mọ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Insecurity: Ilé aṣojú-ṣòfin ní ìpànìyàn, ìjínigbé, ìdigunjalè, ìgbéṣùnmọ̀ọ́mí ń peléke ni 29 Sẹ́rẹ́ 2020 Oríṣun àwòrán, Army HQ Ile Igbimọ Asofin apapọ lorilẹede Naijiria ti pe fun eto pajawiri lati koju eto aabo to n dẹnukọlẹ si lorilẹede Naijiria lojoojumọ.
Pẹlu ayọ̀ ni ẹ fi ń gba àwọn aṣiwèrè, ẹ̀yin tí ẹ jẹ́ ọlọ́gbọ́n!
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Nigeria Independence Day: Wo ìlérí tí àwọn ènìyàn ṣe Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
ati bí agbára rẹ̀ ti tóbi tó fún àwa tí a gbàgbọ́, gẹ́gẹ́ bí iṣẹ́ títóbi agbára rẹ̀.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ìtàn Mánigbàgbé: Ìtàn Adegbọrọ kọ́ wa láti ṣiṣẹ́ kára pẹ̀lú ìforítì Asiko yii ni irawọ Adegbọrọ bẹrẹ si ni tan, ti ogo rẹ n bu yọ nilu Ibada.
Ẹ óo máa fi ẹgbọ̀rọ̀ akọ mààlúù mẹtala, àgbò meji ati ọ̀dọ́ àgbò mẹrinla ọlọ́dún kọ̀ọ̀kan tí kò ní àbààwọ́n rú ẹbọ sísun olóòórùn dídùn sí OLUWA.
Oríṣun àwòrán, SUNDAY DARE/TWITTER Àkọlé àwòrán, Eto idokoowoo awọn ọdọ Àwọn ti o yóò jànfani yìí yóò ni ẹ̀tọ́ si ẹgbẹ̀rún lọ́nà ààdọ́ta lé ni igba náírà sí àádọ́ta mílíọ̀nù náirà ti wọ́n yóò sì maa san elé ìdá marún un lórí owó ti wọ́n bá yá.
Nígbà tí wọ́n gbọ́ pé Jesu wà láàyè ati pé Maria ti rí i, wọn kò gbàgbọ́.
Nígbà tí Jesu parí àwọn ọ̀rọ̀ wọnyi, ẹnu ya àwọn eniyan sí ẹ̀kọ́ rẹ̀; 
” Ṣugbọn Irija kọ̀, kò gbọ́, ó sá mú Jeremaya lọ sọ́dọ̀ àwọn ìjòyè.
Ajọ ọlọpa ni Fulani darandaran ati agbẹ naa ti wa ni agọ ọlọpa ati wipe alaafia ti pada s'agbegbe naa.
Trump kò yẹ láti jẹ́ ààrẹ- Adarí FBI tẹ́lẹ̀rí
Gideoni bá wọlé lọ, ó tọ́jú ọmọ ewúrẹ́ kan, ó sì fi ìyẹ̀fun ìwọ̀n efa kan ṣe burẹdi tí kò ní ìwúkàrà ninu.
Ni Owurọ kutukutu ọjọbọ ọsẹ yii ni iṣẹlẹ naa ṣẹlẹ ti wọn si tun ji Olukọ meji gbe pelu.
Namibia, South Africa, Ivory Coast ati Morocco lo wa ni isọri kẹrin nigba ti Angola, Mauritania, Mali ati Tunisia wa ni isọri karun un.
Wọ́n sọ fún Mose pé, “A ti wo ilẹ̀ tí ẹ rán wa lọ wò, a sì rí i pé ó jẹ́ ilẹ̀ tí ó dára, tí ó kún fún wàrà ati fún oyin ni.
Laarin ọsẹ yii naa lo ṣe eto adura fidau ọjọ kẹjọ iya rẹ.
Opopona Eko si Ibadan ti atunse n lo lowo lori re , ku die ko wa si ipari.
Margaret Keenan ti yoo pe ọdun mọkanlelaadọrun lọsẹ to n bọ sọ pe ẹbun ọjọ ibi to dunmọ oun ju ni wọn fun oun yi.
Seyi Makinde, gómìnà ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́ ti sọ ibi tó ti kó àrùn COVID-19 Èèyàn mẹ́rin míràn kó àrùn Coronavirus Àjọ NAFDAC fọwọ́ sí pípo ògùn chloroquine fún àyẹ̀wò ìtọ́jú coronavirus ‘Ìjọba, ẹ ràn wá lọ́wọ́!
Alẹkisanderu, alágbẹ̀dẹ bàbà fi ojú mi rí nǹkan!
1) Lilo oogun ṣaaju ibalopọ Awọn oogun amarajipepe kan wa tawọn eeyan maa n ra lati lo fun ibalopọ.
Abiola ko duro lori eyi, o tun tẹsiwaju lati gba oye imọ ijinlẹ keji ninu iṣẹ iwadii ati kata-kara ni Governors state University to wa ni University Park, Illinois nilẹ Amẹrika.
Ǹjẹ́ kò ní ìdí tí mo fi yí ètò yìí pada?
 “Orile ede wa , ko ni isoro owo tabi ọgbọn
Wọ́n ta ère Ọ̀ṣun Osogbo sí Togo - Bàbá Ọṣun figbe ta Baṣọ̀run Gáà, tó yan ọba mẹ́rin, pa ọba mẹ́rin àmọ́ ọba karùn-ún ló pa á Ọbasanjọ sọ àsírí sàgbàdèwe rẹ̀ Jesu Oyingbo rèé, pásítọ̀ tó láṣẹ ìbálòpọ̀ lóri ọmọ ìjọ obìnrin Igbó mímu lè ṣe kóríyá, kò lé fi kún orín ẹnu òṣèré - 9ice Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí kan sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
Pásítọ̀ gún ìyàwó rẹ̀ lọ́bẹ nínú ṣọ́ọ̀ṣì, ló bá tì í bọ ara rẹ̀ náà níkùn Ọmọdé tó ń ṣeré pẹ̀lú àdò olóró ló fa ìbúgbàmu Borno- Cameroon Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Adìẹ mẹ́ta ni ìyá mi pa, ó sì se ìrẹsì.
Oluwo Jọgbọdọ ni ti wọn ba kọ lati ṣe atunṣe, oun atawọn awo mii yoo lọ fi idan han wọn ni ẹka Access bank ti wọn ti yọ owo mama oun.
Ohun tí ó kọ sinu ìwé náà ni pé, “Ẹ kéde ọjọ́ ààwẹ̀ kan, ẹ pe àwọn eniyan jọ, ẹ sì fi Naboti jókòó ní ipò ọlá.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Kano Gorilla: Òṣìṣẹ́ 10 wọ gàù lórí ọ̀rọ̀ Ìnàkí tí wọ́n ló gbé owó tí wọn pa lásìkò ìtúnu ààwẹ̀ 14 Òkùdu 2019 Oríṣun àwòrán, JOHN MACDOUGALL Àkọlé àwòrán, Ipinlẹ Kano Ìnàkí jí mílíọ̀nù méje náírà ní sgbà ẹranko Ọjọ́rú ni ọ̀gá àgbà tó ń ṣe àkóso owó lọgba ẹranko ni Kano ké gbàjare pé, owó to ku díẹ̀ ko pé mílíọnù méje ti àwọn pa lásíkò ọdún itunu aawẹ, nígbà ti àwọ̀n ènìyàn wá wo ẹranko ló dédé pòòrá, nínú akoto ti àwọn ko owo si.
Ọdun 2003 ni Naijiria ati Brazil jọ koju ara wọn kẹyin ninu ere bọọlu ọlọọrẹsọọrẹ.
Láti dá Jehoṣafati lọ́lá pẹlu àwọn tí wọ́n bá a wá, Ahabu pa ọpọlọpọ aguntan ati mààlúù fún àsè.
má jẹ́ kí orúkọ Jonatani di ìkékúrò ní ilé Dafidi.
Alhaja Kudirat Abiola akọni obìnrin, tó gba ọkùnrin mẹ́fà kí wọ́n tó leè pa á Ọwọ́ ọlọ́pàá tún tẹ afurasí tó fipá bá odi àti adití lòpọ̀ nílùú Ibadan Àṣírí ẹgbẹ̀rún kan ayédèrú òṣìṣẹ́ SUPEB tú ní Kwara -EFCC Omijé ń p'omijé rán níṣẹ́ níbi ìsìnkú dípiò ọlọ́pàá táwọn ọlọ́ṣà pa ní Kogi Nigba to n salaye ohun ti ikede nnkan ko fararọ naa tumọ, Agbẹjọro kan to ba BBC Yoruba sọrọ, Toyin Taiwo Ojo salaye awọn ohun to lee sẹlẹ pẹlu ikede naa.
gba alejo awon olugbe ilu FCT nile re lojo ayeye odun keresimesi, niluu Abuja.
Nígbà tí mo wà níhòòhò, ẹ daṣọ bò mí.
Àwọn ẹ̀yà Reubẹni ati ẹ̀yà Gadi ati ìdajì ẹ̀yà Manase ti gba ilẹ̀ tiwọn, tí a pín gẹ́gẹ́ bí ilé baba wọn.
Òní ni ètò ìsìnkú George Floyd yóò wáyé Oríṣun àwòrán, EPA Awọn eeyan ilu Houston, ni Texas ni adanu nla ni iku Floyd jẹ.
Èmi, Simoni Peteru iranṣẹ ati aposteli Jesu Kristi, ni mò ń kọ ìwé yìí sí àwọn tí wọn ní irú anfaani tí a níláti gbàgbọ́ bíi tiwa, nípa òdodo Ọlọrun wa ati ti Olùgbàlà wa Jesu Kristi.
Oríṣun àwòrán, NASA Ni oju opo Twitter rẹ, Aldrin to jẹ ẹnikeji to gun inu Osupa naa sọ wi pe‘ aadọta ọdun sẹyin, orilẹede Amẹrika lo kọkọ wọ inu Osupa, ti ọgọọrọ miliọnu ọmọ ilẹ Amẹrika si duro tiwa ni gbogbo asiko naa.
Àwọn ọmọ Lodi, Hadidi ati Ono jẹ́ ẹẹdẹgbẹrin ó lé mọkanlelogun (721).
O tun tesiwaju pe egbe oselu
Bi oke ọya ba ṣe ijọba, ki wọn tun gba awọn ẹkun miran laaye lati se bẹẹ pẹlu tori ẹnikan kii jẹ, kilẹ o fẹ.
Ẹ níláti kórìíra wọn, kí ẹ sì yàgò fún wọn, nítorí ohun ìfibú ni wọ́n.
Yóo sì bu omi náà wọ́n aláìmọ́ náà ní ọjọ́ kẹta ati ikeje.
Ohun tó wù kí ileẹjọ́ kòtẹ́milọ́rùn sọ, Adeleke kò lè di gómínà Ọ́ṣun - APC Dapọ Abiọdun ree, ẹni tó dépò gómìnà ní àyájọ́ ọjọ́ ìbí rẹ̀ Ilé ẹjọ́ gba onídúró Naira Marley pẹ̀lú mílíọ́nù méjì náírà Wo àwọn ìlérí tàwọn Gómìnà tuntun ṣe nínú ìbúra wọn Igbesẹ arabinrin yii ti fa n ha-hin ni agbegbe naa.
18 Àti pé ò dá ènìyàn, ọ́kùnrin àti óbìnrin, ní àwòrán ara rẹ̀ àti gẹ́gẹ́bíi ìrí ara rẹ̀, ní ó dá wọn;
a bí tọ ́ pẹ ́ Àlàbí ní ọjọ ́ kẹtàdínlọ ́ gbọ ̀ n oṣù kẹwàá ọdún 1970 ní ìpínlẹ ̀ Èkó , nàíjíríà fún pa joseph akínyẹlé Ọbáyọmí àti madamu agnes kẹ ́ hìndé Ọbáyọmí .
Adẹrinpoṣonu ọmọ Naijiria to rinrin ajo lọ si ilẹ Gẹẹsi, Justice Nuagbe ti ọpọ mọ si Ushbebe ikede naa ti mu ki wọgile eto ti mo fẹ ṣe lọjọ Aiku to n bọ niluu London ati awọn eto miiran to mu oun rinrin ajo lọ si ilẹ Gẹẹsi.
Ṣugbọn ko sẹni to tun rayo gba wọle ara wọn lẹyin ọgbọn iṣẹju naa, lọrọ ba di wo mi ki n gba siọ ti wọn n pe ni pẹnariti.
Mattis ni ibanujẹ ọkan ls jẹ fun oun pẹlu bi aarẹ Trump ṣe gbe ọrọ ifẹhọnu han lori iṣẹkupani ọmọ ilẹ Adulawo, George Floyd ti awọn ọlọpaa alawọ fufu pa ni Minnesota, ni Amerika.
Sunkanmi, to wá láti ìlú Ilora nipinlẹ Oyo pẹlu baba rẹ, jẹ ọkan lára àwon ọ̀dọ́kùnrin tó jẹ́ gbajumọ amuludun lagbo tíátà lọ́wọ́ lọ́wọ́.
Ẹkọ gbigbona lọrọ yi, o gba ki a fi suuru to'' Kini Ijọba Naijiria ti ṣe?
Ó takò òfin kí àwọn obí jẹ̀yà ti ọmọ ba darapọ̀ mọ́ ẹgbẹ́ òkùnkùn- Ajàfẹ́tọ̀ọ́mónìyàn Ẹgbẹ́ òṣìṣẹ́ ń gbáradì láti gbéná wojú MTN, lórí bó ṣe ń ṣe àwọn òṣiṣẹ́ rẹ̀ ní Naijiria Ìdí rèé tí a ṣe fẹ́ sin Majek Fashek sílẹ̀ Amerika- Randy Fashek Ẹ wo ohun tó yẹ kí ẹ mọ̀ nípa oògùn 'Sputnik V' Russia tó ń wo àrùn Coronavirus Wo àwọn iléèwé gíga tó ti bẹ̀rẹ̀ sí ní ta fọ́ọ̀mù JAMB post UTME screening ní Naijiria Ìtàn sọ pe o kọ awọn ìwé bi i A Duty to Speak: Refusing to Remain Silent in a Time of Tyranny, to jẹ akojọpọ awọn ọrọ rẹ nipa atilẹyin fun ijọba awaarawa àti bo ṣe tako iwa títẹ ẹtọ ọmọniyan loju lasiko isejọba oloogbe Sani Abacha.
Nitori naa, àwọn sẹnetọ ti yóò díje ni APC Eko ni Rẹmi Tinubu (Aarin gbungbun) Olalekan Yayi (Iwọ oorun) àti Bayo Oṣinọwọ (Ila oorun).
Àwọn ìgbìmọ̀ ati àwọn ìjòyè mi wá mi kàn, wọ́n gbà mí tọwọ́ tẹsẹ̀, ìjọba mi tún fi ìdí múlẹ̀, mo sì níyì ju ti àtẹ̀yìnwá lọ ní gbogbo ọ̀nà.
Ní àkókò òtútù-nini, ó tó àkókò Àjọ̀dún Ìyàsímímọ́ Tẹmpili tí wọn ń ṣe ní Jerusalẹmu, 
Nígbà náà ni ọ̀kan ninu wọn, Kayafa, tí ó jẹ́ Olórí Alufaa ní ọdún náà, sọ fún wọn pé, “Ẹ kò mọ nǹkankan!
Ọ̀rọ̀ yìí kọ́kọ́ jẹyọ lórí YouTube láti ẹnú Nnamdi Kanu to jẹ olórí IPOB, ọ̀rọ̀ yìí jà ranyin-ranyin lórí ayelujara tí ọ̀pọ̀ àwọn ènìyàn si n gbé ìròyìn náà kíri.
To ba ri bẹẹ, iroyin yii kan ọ.
Kí OLUWA wà pẹlu rẹ bí ó ti ṣe wà pẹlu baba mi.
Lati Ọjọ Kẹrin, Osu Kọkanla, ọdun 2018 ni awọn oṣisẹ fasiti naa ti bẹrẹ iyansẹlodi lori iwa aibikita si ipo ti ile ẹkọ giga wa lorilẹede Naijiria, ti wọn si n bere fun ki ijọba tun awọn ile ẹkọ giga ṣe pẹlu awọn ohun eto ẹkọ ti igbalode.
Ó dàbí ẹni pé ìlú kan wà ní ìhà ìsàlẹ̀ òkè náà.
Aare orile-ede Naijiria, Muhammadu Buhari ti se ipade po pelu awon toro kan gbongbon ninu egbe oselu All Progressives Congress APC teka gusuu iwo oorun orile-ede Naijiria nile aare ohun lojoBo(Thursday), niluu, Abuja.
Ọba tí ó bá ń ṣe ìdájọ́ òdodo, a máa fìdí orílẹ̀-èdè múlẹ̀,ṣugbọn ọba onírìbá a máa dojú orílẹ̀-èdè bolẹ̀.
N óo tún yín gbé dìde, ẹ óo sì di ọ̀tun, ẹ̀yin ọmọ Israẹli.
kí ó gbé ọwọ́ lé e lórí, kí ó sì pa á níwájú Àgọ́ Àjọ náà; àwọn ọmọ Aaroni yóo sì da ẹ̀jẹ̀ rẹ̀ sára pẹpẹ náà yípo.
Oríṣun àwòrán, Image copyrightHUISGENOOT/NONCEDO MATHIBELA Àkọlé àwòrán, Celeste Nurse ati Cassidy abilekeji ọmọ rẹ Miche gba ki wọn se iwadii ẹjẹ rẹ nipa DNA, ti iwadii naa si fihan pe looto Zephany Nurse ni wọn ji gbe ni ọdun 1997.
Àwọn ni yóo máa ṣe ìtọ́jú àwọn ohun mímọ́ jùlọ ninu Àgọ́ Àjọ.
Ogbeni Lai Mohammed to je minista fun oro asa, irinajo afe ati ifitonileti gbogbo lo so eyi di mimo nilu Abeokuta nipinle Ogun lasiko ti won n se odun Ilu ile Adulawo.
PDP ní Ọlọ́pàá ti mú Sẹ́nétọ̀ Ademọla Adeleke sí àhámọ́ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, '500 level'' ni mo wà nígbà tí mo di adélé Ọba' Agbegbe Ikire si Apomu ni opopona marosẹ Ifẹ si Ibadan ni wọn ti ji ojọgbọn naa gbe.
- Ẹ kò rí ẹnu rẹ̀ báyìí.
Lae, n kò ní gbàgbé ẹ̀kọ́ rẹ,nítorí pé, nípasẹ̀ wọn ni o fi mú mi wà láyé.
Bí a bá ṣàánú ẹni ibi,kò ní kọ́ láti ṣe rere.
Bẹ́ẹ̀ sì ni àwọn ẹ̀yà ara tí ó dùn ún wò kò nílò ọ̀ṣọ́ lọ títí.
Edo APC vs Oshiomole: Ẹ̀kà ìpínlẹ̀ tàbí ìjọba ìbílẹ̀ kò láṣẹ láti yọ alága àpapọ̀ ẹgbẹ́ Oríṣun àwòrán, Jubril A.
Ṣugbọn kinni arun yii, ati pe bawo ni o ṣe n tan ka?
Sanai Agunbiade, ṣoju fun sọ pe atunṣe ofin yii ni wọn yoo fi mu igberu ba
” Nítorí náà ni Isaaki ṣe sọ kànga náà ní Eseki, nítorí pé wọ́n bá a jà nítorí rẹ̀.
Adelaja, to tun je adari eka to n paaro omi ati eje inu kindinrin nnile iwosan ijoba ni: “Ni agbegbe yii lagbaye, owo nina fun ilera ti poju ni eyi ti opo ninu awon alaisan ko ni lowo.
"A gbọ wi pe Adebayo dahun pe ""Eleyi kii ṣe owo ti wa."
Nigba to n sọrọ lori aba isuna ọhun, Makinde ni adinku ida mẹrindinlogoji, 36% lo ba eto isuna naa yatọ si eyi ti ijọba ana gbe kalẹ lọdun to kọja, bakan naa si lo ni ida ogoji lo ba eto isuna ti wọn bu fun ile ijọba ati ẹka asofin nipinlẹ Ọyọ, yatọ si bo se maa n waye tẹlẹ.
 bákan náà ni a mò wọ ́ n mọ àwọn .
Lati odun melo kan seyin, ijoba aare teleri fun orile-ede Zimbabwe  Robert Mugabe ko ni ibasepo ti o donmonran pelu ile biritiko ati awon adari oselu orile-ede naa, latari kikuna lati se iranwo, ti won si bu enu ate lu isejoba re.
Nígbà tí ó yá, Jobu bẹ̀rẹ̀ sí sọ̀rọ̀, ó fi ọjọ́ ìbí ara rẹ̀ bú.
Ooni Adeyeye ti Ile Ife fẹ sèrànwọ́ owó iléèwè fún akẹ́kọ̀ọ́ 5 mílíọ̀nù ní Nàìjíríà Àwọn jàndùkú ṣọṣẹ́ nílé aṣòfin ìpínlẹ̀ Ogun, wọ́n jí ọ̀pá àṣẹ gbé!
bo se tọ ati bo se yẹ.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Ki lo le ṣekun pa ọkunrin lasiko ibalopọ?
ti ya owo to le ni ẹ̀ẹ́dẹ́gbẹ̀ta
Nígbà tí ọba Israẹli rí wọn, ó bi Eliṣa pé, “Ṣé kí n pa wọ́n, oluwa mi, ṣé kí n pa wọ́n?
Ààrẹ àná, Goodluck Jonathan ló fún mi ní 'oògùn' tí mo fi yọ Sanusi nípò Emir Kano- Ganduje Èèmọ̀!
Davido: Kí ló fa ariwo lórí ìdọ́rẹ́ òun àti Chioma aya rẹ̀ lójú òpó Instagram?
A gbọ pe eeyan mẹrindinlogun lo ti ba isẹlẹ naa rin, ti ẹmi kan si bọ sinu rẹ pẹlu, nigba ti awọn olugbe ilu naa n sa kiri lati sa asala fun ẹmi wọn.
Ààrẹ Buhari- Boko haram kò f'ẹsẹ rinlẹ l'ágbègbè kánkan ní Nàìjíríà
Nibayii Ọba Abdulrasheed Adewale Akanbi ti jẹ ko di mimọ pe yatọ si pe oun jẹ pataki Ọba, oun tun ni ẹwa.
Awọn iroyin mii ti ẹ le nifẹ si Duro Ladipọ, ìlúmọ̀ọ́ká òṣèré tíátà àti ọmọ àlúfà tí kò gbàgbé àṣà ìbílẹ̀ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, '500 level'' ni mo wà nígbà tí mo di adélé Ọba' Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
 arabinrin Abike Dabiri lori iroyin Abdur-Rahman
Oríṣun àwòrán, Others Ohun taa gbọ ni pe aṣẹ Gomina Rotimi Akeredolu ni awọn ọlọpa n tẹle.
Ìgbì òkun ti bò ó mọ́lẹ̀.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Parental Guidance: Ọdún méjì ni kí ẹ ti bẹ̀rẹ̀ kíkọ́ ọmọ nípa ìbálòpọ̀ Lati gba owo ni ileefowopamọ ti kii ṣe tiẹ: Nidi ATM wayi, tẹ 'Enter' lara awọn bọtinni to wa lara ATM naa Mu 'PayCode' lara awọn igbesẹ ti o ba gbe wa fun ọ Tẹ numba 'PayCode' ti wọ̀n ti kọkọ fi ranṣẹ sori ẹrọ ibanisọrọ rẹ Tẹ iye ti o fẹ gba ( Eyi ko gbọdọ yatọ si iye ti o ti kọ tẹlẹ nigba ti o bẹrẹ igbesẹ naa lori ẹrọ ibanisọrọ rẹ) Tẹ 'Enter' lati tẹsiwaju Gba owo rẹ Yatọ si pe o le bẹrẹ igbesẹ naa pẹlu 'App' lori ẹrọ ibanisọrọ rẹ, o tun le lo awọn aṣayan numba ti ileefowopamọ rẹ n lo lati fun ẹrọ ibanisọrọ (Fun apẹẹrẹ *111#).
Bi wọn se n jo ile ati eeyan, ni wọn n ba dukia ilu jẹ, paapaa lẹkun iwọ oorun guusu Naijiria, tii se tilẹ Yoruba, eyi to mu ki awọn ologun wa ja ijọba gba lọwọ alagbada lọjọ Kẹẹdogun osu kinni ọdun 1966.
Ọpọ ọkunrin lo n jẹ dodo ẹwa ti Ọba oke fi jinki omidan ọlọpọ ẹwa yii, to si n da gbogbo ọkunrin lọrun bii ọlẹlẹ aawẹ.
Nígbà tí ọba Asiria gbọ́ pé Tirihaka, ọba Etiopia, ń kó ogun rẹ̀ bọ̀ láti bá òun jagun, ó ranṣẹ sí Hesekaya, ọba Juda, ó ní kí wọ́n sọ fún un pé, 
Arabinrin kan to mọ nipa iṣẹlẹ naa, Alabi Rukayat Oyindamola, lo kọkọ gbe iroyin nipa rẹ si ori ayelujara Facebook.
Wọn kò gbé igi tabi kùmọ̀ rara.
A jura wa lo tija kadi ko!
Àwọn àgbààgbà tí wọ́n wà ninu ilé rẹ̀ rọ̀ ọ́, pé kí ó dìde nílẹ̀, ṣugbọn ó kọ̀, kò sì bá wọn jẹ nǹkankan.
Ikolu sele lakooko ti ija waye laarin eya Oromo and Somali .
Gbenga fi ẹsun kan iyawo rẹ, Mojisola Olayemisi Amope, to jẹ ọmọ gbajugbaja oloselu, Ọtunba Alex Ọnabanjọ, pe oun ni ibalopọ pẹlu Ọbasanjọ lati le ri iṣẹ agbaṣe gba lọwọ ijọba.
Ẹ dúró ní ibi mímọ́, kí ẹ sì pín ara yín sí ìsọ̀rí-ìsọ̀rí gẹ́gẹ́ bí iye ìdílé àwọn arakunrin yín.
Ẹ kò mọ̀ ọ́n, ṣugbọn èmi mọ̀ ọ́n.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Kenya Prisioners: Àwọn ẹlẹ́wọ̀n mórí lé ilé-ẹjọ́ kòtẹ́milọ́rùn fún ẹ̀kúnwó owó oṣù ẹlẹ́wọ̀n 15 Bélú 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Kenya Prisioners: Àwọn ẹlẹ́wọ̀n mórí lé ilé-ẹjọ́ kòtẹ́milọ́rùn fún ẹ̀kúnwó owó oṣù ẹlẹ́wọ̀n Awọn to ti ṣẹwọn ri mẹta lorilẹ-ede Kenya ti morile ile ẹjọ kotẹmilọrun bayii lẹyin ti ile ẹjọ giga kan da ẹjọ wọn nu Awọn mẹta yii ni wọn pe ẹjọ fun ẹkun owo oṣu fawọn ẹlẹwọn to n ṣiṣẹ lọgba ẹwọn nibi ọdun mẹrin sẹyin.
Awọn alatako sì sọ pe eyi mu ki o ṣòro lati ko ẹri jọ pé mago-mago ibo waye.
Nígbà tí èmi ati àwọn tí wọ́n wà lọ́dọ̀ mi bá fọn fèrè, ẹ̀yin náà ẹ fọn fèrè tiyín ní gbogbo àyíká àgọ́ náà, ẹ óo sì pariwo pé, ‘Fún OLUWA, ati fún Gideoni.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Bird Flu: Onímọ̀ ní kò sí òògùn tó leè pa àrùn lùkúlùkú ní Nàíjíríà 20 Èrèlè 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Àìsàn lùkúlùkú tí àwọn olóyìnbó ń pè ní bird flu ti pa adìye 3900 ní ìpínlẹ̀ Plateau, lẹ́yìn tó bẹ̀rẹ̀ ní Bauchi.
Ó rí i pé pẹlu ipá ni wọ́n fi ń wa ọkọ̀, nítorí afẹ́fẹ́ ṣọwọ́ òdì sí wọn.
A o forikori pẹlu awọn ọlọpaa lati mojuto ipenija eto abo .
Ẹ ṣe àyẹ̀wò kíkà ni èdè Yorùbá ni ojú ewé yi:
Wọn sọ nipa esi idibo awọn ibudo idibo ti ko si iforukọsilẹ to peye tabi ti wọn ko ri to papọ bi o ṣe yẹ.
Oro yii waye lasiko ti Aare orile-ede Sudan se abewo si orile-ede Russia ninu osu kokanla, nigba ti o so fun akegbe re Vladimir Putin lati daabobo  orile-ede oun lowo orile-ede America.
Iroyin so pe “adari ijoba orile ede naa, Emmanuel Issoze-Ngondet kowe fipo ijoba sile leyin igba ti ile-ejo ti se ipinnu lati fopin si ile igbimo asofin”.
Àti ẹ̀ni tí a bá tan, àti ẹni tí a kò tan mọ́, gbogbo wa náà la parapọ̀ di àwùjọ-ẹ̀dá.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Wale Rapper: Ìya mi gan ti lè yára sọ̀rọ̀ bí ẹni ń kọrin Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Wale Rapper: Ìya mi gan ti lè yára sọ̀rọ̀ bí ẹni ń kọrin 30 Sẹ́rẹ́ 2019 Adewale Adepoju jẹ ọmọ Yoruba lati ilu Ọyọ to si jẹ wi pe lati ile iwe giga fasiti to lọ lo ti yan lati maa ṣe ohun to jọ mọ itage.
Gẹgẹ bi o ti ṣe sọ, wọn ni orukọ awọn akẹkọọ naa ni: Popoola Olaniyi Agboola IDD/ (300L) Oluwadare Faith Tobiloba FST ( 200L) Nandi Yohanna Jessica IPE/ ( 200L) Ajuwon Tolani Emmanuella FAT/ (100L) Emmanuel Funmilayo Taiwo FAT/ (100L) Alao Olabimpe Cecilia CSP/ (100 L) Bakanna ni wọn ni lile tawọn le awọn akẹkọọ naa wa ni ibamu pẹlu ofin ileewe to la ijiya ''lile akẹkọọ kuro ti o ba lu akẹkọọ akẹgbẹ rẹ nibikibi ti kii ṣe ọgba ile ẹkọ'' Wọn ni lnitori eleyi, awọn akẹkọ to huwa aidaa naa ko le e jẹ anfaani kankan to tọ si awọn akẹkọọ fasiti naa mọ bayi.
Irú rẹ̀ kò ṣẹlẹ̀ rí ní ìgbà àtijọ́,bẹ́ẹ̀ ni irú rẹ̀ kò sì tún ní ṣẹlẹ̀ mọ́ títí lae.
Sibẹ ẹ ti gbàgbé mi tipẹ́.
Awọn ẹ̀rí to wa nilẹ si lo mu ki awọn alaṣẹ Saudi tu ọmọbinrin naa silẹ.
lagos state house of assembly jẹ ́ ilé ìgbìmọ ̀ aṣòfin ti Ìpínlẹ ̀ Èkó .
Ìjàmbá iná: Sitofu tó gbaná pàdé ike pẹtiró, ni iná bá sọ
Iroyin to n tẹwa leti ni wi pe wọn da a silẹ pẹlu ikilọ pe ko ma ṣe kopa ninu iwa ipa kankan titi ọdun kan gbako.
Joṣua bá sọ fún wọn pé, “Ẹ má bẹ̀rù, ẹ má sì ṣe jẹ́ kí àyà yín já.
Awọn orilẹede kan nilẹ Afrika ti gbe iranlọwọ dide fun obinrin to n ni idojukọ yii; fun apẹrẹ, ijọba Tunisia ti gbe nọmba ipe kalẹ fun awọn obinrin.
Wọ́n ní ìrù bíi ti àkeekèé tí wọ́n fi lè ta eniyan.
Ó bá bẹ̀rẹ̀ sí bá a wí pé, “O óo ti mu ọtí waini pẹ́ tó?
Adam Johnson: Agbábọ́ọ́lù Sunderland nígbà kan rí jáde lẹ́wọ̀n lẹ́yin ọdún mẹ́ta
Damọla Ọlatunji ati Bukọla Awoyẹmi: Àwọn òṣèré tíátà Yorùbá tó fẹ́ òṣèré ẹgbẹ́ wọn
Adajọ ti sun igbẹjọ naa si Ọjọ Kẹrindinlogun ati ikarundinlọgbọn, Oṣu Kẹjọ, ọdun 2020.
Ó tún ṣiṣẹ ́ fún cardinal richelieu , tí ó ṣe ẹ ̀ ṣọ ́ palais cardinal , tí ó jẹ ́ òfúrufú sorbonne àti àwọn ilé míràn .
Àwọn ìlú rẹ̀ ti di àríbẹ̀rù,wọ́n ti di ilẹ̀ gbígbẹ ati aṣálẹ̀,ilẹ̀ tí ẹnikẹ́ni kò gbé mọ́,tí ọmọ eniyan kò sì gbà kọjá mọ́.
Nítorí náà, àwọn alabojuto ati àwọn gomina wọnyi ń wá ẹ̀sùn sí Daniẹli lẹ́sẹ̀ nípa ọ̀rọ̀ ìjọba, ṣugbọn wọn kò rí ẹ̀sùn kankan tí wọ́n lè kà sí i lẹ́sẹ̀.
takun-takun ninu isewadii ati ise omoniyan ti o yan laayo.
O ni awọn yoo wa ojutu si eto karakata abẹle lorilẹ-ede to bẹẹ ti titi ẹnu ibode ko fi ni nipa awọn eeyan rẹ lara mọ.
Kurunmi woye pé Ibadan gbé igbesẹ náà, ko leè rọrùn fún láti tẹsiwaju nídìí isakọlẹ tó ń gba lọ́wọ́ àwọn ìlú tó wà ní abẹ rẹ ni, tó sì tako Ibadan lórí ìpinnu náà.
Bakan naa lo tun rọ awọn oloṣelu lati gba alaafia laaye lasiko idibo naa.
23 Àti pé nísisìyí, lẹ́ẹ̀kansíi, mo bá ọ sọ̀rọ̀, ìránṣẹ mi Joseph, nípa ọkùnrin náà tí ó fẹ́ ẹ̀rí—
Igi kedari láti Lẹbanoni ni wọ́n sì fi ṣe òpó ọkọ̀ rẹ.
Ṣé amọ̀ lè bèèrè lọ́wọ́ ẹni tí ń mọ ọ́n pé:‘Kí ni ò ń mọ?
dókítà - BBC News Yorùbá BBC News, YorùbáFò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Doctors on Strike: Coro wà Coro ò sí o, èmi á lọ́ sókè òkún bí mo bá ríṣẹ́ - dókítà 17 Agẹmo 2020 Oríṣun àwòrán, Getty Images Awọn dokita Naijiria ti figbe ta pe ki ijba apapọ ma wulọ r awn rara lati ma ko l si oke oku lati lọ maa ṣiṣẹ.
mẹtalelogun-le-ọjilenirinwo ati mẹrin (23,444) nigba ti akẹgbẹ rẹ lati
Àkókò àlàáfíà gbáà, n kò lè gbàgbé ọjọ́ ìgbéyàwó yìí bi ayé yípadà tó bẹ́ẹ̀ ti màlúù ń lóyún ewúrẹ́ tí ológbò ń bí àkùkọ.
Ó ń kọ́ àwọn eniyan ninu Tẹmpili lojoojumọ.
Wọn kò pa àwọn òfin tí OLUWA fún Mose, iranṣẹ rẹ̀ mọ́, wọn kò sì gbọ́ràn.
Wọ́n bẹ̀rẹ̀ sí bu yẹ̀ẹ̀pẹ̀ sórí ara wọn, wọ́n ń sunkún, wọ́n ń ṣọ̀fọ̀.
June 12: Ọjọ́ tí ọ̀pọ̀ ẹ̀yà, èdè àti ẹlẹ́sìnjẹ̀sìn tó wà ní Nàíjíríà papọ̀ di ọ̀kan
Akinọla: Ọdún méjì ni kí ẹ ti bẹ̀rẹ̀ kíkọ́ ọmọ nípa ìbálòpọ̀
Ronaldo fi ikeji si lẹyin iṣẹju mẹẹdogun to gba lakọkọ sawọn.
To ba jẹ pe o ṣi n lo nọ́mbà naa, tẹ àwọn nọ́mbà 'User ID' ati 'OTP' ti NIMC ba fi ṣe atẹranṣẹ si ori nọ́mbà naa lasiko yii, ki o si tẹ 'Proceed'.
’“Nígbà náà ni mo wá mọ̀ pé àṣẹ OLUWA ni.
Eyi lo mu ko sare yẹ gbogbo ọra omi ti wọn ti fun tẹlẹ wo, to si jẹ pe bakan naa ni gbogbo wọn ri.
SAFA so eyi di mi mo lori ero ayelujara, lojo Aje, Baxter ti o je akonimoogba tuntun, ti o dipo, Ephraim Shakes Mashaba, eyi ti egbe ohun da lowo ise duro losu kejila odun ti o koja.
Ilu ohun tesiwaju lati seto iyanselodi naa, bi o tile je pe, o lodi sofin labe ikede ilu-o-fara ro ti ijobe kede re lose to koja, minisita fun eto abo Siraj Fegessa so pe, ikede ilu-o-fara ro naa yoo wa fun osu mefa.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Buhari yóò rí ara rẹ̀ gẹ́gẹ́ bíi Mèsáyà yóò sì gbìmọ̀ràn sáà kẹta nípò-Dele Momodu Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Buhari yóò rí ara rẹ̀ gẹ́gẹ́ bíi Mèsáyà yóò sì gbìmọ̀ràn sáà kẹta nípò-Dele Momodu 22 Agẹmo 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 2 Ọ̀wàrà 2019 Odu oniroyin ni Dele Momodu ti ẹnikẹni ko le jiyan lori iduro rẹ gẹgẹ bi ajafẹtọ araalu pẹlu.
Awọn mii to mọ si iṣẹlẹ ọhun ni Ọgagun Sanni Abacha, Ọgagun Ibrahim Babangida.
A ti di ẹni ẹ̀gàn lójú àwọn aládùúgbò wa;àwọn tí ó yí wa ká ń fi wá ṣe yẹ̀yẹ́;wọ́n sì ń fi wá rẹ́rìn-ín.
Wọ́n ń rúbọ ninu oríṣìíríṣìí ọgbà,wọ́n ń sun turari lórí bíríkì.
Ajọ fẹnuko nibi ipade naa pe ao jọ ṣiṣẹ pọ, ṣugbọn gbogbo nkan lo ni eto.
    Ní ọjọ́ ìgbéyàwó wa, gọngọ sọ ni ìpàdé ayé òun ọ̀run.
” Ọmọ náà ṣa àwọn ọfà náà, ó sì pada sọ́dọ̀ ọ̀gá rẹ̀, 
“Mo ti kọ yín ní ìlànà ati òfin gẹ́gẹ́ bí OLUWA Ọlọrun ti pa á láṣẹ fún mi, kí ẹ lè máa tẹ̀lé wọn nígbà tí ẹ bá dé ilẹ̀ tí ẹ̀ ń lọ gbà.
 Orile ede Iraq ni wọn ti bi onkọrin Majid al-Mohandis naa.
Lara Iṣẹ igbakeji aarẹ ni lati maa koju awọn alatako, itan si fihan pe Harris to gbangbaa sun lọyẹ niruu nkan bayii.
Lẹ́yìn iná náà, ohùn kẹ́lẹ́kẹ́lẹ́ kan rọra sọ̀rọ̀ jẹ́ẹ́jẹ́.
Ṣugbọn ọpọ awọn onile itaja epo ti o jẹ aladani ni ko tii bẹrẹ si ni ta epo, ti awọn kan si n taa ni naira marundinladọjọ ti o wa tẹlẹ.
ko to lo si ile-iwe alakọbẹrẹ St.
Ẹ lọ sórí àwọn òkè, kí ẹ gé igi ìrólé láti kọ́ ilé náà, kí inú mi lè dùn sí i, kí n sì lè farahàn ninu ògo mi.
Ọ̀nà òdodo ni èmi ń rìn,ojú ọ̀nà tí ó tọ́ ni mò ń tọ̀.
Bakan naa ni Kollington kede pe baba Kebe ni oun, baba 'Yuppie', nitori pe to ba di ere lọkọlaya, ara oun si n ta kebe, eegun oun si tun n le.
O n i iyawo oun yan kiniun meji, ti oun naa si mu erin kan.
Bí ẹ bá sì bèèrè, ẹ kò rí ohun tí ẹ bèèrè gbà nítorí èrò burúkú ni ẹ fi bèèrè, kí ẹ lè lo ohun tí ẹ bèèrè fún ìfẹ́kúfẹ̀ẹ́ ti ara yín.
N óo wá ṣe ìdájọ́ fun yín nítorí iṣẹ́ ibi yín, èmi OLUWA ni mo sọ bẹ́ẹ̀.
Awọn miran sọ pe niroti pe awọn obi rẹ jẹ gbajumọ nipinlẹ Oyo ni.
"Èyí ni ipa tí àdínkù owó epo bẹtiró yóò mú bá ọ̀rọ̀ ajé Nàìjíríà Ìjọ kò ní tilẹ̀kùn ilé ìjọsìn nítorí àrùn Coronavirus - Ondo PFN Ẹyin ilé ìjọsìn, ẹ tilẹ̀kùn ṣọ́ọ̀ṣì àti mọ́ṣáláṣí yín láti dènà àrùn Coronavirus - ìjọba Eko Ẹ wo ohun tí baba Adeboye sọ lórí ọ̀rọ̀ Coronavirus Olori ọlọpaa ni agbegbe Msambweni, Nehemiah Bitok sọ pe ""awọn ọdọ naa lo anfaani pe ọkunrin naa ti mu ọti yo, ti wsn si lu u bi ko ku."
Naijiria fi ìgbájú mẹ́ta lé Cameroon kúrò ní AFCON Wilfred Ndidi: Ẹ̀yin èèyàn ẹ kàn ṣáà ní sùúrù, kí ẹ sì gbàdúrà fún wa Báyìí ni àwọn alátìlẹ́yìn Super Eagles ṣe ń dá músò ṣáájú ìdíje tòní Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí 2 sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 2:23 Fídíò, Water Generator: Ó leè ṣiṣẹ fún wákàtí mẹfà, kó tó sinmi, Duration 2,2310 Òkùdu 2020 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
Buhari ba Aarẹ Xi ti China yọ
Kemi sọ pe nkan to ju ọla lọ ni bi wọn ṣe fi oun jẹ oye naa, nipa dida oun mọ bi imọlẹ ati olutọnisọna ni aye ode oni.
A wà níwájú rẹ báyìí pẹlu ẹ̀ṣẹ̀ wa, bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé kò sí ẹni tí ó lè dúró níwájú rẹ báyìí.
Wọn n gbera bayii lẹyin ti wọn ti da wọn duro fun ọpọlọpọ wakati lataarọ.
Wọn yóo wá dá orin arò fún ọ pé:Wò ó bí o ti parẹ́ ninu òkun,ìwọ ìlú olókìkí,ìwọ ìlú tí ó lágbára lórí òkun,ìwọ ati àwọn tí ń gbé inú rẹ,àwọn tí wọn ń mú kí ẹ̀rù rẹ máa ba àwọn tí wọn ń gbé orí ilẹ̀.
Nípa agbára Ọlọrun tí kì í ṣe ti eniyan, ó ti fún wa ní ohun gbogbo tí yóo jẹ́ kí á gbé irú ìgbé-ayé tí ó dára ati ti ìwà-bí-Ọlọrun, nípa mímọ ẹni tí ó fi ògo ati ọlá rẹ̀ pè wá.
Àkọlé àwòrán, Àwòrán àwọn olukopa ti wọn n fi tẹrin tọyaya gboriyin fun awọn oludije ti wọn fẹran aato ti wọn ni fun ipinlẹ Eko Àkọlé àwòrán, Ọmọọbabinrin Adebisi Ogunsanya (YPP) bí ó ṣe n gunlẹ si gbọngan ipade ifọrọwerọ pẹlu BBC Yoruba Àkọlé àwòrán, Atọkun eto n ka iwe kikan kikan ṣaaju eto naa nitori iṣẹ to rọrun kọ lati mọ ati sọrọ nipa gbogbo oludije lai figba kan bọ ọkan ninu paapaa nipa eto oṣelu.
O ni laipe yii, orile ede Naijiria ko ni maa ko ounje wa lati oke-okun mo on .
Ṣugbọn Pilatu bi wọ́n pé, “Nítorí kí ni?
Awọn mejeeji la gbọ pe awọn ajinigbe da lọna lasiko ti wọn n wa ọkọ jade ninu ọgba ile itaja ogun naa.
Àwọn ẹranko ni àwọn ti gbọ́ bi ẹ ti ń pa àwọn ọmọ àwọn, tí kì í ṣe èyí tí ó dàgbà nínú wọn nìkan ni ẹ̀ ń pa jẹ, ti ẹ̀ ń pa èyí ti wọ́n ṣẹ̀ṣẹ̀ bí lóòjọ́, èyí ti ko ju ọjọ́ méjì àti ẹranko ọlọ́jọ́ mẹta.
Ǹjẹ́ nisinsinyii, ẹ̀yin ọmọ, ẹ máa gbé inú rẹ̀, kí á lè ní ìgboyà nígbà tí ó bá farahàn, kí ojú má baà tì wá láti wá siwaju rẹ̀ nígbà tí ó bá dé.
yorùbá tún ní oríkì irú èyí tí àwọn akọ ́ ríkì máa ń lò láti tẹpẹlẹ mọ ́ Àṣeyọrí aṣáájú ti oríṣìíríṣìí ìdílé.
Bí a ti gbọ́, bẹ́ẹ̀ gan-an ni ó rí,ní ìlú OLUWA àwọn ọmọ ogun,ní ìlú Ọlọrun wa:Ọlọrun fi ìdí rẹ̀ múlẹ̀ títí lae.
Olatunji di ilumọọka onilu ni Amẹrika, to jẹ amuyangan fun iran Yoruba, to si gba ami ẹyẹ Grammy nidi orin kíkọ lọdun 1991.
 eto idibo ni ipinle naa, ọjọgbọn
" Àyìndé barrister bẹ ̀ rẹ ̀ iṣé orin kíkọ láti ìgbà kékeré rẹ ̀ gẹ ́ gẹ ́ bí ' ají-sààrì ' tàbí "" ají-wérẹ "" lásìkò Àwẹ ̀ àwọn musulumi ; bí ó ṣe ń ṣiṣẹ ́ rẹ ̀ náà ló ń kọrin pẹ ̀ lú rẹ ̀ ."
kí ni ó wà nínú ọ ̀ rò-sísọ tó ní ìtumọ ̀ ?
Yóo sì bẹ̀rẹ̀ sí gbilẹ̀, bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé orílẹ̀-èdè tí ó jọba lé lórí kéré.
Bo tilẹ jẹ pe ọpọ eeyan lo bu ẹnu atẹ lu ijọba nigba naa pe wọn ko fẹ ẹ ṣe atilẹyin fun akẹgbẹ rẹ nilẹ Africa ni.
Ninu ọrọ rẹ, o ṣalaye pe lati je ki ipo naa ṣe deede kaakiri awọn origun oṣelu mefeefa ni orilẹ-ede Naijiria, lati ni aṣoju ninu akoso igbimọ naa, wọn yan awọn igbakeji miiran lati awọn ipinlẹ kan.
Lori boya wọn ṣi lee pada silẹ Amẹrika, awọn eeyan ọhun fohun ṣọkan pe ohun kan ṣoṣo to lee gbe wọn pada lọ Amẹrika ni ki wọn lọ ṣe abẹwo si awọn ẹbi to wa lọhun, bi bẹẹ kọ, Afrika ni ile ti wọn yan laayo.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Ìgbésí ayé tí kò pariwo ló dára' Fún ènìyàn tó bá ń ní irú ìrírí yìí, yóò nira láti ki òwú tí wọ́n fi ń dá ìsun ẹ̀jẹ̀ dúró bọ ojú ara rẹ̀, yóò jàa fita fita láti ní ìbálòpọ̀ tàbí kí abẹ́ máà ta á.
Sọ ohun tí o ní nílé fún mi.
Eyi mu ki awọn ọta rẹ tubọ maa wariri fun un tori wọn wo o pe ki wa lo lee pa Ogedengbe bi bibẹ lori ko ba lee ran an lọ salakeji.
Ta ni yóò borí láàrin Aisha Buhari àti ọkọ rẹ̀ lórí ọ̀rọ̀ ‘First Lady’?
Ayika Ọkan ninu anfaani ti konile o gbele mu wa ni pe o dabi ẹni pe ijamba si ayika ti dinku ni awọn ibi kan ni agbaye, paapa si ayipada oju ọjọ.
Gomina ipinlẹ Eko tẹlẹ naa bu ẹnu atẹ lu Obaseki , o si fẹsun kan an pe o n fi ofin Naijiria ṣe ẹlẹya ni bo ṣe dena iburawọle fun ida meji ninu mẹta awọn ọmọ ile ọhun ti wọn dibo yan.
 bí owó ti lágbára tó , tó lókìkí tó , kò ṣeé fir a iyì àti ẹ ̀ yẹ .
 a kìí sábà nílò àfikún ìwọ ̀ n àjẹsára náà lẹ ́ yìn èyítí a bá ti kọ ́ kọ ́ fún ni .
Aisha Buhari tọrọ ìdáríjì lórí fídìo tó jáde Egbìnrìn ọ̀tẹ̀!
Bí baba ati ìyá mi tilẹ̀ kọ̀ mí sílẹ̀,OLUWA yóo tẹ́wọ́gbà mí.
Ni Uganda, Boda-boda ni orukọ ti wọn n pe alupupu akero ọkada.
OLUWA sọ fún Joṣua pé, “Lónìí ni n óo bẹ̀rẹ̀ sí gbé ọ ga lójú gbogbo àwọn ọmọ Israẹli, kí wọ́n lè mọ̀ pé bí mo ti wà pẹlu Mose, bẹ́ẹ̀ ni n óo wà pẹlu rẹ.
 ní ìgbà tí ifá fi wà ní ilé ayé , ó gbé ilé-ifẹ ̀ fun ìgbà péréte .
Ijọba wa leri leka pe oun setan lati tilẹkun ileẹkọ, ibudo ijọsin tabi ileesẹ to ba tako ilana to n dena arun Coronavirus pa.
Ẹwẹ, ajọ akoso ileeṣẹ ọlọpaaloriulẹede Naijiria, PSC naa ti ṣalaye pe awọn ko le ọlọpaa meji yii o.
O dá ara rẹ lójú bí ẹni tí ó jẹ́ amọ̀nà fún àwọn afọ́jú, ìmọ́lẹ̀ fún àwọn tí ó wà ninu òkùnkùn.
Isegbe woye pe, o soro dekun itankale aarun, toripe, aarun le seyo nigba-kugba, latari bi awon eniyan se n rinrinajo kaakiri, ko seni to le di enikeni lowo lati maa rin-irinajo, bi won si se n rinrinajo yii, ni won n jeun, ti won si n gbounje rin kiri, eyi le sokunfa awon ounje ti o ti baje ohun lati ibi kan si ibommira.
Pissetzky n rọ adajọ pe ko gba beeli onibara oun, ko si fun laaye lati maa gbe pẹlu ibatan rẹ kan to ni iyawo ati ọmọ, ti wọn yoo si maa tọpinpin rẹ.
Aago Naijiria ti kún àkúnwọ́sílẹ̀ - Tunde Bakare Fulani nìkan kọ́ ló ń pa ènìyàn ní Naijiria -Tinubu Àwọn olówó Naijiria 5 tí owó wọn ju owó ìsúnná Naijiria lọ!
Ó bá sọ fún wọn pé, “Ọ̀rọ̀ tí mo sọ fun yín nígbà tí mo wà lọ́dọ̀ yín nìyí, pé dandan ni kí ohun gbogbo tí a sọ nípa mi kí ó ṣẹ gẹ́gẹ́ bí a ti kọ wọ́n sílẹ̀ ninu ìwé Òfin Mose ati ninu ìwé àwọn wolii ati ninu ìwé Orin Dafidi.
O kede pe akọle ere ti oun n ya ni Adigun ọga ọga, ti aworan naa si se afihan rẹ to wọ asọ ọlọpaa.
“Ṣé o lè fi ìwọ̀ fa Lefiatani jáde,tabi kí o fi okùn di ahọ́n rẹ̀?
Wo ìdí tó fi tọrọ àforíjì fún ọ̀rọ̀ ẹ̀gbin tó sọ sí Pásítọ̀ David Oyedepo Àwọn tó ní Covid-19 ní Nàìjíríà ti pé 56,177, ẹ wo ipò tí ìpínlẹ̀ kọ̀ọ̀kan wà Bí ògbójú ọlọ́sà ajínigbépawó, Bobosky ṣe kú sí àhámọ́ àwọn ọlọ́pàá Oríṣun àwòrán, LASEMA Ajọ to n ri si iṣẹlẹ pajawiri ni kete ti awọn gba ipe nipa iṣẹlẹ yii lawọn kan si agbami iṣẹ.
N óo fi ààrin yín ṣe ibùgbé mi, ọkàn mi kò sì ní kórìíra yín.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù FUTA: Òfin ti wà nílẹ̀ tó ní ká lé akẹ́kọ̀ọ́ tó bá na akẹẹgbẹ́ rẹ̀ 26 Bélú 2019 Oríṣun àwòrán, Google Ile ẹkọ fasiti imọ ẹrọ ijọba apapọ to kalẹ silu Akure, ti fi ọwọ osi juwe ile fawọn akẹkọọ mẹfa ti wọn fẹsun kan pe wọn lu akẹgbẹ wọn.
Oba Adeyeye Ogunwusi ni pe gbogbo igba ti oun ba ti sọ iru ọrọ yii, awọn eniyan a fi ṣe awada, wọn a si gbagbe nipa ẹ.
Akọroyin BBC Yoruba to wa nibi eto isinku naa jabọ pe se ni oju awọn eeyan naa, to peju sibi eto isinku yii faro, ti wọn si n kẹdun iku ojiji to mu arabinrin naa lọ.
3bn Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ankara Design: Ai ri oníbara ló jẹ́ kí n wá ọ̀gbọ́n àtinúdá tèmi.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Osinbajo: Ikẹnnẹ yẹ kó jẹ́ Mẹ́kà òṣèlú ni Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Osinbajo: Ikẹnnẹ yẹ kó jẹ́ Mẹ́kà òṣèlú ni 24 Sẹ́rẹ́ 2019 Ọpọlọpọ ló gbà pé ilẹ̀ Wúrà ni Ikenne jẹ ninu oṣelu Naijiria.
wọ́n ń dẹ ẹ́ kí wọn lè ká ọ̀rọ̀ mọ́ ọn lẹ́nu.
Ọlọrun pàṣẹ pé kí awọsanma wà láàrin omi, kí ó pín omi sí ọ̀nà meji, kí ó sì jẹ́ ààlà láàrin omi tí ó wà lókè awọsanma náà ati èyí tí ó wà ní ìsàlẹ̀ rẹ̀.
Oniruuru ami ẹyẹ lo si ti gba pẹlu titi kan ami ẹyẹ awọn elere sinima agbelewo ni Afirika iyẹn, AMVCA lọdun 2019.
Ile Igbimọ Aṣofin Ipinlẹ Eko ti gbe igbesẹ lati ṣagbekalẹ ofin ti yoo maa mojuto awọn alarun ọpọlọ ni ipinlẹ yii, bi wọn ṣe ka abadofin to nii ṣe pẹlu itọju arun ọpọlọ fun igba ẹkeji ninu ipade ile naa lọjọ Aje (Monday), eleyii ti Agbẹnusọ Ile naa, Aṣofin Mudashiru Ọbasa dari rẹ.
Bi awọn kan ṣe n sọ pe ile ẹjọ Sharia ko lagbara lati ṣedajọ iku fun eeyan ni Naijiria nitori ofin ijọba apapọ ni Naijiria n lo, lawọn miran n sọ pe ile ẹjọ naa ko ṣe daadaa to.
Igbesẹ yii jẹ imọ awọn oloṣelu kan tara n ta lati dẹ okun isede to wa tẹlẹ.
Ó gun orí Kerubu, ó fò,afẹ́fẹ́ ni ó fi ṣe ìyẹ́ tí ó fi ń fò.
 Ó jẹ ́ obìrin àkọ ́ kọ ́ tí ó m , áa kọ ́ kọ ́ wa ọkọ ̀ ayọ ́ kẹ ́ lẹ ́ ní orílẹ ̀ èdè rẹ ̀ .
“Awọn agba inu ẹgbẹ  wa ti n se ise takun-takun lati bi opolopo ose seyin lati yanju awọn isoro to n sele ninu ẹgbẹ , gege bi awọn adari rere se gbodo se.
FEC: Ìgbìmọ tuntun dìde láti sàtúntò ọlọ̀pàá
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ire ṣ'ọjọ́-ìbí, Mide àti ọkọ rẹ̀ lẹ̀pọ̀, Iyabo Ojo f'aṣọ ilẹ̀ Afirika dárà Ọ̀rọ̀ ìtàjẹ̀sílẹ̀ ní Nàìjíríà yìí tí ń kọ àwa Oṣo àti Àjẹ́ lóminú, a fẹ́ wa ǹkan ṣe síi Ilé ẹjọ́ ní kí ''Yahoo boy'' lọ darí ọkọ̀ f'óṣù mẹ́ta pẹ̀lú N50,000 owó ìtanràn Mọ̀ síi nípa Shina Rambo tó pàdé Jesu lọ́gbà ẹ̀wọn lẹ́yìn tó ti jalè Ìpànìyàn tún wáyé ní Akinyele, àwọn ará àdúgbò ṣe ìwọ́de Lọtẹ yii, orilẹede Ireland ni owo to to miliọnu mẹfa ati aabọ dọla ($6.
Adari iko ologun naa wa kilọ
Adamawa: Ọlọ́pàá mú ẹyẹ igún sí àtìmọ́lé ní ìpínlẹ̀ Adamawa
Yàtọ̀ sí coronavirus, wo ìgbà mẹ́wàá míì táwọn mùsùlùmí kò lè ṣiṣẹ́ Hajj Mùsùlùmí tó ń gbèrò láti lọ hajj ni Alhaji, Alhaja - Onímọ̀ Ọmọ Yorùbá mẹ́wàá tó jẹ́ àmúlùúdùn ní Amẹ́ríkà àti Yúróòpù Wo ohun tí ìrìnàjò ààrẹ Buhari fún ìgbà àkọ́kọ́ lásìkò Coronavirus lọ sí Mali yóò bá bọ̀ Àwọn alágbára ni mo bá díje ṣùgbọ́n mo ti gbà f'Olọrun- Agboola Ajayi O ti lé ní ènìyàn mẹ́wàá tí ina jó gúrúgúrú nínú ìjàmbá tó wáyé ní Delta Bakan naa ni wọn ni gbogbo adura ati aawẹ ti Musulumi ba se ni ọjọ naa yoo goke arafa lọ ni ibi ti o sunmọ Ọlọrun julọ Sheikh Aminu Ibrahim Dauraea to jẹ ilumọọka onimọ ẹsin Islam ni orile-ede yii salaye fun BBC nipa gbogbo awọn nkan to rọ mọ Oṣu Dhu al- Hijjah ati awọn nkan ti musulumi gbọdọ ṣe.
Wo ọ̀nà tí àwọn ‘ẹ̀lẹ̀ Daddy’ gbà dé ààfin Ọyọ Ilé ẹjọ́ yẹ àga mọ́ Ọba Ìkirè nìdí lẹ́yìn ọdún 27 lórí ìtẹ́ Báwó ni òògùn dexamethasone ṣe ń ṣiṣẹ́ lára Ìjọba tó wà lóde yìí kò ní ìfẹ́ aráàlú la ṣe dá ẹgbẹ́ NCF sílẹ̀ - Femi Falana Ọjọ́ Kẹ̀jọ, oṣù yíì ní ìrìnà ọkọ́ òfúrufú yóò bẹ̀rẹ̀ padà ní Naijiria Ijọba orilẹ-ede Niajiria ti paṣẹ ki wọn ṣi awọn papakọ ofurufu to wa lorilẹ-ede Naijiria lẹyin oṣu mẹta ti wọn ti i pa nitori ajakalẹ arun Coronavirus.
Ṣé o mọ̀ bí ayé ti tóbi tó?
Ẹ óo máa rú ẹbọ sísun yìí ní gbogbo ọjọ́ ìsinmi pẹlu ẹbọ ojoojumọ ati ẹbọ ohun mímu.
Ejò bu ìdí obìnrin kan jẹ nínú ilé ìgbọ̀nsẹ George Weah tí padà sí ẹnu ìṣẹ́ lọ́fíìsì tí ejo tí lè kúrò Oga mi lo gba 36m Jamb Mọlẹbi rẹ kan Ruby Steenkamp sọ fun ile iṣẹ iroyin News24 pe ''iku rẹ ba wa lojiji.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù BB Naija: Ìjọba Ekiti ní Khafi kò tíì ṣẹ̀ sófin débi pé yóò nílò àtìlẹyìn wọn 14 Ògún 2019 Oríṣun àwòrán, AcupofKhafi Àkọlé àwòrán, BBNaija 2019: Kíní ǹkan tí Khafi ó pàdánu tí iṣẹ́ ba bọ́ lọ́wọ́ rẹ̀ Kọmisana fun eto iroyin nipinlẹ Ekiti, Gboyega Olumilua ti kede pe Khafi Kareem, to n kopa lori eto BB Naija, to si jẹ ọmọ bibi ipinlẹ naa, ko tii se ohun to lodi sofin debi pe yoo nilo atilẹyin abi idasi ijọba ipinlẹ naa.
N óo sọ àwọn ọmọ Israẹli tí ń gbé orí yín di pupọ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Africa Eye: Coronavirus di adákẹ́jà ní Somalia, ikú ọ̀wọ́ọ̀wọ́ ń peléke si Ka ni wọn n ṣe iṣẹ wọn daadaa ni, ko ni i ribẹ.
Ṣé idì ti àkọ́kọ́ kò ní fa gbòǹgbò rẹ̀ tu, kí ó gé ẹ̀ka rẹ̀, kí àwọn ewé rẹ̀ tí wọ́n ṣẹ̀ṣẹ̀ yọ sì rọ?
Ajọ naa wa parọwa si awọn eleto aabo lati wa ẹkun naa ri, sugbọn ki wọn gbiyanju lati ma se pa a ayafi to ba wu iwa ipa si wọn lasiko ti wọn ba ri i mu.
Ẹ bẹ̀rù OLUWA Ọlọrun yín; ẹ sìn ín, kí ẹ sì súnmọ́ ọn.
Dafidi ọba bi í pé, “Kí ni o fẹ́ fi gbogbo nǹkan wọnyi ṣe?
A gbọ pe awọn dukia kan ti ba isẹlẹ naa rin, tori ibugbamu naa mu ki awọn orule ile kan si, to fi mọ ibudo ijọsin, lasiko ti awọn eeyan n jọsin lọwọ, ti awọn ile kan si ti dawo pẹlu.
kí n lè ṣe ẹlẹ́rìí rẹ̀ níwájú gbogbo eniyan nípa ohun tí mo rí, ati ohun tí mo gbọ́.
Ṣé o kò tún ti fi ìwà ainitiju kún ìwà ìríra rẹ?
Bàbá Aláàfin ìlú Ọ̀yọ́, Elérúwà àti àwọn Ọba Ilẹ̀ Yorùbá míràn tí wọ́n rọ̀ lóyè Saraki wa n naka aleebu si ẹgbẹ oselu APC pe oselu ẹtanu ati ibanilorukọ jẹ ni wọn n se pẹlu iwa lilu jibiti lori ayelujara, to si ni aimọye igba ni oun ti pe akiyesi ijọba si ipa ti ọrọ aje ilẹ wa to n se ojojo yoo ni lori awọn mẹkunnu.
ati Joana iyawo Kusa, ọmọ-ọ̀dọ̀ Hẹrọdu, ati Susana ati ọpọlọpọ àwọn mìíràn.
Àwọn eniyan rẹ ati àwọn olórí alufaa ni wọ́n fà ọ́ wá sọ́dọ̀ mi.
Ò kéré tán N1million là ń ná lórí alárùn Coronavirus kọ̀ọ̀kan; àlàyé rèé- Ìjọba Eko Obìnrin àti ọmọdé tó há sábẹ́ ilé tó wó ní Ebute Meta ti ń gba ìtọ́jú, LASEMA ń ṣàyẹ̀wò ilé náà lọ́wọ́ Ọlọ́pàá kan sọ pé òun ní láti ṣàyẹ̀wò ìlédíìí ǹkan oṣù Arabìnrin kan kó tó lè kọjá Ọwọ́ tẹ àwọn ọlọ́pàá tó fìyà jẹ obìnrin kan lọ́nà àìtọ́ n'Ibadan Sanwo Olu to n tukọ ipinlẹ Eko ti fi da awọn eeyan loju pe inira naa ko ni pọ ju nitori pe ijọb eti ṣeto silẹ ko ma ga ju ara lọ.
NYSC: Adigunjalẹ̀ fìbọn fọ́ ọmọ ọdún mẹ́tàdínlọ́gbọ̀n lójú nílú Èkó
Kebbi, Ogun àti Plateau ni ènìyàn méjì-méjì nígbà tí Ekiti ni ènìyàn kan soso.
Ẹkarun-un ni Ṣefataya, ọmọ Abitali; lẹ́yìn rẹ̀ ni Itireamu ọmọ Egila.
Gbogbo igba lo maa n ṣiṣẹ bii jaki lo ṣe mu ki aarẹ yẹn sinmi si i lara.
O sọ pe igbesẹ akọkọ ni titu ileeṣẹ ọlọpaa SARS ka.
Àwọn olùmọ̀ rò wípé ara èèyàn máa ń pèsè èròjà tó máa ń gbógun tí àìsàn nígbà ọ̀tútù.
O ba BBC Yoruba sọrọ lori bi oun ṣe bẹrẹ lati kekere titi di ibi ti Ẹlẹda ran oun lọwọ de bayii.
Má ṣe ìlara àwọn ẹlẹ́ṣẹ̀,ṣugbọn máa bẹ̀rù OLUWA lọ́jọ́ gbogbo.
mi Fabiyi - BBC News Yorùbá BBC News, YorùbáFò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Lizzy Anjorin vs Toyin Abraham: Ẹ wá ọ̀nà láti parí ááwọ̀ ààrin yín - Yomi Fabiyi 20 Owewe 2019 Àkọlé àwòrán, Toyin Vs Lizzy: Ẹ wá ọ̀nà láti parí ááwọ̀ ààrin yín- Yomi Fabiyi Ọ̀pọ̀ àwọn olólùfẹ́ Toyin Abraham àti Lizzy Anjorin láti kí ìdà wọn pada sápó, nítori pé, ọ̀nà tí ǹkan ń gbà lọ yìí kò bóju mú rárá.
Ọpọ awọn akẹkọ to yẹ ko ti kẹkọ gboye bayii ni irinajo wọn ti n fi ẹsẹ kan tiro bayii ti ọpọ akẹkọ atawọn obi si n ti pẹpẹ adura kan bọ si omiran nitori atiwọle pada awọn akẹkọ yii.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Oluwo: Èmi ni atọ́nà oyè Wàzírì nílẹ̀ Yorùbá 28 Ẹrẹ̀nà 2018 Àkọlé àwòrán, Oluwo tilu Iwo so pe oun fẹ di Ọba onilawani (Emir) ilẹ Yoruba Ọ́ba Rasheed Adewale Akanbi, Oluwo tilu Iwo ti fẹ se ohun ti ẹnikan ko se ri nilẹ Yoruba.
Ní àkókò náà àwọn ọmọ-ẹ̀yìn Jesu wá sọ́dọ̀ rẹ̀, wọ́n bi í pé, “Ta ní ṣe pataki jùlọ ní ìjọba ọ̀run?
bi abenugan ile igbimo asoju, niluu Abuja.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Domestic violence: ‘Ẹ̀rù ayé mi sì ń bà mí’ – obìnrin tí ọkọ gé imú rẹ̀ 5 Ògún 2020 Oríṣun àwòrán, BBC Iwa jagidijagan si obinrin kii ṣe ohun tuntun ni Afganistan, koda, iwadii kan tilẹ sọ pe ida mẹtadinlaadọrun un awọn obinrin orilẹ-ede naa lo n dojukọ iwa ipa ninu ile ati nipa ibalopọ.
"Latẹnu ọkan lara awọn oluranlọwọ Seyi Makinde, Dare Adeleke ni o ti fesi lori ayelujara si ohun ti Lere Olayinka, agbẹnusọ Fayose sọ pe ""ati iwọ ati ọga rẹ to n sanwo fun ẹ, ẹwọn ni ipin yin, ko si bi ẹ ṣe fẹ yi idajọ naa to, ẹ o lọ sẹwọn""."
Irú wọn ni àwọn tí ń wá OLUWA,àní àwọn tí ń wá ojurere Ọlọrun Jakọbu.
”Mo bá dáhùn pé, “Bẹ́ẹ̀ ni, OLUWA.
Ninu ọpọ fọto naa la ti mọ bi diẹ lara awọn oṣere tiata naa ṣe ri ni ọdọ, ọpọ wọn si ni ko ni omi lara nigba naa, yatọ si bi wọn ṣe ri bayii.
Oríṣun àwòrán, Facebook/Nigeria Airforce Ileeṣẹ naa sọ nibi ipade oniroyin kan nilu Abuja pe iwadii ti wọn ṣe fihan pe Arotile ku nitori ọkọ to kọlu u lojiji ati pe o padanu ẹjẹ to pọ lẹyin iṣelẹ naa.
Nigba to n fidi awọn isẹlẹ yii mulẹ, Kọmisana kan labẹ ajọ eleto idibo eyi to wa fun eto ilanilọyẹ awọn oludibo, Festus Okoye ni lootọ ni awọn gbọ nipa isẹlẹ yii.
Kò sí ohun tí ó ṣòro fún ọ, 
Bí Ẹsira ti ń gbadura, tí ó ń jẹ́wọ́ ẹ̀ṣẹ̀, tí ó ń sọkún, tí ó sì dojúbolẹ̀ níwájú ilé Ọlọrun, àwọn eniyan bẹ̀rẹ̀ sí dúró yí i ká, tọmọde, tàgbà, tọkunrin, tobinrin.
Lẹ́yìn aṣọ ìkélé keji ni àgọ́ tí à ń pè ní Ibi Mímọ́ jùlọ wà.
    Báyìí ni obìnrin náà bẹ̀rẹ̀ si i kí ẹ̀gbọ́n rẹ̀ tí ojú rẹ̀ pupa bí òòrùn alẹ́, ìgbà tí o sì ti béèrè ìdí rẹ̀ ti àbúrò fi pè è tí àbúrò rẹ̀ ti sọ fún un, ni o ti wí fún ọkùnrin náà kí ó bọ́ síwájú tí òun náà tẹw lé e, pẹ̀lú irungbọ̀n rẹ̀ ti ń wọ́ ilẹ̀ gurugurum, wọ́n múra, ó di ọ̀dọ̀ ọba ti o ń fẹ́ ri i.
Samuẹli tún ní, “OLUWA kò yan eléyìí náà.
18 fún ìwọlé àwọn akẹ́kọ̀ọ́ Ijọba ipinlẹ Eko ti pada kede ọjọ kejidinlogun oṣu kini ọdun 2021 gẹgẹ bii ọjọ iwọle tuntun fun awọn akẹkọọ fun saa eto ẹkọ keji.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Lizzy Anjorin vs Toyin Abraham: Ẹ wòó ẹ fi wọ́n sílẹ̀, ìgbà ọtun ń bọ láipẹ́ -Toyin 4 Ọ̀wàrà 2019 Oríṣun àwòrán, Instagram/Toyin Abraham Gbajugbaja Oṣere tiata Toyin Abraham ti gbogbo aye mọ si Toyin Aimakhu tẹlẹ ni o ti ba awọn ololufẹ rẹ sọrọ lori ẹrọ ayelujara.
Imọ toto lo le bori arun gbogbo ninu ile, lẹnu ounjẹ, fun itọju ara ati gbigba abẹrẹ ajẹsara lasiko le dena awọn arun kọọkan.
Ni bayii, ireti wa pe aare yoo tuko ipade igbimo ijoba lojoRU(Wednesday).
Ọga ọlọpaa sọ pe iṣẹ awọn SARS bayii ko gbọdọ ju ki wọn maa gbogun ti awọn adigunjale tabi awọn ajinigbe lọ.
"Oríṣun àwòrán, @NGRSenate Àkọlé àwòrán, ' A ni lati maa kan sara si wọn fun isẹ takuntakun ti wọn n se ni ileesẹ ati ni ile' "" Ani lati maa fọnrere pataki awọn obinrin lojojumọ."
Ọpọ ileeṣẹ iroyin lo ti n gbe e ka pe ipinlẹ Ondo naa ti kun awọn ipinlẹ to fẹ funra wọn maa fi ọwọ ofin lọ gba nkan tawọn janduku ji ko.
OLUWA dá iná kan ní Sioni tí ó jó ìpìlẹ̀ rẹ̀ run.
 bí a bá ń sọ ̀ rọ ̀ nípa àṣà àti ìṣe yorùbá , a ń sọ ̀ rọ ̀ lórí àwọn ohun tí a máa sẹ ìhùwàsí àti ìrísí wa láàrín àwùjọ .
Eyi si ti mu ki ọpọ eeyan o ma a beere, paapaa awọn ọmọ ilẹ Yoruba pe, ṣe o ṣe e ṣe ko jẹ Akufa ni ọrọ iku wọn to waye ni tẹle n tẹle yii?
Nígbà náà ni olukuluku yóo gba iyìn tí ó yẹ láti ọ̀dọ̀ Ọlọrun.
Auxiliary gbé èèyàn mẹ́fà tó ń jáwèé ayédèrú fáwọn awakọ̀ lọ sí ilèẹjọ́ ní Ibadan Wọ́n ti fa Ààrẹ Amẹrika, Donald Trump kalẹ̀ fún àmì ẹ̀yẹ Nobel Peace Prize Alaga ẹgbẹ Nigerian Scrabble Federation ni, lati igba ti wọn ti lọ san owo ẹmi naa ni wọn ko ti gburo Paul Sodje, Chris Sodje ati ọrẹ rẹ to tẹle Paul, lati lọ san owo fun awọn ajinigbe naa.
Ẹ o le wọ aṣọ olowu Jeans yala ẹwu tabi ṣokoto ninu ileewe to fi mọ ṣokoto abẹnuṣọọrọ.
Akẹkọọ fò ṣanlẹ, o kú lẹyin idanwo.
ọ̀dọ́ 47,000 fẹ́ di Amotekun, agbófinró yẹ̀ wọ́n wò yẹ́bẹ́yẹ́bẹ́ Aáwọ̀ oyè PDP gbé Fayose àti Seyi Makinde kọlu ara wọn, ìjà ń bọ̀ Ènìyàn mẹ́ta pàdánù ẹ̀mí wọ́n lọ́wọ́ àrùn Coronavirus ní Nàìjíríà ní Ọjọ́ọ̀rú Bí nǹkan ọkùnrin bá há sójú ara obìnrin, kìí ṣe Mágùn, ẹ má páyà Bàbálọ́jà márùn ún la ó ò ní l'Oyo tí Makinde bá lè buwọ́lu ìyànsípò YK Abass Ìjọba, e yé dẹ́yẹ sí wa mọ́, àwọn ẹlẹ́sìn ìbílẹ̀ ṣèwọ́de n'Ibadan Auxiliary gbé èèyàn mẹ́fà tó ń jáwèé ayédèrú fáwọn awakọ̀ lọ sí ilèẹjọ́ ní Ibadan Nigba to n sọrọ lori bi Tinubu se joko, nigba ti Ọọni n ki lori iduro, Fani-Kayode ni ọrọ sunnukun ni ọrọ naa, o si yẹ ka fi oju sunnukun wo o.
Bẹ́ẹ̀ ni a kò lè ka àwọn oúnjẹ ayé ìwòyí, àwọn bíi bọ́tà àti búrẹ́dì, àti onírúurú àkàrà òyìnbó títí kan bisikíìtì òde òní tí àwọn ọlọ̀gbọ́n obìnrin fi àgbọn àti iyọ̀ oyìnbó ṣe.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Nigeria Customs: Àwọn ìgbà tí ẹ̀ṣọ́ aṣọ́bodè ti pànìyàn lọ́nà àìtọ́ 18 Èrèlè 2019 Oríṣun àwòrán, yewaloaded.
O sọ lara abuda adamọ eṣú pé wọn kii da rin ati pe wọn kii si loko lasiko ọgbẹlẹ.
Bala Mohammed ni iye ibo 6,376,
Bayi to ti wa fi ọrọ sita, iriwisi ọtọọtọ ti n tẹle ọrọ rẹ tawọn kan si ni o kọ lati soju abẹ niko nipa idasilẹ Amọtẹkun.
O ṣe agbekalẹ ẹgbẹ kan to wa fun awọn obinrin to kawe, eyiun British West Africa Educated Girls Club, amọ orukọ ẹgbẹ naa ti parada si Ladies Progressive Club.
Ó jẹ ìrora oró agbọ́n náà fún ọjọ́ mẹ́ta kí ara rẹ̀ tó bẹ̀rẹ̀sí wálẹ̀.
Lẹ́yìn ọdún mẹ́tàlélọ́gbọ̀n; àwọn èèyàn sí n bèèrè pé: Ta ló pa Dele Giwa?
INEC  lo so eleyii lasiko to n ba awon akoroyin
Oríṣun àwòrán, Mike bamiloye/facebook Àkọlé àwòrán, Mike ati Gloria Bamiloye niyii to n rọ ojo adura le ọmọ wọn lori, boṣe n rele ọkọ Darasimi tun jẹ afi ewi sọrọ ati bẹẹ bẹẹ lọ.
Àwọn ibudó ìdìbò ọ̀rinlérúgbà ó din mẹ́wàá to wa ni agbegbe omi yii, ló wà ni ìjọba ìbílẹ̀ Ese-Odo àti ilaje, ti wọ́n si ni àwọn ilé orí omi bíi méjìlélọ́gọ́ta.
” Ọba náà sì bèèrè fún ọọdunrun ìwọ̀n talẹnti fadaka ati ọgbọ̀n ìwọ̀n talẹnti wúrà lọ́wọ́ Hesekaya ọba Juda.
N óo fìdí majẹmu tí mo bá ọ dá múlẹ̀.
Saaju, alamojuto owo nile-ise ologun ohun, ogagun agba Jahadi Jakko so pe, ile-ise ologun ti n se ojuse won labe akoso owo kan soso.
‘Ọ̀mọ́ ọdún 15 ló yẹge jùlọ ní ìdánwò JAMB’ Ìyá 73 rọ ọmọ ní oúnjẹ dèrò ẹ̀wọ̀n l'Ámẹ́ríkà Àwọn ọmọge wọ gàù l'Abuja nítorí asọ péńpé Naira Mailey àti ikọ̀ rẹ̀ tí wà látìmọ́lé EFCC Bukola Saraki kò kọjá òfin - EFCC 'Ọba tèmi ò ba lórí ohun gbogbo!
 eníkọ ̀ tún lámọdi ló lé ogun Èkìtì-parapọ ̀ títí dé òdò kan tí wọn ń pè ní Àrìgbárá .
1–4, Ipa ọ̀nà Olúwa jẹ́ ọ̀kan yípo ayeraye; 5–15, Joseph Smith gbọ́dọ̀ ronúpìwàdà tàbi kí ó pàdánù ẹ̀bùn láti túmọ̀; 16–20, Ìwé Ti Mọ́mọ́nì wá láti gba irú ọmọ Léhì là.
Alhaji Ayinla Kollington to je agba oje olorin Fuji ni Naijiria gba BBC lalejo nile won fun iforowanilenuwo.
Wo ìgbéyàwó olówó iyebíye tí awakọ̀ Kabúkabú ti jẹ̀bùn ọkọ N3.
Mi o sọ fun ẹnikankan, nitori pe mo ti ma n sọ fun wọn tẹlẹ pe ikun mi kan n wu ni, kii ṣe oyun lo wa nibẹ, ni gba ti wọn ba beere pe ṣe mo loyun.
Oke si ti ṣe iṣẹ fun awọn ileesẹ bi i Lifebank Nigeria, ileesẹ kan to wa fun fifi ẹjẹ silẹ lori ayelujara.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Adeyinka Godson fún ẹ̀yà Igbo ní gbèdéke láti fi ilẹ̀ Yorubá sílẹ̀ 25 Ọ̀wàrà 2020 Oríṣun àwòrán, The cable Ilu London, nil Gẹẹsi lo fi ṣe ibugbe.
Nígbà tí Joṣua súnmọ́ ìlú Jẹriko, ó gbé ojú sókè, ó sì rí i tí ọkunrin kan dúró níwájú rẹ̀ pẹlu idà lọ́wọ́.
Ninu iwe naa to kọ lọjọ kọkanlelogun, oṣu Kẹwaa, ọdun 2020, ti igbakeji adari rẹ, Kolawole Oluwadare buwọlu, SERAP ni o ti pẹ ti ijọba Naijria ti maa n tẹ ẹtọ awọn ara ilu loju mọlẹ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Wo bí Sunday Orimola ṣe gba ikú ẹranko kú ní Ifon ni Ondo lórí ọ̀nà àtijẹ Opin ọsẹ to kọja ni Minisita eto iroyin ni Naijiria, Lai Mohammed kilọ fun Ghana pe 'o to gẹ'.
Bí ó bá jẹ́ pé àwọn ẹbọ yìí ti sọ àwọn tí ń rú wọn di pípé ni, wọn kì bá tí rú wọn mọ́, nítorí ẹ̀rí-ọkàn wọn kì bá tí dá wọn lẹ́bi mọ́ bí ó bá jẹ́ pé ẹbọ tí wọ́n rú lẹ́ẹ̀kan bá ti wẹ̀ wọ́n mọ́.
Àwọn mejeeji di tèmi; wọ́n sì bímọ lọkunrin ati lobinrin.
Wọ́n la àwọn àkànṣe iṣẹ́ ìsọjí àṣà bíi Ọdún Òṣùpá Tuntun àti Àjọ̀dún Àtùpà sílẹ̀, láì pa ìyìókù tì, gẹ́gẹ́ bí ìpàgọ́ tí ó jẹ mọ́ ti àṣà tí ó lákaakì.
Igbimọ naa lo kede bẹẹ ninu atẹjade kan ti Atoloye Aare Ona Kakanfo, oloye Babajide Tanimowo buwọlu O ni lẹyin ọpọ iwadii ati ifimutolẹ ni Naijiria ati loke okun, igbimọ Aarẹ ọna Kakanfo le e fidi rẹ mulẹ pe, awọn agbesumọmi ati Fulani darandaran ti gunlẹ si agbegbe ọhun.
Ó pàṣẹ fún Joabu, ati Abiṣai, ati Itai, ó ní, “Nítorí tèmi, ẹ má pa Absalomu lára.
Oríṣun àwòrán, Arakunrin akeredolu Eeyan mẹta ni ajọ to n dena ajakalẹ arun lorilẹede Naijiria, NCDC ṣi kede pe o laarun naa ni ipinlẹ Ondo eleyi ti o n kọ ijọba ipinlẹ naa lominu ni lọwọlọwọ.
David Adiatu oníṣẹ́ ọnà pẹ̀lú ìṣó àti òwú
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Wo imọran Fọlọrunṣọ Alakija fun awọn ọdọ adulawọ Kíni ó ṣokùnfà làásìgbò àti ẹ̀jẹ̀ nínu ìṣèlù?
Register-to-Open - Eyi tumọ si pe ijọba yoo kọkọ ṣe ayẹwo ile ijọsin, ileeṣẹ, tabi ile itaja to ba fẹ ẹ bẹrẹ iṣẹ pada.
A ngbiyanju lati jẹ olòótọ́ kí a sì sàlàyé nípa ohun ti a ko mọ, bákan náà ni a maa n yago fun wọ́niwọ́n pé.
se pataki, o tun wa gbosuba fun ijoba apapo fun ipa Pataki ti o ko lati satunse
Irọ́ lásán ni ìdìbò tó wáyé ní ẹkùn Ìwọ̀-òòrùn Kogi - Dino Melaye Wòólì Ajayi kú ní ìlú Àgelú, òkú rẹ pòórá, ìjọ sin pósí lásán!
Ní ọjọ́ kẹtala, oṣù kinni, Hamani pe àwọn akọ̀wé ọba jọ, wọ́n sì kọ gbogbo àṣẹ tí Hamani pa sinu ìwé.
Ṣaaju ni Akọwe iroyin fun gomina, Taiwo Adisa, sọ pe ijọba ipinlẹ naa n ṣiṣẹ pọ pẹlu ẹbí Ajimobi, lati fun oloogbe ni eto adura Fidau to bu iyi kun.
Àwọn òṣìṣẹ́ ìjọba ìpínlẹ̀ Oyo láti ipele kẹtàlá yóò padà sí ẹnu iṣẹ́ lọ́jọ́ ajẹ́ Gbogbo ìgbésẹ́ to yẹ ni a gbé nígbà ti àwọn ọ̀daràn dé ọgbà wa- Agbẹnusọ ọgbà ẹ̀wọ̀n Mo ṣetán láti ta ilé tí mo ń gbé, kí n le rí àwọn ìbejì mi padà - Akeugbagold Èèyàn 64 míràn tún ti ní àrùn Coronavirus ní Nàíjírìa O ni adinku yoo de ba ọwọ ofin konile-o-gbele ṣugbọn eto ayẹwo ati ṣisawari awọn to ṣeeṣe ko ni arun naa yoo tubọ gbopọn sii.
O ti kọ́ ọpọlọpọ eniyan,o ti fún aláìlera lókun.
Akọwe agba lẹka ere bọọlu naa ni pe aipẹ yii ni ọkọ ayọkẹlẹ kan pa meji lara awọn agbabọọlu fun Ọlọpaa meji.
Èyí ni ẹbọ sísun ojoojumọ tí a ti fi ìlànà rẹ̀ lélẹ̀ ní òkè Sinai gẹ́gẹ́ bí ẹbọ sísun olóòórùn dídùn sí OLUWA.
Etu ni fasiti Ibadan ni oun wa bii akẹkọọ nigba ti oun ko riran mọ, to si dabi ẹni pe ọna ti pin fun oun sugbọn Ọlọrun la ọna lati ipasẹ isẹ gbogbo elere naa.
Lọsẹ to lọ ni Aisha pada silu Abuja lẹyin to ti wa nilẹ okere fun bi oṣu mẹta.
Asiko rẹ lati jade wa sọrọ.
Gbogbo wọn ti fá irun orí ati irùngbọ̀n wọn; wọ́n ti fi abẹ ya gbogbo ọwọ́ wọn, wọ́n sì lọ́ aṣọ ọ̀fọ̀ mọ́ ìbàdí.
Dennerby ni awọn agbabọọlu oun ti gbaradi, wọn si ti ṣetan lati gbena woju Cameroon lori papa.
O ni gbigba kaadi idibo alalopẹ ṣaaju idibo naa ku diẹ kaato ati pe ajọ eleto idibo INEC ko sa ipa to to lati rii pe awọn eeyan gba kaadi naa bi o ti tọ ati bi o ti yẹ.
Nínú ọ̀rọ̀ wọn ní FIFA, àwọn akọbúlọ́ọ̀gù náà sọ wípé ìkẹ́gbẹ́ẹ wọn nínú Ohùn Àgbáyé ṣe gudugudu méje yàyà mẹ́fà ní àsìkò tí àwọn ń fi aṣọ pénpé ro oko ọba.
“Ohun tí OLUWA sọ nípa ọba Asiria ni pé, kò ní wọ inú ìlú yìí, bẹ́ẹ̀ ni kò ní ta ọfà kankan sí i.
”Eliṣa dáhùn pé, “OLUWA ti fi hàn mí pé o óo jọba ní Siria.
Oríṣun àwòrán, Others Amọ isẹlẹ kan waye lọdun 1971 eyi to milẹ titi, eyi to sọ ile ọla Ọrẹdẹin di ahoro.
Oloye Adelabu jade lati se ojuse re gege bii oludibo ni deede agogo
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù NCC: A ti ri owó ti Iléeṣé MTN sannáà gbà 1 Òkùdu 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, MTN ti san owó ìtanran wọn tán fún Naijiria Biliọnu ọgbọn lé ni ọọdunrun naira ni owó itanran ti Naijiria bù fún ileeṣẹ MTN.
Oloogbe Kunle Ọlasọpe, tii se ọkunrin akọkọ to fi oju han lori mohunmaworan ti waye, to si ti lọ, amọ o yẹ ka ran ara wa leti nipa awọn ohun ribiribi to gbe ile aye se.
Oríṣun àwòrán, CBN Àkọlé àwòrán, Igbesẹ owona tuntun Igbesẹ tuntun yii n fẹ ki gbogbo eniyan maa ṣe owo ilẹ Naijiria ni pẹlẹ, ko ma dọti, ko si ma run tabi ki ẹ maa naa da silẹ.
Nigba to n sọrọ ṣaaju nipa arun Covid-19, Oyedepe sọ pe oun ko gbagbọ pe Covid-19 kan wa nibi kankan .
Wọ́n bi í pé, “Sọ fún wa, ṣé ìwọ ni Mesaya náà?
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Abikẹ Dabiri: Iṣẹ́ pọ̀ lọ́wọ́ Naptin àti àwọn aṣọ́bodè Nàìjíríà Gẹgẹ bi ile iṣẹ iroyin kan ni UAE, Khaleel Times ṣe jabọ lọjọbọ ọṣẹ yii, ẹni to y ko ṣe ikẹsan wọn kan fi wọn oṣu mẹfa gbara ni tori owo ti wọn ji wa lọ́wọ́ rẹ.
Ó yọ́ ojúlówó wúrà bò ó, ó sì fi wúrà ṣe ìgbátí rẹ̀.
Elieseri ọmọ Dodafahu, ará Mareṣa fi àsọtẹ́lẹ̀ bá Jehoṣafati wí.
Wọn a fi owó àbẹ̀tẹ́lẹ́ ra ilé nla si Òkè-Òkun, oúnjẹ àti èso ilú kò dùn lẹnu olówó, aṣọ àti ohun ti ará ilú nṣe kò dára tó, ọjà Òkè-Òkun nikan ni wọn lè fi yangàn.
Nígbà tí wọ́n fẹ́ ṣe ìyàsímímọ́ odi ìlú náà, wọ́n kó gbogbo àwọn ọmọ Lefi jọ láti gbogbo ibi tí wọ́n wà, wọ́n kó wọn wá sí Jerusalẹmu, láti wá fi tayọ̀tayọ̀ ṣe ìyàsímímọ́ náà pẹlu orin ọpẹ́ ati kimbali ati hapu.
Gbogbo ènìyàn ko sì tilẹ̀ tó ti ọ̀gbẹ́ni Ìrèké, o fi mi ṣe ẹgbẹ̀rún-un yẹ̀yẹ̀ ní ìdí ọ̀ràn náà.
Nítorí títà ni à bá ta òróró yìí ní owó iyebíye tí à bá fi fún àwọn talaka.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Eton tọrọ àforíjìn lọ́wọ́ akẹ́kọ̀ọ́ Nàíjíríà lórí ìwà ẹlẹ́yàmẹ̀yà 23 Òkùdu 2020 Oríṣun àwòrán, Dilibe Onyeama Olukọ agba Ile ẹkọ girama olokiki nii, Eton College to wa nilẹ Gẹẹsi, ti sọ fun BBC pe, ọkan ohun bajẹ pẹlu bi akẹkọọ alawọdudu to kọkọ pari ẹ́kọ rẹ nibẹ, Dilibe Onyeama, se koju idẹyẹsi ati iwa ẹlẹyamẹya nigba to n kẹkọ nibẹ.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Tani DCP Kayọde Ẹgbẹdokun, ọ̀gá ọlọ́pàá tuntun ní ìpínlẹ̀ Eko?
Ó pẹ́ kí wọ́n tó jáde, wọ́n ní wọ́n ti wẹ òkú tán, wọ́n sì ti wọ ‘ṣọ fún un tán.
Ìyẹ̀fun kò tán ninu ìkòkò rẹ̀, bẹ́ẹ̀ ni kólòbó òróró rẹ̀ kò sì gbẹ, bí OLUWA ti ṣèlérí fún un láti ẹnu Elija.
Omowe David Oyedepo, ti o je Aare ati oludasile ile-ijosin Living Faith lagbaye gbadura fun  alaafia ipinle Plateau lale ojo-Bo.
Ó tilẹ̀ kọ́ àwọn pẹpẹ ìrúbọ káàkiri ní agbègbè olókè Juda.
Àní, ní àkókò náà, n óo tú Ẹ̀mí misórí àwọn ẹrukunrin miati sí orí àwọn ẹrubinrin mi,àwọn náà yóo sì máa sọ àsọtẹ́lẹ̀.
Àwọ̀tẹ́lẹ̀: Èwo lo ní ìfẹ́ sí nínú orísirísi kọ́mú yìí?
Amofin Sadiku sọ pe ẹnikẹni to ba fẹ ẹ ṣe oniduro fun ẹni to n jẹjọ gbọdọ mọ, ki o si ni oye irufẹ ẹsun ti wọn fi kan ẹni to fẹ ṣe oniduro fun.
Ọpẹ́ ni ó ń fi fún Ọlọrun.
Ṣemu ni baba Elamu, Aṣuri, ati Apakiṣadi, Ludi, Aramu, ati Usi, Huli, Geteri ati Meṣeki.
Nínú ọkùnrin àt'obìnrin, ta ni Coronavirus yóò tètè ṣe lọ́ṣẹ́?
Okun inú mi ti gbẹ bí àpáàdì,ahọ́n mi sì ti lẹ̀ mọ́ mi lẹ́nu;o ti fi mí sílẹ̀ sinu eruku isà òkú.
tí mo bá jẹ ninu ìkórè ilẹ̀ náà láìsanwó rẹ̀,tabi tí mo sì ṣe ikú pa ẹni tí ó ni ín,
Ilé ẹjọ lé Ọba Èrúwà kúrò lórí Àpèrè lẹ́yìn ọdun 21 Agbẹ́sùnmọ̀mí ni ẹni to pa ẹ̀nìyàn méjì ní ìlú London!
Ẹní mú owó wá mú owó wá, èyìí tí ó fún wọn láṣọ-ọ́ fún wọn láṣọ.
Ogun ló ń wáyé ní Kogi, kìí ṣe ìbò dídì - Olùdíje gómìnà Àyẹ̀wò ẹ̀jẹ̀ ti di dandan fáwọn tó bá fẹ́ ṣèyàwó ní Nàìjíríà- Ilé aṣojú-ṣòfin Wo díẹ̀ lára àwọn ọ̀rọ̀ ìkẹyìn ti Alexander Akinyele fi léde kó tó papódà Ẹni tó bá kàwé dé ipele girama leè di Ààrẹ, dandan kọ́ ni ìwé ẹ̀r - í Ilé ẹjọ́ Idi iṣẹ siso bata yii ni Andrew ti n da owo jọ to n fipamọ ko le kawe di ipele iwe giga fasiti O kawe gboye ninu imọ ẹda ede ni fasiti Maiduguri ko to lọ si fasiti London lati kawe de oye ọmọwe lọdun 1990.
N óo dá yín lẹ́jọ́,nítorí ẹ̀ ń sọ pé ẹ kò dẹ́ṣẹ̀.
Nígbà tí wọ́n dé àfonífojì Eṣikolu, wọn gé ṣiiri àjàrà kan tí ó ní èso.
Lati igba yi wa ni awọn agbegbe ti ẹgbẹ agbebọn naa gba ti dinku, bi o tilẹ jẹ wi pe o ṣi n ṣọṣẹ lẹkun naa.
Man United Vs Chelsea: De Gea d'apẹ̀rẹ̀ àjàṣẹ̀, ó fún Chelsea lẹ́bùn góòlù kan
Eduwa ko ni jẹ ka kagbako o, ẹkunrẹrẹ itan awodamiloju yii la mu wa fun yin loni, ẹ wo fidio rẹ loke yii.
Asojusofin Saraki to soju fun Asojusofin Phillip Aduda to je olori awon omo ile to kere julo yombo igbiyanju awon eniyan agbaye fun ipese ohun jije lopo yanturu ni Naijiria.
Ó dá mi lójú pé ẹni tí ó bẹ̀rẹ̀ iṣẹ́ rere ninu yín yóo ṣe é dé òpin títí di ọjọ́ tí Kristi Jesu yóo dé.
ọ̀dọ́ 47,000 fẹ́ di Amotekun, agbófinró yẹ̀ wọ́n wò yẹ́bẹ́yẹ́bẹ́ Oríṣun àwòrán, Others Orin wo la fẹ kọ si gbẹdun eyi, afi ero ya waa wo o, ni eto igbaniwọle awọn osisẹ fun ikọ Amotekun ba de bayii.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Iyaloja Oyo state: Àwọn ọlọ́jà ń sèdárò Ìyálọ́jà ìpínlẹ̀ Oyo, Wuraola aya Kola Daisi tó dolóògbé, wọ́n yan asojú míràn 22 Ọ̀wàrà 2020 Ẹgbẹ awọn ọlọja nipinlẹ Ọyọ ti sapejuwe iyalọja ipinlẹ Oyo gẹgẹ bi akọni obinrin to jẹ oninu ire, lẹyin to papoda lẹni ọdun mẹrindinlọgọrun.
Jesu dá wọn lóhùn pé, “Àwọn ọ̀rẹ́ ọkọ iyawo kò lè máa gbààwẹ̀ nígbà tí ọkọ iyawo wà lọ́dọ̀ wọn, níwọ̀n ìgbà tí ọkọ iyawo bá wà pẹlu wọn, wọ́n kò lè máa gbààwẹ̀.
Olófòófó a máa tú àṣírí,ṣugbọn ẹni tí ó ṣe é gbẹ́kẹ̀lé a máa pa àṣírí mọ́.
Ogbeni Clement ni oun ba Taiwo Adeoluwa sọrọ ni eyi to fidi ẹ mulẹ pe o ti n gba itọju to yẹ Ẹ̀yin jàǹdùkú olóṣèlú, ẹ so ewé gbéjẹ́ mọ́wọ́ - Ọ̀gá ọlọ́pàá EFCC ń wá owó Atiku bọ̀ wálé mi- Fayoṣe INEC kìlọ̀ fáwọn ọmọdé tó fẹ́ dìbò Lónìí ni Nàìjíríà yóò yan ààrẹ̀ ti yóò tukọ̀ sáà ọdún mẹ́rin Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, #NigeriaDecides: BBC ti wa ni gbogbo ìpínlẹ̀ Naijiria láti firoyin gbogbo tóo yin létí Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Ile Igbimọ Aṣofin Ipinlẹ Eko sọrọ lori pipẹ ti
Eyín akọ̀ròyìn fò yọ lásìkò tó n ka ìròyìn lọ́wọ́ lórí tẹlifísàn Wo àwọn olorì àgbà mẹ́rin tí Aláàfin ń wárí fún Ọlọ́paàá ní wọ́n ṣèèṣì yìnbọn pa ọmọ mi tó ń tọ́ ọmọ oṣù mẹ́rin lọ́wọ́ ni- Ìyá Kager Wo díẹ̀ lára àwọn tí yóò kópa nínú ìdíje BBNaija ọdún yìí Àwọn Mùsùlùmí Sudan se ìwọ́de nítorí pé ìjọba gbẹsẹ kúrò lórí òfin tó de ọtí mímu Baba yii ni gbajugbaja olorin ni Naira Marley fun ni ẹbun owo miliọnu kan naira lati fi gbadun ara rẹ lẹyin to ri bi Baba naa ṣe karamaasiki orin oun lori instagram.
Magu n sọrọ nipa ijamba ati ewu ti o wa ninu iwa jẹgudujẹra, lo fi sọ wi pe ohun naa lo fa ajakalẹ arun ọhun.
awon onibara n san fun pipese ina mona-mona ti odun 2018.
Aarẹ Nkurunziza gbagbọ pe atọrun wa ni ipo aarẹ oun o si n fi eyi ṣe atọna igbe aye rẹ ati iṣejọba rẹ.
BBC World: Iléeṣẹ́ BBC fi ètò tuntun lọ́lẹ̀ fún àwọn àkàndá
robert adam wọ ́ n bí adam ní 1728 .
Púpọ̀jùlọ nínú àwọn ìfihàn náà nínú ìkójọpọ̀ yìí ni a gbà nípasẹ̀ Joseph Smith Kékeré, tí ó jẹ́ wòlíì àkọ́kọ́ àti ààrẹ Ìjọ Jésù Krístì ti àwọn Ènìyàn Mímọ́ Ọjọ́-ìkẹhìn.
Ọba wà níbi tí ó jókòó sí ní ibodè Bẹnjamini.
Arsenal ṣẹ́ṣó ìyà, búlálà ẹlẹ́nu mẹ́ta ni Leicester City fi lù wọ́n lálù bami Man Utd Vs Man City: Ọ̀rẹ́ dì ọtá, ọtá dì ọ̀rẹ́ torí ife ẹ̀yẹ Àjọ SERAP ke gbàjarè lóri jíjan àbá owó ìfẹ̀yìti lóntẹ̀ ni Bayelsa Títí di àsìkò yìí Man United ti ń sàkóso ìfẹsẹwọnsẹ wọn síbẹ wọn o féèlì, wọn ò kúrò ni kílààsì, ipò kẹfà náà ni wọn si wà, sùgbọ́n wọn fi àmi àyò mẹ́tà wà lẹ́yìn Chelsea bẹ́ẹ̀ ìfẹsẹwọnsẹ mejì pere lókù fún wọn.
22 Èbibi 2020 Oríṣun àwòrán, Getty Images Irú ewu wo ni eni to dúró tì mí lórí ìlà tí a tò sí láti wọ ọkọ̀ BRT, àbí ṣe mo sì le máa lo si ilé oúnjẹ tàbí ki n máa wọkọ̀ èrò?
Agbabọọlu naa ki awọn akẹgbẹ rẹ atawọn ti wọn ran an lọwọ lati gbami ẹyẹ naa.
Àwọn ènìyàn máa n ròó pé, wọ́n sọ èyí nítorí nǹkan tó ṣẹlẹ̀ kan dùn wọ́n ni, wọn ò ni mọ̀ pé wọ́n ti ni àrùn ọpọlọ.
Bẹ́ẹ̀ ni àwọn ọmọ Lọti mejeeji ṣe lóyún fún baba wọn.
IOnsere to dara juYemi AladeOlootu to dara ju lodunKiddominantKolabo to dara ju (Alajosepo)Ma Lo – Tiwa Savage feat.
” Aare seleri pe “lati mu iderun ba awon ti wahala le kuro ni ibugbe won, ijoba ti fowosowopo pelu ijoba ipinle, ijoba ibile ati ajo agbaye lati da awon ibudo ati lati  se atunse si ona ti won yoo fi maa ri awon itoju ati ounje gba.
Wn ti yọ ọmọ ọdun mẹtadinlọgbọn agbabọọlu ọwọ iwaju naa gẹgẹ bi akọgun ẹgbẹ agbabọọlu Brazil lori ọrọ to ni ṣe pẹlu jijẹ iya ẹṣẹ kan laipẹ.
Mo tẹ́ ẹ̀yìn sílẹ̀ fún àwọn tí ń nani lẹ́gba; mo sì kọ ẹ̀rẹ̀kẹ́ sí àwọn tí ń fa eniyan ní irùngbọ̀n tu.
Koda, eyi wa lara idi ti wọn fi wọgile ṣiṣe eto ayẹyẹ ikẹkọọjade fawọn akẹkọọ ni oṣu kẹta ọdun yii.
Ẹnikẹni to ba ti kọja ọgọ́ta ọdun ni wọn n pe bẹẹGẹgẹ bi kurani ti ṣe alaye, Tunfulu ni wọn n pe ọmọde jojolo, ọdọ wa, lati ọdún mẹwa si mẹẹdọgbọn , lẹyin ọdọ lo kan Halum, fun awọn eeyan to kọja ọgbọn ọdún.
Awọn afurasi mẹtẹẹta, Philip Segun, Owolabi Adeeko, to jẹ ọrẹkunrin oloogbe, ati iya rẹ, Bola, ni wọn gbe lọ sile ẹjọ magistreti.
A gbọ pe bi o tilẹ jẹ pe awọn eeyan tiraka lati doola ẹmi awọn ero omi naa, amọ aayan wọn ko fi bẹẹ ni ipa, tori ọmọde mọkandinlogun lo si papa ba isẹlẹ naa rin, ti wọn si gba ẹmi eeyan meji la.
o ṣe pataki ki wọn le ro wọn lagbara pẹlu nnkan ija, bi bẹẹ kọ, ẹ n fi
Nígbà tí mo bá wó o lulẹ̀ tí mo bá sọ ọ́ sinu isà òkú pẹlu àwọn tí wọ́n ti lọ sí ipò òkú; gbogbo àwọn igi Edẹni, ati àwọn igi tí wọ́n dára jù ní Lẹbanoni, gbogbo àwọn igi tí ń rí omi mu lábẹ́ ilẹ̀ ni ara yóo tù.
Kii kuku se pe Duro Ladipọ ka iwe rẹpẹtẹ ko to se aseyọri, amọ o lo ẹbun atinuda ti Ọlọrun fun lati ta ara rẹ yọ, to si di ilumọọka lawujọ agbanla aye.
Nígbà tí ó gbọ́ ọ̀rọ̀ yìí, inú rẹ̀ bàjẹ́, nítorí ó ní ọrọ̀ pupọ.
 a tún ṣe àgbéyẹ ̀ wò ìyísódì àsìkò , ibá-ìṣẹ ̀ lẹ ̀ àti ojúṣe nínu Ẹi .
Ọgọrun-un talẹnti fadaka yìí ni wọ́n fi ṣe àwọn ìtẹ́lẹ̀ òpó ilé OLUWA ati ìtẹ́lẹ̀ àwọn aṣọ títa.
Ati pe nigbakugba ti wọn ba nilo oun, ko si giri, oun ṣetan lati jẹ wọn ni hoo.
O óo rí omi wàrà ewúrẹ́ rẹ fún, tí o óo máa rí mu,ìwọ ati ìdílé rẹ, ati àwọn iranṣẹbinrin rẹ pẹlu.
Amofin agba kan lorilẹẹde Naijiria ti pe fun agbeyẹwo ofin gẹgẹ bi ọna lati dẹkun iwa jẹgudujẹra lawujọ.
Ohun ẹ̀rù ati àwọn àmì ńlá yóo hàn lójú ọ̀run.
odun mokanlelogbon (31) ati Agbanah Toba, eni odun marundinlogoji (35) ti won
wo àwọn nọ́mba ọlọ́pàá tí o lé pé láti mọ ọ̀nà àbáyọ A ti bẹ̀rẹ̀ ìwádìí lórí ibì tí owó tí àwọn adigunjalẹ̀ gbé ní banki Okeho wọ̀lẹ̀ sí- Ọlọ́pàá Ọpọlọpọ eniyan lo ti n da ẹbi iṣẹlẹ naa ru awọn adari orilẹede ọhun pe wọn ko kọbiara si ilu ati pe iwa ọbayejẹ wọ wọn lẹwu.
O ti le ni miliọnu kan awọn eniyan ti wọn ti buwọlu iwe iwọde lodi si igbesẹ Boris Johnson larin ọjọ kan ti wọn bẹrẹ.
Wọ́n ní etí, ṣugbọn wọn kò gbọ́ràn, bẹ́ẹ̀ ni òye kò yé wọn.
Iye àwọn tí wọ́n jẹ́ ọmọ Israẹli nìyí:
Ejò lé àwọn aṣòfin ìpínlẹ̀ Ondo kúrò nípàdé Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Kayeefi: Facebook ni Wolii Arole Jesu fi tàn an wọ agbo, orí rẹ̀ ni wọ́n fi s'owó Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
"BBC ṣèfilọ́lẹ̀ àmì ẹ̀yẹ 2019 Komla Dumor Award BBC ṣe'filọlẹ ami ẹyẹ Komla Dumor Ọmọ Kenya gba àmì ẹ̀yẹ BBC Komla Dumor award Ọmọ Uganda gba àmi ẹ̀yẹ Komla Dumor BBC tọdun yii Rubadiri yoo bẹrẹ irin ajo olosu mẹta pẹlu BBC ti yoo si lọ gba ẹkọ imọ ni BBC Academy ko to darapọ mọ awon oṣiṣẹ BBC News eka ti amohunmaworan, Radio ati tori ayelujara, eyi yoo fun lanfani lati fi imọ kun imọ jakejado ẹka BBC News "" O ni imọ, o si le fọ awọn ootọ ọrọ si wẹwẹ, bakan naa ni awọn ero iworan yoo maa fọkan baa lọ."
Adekunle ni oun paapa ko mọ idi ti baba oun fi n jẹ orukọ naa.
Iṣẹ́ Alákọ̀wé kò ṣe fi jogún fún ọmọ nitori iwé-ẹ̀ri àti ipò ti èniyàn dé ni iṣẹ́ Akọ̀wé tàbi iṣẹ́ Ìjọba kò ṣe fi jogún fún ọmọ bi oko.
Ìdí tí Air Peace fi fọwọ́ òsì júwe ilé fún awakọ̀ ààdọ́ta rèé O kere tan awakọ baalu aadọrin ni ileesẹ ọkọ ofurufu Air Peace ni Naijiria wọn ti fọwọ osi juwe ile fun.
Ọpọlọpọ ipade lo waye laarin ijọba Naijiria ati awọn olori Biafra, paapa eyi to waye ni Aburi, l'orilẹ-ede Ghana (Aburi Accord).
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Corona virus: Ibi àyẹ̀wò mẹ́ta ló wà fún Coronavirus ní Naijiria 24 Èrèlè 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 25 Èrèlè 2020 Oríṣun àwòrán, AFP Àkọlé àwòrán, Ẹgbẹgbẹrun eniyan lo ti papoda lẹyin aisan coronavirus bẹ silẹ lorilẹede China to si ti tan kalẹ de awọn orilẹede miran.
orile ede miiran to nifẹẹ lati tesiwaju nipa 
Awọn ẹgbẹrun meji to ku yoo jẹ oṣiṣe awọn oṣiṣẹ ile iwe giga kaakiri Naijiria ti yoo to esi papọ, ti wọn yoo si jẹ alabojuto.
Gege bi Ibrahimovic se so lori ero ayelu“ko si ohun ti o ni ibere ti o lopin, asiko ti to ni bayii lati tun tesiwaju ninu irin-ajo boolu afesegba mi, leyin saa meji ti mo lo pelu iko agbaboolu Manchester United.
Akowe agba fun egbe agbaboolu orile ede Niajiria,(Nigeria Football Federation ,NFF), Mohammed Sanusi,ti soro lojo Aiku pe egbe agbaboolu orile ede Naijiria, ti ojo ori won ko ju mẹ́tàdínlógún lọ , ni yoo se aseyori ninu ere boolu ifonsewonse ti woo waye pelu orile ede Burkina Faso ni oni yii.
 Ó jé wíwárí ( papọ ̀ mọ ́ kríptónì àti ksẹ ́ nọ ́ nù ) ní 1898 gẹ ́ gẹ ́ bí ìkan nínú àwọn ẹ ́ límẹ ̀ ntì àìgbéra tósọ ̀ wọ ́ n tó ṣẹ ́ kù nínú afẹ ́ fẹ ́ gbígbẹ , lẹ ́ yìn tí nítrójìn , ọ ́ ksíjìn , árgọ ̀ nù àti dìọ ́ ksídì kárbọ ̀ nù ti jẹ ́ yíyọ kúrò .
Iroyin ti n jade lori bi ọkọ ofurufu Ethiopian Airlines to gbe eniyan mẹtadinlọgọjọ se jabọ to si pa gbogbo eniyan to wa ninu rẹ lọse mẹta sẹyin.
Nítorí ìwọ ni o fi ìdí ẹ̀tọ́ mi múlẹ̀, tí o sì dá mi láre;ìwọ ni o jókòó lórí ìtẹ́, o sì ṣe ìdájọ́ òdodo.
Ẹ gbọ́ ariwo ninu ìlú,ẹ gbọ́ ohùn kan láti inú Tẹmpili,ohùn OLUWA ni,ó ń san ẹ̀san fún àwọn ọ̀tá rẹ̀.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Chelsea ni tirẹ ta ọmi pẹlu Eintranct frankfurt ni orilẹede Germany Amọṣa, ẹgbẹ agbabọọlu Arsenal yii ọrọ naa pada nigba ti wọn na Valencia pẹlu ami ayo mẹta si ẹyọkan ni apapa iṣire Emirates ni ilẹ Gẹẹsi.
Oun lo ṣagbatẹru bi Napoli ṣe gba ami ẹyẹ Serie A ti wọn gba lọdun 1987 ati 1990, ami ẹyẹ Serie A meji pere ti wọn gba ninu itan wọn.
" a gbọ ́ pé , Àjàpadá aṣọdẹ ́ bọ ̀ yèdé tí o jẹ ́ ọ ̀ kan lára àwọn ọmọ odùduwà kúrò ní ìlú Òṣú , ó sì dúró sí ìlú kan tí wọn ń pè ní "" Òyè ' nítòsí Ẹ ̀ fọ ̀ n-alààyè ."
A le sọ pe Ọba Adeyẹmi ri aye wa ni gbogbo ọna nitori gbogbo ohun ti eeyan maa n gbe ile aye se, ni Alaafin ti se ni aseyọri.
Nwachukwu fikun-un pe, iko omo ogun ohun seku pa omo ogun olote kan, bee si nii  won gba enikan ti o wa ninu ihamo sile nibi ti won fi pamo si lagbegbe Afa lojo Aiku(Sunday).
Gẹgẹ bi ohun ti a ri ni akọsilẹ nipa rẹ, Awojobi pegede ninu Ẹkọ rẹ ti o si jẹ ẹni akọkọ to kere julọ lọjọ ori to gba oye imọ ọjọgbọn lẹka imọ ẹrọ, Professor in Mechanical Engineering, ni yunifasiti ilu Eko lọdun 1974.
Darandaran gun awakọ pa l'Ondo Fulani darandaran lo iwa ipa ni guusu Akurẹ ‘‘Àwọn egúngún ń mu òògún olóró ló ń jẹ́ kí wọ́n sì ìwà hù’ Kàyéèfì ni bí àwọn agbébọn ṣe pa akápò ìjọ Anglican l'Akurẹ nítorí owó ṣọ́ọ́ṣì Agbébọn jí Alága Káńsù tẹ́lẹ̀ gbé l‘Ondo Awọn gomina naa ṣe ipade ni ẹka ile ijọba Ipinlẹ Ondo to wa ni Abuja ni ọjọ Ẹti nibi ti wọn ti fẹnu ko lori ọrọ aabo ni apa ila oorun Naijiria.
NCC yoo ri daju pe gbogbo awọn ileeṣẹ ibaraẹnisọrọ ti tẹle asẹ to pa pe ki wọn o da iforukọsilẹ siimu duro.
" O ni sibẹ eyi ko wẹ ile aṣofin mọ bi irufẹ ohun to ṣẹlẹ si Minisita yii ba ṣẹlẹ.
Ìwádìí ilé aṣòfin foríṣánpọ́n lórí ẹ̀sùn Gómìnà Ganduje
OLUWA wà nítòsí àwọn tí ọkàn wọn bàjẹ́,a sì máa gba àwọn oníròbìnújẹ́ ọkàn là.
Àwọn irúgbìn mìíràn bọ́ sáàrin igi ẹlẹ́gùn-ún.
 Mustapha fi kun pe akoko ti to fun awọn olufẹhonuhan lati ba ijọba ni ijiroro nitori ewu to wa ninu iwọde elero pupọ."
ṣugbọn nígbà tí ẹ jẹun yó tán, ẹ̀ ń gbéraga, ẹ gbàgbé mi.
Ó yọ́ wúrà bò ó ninu ati lóde, ó sì tún fi wúrà ṣe ìgbátí rẹ̀.
Wọn ṣe fiimu yii papọ pẹlu Inkblot ati Filmone.
5M ni wọ́n fi n bọ́ El-Zakzaky' Agbẹjọro fun Ibrahim El-Zakzaky ti sọ fun BBC pe irọ ni Alhaji Lai Mohammed pa lori iye ti El-Zakzaky fi n jẹun lojoojumọ.
Ilé Aṣòfin Àgbà fòǹtẹ̀ lu N30,000 owó oṣù òṣìṣẹ́ Ẹgbẹ́ òsìsẹ́ NLC ti kọ #27,000 owó osù òsìsẹ́ Onnoghen jẹ̀bi ẹ̀sùn tí wọ́n fi kàn án, ó pàdánù owó rẹ̀ Eyi waye lẹyin ti igbimọ to jiroro lori ọrọ naa gbe abọ ijiroro rẹ sita.
Jiti ni a ko pegede rara ninu ibọwọ fun ofin, eto ọrọ ajé, ilera, eto ẹkọ, eto aabo, ati ẹtọ ọmọniyan.
Gègé tí wọ́n kọ́kọ́ ṣẹ́ mú Jehoiaribu, ekeji mú Jedaaya.
Osinbajo ni ogiri to gbe Naijiria ro n mi titi, eleyii to le fa ki Naijiria wo lulẹ, ti wọn ko ba kiyesi ara.
Òun ni mò ń rán pada sí ọ.
Bí Timoti bá dé, kí ẹ rí i pé ẹ fi í lára balẹ̀ láàrin yín, nítorí iṣẹ́ Oluwa tí mò ń ṣe ni òun náà ń ṣe.
Awọn mejeeji n beere fun ominira lati lọ fun itọju ara wọn nilẹ okeere.
Àkọlé àwòrán, Wo ninu awọn agbabọọlu Burundi Sugbọn orilẹ-ede Guinea re wọn lẹpa ti ko fi jẹ ki wọn le yege.
Highlighlight of Liverpool vs Chelsea: Liverpool pègúnrẹ́, wọ́n gbé ife ẹ̀yẹ̀ Premier league lẹ́yìn ọgbọ̀n ọdún
Nínú àtẹ̀jádé yii ni wọn ti kede loni ọjọ Aje, ọjọ kẹtadinlọgbọn, osu keje pe awọn ibudokọ ọkọ oju irin ni Naijiria a gba orukọ tuntun.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Asisat Oshoala: ìbẹ̀rẹ̀ mi kò rọrùn rárá nínú eré bọ́ọ̀lù Ta ni Germany ti Naijiria n koju?
Black women lives matter: Ọdún 2015 ní àwọn ọlọ́pàá pa India Kager láìní ìdí- Gina Best
Amọ bayii, o ni inu oun dun gidigidi fun ayipada to de ba orukọ ilu oun.
Kí ló mú kí àyájọ́ June 12 ṣe pàtàkì ní Nàìjíríà Ìtàn tó wà nídi òwe ‘Sebótimọ Ẹlẹ́wà Sàpọ́n’ Ki lawọn ipa to ti ko lagbo oṣelu?
Ni ọjọ kẹrindinlọgbọn oṣu kẹrin ni ifẹsẹwọnsẹ naa yoo waye.
Ni wọ́n bá ní kí ó kálọ sí Òkè Areopagu.
''Aisi ofin to le dẹkun idokowo sogundogoji bayi naa tun se okunfa bi awọn eniyan ti se n wa ọna alumọkọrọyi lati ri owo ifa.
Botilẹjẹ wi pe awọn ọdọmọde ati ọdọ lo pọ ju lara awọn to n gbe pẹlu HIV ni Kenya, ati ilẹ olooru Afrika, ọpọ ninu awọn ti wọn bi pẹlu aarun naa lo n gbe igbeaye wọn laijẹ ki ẹnikẹni o mọ.
O nigba ti oun de lati orilẹede Amerika, lawọn araalu wa ba oun pe ki oun jẹ ọba ilẹ Uba.
Joshua ti oun naa darapọ mọ awọn ilumọọka ọmọ Naijiria to n fẹhonuhan lori iwa ika àwọn ẹka ọlọpaa SARS lasiko to wa si Naijiria.
Lẹ́yìn náà ni gbogbo ìjọba Solomoni ọba wá wà ní ìkáwọ́ rẹ̀.
Kíni ẹ̀yin rántí nínú ǹkan ti o ti ṣẹlẹ lọ́dun díẹ̀ sẹ́yìn àti nísìnyìí Dokita àti Nọ́ọ̀sì fìyà jẹ mí lásìkò tí mò ń rọbí- Alaboyún Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
tabi abuké, aràrá, tabi ẹni tí kò ríran dáradára, tabi ẹni tí ó ní àrùn ẹ̀yi tabi ìpẹ́pẹ́, tabi ẹni tí ó jẹ́ ìwẹ̀fà.
Aṣẹ ileeṣẹ aarẹ lori ọrọ naa ni oṣu kẹrin, lo dun mọ ọmọ Naijiria ninu.
Bakan naa lo dupẹ lọwọ gomina ipinlẹ Eko, Babajide Sanwo-Olu, gomina ipinlẹ Ekiti, Kayode Fayemi, Gomina ipinlẹ Ogun tẹlẹ, Ibikunle Amosun,gomina ipinlẹ Kogi, Yahaya Bello, gomina ipinlẹ Kebbi ati gomina ipinlẹ Jigawa.
Damilọla Oduolowu, akọroyin BBC ba Felix, akọbi Madam Grace onibọọli naa sọrọ lori ipa awọn ọmọ naa lati ran iya wọn lọwọ nidi iṣẹ bọọli tita.
Ẹni tí ó bá jẹ ẹran-ara mi, tí ó sì mu ẹ̀jẹ̀ mi, ní ìyè ainipẹkun, èmi yóo sì jí i dìde ní ọjọ́ ìkẹyìn.
Ẹ̀rù bẹ̀rẹ̀ sí bà wọ́n nígbà tí Josẹfu mú wọn wọ ilé rẹ̀, wọ́n ń wí fún ara wọn pé, “Nítorí owó tí wọ́n fi sí ẹnu àpò wa níjelòó ni wọ́n fi kó wa wọlé, kí ó lè rí ẹ̀sùn kà sí wa lẹ́sẹ̀, kí ó lè fi wá ṣe ẹrú, kí ó sì kó àwọn kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ wa.
Gbigbe ọmọbinrin ti ko ba to ọdun mehidinlogun niyawo lodi si ofin lorilẹede Kenya.
Ó da gbogbo owó àwọn onípàṣípààrọ̀ nù, ó sì ti tabili wọn ṣubú.
tóbẹ́ẹ̀ tí ó fi fi ìbúra ṣe ìlérí láti fún un ní ohunkohun tí ó bá bèèrè.
Wọ́n wà títí lae ati laelae,ní òtítọ́ ati ìdúróṣinṣin.
Ṣugbọn tí eniyan bá kàn ní ìbànújẹ́ lásán, ikú ni àyọrísí rẹ̀.
Ẹ lawọ́ sí ara yín láìní ìkùnsínú.
Bakan naa ni Omolola sọ nipa ipenija rẹ lẹnu iṣẹ yii ni kikun.
Awọn eeyan naa faramọ oun ti Ọṣun beere yii, ti ọdun Ọṣun Oṣogbo si maa n waye lọdọọdun lati igba naa wa, titi di oni yii.
Awọn olukopa ni ọ̀dun egungun lọna abayọ si isoro araalu Lara awọn olukopa nibi ajọdun naa, wa fi igbgabọ wọn han wipe, egungun ni agbara lati sọ gbogbo ibi ti o ba wa laarin ilu di rere lasiko ti wọn ba wọde.
 O fi idagbasoke ti koowa n ri to n sele lowo ni eka ile ise nlanla ni Asia sapere to ye gege bii awokose rere bayii.
Ẹ má sì ṣe gbàgbé àti máa fi òótọ́-inú bá àwọn ènìyàn lò: èyìínì ni pé kí ẹ má ṣe wá ibi fún ọmọnìkejì yín, kí bẹ́ẹ̀ ni yín jẹ́ bẹ́ẹ̀ ni ki bẹ́ẹ̀ kọ́ yín sí jẹ́ bẹ́ẹ̀ kọ́.
Eka to n mojuto bi oro se n lo lorile ede Amerika ti so pe ki aare ana fun orile ede Gambia Yahya Jammeh ati ebi re ko gbodo wa si orile ede naa mọ ọn.
Wọ́n pín aṣọ mi láàrin ara wọn,wọ́n ṣẹ́ gègé nítorí ẹ̀wù mi.
Báwo ni àgọ́ rẹ ti dára tó ìwọ Jakọbu,ati ibùdó rẹ ìwọ Israẹli!
Nítorí wọn kì í wẹ ọwọ́ wọn nígbà tí wọ́n bá fẹ́ jẹun.
Bakan naa, gbogbo awọn eeyan ti awujọ ti ropin pe ko le se rere nitori ko rọrun lati gbe nilẹ Yuroopu, o dabi ilẹ awọn to n se atipo ọrọ aje ni.
Coronavirus: Wo ohun tí o ní láti ṣe láti dáàbò bo ara rẹ Mo kó àrùn Coronavirus lẹ́yìn tí mo ṣalábapàdé ẹni tó ní àrùn náà lára - Idris Elba Buhari fárígá, ó ní kò s'óṣìṣẹ́ ìjọba tó gbọ́dọ̀ rìnrìnàjò sílẹ̀ òkèèrè lọ́wọ́ yìí Eniyan mẹfa pere lo ni arun coronavirus lasiko ti Obi fi ikede naa sita, ṣugbọn o ti pe mẹtadinlaadọta bayii.
Ìsẹ̀lẹ̀ Ghana: Òògùn ẹ̀fọn pa ìbejì àti ẹ̀gbọ́n wọn
Wọn tete gbe e sa lọ lẹyin ti eniyan kan ju ado oloro naa si aarin awọn ẹgbẹgbẹrun awọn oluwọde to wa ni orita Meskel to wa ni olu ilu orilẹede Ethiopa, Addis Ababa.
Òsìsẹ́ Custom tó dédé sọ ara rẹ̀ di Ọ̀gá Àgbà CG ní àrùn ọpọlọ - Attah Kí l'ànfàní àdéhùn okoòwò kan l'Afíríkà, AfCFTA tí Buhari tọ́wọ́ bọ̀?
coretta scott king ( april 27 , 1927 - january 30 , 2006 ) jẹ ́ olùkọ ̀ wé , alákitiyan , aṣíwájú fún àwọn ẹ ̀ tọ ́ aráàlú ará amẹ ́ ríkà , àtí ìyàwó martin luther king jr .
Láti Ijipti ati Kue ni Solomoni ti ń kó ẹṣin wá, àwọn oníṣòwò tí wọn ń ṣiṣẹ́ fún un ni wọ́n ń ra àwọn ẹṣin náà wá láti Kue.
Tabi ti ọrọ ina mọnamọna to lọ soke ni?
"Eeyan daada lọkọ mi, oun si lo mọ idi ti ko fi fẹ wsn sile bi i iyawo.
Ajọ NCDC ṣalaye pe eeyan meji ninu wọn lo ti kuro ni ile iwosan lẹyin ti wọn gba itọju tan.
Nígbà tí wọ́n gbọ́ báyìí, ẹnu yà wọ́n, wọ́n bá fi í sílẹ̀, wọ́n sì bá tiwọn lọ.
Titoro aforiji waye leyin ipade ti o se pelu awon alase orile-ede naa ni ile-ise to n se amojuto gbogbo eka ibanisoro lorile-ede naa,ti won si se agbekale ofin kan ti o fa ariyanjiyan ni bi ose melo seyin.
Jíjó ni a óo jó ilé mọ́ ọ lórí.
Ó bi wọ́n pé, “Kí ló dé tí ẹ dá àwọn obinrin wọnyi sí?
Ọpẹ patakai lọwọ ọkọ mi to maa n ti mi lẹyin ni gbogbo igba.
Ẹniọwọ John Onaiyekan ṣalaye pe bi o ba jẹ pe oun ni aarẹ orilẹede Naijiria lọwọlọwọ bi nnkan ṣe ri yii, nṣe ni oun yoo kọwe fi ipo silẹ lẹyẹ o sọka.
 eyi din atankalẹ ti awọn kokoro atan arun laarin igbẹ ati ounjẹ nipasẹ awọn kokoro .
Àwọn nnkan tí ó ń gbé èdè Yorùbá níyì.
Ó ṣe ohun tí ó burú lójú OLUWA títí di ọjọ́ ikú rẹ̀, nítorí pé ó tẹ̀lé ọ̀nà Jeroboamu ọba, ọmọ Nebati, tí ó mú Israẹli dẹ́ṣẹ̀ títí di ọjọ́ ikú rẹ̀.
Kò gbọdọ̀ ní àbààwọ́n kankan, wọn kò sì gbọdọ̀ tíì fi ṣiṣẹ́ rí.
Wo ìdí tí Osun fi kede ìsinmi fún ọdún ìṣẹ̀ṣe, tàwọn ìpínlẹ̀ yókù kò dáhùn, O ni igba kẹta ree tileesẹ ọlspaa ipinlẹ Kano yoo gunle eto idoola ẹmi fun awọn eeyan ti wọn so mọlẹ fun ọjọ pipẹ bii iru eyi.
Awọn obinrin ati ọdọbinrin ni wọn saba maa n ṣubu sinu ikẹkun yii ni ilepa iṣẹ, ṣugbọn lẹyin o rẹyin wọn yoo di aṣẹwo.
“Ise ti n lo lowo pelu ijoba ipinle yii lati ri daju pe, a se ojuse wa lati ko awon ile ti o ba ye fun kiko, bee si ni lati na owo iranwo si awon ti o ba nilo iranwo,”Ewe, ti  a ba ranti pe, isele buruku naa gba emi àádọ́ta eniyan, O so awon miiran di alainile lori, ti o si tun ba dukia awon eniyan je lopolopo.
A ti pọ́n ọn láti fi paniyan;a ti fi epo pa á, kí ó lè máa kọ mànà bíi mànàmáná.
Oríṣun àwòrán, Reuters Àkọlé àwòrán, Aare Donald Trump Ipa wo ni isẹlẹ yi yoo ni lori awọn olugbe ilẹ Amerika?
Kìnnìín ni alága, àjànàkú ni igbá kejì, àwọn ẹranko kéékèèkéé sì ni ni agbáwo.
“Ẹbọ tí àwọn ọmọ Aaroni yóo máa rú, ní ọjọ́ tí wọ́n bá fi wọ́n joyè alufaa nìyí: Ìdámẹ́wàá ìwọ̀n efa ìyẹ̀fun tí ó kúnná dáradára, gẹ́gẹ́ bí ẹbọ ohun jíjẹ, ìdajì rẹ̀ ní òwúrọ̀, ìdajì tí ó kù ní àṣáálẹ́.
 ní 1901 sí 1902 ni ó tẹ ̀ lé àwọn òbí rẹ ̀ lọ sí glasgow .
Awọn asofin màrúndínlógún lo ti yapa lati inu ẹgbẹ  APC lo sinu ẹgbẹ  alatako ,Peoples Democratic Party (PDP), bakan naa ni awọn ọmọ ẹgbẹ  APC, mẹ́tàlélọ́gbọ̀n to wa nile igbimo asoju kekere ni wọn tun ti yapa lo sinu ẹgbẹ PDP ti awọn mẹ́rin  lati inu ẹgbẹ  APC miiran si ya lo sinu ẹgbẹ   African Democratic Congress (ADC).
O ti koju oniruuru ipenija paapaa julọ lasiko to n dagba ati irú idile to tí wa to fi mọ nipa ibaṣepọ ṣaaju igbeyawo.
OLUWA yóo lo agbára mímọ́ rẹ̀, lójú àwọn orílẹ̀-èdè,gbogbo eniyan, títí dé òpin ayé, yóo sì rí ìgbàlà Ọlọrun wa.
Kí ló wá dé tí mo rí gbogbo ọkunrin,tí wọn ń dáwọ́ tẹ ìbàdí bí obinrin tí ń rọbí?
tijani babatunde folawiyo ( tí a tún mò ís tunde folawiyo ) jé omo orílé èdè nàìjíríà onísòwò .
Ẹgbẹẹgbẹ̀rún eniyan kaakiri agbaye lo n bi ara wọn lere bayii pe: Ṣe kii ṣe pe ẹni ti mo pade nile itaja yẹn sunmọ mi ju?"
Awọn ohun elo ikọle ti ko lagbara Lọpọ igba awọn ohun elo ikọle ti awọn oṣiṣẹ mọlemọle maa n lo kii saba lagbara to.
osu kerin  ati ojo keji , osu kárùn ún lati lee jẹ ki won se ayẹyẹ odun
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: 2019 Elections: Ìlérí àwọn olùdijé nípa ètò ẹ̀kọ́ Saraki gbé N16.
“Nítorí náà, sọ fún wọn pé, èmi OLUWA Ọlọrun ní ẹnikẹ́ni ninu àwọn ọmọ Israẹli tí ó bá kó oriṣa rẹ̀ lé ọkàn tí ó gbé ẹrù ẹ̀ṣẹ̀ tí ń múni kọsẹ̀ siwaju rẹ̀, tí ó wá tọ wolii wá, èmi OLUWA fúnra mi ni n óo dá a lóhùn gẹ́gẹ́ bí ọpọlọpọ oriṣa rẹ̀.
O kò yin Ọlọrun tí ẹ̀mí rẹ wà lọ́wọ́ rẹ̀ lógo, ẹni tí ó mọ gbogbo ọ̀nà rẹ.
Àwọn kan ninu wọn bá fara mọ́ ọn, wọ́n sì gbàgbọ́.
"Asiko iwọde yii si ni awọn akẹkọọ naa n polongo pe ki Minisita feto ẹkọ, Ahmadu Ali kuro nipo naa, eyi ti wọn fi ede oyinbo beere pe ""Ali Must Go""."
O tun gba iwe ẹri jade ni John Curtin College ni Australia.
 “Bi o ti le je pe, a to ilopo meta orile-ede South Africa, owo ti o wole sapo ijoba nipase ipolowo oja ori ero amohun-maworan orile-ede Nigeria ni odun 2016 je milionu o-le loodunrun owo dollars, eyi ti o je iko merindinlogorin ninu ida ogorun, eyi ti o jina pupo si ti orile-ede South Africa.
Ọjà kún inú rẹ,ẹrù rìn ọ́ mọ́lẹ̀ láàrin omi òkun.
Lẹ́yìn eléyìí pẹ̀lú mo fẹ́ kí ẹ yan àwọn ènìyàn Sàǹkòsàǹkò kí ẹ rán wọn lọ sí ọ̀dọ̀ ọba alágbára ibòmíràn gbogbo kí ẹ wí fún wọn nípa ọ̀ràn irìnajo náà kí wọ́n ba à rán àwọn ọdẹ gbogbo jáde.
" Cute Abiola, ẹni to woye pe ajakalẹ arun Coronavirus yii fun wa laaye lati sun mọ Ọlọrun ni.
Lọdun 2014, ajọ aladani kan ti orukọ rẹ n jẹ 'Good Governance Initiative' so pe o to ẹgbẹrun lọna ọgọrun eeyan to salabapade iku ojiji lọwọ eefin.
Amọ sibẹ awọn eeyan ati onwoye ko yee sọrọ lori ipa ti o ṣee ṣe ki igbesẹ yii ni, lori oju ti awọn eeyan yoo fi wo abajade eto idibo apapọ naa.
kọ́ wa láti máa ní ṣùúrù
com/si5BWGZohE— 🇳🇬 Super Eagles (@NGSuperEagles) June 21, 2018.
ipinle naa lati fokanbale , ki won si maa ba isẹ won lo laisi ibẹru , nitori pe
Oríṣun àwòrán, Others Bako ni ọkunrin kan wa pẹlu afurasi naa to fẹ seranwọ fun lati jẹ kawọn ẹrun naa kọja lọdọ awọn agbofinro laisi ayẹwo, amọ awọn osisẹ asọbode yari pe awọn yoo yẹ gbogbo paali naa wo finni-finni.
Damini Ebunoluwa Ogulu Rex tí gbogbo ènìyàn mọ si Burna Boy ni a bí ni ìlú Port Harcourt ni ọjọ́ kejì, oṣù keje, ọdún 1991.
O fi kun un wi pe ki ijọba tun pese ile igbe fun awọn ọmọde ti ko ri ile gbe abi ti awọn obi ti kọ silẹ, ki iru ifiyajẹ ọmọde le dinku ni awujọ.
 Lẹnikọọkan ati lapapọ, o ṣe pataki ki a tẹle ifẹ
O ni pipada si eto abo iṣedale ti awon eeyan mo ni ona abayo O salaye pé APC, APM ati PDP iru kankan naa ni won o si daa bi won se n ba ara won ja Paseda ni Fifi oju isaju gbe ise agbase fun kongila lo n fa omiyale.
Láti ìgbà ayé Joṣua ọmọ Nuni, títí di àkókò náà, àwọn ọmọ Israẹli kò pàgọ́ bẹ́ẹ̀ rí, gbogbo wọn sì yọ ayọ̀ ńlá.
O yẹ ki a kede akoko pajawiri lẹkun eto abo lorilẹede Naijiria."
’ Ṣé ọ̀kankan ninu àwọn oriṣa àwọn orílẹ̀-èdè yòókù ti gba ilẹ̀ rẹ̀ sílẹ̀ lọ́wọ́ Ọba Asiria rí?
Nigeria at 59: Nàiajíríà ni olú ìlú àwọn tó tòṣì jùlọ làgbáyé
Lẹ́yìn náà, nígbà tó yá, Joṣua ọmọ Nuni, iranṣẹ OLUWA kú nígbà tí ó di ẹni aadọfa (110) ọdún.
"Nigba to n fi itara sọrọ loju opo ikansiaẹni Facebook rẹ lori itakun agbaye, Iwobi ni ""Pẹlu inu didun ni mo fi nsọ fun yin pe wọn ti yan mi gẹgẹ bii sẹnatọ."
Òṣèré, olóòtú àti oníṣòwò ni pẹ̀lú.
 iye owó rẹ ̀ lójú pálí jẹ ́ bíi 0.
 wọ ́ n pín ẹbí yìí sí àwọn ẹbí mẹ ́ ta tí ó sì ní àwọn ẹ ̀ yà mẹ ́ rìnlé làádọ ́ rún ní àwọn ìdílé mẹjọ .
O tun so pe“mo nigbagbo pe igbese ti ijoba n gbe yii, yoo tun fi okan  awon ti wahala omiyale ti n da laamu lati ọdun pipe bale”.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ijinigbe ile ẹko Dapchi: Oun ta mọ nipa rẹ 27 Èrèlè 2018 Oríṣun àwòrán, Reuters Àkọlé àwòrán, Ile-iwe Daphchi ni akẹẹkọ to le ni ẹẹdẹgbẹrun Ijinigbe awọn ọmọ ile ẹko Dapchi to le ni ọgọrun ni iwọ oorun ariwa Naijiria ti'n kọni lominu.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Adebayo Shittu: Ìyàlẹ́nu ló jẹ́ pé ń kò jẹ mínísítà lẹ́ẹ̀kejì 26 Ògún 2019 Oríṣun àwòrán, @HMAdebayoShittu Minisita tẹlẹri feto ibaraẹnisọrọ ni Naijiria, Adebayo Shittu ti ṣe'mọ bi aarẹ Buhari ko ṣe yan sipo Minisita.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Òṣìṣẹ́ ìjọba ẹ̀ni ọdún mọ́kàndínláàdọ́ta pokùn so ní Ekiti 28 Bélú 2018 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Aworan okun ti awọn eeyan fi n pokun so Ọrọ di boo lọ o yaa mi ni ileese oṣisẹ nipinlẹ Ekiti nigba ti oṣisẹ ijọba kan, ọgbẹni Abolarinwa Olaoye pokun so.
Ẹ gbé ọwọ́ ẹ̀bẹ̀ sókè sí i,nítorí ẹ̀mí àwọn ọmọ yín tí ebi ń pa kú lọ ní gbogbo ìkóríta.
Akoba ti n wọ iṣẹ tiata bayii, iṣẹ sinima n ku lọ, sinima ti wọn n wo lori ayelujara ko ni jẹ ki ọpọ jade lọ wo sinima.
Johanu jẹ́rìí nípa rẹ̀, ó ń ké rara pé, “Ẹni tí mo sọ nípa rẹ̀ nìyí pé, ‘Ẹnìkan ń bọ̀ lẹ́yìn mi tí ó jù mí lọ, nítorí ó ti wà ṣiwaju mi.
OLUWA rere ni ọ́, rere ni o sì ń ṣe;kọ́ mi ní ìlànà rẹ.
Oríṣun àwòrán, Petra Diamonds Àkọlé àwòrán, Iwakusa eroja okuta Diamond jẹ ara ohun to fa orilẹede Russia loju mọra Koda, awọn ileesẹ kan to jẹ tilẹ Russia lo ti n wa kusa lorilẹede Guinea, ti wọn si tun n wa okuta olowo iyebiye dayamọndi ni orilẹede Angola, to si tun ti gba asẹ lati maa pese afẹfẹ gaasi lorilẹede Mozambique.
O ni Naijiria ko wa ta guguru ni France, a maa bọ si ipele to kan lagbara Olorun ni.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìtàn Mánigbàgbé: Adebisi Idikan ni olówó tó kọ́kọ́ ra ọkọ̀ nílẹ̀ Ibadan 7 Ọ̀wàrà 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 20 Èbibi 2020 Oríṣun àwòrán, Busari Adebisi Ilu Ibadan jẹ ilu to gbajumọ nilẹ Afirika ati lawujọ agbaye, to si ni awọn akọni ẹda ti ko lonka.
Oríṣun àwòrán, Rasaq olayiwola Àkọlé àwòrán, Rasaq Ọlayiwọla (Ojopagogo) ati Moji Afọlayan 'IBB tẹ ń pariwo pé ó kú, kò kú o, Ko ko ko lara ọta ń le!
Idi niyi ti wọn fi n pee ni owo ori alayọọlẹ, iyẹn Witholding tax nitori ileeṣẹ naa ni yoo ti yọ owo naa ki wọn to ko iyoku le Laycon lọwọ lẹyin eto naa.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ọkọ àtìyàwó tó sọ ọmọ wọn ni Adolf Hitler wọ wàhálà ní ilẹ̀ Gẹ̀ẹ́sì 12 Bélú 2018 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 13 Bélú 2018 Oríṣun àwòrán, Getty Images Tọkọ-taya kan to sọ ọmọ wn ni Adolf Hitler ti wọ wahala lẹyin ti iwadi fi idi rẹ mulẹ pe wọn jẹ ọmọ ẹgbẹ́ agbesunmọmi kan.
Fun awọn agbabọọlu Naijiria, ife ẹyẹ agbaye awọn obinrin kọja ere bọọlu lasan.
Ọdún 2012 ni ìdíje Olympics wáyé ní ìlú Lọndon.
Awọn akọroyin ni igbohunsafẹfẹ Mancho Bibixy nii se pẹlu ijajagbara to n waye ni ẹkun ariwa-iwọ oorun ilu Bamenda.
Ṣugbọn Isaaki bi í léèrè pé, “O ti ṣe é tí o fi rí ẹran pa kíákíá bẹ́ẹ̀ ọmọ mi?
Àwọn ìròyìn mìíràn tí ẹ lè nífẹ̀ẹ́ sí: Àwọn òrin tó ń k'ókìkí àwọn ọmọ Yahoo R Kelly sunkún lóri Tẹlifísàn nípa ẹ̀ṣùn ìbálòpọ̀ Hubert Ogunde ló m'órí mi yá láti di òṣèré Mo n wa'yawo - Falz 'Gbogbo mọ̀lẹ́bí mi ló wọ bàtà ti Fẹla bọ́ sìlẹ̀' Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí kan sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
Wọn a ma a lo si ile iwosan ni orekoore fun ayẹwo to peye.
Oríṣun àwòrán, Twitter Tolanibaj Tolani Shobajo jẹ ẹni ọdun mẹtadinlọgbọn.
Oríṣun àwòrán, others Àkọlé àwòrán, Lati kekere ni ọmọ ti yoo jẹ aṣamu ti maa.
Babiloni ìlú ńlá nnì ti tú!
Ìjìyà àwọn eniyan mi pọ̀ ju ti àwọn ará Sodomu lọ, Sodomu tí ó parun lójijì,láìjẹ́ pé eniyan fi ọwọ́ kàn án.
Awọn obinrin wọnyi ni Mozambique n to lati gba nnkan eelo lọjọ Iṣẹgun to kọja.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Allen Onyema: Iro ni ile Amerika pa mo mi lori esun jibiti 23 Bélú 2019 Oríṣun àwòrán, Facebook/Allen Onyema Àkọlé àwòrán, Allen Onyema: Amẹrika fẹ̀sùn jìbìtì $20m kan olùdàsílẹ̀ ilé iṣẹ́ ọkọ̀ òfurufú Air Peace Alaga ilẹ isẹ ọkọ ofurufu Air Peace, Allen Onyema ti ni iro lasan ni ilẹ Amerika pa mọ oun lori ẹsun iwa jibiti ti wọn fi kan oun.
Trump:Ẹ forijinmi lori atuntẹ twita mi
ati irọsẹ , o ni oda oun loju pe abajade esi idibo naa yoo fi ifẹ awon eniyna
Oṣu Kejila lo yẹ ki wọn o yẹgi fun Lee, ẹni ọdun mẹtadinlaadọta, ṣugbọn wọn da a duro lẹyin ti ile ẹjọ pagidina idajọ iku ti wọn da fun.
Joabu bá tọ Dafidi ọba lọ, ó sì sọ ohun tí Absalomu wí fún un.
ati pé ẹnikẹ́ni tí kò bá ṣe bẹ́ẹ̀, a óo sọ ọ́ sinu adágún iná tí ń jó.
Ṣókúwé je eya eniyan ni apa arin afrika .
Atẹjade ọhun fi kun un pe gbogbo awọn ileeṣẹ iroyin, edio, tẹlifiṣan and awọn ileeṣẹ iroyin miran to ba nifẹ sii lee darapọ mọ aarẹ.
Igbakẹji gomina Ipinlẹ Ọṣun, Gboyega Alabi to soju gomina Gboyega Oyetola nibi akanṣe eto naa ni, agbekalẹ Amọtẹkun jẹ ojuṣe awọn gomina nitori ikawọ wọn ni aabo ẹmi ati dukia awọn eeyan ilu wa.
Buhari: Ìkọlù Fulani àti ẹlẹ́gbẹ́ òkùnkùn ní Kaduna àti Rivers burú jáì
Eniyan lè fi ọ̀rọ̀ ẹnu wá oúnjẹ fún ara rẹ̀,a lè jẹ oúnjẹ tí a bá fi ọ̀rọ̀ ẹnu wání àjẹyó ati àjẹṣẹ́kù.
Ará ilé - BBC News Yorùbá BBC News, YorùbáFò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Kò sí ǹkan tó ń ṣe Idris agbébọn ní Kano - Ará ilé 20 Òkùdu 2019 Oríṣun àwòrán, @others Àkọlé àwòrán, Wọn ni lo ba wọle lọ gbe ibọn ni o si dabọn bolẹ ti ọrọ naa di pẹntuka ni Kano.
O n dije fun ipo ile igbimọ aṣofin ipinlẹ, lẹyin to fi ẹyin Raymond Dehn, to ti n ṣoju ẹgbẹ naa fun ọjọ pipẹ, janlẹ l'oṣu Kẹjọ.
Nítorí èyí, àfi bí ẹni pé ó tún gba ọmọ náà pada láti inú òkú.
Inú bí Jakọbu pupọ sí ọ̀rọ̀ tí Rakẹli sọ, ó dá a lóhùn pé, “Ṣé èmi ni Ọlọrun tí kò fún ọ lọ́mọ ni?
awon asise ibi, adalafia ara ilu laamu ohun han lai fi oro naa fale.
Ṣugbọn, ikede wọn naa ko sọ boya ọkunrin tabi obinrin ni alaisan naa.
Ni bayii awon oludibo ti bere si n dibo won .
Àwọ́n ìròyìn mìíràn tí ẹ lé nífẹ̀ẹ́ sí: Ọ̀nà wo lowó osù tuntun yóò tọ̀, kó tó dé àpò òsìsẹ́?
O kan ti rẹ ara ni.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Aláàfin Ọyọ: Pọ́ńbélé Yorùbá ni mí, n ò sì ní tijú rẹ níbikíbi Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Aláàfin Ọyọ: Pọ́ńbélé Yorùbá ni mí, n ò sì ní tijú rẹ níbikíbi 24 Ọ̀wàrà 2018 Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí 2 sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 2:23 Fídíò, Water Generator: Ó leè ṣiṣẹ fún wákàtí mẹfà, kó tó sinmi, Duration 2,2310 Òkùdu 2020 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
“Igbimo  tun fenuko lori iwe ti aare fi ranse si won ,
Wọn ni ijọba beere fun owo lati tun ṣe ṣugbọn wn ko ka ọrọ naa kundebi pe ki wọn ti afara naa pa.
maa ni ilosiwaju ninu kata-kara oro aje eleyi ti yoo mu igbega ba igbe aye
Eyi yatọ si ohun to n ṣẹlẹ lorilẹede Mauritania, nibi ti yoo ti gba wọn to okooleọọdunrun o din mẹsan ọjọ.
Láàrin òdòdó lílì,ni ó ti ń da ẹran rẹ̀.
"Fayose ke s'ijọba lati kede dukia ti EFCC gba Fayose sọ wipe: ""A ti gbọ iroyin awọn to n ko ounjẹ atawọn nkan arẹmọlẹkun gbogbo to wa fun awọn ibudo atipo ati awọn ti ogun le lẹkun ila oorun ariwa orilẹede Naijiria si orilẹede Chad ati Niger, bẹẹni nkan bii igba tọọnu eso ti orilẹede Saudi Arabia gbe kalẹ f'awọn ibudo awọn atipo ati awọn ti ogun le ni wọn ti n ta kaakiri ọja nilu Abuja."
Tí wọn bá pè ọ́, lọ jókòó lẹ́yìn, kí ẹni tí ó pè ọ́ lè wá sọ fún ọ pé, ‘Ọ̀rẹ́ mi súnmọ́ iwájú.
Awọn ikọ mejeeji lo ni kudiẹkudiẹ lọwọ ẹyin wọn ṣugbọn ko si aniani pe awọn atamatase agbawaju fun ikọ Man city yoo lee ṣe ọpọlọpọ ọṣẹ.
Kò sí òògùn kan tí ó lè ran Jakọbu,bẹ́ẹ̀ ni àfọ̀ṣẹ kan kò lè ran Israẹli.
fe ki aare to n saisan naa fi ipo silẹ ni kiakia.
“Nisinsinyii gba ti Ọlọrun,kí o sì wà ní alaafia;kí ó lè dára fún ọ.
Yóo sì jẹ́ ẹrukunrin yín títí lae.
Gègé kinni tí wọ́n ṣẹ́ fún ìdílé Asafu mú Josẹfu; ekeji mú Gedalaya, òun ati àwọn arakunrin rẹ̀ ati àwọn ọmọ rẹ̀ ọkunrin jẹ́ mejila.
Mo wá gbọ́ ohùn kan bíi ti àkọ́kọ́.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Nollywood gba àlejò ọmọkùnrin jòjòló 28 Èbibi 2019 Oríṣun àwòrán, Bidemi Kosoko Idunnu subu layọ ni lowurọ ọjọ Iṣẹgun nigba ti ariwo gba ilẹ kan pe gbajugbaja oṣere ori itage lobinrin kan, Abidemi Kosọkọ ti di iya ikoko.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Sadio Mane lo jẹ goolu naa fun Liverpool.
Awọn gomina tẹlẹri ti aje ọrọ yii si mọ lori ni Amofin Raji Fasola to jẹ gomina ipinlẹ Eko tẹlẹ sugbọn ti o ti di minisita fun ipese ina ọba, ilegbigbe ati akanse isẹ; Rotimi Amaechi to jẹ gomina ipinlẹ Rivers tẹlẹ ti o ti wa di minisita fun igbokegbodo ọkọ.
Tí ẹ bá yẹ àpọ̀ enítọ̀hún wò, ẹ ó rí ẹ̀rọ ayàwòrán, ẹ̀rọ agbórinsétí alágbèéká, ẹ̀rọ ìbánisọ̀rọ̀ alágbèéká, ati bẹ́ẹ̀ bẹ́ẹ̀ lọ.
 o keko akobere re nile eko alakoobere ti ansar-un-deen , oke popo , ni ipinle eko .
Àyà mi kó já, ṣùgbọ́n bí ó ti na ọwọ́, tí ó wí báyìí: ‘Àlááfíà’ ṣe ni ọkan mi balẹ̀.
Ará, ohun tí mò ń sọ ni pé ẹran-ara ati ẹ̀jẹ̀ kò lè jogún ìjọba Ọlọrun, ati pé ohun tíí bàjẹ́ kò lè jogún ohun tí kì í bàjẹ́.
Akin-Olugbade ati iyawo rẹ, Ladun, ti wọn ti fẹ ara wọn fun ogoji ọdun, ni Eledumare fi ọmọ ati ọmọọmọ kẹ.
Ìjọba tèmi náà wá dé, ẹ ní a kò ní fi ara re lo o, ẹ ń da ìjọba láàmú.
Àwọn ọ̀rẹ́ ati àwọn ẹlẹgbẹ́ mi takété sí mi nítorí àrùn mi,àwọn ẹbí mi sì dúró lókèèrè réré.
“Ẹnikẹ́ni kò mọ ọ̀nà ibi tí ó wà;bẹ́ẹ̀ ni kò sí ní ilẹ̀ alààyè.
Ẹ̀mí OLUWA kúrò lára Saulu, ẹ̀mí burúkú láti ọ̀dọ̀ OLUWA sì ń dà á láàmú.
Ni afikun un, O je iyawo akoko lasiko saa ti oko re n tuko ijoba Amerika  lodun 1989 si 1993.
Niṣe ni ijọ naa kun fọfọ ni isin ọjọ isinmi akọkọ to waye ninu ijọ ọhun lẹyin ti woli naa rẹwọn he.
Ẹ wá ná, kí ló ń ṣẹlẹ̀ pẹ̀lú Brexit?
Ìwé àmọ̀jù ti dà ọ́ lórí rú.
Awọn agbofinro ni nkan bii agogo 15:00 ti Texas ni iṣẹlẹ yii bẹrẹ nigba ti awọn ọlọpaa ẹṣọ aabo oju popo meji da ọkọ ọkunrin naa duro ni marosẹ Midland.
ohun tí ó fẹ́ kí wọ́n ṣe fún arakunrin rẹ̀ gan an ni kí ẹ ṣe fún òun náà.
Bí ẹ bá ti ṣe ìwọ́nyí fún mi, inú mi yóò dùn gidigidi nítorí àwọn ọdẹ tí wọ́n ti fi orí mulẹ̀ ní ìkọ̀kọ̀ ni a ó wú jáde.
 Ó jẹ ́ ọ ̀ kan lára àwọn máàrún tí a mọ ̀ ààrùn ẹ ̀ dọ ̀ àwọn àkóràn : a , b , c , d , àti e .
Taraba: Àwọn Ọlọpàá ní ìwádìí ṣì ń lọ lówọ lórí ikú Fadá
, Duration 8,0016 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Ekiti Bishop: Ìjọ Anglican pàṣẹ lọ rọọ́kún nílé fún Bíṣọ́ọ̀bù tó ń bá ìyàwó àlùfáà abẹ́ rẹ̀ sùn l'Ekiti16 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Ó bá pàṣẹ pé kí àwọn eniyan jókòó lórí koríko.
Aare Buhari so fun iko naa pe: “Adari ni ẹ jẹ  ni awon eka ti e wa,ohun ti a n reti lati odo
Mo ti jèrè àpò meji lórí rẹ̀!
#Pittsburg shooting: agbófinró gbé afurasí lọ sílé ẹjọ́
Ó kú ní Kiriati Ariba, ní Heburoni, ní ilẹ̀ Kenaani, Abrahamu sọkún, ó sì ṣọ̀fọ̀ rẹ̀.
N óo sì sọ ìlú yìí di ohun ẹ̀rù ati àrípòṣé, ẹ̀rù ìlú náà yóo sì máa ba gbogbo ẹni tí ó bá kọjá níbẹ̀, wọn yóo máa pòṣé nítorí àjálù tí ó dé bá a.
O fi kun oro re pe, siseto idanilekoo fun awon eso enu-ibode ati awon ti oro kan yoo mu igberu ba eto oro-aje, aleku-oro ati idagbasoke awujo.
Islam kọ́ ló ni kí ọmọ ọdún méjìlá lọ sílé ọkọ- Ààrẹ ilẹ̀ Niger Funmilayọ Ọrẹtuyi to tun n gbe ibẹ naa sọrọ pe omiyale yii ko jẹ ki oun jade nile mọ ati pe awọn miran ni owo atijade nile ti wọn sii.
Olumilua: Gómìnà ìpínlẹ̀ Ondo nígbàkanrí, Bamidele Olumilua, jáde láyé Iroyin to n tẹ wa lọwọ ni yajoyajo n fi yeni pe gomina ipinlẹ Ondo nigbakan ri, Ajihinrere Bamidele Olumilua ti di ara ilẹ.
Ibẹru ta ni yoo fẹ mi lọkọ abi laya?
(Àkọsílẹ̀ rẹ̀ wà ninu ) Orin arò náà lọ báyìí:
- Femi Fani-Kayode Làásìgbò òṣèlú wáyé nílùú Ondo, ọ̀pọ̀ èèyàn fara pa Ajọ EFCC ṣalaye pe awọn afurasi mejeeji naa gbimọ pọ lu Hayatou ni jibiti lori ayelujara ati ẹrọ ibaraẹnisọrọ lẹyin ti wọn parọ fun un pe o jẹ ẹbun ọkọ ati awọn foonu olowo nla pẹlu iṣẹ to n doju ti iṣẹ.
Ṣugbọn ta ni ẹni náà tí àwọn eniyan Israẹli ń fẹ́ tóbẹ́ẹ̀?
Obasanjo wa gbadura pe Ọlọrun yoo mu ki ọdun tuntun 2021 dara fun wa amọ isẹ sise nikan ni amin rẹ.
Joramu ọba pàṣẹ pé kí wọ́n gbé kẹ̀kẹ́ ogun òun wá, wọ́n sì gbé e wá fún un.
O ni bayii ti alaafia ti n joba ni awon ekun kookan ni apa ariwa ila oorun Naijiria, asiko ti to ki won da awon asatipo pada sile won ki onikaluku bere igbe aye alaafia ni perewu.
 Awọn asofin méjílélógójì lo wa nibi ipade naa.
SERAP - BBC News Yorùbá BBC News, YorùbáFò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Bayelsa Lawmakers: Tí o ba buwọlu owo ìfẹyìnti yòó di ọ̀rọ̀ ile ẹjọ - SERAP 28 Ìgbé 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 29 Ìgbé 2019 Oríṣun àwòrán, Dicksonofficial Àkọlé àwòrán, Ajọ náà fi kún pé ti wọn ba fi le buwólu abadofin, owó ìfẹyin ti láílái yìí, ó túmọ si pe, ilé ìgbìmọ àsofin náà ti tàpá si òfin Nàijíría àti ti àgbáye.
Kí Ọlọrun má ṣe ka ọjọ́ náà sí,kí ìmọ́lẹ̀ má ṣe tàn sí i mọ́.
Ní ipò òkú ni ó rí ara rẹ̀, tí ó ń joró.
''$18 miliọnu ni a n na sori itayin, irinwo miliọnu dọla lori rira iyẹfun tomato wole sorilẹede Naijiria.
Àkọlé àwòrán, Èrò àwọn èèyàn ṣọ̀tọ̀tọ̀ lẹ̀yìn tí ìjọba kéde pe ó ṣeṣe ki òfin kónílé-ó-gbélé mìí wàyé Àkọlé àwòrán, Èrò àwọn èèyàn ṣọ̀tọ̀tọ̀ lẹ̀yìn tí ìjọba kéde pe ó ṣeṣe ki òfin kónílé-ó-gbélé mìí wàyé Wo àwọn èèkàn ìlú Kano tó kú láàrín ọjọ́ mẹ́rin sí ara wọn Deaths in Kano Today: Kí ló pa àwọn èèkàn ìlú Kano mọ́kànlá wọ̀nyí láàrín ọjọ́ mẹ́rin Oríṣun àwòrán, AYAGI'S PROFILE Lati nnkan bi ọjọ diẹ sẹyin bayii, ọpọ eekan ọmọ ipinlẹ Kano lo ti ba ajakalẹ iku ọwọọwọ to n waye bayi ni ipinlẹ naa lọ.
Asset Declaration: Buhari, Osinbajo ti fi fọ́ọ̀mù ìkéde Dúkìá sọwọ́
Itan sọ fun wa wipe, fun igba ọdun ni wọn fi kọ ile ijọsin Notre-Dame Cathedral ati wipe ọdun aadọtalelẹgbẹrin sẹyin ni wọn ti kọ.
Opolopo awon ibi ti won gbe apoti idibo  si , ti awon akoroyin  ile akede Naijiria (VON) lọ, lo je pe  won ti ri opolopo awon oludibo to duro  ni sẹpẹ bi I igba ti won n gbaradi fun oogun, lati dibo won.
Gẹgẹ bi Segun to ni eto kan lati ṣe ni ipinlẹ Eko lọjọ kẹtalogun, oṣu Kejila, ọdun 2020 ṣe sọ, o ni oun ti ṣe adinkun si iye eeyan ti yoo wa nibi eto naa.
Kí ló dé tí o fi dojúbolẹ̀?
Ẹ bi mí pé kíni ojú mi rí níbẹ̀ ẹ̀yin èèyàn mi?
Ekiti fẹ́ kówó s'ígbó fún papakọ tí àwọn ará ìlú kò le lò
Lootọ ni pe eeyan le ko arun Coronavirus lati ara ohun ti arun naa ba wa, bii ori tabili, aga iojoko tabi nnka mii.
“Ọmọ eniyan, dojú kọ àwọn òkè Israẹli kí o sì sọ àsọtẹ́lẹ̀ sí wọn.
, o ní ọ̀pọ̀ wọ́n wọ asọ sọja, ti wọ́n sì n rìn káàkiri inú igbó náà.
OLUWA bá sọ pé; “Ẹ̀sùn tí àwọn eniyan fi ń kan Sodomu ati Gomora ti pọ̀ jù, ẹ̀ṣẹ̀ wọn burú jáì!
LASTMET kọ́ ló kó Opay nílẹ̀ ṣùgbọ́n ọlọ́kadà kò láṣẹ látigba ọ̀nà mọ́rosẹ̀ l'Eko- Opeifa Òṣìṣẹ́fẹ̀yìntì, ọmọ ọdún 71 wọ gbaga ọlọ́pàá fún pípe iléeṣẹ́ kan fún ìgbà 24, 000 Ilé ẹjọ́ Eko pàṣẹ, EFCC mú u ṣẹ, Ìjọba gbẹ̀sẹ̀ lé ilé Saraki ní Ilorin Buhari já ọ̀ra lára ọkọ̀ ìjagun ológun tiwantiwa ní Kaduna Agbẹ́nusọ ọlọpàá ní ìpínlẹ̀ Eko Bala Elikana, sọ nínú àtẹjáde kan pe àwọn afurasí náà maa n wá ọmọ ìjọ fún ìjọ Wonders Assembly Ministry to waà ni àdojúkọ Lagos Business School ní márosẹ̀ Lekki/Epe ni Ajah.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Dokita yọ góòlù kílò kan àtààbọ̀ àti owó ṣílè nínú obìnrin kan 26 Agẹmo 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Igba wo ni goolu di ounjẹ nikun eeyan?
Wo ohun mẹwaa to yẹ ko mọ to ba fẹ lọ sinmi lasiko arun Covid-19 Ma rin irinajo ti ara rẹ ko ba da: Orilẹede Amerika lo kọkọ kilọ fun awọn eniyan lati kiyesi ilera ara wọn ti wọn ba n rinrinajo.
Ijọba gbudọ wa wọrọkọ fi s'ada lori ọrọ yii.
Fún wọn ní nǹkankan, OLUWA, OLUWA, kí ni ò bá tilẹ̀ fún wọn?
" Ààrẹ Buhari fẹ́ yan òkú oṣù méjì sípò àkóso iléeṣẹ́ ìjọba àpapọ̀ Oríṣun àwòrán, Laureta Onochie Aarẹ Muhammadu Buhari tun ti yan eeyan kan to ti ku si ipo bayii eleyi to ti n ṣe ọpọlọpọ eeyan ni haahin.
Akọwe ẹgbẹ ọmọ Yoruba, Yoruba Council of Elders (YCE), Kunle Olajide to ba BBC Yoruba sọrọ salaye pe, o ṣeeṣe ki ẹgbẹ agbaagba ilẹ Yoruba tẹle Atiku nitori oun fara mọ atunto Naijiria, ti ẹgbẹ naa ti n sọ fun igba pipẹ.
Oòrùn ati ojú ọ̀run bá ṣókùnkùn nítorí èéfín tí ó jáde láti inú kànga náà.
Olówó náà wá sọ pé, ‘Baba, bí ó bá rí bẹ́ẹ̀, mo bẹ̀ ọ́, rán Lasaru lọ sí ilé baba mi.
 Àwọn ìlú naa ni aáwẹ ́ , kòjòkú agéníge , aràn , fìdítì , abẹnà , akínmọ ̀ ọ ́ rìn , Ìlọràá àti Ìròkò .
Arabinrin ọmọ ọgun ọdun naa, Ada Ifeanyi, si ku loju ẹsẹ ti ibọn ọlọpaa báa.
Ta ló tó ya ẹnu rẹ̀?
Odunlade Adekola, Femi Adebayo, Jenifa ṣi aṣọ lójú àwọn fíìmù tuntun tẹ́ẹ ti ń retí Ìdí ti mo fi da sọ́ọ̀sì rú lásìkò ìgbéyàwó ìyáwó mi tó ló fẹ́ ọkọ míran- Osadebe Amọ oniruuru awọn ọkunrin lo ti jade sita lati kede ifẹ ti wọn ni si Hanan, ni kete ti wọn gbọ pe o fẹ se igbeyawo,to si wu wọn lati fi se aya wọn.
Oríṣun àwòrán, Yinka Ayefele Bi o tilẹ jẹ pe ẹnu kun Abiola Ajimobi lasiko to wa nijọba, sibẹ ọpọ aseyọri lo se lori aleefa, eyi to jẹ manigbagbe.
Alagba Lamidi ni aisi owo ti fọ oju ọpọlọpọ oju awọn eeyan ni ẹsẹ pupu.
Wọ́n fi yé wa pé ó yára dé lọ́dúnìí.
Oríṣun àwòrán, khafibbn_officialfanpage O tẹ siwaju pe, ọkan oun fa si Khafi, ti oun si nifẹ rẹ nitori pe Khafi jẹ ẹni ti kii dibọn, ti kii si hu iwa oniwa.
Amọ sa, o wa mọriri awsn ololufẹ rẹ ọhun fun ifẹ ti wọn ni si ati ireti ohun rere ti wọn fẹ nipa rẹ, sugbọn o wa rawọ ẹbẹ si wọn pe ki wọn jọwọ fi oun lọrun silẹ lati gbe igbe aye to wu oun.
Ko din ni ibudo ọmọ ogun ilẹ Amẹrika meji ti ado oloro lati orilẹ-ede Iran kọlu bayii.
Aya aare orile ede Naijiria Aisha Buhari ni o kọkọ  tewo  gba arabinrin Barrow nigba ti o de si  ile-aare orile ede Naijiria.
Leyin eto agunbaniro, asofin Ayo da-Silva  darapo mo egbe oselu ”Unity Party of Nigeria”  UPN,  ni ojo kejila lodun 1993, lakoko ti oloogbe  MkO Abiola jade gege bi oludije aare ninu egbe oselu SDP.
Nígbà tí a jẹ́ ọmọde, a jẹ́ ẹrú àwọn oríṣìíríṣìí ẹ̀mí tí a kò fojú rí.
“Edomu náà wà níbẹ̀ pẹlu àwọn ọba ati àwọn ìjòyè rẹ̀.
''Emi ati ọrẹ mii ribi tu okun nigba ti wọn sun lọ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Mr Macaroni sọ nípa eré tí Freaky Freaky, Sugar Daddy, You are doing well, Freaky Spicy fẹ́ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Mr Macaroni sọ nípa eré tí Freaky Freaky, Sugar Daddy, You are doing well, Freaky Spicy fẹ́ 15 Ògún 2020 Mo jẹ oniwaasu lori ọrọ ifẹ lọjọkọjọ- Mr Macaroni BBC Yoruba gbalejo alawada adẹrinpoṣonu ni Mr Macaroni Oun naa ni Freaky Freaky, ti wọn tun n pe ni Sugar Daddy, Freaky Spicy, ati You are doing well.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Yoruba gbayì!
lori , nipa eto oro aje , ni eyi ti ayipada rere yoo de  ba eto ise agbe, ohun alumọọni ati epo rọbi.
Bi ọmọ naa ṣe jabọ, mi o ti ẹ wo boya ọkunrin ni, tabi obinrin."
Wọ́n kan àwọn ọkọ̀ náà ní Esiongeberi.
Ìgbájú ìgbámú ni Senegal fi lé Nàìjíríà kùrò ní ìdíje ife àgbáyé FIFA U-20 Liverpool da ata gúngún sójú Tottenham gba ife ẹ̀yẹ Champions League Beckham, àgbábọ́ọ́lù tẹ́lẹ̀ rèé tó ń sọ èdè Yorùbá Mi ò ní gbà!
Ilé Aṣòfin Àgbà fòǹtẹ̀ lu N30,000 owó oṣù òṣìṣẹ́ N13.
Ajọ naa ṣe agbeyẹwo ọgọta ilu lagbaye pẹlu lilo odiwọn ti wọn pe ni Safe Cities Index lori ọrọ eto aabo, ilera ati ohun amayedẹrun.
awọn abule  Tumbuma, Chikun Gudu ati
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ekiti Election: INEC gbé èsì ìdìbò Ekiti síta lẹ́kùnrẹ́rẹ́ 14 Agẹmo 2018 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 15 Agẹmo 2018 Oríṣun àwòrán, @INEC Àkọlé àwòrán, Abajade èsì idibo Ekiti gangan niyi Èyí ni àbájáde èsì ìdìbò Ekiti láti ọ̀dọ̀ INEC gangan.
Ṣugbọn nípa ọ̀pọ̀ ìfẹ́ rẹ tí kì í yẹ̀,èmi óo wọ inú ilé rẹ;n óo fi tọ̀wọ̀tọ̀wọ̀ wólẹ̀, n óo sì kọjúsí tẹmpili mímọ́ rẹ.
Òun ni ojú kò fi ní tì mí,nítorí pé òfin rẹ ni mò ń tẹ̀lé.
Awọn isẹlẹ meje ti ko ba ti sọ Naijiria sinu ogun abẹle: Iwọde EndSARS: Ọpọ ọmọ Naijiria, paapaa awọn ọdọ ni ko le gbagbe iwọde EndSARS yii, eyi to ku diẹ ko sọ Naijria sinu ogun abẹle miran.
Lẹ́yìn ti abenugan ile ìgbìmọ aṣofin Bamidel Oloyelogun síde ọ̀rọ̀ ní gbogbo ọmọ ẹgbẹ́ fẹnukò pé àwón ò lè lo àbá tuntun yìí nítori pé kò sí ìwé ofin tí o ṣe àtilẹ́yìn fún irú àṣà tuntun yìí Tayo Alasọadura tó jẹ́ ọmọ ilé ìgbìmọ aṣofin àgbà fún ẹkùn gbùngbùn Ondo tó darí ìpàdé náà sàlàyé pé bótilẹ̀ jẹ pé o wà nínú ìwé òfin lati lo èyí tó bá wù wọn nínú méjèèjì síbẹ̀ àwọn o lé lòó nítori ọ̀rs ààbo à ti pé lílo ìdìbò ojú àwo lawo fí n gbọbẹ̀ yóò dá rògbòdìyàn silẹ̀ láàrín ẹgbẹ Ondo; 1000 si 2000 naira lowo ori ilẹ fun mẹkunu Oríṣun àwòrán, Rotimi Akeredolu/Facebook Àkọlé àwòrán, Ipinlẹ Ondo fẹ bẹrẹ si gba owo ile ati ilẹ Igbese ipinlẹ Ondo lati bẹrẹ si ni gba owo ori ilẹ lọwọ awọn ara ilu ni ko ba awọn ara ilu lara mu, ti wọn si fero wọn han lori ọna abayọ si owo ori lawujọ.
“Nítorí ẹ wí pé, ‘OLUWA ti gbé àwọn wolii dìde fun wa ní Babiloni.
6 Òkùdu 2019 Ogidi ọmọ Yoruba gbọdọ mọ nipa oriṣi orukọ tí iran Yoruba maa n sọ ọmọ wọn.
"Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Lockdown the world: Awọn ọmọ Nàìjíríà káàkiri àgbáyé sọ ìrírí lábẹ́ àṣẹ kónílé-ó-gbélé O ni: ""mo máa ń rí àwọn ọmọ mi bíi osere akẹẹgbẹ mi lásìkò tí a bá ń ṣíṣẹ sinima lọ́wọ́, gbogbo ohun tí wọn ba si ṣe fún mi lásìkò náà, kii dùn mi rárá."
Bákan náà ló fi kún un pé, ìdáhùn ọkan lára amúgbálẹ́gbẹ̀ẹ́ K1 to bá BBC Yoruba sọ̀rọ̀ tó sí ló àwọn ọ̀rọ̀ kan, ẹgbẹ náà ni láti mọ̀ bóya òun gan ló fún un láṣẹ lati sọ̀rọ̀.
Amọṣa gẹgẹ bi awọn to n ṣagbatẹeru eto agbelewo BBNaija ṣe sọ, eto ti ọdun yii yoo wa ni ibamu pẹlu gbogbo ilakalẹ ti ijọba ba gbe kalẹ lori gbigbogun ti arun coronavirus eleyi to ti da họwuhọwu silẹ lagbaye.
 Bakan naa ni adin-agbon dara fun ise opolo.
Wo ohun tó yẹ kí o mọ̀ nípa àwọn obìnrin méje ti Buhari fẹ́ yàn sípò minista Kíni àwọn ọ̀dọ́ Naijiria ń fẹ́ lọ́wọ́ àwọn mínísta tuntun?
“Ǹjẹ́ o ṣe akiyesi bí Ahabu ti rẹ ara rẹ̀ sílẹ̀ níwájú mi?
Ẹẹdẹgbẹta Naira ni obinrin naa maa n gba lasiko naa lọwọ onibara kọọkan to ba fẹ lo Samuel.
"Tori naa mo ṣe kọ akọle sara igi pe, maalu to ba kọja aye rẹ o, aa sọ ọ di suya""."
Nígbà tí Maria ìyá rẹ̀ wà ní iyawo àfẹ́sọ́nà Josẹfu, kí wọn tó ṣe igbeyawo, a rí i pé Maria ti lóyún láti ọ̀dọ̀ Ẹ̀mí Mímọ́.
A gbẹ́sẹ̀ lé ilé kan tó jẹ́ ti Bukola Saraki, torí àpò ìjọba ló ti mú owó sanwó ilẹ̀ - Ilé aṣòfin Saraki: Ìwà àrékérekè ni ilé mi tí EFCC tì pa Bukola Saraki fi 'Gbas Gbos' ọ̀rọ̀ ránṣẹ́ lórí 'ilẹ̀ bàbá rẹ̀' tí ìjọba Kwara gbà padà Fulani kò leè dúró, táa bá lo ohun ta jogún lọ́dọ̀ àwọn bàbá wa - Sunday Igboho Atẹjade kan ti olori ajọ to n ri si ọrọ ilẹ nipinlẹ Kwara, Ibrahim Salman fi sita ṣalaye pe ijọba ti ra ilẹ ti ile ọhun wa lori rẹ lati ọpọlọpọ ọdun sẹyin lati kọ olu ile iṣẹ ijọba si ori rẹ.
Premier League: Liverpool fẹ́ gbafe yìí ṣá!
Sugbọn ṣa, o ni ijọba ti ṣi wọn pada.
Nígbà tí ó dé, Jesu bi í pé, 
Oríṣun àwòrán, STEFAN HEUNIS Àkọlé àwòrán, Àyájọ́ ọjọ́ àwọn èwe lónìí Lọ́dún tó kọja, ààrẹ́ Muhammadu Buhari ní a gbúdọ̀ ríi dájú wí pé àbò wa fún àwọn èwe Nàìjíríà.
won yoo gba pelu orile-ede Seychelles.
Ile Igbimọ Asọfin Ipinlẹ Eko yoo ṣatunṣe si ofin to jẹ mọ ilana agbeyẹwo
Jamb ni kawọn akẹkọ duro de esi idanwo wọn
Lẹ́yìn náà, pe gbogbo àwọn ọmọ Israẹli jọ, kí àwọn ọmọ Lefi sì dúró ní ẹnu ọ̀nà Àgọ́ Àjọ.
“Nígbà tí ó bá jókòó lórí ìtẹ́ ìjọba rẹ̀, kí ó gba ìwé òfin yìí lọ́wọ́ àwọn alufaa ọmọ Lefi, kí ó dà á kọ sinu ìwé kan fún ara rẹ̀.
 Awon miiran tun ni eto naa din
N óo jẹ àwọn wolii tí wọn ń ríran èké níyà ati àwọn tí wọn ń woṣẹ́ irọ́.
Ní ọjọ́ kẹsan-an ni Abidani ọmọ Gideoni, olórí àwọn ẹ̀yà Bẹnjamini mú ọrẹ tirẹ̀ wá.
Atamátàsé ilẹ̀ Belgium náà ló gbá bọ́ọ̀lù sí Pedro tó jẹ bọ́ọ̀lù àkọ́kọ́ fún Chelsea ní ìṣẹ́jú mẹ́tàdínlógún sí ìgba tí wọ́n bẹ̀rẹ eré.
Oríṣun àwòrán, Others Àkọlé àwòrán, Hushpuppi ati Davido nibi igbeyawo ẹgbọn Davido, Adewale, nibẹrẹ ọdun 2020 Lasisi Elenu: Gbajugbaja adẹẹrinpoṣonu ori ayelujara, Lasisi Elenu, naa jẹ ọkan lara awọn gbajumọ to ti ni ibaṣepọ pẹlu Hushpuppi.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Oúnjẹ alẹ́ ni wọ́n ń fi Ọ̀ọ̀nì ṣe níbí Ìlú Ibadan àti ìjàyè tí Ààrẹ Ọ̀nà Kakanfo ń gbé si ni Aláàfin Atiba gbara le julọ, ti àwọn olórí ìlú méjèèjì náà sì jẹ òye ologun, Aṣáájú Ibadan nígbà náà, Ibikunle jẹ́ Balogun, tí Kurunmi sì ti jẹ́ Ààrẹ Ọ̀nà Kakanfo.
16 usd fún ìwọ ̀ n egbògi náà kanṣoṣo ní ọdún 2014 .
Bo jẹ kaadi idibo tabi iwe irina to fi mọ iwe aṣẹ iwakọ,NIN ti ajọ NIMC n fun eeyan ti wọn ba ti gba orukọ rẹ ati awọn nnkan idanimọ miran silẹ lo ṣe pataki julọ.
Ṣugbọn awọn ẹsun ti ijọba fi kan an lorilẹede India lara eyi ti wọn ni o ti n gbero lati ri agbẹjọro rẹ, yoo jẹ ki ijọba ṣe agbyẹwo iroyin tawọn ọtẹlẹmuyẹ mu bọ lati India ki ijọba to gbe igbesẹ miiran.
Ọ̀rọ̀ àsọkẹ́yìn Diego Maradona ìlúmọọká agbábọ́ọ̀lù rèé kó tó dágbére f'áyé Ohun mẹta ti ẹda kan ko mọ laye ti a wa yii ni pe ko si ẹni to mọ iru iku ti yoo pa a.
Wọn ti wa sun igbẹjọ si ọjọ kejidinlogun, oṣu Kejila, ọdun 2018.
Nítorí pé àwọn ọ̀tá ti tẹ̀ wá mọ́lẹ̀;àyà wa sì lẹ̀ mọ́lẹ̀ típẹ́típẹ́.
Pàṣẹ fún àwọn alufaa tí wọ́n gbé Àpótí Majẹmu náà pé, ‘Nígbà tí ẹ bá dé etí odò Jọdani, ẹ wọ inú odò lọ, kí ẹ sì dúró níbẹ̀.
OLUWA, fi ìjánu sí mi ní ẹnu,sì ṣe aṣọ́nà ètè mi.
” Nítorí náà, mo da ọgbọ̀n owó fadaka tí wọ́n san fún mi, sinu ilé ìṣúra ní ilé OLUWA.
Ó wọn gbọ̀ngàn ti inú, òòró rẹ̀ jẹ́ ọgọrun-un (100) igbọnwọ, ìbú rẹ̀ sì jẹ́ ọgọrun-un (100) igbọnwọ (mita 45), igun rẹ̀ mẹrẹẹrin dọ́gba, pẹpẹ sì wà níwájú tẹmpili.
RCCG Alufa Adeboye ti ijọ Redeemed Christian Church of God ko fi gbogbo ẹnu sọrọ tan lori asọtẹlẹ rẹ fun ọdun 2019.
iyaafin Aisha Buhari ti ro awon omo egbe All Progressives Congress, APC lorile
Lẹyin to darukọ ara rẹ nigba to dide, ọrọ akọkọ to jade lẹnu Bayọ Oṣinọwọ ni pe,: ' Oni kii ṣe ọjọ ẹkun gẹgẹ bi awọn eeyan kan ṣe n sọ, bikoṣe ọjọ ọpẹ nitori Ọlọrun ko ba ẹnikẹni da majẹmu lori akoko ti yoo jade laye nigba to da koowa.
Awọn agbofinro mu u pe o jale ni ṣọọbu kan ni agbegbe naa.
Aṣọ gbajugbaja Nọmba 7 tawọn agbaọjẹ agbabọọlu to ti ṣoju Man United tẹlẹ ri ni Cavani yoo maa wọ.
Nígbà tí Jesu rí i, ó pè é, ó sọ fún un pé, “Obinrin yìí, a wò ọ́ sàn kúrò ninu àìlera rẹ.
Ẹbun ti wọn pin nibi igbeyawo: Oríṣun àwòrán, MojiDelano Ohun to tun jẹ ara meeriri ta gbọ nipa igbeyawo naa ni bi awakọ kabukabu kan, ti orukọ rẹ n jẹ Austin to gbe alejo lọ sibi ayẹyẹ naa, se jẹ ọkọ ayọkẹlẹ Lexus kan ti wọn fi dije nibẹ.
ìyàwó kú sínú kàngà nígbeyàwó kú ọ̀la 'IBB tẹ ń pariwo pé ó kú, kò kú o, Ko ko ko lara ọta ń le!
Keyamo wa rọ àwọn Nàìjíríà láti mase fi ẹ̀tẹ̀ sílẹ̀, kí wọ́n maa pa làpálàpá kiri.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù INEC Amina Zakari: Mi ò tan mọ́ ààrẹ Buhari rárá o!
Ara mi rẹwà ló jẹ́ kí n máa ṣí ara sílẹ̀- Victoria Kolawole Ọ̀rẹ́bìnrin míì dáná sí ọ̀rẹ́kùnrin rẹ̀ lára lẹ́yìn tó kọ̀ láti fẹ́ ẹ gẹ́gẹ́ bí aya Èyí ni ìtàn Ọkùnrin tó rí ẹ̀wọ̀n he nítorí àkùkọ aládúgbò rẹ̀ tó pa Wo ìgbà tí Ààrẹ Buhari yóò ṣí 'bọ́dà' padà Igbimọ oluwadii Foster-Sutton Tribunal kẹfin pe Ọmọwe Azikiwe ko ja okun to so oun ati banki naa pọ lẹyin to jẹ olooyu ijoba ẹkun ila oorun Naijiria.
Ronaldo kùnà lati gba ayo tirẹ wọ awọn ninu wòmí-n-gba-sí-ọ to waye lọjọ naa.
Wọn yóo sì gba ọgọrun-un ìwọ̀n ṣekeli fadaka lọ́wọ́ rẹ̀ fún baba ọmọbinrin náà bíi owó ìtanràn; nítorí pé ó ti bá ọ̀kan ninu àwọn ọmọbinrin Israẹli lórúkọ jẹ́.
Progressives Congress (APC)ti jawe olubori ni ipinlẹ Eko ninu eyi ti ondije
O sọ pe ibanujẹ nla ni lati ri bi baalu ṣe ja ti ọpọ ẹmi si ṣofo.
Oríṣìíríṣìí eniyan ni Ọlọrun yàn ninu ìjọ: àwọn kinni ni àwọn aposteli, àwọn keji, àwọn wolii; àwọn kẹta, àwọn olùkọ́ni; lẹ́yìn náà, àwọn oníṣẹ́ ìyanu, kí ó tó wá kan àwọn tí wọ́n ní ẹ̀bùn láti ṣe ìwòsàn tabi àwọn tí ń ṣe ìrànlọ́wọ́ fún àwọn ẹlòmíràn, tabi àwọn tí wọ́n ní ẹ̀bùn láti darí ètò iṣẹ́ ìjọ, ati àwọn tí wọ́n ní ẹ̀bùn láti sọ èdè àjèjì.
OLUWA bá sọ fún mi pé, “Ìwọ ọmọ eniyan, sọ àsọtẹ́lẹ̀ fún èémí, sọ fún un pé OLUWA Ọlọrun ní: ‘Wá, ìwọ èémí láti orígun mẹrẹẹrin ilẹ̀ ayé, kí o fẹ́ sinu àwọn òkú wọnyi, kí wọ́n di alààyè.
Kò ṣeé ṣàpèjúwèé dáadáa láìfojúrí fúnra ẹni.
Ẹni kẹta ni gbajumọ Bisọọbu David Ibiyeomie, to ni ọmọ Oyedepo ni oun ninu isẹ Oluwa.
Aarẹ Buhari seleri fun awọn iya ati baba awọn ọmọ Chibok naa wi pe oun yoo ri daju wi pe awọn ọmọ Chibok yoo pada wale lalaafia.
" Gomina Watawalle, to ti fẹrẹ wọ ilu Gusau lasiko naa pada sibi isẹlẹ ọhun, to si lo ọpọ wakati lati ko awọn oku lọ sinu ilu fun sinsin.
Somori ni ijọba ti kesi banki apapọ(CBN) lati ri wi pe wọn ran awọn lọwọ lati la awọn ọna ti omi nla kọja.
Ìdí rẹ̀ ni pé, ẹ fi ilé mi sílẹ̀ ní òkítì àlàpà, olukuluku sì múra sí kíkọ́ ilé tirẹ̀.
 jìjì kò sì hùwà àfojúdi kan rí .
Apapọ awọn to ti ni arun naa kaaakiri orilẹ-ede Naijiria ti wa di 15,181 bayii.
OLUWA bá sọ fún Mose pé, “Mú gbogbo àwọn olórí Israẹli, kí o so wọ́n kọ́ sórí igi ninu oòrùn títí tí wọn óo fi kú níwájú OLUWA.
Ṣugbọn àwọn ohun tí ó ń jáde láti inú eniyan ni ó ń sọ ọ́ di aláìmọ́.
Ile ejo naa ti fi ofin dee pe ko gbodo lowo ninu eto idibo odun to n bọ, ni eyi ti o je pe yoo je alatako gidi fun aare Macky Sall.
Sibẹsibẹ n óo dá ẹẹdẹgbaarin (7,000) eniyan sí, ní ilẹ̀ Israẹli: àwọn tí wọ́n jẹ́ olóòótọ́ sí mi, tí wọn kò tíì kúnlẹ̀ fún oriṣa Baali, tabi kí wọ́n fi ẹnu wọn kò ó lẹ́nu.
OLUWA Ọlọrun ti fi ọ̀rọ̀ ìmọ̀ sí mi lẹ́nu.
Àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ sọ fún un pé, “Oluwa, bí ó bá sùn, yóo tún jí.
Ó bá ní kí àwọn arakunrin òun máa lọ, bí wọ́n sì ti fẹ́ máa lọ, ó kìlọ̀ fún wọn pé kí wọ́n má bá ara wọn jà lọ́nà.
A gbúròó rẹ̀ ní Efurata,a rí i ní oko Jearimu.
awon   odaran, ole, agbesunmomi, ikọ ọlọtẹ , ni eyi
Orile ede Naijiria ati Benin ti fenuko lati da igbimo kan sile ti yoo maa gbokun ti iwa fayawọ ni awọn enu bode wọn.
Àwọn agbofinro ti dé si ipinlẹ Ọṣun pẹlu àwọn ohun eelo ti wọn nilo lati pese eto aabo fawọn eniyan ipinlẹ Ọṣun lasiko idibo.
Mo gba ìjọba lọ́wọ́ ìdílé Dafidi, mo sì fún ọ, o kò ṣe bíi Dafidi, iranṣẹ mi, tí ó pa òfin mi mọ́, tí ó sìn mí tọkàntọkàn, tí ó sì ṣe kìkì ohun tí ó dára lójú mi.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Snake bite: Ejò sàn adájọ South Africa tó lọ gbàfẹ ni Zambia pá 21 Èbibi 2019 Oríṣun àwòrán, SPL Àkọlé àwòrán, Aworan ejo irufẹ eleyi to pa adajọ naa Adajọ ile ẹjọ ọrọ oṣiṣẹ kan lorileede South Africa Anton Steenkamp ti ko agbako iku lẹyin ti ejo kan san an jẹ lasiko to lọ gbafẹ lorileede Zambia.
Ni bayii awọn obi awọn ọmọ bi ọgọrun ti wọn sọnu ni ile-iwe abule Dapchi ti n sunkun nigba ti awọn alaṣe n sọ awọn ọrọ ti wọn tako arawọn nipa ipọ ti awọn akẹkọbirin naa wa.
‘Seeing is Believing’ (SIB) ti i se ile ise to n ri si ekunrere itoju oju, se
Àkọlé àwòrán, Awọn oṣiṣẹ pajawiri gbiyanju pupọ lati doola ẹmi awọn ti ile naa wo lu Ogbẹni Idris dupe fun awọn ọlọdani ati ara ilu fun iranlọwọ ti wn ṣe fun awn to farapa.
Sheffield faṣọ iyì ya mọ́ Chelsea lára lọ́nà ìrìnàjò sí Champions League Akanbi mi, má fọ̀ ọ́, mo wà pẹ̀lú ẹ; Ẹni tó ṣe ìgbéyàwó olórùka ló l'ọkọ- Lizzy Anjorin Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Ẹ̀kọ́ pọ̀ fún ọ̀dọ́ ayé òde òní lati kọ́ lára ìgbésí ayé olóògbé Adébáyọ̀ Fálétí.
Super Falcons fẹyin South Korea gba lẹ pẹlu ami ayo meji sodo.
Ọjọ Aje ni Gomina Amosun fọwọ idaniloju sọya bẹẹ, to si tun se adura aseyọri fun oludije naa.
Ifọrọwerọ itagbangba fawọn to n dupo oṣelu ni Naijiria Fun igba akọkọ, BBC News Yoruba ṣagbekalẹ ifojurinju laarin awọn oludije ipo oṣelu ati araalu ni ipinlẹ Oṣun ṣaaju idibo gomina nipinlẹ naa.
A wọlé a fi ìkàlẹ̀ lé e.
O kò gbọdọ̀ gba èlé lọ́wọ́ rẹ̀, ṣugbọn bẹ̀rù Ọlọrun rẹ, kí o sì jẹ́ kí arakunrin rẹ máa bá ọ gbé.
Ẹ ya ara yín sí mímọ́ patapata pẹlu ìbẹ̀rù Ọlọrun.
OLUWA tí ó dá ayé, tí ó sì fìdí rẹ̀ múlẹ̀, tí orúkọ rẹ̀ ń jẹ́ OLUWA, ni ó sọ pé: 
Ẹ̀yin ti di mímọ́ nítorí ọ̀rọ̀ tí mo ti sọ fun yín.
 Ìmọ ̀ tuntun sì ló jẹ ́ lágbooloé ẹ ̀ kọ ́ nípa iṣẹ ́ ọnà .
Awon olopaa fi sori ero ayelujara pe won se ise akanse yii ni Berlin, Bremen, North Rhine-Westphalia ati Saxony nibiti won ti mu opolopo afurasi satimole.
O sì fi èmi iranṣẹ rẹ sí ààrin àwọn eniyan tí o ti yàn fún ara rẹ, àwọn tí wọ́n pọ̀, tóbẹ́ẹ̀ tí wọn kò lóǹkà.
,Mo fẹ fi da yin loju pe ati ẹni gbe epo laja ati ẹni gbaa, awọn mejeeji ni yoo foju wina ofin.
- Madam Saje Lizzy Anjorin: Mi ò bẹ Toyin o!
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Wọn ra iṣẹ ona Tutu ni miliọnu pọun kan ni London 1 Ẹrẹ̀nà 2018 Oríṣun àwòrán, Bonhams Àkọlé àwòrán, O le ni ogoji ọdun ti wọn fi wa ise ona ''Tutu'' ti Ben Enwonu ya.
O jẹ ohun ti ọpọ awọn ololufẹ rẹ ko ni fẹ gbọ seti ṣugbọn gbajugbaja olorin ọmọ iha Ariwa Naijiria naa, Nazir Ahmed ti ọpọlọpọ mọ si Sarkin Waka ti lo wakati mẹrinlelogun bayii ni ọgba ẹwọn Kurmawa ni ipinlẹ Kano.
Ogbeni Okechukwu ko faramo igbese ile igbimo asofin pe ki won kede esi ibo naa ati pe “ikede aare ti  dipo esi ibo to waye ni odun márùndínlọ́gbọ̀n seyin.
”Minisita wa gbosuba fun  akowe agba  ana, Bamgbose,  fun ise ribi-ribi ti o  se lati mu idagbasoke ba ajo naa.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Gbade Ojo Wọn ni kete ti igbimọ yii ti fẹnuko lori odiwọn iye naa ni wọn yoo gbe àbá naa ranṣẹ sawọn aṣojuṣofin lọla ki o le jẹ itẹwọgba.
Kò ní bọ́ kúrò ninu òkùnkùn,iná yóo jó àwọn ẹ̀ka rẹ̀,afẹ́fẹ́ yóo sì fẹ́ àwọn ìtànná rẹ̀ dànù.
- Ààrẹ Akufo-Addo Gbajabiamila balẹ̀ sí Ghana láti pẹ̀tù sááwọ̀ láàrin Nàìjíríà àti Ghana Òtítọ́ ọ̀rọ̀ rè é lórí ilẹ̀ tó fa awuyewuye láàrin Ghana àti Nàìjíríà Ohun tó yẹ kí o mọ̀ nípa ìgbésẹ̀ tí Amẹ́ríkà fẹ́ gbé lórí Nàìjíríà nítorí ọ̀rọ̀ ẹ̀sìn Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Borno Zabamari Massare: Àjọ NCC fẹ́ tú ìwé owó àwọn olúpèsè ìtàkùn ìbánisọ̀rọ̀ wo10 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Andrew Haruna: So-bàtà tó di ọ̀jọ̀gbọ́n fásitì tó di ọ̀gá àgbà9 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Ooni Ile Ife: Ooni Adeyeye Ogunwusi àti Olòrì Naomi gbé Àrẹ̀mọ tuntun wọ ààfin Ilé Oòduà9 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Ṣugbọn Ọlọrun wà pẹlu àwọn olórí Juu, wọn kò sì lè dá wọn dúró títí tí wọn fi kọ̀wé sí Dariusi ọba, tí wọ́n sì rí èsì ìwé náà gbà.
Buhari, pe ìpàdé àpérò ọmọ Nàíjíríà fún àgbékalẹ̀ òfin tuntun - Afe Babalola UK fẹ́ so ìjókòó ilé rọ̀, kíni èyí túmọ̀ sí?
Amọṣa, pẹlu adinku to de ba ijinigbe ni ọdun 2016, o tun ti gbe ẹnu soke bayii paapaa pẹlu iṣẹlẹ ọọdunrun o le mẹwa to waye ni ọdun to kọja.
” Bamgbose naa wa so pe ,inu oun dun lati je akowe agba fun ajo naa, ati pe gbogbo ipinnu oun ,ni oun mu sẹ fun ajo naa lasiko to wa lori ipo naa.
A ní pẹpẹ ìrúbọ kan tí àwọn alufaa tí wọn ń sìn ninu àgọ́ ti ayé kò ní àṣẹ láti jẹ ninu ẹbọ rẹ̀.
Ẹ óo kú ninu aṣálẹ̀ yìí; gbogbo yín; ohun tí ó ṣẹ̀ láti ẹni ogún ọdún lọ sókè, gbogbo ẹ̀yin tí ẹ kùn sí mi.
Àwọn obinrin meji yóo máa lọ ọkà ninu ilé ìlọkà.
El-Zakzaky ti lọ sí India fún ìwòsàn - Femi Falana Jẹjẹrẹ ní ìwà akakítí ẹ̀sìn, ẹ yàgà fún ẹ̀kọ́ òdì -Ààrẹ Buhari Àṣìta ìbọn ló pa obìnrin nílùú Eko lọ́jọ́ Satide- Ọlọ́pàá Ni ọjọ kẹta yii ni awọn tọkunrin-tobinrin, ọmọde ati agba nilẹ yii ati lati oke okun yoo pe biba si gbagede kan lati se ọdun naa nilu Ijẹbu-Ode.
Nígbà tí àwọn alufaa bá wọ ibi mímọ́, wọn kò gbọdọ̀ jáde sí gbọ̀ngàn ìta láìbọ́ aṣọ tí wọ́n lò sinu yàrá wọnyi, nítorí pé aṣọ mímọ́ ni wọ́n.
Amofin kan ni UK, Bradley Rice, sọ pe lọwọ lọwọ, ko si ofin tabi ilana to de okoowo Bitcoin.
Ṣùgbọ́n tí ẹ bá fojú inú wòó, gẹ́gẹ́ bí mo ṣe ṣe ní alẹ́ ọjọ́ kan, ẹ ó ríi pé orúkọ yìí kù díẹ̀ káà tó!
N óo fọ́n àwọn ará Ijipti ká sáàrin àwọn orílẹ̀-èdè mìíràn, n óo sì tú wọn káàkiri gbogbo ilẹ̀ ayé.
“Nítorí pé ẹ̀ ń fi àrékérekè ba àwọn olódodo lọ́kàn jẹ́, nígbà tí n kò fẹ́ bà wọ́n lọ́kàn jẹ́; ẹ sì ń ṣe onígbọ̀wọ́ àwọn eniyan burúkú kí wọn má baà yipada lọ́nà ibi wọn, kí wọn sì rí ìgbàlà.
Pasitọ naa ṣalaye pe Ẹ jẹ ki n bẹrẹ pẹlu iriri temi tikalara mi lọwọ awọn oṣiṣẹ SARS, ninu ọdun to kọja ni iyawo mi pe mi pe awọn ọlọpaa ti mu oun, oun si ti wa ni agọ wọn."
Aramọnda isẹ Olodumare miran lo tun kalẹ silu Ọwa Kajọla nijọba ibilẹ Ifẹlodun nipinlẹ Kwara nibiti omi isẹda kan ti n da lati ori oke wa si isalẹ.
Yọ́ gbogbo ìdọ̀tí tí ó wà lára fadaka kúrò,alágbẹ̀dẹ yóo sì rí fadaka fi ṣe ohun èlò.
Àwọn adarí lágbàyé ṣèpàdé láti ṣèrànwọ́ fún Lebanon lẹ́yìn ìbúgbàmù tó pa ènìyàn 158 Afárá Third mainland gba ẹ̀gbọ́n Bakan naa ni Modi ba awọn to padanu eniyan wọn kẹdun, to si gbadura iwosan pipe fun awọn ti wọn wa ni ileewosan lọwọ nitori iṣẹlẹ naa.
Kenya: Ilu yii ni oriko awọn eranko nla nla, Safari ati awọn ibi itan.
Wọ́n ní, “Kí ni ìdí irú òfò báyìí?
ó di arúgbó kùjọ́kùjọ́, kí ó tó kú.
Ibi ti wọn yoo ti ṣide ipade itagbangba ti ọdun 2019 ni ipinlẹ̀ Kwara eyi ti yoo waye ni ọjọ kẹwaa, oṣu kinni ọdun 2019.
Wọ́n dẹ àwọ̀n sí ojú ọ̀nà mi;ìpọ́njú dorí mi kodò.
Ó ń bọ àwọn ìràwọ̀, ó sì ń sìn wọ́n.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Igbẹjọ Eni, Shell yoo tẹsiwaju lọjọ kẹrinla oṣu kẹta 5 Ẹrẹ̀nà 2018 Oríṣun àwòrán, AFP Àkọlé àwòrán, Eni ni awọn ko jẹbi awọn ẹsun ti wọn fi kan wọn Igbẹjọ awọn ileesẹ ipọnpo nlanla meji, Eni ati Shell to yẹ ko wa ye loni tẹlẹ ni wọn ti sun siwaju bayii.
Obinrin náà dáhùn pé ààrin àwọn eniyan òun ni òun ń gbé.
O ṣalaye ẹṣọ Amotekun ni o le wa ojutu si eto aabo to mẹhẹ nitori awọn lo mọ awọn to wa lagbugbo wọn.
Nibẹ ni wọn ti darapọ mọ awọn agba oye yoku bii Iyalode ilẹ Ibadan, Oloye Theresa Oyekanmi; Agbaakin Olubadan, Lekan Alabi atawọn Mọgaji ati Baalẹ.
Ní ibìkan náà tí a ti sọ fún wọn rí pé, ‘Ẹ kì í ṣe eniyan mi mọ́’ni a óo ti pè wọ́n níọmọ Ọlọrun alààyè.
Ninu atẹjade kan to jade nilu Abuja l'Ọjọru, eyi ti Sẹgun Adeyẹmi, to jẹ oluranlọwọ pataki fun minisita feto iroyin ati asa, Alhaji Lai Mohammed, fi sọwọ, sọọ di mimọ pe akẹkọ mọkọlelọgọrun ninu aadọfa awọn akẹkọ ti wọn ji gbe naa, ni akọsilẹ wa fun pe wọn ji gbe.
Ni ọjọ kẹsan-an, oṣu kẹwaa, ọdun 2012, awọn ọdọ to to aadoje ni Ileesẹ ọlọpaa ṣe afihan wọn pe wọn jẹ ọmọ ẹgbẹ one million boys ladugbo Apapa ati Ajegunle.
Ti a ba ka leni meji, isele iji lile ohun ti gbemi eniyan mọ́kànlélógójì, ti o si ba opolopo ohun ni awon eniyan je ti o fi mo awon ile iwosan.
Ìrìbọmi tí Johanu ń ṣe, láti ọ̀run ni ó ti gba àṣẹ ni, tabi láti ọwọ́ eniyan?
 ní ilẹ ̀ amẹ ́ ríkà iye owó rẹ ̀ jẹ ́ bíi 25 sí 50 usd fún ìwọ ̀ n egbògi náà kanṣoṣo .
Ki lo de ti ijọba fẹ na owo apapọ Naijiria sori iran kan?
Wọn ni alaboyun ko nile ko pa lasiko yii afi to ba bimọ tan.
Oríṣun àwòrán, Rotimi Akeredolu Facebook Alagba Ade Adetimehin sọ pe oun gẹgẹ bi ẹnikan ko mọ igba ti ikọlu naa waye nitori ọkọ ti oun wa ninu rẹ kọja ni Oba Akoko ti wọn ko si kọlu ẹnikankan ''Nigba ti a kọja lọ, a ri pe awọn PDP naa wa nilu Oba Akoko.
Dino fàgilè ìfilọ́lẹ̀ àti ìsìn idupẹ
A bẹrẹ bii ọrẹ, ka to bẹrẹ si fẹ ara wa.
Ni bayi, Prince ati Kiddwaya ni olukopa inu idije Big Brother Naijia ẹlẹẹkejila ati ikẹtala ti wọn yoo ni ko maa lọ sile.
Èmi náà ti hù ìwà tó burú ju àgbèrè lọ sí Abiola Ajimọbi -Florence Ajimọbi Bí àrùn Coronavirus ṣe dá gbogbo àgbáyé gúnlẹ̀ sójú kan náà nìyí Coronavirus in Nigeria: Ǹjẹ́ àwọn arúgbó nìkan ni ààrùn coronavirus ń mú?
Àwọn ọmọ yín yóo rìn káàkiri ninu aṣálẹ̀ fún ogoji ọdún, gẹ́gẹ́ bí ìjìyà ẹ̀ṣẹ̀ wọn fún aiṣododo yín, títí gbogbo yín yóo fi kú tán.
Oludije ogun lo bẹrẹ idije naa, ṣugbọn awọn marun-un, Laycon, Vee, Dorathy, Nengi, ati Neo, lo gbẹyin sori eto.
Mekong Watch ló ni àwòrán, a lò ó pẹ̀lú àṣẹ.
Idi ree ti BBC Yoruba fi se akojọpọ alaye nipa ilana owo osu tuntun ti aarẹ́ Buhari kede fawọn olukọ naa.
Willock gba bọọlu akọkọ wọ inu àwòn Frankurt ni nkan bii iṣẹju metalelọgọta ti ere naa bẹrẹ.
Kò bá àṣà wa mu kí obìnrin máa kó ọmú síta!
Wọ́n á gbìyànjú láti tún un ṣe.
Atunse yoo deba ibi ti won n gbe apoti ibo si, lati dena bi awon eniyan  se n  ri ibo ti won n di lasiko eto idibo , komisona fun ajo eleto idibo lo soro yii ni Awka ,lojo Aje.
Kí ló ṣẹlẹ̀ tí a fi ń pé ọjọ́ kejì Kérésì ní 'Boxing Day'?
Ẹ wà ninu ayé láìní ìrètí ati láìní Ọlọrun.
Aare sapejuwe re gege bii akosemose akoroyin to feran ooto laisegb fenikan ninu ise iroyin re nigab to wa laye.
Ile aṣofin naa, ti o ṣepe awọn ọmọ ẹgbẹ rẹ Republican lo pọju nibẹ, fi ibo mejilelaadọta si mejidinlaadọta ju ti ẹgbẹ Democrat lọ, ti wọn si ni ko jẹbi ẹsun pe o lo ipo ni ilokulọ.
ibowo, sise atileyin ati aanu fun eniyan ati lati mu idagbasoke ba awon abuda
 Àwọn ọba náà ni , Àgùrà olówu , Òsilẹ ̀ àti olúbarà .
Ọọni Adeyeye gbé orúkọ àrẹ̀mọ rẹ̀ jáde, ẹ kọ́ ẹ̀kọ́ nípa àwọn ǹkan tí wọ́n fi gbàdúrà f'ọ́mọ ọba
"Ṣugbọn ibo ti oludije wa daju ko si si eru ninu idibo naa"" gẹgẹ bi APC ṣe sọ ọ ninu esi wọn."
kí wọ́n sì jẹ́ ìmọ́lẹ̀ ní ojú ọ̀run láti máa tàn sórí ilẹ̀ ayé, ó sì rí bẹ́ẹ̀.
Labani tú gbogbo inú àgọ́ rẹ̀, ṣugbọn kò rí wọn.
OLUWA, gbọ́ lọ́run lọ́hùn-ún, kí o sì ṣe ìdájọ́ àwọn iranṣẹ rẹ.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Nitori naa, alaga ẹka to n risi ajakalẹ arun ni ileewosan ẹkọṣẹ ti ileewe giga fasiti eto ilera ni Naijiria, UNIMED, Dokita Ayodeji Akinbodewa naa ni oun ni igbagbọ wi pe bi awọn akẹkọọ ṣe pada si ileewe yii, ko le e ni ipa buburu lori awọn eniyan.
"Nínú ọ̀rọ̀ rẹ, Oluwo ni Olodumare lo rán òun wá sórí ìtẹ láti wá tún Orí ìtẹ Ọba ṣe to si fí àṣẹ ""Kabi ọ ò sí"" lée láti maa sọ òòtọ fún gbogbo Ọba."
lati sin orile ede Naijiria tọkan-tọkan.
Ìjọba tí Ọlọrun fún ọ wà lae ati laelae.
ÌRAN TÍ ỌLỌRUN KỌ́KỌ́ FIHAN ISIKIẸLI.
lati fagba han gomina Dankwambo, ti oun ni apapo ibo ti o le ẹ̀gbẹ̀rún méjídínláàdọ́rùn
Lẹyin naa ni awọn mejeeji da ẹgbẹ oṣelu Northern People's Congress (NPC) silẹ.
"'Ẹnikẹ́ni ò lè tì mí gbọ̀ngbọ̀n láti gbé orúkọ mínísítà jáde' Iṣẹ akanṣe ""Operation Puff Adder"" yii naa ni wọn ṣe agbekalẹ rẹ lati gbogun ti iṣoro eto aabo to wa ni opopona Kaduna si Abuja."
Igbákejì Ààrẹ Yemi Osinbajo a máa bà àwọn ọmọdé ṣeré níbikíbi tó bá tí pàdé wọ́n.
 abigail bí ọmọ àkọ ́ kọ ́ rẹ ̀ tí ó jẹ ́ ọkùnrin tí orúkọ rẹ ̀ ń jẹ ́ alexander babátúndé akínyẹlé .
lati salaye nipa oun ini mi, ni eyi ti mo gbọdọ fọwọ si lasiko saa keji ti mo fẹ
Mose ati Aaroni wà lára àwọn alufaa rẹ̀;Samuẹli pàápàá wà lára àwọn tí ń pe orúkọ rẹ̀;wọ́n ké pe OLUWA ó sì dá wọn lóhùn.
Oríṣun àwòrán, LASEMA Ọga ileeṣẹ to n mojuto iṣẹlẹ pajawiri nilu Eko, Femi Osanyintolu fidi ọrọ yi mulẹ fun BBC ti o si sọ pe awọn doola ẹmi eeyan mẹsan nibẹ.
Ọmọwe Iwuajoku tun ṣalaye siwaju sii pe awọn ro pe minisita Fashọla lo fẹ rinrinajo lawọn ṣe fun un laṣẹ.
Àwọn ọmọ Israẹli ṣẹgun gbogbo ọba àwọn ìlú wọnyi: Jẹriko ati Ai, lẹ́bàá Bẹtẹli; 
Oríṣun àwòrán, Inec Àtẹjáde tí Rose Oriaran-Anthony, tó jẹ́ akọwé àjọ tó n rí sí ètò ìdìbò ní Naijiria (INEC) buwọlù sàlàyé pé, ìdìbò abẹ́nú tó yẹ kó wáyé ní ogúnjọ́ oṣù kèje ọdún yìí, le ma ṣee ṣe nítori pé àlága apapọ ẹgbẹ́ àwọn akọ̀wé apapọ̀ ẹgbẹ́ ló yẹ kí wọ́n jọ buwọ́lùú.
àwọn wolii Israẹli tí wọn ń sọ àsọtẹ́lẹ̀ nípa Jerusalẹmu tí wọn ń ríran alaafia nípa rẹ̀, nígbà tí kò sí alaafia.
BBC ba eeyan meji lara wọn to kagbako aisan yii nigba ti wọn wa ni ọmọde sọrọ lori iriri wsn.
bẹ́ẹ̀ gan-an ni, nisinsinyii tí ẹ̀yin náà rí àánú gbà, wọ́n di aláìgbọràn, kí àwọn náà lè rí àánú Ọlọrun gbà.
Nítorí Ọlọrun kì í ṣe Ọlọrun ìdàrúdàpọ̀.
 O ni awọn oṣiṣẹ alaabo ti n gbe awọn igbesẹ kan bayii ti aabo to peye yoo fi wa fun eto idibo ọdun 2019 yii.
Ẹ gbọdọ̀ fẹ́ràn OLUWA Ọlọrun yín pẹlu gbogbo ọkàn yín, ati gbogbo ẹ̀mí yín, ati gbogbo agbára yín.
Sioni ń wí pé,“OLUWA ti kọ̀ mí sílẹ̀,Oluwa mi ti gbàgbé mi.
Àwọn ọlọ́pàá, ọdẹ asọ́lé dènà adígunjalè láti fọ́ báǹkì l'Ọsun Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Adígunjalè kùnà láti fọ́ báǹkì l'Ọsun Ọwọ́ pálábá àwọn afurasi adigunjale ti ṣegi lọ́jọ́ Ajé nígbà tí wọn gbìyànjú lati kọlu ilé ìfòwópamọ kan ní agbègbè Lagere ílùú Ilé-Ifẹ ní ìpínlẹ̀ Ọsun, nígbà táwọn ará adúgbo to ri wọn dìde láti jà.
'Kìí ṣe pé ìjánu Ọkọ̀ tó pa Tolulope Arotile já tàbí kò já, ìwádìí wà lọ́wọ́ ọlọ́pàá' Mo kábàámọ̀ ìbáṣepọ̀ èmi àti Eric nínú ilé Big Brother - Lilo Ìgbésẹ̀ wo ní aláboyún lé gbé láti dẹ́kun ìjẹkújẹ nínú oyún?
Kaakiri awọn ipinlẹ to wa ni iwọ oorun Guusu Naijiria, si ni ileeṣẹ ọlọpaa sọ pe ajọdun naa ti ma n waye.
    Ibi tí a ti jọ n sọ̀rọ̀ sì ara wa yìí ni ọkùnrin kan ti dé nígbà tí ó sì dé iwájú ẹni ti à ń bá sọ̀rọ̀ yìí, ó dọ̀bálẹ̀ ó sì kìí ‘Kábíyèsí aláṣẹ, èkejì òrìṣà’irú kíkí yìí jọ wa lójú a sì bẹ̀rẹ̀ sí í rò nínú ara wa pé bóyá ni ọkùnrin wọn ṣe máa ń ki ìránṣẹ́ ọba ni ìlú náà.
Yakubu so pe,”Ajo INEC ti se ipade pelu awon oludije egbe oselu kookan ati awon osise won gbogbo lati yanayana bi igbaradi ajo ohun se n lo saaju eto idibo naa.
Ọpọ ọmọ Naijiria ni wọn ti wa n beere pe, bi ọrọ ti ṣe ri yii, o n fẹ amojuto ati apero nitori ko sẹni fẹ mọ mọ bayii, boya Buhari ni aarẹ tabi Mamman Daura.
Oúnjẹ àdídùn ni ó máa ń jẹ, lojoojumọ ni ó máa ń se àsè.
Èmi óo máa yin OLUWA, ẹni tí ó ń fún mi ní òye;ọkàn mi ó sì máa tọ́ mi sọ́nà ní òròòru.
- Agbẹnusọ Kassim Kamaru Usman, Ọmọ Naijiria f'ẹ̀ṣẹ́ gba ìgbànú ẹ̀yẹ mọ́ Covington lọ́wọ́ ní ìdíje UFC 'À ń gbé àkàsọ̀ bọ̀ wá já iná yín ní Togo, Benin bí ẹ kò bá sanwó' Ọ̀jọ̀gbọ́n fásitì OAU pàdánù ẹ̀mí lópoópónà Benin sí Auchi.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Wo ọ̀nà to le gbà tọ́jú arúgbó rẹ lásìkò tí ọpọlọ wọn bá kù díẹ̀ lọ́jọ́ ogbó Ohun tó ti yá kan kìí pẹ́ mọ́, fọ́ọ̀mù ìgbaniṣíṣẹ́ fún Àmọ̀tẹ́kùn dé!
Lẹ́yìn Adániwáyé, Àlá ọmọ ẹ̀dá kan ò le ṣe, Bí ò sí ti tíșà lókè èèpẹ̀.
Wọ́n sì sá wọn sílẹ̀ yí ibùdó wọn ká.
Ẹ̀yin akẹ́kọ̀ọ́ fásítì, ẹ múra sílẹ̀ fún ìwọlé lẹ́yìn ìyanṣẹ́lódì oṣù méje- ASUU Tí mi ò bá fẹ́ ìyàwó mi, n ó tí di àgbégbìn- Ayodele Fayose Pásítọ̀ Sam Adeyemi, Taaooma, Falz àti gbogbo àwọn tí ilé ẹjọ́ fẹ́ rí nìyìí Àwọn oniròyìn ló tú àṣírí ààbò Prof Peller, tí wọn fi ri pa - Lady Peller Ta ni olóògbé Jerry Rawlings, tí wọ́n fún ní àlàjẹ́ 'Junior Jesus' Wo àwọn òṣèré tíátà Yorùbá mẹ́fà tó bẹ̀rẹ̀ eré ṣíṣe láti kékéré ''Ko si awọn oluṣọ ibo tabi awọn onwoye nibi eto idibo naa, ileeṣẹ ti ko lorukọ to dara, Dominion lo tun wa ṣe agbatẹru eto idibo ọhun to fi mọ ayederu ileeṣẹ iroyin,'' Trump lo sọ bẹẹ.
Sanwo Olu àti Okowa dẹwọ́ ìséde ní Eko àti Delta pẹ̀lú àlàyé tuntun Ẹ̀ gbọ́ ọ̀rọ̀ lẹ́nu Adelé Ọba Alade Idanre ló rí ohun tó ṣẹlẹ̀ láàárín òun àti Ọba Aroloye Ǹkan tí a mọ̀ nípa kọ́lẹ̀jì olùdìbò tó ń fìdì ẹni ti yóò jẹ ààrẹ ilẹ̀ Amérika múlẹ̀ Aàbò tó péye yóò wà fún àwọn tí yóò kópa nínú ìfẹsẹwọ̀nsẹ̀ Naijiria àti Sierra Leone ní Benin - Obaseki Wo iye owó tí ìjọba Amẹrika ń na sí ìdìbò Ààrẹ àti ibi tí owó náà ti ń wá Olapade Agoro ni awọn ile iwe loriṣiirisii yatọ si pe o da ẹgbẹ oṣelu National Action Council silẹ.
Awon eniyan ekun Jayapura to je olu ilu Indonesia Paupau ni ko si akosile eni to ku tabi ohun to baje ju ni ekun ti won.
Wo àfipábánilòpọ̀ ẹni ọdún 51 tí ìjọba ìpínlẹ̀ Ekiti tú làṣirí ní gbangba Ẹ fún wa lówó oṣù wa tàbí kí a gùnlé ìyanṣẹ́lódì ọlọ́jọ́ gbọọrọ- Àwọn dokita ìpínlẹ̀ Ondo Ilé aṣòfin ìpínlẹ̀ Oyo jáwée lọ sinmi nílé fún alága ìgbìmọ̀ mẹ́tàlá káàkiri ìjọba ìpínlẹ̀ Wo ǹkan tó yẹ kí o mọ̀ nípa Joe Biden, tó ń kojú Trump nínú ìbò America Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí US election results: Wo ìdí márùn-ún tí Biden fi bórí nínú ìdìbò ààrẹ America8 Bélú 2020 Ondo Accident: Kíní ọ̀nà àbáyọ sí ìjàmbá ọkọ̀ tó ń wáyé lemọ́lemọ́ ní Ọjà Akungba,ní Ondo?
Ẹ̀ ń wí pé, “Òmùgọ̀ ni wolii, aṣiwèrè sì ni ẹni tí ó wà ninu ẹ̀mí,” nítorí ẹ̀ṣẹ̀ ńlá yín, ati ìkórìíra yín tí ó pọ̀.
Aarẹ Trump sọ pe ''Mo le sọ fun yin pe arabinrin naa ati awọn Dokita miran ti wọn faramọ lilo oogun Hydroxychloroquine ni wọn jijọ sọrọ lori afẹfẹ.
Ṣugbọn Paulu ati Banaba dúró ní Antioku, wọ́n ń kọ́ àwọn eniyan, àwọn ati eniyan pupọ mìíràn ń waasu ọ̀rọ̀ Oluwa.
"Àwọn èèyàn to n fẹ̀hónú hàn dáná ṣun iléeṣẹ́ MTN n‘Ibadan ""Ọjà àìmọye mílíọ̀nù naira ni wọ́n kó nílé ìtajà mi torí ìgbẹ̀san ìkọlù South Africa"" ""Naijiria gbọdọ̀ kẹ̀yìn sí ìrẹ́pọ̀ pẹ̀lú South Africa"" Xenophobic Attack: 'Nàìjíríà ló máa forí kó kíkọlu iléeṣẹ́ South Africa jùlọ' Xenophobic Attack: Àwọn ọmọ Nàìjírìá bínú kọlu Shoprite l'Eko Àjọ Commomwealth gbọ̀dọ pé ìpáde pàjáwìrì lori ọ̀rọ̀ Brexit- Wole Soyinka Niwọn igba to si jẹ pe ina eesi kii jo ni lẹẹmeji, awọn alasẹ ileesẹ Shoprite to wa ni ibudo itaja Palm Halm ni Ribgroad naa, ti wa sọ agadagodo sẹnu ọna ibudo itaja Palm Mall lapapọ lati dena ikọlu ẹẹkeji."
Hana bá gbadura báyìí pé:“Ọkàn mi kún fún ayọ̀ ninu OLUWA,Ó sọ mí di alágbára;mò ń fi àwọn ọ̀tá mi rẹ́rìn-ín,nítorí mò ń yọ̀ pé OLUWA gbà mí là.
Osun: Ìjọba kédeìsinmi fáwọn òṣìṣẹ́ láti ṣe àjọ̀dún àyájọ́ ọdún Ìṣẹ̀ṣe
Arabìnrin Folukẹ Adeboye pe ọmọ ààdọrun ọdún lori oke eèpẹ̀ lánàá.
Mo lọ si rinajo mi, pẹlu igbagbọ pe nkan kekere ti a o le yanju ni.
A kó ní sanwó oṣú ASUU láìjẹ́ pé wọ́n gba IPPIS- Ìjọba Àpapọ̀ Diego Maradona ṣiṣẹ́ abẹ lórí ẹ̀jẹ̀ tó dì sí i lọ́pọlọ lẹ́yìn ọjọ́ ìbí ọgọ́ta ọdún A ti gbé ìwádìí dìde lórí ìpànìyàn tó wáyé lásìkò ìwọ́de EndSARS- Ilé ẹjọ́ àgbáyé, ICC Oyinkan Abayomi, akọni obìnrin tó fi ìfẹ́ pa orúkọ ọkọ kejì dà sí ti ọkọ àárọ̀ Ṣe wọn yọọ ni ẹwu idanimọ?
o se atunse si ile igbimo asoju , ni eyi ti yoo mu idagbasoke ba orile ede
Àkọlé àwòrán, Gbunkẹlẹ ni ayẹyẹ iburawọle ni ipinlẹ Kwara yoo jẹ lọla pẹlu bi ohun gbogbo se dakẹ rọrọ Àkọlé àwòrán, Awọn o sisẹ naa n gbaradi fun ọla Akojọpọ aworan naa wa lati BBC Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
"Bakan naa lo sọ pe awọn to fi ara gbọta nibi iṣẹlẹ ipaniyan to waye ni Lekki ""naa ni ẹjọ lati jẹ́""."
Yóo jẹ́ òórùn dídùn sí OLUWA.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Oyo House: Ilé ìgbìmọ̀ Ìpínlẹ̀ Oyo buwọ́lu ìyànsípò kọmíṣọ́nà mẹ́rìnlá àtàwọn míì 9 Ògún 2019 Oríṣun àwòrán, Facebook/Oyo State House of Assembly Àkọlé àwòrán, Ayẹwo fawọn kọmiṣọna tuntun ipinlé Oyo Ile igbimọ aṣofin Ipinlẹ Oyo ṣayẹwo fun awọn kọmiṣọna mẹrinla ti Gomina Ṣeyi Makinde fi orukọ wọn ranṣẹ sile, bẹẹ ni wọn si buwọ lu iyansipo gbogbogbo wọn.
“Lónìí, bí mo ti dé ìdí kànga tí ó wà lẹ́yìn ìlú, bẹ́ẹ̀ ni mo gbadura sí Ọlọrun, mo ní, ‘OLUWA Ọlọrun Abrahamu, oluwa mi, bí ó bá jẹ́ pé o ti ṣe ọ̀nà mi ní rere nítòótọ́, 
Akuna tun ro ijoba ipinle Adamawa lati bere si maa san egberun mejidinlogun ( N18,000) owo to kere julo to ye ki awon osise maa gba losoosu fun won.
Eliṣa bá bèèrè lọ́wọ́ Gehasi pé, “Kí ni mo lè ṣe fún un nígbà náà?
kí gbogbo ayé lè mọ ọ̀nà rẹ̀;kí gbogbo orílẹ̀-èdè sì mọ ìgbàlà rẹ̀.
    Lẹ́yìn tí gbogbo wa wa jẹ́wọ́ ẹ̀sẹ̀ tán báyìí ni ọkuǹrin ti o gbé àáké lọ́wọ́ ní kí a máa kọjá lórí afá odò Ẹ̀jẹ̀.
Isẹlẹ ‘dìbò kòo sebẹ̀’ náà kò gbẹ́yìn níbi ìdìbò tòní lágbègbè ile Bale nílù Òró sùgbọn ọkàn nínú èèkan ẹgbẹ́ òṣèlú APC tó bá BBC sọ̀rọ̀, Lattef Oloyin sàlàyé pé ọwọ́ àwọn agbofínro ti tẹ ènìyàn márùn báyìí lori isẹlẹ naa.
Kí olúwarẹ̀ dàbí àwọn ìlú tí OLUWA parun láìṣàánú wọn.
Nítorí èyí ni àwọn òbí ọkunrin náà ṣe sọ pé, “Kì í ṣe ọmọde, ẹ bi òun alára léèrè.
Fun idi eyi awọn eeyan maa n nilo ohun ti wn lee fi sun.
Wọ́n ní ọwọ́ eniyan lábẹ́ ìyẹ́ wọn mẹrẹẹrin, wọ́n ní ojú mẹ́rin ati ìyẹ́ mẹ́rin.
Nítorí pé ọpọlọpọ eniyan láti ilẹ̀ Israẹli ni wọ́n ti sá wá sọ́dọ̀ rẹ̀, nígbà tí wọ́n rí i pé OLUWA Ọlọrun rẹ̀ wà pẹlu rẹ̀.
soro, leyin ti o kirun Jimoh tan niluu Abuja.
Nítorí náà, ẹ ṣọ́ra, kí ẹ sì fẹ́ràn OLUWA Ọlọrun yín.
Yóo mú díẹ̀ ninu ẹ̀jẹ̀ akọ mààlúù náà, yóo fi ìka wọ́n ọn siwaju ìbòrí ìtẹ́ àánú.
Ẹnu ya gbogbo eniyan sí iṣẹ́ ńlá Ọlọrun.
 austin ) , augustine onibukun ( blessed augustine ) , tabi augustine enimimo onibukun ( st.
El-Zakzaky: Arúfin ni ijọba Muhammadu Buhari gan-an - Ladoja Ọlọ́pàá ló ń fa rúkèrúdò lásìkò ìwọ́de wa-ẹgbẹ́ Shi'ite Drone àti CCTV ni yóò máa ṣọ́ ọ̀pọ̀ igbó tó wà nílẹ̀ Yorùbá - Ooni Jesu orí ayélujára kan rèé tó wa fun isoji ni Afirika Àwa ọmọ ẹgbẹ́ Shiite kò tíì sinmi ìwọ́de, a ṣì ń tẹ̀síwájú - Ọmọ El-Zakzaky Ìyàtọ ìlànà ìgbàgbọ́ Sunni àti Shi'ite lo kun ǹkan to fa èdè àìyede to n bẹ́ sílẹ̀, tó fi mọ ìbérèrè bí tani adele Muhammed lẹ́yì to ti ku Ìwádìí fi hàn pé ni ọdún 2016 ilé ẹjọ fidi rẹ̀ múlẹ̀ pé, ọ̀ọ́dúrún ọmọlẹ́yìn El-Zakzaky ni àwọn ọmọogun orilẹ̀-èdè Nàìjíríà pa.
Ahmed bori pẹlu ibo mọkandinlọgọrin nigba ti Ali Ndume ni ibo mejidinlọgbọn.
Gomina Makinde ni oun ko fẹ ki owo isuna ọdun 2021 naa ga soke debi pe yoo nira lati gbọ bukata rẹ, eyi to le mu alekun ba gbese to wa lọrun ipinlẹ Oyo.
Awọn kẹmica ti ara n gbejade lati pe akiyesi ara wa si kokoro aifojuri yi a ma fa titobi agọ ara ju bo ti se yẹ lọ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Covid 19 vacine updates: America kan sárá si Dókítà Ogbuagbu, ọmọ Nàìjíríà tó ṣàwárí abẹ́rẹ́ àjẹsára COVID-19 àkọ́kọ́ 25 Bélú 2020 Oríṣun àwòrán, others Wo dókítà ọmọ Nàìjíríà tí àgbáyé ń wárí fún nítorí abẹ́rẹ́ àjẹsára COVID-19 Ọjọgbọn imọ nipa iṣegun oyinbo ati ajakalẹ arun ni Dokita Ogbuagu ni ile ẹkọṣẹ iṣegun oyinbo ni Fasiti Yale.
Patoranking - BBC News Yorùbá BBC News, YorùbáFò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Obinrin lo mu mi fẹran orin kikọ - Patoranking Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Obinrin lo mu mi fẹran orin kikọ - Patoranking 26 Sẹ́rẹ́ 2018 Akọrin taka-sufee, Patoraking sọ̀ wi pe ifẹ obinrin lo mu oun fẹran orin kikọ.
Ahmed ni yoo rọpo Hailemariam Desalegn, to kọwe fipo silẹ losu to kọja.
Alápatà fi ìbínú lu ìyàwó rẹ̀ pa ní Ogun
Bákan náà wọ́n yẹ àpò ìsúná rẹ̀ wò, ẹgbẹ̀rún lọ́nà ọgbọ́n Náírà péré ló kù síbẹ̀.
gbogbo ohun tí ó bá ti jẹ́ àkọ́bí ni ẹ gbọdọ̀ yà sọ́tọ̀ fún OLUWA.
Garba lo sọ ọrọ yii loju opo Facebook rẹ lọjọ ọdun Keresimesi latari bi awọn ile iroyin kan lagbaye ṣe n pe Omoyele Sowore ni akọroyin.
Alukoro awon olopaa , Edet Okon  lo soro yii ninu atejade kan ni ipinle Maiduguri, o so pe ikolu yii waye ni owuro ni deede agogo mefa ku ogun iseju ( 5:40am), o ni awon apaniyan yii fi ado oloro ti won di mora pa ara won ati awon to wa josin ni mosalasi naa.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó 11 Sẹ́rẹ́ 2021 Yoruba ni ẹnu ẹni laa fi n pe Temidire nitori ohun ta ba beere, bẹẹ ni yoo ri.
O sọ ninu ẹsun rẹ ti Y!
N óo sì gbé ẹgbaarun (10,000) ìwọ̀n talẹnti fadaka fún àwọn tí a bá fi iṣẹ́ náà rán, kí wọ́n gbé e sí ilé ìṣúra ọba.
Nítorí náà, ẹ pa gbogbo ìwà ibi tì, ati ọgbọ́n ẹ̀wẹ́, àgàbàgebè, owú jíjẹ ati ọ̀rọ̀ àbùkù.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Aremu: Eré ìtàn nípa ìbí, àti jéèyàn pẹ̀lú ìpèníjà Olusegun Aremu Obasanjo O ni o ṣeeṣe ko jẹ wi pe awọn iroyin ti wọn fi silẹ lasiko ti wọn n mura ati rinrinajo naa lo fa segesege aile ri wọn lọwọlọwọ bayii.
Nigba to kọkọ bẹrẹ isẹ, o ṣe atilẹyin fun awọn eeyan ẹkùn Gusu, to tako ki awọn aláwọ̀ dudu ati funfun, jọ ma a wọ ọkọ bọọsi kan naa, tabi jọ lọ sileewe ijọba kan naa.
Nígbà tí ó dára fún mi,ó fi ẹ̀yìn mi wọ́nlẹ̀,ó fún mi lọ́rùn, ó gbé mi ṣánlẹ̀,ó sì gbọ̀n mí yẹ́bẹ́yẹ́bẹ́;ó yàn mí sọjú bí àmì ìtafà sí.
Yọ ọrùn sí ẹ̀wù náà, kí o sì fi aṣọ bí ọ̀já tẹ́ẹ́rẹ́ gbá a lọ́rùn yípo, bí wọ́n ti máa ń fi aṣọ tẹ́ẹ́rẹ́ gbá ọrùn ẹ̀wù, kí ó má baà ya.
Ó lọ mú àgbò náà, ó sì fi rú ẹbọ sísun dípò ọmọ rẹ̀.
Bakan naa lo sọ pe alaisan keji to ni aarun naa ni ipinlẹ Ogun ko ni aarun naa mọ lẹyin ayẹwo ti wọn pada ṣe fun.
Osu Kẹjọ, ọdun 1958 ni wọn bi Baba Suwe ni agbegbe Inabere ni ilu Eko ni ijọba ibilẹ Ikorodu, ko to di wi pe o bẹrẹ isẹ osere ni ọdun 1972 pẹlu fiimu rẹ, Ọmolasan ti Obalende se agbatẹru fun.
Bí òǹgbẹ bá ń gbẹ mí oo
Awọn mii ko tiẹ ki ń jẹ ounjẹ aaro rara ti o si jẹ pe aijẹun yii a máa ṣe àkóbá fún ọpọlọ wa.
Nigba aye rẹ, Tunde Idiagbon jẹ ologun to ni igbega titi to fi di igbakeji olori orilẹ-ede Naijiria laye ijọba ologun Buhari-Idiagbon laarin ọdun 1983 si 1985.
    Ìgbà yìí ni mo lè sọ̀rọ̀ sí obìnrin náà dáadáa, mo sì bèèrè bí o ti ṣe dé ibẹ̀.
Ọkọ̀ ayọ́kẹ́lẹ́ ìyá rẹ̀ ló wà débẹ̀, ó sì kó ibọn oríṣìí mẹ́ta dání.
Nígbà tí yóo sì fi di ìrọ̀lẹ́, ó ti kú.
to wa niluu Abuja lasiko  to n se ifilọlẹ
Ẹ jẹ́ kí wọ́n lọ kí wọ́n lè lọ sin OLUWA Ọlọrun wọn.
O tun sọ siwaju pe ọpọ awọn alejo to ba ri oun ni wọn maa n sọ pe oun burẹwa, toun ba si n rin lọ loju popo nigba miran, awọn eeyan maa n fa oun sẹyin pe oun burẹwa, amọ ti awọn eeyan miran maa n gbeja oun.
Eyi ṣeeṣe ko tumọ si pe eto ẹkọ yoo wa ni owurọ ati ọsan, lati le tẹle ilana titakete siraẹni.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Kí ló yẹ kí ílẹ̀ India se sí ẹkùn tó pa ènìyàn márùn ún?
Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí D.
Oríṣun àwòrán, Bc Àkọlé àwòrán, Ugwummadu ni ẹri nikan ni CDHR nilo lati gbe ileeṣẹ to ba da ọmọ Naijiria pada lọ ile ẹjọ O ni ijọba orilẹede Naijiria lo fa iru ẹgbin bayii ba awọn ọmọ orilẹede yii, nitori awọn lo gbe aye le awọn ileeṣẹ okeere lọwọ.
naa se sọ pe ,Oniwaasu naa ko aarun Ebola lasiko to wa si ilu Butembo, ti ko
Iroyin si sọ pe awakọ baalu naa ko fara pa pupọ.
Ó wà níbẹ̀ títí di òní olónìí.
Sotitobire: Kò sí èléyìí tó kàn mí nípa ìjínígbé Gold Kolawole!
Ṣugbọn níti ọba Juda tí ó sọ pé kí ẹ lọ wádìí lọ́wọ́ OLUWA, ẹ sọ fún un pé, OLUWA Ọlọrun Israẹli ní: Nípa ọ̀rọ̀ tí ó ti gbọ́, nítorí pé ó ronupiwada, 
''Ẹgbẹ elérin ni mo fẹ tẹka fun ṣugbọn òdòdoóni mo ṣeṣi tẹ ẹ sójú ẹ̀'' O salaye yii ninu fọnran fidio lati fi le ṣe apejuwe ami idanimọ awọn ẹgbẹ to kopa ninu idibo naa.
Femi Kuti, tii se ọmọ Kaarọ Oojire, to tun jẹ ilumọọka akọrin lati orilẹede Naijiria, yoo dara pọ mọ awọn gbajugbaja akọrin miran, ti yoo ma a bawọn si idije bọọlu fun ife ẹyẹ ilẹ Afirika, AFCON 2019 pẹlu orin.
Ẹkún sọ ní ìsìnkú Aisha Abimbọla ní Toronto Akẹ́kọ̀ọ́ yìnbọn pa èèyàn mẹ́wàá l'Ámẹ́ríkà Ko sí ifoya Ebola lọ́rọ̀ ìdíje Nigeria àti Congo Olóògbé náà kọkọ jáde láti díje nínú ìdìbo abẹ́le tí ó kọjá yìí ṣugbọn, ìgbà tó yá, ó ní òun kò ṣe mọ, ó sì ṣe àtìlẹ́yìn fun gomina ìpínlẹ̀ náà nígbà kan rí, Kayode Fayemi tí ó jáwé olú bórí.
’ ‘Wakati kan lẹyin rẹ ni mọ gbọ pe nkan buruku ti ṣẹlẹ si.
Ẹni to bori: Morocco Aṣekagba South Africa Morocco South Africa vs Morocco.
Òní ni ẹ̀bí akọni Pius Adesanmi n ṣètò ìkẹyìn fún ogbontarigi náà Ẹlẹ́wọ̀n tẹ́lẹ̀ gboyè ìmọ̀ ìjìnlẹ̀ méjì lọ́gbà ẹ̀wọ̀n Adájọ́ Dogo tí wọ́n jí gbé ti gba ìtúsílẹ̀ Oríṣun àwòrán, @Rebecca Àkọlé àwòrán, Aarẹ ẹgbẹ onimọ Yoruba YSAN, ọjọgbọn Duro Adeleke atawọn ọmọ ẹgbe miran nibi eto isinku Baba Okediji Oríṣun àwòrán, @Rebecca Àkọlé àwòrán, Awọn ọmọ ẹgbẹ onimọ Yoruba YSAN lasiko isinku Baba Okediji nibudo igbalejo ni Omijad Oyo Oríṣun àwòrán, @Rebecca Àkọlé àwòrán, Diẹ ninu Awọn ọmọ ẹgbẹ akọmọlede ati agba ẹgbe lasiko isinku naa ni Oyo Wọ́n ti ṣí ilé oúńjẹ oní ọgbọ̀n náírà (N30) ní Kano Ìdí tí mo ṣe fẹ́ yọ ayédèrú ìdí ńlá tí mo ní- Sophie Ìlú kò mọ ohunkóhun nípa iṣẹlẹ màálù tó kú nilu Ikarẹ- Oba Olukarẹ Ìgbà tí òògùn ẹ̀jẹ̀ ríru lè ṣiṣẹ́ jù rèé- Onímọ̀ Oríṣun àwòrán, @Rebecca Àkọlé àwòrán, Awọn ọmọ ati aya ti oloogbe fi silẹ lọ ninu ile ijọsin lasiko eto isinku naa.
sugbon a ti ri awon oju popo ti o ti baje ti 
Orúkọ tó fún wọn ni wọ́n sì ń jẹ́ di òní.
Àlá Daniẹli Nípa Àwọn Ẹranko Mẹrin.
Ogun olukopa lo wọ inu ile ẹlẹgbọn agba fun eto agbelewo BBNaija lalẹ ọjọ kọkandinlogun oṣu keje.
lọ si ipinle Eko balẹ si papa  ofurufu ti
Ní òwúrọ̀ ọjọ́ keji, Balaki mú Balaamu lọ sí ibi gegele Bamotu Baali níbi tí ó ti lè rí apá kan àwọn ọmọ Israẹli.
Ipo tuntun yii ni o ga julọ lẹnu iṣẹ ologun lọwọ ni Naijiria ni eyi ti Ogagun Tukur Buratai to jẹ adari awọn ọmọ ogun ilẹ̀ Naijiria jẹ bayii.
Nígbà tí a wí fún Òmùgọ́diméjì pé Ilẹ̀ẹ́gbóná kò dára, ó ní ó dára ní ti òun, àti pé òun níí mú ara ènìyàn le, àti pẹ̀lú pé bí Ilẹ́ẹ̀gbóná kò bá tíì mu ènìyàn olúwarẹ̀ kò tíì bọ́ sínú ayé.
Maradona sọ fun ra rẹ pe Dalma ati Giannina ni ojulowo ọmọ oun nigba ti awọn yoku jẹ aṣiṣe atipe tori owo oun loun fi bi awọn ọmọ yoku.
Ila oorun ile Adulawo ti gba ami ida ogun le merin ni eyi to fihan pe won n gbiyanju lati ba gbendeke asiko naa nitori pe eyi san ju ida merinlalaadorun le meta ti won gba lodun 2017 lataari pe orile-ede marun un ninu mejo to wa ni ekun yii ti fi akosile ibi a ba ise de ranse si ajo isokan ile Adulawo, AU.
Idi ti awọn ologun fi yi ibi ifẹhonu han naa ka ko ṣi tii ye.
Ile-ise olopaa ti n fi oro wa baba omo naa lenu wo, idi ti o fi le fi omo re sile laisi olutoju, agbejoro kan so pe, iya omode-kunrin naa ko si ni ilu Paris lasiko isele naa.
Awọn oloṣelu gbọdọ fi ti Gomina Akinwunmi Ambode ti Ipinlẹ Eko kọgbọn.
Gẹgẹ bi agba oloṣelu ti awọn mejeeji jẹ, iwoye yii ni Oloye Bode George fi fi ọrọ agba ba wọn sọrọ nitori Yoruba ni agba la fi n wagba.
" O ni iku agbẹjọrọ to n ba baba oun ṣe ẹjọ ifiyajẹni lọna aitọ naa, Bamidele Aturu, lo mu akude nla ba igbesẹ gbigba owo naa.
Gold Kolawole, ọmọ tó sọnù ní ṣọ́ọ́ṣì Sotitobire kò bá pé ọdún méjì lónìí Mo le búra pé kò sí ìbáṣepọ̀ láárin Olorì Badrat àti Wasiu Ayinde - Olori Folashade Nàíjíríà ti pín yẹlẹyẹlẹ láyé Buhari, ìjákulẹ̀ dé!
Ibi ni ẹ̀ ń fi ọkàn yín rò,iṣẹ́ burúkú ni ẹ sì ń fi ọwọ́ yín ṣe láyé.
“Ẹ má fetí sí ọ̀rọ̀ Hesekaya; nítorí ọba Asiria ní kí ẹ bá òun ṣe àdéhùn alaafia kí ẹ jáde tọ òun wá.
Eliṣa bá dá wọn lóhùn pé, “Ẹ bu iyọ̀ sinu abọ́ tuntun, kí ẹ sì gbé e wá fún mi.
NCDC ni àìsàn náà ko niṣe pẹlú adiyẹ broiler ti àwọn onímọ sayẹnsi si ti ṣiṣẹ́ takuntakun láti mọ ẹrànko to n pín àìsàn náà to ti pa ènìyàn ẹgbẹ̀sàn to si ti ran ẹgbẹ̀run lọ́na ààdọrin ni àgbàyé.
Wiwọgile sisanwo eto ẹkọ lọna meji Pipari awọn yara ikẹkọọ ileewe girama ti wọn ti kọ pati lati pese aye fawọn akẹkọọ to fẹ wọle Ipese ẹrọ Wi-Fi fawọn akẹkọọ lati le mọ ẹrọ ayelujara lo lawọn ileewe Ọrọ aje Agbekalẹ eto ọrọ aje onikoko mẹta papaa julọ lẹka ileeṣẹ to n ṣe nkan atawọn iṣẹ mii .
''Bi owo ti se n wa la se n san fun awọn osisẹ.
Angẹli Oluwa ni ó sọ fún un pé kí ó ranṣẹ pè ọ́ wá sí ilé rẹ̀, kí ó lè gbọ́ ọ̀rọ̀ lẹ́nu rẹ.
Ẹnu ya gbogbo àwọn tí ó gbọ́ ọ̀rọ̀ rẹ̀.
Bii ti Ayanfunkẹ ati Ayanronkẹ Ganiyu, oju ni wọn ni ilu ti wọn ti wa nitori lati igba ti wọn ti wa ni nkan bii ọmọ ọdun méjì ni gangan ti n dun ti bata naa si n ro kola kola lati ọwọ wọn.
Agbẹnusọ fun ileeṣẹ ọlọpaa ipinlẹ Katsina, Gambo Isah ṣalaye pe, ni bii aago marun un aabọ idaji lawọn gba ipe wi pe, aawọ ti bẹ laarin Salis ati iyawo rẹ labule Almakiyayi.
Ẹsita sì fi Modekai ṣe olórí ilé Hamani.
Ó lọ láti àfonífojì Akori títí dé Debiri, ó wá yípo lọ sí apá ìhà àríwá, lọ sí Giligali, tí ó dojú kọ gẹ̀rẹ́gẹ̀rẹ́ Adumimu, tí ó wà ní apá gúsù àfonífojì náà.
Igi gogoro ti í kosũ ni ààlà
Wo bí o ṣe le fi ẹjọ́ sun àjọ FCCPC tí o bá ra ọjà tó ti 'expire' Mi ò tí ì mọ obìnrin rí; kódà, mí ò ní 'Girlfriend'- Mr Macaroni Mọ̀ síi nípa Shina Rambo tó pàdé Jesu lọ́gbà ẹ̀wọn lẹ́yìn tó ti jalè Ilé ẹjọ́ ní kí ''Yahoo boy'' lọ darí ọkọ̀ f'óṣù mẹ́ta pẹ̀lú N50,000 owó ìtanràn 'Àwa ọmọ Nàìjíríà tó farapa fẹ́ wálé láti Lebanon, ìjọba kó wa pamọ́' Èèkàn ẹgbẹ́ òṣèlú APC mií Lanre Razak jáde láyé lẹ́yìn àìsàn ráńpẹ́ Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí 6:10 Fídíò, Yoruba Language: Akomolede ati Asa Yoruba tọ̀sẹ̀ yí rèé lẹ́nu olùkọ́ wa, Duration 6,1030 Ògún 2020 Chadwick Boseman wife: Simone Ledward ni ìyàwó Chadwick Boseman, wọ́n sì 'sègbéyàwó kó tó jáde láyé31 Ògún 2020 Èyí tí a wò jùlọ 5:03 Fídíò, Omolola Arohunmolase Welder: Mo ti fí iṣẹ́ 'Welder' gbayì láwùjọ, tó mo fi tọ́ ọmọ yanjú, Duration 5,039 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 5:39 Fídíò, Akomolede ati Asa lori BBC: Olùkọ́ Kikelomo Ogunboye tan ìmọ́lẹ̀ sí ìwà olè ọ̀gá ọlọ́pàá Audu gẹ́gẹ́ bí àwòkọ́ṣe àsìkò yìí, Duration 5,398 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 4:11 Fídíò, Oba Adeyeye Ogunwusi: Ojú mi ti rí lọ́pọ̀ lọpọ̀, ọ̀pọ̀ èèyàn ni kò tilẹ̀ gbàgbọ́ pé mo lè jọba- Ooni, Duration 4,117 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 4:43 Fídíò, Promise Akinlade: ọmọ ọdún mọ́kànlá tó ń fi ìlù dárà bíi àgbàlagbà sọ̀rọ̀ nípa tálẹ́ǹtì rẹ̀, Duration 4,437 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 0:59 Gbọ́, Ìsẹ̀lẹ̀ jákèjádò orílẹ̀èdè àgbáyé láàárín ìṣẹ́jú kan, Duration 0,59wákàtí 5 sẹ́yìn 7:03 Fídíò, Olumuyiwa Bolade Adedeji Military Bruitality: Bí arákùnrin onípèníjà ara tí sọ́jà lù ṣe dé, Duration 7,035 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 4:45 Fídíò, Yoruba Films: Ẹ̀ẹ́ bẹ̀ mi kúrò láyé ni, mi ò lè kú - Fadeyi Oloro, Duration 4,4526 Èrèlè 2020 2:48 Fídíò, Esther Ajayi: Èmi náà ti borí ìṣòro rí ló ń mu mi ṣojú àánú, Duration 2,481 Ògún 2019 6:08 Fídíò, Adebola Ademilua: Àìrísẹ́ ṣè lẹ́yìn ìwé kíkà ló sọ mi dí ìyá onírú, mo dúpẹ́ tèmi, Duration 6,0827 Bélú 2020 5:55 Fídíò, Soyinka Cancer: Àṣe ara mi ni iso ti n run gbogbo bí mo ṣe n ṣèrànwọ́ lórí jẹjẹrẹ, Duration 5,5527 Bélú 2019 BBC News, Yorùbá Ìdí tí ẹ fi le è nígbàagbọ́ nínú ìròyìn BBC Ìlànà Lílò Nípa BBC Òfin Àṣírí Cookies Kàn sí.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Lagos Marathon: Abraham Kiprotich se ipò Kíní ninu ìdíje ọ̀uń 10 Èrèlè 2018 Oríṣun àwòrán, Twitter.
#RevolutionNow: Ọlọ́pàá ní ẹ̀sùn ìdìtẹ̀ gbàjọba ni ìfẹ̀hónú ọ̀hún
Ọọni Ogunwusi ni Orunmila ni o kọkọ gbe imọ eroja iṣẹ lori ayelujara ti a mọ si 'Google' kalẹ lati ọpọ ọdun sẹyin ki o to di wi pe oyinbo gbee kalẹ.
Aiku to kọja naa ṣe ṣe ọpọ akoba fun ọpọ awọn ọmọ orilẹ-ede Naijiria
Nígbà tí ó bá la ojú rẹ̀, gbogbo ọrọ̀ rẹ̀ yóo ti fò lọ.
Titi di asiko yii, ako tii mọ ohun gan to ṣokunfa iku Sẹnetọ naa, amọ iroyin to gbe e jade pe lẹyin aisan ranpẹ ni.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Coronavirus: Irọ́ ńlá ni pé ewé dongoyaro lè wo aàrùn coronavirus Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Coronavirus: Irọ́ ńlá ni pé ewé dongoyaro lè wo aàrùn coronavirus 20 Ìgbé 2020 Lẹyin ti arun Coronavirus di tọrọ fọnkale lọpọ orilẹede kaakiri agbaye, ọpọ awọn eeyan lo n sọ lori ayelujara pe ewe dongoyaro le wo aarun coronavirus.
Ẹ fetí sílẹ̀ kí ẹ gbọ́ ohùn mi,ẹ tẹ́tí sílẹ̀ kí ẹ gbọ́ ọ̀rọ̀ mi,
Inú mi yóo sì máa dùn ni, 
Inú bí Farao sí àwọn iranṣẹ rẹ̀ mejeeji yìí, 
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Cute Abiola: Agbẹjọ́rò ni bàbá mi fẹ́ kí n ṣe àmọ́ àyànmọ́ mi ni àwàdà 20 Òkùdu 2020 Oríṣun àwòrán, Instagram/thecuteabiola Gbajugbaja adẹrinposonu kan lori ayelujara, Abdulgafar Ahmad Abiola ti fidi rẹ mulẹ pe, oṣiṣẹ ologun oju omi Navy ni oun.
 O fi kun ọrọ rẹ pe, ijọba yoo gbe igbimọ kalẹ lati ṣe iwadii àwọn nkan to fa awọn wahala to waye ọhun."
Ẹ̀mí tí Ọlọrun fun yín kì í ṣe èyí tí yóo tún sọ yín di ẹrú, tí yóo sì máa mu yín bẹ̀rù.
Olùfẹ́, bí Ọlọrun bá fẹ́ràn wa tó báyìí, ó yẹ kí àwa náà fẹ́ràn ọmọnikeji wa.
Bí ó ti ń bá mi sọ̀rọ̀, ẹ̀mí OLUWA wọ inú mi, ó gbé mi nàró, mo sì gbọ́ bí ó ti ń bá mi sọ̀rọ̀.
Nigba ti o n kin ọrọ Akala lẹyin, oluranlọwọ fun gomina ipinlẹ Oyo tẹlẹ, Yusuf Olaniyi sọ fun BBC Yoruba pe Alao-Akala ti di agbaọjẹ ninu oṣelu ipinlẹ, iyẹn lo ṣe ni oun ko ni dije fun ipo gomina mọ.
Wada: Alága àjọ ìdìbò INEC àti ọgá ọlọ́pàá, mò fà yín lè Ọlọrun lọ̀wọ́ Kogi 2019: Àwọn ará ìlú sọ̀rọ̀ lórí ìrètí wọn lọ́wọ́ Yahaya Bello 'Ọ̀la la máa mọ̀ bóyá Jonathan tako òfin PDP pé ó gbàlejò APC ní Bayelsa' Ileeṣẹ ọlọpaa ṣalaye pe edeaiyede waye laarin okunrin kan ti orukọ rẹ njẹ Awolu Zekeri, eni ọdun 35 to jẹ ọmọ ẹgbẹ oṣelu APC, ati Gowon Simeon to jẹ ọmọ ẹgbẹ oṣelu PDP ni agbegbe Ochadamu.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Oladejo Okediji àti ìgbé ayé ìtàn kíkọ rẹ̀ Wa kùsà kóo dáràn!
OLUWA bá rán àwọn ọmọ ogun Kalidea, ati ti Siria, ti Moabu, ati ti Amoni, láti pa Juda run bí ọ̀rọ̀ ti OLUWA sọ láti ẹnu àwọn wolii, iranṣẹ rẹ̀.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Vincent Enyeama: Aṣọ́lé Nàìjíríà tẹ́lẹ̀ rí ṣe tán láti padà sórí pápá 27 Agẹmo 2019 Oríṣun àwòrán, Instagram/Vincent Enyeama Àkọlé àwòrán, Enyeama n gbaradi lati darapọ mọ ikọ agbabọọlu tuntun Aṣọle fun ẹgbẹ agbabọọlu Naijiria tẹlẹ ri, Vincent Enyeama ti ṣe tan lati pada sori papa lẹyi ti ko ṣoju ikọ agbabọọlu kankan fun ọdun meji.
Titi di ba ṣe n sọrọ yi mo tun wa a lọ ti mi o si ri'' O ni bi oun ṣe n wa ọmọ naa lọ ni oun n gbe nkan lọwọ lati fun un ṣugbọn awọn ko pade.
Bẹ́ẹ̀ ni àwọn enìyàn fún èmi àti ẹgbọn mi ní orúkọ tí kò yẹ fún wa.
Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Fídíò, Fire accident victim: AbdulQudus Bello ṣàlàyé bí òun ṣe dí aláàbọ̀ ara nítorí pọpọ́ọ̀fù àti ìbínú jàǹdùkù àdúgbò7 Bélú 2020 Charlie Hebdo: 'Cartoon' nípa Anọbi Muhammed kó Ọ̀jọ̀gbọ́n kan sí ìyọnu ní Egypt7 Bélú 2020 Fídíò, Bose Okeowo: Àárẹ̀ kékeré ló sọ mi dí aláàbọ̀ ara yìí ṣùgbọ́n.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Funke Oshonaike: Uwa Omozua tí wọ́n fipá bá lòpọ̀ kú ní Benin ló mú mi sọ ìrírí tèmi náà 14 Agẹmo 2020 Oríṣun àwòrán, Facebook/Funke Oshonaike ''Ni gbogbo igba ti mo ba ti gbọ iroyin nipa ifipabanilopọ, o maa n mu mi ranti ohun to ṣẹlẹ si mi sẹyin ni.
Sugbọn igbimọ ton s'akoso nkan ọgbin ni pinlẹ Kebbi sọ wipe oun ti gbe igbese to tọ lori awọn eku ati kokoro naa.
Kò sí ìfòyà lásìkò ọdún iléyá ní òpópónà Marosẹ Eko si Ibadan Àkúntúnkú, ìgbà márùn ún rè é tí Shekau kú tí wọ́n ní kò kú mọ Nkan mẹ́wàá (10) tí wọ́n ṣe àkọsílẹ̀ rẹ̀ 1.
"Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: ""Apena fẹ́gbẹ́ Oṣugbo, Opa, Akala àtẹ̀yin awo, ẹ wa ọ̀pá àṣẹ Ọ́ba Akiolu jáde"" Ikú Aráàlú 51, ọlọ́pàá 11, Sọ́jà 7 tó kú lásìkò ìwọ́de EndSARS dùn mí - Buhari Ẹ wo ọ̀rọ̀ àwọn Wòlíì tó ti sọ àsọtẹ́lẹ̀ saájú nípa làásìgbò EndSARS Májèlé olóró lẹ jí l‘Ekiti dípò èròjà oúnjẹ Covid-19 - Ariwo sọ lórí ayélujára Ẹ sọ́ra fún ìwà olè àti jàgídíjàgan nílẹ̀ Yorùbá-Sunday Igboho ₦147m la rí kójọ fún ìwọ́de, a kò fẹ́ owó mọ́, ìwọ́de ti parí - Feminist Coalition Sanwo-Olu kéde ìlànà ìséde tuntun l'Eko Ìjọba ìpínlẹ̀ Kwara sọ̀rọ̀ lórí bí àwọn kan se lọ pín ""CaCovid 19 Palliative"" ní Ilorin pé."
Gbogbo wọn, ati ohun ìní wọn, ati àwọn eniyan wọn, lọ sí ipò òkú láàyè, ilẹ̀ panudé, wọ́n sì ṣègbé kúrò láàrin ìjọ eniyan Israẹli.
Wọn yóo máa ṣubú nígbà tí ẹnikẹ́ni kò lé wọn.
Yóo san ohun tí ó yẹ kí ó san fún OLUWA tí kò san, pẹlu èlé ìdámárùn-ún rẹ̀ fún alufaa, alufaa yóo sì fi àgbò ẹbọ ẹ̀bi náà ṣe ètùtù fún un, a óo sì dárí ẹ̀ṣẹ̀ rẹ̀ jì í.
Segun Ọdẹgbami: Mo kọ̀ láti lọ sí APC àti PDP nítorí ń kò fẹ́ ní 'Bàbá ìsàlẹ̀' Ìdíje ọpọ́n ayò títa ni Ẹ̀gbá ń ṣí ojú àwọn ọ̀dọ́ Yorùbá si àṣà wa Ṣùgbọ́n nínú àtẹ̀jáde tó fi síta lọ́jọ́bọ, Asiha Buhari sọ pé obìnrin tó ń jẹ́ Mariyatu tí wọ́n sì ń pè ní Amina Mohammed kìí ṣe ọmọ ìya òun.
Ẹran tí ẹ fi ipá gbà, tabi èyí tí ó yarọ, tabi èyí tí ń ṣàìsàn ni ẹ̀ ń mú wá láti fi rúbọ.
Mose fún àwọn ọmọ Israẹli ní àwọn òfin; 
O ni iwe ofin Naijiria, abala 162 lo sọ pe apo ifowo pamọ si kan yoo wa fun ijọba ipinlẹ ati ibilẹ ninu eyi ti owo to ba n wa lati ọdọ ijọba apapọ ati ti ipinlẹ si ijọba ibilẹ yoo maa lọ sinu rẹ.
Opolopo awon alatileyin re  ninu egbe oselu Movement for Democratic Change (MDC) ni won wa ninu aso pupa eyi ti o je aso egbe naa lati bowo fun olori egbe oselu naa ti o di oloogbe.
Loju ọpọ ikansiraẹni Twitter ni awọn eniyan ti n sọrọ tako iroyin pe awọn afẹhọnuhan EndSars lo tu awọn ẹlẹwọn naa silẹ.
 a le ríwọn ní nàìjíríà , gáná , orílẹ ̀ -olómìnira bẹ ̀ nẹ ̀ , tógò , sàró àti bẹ ́ ẹ ̀ bẹ ́ ẹ ̀ lọ .
Àwòrán àjọyọ̀ ìjọba ológun ní Sudan Amẹ́ríkà ń béèrè ìròyìn facebook, email arìnrìnàjò tó f'ẹ́ gbà'wé àṣẹ Àwọn òṣìṣẹ́ aláàbò kọlu àwọn tó n ṣe ìwọ́de ní Sudan Wahala iyan rọ dẹdẹ sori South Sudan Kíló fáà tí Póópù fi fẹnú ko ẹsẹ̀ àwọn olórí South Sudan?
nínú àwọn ènìyàn mílíọ ́ nù méjì àti ọgọ ́ rún mẹ ́ ta tí wọ ́ n ti sọ di aláìnílé lasti oṣù karún ọdún 2013 , ókéré jù , bíi ènìyàn 250,000 ti fi nàìjíríà sílẹ ̀ lọ sí cameroon , chad tàbí niger .
Àwọn wọ̀nyí náà a máa gba tẹbí-tará ní àlejò láti ìgbàdégbà.
Mustapha tọka si wipe awọn ṣe iwadii kan to fihan awọn ibi kan wa ni Naijiria ti wọn o ṣi gbagbọ pe COVID 19 wa lootọ ti wọn si n fọwọ yẹpẹrẹ mu u.
Diouf gba ami ayo meji meji sagbon, ti Kanu Nwankwo, Garba Lawal, Obafemi
Ẹ̀wọ̀n oṣù mẹ́ta àti #3,000 ni awakọ̀ tí kò bá ní ‘speed limiter’ yóò fi jura- FRSC Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 3 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 5 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
"Iye awọn eeyan to ṣẹṣẹ ko arun naa ni ipinlẹ kọọkan ree: Eko-193 FCT-85 Oyo-41 Edo-38 Kwara-34 Abia-31 Ogun-29 Ondo-28 Rivers-26 Osun-21 Akwa Ibom-18 Delta-18 Enugu-15 Kaduna-13 Plateau-11 Borno-8 Bauchi-7 Adamawa-5 Gombe-4 Sokoto-1 Florence Ajimobi tahùn sí igbákeji gómìnà Oyo lórí ikú ọkọ rẹ̀, ""Gbogbo wa làó kú"" Ilé ìfowópámọ́ Access ti gbà láti dá owó àwọn oníbàráà wọ́n padà Ẹ wo àwòrán bí ìsìnkú Abiola Ajimobi ṣe lọ!"
Ni bi a ṣe n sọrọ yii, ileesẹ ipolongo ibo fún Sẹnetọ Adeleke tabi ẹgbẹ oṣelu PDP ko tii sọ ohunkohun lori rẹ.
 Ijoba si tun n gbe igbese lati mu idagbasoke ba eto ilera , eto eko ati ipese ise lopo janturu.
Ọ̀tọ̀ọ̀tọ̀ lèrò àwọn èèyàn lórí ìyanṣẹ́lódì SSANU Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Yorùbá gbà pé òrìṣà bí ìyá kò sí!
O wa parọwa si awọn eeyan to wa ni iru ipo to wa yii ati awsn to n la ipenija miran kọja lati di opo Ọlọrun ọba mu.
Àwọn mejeeji yóo jìyà ẹ̀ṣẹ̀ wọn.
Díẹ̀ nínú àwọn tí mo pè mọ ohun tí ó fa sàráà yìí.
Amọ agbẹnusọ fun ileeṣẹ ọlọpaa nipinlẹ Ondo, Tee-Leo Okoro sọ fun BBc Yoruba pe ko ri bẹẹ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Seyi Makinde: Ọ̀sẹ̀ àkọ́kọ́ ní December ni màá sìnkú ìyá mí 15 Ọ̀wàrà 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 20 Ọ̀wàrà 2020 Oríṣun àwòrán, @seyiamakinse Gomina ipinlẹ Oyo, Seyi Makinde ti ṣapejuwe iya rẹ gẹgẹ bi obinrin to ni akinkanju, to ṣe gbẹkẹle, to ṣiṣẹ karakara nigba aye rẹ.
Dafidi wí fún un pé, “Má bẹ̀rù, oore ni mo fẹ́ ṣe ọ́ nítorí Jonatani baba rẹ.
Losu kọkanla ọdun to kọja ni Aarẹ Emmerson Mnangagwa fi anfaani osu mẹta silẹ fun awọn ile isẹ ati aladani to ba fẹ da owo ti wọn ko pamọ pada.
Ninu atẹjade kan to fi sita, Akintoye sọ pe looto ni oun gba pe awọn ọmọ orilẹ-ede Naijiria ni ẹto lati ṣe iwọde lori ipo ti orilẹ-ede wa.
Iroyin fihan pe,alekun ba iye owo oko ti awon arinrin ajo n san.
Ní àkókò náà ohùn rẹ̀ mi ilẹ̀.
Bákan náà ni Àtíkù tún sọ̀rọ̀ lórí ọ̀rọ̀ kan tí ààrẹ tẹ́lẹ̀, Olóyè Olúsẹ́gun Ọbásanjọ́ sọ pé níwọ̀n ìgbà tí òun Ọbásanjọ́ bá sì wà ní ayé, Àtíkù kò leè di ààrẹ́ orílẹ̀èdè Nàíjíríà.
Gẹgẹ bi awọn aṣoju ẹgbẹ naa ṣe sọ, lara ohun ti wọn n bere fun ni ajẹmọnu awọn oṣiṣẹ naa.
nẹ ́ ọ ̀ nù ni ẹ ́ límẹ ̀ ntì kẹ ́ míkà kan tó ní àmí-ìdámọ ̀ ne àti nọ ́ mbà átọ ̀ mù 10 .
adétoun gbà pé àwọn Ìjẹ ̀ bú tí wọ ́ n sí wá sí orílẹ ̀ -èdè nàìjíríà ni a lè bá ní abẹ ́ ọ ̀ wọ ́ mẹ ́ fà ọ ̀ tọ ̀ ọ ̀ tọ ̀ .
EFCC fẹsun kan Fayose ati ẹnikan pe wọn gbe iye owo naa jade lọna aitọ lati fi ṣe ipolongo ibo gomina.
Ogun Stolen Mace: Bí wọ́n ṣe rí ọ̀pá àṣẹ ìpínlẹ̀ Ogun ní Eko rèé
Oríṣun àwòrán, Osun osogbo Ọṣun seleri lati raga bo wọn pẹlu ileri pe awọn naa yoo maa pada wa ni ọdọọdun lati wa maa bọ oun bii orisa.
Bíótilẹ̀jépé àwọn alágbèékalẹ̀ fi ìwé pe aláṣẹ ìlú, bí i Punjab MNA Saadia Sohail láti Pakistan Tehreek e Insaf, àwọn aláṣẹ kò yọjú.
Ibudo okoowo goolu wa kaakiri ni ijọba rẹ, nidi okoowo yii lo ti ri owo to towo.
Ikede to fi sita yii lo mu oju awọn ẹlẹyinju aanu ọmọ Naijiria to ṣe asugba rẹ lọ si ile iwosan, Oluwafayokemi ni ilu Ijebu Ode, ni ipinlẹ Ogun.
Bo tilẹ jẹ pe ọmọ ọba ni, ọkan lara awọn nkan to fi igbeaye rẹ lepa ni adun ibalopọ fun awọn obinrin.
N óo mú ẹ̀gbin bá ọ n óo fi àbùkù kàn ọ́;n óo sì sọ ọ́ di ẹlẹ́yà ati ẹni àpéwò.
Nítori àwọn àtúgbẹ́yẹ̀wò, o níra láti ṣe àkójọpọ fún àwọn ọkọ́ naa Orisun: Johns Hopkins University atawọn ajọ eto ilera ilu Iye akọsilẹ to waye gbẹyin 15 Oṣù Ṣẹ́rẹ́ 2021 20:44 WAT+3 O fikùn pé, àwọn yóò ṣe iranwọ fún àwọn osere tíátà lobinrin àti àwọn aláìní pẹ̀lú nítorí ohun tó máa ń mú inú bàbá òun dùn nìyẹn, èyí tíì ṣe fífún àwọn aláìní ni oúnjẹ.
Ọkọ̀ ojú omi méjì kọlu ara wọn l‘Eko, èèyàn mẹ́ta fayé sílẹ̀ Àjẹ́ àti Aṣẹ́wó ní ìyá Rainbow - Òjòpagogo Sowore àti àwọn ọmọ ẹgbẹ Revolution Now kò ṣẹ̀ ṣófin lórí ìwọ́de, ẹ tú wọn sílẹ̀ - NLC Fayemi fojú Alufa to fipa bá ọmọde lòpọ̀ síta l'Ekiti O ní Siasia tún fi kún fún oun pé kò tilẹ̀ sí ẹni tó pé òun láti fi ọ̀rọ̀ wá oun lẹ́nu wò lóri ǹkan to ṣẹlẹ̀ yálà láti sọ tẹ́nu oun tàbí láti ja fún ẹtọ oun, ati pé ìgbà àkọ́kọ́ rèé tí òun náà ń gbọ́ ǹkan tó ṣẹlẹ̀ Kíní àwọn olúlúfẹ́ bọ́ọ̀lù àti àwọn Nàìjírí[[a ń sọ lóri ìgbésẹ̀ FIFA si Samson Siasia Àjọ FIFA fòfinde Samson Siasia titi lailai Ajo to n se amojuto ilana ere bọọlu afẹsẹgba lagbaye ti fi ọrọ lede wipe Samson Siasia to jẹ́ akoọ́nimọ̀ọ́gbá Super Eagles tẹ́lẹ̀rí, ti jẹbi ẹsun wipe oun lee gba riba bí ààye rẹ̀ bá yọ, pàápàá jùlọ láti yí èsì ìfẹsẹwọnsẹ bọọlu pàda.
Orúkọ tí kò ní parẹ́ laelae, ni n óo fún wọn.
Ọjọ Kẹtala osu Keji ọdun 1959 ni wọn bi gbajugbaja osere tiata naa, to si di olokiki ninu isẹ tiata lati ipasẹ ere kan to se lori mohun maworan, eyiti wọn pe akọle rẹ ni Ẹrin Keke lọdun 1990.
Nkechi Blessing vs Toyin Abraham: Nkechi tí tọrọ ìdáríjí ẹ̀ṣẹ̀ lọ́wọ́ akẹgbẹ́ rẹ̀, Toyin Abraham Ó ti tó àsìkò kí Nollywood fòpin sí èré ilé babaláwo lílọ - Clarion Chukwura Àrẹ̀mọ Ooni Adeyeye Ogunwusi ti wọ Ààfin Ile Ife fún ìgbà àkọ́kọ́ Ara mi rẹwà ló jẹ́ kí n máa ṣí ara sílẹ̀- Victoria KolawoleỌrọ ti Eniola sọ ree loju opo Instagram lati kilọ fun awọn eeyan to maa n bu pe o ti tobi ju.
Oríṣun àwòrán, others Nínú ọ̀rọ̀ tíẹ, Sẹnatọ Opeyemi Bamidele ni, ìjọba tí kò bá mọ ojuse rẹ ni isẹ, ní yóò máa tẹ́wọ́gba àmúlò ẹ̀rọ ìgbàlódé tó léwu fún àwọn araalu.
)Ó bá sọ fún àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ pé, “Ẹ jẹ́ kí wọ́n jókòó ní ọ̀wọ̀ọ̀wọ́ bí araadọta.
“Leyin ilana ofin, eto idibo , ipinnu egbe naa, ile ise egbe naa ati ayewo finni-finni nipa awon adari ati  omo egbe oselu naa, a ri i pe egbe oselu tuntun mẹ́tàlélógún naa yege lati  gbaa won wole gege bi egbe oselu lorile ede Naijiria.
Ara wọn nìkan ni wọ́n ń tọ́jú bí olùṣọ́-aguntan tí ń tọ́jú ara rẹ̀ dípò aguntan.
Atamatase iko agbaboolu Manchester United teleri ohun gba ami-ayo naa wole niseju perete ki ifesewonse ohun o to wa si ipari.
Ifẹsẹwọnsẹ naa to waye nile Chlesea jẹ akọkọ ti wn yoo gba nibẹ lati igba ti saa bọọlu tuntun ti bẹrẹ.
Elomiiran ti oṣiṣẹ inu gun pa ni Parkview Estate Yatọ si Adeleke, ni Parkview Estate yii naa, ọmọ orilẹede Togo kan to jẹ alase gun ọga rẹ Oloye Opeyemi Bademosi pa ni ile rẹ to wa ni Onikoyi Lane, Parkview Estate ni oṣu kẹwaa ọdun 2018.
Bakan naa, akowe agba ajo (NFF), Mohammed Sanusi salaye pe,“iroyin so pe Mgbolu se ise-abe losu ti o koja, leyi ti o si fara-han pe ara re ti mokun, sugbon ti aisan ohun tun peleke si lojo-Ru (Wednesday) leyi ti o sokunfa ile-iwosan ti o ti jade laye.
Nigba ti aarẹ Trump jawe olubori gẹgẹ bi aarẹ orile ede Amerika, o soro lori ero twitter re pe, lati ra baalu ti yoo maa gbe aarẹ yoo na won ni  bilionu merin dola, ni eyi ti o fagile.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Goitre Patients: Àwọn èèyàn tó ní àrùn gẹ̀gẹ̀ ní ọ̀pọ̀ ìkórira àti ìdẹ́yẹsí ní àwọn ń kojú Ọpọ ọmọ Naijiria lo gbana jẹ lori eyi pe, ko tọ ki aarẹ maa fi owo epo Saudi we tí Naijiria nitori anfani ti Saudi n jẹ lati ọdọ ijọba ko ni afiwe, si iya ti ijọba Naijiria fi n jẹ ara ilu .
Ṣe gírí kí o gbé oúnjẹ fún mi.
FIFA U-20 World Cup: Senegal sin Nàìjíríà lọ'lé pẹ̀lù ìgbájú ìgbámú
Lọdun to kọ̀ja ni ìjọba Naijiria fòfin dè iferanje láwọn agbegbe kan, to sí ni ki awon eniyan maa fi ẹran ọsin sí pápá ijẹ̀ko.
Ijipti kò ní tó gbójú lé fún àwọn ọmọ Israẹli mọ́.
Ìwọ Mose, súnmọ́ ọ̀dọ̀ rẹ̀, kí o sì gbọ́ gbogbo ohun tí OLUWA Ọlọrun yóo sọ, kí o wá sọ fún wa, a óo sì ṣe é.
 Yoruba kii mọriri ara wọn, wọn ko mọ ju ki wọn maa rọjo eebu, ki wọn si maa se ariwisi sugbọn ti eeyan kan ba se daada, o yẹ ka le sọ.
fun ile-ise to n gbogun ti sise owo ilu basu-basu ,Economic and Financial
Ileeṣẹ to n sọ iwọlewọde awọn eeyan si orile-ede Naijiria, Nigeria Immigration Service (NIS) ti kọdi ki awọn dokita ọmọ Naijiria mejidinlọgbọn yi ṣe irinajo lọ si ilẹ Gẹẹsi.
Nnamdi Kanu kò sí ní orílẹ̀èdè wa rárá o- Ìjọba Orílẹ̀èdè Israel
Oríṣun àwòrán, Reuters Àkọlé àwòrán, Maradona was regarded as a national hero in Argentina Awọn agbofinro tiẹ ni ikọlu pẹlu awọn oludaro to n gbiyanju lati suu mọ olu ileeṣẹ ijọba nibi ti wọn gbe posi Maradona si.
Ọ̀kan ninu àwọn àgbààgbà mẹrinlelogun yìí bi mí pé, “Ta ni àwọn wọnyi tí a wọ̀ ní aṣọ funfun?
"A ó fimú gbogbo ẹni tó lọ́wọ́ nínú ikú Tiamiyu Kazeem dánrin - Ìjọba ìpínlẹ̀ Ogun Ija eerin meji: Oluwo ati Ọọni Ìgbà mẹ́rin tí ọ̀rọ̀ Oluwo dá awuyewuye sílẹ̀ Oluwo kò gbọdọ̀ kọrin òwe tàbí bá àkọ̀ròyìn sọ̀rọ̀, kó má baà ba ẹjọ́ ara rẹ̀ jẹ́ - Ọ̀ràngún ṣàlàyé Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Oluwo ilu Iwo ba BBC Yoruba sọrọ lori awuyewuye pẹlu awọn Ọba ""Ọlọrun ni kí n lọ sọ pe òun ń bọ̀ ṣùgbọ́n ki n lọ fọ ààfin òun mọ""."
Àwọn yàrá ẹ̀gbẹ́ náà jẹ́ alágbèékà mẹta, ọgbọ̀n yàrá ni ó sì wà ninu àgbékà kọ̀ọ̀kan.
"Ẹlomii, @MrLewinOkotie, sọ pe ""Biodun Fatoyinbo mura daadaa, to si joko si aaye ti wọn ya sọtọ fun awọn pasitọ ni Shiloh."
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Kannywood: A ó fòfín dé eré ìfẹ ṣíṣe fún ọdun díẹ̀ 25 Èbibi 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 26 Èbibi 2019 Oríṣun àwòrán, Kannywood Àkọlé àwòrán, A ó fòfín dé eré ìfẹ ṣíṣe ni Kannywood fún ọdun díẹ̀ Kannywood tó jẹ ẹka àwọn oní fiìmù ní ilẹ̀ Hausa lórilẹ̀-èdè Nàìjíríà tí bẹ̀rẹ̀ ètò láti fòfinde síṣe eré àgbélé wò fún títà fún ọdún díẹ̀ lánà àti taná wó àwọn ìhà ibomíràn.
7 Bélú 2020 Oríṣun àwòrán, Getty Images Bi wọn ba ni pe ki ẹ pe koṣẹlẹri wa, Kamala Harris to jẹ obinrin akọkọ ti yoo dipo igbakeji aarẹ mu ni Amẹrika ni kẹ pe.
Erin fara gbọgbẹ̀, ó ṣekú pa ènìyàn méjì Omi ara Ọ̀pọ̀lọ́, ẹ̀jẹ̀ Ẹlẹ́dẹ̀ àti wáìnì tí wọn fi Èkúté ṣe ń mára jípépé, ẹ máa mú Justice Osei le dún bíi ẹranko 50 Sanwo-Olu ń sanwó Eko!
orile ede Naijiria, , Stuart Symington ti pe fun eto
Iṣoro ara bibo kii ṣe iṣoro to n koju Sri Lanka nikan.
Ọrọ naa tilẹ buru to bẹẹ nigba kan ti Wenger ti Mourinho lulẹ lori papa nitori pe Mourinho sọ ọrọ alufansa si.
O sọ pe ki awọn eniyan o fara da a fun anfaani gbogbo araalu.
1 837 Orilẹede Seychelles 1 1.
Nítorí ìwọ́de, Amosun àti ẹgbẹ́ òṣìṣẹ́ NLC tutọ́ síra wọn lójú nípínlẹ̀ Ògùn
27 Bélú 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
David Okereke lo fọba lee, lẹyin to gba goolu ẹlẹẹkẹrin wọle Libya, bẹẹ lawọn ọmọ Naijiria fijo bẹẹ nilu Asaba ti ere bọọlu ọhun ti waye.
Ojọ kẹwaa, oṣu karun un, ọdun 1991 ni wọn bi i to si dagba ni agbegbe Agege ni ipinlẹ Eko.
Buhari, jáde bá ọmọ Nàíjíríà sọ̀rọ̀, orí àgbá ẹ̀tù la dúró lé - NUJ pariwo Kíní ìtumọ̀ ''Sọ̀rọ̀ Sókè'' tí àwọn afẹ̀họ́núhàn EndSars ń lò káàkiri Wo ohun tí ìwọ́de #EndSARS sọ iléèwé dà ní Oyo, Ekiti, Ondo, Eko Ìpínlẹ̀ Oyo àti Osun sàlàyé ìdí tí wọn kò fi tí ṣè ifilolẹ ìgbìmò igbẹjọ aṣemáṣe SARS Ẹgbẹ awọn ọlọdẹ naa wa jẹ ko di mimọ pe awọn ko ni la oju awọn silẹ ki awọn kọlọransi ẹda kan wa fi iwa buruku ọwọ wọn ba oju awọn oluwọde #EndSARS naa ati ohun ribiribi ti wọn n gbe ṣe jẹ.
Eyi ṣeeṣe nitori pe ọ̀rọ̀ aje dagba soke daada - ṣugbọn ni bayii, ifasẹyin ti de ba a.
ran won lowo lati lee mojuto eto aabo ati ofin lasiko eto idibo to n bọ yii ni
Wọn a máa gbé inú ọlá,wọn a sì máa kú ikú alaafia.
Joabu ati àwọn eniyan rẹ̀ bá gbé òkú Asaheli, wọ́n sì lọ sin ín sí ibojì ìdílé wọn ní Bẹtilẹhẹmu.
 Ẹ má tan ara yín jẹ, kò lè dẹrùn.
Bí ìwọ bá bẹ̀rẹ̀ síí rí nǹkan wọ̀nyí, ronú rẹ dáadáa, kọ ìwọ̀sí tí ó bá yẹ ní kíkọ̀, sì rọ́jú gba èyí tí ó bá yẹ láti gbà mọ́ra.
Nítorí náà, àwọn eniyan Israẹli yóo máa pa ọjọ́ ìsinmi mọ́, wọn yóo máa ranti rẹ̀ gẹ́gẹ́ bí àmì majẹmu ní ìrandíran wọn.
Ní àkókò kan, Hesekaya ṣàìsàn, ó fẹ́rẹ̀ kú.
ní ìjọ Martyhrs of Pencost ní pápá ìṣere Kinshasa ní ọjọkọkanlelọgbọ̀n osu kaarun Oríṣun àwòrán, AFP Àkọlé àwòrán, Ọ̀pọ̀ ẹgbẹ̀run olólùfẹ́ rẹ ní wọn fọ́n sita láti fin ẹdun ọkan wọn han bi wọn se ń gbe oku rẹ̀ kọja ni opopona oluilu Dr Congo Kinshaha ní ọjọ kini oṣù kẹfa.
Ògbóòntarìgì sọ̀rọ̀sọ̀rọ̀ ni olóòtú ètò náà jẹ́ tí orúkọ rẹ̀ njẹ́ Oyèkúnlé Azeez.
Ile iṣẹ ọlọpaa nipinlẹ Eko ti kede pe awọn ti mu afunrasi meji ti o lọwọ ninu bi awọn kan ṣe gun dokita kan ni ọ̀bẹ pa ni ile ẹkọ iwosan LUTH niluu Eko.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù BBNaija 2020: Trikytee àti Ozo ní wọ́n fọ́wọ́ òsì júwe ile fún ni bbnaija lọ́sẹ̀ yìí 2 Ògún 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 20 Owewe 2020 Oríṣun àwòrán, Instagram Gẹ́gẹ́ bí ìṣe ilé ẹlẹ́gbọ̀n àgbà, Laycon mórí ní wan kọ́kọ́ pè jáde sùgbọ́n lẹ́yìn o rẹyin Trikytee ni wọ́n júwe ilé fún.
Iko omo ogun Naijiria ti seku pa iko omo ogun olote boko haram merinla ti won si gba eniyan mokanlelogun ti o wa ninu ahamo labule Pulka nijoba ibilẹ Gwoza Local Government nipinle Borno sile.
Oríṣun àwòrán, Bella Naija Àkọlé àwòrán, Ẹsẹ iya kan ha sinu ile ẹru to subu naa Ko tan sibẹ, awọn ero mẹta mii, ti wọn wa ninu ọkọ tirela naa tun ni wọn gba ọna ọrun lọ lasiko ti ọkọ naa jabọ sinu odo Ogun.
Nibi ipade naa, Aarẹ Buhari ni ''ẹnikẹni to ba ro wi pe ohun lee ko awọn janduku sẹyin lati ji apoti ibo tabi da ibo ru n fi ẹmi ara rẹ ṣere ni.
20 Ògún 2020 Oríṣun àwòrán, others Ibeere nla to gab ọkan awọn eeyan orilẹ̀-ede Namibia ni ilel Afrika ni yii Minisita eto ilera orilẹ-ede Namibia, Kalumbi Shangula ti kilọ fun awọn ọmọ orile¬̣-ede naa pe ki wọn sọra fun lilo igbẹ erin fun iwosan arun Covid-19.
Bakan naa ni abẹrẹ ajẹsara naa yoo tun awọn sẹẹli ara ti arun Coronavirus ti bajẹ ṣe pada.
Bi o se ri bayii, osuwon ipolowo oja lori ero amohun-maworan ko wa ni ilana ti onibara re se po to,ti a ba n se agbeyewo re pelu awon akegbe re ni ekun alawo-dudu ile Africa.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Shiite: Àwa kọ́ la yìnbọn pa ọ̀gá ọlọ́pàá àti akọ̀ròyìn 23 Agẹmo 2019 Oríṣun àwòrán, KOLA SULAIMON Ẹgbẹ musulumi Shiite, Islamic Movement in Nigeria, ti sọ pe, awọn kọ lo ṣeku pa ọga ọlọpaa, Usman Musa ati akọroyin ileeṣẹ Channels.
Báwo ni a ṣe fẹ́ sọ fún un pé ọmọ ti kú?
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, EndSars, EndSwat Protest: Òbí agbábọ̀ọ̀lù Gbenga Tiamiyu Kaka àtàwọn míì tí ọlapàá pa sọ̀r O ni nkan to ku ti ijọba n ṣe ni lati ba ẹgbẹ ASUU lorukọ jẹ, idunkoko mọni ati pipa irọ fun ara ilu lati ri ẹgbẹ ASUU bi alaseju.
Bí ẹnikẹ́ni bá sì ń gbèrò láti ṣe ọ́ ní ibi tabi láti pa ọ́, OLUWA yóo dáàbò bò ọ́ bí eniyan ti ń dáàbò bo ohun ìní olówó iyebíye.
orílẹ ̀ -èdè kuwaiti ( , ) je ile-emiri arabu aladani to ni bode mo saudi arabia ni guusu ati irak ni ariwa ati iwoorun .
Ìjí idágbére ti wọ́ Elozonam àti Ike kúrò nílé ẹlẹ́gbọ̀n àgbà BBNaija Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Bi awọn kan ṣe n sọ idi ti wọn ko fi ro pe Naijiria yoo bori Cameroon bẹẹ ni awọn mii n ṣa n fẹ́ẹ̀ ki Naijiria bori.
”Lẹ́yìn náà, wọn yóo pada lọ sí ilé wọn.
Ṣugbọn wọn kò lè lọ nítorí pé àwọn ọkọ̀ náà bàjẹ́ ní Esiongeberi.
"Oríṣun àwòrán, Others Koda orin ti wọn n kọ nigba naa ni "" Olayode jọba, ilu toro nini."
Bakan naa lo ni ọrọ yiyọ ida kan abọ 1.
Ṣe akiyesi ẹni tí ń fi tọkàntọkàn ṣiṣẹ́ rẹ̀,àwọn ọba ni yóo máa bá ṣiṣẹ́,kì í ṣe àwọn eniyan lásán.
Ní ọjọ́ keje, oṣù kinni ọdún kọkanla, OLUWA bá mi sọ̀rọ̀, ó ní, 
Aare  Buhari ni“ Maa ki ara mi ku ori-ire .
Laipẹ yi ni ijọba ipinlẹ Kwara dẹwọ ofin to de akojọpọ fun ijọsin.
5) Ọlọ́wọ̀ ti ìlú Ọ̀wọ̀ - Olateru Olagbegi Keji: Ọdun 1941 ni Ọba yii gun ori ìtẹ́.
Ṣugbọn ọmọ naa ku, ko to o de ile.
Lẹ́hìn tí mo kì i tán mo bẹ̀rẹ̀ sí hùwwà bí ẹni pé kí ó bínú lọ; mo dákẹ́ n kò sọ̀rọ̀, ó sọ̀rọ̀ n kò rẹ̀rìn-ín, mo dìde níbi tí mo lé góńggó sí mo ṣiré lọ sí ìsàlẹ̀ àpáta, bẹ́ẹ̀ ni n kò tilẹ̀ wí fún un kí n tóó dìde, n kò tọro gááfárà lọ́wọ́ rẹ̀, bí ó ti yẹ kí n ṣe, nígbà ti mo si tún padà dé, mo bá a níbi tí mo fi í sí i mo sì tún rọra jókòó ní tèmi láìjẹ́ mo kí í, láìjẹ́ pé mo fọhùn sí i, láìjẹ́ pé mo tilẹ̀ wò ó lójú rárá, mo ń kọ̀rin, mo ń súfèé, n kò sì wí pé kí ó jókòó.
Premier League: Crystal Palace yẹ̀yẹ́ Arsenal bí Everton ṣe dígbájú ru Manchester U
Ojo kejilelogun, oṣu kẹfa ni idije naa waye.
Eto owo ina tuntun yii pin awọn to n lo ina manamana ni Naijiria si isọri marun un ni ibamu pẹlu bi kaluku ṣe n lo ina si.
Dafidi fún olùtọ́jú ẹrù àwọn ọmọ ogun ní oúnjẹ tí ó gbé lọ, ó sì sáré tọ àwọn ẹ̀gbọ́n rẹ̀ lọ sójú ogun láti kí wọn.
Ní gbẹ̀yìn, ọ̀ré gbé ìtìjú tà, ló bá sùn pé tí ó bá di kùtù hàì, òun yóò jí lọ́ sí ibi tí wọn sin ọ̀rẹ́ òun sí, pẹ̀lú èrò pé, òun nìkan yóò lè gbọ́n yẹ̀pẹ̀ inú ibojì jáde, owo àná yóò si di kíkó jáde.
Section 25 sọ wi pe ọmọ ti wọn ba bi si orilẹede Naijiria, to tun ni iwe ilẹ miiran ni asẹ labẹ ofin lati dije dupo.
 Àwọn ara portugal bẹ ̀ rẹ ̀ síí wá sí ibẹ ̀ ní nǹkan bí 1500 .
Man City pòkọ ìyà fún Swansea pẹ̀lú àmì ayò 3-2 nínu FA Cup Barcelona yóò kojú Man U nínú ìdíje Champions League Iyanrìn làwọn ẹbí olóògbé bàálù Ethiopia rí gbà dípò òkú Òkùnkùn biribiri ni ìjìyà ẹ̀ṣẹ̀ ìjọba ìbílẹ̀ mẹ́fà nílẹ̀ Ìjẹ̀ṣà tó na òṣìṣẹ́ àjọ amúnáwá Agbabọọlu aringbungbun Gylfi Sigurdsson lo fọba le fun Everton pẹlu ami ayo keji nigba ti ifẹsẹwọnsẹ ọhun de iṣẹju mejilelaadọrin.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ọkọ̀ akẹ́rù Dangote rọ́lu BRT lọ́nà Ikorodu, èèyàn kan kú, 59 farapa, ẹsẹ̀ dẹ́rẹ́bà gé Àwọn ọmọ Nàíjíríà ló ṣiṣẹ́ takò mí ní Ireland kí ń má baà wọlé ìbò Káńsélọ̀ - Yemi Adenuga Láti January lọ, gbogbo ẹni tó bá ra ọjà lórí ayélujára yóò máa sanwó orí - FIRS Aṣojú Seyí Makinde lásan ní mo jẹ, òṣìṣẹ́ gbọdọ̀ bọ̀wọ̀ fún mi - Ọ̀dọ́mọdé Kọmísánà Ilẹ Amerika ni ọpọ igba ni awọn ti kesi ijọba Naijiria lati se atunse lori iye owo ti wọn n gba lọwọ awọn ọmọ ile Amẹrika to ba fẹ wọ orilẹede Naijiria, eleyii ti wọn kọ ẹti ikun si.
Ẹwẹ, ipinlẹ Osun naa ti fun awọn araalu ni gbedeke Ọjọọru lati ri wi pe wọn da gbogbo ohun ti wọn jigbe pada.
Ojú kì í ti eégún nínú aṣọ
Ìre tí ó sú fún ẹ̀yà Aṣeri ni pé:“Ibukun ẹ̀yà Aṣeri ta gbogbo ibukun ẹ̀yà yòókù yọ,àyànfẹ́ ni yóo jẹ́ láàrin àwọn arakunrin rẹ̀,ilẹ̀ rẹ̀ yóo sì kún fún òróró olifi.
Ajọ to n ṣamojuto Ofin Sharia nipinlẹ Kano, Hisbah, ti kọ lẹta si ileeṣẹ agbohunsafẹfẹ kan to wa nipinlẹ naa, lori lilo àṣà 'Black Friday'.
Ninu iṣẹ ibanikẹdun to fi ṣọwọ si igbimọ alaṣẹ iwe iroyin Tribune, Makinde ni lootọọ ni mama ti ku, ṣugbọn ipa to ni lawujọ ko le parẹ laelae.
Ìgbà tí ó di ẹ̀ẹ̀kẹta tí ogiri bílà sẹ́yìn tí mo rí ojú ọ̀nà tí mo lọ pẹ̀lú àdá mi, mo gbé ẹsẹ̀mi kan, ó rọra fún díẹ̀, kò fún un pupọ̀, ṣùgbọ́n n kò lè fa ẹsẹ náà yọ mọ́.
Mo sọ fun iya mi pe mi o ti i ṣetan lati ṣe iṣẹ abẹ, nitori pe mo kọkọ fẹ ẹ pari ẹkọ mi.
Ní ọjọ́ kinni ati ní ọjọ́ keje, ẹ óo péjọ pọ̀ láti jọ́sìn.
akoṣẹmọṣẹ Onimọ iṣiro owo ti o ti ni iriri pupọ ninu iṣẹ iṣuna owo.
“Ojú yóo pọn yín tóbẹ́ẹ̀ gẹ́ẹ́, nígbà tí àwọn ọ̀tá yin bá dó tì yín, tí yóo fi jẹ́ pé àwọn ọmọ yín lọkunrin ati lobinrin, tí OLUWA Ọlọrun yín fun yín, ni ẹ óo máa pa jẹ.
BBCCopyright: BBC Ile igbimọ aṣofin agbaImage caption: Ile igbimọ aṣofin agba Article share tools Facebook Twitter ṢàpínlòView more share options Share this post Copy this linkKà síwájú síi nípa àwọn ìtọ́kasí wọ̀nyí.
Nígbà tí a gúnlẹ̀ sí òdì kejì tán, ó wí pé kí àbúrò òun tó jẹ́ iwin wá Fìlásayépọ̀ wá nní ibikíbi tí ó bá ti lè rii.
Iwa ipá ninu idile ti n bi ige ati Adubi ti ko faaye gba alaafia ninu igbeyawo mọ ni eyi ti awọn onimọ ti gba lọkọlaya lati tubọ ni suuru tabi ki wọn yẹra funra wọn ti ọrọ kò ba wọ mọ.
Mose bá pàṣẹ fún àwọn eniyan náà ní ọjọ́ kan náà, ó ní, 
Ni Deji ba fọnmu pe oun ko gba.
marun un nile ati lẹyin odi.
 “A n se eleyii lati mu ohun iwuri ba awon ọjẹwẹwẹ agbẹjọro , ki won lee se ariyanjiyan won ati ejo won niwaju awon adajọ  ile –ejo giga ,ti o wa niwaju lonii yii.
Nítorí Johanu wá sọ́dọ̀ yín ní ọ̀nà òdodo, ṣugbọn ẹ kò gbà á gbọ́.
Alukoro ọlọpaa ni ọwọ ọlọpaa tẹ Fatai plu iranwọ awọn fijilante ati ara adugbo lasiko to lọ fọ ile itaja nla kan ni Ajah.
Coronavirus: Àwíjàre ọlọ́pàá ni pé dókítà múra bíi onínàbì láago mẹ́wàá alẹ́
Wo àmúyẹ kí o tó lè di ọmọ ogun ilẹ̀ Nàìjíríà pẹ̀lú fọ́ọ́mù tó jáde yìí Ẹ̀bùn #500,000 wà fún ẹni tọ bá ba wa rí afurasí ikú Akinyẹle tó sọnù- Iléeṣẹ́ Ọlọ́pàá Ṣé òótọ́ ni pé ìgbẹ́ erin le è wo arùn Coronavirus sàn?
Alufaa yóo ṣe ètùtù fún un nítorí ẹ̀ṣẹ̀ tí ó ti dá, OLUWA yóo sì dáríjì í.
Yemi Elesho tún fi ẹnu já nǹkan níléeṣẹ́ BBC Ọ̀rọ̀ Coronavirus kì ń ṣe ṣeréṣeré o-K1 de Ultimate, Toyin Abraham Iyabode Ogunsola ni aṣa ailojuti, aṣa awọn oyinbo ni awọn oṣere ode oni ti gbe wọ ere tiata Yoruba.
odún 1969 ni orlando gbé ìyàwó .
Fayoṣe ní ìbéèrè mẹ́rin fún Buhari lórí ìwé ẹ̀rí rẹ̀ APC yọ orúkọ Shittu kúrò láti kópa nínú ìdìbò abẹ́lé NYSC ní Adeosun kòwé ransẹ́ láti gbààyè Diẹ lara awọn to dahun ibeere ọhun n fẹ ki Aarẹ Buhari sọ owo oṣu awọn oloṣelu dọgba pẹlu t'awọn oṣiṣẹ ijọba ni Naijiria.
Pasitọ Oba tun fi igboya sọrọ pe ''mo wa nibi ti ẹ ba fẹ gbe mi, ẹ wa gbemi.
Akọroyin ileesẹ wa BBC, Chris Ewokor to se akojọpọ iroyin naa lati Abuja ni, osu kejila ọdun to kọja ni wọn bi awọn ibeji naa nile iwosan alabọde kan to wa ni abule Chanka, nijọba ibilẹ Aikaleri, nipinlẹ Bauchi.
ati ile-ise agbofinro fowosowopo lati le gbogun ti iwa ibaje.
Nítorí náà, kí àwọn tí ó ń jìyà nípa ìfẹ́ Ọlọrun fi ọkàn wọn fún Ọlọrun nípa ṣíṣe rere.
Ẹ̀wẹ̀, ǹkan ti bẹ̀rẹ̀ si ni yatọ ni kéte ti àwọn ti wọn jọ n fi igagbága, bii Pete Buttigieg àti Amy Klobuchar ni àwọn ko ṣe mọ, ti wọn si yan Biden.
" A gbẹ́sẹ̀ lé ilé kan tó jẹ́ ti Bukola Saraki, torí àpò ìjọba ló ti mú owó sanwó ilẹ̀ - Ilé aṣòfin Irọ́ ni Cameron pa mọ́ mi lórí ọ̀rọ̀ àwọn akẹ́ẹ̀kọ́ Chibok- Jonathan figbe ta Ìrọ̀rùn dé l'Ekiti!
Ṣugbọn bí o bá ń ṣe nǹkan burúkú, o jẹ́ bẹ̀rù!
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Omiyale Ile Ife: Dukia sọfọ, awọn eniyan si tun farapa Bayii, ikilọ pataki ni ileeṣẹ eto ilera ti ipinlẹ Eko n kilọ bayii ni pe oju ni alakan fi n ṣọri.
2) Wọn gbọdọ ṣe agbekalẹ ilana Covid 19 lati tete de ile iwosan tabi ipese ayẹwo ni kia ti ifura ba wa.
Alakoso naa ti o woye pe iru idanilẹkọọ ati ilanilọyẹ bayii fun awọn ondibo ṣe pataki lati le jẹ ki awọn ondibo mọ awọn ojuṣe wọn ni asiko idibo, tun ke gbanjari lori bi iwa aifi-ifẹ han si eto idibo ṣe n pọ sii, eleyii to jẹ pe iko mẹrin ninu ida ọgọrun awọn eniyan to n forukọ silẹ lo n jade dibo.
Inú àwọn ará Ijipti dùn nígbà tí wọ́n jáde,nítorí ẹ̀rù àwọn ọmọ Israẹli ń bà wọ́n.
Tolani Alli ni o ti jẹ ayaworan fun gomina ipinlẹ Ọyọ tẹlẹ ri, Abiola Ajimobi.
Akọwe ipolongo fẹgbẹ oselu PDP, Kọla Ọlọgbọndiyan, ninu atẹjade kan to fisita loju opo Twitter ẹgbẹ PDP, lati fesi si gbajare ẹgbẹ APC ni, jinnijinni lo n da bo aarẹ ilẹ wa, Muhammadu Buhari ati ẹgbẹ oselu rẹ, APC, nitori ẹjọ ti awọn Atiku pe lati tako esi ibo to gbe BUhari wọle.
O ni, ọrọ yi ti n ja rain-rain nilẹ ki eto idibo sinu ẹgbẹ awọn akẹkọ to waye.
’ Amọ eyi ko ri bẹẹ mọ lode oni nitori isẹlẹ kan to waye lọjọ Ẹti ninu idile kan.
”Ó sọ fún wọn pé, “Ẹ má ṣe dẹ́rù ba ẹnikẹ́ni láti lọ́ wọn lọ́wọ́ gbà, Ẹ má ṣe fi ẹ̀sùn èké kan ẹnikẹ́ni.
Ọ̀rẹ́bìnrin míì dáná sí ọ̀rẹ́kùnrin rẹ̀ lára lẹ́yìn tó kọ̀ láti fẹ́ ẹ gẹ́gẹ́ bí aya Oríṣun àwòrán, verifiedNG Lẹyin bi ọsẹ meji ti ọdọbinrin kan danu sun ile ọrẹkunrin rẹ nibi ti ina ti mu ololufẹ rẹ to wa nile, ọdọbinrin mii tun ti dana si ọrẹkunrin rẹ lara ni ijọba ibilẹ Gboko nipinlẹ Benue.
Mercy Aigbe: Èmi ni ìyá onílé tuntun Àwòrán ìjàmbá igi tó rélu ọkọ̀ akérò l‘Èkó SARS já wọ ilé àwọn akẹ́ẹ̀kọ́ fásitì Akungba Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, 'Èèwọ̀ ẹ ò gbudọ̀ jajá mọ́ Saaju asiko idajọ yi, jijẹ ẹran aja ko wọpọ mo ni ilu naa nitori awọn ara ilu naa ti n sọ aja di nkan osin.
Ó bá ń sọ̀rọ̀ ìyìn rere fún wọn.
Oríṣun àwòrán, FACEBOOK/Saheed Alatise/Raheem Olawuyi Àkọlé àwòrán, Awọn oludije mejeeji A gbo wi pe ẹgbẹ oselu mẹwa lo fi oludije sile lati du ipo naa ṣugbọn nigba ti yoo fi di ọjọ iṣẹgun nise ni iroyin gbode wi pe awọn ẹgbẹ oṣelu meje ti pa imọran pọ lati yan Raheem Olawuyi gẹgẹ bi oludije wọn.
Ojogbon,Tijjani Bande,to je asoju orile ede Naijiria ni ajo UN  lo soju orile ede Naijiria nibi ipade naa to waye ni Berlin.
Ni irole ojo yen ni igbakeji aare tun lo si ile-ijosin Pentecostal to wa niluu Abuja.
Níbẹ̀ ni yóo máa gbé sunkún tí yóo sì máa payínkeke.
Ọkàn mi balẹ̀ bíi ti ọmọ ọwọ́ tó dákẹ́ jẹ́ẹ́.
Wọ́n wá siwaju ọba, wọ́n sọ nípa àṣẹ tí ó pa pé ẹnikẹ́ni kò gbọdọ̀ bèèrè ohunkohun lọ́wọ́ oriṣa kankan tabi eniyan kankan fún ọgbọ̀n ọjọ́, bíkòṣe lọ́wọ́ rẹ̀, ati pé ẹnikẹ́ni tí ó bá rú òfin yìí, a óo jù ú sinu ihò kinniun.
9 Èyí tí ó ní àkọsílẹ̀ àwọn ènìyàn tí wọn ti ṣubú nínú, àti ẹ̀kúnrẹ́rẹ́ ìhìnrere ti Jésù Krístì sí àwọn Kèfèrí àti sí àwọn Júù bákannáà.
Ahimaasi, ọmọ Sadoku bá sọ fún Joabu pé, “Jẹ́ kí n sáré tọ ọba lọ, kí n sì fún un ní ìròyìn ayọ̀ náà, pé OLUWA ti gbà á lọ́wọ́ àwọn ọ̀tá rẹ̀.
Àwọn ni wọn óo máa jẹ ẹbọ ohun jíjẹ ati ẹbọ ìmúkúrò ẹ̀ṣẹ̀ ati ẹbọ ìmúkúrò ẹ̀bi, àwọn ni wọ́n ni gbogbo ohun tí a bá yà sọ́tọ̀ ní Israẹli.
Ọjọ kọkanlelogun, Osu Keji,ọdun 2019 ni o pe ogun ọdun ti Oba Folagbade Olateru-Olagbegi III gun ori itẹ baba rẹ.
Ninu ọrọ ti awọn agbarijọpọ awọn ẹgbẹ ajafẹtọẹni, wọn ni ipe Buhari yii tako ofin orilẹede wa, Aarẹ apapọ fun ẹgbẹ naa, Malachy Ugwummandu ni ọrọ Buhari naa dabi igba to n gba ojuse ẹka eto idajọ se ni, eyi ti ojuse rẹ wa lati maa tumọ iwe ofin orilẹede yii.
Ọwọ ọlọpaa tẹ eeyan mẹwa lori wahala Kaduna
Adajọ ileẹjọ majisireti Okiti-pupa nipinlẹ Ondo, Banji Ayeomoni pẹlu ọmọkunrin rẹ, Dara ati ibatan wọn kan to fi mọ awakọ la gbọ pe wọn se agbako iku ojiji naa.
Oríṣun àwòrán, Twitter/Sanwo-Olu Sanwo-Olu sọ ọrọ yii lasiko to n kede awọn igbesẹ tuntun ti wọn gbe lati de awọn ofin to de arun Coronavirus ni ipinlẹ Eko.
Ṣùgbọ́n kàkà bẹ́ẹ̀, n ó máa bá ìyàwó mi ṣe àwàdà, n ó máa bá a rẹ́rìn-ín, n ó máa báa ṣiré titi ọjọ́ ayé mi.
Atẹjade naa tun fi lede pe ki pasiparọ yii ati bibẹrẹ iṣẹ waye ni kiakia.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ikú Olumegbon: Ọdún mọ́kàndínlọ́gọ́ta ló lò lókè èèpẹ̀, kó tó mí kanlẹ̀ 25 Ẹrẹ̀nà 2019 Oríṣun àwòrán, Fatai Olumegbon Àkọlé àwòrán, O jade laye ni orilẹede Ghana lọjọ kẹrinlelogun oṣu Kẹta lẹni ọdun mọkandinlọgọta.
Ilu Auchi ni wọn ti bi Toyin Abraham ni ogoji ọdun sẹyin ṣugbọn ilu Ibadan lo ti lo ibẹrẹ aye rẹ.
Ǹkan tí a mọ̀ nípa kọ́lẹ̀jì olùdìbò tó ń fìdì ẹni ti yóò jẹ ààrẹ ilẹ̀ Amérika múlẹ̀ Banki Nàìjíríà, CBN ṣàlàyé nípa àwọn tó máa rí gbà nínú owó ìrànwọ́ N75b tíjọba gbé kalẹ̀ Wo iye owó tí ìjọba Amẹrika ń na sí ìdìbò Ààrẹ àti ibi tí owó náà ti ń wá Ǹkan tí a mọ̀ nípa kọ́lẹ̀jì olùdìbò tó ń fìdì ẹni ti yóò jẹ ààrẹ ilẹ̀ Amérika múlẹ̀ Wo iye owó tí ìjọba Amẹrika ń na sí ìdìbò Ààrẹ àti ibi tí owó náà ti ń wá Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí 6:30 Fídíò, Akomolede ati Aṣa lori BBC: Mọ̀ si nípa oríṣìí ẹ̀ka ìsọ̀rí ọ̀rọ̀ àti ìwúlò wọn, Duration 6,308 Owewe 2020 5:55 Fídíò, Soyinka Cancer: Àṣe ara mi ni iso ti n run gbogbo bí mo ṣe n ṣèrànwọ́ lórí jẹjẹrẹ, Duration 5,5527 Bélú 2019 2:08 Fídíò, John Amanam: Ìfẹ́ tí mo ní sí àbúrò mi ló sọ mi dí ẹni tó ń ṣe 'Prosthetic' báyìí, Duration 2,081 Bélú 2020 5:52 Fídíò, Akomolede àti Aṣa: Ọ̀rọ̀ Ẹ̀yán ni Bunmi Femi Amao ń kọ́ wa lórí ètò Akọ́mọlédè àti Àṣà lórí BBC Yorùbá, Duration 5,5224 Owewe 2020 Èyí tí a wò jùlọ 5:03 Fídíò, Omolola Arohunmolase Welder: Mo ti fí iṣẹ́ 'Welder' gbayì láwùjọ, tó mo fi tọ́ ọmọ yanjú, Duration 5,039 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 5:39 Fídíò, Akomolede ati Asa lori BBC: Olùkọ́ Kikelomo Ogunboye tan ìmọ́lẹ̀ sí ìwà olè ọ̀gá ọlọ́pàá Audu gẹ́gẹ́ bí àwòkọ́ṣe àsìkò yìí, Duration 5,398 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 4:11 Fídíò, Oba Adeyeye Ogunwusi: Ojú mi ti rí lọ́pọ̀ lọpọ̀, ọ̀pọ̀ èèyàn ni kò tilẹ̀ gbàgbọ́ pé mo lè jọba- Ooni, Duration 4,117 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 4:43 Fídíò, Promise Akinlade: ọmọ ọdún mọ́kànlá tó ń fi ìlù dárà bíi àgbàlagbà sọ̀rọ̀ nípa tálẹ́ǹtì rẹ̀, Duration 4,437 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 0:59 Gbọ́, Ìsẹ̀lẹ̀ jákèjádò orílẹ̀èdè àgbáyé láàárín ìṣẹ́jú kan, Duration 0,59wákàtí 5 sẹ́yìn 7:03 Fídíò, Olumuyiwa Bolade Adedeji Military Bruitality: Bí arákùnrin onípèníjà ara tí sọ́jà lù ṣe dé, Duration 7,035 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 4:45 Fídíò, Yoruba Films: Ẹ̀ẹ́ bẹ̀ mi kúrò láyé ni, mi ò lè kú - Fadeyi Oloro, Duration 4,4526 Èrèlè 2020 2:48 Fídíò, Esther Ajayi: Èmi náà ti borí ìṣòro rí ló ń mu mi ṣojú àánú, Duration 2,481 Ògún 2019 6:08 Fídíò, Adebola Ademilua: Àìrísẹ́ ṣè lẹ́yìn ìwé kíkà ló sọ mi dí ìyá onírú, mo dúpẹ́ tèmi, Duration 6,0827 Bélú 2020 5:55 Fídíò, Soyinka Cancer: Àṣe ara mi ni iso ti n run gbogbo bí mo ṣe n ṣèrànwọ́ lórí jẹjẹrẹ, Duration 5,5527 Bélú 2019 BBC News, Yorùbá Ìdí tí ẹ fi le è nígbàagbọ́ nínú ìròyìn BBC Ìlànà Lílò Nípa BBC Òfin Àṣírí Cookies Kàn sí.
Ni ọ̀sẹ̀ tó kọjá, èmi àti àwọn ọ̀rẹ́ mi kan rin ìrìnàjò-ìgbafẹ́ lọ sí ìgbèríko kan.
Koda, awọn miran tiẹ foju laifi wo kaadi ọjọ ibi ti ẹgbẹ akẹkọ naa gbe fun Buhari lati fi ki ku oriire ọjọ ibi.
Àwọn ọ̀nà tí obìnrin fi le gbádùn ìbálòpọ̀ Wo oríṣiríṣi ìgbádun ibálòpọ̀ láwọn orílẹ̀èdè mìíràn Lẹni ọdun mọkanlelogun, Leanne ko tii ṣe Leanne bi ẹni to fẹ ni ibalopọ ri rara.
Lẹyin naa, ọpọ eeyan bẹrẹ si ni beere wi pe ki ni Olori n ṣe gan an?
Owoeye ni Adeleke ṣi yi ni ẹjọ niwaju ile ẹjọ kotẹmilọrun Abuja fun idi eyi,ki awọn eeyan ma ṣe gba ọrọ ẹgbẹ PDP gbọ lori pe Adeleke le du ipo Gomina.
 lójú rè , wàhálà tí ènìyàn ni láti sa agbara láti yo ara eni kúrò ní ipò eni àá fojú ténbélú ( inferiority complex ) .
Yorùbá dùn lédè, ẹ máa sọọ́ Ẹfunroye Tinubu - Ògbóǹtagí oníṣòwò, olówò ẹrú àti afọbajẹ Samuel Ajayi Crowther, òjíṣẹ́ Ọlọ́run tó gbé èdè Yoruba lárugẹ O mẹnuba ominira ninu ede ti ko si fun iran Yoruba ni Port Novo tẹlẹ ṣugbọn ti ayipada ti de ba bayii.
Aare sọ pe isakoso rẹ yoo da lori  otitọ ati lati je ki awon eniyan lo  agbara ati ipa won lona ti idagbasoke yoo se de
Ìlérí yìí dájú, ó sì ṣe é gbẹ́kẹ̀lé.
Ninu ifọrọwerọ rẹ pẹlu BBC Yoruba, agba ọjẹ olorin Juju naa ni, ifarajin ati ọpọ suuru loun ṣe, ki o to di pe oun wa di ologo laarin awọn olorin Juju.
baba Meraiotu, baba Amaraya, baba Ahitubu; 
Ìjà orogún méjì ní London, Arsenal àti Tottenham ta ọ̀mì Wike kìí ṣe dọ́là tí Ganduje leè kó sápò- Agbẹ́nuso ìjọba ìpínlẹ Rivers Digbi n'ijọba Kogi wa - Yahaya Bello Laipẹ́, ọmọ tí kò bá pé ọdún méjìdínlógún kò ní leè jáde girama l’Ọṣun O pọ́ndandan kí a tẹti si ariwo ọja nítori pe oniruuru eso ló wà nibẹ̀ bẹ́ẹ̀ náà lo ṣe ri pé ẹka oniruuru ni o wa ninu ọja, sùgbọ́n ẹgbẹ́ oní ìgbalẹ̀ yóò sọ ara rẹ̀ dí òṣùṣù ọwọ̀ láti gbá gbogbo ìdọti àti ẹyin wá dànù èyi si ni à ó lò lati jáwe olú bori"" Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?"
Ṣùgbọ́n nígbà tí Àgùntàn-ìnàkí ń bọ̀ ṣe ni ó bẹ̀rẹ̀ sí pariwo tí ó ń kígbew ńlá tí ohùn rẹ̀ sì gba gbogbo igbó kankan.
 akin olúṣíná fẹ ́ ràn ẹran ìgbẹ ́ .
Pilatu bá fún un ní àṣẹ láti gbé òkú Jesu.
Aarẹ al-Bashir fun ra rẹ gori oye lẹyin ti awọn ologun fipa gba ijọba lọdun 1989, ko to di akoko yii ọpọ igba awọn ologun ti gbiyanuju lati fipa gbajọba lorilẹede Sudan.
Nígbà tí àjọ̀dún ti fẹ́rẹ̀ kọjá ìdajì, Jesu lọ sí Tẹmpili, ó ń kọ́ àwọn eniyan lẹ́kọ̀ọ́.
Gẹgẹ bi aarẹ ṣe sọ, igbesẹ yii yoo dena bi kiko ounjẹ wọle lati ilẹ okeere ṣe n ṣakoba fun idagbasoke eto ọgbin labẹle.
Iroyin to n tẹ wa lọwọ bayii ni yajoyajo n fi ye ni pe, igbakeji akọwe apapọ ẹgbẹ oṣelu APC, Victor Giadom ti bọ sori oye gẹgẹ bii adele alaga apapọ ọgbẹ oṣelu naa.
Ni Òkè-Òkun, Gó́́mìnà, àgbà Òṣèlú àti bẹ́ ẹ̀ bẹ́ ẹ̀ lọ kò kọjá òfin.
Ṣugbọn Joabu bi ọba léèrè pé, “Kí OLUWA Ọlọrun rẹ jẹ́ kí àwọn ọmọ Israẹli pọ̀ jù báyìí lọ, ní ìlọ́po ọ̀nà ọgọrun-un (100), nígbà tí oluwa mi ṣì wà láàyè; ṣugbọn, kí ló dé tí kabiyesi fi fẹ́ ka àwọn eniyan wọnyi?
awuywuye ti n lọ ni igboro pe ṣiṣe agbekalẹ isuna-owo ilu ọlọdọdọdun ti ọdun 2019 yii ti pẹ
Afrin ni awon omo ogun Turkey tedo si losu to koja lati figbogun ti awon omo ogun olote YPG ti Kurdish eyi ti Anjkara gba pe agbesunnmomi ni won je.
Àwọn Juu ni yóo kọ́kọ́ kàn, lẹ́yìn náà àwọn Giriki.
A gbé ọkunrin yìí lọ sí ọ̀run kẹta.
Awọn ọlọpaa naa yabo ile igbimọ aṣofin naa pẹlu ọkọ wọn, ti wọn si duro wamuwamu sibẹ.
Awọn mejeeji ti ọrọ naa ṣẹ si gbọdọ duro jẹẹ.
Ile iṣẹ ijọba idagbasoke ọdọ ati ere idaraya Agunbanirọ obinrin, Joana Kolo ni Gomina ipinlẹ Kwara yan gẹgẹ bi kọmiṣọnna ile iṣẹ ijọba to n ri si ọrọ idagbasoke ati ere idaraya.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Apapa gridlock: Ìjọba àpapọ̀ ní òun kò ní gbà kí wọ́n ba ọrọ̀ ajé ilẹ̀ yìí jẹ́ 14 Òkùdu 2019 Igbakeji Aarẹ Yemi Osinbajo ti sun gbedeke igba to fun awọn awakọ tirela ti wọn wa loju ọna Apapa ni ọsẹ meji si, lati palẹ gbogbo ọkọ wọn mọ.
10 Ṣùgbọ́n ìran yìí yíò gba ọ̀rọ̀ mi nípasẹ̀ rẹ.
Eniyan á wá sọ igi lásán tí ó gbẹ́ di oriṣa, á sì máa foríbalẹ̀ fún un.
Mo kó ọ̀rọ̀ ọba ìlú pàápàá jùnù, tèmi ló tọ́, èyí tó wùnmí ni mo şe.
Ile-ise akoroyin Voice of Nigeria, ti sefilole gbagede idanileko fun awon osise akoroyin niluu Abuja.
títí di ọjọ́ tí Lọti fi jáde kúrò ní Sodomu, tí Ọlọrun fi rọ̀jò iná ati òkúta gbígbóná lé wọn lórí, tí ó pa gbogbo wọn rẹ́.
Bẹ́ẹ̀náàni Ìyá oge ọlọ́wọ́ ọ síbí ti orúkọ́ wọ́n njẹ́ Tóyìn Sùlàìmán.
Gomina lpinle Osun, Adegboyega Oyetola ti ba awọn ọmọ ipinlẹ naa yọ latari pipe ti ipinlẹ naa pe ọdun mejidinlọgbọn.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Ajọ to n to n ri si idagbasoke kaakiri agbaye(CGD) ṣalaye pe o buru jai lawọn orilẹede ti ko rọwọ họri.
Wo àwòràn ohun tó ṣẹlẹ̀ nílé ìjọsìn Sotitobire tí wọ́n sun ní àná Ọlọ́pàá bẹ̀rẹ̀ ìwadìí lórí ikú olùṣirò owo táwọn agbénipa pa ní Ikorodu Gbajue ń lọ orúkọ mi láti gba owó- Mama Rainbow Wo ìdí tí Tẹni, ọ̀dọ́mọdé olórin obìnrin kìí fi ń ṣí ìhòhò rẹ silẹ̀ Abala keji yoo waye losu kinni, ọdun 2020, nibi ti ile aṣofin agba ni Washington yoo ti ṣe igbẹjọ rẹ boya o jẹbi ẹsun ti wọn fi yọọ nipo.
Oríṣun àwòrán, oyoinsight Gomina Seyi Makinde rawọ ẹbẹ naa lasiko to lọ silu Oyo lati si ibudo ilera alabọde kan nilu Oyo, ti Alaafin tilu Oyo, ọba Lamidi Olayiwola Adeyemi kẹta si gbalejo rẹ .
Bakan naa lo tun gbaṣẹse fun ileeṣẹ Chevron Oil Nigeria Limited fun ọgbọn ọdun, lati ọdun 1989 si 2019.
"Idi si re e ti Adegbọrọ naa fi maa n da wọn lohun pe: ""Ẹni ti ko ba ṣe bii alaaru l'Oyingbo, ko lee ṣe bii Adegbọrọ l'ọja Ọba""."
Ijọba só di mimọ pe igbesẹ naa tọna lẹyin ipade pẹlu awọn lọbalọba ni ipinlẹ Ọyọ.
Àdánwòo Alaa jọ ti ọ̀pọ̀lọpọ̀ ọmọ orílẹ̀-èdè Íjípìtì tí ó wà ní ẹ̀yin gádà nítorí akitiyan wọn nípa ẹ̀tọ́ ọmọnìyàn.
Bakan naa, Ọjọgbọn Bande ti gba oye ọlọla to gaju lọ lorilẹede Naijiria gẹgẹ bi ara ilu, iyẹn ‘Officer of the Order of the Federal Republic (OFR)’.
Ijọba ipinlẹ Eko ti fesi si iroyin iwadii CNN lori ohun to waye ni Lekki Toll gate logunjọ, oṣu kẹwaa, ọdun 2020.
Má bẹ̀rù nítorí mo wà pẹlu rẹ,n óo kó àwọn ọmọ rẹ wá láti ìlà oòrùn,n óo sì ko yín jọ láti ìwọ̀ oòrùn.
OLUWA Ọlọrun àwọn ọmọ ogun ní: “Ẹ̀yin ọmọ Israẹli, n óo rán orílẹ̀-èdè kan láti pọn yín lójú, wọn yóo sì fìyà jẹ yín láti ibodè Hamati, títí dé odò Araba.
Èyí ni òfin tí ó ga jùlọ, òun sì ni ekinni.
Awọn onimọ nipa iṣuna fi kun un pe kii ṣe ọwọ Laycon ni ijọba ipinlẹ to ba kan yoo ti gba owo ori yii bi ko ṣe latọwọ ileeṣẹ to ṣeto idije agbelewo BBNaija naa.
" Ajọ̀ WTO lo ma n mojuto ijiroro ati adehun okoowo laarin awọn orilẹ-ede.
Àwọn Ọba alayé ní Naijiria ṣàbẹ̀wò sí Ọba Eko, Gómìnà Eko àti Bola Tinubu lẹyin ìwọ́de EndSARS Ṣé ẹ rántí àkọ́lé àwọn ìwé àkàgbádùn yìí?
Ọga agba ajọ ọlọpaa tun ni wọn yoo ṣe ilana tuntun jade fun awọn ọlọpaa lori kikoju awọn adigunjale atawọn iwa ipa mii.
Ó pe àwọn eniyan ati àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀, ó wí fún wọn pé, “Bí ẹnikẹ́ni bá fẹ́ máa tọ̀ mí lẹ́yìn, ó níláti gbàgbé ara rẹ̀, kí ó gbé agbelebu rẹ̀, kí ó wá máa tẹ̀lé mi.
Bẹ́ẹ̀ gẹ́gẹ́, ikọ̀-ọba orílẹ̀-èdè America tẹ́lẹ̀ sí ìlú Nepal Scott DeLisi fi ọ̀pọ̀ ọdún wá ẹyẹ yìí  àti láti ya àwòrán-an rẹ̀.
22 Èbibi 2020 Oríṣun àwòrán, femi adebayo Yoruba ni oju to ba dilẹ, ohun ni rorẹ n sọ.
Ahinadabu, ọmọ Ido ni alákòóso agbègbè Mahanaimu.
Elisha Abbo: kí ẹnikẹni ma halẹ̀ mọ Kayọde mi, ẹjọ wà nile ẹjọ́
1993 Wọn dibo yan an gẹgẹ bi aarẹ ẹgbẹ awọn obinrin nilẹ Afrika.
obayeje yii se n ba awon opa epo jẹ ,n se akoba fun opolopo ohun ini awon ti
Nkan bii aadọta dun lo fi ṣejọba, Sultan Qaboos lo wa ni ori akoso igbe aye oṣelu orilẹede Oman nibi ti eeyan to fẹrẹẹ to miliọnu mẹrin abọ o le diẹ (4.
Bakan naa ni iroyin ọhun sọ pe awọn eniyan n duro ki ojo to n rọ da labẹ ile naa ni afi to di wọ̀ọ̀ nilẹ.
Eww, igberu n ba owo naira ninu oja pasi-paro naa, ni eyi ti naira wa lori irinwo din-die N360 si dollars kan ni abala awon alagbata ifiwera, ti a mo si Bureau De Change.
O si tun kilọ fun awọn ọlọpaa pe wọn yoo wọ gau ti wọn ba n mu ọti lẹnu iṣẹ.
 ní Ìwọ ̀ oòrùn Èkìtì gẹ ́ gẹ ́ bí ìwádìí ṣe fi hàn .
Ọmọ Nàìjíríà, àfikún owó iná tuntun bẹ̀rẹ̀ lónìí: ọjọ́ kínní, oṣù kẹsàn án, ọdún 2020- NERC, Disco Ọwá Ale Ikarẹ, Oba Adegbite-Adedoyin papòdà lẹ́ni ọdún márùndínláàdọ́rùn ún!
Oríṣun àwòrán, Genesis Global Wo ìròyìn tuntun tó tún jáde laááàfin Oòduà nípa Àrẹ̀mọ tuntun Ọọ̀ni Ile Ifẹ̀ N1M ní iléẹ́jọ́ béèrè fún béèlì olùwọ́de EndSARS, Eremosele Adene Ìtàn ayé Abiola Peller, ọlọ́wọ́ idán tó fi ọ̀bẹ gé ìyàwó rẹ̀ sí méjì Wo ìròyìn tuntun tó tún jáde laááàfin Oòduà nípa Àrẹ̀mọ tuntun Ọọ̀ni Ile Ifẹ̀ Amotekun gbàràdá ní ìpínlẹ̀ Oyo Èmi ni mo fẹ́ ṣíwájú ìwọ́de ọ̀dọ̀ tí yóò tún wáyé-Oluwo Wooli Oladele ti ṣe olootu oniruuru awọn eto lori mohunmaworan àti Redio jakejado orile-ede Naijiria.
Olubadan bi o se n yan Mogaji ati Baale lona aito.
 Oun ni ololufẹ David de Gea, adiẹyin mu to jẹ ọmọ ilẹ Spain.
Ministerial Position: Gbogbo àwọn ilé iṣẹ́ tí ààrẹ yàn mínísítà fún lo ti wà tẹ́lẹ̀
Ileesẹ ọkọ ofuurufu Dana sọ wipe ''o ṣoro ki ilẹkun baalu ṣi silẹ funrarẹ ti kii ba se wi pe ero kan lo gbiyanju ati ṣii.
Loju opo Instagram rẹ, Alhaja Fausat Balogun, ti gbogbo eeyan mọ si Sajẹtiologa naa ti kede iku gbajugbaja osere naa.
Oríṣun àwòrán, Twitter/Govt of Nigeria Hushpuppi di gbajúmọ̀ ẹlẹ́wọ̀n tó ní nọ́ńbà l‘Amẹrika, orúkọ̀ rẹ̀ wà lórí ayélujára Nǹkan tí ojú rí rè é bí pápákọ̀ òfurufú ṣe di ṣíṣí padà ní Nàìjíríà Ṣé lóòtọ́ ni Lateef Adedimeji àti Adebimpe Oyebade ṣe ìgbéyàwó?
 a tún ní àwọn mìíràn bíi science fiction ( mérìírí ti sáyéńsì ) , action film ( oníjàgídíjàgan ) àti adventure films ( ìtàn lórí ìwádìí ) tí kò tíì bẹ ̀ rẹ ̀ lọ ́ dọ ̀ wa níbí .
dara ki wọn jẹ ki yiyan awon adari ajọ eleto aabo kaari ni awon ẹkun to wa
O tẹsiwaju pe Smitt fun oun lasẹ, to si fọwọ si lati maa fẹobinrin naa, eyi to fidi rẹ mulẹ pe, tọkọtaya gbajumọ osere yii dijọ n ni ifẹ miran nita gbangba lẹyin igbeyawo wọn.
Pápà mímọ́: Ọlọ́run yóò fi ẹ̀mí ìbágbépọ̀ rere sí Nàíjíríà
O bu ẹnu atẹ lu awọn olori orilẹede Naijiria pe ti ara wọn nikan ni wọn n le kiri nipa kikọ ile nlanla, ti wọn si n rinrinajo kaakiri orilẹede Naijiria.
Nítorí ẹ dàbí ibojì tí kò ní àmì, tí àwọn eniyan ń rìn lórí wọn, tí wọn kò mọ̀.
Namibia yoo san owo  gba-ma binu to le ni  ẹ̀gbẹ̀rúnlona-ọgọ́rùn ún dola($8,330; £5,798) owo orile ede naa fun awon ebi eniyan ti eranko bi I ooni ati erinmilokun pa.
Ibi ìkọlu ọgbà ẹ̀wọn naa ni a gbọ́ pé ó ti pàdánù ojú rẹ̀ kan.
Ṣe ni wọn dana sun awọn ohun Eelo, oogun atawọn ohun miran ti ọwọ wọn ba nibẹ lasiko iwọde naa.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Iya Woli: Ẹ̀mí ìjókíjó, Wòó, Ṣọ̀kí, Wojú, Ṣàkùṣákù, One Corner.
Oriṣiriṣi ọrọ lo tun ti n jade bii ka maa yi ẹnu pada.
Ààrẹ àkọ́kọ́ to kọjú Boko Haram, ségun wọn Ohun ìdùnnú miran ti aarẹ Umar Musa Yar'adua tún ṣe, tàwọn ọmọ Nàìjíríà kò fi ní gbàgbé rẹ ni pé, òun ni aarẹ àkọ́kọ́ to fojú wina ikọ asekupani Boko Haram, tó sì wá ọwọ rẹ bolẹ nígbà náà, kí ikọ ọ̀hún tún tó gberi dìde.
Baba rẹ, tí ó rí ohun tí ó wà ní ìkọ̀kọ̀ yóo sì san ẹ̀san rẹ fún ọ.
Sosogee ni oun ko ri idi kan fun Djxgee lati pa ara rẹ nitori iṣẹ to fẹran naa lo n ṣe, ti o si jẹ awokọṣe fun ọpọlọpọ awọn eeyan, paapaa julọ awọn aforin-danilaraya nibi ayẹyẹ, iyẹn DJ ẹgbẹ rẹ.
Àjọ NAFDAC fọwọ́ sí pípo ògùn chloroquine fún àyẹ̀wò ìtọ́jú coronavirus Èyí ni àwọn tí òfin kónílé-ó-gbélé tí ààrẹ Buhari pa l'áṣẹ kò kàn ní Eko, Ogun àti Abuja Coronavirus: Àwọn ohun tí a kò tíì mọ̀ síbẹ̀ nípa àrùn Covid-19 Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Coronavirus: Ìjọba London ti da ọlọ́pàá sí ìgboro láti mú ẹni tó bá ń rìn gbéregbère Iye awọn ti wọn ti gba itoju bayii ti di mẹjọ.
Ọpọ to ba ri mi ko ni i mọ pe mo bi to ọmọ mẹtadinlogun.
EFCC - BBC News Yorùbá BBC News, YorùbáFò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Yahoo Boys: Àwọn ọmọ Yahoo tí kò dín ní igba ni yóò fojú ba ilé ẹjọ - EFCC 31 Ọ̀wàrà 2019 Oríṣun àwòrán, @officialpagemagu Àkọlé àwòrán, Ibrahim Magu Adele alaga ajọ to n ri si iwa jẹgudujẹra lorilẹede Naijiria, Ibrahim Magu, ni o ti fi aidunnu rẹ han si iwa ti iya awọn afẹsunkan lori ọrọ jibiti lilu lori ayelujara ti a mọ si Yahoo Boys.
Lootọ ni pe otutu ara kii ye l'ode ara lasiko ooru, sugbọn a ko le sọ ipa ti o le ni lara arun tuntun coronavirus.
Mo ni lati jade sita lati wa ọna ati ran ara mi lọwọ"" Pẹlu iranlọwọ ọrẹ rẹ kan to maa n kun bata, Whekole bẹrẹ si ni nu bata fawọn eeyan."
Collapsed Building: Ẹ̀mí kankan kò bọ́ nínú ilé míràn tó wó ládugbó Kakawa l'Eko
"Ń ó sọkalẹ lórí aléefa lọ́dun 2023, ń o si ni ráàye láti dupo kankan lọ́jọ́ iwáju.
Trump ko ni aridaju gbogbo ọrọ rẹ to n sọ pe awọn eeyan Biden n gbiyanju pe ki wọn ka ibo toun ti pe wọn ko jẹ ibo to tọ.
Wọ́n sì ti pa ọ̀rọ̀ rẹ mọ́.
Iyawo taku pe oun ko fẹ kọ ọkọ oun Gbogbo igba ni ọkọ mi maa nfura si irin ẹsẹ mi debi pe o tun ngboorun pata mi nigba kuugba ti mo ba pada de lati ode."
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Buhari ba Aarẹ Xi ti China yọ 17 Ẹrẹ̀nà 2018 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Buhari ba aarẹ China, Xi Jinping yọ Aarẹ Naijiria, Muhammadu Buhari ti ba Aarẹ orilẹede China, Xi Jinping, yọ lori saa oye aarẹ tuntun ti igbim asofin ile rẹ fi jẹ.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Olootu Trudeau ni bo tilẹ jẹ pe awọn ara ilẹ Canada fẹran lati gbalejo awọn ladelade, ipade gbọdọ waye nipa bi eyi yoo ṣe waye, ati bi gbogbo rẹ yoo ṣe lọ.
Àwọn ọmọ Israẹli tún ṣe ohun tí ó burú lójú OLUWA lẹ́yìn ikú Ehudu.
ohun to n ṣẹlẹ ni pato laarin Ile Igbimọ Aṣofin ati Igbimọ Amuṣẹṣe.
Oríṣun àwòrán, AFP Àkọlé àwòrán, Nipari, ẹrin lawọn ọmọ ẹgbẹ agbabọọlu obirin orilẹede Ghana bu si l'Abidjan lẹyin igba ti wọn ṣẹgun olugbalejo wọn, ẹgbẹ agbabọọlu Ivory Coast, lati gba ife ẹyẹ awọn obirin Iwọ-oorun Afrika - West African Football Union (UFOA) zone B women's tournament.
Bí ẹni meji tabi mẹta bá jẹ́rìí pé ẹnìkan ṣá Òfin Mose tì, pípa ni wọn yóo pa olúwarẹ̀ láì ṣàánú rẹ̀.
Obìnrin tó bá fẹ́ wọn, igbó Sambisa ló lọ - Lizzy Anjorin Ó mà ṣe o!
Ojú alágbe ni wọ́n fi ń wo alága ìdúró- Ayo Oladokun Ìpanu ‘Cheese ball’ ni wọ́n fi jí Ikimot gbé, àmọ́ ó padà sílé lẹ́yìn ọdún márùn-ún ìfipábánilòpọ̀: Má dákẹ́ - Oluwaseun SERAP tun rọ ileẹjọ ICC lati kan an nipa fun awọn alaṣẹ ijọba Naijiria lati rii wi pe, ọgọọrọ awọn ọmọde ti ko si nile iwe lanfani lati pada sile ẹkọ.
Oríṣun àwòrán, @IsiakaAdeleke1 Àkọlé àwòrán, Awọn ọmọ ẹgbẹ oṣelu PDP meji kan, rasheed Ọlabayọ ati Idowu Oluwaseun, ni wọn gba ile ẹjọ lọ pẹlu ẹbẹ pe ki ileẹjọ paṣẹ lati da Adeleke lọwọkọ gẹgẹ bii oludije PDP Adajọ ni oun rii pe olujẹjọ naa, iyẹn sẹnetọ Ademọla Adeleke, ka iwe de ipele girama eleyi to ni o fi han ninu iwe ibura to fi ran'sẹ si ile ẹjọ naa.
Nigba ti o wa n sọrọ lori ọna abayọ fun eto idibo to dan mọran lorilẹ-ede Naijiria, Ṣoworẹ ni gbigba ilana idibo igbalode, (electronic voting) laaye yoo ṣe ọpọ anfani fun ilọsiwaju eto idibo ati iṣejọba awarawa lorilẹede Naijiria.
Xenophobia: Naijiria á kọ́kọ́ pèsè ọ̀nà láti bá ẹbí sọ̀rọ̀ fún wọn
Ṣugbọn ọrọ ko ri bẹ ti Ibrahim Idris ati adele rẹ ti jọ ṣe ipade pẹlu Aarẹ Buhari nile ijọba ki Idris to tọwọbọ iwe ni afihan idagbere ati iwọle sipo adele ree tuntun.
Ó ní: “Àwọn ará Gasa ń dẹ́ṣẹ̀ kún ẹ̀ṣẹ̀, dájúdájú, n óo jẹ wọ́n níyà; nítorí odidi orílẹ̀-èdè kan ni wọ́n kó lẹ́rú, tí wọ́n lọ tà fún àwọn ará Edomu.
Ẹ̀yin ará, a fẹ́ kí ẹ mọ ohun tí oore-ọ̀fẹ́ Ọlọrun ti ṣe láàrin àwọn ìjọ Masedonia.
Nítorí náà, ranti bí o ti ga tó tẹ́lẹ̀ kí o tó ṣubú; ronupiwada, kí o sì ṣiṣẹ́ bíi ti àkọ́kọ́.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Coronavirus: Ushbebe, adẹ́rínpòṣónú ní bí ìjọba ṣe fòfin de ìrìnàjò wọlé láti ilẹ̀ òkèrè mú òun pàdánù owó l 20 Ẹrẹ̀nà 2020 Oríṣun àwòrán, Instagram/ushbebecomedia Igbesẹ ijọba apapọ orilẹede Naijiria to fofin de irinajọ lọ si awọn orilẹede mẹtala ti arun coronavirus ti n ṣọṣẹ ti ni ipalara fun ọpọ ọmọ Naijiria ti wọn ti rinrin ajo lọ si awọn orilẹede naa tabi ti wọn fẹ ṣẹṣẹ lọ si bẹ.
Ìfẹ́ ni ó so àwọn nǹkan yòókù pọ̀, tí ó sì mú wọn pé.
A ti yọ, bí ẹyẹ tí ó yọ ninu okùn apẹyẹ:okùn ti já; àwa sì ti yọ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, October 1 Celebrant: Atinuke Oladeru ni kẹ yé ṣépè fún Nàíjíríà mọ́, ẹ pa ohùn dà Ọgọta ọdun eto ọrọ aje to dẹnukọlẹ.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Eeyan 35 miran ko aarun iba Lassa WHO yoo kapa aisan Lassa Fever 'Awọn ipinlẹ ni iṣẹ lati ṣe lori iba lassa' Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Nígbà tí mo dé Tiroasi láti waasu ìyìn rere Kristi, Oluwa ṣínà fún mi láti ṣiṣẹ́.
’ rèé Afọnja, ẹni tó finú wénú ní Ilọrin, àmọ́ tó jẹ iwọ 5:30 p.
''Nitori eleyi,wọn gbọdọ gba awẹ kafara lati fi wa itanran ohun ti wọn ṣe.
Ó wí fún mi pẹ̀lú pé bí n kò bá gbàgbọ́ òun ṣet;an láti lọ mu mi rí ìyàwọ mi nibi tí òun àti ọkùnrin ọlọ́kùnrin ti ń lo ìfẹ́ pẹ̀lú ara wọn.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Chinese restaurant: CDHR ní ìjọba Nàíjíríà ló fa ẹ̀gbin náà bá wa 20 Ẹrẹ̀nà 2019 Oríṣun àwòrán, Punch Aarẹ ajọ ajafẹ́tọ ọmọ Naijiria ti a mọ sí CDHR, Amofin Malachy Ugwummadu ti sọ wipe, ajọ naa ṣetan lati ja fun ẹtọ ọmọ Naijiria kan, ti ile iṣẹ ounjẹ awọn ọmọ ilẹ China to wa lorilẹede Naijria ko ba gba laaye, lati wọle jẹun nibẹ.
"O ni ""Happiness Winfred kuro ni ile rẹ lọjọ Aiku, Ọjọ Kọkanlelogun, Oṣu Kẹfa, ọdun 2020, Ṣugbọn inu kanga ni wọn ti ri oku rẹ ni Ọjọ Karundinlọgbọn."
kí ẹ lè jẹ ẹran-ara àwọn ọba ati ti àwọn ọ̀gágun, ati ti àwọn alágbára, ati ẹran ẹṣin ati ti àwọn tí wọ́n gùn wọ́n, ati ẹran-ara àwọn òmìnira ati ti ẹrú, ti àwọn mẹ̀kúnnù ati ti àwọn ọlọ́lá.
Mo fẹ́ kí ẹ gba Febe bí arabinrin wa, ẹni tí ó jẹ́ òṣìṣẹ́ ìjọ tí ó wà ní Kẹnkiria.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ọbasanjo kọ́ ni yóò fi ààrẹ jẹ nínú ìdìbò 2019 - Oshiomole Ọbasanjọ yòǹbó Atiku, ó ní kò ní já Nàíjíríà kulẹ̀ 'Èrè tó tọ́ ni Jonathan, Ọbasanjọ jẹ lórí iṣẹ́ ọpọlọ jíjí' SERAP ní kí Buhari gbé Dasuki, Jonathan lọ síwaju kóòtù àgbáyé Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Adedoyin: Tí mo bá rí Buhari, màá sọ fun kó rántí pé Ọlọ́run wà Ninu ọrọ rẹ, imọtoto pẹlu ounjẹ jijẹ se koko, nitori awọn to ba fi ọwọ kan awọn to ni aisan lassa naa le ko aaarun naa.
ko ni kaare lati seto iranwọ fun gbogbo omo orile ede Niajiria , ni eyi ti yoo
Yóo mú díẹ̀ ninu ẹ̀jẹ̀ akọ mààlúù náà ati ti ewúrẹ́ náà, yóo sì fi ra àwọn ìwo pẹpẹ náà yípo.
Oríṣun àwòrán, Ooni Adeyeye Ogunwusu, Ojaja 11 A si lee ni laisi iranlọwọ Mọremi ni, boya ni ilu ta n pe ni Ile Ifẹ ko ba ti si mọ loni yii, bẹẹ si ni a ko lee sọ itan ilu Ile Ifẹ, ka gbagbe ipa ti Mọremi ko si ilọsiwaju ilu naa.
Alẹ ọjọ Ẹti ni awọn afurasi janduku kọlu ile ẹ̀kọ́ náà, eyi to fa awuyewuye jakejado Naijiria.
Oríṣun àwòrán, Intersurgical Àwọn tí ó bá jẹ pé àmì tiwọn kò nira jú wọn lé máa fi ìbòjú-bomu Fẹntílàtọ̀ mí niti wọn.
 A maa mu awon eto miiran ti o ba wa nile to yin wa lai pe.
A Ltd, ẹgbẹ agbabọọlu Abiọla Football club ati bẹẹbẹẹ lọ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ọdalẹ ni Babangida ati Abacha - Ọmọ Abiola MKO Abiọla gẹgẹ bii ẹlẹyinju aanu, baale ile ati olori ẹsin: Bi MKO Abiọla se jẹ ọlọrọ to yii, Ọba oke fi omi aanu si oju rẹ, ọpọ eeyan to ba si ba ẹkun wọ inu ile abi ọọfisi rẹ lo maa n ba ẹrin jade, nitori oun gan la ba maa pe olowo to n fi owo saanu, ti kii si fẹ ri omije loju mẹkunnu rara Idi ree ti ọpọ agbegbe, ilu, ileto,ẹya ati orilẹede fi n fi oye jankanjankan da Abiọla lọla nigba aye rẹ, a si gbọ pe oye to jẹ le ni igba, to ko tẹri gbasọ.
Adesoji Aderemi, Ọọ̀ni Ifẹ̀ àti gómìnà Adúláwọ̀ àkọ́kọ́ láyé eèbó amúnisìn Wo àdúgbò tó ń jẹ́ orúkọ èèbó amúnisìn tí yóò pa orúkọ dà l’Eko Àjọ NCDC kéde ènìyàn 626 tó tún ṣẹ̀ṣẹ̀ ní Coronavirus ní Nàìjíríà Ṣé òótọ́ ní ìyàwó Gómìnà Ondo lugbadi Covid-19?
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Jaiye Kuti lu àwọn aláṣìmọ̀ lọ́gọ ẹnu lórí ìbáṣepọ̀ pẹ̀lú Pasuma 24 Bélú 2019 Oríṣun àwòrán, OTHER Lootọ kii ṣe ajoji ki ibaṣepọ maa wa laarin oṣere meji lagbo awọn oṣere ṣugbọn ni Jaiyeola Kuti, o ni ohun ti wọn n ro si oun ko jọ ọ rara.
Ìwọ̀nyí ni mo bẹ̀rẹ̀ si í rò ní ọ̀sán gangan ọjọ́ tí mo ń wí yìí, lẹhìn ìgbà tí mo ti kúrò nínú ilé tán, tí mo lé góńgó lórí àpáta.
Diẹ lara awọn opo naa to ba BBC Yoruba sọrọ ṣalaye pe awọn opo n dojukọ ipenija to pọ lawujọ.
Ọjọ́ ti pẹ́ tí agogo ara ti wà Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ọbẹ̀ ayé àtijọ́ yìí ní láti wá ọ̀nà àti tú ara rẹ̀ tò Àwọn onímọ̀ sáyẹ́ǹsì rò wí pé òòrun ba àwọn sẹ́ẹ́lì àkọ́kọ́ jẹ́.
Mí o ni ya aláìmoore' Yewande Adekoya Abiodun Oríṣun àwòrán, Yewande/Instagram Àkọlé àwòrán, Yewande bi'mọ tuntun jòjòló, Mercy pàdánù èèyàn rẹ, Toyin Abraham fèsì lórí ìi asoju NCDC Ayò abara tíntín, lọ́nii gán ni ọmọ túntun jòjòló tún wọ agbo àwọn òṣèré tíátà nígbà ti Yewande gbe si ojú òpó instagram rẹ pe, 'Káàbọ̀ sínú ayé wa, ọmọ ọba, ifẹ́ mi.
Wọ́n dá a lóhùn pé, “Aáwọ̀ tí ó wà láàrin àwa ati Saulu ati ìdílé rẹ̀, kì í ṣe ohun tí a lè fi wúrà ati fadaka parí, a kò sì fẹ́ pa ẹnikẹ́ni ninu àwọn ọmọ Israẹli.
Bi awọn ọlọpaa ṣe n yin ibọn, ni wọn n fin tajutaju naa pẹlu.
N kò ní ọ̀tá kankan rárá, bẹ́ẹ̀ ni kò sí àjálù.
to n se ipade pẹlu awon omo orile ede yii to n gbe ni ilẹ  okeere niluu New York.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ẹ́ gbaradì, to bá lo jẹnẹrátọ̀ àbí tà á, ò ń fi ẹ̀wọ̀n ọdún mẹ́wàá ṣeré - Sẹ́nétọ̀ ń dábàá Agbófinró, tó bá wa ọkada àbí kẹkẹ maruwa l'Eko, o rugi oyin - Sanwo-Olu Ará Yúróòpù ẹ fìdí mọ́lé yín, mo ti gbé ìlẹ̀kùn Amẹ́ríkà tìpa torí Coronavirus - Trump Ìjọba ń ṣe afárá Eko Bridge l'Eko, àwọn ọ̀nà àbùdá tí ẹ lèè gbà nìyí O ni arun asekupani Coronavirus to n se ọsẹ kiri yika agbaye lo ko okuta ba epo rọbi lọja, pẹlu orogun owo ti ilẹ Saudi Arabia n ba Russia se nidi okoowo epo rọbi, eyi to mu ki owo epo ja wa silẹ.
Oríṣun àwòrán, @PoliceNG O ni dipo eyi, se ni awọn ọdọ ilu Isinigbo wa ka oun mọle lọsẹ to kọja pẹlu ohun ija oloro.
Àdúrà ni mo nílò kìí ṣowó - Pa Kasumu Aarẹ Akufo Ado ni ẹnikẹni ti kii ba n ṣe ọmọ orilẹ-ede Ghana ko gbọdọ ta ohunkohun lọja Wana.
Komisona fun eto ogbin nipinle Ogun, Abileko Adepeju Adebajo ti kede ipinnu ijoba ipinle Ogun lati bere awon ise akanse ti yoo mu idagbasoke ba eto ogbin nipinle naa.
Ẹ ṣí sílẹ̀ gbayau, ẹ̀yin ìlẹ̀kùn,ẹ wà ní ṣíṣí sílẹ̀, ẹ̀yin ìlẹ̀kùn ayérayé,kí Ọba ògo lè wọlé.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 9th Assembly: Aráàlú ní àwọn ń fẹ́ ìpèsè àwọn ohun èèlò amáyédẹrùn Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Wọn a gbógun tì wọ́n, wọn a sì ba gbogbo ohun ọ̀gbìn ilẹ̀ náà jẹ́ títí dé agbègbè Gasa.
Bakan naa lo kan sara si ọga ọlọpaa Adeyẹmọ fun iwa ọmọluabi ati ikora-ẹni-ni-ijanu to hu pẹlu bi obinrin yii ṣe n luu to lọjọ naa.
Gege-bi akosile awon ti won fi iwe pe ,eyi ti ile-ise ti o n risi oro ile-okeere lorile-ede naa gbe jade , o se afihan awon Ajo elekunjekun ati ti agbaye meedogun ti won fi iwe pe.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Kí ló mú Sanusi kọrin bù Gómìnà ìpínlẹ̀ Kano, Abdullahi Ganduje?
ki eto aabo to peye ati lati mu igbe aye iderun ba awon arinrinajo.
Bí ikọ afẹjẹwẹ náà sì ṣe ń fojú hàn síta, ní ìjọba rẹ koju wọn, to sì pá asiwaju ikọ náà, Muhammad Yusuf, bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé ikọ náà padà gberi, tó sì ń dààmú Nàìjíríà di òní yìí Irọ́ ńlá ni pé a ǹ dá àwọn òṣìṣẹ́ wa dúró - Access Bank Duro Ladipọ, ìlúmọ̀ọ́ká òṣèré tíátà àti ọmọ àlúfà tí kò gbàgbé àṣà ìbílẹ̀ Ẹ bá mi dúpẹ́ lọ́wọ́ Sunday Igboho, Ajimobi, Seyi Makinde àti àwọn ọlọ́pàá fún iranwọ wọn láti rí ìbejì gbà padà Àwọn èèyàn kò fi bẹ́ ẹ̀ ní ìbálòpọ̀ lásìkò ìgbélé yìí - Iléèṣẹ́ kọ́ńdọ́ọ́mù Durex Ìdáríjì àti sísan owó iranwọ fún ikọ ajijagbara Niger Delta: Lára àwọn àṣeyọrí aarẹ tẹ́lẹ̀ tó di olóògbé yìí ni wíwà àlàáfíà ni agbegbe Niger-Delta tí àwọn ajijagbara tí ń bá ọ̀rọ̀ ajé Nàìjíríà jẹ́.
èmi ni oníṣẹ́ ọnà tí mo wà lọ́dọ̀ rẹ̀,Inú mi a máa dùn lojoojumọ,èmi a sì máa yọ̀ níwájú rẹ̀ nígbà gbogbo.
Bẹẹ ni ọrọ ri pẹlu adele alaga ẹgbẹ oselu APC, tii tun ṣe gomina ana nipinlẹ Oyo, Ṣẹnetọ Isiaka Abiola Akanji Ajimobi to dagbere faye lasiko aisan ranpẹ.
Kí oore-ọ̀fẹ́ ati alaafia pọ̀ sí i fun yín nípa mímọ Ọlọrun ati Jesu Oluwa wa.
'Àáfà aríran yóò jìyà ẹ̀ṣẹ̀ ìfipábánilòpọ̀' Ọjọgbọn Steve fidi ẹ mulẹ pe kẹmikaa kan maa n jade lára ẹni to ba ni aisan ibà ni eyi ti awọn ajá naa le gbọ oorun rẹ lara eniyan.
 / nípa síse ode ni ònà tí àwon okùnrin yaka n gbà sapé won láti gbe ètò orò ajé .
Nígbà tí wọ́n dé ibẹ̀, wọ́n pe gbogbo ìjọ jọ, wọ́n ròyìn ohun gbogbo tí Ọlọrun tọwọ́ wọn ṣe ati bí Ọlọrun ti ṣínà fún àwọn tí kì í ṣe Juu láti gbàgbọ́.
Duro Ladipọ, ìlúmọ̀ọ́ká òṣèré tíátà àti ọmọ àlúfà tí kò gbàgbé àṣà ìbílẹ̀ Oyinkan Abayomi, akọni obìnrin tó fi ìfẹ́ pa orúkọ ọkọ kejì dà sí ti ọkọ àárọ̀ Bawo ni ẹgbẹ Fatai Rolling Doller ṣe bẹrẹ?
Sùgbọ́n díẹ̀díẹ̀ ni aàrun náà ń lọ sóke ni àgbègbè Gauteng tó fi mọ́ Johanesburg.
Lero ti Amofin Ayodeji Olabiwonninu ni ofin Nigeria Land use act 1978 fun gomina ipinlẹ kọọkan lagbara lati sakoso awọn ilẹ ijọba to wa ni agbegbe rẹ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Fulani Kidnapping: Owó púpọ̀ la san kí wọ́n tó fi mi sílẹ̀ Abdullahi ati awọn ọrẹ rẹ ti ṣa asala fun ẹmi wsn bayii lẹyin ti awọn kan bẹrẹ si ni i fi atẹjiṣẹ ranṣẹ si wọn lori ẹrọ ibaraẹnisọrọ pe awọn yoo pa wọn.
Eyi le jẹ ki wọn mu awọn mejeeji lati tukọ Stamford Bridge.
Cuppy fi sori oju opo Twitter ati Instagram rẹ pe oun ti jawee fun Arsenal lẹyin ọdun mẹfa to ti n tẹle ikọ agbabọọlu naa.
“Mo bá dọ̀bálẹ̀ gbalaja níwájú rẹ̀ fún ogoji ọjọ́ nítorí pé ó pinnu láti pa yín run.
Ni ibi isọmọlorukọ Arẹmọ Oba Adeyey Ogunwusi, Ojaja I to jẹ Oọni Ile Ife ni awọn ohun eelo ikomọjade tun ti jade.
Omowe Abiso Kabir to je akosemose lori eto ogbin to fi ariwa Naijiria se ibujoko ti soro lori awon aseyori ti Naijiria ti ni lati igba ti won ti n gbogun ti awon onise ibi boko haram ni apa ariwa ila oorun Naijiria ati ipa to n hande ninu eto ogbin lasiko yii.
Èèyàn kan tó jókòó sibi kan ló kan gbé irọ ńlá yìí kalẹ nítorí Ìkórira, kò leè ṣẹlẹ̀ láéláé.
Oríṣun àwòrán, WATER AID/MACILAU Àkọlé àwòrán, Awọn ọmọde ni agbegbe ibi ti ipenija omi wa nilẹ Mozambique Oríṣun àwòrán, WATER AID/MACILAU Àkọlé àwòrán, Josefina a maa fi ori ru omi lọ ọna jinjin Josefina ti aworan rẹ wa loke ati Eudicia ti won je ọmọ ọdun mejila a maa padanu ile ẹko bi ẹmẹẹrin lọse ki wọn ba le lọ pọn omi.
Senegal Artist: Ojojúmọ́ ni mo ń gbé àwòrán bàbá tó pọnmọ sẹ́yìn sójú pópó
’ rèé Afọnja, ẹni tó finú wénú ní Ilọrin, àmọ́ tó jẹ iwọ Ẹfunsetan Aniwura, obìnrin tó ju ọkùnrin lọ Ọ̀rọ̀ǹpọ̀tọ̀niyùn, Aláàfin obìnrin àkọ́kọ́ rèé, tó ní nǹkan ọkùnrin Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Imperial Majesty ni Olubadadan, Royal Majesty làwa, òfin sì tẹ̀lé e - Ọtun Olubadan Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Ronaldinho: Agbábọ́ọ̀lù Brazil tẹ́lẹ̀, Ronaldinho gba ìtúsílẹ̀ kúrò lẹ́wọ̀n, àmọ́.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Elebuibon: Àwọn àṣà àtọ̀húnrìnwá ló fa títa ẹ̀jẹ̀ nítorí ògùn owo Arakunrin ọmọ Ekiti to ni aarun naa wa lara awọn marun un ti ijọba apapọ kede pe o ni aarun ọhun lọjọru.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Davido fi ọkọ̀ Porsche ṣe ayẹyẹ ọjọ́ ìbí fún Chioma Avril Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Davido fi ọkọ̀ Porsche ṣe ayẹyẹ ọjọ́ ìbí fún Chioma Avril 1 Èbibi 2018 Davido fi da loju Chioma pe oun kò ni pẹ́ fe laipẹ léyin to kọ́ka fi àwo orin tuntun to pe ni assurance pọ́n Chioma lé pé òun fẹ́ràn rẹ̀ púpọ̀.
Oghbẹni Jude ni oun ti maa n kó orin awọn ọdọ to jẹ olorin tipẹtipẹ.
Àwọn eniyan ń gbé gbogbo àwọn tí ó ní oríṣìíríṣìí àrùn ati àìlera wá sọ́dọ̀ rẹ̀ ati àwọn tí ẹ̀mí Èṣù ń dà láàmú, ati àwọn tí wárápá mú ati àwọn arọ; ó sì ń wò wọ́n sàn.
Àwọn tí wọn ń fọn fèrè ogun sì ń fọn ọ́n lemọ́lemọ́.
sàláwà Àbẹ ̀ ní Álídù ni wọ ́ n bí ní ( 5 may 1961 ) , ó jẹ ́ olórin ọmọ orílẹ ̀ èdè nàj ̀ íríà .
" làra àwọn ẹranko mìíràn "" leptospira "" a máa gbé nínú ilé-ọmọ , èyí tó má a ń ṣe òkùnfà àtànká lásìkò ìbálópọ ̀ ."
ati Jeremiah Dogonzo  ti o gba ami eye ti
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, ẹ̀fọ́ rírò jẹ́ alábárìn iyán, fùfú, ẹ̀bà, àmàlà àti ìrẹsi funfun Bi a se n ja awẹ ni asalẹ lasiko Ramadan Eniyan gbọdọ sọra nigba ti eniyan ba n ja aawẹ ni asalẹ, ki eniyan ma baa da awọn eto to n jẹ ki ounjẹ walẹ lagọ ara rú.
Ki lo fa a ti a ko fi mọ ohun to nsẹlẹ gaan?
Ọtunbọ Ayodeji Osibogun: Oríṣun àwòrán, Others Osibogun ní kìí ṣe ènìyàn kan ni yóò yọ ọjọgbọ́n Akintoye, oníruuru ẹgbẹ́ ló parapọ̀ lati yan Akintoye sípò nítori náà ti wọ́n yóò ba yọ àwọn náà ni yóò jọ sọ.
Àṣìkà ìṣirò èsì ìbò ààrẹ nípìnlẹ́ẹ̀ 11, ló fa ìjákulẹ̀ mi - Atiku Àjọ FIFA fòfinde Samson Siasia titi lailai Ayọ̀ abara bíńtín!
Ẹwẹ, Aṣiwaju ati Agbenusọ Ile naa, Aṣofin Mudashiru Ọbasa wa de awọn ọrọ ikini ku oriire si Ọba Akiolu lade, nigba ti o ṣapejuwe Ọba gẹgẹ bi ẹni ti wọn ti gbogbo igbesi-aye wọn sin orilẹ-ede Naijiria, bẹrẹ lati igba ti wọn ti wa lẹnu iṣẹ ọlọpaa, ti wọn fi di ọkan lara awọn ọga agba lẹnu iṣẹ naa, titi di igba ti wọn fi jẹ Ọba Eko, ti wọn si tun tẹ siwaju ninu akitiyan wọnAgbẹnusọ Ile naa ni, “wọn ti n sapa gẹgẹ bi baba fun wa ninu Ile Igbimọ Aṣofin yii, ọpọ igba ni wọn maa n tọ wa sọna ninu awọn igbesẹ wa, ti wọn si n ṣe iranlọwọ fun wa ni gbogbo ọna”.
Adeleke ni oludije ti 'Jackson' wa ninu inagijẹ rẹ, ti o si jẹ oludijẹ ti iwọle rẹ taara sinu agbami oselu orileede Naijiria waye lẹyin igba ti ẹgbọn rẹ papoda.
Bakan naa lo ki awọn oṣiṣẹ iṣẹlẹ pajawiri ninu iṣẹ ibanikẹdun to fi ṣọwọ si ẹbi awọn ti iṣẹlẹ naa mu ẹmi wọn lọ.
Mehitabelle wa n gbarata pe isẹ ile ti wọn gbe le oun lori ti pọ ju, to si n beere pe se egun ni pe kii eeyan jẹ abigbẹyin ninu ile ni?
Lúmọ̀ogun lẹ títí bí ẹ̀mí ìyá aláró kò padà.
Lẹ́yìn tí wọ́n ti pa akọ mààlúù náà tán, wọ́n mú Samuẹli tọ Eli lọ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ẹbí ìyàwó lu ọkọ ìyàwó lẹ́yìn tí ìyàwó rẹ̀ yọjú síbi ìgbéyàwó tó ṣe pẹ̀lú obìnrin mìràn By Riaz Sohail BBC Urdu, Karachi 16 Èrèlè 2020 Oríṣun àwòrán, Social media Àkọlé àwòrán, Awọn ẹbí iyawo tuntun fi iya nla jẹ Asif Rafiq Siddiqi.
Ara ti fu u pe aṣiri rẹ ti tu si mi lọwọ.
Ní ọjọ́ keje, Ọlọrun parí iṣẹ́ ìṣẹ̀dá tí ó ti ń ṣe, ó sì sinmi ní ọjọ́ náà.
Kí ló dé tí ẹ̀dá alààyè kan yóo fi máa ráhùnnígbà tí ó bá ń jìyà ẹ̀ṣẹ̀ rẹ̀?
Ẹ jẹ́ kí a kọ́kọ́ ṣe àtúpalẹ̀ orúkọ “SIM Card” yìí.
18 Àti ẹ̀rí wọn náà yíò jade lọ bákannáà sí ìdálẹ́bi ìran yìí bí wọn bá sé ọkàn wọn le lòdì sí wọn;
Àkọlé àwòrán, Lara tiata ti Aisha se ni Omoge Campus Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Ìròyìn Yàjóyàjó - Ẹ wá gbà wá ní Ijegun o, Ọ̀pá epo ń jóná lọ́wọ́lọ́wọ́!
2 Nítorínáà, gbogbo ẹ̀yin tí ẹ bẹ̀rẹ̀ iṣẹ́-ìsìn Ọlọ́run, ẹ ríi wípé ẹ sìn-ín pẹ̀lú gbogbo ọkàn, ipá, iyè àti okun, kí ẹ̀yin baà lè dúró láì ní ìdálẹ́bi níwájú Ọlọ́run ní ọjọ́ ìkẹhìn.
Ogbeni Scott Isreal to je oga agba agbofinro ni Broward County ni Cruz pa eniyan meta nita ile iwe girama naa, ko too eniyan mejila miran ninu ile iwe ki aown meji miran to gbemi mi nile iwosan ti won gbe won lo fun itoju.
“Ìwọ ọmọ eniyan, kọjú rẹ sí Sidoni, kí o sì sọ àsọtẹ́lẹ̀ nípa rẹ̀ pé 
A gbiyanju lati ba awọn to n bẹ ni ipele ikẹtala soke lati mọ boya wọn ni ibẹru kan tabi omii lori ipada sẹnu iṣẹ wọn ṣugbọn wọn kọ lati ba awọn oniroyin sọrọ.
Láti ìgbà yìí lọ eniyan ni ìwọ yóo máa mú wá.
Nígbà tí wọn kò tíì rìn jìnnà sí ìlú, Josẹfu sọ fún alabojuto ilé rẹ̀ pé, “Gbéra, sáré tẹ̀lé àwọn ọkunrin náà, nígbà tí o bá bá wọn, wí fún wọn pé, ‘Èéṣe tí ẹ fi fi ibi sú olóore?
 o ma gba ni ojo 1378.
NGA VS GUI: Super Eagles àti Syli National Guinea ṣẹ́ eegun ẹ̀yìn Guinea pẹ̀lú 1-0
O ni oun ko ko ọrọ oun jẹ lori imura buruku tawọn ọdọbinrin mii n mura lọ ṣọọṣi ati lori ọrọ awọn to n kanju lati ṣegbeyawo.
Ò leè kó sí pańpẹ́ ọlọ́pàá bí o bá na ọmọ rẹ - Ajàfẹ́tọ̀ ọmọdé Okunnu ni Eleduwa ti kọ ni kadara fun idile oun pe, oke okun ni wọn yoo fi ṣe ibugbe lo jẹ ki wọn wa loke okun bayii.
O si tun ma n fun eeyan ni agbara ati fun ibalopọ.
Ileeṣẹ ọlọpaa lorilẹede Niajiria ṣe apejuwe ikọ SARS naa gẹgẹ bi agbekalẹ to ni aṣiṣe ninu.
Ile iṣẹ iroyin ilẹ Egypt lo kede ipapoda rẹ lọjọ aje.
 Oríṣun àwòrán, Fuji Opera Kwam 1 ṣalaye pe a le fi orin Fuji we orin Reggae laye atijọ, ṣugbọn lode oni, orin Fuji gangan ni ohun ti wọn mọ wa fun kaakiri agbaye.
Iko agbaboolu Super Falcons bale si papako ofurufu Nnamdi Azikiwe International Airport ni wakati die ki aago merin lu.
Ẹ o ranti pe ẹgbẹ naa ti ṣeto latinuu oṣu kọkanla, lati ṣepade ti wọn yoo fi ṣagbeyẹwo ipo ti wọn wa ati ọna fun igbesẹ tuntun latari eto idari ẹgbẹ naa.
Oríṣun àwòrán, helpsuliyatuae O ni oun yoo sọ ọkan lara obinrin to wa ninu ibẹrin naa ni Latifa, ti n ṣe orukọ ile iwosan ti wọn ti gbẹbi rẹ.
Agbenusoro ile-ise olopaa Badghis, Naqibullah Amini, fi oro naa mule pe, ogbon awon omo ogun ni o padanu emi won, ti won si tun sekupa awon merin miiran nibudo ibi ayewo won.
Ẹgbẹ́ IPOB ò tako Ààrẹ Buhari ní Japan- Iléeṣẹ́ Ààrẹ Òfin nìkan ló lè gbadé lórí àwa Ọba ìlú lbadan- Oba Lekan Balogun Irọ́ ló pa, a kò mọ̀ ọ́ rí tàbí fún ọ ní ₦13m - APC tako afurasí ajínigbé Sika Mortoo to gbe igba oroke nibi idije ase naa gba ẹbun owo ẹgbẹrun meji dọla ($2000), ọmọ Naijiria to baa dije, Chef Turay, naa si gba Ẹgbẹrun kan dọla ($1000).
Ó lé ní méjìlélógun nínú àwọn ìkọ̀ Boko-Haram ti wọn sọ di aláìlágbára nígbà ti ọ̀pọ̀ wọn sá lọ pẹ̀lú àpá ọta ìbọn, tí àwọn ọmọogun sì ń sapá láti rí àwọn ọmọ Boko Haram, bó tilẹ̀ jẹ́ pé ọmọogun kan sì ní àpá ìbọn sùgbọn ó ti wà ní ilé ìwòsàn ọmọogun tó ti ń gba ìtójú.
“Ìwọ ọmọ eniyan, gbọ́ bí àwọn ọmọ Israẹli ti ń wí pé, Ìran ọjọ́ iwájú ni ò ń rí, o sì ń sọ àsọtẹ́lẹ̀ ohun tí yóo ṣẹlẹ̀ ní ọjọ́ gbọọrọ.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Buhari wa ẹnu si àwọn ọdọ Nàìjíríà Obinrin gbo‘rinyin l'ayajọ awọn obinrin Buhari ko fontẹ lu atunse ofin idibo Atiku: Itàn mi nínú òṣèlù Ó mẹ́núba ìrírí rẹ̀ sẹ́yìn pé tí áwọn ọmọ orílẹ́-èdè Nàíjirìa bá wo ìtàn òun nínú ètò òṣèlù Nàíjirìa, wọn yóò ri pé òun kìí se olóṣèlù bó-báa-o-pá; bó-bàa-o-bùú-lẹ́sẹ̀.
HIGHLIGHTS: Watch back the goals as Saudi Arabia snatch a last-gasp win over Egypt!
O sọ pe ajọ OYRTMA ti gbiyanju lọpọ igba lati ri i pe, adinku de ba sunkẹrẹ fakẹrẹ ọkọ lopopona Sango-Eleyele, Sango-Mokola ati Sango-Ojoo.
Ràn mí lọ́wọ́ nígbà tí o bá ń gbà wọ́n là.
Àwọn eniyan mi ìbá jẹ́ gbọ́ tèmi,àní Israẹli ìbá jẹ́ máa rìn ní ọ̀nà mi!
Ilé ìwòsàn l'Àbuja ti ya àwọn ìbejì tí wọ́n sọpọ̀ láyà lọ́fẹ̀ẹ́ Fásitì ìpínlẹ̀ Ekiti dá òṣìṣẹ́ 355 padà sẹ́nu iṣẹ́ Gómìnà mẹ́ta àtí ènìyàn 1,242 ló kó sí panpẹ EFCC ni ọdún 2019 Ṣo mọ̀ pé J.
Oman Returnees: Ọ̀kan lára àwọn obìnrin méjèèjì ní òun ṣiṣẹ́ ọdún kan láì mú ₦5 padà wálé
" Bakan naa lo tun mọ riri Toyin Abraham ati ọkọ rẹ fun iranwọ owo ti wọn fun, to si gbadura pe gbogbo awọn eeyan to se iranwọ owo fun oun, ni ọba oke yoo fi ọpọ rọpo fun.
bakan naa ni awọn eeyan to n fi ẹhonu han yii tun gbe apẹ kana loju popo, ti wn si n se ounjẹ lọ lai bikita.
Ẹ̀ẹ̀kan lọ́dún ni í máa ń gé irun orí rẹ̀, nígbà tí ó bá kún, tí ó sì gùn ju bí ó ti yẹ lọ.
” Nítorí wọ́n mọ̀ pé Jona ń sá kúrò níwájú OLUWA ni, gẹ́gẹ́ bí ó ti sọ fún wọn.
ti ẹjọ rẹ  n lọ lọwọ, ki o to di pe ,o jẹ
Hesekaya bá pàṣẹ pé kí wọ́n tọ́jú àwọn yàrá tó wà ninu ilé OLUWA, wọ́n bá ṣe ìtọ́jú wọn.
Ileeṣẹ to n ṣe iwadii ijamba ọkọ ofururu ti wa ni ibẹ bayii lati gbe ajaku baalu naa jade.
Àjàrà yìí bá kọ orí gbòǹgbò ati ẹ̀ka rẹ̀ sí ọ̀dọ̀ idì ńlá yìí, kí Idì náà lè máa bomi rin ín.
Látìgbà náà, wọ́n ti tún un kọ́ lẹ́ẹ̀mẹrin ọ̀tọ̀ọ̀tọ̀.
Ninu atejade kan ti oluranlowo aare lori iroyin ati ikede lorile ede Naijiria,Garba Shehu gbe jade pe, kii se awon Fulani daran-daran nikan lo maa jẹ anfaani yii sugbon gbogbo awon ti won  n sin ẹran ọsin ati agbe ni yoo je ninu anfaani naa.
O fikun un wi pe Kọmisọna ọlọpaa ni ipinlẹ Ogun ti fi panpẹ ọba mu gbogbo awọn ọlọpaa ti ọrọ naa kan.
Nítorí bí Ọlọrun kò bá dá àwọn tí ó jẹ́ bí ẹ̀ka igi láti ìpilẹ̀ṣẹ̀ sí, kò ní dá ìwọ náà sí.
Mo bá àwọn ọlọ́lá Juda wí, mo ní, “Irú nǹkan burúkú wo ni ẹ̀ ń ṣe yìí, tí ẹ̀ ń rú òfin ọjọ́ ìsinmi?
Wọ́n mọ̀ pé ìyàn mú ninu ìlú wa, nítorí náà ni wọ́n ṣe fi ibùdó ogun wọn sílẹ̀ láti sá pamọ́ sinu igbó, pẹlu èrò pé a óo wá oúnjẹ wá.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Boko Haram da ìbọn bo ọkọ̀ gómìnà Borno, ẹ̀ṣọ́ àláàbò rẹ̀ farapa Ikú wo ló pa ọmọ ogun Nàìjíríà mẹ́wàá àti ọ̀kan tó ṣẹ̀ṣẹ̀ ṣe ìyàwó?
Saulu gba Dafidi sọ́dọ̀ ní ọjọ́ náà, kò sì jẹ́ kí ó pada sílé baba rẹ̀.
Femi Okunronmu wa gba awọn ọmọ Naijiria ni iyanju lati gbaruku ti awọn asofin ti wọn buwọlu abadofin naa, ki igbe aye irọrun le ba awọn ọmọ Naijiria.
Oreoluwa ninu fidio Mummy Calm Down fẹ́ di 'Ambassador' Oríṣun àwòrán, Oreoluwa Lawal-Babalola Saaju la ti kọkọ mu iroyin wa fun yin pe, Yoruba ni kirakita ko mọla, ka sisẹ bi ẹru ko da nnkankan, Ọba Oluwa nii gbe ni ga.
Jakọbu sálọ sí ilẹ̀ Aramu, níbẹ̀ ni ó ti singbà, tí ó ṣiṣẹ́ darandaran, nítorí iyawo tí ó fẹ́.
“Lára ilẹ̀ mímọ́ náà, ẹ óo ya apá kan sọ́tọ̀ tí òòró rẹ̀ yóo jẹ́ ọ̀kẹ́ kan ati ẹẹdẹgbaata (25,000) igbọnwọ (kilomita 12½), tí ìbú rẹ̀ yóo sì jẹ́ ẹẹdẹgbaata (5,000) igbọnwọ (kilomita 2½), ilẹ̀ yìí yóo wà fún gbogbo àwọn ọmọ Israẹli.
O ni oun ko lee dáa ṣe lai si iranwọ araalu.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Èkó: Ọ̀bọ lé àwọn ènìyàn kúrò ní Gbàgádà 27 Ẹrẹ̀nà 2018 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Àwọn ènìyàn sọ wípé àwọn ọ̀bọ náà dá ouńjẹ tí wọ́n fi májèlé sí nínú mọ̀ nítorí wọn kò ní jẹ ẹ́ Àwọn ọ̀bọ àti ìnàkí ti lé àwọn ènìyàn kúrò lágbèègbèe Soluyi/ - Sosanya ní Gbàgádà ní ìlú Èkó.
waye lọjọ Abameta  lọ  ni irọwọ ati irọsẹ sugbon ni awon apa ibikan
Nígbà tí àwọn ẹ̀dá alààyè mẹrin náà bá fi ògo, ọlá ati ìyìn fún ẹni tí ó jókòó lórí ìtẹ́, ẹni tí ó wà láàyè lae ati laelae, 
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìgbẹ́tì: Òkè Ìyámàpó ló gbà wá sílẹ̀ lọ́wọ́ ogun Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Ìgbẹ́tì: Òkè Ìyámàpó ló gbà wá sílẹ̀ lọ́wọ́ ogun 28 Ẹrẹ̀nà 2018 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 26 Ẹrẹ̀nà 2020 Ìlú Ìgbẹ́tì jẹ́ ọ̀kan lára ìlú tó wà ní agbègbè Òkè Ògùn ní ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́.
Ó bá fi Jesu lé wọn lọ́wọ́ kí wọ́n fi ṣe ohun tí wọ́n bá fẹ́.
Ẹ̀yin ẹ máa lọ sí ibi àjọ̀dún, èmi kò ní lọ sí ibi àjọ̀dún yìí nítorí àkókò tí ó wọ̀ fún mi kò ì tíì tó.
 ní ìbẹ ̀ ẹ ̀ rẹ ̀ pẹ ̀ pẹ ̀ , ó jẹ ́ alágbára tí ó ń jà fún ẹ ̀ tọ ́ àwọn obìrin ọmọ orílẹ ̀ èdè nàìjíríà .
Oyo 2021 Appropriation Bill: Makinde takú mọ́ àwọn aṣòfin lọ̀wọ̀ pé òun kò fẹ́ ìṣúná gbèsè
Olorin takasufe, Peter Okoye lo kọkọ sọ pe oun ko ṣeleri lati fun Tacha lẹbun ọgọta miliọnu naira.
US Presidential Election: Ṣé ìrànwọ̀ ni Kamala, ìgbákejì tí Biden yàn yóò jẹ́ fún un tàbí ìpalára?
Mose ati Aaroni bá ṣe bí OLUWA ti pa á láṣẹ fún wọn.
Wọn ni ki n buwọ lu awọn iwe kan ti mo si buwọlu wọn, wọn si gba aworan ilewọ mi, mo si gba ile lọ.
Ni afiwe idibo ọdun 2016, ero oludibo ko ṣafihan iyatọ to to eleyi taa n ri nisinsiyi.
Minisita salaye pe aare Buhari banuje pupo nigba ti o gbo ikolu ohun, paapaa julo
 Oro iyanju ti ma ba awon omo ile yii so ni lati ri daju pe, won yan ise miiran laayo  yatosi oselu.
nibẹ “Nitori naa, a o sa ipa wa ni awon
Salah gba àmì ẹ̀yẹ PFA Iniesta: Mò ṣetán láti fi Barcelona sílẹ̀ Barcelona gba ife ẹ̀yẹ La liga Wenger tó ti jẹ́ akọ́nimọ̀ọ́gbá fún ẹgbẹ́ agbábọ́ọ̀lu Arsenal fún bí ọdún méjìlélógún ló fìdí rẹmi pẹ̀lú ikọ̀ rẹ̀ pẹ̀lú ayò méjì s'ódo ní Old Trafford lọ́jọ́ àìkú.
“Ẹ kò gbọdọ̀ dájọ́ èké, ẹ kò sì gbọdọ̀ ṣe ojuṣaaju sí talaka tabi ọlọ́rọ̀, ṣugbọn ẹ gbọdọ̀ máa dá ẹjọ́ àwọn aládùúgbò yín pẹlu òdodo.
nitori lati kekere ni mo ti maa n ṣe akojọpọ awọn awo orin.
Orin náà ń fi ọ̀wọ̀ wọ agbègbè náà: bí ẹni wípé Agbègbè Papa náà ni oòrùn ní àárín àgbá-ńlá Ijó ìta-gbangba àti ohun tí ó kù ń yí i ká.
Ààrẹ Donald Trump: Qasem Soleimani ń gbìmọ̀ràn láti kọ lù wá l'Amerika la ṣe kọ́kọ́ yára pa á
Ninu atejade kan lori adehun  ifenuko leyin ipade naa, orile-ede mejeeji fi erongba han lori akotun ajosepo naa ati mimu igberu ba eto oselu ati ajosepo oro-aje to ti wa lojo-pipe.
Wọ́n tú àṣírí ìfiyàjẹni àwọn Ológun àti SARS káàkiri Nàìjíríà Àwọn jàndùkú dáná sun àwọn arìnrìnàjò lásìkò tí wọ́n sùn nínú ọkọ ní Borno China ṣe àgbéjáde App"" tí ẹ lè fi mọ̀ bóyá ẹ súnmọ́ aláàrùn Coronavirus Ta ni Babtunde Omidina?"
alagbato ati awon ewe funrawon mo bi oju se se pataki si fun ilosiwaju won.
Awóyẹmí ni orúkọ ẹni tí ó bá àwọn Ọlọ́fìn-íntótó níbi tí wọ́n ti ń gbádùn lọ́dọ̀ Ọmọtóṣọ̀ọ́.
Amaechi ni awọn oṣiṣẹ ilẹ China to n ṣe oju ọna reluwe naa ṣi wa lorilẹede China, lẹyin ti ijọba ilẹ wọn paṣẹ ki wọn duro si ile.
Bakan naa ni awọn asaaju ẹgbẹ akẹkọ lo anfaani abẹwo wọn ọhun si ọdọ Buhari, lati ki ku ayẹyẹ oriire ọjọ ibi ọdun mẹrindinlọgọrin to pe loke eepẹ.
Ọ̀nà eniyan burúkú dàbí òkùnkùn biribiri,wọn kò mọ ohun tí wọn yóo dìgbò lù.
O ni oun n sọ iriri oun lati pe kiyesi awọn eeyan si ohun to n ṣẹlẹ, ati ki awọn obinrin miran ba le sọrọ sita lori ohun ti wọn koju nigba ti wọn ba dunkoko ma wọn.
- Mike Bamiloye Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Ọba Mohammed bin-Salman ti Saudi yọ ọmọ rẹ̀, Fahad, Abdulaaziz àti àbúrò rẹ̀, Ahmed kúrò nípò nítorí ìwà àjẹbánu3 Owewe 2020 6:18 Fídíò, Akomolede: Bolaji Faleke ni Olùkọ́ tó ń kọ́ wa ní àṣà oge ṣiṣe lórí BBC Yorùbá, Duration 6,181 Owewe 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
O tun ni awon owo ti orile ede naa yoo pa si apo re yoo le ni ida meje ninu ogorun un lọdun 2019.
Bí ó bá sọ pé kò burú, a jẹ́ wí pé alaafia ni fún iranṣẹ rẹ, ṣugbọn bí ó bá bínú gidigidi, èyí yóo fihàn ọ́ wí pé, ó ní ìpinnu burúkú sí mi.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù NLC Protest: Jànduku ya bo àwọn tó ń fẹ̀hónú hàn nílé Míńísítà fún ọ̀rọ̀ òṣìṣẹ́ 8 Èbibi 2019 Àkọlé àwòrán, NLC Protest: Jànduku yabo àwọn to ń fẹ̀honú han níle Míńísítà fún ọ̀rọ̀ òṣìṣẹ́ Chris Ngige Ọ̀rọ̀ bẹ́yìn yọ níbi ifẹhonu han ti àwọn ẹgbẹ́ òsìṣẹ́ pinu láti gùnlé lóni ọjọrú lòdi si mínísítà fún ọ̀rọ̀ òsìsẹ́, Dokita Chris Ngige.
Mo fi ọ́ ṣe alákòóso ní gbogbo ilẹ̀ Ijipti.
Egbe awon odo to wa fun sise idanilekoo loorekoore ninu ise eto ogbin ti a mo si Youth Agricultural Enterprise Training Programme (YET-P) ti seto idanileko lori ipese ohun jije fawon agbe lobinrin ti won to egberun meji abo nipinle Benue ni aarin gbungbun Naijiria.
Ọjọ́ ọjà ni ọjọ́ tí Orímóògùnjẹ́ máa ń mú owó nínú séèfù rẹ̀ máa ń bọ́ sí.
Wọ́n ń wádìí ọ̀rọ̀ lọ́dọ̀ igi gbígbẹ́, ọ̀pá wọn ń sọ àsọtẹ́lẹ̀ fún wọn.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Iya Rainbow, Jide Kosoko, Ọga Bello, yóò polongo Buhari fún 2019 NLC ní Gómìnà tí kò bá san ẹ̀kúnwó oṣù gbọdọ̀ fipò sílẹ̀ Ọlọpaa gbé àpótí adènà ẹ̀rọ ìbánisọ̀rọ̀ sílé Dino ASUU: A kò ṣetán láti fòpin sí ìyanṣẹ́lódì Bi o tilẹ jẹ pe ko si ẹni to lee sọ pato ohun to mu ko pa ara rẹ gẹgẹ bi o se kede lori Instagram, iroyin sọ pe iyawo rẹ, lo sadede ko kuro ninu ile fun-un, eyi to sokunfa orisun ibanujẹ nla fun.
Ohun to se pataki ni pe ,ki eto aabo to peye wa fun awon oludibo  ati ibo won, ki I se iye olopaa ti won ko lo sibe.
Ti ó bá tún ṣe, a dàbí ojú kìnìhún, ìgbà tí o tún ṣe, a dàbí ojú ẹkùn.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Wàhálà Boko Haram ló lé mi wá sí Eko tí mo fi di èrò abẹ́ afárá' EFCC mo de!
Fólúkẹ́, Omówùmí àti Oládípọ̀ jẹ́ ọmọ Yẹ́wándé.
awon ileto ati agbegbe to wa ni ipinle 
Gẹ́gẹ́ bí mo ti sọ, kí ẹ ti múra sílẹ̀.
Kí ẹsẹ̀ keji jẹ́ òkúta emeradi, ati òkúta safire, ati òkúta dayamọndi.
Labẹ ofin,ile ẹjọ ko le gba ọrọ ti afunrasi ba fi ipa sọ fun ọlọpaa wole.
O ti fi ọ̀nà ìyè hàn mí;ayọ̀ kíkún ń bẹ ní iwájú rẹ,ìgbádùn àìlópin sì ń bẹ ní ọwọ́ ọ̀tún rẹ.
Kọmísọ́nnà fun ọrọ to n lọ ni Kano, Muhammed Garba, sọ pe eyi jẹ ọkan lara igbese ijọba lati tubọ tesiwaju ninu aseyọri rẹ lati gbogun ti aarun Covid-19.
Inú mi ìbá dún bí gbogbo yín bá lè máa fi èdè àjèjì sọ̀rọ̀.
Ajọ naa fidi rẹ mulẹ pe ida mẹrindinlaadọta ninu ọgọrun awọn eeyan to lugbadi aarun naa lọdun yii lo wa lati ipinlẹ Edo nigba ti ida mẹrinlelogun si wa lati Ondo Eeyan marundinlogoji miran ko aarun iba Lassa ni ipinlẹ mẹfa Ajọ to n mojuto ajakalẹ arun lorilẹede Naijiria, NCDC ti kede wi pe eeyan marundinlogoji miran lo tun ti ko aarun iba Lassa lawọn ipinlẹ marun laarin ọjọ kẹrindinlọgbọ oṣu keji ọdun 2018 si ọjọ kẹrin oṣu kẹrin ọdun 2018 kanna.
O ni Ẹka ileeṣẹ ọlọpaa nipinlẹ Eko yoo sa gbogbo ipa rẹ lati rii daju pe awọn to padanu ẹbi ati dukia wọn sinu iṣẹlẹ naa gba idajọ ododo.
Ṣé ẹ lè mu ninu ife ìrora tí èmi yóo mu, tabi kí ojú yín rí irú ìṣòro tí ojú mi yóo rí?
Ẹni ogún ọdún ni Ahasi nígbà tí ó jọba, ó sì wà lórí oyè fún ọdún mẹrindinlogun ní Jerusalẹmu.
Huramu mọ ọpọlọpọ ìkòkò, ó fi irin rọ ọkọ́ pupọ, ó sì ṣe àwọn àwo kòtò.
O si ti n ṣiṣẹ alufaa ijọ Cele fun ọdun mẹrinla gbako.
Àwọn ni wọ́n ń ṣọ́ àgọ́ àwọn ọmọ Lefi tẹ́lẹ̀.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Ọwọ́ tó bá dilẹ̀ ni èṣù ń bl ní iṣẹ́kíṣẹ́' Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Fídíò, Natalia Mufutau ìyá Yakub, Kamil àti Adam sọ̀rọ̀ lórí bí wọ́n ń sọ èdè mẹ́rin pàpọ31 Ògún 2020 Fídíò, Yoruba Language: Akomolede ati Asa Yoruba tọ̀sẹ̀ yí rèé lẹ́nu olùkọ́ wa30 Ògún 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 3 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 5 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Alajo Somolu: Ọdún mẹ́ta ló fi gba àjọ láì kọ ọ́ sílẹ̀, kò sì si owó àjọ san 15 Sẹ́rẹ́ 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 16 Ògún 2020 Oríṣun àwòrán, @Dstoryteller Lọpọ igba ni awọn eeyan maa n pa asamọ pe, ori eeyan kan pe bii alajọ Somolu, to fi ọdun mẹta gba ajọ, ti ko si kọ silẹ, bẹẹ ni ko si owo san.
Coronavirus lè tara òkú Abba Kyari ran àwọn tó péjú síbi ìsìnkú rẹ̀- Ààrẹ ẹgbẹ́ dókítà ní Nàìjíríà Ẹ̀rù ń bà mí láti bímọ, kíni mo fẹ́ ṣé, ní àsìkò yìí ?
Mo bèèrè, mo ni, ‘Bàbá, ṣé kò sí nkan?
 O je ohun ti awon eniyan Naijria lapapo mu lokunkundun,”Ninu ipade igbami aye ohun ti o waye nile itura Eko Hotels and Suites, ni won ti fi ami-eye agbaboolu ti o darajulo ti ajo NFF da agbaboolu iko Chelsea FC,  Victor Moses lola.
7 1676 Orilẹede Niger 80 0.
Badagry: Ojú ọ̀nà àrèmabọ̀ fáwọn ẹrú tó ń lọ sókè òkun
Iroyin ni afurasi naa ma n rọ awọn ọmọde ọhun, to jẹ ẹni ọdun mẹfa ati mẹsan an ni ogun ko to gunle iwa buburu naa.
Yóo bọ́ agbo ẹran bí olùṣọ́-aguntan.
Gomina Samuel Ortom sọ ọrọ yi fawọn akọroyin lọjọ Abamẹta.
NURTW Oyo: Ọwọ́ bàtá Auxiliary tó ń ró ní àrójù, leè ya láìpẹ́ - Ìjọba Oyo dúnkookò Yoruba ni bi ọwọ Bàtá ba ti n le ni aroju, o setan to fẹ ya ni.
Bimbo Oshin Ọjọ kẹrinlelogun oṣu keje ọdun 1971 ni wọn bi Bimbo Oshin, agbaọjẹ si ni ninu iṣẹ tiata.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ondo rape apologist: Olùkọ́ kan di èrò ọgbà ẹ̀wọ̀n fún fífipá bá ọmọ ọdún mẹ́wàá lòpọ̀ ní ìpínlẹ̀ Ondo 11 Ògún 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 14 Ògún 2020 Ile ẹjọ giga kan ni ilu Akure nipinlẹ Ondo, ti dajọ ẹwọn gbere fun olukọ kan, Omotayo Adanlawo fun ẹsun ifipabanilopọ.
Ó kó ọ̀kọ̀ ati apata sinu gbogbo wọn, ó sì fi agbára kún agbára wọn.
Èyí jẹ́ ọ̀nà làti mú ààrùn kúrò, nítorí náà, ó kú ẹ̀fọn nìkan tí kò sì lágbára mọ́ láti fi àìsàn sáwọn ènìyàn lára Tẹ o bá gbàgbé ọmọ ọba Charles àti àwọn ẹlẹ́yinjú àánú yóò pàdé níbi àjọ Commonwealth láti ṣe àgbélakẹ̀ bílíọ̀nù mẹta lé ọwọ mejo dollar láti ṣe ìwádìí sì ọ̀nà àbáyọ lórí ààrùn ibà.
Wọ́n bá rán Banaba sí Antioku.
Sibẹ Saulu kò sọ nǹkankan nítorí pé ó rò pé bóyá nǹkankan ti ṣẹlẹ̀ sí Dafidi, tí ó sì sọ ọ́ di aláìmọ́ ni.
Bayìí ni àwọn ọlọpàá Akure ṣe ko àwọn ará ìlú ti o ji ẹrù ni sọọsi Sotitobirẹ Ọmọ ogún ọdún kan tún di àwátì nílùú Akurẹ nípìnlẹ́ Ondo- PPRO Tápà sí ìlànà tuntun CBN kí o fí owó ìtanràn ₦2m gbára Sambo Dasuki gbòmìnira lẹ́yìn ọdún mẹ́rin Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Thanksgiving day: Why Americans dey like to kill tolotolo for celebration?
" Akekaka ni Tafa gba ìbon lọwọ ọkan lara awọn agbẹ, to si yin in si ọkan lara awọn ọlọpaa naa, eyi to jẹ ọta ìbọn kan ṣoṣo to bẹrẹ ogun Agbekoya.
Bí a fẹ́ báni sọ̀rọ̀ ni, òun ni.
Àní, mo dàbí ẹni tí kò gbọ́rọ̀,tí kò sì ní àwíjàre kan lẹ́nu.
Adájọ́ ní Seun Egbegbe ṣì lẹ́jọ́ láti jẹ́ lórí ẹ̀sùn gbájúẹ̀ Kíní ìtumọ̀ ''Sọ̀rọ̀ Sókè'' tí àwọn afẹ̀họ́núhàn EndSars ń lò káàkiri Ẹ̀mí ọ̀pọ̀ ènìyàn yóò lọ tí ààrẹ Trump kò bá gbé ìpò sílẹ̀ - Joe Biden Báwo làwọn agbébọn ṣe rí ASP Ọlọ́pàá méjìlá jígbé lójú ìbọn?
Abẹwo naa waye lasiko igba ti wahala awọn jaguda to n jin eeyan ati maalu gbe peleke lagbegbe naa.
Minisita fun Eto Irina, Rotimi Amaechi ti pasẹ fun awọn osisẹ to n la oju irin Eko silu Ibadan, CCECC lati ri daju wi pe, wọn pari ọna reluwe naa laarin ọsẹ meji.
Abimeleki tún lọ sí Tebesi, ó gbógun tì í, ó sì gbà á.
Yóo dàbí ìgbà tí eniyan kórè ọkà lóko,tí ó kó ṣiiri ọkà kún apá.
Ọgbẹni Omohon ni aworan gbogbo awọn to ti gbala lati ọdun bọdun ati igba ti o lugbadi omi gbigbona, nigba ti epo gbigbona jọ ọwọ rẹ, amọ ti ko si di i lọwọ isẹ.
Òkúta iyebíye ni wọ́n fi mọ odi náà.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ẹ wo ọmọ ọdún méje tó di Gómìnà l'Ekiti Wo ohun tó yẹ kí o mọ̀ nípa àwọn obìnrin méje ti Buhari forúkọ wọn ránṣẹ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Pope Francis appealed for peace after performing the rare gesture Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Gbé òróró ìyàsọ́tọ̀, kí o dà á lé e lórí láti yà á sọ́tọ̀.
Lẹ́yìn ọjọ́ mẹta, Farao ọba yóo yọ ọ́ jáde níhìn-ín, yóo bẹ́ ọ lórí, yóo gbé ọ kọ́ igi, àwọn ẹyẹ yóo sì jẹ ẹran ara rẹ.
lasiko odun Keresimesi ati odun tuntun.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù RUGA: Gómìnà ìpínlẹ̀ Kano ní gbogbo Fulani lè máà bọ̀ lọ́dọ̀ àwọn 20 Agẹmo 2019 Oríṣun àwòrán, AFP Àkọlé àwòrán, Fulani Darandaran Ọrọ lori boya ki awọn fulani Darandaran maa pada lọ ẹkun ariwa Naijiria gẹgẹ bi ẹgbẹ awọn agba ẹkun naa, NEF ṣe ke si wọn duro nibi ti wọn ba wa ti di ohun a n gba bi ẹni gba igba ọti.
A le pa owe da, bí àpẹẹrẹ: Ojú kì í ti eégún kí ọmọ alágbàá má kọrí sóko.
Numba yii jina pupọ si iye ti wọn ti ma n kede tẹlẹ lati bi oṣu melo kan.
18,621Gbogbo iye ibo ti won fagile
Aare Buhari yoo maa soro lori
Ọ̀pọ̀ òkú ṣùn, dúkìá jóná nínú àkọ̀tun ìṣẹ̀lẹ̀ ìbúgbàmù gáàsì l'Eko Ọrọ ibugbamu to n fi ojoojumọ waye nipinlẹ Eko bayii ti wa di ailasọ lọrun paaka bayii, eyi to to apero fun gbogbo ọmọ eriwo.
Kerubu kọ̀ọ̀kan ní iwájú meji meji.
 ní ọdún 1926 ni ẹgbẹ ́ tí a mọ ̀ sí  Ìjẹ ̀ bú - jẹ ̀ ṣà progressive union "" yí orúkọ ìlú náà kúrò láti Ìjẹ ̀ bú - Ẹrẹ ̀ sí ijẹ ̀ bú - jẹ ̀ ṣà nítorí pé ilẹ ̀ Ìjẹ ̀ ṣà ni Ìjẹ ̀ bú yìí wa ."
A kò ní bá wọn pín ninu ilẹ̀ òdìkejì odò Jọdani nítorí pé a ti ní ilẹ̀ ìní tiwa ní ìhà ìlà oòrùn odò Jọdani níhìn-ín.
Funmi ṣalaye wipe o ni ileeṣẹ foyungbawo kan (Baby Factory) ni awọn ọmọ naa salọ pada nibi to jẹ wipe awọn ti kọkọ ri wọn.
Awọn obìnrin ni wọn saaba maa n ṣe iṣẹ alaga iduro ati ijokoo nilẹ Yoruba paapaa awọn iyawo ilé.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Maradona, ẹni ọgọta ọdun ni akọnimọọgba ẹgbẹ agbabọọlu Gimnasia y Esgrima to n dije ninu liigi orilẹede Argentina.
ati àwọn tí ń gun orí òrùlé lọ láti bọ oòrùn, òṣùpá, ati àwọn ìràwọ̀.
Aimọye eeyan lo ti pade iku wọn latarui wi pe wọn fẹ ẹni ti awọn mọlbi wn ko lọwọ si.
Ìjọba àpapọ̀ yóò ti afárá Third Mainland pa fún oṣù mẹ́fà láti ṣe àtúnṣe Akẹ́kọ̀ọ́ wọlé padà, ìjọba Oyo kò pèsè ìbòmú lòdì sí ìlérí rẹ̀ Ẹ wo bí ọ̀rọ̀ òṣèlú, ẹ̀sìn àti ẹ̀yà ṣe fa ogun abẹ́lé Biafra Ẹ̀kún omi ṣọṣẹ́ ní Ogun, ìjọba yarí láti wó ilé ojú odò Nwajiuba sọ pe idanwo NECO ati NABTEB yoo bẹrẹ ni kete lẹyin ti wọn ba ti pari idanwo WAEC ọhun.
Nígbà tí èèyàn bá kọ́kọ́ tàn án, Roomba á fúnni ní ànfàní àti ṣe ẹ̀tò àsìkò tí èèyàn fẹ́ kó gbálẹ̀ lójúmọ́.
Ọrẹ rẹ kan ni ọmọ ẹgbẹ okunkun ja lole ti ọrọ naa si di ranto.
O korin kaakiri orile  ede Mali pelu egbe Las Maravillas ko to lo si Paris lodun 1980 nibi ti nkan to ti senu re ko to pada wale ni 1998.
"O sọ ninu atẹjade kan pe ""gbogbo ara l'oun fi fọwọ si"" ifẹ ọkan wọn lati bẹrẹ igbe aye tuntun, ṣugbọn ""oun to wu oun ju ni pe ki wọn o maa ṣiṣẹ gẹgẹ bi ọkan lara ẹbi ọba ilẹ Gẹẹsi""."
"Oríṣun àwòrán, lizzyanjorin_original ""Mo nifẹ oge sise, mo si n sisẹ kara, Mo maa n ra awọn ọja asọ ati goolu to yatọ, ti ko si wọpọ."
Brexit: Theresa May yóò ṣèpàdé pẹ̀lú àwọn olórí EU láti dóòlà ìpinnu rẹ̀
O ni nigba ti o ya, Osadebe lo ilu wọn nítorí o se aisan.
Esi ayẹwo ile iwosan lori oku Ogah fi han wi pe, lẹyin lilu ti wọn lu oloogbe naa, ọpọlọ rẹ wu.
"Ọmọ Yahoo fẹ́ pa ìyá rẹ̀ ṣ'owó l'Eko Ẹ̀yin ẹlẹ́gbẹ́ òkùnkùn tẹ fẹ́ ṣe àjọ̀dún lónìí, lákọ la ń dúró dè yín - Iléeṣẹ́ ọlọ́pàá Ohun tí o kò mọ̀ nípa Ebila ""One Million Boys"" àti Ekugbemi, olórí ẹgbẹ́ òkùnkùn méjì tó da ìlú Ibadan rú Oyeyemi ni ibọn yinyin naa waye lasiko tawọn ọmọ ẹgbẹ okunkun naa n ṣe iwọde idaro akẹẹgbẹ wọn to ku."
Àbí yóo sọ fún iranṣẹ náà pé, ‘Tọ́jú ohun tí n óo jẹ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Lagos traffic: Ohun márùn ún tó ń fa súnkẹrẹ-fàkẹrẹ nílùú Eko 23 Bélú 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Gbogbo eeyan lo mọ pe ninu awọn ilu to tobi lagbaye ni ilu Eko wa.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Premier League: Crystal Palace yẹ̀yẹ́ Arsenal bí Everton ṣe dígbájú ru Manchester U 21 Ìgbé 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Idije Premier League Tẹni to de laari, a ko mọ tẹni to n bọ lọrọ awọn ifẹsẹwọnsẹ idije Premier League to waye lọjọ Aiku.
”Ahabu tún bèèrè pé, “Ta ni yóo bẹ̀rẹ̀ ogun náà?
Bẹ́ẹ̀ ni Mose ṣe parí gbogbo iṣẹ́ náà.
5 Ìgbé 2019 Oríṣun àwòrán, Nigeria Bar Association Àkọlé àwòrán, Wọn fi awọn ẹsun to jọ mọ ajẹbanu ati awọn ẹsun miran kan Adajo agba naa Iroyin to n tẹwa lọwọ sọ pe adajọ agba Naijiria ti wọn pasẹ lọ rọọkun nile ti wa papa kọwe fi ipo silẹ.
Tí o bá wa jẹ́ pé inú àkàsọ̀ ìgbàlódé ní ó ká ọ mọ́ tí ẹni náà ba wá sín, ìlọ́po mẹ́wàá ni ìṣòro tìrẹ.
ní Enrimoni, ní Sora, ati ní Jarimutu, 
N óo gbé ẹ̀wù ìgbàlà wọ àwọn alufaa rẹ̀,àwọn eniyan mímọ́ rẹ̀ yóo sì kọrin ayọ̀.
Nigba ti awọn mọlẹbii rẹ yoo fi waa de ibẹ ni wọn fi to wọn leti pe eegun to n jẹ Ọlayẹmi ko fi igba kọọkan sẹyọ ni agọ naa gẹgẹbi o se sọ fun wọn.
Ṣugbọn òun ati àwọn eniyan rẹ̀ dúró gbọningbọnin ninu oko náà, wọ́n bá àwọn ará Filistia jà.
Alaga ẹgbẹ CAN ni ipinlẹ Ondo, Ẹniọwọ Ayo Ọladapo lo fi lede ninu lẹta ti wọn fi ransẹ si awọn adari ẹsin ni ipinlẹ naa lati se idanilẹkọọ fun awọn ara ile ijọsin wọn.
Ni ibẹ lo ti mu mi lọ ba awọn eeyan kan.
Jẹ́ kí n máa gbé inú àgọ́ rẹ títí lae,kí n lè máa wà láìléwu lábẹ́ ààbò ìyẹ́ rẹ.
Jẹ́ kí ojú ó ti àwọn tí ń lépa ẹ̀mí mi,kí wọn ó tẹ́!
Ìyàtọ gbáà ló wà láàrin àwọn tó ń ṣe àyẹwò, àyẹwò ti South Africa ń ṣe pọ̀ jọjọ jú ǹkan pérété ti Nàìjíríà ń ṣe lọ, èyi jẹ abájade ìwádìí WHO.
Wọn a máa tọ́ ṣúgà sí omi.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù FUTA Bullies: Ìgbìmọ̀ aláṣẹ fásitì FUTA pàṣẹ lọ rọọ́kún nílé fakẹ́ẹ̀kọ́ méje tó lù akẹgbẹ́ wọ́n 17 Bélú 2019 Oríṣun àwòrán, Google Igbimọ alaṣẹ fasiti imọ ẹrọ ilu Akure, FUTA ti paṣẹ lọ fidimọle fawọn akẹkọọ meje ni fasiti naa ti wọn da sẹria iya f'akẹgbẹ wọn kan to jẹ obinrin.
Esau bá dáhùn pé, “Jakọbu ni orúkọ rẹ̀ nítòótọ́.
 bi ọkan ninu wọn ba jẹ ọmọ ijẹsa .
Ileesẹ ọmọogun Nàìjìríà: A ò fipá bá ẹnikẹ́ni lò ní ìpàgọ́
Ó tóbi, ó sì níyì pupọ láàrin àwọn Juu, nítorí pé ó ń wá ire àwọn eniyan rẹ̀, ó sì ń sọ̀rọ̀ alaafia fún gbogbo wọn.
Awọn eetan orile-ede naa fẹ ki aarẹ Abdelaziz Bouteflika kọwe fipo silẹ Oríṣun àwòrán, EPA Àkọlé àwòrán, Titi di ọjọ Ajẹ awọn eeyan Algeria ko dawọ iwọde naa duro Ǹjẹ o mọ bí April Fool's Day se bẹ̀rẹ̀?
Ó fẹ́rẹ̀ jẹ́ pé gbogbo ejo burúkú ayé yií ló pé sínú igbó náà tan, ọká, àti paramọ́lẹ̀ àti èjò olóró gbogbo ni wọ́n wà, bẹ́ẹ̀ ni igi ìrònù jẹ́ igi ẹlẹ́gùn-ún tí ó mú bí orí abẹ́rẹ́, ó sì ṣòro ki nn tó lè gùn ún dé orí.
Ènìyàn lásán ni ẹnì keje, kò sí nínú àwọn alátùn-únṣe inú ayé, oníbàjẹ́ ènìyàn ni.
Ẹni kan sọ pé sán-ányán ni aṣọ tí ó wọ̀ níwọ̀n ìgbà tí ó ti jẹ́ pé àwọn ọmọ́dé kìí tètè gbàgbé nnkan, Akin Olúṣínà ní kí awọ́n bèèrè ìbéèrè nípá Fáwọlé lọ́wọ̀ Fólúkẹ́ àti Bándélé.
Oúnjẹ tí èmi yóo fi fún un ni ẹran ara mi tí yóo fi ìyè fún gbogbo ayé.
Àkọlé àwòrán, Iwa rere lẹṣẹ eniyan Awọn onimọ nipa ọrọ ẹlẹwọn ni, ida bii meje ninu mẹwaa awọn ẹlẹwọn ni o tun maa n ṣẹ ẹṣẹ ti yoo ran wọn pada s'ẹwọn.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Afárá Marina àti Eko yóò di ṣíṣí padà lọ́la Iléeṣẹ́ ológun bẹ̀rẹ̀ 'Operation Crocodile Smile' yíká Naijiria fún oṣù méjì Òkú tó jí lọ́jọ́ kejì ní mọ́ṣúárì padà kú síléèwòsàn Ṣé lóòtọ́ ni àjọ ọlọ́pàá dá Abayomi Shogunle àti Dolapo Badmus dúró?
Ìṣẹ̀lẹ̀ yìí dí èyí tó mú j]agídíjàgan dáni, ẹ̀mí àti dúkíà ọlọ́dan àti ti ìjọba ló lọ si pẹ̀lú.
AFCON 2019: Bí Nàìjíríà ṣe gbá eyí tó lọ, mi ò lè sọ àsọtẹ́lẹ̀ti tònìí
, Duration 2,1522 Bélú 2020 Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí 2 sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
Èmi Johanu ni mo ranṣẹ sí ìjọ meje tí ó wà ní agbègbè Esia.
Ọpọ ninu awọn onidanfo a tun duro si aarin titi maa wa ero.
Ti a ko ba gbagbe, laipẹ yii ni Timi Frank ati awọn akẹẹgbẹ rẹ fi ẹsun kan Igbakeji Aarẹ naa wi pe o lu owo ilu ni ponpo lasiko to gba ọgọọrọ biliọnu to to aadọrun kuro ni ẹka to n risi ọrọ abẹle lorilẹede Naijiria, lati fi se idibo gbogboogbo ti ọdun 2019.
Moroni ni ìkẹhìn nínú àwọn ọ̀pọ̀ ònkọ̀tàn tí wọn ti ṣe àkọsílẹ̀ èyí tí ó wà níwájú gbogbo ayé nísisìnyìí gẹ́gẹ́bí Ìwé Ti Mọ́mọ́nì.
Jesu ní, “Àwọn meji kan jẹ gbèsè.
Ó dàbí ìrì òkè Herimoni,tí ó sẹ̀ sórí òkè Sioni.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Àwọn kan ń dunú, àwọn kan ń ṣe ìkìlọ̀ lórí èsì ìdìbò ààrẹ Ọjọ Ẹti to kọja ni ẹgbẹ oṣiṣẹ naa bẹrẹ iyanṣẹlodi.
Lẹ́yìn èyí, a kọjú sí ọ̀nà wa.
"Adamu pari ọrọ rẹ pe ""O lewu lati ṣi ile iwe bayii."
“Ẹ gbọdọ̀ mú àkọ́so oko yín wá sí ilé OLUWA Ọlọrun yín.
Mo ṣì ń péjú níbi ìpàdé ẹgbẹ́, èmi àti àwọn olólùfẹ́ mi kò pinnu láti fi ẹgbẹ́ sílẹ̀ yálà nísinsìn yìí tàbí lọ́jọ́ iwájú.
Mo tún lọ ní ọjọ́ kẹta pẹ́lú, ṣùgbọ́n ó bú mi láti ẹsẹ̀ mi dé orí koko, ó fa àdá yọ, ní ìgbẹ̀yìn ó fi àdá lé mi dé ilé mi koko.
Ẹ wo ìṣẹ̀lẹ̀ nípa ẹ̀sùn ìfipábánilòpọ̀ tí wọ́n fi kan D'banj ní sísẹ̀-n-tẹ̀lé Eji Gbadero, ọmọ Ibadan àti jayé-jayé ọmọ ónílẹ̀ ti wọn yẹgi fun l'Eko Èyí ni àwọn arẹwà ‘ẹ̀lẹ̀ Daddy’, àfẹ́fẹ́ tí Aláàfin fi ń mí ‘Ọ̀pọ̀lọpọ̀ ni inú wọn kò dùn sí bí Hajj kò ṣe ní wáyé lọ́dún yii’ Bakan naa lo ni kaka ki Tinubu o ba aarẹ Buhari sọrọ lati wuwa rẹrẹ si awọn ọmọ Naijiria, ki iya ma ba jẹ wọn, niṣe ni Asiwaju n gbe lẹyin Buhari, ẹni to wa jakulẹ bayii.
Aigbe ipe si ori ẹrọ ibaraẹnisọrọ rẹ lo tun mu ifura dani.
Irufẹ owo bẹẹ ti ẹnikẹni ba fẹ gba gbọdọ wa nipasẹ sọwedowo (cheques) tabi lori ayelujara.
àwọn eniyan wọn tí wọn ń gbé àwọn ìletò a máa wá ní ọjọ́ meje meje, láti ìgbà dé ìgbà, láti wà pẹlu àwọn olórí ọ̀gá aṣọ́nà mẹrin náà.
Oríṣun àwòrán, Instagram/William Troost-Ekong Musa sọ pe awọn duro digbi fun ohun kohun ti Bafana Bafana ba fẹ gbe wa.
eto eyawo yii tun ti fi da awon omo orile ede Naijiria loju pe orile ede
O si tun jẹ aarẹ ẹgbẹ awọn ọmọ bibi ilẹ Ẹgbado, taa mọ si Yewa bayii, ẹka ti Eko ni ọdun 1941 si 1951 Lọdun 1951, J.
Èyí tóbi gaa ni sí irú àwọn èkúté míràn.
Wọn pa ẹnu pọ sọ wi pe, igbogun ti oṣi, ainiṣẹlọwọ, ailanfani si eto ẹkọ ati lilo egbogi oloro n bẹ lara awọn ọna abayọ si ipenija eto aabo.
Ni ọdun 2002 ni wọn da ẹgbẹ Boko Haram silẹ, gẹgẹ bii ẹgbẹ ti kii se oniwahala pẹlu afojusun ati ṣe afọmọ ilana ẹsin Islam lẹkun ariwa orilẹede Naijiria.
Àwọn alufaa ìdílé Lefi pọ̀ nítorí ikú kò jẹ́ kí èyíkéyìí ninu wọn lè wà títí ayé.
Awọn atukọ̀ títí kan òṣìṣẹ́ gbogbo, ọkọ̀ òfuurufú láti Addis Ababa ní Ethiopia sí Èkó ní Nàìjíríà  jẹ́ obìrin pátápátá porongodo.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù A ó ò dasẹ́ sílẹ̀ fún ojọ́ gbọọrọ tí ìjọba bá kọ̀ láti san owó oṣù mẹ́rin tó jẹ wa- Àwọn dokita ìpínlẹ̀ Ondo 4 Bélú 2020 Oríṣun àwòrán, Western Post Ẹgbẹ awọn dokita ipinlẹ Ondo ti bu ẹnu atẹ lu ijọba ipinlẹ naa lori bo ṣe maa n fi iya owo oṣu jẹ wọn nigba de igba.
"Kii ṣe ikọlu awọn agbesumọmi, iṣẹ ọwọ awọn majeṣin to n wa ohun ti wọn yoo jẹ tabi ta ni.
Lẹnu ọjọ mẹta yii ni awuyewuye n waye laarin awọn ọmọ ẹgbẹ kan pe, wọn yoo koro oju si igbimọ naa ti ko ba fi ṣeto ipagọ gbogboogbo 'National Convention' ẹgbẹ naa ni kiakia.
Awọn agbẹjọro ijọba orilẹ-ede Chad sọ pe awọn eeyan yii jẹ afurasi oniṣẹ ibi Boko haram nigba ti awọn ajafẹtọ ọmọniyan ni irọ ni pe ara ilu lasan to n ṣẹwọn ni wọn jẹ.
Iṣẹlẹ yii si ti n gbe ọpọlọpọ ariwo sita loju opo ayelujara bii Twitter.
Àwọn ọmọ Nàìjíríà bu ẹnu ẹ̀tẹ́ lu NTA lórí ìgbóhùnsáfẹ́fẹ́ ìdíje bọ́ọ̀lù Ilé ẹjọ́ ni agbábọ́ọ̀lù ọmọ Nàìjíríà, Dickson Etuhu jẹ́bi ẹ̀sùn títa ìdíje Sweden Èèyàn mẹ́tàlá dèrò ọ̀run nínú ìjàmbá ọkọ̀ lópòpónà Ìbàdàn s'ÈKó Zlatan: Èyí mo ṣé tó, àsìkò tó láti tèsíwájú nínú ìrìnàjò mi Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Wọn ni o fẹ ṣe awọn idije kan bo ṣe wuu ni alsiko naa Ṣugbọn ajọ FIFA ko sọ ni pato ohun to ṣe ati idije to da bi ọgbọn si.
Lẹyin yiyẹra funra ẹni fun ọdun mẹta yii ni lọkọ laya ṣẹṣẹ le beere fun ikọsilẹ ni eyi ti agbara wa lọwọ Adajọ lati ṣe tabi ko tun fun wọn ni igbesẹ alaafia miran.
O ni o ti wa lati atunṣẹ ti wọn gba aṣẹ lati ṣe ninu agbeyẹwo todun 2016 si 2018 ni.
Bakan naa, kikuna ijoba lati san awon owo ajemonu, pipese isuna lati se atunse si awon ile-iwe lapapo abbl.
Igbakeji gomina ipinle Oyo, Otunba Moses Adeyemo lo soro yii lasiko to n soju fun asofin Ajimobi, pe ijoba oun ti se gudu-gudu meje ,yaya mefa  lati mu igbaye-gbadun ba awon  osise Ipinle oyo , paapaa julo  nipa sisan owo osu ati ajesile owo osu awon  osise,  igbega lenu ise  lasiko to yẹ.
Ọrọ iku rẹ jẹ nnkan to ṣokunkun titi di bi a ti ṣe n sọrọ yi.
Maharaji kesi aarẹ Buhari bẹẹ, lasiko ipade akọroyin to se eyi to fi n sami ajọdun ọdun kẹrindinlọgbọn to kede Naijiria bii ilẹ mimọ lagbaye.
Amọṣa, Mimiko ti ni oun ko ni lọ lọwo ofo o nitori naa ipo sẹnetọ ni oun yoo maa lọ fun bayii ni abẹ aṣia ẹgbẹ oṣelu kan naa.
s tí ó maa ràn-àn lọ ́ wọ ́ .
OLUWA pè é láti orí òkè náà, ó ní, “Ohun tí mo fẹ́ kí o sọ fún àwọn ọmọ Israẹli nìyí, 
Deede aago meji oru ni ajọ INEC kede pe oun fẹ lọ rẹju diẹ naa lati sinmi, ti oun yoo si pada ni aago mẹsan owurọ ọjọ Aiku, lati kede awọn esi ibo to ku lawọn ijọba ibilẹ mẹfa.
Ìjà ẹ̀sìn Kaduna: Ìjọba ìpínlẹ̀ Kaduna dá kóníléógbélé padà Iku olori ilu kan nipinlẹ Kaduna ti ṣokunfa ki ijọba fúnkùn mọ ofin konileogbele ti wọn dẹ tẹlẹ.
Bo ṣe lee ko ifẹ rẹ sori awọn oludibo naa lo ṣe jẹ eeyan to lee ma pẹ da wahala silẹ.
 lásìkò yìí , àwọn ènìyàn kan a má a bẹ ̀ rẹ ̀ sí ní ìṣòro ẹ ̀ jẹ ̀ sísun .
Lẹyin ti eruku ẹjọ lọ ọ lẹ lori fọto naa, ni Adebimpe sọ nigba naa pe, Lateef kii ṣe iru ọkunrin ti oun le fẹ.
Ọna abayọ ni kiakia ni pe ki ijọba maa sanwo fawọn oṣiṣẹ atawọn oniṣowo.
 Àwọn aamì tí o ń farahàn ni granuloma ti àwọn isan imọ ̀ , ibi atẹ ́ gùn ìmí ńgbà , àwọ ̀ ara , àti àwọn ojú .
Gẹgẹ bi iṣẹlẹ ipaniyan ijinigbe ṣe n waye lọtun losi lorilẹede Naijiria eyi ti ariwo rẹ kọkọ pọ ni iha ariwa to fi wa di pe o tun sun de ipinlẹ Eko naa bayii ti ibẹru bojo si bo awọn eniyan lati rinrin ajo, Elkanah fesi.
Maa mu omi dede lati jẹ ki igbẹ rẹ rọ, ki ounjẹ si da lasiko ti o yẹ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Lagos State: Ẹbí èèyàn márùn ún àti àlejò kú sínú ilé l'Eko 4 Owewe 2019 Oríṣun àwòrán, Twitter/@sagagist Igbe oro lawọn agbebe lawọn olugbe agbegbe Mafoluku l'Oshodi n ke l'Ọjọru lẹyin ti wọn ba oku eeyan meje pẹlu alejo wọn ninu ile laarọ Ọjọru.
won tubo maa se iranwọ fun ile-ise ọlọpaa lati gbogun ti gbigba owo abetele.
Elinatani, Dilaaya ati Gemaraya tilẹ̀ bẹ ọba pé kí ó má fi ìwé náà jóná, ṣugbọn kò gbà.
Iyọkuronipo rẹ ko ṣẹyin bi adari ọmọ ile to pọju lọ, Henry Okhurobo ṣe ni ki wọn yọ ọ lori ẹsun pe oun lo iwa agbara pẹlu wọn.
Nigba ti mo pinnu lati sọ fun alufaa ijọ Katoliiki ti a n lọ, niṣe l'oun naa tun fi ipa bamilopọ.
Ahimeleki bá a ṣe ìwádìí lọ́dọ̀ OLUWA, lẹ́yìn náà ó fún Dafidi ní oúnjẹ ati idà Goliati, ará Filistia.
’ Ṣugbọn, ń ṣe ni wọ́n ń múra kankan, 
Ișẹ́ tó lérè púpọ̀ kúkú ní í ṣe.
Kò séwu nínú ìdìbò tó ń bọ̀ l'Ondo àfi gìrì àparò- Akeredolu Ṣaaju ni oriṣiiriṣii ti ṣẹlẹ nipa oju buluu Risikat ati awọn ọmọ rẹ̀: Wo ìdí tí Risikat Moromoke Azeez n'Ilorin fi ní ''Blue Eyes- Dókítà: Awọ oju arabinrin Risikat Alabi atawọn ọmọbinrin rẹ meji ti wọn n gbe niluu Ilorin, orilẹ-ede Naijiria ti n ya ọpọlọpọ lẹnu.
Bẹ́ẹ̀ gan-an ni: gbogbo igi tí ó bá dára a máa so èso tí ó dára; igi tí kò bá dára a máa so èso burúkú.
Ẹwẹ, ileeṣẹ ọlọpaa FSARS meji, Monday Uchiola and Okechukwu Ogbonna lori ẹsun iwa idunkoko mọ araalu lọni aitọ.
Igbakeji gomina naa, Phillip Shaibu so eyi di mimo lojoIsegun nilu Benin nibi eto idanilekoo olojo kan lori eto okowo, eyi ti akole re dale: “Ipolongo idokowo ni ipinle Edo: gege bi ona kan gboogi lati mu idagbasoke ba eto oro-aje”.
” Nígbà tí mo gbẹ́ ara ògiri náà, mo rí ìlẹ̀kùn kan!
Ogbeni Obia Edmund, ti o je adele oludari agba eka ipese ohun ikeko(Education Resource Centre), leni ti o lo soju minisita olu-ilu Naijiria FCT, gbosuba kare lai fun awon olusakoso ile-ise Voice of Nigeria fun ise takun-takun won.
Ta ni lè dárí ẹ̀ṣẹ̀ ji eniyan lẹ́yìn Ọlọrun nìkan ṣoṣo?
O tun tenumo pe, ile ise ologun lorie ede Naijiria  ni eto ati ilana labe ofin ti won maa n tele ninu
15 Agẹmo 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Awuyewuye ló tẹ̀lẹ́ ọrọ ti Asiwaju Bola Ahmed sọ lásìkò tó ń se àbẹ̀wò ibanikẹdun si ile baba Fasọranti ti awọn agbẹbọn pa ọmọ rẹ.
Ọdun 2012 ni o da ileẹkọ imọ nipa adari silẹ, bakan naa lo ni ajọ ti kii ṣe ti ijọba miran to n jẹ Israel Oladele Ogundipe Foundation oun si ni aarẹ ajọ naa.
Ẹnikẹ́ni tí ó bá fọwọ́ kan omi náà yóo di aláìmọ́ títí di ìrọ̀lẹ́ ọjọ́ náà.
Ṣugbọn nígbà tí ẹni tí ó lágbára jù ú lọ bá dé, tí ó ṣẹgun rẹ̀, a gba ohun ìjà tí ó gbẹ́kẹ̀lé, a sì pín dúkìá rẹ̀ tí ó jí kó.
Ìparun ti dé ba yín, ẹ̀yin tí ẹ̀ ń gbé ilẹ̀ yìí.
Oríṣun àwòrán, OTHERS Igbaradi Shina Rambo lati ṣe aseyori bii adigunjale Shina Rambo gba pe idi isẹ ẹni laa ti mọ ni ni ọlẹ, to si tiraka lati lu aluyọ nidii isẹ adigunjale.
Ṣugbọn, o ti di nkan ti awọn eniyan n rin irinajo igbafẹ lati wo.
Bale ni yóò rọ́pò Ronaldo nínú Super Cup Tinubu: Ọbasanjọ kò lè yan olùdíje fún wa Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Ọ̀lọ́wọ́ òsì kọ́ndọ́rọ́' Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Níwọ̀n ìgbà tí mo bá ń ṣe àwọn nǹkan tí n kò fẹ́, mò ń jẹ́rìí sí i pé Òfin jẹ́ ohun tí ó dára.
Yóo fi yàrá ńlá kan hàn yín ní òkè pẹ̀tẹ́ẹ̀sì, tí a ti ṣe lọ́ṣọ̀ọ́.
OLUWA sọ fún Mose pé, “Mò ń tọ̀ ọ́ bọ̀ ninu ìkùukùu tí yóo bo gbogbo ilẹ̀, kí àwọn eniyan náà lè gbọ́ nígbà tí mo bá ń bá ọ sọ̀rọ̀, kí wọ́n sì lè gbà ọ́ gbọ́ títí lae.
Nígbà tí ìyá ìyá ìkókó báti jókòó níwájú ilé tán, àgbà obìnrin kan yóò wọlé lọ gbé ọmọ náà jáde láti inú ìyàrá.
Virgin Island si papakọ ofurufu wọn ni Oṣu Kẹfa.
Nígbà tí wọ́n dé Salami, wọ́n waasu ọ̀rọ̀ Ọlọrun ninu àwọn ilé ìpàdé àwọn Juu.
 Alaga ijọba ibilẹ Amuwo odofin, ọgbẹni Valentine Buraimoh ba BBC sọrọ lẹyin wakati diẹ ti iṣẹlẹ ọhun waye, o ni ibugbamu ọhun waye nitori ọpa epo to fọ ."
”“Èmi ni, èmi tí mò ń kéde ẹ̀san,tí mo sì lágbára láti gbani là.
ipade bonkẹlẹ to se pelu ile igbimo asofin agba,“Ile igbimo asofin ti seleri lati satileyin
"Idi si ree ti awọn ọkunrin fi maa n ba obinrin sere pe ""ṣe nnkan oṣu rẹ tun ti de si ọ ni?"
"Yinka Ayefele di bàbá ìbẹta Yinka Ayefele di asojú Àjọ INEC Yinka Ayefele ṣe ìkọ́mọ ìbẹta rẹ̀, ọ̀nà ò gbẹsẹ̀ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Yinka Ayefele: Oṣù àwọn ìbẹ́ta mi kò pé ní kò jẹ́ kí n kọ́kọ́ kéde ìbí wọn Ayefele ni ""Mo le duro kọrin nibikibi bayii pẹlu kẹkẹ tuntun naa, 'action' bẹrẹ bayii, mo dupẹ pupọ lọwọ Dare Obama."
Ọwọ awọn ọlọpaa ni ipinlẹ Ogun ti tẹ abilekọ ẹni ogoji ọdun kan to n fi irin gbigbona ati ada da sẹria fun ọmọdekunrin ọmọ ọdun mejila kan.
Ninu ọrọ tirẹ, ẹgbẹ awọn oṣiṣẹ lorilẹede Naijiria NLC ṣalaye pe n ṣe ni ijọba n mu awọn ọmọ Naijiria ni suẹgbẹ pẹlu igbesẹ naa.
“Ẹ má bẹ̀rù mọ́, agbo kékeré; nítorí dídùn inú Baba yín ni láti fun yín ní ìjọba rẹ̀.
“Ọba ni yóo ni ilẹ̀ tí ó yí ilẹ̀ mímọ́ náà ká nì ẹ̀gbẹ́ kinni keji, ati àwọn ilẹ̀ tí ó wà ninu ìlú náà, ní ìwọ̀ oòrùn ati ìlà oòrùn, yóo gùn tó ilẹ̀ ọ̀kan ninu àwọn ẹ̀yà Israẹli, yóo bẹ̀rẹ̀ ní òpin ìwọ̀ oòrùn yóo sì dé òpin ìlà oòrùn ilẹ̀ náà.
Àwọn Juu mú ọkunrin yìí, wọ́n fẹ́ pa á.
Alaga Igbimọ Agbẹnusọ Ile Igbimọ Aṣofin Ipinlẹ ni orilẹ-ede Naijiria, ti o tun jẹ Agbẹnusọ Ile Igbimọ Aṣofin Ipinlẹ Eko, Aṣofin Mudashiru Ọbasa ti rọ awọn ọmọ orilẹ-ede Naijiria paapaa awọn musulumi lati ni ẹmi Ọlọrun, ifarada, suuru ati ifaraji fun alaafia ati irẹpọ laarin wọn.
Ẹ dẹkun ere sísá lójú pópó láti dẹkun ìjàmbá- FRSC Àgbéyẹ̀wò àṣà: Ìdí tí Yorùbá kìí fí tufọ ikú òjìji fún èèyàn Ìpínlẹ̀ Ọ̀ṣun kò le è sanwó o ọmọ́gọ̀ lórí LAUTECH- Gómìnà Oyetola Iwa nabi tu igbeyawo ọgbọn ọdun ka Adekunle Gold, Simi tú àṣírí ètò ìgbéyàwó wọn Opọ igba ni Aisha Buhari ti maa n sọrọ tako Maamman Daura lori ipa to n ko nile ijọba ni Abuja.
Bakan naa ẹwẹ, Ajax lo tun kọkọ gbayo meji wọle Tottenham ninu ipele keji ere bọọlu ọhun, ko to di pe ẹlẹsẹ ayo Lucas Moura dayo meji naa pada ni kete ti abala keji bẹrẹ.
Kì í ṣá ṣe pé òun ni ó ń bọ́ wa, a kò sì gba nǹkankan lọ́wọ́ rẹ̀.
Esi ti gomina lo jasi bẹẹni ti ti akọwe ijọba ipinlẹ naa si ja si bẹẹkọ.
Iwe akọsilẹ naa si ni wọn fi n sami ayajọ ọjọ gbigbogun ti iwa sawọn obinrin eyi to maa n waye lọjọ kẹẹdọgbọn osu kọkanla ọdọọdun, to ko lọjọ aje lọdun 2019.
Ọrọ lori iwọde tawọn ẹgbẹ oṣiṣẹ n gbero lati ṣe ni ọjọ Iṣẹgun, ọjọ karun un, oṣu kẹta, ọdun 2019 ni ilu Abẹokuta.
Chelsea run Norwich mọ́ lẹ̀ jégéjégé Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Oríṣun àwòrán, @doks Àkọlé àwòrán, Okan lara awon ise akanse ti Oyedele ti se lati safihan awon ipenija to n koju odo Naijiria Messi ló gb'àmì ẹ̀yẹ Ballon D'or lóòtọ́ọ́, àmọ́ Ronaldo ló dára jùlọ (GOAT)- Mendes Ilé ẹjọ́ Eko pàṣẹ, EFCC mú u ṣẹ, Ìjọba gbẹ̀sẹ̀ lé ilé Saraki ní Ilorin Kí ni pàtàkì ọ́fíìsì agbègbè fún aṣòfin?
Ìwọ̀n ọ̀kọ̀ọ̀kan ninu àwọn àwo kòtò mejeejila tí wọ́n kún fún turari jẹ́ ṣekeli mẹ́wàá mẹ́wàá.
Ori wa ni ojo n rọle, mọngoro nikan si ni wọn n ka fun wa jẹ lori igi kan to wa nitosi ibẹ fun ọjọ mẹta.
Arọmọdọmọ Ṣemu títí fi dé orí Abramu nìyí: Ṣemu, Apakiṣadi, Ṣela; 
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Deeper Life: Deeper Life High School ti sọ̀rọ̀ lórí ibi tí nkan dé nípa ọ̀rọ̀ tí wọ́n fi ipá bá lòpọ̀ 29 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Oríṣun àwòrán, Twitter Awọn alaṣẹ ileewe Deeper Life High School, to jẹ ti ijọ Deeper Life Bible Church, ti fi atẹjade sita, lori ibi ti iwadii de nipa akẹkọọkunrin ti wọn fi ipa balopọ ni ẹka ileewe naa nipinlẹ Akwa Ibom.
Ní ìparí oṣù kejila, bí ó ti ń rìn lórí òrùlé ààfin Babiloni, 
O ni ìjìyà tó dájú wà fún ẹnikẹ́ni tí ó bá lu òfin ninu wọn.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Gomina Benue gbe asẹ isede kalẹ Ganduje pe awọn darandaran si Kano Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Awọn daran daran fi ọbẹ ge baba mi lori - ọmọ ọdun mọkanla Bí ó tilẹ̀ jẹ́pé àwọn agbófinró gbàródan sáwọn agbègbè kan ní ìlú Makurdi, síbẹ̀, àwọn èèyàn ìlú náà sì ń kó àyà sókè pé eégún àwọn darandaran náà tún leè sẹ́ lẹ́ẹ̀kan síi, tí wọn sì ń késí ìjọba ìpínlẹ́ náà láti dààbò bo àwọn àti dúkìá àwọn lọ́wọ́ ikú àti àdánù.
Gẹ́gẹ́ bí olùkọ́ kan tí kò dárúkọ araa rẹ̀ ṣe sọ, wọn kò yẹ àwọn ìwé ìkọ́ni wọ̀nyí wò fún àìmọye ọdún, àwọn akẹ́kọ̀ọ́ sì máa ń pín in lò ni, fún ìdí èyí ó nira láti mọ ẹni tí ó kọ nǹkan sí i ní pàtó.
Awọn ẹgbẹ alatako ni o lodi si ofin ilẹ naa fun ẹnikẹni lati lọ fun saa kẹta ni orilẹede naa.
O tẹsiwaju pe awọn yoo gbe e lọ si ile ẹjọ lori ẹsun irina are nitori wọn ko gba awọn ọkunrin laye lati wọ aaye ibusun awọn obinrin akẹkọọ.
APC kò ní olórí tí yòó tọwọ́ bọ̀wé, INEC yarí fún ìbò abẹ́nú l‘Ondo Ìhòhò ọmọlúàbí ni mo má a ń bá àwọn ọmọkùnrin mi wí - Elesho Onyeama, jọ̀ọ́ má bínú ìdẹ́yẹsí tá a ṣe torí pé o jẹ́ adúláwọ̀ - Ilé ẹ̀kọ́ Eton Bi ẹ ko ba gbagbe, ileẹjọ lo yọ alaga tẹlẹ fun ẹgbẹ oselu APC, Adams Oshiomọlẹ, ti igbimọ amusẹya ẹgbẹ si kede pe Senatọ Abiola Ajimobi ni ipo naa tọ si.
Aláàfin tó rí ìbẹ̀rẹ̀ àti opin sáà gómìnà mọ́kànlélógún l‘Oyo Ẹ̀yin oríadé, tẹ bá fẹ́ mọ ìtàn Yorùbá, ẹ lọ kọ́ lọ́dọ̀ Alaafin - Oluwo Ìbẹ̀rù-bojo gbalẹ̀ lórí ṣíṣí iléèwé padà lọ́jọ́ Ajé bí èèyàn 1867 ṣe kó covid-19 lọ́jọ kan ṣoṣo Ẹ ṣọ́ra o, ayédèrú abẹ́rẹ́ àjẹsára COVID-19 gbòde ní Nàìjíríà, NAFDAC pariwo síta Ọgbẹni Hassan to ti jẹ Ọba ilẹ Uba Imobi bayii sọ pe, lootọọ ni pe wọn gbọdọ ṣe awọn eto, amọ ni toun, ko si ohun to jọ etutu rara.
Nígbà tí àwọn olówó ọdọmọbinrin náà rí i pé ọ̀nà oúnjẹ wọ́n ti dí, wọ́n ki Paulu ati Sila mọ́lẹ̀, wọ́n fà wọ́n lọ sọ́dọ̀ àwọn aláṣẹ ní ọjà.
Ṣaaju ọdun 2015 to ti bọ si ipo aarẹ Naijiria ni ọpọ ọmọ orilẹede yii ti n pariwo pe ọjọ ori rẹ ko ni i jẹ ko ṣaṣeyọri nipo.
Ó bí ọmọkunrin meje ati ọmọbinrin mẹta.
Ajọ to n gbogun ti ajakalẹ arun lorilẹede Naijiria, NCDC lo kede bẹẹ loju opo Twitter rẹ lọjọ Ẹti.
Gbogbo wọn ni wọ́n pa láìku ẹnìkan.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù CAN: Samson ni ọrọ awọn ajinigbe ti gba àpérò ní Naijiria Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ CAN: Samson ni ọrọ awọn ajinigbe ti gba àpérò ní Naijiria 3 Agẹmo 2019 Eeyan fẹrẹ le maa maa jade laini ọlọpaa lẹ́gbẹ̀ mọ ni Naijiria -Samson Ayorinde Alufaa Samson Ayokunle to n dari ajọ ọmọlẹyin Kristi ni Naijiria ba BBC Yoruba sọrọ lori eto aabo Naijiria paapaa ti ẹkun iwọ oorun to mẹhẹ lasiko yii.
Awọn ara India fẹ ki ẹkun naa wa laaye Bi o tilẹ je pe ajọ eleto aabo n gbiyanju lati sawari ẹkun naa, awọn olowo ati gbajumọ to fẹran ẹkun n parọwa si ajo eleto aabo lati ma se pa ẹkun naa.
Aigbọran Ayefẹlẹ lo mu ka wo ile iṣẹ rédíò rẹ - Ijọba Ọyọ Òbí tó n fa sìgá n fi ọmọ rẹ̀ sínú ìdè àìsàn l'ọ́jọ́ iwájú Ṣugbọn, o ku diẹ ki aago lu ni Laolu Akande, to jẹ Oluranlọwọ pataki fun igbakeji aarẹ, Yẹmi Ọṣinbajo, fi ikede kan sita lori Twitter pe, ijọba ti fi ipinnu rẹ ranṣẹ si ajọ FIFA.
Obinrin náà bèèrè pé, “Ṣé ìwọ ni Joabu?
Ẹ wo awọn nnkan miran ti awọn eeyan n sọ: Kogi Lockdown: Adájọ́ àgbà ìpínlè Kogi, jẹ́ Ọlọ́run nípè nílé ìtọjú àwọn àláàrùn Covid-19 Oríṣun àwòrán, others Adajọ agba ipinlẹ Kogi, Nasir Ajanah ti dagbere faye.
’ rèé Hubert Ogunde rèé, baba àwọn òsèré tíátà Ẹgbẹ Stationery Stores jẹ ẹgbẹ tawọn ololufẹ ere bọọlu nifẹ si pupọ ti pupọ ninu awọn agbabọọlu naa si kopa ninu idije fun ikọ agbabọọlu Naijiria Green Eagles nigba naa.
2 15925 Orilẹede Congo 350 0.
"Oríṣun àwòrán, Facebook/Mike Bamiloye ""Eyi si ni mo tọrọ idariji fun lọwọ rẹ, lonii."
nipa iwa otito yii nipa pe gbogbo awon to wa dipo mu lawujo ko tapa si ilana
 níwọ ̀ n ìgbà tí kòsí ìtọjú kan pàtó , paracetamol ( acetaminophen ) lèṣe ìrànwọ ́ pẹ ̀ lú àwọn aamì .
 a ṣe àgbéjáde àwọn kan nípasẹ ̀ ìlànà dna aláàtùnkójọpọ ̀ , àwọn mìíràn nípasẹ ̀ kòkòrò afàìsàn àìlèfojúrí tí a ti sọ di aláìlágbára , bẹ ́ ẹ ̀ sì ni àwọn mìíràn jẹ ́ nípasẹ ̀ kòkòrò afàìsàn àìlèfojúrí tí a ti pa .
O ni nkan bi aago mọkanla abọ owurọ yii ni ọba tọ ọlọjọ lọ.
Nítorí OLUWA ní:“N óo tú ibukun sórí rẹ̀,bí ìgbà tí odò bá ń ṣàn.
Awọn eniyan ku nigba ti ọpọ farapa nibi ijamba ọkọ epo petiro to waye ni ipinlẹ Delta ni ẹkun Guusu-guusu Naijiria.
ẹ ri pe asiri idibo bo pẹlu asọ Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Kaabọ o, ṣe daada lo de.
Ní àfikún, Buhari tí ó ṣe olórí ìjọba ológun ní ọdún (1983 sí 1985) jẹ́ ọ̀kan lára àwọn ọmọ ‘ẹgbẹ́’ ọ̀gágun tí ó ti fẹ̀yìntì tí ó ti takú ti ètò òṣèlú orílẹ̀-èdè Nàìjíríà.
Mohammed fẹ Badriyya to jẹ ọmọ gomina Bauchi Ahmed Muazu to tun jẹ alága ẹgbẹ́ òṣèlú PDP tẹ́lẹ ri.
Ibi, igbe aye ati iku Bamidele Olumilua: Oríṣun àwòrán, Others Àkọlé àwòrán, Iroyin to n tẹ wa lọwọ ni yajoyajo n fi ye wa pe Olumilua jade laye ṣugbọn a ko tii lee fi idi iku to paa mulẹ.
Wọ́n bá mú Jesu, wọ́n fà á lọ sí ilé Olórí Alufaa.
Wọn ti sun igbejọ naa si ọjọ kọkandinlọgbọn, ọsu kesan an, ọdun 2020.
rere lori awon obinrin ati ọdọmọbinrin , ni eyi ti yoo jẹ ipilẹ ti won yoo maa
Ọpọ igba ti ijamba ba ṣẹlẹ lopopona awọn oṣiṣẹ bii ti eleto ilera fun iṣẹlẹ pajawiri, panapana, adari ọkọ, atawọn agbefoba miran ni wọn ko ni tete ṣe ohun to yẹ lasiko.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Kí lo fẹ́ mọ̀ nípa ‘Ajala Travels’?
Ọgbẹni Kọlawọle Ajeyẹmi ni o fẹ ni Oṣu kẹjọ ọdun 2019 lẹyin ti Toyin funrarẹ sọ ọ ninu ifọrọwerọ kan pe ọdun 2017 lawọn pade Awọn mejeeji si ti n tamige ifẹ lati igba yii wa ti eleduwa si ti fi ọmọ ọkunrin, Ire, ta wọn lọrẹ.
Nigba ti ijọba apapọ bẹrẹ iṣe lori afara Niger keji (Second Niger Bridge) wọn sọ pe iṣẹ akanṣe naa yoo gba igba ati ogun biliọnu.
Ijoba ipinle Eko labe akoso, Gomina Ambode Akinwunmi ti gbe oko alagbeka to wa fun itoju arun jejere kale fun ilo ilera awon eniyan ipinle naa pelu ileri lati tubo polongo lodi si itankale arun jejere.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Àwọn aránṣọ yarí pé gbogbo ẹ̀bi kìí ṣe tàwọn, díẹ̀ wà lọ́wọ́ àwọn oníìbárà náà Nínu èsì tìrẹ, alukoro àjọ ọlọ́pàá ni Ipinle Ondo, Femi Joseph ṣàlàyé pé, gbogbo àwọn mẹ́tàlá tí adé ọ̀rọ̀ náà sì mọ lórí ni wọn yóò jìyà tó tọ́ àti èyí tí ó yẹ leyin igbẹjọ.
O kò gbọdọ̀ kórè gbogbo àjàrà rẹ tán patapata, o kò sì gbọdọ̀ ṣa àwọn èso tí ó bá rẹ̀ sílẹ̀ ninu ọgbà àjàrà rẹ, o níláti fi wọ́n sílẹ̀ fún àwọn talaka ati àwọn àlejò.
Awon omo ogun ijoba orile-ede Syria to fe wole si ekun Afrin lojo Isegun ti sa pada seyin nigba ti awon omo ogun Turkey ju ado oloro lati Kurdish sibe.
Ninu fọnran aworan to lu sita lẹyin abẹwo naa, ni Akpan ti salaye pe awọn akẹkọ Naijiria pọ pupọ, ti wọn si fẹẹ to ọgọrin miliọnu niye.
Ẹ̀ ń fi ẹnu yín sọ̀rọ̀ ìgbéraga sí mi, ẹ sì ń dá àpárá lù mí; gbogbo rẹ̀ ni mo gbọ́.
Jesu Wo Ẹni tí Wọ́n Bí Ní Afọ́jú Sàn.
lataari ise takun-takun re, O tun ran iko agbaboolu Super Eagles lowo lati fagbahan iko agbaboolu orile-ede Seychelles ninu ifigagbaga ipegede idije boolu afesegba ile Afrika 2019 Africa Cup of Nations (AFCON).
Olóògùn bí Ewé-ẹ̀yẹ kò sí àfi bí a bá máa purọ́ tan ara ẹni jẹ, nítorí ọdún mẹ́fà ni o gbé nínú igi Ìrókò ti o ń ṣe babaláwo fún àwọn ẹ̀mi búburú ti ń gbé inú igi.
Wọ́n ta gbogbo ohun tí wọ́n ní, wọ́n sì pín owó tí wọ́n rí láàrin ara wọn, gẹ́gẹ́ bí ẹnìkọ̀ọ̀kan ti ṣe aláìní sí.
Bí Buhari wọ́gilé wíwọ bàálù olówó gọbọi fún òṣìṣẹ́ ìjọba kó ṣe aráàlú láǹfàní - SERAP Conwell ṣalaye pe oun gbiyanju lati bori ninu ija naa ṣugbọn oun ko mọ pe iku ni yoo jasi fun alatako oun, Day.
Mama Rainbow pe 77 lónìí, àwọn òṣèré tíátà kọrin re kìí Ẹbí Buhari lásán ni Mamman Daura kò nípò òṣèlú kankan Ìná ẹgbẹ́ òṣìṣẹ́ NLC ati ìjọba kò wọ̀ níbi ìpadé Ọkọ̀ agbépo tó gba iná ṣe àkóbá ní ọjà Onitsha Gomina Makinde, àgbọ́gbọn'tí ni kẹ́ẹ gbọ́ àwọn ará Oyo o lórí sáà kejì 'torí.
Esi ifẹsẹwọnsẹ yii ti ṣakoba fun ikọ Man U lati kopa ninu idije Champions League ni saa to n bọ.
Akọwe ẹgbẹ obi ati olukọ nile iwe naa, Bakar Kachalla sọ fawọn akọroyin pe awọn asoju naa yoo kan sawọn ẹgbẹ to n polongo fun itusilẹ awọn akẹkọbinrin atawọn ẹlẹgbẹjẹgbẹ obinrin nilu Abuja ti wọn pejọpọ fun ayajọ ọjọ obirin lagbaye lọjọbọ.
Alaga tẹlẹ ri ọhun ni pẹlu bi owo oṣu ko ti ṣe ma wa deede fawọn oṣiṣẹ kan lawọn ipinlẹ kan,o yẹ ki wọn ''lu eyikeyi Gomina to yara san owo lọgọ ẹnu'' Laarin ọṣẹ si igba ti wọn gba owo oṣu to kọja ni Gomina Ben Ayade paṣẹ ki wọn san owo oṣu eleyi ti awọn oṣiṣẹ ko ti ṣiṣẹ fun.
Aṣẹ ileẹjọ naa yoo duro titi digba ti igbẹjọ lori idaduro Baṣọrun Musulumi ilẹ Iwo.
Mudashiru Ọbasa wa paṣẹ fun Akọwe agba Ile Igbimọ Aṣofin Ipinlẹ Eko,
Sẹriki Fulani naa tẹ siwaju pe ọkan awọn darandaran balẹ ni ipinlẹ Ọṣun, wọn ko ni ikayasoke kankan nipa abo ati alaafia awọn ati agbo ẹran wọn.
Wo àwọn ojúṣe àti èèwọ̀ fún ikọ̀ ọlọ́pàá SWAT tó gba iṣẹ́ lọ́wọ́ SARS Mi ò mọ̀ nípa àwọn tọ́ọ̀gì tó da ìwọ́de EndSARS Alausa rú, mo ṣì wà lẹ́yìn yín digbí!
Ṣebí obinrin kan ni ó ju ọlọ ata sílẹ̀ láti orí ògiri ní Tebesi, tí ó sì pa á.
Ẹni to bori: Tanzania Namibia vs Mauritania.
“Ẹ máa bímọ lémọ, kí ẹ máa pọ̀ sí i, kí ẹ sì kún gbogbo ayé.
    Ìyàlẹ́nu tí ó wá ti ìdí ọmọ náà jáde ni pé ìgbà tí ó pẹ́, apá Èṣù kò ká a mọ́, bí Èṣù bá rán an níṣẹ́ a ṣe èyí tí ó wù ú, bí Èṣù bá rán an kí o yára wá sínú ayé kí ó dá ìjà sílẹ̀ láàrin ọ̀rẹ́ méjì, á wá á sọ wọ́n di ọ̀rẹ́ ara wọn, ìgbà tí Èṣù ba ń jà ọ̀run Àpáàdì á máa wáàsù fún àwọn ọmọ Èṣù.
Kunle Afod: Òṣèrébìnrin tí wọ́n bá fi ìbálòpọ̀ lọ̀ 'torí ìṣẹ́, kó bọ́ síta láti sọ̀rọ̀
Gege bi aare Buhari se so: “A o tesiwaju lati maa sagbekale awon eto ti o peye lojuna ati mu igberu ba idagbasoke ati fifi ese isokan mule lorile-ede Naijiria.
”OLUWA sì dá a lóhùn pé, “Lọ.
Howards Graduates: Barrack Obama gba àwọn akẹ́kọ̀ọ́jáde nímọ̀ràn láti fi àwọ̀ wọn yangàn
Bákan náà ni ẹ gbọdọ̀ ṣe ní ọjọ́ keje oṣù láti ṣe ìwẹ̀nùmọ́ fún ẹnikẹ́ni tí ó bá ṣèèṣì dẹ́ṣẹ̀; kí ẹ lè ṣe ètùtù fún tẹmpili.
Ènìyàn méjì míràn ti ní coronavirus ní ìpínlẹ̀ Oyo, mẹ́ta l'Abuja Oríṣun àwòrán, Google Eniyan maarun miran tun ti ni aarun coronavirus ni orilẹ-ede Naijiria.
ó gbàgbé pé ẹnìkan le tẹ̀ wọ́n mọ́lẹ̀ kí wọn sì fọ́,ati pé ẹranko ìgbẹ́ lè fọ́ wọn.
Àsìkò ìwọ́wé tó jẹ, àwọn ewé ti wọ́ dà sílẹ̀, wọ́n wá pọ́n kuku.
Zimbabwe fẹ́ darapọ̀ mọ́ Àjọ Commonwealth Ó dìgbà!
Laipẹ ti iroyin yii jade ni iroyin miran tun gbode kan wi pe Gomina Bello ti yi ohun rẹ pada, ti o si ti pe awọn ti o da duro pada sẹnu iṣẹ wọn.
Ìkúnlẹ̀ abiyamọ, ìkókó mẹ́jọ kú nílé ìwòsàn lálẹ́ ọjọ́ kàn Mamman Daura rí ìjà ọmọ Nàíjíríà torí ó pè fún wíwọ́gilé pínpín ipò ààrẹ lẹ́lẹ́kùn jẹkùn Oríire dé!
" Oríṣun àwòrán, Sahara Reporters Kazeem ni eto ẹkọ ati eto ilera ti dẹnukọlẹ ti awọn to n ṣejọba ko si bikita fun igbeaye awọn ti wọn n ṣejọba le lori.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Kehinde Wiley jẹ ayawoyan l'Amerika, sugbọn baba rẹ jẹ ọmọ bibi Nigeria O se awada pe aworan rẹ jẹ eyi ti o dara julọ ninu awọn aworan ara rẹ ti o ti ri lati igba ewe rẹ nile iwe giga.
Òun níí fi àṣírí ati ohun ìjìnlẹ̀ hàn;ó mọ ohun tí ó wà ninu òkùnkùn,ìmọ́lẹ̀ sì ń bá a gbé.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, #Queen Dihya: Obinrin tó gbógun tàwọn agbésùnmọ̀mí ni Algeria Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 3 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 5 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Ṣugbọn a fa àjàrà náà tu pẹlu ibinu,a sì jù ú sílẹ̀.
 Fani-Kayode ko ọrọ rẹ jẹ Minisita Naijiria nigba kan ri, Femi Fani-Kayode ni oun ko ọrọ pe akọroyin Daily Trust jẹ."
Ọ̀fẹ́ ni kí ẹ máa lò wọ́n.
Ìgbà tí oníṣẹ́ pada dé o ní ọba wí pé ó rẹ òun lọ́jọ́ náà púpọ̀ nítorí ẹrù ti òun rù bọ̀ láti oko lọ́jọ́ tí a kọ́ wá a lọ́ pọ̀ ju èyí ti òun ti ń rù bọ̀ ri lọ, nǹkan agogo mẹ́sàn-án, èyí nì ní ọjọ́ kẹta tí a ti n wá a lọ sí aafin.
O ti wa di ọ̀kan lara awọn agba akọrin Afrobeat l'Afirika pẹlu eyi to ti fun ara rẹ niyi lẹnu iṣẹ to yan laayo ati nilẹ Afirika gẹgẹ bi olorin, oniṣowo, akọni ati iyaleele.
Oríṣun àwòrán, GEMMA PURKISS Igbagbọ wọn nipe lọwọ awọn ẹlẹsin ibilẹ ni awọn Kristiẹni ti ja akoko ayẹyẹ naa gba.
Iroyin ọhun tun fi kun un pe idarudapọ waye ninu gbọngan ile aṣofin ọhun lẹyin ti igbesẹ ati yọ olori ile naa ati igbakeji rẹ ti waye tan pẹlu bi awọn janduku kan, ti awọn ti iṣẹlẹ naa ṣoju wọn sọ pe wọn jẹ ọmọ ẹgbẹ ọlọkọ ero, NURTW ti ṣe ya wọ ile aṣofin naa ti wọn si le gbogbo awọn aṣofin atawọn oniroyin to fi mọ awọn oṣiṣẹ nile aṣofin naa da sigbo.
Won da orile ede Naijiria sile ni 1960.
Nígbà tí a wí báyìí ọkùnrin náà béèrè nǹkan tí a fẹ́ rí ọba fún, a sì wí fún un pé a kòì tíì ṣeran láti sọ èyí nì fún ẹnikẹ́ni àti wí pé o di ìgbà tí a bá rí ọba kí a sọ fún un.
NYSC ní Adeosun kòwé ransẹ́ láti gbààyè Kane yoo ni anfani lati fi kun ami ayo rẹ nigba ti ilẹ Gẹẹsi ba koju Croatia ninu ifẹsẹwọnsẹ to kangun si aṣekagba wọn l'Ọjọru.
" Ṣé àwọn ọmọ rẹ lè sọ Yorùbá tó àwọn ọmọ Amẹrika yìí?
Iyalẹnu ati ibanujẹ nla lo jẹ fun nigba to mọ pe oun ni aarun HIV nigba to pe ọmọ ọdun mejila.
Ẹ̀ gbọ́ ọ̀rọ̀ lẹ́nu Adelé Ọba Alade Idanre ló rí ohun tó ṣẹlẹ̀ láàárín òun àti Ọba Aroloye Ǹkan tí a mọ̀ nípa kọ́lẹ̀jì olùdìbò tó ń fìdì ẹni ti yóò jẹ ààrẹ ilẹ̀ Amérika múlẹ̀ Aàbò tó péye yóò wà fún àwọn tí yóò kópa nínú ìfẹsẹwọ̀nsẹ̀ Naijiria àti Sierra Leone ní Benin - Obaseki Wo iye owó tí ìjọba Amẹrika ń na sí ìdìbò Ààrẹ àti ibi tí owó náà ti ń wá Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, John Amanam: Ìfẹ́ tí mo ní sí àbúrò mi ló sọ mi dí ẹni tó ń ṣe 'Prosthetic' báyìí Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Lílo oògùn Sniper fún ìtọ́jú oúnjẹ leè yọrí sí ikú àìtọ́jọ́ - NAFDAC kìlọ̀2 Bélú 2020 Fídíò, Soyinka Cancer: Àṣe ara mi ni iso ti n run gbogbo bí mo ṣe n ṣèrànwọ́ lórí jẹjẹrẹ27 Bélú 2019 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
O ni igbimọ naa yoo jabọ iṣẹ rẹ ni ọjọ kẹẹdọgbọn, oṣu Kiini, ọdun 2021, nibi ti yoo ṣe agbeyẹwo awọn nkan ti yoo mu ki nkan fi ẹsẹ mulẹ ni ẹka eporọbi.
Ogunlọgọ awọn eniyan miran tun f'arapa ninu ile ijọsin yi lẹyin ti awọn mẹrindinlogun ku lẹṣẹkẹsẹ ni agbegbe Nyaruguru gẹgẹbi aṣoju ijọba Habitegeko Francois ṣe sọ fun ileeṣẹ iroyin AFP.
Eto ẹkọ ati ọrọ awọn oṣisẹ wa lara awọn ohun ti Gbajabiamila gbajumọ, to si ma n sọrọ nipa mimu idẹrun ba ara ilu.
 Ìsìnkú àwọn wọ ̀ nyí máa ń lárinrin , ayé á gbọ ́ , òrun á sì tún mọ ̀ pẹ ̀ lú .
Sanwo-Olu kéde ìgbésẹ̀ rẹ̀ lórí ìrìnnà ọkọ̀ àjàgbé l'Eko A ṣe tán láti yọ ìjìyà ikú kúrò nínú àbá ọ̀rọ̀ ìkórìra- Sẹ́nẹ́tọ̀ Sabi Darandaran Fúlàní kankan kò ṣí kúrò l'Ọ́ṣun - olórí Fulani Tí o bá rí àpẹrẹ mẹ́fà yìí, sá àsálà fún ẹ̀mí rẹ̀!
Oríṣun àwòrán, Getty Images Iṣẹju kẹrinlelaadọrin ni ifẹsẹwọnsẹ naa wa nigba ti Rodrigo fi gba bọọlu sinu awọn Chelsea.
Gbajugbaja agbabọọlu orilẹede Argentina ni, Lionel Messi gba goolu wọle ni iṣẹju kẹta, iṣẹju karuninlaadọta ki marcos Rojo to gba ikẹta wọle fun Argentina nigba ti ifẹsẹwọnsẹ naa wọ iṣẹju aadọta.
Yóo wá tún jáde lọ láti máa tan àwọn eniyan jẹ ní igun mẹrẹẹrin ilẹ̀ ayé.
oruko awon minisita ti yoo baa sisẹ papọ ransẹ si ile igbimo asofin gẹgẹ bi ise
Ṣugbọn eleyii yọ awọn minisita, akọwe agba, olugbaninimọran pataki, oluranlọwọ pataki fun aarẹ, awọn alaga ile iṣẹ, atawọn lọga lọga agba patapata, tori awọn ni tiwọn yoo ṣi maa wọ olowo gọbọi yii.
Bi ẹ o ba gbagbe, awọn afurasi ọgọrin, ti ọpọlọpọ wọn jẹ ọmọ Naijiria ni ajọ FBI ti fi ẹsun kan wi pe, wọn lu gbajuẹ nilẹ Amẹrika.
Idi pataki fun aba yii ni lati pese aaye fun idahun si ọrọ eto ilera fun aisan ọpọlọ.
si wa ni atimọle bayii, awon si tun  n
Wọn ṣe ayẹwo fun awọn mẹwaa ni ọjọ Ẹti nigba ti wọn ṣe ti awọn meje
Lẹ́yìn pé a ní ìtùnú, a tún ní ayọ̀ pupọ nígbà tí a rí bí ayọ̀ Titu ti pọ̀ tó, nítorí ọkàn rẹ̀ balẹ̀ láàrin gbogbo yín.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Marriage dispute: Ìyàwó mi fi mí sílẹ̀ kó lọ sílé ọkùnrin míì nínú báráàkì kan náà, àmọ́ mò sí tún fẹ́ràn rẹ̀ 16 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Oríṣun àwòrán, Getty Images Sọja kan to ti fẹyin ti lẹnu iṣẹ ologun, Richard Imana ti sọ fun ileẹjọ ibilẹ (Customary court) niluu Eko pe ko tu igbeyawo ọdun mẹwaa oun pẹlu aya rẹ ka.
Oríṣun àwòrán, Dino Melaye Wo ìjìyà tó wà fún àwọn ọmọ Naijiria tí kò bá fi nọ́mbà NIN kún ìforúkọsílẹ̀ Siimu wọn láàrin ọ̀sẹ̀ méjì Ìyàwó mi fi mí sílẹ̀ kó lọ sílé ọkùnrin míì nínú báráàkì kan náà, àmọ́ mò sí tún fẹ́ràn rẹ̀- Sọ́jà Oríṣun àwòrán, Presidency O ni labẹ eleyi ati iwoye iru nkan to n sẹlẹ ni Amẹrika ti aarẹ Donald Trump ko fẹ gba pe oun ti fidirẹmi ninu idibo, o yẹ ka kan saara si Jonathan.
CBN: A ń pariwo tó lórí MMM fáwọn ọmọ Nàíjíríà Àpò 65 là fi gbé owó N1.
lẹ́yìn tí ó ti dúpẹ́ tán, ó bù ú, ó ní, “Èyí ni ara mi tí ó wà fun yín.
Ilumọọka olootu fiimu lobinrin naa lo gba ami ẹyẹ pe oun lo gbe fiimu ede ibilẹ to pegede julọ sita ni ẹka awọn fiimu ti wọn se lede Yoruba fun ọdun 2019 ( Best Indigenous Language Movie/TV Series Yoruba.
Oríṣun àwòrán, babasuwe_official Àkọlé àwòrán, Baba Suwe ti orukọ rẹ gangan n jẹ Babatunde Omidina jẹ ọmọ bibi ilu Eko ni Ikorodu.
Ati pé èwo níbẹ̀ lo wuyì jù?
Ó pẹ́ lẹ́yìn tí OLUWA ti fún Israẹli ní ìsinmi, tí kò sí ogun mọ́ láàrin àwọn ati gbogbo àwọn ọ̀tá tí ó yí wọn ká, Joṣua ti di àgbàlagbà ní àkókò yìí, ogbó sì ti dé sí i; 
Ní ìgbẹ̀yìn-gbẹ́yín, obinrin náà alára wá kú.
Agbofinro to gbe ọrọ naa lọ silẹ ẹjọ, E.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Lagos City Marathon: Sintayehu Legese láti Ethiopia ló jáwé olúborí 2 Èrèlè 2019 Oríṣun àwòrán, TWITTER/MYACCESSBANK Àkọlé àwòrán, Ẹni tó jáwé olúborí lọ́dún tó kọjá,Joshuna Kipkorir ló se ipò kejì ní ipele àwọn okùrin láti ilẹ̀ Ethiopia.
Ami ayo meji si ẹyọkan ni Manchester City fi ṣagba Real Madrid ninu ifẹsẹwọnsẹ naa.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ṣọla Allyson: Obìnrin tí kò bá rẹwà ni yóò máa ṣí ara sílẹ̀ Ayajọ ọjọ yii si ni awọn olulanilọyẹ nipa arun jẹjẹrẹ ọyan fi maa n gba awọn obinrin nimọran lati yan kọmu lodi, eyi ti yoo fun awọn akọsẹmọsẹ onimọ ilera nipa arun jẹjẹrẹ ni anfaani lati se ayẹwo ọyan wọn boya arun naa ti lugọ sibẹ abi bẹẹkọ.
Macron fi soju òpó ayelujara rẹ pe, iṣẹ ajumọṣe ni atunṣe ile ijọsin naa yoo jẹ pe, iṣẹ ti de naa ni yẹn lori orirun wọn.
Nítorí ó wà ní àkọsílẹ̀ pé, ‘Oluwa Ọlọrun rẹ ni kí o máa júbà, òun nìkan ni kí o máa sìn.
Ilé wọn yóo di ilé onílé,oko wọn, ati àwọn aya wọn pẹlu, yóo di ti ẹni ẹlẹ́ni.
Iya Rainbow kawe alakọbẹrẹ ati girama ni Ijẹbu Ode, ni ilu kan naa si lo ti lọ ile iwe awọn nọọsi.
Opo lo maa n gbadura ki onikaluku fọwọ rọri ku lai kuku inira tabi ti ijamba.
Inú mi ń ru sí wọn.
Bẹ́ẹ̀ náà ni wọ́n ṣe pẹlu àwọn mààlúù.
Nebukadinesari, ọba àwọn ọba óo wá, pẹlu ẹṣin ati kẹ̀kẹ́ ogun ati àwọn ẹlẹ́ṣin ati ọpọlọpọ ọmọ ogun.
(N kò fi ẹnu mi ṣẹ̀kí n gbé e ṣépè pé kí ó lè kú);
Nígbà tí wọ́n dé Efesu, Paulu fi Pirisila ati Akuila sílẹ̀, ó lọ sinu ilé ìpàdé àwọn Juu, ó lọ bá àwọn Juu sọ̀rọ̀.
Ìṣẹ̀lẹ̀ burúkú kan ló ṣẹlẹ̀ ní ìlú Newton ní ìpínlẹ̀ Connecticut ní àárọ̀ ọjọ́ Ẹtì tó kọjá o.
apero pelu awon tọrọ  kan , o seleri pe eto
Àwọn mìíràn ń rìn kiri, wọ́n wọ awọ aguntan ati awọ ewúrẹ́, ninu ìṣẹ́ ati ìpọ́njú ati ìnira.
Ohun to tun sikẹta ninu awọn aba gbigbe awọn ofin kan lọ sabẹ isọri ofin atigbadegba ni ọrọ to nii se pẹlu awọn osisẹ, ti El-Rufai si kede pe eyi yoo mu ko rọrun fun ijọba apapọ atawọn ipinlẹ lati se ofin lelori.
O ti ya ju lati mọ boya o ni ìgbà ti aarun coronavirus tuntun yii ma n jade.
Bẹ́ẹ̀ ni eniyan kò lè rí èso ọsàn lórí igi ọdán.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ẹgbẹ́ àpapọ̀ àwọn òṣìṣẹ́ ṣì dúró lórí ọ̀rọ̀ wọn 29 Ògún 2018 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 16 Bélú 2018 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Awọn gomina lawọn o le san ọgbọn ẹgbẹrun Naira f'oṣiṣẹ Àpapọ̀ ẹgbẹ́ àwọn òṣìṣẹ́ àti ẹgbẹ́ àwọn òṣìṣẹ́fẹ̀yìntì ní Nàìjíríà ti gba Ààrẹ Muhammadu Buhari nímọ̀ràn láti ṣọ̀ra fún ẹgbẹ́ àwọn Gómìnà Nàìjíríà tí wọ́n ṣàpèjúwe gẹ́gẹ́ bí aṣòdì sí òṣìṣẹ́.
Ẹ wo fídíò òfò àti àdánù tó wáyé níbi ìkọlù sáwọn àjèjì ní South Africa A ti nílé, dúkìá àti ẹbí ní South Africa, àwa kò ṣetán láti padà sílé"" ""Ọ̀pọ̀ ń gbé nínú ìbẹ̀rù ní South Africa ́lọ́wọ́lọ́wọ́ báyìí"" Ìdájọ́ ọmọ mi tó gbé àdó ìkú wọ bàálù le púpọ̀, ẹ bá mi wòó ṣe - Bàbá Mutallab Ọ̀dọ́mọdé Onímọ̀ ẹ̀rọ rèé tó ń ṣe bàálù, ọkọ̀, ilé àti ọkọ̀ ojú omi Oluomo tẹsiwaju pe oun dupẹ lọwọ Ọlọrun fun oore ọfẹ rẹ lori oun to fi mu ki iru ọjọ bayii waye ati awọn eniyan jankan lawujọ ti wọn ṣe atilẹyin fun oun lati dori ipo naa."
Lẹyin iku rẹ lọdun 1996, nigba to di oṣu kẹwaa, ọdun 1998, Hamza Al-Mustapha ati ọmọ aarẹ ana, Abacha Mohammed farahan nile ẹjọ pẹlu ẹsun pe awọn ni wọn pa Kudirat Abiola.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Amọ aisini ori papa wọn ko fi Liverpool rara.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Awọn ọmọ ogun Biafra n ṣe ajọyọ pẹlu ibọn wọn lori ọkọ ijagun Naijiria ti wọn bajẹ lọdun 1968 Awọn ọmọ ogun ilẹ okeere yii kọlu ibudo ijagun Naijiria to wa ni Port Harcourt, Enugu, Benin ati Ughelli, ti wọn si ba ọpọ awọn baalu ijagun wọn jẹ.
n so iru aheso oro bayii kiri,nitori Bola Tinubu n fẹ  ki orile ede yii ni idagbasoke.
Ko si ẹni to ri oogun iku ṣe lọjọ ti ọlọjọ ba de ni Nǹkan mẹ́sàn án tí Mùsùlùmí gbọdọ̀ ṣe nínú oṣù Dhual- Hijjah Ilé ẹjọ́ wọ́gilé ìgbẹ́jọ́ Olalekan 'Woodberry' Pọnle Ẹgbẹ́ Boko Haram pa àwọn òṣìṣẹ́ UN márùn ún tó wá ṣiṣẹ́ ìrànwọ́ ní Nàìjíríà Wo ohun tí ìrìnàjò ààrẹ Buhari fún ìgbà àkọ́kọ́ lásìkò Coronavirus lọ sí Mali yóò bá bọ̀ O ti lé ní ènìyàn mẹ́wàá tí ina jó gúrúgúrú nínú ìjàmbá tó wáyé ní Delta Oríṣun àwòrán, NAF Iléeṣẹ́ ológun òfurufú Nàìjíríà fa àwọn mẹ́ta tí ọwọ́ tẹ̀ lórí ikú Tolulope Arotile lé Ọlọ́pàá lọ́wọ́ Iléeṣẹ́ ológun òfúrufú àti ẹbí Tolulope Arotile ti ṣe ètò ìdágbére ìkẹyìn fun-un.
Bakan naa ,Ogbeni Agboke fi idunnu re han nigba ti o
Ìròyìn kan sọ wí pé, àwọn ajínigbé náà ti bẹ̀rẹ̀ sí ní kàn sí àwọn ẹbí fún owó.
“Múra gírí bí ọkunrin,mo ní ìbéèrè láti bi ọ́, o óo sì dá mi lóhùn.
Owó epo rọ̀ọ̀bì ni Nàìjíríà fí ń ri ìdá mọ́rùndínláádọ́rin owó tó n wọ́le fún ìjọba àpapọ̀, èyí túmọ̀ sí pé, tí wàhálà bá ti de ba ọ̀rọ̀ epo lágbàyé, ó ti di dandan ki Nàìjíríà fi ẹnu fẹ́ra.
"Wo ìjìyà tó wà fún àwọn ọmọ Naijiria tí kò bá fi nọ́mbà NIN kún ìforúkọsílẹ̀ Siimu wọn láàrin ọ̀sẹ̀ méjì Ìyàwó mi fi mí sílẹ̀ kó lọ sílé ọkùnrin míì nínú báráàkì kan náà, àmọ́ mò sí tún fẹ́ràn rẹ̀- Sọ́jà Ààrẹ àná, Goodluck Jonathan ló fún mi ní 'oògùn' tí mo fi yọ Sanusi nípò Emir Kano- Ganduje Wo àwọn ìṣesí ojoojúmọ́ mẹ́wàá tó le ṣàkóbá fún ọpọlọ rẹ Gẹgẹ bi lẹta ti awọn ileeṣẹ iroyin abẹle kan ni wọn kọ ṣọwọ si Biṣọọbu naa lati fi pe ko lọ rọọkun nile, Wọn ni Biṣọọbu Adepọju ""jẹwọ pe lootọ loun ba iyawo alufaa to wa labẹ oun sun"" Bisọọbu yii lo n dari ijọ Anglican to wa ni Iwọ oorun Ekiti ni Amọṣa, Biṣọbu Adepọju ko tii sọrọ kankan lori iṣẹlẹ yii."
Eeyan 42,681 ni apapọ ni arun naa ti fara kan labẹ ayẹwo lorilẹede Naijiria.
Ẹ mú wọn wá,kí ẹ sì sọ ohun tí yóo ṣẹlẹ̀ fún wa;kí ẹ sọ àwọn ohun àtijọ́ fún wa.
"Oreofeoluwa di gbajumọ lẹyin ti fidio kan fa ori ayelujara ya, nibi to ti n bẹ iya rẹ to fẹ na a lẹyin to ṣaṣemaṣe kan, to si n logun ""mummy calm down."
Lẹyin ibo naa lọjọ Aje aarẹ ti wọn ṣẹṣẹ dibo yan, Joe Biden abajade ibo awọn igbimọ agbaọjẹ oludibo alaṣẹ ni ilu Amẹrika, Electoral college fihan pe ifẹ araalu lo papa ṣẹ.
Lọjọru ni Cardi B sọ eleyi di mimọ lori Instagram to si sọ wi pe oun yoo maa nifẹ olorin Migos oun lailai.
Ayẹyẹ iside ipade apapọ ajọ isọkan orilẹede nilẹ Afrika, AU to waye loni waye nilu Addis Abba, olu ilu orilẹede Ethiopia.
Awọn ọ̀rọ̀ náà ni ìtumọ àti bi wọ́n se ń sọ nínú èdè gẹ́ẹ̀sì, Buka / tẹria, guber, agric, ember Months, next tomorrow, Kannnywood.
Onisowo kan Shinkafi Aliu, ti o je oga agba ile-ise Alibarika Bureau De Change so pe, iduro deedee idokowo owo ori oja ohun je igberu ti o n ba owo ipamo orile-ede Nigeria.
Ninu ọrọ ikini to fi sita, Ọgbẹni Dare ṣapejuwe Ọba Adeyẹmi gẹgẹ bi ẹni to n mu iṣọkan wa nilẹ Yoruba, to tun n gbe aṣa larugẹ.
Ọpọ eeyan kọ lati gbagbọ ninu aridaju imọ sayẹnsi ti ijọba fi n ṣẹlẹri gbogbo ohun ti wọn n sọ nitori naa wọn n sọ pe ọna ati kowo jẹ ni awọn oṣiṣẹ ijọba n lo.
Ọba Jehoiakimu fi idà pa á, ó sì ju òkú rẹ̀ sí ibi tí wọn ń sin àwọn talaka sí.
Fun àpẹẹrẹ, irinajo to yẹ ko gba ọgbọn isẹju yoo di isẹju marunlelogoji.
Geeg bi o se sọ, o ni oun wa
Awọn milionu márùndínlógójì eniyan  lati opolopo orile ede lo tun  jẹ  pe omi yii ni wọn gbọkan lee.
O kó ṣẹ́kẹ́ṣẹkẹ̀ sí mi lẹ́sẹ̀,ò ń ṣọ́ ìrìn ẹsẹ̀ mi,o sì pa ààlà tí n kò gbọdọ̀ rékọjá.
O sọ pe o jọ bi ẹni pe Buhari fẹ tun orilẹede Naijria ni.
A óo pa ibi pẹpẹ ìrúbọ Afeni, tíí ṣe ẹ̀ṣẹ̀ fún Israẹli run; ẹ̀gún ati òṣùṣú yóo hù jáde lórí àwọn pẹpẹ wọn.
Nítorí oriṣa lásán ni àwọn orílẹ̀-èdè yòókù ń sìn,ṣugbọn OLUWA ni ó dá ọ̀run.
Awọn musulumi lo pọ ju ni agbegbe yii ni eyi ti ko fi kọkọ rọrun ki obinrin da ni ominira ṣugbọn ajọ isọkan agbaye United Nations ni iyatọ ti n wa sii bi olaju ṣe n de ibẹ sii.
Nàìjírìa fakọyọ nínú ìdíje AWCON Nàìjírìa ti gba ife ẹ̀yẹ ere bọọlu awọn ilẹ Afirika AWCON lẹ́ẹ̀kẹsàn an lẹyin ti wọn na South Africa pẹlu ami ayo mẹrin si mẹta nínú ifẹsẹwọnsẹ aṣekágba ìdíje náà.
APC ìpínlẹ̀ Edo láwọn kò fẹ́ rí imi Adams Oshiomole lákìtàn mọ́ Ọmọ ọdún kan póòrá!
Nígbà tí òun ati ẹ̀gún jọ dàgbà, ń ṣe ni ẹ̀gún fún un pa.
Lati igba ti iroyin naa ti jade ni ọpọ eeyan ti n fi ẹnu kun awọn to wa nile isẹ ijọba apapọ to n mojuto ọrọ irọrun nipa ipese iranwọ lẹyin isẹlẹ pajawiri fun awọn ara ilu ti wọn pe ni: Federal Ministry of Humanitarian Affairs Eyi ko seyin bo se jẹ pe ile isẹ yii lo mojuto pinpin ounjẹ fawọn akẹkọọ lasiko isede Coronavirus Ko pe sii ni ileese yii naa fesi loju opo twitter wọn pe ọwọ awọn mọ lori iwadii ajọ ICPC yii nitori awan pin ounjẹ naa bi o ti yẹ Alaye lori esi ileese ti ICPC fi ẹsun kan ree: Won ni awọn eeyan kan to fẹran wahala ati laasigbo lo wa nidi ọrọ naa.
 àwon ènìyàn ; mùtúmùtú ' .
Ó ní, “Ẹ̀yin oluwa mi, ẹ jọ̀wọ́ ẹ yà sí ilé èmi iranṣẹ yín, kí ẹ ṣan ẹsẹ̀ yín, kí ẹ sì sùn ní alẹ́ yìí, bí ó bá di ìdájí ọ̀la, kí ẹ máa bá tiyín lọ.
Adebiyi ni eyi je okan lara ipinnu ile ise MTN lati sawari awon akorin tuntun nibi awon ayey odun ibile wonyii.
Nítorí pé àwọn ọmọbinrin Manase gba ilẹ̀ gẹ́gẹ́ bí àwọn ìbátan wọn tí wọ́n jẹ́ ọkunrin.
Coronavirus symptoms: Kí ni àwọn àpẹẹrẹ àrùn yìí, àti pé báwo ni mo ṣe leè dáàbò bo ara mi?
O ni fun apẹẹrẹ, LASTMA ko lee ṣadede da ọkọ duro bi ọkọ ko ba ṣẹ, bakan naa pẹlu awọn ẹṣọ oju popo FRSC.
 Bakan naa ni igbimo asofin tun yan asofin Akeem Adedibu
Ẹ̀rí túbọ̀ ń tẹnu àwọn ẹni-orí-kó-yọ jáde lẹ́yìn ọgbọ̀n ọdún.
Tí mo bá tún ayé wá, ó wù mí kí n bí ju ọmọ 17 tí mo bí lọ
Wo ohun to yẹ ki o mọ nipa ẹni ti Megan Rapinoe jẹ?
Full Time Statistics Madagascar vs Nigeria #TotalAFCON2019 pic.
5 #11,099,520 sí #18,423,360 #924,960 sí #1,535,280 Ẹ̀wẹ̀, Àwọn to ń ṣe àmójúto ìgbóhùn sáfẹ́fẹ́ Khafi sàlàyè pé, Kafayat Kareem kò gbọ́ sí gbogbo ǹkan tó ń lọ lóde, yòó si fèsì sí gbogbo ẹ̀sùn yìí nígbà to ba jáde.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Alaafin Oyo: Kí ló ń ṣẹlẹ̀ láàfin Oyo táwọn èèyàn fi ń ki Alaafin ní mẹ́sàn án mẹ́wàá?
 Ó ṣiṣẹ ́ pẹ ̀ lú ilé iṣẹ ́ móhùnmáwòrán nigerian television authority ( nta ) Ìbàdàn gẹ ́ gẹ ́ bìi akọ ̀ ròyìn lábẹ ́ àbójútó ọ ̀ gbẹ ́ ni yanjú adégbìtẹ ́ , láàrin ọdún 1990 sí 1991 .
Nígbà tó ó di alẹ̀ ọjọ́ kan, ọkùnrin yìí àti ìyáálé náà wà nínú iyàrá, ìyàwó wà lóde, ibi tí wọ́n ti wà nínú iyàrá ni ọkùnrin náà ti ń gbọ́ tí àwọn èkúté méjì ń sọ̀rọ̀ sí ara wọn tí wọ́n ń bú ọkùnrin náà pé kò tètè sùn kí àwọn baà rí àyè lọ jẹun.
Obinrin náà sọ fún un pé, “Mo mọ̀ pé Mesaya, tí ó ń jẹ́ Kristi, ń bọ̀.
Balaki tún rán àwọn àgbààgbà mìíràn tí wọ́n pọ̀, tí wọ́n sì ṣe pataki ju àwọn ti iṣaaju lọ sí ọ̀dọ̀ Balaamu.
Ẹranko oníwà pẹ̀lẹ́ gbáà ni àgùntàn nṣe.
O fi kun pe ko si ibi ti ile ẹjọ naa ti sọ pe wọn ko dibo yan awọn nitootọ nitori naa ohun to tọna ni ki gomina Makinde fi aye gba awọn alaga kansu naa lati lo saa wọn eleyi ti yoo pari ni ọdun 2021.
Iná fìtílà ibi mímọ́ kò tíì jó tán.
Isẹlẹ naa ni se pẹlu ikọ ọmọogun 93 Battalion ni ilu Takum, ni ipinlẹ Taraba.
Oríṣun àwòrán, @officialEFCC Ọga agba fun ajọ EFCC ni Ilọrin, Isyaku Sharu, ti o soju alaga fidihẹ fun ajọ naa, Ibrahim Magu, lo fi ọrọ naa lede nibi ifọrọwerọ pẹlu awọn oniroyin nilu Ilọrin.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Fulani Kidnapping: Owó púpọ̀ la san kí wọ́n tó fi mi sílẹ̀ Èyí ni ọ̀nà tí àwọn obìnrin n gbà kó ara wọn sí wàhálà nítorí ara bíbó Ṣé o ti gbọ́ ohun ti Ọọni Ifẹ́ àti Soyinka parí ọ̀rọ̀ Yorùbá sí?
" Idris tun fọwọ gbaya pe ijọba ko ni dọwọ bo isẹlẹ yii, ti wọn yoo si tun tọju Christiana bo se yẹ.
Àkọlé àwòrán, Aworan agbegbe ti Boko Haram kọ̀lu julọ̀ lọ̀dun 2016 Àkọlé àwòrán, Awọn agbegbe ti Boko Haram kọlu Lọdun 2017 Ọna ti Boko Haram maa ngba se ikọlu rẹ.
Ọkọ̀-ofurufú ti wọ́n fi njagun ní wọ́n jẹ́.
O ṣeeṣe ki ibaṣepọ wọn o tayọ fọto yiya, nitori pe Hushpuppi naa lọ sibi ayẹyẹ ọjọ ibi ti Melaye ṣe nilu Dubai lọdun 2019.
Wọn lawọn ba awọn mọlẹbi wọn kẹdun.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ondo accident: Tírélà méjì tẹ ìyá àti ọmọ pẹ̀lú èèyàn méjì míì pa ní Ikare-Akoko, awakọ̀ sá lọ 30 Ògún 2020 Oríṣun àwòrán, Other Agbẹnusọ ileeṣẹ ọlọpaa ipinlẹ Ondo, Tee-Leo Ikoro sọ fun BBC Yoruba pe awọn eeyan to farapa nibi iṣẹlẹ naa si n gba itọju lọwọ nile iwosan.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Iran ni pe eyikeyi ninu wọn ti wọn ba lo lati fi ṣina ikọlu si Iran yoo fara kaaṣa ibinu Iran.
Eyí tó mú kí wọn ráyè kò àwọn ohun ìjà ìgbàlódé láti Eko wá sí Ibadan.
    Báyìí ni ọba náà sọ, ẹ̀rù sì ba gbogbo wa pé bí ìlú rẹ̀ ti bàjẹ́ to nì, ó dárá lójú ọba!
agba fun ile-ise  to n ri si ọrọ  ile okeere,Mustapha Suleiman.
Ọ̀pá àṣẹ ọba kì yóo kúrò ní ilé Juda,arọmọdọmọ rẹ̀ ni yóo sì máa jọba,títí tí yóo fi dé ọ̀dọ̀ ẹni tí ó ni ín;gbogbo ìran eniyan ni yóo sì máa pa àṣẹ rẹ̀ mọ́.
Oríṣun àwòrán, West Mids Police Àkọlé àwòrán, Tọkọ-taya Patatas ati Adam Thomas sọ ọmọ wọn ni Adolf nitori ifẹ ti wọn ni si Hitler Ṣaaju asiko yii ni wọn ti fi ofin de ẹgbẹ National Action nilẹ Gẹẹsi, lẹyin ọdun mẹta ti wọn bẹrẹ rẹ l'ọdun 2013, ti wọn si ṣe ajọyọ lẹyin ṣiṣekupa aṣofin Jo Cox.
Oríṣun àwòrán, Joke Silva Bi wọn ṣe ṣe ayẹyẹ ọdun ikarundinlogoji igbeyawo wọn, gbogbo eeyan to fi mọ awọn oṣere akẹgbẹ wọn lo n wari fun bi igbeyawo ọhun ṣi ṣe duro di oni.
O wa parọwa lapapọ pe ki ijọba Naijiria mojuto eto aabo awọn ara ilu lasiko yii nitori bi ọrọ ṣe n lọ yii ko dara to.
Ọ̀jọ̀gbọ́n Mojisola Adeyeye, to je oludari ajọ NAFDAC, ni A o gbé igbesé to ba yẹ ni kete ti a ba pari ìwádìí nínú awọn ile ise mereerin ti Fídíò BBC tú síta""."
Bàbá mi kàn dáhùn pé, ‘Bẹ́ẹ̀ni ara àbúrò òun ni kò dá.
A sì kà á kún òdodo fún un,láti ìrandíran títí lae.
Magun Olokiti: Bi ọkunrin ba ti lu Magun yii lara obinrin, ọna bi yoo ṣe takiti ni yoo maa wa, bi o ba si ti le e takiti bayii, ọrun laalaa ni.
Lẹ́yìn náà ó ní kí wọ́n mú ọtí jáde, wọ́n kó ìgò méjì jáde, ọba pàápàá ni ó sì bu ọtí náà, kì n má fa ọ̀rọ̀ gùn lọ títí ṣá, a parí ìgò méjì yìí ki n tó kúrò ní ààfin, ojú mi ń pọ́n ṣẹ̀ẹ̀, èmi náà ta fìlà mi han ha mo ń ta ráńgọ́ ráńgọ́ lọ.
Gege bi ojogbon Yemi Osinbajo se so,”Mo wa lati wa soju aare Muhammadu Buhari lati kedun pelu awon eniyan ijoba ibile Jibia ati apapo ijoba ipinle Katsina fun isele omiyale eleyi ti o waye nipinle naa.
Àwọn ọmọ Aṣeri náà kò lé àwọn wọnyi jáde: àwọn ará Ako ati àwọn ará Sidoni, àwọn ará Ahilabu ati àwọn ará Akisibu, àwọn ará Heliba ati àwọn ará Afeki, ati àwọn ará Rehobu.
 Iyabo Ojo wa n fi ika hanu pe ki lo de ti orilẹede Naijiria ko mọ ju owo lọ, a si ku imura ajọdun ominira ọgọta ọdun Naijiria o.
Bi apapọ wọn ipinlẹ to ṣẹṣẹ ni arun naa ṣe lọ ree: Lagos-51 Rivers-26 Imo-12 Osun-8 Plateau-6 FCT-5 Kaduna-4 Ogun-3 Edo-2 Niger-1 Èèyàn 133 ní àrùn Coronavirus tún ṣẹ̀ṣẹ̀ ràn ní Nàìjíríà Ajọ to n gbogun ti ajakalẹ aarun ni Naijiria, NCDC ti kede pe eeyan 133 miran ti kun iye awọn to ti ni aarun COVID-19 lorilẹ-ede yii.
"Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Salah ni ọmọ ilẹ̀ Áfíríkà kejì tí yóò gba àmì ẹ̀yẹ yìí, lẹ́yìn Riyad Mahrez ""Iyi nla lo jẹ fun mi paapaa julọ bo ṣe jẹ pe àwọn agbabọọlu akẹẹgbẹ mi lo di ibo yan mi."
Ní àsìkò kan Kanu ni àìsàn ọkàn, to sì jà fitafita, èyí sì ni ó ṣe okùnfà ti Kanu fi ṣe àgbékalẹ àjọ Kanu Heart Foundation lati máa ran àwọn to ba ni irú ìpèníjà yìí lọ́wọ́.
 A tun jiroro lati yanju aawọ to n waye laarin awon omo egbe APC nile igbimo asofin, mejeeji, aawo to wa laarin gomina ati awon asoju-sofin ni awon ipinle kan, egbe si n gbe igbese lati yanju awon aawọ yii.
Ẹ jẹ́ kí wọn yin orúkọ OLUWA,nítorí pé orúkọ rẹ̀ nìkan ni ó ga jù;ògo rẹ̀ sì ga ju ayé ati ọ̀run lọ.
O ni Olu Jacobs ni itansan oorun, ologo didan ati aba ọkan oun ninu ifẹ.
Ile-isẹ ologun ilẹ yii ti jẹwọ wipe looto ni awọn ko awọn ọmọogun kuro ni agbeegbe Daphchi- awọn ọmọ Naijiria si n bere, wipe ta lo ni kii wọn ko awọn ọmọogun kuro loju ọna, ni wakati diẹ sigba tawọn ajinigbe wa ko awọn ọmọ naa.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Cornavirus: Makinde tọrọ aforiji fun ìpàdé ìta gbangba ẹgbẹ́ PDP tó wáyé nílu Ibadan 20 Ẹrẹ̀nà 2020 Oríṣun àwòrán, @seyiamakinde Gomina ipinlẹ Oyo, Seyi Makinde titọrọ aforiji lọwọ awọn eeyan ipinlẹ naa fun ipade ita gbangba ẹgbẹ PDP to waye nilu Ibadan laarin awuyeeuye Coronavirus to gbode.
UEFA wọ́gilé ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ Real Madrid àti Manchester City nítorí coronavirus Bi awada bi ere aarun coronavirus ti di ajakalẹ aarun kaakiri agbaye bayii, eyi to si ti mu ki awọn eeyan maa so ọpọ apejọpọ ati idije ere idaraya rọ.
Àgbo tí mò ń lò láti jò kó bá mi, ìdí mi ti yọ́ tán - Nkechi Blessing figbe ta Ọba ilu Ode lo ni oun lo ni ilẹ kan to wa ni agbegbe Isinigbo tawọn eeyan ti kọle le lori, to si ni ki wọn wa sanwo fun ilẹ naa.
"Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Toríi ""Coro"", ẹ wo bí ètò ìsìn ìgbéyàwó orí ayélujára Zoom ṣe lọ Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!"
Ọlọ́pàá Kwara ti rí ọmọ orílẹ̀-èdè Turkey mẹ́rin gbà padà lọ́wọ́ ajínigbé!
Ekeji fi ara jọ ọ́: ‘Fẹ́ràn ọmọnikeji rẹ bí o ti fẹ́ ara rẹ.
” Tabi ki o jẹ pe awon kan fẹ
” Awon Gomina kookan naa kopa ninu ipade apero, ti o fimo awon ile-ise ijoba apapo ni erongba lati wa ojutu si eto oro aje orile-ede yii.
Oun naa ni wọn tun maa lo fun Summer Olympics to m bọ ni 2024.
Adisa fikun wi pe o da oun loju wi pe ayẹyẹ ohun koni tako ofin yiyagofunraẹni ati wi pe ti awọn eniyan naa ba pọju mẹwa lọ, awọn yoo wa n kan ṣe si.
“Ní àkókò gan-an tí iyè mi pada bọ̀ sípò, ògo, ọlá, ati iyì ìjọba mi náà sì tún pada sọ́dọ̀ mi.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Nike Suliyat: Ọ̀dọ́mọdébìnrin akéwì tó n fi ẹ̀ṣà kìlọ̀ ìwá lásìkò yìí Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Nike Suliyat: Ọ̀dọ́mọdébìnrin akéwì tó n fi ẹ̀ṣà kìlọ̀ ìwá lásìkò yìí 24 Ẹrẹ̀nà 2020 Ọmọ tó bá sọ ile nu.
OLUWA ní, “Efuraimu jẹ́ oníṣòwò tí ó gbé òṣùnwọ̀n èké lọ́wọ́, ó sì fẹ́ràn láti máa ni eniyan lára.
“Mo sọ fún Joṣua nígbà náà pé; ‘Ṣé ìwọ náà ti fi ojú ara rẹ rí ohun tí OLUWA Ọlọrun rẹ ṣe sí àwọn ọba meji wọnyi?
Ṣe lilo Methtoletom lé koju aarun Corornavirus?
Ìrìnàjò afẹ́ ojúnà oní kìlómítà 1.
The Blessed Vost – Sefia Djama – Algeria
" Ile ifowopamọ naa ṣalaye pe wọn da iṣẹ duro lawọn ẹka kan nitori ajakalẹ arun Covid-19 to n ba gbogbo aye finra.
Àwọn tí ń kọjá lọ ń sọ ìsọkúsọ sí i, wọ́n ń já apá mọ́nú, wọ́n ń wí pé, “Kò tán an!
Wọn ń wí pé, “Ṣé Mose nìkan ni OLUWA ti lò láti bá eniyan sọ̀rọ̀ ni?
No reception wedding: Adewale ni àpèjẹ kò ṣe pàtàkì sí òun Alásè Buhari kú, Buhari ń ṣọ̀fọ̀ A kò lòdì sí kí àwọn mùsùlùmí ṣé ìwọ́de àyájọ́ Ashura-Ọlọ́pàá Nàìjíríà Adajo naa ni Olujimi bori ninu idibo naa nitori o fihan gbangba niwaju ofin pẹlu ẹri wi pe magomago waye ni awọn ijọba ibilẹ bii Ikere, Gbonyin ati Emure.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ohun mẹ́jọ tóo ní láti mọ̀ bí o bá fẹ́ lọ ilé ọdun Omowe Goodluck Ebele Jonathan to ti tukọ Naijiria sẹyin ninu ikinni ọdun keresi ti é ṣalaye nipa ibi Jesu ati ohun to duro fun.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Iku Fẹ́lẹ́: MC Oluọmọ, àwọn èèkàn ìlú sọ̀rọ̀ lórí ikú alága NURTW, Fẹ́lẹ́ 21 Ògún 2018 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 22 Ògún 2018 Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, MC Oluọmọ, àtàwọn èèkàn ìlú míràn sọ̀rọ̀ lórí ikú alága NURTW, Fẹ́lẹ́ Ọpọ awọn eekan ẹgbẹ awakọ ero lorilẹede Naijiria ni wọn peju sibi isinku oloogbe Taofeek Oyerinde ti pupọ eeyan mọ si Fẹlẹ.
ní ọjọ ́ karún osù karún , ó se ayẹyẹ ọgọta odún ìbí rẹ ̀ .
Ati Ademọla Adeleke ati Gboyega Oyetọla gbagbọ pe awọn lo jawe olubori ninu idibo naa.
Itan igbesi aye Afọnja: Laderin, tii se ọmọ bibi ọkunrin kan ti wọn n pe ni Alugbin, toun naa jẹ ọmọ bibi inu Pasin, lo bi Afọnja.
Oludanilekoo ohun wa gba ijoba niyanju lati  wa awon ona ti won yoo fi maa pa owo si  apo asuwon ijoba ,bii gbigba owo ori lori
Ṣugbọn kii ṣe fun itọju gbogbo awọn ounjẹ ti wọn n ta nigboro ti awọn eeyan nb ra.
Obinrin kan to wa pẹlu Mallet ni wọn sọ pe o fa a kuro nibi tawọn mejeeji ti jọ fija pẹta.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ilé tó yẹ kí Abiọla gbé, àwọn wo ló ń gbé níbẹ̀?
Ìdí èyí ni pé ilé-aiyé rọra fì sí egbẹ́ kan.
Ọkùnrin kan, Saliu ti o jẹ́ olùgbé agbègbè náà ló sọ fún oníròyìn pé, ènìyàn méje ló ti jẹ́ ọlọrun nípe nínú ìṣẹ̀lẹ̀ náà, tí wọ́n sì tí dáná sun ilé bíi méje pẹ̀lú.
Èso ọ̀pọ̀tọ́ tí ó wà ninu apẹ̀rẹ̀ kinni dára gbáà, ó dàbí èso ọ̀pọ̀tọ́ tí ó kọ́kọ́ pọ́n.
Nigba to n fidi itusilẹ awọn akẹkọọ naa mulẹ, gomina ipinlẹ Katsina, Aminu Bello Masari ni koko lara awọn akẹkọ naa le, ti wọn si wa nilu Tsafe nipinlẹ Zamfara, nibi ti wọn yoo ti gbe wọn wa silu wọn Kankara loni ọjọ Ẹti.
Lori ero amohun-maworan, gomina Akinwunmi dupe pupo lowo awon eniyan ipinle Eko fun igbekele won lori egbe oselu APC, papaa julo fun aaye ti won gba oun lati sin ipinle Eko.
Òkú rẹ̀ yóo fọ́n ká bí ìgbẹ́ tóbẹ́ẹ̀ tí ẹnikẹ́ni kò ní lè dá a mọ̀ mọ́.
Won dupe lowo Olorun pe o da ẹmi
Ọlajide fi kun ọrọ rẹ wi pe ohun ti o tọ ni ki ijọba ipinlẹ Ọyọ ati ile igbimọ aṣofin ipinlẹ Ọyọ jawọ ninu abosi,  bi wọn ko ba fẹ fi ọwọ ara wọn gbe ọmọ sin."
Ba a ṣe n sọrọ yii, iroyin kan ti ni Ibrahim El-Zakzaky ti n ṣẹri bọ wa sile.
Election Update 2019: Aráàlú ní ẹ́yìn lílọ Saraki, Kwara yóò ṣún síwájú ni
Bí n kò bá waasu ìyìn rere, mo gbé!
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Otedola Bridge: Àwọn ẹ̀ṣọ́ ojú pópó ti gbé Ọkọ̀ agbépo tó dànù kúrò lọ̀ná 23 Èrèlè 2020 Ajọ to n risi irinna ọkọ oju popo ti ni awọn ti gbe ọkọ agbepo to ja naa kuro ni oju popo.
Àlàyé rèé lẹ́nu awakọ̀ tó mọ̀ nípa ìbúgbàmù tó la ọ̀nà sí méjì l'Akurẹ̀ 28 Ẹrẹ̀nà 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 1 Ìgbé 2020 Oríṣun àwòrán, Twitter Àkọlé àwòrán, Oju opo ikansiraẹni Twitter ni awọn eniyan ti n bere wi pe ibugbamu kan dun ni oru ni ipinlẹ Ondo.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Coronavirus Update: Iná jó àwọn ènìyàn 10 tó ń gbà ìwòsàn àrùn Coronavirus ní Isolation Center 9 Ògún 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 10 Ògún 2020 Oríṣun àwòrán, Others Eniyan mẹwa lo ti ku ninu ina to sọ ni ile itura ti wọn n lo lati fi tọju awọn to ni arun Coronavirus lorilẹ-ede India.
mẹ́tàdínlọ́gbọ̀n naira ẹkunwo owo osu awon osise ti apapo igbimo ipinlẹ  fọwọsi fun won lojo Isegun , niluu Abuja.
Àkọlé àwòrán, Èèyan kan, ìlù mẹ́wàá Àkọlé àwòrán, Jó ṣàkùṣákù sí dùǹdún àti ṣẹ̀kẹ̀rẹ̀ BBC News, Yorùbá Ìdí tí ẹ fi le è nígbàagbọ́ nínú ìròyìn BBC Ìlànà Lílò Nípa BBC Òfin Àṣírí Cookies Kàn sí.
Irinajo igba akoko lati odun 1998
Kolapo Ishola lo wa ni ipo gomina ni ipinle Oyo laarin odun 1992 si odun 1993 labẹ Ijọba Alagbada.
Bakan naa ni ẹlomiran gbe e jade wi pe, ko si ohun to jọọ wi pe wọn fẹ fi Festus Adedayo si ipo kankan, ati wi pe Ile Igbimọ Asofin ti gbe orukọ awọn to fẹ ba Lawan sisẹ jade, ti orukọ Adedayọ si ti poora nibẹ.
‘Ìṣúnsíwájú ìbò: Àdínkù yóò bá owó epo bẹntiróòlù Ẹnikẹ́ni tó bá ṣáájú láti jì àpótí ìbò, ẹ̀mí rẹ̀ ló fi ń ṣeré - Buhari APC, PDP, CUPP kọ etí ikún sí òfin INEC Lori awọn ibeere yii ni awọn ọmọ Naijiria ti n wu oriṣiriṣi ọrọ jade ati isẹlẹ ti wọn ranti tabi ti wọn ni iriri rẹ pẹlu awọn ẹṣọ aṣọbode.
Fẹmi Adebayọ ṣe afihan sinima Survival of Jelili Oríṣun àwòrán, femi adebayo/Instagram Gbogbo wa lo fẹrẹ wo sinima apanilẹrin ti Fẹmi Adebayọ ṣe, to pe akọle rẹ ni Jẹlili, nibayii, o ti tun gbe eyi ti a lee pe ni ipadabọ Jẹlili lẹẹkeji jade bayii.
Angẹli náà bi mí pé, “Kí ni ó yà ọ́ lẹ́nu?
“A gbusuba fun igboya ati gbogbo akitiyan yin ni ona lati daabo-bo ipinle yii lowo ikolu awon darandaran, a mu dayin loju pe, a wa pelu yin lorekoore.
Wọ́n tún mú aṣọ títa mọkanla tí wọ́n fi irun ewúrẹ́ ṣe, wọ́n rán an pọ̀, wọ́n fi ṣe ìbòrí sí àgọ́ náà.
Sibẹsibẹ awọn ẹgbẹ wọn yi ko jáwọ nínú iwa buruku yi ti wọn si n pẹka sii paapa julọ lawọn fasiti Naijiria nibi ti wọn ti ko awọn ọmọ ẹgbẹ mii wọle.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Alafia de Mubarak jawe olubori gẹgẹ bi aarẹ pẹlu ida mejidinlọgọrun gbogbo ibo to jẹ pe oun nikan ni oludije.
Eyi lo fa a ti olori ẹgbẹ naa, Indomie, fi ko awọn ọmọ ẹgbẹ rẹ, ti wọn si lọ ọ doju ogun kọ Abiola 'Ebila' , to jẹ olori ẹgbẹ one million boys.
Kí ló dé tí o fi ń jẹ́ kí n máa rí àwọn nǹkan tí kò tọ́, tí o jẹ́ kí n máa rí ìyọnu?
Tí ẹ kò ba gbàgbé, akọròyìn yìí náà lo ṣe àbẹ̀wò si ọgbà ẹwọn Ikoyi àti àgọ ọlọpàá to díbọ́n bíi ọ̀daràn láti tú àṣiri àwọn ìwà ìbàjẹ́ to n ṣẹlẹ̀ níbẹ̀.
Ìmọ̀ràn wo ni ẹ ti fún àwọn aláìgbọ́n?
Dáhún ìbéèrè yìí kí o wo àkókò tí yóò ná ọ̀ Amofin Kayode Ajulo to jẹ onimọ nipa ofin ati ajafẹtọ araalu sọfun BBC Yoruba pe ko tọ ki ajọ INEC kàn ṣalaye idi ti wọn fi sun eto idibo naa siwaju.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Òṣìṣẹ́ Bánkì ni mí l'Amẹ́ríkà kí n tó bẹ̀rẹ̀ Tíátà' Baba Aduku ni koko to mu ohun foriti gbogbo ẹkọ ati ijiya lẹnu ikọṣẹ ṣọja ni ireti pe ti oun ba ṣetan, oun a gbẹsan ni abule.
Awon ajo aranilowo nisele pajawiri wa lori papa naa lati se iranlowo to ye, won ni won ti ri oku awon eniyan meji.
Ẹ̀wẹ̀ àjọ ọlọpàá ni àwọn sa gbogbo ipá àwọn la'ti ri dáju pé, gbogbo àwọn oniwa janduku yìí so agbéjẹ́ mọ́wọ́ Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Oríṣun àwòrán, AFP/Getty Images Fọ́nran kan lori ayélujára sàfihan bi wọ́n ṣe n di okunrin kan mọlẹ lori afára náà, lẹ́yìn náà ni àwọn ọọpàá de ti wọ́n si ni ki àwọn ènìyàn kúrò lọ́dọ̀ rẹ̀ ti wan si yín ọkùnrin náà nibọ̀n.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Canada Visa Application: Canada bẹ̀rẹ̀ iṣẹ́ lórí fọ́ọ̀mù àwọn tó fẹ lọ sí orílẹ̀-èdè náà 1 Agẹmo 2020 Oríṣun àwòrán, @truwayofficial Ijọba ilẹ Canada ti bẹrẹ si n ṣiṣẹ lori fọọmu awọn to nifẹ lati tẹko leti lọ silẹ naa lati Ọjọ Kinni, Oṣu Keje, ọdun 2020.
Mo ní ọpọlọpọ ọgbà ati àgbàlá, mo sì gbin oríṣìíríṣìí igi eléso sinu wọn.
Oun pẹlu wa fi gbolohun diẹ ṣọwọ si Gomina Oyetọla pe oun dupẹ toun o pe oun jẹ onijo, ṣugbọn ijo jijo kii ṣe aisan.
0 40 Saint Kitts and Nevis 0 0.
 ní ọdún 2009 , all-ireland league nílé ìwé dublin university bá fìwé pèé lábẹ ́ àṣẹ olùdarí bọ ́ ọ ̀ lù rugby ìyẹn tony smeeth .
Nítorí náà, ẹ̀yin ará mi, àyànfẹ́, tí ọkàn mi ń fà sí, ayọ̀ mi, ati adé mi, ẹ dúró gbọningbọnin ninu Oluwa.
OLUWA bá sọ fún Mose pé, “Kọ ìṣẹ̀lẹ̀ yìí sinu ìwé kan fún ìrántí, sì kà á sí etígbọ̀ọ́ Joṣua, pé n óo pa Amaleki rẹ́ patapata, a kò sì ní ranti rẹ̀ mọ́ láyé.
Idi si niyii ti wọn fi ránṣẹ si awọn oṣiṣẹ pana-pana lati koju wọn.
Ibrahim Chatta: 'Àìnání ìgbẹ́kẹ̀lé ló mú mi kọ ìyàwó àkọ́kọ́' Nollywood: Àwọn òsèré tíátà Nàìjíríà tó jẹ́ ọmọ Yorùbá Nollywood: Àwọn obìnrin Yollywood tó ń tà wàrà-wàrà Eré Obìnrin Àsìkò tí olóògbé Alade Aromire ṣe ni Toyin Afolayan ti rí ìnagijẹ rẹ̀ tíi ṣe Lola Idijẹ.
Ẹ̀rù ba àwọn tí wọn ń tu ọkọ̀ náà gidigidi, wọ́n sọ fún un pé, “Kí ni o dánwò yìí?
Ilumọọka ni Sophie ni orilẹ-ede Norway nibi to ti n gbe eto oriṣiriṣi sori afẹfẹ to tun ni awọn to le ni ẹgbẹrun ẹẹdẹgbẹta to n tẹlẹe.
Ẹ dákẹ́ jẹ́ẹ́, ẹ̀yin tí ń gbé etí òkun,ẹ̀yin oníṣòwò ará Sidoni;àwọn iranṣẹ yín ti kọjá sí òdìkejì òkun,
Loju opo Twitter rẹ ni Zlatan fi ikede idagbere fawọn alatilẹyin ẹgbẹ naa si lọjọru.
Ìkùukùu óo bò ó mọ́lẹ̀; wọn óo sì kó àwọn ọmọbinrin rẹ̀ lọ sí ìgbèkùn.
Ki i ṣe ẹgbẹ oṣelu Conservative ni ko ni iṣokan lori ọrọ Brexit, ọrọ ẹnu awọn ọmọ ẹgbẹ oṣelu Labour naa ko ko lori ọrọ naa.
Ọ̀pọ̀lọpọ̀ ọ̀dọ́ ayé òde òni ti kọ àṣà fi fẹ́ iyàwó púpọ̀ silẹ̀ nitori ẹ̀sìn, ìmọ̀ àti si sá fún rògbòdiyàn ti ó lọ pẹ̀lú iyàwó púpọ̀.
Idris Mohammed to jẹ Baalẹ abule naa sọ fun BBC pe ni nkan bi aago mejila ọsan ọjọ Aiku, ni awọn deede ri ti oyin ya bo gbogbo abule.
Ṣugbọn, ní tèmi, mo fẹ́rẹ̀ yọ̀ ṣubú,ẹsẹ̀ mi fẹ́rẹ̀ tàsé.
Ileeṣẹ ilera ni ipinle Eko ṣalaye fun BBC pe o le ni iṣẹlẹ aadọrin le ni ọọdunrun to ti ṣẹlẹ bayii.
Bakan naa ni wọn fikun wi pe ileeṣẹ kankan ko ni ṣi, awọn ileepo ko ni ṣi, ojuko iwapo, ileewosan, ileeṣẹ ijọba, ileeṣẹ ofurufu ati bẹẹ lọ ni yoo darapọ.
Ọmọ Yahoo fẹ́ pa ìyá rẹ̀ ṣ'owó l'Eko Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Bọlanle Ninalowo: Ọ̀rẹ́ lásán àti olóore mi ni Mercy Aigbe Wọn fi kun ọrọ wọn wipe, oloogbe naa to dagbere faye lẹni ọdun mejidinlọgọta ni ko duro jẹ ere ise rẹ, gẹgẹ bi wọn se rawọ ẹbẹ si Ọlọrun lati tu aya, ọmọ ati awọn mọlẹbi to fi silẹ ninu.
bakan naa ni Gomina ipinlẹ Eko, Babajide Sanwo-Olu naa ṣe ayẹwo arun naa lẹyin ti mẹwaa lara awọn to n ṣiṣẹ nile ijọba ipinlẹ Eko to wa ni Marina lugbadi arun ọhun.
Ninu oṣù Sifi, ní ọdún kẹrin ìjọba Solomoni, ni wọ́n fi ìpìlẹ̀ ilé ìsìn náà sọlẹ̀.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ojo arọrọda Eko ṣe idiwọ fún káràkátà Ṣugbọn ni kete ti wọn tun bẹrẹ si ni gba owo iwọle pada ni sunkẹrẹ fakẹrẹ ọkọ tun gbera sọ.
Kò ye yín pé ikùn ni gbogbo ohun tí eniyan bá fi sí ẹnu ń lọ ati pé eniyan óo tún yà á jáde?
Rekabu ati Baana bá rọra yọ́ wọlé.
"'Ó ṣeéṣe kí Ààrẹ Buhari pàṣẹ ìgbélé jákèjádò Nàìjíríà lónìí' Dibu Ojerinde, akọ̀wé JAMB tẹ́lẹ̀ pàdánù ọ̀pọ̀ dúkìá sọwọ àjọ ICPC""Bí àwọn agbebọn náà ṣe múra kò jọ tí ọmọlúwàbí, kí ló dé tí wọn kò kan 'Road Block' kankan lójú ọna, mo wá ń rọ gomina Makinde láti mojuto eto ààbò."
Tí ọkọ̀ méjì bá pàdé arawọn báyìí, ọ̀kan nínúu wọn gbọdọ̀ dúró sí ẹ̀gbẹ́ kan kí ó yọ̀nda ọ̀nà fún èkejì láti kọjá.
Ewe, leyin ojo kerin si ifigagbaga pelu orile-ede Poland, Super Eagles yoo lo koju Serbia ni papa isere The Hive, ni London.
"Kia ni mo sa pada si ibi ti mo n fara pamọ si lati lọ ṣe ọna bi n o ṣe sa kuro ni Naijiria""."
”Hafiz tun so pe ”sugbon o seni laanu pe isele to n sele ni ipinle yii to nii se pelu eto iselu, ipinnu mi, ati ẹri ọkan mi ko ni lee je kin n tesiwaju lati tun maa baa yin sisẹ papọ gege bi adari ijọba , ki emi naa si tun wa ni ipo igbakeji gomina.
Odiwon ile riri to to ida meji le ni meje sele ni Snatiago fun bii kilomita marundinlaadota ni eyi to mu ina monamona lo.
Wọ́n wá ta aṣọ-ọkọ̀ tí ó wà lókè patapata níwájú ọkọ̀.
Àwa pọ̀ ní tiwa, nítorí náà, a ti fi ilẹ̀ yìí fún wa, kí á gbà á ló kù.
Oriṣiríṣii nkan lo ṣelẹ lágbo oṣere ni Naijiria lọdun 2018 nibi ti ọpọlọpọ fiimu agbelewo ati ti sinima ti jade loniruuru.
Ọ̀pọ̀ àwọn afẹ̀hónúhàn ló ti lo dáná sun ilé ẹbi àwọn ọmọkùnrin náà ti wọ́n sì ń péjọ síwájú ilé iṣẹ́ ọlọpàá Islam ti a mọ sí Hisbah pé a fi ti wọ́n bá ṣe ìdájọ́ to yẹ lórí ọmọkùnrin ọ̀hún.
Lanre Kuti ni mo fẹ́ - Jaiye Kuti Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
nipa ti  orilẹ-ede Naijiria ; ona lati
O-lokan-o-jokan ere idaraya ni won fi saami ayeye ohun lara eyi ti a ti ri, ijo-jijo, fifun awon ologun lami eye o-kare lae abbl.
Àwọn mẹta ni ọmọ Bẹnjamini: Bela, Bekeri, ati Jediaeli.
Lọjọ kẹjọ oṣu keje ọdun 2003 lẹgbẹ NLC kede pe ohun wọgile le iyanṣẹlodi to gunle lẹyin to faramọ igbesẹ ijọba lati gbe owo epo si N34 lati N40.
Agbẹnusọ fu minisita eto ibanisọrọ, Uwa Suleiman lo fidi ọrọ naa mulẹ ninu atẹjade kan to fi sita.
erongba rẹ han lati dije fun ipo abenugan niluu Abuja.
Ní ọjọ́ mélòókan sẹ́yìn, ẹnìkan bèèrè lórí Twitter pé kí l’àá ṣe npe “SIM Card” ní èdè Yorùbá.
 Mo rọ gbogbo ẹ̀yin olólùfẹ́ wa kí ẹ lọ fi ọkàn balẹ̀, ẹ má fòyà, àsìkò yìí yóò kọjá Ọkùnrin ẹni ọdún mẹ́tàdínlọ́gọ́rin náà ti lókìkí nínú iṣẹ́ to yàn láàyò lọ́jọ́ pípẹ́ wá, ti ó sì ti fàra hàn nínú eré tó tó ọgọ́sàn-án láti bi ààdọ́ta ọdún sẹ́yin.
"Duro Ladipọ, ìlúmọ̀ọ́ká òṣèré tíátà àti ọmọ àlúfà tí kò gbàgbé àṣà ìbílẹ̀ Ọ̀rọ̀ǹpọ̀tọ̀niyùn, Aláàfin obìnrin àkọ́kọ́ rèé, tó ní nǹkan ọkùnrin ""Awọn ọlọpaa gbe kẹkẹ wọ ilu Atali pe ki ọmọkunrin kan wọle."
Solomoni ati àwọn tí wọ́n péjọ lọ sí ibi gíga tí ó wà ní Gibeoni, nítorí pé àgọ́ ìpàdé Ọlọrun tí Mose, iranṣẹ OLUWA, pa ninu aginjù wà níbẹ̀.
Adura Ẹni tí Ìyà ń Jẹ.
Ubani sọ fun BBC Yoruba bẹẹ lẹyin ti Gomina ipinlẹ Bẹnuẹ, Samuel Ortom rọ ijọba lati fun awọn ọmọ Naijiria laaye lati gbe ibọn bii AK47 lati daabo bo ara wọn.
Kẹmika yii jẹ eyi ti awọn ileeṣẹ fi n yọ idọti ninu eyi to hande pe wọn pe e fun wọn ni Omi iṣẹ iyanu, ti wọn si ni o n wo aisan bi i jẹjẹrẹ ati ibà san lara.
 Ọ ́ pọ ̀ lọpọ ̀ àwọn ẹyẹ fún ìdáraya nió wà ní ẹbí yìí .
Bo tilẹ jẹ wipe atẹjade kan ti ajọ aṣọbode fi sita sọ pe ''oṣiṣẹ awọn ti wọn lọ yinbọn mọ arakunrin naa, ko ni ọkan lati ṣe bẹ, amọ ibọn to gbe dani lo ṣeeṣi yin ara rẹ.
A ti kàn mí mọ́ agbelebu pẹlu Kristi.
'Àìjáfáfá àwọn panápaná ló mú kí ọṣẹ́ iná Akure pọ̀' Wòlíì Sotitobire gúnlẹ̀ sí ilé ẹjọ́ ní ìtẹ̀síwájú ìgbẹ́jọ́ rẹ̀ Kí ló ṣekúpa Ibidunni Ighodalo tí gbogbo ọmọ Nàìjíríà ń selédè lẹ́yìn rẹ̀?
Ikede naa jẹ́ ohun ti eniyan fẹ́ẹ̀ le ni ọpọ ti ń reti fún ìgbà pípẹ́.
Ó wó aláìṣẹ̀ mọ́lẹ̀, ó tẹ orí wọn ba,ó sì fi agbára bì wọ́n ṣubú.
Demilade ni ẹru kii ba oun ti mama oun ba wa lode ariya, ti oun si n fọn fere, nitori oun kii wo oju rẹ, oun yoo gbe oju soke ni, ki ẹru ma baa maa ba oun.
Ògo ni fún Ọlọrun ọlọ́gbọ́n kanṣoṣo nípa Jesu Kristi títí laelae.
Lara awọn eeyan to ba Lizzy se jaginni yodo oye tuntun naa ni Alaafin tilu Ọyọ, Ọba Lamidi Ọlayiwọla Adeyẹmi Kẹta ati awọn olori rẹ meji.
Aare fi ẹdun ọkan rẹ ransẹ si ijoba
Láìpẹ́ rẹ̀ ni ó tún kẹ́kọ̀ọ́ gboyè àgbà ìmọ̀ okòwò ni fásìtì kan náà.
Lójijì ni n óo gbà á, o kò sì gbọdọ̀ banújẹ́ tabi kí o sọkún, bẹ́ẹ̀ ni omi kò gbọdọ̀ kán sílẹ̀ lójú rẹ.
Gbogbo àwọn ọmọ Israẹli jáde wá, bẹ̀rẹ̀ láti Dani ní apá ìhà àríwá títí dé Beeriṣeba ní apá ìhà gúsù ilẹ̀ Israẹli ati àwọn tí wọ́n wà ní ilẹ̀ Gileadi, ní apá ìwọ̀ oòrùn.
Èèyàn kẹta tó wà nínú ẹlikọ́pítà Quarom aviation tó já lulẹ̀ ní Ikeja náà ti jáde láyé!
Ẹ̀yin ará Moabu,ìpayà, ọ̀gbun ati tàkúté ń bẹ níwájú yín!
Efunsetan ni aṣa buruku gbaa ni, o ṣalaye pe kiii ṣe ohun to dara ki aṣiri ọyan maa han sita, iṣẹ Eṣu ni.
A fẹ́ lo ẹ̀jẹ̀ àwọn èèyàn tó ye àrùn Coronavirus láti fi ṣe ìwòsàn fún àwọn tó wà lórí àárẹ- UK Àwọn tó jí kọmíṣọ́nnà gbé l'Ekiti ń bèèrè fún N30 mílìọnù kí wọ́n tó le è tú u sílẹ̀ Aàrẹ Donald Trump ní America ṣetán láti fi ẹ̀rọ fẹntilátọ̀ tọrọ fún Mexico, Italy, Spain àti.
Khadijat Oluboyo, ti ọrẹkunrin rẹ oniyahoo yahoo ṣeku pa: Ni oṣu kẹta ọdun 2019 ni ile ẹjọ giga ni ipinlẹ Ondo da ẹjọ iku fun Seidu Adeyemi to pa ọmọ igbakeji gomina ana nipinlẹ Ondo, Khadijat Olubọyọ ni ọdun 2018.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Okùnrin SARS náà sọ pé òun máa pa èèyàn síbi ni- Aladugbo Awọn ara adugbo ni ariwo iyawo oloogbe naa ni awọn gbọ ti wọn si sa lọ ibi iṣẹlẹ naa nibi ti wọn ti ba Obok ninu agbara ẹjẹ.
Ile asofin agba buwọlu ofin SADC lati gbogun ti ọwọja arun Lassa Amọṣa, minisita fun eto ilera lorilẹede Naijiria, Ọjọgbọn Isaac Adewọle ni, ijọba orilẹede Naijiria n sa ipa gidigidi lati dẹkun ọwọja arun naa.
Oríṣun àwòrán, Osun Osogbo Lọwọlọwọ bayii, ọdun Ọṣun Osogbo ti di itẹwọgba jakejado agbaye, tawọn onileesẹ nla nla si n wa lati ilẹ okeere wa se onigbọwọ rẹ.
2 5575 Erekusu Reunion Island 41 4.
Wo awọn iroyin manigbagbe to waye ni ọsẹ yii Ìtàn Manigbagbe: Àwọn àjakalẹ-àrun to ti wáyé rí ṣáájú Coronavirus Ọba Lamidi Adeyẹmi, òṣìṣẹ́ adójútòfò àti Abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò kó tó jọba Oyinkan Abayomi, akọni obìnrin tó fi ìfẹ́ pa orúkọ ọkọ kejì dà sí ti ọkọ àárọ̀ Duro Ladipọ, ìlúmọ̀ọ́ká òṣèré tíátà àti ọmọ àlúfà tí kò gbàgbé àṣà ìbílẹ̀ Eto Akomolede ati Aṣa lori BBC Yoruba jẹ eyi ti BBC n ṣe pẹlu ajọṣepọ ẹgbẹ onimọ Yoruba (YSAN) ati apapọ ẹgbẹ Akomolede ni Naijiria.
Aṣofin Ọbasa ti Igbakeji Olori ọmọ ẹgbẹ oṣelu to pọju lọ ninu Ile Igbimọ Aṣofin naa, Aṣofin Olumuyiwa Jimoh ṣoju fun sọ pe ijoba n sa gbogbo ipa lati fi kun imọ awọn oṣiṣẹ lati le mu igberu ba wọn lẹnu iṣẹ.
Ẹ wo bí Amotekun ṣe gba ilẹ̀ Yoruba silẹ̀ lọ́wọ́ agbéṣùnmọ̀ní ní igba ọdún sẹ́yìn Àwọn àpọ́n ọmọ Yorùbá olówó Marun tí kò tíì laya O ni awọn agbegbe ayẹwo iyasọtọ ti wa kaakiri lati tọju awọn eeyan to ba lugbadi aisan naa; ti oogun ati itọju to bagbamu pẹlu ilana agbaye si ti wa nikalẹ fun wọn.
World Malaria Day:Kí gaan láwọn nkán tó n fa àìsàn ibà?
 Bakan naa, gbedeke yoo wa fun irinna lasiko eto idibo naa.
Gbajugbaja olorin takasufe, David Adeleke ti gbogbo eeyan mọ si 'Davido' naa ko gbẹyin nibi ipolongo ibo fun aburo baba rẹ, Ademọla Adeleke ti o jẹ oludije si ipo gomina lati inu ẹgbẹ oṣelu PDP.
Ìlú ò rẹ́rìn ín rárá, Alaafin Adeyemi III fárígá fún Buhari nínú lẹ́tà tuntun Àgùnbánirọ̀ akọ̀ròyìn Channels náà ti dágbére fáyé látààrí ìkọlù Shiite l'Abuja Àwa ò mọ ẹgbẹ́ kankan tó ń jẹ́ fijilanté fulani l'Ondo- Ìjọba ìpínẹ̀ Ondo Dalung, Audu Ogbe, Shittu Adebayo àti Isaac Adewole kò wọlé Ganduje ni ipese ruga lo le dẹkun iṣoro tawọn Fulani n koju, o ni ti wọn ba loju kan ni wọn fi le jẹgbadun awọn ohun ameyedẹrun bi awọn ara ilu yoku.
Bakan naa, awon osise eleto ilera tun so pe,, itoju tun lo lowo bayii lori awon meje miiran.
Aarẹ ẹgbẹ awọn ọlọja naa ni ilu Ibadan, Alhaji Dauda Oladepo lo sọrọ naa lasiko to n ba awọn ẹgbẹ kẹdun ni ilu Ibadan.
Bàbá mi náà sì tún fèsì ó wí báyìí pé, Kábíyèsí, Akọ̀wédìran ni.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Àṣà àti ìgbàgbọ́ Yorùbá ni pé òbí wọn máa ń padà wá sáyé Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àṣà àti ìgbàgbọ́ Yorùbá ni pé òbí wọn máa ń padà wá sáyé 31 Ọ̀wàrà 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 11 Èbibi 2020 Yewande, Yetunde, Yejide, Iyabọ: awọn orukọ to mu itan da ni!
Àwọn ìgbìmọ̀ bá tún pè wọ́n wọlé, wọ́n pàṣẹ fún wọn pé wọn kò gbọdọ̀ tún dárúkọ Jesu mọ́, bẹ́ẹ̀ ni wọn kò gbọdọ̀ tún fi orúkọ Jesu kọ́ àwọn eniyan mọ́.
Isakoso ijoba yii yoo gbiyanju lati ja fita-fita, lati mu igberu ba ilana ati igbese re, lati je ki ilu Eko je awokose rere lagbaye.
 orísirísi àǹfàní ni ó wà nínú ìbágbépọ ̀ ẹ ̀ dá .
Iṣẹ́ ìdọ̀tí ni ẹran títá, ṣùgbọ́n nínú ẹ̀gbin lowó wà
Ó mú mi lọ sí apá ìhà gúsù, mo sì rí ẹnu ọ̀nà kan níbẹ̀.
Tori naa, oun bọwọ fun aṣẹ igbimọ lọbalọba to ni ki oun lọ rọkun nile fun igba diẹ.
Àmúwá Ọlọ́run lásán ní ìṣẹ̀lẹ̀ tó wáyé ní Iba-Eburu Iba Oba Okunoye Bi nnkan ṣe duro niyi: Arsenal ti de ipele aṣekagba idije ife ẹyẹ FA cup lorilẹ-ede Gẹẹsi fun igba mọkalelogun Igba mẹtala ọtọọtọ ni Arsenal ti gba ife ẹyẹ naa.
 nígbàmíràn , wọ ́ n máa ń tọ ́ jú àwọn ẹbí àti ẹyẹ míràn bí ẹbí yìí .
Wón maa ṣe akọsile awon iwa buruku ti aarẹ ana, Idi Amin ṣe laarin ọdun mẹjọ to buruju ninu itan Uganda.
ede Naijiria ti fun awọn awakọ ogun Mi-35m marun un ti won padanu ẹmi won ninu
 ọ ̀ pọ ̀ nínú irinṣẹ ́ ìmọ ̀ ẹ ̀ rọ tí àwọn àgbẹ ̀ ńlò ló jẹ ́ pé àwọn alágbẹ ̀ dẹ ́ ló máa ń ṣe e .
" Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Obateru Akinruntan: Wíwá ohun tá jẹ títí láé ló gbé wa kúrò nílé Ife Awọn mẹtẹẹta jẹwọ wi pe lootọ ni awọn hu iboji oku, ti awọn si ge ori rẹ kuro.
 ní ọdún 1880 ní wọn fi jẹ Ọba èyí ni Ọọ ̀ ni ti ifẹ ̀ , ṣùgbọ ́ n kò wá sí ifẹ ̀ wá ṣe àwọn ètùtù tí ó rọ ̀ mọ ́ ayẹyẹ ìgbádé ọba , Òkè-igbó ni ó jókòó sí1 Òkè-igbó yìí ní ó wà tí ọlọ ́ jọ ́ fi dé bá a ní ọdún 18922 .
Àwọn ọba wọn ń gbọ̀n jìnnìjìnnì, ẹ̀rù sì hàn ní ojú wọn.
Ìpínlẹ̀ Kebbi Bí àwọn Sokoto ṣe ṣe bẹ́ẹ̀ náà ni Kebbi, gẹ́gẹ́ bi ọkan lára àwọn oṣìṣẹ́ ìjọba to ba BBC sọ̀rọ̀ ṣe sọ níbẹ̀ pé, kò sí ìpínu kankan láti ti ilé ìwé nítori pe àwọn ìpínlẹ̀ tó kù ń ṣe bẹ́ẹ̀.
“Ẹnikẹ́ni tí ó bá rúbọ sí oriṣa-koriṣa kan lẹ́yìn OLUWA, píparun ni kí wọ́n pa á run.
Oníròhìn ná wà tín jẹ́ Sẹ̀san Fáfiólú tí wọ́n ṣe atótó arére sí etí ìgbọ́ wa.
Tabi, kí ni ẹ óo mu?
Yahoo Boys: Àwọn ọmọ Yahoo tí kò dín ní igba ni yóò fojú ba ilé ẹjọ
Abẹ̀sẹ́kù bí òjò wọ gàù lẹ́yìn tó fẹnu ko ''Jennifer'' lẹ́nu Man U ti fi òǹtẹ̀ lu Gunnar Solskjaer gẹ́gẹ́ bí akónimọ̀ọ́gbá Amuneke àti olóògbé Keshi ló gbé orílẹ́èdè míràn lọ sí ìdíje AFCON Bakan naa ni Leicester City naa Huddersfield pẹlu ami ayo meji si ẹyọkan.
Iwe irohin Vanguard sọ pe aridaju wa pe bii ẹgbẹrun mẹrin ninu wọn ni awọn ti wọn wa ninu itubu ni wọn n duro de idajọ - awọn kan sọ fun igbakeji aarẹ wipe awọn ti n duro de idajọ nile ẹjọ fun bii ọdun marun.
Ẹ̀yin tí ẹ fi ibinu fún aládùúgbò yín ní ọtí mu, tí ẹ jẹ́ kí inú wọn ru, kí ẹ lè rí ìhòòhò wọn.
Ọsẹ tó nira julọ fún mi rèé- Neil Warnock Ipinlẹ Ọ́yọ̀: Ile-iwe wa ni titi pa nitori iyansẹ̀lodi Ọ̀rọ̀ LAUTECH gba àpérò f'áwọn Olúdíje Ọṣun Àwọn ohun mánigbàgbé níbi ìfọ̀rọ̀wérọ̀ BBC Yorùbá l'Ọyọ David Mearns, to n dari awọn to n wa ọkọ naa lati ọjọ to sọnu ni agbegbe Guernsey ni wọn ti ri ajaku ọkọ naa labẹ omi ni ọjọ Aiku.
Ní gbogbo àkókò tí Samuẹli wà ní ọmọde, tí ó ń ṣiṣẹ́ fún OLUWA lábẹ́ Eli, OLUWA kò fi bẹ́ẹ̀ bá àwọn eniyan sọ̀rọ̀ mọ́, kò sì fi bẹ́ẹ̀ sí ìran rírí láti ọ̀dọ̀ OLUWA mọ́.
Saájú àsìkò yìí, o ni àwọn àgbègbè eti odò náà fi han pé, màgòmágó le ṣẹlẹ̀ níbẹ̀, nítorí bi ibẹ̀ ṣe rí.
Fún ẹni tí ń ṣègbé lọ ní ọtí mu,fún àwọn tí ọkàn wọ́n bàjẹ́ ní ọtí líle,
Mo ronú bí mo ti ṣe lè fi waini mú inú ara mi dùn, ṣugbọn tí kò ní pa ọgbọ́n mọ́ mi ninu; mo tún ronú ohun tí mo lè ṣe pẹlu ìwà òmùgọ̀ títí tí n óo fi lè rí ohun tí ó dára fún ọmọ eniyan láti máa ṣe láyé níwọ̀n àkókò díẹ̀ tí Ọlọrun fún wọn láti gbé lórí ilẹ̀ ayé.
Ni kia lo si yẹ ki a se atunse si ofin to de gbigbogun ti iwa ipa ninu ile ti ọdun 2017 pẹlu awọn ijiya tuntun lati fi awọn ti aje iwa yii ba si mọ lori jofin daindain."
 nígbà tí ó bá n ṣerè , a mọ ̀ pé ó lè jalè .
May tún sọ wípé nínú ọkàn òun, ohun tí àwọn se yìí gaan ló tọ́.
FIFA fofin de Siasia pe ko gbọdọ ni nkankan ṣe pẹlu ere idaraya bọọlu alafẹsẹgba mọ titi aye.
A gbọ pe inu rirun ati bi ọmọ naa ko ṣe le rin daadaa, lo mu ki iya rẹ gbe e lọ sileewosan fun ayẹwo, ki aṣiri o to o tu pe wọn fi ipa ba lopọ ni.
Maryam yii ni wọn lo fi ọbẹ gun ọkọ rẹ, Bilyaminu Bello, eyi to ran sọrun ọsan gangan lọdun 2017.
Ni ọjọ Iṣẹgun, ọjọ kẹtadinlogun oṣu keji ọdun 2020 ni kọmiṣọna feto ilera ni ipinlẹ Eko, Ọjọgbọn Akin Abayọmi gbe atẹjade kan sita pe ijọba ti ri eeyan kan, to ti ko aisan iba naa, ti wọn si ti fi onitọun si abẹ itọju makan nileewosan nla LUTH.
Ronaldinho to gba ife ẹyẹ agbaye pẹlu Brazil lọdun 2002 gba bọọlu fun Paris St-Germain, Barcelona ati AC Milan ilẹ Yuropu ko to fẹhinti lẹyin to ṣoju Fluminense fun igba diẹ ni Brazil.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Èsí ìdánwò WAEC: Ìdá 53 nínú ọgọ́rún akẹ́ẹ̀kọ́bìnrin fakọyọ 5 Agẹmo 2018 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Àjọ tó ń rísí ìdánwò àwọn akẹ́ẹ̀kọ́ jáde, WAEC ti fi esì ìdánwò àwọn akẹ́ẹ̀kọ́ Girama jáde Ajọ to n risi idanwo awọn akẹẹkọ jade Girama ni agbeegbe Iwọ- oorun Afirika, WAEC ti fi esi idanwo asekagba(SSCE) ti ọdun 2018 si ita.
Omí pọ̀ ju ọkà lọ fún Unai Emery, ìfìdírẹ̀mi mí ló bade fún lọ́wọ́ Frankfurt
Miòṣé, lọ si oko, ó pa Igun, ó din láta, ó si jẹ́, ṣùgbọ́n ó pa adiẹ, ó da iyẹ́ adiẹ si ààtàn bi ẹni pé adiẹ ló jẹ.
Amọṣa awọn to nimọ nipa ọrọ abo lorilẹede yii kan ti n ti ipe naa lẹyin.
"Oríṣun àwòrán, Lizzy Anjorin ""Oju wa maa n kun fun omije pupọ nigba ti awọn ta jẹ ni gbese ba n fi wa se ẹlẹya, ti wọn si n pe wa ni orukọ buruku."
Awọn ijoye naa fi ẹsun kan Oba Akanbi pe o kede ara a rẹ gẹgẹ bi Olu Ọ̀ba 'Emperor', lẹyin ti wọn fi jẹ ọba lọdun 2016.
"Ṣugbọn bi wọn o bá gbà, fi ẹjọ wọn sun Banki to ga ju""."
ni abala kínní sáà ètò ẹ̀kọ́ yóò wáyé Ijọba ipinlẹ Oyo ti kede pe awọn ile ẹkọ rẹ yoo di ṣiṣi pada ni ọjọ kọkanlelogun oṣu kẹsan-an taa wa yii.
basu-basu ti ipinle naa lati bẹrẹ isẹ ni kiakia.
Ó ní òun óo gbé ọ ga ju gbogbo àwọn orílẹ̀-èdè yòókù tí ó dá lọ.
Mo mọ̀ pé àwọn iranṣẹ rẹ mọ̀ bí wọ́n ṣe ń gé igi ní Lẹbanoni, àwọn iranṣẹ mi náà yóo sì wà pẹlu wọn, 
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Afeez Agoro: O ṣòro fún mi láti wọ Danfo jáde Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Ó wí fún un pé, “Má wí ohunkohun fún ẹnikẹ́ni.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Lisa Hanna: Ojú kìí rí arẹwà kó má kí i.
Anfaani nla ni eyi fun mi lati sisẹ sin, ki n si mu iyatọ rere ba ọpọ isẹlẹ to n waye eyi to jẹ mi logun.
Pẹlu pe o mọ gbogbo aiṣedede mi, o jẹ mi ni oo!
Samuel Umtiti, agbabọọlu ọwọ ẹyin lo fi ori kan bọọlu wọ awọn Belgium eleyi to fun wọn lanfani lati tẹsiwaju si ipele aṣekagba.
Mo ti ṣe ìlérí pé n óo ṣe àwọn nǹkan wọnyi sí ẹ̀yin eniyan burúkú, tí ẹ̀ ń lòdì sí mi wọnyi.
Ẹni to bori: Nigeria Egypt vs Algeria.
Ẹnu ọ̀nà kan wà ní Jerusalẹmu tí wọn ń pè ní ẹnu ọ̀nà Aguntan.
A ò gba ìbálòpọ̀ akọ ṣákọ tàbí abo sábo Ẹ wo àwọn ẹlẹ́sìn Hindu tó ń jẹ ènìyàn Èèyàn ogún bá ìjàmbá ọkọ̀ lọ Nadia sọ fun BBC pe iṣoro oun bẹrẹ nigba ti oun wa ni ọmọ ọdun mẹtala.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Coronavirus Update in Nigeria: 'Ewu ń bẹ pẹ̀lú bí àwọn ọmọ iléèwé ṣe wọlé padà lásìkò àrùn Coronavirus' 27 Sẹ́rẹ́ 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 22 Owewe 2020 Oríṣun àwòrán, Getty Images Dokita Onimọ nipa eto ilẹra lorilẹede Niajiria ti ni ewu nla ni yoo jẹ fun eto ilẹra ni Naijiria ti ijọba apapọ ba paṣẹ ofin konile-o-gbele ọlọjọ gbọọrọ mii, ti arun Coronavirus ba peleke si ni Naijiria.
Nítorí pé wọn kì í sọ̀rọ̀ alaafia sí àwọn tí wọn ń lọ jẹ́ẹ́jẹ́ wọnàfi kí wọ́n máa pète oríṣìíríṣìí ẹ̀tàn.
"Fún ìdí èyí gbogbo ǹkan tó bá mú ààrùn Coronavirus jáde sínú afẹ́fẹ́ láti inú ẹ̀dọ̀ fóóró yóò pọ̀ gidigidi, bótilẹ̀ jẹ́ pé kíkó ààrùn yìí nínú afẹ́fẹ́ kò tíì fìdí múlẹ̀ dáadáa síbẹ̀ ìtànkálẹ̀ ààrùn yàtọ̀ sí láti inú ilé máa n wáyé latari àwọn ti kò fàmì hàn.
Bí ìwọ bá nà mí ní pàṣán, èmi náà á nà ọ́ ní pàṣán; bí ìwọ bá gbá mi lójú, èmi náà á gbá ọ létí; bí ìwọ bá ṣo mí ní òkúta, èmi náà á sọ ọ́ ní ìdàrọ́, èmi Olówó-ayé, ènìyàn tí ó ju ènìyàn, ọdẹ tí ó jẹ́ olórí ọdẹ.
Ninu iwe abẹnu ọfiisi ijọba eyi ti akọwe agba gomina fọwọ si fihan pe ki kọmiṣọna fun ọrọ akanṣe iṣẹ, Oloye Bayo Lawal, kuro nibẹ lọ si ileeṣẹ to n ri si ọrọ ijọba ibilẹ ati oye jijẹ gẹgẹ bii kọmiṣọna nibẹ nigba ti ẹni to wa nibẹ naa lọ si ileeṣẹ to n ri si akanṣe iṣẹ.
Àwọn olórí alufaa àwọn Juu sọ fún Pilatu pé, “Má ṣe kọ ọ́ pé ‘Ọba àwọn Juu,’ ṣugbọn kọ ọ́ báyìí: ‘Ó ní: èmi ni ọba àwọn Juu.
Otedola Bridge: Àwọn ẹ̀ṣọ́ ojú pópó ti gbé Ọkọ̀ agbépo tó dànù kúrò lọ̀ná
Aarẹ ẹgbẹ awọn dokita lorilẹede Naijiria(NMA), Dokita Francis Faduyile sọ pe oṣeeṣe kawọn agboku atawọn to wa leti iboji lasiko isinku olori awọn oṣiṣẹ Aarẹ Muhammadu Buhari, Abba Kyari ko aarun coronavirus lati bẹ.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Àwọn obìnrin tí kò lọ́kọ ń kojú ìsòro ilé gbígbà Mo ti fọ́ bàbá mi, Ọ̀gá Bello létí rí - Fẹmi Adebayọ̀ Òbí tó n fa sìgá n fi ọmọ rẹ̀ sínú ìdè àìsàn l'ọ́jọ́ iwájú Èèwọ̀!
Nàìjíríà ni orílẹ̀-èdè kẹta tí ìkọlù ìgbésùnmọ̀mí pọ̀ sí jùlọ láàgbáyé
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ọwọ́ ọlọ́pàá tẹ ọmọ Britain tó ń ta kẹ́míkà gẹ́gẹ́ bi omi ìyanu Mohammed Adamu ti di Ọ̀gá ọlọ́pàá Nàìjíríà tuntun Fayemi ṣetán láti ṣáájú àwọn gomina láti mójútó ètò ààbò Ileeṣẹ ayelujara naa fẹ bẹrẹ si nii gbe owo ori ayelujara tirẹ, eyi to pe orukọ rẹ ni Global Coin yẹwo ni opin ọdun yii.
Nítorí náà, èmi OLUWA Ọlọrun Israẹli ni mo sọ pé, mo ti ṣèlérí tẹ́lẹ̀ pé, ìdílé rẹ ati ìdílé baba rẹ ni yóo máa jẹ́ alufaa mi títí lae.
Owó Abacha sì kú, kò tíì tán, $319m kan sì wà ní UK àti France - Amẹ́ríkà Oríṣun àwòrán, @MaziAsochukwu Ijọba ilẹ̀ Amẹ́ríkà tún ti sísọ lójú rẹ pé, owó tó to okoolelọọdunrun ó dín kan dọla ($319m), owó tí Abacha jí kò pamọ sì ìlú ọba, UK àti Faranse sì tún wà nilẹ.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Ọjọ́ Kẹsàn àn, Osu Kẹta ní mínísítà fún ètò ìwòsàn lórilẹ̀èdè Naijiria, Osagie Ehanire kéde ẹnikejì tó ní Coronavirus naa.
Jeroboamu ati gbogbo àwọn eniyan náà bá pada wá sọ́dọ̀ Rehoboamu ní ọjọ́ kẹta, gẹ́gẹ́ bí ó ti pàṣẹ fún wọn.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'A rí wàhálà táwọn èèyàn ń kojú nilẹ̀ẹ̀ Yorùbá la ṣe fi Amotekun"" fi ọkàn wọn balẹ̀' Wayi o, Kọmisana feto ilera nipinlẹ Ondo, Dokita Wahab Adegbenro ti wa fi ọwọ idaniloju sọya fawọn dokita naa pe, wọn yoo maa ri alaati gba lati ile ifowopamọ wọn pe owo osu ti wọ apo asunwọn owo wọn."
Nígbà tí ó sọ pé, “Lẹ́ẹ̀kan sí i,” ó dájú pé nígbà tí ó mi àwọn nǹkan tí a dá wọnyi, ó ṣetán láti mú wọn kúrò patapata, kí ó lè ku àwọn ohun tí a kò mì.
Oríṣun àwòrán, Bukola Saraki/Facebook Àkọlé àwòrán, Bukola Saraki ṣe gómìnà ìpinlẹ̀ Kwara fún ọdún mẹ́jọ Lawal lo wa lori oye gẹgẹ bi gomina ipinlẹ Kwara nigba naa, pẹlu atilẹyin oloogbe Oloye Olusola Saraki to jẹ baba-isalẹ rẹ.
Má kọ̀wé fipò sílẹ̀, àwọn àgbààgbà Yorùbá sọ fún Osinbajo Àwọn Agbẹjọ́rò Makinde àti Adelabu sọ́rọ́ nípa ìdájọ́ òní Ọjọbọ ọsẹ to lọ ni ọga ile iṣẹ aṣọbode, Hameed Ali kede igbesẹ ijọba to fi ofin de gbigbe epo lọ si awọn agbegbe ti ko ju ogun kilomita lọ si ibode Naijiria si awọn orilẹede mii.
Ẹ yé gba owó orí níbi ìdána ìyàwó mọ́, sísọmọbìnrin s'óko ẹrú ni- Daddy Freeze A kò fòfin de owó naira tó ti pẹ́ ní Naijiria -CBN Ẹmi marun sọnu ninu ija Kaduna Akẹkọ kan ku,ileẹkọ jona ninu ija akẹkọ fasiti Modibbo Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Chelsea vs Crystal Palace: Chelsea bínú gbẹ̀san ìyà Tottenham lára Crystal Palace
 Mo dupe pupo fun ife ti e ni si mi ati atileyin yin ti
Eniyan lè farada àìsàn,ṣugbọn ta ló lè farada ìrẹ̀wẹ̀sì ọkàn?
Ọjọ́ ìsọmọlórúkọ ni a ó tó gbé ọmọ náà jáde láti inu ìyàrá bí ó bá jẹ́ ọ̀kan.
Nígbà tí àwọn ọba tí wọ́n wà lẹ́yìn Hadadeseri rí i pé, àwọn ọmọ Israẹli ti ṣẹgun àwọn, wọ́n bá Israẹli làjà, wọ́n sì ń sìn wọ́n.
Awon agbofinro orile-ede Turkey ti mu awon afurasi mejila lara awon omo ogun olote Islaamu ni Ankara laaro kutu ojo Aje satimole lori iwadii ogun Jihad leyin ti won kede pe won yoo ti ile ise Embasi ile America pa fun eto aabo.
"Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ìṣẹ̀lẹ̀ Kàyéèfì: Ìpáǹle tú Abass Owonikoko sí ìhòòhò ayé, kó tó gba kéú lọ́gbà ẹ̀wọ̀n O ni isoro naa ko fi bẹẹ niṣe ""pẹlu awọn eniyan orile-ede yii, bikose awọn ọtọkulu rẹ"" ""Mi o lero pe awọn ti wọn ni awọn n ja fun ẹya Hausa, Igbo tabi Yoruba ni ifẹ awọn eniyan naa lọkan."
Sc, ati iwe ẹri imọ ijinlẹ
O sọ ninu atẹjade to fi sita pe gbogbo awọn ọmọ igbimọ alaṣẹ ipinlẹ Kano lo fẹnuko pe ki wọn o yọ Emir Sanusi l'oye.
"Nitori naa, nnkan mba awọn obinrin finra labẹ asọ sugbọn wọn nbu ẹrin kẹẹ soju bii pe ko si nkankan ni""."
Amisabadi ọmọ rẹ̀ ni ó ń ṣe àkóso ìpín rẹ̀.
Wọ́n sì fi àwọn olùṣọ́ sibẹ pẹlu.
Ezekwesili sọ pe, Omotola lẹtọ lati sọrọ lori ohun ti ko ba tẹ lọrun gẹgẹ ọmọ Naijiria, bẹẹ lo rọ awọn ti wọn n sọrọ kobakungbe sii lati sọrọ ti wọn naa.
Aarẹ ọmọ ẹgbẹ ilu Ibadan Oloye Adeyemi Soladoye fidi ọrọ yi mulẹ fun ileesẹ BBC Yoruba, to si sọ pe nilu Eko ni agba ọjẹ yi ku si.
Ṣugbọn ẹ tún yí ọ̀rọ̀ pada, ẹ ba orúkọ mi jẹ́ nípa pé olukuluku yín, ẹ tún mú ẹrukunrin ati ẹrubinrin tí ẹ dá sílẹ̀ gẹ́gẹ́ bí ìfẹ́ ọkàn yín, ẹ sì tún sọ wọ́n di ẹrú pada.
Ninu ọrọ rẹ, Ọba naa ni wi pe ‘awọn oun to n fa ẹlẹyamẹya ni ilẹ yii ni ọrọ sabuke ibi to ti wa(State of Origin Certificate ), ati ai le dije dupo ni ibi to ba ti wu o’.
Ẹni to bori: Nigeria Cameroon vs Tunisia.
Wọn yóo wé lawani tí a fi aṣọ funfun rán, wọn yóo sì wọ ṣòkòtò aṣọ funfun.
Ọrọ airounjẹ jẹ ati ebi ti isede naa ti fa ni ọpọlọpọ awọn to sọrọ fi sita, pe o yẹ ki ijọba o pese nkan amayedẹrun fun araalu ki ebi o ma ba pa wọn saaju coronavirus.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Say no to rape: Àwọn òṣèré tíátà Yorùbá pariwo síta lórí wàhálà ìfipábánilòpọ̀ D'banj fi iwe owo itanran da Seyitan l'ohun Ọsẹ kan lẹyin ti ẹsun naa jade ni D'banj to o f'esi lẹyin ayẹyẹ ọjọ ibi ogoji ọdun to ṣe lọjọ kẹẹdogun, oṣu Kẹfa, ọdun 2020.
Baba Sala tun gba Ami Ẹyẹ lati ọw Ile-isẹ Amohunmaworan ati Ile isẹ Iwe Iroyin Concord Press of Naijiria ni ọdun 1986.
Wọn fun Oluwatobi ni ọna abayọ meji: ikinni ni pe ko fi ọwọ si iwe pe ki wọn o yọ oyun inu rẹ, ki wọn le ṣe iṣẹ abẹ fun ẹsẹ.
Wọ́n ń pète ibi sí i ní Heṣiboni,wọ́n ní, ‘Ẹ jẹ́ kí á lọ pa á run, kí ó má jẹ́ orílẹ̀-èdè mọ́!
Ni ọsẹ to gbẹyin oṣu Kẹta, irinajo ọkọ ofurufu dinku si ìdá mẹtalelọgọ́ta nitori pe awọn orilẹ-ede kan tun fi ofin de irinajo oju ofurufu.
Ṣugbọn sọ gbolohun kan, ara ọmọ-ọ̀dọ̀ mi yóo sì dá.
Onisegun oyinbo to je akosemose fun itoju, Dokita Taoheed Abdullahi ti kilo fawon eniyan Naijiria lati sora fun lilo oogun abalaye fun itoju oju ki oju ohun ma lo fo tan patapata.
Àwọn aposteli sọ fún Oluwa pé, “Bù sí igbagbọ wa!
Sẹnetọ Tayọ Alaṣọ Adura- Minisita abẹle fun ọrọ oṣiṣẹ ati igbanisiṣẹ Rauf Arẹgbẹṣọla -Minisita fun ọrọ abẹle Sunday Dare - Minisita fun ọrọ ọdọ ati ere idaraya.
Ohun to kọ iwaju si ẹnikan, ẹyin lo kọ si ẹlomii, bi ilu gangan ni ọrọ awọn Fulani darandaran ati ijinigbe yii n bi nibi apero to n lọ ọhun.
Ọọni, Aláàfin, Ojisẹ Ọlọ́run àti oniṣẹ ìwádìí fi Ògún gbari pé òògùn ìbílẹ̀ le wo Covid-19 Lóòtọ́ lò n lo ìbomú-bẹnu, ṣùgbọ́n ṣe bóṣeyẹ kí o wọ̀ ọ́ ló ṣe n ṣe?
Ó ní ó dé filà sán-ányán, ó wọ́ bàtà aláwọ̀ funfun ràkọ̀ràkọ̀ Bándélé ni ó bomi fún Fáwọlé ní ọjọ́ tí ó wá sí ọ̀dọ̀ Orímóògùnjẹ́.
Gomina fi sita loju opo Twitter rẹ lowurọ Ọjọbọ.
Ṣaaju akoko naa, gomina ọhun ti kopa ninu ọpọ ayẹyẹ nibi to ti ṣalabapade ọpọ ero.
Kí ló ń mú àwọn adarí obìnrin lágbáyé rọwọ mú nípa kíkojú covid 19?
lẹta ti Ọbasanjọ kọ lati tabuku si isejọba aare Buhari.
Ẹ máa yọ̀ ninu Oluwa nígbà gbogbo.
Ko ju iṣẹju kan lẹyin igba ti Suarez gba bọọlu wole lati ọna jinjin ti Lionel Messi na gbe iṣe rẹ de.
Oríṣun àwòrán, Fatima Muhammad Itumọ Mpape ni Apata ni ede Gwari, ibudo yii si ni wọn ti ri ọpọ okuta girafu ti wọn lo fi sọ ilu Abuja di ilu nla ni saa ọdun 1980.
Kenya Prisioners: Àwọn ẹlẹ́wọ̀n mórí lé ilé-ẹjọ́ kòtẹ́milọ́rùn fún ẹ̀kúnwó owó oṣù ẹlẹ́wọ̀n
11 Nítorí, kíyèsíi, èmi ni ẹnití ó sọ̀rọ̀; èmi ni ìmọ́lẹ̀ tí ó ńtàn nínú òkùnkùn, àti pé nípa agbára mi èmi fi àwọn ọ̀rọ̀ wọ̀nyìí fún ọ.
Sogidi Lake: Ṣọ́jà tó dẹ́jàá láti pa ẹja odò Sogidi pàdánù ọmọ mẹ́ta láàrín ọ̀sẹ̀ kan -Ojedele
FIFAWWC: Falcons fìdí rẹmi, sùgbòn ọmọ Nàìjíríà gbóríyìn fún wọn
gbe orile ede Naijiria siwaju; ṣagbero ọna lati  le koju awọn iṣoro ti o dojuko orile ede
        Mo yọ̀ pupọ̀ nígbà tí mo rí oníṣẹ́ rẹ nítorí ó pẹ́ tí mo ti ń ṣe àníyàn wí pé ki n tilẹ̀ mọ bí o ti rìn, àfi bí ẹnipé o dé ọkàn mi ni.
Ọlọrun olùmọ̀ràn ọkàn fún wọn ní ìwé ẹ̀rí nígbà tí ó fún wọn ní Ẹ̀mí Mímọ́ gẹ́gẹ́ bí ó ti fún wa.
Gbogbo àwọn ojúlùmọ̀ rẹ̀ ati àwọn obinrin tí wọ́n tẹ̀lé e wá láti Galili, gbogbo wọn dúró lókèèrè, wọ́n ń wo gbogbo ohun tí ó ń ṣẹlẹ̀.
Bi awọn ijọba orilẹ-ede kaakiri agbaye ti ṣe idasilẹ awọn ilana tuntun lati koju rẹ.
Charles Okah ati Obi Nwabueze gba'dajọ ẹwọn gbere
Ẹ̀gún ati ẹ̀wọ̀n agogo ni yóo hù níbẹ̀.
Orilẹede Naijiria, Brazil, Germany ati Amẹrika nikan ni orilẹede mẹrin ti ko tii figbakan ri jẹ awati nibi ọdọbinrin ti ọjọ ori wọn ko ju ogun ọdun lọ.
Elo ni owo ti awọn oṣiṣẹ labẹ N-Power yoo ma gba loṣoṣu?
Agbẹjọro Falana sọ pe ijọba ologun Buhari lo ju Dokita Beko si ọgba ẹwọn Kirikiri fun oṣu mẹfa lọdun 1984 nitori o jijagbara lati beere fun eto ilera to peye lọwọ ijọba.
Oba adeyẹmi tun kan saara si Dangote fun igbiyanju rẹ lati wa ọna jijẹ-mimu fawọn ọdọ Naijiria, eleyi to ni o jẹ ọna kan gbogi lati mu idagbasoke ba orileede Naijiria.
Naijiria gbọdọ̀ jáwọ́ nínú ìwà rádaràda kí ‘Change’ lè wáyé -Buhari Ǹ jẹ́ o mọ àwọn èèyaǹ wọ̀nyí tó jà fún òmìnira Nàìjíríà?
Méjìlá-méjìlá ni ó to àwọn ihò tiẹ̀ lákọ̀ọ́kọ́.
Adajọ Inyang Ekwo to gbe idajọ naa kalẹ ni ẹgbẹ oṣelu AA ko tẹle awọn alakalẹ ajọ eleto idibo INEC, lori fifi orukọ oludije silẹ fun eto idibo naa, ti yoo waye lọjọ kẹrindinlogun oṣu kọkanla ọdun 2019.
Àwọ̀ àlà rẹ ń wọ̀ mí lójú
Ẹ gbọ́ ohun tí Desmond Elliot sọ lórí ayélujára tó bí àwọn ọmọ Nàìjíríà nínú Àwàdà tàbí óótọ́, kì lò f'ẹkún Kọmíṣọ́nnà ìlera Kogi lórí amóhùnmáwòrán?
Lara wọn ni: Onjo ti Okeho, Onitede ti Tede, Asẹyin ti Iṣẹyin, Timi ilu Ẹdẹ nigba kan, Ọba Oyelusi Tijani Agbaran II Lọdun 1980 si 1981, Ọba ilu Kisi, Okere ilu Saki, ati Sabi ti Iganna gba igbega.
A óo ṣẹgun wọn, nítorí kò sí ààbò fún wọn mọ́.
fara pa yanana  bee si ni iroyin fi n
Libya: Ọmọ Naijiria mejilelaadoje miran pada sile
Ko pẹ ni awọn oyinbo ẹlẹsin Kristiẹni de ni eyi to fi Adesọji sile iwe alakọbẹrẹ St Phillips, Ile Ifẹ lọdun 1901 Ọmọ ti yoo jẹ asamu, kekere ni yoo ti maa jẹnu samu-samu, Adesọji korira isẹ agbẹ tawọn ẹgbọn rẹ n se nigba naa, ọna iwe si lo fẹ gbajumọ O nifẹ lati lọ kawe nipa isẹ amofin sugbọn nitori pe o ti wa lori ẹmi rẹ lati jọba, ko seese fun un Adesọji gbajumọ isẹ, o ti lowo lọwọ, to si ti di gbajumọ nigba ti Ọba Ademiluyi to wa lori itẹ Ọọni fi waja, oun si ni wọn yan bi Ọọni tuntun Adesọji si gori itẹ awọn baba nla rẹ lọjọ Keji, osu Kẹsan an, ọdun 1930 gẹgẹ bii Ọọni Kọkandinlaadọta tilu Ile Ifẹ Adesọji ni Ọọni akọkọ ti yoo jẹ ọmọwe, oun si ni Ọba alaye nilẹ Yoruba to kere julọ nigba naa, ti yoo gun ori itẹ awọn baba nla rẹ lẹni ogoji ọdu Àwọn ògo Ibadan márùn ún tí ikú mú lọ lọ́dún 2020 Mo ti lùgbàdì àrùn Coronavirus - Akeredolu figbe ta Ọba Adesoji Aderemi tun ni gomina Adulawọ akọkọ ti yoo dari agbegbe ti ilẹ Gẹẹsi n mu sin, oun si lo gba ipo lọwọ gomina John Frankline Lasiko Ọba Adesọji Aderẹmi, ni agbega nla nla ba ilu Ile Ifẹ, ọkan lara rẹ ni agbega to mu ba ba eto ẹkọ.
Arsene Wenger: Idi tawọn ololufẹ Arsenal se nfi we Mugabe
Aṣa oge ṣiṣe ni ilẹ Yoruba ni a n gbe yẹwo loni lori eto Akọmólede ati aṣa lori BBC Yoruba ti ọsẹ yii.
Gbogbo àkọ́so oniruuru èso ati oniruuru ọrẹ gbọdọ̀ jẹ́ ti àwọn alufaa.
Omar al-Bashir ko bimọ kankan Omar al-Bashir ko ni ọmọ kankan.
Fi sọkan pe, ẹnikẹni to ba fẹ ẹ fi orukọ silẹ fun iṣẹ yìí, gbọdọ jẹ ọmọ orilẹ-ede Naijiria.
Gomina Gboyega Oyetọla ati Sẹnẹtọ Ademola Adeleke ni wọn jijọ n ṣẹjọ lori ọrọ yii.
Leyin ti ile –ejo tẹẹkotọ gbo atotonu
Àwọn ilé inú rẹ̀ ti ń jóná,àwọn ọ̀pá ìdábùú ìlẹ̀kùn bodè rẹ̀ sì ti ṣẹ́.
Aare so pe oun nigbagbo pe ise ribi-ribi ti Fayemi ti se lati mu atunse to monyan lori ba  eto eko ni ipinle Ekiti ati lati mu igbesi aye iderun ba awon mekunnu,yoo ran lowo lati jawe olubori ninu eto idibo to n bo.
"Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Wo nǹkan tí yóò ṣẹlẹ̀ sí ọba tí wọ́n bá gbé ọ̀pá àṣẹ rẹ̀ lọ nílẹ̀ Yorùbá Àìsọ̀rọ̀ Buhari lórí ìṣẹ̀lẹ̀ Lekki, ìkọjú ìjà sí Yoruba ni - YWC ₦147m la rí kójọ fún ìwọ́de, a kò fẹ́ owó mọ́, ìwọ́de ti parí - Feminist Coalition Wo ìròyìn, àwòrán àti fídíò èké nípa ìwọ́de EndSARS Super Eagles, ẹ máṣe gbá bọ́ọ̀lù fún Nàìjíríà mọ́ nítorí ìhà tí ìjọba kọ sí ìwọ́de EndSARS - John Ogu Ará Eko, ẹ pariwo ó tó gẹ́ẹ́ lórí làásìgbò tó gbòde torí ìwọ́de EndSARS - Sanwo-Olu Ọ̀tá Yorùbá ló lo ìwọ́de láti dojú ogun kọ wá - OPC ""Àwọn ọ̀tá Nàíjíríà tó fẹ́ dojú ìjọba bolẹ̀ ló wà lẹ́yìn ìwọ́de EndSARS"" Ó parí ni ohùn tó gbẹnu ọ̀pọ̀ ọmọ Nàíjíríà lẹ́yìn ọ̀rọ̀ Buhari Olajide sọ pe ""lakọkọ, o yẹ ko kọkọ ba awọn ẹbi awọn to padanu ẹmi wọn ni Lekki kẹdun, ko si gbadura pe iru rẹ ko ni waye mọ."
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù ISWAP vs Muric: À kò ni ìbáṣepọ̀ kankan pẹ̀lú àwón agbésùmọ̀mí- Ishaq Akintola 5 Èrèlè 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 11 Ògún 2020 Oríṣun àwòrán, Muric Ọ̀kan nínú ẹgbẹ́ àwọn Sahara Strategy Group (SSG) ti rọ ìjọba àpapọ láti wádìí àbájáde ẹgbẹ́ Muslim Rights Concern (MURIC) Wọ́n ní eyí ṣe pàtàkì nítori wọ́n gbá ẹgbẹrun lọ́nà igba dọ́lá lọ́wọ́ àwọn ọmọ ẹgbẹ́ agbésùmọ̀mí Islamic State For West Africa Province (ISWAP).
Ọwọ tẹ awọn ọkunrin mẹrin naa ti wọn jẹ agbẹboji ni ile isinku to jẹ ti ijọba ibilẹ Guusu Akure ni ọsu karun un ọdun 2020.
Wo ìdí tí Osun fi kede ìsinmi fún ọdún ìṣẹ̀ṣe, tàwọn ìpínlẹ̀ yókù kò dáhùn, Ṣugbọn o, ọpọ eeyan ni ko mọ wi pe awọn larubawa ti n ṣe amulo ọdun oloṣu mejila naa, ṣaaju ki Anọbi Muhammad (SAW) to daye.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Itan Ilu gangan Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Nítorínáà, mo yára sáré lọ sí ilé-ìtajà Apple kan tí nbẹ láàrin ìlú.
Wọn ni niwọn igba to se pe Alaafin kọ lo dẹnu kọ awọn obinrin naa, bawo ni awọn ẹlẹ Daddy se n de inu aafin lati di olori?
" Kíni Gómìnà ìpínlẹ̀ Ekiti, Kayode Fayemi ṣe fun baba tó ni ọmọ òun ko gbọdọ tèlé oun déle?
O ni oun ranti pe, oun maa n ri Arabinrin Jallow nile ijọba, ni awọn 'aago ti ko bojumu nigba mii.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Fulani herdsmen: Mo ti Buhari lẹ́yìn ṣùgbọ́n ìjínigbé ìgbà gbogbo yìí náà ń kọmí lóminú 22 Agẹmo 2019 Oríṣun àwòrán, Alaafin Oba Adeyemi III Àkọlé àwòrán, Alaafin ni oun to dunni ju ni pe bi gbogbo eyi ṣe n ṣẹlẹ bọọ lawọn agbofinro n wo Kii ṣe tuntun mọ pe aarẹ Muhammadu Buhari ri lẹta kan gba laipẹ yii lati tete wa wọrọkọ fi ṣada lori bi nnkan ṣe n lọ lorilẹede Naijiria.
yala fun awon to wa fun eto igbafẹ, awon onisowo tabi eni to ba wu ko jẹ lorile
àgọ́ àjọ, ati àwọn ìbòrí rẹ, àwọn ìkọ́ rẹ̀ ati àwọn àkànpọ̀ igi rẹ̀, àwọn ọ̀pá rẹ̀, àwọn òpó rẹ̀, ati àwọn ìtẹ́lẹ̀ wọn.
A bí Adedibu ni ọjọ́ kẹrinlélógún, oṣù kẹwàá ọdun 1927 ni Oja -Oba Ibadan, ó jẹ́ ọkan lára to wá láti ilé tó ń joyè Olupoyi, tí a si le tọ ìràn rẹ̀ si Iba Oluyole.
OLUWA níí fún ni ní nǹkan, OLUWA náà ní í sì í gbà á pada, ìyìn ni fún orúkọ OLUWA.
Awọn ipinlẹ naa ni Pennsylvania, Arizona, Texas, Florida, Georgia ati Winsconsin.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ajimobi Vs Seyi Makinde: Amòfin ní tí Ajimobi bá jẹ́ mẹ̀kúnnù, ṣé Makinde yóò gbà kí wọ́n sín sí GRA?
Oun ati awọn obi rẹ dagbere lai mọ pe ọtọ ni ibi ti o n lọ gẹgẹ bi ọrẹkunri rẹ ṣe ti sọ fun un pe ko wa ba oun ni ilu Ikoyi Ile.
Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Omotara: Mo kábámọ̀ ìwà tí mo hù sí ọmọ alágbe, mo wá a títí ṣùgbọ́n mi ò mọ ibi tó wà26 Bélú 2020 Hisbah Kano fi òfin de lílo èdè 'Black Friday', àwọn ọmọ Naijiria kan yarí lórí ayélujára29 Bélú 2020 Yoruba Taboo: Èèwọ̀ ni fún ọba láti gbé Bibeli tabi Kurani dání dípò ifá- Elebuibon, Agẹṣin Àdìmúlà29 Bélú 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
ayẹwo orukọ ki idibo to bẹrẹ.
D Beetle, Fúnwọntán 1&2 ọ̀rọ̀ láti orí ìtẹ́ mímọ 1&2, Versatility, Aiyetoro, Controversy, Supremacy, ijinlẹ àti Laisi Abesupinlẹ Buhari fi ọ̀kadà, ọkọ̀ àti $500,000 ta orílẹ̀èdè Guinea Bissau l'ọ́rẹ Game of Thrones tàbí Ìrèké Oníbùdó, èwo lẹ dìbò fún?
Florence Okpe to jẹ alukoro fun ileeṣẹ ẹshọ oju popo nipinlẹ Ogun sọ fawọn onimọto pe ki wọn farabalẹ pe awọn ẹshọ oju popo yoo giyanju lati gbe ọkọ naa kuro loju ọna.
    ‘Bá mí kí àwọn Òmùgọ̀ ti ń bẹ nínú ilé Òmọ̀parapọ̀ wọ̀n-ọn-nì.
 loni indonesia je orile-ede olominira aare oniparapo to ni awon igberiko meta le logbon .
Rabiu ti ko ri adirẹẹsi ile to n gbe fi silẹ nitori o ni ibi ti ilẹ ba ṣu si naa ni ile bẹbẹ pe ki adajó foju aanu wo oun.
Ojogbon Abiodun Bashua to jẹ oṣiṣẹ fẹyinti aṣoju Naijiria ni Sudan ati ọjọgbọn Pius Adesanmi to jẹ olukọ agba lori aṣa ilẹ Adulawọ ni fasiti ni Canada.
Agbẹnusọ fun ajọ JAMB to ba BBC sọrọ, sọ pe àṣẹ tuntun naa waye lati le fun gbogbo akẹkọọ, to fi mọ awọn to fẹ ẹ lo esi idanwo WAEC tabi NECO ti wọn ko ti i gbà, ni anfaani lati ṣe idanwo Post-UTME, ti awọn ileewe giga ma n ṣe lẹyin idanwo Jamb.
Mo gbẹ́ adágún omi láti máa bomirin àwọn igi tí mo gbìn.
Awọn ara ilu ti wi nkan oriṣii si awọn minsta yii lataari ihuwasi, ọrọ ẹnu wọn ati ohun to ṣẹlẹ ni ile iṣẹ ijọba apapọ ti wọn n mojuto.
Ọwọ́ ọlọ́pàá tẹ afurasí ọkùnrin tó gé akẹ́kọ̀ọ́ ọ̀rẹ́bìnrin rẹ̀ wẹ́lẹ́ wẹ́lẹ́ fún òògùn owó ní Ikorodu Wo àwọn báńkì tó wà lẹ́yìn àwọn olówó èlé bí MMM Ọlọ́jọ́ Festival 2020:Ọ̀ọ̀ni ti Ilé Ifẹ̀ tí wọ ìléèdí ọlọjọ méje tí kò ní rí ẹnikẹ́ni sójú Ọwọ́ ọlọ́pàá tẹ afurasí ọkùnrin tó gé akẹ́kọ̀ọ́ ọ̀rẹ́bìnrin rẹ̀ wẹ́lẹ́ wẹ́lẹ́ fún òògùn owó ní Ikorodu JOHESU ni awọn gbegile iyanṣẹlodi naa bi o tilẹ jẹpe ijọba apapọ ko i tii dahun si ibeere wọn.
Ninu atẹjade kan to fisita, Soyinka sọ pe Balarabe kuna pẹlu ọrọ to sọ nipa Amọtẹkun, eyi to ni o lee se okunfa iyapa ni orilẹede Naijiria ati agbekalẹ orilẹede Oduduwa.
Wọn kò gbọdọ̀ fi ohunkohun tí ń mú kí ooru mú eniyan di ara wọn ní àmùrè.
Kíní ó yẹ ki ìjọba ṣe dípò ìpàdé yìí Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fọ́nrán ohùn, Àwa ò le jọ jókòó pọ̀ ṣèpàdé pèlú ẹgbẹ́ àwọn darandaran Nínú ọ̀rọ̀ rẹ agbẹnusọ fún ẹgbẹ́ Afẹnifẹre, Yinka Odumakin nínú ọ̀rọ̀ rẹ̀ sàlàyé pé àrífin àti àìkanikún ní irú ìpàdé bẹẹ.
Tó bá di ìgbà náà, OLUWA yóo mú ìbẹ̀rùbojo bá wọn tóbẹ́ẹ̀ tí wọn yóo fi máa pa ara wọn; 
O ni aifi owo to jọju sẹka eto ẹkọ latọdọ ijọba apapọ atawọn ijọba ipinlẹ lo fa eyi.
Oríṣun àwòrán, Samuel Ladoke Akintola Ẹ ko loye lori ohun to n lọ, nitori ẹ kii se ara rẹ."
Èmi ò r'óhun tó burú kí obìnrin opó fẹ́ ọkọ míì sínú ilé ọkọ rẹ̀ Ará ìlú fárígá, wọ́n wọ́ alàkóso ìlú nilẹ́ pẹ̀lú ọkọ̀ UNILAG ní kí olùkọ́ míì, Samuel Oladipo to ń bèèrè ìbálòpọ̀ lọ́wọ́ akẹ́kọ̀ọ́ lọ fìdí mọ́lé Nàìjíríà kò nílò sénétọ̀ kankan- Fayemi Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, CS Mum: Omotolani Ekene ní ọ̀pọ̀ èèyàn gbà pé ọ̀lẹ, arugún, aláìlera ni ẹni tó fi abẹ bímọ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Kini Yoru[bá ń pe Necklace?
O fẹran lati maa kọrin, ko maa jade, ko si maa gbadun ara rẹ.
O wọọ nibi ajọdun fiimu agbaye to waye ni Vernice ni orilẹ-ede Italy.
Amọ ṣa, awọn adajọ ile ẹjọ to gaju naa damọran pe awọn ile ẹjọ to n gbọ awọn ẹsun naa lati maa fi arabalẹ wo o boya lootọ ni ọkunrin fẹ fi obinrin to ba lopọ ṣ'aya tabi boya o ni erongba miran lati ibẹrẹ irinajo 'ifẹ' wọn, ṣugbọn to ṣe adehun eke ko le ba a ri ifẹkufẹ rẹ tẹlọrun.
Ti o ba ni iba, ikọ, tabi idiwọ si bi o sẹ n mi, tọ ileewosan lọ, nitori eyi le jẹ pe aarun ti kọlu ẹdọfooro rẹ, tabi aisan miran to tun le.
" Arakunrin Daud wa dupẹ lọwọ gbogbo ọmọ orilẹede Naijiria pẹluu adura wi pe a o ni fi iruẹ gbaa""."
olote,  to gbode kan lorile-ede Naijiria
Bí Baraki ti ń wá Sisera kiri, Jaeli lọ pàdé rẹ̀, ó wí fún un pé, “Máa bọ̀ níhìn-ín, n óo sì fi ẹni tí ò ń wá hàn ọ́.
Bruce ni ọ̀rẹ́ wọléwọde ni òun àti Kasamu kó tó jẹ́ Ọlọrun nípè.
Àwọn fèrèsé rẹ̀, ati ìloro rẹ̀ ati àwọn àwòrán ọ̀pẹ ara rẹ̀ rí bíi àwọn ti ẹnu ọ̀nà tí ó kọjú sí ìlà oòrùn.
Nígbà tí Hesekaya ọba gbọ́, ó fa aṣọ rẹ̀ ya, ó fi aṣọ ọ̀fọ̀ bora, ó bá lọ sinu ilé OLUWA.
Tógò àti apá kan ní Gúúsù ilẹ̀ Amẹ́ríkà bí i Cuba, Brasil, Haiti, àti Trinidad.
Mohammed ati Nasreem se igbeyawo nilu London lọdun 1998 niwaju Imaamu ati awọn ẹlẹri aadọjọ, ti ọba oke si fi ọmọ mẹrin si aarin wọn.
Máàkì tí wọ́n maa n ló láti fi gba àwọn tó fẹ́ kẹ́kọ̀ọ́ gboyè nínú àwọn iṣẹ́ bi i ìṣègùn òyìbó maa n pọ́, ṣùgbọ́n ti àwọn tó fẹ́ kọ̀ iṣẹ́ olùkọ́ maa n kéré.
Ọmọbìnrin náà ní àwọn ara àdúgbò naa gbe sórí ẹ̀rọ ayélujára pé àwọ̀n ri ninu àgbàrá òjò.
Wọn ni oṣu mẹfa pere ni maa fi ṣe owo aṣẹwo.
N óo gbadura, OLUWA yóo sì jẹ́ kí ààrá sán, kí òjò sì rọ̀.
Àwọn ẹ̀mí èṣù náà bẹ̀ ẹ́ pé kí ó rán wọn sí ààrin ẹlẹ́dẹ̀ náà, kí wọ́n lè wọ inú wọn.
Randy tun fikun ọrọ rẹ pe ajakalẹ aarun coronavirus naa jẹ ọkan gboogi lara idi ti ẹbi fi pinnu lati sin ogbontarigi olorin to lọ si ilẹ Amerika.
Eyi to mu ki orin kikọ rọ Ayinla Ọmọwura lọrun.
Aare Buhari loruko ijoba ati gbogbo awon omo orile-ede Naijiria ba ebi, ijoba ati gbogbo omo orile-ede  South Afirika oloogbe na kedun iku oloogbe naa.
Ẹgbẹ́ Agbẹjọ́rò NBA ti kéde pé àwọn yóò ṣojú awọn Olùwọ́de #EndSARS lọ́fẹ̀ẹ́ nílé ẹjọ́ Àwọn ìṣẹ̀lẹ̀ mánigbàgbé tó wáyé nibi ìwọ́de ENDSARS Nàìjíríà Ìjàmbá ọkọ̀ akérò àti tírélà pa èèyàn mẹ́rin lọ́nà mọ́rosẹ̀ Ore sí Benin Wo àwọn ojúṣe àti èèwọ̀ fún ikọ̀ ọlọ́pàá SWAT tó gba iṣẹ́ lọ́wọ́ SARS Ọlọ́pàá mẹ́sàn án tó farapa nínú ìjàmbá ọkọ̀ Akure t'éèyàn méjì ti kú sì wà nílé ìwòsàn Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ìya Emma oní POS ṣẹ̀ṣẹ̀ rékọjá lọ síbí ilé yẹn ni àtọmọdé, ó sì wó pa wọ́n - Láńlọọ̀dù Obalende Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí EndSWAT: Wo àwọn Májẹ̀kóbàjẹ́ tó wà nídìí ìwọ́de #EndSARS / End SWAT16 Ọ̀wàrà 2020 Fídíò, Soyinka Cancer: Àṣe ara mi ni iso ti n run gbogbo bí mo ṣe n ṣèrànwọ́ lórí jẹjẹrẹ27 Bélú 2019 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Ogagun agba Elias Mawela to jẹ kọmiṣọna ọlọpaa fun ẹkun yii sọ pe awọn ti n da ohun gbogbo pada si ipo.
Tinubu fi ẹsun kan Obasanjọ pe ka ni o ti ṣe ipilẹ to dara silẹ fun iṣelu awa-ara-wa lasiko to n ṣe aarẹ ni, gbogbo wahala oṣelu yii ko ni si nibẹ.
Atẹjade naa fi kun un pekawọn agunbanirọ o lọ bẹrẹ isinruulu wọn lawọn ibudo ti wọn pin wọn si ati pe nigba ti nnkan ba ṣẹnuure, wọn yoo pe wọn pada.
Ninu ọrọ to ba BBC Yoruba sọ, Akọwe Iroyin Agba fun gomina ipinlẹ Ekiti, Yinka Oyebode, sọ pe gbogbo àwọn lọba lọba ni ijọba ń ba ṣe ijiroro.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Iyabo Ojo: Ìjà òṣèré tíàtà nìkan kọ́ nìkọlù South Africa, ti gbogbo wa ni 5 Owewe 2019 Oríṣun àwòrán, Instagram/iyaboojofespris Yoruba ni itẹlẹ idi ẹni kii ri ni ti, asọ to ba si kangun si eegun ni wọn n pe ni Jẹpẹ, ko si si ẹni to lee sọrọ nipa awọn osere tiata, bi kii ba se ẹni to jẹ ara wọn.
Ó tún fúun wa ní ìgò omi kan ó sì wí fún wa pé bí a bá ri ìṣòro kan lójú ọ̀nà, omi náà yóò jẹ́ ìrànlọ́wọ́ fún wa.
"Àwọn ọmọ iléèwé máa ń pe àwọn ọmọ mi lólójú àjẹ́ toríi ""Blue Eyes"" Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí 3 sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 2:23 Fídíò, Water Generator: Ó leè ṣiṣẹ fún wákàtí mẹfà, kó tó sinmi, Duration 2,2310 Òkùdu 2020 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn."
O tesiwaju pe awon ko tun ni pẹ kede ojo ti aaare yoo wa si ipinle na.
O ni oun mọ pe kii ṣe gbogbo obinrin lo le wọ nkan to ba wu wọn lọjọ igbeyawo wọn ni India, Ṣugbọn ni kete ti oun sọ ero oun lori Instagram, ọpọ awọn obinrin iran lo fohun pé nkan to sọ ti fun awọn nigboya lati dide si awọn iya ọkọ ti o maan la le awọn lọwọ.
Ogunlogo awon ajafetomoniyan ,awon onile- ise lori ero alatagba ati awon ti won n se amulo ero alatagba fesun kan ijoba orile-ede naa wi pe ofin yi tako eto omo eniyan.
Bákan náà ni ọkọ mẹ́ta jóna nínú ìṣẹ̀lẹ̀ náà Lagos gas explosion: Iná míì tún ti ṣẹ́yọ ní agbègbè Ipaja lówùrọ òní!
Nítorí pé ó tẹ́tí sí mi,nítorí náà, n óo máa ké pè éníwọ̀n ìgbà tí mo bá wà láàyè.
Lọdun 1998 ni wọn mu Kashamu ni ilu Oba ni United Kingdom lori ẹsun to nii ṣe pẹlu egbogi oloro ati owo to to $230, 000 to fẹ ko wọ ilu lọna aitọ, ki wọn to tuu silẹ lọdun 2003.
OLUWA bukun ìgbẹ̀yìn Jobu ju ti iṣaaju rẹ̀ lọ, ó ní ẹgbaaje (14,000) aguntan, ẹgbaata (6,000) ràkúnmí, ẹgbẹrun (1,000) àjàgà mààlúù ati ẹgbẹrun (1,000) abo kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́.
Àwọn ìṣòro àtijọ́ yóo ti di ohun ìgbàgbé,a óo sì ti fi wọ́n pamọ́ kúrò níwájú mi.
IRCC tun ti bẹrẹ iṣe lori fọọmu awọn akẹkọ to fẹ lọ kawe ni Canada, iwe fun awọn to ti ri iṣe nilẹ naa ati iwe awọn to fi orukọ silẹ lati di ọmọ onilu.
Ati Ọọni Ilẹ Ifẹ, ati Aarẹ Ọna kakanfo, awọn mejeeji wa ki Alagba Rueben Faṣọranti ku atẹmọra ti ọmọ rẹ to jade laye.
Arun naa ko yọ orilẹ-ede Naijiria silẹ ni bo ṣe n gbẹmi awọn eeyan lojojumọ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù FIFAWWCUP: Wo ohun mẹ́rin tó jẹ́ ki America tún gbá ife ẹ̀yẹ àgbáyé 8 Agẹmo 2019 Oríṣun àwòrán, others Àkọlé àwòrán, Ta ni ẹlẹ́sẹ̀ ayò Megan Rapinoe tó gba ife ẹyẹ àgbáyé tàwọn obìnrin?
"Oyedepo ni ""ni iwoye temi eyi ni ohun to buru juls ti yoo ṣẹlẹ si orilẹede Naijiria, iyẹn ijọba yii."
Oríṣun àwòrán, Getty Images Ajọ to n ṣoju awọn eekan liigi ere bọọlu nilẹ Yuroopu sọ pe nigba yoowu ti wọn ba bẹrẹ si ni gba idije liigi kọọkan pada, wọn yoo maa se ilẹkun papa iṣire ni.
Oríṣun àwòrán, JustNnaemeka Igbẹ aa fẹwe, awọn ọdọ gba agbo sori, ka si to sẹju pẹ, marun ninu wọn tun ti dagbere faye latọwọ awọn sọja, ti ọpọ wọn si ti farapa.
Ẹdọforo ẹni ni aruin Coronavirus ma n kọ lu, apẹrẹ arun ọhun si ma n bẹrẹ pẹlu iba, lẹyin rẹ ni ikọ, leyi to le yọri si isọro ati mi.
Ẹranko lásán sì ni ẹṣin wọnwọn kì í ṣe àǹjọ̀nnú.
Ẹnikẹ́ni kò mọ orúkọ titun yìí àfi ẹni tí ó bá gba òkúta náà.
Sunkanmi Omobolanle: Oríṣun àwòrán, Sunkanmi omobolanle Àkọ́bí Sunday Omobolanle, taa mọ sì Aluwẹ, ni Ṣunkanmi jẹ, tó si jogún eré tíátà lọdọ bàbá rẹ̀.
Ojogbon Yemi Osinbajo fikun oro re pe“gege bi omo orile-ede yii, a ni eto lati ma a gbe igbe-aye irorun ati alafia, a si leto si itoju ti o peye,’’O wa gbadura si olorun lati yii isele buruku miran ti yoo ba tun sele lojo iwaju si rere.
’’Akowe agba naa ,wa ro awon osise ajo naa, lati maa kaare lori igbiyanju won , ki won si fi apere rere lelẹ.
"Ìjà orogún méjì ní London, Arsenal àti Tottenham ta ọ̀mì Wike kìí ṣe dọ́là tí Ganduje leè kó sápò- Agbẹ́nuso ìjọba ìpínlẹ Rivers Digbi n'ijọba Kogi wa - Yahaya Bello Laipẹ́, ọmọ tí kò bá pé ọdún méjìdínlógún kò ní leè jáde girama l’Ọṣun ""O pọ́ndandan kí a tẹti si ariwo ọja nítori pe oniruuru eso ló wà nibẹ̀ bẹ́ẹ̀ náà lo ṣe ri pé ẹka oniruuru ni o wa ninu ọja, sùgbọ́n ẹgbẹ́ oní ìgbalẹ̀ yóò sọ ara rẹ̀ dí òṣùṣù ọwọ̀ láti gbá gbogbo ìdọti àti ẹyin wá dànù èyi si ni à ó lò lati jáwe olú bori"" Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!"
Ẹ gbé oúnjẹ pàdé ẹni tí ń sá fógun, ẹ̀yin ará ilẹ̀ Tema.
Ko si si bi a se maa sọ nipa itan awọn ọmọ Oodua to jẹ akinkanju ati ọlọpọlọ pipe, ti a ko ni sọrọ Ọba alaye naa.
“Ẹ lọ bèèrè ohun tí a kọ sinu ìwé yìí lọ́wọ́ OLUWA fún èmi ati fún gbogbo eniyan Juda.
Olùkọ́ náà n bèrè fún ìbálòpọ̀ lọ́wọ́ ọ̀kan lára àwọn akẹ́kọ́bìnrin tó fìdírẹmi nínú ìmọ̀ ẹ̀kọ́ fún ìkẹ́kọ̀ọ́-gboyè ìmọ̀ ìjìnlẹ̀ kejì nínú ìṣàkóso okòòwò.
Gbogbo àfonífojì tí wọn ń da òkú ati eérú sí, ati gbogbo pápá títí dé odò Kidironi, dé ìkangun Bodè Ẹṣin, ní ìhà ìlà oòrùn, ni yóo jẹ́ ibi mímọ́ fún OLUWA.
Eni ti won yoo tun fi oye da lola tun ni a-ji-ja-fetomoniyan , oloogbe Gani Fawehinmi.
 “Awon ti oro kan naa tun fohun kan so pe o ye ki won se atunse si  igbimo alaafia lorile ede Naijiria ,ti won se ise takun-takun lasiko eto idibo to waye lọdun 2015.
A ò ní ṣe àṣetì nídǐ iṣẹ́ wa
Obinrin yìí bá lọ, ó ṣe bí Elija ti wí.
Gbogbo wọn dákẹ́, kò sí ẹnìkan tí ó sọ nǹkankan nítorí ọba ti pàṣẹ pé ẹnikẹ́ni kò gbọdọ̀ dá a lóhùn.
apapo awon elesin kristiani lorile-ede Naijiria ati lagbaye lataari pipadanu orisirisi
Ọba bi wọ́n pé, “Gẹ́gẹ́ bí òfin, kí ni kí á ṣe sí Ayaba Faṣiti, nítorí ohun tí ọba pa láṣẹ, tí ó rán àwọn ìwẹ̀fà sí i pé kí ó ṣe kò ṣe é.
Wọ́n yọ àwọn ohun ìjà ti akọ̀ròyìn Marco Ruiz, Luz Mely Rehes àti Federico Black [pẹ̀lú àwọn ọmọ ẹgbẹ́ òṣìṣẹ́ ìròyìn.
 a má a ń nílò láti fa omi jáde láti inú ọ ̀ pá-ẹ ̀ yìn láti lè mọ ìyàtọ ̀ laarin ipele èkíní àti èkejì àrùn náà .
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Hmmn.
Ẹ óo wá máa ṣe ẹlẹ́rìí mi ní Jerusalẹmu, ati ní gbogbo Judia ati ní Samaria ati títí dé òpin ilẹ̀ ayé.
Ikú tí yóò pamí, kìí ṣe tòṣì
gbeyin lara awọn ti wọn gba boolu sagbon ninu ifẹsẹwọnsẹ ohun.
- Yinka TNT Iwulo ere idaraya Kegel fun awọn obinrin Oriṣiriṣi nkan lo le mu ki aarẹ ba 'pelvis' obinrin tabi ba a jẹ.
Ti a ba mu aṣa wa, a lee ko ilẹ Afirika jọ tii a o si fun wọn ni iwuri lati fi imọ ṣọkan.
Jeroboamu lọ gba àmọ̀ràn, ó bá fi wúrà yá ère akọ mààlúù meji, ó sì wí fún àwọn eniyan rẹ̀ pé, “Ẹ̀yin ọmọ Israẹli, ó pẹ́ tí ẹ ti ń lọ rúbọ ní Jerusalẹmu.
Nibayii, ileeṣẹ ọlọpaa New South Wales ti ni awọn yoo ṣe iwadii ẹsun naa yẹwo finifini ati pe awọn yoo si gbe abajade iwadii naa sita.
Nígbàtí a gba ìdàgbàsókè yìí wọlé, ẹjọ́ọ Wa Lone àti Kyaw Soe Oo jẹ́ ẹ̀rí wípé ẹ̀mí àwọn akọ̀ròyìn tí ó ń ṣe àyẹ̀wò sí ìṣèlú wà nínú ewu ìgbẹ̀san òṣèlú.
Kò mọ̀ pé òtítọ́ ni ohun tí ó ti ọwọ́ angẹli náà ṣẹlẹ̀, ó ṣebí àlá ni.
Ìlú tí ọ̀daràn bá tí dẹ́ṣẹ̀ ló yẹ kí wọn tí gbẹjọ́ rẹ̀ -Agbẹjọ́rò Àgùnbánirọ̀ gbẹ́mìí mì látàrí 'Snipper' tó fi fọ irun rẹ̀ ''Òsìsẹ́ Custom tó déédé sọ ara rẹ̀ di Ọ̀gá Àgbà CG ní ìdàmú ọpọlọ'' Manza ni idi ree ti wọn fi yinbọn mọ ọlọpaa meji lẹsẹ, ti wọn si tun lo okuta ati ọkọ lati fi da ọgbẹ si ọlọpaa mẹfa lara, ti wọn si ti gbe wọn lọ sile iwosan.
Arsenal jẹ ẹgbẹ agbabọọlu ti wọn ko fẹyin wọn gbole lati igba pipẹ sẹyin ṣugbọn nkan ti n yipada sidakeji bayii nigba ti Southampton ti nà wọn bayii ninu idije.
” Ṣugbọn Josẹfu bọ́rí kúrò ninu ẹ̀wù rẹ̀, ó sá jáde kúrò ninu ilé.
Nitori naa ni wọn ṣe fẹ ki ijọba wadii awọn to lọwọ si iṣẹlẹ naa.
    Báyìí ni Kùmọ́dìran parí ọ̀rọ̀ rẹ̀, nígbà tí ó sọ ọ tán mo ṣàkíyesí pé inú àwọn ènìyàn mi dùn ṣùgbọ́n ẹru ti ń bà mí bí o ti ń sọ̀rọ̀ náà bọ̀ kí ìjà má ba bẹ́ sílẹ̀ nígbà tí o parí ọ̀rọ̀ rẹ̀, nítorí ọ̀rọ̀ tí ó sọ le, ṣùgbọ́n ìyàlẹ́nu ló jẹ́ fún mi pé nígbà tí Kùmọ́dìran parí ọ̀rọ̀ rẹ̀, ẹ̀rín ni ọba Òmùgọ̀di-méjì bú sí, ó rẹ́rìn-ín títí o fi yí lulẹ̀ lórí ogiri kékeré tí ó jókòó lé nígbà tí o sì dákẹ́ ẹ̀rín náà ṣe ló kọjú sí ọkùnrin tí ó dé bá wa níbẹ̀ tí ó wí fún un pé kí o mú wa lọ sí ààfin kí a lọ jókòó de òun, òun ń bọ.
Láti ibẹ̀ wọ́n pada sẹ́yìn lọ sí Pi Hahirotu tí ó wà níwájú Baali Sefoni, wọ́n pàgọ́ siwaju Migidoli.
ile-geesi (English Premier League), ti o waye lopin ose to lo ni papa
Bakan naa ni ọpọ akọle ti n wa lawọn iwe iroyin miran lawọn orilẹede miran eyi tawọn eeyan bẹrẹ si pin kiri.
Mẹrin ninu awọn ọmọ ti wọn bi lo ni ipenija ara,'' Dokita Musa lo sọ bẹẹ.
Àwọn nnkan wọ̀nyí jẹ́ ara àwọn ìṣòro tó n kojú àwùjọ-ẹ̀dá.
bv jẹ ́ àkóràn tí ó wọ ́ pọ ̀ jùlọ ní àwọn obìrin tí o tí tó ọjọ orí àtilèbímọ .
Oríṣun àwòrán, Google Ẹ wo ọ̀nà àbáyọ sí ọ̀rọ̀ àgbàlagbà tò ń tọ̀ sílé Mo mọ̀ọ́mọ̀ sin ọmọ-ọmọ mi, ìkókó jòjòló láàyè ni, nítorí wọ́n fipá bá ọmọbìnrin mi lòpọ̀ ló fi lóyún rẹ̀!
Eleyii ti o lagbara ju ninu awon eto ohun ni ‘Operation Deep Punch 2’ti a lo ni apa ariwa ila-orun, ryi ti o sokunfa isubu aginju Sambisa.
Nígbà tí mo pa gbogbo àwọn àkọ́bí ní ilẹ̀ Ijipti ni mo ya gbogbo àwọn àkọ́bí ní ilẹ̀ Israẹli sọ́tọ̀; kì báà ṣe ti eniyan tabi ti ẹranko, tèmi ni gbogbo wọn.
Àwọn ọjọ́ ìsìnmi tó máa wà nínú ọdún 2020 ní Nàìjíríà Bí ìtàn ayé Toyosi Arigbabuwo ṣe lọ rèé láti ẹnu Musiliu Dasofunjo àti Ogun Majek Àsọtẹ́lẹ̀ Fada Mbaka, tó yẹ àga mọ́ gómìnà Imo nídìí rèè Wo ipa tí Mayegun yóò ma kó ní ilẹ̀ Yoruba!
Gege bi o se so, “ohun ti a fi sun ipade yii siwaju ni, nipa eto idibo  inu egbe oselu to n lo lowo , paapaa julo ibo inu egbe fun awon oludije  kaakiri orile ede yii, ni eyi to je pe lara awon igbimo ijoba apapo yoo kopa nibe.
"Ìgbónára ló máa ń mú àwọn èèyàn ṣe ""Jungle justice"" tí ìjàmbá ọkọ̀ bá ṣẹlẹ̀- Dokita Oṣú mẹ́fà ni òṣìṣẹ́ ìjọba tó bá bímọ yóò máa lò nílé kó tó wọṣẹ́ padà- Seyi Makinde A ti gbé ìwádìí dìde lórí ìpànìyàn tó wáyé lásìkò ìwọ́de EndSARS- Ilé ẹjọ́ àgbáyé, ICC Oyinkan Abayomi, akọni obìnrin tó fi ìfẹ́ pa orúkọ ọkọ kejì dà sí ti ọkọ àárọ̀ Àlàyé rèé lóríi ìdí tí wọ́n fi ń pe aya ní ìyàwó Ijọba orileede naa lo ṣeto isinku awọn ọmọ yi ti olootu ijọba Joseph Dion Ngute si soju Aarẹ Biya níbẹ."
Mose ti ṣẹgun gbogbo wọn, ó sì ti lé wọn jáde.
Ojú ọ̀run fẹ́ lọ bí ìgbà tí eniyan bá ká ẹní.
Jibrin ni lẹyin ti wọn ji awọn ọmọ naa gbe, minisita dari ikọ awọn olori awọn ologun ati olugbaninimọran nipa abo lọ si Katsina ati Kankara.
Amọṣa iroyin to wa jẹyọ lẹyin iṣẹlẹ ti ipinlẹ Ọṣun lo ko awọn eeyan laya soke pe awọn darandaran Fulani kan ti n fi ipinlẹ naa silẹ ni ibẹru-bojo pe ki atunṣẹ ikọlu ara to ti fẹ maa di lemọlemọ lori awọn maluu o ma baa kan awọn pẹlu.
Kurunmi: Akọni Ààrẹ Ọ̀nà Kakanfo tó pàdánù ọmọ márùn-ún to bí sínú ogun Ìjàyè
Àwọn ọmọ Nàíjíríà ń bèèrè pé taa ní ààrẹ Nàíjíríà ní Aso Rock?
Kí ẹnikẹ́ni tí ó bá fara kan ibùsùn rẹ̀, fọ aṣọ rẹ̀, kí ó sì wẹ̀; yóo jẹ́ aláìmọ́ títí di ìrọ̀lẹ́.
Munagagwa ni o ti to oṣu meji ti Mugabe ti n gba itoju fun ailera ni orileede Singapore ti ko si le rin mọ latari aarẹ naa.
O ṣalaye pé ohun tó kù díẹ káàtó ni lati máa dárúkọ láì jẹ́ kí aráàlú ri àbájáde gbogbo ariwo orúkọ tí wọ́n ń fi síta.
Iwo Kingmakers: Ìjọba Osun ní òun sí ń wo ọ̀rọ̀ Oluwo àtàwọn afọbajẹ lọ́wọ́ kó tó mọ ìgbésẹ̀ tó kàn
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Woman who gave birth in Dubai: Nàìjíríà ní Suliyat Abdulkareem fẹ́ bímọ sí ṣùgbọ́n wọ́n há sí Dubai nítorí Coronavirus 30 Agẹmo 2020 Oríṣun àwòrán, @OvieSheikh/@helpsuliyatuae Ọmọ Ọba Dubai, Sheikh Hamdan bin Mohammed bin Rashid Al Maktoum ti ni oun yoo san owo itọju ọmọ Naijiria kan to bi ibẹrin si Dubai, ṣugbọn ti wọn ko ri owo ile iwosan san.
Gomina Fayose ni niwọn igbati owo ilu ba n tipasẹ awọn ibudo yii wọ apo awọn eeyan kan, ko lee si bi opin se lee de ba wahala Boko Haram lorilẹede Naijiria.
yóo mú ìpọ́njú ati ìṣòro bá gbogbo àwọn tí ó ń ṣe iṣẹ́ ibi.
Ọlọrun sọ fún Mose pé, “Gbẹ́ wàláà òkúta meji bíi ti àkọ́kọ́, n óo sì kọ àwọn ọ̀rọ̀ tí mo kọ sára wàláà ti àkọ́kọ́ tí ó fọ́ sára wọn.
 Mo n se okoowo lorisirisi ki n to bere si ni n se oselu.
Gomina Oyetola sọ siwaju wi pe ọkọ ijagun ti ko din ni ogun ni ijọba ipinlẹ naa yoo fi ṣe atileyin latari idasilẹ ajọ tuntun fun eto abo ilẹ Yoruba.
''Ni nkan to ti n sẹlẹ lati osu kini ọdun yi, Oloye Bode Akindele ni ẹnikeeje ogo ilẹ Ibadan to jẹ Ọlọrun nipe lọdun yi'' Ninu apejuwe to se, o sọ pe Oloye Akindele jẹ jagunjagun aye isin lẹka oko owo.
Ó bọ́ ògo mi kúrò,ó sì gba adé orí mi.
Oṣiṣẹ inu baalu gbọdọ pọ si, lati le mu ki o rọrun lati gba iṣẹ lọwọ aara wọn.
Kí àánú, alaafia ati ìfẹ́ kí ó máa pọ̀ sí i fun yín.
Asise asole iko agbaboolu Ac Milan Gianluigi Donnarumma ti sokunfa bi iko ohun se padanu ifesewonse asekagba idije Coppa Italia sowo iko agbaboolu Juventus ninu ifigagbaga ti o waye lojoBo(Thursday).
Idije yii bẹrẹ lojo Aje, ọjọ kẹfa, oṣu kẹjọ yoo si pari ni ọjọ Aiku, ọjọ keji, oṣu kẹsan, ọdun 2018 ni agogo 23:59 GMT.
Alaga igbimọ alakoso gareeji ọkọ naa wa gba awọn ọmọ igbimọ rẹ nimọran lati maa kan si awọn ọlọpaa atawọn Ileesẹ agbofinro lagbegbe wọn, ki alaafia lee jọba nibẹ.
“Tó bá di ìgbà náà,a óo rẹ ògo àwọn ọmọ Israẹli sílẹ̀,ọrọ̀ wọn yóo di àìní.
com 3: Ibi to ṣaba maa n ni awọ buluu lara ibomu-bẹnu naa ni ki o jẹ ko kọju sita.
Xenophobic Attacks: Ìjọba South Africa ní k'áwọn agbófinró ṣisẹ́ wọn bíi iṣẹ́
Adele akọwe ajọ naa Umaru Marafa ninu atẹjade kan to fi sita lọjọ Isẹgun ni digbi ni asẹ pe ki awọn ileeẹkọ wa ni titi pa si wa ti yoo si ri bẹ titi di igba ti asẹ mi yoo fi waye.
O Abiola’ Falz f'ohùn lẹ̀ fún PDP, APC, MURIC, àwọn ọmọ Yahoo Soyinka: Ọ̀pọ̀ ìgbà ni ayédèrú ìròyìn ti pa mí Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Eko Akete yóò gbàlejò BBC Yoruba Iba Gani Adams ni lati aye Iba akọkọ ni wọn ti n yan oloye si igbimọ aarẹ Ọna kakanfo ati pe, awọn oloye wọnyii ni wọn maa n ran aarẹ lọwọ lati ṣakoso ipese eto abo fun gbogbo ilẹ Yoruba, de ibi gbogbo to ruwe de tabi ta gbongbo de.
Ọkùnrin kan rí ẹ̀wọn he lẹ́yìn tó lu obìnrin ní jìbitì ìfẹ́ tí iye rẹ̀ tó $15,000 lórí ayélujára Fr Mbaka, ọmọ ìjọ rẹ̀ kọ̀lu akọ̀ròyìn BBC, wọ́n lù wọ́n ní àlùdojúbolẹ̀ Háà!
Ẹ bá mi gbé OLUWA ga,ẹ jẹ́ kí á jùmọ̀ gbé orúkọ rẹ̀ lékè!
Losu to kọja, Philomina sọ wipe miliọnu mẹrindinlogoji naira ti wọn pa wọle nigba ti wọn ta kaadi fawọn akẹkọ to se idanwo Jamb fi n wo esi idanwo wọn lori ẹrọ ayelujara, ni ejo ma n wa sibi ti oun gbe owo naa pamọ si ninu ọọfisi oun lati rọọ owo yi mi.
Wọ́n dá a lóhùn pé, “Lánàá, ní nǹkan bí aago kan ni ibà náà lọ.
Ọba Thailand Vajiralongkorn sọ ẹ̀ṣọ́ rẹ̀ di olorí láàfin
Ile isẹ ajọ UN to nrisi ọrọ awọn atipo, UNHCR ran orilẹede Naijiria leti ojuse rẹ labẹ ofin agbaye ati ofin ilẹ Naijiria.
Lopin ọsẹ yii ni Gomina ipinlẹ Oyo, Seyi Makinde fi ọkọ jiipu bọginni Toyota Prado 2020 ta a lọrẹ.
“Ǹjẹ́ òtítọ́ inú ati ọ̀nà ẹ̀tọ́ ni ẹ fi fi Abimeleki jọba?
Bẹẹ si ni o dupẹ pẹ iya ati ọmọ tuntun naa wa ni alaafia, ti ara wọn si mokun.
Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Ìdí nìyí tí wọ́n fi sọ orúkọ ibẹ̀ ní Bokimu, wọ́n sì rúbọ sí OLUWA níbẹ̀.
Adele akonimoogba orile-ede ohun, Luigi Di Biagio lo gba ise lowo Gian Piero Ventura ninu osu kokanla odun ti o koja, latari kikuna lati pegede fun idije boolu agbaye fun igba akoko lati odun 1958.
Ọmọ ìgboro ní mí, ọdún 13 ní wọ́n fipá bámi lòpọ̀ àmọ́ mo fẹ́ dà bíi Muhammed Alli - Kọńgílá Aṣẹ́wó Ojora ń mú mi lọ́wọ́ lórí ìkọlù tó wáyé, ara mi kò tíì balẹ̀ - Toyosi Adesanya Ẹ̀mí 15 bọ́, èèyàn 38 farapa nígbà tí ọkọ̀ akẹ́rù kan bọ́ sínú odò Ogun O ni oun a ma saba fa irungbọn yii, to si maa n mu ki ara maa ja oun jẹ.
Àwọn ẹnubodè rẹ̀ ti rì, wọ́n ti wọlẹ̀;ó ti ṣẹ́ àwọn ọ̀pá ìdábùú ìlẹ̀kùn bodè;ọba rẹ̀ ati àwọn olórí rẹ̀ wà láàrin àwọn orílẹ̀-èdè mìíràn;òfin kò sí mọ́, àwọn wolii rẹ̀ kò sì ríran láti ọ̀dọ̀ OLUWA mọ́.
Fayoṣe: Mi ò jẹ̀bi ẹ̀sùn kankan Àkọlé àwòrán, Fayoṣe àti Fani Kayode ní ilé ẹjọ́ gíga ìpínlẹ̀ Eko Lẹ́yìn ẹ̀sùn ìkarùn ún, ni agbẹjọ́rò Fayoṣe bá bèrè lórúkọ rẹ̀ pe ki wọn gba oníduró fún òun.
Yara kan lo kọkọ pari ti oun ati ẹbi rẹ si ko sinu ẹ titi ti wọn fi kọ ọ de ibi ti o de bayii.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ní Àwòrán: Ètò Ìsìnkú Winnie Madikizela-Mandela 11 Ìgbé 2018 Ẹgbẹẹgbẹrun eniyan peju-pesẹ si ibi akanṣe eto iranti ati ayẹyẹ isnku fun gbajugbaja ọmọ orilẹede South Africa, Winnie Madikizela-Mandela.
Ẹ̀rí Kristi ti fẹsẹ̀ múlẹ̀ láàrin yín, 
Ninu ọrọ rẹ, Arlene ni ọrọ ọhun ju ti tẹlẹ lọ, ti awọn miran ti ẹ n beere fun gbagede ti wọn ti fẹ se igbeyawo naa, ati wi pe, awọn mọlẹbi ati ibatan ti oun ko gburo lati bii ogun ọdun sẹyin bẹrẹ si ni pe oun.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Samuel Ajayi Crowther, òjíṣẹ́ Ọlọ́run tó gbé èdè Yoruba lárugẹ Mọrèmi Àjàṣorò, akọni obìnrin tó gba Ilé Ifẹ̀ sílẹ̀ lóko ẹrú Ọ̀rọ̀ǹpọ̀tọ̀niyùn, Aláàfin obìnrin àkọ́kọ́ rèé, tó ní nǹkan ọkùnrin Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'IBB da Abiola lẹ́yìn tó búra pẹ̀lú Quran' Ki lo bi iṣẹlẹ June 12 Ijagudu awọn ọmọ Naijiria fun isejọba tiwa n tiwa lo mu ki Ibrahim Babangida fi se agbekalẹ ẹgbẹ oṣelu meji, eyiun ẹgbẹ oṣelu Social Democratic Party, SDP, ti ami idamọ rẹ jẹ Ẹṣin, ti ọpọ eeyan si mọ si ẹgbẹ oselu ẹlẹṣin.
Awọn ileesẹ nla nla, ileesẹ alabọde atawọn ileesẹ kereje kereje lo ti lalẹ hu nilu Ọyọ lẹyin ti Ọba Adeyemi di Alaafin.
Aṣofin Ọbasa sọ pe ibaṣepọ to dan mọran lo wa laarin Ile Igbimọ Aṣofin naa ati Igbimọ Amuṣẹṣe Ijọba paapaa fun ilọsiwaju ipinlẹ yii.
 Òrò yí jẹ mí lógún , ọ ̀ rọ ̀ àṣà àti ìṣe ilẹ ̀ yorùbá .
Amofin Obiagwu ṣalaye pe, lootọọ ni ileẹjọ to n ri si ọrọ osisẹ paṣẹ pe ki ẹgbẹ osisẹ mase gunle iynaṣẹlodi ṣugbọn ileẹjọ ko ni ki wọn maa ṣe iwọde.
Bí àwọn adarí ìjọba ṣe ń kó Coronavirus, ń kọ wá lóminú - Ìjọba àpapọ̀ Ẹ̀yin ẹlẹ́gbẹ́ òkùnkùn tẹ fẹ́ ṣe àjọ̀dún lónìí, lákọ la ń dúró dè yín - Iléeṣẹ́ ọlọ́pàá Ìjọba Akeredolu kò ní omi àánú lójú, a kò tọ́jú alárùn Coronavirus mọ́ - Dókítá Ondo Òṣìṣẹ́ LASTMA gún olólùfẹ́ rẹ̀ l'ọ́bẹ, ó tún gba ẹ̀mí ara rẹ̀ l'Eko Kọmiṣọnna eto irinna, Frederic Oladeinde sọ pe ijọba yoo fun awọn to n bọ lati Mainland si Island laaye ati gba ori afara ọhun ni aarọ ati ọsan nigba ti awọn ọkọ to n bọ niwaju yoo ni lati lọ gba ọna miran.
Ẹgbẹ oṣelu PDP wa pe fun iwadi iṣẹ ileeṣẹ eto iṣuna apapọ orilẹede Naijiria lasiko ti Kẹmi Adeọṣun fi jẹ minisita nibẹ lati lee ṣawari awọn iwa kots ti awọn agbẹyinbẹbọjẹ to wa ni iṣejọba aarẹ Buhari n ṣe titi to fi kan kiko owo epo rọbi sapo ara wọn pẹlu adinku owo to wa ninu aṣuwọn apapọ orilẹ-ede yii nilẹ okeere Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'A máa ń bẹ́ orí ẹni tó bá gbé imọlẹ̀ ọdún ìjẹṣu tó bá ṣubú ni' Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Bọla Tinubu: Ìpínlẹ̀ Ọ̀ṣun kò ní owó mi lọ́wọ́ Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Oní gègé àrà Oladejo Okediji d'ẹni ilẹ!
Lójijì àgọ́ mi wó lulẹ̀,aṣọ títa mi sì fàya ní ìṣẹ́jú kan.
Lara omo egbe APC nile igbimo
gbogbo eto idibo yii de ibi aseyọri.
” Iranṣẹ náà dá a lóhùn pé, “Olúwa mi ni.
Ó bi wọ́n pé, “Ǹjẹ́ ẹ gba Ẹ̀mí Mímọ́ nígbà tí ẹ gba Jesu gbọ́?
titi di bi a ṣe n sọrọ yii ileeṣẹ ọlọpaa ati ijọba ipinlẹ Ọṣun ko tii ṣọ̀ ohunkohun lori iṣẹlẹ naa.
Àwọn ọmọ ẹgbẹ́ Democrats jakejado ilẹ̀ Amerika ti ṣe oníruuru wọlewode, láti ṣe ìpàdé sùgbọ́n ìdìbò gbàngba ni wọn yoo pada ṣe to bá yá.
Buhari gbé 'Next Level' jáde bíi ìwé ìpolongo ìbò rẹ̀ Aarẹ Buhari ti sẹ ifilọlẹ eto isejọba rẹ tuntun labẹ eto ipolongo idibo Aarẹ 2019 Lọjọ Aiku ni Aarẹ Buhari ṣe ifilọlẹ iwe eto ijọba ohun ti o pe akori rẹ ni Next Level.
Akọroyin BBC Yoruba to ti kalẹ silu Ilọrin fi ye wa pe, ko si pọpọsinsin kankan to n waye nipa ibura naa.
Akọsilẹ iye awọn ti ko niṣẹ lọwọ ti ileeṣẹ National Bureau of Statistics fi sita ju ìdá ogun lọ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Black lives Matter: Ọmọ Naijiria sọ ìrírí rẹ̀ lọ́wọ́ àwọn ọlọ́pàá nílẹ̀ Amerika.
'Ẹwẹ, ẹgbẹ awọn olukọni fasiti ni Naijiria, ASUU ti kilọ fun awọn ijọba ipinlẹ pe ki wọn ma ṣe ṣi awọn ile ẹkọ giga lasiko yii.
Ṣugbọn àwọn eniyan mi ti pààrọ̀ ògo wọn,wọ́n ti fi ohun tí kò ní èrè pààrọ̀ rẹ̀.
Ilẹ̀ pápá yóo sì wà ní ẹ̀gbẹ́ mẹrẹẹrin ìlú náà, ẹ̀gbẹ́ kọ̀ọ̀kan yóo gùn ní igba ó lé aadọta (250) igbọnwọ (mita 125).
Ojú ti àwọn ère rẹ̀, ìdààmú sì bá wọn.
    “Fún odidi ọjọ́ mẹ́ta tí mo ti kúrò ní ilé, ọkàn mi kò kúrò lára bàbá mi, ṣùgbọ́n nígbà tí ó ṣe díẹ̀, mo bẹ̀rẹ̀ síí mú ọkàn kúrò ní ilé mò ń ronú ibi tí mo ń lọ.
Ọpọ awọn olugbe ilu Ibadan lo tu sita fun ifẹhonuhan lẹyin ti iroyin jade pe afurasi naa ti salọ mọ awọn agbofinro lọwọ.
Oríṣun àwòrán, Oyo Affair O ni awọn ọlọpaa naa ni kò sí DPO nílé, wọn sì ni kí wọ́n maa lọ si àgọ́ ọlọ́pàá Iyaganku.
Ireti ati iwoye ọpọ eeyan ni pe ki awọn olori tuntun yii o wa ọna ti wọn yoo fi fa awọn ọmọ ẹgbẹ wọn bi miliọnu mẹrindinlogun mọra.
Wo ọ̀pọ̀ àsọtẹ́lẹ̀ igba tí Primate Ayodele gbé síta fọ́dún 2021 Iṣẹlẹ idajọ ọwọ ti di eyi to n fi ojojumọ waye ni ipinlẹ Ọyọ bayii,eyi to si nkọ ọpọ eeyan lominu nibẹ.
Leyi eyi ni won wa gbe asia egbe
tí a bá ń sọ nípa ọ ̀ rọ ̀ agbẹ ̀ , kí tilẹ ̀ ni pàtàkì àti ìwúlò iṣẹ ́ àgbẹ ̀ ní ilẹ ̀ aláwọ ̀ -dúdú àti ní àgbáyé lápapọ ̀ ?
Ni aye ode oni ti ọpọlọpo eniyan n reti ohun rere lati ọwọ ẹlomiran, pẹlu ero ayelujara ati ọpọlọpọ awọn ohun amayedẹrun to wa ni ikawọ awọn eniyan, ko soro fun eniyan lati ma a se ohun pupọ lẹẹkan naa, eleyii ti o le mu ki eniyan tete ma a binu, ti awọn to ba wa lẹgbẹ rẹ ko ba se ohun to tọ, abi ti o yẹ.
110 ni ìyè àwọn àgbẹ̀ tí Boko haram dúmbú ní Borno tí dì báyìí-UN Bí mo bá leè rí ọmọ alágbe t'áyé fẹnu sí pé mo fi ẹlẹ́rìndòdò lá lójú, máa kúnlẹ bẹ ẹ - Motara Wo ohun tó ṣẹlẹ̀ sí àwọn ọba tó kọ ifá sílẹ̀ gbé Bíbélì àti Kùránì Èèyàn 82 tún ti ní COVID-19 ní Nàìjíríà Ẹ wo ìdí tí Oby Ezekwesili ṣe ń pè fún àyẹ̀wò ọpọlọ fún Ààrẹ Buhari Bakan naa ni ijọba ni awọn eniyan yii yoo ma a san ẹgbẹrun mẹrin loṣooṣu fun ọ̀dun mẹta ti wọn yoo fi san owo naa tan.
Wumi Toriọla, tíí se òsèré tíátà lóbìnrin, sọ fún BBC Yorùbá ninu ifọrọwanilẹnuwo kan ìpa tó kó nínú ìgbeyàwó Toyin Abraham pẹ̀lú Adeniyi Johnson, lati ri pe o tọjọ, amọ tó papa forí sánpọ́n tori oun nawọ iranwọ́ ṣugbọn epe ni Toyin gbe oun ṣẹ.
''Ko si apa kankan lara wọn nigba ti mo yẹ wọn wo.
 CNN ni o pa ara rẹ ni.
girama ni  Igbobi to wa ni Yaba,ni ipinle
 Ọgbẹni Adegboyega fi kun ọrọ rẹ.
Joṣua ati gbogbo àwọn ọmọ Israẹli bá gbéra láti Libina lọ sí Lakiṣi.
igbejo ilu ati LASIEC, iyen asofin Braimoh tun ke pe ogbeni Babatunde Raji
”Bẹ́ẹ̀ ni gbogbo àwọn ọ̀rẹ́ mi ń wí,tí wọn sì ń retí ìṣubú mi.
"Ọ̀kan lara wọn, Adeniji Jacobson Gbenga sọ pe oun yoo ni ''ki Aarẹ Buhari o fi kurani bura fun mi pe ìwé ẹri ti ajọ WAEC fun òun kii se ayederu""."
Èmi ni OLUWA tí ó sọ yín di mímọ́.
Awọn agbebọn naa ti wọn jọ marundinlogun niye ji akẹkọ mẹfa to jẹ ọkunrin gbe.
Ẹwẹ, agbabọọlu Manchester United nigba kan ri, Rio Ferdinand sọ pe asiko ti to fun ẹlẹsẹ ayo Lionel Messi lati ronu lori ibaṣepọ rẹ pẹlu Barcelona.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ìjọba Oyo gbé ilé ẹ̀kọ́ gíga kan tìpa torí àrùn Coronavirus A ó ṣèrànwọ́ fáwọn ẹbí ọlọ́pàá tó bá rògbòdìyàn EndSARS lọ láti inú N500m tí a yà sọ́tọ̀- Makinde Díẹ̀ ló kú kí owó tán l‘ápò mi torí ìrànwọ́ Coronavirus - Pasuma Mo ṣèlérí láti rí sí ìrẹ́pọ̀ àti ìwòsàn Amẹ́ríkà - Joe Biden Bí ọwọ́jà ìjọba mi kò bá tíì dọ́dọ̀ yín, ẹ ṣe sùúrù pẹ̀lú wa- Ààré Buhari bẹ̀bẹ̀ Èèyàn méjì àti ọkọ̀ 29 ló jóná níbi ìṣẹ̀lẹ̀ táńkà agbépo tó gbiná ní mọ́rosẹ̀ Eko sí Ibadan Awọn to n gbe agbegbe naa, ti wọn ri eefin ina to sọ lala, ni wọn kan si ileeṣẹ panapana ipinlẹ Oyo, ni nnkan bii aago mẹfa owurọ ọjọ Abamẹta.
 Agbẹnusọ Ile Igbimọ Aṣofin Eko, ti wọn dibo yan pada lati
pe: “Ọlọrun yìí ni Ọlọrun wa,lae ati laelae.
ede Naijiria,(Nigeria Medical Association ,NMA), ti bẹnu atẹ lu bi awon gomina
Ẹlòmíràn lè jẹ́ afọ́jú, arọ, alápá'kan, àti bẹ́ẹ̀ bẹ́ẹ̀ lọ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Obasanjo: Atiku kìí se Áńgẹ́lì, àmọ́ yóò se dáadáa ní ìlọ́po méjì ju Buhari lọ Alaye to ṣe ni pe, awọn oludije wọn yii darapọ mọ awọn ẹgbẹ oṣelu to ti wa nilẹ tẹlẹ ṣugbọn oun da ti oun silẹ ni tuntun ni.
N óo fara da ìyà tí OLUWA bá fi jẹ mí Nítorí pé mo ti ṣẹ̀ ẹ́, títí tí yóo fi gbèjà mi, tí yóo sì dá mi láre.
Nígbà tí ó ti di ọdún kẹta tí ó ti dó ti Samaria, ó ṣẹgun rẹ̀.
Owo yii ti kọ opopona, ileewe ati ileewosan ṣugbọn lẹyin aadọta ọdun, ọpọ eeyan lo n woye pe owo to yẹ ki o maa wọle yẹ ko pọ ju eyi lọ.
Oríṣun àwòrán, Facebook/Adams Oshiomole Ninu atẹjade ti Obaseki fi sita lọjọ Ẹti nipasẹ oluranlọwọ rẹ lori ọrọ iroyin, o ṣalaye pe ko ni itumọ ti oun ba ni ki oun pe ẹjọ kotẹmilọrun.
South Africa Election: Ẹgbẹ́ òsèlú 50 ló ń kópa nínú ìdìbò
"Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Aláàfin ní tí kìí bá ṣe òṣèlú ni, Ìwó ló yẹ kó jẹ́ olú ìlú ìpínlẹ̀ Osun 26 Ọ̀wàrà 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 2 Bélú 2020 Oríṣun àwòrán, Oluwo's Palace ""Ogun ọdun akọkọ ti mo lo lori oye ko dẹrun rara, mo lee sọ pe ojumọ kan idamu kan ni""."
Oun si ni ọmọ ilu Ibadan keji ti yoo jẹ oye alagbara yii lẹyin Oluyedun.
ekun Gusu orile ede Naijiria je logun ti fenu oro jona pe digbi ni awon wa
Bí ẹnìkan bá jí dìde ninu òkú, tí ó lọ sọ́dọ̀ wọn, wọn yóo ronupiwada.
  Sùgbọ́n nínú gbogbo nǹkan ìyanu tí mo rí, èyí tó pe àkíyèsí mi jùlọ ni bí igi ọ̀pẹ ṣe pọ̀ níbẹ̀ tó.
Oríṣun àwòrán, Mike bamiloye/facebook Àkọlé àwòrán, Asiko yii ni awọn obi ọkọ, ṣi oju iyawo ọmọ wọn wo.
Buhari: Mo gbọdọ̀ lọ́ra kàwé, kí ń tó buwọ́ lùú
Oku ọmọ meji pere ni wọn ṣi rí.
Ikede yii wa loju opo ajọ NSCIA to wa ni Facebook ti wọn fi sita lorukọ Sultan Sokoto, tii ṣe olori awọn musulumi Naijiria.
Ninu ọrọ to ba BBC yoruba sọ, akọwe ipolongo fun ẹgbẹ oṣelu APC ni ipinlẹ Ọyọ, ọgbẹni Mojeed Olaoya fidi iṣẹlẹ yii mulẹ Lasiko ti a fi n ko iroyin yii jọ, wọn ti gbe oku aṣofin Michael Adeyemo si ile igbokusi.
Lara awọn nkan to fa tí tako ijọba Ọgbẹni Lukashenko, ni bo ṣe fi ọwọ yẹpẹrẹ mu itankalẹ aarun coronavirus.
Abájáde ìpàdé èètò ààbò naa ti Samuel Aruwan oluranlọwọ fun Gomina Kaduna lori ọrọ ibanisọrọ fi sita ṣe àlàkalẹ ètò kóníléógbélé naa.
Gege bi ohun ti o wa ninu
Meje ninu awọn ti wọn ti fi idi iku wọn mulẹ naa lo jẹ Ọkunrin ti ọkan si jẹ obinrin.
4m Abúlé tí wọn kìí ti sọ ọmọ ní orúkọ, ohùn arò ni wọ́n fi ń pè wọ́n Wo àwọn nǹkan tí o kò mọ̀ nípa 'Church of Satan' Èèmọ̀!
O ṣalaye pe ijọba n te kaadi idanimọ naa jade diẹ diẹ ni, idi ree ti ọpọ awọn to ti forukọ silẹ ko ṣe tii fi ri kaadi wọn gba.
 Lojo Aje ni eto idanilekoo naa yoo pari.
oju omi naa ti o je ti igbalode ,ni won so pe ko lee sisẹ lasiko naa nitori
Aarẹ Buhari darapọ mọ awọn ara ipinle Benue , egbe agbejọro lorilẹ ede Naijiria ati ajo to n ri si eto idajọ lorilẹ ede Naijiria lati kẹdun ogbontarigi adajọ ti o ko ipa ribiribi nipa atunse lori eto idajọ.
Ọkan gboogi ninu awọn oloselu ni ilẹ Amẹrika, John McCain ti dagbere faye ni ọmọ ọdun mọkanlelọgọrin.
 lára àwọn tí ó ṣẹ ̀ ṣẹ ̀ bọ ́ lọ ́ wọ ́ àkóràn , àtún-kóràn maa ń mú àwọn ààmì tí kò le jáde .
Àwọn ìjòyè ní àwọn agbègbè wọn ń gbé Jerusalẹmu, ṣugbọn ní àwọn ìlú Juda, olukuluku àwọn ọmọ Israẹli ń gbé orí ilẹ̀ rẹ̀, ní ìlú wọn, títí kan àwọn alufaa, àwọn ọmọ Lefi, àwọn iranṣẹ tẹmpili, ati àwọn ìran iranṣẹ Solomoni.
OLUWA bá pe Kaini, ó bi í pé, “Níbo ni Abeli, àbúrò rẹ wà?
Odò tí Ń Ṣàn láti Tẹmpili.
Arabirin kan so wipe awon omo egbe oselu Sierra Leone People’s Party (SLPP) fi ipa ba oun ati omo re sun ,ti won si n dunkoko mo lati dana sun ile re.
" Lẹyin naa lo ni ki a kan si kọmiṣọnna fun eto ilera, iyẹn Ajibayo Adeyeye, ṣugbọn gbogbo akitiyan wa lati kan si kọmiṣonna ọhun lo ja si pabo.
O pe aadọta ọdun ti Ọba Lamidi Adeyẹmi kẹta ti di Alaafin ilu Ọyọ, ko si ṣe e ṣe lati ṣami ajọdun naa lai tọka si diẹ lara awọn nnkan aritọkasi to gbe ṣe.
Àwọn wo ni gómìnà mẹ́rin tí yóò kojú àjọ EFCC lẹ́yìn tí wọ́n bá kúrò nípò?
Àwọn ará ìlú ń bèèrè pé, “Ta nìyí?
Bẹ́ẹ̀ ni, à ń mọ odi náà, a mọ ọ́n já ara wọn yípo, ó sì ga dé ìdajì ibi tí ó yẹ kí ó ga dé, nítorí pé àwọn eniyan náà ṣiṣẹ́ tọkàntọkàn.
Ṣugbọn eyi ko ni ki n di olundun, ti ko le f'esi si awọn ọrọ aida ti wọn n sọ kiri nipa mi lori ayelujara.
Khadiza ni oun ti woye pe kaka ki iya to n jẹ awọn obinrin dinku ni Bangladesh, niṣe lo n peleke sii nitori pe aṣa wọn fun ọkunrin ni agbara pupọ.
Minisita feto abo ni ilẹ Amẹrika, Jim Mattis ti sọ wipe oun ri awọn ọmọogun ilẹ Indonesia kan ti wọn nmu ẹjẹ ejo ti wọn si n fi ori fọ bulọọku ikọle lọjọọru.
Everton já Manchester United sí ìhòhò lọ́jọ́ Àjíǹde Beckham, àgbábọ́ọ́lù tẹ́lẹ̀ rèé tó ń sọ èdè Yorùbá UEFA Champions League: Barca yọ Man U dànù bí ẹni yọ jìgá!
Nitori naa si ni mi o ṣe fẹran lati ma a lọ si ode ariya, nitori ọpọ eeyan ni mi o damọ mọ."
Alukoro ileeṣẹ ọlọpaa ipinlẹ Ogun, DSP Abimbola Oyeyemi to ba BBC Yoruba sọrọ, ṣalaye pe awọn akẹgbẹ awọn ajinigbe mẹrin ti ọwọ awọn ọlọpaa tẹ lo doju ija kọ awọn ọlọpaa nigba ti wọn n kọ wọn si Abeokuta lati Ode Omi ti wọn ti ji ọmọ Imaamu ati eeyan meji mii gbe.
Ẹ ri pe awọn ounjẹ aramọnda pọ lorilẹ aye, ewo ni ẹyin fẹ ko jẹ ninu wọn?
Ó fún àwọn ẹlòmíràn ní ẹ̀bùn láti jẹ́ aposteli, àwọn ẹlòmíràn, láti jẹ́ wolii, àwọn ẹlòmíràn, láti jẹ́ ajíyìnrere, àwọn ẹlòmíràn, láti jẹ́ alufaa ati olùkọ́ni.
Atiku fẹjọ́ Buhari sun US, UK, France àti EU lórí ọ̀rọ̀ Onnoghen Ẹwẹ, oludije aarẹ fẹgbẹ oṣelu alatako PDP, Atiku Abubakar ti fẹjọ aarẹ Muhammadu Buhari sun orilẹede Faranse, Germany, Amẹrika, Ilẹ Gẹẹsi ati ajọ ilẹ alawọ funfun lori bi o ti ni ki adajọ agba Walter Onnoghen lọ rọkun nle.
Ọlọrun tọ Balaamu wá, ó bi í pé, “Àwọn ọkunrin wo ni wọ́n wà lọ́dọ̀ rẹ yìí?
Ìrìnàjò Toyin Abraham, láti orí gbèsè jíjẹ, ó di onílé, onimọto àti aya lọ́dọ̀ ọkọ Èèyàn 5 mííràn tún ti lùgbàdì ààrùn Coronavirus ní Naijiria Àwọn Alákòso gárèjì ló kó ìbọn àti àdá tọ ọlọ́kadà wá ní Soka-Alága ẹgbẹ́ ọlọ́kadà Ọyọ Ogun àgbáyé ni COVID-19, ìgbọ́nran sáwọn ìjọba lẹ́nu ṣe pàtàkì-Ọọ̀ni Ilé- Ifẹ̀ Oloye Sunday Babatunde Olalere to n gbe eegun Danafojura lọwọ ṣalaye lẹkunrẹrẹ ohun to sọ akọwe ijọ di eegun l'Ogbomọṣọ.
Kí Oluwa wà pẹlu ẹ̀mí rẹ.
Disu ni ó yẹ kí ìjọba sàlàyé fún ará ilú pé àrùn yìí kìí ṣe ǹkan ti yóò lọ nísin yìí, kí wọ́n si maa tẹ̀lé ìlànà ìmọtótó tó yẹ.
 Ọ ̀ pọ ̀ àwọn orílẹ ̀ èdè erékùsù ni kòní dìgbòlugi .
"Amọṣa ninu fidio kan to fi si ori ikanni ayelujara, Facebook, eekan apanilẹrin ati elere itage, Ọlanrewaju Omiyinka ti ọpọ mọ si Baba Ijeṣa jẹ ko di mimọ pe ""ikọ lasan"" lo pa oloogbe Oriṣabunmi."
Aṣòfin Tunde Braimoh wọ káà ilẹ̀ sún ní Eko Iṣẹ́ abẹ tí mo ṣe láti fi kún ìkébé mi ṣàkóbá fún mi- Omotola Taiwo Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí N-Power 2020 recruitment: Ṣé lóòtọ́ ní pé àwọn alákòso tí kéde àwọn tó ṣe àṣeyọrí nínú ètò ìgbanisíṣẹ́ ọdún 2020?
Ẹ wo awọn ohun miran ti awọn ọmọ Naijiria n sọ nipa idajọ Ọhun.
Ẹ ó rantí wí pé ní ọjọ́ ìṣẹgun ni ìròyìn gbálẹ̀ pé Dino ti jọ̀wọ́ ará rẹ̀ fún àwọn ọlọ́paa.
Láìpẹ́ yìí ni ìgbìmọ̀ àwọn gómìnà lórílẹ̀-èdè Nàìíríà ti sọ wí pé àwọn kò tako fífi owó kún owó àwọn òsìsẹ́, àmọ́ àwọn kò ní owó láti san án ni.
Lesotho kọkọ ta biọbiọ lẹyin ti Masoabi Nkoto gbayo sawọn Naijiria lẹyin mọkanla ti wọn bẹrẹ ifẹsẹwọnsẹ ọhun.
DSP Ezekiẹli ni ọja naa jẹ ti ọgbẹni Mohammed Muraina to n ta worobo ati atẹ ninu ṣọọbu rẹ ni Abule Ẹgba.
Kí tọkọtaya mọ̀ pé bí sùúurù tì àwọn bá mú fún ara àwọn lónìí bá ju ti àná lọ, àwọn yóò ní owó, àwọn yóò ní ọmọ, àwọn yóó sì ní àlàáfìá tí í ṣe olùborí owó àti ọmọ.
Ẹ̀ ń sọ pé, ‘Bí eniyan bá fi Tẹmpili búra, kò ṣe nǹkankan.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ọlọwọ: Olùdarí ètò ìṣúná àti àkóso ní Ondo ni Ogunoye tó di Ọlọwọ tuntun 12 Agẹmo 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 13 Agẹmo 2019 Ilu Ọwọ ti ni ọba tuntun bayii, orukọ ọba tuntun ti awọn afọbajẹ ilu Ọwọ ṣẹṣẹ dibo yan lọjọ Ẹti ni Ọmọọba Ajibade Ogunoye.
Awọn ijoye naa fi ẹsun ikowojẹ ati awọn ẹsun iwa ibajẹ kan an, eyi to mu ki ijọba rọ ọ loye, to si tun ju si ẹ̀wọ̀n nilu Ìjẹ̀bú Òde, ati awọn meji miran.
Asiko ogun nla kan nilẹ Yoruba ni Ọmọọba Gbadebọ lati idile Ọba Ọsinkọla nilu Ile Ifẹ ati aya rẹ, Adekunbi to wa lati ilu Ipetumodu, biI.
idibo, ko to di pe awon eniyan n bẹrẹ si maa dibo, ni eyi ti won fẹ gbe sinu ẹrọ
Ọdun1952 ni wọn gbe idanwo WAEC kalẹ fun awọn akẹkọ lawọn orilẹ-ede iwọ-oorun ilẹ Afirika ti wọn ti n sọ ede Gẹẹsi.
Amọ ni Berlin, bi o ti se ri lawọn orileede to ku l'agbaye, asiko Coronavirus yi sebi ẹni da eto awẹ ru lọdun yi.
Ti ó ba ki, fi omi diẹ si lati po gbogbo ẹ pọ
Yatọ si pe o kọ lati kopa ni apero ọrọ aje to n waye naa, Naijiria tun ti ni ki aṣoju rẹ nilẹ South Africa pada wa sile.
jẹ eyi ti  o lodi si ofin  latari pe ile-ejo naa kọ lati wo iwe –eri WAEC  ti asofin Adeleke fi silẹ, ni eyi to wa ni
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Eid-Al-Fitr: ìjọba Nàìjíríà ti kéde ìsinmi lọ́jọ́ Ìṣẹ́gun àti Ọjọ́rú 3 Òkùdu 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Eid-Al-Fitr: ìjọba Nàìjíríà ti kéde ìsinmi lọ́jọ́ Ìṣẹ́gun àti Ọjọ́rú Ile iṣe ijọba apapọ to n risi ọrọ abẹle Naijiria kede isinmi fawọn eniyan.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Huspuppi arrestgedi: Hushpuppi l'ẹ́jọ́ láti jẹ́, Invictus Obi gbà pé òun jẹ̀bi ẹ̀sùn gbájúẹ̀ ẹgbẹ̀lẹ́gbẹ̀ owó lágbáyé 19 Òkùdu 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 26 Òkùdu 2020 Oríṣun àwòrán, Screenshot/DUBAI MEDIA OFFIC Àkọlé àwòrán, Invictus Obi, Hushpuppi, àwọn ọ̀dọ́ Nàìjíríà méjì tí ẹ̀sùn gbájúẹ̀ wà lọ́rùn wọn Ramoni Igbalode ti ọpọ eeyan mọ si Hushpuppi to fi orilẹ-ede Dubai ṣe ibujoko lasiko yii ni ọwọ awọn agbofinro ilẹ Dubai ti tẹ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Iyabo Ojo house: Iyabo Ojo ṣílé tuntun, Eko mì tìtì 11 Owewe 2020 Gbajugbaja oṣere tiata Yoruba, Iyabo Ojo ṣi ile tuntun nibi ti ọpọlọpọ awọn ẹbi, ọrẹ ati ojugba rẹ ninu iṣẹ tiata peju si.
“Nígbà tí ẹ bá jáde lọ láti bá àwọn ọ̀tá yín jagun, tí ẹ bá sì wà ninu àgọ́, ẹ níláti yẹra fún ohunkohun tíí ṣe ibi.
Lẹ́yìn tí Jesu ti gba adura yìí tán, òun ati àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ jáde lọ sí òdìkejì àfonífojì odò Kidironi.
Eliṣa bá pada lẹ́yìn rẹ̀ sí ibi tí àwọn akọ mààlúù rẹ̀ wà, ó pa wọ́n.
Ọwọ́ ọlọ́pàá Ogun tẹ afurasí apaàyàn tó ń ṣọṣẹ́ ní Ogere ati Iperu Mo kó gbogbo ọ̀rọ̀ ti mo sọ sí akòròyìn Daily Trust jẹ-Femi Fani-Kayode Ìjọba àpapọ̀, ẹ gbà lọ́wọ́ ìrẹ́jẹ iléeṣẹ́ DSTV àti èlé owó rẹ̀ - ọmọ Nàìjíríà faraya 'Orísúnmibáre ni àìsàn 'Polio' tó kọlù mí ní kékeré' Awọn ẹgbẹ agbabọọlu bii Manchester City, Manchester United, PSG ati Inter Milan lawọn kan n sọ pe o ṣeeṣe ki Messi mori le.
Mugabe lo ti ye ko farahan nile igbimo asofin , leyin igba to so fun awon oniroyin nibi iforowanilenuwo lojo to n se ayeye ojo ibi re , to waye lodun 2016 pe Zimbabwe padanu okuta iye-biye ti iye re je  bilionu marundinlogun owo dola nipase awon olote, ti ko daruko won .
Inú bí Dafidi gidigidi nítorí pé OLUWA lu Usa pa.
Oya ẹ wa foju lo n jẹ ninu fidio yiii: Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí kan sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
Eyi yani lẹnu botilẹjẹ pe ijọba ipinlẹ Eko ti kede pe ki awọn ile ijọsin bẹrẹ sini ṣi pada lati ọjọ Jimọ, ọjọ keje, oṣu Kẹjọ, lẹyin oṣu bi i maarun ti wọn ti ti ilẹkun wọn nitori isede aarun coronavirus.
Ó ń pa ni lára,ṣugbọn ọwọ́ rẹ̀ ló tún fi ń ṣe ìwòsàn.
Lọsẹ to lọ ni igbimọ oludajọ ẹlẹni meje ile ẹjọ to ga julọ ni Naijiria labẹ idari adajọ agba ni Naijiria, Tanko Mohammed gbọ ẹjọ ti oludije ibo gomina fẹgbẹ oṣelu PDP, Musa Wada pe Gomina Yahaya Bello to wọle ibo naa.
Ẹ sì níláti fọ gbogbo aṣọ yín, ati gbogbo àwọn ohun èlò tí a fi awọ ṣe, tabi irun ewúrẹ́, tabi igi.
Saaju ki awọn oloṣelu ode oni to ma mu igbe yi bẹnu,ni ọjọgbọn onimọ ẹrọ ọmọ kaarọ ojiire kan ti pe fun wiwọgile ibo aarẹ Naijiria lọdun 1983.
Ǹjẹ́ orílẹ̀-èdè kankan tíì pààrọ̀ ọlọrun rẹ̀ rí,bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé wọn kì í ṣe ọlọrun tòótọ́?
Lati ọdun 2015 ti ijọba ti fi El Zakzakky to jẹ olori Islamic Movement of Nigeria si atimọle ni oriṣiiriṣii nkan ti n ṣẹlẹ.
F salaye pe, iwadii n lọ lọwọ lori bi Ẹniola ti se di awati ati pe, ileesẹ ọlọpa naa yoo se iwadii to ye kooro, ki won to sọ ohunkoun lori ọrọ naa.
”Eliṣa dá a lóhùn pé, “O óo fi ojú rí i, ṣugbọn o kò ní jẹ ninu rẹ̀.
Aarẹ ẹgbẹ FIBAN, Desmond Nwachukwu lo fi lede ninu atẹjade kan lati fesi si iṣẹlẹ to ṣẹlẹ laarin Wasiu Ayinde ati oniroyin Wole Sorunke ti wọn n pe ni MC Murphy.
Farao ní kí Josẹfu gun ọkọ̀ ogun rẹ̀ keji gẹ́gẹ́ bí igbákejì ọba, wọ́n sì bẹ̀rẹ̀ sí hó níwájú rẹ̀ pé, “Ẹ yàgò lọ́nà!
Gbogbo ohun tí o wí ni mo ti ṣe, OLUWA Ọlọrun mi, mo sì ti pa gbogbo àṣẹ rẹ mọ́.
Wọn ge ọrun awakọ ọkọ naa ki wọn to bẹrẹ si ni yinbọn fun gbogbo awọn to wa ninu ọkọ naa lai ṣẹ ẹyọ ẹmi kan ku, lẹyin eyi ni wọn wa da ina sun ọkọ naa.
" Arabinrin Fola sọ pe oun dupẹ pe ko gba ju ẹsẹ ọtun oun lọ, nitori pe awọn kan wa ti aarun yii rọ lapa, ẹsẹ, to tun sọ wọn di aditi.
Minisita fun eto iroyin ni Naijiria, Alhaji Lai Mohammed lo sọ eleyii ni ilu Abuja lasiko ti wọn n ṣe ifilọlẹ atunṣe fun ofin to rọ mọ iroyin ni Naijiria.
Ọkan lára àwọn òbí awọn ọmọ ti ikọ̀ Boko Haram jí gbé ni Chibok ló ti jáláisí nínú ìjàmbá ọkọ̀ kan to wáyé lọ́jọ́ ìsinmi.
Awọn eeyan wa kan saara si fun iwa akin ti o wu yii.
awon osise fẹran orile ede yii to bẹ ti won fi ko ipa Pataki ni eyi ti o je ki
Ọlọrun, mímọ́ ni ọ́, sí gbogbo àwọn tí wọ́n bá mọ́,ṣugbọn o kórìíra gbogbo àwọn eniyan burúkú.
E ó rántí wípé ní oṣù kínní ọdún yìí ni ìjọba ìpínlẹ̀ Benue sin òkú métàléláàdọrin tí àwọn agbébọn pa.
6 Bí ó tilẹ̀ rí bẹ́ẹ̀, a kò kọọ́ pé kò ní sí òpin sí oró yìí, ṣùgbọ́n a kọọ́ pé oró àìnípẹ̀kun.
Ooni Ifẹ bu ẹnu ẹ̀tẹ́ lú ètò BBNaija nítorí ó tàbùkù àsà Yoruba Ọwọ́ tẹ Bàbá ọgọ́rin ọdún tó fipá bá ọmọ ọdún márù'n ún lò pọ̀, Adájọ́ kọ láti gba onídúrò rẹ̀ Ẹ jẹ́ kí àwọn ọmọ Naijiria má a gbebọn bíi AK47 láti fi dáàbò bo ará wọ́n- Gómìnà Benue A ti ń sin òkú méjì sínú ibójì kan náà nítorí ọ̀wọ́ngógó ibojì ìsìnkú"" Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Alaafin: Olori Aanu Adeyemi ṣàlàyé ìdí tó ṣe gẹ́ Oba Lamidi Adeyemi ti ìlú Oyo Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Gun control in Nigeria: Wo ọ̀nà márùn ún tí o lè gbà dábòbò ara rẹ lọ́wọ́ ìjàmbá!"
Lilo ẹyẹle fun idije ere sisa ti di gbajugbaja lorilẹede China.
Inu ọpa to n gbe eemi ni arun bi coronavirus n gba wọ inu ara.
Ọkan lara awọn asaaju ẹgbẹ, Emeka Ezeife lo pe fun ki wọn le Sowore ati awọn mejilelọgbọn miran kuro ninu ẹgbẹ, ti awọn ọmọ ẹgbẹ to kun naa si faramọ.
 Ó di ipò yí mú láti ọdún 1974 títí dé 1975 .
Kò tọ́ sí Ọlọ́pàá láti ti ọmọ mi mọ́lé tórí ore tó ṣe lásìkò ìwọ́de EndSARS - Iya Eremosele Èmi ni mò ń jóko sórí ìtẹ́ Ọlọrun alààyè nílé ayé - Oluwo Wo ìdí tí wọ́n fi ta ẹyẹlé kan ṣoṣo ní ₦893,000,000 Àwọn ọmọ Naijiria kó owó wọn kúrò ní Access Bank lẹ́yìn tó gbẹ́sẹ̀lé àpò owó àwọn olùwọ́de EndSARS Olu Jacobs àti Joke Silva yan orúkọ ọ̀tọ̀ọ̀tọ̀, àmọ́ wo ohun tó mú ìgbéyàwó wọn dúró Gudugudu ni olukọ toni gan funrarẹ ti ko figba kan tura silẹ ninu pipe ẹṣa eegun.
18 Èbibi 2020 Ọna kan gboogi ti arun Covid-19 fi n wọ ara eeyan ni lati ẹnu, imu tabi oju.
Bákan náà ni bàbá rẹ̀ dúpẹ lọ́wọ́ àwọn Hisbah fún ìgbésẹ̀ oní wàrànsesà ti wọ́n gùnlé láti dáàbò bo ẹmí òun àti àwọn ẹbí òun lásìkò ti àwọn ọdọ́ wa kógun bá òun nílé ti wọ́n si dána su ilé òun.
Ọmọ náà dá a lóhùn pé, ‘N kò ní lọ.
Bakan naa ni wọn a maa dẹru ba awọn oludibo tabi tilẹ ṣe wọn ni ijamba.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Buns ni ọmọ mi jẹ tán ní ṣọ́ọ̀ṣì, ló bá di àwátì' Oríṣun àwòrán, UN WOMEN Bakan naa ni ẹka to n risi oro obinrin ni Ajo Isọkan Agbaye, UN ti kede wi pe ọjọ mẹrinlelogun ni awọn yoo fi jijagbara fun eto awọn obinrin lagbaye, ati ifopin si iwa ipa si obinrin kaakiri orilẹede to wa ni agbaye.
Nítorí nígbà tí oòrùn bá yọ, tí ó mú, koríko á rọ, òdòdó rẹ̀ á sì rẹ̀, òdòdó tí ó lẹ́wà tẹ́lẹ̀ á wá ṣègbé.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ọ̀rọ̀ Imam yìí ṣe kòńgẹ́ bó ti ń rí láàrin lọ́kọ láya 4) Nkan iyatọ kan a ṣẹlẹ to maa ṣokunfa ipaniyan naa bii ki ẹnikeji ni oun ko ṣe mọ tabi pe oun n fẹ ayipada si ija, iya ati nina lojoojumọ.
Olukopa kan ni yiyan omo ile Ghana, Edward Eninnful, gege bii alase iwe iroyin atigbadegba British Vogue ti fihan pe idagbasoke n ba ile Adulawo nitori pe oun ni eniyan dudu akoko ti yoo di ipo nla yii mu nile ise iwe iroyin to ti wa lati ogorun odun seyin.
Tí ẹ o bá gbàgbé Ramaphosa tí pé ààrẹ Buhari láti wá si orilẹ̀-èdè South Africa ní ọjọ kẹta oṣu kẹ̀wáà láti fọ̀rọ̀wẹ́rọ̀ lójùnà àti mú ìṣọkàn wà láàrin orílẹ̀-èdè méjèèjì Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
tí wọn ń lọ káàkiri láti orílẹ̀-èdè kan dé ekeji,láti ìjọba kan sí òmíràn,
Ẹ̀kọ́ kẹta ni pé rògbòdìyàn kò dára, ó leè gba ẹ̀mí alaiṣẹ̀, kò sì tún fi ọ̀pọ̀lọpọ̀ dúkìá ṣòfò, ẹ jẹ́ ká yàgò fún làásìgbò.
Bí Mose bá ti wọ inú àgọ́ àjọ náà lọ, ìkùukùu náà á sọ̀kalẹ̀ gẹ́gẹ́ bí òpó, a sì dúró lẹ́nu ọ̀nà àgọ́ náà.
Kì í ṣe èyí tí wọ́n kọ sí orí òkúta; ọkàn eniyan ni wọ́n kọ ọ́ sí.
Naijiria lati tun nigbagbo ninu orile ede Naijiria , o tun wa ro awon oloselu  pe bi eto idibo se n sunmọle, ki won ri i  pe won  n tele ofin eto ajo eleto idibo.
Sri Lanka, Czech Republic ati Serbia ni Minisita fọrọ ilẹ okere kede pe awọn yoo ti pa.
Orúkọ ọba óo wà títí lae,òkìkí rẹ̀ óo sì máa kàn níwọ̀n ìgbà tí oòrùn bá ń ràn;àwọn eniyan óo máa fi orúkọ rẹ̀ súre fún ara wọn,gbogbo orílẹ̀-èdè óo sì máa pè é ní olóríire.
Lemọ lemọ si ni Erica, to han pe o ti mu ọti yo, n sọ pe oponu ati oburẹwa to jẹ kikida egungun , ti ko mu agbega kankan ba inu ile naa ni Leycon.
 Àwọn yìí ni ọ ̀ rọ ̀ tí a ṣẹ ̀ dá tí wọ ́ n sì ń fún wa ní òye ìyísódì .
Ajayi to woye pe ojuṣe awọn ẹṣọ abẹle yii yoo ṣeranwọ fun iṣẹ awọn
Ẹkẹrin mú Isiri, òun ati àwọn ọmọ rẹ̀ ọkunrin, ati àwọn arakunrin rẹ̀ jẹ́ mejila.
Naijiria bu owó itanran yii fun ileeṣẹ yii nitoripe wọn ko tẹlẹ aṣẹ pe ki wọn re awọn onibara ti ko kopa ninu eto iforukọ silẹ tijọba pa kúrọ lasiko.
A jẹ́ pé kòrí-kòsùn gẹ́lẹ́ lọ̀rọ̀ èmi àti iPhone mi jẹ́ o.
Ní ọjọ́ keji, bí wọ́n ti ń mu ọtí, ọba tún bi Ẹsita pé, “Ẹsita, Ayaba, kí ni ẹ̀bẹ̀ rẹ, a óo ṣe é fún ọ.
Kí ló pa ọmọbìnrin Ajagun òfúrufú àkọ́kọ́ ní Nàìjíríà?
Trump ni o da oun loju pe oun yoo pada wọle ibo aarẹ ilẹ Amẹrika.
anfaani yii lati rọ awon arinrinajo lati tete de papa ofurufu lasiko  fun irinajo won, ki won maa  baa kuna irinajo won.
Bẹẹ, wọn ko fi aaye gba awọn obinrin lati da si ọrọ oṣelu, ko si ọna fun awọn obinrin lati gbe ọrọ wọn jade.
Eyi ni ikilọ ọga ọlọpaa orilẹede Nàìjíríà, Mohammed Adamu fawọn to n gbero lati fi ẹhonu wọn han fun ijọba Naijiria lọjọ Aje lori aifararọ ilu.
Litireso alohun jẹyọ pupọ̀ ninu awn iwe yii bii ẹ̀sà eeegun, oriki, ọ̀rọ̀ asọregee ati bẹ́ẹ̀ bẹ́ẹ̀ lọ.
Angẹli OLUWA náà dá Manoa lóhùn, ó ní, “Bí o bá dá mi dúró, n kò ní jẹ ninu oúnjẹ rẹ, ṣugbọn tí o bá fẹ́ tọ́jú ohun tí o fẹ́ fi rú ẹbọ sísun, OLUWA ni kí o rú u sí.
Ahabu dá a lóhùn pé, “Mo sọ fún Naboti pé mo fẹ́ ra ọgbà àjàrà rẹ̀, tabi bí ó bá fẹ́, kí ó jẹ́ kí n fún un ni òmíràn dípò rẹ̀; ṣugbọn ó ní òun kò lè fún mi ní ọgbà àjàrà òun.
Naijiria: Asiri awọn ibudo igbafẹ ẹranko
Asofin to n soju agbegbe naa tẹlẹ Funke Adedoyin papoda laipẹ, eleyii to mu ki INEC seto idibo miiran.
OLUWA bá na ọwọ́, ó fi kàn mí lẹ́nu, ó sì wí fún mi pé,“Wò ó, mo ti fi ọ̀rọ̀ mi sí ọ lẹ́nu.
 “O yẹ ki won mo pe ọgbọ̀n egberun (30,000)
Ighalo kede ifẹyinti ninu ere bọọlu fun Super Eagles lẹyin idije 2019 AFCON to waye lorilẹ-ede Egypt.
 Ó ní báṣẹ ́ lọ ̀ ( b.
Ọba mi a ṣèkan bí àpáta gbànyàyà, Ọba kannáà yìí a ṣe òmíràn bí ọ̀kúta wẹwẹ tí ń bẹ nínú erùpẹ̀.
Bọde George: Àwọn èèyàn mọ ẹni to yìnbọn pa Adeniyi Aboriṣade
Níbẹ̀ ni n óo máa gbé láàrin àwọn eniyan Israẹli títí lae.
L'Ọjọru ni igbimọ amuṣẹya ẹgbẹ APC kede pe Giadom ko si lara awọn oloye ẹgbẹ naa mọ, wọn ni ko si ni ipo to di mu tẹlẹ mọ lati ọdun 2018.
Ó tẹ̀ síwájú sí i pé ìwà àwọn akẹ́kọ̀ọ́ akẹgbẹ́ òun láti gbùngbùn China tí ń yí padà.
 Bakan naa ni o rọ awọn oniroyin lati fi otitọ ṣiṣẹ wọn paapaa nipa titẹle ilana ati ofin iṣẹ wọnIpade awọn tọrọ kan naa ni ọpọ ẹgbẹ oṣelu, awọn ẹlẹgbẹjẹgbẹ, awọn ile-iṣẹ ẹka adani, awọn aṣoju awọn oṣiṣẹ alaabo, ati awọn miiran wa nibẹ.
Eyi wa lara eto fifun ọpọ eeyan labẹrẹ yi kaakiri ilẹ naa.
Nípasẹ̀ rẹ ni n óo bukun gbogbo ìdílé ayé.
Lẹ́yìn náà, ó jáde lọ sí ibi orísun omi náà, ó da iyọ̀ náà sí i, ó sì wí pé, “Báyìí ni OLUWA wí, ‘Mo sọ omi yìí di ọ̀tun lónìí, kò ní fa ikú mọ́, bẹ́ẹ̀ ni kò ní ba oyún jẹ́ mọ́.
Bi Ijọba àpapọ̀ Nigeria ti ri owó ori gbà ni Èkó ju gbogbo àwọn ilú yoku lọ tó, kò si irànlọ́wọ́ lati tú ọ̀nà Ijọba àpapọ̀ ṣe.
 Ni ibudo idibo Ademola Adeleke, Abegunde/Sagba Ede North ni ijọba ibilẹ Osun West, aworan re  nibi ti o ti n se ojuse  gege bi omo bibi orile-ede Naijria ti o fe ilosiwaju fun orile-ede re.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Access Bank: A kò dá ẹnikẹ́ni dúró lẹ́nu iṣẹ́, Coronavirus ló jẹ́ ká ti àwọn ẹ̀ka wa 18 Ọ̀pẹ̀̀ 2018 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 4 Èbibi 2020 Oríṣun àwòrán, others Àkọlé àwòrán, Wọn ni Covid-19 lo da iṣẹ duro lawọn ẹka kan Ile ifowopamọ Access Bank ti sọ pe irọ pata ni ọrọ kan to n tan kalẹ loju opo ikansiraẹni pe ile ifowopamọ naa n da awọn oṣiṣẹ rẹ duro.
Àdéhùn èmi àti Ọlọ́run ni pé èèyàn láti Yewa yóò jẹ́ Gómìnà -Amosun Àwọn oun àjòjì tó ṣẹlẹ̀ nígboro níbi àjọyọ̀ ìṣẹ́gun Buhari Àwọn kókó márùn-un tí ìdìbò ààrẹ Naijiria kọ́ wa Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Wale Ahmed: APC kò ṣe mọ̀dàrú, PDP ló fẹ́ gbà'jọba tipátipá Babajide Sanwo-Olu to n dije fun ipo gomina labẹ asia ẹgbẹ oṣelu APC ni Tinubu n ṣe atilẹyin fun ninu ibo gomina ọsẹ to n bọ.
Ayeye igbami eye ohun lo waye nile itura Eko Hotels and Suites, Victoria Island, nilu Eko.
Awon ti oro kan ninu ajo awon orile-ede alajo sowopo nile adulawo Economic Community of West African Countries (ECOWAS) ti tenumo idi pataki ti won fi gbodo yo awon idena ti o wa ninu eto kara-kati ni awon ekun naa.
ipinnu isakoso ijoba aare Buhari lati gbogun ti iwa ibaje, iwa jegudu jera koi
Wọn kò ní bá àwọn eniyan mi péjọ mọ́, tabi kí á kọ orúkọ wọn mọ́ ilé Israẹli, tabi kí wọ́n wọ ilẹ̀ Israẹli mọ́.
Leyin isele iji lile to pa awon eniyan mejo lojo Abameta, osu kefa.
Ṣọ́ọ̀ṣì tí wọ́n ti ń fi ọtí àmupara bá Ọlọ́run sọ̀rọ̀ ní kí ìjọba dẹwọ́ọ òfin títà ọtí lásìkò Covid-19 'Ọkọ mi mú ọ̀bẹ jáde lápò, ó sì gé imú mi jábọ́.
Jehoramu ní arakunrin mẹfa, tí wọ́n jọ jẹ́ ọmọ Jehoṣafati, orúkọ wọn ni, Asaraya, Jehieli, ati Sakaraya, Asaraya, Mikaeli ati Ṣefataya.
C Phillips ni nǹkan pàtàkì láti kọ́ ọmọ Yorùbá.
 agígírí fẹ ́ ràn ajíbógun ọwá obòkun púpọ ̀ nítorí pé ọmọ ìyá rẹ ̀ ni .
Agbenusoro ile igbimo asoju-sofin ohun wa ro awon osise alaabo lati ri pe ilera asofin Melaye pe daradara ki won o to pe sile ejo.
Ọ̀wọ́n epo-ọkọ̀ ti ó gbòde ni igbà ọdún Kérésìmesì ti ó kọjá àti ni ibẹ̀rẹ̀ ọdún tuntun ti lọ ṣùgbọ́n epo-ọkọ̀ wọn ni ọ̀pọ̀lọpọ̀ ilé epo ni àwọn olú ilú yókù ju ti Èkó.
Bakan naa nile asofin Amẹrika tun fi aidunnu rẹ han si ohun to pe ni iwa titi awọn ileesẹ iroyin ati ayelujara pa ni Naijiria, pẹlu afikun pe igbesẹ ijọba ati tawọn ileesẹ agbofinro rẹ safihan aikọbi ara si ominira araalu.
 a pin sí ìpele àrùn ipa ọ ̀ nà orùn tí a gbàgbé .
Wọn ni awọn alaṣẹ ile aṣofin fẹ ẹ dena ominira awọn oniroyin ni.
O ni ajọ ọhun ti gbẹsẹ le kiko ohunkohun wọle si orilẹ-ede yii ni gbogbo ẹnu ibode ilẹ to wọle si Naijiria.
Babaláwo rèé pẹ̀lú afurasí adigunjalè mẹ́rin láhàmọ́ọ́ ọlọ́pàá Aàrẹ Buhari buwọlu yíyí orùkó àwọn ibùdókọ ọkọ ojú ìrìn bíi ti Apapa padà fi sọrí àwọn èèkàn ìlú 'kò sí ẹ̀rí àrídájú níńu ọ̀rọ̀ Akpabio' Ìyá òòṣà fẹ̀sùn àjẹ́ kan ìyá ẹni ọdún 90, aráàlú bá sọ ọ́ lókò pa Nàìjíríà ṣí àwọn ilé ìwé padà; Ìdánwò WAEC á bẹrẹ lẹyìn ọdún Iléyá!
Aworan aṣa ati iṣe awọn ọmọ Yoruba Awọn aworan awodamiẹnu latilẹ Afrika lọsẹ yi Ben Okri, to je akọwe ami ẹyẹ Booker ni ''iṣẹ ọna yi jẹ ọkan gbogi ti wọn ṣe awari rẹ ni bii aadọta ọdun sẹyin'' Oríṣun àwòrán, Bonhams Àkọlé àwòrán, Ọpo eeyan ri Ben Enwonwu gẹgẹ bi oludasile ise ọna igbalode lorilẹẹde Naijiria Alakoso iṣẹ ọna igbalode ni ile afihan iṣẹ ọna Bonham, Giles Peppiatt ni ẹni to ri iṣẹ ọna Adetutu nigbati ẹnikan ni ko wa a ṣe ayẹwo rẹ ni filati onile kẹjẹbu kan ni ariwa ilu London.
"Akinlade ni ibi ti ọ̀rọ̀ náà lágbára dé, àwọn ẹgbẹ́ dókìta ló dáwó láti ra ìbòmú ti wọn fẹ́ pin fun àwọn ọmọ ẹgbẹ́ tó kù Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Niyi Akinmolayan tó ṣe fíìmu àwòrán-dèèyàn Cartoon nípa COVID-19 tó la ayé já ní N ""Pálí ìbòmú ńla méjì ti a rà, owó rẹ̀ to mílíọnù kan náírà."
Nítorí pé ọpọlọpọ orílẹ̀-èdè ni o ti kó lẹ́rú, gbogbo àwọn tí wọ́n ṣẹ́kù ni wọn yóo sì kó ìwọ náà lẹ́rú, nítorí ẹ̀jẹ̀ àwọn eniyan tí o ti pa, ati ìwà ipá tí o hù lórí ilẹ̀ ayé, ati èyí tí o hù sí oríṣìíríṣìí ìlú ati àwọn tí wọn ń gbé inú wọn.
Ọ̀ràn wọ̀nyí ti fi hàn wípé àhesọ ni ó máa fi ń bẹ̀rẹ̀.
atejade kan lati ile –ise to n mojuto eto ise ati igbanisisẹ so  pe wiwa ti awon asoju orile ede Amerika wa si
Aṣofin Ọbasa wa sọ pe ṣiṣe alekun owo naa ṣe pataki lati jẹ ki ijọba ṣe alekun owo to n wọle labẹle nitori eyi to n wọle lati ọdọ ijọba apapọ kere pupọ.
Ayederu fidio yii kan naa ni wọn pin ninu oṣu kẹfa lori ayelujara ti wọn ni pe o nii ṣe pẹlu aawọ to n lọ lwọ laarin apa orilẹede Cameroon to n sọ ede oyinbo ati ijọba nibi maili to din diẹ ni ẹgbẹrun meji lapa iwọ oorun Ethiopia.
Ìbáwí ọlọ́gbọ́n dàbí òrùka wúrà,tabi ohun ọ̀ṣọ́ tí a fi wúrà ṣe,fún ẹni tí ó ní etí láti fi gbọ́.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ọbásanjọ́: Ojú bọ̀rọ̀ kọ́ lẹgbẹ́ alájùmọ̀se yóò fi gba ìjọba 29 Ìgbé 2018 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ọ̀pọ̀ igbà ni Olúsẹ́gun Ọbásanjọ́ ti sọ̀rọ̀ àbùkù sí ìjọba Muhammadu Bùhárí Ààrẹ Naijiria nígbà kan rí Olusegun Obasanjo ti ní kí àwọn ẹgbẹ́ atúnlùúṣe gbára dì nítorí àtakọ ń bọ̀ láti ọ́wọ́ ìjọba to wà lóde yìí.
Aarẹ Rajoelina sọ pe orilẹ-ede naa n sisẹ pẹlu awọn akọṣẹmọṣẹ lati ilẹ okeere, lati ṣọ agbo naa di abẹẹrẹ.
    Báyìí ni ìtàn kejì parí nínú ilé Òpìtánparapọ̀.
Sibẹ o pa gbogbo nǹkan wọnyi mọ́ sọ́kàn rẹ,mo mọ̀ pé èrò ọkàn rẹ ni pé,
Ajọ to n mojuto iṣẹlẹ pajawiri nipinlẹ Eko, LASEMA ṣalaye fawọn oniroyin nibi ipade iroyin kan lowurọ ọjọbọ pe iwadii yoo waye lati mọ awọn ohun to ṣokunkun ati awọn ohun to ku diẹ kaato ṣaaju ijamba ile wiwo naa.
Kpomassie rii ka ninu iwe pe ilu kan wa ti orukọ rẹ n jẹ Greenland, nibi to tutu debi wi pe ejo ko si nibẹ.
APC ṣalaye pe Giadom kọwe fipo silẹ lọdun 2018 lati dije ipo igbakeji gomina nipinlẹ Rivers.
Eniyan to ti padanu ẹmi wọn lati bi oṣu mẹsan nitori ibi ti ile naa wa , koda osisẹ wọn kan naa jana mọ mọto lẹnu.
Ninu oṣu Kọkanla bakan naa ni wọn ji alaga ẹgbẹ oṣelu African Democratic Congress ADC), Bisi Ogungbemi, ati awọn oloye ẹgbẹ mẹta mi i, lara eyi ti oludije fun ipo sẹnetọ kan Jide Ipinsagba wa.
Lọjọ abamẹta to kọja ni alaga ajọ INEC, ọjọgbọn Mahmood Yakubu ṣalaye awọn idi ti wọn fi sun eto idibo naa siwaju to si ni gbogbo ipolongo ti wa sopin lọjọbọ ọsẹ kan naa.
Lati mọ eyi, ao nilo lati sakiyesi ayipada to n deba itankalẹ rẹ ni ibi kan lati ibẹrẹ ọdun si opin ọdun.
"O ni, ""Mi o ni lero lati wa iṣẹ kankan."
Daura ni ẹni to ba kunju iwọn julọ ni wọn gbọdọ gbe ijọba fun ni ọdun 2023, wọn ko gbọdọ fi ṣe ọrọ ẹkun mi lo kan.
Oríṣun àwòrán, Nigeria Army Àkọlé àwòrán, Aworan awọn ọmọ ogun naa farapa nibi iṣẹlẹ naa O sọ pé ''àwọn ọmọ ẹgbẹ́ Shiite péjọ sí agbègbè Maraba, wọ́n n gbìyànjú láti wọ ìlú Abuja.
" Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Cute Abiola: Agbẹjọ́rò ni bàbá mi fẹ́ kí n ṣe àmọ́ àyànmọ́ mi ni àwàdà20 Òkùdu 2020 Yoruba Films: Adewale Elesho ní àìkàwé ló ṣàkóbá fún òun nínú iṣẹ́ tíátà23 Òkùdu 2020 Omo Ibadan: Ó wù mí láti kàwé di dókítà oníṣègùn òyìnbó tàbí ọ̀mọ̀wé ni Fáṣítì - Lizzy Jay ọmọ Ibadan16 Èbibi 2020 Opeyemi Ayeola: Inú sinimá ni ọkọ mi ti rí mi, ọdún mẹ́ta ló fi wá nọ́mbà mi, kó tó fẹ́ mi6 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 3 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 5 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Nígbà tí òjò bá ṣú dẹ̀dẹ̀, orí ilẹ̀ ni yóo rọ̀ sí, níbi tí igi bá wó sí, níbẹ̀ náà ni yóo wà.
A ti da ẹẹdẹgbta miliọnu naira sọtọ fun iranwọ idokoowo kekeke a o si gba ọdọ ẹgbẹrun marun-un si iṣẹ ijọba ni oṣu diẹ si isisiyii""."
Nígbà tí Jesu wọ inú Tẹmpili, ó bẹ̀rẹ̀ sí lé àwọn tí ń tajà jáde.
O ni ko si iwe faili kankan to sọnu tori awọn ṣe eto gbigbe ibi ti iṣẹ de duro le awọn tọrọ kan lọwọ daadaa.
Eleasari láti inú ìdílé Mahili, Eleasari kò bí ọmọkunrin kankan.
Amọ, iroyin kan ni wipe oun ni ẹyinoju Alaga Ẹgbẹ Oselu APC, Asiwaju Ahmed Tinubu ati Gomina Ipinlẹ Osun, Rauf Aregbesola Alhaji Fatai Akinbade African Democratic Congress (ADC) < Padà lọ sí ọ̀dọ̀ Olùdíje Kíni ọjọ́ ìbí yin?
Ó ní, “Mo fẹ́ kí ẹ mọ̀ dájúdájú pé, owó ọrẹ talaka opó yìí ju ti gbogbo àwọn yòókù lọ.
Alaga INEC sàlàye pé lẹ́yin ti àwọn ti fi gbèdèke fún ìdìbò abẹlé APC ti wọn o si mu èsì ìdìbò abẹle ti won wa ni àwọn o fi ka wọn kún ti wọn si gbe ẹjọ lọ si ilé ẹjọ.
Oríṣun àwòrán, @FAAN_Official Àkọlé àwòrán, Hadi so pé ìṣẹlẹ manigbagbe ni igboruko jade náà jẹ.
Awọn ọmọ Nàìjíríà yarí lórí àfikún ọjọ ìséde tí Ààrẹ Buhari kéde Lockdown: Àwọn ọmọ Nàìjíríà yarí lórí àfikún ọjọ ìséde tí Ààrẹ Buhari kéde Oníruuru fọnran ló lu orí àtẹjisẹ twitter pa láti fi han bi olúkúlùkù ṣe n se ààbò lóri àdúgbò wọ́n.
Usman din dundun iya fun Tyron Woodley lati di ọmọ Afirika akọkọ ti yoo bori ni idije naa.
Ó ṣeéṣe kí ọ̀rọ̀ yìí níí ṣe pẹ̀lú ìpè tí àwọn aṣòfin pè fún ìyọkúrònípò àwọn aṣíwájú ẹ̀ka iléeṣẹ́ ológun gbogbo lórílẹ̀èdè Nàìjíríà nítorí gbọnmọgbọnmọ ìkọlù àti ìpànìyàn tó ń wáyé.
O ni laijẹ pe a gbogun ti iwa
ipinle Bauchi, o ni ile-ise agbofinro ti pese eto aabo to peye si gbogbo ijọba
Àwọn olórí alufaa ati àwọn amòfin, pẹlu àtìlẹ́yìn àwọn eniyan pataki-pataki ní ìlú, ń wá ọ̀nà láti pa á, 
Bi o ba ti n bawọn pin ọrọ yii, iwọ naa ti dara pọ mọ awọn ti BBC ati ọpọ awọn amoye lawujo ni wọn n dakun wahala iroyin ẹlẹjẹ to gbode.
Wọ́n ti búra wọlé fún Akinwunmi Adesina gẹ́gẹ́ bí ààrẹ Banki ilẹ̀ Afrika, AfDB Ìwọ tó ń ṣí ara sílẹ̀ lọ ṣọ́ọ̀ṣì, ṣé apàyàn kọ́ ni ẹ́ báyìí?
Oríṣun àwòrán, Reuters Igbakeji Minisita naa ni oun gbagbọ pe oun yoo bori aarun naa, ti ago ara oun yoo si pada si po.
Ó di ogún ọdún tí mo ti dé ọ̀dọ̀ rẹ, mo fi ọdún mẹrinla sìn ọ́ nítorí àwọn ọmọbinrin rẹ, ati ọdún mẹfa fún agbo ẹran rẹ.
Nígbà tí ó di òwúrọ̀ ọjọ́ kejì, bàbá mi jí ní kùtùkùtù ó lọ dúpẹ̀ lọ́wọ́ rẹ̀.
 shasore jẹ ́ agbẹjọ ́ rò Àgba ~ a ti nigeria ( san ) ati okan gboogi ninu egbe awon alagbawi ni orile ede naijiria .
Lásìkò yìí, Kurunmi tí di alágbára ńlá, tí oun ati awọn Ẹ̀gbá pẹ̀lú Ìjẹ̀bú sì ń ṣiyèméjì lórí àwọn òfin tí Ibadan gbé kalẹ ọhun Iyẹn eyi tí Ààrẹ Kurunmi sì ń fura pé, Ibadan fẹ dá ìjọba tiẹ̀ silẹ ni, tó sì fẹ́ gba agbára lọ́wọ́ ìlú Ọ̀yọ́.
O tumọ si pe wọn ko ni jẹ ki awọn eeyan lati awọn orilẹede mii papaajulọ lati awọn orilẹede ti arun covid-19 ba n finra wọ le.
Ọmọ yìí yóo mú kí adùn ayé rẹ sọjí, yóo sì jẹ́ olùtọ́jú fún ọ ní ọjọ́ ogbó rẹ, nítorí iyawo ọmọ rẹ tí ó fẹ́ràn rẹ, tí ó sì ju ọmọkunrin meje lọ ni ó bímọ fún ọ.
Ṣugbọn gbogbo nǹkan wọnyi kò lè tẹ́ mi lọ́rùn, bí mo bá ń rí Modekai, Juu, tí ó ń jókòó ní ẹnu ọ̀nà ààfin ọba.
Bákan náà, ó kọ́ ọpọlọpọ ìlú fún ara rẹ̀, ó sì ní agbo ẹran lọpọlọpọ, nítorí Ọlọrun ti fún un ní ọrọ̀ lọpọlọpọ.
Àyọrísí èyí ni pé láti Jerusalẹmu títí dé Iliriku ni mo ti waasu ìyìn rere Kristi lẹ́kùn-únrẹ́rẹ́.
Ile isẹ ọlọọpa ipinlẹ naa gba ẹnu agbẹnusọ wọn, ASP Moses Yamu sọwipe lati ibẹrẹ ọdun yii ni ikọlu awọn Fulani darandaran ti n waye lagbeegbe naa, ti ọpọlọpọ ẹmi si ti ba isẹlẹ naa lọ.
Nitori naa, o ni gbogbo igba ti iya naa ba bere ohukohunn lọwọ ohun ni oun maa fi fun.
Aare Buhari seleri lati tun oju ona se
Nígbà tí wọn ń gbé ilẹ̀ Ijipti bí àlejò, Ọlọrun sọ wọ́n di eniyan ńlá.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Wo bí Sunday Orimola ṣe gba ikú ẹranko kú ní Ifon ni Ondo lórí ọ̀nà àtijẹ Kò sí ìfòyà tí ẹ bá ti ní nọ́mbà ìdánimọ̀, kékeré ni káàdì ìdánimọ̀ - NIMC Ajọ to n pin kaadi idamọ Naijiria, NIMC, ti sọ pe nọmba idanimọ lo ṣe pataki ju kaadi idanimọ, nitori naa, ki awọn ti ko ba tii ri kaadi wọn gba ma foya.
Awon ile iwosan ijoba fun ile iwe fafiti mejeeji to wa ni Enugu bayii ni  ti Fafiti Naijiria UNTH to wa ni Ituku/Ozala ati ti Fafiti ipinle Enugu to wa ni Parklane, Enugu.
Kaduna-18 FCT-17 Lagos-6 Plateau-5 Kano-3 Kwara-2 Yobe-2 Ekiti-1 Niger-1 Rivers-1 Apapọ awọn to ti ni jẹ 66,439, ti 62,241 si ti ri iwosan.
Ṣugbọn bí ó bá jẹ́ mààlúù náà ti kan eniyan tẹ́lẹ̀, tí wọ́n sì ti kìlọ̀ fún ẹni tí ó ni ín, tí kò sì so ó mọ́lẹ̀, bí ó bá pa eniyan, kí wọn sọ mààlúù náà ní òkúta pa, kí wọn sì pa ẹni tí ó ni ín pẹlu.
Ohun elo ti wọn fi n se awọn nylon ati rọba jẹ ohun to n ba oju ọjọ jẹ, eleyii ti wọn n pe ni ‘polyethylene’.
Bí ẹ̀ṣẹ̀ yín tilẹ̀ pọ́n bí iná,yóo di funfun bí ẹfun.
OLUWA Ọlọrun, tún fi ìran mìíràn hàn mí.
Kí àwọn ọmọ yín má baà wí fún àwọn ọmọ wa ní ọjọ́ iwájú pé, ‘Ẹ kò ní ìpín ninu nǹkan OLUWA.
Nítorí kí ni n kọ, nítorí òmùgọ̀ rẹ rékọjá méjì, òmùgọ̀ rẹ ju méjì lọ.
 Èdè africa máa ń lo ohùn nígbà mìíràn .
titapa si ofin  to ba fẹ waye ni won se
Bi a ko ba tun gbagbe, o ti figba kan naa je olori awon odo fun
Sugbọn ara Sara ko lelẹ nigba to dagba, to si ri pe awọn alawọ funfun lo wo oun dagba ni ilu ọba, UK, eyi lo mu ko pinnu lati se awari orisun ibi to ti sẹ wa lagbaye, to si mu irin ajo rẹ pọn pada wa si orilẹede South Afrika.
Wọ́n gba àpótí ẹ̀rí Ọlọrun lọ́wọ́ àwọn ọmọ Israẹli, wọ́n sì pa Hofini ati Finehasi, àwọn ọmọ Eli mejeeji.
Àgbáríjọpọ ẹgbẹ OPC, fijiláńté VGC, Agbẹkọyà ti bẹrẹ ètò aàbò ní ilẹ Yorùbá Iwadii naa fi han pe, awọn ohun to wa lori ẹrọ alagbeka to n ka igba ti obinrin ba n ṣe nkan oṣu yii, maa n pin lara iwadii wọn pelu ileeṣẹ Facebook.
Osisẹ agbofinro agba fun ibudo itaja naa, Tony, salaye pe ọpẹlọpẹ awọn osisẹ agbofinro, ninu eyi ta ti ri awọn ọlọpa atawọn aabo ara ẹni laabo ilu (Civil Defence) ti wọn tete pana ikọlu tawọn ọmọ Naijiria se si ibudo itaja naa lọjọ Isaẹgun eyi ti wọn fi n gbẹsan.
O kò gbọdọ̀ ní oríṣìí òṣùnwọ̀n meji ninu ilé rẹ, kí ọ̀kan kéré, kí ekeji sì tóbi.
 Awọn to n ṣe iwọde ni ohun ti n won fi sun, ko si ohun to da ti ko ni idakeji nitori naa, ẹ ba wa bẹ ijọba ki wọn yanju ọrọ yii Oríṣun àwòrán, @Omojuwa Amọ o wa woye pe isunsiwaju gbogbo igba yii ti mu irẹwẹsi ba ọkan olukọ ati akẹkọọ.
Wọ́n dó tì í, wọ́n sì bá a jagun.
Má wá nǹkan ńlá fún ara rẹ.
ng Kí ló ń fa 'tsunami' tó pa 220 ènìyàn ní Indonesia?
Ọ̀wọ̀n ìkùukùu náà wà ní ẹ̀bá ẹnu ọ̀nà àgọ́.
Mabinuori ni oun ko fẹ iyawo oun mọ nitori iwa ipa ati wi pe ọlọkan lile lo jẹ.
Ifidirẹmi ninu idibo gbogbogbo to kọja lo sokunfa bi Bukola Saraki ko ṣe pada wa si ile aṣofin agba bo tilẹ jẹ pe yoo fẹ ṣoro diẹ fun un lati di ipo naa mu.
Jehu pàṣẹ pé kí àwọn ọmọlẹ́yìn rẹ̀ mú wọn láàyè.
Bo ṣe n pọ si ni America ati Europe, si ti n mu ki iporuru ọkan wá, nipa eto ọrọ aje agbaye to ti dẹnu kọlẹ.
Ẹ gbọ́ tèmi, ẹ dá àwọn arakunrin yín tí ẹ ti kó lẹ́rú pada, nítorí ibinu OLUWA wà lórí yín.
Ti burẹdi meje ńkọ́, tí mo fi bọ́ ẹgbaaji (4,000) eniyan ati iye apẹ̀rẹ̀ àjẹkù tí ẹ kó jọ?
 Ó jẹ ́ ọ ̀ rọ ̀ tàbí gbólóhùn tí ìtumọ ̀ rẹ ̀ kò dúró sójú kan .
oludije miiran fun egbe naa ti yoo dije fun eto idibo odun 2019.
Nítorínáà, àwọn ọlọ́pàá wòye wí pé ìròyìn àìtọ́ ni.
Ọpọ ipade alaafia lorisirisi lo waye lati jẹ ki ọba Kosoko pada silu Eko, sugbọn awọn oyinbo ko gba, wọn ni ki Oshodi nikan maa pada bọ wale, sugbọn o fi aake kọri lati ṣe bẹẹ, nitori ẹyẹle kii ba onile jẹ, ko di ọjọ ipọnju ko yẹri.
Ẹlòmíràn ń ṣe àròyé nípa irun orí òun wí pé kò pọ̀ tó òmíràn a wí pé irun orí kò dúdú tó bí ó ti yẹ bẹ́ẹ̀ ni òmíràn ń ṣe àròyé wí pé irun tí ó ti pọ̀ ri bẹ̀rẹ̀ sí dínkù.
Lara awọn to kọkọ jade sọrọ ni iyawo ọmọ rẹ Fatima Ganduje Ajimobi.
Ojúlówó wúrà tí wọ́n fi òòlù lù ni kí wọ́n sì fi ṣe gbogbo rẹ̀.
Wọn kò náání ọ̀rọ̀ rẹ̀, wọ́n sì ń kẹ́gàn àwọn wolii rẹ̀ títí tí OLUWA fi bínú sí wọn, débi pé kò sí àtúnṣe.
Ayọ̀ ń bẹ fún ẹni náàtí kò gba ìmọ̀ràn àwọn eniyan burúkú,tí kò bá àwọn ẹlẹ́ṣẹ̀ rìn,tí kò sì bá àwọn ẹlẹ́gàn kẹ́gbẹ́.
Ní apá karùn-ún Ìgbésí-ayé Alákọ̀wé, ẹ jẹ́ ká yà sí agbègbè Waterloo, létí bèbè gúsù odò Thames, ní olú-ìlú Igilàńdì wa yìí.
Nígbà tí Mose sọ ohun tí OLUWA sọ fún àwọn ọmọ Israẹli, wọ́n káàánú gidigidi.
Òsìsẹ́ Custom tó wọ asọ Ọ̀gá Àgbà CG ti wà ní ile iwosan!
"Oríṣun àwòrán, Getty Images ""Wọn yóò mú àwọn obìnrin wá tí wọ́n á máa bá lòpọ̀."
Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Lebanon Explosion: Ibùdó tí igba èèyàn ti kú lóṣù kẹjọ ní iná míràn ti jó Ikọ alagbelebu pupa tilu Beirut ni ko sẹni to fara pa tabi ku ninu ijamba ina naa amọ awọn eeyan kan, to sun mọ ina naa, ko le mi daadaa.
Ẹ̀yin ènìyàn mi gbogbo, ẹ má ṣe pa èrò kékeré fún ara yin láéláé, ẹ máa lépa nǹkan tí ó tóbi, ẹni tí ó lepa nǹkan ńlá tí kò le bá ǹkan ńlá olúwarẹ̀ yóò bá ǹkan tí ó súnmọ́ nǹkan ńlá, ṣùgbọ́n ẹni tí ó lépa nǹkan kékeré kò ní í lè duró ní awùjọ àwọn alágbára.
OLUWA Ọlọrun, n kò sọ ara mi di aláìmọ́ rí láti ìgbà èwe mi títí di ìsinsìnyìí, n kò jẹ òkú ẹran rí, tabi ẹran tí ẹranko pa, bẹ́ẹ̀ ni ẹran àìmọ́ kankan kò kan ẹnu mi rí.
Iṣẹ ati ojuṣe amotẹkun lawọn ipinlẹ Guusu-Iwọ Oorun Naijiria tii ṣe ilẹ Yoruba ti wa ninu alakalẹ ofin to ti agbekalẹ rẹ lẹyin ireti siwa pe wọn yoo ṣe ni ibamu pẹlu ofin naa lai foju di ẹtọ ẹnikẹni.
Amọ, Obaseki dahun wi pe oun ko laṣẹ lati burawọle fun awọn mẹrinla naa, lẹyin ti wọn kọ lati ṣe ayẹyẹ iburawọle.
Gbogbo èyí kò sì tó nǹkan lójú rẹ, Ọlọrun, o tún ṣèlérí nípa ìdílé èmi iranṣẹ rẹ fún ọjọ́ iwájú, o sì ti fi bí àwọn ìran tí ń bọ̀ yóo ti rí hàn mí, OLUWA Ọlọrun!
Òjú ẹsẹ̀ ni wọ́n gbé ọmọ nàá lọ silé ìwòsàn.
“Ẹ kò gbọdọ̀ máa ṣe bí a ti ń ṣe níbí lónìí, tí olukuluku ń ṣe èyí tí ó dára lójú ara rẹ̀.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù AfCFTA: Adùn wo gan ló wà nínú adehun okoòwò kan l'Áfíríkà?
"Ẹ gbiyanju tiyin, ti awọn ololufẹ BBC News Yoruba kan ree Ọmọkùnrin tó pa ọmọ igbákejì Gómìnà Ondo gba ìdàjọ́ ikú '$800 ni Amẹ́ríkà ń fún ọmọ Yorùbá tó bá gba ìṣẹ́ ológun rẹ̀ lóṣooṣù' Ẹ wo ọmọ ọdún méjì tó mọ orúkọ orílẹ̀èdè 40, àwọn ààrẹ l'ágbàáyé láì lọ síléèwé Ìpanu ‘Cheese ball’ ni wọ́n fi jí Ikimot gbé, àmọ́ ó padà sílé lẹ́yìn ọdún márùn-ún ìfipábánilòpọ̀: Má dákẹ́ - Oluwaseun Wọ́n ta ère Ọ̀ṣun Osogbo sí Togo - Bàbá Ọṣun figbe ta World TB Day: ""Ó dùn mí jù pé ń kò rí ọmọ mi fún ọdún kan"" World water day: Ẹrin Ijesa, Ọ̀ṣun Oṣogbo, àwọn ibùdó ìgbafẹ́ omi tí ó yẹ kí o mọ̀ Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí 2 sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 2:23 Fídíò, Water Generator: Ó leè ṣiṣẹ fún wákàtí mẹfà, kó tó sinmi, Duration 2,2310 Òkùdu 2020 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn."
Àwọn ààrùn to niṣe pẹ̀lú ọpọlọ abbl O fi kun pé, wọ́n ti lòó láti fi ṣe ìtọ́ju ẹni to ni ààrùn fòníkú, fọ̀la dìde.
Ọ̀pọ̀lọpọ̀ ìnira lojú àwọn ọ̀dọ́ ilẹ̀ Áfíríkà t''o ń wá ìgbé ayé rere lọ sí Yúróòpù ń rí Ìtàn ìgbésí ayé Oshodi, ọmọ Tápà léǹpe tó di akọni ní ìlú Eko Eruku ẹjọ́ tún sọ lórí ìgbéyàwó Toyin Abraham àti Adeniyi Johnson tó forí ṣánpọ́n Ẹ wo bí ìpínlẹ̀ Eko, Ondo àti Oyo yóò ṣe dá ilé ìjọ̀sìn padà Aarẹ wa kesi i lati da gbogbo ẹru ijọba to wa ni ọwọ rẹ pada fun adele dari ajọ naa to wa nibẹ lọwọlọwọ.
Ẹ ní ìfẹ́ sí ara yín.
Bakan naa lo sọrọ lori awọn Boko Haram ati pe 2021 ni ọwọ maa tẹ Shekau olori wọn.
Ìgbà tí a béèrè isẹ́ tí a fẹ́ ṣe yìí, o ní òun fẹ́ kọ́ ilé ‘Ìgbéga-ọ̀run’.
Nítorí pé mo pa àwọn òfin OLUWA mọ́,n kò sì ṣe agídí, kí n yipada kúrò lọ́dọ̀ Ọlọrun mi.
hepataitisi a ( tí a mọ ̀ tẹ ́ lẹ ̀ sí àjàkálẹ ̀ hepataitisi ) jẹ ́ àjàkálẹ ̀ àrùn kan tó jẹ ́ ara àwọn àìsàn-kẹ ̀ kẹ ̀ tó máa n bá ẹ ̀ dọ ̀ jà èyí tí kòkòrò-àrùn hepataitisi a { hav } máa n tàn kálẹ ̀ .
Olurawo aare lori iroyin ati ipolongo, Femi Adesina so pe aare yoo lo anfaani naa lati tun soro nibi ayeye ajodun ogun odun ti  orile ede Rome wa lara ile-ejo agbaye to n ri si iwa odaran.
Wọ́n ṣìnà ní ti ìdájọ́ nítorí pé Ọlọrun ti dá aláṣẹ ayé yìí lẹ́bi.
Ni deede aago mẹwa ku isẹju diẹ ni olujẹjọ naa ati awọn afurasi yoku to n jẹjọ pẹlu rẹ de sile ẹjọ, ninu asọ ọgba ẹwọn alawọ eweko ti wọn maa n wọ.
Oríṣun àwòrán, Baba Oloye Àkọlé àwòrán, Awọn dokita bẹrẹ iwọde itaniji lori wiwawọ iba lassa bọlẹ nipinlẹ Ọsun Dokita Ọlajumọkẹ ni, biotilẹjẹ wipe ẹni tarun yii ran lọ sọrun ni ibudo ẹkọsẹ isegun fasiti Ọbafẹmi Awolọwọ nilu Ile ifẹ, wa lati ipinlẹ Ondo, o se pataki lati tete fi gbogbo awọn to fara kanra lọna kan tabi omiran pẹlu alaisi naa sabẹ aabo, ki arun naa to tan kale-n-kako.
Bayii, o le ni milionu meji asatipo ti won n satipo lati aarin gbungbun ila oorun ni eyi ti yoo yo sile ni kete ti Amerika ba ti yowo kuro.
Ẹni to bori: Mali Morocco vs Kenya.
Ìlú Ṣamiri tí ó wà ní agbègbè olókè ti Efuraimu ni ìlú rẹ̀.
To ò, mo sọ fun yín o!
Àkọlé àwòrán, Ọ̀rọ̀ lórí ìfilọ́lẹ̀ ìjọba Kayode Fayemi gẹ́gẹ́ bí gómìnà tuntun fún Ìpínlẹ̀ Ekiti Fayose ti kọ iwe ranṣẹ pada si ajọ to n ri si iwa ajẹbanu ati siṣe owo ilu kumọ-kumọ EFCC tẹlẹ pe ọjọ kẹrindilogun oṣu kẹwa ti awọn jọ fi adehun si l'oun yoo yọju si wọn.
Ọjọgbọn Adeyeye sọ pe oun gba ijọba ni imọran pe ki wọn o maa wulẹ ṣe ayẹwo agbo ti orilẹ-ede Madagascar ko ranṣẹ.
Ni ọjọ Ẹti ni ireti wa pe El-Zakzaky yoo gunlẹ pada si Naijiria, papakọ ofurufu Nnamdi Azikwe nilu Abuja si ni yoo balẹ si.
Ọba bèèrè lọ́wọ́ rẹ̀ pé, “Kí ni o fẹ́?
Ti ẹni naa ba sa lọ, ori rẹ ni gbogbo atunbọtan ẹjọ yoo da le lori.
O ni ijọba ibilẹ mẹrindinlogun nínú eyi ti eto idibo yoo ti waye kaakiri lonii.
Wọn tun ni idajọ ọhun tabuku Naijiria gẹgẹ bi orilẹede olominira.
"29 Owewe 2020 Fídíò, Akomolede àti Asa lórí BBC Yorùbá: Mọ̀ síi nípa ẹ̀kún ìyàwó níbí3 Bélú 2020 Fídíò, Akomolede Yoruba: Ìtàn ọ̀rẹ́ tó fi ògùn gba ọkọ ọ̀rẹ́ rẹ̀ nílùú òyìnbó rèé15 Owewe 2020 Fídíò, Akinwumi Isola: Wo ohun tí Abeni fi ojú ọkọ rẹ rí tórí iṣẹ́ bọ́ lọ́wọ́ rẹ̀ nínú ìwé ""Nitori Owo""27 Ọ̀wàrà 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?"
Aare Buhari lo je ipe Oba Mohammed V1 llati wa si orile ede naa fun ipade pataki, ni eyi ti yoo je ki awon adari mejeeje yii jo jiroro lori eto oro aje ati igbe-aye gbadun orile ede won.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Amotekun: Soyinka fèsì padà fún Balarabe Musa pé ó kùnà lóríí ikọ̀ aláàbò náà 21 Sẹ́rẹ́ 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 22 Sẹ́rẹ́ 2020 Ọjọgbọn Wole Soyinka ti dasi ọrọ Amọtẹkun to n ja rain rain ni Naijiria eyi ti wọn ni gomina tẹlẹ nipinlẹ Kaduna, Balarabe Musa sọ nipa ikọ alaabo Amotekun.
Òpó mẹrin ni aṣọ títa tí ẹnu ọ̀nà yìí ní, pẹlu ìtẹ́lẹ̀ idẹ mẹrin.
pe ni “ Iwa amunisin buruku” .
Àtipa àwọn Ilé-iṣẹ́ Akọ̀ròyìn, ìyọlẹ́nu àwọn alátakò, ìfòfinlíle mú àwọn ìdásílẹ̀ tí kì í ṣe ti ìjọba (NGOs) àti ìdiwọ́ fún àwọn mìíràn láti sọ̀rọ̀ tàbí ṣe àfihàn ara wọn ní ààyè òṣèlú.
ati pe awọn miran ni igba miran, ibi ti eeyan wa tẹlẹ maa n san ju ibi tuntun lọ ti eeyan ko ba kiyesara.
Ninu aba isuna naa, oniruuru ileesẹ ijọba ati lajọlajọ ni ijọba se alakalẹ iye ti wọn yoo naa fun ọdn to n bọ, to si bu owo naa fun wọn.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ọba Èkó; Ẹ dìbò fún Bùhárí, ó dára ju Ọbásanjọ́ lọ 1 Èbibi 2018 Oríṣun àwòrán, @GbengaGOLD Àkọlé àwòrán, Akiolu ní tí Bùhárí bá se ẹ̀ẹ̀kejì, ọrọ̀ ajé Nàíjíríà yóò rú gọ́gọ́ síi Ọba Ilu Eko, Rilwan Akiolu ti gba awọn ọmọ Naijiria ni imọran lati fun Aarẹ Muhammadu Buhari laaye lati se aarẹ fun igba keji.
Ṣugbọn nisinsinyii mò ń bọ̀ wá sọ́dọ̀ rẹ.
 lára àwọn oyè pàtàkì tí ó wà ní ìlú ilésà gangan ní wọ ̀ nyí .
Sugbọn awọn kan ni kii se ẹbi olóngbo àti ẹlẹdẹ ni kan.
Ninu gbogbo ìlérí dáradára tí OLUWA ṣe fún ilé Israẹli kò sí èyí tí kò mú ṣẹ; gbogbo wọn patapata ni ó mú ṣẹ.
Èmi wí tèmi, àmọ́ ẹnu ọlọ́rọ̀ lọ̀rọ̀ ti ń dùn.
Ní gbogbo ìgbà, èmi a kúkú máa kan sáárá sí gómìnà Èkó àná – Alàgbà Raji Faṣọla.
sérbíà ( ) , fun ibise gege bi orile-ede olominira ile serbia ( ) , je orile-ede alafileyika to budo si oritameta arin- ati apaguusuilaorun europe , to gbale apaguusu pannonian plain ati apa arin balkani .
Bi wọn se n sare lọ kijokijo, lo pa awọn agbofinro yii lẹrin, ti awọn naa si mu orin sẹnu pe awọn rẹyin awọn alagidi.
Àwọn tí wọ́n gbé pósí bá dúró.
OLUWA, mo ti gbọ́ òkìkí rẹ,mo sì bẹ̀rù iṣẹ́ ọwọ́ rẹ.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ṣeyi Makinde ṣèdánrawò fún ayẹyẹ ìbúra Nigeria swearing-in: Ọjọ́ kò!
O ni ọrọ LAUTECH yoo jẹ afẹnuko ijọba ipinlẹ Ọyọ ati Ọṣun ni.
Ọjọ kẹrinla oṣu karun ni wọn bi i, ọmọ ilu Ilesa nipinlẹ Oṣun ni idile wọn nilẹ Yoruba.
Wọ́n jẹ́ aláìbọ̀wọ̀ fún Ọlọrun, wọ́n yí oore-ọ̀fẹ́ Ọlọrun wa pada sí àìdára láti ṣe ìfẹ́kúfẹ̀ẹ́ inú wọn, wọ́n sẹ́ Ọ̀gá wa kanṣoṣo ati Oluwa wa Jesu Kristi.
Bakan naa, oloye Jim Nwobodo, ti o je gomina teleri fun ipinle Anambra, ti gbosuna fun ijoba ibile Udi lataari eto idibo to waye nipinle naa ni irowo-iroseEto idibo ohun waye ni gbagede Nsukka, ti o si bere laago meta aabo osan lataari aitete de awon ohun elo idibo ohun, eleyi ti ireti wa tele pe yoo bere laago mejila osan.
Ipinlẹ Kano jẹ ọkan lara awọn ipinlẹ ti atundi ibo gomina yoo ti waye lọjọ Abamẹta.
”“ Nitori naa, ni a se n fowosowopo pelu banki agbaye gege bi alajumo-sise-po  lati le ri I pe a mu gbogbo awon ileri wa se lori atunse  to moyan lori ,ni eyi ti yoo ko ipa pataki nigbesi aye omo orile ede Naijiria.
Adugbo Kudeti kii ṣe ibi to pamọ rara.
Olè gbé òrùka ìgbéyàwó mì ní Eko Bakan naa ni wọn sọ pe ibo Gomina ipinlẹ Eko to waye lọjọ kẹsan an, oṣu Kẹta ni aisedeede ati magomago kun inu rẹ.
ni won sun oko nina, sun ile-ise ati awon ohun ini miiran nina.
Ọlọpaa to ba ṣẹṣẹ gba iṣẹ a maa gba owo osu to to aadọta ẹgbẹrun lọdun eyi to tumo si bii ogun miliọnu owo naira lọdun.
Ọkọ igboku si lo gbe posi Maradona lo si ilẹ isinku si Bella Vista ni bi ti o ti sun.
Earlier today, @NGRPresident @MBuhari was briefed by the Service  Chiefs and leaders of other security agencies on the security status of the nation.
Afojusun ijọ Gabola ni lati gba awọn ọmuti mọra ti awọn ijọ mii kii fẹ ni nkan ṣe pọ pẹlu wọn.
awon to fẹ wọ fafiti , ile ẹkọ gbogbonse 
O Fagunwa kú, dúkìá rẹ̀ sì ń fọhùn síbẹ̀, ilé rẹ̀ rèé Iléeṣẹ́ ológun Nàìjíríà àti àwọn ọmọ ẹgbẹ Shiite tún kọlu ara wọn l'Abuja Ìròyìn tó tẹ̀wá lọ́wọ́ sọ pé iléèṣẹ́ ológun Nàìjíríà àti àwọn ọmọ ẹgbẹ́ ẹlẹ́sìn Shiite tún ti n kọlu ara wọn ní agbègbè Maraba nílùú Abuja.
Meje ninu ẹkun idibo mẹrindinlogun to wa ni Ghana ni ajọ EC ti kede esi rẹ bayii.
Wọ́n sọ òru di ọ̀sán,wọ́n ń sọ pé, ‘Ìmọ́lẹ̀ kò jìnnà sí òkùnkùn.
Ìdí tí àlá kabiyesi náà fi jẹ́ meji ni láti fihàn pé Ọlọrun ti fi ìdí rẹ̀ múlẹ̀, láìpẹ́, Ọlọrun yóo mú un ṣẹ.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Buhari, ó yá, tètè kọ̀wé fipò sílẹ̀ - Oyedepo Jàǹdùkú yìnbọ́n pa alága PDP kan l‘Èkó Ọ̀gá ọlọ̀pàá tún ránsẹ́ pe Saraki lóri ìdigunjalè Ọ̀ffà Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí kan sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
"Nigba ti aṣọ Kokomba bands ko wọ igba mọ, lo ba bẹrẹ si ni lu ìlù ""Agidigbo""."
Osinbajo siluu Ikenne, nipinle Ogun,  sugbon
Dafidi bá dìde dúró, ó ní, “Ẹ gbọ́ mi, ẹ̀yin ará mi ati eniyan mi, mo ní i lọ́kàn láti kọ́ ilé ìsinmi fún Àpótí Majẹmu OLUWA, ati fún àpótí ìtìsẹ̀ Ọlọrun wa; mo ti tọ́jú gbogbo nǹkan sílẹ̀, mo sì ti múra tán.
Eyi si ja si ida ogoji ninu ọgọrun eto ọrọ aje ilẹ naa.
Ṣé àwọn oníṣòwò lè yọwó rẹ̀?
Afurasí ikú ọ̀wọọ̀wọ́ l'Akinyele jápa mọ́ ọlọ́pàá lọ́wọ́ Kí ló mú Obasanjo ti ilẹ̀kùn mọ́ ẹbí, òṣìṣẹ́, ojúlùmọ̀ ní ibi òkú àna rẹ̀?
Ojú Lea kò fi bẹ́ẹ̀ fanimọ́ra, ṣugbọn Rakẹli jẹ́ arẹwà, ojú rẹ̀ sì fanimọ́ra.
Erica wọjọgbọn lẹyin ti Biggie ṣafihan fọrọn rogbodiyan ọhun fun un, to si tun sọ pe o ba ohun ini oun jẹ ni bo ṣe da omi sori ibusun olori ile naa, eyii to ni ko ṣetẹwọgba.
Mobolaji Johnson: Yàtọ̀ sí Onikan stadium, wo àwọn dúkìá ìlú tí a fi sọ orí àwọn akọni
kí wọ́n wí fún àwọn àgbààgbà ìlú náà pé, ‘Ọmọ wa yìí ya olóríkunkun ati aláìgbọràn, kì í gbọ́rọ̀ sí wa lẹ́nu.
Ó tún lọ láti ibẹ̀ títí dé Geseri, ó sì pin sí Òkun Mẹditarenia.
LAti ọwọ onka iroyin loju òpó BBC James Gallagher Akọroyin nipa eto ilera Awọn onimọ sayẹnsi n ṣe iwadii lati mọ sii nipa covid 19 ati ipa to le ni lori alaboyun ṣugbọn iṣẹ ṣi n lọ A ko tii mọ boya o ṣeeṣe ki alaboyun ko arun coronavirus ran ọmọ inu rẹ ninu oyun tabi lasiko irọbi, ṣugbọn titi di asiko yii , a ko tii rii ninu omi ọmu ati omi inu ọlẹ oyun Ko tii si iwadii to fidi ẹ mulẹ pe ewu nla wa fun oloyun lori coronavirus ju awón eeyan to ku lọ.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Àwọn àmì tó fi mọ̀ pé wọn ń fipá bá ọmọdébìnrin rẹ lòpọ̀ Tó o bá ṣàdéhùn ìfẹ́ tó ò mú u ṣẹ, ẹ̀wọ̀n lo fi ń ṣeré 'Ìyá mi kó HIV ràn mí, tó sì kú láì sọ fún mi pé mo ni i' Àwọn ará Ijegun fara ya lórí ọ̀pá epo tó ń gbaná ní gbogbo ìgbà O salaye wipe, Eze to n gbe adugbo Arowojọbẹ ni Oshodi, ran ọmọbinrin naa niṣẹ nitori pe o jẹ alaabọ ara nigba to fipa ba lo pọ.
 Àmọ ́ ṣá , ó bẹ ̀ rẹ ̀ ayé rẹ ̀ ní ìlú Ìbàdàn , tí ó jẹ ́ olú ìlú ìpínlẹ ̀ Ọ ̀ yọ ́ ní ìwọ ̀ oòrùn ilẹ ̀ nàìjíríà .
Òǹkọ̀wé Tania Kamrun Nahar tan ìmọ́lẹ̀ sí ìdí tí kò fi yẹ kí ilé yìí di àdàwólulẹ̀:
Ọjọ Ẹti ni Kyari d'oloogbe ni ipinlẹ Eko lẹyin ọsẹ diẹ toni aarun coronavirus.
Isẹlẹ yii kii saba waye lasiko ti takọ-tabo ba n sere ifẹ, amọ to ba waye, ko si ohun ijaya rara nipa rẹ.
Àkọlé àwòrán, Ipade itagbangba BBC Yoruba Gbọngan Mapo re e to kalẹ sori oke Mapo ti wọn fi sọ orukọ rẹ nilu Ibadan.
Aare wa ro iko ohun lati tun bo gbaradi si daradara saaju idije iko obinrin to n bo lagbaye lorile-ede France, lodun 2019.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, '500 level'' ni mo wà nígbà tí mo di adélé Ọba' Igbakeji aarẹ Osinbajo ni tirẹ ki aarẹ Buhari ku oriire opin awẹ Ramadan, o ni Ọlọrun dara si aarẹ ati ijọba gan ni.
Olowo Igbalode se afiwe Dagrin pẹlu 2pac Shakur ọmọ ilẹ Amerika, ti oun na ku lewe, to si ni ki ẹlẹda dẹ ilẹ fun Dagrin.
Wọ́n sì kọ́ ibi ìdáná wọn mọ́ ara ògiri.
Wolii Jeremaya bá dá wọn lóhùn pé, “Mo gbọ́, n óo gbadura sí OLUWA Ọlọrun yín bí ẹ ti wí; gbogbo ìdáhùn tí OLUWA bá fún mi ni n óo sọ fun yín, n kò ní fi nǹkankan pamọ́.
"Ẹyin lẹ fun mi ni orukọ ọlọla.
Ikoyi Ile Farmers Herders Clash: Àwọn àgbẹ̀ Ikoyi Ile kérora síjọba ìpínlẹ̀ Oyo!
Gẹgẹ bi a ṣe mọ, Kìnìún àti Ẹkùn, ọ̀gá ni onikálùkù láyé ara wọn, wọn ki ja.
 Oríṣun àwòrán, @HQNigerianArmy Ileeṣẹ ologun sọ pe, o yẹ ki ileeṣẹ ọlọpaa maa fi to awọn leti to ba fẹ ṣe iru iṣẹ ikọkọ bẹẹ, nitori pe afojusun kan naa ni awọn jọ ni lati fi opin si awọn iwa ọdaran bi ijinigbe, ati awọn ipenija eto aabo miran ni Naijiria, lati le dena iru iṣẹlẹ bẹ ẹ."
“Ranṣẹ sí gbogbo àwọn tí wọ́n wà ní ìgbèkùn wí pé ohun tí OLUWA wí nípa Ṣemaaya ará Nehelamu ni pé: nítorí pé Ṣemaaya sọ àsọtẹ́lẹ̀ tí òun kò rán an, ó sì mú kí ẹ gbẹ́kẹ̀lé ọ̀rọ̀ èké, 
Ninu idibo naa to waye lọjọru, ile kọ lati yọ aarẹ Trump to jẹ aarẹ karundinlaadọta orileede Amẹrika.
wọn nile igbimo asofin, nitori eyi ni  ijoba apapo se  pase pe ki won ti gbogbo ojo ona ati omi pa
Tinubu s'abẹwo si iwọ orun ariwa Naijiria lati yanju aawọ APC
"Mọ̀ nípa iPhone 12, fóònù ológo 5G tí kìí lo ""Charger” tó ṣẹ̀ṣẹ̀ jáde Mi ò mọ̀ nípa àwọn tọ́ọ̀gì tó da ìwọ́de EndSARS Alausa rú, mo ṣì wà lẹ́yìn yín digbí!"
Ọọ̀ni'rìsà tẹ́wọ́ gba Naomi, olorì tuntun láàfin Iṣẹ́ Visionscape tan l'Eko, PSP gbàjọ́ba ilẹ̀ kíkó Ǹjẹ́ o nímọ̀ nípa agogo inú ara rẹ?
Ní gbogbo ayé, orílẹ̀-èdè wo ni ó tún dàbí Israẹli, àwọn eniyan rẹ, tí ìwọ Ọlọrun rà pada láti jẹ́ eniyan rẹ, tí o sì sọ orúkọ rẹ̀ di ńlá nípa àwọn iṣẹ́ ìyanu tí o ṣe nígbà tí ó lé àwọn orílẹ̀-èdè kúrò níwájú àwọn eniyan rẹ, tí o rà pada láti ilẹ̀ Ijipti?
Eyi tumọ si pe ìpè oni fidio ati atẹranṣẹ ori ayelujara ti di irin'ṣẹ pataki.
Lẹ́yìn náà ó tún fara han ẹẹdẹgbẹta (500) àwọn onigbagbọ lẹ́ẹ̀kan náà.
Ọjọ Iṣẹgun to kọja ni ijọba kede isede ataarọ di alẹ, nitori rogbodiyan iwọde #ENDSARS.
Mo dá Jerusalẹmu ní ìlú aláyọ̀,mo sì dá àwọn eniyan inú rẹ̀ ní onínú dídùn.
 O fi idunnu re han bi eto idibo se n lo si, paapaa julo fun ipa ribi-ribi ti awon osise ajo  eleto idibo ati ile-ise agbofinro n ko.
Zainab Habib tí ilẹ̀ Saudi Arabia pa irọ́ mọ́ pé o gbé cocaine tí gba sabuké NYSC!
Sawiju si, awọn adoola ẹmi tun ti tesiwaju ninu wiwa ọkọ oju
"Sola Kosoko ni: ""Ṣe lo yẹ ki ijọba maa tẹ awọn ọkunrin to ba fipa ba obinrin lopọ ni ọda lọna ati fi wọn jofin, eyi ti yoo mu wọn dẹkun iwa ika ati ipaniyan naa, O ni eyi dara nitori iwa ifipa bani lopọ kii kuro ni ọpọlọ obinrin laelae, bi o tilẹ jẹ pe awọn obinrin agbaaya kan naa wa, to n fi tipa ba awọn ọmọdekunrin sun."
ati gbogbo àwọn ọba ilẹ̀ àríwá, ati àwọn tí wọ́n wà nítòsí, ati àwọn tí wọ́n wà lọ́nà jíjìn.
4 170895 Orilẹede Greece 5421 51.
Bí wọ́n ti lágbára tó, wọ́n sùn pẹlu àwọn tí wọ́n kú lójú ogun.
Ìdí nìyǐ tí a fi ń pe ọjọ́ ìsọmọlórúkọ ní ọjọ́ ìkómọjáde.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ilé ìtura Amazonia ní wọn kó àwọn ọmọ òhun pamọ́ si Ta ni Funmilayọ Ransome-Kuti?
 O ni:“A fi gbogbo ara ta ko ikọlu yii ati ọwọ yẹpẹrẹ
Kí ló ń fa ìdádúró nípa ìfilọ́lẹ̀ 'Amotekun' tó yẹ kò wáyé lónìí?
O de si ile igbimo alase naa ni deede agogo mokanla ku iseju mefa owurọ.
Ìbéèrè ni pé, ṣe kìí ṣe àṣemọ Erica rèé ti wọ́n o fi júwe ilé fún kúrò nílé BB Naija.
Nígbà tí ẹ̀mí rẹ̀ ń bọ́ lọ, kí ó tó kú, ó sọ ọmọ náà ní Benoni, ṣugbọn baba rẹ̀ sọ ọ́ ní Bẹnjamini.
Cristiano Ronaldo: ''Ronaldo ṣì lè padà sí ẹgbẹ́ agbábọ́ọ̀lù Real Madrid''
ati wi pe ṣe igbe aye awọn eniyan ti dara si abi bẹẹ kọ?
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Divorcee: Ó sàn kí wọ́n yàgò fúnra wọn ju ki wọ́n ṣe ara wọn léṣe- Fisayo 4.
Èyí sì ló fàá tí wọ́n fi kójú ìjà sí ara wọ́n.
Ìfihàn àtìlẹ́hìn àti ìbásowọ́pọ̀ àti ìrànlọ́wọ́ fún akitiyan àwọn tí wọ́n nṣe ìwádìí tó jẹmọ́ àrùn Kògbóògùn.
Alakoso to n ri si oro ilẹ ,Malam Adamu Jibrin Husssaini lo soro yii niluu Abuja, o ni oruko ijọba ibilẹ naa ni ila oorun Mamusa ,iwo oorun Mamusa , iwo oorun Parfun ati ila Gusu Parfun lati le jẹ ki idagbasoke ba awọn to n gbe ni igberiko to wa niluu Abuja.
Ìdí nìyí tí ibi yìí fi bá wọn.
Mose tún bẹ̀rẹ̀ sí bá àwọn ọmọ Israẹli sọ̀rọ̀.
Ẹsun ti wọn n fi kan an da lori igbimọpọ ṣeku pani, ati igbimọpọ huwa ọdaran.
Ni kete ti wọn ba de Adeniyi Adele, ni wọn yoo fi oju ọna ti wọn silẹ, lati ya si oju ọna to wa lati Iyana Oworo.
Abiola Ajimobi kò gbọdọ̀ kú, ẹ lọ wọlé àdúrà - APC Oyo pariwo Àlààyé rèé lórí ìdí ta fi gbé ìlẹ̀kùn olú iléeṣẹ́ APC tì pa l‘Abuja Ohun tí ọlọ́pàá ń ṣe rèé láti sàwárí àwọn ‘mùjẹ̀-mùjẹ̀’ ní Akinyele Wo bí ìpinu Amẹ́ríkà lórí gbígba físà ṣe kan ọ́ Ẹwẹ ni ipinlẹ Edo, wọn pa ọmọ fasiti Benin kan lẹyin ti wọn fipa ba a lopọ ninu ṣọọṣi.
Baldness: Àwọn tí irun wọ́n ti gbá rìfáàsì sọ ìrírí wọn àti àǹfàní tí wọ́n ń jẹ Alága ìjọba ìbílẹ̀ Iganna, Jacod Adeleke ti gba òmìnira lọ́wọ́ àwọn ajínígbé - Ọlọ́pàá ìpínlẹ̀ Oyo Wumi Toriọla ti sọ̀rọ̀ sóke láti fi idí rẹ̀ múlẹ̀ pé òun àti ọ̀rẹ́ òun níjà Ọlọ́pàááá!
 O ni akoonu idanilẹkọọ naa ni lati jẹ ki awọn oṣiṣẹ yii ni imọ sii ninu bi a ṣe n jabọ ohun to ṣẹlẹ gbogbo ninu Ile ati bi a ṣe n ko wọn silẹ lati le mu igberu ba iṣẹ Ile Igbimọ Aṣofin Ipinlẹ Eko.
Amọṣa awọn alaṣẹ ṣalaye pe ile iko nnkan ija si ati ibi ti awọn ti wọn timọle ba wa lawọn ọlọpaa maa n ṣọ ju lọ.
Ó sun egungun àwọn babalóòṣà lórí pẹpẹ oriṣa wọn.
Eeyan marun un lo ku nibi ikọlu naa, ninu eyi ti ọlọpaa kan wa.
1 Kíyèsíi, mo wí fún ọ, ọmọ mi, pé nítorí tí ìwọ kò túmọ̀ gẹ́gẹ́bí èyíinì tí ìwọ fẹ́ lati ọ̀dọ̀ mi, àti bí o ṣe tún bẹ̀rẹ̀ láti máa kọ̀wé fún ìránṣẹ́ mi Joseph Smith, Kékeré, àní bẹ́ẹ̀ gẹ́gẹ́ ni èmi yíò fẹ́ kí o tẹ̀ síwájú títí ìwọ yíò fi parí àkọsílẹ̀ náà, èyí tí mo ti fi lé e lọ́wọ́.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Coronavirus: Ọ̀rá ni àwọn dókítà fi ń dáàbò bo ara wọn nílẹ̀ẹ Gẹ̀ẹ́sì 6 Ìgbé 2020 Bi iye awọn eeyan to ti gbẹmi mi nitori Coronavirus ṣe n peleke sii nilẹ Gẹẹsi, bẹ naa ni awọn ile iwosan atawọn oṣiṣẹ eto ilera n wa ọna lati koju arun ọhun.
Tọkàntọkàn ni mo fi ń ṣe ìfẹ́ rẹ,má jẹ́ kí n ṣìnà kúrò ninu òfin rẹ.
Ẹni tí ó mú ayé doríkodò, tí ó gbé elékèé gorí ìtẹ́, tí óo fi olódodo sí ibi ìsàlẹ̀, nítorí ẹni ilẹ̀ ni òun í ṣe, kò lè bá ará òkè ṣe dọ́gbadọ́gba tító láéláé.
Ṣé a kò ní ẹ̀tọ́ láti máa mú aya lọ́wọ́ ninu ìrìn àjò wa gẹ́gẹ́ bí àwọn aposteli yòókù ati àwọn arakunrin Oluwa ati Peteru?
24 Èbibi 2019 Oríṣun àwòrán, AFP Àkọlé àwòrán, Oríṣiríṣi nkan bí ìwé ìrìnnà sílẹ̀ òkèèrè ni àwọn ọmọ orílẹ̀èdè Uganda ma n gba àdúrà fún Ọwọ ileeṣẹ ọlọpaa ti tẹ ọkunrin ọmọ orilẹ-ede Britain kan, to n pin kẹmika to n yọ idọti 'bleach' fun awọn eniyan gẹgẹ bi omi iyanu.
Odò Jọdani ni ààlà ilẹ̀ àwọn ẹ̀yà Reubẹni.
ibo APC  pata-pata “OFO bante” lo je, o kede wipe gbogbo egbe oselu to ku, ti won
Saulu bá kó wọn jọ ní Beseki.
Ipinle Oyo ti won sese yan, asofin Adebo Ogundoyin ti fi emi imoore han si bi
Olólùfẹ́ mi, mo fi ọ́ wé akọ ẹṣin tí ń fa kẹ̀kẹ́ ogun Farao.
Nígbà tí àwọn ará Siria gbìyànjú láti mú un, ó gbadura pé kí OLUWA jọ̀wọ́ fọ́ àwọn ọkunrin náà lójú.
Ikogosi-Ekiti: Ilu ti omi tutu ti dapọ mọ gbigbona
Coronavirus Cases in Africa: Gomina Makinde gbàlejò àwọn Imam lásìkò àrùn Coronavirus
Nígbà tí ọkùnrin yìí yọ sí ìyàwó rẹ̀, ó fa ojú ro, ṣùgbọ́n nígbà tí onítọ̀hún bèèrè ìdí ọ̀rọ̀ tí ó sọ fún un, ṣe ni ìyàwó rẹ̀ bú sí ẹ̀rín, tí ó wí pé èyí ni kò tó nǹkan, ó dáhùn ó ní, ‘Aṣọ tí bàbá rẹ bèèrè wà ní ìsàlẹ̀ àpótí mi, àwọn èenìyàn ti bọ́ sí ààrin rẹ àti bàbá rẹ, ṣùgbọ́n eléyìí nì kò tó nǹkan ohunkóhun tí ó bá dé sí ọdé sí mi ti àwọn onítọ̀hún ló ṣoro.
Èmi ntèmi, ọkọ̀ ti kọja ibi tí mò nlọ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Tomomewo Favour: olóṣèlú kìí ṣe ọ̀daràn tàbí alágbèrè O ni nigba ti oun jaja ri atupa onibatiri kan ti o fi ṣe atẹrin de ibi to ti ri ilẹkun ọkọ ofurufu naa ṣi.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Eegunjobi Omotanbaje Ajobiewe- Èébú ní wọ́n kọ́kọ́ ń bù mí nígbà tí mo bẹ̀rẹ̀ ẹ̀ṣà pípé ní Wọn ni alaafia lawọn n lepa lo jẹ kawọn maa ṣe ifẹhọnuhan eyi ti ko lodi si ofin.
Wo àwọn oúnjẹ márùn ún tó ń mú kí àtọ̀ ọkùnrin dára síi Wo ibi mẹ́rìnlá tí o kò gbọdọ̀ gbé ọkọ̀ rẹ sí lásìkò yìí.
OLUWA sọ pé, “N óo ṣe ohun tí mo ṣe sí Israẹli sí Juda, n óo pa àwọn eniyan Juda run, n óo sì kọ Jerusalẹmu, ìlú tí mo yàn sílẹ̀, ati ilé OLUWA tí mo yàn fún ìsìn mi.
Pẹ̀lú pé ìpàdé fún oníròyìn wáyé ní Ilé Ẹgbẹ́ Akọ̀ròyìn Lahore, Ìyíde Ìgbéraga náà ó jáde nínú ìròyìn.
Eliaṣibu, Olórí alufaa, ati àwọn arakunrin rẹ̀ tí àwọn náà jẹ́ alufaa bíi rẹ̀ múra, wọ́n sì kọ́ Ẹnubodè Aguntan.
Ni oju opo ikansiraẹni Instagram rẹ ni Pasuma ti fi ero rẹ han wi pe gbogbo ilọsiwaju ati ibugbooro ti oun ti la kọja, Ọlọrun lo gbe oun leke.
Oríṣun àwòrán, Instagram/bukunmioluwasina Sugbọn ọpọ eeyan lo n kede pe, ifa to wọle tọ Bukunmi yii ko lee kọja pe Funke Akindele ke si lati wa kopa ninu isẹ tiata kan, eyi to le mu owo nla wọle fun.
Iṣẹ́ tí Jeremaya Jẹ́ fún Ìdílé Ọba Juda.
Ninu ọrọ to ba BBC News Yoruba sọ, Ọgbẹni Onyekachi ni ko sohun to buru nibẹ, niwọn igba to jẹ pe awọn orilẹede to nifọn leekannna lagbaye gan n lo ajagunta.
Dokita Saraki so oro naa di mimo lasiko abewo ti oun ati awon omo egbe ile igbimo ohun se si ile aare lojoBo(Thursday).
Ileeṣẹ to n risi irinna ọkọ ni ipinlẹ Eko, LASTMA to fi iroyin naa lede, sọ pe aago mẹjọ aabo ni ijamba ọkọ naa waye laarọ Ọjọọbọ.
Nítorí ó mọ àwọn eniyan lásán,ṣé bí ó bá rí ẹ̀ṣẹ̀,kí ó má ṣe akiyesi rẹ̀?
" orísìírísìí ìlú ló tẹ ̀ ẹ ́ dó , ìdí nìyí tí àwọn Ẹ ̀ gbá tó kù se ń sọ pé "" Ẹ ̀ gbÁ kẸ ́ gbÁ pỌ ̀ lÁkÉ "" ."
Mo dá wọn lóhùn pé kì í ṣe àṣà àwọn ará Romu láti fa ẹnikẹ́ni lé àwọn olùfisùn rẹ̀ lọ́wọ́ láì fún un ní anfaani láti fojúkojú pẹlu wọn, kí ó sì sọ ti ẹnu rẹ̀ nípa ẹ̀sùn tí wọ́n fi kàn án.
O ni ọmọ ọdọ oun lo jẹwọ nibi adura kan pe oun ni oun wa nidi ọrọ oun ti ejo fi n poora owo mọ oun lọwọ.
Amọ ṣaa, aṣoju ileeṣẹ Iyare Motors to ba BBC sọrọ, Solomon, ṣalaye pe, awakọ wọn jabọ pe awọn oṣiṣẹ aṣọbode ọhun ti mu ọti yo ni owurọ ọjọ Kẹtadinlogun, oṣu Keji ti iṣẹlẹ naa waye.
Oríṣun àwòrán, AFP Bakan naa si lawọn ọdọlangba gbọdọ kọgbọn pe, ifẹ abo tabi akọ ko gbọdọ ti awọn ni itikuti lati siwa hu nitori to ba buru tan, iwọ nikan ni yoo ku.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Mi ò kí ń ṣèèyàn burúkú tàbí Babalawo bí ẹ ṣe mọ̀ mí nínú eré - Fadeyi Oloro O ni ọkọ oun kii ṣe ololufẹ ere sinima, ṣugbọn o faramọ fun oun.
OLUWA sọ ìmọ̀ àwọn orílẹ̀-èdè di asán;ó sì mú kí ètò àwọn eniyan já sófo.
 O ni: “Awon ise ona wa ti rin jinna kaakiri oke okun bayii nitori pe olopolo pipe lawon amunidara Naijiria.
bí kò bá sí ilé iṣẹ ́ , kò ní sí iṣẹ ́ fún àwọn ènìyàn lati se .
 Ninu ọrọ igbriyin yii ni Aṣofin Ogunyẹmi tun ti fi orin kekere to gbajumọ laarin Isalẹ- Eko yonbo Kabiyesi, nigba ti o ṣapejuwe wọn gẹgẹ bi ẹni to mọ riri aṣa pupo.
Àwọn mejila bá jáde láti ẹ̀gbẹ́ kinni keji; àwọn mejila ẹ̀gbẹ́ kan dúró fún ẹ̀yà Bẹnjamini ati Iṣiboṣẹti ọmọ Saulu, wọ́n sì bá àwọn iranṣẹ Dafidi mejila, tí wọ́n jáde láti inú ẹ̀yà Juda jà.
Ó sì rán ọ jáde pẹlu àṣẹ pé kí o pa gbogbo àwọn ẹlẹ́ṣẹ̀, ará Amaleki run.
O salaye fun BBC Yoruba pe, awọn n gbiyanju ki awọn nnkan aṣa Yoruba mase parẹ.
Gomina tun salaye pe ipinnu isejoba oun ni lati je ki ile eko giga tubo po si ni Ipinle Oyo, idi niyi ti  oun fi mu igbega ba ile eko giga awon oluko to wa ni Lanlate ati ile eko giga ise ogbin ati imo ero to wa ni Igboora, ti won si di ile eko gbogbonse.
Oloṣelu to ni ọgbọn alumọkọrọyi pupọ ni, o o lee fi ọrọ ẹnu so ọta pọ di ọrẹ ṣugbọn iru imọlara rẹ si nkan naa lo maa n di iṣoro.
Agbára rẹ̀ yóo pọ̀, ṣugbọn kò ní jẹ́ nípa ipá rẹ̀, yóo máa ṣe àṣeyọrí ninu gbogbo ohun tí ó bá ń ṣe, yóo sì mú kí á run àwọn eniyan Ọlọrun ati àwọn alágbára.
Ẹni to bori: Senegal Aṣekagba Madagascar Senegal Madagascar vs Senegal.
Fonte ni Ronaldo si Madrid nitori o fẹran ẹgbẹ agbabọọlu Real Madrid pupọ, o ni bakan naa lo fi ọpọ awọn ọrẹ sibẹ.
Ẹwẹ, Emir ilu Kano tẹlẹ ti wọn rọ loye, Sanusi Lamido Sanusi ko fi ọwọ yẹpẹrẹ mu ọrọ ọhun rara, tori o ti bẹ awọn agbẹjọro agba mejila lọwẹ lati ja fun ẹtọ rẹ.
< Fela Durotoye Gbogbo eeyan to ba ti kọja ọgọ́ta ọdun yoo laanfaani ilera ọfẹ.
Awọn oṣiṣẹ yi pinnu lati yin ibọn fun awon ẹranko naa lọna lati gbe oku rẹ kuro ni ibẹ.
Ni bayii, awọn eeyan n bere ibeere koda wọn n ṣewadii lori ayelujara lati mọ ọjọ ti aye yoo parẹ.
Lọdun 1909, ni Pope Pius X dá Joan ti Arc to ba awọn eniyan France jagun awọn iran Gẹẹsi fun ọpọlọpọ ọdun lọla nibẹ.
Esi to fọ lagbara, o wa ninu fidio naa.
Ìlú Ijagun ní Ijẹbu ìpínlẹ̀ Ondo ló ti wá.
 aṣọ òfì ni yéwándé wọ ̀ nígbà tó wọ ́ n ń ṣe ìwádìí yìí torí òtútù .
- Òǹwòye ìdìbò YIAGA 7 Èrèlè 2019 Oríṣun àwòrán, Twitter Àkọlé àwòrán, Gómínà Nasir El-Rufai dá ogunlọ́gọ́ àwọn olùkọ́ ìpínlẹ̀ náà dúro l'ọdún tó kọjá Ọpọlọpọ iriwisi lo ti n jẹ jade latari ọrọ ti gomina ipinlẹ Kaduna, Nasir El Rufai sọ si awọn onwoye idibo wi pe 'Onwoye kankan lati ilu okere to ba n bọ lati dasi idibo Naijiria ko ni fara re pada sile.
Ijọba apapọ ti sọ pe Aarẹ Muhammadu Buhari ko ni ba awọn ọmọ Naijiria sọrọ lọni lori ibi ti iṣẹ de duro lori ajakalẹ arun Covid-19.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, October 1 Celebrant: Atinuke Oladeru ni kẹ yé ṣépè fún Nàíjíríà mọ́, ẹ pa ohùn dà Nitori ọrọ yii nijọba Babangida fi yẹba kuro lori aleefa, ti ijọba ologun miran, ti Sani Abacha lewaju rẹ, si gba akoso orilẹede yii lọwọ rẹ.
Nígbà tí wọ́n dé ibẹ̀, wọ́n lọ sí ilé ìpàdé àwọn Juu.
Nígbà tí ó jọba tán, tí ó sì ti fìdí ìjọba rẹ̀ múlẹ̀, ó fi idà pa gbogbo àwọn arakunrin rẹ̀ ati díẹ̀ ninu àwọn olóyè ní Israẹli.
15 Nítorí wọ́n ti yapa kúrò ní àwọn ìlànà mi, wọn sì ti sẹ́ májẹ̀mú ayérayé mi;
N óo gbé aṣọ rẹ wọ̀ ọ́, n óo sì dì í ní àmùrè rẹ; n óo gbé àṣẹ rẹ lé e lọ́wọ́, yóo sì di baba fún àwọn ará Jerusalẹmu ati àwọn ará ilé Juda.
Mo bẹ̀ ọ́ kí o foríji ẹni wà tó lọ
Spain fagbahan Argentina pelu ami-ayo mefa sookan(6-1), ti awon ayo ohun si wa lati owo: Costa, Thiago Alcantara, Iago Aspas ati Isco ti o gba ami-ayo meta wole.
Wọ́n wí fún Nahaṣi pé, “Lọ́la ni a óo jọ̀wọ́ ara wa fún ọ, ohunkohun tí ó bá sì wù ọ́ ni o lè fi wá ṣe.
N óo sì fi ìdí ìjọba rẹ̀ múlẹ̀ títí lae.
Ṣaaju ni obinrin ọhun ti kọkọ di awati ni nnkan bi ọsẹ meji ṣeyin ki asiri to tu pe awọn to sun mọ ọ lo dẹmi rẹ legbodo.
O mú ninu àwọn aṣọ rẹ, o fi ṣe ojúbọ aláràbarà, o sì ń ṣe àgbèrè ẹ̀sìn níbẹ̀.
Nígbà tí àwọn iranṣẹ náà rí ẹgbẹ́ àwọn wolii tí wọn ń jó, tí wọ́n sì ń sọ àsọtẹ́lẹ̀, pẹlu Samuẹli ní ààrin wọn gẹ́gẹ́ bí olórí wọn, ẹ̀mí Ọlọrun bà lé àwọn iranṣẹ náà, àwọn náà bá bẹ̀rẹ̀ sí sọ àsọtẹ́lẹ̀.
Iṣẹ́ bọ́ lọ́wọ́ ọ̀gá ilé iṣẹ́ tó bẹ́nu àtẹ̀ lu Obinrin Fatimah: Kò sí ẹni ti kò le yi agbègbè rẹ padà Ọlọpa Spain mu awọn onigbowo nabi Ireti Ramla ni pe ki oun lè ṣoju Somalia nidije Olympics tọdun 2020 to m bọ lọna.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Unko Museum yìí n ran àwọn ènìyàn lọ́wọ́ láti rí ìgbọ̀nsẹ̀ bí nkan tó rẹwà Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Unko Museum yìí n ran àwọn ènìyàn lọ́wọ́ láti rí ìgbọ̀nsẹ̀ bí nkan tó rẹwà 27 Ìgbé 2019 Unko Museum to wa ni orilẹede Japan yii n ran awọn eniyan lọwọ lati ri igbọnsẹ bi nkan to rẹwa.
Bela, ọmọ Beori jọba ní Edomu, orúkọ ìlú rẹ̀ ni Dinhaba.
Ilu Okuku ni aṣofin Oyeniran ti kede pe ohun ti darapọ mọ ẹgbẹ oṣelu ADC eyi ti ko tii pe wakati merinlelogun ti awọn aṣofin mẹta kan ti kọkọ kede awọn n fi ẹgbẹ oṣelu APC silẹ nipinlẹ ọhún.
Serena ni gbajugbaja ti gbogbo wa n wo loke ninu ere idaraya yii.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Gbajúmọ̀ gbọdọ̀ jẹ́ àwòkọ́ṣé rere torí bí ìràwọ̀ ṣe ń kú, ni òmíràn ń tàn - Foluke Daramola Ann Grace Aguti, Obìnrin kan to fẹ́ ọkọ mẹ́ta lẹ́ẹkàn ṣoṣo A kò tíì rí ọmọ ọdún méjì tó kó sí kànga- Olootu India Fọ́tò ló ṣàfihàn ibi tí ọmọ ti Nọọsi jígbé lódún 1997 wà Ipenija ẹkun omi kii ṣe ohun tuntun lagbegbe Koton Karfe, to sun mọ ilu Lokoja nibi ti odo Benue ati Niger ti pade.
Tí a fiṣọwọ́ ní 12:41 11 Òkùdu 201912:41 11 Òkùdu 2019 Àwọn ìkíni tí ẹ fi ráńṣẹ́ sí ààrẹ ilé aṣòfin àgbà tuntun Ni kete ti wọn kede Ahmed Lawan gẹgẹ bi aarẹ ile igbimọ aṣofin agba ni awọn ọmọ Naijiria ti n fi ikini ku oriire ranṣẹ́ si i.
Oníkẹ̀kẹ̀ NAPEP: Àwọn ọlọ́pàá ń gba owó kòtọ́ lọ́wọ́ wa
A gbọ pe wọn lọ rọ ayederu ọpa aṣẹ ile naa eyi ti wọn fi fẹ ya bo ile igbimọ aṣofin ti ko si lẹnu iṣẹ bayii nitori atunṣe to n lọ lọwọ nibẹ, lati gbọna ti ko tọ ṣe agbekalẹ ileegbimọ aṣofin miran lowurọ Ọjọbọ.
Isọri keji ija naa ni Adesanyta ti rọjo ẹsẹ lu Costa ti adari ija naa si bọ si aarin wọn lati pari rẹ ni kiakia.
Lasiko ti awọn ayaba ba n yungba naa, ti inu Alaafin ati awọn eeyan n dun, wọn yoo nawo fun awọn ayaba naa, ti ori wọn pẹlu yoo si wu siwaju si lati tigba, ati lati ki oriki Alaafin.
Ẹkunrẹrẹ lori iroyin yii wa ni: Ààrẹ Buhari jámi lórí ètò RUGA ná Osinbajo ta kété sí ọ̀rọ̀ 'Ruga Settlement' Ẹ̀tàn lásán ni ìkéde ìjọba àpapọ̀ lórí RUGA - Afenifere Ìpínlẹ̀ Oyo àti Eko kò nífẹ̀ẹ́ láti gba 'Ruga Settlement' láyè Ẹ̀yin tẹ́ẹ tako àgbékalẹ̀ àgọ́ Fulani, ìkórira ló ń yọ yín lẹ́nu - Ìjọba àpapọ̀ Ẹ má dá NEF lóhùn, kò síbi t'ọ́mọ Nàìjíríà kò lè gbé nílẹ̀ yìí - Buhari Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, CAN: Samson ni ọrọ awọn ajinigbe ti gba àpérò ní Naijiria Alhaji Sikiru Ayinla Kollington: Rashidi Yekini ṣì ni mí b'óbìnrin bá sún mọ́ mi Àkọlé àwòrán, Alhaji Kolington Gbajugbaja olorin Fuji nni, Alhaji Ayinla Kollington ti kede fun araye pe titi aye ni akọrin Waka nni, Alhaja Salawa Abẹni yoo maa jẹ iyawo oun, ti awọn yoo si jọ pẹ fun ara awọn.
Idile ọkọ rẹ to jẹ ọmọ ọdun mejila ra a ni $3,500 ni dun mẹfa sẹyin.
 irúfẹ ́ ọ ̀ wọ ́ tí àwọn sòbìà ńfa àrùn lára àwọn ẹranko .
Nigba to n sọrọ lori idi to fi yan isẹ tiata laayo, Chukwuka ni awọn agba osere bii Baba Wande, Lere Paimo ati Lalude, to maa n sọ ede Yoruba ti ko ni abula ninu ere, lo se koriya fun oun lati dara pọ mọ wọn.
Wọ́n wá tẹ́ ẹ sí orí ìbùsùn bàbá mi tí wọ́n ti tẹ́ aṣọ funfun lé.
"O ni, ""Ati ẹni to lowo, ati ẹni ti o toṣi, Ọlọrun lo da gbogbo wa."
otitọ rara nitori Gomina kọ ni o n gbe inawo awọn oloṣelu ti n lọ si ipo
 bakanna die tun wa lati ile europe , agaga awon ara fransi ati awon eniyan lati apaariwa asia bi lebanon ati ilaoorun asia bi india .
O maa n ta wara wara gan ni to si jẹ na ati pa owo wọle gidi gan fun awọn to n ta a.
Olówó náà ní ilẹ̀ kan tí kún fún igi ọ̀pẹ.
O ni koda, Walter seto iranwọ fun awọn ẹbi oun nigba ti oun wa ni atimole lẹyin irinajo oun pada si Naijiria, Oloye Obasanjo ni igba gbogbo ni Walter maa n wa sabewo si oun nigba ti oun wa lọgba ẹwọn, ati pe o jẹ ọkan lara awọ́n asoju ilẹ̀ okeere to maa n wa wo iyawo oun wo gẹgẹ bii ọrẹ ati ẹbi.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Mo ti ní ìyàwó àfẹ́sọ́nà, ayẹyẹ ìgbeyàwó mi ń bọ̀ láìpẹ́ - Lateef Adedimeji Dókítà 66 síṣẹ́ abẹ fún ìbejì tó lẹ̀pọ̀ nílé ìwòsàn fasiti Ilorin Ẹ ṣọ́ra o, ayédèrú abẹ́rẹ́ àjẹsára COVID-19 gbòde ní Nàìjíríà, NAFDAC pariwo síta Wo àwọn ààrẹ Amẹ́ríkà mẹ́rin tí wọn rọ̀ lóyè àti ẹ̀ṣẹ̀ wọn Wo ẹ̀kọ́ mẹ́rin tí Naijiria kùnà láti kọ́ lára ogun abẹ́lé Owoseni, ẹni to koro oju si ipo ti eto aabo naa wa, wa sisọ loju rẹ pe awọn agbẹyinbẹbọjẹ kan nilẹ Yoruba lo wa nidi isẹlẹ yii.
O kò ní ipa tabi ìpín ninu ọ̀rọ̀ yìí, nítorí ọkàn rẹ kò tọ́ níwájú Ọlọrun.
" Lori ẹsun keji to ni iyawo Obasa n gba miliọnu mẹwa naira losoosu ninu owo ile, igbimọ oluwadii naa salaye pe ofuutu fẹẹtẹ, aasa ti ko ni kaun ni ọrọ naa.
Nígbà tí o bá fi ọ̀pá lu àpáta náà, omi yóo ti inú rẹ̀ jáde, àwọn eniyan náà yóo sì mu ún.
Lara awọn abawọn ti awọn eeyan ṣaaba maa n tọka si ni mimu oogun oloro ati ọti lile nigba to n gbabọọlu.
Ninu atẹjade iye awọn to laarun naa, eyi ti ajọ NCDC fi sita lalẹ ọjọ Ẹti, ninu ọgọjọ eeyan to kun iye awọn to laarun coronavirus lorilẹede Naijiria lọjọ Ẹti, mẹrinlelogoji ninu wọn lo wa lati ipinlẹ Plateau.
ipo ti ipinle naa wa bayii.
”Ó dá wọn lóhùn pé, “Ẹnu ara yín ni ẹ fi sọ pé, èmi ni.
Oríṣun àwòrán, Reuters Àkọlé àwòrán, Orílẹ̀-èdè Egypt ni ilu Cairo ni a rti ri oorun to yọ yìí lọjọ satude.
 Ọ ̀ wẹ ́ wẹ ́ 2 ni ìlù tí a ń wí yìí .
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Owó tí Kiddwaya bá rí ní BB Naija, ìdá kan fún Erica, ìkejì fọ́mọ aláìníyàá - Baba Kiddwaya Kí ló le è mú kí agbábọ́ọ̀lù subú, kó sì kú lásìkò ìfẹsẹ̀wọ̀nsẹ̀?
Oríṣun àwòrán, PHA Akọsilẹ ajọ eleto ilera lagbaye naa si fi han pe orilẹede bii aadọsan (170) lo ti ke gbajare sita nipa itankalẹ arun Ẹyi lara awọn eeyan to to ẹgbẹrun lọna mejilelaadọfa ati mẹtalelọgọjọ (112,163) lagbegbe wọn.
Mercy Aigbe ṣá ọmọ rẹ̀ sínúu fíìmù tuntun, wo itú tí ọmọ ọdún mẹ́wàá náà pa Daddy Freeze túbá!
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, The seed: Àwa sì wá láti mú ẹ̀bùn fún Ọba tí a bí lónìí Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ipenija ojú kò di Ademola lọ́wọ́ láti kẹkọọ gboye Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Èpo ọwọn, sunkere-fakere ọkọ àti àwọn olósà jẹ́ ipenija lójú pópó Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
com/ALFQvx4AV9Bakan naa, ogagun Sadiq tun tenumo ipinnu NAF lati ri daju pe awon pese ile iwosan ti odangajia fun itoju ti o peye awon omo ogun ati ebi won.
Ó tún fi kún un pé, “Àwọn nǹkan tí ń jáde láti inú eniyan ni ó ń sọ ọ́ di aláìmọ́.
Arakunrin Ibrahim Aku lati ijọ Church of Brethren ni ipinlẹ Adamawa ni o gba wi pe oun jẹbi ẹsun onigun mẹfa lilo owo ni ponpo ati ole jija.
Ninu ọrọ to sọ lorii ẹrọ amohumaworan lalẹ ọjọ Aiku ni aarẹ Akufo-Addo ti sọ pe igbesẹ yii waye lẹyin ọpọlọpọ gbigba imọran lọdọ awọ tọrọ kan ni ẹka eto ẹkọ.
Amọṣa, lati igba yii wa ni o ti n ba ijakulẹ pade.
Wo àwòdamiẹnu àwòrán Mọ́ṣáláṣí Ànọ́bì ní Medina!
 Ée ṣe ni atọ ́ ka ìyisódì èyán asòǹka nínu Ẹi .
Ẹ̀yin tẹ̀ ń parọ́ ẹlẹ́yà-mẹ̀yà mọ́ Amotekun Oyo, Seyi Makinde lẹ̀ ń dojú ìjà kọ"" Kí ló ma n fa Àkúfà nílẹ̀ Yorùbá, àti ọ̀nà àbáyọ?"
Aale yiyan lagbara pupọ, o kan jẹ pe ọpọ ti tẹwọ gba a ni gẹgẹ bi agbelebu.
Èyí ni majẹmu tí mo bá gbogbo ẹ̀dá alààyè tí ó wà láyé dá.
Bakan naa lo tun kilọ fun awọn ọmọ Naijiria lati ṣọra fun gbigba alejo tabi ṣiṣe abẹwo si awọn orilẹ-ede bii Amẹrika, ilẹ Gẹẹsi, India, Rusia ati France.
5 million MT) já sí bílíọ́nù mẹ́sàn àti ààbọ kílò (9.
Ebenezer Obey ni pẹlu aṣẹ Ọlọrun 'mo pada wa di ẹni to ra ileeṣẹ rẹkọọdi ọhun, ti mo si yi orukọ rẹ pada si ‘Afrodisiac records.
PDP: APC ń kéde pé Saraki ni ipa tó ń ko láti yan olori ile asofin agba
Ọjọgbọn Yẹmi Osinbajo sọ ọrọ yii nibi apero lori eto aabo n'ilu Abuja.
Ó ti fi ibinu gbígbóná rẹ̀,pa àwọn alágbára Israẹli;ó kọ̀, kò ràn wọ́n lọ́wọ́,nígbà tí àwọn ọ̀tá dojú kọ wọ́n.
E̩tó̩ wo̩n dó̩gba nínú ìgbeyàwó ìbáà jé̩ nígbà tí wo̩n wà papò̩ tàbí lé̩yìn tí wó̩n bá ko̩ ara wo̩n.
Jese mú kí àwọn ọmọ rẹ̀ mejeeje kọjá níwájú Samuẹli.
Maina ni laga igbimọ to wa fun ọrọ owo ifẹhinti ni Naijiria.
26 Owewe 2020 Oríṣun àwòrán, Instagram/currentalhaja Lai si ani-ani, Olori Abbey jẹ ọkan lara awọn ''Ẹ̀lẹ̀ Daddy, afẹ́fẹ́ tí Alaafin Oyo, Oba Lamidi Olayiwola Adeyemi fi n mi.
Amọ ni ipinlẹ Ogun, Gomina Dapo Abiodun ti fi ọsẹ kan kun ofin konile-o-gbele naa nitori awọn eniyan ko bọwọ fun ofin yiyagofunraẹni, eleyii to n mu ki iye eniyan to ni arun naa ni ipinlẹ ohun peleke si.
Èyí ni iṣẹ́ ìsìn tí ó yẹ yín.
 Ìwádìí tún fi yé mi pé wón máa ńki àwon omo bíbí ilé yìí báyìí .
    Ìgbá tí Òmùgọ̀dimẹ́ta parí àwọn òfin yìí tán ó parí wọn pẹ̀lú ọ̀rọ̀ wọ̀nyí: Èmi, ọba ńlá, tí ó ju gbogbo ọba lọ, Aláyélúwà Òmùgọ́dimẹ́ta ọba èdìdàrẹ́, tí Ìlábùrù bí fún Òmùgọ́diméjì, baba Dánásungbó, mo fi ọwọ àti ẹsẹ̀ mi, ojú àti imú mi, orí àti ọrùn mi, inú àti ẹ̀yìn mi, orí ahọ́n àti ihò imú mi, sí ìwé yìí, ní ọjọ́ kẹ́ẹ̀sán, oṣù kẹfà, ni ẹ̀ẹ́dẹ́gbẹ̀wá ọdún ó le méjìlá méjìléláàdọ́tá lẹ́yìn ikú Olúwa wa.
N óo dà wọ́n sinu ilé ìdáná ati sinu àwo tí wọ́n fi ń tọ́jú oúnjẹ.
Gbogbo àwọn ohun èlò tí Ahasi ọba ti patì nígbà tí ó ṣe aiṣododo ni a ti tọ́jú, tí a sì ti yà sí mímọ́.
Ṣaaju ni iroyin kan jade pe, ijọba ipinlẹ Oyo gbẹsẹ le awọn ilẹ kan lagbegbe Agodi ati Jericho, nilu Ibadan nitori awọn idi kan.
Orilẹ-ede Amerika ni Dadashev n gbe to ti gba ami ẹyẹ mẹtala nibi ija mẹtala to ti bori sẹyin.
N óo wá mu yín pada wálé nígbà náà,nígbà tí mo bá ko yín jọ tán:n óo sọ yín di eniyan patakiati ẹni iyì láàrin gbogbo ayé,nígbà tí mo bá dá ire yín pada lójú yín,Èmi OLUWA ni mo wí bẹ́ẹ̀.
Coronavirus cases in Africa- Ó tí lé ni mílíọ̀nù kan ènìyàn to ti lùgbàdì ààrùn Covid-19 Ẹ̀rọ CCTV tú àsírí ọkùnrin ẹni ọgbọ̀n ọdún tó fi ipá bá ọmọ ọdún mọ́kànlá lòpọ̀ Ìjọba ìpínlẹ̀ Eko ti kéde ọjọ́ ìwọlé àwọn ọmọ ilé ìwé alákọ́bẹ̀rẹ̀ àti girama Ìjọba ìpínlẹ̀ Eko ti kéde ọjọ́ ìwọ́lé ọ̀tọ̀ọ̀tọ̀ fún àwọn ìpele ẹ̀kọ́ ni ìpíńlẹ̀ yìí.
 spektroskopi bere ninu iwadi itanna fifojuri to fonka gegebi ìbú ìlàrúrú rẹ ̀ , f.
Oludamọran si ararẹ Muhammadu Buhari lori ọrọ oṣelu, Babafemi Ojudu lo fọrọ naa lede loju opo Twitter rẹ.
Òdú ni ipejọpọ nla ijọ Redeem Christian Church of God eyi ti ilumọọka ojiṣẹ Ọlọrun, Pasitọ Enoch Adejare Adeboye n dari.
"Ẹ wá dánrawò níbí pẹ̀lú Àpólà Ọ̀rọ̀ Orúkọ, ""Noun Phrase"" Ẹ̀yin tí ẹ kò gbọ́ Yorùbá, ẹ ṣúnmọ́ bí láti kọ́ lítíréṣọ̀ èdè Yorùbá lórí BBC Wo ìyàtọ̀ tó wà láàrin Àjọ, Àáró àti ọ̀wẹ̀, tí wọn jẹ́ àṣà ìran ara ẹni lọ́wọ́ nílẹ̀ Yorùbá Ẹ ṣúnmọ́ bí láti kọ́ ẹ̀kọ́ nípa ìsọ̀rí ọ̀rọ̀ nínú gbólóhùn Yorùbá Akọṣẹmọṣẹ Ogunboye sọ itan iwe naa ni kukuru pẹlu ipa ti awọn ẹda itan bii Lapade, Tafa Igiripa, Olopaa Audu Kareem, Gbekude, Angelina, Tola, Gbekuta, Dele, Taiwo, Jakumọ, Kola Tiamiyu ati bẹẹ bẹẹ lọ ko ninu iwe naa."
5), òòró rẹ̀ yóo rí bákan náà pẹlu ti àwọn ìpín yòókù láti ìlà oòrùn títí dé ìwọ̀ oòrùn.
“Ṣugbọn ẹ̀yin yòókù ní Tiatira, ẹ̀yin tí ẹ kò gba ẹ̀kọ́ obinrin yìí, ẹ̀yin tí ẹ kò mọ̀ nípa àwọn ohun tí wọn ń pè ní ohun ìjìnlẹ̀ Satani, n kò ní di ẹrù mìíràn rù yín mọ́.
Ikede ajọ NCDC ni nkan bii aago mọkanla kọja lalẹ ọjọru fi han pe ilu ipinlẹ Eko ti gba ipo iwaju pada ti Abuja si to tẹle e lẹyin.
Oríṣun àwòrán, Olarewaju Onigegewura Àkọlé àwòrán, Meji ninu awọn aarẹ ọna kakanfo marun to jẹ kẹyin ni wọ̀n jẹ oloselu Ni osu kẹjọ ọdun 1964 ni wọn fi Ladoke Akintọla jẹ gẹgẹbii aarẹ ọna kakanfo.
Wọn ṣe agbekalẹ abadofin yii lẹyin ti ẹka ileeṣ BBC to n tu aṣiri awọn ohun ti ko dara lawujọ, BBC Africa Eye gbe fidio iwadii kan sita.
Àbí o kò gbọ́ nígbà tí Jesebẹli ń pa àwọn wolii OLUWA, pé mo kó ọgọrun-un ninu wọn pamọ́ sinu ihò àpáta meji, mo kó araadọta sinu ihò kọ̀ọ̀kan, mo sì ń fún wọn ní oúnjẹ ati omi.
ni ipo gangan ti a kàn mọ agbelebu jẹ ọrọ ti itumọ , ṣugbọn awọn iwe-mimọ bibeli fihan pe o wa lẹhin odi odi ilu jerusalemu , [ jn .
Ó dàbí ọkunrin kan tí ó gbin irúgbìn rere sí oko rẹ̀.
Sanwo-olu gbé ìwé ẹ̀dùn ọkàn olùwọ́de ENDSARS lé Buhari lọ́wọ́ Gẹgẹ bi ileri ti gomina ipinlẹ Eko ṣe fun awọn olufẹhonuhan nigba to lọ yọju siwọn, Babajide Sanwoolu ti mu iwe ẹdun ọkan awọn oluwde ti wọn fi ran an jiṣẹ fun aarẹ Buhari l'Abuja.
Gomina Ajimobi tun fi kun ọrọ pe, o je idunnu oun pe ipo
 laipẹ diẹ , ilu naa ti di ibudo ile-igbimọ ti igbimọ ile-iṣẹ pan-european european 8 .
Olórí ẹ̀ka ìròyìn f'un àjọ náà, Fabian Benjamin sọ fún àwọn oníròyìn ní ọjọ́ ìsinmi pe ìgbìmọ̀ aláṣẹ ti ń fi ojú rẹ̀ wináà ìjìyà tí o yẹ, àti wípé àwọn iléèṣẹ́ ètò ààbò ti ń ṣe ìwádi lori ọ̀rọ̀ nàá.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Bobrisky: Ìléeṣẹ́ ọlọ́pàá ṣàlàyé ohun tó gbé wọn dé ibi ìnáwó ọjọ́ ìbí 1 Owewe 2019 Oríṣun àwòrán, Bobrisky Gbogbo aye lo fẹrẹ mọ ọ tan, ọna ti olukuluku gba mọ ọ lo yatọ, Iyẹn Idris Okuneye, Bobrisky.
Ọga ajọ ẹṣọ aabo ara ẹni labo ilu ni Nasarawa lo sọ bẹẹ fun BBC pe, NCDC yoo fi panpẹ ọba mu Ahmadu Yaro, awọn yoo si ri i daju pe wọn fi iya to tọ jẹ ẹ.
Lẹ́yìn ò rẹyìn, Seyi Makinde bori arun CoronavirusÈèyàn mẹ́jọ míràn tún ti ní àrùn Coronavirus ní Naijiria Èèyàn mẹ́jọ míràn tún ti ní àrùn Coronavirus ní Naijiria Kí ló pa bàbá Adeboye, bàbá Davido àti Ọ̀ọ̀ni Ifẹ̀ pọ̀ lásìkò ìgbélé l'Ọ́ṣun?
Bí ó ti lẹ̀ jẹ́ wípé wọ́n ri bi ohùn fún àwọn aláwọ̀ dúdú tó jẹ́ akúṣẹ̀ẹ́, bí ọdún ṣe n yí lura wọn, ni iyì rẹ̀ n dínkù nítorí àwọn àríwísí kan.
Koda o ṣabẹwo si Aarẹ Buhari nile aarẹ to wa niluu Abuja lọjọ kinni, oṣu Kọkanla, ọdun 2018, lati jẹjẹ atilẹyin rẹ.
 Ó gba oyè ẹlẹ ́ kejì ìyẹn ( masyer ' s degree ) nínú ( media and communication ) láti ilé-ẹ ̀ kọ ́ fásitì pan african , ní ìpínlẹ ̀ Èkó ní ọdún 2009 .
Gbogbo wọn ni Ọlọrun ti ṣe lóore: ó dá wọn láre lọ́fẹ̀ẹ́ nípa ìràpadà tí Kristi Jesu ṣe.
- Ìjọba àpapọ̀ Ọmọ Yorùbá mẹ́wàá tó jẹ́ àmúlùúdùn ní Amẹ́ríkà àti Yúróòpù Ta ni Yusuf Satia ti iku mu lọ?
"Wo ojú àwọn òṣèré yìí láì lo ""Make-up"" orí ìtàgé bó ṣe rí gẹ́lẹ́ Wumi Toriọla ti sọ̀rọ̀ sóke láti fi idí rẹ̀ múlẹ̀ pé òun àti ọ̀rẹ́ òun níjà Gómìnà Sanwo-Olu dẹ okùn ìséde l'Eko, ó gbé ìlànà tuntun jáde Wo àwọn Ṣọ́ọ̀ṣì Nàìjíríà àti l'Áfíríkà tó ń wólẹ̀ àdúrà kí Trump lè wọlé ìbò ààrẹ America Ọ̀gá àgbà ọlọ́pàá ṣèwúrí fáwọn ọlọ́pàá tó kúrò lójú pópó fún ọjọ́ márùn-ún Eyitayo Jegede gbé Akeredolu lọ síwájú ìgbìmọ̀ tó n gbọ́ ẹ̀sùn ìdìbò Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Tóo bá pá lórí, Mílíìkì sóyà àtàwọn ǹkan mẹ́ta yìí leè mú irun rẹ hù padà!"
Ìtàn mánigbàgbé: Ajayi Crowther ní ọjọ́ ìbànújẹ́ àmọ́ tó di ọjọ́ ayọ̀ ni ọjọ́ tí wọ́n kó òun lẹ́rú
Ṣugbọn minisita tutọ soke o si foju gba a, lẹyin to sọ pe Naijiria ko lẹbi rara ninu ọrọ to wa nilẹ yii.
Ileeṣẹ irinna Iyare Motors to ni ọkọ ti awọn oṣiṣẹ ajọ aṣọbode Naijiria mu, ninu fidio kan to ṣafihan bi wọn ṣe yinbọn mọ arakunrin kan , ti sọ pe, awọn oṣiṣẹ aṣọbode naa ti mu ti yo.
O wa parọwa si awọn ọmọogun ati awọn akọroyin lati ri wi pe, wọn n ṣe ijiroro lati igba de igba ki agbọye le wa laarin awọn agbofinro ati akọ̀ròyìn nigba gbogbo.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: 'Ìwádìí ńlọ lórí àwọn alákatakítí agbébọ̀n tuntun tó wọ Nàìjíríà’ Ǹjẹ́ o mọ àwọn ǹkan èlò ilé tó léwu fún ẹ̀mí?
“Ní ọdún jubili yìí, olukuluku yín yóo pada sórí ilẹ̀ rẹ̀.
Agbẹnusọ ọlọ́pàá ìpińlẹ̀ náà, Haruna Mohammed to fi ìdí ìṣẹ̀lẹ̀ náà múlẹ̀ sàlàyé pé ilé iṣẹ́ ọlọ́pàá ti dárí ẹjọ́ náà sí ẹ̀ka ìwádìí ìwà ọ̀daran.
Ọgbẹni Kayode Ogundamisi, ọmọbibi orilẹ-ede Naijiria to fi Ilẹ Gẹẹsi ṣe ibugbe ba BBC Yoruba sọrọ, o ni ero t'oun ni pẹ ju gbogbo rẹ lọ, ile labọ isinmi oko boya Ilẹ Gẹẹsi kuro ninu ajọ EU tabi wọn o kuro nibẹ.
Wọn yóo bá Ọ̀dọ́ Aguntan náà jagun, ṣugbọn Ọ̀dọ́ Aguntan náà yóo ṣẹgun wọn nítorí pé òun ni Oluwa àwọn oluwa ati Ọba àwọn ọba.
Lẹyin ayẹwo yii ni wọn yoo fi nọmba ṣọwọ si awọn alaṣẹ fun iwadii siwaju si.
Aarẹ tẹlẹ naa wa fewe ọmọ mọ awọn eeyan to n lu ilu ogun, ti wọn si ni awọn yoo ya kuro lara Naijiria ni lati sọra se.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Aaron Ramsey: £400k lọ́sẹ̀ ni Ramsey yóò maa gbà ní Juventus 11 Èrèlè 2019 Àkọlé àwòrán, Aaron Ramsey dero Juventus Agbabọọlu Arsenal Aaron Ramsey yoo darapọ mọ ikọ Juventus ni ipari saa bọọlu yii, lẹyin ti o bọwọ luwe adehun lati darapọ mọ ikọ naa.
Aaroni ati àwọn ọmọ rẹ̀ ni wọ́n máa ń rúbọ lórí pẹpẹ ẹbọ sísun ati lórí pẹpẹ turari; àwọn ni wọ́n máa ń ṣe gbogbo iṣẹ́ ìsìn ninu ibi mímọ́ jùlọ, tí wọ́n sì máa ń ṣe ètùtù fún àwọn ọmọ Israẹli gẹ́gẹ́ bí ìlànà tí Mose, iranṣẹ Ọlọrun là sílẹ̀.
oríṣìí méjì ni ẹ ̀ yà èdè yìí ni ayé òde òní .
O ni: “Iru ile ise bayii yoo safikun si ere ipinle Eko ni, yoo je ki ise tun wa fun awon eniyan.
Wọn a máa pè wọ́n ní Refaimu gẹ́gẹ́ bí àwọn ọmọ Anakimu, ṣugbọn àwọn ará Moabu ń pè wọ́n ní Emimu.
Asofin Lawan lati Gumi ni ipinlẹ   Zamfara lo sọrọ yii nigba to n  ba awọn akọrọyin ile igbimọ asofin sọrọ nipa isẹlẹ lorilẹ ede Naijiria, niluu Abuja.
Nigba to n ba BBC News Yoruba sọrọ, alukoro agba fun ileeṣẹ ọlọpaa lorilẹ-ede Naijiria, Frank Mba ni ọga agba ọlọpaa ti paṣẹ pe ki iwadii to rinlẹ o bẹrẹ ni pẹrẹu lori iṣẹlẹ naa.
Ìjàmbá iná pa èèyàn 23, tó fi mọ ọmọ iléèwé àlákọ́bẹ̀rẹ̀ ní Lokoja-Abuja Ǹjẹ́ o ti gbọ́ nípa Da Rocha?
Ó pa á láṣẹ fún àwọn baba ńlá wa,pé kí wọ́n fi kọ́ àwọn ọmọ wọn.
Kòkòrò ajokorun da ìpòruru sí ọkan àwọn àgbẹ̀ Nàìjíríà
Ẹ̀yin ọ̀rẹ́-ẹ̀ mi tòótọ́, ẹ jẹ́ kí á sinmi ìtan dídùn yìí fún òní.
Iwe aṣẹ fun ọkọ wiwa: Ajọ ẹṣọ oju popo, FRSC, naa ti n beere fun NIN lọwọ ẹnikẹni to ba fẹ ẹ gba laisẹnsi gẹgẹ bi awakọ.
Atẹjade kan eleyii ti ajọ to n ri si igbogun ti ajakalẹ arun lorilẹede Naijiria fi sita loju opo twitter wọn ṣalaye wi pe eeyan mẹsan ninu awsn ti ayẹwo ṣẹṣẹ fi han naa lo wa ni ipinlẹ Ọṣun, meji wa ni ipinlẹ Edo, Ẹyọkan toku si wa lati ipinlẹ Ekiti.
O ni o tẹẹ mọ oun leti pe ki awọn maa dupẹ ni nitori pe wọn ko duro ibanujẹ lori ẹnikẹni ninu ẹbi naa laimọ pe yoo jade laye laipẹ.
Àwọn alufaa kú ikú ogun;àwọn opó wọn kò sì rójú sọkún.
Awọn asofin mẹta to se onigbọwọ aba naa, eyiun Asofin Asimiyu Alarape, Sanjọ Adedoyin ati Abiọdun Fadeyi naa salaye pe, darandaran to ba tapa si aba ọhun to ba di ofin tan, yoo lọ si ẹwọn osu meje, tabi ko san owo itanran tii se ẹgbẹrun lọna igba naira tabi ko se mejeeji.
Gẹgẹ bii Atọnisọna lori oke naa, Gbenga Oyinbo ti wi, ibudo isinmi bii ogun lo wa lori oke yii, fawọn eeyan to n rin irinajo afẹ lati sinmi.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Coronvirus in Nigeria: Àjọ NCDC ti kede pé ènìyàn méji míran ti ni àrun náà 24 Ẹrẹ̀nà 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 25 Ẹrẹ̀nà 2020 Àkọlé àwòrán, O ti di ènìyàn Mẹrinlelógóji to ti ni ààrun Coronavirus ni Naijiria Ní ìròlẹ́ òní ni àjọ to n ri si itankalẹ ajàkálẹ̀ àrun ti tún kéde pé ènìyàn méji míràn tú ti kú àwọn méjilelogoji to wà nilẹ̀ tẹ́lẹ̀ ti o si ti di ẹni mérinlélógójì báyìí to to ti ni ààrun náà ni Naijira.
Oríṣun àwòrán, TWITTER Àkọlé àwòrán, Àwòrán lẹ́tà jáde lórí ẹ̀rọ Twitter níbí tí Alaafin oyotí kìlò fún gomina ìpínlẹ̀ Ekiti pé kó tẹlẹ̀ jẹ́jẹ́ lórí àwọn ọba tó wà ní ìpínlẹ̀ Ekiti.
Kí olukuluku yẹ ara rẹ̀ wò kí ó tó jẹ ninu burẹdi, kí ó sì tó mu ninu ife Oluwa.
Ewe, ogbeni Bala darapo mo ise ijoba lọdun 1999, ti o si tun ti figba kan je asoju sorile-ede Brazil, Sudan, Gambia, Netherlands ati orile-ede Thailand.
Oríṣun àwòrán, iyaboojofespris Àkọlé àwòrán, Inu ile ọhun ree.
"O ni ""fun bii oṣu marun un ni EFCC ko fi ṣiṣẹ da bi alara lọdun 2020 nitori ajakalẹ arun coronavirus."
Kí ni mo jẹ́ tí n óo fi kọ́ ilé fún un, bíkòṣe pé kí n kọ́ ibi tí a óo ti máa sun turari níwájú rẹ̀?
Mo bá bẹ̀rẹ̀ sí bẹ OLUWA Ọlọrun tìrẹ̀lẹ̀-tìrẹ̀lẹ̀ mò ń gbadura tọkàntọkàn pẹlu ààwẹ̀; mo wọ aṣọ ọ̀fọ̀, mo sì jókòó sinu eérú.
Ọpọ ẹmi lo bọ sọwọ awọn ọmọ ikọ Boko Haram eyi to si tun n peleke si bayii, bi o tilẹ jẹ pe ẹkun ariwa Naijiria lo n fi ara gba ikọlu wọn julọ.
Eyi lo mu ki igbimọ awọn ọba alaye to wa nipinlẹ Eko fi pakiti mọlẹ lọ ba Ọba ilu Eko, Rilwan Akiolu kẹdun lori ọpa asẹ rẹ tawọn janduku gbe lọ .
Aworan yi se afihan awọn ibudo ti Boko Haram yan mu lati kọlu lọdun 2016, amọ iyatọ diẹdiẹ wa laarin ọdun meejeeji, ti orilẹede Naijiria si ni iriri ikọlu to pọ julọ lọdun 2017, ti orilẹede Niger si ni ikọlu Boko Haram to kere julọ lọdun naa.
 iṣẹ ́ yìí tún ṣe àlàyé lórí àjọṣepọ ̀ ààrin Ṣàkání-Ìtumọ ̀ , afọ ̀ àti ìtumọ ̀ nítorí pé bí atọ ́ nà ni wọ ́ n jẹ ́ sí ara wọn .
Jaiye Kuti lu àwọn aláṣìmọ̀ lọ́gọ ẹnu lórí ìbáṣepọ̀ pẹ̀lú Pasuma
Ijọba mọ pe isẹ si  ku
Ará Hiti ni ìyá rẹ, ará Amori sì ni baba rẹ.
Sugbọn sa, bi àwọn onimọ kan ṣe sọ pe eto okoowo Bitcoin, ni 'ayẹta', ni awọn miran gba ẹnikẹni to ba fẹ ẹ dokowo Bitcoin láti má fi gbogbo owó to ni sinu rẹ.
2 7769 Orilẹede Mali 164 0.
Ọlọ́pàá yìnbọn pa àgùnbánirọ̀ nígbà tó ku ọjọ́ méjì kó gbàwé ẹ̀rí
Ijoba to wa lori aleefa yii wa lakooko ti awon omo orile ede Naijiria fe iyipada rere, iyipada ti a seleri, eto iyipada ti a o tubo  maa se fun un yin.
Ẹnú ya àwọn ọdẹ láti gbọ́ ohun tí ètè ọkùnrin náà sọ.
Wọn yóo máa lọ káàkiri láti òkun dé òkun, láti ìhà àríwá sí ìhà ìlà oòrùn.
Orisun omi orioke Olumirin ni orukọ rẹ ṣugbọn Ẹrin Ijẹṣa Water falls ni ọpọ mọọ si.
Lára ẹ̀kọ́ itàn yi ni pé, ó dára lati lo ọgbọ́n ọlọ́gbọ́n nitori “Ọgbọ́n ọlọ́gbọ́n ni ki i jẹ ki á pe àgbà ni wèrè”.
Studies and Practice), Omowe Nathaniel Danjibo se alaye pe fifi amin eye yii da
Ó wò ó, ó sì rí i pé ó dára.
Ninu idajọ rẹ, Onidajọ Samuel Bola sọ pe ẹri ọmọdebinrin naa niwaju ile ẹjọ mudadoko, lai fi ọjọ ori rẹ ṣe, amọ ti Adanlawọ ko ri ẹri mu wa sile ẹjọ pe lootọ ni o ni aarun , tabi pe ile ara rẹ lo wa lasiko iṣẹlẹ naa.
Bí àrùn Coronavirus ṣe dá gbogbo àgbáyé gúnlẹ̀ sójú kan náà nìyí Àìsí owó ń fọ́ ọ̀pọ̀lọpọ̀ èèyàn lójú tó jẹ́ ìmọ́lẹ ara FRSC o gbọdọ ni ju 500 naira lọwọ Facebook gbégilé àwọn ojú òpó ayédèrú BBC koro oju si ikọlu ijọba ipinlẹ Eko Oṣere yii royin oun ti oju obinrin to ti kọ ọkọ silẹ n ri lawujọ Yoruba.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Joe Biden: Ṣé ó lè fẹ̀yìn Trump kó di ààrẹ America tó kàn?
Ọ̀fẹ́ ní à ń kò àwọn ọmọ Nàìjíríà tó há sí Lebanon bọ̀ wá sílé- Abike Dabiri Àgbo Covid-19 Madagascar kò ṣiṣẹ́, àwọn ènìyàn tí bẹ̀rẹ̀ sí ní kú níbẹ̀ Mo fi Àlìkùrání búra pé mò ń tọ́jú Risikat àti àwọn ọmọ mi- Bàbá àwọn ọmọ olójú búlúù Ilé ẹjọ́ ju olè orí omi mẹ́ta sí ẹ̀wọ̀n, ó tún ní kí wọ́n san 60 miliọ̀nù Abọ́ fífọ̀ àti ilẹ̀ ọkọ̀ ojú omi ní gbígbá ní mó fi kọ́kọ́ bẹ̀rẹ̀ iṣẹ́- Victor Agunbiade Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Peers of Heaven: Ààrẹ ẹgbẹ́ Emèrè ní àwọn ti wà tipẹ́, wọn kò pariwo síta ni18 Ògún 2020 Kano Torture: Inúu gáréèjì ni àwọn ẹlẹ́yinjú àánú ti rí Ahmed tú sílẹ̀14 Ògún 2020 Burna Boy Twice as Tall: Ǹkan tí ó yẹ ki o mọ̀ nípa Damini Ebunoluwa Ogulu Rex (Burna Boy) ti orin rẹ̀ lu ìgboro pa báyìí25 Bélú 2020 Èyí tí a wò jùlọ 5:03 Fídíò, Omolola Arohunmolase Welder: Mo ti fí iṣẹ́ 'Welder' gbayì láwùjọ, tó mo fi tọ́ ọmọ yanjú, Duration 5,039 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 5:39 Fídíò, Akomolede ati Asa lori BBC: Olùkọ́ Kikelomo Ogunboye tan ìmọ́lẹ̀ sí ìwà olè ọ̀gá ọlọ́pàá Audu gẹ́gẹ́ bí àwòkọ́ṣe àsìkò yìí, Duration 5,398 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 4:11 Fídíò, Oba Adeyeye Ogunwusi: Ojú mi ti rí lọ́pọ̀ lọpọ̀, ọ̀pọ̀ èèyàn ni kò tilẹ̀ gbàgbọ́ pé mo lè jọba- Ooni, Duration 4,117 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 4:43 Fídíò, Promise Akinlade: ọmọ ọdún mọ́kànlá tó ń fi ìlù dárà bíi àgbàlagbà sọ̀rọ̀ nípa tálẹ́ǹtì rẹ̀, Duration 4,437 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 0:59 Gbọ́, Ìsẹ̀lẹ̀ jákèjádò orílẹ̀èdè àgbáyé láàárín ìṣẹ́jú kan, Duration 0,59wákàtí 6 sẹ́yìn 7:03 Fídíò, Olumuyiwa Bolade Adedeji Military Bruitality: Bí arákùnrin onípèníjà ara tí sọ́jà lù ṣe dé, Duration 7,035 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 4:45 Fídíò, Yoruba Films: Ẹ̀ẹ́ bẹ̀ mi kúrò láyé ni, mi ò lè kú - Fadeyi Oloro, Duration 4,4526 Èrèlè 2020 2:48 Fídíò, Esther Ajayi: Èmi náà ti borí ìṣòro rí ló ń mu mi ṣojú àánú, Duration 2,481 Ògún 2019 6:08 Fídíò, Adebola Ademilua: Àìrísẹ́ ṣè lẹ́yìn ìwé kíkà ló sọ mi dí ìyá onírú, mo dúpẹ́ tèmi, Duration 6,0827 Bélú 2020 5:55 Fídíò, Soyinka Cancer: Àṣe ara mi ni iso ti n run gbogbo bí mo ṣe n ṣèrànwọ́ lórí jẹjẹrẹ, Duration 5,5527 Bélú 2019 BBC News, Yorùbá Ìdí tí ẹ fi le è nígbàagbọ́ nínú ìròyìn BBC Ìlànà Lílò Nípa BBC Òfin Àṣírí Cookies Kàn sí.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Wọn dóòlà ẹ̀mí ọ̀pọ̀ èrò níbi ìṣẹlẹ̀ ilẹ̀ rírì erékúṣù Lombok 6 Ògún 2018 Oríṣun àwòrán, AFP Àkọlé àwòrán, Àwọn olutọju alaisan n gbe alaisan kuro nile iwosan Mataram Irinajo afẹ́ to di irinajo to n gbẹ̀mí àwọn ènìyàn ni Indonesia.
Human traffiking: Òyìnbó kòráà, amòfin kan wọ gbaga òfin fún títa obìnrin kan sóko ẹrú
Coronavirus: Ó dá mi lójú pé ìwá ìbàjẹ́ ló fa àrùn yìí - Ọ̀gá àgbá EFCC Ṣé lóòtọ́ọ́ ni Adìyẹ Broiler ń fa àìsàn Coronavirus?
leti lo sorile-ede Egypt lojo kesan osu kefa odun ti wayii, lati lo fi ipago
Ati pe at'awọn ati agbẹnusọ fun wọn (Spinky Victor Lee), ko si ẹni to ri wọn ri lori ayelujara ko to digba ti iroyin ọhun jade lori Twitter ninu oṣu kẹwaa gẹgẹ bi iwaadi ile isẹ iroyin AFP 2.
Nígbà tí òṣùmàrè bá yọ, n óo wò ó, n óo sì ranti majẹmu ayérayé tí èmi Ọlọrun bá gbogbo ẹ̀dá alààyè tí ó wà láyé dá.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù West Ham vs Chelsea: West Ham fi omi àbùkù wẹ Chelsea láwọlé sùn, Arsenal yìnbọn pa Norwich 2 Agẹmo 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 3 Agẹmo 2020 Oríṣun àwòrán, Twitter/Chelsea FC Abuku oloronbo ni ẹgbẹ agbabọọlu West Ham United fi kan Chelsea lalẹ Ọjọru ninu idije Premier League.
Igbesẹ Gomina ipinlẹ Cross River to yara san owo osu fawọn oṣiṣẹ lati fi ṣe moriwu ni asiko ayajọ ọjọ oṣiṣẹ lo mu ọrọ wa.
Arabinrin ọmọ ilẹ Singapore naa sọ awọn ọna ti obinrin le gba lati le gbadun ibalopọ, pẹlu eemi ati awọn isẹpo ara lasan, eleyii ti o ni ko wọpọ ni awujọ wa.
Ẹni Ayérayé sì jókòó lórí ìtẹ́ tirẹ̀,aṣọ rẹ̀ funfun bíi ẹ̀gbọ̀n òwú.
kim jong-il , abiso yuri irsenovich kim ( gegebi akoole sofieti se fihan ) ( ojoibi 16 february 1941 ( akoole sofieti ) tabi 16 february 1942 ( akoole korea ariwa ) - 17 december 2011 ) , ni olori gigajulo orile-ede oseluarralu awon eniyan olominira ile korea ( korea ariwa ) .
Lẹ́yìn náà, yóo mú ọ̀kan ninu àwọn ọ̀dọ́ àgbò náà, yóo fi rú ẹbọ ìmúkúrò ẹ̀bi, pẹlu ìwọ̀n ìgò òróró kan, yóo fì wọ́n gẹ́gẹ́ bí ẹbọ fífì níwájú OLUWA.
Nítorí Ọlọrun kò jẹ́ kábàámọ̀ pé òun fún ẹnìkan ní ẹ̀bùn kí ó wá gbà á pada.
Yoruba Staff of Office: Àwọn ọbá aláye ilẹ̀ Yorùbá márùn-ún rèé pẹ̀lú ọ̀pá àṣẹ wọn
Ṣekanaya, ọmọ Jehieli, ọ̀kan ninu àwọn ọmọ Elamu bá sọ fún Ẹsira pé: “A ti hùwà ọ̀dàlẹ̀ sí Ọlọrun wa, nítorí a ti lọ fẹ́ aya láàrin àwọn ẹ̀yà tí wọ́n yí wa ká, sibẹsibẹ, ìrètí ń bẹ fún àwọn ọmọ Israẹli.
O ti pàṣẹ pé kí á fi tọkàntọkàn pa òfin rẹ mọ́,
Minisita fun eto iroyin lorilẹede Naijiria, Alhaji Lai Mohammed, ti ni ko sọrọ lori ipe ti ẹgbẹ ọmọlẹyin Kristi lorilẹede Naijiria, CAN pe wipe ki Aarẹ Muhammadu Buhari o se atunto awọn adari ileesẹ ọmọogun rẹ pẹlu awọn ẹjẹ tuntun ti yoo le mu ayipada ati igbona ọkan ba eto abo ati igbesẹ gbigbogun ti awọn adukukulaja.
Naijiria pe won yoo jegbadun lilo ero ibanisọrọ laije pe won ba ijakule pade.
Nítorí ìrẹ́pọ̀ wo ni ó wà láàrin ìwà òdodo ati aiṣododo?
Àkọlé àwòrán, Kilaasi kan ni yi ni Fasiti ikọni nimọ ijinlẹ sayẹnsi ni Fasiti Pọta nipinlẹ Rivers.
“Tabi bí ó bá fara kan ohun aláìmọ́ kan lára eniyan, ohun yòówù kí ohun náà jẹ́, ó ti sọ ẹni náà di aláìmọ́, bí irú ohun bẹ́ẹ̀ bá pamọ́ fún un, ìgbà yòówù tí ó bá mọ̀, ó jẹ̀bi.
Oríṣun àwòrán, AFP Contributor Àkọlé àwòrán, Aisi isẹ fun awọn ọdọ kun ara ipenija to n ba orilẹede Ghana finra Banki agbaye ti salaye saaju asiko yii wipe idagbasoke oniida mẹjọ ninu ọgọrun ni yoo de ba ọrọ aje orilẹede Ghana eyi ti yoo sun soke gẹgẹbii ọrọ aje to n dagbasoke ju lọ lagbaye.
Oríṣun àwòrán, TWITTER/LASEMA Ibeere re to gbẹnu awọn ọmọ Naijiria paapa julọ awọn olugbe ilu Eko lori iṣẹlẹ ibugbamu to n waye leralera.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Dodo Farm: Ẹ wo bí àwọn ọmọ Yoruba ṣe làlùyọ nídìí iṣẹ́ àgbẹ̀ ní Amerika Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Dodo Farm: Ẹ wo bí àwọn ọmọ Yoruba ṣe làlùyọ nídìí iṣẹ́ àgbẹ̀ ní Amerika 16 Òkùdu 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 18 Òkùdu 2020 Ọpọ ọmọ orilẹ-ede Naijiria lo ti fi ilẹ yii silẹ fo fẹrẹ roke okun ni ilepa ilẹ to lọọra.
Bakan naa lo ni awọn eeyan marun yoku ti wọn n jẹjọ pẹlu rẹ, naa jẹbi sise onigbọwọ jiji ọmọ ọdun kan naa, Gold Kolawole gbe, ni ọdun to kọja.
O tun yanana bi awon asofin se n kuro ninu egbe APC si egbe alatako, o salaye pe iru igbese bayii ko lena aye aare .
Kọmísọ́nà fún ètò ìròyìn ni ìpínlẹ̀ Eko Gbenga Omotsho ló sọ eyí lásìkò to n ba BBC News Yoruba sọ̀rọ̀.
Ojú wo ni o sì fẹ́ kí n fi wo Joabu ẹ̀gbọ́n rẹ?
Èyí ni ọ̀nà tí àwọn obìnrin n gbà kó ara wọn sí wàhálà nítorí ara bíbó Titi di asiko yii, awọn orilẹ-ede Afrika n ba ilẹ Yuroopu da ọrọ aje pọ ju bi wọn ṣe n ṣe laarin ara wọn lọ.
"A ti de sibi isẹlẹ naa, a n sisẹ lọ lati pa ina yii, ọwọ wa si ti n kaa, amọ a ko tii mọ bii ọsẹ to se ti nipa si.
Kabiyesi, n ko mọ pe ẹ ti kọ lẹta kankan nitori lati oṣù kẹsan-an ọdun 2019 ni ọga agba olopaa ti pàṣẹ pe ki wọn gbe Ileesẹ ọlọpaa kogberegbe ọhun wa si agbegbe Oke Ogun lati pinwọ iwa ijinigbe atawọn iwa ọdaran miran."
- Lo tewe tegbo - Didin ẹjẹ riru ku, ipaya, irẹra ati ironu oju kan ṣe pataki.
Sirika fi kun un pe ìjọba tun fòfin de Ileeṣẹ ọkọ ofurufu Cabo Verde ati South Africa nitori irinajo ofurufu ko tii bẹrẹ lorilẹ-ede wọn.
Àwọn tí ń ṣe inúnibíni mi súnmọ́ tòsí;wọ́n jìnnà sí òfin rẹ.
Alaga igbimo oluwadii lori awon akekoo Dapchi ninu ile-ile igbimo asoju sofin naa, Yusuf Buba Yakubu so pe, orile-ede Naijiria ko tun gbodo foju wina isele awon akekoo Chibok ti won jigbe ni nnkan bi odun merin seyin, ni eyi ti ile-igbimo asoju sofin ohun ti setan lati mo fin-in idi-koko isele naa.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Yinka Ayefele ṣe ìṣirò owó tí Dino ná ní ìsìnkú ìyá rẹ̀ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Yinka Ayefele ṣe ìṣirò owó tí Dino ná ní ìsìnkú ìyá rẹ̀ 27 Agẹmo 2019 A o kuku ki n fa ori lẹyin olori ni Yoruba wi.
Ọga ọlọpaa nipinlẹ Imo Dasuki Galadanchi ni orukọ awọn agunbanirọ ni Abiola Temitope, Olubisi Adekanmi, Jose Temitayo, Folarin Opeyemi and Shonibare Ademola.
Ẹfunsetan Aniwura, obìnrin tó ju ọkùnrin lọ Hubert Ogunde rèé, baba àwọn òsèré tíátà Ìrọ̀rùn dé l'Ekiti!
"Ninu iwe to kọ ohun, ni aarẹ ilẹ Amẹrika ti ni ""mo fẹ tẹnumọ pe ilẹ Amẹrika ni ọwọ ati iyi to pọ fun ilẹ Afrika, ti mo si tun mu ibasepọ to lagbara ati eyi to ni ọwọ pẹlu awọn orilẹede nilẹ Afrika gẹgẹbi orilẹede olominira lọkunkundun."
"Kìí ṣe emí ni mó ràn amúgbálẹ́gbẹ̀ẹ́ mi tó sọ̀rọ̀ abùkù sí FIBAN níṣẹ́- Wasiu Ayinde ENDSARS: Ẹ̀yin ọmọ Nàìjíríà, ẹ ṣè ìrànwọ́ irinṣẹ́ fáwọn ọlọ́pàá- Naira Marley bẹ̀bẹ̀ Ẹ̀wọ̀n ni wàá gbẹ̀yìn sí, kò sí bóo ṣe dọ́gbọ́n tó - Seyi Makinde wa ègúná ọ̀rọ̀ lé Fayose Ibadan ń jó àjórẹ̀yìn láàrin ẹgbẹ́, ẹ fún wa ní ìpínlẹ̀ tiwa - Kola Balogun bẹ ilé aṣòfin Gomina Abiodun ni ""Emi funra mi n foju sọna lati ba ọ sisẹ gẹgẹ bi awokọse iwa rere, aseyọri, abuda gidi, iwa tutu ati ododo, eyi tii se ara abuda ijọ̀ba ipinlẹ Ogun, koda, agbegbe Odeda lo ti wa."
”Fayemi tun gbosuba fun awon eniyan to wa sibi ayeye ibura ti o waye naa pe, eleyii je okan lara eto ’Ekiti Parapo’ ti oun da sile lasiko ijoba re lọdun 2014.
Ko pẹ ti wọn kọ ara wọn silẹ ni Albert Einstein gba ami ẹyẹ nobel prize ni eyi ti ọpọ gba pe yoo fun Mileva ninu owó naa.
Gẹgẹ bi ipe ti wọn pe e, oun ni yoo jẹ alejo pataki nibi eto naa.
Ó fi àwọn ọmọ rẹ̀ obinrin fọ́kọ láàrin àwọn tí wọn kì í ṣe ìbátan rẹ̀, ó sì fẹ́ ọgbọ̀n ọmọbinrin láti inú ẹ̀yà mìíràn wá fún àwọn ọmọ rẹ̀ ọkunrin.
Ọjọgbọn Ọṣinbajo sọrọ yii nigba ti o n ka ọrọ apilẹkọ nibi ipade ijiroro Pataki Ile Igbimọ Aṣofin Ipinlẹ Eko, ti wọn fi n ṣe ayẹyẹ ọdun kẹta ti saa kẹjọ igbimọ aṣofin yii ti wa lori aleefa, eleyii to waye ninu gbọngan igbimọ aṣofin naa ni Alausa, ni ilu Ikẹja ni Ipinlẹ Eko.
Man City vs Chelsea: Wọn ṣe ìyà fún Chelsea pẹ̀lú àmì ayo 6-0
Makinde tẹsiwaju pe agbẹkale Amọtẹkun waye fun igbaye-gbadun ati eto aabo to nipọn fun gbogbo ọmọ Oodua.
Bakan náà lo n lo orúkọ ti kìí jẹ Akinwumi Sorinmade, lati sí àpò ikówópamọ meji ni First Bank àti Guaratee Trust Bank (GTB), o ra oun ini si Fountain Spring Estate ni Lekki lọdun 2018 ni mílíọnù mejilélógun àti Lexus RX 350 fún iyawo rẹ̀ Maria Jennifer Aroke.
Gbogbo awọn ontaja lo si gbọdọ lo ibomu-bẹnu, ki wọn o si tun ṣeto sanitaisa ni ọja wọn.
9 187320 Agbegbe Palestine 1687 34.
Sugbọn ṣaa, fọto aboyun ti owo rẹ ti jawalẹ ti mu ko rọrun fun awn obinrin lati maa mọ ipo ti apo ile ọmọ wọn ba wa.
Ẹwẹ, aarẹ tuntun yoo ni lati bẹrẹ ijọba tirẹ lakọtun ni ti yoo si ṣẹṣẹ tun ṣagbejade ilana adari tuntun ni Burundi.
Ninu akọsilẹ ajọ naa lori ọrọ covid-19 fun ọjọ Abamẹta, eeyan marunlelogoji lo jajabọ lọwọ aarun naa ti wọn si ti pada sile wọn.
Adájọ tí so ìjòkò igbẹ́jọ́ Omoyele Sowore rọ dì ago mọ̀kànlá Wọn fẹsun kan wọn pe wọn lẹdi apo pọ pẹlu ikọ Boko Haram.
”Lasiko mi nilu Amerika, mo je okan ninu awon to ran Barack Obama lowo nigba to n dije fun ipo aare niluu Amerika, opolopo awon oloselu ni mo tun ran lowo niluu Amerika.
OLUWA, kò sí ẹni tí ó dàbí rẹ, o tóbi lọ́ba,agbára orúkọ rẹ sì pọ̀.
Na òṣìṣẹ́ Amotekun, ko san ₦250,000 owó ìjìyà, ko sì tún fi ẹ̀wọ̀n oṣù kan jura Ìkede ti jáde pe ẹnikẹni to ba na tabi kọju ija si osisẹ ikọ Àmọ̀tẹ́kùn lẹ́nu iṣẹ́, yóò fi ẹ̀wọ̀n osù kan jura àti ko san ẹgbẹ̀rún lọna igba naira ati abọ.
Ohun to kọkọ ṣẹlẹ ti iléẹjọ́ fi fk dájọ́ bóyá Gómìnà Akeredolu yẹ láti du ipò gómìnà ní ìpínlẹ̀ Ondo Oríṣun àwòrán, Twitter/akeredolu Nigba ti wọn kọkọ pe ẹjọ naa, o dabii pe ọrọ ko tii tan fun Akeredolu, gomina ipinlẹ Ondo lẹyin ọpọlọpọ ọsẹ ti eto idibo gomina ipinlẹ Ondo ti gbee wọle fun saa keji.
Ta òróró sí ara pẹpẹ ẹbọ sísun pẹlu, ati sí ara gbogbo àwọn ohun èlò rẹ̀, kí o ya pẹpẹ náà sí mímọ́, pẹpẹ náà yóo sì di ohun mímọ́ jùlọ.
Kini yoo sẹlẹ si awọn osisẹ Diamond Bank?
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Christmas & Border Closure: ìrẹsì dí góòlù fún Kérésì 2019 Awọn ẹbun ọhun ni awọn ẹru naa maa n gbe lọ fun awọn ara ile wọn ki wọn fi ṣafihan bi awọn olowo awọn ṣe mọ riri iṣẹ ti wọn ṣe lodindin ọdun kan to.
Ẹnikẹ́ni tí ó bá ṣe irú rẹ̀, tabi ẹnikẹ́ni tí ó bá dà á sórí ẹnikẹ́ni tí kì í ṣe alufaa, a óo yọ olúwarẹ̀ kúrò lára àwọn eniyan rẹ̀.
Wọn ni oye Babalọja kii ṣee fun ilu Ibadan nikan, gbogbo ipinlẹ Oyo lo wà fún.
Àwọn tí wọ́n ṣiṣẹ́ náà, pẹlu àwọn ọmọ wọn nìwọ̀nyí:Ninu ìdílé Kohati: Hemani, akọrin, ọmọ Joẹli, ọmọ Samuẹli, 
Oríṣun àwòrán, Kola Stephen Àkọlé àwòrán, Awon ti pota ree ni Garaji ọkọ Wọn ni asọ ti yóò lé wọ òde ìgbéyawo náà ni Pepper-dem àtio wailers White Ìyá Micho àti awọn alágbàse míràn lo soju nibi iyẹyẹ náà Oríṣun àwòrán, AbiolaGenus8 Àkọlé àwòrán, Awọn olunjẹ ti bẹ̀rẹ̀ si ni in ounjẹ Oríṣun àwòrán, Johannx Àkọlé àwòrán, Mr JAG naa wa lara awon kongila olounje Oríṣun àwòrán, Bolatito Àkọlé àwòrán, Awon ounjẹ to joju ni gbese Oríṣun àwòrán, Bolabelyncon Àkọlé àwòrán, Mo gbo moya ti fẹ pari oujẹ inawo Alaga idúro fú ìdíle ayẹyẹ igbeyawo náà ti bẹ̀rẹ̀ iṣẹ́ ni pẹrẹwu Oríṣun àwòrán, Modabba Àkọlé àwòrán, Ogbeni Raufu ti bẹ̀rẹ̀ isẹ́ Oríṣun àwòrán, Bababosso Àkọlé àwòrán, Won ti bẹ̀rẹ̀ sinu gbọ́wọ́ ijo gẹngẹ Gbogbo elere fún ayẹyẹ naa ooo Oríṣun àwòrán, Lucasscot_101 Àkọlé àwòrán, Igbakeji àarẹ ni Gbogbo elere nibi ode yii Oríṣun àwòrán, Optimistic_Ade Àkọlé àwòrán, Ààrẹ aná ni Naijiria, tí n mura silẹ fun ayẹyẹ yìí Oríṣun àwòrán, HelloMilez Àkọlé àwòrán, Awon Orẹ Oko Awọn asọna fun ayẹyẹ igbeyawo naa Oríṣun àwòrán, @Uwayasi Àkọlé àwòrán, Awon asona ti yóò ma ran alejo lọ́wọ́ nibi ayẹyẹ yii Minisita fun ere idaraya tẹlẹ ni odẹ aperin ti yóò pese gbogbẹlan ti wan nilo.
O ni : “Mo nigbagbo pe ijoba wa yii ye fun
OLUWA dá a lóhùn: ó rán iná sọ̀kalẹ̀ láti jó ẹbọ sísun náà.
A máa ń jogún ilé ati ọrọ̀ lọ́wọ́ baba ẹni,ṣugbọn OLUWA níí fúnni ní aya rere.
Sibẹsibẹ, jọ̀wọ́ fetí sí adura ati ẹ̀bẹ̀ èmi iranṣẹ rẹ.
Ẹ bu omi wá fún ẹni tí òùngbẹ ń gbẹ.
Brọ̀dá Shaggi: Shagidon ni mo gé kúrú sí Shaggi bíi ìnagijẹ nínú eré
Iwadii BBC fihan pé ọmọbinrin Gẹẹsi mii ku latari iṣẹ abẹ naa.
"Orukọ inagijẹ ti wọn fun oloogbe Amadou Toumani Toure si ni ""Ologun fun ijọba alagbada."
Ọkan lara wọn ku, wọn n ṣe isẹ abẹ fun ọkan lara wọn lọwọ nileewosan.
Ni kete ti iroyin lu sita ni ibẹrẹ oṣu Kejila ni awọn agbofinro ti kede pe awọn n wa Teixeria.
Obaseki la Ize-Iyamu mọ́lẹ̀ wọlé ìbò gómìnà lẹ́ẹ̀kejì ní ìpínlẹ̀ Edo A fẹ́ gbé orò láti lé àwọn ajínigbé kùrò ní ìpínlẹ̀ Oyo- Áṣẹyin ti Iṣẹyin 'Mo mọ̀ọ́mọ̀ sin ọmọ-ọmọ mi, ìkókó jòjòló láàyè ni, nítorí wọ́n fipá bá ọmọbìnrin mi lòpọ̀ ló fi lóyún rẹ̀'!
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Afẹnifere: Omisore kò jẹ́ ká mọ ìgbésẹ̀ rẹ̀ nínú ìdìbò Oṣun 26 Agẹmo 2018 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 4 Bélú 2018 Àkọlé àwòrán, Ẹgbẹ́ ọmọ Yoruba lápaapò, Afenifere tí kòwé lọ gbé ilé rẹ fún Sẹnetọ Omisore fún ọdún kan lórí ipa tó kó lásìkò ìdìbò gomina ni Ọsun.
Ẹfunsetan Aniwura, obìnrin tó ju ọkùnrin lọ Ọ̀rọ̀ǹpọ̀tọ̀niyùn, Aláàfin obìnrin àkọ́kọ́ rèé, tó ní nǹkan ọkùnrin Àwọn òṣèré Yollywood tó ń pàrònú rẹ́ Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Ṣe ofin ijinasiraẹni ko tako ẹsin Musulumi?
Òun pàápàá ń kérora, ó sì fi ojú pamọ́.
Nítorí ìwọ náà tí ò ń dáni lẹ́jọ́ ń ṣe àwọn nǹkan gan-an tí ò ń dá ẹlòmíràn lẹ́bi fún.
0 11063 Orilẹede Chad 102 0.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Mo máa n forin mi kìlọ̀ ìwà ìbàjẹ́ láwùjọ ni -Hameen Iṣẹlẹ yi mu ki ile iṣẹ Naijiria ni London kede pe bẹrẹ lati ọjọ kẹrinlelogun, oṣu yi,wọn yoo ma fi iwe irinna ranṣẹ si awọn to ba fi adirẹsi ati apo iwe kalẹ sọdọ awọn.
si n lọ lọwọ lori isẹlẹ  naa nipa bi owo
Ṣugbọn níbo ni a ti lè rí ọgbọ́n?
 a gba idanimọ ile lati awọn awọn ti awọn alabaṣepọ roy w.
Oniruru awuyewuye lo ti n waye lori iwe ẹri girama aarẹ Buhari.
O ni ọgbọn awọn oniwa aburu ẹda lati tẹmbẹluu agbara ọlọpaa nipinlẹ Oyo ni.
Ohun marun t'ejo n jẹ Oró ò!
Ajenifuja wa dupẹ lọwọ gbogbo awọn ara ilu Offa to fi mọ awọn to duro ti wọn lasiko ijinigbe yi.
Ọdún kan si ló gba àwọn tó ṣe ère nàá láti pari rẹ̀.
Oríṣun àwòrán, jigawa Ko si ẹni to le sọ pato iye awọn ọmọ kewu yi ti wọn fi n ransẹ sugbọn ipinlẹ Kaduna nikan sọ pe ẹgbẹrun lọna ọgbọn awọn ọmọ yi lawọn da pada si ipinlẹ wọn.
O ni ko si ija laarin Buhari ati Osinabjo lasiko yii.
Ní àkókò yìí, gbogbo àwọn ọmọ ogun Israẹli ti sá, olukuluku ti pada sí ilé rẹ̀.
O ni ajọ FRSC gbodọ rii pe awọn awakọ to n kọja loju opopona yii mu aṣẹ ijọba naa ṣẹ ni kiakia.
Wọ́n tún mọ odi mìíràn yípo wọn.
Wọ́n bá Adonibeseki ní Beseki, wọ́n gbógun tì í, wọ́n sì ṣẹgun àwọn ará Kenaani ati àwọn ará Perisi.
Guru Maharaji: Ó yẹ kí ìjọba àpapọ̀ fíkún owó oṣù òṣìṣẹ́ àti ti adájọ́
Josaya pàṣẹ pé kí àwọn eniyan náà ṣe Àjọ̀dún Àjọ Ìrékọjá fún ògo OLUWA Ọlọrun wọn, gẹ́gẹ́ bí ó ti wà ninu ìwé majẹmu; 
Ada ni wọn fi ṣá a yanna-yanna.
Bi ọrọ ba wọ, ohun to kan ni ki wọn ṣe idana, ki igbeyawo si tẹle.
Àwọn èròjà wọ̀n-ọn nì ní wọ́n fún oújẹ wọn ní adùn tó dára dé ibi pé, wọ́n sọ ọ́ ní ‘àjẹ-lá-ìka’ – ajẹ́pé ení bá jẹ adìẹ díndín wọn, ńṣe ni olúwarẹ̀ á máa lá ìka tó fi mún adìẹ náà sẹ́nu nígbà tó bá jẹ ẹ́ tán.
Agbẹjọrọ ati olukọ ni Ile Iwe Giga Leads University, Arabinrin Abiade ti parọwa si awọn obinrin lati mọ wi pe ẹni iyi ni wọn nitori naa ki wọn ma fi aye gba iwa ipa.
” Doegi ará Edomu sì pa alufaa marunlelọgọrin, tí ń wọ aṣọ efodu.
Eeyan kan loju opo twitter ni ṣekarimi lawọn iranṣẹ Ọlọrun naa n ṣe kaakiri.
Àwọn ọba Yorùbá kan rèé tí wọ́n rọ̀ lóyè, tí ọba míràn jẹ lójú ayé wọn Ìtàn Gbọnka àti Timi, akọni méjì tó borí Aláàfin Ṣango Ìdílé márùn-ún tó gbajúmọ̀ fún òwò ẹrú nílẹ̀ Yorùbá Ìtàn ayé Ọba Seriki Abass ti Badagry, tó ní aya 128, ọmọ 144 Ìtàn rèé nípa bí Ogbomoso ṣe pa ọba, yọ nǹkan ọkùnrin rẹ jó kiri ìlú Àwọn ọba Yorùbá kan rèé tí wọ́n rọ̀ lóyè, tí ọba míràn jẹ lójú ayé wọn Kí ló fà ogun Ìjàyè àti ìṣubú Kurunmi, ìfẹ́ ìlú ni àbí orí kunkun?
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Idi ti esi idanwo Jamb yoo se pẹ ko to jade JAMB f'ọjọ kun asiko iforukosilẹ O ṣi ṣe ileri wipe wọn n tin ṣatunṣe lori gbogbo ipenija ẹrọ ti awọn eeyan n ko lori opo ẹrọ ayelujara rẹ l'ọwọ-l'ọwọ bayii.
Eto WASA yii maa n waye lodoodun pelu erongba ati polongo isokan ati igbekele ninu ara eni awon ologun ninu ati lode ibugbe won.
omo ogun olote to ba n ni alaafia orile-ede yii lara.
Eyi lo mu Titi maa fẹ fi ọgbọn já Deji silẹ.
Awọn orilẹ-ede mẹwa to n gbeero lati sọ igbo gbigbin din ọ̀rọ̀ Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ọ̀pọ̀lọpọ̀ló ń fara pamọ́ mu igbò Yatọ si gomina Akeredolu to fẹ ki orilẹ-ede Naijiria o sọ igbo gbigbin di irinṣẹ ọrọ aje, awọn orilẹ-ede bi Lesotho, South Africa ati Zimbabwe ni awọn orilẹ-ede ilẹ Africa ti wọn ti n gbeero lati sọ igbo di ọ̀rọ̀.
Nkan tí a mọ̀ nìyíì Awọn eleto aabo sọ pe bi ọjọ ṣe n gun ori ọjọ, ni didoola àwọn ọmọ naa yoo ma a ṣòro si, paapa ti awọn ọmọ naa ba ti tuka, tabi ti awọn agbebọn ba ko wọn si ibi ọtọọtọ.
Ẹsita Ayaba, ọmọbinrin Abihaili, ati Modekai, tíí ṣe Juu kọ ìwé láti fi ìdí ìwé keji nípa Purimu múlẹ̀.
Gbàrà tí òjò ba bẹ̀rẹ̀ ni olúkálukú ń nà án sókè borí.
Bí ẹnikẹ́ni bá jẹ́ iranṣẹ mi, Baba mi yóo dá a lọ́lá.
Láti ọ̀dọ̀ àwọn olùṣọ́ ni ìdájọ́ yìí ti wá, ìpinnu náà jẹ́ ti àwọn Ẹni Mímọ́; kí gbogbo àwọn ẹ̀dá alààyè lè mọ̀ pé Ẹni Gíga Jùlọ ní àṣẹ lórí ìjọba eniyan, ẹnikẹ́ni tí ó bá sì wù ú níí máa gbé ìjọba lé lọ́wọ́, pàápàá láàrin àwọn ẹni tí ó rẹlẹ̀ jùlọ.
Njẹ ajọsepọ awọn to kora jọ lati doju ija kọ ara wọn wọn yi, yoo jẹ ọlọjọ pipẹ tabi awọn naa yoo pada wa tutọ si ara wọn loju?
Wọ́n bá gbé wọn tẹ̀wù tẹ̀wù kúrò láàrin ibùdó gẹ́gẹ́ bí Mose ti wí.
4 Bẹ́ẹ̀ni, ẹnikẹ́ni tí ó bá fi dòjé rẹ̀ gún un tí ó sì kórè, ẹni náà ni Ọlọ́run pè.
com/YahgLdcB7pArsenal 2-3 Crystal Palace Cardiff City 0-2 Liverpool Chelsea 2-2 Burnley Idije Serie A(Italy) Parma 1-1 Milan Bologna 3-0 Sampdoria Cagliari 1-0 Frosinone Empoli 2-4 SPAL Genoa 0-1 Torino Lazio 1-2 Chievo Udinese 1-1 Sassuolo Juventus 2-1 Fiorentina Inter 1-1 Roma Napoli 1-2  Atalanta Idije La Liga(Spain)Celta Vigo 2-1 Girona Eibar 0-1 Atletico Madrid Rayo Vallecano 0-0 SD Huesca Barcelona 2-1Real Sociedad Levante 2-2 RCD Espanyol Getafe3-0 Sevilla Real Madrid 3-0 Athletic Bilbao Villarreal 2-1 Leganes Real Betis 1-2  Valencia Idije
Arakunrin Jeremy ti orukọ rẹ gangan n jẹ Ronald Jeremy Hyatt foju bale ẹjọ ni Osu Kẹfa ọdun yii fun ẹsun ifipabanilopọ.
"Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Africa Eye: Coronavirus di adákẹ́jà ní Somalia, ikú ọ̀wọ́ọ̀wọ́ ń peléke si ""Nise ni mo ya owó ni banki ti mo ti n sisẹ, ati lọwọ awọn ojulumọ mi, ki n to ri ìdá aadọta owo naa kó fun wọn nipasẹ agbejọro mi."
Fifẹ aya rẹ gẹgẹ bii ọkunrin ko gbọdọ pọ ju iwọn 34 inches lọ.
nipa fifi iroyin to won leti ,nipa iwa odaran ni awon ipinle naa.
Ọdọmọkunrin Heberu kan wà níbẹ̀ pẹlu wa, ó jẹ́ iranṣẹ olórí àwọn tí wọn ń ṣọ́ ààfin, nígbà tí a rọ́ àlá wa fún un, ó túmọ̀ wọn fún wa.
Mojisola bi ọmọbinrin kan ati ọmọkunrin fun ọba Adeyemi, to si tun daju yoo bi si.
Olùfẹ́, ohun rere ni ò ń ṣe fún àwọn arakunrin, bí wọ́n tilẹ̀ jẹ́ àlejò.
Ìgbẹ́jọ́ọ rẹ̀ tún di ọjọ́ 9, oṣù Èbìbì ọdún-un 2019.
Ajo NCDC ni awon iko to n pese iranwo nisele pajawiri si n sa ipa won lati maa tete pese iranlowo ni Ebonyi, Ondo Edo.
Amọ gomina ipinlẹ Ogun naa ko si nibi ayẹyẹ naa lati fesi si oun ti awujalẹ sọ.
Ẹni to bori: Mali Angola vs Namibia.
ile –ise to n mojuto papa ofurufu ,arabinrin Henrietta Yakubu se sọ pe awon ti seto
Ninu ọrọ kan to ba awọn akọroyin sọ lẹyin to kirun ọdun ileya tan ni yidi Agodi nilu Ibadan, ni gomina Ajimọbi ti sọ ọrọ yii.
Ilẹ̀ tí ó wá yí wọn ká jẹ́ ti Pubiliusi, baálẹ̀ erékùṣù náà.
Irú èyí nṣẹlẹ̀ lọ́wọ́-lọ́wọ́ ní ìlú Faransé, Séríbíà, ati bẹ́ẹ̀ bẹ́ẹ̀ lọ.
rẹ, Alaga Igbịmọ Alakoso Agbeyẹwo Iṣuna Owo Ilu ni Ipinlẹ Eko, Ọgbẹni
Christopher Ayẹni ṣe ikede èsi idibo yii.
Ojú àánú wọn ti fọ́,ọ̀rọ̀ ìgbéraga sì ń ti ẹnu wọn jáde.
Aarẹ Naijiria sọ pe laarin ọdun mẹrin saa keji ijọba oun, oun yoo jẹ ki ina mọnamọna wa lowo pọọku fawọn ọmọ Naijiria.
Gomina ana nipinlẹ Ọyọ naa wa jẹ ko di mimọ faraalu pe, arun Coronavirus kii ṣe idajọ iku o, bo pẹ, bo ya ilẹ agbaye yoo bori rẹ.
Ẹgbẹ́ IMN:ọmọ ẹgbẹ́ wa mẹ́tàlá ní ọlọ́pàá yìnbọn pa níbi ìwọ́de ìdárò Ashura
Lara eṣinṣin eso nikan ni iwadii tii fi mulẹ pe wọn ti n ṣiṣẹ daadaa.
Eyi lo mu ki ikọ Manchester city pariwo ki lo ṣubu lu mi yii?
Lẹyin eyi ni ọrọ naa wa di fa-ki-n-fa laarin awọn mejeeji.
Nítorí pé nígbà gbogbo ni à ń fi ẹ̀mí wa wéwu nítorí Jesu, níwọ̀n ìgbà tí a wà láàyè, kí ìyè Jesu lè hàn ninu ẹran-ara wa tí yóo di òkú.
Ohun tí a mọ̀ nípa ikú ọ̀wọọ̀wọ́ ní Kano nìyí Aláàfin pín oúnjẹ́ fárá Ọ̀yọ́ Èèyàn 91 míràn tún ti ní àrùn Coronavirus ní Nàíjírìa Dibu Ojerinde, akọ̀wé JAMB tẹ́lẹ̀ pàdánù ọ̀pọ̀ dúkìá sọwọ àjọ ICPC Ìlànà IVF là fi bí ìbejì tẹ gbé lẹ́yìn idaduro ọdún méjìlá, ẹ jọ̀ọ́, ẹ tú wọn ṣílẹ̀ - Akeugbagold, aya rẹ bẹ̀b Bákan náà lo tún rọ gbogbo àwọn agbofinro yíká orílẹ̀ èdè Nàìjíríà, láti pawọpọ ṣe àwárí ìbejì ọhun, kí wọ́n si tún rí dájú pé àwọn olubi ẹ̀dá to ṣiṣẹ láabi náà, fi imú kò ata òfin.
Coronavirus tips: Ìdí nìyí tí ààrùn coronavirus ṣe n ṣekú pa àwọn tó pa
fawọn to ba n gbero lati da rogbodiyan sile lakoko eto idibo gbogbogbo-o to n
Lọtẹ yii, ori ẹrọ ibaraẹnisọrọ ni Tinubu ti bawọn ọdọ kan takurọsọ nipa isẹlẹ naa lọjọru.
Baba rẹ̀ gbóòórùn aṣọ rẹ̀, ó sì súre fún un, ó ní,“Òórùn ọmọ mi dàbí òórùn oko tí OLUWA ti bukun.
Ninu atejade kan ti komisona to n ri si iroyin ati ikede nile –ise ajo
Lapapọ, ẹgbẹrun lọna ọrinlelẹgbẹta din mẹrin ati ọrinlelẹgbẹta din maarun (676,675) awọn ọmọ Naijiria lo forúkọ silẹ fun eto igbani sisẹ naa.
O ni nilẹ Yoruba, ọba ti ọ̀pá àṣẹ ba ra mọ lọwọ, boya wọn ji lọ ni o, tabi nitori nkan miran, kii ṣe ọba mọ, idi ni pe, ọ̀pá naa lo fi n pasẹ fun gbogbo ilu to jẹ ọba le l'ori.
Jerusalẹmu, bí mo bá gbàgbé rẹ,kí ọwọ́ ọ̀tún mi kí ó rọ.
" Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Fire Eater: Azonto ní àfojúṣùn òun ni láti lọ fi idán iná yìí pa owó lókè òkun Ọpọ awọn eeyan jankajankan miran to n se agbeaga fun asa ati ede ilẹ wa ni wsn tun fun lami ẹyẹ nibi ayẹyẹ naa, to fi mọ afihan awọn ohun isẹmbaye wa, to jẹ manigbagbe.
Ninu atejade kan  ni ogbeni Okechukwu  ti so pe  “ aheso oro patapata gbaa ni oro ti awon eniyan n so nipa orile ede Naijiria ati pe ireti si wa lorile ede yii’.
Lóde òní wàyí, ó ti di ayẹyẹ gbogbo gbòò, gbogbo ẹ̀yà, gbogbo ìran ni.
Mo fi àwọn aṣọ́nà ṣọ́nà nítorí yín.
    Nígbà tí mo máa kúrò nílé, bàbá mi pè mí sí yààrá, nígbà tí mo sì dé ọ̀hún tán o ní ki n súnmọ́ oun, mo sì súnmọ ọ, lẹ́yìn èyí ó fi ọwọ́ kọ́ ni lọ́rùn ó sì bẹ̀rẹ̀ sí ọ̀rọ̀ i sọ ó ni:
Bàbá akẹ́kọ̀ọ́ LASU tí ọ̀rẹ́kùnrin rẹ̀ àti pásítọ̀ fi ṣ'oògùn owó ń bèèrè fún ìdájọ́ òdodo Ọwọ́ ọlọ́pàá tẹ afurasí tó ní òun ló jí ọmọ gbé láti parọ́ mọ́ pásítọ̀ ìjọ Sotitobire Ìdájọ́ ikú ń dínkù, àmọ́ orílẹ̀-èdè mélòó ló sì ń pa ẹlẹ́sẹ̀?
Oríṣun àwòrán, @imnigeria_org Ninu atẹjade kan ti akọwe agba fun ileeṣẹ eto iroyin labẹ ijọba apapọ fi sita, o salaye pe se ni Zakzaky da ọwọ ru ni kete to gunlẹ si India.
Ṣe ibi gbogbo ni ijinigbe ti n waye?
Ni kete  ti oko ofurufu to gbe
Amọ ṣa Ojikutu fesi pada pe kii se ẹya kan ni o n fi ẹhonu han bi kii ṣe gbogbo awọn ti ọrọ kan ni ọja naa.
Agbado, epo ati awọn eroja miiran ni wọn fi n ṣe.
Àkọlé àwòrán, Awon eniyan kan n satileyin fun Busola Dakolo Ero pupọ lo ti kun ita ile ijọsin Commonwealth of Zion Assembly nipinlẹ Eko.
 Òun ni wọ ́ n ń lò ní orílẹ ̀ -èdè armenia .
“Nígbà kan rí èmi náà rò pé ó jẹ mí lógún láti tako orúkọ Jesu ará Nasarẹti.
”Wọ́n dáhùn pé, “A kò ní oúnjẹ pupọ, àfi burẹdi marun-un ati ẹja meji, ṣé kí àwa fúnra wa lọ ra oúnjẹ fún gbogbo àwọn eniyan wọnyi ni?
Nítorí ẹni tí ó bá ń jẹ, tí ó ń mu láìmọ ìyàtọ̀ tí ó wà ninu ara Kristi, ìdájọ́ ni ó ń jẹ, tí ó sì ń mu, lórí ara rẹ̀.
Tottenham sọ ifẹsẹwọnsẹ naa di tawọn ọmọ girama pẹlu bi awọn agbabọọlu rẹ meji ṣe gba kaadi alawọ pupa eyi to tumọ si pe wọn le wọn jade kuro ninu ifẹsẹwọnsẹ naa fun iwa aṣemaṣe.
Kanye West ṣèrànwọ́ $2m fún ẹbí George Floyd, yóò tún rán ọmọ rẹ̀ nílé ìwé Afipábánilòpọ̀ méjì tún ṣọṣẹ́ lára ọmọ ọdún 17 l'Ekiti Wo àwọn gbajúmọ̀ òṣèré Yorùbá tí kìí ṣe ọmọ káàárọ̀ oòjíire Ẹ̀wọ̀n gbére ni fún ẹnikẹ́ni tó bá fipá bánilòpọ̀ ní ìpínlẹ̀ Ọ̀ṣun Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí 3 sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 2:23 Fídíò, Water Generator: Ó leè ṣiṣẹ fún wákàtí mẹfà, kó tó sinmi, Duration 2,2310 Òkùdu 2020 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
Kì í ṣe nítorí iṣẹ́, ẹ̀bùn Ọlọrun ni.
Ó sì wà lórí oyè fún ọdún mẹrindinlogun.
Adùn rẹ̀ ṣì wà lára rẹ̀, òórùn rẹ̀ kò sì tíì yipada.
Ó ní, “Ẹ kọjá sí èbúté àwọn ará Kipru kí ẹ wò yíká,tabi kí ẹ ranṣẹ sí Kedari kí ẹ sì ṣe ìwádìí fínnífínní,bóyá irú rẹ̀ ṣẹlẹ̀ rí.
Wọ́n bẹ Jẹfuta, wọ́n ní, “A fẹ́ lọ gbógun ti àwọn ará Amoni, ìwọ ni a sì fẹ́ kí o jẹ́ balogun wa.
Sibẹ wọn kò gbọ́ tèmi, wọn kò tẹ́tí sí mi.
Amọ awọn eeyan tako ikede naa, ti wọn si bọ sita lati fi ẹhonu han lai bikita fun aabo ẹmi wsn rara.
Ẹnìkan báyìí tí n óò tún sọ̀rọ̀ rẹ̀ ni ọkùnrin kan tí ó ṣe ìbéèrè tí ó jọ gbogbo ènìyàn lójú gidigidi.
aabo ko ba si, ki won si ri i pe won daabo bo ẹmi eniyan ati dukia.
Díẹ̀ ló kù kí wọ́n mu Ìjàǹbáforítì ṣùgbọ́n tí wọ́n yẹ̀ ẹ́ wò dáadáa wọ́n ní kò sanra tó fún jíjẹ.
Ṣugbọn Jesu kò dá a lóhùn.
, nitori naa o jawe olubori gẹgẹ  bi gomina ni ipinlẹ Benue  ninu eto idibo gomina  to waye ni ọjọ kẹ́rìnlélógún, osu kẹ́ta,
Ọ̀pọ̀ àwọn àwọn ọmọ Nàìjíríà ló ti bẹ̀rẹ̀ si ni ki Kanu kú orire ọjọ́ ìbí.
 Ebi ti a le bo ti yoo yo, t’ale dasọ ro,
eniyan padanu ẹmi wọn, tabi eleyii ti o lee tu awon orile ede kaa.
Nítorí náà, ẹ jẹ́ kí á máa lépa àwọn nǹkan tí ń mú alaafia wá, ati àwọn nǹkan tí yóo yọrí sí ìdàgbàsókè láàrin ara wa.
Gbogbo àwa tí a wà ninu ọkọ̀ náà jẹ́ igba ó lé mẹrindinlọgọrin (276).
Ìtàn Mánigbàgbé: Ó pé ọdún mẹ́rìnlélàádọ̀ta tí Akintola kú, ìdí abájọ ìja rẹ̀ pẹ̀lú Awolowo rè é
Tony Elumelu 2018: Mahassin Quadri ló gbà ìrànwọ owó
A sì pa àwọn ìpínlẹ̀ àwọn ọmọ Lefi kan ní Juda pọ̀ mọ́ ti àwọn ọmọ Bẹnjamini.
Mo tún rí angẹli alágbára mìíràn, tí ó sọ̀kalẹ̀ láti ọ̀run wá.
Oríṣun àwòrán, Twitter Ayọdele ni ijọba gbọdọ pese aabo fun awọn eniyan ara Guusu Kaduna naa ki wọn ba le ni igbagbọ ninu ijọba.
Ọmọ Lefi Kan ati Obinrin Rẹ̀.
Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Fídíò, Kọmisọnà ọlọ́pàá ni àwọn yóò tú iṣu dé ìṣàlẹ̀ ìkòkò lóri ọ̀rọ̀ náà2 Ìgbé 2019 Kolade Johnson: Adájọ́ pàṣẹ kí wọ́n fi ọlọ́pàá tó lọ́wọ́ nínú ikú Kolade Johnson sí àhámọ́5 Ìgbé 2019 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Lórí òkè gíga Israẹli ni n óo gbìn ín sí,kí ó lè yọ ẹ̀ka, kí ó so,kí ó sì di igi Kedari ńlá.
Ìjọba ìpínlẹ̀ Kano pàṣẹ pé kí gbogbo ilé ẹ̀kọ́ ètò ìlera di títì pa Oríṣun àwòrán, @Dawisu Gomina ipinlẹ ipinlẹ Kano, Abdullahi Umar Ganduje, ti paṣẹ pe ki awọn ile ẹkọ eto ilera nipinlẹ naa ko wa ni titi pa.
Segun Abraham jẹ́ ọ̀kan lára àwọn méjìlá tó ń dije lábẹ́ àsíá ẹgbẹ́ APC tó sì ti gbá ìwé láti fi èrò rẹ̀ hàn pé, òun ṣetan láti kópa nínú ìdìbò abẹ́lé ẹgbẹ́ náà ti yóò wáye ní Ogúnjọ́, Oṣù Keje ọdún yìí.
O ti gba amiẹyẹ to ga julọ mni Naijiria pẹlu Member of the FederalRepublic of Niger"" Abdulsalam Ishola Sanyaolu (Charles Olumo) Oríṣun àwòrán, Others Abdulsalam Ishola Sanyaolu ti gbogbo eniyan mọ si Charles Olumọ tabi ""Agbako naa jẹ gbajugbaja elere agbelewo."
Tirẹ̀ ni òkun, nítorí pé òun ni ó dá a;ọwọ́ rẹ̀ ni ó sì fi dá ìyàngbẹ ilẹ̀.
Ọ̀pọ̀ tilẹ̀ fẹ́ yọ ẹ̀ṣẹ́ sí ara wọ́n lórí ayelujara lórí bóya, Daddy Freeze lo jẹ̀bi lórí ọ̀rọ̀ to kọ si Bíṣọ̀ọ̀bù David Oyedepo tàbí ọ̀rọ̀ tí Pásítọ̀ Ibiyeomie sọ náà ti pọ̀ju, gẹ́gẹ́ bi ènìyàn Ọlọ́run.
Idajọ yii waye lẹyin ti ile ẹjọ to n gbọ awuye abajade esi idibo gomina nipinlẹ Ekiti gbe kalẹ ṣaaju pe Fayẹmi lo wọle gẹgẹ bii gomina nitootọ.
Bẹẹ ni ọrọ ri pẹlu itan igbe aye arakunrin kan, Matthew Oluwafemi, ti ọpọ eeyan mọ si Shina Rambo.
Ẹ ó rántí wípé Saudi Arabia ló kọ́kọ́ kéde pé Ọjọ́bọ ni ààwẹ̀ ń bẹ̀rẹ̀.
Lọwọlọwọ bayii, ileesẹ ọlọpaa ti ransẹ pe tọkọtaya naa pe ki wọn yọju si ilu Abuja, lọdọ ọga ọlọpa kan, Ibrahim Agu fun ifọrọwanilẹnuwo.
Abajade ipade naa si ni pe ile ijọsin ko i tii le ṣi lasiko yii, amọ awọn yoo tẹsiwaju lati ma a gba awn adari ile ijọsin ni imọran lori arun Coronavirus ati bi o ṣe lẹwu si ni ibi ti awọn eniyan ba parapọ si.
Bakan naa ni Minisita fun ọrọ to niiṣe pẹ awọn obinrin lorilẹ-ede Naijiria fikun un wi pe oun yoo fun Abilẹkọ Martins ni iṣẹ ki o ba le e ran idile rẹ lọwọ.
Gominọ Ganduje ti o jẹ Fulani funra rẹ, sọ eyi lakoko ti o nwo itọju ati ajẹsara ọfẹ fun awọn maluu ati awọn ẹranko kekere ti o to bii ẹẹdẹgberun ni ile-iṣẹ ti o wa ni agbegbe ijọba ibilẹ Garum Malam gẹgẹbi apakan ninu awọn iṣẹ isaami fun ọdun 2017/2018.
’’Aare ni awon agbofinro ti n se ise lati mu awon odaran wonyi.
Wo iye àwọn tí wọ́n ti gbà sí ikọ̀ SWAT báyìí àti òfin ti wọ́n fún wọn Àwọn ọ̀dọ́ dáná sun ọkọ̀ akérò tó ṣekúpa ọlọ́kadà ní Ibadan A ó ṣèrànwọ́ fáwọn ẹbí ọlọ́pàá tó bá rògbòdìyàn EndSARS lọ láti inú N500m tí a yà sọ́tọ̀- Makinde Ọ̀rọ̀ ìjókòó ìgbìmọ̀ ìwádìí #EndSARS náà dé ìpínlẹ̀ Ogun Niluu Benin nipinlẹ Edo ni Adamu ti sọrọ yii nigba to ṣabẹwo si olu ileeṣẹ ọlọpaa to wa ni Benin.
Lẹ́yìn náà ni Willian bá sá tẹ̀lé bọ́ọ̀lù tí Leon Balogun tó sì tarí rẹ̀ sí Hazard, ẹni tó sáré láti ìdajì pápá tó sì kọjá àwọn olùsọ́lé Brighton, kó tó gb;a bọ́ọ̀lù sáwọ̀ lẹ́yìn Mat Ryan.
Ọjọ Aje tii ṣe ọjọ kọkandinlọgbọn oṣu kẹfa ni ijọba Seyi Makinde n gbero tẹlẹ lati ṣi ileewe pada, amọ ijọba ti so o rọ bayii nitori bi awọn eeyan to n karun coronavirus ṣe pọ si nipinlẹ naa.
ọgbọ̀n  egberun naira ti aare Mohammadu Buhari buwọlu
ati ẹ̀wọ̀n wúrà meji tí a lọ́ pọ̀ bí okùn, kí o sì so àwọn ẹ̀wọ̀n wúrà náà mọ́ àwọn ìtẹ́lẹ̀ wúrà náà.
Lẹ́yìn èyí, Paulu kúrò ní Atẹni, ó lọ sí Kọrinti.
Kamaru Usman: Ọmọ Áfíríkà àkọ́kọ́ tó gba ìgbànú ẹ̀yẹ ẹ̀ṣẹ́ kíkàn UFC
O rọ awọn obinrin lati kan si awọn ajafẹtọẹni loju opo ikansiraẹni ti wọn le fọkan tan.
Ibẹwo aarẹ Buhari yii da lorii ifọrọwerọ pẹlu aarẹ ana ti orilẹede Naijiria, Goodluck Jonathan to jẹ ọkan lara awọn abanijiroro fun ajọ ECOWAS to lọ si orilẹede Mali lati lọ yanju ọrọ.
Kò sí ẹni tí ó rí Baba rí àfi ẹni tí ó ti wà pẹlu Baba ni ó ti rí Baba.
"Ohun ti Igbakeji aarẹ Yẹmi Ọsinbajo sọ ""Fun ijafafa ẹka eto abo, a ni lati tubọ sisẹ awọn nkan wọnyii: Eni- A nilo lati se agbeyẹwo awọn nkan bii aato ileesẹ ọlọpa nipa sise alekun iye ọlọpa orilẹede yii ni ilọpo mẹta iye rẹ bayii fun amojuto aabo tẹru-tọmọ."
O le ni miliọnu mọkanlelogun awọn eniyan to n gbe ni ipinlẹ Eko.
Bí wọn tí ń lọ lọ́nà, wọ́n dé odò kan.
Àwọn ẹlẹgbẹ́ rẹ̀ bá fi jọba ní Damasku.
Orilẹede America si fọwọ sọya wipe ohun yoo ṣeto aabo to daju fun orilẹede North Korea Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Ile da aba pe ki ijọba sun iwọle awọn akẹkọọ siwaju pẹlu oṣu mẹta siwaju sii nitori bi arun coronavirus ti n pọ si lojoojumọ.
O ni: inu mi dun gidi, mo mọ oore nitori mo ti n tiraka tipẹ ti mo ti n woye ọjọ ti maa pade Serena Williams ninu idije.
"Bakan naa lawọn obinrin kan ti wọn ni awọn wa lati ilu Ado ekiti si ilu Eko nitori igbẹjọ naa ṣalaye pe ""ajọyọ nla lo jẹ, o si da wa loju pe ọga wa yoo bọ ninu idamu yii."
Kete ti Modupe ba ti pari agunbanirọ rẹ ni yoo bẹrẹ iṣẹ yii gẹgẹ bi gomina ṣe seleri.
Ẹwẹ, awọn osisẹ agbofinro ti gba akoso ọja naa, ti wọn si ti n pese eto aabo to yẹ sibẹ.
Ọba bi Ìjàpá bóyá ohun tí ó sọ dáa lójú daadaa à bí eré ló ń ṣe.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù AFCON 2019: Òde kò dùn fún super Eagles, Madagascar nà wọ́n pẹ̀lú 2-0 30 Òkùdu 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Nkan ko ṣẹnu're fun ẹgbẹ agbabọọlu Super Eagles ti Naijiria ni abala akọkọ ati ikeji idije wọn pẹlu akẹẹgbẹ wọn lati orilẹede Madagascar.
Bakan naa, John Okoro, ti o je alamojuto  ile-ise epo-robi ati afefe gaasi aladani, tun ro ijoba lati ran won lowo, ki awon naa le seranlowo fun awon alagba ta nipa titun awon agba ifopo wa se.
Kó àwọn ẹ̀wù mímọ́ náà wọ Aaroni, ta òróró sí i lórí, kí o sì yà á sí mímọ́ kí ó lè máa ṣe alufaa mi.
olubori ninu eto idibo aare to waye ni ojo kejila , osu kefa, odun 1993 lorile
Àwọn agbebon tí wón wo aṣọ ọmọ iṣẹ́ ológun ni a gbọ́ pé, wón ti jí alága ẹgbẹ́ òṣèlú PDP tí ìjọba ìbílè Okene, Ogbeni Musa Adelabu, gbé lọ ni dédé agogo kan òru ọjọ́ ìsimi.
"Kii se pe o fi tipa ba mi lopọ amọ o dibọn bi ẹni pe o nifẹ mi, o si ti pẹ ju fun mi ko to ye mi pe o kan n lo mi ni.
Ọpọ eeyan ti ara aje n ta, lo n gbarata lori igbesẹ ijọba naa, tawọn eeyan miran si n bu sẹkun nibẹ.
Lodun 2010 ni won se oko ofurufu yii to tobi lati ko ero marundinlaadorin atiawon osise inu oko ofurufu mefa.
Nipa ọrọ Fatoyinbo to jẹ pe ilu Eko ni wọn ti fẹsun kan an ṣugbọn to n gbe ilu Abuja, Alaaya ni ohun to sunmọ ju pe yoo ṣẹlẹ ni ''ki wọn gbẹjọ naa ni lọ ilu to ba ti dẹsẹ naa''.
Eeyan kan ti ko fẹ darukọ rẹ sọ pe iṣẹlẹ naa da a lagara gan o si nilo imọran gidi""."
Awọn ọmọ ogun ilẹ Cameroon naa sọ pe ootọ ni iṣẹlẹ yii.
Makinde lo sọ ọrọ naa ninu atẹjade kan to fi soju opo Twitter rẹ.
Afcon Qualifiers: Àmì ayò 2-1 ni Naijiria fi ṣàgbà Benin Republic
” Lara awon asoju ile –ejo naa  ti won yoo maa kan si aare Muhammadu Buhari
Wọn ti fá afura si náà le ọlọpàá Okporo ni àgbegbe Rumuodara lọ́wọ́ fún ìwádìí.
Oríṣun àwòrán, Wale Olagunju Àkọlé àwòrán, Wooli Wale Olagunju Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Mi ò tan mọ́ ààrẹ Buhari rárá o!
Ogunbuyide wa tẹsiwaju lati sọ ohun ti awọn eniyan ko mọ nipa Baba Obasanjo: Oni inu ire to si ni ifẹ awọn eniyan Baba Obasanjọ ni ọgbọn lati tun nkan to nibikibi ti o ba wa.
florence delorez griffith joyner ( december 21 , 1959 - september 21 , 1998 ) , bakanna bi flo-jo , jẹ ́ eléré ìdárayá orí pápá ará amẹ ́ ríkà .
Ṣebí ojoojumọ ni mo wà pẹlu yín ninu Tẹmpili.
Nigba ti aare n tewogba ami eye yii , o dupe lowo egbe Rotary International  fun ami eye ti won fi da a lola .
Nítorí pé wọ́n kọ ìlànà mi sílẹ̀, wọn kò tẹ̀lé òfin mi, wọ́n sì ba ọjọ́ ìsinmi mi jẹ́, nítorí pé ọkàn wọn kò kúrò lọ́dọ̀ àwọn oriṣa wọn.
1 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Borno Zabarmani massacre: Ípànìyàn tó wáyé ní Borno fihàn pé omi n bẹ lámù fún ètò ààbò - Tinubu3 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Borno Zabarmani Rice Farmer Massacre: Àwọn àgbàgbà Òkè Ọya ní ẹ̀mí èèyàn kò níyì mọ́ lábẹ́ ìṣèjọba Buhari5 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Katsina Child sale: Obìnrin olówònààbì ta ọmọ rẹ̀ tuntun jòjòlò ní N300,0002 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Ọjọ kẹrinla oṣu keje ọdun 2020 yii ni akọni awakọ-ofurufu jagun Tolu ṣagbako iku ojiji ninu ijamba ọkọ niluu Kaduna.
500 Teeth: Àgbọ̀n ọmọ náà tó wú làwọn obi rẹ̀ gbe lọ sí ilé ìwòsàn
Nítorí náà ni ó ní ìjọba àpapọ̀ yóò ti ibodè rẹ̀ pẹ̀lú orilẹ̀èdè n láti ríi pé àwọn onífàyàwọ́ kò kó oúnjẹ náà wọlé.
" Iditẹ gbajọba naa si lo yẹ aga akoso mọ aarẹ ana, Boubacar Keita ati olootu ijọba rẹ nidi lọjọ Isẹgun.
Ṣugbọn mo tún ń gbadura fún àwọn tí yóo gbà mí gbọ́ nípa ọ̀rọ̀ wọn, 
Naijriria lo wa loke tente ni isọri ''L'' lẹyin ti wọn pokọ iya fun Benin pẹlu ami ayo meji sodo l'Ọjọbọ niluu Uyo.
Àkọlé àwòrán, Gomina Oyo nigba kan ri, Rasheed Ladoja naa de Yidi Àkọlé àwòrán, Adua a gba o Àkọlé àwòrán, Sultan ti Kano ati Gomina Ipinlẹ Kano pade ni Yidi Àkọlé àwòrán, 'Baba, ẹ ba wa lọwọ adua' Àkọlé àwòrán, Aarẹ Muhammadu Buhari ati ọmọ rẹ ọkunrin Àkọlé àwòrán, Ti ẹṣiṣi ba fo gan nibi ti Aarẹ wa gan, awọn alaṣọ dudu wọnyii yoo han!
Nígbà tí Mose ati Aaroni lọ bá Farao sọ̀rọ̀, Mose jẹ́ ẹni ọgọrin ọdún; Aaroni sì jẹ́ ẹni ọdún mẹtalelọgọrin.
Minisita naa to lọ farahan niwaju awọn aṣofin ni ọjọ kọkanlelogun, oṣu Karun un, ni ọrọ owo ni o n jẹ awọn ile iwosan naa ni iya.
Awọn obinrin naa ni iṣẹlẹ naa waye ni ọdun 2004.
S Embassy Bi ẹ o ba gbagbe, laipẹ yii ni ajọ FBI fi orukọ ọgọrin eniyan lede ti wón fi ẹsun kan wi pe, wọn ṣe gbajuẹ nilẹ Amẹrika, ti ọpọlọpọ wọn jẹ ọmọ Naijiria.
Abuja si Eko nikan si ni ijọba fun wọn laṣẹ Àkọlé àwòrán, Ilumọka oṣere Zack Orji naa ba wa rinrinajo lati Abuja si Eko Àkọlé àwòrán, Ọwọ ara rẹ loo fi mu omi ninu apo ẹyin aga to ba wa niwaju rẹ Àkọlé àwòrán, Ẹnikẹni ko lee ran ẹ lọwọ lati gbe ẹru rẹ soke koda ko danu, ọwọ ara rẹ loo fi ko o afi bi ẹni naa ba kan fẹ yoo si fi sanitizer pawọ Àkọlé àwòrán, Fọto lati oju ferese ọkọ baalu bi ẹni n loṣo wo awọn ọkọ baalu to ku Àkọlé àwòrán, Aye o le, ibi to ba ti ba wa, ẹ́ jẹ ka jẹ ẹ Àkọlé àwòrán, Ofin iijinasiraẹni lasiko ijoko Àkọlé àwòrán, Lọkọọkan lẹ o to jade tẹ o si jina si ara yin - ofin ijọba ree ṣugbọn ṣe bẹẹ lo ri ninu aworan yii?
Mo sì ń rọ àwọn èèyàn láti mase ro ara wọn pín, tàbí mú ìrẹ̀wẹ̀sì bá ọkàn wọn nitori ohun tí àwọn ènìyàn ba n sọ.
Èyí ni ìgbà kẹrin tí America yóò gba ife ẹ̀yẹ àgbáyé nínú ìdíje tàwọn obìnrin tí kò ṣẹ̀yìn Rapinoe tó gba bàtà gòólù.
''Awọn ti owo oṣu wọn ju ẹgbẹrun lọna ọgbọn Naira lọwọlọwọ yoo kan gba ẹkunwo kekere ni.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Waste to Wealth: Ẹ̀gbin tìrẹ ni èròjà táwọn èèyàn míràn fi n ṣiṣẹ́ ajé, okoòwò ńlá ni Lara awọn ti Sanusi pe lẹjọ ni; ọga agba ileeṣẹ ọlọpaa, Mohammed Adamu, ọga agba ileeṣẹ ọtẹlẹmuyẹ, DSS, Yusuf Bichi, adajọ agba ipinlẹ Kano Ibrahim Muktar ati adajọ agba Naijiria, Abubakar malami (SAN).
Gbogbo igbiyanju lati gbọ latẹnu ọfiisi gomina Seyi Makinde lori ọrọ owo naa titi di bi a ṣe n sọrọ yii ko tii so eso rere.
Iwe iroyin Metro nilẹ Gẹẹsi fidi rẹ mulẹ pe, ninu apo aṣuwọn ile iṣẹ Doraville Properties Corporation ni ile ifowopamọ Jersey ti ri owo naa.
Ṣugbọn bí OLUWA bá ṣe ohun tí etí kò gbọ́ rí, tí ilẹ̀ bá yanu tí ó gbé wọn mì pẹlu àwọn eniyan wọn ati àwọn ohun ìní wọn, tí wọn sì bọ́ sinu ibojì láàyè, ẹ óo mọ̀ pé wọ́n ti kọ OLUWA sílẹ̀.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Làá hàn mí: Ètò yìí ló ń kìlọ̀ fún wa láti mú ìmọ́tótó ní pàtàkì láti dènà Coronavirus Awari kanmọ n kia nipa awọn to ba ẹni to ko arun ọhun wọ Naijiria: Ko pẹ ti arun naa de Naijiria ti ijọba ipinlẹ Eko bẹrẹ igbeṣẹ lati ṣawari gbogbo awọn eeyan to wọ ọkọ baalu kan naa pẹlu ọmọ ilẹ Italy, to ko arun naa wọn Naijiria.
Mo bá pàṣẹ pé kí wọ́n tún yàrá náà ṣe kí ó mọ́, ẹ̀yìn náà ni mo wá kó àwọn ohun èlò ilé Ọlọrun pada ati ọrẹ ẹbọ ohun sísun ati turari.
Nítorí pé Ọlọrun rẹ ń ràn ọ́ lọ́wọ́.
Àwọn ọkunrin ààrin yín nìkan ni wọ́n gbọdọ̀ jẹ wọ́n nítorí wọ́n jẹ́ ohun mímọ́ jùlọ.
Adamu Danze,ni o jawe olubori gege bi alaga ijoba ibile  Gwagwalada.
Bí  mo ti dákẹ́ ṣe ni mo déédéé rí Ewédayépọ̀ tí ó bu oògùn funfun kan láti inú àdó tí ó bẹ̀rẹ̀ sí fi ra mi lórí, orí mi sí di funfun, bẹ́ẹ̀ ni Ewédayépọ̀ sọ mí di olórí funfun lọ́sàn-án gangan, gbogbo ènìyàn ló sì ń wo àtàrí mi bí wọ́n bá ti ń kí mi.
Wọn ni òun to tún wá yani lẹ́nu jùlọ ni pe Aroke lọ fun ìtọjú ara rẹ ni ilé ìwòsàn àwọn ọlọpàá ní Falomo nilú Eko fun àisan kan.
Ọkùnrin kan kú si ìyárá ìtura Ó rẹ ẹni ọdún 49 tó ri ẹ̀wọ̀n ọgọ́ta ọdún he lẹ̀yìn tó bá ọmọ ọdún méjì lòpọ̀ Bíbéèrè fún ìbálòpọ̀ gbogbo ìgbà sọ ìyàwó ilé dèrò ilé ìwòsàn Wo oríṣiríṣi ìgbádun ibálòpọ̀ láwọn orílẹ̀èdè mìíràn Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Àwọn ọkùnrin tó wà nínú ayé wa gbúdọ̀ bọ̀wọ̀ fún wa - Adarí FIN Báwo lọ̀rọ̀ ṣe bẹ̀rẹ̀?
Ipinnu lati fikun iye odun ti awon alakoso egbe naa maa n lo tele waye , leyin ti aare Muhammadu Buhari ti fi ehonu re han, nigba ti won bere ipade pe  , o tako ofin lati fikun odun ti awon alakoso naa maa n lo .
Ikọ igbimọ aabo ajọ naa kan ṣe ipade pẹlu olootu ijọba Mali, Soumeylou Boubeye Maiga, lori ọrọ idunkoko mọni lati ọwọ awọn ajijagbara laarin gbungbun Mali.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù EndSARS Protest Update: Ìjọba ìpínlẹ̀ Eko ní àwọn ń wádìí èèyàn 229 lọ́wọ́ lórí làásìgbò tó wáyé l'Eko 18 Ọ̀wàrà 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 25 Ọ̀wàrà 2020 Ijọba ipinlẹ Eko ni eeyan igba o le mọkandinlọgbọn lọwọ tẹ fun lilo anfani iwọde #EndSARS lati fi jale ni ipinlẹ Eko Ileeṣẹ eto idajọ ni ipinlẹ Eko ni ijọba ti n yẹ iwe ẹsun ọkọọkan wọn wo bayii.
 ní ọdún 2013 , orílẹ ̀ -èdè 184 ni wọ ́ n fi sí ara àwọn àjẹsára òòrèkóòrè wọn .
Jehu kú, wọ́n sin òkú rẹ̀ sí Samaria, Jehoahasi ọmọ rẹ̀ sì jọba lẹ́yìn rẹ̀.
Silifanu ni ó bá mi kọ ìwé kúkúrú yìí si yín.
Ẹ̀yin ni a yàn gẹ́gẹ́ bí ìmọ̀tẹ́lẹ̀ Ọlọrun Baba fún ìwà mímọ́ nípa Ẹ̀mí Mímọ́ kí ẹ lè máa gbọ́ ti Jesu Kristi, kí ẹ̀jẹ̀ rẹ̀ sì lè wẹ̀ yín mọ́.
Kí ló dé tí n óo fi bẹ̀rù ní àkókò ìyọnu,nígbà tí iṣẹ́ ibi àwọn tí ń ṣe inúnibíni mi bá yí mi ká,
5bn Kini àwọn eniyan Naijiria n sọ nipa Fọnra ti Aisha fi sita naa: Ọpọlọpọ àwọn eniyan ni wọn ti n sọ oriṣiiriṣii nipa fọnran fidio naa lori ayelujara.
OLUWA ní kí wọn sọ fún Sedekaya ati àwọn ará Juda kí wọn má tan ara wọn jẹ, kí wọn má sì rò pé àwọn ará Kalidea kò ní pada wá sọ́dọ̀ wọn mọ́, nítorí wọn kò ní lọ.
Afọnja, ẹni tó finú wénú ní Ilọrin, àmọ́ tó jẹ iwọ Àwọn Ọba Yorùbá kan rèé tí wọ́n rọ̀ lóyè, tí ọba míràn jẹ lójú ayé wọn Ẹfunsetan Aniwura, ọmọ Ẹ̀gbá tó di akíkanjú obìnrin nílẹ̀ Ibadan Aarẹ ọna kakanfo Yoruba Igbe aye akínkanjú obìnrin yii si lo n kọ wa pe obìnrin kii ṣe ohun elo alailagbara, ti ko wulo.
Aarẹ Latooṣa ni aarẹ kejila to jẹ.
Gbogbo awọn oloṣelu to n ṣe magomago lati fi ibo gbe ẹni tiwọn sori ipo ki wọn lee ko ọrọ ilu ati ipinlẹ si apo ara wọn.
Ko tan sibẹ, nipinlẹ Rivers naa, oludije kan tun san iru asọ yii soro, ọwọ wa tun tẹẹ.
Mercy Aigbe ṣá ọmọ rẹ̀ sínúu fíìmù tuntun, wo itú tí ọmọ ọdún mẹ́wàá náà pa Ariwo ayọ̀ sọ nílé Remi Surutu, ọmọ rẹ̀ mú ọkọ wale Ikú Williams Aanuoluwa lágbo òṣèré hú ọ̀pọ̀ ọ̀rọ̀ síta Sinimá tí Lateef Adedimeji dá nikan jẹ́ òṣèré yóò jáde, Yemi Solade fi ọ̀pọ̀ fọ́tò dẹngẹ pó"" lọ́jọ́ ìbí rẹ̀ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Pásítọ̀ ló sọ fún mi pé Ọlọ́run pè mí láti di Olokun tó ń bọ omi' O ni iṣẹ arinrin oge (model) ni oun fi bẹrẹ."
Nítorí náà àwọn ẹ̀yà Reubẹni, ẹ̀yà Gadi ati ìdajì ẹ̀yà Manase fi àwọn ọmọ Israẹli yòókù sílẹ̀ ní Ṣilo, tí ó wà ní ilẹ̀ Kenaani, wọ́n sì pada lọ sí ilẹ̀ Gileadi tí í ṣe ilẹ̀ tiwọn tí wọ́n pín fún wọn, gẹ́gẹ́ bí OLUWA ti pàṣẹ láti ẹnu Mose.
Ni ọjọ kẹrin osu kejila, ọdun to kọja, ile isẹ ogun oju ofurufu orilẹede Naijiria ran awọn ọkọ ija baalu lati fi ina ja ninu afẹfẹ lori awọn ilu kọọkan gẹgẹ bi ikilọ fun ikọlu to ma nwaye nigbati awọn daran daran kọlu o kere tan, ilu marun ni ipinlẹ Adamawa lati gbẹsan iku ara ilu wọn mọkanlelaadọta losu to kọja to jẹ wipe ọmọde lo pọ ju ninu wọn.
Lẹyin ọdun mẹtadinlogoji lori ipo aarẹ, wọn kan nipa fun Mugabe lati fi ipo naa silẹ lorilẹede Zimbabwe losu kọkanla sdun to kọja, ti ọpọ ololufẹ ere bọọlu si nfi Wenger se afiwe Mugabe nitori isẹlẹ yii.
Ẹgbẹ́ òṣèlú PDP ní ìpínlẹ̀ Bayelsa jáwé olúbori nínú ìdìbò ìjọba ìbílẹ̀ Manchester United dáná sun Chelsea bi ẹràn àgbò iléyá N jẹ Arsenal ò ti dà òkùtà sí Newcastle nígbá báyìí?
A rí ọkọ̀ ojú omi kan níbẹ̀ tí ó fẹ́ sọdá lọ sí Fonike.
Àsìkò tó láti dóòlà Nàíjíríà, a ti gbé ẹ̀ṣùn ìbò lọ sílé ẹjọ́ tó ga jùlọ - PDP Wo aṣọ òtútù tó wọ́n jùlọ ní àgbáyé!
"Lara orin wọn mii ti wọn tun kọ ni ""Kpolongo"" eyi to gbe wọn rinrinajo kuro ni Naijiria lọ silẹ Yuroopu lọdun 2006."
Bákan náà ni ó kọ́ ekeji ati ẹkẹta ati gbogbo àwọn iranṣẹ tí wọ́n tẹ̀lé àwọn agbo ẹran náà.
"Oríṣun àwòrán, Others O fí kún pé, wọ́n kìí ṣe Boko Haram tàbi Fulani daran-daran ti wọ́n ti mọ̀ tẹ́lẹ̀, ""ìmúra wọ́n kò jọ bi àwọn ti a mọ̀ tẹ́lẹ̀"" Wọ́n ti wọ Ibariba nipìnlẹ̀ Niger, wọ́n ti wọ òkè-ògùn."
Arakunrin Akeredolu kede eyi nibi ayẹyẹ yiyan bii ologun lati bẹrẹ iṣẹ eyi ti ikọ Amotekun ṣe ni ipinlẹ naa to waye ni gbagede Fawehinmi Freedom Arcade lagbegbe Igbatoro, Akure, olu ilu naa.
Ni ọdun 2007 ni Faṣọla di gomina ipinlẹ Eko.
Ẹ ranti pé wọ́n jẹ́ alábàápín ẹ̀bùn ìyè pẹlu yín.
Láti ṣe ẹ̀dá àkọsílẹ̀ tí yío pẹ́ títí síi, láìpẹ́ àwọn àkọ̀wé ṣe ẹ̀dà àwọn ìfihàn wọ̀nyí sí inú àwọn ìwé àkọsílẹ̀ àfọwọ́kọ, èyítí àwọn olùdarí Ìjọ lò ní ṣíṣe ìpalẹ̀mọ́ àwọn ìfihàn náà lati jẹ́ títẹ̀.
Ninu alaye re, oga agba ile ise oloopa ni ipinle Oyo,
Si eyi, sẹnetọ Adeleke ni ohun ko jẹbi awọn ẹsun naa ti adajọ Mohd Zubairu si gba beeli rẹ pẹlu iye owo miliọnu meji naira ati pipese oniduro kan bakan naa.
’ Ọba bá tẹríba, ó sì sin Ọlọrun lórí ibùsùn rẹ̀, 
Rakẹli bá sáré lọ sọ fún baba rẹ̀.
Títí di igba ti a n kọ iroyin yii, ọjọ keje ọsù kẹwàá ọdún 2020, Omotosho sì n wá ọ̀nà láti pe ẹjọ́ kòtẹ́milọ́rùn.
OLUWA, Ọba Jakọbu, ní:“Ẹ̀yin oriṣa àwọn orílẹ̀-èdè, ẹ ro ẹjọ́ yín,kí ẹ mú ẹ̀rí tí ó dájú wá lórí ohun tí ẹ bá ní sọ.
Ohun ifarahan meji ti o maa n jẹyọ bi eyan ba ni arun corona virus ni ikọ ahugbẹ ni lemọlemọ ati iba.
Ikede naa se atupalẹ owo itanran ti awọn Banki naa yoo san bayi pe: Standard Chartered yoo san N2.
Ogbeni Amaechi wa salaye siwaju pe awon eru to ba de
eni ti o ba sẹ ko ni lọ laijiya , iru eniyan to wu ki o jẹ.
Aisha Buhari tọrọ ìdáríjì lórí fídìo tó jáde BBC 100 Women 2019: Wo ọmọ Nàíjíríà kan tó wà nínú wọn Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
OLUWA Ọlọrun yín yóo gbé wolii kan dìde tí yóo dàbí mi láàrin yín, tí yóo jẹ́ ọ̀kan ninu àwọn arakunrin yín, òun ni kí ẹ máa gbọ́ràn sí lẹ́nu.
Àwọn ajínigbé: 'Ẹ mú N20m wá tàbí ká pa ìyàwó ọba'
OLUWA Ọlọrun ní, “Ní ọjọ́ tí mo bá wẹ̀ yín mọ́ kúrò ninu ẹ̀ṣẹ̀ yín, n óo jẹ́ kí àwọn eniyan máa gbé inú àwọn ìlú yín, n óo sì mú kí wọ́n tún àwọn ibi tí ó wó lulẹ̀ kọ́.
Awon ti won tun kopa nibi ipade naa ni Veronica Songwe, minisita fun eto isuna teleri lorile-ede Nigeria Ngozi Okonjo-Iweala ati awon omo egbe ipenija erongba elegberun odun ile America.
Kí ìgbé-ayé yín láàrin àwọn abọ̀rìṣà jẹ́ èyí tí ó dára, tí ó fi jẹ́ pé bí wọ́n bá tilẹ̀ ń sọ̀rọ̀ yín ní àìdára, sibẹ nígbà tí wọ́n bá ṣe akiyesi ìwà rere yín, wọn yóo yin Ọlọrun lógo ní ọjọ́ ìdájọ́.
Ó bí ọmọkunrin kan, ó sì sọ ọmọ náà ní Geriṣomu, ó wí pé, “Mo jẹ́ àtìpó ní ilẹ̀ àjèjì.
" Ni ti dokita, o sọ oniruuru idi ti eeyan le fi pa lori yala kunrin tabi obinrin.
Rubadiri ni ẹni kẹẹfa to gba ami ẹyẹ Komla Dumor ni ilẹ Africa, oun lo tẹle Solomon Serwanjja, Waihiga Mwaura, Amina Yuguda, Didi Akinyelure ati Nancy Kacungira.
LASEMA Lagos Accident: Ọkọ̀ akóyanrìn tẹ èèyàn kan pa ní Epe
Mú wa bọ̀ sípò, Ọlọrun;fi ojurere wò wá,kí á le gbà wá là.
Nigba ti o fesi, Abiodun gba wipe lootọ ni adari ile sọ ọrọ yii lọdun to kọja o si ṣeleri pe ijọba oun yoo moju to ọrọ yii lọdun to m bọ.
Ó sọ fún èyí tí ó ṣáájú patapata pé, “Nígbà tí Esau arakunrin mi bá pàdé rẹ, tí ó sì bi ọ́ pé, ‘Ti ta ni ìwọ í ṣe?
Wọ́n ń foríbalẹ̀ wọ́n ń bọ oòrùn.
Lilẹ idi apo pọ pẹlu Iran?
Ṣugbọn mo tún ro ti orúkọ mi, nítorí n kò fẹ́ kí wọ́n ba orúkọ mi jẹ́ láàrin àwọn eniyan tí wọn ń gbé, lójú àwọn tí mo ti fi ara mi hàn wọ́n ní ilẹ̀ Ijipti, nígbà tí mo kó wọn jáde kúrò níbẹ̀.
Oríṣun àwòrán, Facebook/FemiAdesina Femi Adesina wa tọkasi awọn ẹri kan to fidi rẹ mulẹ pe wọn ko fi ẹlomiran rọpo aarẹ Buhari rara, oun fura rẹ lo n dari ijba Naijiria.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Faari Buhari 'Gba Buhari ni'mọran ifẹyinti' Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Okunrounmu: Ijọba Buhari jẹ ijiya Ọlọrun fun Naijiria A gbọ́dọ̀ sọra nípa bíbu ọwọ́ lu àwọn ìwé àdéhùn tí yóò bá figa-gbága pẹ̀lú ètò ìgbani-sísẹ àti kárà-kárà ọjà ní orílẹ̀-èdè yìí, tó sì tún leè se àkóbá fún àseyọrí àwọn iléesẹ̀ ńlá-ńlá gbogbo nílẹ̀ yìí."
Oríṣun àwòrán, Amiloaded media hub Arakunrin naa ni wọn ni o wa ni ahamọ awọn ọlọpaa bayii ti iroyin si n jẹ ko di mimọ pe o ti ba wọn lalejo ni ẹka ọtẹlẹmuyẹ ileeṣẹ ọlpaa ni Oṣogbo.
Ni ipari won ro awon ajo NEMA ati ajo Asatipo lati ji giri sise won nipa ipese iranlowo to ye lasiko fawon asatipo.
Adele oluṣọ woli Oladele, Samuel Oba sọ ninu iwaasu rẹ pe ohun to ṣẹlẹ ko le fa iwariri ninu ijọ naa.
Finehasi ọmọ Eleasari, ọmọ Aaroni ló ń ṣe iṣẹ́ alufaa ní àkókò náà, àwọn ọmọ Israẹli tún bèèrè pé, “Ṣé kí á tún lọ gbógun ti àwọn ará Bẹnjamini tíí ṣe arakunrin wa àbí kí á dáwọ́ dúró?
Rántí pé ó jẹ́ mímọ́ ó sì wá láti òkè—
Granit Xhaka ati Mesut Ozil lo kọkọ gbayo kọkọkan wọle nigbati Arsenal bẹrẹ si siwaju Newcastle pẹlu ami ayo meji sodo.
Ayeye yii maa n waye lojo keta si odun ileya lodoodun nibi ti awon eekan orile ede NAijiria ti n pade jiroro lori idagbasoke ileIjebu ati Naijiria lapapo.
Mo nifẹ iṣẹ ranṣọ ranṣọ gaaan.
Wòlíì Kasali ní Dolapo Awosika kò lé ìyàwó òun jáde Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Okùnadé Alade Sijúwadé, Olúbùṣe Keji, gun ori oyè Ọọni Ifẹ̀ nigbati ó pé aadọta ọdún, ó lo ọdún mẹ͂dógóji ni ipò Ọọni Ifẹ̀.
Wo àwọn èèyàn jáńkán tó ṣe ọdún tuntun ní ọgbà ẹ̀wọ̀n Iyipada ijọba, ilẹ riri yoo waye ni ọpọlọpọ orilẹ-ede lagbaye- Pasitọ Adeboye Bakan naa ni Baba Adeboye ti ijọ Redeemed Christian Church of God naa pe fun adura ki ọrọ iṣipo pada to maa waye ni 2020 ati ilẹ riri ma ga ju ara lọ.
Lara awọn to wa nibi ipade naa ni asoju awọn ileeṣẹ ijọba ti ọrọ kan, lajọ-lajọ, Minisita fun ipese ina, iṣẹ ode ati ilegbigbe, Babatunde Raji Faṣhọla; Ọga Agba ileeṣẹ ọlọpaa, Ọgbẹni Mohammed Adamu; Akọwe Agba nileeṣẹ to n risi eto irinna nipinlẹ Eko, ati Oludari Agba fun igbokegbeodo ọkọ ori omi, ati ileeṣẹ to n mojuto ibudokọ oju omi ni Naijiria, Ọmọwe Sokonte Davies.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Lẹyin o rẹyin goolu mẹta ti ko labula ni wọn fi na Real Madrid.
Ó ń mú kí odò rẹ̀ ṣàn lọ síbi gbogbo igi igbó.
Israẹli ṣẹgun Juda, gbogbo àwọn ọmọ ogun Juda sì pada sí ilé wọn.
"Torinaa, ẹyin tẹẹ jẹ Kristẹni gangan ni wọn korira""."
Wọ́n tú àṣírí ìfiyàjẹni àwọn Ológun àti SARS káàkiri Nàìjíríà 'Ẹ jọ̀ọ́, a ò fẹ́ gbọ́ òfófó ìròyìn mọ́ pé àbúrò mi gún bàbá àti ìyá mi pa, ó ti tó gẹ́!
 nígbà tí ó tàtaré bọ ́ sí orílẹ ̀ èdè jámánì nílùú hamburg lẹ ́ ni ọmọ ọdún méjìdínlógún , ó mú orin gẹ ́ gẹ ́ bí iṣẹ ́ ajẹ ́ pẹ ̀ lú ìkẹ ́ kọ ̀ ọ ́ gboyé nínú ìmọ ̀ àṣà àti ìṣe ènìyàn .
PFN: Fatoyinbo kọ̀ láti yọjú ni ìwádìí wa kò ṣe parí Victor Taiwo to jẹ́ asojú ẹgbẹ́ ọmọ òòdua Redemption Alliance sàlàyé pé ẹgbẹ́ afẹ́nifẹ́re kìí ṣe asoju ọmọ Yoruba náà ni Odumakin fi kún pé ẹgbẹ́ tó ṣe ètò náà kó to ẹru yoruba gbé.
Ní kété tí àṣẹ yìí tàn káàkiri, wọ́n mú ọpọlọpọ àkọ́so ọkà, ati ọtí ati òróró ati oyin, ati àwọn nǹkan irè oko mìíràn wá.
O wa dupe lowo aare Buhari fun atileyin re , o ni ibasepo to wa laarin orile ede Britain ati orile ede Naijiria ti tun ni idasoke ju bi o se wa tele lo laarin odun meta ti oun ti je asoju orile ede naa.
Laipẹ yii ni iroyin gbe e pe, awọn agba oye ti wọn gbe ade le lori naa ti fi igba kan faake kọri pe, ko sẹni to lee gba kanbo lọwọ imu, ko si ẹni to lee gba ade naa lori awọn.
OLUWA bá Mose sọ̀rọ̀ lórí òkè Sinai, ó ní, 
Ṣugbọn ṣaaju eto idibo abẹle ẹgbẹ naa ni aṣiri tu pe Shittu ko kopa ninu eto isinru ilu (NYSC) to maa n waye fun gbogbo awọn akẹkọ jade ni Naijiria.
Lorilẹede Naijiria si ni igbimọ oloye Aarẹ ọna kakanfo.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Revolution protest: Àjọ DSS ṣàlàyé ìdí tí wọ́n fi gbé Sowore 5 Ògún 2019 Oríṣun àwòrán, omoyele Ajọ ọlọpaa ọtẹlẹmuyẹ DSS ti fidi rẹ mulẹ pe lootọ, oun l'oun mu oludije fun ipo aarẹ tẹlẹ ninu ẹgbẹ oṣelu African Action Congress, Omoyele Sowore si ahamọ.
O tun jẹ ajijagbara fun oṣelu.
Gomina Obiano kede eyi lasiko to darapọ mọ awọn ọdọ to n ṣewọde tako iwa buruku awọn ọlọpaa ni ipinlẹ Anambra.
Lara irufẹ ohun ti a n jẹ si lati le ri Vitamin C.
Ṣugbọn ará Samaria kan tí ó ń gba ọ̀nà yìí kọjá lọ dé ọ̀dọ̀ ọkunrin náà.
Alamojuto eto iranwọ labẹ ajọ iṣọkan agbaye lorilẹede Naijiria ti sọ wi pe, ajakalẹ arun onigbameji lee pa ẹgbẹlẹgbẹ awọn eeyan, paapaa julọ awọn obinrin ati awọn ọmọde ti wọn n gbe lawọn iagbegbe bii ibudo awọn ti wahala Boko Haram le kuro nile.
 Ọ ̀ kan pàtàkì lára ẹ ̀ yà ewì alohùn ilẹ ̀ yorùbá ni pẹ ̀ lú .
Mo ti ṣe àìgbọràn sí òfin OLUWA ati sí ọ̀rọ̀ rẹ̀ nítorí pé mo bẹ̀rù àwọn eniyan mi, mo sì ṣe ohun tí wọ́n fẹ́.
Adegbọrọ di igba ati agbọn rẹ, to si gba ilu Eko lọ lati wa isẹ Aje ṣe, ko le e riba ti se, ko si ri ọna gbegba.
Mo ṣe bí àwọn àgbàlagbà tí wí fún wa ní ijọ́sí wí pé, ọjọ́ gbogbo ni ti olè ọjọ́ kan ni ti onínnǹkan.
Ìwọ ọdọmọkunrin, máa yọ̀ ní ìgbà èwe rẹ, kí inú rẹ máa dùn; máa ṣe bí ọkàn rẹ ti ń fẹ́, ati bí ó ti tọ́ lójú rẹ.
Sáájú ní alága àjọ tó n rísi bí ìjọba ṣe n setò owó (RMAFC) Elias Mbam, tí ṣe àgbékalẹ̀ ìgbìmọ̀ tẹ̀ẹ́kótó ti yóò jòkó láti jíròrò lórí bi wọ́n yóò ṣe maa pin owo sí ipele ìjọba mẹ́tẹ̀ẹ̀ta.
"Wọn ni ""awọn ọmọ Naijiria mẹta, Stanle Didia, ti ọpọ awọn ololufẹ rẹ mọ si Omah Lay, Temilade Openiyi, ti ọpọ mọ si Tems, ati Muyiwa Awoniyi ti foju bale ẹjọ."
Joṣua bá dá àwọn ọmọ Josẹfu: ẹ̀yà Efuraimu ati ti Manase lóhùn, ó ní, “Ẹ pọ̀ nítòótọ́, ẹ sì ní agbára, ilẹ̀ kan ṣoṣo kọ́ ni yóo kàn yín, 
Kò tíì dákẹ́ ọ̀rọ̀ tí ń sọ tí iranṣẹ mìíràn fi tún dé, ó ní, “Àwọn ẹgbẹ́ ogun Kalidea mẹta kọlù wá, wọ́n kó gbogbo ràkúnmí wa lọ, wọ́n sì fi idà pa gbogbo àwọn iranṣẹ rẹ, èmi nìkan ni mo sá àsálà láti wá ròyìn fún ọ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Coronavirus Updates: Àì gba ìwé àṣẹ ìjọba ṣàkóbá fún sinima orítá ọmọkùnrin yìí Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 3 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 5 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Ẹka ile iṣẹ ọlọpaa to wa ni ilu Kuru ni Ipinlẹ Plateau ni ọgbẹni Mohammed ti n ṣiṣẹ lọwọ yii.
com, Akufa ni ki iku aitọjọ o waye lera-lera lẹyin iku eeyan kan ninu ẹbi kan, agboole tabi ilu.
Ewe, lara awon ti o lo ki aare Buhari kaabo ni papako ofurufu lati ri: Minisita FCT, Mohammed Bello, oga agba awon osise,  Abba Kyari ati oludari agba awon osise alaabo.
Nígbà tí ó tó àkókò àti sùn mo bọ́ sí orí ibùsùn mi wéré mo ti ṣe bí ẹni pé mo sun lọ bẹ́ẹ̀ ni n kò sùn, ṣùgbọ́n ohun tí ó jẹ́ kí n lé ṣe bẹ́ẹ̀ ni pé nígbà tí mo máa jẹun alẹ́ ọjọ́ náà n kò mu omi tí obìnrin náà fún mi, mo dà á nù ní ibi ojú fèrèsé mi láì jẹ́ pé ó pé mo ṣe bẹ́ẹ̀.
Kiniun pa olusọ ọgba ẹranko Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Justice Osei le dún bíi ẹranko 50 Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Kollington ṣàlàyé bí orin Fuji ṣe bẹ̀rẹ̀ gan an ní Nàiìjíríà Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Muyiwa Ademola: A ó jọ rọ́ọ̀kì ọdún 2021 papọ̀ ni lágbára Ọlọ́run26 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Nigerian doctor shoots wife: Dr Benjamin Okigbo pa ìyàwó rẹ̀, pokùnso lẹ́yìn tó gbìyànjú láti pa ọmọ21 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 3 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 5 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
 Bakan naa lo tun gba awọn olori laarin ilu nimọran lati ba awọn ara ilu ṣọrọ lati jade dibo gẹgẹ bi ẹtọ wọn labẹ ofin.
“Ṣugbọn, bèèrè lọ́wọ́ àwọn ẹranko, wọn óo sì kọ́ ọ,bi àwọn ẹyẹ, wọn yóo sì sọ fún ọ;
Awọn asaaju ẹgbẹ oselu naa, to fi mọ alaga wọn, Uche Secondus to siwaju ifẹhonu han naa, lo lọ si olu ileesẹ ajọ eleto idibo, INEC ati ile asofin apapọ ilẹ wa lati gbe iwe ẹsun wọn kalẹ siwaju awọn asofin naa lori bi ileesẹ ọlọpaa ilẹ wa se kọlu gomina ipinlẹ Ekiti, Ayọdele Fayose ni ilu Ado-Ekiti.
Ninu fidio naa, ọlọpaa kan gbé ìbọn lọwọ, ti awọn ọkunrin melo kan ti wọn jọ n ṣe ariyanjiyan si di i mu.
Nítorí náà àwọn ará Jerusalẹmu bá fi Ahasaya jọba lẹ́yìn Jehoramu.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Kí láwọn ohùn àmúyẹ tí kọmẹńtátọ̀ tó dáńtọ́ gbọ́dọ̀ ní?
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Iṣẹ́ ju iṣẹ́ lọ: Wọ́n ra Ronaldo ọmọ ọdún 33 ni £99m 10 Agẹmo 2018 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 15 Agẹmo 2018 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Cristiano Ronaldo ni agbábọ́ọ̀lù tó dàgbà jùlọ tí wọn yóò ra ní owó tó tó £99m Agbabọọlu iwaju fun ikọ Real Madrid, Cristiano Ronaldo darapọ mọ ẹgbẹ agbabọọlu Juventus lẹyin ti Juve san £99m fun Real Madrid to ti wa.
Atẹjade kan ti akọwe iroyin si igbakeji aarẹ, Laolu Akande fisita ni irọ to jinna sootọ ni awọn iroyin nipa isẹlẹ naa, to wa lawọn oju opo iroyin kan.
"''Ìséde káàkiri Nàìjíríà lọ̀nà àbayọ sí ìtànkálẹ̀ coronavirus, bí bẹ́ẹ̀ kọ́ àpá kò ní ká covid-19 mọ́''- Onímọ̀ Ọkùnrin Lebanese tó lu ọmọ Nàìjíríà ní gbàǹjo lórí Facebook ti kó sí páńpẹ́ ọlọ́pàá ""Ọlọ́pàá ní kí n bọra sílẹ láti mọ bóyá obìnrin ní mí torí mo ní irùngbọ̀n"" Nàìjíríà yóò wo tí aráàlú bá bínú lórí àfikún igbele Covid-19 - Dele Momoodu Wọn wa rọ awọn olori ijọ musulumi gbogbo lati lo ayelujara fun eto iwaasu atawọn nnkan miran ti wọn ba ni lọkan lati ṣe lasiko awẹ yii."
ati ọtí waini tí ń mú inú eniyan dùn,ati epo tí ń mú ojú eniyan dán,ati oúnjẹ tí ń fún ara lókun.
La òfin rẹ yé mi,n óo sì máa ṣe àṣàrò lórí iṣẹ́ ìyanu rẹ.
O ni bayii ni ile iṣẹ naa tẹsiwaju ti wọn si kọ Ile Arugbo si ori ilẹ naa nibi ti ijọba ya sọtọ fun garaaji igbekọ si ati ibi ti ijọba tun fẹ kọ ile iwosan nla si lọjọ iwaju.
Oludari ajọ to n mojuto irinajo ọkọ ofufuru, Nigeria Civil Aviation Authority (NCAA), Captain Musa Nuhu, lo kede eyi lasiko to n jabọ niwaju igbimọ amuṣẹya to n mojuto ọrọ Covid-19 nilu Abuja lọjọbọ.
Nígbà tí Ṣaulu kú, Baali Hanani, ọmọ Akibori gorí oyè.
Ṣugbọn ẹ̀yìn Dafidi ni gbogbo ẹ̀yà Juda wà.
Atẹjade kan ti akọle rẹ n jẹ 'ẹ gba ẹmi wa la', ti ẹgbẹ Majeobaje naa kọ si gomina ipinlẹ Ondo, Rotimi Akeredolu, tii se alaga awọn gomina lẹkun yii, lo sisọ loju ọrọ naa.
Ó sọ fún Edomu pé, “Wò ó, n óo sọ ọ́ di yẹpẹrẹ láàrin àwọn orílẹ̀-èdè yòókù;gbogbo ayé pátá ni yóo máa fi ọ́ ṣẹ̀sín.
Odi ìlú náà sì wó lulẹ̀.
Ìbẹ̀rẹ̀ ìrora bíi ti ìrọbí ni gbogbo èyí.
asa lorile ede Naijiria, Lai Mohammed , ti o wa nibi  ipade naa tun so pe, ile-ise to n mojuto eto
Ni afikun, iko agbaboolu Sudan jawe olubori ninu ifigagbaga idupo keta, leyin ti won fagbahan orile-ede Lbya.
Awọn ayederu iranṣẹ Ọlọrun to n fi iṣẹ Ọlọrun boju ṣiṣẹ ibi lati yan araalu jẹ.
 “Ilana akotun  ati Eko igbalode, eyi ti o so ipinle di okan Pataki   fun isakoso ijoba rere je agbekale ise owo Asiwaju Bola Tinubu”.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Sanwo-Olu: Kò ní sí súnkẹrẹ-fàkẹrẹ ọkọ mọ́ l‘Eko tí mo bá dé ipò 3 Ọ̀pẹ̀̀ 2018 Oríṣun àwòrán, Jide Sanwo-Olu Campaign Olùdíje fún ipò Gómínà Ipinlẹ Eko lábẹ́ àṣíá ẹgbẹ́ oṣèlú APC, Jide Sanwo-Olu gbé ìgbésẹ̀ láti dáhùn ọ̀pọ̀lọpọ̀ àwọn ibéérè tí awọn ará ìlu Eko ni fún loju opo Twitter rẹ lọ́jọ́ Àìkú.
Nígbà tí àwọn Juu tí ó wà ninu ilé pẹlu Maria, tí wọn ń tù ú ninu, rí i pé ó sáré dìde, ó jáde, àwọn náà tẹ̀lé e, wọ́n ṣebí ó ń lọ sí ibojì láti lọ sunkún ni.
” Ahimaasi bá sáré gba ọ̀nà pẹ̀tẹ́lẹ̀ lọ, ó sì ṣáájú ará Kuṣi náà.
Ìbá tẹ́ wa lọ́rùn kí á wà ní òdìkejì odò Jọdani, kí á sì máa gbé ibẹ̀.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ethiopia: Abiy Ahmed ni olóòtú ìjọba tuntun 2 Ìgbé 2018 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Abiy ni olotu ijọba akọkọ ọmọ ẹya Oromo lati ọdun mẹtadinlọgbọn ti EPRDF ti wa ni ijọba.
 Awon naa ni: Tajudeen Sulaiman (Badminton), Sidiq Bolaji (Wushu Kung Fu) ati Sulaiman Abd naaulkareem Angulu (Rugby).
Ileeṣẹ to n risi eto irinajo ilẹ okere lorlẹ-ede naa, IRCC sọ pe bo tilẹ jẹ pe awọn gbedeke kan yoo wa fun awọn arinrinajo, ṣugbọn o ti bẹrẹ iṣe pada nitori awọn ti yoo bẹrẹ si n rinrinajo lọ ilẹ ọhun laipẹ.
O ti fi igba kan naa jẹ olori ẹka agbogun ti iwa ijẹkujẹ nileeṣẹ ọlọpaa olu ilu orilẹ-ede Naijiria, Abuja.
O ni ẹgbon oun, Tunde ati ọrẹ rẹ kan lo kọkọ rin irinajo ọlokada yii wa si Naijiria lọdun melo sẹyin ni èyí tó wa jẹ́ ìwúrí fún òun atawọn to ku.
” Abdullahi salaye pe o seese ki owu kiko wole yi gba ounje lenu ile ise owu to le laadota to wa ni Naijiria lasiko yii ki opolopo awon ile ise to n se aso si kogba wole ki ise bo lowo opolopo eniyan.
A Pa Àwọn Ọmọ Ọba Ahabu.
Ìpolongo tó nlọ lọ́wọ́ ni orilẹ́ èdè Nigeria ni pé “Àyípadà tàbi Àtúnṣe bẹ̀rẹ̀ pẹ̀lú mi”.
Nítorí gẹ́gẹ́ bí a ti ní ìpín ninu ọpọlọpọ ìyà Kristi, bẹ́ẹ̀ náà ni a ní ọpọlọpọ ìwúrí nípasẹ̀ Kristi.
Lai pẹ yi ni ile isẹ iròyìn kan kọ si oju opo Twitter rẹ pe, Mutua sọ pe ''àwọn ilé ìwòsan ti mo kọ, lo mọ jùlọ lorílè-èdè Kenya.
5% láti 5% lẹ́yìn tí ààrẹ Buhari buwọ́lu àbá ètò ìnáwó Àwọn sẹ́nétọ̀ Nàìjíríà fa ìbínú yọ 'torí N2Miliọ̀nù owó àjẹmọ́nú Kérésì tí wọ́n fún wọn Ọdún mọ́kànlá sẹ́yìn ni K1 ti ń béèrè fún oyè Mayegun lọ́wọ́ mi - Alaafin Production:Yemisi Oyedepo àti Joshua Akinyemi Èyí tí a wò jùlọ 5:03 Fídíò, Omolola Arohunmolase Welder: Mo ti fí iṣẹ́ 'Welder' gbayì láwùjọ, tó mo fi tọ́ ọmọ yanjú, Duration 5,039 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 5:39 Fídíò, Akomolede ati Asa lori BBC: Olùkọ́ Kikelomo Ogunboye tan ìmọ́lẹ̀ sí ìwà olè ọ̀gá ọlọ́pàá Audu gẹ́gẹ́ bí àwòkọ́ṣe àsìkò yìí, Duration 5,398 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 4:11 Fídíò, Oba Adeyeye Ogunwusi: Ojú mi ti rí lọ́pọ̀ lọpọ̀, ọ̀pọ̀ èèyàn ni kò tilẹ̀ gbàgbọ́ pé mo lè jọba- Ooni, Duration 4,117 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 4:43 Fídíò, Promise Akinlade: ọmọ ọdún mọ́kànlá tó ń fi ìlù dárà bíi àgbàlagbà sọ̀rọ̀ nípa tálẹ́ǹtì rẹ̀, Duration 4,437 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 0:59 Gbọ́, Ìsẹ̀lẹ̀ jákèjádò orílẹ̀èdè àgbáyé láàárín ìṣẹ́jú kan, Duration 0,59wákàtí 5 sẹ́yìn 7:03 Fídíò, Olumuyiwa Bolade Adedeji Military Bruitality: Bí arákùnrin onípèníjà ara tí sọ́jà lù ṣe dé, Duration 7,035 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 4:45 Fídíò, Yoruba Films: Ẹ̀ẹ́ bẹ̀ mi kúrò láyé ni, mi ò lè kú - Fadeyi Oloro, Duration 4,4526 Èrèlè 2020 2:48 Fídíò, Esther Ajayi: Èmi náà ti borí ìṣòro rí ló ń mu mi ṣojú àánú, Duration 2,481 Ògún 2019 6:08 Fídíò, Adebola Ademilua: Àìrísẹ́ ṣè lẹ́yìn ìwé kíkà ló sọ mi dí ìyá onírú, mo dúpẹ́ tèmi, Duration 6,0827 Bélú 2020 5:55 Fídíò, Soyinka Cancer: Àṣe ara mi ni iso ti n run gbogbo bí mo ṣe n ṣèrànwọ́ lórí jẹjẹrẹ, Duration 5,5527 Bélú 2019 BBC News, Yorùbá Ìdí tí ẹ fi le è nígbàagbọ́ nínú ìròyìn BBC Ìlànà Lílò Nípa BBC Òfin Àṣírí Cookies Kàn sí.
Ṣugbọn niwọn igba to jẹ pe, ba ku la a dere, eeyan ko sunwọn laaye, idi si ree ti BBC Yoruba fi boju wẹyin lati ṣe akọsilẹ iṣẹ awọn akọni oṣere mẹwaa to ti ku, lati fi ṣe iranti wọn.
 Ìlé ẹ ̀ kọ ́ yìí maa ń gba ọkùnrin nìkan , bíótilẹ ̀ jẹ ́ wípé àwọn obìnrin díẹ ̀ díẹ ̀ wà lára wọn ( a level ) àwọn akẹ ́ kọ hsc kí wọ ́ n tó dá queen ' s college lagos , sílẹ ̀ tí a mọ ̀ sí kọ ́ lẹ ́ jì obìrin .
Omole ni afurasi ọhun yoo foju bale ẹjọ ni kete ti wọn ba ti pari iwadii lori iṣẹlẹ naa.
O ṣalaye pe ọja to ṣofo nibi ijamba ina naa le ni ẹgbẹgbẹrun miliọnu naira.
ICC pari iwadi lori iparun awọn Shiites, IPOB
Ilumọọka osere tiata kan, Fẹmi Adebayọ ti ni ohun to buru julọ ti oun tii se ninu ere ori itage ni ere kan ti wọn ti ni ki oun gba baba oun, Adebayọ Salami, ti gbogbo eeyan mọ si Ọga Bello leti.
OLUWA Dá Ìwà Ìbọ̀rìṣà Israẹli lẹ́bi.
Fidio kan ti arabinrin Ajayi Ọmọlọla fi sita laipẹ yii lo di alatagba lori ayelujara nibi ti o ti n ṣalaye pẹlu omije loju pe, awọn eeyan kan ta oun si orilẹ-ede naa labẹ pe oun yoo ri iṣẹ aje se.
Ó fún Nàìjíríà l'èsì àwọn ẹ̀sùn tó fi kàn-án Ọba ni mí, mi ò le b'ọ̀rìṣà, Olorì tuntun tó ń bọ̀ já gbogbo ''scale''- Oluwo ti Iwo Èèyàn méjì kú, méjìdínlógóje míì ṣẹ̀ṣẹ̀ kó COVID-19 lọ́jọ́ Àìkú Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Fídíò, Natalia Mufutau ìyá Yakub, Kamil àti Adam sọ̀rọ̀ lórí bí wọ́n ń sọ èdè mẹ́rin pàpọ31 Ògún 2020 Oluwo: Èmi l'ọba lórí òrìṣà, oṣó àti ajẹ́, Olorì tuntun tó ń bọ̀ lẹ́tikẹ31 Ògún 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
, sùgbọ́n àwọn akẹẹgbẹ́ mi yóò ra mọ́tò lásán, wọn yóò máa gbé wá sórí ayélujára, kódà, ẹnití kò tíì tó ogójì ọdún náà yóò máa polongo pé òun ń se ọ̀jọ́ ìbí ogójì ọdún.
Ó wọ ẹ̀wù tí ó balẹ̀ dé ilẹ̀.
Gege bi o se sọ, o ni ijoba
“Ìgbà mélòó ni à ń pa fìtílà ẹni ibi?
Ìmúra láti Gbé Àpótí Majẹmu Pada.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Àwa táa jẹ́ alágbàtọ̀ gan, èèyàn ni wá, ẹ ye ṣe wa bí ẹranko' Bi itan naa se lọ ree: Obinrin kan ti wọn pe orukọ rẹ ni Iyalufa lo n gbe ni ilu kan laye atijọ, eyi ti wọn n pe ni Ijaye, obinrin yii ati ọkọ rẹ ti pinya nitori aawọ ti ko ni ojutu, ti onitọun si ti fẹ iyawo miran si agbegbe Ibarapa, ti Iyalufa si n da gbe pẹlu awọn ọmọ rẹ.
Akitiyan gẹgẹ bi ajafẹtọ ẹni Awojọbi jẹ eni ti a ma ja fun ohun kohun to ba ni igbagbọ ninu rẹ.
kejidinlọgbọn oṣu kejila ọdun 2018 ni asiko ti awọn wa lẹnu isinmi ranpẹO
Bí ó ti yẹ kí eniyan máa rò nípa wa ni pé a jẹ́ iranṣẹ Kristi ati ìríjú àwọn nǹkan àṣírí Ọlọrun.
Liverpool de ipele aṣekagba Champions League ni saa to lọ ṣugbọn ikọ Real Madrid lo gba ife ẹyẹ naa.
Aare wa gbadura pe ki Olorun fun Alaafin ni emi gigun, ilera , ogbon ati imo lati tun lee tesiwaju  ninu ilana ti awon baba re ti la sile.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ebola Virus: ìdí tí Ebola fi ń tàn kálẹ̀ Bẹẹ, awọn Super Falcons naa ti joye Akintọla taku yii lọdun 2016 ni Cameroon ati nigba ti wọn fẹhonuhan ni Abuja lẹyin idije pe wọn ko san awọn owó ajẹmọnu awọn.
Ninu ìṣòro ńlá ni mò ń ké pè ọ́, OLUWA!
Oríṣun àwòrán, LASG Ikú Barakat Bello ní Akinyele gbé aláàánú pàdé ẹ́bí rẹ̀ Ọlọ́pàá ìpínlẹ̀ Kwara lé ọlọ́pàá mẹ́rin kúrò lẹ́nu iṣẹ́ fún ẹ̀sùn ìwà ìbàjẹ́ Mínísítà àti iléèṣẹ́ Nipost ń jiyàn lórí àfikún owó ìfìwéránṣẹ́ tuntun Wo àwọn nǹkan tí o kò mọ̀ nípa 'Church of Satan' Bí o lé rìn láàrin Eko pẹ̀lú Ferry Ní oṣù keji ọdún ni ìjọba Ipinle Eko kede aapu ti won n lo fun awon to n wo ferry lái le jẹ́ ki àwọn ènìyàn máá ṣàmúlò ìrìn ojúomi ní ìlú Eko.
Arabinrin Comfort Lamptey ni awọn obinrin lẹkun iwọ oorun Afrika yoo korajọ nilu Abuja fun apero kan laipẹ lati yanana ipenija to n dojukọ awọn obinrin lagbo oṣelu ati ojuṣe ajọ INEC ati awọn ẹgbẹ oṣelu fun idagbasoke awọn obinrin.
Wọ́n bá wọlé, wọ́n fi idà pa gbogbo wọn, wọ́n sì wọ́ òkú wọn síta.
Ogunlọ́gọ̀ àwọn eniyan ni wọ́n ń tẹ̀lé wọn, tí wọn ń kígbe pé, “Ẹ pa á!
Ẹgbẹ́ IPOB ò tako Ààrẹ Buhari ní Japan- Iléeṣẹ́ Ààrẹ Òfin nìkan ló lè gbadé lórí àwa Ọba ìlú lbadan- Oba Lekan Balogun Irọ́ ló pa, a kò mọ̀ ọ́ rí tàbí fún ọ ní ₦13m - APC tako afurasí ajínigbé Gẹ́gẹ́ bi olùdari LASEMA Osanyintolu Oke ṣe sọ, kò sí ẹni ti kò farapa nínú ọkọ náà àfi ọmọbinrin kan ló pàdánu ẹmi rẹ̀.
 nígbà tí aláàfin Àdélú rí wípé kúrunmí ti tàpá sí àse àti òfin ìlú Òyó , ó gbé onísé oba dìde wípé kí wón lo fun ní àrokò méjì kan kí ó mú èyí tí ó wùú .
#EndSARS: Pe nọ́mbà wọ̀nyìí láti fẹjọ́ ọlọ́pàá SARS sùn Bí Ọlọ́pàá SARS bá dá ènìyàn dúró kó gbọ́ sùgbọ́n.
Àwọn ọ̀nà tó lọ sí Sioni ń ṣe ìdárò,nítorí kò sí ẹni tí ó ń gba ibẹ̀ lọsíbi àwọn àjọ̀dún tí a yà sọ́tọ̀ mọ́.
” Mose bá sọ ọ́ sílẹ̀, ọ̀pá náà sì di ejò, Mose bá sá sẹ́yìn.
jẹ eni akọkọ ti o fi ipe ransẹ si aare Muhammadu Buhari lati ki ku ori ire, leyin
a níláti tọ ́ ka sí i pé Ìjẹ ̀ bú ti Ìjẹ ̀ ṣà yí lè ní nǹkan kan í ṣe pẹ ̀ lú Ìjẹ ̀ bu ti Ìjẹ ̀ bù -Òde .
Lọdun 2010 ni Ebuka morile Washignton College of Law lati gba ipele oye keji ninu imọ ofin ni America.
Ó ní kí ó máa há a mọ́lé, ṣugbọn kí ó ní òmìnira díẹ̀, kí ó má sì dí àwọn ọ̀rẹ́ rẹ̀ lọ́wọ́ láti ṣe ìtọ́jú rẹ̀.
“Nisinsinyii wọ́n fọ̀rọ̀ kan tó mi létímo gbọ́ wúyẹ́-wúyẹ́ rẹ̀.
Àwọn mìíràn ní ọ̀kan ninu àwọn wolii àtijọ́ ni ó tún pada.
Ó sọ ọ́ ní Noa, ó ní: “Eléyìí ni yóo mú ìtura wá fún wa ninu iṣẹ́ ati wahala wa tí à ń ṣe lórí ilẹ̀ tí OLUWA ti fi gégùn-ún.
Eto Idajọ ti wọn fi ikede rẹ sita ninu iwe ile ẹjọ naa ni awọn alatilẹyin awọn ti ọrọ naa kan fi sọwọ sawọn oniroyin yoo waye laago mẹsan owurọ nile ẹjọ kotẹmilọrun nilu Abuja.
"Fatai wi pe, ""Kii ṣe pe awọn aṣofin n dẹyẹ si Ambode, sugbọn ojuṣe wa la n ṣe gẹgẹ aṣofin."
Ṣugbọn bí ẹni tí ó ni ẹran náà bá wà níbẹ̀ nígbà tí ó kú, ẹni tí ó yá a kò ní san ẹ̀san pada.
Ninu atẹjade kan ti wọn fi sita, ni wọn ti ni awọn ṣe ikọlu si ibudo ọmọ ogun ilẹ to wa nibẹ nibi ti wọn ti ṣe awọn miran leṣe.
OLUWA ṣe ohun tí Mose fi adura bèèrè, àwọn ọ̀pọ̀lọ́ tí wọ́n wà ninu gbogbo ilé, ati ní àgbàlá, ati ní gbogbo oko sì kú.
Ọmọ Israẹli ni mí, láti inú ẹ̀yà Bẹnjamini, Heberu paraku ni mí.
Gẹgẹ bi ohun ti ileeṣẹ ọlọpaa sọ, wọn ni Umar ti ọwọ tẹ lalẹ ọjọ Abamẹta ti jẹwọ pe oun kan fẹ lọ fọwọ kan awọn obinrin naa ni.
"Maa fi asọtẹlẹ ba arun Coronavirus jẹ.
Ika ọwọ kẹfa yii ni awọn eeyan gba pe Ajé ni.
Akọwe fun ẹgbẹ awọn onitiata ni ipinlẹ Ọṣun, Ademọla Adedokun fi idi iroyin iku rẹ mulẹ fun awọn oniroyin.
Jọgbọdọ Orunmila sọ pe, nigba ti mama oun fẹ gba ninu owo ọhun ni ẹka ile ifowopamọ Access Bank kan ni o bẹrẹ si ni awọn idojukọ kan eleyi ti ko jẹ ko ri owo gba.
Ó ní jákèjádò orílẹ̀-èdè mẹ́fà pẹ̀lú ní ọmọ tó dín díẹ̀ ni mílíọ̀nù méjì ni ó wà nínú ewu àìrí oúnjẹ jẹ.
 níbi tí a kò bá ti lo àmì yìí , gbogbo ìsòrí òrò tí ó tèlé àmì ofà yen ni ó pon dandan nìyàn .
Ifẹhonuhan to waye l'oṣu Kẹwaa, ti awọn ọmọ ologun si pa lara wọn.
Makinde ni àwọn ǹkan ìrànwọ ti ìjọba pèsè fún ará ìlú ti wà ni ṣẹpẹ báyìí ti wan si ti yan ìdílé ẹgbẹ̀run 'lọ́nà ààdọ́rùn sọtọ̀ láti jẹ àǹfàní ètò náà Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Coronavirus ti di ara wa, kò le è kúrò mọ láéláé - WHO 'Bí Covid19 bá peléke síi l'Eko, ilé la ó ti máa tọ́jú àwọn kan' - Ìjọba ìpínlẹ̀ Eko Àjẹ́ àti Aṣẹ́wó ní ìyá Rainbow - Òjòpagogo Ìdí rèé tí ilẹ̀ Afirika fi gbọdọ̀ kópa nínú dídán abẹ́rẹ́ coronavirus wò Wo orílẹ́èdè tí wọ́n tí ń dáwó ìsìnkú ara wọn pámọ́ Èmi àti Saheed kìí ṣe ọmọdé, a ti jọ ṣe Sinimá papọ̀, èyí túmọ̀ sí pé ìjà ti parí - Fathia Balogun Ike Ekweremadu, igbákejì ààrẹ ilé aṣòfin àgbà tẹ́lẹ́ rí èèmọ̀ he nilùú Germany!
Orilẹede Amerika naa ni awọn ko ni kuna lati ma a da abo bo awọn ọmọ orilẹede wọn kaakiri ibi ti wọn ba wa ni agbaye.
“Ìwọ ọmọ eniyan, kọjú sí ìhà gúsù, fi iwaasu bá ìhà ibẹ̀ wí, kí o sì sọ àsọtẹ́lẹ̀ nípa àwọn ilẹ̀ igbó Nẹgẹbu.
O ṣe alaye wi pe alupupu bii ọgọrun mii tun wa kaakiri awọn ipinlẹ to n bẹ ni iwọoorun guusu fun iwọde Amọtẹkun.
Báyìí ni mo ṣe tí ilẹ̀ ṣú mi sí inú igbó náà lọ́jọ́ yìí.
 Oríṣun àwòrán, Nkechi Blessing ""Ninu sinima naa, a jẹ ete ara wa, bi ifẹ wa si se bẹrẹ ree."
Ìgbà mẹrin ni wọ́n ranṣẹ pè mí bẹ́ẹ̀, èsì kan náà sì ni mo fún wọn ní ìgbà mẹrẹẹrin.
Ipade naa to waye ni ilu Ibadan ni wọn ti jiroro lori ohun ti abadofin naa da le lori ati ohun ti wọn gba laaye fun ikọ naa.
 olú-ìlú rẹ ̀ ni ìlọrin .
 O rọ awọn ọmọ orilẹ-ede yii lati lo anfani oṣu Ramadan yii lati fi ifẹ han sira wọn, ki wọn si jẹ ki ẹmi iṣọkan ati alaafia wa laarin wọn.
OLUWA ni mo sá di;ẹ ṣe lè wí fún mi pé,“Fò lọ sórí òkè bí ẹyẹ;
Amọ ajọ isọkan orilẹede agbaye ni a lee dena arun ẹyi naa pẹlu abẹrẹ ajẹsara sugbọn akude ti wọ bawọn orilẹede se n gba abẹrẹ ajẹsara naa.
Ó bá sọ ọmọ náà ní Ikabodu, ìtumọ̀ rẹ̀ ni pé, “Ògo Ọlọrun ti fi Israẹli sílẹ̀.
 Ẹyin lẹ yan mi gẹgẹ bi aṣofin, ohun tẹẹ ba fẹ naa ni maa sọ ninu Ile Aṣofin naa”.
Lai Mohammed ló wà nídìi wàhálà APC Kwara- Fulani Ẹ̀ka Bọlarinwa-Àwọn Balogun-Fulani ń ṣiṣẹ́ fún Saraki ní 'Ìdìbò Ọsun fihàn pé agbára wà lọ́wọ́ àwọn olùdìbò’ Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí kan sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Omar Victor Diop: Ipa Áfíríkà nínú àkọsílẹ̀ ìwé kọja ògo tí wọ́n ń fún un lágbáyé Ìwọ́de lórí ẹ̀kúnwó owó oṣù ẹka ti ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́ ti darapọ̀ mọ́ àwọn ojúgbà wọn káàkiri Nàìjíríà níbi ṣíṣe ìwọ́de láti fẹ̀hónú hàn lórí owó oṣù òṣìṣẹ́ tí ó kéré jù.
Awọn alaṣẹ ẹgbẹ naa ti kọkọ ṣepade pọ pẹlu ijọba apapọ lọjọ Ẹti lori erongba rẹ lati gunle iyanṣẹlodi.
O bori idije dupo oye Baale Arekujaye naa nipa pipe ohun ẹsa ati nipa idan pipa nilu Oyo.
Ó ní, “Ẹlẹ́wọ̀n tí ń jẹ́ Paulu ni ó pè mí, tí ó ní kí n mú ọdọmọkunrin yìí wá sọ́dọ̀ yín nítorí ó ní ọ̀rọ̀ kan láti sọ fun yín.
Ẹgbẹrun lọna aadọta Naira (N50,000) o kere tan ni Arole Oodua ṣe leto fun miliọnu marun akẹkọọ fun ọdun mẹrin gbako o si ṣalaye pe eto iranwọ yii yoo maa gbe miliọnu marun mi lọdọọdun.
Ni ọjọ ẹti ni aarẹ Buhari ṣalaye ọrọ yii lasiko to fi n tẹwọ gba iwe ẹri rẹ lọwọ awọn alaṣẹ ajọ eleto idanwo oniwe mẹwa, WAEC ni ile ijọba to wa nilu Abuja.
Koda lọdun 2017, ajọ eleto ẹyawo lagbaaye, IMF sọ pe ẹka eto igbafẹ nikan ko ida ogoji ninu iko ọgunrun un ọrọ-aje orilẹ-ede naa.
Lara wọn ni ọlọpaa ati ọmọ ogun mẹrinla wa ti awọn ara ilu mẹrin si pẹlu.
O kì bá tí fi arakunrin rẹ ṣẹ̀sínní ọjọ́ ìpọ́njú rẹ̀;o kì bá tí jẹ́ kí inú rẹ dùn,ní ọjọ́ ìparun àwọn eniyan Juda;o kì bá tí fọ́nnu ní ọjọ́ ìbànújẹ́ wọn.
Ẹgbọn oloogbe naa, Chinenye ṣalaye fun BBC bi ọrọ naa ṣe jẹ, o si fẹsun kan ọlọpàá pe wọn parọ lori ọrọ naa.
Hushpuppi di gbajúmọ̀ ẹlẹ́wọ̀n tó ní nọ́ńbà l‘Amẹrika, orúkọ̀ rẹ̀ wà lórí ayélujára Àlàyé rèé lórí ìdí tí Magu àti awọn alága EFCC míràn ṣe bá ìtìjú kúrò nípò Ẹ wo nkan tí àwọn akẹẹgbẹ́ Lateef Adedimeji sọ nípa f'ọ́tò ìgbéyàwó òun àti Adebimpe tó jáde Wo ìgbésẹ̀ méjọ tí ilé aṣòfin ìpínlẹ̀ gbọdọ̀ tẹ̀lé láti yọ igbákejì gómìnà Igbimọ naa, ti Aarẹ nigba kan fun ile ẹjọ kotẹmilọrun, Ayo Salami, jẹ alaga, ranṣẹ pe Magu lati wa a sọ tẹnu rẹ nipa awọn ẹsun naa.
Aarẹ ẹgbẹ naa ninu ọrọ ikini sibi ipade naa fawọn oloye ẹgbẹ lami ẹyẹ fun iṣẹ takuntakun ti wọn ti ṣe.
"Ẹ wo fídíò òfò àti àdánù tó wáyé níbi ìkọlù sáwọn àjèjì ní South Africa ""A ti nílé, dúkìá àti ẹbí ní South Africa, àwa kò ṣetán láti padà sílé"" Àwọn ọ̀rọ̀ apanílẹ̀rín tí Mugabe sọ tó jẹ́ mánigbàgbé ""Ọ̀pọ̀ ń gbé nínú ìbẹ̀rù ní South Africa ́lọ́wọ́lọ́wọ́ báyìí"" Ìdájọ́ ọmọ mi tó gbé àdó ìkú wọ bàálù le púpọ̀, ẹ bá mi wòó ṣe - Bàbá Mutallab Gẹgẹ baa ti gbọ, awọn ọlọpa lorilẹede naa ti fidi rẹ mulẹ pe awọn eeyan naa ko tii dẹkun isẹ ibi ti wọn n se lati ọjọ Aiku, ti awọn ko si tii sinmi kika apa wọn ko ninu iwa ibajẹ naa."
Ta ló fi ọgbọ́n sinu ìkùukùuati ìmọ̀ sinu ìrì?
Dafidi gba ẹ̀bùn tí ó mú wá, ó sì sọ fún un pé, “Máa lọ sílé ní alaafia, kí o má sì ṣe bẹ̀rù, n óo ṣe ohun tí o sọ.
Nígbà tí Josẹfu rí i pé ọwọ́ ọ̀tún ni baba òun gbé lé Efuraimu lórí, kò dùn mọ́ ọn.
Òun a máa fò lọ́sàn-án, òun a má fò lóru, òun a si máa fi agbárí ènìyàn mu omi.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Afcon 2019: Àwọn olólùfẹ́ Super Eagles fẹ́ kí Rohr tún wọn tò Ijọba apapọ n fi ẹsun kan wọn pe wọn ṣe owo to to miliọnu mẹjọ ati irinwo ẹgbẹrun dọla owo ilẹ Amẹrika to jẹ owo ajọ NFF baṣubaṣu.
Bakan naa, ileeṣẹ Expanded Global Industries Limited ti n ṣiṣẹ pọ pẹlu awọn ọlọpaa ati ileeṣ to n ri si ọrọ awọn oṣiṣẹ l'Oyo lati tuṣu de isalẹ koko ohun to fa sababi iku Richard gangan.
O ni, “bi a ba fun eniyan ni ami ẹyẹ yii lori iṣẹ takuntakun ti ẹnikan ti ṣe, yoo je nnkan iwuri fun awọn to wa laye ati awọn to n bọ lẹyin nitori ti a ba bẹrẹ ati maa fun awọn eniyan ni ami idanilọla yii, lapa kan, wọn ko ni jawọ ninu iṣẹ takuntakun wọn fun ilu, bẹẹ ni yoo jẹ ohun iwuri fun awọn to n bọ lẹyin naa”.
Ṣugbọn ṣa, ẹgbẹ oṣiṣẹ n fẹ ki ofin naa di lilo ni kiakia, pẹlu alaye pe ọdun meji ni igbesẹ naa fi falẹ.
Ta ni afọ́jú, bíkòṣe iranṣẹ mi?
"ó túmọ sí ìkọlù, láti já wọle, tàbí láti jale"" ""Ìwádìí ń lọ lọ́wọ́ tí ẹ ò bá gbàgbé a fí àtẹ̀jáde kan síta laipẹ nígbà ti a lọ sí ilé ẹjọ láti gbéṣẹ̀ lé owó nilé ìfówópamọ mẹ́ta kan ti wọ́n lò láàrín inú oṣù kẹsan an ọdun 2018 sí osù karún un ọdún yìí nílu Eko."
Gbogbo ohun tí ó wà ninu oko ní gbogbo ilẹ̀ Ijipti ni yìnyín náà dà lulẹ̀, ati eniyan ati ẹranko; o sì wó gbogbo àwọn ohun ọ̀gbìn oko ati gbogbo igi lulẹ̀.
" Àwọn òṣèré tíátà Yorùbá ọkùnrin táyé ni wọ́n rẹwà Toyin Abraham jọ̀wọ́ dáríjì mí - Yomi Fabiyi Ilu Ilọra ni ipinlẹ Ọyọ, ni wọn bi Aluwẹ si ni ọdun 1954.
Isakoso isejoba aare Muhammadu Buhari lati gbogun ti iwa ibajẹ lorile-ede Naijiria n so eso rere.
Ó dá ọba lóhùn, ó ní, “Kabiyesi, ìwọ ni o ṣe ìlérí fún èmi iranṣẹbinrin rẹ, tí o sì fi orúkọ OLUWA Ọlọrun rẹ búra pé, Solomoni ọmọ mi ni yóo jọba lẹ́yìn rẹ.
Ilé ẹjọ́ ju ọmọ ìjọ tó fi ìpá bá ọmọ pásítọ̀ rẹ̀ sùn ní ìpínlẹ̀ Ondo sí ẹ̀wọ̀n gbére Àwọn ẹgbẹ́ Tijjaniyya ti yọwọ́ kílàńkó Yahaya Sharif kúrò láwo ẹgbẹ́ wọn ní Kano Mi ò ní wọ Uber mọ́ tí wọ́n bá leè fi owó lée nítorí àfikún owó orí tí Sanwo Olu ṣe"" 'Àwa ọmọ Nàìjíríà tó farapa fẹ́ wálé láti Lebanon, ìjọba kó wa pamọ́' Amọ agbẹjọro ọmọkunrin naa, Rotimi Oyagbola rawọ ẹbọ si ileẹjọ lati fi oju aanu wo ọdọkunrin naa nirori igba akọkọ ree ti yoo ṣe iru nnkan bẹẹ."
Lowurọ ọjọru lo fi ọrọ yi lede ninu iwe to ka seti igbọ awọn ọmọ ile aṣofin agba nilu Abuja.
Laipẹ yi ni awọn ọmọ ikọ Boko Haram ṣigun lọ ba awọn ọmọ ogun Naijiria labule kan ti wọn n pe ni Metele nipinlẹ Borno.
Ìṣẹ́ ló jẹ́ kí n sọ ọmọ nù sórí ààtàn- Dupẹ, Ìyá Muiz Sinimá àwòdamiẹnu, Ẹ̀fáńjẹ́líìsì jìyà àjẹmumi nílé aṣẹ́wó l'Ejigbo ní ìlú Eko Gbajúgbajà òṣèré “Blue film'' wọ gàù ẹ̀sùn fífipá bá obìrin 13 lòpọ̀ Ọba Saudi Arabia yọ ọmọ rẹ̀ àti àbúrò rẹ̀ kúrò nípò nítorí ìwà àjẹbánu lórí owó tó yẹ fún ààbò ìlú Kini Ejiogbe NURTW sọ?
O san owo si akoto Chidozie ti oun naa si fi idupe sita loju opo Twitter pe oun ti ri ''alert'' gba Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Coffee Painter: Adebukola ní kò sí ìrànwọ́ lẹ́yìn ẹ̀kọ́ girama lòun ṣe ń ya àwòrán Bi igbẹjọ naa ba se lọ, ni BBC Yoruba yoo maa mu wa fun yin.
esi idibo naa ni Kabba, lọjọ Aiku.
Àwọn tí ó gbẹ́kẹ̀lé OLUWA dàbí òkè Sioni,tí ẹnikẹ́ni kò lè ṣí nídìí, ṣugbọn tí ó wà títí lae.
Akẹ́kọ̀ọ́ náà sọ wípé ó já òun kulẹ̀ nínú ẹ̀kọ́ nígbà tí òun kò gbà fún un.
"Oríṣun àwòrán, Getty Images Dokita Aliyu ni, "" Ijọba apapọ orilẹede Naijiria ni eto to rinlẹ pẹlawọn alabaṣiṣẹ pọ rẹ lori igbogun ti kokoro arun HIV/AIDS lati ṣeto iranwọ ati atilẹyin fawọn to ba ti ni kokoro arun ọhun, lati pese itọju, ati lati daabo bo awọn ẹbi wọn ki wọn lee gun lẹmi, ki wọn si gbe igbe aye alaaafia."
" Ni arabinrin Juliet Ehimuan-Chiazor ti o jẹ adari ileeṣẹ Google Nigeria ṣalaye fun ikọ BBC.
“Sáré lọ sọ fún ọmọkunrin tí ó ní okùn ìwọ̀n lọ́wọ́ pé, eniyan ati ẹran ọ̀sìn yóo pọ̀ ní Jerusalẹmu tóbẹ́ẹ̀ tí a kò ní lè mọ odi yí i ká.
Igi náà bẹ̀rẹ̀ sí tóbi, ó sì lágbára; orí rẹ̀ kan ojú ọ̀run, kò sí ibi tí wọn kò ti lè rí i ní gbogbo ayé.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsèjẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọ Masari tun fikun pe awọn janduku agbesunmọmi lasan lo ko awọn akẹkọọ naa, wọn kii se Boko Haram.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù BBC OSUN DEBATE: Àwọn olùdíje sípò gomina sọ̀rọ̀ lórí ètò Èkọ́ 17 Owewe 2018 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 19 Owewe 2018 Awọn oludije si ipo gomina ni ipinlẹ Ọsun fi erongba wọn han lori ọna abayọ siṣoro eto ẹkọ ni ipinlẹ Ọsun.
Àwọn ọba ayé ati àwọn tí wọ́n ti bá a ṣe àgbèrè, tí wọ́n ti ń bá a jayé yóo sunkún, wọn óo ṣọ̀fọ̀ lé e lórí nígbà tí wọ́n bá rí èéfín iná tí ń jó o.
Idi niyi ti ileesẹ BBC Yoruba se n tiraka lati mase jẹ ki asa naa parun nitori ede Yoruba jẹ ede to ni iro ọrọ.
Lukuluku Bantaṣi: Oríṣun àwòrán, others Adẹrinposonu ati alawada gidi ninu ere tiata ni Lukuluku Bantasi, ẹni to ki aye pe o digbose lọdun 1995.
A ko le ni ki ọmọ ẹgbe ma sọ ero ọkan rẹ amọ to ba jẹ wi pe o sọ nnkan to ba tako ẹgbẹ nigba yẹn lẹgbẹ to le gbe igbesẹ lati fi iya to tọ jẹ'' Onilu ni boya igbonara lo mu ki Amosun ṣọ oun to ṣọ ati wi pe ko ti ṣọ ọrọ na di mimuṣẹ."
Ni bayii ti asofin agba naa wọ kaa ilẹ lọ lonii, BBC Yoruba ṣe akojọpọ ohun mẹwaa to yẹ kẹ mọ nipa asofin agba naa, to fi ta yọ Seyi Makinde ṣí iléèwé padà ní ìpínlẹ̀ Oyo Ọlọ́run ló ní kí Abacha kú, àwọn àgbà Yorùbá púpò kò bá ṣòfò- Dele Momodu Wọ́n ti gbé òkú Ibidunni Ighodalo sílé ìgbókúpamọ́sí l'Eko Ìyà ń jẹ wá ló jẹ́ kí a daṣẹ́ sílẹ̀ - ẹgbẹ́ àwọn dókítà Ohun mẹwaa nipa Ṣẹnetọ Adebayo Osinowo: Ọmọ bibi ilu Ijebu Ode, nipinlẹ Ogun ni asofin agba naa, amọ to fi ilu Eko ṣe ibujokoo Oshinowo gba iwe ẹri Diploma ninu ẹkọ imọ ẹrọ nipa ile kikọ ni ilu Rome, to si tun kọ ẹkọ nipa ede orilẹ-ede Italy Bakan naa lo tun gba iwe ẹri keji ninu ẹkọ nipa ibaraẹnisọrọ ni fasiti Urbaniana nilu Rome, nilẹ Italy Oshinowo ti jẹ alaga fẹgbẹ ọdọ ninu ẹgbẹ oselu NPN ni ọdun 1979 lasiko saa isejọba alagbada keji Asofin agba to di oloogbe yii, tun ti fi ọdun mọkanla jẹ alaga igbimọ ile asofin nipinlẹ Eko, eyi to wa fun ọrọ ilẹ ati ilegbe Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Lockdown in Africa: Nínú Ọlọ́pàá àti Coronavirus, èwo gan an laráàlú ń bẹ̀rù jùlọ?
Ibadan NURTW: Àwọn ti Auxilliary àtàwọn tí Ajanaku gangan ló ń dàgboro rú Inú mi dùn pé ẹni tó gbà ìjọba lọ́wọ́ mi ń san gbèsè tí mo fi kalẹ - Aregbesola Àkúntúnkú, ìgbà márùn ún rè é tí Shekau kú tí wọ́n ní kò kú mọ Òṣèré tíátà, Kemi Afolabi dùbúlẹ̀ àìsàn ní ìlú Mecca Agbẹjọro Farintọ ni agbẹjọro awọn alaga ibilẹ naa fẹ maa fi akoko ṣofo lori ẹjọ ọhun ni, ileẹjọ si gba pẹlu wọn.
Àsìkò òtútù ti wọlé dé tán, ilẹ̀ sì ti ń tètè ṣú lọ́dọ̀ wa níbí.
 Milionu mesan an omo orile ede Naijiria lo ti je anfaani yii.
Ó ní, “Dìde, lọ sí ilé Betueli, baba ìyá rẹ, ní Padani-aramu, kí o sì fẹ́ ọ̀kan ninu àwọn ọmọ Labani, arakunrin ìyá rẹ.
Wọ́n pín àwọn ìlú wọnyi fún àwọn ìdílé tí ó kù ninu àwọn ọmọ Merari.
Mo fún ọ ní ìyẹ̀fun tí ó kúnná, ati òróró, ati oyin pé kí o máa jẹ, ṣugbọn o fi rú ẹbọ olóòórùn dídùn sí wọn.
Aini imọ to kunna lori igbimọ yii lo n fa gbọyi-sọyi ati awuyewuye to n waye naa, Osaze-Uzzi ṣalaye fun BBC News Yoruba.
Àwọn ọmọ Miṣima nìyí: Hamueli, Sakuri, ati Ṣimei.
Èyí níláti rí bẹ́ẹ̀, ṣugbọn kò ì tíì tó àkókò tí òpin ayé yóo dé.
Ó bí ọmọ meji fún un: Ṣeberi ati Tirihana.
Fun iyalẹnu, ni aginju idakẹrọrọ ninu Igbo Olodumare loju aye, wọn kii faye gba ki ẹnikẹni bara wọn sọrọ, wọn kan maa n fi ọwọ se apejuwe fun ara wọn ni.
O ni RCCG da ara rẹ pọ mọ awọn ọmọ Naijiria to n ṣe iwọde lọwọlọwọ tako bi awọn ọlọpaa ṣe maa n fiya jẹ ni, ti wọn si n ṣi agbara wọn lo.
4> Bi ajọ eleto idibo INEC se n segbe si ibikan- Wọn ni awọn ti hu gbọ pe wọn ti pasẹ fun awọn osisẹ ajọ eleto idibo kọọkan lati ri daju pe oludije fun ipo gomina labẹ asia ẹgbẹ oselu APC lo jawe olubori ninu eto idibo naa.
Ẹ fún OLUWA ní iyì tí ó tọ́ sí orúkọ rẹ̀,ẹ mú ọrẹ lọ́wọ́ wá sinu àgbàlá rẹ̀.
Iyawo rẹ, Katie Miller, to tun jẹ agbẹnusọ fun Igbakeji aarẹ Mike Pence, ko Covid-19 l'oṣu Karun-un, amọ o pada ri iwosan.
Sẹ́nátọ̀ àti Gómìnà àná, ẹ dá owó ìfẹ̀yìntì yín padà sápò ìjọba- Adájọ́ Ọwọ́ EFCC tẹ káńsẹ́lọ̀ olórí adigunjalè tó ń jí ọkọ̀ ní Kwara Ọwọ́ tẹ àwọn pásítọ̀ oniíṣẹ́ ìyanu èké méji nílùú Eko 8) Ṣe adinku si bi oju foonu rẹ ṣe mọlẹ to.
Jakọbu gbé ọ̀wọ̀n òkúta kan nàró níbẹ̀, ó fi ohun mímu rúbọ lórí òkúta náà, ó ta òróró sórí rẹ̀, 
Oríṣun àwòrán, Twitter/OkayAfrica Wọn kede ni ipinl\\e Eko pe alekun yoo ba iye owo burẹdi ati awọn ohun jijẹ ti wọn fi iyẹfun ati ṣuga ṣe laipẹ nitori pe awọn ti bẹrẹ igbesẹ lati mu ẹkunwo naa di ajumọṣe.
Ajọ WHO n mojuto pe ki Ebola má tankalẹ sii, wọn ń ṣayẹwo fun iṣẹlẹ Ebola tuntun, wọn tun n pese iranwọ lori ipolongo abẹrẹ ajẹsara Ebola to n lọ lọwọ.
Ọrọ iwọde #EndSARS to bẹrẹ bi ipe alaafia awọn ọdọ fun ijọba lati dẹkun iwa aitọ awọn ọlọpaa, paapaa, ikọ SARS ti wa di wahala to n mu ki ijọba o maa kaya soke lori igbayegbadun araalu.
Fatai lórí eto naa ni o n rí òun lara bi awọn olorin kan to ya ọlẹ tí wọn a kan maa wa owo ọ̀fẹ́ kiri.
OLUWA yóo fà wọ́n tu kúrò ninu ilẹ̀ dáradára tí ó fún àwọn baba ńlá wọn, yóo sì fọ́n wọn káàkiri òdìkejì odò Yufurate, nítorí ère oriṣa Aṣerimu tí wọ́n ṣe tí ó mú OLUWA bínú.
Minista fun FCT, Muhammed Bello, eni ti Ogbeni Isiaku Ismaila, to je oludari ibi owo to dabi akapo soju fun ba awon oniroyin soro pe igbese yii wa niba mu pelu erongba ijoba lati pese awon ohun amayederun gbogbo fawon ara ilu.
Bakan naa nibi ijọsin ọhun, ajagun fẹyinti Gowon rawọ ẹbẹ sawọn ọmọ Naijiria lati yago fun iwa to le da wahala lorilẹede Naijiria.
Aisha Buhari: Torí òtítọ̀ ni mo fi sọ̀rọ̀ tako ọkọ mi
Awọn ololufẹ ikọ super Eagles to n gbe orillẹ̀ede wọn larugẹ ni o yẹ ki awọn agbabọọlu gan ni imọ lara eyi ki wọn si lo gbogbo ọgbọn ati agbara ti wọn ba ni lati mu ori awọn ololufẹ wọn wu.
O tun ṣalye pe awọn ti wọn ni ibalopọ lagbo oṣere tiata nitpri ko si ẹni to le fi tipa mu wọn.
 Ó lè fa àkóràn tí kò léwu àti èyí tí ó léwu .
Awọn ọmọ ologun kede pe, awọn gbe igbesẹ naa, nitori bi ilesẹ iroyin naa se fi aṣiri igbogun ti Boko Haram awọn lede ninu iroyin ti wọn gbe sita ninu iwe iroyin Daily Trust ni Ọjọ Karun, Osu Kini, ọdun 2019.
" Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Dangote, jọ̀ọ́ nawọ́ ìrànwọ́ láti dá iléeṣé sílẹ̀ fún wa ní Ọyọ - Aláàfin rawọ́ ẹ̀bẹ̀ Ọlọkọ tó ṣàfihàn ìhòòhò obìnrin ní Lekki n fí ẹwọn ọdún mẹ́ta runmú- Ìjọba Èkó Ó tó gẹ́ẹ́!
O sọ fun iwe iroyin Hindustan Times pe Igba naa ni o to o yemi, idi ti ọkọ mi fi ni ki n pa ẹnu mi mọ lori iṣẹ abẹ naa."
Ó wí fún wọn pé, “Ẹ máa wò mí, kí ẹ sì máa ṣe bí mo bá ti ń ṣe.
"Oríṣun àwòrán, funkejenifaakindele Kii ṣe ere yii ni akọkọ rẹ gẹgẹ bi oṣere, ati igba ti ọjọ ori rẹ ṣi din ni ogun ọdun lo ti kopa ninu ere to n kọ ni lẹkọ kan ti ajọ UNICEF ṣe onigbọwọ, ""I Need to Know""."
Rin iṣu yi (pẹ̀lú pãnu ti a dálu lati fi rin gãri, ilá tàbi ewùrà)
Ìgbìmọ̀ iṣedajọ orílè-èdè Nàìjíríà NJC fẹ́ ṣèpàdé lórí Onnoghen
  Aare dupe Olorun fun oore ọfẹ ti o fun oloye Ikpea lati mu
Ooni Ile Ife: Emir Kano bẹ ààfin Ọọ̀ni wò, Ọọni Ogunwusi ṣàlàyé ìpayà tó gbòde lórí yíyọ tí Ganduje yọ Sanusi lóyé Emir Kano
Ìbálòpọ̀ ọ̀lọ́jọ́ méje mú kí ilé ẹjọ́ tú ìgbéyàwó ọdún mẹ́wàá ká ní Ibadan Taa ni Ọọni àná tí Ọba Ogunwusi forúkọ ọmọ rẹ̀ sọ?
2b) baṣubaṣu ti ajọ EFCC fi kan an, waye lọjọ Aje ni ile ẹjọ giga apapọ to wa ni Eko.
O Fagunwa, Akinwumi Isola, Lawuyi Ogunniran àti Oladejọ Okediji ni awọn agbaọjẹ onkowe ti a fẹ gbe iṣẹ wọn wo bayii.
N óo máa fi tọkàntọkàn rin ìrìn pípé ninu ilé mi.
Awon to ba yege ninu idije ere boolu ifesewonse WAFU ni yoo maa lọwọ ninu idije ere boolu ti ile Afirika, U-17 African Cup of Nations (AFCON) ti yoo waye ni orile ede Tanzania , awon to ba si yege nibi idije naa, ni yoo maa lowo ninu idije ere boolu agbaye ti yoo waye ni Peru lodun 2019.
A kó ní sanwó oṣú ASUU láìjẹ́ pé wọ́n gba IPPIS- Ìjọba Àpapọ̀ Oṣú mẹ́fà ni òṣìṣẹ́ ìjọba tó bá bímọ yóò máa lò nílé kó tó wọṣẹ́ padà- Seyi Makinde DPO ọlọ́pàá ju télọ̀ sátìmọ́lé, gbé e lọ sílé ẹjọ́ n'Ibadan torí ''ó ba aṣọ rẹ̀ jẹ́'' ₦50 bílíọ́nù ni a pín fún gbogbo ìpínlẹ̀ ní Naijiria láti kojú àrùn Covid-19- Ìjọba àpapọ̀ Fun nnkan bi ọsẹ meji ni awọn oluwọde fi fọ si igboro kaakiri Naijiria lati bere fun opin si ẹka ileeṣẹ ọlọpaa to n ri si iwa idigunjale, SARS, ki ijọba pana iwọde ọdhun.
Báwo ni a ṣe lè fi ìyàngbò wé ọkà?
Ó fi ọ̀nà rẹ̀ han Mose,ó sì ṣe iṣẹ́ ìyanu rẹ̀ han àwọn ọmọ Israẹli.
Yóo sì mú ọ̀dọ́ àgbò, ọlọ́dún kan tọ alufaa wá fún ẹbọ ìmúkúrò ẹ̀bi.
"Adam Granite to n bojuto ẹka idagbasoke katakara fun ajọ UMG, ni ""a n foju sọna lati ni ajọṣepọ pẹlu Tiwa ati ikọ rẹ lati ran iṣẹ orin kikọ rẹ lọwọ ki o le tan ka gbogbo agbaye tori a rii pe Tiwa ni afojusun to dara""."
   Aṣofin Ọbasa, ti o tun jẹ alaga fun Igbimọ
Ipin idokoowo ileeṣẹ rẹ to n ṣe ọkọ to n lo ina manamana, electric automaker bu igba jẹ gidigidi.
Maloni ati Kilioni náà kú, Naomi sì ṣe bẹ́ẹ̀ ṣòfò àwọn ọmọ rẹ̀ mejeeji ati ọkọ rẹ̀.
Lucas darapọ mọ PSG lati Sao Paulo ni ọdun 2013 ṣugbọn o r'aye gba bọọlu lẹẹmẹfa pere ni akoko yii ati pe wọn ti sọ fun un pe ki o wa ẹgbẹ agbabọọlu miran lati darapọ mọ.
Àkọlé àwòrán, Ipade ita gbangba BBC Yoruba Tabili yii ni wọn maa n tẹ awọn oku Olubadan to ba ti waja si ki gbogbo ara ilu le rii.
Bakan naa ni alaga gbogboogbo fun ẹgbẹ oṣélu PDP, Uche Secondus, ati oludari eto ipolongo ibo fun Atiku, Gbenga Daniel, naa kọwọrin pẹlu rẹ.
Wọ́n tú yàráa Deng Chuabin wò fún bíi wákàtí kan, wọ́n sì gbé ẹ̀rọ 20 àti agbaná sí ara ẹ̀rọ.
Awọn agbalagba tọjọ ori wọn kọja aadọrun ọdun ati awọn oṣiṣẹ ilera ni yoo kọkọ jẹ anfaani abẹrẹ yi lọna ati daabo bo awọn to wa ninu ewu julọ.
Kábíyèsì fẹnu ara rẹ̀ tú àṣírí àwọn Fulani Daran daran tó ń ṣọṣẹ́ nílùú rẹ̀ Ọ̀pọ̀ èèyàn bẹnu ẹ̀tẹ́ lu Mercy Aigbe lórí bó ṣe ki Adeniyi Johnson Díẹ̀ lára àwọn òṣèré Nollywood ti wọ́n ti ṣe ìgbéyàwó lẹ́ẹ̀kejì Orìlẹ-èdè mẹrindínlọgbọn tí ọmọ Nàìjíríá lè wọ̀ láì ní àṣe ìwé ìgbélùú Makoda n kọminu lori ewu to wa ninu airilegbe rẹ nitori bi eto aabo ti mẹhẹ kaakiri orilẹ-ede Naijiria bayii.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Bàyíì ni mo ṣe kílọ̀ fún Donald Trump, àmọ́ kò gbọ́rọ̀ - Primate Ayodele Ajínigbé jí èèyàn méjì gbé l‘Ekiti, Amotekun gba ọ̀kan sílẹ̀ Ṣé o mọ iye òṣèré fíìmù Yorùba àti olórin tó bá ọdún 2020 lọ?
OLUWA ní, “Nítorí pé ẹnu nìkan ni àwọn eniyan wọnyi fi ń súnmọ́ mi,ètè lásán ni wọ́n sì fi ń yìn mí;ṣugbọn ọkàn wọn jìnnà sí mi.
” Ǹjẹ́ nítorí mààlúù ni Ọlọrun ṣe sọ èyí?
Nítorí gẹ́gẹ́ bí ara ti jẹ́ ọ̀kan, tí ó ní ọpọlọpọ ẹ̀yà, bí gbogbo àwọn ẹ̀yà ara ti pọ̀ tó, sibẹ tí ara jẹ́ ọ̀kan ṣoṣo, bẹ́ẹ̀ ni Kristi rí.
 Àwọn ìgbésẹ ̀ yòókù tí a tún lè fi dènà rẹ ̀ ni fífọ-ọwọ ́ àti ṣíṣe oúnjẹ wa ní àṣèjínna .
Amọtẹkun jẹ ọkan lara awọn eto ti awọn ijọba ipinlẹ lẹkun iwọ oorun gusu Naijiria gbe kalẹ lati koju oniruuru ipenija ọrs to n doju kọ awọn eeyan nibẹ.
Àkọlé àwòrán, Ajiboye bẹnu atẹ lu ijọba ipinlẹ Ọyọ pẹlu ẹsun wipe igbese naa lọwọ oṣelu ninu.
Iwin tí kò ní òun ni o ye kí o se Alága ìpàdé àwọn iwin, iwin olórí kan kò gbọ́ràn sí olórí mẹ́wàá lẹ́nu mọ́, ologbo wí pé òun lágbára ju ẹkùn lọ, ggbogbo àwọn ẹyẹ bẹ̀rẹ̀ sii wa sí ọdọ wa ní à
Adari ijọba Joseph Muscat ni nkan buburu ni ikọlu naa.
Awọn ọba maa n saba jo si orin ti won ba lu ilu yii si, ẹlomiran ko le ba ọba jo si, o si maa n safihan ami Dansaki nibi kibi to ba ti jẹyọ.
2) Aisan ọkan: Dr McGinger Ibeneme sọ fun BBC pe nitori ibalopọ a maa mu ki eeyan ṣiṣẹ agbara, eyi le ṣakoba fẹni ba ni aisan kan.
Buhari sọrọ yii mimọ nibi ipade igbimọ alaṣẹ ẹgbẹ osẹlu APC to waye niluu Abuja lọjọ Ẹti.
Ile-ise olopaa lorile-ede Zambia ti fi eniyan méjìlélọ́gọ́rùn ún afehonu han si atimole lojo Aje(Monday), lataari fi fi esun kan ijoba orile-ede ohun pe won ta okan lara ile-ise to gboro lorile-ede fun orile-ede China.
 Àwọn akẹ ́ kọ yìí dínkù dé ìdajì láti 2155 ní ọdún 1998 sí 1999 , látàrí láti ri wípé kí oun èlò fún ẹ ̀ kọ ́ lè tó won .
EFCC fẹ̀sùn kan ọmọ ilẹ̀ Britain méjì EFCC tun gbe Akala yọju sile ẹjọ Bukola Saraki kò kọjá òfin - EFCC Olùdásílẹ̀, akẹ́kọ̀ọ́ iléẹ̀kọ́ Yahoo-Yahoo wọ gàù EFCC Wọn tun fi ẹsun kan an pe, awọn 'ọta' aarẹ Obasanjo nikan lo n doju 'ija igbogun ti iwa ibajẹ kọ.
Ọkàn rẹ̀ ń dá méjì, ó ń rò bóyá òkú ló mọ̀ọ́mọ̀ gba owó lọ́wọ́ òun, èrò m̀íràn sọ sí I lọ́kàn pé, kó lọ, ṣebí àṣìṣe lásán ni owó fi dà sínú kòtò.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Kò sí ìwé ẹ̀rí fun olùdíje tí tó ba wóle lábẹ hílàhílo Bílíọ̀nù kan náírà ni INEC ń san fún CBN àti ọmọogun oju òfurufú Ní'lùú Ilọrin, èèyàn méjì fara gbọta ìbọn Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ìbádọ́gba nínú ìsèlú àti iṣẹ́ láwùjọ ṣe pàtàkì fún ìdàgbàsóké Gomina Ganduje sọ eyi di mimọ lasiko ti o fi n tọwọ bọwe adehun alaafia ni ilu Kano.
“Mo fi Ọlọrun tí ó gba ẹ̀tọ́ mi búra,mo fi Olodumare tí ó mú kí ọkàn mi bàjẹ́ ṣẹ̀rí,
Bí mo ṣe fẹ́ máà bá ìgbádùn mi lọ ni mo fura pé ẹnìkan nbẹ lẹ́hìn mi.
  Awon isele buruku nipa igbesunmomi,ikolu laarin awon agbe ati daran-daran ni awon agbegbe kan lorile ede yii, ni eyi to je pe opolopo emi  ati dukia lo padanu nibe, ni a ti n mujoto bayii, ti a o si rii pe awon odaran ati awon to n se onigbonwo won  yoo  foju wina ofin.
 o je okan ninu ara ile-eko frankfurt irojin awujo bakanna mo max horkheimer , walter benjamin , herbert marcuse , jürgen habermas , ati awon miran .
Tunde Idiagbon, ọ̀gágun kògbagbẹ̀rẹ́ tó ní ẹ̀ẹ̀kan lóṣù ló yẹ kí ológun máa rẹ́rìín Ìtàn ayé Ọba Seriki Abass ti Badagry, tó ní aya 128, ọmọ 144 Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Oyenusi ló mú mi wọ ẹgbẹ́ adigunjalè kó tó di pé mo b'Ólúwa pàdé' Báwo ni obìnrin ṣe ń ní ìtura ìbálòpọ̀?
 a gbódò máa yanjú wàhálà láàrin àwon orílè-èdè pèlú àjosoyépò , kìí se pèlú ogun jíja .
Kini awọn Oluṣọ agutan n sọ?
Aisha Buhari ké sí àwọn aya gómìnà pé kí wọ́n lọ paná ìdàrúdàpọ̀ lágbègbè yín Ta ni ìgbẹ́jọ́ ìbò gómìnà Ondo yóó gbè nínú Akeredolu àti Jegede?
O ò bá mú ẹ̀bi wá sórí wa.
Peter Kofi Sedufia – Sidechic Gang
O ko mọ bi ẹru ọran ti onitọhun da ṣe wuwo to.
“Ọba olókìkí kan yóo wá gorí oyè, pẹlu ipá ni yóo máa fi ṣe ìjọba tirẹ̀, yóo sì máa ṣe bí ó bá ti wù ú.
Ogun Àgbẹ́kọ̀yà, ẹ̀kọ́ wo ló yẹ́ kí àwá ọ̀dọ́ kọ́ níbẹ̀?
Wọ́n rí i pé wọ́n ti yí òkúta kúrò ní ẹnu ibojì.
Ohun tí ọlọ́pàá ń ṣe rèé láti sàwárí àwọn ‘mùjẹ̀-mùjẹ̀’ ní Akinyele Ọwọ́ ọlọ́pàá tún tẹ afurasí tó fipá bá odi àti adití lòpọ̀ nílùú Ibadan Èèmọ̀!
Ènìyàn kán kú, méèje farapa nínú ìjàmbá afárá Otedola ní Eko Àwọn ìbejì mi kò le rìn dáadáa nítorí ọgbẹ́ tí wọ́n dá sí wọn lára ní ìgbèkùn - Akeugbagold Ènìyàn 284 ló ní àrùn Coronavirus ní Ọjọ́òrú ní Nàíjíríà Ààrẹ Buhari ti fi ọwọ́ òsì júwe ilé fún Ọ̀gá Àjọ ìdánwò NECO àti àwọn mẹ́rin míràn Ninu atẹjade kan ti ẹgbẹ naa fi sita, wọn ni ki awọn dokita o pada si ẹnu'ṣẹ wọn laago mẹfa irọlẹ oni.
Lẹ́yìn tí wọ́n ti parí ọ̀rọ̀ tí wọ́n níí sọ, Jakọbu bá fèsì pé, “Ẹ̀yin arakunrin, ẹ fetí sí mi.
Hushpuppi ati awọn iyoku rẹ le lọ si ẹwọn to to ogun ọdun nilẹ Amẹrika, ti wọn ba fi le sọ pe wọn jẹbi awọn ẹsun naa nile ẹjọ.
O mẹnuba iṣẹ akọni ti awọn ọṣiṣẹ eleto aabo gbogbo pawọpọ ṣe ki awọn oniṣẹ ibi ajinigbe to tu awọn ọmọ wọnyii silẹ.
se fun awon omo orile ede Naijiria sẹ.
Nítorí náà, ẹ gbọ́ ohun tí OLUWA wí,ẹ̀yin oníyẹ̀yẹ́ eniyan,tí ẹ̀ ń ṣe àkóso àwọn eniyan wọnyi ní Jerusalẹmu.
Oríṣun àwòrán, @82ndBigCountry Atiku pari ọrọ rẹ pe eto ilera Naijiria ko munadoko debi ti yoo le tọju awọn to ba lugbadi arun naa.
1–6, Àwọn òṣìṣẹ́ nínú ọgbà àjàrà yíò gba èrè ìgbàlà; 7–9, Gbogbo ẹnití ó bá fẹ́ tí wọ́n sí kún ojú òsùnwọ̀n lè ṣe ìrànlọ́wọ́ nínú iṣẹ́ Olúwa.
Ko si ofin to de yiya Tatuu si ara rẹ ṣugbọn o ni gbendeke asiko ti o gbọdọ fi duro koo to le fi ẹjẹ silẹ.
Kí ó má ṣe jẹ́ pé nígbà tí mo bá dé ni ẹ óo ṣẹ̀ṣẹ̀ máa gba ọrẹ jọ.
Ni oju opo Twitter ibeere ti awọn eeyan n bere ni pe kini iyato to wa laarin SARS ati FSARS ati wipe ṣebi FSARS lorukọ ti wọn ti n jẹ latilẹ tẹlẹ ri?
“Bí ẹnìkan bá ṣá aládùúgbò rẹ̀ lọ́gbẹ́, irú ọgbẹ́ tí ó ṣá aládùúgbò rẹ̀ gan-an ni wọn yóo ṣá òun náà.
Ṣọra fun awọn agbegbe ti ero ba pọ siBi o tile jẹpe ọpọlọpọ awọn eniyan lo ma n lo gbafẹ ni eti okun, O pọn dandan lati yago fun ibi ti ọpọ ero ba wa, eleyii ti o mu ki arun Coronavirus tete ranlẹ si nitori awon to sunmọ ara wọn pẹkipẹki.
Yatọ si orin kíkọ, Chamillionaire tun jẹ onileeṣẹ adani ati gbajumọ oloko-owo to dantọ, to si jẹ amuyangan fun iran Kaarọ Oojiire.
Ninu awọn ifẹsẹwọnsẹ to ti waye ni abala to kangun si aṣekagba idije naa,awọn agbabọọlu kan ti pitu ti wọn si yii oju esi ifẹsẹwọnsẹ pada bi ẹni pidan.
Ajínigbé ń bèèrè fún epo, iṣu àti ọ̀tí Schinap gẹ́gẹ́ bí owó ìtanràn 'Ẹ má ṣi Fayemi túmọ̀ lórí àṣẹ tó pa nípa sísọ èdè Yorùbá' Wo ipò tí Buhari fún Faṣọla, Lai Mohammed, Saraki àti bẹ́ẹ̀ bẹ́ẹ̀ lọ Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Iwa ọdaran paraku ni iwa ipa ninu ile ko si si ọwọ miran lati fi muu ju ọwọ lile lọ.
23 Ìgbé 2020 Fídíò, Nigeria movie industry: Àgbà òṣèré, Lere Paimo ní àìgbọràn ló ń da ọ̀pọ̀lọpọ̀ àwọn òṣèrè sinimá láàmú11 Ọ̀wàrà 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Ẹsun mẹta to ni i ṣe pẹlu ole jija, ipaniyan ati nini nkan ija oloro lọna aitọ ni wọn fi kan wọn.
Ajafẹtọmọniyan yi to lewaju paapa ni ile ijọba ni Eko wa lara awọn to kọkọ gbe igba iwọde ki awọn gbajumọ mii to wa darapọ mọ wọn.
Ó ba dè mí bí ẹranko ìjàkùmọ̀,ó lúgọ bíi kinniun,
Nínú àtẹjáde ti kan ti ilé iṣẹ́ tó ri si ọ̀rọ̀ ilẹ̀ òkèrè ni Nàìjíríà fi síta pe ilẹ Amẹrika ti yọ owó gọbọi ti wọ́n fi le owo físà fáwọn Nàìjíríà kúrò.
Bakana sini ireti wa wipe igbesẹ naa yo se ayipada amojuto igbokegbodo ọkọ nipinle ọhun.
Nígbà tí mo ka ìwọ̀nyí tẹ̀lé iwin tí o ṣe ìgbéyàwó náà fún ni tán.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Cerebral Palsy: àrùn tó n gba omijé lójú ẹni láìnídìí Bi Egypt ṣe bori lati kopa lẹyin ti idije ẹlẹgbẹjẹgbẹ ni wọn gba akọnimọọgba ọmọ Mexico naa ko le wa wọn de ebute ogo nipa gbigba ife ẹyẹ AFCON.
E̩nì kò̩ò̩kan ló ní è̩tó̩ láti gbé ìgbé ayé tó bójú mu nínú èyí tí òun àti e̩bí rè̩ yóò wà ní ìlera àti àlàáfíà, tí wo̩n yóò sì ní oúnje̩, as̩o̩, ilégbèé, àti àn fàní fún ìwòsàn àti gbogbo ohun tó lè mú è̩dá gbé ìgbé ayé rere.
Iye ìgbà tí ọrọ̀ ajé Nàìjíríà ti dẹnukọlẹ̀ lábẹ́ ìjọba ààrẹ Buhari Òtítọ́ làwọn sọ́jà gbé ìbọn tó lọ́ta gidi nínú lọ sí Lekki Toll Gate lásìkò ìwọ́de EndSARS- Ọ̀gágun Taiwo Wòlíì míì, tún wọ gàù lẹ́yìn tó tàpá sí ìlànà béèlì tí wọ́n fún un nílé ẹjọ́ Ṣé Sanwo-Olu, gómìnà Eko yóò farahàn níwájí ìgbìmọ̀ olùwádìí ìṣẹ̀lẹ̀ Lekki Tollgate?
Àwọn ọmọ Amramu ni Aaroni ati Mose.
"Tope ni ""Mo ti tọrọ aṣọ àti yẹtí rí nígbà kan láti fi yà fídíò orin mi, àwọn èèyàn kan sì wà tó jẹ́ pé, isẹ wọn ní lati maa tàbùkù mi nítorí ìbẹ̀rẹ̀ mi, àmọ́ mo fi ìdájọ́ wọn si ọwọ Ọlọ́run."
O wa ro awon omo orile-ede Naijiria lati tuyaya-tuyaya sita gbaruku ti aare Buhari lati jawe olubori ninu eto idibo gbogbogbo to n bo lona lọdun 2019.
Makinde ṣe agunbanirọ ni ile iṣẹ epo Shell lọdun 1990, lati ibẹ lo ti bẹrẹ iṣẹ nipa biboju to oniruuru ẹka ile iṣẹ epo naa.
Akoba fun eto oro ajeDakingari tun daruko oko miiran kan, ti o  ko iresi sinu apo gbado ,ni eyi ti won tun gba sile.
Àwọn ọmọ ń ti ara wọn síhìn-ín sọ́hùn-ún ninu rẹ̀, ó sì wí pé, “Bí ó bá jẹ́ pé báyìí ni yóo máa rí, kí ni mo kúkú wà láàyè fún?
Lori ipade awọn gomina ilẹ Yoruba lori ọrọ aabo ti wọn ba Buhari sọrọ le lori, Odumakin ṣalaye pe, ipade ẹ̀tàn ni wọn n ṣe.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Èmi ni afunfèrè àkọ́kọ́ lágbo eré KWAM 1 ní 1983' O ni pẹlu oogun abẹnugọngọ, awọn lee lo ọpa lai si ibọn tabi ọ̀kọ̀ lati dẹkun gbogbo ero inu awọn ajiinigbe.
 Gẹgẹ bi o se sọ, o ni “Ipinnu yii ko ni fẹsẹmulẹ , nitori yoo je
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Yaa Asantewaa: Ti ẹyin ọkunrin Ashanti kò bá tẹsiwaju, awa obinrin yóò lọ Alaafin Majẹogbe tiẹ lo ọdun kan soso pere lori itẹ, ki Basọrun Gaa to ran an sọrun ọsan gangan Lọdun 1774 ni Alaafin Abiọdun gori itẹ, to si n wọna bi yoo se rẹyin Basọrun Gaa.
Àwọn ìjọba ológun wá sọ ìṣèlú ilẹ̀ Afirika di pàsí-pàrọ̀.
Ẹ̀dá ńlá yìí sì bẹ̀rẹ̀ sí jà ṣùgbọ́n ibi tí ó ti ń ṣe èyí ni gbogbo ìfun rẹ̀ ti jáde tí gbogbo ilẹ̀ kún fún ẹ̀jẹ̀, ìṣẹ̀lẹ̀ sì ṣẹ̀ láàárin àwọn èjó wọn-ọnnì.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù OsunDecides: Olùdíje fún igbákejì gómìnà fẹ́gbẹ́ ADC ní àwọn yóò pèsè ọ̀pọ̀ isẹ́ l‘Ọ́sun Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ OsunDecides: Olùdíje fún igbákejì gómìnà fẹ́gbẹ́ ADC ní àwọn yóò pèsè ọ̀pọ̀ isẹ́ l‘Ọ́sun 20 Owewe 2018 Adájọ́-fẹ̀yìntì Ọlamide Oloyede, tíí se olùdíje fún ipò igbákejì gómìnà fẹ́gbẹ́ òsèlú ADC l‘Ọ́sun, lásìkò tó ń bá BBC Yorùbá sọ̀rọ̀ ní, ìgbìnyànjú òun ni láti máa pe àkíyèsí àwọn olórí sí ẹ̀jẹ́ tí wọn jẹ́, láti mú ìgbáyé-gbádùn bá ará ìlú.
Awọn ami to wọpọ ni: Ẹjẹ to ba n jade lasiko nkan oṣu yoo pọ ju bo ṣe yẹ.
Oluwatobiloba ni tirẹ ṣe katakata to maa n ko nnkan lati ibikan si imiiran, nigba ti Fathia ṣe ẹrọ to n maa kaṣọ.
Akọwe igbimọ to n ṣe aayan idibo abẹnu naa, Ajibọla Bashiru ṣalaye fun ileeṣẹ mohunmaworan abẹle kan lọjọ Aiku pe yẹkini kan ko ni yẹ eto naa.
N óo wá sọ fún ọkàn mi pé: ọkàn mi, o ní ọ̀pọ̀ irè-oko tí ó wà ní ìpamọ́ fún ọdún pupọ.
Ohun tí ó wà lọ́kàn wọn ni wọ́n ń sọ.
Láti ìjẹta tí mo ti de síhìn-ín lo ti bẹ̀rẹ̀ síi náwó fún mi, òun àti ìyàwó rẹ̀ kò tilẹ̀ jẹ ki n mọ̀ pé mo kúrò nílée rárá, nítorí náà, mo fẹ́ kí ẹ bá mi dúpẹ́ lọ́wọ́ wọn dáadáa.
Àwọn tí ó bá sì ṣe àfojúdi yóo forí ara wọn gba ìdájọ́.
 nri ati aguleri , nibi ti itan ariso ida igbo ti bere , wa ni agbegbe iran umueri , awon ti won so pe iran awon de ile oba eri fun ra re .
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Rice Subsidy: Ìjọba àpapọ̀ gbé ₦60bn kalẹ̀ bíi owó ìrànwọ́ 17 Bélú 2018 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Rice Subsidy: Ìjọba àpapọ ṣétàn láti yá àwọn àgbẹ̀ ìrẹ̀sì lówó Mínísítà feto ọ̀gbìn, Audu Ogbeh ní ìjọba àpapọ̀ tí buwọ́lu ọgọ́ta bílíọ̀nù náírà gẹ́gẹ́ bíi owó iranwọ fún ìpèsè ìrẹsì ní orílẹ́-èdè Nàìjíríà.
Ní ọjọ́ náà gan-an ni ọba Ahasu-erusi fún Ẹsita Ayaba ní ilé Hamani, ọ̀tá àwọn Juu.
Fún mi ni èso àjàrà gbígbẹ jẹ,kí ara mi mókun,fún mi ní èso ápù jẹ kí ara tù mí,nítorí pé, àìsàn ìfẹ́ ń ṣe mí.
”Yari so pe“ mi o mo idi ti ajo EFCC se gbe iru igbese yii, mi o lero pe iru igbese yii  dara rara.
“Isà òkú ti lanu sílẹ̀ láti pàdé rẹ bí o bá ti ń dé.
O ní gbogbo àwọn ọ̀dọ́mọkurin náà ló fí àwọn boju pélù àwọn ohun ìja tó bani lẹ́ru.
Ìdí tí ìjóba ìpínlẹ̀ Eko fí ṣí àwọn ilé ìwé kan padà Èèyàn 290 míràn ló ṣẹ̀ṣẹ̀ fara káásá àrùn Covid-19 ní Nàìjíríà, 160 gbàwòsàn Baba Obasanjọ kò ní àrùn Coronavirus- NCDC Ìdí rèé tí igbákejì Gómìnà Ondo Agboola Ajayi tún ṣe fi ẹgbẹ́ òṣèlú PDP sílẹ̀ Wọ́n ti sún ọjọ́ ìjà Mike Tyson pẹ̀lú Roy Jones Jr síwájú Oríṣun àwòrán, Getty Images Saaju ni ijọba ti kọkọ sọ eyi ṣugbọn ohun gbogbo ti yipàda, idanwo WAEC di ṣiṣe.
Oríṣun àwòrán, other Laipẹ yii ni Aarẹ Buhari paṣẹ fun awọn oṣiṣẹ lasiko ti oun ṣe ipade pẹlu wọn lati ri pe wọn yanju ọrọ naa pẹlu minisita fun eto ẹkọ lorilẹede Naijiria, Adamu Adamu.
Lẹyin idibo 2019, orilẹede naijiria ni yoo si papa bori lai naani ẹgbẹ oselu to moke tabi fidi rẹmi.
"Awọn to n ṣiṣẹ lati ile ti inu wọn o dun ni lati ronu jinlẹ daadaa pe ibo lo ku si ti wọn fi n ṣaaro ọfiisi.
Ninu atẹjade ti ajọ to n mojuto iṣẹlẹ pajawiri nilu Eko fi sita lorukọ ọga agba Femi Osanyintolu, wọn ni epo bẹntiro ni ọkọ naa gbe lasiko to dẹgbẹ lulẹ.
Ohun tí ẹ fẹ́ ṣe yìí kò ní yọrí sí rere.
Afi bi awada bi ere ni ifẹsẹwọnsẹ naa bẹrẹ ti Sheffield ba gbayo akọkọ wọle Chelsea.
Igbesẹ yii wa lati fun awọn ti ọrọ kan laaye lati dasi ohun ti Naijiria yoo gbe se lori ilana adehun naa.
“Ṣugbọn ní tiwa, OLUWA Ọlọrun ni à ń sìn; a kò kọ̀ ọ́ sílẹ̀.
Ikú akọni ni n ó kùú
Èmi náà fẹ́ràn orin yìí púpọ̀ láti ọwọ́ olóògbé Sikiru Àyìndé Barrister.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù HIV Patients: N kò ní ìbálòpọ̀ rí kí ń tó ní HIV 4 Agẹmo 2019 Àkọlé àwòrán, Brian Omondi sọ pe ko rọrun lati ni ọrẹ tabi ololufẹ nitori aarun HIV Brian Omondi, ti wọn bi pẹlu aarun HIV, bẹrẹ si ni lo akanṣe oogun fun aarun naa, anti-retroviral (ARV) nigba to wa ni ọmọ ọdun mẹwaa.
Nàìjíríà na Equatorial Guinea ní 6-0 Ògbóntarigì agbábọ́ọ̀lù Nàìjíríà, Asisat Oshoala wẹ̀ 'yan kàìn-kàìn nígbà tí ikọ̀ agbábọ́ọ̀lù Nàìjíríà na Equatorial Guinea pẹ̀lú àmì ayò 6-0.
Ṣaaju ni ileeṣe naa ti kọkọ ka jale lati ga beeli wọn lẹyin ti wọn ni iwa ti wọn wu le yọri si iburẹkẹ arun naa lorilẹ-ede ọhun.
láàrin ọdún 1973 - 5 ni àwọn àyípadà díẹ ̀ bẹ ̀ rẹ ̀ sí ní dé bá àwọn adúláwọ ̀ tí ó wà lábẹ ́ ìjọba brazil .
 ní àwọn orílẹ ̀ èdè tí ó ṣẹ ̀ ẹ ̀ ṣẹ ̀ ń gbèrú ìdá 90 % àwọn ọmọdé ni o tiní àkóràn ní ọmọ ọdún 10 wọn kòsì le ni mọ ́ ní àgbà .
Ẹgbẹ naa ni bi nkan ṣe wa lasiko yii, o fẹrẹẹ ma le tii si aaye fun awọn ile iwe giga ijọba lati tẹle ofin ijinasiraẹni.
'A ò lè ṣọ dájú pé èèyàn 66 ló kú ní Kaduna - Iléeṣẹ́ ọlọ́pàá, NEMA Ṣé o fẹ́ lọ sí Canada?
Amọṣa ni bayii, Bobrisky ti ni oun yoo fun Tacha ni miliọnu kan naira.
Ní àkókò tí ó jọba ni OLUWA bẹ̀rẹ̀ sí rán Resini, ọba Siria, ati Peka, ọmọ Remalaya, tí í ṣe ọba Israẹli, láti gbógun ti Juda.
Ibanuje d'orí agbà k'odò, Ruiz fi ẹ̀ṣẹ́ sọ Anthony Joshua di ọmọ ológo àná Liverpool da ata gúngún sójú Tottenham gba ife ẹ̀yẹ Champions League Ọ̀fọ̀ ṣẹ̀ lágbo eré bọ́ọ̀lù, Reyes to gbá bọ̀ọ́lù fún Arsenal rí jáde láyé Donald Trump ti pàdé Ọbabìnrin Elisabeth tilẹ̀ Gẹ̀ẹ̀sì Ilé wó pa Jide, ọmọ ọdún mọ́kànlá, l'Oṣogbo Ibrahima Niane fọba le fun Senegal ni iṣẹju to kẹyin ni ipele akọkọ ere bọọlu naa, lo ba bi ami ayo meji sodo.
 Awon nnkan wonyi lo jemi logun.
Ninu awọn gbajumọ to gbalafẹ nilu Eko lasiko aye rẹ, ko fẹrẹẹ si ẹlẹgbẹ Israel Adebajo.
Ninu ọrọ kan to sọ fawọn ọmọ ijọ rẹ lo ti ṣalaye ọrọ yii.
Jesu wí fún wọn pé, “Mo fẹ́ kí ẹ mọ̀ dájúdájú pé, kì í ṣe Mose ni ó fun yín ní oúnjẹ láti ọ̀run wá.
Ǹjẹ́ bí ìṣìnà wọn bá ṣe ayé ní anfaani, bí ìkùnà wọn bá ṣe orílẹ̀-èdè yòókù ní anfaani, báwo ni anfaani náà yóo ti pọ̀ tó nígbà tí gbogbo wọn bá ṣe ojúṣe wọn?
O sọ pé, “Mo ti dá majẹmu kan pẹluẹni tí mo yàn,mo ti búra fún Dafidi, iranṣẹ mi, pé,
Ṣé èmi wá jẹ́ bí olùṣọ́ àbúrò mi ni?
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ìpínlẹ̀ Oṣun kò nílò Gómìnà oníjó - Oshiomole Ọ̀rọ̀ LAUTECH gba àpérò f'áwọn Olúdíje Ọṣun Olórí ilé asòfin l‘Ọ́sun pàdánù N38m sọ́wọ́ gbájúẹ̀ Àwọn ohun tó yẹ kó o mọ̀ nípa Adémọ́lá Adélékè Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, OsunDecides: Omisore ní ẹni tó bá fẹ́ ra ìbò, àwọn yóò lọ lásọ mú ni Igba to ku bii ọsẹ kan si idibo ni wọn wa san diẹ lara owo yin."
Gbogbo nǹkan yòókù tí Sakaraya ṣe ni a kọ sinu Ìwé Ìtàn Àwọn Ọba Israẹli.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ibadan Tailor: Ilé-ẹjọ́ dá ẹjọ́ lòdì sí ìwà ọ̀gá ọlọ́pàá sí télọ̀ rẹ̀ 4 Bélú 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 18 Bélú 2020 Oríṣun àwòrán, Oyo Insight Ileẹjọ majisreeti to wa lagbegbe Iyakangu niluu Ibadan ti yi ẹjọ ti ọga ọlọpaa DPO, CSP Alex Sani Gwazah pe telọ kan, Lukman Adeniyi danu.
Bákan náà ni ilé iṣẹ́ BBC bèrè pé ṣe wọn ti pe Akinwumi Ambode fún ìfọ̀rọ̀wánilẹ́nùwò súgbọn ọgbẹ́ni Orilade ní Ambode mọ pé àwọn ń ṣe ìwádìí lọ́wọ́.
Wọn ni awọn ṣi n wa awọn to ku ti iwadii ṣi n tẹsiwaju.
“N óo fun yín ní alaafia ní ilẹ̀ náà, ẹ óo dùbúlẹ̀, kò sí ẹnìkan tí yóo sì dẹ́rùbà yín.
tun di ipo ti won wa tẹlẹ mu gẹgẹ bi igbakeji oludari omo egbe oselu to kere
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ọgbà ẹ̀wọ̀n ni wọ́n ti já àbálé Esra lábẹ́ àwáwí àyẹ̀wò wúndíá O rọ ileẹjọ lati bawọn yanju aawọ to wa laarin nitori oun si nifẹ ọkọ oun bo tilẹ jẹ pe ko nifẹ oun.
Ojú ọ̀nà ni a óo máa tọ̀, a kò ní yà sí ọ̀tún tabi òsì títí tí a óo fi kọjá ilẹ̀ rẹ.
Wọn yóo gbógun tì ọ́, ṣugbọn wọn kò ní ṣẹgun rẹ.
Ǹjẹ́ ọmọ Buhari lásẹ láti wọ Ọkọ̀ òfúrufú Nigeria Air force 1 lọ sí òde?
8 313688 Orilẹede Tunisia 3758 32.
O ni igbasoke awọn ayanfẹ yoo ṣẹlẹ lọjọ naa idajọ yoo si waye lẹyin oṣu mẹfa iyẹn ọjọ kọkanlelogun, oṣu kẹwaa.
Fayemi, lasiko to n sọrọ lori ajọṣepọ rẹ pẹlu gomina tẹlẹ ni Ekiti, Segun Oni, o ni ko si aawọ laarin oun ati Oni, ti ọpọ awọn to n tẹle gomina ana naa si wa ninu ijọba oun.
Ọlọrun Ológo farahàn fún baba wa, Abrahamu, nígbà tí ó ṣì wà ní ilẹ̀ Mesopotamia, kí ó tó wá máa gbé ilẹ̀ Kenaani.
Wọ́n gbéra, wọ́n lọ sí agbègbè olókè náà, títí tí wọ́n fi dé àfonífojì Eṣikolu, tí wọ́n sì ṣe amí rẹ̀.
Kii ṣé dandan kí Alalaaji gún orí òkè Arafat ko to kópa nínú isọri isẹ yii.
Rashida Adamu maisa'a isa ferushkan 157.
Ẹ̀rí ọkàn wọn ń ṣiṣẹ́ ninu wọn: àwọn èrò oríṣìíríṣìí tí ó wà ninu wọn yóo máa dá wọn láre tabi kí ó máa dá wọn lẹ́bi, 
Eto wa nilẹ lori bi awọn ile ẹkọ ni ilẹ Gẹẹsi yoo se bẹrẹ si ni si pada losu to n bọ.
Jennifer Creery ni ẹni tí ó kọ ìròyìn yìí, tí Ilé Iṣẹ́ Atẹ̀wé Olómìnira Hong Kong sì tẹ̀ ẹ́ jáde ní ọjọ́ 24 oṣù Èbìbí ọdún-un 2019.
O ni ko sẹni to mọ pé iku ti fẹ mu akẹkọọ jade fasiti ti ilu Benin ti a mọ si UNIBEN naa lọ lọwọ ibọn SARS laiṣẹ.
 Iru ilana yii ṣaa ni wọn lo ni aye ijọba awọn Awolọwọ, ti wọn fi aaye gba awọn ọba lati lọwọ ninu oṣelu ilu, ti nnkan si tuba tuṣẹ ni asiko naa”.
Ọpọ awọn eeyan jankan nilẹ Yoruba lo si peju sibi ifilọlẹ ọhun.
 lẹ ́ yìn ọ ̀ sẹ ̀ díẹ ̀ sí oṣù díẹ ̀ , ipele kejì a má a bẹ ̀ rẹ ̀ pẹ ̀ lú àìmọ ohun tí ènìyàn ńṣe mọ ́ , àìlèronú bí ó ti tọ ́ , àìlègbé ọwọ ́ tàbí ẹsẹ ̀ , àti àìrí oorun sùn .
Gẹ́gẹ́ bo ṣe sọ oni aluṣẹkẹrẹ oun lágbo ere lo n jẹ orúkọ náà, sùgbọ́n ko nífẹ si orúkọ náà o si maa n bá àwọn èni[yàn ja nítori rẹ.
n ba awon akoroyin soro ni ipinle Kaduna leyin ipade ti o se pelu gomina naa, Nasiru
Máfọ́, mo wà pẹ̀lú ẹ, Ajimọbi kàn sí Makinde lóri Coronavirus to ni Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Coronavirus: Ǹjẹ́ fífi omi àti iyọ̀ yọnu leè dènà àrùn Coronavirus?
Ni ẹnu ọna abawọle ọgba fasiti Ibadan, ta gbọ pe awọn oluwọde ọhun yoo ti gbera, se ni awọn agbofinro ji de adugbo naa, ti wn si duro wa wa wa sibẹ.
 O maa n sakoba fun eto ogbin atawon eso to wa nile ni.
Bo tilẹ jẹ wi pe awọn ti wọn fi ẹsun kan sọ pe bẹẹkọ.
Ṣugbọn Ọlọrun sọ fún Labani ará Aramea lóru lójú àlá, ó ní, “Ṣọ́ra, má bá Jakọbu sọ ohunkohun, kì báà jẹ́ rere tabi buburu.
Zainab ni o jẹ minista abẹle fun eto iṣuna ati ilana aatẹle fun ijọba apapọ lọdun 2015.
Eyi ti sun iye awọn to ti lugbadi arun naa siwaju di ẹgbẹrunlenigbalemẹtalelaadọrin.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ti o bá dá ara ẹ lójú, ki ẹni tó n ṣe irun kí n gbọ́?
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Owó ìrànwọ́ Covid-19 dé, ìjọba fẹ́ san ₦75bn fún 54,000 olókoòwò Ìjọba ìpínlẹ̀ Eko ti iléèwé pa nítorí ìwọ́de #EndSARS Ìrẹ̀wẹ̀sì ń bá wa torí ìdánwò NECO tẹ ń ṣún síwájú lọ́pọ̀ ìgbà - Akẹ́kọ̀ọ́, ọ̀gá iléèwé Agbára ìgbìmọ̀ ìdájọ tí mo gbé kàlẹ̀ yóò dé ọ̀dọ̀ àwón ólọ́pàá tó ti kúrò lẹ́nu iṣẹ́ tẹ́lẹ̀- Sanwo Olu Wo àwọn orílẹ̀èdè míràn tó ń fojú winá ìwọ́de bíi ti ENDSARS Mo fura pé ẹ fẹ́ da Nàíjíríà rú, ń kò ṣe ìwọ́de mọ́ - Segalink, agbátẹrù ìwọ́de yọwọ́ SERAP pe Buhari, igbákejì rẹ̀ lẹ́jọ́ lórí àfikún owó iná àti epo bẹntiró Bakan naa lo tun kan sara si ipinnu awọn oluwọde naa, to si bẹnu atẹ lu awọn janduku to n da omi alaafia Naijiria ru.
Bẹ́ẹ̀ ni wwọ́n la inú ẹja tí wọ́n tún bá ẹja, ti wọn tún la inú ẹja tí eọ́n bá ejò, tí wọ́n la inú ejò tí wwọ́n bá ẹranko, tíi wọ́n la inú ẹranko tí wọ́n bá ẹja, tí wọ́n la inú ẹja tí wọ́n ba ọ̀mùtí ènìyàn tí ó ku giliti bí olójúkòkòrò tí o ń lẹ́pa ohun ìní ọmọnìkejì rẹ̀ tí ó sáré tí ó sáré títí tí ó fi ojú gún igi.
 Ó gba dókítà amòfin ní unifásíti ' ́ gúsù kalifónìa , los ánjẹlísì .
Iṣẹ Garri yiyan nilo agbara ati ọpọlọpọ iṣẹ gẹgẹ bi Felicia ati awọn akẹgbẹ rẹ to ku ṣe n ṣe e ni ibudo yii.
Ẹni to bori: Uganda Ìpele to ṣaaju eyi to kangun si aṣekagba Tanzania vs Namibia.
Aare Buhari ki gbogbo oludije  fun ise ribi-ribi ti won se lati dije fun ipo gomina naa, o wa ro won lati tubo di opo egbe naa mu , ki ina egbe naa to n jo maa se lo seyin, ki won si tun fowosowopo lati sateleyin fun oludije ti  egbe yan  lati dije ninu ibo to n bo .
Bo tilẹ jẹ pe iṣẹ wọn ni lati da awọn eeyan lara ya, akoko naa tun pese anfani lati wo ere idaraya funrawọn.
Iwadii inu Plos Biology fihan pe kokoro to wa ninu ẹnu lee fa aisan sara erigi ati eyin eyi to lee fa BV.
Ìdí tí mi ò fi lè parí ìjà pẹ̀lú Ààrẹ Ọ̀nà kakanfò, Gani Adams - Obasanjo Olorì Aláàfín tẹ́lẹ̀, Anuoluwapo Adeyemi gba àmì ẹ̀yẹ lórí ipa tó kó nínú oge ṣíṣe Mi ò ṣe ẹ̀tánú Ọọ̀ni ilé Ifẹ̀, ọmọ ìyá mi ni ṣùgbọ́n.
Ẹ óo máa rú ẹbọ yìí pẹlu ẹbọ ohun jíjẹ ati ẹbọ ohun mímu rẹ̀, gẹ́gẹ́ bí ìlànà ọjọ́ kinni; 
Ọjọ Abamẹta, ọjọ Kẹrindinlogun, oṣu Keji lo yẹ ki eto idibo aarẹ ati tile aṣofin o waye, ṣugbọn ajs INEC sun un siwaju.
Doegi, olórí darandaran Saulu, ará Edomu wà níbẹ̀ ní ọjọ́ náà, nítorí pé ó ń jọ́sìn níwájú OLUWA.
aare ti pasẹ pe ki ise akanse  bẹrẹ lori eto oko oju irin, ki o to di osu kejila odun yii, ẹ maa jẹ ki awon eniyan tan yin jẹ.
Bákan náà ni bí ènìyàn bá muti tabi jale, ìdájọ Sharia ni wọ́n yóò dájọ́ fún irú ẹni bẹ́ẹ̀.
Nitori naa, kẹyin ololufẹ rẹ maa mura silẹ.
Ile-ise olopaa ati iko omo Ologun gbodo wa ni ipinle Ekiti.
To si tun kopa nibi ayẹyẹ naa to waye nilu Abuja.
”Ọba dáhùn pé, “Eniyan dáradára ni, ìròyìn ayọ̀ ni ó sì ń mú bọ̀.
Ègún ni fún ẹni tí ó yọ̀ fún baba mi,tí ó sọ fún un pé,“Iyawo rẹ ti bí ọmọkunrin kan fún ọ,tí ó mú inú rẹ̀ dùn.
O ni ohun to panilẹrin ni iroyin eke naa nitori pe Dapọ Abiọdun gan lo jẹ eeyan kan gboogi to ta ọpọ awọn ohun ija naa, paapa awọn ọkọ ijagun .
"Diẹ lara awọn iroyin manigbagbe to waye laarin ọdun kan naa niwọnyii: Ifọrọwanilẹnuwo pẹlu ọjọgbọn Wọle Soyinka Ọkan pataki lara awọn iroyin to waye ni ifọrọwanilẹnuwo kan pẹlu agba ọjọgbọn, Wọle Soyinka, nibi to ti pariwo pe ""Ti mo ba dara pọ m'ẹgbẹ Ọbasanjọ, wọn gbọdọ yẹ mi lọpọlọ wo"" Iroyin yii di itẹwọgba kaakiri agbaye bi ọmọ tuntun."
Báyìí ní apá kan tí ó ṣe pàtàkì ní ìgbésí-ayé bàbá mi parí.
Ṣugbọn, ìwọ ní tìrẹ, dúró gbọningbọnin ninu àwọn ohun tí o ti kọ́, tí ó sì dá ọ lójú.
Eyi wa da lori ti ija mii ba waye laarin wọn, to si bori.
Lọjọ Aiku to kọja ni awọn alufaa naa ṣe abẹwo ọhun si ijọ Commonwealth of Zion Assembly.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ẹ̀bùn ọdún tuntun tó yááyì ni ikọ̀ Amotekun - Soyinka Ẹ̀yin gómìnà Yorùbá, ẹ gbé òfin kalẹ̀ láti ti Amotekun nídìí, kí àròyé leè dópin - Falana Ìbẹ̀rù nípa Amotekun ló ń mú káwọn èèyàn kan máa wí ìwíkùwí - Soyinka Ẹ̀yin gómìnà Yorùbá, ẹ gbé òfin kalẹ̀ láti ti Amotekun nídìí, kí àròyé leè dópin - Falana Ilu ti ko ba si ofin, ẹsẹ ko si nitori naa, ni ilumọọka agba amofin nni, Femi Falana se n ke tantan tan fun awọn gomina lẹkun iwọ oorun guusu Naijiria pe, ki wọn fi ofin gbe idasilẹ eto Amotekun nidi.
“Ṣugbọn ní ọjọ́ tí Gogu bá gbógun ti ilẹ̀ Israẹli, inú mi óo ru.
Dárúkọ àwọn tọ ń gbaṣẹ́ lọ́wọ́ NDDC tàbí kí o fojú winá òfin- Gbajabiamila sọ̀kò ọ̀rọ̀ sí Akpabio Isa Funtua, Abba Kyari, Zulaihat Buhari àwọn tó súnmọ Aàrẹ tó papòdà láìpẹ́ O ni ohun to ba wu ẹlẹnu ni ko maa fi ẹnu wọn sọ, amọṣa, Kabiyesi Alaafin ko dagba ju fun oun lati fẹ.
Alaga igbimo alamojuto naa to tun je omo egbe ajo awon akosemose onimo ero ni Naijiria, COREN, Ogbeni Ose Ochoga se ileri lati se aown ofin amuye ti ko ni le ju ara lo.
Dafidi bá pe àwọn ará Gibeoni, ó sì bi wọ́n pé, “Kí ni ẹ fẹ́ kí n ṣe fun yín?
Kò sí ẹni tí yóo fọwọ́ kàn ọ́ láti ṣe ọ́ níbi.
Gbogbo àwọn tó sọ̀rọ̀ nípa ọ̀jọ̀gbọ́n Adesanmi pẹlu BBC Yoruba sàlàyé pé, oloogbe naa jẹ ẹni ti a n pe ni olùfẹ ọmọ ènìyàn, ẹni to fẹ́ràn ará ìlú ti kìí fi ti ẹya ṣe.
Ijoba orile ede Naijiria ti ni ohun ko ni kaare lati tubo maa gbogun ti iwa ibajẹ lawujo.
Independence Day Nigeria: Ọ̀kọ̀ọ̀kan àwòrán mẹ́fà yìí ló dúró fún ọdún mẹ́wàá ìtàn ilẹ̀ wa
naa ti gbe igbesẹ ti o le lati, “Daabo bo awon ala orile ede yii, ki aabo lee
Nínú fárán ti ẹni kan ti ọ̀rs náà ojú rẹ̀ fi lede ni a ti rí bi ọkunrin náà ṣe àti Bobrisky ṣe wọdimu lẹ́yìn ti ọ̀kunrin náà la fóònù Bibrisky mọlẹ ti oun náà si fi ìbinu mú fóònu ọkún oun.
, ti oju opo itakun agbaye awọn to da a silẹ ko si ṣiṣẹ mọ di asiko yii.
Iroyin sọ pe irisi awọn to wa lahamọ yii jọ ti awọn ti ko ri itọju rara ti ko si rounjẹ jẹ fun ọpọlọpọ ọjọ.
Akoko kan wa ti wọn bi leere pe kí lo de ti kii rẹrin, amọ idahun rẹ ni pe ẹẹkan lọdun lo yẹ ki ologun maa rẹrin.
Nigba ti BBC Yoruba beere lọwọ rẹ boya o ṣi n ṣe ere sinima,Yemi Ayebọ sọ pe ''oun ko fi igba kan fi sinima lọrun silẹ' Ibi tí àwọn àwàdà Okunnu ti bẹ̀rẹ̀ rèé Iṣẹ́ ọpọlọ ló yẹ ká ṣe nínú tíátà, kìí ṣe àfihàn ara bíbó àbí ìhòòhò wa - Binta Mọgaji Kunle Afolayan, òṣìṣẹ́ báńkì tẹ́lẹ̀ kó tó di gbajúgbajà òṣèré Oríṣun àwòrán, Yemi Ajebo ''Ninu igbagbọ temi,ki eeyan ma han ninu sinima ni gbogbo igba ko tumọ si pe ere to n gbe jade ni ẹkọ tawn eeyan le kọ'' O tẹsiwaju pe ''bi eniyan ba ni sinima kan laarin ọdun mẹta awọn eeyan ko ni gbagbe rẹ'' Àwọn òṣèré tíátà kan rèé, tí wọn fẹ́ ara wọn, tí ìgbeyàwó wọn sì pẹ́ Ọ̀nà kan ò wọjà fáwọn òṣèré tíátà, bí wọn ṣe ń ta ìpara ìbóra ni wọ́n ń ta aṣọ ẹbí Madam Sajẹ pé eni ọgọ́ta ọdún O tun ṣalaye idi ti orin fi maa n pọ ninu awọn ere sinima rẹ nipe oun feran orin kiko gan an ni.
Wọn óo fi ìtì igi wó odi rẹ, wọn óo sì fi àáké wó ilé-ìṣọ́ rẹ lulẹ̀.
Amr Marey lo gba ami ayo kinni wole niseju meji gbara ti saa akoko ifesewonse ohun bere, kii Amine Chemiti o to gba ami-ayo meji miran wole laipe si rawon.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìtàn Mánigbàgbé: Samuel Taiwo Oredein, àgbà òṣèlú tó fi ẹ̀wọ̀n jura lárúgbó ara 1 Ẹrẹ̀nà 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 6 Ẹrẹ̀nà 2020 Oríṣun àwòrán, Others Àkọlé àwòrán, Ìtàn Mánigbàgbé: Ìgbé ayé Samuel Taiwo Oredein kọ́ wa láti máa ni ìtẹ́lọ́rùn Aye n yi, a n tọọ lẹyin, aye ko tọ lọ bii orere, igba ko tọ lọ bii ọpa ibọn, bẹẹ si ni arugbo ti soge ri, akisa si ti lo igba ri.
Boko Haram: Ikọ̀ afẹ̀jẹ̀wẹ̀ náà kó òògùn òyìnbó, oúnjẹ́ tí wọ́n sì tún pa ọmọogun mẹ́ta
Ajo Inec bere eto ayẹyẹ yii ni
Oshiomole pajúdà sí àwọn olóyè ẹgbẹ́ APC Ìkéde Oshiomole kò ṣẹ̀yìn ìròyìn kan to gbòdé pé àwọn tọ́rọ̀ kan tó fi mọ àwọn to sún mọ ààrẹ Muhammadu Buhari àti àwọn gómínà míràn tí kò dárúkọ ń pinu láti yọ òun kúrò lẹ́gbẹ̀.
Nítorí fèrè yóo dún, a óo wá jí àwọn òkú dìde pẹlu ara tí kì í bàjẹ́, àwa náà yóo wá yipada.
Wọ́n kúkú ti dámi mọ̀n níbẹ̀ pé jata-jata ni mo jẹ́.
Lẹyin naa lo sọ pe oun ko lee gba ki ẹnikẹni ba orukọ oun jẹ lẹyin ọpọlọpọ ọdun to ti n to orukọ ọhun jọ, idi re ti oun ṣe fi ọrọ naa to awọn agbofinro leti.
Bakan naa, atunṣe yii waye nitori ọpọ ẹmi lo ti sun nigba tawọn oniṣẹ Haji n lẹ oko mọ Asitani fu ọpọlọpọ ọdun.
Irú nǹkan báwọ̀nyí ni àwọn baba wọn ṣe sí àwọn wolii.
Ṣugbọn o ni iwe ẹri idanwo naa to fi han pe o gba kirẹditi meje ati paasi kan.
Ifẹnuko yii waye nibi ipade ti awon asofin
Ẹwẹ, oju lasan ni ọpọlọpọ ri lara awọn alaisan yii ṣugbọn gẹgẹ bi iwadi ṣe fi han, diẹ lara awọn nkan ti ẹ ko mọ tabi ti ẹ ko tii gbọ ri nipa awọn to n ṣaisan foniku fọla dide pọ.
Bàbá Aláàfin ìlú Ọ̀yọ́, Elérúwà àti àwọn Ọba Ilẹ̀ Yorùbá míràn tí wọ́n rọ̀ lóyè Akeredolu ni oun ko nilo lati kọ orukọ oun si ara igo ọti kankan ki awọn eeyan ipinlẹ Ondo to dibo fun oun ninu eto idibo sipo gomina to n bọ.
Amọ iroyin kan sọ wi pe sẹnetọ John McCain sọ ninu iwe ikeyin rẹ wi pe Aarẹ ilẹ Amerika, Donald Trump kò gbọdọ wa si ibi ayẹyẹ ikẹyin oun.
guard : n ; ( as i walked into the army camp , the guards stopped me .
Bẹẹ lo rọ ẹni to ba n lo ogun iblẹ funn aisan ṣuga lati ma lo papọ pẹlu ogun oyinbo.
"O ni ""Ootọ ni pe a ko ni awọn oṣiṣẹ to to niye tẹlẹ, ṣugbọn lẹyin ti Coronavirus bẹrẹ, awọn oṣisẹ wa tun din sii pẹlu ida ọgbọn."
Nígbà náà ni àwọn ọ̀tá mi yóo rí i, ojú yóo sì ti ẹni tí ń pẹ̀gàn mi pé, níbo ni OLUWA Ọlọrun mi wà?
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Eré ìtàgé lórí ayélujára, àbíkẹ́yìn faraya pé iṣẹ́ ilé ń pá òun lórí, ó gbé òfin kalẹ̀ fún ẹbí Boko Haram 601 parí iléẹ̀kọ́, ìjọba yóò san ₦20,000 lóṣù fún ẹnì ìkọ̀ọ̀kan Aráàlú faraya torí èèyàn 63 tó dèrò ọ̀run ní Gúúṣù Kàdúná láàrin ọ̀sẹ̀ kan Hospital Wedding: Oṣù kan péré ni Tash fi ṣe ìgbéyàwó pẹ̀lú Simon kó tó kú Èèyàn 11 kú, èèyàn 438 míràn tún kó COVID-19 ní Nàìjíríà l'Ọ́jọ́ Àbámẹ́ta Lizzy Anjọnrin fẹ̀si fáwọn agbọ́yì-sọ̀yí lórí ìgbéyàwó rẹ̀, Madam Sajẹ dasójú ilé iṣẹ́, àti àwọn ǹkan míràn tó ṣẹlẹ̀ lágbo tíátà lọ́sẹ̀ yìí Kọmisana ọlọpaa Janet Agbede, to wa fun ipinlẹ Abia nibi ti isẹlẹ naa ti waye ni, awọn afurasi ajinigbe yii lo ri nọmba ipe ọkunrin ti wọn ji gbe lara sọọbu rẹ, to kọ si.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Àwọn ẹlẹ́sìn ìbílẹ̀ ń bèèrè owó lọ́wọ́ àwọn Alfa lórí ìsìnkú ẹni tó pokùnso Hushpuppi di gbajúmọ̀ ẹlẹ́wọ̀n tó ní nọ́ńbà l‘Amẹrika, orúkọ̀ rẹ̀ wà lórí ayélujára Nǹkan tí ojú rí rè é bí pápákọ̀ òfurufú ṣe di ṣíṣí padà ní Nàìjíríà Ṣé lóòtọ́ ni Lateef Adedimeji àti Adebimpe Oyebade ṣe ìgbéyàwó?
“Ti ti ayeraye ni won yoo maa se iranti oloogbe naa si rere, ifarajin fun orile-ede ati ebi re.
”Lara awon to wa nibi ipade naa ni.
Báyìị́ ni Bádérù ṣe gbọ́ ọjọ́ ikú rẹ̀.
O ni dipo isin oru ọjọ ọdun, awọn yoo se isin lọjọbọ ti yoo gba awọn ni nkan bi wakati meji si mẹta, ati pe, lọjọ ọdun awọn yoo se isin kan laago meje aarọ, tawọn yoo si fi han lori ayelujara.
Ọpọ ami ẹyẹ lo ti gba to fi mọ Excellent Leadership Award (2013) ati Young Professional Role Model in Governance Award ti ikọ Young Professionals and Youth Coalition Initiative fi da lọla ni 2014.
Nigba ti BBC News Yoruba kaa mọ ile rẹ nilu Ibadan fun ifọrọwanilẹnuwo, ko daju pe inu rẹ dun si ibi ti nnkan de duro lori iṣẹ sinima agbelewo bayii paapaa fun awọn to n dẹrin pẹrẹkẹ araalu nibẹ.
Ohun tí wọn fẹ́ lọ́kàn wọn ni wọ́n ń sọ, kì í ṣe ẹnu èmi OLUWA ni wọ́n ti gbọ́ ọ.
"Ẹyin e woo nnkan ti ijọba Eko ṣe pẹlu ile ise to n ṣe ọṣẹ kan nipa bi wọn ti ṣe kọ ile iyagbe si awọn arin ọja kaakiri.
O fikun oro re pe,“Bi ise akanse Operation THUNDER STRIKE 2 se wo ojo kewa bayii, orisirisi aseyori ni ikolu Operation LAFIYA DOLE si iko omo ogun olote ti se nipinle Borno.
Orilẹede Angola ati Guinea-Bissau ko si lara eto yii.
Ọrọ naa ka awọn eeyan lara lagbaye titi ti orukọ awọn mejeji naa si jẹ eyi ti awọn eeyan n sọ niparẹ ju lori ero ayelujara.
oni  lo yẹ ki eto idibo pari sugbon ni
Àwọn ìlẹ̀kùn àwọn yàrá ẹ̀gbẹ́ ṣí sí apá pèpéle tí kò sí ohunkohun lórí rẹ̀.
ẹlòmíràn ní ẹ̀bùn àtiṣe iṣẹ́ ìyanu, ẹlòmíràn ní ẹ̀bùn iwaasu, ẹlòmíràn ní ẹ̀bùn òye láti mọ ìyàtọ̀ láàrin ẹ̀mí òtítọ́ ati ẹ̀mí èké, ẹlòmíràn ní ẹ̀bùn láti fi èdè àjèjì sọ̀rọ̀, ẹlòmíràn ní ẹ̀bùn láti túmọ̀ àwọn èdè àjèjì.
Nínú àìsàn, yóò máa wù mí; nínú ìlera yóò máa wùu mí; ìgbà tí ó bá lóyún, tí ikùn rẹ̀ bà yọ bọ̀ǹbọ̀, tí ètè rẹ gbẹ, tí ara rẹ̀ funfun, yóò máa wù mí síbẹ̀ náà ni.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Bí Nàíjíríà bá fẹ́ kí ọdún 2021 dára, ohun tí yóò ṣe rèé - Obasanjo Ẹgbẹ́ ọ̀dọ́ méjì fìjà pẹẹ́ta, ẹ̀mí kan bọ́, ọ̀pọ̀ farapa Àhámọ́ ajínigbé ni ń bá wà lónìí, ọ̀pẹ́ awakọ̀ mi"" Ẹ wo nkan tí Deeper Life High School tún sọ lórí Don Davis, akọ́kọ̀ọ́ JS1 tí wọ́n fi ipá bálòpọ̀ Àjọ NIMC ti gbé ìlànà tuntun jáde fún gbígba NIN lọ́nà ìrọ̀rùn Wo ọ̀pọ̀ mílíọ̀nù fóónù tí Whatsapp kò ní bá ṣiṣẹ́ mọ́ lọ́dún 2021 Ibodè àgbáyé ní Saki, ìbẹ̀ ni agbébọn ń gbà wọ ilẹ̀ Káàrọ̀ Oòjíire - Makinde gbarata Bakan naa ni awọn ọmọ Naijiria jankan-jankan bii Abdulrasheed Maina, Mohammed Adoke ati Doyin Akupe naa n koju ẹsun iwa ibajẹ lọwọlọwọ, ti igbẹjọ wọn yoo si tẹsiwaju di ọdun 2021."
Fún ogún ọdún tí mo fi bá ọ gbé, ewúrẹ́ rẹ kan tabi aguntan kan kò sọnù rí, bẹ́ẹ̀ ni n kò jí àgbò rẹ kan pajẹ rí.
Lára àwọn eré Yorùbá ti olóògbé Adébáyọ̀ Fálétí kọ, ti ó si ṣe ni “Mágùn, Àfọ̀njá, Baṣọ̀run Gáà àti bẹ́ ẹ̀ bẹ́ ẹ́ lọ.
Ṣìṣe-ṣìṣe bá Man City, Norwich fi wọ́n ṣe fàájì òpin ọ̀sẹ̀
Nigba ti yoo fi di ọmọ ọdun mẹrindinlogun, o ti lọ sawọn ileẹkọ nipa ijo jijo mẹta to dantọ julọ lagbaye.
Oríṣun àwòrán, @topsy_adeusi Alaye lori afikun owo ina naa: Ajọ naa ni afikun owo ina to bẹrẹ lọjọ kinni oṣu kẹsan an yoo da le iya wakati tawọn onibara fi n lo ina lori.
Ìgbẹ̀yìn ẹni náà wá burú ju ti àkọ́kọ́ lọ.
Oríṣun àwòrán, Others Gẹ́gẹ́ bi àjọ WHO ṣe sọ, ipò kẹẹdógún ni Nàìjíríà wà lárá àwọn orílẹ̀-èdè tí wọ́n ti sábà máa ń gba ẹmi ara wọ́n jùlọ.
Ọpọlọpọ ile lo ṣi wa ninu ibanujẹ ti iṣẹlẹ ojo arọọrọda naa mu ba ẹbi wọn.
Taye jẹ́ eni dúdú, Kehinde jẹ́ àfín; báwo ló ṣe jẹ́ bẹ́ẹ̀?
Nibayii, ileesẹ BBC lagbaye ati ni orilẹ-ede Naijiria ti wa n kede bayii pe, irọ to jinna sootọ ni ahesọ ọrọ yii, oun ko gbero lati seto iranwọ iranwọ owo eto ẹ́kọ fun akẹkọọ kankan ni Naijiria tabi loke okun.
Àwọn náà kígbe pé, “Oluwa mímọ́ ati olóòótọ́, nígbà wo ni ìwọ yóo ṣe ìdájọ́ fún àwọn tí ń gbé orí ilẹ̀ ayé, tí ìwọ yóo gbẹ̀san ẹ̀jẹ̀ wa lára wọn?
Oṣu Kẹsan, ọdun 2017 ni ẹgbẹ́ naa so iyanṣẹlodi to ṣe kẹhin rọ, wọn si n fẹ ki ijọba mu gbogbo adehun to sẹ fun wọn lọdun 2009 ṣẹ.
Kii ṣe iwọde EndSARS nigba akọkọ tawọn ọdọ Naijiria yoo kọju oro si ijọba nitori idi kan tabi omiran, eyi ti yoo si mu ẹmi lọ, o ti waye saaju.
Ninu oro kan , nibi ti orile-ede America ti se amulo sisan iko mewaa ninu ida ogorun lori owo ori oja, eyi ti o mu ki gbogbo awon orile-ede lagbaye tako igbese naa, akosemose kan so pe,  adinku ti ko to iko kan 0.
 thi di apàṣẹ 1st division , kí ó tó di alákóso i corps lẹ ́ yìn ìgbà díẹ ̀ lọ ́ dún náà .
Oríṣun àwòrán, Twitter/FRSC Àkọlé àwòrán, Ijamba ọkọ Ẹnikan ti isẹlẹ naa ṣoju rẹ sọ pe awọn tọkọ taya ti wọn wa ninu ọkan ninu awọn ọkọ ọhun mori bọ Ẹlomiran tun sọ pe ẹni to wa ọkọ keji wa lẹsẹ kan aye ẹsẹ kan ọrun.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Oba Adedokun Abolarin ti Oke Ila: Ó ya ọ̀pọ̀ tó súnmọ́ mi lẹ́nu bí mo ṣe ń kọ́ Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
ajo CAF ti setan lati je ki orile-ede Egypt sagbateru idije naa.
Wò ó, OLUWA Ọlọrun yín ni ó ni ọ̀run, ati ayé ati gbogbo ohun tí ó wà ninu rẹ̀; 
A ní, “Ìfẹ́ Oluwa ni kí ó ṣẹ.
 olófìn-íntótó , ọmọ olusínà kọ ̀ wé sí túndé atọ ̀ pinpìn .
Ibi ti o tí n káàkiri ní òun nìkan ni ó ti bá iwin kan pàdé, ti ó fi inú òkúta ṣe ibùgbé tí ó ní ojú mẹrin, imú méjì, àti ẹnu méjì tí o sì ni ìwo méjì tí ó dábì ìwo àgbáǹkéré ní àtàrí.
Bẹẹ si ni awọn ọdọ ti ko ri isẹ se n wa isẹ kiri gbogbo ẹkun to wa ni Naijiria, ẹkun iwọ oorun guusu si ni gbogbo awọn eeyan ta mẹnuba yii n sa wa.
Adari eka to n mojuto ọrọ to jẹ
Ojú yóo tì wọ́n nígbà ìkórè,nítorí ibinu gbígbóná OLUWA.
Wọn ṣalaye wi pe, idibo to waye ni orilẹede Benin ni ọjọ Kejildinlọgbọn oṣu Kẹrin ọdun 2019, ninu eyi ti wọn ko jẹ ki awọn ẹgbẹ alatako ti kopa, jẹ ohun to tẹ ẹtọ awọn aarẹ ana lorilẹede Benin, Boni Yayi ati awọn olori ẹgbẹ alatako to ku mọlẹ.
Ejiogbe ni kete ti wọn bura tan fun Alhaji Mukaila lo bẹrẹ si ni pa orukọ NURTW rẹ lara awọn ọfiisi ajọ naa to n si yi pada si PMS.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Obinrin Akansẹ: Ẹsẹ kiku bi ojo kọ mi lati di alagbara Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Obinrin Akansẹ: Ẹsẹ kiku bi ojo kọ mi lati di alagbara 22 Ìgbé 2018 Nigba ti Aya bẹrẹ, o fi da olukọni rẹ loju wipe oun yoo se daradara.
Bi iṣẹ ba wa gbomimu to fi kan pe ki wọn ṣe kọ ogoji wakati yii, o ṣeeṣe ki owo wọn tun gbe ẹnu soke ju eyi lọ Ìdí táwọn olùwọ́de EndSARS fi kọ oúnjẹ àti ọtí ẹlẹ́rìndòdò tí MC Oluomo gbé wá rèé Wo nọ́mbà tí o le è pè láti gba owó gbà-má-bínú tí ọlọ́pàá bá fìyà jẹ ọ́ lọ́nà àìtọ́ l'Eko Ẹfunsetan Aniwura, ọmọ Ẹ̀gbá tó di akíkanjú obìnrin nílẹ̀ Ibadan Ìjọba ìpínlẹ̀ Eko ti kéde orúkọ àwọn ọlọ́pàá tó fi ìyà jẹ àwọn olùwọ́de #EndSARS Elo wa ni owo osu awọn ọlọpaa Naijiria?
Kó wa erúpẹ̀ bo òkú náà ṣùgbọ́n ó dì í ó gbé e sí ibẹ̀ nírètí pé ọjọ́ kan ń bọ̀ ti òkú náà yóò yípadà tí olúfẹ́ òun yóó díde wáá bá òun.
    Ní òpin ọgọ́ta ọjọ́, mo jáde.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù NYSC: Adigunjalẹ̀ fìbọn fọ́ ọmọ ọdún mẹ́tàdínlọ́gbọ̀n lójú nílú Èkó 11 Bélú 2019 Oríṣun àwòrán, OTHER Ẹni ọdun mẹtadinlọgbọn kan ti padanu oju rẹ mejeji lẹyin ti awọn adigunjale yinbọn lu oju rẹ nilu Eko.
Bí ẹnikẹ́ni bá ń sọ̀rọ̀, kí ó mọ̀ pé ọ̀rọ̀ ìjìnlẹ̀ Ọlọrun ni òun ń sọ.
Mo má nlo ọgbọ̀n ìṣẹ́jú sí wákàtí kan níbẹ̀.
O ni iwa ati ise ojogbon yii to awokose rere fun awon onkowe ati iran Yoruba lapapo.
Wo àwọn tí gómìnà ìpínlẹ̀ Oyo fi orúkọ wọn sílẹ̀ fún ipò kọmísánnà Ẹ wo ọmọ ọdún méje tó di Gómìnà l'Ekiti Ẹni orí yọ, ó dilé!
Pópóọlá sọ pé, ‘Ẹni tí ó pe tóró, Á ṣẹnu tọ́ńtọ́.
Ìdájọ́ ẹ̀wòn gbére kò ní kí Wòlíì Sotitobire má lọ sí ilèẹjọ́ kòtẹ́milọ́rùn - Agbẹjọ́rò Pásítọ̀ Alfa Babatunde Ẹ̀wọ̀n ni wàá gbẹ̀yìn sí, kò sí bóo ṣe dọ́gbọ́n tó - Seyi Makinde wa ègúná ọ̀rọ̀ lé Fayose Bode George ní Fayose gọ̀, ó fẹnu họra, Fayose ní ''ẹ ò lè pa mí bí ẹ ṣe pa Bola Ige MC Murphy ko sọ òótọ́ ọ̀rọ̀ to wà níbẹ̀, tó ba wùú kó sọ òótọ- Adebayọ 'N500 dé fún gbogbo ọmọ tuntun lóṣooṣù bí mo bá di gómìnà Ondo - Adeleye AAC Obinrin ni awọn mejeeji.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ogun state lockdown update: 'Èèyàn 104 tó kó covid-19 ní ílééṣẹ́ kan ní Sagamu fihàn pé ààrùn náà ti wà láwùjọ' 11 Òkùdu 2020 Oríṣun àwòrán, Twitter/Prince Dapo Abiodun Bi awọn eeyan mẹrinlelọgọrun un ṣe lugbadi aarun coronavirus ni ileeṣẹ kan niluu Sagamu nipinlẹ Ogun fihan pe aarun naa ti wa lawujọ.
Lẹ́yìn náà Jesu tún fi ọwọ́ kàn án lójú.
Ilẹ̀ tí ọba rẹ̀ kì í bá ṣe ọmọ ẹrú ṣoríire!
Eliṣa bèèrè pé, “Níbo ni ó bọ́ sí?
Ajọ INEC ni iṣipo pada awọn eeyan kun ara ohun to n faa ti ọpọ ko fi lee gba awọn kaadi wọn.
Nigba to de ilu Eko, ọja Oyingbo lo balẹ si, to si n sisẹ alabaru nibẹ, bo se n fi ori rẹ gbe apo ata, lo n gbe apo ẹwa, irẹsi, apo elubọ, Sẹmo, agbado ati bẹẹ bẹẹ lọ.
Ọkọ Mama Rainbow ni Augustine Ayanfemi Phillips, to ṣe iṣe pẹlu aṣaaju-ọna ninu iṣẹ oṣere tiata, Sir Hubert Ogunde, fun ọpọ ọdun.
ní Homa, Boraṣani, ati ní Ataki, 
Immaculate Okochu ń múra ìyàwó lọ́wọ́ ló k'àgbákò ikú 'Inú mi dùn pé wọ́n dájọ́ sísọ̀kò pa bàbá arúgbó tó fipá b'ọ́mọ lòpọ̀' Ilé iṣẹ́ tó ri si ètò ẹ̀kọ́ l'Abuja kò tí ì rànsẹ́ pé UNILAG ti ni Giwa tuntun Ìjọba ìpínlẹ̀ Osun tí búwọlù ìlànà àyẹyẹ Ọṣun-Oṣogboo ọdún 2020 Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Olusegun Obasanjo sọ̀rọ̀ síta pé ọpẹ́lọpẹ́ Walter Carrington láyé òun nígbà tí Sani Abacha ń lé òun kíri18 Ògún 2020 Gun control in Nigeria: Wo ọ̀nà márùn ún tí o lè gbà dábòbò ara rẹ lọ́wọ́ ìjàmbá!
Onigbọwọ Joshua, Eddie Hearn ti kede pe ninu oṣu kọkanla tabi ekejila ni atunja ija naa yoo waye laarin awọn mejeeji.
 O si gboriyin fun akitiyan awọn alasẹ Ile yii lati tubọ mu igberu ba iṣẹ to nii ṣe pẹlu gbigba awọn iṣẹ ati ijiroro inu gbgede Ile silẹ.
Nígbà tí ọkùnrin náà sọ báyìí tán, inú ọba tí ó ń sọ̀rọ̀ fún bàjẹ́.
Ṣé eniyan lè fi ọwọ́ ara rẹ̀ ṣẹ̀dá ọlọrun?
Ko ni si eto irinna lati ipinlẹ si ipinlẹ, afawọn ti iṣẹ wọn ba kan dandan.
BBC 100 Women jẹ ọna ti BBC fi máa n ṣe ayẹsi fun awọn obinrin ti o lamilaaka lagbaye ti a si máa n gbiyanju lati ṣọ itan wọn.
O ni bi oun ati mọlẹbi oun ti se bẹrẹ si ni gbe igbe aye wiwapọ pẹlu ara wọn yi, oun ti se awari awọn kudiẹ-kudiẹ to wa ninu iwa oun ti oun si ti n se atunse.
Àṣà Oge Ṣíṣe ní Akọ́mọlédè BBC Yorùbá ń gbé yẹ̀wò lónìí, Ó yá, iṣẹ́ ti bẹ̀rẹ̀.
Ẹwẹ, gomiona ipinlẹ Wisconsin, Tony Evans ti bu ẹnu atẹ lu iṣẹlẹ naa.
Ṣugbọn kò pa òfin OLUWA mọ́.
Wo àwọn ohun tí a mọ̀ lọ́wọ́ yìí nípa ìṣẹ̀lẹ̀ ikú Barakat Bello Ẹ̀wọ̀n gbére ni fún ẹnikẹ́ni tó bá fipá bánilòpọ̀ ní ìpínlẹ̀ Ọ̀ṣun Wo àwọn ohun tí a mọ̀ lọ́wọ́ yìí nípa ìṣẹ̀lẹ̀ ikú Barakat Bello Bamidele Olumilua fi òsèlú tiẹ̀ sin Ọlọ́run àti ènìyàn - Mimiko Eyi ti mu ki ọpọ awọn ọmọ Naijiria maa lọgun iru ijiya to yẹ fun ẹnikẹmi ti aje iwa ifipabanilopọ ba ṣimọ lori.
Ilẹ́-ẹjọ́ fagilé ìdìbò tó gbé Adeyeye wọlé ní Ekiti Òní lòní ń jẹ́.
Wọn nigbagbọ pe a yoo sọ ohun ti wọn wi lai bomi laa.
Bí òmùgọ̀ rẹ kò bá rekọja méjì, ìlú rẹ a bàjẹ́ tó báyìí lójú ara rẹ, ìwọ a tún máa rí ẹnu sọ̀rọ̀!
Gẹgẹ bi ohun ti a ri gbọ lẹnu Dele Adeleke ati atẹjade kan ti igbimọ ipolongo Sẹnẹtọ Adeleke fi sita lorukọ agbẹjọro Niyi Owolade idajọ ti ile ẹjọ kotẹmilọrun nilu Akure da ti fi han gbangba pe idajo ile ẹjọ giga nilu Bwari ko fẹsẹrinlẹ.
Àwọn ọmọ Israẹli bá ranṣẹ sí Sihoni ọba àwọn ará Amori pé, 
 O so pe“O wa lara ofin eto omoniyan lati fi ehonu han ni Somaliland.
Nise ni awọn eero le ọkọ iyawo kan kabakaba kuro ni ibi ayẹyẹ igbeyawo rẹ lẹyin ti iyawo rẹ akọkọ ṣadeede yọju sibi ayẹyẹ naa, to si sọ fun iyawo tuntun pe, ọkọ rẹ ti ni iyawo meji tẹlẹ.
Lara ohun ija naa lati ri: ibon Kalashnikov.
Àwọn ìṣẹ̀lẹ̀ Ebola to lágbára sẹyìn: Ikú ènìyàn 11,308 lorilẹ-ede Guinea, Liberia, Sierra Leone, laarin ọdun 2014 si ọdun 2016 Ikú ènìyàn 280 lorilẹ-ede DR Congo, l'ọdun 1976 Ikú ènìyàn 254 lorilẹ-ede DR Congo, l'ọdun 1995 Ikú ènìyàn 224 lorilẹ-ede Uganda, l'ọdun 2000 Ikú ènìyàn 187 lorilẹ-ede DR Congo, l'ọdun 2007 (Orisun: WHO) Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Nàìjíríà ń ṣọ́ pápákọ̀ òfurufú tórí Ebola Ebola sẹ́yọ ní DR Congo Ko sí ifoya Ebola lọ́rọ̀ ìdíje Nigeria àti Congo Àláìsàn Ebola sá kúrò níléwòsàn lọ sí ṣọ́ọ̀ṣì Bayii, Ebola ti pa eniyan mẹtadinlọgbọn ni DR Congo ni eyi to dẹ tun ń tàn kalẹ lati ileto lọ si àwọn ilu nla bii Mbandaka, ti wọn ti ri iṣẹlẹ Ebola tuntun lọjọ kẹtadinlogun oṣu karun un.
Yóo gba ìdámẹ́wàá ọkà yín ati ti ọgbà àjàrà yín fún àwọn ẹmẹ̀wà ati àwọn iranṣẹ rẹ̀.
Lara awon to wa nibi eto apeje
Nígbà tí ó di ìrọ̀lẹ́, Jesu wá sibẹ pẹlu àwọn ọmọ-ẹ̀yìn mejila.
Dafidi ati àwọn ọmọ ogun rẹ̀ tí wọ́n jẹ́ ẹgbẹta (600), bá lọ sọ́dọ̀ Akiṣi, ọmọ Maoki, ọba Gati.
Òfin Amẹrika gbàá láàyè fún ẹnikẹ́ni láti ní ìbọn.
" Dasofunjo ni ohun to dun oun ju ni pe, oun ko ni ri mọ, ti wọn ko si ni lee sọrọ lori ẹrọ ilewọ mọ.
Ezeemo soro yii nijoba ibile Umuchu Aguata nipinle Anambra pe arowa yii di dandan lasiko yii nitori ina ajoreyin ti oro-aje wa n jo bayii.
Lawan, ni won bura fun un gege bi abenugan fun ile igbimo asofin agba niluu
Ọkunrin náà bá dáhùn pé, “A kò ní pè ọ́ ní Jakọbu mọ́, Israẹli ni a óo máa pè ọ́, nítorí pé o ti bá Ọlọrun ati eniyan wọ ìjàkadì, o sì ti ṣẹgun.
''Amẹrika nikan kọ lo yẹ ki wọn gbe igbeṣẹ yi, ni Yuroopu ati ilẹ Gẹẹsi,awọn na ay ki wọn ṣe bẹ'' Ologbondiyan wa fi ifarajin ẹgbẹ oṣelu PDP han lati ma mu idagbasoke ba eto oṣelu ni Naijiria Kini APC sọ?
Isọwọ sisẹ wọn yatọ si ti ọlọpa gbogboogbo ; awọn ni wọn n mojuto igboke-gbodo ọkọ lawọn oju popona to jẹ ti ijọba ipinlẹ, aabo awọn araalu,ipese aabo fun gomina ipinlẹ, to fi mọ eto ẹkọṣẹ awọn to ṣẹṣẹ fẹ ẹ darapọ mọ ileesẹ ọlọpa abẹle, ati ọgbọn atinuda lori imọ ẹrọ ati sayẹnsi.
Ẹ má mú un lọ́tàá, ṣugbọn ẹ máa gbà á níyànjú bí onigbagbọ.
Ẹni ìtìjú ni ọ́ lójú Ọlọrun.
Ìyàlẹ́nu ni ó jẹ́ fún gbogbo ènìyàn pé wọn kò rìn ju wákàtí mẹ́ta lọ nígbà tí wọ́n dé odò abàmì náà bẹ́ẹ̀ ni ẹnikẹ́ni kò sí rí odò náà rí níbi tí wọ́n gbé bá a.
Mo ri awọn ti wọn so lokun mọ oke ti wọn si da ori wọn kodo ko maa mi jolojolo.
Ẹ óo di ẹni ègún, ẹni àríbẹ̀rù, ẹni ẹ̀gàn ati ẹni ẹ̀sín.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù 2019 Elections:Yuguda, Mu'azu fi PDP sílẹ̀ lọ APC ní Bauchi 12 Sẹ́rẹ́ 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 13 Sẹ́rẹ́ 2019 Oríṣun àwòrán, Adamu Muazu and Isa Yuguda Àwọn èèkàn ẹgbẹ oṣelu PDP ni ipinlẹ Bauchi ti fi ẹgbẹ naa silẹ lọ si APC nigba ti Ààrẹ Muhammadu Buhari ṣe abẹwo si ipinlẹ naa ni Ọjọ Abamẹta.
Ọkẹ aimoye awọn eeyan ni wọn ti ran lọ sọrun apapandodo, ti awọn bi miliọnu meji miran si ti di atipo.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Àgbà ni Obasanjo, oun tó ń sọ yé e, ìjọba ni kó tají - Wale oke Buhari ni aarẹ orilẹ-ede Naijiria kẹta ti yoo lọ fun apero ẹgbẹ OIC lẹyin oloogbe aarẹ tẹlẹ ri, Umaru Yar'Adua ati aarẹ ana, Goodluck Jonathan ti kọkọ lọ fun irun apero bẹẹ.
0 34 Falkland Islands 0 0.
dúró : dúró ni àkọ ́ bí ọmọ Àkàngbé orímóògùnjẹ ́ .
Bobrisky náà ti fèsí sí alákóso Arts & Culture pé ọmọ ọwọ́ ní, àwọn to jẹ́ ọ̀gá ni ìjọba fún ni òun ń ba ṣe.
Nítorí náà, wọ́n fi ìṣe wọn sọ ara wọn di aláìmọ́,wọ́n sì sọ ara wọn di alágbèrè.
Iléeṣẹ́ Ọlọ́pàá dènà ọkùnrin tó fẹ́ pa ara rẹ̀ nítorí ọmọbìnrin Buhari Oríṣun àwòrán, Aishabuhari Saaju la ti kọkọ mu iroyin wa fun yin pe ileeṣẹ ọlọpaa ni ipinlẹ Kano ni oun ti pẹtu sinu arakunrin kan, Abba Ahmed, to ni oun yoo pa ara oun ti ọmọ aarẹ Buhari, Hanan ko ba fẹ oun.
Nígbà tí Dafidi ọba dé Bahurimu, ọkunrin kan tí orúkọ rẹ̀ ń jẹ́ Ṣimei, ọmọ Gera, láti inú ìdílé Saulu, jáde sí i, bí ó sì ti ń bọ̀, bẹ́ẹ̀ ni ó ń ṣépè lemọ́lemọ́.
Ètò àbò, ètò ẹ̀kọ́, gbégbá orókè nínú àbádòfin 2019 Ilé ìgbìmọ aṣofin ti dájọ tí wọn ó fọwọsi àbádofin ìsúna 2019 Kí ló fà 'pàsán ojú' tí Buhari na aṣòfin?
 bí Ọbàtálá ; Ọbàtárìṣà ; Ọba tapatapa tí í bá wọn gbóde ìrànjé ti ní orin tirẹ ̀ náà ni orò : yínni-yínni gbín-ín-kin ; Ọ ̀ gọ ̀ gọ ̀ rumọ ̀ -rumọ ̀ .
“Nisinsinyii, wo àwọn ọmọ ogun Amoni, ati ti Moabu ati ti Òkè Seiri, àwọn tí o kò jẹ́ kí àwọn ọmọ Israẹli bá jà nígbà tí wọ́n ń bọ̀ láti Ijipti, o kò jẹ́ kí wọ́n pa wọ́n run.
Ninu atẹjade ti Oloye Wale Oladoja fi sita, awọn Mogaji sọ fun Fayemi pe ọdun mẹji nikan lo lanfaani lati lo gẹgẹ bi gomina ipinlẹ Ekiti, ṣugbọn laelae ni ipo awọn lọbalọba.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Covid 19 Update: Àwọn orílẹ̀-èdè kan tún ti kéde kó nílé-ó-gbélé nítorí coronavirus 10 Bélú 2020 Oríṣun àwòrán, others Àwọn orílẹ̀-èdè kan tún ti kéde kó nílé-ó-gbélé nítorí coronavirus Orilẹ-ede Germany, lo kọkọ tun kede isede coronavirus nilẹ Europe, eyi to ti fa awuyewuye jakejado ilẹ naa.
Ọgbẹni Badmus wipe iṣẹlẹ yi tako ofin ijọba ati eto aabo fun awọn ohun meremere ninu igbo ọba.
Se ẹ ri pe ilu n gbona bayii.
”Gege bi Mancini se so, “o je ohun iwuri fun mi lopolopo lati je akonimoogba agba okan lara iko agbaboolu orile-ede ti o lamilaaka julo ninu ere boolu afesegba lagbaaye,” Ni bayii, ireti wa pe, Mancini yoo bere ise re ni kete ti idije orile-ede Russia ba pari ni ojo ketala osu karun un odun ti a wa yii.
Ẹni tí ó kẹ́gàn aládùúgbò rẹ̀ dẹ́ṣẹ̀,ṣugbọn ayọ̀ ń bẹ fun ẹni tí ó bá ṣàánú talaka.
Kí ọ̀kọ̀ọ̀kan ninu àwọn ẹ̀ka mẹfẹẹfa yìí ní iṣẹ́ ọnà bí òdòdó aláràbarà mẹta mẹta tí ó dàbí òdòdó alimọndi.
Ẹ máa ta á lọ́fà, ẹ má ṣẹ́ ọfà kankan kù, nítorí pé ó ti ṣẹ OLUWA.
Nígbàkúùgbà tí OLUWA bá gbé aṣiwaju kan dìde fún wọn, OLUWA a máa wà pẹlu aṣiwaju náà, a sì máa gbà wọ́n lọ́wọ́ gbogbo àwọn ọ̀tá wọn, ní àkókò aṣiwaju náà.
Gbogbo igbiyanju BBC lati ba Onyema funra rẹ sọrọ ko tii so eso kankan di asiko yii.
Àwọn aláṣẹ ń gba owó àbẹ̀tẹ́lẹ̀ kí wọ́n tó ṣe ìdájọ́, àwọn alufaa ń gba owó iṣẹ́ wọn kí wọ́n tó kọ́ni, àwọn wolii ń gba owó kí wọ́n tó ríran; sibẹsibẹ, wọ́n gbẹ́kẹ̀lé OLUWA, wọ́n ń wí pé, “Ṣebí OLUWA wà pẹlu wa?
Ó bá sọ fún mi pé, “Ìwọ ọmọ eniyan, mo fẹ́ kí o mọ̀ pé ìran ohun tí yóo ṣẹlẹ̀ lẹ́yìn ọ̀la ni ohun tí o rí.
Akunyili ku ni ọjọ keje oṣu kẹfa ọdun 2014 lẹyin to ba aisan jẹjẹrẹ finra fun ọpọlọpọ igba.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ogun Police: Ọlọ́pàá Ogun rí ₦2m, oògùn olóró ₦10m àti ọ̀pọ̀ ohun ìjà olóró kó níbùba olóògùn olóró 15 Sẹ́rẹ́ 2021 Oríṣun àwòrán, NPF Ileeṣẹ ọlọpaa ipinlẹ ogun ti ri owo to le ni miliọnu meji abọ naira ati oogun oloro, ti iye rẹ to miliọnu mẹwaa naira lẹyin ti wọn kọlu awọn eeyan kan ti wọn fura si pe wọn n gbe oogun oloro.
OLUWA ní, “Ní ọjọ́ náà, ariwo ńlá ati ìpohùnréré ẹkún yóo sọ ní Ẹnubodè Ẹja ní Jerusalẹmu; ní apá ibi tí àwọn eniyan ń gbé, ati ariwo bí ààrá láti orí òkè wá.
Ninu iwadii ti ajọ YIAGA gbe jade ṣaaju idibo, eyi ti wọn fi ṣọwọ ṣawọn akọroyin, wọn darukọ awọn ijọba ibilẹ mẹfa ti iwa ipa ti le waye lasiko ibo ni Ondo.
Ayé ti kúrò ní ibi ti ẹ̀yin wà yìí, o nílati lọ múra kí o tún èrò ara rẹ pa.
'Ọmọ Naijiria 25,794 ló kú sí rògbòdìyàn láàrin ọdún mẹ́rin' SARS fi ìyà jẹ àwọn akẹ́ẹ̀kọ́ fásitì Akungba A kò lè gba àwọn jandùkú Fulani láàyé nílẹ̀ Yoruba -Awọn gómínà Loṣu keje, ọdun 2018 ni fidio obinrin meji ti wọn ni Boko Haram pa ati awọn ọmọde meji n tan kale lori ayelujara.
  iroyin gidiOgbeni Mohammed ni ohun to n sabaa maa n fa ija yii ni bi oju ojo se n yi pada, ibugbe ati bi awọn eniyan se n pọ si ni orile ede yii.
Fetí sí adura mi, OLUWA,gbọ́ igbe ẹ̀bẹ̀ mi.
Silas Adekunle: Ó tún sẹ̀sẹ̀ fọwọ́sí àdéhùn alàìmọye mílíọ́nù dọ́là
Yóo pa àwọn alágbàro wọnyi, yóo sì gbé ọgbà rẹ̀ fún àwọn mìíràn láti tọ́jú.
Ọmọbinrin náà tí orúkọ rẹ̀ ń jẹ́ Jemila Ibrahim àti ọ̀rẹ́ rẹ̀ Fatima Mohammed ẹni ọdún mọ́kànlélógún lágbègbè Monkey village, Festac nílù Eko.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, June 12 declaration: Àjọ eléto ìdìbò gbọdọ̀ kéde MKO Abiola bí ààrẹ Nigeria Lẹ́yìn èyí, ní wọ́n mu Abiola si atimọle tí ọ̀pọ̀ ọmọ Nàìjíríà sì gba ìgboro láti fẹ̀honu han ní ìpínlẹ̀ Eko àti Abuja pé kí wọ́n fi Abiola silẹ̀ lẹ́wọ̀n nítori pé wọ́n ni ìgbàgbọ pé òun ló jáwe olúbori nínú ìdìbò náà.
 Àwọn òṣèré náà sì máa ń gbìyànjú láti túmọ ̀ gbogbo ohun tí ó bá yẹ kí wọ ́ n sọ kí ó le yé gbogbo ènìyàn .
Nítorí náà, o óo fi ojú rí ilẹ̀ náà, ṣugbọn ẹsẹ̀ rẹ kò ní tẹ ilẹ̀ tí n ó fún àwọn eniyan Israẹli.
Rashid Lootah, alaga, Nakheel Properties ati Limitless Group.
Nígbà tí ó wọ́ ọ kúrò lójú ọ̀nà tán, gbogbo àwọn eniyan bẹ̀rẹ̀ sí sá tẹ̀lé Joabu, wọ́n ń lépa Ṣeba lọ.
Bi eto idibo se bẹrẹ ni pẹrẹu, ni aare Buhari  ati  iyawo rẹ naa lo sile idibo niluu Daura lati lo
Lọjọ ti eto idibo naa ba fẹ ẹ bẹrẹ, awọn cardinal naa yoo ṣe Isin ni owurọ, ki wọn o to to o wọle sinu ijọ.
Ní Japan ẹjá ti wọn máa n pe ni Fugu, wọn máá n jẹ ẹ ni tútú tàbi kí wọn dín ata si i.
May Workers day: Ìkáyàsókè bá àwọn òṣìṣẹ́ nítorí àìmọ ọjọ́ ọ̀la lẹ́yìn Coronavirus
Yirinyirin aláràbarà ọlọ́kanòjọ̀kan ni èèyàn a máa rí níbikíbi tí èèyàn bá lọ.
Ṣugbọn Ẹ̀mí Mímọ́ gbé Stefanu, ó tẹ ojú mọ́ òkè ọ̀run, ó rí ògo Ọlọrun, ó tún rí Jesu tí ó dúró lọ́wọ́ ọ̀tún Ọlọrun.
Awa ti a jẹ ọmọ Naijiria ni ọrọ naa n dùn.
pasẹ fun gbogbo awon agbofinro to wa lorile ede Naijiria lati ri i daju pe won
Ẹni tí ó bá ń ṣiṣẹ́ àánú, kí ó fọ̀yàyà ṣe é.
08trn) kalẹ sile asofin apapọ ilẹ fun ọdun 2021, Aba isuna naa lo fi triliọnu meji o le diẹ (₦2.
Kí èyí jẹ́ ìlànà ayérayé fún àtìrandíran yín, ní gbogbo ibùgbé yín, pé ẹ kò gbọdọ̀ jẹ ọ̀rá tabi ẹ̀jẹ̀.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Eégun àti orò, bí wọ́n ṣe jọ bí Ẹ̀ṣà Egúngún nílẹ̀ Yorùba rèé Ìdája òdodo ni Ifeanyi yóò rí gbà Ẹ̀wẹ̀, Gbajabiamila ti fi ọkàn gbogbo àwọn fẹ́ndọ̀ tó kù balẹ̀ lónìí ọjọ́ àìkú pé òun yóò rí dájú pé Ifeanyi kò kú lásán.
Igbó Funfun  – Apá kẹta Ìrìnkèrindò Moravia
Ojo yi bakan naa maa jẹ anfaani lati ṣe ayẹwo awọn ipenija to n ba awọn eeyan Naijiria nile ati lẹyin odi.
nítorí pé wọ́n ti hùwà òmùgọ̀ ní Israẹli, wọ́n bá aya àwọn aládùúgbò wọn ṣe àgbèrè, wọ́n fi orúkọ òun sọ ọ̀rọ̀ èké tí òun kò fún wọn láṣẹ láti sọ.
bayii n sa gbogbo ipa re lati ri wipe won gbogun ti iwa ibaje lorile-ede
Ǹjẹ́ ohun tí ó dára yìí ni ó ṣe ikú pa mí?
N kò ní jẹ́ kí ìyàwó mi tẹ́ láàrin ẹgbẹ́, n kò sì ni fii sílẹ̀ kí ojú máa pọ́n ọn.
“Ajosepo tuntun yii yoo je ki idagbasoke wa bere lati ijoba ibile lo sijoba ipinle.
Gun orí òkè Pisiga lọ, gbé ojú sókè, kí o sì wo apá ìwọ̀ oòrùn, ati apá àríwá, ati apá gúsù, ati apá ìlà oòrùn.
Oríṣun àwòrán, Firdausi Okezie Àkọlé àwòrán, Samuel ati ẹgbọn rẹ lọjọ ti o n ṣe igbeyawo, lẹyin bi ọdun meji to ri i.
Defence HQ: Ilé iṣẹ́ ológun Nàìjíríà fèsì sí awuyewuye pé wọ́n yọ́lẹ̀ sìnkú
Lẹ́yìn tí ó ti gbà láti fún àwọn òṣìṣẹ́ náà ní owó fadaka kan fún iṣẹ́ ojúmọ́, ó ní kí wọ́n lọ ṣiṣẹ́ ninu ọgbà àjàrà òun.
Ija ẹsin ati ti ẹlẹyamẹya: Eto aabo to mẹhẹ pupọ lorilẹede Naijiria ti sokunfa ọpọ aisedeede eyi to dunkooko mọ ifẹsẹmulẹ ati isọkan rẹ.
O salaye pe ohun to wu Baba ni ki wọn tete sin in ni eyi ti awọn ẹbi si ti pinnu lati mu sẹ pẹlu ajọsepọ awọn Gomina Iwo Oorun Naijiria ati awọn oloselu ti wọ́n ba Baba rin nigba aye rẹ̀.
Lara awọn agbabọọlu miran to gba ami ẹyẹ ni Samuel Chukwueze to gba ẹyẹ agbabọọlu ọjẹwẹwẹ ọkunrin to fakọyọ.
Fall so pe, “Inu wa dun pea won omode-binrin naa pada sile layo ati alaafia, ajo ohun n fowosowopo pelu ile-ise ti o n ri si oro awon odo nipinle Yobe, lati satileyin ti o ba ye fun awon omode-binrin naa ati awon ebi won, lati bi osu kan seyin, awon omode-binrin ti le koju ifipa-bani lo po tabi ifiya-jeni, won niloo atileyin awon molebi won, ati awon ara-ilu, lati le pada sile-eko won”.
Nítorí OLUWA ti pàṣẹ fún mi pé, n kò gbọdọ̀ fi ẹnu kan ohunkohun; ati pé, ọ̀nà tí mo bá gbà wá síbí, n kò gbọdọ̀ gbà á pada lọ sílé.
Eyii ni awọn ohun meje to yẹ ki ẹ mọ nipa Emir ana ọhun.
Kí o gbà á sí àárín àwọn èèyàn réré l'ọ́run
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ìdìbò Ọṣun: Omisore, Akinbade ni ìjọba àpapọ̀ fẹ fi N10,000 rà'bò ni Ọmọ ẹgbẹ́ òsèlú APC tako Oshiomole Ààwẹ̀ gbẹ̀mí ọmọ Naijiria ní orílẹ̀èdè Amẹ́ríkà Adekunle to jawe olubọri gẹgẹ bi oludije ayanfẹ ẹgbẹ jẹ asoju sofin nile asofin orileede Naijiria.
 tí ènìyàn bá gba ojú títì ọlọ ́ dà wọ ìlú Ìrè , ó rí bi kìlómítà márùndínlógójì sí Ìkọ ̀ lé-Èkìtì tí í ṣe olú ìlú fún gbogbo agbègbè àríwá Èkìtì .
Nigba to di ọjọ kan, ṣaa deede ni ọja ti Ọmọyẹ fi pọn ọmọ rẹ sẹyin ba tu lojiji laimọ nibi to ti bẹrẹ mọlẹ, to n fọ asọ.
Ìbá jẹ́ pé mo lè gún òkè ni, èmi ìbá lọ ní ti eléyìí ná kí n tóó padà wáá ṣe ìrànlọ́wọ́ fún ọ.
Ẹ wá, ẹ jẹ́ kí á pa á, kí ogún rẹ̀ lè di tiwa.
Iyẹn lẹyin ọpọlọpọ iwọde, iyanṣẹlodi fun ikilọ ati ifẹhonuhan awọn oṣiṣẹ.
Orúkọ àwọn alákòóso mejeejila ati agbègbè tí olukuluku wọn ń mójú tó nìwọ̀nyí: Benhuri ní ń ṣe àkóso agbègbè olókè Efuraimu; 
Awọn kan gbagbọ pe ifiyajẹra ẹni ni ki eniyan fi ile rẹ silẹ lọ sibi ayẹyẹ, ki wọn o wa fun ni ounjẹ bi gari ati ẹja dindin.
Bẹẹ lo tun ni ki awọn ile iṣẹ naa maa san miliọnu marundinlọgbọn naira lọdọọdun fun awọn gẹgẹ bi owo ori lori ọkọ ẹgbẹrun un kan ati ọkan to ba wa nikawọ rẹ.
 Kọmiṣọna naa ṣalaye pe, eto aabo ayika ki n ṣe nnkan tuntun nipinlẹ Eko, nitori ipinlẹ ọhun ti ni ẹsọ alabo ayika to dantọ tẹlẹ."
BB Naija: Ìjọba Ekiti ní Khafi kò tíì ṣẹ̀ sófin débi pé yóò nílò àtìlẹyìn wọn
Iwadii naa ni awọn to ku ninu oriṣiriṣi rogbodiyan ni orilẹ-ede yii ni lati ọdun mẹrin sẹyin din diẹ ni ẹgbẹrun mẹrindinlọgbọn.
Oríṣun àwòrán, @ELBINAWI Àkọlé àwòrán, Ìjọba fi ẹ̀sùn kan Zakzaky pé ó ń kó àwọn èèyàn jọ, lọ́nà tó lòdì sófin Amòfin kyon fi kun pé wọn kò leè tẹ̀síwájú lórí ẹjọ́ náà nítorí méjì nínú àwọn olùjẹ̀jọ́ ni kò yọjú sílé ẹjọ́.
Oríṣun àwòrán, Ayinla Omowura Àkọlé àwòrán, Ayinla Ọmọwura, orin èébú àti oríyìn lo fi di ọ̀rẹ́ àwọ̀n obìnrin Taa ni Ayinla Ọmọwura?
Ewe, o salaye pe, ofin orile-ede Ghana so pe, ile-ise ijoba ti o n ri si oja ohun alumoni orile-ede naa gbodo se ayewo, ki si wa ni ibamu, ki won to ta si ile-okeere.
Oríṣun àwòrán, @lasemasocial Àkọlé àwòrán, ni nnkan bi aago mẹsan abọ alẹ ọjọ Abamẹta ni ọkọ naa yọnu ti o si da ero inu rẹ sodo O ni wọn n lọ si Badagry, sugbọn bi wọn ṣe n lọ, ọkan ninu awọn ero ọkọ tako iye ti awakọ pe owo ọkọ.
Ẹ jẹ ka bẹrẹ lati ọdọ oṣere to si ile tuntun laarin ọsẹ yii.
Ìkookò ati ọmọ aguntan yóo jọ máa jẹ káàkiri; kinniun yóo máa jẹ koríko bíi mààlúù,erùpẹ̀ ni ejò yóo máa jẹ, wọn kò ní máa panilára.
Wọ́n ya ara wọn sọ́tọ̀ kúrò lọ́dọ̀ àwọn àlejò, wọ́n dìde dúró, wọ́n sì jẹ́wọ́ ẹ̀ṣẹ̀ wọn ati gbogbo ẹ̀ṣẹ̀ àwọn baba wọn.
Alaaji Sulukaleem Ọsinbẹru, Alaga Igbimọ Aṣamojuto Adugbo ni ilu Ikẹja ti oun naa gboriyin fun agbekalẹ abadofin naa sọ pe o yẹ ki abadofin naa le dabaa iye owo ti awọn oṣiṣẹ naa yoo maa fi forukọ silẹ labẹ eto yii.
Lẹ́yìn tí àpótí OLUWA ti wà ní ilẹ̀ Filistini fún oṣù meje, 
Ogbeni ,Livinus Okoh ti o je
Ewe, jijawe olubori ninu ifesewonse ohun, lo so di ifesewonse mokanla ti iko Bayern ti yege le ra won.
Ìjìyà wa mọ níwọ̀n, ati pé fún àkókò díẹ̀ ni.
Nígbà tí Huṣai dé, Absalomu wí fún un pé, “Ìmọ̀ràn tí Ahitofeli fún wa nìyí, ṣé kí á tẹ̀lé e?
Àlàyé rèé lórí ìdí tí ẹgbẹ́ òṣìṣẹ́ kò fi ní bẹ̀rẹ̀ ìyanṣẹ́lódì mọ́ lónìí Ẹgbẹ awọn oṣiṣẹ lorilẹede Naijiria, Nigeria Labour Congress ati akẹẹgbẹ rẹ, Trade Union Congress, ti fagile iyanṣelodi ọlọjọ gbọọrọ to yẹ ko bẹrẹ loni.
Ní àkókò yìí, Heberi ará Keni ti kúrò ní ọ̀dọ̀ àwọn ará Keni yòókù tí wọ́n jẹ́ ìran Hobabu, àna Mose, ó sì pàgọ́ sí ẹ̀bá Kedeṣi lẹ́bàá igi oaku kan ní Saananimu.
Ninu ọrọ tirẹ, Adedibu ni alaamọrẹ ẹda ni Ladọja, ti o si saa gbogbo ipa rẹ lati jẹ ki o kuro nipo gomina nipinlẹ naa, amọ o lo saa rẹ tan, idibo miran ni ko bori ninu rẹ mọ.
mo hùwà òmùgọ̀, n kò sì lóye,mo sì dàbí ẹranko lẹ́gbẹ̀ẹ́ rẹ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Jeremiah Addo: Ọmọ ọdún méjì tó ṣeeṣe kò mọ̀wé jù l'ágbàáyé Apapọ esi idibo ti wọn ti ka ni: PDP: 763,603 AAC: 162,180.
Ọjọ kọkandinlọgbọn oṣu kẹta ọdun 2019 lo yẹ ki ilẹ Gẹẹsi of fi aaarin awujọ ilẹ Yuroopu, EU silẹ ṣugbọn nitori awọn aigbọraẹniye ti o n waye laaarin awọn adari orilẹede naa lori rẹ,ajọ EU ti fun wọn di ọjọ kejila oṣu kẹrin lati fi tun ile wọn to.
Buhari sọrọ naa lẹyin wakati mejidinlaadọta ti iroyin sọ pe, awọn ọmọogun kan lọ ṣina ibọn bolẹ fawọn oluwọde lagbegbe Lekki nilu Eko.
jẹ́ kí apá mi já kúrò léjìká mi,kí ó yọ ní oríkèé rẹ̀.
Ẹni to bori: Congo DR Ìpele to ṣaaju eyi to kangun si aṣekagba Egypt vs South Africa.
Nítorí pé ẹ kò tíì dé ibi ìsinmi ati ilẹ̀ ìní tí OLUWA Ọlọrun yín yóo fun yín.
Ko jẹ bo ṣe jẹ, awọn ọmọ Naijiria ti n wa ọna ati kowojọ lati mu ọmọdebinrin alagbe naa kuro loju popo ki wọn si ran an lọ ileewe.
O ti mú ìlérí rẹ ṣẹ fún baba mi, Dafidi, iranṣẹ rẹ.
City kanra mọ́ Brighton gba Líìgì mọ́ Liverpool lọ́wọ́ Àkọ́dá oró.
Ó sọ fún wọn pé, ‘Ẹ̀yin náà ẹ lọ sinu ọgbà àjàrà mi, n óo sì fun yín ní ohun tí ó bá tọ́.
Wọ́n wí fún àwọn amí náà pé, “Ẹ lọ kí ẹ sì yẹ ilẹ̀ náà wò.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ilaji ọlọpa Naijiria lo n se dongari fun oloselu 20 Èrèlè 2018 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ariwo ko si ọlọpa to to ni awọn eeyan orilẹede Naijiria npa Aadọjọ ẹgbẹrun ọlọpa lorilẹede Naijiria lo n se isẹ dongari fawọn oloṣelu lorilẹede Naijiria.
" Ni ti awọn ọmọ Naijiria to wa loke okun, o ni ajọ naa ti wa lawọn orilẹ-ede bii Amẹrika ati Canada, ki awọn ọmọ Naijiria to wa lọhun lee forukọ silẹ lai si idiwọ.
Ọjọ Iṣẹgun ni iṣẹlẹ naa waye nibi ipade oniroyin kan ti Fani-Kayode, ti n ba awọn akọroyin sọrọ nilu Calabar, lori irinke-rindo rẹ ni awọn ipinlẹ to wa ni Gusu-Gusu Naijiria.
Nigerian high commission in Ghana: Ọ̀rọ̀ n yanjú bọ̀, ìjọba Ghana ni yóò kọ́ ilé tí àwọn kan wó
Ọkunrin náà dáhùn pé, “Ta ló fi ọ́ jẹ olórí ati onídàájọ́ wa?
Ó bi iranṣẹ Abrahamu náà pé, “Ta ni ó ń rìn ninu pápá lọ́ọ̀ọ́kán tí ó ń bọ̀ wá pàdé wa yìí?
 o je eni akoko to soro nipa iseona tuntun to un je jazz poetry .
Igbimọ oluwadii yii si lo ṣe iwadii olori ile ni ọjọ abamẹta to kọja, ti wọn si ti jabọ iwadii wọn bayii nipa awọn ẹsun mẹrẹẹrin naa.
Kò fẹ́ kí ẹnikẹ́ni mọ̀, ṣugbọn kò lè fi ara pamọ́.
Ilé-isẹ́ ìpòogùn Johnson & Johnson san biliọnu 8 dọ́là fún ẹni tóògùn gbòdì lára rẹ̀!
Bẹ́ẹ̀ ni ọ̀wọ́ mejeeji àwọn tí wọ́n wá ṣe ìdúpẹ́ ṣe dúró ninu ilé Ọlọrun, ati èmi pẹlu ìdajì àwọn baálé baálé.
Ṣùgbọ́n ọmọlúàbí ni, kò jẹ́ fi ojú pa ẹnikẹ́ni rẹ́ kó sì mọ ti ara rẹ̀ nìkan.
Wo àwọn orílẹ̀èdè míràn tó ń fojú winá ìwọ́de bíi ti ENDSARS Oríṣun àwòrán, Reuters/aisha yesufu Bi awọn ọdọ lorilẹede Naijiria ṣe n wọde lati tako iwa kotọ awọn ọlọpaa ati iṣejọba ti ko fararọ lati nnkan bii ọsẹ kan sẹyin,iwọde n lọ lawọn agbegbe miran lagbaye, ojo iwọde Naijiria to n rọ ni ko jẹ kaye mọ pe awọn eeyan iwọde ,miran lagbaye n tọ sara.
 bába mi fi yé mi pé àwọn ojúlé tí wa ní Ọ ̀ ra nígbà òun gbọ ́ njú ni Ìperin , Ìjásíọ ̀ , Òkè-Òpọ ́ , Òkèágbalá , ilé atè , odò àbàtà , Òkè-akànangi , okèkàngá , Òkèọ ́ jà , odìda , odòò mìjá , Òkèwugbó , ilé Ásánlú , ilé akòoyi , ilé sansanran , odònóíṣà ilé ọba-jòkò , ilé eésinkin-Ọ ̀ ra ilé ìyá Ọ ̀ ra , ilẹ ́ ọ ̀ dogun , ilé ọ ̀ gbara , ilé olúpo , kereèjà , àti ilé jégbádò .
Lati ọjọ kejilelogun oṣu kejila ọdun 2018 ni iṣejọba ni Amerika ti dẹnu kọlẹ nitori pe awọn ọmọ ile asofin kọ lati buwọlu owo ti Aarẹ Trump fẹ fi kọ ogiri ti yoo ya Amerika ati Mexico lọtọọtọ.
“Ní ọjọ́ náà OLUWA yóo súfèé pe àwọn eṣinṣin tí ó wà ní orísun gbogbo odò Ijipti ati àwọn oyin tí ó wà ní ilẹ̀ Asiria.
Kí ló dé tí àpẹrẹ tó fi hàn fún àwọn kan lágbára jù tí àwọn míràn lọÀàrùnCovid-19 kii se nkan tó nira fún ọ̀pọ̀ ènìyàn rárá.
 Wo pàtàkì ayájọ́ ‘Má wọ kọ́mú’ tó kò lónìí Ẹ jọ̀ọ́, òógùn ojú mi kò gbọdọ̀ já sásán lórí sinimá tí mo yà pẹ̀lú oyún oṣù mẹ́fà - Toyin Abraham Ẹgbẹ́ òṣìṣẹ́ ẹ múra sílẹ̀, ìjà ń bọ̀ lórí owó oṣù tuntun lọ́jọ́rùú - NLC kéde fáráyé Àwòrán bí ẹ̀kún omi ti ṣọṣé l'Eko àtàwọn ìlú míì nílẹ̀ Yorùbá rèé Aisha tẹsiwaju pe ""Ẹni ti wọn ni Buhari yoo gbe niyawo gan ko lero pe igbeyawo naa ko ni waye, nitori o duro titi di igba ti igbeyawo ọhun ko ṣeeṣe, ki obinrin naa to sọrọ lori iroyin naa."
Kemi Olunloyo ń làjà láàrin Toyin àti Lizzy lọ́wọ́ Ìjà Toyin àti Lizzy kìí ṣe àkọ́kọ́, àwọn òṣèré t'ọ́rọ̀ ìjà kàn rí rèé Àjò ní ààrẹ Tunísia nígbà kan rí kú sí.
Wọ́n bá ń súré láti gbogbo àdúgbò ibẹ̀, wọ́n ń gbé àwọn aláìsàn wọn lórí ibùsùn wá sí ibikíbi tí wọn bá gbọ́ pé Jesu wà.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Johesu ni oun mo wi pe ara yoo ni awọn ara ilu lori idasẹsile naa ''Awọn Dokita nikan kọ ni osise ilera to wa ni Naijiria.
Ayọ̀ ni ìrántí olódodo,ṣugbọn orúkọ eniyan burúkú yóo di ohun ìgbàgbé.
Awn olorin ẹmi ni Naijira ati lati awọn orilẹede mii - Tope Alabi, Ron Kenolly, Sammy Okposo, Yetunde Are, TY Bello, Muyiwa Olanrewaju, BJ SAx, Ibiayo Jeje, Polmira, USA, Alabi Oke, Psalmos, Efe Nathan, Seyi Ajayi, Tosin Alao, Mike Aremu ati bẹẹ bẹẹ lọ.
Ọwọja ikọlu wọn naa wa tubọ peleke si lasiko ti ijọba Muhammadu Buhari de ori aleefa, ẹni ti oun gan jẹ ẹya Fulani.
ipa ati agbara ti o ni sin orile ede re fun ogbon odun.
Oríṣun àwòrán, Twitter/ajimobi Àkọlé àwòrán, Ajimobi pelu Emir tilu Kano tẹlẹ, Sanusi Lamido Sanusi lasiko ti wọn jọ n fi ọrọ jomitooro ọrọ Oríṣun àwòrán, Twitter/ajimobi Àkọlé àwòrán, Kò ṣẹlẹ rí nilẹ Ibadan, Ajimọbi pẹlu awọn agba oye ilẹ Ibadan to gbe soke di Ọba lọjọ kan ṣoṣo Oríṣun àwòrán, Twitter/ajimobi Àkọlé àwòrán, Ajimobi pelu Alaafin Oyo, iku baba yeye Adeyemi kẹta lasiko ti Ajimọbi fi n tukọ ipinlẹ Oyo gẹgẹ bii gomina Oríṣun àwòrán, twitter/Ajimobi Àkọlé àwòrán, Ọrẹ la o maa ṣe!
Bí ẹ̀gún ṣe máa ń ta ninu iná, lábẹ́ ìkòkò, bẹ́ẹ̀ ni ẹ̀rín òmùgọ̀ rí.
Ẹ̀yin aṣòfin túntun, ẹ má gbàgbé ẹni gbé'ṣẹ́ fún ni o - Saraki #Democracy Day: Pápá ìṣeré Abuja di MKO Abiola Stadium Buhari kò tíì ṣe to lóri June 12- NADECO MKO Abiola, iṣẹ́ aṣẹ́gità ló fi bẹ̀rẹ̀ okoòwò Kókó inu ọrọ Aarẹ Buhari: Aarẹ Buhari bẹrẹ nipa ṣiṣe alaye kikun lori pataki Naijiria ninu idagbasoke iṣejọba alagbada nilẹ Adulawọ.
Naijiria ,nibi won gbe  safihan awon
Òkùnkùn bò wọ́n ní ọ̀sán gangan,wọ́n ń fọwọ́ tálẹ̀ lọ́sàn-án bí ẹnipé òru ni.
Bakan naa ni Hon Kawu fikun pe ti wọn ba pari iforukọsilẹ awọn ọmọ ẹgbẹ pẹlu yiyanju aawọ aarin wọn, ni eto ipade apapọ yoo to waye.
Ìjàǹbáforítì ló kọ́kọ́ ddí mọ́ra tán nínú wa bí ó sì ti múra ni ó bọ́ sí òde tí ó kígbe ńlá, ó ní, Ẹni tí ó bá tóó jáde kí ó jáde, Ìjànbáforítì ṣetán, Ìjànbáforítì ń lọ.
Hakeem: Idán inú eré sinimá ti gbàràdá ní Nàìjíríà
Opọ̀ ìgbà ni NDLEA máa ń jáde lọ kó àwọn ti wón ń mu oògùn ikọ́ olómi Codeine bíi egbògi olóró pàápàá ní ìpínlẹ̀ Kano.
Nítorí pé ọjọ́ ti lọ,ilẹ̀ sì ti bẹ̀rẹ̀ sí ṣú!
Ní tèmi o, mo lérò pé ó yẹ ki àwọn oníṣòwò wa yé ná UK lemọ́-lemọ́.
Ẹ má fetí sí ọ̀rọ̀ wọn.
Ẹ jókòó sí ilẹ̀ yín gbogbo ẹ̀yín tó fẹ́ lọ sí Mecca Òbinrin kan fẹ́ ọkọ méjì torí ọkọ àkọ́kọ́ rìnrìnàjò fún ọdún méjì péré Pupọ awọn to ba kọlu aarun yii maa n ni ailera diẹ, wọn o si tun pada bọ sipo ilera wọn pada, ṣugbọn bẹẹ kọ lọrọ ri fun fun awọn miran.
Aladugbo miran ṣalaye pe kii ṣe igba akọkọ niyi ti yoo waasu wa si ile itura naa, Ṣugbọn kii sunmọ wọn pupọ to bi o ṣe ṣe lọjọ naa.
- Sanwoolu Ṣé Èdùà dá ààtàn isó ni?
Ireti wa pe ijọba orilẹ-ede Italy naa yoo kede ilana tuntun lọjọ Aje.
Ọjọ́ kẹjọ lẹhin ọdún Kérésìmesì ni ọdún  tuntun.
Eyi jẹyọ ninu atẹjade kan ti ọga agba ajọ naa, Ọjọgbọn Christianah Adeyeye fi sita.
Ọ̀kẹ́ kan ó dín ẹgbaa (18,000) ninu àwọn akikanju ará Bẹnjamini ni àwọn ọmọ Israẹli pa.
Kọmisana ajọ ọlọpaa nipinlẹ Ọyọ, Ṣina Olukolu lo ṣe afihan awọn ọdaran naa lọjọ Aje ni olu ileeṣẹ ọlọpaa to n bẹ ni agbegbe Ẹlẹyẹle niluu Ibadan.
Ni ọṣẹ to n bọ lawọn ikọ orilẹede Gẹẹsi naa yoo ma mọ ohun ti ifa bọọlu fọ fun wọn.
labe asia egbe oselu PDP nitori pe o tako ofin 
Ó di ìgbà ayé ọmọ rẹ̀ kí n tó jẹ́ kí ibi ṣẹlẹ̀ sí ìdílé rẹ̀.
Agassi, eni akoko lagbaye teleri, ni yoo wa pelu Djokovic ni orile-ede Faranse ni ilu Paris, ninu idije boolu afibaati gba miran ti yoo bere lojo kejidinlogbon osu karun un odun yii.
Nígbà tí OLUWA bá ti ké gbogbo àwọn ọ̀tá Dafidi kúrò lórí ilẹ̀ ayé, 
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ọ̀fẹ́ ló bá dé, Boko Haram kọ́ ló jí akẹ́kọ̀ọ́ gbé, a kò san kọ́bọ̀ fún ìdáǹdè wọn - Masari Ṣé lóòtọ́ ni Bimpe Oyebade lóyún fún Lateef Oladimeji?
Alufaa yóo fi àgbò ẹbọ ìmúkúrò ẹ̀bi náà ṣe ètùtù fún un níwájú OLUWA nítorí ẹ̀ṣẹ̀ tí ó dá, OLUWA yóo sì dárí ẹ̀ṣẹ̀ rẹ̀ jì í.
" Ó ṣàlàyé pé ẹgbẹ́ Atunbi dá dúró gedegbe, ó sì ń ṣe igbe lárugẹ àṣà, kò fi ti òṣèlú àti ẹ̀sìn ṣe.
Wọ́n sọ fún wọn wípé àwọn dúró lé oríi ẹ̀sùn tí wọ́n fi kan àwọn.
- Madam Saje Fidio tuntun yii ni Lizzy gbe jade lẹyin ti awọn oniroyin kan n gbe iroyin pe, o ti rawọ ẹbẹ si Toyin, sugbọn o ni ọrọ ko ri bẹẹ rara.
Abiola Ajimobi: Irọ́ ikú làá pa mọ́ àdá, kokoko lara baba wa le, ẹbí Sẹ́nétọ̀ Abiola Ajimobi pariwo síta láàrín ìròyìn ikú rẹ̀
Jeṣua, ọmọ Josadaki pẹlu àwọn alufaa ẹgbẹ́ rẹ̀ ati Serubabeli, ọmọ Ṣealitieli, pẹlu àwọn ìbátan rẹ̀ tún pẹpẹ Ọlọrun Israẹli kọ́, kí wọ́n baà lè máa rú ẹbọ sísun lórí rẹ̀ gẹ́gẹ́ bí a ti kọ ọ́ sinu ìwé òfin Mose, eniyan Ọlọrun.
Pásítọ̀ gún ìyàwó rẹ̀ lọ́bẹ nínú ṣọ́ọ̀ṣì, ló bá tì í bọ ara rẹ̀ náà níkùn Wo àwọn ọ̀tá tó ń da orílẹ̀èdè Nàìjíríà láàmú Kí ni Buhari sọ nípa ààrẹ tó kàn lọ́dún 2023?
Ni bayii ti ọwọja eruku rogbodiyan to gbode nitori iwọde ENDSARS ko tii lọ silẹ, o yẹ ka ran ara wa leti nigba iwọde alagbara naa ati bi ologun ṣe kọlu awọn akẹkọọ.
Nígbà tí ó bá yá, lẹ́yìn ọpọlọpọ ọdún, yóo pada wá pẹlu ikọ̀ ọmọ ogun tí ó lágbára, pẹlu ọpọlọpọ ihamọra ati ohun ìjà.
Bi Marie Bonaparte ṣe n dagba si, mu ki o yi ero rẹ pada lori imọ ijinlẹ rẹ lori ibalopọ fun obinrin.
Oríṣun àwòrán, @KhafiKareem Fọnran fidio yii ṣe afihan rẹ nibi ti o ti n gbiyanju lati sọ Yoruba lasiko ọdun Keresimesi ni ọdun 2016 Khafi ni oun to le mu ki oun kuro lori eto naa ni ki wọn fi dandan mu oun lati ṣe nkan to niṣe pẹlu ibalopo.
Ẹ lọ wá inú ìwé OLUWA,kí ẹ ka ohun tí ó wà níbẹ̀.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: 'Ìwà ìdòjútì láwọn olólùfẹ́ Chelsea hù' Buhari, tọwọ́ ọmọ rẹ basọ- Timi Frank Linda ní òun àti bàbá ọmọ òun ti túká Nigba ti o n ba BBC sọrọ, Salah ni inu oun dun lati gba ami ẹyẹ naa lẹẹkan si.
Ní ọ̀nà kejì, Ezekwesili, Moghalu, Sowore, àwọn “agbára ìkẹ́ta”, jẹ́ ẹgbẹ́ tí ó ń wọ inú ètò ìṣèlú fún ìgbà àkọ́kọ́.
Gbogbo wa ló sì yẹ ko maa huwa bi o ti tọ̀ gẹ́gẹ́ bí Ọba ilẹ̀ Yoruba.
Eyi ti mu ki ọpọlọpọ wa bẹrẹ si ni ro meni meji pọ pe ọkọ ati aya ti pada fa oju ara wọn mọra.
Koffi Olomide: Ilé ẹjọ́ kan nílẹ̀ Faranse ló sọ́ sẹ́wọ̀n ọdún méjì
Gígùn àkànpọ̀ igi kọ̀ọ̀kan jẹ́ igbọnwọ mẹ́wàá, fífẹ̀ rẹ̀ sì jẹ́ igbọnwọ kan ààbọ̀.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Charles Okah ati Obi Nwabueze gba'dajọ ẹwọn gbere Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Charles Okah ati Obi Nwabueze gba'dajọ ẹwọn gbere 8 Ẹrẹ̀nà 2018 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 9 Ẹrẹ̀nà 2018 Ileẹjọ giga ijọba apapọ to kalẹ silu Abuja ti ran Charles Okah ati akẹẹgbẹ rẹ ti wọn dijọ njẹjọ, Obi Nwabueze ni ẹwọn gbere.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Nigeria Visa: Ìjọba Naijiria ti mú ẹ̀dínkù bá owó ìwé ìrìnnà fún àwọn ọmọ ilẹ̀ Amerika láti wá sí Naijiria 28 Ògún 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 30 Ògún 2019 Oríṣun àwòrán, Google Àkọlé àwòrán, Láìpẹ̀ yìí ni ìjọba orílẹ̀-ède Amerika polongo àfikún owó ìrìnna fún àwọn ọmọ Naijiria tí ó bá fẹ́ wá sí Amerika.
OLUWA àwọn ọmọ ogun ti pinnu; ta ni ó lè yí ìpinnu rẹ̀ pada?
Minisita fun oro ile Okere lorile-ede Sudan so pe, orile-ede Sudan yoo da asoju re pada sorile-ede Egypt ti o je amulegbe re lojo-Aje, leyin ti o pe asoju naa pada lati bi osu meji latari igbokan soke ati papaleke to n waye.
DAAR Communications: AIT, RayPower padà lẹ́yìn àṣẹ ilé ẹjọ́
O ni ayeye ajodun asa kii se fun ere idaraya nikan, bi kii se lati tun pese ise ati idagbasoke fun eto oro aje lorile ede Naijiria.
Ọdaju ni iku, iku ti kii gba owo tabi dukia afi ẹmi ẹda, ka ni iku n gba owo ni, owo nla ni ko ba gba lati fi ẹmi ọlọla Akin-Olugbade silẹ.
0 509 Orilẹede Liechtenstein 19 50.
Amọ ki wọn to gbe ilẹkun ti, ni Auxillary ti sọ fun ọga rẹ atijọ pebaba ni baba rẹ yoo maa jẹ lọjọkọjọ, tori Tokyo si ni baba awọn ọmọ ẹgbẹ ọlọk ero nipinl Ọyọ.
Gẹ́gẹ́ bá ṣe rii ka lójú òpó itakun agbaye àti nínú àwọn inú ìwé ìtàn lorisirisi, onírúurú nkan lo ṣokùnfà ogun Ìjàyè àti ìṣubú Ààrẹ Kurunmi.
Ẹyin ni wọ́n fi n gba ìbále ẹlòmiran lára wa ki a to lọ pàde àwọn oníbara Yaba Left: Àṣírí tú!
Obìnrin míràn gbẹ́mi mi torí pé o fẹ́ ki ìdí òun tóbi síi
Ooni of Ife: Ọ̀wọ́ Ọlọ́pàá ti tẹ arákùnrin tó fi tipá wọ ààfin Ọ̀ọni ilé ifẹ̀
Awakọ̀ Maruwa tó bá gbé okùnrin àti obìnrin papọ ní Kano yóò jẹ búlálà mẹ́wàá- Hisbah Ilorin gbàlejò Wizkid, àwọn olólùfẹ́ rẹ̀ fẹ́ ẹ̀ gbée lójú agbo Èyí ni bí wọ́n ṣe n dìbò yan Póópù tuntun nínú ìjọ Àgùdà Ẹ ronúpìwàdà lásíkò ọdún, àti àwọn ìkíni mìrán tó jẹ yọ fún Kérésì Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Mo n wa'yawo - Falz Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Lẹ́hìn ìgbà yí ni Ọ̀gbẹ́ni Barbier bá Ọ̀gbẹ́ni Braille pàdé ní ìlú Paris ní ọdún 1821 nígbàtí ó ṣe àbẹ̀wò ló sí ilé-ẹ̀kọ́ àwọn afọ́jú.
Gẹgẹ bi Afod ṣe sọ, o ni ọdun 1973 ni wọn bi oun.
 ní ọdún yì , ààrùn yí ti pa ó kééré láàrin 473,000 àti 789,000 ènìyàn , ọ ̀ pọ ̀ tí ó jẹ ́ àwọn ọmọdé ní Áfíríkà .
Oríṣun àwòrán, Others Sharia Law in Nigeria: Wọ́n dájọ́ ikú fún Baba 61 tó fipá b'ọ́mọdé kan lò pọ̀ ni Kano Iléẹjọ́ Sharia kan ní Kano ti ní kí wọ́n lọ sọ̀kò pa bàbá ẹni ọdún mọ́kanlélọ́gọ́ta kan.
Nigbati o n sọrọ iṣẹlẹ naa, darandaran Fulani to ni agbo maalu ọhun Abdulkadri Kadiri sọ pe ọrọ naa ko gba ibi kankan ye oun.
Ti ẹ ba ranti, ọjọ kejilelogun oṣu kẹrin ni ajọ naa fi to ọmọ Naijiria leti wipe ileeṣẹ to n boju to abo ara ẹni ati aabo ilu (NSDCD) fi panpẹ ọba mu awọn ọgọrun eniyan to n ṣe idanwo UTME.
oloogbe Abiola ku ninu iyanju lati ja fun eto re.
O so bi iya rẹ to jẹ ogbologbo ajẹ ati baba rẹ, Olowolayemmo se ku ki oun to di akọni eda.
Ibukun ni ọmọ jẹ, yoo si wu mi lati bi ju mẹtadinlogun lọ ti mo ba tun aye wa.
Gbogbo ayé mọ́lẹ̀ nítorí ẹwà ògo rẹ̀.
Pupọ ninu awọn gomina to ko arun naa lo ti gba iwosan.
Awon miran ti o tun kopa ninu igbami-eye ohun ni, amofin Seyi Akinwunmi, ti o je igbakeji aare NFF teleri, bakan naa ni awon omo egbe miran, alaga awon toro kan gbangban ninu ajo NFF, Mallam Shehu Dikko, abbl.
5 14375 Orilẹede Liechtenstein 49 129.
si awọn  ikọ agbabọọlu  Burundi ti won ko si lee ta putu titi ti idije
Lẹ́yìn wọn, Meṣulamu ọmọ Berekaya, ọmọ Meṣesabeli náà ṣe àtúnṣe abala ọ̀dọ̀ wọn.
nibi ayẹyẹ lati sami si ajọdun  ajo agbaye
Ipade naa to bẹrẹ ni irọlẹ Ọjọ Aje naa jẹ ọna lati wa wọrọkọ fi se ada lori awọn ohun ti ẹgbẹ osisẹ ASUU n beere fun ti wọn fi gunlẹ iyansẹlodi.
Lóòótọ́ èdè Gẹ̀ẹ́sì ló pabambarì káàkiri àgbàyé, àmọ́ a láti gbé èdè tiwa náà lárugẹ gẹ́gẹ́ bí àwọn ọmọ ibòmíràn ṣe máa ń ṣe.
Ṣé àjẹkù tí ẹ ti fi ẹsẹ̀ tẹ̀ mọ́lẹ̀ ni ó yẹ kí àwọn aguntan tèmi máa jẹ; omi àmukù tí ẹ ti fi ẹsẹ̀ dàrú sì ni ó yẹ kí wọn máa mu?
Áfíríkà yóò gba ife ẹ̀yẹ UEFA Champions league lónìí Kéré o!
Neko sì fi Eliakimu, ọmọ Josaya, jọba dípò rẹ̀, ṣugbọn ó yí orúkọ rẹ̀ pada sí Jehoiakimu.
Joshua gba awọn igbanu rẹ mẹtẹẹta, IBF, WBA ati WBO pada lọwọ Andy Ruiz Jr pada lẹyin ti Ruiz ti kọkọ lu u bi aṣọ ofi nigba ti wọn kọkọ koju ara wọn.
“Ó di ẹ̀ṣẹ̀ mi bí àjàgà,ó gbé e kọ́ mi lọ́rùn,ó sì sọ mí di aláìlágbára.
Àkọlé àwòrán, Awọn ọmọ Nàìjíríà bá aarẹ Buhari sọ̀rọ̀ lójú òpó BBC lórí ètò ààbò ìlú Idi ti EFCC ṣe mu Sheu Sani S'ahamọ.
Nígbà tí ohùn wọn kò dọ́gba láàrin ara wọn, wọ́n bá ń túká lọ.
Àwọn ọlọ́gbọ́n láti ilẹ̀ Ṣemeri wà lọ́dọ̀ rẹ,àwọn ni wọ́n ń darí ọkọ̀ ojú omi rẹ.
Ọna abayọ si awọn ipenija bi ọmọbinrin se n darugbo ni ki ọmọbìnrin bimọ tan ni ọmọ ọdun marundinlogoji Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Dokita onimọ nipa obinrin ni irinwo ẹyin lo wa lara obinrin ati wi pe osoosu si ni ẹyin naa n dikun lasiko ti wọn ba n se nkan osu.
Lasiko ti ikọ iroyin BBC Yoruba ṣe abẹwo si ilu naa, pupọ ninu awọn olugbe ilu naa ni wọn ti di asunta nitori airi'le gbe.
pé kí ó lọ pa ẹran wá fún òun, kí ó sì se oúnjẹ aládùn kí òun lè jẹ ẹ́, kí òun sì súre fún un níwájú OLUWA kí òun tó kú.
Oniruuru owe ati asamọ lo wa nilẹ Yoruba.
‘Olùkọ́ fipá bá akẹ́ẹ̀kọ́ girama lòpò nítorí máàkì’ Gómìnà mẹ́rin yóò jẹ́jọ́ lẹ́yìn sáà wọn - EFCC Oju opo imọ ẹrọ Google naa ko gbẹyin ninu itanjẹ Ọjọ April Fool.
Ni ọjọ kẹrinlelogun, oṣu kẹfa, ọdun 1923, Macaulay da ẹgbẹ oṣelu Nigerian National Democratic Party (NNDP) silẹ, eyi to jẹ ẹgbẹ oṣelu akọkọ nilẹ Naijiria.
Tọ́ wọn sí ọ̀nà tí wọn yóo máa tọ̀, kí o sì jẹ́ kí òjò rọ̀ sí ilẹ̀ tí o fún àwọn eniyan rẹ gẹ́gẹ́ bí ìní wọn.
Nibayii, ijọba sọ pe o ti wa nileewosan Mainland General Hospital, nibi ti wọn ti n tọju rẹ.
Ọlọpaa to wa nidi ẹjọ naa, Sajẹnti Regina Ishaya sọ fun ile ẹjọ pe, Arabinrin Myina Ifeyunwa lo mu ẹjọ naa wa si agọ ọlọpaa 'D' Division ni Markudi ni ogunjọ, oṣu kẹjọ, ọdun 2020.
Nígbà tí ìwọ bá ronupiwada, mu àwọn arakunrin rẹ lọ́kàn le.
pupo ninu won lo sese n ri iwe eto isuna naa gba bayii, ni eyi ti won si nilo
Akọsilẹ yii fihan pe tọdun 2008 lo peleke julọ si awọn aṣatipo ati alejo to n gbe ni South Africa.
Bí obinrin tí ó ní ọkọ bá jẹ́ ẹ̀jẹ́ tabi tí ó bá ṣe ìlérí láti yẹra fún ohunkohun, 
Ajọ iṣọkan agbaye ti sọ pe abọ iwadii ti oun ri gba fihan pe niṣe ni awọn oṣiṣẹ alaabo n yinbọn mọ awọn aṣatipo to n gbiyanju lati sa fun ado oloro.
Wọn ni alagidi ọkan kii gbọ ọrọ awọn eniyan ni loju ti wọn Oríṣun àwòrán, Tweet Àkọlé àwòrán, Ẹ̀kọ́ ọ̀fẹ́, ètò iléra ọ̀fẹ́ àti iná ọba lo jé wá lo jẹwa lógun Òṣèrébìnrin tí wọ́n bá fi ìbálòpọ̀ lọ̀ 'torí ìṣẹ́, kó bọ́ síta láti sọ̀rọ̀ - Kunle Afod Aisha Buhari, ohun mẹ́fà tò fi yàtọ̀ sí àwọn aya ààrẹ tó ti jẹ kọjá!
Nígbà tí àwọn ọmọkunrin wọnyi dàgbà, wọ́n lé Jẹfuta jáde, wọ́n sọ fún un pé, “O kò lè bá wa pín ninu ogún baba wa, nítorí ọmọ obinrin mìíràn ni ọ́.
Lati igba yẹn lati bẹrẹ si ni fi ọrọ ranṣẹ si ara wa daada, koda a maa n pe ipe oni fidio."
Ìdílé Pius Adesanmi ti gbé Boeing lọ sílé ẹjọ́ A kò lè gba àwọn jandùkú Fulani láàyé nílẹ̀ Yoruba -Awọn gómínà Ìwádìí fídíò ayélujára tú àṣìrì ìpànìyàn Boko Haram Lalẹ oni ni àwọn ikọ agbabọọlu Super Falcon to n ṣoju Naijiria yoo koju akẹgbẹ wọn lati Norway.
Ẹ wo, ẹ jẹ ka sọ diẹ lọrọ ka dakẹ, ẹ f'oju l'ounjẹ ayọ ninu fidio.
Kàkà bẹ́ẹ̀, Amnoni pe iranṣẹ rẹ̀ kan, ó wí fún un pé, “Mú obinrin yìí jáde kúrò níwájú mi, tì í sóde, kí o sì ti ìlẹ̀kùn mọ́ ọn.
Isaaki baba rẹ̀ bá pè é ó ní, “Súnmọ́ mi, ọmọ mi, kí o sì fi ẹnu kò mí lẹ́nu.
 ) Ó kọ ́ wa nípa irúfẹ ́ ìlò-èdè nínú ọ ̀ rọ ̀ geere .
Taye Currency: Seyi Makinde fún Taye Currency lẹ́bùn ọkọ̀ bọ̀kìnnì Toyota Prado 2020
Àjálù yóo máa yí lu àjálù, ọ̀rọ̀ àhesọ yóo máa gorí ara wọn.
”Awon musulumi  ni gbogbo agbaye ni won n sajodun yii.
Boya nitori pe ni ọdun yii ni baba ọkọ afẹsọna Darasimi Mike-Bamiloye, iyẹn Rev.
"A o le sọ nkan ti yoo sẹlẹ lọjọ iwaju sugbọn nkan to ṣe pataki julọ ni pe, didaabo bo awọn ọmọ Naijiria lo ṣe pataki julọ.
Ninu aduru ọrọ to fi sita, eyi ti awọn eniyan han ni bi o ti ni  Oni lọjọ ibi iyawo mi mo si fẹ́ ki awọn obinrin kọ awọn ẹkọ kan latara rẹ paapaa ọpọlọpọ awọn ọdọ."
Cross River, Rivers ati Delta loju eegun lojo naa.
Amọ, ile-isẹ Facebook ati Cambridge Analytica sọ ninu idahun wọn wipe awọn ko se ohun ti ko tọ Bi o se le da abo bo iroyin rẹ lori Facebook: Ẹma sọra fun awọn ẹrọ igbalode ti wọn maa n bere awon nọmba ti ẹ fi n si oju opo Facebook yin.
''Ọpọ nínú wọn ló yá owó ìrànwọ́ láti ọdọ àwọn àjọ àlàjẹ́sẹku ṣugbọn tí wọn kò lè rí sàn padà mọ nítorí pé kòkòrò yii tí ṣé àkóbá fún nnkan oko won.
Gbemisola Saraki: APC ló ni ìbò gomina ní Kwara ní Satide
Ìgbà tí a jẹ́un àárọ́ tán, mo bọ́ sí ibi tábìlì mi, mo kó àwọn ohun ìkọ̀wé jọ, mo sì pè é kí o jókòó tì mi kí ó bẹ̀rẹ̀ sí í sọ ìtàn ìgbésí ayé rẹ̀ fún mi.
Láti Saridi, ààlà ilẹ̀ náà lọ sí òdìkejì, ní ìhà ìlà oòrùn, títí dé ààlà Kisiloti Tabori, láti ibẹ̀, ó lọ sí Daberati títí lọ sí Jafia; 
Mohammed Adamu, jabo oro naa fun awon akoroyin leyin ipade igbimo NEC ti o waye
Bí ìjọba kan náà bá gbé ogun ti ara rẹ̀, ìjọba náà yóo parun.
Agbeyẹwo bi iṣẹlẹ yii ṣe n waye kaakiri Naijiria, eyi ko ri bẹẹ pẹlu bi o ṣe jẹ pe iha ila oorun ariwa orilẹede Naijiria ni wọn ti n ṣọṣẹ.
 dáúdà ( 1994 : 5 ) nínú ìwádìí tí ó ṣe pẹ ̀ lú alàgbà Ọládépò Ọbasá , èyí tó sẹ àkọsílẹ ̀ rẹ ̀ nínú iṣẹ ́ àpílẹ ̀ kọ rẹ ̀ , sọ pé ọ ̀ nà mẹ ́ rin ni a lè gbà pín àwọn Òrìṣà Òrìṣà ilè yorùbá sí .
Pupọ ninu awọn ẹsun naa niroyin sọ pe, o wa lati ọdọ Agbẹjọro Agba fun Naijiria, Abubakar Malami, ati aabọ iwadii ti ajọ DSS fun ile aṣofin laarin ọdun 2016 si 2017.
Ọmi odo ni ikọ mejeeji gba ni abala akọkọ idije naa.
Aarẹ Ali Bongo gba ipo ni ọdun 2009 ti o si ti fi orilẹede naa silẹ lati bi osu meji sẹhin.
Àfi bí eniyan bá lè wọn ojú ọ̀run,tí ó sì lè wádìí ìpìlẹ̀ ayé,ni òun lè ké àwọn ọmọ Israẹli kúrò,nítorí gbogbo ohun tí wọ́n ṣe.
 A ti ni omo egbe mẹ́tàdínlógójì  bayii sibe anfaani si wa lati gba awon omo egbe tuntun to ba fẹ darapo mọ wa,ki a le jo gbogun ti itankale arun kogboogun lorile ede Naijiria.
Ọmọ mi, gbọ́ tèmi,kí o sì máa kíyèsí ọ̀nà mi.
Ó tún bi wọ́n pé, “Ta ni ẹ̀ ń wá?
Oríṣun àwòrán, @AyowoleSanyaolu Ijọba ipinlẹ Eko ti fesi si iroyin iwadii CNN lori ohun to waye ni Lekki Toll gate logunjọ, oṣu kẹwaa, ọdun 2020.
2019 Election: Bí Buhari ba le lọ Kóòtù ní ẹ̀ẹ̀mẹ́ta- Obasanjo Èmi kò ṣeku-ṣẹyẹ, àyípadà ìṣàkóso Nàìjíríà ni mo faramọ́ - Ọbasanjọ Bí mo ṣe ń tako Buhari bá ìjọba tiwantiwa mu - Ọbasanjọ Ẹ múra fún ogun ijọba àpapọ̀ - Ọbásanjọ́ Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Olubowale ti gba ọpọ ami ẹyẹ, to si gbe ogo iran Yoruba larugẹ.
Erin fara gbọgbẹ̀, ó ṣekú pa ènìyàn méjì ni Liberia
” Àwọn ará Filistia bá lọ dáná sun iyawo náà ati baba rẹ̀.
Wọn ti ja ibale rẹ lati ọdun kẹtadinlogun nigba ti yoo si fi pe ọdun mọkanlelogun, o ti ni ibalopọ pẹlu ọkunrin ti ko lonka sugbọn ajọṣepọ oun pẹlu gbogbo wn ko pẹ rara.
Ó tún bí ọmọkunrin meje ati ọmọbinrin mẹta.
ọlọpaa lee ni ki o ṣe awọn ayẹwo kanbi ririn lori oju ila to gun kan.
Oríṣun àwòrán, Facebook/Kano Alhaji ṣalaye pe igbesẹ ijọba wa ni ibamu pẹlu ofin ajọ afọbajẹ ilu Kano ti ọdun 2019.
Lẹyin ọdun mẹwaa, o tun bori ni 1992, 1997, 2004 ati 2011.
Ọrọ pọ ninu iwe kọbọ eleyi ti Ọbasanjọ ti sọ fun aarẹ Buhari to fi mọ wipe nigbẹyin gbẹyin o gba aarẹ nimọran wipe ko fipo silẹ gẹgẹ bi aarẹ orilẹede Naijiria.
Àwọn ará Arifadi ati Heleki wà lórí odi rẹ yíká, àwọn ará Gamadi sì wà ninu àwọn ilé-ìṣọ́ rẹ.
Ile-ise iko omo-ogun Naijiria ti gba awon osise re niyanju ti o fi mo awon ebi won lapapo lati bere okoowo ohun osin ni papajulo lati tun fi mu igberu ba eto oro aje lorile-ede yii.
Àwọn ìjọ Kristi tí ó wà ní Judia kò mọ̀ mí sójú.
Ènìyàn 30 dé ojú ikú 'tori èéfí gẹnẹrétọ̀ NASS 2019: Gbùngbùn Àríwá ní Agbẹnusọ kàn- Umar Bago Lẹ́yìn ọ̀ rẹyìn, 'June 12' di àyájọ́ ọjọ́ ìjọba àwarawa Gẹ́gẹ́ bó ṣe sọ nínú àtẹjade kan to fi síta láti ọwọ́ akọwé rẹ̀ Alli Ibraheem, Oba Abdulrasheed ní okiki wọ́n ti dínku nípa àwọn ẹgbẹ́ ti wọ́n ń ṣe.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: OAU fẹ́ wádìí olùkọ́ tó fẹ́ bá akẹ́kọ̀ọ́ lò fún máákì Ọwọ́ tẹ afurasí 29 lórí ìpànìyàn Ìjẹ̀bú Igbó Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Olú Fálaè: Orúkọ àwọn jẹgúdújẹrá tí APC tẹ̀ jáde kò tíì pé Wọ́n se àgbéjáde òǹkà yìí ní New York lọ́jọ́ ajé níbi ìjókòó ìkọkànléláàdọ́ta ti àjọ náà lórí iye ènìyàn àti ìdàgbàsókè.
Pada lọ nisinsinyii, kí o sì kó àwọn eniyan náà lọ sí ibi tí mo sọ fún ọ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Cameroon: Àṣírí èèyàn kan tó dìbò ní ìgbà 89 tú, Ọlọ́pàá gbé e jàǹtò!
Ẹ má máa da omi tútù sí àwọn tí ó ní ẹ̀bùn Ẹ̀mí Mímọ́ lọ́kàn.
Ọlọrun Baba Oluwa wa Jesu, ẹni tí ìyìn yẹ fún títí lae, mọ̀ pé n kò purọ́.
Oríṣun àwòrán, Ajimobi Lara wọn ni Idris Ajimobi, to fẹ ọmọbinrin Gomina Abdullahi Ganduje tipinlẹ Kano ni aya pẹlu Abisola to fẹ ọmọ Oloye Kola Daisi, tii ṣe gbajugbaja olokoowo ni ọkọ.
Baba-onírùngbọ̀n-yẹ́úkẹ́ wí fún wa pé àjèjì omi ní ń bẹ nínu’igò tí ó fún wa nì àti wí pé kò sí nǹkan tí a kò lè fi í ṣe: bí a bá dà á sí orí ewéko tí a wí pé ewéko náà yípadà kí ó di ènìyàn, yóó di ènìyàn, bá a wí pé kí ó di ẹranko, yóó dí ẹranko nítorí àṣẹe Ọlọ́run ń bẹ lára rẹ̀.
Ìbòrí kan tí a fi pákó ṣe wà níwájú ìloro ní ìta.
 aberdeen angus ni wọn máa ń pe orúkọ àgùntàn kan tí ó gbajúmọ ̀ ní aberdeen .
Ṣugbọn Jesu mọ ohun tí wọn ń sọ, ó ní, “Kí ló dé tí ẹ fi ń sọ láàrin ara yín nípa oúnjẹ tí ẹ kò ní, ẹ̀yin onigbagbọ kékeré?
Nigba to ya, Adegbọrọ ranti pe ile ni abọsinmi oko, to si gba ilu Ibadan, tii se ilu abinibi rẹ lọ lati kọ ile.
Ìròyìn to tẹ wá lọ́wọ́ so pé, àwọn ọmọ onílẹ̀ ló ń gbìyànjú láti gba ilé kan, táwọn onílé náà si kọ jalẹ̀ láti jọ̀wọ́ ilé náà fún wọn.
Rida jẹ agbabọọlu nigba kan ri ko to wa gba ipo adari ajọ naa lọdun 2016.
5m owó oyè tó gbà lọ́wọ́ òkú padà, àwọn ará ilé rẹ̀ ń bèèrè - Olúbàdàn Oyè Ibadan kò sí fún títà - Otun Olubadan, Lekan Balogun Owó àwọn aṣòfin kò pọ̀jù, iṣẹ́ kàbàtì tí wọn ń ṣe ju owó oṣù wọn lọ - Buhari Kò síbi tó dàbí ilé, tìlù-tìfọn ni wọ́n fi kí Anthony Joshua tó bẹ ìlú rẹ̀, Ṣágámù wò káàbọ̀ Àbòsí ló wà níbẹ̀ tí ìpínlẹ̀ Eko ò bá ṣe Amotekun- Bode George Nigba to n gbe idajọ rẹ kalẹ lori ẹsun naa, Adajọ Josephine Oyefẹsọ ni afurasi naa mọ bi ọran to da se lowura to, ati bi ijiya rẹ se gbopọn si, nitori oun lo fi tipa jabale ọmọ naa.
Wo ọ̀nà tí o fi lè dáàbò bo ọmọ rẹ lọ́wọ́ COVID-19 níléèwé Kò sí iléẹjọ́ tó le dá wa dúró, ìyanṣẹ́lódì yóò bẹ̀rẹ̀ ní Ọjọ́ Ajé - NLC Wo iye ìgbà tí ẹgbẹ́ òṣìṣẹ́ àtàwọn ọmọ Nàìjíríà ti ṣèwọ́de lórí àfikún owó epo bẹntírò Èkúté tó sàwárí bọ́mbù ilẹ̀ gbàmi ẹ̀ye wúrà fún iṣẹ́ takuntakun Agbára àwọn bàbá ìsàlẹ̀ ti ń lọ sílẹ ní Nàìjíríà, Ọlọ́run ni bàbá ìsàlẹ̀ mi Gomina Ipinlẹ Ondo, Rotimi Akeredolu ti ni ilana bi oun ṣe di gomina ti safihan pe oun ko ni gbagbọ rara ninu agbara baba isalẹ.
Wọn ni ayẹwo awọn yoo sọ boya awọn ṣe ẹjọ ọhun bii ẹjọ titẹ oju ẹtọ ara ilu mọlẹ, tabi iṣekupa ọpọ ero.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Yoruba Language: Ìran Yorùbá gbayì ní Austria 17 Òkùdu 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 18 Òkùdu 2019 Ni ilu Salzburg orilẹede Austria, awọn omo Yorùbá para pọ̀ lati ṣe Ọdún Yorùbá.
"Ọwọ́ wa ti tẹ àwọn afurasí tó lọ́wọ́ nínú ikú Olufon ti Ifon, Oba Israel Adeusi - Amotekun ""Ọlọrun ṣeun fun alaafia to jọba nigba ti Emir tuntun joye ni ilu Kano."
Àwòrán aràmbarà nípa ìdìbò 2015 #BBCNigeria2019 Day 19: Wo ohun àràmàndà tí àwọn olósèlú máa ń ṣe lásìkò ìbò #BBCNigeria2019 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Ọjọ́ meje ni ó fi dúró de Samuẹli, bí Samuẹli ti wí.
Oríṣun àwòrán, Seyi Makinde Facebook Ṣugbọn agbẹnusọ fun ile iwosan UCH, Toye Akinrinola sọ fun BBC Yoruba pe, iranwọ aṣọ idaabobo lọwọ arun, (PPE) bii ọtalerugba o din mẹwaa(250) nikan UCH gba lọwọ ijọba.
Orisiirisi eto bii idije ounje sise ati titowo, ere onile iwe kan si ikeji, orin kiko, ijo jijo, idije ta n moo?
Wo àwọn Ṣọ́ọ̀ṣì Nàìjíríà àti l'Áfíríkà tó ń wólẹ̀ àdúrà kí Trump lè wọlé ìbò ààrẹ America Oríṣun àwòrán, Getty Images Pẹlu oniruuru ọrọ to ti sọ si awọn orilẹede Afirika, sibẹ awọn ẹlẹsin Kristẹni to n fọ fun aarẹ ilẹ Amẹrika, Donald Trump ṣi wa.
woodu re, ti n se Sarkin Yara ‘A’ niluu Daura, eleyi ti ko ju iseju marun un lo
Laarin ọdun 2011 si 2015, iyatọ to wa laarin awọn alawọ dudu ati funfun to n gbe ninu ìṣẹ́ pọ si, gẹgẹ bi akọsilẹ ijọba ṣe sọ.
Oríṣun àwòrán, Other Nitori idi eyi, ọpọ ipenija ni Olusola koju nidi iṣẹ to yan laayo ọhun, tawọn ẹbi ati ọrẹ si kọ ẹyin sii.
“Mo ké pè ọ́, Ọlọrun, O kò dáhùn,mo dìde dúró, mo gbadura, o kò kà mí sí.
Adari Ajọ FRSC nipinlẹ naa, Ahmed Umar wa fikun pe awọn yoo fi eri iwadii awọn lede lẹyin ti wọn ba ti pari iwadii wọn tan.
Eyi waye ninu atẹjade kan ti minisita to n ri si ọrọ awọn ọdọ ati ere idaraya, Sunday Dare fi sita loju opo Twitter rẹ.
Òfìfo ṣọ́ọ̀ṣì pa aṣọ dà fún àwọn Páṣítọ̀ Nàìjíríà Dánáfojúrà nìyí, abàmì eégún tí ń gbé inú iná ṣọlá Ìrìnàjò Toyin Abraham, láti orí gbèsè jíjẹ, ó di onílé, onimọto àti aya lọ́ọ̀dẹ̀ ọkọ Àwọn Alákòso gárèjì ló kó ìbọn àti àdá tọ ọlọ́kadà wá ní Soka-Alága ẹgbẹ́ ọlọ́kadà Ọyọ Ìjọba yóò lo BVN àtàwọn ọ̀nà méjì míràn láti pín owó ìrànwọ̀ fún aráàlú Yewande bí'mọ tuntun jòjòló, Mercy Aigbe pàdánù èèyàn rẹ̀, Toyin Abraham fèsì lórí aṣoju NCDC Ṣé Irọ́ ni pé àwọn adigunjalè ń ṣọṣẹ́ ní ìpínlẹ̀ Eko àti Ogun?
Olori ile ni tiẹ sọ pe o di dandan lati daabo bo awọn lọbalọba lọwọ awọn aṣa to tabuku ba ijẹọmọniyan .
Arakunrin yii ni o ta oògùn ikọ́ olómi oní coedine fun ikọ̀ BBC to wa ṣiṣẹ́ ọ̀tẹlẹ̀múyẹ́ to tu sita naa.
“Wọn yóo ṣubú láàrin àwọn tí wọ́n kú ikú ogun; ogunlọ́gọ̀ àwọn eniyan rẹ̀ yóo ṣubú pẹlu rẹ̀.
Nígbà tó ń sọ̀rọ̀ lórí ìgbésẹ̀ tí wọ́n gbé náà, ollórí ikọ̀ amúsẹ́yá fọ́rọ̀ owó orí ní ìpínlẹ̀ Ọ̀sun, ọ̀gbẹ́ni Ọládípọ̀ Babátúndé ní, bílíọ̀nù kan àti ẹgbẹ̀rin mílíọ̀nù náírà, (1.
Wọ́n mú kí ibinu OLUWA ru pẹlu ìwà burúkú wọn, 
Egbe akoroyin lobinrin ni Naijiria, NAWOJ ti Abuja ati agbegbe re ti fowosopo pelu awon ajo aranilowo ti kii se tijoba lati sami ayajo ojo arun jejere lagbaye.
Ewe, lara awon ohun ti egbe osise oluko tun bere ni lati ropo alaga to n mojuto idunadura pelu egbe awon osise, ti n se dokita Wale Babalakin.
Kunle ni oun naa ko kuku binu pe wọn ko pe oun wa kopa ninu fiimu wọn.
Síbẹ̀síbẹ̀ bàbá mi kò kọ ikú, kò kọ àrùn, kò bẹ̀rù ìbànnùjẹ́ àìròtẹ́lẹ̀, kó bẹ̀rù wàhálà inú igbó tí ó dúdú mirinmirin.
Ìwọ kò gbọ́ bí wọ́n ti ń fi oríṣìíríṣìí ẹ̀sùn kàn ọ́ ni?
Alagba Faṣọranti dupẹ lọwọ rẹ fun abẹwo ati ibanikẹdun rẹ.
Ìbúrawọlé Nàìjíríà ṣojú àgbáyé Dúkìá mi ò lé kan o, mo ti dá fọ́ọ̀mù padà bó ṣe wà tẹ́lẹ̀ - Buhari, Osinbajo Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ẹni bá láyà kó wá wọ̀ọ́!
Ọlọrun súre fún Noa ati àwọn ọmọ rẹ̀, ó ní, “Ẹ máa bímọ lémọ, kí ẹ máa pọ̀ sí i, kí ẹ sì kún gbogbo ayé.
Ṣugbọn awọn agbẹjọro kan ni ileeṣẹ ọlọpaa ko lagbara labẹ ofin lati da ẹgbẹ awọn oṣiṣẹ duro pẹlu iwọde ti wọn fẹ ṣe.
Aarẹ Muhammadu Buhari ti de si ilu rẹ ni Daura lati lo se ọdun Sallah, ti a mọ si ọdun Ileya, lẹyin ti o kuro ni ilu Abuja ni Ọjọ Kẹsan, Osu yii.
Ẹni to bori: Namibia Cameroon vs Egypt.
Ẹkùn gbàgbọ́, nitori ó mọ̀ wi pé ọ̀rẹ́ gidi ni Ìjàpá àti Ọ̀bọ.
Ogu ọba Baṣani sì bá wọn jagun ní Edirei.
Wọ́n bá kàn án mọ́ agbelebu.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ilé Arúgbó Saraki: Èyí ni ìdí tí ìjọba ìpínlẹ̀ Kwara fí wó ìlè arúgbó ní ìdàjí 2 Sẹ́rẹ́ 2020 Oríṣun àwòrán, Facebook/RealAARahman Ijọba ipinlẹ Kwara ti ṣalaye idi tawọn fi gbe igbesẹ wiwo ile arugbo nilu Ilorin.
Aṣòfin ìpínlẹ̀ Èkìtì tí wọ́n yìnbọn fún ti dolóògbé Gómìnà Willie Obiano lọ forí balẹ̀ f'órí adé Lẹnu ọjọ mẹta yi ni iroyin orisirisi ti n ja ranyin lori ẹgbẹ ti yoo gbe lẹyin ninu atundi ibo Gomina Osun .
“Ṣé o kò gbọ́ ohun tí àwọn eniyan wọnyi ń sọ tí wọn ní, ‘OLUWA ti kọ ìdílé mejeeji tí ó yàn sílẹ̀?
Ní àkókò náà Merodaki Baladani ọmọ Baladani, ọba Babiloni, fi ìwé ati ẹ̀bùn rán àwọn ikọ̀ kan sí Hesekaya, nítorí ó gbọ́ pé ara rẹ̀ kò ti dá tẹ́lẹ̀ ṣugbọn ara rẹ̀ ti wá le.
“Oluwa, wọ́n ti pa àwọn wolii rẹ, wọ́n ti wó pẹpẹ ìrúbọ rẹ, èmi nìkan ṣoṣo ni ó kù, wọ́n sì ń wá mi láti pa.
Eyi tumọ si pa kaka ki wọn lọ si isinmi asiko yii, o di ọjọ kẹwaa, oṣu kẹsan an ki wọn to le lọ.
Wọn woye pe, ete ati doju ijọba Buhari bolẹ ni iwa ipa, janduku ati ẹlẹyamẹya to gbode nitori ipe fun wiwọgile awọn ọlọpaa SARS.
Onyema sọ eyi ninu atẹjade ti wọn fi lede si oju opo ikansiraẹni Twitter wọn.
ẹ̀yin tí ìlú yín kún fún ariwo, tí ẹ jẹ́ kìkì ìrúkèrúdò ati àríyá?
Ọba yóo máa ṣọ̀fọ̀; àwọn olórí yóo sì wà ninu ìdààmú; ọwọ́ àwọn eniyan yóo sì máa gbọ̀n nítorí ìpayà.
Síbẹ̀ ẹlòmíràn tún lè kí wa pé:
Dídé rẹ̀ dájú bí àfẹ̀mọ́jú; yóo sì pada wá sọ́dọ̀ wa bí ọ̀wààrà òjò, ati bí àkọ́rọ̀ òjò tí ń bomirin ilẹ̀.
Wọ́n kéde káàkiri Jerusalẹmu ati Juda pé kí wọ́n máa mú owó orí wá fún OLUWA gẹ́gẹ́ bí Mose iranṣẹ Ọlọrun ti pàṣẹ fún Israẹli ninu aṣálẹ̀.
Ambassador Mamman Daura: O ti ṣe aṣoju orilẹede Naijiria si Uganda, Saudi Arabia, South Korea, Belgium ati Cameroon.
Ó wọ aṣọ ìlékè aláwọ̀ elése-àlùkò, ìlú Susa sì ń hó fún ayọ̀.
Ó sì mọ̀ ninu ara rẹ̀ pé a ti mú òun lára dá ninu àìsàn náà.
Sibẹsibẹ, emi ko setan lati tu igbeyawo mi ka.
Ọjọree bi ana yii lọdun meji sẹyin nigba ti ọmọ tuntun jojolo, Gold Kolawole dele aye, lai mọ ohun to n duro de oun.
O tó gẹ́; A kò fẹ́ ìwòkuwò mọ́ ní Nàijíríà- Runsewe (NCAC) Falana àtàwọn míì péjú síbi àpérò #RevolutionNow l'Eko O dìgbà tí mo bá dórí àgá kí ń tó sọ ìpinnu mi - Fatai Owoseni SSANU, NASU gbé fásitì Ibadan tì pa Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí kan sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
Elesho sọ pe nipasẹ Ade Love loun fi mọ Oga Bello, Isho Pepper ati Iya Awero ninu ere ṣiṣe.
Agbẹnusọ ilé iṣẹ́ ọlọ́pàá ìpínlẹ̀ Eko, Bala Elkana ló fìdí ọ̀rọ̀ yìí múlẹ̀ fún àwọn akọròyìn pé awọn ọlọ́pàá náà ti fojú ba iléẹjọ́ l'Ọjọ́bọ̀ ní ìpínlẹ̀ Eko.
Jesu bá wo ọ̀tún, ó wo òsì, ó wí fún àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ pé, “Yóo ṣòro pupọ fún àwọn ọlọ́rọ̀ láti wọ ìjọba Ọlọrun!
Oríṣun àwòrán, Instagram/Olori anu ati Bobrisky Wo àwọn òṣìṣẹ́ kólẹ̀-kódọ̀tí tó ń fi ẹ̀mí wọn wéwu kí Abuja leè mọ́ tónítóní Èèyàn 576 míràn tún kún àwọn tó ní àrùn COVID-19 ní Nàìjíríà Mo ti bẹ̀rẹ̀ sí ń bá àwọn tí a jọ díje nínú ìdìbó abẹ́lé sọ̀rọ̀ kí àláàfíà léè jọba - Akeredolu Wo àwọn nkan tó yẹ́ kí o mọ̀ nípa 'Awawa Boys', ọ̀kan lára ẹgbẹ́ òkùnkùn tó n dá Eko rú Koda, Olori tun sọ ọrọ yii debi pe awọn eeyan kan n fi oun we Bobrisky pe awọn mejeeji jọra pupọ.
Nítorí pé ẹni tí Ọlọrun rán wá ń sọ ọ̀rọ̀ Ọlọrun.
Gẹ́gẹ́ bí àṣà àwọn àgbàlagbà Yorùbá, òwe àgbà kan ni alàgbà yìí gbéyọ tí wọ́n sì kọ̀ọ́ ní ọ̀nà tí ó fi kó gbogbo álúfábẹ́ẹ̀tì Yorùbá mọ́ra, ṣùgbọ́n tí ìtumọ̀ rẹ̀ kò yí padà rárá.
Bi ọwọ se tẹ awon odaran naa
Ọgbẹni Adewale Adeniran, lasiko to n ba BBC Yoruba sọrọ lori igbesẹ ijọba naa ni, eyi yoo mu ki afikun owo ọjà ati iye ti wọn n ba ni fi nkan ránṣẹ.
”Bakan naa,Chukwu tun so pe iko omo oogun orile ede Naijiria tun kọlu iko omo oogun olote Boko Hram ni agbegbe kan ni ipinle Borno nibi ti won ti gbe dena de won, ni eyi ti awon iko omo oogun olote Boko Haram si salọ, ti awon kan si fara gba ibọn lasiko ikolu naa.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ẹni bá láyà kó wá wọ̀ọ́!
” Àwọn eniyan náà bá ronupiwada, wọ́n ní, “OLUWA àwọn ọmọ ogun ti ṣe wá bí ó ti pinnu láti ṣe, nítorí ìwà burúkú ati iṣẹ́ ibi wa.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Kàyééfì Promo: Ìyá, ọmọ tuntun àti olubi ló wà níbùdó ìgbókùsí, àmọ́ òkú ọmọ di àwátì Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Kàyééfì Promo: Ìyá, ọmọ tuntun àti olubi ló wà níbùdó ìgbókùsí, àmọ́ òkú ọmọ di àwátì 26 Òkùdu 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 27 Òkùdu 2019 Yoruba ni gbogbo awọn to ba mọ nkan fi pamọ, ni ki wọn maa ranti ẹni to mọ wa.
OLUWA ní: “Àwọn ará Moabu ń dẹ́ṣẹ̀ kún ẹ̀ṣẹ̀, dájúdájú, n óo jẹ wọ́n níyà; nítorí wọ́n sọná sí egungun ọba Edomu, wọ́n sun ún, ó jóná ráúráú.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Election 2019 Updates: Atiku pe ẹjọ́ tako Buhari pẹ̀lú 20 àgbà amòfin 19 Ẹrẹ̀nà 2019 Oríṣun àwòrán, @Atiku Oludije fun ipo aarẹ labẹ asia ẹgbẹ oselu PDP, Alhaji Atiku Abubakar ti pe aarẹ Muhammadu Buhari, to n soju ẹgbẹ oselu APC lẹjọ, wipe esi bio to gbe wọle fun saa keji lọwọ magomago ninu.
"Nigba ti wọn de ile iwe naa, Sikiru Adeleke nikan ni wọn ri lori ijoko, ṣugbọn ko si Sẹnetọ Ademola Adeleke nibẹ.
eto oro aje lorile ede yii.
òun pàápàá wí fún Adéforítì ó ní, ‘A, Adéforítì, inú mi kò le dùn láéláé nítorí èmi pàápàá ń fẹ fi ibi ṣíṣe sílẹ̀ n kò le fi i sílẹ̀ ni.
Oríṣun àwòrán, Kizit Photography Pupọ ninu awọn akẹgbẹ rẹ ninu iṣe tiata Yoruba lo peju-pesẹ sibi ti ayẹyẹ isinkun naa ti waye, lai yọ awọn ibatan rẹ silẹ pẹlu.
Ògo rẹ̀ bo ojú ọ̀run,gbogbo ayé sì kún fún ìyìn rẹ̀.
‘ASUU da ìyanṣẹ́lódì dúró' El-Rufai, lọ tọwọ́ ọmọ rẹ bọ aṣọ!
Kí ni ètò òfin tó kàn fún Àmọ̀tẹ́kùn láti dúró?
Eyi lo mu ki ẹgbẹ́ Afẹnifẹre maa ti sọ pato ẹni ti wọn yoo gbe lẹyin rẹ fun idibo Aarẹ ọdun 2019.
Ọ̀rọ̀ Oluwa tàn ká gbogbo ilẹ̀ náà.
“Gbogbo yín pátá ni ẹ dúró níwájú OLUWA Ọlọrun yín lónìí, ati gbogbo àwọn olórí ninu àwọn ẹ̀yà yín, ati àwọn àgbààgbà ati àwọn olóyè ati àwọn ọkunrin Israẹli.
 a le rí èsìn ìgbàgbọ ́ gẹ ́ gẹ ́ bí iş ̣ ẹ ́ ìsìn , a tún lé ríí gẹ ́ gẹ ́ bií àşà , gbogbo itumọ ̀ yìí tàbì jù bẹ ́ ẹ ̀ lọ ni a le fún ẹ ̀ sìn ìgbàgbọ ́ .
Lyon fìgbájú gba Emirate Cup lọ́wọ́ Arsenal, wọ́n fi pánda rọ́pò Ọlọ́pàá fi páńpẹ́ ọba mú ọmọ ogun ilẹ̀ Naijiria Iléeṣẹ́ ọmọ ogun dá Bashir tó ri owó he lọ́lá Ọmọ Yorùbá tó bá ti rú òfin, ẹ gbé e jàntò - Oluwo Bi ọlọpaa ṣe mu mi da ibẹrubojo simi lọkan Ileeṣẹ ọlọpaa ti gba pe awọn yoo san owo gba ma binu ẹgbaa le ẹdẹgbẹta poun fun un tori bi wọn ti ṣe fipa gba bibeli rẹ ti wọn si doju ti .
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Coronavirus: Iléèṣẹ́ ààrẹ̀ Nàìjíríà sọ pé ọ̀rọ̀ òṣèlú ni sísọ́ pé dandan ní kí Buhari bá ọmọ Nàìjíríà lórí coronavirus 20 Ẹrẹ̀nà 2020 Oríṣun àwòrán, Getty Images Ileeṣẹ aarẹ Naijiria ti sọ pe pe ko si nkan to yẹ ki aarẹ Muhammadu Buhari ṣe lori arun coronavirus ti ko ti i ṣe.
Ìgbà tí mo yọ lọ́kàn-án kán, tí ó rí mi, agara ti dá a, o ju ọwọ́ sí mi pé kí n máa bọ̀, èmi náà sì lọ, mo wọ inú ilé rẹ̀ pẹ̀lú ìbẹ̀rù ṣùgbọ́n láìpẹ́ ni mo rí i pé èrè ìforítí mi ti dé, mo ti ṣẹ́gun, mo ti gun òkè dé orí, mo ti ṣe dáadáa nínú ìdánwò, mo ṣẹ́gun Ìbínú-ẹkùn pátápátá, ojú rẹ̀ rọ̀, mo pe ọmọ rẹ̀ wọlé, o túúbá níwájú baba rẹ̀.
Ṣaaju ni agbefọba ninu ile ẹjọ naa, Udom Ulo, ti ṣalaye pe awọn ajọ to n ja fẹtọ ọmọniyan tí pé fún gbigba ẹjọ́ náà lọ́wọ́ òun láti gbé fún àjọ miran to dantọ.
Ẹ pada sọ́dọ̀ OLUWA, kí ẹ sọ pé, “Mú ẹ̀ṣẹ̀ wa kúrò, gba ohun tí ó dára a óo sì máa yìn ọ́ lógo.
Ẹ óo jẹ, ẹ óo yó, ẹ óo sì máa gbé inú ilẹ̀ yín láìléwu.
Awọn alaṣẹ ijọba apapọ ti fi imọran sita gẹgẹ bi awọn ijọba ipinlẹ kọọkan ṣe ti kede ọjọ ti awọn ileewe yoo wọle.
Ìfẹ́ OLUWA yóo ṣẹ lọ́wọ́ rẹ̀.
Ijsba orilẹede Togo ṣalaye pe awọn ti fi arabinrin naa si abẹ ayẹwo fun itọju to peye; atipe ara rẹ n balẹ.
Nítorí wọn óo máa kó ọrọ̀ jọ láti inú òkun,ati dúkìá tí ó farasin láti inú yanrìn etí òkun.
Ìwọ náà mọ̀ ní ọkàn rẹ pé, ní ọpọlọpọ ìgbà ni ìwọ náà ti bú eniyan rí.
Ninu fọnran fidio rẹ́ towa loju opo You tube, o ni o nira fun oun lati jẹ́ iṣẹ yi pe Sowore ni Olọrun fẹ lo lati tun Naijiria ṣe ṣugbọn oun yoo jẹ.
Ọlọpàá náà lo tun jẹyọ, tí o si tó ìdá mẹ́rìnlelọgọrin nínú ìdá ọgọrún.
Pàápàá jùlọ àwọn oúnjẹ tí wọ́n njẹ ní ọjọ́ ìsinmin àbámẹ́ta àti àìkú.
Lẹyin eyi ni awọn ọdọ miran fariga pe dandan Fakorede gbọdọ di kọmiṣọna nipinlẹ Oyo nitori pe ọdọ ni wọn n fẹ.
Ìdí tí mo fi ń ṣe ayẹyẹ ọjọ́ ìbí 35 lọ́dọọdún rèé- Allwell Ademola Ìjà d'ópin, fún ìgbà àkọ́kọ́, bàálù gbéra láti Israel lọ sí UAE Wọ́n ti sún ìdájọ́ àwọn sójà tó pa ìyá àti ọmọ ní ọdun 2018 sí oṣù tó m bọ̀ Ààrẹ Buhari buwọ́lu gbígbé ìṣàkoso nọ́mbà ìdánimọ̀ (NIMC) lọ sí ẹ̀ka ìjọba tó ń rí sí ìbáraẹnisọ̀rọ̀ Nigba ti mo gbọ pe o fẹ se iyawo mo pe ẹgbọn mi ni abule láti bere boya o mọ nipa.
Àwọ̀ ojú pọ̀ bíi àwọ̀ òṣùmàrè, àmọ́ ojú búlúù Risikat kò nílò àtúnṣe- Dókítà Feyi Ẹlẹ́wọ̀n 44 kú sọ́gbà ẹ̀wọ̀n nítorí ooru tó mú púpọ̀ ‘Àwọn òlóṣèlú kò ní ìwà ọmọlúwàbí ló jẹ́ kí wọ́n má a lọ láti ẹgbẹ́ òṣèlú kan lọ sí òmìràn’ À kò gba owó kankan lọ́wọ́ àwọn ẹgbẹ́ agbésùmọ̀mí ISWAP- MURIC Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Sextuplet: Àdúrà Ìbùkún ló kú lẹ́yìn ọmọ mẹ́fà yìí- Ifeoma Thelma àti Onyemaechi Chiaka Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Agbekoya War: Ọta ìbọn kan ṣoṣo ló fa ogun tó fi ọ̀pọ̀ ẹ̀mí ṣòfò nínú ìtàn mánigbàgbé lẹ̀ Yorùbá13 Ògún 2020 Osun-Osogbo Festival 2020: Àwọn ẹlẹ́sìn àdáyébá rú òfin Covid-19 níbi àṣekágbá ọdún Osun Osogbo16 Ògún 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Americans in Africa: Wo ìdí tí àwọn ọmọ ilẹ̀ Amẹ́ríkà kan ṣe ń kó bọ̀ wá fi ilẹ̀ Áfríkà sebùgbé 3 Ògún 2020 Ọpọ awọn eeyan nilẹ Afirika lo n gbiyanju lati tẹkọ leti lọ si Amẹrika lati fi ibẹ ṣebugbe, ṣugbọn awọn adulawọ kan to jẹ ọmọ Amẹrika ti bẹrẹ si nii sa kuro lọhun lati maa wa gbe nilẹ Afrika.
Aarẹ Buhari aaye ṣi silẹ pupọ fun ẹnikẹni to ba fẹ kuro ni South Africa tẹbi tẹbi bayii.
O ni awọn ko ni fi aye gba akojọ kankan tabi iwọde, to fi mọ ifẹhonu han eyi to le mu ipalara ba iṣọkan Naijiria.
Ẹgbẹ agbabọọlu Napoli ti Maradona ran lọwọ lati gba liigi Serie A lẹẹmeji naa ranṣẹ si i loju opo Twitter wọn.
Dokita onisegun oyinbo kan, Adekunle Obilade salaye pe awọn ọti lile ti ọpọ eeyan yan laayo yi lo jẹ ọta ara.
Ti a ko ba kọ ibi ara si nnkan bayi lati ibẹẹrẹ, ohun ni o maa n fa ki ipaniyan o peleke sii."
Emerald fi tiẹ ṣe loju opo Twitter rẹ, o ni ko lo ṣeeṣe ki ọrọ ifẹ da Mercy Aigbe ati Adeniyi Johnson pọ.
Nítorí náà, èmi OLUWA Ọlọrun ní nítorí pé rúdurùdu yín ju ti àwọn orílẹ̀-èdè tí ó yí i yín ká lọ, ati pé ẹ kò tẹ̀lé ìlànà mi, ẹ kò sì pa òfin mi mọ́.
Oluwo ti ìlú Iwó kìí ṣe ẹgbẹ́ Àtaọjà Osogbo - Alaafin ìlú Ọ̀yọ́ Ẹ̀ gbọ́ ọ̀rọ̀ lẹ́nu Adelé Ọba Alade Idanre ló rí ohun tó ṣẹlẹ̀ láàárín òun àti Ọba Aroloye Ẹ̀yin ọlọ́pàá, ẹnikẹ́ni tó bá fi ọwọ́ kàn yín, ẹ dojú ìjà kọ ọ́ padà- Ọ̀gá Àgbá Ọlọ́pàá Owatapa ti Itapa Ijesha, Wolii Olapade Agoro jáde láyé Nitori naa ẹ jẹ ki a wo awọn ohun ti aarẹ Trump ṣe to yatọ si awọn aarẹ to ku, to si kan awọn eniyan kaakiri lagbaye.
NDDC Acting MD, Pondei dákú lásìkò tí lásìkò tí ìwádìí n lọ lórí ẹ̀sùn ìnákúnàá Oríṣun àwòrán, Screenshot Adele Ọga Agba ajọ to n mojuto idagbasoke agbegbe Niger Delta, Ọjọgbọn Kemebradikumo Pondei, daku rangbọndan lasiko ti iwadii ẹsun n waye.
Ewe, Rohr ti kede pe ohun yoo mu awon agbaboolu ti yoo kopa fun oun ninu awon ifesewonse olorejore olokan-o-jokan ti iko Super-Eagles ba gba fun igbaradi idije agbaye ohun to n bo lona.
Àdéhùn tí kò Wúlò pẹlu Ijipti.
Sugbọn ko si ohun to fidi ẹ mulẹ pe iye awọn ti ajakalẹ arun Covid 19 n pa pọ ju nitori pe iku Covid 19 ko ṣe e bo mọlẹ.
Ni Vietnam, ọkan ejo Sèbé ni awọn eniyan ma fi n se ounjẹ jẹ.
Bí ó ti wọ ilé Ọlọrun lọ, tí ó mú burẹdi tí ó wà lórí tabili níwájú Oluwa, tí ó jẹ ẹ́, tí ó tún fún àwọn tí ó wà pẹlu rẹ̀, bẹ́ẹ̀ sì ni ẹnikẹ́ni kò gbọdọ̀ jẹ ẹ́ àfi àwọn alufaa nìkan?
 Ìtọ ́ jú àwọn ẹnití ó ní neurocysticercosis lè jẹ ́ nípasẹ ̀ àwọn egbògi tí a npè ní praziquantel tàbí albendazole .
N óo pa ìlú yìí run ni; ṣugbọn n kò ní tíì pa á run, títí ẹni tí ó ni í yóo fi dé, tí n óo sì fi lé e lọ́wọ́.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Òbítíbitì ẹ̀gbin ti sọ ìlú Ibadan di ààtàn - Aráàlú figbe bọnu Àwọn ẹni òkùnkùn ló já ìṣẹ́gun mi gbà, mò ń lọ sílé ẹjọ́ tó ga jùlọ - Bayo Adelabu Ọ̀pọ̀ àwòrán rèé tó ń sàfihàn bí Ibadan se kún fún ẹ̀gbin àti òórùn Àbádòfin ìdájọ́ yíyẹ igi fún 'ni tórí ọ̀rọ̀ ìkóríra!
Oríṣun àwòrán, Realmercyaigbe Fun iyalẹnu ọpọ eeyan, obinrin ni kikida awọn osere tiata mẹta to gba ami ẹyẹ AMVCA7 naa lọdun yii ni ẹka ede Yoruba, ti ko si si ọkunrin ni aarin wọn.
Ènìyàn méjì pàdánù ẹ̀mí wọn nínú ìjàmbá ọkọ̀ tó wáyé ní Abúlé Ẹ̀gbá, ní ìpínlẹ̀ Eko Ẹ̀ gbọ́ ọ̀rọ̀ lẹ́nu Adelé Ọba Alade Idanre ló rí ohun tó ṣẹlẹ̀ láàárín òun àti Ọba Aroloye Oluwo ti ìlú Iwó kìí ṣe ẹgbẹ́ Àtaọjà Osogbo - Alaafin ìlú Ọ̀yọ́ Ẹ̀yin ọlọ́pàá, ẹnikẹ́ni tó bá fi ọwọ́ kàn yín, ẹ dojú ìjà kọ ọ́ padà- Ọ̀gá Àgbá Ọlọ́pàá O ni ajọ naa ti bẹrẹ ilanilọyẹ kaakiri Naijiria pẹlu ajọṣepọ awọn ileeṣẹ ti ọrọ kan lori ọna ti awọn eeyan le maa fi tọju ounjẹ ati ọja wọn lọna ti ko ni mu ewu lọwọ.
Ó bá ọba àwọn ará Amoni jà, ó sì ṣẹgun wọn.
O ni awọn iroyin ti oun n ka nipa iwa ifipabanilopọ ko dun un gbọ leti, eyi lo jẹ ki oun ṣiṣọ loju eegun iriri t'oun naa to jẹ iso inu ẹku tẹlẹ.
Ọmọ ọmú yóo máa ṣeré lórí ihò paramọ́lẹ̀,ọmọ tí ó ṣẹ̀ṣẹ̀ já lẹ́nu ọmúyóo máa fi ọwọ́ bọ inú ihò ejò.
Ìbálòpọ̀ ọ̀lọ́jọ́ méje mú kí ilé ẹjọ́ tú ìgbéyàwó ọdún mẹ́wàá ká ní Ibadan Iléeṣẹ́ ọlọ́pàá palẹ̀ òkú ọmọ ọjọ́ kan mọ́ lẹ́yìn t́i wọ́n jùú sórí ààtàn Àwọn Olúkọ ìpínlẹ̀ Oyo fakọyọ lórí ètò Akọ́mọlédè àti Àṣà púpọ̀ Ọwọ́ Interpol àti ọlọ́pàá Nàìjíríà ti tẹ ọmọ Nàìjíríà mẹ́ta tó lu èèyàn 50,000 ní gbájúẹ̀ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Akọ́mọlédè àti Àṣà lórí BBC Yorùbá: Kọ̀ síi nípa iṣẹ́ tí oúnjẹ ń ṣe lára níbí Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Ọmọ Jerry Rawlings ké gbàjarè pé àwọn gbájúẹ̀ fẹ́ forúkọ bàbá rẹ̀ gbowó ìsìnkú27 Bélú 2020 Hisbah Kano fi òfin de lílo èdè 'Black Friday', àwọn ọmọ Naijiria kan yarí lórí ayélujára29 Bélú 2020 Saudi Arabia: Ìtàn kíkùn lórí Mọ́ṣáláṣí Anabi tí wọ́n dá sílẹ̀ lọ́dún 1440 sẹyin.
Tinubu ti bẹrẹ isẹ ti Buhari gbe le lọwọ Tinubu ni k'Ọ̀basanjọ, IBB lọ rọ ọ kun ni'le A gbiyanju lati ba agbẹnusọ ẹgbẹ APC Bolaji Abdullahi s'ọrọ nipa iṣẹlẹ yi ṣugbọn ko gbe ipe rẹ.
” Ẹ̀rù ba ọmọkunrin náà láti ṣe bẹ́ẹ̀.
Eeyan 900 ni wọn ṣayẹwo fun, ti wọn si ti tọju awọn 600 to fara kasa Covid-19 lọdun 2020 nikan ṣoṣo.
Nígbà tí àwọn ará Jabeṣi Gileadi gbọ́ bí àwọn ará Filistia ti ṣe Saulu, 
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Fuel Reduction: Awọn ọmọ Naijiria ni muri kan ti kéré ju láti yọ nínú jálá epo 19 Ẹrẹ̀nà 2020 Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Coronavirus: Àwọn alágbàtà epo bẹntiró kọ̀pàkọ́ sí àṣẹ àdínkù owó epo Aṣẹ ti ijọba apapọ orilẹede Naijiria pa lori adinku jala epo bẹntiro si naira marundinlaadoje(125) ko tii fi bẹẹ fẹsẹmulẹ ni ilu Ibadan tii ṣe olu ilu ipinlẹ Ọyọ.
Notre-Dame Cathedral: ilé ìjọsin jù ara wọn lọ
Obinrin to ba si ti pa iṣẹ jẹ yoo san owo itanran.
Ṣé Hesekaya rò pé a óo gba òun là ni?
Tí a fiṣọwọ́ ní 14:4314:43 Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún un Wahala ijinigbe ati ipaniyan lagbegbe Ibarapa ni ipinlẹ Ọyọ n di lemọlemọ lẹnu ọjọ mẹta yii.
Ninu iwe ipẹjọ oloju ewe mejila ni agbẹjọro awọn afọbajẹ naa, John Enworo, ti fẹsun kan Oluwo pe, o ti n gbe igbesẹ lati fi awọn eeyan miran rọpo awọn afọbajẹ ọhun.
Irú ewu ati òfò yìí ìbá tí sí.
Ṣùgbọ́n bí ẹ bá ń bá òótọ́-inú yín lọ, inú ọ̀gbun tí òun ń ffẹ́ẹ́ tì yín sí ni yóò bá ara rẹ̀ tí yóò kún inú kòtò bámúbámú.
Ṣé ó leè jẹ́ ilẹ̀ tí Makinde kò jẹ́ kí Florence Ajimobi gbà ló ń bi nínú?
Mo ti mú kí ojú rẹ le sí tiwọn.
Ojuse Imaamu ni lati maa sọrọ ẹṣin fun awọn musulumi ati ohun gbogbo ti Ọlọrun fẹ ki wọn ṣe, Imaamu si ni wọn maa n fi eto ẹṣin le lọwọ ni awujọ musulumi.
Gómìnà Beruit lo fìdí ọ̀rọ̀ yìí múlẹ̀ pé ìbúgbàmù ọjọ́ Iṣẹ́gun tó kọjá ti pa ènìyàn igba.
Gbogbo igbiyanju BBC Yoruba lati ba ileeṣẹ ọlọpaa ni ipinlẹ Ondo sọrọ lori isẹlẹ yii, si lo ja si pabo.
Àbádòfin ìdájọ́ yíyẹ igi fún 'ni tórí ọ̀rọ̀ ìkóríra!
O ni to ba see se ni, obinrin naa lo wu oun lati fi se aya.
Gbogbo yín ni ẹ ti fojú yín rí i,kí ló wá dé tí gbogbo yín fí ń sọ ìsọkúsọ?
Jesu Oyingbo rèé, pásítọ̀ tó láṣẹ ìbálòpọ̀ lóri ọmọ ìjọ obìnrin Igbó mímu lè ṣe kóríyá, kò lé fi kún orín ẹnu òṣèré - 9ice Ìtàn tó wà nídi òwe ‘Sebótimọ Ẹlẹ́wà Sàpọ́n’ Ọba Adesoji Aderemi, Ọọ̀ni Ifẹ̀ tó gba ipò ọba mọ́ tòṣèlú MKO Abiola, iṣẹ́ aṣẹ́gità ló fi bẹ̀rẹ̀ okoòwò Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí 3 sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 2:23 Fídíò, Water Generator: Ó leè ṣiṣẹ fún wákàtí mẹfà, kó tó sinmi, Duration 2,2310 Òkùdu 2020 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
40 usd fún ìwọ ̀ n egbògi náà kanṣoṣo ní ọdún 2014 .
Gbogbo àwọn eniyan náà dáhùn pé, “Kí ẹ̀jẹ̀ rẹ̀ wà lórí àwa ati àwọn ọmọ wa!
 Ni bayii: Morocco ni o si lanfani bayii lati sagbateru re, ti yoo si tun fayesile fun ile-Afrika!
Oríṣun àwòrán, @UN_Nigeria Àkọlé àwòrán, Awọn omi ati ounjẹ ti ko mọ pẹlu ayika ti o kun fun ẹgbin kun ara awọn ohun ti wọn ni o n ṣokunfa aarun onigbameji Amọ ṣa, ajọ iṣọkan agbaye ti ni, wọn ṣi nilo alekun owo, paapaa lasiko ojo, nigba ti aisan to rọ mọ omi yoo pọ.
"Lapapọ awọn eeyan ni ""lootọ, Kudirat Abiola ni akinkanju ọjọ kejila, oṣu kẹfa (June 12)."
FG Survival Fund: Ènìyàn 174,574 ló ti forúkọ sílẹ̀ fún ètò ìrànwọ́ ìjọba fáwọ̀n olókoòwò kéékèé
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Òkè Ìdànrè: Òkè tó kéré jùlọ jẹ́ ẹsẹ̀ bàtà 3000 Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Òkè Ìdànrè: Òkè tó kéré jùlọ jẹ́ ẹsẹ̀ bàtà 3000 12 Ọ̀pẹ̀̀ 2018 BBC Yoruba rin irinajo lọ silu Idanre nipinlẹ Ondo, niti ti Oke Idanre wa lati mọ nipa ohun to se ara ọtọ nipa ori oke yii.
Oríṣun àwòrán, Twitter/NNPCgroup Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Balaki sọ fún Balaamu pé, “N óo mú ọ lọ sí ibòmíràn bóyá Ọlọrun yóo gbà pé kí o bá mi ṣépè lé àwọn eniyan náà níbẹ̀.
 a le sọ pé iṣẹ ́ ògbufọ ̀ ni ó fẹ ́ rẹ ̀ nira jùlọ nínú gbogbo iṣẹ ́ .
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Sẹ́nétọ̀ Ademọla Adeleke ń jẹ́jọ́ aṣemáṣe lásìkò ìdánwò 19 Owewe 2018 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 31 Ọ̀wàrà 2018 Oríṣun àwòrán, @IsiakaAdeleke1 Àkọlé àwòrán, Ṣaaju idibo ọṣun ni wọn ti fi ẹsun yii kan sẹnetọ Adeleke Lẹyin ti awọn ọlọpaa ti gbe e lọ siwaju ile ẹjọ ni ọjọru fun ẹsun iwa aitọ lasiko idanwo, ile ẹjọ giga apapọ kan nilu Abuja ti gba oniduro Sẹnetọ Ademọla Adeleke, oludije fun ipo gomina ipinlẹ Ọṣun labẹ ẹgbẹ oṣelu PDP.
Nítorí pé OLUWA ti sọ pé gbogbo àwọn ti ìgbà náà ni yóo kú ninu aṣálẹ̀.
Àwọn tí ń tẹ dùùrù ti dáwọ́ dúró.
Àwọn kan wà tí eyín wọn dàbí idà,kìkì ọ̀bẹ ló kún èrìgì wọn,láti jẹ àwọn talaka run lórí ilẹ̀ ayé,ati láti pa àwọn aláìní run láàrin àwọn eniyan.
 Òun ló jẹ ́ ẹgbẹ ́ òṣèlú tí ó ṣe ìgbé-lárugẹ fún ètò ẹ ̀ kọ ́ ọ ̀ fẹ ́ fún gbogbo àwọn akẹ ́ kọ ̀ ọ ́ .
Ọlọ́run nìkan ló mọ bí ìrìnàjò ìfẹ́ ẹ̀dá á ṣe rí láyé, ọ̀dọ́ Aláàfin ní orí gbémí yà sí, ó sì tẹ́milọ́rùn- Olorì Aanu Wo ọ̀nà tí àwọn ‘ẹ̀lẹ̀ Daddy’ gbà dé ààfin Ọyọ Rògbòdìyàn bẹ́ sílẹ̀ l'Ogbomọṣọ, àwọn ọ̀dọ́ kọlu ààfin Ṣọun Wo ìdí tí Tẹni, ọ̀dọ́mọdé olórin obìnrin kìí fi ń ṣí ìhòhò rẹ silẹ̀ Ẹ̀yin olùwọ́de, ẹ lọ kọwọ́ ọmọ yín bọṣọ, bí bẹ́ẹ̀ kọ́.
Nítorí OLUWA ti kọ àwọn tí ẹ gbójúlé,wọn kò sì ní ṣe yín níre.
Biṣọbu Godwin ni gbogbo awọn onigbagbọ gbọdọ ke pe Ọlọrun ninu adura bayii pe ko wa ja ni Naijiria nitori orukọ rẹ.
Ọmọ Yahoo fẹ́ pa ìyá rẹ̀ ṣ'owó l'Eko #BBCGOVDEBATE: Kò sí ètò ilera ọfk fun àwọn obinrin- Ogunbanjọ Ajọ iṣọkan agbaye to n risi ọrọ ọmọde ni agbaye UNICEF ni orilẹ-ede Naijiria lo ni ọmọde ti ko lọ sile iwe ti pọju lagbaye.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Aisha Buhari-Aya ààrẹ, Aisha Buhari ni ààrẹ gan kó mọ nípa ọ̀rọ̀ ìyàwò tuntun 7 Ọ̀pẹ̀̀ 2019 Oríṣun àwòrán, Aisha Buhari/ twitter Aya aarẹ orilẹede Naijiria, Aisha Buhari ti sọ wi pedigbi bayii ni ọkan oun duro nigba ti ariwo aarẹ fẹ gbe iyawo tuntun bọ si igboro aye lorilẹede Naijiria.
Kìí ṣe ohun tó bá ojú mu láti gẹ núdúlù sí wẹ́wẹ́ 8.
OLUWA bá dá a lóhùn pé, “Ojú mi yóo máa bá ọ lọ, n óo sì fún ọ ní ìsinmi.
O maa n mu ara eeyan balẹ pẹsẹ a si ran ipo ọkan wọn lọwọ.
Eniyan burúkú ń fọ́nnu lórí ìfẹ́ ọkàn rẹ̀,Ó ń bu ọlá fún wọ̀bìà, ó sì ń kẹ́gàn OLUWA.
Obinrin kan to wa lara wọn sọ pe wọn fiya jẹ awọn ki wọn to gbe awọn lọ si ibi tawọn ko mọ rara.
Bi ibẹ ti ṣe ma n ri ni gbogbo igba ni yẹn'' Igbimọ Amuṣẹya fi ontẹ lu Ajimobi ati awọn oloye ẹgbẹ tuntun mi Ni ọjọru kannna ti awuyewuye lori aṣẹ lọ rọọkun nile Oshiomole n waye, akọwe ipolongo ẹgbẹ Lanre Issa Onilu ti fi atẹjade sita pe ẹgbẹ ti fontẹ lu awọn oloye apapọ ẹgbẹ mẹta tuntun.
Ẹ wò ó, ó mú àwọn erékùṣù lọ́wọ́ bí àtíkè.
Ọdun mẹtadinlọgọrun lo lo loke eepẹ, ko to tẹri gbasọ.
Opo lo ti fi ewon ogoji odun gbara lataari lilowo si jiji gbe awon afin lorile-ede Mozambique, ti awon miiran si padanu emi won sinu esun naa.
Wike, má gbé jàgídíjàgan wá sí Ondo, APC kò ní ṣ'èèrú nínú ìdìbò gómìnà tó ń bọ̀- Kalejaye Trump to jẹ ẹni ọdun mẹrinlelaadọrin ni awọn eniyan ti bu ẹnu atẹ lu wi pe o fi oju tẹmbẹlu arun naa, lai wọ ibomu tabi ofin iyagofunraẹni lo ṣe lugbadi arun naa.
"Emi gan-an si ni ayaba akọkọ nilẹ Yoruba to bi ibẹta.
Sheihk Mohammed to jẹ Igbakeji Aarẹ ati Olootu ijọba ilẹ UAE, to si tun jẹ Ọba ilu Dubai, sọ pe wọn gbe igbesẹ naa lati le sọ ilẹ UAE di orilẹede ti awọn arinrinajo igbafẹ yoo maa lọ ju l'agbaye.
Igbimọ naa sọ ninu abajade rẹ pe ki ileeṣẹ aarẹ yọ akọwe agba ajọ adojutofo ilera Naijiria (NHIS) naa nipo.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ẹtàn ni àwọn ọ̀rẹ́ fi ń tan èèyàn lọ si Libya pé iṣẹ́ gidi wà níbẹ̀ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Abikẹ Dabiri: Iṣẹ́ pọ̀ lọ́wọ́ Naptin àti àwọn aṣọ́bodè Nàìjíríà Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Ẹ kọrin ìyìn sí OLUWA, tí ó gúnwà ní Sioni!
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ìpínlẹ̀ Oṣun kò nílò Gómìnà oníjó - Oshiomole Olórí ilé asòfin l‘Ọ́sun pàdánù N38m sọ́wọ́ gbájúẹ̀ Àgbárá òjò bà'lú jẹ́ n'Ípínlẹ̀ Ogun Ọmọ Yorùbá ni onímọ̀ ẹ̀rọ ‘Rọ́bọ́tì’ tó ń gbowó jùlọ ní UK Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, OsunDecides: Omisore ní ẹni tó bá fẹ́ ra ìbò, àwọn yóò lọ lásọ mú ni Raji Ayoola baba rẹ jẹ Musulumi, ọmọ bibi ilu Ede nipinlẹ Osun, sugbọn mama rẹ Nnena Esther Adeleke jẹ ẹya Igbo, ti o si jẹ Kristẹni .
Toma Unu jẹ ẹni ìwúrí pẹ̀lú bí kò ṣe ro ti ìpèníjà rẹ̀ tó sì ń ṣe ohun ribi ribi to tayọ òye ènìyàn.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Boris Johnson: Olukemi Olufunto Badenosh di mínísítà ní London 30 Agẹmo 2019 Oríṣun àwòrán, Olukemi Olufunto Badenosh Olootu ijọba ilẹ Gẹẹsi, Boris Johnson ti yan ọmọ Yoruba atata kan, Olukemi Olufunto Badenosh, gẹgẹ bii ọkan lara awọn minisita rẹ.
Codeine: Àjọ aṣọ́bodè gba ògùn ikọ́ N200m lọwọ awọn onífàyàwọ́
omo ogun ọlọtẹ Boko Haram lọjọ kẹ́tàlá Abameta , osu kẹ́rin,ni
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù 2020: Ọdun 2020 yii ko nìí nira fún àwọn tó bá bẹ̀rù Olorun Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ 2020: Ọdun 2020 yii ko nìí nira fún àwọn tó bá bẹ̀rù Olorun 2 Sẹ́rẹ́ 2020 Aafa bẹ Olorun pe ko ṣe 2020 ni ọdun irọrun fun gbogbo wa- Sheikh Yahaya.
Wọn óo bímọ lémọ, wọn óo sì máa pọ̀ sí i.
Èyí mú kí onídàjọ́ Okon Abang, sún ìgbẹ́jọ́ rẹ̀ sí ọjọ́ mì í.
Ẹni tí ń pète àtiṣe ibini a óo máa pè ní oníṣẹ́ ibi.
Ileeṣẹ ọlọpaa nipinlẹ Eko ni ko din ni awọn ọdọmọkunrin mẹtadinlọgọta ti awọn ọlọpaa nipinlẹ Eko fi ofin mu 'lasiko ti wọn n ṣe eto igbaniwọle fun awọn to fẹ maa sẹ ibalopọ ọkunrin s'ọkunrin.
Awọn to n ta burẹdi lẹgbẹ titi naa faragba ninu iyanṣẹlodi yii, eleyii to fa ọwọngogo burẹdi kaakiri orilẹede Naijiria.
Àpótí ẹ̀rí, ati àwọn ọ̀pá rẹ̀, ìtẹ́ àánú rẹ̀, ati aṣọ títa rẹ̀.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Aarẹ Trump ati Kim Jong-un ti gba lati jọ ṣe'pade 9 Ẹrẹ̀nà 2018 Oríṣun àwòrán, AFP Àkọlé àwòrán, Trump ati Kim Jong-un ko fe imi ara wọn ri lakitan lenu ojo meta yi Aarẹ Donald Trump orilẹẹde Amerika ati akẹgbe rẹ lati North Korea Kim Jong-un ti gba lati jo ṣe ipade.
 Aya minista fun eto irinna ni Naijiria, Abileko Judith Amaechi to da ajo Empowerment Support Initiative sile ro awon obinrin lati fowosopo gbogun ti itankale arun jejere lasiko yii, bee naa lo parowa fun ijoba lati tubo sagbekale awon ibudo ayewo jejere kaakiri.
O ò fẹ́ ẹbọ, bẹ́ẹ̀ ni o ò fẹ́ ọrẹ,ṣugbọn o là mí ní etí;o ò bèèrè ẹbọ sísun tabi ẹbọ ẹ̀ṣẹ̀.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Blasphemy against Mohammed: Olórin Kano Yahaya Shariff-Aminu tí wọ́n dájọ́ ikú fún ti pe ẹjọ́ kòtẹ́milọ́rùn 11 Ògún 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 5 Owewe 2020 Oríṣun àwòrán, Idris Ibrahim Yahaya Shariff-Aminu ti wọn dajọ iku fun pe o sọrọ odi si Mohammed ni ilu Kano ti pe ẹjọ kotẹmilọrun niwaju ile ẹjọ giga kan niluu Kano.
Wọn á fi fadaka ati wúrà ṣe é lọ́ṣọ̀ọ́,wọn á sì fi ìṣó kàn án mọ́lẹ̀,kí ó má baà wó lulẹ̀.
Àwọn ajáko a máa fún àwọn ọmọ wọn lọ́mú.
Awọn fidio naa safihan awọn sẹnetọ meji kan ti ko gba t'ọkọ rẹ sita loju opo Twitter rẹ.
Olamide ni ọtọ ni ọrọ naa ri nitori pe ko sẹni to mọ ede ayan bii ẹni to mu ọpa ẹ dani, pe oun ti oun mu omele dani ni oun mọ nkan ti oun n sọ.
N kò ní ranti gbogbo ẹ̀ṣẹ̀ tí o ti dá mọ́.
 Àwọn ọmọ Nàìjíríà láti ilẹ̀ Gẹ̀ẹ́sì wọ̀ gàù l'Eko Gbajúmọ̀ agbábọ́ọ̀lù ni ǹ bá jẹ́, ká ní ń ko ṣeré tíátà - Bàbá Wande Ilé ẹjọ́ tó ga jùlọ ní Nàìjíríà wọ́gilé ẹ̀wọ̀n Orji Uzor Kalu, pàṣẹ ìgbẹ́jọ́ tuntun Ẹ̀mí mẹ́rin bọ́ sọnù, ọ̀pọ̀ èèyàn fara pa nínú ìjàmbá ọkọ̀ l'Ogbomoṣọ Àmọ́ Femi, tí ọ̀pọ̀ olólùfẹ́ rẹ tún ń pè ní Jelili Oniso wá yàn pé, òun kó tíì fi iṣẹ agbejoro sílè, nítorí òun sì ń gbèrò láti lọ gba òye ọmọwe nípa imọ òfin nílé ẹ̀kọ́ Fáṣítì, erongba òun sì ni lati maa kọ àwọn amofin nisẹ Lórí èrò àwọn èèyàn pé òfin Nàìjíríà àti ẹ̀ka èto ìdájọ́ wá fún olówó nìkan, tí idajọ sì ń fi iya jẹ àwọn mẹkunnu, Femi ni èyí kò rí bẹ́ẹ̀ nítorí ilé ẹjọ́ di ojú ni, tó sì ń fi etí gbọ ẹjọ́, bẹ́ẹ̀ lo ni ida láti ṣèdájọ́ fún ẹni tó bá jẹbi, bóyá olówó ni àbí mẹkunnu."
N óo fi ìgbàlà mi sí Sioni, fún Israẹli, ògo mi.
Àyẹ̀wò orúkọ olùdìbò bẹ̀rẹ̀, so tí yẹ orúkọ rẹ wò láàyè ìdìbò rẹ̀?
Nitori orisirisi isẹlẹ lo ti n sẹlẹ lẹnu ọjọ mẹta yii to n fẹ awofin daadaa.
Nítorí náà, n óo sọ iná sí orí odi ìlú Raba, yóo sì jó ibi ààbò rẹ̀ ní àjórun.
A máa bá igi sọ̀rọ̀, ó gbọ́ èdè ẹranko, ó gbọ́ ti ẹyẹ, ó sì gbọ́ ti ẹja inú omi.
"Ṣe ló dà bí ìgbésẹ̀ tó dára fún ìgbé ayé ìbálòpọ̀ mi""."
Wo àwọn ẹranko tí wọ́n máa figagbaga ni Egypt nínú AFCON 2019 Èyí ẹ ṣe tó, England àti VAR júwe ilé fún Cameroon Sọ àsọtẹ́lẹ̀ orílẹ̀èdè tí yóò borí ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ t'òní Ìdíje ife ẹ̀yẹ láàrin orílẹ̀èdè Áfíríkà 2019 Awọn ẹgbe agbabọọlu naa ko lati lọ fun ipade ti wọn ma n se saaju ifẹsẹwọnsẹ.
Nítorí náà, Asa kó fadaka ati wúrà láti ilé ìṣúra ilé OLUWA ati láti ààfin ranṣẹ sí Benhadadi, ọba Siria tí ó ń gbé Damasku, ó ranṣẹ sí i pé: 
"Osisẹ ile isẹ asọbode orilẹede Naijiria, Assistant Superintendent Nura Dahiru ti wa ni ile iwosan bayii, lẹyin to wa si olu ile isẹ naa pẹlu asọ ọga patapata to si kede ara rẹ gẹgẹ bii ọga patapata ""Comptroller-General""."
nítorí náà, ogun yóo bẹ́ sílẹ̀ láàrin àwọn eniyan yín, gbogbo ibi ààbò yín ni yóo parun.
Ẹ̀bùn #500,000 wà fún ẹni tọ bá ba wa rí afurasí ikú Akinyẹle tó sọnù- Iléeṣẹ́ Ọlọ́pàá Ilé ẹjọ́ yá lórí òfin CAMA tó fẹ́ gba àkóso ilé ìjọsìn, tẹ ẹ̀tọ́ aráàlú mọ́lẹ̀ - SERAP Oríṣun àwòrán, others Ki lo ti ṣẹwlẹ sẹyin?
Mo ti fún ọ ní irinwo ọjọ́ ó dín mẹ́wàá (390) láti fi ru ìjìyà ẹ̀ṣẹ̀ ilé Israẹli.
”“lati maa je ki o ba wa lojiji , a gbodo ti le mojuto eto oro aje wa, lati le satileyin fun iye awon eniyan, lati le pese ise ,eto eko, eto ilera, ireti ati  lati ni afojusun to dara.
OLUWA ti gbọ́ ẹkún ati ìráhùn yín pé, ‘Ta ni yóo fún wa ní ẹran jẹ, ó sàn fún wa jù báyìí lọ ní ilẹ̀ Ijipti.
Gbogbo bi ọrọ ọhun ṣe jẹ wa ninu fido yii.
" Ọkọ mi bẹrẹ si ni kan mi ni abuku, o ni asẹwo ni mi, to si n sọ fun mi pe oun kọ ni oun ni ọmọ naa, oun ko mọ ibi ti mo ti rii"" Catherine ni aye su oun, ti ọkan oun si daru."
Naijiria  tun maa n bu ola fun awon opo,
Ọdun mẹjọ to lo nile ijọba ilẹ America, White House, mu ko ṣe e ṣe fun Biden, lati ma a fi lara iṣẹ ti Obama ṣe polongo ibo.
Ẹ kọrin sókè, kí ẹ sì hó;ẹ̀yin ọmọ Israẹli!
Bi a ko ba gbagbe Lẹ́yìn ọ̀sẹ̀ kan tí wọ́n ti ń wá Khadijat tó jẹ́ ọmọ igbákeji gómínà tẹ́lẹ̀rí ní ìpínlẹ̀ Ondo,ni wọ́n bá òkú rẹ̀ ní ilé àfẹ́sọ́nà rẹ̀, Adeyemi Alao.
Báyìí ni ọ̀rọ̀ Oluwa fi agbára hàn; ó ń tàn kálẹ̀, ó sì ń lágbára.
Òkè náà súnmọ́ Jerusalẹmu, kò tó ibùsọ̀ kan sí ìlú.
BBC Yoruba wa n ki Alhaja Fausat Balogun pe oju yoo maa ri ọdun, Ọlọrun yoo si fun wọn ni ẹmi gigun ati alaafia lati lo iyoku ọjọ aye wọn ninu irọrun.
Ní ọjọ́ kan Eliṣa lọ sí Ṣunemu, níbi tí obinrin ọlọ́rọ̀ kan ń gbé; obinrin náà sì pe Eliṣa wọlé kí ó wá jẹun.
Gbogbo wọn pàdé ninu ilé Ọlọrun, wọ́n sì bá ọba dá majẹmu níbẹ̀.
Mekoh so pe, gbogbo awon agbe alada nla ati alaroje ni yoo janfaani ilana eto ogbin yii ti gonima ba se amulo re.
Ṣé ìwọ ti sáré pé ọmọ ọdún 40 ni?
Ọjọ kọkandilogun ọdun 2019 (Ifọrọwerọ oludije Aarẹ) Ayẹwo<br>lati mọ otitọ.
Oríṣun àwòrán, Instagram/lola margaret Oríṣun àwòrán, Instagram/adebayo tijani Agba oṣerebinrin, Joke Muyiwa ṣọjọ ibi tiẹ naa lọsẹ yii, ọmọ rẹ tun bimọ tuntun.
Nàìjíríà kò ní olórí, ẹ pín sí ẹlẹ́kùnjẹkùn - Soyinka Ọmọ pupa làwọn olólùfẹ́ wa fẹ́ wò nínú fíìmù làwọn òṣèré tíátà fi ń bóra- Muka Ray Olorì Anu Adeyemi ń ṣe ọjọ ìbí, ẹ gbọ́ ǹkan tò sọ sí Kábíyésì Nǹkan oṣù obìnrin le jáde ní imú tàbí ìdodo yàtọ̀ sí ojú ara - Dókítà Ni ti Azeezat, iroyin sọ pe alaga ẹgbẹ awọn onile ni Ijefun, Alhaji Taiwo Adeyemo ṣalaye pe okuta nla ni wọn fi fọ ori rẹ ninu yara rẹ.
ìlú Eko kọ́ ló léwu jùlọ láti gbé lágbàáyé- Ìjọba Eko Iroyin to tẹ wa lọwọ lati orilẹ-ede Amẹrika sọ pe laipẹ yii ni iṣẹ bọ lọwọ Ọgbẹni Ator, eleyi to fihan pe o ṣeeṣe ki inu si maa bi lọwọ nitori o ṣẹṣẹ padanu iṣẹ rẹ.
Mose bá fi ilẹ̀ Sihoni, ọba àwọn ará Amori, ilẹ̀ Ogu, ọba Baṣani ati àwọn ilẹ̀ ati àwọn ìlú tí ó yí wọn ká fún àwọn ọmọ Gadi, àwọn ọmọ Reubẹni ati ìdajì ẹ̀yà Manase ọmọ Josẹfu.
OLUWA dáhùn, ó ní, “Èmi nìkan ni mo tí ń fún ọtí waini, ẹnikẹ́ni kò bá mi fún un ninu àwọn eniyan mi.
Bí òjò tí ó ṣú dudu tí ó fẹ́ atẹ́gùn títíṣugbọn tí kò rọ̀,ni ẹni tí ó ń fọ́nnu láti fúnni lẹ́bùn,tí kò sì fúnni ní nǹkankan.
 pípọ ́ n yòò ibi ojú abẹ ́ rẹ ́ náà àti ìrora díẹ ̀ lè wáyé .
Jẹfuta bá sá jáde kúrò lọ́dọ̀ àwọn arakunrin rẹ̀, ó ń gbé ilẹ̀ Tobu.
O ni ko din ni eeyan marundinlogun to di oloogbe nibi iṣẹlẹ naa, ti oun atawọn olufẹhonuhan miran si gbe awọn to ṣeṣe lọ ba awọn ọmọ ogun, ti awọn ọmọ ogun naa si gbe oku wọn lọ.
Olùkọ́ fásitì méjì ń bèèrè ìbálòpọ̀ lọ́wọ́ akẹ́kọ̀ọ́ fún máákì Àwọn ọmọ Nàìjíríà faraya lórí Boniface tó fẹ́ bá àkẹ́kọ̀ọ̀ sùn Wo ìdí to fi gbọdọ̀ yàgò fún Bobrisky, akọ tó ń ṣe bíi abo Ìjọba, ẹ yé fi ẹ̀tọ́ ọmọnìyàn dun ọmọ Nàìjíríà mọ́- SERAP Makoda sọ fun BBC pe airilegbe jẹ iṣoro to buru julọ ti ẹda le maa doju kọ laye.
Yóo jẹ́ ọmọ òun, òun náà yóo sì jẹ́ baba rẹ̀.
Nigba ti ojogbon  Osinbajo, n ba
Ile iṣẹ iroyin NAN sọ pe eniyan mẹjọ lo ṣe ẹlẹri pe olujẹjọ lọwọ si ẹsun naa.
Awọn ọna wọnyii ni aarẹ yoo foju ba laarin aago mẹsan owurọ si mẹta ọsan ree: 1.
Mi ò fipá bá obìrin kankan lò- Agbábọ́ọ̀lù Neymar Ibanuje d'orí agbà k'odò, Ruiz fi ẹ̀ṣẹ́ sọ Anthony Joshua di ọmọ ológo àná Eyi n hande pẹlu bi Dino ṣe ṣẹṣẹ wọle gẹgẹ bi sẹnetọ fun igba keji ninu idibo to kọja ti wọn yoo bura wọle fun.
Igi yìí ní oríṣiríṣi èèso, èèso rẹ̀ sì dára lẹ́wà gidigid, ṣùgbọ́n ẹnikẹ́ni kì í fi ọwọ́ kàn án, nítorí ẹni tí ó bá fi ọwọ́ kàn án yóò rí ọ̀ràn, ẹni tí ó bá ká èèso Tèmi-nìkan yóò bá ìbínú Ọlọ́run pàdé.
Oríṣun àwòrán, Nigeria police force Àkọlé àwòrán, Olórí ikọ̀ adigunjalè tó ṣ'ọṣẹ́ ní Ọ̀ffà ti kú Banki marun un ni awọn adigunjale naa kọlu nigba naa ti wọn si pa eeyan ti ko din ni ọgbọn ninu eyi ti awọn ọlọpaa wa.
Akande ṣe alaisi l'ọjọ Abamẹta lẹni ọdun mẹtadinlọgọrin lẹyin aisan ranpẹ.
Ṣé a lè rí mààlúù tabi aguntan tí yóo tó láti pa fún wọn?
Nwachukwu ní, lẹ́yin ọjọ́ náà, ti Wasiu Ayinde ko ba bẹ̀bẹ̀ gẹ́gẹ́ bi àwọn ṣe kọ̀wé ránṣẹ́ sí í lórí ǹkan ti àwọn ń fẹ́ kó ṣe, lawọn yoo ṣe iwọde lọ sọdọ Kabiyesi iku baba yeye lati rọ ọ loye gẹgẹ bi Mayegun ilẹ Yoruba.
Ẹbọra kúkúrú bìlísì ni, a máa gbé ẹrù pàṣán kiri ọjọ́ ayé gbogbo.
Oríṣun àwòrán, Google Èyí sì ti mu ki ọpọlọpọ wárí fun un koda tohun ti oríṣiríṣi ayẹsi àti ami ẹyẹ to ti gba lagbaye.
Aarẹ Buhari to n dije dupo aarẹ fun igba keji lọdun 2019, yoo gbiyanju lati jẹ ki awọn eniyan mọ wipe eto oselu tiwantiwa jẹ oun logun lọpọlọpọ, ati wipe, oun yoo teramọ gbigbogun ti iwa ibajẹ lorilẹede Naijiria.
A kò ní ǹkan ṣe pẹ̀lú ẹgbẹ́ òsèlú -Adeboye Àwọn olùdíje Ọṣun jẹ́wọ́ ara wọ́n Àwọn ohun tó yẹ́ kí o mọ̀ nípa Ọ̀gá DSS tuntun Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ọ̀rọ̀ Imam yìí ṣe kòńgẹ́ bó ti ń rí láàrin lọ́kọ láya Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Orílẹ̀-èdè bí Kenya, Canada, Australia, India, Colombia, Malayhsia, Nicaragua, Jamaica, Uganda, Lebanon àti Trinidad & Tobego náà ti yọwó orí nínú ìléèdí obìnrin Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Akọ́mọlédè àti Àṣà lórí BBC Yorùbá: Kọ̀ síi nípa iṣẹ́ tí oúnjẹ ń ṣe lára níbí Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Ondo Heardsmen vs Falae: Ilé iṣẹ́ ọlọ́pàá ìpińlẹ̀ Ondo ni Olóyè Falae kò tí ì mú ẹjọ́ wá si àgọ́ ọlọ́pàá kankan24 Bélú 2020 India Wedding: Ìyàwó kan ní India wọ sòkòtò fún ayẹyẹ ìgbéyàwó rẹ̀- Wo ìdí tó fi ṣe bẹ́ẹ̀25 Bélú 2020 Amos Dauda, Iphone: Ilé ẹjọ́ dájọ́ ẹgba mẹ́ẹ̀dóògún fún ọ̀daràn tó jí Iphone ní Kaduna25 Bélú 2020 Senator Ishaku Abbo: ìdí rèé tí mò fi fi kọ̀wé fi PDP sílẹ̀ darapọ̀ mọ́ ẹgbẹ́ òṣèlú APC25 Bélú 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 3 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 5 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
’’ “Mo duro digbi labe asia egbe APC, bee si ni mimi kan ko le e mimi,”Alaga egbe APC, Adams Oshiomhole wa so pe, oun yoo wa ojutu si gbogbo rogbodiyan ti o le wu to le ma a sele laarin awon omo egbe naa nipinle Benue.
Díẹ̀ díẹ̀, á máa dín agbára ara ẹni láti dáàbò bo ararẹ̀ kù.
Ṣugbọn àwọn ọmọ Israẹli dìtẹ̀ sí mi ninu aṣálẹ̀, wọn kò pa òfin mi mọ́; wọ́n sì kọ ìlànà mi sílẹ̀, èyí tí ẹnikẹ́ni tí ó bá tẹ̀lé yóo yè.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Lockdown updates: Naira Marley gbóríyìn fún Jude Chukwuka pẹ̀lú #1 míliọnù Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
- Ijebu Ọkọ̀ méjì jóná ráùráú níbi tí ọkọ̀ tó gbé bẹntiróò ti gbiná Ẹgbẹ́ aláwọ̀ dúdú àti ẹgbẹ́ aláwọ̀ fúnfun.
To ba jẹ eeyan ti ọpọlọ rẹ pe, ti o jẹ olootọ, ti ẹni naa ko si ya ọlẹ, yoo ba Ajimobi sisẹ pọ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Coronavirus: Ọkùnrin kan kú lẹ́yìn tí wọ́n lù ú nítorí ìbẹ̀rù coronavirus 19 Ẹrẹ̀nà 2020 Ọkunrin kan ti wọn fi ẹsun kan pe o ni arun coronavirus ti dero ọrun lọsan gangan lẹyin ti awọn ọdọ tinu n bi dawọjọ lu u.
Ogun tí ó wà láàrin Rehoboamu ati Jeroboamu tún wà bẹ́ẹ̀ ní gbogbo ìgbà tí Abijamu wà lórí oyè.
Ẹ bá mi wá nọ́ńbà ìpè òbí ọmọ Mummy Calm Down jáde - Yinka Ayefele Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Mummy calm down: Ìyá Ore sọ pé gbogbo ìgbà tí óun bá n bá a wí ló ma n ṣe àwàdà Dandan kọ́ ni kí Buhari ó bá ayín sọ̀rọ̀ lórí coronavirus, ó ti ṣe gbogbo nkan tó yẹ kó ṣe - Iléèṣẹ́ ààrẹ Ǹjẹ́ ọmọ Buhari lásẹ láti wọ Ọkọ̀ òfúrufú Nigeria Air force lọ sí òde?
Kọmiṣọnna fun ọrọ awọn obinrin ati idagbasoke ilu, Alaaja Faosat Sanni to ṣalaye ọrọ naa ni Ibadan.
Àwọn ènìyàn wọ̀nyi fi orúkọ sílẹ̀ láì sí kọ́nukọ́họ nínú fún owó ẹgbẹ̀rún márùndílagọ́rin bílíọ̀nù náírà, owó ìràwọ ìjọba fún àwọn tó n ṣe oko-òwò ara wọn.
Nínú ọ̀rọ̀ tí Lizzy gbe sojú òpó instagram rẹ̀, ó dúpẹ́ lọ́wọ́ ọkọ rẹ̀ tí a kò tí ì le fìdí orúkọ rẹ̀ múlẹ́, fún gbogbo oore tó ti ṣe òun, àti ìyá Lizzy tó ti d'ológbèé, láti ìgbà tí wọ́n ti páde.
a dá ẹni ibi sí ní ọjọ́ ìdàrúdàpọ̀,ati pé a gbà á là ní ọjọ́ ibinu?
Àbí ẹran ara mi jẹ́ idẹ?
O ti di eewọ fun olukọ lati gbá ibadi akẹkọo mu, tabi ko dimọ ọ, ko fi ẹnu ko o ni ẹnu tabi ko fi ọwọ kan ara tabi ọyan irufẹ akẹkọọ bẹẹ.
Ọgọọrọ eeyan lo ti n ki Alaafin Oyo, Oba Lamidi Olayiwola Adeyemi kẹta ku ayẹyẹ ọjọ ibi ọdun mejilelelọgọrin loke eepẹ.
"Oríṣun àwòrán, Adedayo Owolabi Bakan naa lo fikun pe, ""igbimọ̀ alasẹ́ ẹ́gbẹawakọ ero nipinlẹ Ọyọ ti fi isẹlẹ yii to olu ile ẹgbẹ NURTW ni Abuja leti, bi o tilẹ jẹ pe wọn wa nilu Mecca lọwọ-lọwọ fun eto Umura."
Solomoni bá búra lórúkọ OLUWA pé, kí Ọlọrun pa òun bí òun kò bá pa Adonija nítorí ọ̀rọ̀ yìí.
Homepage Accessibility links Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Ìrànlọ́wọ́ Ìwọlé News Sport Weather Radio Arts Ààtò BBC News Yorùbá BBC Yoruba ÀkọléÀkọlé abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Àkọlé bọ̀tìnnì síwájú síi Olùmúdọ́gba bọ́tìnnì síwájú síi Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Media player Close player Close player Close player Lọ́wọ́lọ́wọ́Lọ́wọ́lọ́wọ́ Ìjọba ìpínlẹ̀ Ogun ti pàṣẹ kí wọ́n ṣí gbogbo ilé ìjọsìn, ilé ìgbafẹ́ padà lẹ́kúnrẹ́rẹ́ Eyi ni akojọpọ iroyin lori bi nkan ṣe n lọ lori eto idibo gomina nipinlẹ́ Ondo Related Video and Audio Video 5 minutes 42 secondsVideo 5 minutes 42 seconds5:42 Play video Ojú àwọn èèyàn Ondo ti là pé ìnira ni ẹgbẹ́ APC mú wá - Jegede PDP from BBCOjú àwọn èèyàn Ondo ti là pé ìnira ni ẹgbẹ́ APC mú wá - Jegede PDP BBCPlay video Ojú àwọn èèyàn Ondo ti là pé ìnira ni ẹgbẹ́ APC mú wá - Jegede PDP from BBC I'll sign in later And we'll keep you signed in.
Fun Asari Toru LGA, AAC ni ibo 18945 nigba ti PDP ni ibo 32172.
Oríṣun àwòrán, TWITTER ''Lasiko ti iditẹgbajọba naa waye ni Bajọwa bi ọmọ ọkunrin jojolo, ti o si fẹ sọ ni orukọ mi, nitori naa o sọ wi pe, oun n bọ wa si ile ọdọ mi.
Ẹ̀bùn ọ́kọ N303m: Fún ààbò ẹ̀mí ni àbí àbẹ̀tẹ́lẹ̀?
Oko ofurufu to n gbe minista fun oro abele ni orile-ede Mexico ati gomina ipinle kan ti jabo lori oko akeru meji kan ni ori papa lasiko to n gbiyanju lati bale ni Santiago Jamiltepac lojo Eti.
Ni gbogbo agbaye ọjọ ori awọn to ku to pọ julọ jẹ lati ọgọrin ọdun soke.
Ogun náà le fún Saulu gidigidi, àwọn tafàtafà ta á ní ọfà, ó sì farapa lọpọlọpọ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Coronavirus: Ìwádìí ń lọ láti fi ẹ̀jẹ̀ àwọn tó ti jajabọ lọ́wọ́ Coronavirus ṣe ìwòsàn fáwọn alárùn míràn 21 Ìgbé 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 28 Ìgbé 2020 Ìjọba ilẹ̀ United Kingdom (UK) tí ń palẹ mọ láti lo ẹ̀jẹ̀ àwọn èèyàn ti orí kò yọ lọ́wọ́ àrùn Coronavirus fi ṣe ìwòsàn fún àwọn èèyàn ti àrùn náà ń bá fínra lọ́wọ́ lọ́wọ́.
“Nígbà náà ìjọba ọ̀run yóo tún rí báyìí.
‘Ọ̀kan ninu àwọn tí ó ti ilẹ̀ Ijipti wá, láti ẹni ogún ọdún sókè kò ní rí ilẹ̀ náà tí mo ṣèlérí fún Abrahamu, fún Isaaki ati fún Jakọbu, nítorí pé wọn kò fi tọkàntọkàn ṣe tèmi.
Àtúnṣe òpópónà Lagos-Ibadan àwọn ọ̀ná míràn ti e lè gba Bianca júwe ilé fún Serena Williams nínú ìdíje l'America Wọn ni awọn ọdọ ẹya Hausa marun un kan ni wọn wa gba lati gbe oku wọn jade lati inu kọnga naa.
Bakan naa, ni Omotayo tun gbo ewuro soju akegbe re lati orile-ede  Belize Rohit Pagarani pelu ami-ayo (11-4), (11-2), (11-2).
Nítorí wọn a máa fi ibinu paniyan,wọn a sì máa ṣá akọ mààlúù lọ́gbẹ́ bí ohun ìdárayá.
Ijọba ipinlẹ Ekiti ti kede pe oṣiṣẹ eleto ilẹra meji wa ninu awọn marun un to ṣẹṣẹ lugbadi arun naa ni ipinlẹ Ekiti.
Sylvia ni awọn ọkọ ayọkẹlẹ ni wọn ṣe lati maa lo gaasi ati epo petirolu papọ, bẹẹ si ni afẹfẹ gaasi dinwo ju epo petirolu lọ.
Nítorí náà gbé ohùn ẹ̀bẹ̀ sókè kí o gbadura fún àwọn eniyan tí ó kù.
Oríṣun àwòrán, Betty Abah/twitter Àkọlé àwòrán, Sàdédé ni àwọn ọmọ onílẹ̀ tún yọjú, ni ifowosowopo pẹ̀lú àwọn ọlọ́pàá Lásìkò to ń sọ̀rọ̀ lórí ìkọlù táwọn ọmọ onílẹ̀ ohun ṣe, agbajero kan, tó tún jẹ́ ajá fẹ́tọ̀ọ́ ìlú, Ebun-Olú Adegboruwa ṣàlàyé pé, ó ṣe ni láàánú pé irú ìṣẹ̀lẹ̀ bẹ́ẹ̀ wáyé.
Ọba ti etutu rẹ ko ba ti pe, le kọ aya rẹ silẹ, ki ẹlomii si gori rẹ laisi ohunkohun ti yoo ṣẹlẹ, ṣugbọn ti o ba ṣe etutu pe, ko sọkunrun kankan to gbọdọ gori iyawo iru Ọba bẹẹ laijẹ iyan rẹ niṣu.
Awọn onimọtoto: Iyatọ kan gboogi to wa laarin iwọde End SARS yii ati awọn to ti kọja lọ ni bi awọn eeyan kan ṣe palẹmọ ojuko iwọde lẹyin ti awọn eeyan ba pada sile wọn tan.
Ó tún jẹ́ òjíṣẹ́ ati aṣojú yín tí ó ń mójútó àìní mi.
Gbogbo wa mà ni a óo dúró níwájú ìtẹ́ ìdájọ́ Ọlọrun!
Wọ́n fi ewúrẹ́ rúbọ, wọ́n fi àgùntàn rúbọ, wọ́n pa mààlúù sí oríta, wọ́n pa àkùkọ, wọ́n pa àgbébọ̀, wọ́n sì fi odidi ènìyàn ṣeẹbọ, ṣùgbọ́n síbẹ̀ Olódùmarè kò rán ẹ̀dá náà wá àfi ìgbà tí ọdún mẹ́rìnlá tóó pé.
olorun dari ipinle naa nipa yiyan gomina ti yoo mu eto idagbasoke ati itẹsiwaju
Gbajugbaja oniroyin, Dele Momodu ni tirẹ ṣalaye lori ikanni twitter rẹ pe '.
Joṣua bá sọ fún àwọn ọmọ Israẹli pé, “Ìgbà wo ni ẹ fẹ́ dúró dà kí ẹ tó lọ gba ilẹ̀ tí OLUWA Ọlọrun àwọn baba yín ti fun yín.
Ní kúkúrú, Fẹntíletọ̀ lọ máa ń gba isẹ́ mímí ṣe nígbà tí àìsàn bá ń bá ẹ̀dọ̀ fòòró ja tí kò sì lè ṣe ojúṣe rẹ̀ mọ́.
Ṣé ẹ ti gbàgbé ibi tí àwọn baba ńlá yín ṣe ní ilẹ̀ Juda ati ìgboro Jerusalẹmu, tí àwọn ọba Juda ati àwọn ayaba ṣe ati ẹ̀yin pẹlu àwọn iyawo yín?
Oríṣun àwòrán, @ABBAYOLA447 Àkọlé àwòrán, Ọranyan kọ ni gbigba aawẹ Ramadan fun awọn ọmọ ẹgbẹ Hakika Wọn ni kekere ni awọn ti fẹ pa eekan ikọ ẹlsin Hakika, tori ti wọn ba dagba tan, wọn lee maa gba ẹbọ lọwọ awọn ọmọ ilẹ Naijiria bii Boko Haram.
New Minimum Wage: Òṣìṣẹ́ ń fẹ́ kí ìjọba bẹ̀rẹ̀ sí san owó oṣù tuntun kíákíá
O soro lori irinajo abewo ti eka ibanisoro ajo IFAD gun le ki won le fi mo isoro to n dojuko awon agbe ati ona abayo sisoro wonyii.
30 Bélú 2020 Oríṣun àwòrán, Google Ijọba apapọ lorilẹede Naijria ti kede pe awọn ọmọ Naijiria to to miliọnu marundinlọgbọn ni yoo jẹ anfaani ina ọba ti oorun n pese, iyen Solar Power.
Ọrọ naa fẹ ṣe bi itahunsiaraẹni laarin awọn mejeeji yii.
"Ileewe to n lọ ni wọn ti ya ọjọ kan sọtọ fun ẹgbẹ awọn to n ta ayo Chess ni Ọjọbọ lọsọọsẹ.
Àwọn ọmọ Nàìjíríà la ohùn Èèyàn mẹ́tàlá dèrò ọ̀run nínú ìjàmbá ọkọ̀ lópòpónà Ìbàdàn s'ÈKó Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Aeroplane House: Látọdún 1999 ni mo ti bẹ̀rẹ̀ kíkọ́ ilé yìí fún ìyàwó mi ọ̀wọ́n Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
majẹmu náà ni pé, lae, n kò tún ní fi ìkún omi pa gbogbo ẹ̀dá alààyè run mọ́, bẹ́ẹ̀ ni kò ní sí ìkún omi tí yóo pa ayé rẹ́ mọ́.
Iṣẹ́ tíátà kìí jẹ́ kí obìnrin tètè rí ọkọ fẹ́, wọ́n maa n ro pé mo ti lajú jù - Aisha Lawal Àwọn Kristiẹni tó ṣe ìwọ́de lórí ètò àbò ń tako ìjọba ni - MURIC Ṣíṣe iṣẹ́ ọlọ́pàá agbègbè láì gbowó, òfo ni - Onímọ̀ ètò ààbò Mímu ọtí líle àti oúnjẹ oní sítáṣì le è fa àrùn jẹjẹrẹ ọyàn - Onímọ̀ Naijiria ati Ilẹ Amerika buwọ́lu ìwé àdéhùn lórí owó ìlú tí Abacha lù ní póńpó Isah ni iyawo Salisu gun un lọbẹ kaakiri ara rẹ to fi mọ inu, nigba ti Salisu n sun lọwọ.
 Looking forward to the next Chapter and hoping God will Bless me as much as he did for my football career 🙏🏾🙏🏾🙏🏾 DD11 1989 Là où tout à commencé !
Ó ní, “Omi yìí ń ṣàn lọ sí Araba, ní ìhà ìlà oòrùn, nígbà tí ó bá sì ṣàn wọ inú òkun, omi inú òkun, yóo di omi tí ó mọ́ gaara.
Ìwà ọ̀dàlẹ̀ ni bí ẹ kò bá gbé iléèwé ìkọ́ṣẹ́ olùkọ́ni kalẹ̀ sí ìlú Ìwó- Oluwo Oluwo àti Olorì àná, Chanel Chin tahùn síra N kò fẹ́ eégún onídọ̀tí ní ààfin mi - Oluwo Ni bayi ti o ti gba idajọ naa, ko ni laanfaani lati kopa ninu ipade awọn lọbalọba fun oṣu mẹfa gbako.
Olorin kan nipinlẹ Kano ti orukọ rẹ n jẹ Sanusi Abdullahi, lo ri ibinu ọlọpaa lori ẹsun pe o kọrin bu Gomina Abdullahi Ganduje.
Ami ayo meji soodo ni Madagascar fi fi ẹyin Super Eagles janlẹ.
OLUWA ní,“Bí o bá àwọn tí ń fi ẹsẹ̀ sáré sáré, tí ó bá rẹ̀ ọ́,báwo ni o ṣe lè bá ẹṣin sáré?
Ìhun ni èdè ènìyàn gùn lé tàbí dálé.
Mọ́kanlélọ́gọ́rin àwọn tó ṣẹ̀ṣẹ̀ lùgbàdì ààrùn náà wá láti ìpínlẹ̀ Eko, márùndínlógójì láti Jigawa, nígbà tí ìpínlẹ̀ Borno àti Kano ní ènìyàn mẹ́rìndílọ́gbọ̀n.
Sùgbọ́n ní báyìí, mo ti dínkù sí ẹyọ kan tabi ààbọ̀, tí Kolo kò sì setán láti sọ̀rọ̀ síwájú."
” Wí fún wọn pé, “Ẹ̀yin gan-an ni ẹ jẹ́ ẹrù.
Aarẹ Buhari mẹnu ba awọn iwa ikọlu gbogbo tawọn oluwọde naa ti gbe ṣe eleyi to si ni o mu ibanujẹ ba oun gẹgẹ bi aarẹ, paapaa julọ iku awọn eeyan kan lasiko naa.
Aládugbò kan ti ọ̀rọ̀ náà soju ẹ to si ba BBC sọ̀rọ̀ sàlàye pé àwọn adigunjale náà ko ni àànfani láti de ibi ti àwọn akẹkọ̀ọ́ náà sùn si.
Ohun to jẹ iyalẹnu ni pe awọn ogo-wẹẹrẹ ti a mọ si ''Nursery pupils'' ti ijọba paṣẹ pe ki wọn maa tii wọle rara naa wọle pẹlu awọn akẹkọọ ileewe alakọbẹrẹ lawọn ileewe kan niluu Eko.
Oríṣun àwòrán, Twitter/The Senate President Ijiroro gbagade lori eto iṣuna ile Ile igbimọ aṣofin agba l'Abuja ṣe ijiroro gbagade ẹlẹẹkẹta iru rẹ lori eto iṣuna ile ninu oṣu kẹta, ọdun 2019.
“Ipinle márùndínlọ́gbọ̀n lorile ede yii ni won ti n fun awon omo ile –iwe alakọọbẹrẹ ni ounjẹ, a ti gba ẹ̀ẹ́dẹ́gbẹ̀ta si ise nipa eto ironi-lagbara( N-Power), a si tun n fun awon milionu meji onisowo keekeeke ni owo ise ni gbogbo ipinle to wa lorile ede yii”.
Ọwọ́ mi ni mo fi ṣe gbogbo nǹkan wọnyi, tèmi sì ni gbogbo wọn.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, SS3 ní mo wà báyìí, mo sì ti gba àmì ẹ̀yẹ̀ púpò nílé-lóko gẹ́gẹ́ bí onílù - Ayansike Bi o tilẹ jẹ pe BBC Yoruba ko le sọ pato boya aafin Ọyọ si ni Olori Badra si n gbe abi o ti kuro ninu aafin, gẹgẹ bawọn iroyin kan se n wi kiri.
Eyi si yatọ si awọn ọtọkulu kaakiri agbaye ti awọn pẹlu yoo peju sibi eto igbeyawo naa.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ọmọ ọdún méjìlá yìí sọ bó ṣe di téélọ̀ táwọn àgbà ń bẹ́rí fún Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
gbosuba fun ajo to n samojuto gbigbe ati mimu oogun oloro lorile ede Naijiria (National
O ni ki ijọba wo awokọṣe awọn orilede mii to ti ṣe iru rẹ fun awn araalu lati pọn wọn le.
Bẹnjamini bí ọmọkunrin marun-un, Bela ni àkọ́bí, lẹ́yìn rẹ̀ ni Aṣibeli, 
Nnamdi Kanu: Mo lè dá wàhálà sílẹ̀ ní Nàíjíríà, tí ìjọba bá bími nínú
Eyi waye latari ibẹru ati ifoya pe o ṣeeṣe ki wahala ṣẹlẹ ni awọn agbegbe kan ni Naijiria lasiko eto idibo 2019.
Àbí bẹ́ẹ̀ kọ́, ẹ̀yin ọmọ Israẹli?
fi emi imoore han si awon ara ilu, nigba ti o n ba awon akoroyin soro ni ile re
Ile ise to n gbe fiimu sita, Marvel studio, ti kede pe, sinima won tuntun “Avengers: Infinity War” ti pa owo to to milionu dola ogbon o le ni eedegbefa wole lagbaye bayii.
A ti bẹ̀rẹ̀ ìwádìí lórí ibì tí owó tí àwọn adigunjalẹ̀ gbé ní banki Okeho wọ̀lẹ̀ sí- Ọlọ́pàá Ìyàwó Bukola Saraki fún tìyá-tọmọ olójú búlúù ní N250, 000!
A sì sọ fún ọ pé, ‘Ọmọ náà kò lè fi baba rẹ̀ sílẹ̀, nítorí pé bí ó bá fi baba rẹ̀ sílẹ̀, baba rẹ̀ yóo kú.
Ewe, saaju iyansipo tuntun ohun, ogbeni Muri-Okunola je akowe agba ile-ise to n mojuto lilo ati pipin ile nipinle naa(Land Use and Allocation Committee) (LUAC), ipo ti o wa lati odun 2005 si odun 2011.
Ajakalẹ arun coronavirus lo jẹ ki wọn sun ibẹrẹ idije liigi bọọlu orilẹede China siwaju lai lọjọ.
"Iwe fidihẹ ti wọn ti gba láti ìbẹ̀rl náà ni w\\]on si fi ń lóju pópó ti wọn bá dá wọn dúró láti bèrè ìwé ìrìnà wọn, kódà kii àsìkò lílò ìwé náà ti kọjá, Awọn ǹkan ti àn gbìyànjú láti fi òpín sí rèé"" "" Tí a bá gbá ọkọ̀ rẹ̀ mú tí ó si le fi ìwé ìrìnà ojúlówó rẹ hàn wá, láárìn wákàti mẹ́rìnlélógun, ó san owó ìtànran, lẹ̀yìn owó ìtanràn òó si tún lọ gba ìwé ìrùnà náà kí ó to gbé mótò rẹ̀ ni àgọ wá,'' Eyí jẹ ọ̀rọ̀ Omeje O ní kò tọ̀nà láti má ṣe àfihan ẹ̀dà ìwé ìrina ọkọ̀ kò ba ofin mu, ojulówó ni ǹkan ti àjọ FRSC ń bèrè."
Wọ́n dáhùn pé, “Saulu fẹ́ pa wá run, kò sì fẹ́ kí ẹnikẹ́ni ninu wa wà láàyè níbikíbi, ní ilẹ̀ Israẹli.
Fi irẹlẹ beere idi ti ọlọpaa fẹ fi mu ọ: Ẹtọ rẹ ni lati mọ.
 Ìmò elédè nípa èdè rè ni yóò je wá lógún nínú jùlo .
Ewe, Kenneth Omeruo, Ogenyi Onazi, Tyronne Ebuehi ati Ahmed Musa yoo ropo won saaju ifesewonse naa, sugbon Francis Odinaka Uzoho, Joel Obi ati Brian Idowu yoo di ipo won mu bi o se wa tele.
Kò sì ní yipada, bẹ́ẹ̀ ni nítorí ẹ̀ṣẹ̀ olukuluku, ẹnikẹ́ni ninu wọn kò ní sí láàyè.
Ibaṣepọ laarin awọn mejeeji ti fori sanpọn, ti Obaseki si ti mura lati darapọ mọ ẹgbẹ oṣẹlu PDP.
Nínú ọ̀rọ̀ rẹ̀, ipele kejì yìí yóò wà fún ọ̀sẹ̀ mẹ́rin láti ọjọ́ kejì oṣù kẹfa sí ọjọ́ kọkàdínlọ́gbọ̀n oṣù kẹfà, ọdún 2020.
4 1720056 Orilẹede Russia 45370 31.
Bẹ́ẹ̀ ni àwọn ọmọ ogun ṣe jáde ní ìlú: àwọn ọ̀dọ́ ọmọ ogun ni wọ́n ṣáájú ogun, lẹ́yìn náà, àwọn ọmọ ogun Israẹli tẹ̀lé wọn.
Agbára OLUWA kò dínkù, tí ó fi lè gbani là,etí rẹ̀ kò di, tí kò fi ní gbọ́.
Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Ọjọ kọkandinlọgbọn, ọdun 1936 ni ibugbe awọn ologun oju omi ni Coco Solo Naval Air Station ni wọn ti bi John McCain.
Bàbá-à mi ti kìlọ̀ fún mi wí pé ó yẹ ki nsọ́ra kí n tó ní ìyàwó, kí n sì kún fún àdúrà kí n tό lóbìnrin.
 kí ó lè di ààrẹ orílẹ ̀ èdè nàìjíríà , ó ń tẹ ̀ lé ọkọ rẹ ̀ kákàkiri orílẹ ̀ èdè nàìjíríà láti rọ àwọn ènìyàn kí wọn ó dìbò fún .
Okiki rẹ bẹrẹ si n kan lẹyin ti oun ati ẹgbẹ rẹ Da Pulse jawe olubori ninu idije orin Star Quest lọdun 2009.
Ṣugbọn lẹyin oṣu diẹ ti o bimọ, John tun ji lọjọ kan, lo tun ri i pe o ti de e mọ ibusun.
O salaye pe, ayajo ojo oni je ibanuje latari bi awon odaran kan se n ji awon akekoo gbe, ni paapaa awon akekoo  Chibok ati Dapchi.
INEC fun ipinle Plateau, ọjọgbọn Richard  lo kede abajade esi idibo lọjọ Aiku Kimbir  niluu Jos.
Ẹni tí yóo jẹ́ aṣaaju níláti máa ṣe bí iranṣẹ.
Oríṣun àwòrán, Bolanle Ninalowo/Instagram Lọdun 2018 ni Bolanle Ninalowo ati iyawo rẹ ti wọn yara wọn lati nkan bi ọdun mejila pada gẹgẹ bi tọkọtaya.
Ijọba tun kede orukọ Ileeṣẹ ọkọ ofurufu mẹsan an gẹgẹ bi awọn iléeṣẹ́ tó fi ountẹ lu lati maa ko awọn arinrin ajo lọ si oke okun.
Gichuru ni lati lọ tọrọ aforiji lori Twitter lọwọ awọn alatẹle rẹ, bẹẹ lo yọ iroyin naa kuro.
  Èmi náà bá ranjú mọ́n wọn padà.
Ìró yìí ni a le pè ní ariwo tí a fi ẹnu pa.
Mo kàn fẹ́ fi ọmọ tó sọnù gba owó lọ́wọ́ Sọtitobire ni - Afurasí Ẹ̀yin ẹ máà wò ó, ó ṣeéṣe kí APC túká lẹ́yìn ìṣèjọ́ba Buhari!
” Aare egbe ohun tun fi kun un pe alaafia obinrin je egbe
Ó ni wọn ri aṣọ oogun tawọn fi n ṣe ere lọwọ oun, wọn na oun pupọ, amọ oun ko jawọ lẹyin isẹ tiata.
Garba Sheu: Rárá kò kòwé bèrè ìwé ẹ̀rí.
Nítorí ó wá láti ọ̀nà jíjìn láti gbọ́ ọgbọ́n Solomoni.
Koda asia orilẹede Argentina ati jẹsi rẹ pẹlu nọmba ''10'' ti o maa n wọ wa lori posi Maradona fun awọn eeyan lati ri lolu ileeṣẹ ijọba ilẹ naa.
Amọṣa, ilẹkẹ maa ja sile, maa ja sita, ibi kan naa ni yoo jasi.
Abacha, lati ipasẹ Al Mustafa fi ọwọ lile dari Naijiria, Isẹlẹ Ado oloro yinyin gba ilu kan, ọpọ awọn ọmọ ẹgbẹ ajafẹtọ ilu ati ẹgbẹ to n ja fun ifẹsẹmulẹ ijọba alagbada NADECO, di ero ẹwọn.
Ó mú kí ibú hó bí omi inú ìkòkò,ó ṣe òkun bí ìkòkò òróró ìpara.
Ibudo yii ni wọn wa ti Yemoja ti wọn n pe ni Ọṣun fi yọju si Olutimẹyin, ti onitọun naa si rọ Ọṣun lati lewaju oun ati awọn eeyan rẹ ls si ibi ti wọn yoo tẹdo si ta mọ si ilu Oṣogbo bayii.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Yoruba ni bi eegun ẹni ba jo re, ori a maa ya atọkun rẹ.
A ri ómó ódun merindinlogun kan to fi hijab bo ojú rẹ̀ lára àwọn to wa niyàrá tí kò ni fèrèsé.
 ) olórun awòn elésìn kìrìsìtééní àti àwon mùsùlùmí gbàgbó nínú olórun an , nínú awon èsùn ìyókù , orísìírísìí àwon olórun ló wà fún ; òjò , má , ìlera àti béè béè lo .
Bákan náà ni ẹni tí ó gba àpò meji.
Òkìkí rẹ̀ pọ̀ nítorí pé o ràn án lọ́wọ́;o sì fi iyì ati ọlá ńlá jíǹkí rẹ̀.
Ṣé irú ọ̀rọ̀ tí eniyan máa sọ nìyí, ẹ̀yin ará ilé Jakọbu?
Ahmed Musa gbàmì ẹ̀yẹ agbábọ́ọ̀lù tó pegede ní ọdún 2018 Ẹ̀ wo bí àwọn ẹ̀ṣọ́ ojú etí òkun ṣe ń ṣiṣẹ́ l'Eko Awakọ̀ òfúrufú Ethiopian Airlines pariwo 'lọ sókè!
Kayeefi BBC Yoruba toṣu yii gba ọna ọtọ yọ, bi àwọn kan ṣe ṣe ni pe wooli yii ku ti wọn ko ri oku rẹ sin.
Ọjọbọ ọsẹ ni Gbajabiamila n sọ fun awọn oniroyin lẹyin to ṣepade kan pẹlu aarẹ ni ile rẹ.
" Akeugbagold ni bi asiri awọn afurasi ajọmọgbe naa ṣe tu, lo fihan pe Ọlọrun jẹri oun pe oun nikan soso ni oun n sin.
O wa beere pe 'ṣe bi awọn olori Saudi Arabia ṣe n ṣe àwọn eniyan wọn nìyí?
 Ẹya àwọn ti ó ń sọ èdè ibibio ni wọn , wọ ́ wà ní Ìpínlẹ ̀ akwa-ibom ni orílẹ ̀ èdè nigeria .
Some pictures of our team in training.
to n gbero lati lu orile-ede Naijiria ni jibiti ogunlogo bilionu owo
Èyí dà wọ́n láàmú, ó sì yà wọ́n lẹ́nu.
World Cup 2018: Ijàkàdì kọ́, Ipele àkọ́kọ́ nínú ìdíje pari!
Bakan naa ni awọn ọdọ to ba n lo oogun oloro naa le bẹrẹ si ni tọ si ara ati si ori ibusun wọn.
 nígbà tí ẹnìkan bá rò pé òun ló mọ nǹkan ṣe jú , èrò tòun ló tọ ̀ nà jù , kò sí ẹni tó gbọ ́ dọ ̀ ta ko ohun tí òun bá sọ .
Alukoro fun ileeṣẹ ọlọpaa ipinlẹ Bayelsa, Butswat Asimin naa tun fidi rẹ mu lẹ pe iya Siasia ti gba ominira lọwọ awọn ajinigbe.
Ọlọ́pàá Uganda rí ohun ìpara olóró nínú ‘baby’ tí ẹnìkan pọ́n sẹ́yìn bí ọmọ Àwọn ọjọ́ ìsìnmi tó máa wà nínú ọdún 2020 ní Nàìjíríà Ìjọba Nàìjíríà ti rí obìnrin tó wà l'óko ẹrú ní Lebanon gbà Ẹ̀bùn ọdún tuntun tó yááyì ni ikọ̀ Amotekun - Soyinka Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ifa Priest: ọdún mọ́kànlá ni mo fi ṣe iṣẹ́ agbejọ́rọ̀ kí n tó gbọ́ràn si Ifá lẹ́nu Ariwo kò jẹ́!
O ni o ''ṣe ni laanu pe awọn ọmọ ẹgbẹ naa mẹta padanu ẹmi wọn ninu ikọlu ohun ṣugbọn awọn ọmọ ogun meji naa farapa.
Mo kan ranti pe nigba ti mo wa l'ọmọde, mo maa n ṣaiṣan nigbogbo igba, iya mi si mu mi lọ sile iwosan fun ayẹwo.
-Olugbo Obateru Akinruntan Yatọ si eyi, àwọn oṣiṣẹ pana-pana ti wa ni ilu naa lati koju awọn kokoro ọhun.
Àwọn iranṣẹ náà bá tẹ̀lé àṣẹ rẹ̀, wọ́n sì pa Amnoni.
Ni ọsu kini ọdun yi ni awọn alagba ijọ aguda panupọ lati bẹnu atẹ lu bi ijinigbe ati ipaniyan ti ṣe peleke lorileede Naijiria.
nomba alodi ni awon nomba tiwonkere ju òdo lo fun apere -formula _ 1 , -1.
Wọ́n mú ìyẹ̀fun tí wọ́n ti pò ní ilẹ̀ Ijipti, wọ́n fi ṣe burẹdi tí kò ní ìwúkàrà, nítorí pé lílé ni àwọn ará Ijipti lé wọn jáde, wọn kò sì lè dúró mú oúnjẹ mìíràn lọ́wọ́.
A ti já gbogbo ojú òpó ìjọba Nàìjíríà gbà lórí Twitter láti ṣàtìlẹyìn ìwọ́de End SARS"" - Anonymous Wo ìsọ̀rí àwọn tó jẹ́ kí ìwọ́de End SARS / end SWAT lárinrin àti ìtumọ̀ Ìjọba ìpínlẹ̀ Eko ti kéde orúkọ àwọn ọlọ́pàá tó fi ìyà jẹ àwọn olùwọ́de End Sars Toyin Abraham tú àṣírí ohun tí ọlọ́pàá Náìjíríà sọ mọ́lẹ́bí rẹ̀ kan dà Sanwo Olu ni awọn ara ilu le bẹrẹ si ni pe awọn nọmba wọnyi 0901 051 3203; 0901 0513204 ati 0901 051320 lati fi ọrọ awọn ọlọpaa to ba tasẹ agẹrẹ to ijọba leti."
naa, eleyi iroyin fi mule pe won lo ji gbe nile re ni agbegbe Muchelelene ni
Opó ni mí, ṣùgbọ́n ọ̀pọ̀ ló ń rí opó bíi gbọkọgbọkọ Ta ni awàdà rẹ̀ wú u yín lórí jù ní Yollywood?
Nígbà náà ni o óo máa rìnláìléwu ati láìkọsẹ̀.
"Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Bí ìrẹsì tèmi Ayinde bá ń pàkùta, kò tọ́ sẹ́nu aláàrù Barrymaade' O ni "" A wa lati kọ im nipa bi igbo gbingbin ṣe le ṣanfani fun ipinlẹ Ondo ati orilẹede Naijiria lapapọ gẹgẹ bi orilẹede Thailand ṣe ṣe e gẹ́lẹ́."
Ogun abẹ́lé tó ń ja Akeredolu l'Ondo, òní la ó mọ̀ bóyá yó borí rẹ̀ Wo àwọn ohun tí Amotekun kò ní le è ṣe mọ́ ní ìpínlẹ̀ Oyo.
Ẹgbẹ Afenifere kede bẹẹ lasiko to n sọ ero rẹ lori bi ile asoju-sofin se pariwo sita pe si ijọba apapọ ti ta ominira Naijiria fun ilẹ China lati fi ya owo.
Ayinla Kollington: Ìyàwó mí títí láéláé ni Salawa Abẹni
Fidio naa tun ṣe afihan bi awọn ẹlẹwọn ohun ṣe n rin loju titi lẹyin ti wọn tu wọn silẹ.
adeboye/facebook Ajọ naa ni bi iwa ifipabanilops ṣe n fojojumọ pọ si lorilẹede Naijiria ko ṣẹyin ijakulẹ awọn agbofinro atipe ọpọ awọn ti wọn hu iwa ifipanilopọ ni wọn maa n bọ ms ofin lọwọ lẹyin o rẹyin.
Dandan ni pé kí Mesaya jìyà, kí ó tó bọ́ sinu ògo rẹ̀.
Briyai ,lo soro yii ,nibi ipade to waye ni olu –ilu naa to wa ni Calabar.
Rírò ni t'ènìyàn , ṣíṣe ni ti Ọlọ́run.
Ni ti tiẹ, Klaus ni ṣe ẹṣẹ ni ki awọn irunmọlẹ ma gbe owo fun eeyan ni?
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Dino Melaye: Ki lo tun ku ti o sọ?
2500 kwanzas (owó dollar orílẹ̀-èdè US mẹ́jọ) ni ó jẹ́ tẹ́lẹ̀tẹ́lẹ̀.
"Ààrẹ Muhammadu Buhari gbè sẹ́yìn Keyamo lórí ètò ìṣẹ́ 774,000 Bí o ṣe lè forúkọ silẹ̀ fún ètò ""N75BN Nigerian Youth Investment Fund"" rèé."
Ipade Omisore ati awọn oludije meji Ko si ẹni to gbọ iroyin naa ti ko yanu lati gbọ pe ẹgbẹ mẹta gboogi ninu awọn ẹgbẹ ninu awọn mejidinlaadọta ti yoo kopa ninu idibo sipo gomina ti yoo waye nipinlẹ Ọsun lọjọ satide ṣe ipade bonkẹlẹ loru ọjọru nilu Osogbo.
Igbakeji gomina ni ipinle Kano ojogbon Hafiz Abubakar ti kowe fipo sile.
”Ṣugbọn bí èéfín ni irú wọn rí ní ihò imú mi,bí iná tí ó ń jó lojoojumọ.
 Àwa mùtúmùtú , kí la ó se lónìí ?
Àkọlé àwòrán, Aṣọ funfun ni awọn to fẹhonu han wọ lati polongo tako ifipabanilopọ Àkọlé àwòrán, Bi wọn ṣe n sọ pe Pasitọ ko ga ju ofin lọ, ni wọn pe iwọ ko gbọdọ fi ipa banilopọ.
Wọ́n mú Orebu ati Seebu, àwọn ọmọ ọba Midiani mejeeji, wọ́n pa Orebu sí ibi òkúta Orebu, wọ́n sì pa Seebu níbi ìfúntí Seebu, bí wọ́n ti ń lé àwọn ará Midiani lọ.
fẹ fi da awon obinrin orile ede Naijiria loju pe, maa se atileyin fun wọn.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Grace Oyin Adejobi: Ẹ̀yin òṣèré tíátà lóbìnrin tẹ́ ǹ bọ́ra sí ìhòhò, ẹ sá fún ìtànjẹ́ ayé 19 Ògún 2020 Oríṣun àwòrán, Grace Oyin Adejobi Gbajugbaja osere tiata lede Yoruba, Grace Owoola Oyin Adejobi ti sọ pe ibi tohun ba iṣẹ ere itage de bayii, ohun ko lero wi pe ohun yoo le ṣe ere mọ.
Omotola wa kesi Aarẹ Buhari lati wa nnkan ṣe si airowo na to gbode kan ati awọn agbofinro ti wọn n pa awọn alaiṣẹ loorekoore ni kiakia.
Àwọn kan tilẹ̀ ní àwọn fẹ́ pá a jẹ bi àwọn kan ṣe ní àwọn fẹ́ fi ṣe àsun lẹ́yìn tí àwọ agbábọ́ọ̀lù Croatia fi ojú ikọ̀ Super Eagles gbolẹ̀ pẹ̀lú àmì ayo mẹ́jì sí òdo.
'Kristẹni lo n fara kaaṣa ikọlu fulani ju' Fulani nìkan kọ́ ló ń pa ènìyàn ní Naijiria -Tinubu 'Iha kokanmi Buhari lewu fun Nigeria' Darandaran Fulani kìí lo ìbọn, 'pọ̀pá' la máa ń lò Awọn mọlẹbi ṣalaye pe ọdun Ileya to kọja ku ọla ni awọn ajinigbe yii gbe awọn mẹtẹẹta.
Van Dijk wa lara awọn agbabọọlu to pegede nigba ti Liverpool na Tottenham pẹlu ami ayo meji sodo ninu ifẹsẹwọnsẹ aṣekagba idije UEFA Champions Laegue ti saa to lọ.
Ni bayii naa, maa reti miliọnu kan ninu aṣuwọn banki rẹ lọjọ Aje lati ọdọ mi.
Ẹbun owo to le ni miliọnu mejidinlogun naira ni Barmasai yoo mu re 'le fun ipo kinni to gba ninu ere ọhun.
Dagunro ní ìtẹríba, tó sì ń gbé àṣà lárugẹ - Ọ̀gá Bello Wo àwòrán pápá ìṣeré MKO Abiola National Stadium Kókó ọ̀rọ̀ tí Buhari sọ ní àyájọ́ June 12 ‘Mo ké bòòsí tòò bí mo ṣe bí ìbejì, ti ọ̀kan jẹ́ àfín, ìkejì jẹ́ dúdú’ Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí kan sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
Oju opo ikansiraẹni WhatsApp ko ni ṣiṣẹ mọ lori ọpọlọpọ ẹrọ alagbeka to ba ti dagba ju ọdun marun lọ.
Gbemisola Saraki to jẹ ìbátan Aarẹ Ile Igbimọ Asofin, Sẹnetọ Bukola Saraki to jẹ ti ẹgbẹ oselu PDP fikun un pe AbdulRahman AbdulRasaq ni yoo fopin si saa gomina Abdulfatah Ahmed ti ẹgbẹ oselu PDP nipinlẹ naa.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Building Collapse: Àwọn èèyàn mẹ́rìndínlọ́gbọ̀n ló n ṣiṣẹ́ níbẹ kí ilé náà tó wó 15 Ẹrẹ̀nà 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 16 Ẹrẹ̀nà 2019 Àkọlé àwòrán, Awọn ara adugbo ni ṣadede ni ile na wo mọ awọn to n ṣiṣẹ nibe lori Ajọ to n mojuto iṣẹlẹ pajawiri lorileede Naijiria NEMA ni ko si ẹnikankan to ku ninu iṣẹlẹ ile to wo nilu Ibadan lọjọ ẹti.
Oun ni ọdọmọde ẹni akọkọ ni Canada to maa gba ami ẹyẹ idije nla bọọlu ẹlẹyin ori tabili.
Ara kò ní rọ̀ yín rárá láàrin àwọn orílẹ̀-èdè wọnyi, bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò ní rí ìdí jókòó.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ṣọla Allyson: Obìnrin tí kò bá rẹwà ni yóò máa ṣí ara sílẹ̀ Wọ́n fi ẹ̀sùn kan wọ́n pé wọ́n gba àwọn ènìyàn kan láti jí ọkùnrin kan gbé, tí wọ́n sì tún pa á nítorí ilẹ̀ ní ìpínlẹ̀ Imo.
Ṣaaju ni igbimọ to n ri si ọrọ NDDC nile naa ti kọkọ gbiyanju lati tu iṣu de isalẹ ikoko nipa ẹsun iṣowo baṣubaṣu ti wọn fi kan ajọ ọhun laarin oṣu Kinni si oṣu Keje ọdun 2020.
Àwọn ọmọ Israẹli tí wọ́n wà ní Jerusalẹmu pa Àjọ Àìwúkàrà mọ́ fún ọjọ́ meje pẹlu ayọ̀ ńlá.
Dimna, Nahalali pẹlu àwọn pápá ìdaran tí ó wà ní àyíká wọn, gbogbo wọn jẹ́ ìlú mẹrin.
Yóo yọ gbogbo ọ̀rá rẹ̀ yóo sì sun ún lórí pẹpẹ.
"Toyin Abraham rèé, ọmọ ìpínlẹ̀ Edo tó di àràbà nínú tíátà Yorùbá Kemi Olunloyo dá sí ìjà Toyin Abraham àti Lizzy Anjorin Iyabo Ojo sọ̀rọ̀ nípa iṣẹ́ abẹ tó ṣe, Nkechi Blessing ra ǹkan irinsẹ fún arọ Funke Akindele fún mi lówó tí mo fi gba ilé, kò ra ilé fún mi o - Ajirebi Tí òṣèré tíátà yóò fi kú, eré ni wọn yóò ló ń ṣe - Ibrahim Chatta Diẹ lara ohun ti awọn eeyan naa sọ ni pe ""ẹni to wa laye lo n wo sinima, ati pe o yẹ ki Toyin naa da si ọrọ #EndSars to n lọ lọwọ."
Àwọn ọmọ Nàìjíríà la ohùn APC nìpinlẹ̀ Edo láwọn kò fẹ́ rí imi Adams Oshiomole lákìtàn mọ́ Ọmọ ọdún kan póòrá!
Mo pàdánù ọkọ méjì láàrin ọdún kan lórí Facebook Owe ni Woli Arole fi ọrọ to wa loke yii pa nitori o mọ ohun ti o ti la kọja ninu irin ajo ere sinima o si mọ ohun ti awọn eniyan ti sọ si i.
Party (PDP), ti iyen naa ni iye ibo 546,813.
Ó yan àwọn adájọ́ ní gbogbo àwọn ìlú olódi ní ilẹ̀ Juda.
Ijọba Ipinlẹ Eko ti fesi si ọrọ ile ounjẹ China naa pe, ko si ootọ kankan ni ọrọ naa, nitori wipe awọn ti ran awọn eeyan kan lọ si ileeṣẹ ounjẹ naa ni bonkẹlẹ, ti wọn si da wọn lohun.
Ojelade ni olu ẹda itan naa ti Iyaduuni, iyawo Ọjẹlarinaka bi nigba ti ko si nile to ti sawo egungun ló.
Gbogbo nǹkan yòókù ti Abija ṣe ní àkókò ìjọba rẹ̀, ati ohun tí ó sọ, ni a kọ sinu Ìwé Ìtàn wolii Ido.
Ẹ óo rí i, inú yín yóo dùn, egungun yín yóo sọjí,bí ìgbà tí koríko bá rúwé.
Wọ́n dá ọkọ rẹ̀ mọ̀ lẹ́nu ibodè,nígbà tí ó bá jókòó pẹlu àwọn àgbààgbà ìlú.
O ṣàlàyé pé nígbà tí bàbá òun wà láyé, ojoojumọ ni ile àwọn máa ń kùn, tí àwọn èèyàn máa ń wa, táwọn yóò sì gba àlejò, tí bàbá òun yóò sì máa ń ṣe awada pẹlu wọn, tí inú àwọn èèyàn yóò sì máa dùn, tí wọn kò sì ní fẹ́ kúrò nínú ilé àwọn.
Eeyan mẹtadinlọgọjọ lati orilẹdede marundinlogoji lo padanu ẹmi wọn ninu ijamba baalu naa to ṣẹlẹ nigba ti wọn n rinrin ajo lati ilu Addis Ababa lọ si ilu Nairobi.
Ọba, àwọn ìjòyè, ati àwọn eniyan ní Jerusalẹmu ti pinnu láti ṣe àjọ náà ní oṣù keji.
“Gbogbo yín wá sọ́dọ̀ mi, ẹ sì wí pé, ‘Ẹ jẹ́ kí á rán àwọn eniyan lọ ṣiwaju wa, láti lọ ṣe amí ilẹ̀ náà, kí wọ́n lè wá jábọ̀ fún wa, kí á lè mọ ọ̀nà tí ó yẹ kí á tọ̀, ati àwọn ìlú tí ó yẹ kí á wọ̀.
Ọmọwe Daniel Olukọya, Alufa agba ijọ MFM Oríṣun àwòrán, Mfm Àkọlé àwòrán, Ọmọwe Daniel Olukọya, Alufa agba ijọ MFM Iran mọkanlelọgbọn ni Alufa Olukọya fi sita ninu akojọpọ iran ti Ọlọrun fi han an fun ọdun 2019, eyi to dà pe ni ọdun irọrun ati alekun ọla.
Kọmisọna fun ọrọ iroyin ni ipinlẹ Eko, ọgbẹni Kẹhinde Bamigbetan nigba to n sọrọ lori ofin tuntun to de ede Yoruba naa, sọ wi pe ohun idunnu ni o jẹ fun awọn wipe ede Yoruba ti di gbajugbaja lawujọ ipinlẹ Eko.
Pasitọ Adeboye sọ ọrọ naa lasiko to n waasu ni ibi ayẹyẹ idupẹ ni ijọ Throne of Grace in ilu Eko.
O ni aarẹ sọ pe” ipade igbimo naa yoo jẹ ki idagbasoke tete wa si Niger Delta nibi ti won gbe n wa epo rọbi.
"Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Èmi ni afunfèrè àkọ́kọ́ lágbo eré KWAM 1 ní 1983' Arulogun fikun pe ""a fẹ ki ọdun Ọsun Osogbo si tẹsiwaju lati maa jẹ ọdun fun eto irinajo afẹ lagbaye pẹlu ifọwọsowọpọ ijọba ipinlẹ Ọsun."
Ẹṣẹ ipaniyan to hu yii si lo tako ofin ọdaran tipinlẹ Eko, abala okoolerugbao le kan.
Wọn á sè é ninu ìkòkò, wọn á fi ṣe bíi àkàrà, adùn rẹ̀ sì dàbí ti àkàrà dídùn tí a fi òróró olifi dín.
Ní ìbẹ̀rẹ̀ oṣù Ṣẹẹrẹ ọdún 2019, fídíò náà dédé pòórá pẹ̀lú àlàyé ránpẹ́ nípa arábìnrin Knežević.
Fidio kan, to da bi ẹni pe lati inu ọkọ miran ni ẹni to ya a ti ya aworan naa, ṣafihan ọkunrin kan to joko sinu ọkọ akẹru naa, ti wọn fi gilaasi sẹ ara rẹ, to si n nawo fun awọn obinrin to n jo pẹlu awọtẹlẹ wọn nikan.
The president prays Allah to grant all Muslims the strength to successfully complete the fasting period.
Àìní yóo sì dé bá ọ bíi jagunjagun dé báni.
yii“Aseyọri nikan  ti to fun awon wahala yin.
Aare Buhari ti o jẹ alaga ajo
 Timothy yi lo ti kọkọ mu ife ọti ogogoro kan lai sanwo, to si tun fk gba omii si.
Sibẹ mo gbìn yín gẹ́gẹ́ bí àjàrà tí mo fẹ́,tí èso rẹ̀ dára.
Lẹyin naa lo dupe lọwọawọn ololufẹ rẹ, to si parọwa fun wọn ki wọn duro sile wọn lasiko yii.
Nítorí náà, nígbà tí Sara gbọ́ pé òun óo bímọ, ó rẹ́rìn-ín sinu ara rẹ̀, ó ní, “Lẹ́yìn ìgbà tí mo ti di arúgbó, tí ọkọ mi náà sì ti di arúgbó, ǹjẹ́ mo tilẹ̀ tún lè gbádùn oorun ọmọ bíbí?
Ki ni awọn ohun ti Adams Oshiomhole ṣe gan an to n fẹ bu u lẹsẹ bayii?
Akowe agba egbe naa, Francis Sokomba so pe, AFCO yoo sagbateru eto kan, ti a mo si ‘ayeye ore agbe’ ni iyanju ati polongo ipese ounje ati ilana igbe aye irorun.
O di aarẹ Uganda lọdun 1971 lẹyin to ditẹ-gbajọba lọwọ aarẹ Milton Obote, o si ṣejọba fun ọdun mẹjọ gbako.
Ajo INEC lo pasẹ pe ki abajade
Ẹ̀rù ba àwọn eniyan tí ó rí i.
Nítorí náà, ọlá ni fún ẹ̀yin tí ẹ gbàgbọ́.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Power: Ṣé ẹ̀mí ilé aṣòfin lè gbé ṣíṣe ìwádìí 16 bílíọ̀nù owó àgbàṣe iná ọba Nàìjíríà?
Agbo ọ̀pọ̀ ẹlẹ́dẹ̀ kan wà níbẹ̀, wọ́n ń jẹ lẹ́bàá òkè.
Tanko Muhammed lati ropo adajọ Walter Onnoghen gege bi adajọ agba tuntun lorilẹ-ede
Wọ́n ní ń fi dá ọ lójú pé
25 àárọ̀ ni olùkọ́ fi tipá bá akẹ́kọ̀ọ́ náà lòpọ̀ nínú ọọ́fìsì 21 Èrèlè 2020 Oríṣun àwòrán, Getty Images Yoruba ni ẹni to ba mọ isin jẹ, o yẹ ko mọ ipin oju rẹ yọ nitori ohun ti eeyan ba mọ jẹ, nii yo.
Oyinkan pada sile lati ilu ọba lọdun 1920 lẹyin to kawe tan nile ẹkọ orin nilẹ Gẹẹsi, to si n ṣíṣẹ olukọ nile ẹkọ girama Anglican Girls, to ti kẹkọọ jade.
Awọn mẹtadinlọgbọn tawọn apẹja doola ẹmi wọn ṣalaye pe, awọn ọmọde marun un wa lara awọn to bomi lọ naa.
Òrìṣà ayé-àtijọ́ kan nílẹ̀ yìí ni ó ń jẹ́ Sulis.
Ìká kan ni òòró rẹ̀, ìká kan náà sì ni ìbú rẹ̀.
Ṣugbọn Sila pinnu láti dúró níbẹ̀.
Àwọn ìlà fún àyẹ̀wò: Editorial Guidelines on Accountability Editorial Guidelines on Removal of Online Content Àyẹ̀wò/ìwádìí tó yè kooro: Àyẹ̀wọ̀ àti ìlànà pípéyé ni a ti sàlàyé nínú Editorial Guidelines on Accuracy.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Igbakeji Aarẹ ẹgbẹ oṣelu UDC, Dumelang Saleshando ṣalaye fun BBC debate pe 'o da lori eto ọrọ aje eyi to yọ ọwọ awọn araalu sẹyin.
Lẹ́yìn náà, ó ní kí àwọn ẹ̀yà Bẹnjamini ati àwọn ará Jerusalẹmu bá OLUWA dá majẹmu kí wọ́n sì pa á mọ́.
Ọlọrun fi ìṣẹ́gun ńlá fún ọba rẹ̀,ó sì fi ìfẹ́ tí kì í yẹ̀ han ẹni tí ó fi àmì òróró yàn,àní Dafidi ati arọmọdọmọ rẹ̀ laelae!
Ẹ fi òkúta kọ́ pẹpẹ kan fún OLUWA níbẹ̀; ẹ kò gbọdọ̀ fi irin gbẹ́ òkúta náà rárá.
Fake Facebook: Ọkùnrin kan dèrò iléejọ́ lórí ẹ̀sùn pé ó f'orúkọ Adeboye lu jìbìtì
Aare Muhammadu Buhari ti gbe ise onilaja fun olori egbe oselu All Progressives Congress (APC), Asiwaju Bola Ahmed Tinubu lori pipari aawo laarin awon omo egbe ti won ni ikunsinu lorisiirisii.
Wọn ni ọwọ ti tẹ eeyan mẹta kan ti wọn si ni meji ninu wọn kii ṣe ọmọ orileede Tanzania.
Iwadii ti fihan pe awọn ọlọpaa ni orile-ede Australia, paapaa ni ilu Sydney, maa n ni ki awọn obinrin bọ aṣo wọn ti wọn ba n ṣe ofintoto wọn.
Àgbà ló ń báni ṣèlú, ọmọ kékeré ni ń báni tún ilé ẹni ṣe
Garba se lalaye pe, iko Falconets ti n sise takun-takun lateyin wa ninu awon ifesewonse won, eleyi ti o si da oun loju pe won ni afojusun lati de bi ti o lapere ninu idije naa.
Àbí ẹ rí ibi tí ọmọ Ilẹ̀ Faransé ti ń ránmú sọ Faransé bí?
Ẹ máa fi akọ mààlúù kan ati àgbò kan tí kò ní àbààwọ́n rú ẹbọ sísun olóòórùn dídùn sí OLÚWA.
Obìnrin bíi Ruth Bader ni yóò gba ipò rẹ́ ní iléẹjọ́ tó gajùlọ nílẹ̀ Amerika- Donald Trump Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Bolaji Faleke ni Olùkọ́ tó ń kọ́ wa ní àṣà oge ṣiṣe lórí BBC Yorùbá Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Coronavirus Update in Nigeria: 'Ewu ń bẹ pẹ̀lú bí àwọn ọmọ iléèwé ṣe wọlé padà lásìkò àrùn Coronavirus'22 Owewe 2020 Abiola Ebila: ''Operation Burst'' ti mú arákùnrin Eji olórí ''One Million Boys'' tó gba ipò Ebila21 Owewe 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 3 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 5 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
 Emi ko lero pe o to lati lee maa yàn fun oga olopaa lori iye awon olopaa to ba fe lo lasiko eto idibo.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Osun Election: Secondus sèpàdé pẹ̀lú Adeleke àtàwọn tó ń fapá-jánú 31 Agẹmo 2018 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Awọn oludije kan n fapa janu lori ètò ìdìbò abẹnu PDP típínlẹ̀ Osun Alaga apapọ̀ fẹgbẹ òṣèlú People's Democratic Party, PDP, Ọgbẹni Uche Secondus, ti dasi aawọ tó n wáyé láàrin àwọn ọmọ ẹgbẹ PDP, lori Ìdìbò abẹnu fun ipò Gómìnà to waye laipe yi nipinlẹ Osun.
"Nigba ti mo dako yii lọdun to kọja wọn ji gbogbo rẹ lọ, mo tun ra eso miran ni ilẹ Yoruba mo si gbin in ki wọn to tun mu mi bayii""."
Ṣalumu ọmọ Kore, ọmọ Ebiasafu, ọmọ Kora ati àwọn ará ilé baba rẹ̀.
Gómìnà ìpínlẹ̀ Osun wọ́gilé ìrìnàjò àwọn alága sí Dubai Ipò àgbà ló yẹ́ kí a ti bá olórí - Fani-Kayode Kíni itunmọ ọrọ 'body bag' tí Gómìnà El-Rufai sọ?
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Sex: Aṣà tó wọ́pọ̀ fún ìgbádùn ìbálopọ̀ lágbáyé 4 Ògún 2018 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ǹjẹ́ bákan náà ní ǹkan rí ní gbogbo àgbáyé?
Wọn ni Auxiliary ko ko ohun ija wa, bẹẹ si ni wọn ko yinbọn ni asiko abẹwo naa, ṣugbọn ifarahan wọn lo mu ki awọn olugbe Ẹgbẹda sa kijokijo lasiko naa.
Aisaya dáhùn pé, “OLUWA yóo fún ọ ní àmì láti fihàn pé òun yóo mú ìlérí òun ṣẹ.
Ninu idibo gbogbogbo ọdun 2015 ni wọn kọkọ dibo yan Oko gẹgẹ bi sẹnẹtọ lati ṣoju ẹkun rẹ ki wọn to dibo yan pada fun saa keji lọdun 2019.
Lanre Kuti ni mo fẹ́ - Jaiye Kuti Darandaran Fúlàní kankan kò ṣí kúrò l'Ọ́ṣun - olórí Fulani Unai Emery máa lọ!
Iṣẹ̀lẹ̀ burúkú gbáà lo ṣẹlẹ̀ yìí.
Amọṣa ninu ifọrọwerọ rẹ pẹlu BBC news, kọmiṣọna feto iroyin ni ipinlẹ Eko, Ọgbẹni Gbenga Ọmọtọṣọ ni ijsba ipinlẹ naa ti bẹrẹ igbesẹ lati beere fun iranwọ ati ajọṣepọ lọdọ awọn ileetura lati koju ipenija ọhun.
Lọjọ kẹrin, oṣu kẹfa to ku ọjọ perete ti awọn ọmọ Naijiria yan lati dibo yọ ijọba ologun kuro lori oye ni ẹmi Kudirat kuro loke eepẹ pẹlu ọpọlọpọ ọta ibọn.
Àwọn ìyàwó tó jẹ́ igi lẹ́yìn ọgbà fún Isola Ogunsola Mojisola Ogunsola: Oloogbe Mojisola Ogunsola ti awọn eeyan mọ si Iya Alakara nigba aye rẹ, ni iyale patapata ninu awọn iyawo Isho Pepper, to si maa n tẹle ọkọ rẹ lọ ṣe ere tiata kaakiri.
Ṣugbọn ọkàn mi kò balẹ̀ nígbà tí n kò rí Titu arakunrin mi níbẹ̀.
Dokita ẹranko kan, Alexander Clark, ti awọn ọlọpaa gba lati fi ọrọ wa ẹyẹ naa lẹnuwo sọ pe ''niṣe ni ayekootọ kọ̀ lati sọ ohunkohun.
Ìfọ̀rọ̀wánilẹ́nuwò fún ìgbàniwọlé yóò wáye ni ọjọ́ kẹrìnlélógún oṣù kẹ̀sán ọdún 2020 sí ọjọ́ kejìlá oṣù kọkànkánlá ọdún 2020.
Bí ẹnikẹ́ni bá wẹ ara rẹ̀ mọ́ kúrò ninu àwọn nǹkan wọnyi, olúwarẹ̀ yóo di ohun èèlò tí ó níye lórí, tí a yà sọ́tọ̀, tí ó wúlò fún baálé ilé.
Jonatani, arakunrin baba Dafidi ọba, ni olùdámọ̀ràn nítorí pé ó ní òye, ó sì tún jẹ́ akọ̀wé.
Àwọn ọmọ Juda ni Eri ati Onani.
Bojúwo ilẹ̀ láti ọ̀run,láti ibùgbé rẹ mímọ́ tí ó lógo.
Awọn  asofin naa wa beere pe kin lo de ti ile igbimo asofin fẹ tapa si igbese ijọba lati gbokun ti iwa ibajẹ.
awon ajo ti kii se ti ijoba , awon osise ijoba ati awon ti ọrọ kan lasiko ti
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ẹ ka díẹ̀ lára àwọn ìṣẹlẹ̀ ayọ̀ lágbo òṣèré tíátà Yollywood láàrin ọ̀sẹ̀ yìí 19 Ọ̀wàrà 2019 Oríṣun àwòrán, @Others Àkọlé àwòrán, Bi awọn kan ṣe n ṣe ọjọ ibi, awọn mii bimọ tuntun, awọn miran si goke agba sii lẹnu iṣe pẹlu awọn oloṣelu Ọpọlọpọ nkan lo ṣẹlẹ laarin ọsẹ yii lagbo oṣere tiata Yollywood.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù AFCON 2019: Báwo ni ìdíje Super Eagles àkọ́kọ́ yóò ṣe lọ?
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Eré bọ́ọ̀lù: Musa gbá bọ́ọ̀lù sáwọ̀n fún ikọ̀ tuntun 13 Ògún 2018 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ahmed Musa ti bẹ̀rẹ̀ sí máa sanjọ́ fún ikọ̀ agbábọ́ọ̀lù tuntun rẹ̀ Aaya bẹ silẹ o bẹ sare ni Ahmed Musa fi ṣe lẹyin to saaju ikọ Al Nassr FC to ṣẹsẹ darapọ mọ nibi ti wọn jawe olubori pẹlu ami ayo meji si ẹyọkan lọjọ Aje.
Ẹni to bori: Madagascar Congo DR vs Kenya.
Àwọn ọmọ Israẹli bá tẹ̀lé e lẹ́yìn láti agbègbè olókè, ó sì ṣiwaju wọn.
Oladejo Okediji, gbajúgbajà òǹkọ̀wé Yorùbá papòdà lẹ́ni ọdún 89
Dafidi Bá Àwọn Ará Amaleki Jagun.
Iṣejọba wa ni ifarajin fun ṣiṣe ohun to yẹ fun eto ẹkọ ati pipese ẹkọ to yekoro fun awọn ọmọ ipinlẹ Ogun lai fi ti ipo wọn lawujọ ṣe.
 tógò àti apá kan ní gúúsù ilẹ ̀ amẹ ́ ríkà bí i cuba , brasil , haiti , àti trinidad .
si jade lati wa dibo pada.
 Ìwé náà sì lè fún wọn ní ìpìlẹ ̀ tí ó dájú fún ẹ ̀ kọ ́ yorùbá ní ilé-ẹ ̀ kọ ́ gíga .
Nígbà tí Jehu dé láti pa ilé Ahabu run bí Ọlọrun ti fún un láṣẹ, ó pàdé àwọn ìjòyè Juda ati ọmọ arakunrin Ahasaya tí ó bá Ahasaya wá, ó bá pa wọ́n.
Ní ọdún kẹtadinlọgbọn tí Jeroboamu jọba ní Israẹli ni Asaraya ọmọ Amasaya, jọba ní Juda.
Oríṣun àwòrán, AEPA Ọpọlọpọ awọn eniyan ti wọn fipa balopọ naa ni wọn tun n pa lasiko naa ti iwadii.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Abiola Ajimobi: Ìtùnú tí mo ní nípa ikú ọkọ mi, ni pé Sẹ́nétọ̀ Abiola Ajimobi rí ọ̀run rere wọ̀- Florence Ajimobi 3 Ògún 2020 Oríṣun àwòrán, Instagram/abiola ajimobi Iyawo gomina ana ni ipinlẹ Ọyọ, Abiọla Ajimọbi to d'oloogbe l'oṣu kẹfa ọdun 2020, arabinrin Florence Ajimọbi ti ṣalaye wi pe itunu kan ṣoṣo ti oun ni lẹyin iku ọkọ oun ni pe o ri ọrun rere wọ lalaafia.
Amọ Ọba Adeyẹmi ni Ọlọrun ran oun lọwọ lati tọ awọn iyawo oun, ati lati maa dari wọn lai jẹ wi pe igbeyawo naa tuka, tabi ki ija orogún o da ile oun ru.
Van Dijk gbadé UEFA mọ́ Messi àti Ronaldo lọ́wọ́ Buhari, pe ìpàdé àpérò ọmọ Nàíjíríà fún àgbékalẹ̀ òfin tuntun - Afe Babalola A ṣetán láti ran àjọ aláàbò alájùmọ̀ṣe lọwọ fún ààbò tó péye nílẹ Yorùbá - Ọlọ́pàá Ogun Nínú gbèsè Nàíjíríà, ₦121,000 ló kàn ẹnìkọ̀ọ̀kan, ṣó o ṣetán láti san tìẹ?
Ìfẹ́ OLUWA ní Ìgbésí Ayé Jeremaya.
Apẹrẹ iṣẹlẹ yi kan ni igba ti wọn n fi ohun ẹṣọ sara akaba ile, mi o ribi ṣe daada ṣugbọn ẹnikeji mi yara ṣe tiẹ'' Èyí ni ìdí tí Bàbá Kérésì fi máa n wọ aṣọ pupa àti funfun nígbà gbogbo Ẹ̀sìn kò fàjà!
Ni igbẹyin, Derin gba awọn ọdọ nimọran lati ma tiju iṣẹ wọn ki ebi ma baa pa wọn.
Ghana Floods: Èèyàn méje pàdánú ẹ̀mí wọn nínú ìjàmbá ẹ̀kún omi
Àwọn oníṣòwò orílẹ̀-èdè ayé ń pòṣé lé ọ lórí.
Igbimo alagbelebu pupo lagbaye, International Committee of the Red Cross (ICRC) kinlo pe, siseto idanilekoo fun awon ologun nikan  ko ni ona logbon amulo, bikose wiwa iyanju si awon ohun ti o n sokunfa laasigbo ninu ise ohun osi, isakoso ijoba to mehe ati ipenija isoro oju ojo.
OLUWA, ìwọ ni o yan àwọn ará Babiloni gẹ́gẹ́ bí onídàájọ́.
Ọpọ lo bẹnu atẹ lu igbesẹ yi sugbọn lẹyin o rẹyin Ajimọbi ati Ayefẹlẹ pari ija ti Gomina Ajimọbi si tun ṣe iranwọ lati tun ile iṣẹ naa kọ.
A ko lee sọ boya 'were' lọkunrin to sa ọmọ meji Ibẹru ipalara awọn darandaran mu'pinlẹ Ogun Oríṣun àwòrán, The Punch Àkọlé àwòrán, Oluwatobiloba Ipense sinku arabinrin ololufẹ rẹ sinu ileejọsin rẹ Ọgbẹni Illiyasu wipe arakunrin kan to roukọ rẹ n jẹ Adebola Saheed ta awọn lolobo nigbati wọn ko ri ẹgbọn rẹ, Raliat Sanni ti o jẹ ẹni ọdun márùndínlógójì pẹlu ọmọ marun nile mọ lati ọjọ kejilelogun oṣu kẹta ọdun.
Orúkọ ìyá rẹ̀ ni Asuba, ọmọ Ṣilihi.
O ni igba ti ọmọ yoo ba fi gbọnju di bii ọmọ ọdun mejidinlogun, owo naa yoo ti maa wọ ẹgbẹrun lọna ọọdunrun eyi to to bẹrẹ okoowo tabi san owo ile iwe fasiti bo ba ṣe pe iwe ni ọmọ naa n ka.
Nǹkan wọnyi wọ́pọ̀ láàrin àwọn tí orí wọn ti kú, tí wọ́n ti yapa kúrò ní ọ̀nà òtítọ́.
Oríṣun àwòrán, @officialEFCC Lati ọjọ Aje ti alaga ajọ EFCC ti wọn ṣẹṣẹ gba iṣẹ lọwọ rẹ, Ibrahim Magu, ti farahan niwaju igbimọ oluwadii, ni ọpọ ọmọ Naijiria ti n fẹ mọ igbesẹ ijọba lori awọn ẹsun ti wọn fi kan an.
Obinrin kan lọ pàdé rẹ̀,ó wọ aṣọ aṣẹ́wó,ọkàn rẹ̀ kún fún ẹ̀tàn.
Lọdun 2012 lo fi ọrọ yi sita, ti a ko si le sọ boya o ṣi n ṣe ẹsin Islam titi di igba ti wọn fi mu bii afurasi onijibiti.
Wọ́n lọ sọ́dọ̀ Filipi tí ó jẹ́ ará Bẹtisaida, ìlú kan ní Galili, wọ́n sọ fún un pé, “Alàgbà, a fẹ́ rí Jesu.
Ó bí àwọn ọmọ mẹfa wọnyi fún Abrahamu: Simirani, Jokiṣani ati Medani; Midiani, Iṣibaki ati Ṣua.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ẹ̀sun olè ní a fi kan Akoroyin Samuel Oun mẹ́sàń-án tí ẹ lè má mọ̀ nípa Victor Moses Bale kò le gba Real Madrid lọ́wọ́ ìyà Ẹlẹ́wọ̀n 157 yọò kọ WASSCE, méjì fẹ gba PHD Kí lo mọ̀ nípa Olùṣirò owó Àgbà àkọ́kọ́ ní Afrika?
Jehoiada fún àwọn ọ̀gágun ní ọ̀kọ̀ ati apata Dafidi tí wọ́n ti kó pamọ́ sinu ilé Ọlọrun.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Atagitá Fẹ́mi Aníkúlápó-Kútì bá obìnrin lọ l‘Amẹ́rika Ẹ̀kún omi kò yọ àwọn akẹ́kọ̀ọ́ fásitì OAU sílẹ̀ Pásítọ̀ àti Ìmàámù yóò gba owó osù lọ́wọ́ ìjọba Àwọn ọmọ Iyabọ Ojo rí Bàbá lẹ́yìn ọdún mẹ́fà To ba n wa ọkọ̀, yàgò fáwọn ìgbésẹ̀ yìí Buhari, ó yá, tètè kọ̀wé fipò sílẹ̀ - Oyedepo Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Èkó: Àwọn akínkánjú obìnrín tó ń wa Márúwá Ọkan lara ẹlẹsin Hakika to ba BBC sọrọ labẹ asọ ni oun n foju sọna lati de ipo giga ninu ẹsin naa, nibi ti oun yoo ti ni anfaani lati paarọ iyawo oun pẹlu ẹlomiran.
Ènìyàn 700 r'ẹ́wọ̀n he lórí ìfẹ̀hónúhàn Ààwẹ̀ ọjọ́ 43 ni àwọn Krìstẹ́ní yíì n gbà kí wọ́n tó ò ṣe Kérésì ní January 7 Salah gba àmì ẹ̀yẹ̀ agbábọ́ọ̀lù Afirika BBC lẹ́ẹ̀kejì Ìgbìmọ̀ ìgbẹ́jọ́ wọ́gilé ẹ́jọ tó takò iyansipo Sanwo Olu Iwọde nla to ṣẹlẹ lọdun kan lẹyin to gori aleefa lo ṣokunfa bi wọn ṣe yọo nipo.
Owurọ ọjọ Aiku ni Davido kede bẹẹ loju opo Instagram rẹ, to si ni Ọmọọba ti de, ile iwosan kan nilu London si ni Chioma bimọ naa si.
Awọn eeyan to ni aarun naa nipinlẹ Eko ti di mejilelọgbọn, FCT jẹ mẹwaa, Ogun ni mẹta, eeyan kọọkan lo ni aarun ọhun ni ipinlẹ Ekiti, Oyo, Edo, Bauchi, Osun ati Rivers.
Olori ikọ̀ Operation 'Lafiya Dole', Rogers Nicholas lo sọ eyi nibi ìfilọ́lẹ̀ ikọ̀ ọmọ ogun apapọ orilẹede Naijiria ati orilẹede Cameroon ni ilu Maiduguru.
Kò sí ohun tí etí kò gbọ́ tán.
"Ara Jessica ko dape lati igba ti wọn ti bi.
Ó bí ọgbọ̀n ọmọkunrin, tí wọ́n ń gun ọgbọ̀n kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́, ọgbọ̀n ìlú ni wọ́n sì tẹ̀dó, tí wọn ń pe orúkọ wọn ní Hafoti Jairi títí di òní olónìí.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Lai Mohammed, Ayo Fayose, Afẹnifẹre, Ndigbo, Arewa dá sí ọ̀rọ̀ Buhari àti Obasanjo Awọn ọmọ Naijiria ti bẹrẹ si ni da si ọrọ ti Aarẹ tẹlẹri lorilẹede Naijiria, Olusegun Obasanjo sọ ati esi ti Aarẹ Muhammadu Buhari fun Obasanjo.
Mo fẹ́ kí ẹ mọ̀ dájú pé kì í ṣe nítorí yín ni n óo fi ṣe bẹ́ẹ̀.
 ""Mo di alagbara pupọ, mo lọ sinu igi iroko, to fẹ to odidi ilu kan, ọpọ ile to rẹwa lo wa nibẹ ninu igi Iroko, koda, mo nile temi nibẹ nibi ti ọpọ oloselu atawọn ọlọrọ maa n wa."
Folasade Sokunbi, tii se awakọ danfo akọkọ to n na ipinlẹ kan si omiran salaye fun BBC Yoruba pe, awọn ẹbi, ara ati ọrẹ tako isẹ naa nibẹrẹ, amọ oun ko gba fun wọn.
Amọ ṣa nigba ti a kan si akọwe ipolongo ẹgbẹ naa lori ẹrọ alagbeka lori ohun ti ẹgbẹ ri si igbesẹ yi,o ni ohun ko ti le fesi si bayi.
Ẹni to bori: Mali Algeria vs Burundi.
Thanksgiving Trump: Aàrẹ Trump kọ̀ láti jẹ Tọkí ìsìn ìdúpẹ́ 2019 nílé, ó gba Afghanista lọ!
Angẹli keji da ohun tí ó wà ninu àwo rẹ̀ sinu òkun, ni òkun bá di ẹ̀jẹ̀, bí ẹ̀jẹ̀ ara òkú, gbogbo nǹkan ẹlẹ́mìí tí ó wà ninu òkun sì kú.
Ọdún mẹfa ni kí ẹ máa fi gbin èso sinu oko yín, ọdún mẹfa náà sì ni kí ẹ máa fi tọ́jú ọgbà àjàrà yín, tí ẹ óo sì máa fi kórè èso rẹ̀.
Ni onka awọn to ti gba itọju tara wọn si ti ya, iye wọn ni Naijiria jẹ 20,663 bayi.
Kí ló ṣekúpa Ibidunni Ighodalo tí gbogbo ọmọ Nàìjíríà ń selédè lẹ́yìn rẹ̀?
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, LASU Ritual: Àwọn akẹẹgbẹ́ akẹ́kọ̀ọ́ LASU tí wọn fi ṣowó sọ̀rọ̀ lórí ìgbé ayé olóògbé Siasia ni: Mo kan ṣadeedee gba ipe lati ọdọ ọwọ aarẹ ajọ NFF to n dari ere bọọlu ni Naijiria ninu eyi to ti bi mi leere boya mo ti ri lẹta lati ọdọ FIFA, Oríṣun àwòrán, Twitter/Samson Siasia O ni lẹyin naa loun ri lẹta ọhun ninu ẹrọ agbọrọkaye oun ṣugbọn Siasia sọ pe oun ko mọ nnkankan lori ẹsun ti wọn fi kan oun.
Sibeoni ni baba Aia ati Ana.
ti iye won le ni milionu meji lapapo jake-jado orile-ede Naijiria, ti gba lati
 Kabiesi tẹsiwaju pe Ti ẹ ba ṣakiyesi, ẹ o ri pe mi o fi ọwọ yẹpẹrẹ mu ọrọ aṣọ wiwọ, bi a ṣe n ki ni ati ede Yoruba.
Lórí wọn ni wọ́n tí ń pa ẹran ìrúbọ.
 Àwọn ọmọdé ni ó má a nsábà ní àkóràn àrùn náà , láàárín àwọn ọmọdé bẹ ́ ẹ ̀ , àkóràn àrùn náà tún lè ṣe òkùnfa àìlẹ ́ ranlára , àìtó èròjà oúnjẹ lára àti àwọn ìṣòro nípa ẹ ̀ kọ ́ -kíkọ ́ .
Kí sì ni orúkọ ọmọ rẹ̀?
Nígbà tí Jeremaya parí gbogbo ọ̀rọ̀ tí OLUWA Ọlọrun wọn rán an sí gbogbo àwọn ará ìlú, 
Nitorinaa, Akala ni agbalagba bii t'oun to ni ọpọlọpọ iriri ni ipo gomina Ọyọ tọ si lọdun 2019.
Igba keji ni igba to kere, ti ẹnu rẹ ko si fẹ, igba ẹlẹnu kekere yii si ni wọn yoo da ẹnu rẹ kodo sinu omi.
Ṣugbọn o ṣeni laanu pe, eeyan kan kú.
Lẹsẹkẹsẹ, ọwọ́ ọba bá gan, kò sì lè gbé e wálẹ̀ mọ́.
Olupẹjọ naa ni lati ipasẹ ọọfisi olori oṣiṣẹ fun gomina, ni oun ti gbe akọsilẹ ilana tuntun ọhun silẹ fun ijọba ipinlẹ Oyo ni ọjọ keji, oṣu Kẹwa ọdun 2019, ti wọn si ṣe ifilọlẹ ilana naa ni ọjọ kẹtadinlogun oṣu keji ọdun 2020, lai bun oun gbọ mọ.
 Ó wà lórí Àkójọ Àwọn egbògi kòṣeémáàní ti Àjọ Ìlera Àgbáyé ( world health organization ) , àwọn òògùn tó ṣe pàtàkì jùlọ tí a nílò fún ètò ìlera ìbẹ ̀ rẹ ̀ pẹ ̀ pẹ ̀ yòówù .
Ṣugbọn ìwọ OLUWA ni ó jọba títí ayé,ìtẹ́ rẹ sì wà láti ìrandíran.
Bí wọ́n pé ẹgbẹ̀rún kú, n ò ní sí láàrín- ín wọn
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Funke Akindele Nollywood: Mi ò gbẹ́kẹ̀lé ènìyàn!
wa nigbekun bayii , ti awon àádọ́ta odaran tun ti n fi aso penpe roko ọba.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Inu rirun lasiko nkan oṣu: Nkan oṣu obinrin naa ma n fa inu rirun.
ti n hu iwa lati si awon adari orile ede yii lọkan.
Ẹ wò ó, ìlú tí ó wà lọ́hùn-ún nì súnmọ́ tòsí tó láti sálọ, ó sì tún jẹ́ ìlú kékeré.
Eyi ni igba akọkọ ti iru idije yii yoo waye lati igba ti BBC Pidgin ti bẹrẹ.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Adelé Ààrẹ, Yẹmi Ọṣinbajo gba ìṣẹ́ lọ́wọ́ ọ̀gá àjọ DSS, Lawal Daura nítorí wàhálà tó wáyé nílé aṣòfin Ẹwẹ, ohun kan ti isinmi wọn yii tun ṣeeṣe ko ṣe akoba fun ni eto ọrọ aje orilẹ-ede Naijiria, nitori pe igbesẹ pinpin owo lati ẹka ijọba kan si mi i ko ni ṣeeṣe lai si aṣẹ awọn aṣofin, eyi ti yoo ran awọn ẹka eto ọrọ aje yooku lọwọ.
Awọn miran jẹ ọmọlẹyin Ọṣun ninu wọn nigbati ọpọ si jẹ arinrinajo afẹ.
Awọn naa ni wọn gba a lọdun 2017 ti wọn gbogo wale fun Naijiria.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Kengbe Ilorin: Àṣà ẹ̀yà Fulani, Bariba àti Gambari tó dàpọ̀ mọ́ ti Yoruba Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Ikọ iroyin BBC Yoruba kofiri awọn Kafinta ti wọn ti ra igi da silẹ lati tun orule to jona kan, to si seese ki isẹ atunse naa bẹrẹ lọla.
"Fulani kò leè dúró, táa bá lo ohun ta jogún lọ́dọ̀ àwọn bàbá wa - Sunday Igboho Àwọn èèyàn ń san ìdámẹ́wàá tó ""Heavy"" fún mi ni mo fi ń r'áànú ṣe - Iya Adura Esther Ta ni ó bẹ̀rẹ̀ Fújì?"
Taa ba si wo ipa ti awọn Ekiti ko ninu ogun Kiriji, ko yẹ ka fọwọ rọ wọn sẹyin.
Nibayii, ileeṣẹ ọlọpaa ti n fi ọrọ wa ẹni ti ọwọ tẹ lẹnu wo ninu iṣẹ iwadii wọn.
Inu apo ajọni ijọba ibilẹ ni wọn ti gbe owo sita lọna aitọ Awọn olujẹjọ yii nkoju ẹsun onikoko mọkanla to da lori iditẹpọ, gbigbe isẹ agbase jade laisi ninu eto isuna ati irọ pipa.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Oúnjẹ àràmọ̀ǹdà mọ́kànlá tí wọ́n ń jẹ lágbààyé rèé, ẹ tẹ́wọ́ gbàá 25 Ògún 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Turkey n fi omi ara ọpọlọ ti wọn ti rẹ se ara rindin Ounjẹ jijẹ jẹ ọrẹ ara, amọ jijẹ idin ninu burẹdi jẹ ohun to so si ni lẹnu, to si bu iyọ si.
2bn Naira tó fẹ́ ẹ yá lọ́wọ́ Brazil Oríṣun àwòrán, @Agborem Àwọn agbébọn kọlu iléèwé, wọn bọ́ olùkọ́ àti akẹ́kọ̀ọ́ sí ìhòhò Cameroon students killing: Àwọn agbébọn bíi ogún kọlu iléèwé, wọn bọ́ olùkọ́ àti akẹ́kọ̀ọ́ sí ìhòhò Àwọn agbébọn kọlu iléèwé, wọn bọ́ olùkọ́ àti akẹ́kọ̀ọ́ sí ìhòhò Ọkunrin agbebọn bi ogún lo kọlu ileewe girama Kulu memorial comprehensive, to wa ni Gusu orilẹ-ede Cameroon.
 Foluke fikun pe mo da ara mi lẹbi pe n ko lọ bẹ Baba Legba wo nigba to pe mi, ams sa, o dara, Sun re o, Baba.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Tomomewo Favour: olóṣèlú kìí ṣe ọ̀daràn tàbí alágbèrè O ni owo ọhun le ni biliọnu naira ki Fayose le wọle lasiko idibo gomina Ekiti lọdun 2014.
Inu mi dun fun awon ijiroro ti a jo se papo.
"Tope tún sọ síwájú pé ""bí àwọn èèyàn ṣe sọ̀rọ̀ mi ni aidaa lórí ijo tí mo jo lásìkò ìsìnkú bàbá mi, dùn mi gidigidi àmọ́ ó dà mí lójú pé, ijo náà jẹ ìtẹ́wọ́gbà lọdọ Ọlọ́run ló ṣe mú awuyewuye lọ́wọ́."
Oríṣun àwòrán, others 2) Sikiru Adepoju: Ilu Eruwa lagbegbe Ibarapa nipinlẹ Oyo ni wọn bi Sikiru Adepoju si ni ọjọ Kẹwaa, oṣu Kọkanla, ọdun 1950, iyẹn ọdun mọkandinlaadọrin sẹyin.
Bakan naa lo pe e ni aja digbolugi.
Ọkọọkan ejeeji lawọn aṣofin n sagbeyẹwo aba isuna naa t'awọn kan si n naka abuku si ibi to ku diẹ si b'awọn mii ṣe n gbosuba fún ùn.
Ẹ wá OLUWA, gbogbo ẹ̀yin onírẹ̀lẹ̀ ilẹ̀ náà, ẹ̀yin tí ẹ̀ ń pa àṣẹ rẹ̀ mọ́; ẹ jẹ́ olódodo, ẹ jẹ́ onírẹ̀lẹ̀, bóyá OLUWA a jẹ́ pa yín mọ́ ní ọjọ́ ibinu rẹ̀.
 Ni bayii ti ọdanran naa ti jẹwọ, yoo foju bale ẹjọ laipẹ.
Eli bá dá a lóhùn, ó ní, “Máa lọ ní alaafia, Ọlọrun Israẹli yóo fún ọ ní ohun tí ò ń tọrọ lọ́wọ́ rẹ̀.
Ètò Ìkànìyàn Àkọ́kọ́ láàrin Àwọn Ọmọ Israẹli.
O ṣalaye pe awọn ti n jiroro pẹlu ijọba Naijiria lori ọrọ yi.
Ninu eyi afiniṣ'owo ru mọkanla ni wọn fi jofin.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù EndSars Protest: Wo awọn iroyin manigbagbe to waye ni ọsẹ yii 31 Ọ̀wàrà 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 1 Bélú 2020 Oríṣun àwòrán, Google Ọpọlọpọ iroyin manigbagbe lo ti waye lọsẹ yii kaakiri orilẹede Naijiria, paapaa lori jagidijagan to waye lẹyin ifẹhọnuhan tako bii ọlọpaa ṣe n fi iya jẹ awọn eniyan ti o ba ti bọ si ọwọ wọn.
Èèyàn 590 ló tún ti ní covid-19 ní Naijiria Ajọ NCDC ti kede eeyan ojilelẹẹdẹgbẹta ati mẹwa to tun ṣẹṣẹ ni Covid-19 ni Naijiria.
Oluranlọwọ pataki fun gomina ipinlẹ Kaduna lori eto iroyin ati ibaraẹnisọrọ, Abdallah Abdallah fidi iṣẹlẹ yii mulẹ fun BBC pe lootọ ni ọwọ tẹ awọn eeyan naa.
Aafa Akeugbagold ni ṣiṣe ahun si awọn obinrin ko yatọ si ki eeyan ṣi ilẹkun fun ole.
Ọmọyẹ bu sẹkun, to si sọ fun iya rẹ pe Ṣangba ti fọ, ọmọ oun ti jabọ lẹyin oun.
Fasiti ilu Eko ni baba Ijeṣa pada lọ lati lọ kawe gba ims nipa ere tiata.
Ọrọ naa jẹyọ nígbà to n ba Biṣoobu àgbà ìjọ Anglican, ẹ̀ni ọwọ Justin Welby, sọrọ ní London lọ̀jo ọjọ́rú.
Paulu dáhùn, ó ní, “Ẹ̀bẹ̀ tí mò ń bẹ Ọlọrun ni pé, ó pẹ́ ni, ó yá ni, kí ẹ rí bí mo ti rí lónìí, láìṣe ti ẹ̀wọ̀n yìí.
naira je abajade ijiroro , ki i se abadofin, kii se imọran, bẹẹ si ni kii se
Láti ìran àwọn òmìrán ìlú Gati ni àwọn mẹrẹẹrin ti wá, Dafidi ati àwọn ọmọ ogun rẹ̀ ni ó sì pa wọ́n.
Ni oṣu kejila ọdun 2011 Oríṣun àwòrán, AFP Àkọlé àwòrán, Ikọlu loniran an ran lo ti waye lawọn ileewe girama lorilẹede Naijiria Ninu ikọlu kan ti awọn eeyan woye wipe o ṣeeṣe ko jẹ ikọlu lati gba ẹsan oniruuru ikọlu awọn ikọ Boko Haram si awọn ṣọọṣi ni apa ariwa orilẹede Naijiria, awọn eeyan kan ju ado oloro atọwọda si ileewe ẹkọ larubawa kan ni ipinlẹ Delta lasiko ti awọn akẹkọ naa fi n kẹkọ.
Oríṣun àwòrán, Instagram Lẹyin ti wọn ti ṣe igbeyawo Nikkah nilana ibilẹ, Adama ati Malik ni awọn yoo mu ọjọ mii lọtọ fun igbeyawo nilanaa tawọn oyinbo alawọ funfun.
Nígbà tó bá yá, tí àkókò bá tó, n óo mú kí ẹ̀ka òdodo kan ó sọ jáde ní ilé Dafidi, yóo máa ṣe ìdájọ́ ẹ̀tọ́ ati ti òdodo ní ilẹ̀ náà.
Kabiesi ṣalaye pé ọmọbinrin to rẹwa ní aya ti òun fẹ́ síle, eyi jẹyọ lásìkò ti BBC bèrè ọ̀rọ̀ lóri ẹ̀sùn ti Alfa kan ni ìlú Iwó fi kan an.
Fun idi eyi, ile ẹjọ ti sun igbẹjọ si ọjọ kẹtadinlogun oṣu kinni ọdun 2020.
Lọjọbọ ni awọn aṣofin agba tẹti si kika rẹ ti wọn sì ni ko tẹsiwaju abala to kan.
Lẹ́yìn náà Hanameli ọmọ arakunrin baba mi tọ̀ mí wá sí àgbàlá àwọn olùṣọ́ gẹ́gẹ́ bí OLUWA ti sọ, ó sì wí fún mi pé, ‘Jọ̀wọ́ ra oko mi tí ó wà ní Anatoti ní ilẹ̀ Bẹnjamini, nítorí pé ìwọ ni ó tọ́ sí láti rà á pada; rà á fún ara rẹ.
"Ẹ dẹ́kun àbùkù tẹ fi ń kan Nàíjíríà, ẹ fi Sowore sílẹ̀ láhàmọ́- Soyinka ""Aug 2018 ni ìgbìmọ̀ aláṣẹ APC ti ṣe ìpàdé kẹ́yìn, Oshiomole ti kùnà"" Òbítíbitì ẹ̀gbin ti sọ ìlú Ibadan di ààtàn - Aráàlú figbe bọnu Àwọn ẹni òkùnkùn ló já ìṣẹ́gun mi gbà, mò ń lọ sílé ẹjọ́ tó ga jùlọ - Bayo Adelabu Ile ẹjọ naa ni ẹṣẹ nla ni agbabọọlu Dickson yii ṣe si orilẹ-ede wọn."
Ó ń gbani là,ó ń dáni nídè.
Nígbà tí ó dé Romu, ó fi ìtara wá mi kàn, ó sì rí mi.
Nígbà tí àjọ̀dún parí, tí wọn ń pada lọ sí ilé, ọmọde náà, Jesu, dúró ní Jerusalẹmu, ṣugbọn àwọn òbí rẹ̀ kò fura.
19 Àti pé bí ẹ̀yin kò bá ní ìgbàgbọ́, ìrètí, àti ìfẹ́ aláìlẹ́gbẹ́, ẹ̀yin kò lè ṣe ohunkóhun.
Atamatase iko agbaboolu orile-ede Belgium, Michy Batshuayi fi ara re han gege bi eni ti o kaju osuwon lati ropo Romelu Lukaku ti o farapa, leyin ti o gba ami ayo meji sagbon ninu ifigagbaga pelu iko agbaboolu Iceland ninu idije UEFA Nations League ti o waye lojoBo(Thursday).
Bí OLUWA Ọlọrun yín bá ti bukun yín tó, bẹ́ẹ̀ ni kí ẹ ṣe fún un tó.
Ọbasa ti rọ awọn ọmọ orilẹ-ede Naijiria, paapaa awọn ọmọlẹyin Kristi
to tọ gẹgẹ bi o ṣe wa ninu ofin, ni titẹ le abala kọkanlelọgọfa (121)
Ó fún ẹnìkọ̀ọ̀kan ní ìṣù àkàrà kọ̀ọ̀kan, ati ègé ẹran kọ̀ọ̀kan, ati àkàrà tí wọ́n fi èso resini sí ninu.
si ofisi awon iko akoroyin ni Ipinle Oyo (Correspondents’ Chapel of Oyo NUJ) ti
OLUWA wí pé, “Nítorí ìnira àwọn aláìṣẹ̀,ati nítorí ìkérora àwọn tí à ń pọ́n lójú,n óo dìde nisinsinyii,n óo sì dáàbò bò wọ́n bí ọkàn wọn ti ń fẹ́.
Òfin to de ìlànà àmúlò: Awọn BBC's Editorial Guidelines ṣe àlàálẹ̀ àwọn ìlànà ti à n gbà ṣe ìsẹ́ ìròyìn ati bí àwọn ìroyin wa yẹ kó wà.
Bí àwọn ìlú ti pọ̀ tó ní ilẹ̀ Juda bẹ́ẹ̀ ni àwọn oriṣa ibẹ̀ pọ̀ tó.
n kò gòkè lọ sí Jerusalẹmu sọ́dọ̀ àwọn tí wọ́n jẹ́ aposteli ṣiwaju mi, ṣugbọn mo lọ sí ilẹ̀ Arabia, láti ibẹ̀ ni mo tún ti pada sí Damasku.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Nigeria Kidnapping: Ọ̀gá ọlọ́pàá Adamu Pàṣẹ́ iṣẹ́ àkànṣe nílẹ̀ Yorùbá 14 Agẹmo 2019 Oríṣun àwòrán, @NPF Àkọlé àwòrán, Ọ̀gá ọlọ́pàá Adamu Pàṣẹ́ iṣẹ́ àkànṣe nílẹ̀ Yorùbá E lọ gbọn gbogbo opopona marọsẹ guusu Naijiria yẹ́bẹ́yẹ́bẹ́ - Oga ọlopaa Adamu Adari agba fun gbogbo agbofinro Naijiria, Mohammed Adamu, ti kede pe ki awọn ọlọpaa kogberegbe fọnka si ẹkun Guusu Naijiria.
Àwọn eniyan wọnyi ti dẹ́ṣẹ̀ ńlá; wọ́n ti fi wúrà yá ère fún ara wọn; 
Oga agba ile iwe naa ati awọn olukọ meji lo ṣe elegbe lẹyin rẹ fun aṣemaṣe yii.
Gege bi Adesina se so: “Ni ojo isegun(Tuesday), ojo kokanlelogun, osu kejo odun ti a wayii, Akin Oshuntokun, ti o je oloye kan gbogi ninu igbimo Coalition for Nigeria Movement (CNM), fara han ninu eto “Iselu asiko yii” lori ero amohun-maworan Channels, ti o si kede pe, ibugbamu ado oloro  waye nipinle Borno ti o si sekupa eniyan méjídínláàdọ́rùn ún.
 tó bá jẹ ́ adirapọ ̀ , ó ní ojúàmì ìyọ ́ ati ìhó kúkúrú .
Nítorí náà ni OLUWA ṣe bínú sí Juda ati Jerusalẹmu, ohun tí Ọlọrun fi wọ́n ṣe sì dẹ́rùba gbogbo eniyan.
mojuto eto iroyin ati igbafẹ lorile ede Naijiria ti ro ijoba orile ede Naijiria
Àti pàápàá nígbà tí ata pẹ̀lú àlùbọ́sà bá ṣe ìpàdé lórí àparò, nǹkan náà yóò bọ́ sí i.
lojo Isẹgun nibi ipolongo eto idibo aare ti egbe ,All progressives Congress APC
Nítorí a ti wí ṣáájú pé ati Juu ati Giriki, gbogbo wọn ni ó wà ní ìkáwọ́ ẹ̀ṣẹ̀.
Nibayii, a o bẹrẹ si ni ṣiṣẹ pọ pẹlu awọn ẹgbẹ tabi ajọ ajafẹtọ ọmọniyan, awọn ajọ agbaye, ajọ to n ri si idagbasoke ati awọn ẹgbẹ araalu.
A-jí-kó-òórùn- hárí a b̂ara dúdú kunkun.
Tí a fiṣọwọ́ ní 13:43 11 Òkùdu 201913:43 11 Òkùdu 2019 Ilé ìgbìmọ̀ aṣojú-ṣòfin bẹ̀rẹ̀ ìdìbò Ni kete ti wọn bura wọle fun aarẹ ati igbakeji aarẹ tuntun fun ile igbimọ aṣofin agba tan ni akọwe ile lọ si ile igbimọ aṣoju ṣofin lati bẹrẹ idibo ti awọn ọmọ ile igbimọ.
Ahọ́n lágbára láti pani ati láti lani,ẹni tí ó bá fẹ́ràn rẹ̀ yóo jèrè rẹ̀.
Ṣugbọn ohun tí ó sọ fún Ọmọ náà ni pé,“Ìfẹ́ rẹ wà títí laelae, Ọlọrun,ọ̀pá òtítọ́ ni ọ̀pá ìjọba rẹ.
Aarin ṣaa onka ẹgbẹrun ọdun kẹrindinlogun si ikọkandinlogun (16th-19th century) si ni owo ẹru gbilẹ nilẹ Afirika Lasiko yii ni wọn si ta adulawọ bii miliọnu mejila soko ẹru loke okun nigba naa.
 Bakan naa ni ẹkun idibo keji Badagry, Aṣofin David Sentoji
Eyi jẹyọ lasiko ti awọn ijoye naa wa si aafin Olubadan to wa ni adugbo Popoyemọja nilu Ibadan, ti ọkọọkan wọn ko si de ade.
Ó yọ́ ìwọ̀n ẹgbẹta (600) talẹnti ojúlówó wúrà, ó fi bo gbogbo inú rẹ̀.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Buhari dára ju Ọbasanjọ lọ - Ọba Èkó Ìpànìyàn gbọdọ̀ dópin ní Nàíjíríà - Trump Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Amọ saaju, ki a to bẹrẹ akojọ ọrọ wọn yi, a fẹ ki ẹ mọ wi pe ohun gbogbo ti ẹ ba ka, awa kọ la sọ, awọn ololufẹ Micheal Jackson ati Beyonce ni wọn n sọrọ.
Kò sí ẹnikẹ́ni láàrin wa tí ó dàbí rẹ̀.
Lóòtọ́ ni àwọn ọmọ ẹgbẹ́ Shiite kú Iléeṣẹ́ ológun Nàìjíríà ti fidi ọrọ mulẹ pe awọn ọmọ ẹgbẹ́ ẹlẹ́sìn Shiite mẹta lo ku ninu ikọlu to wáyé láàrin àwọn ọmọ ogun Nàìjìríà àti ẹgbẹ Shiite l'Abuja.
”Abineri dá a lóhùn pé, “Kabiyesi, n kò mọ̀.
Aare  teleri ni ile  ejo kotemilorun ,ti o si tun je alaga ile-ise to ngboogun ti sise owo ilu kumokumo ati awon iwa ibaje miran ( Independent Corrupt Practices and other related Offences Commission (ICPC) teleri, Adajo fehinti Mustapha Akanbi ti pe ijoba apaapo orile-ede Naijiria lati gbe oruko enikeni ti o se owo ilu kumokumo si ta ,lai wo egbe oselu  oselu ti won wa.
Eyi wa lara abẹwọ rẹ si ilẹ Afirika ati si Ajọ World Food Programme to wa ni Maiduguri.
ile-ẹjọ, ẹni ti won fi ẹsun kan naa jẹbi lati dije fun ipo gomina  ati pe ko lẹtọọ lati kọọ dije ninu eto idibo abẹle
Ẹ lọ sìmẹ̀dọ, ẹ jẹ́ ki a kóju mọ iṣẹ́ ìlú- Agbẹnusọ APC Ewé súnko!
Eyi waye lẹyin ti awọn onimọ lati orilẹede Brazil gbe abajade iwadii wọn sita wi pe, isoro si ọwọn gogo ounjẹ lagbaye ni ki eniyan bẹrẹ si ni lo eroja asaraloore protein, lati fi pese ounjẹ to se ara loore.
Ọ̀rọ̀ èmi àti Olorì Chanel Chin kò yé ara wa mọ́ nínú ilé- Oluwo Ariwo kò jẹ́!
Owó oṣù tuntun fáwọn olùkọ́ tí Buhari kéde yóò dá aáwọ̀ sílẹ̀- Wike Kíni ìyàtọ̀ tí yóò wà láàrin SARS àti SWAT?
Ogun mìíràn tún bẹ́ sílẹ̀ láàrin àwọn ará Filistia ati àwọn ọmọ Israẹli.
Ẹni tí kò bá pọ́n àáké rẹ̀ kí ó mú,yóo lo agbára pupọ bí ó bá fẹ́ lò ó,ṣugbọn ọgbọ́n a máa ranni lọ́wọ́ láti ṣe àṣeyọrí.
Àdó olóró dáhùn lára èèyàn mẹ́ta ní ìlú Konduga Sunday James ni, àkọkọ kòsí ẹni ti ó wọ̀lú lọ́nà ti kò bá òfin mu, sùgbọ́n ọ̀nà àìṣe déédé nìkan ló wà.
Bakan naa ni awọn eniyan kan n bere wi pe ẹni to ba n lọ banki mejeeji, kini yoo sẹlẹ si wọn?
Ó wádìí àwọn òwe fínnífínní, ó sì tò wọ́n lẹ́sẹẹsẹ.
Dafidi bá mú àwọn iyawo rẹ̀ mejeeji; Ahinoamu ará Jesireeli, ati Abigaili, opó Nabali, ará Kamẹli lọ́wọ́ lọ.
Òjò àrọ̀ọ̀rọ̀dá dá wàhálà sílẹ̀ l'Eko Gómìnà márùn ún tó fojú winá ìbínú bàbá ìsàlẹ̀ wọ̀n A kò tíì fi ìdí ẹ̀ múlẹ̀ pé ògùn Dexamethsaone ń ṣiṣẹ́ fún àrùn coronavirus- WHO Adeboye gbadura pe ki Eleduwa tu ẹbi Pasitọ Ituah Ighodalo to fi silẹ lọ ninu.
"O ti pẹ ti ileeṣẹ ọlọpaa ti n wa Hamisu fun ijinigbe l'oriṣiriṣi to ti waye lati ọwọ rẹ.
Ó yí òkúta ńlá kan dí ẹnu ọ̀nà ibojì náà.
Bakan naa lo gba bọọlu sinu awọn fun orilẹede rẹ, Egypt lẹẹmeji lasiko idije ife agbaye to waye ni Russia.
ẹni tí yóo tún ara ìrẹ̀lẹ̀ wa ṣe kí ó lè dàbí ara tirẹ̀ tí ó lógo, gẹ́gẹ́ bí agbára rẹ̀ tí ó fi lè fi ohun gbogbo sí ìkáwọ́ ara rẹ̀.
Wọn fẹsun kan awon ọlọpaa pe wọn fẹ pa a, ni wọn ṣe yinbọn lu u.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Kò tíì dájú bóyá ọwọ́ àwọn agbófinró tíì tẹ ẹnikẹ́ni lórí ìṣẹ̀lẹ̀ náà ICPC n ṣe agbeyẹwo iwe ẹri awọn oṣiṣẹ to le ni ẹgbẹrun lọna ogoji ninu eyi ti aṣiri ti tu lori awọn to n lo ayederu iwe ẹri wọnyii.
Ifọrọwerọ naa waye lataari bi ile ẹjọ kan nilu Eko ṣe ran ẹni ọdun mọkandinlaadọrun un to fi ipa ba ọmọ ọdun meji lopọ lẹwọn.
A gbọ́ pé wọ́n ti jẹ́ tọkọtaya fún ọdún mẹ́wàá kí ìṣẹ̀lẹ̀ náà tó ṣẹlẹ̀.
Akọnimọọgba Brazil ni o yẹ ki Messi gba kaadi ikilọ yẹlo, lẹyin naa lọ sọ pe ki oun gbẹnu dakẹ, bayii loun sọ fun un pe ko dakẹ ẹnu rẹ.
Àwọn ẹbọ wọnyi wà lọ́tọ̀ ní tiwọn, yàtọ̀ sí ti àwọn ọjọ́ ìsinmi fún OLUWA, ati àwọn ẹ̀bùn yín, ati àwọn ẹbọ ẹ̀jẹ́ yín, ati àwọn ọrẹ ẹbọ àtinúwá tí ẹ óo máa mú wá fún OLUWA.
Ẹ kò ní pẹ́ níbẹ̀ rárá, ṣugbọn píparun ni ẹ óo parun.
Ìgbéraga, irọ́ pípa,ẹni tí ń déédé pa aláìṣẹ̀,
Ọ̀pọ̀lọpọ̀ ènìyàn ló ti ń sọ èrò ọkàn wọ́n lóri awuyewuye tó bẹ́ sílẹ̀ lóri Khapilat Kareem ti gbogbo ènìyàn mọ̀ sí Khafi, tó ń kopa nínú eré àgbéléwò BBNaija tó ń lọ lọ́wọ́.
Igba ogun ni Etuhu ti gba bọọlu fun orilẹ-ede Naijiria labẹ Super Eagles, yatọ si ti ẹgbẹ ninu idije 2008 ati 2010 pẹlu ti idije agbaye ni South Africa.
Ẹ kí Epenetu àyànfẹ́ mi, ẹni tí ó jẹ́ onigbagbọ kinni ní ilẹ̀ Esia.
Yóo gbé àsíá sókè fún àwọn orílẹ̀-èdè,yóo kó àwọn Israẹli tí a ti patì jọ.
 itán sọ fún wa pé ibẹ ̀ náà ló ti mú un bọ ̀ .
Ó ní kí wọn wá oúnjẹ fún ọmọde náà kí ó jẹ.
Bí ìdílé kan bá wà tí ó kéré jù láti jẹ ẹran ọ̀dọ́ aguntan kan tán, ìdílé yìí yóo darapọ̀ mọ́ ìdílé mìíràn ní àdúgbò rẹ̀, wọn yóo sì pín ẹran tí wọ́n bá pa gẹ́gẹ́ bí iye eniyan tí ó wà ninu ìdílé mejeeji, iye eniyan tí ó bá lè jẹ àgbò kan tán ni yóo darapọ̀ láti pín ọ̀dọ́ aguntan náà.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Iléeṣẹ́ ológun, ẹ kú àpọ́nlé mi, èmi náà yóò máa ṣúgbàá yin - Seyi Makinde Ẹ gbà wá o!
Ó mú àwọn àkísà ati àwọn aṣọ tí wọ́n ti gbó níbẹ̀, ó so okùn mọ́ wọn, ó sì nà án sí Jeremaya ninu kànga.
Omar Al-Bashir ti wọ́n gbajọba lọ́wọ́ ẹ ló di wàhálà
O ni Amọtẹkun ko waye lati rọpo awọn ileeṣẹ aabo to n bẹ nilẹ tẹlẹ, ṣugbọn yoo ṣiṣẹ papọ pẹlu awọn ẹṣọ aabo to ku, ki eto naa le kẹsẹjari.
Ṣaaju ni ajakalẹ arun Coronavirus ti ṣe akoba fun idanwo awọn akẹkọọ jade gírámà, ti wọn si sun lati oṣù kẹfà di oṣù Kẹwa.
Yóo di aṣálẹ̀ láti ìrandíran,ẹnikẹ́ni kò ní gbabẹ̀ kọjá mọ́ títí lae.
Láti ibẹ̀ wọ́n jáde lọ, wọ́n ń la Galili kọjá.
Ogagun Ibrahim Idris  wa fi da awon omo orile-ede Naijiria loju pe, ko ni si iwa ipanle tabi aaye ibasepo ti o le fayegba iwa mago-mago laarin osise alaabo ati egbe oselu Kankan bi o ti le wu ko mo.
Iroyin ti a kọkọ gbọ sọ pe o le ni aadọrin eniyan lo ku si iṣẹlẹ naa tẹlẹ.
N kò sí ní Jerusalẹmu ní gbogbo àkókò tí nǹkan wọnyi ṣẹlẹ̀, nítorí pé ní ọdún kejilelọgbọn ìjọba Atasasesi, ọba Babiloni, ni mo ti pada tọ ọba lọ.
 Ọjọ ́ kẹsàn-án lẹ ́ yìn tí wọ ́ n ti rí oṣù tuntun , ọba yóò rán ikọ ̀ lọ láti lọ kéde ayẹyẹ ọdún .
Missing Child: Òbí àti asọ́nà ṣọ́ọ̀ṣì 14, lọ́ búra nì'dí imọlẹ̀ l'Akure Arsenal ti padà júwe ilé fún Unai Emery Adekunle Esther Boluwatife, ti ọrọ kan ba BBC Yoruba sọrọ lori ohun to ṣẹlẹ gangan ni Akurẹ .
AWỌN IROYIN TẸẸ LE NIFẸ SI NIPA RẸ Ẹ má gbàbọ̀de kankan láti tú Wolii ìjọ Sotitobire sílẹ̀ o!
 eléyìí ló wá fà á tí ìjà fi wà láàárín òun àti àwon ènìyàn , ni wón bá fim ni orúko wí pé , baba ológbà .
Àwọn tó fẹ́ kí ọba máa ta ilẹ̀ ilú ló fẹ́ yọ Oluwo lóyè- Ẹgbẹ̀ Baálẹ̀ Iwo.
Kìí ṣe àwọn ọmọ akẹ́kọ̀ọ́ ni Boko Haram fẹ́ jí gbé Ìjínigbé àwọn akẹ́kọ̀ọ́ Chibok tó wáye ní ọjọ́ kẹrìnlá, oṣù kẹrin, ọdún 2014 kìí ṣe láti ji àwọn ọmọbinrin Chibok gbe bíkò ṣe láti jí ẹ̀rọ tí wọ́n fí ń mọ búlọkù, ìṣẹ́ ilé kíkọ to ń lọ witiwiti nínú ọgbà ilé ẹkọ́ náà ní bi ọsẹ̀ díẹ̀ sí ìgbà náà.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Fẹmi Adebayọ: Òsèré tíátà Yorùbá kò leè gba owó ju òsèré olóyìnbó lọ 19 Òkùdu 2018 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 19 Ògún 2018 Oríṣun àwòrán, @realfemiadebayo Ọmọ to ba mọ́ iya abi baba rẹ loju osi ni yoo ta ọmọ naa pa ni Yoruba maa n sọ.
 A fe ki won wa nipo ti o dara bi won ba se n dagba si, bi a se gbaradi lopolopo fun iko Super Eagles fun idije boolu agbaye, beeni a tun se gbaradi fun iko Eaglets saaju idije naa.
ki ile igbimo asofin naa to fenuko lori rẹ bayii.
Asa ké pe OLUWA Ọlọrun rẹ̀, ó ní, “OLUWA, kò sí olùrànlọ́wọ́ tí ó dàbí rẹ nítorí pé o lè ran àwọn ọmọ ogun tí wọn kò lágbára lọ́wọ́ láti ṣẹgun àwọn tí wọ́n lágbára.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Amuneke fipò sílẹ̀ gẹ́gẹ́ bí akọ́nimọ̀ọ́gbá Tanzania Ta ni ẹlẹ́sẹ̀ ayò Megan Rapinoe tó gba ife ẹyẹ àgbáyé tàwọn obìnrin?
Service Chiefs: Ilé aṣòfin ní kí àwọn ọ̀gá àgbà ológun kúrò lẹ́nu iṣẹ́
Alaafin ni oun kọkọ kọ eti ikun si ọrọ naa, lẹyin igba yii loun ṣe iwadii lẹmi ati lara ki oun to gba lati fi Wasiu jẹ oye naa.
Awon gomina ati adari eso eto aabo lorile ede Naijiria lo wa si papa ofurufu, lati pade aare naa.
Ọ̀kan ninu àwọn tí ó wà pẹlu Jesu bá na ọwọ́, ó fa idà yọ, ó sì fi ṣá ẹrú Olórí Alufaa kan, ó gé e létí.
Fayoṣe sọrọ yii ni Ọjọbọ lẹyin ti iroyin bọ sita pe Rochas Okorocha pẹlu iyawo rẹ ti wọ gbaga ajọ EFCC, bi o tilẹ jẹ pe, ajọ naa ti kede sita pe ko si ohun to jọọ, oun ko mu Okorocha.
Ranti pé, amọ̀ ni o fi mọ mí,ṣé o tún fẹ́ sọ mí di erùpẹ̀ pada ni?
Simoni náà gbàgbọ́, ó ṣe ìrìbọmi, ni ó bá fara mọ́ Filipi.
Iwe ofin to de ihuwasi awọn to di ipo oṣelu mu ( The code of conduct) yannana rẹ pe ẹnikẹni to ba di ipo ilu mu gbọdọ fi ipo yoowu to ba dimu ni ileeṣẹ aladani gbogbo silẹ ni kete to ba ti de ori oye.
Ni wọn igba to jẹ pe ọna kan ko wọ ọja, owo to n ri nidi èsó tita ko to na mọ fun Eji Gbadero, ó bẹrẹ si ta ilẹ, ra ilẹ, o n ta ile, ra ile, ko si si ẹni to lee gbe ina wo oju Kiniun baba Moradewun, ko ma ge ika jẹ ni igbẹyin.
Nítorí náà ẹ gbọdọ̀ máa gbọ́ràn sí OLUWA Ọlọrun yín lẹ́nu, kí ẹ sì máa pa òfin ati ìdájọ́ rẹ̀ mọ́, bí èmi Mose ti pàṣẹ fun yín lónìí.
Gbogbo igi inú igbó yóo sì máa pàtẹ́wọ́,
“Fẹ́ràn ẹnìkejì rẹ bí ara rẹ” ni kókó òfin bíi, “Má ṣe àgbèrè, má jalè, má ṣe ojúkòkòrò,” ati èyíkéyìí tí ó kù ninu òfin.
Oju ọpọ ikansiraẹni Twitter rẹ ni aarẹ naa fi idupẹ ohun si, lẹyin ti awọn ololufẹ rẹ ṣewọde pẹlu asia ''Make Americas Great Again'' ni iwaju ileewosan Walter Reed Medical Center nibi ti aarẹ naa ti n gba iwosan.
Gómìnà ìpińlẹ̀ Eko Babajide Sanwo-Olu ti wá kédé pé láìpẹ́ yìí ni ìjọbna yóò ṣe àfilọ́lẹ̀ ọkọ̀ ojú omí mẹ́fà míràn láti fún àwọn ará Eko ni ìwúrí láti ma wọ ọkọ̀ ojú omi fún oṣù mẹ́ta tó n bọ̀ yìí.
 oníṣẹ ́ lámèyítọ ́ ni taine láàárín ọdún 1828-1893 .
Kọmiṣọna feto Ẹkọ, arabinrin Fọlaṣade Adefisayọ to kede eyi ni nitori abo ẹmi ati dukia awọn akẹkọọ , obi atawọn olukọ wọn ni wọn fi gbe igbesẹ yii.
Inu apoti gilaasi lo fi ara rẹ si ko too ko sodo naa ni eyi ti ori koo yọ pẹlu ariwo nla lasiko ọhun.
Ọdun 1972 ni Owa Ale gun ori apere awọn babanla rẹ gẹgẹ bi Owa Ale ikẹtadinlogun ilu Ikare.
Iyawo re Dolapo Osinbajo si wa legbee re.
Nígbà tí mò ń lọ sí Masedonia, mo gbà ọ́ níyànjú pé kí o dúró ní Efesu, kí o pàṣẹ fún àwọn kan kí wọn má ṣe kọ́ eniyan ní ẹ̀kọ́ tí ń ṣini lọ́nà, 
Oríṣun àwòrán, prophet_i_o_samuel Ninu asọtẹlẹ naa lo ti kede pe oun ri awọn eeyan to mura bii ologun, ti wọn n se iwa ika sawọn araalu ati ọpọ ọmọ orilẹede Naijiria.
Saaju, agbenusoro aare Buhari, ogbeni Femi Adesina, so lojo Eti(Friday) tele pe aare yoo soro lakoko ipade ohun, nibi ti yoo ti yanana ipinnu orile-ede Naijriia lori ipa iyipada oju ojo.
O ni ohun to mi oun lọkan ni bi o ṣe jẹ pe awọn ọdọ olorin ko fẹ kọ orin Fuji mọ bi ko ṣe orin takasufe, HipHop.
Agba akọroyin kan, to tun jẹ alẹnulọrọ ninu ọrọ gbogbo to n lọ, Lasisi Olagunju ni, igbesẹ naa ko jọ eyi to lee so eso rere pẹlu bo se jẹ wipe tinubu funrarẹ gan ni ẹhonu.
Cancer center: Ọdún 38 ni ìyá mí fi ṣiṣẹ́ ní UCH, màá kọ́ ibùdó ìtọ́jú àrùn jẹjẹrẹ ní ìrántí rẹ
Ẹ óo sá bí àwọn baba ńlá yín ti sá nígbà tí ilẹ̀ mì tìtì ní àkókò Usaya, ọba Juda, OLUWA, Ọlọrun yín yóo wá dé, pẹlu gbogbo àwọn eniyan mímọ́ rẹ̀.
Jẹ́ kí ìpèe rẹ̀ ta ọ́ jí!
Ikú ń pa àwọn ọmọde nígboro,ati àwọn ọdọmọkunrin ní gbàgede.
Arabinrin Ehuriah ni awn ile ijọsin Kristẹni lawọn maa n sába fun ni iwe ẹri ṣugbọn awọn agbo mii ko si ninu iwe ofin to ni ṣe pẹlu igbeyawo to faaye gba ọkọ kan ati aya kan.
Tọ́ mi sí ọ̀nà òtítọ́ rẹ, sì máa kọ́ mi,nítorí ìwọ ni Ọlọrun olùgbàlà mi;ìwọ ni mo gbẹ́kẹ̀lé ní ọjọ́ gbogbo.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ẹ ṣe àwárí ọ̀daràn tó bọ́ mọ́ yín lọ́wọ́ - Turkur Buratai Àlàyé rèé lóríi ìdí tí wọ́n fi ń pe aya ní ìyàwó Lórí ìmọ̀ràn Sunday Igboho, Ẹlẹbubọn ní yóò dára kí Yorùbá padà sí àmúlò èròjà ìbílẹ̀ fún ààbò Khafi wọ gàu lẹ́nu iṣẹ́ lórí ẹ̀sùn ìbálòpọ̀ ní BB Naija Ọdun awọn musulumi ni ọpọ eeyan ri ọdun Ojude Ọba si nigba to bẹrẹ, to si jẹ ọdun awọn ẹlẹsin kan, asiko yii si ni awọn musulumi yoo gba aafin ọba lọ lati lọ se aku ọdun sọdọ rẹ lasiko ọdun ileya, lọna ati fi ẹmi imoore wọn han fun ọwọ aanu ati ọrẹ to se fun wọn.
Bí ọkunrin yìí kò bá wá fẹ́ ṣú aya arakunrin rẹ̀ tí ó kú lópó, obinrin náà yóo tọ àwọn àgbààgbà lọ ní ẹnubodè, yóo sì wí pé, ‘Arakunrin ọkọ mi kọ̀ láti gbé orúkọ arakunrin rẹ̀ ró ní Israẹli, ó kọ̀ láti ṣe ojúṣe rẹ̀ gẹ́gẹ́ bí arakunrin ọkọ mi.
Àṣẹ tuntun tó kalẹ̀ ní Zamfara Nàìjíríà ló wà nípò kẹfà nínú ewu ikú àìtọ́jọ́ l'ágbàáyé nítorí nkan mímú tó ní ṣúgà Awọn eeyan orilẹede Sudan ṣi n reti ohun ti ileeṣẹ iroyin ijsba orilẹede naa gbe jade lori ikede kan ti ileeṣẹ ọmọogun orilẹede ọhun n gbero lati ṣe lori bi eto iṣejọba orilẹede naa yoo ṣe ri.
Èmi ati àwọn iranṣẹ mi náà yóo máa gbààwẹ̀ níhìn-ín.
Ọkan pataki lara awọn ọmọ ẹgbẹ oṣelu PDP nipinlẹ Ọṣun ni oloye Fatai Akinbade koda o wa lara awọn oludije mẹrin to kopa ninu idibo abẹnu lati yan oludije fun ipo gomina labẹ aṣia ẹgbẹ oṣelu PDP.
Ọjọgbọn Adeyẹye fikun ọrọ rẹ pe ajọ to n ri si ọrọ ilera lagbaaye, WHO ti ko bi ẹgbẹrun lọna mẹjọ paali ayederu oogun ọhun nilẹ.
Shuaib salaye pe, awon agbegbe ni ogoro awon omode ti ojo ori won koi ti odun marun, eyi ti a n gbiyanju lati fun won ni abere  ti yoo gbemi won la, O digba ti a ba de odo awon omode wonyii, a ko idaniloju pe,  ko si aarun ropa-rose lorile-ede Naijiria.
Ọ̀kan nínú wọn ní àwọn tó ń bá oun wa kẹ̀kẹ́ náà tẹ́lẹ̀, kìí se sọ òtítọ́ ló mú kí òun máa wa kẹ̀kẹ́ náà fúnra ara òun.
BBNaija: Kiki Osinbajo gbóṣùbà fún Seyi Awolowo, MC Oluomo gbárùkù ti Mike
Kara bridge explosion: Àjọ Lasema sọ pé wọ́n rí òkú nínú èèrù iná tó jó nítòsí Berger
Èyí yóo mú kí ìṣògo yín ninu Kristi Jesu lè pọ̀ sí i nítorí mi, nígbà tí mo bá tún yọ si yín.
Ní ọjọ́ kẹẹ̀rin ètò yìí, ìyẹn ọjọ́ Ìṣẹ́gun, Elizabeth ati Àrẹ̀mọ rẹ̀ Charles àti aya rẹ̀, àti àwọn ọmọ àrẹ̀mọ William àti Harry pẹ̀lú ìyàwó William, wọ́n yọjú sí èrò nlá tí wọ́n péjọ sí iwájú àfin rẹ̀.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Iléeṣẹ́ ọlọ́pàá sọ afurasí ọlọ́pàá tó yìnbọn fún ọ̀dọ́kùnrin tó fún èèyàn lóyún s'átìmọ́lé 21 Owewe 2020 Oríṣun àwòrán, Facebook/Mohammed Adamu Ileeṣẹ ọlọpaa ipinlẹ Rivers ti ju afurasi ọlọpaa kan to yinbọn fun ọdọkunrin ẹni ọdun mọkandinlogun, Ledisi Kote lẹsẹ lori ẹsun pe o fun ọmọdebinrin kan loyun.
Sonko ni gomina keji to wa lori oye ti wọn yoo yọ nipo lori awọn ẹsun asemase.
O wa gba wọn ni imọran pe dipo awọn iwa buruku bayii, ki wọn gbiyanju lati jẹ aṣoju rere fun awọn obi wọn, ilu wọn ati orilẹ-ede wọn lapapọAgbẹnusọ Ile Igbimọ Aṣofin naa sọrọ iṣiti yii ninu ọrọ ikini rẹ si awọn ọmọde ninu ajọdun ayajọ awọn ewe (ọmọde) lagbaaye, eleyii ti alukoro rẹ, Ọgbẹni Musibau Rasak fọwọ si.
Nígbà tí baálé ilé bá ti dìde, tí ó bá ti ìlẹ̀kùn, ẹ óo wá dúró lóde, ẹ óo bẹ̀rẹ̀ sí kanlẹ̀kùn, ẹ óo wí pé, ‘Alàgbà, ṣílẹ̀kùn fún wa!
MRKH syndrome: 'Ọjọ́ lọjọ́ tí mo mọ̀ pé wọ́n bí mi láì ní ojú ara obìnrin àti ilé ọmọ'
Ẹni tí ó bá fẹ́, kí ó gbọ́, ẹni tí ó bá fẹ́ kí ó má gbọ́, nítorí pé ìdílé ọlọ̀tẹ̀ ni ìdílé wọn.
Kíni Condom nse níbi ìdíje Olympic?
Amọ, ẹgbẹ oselu PDP ti tako esi ibo naa, ti wọn si sọ pe awọn yoo sa ipa wọn lati fihan wi pe magomago waye ninu eto idibo naa.
Haram, titi ti won yoo fi pa gbogbo awon iko olote Boko Haram ti o ku rẹ bi iso”.
Awon osise feyinti lati ile-ise eto ibanisoro NITEL ati papa oko  ofurufu lo le salaye nipa owo ifeyinti won
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Minimum wage: Àwọn ọmọ Nàìjíríà sọ èrò wọn lórí ìyanṣẹ́lódì àwọn òṣìṣẹ́ Ṣugbọn, awọn gomina sọ pe ẹgbẹrun mejilelogun Naira ni awọn le san, nitori agbara awọn ko gbe ọgbọn ẹgbẹrun Naira.
Nígbà ti àwọn ọ̀tá Juda ati ti Bẹnjamini gbọ́ pé àwọn tí wọ́n ti ìgbèkùn dé ti bẹ̀rẹ̀ sí kọ́ ilé OLUWA Ọlọrun Israẹli, 
Binta Ayo Mogaji: Kìí ṣe iṣẹ́ tíátà làwọn òṣèré ti rí owó ra ọkọ̀ ńlá àti ilé àwòdamiẹnu
Wọ́n fi igbe búra ní orúkọ OLUWA pẹlu ariwo ati fèrè.
 Èyí jẹyọ nínú fídíò rẹ ̀ tó fi léde nínú àpo youtube  olajumoke sauce 7 : "" ní oṣù kejì ọdún 2018 ."
Àwọn ará ibẹ̀ ṣe ìtọ́jú wa lọpọlọpọ.
Wọn fi kún ọ̀rọ wọn pé, ilé olùdíje ẹgbẹ PDP ninu atundi ibo naa, onímọ-ẹrọ Dare Bankole, ni Seriki Gambari ko awọn tẹlẹmuyẹ lọ lati mu si ahamọ̀, sùgbọn àwọn ọmọ ìlú kò gbà kí èyí wáyé.
O fi da awon omo orile ede Naijiria loju pe pẹlu iwa otitọ ti aare Buhari ni  ati ipinnu ijoba Buhari lorile ede Naijiria
Ilé ẹjọ tó ga jùlọ ní Ibadan ní ohun yóò bẹ̀rẹ̀ ìgbẹ́jọ lóri ẹjọ tí àwọn ẹgbẹ́ alága ìjọba ìbílẹ̀ nipinlẹ Ọyọ, (ALGON) gbé wá lóri àṣẹ tí gómìnà Seyi Makinde pa pé ki gbogbo alága ìjọba ìbílẹ̀ ọ̀yọ́ mẹ́tàlélọ́gbọ̀n ló maa simi nilé.
Bawo ni iṣẹlẹ naa ṣe waye?
 nínú ìtàn yìí , wọn sọ pé Ọbàlùfọ ̀ n Ògbógbódirin ni àkọ ́ bí odùduwa , èyí tó tako ìtàn tí a ti mọ ̀ tẹ ́ lẹ ̀ nípa odùduwa .
Odunlade, Toyin, Ijebu dásí ìwọ́de #EndSARS, Mercy Aigbe gbébọn Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Fídíò, Soyinka Cancer: Àṣe ara mi ni iso ti n run gbogbo bí mo ṣe n ṣèrànwọ́ lórí jẹjẹrẹ27 Bélú 2019 End SARS protest: Lára àwọn ìlú tí ìwọ́de ti wáyé ní Ibadan, Ado Ekiti, Osogbo, Ado Ekiti ati Eko19 Ọ̀wàrà 2020 Fídíò, End SARS, End SWAT: Ó pé mi bí SARS kò ṣe sọ mí dolówọ́- Fulani Kwajafa17 Ọ̀wàrà 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Abiru wọlé àtúndi ìbò Sẹnẹtọ l'Eko, olùdíje méjì ṣojú APC ní Imo, òṣìṣẹ́ INEC méjì sọnù ní Zamfara Awọn sẹnẹtọ tuntun ti foju han lẹyin atundi ibo to waye kaakiri orilẹede Naijiria lọjọ Satide, ọjọ karun un oṣu kejila, ọdun 2020.
Ajakale àrùn sì lọ sún mọ́ wá julọ nítorí ọdún mejilelogorun tó wáyé rèé, gbogbo agbaye sì lo gbo kìkì rẹ.
Ọ ̀ kan nínú ìṣọ ̀ rí tíátà ni , tíátà nípa àwùjọ àti òsèlú .
Lara awọn ohun ti wọn maa n ṣe iwadi rẹ ni, awọn ẹgbẹ olokoowo egboogi oloro, awọn onifayawọ ibọn ati awọn ogbontagi ọdaran mi i.
" Ó yọjú nínú àtẹ ̀ jáde ojú ewé kẹfà ti "" the washington post "" ti ọjọ ́ karùndínlọ ́ gbọ ̀ n oṣù kẹwá ọdún 1911 , báyìí : "" kò ṣeéṣe kí ọlọ ́ gbọ ́ n ènìyàn bá ara rẹ ̀ nínú kòtò , kí ó lọ ibiṣẹ ́ kí ó sì tún maa gbẹ ́ ẹ lọ "" ."
Ṣugbọn Jesu dáhùn pé, “Ẹ má ṣe dá a lẹ́kun, nítorí kò sí ẹni tí yóo fi orúkọ mi ṣe iṣẹ́ ìyanu tí yóo yára sọ ọ̀rọ̀ ibi nípa mi.
O salaye pe, “ Ko si ayinike tabi ayida si itumo oro Olorun, ohun to ba pase ni sise, ti o ba se amulo re, o je ona ti iye, ayo, alaafiaati igbega”.
Ènìyàn wo ló gbọn bí èmi?
0 161421 Orilẹede China 4746 0.
“Ìwọ ọmọ eniyan, ọ̀nà wo ni ẹ̀ka igi àjàrà gbà dára ju ẹ̀ka igi yòókù lọ; àní igi àjàrà tí ó wà láàrin àwọn igi inú igbó?
Agbabọọlu Real Madrid tẹlẹ ri, Roberto Carlos ti sọ pe ẹlẹsẹ ayo, Ronaldo Nazario Delima pegede ju Lionel Messi ati Cristiano Ronaldo lọ nigba to si fi n gba bọọlu.
Oríṣun àwòrán, Gal Pissetky Ọpọlọpọ ẹjọ to ta koko ni Pissetzky ti gba ro nile ẹjọ to gaju lọ nipinlẹ Illinois, ati ile ẹjọ kotẹmilọrun ijọba apapọ.
Gbogbo àwọn tí a kà ninu ẹ̀yà Juda jẹ́ ẹgbaa mejidinlogoji ó lé ẹẹdẹgbẹta (76,500).
”OLUWA dáhùn pé, “Bẹ́ẹ̀ ni, wọn yóo fà ọ́ lé e lọ́wọ́.
Sẹnetọ Ndume gba lati ṣe oniduro Maina, lasiko ti ajọ EFCC, gbe lọ sile ẹjọ fun pe o ṣe mago-mago ọgọrun biliọnu Naira owo ajọ naa.
" Aarẹ Gani Adams ni ọpọ ibeere lo n ru jade lati ipasẹ iku ojiji to pa Arotile, ti ko tii si idahun fun rara.
Lai sọ pe, inu ijọba apapọ dun si iṣẹ ti awọn ologun ati awọn agbofinro ṣe ni Lekki Toll gate, nitori wọn fi ẹmi ara wọn sinu ewu fun abo ilu.
Lara awọn nkan to ṣe lati mu itura ba araalu ni ẹ̀kọ́ kikọ lori redio ati tẹlifisan fun awọn akẹ́kọ̀ọ́.
Nítorí pé mo ti ké títí, kò sì sí ẹni tí ó gbọ́,mo ti na ọwọ́ si yín ṣugbọn kò sí ẹni tí ó dá mi lóhùn,
Ọwọ́ ọ̀lọ́pàá tẹ́ àwọn afurasí ayédèrú apòógùn l'Eko
Lójó òpó twitter àwọn ọmọ Nàìjírtíà ń ṣelédè lẹ́yìn rẹ̀.
Ó sọ̀rọ̀ gẹ́gẹ́ bí ó ti máa ń sọ ọ́; Dafidi sì gbọ́.
A gbọ pe ọpọ adugbo to sun mọ ibi ti ibugbamu naa ti waye, bii Akọta, Festac ati Abule Ado ni ariwo naa rinlẹ de, ti ilẹ mi titi eyi to se ẹru ba ọpọ eeyan.
Gomina Makinde ni ijọba oun ko ni kaarẹ nipa eto ilanilọyẹ lori ati dena Coronavirus nipinlẹ Oyo.
UNICEF: Ìyàn ń bọ̀ nílẹ̀ Áfíríkà Ologun Nigeria gbakoso ibuba Boko Haram Nàìjíríà á bí ọmọ 25, 685 lọjọ́ kínni, oṣù kinni, ọdún 2019.
OLUWA wá láti Temani,Ẹni Mímọ́ sì wá láti òkè Parani.
Cedric Bakambu l'agbabọọlu to wọn ju l'Afirika
“Sọ fún àwọn eniyan Israẹli pé, ‘Ẹ pa ọjọ́ ìsinmi mi mọ́, nítorí pé òun ni àmì tí ó wà láàrin èmi pẹlu yín ní ìrandíran yín; kí ẹ lè mọ̀ pé, èmi OLUWA yà yín sọ́tọ̀ fún ara mi.
Ọmọ orilẹede Portugal naa, to tukọ Chelsea fun saa meji ko to tukọ Man U fun saa kan, ni lootọ ni wipe, awọn kọlu ara wọn nigba ti wọn jọ wa lẹnu iṣẹ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Jose Antonio Reyes: Agbábọ́ọ́lù Arsenal nígbà kan rí kú ní ẹni ọdún márùndínlógójì 1 Òkùdu 2019 Oríṣun àwòrán, PA Àkọlé àwòrán, Reyes wa lara ikọ Arsenal to ṣegun awọn agbọọlu to ku lati gba ife ẹyẹ Premier League ni ọdun 2003 si 2004 Jose Antonio Reyes to gba bóólu fun Arsenal nigba kan ri ti ku ninu ijamba ọkọ kan ni ẹni ọdun marundinlogoji.
Atẹjade naa salaye pe awọn iroyin bẹẹ ''a ma mu irẹwẹsi ọkan ba awọn ọmo ogun ti o si le ko ipalara ba akitiyan lati koju awọn ọmọ ikọ Boko Haram.
Àwọn eniyan ń fi mí ṣe ẹlẹ́yà,wọ́n ń gbá mi létí,wọ́n kó ara wọn jọ sí mi.
Nítorí OLUWA ń wó Babiloni lulẹ̀,ó sì ń pa á lẹ́nu mọ́.
Òpùrọ́ ni ẹni tí ó bá wí pé òun mọ̀ ọ́n, ṣugbọn tí kò bá máa pa àṣẹ rẹ̀ mọ́, kò sí òtítọ́ ninu olúwarẹ̀.
Kìí ṣe ààrẹ ní yóò kó orúkọ àwọn tí yóò ṣiṣẹ́ jọ, àwọn òsìsẹ́ ni, ẹnikẹ́ni kò sì lée gba ẹ̀rí wọn jẹ.
Amọṣa ninu ọrọ tirẹ, olubadan ti ilẹ Ibadan, Ọba Saliu Adetunji ṣalaye pe, oye onilẹkẹ ni oye Babalọja-General, nitori naa ọba lo laṣẹ lati fi eeyan jẹ.
Àkọlé àwòrán, Akinyele Murder: Iléeṣẹ́ ọlọ́pàá ní aago márùn-ún ìdájí ni wọ́n pa obìnrin náà níwájú ilé rẹ̀ O tẹsiwaju wi pe o fẹẹ to bii iṣẹju mẹwaa ki wọn to ri arabinrin naa gbe kuro ninu agbara ẹjẹ lọ si ile iwosan, ṣugbọn igbiyanju wọn ja si pabo.
Ọna ti wọn ba gbe e gba ni yoo sọ boya ẹgbẹ naa yoo duro, paapa iru awọn eeyan ti wọn ba fun ni tikẹẹti ẹgbẹ lati dije dupo.
Mo bá gbọ́ tí ọkunrin tí ó wọ aṣọ funfun, tí ó sì ní àpótí ìkọ̀wé lẹ́gbẹ̀ẹ́, ń jábọ̀ pé, “Mo ti ṣe bí o ti pàṣẹ fún mi.
Ninu ọrọ kan to fi sọwọ si ori ikanni ayelujara twitter rẹ lowurọ ọjọọbọ.
Joabu bá dáhùn pé, “Ọlọrun mọ̀, bí o bá dákẹ́ tí o kò sọ̀rọ̀ ni, àwọn eniyan mi kì bá máa le yín lọ títí di òwúrọ̀ ọ̀la.
Aare Muhammadu Buhari ti yan ogbeni Kabiru Bala gege bi asoju tuntun sorile-ede South Africa, bakan naa si orile-ede Swaziland ati Lesotho.
Wọ́n fẹ̀sùn kan igbákejì gómìnà ìpínlẹ̀ Ondo lórí ayédèrú ìwé ìdìbò níbi ìdìbò abẹ́lé PDP tó ń lọ lọ́wọ́ Ikú ti yọ́wọ́ òṣèré Nollywood Yorùbá, Yusuf Satia l'áwo Gómìnà ìpínlẹ̀ Ekiti, Kayode Fayemi nàá ti ni aàrùn Coronavirus Kí ló dé tí ìjọba ìpínlẹ̀ Oyo kéde fífagilé Sáà ètò ẹ̀kọ́ kẹta fún àwọn akẹ́kọ̀ọ́?
 Ìyànjú carr àti àwọn ìmòràn rẹ ̀ ní ó jẹ ́ kí wọ ́ n dá king ' s college sílẹ ̀ .
láti fi ohun tí ó tọ̀nà tí ó sì jẹ́ òtítọ́ hàn ọ́,kí o lè fi ìdáhùn pípé fún ẹni tí ó rán ọ.
Kíni ilé iṣẹ́ Akọ̀wé ìjọ̀ba Naijiria fẹ fí ojú òpó 64,000000 ṣé?
Lati igba ti ajọ eleto idibo Naijiria ti da ọjọ kẹtalelogun oṣu keji ọdun 2019 ni ọjọ tuntun ti wọn yoo di ibo yan aarẹ ati sẹnetọ ni awọn ọmọ Naijiria ti n fi ẹhonu han si igbesẹ naa.
O ti di eeyan mẹrindinlogoji to ni ni arun naa ni Naijiria bayii ninu eyi ti awọn meji ti jade nile iwosan.
Èèèyàn márùn ún péré ló leè lọ ayẹyẹ ìgbéyàwó ní Australia báyìí nítorí Coronavirus Ijọba orilẹ-ede Australia ti sọ pe oun ko faaye gba ju eeyan marun un pere ti yoo wa nibi ayẹyẹ igbeyawo ati mẹwaa nibi isinku lọna ati dẹkun itankalẹ aarun Coronavirus.
Gbogbo nǹkan yòókù tí Simiri ṣe: gbogbo ìwà ọ̀tẹ̀ rẹ̀, ni a kọ sinu Ìwé Ìtàn Àwọn Ọba Israẹli.
ng/ Arinrin ajò gbọdọ fi esi ayẹwo pé wọ́n ko ni ààrun náà soju opo NCDC Lẹ́yìn ọjọ́ méje ti arìnrinajò náà bá de, yóò lọ tun àyẹwò ọhun ṣe Àyẹwò ara gbigbona náà yoo ma wáye ni àwọn pápákọ̀ òfurufú gbogbo.
Kabiyesi Alawe ni awọn lọbalọba Ekiti ko ranṣẹ pe Alaafin lati da si ọrọ to n lọ laarin wọn, nitorinaa ko duro si aye rẹ.
Serena ti ṣetan lati kopa ninu dije US Open ti yoo bẹrẹ lọjọ Aje to mbọ lorilẹ-ede Amẹrika.
  Mo rí awọn ìlú kan tí ó jẹ́ pé òkúta funfun gbòò ni wọ́n fi kọ́ gbogbo àwọn ilé ibẹ̀.
Bẹ́ẹ̀ ni, gbogbo ìlúkílùú tabi ilékílé tí àwọn eniyan ibẹ̀ bá ń bá ara wọn jà yóo tú.
Nítorí náà, kí ẹnikẹ́ni má ṣe ìdájọ́ kí àkókò rẹ̀ tó tó, nígbà tí Oluwa yóo dé, tí yóo tan ìmọ́lẹ̀ sí ohun gbogbo tí ó fara pamọ́ sinu òkùnkùn, tí yóo mú kí gbogbo èrò ọkàn eniyan farahàn kedere.
Awọn ti isẹlẹ naa sojurẹ wi pe, lara awọn ọrẹ Fulani darandaran naa, Usman Olaniyi lo sọ fun un wipe, ọkunrin awakọ naa n sọrọ odi si, loba fa ọkọ yọ, ti o si seku pa ọkunrin awakọ naa.
 O tesiwaju pe ko si osise won Kankan ti o farapa tabi ti won se ni
Bakan naa lo pẹ̀ka ìkọ́ni rẹ lọ ṣiṣẹ olukọni alábẹ̀wò lori ikọni nipa eto aabo nibudo ilẹ Adulawọ ni fasiti National Defense University, USA.
Ọpọlọpọ ariyanjiyan lo n lọ lori eto aabo fun awọn ẹbi ọba naa lasiko ti wọn ba n gbe ni Canada.
com/id25RUw2ltFULL-TIME Liverpool 2-0 WolvesIt's not enough to claim the title – but a strong performance from Liverpool and two strikes from Sadio Mane ends an incredible season for the hosts with 97 points 👏👏#PL #LIVWOL pic.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Fayoṣe yin Ngige fún bó se polongo ìbò fún PDP Ọlọ́pàá 30,000 ní yóò mójútó ìdìbo Ekiti Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ekiti Election: Ará Èkìtì ń fẹ́ gómìnà tí yòò tù wọ́n lára Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fọ́nrán ohùn, Àdéhùn ètò ọrọ̀ ajé ilẹ̀ Afirika le lẹ́yìn Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, #EkitiDecides: Fayose sùn lórí ibùsùn aláìsàn Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Ṣùgbọ́n bẹ́ẹ̀ kọ́, Òmùgọ́dimẹ́ta kò mọ ìyí mi rárá.
Oun naa ni wọn ni o dari ikọ to pa ọlọpaa ni Lugbe ati Gwagwalada.
Eyi ni awọn ọna abuda fun awọn ọlọkọ lasiko ti atunṣe afara Eko bridge naa yoo maa fi waye: Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Yollywood: Yomi Fabiyi ní ìwà aṣiwèrè ni bí ọlọ́pàá ṣe ń tẹ ẹ̀tọ́ ọmọnìyàn lójú, táwọn òṣèré tíátà náà ń lò nínú fíímù
Philomeno Philemon Otieno, ọmọ ilẹ Kenya, gbe ori yọ ju Sadio Mane tilẹ Senegal lọ̀ ninu idijeAFCON, amọ Senegal papa fi ayo mẹta tẹ́ ori Kenya naa ba ni.
Nínú gbogbo ikú tí o ń pa ọmọ aráyé, èyí tí ojú-kòkòrò owó ń mú wá kò mọ ní ìba.
Nass: A ó tí ilé aṣòfin pa fún ọjọ́ méjì AWCON: Ikọ̀ Super Falcons kijó mọ́lẹ̀ lẹ́yìn tí wọ́n gba ife ẹ̀yẹ Afirika Awọn akọrin mejeeji naa jọ kọrin pọ lọjọ Aiku ni ode kan.
3 billiọnu lati fi ra awọn ọkọ nla fun irinna ọkọ laarin ipinlẹ naa.
Àkókò tí oníṣẹ́ dé, mo ń ṣiṣẹ́ pàtàkì kan fún bàbà mi.
Íslándì ( ; ) je is orile-ede erekusu europe ni to budo si okun ariwa atlantiki lori ebe arin-atlantiki .
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ohun tẹ́ẹ gbúdọ mọ nípa kókó orí ọyàn yín lásìkò fífọ́mọlọ́yàn Ṣé lóòtọ́ ni aya ààrẹ, Aisha Buhari fò lọ sí Dubai fún ìtọ́jú?
Ileewosan Odessa Medical Center ti wọn ko ninu wọn lọ ni awọn meje ni ti wọn le ju ti wọn n du ẹmi wọn nigba ti ọmọ kekere ọdun meji kan wa lara wọn.
Ẹka Ajọ Isọkan Agbaye to n risi eto ẹkọ, Unesco sọ wi pe eto igbani si ile iwe laarin akọ si abọ, gbọdọ jẹ 98 ati 102 awọn obinrin si iye 100 ọkunrin to ba wọle si ile iwe.
Davido gbá góòlù méjì sí àwọn Coronavirus Àwọn jàndùkú jí agbábọ́ọ̀lù Nàìjíríà méjì gbé lópòpónà Owo sí Benin Agbábọ́ọ̀lù Manchester United tẹ́lẹ̀, Marouane Fellaini lùgbàdì àrun coronavirus Nítorí coronavirus, Mikel Obi sá kúrò ní ikọ̀ Trabzonspor Lara awọn to lewaju iko Ivory Coast ni akinkanju agbaboolu kan ti orukọ rẹ n jẹ Didier Drogba.
Ajọ alagbelebu pupa to n mojuto eto didoola ẹmi awọn eniyan to ri sinu ile to wo ni Jos ni oku ti wọn ri ti pọ sii.
Fun idi ẹyi, ijinigbe ọgbẹni Dewji jẹ oun iyalẹnu.
“Ní ọjọ́ kẹjọ ẹ óo máa ní àpèjọ mímọ́, ẹ kò sì ní gbọdọ̀ ṣe iṣẹ́ líle kankan.
O so pe ayeye naa yoo bere ni ojo Eti(Friday) pelu adura (Juma’at) ni National Mosque, ti o gunle si aarin gungun iluu Abuja lojo kárùndínlọ́gbọ̀n, osu kárùn ún.
Bawo ni arun yi ṣe loro si Bi a ko ba mọ iye eeyan to ni arun yi,yoo ṣoro ki a to le sọ iye awọn to padanu ẹmi wọn lọwọ arun yi.
“Siwaju sí i, ranti ohun tí Joabu ọmọ Seruaya ṣe sí mi, tí ó pa àwọn ọ̀gágun Israẹli meji: Abineri ọmọ Neri ati Amasa ọmọ Jeteri.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù AEDC: Ìdí rèé ti Nàìjíríà fí ń gbé inú òkùnkùn 8 Owewe 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ìdí rèé ti Nàìjíríà fí gbé inú òkùnkùn Ọpọ lo ro pe dida ájọ ìná mọ̀nàmọ́na gẹ́gẹ́ bi wọ́n se ti n ṣe láti ọdún díẹ̀ sẹ́yìn yẹ ko fopin si airina ọba lo ni Naijiria.
Oríṣun àwòrán, Others Bakan naa lo ni ileeṣẹ ọlọpaa ti mu awọn adigunjale meji to wa ni panpẹ wọn naa wa si ilu Ibadan fun iwadii ijinlẹ to munadoko.
Awon amohunmaworan safihan ijamba naa ato ti ajaku oko ofurufu naa lori yinyin ni papa to bale si nigbaeyin.
Manchester City lo kọkọ ki bẹbdẹ si Arsenal ninu, ami ayo mẹta si odo ni wọn fi lu wọn bi aṣọ ofi.
Sugbon ohun to se koko bayii ni lati du ẹmi awon to si ha si
Ààrẹ Buhari wọ́gilé kí àwọn òṣìṣẹ́ ìjọba máa wọ ọkọ̀ bàálù olówó gọbọi 'Kìí ṣe ojúṣe mi láti sọ bóyá òótọ́ ni Buhari fẹ́ gbéyàwó tàbí irọ́' 'Ọwọ́ wa tún tẹ ojúkòó tí wọ́n tí ń bá àwọn ọmọdékùnrin lò pọ̀ ní Daura' Daura kò tan mọ́ Buhari àmọ́ òun àti ọmọ rẹ̀ ti fẹ́ ba ẹbí mi jẹ́ - Aisha figbe ta Juliana Afọnrewo, tii se ọkan lara oludari ileesẹ naa ni awọn seto naa fun Mama Rainbow nitori ohun to dara ni lati se ajọyọ awọn osere wa nigba ti wọn wa laaye.
Bẹ́ẹ̀ ni ẹ óo ṣe wẹ ara yín mọ́ kúrò ninu ẹ̀bi ẹ̀jẹ̀ aláìṣẹ̀, bí ẹ bá ṣe ohun tí ó tọ́ lójú OLUWA.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Police brutality during lockdown: Nínú Ọlọ́pàá àti Coronavirus, èwo gan an laráàlú ń bẹ̀rù jùlọ?
Àdájọba tabi Ìdọ ́ bajẹ (  monarchy "" ) je iru ijoba kan nibi ti gbogbo agbara oloselu wa patapata tabi ni oloruko lowo enikan tabi awon eyan kan ."
UNILAG TV: 'Isẹ yoo bẹrẹ laipẹ' Siga tita d‘eewọ lẹba ile ẹkọ Ile-ẹkọ giga fasiti ti Alabama ninu idahun rẹ, sọwipe awọn ko se ikankan to buru, atiwipe awọn tẹle gbogbo asẹ ati adehun pẹlu ijọba orilẹede Naijiria.
Ki Olorun tun je ki orile ede yii wa ni alaafia’’.
  Ẹni tí ó bá ní ìgbàgbọ́ nínú nkan báyìí lè rò pé iwin inú igi ló yọ sí òun ni!
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Oba Adedokun Abolarin ti Oke Ila: Ó ya ọ̀pọ̀ tó súnmọ́ mi lẹ́nu bí mo ṣe ń kọ́ Oloye Agẹṣin Adimula u Ila Ọrangun tun fi kun un pe gẹgẹ bi o ṣe jẹ Ile ifẹ ni aṣa yoo gbilẹ bi o ti yẹ nibẹ gẹgẹ bi awokọṣe fun gbogbo ilẹkilẹ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù US presidential election 2020: Bí ààrẹ Trump kò ṣe gbé ipò sílẹ̀ yóò ṣe àkóbá fún ọ̀pọ̀ ènìyàn 2 Bélú 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 17 Bélú 2020 Oríṣun àwòrán, Google Aarẹ ti wọn ṣẹṣẹ dibo yan lorilẹede Amerika, Joe Biden ti ni o ṣeeṣe ki ẹmi ọpọ eniyan bọ ti aarẹ Donald Trump ko ba kuro ni ipo fun oun gẹgẹ bi aarẹ.
Àwọn ará Pasia, ati àwọn ará Kuṣi, ati àwọn ará Puti wà pẹlu rẹ̀; gbogbo wọn, tàwọn ti apata ati àṣíborí wọn.
je pe ile-igbimo eleekejo ti o see gbele sile pin isuna ile-ise epo robi ohun
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Buhari: Àwọn ọmọ Nàìjíríà faraya lórí Ìrìn-àjò ààrẹ lọ sí Jordan 4 Ìgbé 2019 Oríṣun àwòrán, @NGRPresident Àkọlé àwòrán, Lẹyin ti aarẹ Buhari ba pari ipade tan ni Jordan,yoo tẹsiwaju lọ si Dubai ni UAElati kopa ninu ipade miran Iriwisi ọtọọto lo n tele ikede ti ileeṣẹ aarẹ Naijiria fi si oju opo Twitter wọn pe aarẹ Buhari n lọ si orileede Jordan fun ipade.
se pase pe ki won ti gbogbo ala orile ede Naijiria pa lati aago mejila osan , ojo kàrúndínlógún, Ẹti titi di ojo kẹ́tàdínlógún , aago mejila ojo
Ireti wa si ni wipe gbogbo rẹ yoo wa s'opin.
Bí àwọn òkè ńlá tilẹ̀ ṣí kúrò, tí a sì ṣí àwọn òkè kéékèèké nídìí,ṣugbọn ìfẹ́ mi tí kì í yẹ̀, kò ní yẹ̀ lára rẹ,majẹmu alaafia mi tí mo bá ọ dá kò ní yẹ̀.
Àkọsílẹ̀ ìran wọn ní ìdílé, àwọn baálé baálé ní ilé baba wọn, tí wọ́n jẹ́ akọni jagunjagun, gbogbo wọn jẹ́ ọ̀kẹ́ kan ati igba (20,200).
Awon obinrin orile ede Naijria ti darapo mo awon obinrin lagbaaye lati tako iwa aito ati iwa aparo kan, ga ju okan lo ,ti won maa n hu si awon obinrin lawujo wa.
" Orúkọ Burna Boy wọ àmì ẹ̀yẹ Grammy nítorí orin rẹ̀ 'Twice as Tall' Wo dókítà ọmọ Nàìjíríà tí àgbáyé ń wárí fún nítorí abẹ́rẹ́ àjẹsára COVID-19 Ìdí rèé tí ìjọba fi ń gbèrò pé kí àwọn tó ń gba 'minimum wage' má san owó orí mọ́ Ilé ẹjọ́ dájọ́ ẹgba mẹ́ẹ̀dóògún fún ọ̀daràn tó jí Iphone ní Kaduna Ǹkan tí ó yẹ ki o mọ̀ nípa Burna Boy Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Divorcee: Ó sàn kí wọ́n yàgò fúnra wọn ju ki wọ́n ṣe ara wọn léṣe- Fisayo Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Amos Dauda, Iphone: Ilé ẹjọ́ dájọ́ ẹgba mẹ́ẹ̀dóògún fún ọ̀daràn tó jí Iphone ní Kaduna25 Bélú 2020 Ondo Heardsmen vs Falae: Ilé iṣẹ́ ọlọ́pàá ìpińlẹ̀ Ondo ni Olóyè Falae kò tí ì mú ẹjọ́ wá si àgọ́ ọlọ́pàá kankan24 Bélú 2020 Jemila dáná sún ilé ọ̀rẹ́kùnrin rẹ̀ àti ọ̀rẹ́bìnrin tó bá nílé24 Bélú 2020 Helicopter crash in Lagos: Àbájáde ìwádìí ẹlikọ́pítà to já ni Opebi laipẹ yii ti jáde21 Owewe 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Bákan náà ni àwọn tó dìbò lòdi sí òfin ọ̀hún ni kò ni àwọn ìlànà tó fésẹ̀ múlẹ̀ tó.
Amọ o ni bi oun ṣe wole ni o gbe igbesẹ lati gba ara rẹ lọwọ Adedibu, ti oun ko si tẹle awọn ilana rẹ mọ.
Ọlọrun tun sọ ohun miiran fun mi lẹyin ti mo ka iwe ti Kenneth ati Gloria Copeland lori ilọrọ ninu Oluwa tan.
“Nítorí náà, má ṣe gbadura fún àwọn eniyan wọnyi.
Ọpọ eeyan lo maa n da asa nipa ẹnikan to rin irinajo afẹ yika gbogbo agbaye pẹlu alupupu lasan, taa mọ si Ọkada, ti wọn si maa n pe ẹni to ba n ti ilu kan si ekeji ni orukọ onitọun.
Coronavirus Cases in Africa: Olórí ẹ̀ṣọ́ Adarí ẹgbẹ́ òṣèlú APC, Bola Ahmed Tinubu ti kú lẹ́yìn tó lùgbàdì àrùn Coronavirus Oríṣun àwòrán, Others Adari ẹgbẹ oṣelu APC, Asiwaju Bola Ahmed Tinubu ti kẹdun Olori ẹsọ alaabọ rẹ,Alhaji Lateef Raheem to ku lẹyin to lugbadi arun Coronavirus.
Ajọ ilera agbaye WHO ni ki iru ẹni bẹe duro fun oṣu mẹfa lẹyin ti o ya Tatuu, wakati mejila lẹyin ti o da ara rẹ lu yii ki o to le fi ẹjẹ silẹ.
Ṣugbọn agbẹjọro Femi Falana jade bi awọn oṣiṣẹ eleto aabo ti sọ fawọn akọroyin pe ki wọn ba eṣẹ wọn sọrọ.
Nigba ti Minisita fun eto isuna
Oríṣun àwòrán, @nysc_ng Àkọlé àwòrán, Ajọ NYSC ko fi ojuure wo awọn to ba n ko lati kopa ninu eto isinlu ọlọdunkan O tesiwaju pe ''fún iṣẹ aladani àti iṣẹ ìjọba ní òfin yìí wà fún labẹ́ ètò àgùnbánirọ̀.
O ni ṣáájú ni ile asofin tí buwolu pé kí ìjọba lọ ya owó náà lókè òkun kí àrùn Covid-19 tó dé, àmọ́ nígbà tí àrùn náà dé, ní ìjọba tún padà wá síwájú ilé pé, kí ilé fontẹ lu u pé kí ìjọba lọ yà owó náà ni abẹle dípò òkè òkun."
Nítorí ẹni tí ó bá ń ṣe àìdára, yóo gba èrè àìdára.
Èmi ati ìdílé baba mi ni ó yẹ kí ó jẹ níyà.
“Bí arakunrin rẹ bá di aláìní tóbẹ́ẹ̀ tí kò lè bọ́ ara rẹ̀ mọ́, o níláti máa bọ́ ọ, kí ó sì máa gbé ọ̀dọ̀ rẹ, gẹ́gẹ́ bí àlejò ati àjèjì.
Jẹ ki aawọ ara rẹ tẹ ọ lọrun.
Wọ́n sọ fún baba arúgbó tí ó ni ilé náà pé, “Mú ọkunrin tí ó wọ̀ sinu ilé rẹ jáde, kí á lè bá a lòpọ̀.
Dexbrown Civil @Eni_kanda naa sọ pe, Tinubu ko sọ ododo nitori pe o n gbero lati jẹ aarẹ Naijiria.
Ivory Coast: Lẹ́yìn ìpàdé aláṣẹ ìjọba ni wọn gbé lọ sílé ìwòsàn níbi tó kú sí
Lọ́jọ́rú ni ilé iṣẹ́ DSS ṣe àfihàn obìnrin kan tí wọ́n fi ẹ̀sùn lílo ilé ààrẹ láti lu àwọn èèyàn ní jìbìtì.
Bisi Kazeem salaye pe awọn eeyan to din diẹ ni ẹgbẹrun meje ni ajọ ẹṣọ oju popo FRSC doola ẹmi wọn ninu ijamba ọkọ to ṣẹlẹ kaakiri Naijiria O parọwa fun awọn awakọ lati ṣọra nipa sisare asapajude loju popo nitori pe ẹmi ko ni aarọ rara.
Biotilẹjẹpe ileeṣẹ ọlọpa fi ọrọ wa Gareth Barry, Jonny Evans, Jake Livermore ati Boaz Myhill l'ẹnu wo, sibẹ wọn ko fi panpẹ ofin gbe wọn, ko to di wipe wọn gbe ẹjọ naa lọ siwaju ile ẹjọ ibilẹ kan.
Eniyan burúkú bọ́ sinu àwọ̀n ẹ̀ṣẹ̀ rẹ̀,ṣugbọn olódodo lè kọrin, ó sì lè máa yọ̀.
Nida miiran ẹwẹ, awọn ẹgbẹ oṣelu miiran n fẹ ko fi ipo silẹ ko lọ simi bo ba ti pari saa akọkọ rẹ.
Ó dá wọn lọ́kàn le, ó ní, 
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Yobe: Obi awọn akẹkọ Dapchi nbeere ọmọ wọn 8 Ẹrẹ̀nà 2018 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ọpọ obi awọn ọmọ ti Boko Haram ji gbe lo ti salaisi tabi se aarẹ Awọn obi aadọfa akẹkọ ti ikọ adunkoko mọni Boko Haram ji gbe ni ọjọ mejidinlogun sẹyin ti ran asoju ransẹ silu Abuja lati beere fun idande awọn ọmọ wọn.
won o so nnkankan fun mi.
Ti o ba wa di dandan pe eeyan fẹ san owo lati gba nọmba yi,ko le san ju ẹẹdẹgbẹta naira lọ amọ yi o tẹle awọn igbesẹ kan ki o to le gba.
Oloogbe Ogunjọbi jẹ alaga ajọ ere bọọlu nipinlẹ Oṣun ki ọlọjọ to de.
Beckham, àgbábọ́ọ́lù tẹ́lẹ̀ rèé tó ń sọ èdè Yorùbá Ta ló gé orí ọkùnrin mẹ́ta ní Lekki?
 O je agbaboolu ti o ni afojusun ati ebun ti o dayato.
 bẹ ́ ẹ ̀ gẹ ́ gẹ ́ ni frederick douglass ní ilẹ ̀ amẹ ́ ríkà pẹ ̀ lú cugoana , equiano , àti antoine amo ṣe ní ilẹ ̀ europe .
Ṣugbọn ní tèmi, kí á má rí i pé mò ń fọ́nnu kiri àfi nítorí agbelebu Oluwa wa Jesu Kristi, nípasẹ̀ ẹni tí ayé yìí ti di ohun tí a kàn mọ́ agbelebu lójú mi, tí èmi náà sì di ẹni tí a kàn mọ́ agbelebu lójú rẹ̀.
Nítorí pé bí ẹ bá dúró gbọningbọnin ninu Oluwa nisinsinyii, a jẹ́ pé wíwà láàyè wa kò jẹ́ lásán.
Bẹrẹ lati igba ti orilẹede Naijiria ko tii gba ominira ati lẹyin igbominira rẹ.
Amọṣa alukoro ileeṣẹ ọlọpaa ṣalaye pe ni ipele-ipele ni wọn fẹ ṣeto ayẹwo naa ati pe niwọn igba ti ileeṣẹ ọlọpaa ko lee wa ni titipa ni wọn ṣ n ṣe ni ipele.
Manoa bá gbéra, ó bá tẹ̀lé iyawo rẹ̀ lọ sọ́dọ̀ ọkunrin náà, ó bi í pé, “Ṣé ìwọ ni o bá obinrin yìí sọ̀rọ̀?
A lè sọ pé núdùlù ń gbégbá orokè ní Japan Lẹ́yìn ọ̀pọ̀ míléníọmú tí ìdìbò kan sì wáye, àwọn Japan gba wípé Nudulu ní ǹkan tó làmìlaka jùlọ ti àwọn ti gbéṣe 5.
Omotola Jalade Gbajugbaja osere Nollywood, Ọmọtola Jalade-Ekeinde ti dupẹ lọwọ ọkọ rẹ fun atilẹyin rẹ ni igba gbogbo.
Dípò èyí tí ọkàn yín ìbá fi bàjẹ́, tí ẹ̀ bá sì yọ ẹni tí ń ṣe irú nǹkan bẹ́ẹ̀ kúrò láàrin yín, ẹ wá ń ṣe fáàrí!
Nítorí náà, ẹni tí ó bá rò pé òun dúró kí ó ṣọ́ra kí ó má baà ṣubú.
Natani dá a lóhùn pé, “Ṣe ohunkohun tí ó bá wà ní ọkàn rẹ, nítorí pé OLUWA wà pẹlu rẹ.
Wọ́n so pọ̀,wọ́n lẹ̀ mọ́ ara wọn tóbẹ́ẹ̀,tí ohunkohun kò lè ṣí wọn.
Kòṣẹlẹ̀rí ni Hajj ọdún 2020, wo ìyàtọ̀ tó wà nínú rẹ̀ sí ti tẹ́lẹ̀ Idi si ree ti BBC Yoruba fi kan si akọwe ijọba tẹlẹ nipinlẹ Ondo, Ifedayo Abegunde, lati wadi okodoro ọrọ nipa isẹlẹ naa.
ri awon owo ilẹ okeere nile rẹ.
A tun le dena aisan iba nipa lilo awọn oogun to le gbogun ti iba fun awọ̀n arinrinajo, alaboyun, awọn obinrin ati awọn ọmọde.
’’ “Alaga egbe yii si ti fi damiloju pe, ipinnu ati ase oun ju ti enikeni lo ninu egbe yii, mo si lero pe oro ohun ti to mi.
Mo lero pe o ṣe apataki ki a tẹti gbọ ọrọ rẹ ṣugbọn mi o mọ nkankan nipa rẹ'' Kete to sọrọ yii tan lo ba wọ inu ọfisi rẹ lọ pada.
Ọrọ ko ri bẹẹ mọ bayii.
Ṣugbọn OLUWA dáhùn, ó ní, “Rárá o!
Ọlọrun, iṣẹ́ òdodo rẹ kan ojú ọ̀run,ìwọ tí o ṣe nǹkan ńlá,Ọlọrun, ta ni ó dàbí rẹ?
Awọn ọlọpa si tun sọ wipẹ orukọ afurasi naa ni Nikolas Cruz, ọmọ ọdun mọkandinlogun, to jẹ ọmọ ile-iwe ti ile ẹkọ̀ naa le kurọ.
Lootọ ni ijọba fofin de igbokegbodo awọn ọkọ sugbọn wọn faaye silẹ fawọn ọkọ lati ko awọn ọmọ naa lọ si abule ibi ti wọn ti fiwọn ransẹ sọdọ awọn Aafa ile kewu to n kọ wọn ni kewu.
Èmi ni mo da yín, n óo sì máa tọ́jú yín,n óo máa gbé yín, n óo sì gbà yín là.
Èdè míràn sì ni èdè nmú mọ́ra kí ó fi gbòòrò síi, ìyẹn nípasẹ̀ èdè-àyálò.
Oríṣun àwòrán, The Guardian Nigeria Àkọlé àwòrán, Ilumọọka onkọwe ni Areoye Oyebola nigba aye rẹ Bi a ba n darukọ awọn to lalẹ gaara fawọn to n bọ lẹyin wọn nipa iroyin oniwadi, Oyebola jẹ ọkan gbogi.
Aare Muhammadu Buhari ti gbosuba fun ile-isẹ to se atilẹyin fun
Tinubu ni sibẹsibẹ, oun ko ran sọja tabi ọlọpaa lati dena oun ti wọn ṣe si awọn ileeṣẹ oun tori oun ko fẹ ki ẹnikẹni ku bo tilẹ jẹ pe idokoowo oun ni wọn bajẹ.
2m dọlà ni obìnrin yìí ń gbà tó bá kọ ǹkan sí ojú òpó Instagram rẹ̀ Osù tó ń bọ̀ la ó gbé ètò ààbò ilẹ̀ Yoruba jáde!
Wò ó bí ọ̀nà ibi kan bá wà tí mò ń tọ̀,kí o sì tọ́ mi sí ọ̀nà ayérayé.
Plateau United padanu ami-ayo merin sodo(4-0) sowo USM Alger torile-ede Algeria  lojo Isegun(Tuesday), ti apapo esi ifesewonse ohun si pari ami ayo marun un si meji(5-2).
Wọ́n ń dún bíi kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ ninu igbó,wọ́n ń kó ara wọn jọ sí abẹ́ igi ẹlẹ́gùn-ún.
Bẹẹ ni ọrọ ri pẹlu gbajugbaja oṣere tiata , Olusola Isola Ogunsola, ti ọpọ eeyan mọ si Isho Pepper ati awọn aya rẹ, ti wọn dìjọ mi agbo tiata Yoruba logbo-logbo laarin ọdun 1965 si 1992.
Gẹgẹ bi ọrọ ti ọga ọlọpaa ni ipinlẹ Ọyọ, Kọmiṣọna Olukolu sọ, ko si ẹni to roo kan arakunrin naa.
"O ni ""Igbimọ amuṣẹya lori ọrọ ayika ni ipinlẹ Eko fẹ fi akoko yii sọ fun awọn eeyan ilu pe, lẹyin ti a gba aṣẹ lọwọ ile ẹjọ gẹgẹ bi ilana ofin, a o lu awọn ọkọ ti a gbẹsẹle lọwọ awọn to tapa s'ofin ni gbanjo."
Ẹnìkọ̀ọ̀kan wọn mú hapu kọ̀ọ̀kan lọ́wọ́, ati àwo wúrà kéékèèké, tí ó kún fún turari.
 yaya mefa lati mu awon opo omo orile ede Naijiria kuro ninu osi ati ise.
Angẹli keje da ohun tí ó wà ninu àwo rẹ̀ sinu afẹ́fẹ́.
Balaamu tún fi òwe sọ ọ̀rọ̀ wọnyi:“Ta ni yóo là nígbà tí Ọlọrun bá ṣe nǹkan wọnyi?
Wọ́n kìlọ̀ fun yín pé ní àkókò ìkẹyìn, àwọn kan yóo máa fi ẹ̀sìn ṣe ẹlẹ́yà, wọn yóo máa tẹ̀lé ìfẹ́kúfẹ̀ẹ́ ara wọn láì bẹ̀rù Ọlọrun.
Ojabo ni ayeye ajodun eto ijoba tiwa-n-tiwa to maa n waye lojo kọ́kàndínlọ́gbọ̀n ni lati fi se iranti ayeye ojo ti orile ede Naijiria tun pada si eto ijoba tiwa-n-tiwa lodun 1999, leyin opolopo odun ti awon omo –oloogun ti n dari orile ede yii.
Iṣẹ́ Àwọn Alufaa ati Àwọn Ọmọ Lefi.
Ogbeni Kabila kọ so boya ohun yoo tun dije lọjọ iwaju fun
Kí ló ha tún kù fún mi nígbà náà!
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Rivers Governorship Election: Àwọn janduku àti ọmọ ilé ìṣẹ́ ológun ló wà nìdí ìdìbò tó dàrú 16 Ẹrẹ̀nà 2019 Àkọlé àwòrán, Wahala to tẹyin idibo naa pọ debi wi pe awọn eeyan koribijade lo si ibi'ṣẹ Ajọ eleto idibo orileede Naijiria ti gbe esi iwadi ti wọnṣe jade lori ohun ti o fa wọduwọdu lasiko idibo Gomina nipinlẹ Rivers.
Ìlànà ojúlówó márùn ún tó dènà àrùn Coronavirus Èèyàn 20 mííràn tún ti lùgbàdì ààrùn Coronavirus ní Naijiria Bàbá ẹni ọdún 71 fi ẹ̀ṣẹ́ rán ìyàwó rẹ̀ lọ s'ọ́run àpàpàǹdodo ní Ìdànrè Oríṣun àwòrán, others Agbẹ kan ni ilu Idanre ni ipinlẹ Ondo ti fi ẹṣẹ lu iyawo rẹ pa.
Bẹẹ ba gbagbe, laipẹ yii ni gbajumọ osere tiata kan lobinrin, Ronke Ojo, ti ọpọ mọ si Ronke Oshodi Oke, n kabamọ pẹlu omije loju opo Instagram rẹ.
Mo le búra pé kò sí ìbáṣepọ̀ láárin Olorì Badrat àti Wasiu Ayinde - Olori Folashade Kí ló wà láàrin Olorì Badra àti Bobrisky, tí ọ̀rọ̀ wọn fi wọ̀?
Orilẹede Egypt ni yoo gbalejo idije ọhun to jẹ ẹlẹkẹẹta iru rẹ, ninu oṣu kọkanla ọdun yii.
Agbẹnusọ Gomina Babajide Sanwo-Olu, Gboyega Akosile ṣalaye fun BBC Yoruba pé gomina naa ko gbero lati fofin de ẹgbẹ naa nilu Eko.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Ikọ Manchester City fẹ gba ami ẹyẹ mẹrin ọtọtọ ni saa yii eyi ti idije UEFA Champions League jẹ ọkan lara wọn.
Sadi Sadi Oríṣun àwòrán, @Aishaofficial Àkọlé àwòrán, 2019 Elections: Àwọn òṣèré Yorùbá tó wà nínú ìgbìmọ̀ ìpolongo APC 48.
-Ọlọ́pàá Àpò 65 là fi gbé owó N1.
Ṣé bí èèyàn bá ṣe rere, ara kì yóò ti onítọ̀ún ní ìgbésẹ̀ kí gbésè yòó wù kó gbé láyé.
Àlàá, Àkin àti Ilésanmí fi kọ́kọ́rọ́ náà dán séèfù wò, kò sí i.
 Àkọ ́ kọ ́ , a lè yí gbogbo gbólóhùn sí òdì .
O kọ́ àwọn eniyan lẹ́kọ̀ọ́ ní ìgboro wa.
Eyi waye lẹyin iku agbabọọlu Nasarawa United, Chineme Martins to di oloogbe nigba ti ifẹsẹwọnsẹ NPFL n lọ lọwọ pẹlu ẹgbẹ agbabọọlu Katsina United lọjọ Aiku.
Mose sì yí orúkọ Hoṣea ọmọ Nuni pada sí Joṣua.
" Ọ ̀ pọ ̀ lọpọ ̀ ìtàn wolof ni a le rí nínú àwọn orin oríkì èyí ti a ma ń gbọ ́ láti ẹnu àwọn "" griots ' àwọn akéwì ."
Ninu ọrọ rẹ, o ni ‘Owo-ori nnkan-ini Ajẹmọ Ilẹ ati Ile (Land Use Charge) ṣe pataki lati le pa owo si apo ijọba lati fi ṣe iṣẹ idagbasoke ilu.
Lucky Izebhokun ni awọn yoo jọ wọya ija pẹlu NCAA ti wọn ba kọ lati ṣe igbega lẹnu iṣẹ fun awọn ọmọ ẹgbẹ awọn ki ọdun 2018 to pari.
Source: Johns Hopkins University, national public health agencies Figures last updated 15 January 2021, 17:44 GMT Akíyèsí: A le ri àkọsilẹ̀ Egypt tí a bá yan Middle East láti ara akọle tó wà lórí máàpù àti àwọn orilẹ̀-èdè to wà ni ìsàlẹ yìí Mauritania náà ti n ni àwọn ènìyàn to pọ́ pẹ̀lú aàrùn náà láti ǹkan bi ọsẹ̀ díẹ̀ sẹ́yìn.
Tu itọ́ sókè fi ojú gbà á .
 news ) pẹ ̀ lú bill ritter , tí òun náà sì ń rọ ́ pò liz cho , tí ó kúrò ní ip ̀ o adarí fún ìwé ìròyìn ( new wabc 4 p.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Xenophobia: Naijiria á kọ́kọ́ pèsè ọ̀nà láti bá ẹbí sọ̀rọ̀ fún wọn 7.
Bí ó bá jẹ́ obinrin ni, ẹni náà yóo san ọgbọ̀n ìwọ̀n ṣekeli.
Ko si oko ofurufu Kankan to n fo ni papako ofurufu Komo titi ti won yoo fi sayewo to ye sibudoko ohun.
Ojọgbọn Yemi Osinbajo ni o gbe ami ẹyẹ ti ileeṣẹ ologun Naijiria fi daa lọla fun un nibi ayẹyẹ Nigeria Army Day Celebration (NADCEL).
"Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, SS3 ní mo wà báyìí, mo sì ti gba àmì ẹ̀yẹ̀ púpò nílé-lóko gẹ́gẹ́ bí onílù - Ayansike ""Lẹyin ti a gbọ iroyin, a pe gbogbo awọn ti ọrọ kan."
Wọ́n bá tún ń bá ìrìn àjò wọn lọ, oòrùn ti wọ̀ kí wọ́n tó dé Gibea, ọ̀kan ninu àwọn ìlú ẹ̀yà Bẹnjamini.
Jesu ní, “Mo ṣebí olùkọ́ni olókìkí ní Israẹli ni ọ́, sibẹ o kò mọ nǹkan wọnyi?
Mohammed Adamu wa kilọ fawọn agbofinro lati ma ṣe jẹ ki ina esisi tun jo wọn lori ọrọ yi ki wọn si ṣapa lati yanju ẹjọ to wa nilẹ yi.
Ọ̀gá ọlọpàá gbẹ̀mí ara rẹ̀ l'Ógun Alex Badeh: Ọwọ́ ba afunrasí mejì Ọmọ ọgbọ́n ọdún pa bàbá rẹ̀ ní ìpínlẹ̀ Ogun Ilé iṣẹ ọlọpàá yóò gba ènìyàn 40,000 sí isẹ Agbẹnusọ iléeṣẹ́ ọlapàá ṣàlàyé pé àwọn ọlọ́pàá náà jẹ̀bi ẹ̀sùn tí wọ́n fi kàn wọ́n.
ni gomina tun wa pasẹ fun awon agbofinro lati ri i pe wọn pese aabo  to peye lojo ọna naa ki won si ri i pe gbogbo
Bi arúgbó bá kú ni ilé Yorùbá ki ṣe òkú ọ̀fọ̀ ṣùgbọ́n òkú ijọ àti ji jẹ, mi mu ni pàtàki bi irú arúgbó bá bi àwọn ọmọ ti ó ti dàgbà.
Iyẹn ni a n mojuto lọwọ mo n pe Ọlọrun pe aanu, aanu o.
Ọkunrin náà bá dáhùn pé, ohun tí yóo jẹ́ kí òun mọ̀ pé olóòótọ́ eniyan ni wá ni pé kí á fi ọ̀kan ninu wa sílẹ̀ lọ́dọ̀ òun, kí á gbé ọkà lọ sílé, kí ebi má baà pa ìdílé wa.
Mímú ara wà lọ́nà Oríṣun àwòrán, Eve Lloyd Knight Àkọlé àwòrán, Ó jẹ́ èèwọ̀ tẹ́lẹ̀ láti sọ̀rọ̀ ìgbádùn ìbálòpọ̀ Láàrin ọdún 2000 sí 2009, àwọn tó ń ṣe é bá bẹ̀rẹ̀ sí ní ṣe ẹ̀dà àti àwọ̀ oríṣiríṣi jáde.
Mo si ri i pe diẹ lara awọn to finu tan yoo kọwe fipo silẹ ninu iṣakoso rẹ.
- Amina Zakari Ọmọ Nàíjíríà fèsì lórí ààrẹ NANS tó ń sèlérí ìbò fún Buhari Ronke mẹnuba iṣẹ awọn sọrọ-sọrọ loju agbo ode inawo ni Naijiria pe: Gbogbo MC Nàìjíríà ló n ṣagbe lọna kan tabi omiran.
Dùǹdù kò jámọ́ nǹkan kan bẹ́ẹ̀ ni ẹnikẹ́ni kò bìkítà fún dòdò lọ́jọ́ ìgbéyàwó yìí.
" Idi eyi ni lati rii pe awọn eeyan ti wọn jẹ ọdaran ko bọ si ipo ọṣelu.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Nigeria Swearing in 2019: Makinde ní omi tuntun rú, ìgbà ọ̀tun dé sí ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́ 29 Èbibi 2019 Gomina tuntun ti wọn ṣẹṣẹ bura fun nipinlẹ Ọyọ, Onimọ-ẹrọ Ṣeyi Makinde ti ṣe alaye wi pe, asiko ti to fun imuṣẹ awọn ileri ti oun ṣe lasiko ipolongo idibo.
 Ó seé se kí àpólà jé òrò kansoso .
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ìnú mi kìí dùn nígbà trí mo ń ṣiṣẹ́ ni bánkì tó ìgbà ti mo bẹ̀rẹ̀ mẹkáníìkì Ni oṣu diẹ sẹyin ni wọn ti kọkọ yọ Bamidele Oloyelogun kuro ni ipo gẹgẹ bii olori ile naa ṣugbọn ti wọn ni gomina ipinlẹ naa, Rotimi Akeredolu paṣẹ ki wọn daa pada sipo.
Ori eto kan lori mohunmaworan apapọ ilẹ wa ni Minisita ti kede bẹẹ laarọ ọjọ Aje.
O kere tan, eniyan metadinlogun lo ti gbemi mi lataari ibon ti omo odun mokandinlogun kan yin nile iwe girama ni Parkland ni Florida lorile-ede America.
Àwọn ọmọ Israẹli ṣe ohun tí ó burú lójú OLUWA, wọ́n gbàgbé OLUWA Ọlọrun wọn, wọ́n bẹ̀rẹ̀ sí bọ oriṣa Baali ati Aṣerotu.
Iwo Kingmakers: Osa tìlú Iwo ní Oluwo fẹ́ máa dá owó ilú ná ló fa wàhálà Oríṣun àwòrán, Instagram/oluwoofiwoland Ani ka jẹ ekuru ko tan, se ni wọn tun n gbọn ọwọ rẹ sinu awo, ni ọrọ ariwo pe wọn fẹ yọ Oluwo tilu Iwo lori oye, eyi to gba igboro kan.
Mo mọ̀ọ́mọ̀ dá €37,000 ti mo rí he padà ni -Ọmọ ogun Bashir Iléeṣẹ́ ọlọ́pàá Èkó ní àwọn kò mọ ohunkohun nípa ìwadìí ẹjọ́ Dakolo àti pásítọ̀ COZA mọ́ Àgùnbánirọ̀ akọ̀ròyìn Channels náà ti dágbére fáyé látààrí ìkọlù Shiite l'Abuja Èèmọ̀!
''Ohun ti wọn ni lati ṣe ni pe ki wọn fi apo iwe kalẹ, eleyi ti wọn kọ adirẹsi wọn si lasiko ti wọn ba n ṣeto ati gba iwe irina wọn.
Àwọn ilé ìwòsàn ti sọ fún àwọn alábójútó ètò ìlera orílẹ̀-èdè.
feran lati maa gbọna ẹburu, ojuse wa si ni lati je oloootọ nibi ipo ti a ba wa.
Oríṣun àwòrán, Others ''Awọn lo gbe e oku rẹ lọ si ileewosan ijọba apapọ to wa ni ilu ọwọ titi di asiko yii.
” Paulu bá nawọ́, ó bẹ̀rẹ̀ sí ro ẹjọ́ tirẹ̀.
Nítorí Ọmọ-Eniyan ni Oluwa Ọjọ́ Ìsinmi.
Awon kan kaanu rẹ pẹlu isẹlẹ naa ti wọn si ni ki ijọba forijin fun ẹsẹ pe o lo ayederu iwe.
Iwadii ti wọn ṣe lori eyin naa fi han pe ẹnu oloogbe naa lo ti jade.
Ibidokun ni eto ẹkọ ile-iwe ti awọn akẹkọọ maa n gbe ma n fi aaye silẹ fun awọn ọmọ lati kọ ẹkọ to yanju fun aseyege.
Dúkìá mi ò lé kan o, mo ti dá fọ́ọ̀mù padà bó ṣe wà tẹ́lẹ̀ - Buhari, Osinbajo Ìtàn ayé Seyi Makinde, gómìnà tuntun ní Ọ̀yọ́ Èèyàn 5 farapa, ọ̀pọ̀ ọkọ̀ jóná nínú ìjàmbá iná márosẹ̀ Ibadan sí Eko Ẹ darijin mi, Maa gbe igbesẹ to yẹ bayii- El Rufai Gomina ipinlẹ Kaduna, Mallam Nasir El Rufai to ṣe ibura lẹẹkeji lati tun tukọ ipinlẹ Kaduna ti tọrọ aforijin lọwọ awọn eniyan Kaduna.
Ẹgbẹẹgbẹ̀rún oriṣiriṣi owó crypto-currency lo ti wa bayii, sugbọn Bitcoin ṣi lo gbajúmọ julọ laarin wọn.
Ìyàlẹ́nu lójẹ́ fún mi láti ri i pé nígbà tí ẹni ti ọba rán kí ó lọ mu ẹṣin wa máa yọ, màlúù ló mú wa.
Heferi, ará Mekerati, ati Ahija, ará Peloni; 
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Lagos King: Mátikú ọba tó lo lo ọdun mẹta lórí oyé latari rogbodiyan Eko Arun aseku pani Aids àti kòkòrò rẹ, HIV náà jẹ ajakalẹ àrùn to gbẹmi ọpọ èèyàn, pàápàá ní ìran wa yìí.
Fún ire ara yín ni mo fi ń sọ èyí fun yín, kì í ṣe láti dín òmìnira yín kù.
Àkókò tí ó bá wá, àkókò ńlá ni ó máa ń jẹ́ ní òde ayé, orin a máa kọlu orin, ìlù a máa kọlu ìlù, ijó a máa kọlu ijó, àwọn ènìyàn a sì máa ṣe àríyá pàtàkì gẹ́gẹ́ bí àmì ìyẹ́sí Ẹni tí ó dá wọn.
Kí àwọn tí ń sunkún máa ṣe bí ẹni pé wọn kò sunkún.
Bakan naa ni ọpọlọpọ awuyewuye wa lori eni ti yoo gbe asia ẹgbẹ oselu APC fun idibo si ipo gomina ni ipinlẹ Eko.
Ó tún bèèrè pé, “Bí a bá rí ogoji ńkọ́?
lori , nipa asa , eto oro aje ati iye awon eniyan to n gbe lorile ede naa.
Ìpínlẹ̀ Ogun fẹ́ fi òfin wọ́gilé ìsìnkú ọba lọ́nà ìṣẹ̀mbáyé Ìtàn ayé Taiwo Oredein rèé, àgbà òṣèlú tó parí ayé rẹ̀ sọ́gbà ẹ̀wọ̀n A fẹ́ ìdájọ́ òdodo lórí ìsẹkúpani- àwọn akẹ́kọ̀ọ́ FUOYE Alásè Buhari kú, Buhari ń ṣọ̀fọ̀ Ọjọ mejila ni Aarẹ Akufo-Addo fi rin irinajo abẹwo si ilẹ Yuroopu pẹlu awọn mẹwaa ninu oṣiṣẹ ileeṣẹ Aarẹ Ghana.
Sefanaya Alufaa ka ìwé náà sí etí Jeremaya wolii.
 Mo ti sise takuntakun bee si ni inu mi dun lopolopo lati gba ami-eye yii.
Ó ní gbogbo ìgbìyanjú òun láti ṣàlàyé fún wọn pé kò rí bẹ́ẹ̀, wọ́n ni kí òun bọ́ asọ wọ́n sì bẹ̀rẹ̀ sí ni na òun.
eniyan ti won padanu emi won nibi isele naa kedun .
Eyi ni ibi ti nkan de duro ni ipinlẹ kọọkan fun: Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Bí rere ni àbí búburú, wo ohun tí Covid-19 leè ṣe sí àgọ́ ara rẹ Ajọ to n gbogun ti ajakalẹ arun lorilẹede Naijiria, NCDC ti kede pe eeyan 197 miran ti lugbadi arun Covid-19 ni Naijiria.
Zhao Yunlin ni ó tú ìmọ̀ọ rẹ̀ sí èdèe Gẹ̀ẹ́sì.
BBNaija: Kayọde Ogundamisi ní akọ́nilọ́gbọ́n, amúlùúdùn ni BBNaija, kìí ṣe òṣèlú
Ìdẹ̀ra ni orúkọ ilé-ẹ̀kọ́ àbúrò Túndé Atọ̀pinpin.
Mose bá ranṣẹ lọ pe Datani ati Abiramu, àwọn ọmọ Eliabu, ṣugbọn wọ́n kọ̀ wọn kò wá.
Ṣugbọn Jesu fà á lọ́wọ́, ó gbé e dìde, ọmọ náà bá nàró.
Awọn eeyan a ma lọ sọdọ ogbologbo Ijapa yii lati tọrọ ẹbẹ adura to si n wa si imuṣẹ Àwọn àrídájú 'ọ̀rọ̀ yìí wá látẹ́nu akọ̀wé àgbà Toyin Ajamu ní ààfin Kábíyèsí Ṣọun ti ilu Ogbomosho fún BBC Yorùbá.
AMAA 2018 Ami eye fun alalaye ti won ya nile okeere
Báwo ni wọ́n ṣe n lòó fún ìtójú Ohun méje tí o kò gbọ́ rí nípa aláìsàn fòníkú fọ̀ladìde- Dókítà Igbekele Ìlànà ìjìnàsíraẹni 'social distancing' forí ṣánpọ́n bí ìrun Jímọ̀ ṣe bẹ̀rẹ̀ padà ni Ilorin Godwin Obaseki ti darapọ̀ mọ́ ẹgbẹ́ òṣèlú People's Democratic Party Ìjọba Amẹrika fi ojú àwọn ọmọ Yahoo mẹ́fà léde, wọ́n gbẹ́sẹ̀ lé dúkìá wọn Wọ́n ti dán òògùn náà wò lára àwọn tó ni Covid-19 ní ilẹ gẹ̀ẹ́sì ti ó sì ti dájú pé ó ń dóòlà ẹmi àwọn ènìyàn, èyí sì yi jẹ́ kí wọ́n maa maa lòó lẹ́sẹ̀kẹsẹ̀.
Ọgbẹni Ramaphosa, ti wọn bura fun ni ọjọbọ, se adehun ati gb'ogun ti iwa ibajẹ.
Ìwọ́de #RevolutionNow forí ṣánpọ́n ní Ibadan, àgbófinró gbàkóso ojú pópó Ìjọba Buhari ń wùwà bíi ìjọba Abacha lórí ọ̀rọ̀ Ṣoworẹ- Ṣoyinka Bí ọdún Ọ̀ṣun Oṣogbo ṣe bẹ̀rẹ̀ rèé àti pàtàkì rẹ̀ fún Nàíjíríà Èmi kò gbé pọ̀ pẹ̀lú Kollington Ayinla àmọ́ ọjà t'ọ́mọ ti wọ̀ lọ̀rọ̀ àwa méjééjì - Salawa Abẹni Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Snake Market: Àwọn òńtàjà ẹran ejò ní ẹran ejò dùn ju ẹran adìẹ lọ Igbesẹ yii wa lara itọpinpin lati rii wi pe eto jiju oko mọ Asitani ti yoo waye lọjọ kẹwaa Oṣu kẹjọ lọ ni irọwọ rọsẹ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, APC jáwé olúborí nípínlẹ̀ Ekiti Bí Ganduje bá pàdánù ìdìbò gómínà, kí ni yóò ṣe?
Iná sọ ní Eko, ọkọ̀ agbépo tún tí gbiná lórí afárá Magboro Ìdí tí a fi pa àwọn àgbẹ̀ onírẹ̀sì ní Borno, Boko Haram ṣàlàyé nínú fídíò tuntun Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Barister lo bi gbogbo oníṣẹ́ fújì -Oṣupa Oríṣun àwòrán, Olasunkanmi Marshal/Facebook Gbogbo awọn ọmọ oloogbe at'awọn iyawo lo wa níbẹ, awọn kan tiẹ tun darapọ nipasẹ ẹrọ ayelujara Zoom."
Gbogbo eniyan yóo sì mọ̀ pé èmi OLUWA ni mo fa idà mi yọ, n kò sì ní dá a pada sinu àkọ̀ mọ́.
Eyi yoo fi han pe idile ọmọọba Osu gba owo pe awọn ta ilẹ fun ileesẹ ijọba Naijiria l'oṣu Kẹjọ, ọdun 2000.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Lilo ede: Kini ‘technology’ ni ede Yoruba?
Ẹni ti o ṣoju awọn oniṣegun ibilẹ nibi ipade naa Ọgbẹni Taye Oyerinde ṣe alaye wi pe ogun ibilẹ ni ọna abayọ ti daju fun iwọsan aarun Corona.
Òwe Yorùbá ti ó ni “Bi Egúngún/Eégún bá ńlé ni ki a má rọ́jú, bi ó ṣe ńrẹ ará ayé, ló ńrẹ ará Ọrun”, ṣe gba ẹni ti ó bá wà ninú ìṣòro ni ìyànjú pé, ìṣòro yi ki ṣe ohun ti kò ni tán tàbi ni òpin.
Ṣugbọn ọkunrin náà kọ̀, ó ní òun kò ní di ọjọ́ keji.
Oríṣun àwòrán, Getty Images, @DinoMelaye Àkọlé àwòrán, Dino àti Ọ̀gá Ọlọ́pàá Dino lọ si olu ile iṣẹ ọlọpaa to wa nilu Abuja lati le yọju si ọga agba ọlọpaa ṣugbọn a gbọ pe wọn ni ko lee ri ọga tori o wa ninu ipade.
Umbilical cord: Àìsàn Màrùndíláàdọ́rùn ni ìwọ́ ọmọ tuntun le wòsàn
Jẹ́ kí àwọn tí ń gbìmọ̀ ibi sí mi dààmú,kí wọ́n sì sá pada sẹ́yìn!
Ìfẹ́ mú mi dọ̀bálẹ̀, gbogbo wọn bẹ̀rẹ̀ sí í bá mi gbọn ipàntí àti eruku igbá àyàmi, wọ́n rọra rẹ́rìn-ín, wọn ń ni, [Ẹ rọra o, ọ̀gá, ẹ rọra o, ọ̀gá’ ‘Ẹ rọra’ yẹ̀yẹ́ ni wọ́n ń wí.
Nítorí náà ni òjò kò ṣe rọ̀,tí òjò àkọ́rọ̀ kò rọ̀ ní àkókò tí ó yẹ.
 Àwọn èbún nínú fisiksi , kemistri , Ìwòsàn , litireso , ati alafia koko je bibun ni 1901 .
Atiku fii kún-un pé, àwọn ọmọ Nàìjíríà le gbé ìwé jáde fún òun lati tọwọ́ bọ̀ọ́ fún ẹ̀ri ọjọ́ iwájú, bí òún bá fẹ́ yẹ̀ kúro lórí àdéhùn.
Àwọn tó ní Covid-19 ní Nàìjíríà tún ti pọ̀ si, ènìyàn 661 ló tún ṣẹ̀ṣẹ̀ ni i Báwó ni òògùn dexamethasone ṣe ń ṣiṣẹ́ lára Wákàtí márùn ún márùn ún ní wọ́n ń fipá bá obìnrin kàn lò pọ̀ ní Nàìjíríà- Ọga Ọlọpaa Lẹ́yìn tí mo gbé ayé mi yẹ̀wò, mo ríi pé asán layé - Toyin Abraham Oríṣun àwòrán, facebook/godwin obaseki Ẹgbẹ́ òṣèlú PDP sún ìdìbò abẹ́nú Edo síwájú síi Obaseki: Ẹgbẹ́ òṣèlú PDP sún ìdìbò abẹ́nú Edo síwájú síi Ẹgbẹ oṣelu Peoples Democratic Party PDP nipinlẹ Edo to sun ọjọ idibo abẹnu fun awọn to fẹ dipo Gomina ni ipinlẹ naa siwaju.
Agbára wo ni mo ní,tí mo fi lè tún máa wà láàyè?
a lo àjẹsára bcg fún ìwòsàn fún ìgbà àkọ ́ kọ ́ ní ọdún 1921 .
Oyetọla sọ ọrọ yii lasiko ayẹyẹ ọdun mejidinlọgbọn ti wọn da ipinlẹ naa silẹ,O ni eto aabo ilẹ Yoruba jẹ Ohun logun.
Ọwọ́ tẹ babaláwo àti adigunjalè márùń ni Imo - Olọpàá Àwọn ọmọ ilẹ Indonesia ṣe ìwọ́de lóri fífòfin de ìbalòpọ ṣáájú ìgbéyàwó Kunle Afolayan, òṣìṣẹ́ báńkì tẹ́lẹ̀ kó tó di gbajúgbajà òṣèré Wọ àwòrán àwọn ẹbí òṣèré Nollywood yii!
Ajọ Lasema loju opo ikansiraẹni Twitter wọn ni awọn ọkọ nla to gbina naa gbe afẹfẹ gaasi wa si agbegbe naa ni ki o to gbina.
Sìgá mímu ń di èèwọ̀ oògùn ìlera pípé lagbaye Wọn si pinnu lati gbe e pada sileewosan to ti sa kuro.
Jesu ń rìn kiri ní apá ọ̀dẹ̀dẹ̀ tí wọn ń pè ní Ọ̀dẹ̀dẹ̀ Solomoni ninu Tẹmpili.
N óo mú òpin tí ó bani lẹ́rù dé bá ọ, o kò sì ní sí mọ́; bí ẹnikẹ́ni tilẹ̀ ń wá ọ, ẹnìkan kò ní rí ọ mọ́ títí lae.
williams butler yeats ( ; 13 june 1865-28 january 1939 ) je akewi ati onimo ninu litireso ede geesi .
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Year 2020: Iléri Àarẹ Buhari fún ọdún 2020 rèé 1 Sẹ́rẹ́ 2020 Oríṣun àwòrán, others Àkọlé àwòrán, Iléri Àarẹ Buhari fún ọdún 2020 rèé Ààrẹ Muhammadu Buhari ti tún fi dá àwọn ọmọ Naijiria lóju pé didun lọsan ọdun 2020 a so fun wọn.
Dokita Olanrewaju ni, lawọn ipinlẹ bii Kebbi, Sokoto ati Zamfara nibi ti awọn ijọba wọn ko ti kọ ibi ara si kikọ ile igbọnse, orisirisi aisan a ma ba awọn ara ilu finra.
” Nítorí ẹ̀ ń sọ pé, “Gbogbo àwọn tí wọn ń ṣe burúkú jẹ́ eniyan rere níwájú OLUWA, inú rẹ̀ sì dùn sí wọn.
, ogbontarigi onkọwe iwa ọdaran, Oladejo Okediji rele Ọpọ àwọn eniyan Naijiria lo n ṣe ilede lẹyin Oloogbe Oladejọ Okediji.
Ẹ̀ẹ̀kejì tí bàbá mi sì tún máa bojúwo ẹ̀hìn náà ńkọ́, ṣe ni ojú òuun àti obìnrin yìí tún ṣe dọ́gbadọ́gba – bẹ́ẹ̀ ni bàbá mi koì tí ì ní obìnrin, àpọ́nni, síbẹ̀síbẹ̀ náà, ó tún rọ́jú, ó ń lọ.
” Wọ́n sì gbáradì láti ṣe iṣẹ́ rere náà.
ogun eniyan ni o padanu emi won sinu isele ohun, bee si ni ile ogbon si ba isele
won ri awon ohun ija oloro bii ibon AK 47 ati kẹkẹ atapupu meji gba lọwọ wọn.
Ǹjẹ́ mo gba àbẹ̀tẹ́lẹ̀ lọ́wọ́ ẹnikẹ́ni rí?
O kere tan ile meji ti awọn eniyan n gbe, ileewe ati ile ijọsin lo wo ni ilu Akure lẹyin ti ibugbamu dun ni ipinlẹ Ondo.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ghana 2020 election: Jean Adukwei Mensa,Tani akíkanjú obìnrin tí yóò kéde èsì ìbò aàrẹ Ghana?
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Lizzy Anjorin vs Toyin Abraham: Kolawole Ajeyemi ní kò dára kí àwọn òṣèré máa bú ara wọn lórí ẹ̀rọ ayélujára 19 Owewe 2019 Oríṣun àwòrán, @willamazen Kolawole Ajeyemi, to jẹ ọkọ Toyin Abraham ti sọrọ lori aawọ to waye laarin iyawo rẹ ati ojugba rẹ ninu iṣẹ sinima, Lizzy Anjorin.
Àyẹ̀wò òkú tú àṣírí bí òṣìṣẹ́ NSCDC tí ọlọ́pàá lù ní Abuja ṣe kú Ìbọn ti kò lo ọ̀ta làwọn ọlọ́pàá a máa kọ́kọ́ yìn- IG Aarẹ orilẹede France, Emmanuel Macron ti ṣe ileri lati tun ile ijọsin naa ṣe lẹyin ina naa.
Ninu fidio naa Sanusi sọ ni ede Hausa pe ''Ọlọrun ti kọ wi pe oun yoo jẹ́ ọba Kano bẹẹ naa si ni akọsilẹ wa wi pe wọn yoo yọ oun.
Ẹni ti a bẹ lori to n sẹnu wuyẹ, kilo tun ku ti o sọ?
"Orilẹede Russia Russia ni gbogbo ara lòún fi lòdì si bi orilẹede Amerika se kọlu orilẹede Syria ""níbití orilẹede Russia ti n se ìrànlọ́wọ́ fun ìjọba to ba òfin mu lorilẹede Syria lati koju awọn ajìjàgbara."
Amọṣa ko tun pẹ pupọ ni iroyin miran ba tun lu igboro kan pe aisan to n ṣe agba oṣelu naa tun ti burẹkẹ sii koda wọn ti gbee si ẹka awọn alaisan tọrọ wọn le diẹ nileewosan aladani kan ti a ko ni fẹ darukọ nilu Eko.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Fadele: Dán an wò, lóbí ìyá ọ̀kẹ́rẹ́ ni a fi ọ̀rọ̀ ọ̀kadà náà ṣe Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Ki wọn wa fi ori ru aaru, amọ ọpọ wọn lo fi ọwọ osi ta ika oṣi danu pe, laalae, awọn ko le e ṣiṣẹ aaru gbigba.
Ẹyẹ àṣá kò mọ ipa ọ̀nà ibẹ̀,bẹ́ẹ̀ ni ojú gúnnugún kò tó o.
" Oríṣun àwòrán, oluwo of iwo Ọba Akanbi ni isẹ ti ń lọ láti ṣe agbelaruge àwọn aṣọ ìbílẹ̀ wá, èyí tí yóò fara jọ 'Jeans' oloyinbo, tí yóò sì tún wúlò fún wa lásìkò yìí tí ìlú Oyinbo kò ṣeé lọ fún wa mọ.
Nigba to n sọrọ lori iroyin yii, Ọmọwe Michael Head, lati fasiti Southampton ni irọ nla gba ni.
Ìwọ ni o fọ́ orí Lefiatani túútúú;o sì fi òkú rẹ̀ ṣe ìjẹ fún àwọn ẹranko inú aṣálẹ̀.
9 156964 Orilẹede Latvia 935 48.
Ọgbẹni Abba ṣalaye pe, iwadii si n lọ lori ẹsun ẹgbẹrun meje ati ojilelọdunrun (7,340) ninu ẹsun ti ajọ EFCC ri gba lọdun 2020.
Olúwarẹ̀ yóo joró ninu iná àjóòkú níwájú àwọn angẹli mímọ́ ati Ọ̀dọ́ Aguntan.
Ọ̀tẹ̀ tí Absalomu ń dì ń gbilẹ̀ sí i, bẹ́ẹ̀ sì ni àwọn ọmọlẹ́yìn rẹ̀ náà ń pọ̀ sí i.
Oru ọjọ Aje, ọjọ karundinlogun oṣu kẹfa ọdun 2020 ni awọn dọkita to n ṣiṣẹ nile ẹkọṣẹ iṣegun ni Naijiria bẹrẹ iyanṣẹlodi.
Jona gbadura sí OLUWA Ọlọrun rẹ̀ láti inú ẹja náà,
2 miliọnu lati ra ọkọ awọn eleto ilera Ambulansi.
Àṣírí tó ń bẹ láàrín Oluwo àtàwọn ọ̀dọ́ Iwo tí wọ́n fi fi ẹ̀mí wọn lélẹ̀ dáàbò bo ààfin rẹ̀ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Àjẹ́ ké lánàá, ọmọ kú lónìí ni ọ̀rọ̀ Tinubu àti ìṣẹ̀lẹ̀ Lekki Tollgate - Bode George Bi ifẹhonuhan Ali Must Go ṣe waye ree: Awọn akẹkọọ naa, to ṣe ipade nilu Maiduguri, Ilorin ati Calabar gbọnmu lori ele owo oúnjẹ naa, ti wọn si sọ fun ijọba lati yi ipinnu rẹ pada.
Nibayii, wọn yoo ma a san aadọjọ owo ilẹ okeere ($150), dipo ọgọsan dọla ($180) ti wọn n san tẹlẹ.
Lára ẹ̀kọ́ yi ni wi pe, ìwé kí kà ṣe pàtàkì, bi kò ti ẹ̀ si ìrànlọ́wọ́ lati ka ìwé ni ọmọdé, bi enia bá ka ìwé ni àgbà yio wúlò.
Oríṣun àwòrán, Reuters Àkọlé àwòrán, Niṣe ni ẹkun gba ẹnu awọn afgbabọọlu Cameroonlẹyin ti VAR fagile goolu ti wọn jẹ Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Egypt ṣíná fún Zimbabwe, ẹ̀kọ́ mẹ́rin tó yẹ ní kíkọ́ Super Falcons gòkè odò bọ́ sípele ìkẹrìndínlógún ní France Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Yóo dàbí ìgbà tí eniyan ń sálọ fún kinniun, tí ó pàdé ẹranko beari lọ́nà; tabi tí ó sá wọ ilé rẹ̀, tí ó fọwọ́ ti ògiri, tí ejò tún bù ú jẹ.
    Ìgbà tí a sì parí ogun yìí, gan-an ran ni a lọ sí òkè Ìrònù.
iye-nísirò akoran kokoro ga ni awọn orilẹ ede kan ni afrika ati asia .
Ọkọ Oloogbe Olakunrin ati ọkọ Toyota Camry kan ti ileeṣẹ akero The Young Shall Grow ni wọn da duro.
A kìí bómi ṣọ̀tá – ó ṣèwọ̀.
Ọti wiski ni wọn fi jẹ ounjẹ alẹ Oluwa dipo ẹjẹ Jesu.
Plateau Agbegbe Buruku ni awọn eeyan ipinlẹ Plateau ti ri ile ti ijọba ko awọn ounjẹ naa si, wọn si ji gbogbo rẹ ko daadaa.
Yóo gbógun ti ọ̀pọ̀ orílẹ̀-èdè, Ijipti pàápàá kò ní lè bọ́ lọ́wọ́ rẹ̀.
Wọ́n wà níbẹ̀ títí di òní olónìí.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Kí ni àmì ohùn 'Aguntaṣọọlo'?
Alhaji Alhassan Kabiru Rurum ni igbakeji abẹnugan ile Igbimọ asofin ki o to di pe  wọn yọ abẹnugan naa nipa iwa esun ti  wọn fi kan an lori iwa  sise owo ilu basu-basuLeyin oreyin ni awọn Igbimọ ti  wọn ni ko se iwadi esun naa , ni won  ri i pe ko jebi esun ti  wọn fi kan an.
Yóo pa wọ́n run nítorí ohun tí wọ́n fi ẹnu wọn sọ;gbogbo ẹni tí ó bá rí wọn ni yóo máa mirí nítorí wọn.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Beauty tips: Ṣé ẹ gbà pé obìnrin lè kun ojú láàrín ìṣẹ́jú mẹ́ta?
Ni bayii, France yoo koju iko agbaboolu ti o ba jawe olubori ninu ifigagbaga ti yoo laale oni laarin orile-ede Croatia ati England.
àwọn ọmọ Asina, àwọn ọmọ Meuni, ati àwọn ọmọ Nefisimu;
8 Lõtọ́, lõtọ́, ni mo wí fún ọ, àní bí ìwọ ṣe fẹ́ lati ọwọ́ mi bẹ́ẹ̀ gẹ́gẹ́ ni a ó ṣe é fún ọ; àti, bí ìwọ bá fẹ́, ìwọ yíó jẹ́ ohun èlò fún ṣíṣe ọ̀pọ̀ iṣẹ́ rere ní ìran yìí.
“A ni igbagbọ pe awọn eniyan wa le ṣe ohun ara ọtọ pẹlu ẹbun wọn, pẹlu atilẹyin wa loriṣiriṣi, bii ṣiṣe agbatẹru, ṣiṣe iṣẹ atilẹyin ilu ati awọn ojuṣe miiran”.
Iyàlẹ́nu ni ó jẹ́ fún mi pé nígbà tí kìnnìún náà ti kù bíi ẹsẹ̀ mẹ́fà kí ó dé ọ̀dọ̀ mi ni ó ti dúró tí ó bẹ̀rẹ̀ sí ké, ohùn rẹ̀ sì dàbí ìgbà tí ẹ̀ẹ́dẹ́gbẹ̀wá àpáàrà bá sán pọ̀ lójú ọ̀run lẹ́ẹ̀kan ṣoṣo.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù 2019 elections: Awọn jàǹdùkú yìnbọn f'éèyàn méjì nítorí owó ní Kwara 7 Ẹrẹ̀nà 2019 Àkọlé àwòrán, Ṣọ́ọ̀bù àti ọkọ lóríṣiríṣi ni wọ́n bàjẹ́ lásìkò tí àwọn agbébọn naa kọlu àdúgbò náà Nṣe ni ọrọ di pẹntuka, boolọ o yago fun mi nilu Ilọrin loru ọjọru mọ ọjọbọ ninu eyi ti eyan meji ọtọọtọ ti ṣe kongẹ ọta ibọn.
Ní ọdún kinni ìjọba Kirusi, ọba Pasia, kí àsọtẹ́lẹ̀ láti ẹnu wolii Jeremaya lè ṣẹ, OLUWA fi sí Kirusi ọba lọ́kàn láti kéde yíká gbogbo ìjọba rẹ̀ ati láti ṣe àkọsílẹ̀ rẹ̀ pé: 
Dajudaju, wọn yoo kawọ pọnyin rojọ.
Nígbà tí ó tọ́ ọtí náà wò, ó pàṣẹ pé kí wọn kó àwọn ife wúrà ati ti fadaka tí Nebukadinesari, baba rẹ̀, kó wá láti inú tẹmpili ní Jerusalẹmu jáde, kí òun, ati àwọn ìjòyè òun, àwọn ayaba ati àwọn obinrin òun lè máa fi wọ́n mu ọtí.
Ọgagun Komolafe kilọ fawọn ọdaran to wa ni ipinlẹ Ekiti pe ki wọn lọ tọwọ ọmọ wọn bọ aṣọ nitori Amotekun ti gberasọ.
Nítorí náà Jehoramu ati àwọn ọ̀gágun rẹ̀ ati àwọn kẹ̀kẹ́ ogun rẹ̀ lọ gbógun tì wọ́n.
Bo ṣe ka sọ nipa itu to pa lorileede rẹ ni Argentina ni , tabi bo ti ṣe ko ipa ribiribi biwọn ti ṣe gba ife ẹyẹ agbaye, igbe aye Maradona kun fun manigbagbe itan.
Díaz jẹ́ ajábọ̀ ìròyìn àti a-jà-fún-ẹ̀tọ́-ọmọ ènìyàn tí ó jẹ́ ògbólógbòó ajàfúnẹ̀tọ́ òmìnira ọ̀rọ̀ sísọ tí wọ́n sì mọ ìṣe rẹ̀ fún un l'órílẹ̀ èdè Venezuela àti òkè òkun fún ìdásọ́rọ̀ àti ìtakò ìjọba Nicholas Maduro.
Àwọn olùfọkànsìn sin òkú Stefanu, wọ́n sì ṣọ̀fọ̀ pupọ lórí rẹ̀.
Aare Naijira nigba kan ri, Oloye Olusegun Obasanjo, lo sipinle Bayelsa latilo ba won se ifilole ibudo ayewo tuntun.
Gbogbo orin egúngún bìkiafù tí wọ́n kọ sí mi l'étí nípa Ajayi tí mi o gbọ̀ ló bu mí lọ́wọ́- Akeredolu Awọn akẹgbẹ rẹ ọhun, Nehemiah Adejoh, Igbekele Folorunsho ati Festus Gbayegun wa ọkọ ayọkẹlẹ Kia Sorento to ni nọmba idanimọ AZ 478 MKA kọja lẹgbẹ rẹ.
Ọjọ́ kẹẹdogun oṣù náà ni ọjọ́ àjọ̀dún, ẹ óo máa jẹ burẹdi tí kò ní ìwúkàrà fún ọjọ́ meje.
ile-ise eto irinna ọkọ yoo maa tele ni ibamu eto ilana ile-ise naa, ni eyi ti
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Taiwo Bamidele Ondo Dwarf Judge: Ọlọ́run kò ṣe àṣìṣe pé ó dá mi ní aràrá Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Taiwo Bamidele Ondo Dwarf Judge: Ọlọ́run kò ṣe àṣìṣe pé ó dá mi ní aràrá 14 Owewe 2020 “Gbogbo awọn ti wọn bi ṣiwaju mi lo ga to sin gbọnlẹ!
India Wedding: Ìyàwó kan ní India wọ sòkòtò fún ayẹyẹ ìgbéyàwó rẹ̀- Wo ìdí tó fi ṣe bẹ́ẹ̀
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Kí ló dé tó jẹ́ sọ́ọ̀sì nìkàn ni ìjọba ń tìlẹ̀kùn mọ́ torí Covid-19?
 orí méje ni ìwé náà ní .
Ṣugbọn àwọn eniyan mọ̀, ni wọ́n bá tẹ̀lé e.
Ṣugbọn, itọju naa yoo jẹ nipa oogun lilo tabi iṣẹ abẹ.
orilẹ-ede nla, a gbọdọ ni awọn awomọ bayii ninu awọn iwa wa, ki a si maa
Ọjọ 28, Osu Keji Akowe gbogboogbo fun Ajọ Agbaye (UN), Antonio Guterres bu ẹnu atẹ lu ijinigbe awon ọmọ Dapchi naa.
Ilé ẹjọ́ pàṣẹ kí Sẹ́nétọ̀ Elisha Abbo san N50m fún obìnrin tó fìyà jẹ Mi o fi ìgbà kankan sọ pé Buhari ni yóò jẹ ààrẹ kẹ́yìn ní Nàìjíríà- Akintoye Wo àwọn olóríire tó borí nílé BB Naija sẹ́yìn àti iye òjò owó tó rọ̀ fún wọn Iroyin latẹnu awọn akọroyin iwe iroyin abẹle kan ṣalaye pe igbiyanju Chris afurasi naa lati sa mọ ofin lọwọ lo bọ si pabo pẹlu bi awọn ara adugbo ṣe mu u ti wọn si lu u bi ẹni maa ku .
Ní ti Ekiti, ìjà tó tẹ̀lẹ̀ ètò ìdìbò April 14 ọdún 2007 lo fi di ọrọ ile ẹjọ́ tó ń ri si awuyewuye tó súyọ lẹ́yìn ìdìbò, (Tribunal).
awon alatileyin re ,kuro ninu egbe All Progressives Congress (APC) lo sinu egbe
Laarin ọsẹ mẹwaa ti wọn yoo lo ni ile naa, ẹgbẹgbọn agba, iyẹn Big Brother yoo maa fun wọn ni iṣẹ kan tabi omiran lati ṣe.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ẹṣọ oju-popo ti a ba ri ju 500 naira lọwọ re wọ gau Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Ẹṣọ oju-popo ti a ba ri ju 500 naira lọwọ re wọ gau 19 Ẹrẹ̀nà 2018 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 1 Èbibi 2020 Ọga awọn ẹṣo alaabo oju popo kan ti ke si awọn ọlọkọ ati awọn arinajo wi pe ki wọn pa ofin ọna mọ.
agbofinro lati wa ojutuu si eto aabo to n se sege-sege bi ẹsẹ telọ lorile ede
Orin náà tilẹ̀ tọ̀ka sí oríṣiríṣi ọ̀nà tí àwọn apani-lẹ́kún ọ̀hún n gbà ṣiṣẹ́ wọn.
Ofin to rọ mọ aran ma gbigba ati oriṣii Aranmọ mẹrin to wa wa lara koko ti a gbe yẹwo lonii pẹlu apẹẹrẹ.
Ekeji ni pe, nitori pe o jẹ ọmọ Ọba, o ni iru awọn eeyan to le e wa nibi ifari rẹ.
Nígbà tí àwọn eniyan náà gbọ́ bí ààrá ti ń sán, tí wọ́n rí i bí mànàmáná ti ń kọ, tí wọ́n gbọ́ dídún ìró fèrè, tí wọ́n rí i tí òkè ń rú èéfín, ẹ̀rù bà wọ́n, wọ́n sì wárìrì.
A tun ni ọgọta sẹnetọ lọdun 2015, nibayii mẹtadinlọgọta la ni."
Nigba to n fesi awọn ọrọ awọn akopa naa, Aṣofin Ọbasa fi da wọn loju pe Ile Igbimọ Aṣofin naa yoo tẹ siwaju lati daabo bo ifẹ awọn ara ilu.
Ìwọ tí o faraya nítorí inú ń bí ọ,ṣé kí á sá kúrò láyé nítorí rẹ ni,tabi kí á ṣí àwọn àpáta nípò pada?
Ojú OLUWA ń ṣọ́ ìmọ̀ tòótọ́,ṣugbọn a máa yí ọ̀rọ̀ àwọn alaigbagbọ po.
Siwaju si,  ikolu ibugbamu ado oloro miiran tun waye, eleyi ti o sekupa ara ilu merin ti awon marun un miiran si farapa yanayana, laarin oja agbegbe Bulomarer ni ekun gusu iwo oorun Mogadishu.
Sowore pàtẹ ìfẹ̀hónú hàn míì lónìí Èèyàn 78 kú ó lé ní 4000 tó farapa níbi ìbúgbàmù tó wáyé ní Beirut, Lebanon Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Ìyìn irú ẹni bẹ́ẹ̀ wà lọ́dọ̀ Ọlọrun, kì í ṣe ọ̀dọ̀ eniyan.
Ẹgbẹ́ òṣèlú APC tí lé gómìnà ìpínlẹ̀ Ekiti, Kayode Fayemi kúrò ní APC Eèyàn 174,574 ló ti forúkọ sílẹ̀ fún ètò ìrànwọ́ ìjọba fáwọ̀n olókoòwò kéékèèké- Ìjọba Nàìjíríà Kò sí iléẹjọ́ tó le dá wa dúró, ìyanṣẹ́lódì yóò bẹ̀rẹ̀ ní Ọjọ́ Ajé - NLC Oúnjẹ́ aṣaralóòre nìkan kò tó ò tí o bá n gbèèrò láti lóyún tàbí tí ó bá lóyún Bakan naa ni wọn ṣeleri pe iyanṣẹlodi wa lara irinṣẹ ti awọn yoo lo lati fi ẹhonu awọn han lori awọn igbesẹ ijọba naa.
 lára àwọn ómọ tó bí fun ni ' ogborogannida ' tí ó oadà di Ọbanta ; lénúwà tí ó di Óba Òde omi , àti líken tì òun náàpadà di Ọba Ìwòpin létí Ọ ̀ sà .
 bíi bílíọ ́ nù ènìyàn ni o ń gbé ní agbègbè àgbayé níbi tí àrùn náà ti wọ ́ pọ ̀ .
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Mobile Wash: iṣẹ́ fífọ́ mọ́tò tà ni mó yàn láààyò- Slay Mama Invictus Obi, Hushpuppi, àwọn ọ̀dọ́ Nàìjíríà méjì tí ẹ̀sùn gbájúẹ̀ wà lọ́rùn wọn Ajọ to n koju iwa jẹgudujẹra lorilẹede Naijiria, EFCC ti ni Ramoni Igbalode, alias Ray hushpuppy ni ẹjọ lati jẹ ni ọdọ wọn.
A ti gbà á bí ojúṣe wa pé àkọ́so èso ilẹ̀ wa ati àkọ́so gbogbo èso igi wa lọdọọdun, ni a óo máa gbé wá sí ilé OLUWA.
Ọ̀rọ̀ àjakalẹ-àrun Coronavirus to gbòde yìí, tó ń pá ọmọdé àti àgbà, ọkùnrin at obìnrin, aláwò funfun àti dúdú, kò jẹ tuntun rárá nítorí ìgbà èyí kii ṣe akọkọ tí irú àjakalẹ-àrun báyìí yóò wáyé yíká agbaye.
 Èyí táwọn ti fi àsìkò wọn ṣòfò lóró ọ ̀ rọ ̀ jìjì tit ó gẹ ́ ẹ ́ , alu-dùndùn kì í dárin .
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Jide Kosọkọ: Isẹ́ tíátà yóò gòkè tíjọba bá gbówó kalẹ̀ láti seré Fun ọjọ mẹrin, iwe iroyin Daily Monitor fabọ jẹni pe Sheikh Mutumba ko tii si nile.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Mercy Aigbe: Àwọn òṣèré tíátà Yorùbá mẹ́wàá tí kìí ṣe Yorùbá 5 Òkùdu 2020 Oríṣun àwòrán, others Agbo nla ni ẹka awọn oṣere tiata ni ede Yoruba, ti wọn si ni ogunlọgọ awọn oṣere tiata ti ko see fi ọwọ rọ danu.
leventis lọ sí ilé -ẹ ̀ kọ ́ mitsis commercial school nígbà tí ó pé ọmọ ọdún mẹ ́ rìndínlógún ( 16 ) , ó ṣàtìpó lọ sí ilẹ ̀ farasé láti lọ wá iṣẹ ́ àtí láti ẹkẹ ́ kọ ̀ ọ ́ .
"O ni, ""Mo fi da yin loju wipe ijọba ko ni duro fun iyanṣẹlodi ki a to ṣe oun to dara fun ara ilu."
Ajọ eleto idibo INEC, kede ni oru ọjọbọ pe Fintiri lo gbegba oroke , lẹyin atundi ibo to waye ni awọn ijọba ipinlẹ kan nipinlẹ naa.
Femi Joseph sọ pe ni nkan bi aago meji ọsan ọjọ Ẹti, ọjọ kejila, oṣu Keje ni iṣẹlẹ naa waye.
N óo fún ọba Babiloni lágbára, n óo sì fi idà mi lé e lọ́wọ́; ṣugbọn n óo ṣẹ́ Farao lápá; yóo máa kérora níwájú rẹ̀ bí ẹni tí a ṣá lọ́gbẹ́ tí ó ń kú lọ.
Àwọn ará South-Africa yarí nítorí torí gbọ̀ngàn kọ̀ ìgbéyàwó abo-sábo Oyinbo naa to jẹ alase n ṣiṣẹ nile ounjẹ orilẹ-ede Afghanistan kan nilu California, sọ pe oṣu to n bọ ni oun yoo pada si America, ki oun tun to o pada wa ni oṣu Kẹta fun igbeyawo naa.
Aago mẹjọ aabọ alẹ ọjọ Iṣẹgun ni awọn ọlọpaa to n gbogun ti ijinigbe ni Ipinlẹ Eko da Ayodeji Obadimeji to jẹ ọmọ ọdun mejidinlogun ati ẹgbọn rẹ Saheed Obadimeji duro ni opopona Ajah si Ẹpẹ nilu Eko.
Iroyin to gbalẹ kan lẹyin ti fidio naa jade sori ayelujara ni pe, oṣiṣẹ aṣọbode kan lo yinbọn pa ọkunrin naa to jẹ ọkan lara awọn ero ọkọ bọọsi to n rinrinajo ni opopona Ọ̀rẹ̀ si Benin, nitori owo.
tabi ẹni tí ó bá fara kan èyíkéyìí ninu àwọn ẹ̀dá alààyè tí ń káàkiri, èyí tí ó lè sọ eniyan di aláìmọ́, tabi ẹnikẹ́ni tí ó lè kó àìmọ́ bá eniyan, ohun yòówù tí àìmọ́ rẹ̀ lè jẹ́.
U si dipo kefa won mu pelu ami mẹ́rìnlélọ́gọ́ta lori tabili, ti o tun mo si pe, ti
Bí olódodo bá yipada kúrò ninu ìwà òdodo rẹ̀, tí ó bẹ̀rẹ̀ sí dẹ́ṣẹ̀, yóo kú nítorí ẹ̀ṣẹ̀ tí ó dá.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Oronsaye reports: Kí ló wà nínú àbájáde ìwádìí ìgbìmọ̀ Oronsaye gan an tó ń kó ọ̀pọ̀ òṣìṣẹ́ láyà sókè?
Ewe, niseju mẹ́tàdínllọ́gọ́ta  saa keji ifesewonse naa, Marco Asensio gba ami ayo miran wole leyi ti o ran iko re lowo lati jawe olubori ninu ifigagbaga naa.
Samsoni dá a lóhùn pé, “Bí wọ́n bá fi awọ tí wọ́n fi ń ṣe ọrun, tí kò tíì gbẹ meje dè mí, yóo rẹ̀ mí, n óo sì dàbí àwọn ọkunrin yòókù.
Àpáta mi ati ìgbàlà mi,ààbò mi ati ibi ìpamọ́ mi,olùgbàlà mi, ìwọ ni o gbà mí lọ́wọ́ ìwà ipá.
"Omotosho ni, ""EFCC n fi oju ẹtọ mi gbolẹ wọ́n si n halẹ mọ mi."
Sultan ti ilu Sokoto ṣe ikede yii lori Redio ati Tẹlifiṣan kan ni ilu Sokoto lẹyin ti wọn ri oṣu to le fun oṣu Shawwal.
Ṣowore to sọrọ yii nipaṣẹ agbẹjọro rẹ, Femi Falana ni bi ajọ DSS ṣe ti oun mọ le lodi si ẹtọ oun gẹgẹ bi iwe ofin orilẹede Naijiria ṣe laa kalẹ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Mummy calm down: Ìyá Ore sọ pé gbogbo ìgbà tí óun bá n bá a wí ló ma n ṣe àwàdà Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Mummy calm down: Ìyá Ore sọ pé gbogbo ìgbà tí óun bá n bá a wí ló ma n ṣe àwàdà 1 Ògún 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 2 Ògún 2020 Laarin ọsẹ to kọja ni di ilumọọka, lairo tẹlẹ.
Ìwọ ní tìrẹ, wá máa waasu ìjọba Ọlọrun.
Wọn fi kun un pe lootọ lawọn araalu lẹtọ lati se iwọde wọọrọwọ, ko si si ijọba kan to lee tako eyi.
Igbagbọ Ozo ni pe ko si ohun ti eeyan ko lee ṣe to ba ti ni igbagbọ.
Bí àpẹẹrẹ, ẹ wo àwọn ọkọ̀ ojú omi.
Nǹkan burúkú tó yani lẹ́nu,ní ń ṣẹlẹ̀ ní ilẹ̀ náà:
O rọ awọn akẹgbẹ pe ko tọ si ẹnikankan ninu awọn ki ẹnikeji maa dun koko mọ ọ loju opo ayelujara ara wọn.
"Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ọba Adesoji Aderemi, Ọọ̀ni Ifẹ̀ tó gba ipò ọba mọ́ tòṣèlú MKO Abiola, iṣẹ́ aṣẹ́gità ló fi bẹ̀rẹ̀ okoòwò Iṣọla Oyenusi rèé, ẹnití ìfẹ́ obìnrin ṣun dé ìwà ìdigunjalè Ayinla Ọmọwura, orin èébú àti oríyìn lo fi di ọ̀rẹ́ àwọ̀n obìnrin ""Gbogbo wa la n lọgun pe awọn Fulani lo n yọ agbegbe wa lẹnu, sugbọn kii se gbogbo Fulani rara, awọn kanda kan ninu irẹsi to wa laarin wọn ni, awọn si la fẹ le jinna si sakani wa, ta si ri daju pe alaafia ati idajọ ododo jọba ni Naijiria."
ìnàkunà ni Arsenal na ojúgbà rẹ ti Frankurt.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù CAN: Ó pọn dandan kí wọn fágile ìdánwò ọlọ́pàá 29 Èbibi 2018 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 30 Èbibi 2018 Oríṣun àwòrán, Dan Kitwood Àkọlé àwòrán, Ẹ́ fágile ìdánwò ọlọ́pàá Agbarijpọ ẹgbẹ awọn onígbàgbọ́ ni orílẹ̀-èdè Nàìjíríà (CAN), tí ké gbànjarè pé, kí àjọ ọlọ́pàá fagilé ìdánwò gbogbo-gboo fún ìgbanisíṣẹ́ to wayé láìpẹ́ yìí jakèjádò Nàìjíría.
ẹ mú àwọn mejeeji jáde wá sí ẹnubodè ìlú, kí ẹ sì sọ wọ́n ní òkúta pa.
Ọ̀nà tí ọba Asiria gbà wá ni yóo gbà pada lọ, kò ní fi ẹsẹ̀ kan inú ìlú yìí.
Se ni Oyenusi n laagun lakọlakọ lasiko ti wọn fi ọkọ ẹlẹwọn black Maria ko oun ati awọn ẹmẹwa rẹ de, amọ o n rẹrin, rẹrin titi ti wọn fi fi okun so mọ agba, amọ o nira fun lati fi ẹrin musẹ bo ibẹrubojo ati abamọ to loju rẹ, tawọn ologun si yinbọn fun lẹyin o rẹyin.
Funke Akindele ti di ìyábejì ni ọdun melo kan sẹyin.
Amofin - BBC News Yorùbá BBC News, YorùbáFò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Tiamiyu Kazeem: Ọlọ́páà kò lẹ́tọ̀ọ́ láti fìyà jẹ ará ìlú tó bá wọ aṣọ ológun - Amofin 24 Èrèlè 2020 Oríṣun àwòrán, @others Amofin kan, Banjo Ayenakin ti sọ pe ọlọpaa ko lẹtọ labẹ ofin lati fiya jẹ ẹnikẹni ti wọn ba gbamu pe o wọ aṣọ ologun ti kii si n ṣẹ ọmọ ologun.
Mo bi í pé, “Níbo ni ò ń lọ?
A máa jẹ́ ìyàlẹ́nu fún gbogbo ẹni tó lọ síbẹ̀ nígbà tí kìí ṣe àsìkò tí àwọn òdòdó máa ń ṣábàá yọ.
Àwọn olóyè kan ninu wọn bi Modekai léèrè pé, “Kí ló dé tí o fi ń tàpá sí àṣẹ ọba?
Ko pẹ ti wọn fi Ekugbemi silẹ ni ọgbà ẹ̀wọ̀n Agodi nilu Ibadan, ni wọn pa a.
Ìlé ẹjọ́ ti pàṣẹ pé kí ilé iṣẹ́ ọ̀lọ́pàá dá ìgbaniwolé dúró Ṣé àbáwọle sójú òpó NPF policerecruitment.
"Ohunkohun to ba yan, ki n kan ṣaa ti fun un ni ibukun baba ni""."
Lẹ́yin náà ni àwọn ọlọpàá de ti wọ́n sì da ìbọn bolẹ̀ àwọn ọlọpàá to dé ibẹ̀ Awọn ọlọpàá ti gba àwọn ènìyàn ni ìyànjú pé ki maa tẹ̀lé ìlànà ti àwọn ọlọpàá fi lélẹ̀.
Ó ku ọjọ́ díẹ̀ kí ìwọ́de náà ó kò, ajàfúnẹ̀tọ́ ọmọ orílẹ̀-èdè Angola Pedrowski Teca sọ wípé ìwé ẹ̀rí ọmọ-ìlú-fún-ìrìnná pọn dandan ju ìwé ìdánimọ̀ pélébé lọ, ó rọ àwọn ènìyàn láti kọ́wọ̀ọ́ rìn, nítorí àìkọ́wọ̀ọ́ rìn, ní í ṣe ikú pa ọmọ ejò:
Naira Marley rọ awọn ọmọ Naijiria lati ṣe iranwọ fun ileeṣẹ ọlọpaa nipa pipese awọn ohun elo ti wọn nilo lẹnu iṣẹ.
 orin ayẹyẹ ni orin àpàlà , orin ìgbàlóde ni pẹ ̀ lú .
Èmi fẹ́ gùn ún dókè pátápátá.
Oríṣun àwòrán, Others Igbesẹ wo lo nṣaaju ki eeyan to le ni iwe aṣẹ lati gbe ibọn?
Ranti lati tẹ ẹ boya ẹka ileefowopamọ rẹ lo ti fẹ gba owo tabi ileefowopamọ mii.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Inu mi bàjẹ́ nígbà tí mo bí i, odidi oṣù mẹ́ta, mi ò lè gbàdúrà s'Ọ́lọ́run' O ṣalaye pe, awọn to gbẹbi ọmọ naa sọ pe ko kè é, bẹẹni ko mí.
 * Ṣíṣàgbéyẹ ̀ wò fiímù Àgbéléwò .
Irun orí ẹnikẹ́ni kò tilẹ̀ ní ṣòfò.
Ọpọ awọn ọmọ ijọ Jesu Oyingbo lo n ta ohun ini wọn, wọn pa awọn mọlẹbi wọn ti lati dara pọ mọ 'Olugbala' wọn Lọdun 1959 gan ni Odumosu kede ara rẹ bii Jesu, o se adinku iwaasu rẹ, to si dawọle ọpọ okoowo sise lati fi gbọ bukata Jerusalem tuntun to dawọle.
Oríṣun àwòrán, others Ni Ọjọbọ ni oludari agba ajọ to n gbogun ti ajakalẹ arun lorilẹede Naijiria, Dokita Chikwe Ihekweazu pariwo faye gbọ pe ipenija to ga julọ ti eto kikoju ajakalẹ arun COVID-19 n koju ni aisi iye ibusun to to lawsn ibudo itọju awọn alaarun naa ni ipinlẹ Eko.
Police Recruit - N108, 233 2a.
Bakan naa, Iyiola Omisoore n jade lati ẹgbẹ oselu Social Democratic Party (SDP), nigba ti Fatai Akinade Akinbade, yoo ma di je du ipo labẹ ẹgbẹ oselu African Democratic Congress (ADC).
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Stray Bullet: Bàbá ọmọ ni ogún náírà péré ni àwọn ọlọ́pàá fi lọ òun àmọ́ òun kò gbàá O wa rọ awọn agbofinro lati ri daju pe wọn ko maa gba owo mọ lọwọ awọn ọlọkada, bẹẹ si ni gbogbo awọn asaaju ẹgbẹ onimọto tijọba ti fofin de ko lẹtọ mọ lati maa gba owo lọwọ awọn awakọ ati ọlọkada.
Iwe naa lo wa lati ran wọn leti ileri wọn pe, awọn yoo ja fun aise idajọ ododo lori ọrọ to kan obinrin, ti wọn yoo si ri daju pe ibaradọgba ati ironilagbara wa fawọn obinrin ati ọdọbinrin ko to di ọdun 2030.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ondo:Igbìmọ̀ eré ìdárayá di títúká 2 Èrèlè 2018 Oríṣun àwòrán, facebook/Saka Yusuf Ogunleye Àkọlé àwòrán, Saka Yusuff Ogunlẹyẹ ni ijọba ipinlẹ Ondo nla kaka lati mu igbega ba ere idaraya ni.
Itara mi fun ipinlẹ Imo si ti sọ mi di ẹni ti ori rẹ ko pe, nitori o wumi lati yi gbogbo nnkan pada ni kiakia.
Ẹ̀mí 18 ṣòfò ní Òpópónà Akure sí Ọwọ Iba Gani Adams jẹ ko di mimọ pe Kò sí ìdàmú ìlú tó kọjá ọjọ́ mẹ́ta láì lọ́wọ́ ìjọba nínú.
Ati tọmọde-tagba ni oun maa n da lẹkọ lori ere idaraya naa ni Naijiria.
Àwọn ìròyìn mìíràn tí ẹ lè nífẹ̀ẹ́ sí: Ìtàn ìgbé ayé Abdulrahman Abdulrazak, gómìnà Kwara Ìtàn ayé Seyi Makinde, gómìnà tuntun ní Ọ̀yọ́ Wo àwọn ìlérí tàwọn Gómìnà tuntun ṣe nínú ìbúra wọn Ohun tó yẹ kí o mọ̀ nípa OIC rèé Dapọ Abiọdun ree, ẹni tó dépò gómìnà ní àyájọ́ ọjọ́ ìbí rẹ̀ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Àgbà ni Obasanjo, oun tó ń sọ yé e, ìjọba ni kó tají - Wale oke Ọpọ awọn ọmọ Naijiria lo n kọminu lori bi ijọba ṣe n san iru owo bayii lai nii fi ṣe awọn ibo miran ti wọn gab pe o le ṣe anfaani ti wọn ba naa sibẹ.
Ó ti pa gbogbo ààfin rẹ̀ run,ó sọ àwọn ibi ààbò rẹ̀ di àlàpàó sì sọ ọ̀fọ̀ ati ẹkún Juda di pupọ.
Ṣebí gbẹ́nàgbẹ́nà ni, ọmọ Maria, arakunrin Jakọbu, ati Juda, ati Simoni?
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Wọ́n gún ọkùnrin kan lọ́bẹ pa torí ó tako yínyin báńgà sínú Mọ́ṣálásí Ìjọba kéde ọjọ́ tuntun fún ṣíṣí afárá Third Mainland Bridge Àwọn àṣà tó milẹ̀ lọ́dún 2020 pẹ̀lú ìtàn lórí bí wọ́n ṣe jáde Kò bá wù mí kí n padà sí àwọ̀ tí Ọlọ́run dá mi, wàhálà ni ara bíbó - Bobrisky Nàíjíríà yóò gbóná janjan lẹ́yìn ìbò ààrẹ 2023 àyàfi.
 Àwọn olùsìn ifá lọ ́ kùnrin ni a mọ ̀ sí .
Kí alaafia ó wà ninu rẹ,kí ìbàlẹ̀ àyà wà ninu ilé ìṣọ́ rẹ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fọ́nrán ohùn, Pius Adesanmi ní Wole Soyinka ìran yìí - ọmọ Naijiríà Wọn ní akikanju ẹdá ni ọjọgbọ́n Adesanmi, ẹni to ṣetan láti jàjà ominira fun ilẹ adúlawọ nípa kíkọ ìwe ati ṣise ìlanilọye fun àwọn ọdọ.
Níbi ìpàdé àtilẹ̀kùnmọ́rí ṣe ọ̀hún, àwọn lọ́ba lọ́ba wà níbẹ̀ tó fi mọ́ olùgbani nímọ̀ràn àgbà fún gómìnà lórí ìṣe dára dára, ọ̀mọ̀wé Isaac Ayandele.
Bakan naa, Olori Badra ti si ile itaja asọ nla kan si adugbo Ikeja nilu Eko ninu ọdun 2020 yii, eyi to tun n mu kawọn eeyan maa ni ilu Eko ni Ayaba Badra n gbe bayii, kii se Oyo mọ.
Ojogbon Oluṣola Eleka (PDP) ni wọn jọ dije pẹlu awọn miran ni Ekiti.
Ko wa duro nibi igbesẹ orilede Amẹrika nikan o, awọn eekan ni Naijiria da si ọrọ naa.
Oríṣun àwòrán, Facebook/SenatorIbikunleAmosun Àkọlé àwòrán, Gomina Ibikunle Amosun ko awọn alase ijoba sodi lo si awọn agbegbe ti isẹle naa kan.
Sẹnetọ Ahmed Lawan ni iye awọn ologun to ti fiṣẹ silẹ ti to igba bayii wọn si ni awọn yo tọpinpin bi iru nkan bayii ṣe ṣẹlẹ.
Ẹkún ati ìpayínkeke yóo wà nígbà tí ẹ bá rí Abrahamu ati Isaaki ati Jakọbu ati gbogbo àwọn wolii ní ìjọba Ọlọrun, tí wọ́n wá tì yín mọ́ òde.
ikinikaabọ rẹ, Alaga Igbimọ to n moju to Iṣuna owo ilu ninu Ile Igbimo Asọfin
"Awọn ibudo miran ti Buratai tun s'abẹwo si ninu igbo Sambisa ni Bita ati Tukumbere, ti gbogbo awọn adunkoko mọni ti fẹsẹ fẹẹ nibẹ Ọmọ ẹgbẹ Boko Haram ogun gba'dajọ ẹwọn Idaamu Boko Haram: Igbẹjọ awọn afunrasi bẹrẹ ni gbangba loni ""Ẹ jẹ ki n ki yin ku oriire, amọ o yẹ ka kọja lọ s'ibiti ọkunrin ọdaran yi, Shekau wa, ka si mu laaye."
Ó fẹ́rẹ̀ tó àkókò Àjọ̀dún Ìrékọjá, tíí ṣe àjọ̀dún pataki láàrin àwọn Juu.
Oríṣun àwòrán, Lizzy Anjorin Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Asofin Nicolas, to n soju fun ipinle Delta lo dari oro yii lati pe akiyesi igbimo asoju pe igbese ti ijọba apapo fe gbe lori ase lodi si ofin orile ede Naijiria, ati pe o tun jẹ  ojuse ile igbimo asoju -sofin.
Ọlọrun kò jọ eniyan tí máa ń purọ́,bẹ́ẹ̀ ni kì í ṣe eniyan tí máa ń yí ọkàn pada.
Mo dúpẹ́ lọ́wọ́ Ọlọrun nítorí mò ń sọ ọpọlọpọ èdè àjèjì ju gbogbo yín lọ.
20 Ìgbé 2019 Oríṣun àwòrán, thecable.
Ijoba tiwantiwa, ijoba araalu, ti yoo pa araalu lẹrin ni awọn yoo ṣe.
Orilẹede Naijiria si lo faragba ọpọ ikọlu naa julọ lọdun 2016 ati 2017, ti ipinlẹ Borno si jẹ ilu abinibi awọn adunkoko mọni ọhun, ti wọn n dojukọ julọ.
  “Isele yii gbọdọ jẹ ki a se ara
kinni 2019 fun ojuse ati iwa akin ti won ko lorile ede Naijiri,a lasiko ti won
Yóo sì máa fi sùúrù da àwọn tí wọn lọ́mọ lẹ́yìn láàrin wọn.
Mo fẹ́ kí ẹ mọ̀ pé láti ọjọ́ tí a ti ń ránṣẹ́ yìí, onísẹ́ wa pàápàá kì í fi ojú rí ọba náà, ṣe ni wọn máa ń jíṣẹ́ fún un tí ẹni tí a bá ran náà máa ń ránṣẹ́ wọ ààfin lọ bí a si ṣe rí ọba yóò yà yín lẹnu.
Ẹ san ₦200,000 fún Sowore lórí bí ẹ ṣe ń fi ẹjọ́ falẹ̀ - Iléẹjọ́ pàṣẹ fún ìjọba Ìdí tí àwọn ọmọ Nàíjíríà ṣe ń pariwo lé Buhari lórí lójú ayé àti lórí ayélujára Ẹ̀yin ọba alayé, ẹ mà ń dákẹ́ pọ̀ lórí ààbò tó mẹ́hẹ ní Nàíjíríà - Sultan figbe ta Láì lọ́wọ́ ẹ̀yin aráàlú nínú, yóò nira fún Boko Haram láti ṣọṣẹ́ - Buhari sọ fáwọn èèyàn Borno Nigba to si n fidi isẹlẹ naa mulẹ fun BBC Yoruba, Igboho ni lootọ loun dide lati gbeja awọn eeyan oun ladugbo Soka,nitori adugbo naa ni oun n gbe, ikọlu awọn ọmọ onilẹ si awọn mẹkunnu to wa nibẹ si ti n di lemọlemọ bayii.
5m, N8bn tí wọ́n kó pamọ́’ Ṣé ìwọ mọ̀ pé Funmilayọ Ransome- Kuti ni obìnrin àkọ́kọ́ ti.
"Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Akomolede ati Asa Yoruba: Kí ni ""Future tense"" lédè Yorùbá?"
kí n lè kọrin ìyìn rẹ,kí n sì lè yọ ayọ̀ ìgbàlà rẹ lẹ́nu ibodè Sioni.
Oun ni ọba alaye akọkọ ti yoo pa ipo ọba mọ sise olootu ijọba lẹkun Iwọ Oorun Guusu Naijiria ijọhun.
Bi o tilẹ jẹ pe ogun ọdun niyi ti Oyetọla ti n ṣe oselu, igba akọkọ ni yii ti yoo ma a dije du ipo labẹ ẹgbẹ oṣelu kankan.
Mi ò to iṣẹ́ Regina Daniels rárá kí n tó fẹ́ ẹ láàrin ọ̀sẹ̀ mẹ́ta, mo sì tún le fẹ́ ìyàwó míì - Ned Nwoko Ìwé àkàgbádùn láti ọwọ́ Fagunwa, Faleti, Iṣọla, Ogunniran àti Okediji tó yẹ kí o kà lásìkò yìí.
Awon alase ile-ise oko oju ofurufu orile-ede Uganda so pe, awon ti bere iwadii lori isele naa.
Ọna ati gbe aṣa ilẹ wa larugẹ ti Femi Adebayo gbe yọ ninu imura tirẹ ati ọmọ ọlọjọ ibi ti wọn jọ fọ si agbada aṣo oke ibilẹ Yoruba jẹ ohun to wu awọn ololufẹ rẹ lori jọjọ́.
Láti Haserotu wọ́n lọ sí Ritima.
Èéṣe tí ẹ fi jí ife fadaka ọ̀gá mi?
Ẹ̀yà Manase ni yóo pàgọ́ tẹ̀lé ẹ̀yà Efuraimu; Gamalieli, ọmọ Pedasuri, ni yóo sì jẹ́ olórí wọn.
Oríṣun àwòrán, @Atiku Àkọlé àwòrán, Atiku Abubakar #Otogelagos Ẹda O to gẹ̀ẹ́ ti Kwara ni #Otogelagos eleyi ti o ti n gbalẹ diẹ diẹ.
Wọn ni ẹrọ ibanisọrọ̀ laarin ara wọn.
Wahala Kaduna: Ọwọ ọlọpaa tẹ eeyan mẹwa Afẹnifẹre koro oju si ikọlu 'awọn ọmọ Yobe' Alupupu marun, ada meji, oogun abẹnu gọngọ ati ẹgbẹrun lọna ọgọfa naira ni wọn gba lọwọ awọn afurasi naa Atẹjade kan eyi ti alukoro fun ileesẹ ọmọ ogun lorilẹede Naijiria, Ọgagun Texas Chukwu fi sita nilu Abuja salaye wi pe, awọn afunrasi naa bẹlu'gbo nigba ti wọn ri awọn ọmọogun naa.
‘Láti ìgbà tí mo ti mú àwọn eniyan jáde kúrò ní ilẹ̀ Ijipti, n kò tíì yan ìlú kankan ninu ẹ̀yà Israẹli láti kọ́ ilé sí fún ìjọ́sìn ní orúkọ mi, bẹ́ẹ̀ ni n kò yan ẹnìkan kan láti jẹ́ olórí àwọn eniyan mi.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù CAN: ó pọn dandan kí wọn fágile ìdánwò ọlọ́pàá Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ CAN: ó pọn dandan kí wọn fágile ìdánwò ọlọ́pàá 29 Èbibi 2018 Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí kan sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
O tesiwaju pe”idibo egbe to waye ni irowo-irose ni ipinle naa , yoo ya awon olote lenu , nitori ohun buruku ti won lero  pe yoo sele ,ni  ko wa si imuse.
F Odunjo kó ipa ribiribi sí àgbéga èdè Yorùbá
Saa mẹfa ọtọọtọ ni Sẹnetọ John McCain fi jẹ sẹnetọ, ti o si dije dupo fun Aarẹ ilẹ Amerika labẹ ẹgbẹ oselu Republican ni ọdun 2008.
Ìrètí àwọn onímọ̀ ìlera lórí igbesẹ yìí ni pé, àwọn èròjà tó ń gbógun ti àìsàn nínú agọ ara àwọn èèyàn tórí tí kò yọ lọ́wọ́ àrùn Covid-19 yóò seranwọ láti pá kòkòrò àrùn náà rún lára àwọn èèyàn miran.
Josẹfu bá sọ fún un pé, “Ìtumọ̀ rẹ̀ nìyí: àwọn ẹ̀ka mẹta tí o rí dúró fún ọjọ́ mẹta.
Nǹkan tí ń ṣẹlẹ̀ ní Jerusalẹmu ati Juda burú débi pé inú fi bí OLUWA sí wọn tóbẹ́ẹ̀ tí ó fi tì wọ́n jáde kúrò níwájú rẹ̀.
Ní alẹ́ ọjọ́ náà gan-an ni wọ́n pa Beṣasari, ọba àwọn ará Kalidea.
Nígbà náà ni Aisaya ọmọ Amosi ranṣẹ sí Hesekaya ọba pé, “OLUWA Ọlọrun Israẹli ní: Mo ti gbọ́ adura rẹ nípa Senakeribu, ọba Asiria.
Aare so oro ohun laale ojoRu(Wednesday) nile ipinle naa, lasiko ipade apeje re pelu awon adari egbe oselu ohun ati awon oludije dupo patapata nipinle Ekiti.
Malema gba Ramaphosa niyanju pe ko kọ̀ lati gbọran sawọn alagabagebe, arijẹ-nidi-madaru lẹnu.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Akomolede ati Aṣa lori BBC: Mọ̀ si nípa oríṣìí ẹ̀ka ìsọ̀rí ọ̀rọ̀ àti ìwúlò wọn Bakan naa ni Auxilliary rọ awọn ẹgbẹ onimọto, RTEAN at'awọn ẹgbẹ ọlọkada lati bọwọ fun ofin ijọba nipa sisanwo wọn deedee ti awọn oṣiṣẹ ajọ PMS ba ti n jawe fun wọn ni ibudokọ.
Emery ṣapejuwe Iwobi gẹgẹ bi awokọsẹ rere fawọn ọjẹwẹwẹ agbabọọlu, bẹẹ lo gbadura fun un wi pe yoo ṣoriire nibi to n lọ Bi Iwobi ṣe fi Arsenal silẹ lọ Everton jẹ ibanujẹ fun ọpọlọpọ ololufẹ rẹ, ko da aworan ẹni tomi n bọ loju rẹ lọpọ wọn ṣapejuwe bi ọrọ naa ṣe dun wọn to.
City kanra mọ́ Brighton gba Líìgì mọ́ Liverpool lọ́wọ́ Sadio Mane Senagal àti Mohammed Salah Liverpool Salah ti gba ami ẹyẹ Golden Boot ri tẹ́lẹ̀ ko to tún gbàá ni sáà yìí pẹlu bó ṣe gbá bọ́ọ̀lù sáwọn nínú gbogbo ìdíje to ti kópa nínú ìdíje ti Liverpool ti kópa ni sáà yìí.
Àwọn angẹli náà pọ̀ pupọ: ẹgbẹẹgbẹrun ọ̀nà ẹgbẹẹgbẹrun àìmọye.
"Ọ̀pọ̀ ẹ̀mí ló ṣòfò nibi ìjàmba tó wáye ni Akungba nìpińlẹ̀ Ondo England kéde ìséde ọ̀sẹ́ mẹ́rin míràn láti dẹ́kun ìtànkálẹ̀ Covid 19 Èèyàn 162 ló kó àrùn Coronavirus ní Nàìjíríà lọ́jọ́ Ajé Wo ojú àwọn òṣèré yìí láì lo ""Make-up"" orí ìtàgé bó ṣe rí gẹ́lẹ́ Kini Gomina Okowa kede ni ipinlẹ Delta lori konileogbele?"
" Bakan naa ni Arabinrin Njamanze sọ pe ajọ oun yoo fi atẹjade sita lori ọrọ naa.
Àmọ́sá, ẹgbẹ́ òṣìṣẹ́ ní Nàìjíríà ti f'ewé ọmọ mọ́ ìjọba àpapọ̀ létí láti máse jẹ́ kí ohunkóhun yẹ ṣíṣe ámúsẹ owó oṣù tuntun.
Adájọ́-fẹ̀yìntì Oloyede fikun pé, òfin African Growth Development Act tí Nàíjíríà pa tì láì lò, ló mú kí ọ̀pọ̀ èèyàn wà nínú ìsẹ́ àti òsì.
Joabu bá gún un ní idà níkùn, gbogbo ìfun rẹ̀ tú jáde.
Saaju ni olupẹjọ ti rọ ile ẹjọ naa lati wọgile ibo to gbe ọgbẹni Kalu wọle, nitori ko wa pẹlu ibamu ofin to ni i ṣe pẹlu ọrọ eto idibo ti ọdun 2010.
Bí ojú yín tilẹ̀ fọ́ ẹ ó sọ pé ẹ kò rí adé mi ni?
$2,600 àǹtí mi ni mo jí láti lọ sókè òkun àmọ́ àbámọ̀ ló gbẹ̀yìn ọ̀rọ̀ mi"" Yahaya Bello, Gomina ìpínlẹ̀ Kogi kéde Onoja ní ìgbákejì tuntun ""Olóṣèlú ní Kogi àti Bayelsa ti ń pín Irẹ̀sì, iyọ̀ lásìkò ìpolongo ìbò, INEC, ẹ mú wọn"" Dino Melaye tó ń díje dupò gómínà Kogi ni irọ́ ni pé òun ti ju awà sílẹ̀ Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?"
Senator Abiola Ajimobi ti yan igbimo elenu mẹ́rìndínlọ́gbọ̀n (26) ti yoo se kokari eto
Nígbà tí ọ̀pọ̀lọpọ̀ wa lè rántí bí ìbálòpọ̀ àkọ́kọ́ ṣe fún tó tàbí rí bákan bákan, ó jẹ́ ohun tí ènìyàn ò kí ń fẹ́ sọ nípa ti Isley.
Ọkùnrin kan gbé ‘búrọ́ọ̀ṣì ìfọyín’ mì Àwọn dókítà ìpínlẹ̀ Eko tó ń yanṣẹ́lódì ti padà s'ẹ́nu iṣẹ́ Ààrẹ Buhari ti fi ọwọ́ òsì júwe ilé fún Ọ̀gá Àjọ ìdánwò NECO àti àwọn mẹ́rin míràn Ènìyàn 284 ló ní àrùn Coronavirus ní Ọjọ́òrú ní Nàíjíríà Ọkan lara awọn ọmọbinrin naa ti ọjọ ori wọn wa laarin ọdun mẹrinla si mẹtadinlogun sọ pe ' 'O se pataki ki a sa ipa tiwa naa lori ajakalẹ aarun Covid 19, koda bo ba se eeyan kan la le doola ẹmi rẹ pẹlu igbiyanju wa'' Oríṣun àwòrán, Reuters Agbegbe Herat nibi ti eeyan akọkọ ti safihan arun Covid 19 ni ilẹ ọhun lawọn ọmọbinrin yi ti wa.
Ìgbà tí wọ́n bá sì wà ní oko, àgbà ni ó nílati dá iná kí ó ṣe oúnjẹ.
"Ooni Ile Ife pàdánù Màmá àgbá A kò tíì lè sọ pé ọmọ Ọba tuntun ni yóò jẹ Ooni lọ́jọ́ iwájú - Elebuibọn Kà nípa ibi tí wọ́n bí Àrẹ̀mọ tuntun Ọọ̀ni Ife sí, àti orúkọ tó ń jẹ́ Femi Fani-Kayode sọ̀kò ọ̀rọ̀ sí Tinubu tori kò dìde kí Ooni 'Ìbọn dún láàfin Ọ̀ọ̀ni ilé ifẹ̀ lóòtọ́, ṣùgbọ́n kò séwù' Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Kayeefi: 'Ọkọ mi ṣẹ̀ṣẹ̀ ní kí n lọ se mọ́í-mọ́í, tó ṣẹ̀ bá mi ṣeré tán ni mo gbọ́ pé ""Mopol"" yìnbọn pa á' Ṣe eewọ kankan wa to de Ọba lori ọrọ ọmọ tuntun?"
Ọba mẹ́wàá tí wọ́n ti lé kúrò nípò: Alaafin, Ọlọ́wọ̀, Elérúwà , Awujalẹ àti .
agbẹ́gilére, àwọn mọlémọlé àti àwọn kanlékanlé.
Ẹni méjì kú, ọ̀pọ̀ dèrò ilé ìwòsàn níbi ìjàmbá ọkọ̀ tó ṣẹlẹ̀ ní Okokomaiko nípínlẹ̀ Eko Duro Ladipọ, ìlúmọ̀ọ́ká òṣèré tíátà àti ọmọ àlúfà tí kò gbàgbé àṣà ìbílẹ̀ Akeredolu ti mókè nínú ìbò gómìnà níjọba ìbílẹ̀ méjìlá l‘Ondo, PDP gba mẹ́ta Ìdí márùn ún tí agbára Covid 19 ní ilẹ̀ Adúláwọ̀ kò fi tó tí àwọn ilẹ̀ àgbáyé míràn Ìdí tí ìjọba fi tú FSARS ká rèé!
Àwọn ọmọ Israẹli kúrò ní Ramesesi, wọ́n lọ pàgọ́ sí Sukotu.
Buhari wọle , Pe iyaafin Dabiri-Erewa yege lati di ipo adari  ajo naa mu, leyin ti awon ti se ayẹwo
Ọlọ́wọ̀: Ayẹyẹ ìgbadé ń bọ̀ ní ọjọ́ mẹ́tàdínlógún sí àsìkò yìí
Wọn a máa retí ìgbà tí omi yóo rú pọ̀; [ 
Gomina Sanwo-Olu kede awọn igbesẹ naa eleyi ti yoo bẹrẹ ifidimulẹ lati ọjọ kẹrin oṣu karun ọdun 2020.
Àwọn tí wọ́n bá gbọ́ ìròyìn rẹ yóo pàtẹ́wọ́ lé ọ lórí, nítorí kò sí ẹni tí kò tíì faragbá ninu ìwà burúkú rẹ.
ati abiyamo) to wa ni LASUTH ati ile igbẹbi to wa ni aarin gbungbun ipinle Eko.
’ rèé Ṣẹ gbọ́ nípa Alájọ Ṣómólú, tó ta mọ́tò ra kẹ̀kẹ́?
Joṣua bá pàṣẹ fún àwọn alufaa náà pé kí wọ́n jáde ninu odò.
Wèrè tí mò ń ṣe ní Facebook ló pawó fún mi-Esabod Àwọn kókó ohun tó wà nínú lẹ́tà tí Aláàfin kọ sí Fayemi rèé Ọmọ ti lọ kí baba, Fayemi bẹ Aláàfin wo l‘Ọyọ, wọ́n jírórò lórí lẹ́tà Ìjà Aole àti Afonja 'tó bí èpè' fún Yorùbá, ẹ̀bi ta ni?
Bi ojumọ si se n mọ ni deede aago mẹjọ aarọ, ni papa isere idaraya Lekan Salami ti kun babi, nibi ti eto ayẹwo awọn to fẹ di Amotekun ti n waye.
Idi ree ti Big Brother ninu eto ile ẹlẹgbọn ọn agba ti ṣe ni ki ọkan lara awọn oludije, Dorothy wọle lati lọ paarọ asọ to wọ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Iléesẹ́ ọlọ́pàá: Ihò tí wọ́n gbẹ́ fún wáyà, ni eku gbà wọlé 20 Òkùdu 2018 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ó ya ọ̀pọ̀lọpọ̀ lẹ́nu pé eku jẹ owó nínú ẹ̀rọ tó ń pọ owó Awọn amoju-ẹro ti wọn n tun ẹrọ apọwo to bajẹ ṣe ni ilu Assam l'orilẹede India, ti ṣ'akiyesi pe, awọn eku ti jẹ owo ti wọn ko si inu ẹrọ naa.
Wọn ni Orilẹede Benin, Germany, France ati Turkey lawọn orilẹede ti arabin naa bẹ wo loṣu keji ati ikẹta ọdun yii.
Èyí ni ipa tí àdínkù owó epo bẹtiró yóò mú bá ọ̀rọ̀ ajé Nàìjíríà Ẹyin ilé ìjọsìn, ẹ tilẹ̀kùn ṣọ́ọ̀ṣì àti mọ́ṣáláṣí yín láti dènà àrùn Coronavirus - ìjọba Eko Oníṣẹ́ ikú Coronavirus tún ti jẹ́ fún wọn ní orílẹ̀èdè Cameroon Lori ọrọ ti ijọba ipinlẹ Ekiti sọ pe awọn sọ fun ijọba ipinlẹ Ọyọ nipa ọmọ America to ku si ipinlẹ Ekiti, ati awọn ti wọn jọ wa si Ekiti, ti ọkan lara wọn si ti ni coronavirus, Adisa sọ pe ijọba Ekiti ko sọ fun ijọba Ọyọ tẹlẹ.
Wọ́n tún wòye pé Jesu kò bá àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ wọ ọkọ̀; àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ nìkan ni wọ́n lọ.
Àwọn ọmọ Israẹli sin egungun Josẹfu tí wọ́n gbé wá láti ilẹ̀ Ijipti sí Ṣekemu, lórí ilẹ̀ tí Jakọbu fi ọgọrun-un fadaka rà lọ́wọ́ àwọn ọmọ Hamori, tíí ṣe baba Ṣekemu, ilẹ̀ náà sì di àjogúnbá fún arọmọdọmọ Josẹfu.
O seleri pe, egbe ohun yoo tesiwaju lati maa samoju to sise amulo erongba eto ABP, ni eyi ti o so pe, “a o ni jafara lati fiya je enikeni lara awon agbe, ti o ba tapa si ilana isamulo owo ti o ya naa bi o ti to ati bi o se ye”.
Mò ń dán àwọn eniyan mi wò,bí wọ́n bá sì kọ̀, tí wọn kò ronupiwada,gbogbo nǹkan wọnyi yóo ṣẹlẹ̀ sí wọn,Èmi OLUWA Ọlọrun ni mo sọ bẹ́ẹ̀.
n se ojuse wọn lasiko idibo , ti won si yinbọn pa Usman to jẹ awakọ wọn.
" Wọn sọ eyi nitori igbagbọ wọn pe ẹni ire kan kii sẹgbẹ oṣelu.
Eyi tun ti jẹ ki awọn kan maa beere orisun owo gomina Seyi Makinde ni bi eto ọrọ aje ṣe ri lasiko yii.
Nígbà tí mo bá ranti ẹkún tí o sun, a dàbí kí n tún rí ọ, kí ayọ̀ mi lè di kíkún.
Ti eniyan ba jẹ ori ahun yoo ba Joy Chioma kẹdun iru
Ẹwẹ, Ẹgbẹ MOSOP ati ajọ ajafẹtọ kan Social Development Integrated Centre (Social Action) ti koro oju si Aarẹ orilẹede Naijiria, Muhammadu Buhari lori ọrọ kan to sọ laipẹ yii pe isẹ afọmọ agbegbe Ogoni nlọ ni sẹpẹsẹpẹ."
Oríṣun àwòrán, @Sanwoolu SERAP ni ki ile ẹjọ ọhun wadii awọn to wa nidi ikọlu naa, paapaa bi awọn oloṣelu, ọmọ ogun ati awọn oṣiṣẹ eto aabo to lọwọ ninu iṣẹlẹ naa.
Arabinrin Omar ati Tlaib tun tẹnumọ ọ pe ki wọn yọ aarẹ Donald Trump kuro nipo.
Àwọn ẹni tí a jọ bẹ̀rẹ̀ iṣẹ́ nígbà kan náà ti sanra nísisìyí, ẹ̀hìn ọrùn wọn ti tóbi, orúnkún wọn lásán sì ti tóbi ju ibàdí mi lọ.
Ìṣẹlẹ náà to waye lagbègbè Ìkóríta Ọ̀tẹ́dọla, Berger, ní opópónà márosẹ̀ Ìbàdàn sí ìlú Èkó lọjobo ní ọpọ èèyàn tí ṣé àpèjúwe rè gẹgẹ bí ìṣẹlẹ tó gbenilọkan soke .
Ìyá dú ọmọ rẹ̀, o yíi láta, ó sì tún jòkó jẹ ẹ́ Àráàlú yarí fún fásitì Babcock fún bo ṣe lé akẹ́kọ̀ọ́ tí wọn bá lòpọ̀ nínú fídíò Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 3 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 5 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Lati ọjọ Isẹgun ti isẹlẹ naa ti waye, awọn olugbe agbegbe naa ṣe alaye wi pe, awọn ko tun tii ri ọmọ onilẹ kankan mọ ni agbegbe Soka niluu Ibadan.
dara pọ mọ́ Arsenal so pe asiko ti to lati kaṣẹ kikopa ninu ere bọọlu gẹgẹ bi
44 fún lítà kan O ni oun ni lati fi ọrẹkunrin naa silẹ nitori ifẹ ti oun ni si ere tiata.
Ladoke Akintọla Ladoke Akintọla ni Aarẹ ọna kakanfo kẹtala to jẹ.
Àwọn ẹlẹ́ṣin ti múra ìjàpẹlu idà ati ọ̀kọ̀ tí ń kọ mànà.
Gbogbo àwọn ilé ńláńlá tí ó wà níbẹ̀ ni ó sì dáná sun.
Ti ọlọpaa to jẹ olori ikọ alaabo naa si sọ pe ki wọn o sun kuro ni ayika ibi ti wọn wa nitori pe aarin igboro ni.
Oshodi-Oke: Kò dára báwọn òsèré se ń fi dúkìá sakọ
Kashamu ní òfin kò dá Ladi tí PDP gbé àṣíá fún mọ̀ láti díje gómìnà Ìgbà tí Aisha Buhari ti f'ọ̀rọ̀ da ìgboro rú lórí ìjọba ọkọ rẹ̀ Igbimọ amuṣẹya ẹgbẹ APC ti gbe igbimọ kan kalẹ lati yanju wahala to n waye laarin awọn ọmọ ẹgbẹ ni ẹkùn idibo mẹfẹẹfa to wa ni Naijiria ṣaaju eto idibo to n bọ.
Nítorí ìfẹ́ rẹ̀ tí kì í yẹ̀ tóbi sí wa,òtítọ́ rẹ̀ sì wà títí laelae.
Ajọ naa ni lẹyin oniruuru abẹwo fun bi oṣu mejidinlogun, awọn alaṣẹ orilẹede naa ko tii mu awọn amuyẹ to yẹ fun gbigbalejo idije naa ṣẹ.
Lootọ ni ọwọ ajọ to n gbogun ti iwa ibajẹ ni Naijiria, EFCC, ti tẹ awọn oloṣelu kan to hu iwa ibajẹ, ṣugbọn awọn kan n koro oju si Buhari pe awọn ọmọ 'to jẹ ọ̀tá iṣakoso rẹ' nikan lo n fi igbesẹ rẹ gbogun ti.
Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí 4:15 Fídíò, Pa Olabode Olajide: Pé Osinbajo wá kí mi ló mú inú mi dùn jù nílé ayé mi, Duration 4,1520 Èbibi 2019 Naira Marley: Ẹ wo bí ìgbẹ́jọ́ ṣe lọ lórí ẹ̀sùn tí wọ́n fi kan Marley7 Ògún 2020 Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí kan sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
Ẹ jẹ́ kí á dojúbolẹ̀ kí ìtìjú wa sì bò wá,nítorí pé a ti ṣẹ̀ sí OLUWA Ọlọrun wa;àtàwa, àtàwọn baba ńlá wa,a kò gbọ́ ti OLUWA Ọlọrun wa, láti ìgbà èwe wa títí di òní.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Olumilua: Mimiko ní olóògbé náà kìí ṣe olóṣèlú jẹgúdú-jẹrá, irú rẹ̀ kò sì wọ́pọ̀ mọ́ 4 Òkùdu 2020 Oríṣun àwòrán, others Idi ree ti kọmisana tẹlẹ nigba ti oloogbe Bamidele Olumilua jẹ gomina nipinlẹ Ondo ijọun, toun naa si pada jẹ gomina nipinlẹ naa lẹyin rẹ, Dokita Olusegun Mimiko fi n ṣe idaro ọga rẹ, Olumilua, to papoda ni owurọ Ọjọru lẹni ọgọjọ ọdun.
Oṣù kẹta lẹ́hìn tí ìyá mi kú ni mo di obinrin.
BBC Yoruba pẹlu akanṣe eto gbigbe ede Yoruba larugẹ mu ibeere naa tọ awọn ọmọ Yoruba atata lọ boya mimọ ede wọn daju ṣi n ṣiṣẹ wara wara lori wọn.
Ajọ naa wa parọwa si awọn ọmọ Naijiria lati sọra fun pọnmọ jijẹ, ki o ma ba a fa aisan aimọdi si ara awọn eniyan.
Ẹlomiran le mi iru afẹfẹ bẹ simu, tabi to ba fọwọ kan ibi (ori aga ijoko tabi ori tabili) ti arun naa ti bale, ti iru ẹni bẹ si fi ọwọ naa si oju, imu tabi ẹnu rẹ.
O kawe gboye Apa ariwa Naijiria ni Bayero ti ka pupọ ninuiwe to ka .
Wọ́n sì bẹ̀rẹ̀ sí bá a lòpọ̀ títí di òwúrọ̀ ọjọ́ keji, nígbà tí ilẹ̀ bẹ̀rẹ̀ sí mọ́, wọ́n fi sílẹ̀ pé kí ó máa lọ.
Awọn ọmọ ẹgbẹ ọlọkọ ero lo si kọlu wa.
Aya rẹ ti wọn jọ ṣẹwọn ni alagbọn sọrọ ni kikun.
Embassy: À kò ni dási ọ̀rọ̀ ìdìbò Nàìjíríà Bí wọ́n ṣe ń ta káádì ìdìbò ní Kano nìyì Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Sẹ́gílọlá: Arúgbó awẹ́lẹ́wà tó ń ṣiṣẹ́ omidan Awọn elétò ìlera ti wádìí ọ̀rọ̀ náà ti wọn si ri pe ẹlẹrindodo náà ni ǹkan ti wọn ń pè ni Sildenafil Citrata to jẹ èròjà gbòógi nínú Viagra, ti ìjọba Zambia pàápàá tún sọ pé àwọn yòó ṣe ìwádìí tí àwọn Àbájáde ìwádìí Zimbabwe àti South Africa tí ìjọba Zambia gbé jáde fí hàn pe òòtọ́, àjọ tó ń ri si Ounjẹ àti Oogun ri pé Sildenafil Citrata wà nínú ẹ.
Agbára Ọlọrun Jakọbu ni ó fún apá rẹ̀ ní okun,(ní orúkọ Olùṣọ́-aguntan náà,tí í ṣe Àpáta ààbò Israẹli),
Iye awọn eeyan to ṣẹṣẹ ko arun naa ni ipinlẹ kọọkan ree: Delta-166 Eko-120 Enugu-66 FCT-65 Edo-60 Ogun-43 Kano-41 Kaduna-39 Ondo-33 Rivers-32 Bayelsa-29 Katsina-21 Imo-20 Kwara-18 Oyo-11 Abia-10 Benue-6 Gombe-4 Yobe-2 Bauchi-2 Kebbi-2 Oríṣun àwòrán, Getty Images Eeyan 561 tuntun mii lo ṣẹṣẹ lugbadi arun Coronavirus ni Naijiria.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Coronavirus: Ohun tó ṣì ṣókùnkùn sí ìgboro ayé nípa àrùn Covid-19 By James Gallagher Health and science correspondent 30 Ẹrẹ̀nà 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 31 Ẹrẹ̀nà 2020 Oríṣun àwòrán, Getty Images Niṣe ni ọrọ naa jọ bi ẹni pe ati ogun ọdun la ti n ba bọ ṣugbọn ko ju oṣu Kejila ọdun 2019 to kọja ta bẹrẹ si ni jẹ ọrọ Coronavirus lẹnu.
Ọyọ: Olubadan ni saa kẹta tọ si Ajimọbi
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Coronavirus: Àjọ elétò ìlera lágbàyé tí pe Coronavirus ní àjàkálẹ̀ àrùn káàkiri àgbáyé 11 Ẹrẹ̀nà 2020 Oríṣun àwòrán, Getty Images Ajọ eleto ilera ni Agbaye, WHO ti pe arun Coronavirus ni ajakalẹ arun to n ja kaakiri agbaye.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Lẹyin eyi, Arọni Arsenal ko simi rirọjo bọọlu lọ si oju ile Burnley bi o tilẹ jẹ pe Burnley pẹlu ko sun asunpiye, awọn naa ja fitafita ti wọn si da goolu akskọ pada nigba ti ifẹsẹwọnsẹ naa wọ iṣẹju kẹtalelogoji.
" Nítorí ìdí èyí, ó ṣe pàtàkì láti ni àwọn onímọ labẹ́ ilé àti jákèjádò gbogbo àgbáyé.
Ilẹ naa ni awọn ẹrọ to n tani lolobo ti eefin ba ṣeyọ nile ṣugbọn ayekootọ naa lo kọkọ figbe ta"" Iwadii n lọ lọwọ lati mọ ohun to fa ina yi titi di bi a se n ko iroyin yi jọ."
Goolu kilo kan ati aabọ ni awọn dokita yọ ninu obinrin kan ti wọn ṣiṣẹ abẹ fun ni India.
Ile ẹjọ kotẹmilọrun nigba to n da ẹjọ ni dandan Adajọ Agba naa gbọdọ lọ jẹjọ iwa ibajẹ.
Gbogbo ọ̀rá ara rẹ̀ ni wọ́n gbọdọ̀ fi rúbọ; ìrù tí ó lọ́ràá ati ọ̀rá tí ó bo ìfun rẹ̀, 
Oríṣun àwòrán, @adetutuoj8811 Koda, ila kikọ yii ni Adetutu sọ pe o tun mu ki baba ọmọ oun kọ oun silẹ, nitori pe oju maa n tii lati ba oun rin loju popo.
 Oga agba Adami so pe: “Igbimo toro
Yorùbá kìí ṣe egúngún oníhòhò, ìwà wèrè ni sinimá oníhòhò táwọn òṣèré kan ń ṣe- Lere Paimo Àwọn èèkàn òṣèré Nollywood nìyí pẹ̀lú àmì ohùn èdè Yorùbá Hubert Ogunde rèé, baba àwọn òsèré tíátà Bakan naa lo fikun pe, ẹni ti ori rẹ ba ku, to ba fi Yoruba to yaayi gbe ọrọ rẹ kalẹ, oju ọlọgbọn lawọn eeyan yoo fi maa wo.
Kí ẹ fi ẹgbọ̀rọ̀ akọ mààlúù kan, ati àgbò kan ati ọ̀dọ́ àgbò meje ọlọ́dún kọ̀ọ̀kan tí kò ní àbààwọ́n rú ẹbọ sísun olóòórùn dídùn sí OLUWA.
 ) amuga a lè fi amuga ìjeun je ìresì .
Wolii kan bá tọ Ahabu ọba lọ, ó wí fún un pé, “OLUWA ní kí n wí fún ọ pé, ‘Ṣé o rí gbogbo àwọn ọmọ ogun yìí bí wọ́n ti pọ̀ tó?
Àwọn ọmọde pàápàá ń fojú tẹmbẹlu mi;bí mo bá dìde wọn á máa sọ̀rọ̀ sí mi.
Wọ́n fi òróró yàn án ní ọba lórí Israẹli, gẹ́gẹ́ bí ọ̀rọ̀ OLUWA láti ẹnu Samuẹli.
Lórí ọ̀rọ̀ Ogun Majek, mi ò lọ́rọ́ láti sọ, ẹ lọ pe ẹni tára rẹ̀ kò yá- Mr.
"Mi ò ní wọ Uber mọ́ tí wọ́n bá leè fi owó lée nítorí àfikún owó orí tí Sanwo Olu ṣe Ẹ̀gbọ́n àti àbúrò wà ní ilé ẹ̀jọ́ lórí ikú Tolulope Arotile Ooni Ifẹ bu ẹnu ẹ̀tẹ́ lú ètò BBNaija nítorí ó tàbùkù àsà Yoruba ""Mi ò ní wọ Uber mọ́ tí wọ́n bá leè fi owó lée nítorí àfikún owó orí tí Sanwo Olu ṣe"" Gẹgẹ bi ọrẹ rẹ kan, Lucy Ibe ṣe sọ, ""opopona Badore ni o wa ti ọlọjọ de."
Aṣẹ yii waye lẹyin ipade pajawiri ti Aarẹ Muhammadu Buhari ati Igbakeji rẹ, Yẹmi Ọṣinbajo ṣe lọjọ kẹẹdọgbọn, oṣu Kẹrin, ọdun 2019.
ṣugbọn nígbà tí a gbìn ín, ó dàgbà, ó wá tóbi ju gbogbo ewébẹ̀ lọ, ó ní ẹ̀ka ńláńlá, àwọn ẹyẹ wá ń tẹ́ ìtẹ́ wọn sábẹ́ òjìji rẹ̀.
Àwọn ọmọ Naijiria ni, èyí n wáye nítori pé Naijira ni ibi ti gbogbo ńkan ti le ṣẹlẹ̀ láìsì ǹkan ti yóò tẹ̀yì rẹ̀ jáde.
bayii lati se ofin ti yoo maa mu iyipada rere ba awon ara ilu.
Sẹbi awọn ẹbun naa lo wa niwaju wa yi?
Olórí Alufaa wá bi wọ́n pé, 
Ẹnikan ninu awọn to ṣẹṣẹ larun naa wa lati ipinlẹ Osun, nigba ti ẹnikeji wa lati ipinlẹ Eko.
Orin ‘Sunshine of Eritrea’ to ko ni Tigrinya di gbajugbaja ni Kirar.
Wọn kọkọ ni ọta ibọn kan to wa lati agọ ọlọpaa Makinde lo ran ọdọkunrin naa sọrun lori ayelujara, lasiko tawọn janduku ya bo agọ ọlọpaa naa lati sun nina.
Ipade naa ko olori awon agbofinro sile, iyen, Ibrahim Idris; Minista fun eto aabo, Mansur Dan ali; minista fun oro abele, Abdulrahaman Danbazau; minista fun oro ile okeere, Geoffery Onyeama.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ilé orin wa tí Ajimobi tun kọ́ dára púpọ̀, ṣùgbọ́n a kò ní dẹ́kun òtítọ́ Pẹlu oye yii, ajọ naa ni ireti wi pe Ayefele yoo lo ipo rẹ lati mu ibugboro ba iroyin tootọ lasiko idibo gbogbogbo ti ọdun 2019.
Kò sí níhìn-ín; ó ti jí dìde.
Ó ní àtẹ̀gùn meje, ìloro rẹ̀ wà ninu, àwòrán ọ̀pẹ sì wà lára àtẹ́rígbà rẹ̀ lẹ́gbẹ̀ẹ́ kinni keji.
Nígbà tí Mose gbọ́ ọ̀rọ̀ yìí, inú rẹ̀ rọ̀.
Yóo dìde, yóo sì mójútó àwọn eniyan rẹ̀ pẹlu agbára OLUWA, àní, ninu ọláńlá orúkọ OLUWA Ọlọrun rẹ̀.
OLUWA, bukun àwọn ohun ìní wọn,sì jẹ́ kí iṣẹ́ ọwọ́ wọn jẹ́ ìtẹ́wọ́gbà lójú rẹ,Fọ́ egungun itan àwọn ọ̀tá wọn,tẹ̀ wọ́n ní àtẹ̀rẹ́,kí àwọn tí wọ́n bá kórìíra wọn má sì lè gbérí mọ́.
Adura ati awẹ, titi kan ipade adura ita gbangba ni awọn ẹgbẹ oṣelu mejeeji, APC ati PDP ṣe ṣaaju idajọ ti yoo waye loni.
Gege bi agbenusoro fun ile-ise olopaa, Mohamed Aden ati asofin Mahad Dhoore se so, won ni,  isele ohun lo je akoko iru re ti yoo waye ni papa isere lorie-ede naa.
láìka èyí tí àwọn oníṣòwò ń san fún un, èyí tí ń wá láti ibi òwò rẹ̀, ati èyí tí àwọn ọba Arabia ati àwọn gomina ilẹ̀ Israẹli ń san.
Àwọn tí ó ní ẹ̀bùn ìsọtẹ́lẹ̀ níláti lè káwọ́ ara wọn nígbà tí ẹ̀mí bá gbé wọn láti sọ àsọtẹ́lẹ̀.
Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Tunde Bakare: Àwọn èèyàn kò gbọ́ ìwàáṣù mi délẹ̀, kí wọn tó bú mi lórí ọ̀rọ̀ Tinubu28 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Tinubu 2023: Àwọn èèkàn ilẹ̀ Yorùbá ń ṣèpàdé ṣáájú dídìbò fún Tinubu ní 202315 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 PasitoTunde Bakare: Aago Nàìjíríà ti kún àkúnwọ́sílẹ̀15 Agẹmo 2019 Tunde Bakare: Irọ́ ni, mi ò sọ pé mọ fẹ di Ààrẹ ní 202330 Owewe 2019 Nigeria 2019 Elections: Tinubu ní òun yóò sàjọyọ̀ ìsẹ́gun lọ́sẹ̀ tó ń bọ̀21 Èrèlè 2019 Femi Fani-Kayode; Ìrọ́ ní o, mi ò fí ìyà jẹ ìyàwó tí mo kọ̀ sílẹ4 Ọ̀wàrà 2020 Femi Fani-Kayode: Ọ̀rẹ́ lásán ni Halima Yusuf jẹ́ sí mi, kìí ṣe àfẹ́sọ́nà mi30 Owewe 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 3 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 5 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Nígbà tí Ọlọrun bá mu yín wá sí ilẹ̀ àwọn ará Kenaani ati ti àwọn ará Hiti, ati ti àwọn ará Amori, ati ti àwọn ará Hifi, ati ti àwọn ará Jebusi, tí ó ti búra fún àwọn baba yín pé òun yóo fi fún yín, tí ó kún fún wàrà ati oyin, ẹ óo máa ṣe ìsìn yìí ninu oṣù yìí lọdọọdun.
Anfaani lati fi arokọ ranṣẹ ti ṣi silẹ lati ọjọ kinni, oṣu Kẹjọ, yoo si wa si opin ni ọgbọnjọ, oṣu Kẹjọ, ọdun 2019.
Iku ọrẹ mi lo so wa pọ!
Ó ti le ni ọdún méje ti Ifeanyi ti n ta ìwé ìròyìn lágbègbè Federal Secretariat tó sì jẹ́ pé ọ̀pọ̀ àwọn ọmọ ilé ìgbìmọ̀ aṣòfin ló mọ̀ọ́.
Rakẹli bá sọ pé, “Ọlọrun dá mi láre, ó gbọ́ ohùn ẹ̀bẹ̀ mi, ó sì fún mi ní ọmọkunrin kan.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù UI: Kélé yóò gbé ọkùnrin tó bá ń rin gb;eregbére lágbègbè ibùgbé obìnrin ní fásitì Ibadan 13 Ògún 2019 Oríṣun àwòrán, University of Ibadan Àkọlé àwòrán, Laipẹ yii lawọn janduku kan ya wọ ileegbe awọn obinrin lọgba fasiti naa ti wọn si ṣe ọṣẹ Laipẹ yii ni iroyin kan pe awọn janduku kan ti ya wọ ibugbe awọn akẹkọ to jẹ obinrin ni fasiti Ibadan.
Kò sí ẹni rere kan, àfi Ọlọrun nìkan.
Lẹ́yìn náà ọbabinrin náà pada lọ sí ìlú rẹ̀.
“Nítorí náà, sọ fún Dafidi iranṣẹ mi pé, ‘Èmi OLUWA àwọn ọmọ ogun ni mo mú un kúrò níbi tí ó ti ń ṣọ́ àwọn aguntan, ninu pápá, mo sì fi jọba Israẹli, àwọn eniyan mi.
Ó ti kọ́ kó gbogbo àwọn eniyan pataki pataki ilẹ̀ náà lọ, 
Kíni 'Ẹ̀lẹ̀ daddy' Olorì Abbey Adeyemi ṣe tí ojú òpó ayélujára Instagram rẹ̀ fi ń yeruku lálá?
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Super Tuesday: Kí ni ìtumọ̀ àti pàtàkì rẹ̀?
(ohun tí àwọn ọ̀jọ̀gbọ́n sọ,tí àwọn baba wọn kò sì fi pamọ́,
Ọrẹ bi ọmọ iya la jẹ.
Awọn olololufẹ wọn ni, ẹni ti ko ba ti ba idile Toyin Abraham pade, ko gbiyanju lati ṣe bẹẹ nitori idile ti o dara ni.
Kí alufaa tún yẹ̀ ẹ́ wò, bí ibi tí ó wú náà bá tàn káàkiri sí i ní ara rẹ̀, kí alufaa pè é ní aláìmọ́; àrùn ẹ̀tẹ̀ ni.
Nipa bayii, eeyan marunlelọọdunrun ni iye awọn ti ayẹwo ti fihan pe o ni arun Coronavirus lorilẹede Naijiria.
Ukraine ati USA lawọn orile-ede meji to ku ni isọri kẹrin, Group D.
Nelson Mandela gbami  ami eye ni odun 2007.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Niyi Akinmolayan tó ṣe fíìmu àwòrán-dèèyàn Cartoon nípa COVID-19 tó la ayé já ní N O fi kun un pe ọfiisi kii ṣe eyi ti gbogbo awọn gomina ni lati maa fojojumọ kọ lẹta ifẹ ranṣẹ si.
"Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Èmi àti Saheed kìí ṣe ọmọdé, a ti jọ ṣe Sinimá papọ̀, èyí túmọ̀ sí pé ìjà ti parí - Fathia Balogun ""Mo fẹ́ pa ara mi torí ojú àbùkù tí wọn ń fi wò mí pé mo fi iṣẹ́ abẹ bímọ"" Fulani kò leè dúró, táa bá lo ohun ta jogún lọ́dọ̀ àwọn bàbá wa - Sunday Igboho Ọjà Àgbáláta ní Badagry rèé, níbití ẹran ejò ti dùn ju ẹran adìẹ lọ Ọlọ́run yóò ṣe ìdájọ́ nkan tó wà láàrin èmi àti Ireti Ajanaku - Tope Alabi A ko si gbọdọ fi aaye gba awọn oṣiṣẹ alaabo wa, lati maa fi ara wọn han gẹgẹ bi ọta iṣejọba awa ara wa gẹgẹ bo ṣe han ninu iwa wọn l'ọjọ Aje."
Lẹ́yìn náà ó mú mi wọ gbọ̀ngàn ti inú.
Awọn osisẹ ti ọrọ yii kan lo lee sọ, ti idaduro ojiji yii si ran ọpọ wọn sọrun ọsan gangan, nigba ti awọn miran di alarun, to fi mọ awọn osisẹ fẹyinti.
Wọn ni ibalopọ gan an ko jọwọn loju ati pe ọmọ ọdun mẹrinla le maa fẹnu ko ẹnu pẹlu ọmọ ọdun mẹrinla mii loju titi ti ẹnikan o si le sọ pe ki lẹ n ṣe ni bẹyẹn.
 O ko le ri ijọ Satani kankan ni agbegbe rẹ: Gẹgẹ bi o ṣe wa lori itakun agbaye wọn, ijọ Satani ko ni ile ijọsin kankan, nitori pe o tako ilana ti ẹnikọọkan wa n gba lo igbeaye wa.
BBC Yoruba, ninu iwadii alagbara yii se awari ọna meje ti asise fi le waye, ti ọmọ ale yoo si foju han lai jẹ pe obinrin kan yan ale.
27 Ṣùgbọ́n bí òun bá sẹ́ èyìí òun yíò sẹ́ májẹ̀mú èyí tí ó ti dá pẹ̀lú mi ṣaájú, àti kíyèsíi, òun ti di ìdálẹbi.
O ni iru idanilẹḳọ yii yoo le maa fi akọmona Ile Igbimọ Aṣofin naa, iyẹn “Tita wọn yọ ninu Igbelewon Aṣeyọri” mulẹ.
Jacobs ti kopa ninu ọpọlọpọ sinima nilẹ Naijiria ati okeere.
N óo lé àwọn ìjọba kúrò ní ipò wọn; n óo sì ṣẹ́ àwọn ìjọba orílẹ̀-èdè lápá.
Lasiko to n kasẹ isin ipagọ ẹmi mimọ ọlọdọọdun ijọ Redeem nilẹ, ni Adeboye sisọ loju ọrọ yii pẹlu afikun pe awọn ọmọ ijọ naa kan tun maa n lo aworan iyawo oun sara ẹbun pẹlu.
 O ki iko naa, papaajulo agbaboolu owo iwaju iko ohun, Odion Ighalo ti o gba ami-ayo meta sagbon ku oriire.
Àwọn ará Amaleki ati Kenaani tí ń gbé ibẹ̀ bá wọn jagun, wọ́n ṣẹgun àwọn ọmọ Israẹli, wọ́n sì lé wọn títí dé Horima.
‘Ìrìn tí ẹ rìn káàkiri ní agbègbè olókè yìí tó gẹ́ẹ́; ẹ yipada sí apá àríwá.
"O ni nigba ti ọmọde yii ri oun, ""o sun sẹyin, o jẹ ki n gba owo tan, o tun wa pada wa, ."
Abrahamu bá gbadura sí Ọlọrun, Ọlọrun sì wo Abimeleki sàn ati aya rẹ̀ ati àwọn ẹrubinrin rẹ̀, tí wọ́n fi lè bímọ, 
O kere tan eniyan marun un lo ba isele ibugbamu ado oloro  ti o waye lakoko ifesewonse ni papa isere kan ti o wa ni guusu orile-ede Somalia lojoBo(Thursday).
Gbajúgbajà òǹkọ̀wé èdè Yorùbá, Lawuyi Ogunniran tí gbogbo àwọn olólùfẹ́ ìwé ìtàn Yorùbá mọ̀ sí Eégún Aláré ti dágbére fún ayé.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Pápà mímọ́: Ọlọ́run yóò fi ẹ̀mí ìbágbépọ̀ rere sí Nàíjíríà 30 Ìgbé 2018 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Popu gbarata, tàwọn ọmọlẹ̀yin kírístí sì n fẹhọnu lori ìsekúpani ní ípínlẹ̀ Benue Olori Ijo Aguda ni agbaye, Pápà mímọ́ Francis, ti bu ẹnu atẹ lu ikọlu si ile ijọsin kan nibi ti wọn ti pa Fada meji ati awọn olujọsin ni ipinlẹ Benue, lorilẹede Naijiria.
 Bi o ti le je pe, a ko ni esun ti o po lori ifipabanilopo nipinle Zamfara, sugbon a nilo lati mojuto awon ebi kookan ti isele ohun ti sele si,”O wa ro awon oniroyin lati kede, ki awon ile-ise tabi ajo toro kan miiran si tun tan imole si oro ohun lawujo lati mo ewu ti o ro mo esun ifipabanilopo.
 ohun ni obinrin akoko ti yio bo si ipo yi .
Mose bá gbé iyawo rẹ̀ ati àwọn ọmọkunrin rẹ̀ gun kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́, ó pada lọ sí ilẹ̀ Ijipti, tòun ti ọ̀pá Ọlọrun ní ọwọ́ rẹ̀.
O ní ìgbésẹ̀ yìí yóò fún wọ́n ni ànfàni láti ṣe gbogbo ǹkan ti àwọn akẹgbẹ́ wọ́n ọkunrin ń ṣe, bákan náà ni òfin yìí yóo jẹ́ ki wọ́n yẹ láti rí iṣẹ́ ìgbàlóde lái si ìdẹ́yẹ si.
Amọ kaka ki ewe agbọn ẹgbẹ okunkun naa dẹ nidii iṣẹ ibi wọn, ko ko ko lo n le si, ti ọkunrin kan ti orukọ rẹ n jẹ Abiola, ti ọpọ mọ si Ebila si n lewaju wọn nilu Eko lọdun 2014.
Ó tún lọ sí apá ìhà àríwá òkè Beti Hogila, kí ó tó wá lọ sí apá etí Òkun Iyọ̀, níbi tí ó ti lọ fi orí sọ òpin odò Jọdani, ní ìhà gúsù.
Lẹsẹkẹsẹ ó wá kúnlẹ̀ níwájú rẹ̀.
Rebeka ní arakunrin kan tí orúkọ rẹ̀ ń jẹ́ Labani.
Ìjọba Bùhárí gan tó ń sọ̀rọ̀ kò tẹ̀lé ìlànà òfin lórí bàálù tó rà láì gb'àṣẹ; ìwà ìbàjẹ́ lèyí pẹ̀lú.
Bi aje ẹsun yi ba ṣi mọ Naira Marley lori, o lee fi ẹwọn ọdun meje jura tabi ki o san owo itanran to to miliọnu marun naira.
Mo jẹ́wọ́ ẹ̀ṣẹ̀ mi fún ọ;n kò sì fi àìdára mi pamọ́ fún ọ.
Bakan naa ni ohun sọ awọn ọdọ pada si arugbo, ti wọn ba ti fi aworan wọn si ori ẹrọ naa.
Nítorí ó wu Ọlọrun pé kí ohun tí Ọlọrun tìkararẹ̀ jẹ́ máa gbé inú rẹ̀ lẹ́kùn-únrẹ́rẹ́.
Ile Igbimọ Aṣofin Ipinlẹ Eko fọwọ si awọn ọmọ ẹgbẹ Igbimọ Aṣakoso Ile Igbimọ Aṣofin Ipinlẹ Eko (Lagos State House of Assembly Service Commision) marun-un ti Gomina Ipinlẹ Eko yan.
Ewe, jijawe olubori Edmund ninu ifigagbaga naa, lo so aseyori jijawe olubori re ninu ifigagbaga di igba merinla otooto bayii.
Ní àkókò tí kò sí ọba ní Israẹli, ọmọ Lefi kan ń gbé apá ibìkan tí ó jìnnà ní agbègbè olókè ti Efuraimu.
Ṣugbọn wọn kò rò ó pé mò ń ranti gbogbo ìwà burúkú àwọn.
" Mohammed Yusuf: Irú èèyàn wo ní olùdásílẹ̀ Boko Haram?
Atilẹyin àwọn oyinbo Gẹ̀ẹ́sì nìdí ìpèsè ohun ìjà igbalode tí Ibadan rí gbà yii, lo mú kó rọrùn fún láti ṣẹ eegun ẹyin àwọn ọmọ ogún ìjàyè lọ́dún 1862, tí ogún náà sì wà sopin lẹ́yìn odidi ọdún kan gbáko.
Ó rí àwọn ọmọ-ẹ̀yìn Jesu mélòó kan níbẹ̀.
Ndidi ti gba ami ẹyẹ ọdọmọde agbabọọlu to dantọ julọ fun saa meji lẹyin to darapọ mọ Leicester lati KRC Genk ti Belgian Jupiler League.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Yetunde Bakare dárà lórí ètò Ṣé o láyà, ẹ ràn án lọ́wọ́ nínú ìbéèrè tó ṣì Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Lẹ́yìn náà, Modekai pada sí ẹnu ọ̀nà ààfin, ṣugbọn Hamani sáré pada lọ sí ilé rẹ̀ pẹlu ìbànújẹ́, ó sì bo orí rẹ̀.
Akọsilẹ tuntun nipa aisan ibà l'agbaye fihan pe orilẹede mejidinlaadọrin lo jábọ̀ pe agbara oogun apẹfọn ko ka ẹfọn l'awọn akoko kan laarin ọdun 2010 si 2017.
Igbakeji asoju naa wa kede fun
Ogun ninu awọn to ni arun ọhun ni Naijiria ti ri iwosan gba, ṣugbọn awọn meji ti filẹ ṣaṣọ bora.
Oríṣun àwòrán, Policeng Àkọlé àwòrán, Ọwọ́ ti tẹ ọlọpàá mẹ́rìn to pa afunrasí Elkana fi kun un pé àwọn ti mú àwọn ọlọpàá náà si àtìmọ́lé lẹ́yìn ti fọ́nran náà lu sí ìgboro.
Ìwé ẹ̀hónú náà, tí alága ẹgbẹ́, Ojo Ayodeji àti akọ̀wé ẹgbẹ́, W.
Ẹ kò tíì kà á pé, ‘Lẹ́nu àwọn ọmọ-ọwọ́ ati àwọn ọmọ-ọmú ni ìwọ ti gba ìyìn pípé?
6 1,048,662 South Africa 35,852 62.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Babajide Sanwo-Olu 'pa'lù ẹnu dá',o lóun kò ṣèlérí nípa súnkẹrẹ-fàkẹrẹ Apapa láàrín ọgọta ọjọ 19 Òkùdu 2019 Oríṣun àwòrán, @jimidisu Àkọlé àwòrán, Ti a ba ni ka ka gbedeke ti ileri ọgbọn ọjọ ti wọn ni Gomina ṣe yi,yoo pe ni ọjọ kọkandinlọgbọn oṣu Keje ọdun 2019.
Ọpa aṣẹ amurode ni Ọba maa n gbe kaakiri eyi si ni eyi ti awọn janduku ri gbe lọ."
iran Yoruba yoo se gbogbo ohun to wa ni ikawọ rẹ lati daabo bo awon ẹya Yoruba
Mi o fẹ ki awọn ọmọ lọ sile olorogun, ṣugbọn to ba jẹ pe akọsilẹ Ọlọrun ni pe ko ribẹ fun wọn, a jẹ pe yoo dari ẹsẹ wọn.
Sadoku alufaa, bá mú ìwo tí wọ́n rọ òróró olifi sí, tí ó ti mú láti inú àgọ́ OLUWA jáde, ó sì ta òróró náà sí Solomoni lórí.
''O di dandan ki a ni igbẹkẹle pe opin aarun Covid-19 ti n sun mọ etile, ti ko si jinna mọ.
Èmi nìkan kọ́ ni yóo sì fún, yóo fún gbogbo àwọn tí wọn ń fi tìfẹ́tìfẹ́ retí ìfarahàn rẹ̀.
Agọ ọlọpaa meta ni wọn dana sun, koda awọn janduku ọhun tun sọ ina si ileẹjọ to wa ni Oyigbo.
‘Ń jẹ́ o kò gbádù ìwé náà?
Elija bọ́ aṣọ àwọ̀lékè rẹ̀, ó fi lu odò náà, odò sì pín sí meji títí tí Elija ati Eliṣa fi kọjá sí òdìkejì odò lórí ìyàngbẹ ilẹ̀.
Drums musical instrument: Ka bí o ṣe le mọ èdè Àyàn àti àgbọ́yé ìlù
" Muftau ni ggẹ bi akọsilẹ, laarin ẹgbẹrun mọkanlelogun si ọgbọn ni ọmọ ẹgbẹ Shiite to wa ni Naijiria.
18 Ìjìyà tí èyítí ó mú èmi tìkara mi, àní Ọlọ́run, tí ó tóbi jù ohun gbogbo lọ, láti gbọ̀n-rìrì nítorí ìrora, àti lati ṣẹ̀jẹ̀ nínú gbogbo ihò ara, àti láti jìyà ní ara àti ẹ̀mí—àti lati fẹ́ pé kí èmi máṣe mu nínú aago kíkorò náà, tí èmi sì fàsẹ́hìn—
Nígbà náà ni n óo lè dá àwọn tí ń gàn mí lóhùn,nítorí mo gbẹ́kẹ̀lé ọ̀rọ̀ rẹ.
Eyi n waye lẹyin ti Akpabio kọ lati darukọ awọn aṣofin ti ajọ NDDC gbe iṣẹ fun, gẹgẹ boṣe sọ lasiko ti ile n wadii ẹsun inakuna ti wọn fi kan ajọ naa l'abẹ iṣakoso rẹ.
ni ile-itaja  ti o le ni mẹ́rìnlélọ́gọ́jọ (164)
Ni ọdun 2014, ikọ alakatakiti Al-Shabaab ṣe irufẹ ikilọ yii to rọ mọ ẹrọ ibanisọrọ alagbeka ti wọn kede nigba naa wi pe ko saye lilo ohun elo ayelujara nibẹ titi di akoko yii.
ifowosowopo gbogbo omo ile igbimo asofin naa lati se agbekale ofin ti yoo mu
Awon odo ti o kogun si guusu, ila-oorun ati iwo oorun orile-ede yii, ti sekilo fun ijoba apapo lati wa woroko fi sada si ikolu awon darandaran lorile-ede yii, leyi ti o le sokunfa adinku ounje fun awon ara-ilu.
ede yii fun iwa ọmọluabi ti won hu lasiko ti won n beere  fun ekunwo fun awon omo egbe won.
Olúwarẹ̀ yóò kọjá odò aró ṣùgbọ́n èèm-ejì ni olúwarẹ̀ yóò dá odò ẹ̀jẹ̀ kọjá.
Muhammadu Buhari  ti fontẹ lu sise atunto
Tí èyí bá ti ṣẹlẹ̀, kí àwọn tí ó wà ní Judia sálọ sí orí òkè.
Lara awon asoju to lo sabewo naa ni olori otelemuye Suh Hoon ati oludamoran lori eto aabo, Chung Eui-yong.
Ó ní, “Ọjọ́ ń bọ̀, tí n óo fìyà jẹ àwọn tí a kọ nílà, ṣugbọn tí wọn ń ṣe bí aláìkọlà, 
Njẹ́ ẹ mọ̀ pé orílẹ̀-èdè Nàìjíríà ló n wo 'Blue film' jù?
World Food Day: Wo àwọn oúnjẹ ìṣẹ̀mbáyé Yorùbá tó ti ń di àpatì Kò sí ìdí fún àjọyọ̀ lórí ọdún kan ìṣèjọba Fayemi - Ekiti PDP Kíni ẹ mọ̀ nípa Mama Rainbow tó jẹ́ àgbà òṣẹ̀ré tíátà Yoruba?
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Bàbá ọmọ tí Mammadou Gassama dóòlà ẹ̀mí rẹ̀ rẹ́wọ̀n he ní France 28 Èbibi 2018 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 25 Owewe 2018 Oríṣun àwòrán, Reuters Àkọlé àwòrán, Aare France Emmanuel Macron gba Gassama lalejo lojo Aje.
Ọ̀rọ̀ǹpọ̀tọ̀niyùn, Aláàfin obìnrin àkọ́kọ́ rèé, tó ní nǹkan ọkùnrin Barca dín dòdò ìyà fún Man United nílé wọn Oní gègé àrà Oladejo Okediji d'ẹni ilẹ!
''Ọọdunrun miliọnu Naira ni mo na lati ri wi pe gbogbo eto to ki wn ba le pada wa sile.
Boṣe gori alefa Emir Awọn kan gbagbọ pe bi Sanusi ṣe gori alefa Emir lọwọ oṣelu ninu.
Sim Card Regulation: Amòfin kan ní iye ‘Sim Card’ ta bá ní, kò ní ǹǹkan ṣe pẹ̀lu ìwà ọ̀daràn
Oríṣun àwòrán, Dele Momodu Mercy Aigbe ṣá ọmọ rẹ̀ sínúu fíìmù tuntun, wo itú tí ọmọ ọdún mẹ́wàá náà pa Ọkọ mi kò fẹ́ràn oúnjẹ òyìnbó àfi ti ìbílẹ̀ - Lizzy Anjorin Daddy Freeze túbá!
Ṣebí èmi ni mo fọwọ́ mi ṣe gbogbo nǹkan wọnyi?
CAS CONDUCTS OPERATIONAL VISIT TO KANO, COMMISSIONS MODULAR THEATRE AT 465 NAF HOSPITALhttps://t.
Ohùn OLUWA ń yọ iná lálá.
Corornavirus:A o gbé pápákọ̀ ofurufu Eko ati Abuja ti laipẹ- Hadi Sirika
Ọgbẹni Odinga lo fidi rẹmi ninu eto idibo lorilẹede Kenya lọdun to kọja,bẹẹ si ni ipinnu rẹ lati sebura fun ara rẹ loju taye gẹgẹbi olori orileede ọhun nijọba sọ pe o ta'pa si ofin, ti awọn alaṣẹ si ni o jẹ iwa iṣọtẹ sijọba.
Ni eyi ti o n ro awon odo lati lo anfaani yii, lati maa jiroro lori awon ohun ti o le mu idagbasoke ba eto oselu, isejoba ati orile-ede Naijiria”.
Ẹ pa wọ́n run patapata, ati gbogbo ohun tí ó wà níbẹ̀; ẹ fi idà pa gbogbo wọn ati àwọn ẹran ọ̀sìn wọn.
A ko ridi ọrọ fi mulẹ ibi ti iroyin yii ti kọkọ jẹ yọ, ṣugbọn o bẹrẹ lẹnu igba ti awọn eeyan ko ri Olori Naomi nita lasiko ọdun Ọlọjọ to waye.
Lara awọn ololufẹ rẹ tilẹ ki i pe ọgọta ọdun lo pe loke eepẹ bo tilẹ jẹ pe ọlọjọ ibi funrarẹ ko sọ ọ jade pe ọgọta ọdun loun pe.
Nítorí náà, nisinsinyii, ẹ kíyèsí àwọn ohun tí ń ṣẹlẹ̀ si yín: 
Oríṣun àwòrán, Saharareprters Ni awọn ibi kan, awọn to n ba wọn kọ idanwo tilẹ sapamọ sinu ile igbọ̀nsẹ̀.
Nítorí náà, ọmọ mi, fetí sílẹ̀ kí o sì ṣe ohun tí n óo sọ fún ọ.
Nigeria 2019 Elections: Akala ní APC kò tó bẹ́ẹ̀ láti yọ ọmọ òun nípò alága
5 fun aṣofin kọọkan ni ọmọ Naijiria ti bẹnu atẹ lu eyi to mu ki ajọ SERAP sọ lori Twitter wi pe awọn n lọ ile ẹjọ lori ọrọ naa.
Ilé Ìgbìmọ Aṣofin Ipinlẹ Eko pe Ipade Ita gbangba awon Alẹnulọrọ si atunṣe ofin eto ilera to nii ṣe pẹlu eto Madanidofo ni Ipinlẹ Eko (Lagos State Health Insurance Scheme), eleyii to waye ni gbagede Ilé Ìgbìmọ Aṣofin naa ni ọjọ Ẹti, Friday.
Bí ẹyẹ idì tií tú ìtẹ́ rẹ̀ ká,láti kọ́ àwọn ọmọ rẹ̀ bí à á tíí fò,tíí sì í na apá rẹ̀ láti hán wọntí wọ́n bá fẹ́ já bọ́,bẹ́ẹ̀ ni OLUWA ń ṣe sí Israẹli.
Lasiko ti wọn n fọrọ werọ pẹlu ikọ̀ BBC, awọn oluwọde naa ni ẹru awọn agbofinro ti oju wọn ko rẹrin naa ko ba awọn rara, nitori paa jẹ, baa lẹru, ko si iku ti yoo pa agba, ti wọn ko ni ba poolo ori rẹ nibẹ.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ọ̀gá àgbà ọlọ́pàá, DSS, ẹ fún Sanusi lómìnira àti rìn fanda padà - Iléẹjọ́ pàṣẹ Ọkùnrin tó bẹ́ sì òdò ọ̀sà pa ọ̀rẹ́bìnrin rẹ̀, lòun náà fi fẹ́ kú - Iléeṣẹ́ ọlọ́pàá Kò sẹ́ni tó fẹ́ pa Buhari o, ọkùnrin tó pakuru mọ́ ààrẹ kàn fẹ́ bọ̀ọ́ lọ́wọ́ ni - Femi Adesina Yorùbá rẹwà, kọ́ nípa àwọn ọ̀rọ̀ tí ìró ẹnu wọn jọra àmọ́ tí ìtumọ̀ wọn yàtọ̀ Iwọnyi si ni awọn ẹkọ marun un ti awọn orilẹ-ede mii lagbaye n kọ lara Naijiria nidi aṣeyọri rẹ lati kapa arun ọhun.
Aisha lo sọ ọrọ naa nibi idanilẹkọ kan lori ọna ti alaafia le gba jọba lawujọ pẹlu ifọwọsowọpọ awọn ọdọ atawọn obinrin lẹyin ajakalẹ arun Covid-19.
'Àwọn ọmọ 5 kọ́ ló sọnù, ọmọ 28 ló sálọ síléeṣẹ́ foyúngbowó nípinlẹ̀ Ogun' Àwọn afurasí ṣá ìgbákejì kọmísọ́nà ọ̀gá ọlọ́pàá láàké dójú ikú Nwoko fikun ọrọ rẹ pe àṣà Igbo faaye gba ki ọkunrin fẹ iyawo pupọ.
Lọdun 1998 ni MKO Abiọla papoda ni ahamọ ijọba ologun lẹyin to ja fitafita lati gba ipo rẹ gẹgẹbi ẹni ti ilu dibo yan sipo aarẹ orilẹede Naijiria lọdun 1993.
Ọmọọba Ademiluyi ni pe ere itage ati orin kikọ ti yoo jẹ oni wakati kan ataabọ fun ọjọ mẹtala naa, ni yoo waye ni Osu Kejila ni Ilu Eko.
Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Lateef Adedimeji: Nkan tí a mọ̀ nìyíì nípa ìgbéyàwó tí Lateef àti Adebimpe Oyebade7 Agẹmo 2020 Mercy Aigbe: Iṣẹ́ ọwọ́ mi ni mó n jẹ, gómìnà àbi ààrẹ kò gbọ́ bùkátà mi17 Agẹmo 2019 Fídíò, Lateef Adedimeji: Owó wa kò bá máa jóná ṣùgbọ́n aàyè ọpẹ́ ń yọ fún wa19 Ògún 2019 Toyin Abraham: Ọ̀pọ̀ èèyàn ní èké ni Mercy Aigbe ń ṣe lórí bó ṣe ki Adeniyi Johnson17 Ògún 2019 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 3 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 5 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Emi o gba 13.
Wákàtí méje ti ré kọjá lọ tí Luis Carlos Díaz ti di àwátì.
Mi ò ní wọ Uber mọ́ tí wọ́n bá leè fi owó lée nítorí àfikún owó orí tí Sanwo Olu ṣe"" Ọ̀fẹ́ ní à ń kò àwọn ọmọ Nàìjíríà tó há sí Lebanon bọ̀ wá sílé- Abike Dabiri Abọ́ fífọ̀ àti ilẹ̀ ọkọ̀ ojú omi ní gbígbá ní mó fi kọ́kọ́ bẹ̀rẹ̀ iṣẹ́- Victor Agunbiade Mo fi Àlìkùrání búra pé mò ń tọ́jú Risikat àti àwọn ọmọ mi- Bàbá àwọn ọmọ olójú búlúù Natalia Mufutau to jẹ iya awọn ọmọ yii wa lati orilẹ-ede Poland."
Obinrin to jajabọ naa fikun pe, wọn se igbeyawo tipa fun oun pẹ́lu ọmọ ẹ́gbẹ Boko Haram kan, ti oun si bimọ obinrin kan fun, bẹẹ ni wn yi orukọ oun pada si ti musulumi.
Àwọn ará ìlú Ṣekemu sì dìtẹ̀ mọ́ Abimeleki.
Ó fún àwọn tí wọn dúró ṣinṣin ní ìjìnlẹ̀ ọgbọ́n,òun ni ààbò fún àwọn tí wọ́n ń rin ọ̀nà ẹ̀tọ́.
Zelensky fẹ ṣe ni ọjọ Aiku ọjọ to jẹ ayajọ idaro awọn to ku lasiko ijọba Stalin lorileede naa.
Ọkunrin ọhun ti orukọ rẹ n jẹ Jacob Blake ti wa ni ẹsẹ kan aye ẹsẹ kan ọrun bayii nile iwosan.
Èdè Yorùbá ni wọ́n fi ngbé ètò náà s’afẹ́fẹ́ fún ìgbádùn àwa elédè káàárọ̀-oòjíire.
Esi ayẹwo ti ajọ to n gbogun ti ajakalẹ aarun, NCDC, fi sita ni ọjọ Aje fihan pe ipinlẹ mọkandinlogun, ati ilu Abuja ni awọn esi naa ti wa.
Bakan naa ni ogbeni  Joe Ajearo, aare
 Bákan náà, JJ Ọmọjuwà tẹ̀ẹ́ síta wípé dídákẹ́ Kẹ́mi Adéọ̀ṣun ti bábá pariwo ara rẹ̀.
" Mamman Daura rí ìjà ọmọ Nàíjíríà torí ó pè fún wíwọ́gilé pínpín ipò ààrẹ lẹ́lẹ́kùn jẹkùn Ìkúnlẹ̀ abiyamọ, ìkókó mẹ́jọ kú nílé ìwòsàn lálẹ́ ọjọ́ kàn Dayo Amusa gbarata lórí bí agbófinró ṣe ń pa ọ̀dọ́ láì nídìí Ẹyìn tí Hydroxychloroquine, Zinc ati Zithromax da lára yá,ẹ bọ síta wà jẹrìí mí-Dr Stella Emmanuel Gomina ọhun ni ki awọn olugbe ipinlẹ Eko farabalẹ nitori ajakalẹ arun Coronavirus ṣi n ba gbogbo agbaye finra.
Kókó gbogbo ọ̀rọ̀ náà ni ohun tí a ti gbọ́ tẹ́lẹ̀ pé, bẹ̀rù Ọlọrun, kí o sì pa òfin rẹ̀ mọ́, nítorí èyí nìkan ni iṣẹ́ ọmọ eniyan.
20 Nítorí-èyí, mo pàṣẹ fún ọ lẹ́ẹ̀kansíi lati ronúpìwàdà, bí bẹ́ẹ̀ kọ́ èmi yíò rẹ̀ ọ́ sílẹ̀ pẹ̀lú agbára mi títóbi jùlọ; àti pé kí ìwọ jẹ́wọ́ àwọn ẹ̀ṣẹ̀ rẹ, bí bẹ́ẹ̀ kọ́ ìwọ yíó jìyà àwọn ìbáwí èyítí èmi ti sọ, nínú èyíti ó jẹ́ kékeré jùlọ, bẹ́ẹ̀ni, àní nínú ìwọ̀n tí ó kéré jù ni ìwọ ti tọ́ wò ní àkókò tí mo gba ẹ̀mí mi kúrò.
Wọ́n tilẹ̀ ṣe òun léṣe ni, ní tirẹ̀, wọ́n bá lé e jáde.
Ẹnikẹ́ni tí ó bá rú èyí tí ó kéré jùlọ ninu àwọn òfin wọnyi, tí ó sì tún ń kọ́ àwọn eniyan láti máa ṣe bẹ́ẹ̀, òun ni yóo di ẹni ìkẹyìn patapata ní ìjọba ọ̀run.
Aare ni pelu owo gọbọi ti ijoba egbe  PDP lo lorile aleefa sibẹ, gbogbo nnkan ohun
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Seyi Makinde ṣe ìbúra fún kọmísánà tuntun mẹ́rìnlá 15 Ògún 2019 Oríṣun àwòrán, Seyi Makinde Gomina Ipinlẹ Oyo, Ṣeyi Makinde ti bura fawọn kọmiṣọna mẹrinla to ṣẹṣẹ yan l'Ọjọbọ nileeṣẹ ijọba ni Agodi niluu Ibadan.
Ó tún fún un ní àwọn ọmọbinrin meje ninu àwọn iranṣẹbinrin tí wọ́n wà ní ààfin.
Oríṣun àwòrán, Alamy O ni apẹẹrẹ nla gba a ni awọn ibẹta mi jẹ, nitori pe ibeji ni mo tọrọ lọwọ Ọlọrun, mẹta lo fun mi lẹẹkan naa, lati san ẹsan ọdun mẹta ti mo fi ni idaduro."
Bí Ìjàpá tí gbọ́ pé àwọn kan ti pa abukẹ́ Ọsìn, ni ó bá lọ sí ọ̀dọ̀ Ọba láti lọ sọ fún un pé ọ̀rẹ́ òun ìgbín ni o pa abukẹ́ Ọsìn.
₦30,000 owó oṣù yòó bẹ̀rẹ̀ ní September - Alága ẹgbẹ́ òṣìṣẹ́ l‘Ekiti Ìyá tó lu ọmọ ọdún mẹ́rin pa l‘Akurẹ bọ́ sọ́wọ́ ọlọ́pàá Bíodun Fatoyinbo ti fojú hàn ní àgọ ọlọpàá Idije Onga Jollof Battle to waye lopin ọsẹ to kọja nilu Accra laarin awọn alase meji naa lati mọ orilẹ€de ti irẹsi jọlọọfu rẹ dun julọ.
Ó ní ọ̀rọ̀ rẹ̀ dàbí ẹni tí ó ń fi igi tí kò ní agbára ṣe ọ̀pá ìtilẹ̀.
Kinniun kan ti jáde lọ láti inú igbó tí ó wà;ọ̀kan ninu àwọn tí wọ́n máa ń run àwọn orílẹ̀-èdè ti gbéra;ó ti jáde kúrò ní ipò rẹ̀,láti sọ ilẹ̀ yín di ahoro.
Ṣugbọn, Radhika Sanghani to jẹ akọroyin gba pe eyi ko ri bẹ ẹ.
Sarai, aya Abramu, kò bímọ fún un.
Nàìjíríà ṣí àwọn ilé ìwé padà; Ìdánwò WAEC á bẹrẹ lẹyìn ọdún Iléyá!
O sọ pe o dun mọ oun ninu pe Isa ti gba lati fẹ oun.
Àwọn ẹṣin sáré dé, pẹlu ariwo pátákò ẹsẹ̀ wọn,wọ́n bẹ̀rẹ̀ sí fi ẹsẹ̀ kilẹ̀.
” Uraya kúrò lọ́dọ̀ ọba, Dafidi sì di ẹ̀bùn ranṣẹ sí i.
Tijjani Muhammad-Bande to jẹ ẹni ọdun mọkanlelọgọta ni wọn bi ọdun Ọjọ Keje, Osu Kejila, ọdun 1957 ni ilu Zagga, ipinlẹ Kebbi ni ariwa orilẹede Naijiria.
Yan ipinlẹ rẹ Yan ilu rẹ (O n gbe ilu jade lọwọ .
Capital Territory, FCT), Mohammed Bello lo soro yii  lasiko to n ba awon akoroyin soro leyin ipade
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Akomolede ati Aṣa: Mọ̀ síi nípa ìró afárànma àti agbárànmọ́ fáwẹ́ẹ̀lì Yorùbá Ninu ọrọ tiẹ, Nkem sọ fun ileẹjọ pe ọdọ ọrẹ oun obinrin to wa nile ọkọ loun ko lọ lẹyin ti ọkọ oun ko fowo ounjẹ ranṣẹ si oun atawọn ọmọ mọ.
Lara iṣẹ iranṣẹ naa si ni wipe bi awọn eeyan ba fẹ gbeyawo.
"Oríṣun àwòrán, ooniadimulaife Ṣaaju akoko yii, Ọọni ni oun ti n ṣeranwọ owo ileewe tẹlẹ to fi mọ ẹkọṣẹ ati riro ọdọ lagbara ""ṣugbọn mo n ṣe eyi lati tun ko ọpọlọpọ awọn ti yoo janfani mọ wọn."
Ìgbà tí ọba gbọ́ bẹ́ẹ̀, ó pinnu òun ó fi Ẹwadapọ fún èyíkéyìí nínú àwọn ọmọ òun tí ó bá lè ṣe nǹkan tí ó jọ òun lójú jùlọ.
Ọba Ilorin ló pàṣẹ pé kí ń padà sọ́dọ̀ ọkọ mi - Risikat olójú búlúù Kére o!
Eyi si ni igba akọkọ ti orilẹede france ati Belgium yoo forigbari ni idije ife ẹyẹ agbaye lati ọdun mejilelọgbọn sẹyin ti wọn ti pade ni idije ife ẹyẹ agbaye to waye lorilẹede Mexico lọdun 1986.
"Ko to pe ogun ọdun lo ti padanu gbogbo ẹbi rẹ lọwọ ajakalẹ arun ""Spanish flu"" to kọlu agbaye lọdun 1918, lẹyin naa lo la ogun agbaye meji ọtọọtọ kọja."
Ni apapọ ẹniyan mẹrinlelaadọtalenigba lo ti ni arun Coronavirus ni Naijiria, ti ẹniyan mẹrinlelogoji si ti ri iwosan gba, amọ ti ẹniyan mẹfa si ti ku.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Obinrin jẹ amuludun' Ọmọde ṣi ni mi, ọmọ ọdun mẹtadinlogun.
"Tí ọ̀rọ̀ bá ṣẹlẹ̀ láàrín K1 àti MC Murphy ti Murphy kò si le pé Wasiu Ayinde to wá gbé ẹjọ lọ sí ọ̀dọ̀ àwọn oníròyìn , òun ló mọ ""Tí àwọn FIBAN bá sì fẹ́ lọ sí ilé ẹjọ́, kí wọ́n nìsó níbẹ̀"" Ọ̀rọ̀ ti a ń múgbọ́ jú ti Murphy lọ, a ò ni ẹjọ́ kankan ti a fẹ́ bá a rò"" Alakoso orin Kwam 1, Adebayo Olaasoju sọ fun BBC Yoruba pe, ọrọ naa ko ri bẹẹ rara nitori Kwam 1 ko lee gba ẹnikẹni leti rara."
Iyawo ọ̀kan ninu àwọn ọmọ àwọn wolii tọ Eliṣa lọ, ó sì sọ fún un pé, “Olúwa mi, iranṣẹ rẹ, ọkọ mi, ti kú, gẹ́gẹ́ bí o ti mọ̀, ó jẹ́ ẹni tí ó bẹ̀rù OLUWA nígbà ayé rẹ̀.
"Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Yomi Fabiyi: Fíìmù ‘Owó orí ẹlẹ́wọ̀n’ jẹ́ ká mọ̀ pé ìgbà ìpọ́njú làá mọ ọ̀rẹ́ ""Mo maa n promote awọn olorin, mo si mọ pe Wasiu gbọ ọrọ ti ko yẹ ni nitori ko ye mi nipa oun ti wọn gba mi leti si, kii si se eeyan bẹẹ."
'Ẹ̀yin tẹ́ẹ fẹ́ pa ara yín torí olóṣèlú, ẹ wò Fayemi àti Fayose' Ọwọ tẹ akẹkọ to fowo ileewe rẹ ta MMM Fayemi ránṣẹ́ ìbánikẹ́dùn sí ẹbí akẹ́kọ̀ọ́ FUOYE méjì t'ọ́lọ́pàá pa Ẹwẹ, fasiti FUTA tun sọ pe kii ṣe nitori pe awọn eeyan ke gbajare lori iwa awọn akẹkọọ to lu akẹgbẹ wọn naa, bi kii ṣe pe awọn tẹle ofin ti ile ẹkọ la kalẹ lori fifi iya jẹ ẹni ba tasẹ agẹrẹ sofin wọn.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù NAFDAC: Fifi òògùn apakòkòrò 'Sniper' sinu ẹwà leè jásí ewu 24 Ìgbé 2018 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 12 Bélú 2018 Àkọlé àwòrán, Ẹwa jẹ ounjẹ aayo fun ọpọlopọ ni Naijiria Bi iwọ tabi mọlẹbi rẹ ba fẹran ẹwa ni jijẹ, tete yaa tẹti si ikede pataki yi.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Àbẹ̀wò Macron: Iṣẹ́ Fela kò le parẹ́ Bakan naa ni Oyedele ni ipenija to n koju awọn ọdọ Naijiria maa n jẹyọ ninu iṣẹ oun loorekoore.
Àkíyèsí fí hàn pé irúfẹ ́ ọ ̀ rọ ̀ méjì ló wà : ọ ̀ rọ ̀ ìpìlẹ ̀ ( èyí ti a kò ṣẹ ̀ dá ) àti ọ ̀ rọ ̀ aṣẹ ̀ dá .
Gẹ́gẹ́ bí OLUWA ti pàṣẹ fún Joṣua, ó fún Kalebu ọmọ Jefune ní Heburoni gẹ́gẹ́ bí ìpín tirẹ̀ ninu ilẹ̀ ẹ̀yà Juda.
Ọjọgbọn Mohammed ṣalaye pe oludije fẹgbẹ oṣelu PDP, Lawal Wandi lo ṣe ipo keji lẹyin to ri ibo 11,062.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Iba Gani Adams: Bẹ́ẹ gbé màláíkà kan lọ sí Aso Rock, kò lè ṣàṣeyọrí O ni afurasi naa sọ pe 'ẹnikan lo bẹ awọn niṣẹ lati gba ilẹ lọwọ awọn kan ni ilu Ẹpẹ.
Gẹgẹ bi iwe akọsilẹ to wa lọdọ ọlọpaa, obinrin naa ti wn ko darukọ rẹ pade Neymar loju opo Instagram ti Neymar si dabaa pe ki wọn jọ pade ni Paris.
Alágàbàgebè yóo jèrè iṣẹ́ ọwọ́ rẹ̀ lẹ́kùn-únrẹ́rẹ́,ẹni rere yóo sì jèrè ìwà rere rẹ̀.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù 2019 Flood Alert: Àṣírí ọ̀nà tí ẹ le gbà dèna omí yale rèé.
NNPC: Òpó ọ̀pá epo tí wọn ń rì lọ́wọ́ ló fa ìṣẹ̀lẹ̀ ìbúgbàmú náà
gomina labe asia egbe oselu, All Progressive Congress, APC ti jawe olubori gege
Ìloro rẹ̀ kọjú sí gbọ̀ngàn òde, àwòrán ọ̀pẹ wà lára àtẹ́rígbà rẹ̀ lẹ́gbẹ̀ẹ́ kinni keji, àtẹ̀gùn rẹ̀ sì ní ìgbésẹ̀ mẹjọ.
Jọ̀wọ́ gba ẹ̀bùn tí èmi iranṣẹbinrin rẹ mú wá fún ọ kí o sì fi fún àwọn ọkunrin tí wọ́n tẹ̀lé ọ.
Adajọ ile ẹjọ naa, Abdullahi Ilellah sọ wi pe awọn oniduro rẹ mejeeji gbudọ ni adirẹsi ile ti wọn n gbe ni Abuja pẹlu aridaju.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Awon Gomina s'agbatẹru fun ọlọpa ipinlẹ 13 Èrèlè 2018 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Awọn Gomina ti n pe fun akoso ọlọpaa ipinlẹ fun igba diẹ Alaga ajọ awọn Gomina ni Naijiria (Nigeria Governors Forum), Abdulaziz Yari ti sọ wipe dida ọlọpa ipinlẹ silẹ yoo bojuto eto aabo to mẹhẹ lorilẹede Naijiria.
Ṣugbọn Adamu ti sọ pe ko yẹ ko ri bẹ nitori bi ẹni fi ẹmi awọn ekẹkọọ wewu ni ọrọ naa yoo ja si.
Abọ yii lo jẹ fun Olodumare, pe awọn ẹlẹyẹ naa lo n pa ara wọn.
Ayọ̀ ń bẹ fún àwọn tí ó mọ ìhó ayọ̀ nnì,àwọn tí ń rìn ninu ìmọ́lẹ̀ ojurere rẹ, OLUWA,
o fi mulẹ pe eto iṣuna owo ọlọdọọdun bayii ṣe pataki, gẹgẹ bi o ṣe wa
Kí ló ń fa ikú ọ̀wọwọ̀ọ́ níjọba ìbílẹ̀ Lagelu, n‘Ibadan?
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Arìnrìnàjò sí Libya ní iṣẹ́ agbẹjọ́rò ló wù òun, àmọ́ iṣẹ́ aṣẹ́wó ló mú ṣe ní Libya Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Arìnrìnàjò sí Libya ní iṣẹ́ agbẹjọ́rò ló wù òun, àmọ́ iṣẹ́ aṣẹ́wó ló mú ṣe ní Libya 16 Ìgbé 2020 Oniruuru iroyin lo ti n waye lori ohun toju awọn ọmọ Naijiria n ri lsna aṣalẹ ilẹ lọ sorilẹede Libya ati ni Libya gangana lọna ati jẹ ati mu.
Inú ayé tí ó fẹ́rẹ̀ dópin ni ẹ̀ ń to ìṣúra jọ sí!
Awọn aworan naa ni wọn ya lasiko ti awọn akẹẹkọ n kọ idanwo ni ile iwe fun awọn to fẹ wọ ile iwe giga Bhagat ni Haveri, ni India.
Aare egbe awon osise (Nigeria Labour Congress,NLC) ogbeni Ayuba Wabba, ni o gbe atejade yii sita  pelu awon akegbe re ogbeni Bobbio Kaigama alaga egbe awon osise Trade Union Congress (TUC)  ati ogbeni Joe Ajaero, ti oun naa je alaga egbe United Labour Congress (ULC) ni won jo fenuko lori igbese yii.
O óo jìnnà sí ìpayà, nítorí kò ní súnmọ́ ọ.
Ní àárín-in àjàkálẹ̀ náà, Alákòóso-ìlú Àríwá Dhaka ti fagilé ìsinmi ránpẹ́ àwọn ikọ̀ tí ó ń rí sí pàntí kíkó àti ìgbégidínà àpọ̀si ẹ̀fọn.
Lẹyin eyi ni awọn to ni n pọ si.
Jesu bi wọ́n pé, “Ṣé gbogbo ọ̀rọ̀ wọnyi ye yín?
Patience Udoh Patience Udoh jẹ ọkan gboogi lara awọn obinrin akinkanju to n ja fun ẹtọ awọn eeyan ni ipinlẹ Eko.
Ìjọba Róòmù kásẹ̀ nílẹ̀ káàkiiri àyé, àwọn Gẹ̀ẹ́sì gba àkóso ìlú náà, wọ́n sì yí i lórúkọ padà sí Bath.
Ó ní a kò gbọdọ̀ kọ́ ilé tí a óo máa gbé.
Lẹ́yìn náà, ni Ọlọrun gbọ́ adura tí wọ́n ń gbà fún ilẹ̀ náà.
Nígbà tí ẹ bá gbà á tán, tí ẹ̀ ń gbé inú rẹ̀, 
Aawọ naa, to n ja rainrain lori ayelujara lo da lori fidio kan to lu sita lati ọdọ ọmọ Daura, Fatimọ, eyi to se afihan Aisha to n pariwo pe wọn n gbo oun lẹnu.
"Ilẹ̀ yaara ìdáná mi ni mo joko si, ti mo n fi oogun apakokoro nu ara apo oúnjẹ onihoro kan, ni mo ri ifihan kan: Bi ogun ọdun ni mo n mura silẹ fun ajakalẹ aarun coronavirus.
Bí wọ́n bá gbọ́ràn, tí wọ́n sì sìn ín,wọn yóo lo ọjọ́ ayé wọn pẹlu ìdẹ̀rùn,wọn yóo ṣe ọ̀pọ̀ ọdún ninu ìgbádùn.
Pẹlu ojuṣe yi lawọn omiran bi ki wọn ṣe ayẹwo finifini fun awọn ti ẹka alaṣẹ ijọba wa eleyi ti wọn a ma ṣe nigbadegba.
Bẹ́ẹ̀ ni àwọn ará Asiria ṣe kó gbogbo àwọn ọmọ Israẹli lọ sí ìgbèkùn ní ilẹ̀ Asiria, níbi tí wọ́n wà títí di òní olónìí.
Oyedepo: Ẹ ṣílẹ̀kùn ọjà àmọ́ ẹ ti ilẹkun ilé Ọlọ́run, ejò lọ́wọ́ nínú - Oyedepo pariwo Oríṣun àwòrán, @DavidOyedepoMin Oyedepo, ẹni tó pariwo bẹẹ lásìkò ìsìn wákàtí àdúrà tó wáyé ní Ọjọru ni, òun fura pé ejò lọ́wọ́ nínú lórí bí ìjọba kò ṣe tíì pàṣẹ láti ṣílẹ̀kùn ilé Ọlọ́run padà.
Ibikíbi tí ẹ̀mí bá fẹ́ lọ ni àwọn ẹ̀dá náà máa ń lọ, àwọn àgbá kẹ̀kẹ́ náà a sì máa yí lọ pẹlu wọn, nítorí pé ninu àwọn àgbá náà ni ẹ̀mí àwọn ẹ̀dá alààyè náà wà.
 Alhaja Silifat ni bó tilẹ̀ jẹ́ pé òun àti professor jẹ́ músulumi, iṣẹ́ ajé àwọn kò dí ẹsìn lọ́wọ́ nítori ọ̀tọ̀ọ̀tọ̀ ni wọ́n."
Pasitọ Sam Adeyemi sọ ọrọ naa loju opo ikansiraẹni Twitter rẹ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Àwọn fíìmì òde òní ń kọ́mọ lólè àti ọ̀pọ̀ ìwà burúkú Ko ju ọjọ mẹta ti wọn sin oku akọbi, ni ọmọ keji naa bẹrẹ aisan, ti iya wọn tun sare lọ sọdọ Ọrunmila, ṣugbọn ọmọ naa tun ku.
Oówo Liliya tún ni ìbẹ̀rẹ̀ ọdún yìí nígbà to gba ara rẹ̀ bi ó ṣe rí, ó kọ ọ̀rọ̀ si ojú òpó facebook rẹ̀lóri gbogbo ǹkan to n koju tó si gbe fọtọ rẹ̀ síbẹ̀ pẹ̀lú lái lo wíígì.
Awon adari agba meji ti won je
Ọjọ kẹrindilogun oṣu Kejìlá ọdun 2020 yii ni yoo pe ọdun mẹwaa ti Barrister dagbere faye.
 sibesibe , awon eniyan je eyi soso to nlo sistemu ibanisoro lati so tenu ara re , pasiparo iyenu , ati igbajo .
Ninu wọn la ti ri Gini Wijnadum ati Divock Origi ẹgbẹ agbabọọlu Liverpool ti wọn jẹ goolu meji meji ninu mẹrin ti Liverpool fi sagba Barcelona.
Ó sọ òkú náà kalẹ̀ lórí agbelebu, ó fi aṣọ funfun wé e, ó bá tẹ́ ẹ sinu ibojì tí wọ́n gbẹ́ sinu àpáta, tí wọn kò ì tíì tẹ́ òkú sí rí.
Òun ati àwọn ọmọ rẹ̀ ni òun óo sì fún ní ilẹ̀ tí ó ti fi ẹsẹ̀ rẹ̀ tẹ̀, nítorí pé, ó fi tọkàntọkàn tẹ̀lé òun.
Salah kopa ribiribi ni saa ti o koja ninu idije EPL, eleyi ti o sokunfa bi iko ohun se gba lati sun saa re siwaju si.
 ní òwúrọ ̀ ọjọ ́ kejì tó ṣe iṣẹ ́ ibi rẹ ̀ tán , àwọn ọlọ ́ ọ ̀ pá gbá roof mú ní shelby , north carolina .
Awọn oluworan ni wọn n wo ọgọọrọ awọn ọlọpaa ninu aṣọ dudu ati alawọ ewe ti wọn wọ.
Oríṣun àwòrán, others Awọn ajọ adojutebi lo fi lede pe awọn oṣiṣẹ awọn wa lara awọn to ku.
"O ni: ""Ikọ wa lo ri oku rẹ ni abule Kibori lasiko ti a n ṣe iṣẹ idoola""."
Ẹ̀yìn yín bá ẹ ba ń kọja àti iwájú yín bí ẹ ba ń bọ̀ jẹ́ ohun iyí pàtàkì lójú mi.
ifesewonse ti yoo waye lopin ose ti a wa ninu re yii, paapaa julo ifesewonse
4 71241 Orilẹede Venezuela 1090 3.
Ṣùgbọ́n ní gbogbo àwọn ẹ̀bùn tí àwọn tọkọtaya yìí gbà lọ́wọ́ àwọn tí ó yẹ́ wọn sí, kò sí èyí tí ó dára tó ibùsùn idẹ tí Bìlísì fi ta wọ́n lọ́rẹ.
Olisah Metuh nàá ṣe bẹ̀ ẹ́ Olisah Metuh, tó ti fìgbàkan jẹ́ akọ̀wé ìpolongo gbogboogbò fún ẹgbẹ́ òṣèlú Peoples Democratic Party, PDP, farahàn nílé ẹjọ́ gíga tìjọba apapọ̀ nílùú Abuja, lọ́jọ́ karùn ún, oṣù Kejì, 2018 lórí kẹ̀kẹ́ aláàrẹ̀, lásìkò tó lọ fún ìgbẹ́jọ́ ẹ̀sùn gbígba irinwó mílíọ́nù Naira láti ọ́ọ̀físì olùgbani nímọ́ràn lóri ètò àábò gbogboogbò lọ́dún 2014, ṣáàjú ètò ìdìbò gbogboogbò tó wáyé lọ́dún 2015.
Gbogbo àwọn tí wọn rí ni wọ́n mú,bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé wọ́n ti sá jìnnà.
Esau bẹ̀rẹ̀ sí bẹ baba rẹ̀ pé, “Ṣé ìre kan ṣoṣo ni o ní lẹ́nu ni, baba mi?
Awuyewuye naa lọ silẹ diẹ ko tun to di ọdun 2018 ti Buhari tun kọ lati fun ajọ INEC ni iwe ẹri naa nitori pe o fẹ tun dije fun ipo aarẹ l'ọdun 2019.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù 2023 Presidency: Àwọn ọmọ Nàìjíríà ń dá awuyewuye sílẹ̀ lórí Tinubu ní Twitter 13 Ògún 2019 Oríṣun àwòrán, @AsiwajuTinubu Tinubu, Tinubu, Bọla Ahmed Tinubu!
Bi o tilẹ jẹ wi pe ajọ INEC to n ṣe agbatẹru eto idibo lorilẹede Naijiria ko lee fi ẹnu idibo naa jona sojukan naa lọjọ naa, nibi ti oludije fun ẹgbẹ oṣelu PDP, Ademọla Adeleke ti n lewaju; eto atundi ibo waye lawọn ẹkun idibo melo kan ni ọjọ diẹ si idibo naa lo yi ohun gbogbo pada ti oludije APC, Gboyega Oyetọla si wa bori lẹyin ajọṣepọ to waye laaarin ẹgbẹ oṣelu APC ati gbajugbaja oloṣelu ni, Iyiọla Omiṣore ti oun pẹlu jẹ oludije ni abala akọkọ idibo naa.
Àkójọ́pọ̀ àwòrán rèé lórí bí ìwọlé akẹ́kọ̀ọ́ ṣe lọ sí ní Oyo Ilé aṣofin Ondo fọwọ́ òsì júwe ilé fún aṣòfin mẹ́ta pé wọ́n tàpá sí òfin ilé Olórí òṣìṣẹ́ ìjọba ìpínlẹ̀ Kwara, Adisa Logun ti dágbére fáyé lẹ́yìn tó lùgbàdì àrùn Covid-19 Fọwọ́ kan obìnrin lọ́nà àìtọ́, kí o rẹ́wọ̀n ọdún mẹ́rìnlá he- Àwọn aṣòfin yarí Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Kemi Dairo: Iṣẹ́ abẹ nínú ọpọlọ àti ẹ̀rọ ni mo fi ń gbọ́ ọ̀rọ̀ báyìí Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Oríṣun àwòrán, Getty Images Ẹni ọgọta aọdun ni Maradona ko to fi aye silẹ.
Ṣaaju ọjọ Ẹti, eeyan mọkandinlogun ti ri iwosan kuro lọwọ arun naa.
Àwọn ọmọ ẹgbẹ́ PDP tó sápamọ́ kọlù mí lásìkò tí mò ń lọ sí ibi iṣẹ́, ló fa rògbòdìyàn - Olamiju Akala Ìtàn ìgbé ayé Arap Moi, ààrẹ kejì ní Kenya tí ọ̀pọ̀ ń rántí ìjọba rẹ̀ fún ìwà àjẹbánu 'Ẹ bá wa sọ fún Sanwoolu kó dárí jì wá o, ìpinú tí wọ́n ṣe l'Eko kò m'ọ́gbọ́n wá rárá' Kò sí ìfòyà tí ẹ bá ti ní nọ́mbà ìdánimọ̀, kékeré ni káàdì ìdánimọ̀ - NIMC Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Òye nǹkan wọnyi yóo ye yín ní ọjọ́ ìkẹyìn.
Ọrọ yii mu iriwisi orisirisi wa ti awọn eeyan kan n si n binu pe ko yẹ ki ajọ naa ma gba owo ki o to fun awọn ọmọ Naijiria ni kaadi mi .
Oga agba Abdulmalik wa ro awon adari iko omo ogun naa ti o je anfaani eto idanileko ohun lati samulo eko ti won ko lakoko idanileko naa.
Nígbà tí Jaredi di ẹni ọdún mejilelọgọjọ (162) ó bí Enọku.
osise ijoba lorile ede Naijiria iyaafin, Winifred Eyo-Ita, adari awon obinrin
Ọ̀rẹ́ Juda bá pada tọ̀ ọ́ lọ, ó ní òun kò rí i, ati pé àwọn ọkunrin tí wọ́n wà níbẹ̀ sọ pé kò fi ìgbà kan sí aṣẹ́wó kankan níbẹ̀.
Gẹ́gẹ́ bi ọlọ́pàá náà ṣe sọ, Dauda jí fóònù nínú ilé òun lásìkò tí òun sùn lọ́wọ́ to sì jí fóònù tó tó ẹgbẹ̀rún lọ́nà àádọ́jọ náírà.
Ó wí báyìí pé: ‘Ìwọ ẹni tí ń bẹ lórí igi, àánú rẹ ṣe mí jọjọ; ṣùgbọ́n kò sí nǹkan tí mo lè ṣe fún ọ.
 O ni: “Nitooto, ko tii si oogun to gbo arun naa sugbon oogun ti wa to n din ipa agbara re ku lara awon to ba ti lugbadi re lawujo.
Bẹ́ẹ̀ náà ni Maku, ọmọ mi.
“Ìwọ ọmọ eniyan, nígbà tí àwọn ọmọ Israẹli ń gbé ilẹ̀ wọn, wọ́n fi ìwà burúkú ba ilẹ̀ náà jẹ́.
Awọn onimọ eto ilkera ti sọ pe Lilo iboju ko le fun eeyan ni abo to koju oṣuwọn lori arun naa.
Gbogbo ọkunrin tí kò bá kọlà abẹ́ ni a óo yọ kúrò láàrin àwọn eniyan rẹ̀, nítorí pé ó ti ba majẹmu mi jẹ́.
 O ni, “alaafia bayii lo n foju han ni asiko ọba yii, ti eku n ke bi eku, ti ẹyẹ si n ke bi ẹyẹ”.
Àwọn ṣiiri ọkà tí kò níláárí wọnyi gbé àwọn tí wọ́n dára mì.
"Pásítọ̀ Enoch Adeboye darapọ̀ mọ̀ #ENDSARS, ó fún ìjọba Nàìjíríà ní ìmọ̀ràn ọ̀nà àbáyọ Mọ̀ nípa iPhone 12, fóònù ológo 5G tí kìí lo ""Charger” tó ṣẹ̀ṣẹ̀ jáde Mi ò mọ̀ nípa àwọn tọ́ọ̀gì tó da ìwọ́de EndSARS Alausa rú, mo ṣì wà lẹ́yìn yín digbí!"
 Àpèja orúkọ rẹ ̀ ni ebenezer rẹ ̀ mílẹ ́ kún Àrẹ ̀ mú Ọláṣùpọ ̀ obey-fabiyi .
Jẹ́ kí àwọ̀ rẹ̀ jọ̀lọ̀ bí ara ọmọde,kí agbára rẹ̀ sì pada dàbí ti ìgbà ọ̀dọ́;
” Ó dáhùn pé, “Ọ̀pá ni.
Wọ́n mu wọn nilu Zaragoza nibi ti awon ọlọpaa ti doola ẹmi awọn obirin mẹrindinlogun lọwọ awọn to'n gbe won wa si ile okeere lati sowo nabi.
Oríṣun àwòrán, @AuduOgbeh Àkọlé àwòrán, Ọrọ Minisita Audu Ogbeh ti fa ọpọ ariyanjiyan laaarin awọn ọmọ Naijiria Apapọ gbogbo owo yii yoo jẹ laarin ẹgbẹrun lọna aadọja naira si ẹgbẹrun lọna irinwo o le diẹ naira.
Sùgbọ́n nínú ìfọ̀rọ̀wáni lẹ́nu wò ti BBC News Yoruba ṣe fún olùdíje náà, Ó fi ìdí rẹ̀ múlẹ̀ pé títí di àsìkò yìí, ìgbìmọ̀ kò ti fi tó òun léti pé òun ni wọ́n yọ.
Koda, dẹrẹba rẹ gan an ku, Oluranlọwọ rẹ ti wọn fẹsun kan pe o mọ nipa iku rẹ naa wa ninu ọkọ ṣugbọn oun o farapa rara.
Yatọ si pe ẹni ọdun mejidinlaadọta ni, ohun to n ṣe ọpọ eeyan ni haa-hin bayii ni iroyin pe o yinbọn pa ara rẹ ni.
Kò sí ẹni tí yóo gbèjà mi ninu nǹkan wọnyi àfi Mikaeli, olùṣọ́ Israẹli; Ṣugbọn n óo sọ ohun tí ó wà ninu Ìwé Òtítọ́ fún ọ.
Enitan Ogunwusi, Ojaja 2, ti  Laroka Wanikin ti ile-ife, Oba Kole
Jada, osere binrin naa ni lasiko ti oun ati akọrin naa, August n sere ifẹ, oun ati ọkọ oun, Smith ko dijọ gbe papọ mọ bii lọkọlaya .
Bí ọ̀rọ̀ kan bá wà tí o kò fẹ́ kọ sí ìwé, kí o wí fún àbúrò mi yìí kí ó wá sọ fún mi.
Iṣẹ iwadii awọn onimọ iṣegun fidi rẹ mulẹ pe, wahala arun maa n ṣẹlẹ nigba ti igbeyawo ba waye laarin ọmọ tẹgbọn taburo.
Ẹnikẹ́ni tí kò bá tẹríba fún òfin Ọlọrun rẹ ati àṣẹ ọba, pípa ni a óo pa á, tabi kí á wà á lọ kúrò ní ìlú, tabi kí á gba dúkìá rẹ̀, tabi kí á gbé e sọ sẹ́wọ̀n.
BBC Yorùbá fọ̀rọ̀ wa Olootu Parental Guidance and counselling, Akinọla Akinrọpo lẹnu wo lori ọna abayọ siṣoro ifipaba-ọmọde-lopọ to n ṣẹlẹ lẹraléra lasiko yii.
Iwadii fihan pe lilo ilana Mediterrania to n polongo jijẹ eso, ewebẹ, ẹfọ loriṣiiriṣi, girepu, kabeeji, ẹwa ati awùsá a maa fun tọkunrin tobinrin ni agbara sii lasiko ibaraẹnilopọ.
 ipa tí ó kọ ́ kọ ́ kó ni adéjàre nínú eré orogún adédigba , èyí tí ó jẹ ́ ìgbésí ayé oyin adéjọbí .
Àwọn ni ọmọ Gileadi, ọmọ Makiri, ọmọ Manase.
Ìlànà sogúndogójì MMM tí Mavrodi dá sílẹ̀ ni àwọn olùdókówò ti máa ń jẹ èrè ìdá ogún sí ìdá márùndínlagọ̀rin owó tí wọn fi dókòwò láàárín osù kan, tó fi mọ́ owó àjẹmọ́nú mìíràn.
Wúrà ati fadaka ni wọ́n yọ́ lé e, kò sì ní èémí ninu rárá.
Kò dára kí eniyan lá oyin ní àlájù,bẹ́ẹ̀ ni kò dára kí eniyan máa wá iyì ní àwájù.
” Mo bá gbójú sókè sí apá àríwá.
Amọ lasiko ayẹyẹ ọdun kan rẹ lori aleefa ni Gomina Makinde lọ si Ileesẹ ọlọpaa kogberegbe naa nilu Agọ Arẹ to wa ni agbegbe Oke Ogun, eyi to bi awọn ọmọ Oyo, Alaafin ati Oyomesi ninu.
Nibayii, adajọ ti paṣẹ pe ki wọn o fi wọn pamọ si ọgba ẹwọn to wa ni ilu Ọwọ nipinlẹ Ondo titi di ọjọ kẹta, oṣu Kẹfa, ọdun 2020, ti igbẹjọ yoo tẹsiwaju.
Wọn rọ awọn eeyan ti wọn ti ri iroyin naa lori ayelujara wi pe ki wọ kọ eti kun sii nitotri kosi otitọ kankan nibẹ.
O nitori naa, ko le wa maa faraya lori idajọ ti ile ẹjọ gbe kalẹ nitori ile ẹjọ ni gbogbo agbara lati gbe idajọ to ba wu u kalẹ fẹni tapa si ofin.
Ewe, gomina tuntun ohun yan ogbeni Abiodun Oyebanji gege bi akowe agba fun ijoba ipinle Ekiti(Secretary to the State Government), ogbeni Biodun Omoleye gege bi oludari agba fun awon osise(Chief of Staff), bee si ni, ogbeni Olayinka Oyebode gege bi adari eka iroyin fun ile-ise gomina(Chief Press Secretary).
" imọlara [ [ iporuru ọkan ] ] tabi "" ewu kan ti o nbo wa "" ni a ti ṣe apejuwe rẹ ri ."
  Òngbẹ á sì ti máa gbẹ ènìà pẹ̀ lú.
Aarẹ Donald Trump fi fọnran ara rẹ soju opo Twitter rẹ ninu eyi to ti gbe bibeli soke to si n sọrọ wi pe titobi ni Ọlọrun.
yoo se lọ maa dibo fun awon asoju tuntun  lọjọ kẹ́tàlélógún, osu keji, odun yii, leyin igba
“Ẹ kò gbọdọ̀ di arakunrin yín sinu, ṣugbọn ẹ gbọdọ̀ máa sọ àsọyé pẹlu aládùúgbò yín, kí ẹ má baà gbẹ̀ṣẹ̀ nítorí tirẹ̀.
Wọn óo máa bẹ̀ ọ́ pé,‘Lọ́dọ̀ rẹ nìkan ni Ọlọrun wà,kò tún sí Ọlọrun mìíràn.
Bótilẹ jẹ́ pé Kanran ni oun ti di Bisóóbu síbẹ̀ ko di oun lọwọ lati ṣe ere agbelewo ti oun ba ri, nítori, ko fi bẹẹ si iyatọ laarin mejeeji.
Hamani Dìtẹ̀ láti Pa Àwọn Juu Run.
Aare tun bu ẹnu atẹ lu  bi awon kan se n  fi ero ayelujara da wahala sile lorile ede
Fun àwọn tó mọ rírì iṣẹ ti ẹrọ lee ṣe lati din wahala akoko gbọọrọ ku lori iṣ kan.
Eyi lo mu ki Marie pinnu lati pe afojusun oyun yoo jẹ iwadii nipa ibalopọ fun awọn obinrin ati ọna ti wọn fi le jẹ adun rẹ.
Sade Adu gba ọpọ ami ẹyẹ, to si tun jẹ olowo rẹpẹtẹ nilu London, aridunnu ọmọ bibi ilẹ Oodua nii ṣe.
Mo wo ẹ̀gbẹ́ ọ̀tún mi yíká,mo rí i pé kò sí ẹni tí ó náání mi;kò sí ààbò fún mi,ẹnikẹ́ni kò sì bìkítà fún mi.
Iha wo ni awọn asaaju ẹsin ati awujọ kọ si Hakika ?
ti bẹrẹ si n sọ fun awon alatileyin won lati dibo fun oludije ti egbe APC.
Pada sọ́dọ̀ mi, nítorí mo ti rà ọ́ pada.
“Lara awon to wa nibi ipolongo naa ni awon gomina ana  Babangida Aliyu ti  ipinle Niger, Sule Lamido ti Jigawa, Ayo Fayose ti Ekiti ati Attahiru Bafarawa ti ipinle  Sokoto .
Coronavirus: Bàyíì ní àwọn ọmọbìnrin Afghanistan ṣe fi èròjà ara ọkọ ṣe fẹntilátọ
Kò fibẹ́ẹ̀ tíì sí ẹ̀kúnrẹ́rẹ́ ìròyìn ìsẹ̀lẹ̀ náà sùgbọ́n ará ìjọba ìbílẹ̀ Maru kan tí kò fẹ́ kí a dá orúkọ rẹ̀ nítorí àbò sàlàyé wípé àwọn adigunjalè ọ̀hún bẹ̀rẹ̀ ọsẹ́ ní ìlú Kabaro lálẹ́ ọjọ́rú ọ̀sẹ̀ kí wọ́n tó tún sí l sí Damani Hausawa àti Damani Dankarkari lówurọ̀ ọjọ́bọ̀.
Ọlọ́pàá kò rí ǹkankan lábẹ́ pẹpẹ ilé ìjọsìn mi - Olùṣọ́àgùntàn Akure Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Mo fọ kọ́mú, pátá, ògiri ilé lórí 200,000 láìlèfọhùn lórílẹ̀èdè Oman' Fathia ati Saheed Balogun Oríṣun àwòrán, Fathia Williams Balogun Àkọlé àwòrán, Fathia ati Saheed Balogun Lẹyin igbeyawo to bi ọmọ meji, wọn tapo ija si ara ifẹ laarin tọkọ taya oṣere, Saheed ati Fathia Balogun.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Davido: Àpètàn orukọ̀ ọmọ tuntun náà ní David Adedeji Ifeanyi Adeleke 20 Ọ̀wàrà 2019 Oríṣun àwòrán, @davidoofficial Ayọ abara tintin.
Ọba Abdulrasheed Akanbi ni lati ọjọ akọkọ ti Chin to wọ aafin Iwo lo ti bẹrẹ si ni ka gbogbo ohun to n ṣẹlẹ laafin silẹ.
Boko Haram so di alainile lori.
Bí a bá wojú ẹlòmíràn nínú àwọn Ọkùnrin tàbí àwọn obìnrin tí ó kó ilà, a ó ri pé ilà náà dára púpọ̀ lójú ọ̀pọ̀lọpọ̀ wọn.
agbẹnusọ ile igbimọ aṣofin orilede Naijiria aṣofin, ninu ọrọ apilẹsọ rẹ gẹgẹ bi olugbalejo, yan-nan-na oniruuru ipenija ti o n doju kọ alaafia ẹkun apa Iwọ Oorun Gusu orilẹ-ede Naijiria.
 kii se agbara mi, bi ko se oore-ofe Olorun.
Àwọn ọmọ Israẹli yòókù náà sì pinnu bákan náà.
Ọmọ Nàìjíríà kan gbé Fásitì Oxford lọ sílé ẹjọ́ tàko oríkí ọrọ 'Mortgage' nínú ìwé àtúmọ̀ ọrọ Wo ohun tí ilé ẹjọ́ ní kí wọ́n ṣe fún Sunday Shodipe, afunrasí ìṣekúpani l'Akinyele Ki lo kọkọ ṣẹlẹ?
Elebuibon: Àwọn asòfin Ogun yóò ṣe àkóbá fún ilẹ̀ Yoruba pẹ̀lú òfín tó fágilé àsà
Bí ẹran náà bá jẹ́ afọ́jú, tabi amúkùn-ún, tabi ẹran tí ó farapa, tabi tí ara rẹ̀ ń tú, tabi tí ó ní èkúkú, ẹ kò gbọdọ̀ fi wọ́n fún OLUWA, tabi kí ẹ fi wọ́n rú ẹbọ sísun lórí pẹpẹ sí OLUWA.
Ọdun 1982 ni Tanko bẹrẹ iṣẹ gẹgẹ bi amofin lẹyin ti wọn gba a wọle sinu iṣẹ naa lọdun 1981 eyi tii ṣe ọdun kan naa to kẹkọọ nile iwe ikọṣẹmọṣẹ ofin.
Ó mú kí kòkòrò jẹ èso ilẹ̀ wọn;eṣú sì jẹ ohun ọ̀gbìn wọn.
    Èmi ni Ìgbéraga-ìbànújẹ́, ọmọ ìmọ́lẹ́ òun òkùnkùn, ti ń gbé ìpàdé ayé òun ọ̀run.
Oun ati awọn ti wọn jọ n ṣe ijọba yoo maa sare lati jẹ ki ijakulẹ naa mọ niwọnba.
ti o ye ki ijoba apapo gbe lo  sile igbimo asofin.
Mo fẹ́ kí ẹ mọ̀ dájúdájú pé yóo fi í ṣe olùtọ́jú ohun gbogbo tí ó ní.
Eyi ni iroyin tuntun to jade pe awọn agbofinro Àwọn agbófinró ń gba ńkan sílẹ̀ lọ́wọ́ àwọn olùjọ́sìn ni COZA Abuja bii iwe jọ́tà, atawọn ohun eelo ikọwe silẹ.
Ẹ dẹkun ere sísá lójú pópó láti dẹkun ìjàmbá- FRSC Àgbéyẹ̀wò àṣà: Ìdí tí Yorùbá kìí fí tufọ ikú òjìji fún èèyàn Ìpínlẹ̀ Ọ̀ṣun kò le è sanwó o ọmọ́gọ̀ lórí LAUTECH- Gómìnà Oyetola Awakọ̀ bàálù ológun òfurufú obìnrin àkọ́kọ́ ní Nàìjíríà rè e O ṣalaye pe awọn eeyan Naijiria ni ẹtọ labẹ ofin lati rinrin ajo lọ sibikibi, ṣugbọn wọn ko fi aaye gba ẹnikẹni lati ko ohunkohun wọle si Naijiria lai gba aṣẹ.
Àwọn ati àwọn ọmọ wọn yóo wà láàyè,wọn yóo sì pada wá sí ilẹ̀ wọn.
"Nigeria Police recruitment 2020: Bí ó bá fẹ́ dara pọ̀ mọ́ ìṣẹ́ ọlọ́pàá, forúkọ́ sílẹ̀ níbí Ohun tí o kò mọ̀ nípa Ebila ""One Million Boys"" àti Ekugbemi, olórí ẹgbẹ́ òkùnkùn méjì tó da ìlú Ibadan rú Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?"
Ó ní Jeremaya sọ pé dájúdájú, OLUWA óo fi òun Sedekaya lé ọba Babiloni lọ́wọ́, àwọn yóo rí ara àwọn lojukooju, àwọn yóo sì bá ara àwọn sọ̀rọ̀.
" du bois gbiyanju gbogbo ojutu to se e se si isoro iseleyameya orundun ogun - igbowo eko , propaganda , ilopo , ipinu funraeni tomoorile-ede , awon eto omoniyan , isepinya asa ati okowo , iselu , isekomunisti kariaye , ikoreyinodi , itileyin orile-ede agbaye keta "" ."
2 2337 Orilẹede Lithuania 637 22.
 lábẹ ́ àwọn ìṣẹ ̀ lẹ ̀ onídéédé , díámọ ́ ndì , nánótúbù kárbọ ̀ nù àti grafínnì ní ìgbéwọra onígbígbóná tó gajùlọ ní àrin àwọn èròjà tí a mọ ̀ .
Dafidi sì gba àwọn eniyan rẹ̀ pada, ati gbogbo nǹkan tí àwọn ará Amaleki náà kó, ati àwọn iyawo rẹ̀ mejeeji.
Ọgbẹni Johnson ti ṣepade pẹlu Ọbabinrin ilẹ Gẹẹsi, Queen Elizabeth lati gba iyọnda ko le fi ijọba tuntun lọlẹ.
Ó sọ fún mi pé, “Ọmọ eniyan, jẹ ìwé tí a ká, tí mo fún ọ yìí, kí o sì yó.
Aare Buhari tun so pe orile ede Naijria ti dekun bi wọn se n ko irẹsi wọle si orile ede Naijiria, sibe awọn kan si n gbọna ẹburu ko awọn irẹsi wọle lona aitọ, ni eyi ti o  tako igbiyanju ijọba ati kiko  irẹwẹsi ba awọn agbe.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ojú mi ti rí lọ́pọ̀ lọpọ̀, àmọ́ mo dúpẹ́ pé mo ti pé ọdún márùn ún lórí oyé- Ooni Gbogbo wọn pata lo ki Arẹmọ ati iya rẹ, Olori ShilekunOla Ogunwusi (Yeyeluwa), ẹbi, ara ati ojulumọ kaabọ si aafin.
Ọba yóo mu omi ninu odò ẹ̀bá ọ̀nà,nítorí náà yóo sì gbé orí rẹ̀ sókè bí aṣẹ́gun.
Kódà, àwọn kan tún ń gbé ìròyìn òfégè kiri pé ọkọ̀ tó pọ̀, ti wọ́n ń gbé òkú lọ sí ìlú Iseyin.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù #RevolutionNow: Àwọn olùwọ́de ń fẹ́ kí ìjọba wọ́nà àbáyọ sí ààbò tó mẹ́hẹ 5 Ògún 2019 Ko dabi ẹni pe eto iwọde Revolution now seso rere nilu Ibadan, tii se olu ilu ipinlẹ Oyo nitori paro-paro lawọn oju popo da lasiko to yẹki iwọde naa waye.
Bí wọn ta á lọ́fà, kò ní torí rẹ̀ sá,àwọn òkúta kànnàkànnà dàbí àgékù koríko lójú rẹ̀.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù NASS media coverage: À n ṣe àgbéyẹ̀wò ìlànà túntún fún àwọn akọ̀ròyìn 22 Èbibi 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Awọn alasẹ ile igbimọ aṣofin apapọ Naijiria ti ṣe atungbeyẹwo awọn ofin ati ilana ti awọn akọroyin ti yoo ṣiṣẹ nile aṣofin kẹsan gbọdọ tẹle.
Oríṣun àwòrán, @Seyi Makinde Gómìnà ìpińlẹ̀ Oyo Seyi Makinde ko gbẹ́yìn lára àwọn tọ kọ́kọ́ ki gómìnà Obaseki àti igbákeji rẹ̀, Phillip Shaibu ku oríire àṣeyọri ìdìbò.
”Jesu wí fún un pé, “O wí ire pé o kò ní ọkọ, 
Ankara ti je ohun ti onikaluku n ran ni ona ara loniranran bii aso awon oyinbo ti o n gbe ewa kaluku sita”.
Wọ́n bá kó àjẹkù burẹdi ati ẹja jọ, ó kún agbọ̀n mejila.
Laipe yii ni akọwe ile ẹjọ naa ranṣẹ wi pe o di aago meji ọsan oni ki idajọ to waye.
Kíní ṣe tí àwa ò máa ṣe àmúlò èdè wa lórí àwọn àwùjọ wọ̀nyí déédé.
Balaamu sọ fún wọn pé, “Ẹ sùn níbí ní alẹ́ yìí, bí ó bá di ọ̀la, n óo sọ ohun tí OLUWA bá sọ fún mi fun yín.
Diẹ ninu wọn re e gẹgẹ bi ọjọgbọn Nyenswah ti se sọ 1.
Ṣugbọn wolii Ọlọrun kan lọ bá Amasaya, ó sọ fún un pé, “Kabiyesi, má jẹ́ kí àwọn ọmọ ogun Israẹli bá ọ lọ, nítorí OLUWA kò ní wà pẹlu Israẹli ati àwọn ará Efuraimu wọnyi.
O ni eyi ni Sani fesi si pe oun ko ni owo fun eyi lọ́wọ.
24 Agẹmo 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 25 Agẹmo 2020 Oríṣun àwòrán, Getty Images Awon obinrin le ma jẹ awon ounjẹ kan bi wọn ba loyun, yala ki wọn fẹ ma jẹ awọn ounjẹ to sara loore lati tele ilana dokita, paapaa julọ lori awon nkan bi Sushi jijẹ, ẹran ati awọn ounjẹ miran.
Orisabunmi: Elebuibon ní àfọwọ́fà wà lára nǹkan tó n fa Àkúfà nílẹ̀ Yorùbá
Òòró ilẹ̀ tí ẹ óo yà sọ́tọ̀ fún OLUWA yóo jẹ́ ọ̀kẹ́ kan ati ẹẹdẹgbaata (25,000) igbọnwọ (kilomita 12½), ìbú rẹ̀ yóo sì jẹ́ ọ̀kẹ́ kan (20,000) igbọnwọ (kilomita 10).
atileyin fun un yin, lati fi iwa oore han fun awon ebi oloogbe naa’’.
Adeọla Shorẹmi ti ọpọ eeyan mọ si 'Princess Lanko ọmọọba Dubai' ti oun pẹlu jẹ eekan adẹrinpoṣonu lagbo ere tiata Yoruba ni ọkọ 'No Network' Iroyin sọ pe kii ṣe inu agbo ere tiata ni awọn mejeeji yii ti pade ṣugbọn ọpọ aimoye awọn araalu ni wọn ti dẹrin pẹẹkẹ wọn.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Agbenusọ fun ile isẹ ọlọọpa ni ipinlẹ Ondo ni iwadii ti bẹrẹ ni pẹrẹwu lori isẹlẹ naa.
Ìdí tí mo fi kọ ìwé tí mo kọ si yín nìyí, nítorí n kò fẹ́ wá kí n tún ní ìbànújẹ́ láti ọ̀dọ̀ ẹ̀yin tí ó yẹ kí ẹ fún mi láyọ̀.
Afeez Ọwọ: Èmi kọ́ ni mo kọ́kọ́ làwòrán Orisabunmi, ẹ ti ṣe wá rangun mọ́ mi?
nítorí náà, ibi yóo dé bá a lójijì,yóo parun kíá láìsí àtúnṣe.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Aare Muhammedu Buhari ti setan lati yan ise fun awon minisita tuntun Ìjọba Buhari ń lo agbára láti jà ìjà ẹsìn- Jiti Ogunye Òpópónà márosẹ̀ Eko sí Ibadan tún dí pa lásìkò tí ọkọ̀ epo dànù A kò ní ṣe ìwọ́de mọ́ torí a ti gbé ìjọba lọ sílé ẹjọ́ - Shiite kéde fáráyé Ipade yii to waye lọjọru ni ẹlẹkeji iru rẹ ti yoo waye laarin ọsẹ kan, ti wọn lero pe yoo wa ojutu si ipenija aabo to ba awọn ipinlẹ guusu iwọ oorun.
 Se ẹ ri awon eniyan to wa lati ipinle Borno.
Ile-ise to n mojuto irinna oko oju-omi,”The National Inland Waterways Authority (NIWA) ti setan lati fopin si aawo to wa laarin won ati ijoba ipinle Eko, eyi ti o wa ni ile-ejo lona lati mojuto ise won bi o ti to ati bi o ti ye.
Loṣu keji, ọdun 1978 ni wọn ju Funmilayọ Kuti lati oju ferese nile ọmọ rẹ Fela Anikulapo Kuti ni eyi to ja si aarẹ fun un.
A sì ti pa gbogbo àwọn yòókù run patapata.
Iwadii ajọ UNICEF, WHO, UNFPA ati banki agbaye kan fi idi rẹ mulẹ pe ninu ẹgbẹrun lọna ọgọrun igbẹbi, o din diẹ ni ẹgbẹta ninu wọn ni kii ruu la.
Àdúrà ni mo nílò kìí ṣowó - Pa Kasumu Ọlọ́pàá fi pampẹ́ òfin mú Duncan Mighty lórí ẹ̀sùn jìbìtì mílíọ̀nù mọ́kànlá 'Penis Fish,' ẹ̀ja tuntun tó rí bí nǹkan ọmọkùnrin lúwẹ̀ẹ́ jáde nínú òkun Oríṣun àwòrán, Atinuke ogungbe Àkọlé àwòrán, Ṣẹgun Ogungbe ati Ọmọwunmi, Atinukẹ Ogungbe Ṣẹgun Ogungbe ati Atinukẹ, Ọmọwunmi Ogungbe Bakan naa, Ṣẹgun Ogungbe, gbajumọ oṣere tiata naa pẹlu kun ara awọn oṣere tiata to fẹ oṣere tiata ẹgbẹ wọn lagbo oṣere Tiata Yoruba.
(DA) ati egbe oselu  Economic Freedom
Èmi ni àwọn tí ń jókòó lẹ́nu ibodèfi ń ṣe ọ̀rọ̀ sọ;àwọn ọ̀mùtí sì ń fi mí ṣe orin kọ.
Nítorí pé mo ní anfaani pupọ láti ṣiṣẹ́, bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé àwọn alátakò pọ̀.
Opolopo awon ajajan gbara lo ti benu ete lu awon idibo to ti waye seyin ni Sudan nibi ti Bashir ti gbegba oroke pelu ida merinlelaadorun ninu ogorun idibo to waye naa.
Oríṣun àwòrán, Oluwo/instagram Sugbọn bi eruku laasigbo naa se n sọ lala to nilu Iwo, ijọba ipinlẹ Osun ko fọhun rara lori ọrọ naa, titi to fi de ile ẹjọ bayii.
Tìrẹ ni wọ́n, ìwọ ni o wá fi wọ́n fún mi.
Oluwo Divorce: ko si ẹni ti kò mọ pé ọmọ ilẹ̀ òkèrè ni mó fi ṣe aya
Ṣugbọn mò ń lépa ohun tí Kristi ti yàn mí fún.
Lẹyin naa ni ọkan lara awọn ọlọpaa naa ba yinbọn fun un, wọn gbe Kolade digbadigba lọ sile iwosan ṣugbọn ẹpa ko boro mọ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Oladejo Okediji, gbajúgbajà òǹkọ̀wé Yorùbá papòdà lẹ́ni ọdún 89 10 Ìgbé 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 11 Ìgbé 2019 Oríṣun àwòrán, Acebook/Oladejo Okediji Àkọlé àwòrán, Iku mu ẹni re lọ Iku doro, iku ṣe 'ka, iku mẹ'ni 're lọ.
"Iléeṣẹ́ Instagram wọ́gilé App ""Augmented Reality filters"" lórí ẹ̀rọ rẹ̀ Kí làwọn ọmọ Nàìjíríà rí sí iléeṣẹ́ tí ààrẹ yí padà sí Ministry of Communication and Digital Economy?"
Ó gba Siria ati Silisia kọjá, ó ń mú àwọn ìjọ lọ́kàn le.
 Ó fi ẹranko sígbó { àwọn olóró } .
Igba akọkọ kọ niyii ti ipe lọ si ọ̀dọ̀ ijọba lati f'opin si eto isinru ilu, paapa nitori bi awọn agunbanirọ sẹ maa n padanu ẹmi wọn nibi ti wọn ti n sinru ilu.
"Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Mama Arsenal: Màmá àgbà yìí máa ń lọ sí ìbùdó tí wọ́n ti ń wo bọ́ọ́lù láti wòran ""Ẹni kan soso to lee fun akọrin naa lati fẹ mi ni emi funra mi, ko si ye mi bo se ni ọkọ mi fun oun ni asẹ lati fẹ mi nitori emi ati ọkọ mi ko gbe pọ mọ nigba naa, bẹẹ ni kii si se ọrọ rẹ lo pin emi ati ọkọ mi niya."
Ayé ń lọ, à ń tọ̀ ọ́ ni.
Àwọn akọni Nàìjíríà padà sílé pẹ̀lú àmì ẹ̀yẹ 121 láti Morocco Òní nilé ẹjọ́ tó ga jùlọ yóò gbẹ́jọ́ ẹ̀sùn ayédèrú sabuké tí wọ́n fi kan Buhari A fẹ́ bẹ̀rẹ̀ òfin má lo fóònù mọ́ fàwọn ọmọ wa -Òbí Iṣẹ́ ṣẹ̀ṣẹ̀ bọ́ lọ́wọ́ Seth Ator tó yìnbọn pa ọ̀pọ̀ èèyàn ní Texas ni- ọlọ́pàá Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Àwọn nǹkan tí wọ́n fi sílẹ̀ fún iṣẹ́ ilé OLUWA nìwọ̀nyí: ẹgbẹẹdọgbọn (5,000) talẹnti wúrà, ẹgbaarun (10,000) ìwọ̀n talẹnti fadaka, ẹgbaasan-an (18,000) ìwọ̀n talẹnti idẹ ati ọ̀kẹ́ marun-un (100,000) ìwọ̀n talẹnti irin.
Nínú ìwé ti Naomi kọ, ó sàlàyé pé lẹ̀yìn gbọnmisi-omi-o-tó láàrin wọn ni wọ́n pa ọkan pọ láti ji àwọn akẹ́kọ̀ọ́, ó fi kún un pé lẹ́yìn ti àwọn dé ibẹ̀ wọ́n kò mọ ǹkan ti wọ́n ó fiwọ́n ṣe kóda wọ́n gbèrò láti sun wọ́n níná ni nibẹrẹ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Nigeria Army: Ta ni Ọgágun àgbà Lamidi Adeosun tó ṣẹṣẹ gba ìgbága?
Alaṣe ijọba ba ṣe tan lati gbe e wa lọna ti o tọ.
 Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, BBC Africa Eye: ìwádìí ìkọ̀ks BBC fihàn pé àwọn kan ń jí ohun èèlò ìdáàbòbò ìjọba tà nígbo Owo ti awọn adigunjale naa ji ko din ni ọgọta miliọnu naira, ṣugbọn a ko ri kọbọ gba pada nitori awọn ara ilu to ko gbogbo rẹ tan.
won tun ro awon osise alaabo lati se ise won bi ise lojuna ati daabo bo emi ati
Miṣima, Duma ati Masa; Hadadi ati Tema; 
Ijoba apapo yoo kede owo osu tuntun awon osise leyin ti igbimo alabe sekele to n mojuto afikun owo osu naa ti setan lati jabo ipade ohun fun aare Muhammadu Buhari.
Ero ọkan gomina banki apapọ ilẹ wa, CBN Akinsola naa ko yatọ.
 lára ìpalẹ ̀ mọ ́ fún ọdún ni títún afárá ṣe àti yíyẹ ọ ̀ nà .
Ifenuko yi  je lori mimu igbeeru deba ipese omi ero  fun ipinle Kano, aleekun ba ile gbigbe ni ipinle Eko ati eto igi gbingbin  ni ipinle Ogun.
igbimo asofin ko to di pe ile igbimo asofin sun ijokoo won di ojo miiran.
Àwọn eṣú kò ní ọba,sibẹsibẹ wọ́n ń rìn ní ọ̀wọ̀ọ̀wọ́.
7 111023 Orilẹede Israel 2917 34.
Ẹkunrẹrẹ iwadii naa ni yii: Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Africa Eye: Olùkọ́ méjì ní fásitì Eko àti Ghana lùgbàdì ọ̀fíntótó BBC lórí ìwà ìbàjẹ́ Ni oju opo BBC New Yoruba ni Facebook, ọpọ ló n bu ẹnu ẹ̀tẹ́ lu iwa ti awọn olukọ yii hu nitori pe ko bojumu rara ati pe o ṣeni laanu pe ọpọ awọn olukọ to mọṣẹ olukọ daadaa lo n huwa yii.
Bird Flu: Onímọ̀ ní kò sí òògùn tó leè pa àrùn lùkúlùkú ní Nàíjíríà
Ohun tí ó ti wà láti ìṣẹ̀dálẹ̀ ayé, ohun tí a ti gbọ́, tíí ṣe ọ̀rọ̀ ìyè, tí a ti fi ojú ara wa rí, tí a wò dáradára, tí a fi ọwọ́ wa dìmú, òun ni à ń sọ fun yín.
OLUWA, Ọlọrun àwọn ọmọ ogun, ta ló lágbára bíi rẹ?
Nígbà tí kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ náà rí angẹli tí ó dúró ní ọ̀nà pẹlu idà ní ọwọ́ rẹ̀, ó yà kúrò ní ojú ọ̀nà sinu igbó.
Ile asofin agba buwọlu aba to fofin de tita siga leyọ ẹyọ
Dino Melaye fìdí rẹmi, Smart borí nílé ẹjọ́ kòtẹ́milọ́rùn Ìjọba, ẹ yé fi ẹ̀tọ́ ọmọnìyàn dun ọmọ Nàìjíríà mọ́- SERAP Ileeṣẹ ologun ni awọn akẹkọọ naa n lọ si ileewe nigba ti awọn ajinigbe ọun gbe wọn lọ.
"Lẹ́yin o rẹyin, ti mo ri pé ọmọ náà ko nifẹ si orukọ ""Obesere"" ni mo ba fi kọrin pe ẹmi ni mo n jẹ bẹẹ, botilẹ̀ jẹ́ pé mo tun fi igba kan gbé orukọ náà jù sílẹ̀ nígba ti o mú awuyewuye dáni pé àwọn obinrin ni mo n fi orin náà bu"" Ẹ̀yin o rẹyin, gbogbo aye gba orúkọ náà ti o si di ilú mọọka ti gbogbo ènìyàn n pariwo lónìí."
” Nítorí náà ni a ṣe ń pe orúkọ ibẹ̀ ní Baali Perasimu.
Aarẹ ile asofin Lawan Ahmed lo ka awọn orukọ naa sita lowurọ ọjọ Iṣẹgun.
Dokita naa ṣalaye pe iru arun yii yoo maa ran lọ ni ti awọn ọmọ tẹgbọn taburo to ba ni iru ẹjẹ bẹẹ ba si n fẹ ara wọn.
Ọmọwe Qasim Akinreti, Alaga Ẹgbẹ Akọroyin orilẹ-ede Naijiria (NUJ), ẹka ti Ipinlẹ Eko rọ Igbimọ Aṣofin naa lati ṣe agbekalẹ abadofin kan lojuna ati ri i daju pe awọn onileeṣẹ-iroyin n san owo oṣu awọn akoroyin wọn loorekoore.
Arsenal ṣẹ́ṣó ìyà, búlálà ẹlẹ́nu mẹ́ta ni Leicester City fi lù wọ́n lálù bami Igbìyànju Barcelona wá tún di ọbẹ fún wọn ti wọn si ṣe bẹ ṣe ìrìbọmi mẹ́tà lọkan fún wọn àmi àyo mẹta sodo gbáko.
Tambuwal ni iye ibo  512002 , nigba ti alatako rẹ ti omo egbe
ẹgbẹ oselu APC Adams  Oshiomhole fun  ọdun mẹ́tàdínláàdọ́rin  to pe leepẹ ilẹ.
Bọla Tinubu sọ eyi di mimọ lasiko to ṣabẹwo si gomina Sanwo-Olu ni ile ijọba ipinlẹ Eko to wa lagbegbe Marina.
Tani: Boko Haram ló lé àwọn òbí rẹ̀ lọ sí Amẹrika
Àwọn orílẹ̀èdè tó ti ṣáájú Nàìjíríà wọ ọdún 2020 Àfàìmọ̀ kí Naira Marley má fi ẹ̀wọ̀n bẹ̀rẹ̀ ọdún 2020 Iná sọ ní ọjà Kara l'Eko l'ọ́dún ku ọ̀la Saraki àgbà ló kọ́ ilé yìí fáwa arúgbó kìí ṣe Bùkọ́lá- Arúgbó Ilọrin Ààrẹ sọ èyí di mímọ nínú ìwé to ko rànṣẹ́ si àwọn ọmọ Naijiria fún ìkíni ọdun tuntun lọ́jọ́rú.
Ilé aṣòfin orílẹ̀-èdè UK n gbèrò fífí ìyà jẹ àwọn adarí Naijiria tó lọ́wọ́ nínú rògbòdìyàn ENDSARS Jemila dáná sún ilé ọ̀rẹ́kùnrin rẹ̀ àti ọ̀rẹ́bìnrin tó bá nílé Èyí ni ohun tí Ọọ̀ni sọ nípa Àrẹ̀mọ rẹ àti ètùtù tó ń ṣe lọ́wọ́ Rògbòdìyàn bẹ́ sílẹ̀ láàrin àwọn ọlọ́kadà àti àwọn òṣìṣẹ́ ọgbà ẹ̀wọ̀n ní Ibadan Adájọ́ ti pàṣẹ pé kí wọ́n mú ọmọ Rasheed Maina, Faisal, tó sá mọ́ ilé ẹjọ́ lọ́wọ́ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, LASU Ritual: Àwọn akẹẹgbẹ́ akẹ́kọ̀ọ́ LASU tí wọn fi ṣowó sọ̀rọ̀ lórí ìgbé ayé olóògbé Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Kegel: Eré ìdárayá tí àwọn onímọ̀ sọ pé ó n fikún adùn ìbálòpọ̀ fún obìnrin, tó tún n fún ọkùnrin ní agbára24 Bélú 2020 Covid 19 vacine updates: America kan sárá si Dókítà Ogbuagbu, ọmọ Nàìjíríà tó ṣàwárí abẹ́rẹ́ àjẹsára COVID-19 àkọ́kọ́25 Bélú 2020 Fídíò, Akọ́mọlédè àti Àṣà lórí BBC Yorùbá: Kọ́ síi nípa iṣẹ́ tí oúnjẹ ń ṣe lára níbí24 Bélú 2020 Fídíò, Oba Adedokun Abolarin ti Oke Ila: Ó ya ọ̀pọ̀ tó súnmọ́ mi lẹ́nu bí mo ṣe ń kọ́ àwọn akẹ́kọ̀ọ́ pẹ̀lú ipò Ọba23 Bélú 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Ní ọdún tí ó tẹ̀lé e, ní ìbẹ̀rẹ̀ àkókò òjò, ó kó àwọn ọmọ ogun rẹ̀ jọ, ó sì kó wọn lọ sí ìlú Afeki, láti gbógun ti àwọn ọmọ Israẹli.
Igba to lọ gbe lọdọ ibatan rẹ kan lẹyin ti iya rẹ ku, ni awọn aladugbo mọ pe o ni HIV, awọn ẹlẹgbẹ rẹ si bẹrẹ si ni i fi ṣe ẹlẹya.
Ninu atejade ti egbe awon osise gbe jade ,ti aare egbe naa Ayuba Wabba fowosi leyin ipade pe , igbimo elenu meta ti fenuko lori ogbon egberun naira ti awon osise orile ede yii yoo maa gba gege bi owo osu to kere julo, ni eyi ti won yoo fun ijoba apapo lati tọwọbọ.
Ibẹru to wa ni pe o ṣeeṣe ki awọn irinṣẹ idena ati amojuto to wa bayii le dawọ iṣẹ duro.
Ẹgbẹ́ agbésùmọ̀mí ISWAP ti ní adarí tuntun Ọmọbíbí ìlú Benin di ìlúmọ̀ọ́ká akẹ̀ṣẹ́ lágbàáyé Tinubu - Irọ́ ni pé mo lé Ajimobi kúrò nínú ìpolongo ìbò gómìnà l'Ọyọ Ni ọpọlọpọ igba, awọn pasitọ ti ọrọ kan maa n funra wọn jẹwọ wipe awọn ti ṣe aṣemaṣe ni tootọ, ti wọn a si tọrọ idariji ẹsẹ.
Ọdún mẹtalelaadoje (133) ni Kohati gbé láyé.
 O jẹ akọṣẹmọṣẹ ninu imọ ẹrọ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Fulani Ilorin l'ọkọ mi' Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
O ni afi ki wọn tete fi panpẹ ofin gbe aṣofin naa ni.
A óo wá gbé àwa tí ó kù lẹ́yìn, tí a wà láàyè, lọ pẹlu wọn ninu awọsanma, láti lọ pàdé Oluwa ní òfuurufú, a óo sì máa wà lọ́dọ̀ Oluwa laelae.
Novak Djokovic: Ògbóǹtarìgì agbábọ́ọ̀lù tẹníísìì Novak Djokovic ti lùgbàdì coronavirus
Ni eyi ti ọpọ ẹmi ati dukia si sọlu si aigbọra-ẹni-ye naa laarin ẹkun mejeeji.
Wọn óo di ẹni ẹ̀gàn, ẹni ẹ̀sín, ẹni yẹ̀yẹ́ ati ẹni tí a fi ń ṣẹ́ èpè ní gbogbo ibi tí òun óo tì wọ́n lọ.
Kí wọn dàbí ìgbín tí a tẹ̀ ní àtẹ̀rẹ́, tí ó domi,ati bí òkúmọ tí kò fojú kan ìmọ́lẹ̀ ayé rí.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Taribo West: Àwọn aláìní ní Italy ní mò ń fi owó ìjọ mi ràn lọ́wọ́ 26 Owewe 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 19 Ògún 2020 Oríṣun àwòrán, Others Ilumọọka agbabọọlu ọmọ Naijiria to ti di ajihinrere bayii, Taribo West ti salaye lori bo se n gba awọn ọmọ Naijiria, to lọ se asẹwo lorilẹede Italy, silẹ.
OLUWA ní ń gbé àwọn onírẹ̀lẹ̀ ró,òun ni ó sì ń sọ àwọn eniyan burúkú di ilẹ̀ẹ́lẹ̀.
Ọlọ́pàá Ìpínlẹ Ondo: Egúngún tó pa ọ̀dọ́kùnrin yóò fojú ba Ilé- Ẹjọ́
Ṣugbọn wọ́n jẹ ninu èso ilẹ̀ Kenaani ní gbogbo ọdún náà.
“Kọlu àwọn ará Midiani, kí o sì pa wọ́n run 
5 21485 Orilẹede Gambia 123 5.
Ìlú Tire ti mọ odi ààbò yí ara rẹ̀ ká, ó ti kó fadaka jọ bí erùpẹ̀ ilẹ̀, ó sì rọ́ wúrà jọ bíi pàǹtí láàrin ìta gbangba.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Mistura Oseni Akintunde: Ara múmú kìí ṣe oríṣun ìfipábánilòpọ̀, ìran àwòjù ló ń fà á Gẹgẹbi, iroyin ṣe sọ, ni aṣalẹ Ọjọbọ ni iṣẹlẹ naa wa'ye.
2 418848 Orilẹede Iran 12432 32.
Ohunkohun ti onikaluku ba ṣe loni, ọrọ itan ni yoo da lọla.
Bótilẹ jẹ pé, ilé ẹjọ kòtẹmilọ́rùn náà ni kí wọ́n pa Rev King, titi di àsìkò yìí wọn ko paa.
Ẹni tí ó bá ń pa òfin mọ́ kò ní rí ibi; ọlọ́gbọ́n mọ àkókò ati ọ̀nà tí ó yẹ láti gbà ṣe nǹkan.
Àkọlé àwòrán, Awọn ọmọ Yoruba ni Austria Orukọ wọn ni ẹgbẹ ọmọ̀ Oduduwa Salzburg Austria, ọdọọdun si ni wọn maa n ṣe ayẹyẹ Oduduwa pẹlu iwde aṣa kaakiri igboro ilu.
Oríṣun àwòrán, AFP Àkọlé àwòrán, Ni eyi ti ọpọ ẹmi ati dukia si kọlu si aigbọra-ẹni-ye naa laarin ẹkun mejeeji.
- Aregbesola Ọ̀rọ̀ SARS kọ èmi àti ààrẹ Buhari lóminú - Yemi Osinbajo Igbakeji aarẹ orilẹede Naijiria, Yemi Osinbajo ni ọrọ ikọ ọlọpaa SARS ṣe n pa awọn araalu gbọdọ wa si opin.
Iwe apileko merin ni won ka nibi idanilekoo naa, eyi ti o dale awon ipenija  ti awon onisowo n koju ni awon enu ibode orile-ede Naijiria.
Iléèwòsàn ńlá UCH nílù Ìbàdàn ni àyẹ̀wò yii yoo ti waye.
Kọmisana ọlọpa nipinlẹ Ogun, Edward Ajogun lo sisọ loju isẹlẹ yii lasiko to n safihan awọn afurasi ọdaran naa nibi ipadepẹlu awọn alẹnulọrọ lori eto aabo lẹkun ileesẹ ọlọpaa to wa nilu Ijebu Ode.
Ni ẹnu ọna ile itaja Marie-Amélie Vaillat ni Rue Bichat,awọn ara adugbo kẹdun pẹlu iwọde.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù 2018 films: Sinimá ju sinimá lọ táwọn ọmọ Naijiria gbádùn 26 Ọ̀pẹ̀̀ 2018 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 30 Ọ̀pẹ̀̀ 2018 Oríṣun àwòrán, @kemi Adetula Àkọlé àwòrán, Ṣọla Ṣobọwale di iya àwọn ọmọ to lé Eré ju eré lọ, ìran ju ìran lọ lawọn sinimá to jade lọdun 2018.
Ati pé, kí ni orúkọ àwọn tí wọ́n ń kọ́ ilé yìí?
O ti le ni ẹgbẹrun lọna ọgọrun eeyan bayii to ti ko aarun yii lagbaye, gẹgẹ bii fasiti John Hopkins University ṣe fidi rẹ mulẹ ninu iwadii kan.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Dele Momodu : Lẹ́yìn Buhari àti Atiku, èrò ọjà làwọn olùdíje yóòkù ní ìdìbò 2019 Nigba ti yoo tun pari ọrọ, Adamu ni miliọnu mẹwa ninu awọn majeṣin yii lo yẹ ko wa nileewe alakọbẹrẹ ṣugbọn ti wọn ko si nibẹ bayii.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Awọn dokita nilu Australia fẹ f'ofin de ọti mimu f'ọdun marun 9 Ẹrẹ̀nà 2018 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Tenant Creek ti ri alekun ninu iwa ipa ati gbigba ẹmi ara ẹni latari ọti amupara Awọn onimọ eto ilera ni ilu kan to wa ni gbungbun Australia ti ke gbajare ki wọn f'ofin de ọti mimu f'ọdun marun.
Oríṣun àwòrán, Science Photo Library Ní ọ̀pọ̀ ìgbà, ọ̀rọ̀ abẹ́rẹ́ àjẹsára maa n ni ọwọ òṣèlú nínú, fún àpẹrẹ, bí mínísita fún ọ̀rọ̀ abẹle ni Italy ṣe dara pọ mọ àwọn ẹgbẹ́ ti kìí gba abẹ́rẹ́ ajẹsára.
Oríṣun àwòrán, @AsoRock Lawọn oju opo ikansiraẹni, paapa Twitter, awọn ọmọ Naijiria kan ni, bi ẹgbẹ awọn olukọ fasiti se n wo isẹ niran lo yẹ ko mumu julọ laya awọn akẹkọ yii, ki wọn si wa ọna ti ijọba ati ASUU yoo se fi eegun otolo to aawọ aarin wọ.
Ipinlẹ Eko gan an ni ju ọọdunrun eniyan lọ (337).
Bẹẹ ni ọrọ baba ẹni ọgọrun ọdun kan ri, Celestine Egbunuche, ẹni ti ijọba tu silẹ ni ọgba ẹwọn lẹyin ọdun mejidinlogun to ti fi asọ penpe ro oko ọba.
Àwọn ará Kenaani ni wọ́n ń gbé ilẹ̀ náà nígbà náà.
Nigeria Visa: Ìjọba Naijiria ti mú ẹ̀dínkù bá owó ìwé ìrìnnà fún àwọn ọmọ ilẹ̀ Amerika láti wá sí Naijiria
Oyo 2020 Budget: Èyí ni àtúpalẹ̀ abá ìṣúná 2020 tí Seyi Makinde gbé kalẹ̀
OLUWA tóbi, ìyìn tọ́ sí i lọpọlọpọó sì yẹ kí á bọ̀wọ̀ fún un ju gbogbo àwọn oriṣa lọ.
" Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Bolaji Faleke ni Olùkọ́ tó ń kọ́ wa ní àṣà oge ṣiṣe lórí BBC Yorùbá Ni ọjọ kọkanla, oṣu Kẹjọ, ọdun 2020, ni ọmọ bẹrẹ sini mu Dupẹ, ko sọ fun ẹnikẹni, nitori pe 'wọn o mọ pe o loyun'.
 wọ ́ n bí ọmọkùnrin kan tí ó ń jẹ mọnigbùwà .
Lẹ́yìn náà àwọn ọmọ Lefi wọnyi: Jeṣua ọmọ Asanaya, Binui ọ̀kan ninu àwọn ọmọ Henadadi, ati Kadimieli, 
Nṣe lo maa dabi pe ki eeyan kuku wọ inu rẹ lọ ni bi eeyan ba n woo, ọpọ ara to wu olowo ẹ lo le fi da nigba kigba ninu ile.
Asori bí Sadoku, Sadoku bí Akimu, Akimu bí Eliudi.
Lẹ́yìn ọdun mẹ́ta tó kú, ilé ẹjọ́ dájọ́ ikú fún alásè tó pa Temidayo Adeleke Ǹjẹ́ o tilẹ̀ mọ Samuel Okwaraji, agbábọ́ọ̀lù Nàìjíríà tó 'ṣubú lójú ìjà?
Ọmọbìnrin ọdún 25 gún ọ̀rẹ́kùnrin rẹ̀ pa nítorí ó ní ko lọ ṣẹ́ oyún Diẹ lara awọn ohun t ri fayọ ninu ifọrọwerọ naa ree: Ifarada pọ fawa oṣere nigba ta fi n kopa ninu ere sinima yatọ si tode oni Gẹgẹ bi agba ọjẹ oṣere sinima yi ti ṣe ṣalaye, o ni tifẹtifẹ, tọkantọkan lawọn fi n se ere sinima lasiko tawọn.
Wọ́n ti dáná sun ilé mímọ́ wa tí ó lẹ́wà,níbi tí àwọn baba wa ti yìn ọ́,gbogbo ibi dáradára tí a ní, ló ti di ahoro.
Nígbà ti BBC ló síbẹ̀ láti wo ǹkan to ṣẹ̀lẹ̀ kò rí ilé kankan ti wọ́n wó lóri ilẹ̀ náà Ǹkan mẹ́jọ tó máa kọ́kọ́ ṣẹlẹ̀ kí olólùfẹ́ méjì tó pa ara wọn Owó dé!
Ijọ Satani kii ṣe fun talika: Igba ati marundinlọgbọn Dọla (N81,000) ni ọmọ ẹgbẹ tuntun ma n san lati darapọ.
Wo bí ọwọ́ orílẹ̀-èdè Dubai ṣe tẹ Ramoni Igbalode tí gbogbo ayé ń pè ní Hushpuppi Bí àdúrà Fìdáù ọjọ́ mẹ́jọ fún Abiola Ajimobi yóò ṣe lọ lónìí rèé Ènìyàn 603 ni èsì àyẹ̀wò fihàn pé ó tún ti ní ààrùn Coronavirus ní Nàìjíríà Irọ́ ni o, Ebenezer Obey ò kú!
Àwọn ọmọ oníjó wọ̀nyí, púpọ̀ nínú wọn a máa wọ aṣọ bí eléégún aláràbarà.
Nítorí pé àwọn alufaa tí ó gbé Àpótí Majẹmu OLUWA dúró láàrin odò Jọdani, títí tí àwọn eniyan náà fi ṣe gbogbo ohun tí OLUWA pa láṣẹ pé kí Joṣua sọ fún wọn, gẹ́gẹ́ bí Mose ti pàṣẹ fún un.
Ajọ Lasema sọ pe awọn oṣiṣẹ pana-pana ri ina naa pa lẹyin to jo ọkọ agbepo mẹrin, o si tun sọ pe iwakuwa ọkọ lo fa ijamba naa.
Baba ati ọmọ ń bá ẹrubinrin kanṣoṣo lòpọ̀, wọ́n sì ba orúkọ mímọ́ mi jẹ́.
Ni ọjọ Kẹta oṣu Kẹwa ọdun yii ni idibo aarẹ yoo waye ni Amẹrika.
ẹ gun orí òkè Lẹbanoni lọ, kí ẹ kígbe.
Nígbà tí mo wo ààrin àwọn wọnyi, kò sí olùdámọ̀ràn kan,tí ó lè dá mi lóhùn nígbà tí mo bá ní ìbéèrè.
Apongbon flyover, Bridge Ijọba ibilẹ Ikeja Lagos Island 38.
O ni aifi ẹnikankan jofin lo faa ti awọn olubi ẹda naa fi n tẹsiwaju ninu iwa ọdaran.
Ìbànújẹ́ dorí mi kodò patapata,mo sì ń ṣọ̀fọ̀ kiri tọ̀sán-tòru.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Omolola Arohunmolase Welder: Mo ti fí iṣẹ́ 'Welder' gbayì láwùjọ, tó mo fi tọ́ ọmọ yanjú Dipo bẹ ẹ, igbimọ aṣoju lati ilu Abuja, ni Buhari ran lọ.
Bí ó bá ṣẹ̀, n óo bá a wí, n óo sì jẹ ẹ́ níyà, bí baba ti í ṣe sí ọmọ rẹ̀.
Bí ẹ óo ti máa bèèrè lọ́wọ́ àwọn wolii ni pé, “Kí ni ìdáhùn tí OLUWA fún ọ?
Ogbeni Miyazaki salaye pe, ijoba orile-ede Japan ti seto idanilekoo lati mu igberu ba eto oro-aje orile-ede United Arab Emirate (UAE), orile-ede India ati awon orile-ede miiran nile Asia.
Àwọn tí Ọlọrun ti yàn tẹ́lẹ̀, àwọn ni ó pè.
Ṣugbọn nígbà tí ó gbé ara rẹ̀ ga, tí ó sì ṣe oríkunkun, a mú un kúrò lórí ìtẹ́ rẹ̀, a sì mú ògo rẹ̀ kúrò.
Mo sì rò pé èmi náà ní Ẹ̀mí Ọlọrun.
 Itumọ rẹ ni pe, ile Adebisi to wa ni Idikan nilu Ibadan jẹ ile to gbajumọ, to tobi pupọ, to si ni ọgọrun-un yara, eyi ti ẹnikan ti ko ni owo nla lọwọ, ko lee dasa pe oun fẹ kọ rara."
Lara awọn ohun ẹṣọ abalaye ti awọn ara Benin mọ ni ọkan lara aworan adiyẹ ide ti Ilẹ Gẹẹsi fẹ da pada yii.
Agbẹ onikoko parau ni baba MKO Abiọla, ti iya rẹ si n ta obi, to si maa n ran baba rẹ lọwọ ninu isẹ naa, amọ lọdun 1946, nkan dakun, nigba tawọn eebo to n ra koko ni koko ti baba rẹ gbin ko dara, ki wọn lọ jo nina ni, isẹlẹ yii si lo ran baba naa sọrun ni aipe ọjọ Oríṣun àwòrán, @mko_abiola Eto ẹkọ MKO Abiọla: Ọmọ ọdun mẹsan ni Moshood wa to fi n sẹ igi ta ni owurọ kutukutu ko to lọ sile iwe nitori ati jẹnu, eyi si la lee pe ni okoowo akọkọ ti yoo dawọ le ni kutukutu aye rẹ, ileẹkọ alakọbẹrẹ African central school, si lo kọkọ ti bẹrẹ eto ẹkọ rẹ Nigba to pe ọmọ ọdun mẹẹdogun, Moshood da ẹgbẹ olorin kan silẹ, ti wọn yoo kọ orin fawọn alejo lasiko ayẹyẹ, ọna lati ri ounjẹ oojọ jẹ ni, wọn kii si fun wọn ni owo afi ounjẹ.
Nigba to dagba, Ogedengbe doju ọpọ ifẹhonu ija han kọ awọn ara Ibadan ti wọn n fiya jẹ awọn ara Ijeṣa.
O po oogun eku naa mọ ẹwa to fẹ jẹ, ko le pa ara rẹ ati ọmọ tuntun naa, sugbọn nigba to ku diẹ ko gbe oogun naa jẹ, lo ba yi ọọkan rk pada, to si gba ile ijọsin kan lọ lati lọ ri Olusọaguntan ibẹ.
Ẹ ya ọdún tí ó gbẹ̀yìn aadọta ọdún náà sí mímọ́, kí ẹ sì kéde ìdáǹdè jákèjádò gbogbo ilẹ̀ yín fún gbogbo àwọn tí wọn ń gbé inú rẹ̀, yóo jẹ́ ọdún jubili fun yín.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Mamman Daura: Ohun tó yẹ kóo mọ̀ nípa ìbátàn Buhari tó ń bá a gbé l'Abuja 15 Ọ̀wàrà 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 16 Ọ̀wàrà 2019 Oríṣun àwòrán, Mamman Daura Àkọlé àwòrán, Mamman Daura Iwadii ti ile iṣẹ iroyin BBC ṣe fihan pe Mamman Daura ko ni ipo oṣelu kankan to di mu lorilẹede Naijiria bo tilẹ jẹ pe ibatan rẹ ni.
Àwọn ọmọ Nàìjíríà la ohùn Ọmọ ọdún kan póòrá!
Nígbà náà ni wọ́n tó yipada tí wọ́n sì wá sí Enmiṣipati (tí ó tún ń jẹ́ Kadeṣi), wọ́n sì ṣẹgun gbogbo ilẹ̀ àwọn ará Amaleki ati ti àwọn ará Amori tí ń gbé Hasasoni Tamari.
Ni ọsan ọjọ aiku ni wọn pa arakunrin naa lasiko to n pada bọ lati oko rẹ.
Iroyin naa ni ọkọ akẹru ọhun, ti nọnba rẹ jẹ XE331MKA lo ko ero bii mejidinlọgọta, to si n bọ lati ilu Sokoto wa si Ijẹbu Ode lasiko to rebọ sinu odo Ogun ni idaji kutu hai ana.
wa nibẹ kuro ,ti awon oludibo si n sa asala fun ẹmi wọn, won si n dana sun awon
Ọpọlpọ iroyin lo jade pe ẹsẹ rẹ rinlẹ gan ni nigba akọkọ ti Buhari jẹ adari orilede Naijiria labẹ ijọba ologun lọdun 1983.
Kò sí àwọn tí ó ń pọn ọtí ninu rẹ̀ mọ́bẹ́ẹ̀ ni a kò gbọ́ ariwo àwọn tí ń pọn ọtí mọ́.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Iya Rainbow: Olùtọ̀jú aláìsàn ni kó tó di òsèré 16 Ọ̀wàrà 2018 Oríṣun àwòrán, @mamarainbowofficial Gbaju-gbaja oṣere tiata, Idowu Philips, ti gbogbo eniyan mọ si Mama Rainbow wa lati ilu Ijẹbu Ode, nipinlẹ Ogun.
Ore Helicopter: Iléeṣẹ́ ọkọ̀ òfurufú ní wọn fi ẹlikọ́pútà tó dá àríyànjiyàn sílẹ̀ dóòlà ẹmí ni
Iwe itan aroso: Notre-Dame of Paris ti Victor Hugo gbe jade lọdun 1831 ni o ṣi oju awọn eeyan pada sile ijọsin ti wọn ti pati naa.
Ṣugbọn pupọ ninu awọn ọmọ igbimọ to n ṣe iwadii owo ọhun fesi pe, Pondei ko lẹtọ lati pa iru aṣẹ bẹẹ niwaju igbimọ ọhun.
Prophet Israel Oladele: Wo bi wọ́n ṣe n ṣe àmójútó ilé ìjọsìn CCC Genesis Global
 A ko gbodo bẹnu atẹ lu ipo Pataki ti o wa, nitori orile ede Naijiria
Cancer Marriage: Oṣù kan péré ni Tash fi ṣe ìgbéyàwó pẹ̀lú Simon kó tó kú
Absalomu ati gbogbo Israẹli dáhùn pé, “Ìmọ̀ràn ti Huṣai dára ju ti Ahitofeli lọ,” nítorí pé OLUWA ti pinnu láti yí ìmọ̀ràn rere tí Ahitofeli mú wá pada, kí ibi lè bá Absalomu.
Bakannaa, o dupe gidi lowo Oba-birin naa fun gbigba alejo ipade naa,ti o si se apejuwe re ni “asegun ti o duro sinsin”Saaju ninu oro re,Omo-oba kunrin Charles so fun awon olukopa wi pe Ajo Commonwealth titun yi ni ojuse lati se,oun si gba ladura wi pe ipade naa yoo tun mu ibasepo to danmoran wa laarin awon orile-ede metalelaadota naa,O le ni awon ogorun oloogun  ti won duro leselese niwaju afin naa , ti won duro sepesepe ,ti won si yinbon ota metalelaadota lati si ipade naa.
Nítorí ó wà ní àkọsílẹ̀ pé, “Ẹni tí ó mú àwọn ọlọ́gbọ́n ninu àrékérekè wọn.
Ó ṣe ìwo kọ̀ọ̀kan sí igun mẹrẹẹrin pẹpẹ náà, àṣepọ̀ mọ́ pẹpẹ ni ó ṣe àwọn ìwo náà, ó sì yọ́ idẹ bò wọ́n.
Yoruba Films: Femi Adebayo sọ ẹran àgbò rẹ̀ lórúkọ tuntun, Bukky Wright ṣ'ọjọ ìbí
’ Ohun tí ẹ kò mọ̀ tí ẹ̀ ń sìn, òun ni mò ń sọ̀rọ̀ rẹ̀ fun yín.
Koda, n se ni wọn n gbarata pe eto isakoso ijọba apapọ ti duro soju kan soso ju, o si yẹ ki Buhari tete mọ odo ti yoo da ọrunla si nipa yiyan awọn minisita ti yoo ba sisẹ.
'Obinrin jẹ amuludun' Fọlọrunṣọ Alakija: Obinrin nilo imọ Obinrin kan rèé tó borí ogun Gẹ̀ẹ́sì Kíni ìdí ti wọn fi ń lọ ọmú obinrin Derin Eleran ṣalaye nipa idojukọ ati ipenija to wa ninu iṣẹ alapata pe ko rọrun rara ṣugbọn inu idọti ni owo wa.
O soro lori ise akanse ijoba lori ipese omi to mo gaara fawon olugbe ekun naa lasiko.
gomina labe asia egbe oselu PDP (People’s Democratic Party )  gege bi eni to jawe olubori ninu eto idibo
Wọ́n dá Farao lóhùn pé, darandaran ni àwọn gẹ́gẹ́ bí àwọn baba wọn.
 ÀÌrìnpọ ̀ ejò ló sá ǹ jẹ ejò níyà.
Onnoghen: Ẹ má yọ́nú sí ọ̀rọ̀ orílẹ́èdè wa - Buhari Yorùbá, ọmọ ọdún mẹ́jọ tà ọmọ òyìnbò yọ nínú ayò Chess l‘Amẹrika Lọ́wọ́lọ́wọ́: Ìjọ àgùdà tó ti wà lát'ayédáyé ǹ jóná Àwọn ìkìlọ̀ tí ọ̀gá àgbà ọlọ́pàá là kalẹ̀ lórí ìpànìyàn Eko Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Colorado ni Amẹrika àti odò Awaye ní Naijiria nikeji àdágún órí àpáta ní gbogbo àgbáyé!
Gbajabiamila kéde èróńgbà rẹ̀ láti jẹ adarí ilé aṣojú ṣòfin l'Abuja Ọ̀jọ̀gbọ̀n Pius Adesanmi kú nínú ìjàmbá bàálù Ethiopia!
    Gẹ́gẹ́ bí ètò tí a ti ṣe tẹ́lẹ̀, gbogbo àwọn ọdẹ ti yóò ba ni lọ sí ìrínàjò náà yóò kọ́kọ́ wá sí ilé mi, ibẹ̀ ni a o ti ko ẹsẹ̀ lọ sí ààrin ọjà.
" 'Awọn eeyan n ku' Eeyan mejila lo fo ṣanlẹ to ku lowurọ ọjọ Aiku, ọjọ kẹrindinlọgbọn oṣu kẹrin ọdun 2020 nikan eleyi si tun mu ki ohun tawọn eeyan nsọ lori pe boya arun coronavirus lo n ṣokunfa iku naa ga soke sii paapaa julọ pẹlu bi ko ṣe si ayẹwo ni ipinlẹ Kano fun ọjọ mẹta gbako bayii.
 Ile igbimọ asofin l'Ekiti ranṣe pe Fayose lori owo Kansu Ṣe ẹ mọ Oṣokomọlẹ ipinlẹ Ekiti?"
Ẹ jẹ́ ká mú u lọ́kọ̀ọ̀kan ní ṣókí-ṣọ́kí.
Òfin ìhun gbólóhùn ni a ń pe ( 4 ) .
Lara oun ti awọn dokita naa tọka si nipe ileeṣẹ ọlọpaa n da awọn ọmọ ẹgbẹ wọn duro, eyi ti ko yọ awọn ọkọ to n gbe alaisan silẹ.
Ta ló ṣe oriṣa, ta ló sì yá ère tí kò lérè?
Ọlọrun tún wí pé, “Mo ti pèsè gbogbo ohun ọ̀gbìn tí ń so èso ati igi tí ń so èso tí ó ní irúgbìn ninu fún yín láti jẹ.
Nínú mílíọ̀nù mẹ́rìn o lé díẹ̀ náà tí ó jí, ẹgbẹ̀rún lọ́nà ẹgbẹ̀rín pọ́ùn péré ní wọ́n rí gbà padà.
Ènìyàn lásán ní ọba ilẹ̀ Yoruba tí kò bá ṣe ètùtù, ẹ má tẹ ìṣẹ̀ṣe mọ́lẹ̀ - Elebuibon Ìpínlẹ̀ Eko kéde afurasí mẹ́ta míràn tó ṣeéṣe kó ni Coronavirus Àgunlá!
Ọmọ oloogbe fi iroyin naa si oju opo ayelujara Twitter rẹ, o si lo dupẹ lọwọ aarẹ Buhari.
Ẹwẹ̀, ìdá ogún lọ padà wá ń tún ní ìpèníjà tó pọ̀.
 Aare ana, naa dibo ni deede aago mẹ́sán án abọ (9:30 a.
Jide Kosọkọ: Isẹ́ tíátà yóò gòkè tíjọba bá gbówó kalẹ̀ láti seré
Gbajamiala to kọwọrin pẹlu awọn aṣofin ilẹ Naijiria la gbọ pe adari ile aṣojuṣofin ilẹ Ghana, Mike Oquaye gba lalejo.
Nígbà tí àwọn ará ìlú náà jí ní òwúrọ̀ kutukutu, wọ́n rí i pé, wọ́n ti wó pẹpẹ oriṣa Baali lulẹ̀, wọ́n sì ti gé ère oriṣa Aṣera tí ó wà ní ẹ̀gbẹ́ rẹ̀ ati pé wọ́n ti fi mààlúù keji rúbọ lórí pẹpẹ tí wọ́n ṣẹ̀ṣẹ̀ kọ́.
Ninu awọn oludije mẹfa ti wọn fi iwe pe,mẹta lo yọju iyẹn Rabiu Ahmed Rufai AAN,Kunle Olagbegi ti National Democratic Party ati Khadijah Abdullahi ti ẹgbẹ Alliance for New Nigeria ANN.
Operation Amotekun: Àwọn ajínigbé ṣá mi láàkéé nínú igbó, ìdásílẹ̀ Amotekun dára
"Bakan naa ni mo tun fẹ sọ pe eeyan bii temi ko nilo awawi, ọmọ mi (Dereck) Chisora sọ fun mi pe bi mo ba fẹ bori ninu ija yii mo gbọdọ ṣetan lati ku.
“Nítorí náà, n kò ní dákẹ́;n óo sọ ìrora ọkàn mi;n óo tú ìbànújẹ́ mi jáde.
Oríṣun àwòrán, @raufaregbesola Àkọlé àwòrán, Oyetọla ni INEC kede pe o bori idibo naa Ni bayii ti idajọ yoo waye loni, igun mejeeji lo ti n fọwọ sọya pe lọdọ awọn ni ọsan didun yoo so si lori idajọ naa.
Boss Mustapha, ẹni ti o jẹ akówe gbogbogbo ijọba orilẹ-ede yii lo fi ọrọ naa lede ni ọjọ Isẹgun pe, ayẹyẹ yiyan awọn minisita tuntun naa yio waye ni deede aago mọkanla owuro loni.
Wọn kò sìn ọ́ ní agbègbè ìjọba wọn, ati ninu oore nla rẹ tí o fun wọn, àní ninu ilẹ̀ ẹlẹ́tù lójú nla tí o bùn wọn, bẹ́ẹ̀ ni wọn kò sì yipada kúrò ninu iṣẹ́ burúkú wọn.
 bákan náà ló tún lọ sí ilé ìwé ẹ ̀ kọ ́ àgbà ti Ìbàdàn ( university of ibadan ) , níbi tí ó ti gba oyè b.
Ó di dandan kí ará India yìí sọ ìdí tó fi ń sìn kìnìhún- Egbeyemi Ṣugbọn nigba ti awọn ara adugbo figbe ta, igbimọ amuṣẹya fun ajọ alatunṣe agbegbe ni ìpínle Eko, Lagos Environmental Sanitation & Special Offences mu iṣẹ ṣe ni wara n sesa lati lọ gbe e kuro ni ile naa ki ọrọ to di idakeji rẹ.
Ó bá wá dojúbolẹ̀, ó ń bẹ̀ ẹ́ pé, “Alàgbà, bí o bá fẹ́, o lè sọ ara mi di mímọ́.
Ijọba ni o di dandan lati maa ṣe ayẹwo  Mo ṣi wa láyé"" fawọn oṣiṣẹ fẹyinti loorekoore ki wọn le mọ ohun to yẹ ni ṣiṣẹ fun wọn."
Ogbeni Bashir Garrga to je oludari ile-ise naa ni  ekun ila oorun Ariwa , fi isele naa mule pe awon meta lara awon olugbe naa farapa.
BBC gbadura fun gbogbo ololufẹ wa to n woju Oluwa pe, iru ẹbun wọnyii a wọle tọ yin bi o ṣe wu yin laipẹ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù 2019 Elections: Àjọ tó ń wo bí ìdìbò se ń lọ ní ìsẹ̀lẹ̀ náà léwu 21 Ẹrẹ̀nà 2018 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 19 Bélú 2018 Oríṣun àwòrán, @Dammyadeola Ajọ ajafẹtọ fun eto idibo ti kesi Aarẹ Muhammadui Buhari, Ile Igbimọ Asofin Agba ati kekere lorilẹede Naijiria lati wa ọna abayọ si eto isuna Ajọ INEC saaju idibo ọdun 2019.
Ó bá sọ fún gbogbo ọmọ ilẹ̀ Juda pé, “Ẹ jẹ́ kí á kọ́ àwọn ìlú wọnyi, kí á mọ odi yí wọn ká pẹlu ilé ìṣọ́, kí á kan ìlẹ̀kùn sí àwọn ẹnubodè wọn, kí á sì fi àwọn ọ̀pá ìdábùú sí wọn.
Ṣugbọn Jesu dá wọn lóhùn pé, “Ẹ̀yin kò mọ ohun tí ẹ̀ ń bèèrè.
Nínú àwọn òfin wọ̀nyí ni pé kí wọ́n máa kọ Braille sára àwọn nkan bíi agolo òògùn, kí àwọn afọ́jú fi lè ríi kà fúnra wọn.
Adajọ fẹyinti Oloyede, to ba BBC Yoruba sọrọ lẹyin ti igbimọ CCT sun igbẹjọ naa siwaju, sọ pe ọna kan ṣoṣo lati yọ adajọ agba nipo, ni pe Aarẹ orilẹede Naijiria gbọdọ da laba fun apapọ ile igbimọ aṣofin l'Abuja.
Ọmọ iléèwé mẹfà pẹlú Olùkọ méjì ni wọn jígbé ni Kaduna.
ọna kan ti aarẹ si le gba pari aawọ ẹgbẹ oselu yii ni ki oun pẹlu yi iwa ati ise rẹ pada.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 2020: Oloye Awurela Ifaleke ti wúré ọdún ìgbéga fún kóówá Suleiman ni sẹnatọ náà kan lọ lati lọ ba ASD kẹdun lori wàhálà ti o ni pẹ̀lú àjọ EFCC, lẹ́yìn náà ni ASD ri ọkọ píjo rẹ̀ to sì gbàá nimọràn pé ko paarọ rẹ̀ si èyi to tún gbayi jù bẹ́ẹ lọ.
Mo fẹ ki awọn ewe to n bọ lẹyin le ri aaye wọle.
’ Àwọn adigunjalè pa èèyàn mẹ́fà ní báńkì kan nìpínlẹ̀ Ondo Ìlú kò mọ ohunkóhun nípa iṣẹlẹ màálù tó kú nilu Ikarẹ- Oba Olukarẹ Ogbẹni Peter Olugbenga to jẹ aṣoju awọn akanda ati Ilesanmi Olatunji ṣalaye ni kikun diẹ lara ipenija to n koju awọn akanda ẹda ati ọna iranlówọ ti awujọ le ṣe Iná ńlá ṣẹ́yọ nílú Ibadan, ó sọ ọ̀pọ̀ dí onígbèsè Èèwọ!
Nígbà tí Ọlọrun rí i pé wọ́n ti ronupiwada, ó sọ fún wolii Ṣemaaya pé, níwọ̀n ìgbà tí wọ́n ti rẹ ara wọn sílẹ̀, òun kò ní pa wọ́n run mọ́, ṣugbọn òun óo gbà wọ́n sílẹ̀ díẹ̀.
Ta ni lè ṣe yín ní ibi tí ẹ bá ní ìtara fún ohun tíí ṣe rere?
Ìjàmbá ṣàwọn ajínigbé tó fẹ́ fipá gba akẹgbẹ́ wọn lákàtà àwọn ọlọ́pàá Ọlọ́pàá Ogun dóòlà àwọn ọmọ ìjọ Redeem mẹ́rin tó kù lọ́wọ́ ajínigbé Òṣìṣẹ́ àjọ FRSC méjì bọ́ sọ́wọ́ àwọn ajínigbé l'Ọsun Alásè Buhari kú, Buhari ń ṣọ̀fọ̀ Kin lo ti ṣẹlẹ sẹyin?
OLUWA ti búra, kò sì ní yí ọkàn rẹ̀ pada, pé,“Alufaa ni ọ́ títí lae,nípasẹ̀ Mẹlikisẹdẹki.
”Minisita ohun fikun un oro re pe,
“A sise takun-takun lati mu awon ileri wa se  – bi o ti le je pe ko rorun rara, a ti sagbekale ipile ti o duro nile sinsin fun igbe aye irorun awon eniyan wa patapata.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Obateru Akinruntan: Wíwá ohun tá jẹ títí láé ló gbé wa kúrò nílé Ife Odumakin fikun wipe, o pọn dandan ki ijọba wa ọna abayọ si iṣoro to n koju awọn ọmọ orilẹede Naijiria.
 “O jẹ akoko ti o ye ki a ni amumọra fun iwa ara wa.
Wo orúkọ àwọn ẹ̀yà ara rẹ̀ ní èdé Yorùbá Gomina Yahaya Bello ti Kogi àti David Lyon ti Bayelsa gba ìwé ẹ̀rí INEC Koda, wọn ni ti ọkan ninu wọn ba ṣaisan, awọn mejeeji ni wọn jọ maa lo oogun!
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Awọn to fi ara wọn silẹ lati jagun fun orilẹ-ede Biafra Ibéré ọrọ: Ni nkan bi ọdun 1940 si 1950, awọn ẹgbẹ oṣelu nilẹ Yoruba ati Igbo lo n lewaju ija fun ominira kuro lọwọ orilẹ-ede Britain.
Ẹ má ta ẹ̀jẹ̀ sílẹ̀, jíjù ni kí ẹ jù ú sinu kànga gbígbẹ láàrin aginjù yìí, ẹ má pa á lára rárá.
Ọjọ kẹrinlelogun, oṣu Keje ni ile aṣofin agba gunle isinmi ẹnu iṣẹ, lẹyin ti awọn aṣofin kan fi ẹgbẹ oṣelu Peoples Democratic Party, PDP, silẹ lati darapọ mọ APC.
Bí ó ti ń wọ ìlú bọ̀ tààrà nìyí, ẹ yára lọ bá a.
"O Sọ siwaju wipe "" Eeyan wa ni wọn"" Ọlafare ninu esi rẹ fi kun un wipe o le ni ọgọrun awọn oniroyin ati o le ni ọgbọn ayaworan to wa nibi eto naa, o ni bi iru nkan bẹẹ ba sẹlẹ, o yẹ ki iroyin ti gbe e lati ọsẹ ti eto naa ti waye."
Ìpolówó ọjà pọ̀ ni àsikò yi ni Òkè-Òkun, nitori eyi, ọ̀pọ̀ nlo ike-igbèsè tàbi ki wọn ya owó-èlè lati ra ọjà ti wọn kò ni owó rẹ.
“Awon eto bi I pipese ise fun awon odo  (N-Power), ironi-lagbara nile ise ijoba,(Government Enterprise and Empowerment Programme (GEEP), fifun awion akekoo alakoobere ni ounje,( Home Grown School Feeding Programme ,HGSFP)  ati owo kekere fun awon onisowo ( the Conditional Cash Transfer ,CCT) ati awon ohun to ni se pelu imo ero igbalode.
Oríṣun àwòrán, Seyi Makinde/Facebook Makinde ni ẹgbẹrun mẹta ninu awọn eeyan ọhun ni ayẹwo fihan pe wọn ni covid-19.
"Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: ""Mo fẹ́ pa ara mi torí ojú àbùkù tí wọn ń fi wò mí pé mo fi iṣẹ́ abẹ bímọ"" Fulani kò leè dúró, táa bá lo ohun ta jogún lọ́dọ̀ àwọn bàbá wa - Sunday Igboho Ọjà Àgbáláta ní Badagry rèé, níbití ẹran ejò ti dùn ju ẹran adìẹ lọ Ọlọ́run yóò ṣe ìdájọ́ nkan tó wà láàrin èmi àti Ireti Ajanaku - Tope Alabi A kò jáde ṣe ìwọ́de ìtagbangba mọ́, inú ọkàn wa lá ti máa ṣe ìfẹ̀hónú hàn - Revolution Now Nigba to n kede Adeyẹmọ bii aarẹ fun ajọ naa, ọkan lara awọn oludari ajọ ajọ alaanu Obama, Martin Nesbitt salaye pe Adeyẹmọ ni ẹni to tọ lati gba ipo naa, ika to tọ si ni awọn fi re imu pẹlu iyansipo rẹ ọhun."
Nígbà tí Hẹrọdu gbọ́, ara rẹ̀ kò balẹ̀, ara gbogbo eniyan ìlú Jerusalẹmu náà kò sì balẹ̀.
Oniṣowo to gbajugbaja kaakiri agbaye ni MKO Abiọla jẹ.
Yatọ si eyi, wọ́n ń fọ́wọ́sowọ́pọ̀ pẹ̀lú ilé ìfówópamọ ìjọ́ba àpapọ̀, (CBN) pẹ̀lú ilé iṣẹ́ ìṣúná tó fi mọ́ àwọn ajọ míràn láti wá owó ti wọn yóò fi bẹ̀rẹ̀ ètò ọhun.
Gẹ́gẹ́ bí Baba alààyè ti rán mi, bẹ́ẹ̀ ni mo wà láàyè nítorí ti Baba.
A Akinyẹmi, sọ wipe ohun ko jẹbi ẹsun ti wọn fi kan ohun.
Ọkùnrin kan pa ara rẹ̀ sínú ọgbà àjọ TRACE tó n mójútọ ìrìnnà ọkọ̀ nípìnlẹ̀ Ogun A yìnbọn lu Precious láti dáa dúró ni, akò mọ̀ pé o máa kú- Ọlọ́pàá Eid-el-Kabir jẹ ayẹyẹ to mọ julọ ti awon misulumi maa n se lati buyi kun ifẹ Ibrahim to gba lati fi ọmọ rẹ rubọ, ni igbọran si aṣẹ Ọlọrun Garba ni ipinnu ijọba yii ko sẹyii ifẹnuko igbimọ alaṣẹ leyin ipade to waye.
Wòlíì Kasali ní Dolapo Awosika kò lé ìyàwó òun jáde Àwọn àṣà àti ìse tó yọ obìnrin sílẹ̀ nílẹ̀ Yorùbá Eré Mọrèmi rèé, obìnrin tó gba Ilé-Ifẹ̀ là lọ́wọ́ ìparun Rashidat, to ni ọmọ bibi ipinlẹ Ondo ni oun, ti oju kii si ti oun lati sọ ede oun ni oke okun, wa tun rọ awọn ọmọ ilẹ Oodua, lati mase fi ọwọ osi juwe ile baba wọn, ki wọn ma si sọ ile nu, tori ọmọ to ba sọ ile nu, o so apo iya kọ.
Idi ree ti ilumọọka osere tiata lobinrin, Toyin Abraham aya Ajeyẹmi ko se maa sun asun hanrun lẹyin igba to bimọ tuntun tan, eyi ti ko tii pe osu mẹta bayii.
N óo jẹ́ kí ẹranko burúkú pa àwọn tí wọ́n wà ninu pápá jẹ, àjàkálẹ̀ àrùn yóo sì pa àwọn tí wọ́n sápamọ́ sí ibi ààbò ati ninu ihò àpáta.
Ifọti ti tu igbeyawo ka ri.
CP Akeem Busari - CP Kogi Command xlix.
 bákan náà ni ó tún ń ṣe àgbéyẹ ̀ wò Ètò orí amóhùnmáwòrán àti ipò tí wọ ́ n wà .
Fonron ati awon aworan yii safihan bi ifesewonse naa se lo;THAT FEELING ❤️🏆 #UEL pic.
Idajọ yii waye lẹyin ti ijọba apapọ ni ki ileẹjọ gbe igbesẹ naa lẹyin ti ọga ọlọpaa ati akọroyin Channels ku lasiko iwọde Shiite l'Abuja.
 Àwọn ọlọ ̀ tẹ ̀ yìí borí ṣùgbọ ́ n thi kò fi taratara fẹ ́ borí ogun náà tí ó sì fa ìdíwọ ́ fún ìfipá gba ìjọ ́ ba náà , lẹ ́ yìn tí diệm fi ẹ ̀ tàn ṣèlérí lati ṣe àtúnṣe láti fi àkókò ṣòfò kí àwọn ènìyàn tiẹ ̀ lè gbàá sílẹ ̀ .
Ìtàn Manigbagbe: Àwọn àjakalẹ-àrun to ti wáyé rí ṣáájú Coronavirus Ṣé Irọ́ ni pé àwọn adigunjalè ń ṣọṣẹ́ ní ìpínlẹ̀ Eko àti Ogun?
Ọjọ kẹrindinlogun, oṣu Keje, ọdun 2020 ni Arotile jade laye ninu ọgba ileeṣẹ ologun ofurufu to wa ni Kaduna.
Ẹ̀yin tí Olódùmarè fún ní ọgbọ́ ti kò lè ó, ẹ̀yin gbọ́ kí kìnnìún wá sí ọdọ Ọlọ́run Ọba ní ọjọ́ kan ki ó wí fún un pé kí ó kọ́ ààfin fún òun nítorí pe òun ni ọba àwọn ẹranko?
Nígbàkúùgbà tí Mose bá ń lọ sí ibi àgọ́ àjọ, olukuluku á dúró lẹ́nu ọ̀nà àgọ́ rẹ̀, wọn a sì máa wò ó títí yóo fi wọ inú àgọ́ àjọ lọ.
”IGP condemns the unprovoked attack on Police personnel and setting ablaze of Police vehicle; directs total clamp-down on perpetrators, thorough investigation & prosecution of the 400 members of the El-Zakzakky Islamic Movement now in Police custody.
 Inu mi dun bi abajade eto
A óo fi ẹ̀tọ́ ra Sioni pada;a óo sì fi òdodo ra àwọn tí ó bá ronupiwada ninu rẹ pada.
Inú mi dùn nígbà tí àwọn arakunrin dé, tí wọ́n ròyìn rẹ pé o ṣe olóòótọ́ sí ọ̀nà òtítọ́, ati pé ò ń gbé ìgbé-ayé òtítọ́.
Ninu ọrọ rẹ, Gomina ipinlẹ Ogun, Dapo Abiodun sọ pe, awokọṣe nla ni Obasano jẹ lawujọ awọn oloṣelu ni Naijira ati kaakiri agabye.
Àkọlé àwòrán, Kílódé tó jẹ́ pé ìdámẹ́wàá nìkan ni wọ́n n rí tọ́ka sí?
soro yii lasiko ifilọlẹ aare todun 2019,ti won se  lọjọ Aiku, nile ijọsin National
Ṣugbon iya mi duro ti mi, mo lọ sile ẹkọ fasiti miran to jẹ aladani, mo kawe, mo si pinnu lati ṣe aṣeyọri nibẹ, eyi to see ṣe.
Iya rẹ jẹ ẹlẹsin musulumi nigba ti baba rẹ jẹ ẹlẹsin Kristẹni.
Amasaya, ọmọ Joaṣi, ọba Juda gbé ọdún mẹẹdogun lẹ́yìn ikú Jehoaṣi, ọmọ Jehoahasi, ọba Israẹli.
Pius Adesanmi: Ìdílé ọ̀jọ̀gbọ́n tó kú níjàmbá Ethiopian Airlines ló ilé ẹjọ́
Awon eniyan ni Makurdi ki awon osise eleto aabo ku ise pelu adura pe ki abewo Aare yii fopin si isoro eto aabo to n koju ipinle naa.
Arun Coronavirus ti sọ ara rẹ di ẹrujẹjẹ ni gbogbo ilẹkilẹ, ẹbọra ti n se gbogbo aye mọle porogodo.
''Wọn ko la ojú ọnà tí omi le gbà lo se okunfa ìjàmbá yí'' Ṣugbọn Gómìnà ìpínlẹ̀ Ogun Ibikunle Amosun ní aitele ìlànà tó dé ilé kíkọ lo ṣokunfa ìṣẹlẹ náà.
Nígbà tí o bá gbọ́ ìró kan, tí ó bá dàbí ẹni pé, eniyan ń fi ẹsẹ̀ kilẹ̀ lọ lórí àwọn igi, ni kí o tó kọlù wọ́n, nítorí pé, OLUWA ti kọjá lọ níwájú rẹ láti ṣẹgun àwọn ọmọ ogun Filistini.
ati ile-ise olopaa n fowosowopo lati se ikede rẹ.
Ìyàwó mi ló ṣì ń dáná, bu oúnjẹ mi, gé èékáná fún mi - Pásítọ̀ Adeboye Ọlọ́pàá kọ́ lo pa olórí àwọn ''One Million Boys'' Ebila n'Ibadan- Ọ̀gá ọlọ́pàá Oyo Wo agbábọ́ọ̀lù Super Eagles Nàìjíríà àkọ́kọ́ tó lùgbàdì coronavirus Ayé le!
Iṣẹlẹ yii waye lọjọ kan lẹyin ti awọn ọlọpaa lọ fi ẹsun kan baba ọmọ naa ni ilu Birnin Kebbi lọjọ aiku ọsẹ eyi ti iyawo rẹ sọ pe oun lo de e mọlẹ.
    Ìgbà tí ó wọlé tán ti mo rí i ni mo mọ̀ pé ènìyàn pàtàkì ni, nítorí ojú olè yàtọ̀ sí ojú ọmọlúàbí, ọ̀rọ̀ ẹnu olè yàtọ̀ sí ti ọdẹ aperin.
Laipẹ yii ti Toyin Abraham bimọ fun ọkọ ti o ṣẹṣẹ fẹ, Kolawole Ajeyemi ni iroyin kan tun ru sita pe lootọ Wumi ki oun ati ọkọ rẹ ku ewu ọmọ amọ ko pẹ rẹ lọrọ ija ranpẹ mii tun suyọ.
Nítorí náà, ẹ má ṣe jẹ́ kí ẹ̀mí ìfọkàntán tí ẹ ní bọ́, nítorí ó ní èrè pupọ.
12 Bẹ́ẹ̀ni, wọn yíò mọ̀ pẹ̀lú ìdánilójú pé àwọn ohun wọ̀nyí jẹ́ òtítọ́, nítorí láti ọ̀run ni èmi yíò ti kéde rẹ̀ fún wọn.
O ni a ko le sọ pe oju kan ni ki nkan maa lọ lagbo iṣelu lagbaye.
1991 Wọn fi ẹsun ijinigbe ati ifiyajẹni kan an nipa ọmọ ọdun mẹrinla kan, Stompie' Seipei.
Àkọlé àwòrán, Àwọn iléèwé láti ìjọba ìpínlẹ̀ mọ́kànlá tó wà ní Ibadan ló kópa níbi ìdíje nàá tó wáyé lọ́gbà Fáṣitì Ìbàdàn.
O sọrọ yi fawọn oniroyin lẹyin ifidirẹmi Ghana lọwọ Tunisia ninu idije AFCON to n lọ lọwọ ni orilẹ-ede Egypt.
"Mo kábàámọ̀ pé n kò kàwé, kí n tó bẹ̀rẹ̀ iṣẹ́ tíátà - Sanyeri Femi Adebayo di àgbà àáfà òníláwàní, Iyabo Ojo fi sìgá dárà, Allwell Ademola di ọmọdé padà, tí Wazo si bímọ tuntun Ẹ wo àwọn gbajúmọ̀ òṣèré tíátà tó jogún eré ṣíṣe lọ́dọ̀ òbí wọn Ìtàn ìgbésí ayé Oshodi, ọmọ Tápà léǹpe tó di akọni ní ìlú Eko Àwọn ìbejì Akeugbagold kò le rìn dáadáa mọ́ lẹ́yìn tí wọ́n dáwọn padà Mercy ni ""lẹyin ọpọ arọwa pupọ, ọlọla julọ lobinrin ti dara pọ mọ awọn isọri eeyan to n lo ọkọ ayọkẹlẹ ọbọkun ọlọyẹ Benz."
Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí 5:55 Fídíò, Soyinka Cancer: Àṣe ara mi ni iso ti n run gbogbo bí mo ṣe n ṣèrànwọ́ lórí jẹjẹrẹ, Duration 5,5527 Bélú 2019 Coronavirus in Nigeria: Èèyàn mẹ́jọ kú , 1585 míràn tún ṣẹ̀ṣẹ̀ lùgbàdì ààrùn náà ní Nàìjíria10 Sẹ́rẹ́ 2021 US Elections 2020: Primate Ayodele ní òun ti sọ àsọtẹ́lẹ̀ pé Trump yóò fìdírẹmi, tí kò bá ṣọ́ra ṣe8 Bélú 2020 Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí kan sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
Àwọn olórí wọn kò ní àléébù kankan,Ọwọ́ wọn mọ́, inú wọn funfun nini,wọ́n dára ju egbin lọ,ẹwà wọn sì dàbí ẹwà iyùn.
Opolopo eniyan ni wọn n ki onkowe naa ku oriire.
Agbẹjọ́rò ni n kò bá jẹ́, tí n kò bá bá bàbá mi ṣe tíátà - Sola Kosoko Àbúrò mi ni Babatunde Fashola- Naira Marley Kí ló ṣokùnfà afárá tó já tó pa ènìyàn kan ní Ilorin?
Ó dàbí àfonífojì tí ó tẹ́ lọ bẹẹrẹ,bí ọgbà tí ó wà lẹ́bàá odò.
5 miliọnu lati bọ Ibrahim El-Zakzaky loṣu, ko si idi ti ko yẹ ko ri ọgbọn ẹgbẹrun naira, N30, 000 lati san owo oṣu oṣi'\\sẹ to kere ju lọ.
" O lee ma rọrun lati gbọ irufẹ ẹjọ yii, paapa to ba jẹ pe awọn ẹjẹ kan naa ni wọn sẹ ara wọn, bii ki baba ba ọmọbinrin rẹ lo pọ lọna aitọ abi ki ẹgbọn fi tipa ba aburo rẹ obinrin sun tipatipa.
uk/fakenews Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
ọdun 2016 lo bẹrẹ si ni wọ iya ija pẹlu aisan jẹjẹrẹ ki o to kọja afarada, to si gba ẹmi rẹ ni Los Angeles ni ipinlẹ California, Amẹrika.
iko agbaboolu obinrin orile-ede Naijriia, Asisat Oshoala, ti darapo mo iko agbaboolu Barcelona ninu idije orile-ede.
Ṣugbọn ẹni tí a bá dárí ẹ̀ṣẹ̀ díẹ̀ jì, ìfẹ́ díẹ̀ ni yóo ní.
Gbogbo ẹni tí ìjọba bá fi ọwọ́ọ ṣìgún òfin mú ní Íjípìtì ní í jẹ ìyà oró, ìfarasin, àtìmọ́lé ọjọ́ pípẹ́ àti àdánìkangbé inúu túbú.
    Gbogbo bí mo ti ń ṣe ni Olódùmarè ń wò mi, ìgbà ttí mo sì n padà bọ̀ wá sí ilé, mo gbọ́ ohùn kan láti òkè wí pé, ‘Nítorí ìwọ ṣe èyí a ki yóò pè ọ ni orúkọ àtijọ́ mọ́, Adéforítì la ó máa pè ọ, nítorí ìwọ ní ìforítì ju àwọn ẹ̀dá ìyókù lọ.
ẹ mú kí ayọ̀ mi kún nípa pé kí ọkàn yín ṣe ọ̀kan, kí ẹ fẹ́ nǹkankan náà, kí ẹ ní inú kan, kí èrò yín sì papọ̀.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Àbẹ̀wò Buhari: Gómìnà márùn-ún ki káábọ̀ 14 Èbibi 2018 Oríṣun àwòrán, @BashirAhmaad Àkọlé àwòrán, Ṣaaju abẹwo yii, aarẹ ti kọkọ ṣabẹwo si ipinlẹ Taraba, Plateau, Benue ati Zamfara Aarẹ Muhammadu Buhari ti gunlẹ si ipinlẹ Jigawa fun abẹwo ọlọjọ meji.
Ọjọ Iṣẹgun ọjọ ikeji oṣu keje ni fidio iṣẹlẹ kan to ti ṣẹlẹ ṣaaju ọjọ naa jade to ṣafihan bi Sẹnetọ naa ṣe n lu obinrin kan nile itaja eroja ibalopọ.
Balogun yanyan fun ile-ise omo ogun Naijiria, Tukur Buratai lo so oro naa di mimo lasiko to n yanana oro ohun fun awon akoroyin nilu Abuja.
Inu sinima kan to ṣe pẹlu orukọ yii, si ni inagijẹ naa ti jade fun un.
Iwe iroyin naa ni lasiko ti minisita pari ẹkọ rẹ ko tii pe ọmọ ọgbọn ọdun ati pe lẹyin ọpọlọpọ ọdun ni arabinrin Adeọṣun to lọ gba iwe ẹri to wa fun awọn ti wọn yọọ lẹ kuro leto isinruulu nitori ọjọ ori wọn eleyi ti iwe iroyin naa ni iwadi awọn fihan pe ayederu ni.
Nígbà tí wọ́n pàdé Isaaki, iranṣẹ náà ròyìn gbogbo ohun tí ó ṣẹlẹ̀ fún un.
Amọ adura yii ko gba rara fun idile ẹlẹni mẹjọ kan labule Auki, nijsba ibilẹ Bungudu nipinlẹ Zamfara.
Gbogbo àníyàn ọkàn mi ni pé kí n mọ Kristi ati agbára ajinde rẹ̀, kí èmi náà jẹ ninu irú ìyà tí ó jẹ, kí n sì dàbí rẹ̀ nípa ikú rẹ̀, 
Òdòdó Ṣaroni ni mí,ati òdòdó Lílì tí ó wà ninu àfonífojì.
nígbà tí OLUWA Ọlọrun yín bá fi wọ́n le yín lọ́wọ́, tí ẹ bá sì ṣẹgun wọn, píparun ni ẹ gbọdọ̀ pa wọ́n run.
Lẹ́yìn náà, ọba sọ fún Amasa pé, “Pe gbogbo àwọn ọkunrin Juda jọ, kí o sì kó wọn wá sọ́dọ̀ mi láàrin ọjọ́ mẹta; kí ìwọ náà sì wá.
O ni lẹyin-o-rẹyin ni awọn mọlẹbi san agba epo pupa jálá lita ọgbọn, ọti Schinapu, ọpọlọpọ iṣu ati miliọnu mẹta ati aabọ naira.
Dokita Stella Adadevoh kò bá pé ọdún 62 Nàìjíríà ń ṣọ́ pápákọ̀ òfurufú tórí Ebola Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Kayefi BBC Yorùba: Bàbá ọmọ, Mọ́ṣúárì, Ọlọ́pàá kẹ́jọ́ rò nípa òkú ọmọ tó pòórá Ọjọ kọkandinlogun, oṣu Kẹjọ, ọdun 2014 ni Stella ku sọwọ oro aisan Ebola.
O ni bakan naa ni wọn ti fa gbogbo awọn mọkanla ti ọrọ kan naa lọ sile ẹjọ gẹgé bi o ṣe yẹ labẹ ofin.
A ní iṣẹ́ Ẹlẹ́dàá ò dára tó, àfi ká tún un ṣe ní ìlànà tiwa.
” Àwọn ìwẹ̀fà meji tabi mẹta sì yọjú sí i láti ojú fèrèsé.
- arìnrìn oge Lẹ́yìn ìgbeyàwó ọdún mọ́kànlá àti ọ̀pọ̀ ìjà, Bọsẹ di èrò ọ̀run nílé Saidi Xenophobic Attack: 'Nàìjíríà ló máa forí kó kíkọlu iléeṣẹ́ South Africa jùlọ' Àjọ Commomwealth gbọ̀dọ pé ìpáde pàjáwìrì lori ọ̀rọ̀ Brexit- Wole Soyinka Ìdí ti àwọn kọmísọna ṣe to láti kí ìyáwó gómìnà tuntun káàbọ̀ Awọn nnkan miran ti iwadi naa sọ ni pe: Swaziland ni aiṣedede laarin awọ́n to ni ati alaini ti peleke ju nibi ti olowo kan Nathan Kirsh to ni biliọnu dọla mẹrin le diẹ.
Ọwọ wọn si ti tẹ awọn ọmọkunrin to mu alase naa wa fun oloogbe Bademusi.
Ó ti ra ohun gbogbo bẹ̀ẹ́ sì ni ó ti ṣe gbogbo ètò tó yẹ.
3 Ògún 2019 Laipẹ ni iroyin kan pe awọn Ọba tuntun ti gomina ana ni ipinlẹ Ọyọ, Sẹnetọ Ajimobi fi jẹ ọba ti pari aawọ to wa laarin wọn àti Olubadan, Oba Saliu Adetunji.
Lasiko ti Kọmiṣọnna n fidi ọrọ yii mulẹ lo sọ pe ijọba ti ya awọn eeyan yii sọtọ nile ifinipamọ to wa ni adugbo Yaba ni ipinlẹ Eko.
Elere ori papa ni Frimpong je tẹlẹ sugbọn ijakule eṣe ibi gigise rẹ mu ki o yan ere idaraya mi laayo.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Ogoje iṣẹju nikan lo lanfani ati gba.
Ìpín tí ó bọ́ sí mi lọ́wọ́ dára pupọ;ogún rere ni ogún ti mo jẹ.
Ọpọ awọn ololufẹ olorin naa ni Najiria lo ti bẹrẹ si n bu ẹnu atẹ lu ẹsun ti wọn fi kan an, ti awọn mii si sọ pe ejo lọwọ ninu.
Kolade Johnson; Iléeṣẹ́ ọlọ́pàá ní ọwọ́ ti tẹ àwọn afurasí ọlọ́pàá tó ṣekúpaá Ọlọ́pàá Sharia Kano mú èèyàn tó lé ní 80 tori oúnjẹ nínú ààwẹ̀ Irú àtúntò wo ni àwọn ọmọ Nàìjíríà fẹ́ kó bá FSARS?
Nigeria Diaspora Day: Ìjọba ní láti ronú jinlẹ̀ nípa òun tó n sọ ọmọ Nàìjíríà d'ero ilẹ ókéèré
Bí Fayemi bá tasẹ̀ àgẹ̀rẹ̀, àwọn oníbáwí rẹ̀ wà l'Ekiti-Peter Fatomilọla Ààrẹ Buhari sún eré ìdárayá àpapọ̀ Edo 2020 síwájú Àwọn ọba Yorùbá kan rèé tí wọ́n rọ̀ lóyè, tí ọba míràn jẹ lójú ayé wọn Kí ni àwọn ayédèrú ìmọ̀ràn ìwòsàn tó rọ̀ mọ́ àrùn coronavirus?
Jẹ́ kí n lọ sọ́dọ̀ rẹ̀, kí n sì sọ orí rẹ̀ kalẹ̀ kúrò ní ọrùn rẹ̀.
Bolatito ko ipa manigbagbe ninu iṣẹ tiata lasiko ti ọkọ rẹ, Ishola Ogunsola wa loke eepẹ, sugbọn lẹyin to ku tan, oju obinrin naa ko han mọ ninu ere tiata.
Aare soro naa di mimo lojoBo(Thursday), lasiko to n se ifilole ikunwo ipolongo idibo re, eleyi ti won pe akole re ni “Ikunwo Isokan fun ipolongo, saaju idibo gbogbogbo” ‘Buhari Unity Band.
Wọ́n ta ère Ọ̀ṣun Osogbo sí Togo - Bàbá Ọṣun figbe ta Baṣọ̀run Gáà, tó yan ọba mẹ́rin, pa ọba mẹ́rin àmọ́ ọba karùn-ún ló pa á Ọbasanjọ sọ àsírí sàgbàdèwe rẹ̀ Jesu Oyingbo rèé, pásítọ̀ tó láṣẹ ìbálòpọ̀ lóri ọmọ ìjọ obìnrin Igbó mímu lè ṣe kóríyá, kò lé fi kún orín ẹnu òṣèré - 9ice Èyí tí a wò jùlọ 5:03 Fídíò, Omolola Arohunmolase Welder: Mo ti fí iṣẹ́ 'Welder' gbayì láwùjọ, tó mo fi tọ́ ọmọ yanjú, Duration 5,039 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 5:39 Fídíò, Akomolede ati Asa lori BBC: Olùkọ́ Kikelomo Ogunboye tan ìmọ́lẹ̀ sí ìwà olè ọ̀gá ọlọ́pàá Audu gẹ́gẹ́ bí àwòkọ́ṣe àsìkò yìí, Duration 5,398 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 4:11 Fídíò, Oba Adeyeye Ogunwusi: Ojú mi ti rí lọ́pọ̀ lọpọ̀, ọ̀pọ̀ èèyàn ni kò tilẹ̀ gbàgbọ́ pé mo lè jọba- Ooni, Duration 4,117 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 4:43 Fídíò, Promise Akinlade: ọmọ ọdún mọ́kànlá tó ń fi ìlù dárà bíi àgbàlagbà sọ̀rọ̀ nípa tálẹ́ǹtì rẹ̀, Duration 4,437 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 0:59 Gbọ́, Ìsẹ̀lẹ̀ jákèjádò orílẹ̀èdè àgbáyé láàárín ìṣẹ́jú kan, Duration 0,59wákàtí 5 sẹ́yìn 7:03 Fídíò, Olumuyiwa Bolade Adedeji Military Bruitality: Bí arákùnrin onípèníjà ara tí sọ́jà lù ṣe dé, Duration 7,035 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 4:45 Fídíò, Yoruba Films: Ẹ̀ẹ́ bẹ̀ mi kúrò láyé ni, mi ò lè kú - Fadeyi Oloro, Duration 4,4526 Èrèlè 2020 2:48 Fídíò, Esther Ajayi: Èmi náà ti borí ìṣòro rí ló ń mu mi ṣojú àánú, Duration 2,481 Ògún 2019 6:08 Fídíò, Adebola Ademilua: Àìrísẹ́ ṣè lẹ́yìn ìwé kíkà ló sọ mi dí ìyá onírú, mo dúpẹ́ tèmi, Duration 6,0827 Bélú 2020 2:36 Fídíò, Sotitobire: Ìdájọ́ òdòdò ló fẹsẹ̀ múlẹ̀ lórí ọ̀rọ̀ Pásítọ̀ Sotitobire - Agbẹjọ́rò fún ìjọba, Duration 2,367 Ọ̀wàrà 2020 BBC News, Yorùbá Ìdí tí ẹ fi le è nígbàagbọ́ nínú ìròyìn BBC Ìlànà Lílò Nípa BBC Òfin Àṣírí Cookies Kàn sí.
Nígbà tí mo bá jẹ tán, tí mo mu tán, kí o wá jẹ tìrẹ.
ẹni tí ó lè máa ṣáájú wọn lójú ogun, kí àwọn eniyan rẹ má baà wà bí aguntan tí kò ní olùṣọ́.
Ni kete ti iṣẹlẹ naa waye ni awọn ẹbi ọmọ ọhun fi ọrọ naa to awọn agbofinro leti ni agọ ọlọpaa to wa ni Funmbi Fagun ni ilu Ondo, ti iwadii si fihan pe, wọn ti ba ọmọ naa lo, ati pe o ti fara kasa arun jẹdọjẹdọ.
Ẹ múra gírí, kí ẹ sì mọ́kàn le,gbogbo ẹ̀yin tí ẹ gbẹ́kẹ̀lé OLUWA.
Wọn yan aarẹ yii nibi ipade to n waye ni Niamey to jẹ olu ilu orilẹ-ede Niger loni ọjọ Aje.
Ànfàní nbẹ́ fun Naijiria ninu àdéhùn okòwò ní Afrika,AfCFTA ṣugbọ́n.
 Adura ni a n gba ki ijoba se atunse si awon aisan ti eto inu adojutofo NHIS ka nipa fifi awon itoju aisan bii itoju kindinrin ati inawo sise pasipaaro kindinrin.
'Bí a kò bá fẹ́ ìbínú Ọlọ́run, a gbọ́dọ̀ jẹ́ kí Tinubu du ipò ààrẹ̀ lábẹ́ àsìá ẹgbẹ́ APC ní 2023' Kọmísọ́nà ètò ìlera ìpińlẹ̀ Eko ọjọ̀gbọ́n Akin Abayomi ti lùgbàdì ààrùn Covid-19 Iròyìn àyọ, àdínkù tún bá iye ènìyàn tó lùgbàdì Covid -19 ní Nàìjíríà lọ́jọ́ Àìkú Rúfin kóo san N1M táa bá ṣí òtẹ́ẹ́lì, ilé sinimá, gbọ̀ngàn ayẹyẹ padà - Ijọba Eko Oṣojumi koro miran sọ pe Wọn ṣakọlu si Taoreed nigba to n gbiyanju lati ṣa mọ wọn lọwọ pẹlu alupupu rẹ lẹba ile gomina, ṣugbọn wọn da duro wọn si yinbọn lu nigba meji lẹyin ti wọn gba owo naa tan, wọn si salọ."
Mú ẹsẹ̀ mi dúró gẹ́gẹ́ bí ìlérí rẹ,má sì jẹ́ kí ẹ̀ṣẹ̀ kankan jọba lórí mi.
’ Yóo dáhùn pé, ‘Ọgbẹ́ tí mo gbà nílé àwọn ọ̀rẹ́ mi ni.
Àkàrà tú sépo, Trump ló kọ èsì ìlera ara rẹ̀ Trump yọ Tillerson kuro nipo Ìpànìyàn gbọdọ̀ dópin ní Nàíjíríà - Trump Amẹrika àti North Korea fi ìtàn àlàáfíà lélẹ̀ Ààrẹ Trump tàpá sí àbájáde ìpàdé G7 Awọn ikọ 'Stop Trump Coalition'ati 'Stand Up to Trump' ni awọn a jọ ṣe iwọde naa ni.
Oríṣun àwòrán, others Ọwọ tẹ ààrẹ Gbagbo ti ọ sí dero ile-ejo agbaye níbi tí wọn ti fesuny kan pe o da ẹsẹ nla to fako ijẹ ọmọnìyàn.
A kò lè fi wúrà Ofiri díwọ̀n iye rẹ̀,tabi òkúta onikisi tabi safire tí wọ́n jẹ́ òkúta olówó iyebíye.
Wúrà tí wọ́n fi òòlù lù ni wọ́n fi ṣe ọ̀pá fìtílà náà, láti ìtẹ́lẹ̀ rẹ̀ títí dé ìtànná orí rẹ̀.
Link Dandan ní kí a mú Dino sí àhámọ wa- Ọlọ́pàá Àkójọpọ̀ àwòrán ọdún Kérésìmesì lágbáyé Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Èpo ọwọn, sunkere-fakere ọkọ àti àwọn olósà jẹ́ ipenija lójú pópó Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Asisat Oshoala: ìbẹ̀rẹ̀ mi kò rọrùn rárá nínú eré bọ́ọ̀lù Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Saba Gul: Ọmọbìnrin aláìlápa tí o fẹ̀ dì agbẹjọro Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Iko agbaboolu Abia Warriors FC lojo Aiku(Sunday) gbo ewuro si akegbe won loju lati ipinle Yobe, Yobe Desert Stars FC pelu ami-ayo meta sookan(3-1), ni papa isere Umuahia Township StadiumAtamatase iko ohun Effiong Ndifereke lo gba ami-ayo kinni wole niseju mokandinlogbon saa akoko ifesewonse ohun, besini  Sam Obi gba ami-ayo keji wole kii saa akoko ifesewonse naa o to wa si ipari.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù World water day: Ẹrin Ijesa, Ọ̀ṣun Oṣogbo, àwọn ibùdó ìgbafẹ́ tí ó níi ṣe pẹ̀lú omi ní ilẹ̀ Yorùbá 1 Ọ̀pẹ̀̀ 2018 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 22 Ẹrẹ̀nà 2019 Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ẹrin Ijesa, Ọ̀ṣun Oṣogbo, àwọn ibùdó ìgbafẹ́ tí ó níi ṣe pẹ̀lú omi ní ilẹ̀ Yorùbá Oniruuru ibudo irinajo afẹ lo wa ni ilẹ Yoruba lapa iwọ oorun gusu orilẹede Naijiria.
Laisi nile rẹ, Abacha kede pe pipa ni wọn yoo pa a.
Èyíkéyìí ninu arọmọdọmọ Aaroni, alufaa tí ó bá ti ní àbùkù kan lára kò gbọdọ̀ súnmọ́ ibi pẹpẹ láti rú ẹbọ sísun sí èmi OLUWA, níwọ̀n ìgbà tí ó bá ṣì ní àbùkù lára, kò gbọdọ̀ súnmọ́ ibi pẹpẹ láti rú ẹbọ ohun jíjẹ sí Ọlọrun rẹ̀.
    Lẹ́yìn náà, àti Èṣù àti àwọn ọmọ ogun Èṣù, kò sí èyí tí inú rẹ dùn rárá nínú wọn, ṣe ni gbogbo wọn fajúro.
Tí koríko náà bá hù tán, òun náà di oúnjẹ eranko.
Lẹyin eyi wọn tun ti kan si AFN lọpọlọpọ igba ti minisita yoo tun ṣe ilere.
Eeyan bi ẹgbẹrun lọna irinwo le mẹjọ, lo n tẹle Neo loju opo Instagram rẹ.
oorun orile ede Naijiria , Abdullahi Umar Ganduje ti pasẹ fun ajo to n ri si
Àwọn tí ó ń kú nh pọ̀ ọ́ sí i.
A rí i pé bẹ́ẹ̀ ni ó rí nítorí nígbà tí Mose fẹ́ kọ́ àgọ́, ohun tí Ọlọrun sọ fún un ni pé, “Ṣe akiyesi pé o ṣe ohun gbogbo gẹ́gẹ́ bí àwòrán tí mo fihàn ọ́ ní orí òkè.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Atunto lo le yanju ọrọ Naijiria Sugbọn loju opo ayelujara awọn eeyan ti dari ọrọ ipade naa si ibo miran.
Kò sí aáwọ̀ láàrin èmi àtàwọn Ọba Yorùbá tó kù, àhesọ ni: Oluwo ni lori ọrọ ibaṣepọ laarin oun atawọn Ọba alaye to ku nilẹ Yoruba, awọn jọ maa n ṣepade pọ ni.
Buhari lo sọ orọ yii nibi ipade kan to ṣe pẹlu aarẹ orilẹ-ede Burkina Faso, Roch Marc Christian Kabore, to si ṣeleri pe atunṣe yoo waye lori ọrọ ibode naa to di titi pa laipẹ.
Àwọn ọmọ Israẹli bá fi àwọn eniyan pamọ́ ní ibùba, yípo gbogbo Gibea.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, SS3 ní mo wà báyìí, mo sì ti gba àmì ẹ̀yẹ̀ púpò nílé-lóko gẹ́gẹ́ bí onílù - Ayansike Ti ẹjẹ ko ba pọ to lara obinrin, o le ṣe akoba fun ọmọ inu obinrin naa ninu oyun - bibi ọmọ naa laipe ọjọ, ki ọmọ naa kere ju boṣe yẹ lọ, irẹwẹsi ọkan fun iya , tabi iku fun ọmọ naa ṣaaju tabi lẹyin ti wọn ba bi i.
Mubarak fẹ Suzanne, ọmọ ọdun mtadinlogun to tun jẹ ọmọ dokita.
O wa n pe ijoba apapo lati tunbo seto itaniji lori pataki eto ogbin anfaani re.
Bí wọ́n ti jọ ń sin Oluwa, tí wọ́n ń gbààwẹ̀, Ẹ̀mí Mímọ́ sọ fún wọn pé, “Ẹ ya Banaba ati Saulu sọ́tọ̀ fún mi, fún iṣẹ́ pataki kan tí mo ti pè wọ́n fún.
àwọn ìjòyè á dákẹ́ rọ́rọ́,wọn á fi ọwọ́ bo ẹnu wọn.
"Rọbọọti ""Doctor car"": Awọn onimọ ẹrọ nile iwe gbogboniṣe kan ni orilẹ-ede Senegal lo ṣe rọbọọti naa lati ṣadinku bi awọn oṣiṣẹ eto ilera ṣe n ko arun Covid-19 lara awọn ti wọn n tọju."
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Yoruba Culture: Ọjọ́ méje ni wọ́n fí n rẹ ẹ̀kú Danafojura kó tó jáde Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Yoruba Culture: Ọjọ́ méje ni wọ́n fí n rẹ ẹ̀kú Danafojura kó tó jáde 25 Ọ̀wàrà 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 13 Ìgbé 2020 Ojúbọ Ogun àti Eṣu ṣe pataki si eegun Danafojura - Danafojura Aṣa ati iṣe Yoruba ṣe pataki si BBC Yoruba ki a to ṣẹṣẹ wa sọ ti iṣẹṣe ati igbagbọ awọn Baba nla wa.
Ounjẹ afara lokun Oríṣun àwòrán, Food Ace Adanna ṣalaye siwaju pe awọn ounjẹ afara lokun bi irẹsi ti eeyan ba kore rẹ ninu oko dara fun ara.
Ọga ọlọpaa naa ti wọn pe orukọ rẹ ni ASP Adeyẹmọ Ogunyẹmi lo lọ si agbegbe Gbọlaguntẹ Okeọola ni Eruwa iyẹn nijọba ibilẹ Ibarapa East ni ipinlẹ Ọyọ lati lọ fidi ofin konile o gbele mulẹ nibẹ.
Adeola ni ipade alaafia bẹrẹ ni Ọjọ Aje ni ibi ti Olubadan ati meji ninu awọn ọba naa se fọwọsowọpọ lati kuro lori rogbodiyan to wa laaarin Olubadan ati awọn ọba to je ijoye tẹlẹ labẹ Olubadan.
Obinrin opo kan ku pẹlu ọmọ mẹta Isẹlẹ ẹkun omi yii tun da họu-họu silẹ ninu ile kan nigba to gbe opo kan ati ọmọ rẹ mẹta lọ.
Joṣua dá wọn lóhùn, ó ní, “Bí ẹ bá pọ̀, ẹ lọ sí inú igbó, kí ẹ sì gba ilẹ̀ níbẹ̀ ninu ilẹ̀ àwọn ará Perisi ati ti àwọn Refaimu, bí ilẹ̀ olókè ti Efuraimu kò bá tóbi tó fun yín.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìtàn Mánigbàgbé: Ṣé òótọ́ ni pé èpè Alaafin Aole ń ja Yorùbá?
Fadaka ati wúrà wọn kò ní lè gbà wọ́n sílẹ̀ lọ́jọ́ ibinu OLUWA, gbogbo ayé ni yóo jó àjórun ninu iná owú rẹ̀; nítorí pé yóo mú òpin dé bá gbogbo àwọn tí wọn ń gbé orílẹ̀ ayé.
Nígbà tí ó di ọjọ́ keje, kí ó tó di pé oòrùn wọ̀, àwọn ará ìlú rẹ̀ náà wá sọ ìtumọ̀ àlọ́ Samsoni wí pé,“Kí ló dùn ju oyin lọ;kí ló lágbára ju kinniun lọ?
BBC Yorùbá ṣe ìwádìí lọ́wọ́ onímọ̀ nípa ètò ẹ̀kọ́ àti kíni ọ̀nà abáyọ láti le bori ìṣòrò eto ẹ̀kọ́ tó ti dàyà bolẹ̀.
Ṣugbọn ohun ti a ri ni pe, awọn to ti forukọ silẹ ti le ni ẹgbẹrun mẹtadinlaadọta.
'Vision 2020' Ọpọlọpọ ijọba kaakiri agbaye ninu ikini ọdun tuntun wọn lo ṣe ileri awọn nkan ti wọn yoo ṣe lati mu idagbasoke ba orilẹede wọn.
Tí ó bá dé ọ̀dọ̀ yín, kí ẹ gbà á tọwọ́-tẹsẹ̀.
"Oni ni ọjọ ibi mi, mo si gbadura fun alaafia, ki n bori gbogbo ipenija aye pẹlu irọrun, ki ayọ ati inu didun si jẹ temi.
Ronke Oshodi-Oke lasiko ifọrọwanilẹnuwo pẹlu BBC Yoruba salaye pe, nitori asa to gbode kan bi awọn eniyan ṣe n gbe igbesẹ lati kọ ọkọ tabi aya silẹ.
Bí a bá mú ti ariwo yìí kúrò, ìlú náà dára, nítorí wọ́n ni mọ́tò, wọ́n ní kẹ̀kẹ́, wọ́n ni alupùpù, ọ̀pọ̀lọpọ̀ nǹkan ọ̀làjú ni wọ́n ni.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Boxing Day: Kíni ìdí tí wọ́n fi ń pe ọjọ́ kejì ọdún Kérésì ní Boxing Day?
mú burẹdi tí kò ní ìwúkàrà, ati àkàrà dídùn tí kò ní ìwúkàrà tí a fi òróró pò, ati burẹdi fẹ́lẹ́fẹ́lẹ́ tí kò ní ìwúkàrà, tí a da òróró sí lórí.
Coker Pẹlumi, @ cokeroluwapelu2 woye pe ileri ibo ti aar ẹgbẹ NANS se fun Buhari yii, lo se afihan bi ẹka asaaju ẹgbẹ NANs ti bajẹ, to si jẹra si.
Ọkunrin tí àwọn ẹ̀mí èṣù jáde ninu rẹ̀ bẹ Jesu pé kí ó jẹ́ kí òun máa wà lọ́dọ̀ rẹ̀.
5 mílíọ̀nù lórí El-Zakzaky, kíni àwọn ọmọ Nàìjíríà ń sọ?
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Owu Water Fall: Ọba Oyewole ni ibùdó ìrìn àjò afẹ́ gidi ni àmọ́ ọ̀nà ibẹ̀ burú jáì O fi kun n pe, ọṣẹ pupọ ni ijọba ologun gbogbo to wa ni ṣisẹ n tẹle, tun ṣe fun ẹya Yoruba nigba ti wọn gbẹsẹ le gbogbo dukia ajumọni ilẹ Yoruba.
Wọn  tun  safihan fiimu baalu tuntun fun orilẹ ede  Naijria nibi ayeye naa.
Lẹ́yìn tí ó wí báyìí tán, ó ju egungun ẹ̀rẹ̀kẹ́ kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ náà sílẹ̀, wọ́n sì sọ ibẹ̀ ní Ramati Lehi.
Eyi si ti mu ki ibẹru wa pe Boko Haram ti n pẹka.
 ile adajo ni ominira lowo ijoba ati asofin .
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ramadan 2020: Ṣọ́ọ́ṣì kan sí ìlẹ̀kùn rẹ̀ fún àwọn mùsùlùmí láti kírun Jímọ̀ ní Germany 22 Ìgbé 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 23 Èbibi 2020 Oríṣun àwòrán, Reuters Sọọsi kan nilu Berlin, l'orilẹ-ede Germany, ti silẹkun rẹ fawọn musulumi lati jọsin nibẹ nitori pe mọsalasi wọn ko gba wọn mọ.
  Èso igi náà kò jọ wọ́n lójú pẹ̀lú.
“Ìbá jẹ́ pé o ti fetí sí òfin mi,alaafia rẹ ìbá máa ṣàn bí odò,òdodo rẹ ìbá lágbára bi ìgbì omi òkun.
Akọroyin BBC naa to jẹ ọmọ ọdun mọkandinlọgbọn(29) , Ahmad Shah lo ti sisẹ fun ọdun kan pẹlu ile ise BBC Afghan Service, ki ikọlu naa to waye ni Ọjọ Aje, Osu Kẹrin, Ọdun 2019.
Ko si ẹnikẹni to mọ oun ti Brexit yoo ja si, ọrọ naa si le ma fori sibi kan titi opin ọsẹ.
Nítorí náà, kí Moabu máa pohùnréré ẹkún,kí gbogbo eniyan máa sun ẹkún arò ní Moabu.
”Ewe, Rohr wa fi mule pe, awon asole iko meteeta ohun yoo kopa daradara ninu idije agbaye naa.
Lai Muhammed yóò fojú ba'lé ẹjọ́ - ICPC COZA: Mi ò fípá bá obìrin lò pọ̀ rí láyé mi - Pásítọ̀ Fatoyinbo Stella Damasus, Omotola Ekehinde, Ezekwesili, Funmi Iyanda dá sí ẹ̀sùn ìfipábánilòpọ̀ Fatoyinbo Tarúgbó tomidan ló wà ní Guzape ṣe lòdì sí ẹ̀sùn ìfipábánilòpọ̀ Fatoyinbo Nínú ìpàdé ti wọ́n ṣe kẹ́yin , wọ́n o fẹ́nu ọ̀rọ̀ jóna lóri ọ̀nà ati dáwọ agbékalẹ ọ̀rọ́ ǹkan ìjà ogun ti North Korea n gbèrò lati ṣe.
Kalebu ní ẹnikẹ́ni tí ó bá gbógun ti ìlú Kiriati Seferi tí ó sì ṣẹgun rẹ̀, ni òun óo fi Akisa, ọmọbinrin òun fún kí ó fi ṣe aya.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Bùhárí padà dé sí Nàíjíríà Àwọn mọ̀lẹ́bí tó ti kópa nínú ife ẹ̀yẹ àgbáyé Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Obinrin Akansẹ: Ẹsẹ kiku bi ojo kọ mi lati di alagbara Lásìkò tó ń bá àwọn akọ̀ròyìn sọ̀rọ̀, Emir Sanusi korò ojú sí ìwà àílákàsí àwọn alásẹ tí ọ̀rọ̀ ìdókówò náà kàn ní Nàíjíríà.
Bí pínpín owó ilù ṣe díjà sílẹ̀ láàrin àwa ìjòyè àti Oluwo rèé - Osa Iwo Kí ló mú kí ọkọ̀ kan tó jóná ráùráú lórí afárá Ojuelegba?
Shiite protest: Ọ̀gà ọlọ́pàá pàṣẹ́ kí ètò ààbò le si kárakára
Lataari esi ami ayo kookan(1-1) ti iko naa gba pelu iko agbaboolu South Africa, iko Super Eagles yoo bere sini n gbaradi bayii fun idije AFCON ohun ti yoo bere ninu osu keta lọdun to n bo.
Olùforukósilẹ̀ ko gbọdọ̀ ni àkọsilẹ̀ ìwà ọ̀daràn níle ẹjọ.
Shiite: Tinúbú, bá Buhari sọ̀rọ̀ kó tú ZakZaky sílẹ̀ kó tó pẹ́ jù
Obinrin náà bá gbé òkú ọmọ náà lọ sí yàrá Eliṣa, ó tẹ́ ẹ sí orí ibùsùn rẹ̀, ó ti ìlẹ̀kùn, ó sì jáde.
Awọn agbegbe wo lo wọpọ si ju?
Èèyàn kò lè di ipò mú ní Nàìjíríà tí o bá fi ìwé ẹrí gbarọgudu ṣọ́wọ́ Àyẹwò fún ẹni tó bá fẹ jẹ Mínísítà ni iwájú ilé aṣòfin àgbà má n n'ise pẹlú àyẹwò ìwé ẹrí ti ẹni náà fi ṣọwọ́ sí ilé.
Èyí rí bẹ́ẹ̀ kí ọ̀rọ̀ tí a kọ ninu Òfin wọn lè ṣẹ pé, ‘Wọ́n kórìíra mi láìnídìí.
Wòlíì Kasali ní Dolapo Awosika kò lé ìyàwó òun jáde Agbọn n sẹ, oyin n sẹ, taa wa lo ni ojulowo Ọsun wa lọdọ rẹ?
O sọ pe ara iṣẹ oun ni lati daabo bo awọn eeyan, o ni ti eeyan ba ṣeṣe, mo le fi ara mi sinu ewu lati ran wọn lọwọ."
 Ìdí nìyẹn tí wọn ṣe máa ń we pé -.
Ọkunrin náà wọn ibẹ̀ láti ẹnu ọ̀nà kan sí ikeji, ó jẹ́ ọgọrun-un (100) igbọnwọ (mita 45).
Bí Jesu ti ń sọ̀rọ̀ lọ́wọ́, bẹ́ẹ̀ ni Judasi, ọ̀kan ninu àwọn mejila yọ, pẹlu ọ̀pọ̀ eniyan tí wọ́n mú idà ati kùmọ̀ lọ́wọ́.
Nígbà tí wọn kò ka ìmọ̀ Ọlọrun sí, Ọlọrun fi wọ́n sílẹ̀ pẹlu ọkàn wọn tí kò tọ́, kí wọn máa ṣe àwọn ohun tí kò yẹ.
World water day: Ẹrin Ijesa, Ọ̀ṣun Oṣogbo, àwọn ibùdó ìgbafẹ́ omi tí ó yẹ kí o mọ̀ Ayinla Ọmọwura, orin èébú àti oríyìn lo fi di ọ̀rẹ́ àwọ̀n obìnrin Adeleke bori ni ipele akọkọ ni ile ẹjọ to gbọ awuyewuye idibo l'Ọṣun, Oyetọla lo rẹrin bọ ni ile ẹjọ kotẹmilọrun, ni bayii ọrọ ti wa di ti ile ẹjọ to ga julọ.
Di ohun tí ń bẹ lọ́wọ́ rẹ mú ṣinṣin, kí ẹnikẹ́ni má baà gba adé rẹ.
Iwe iroyin ayelujara Rythm Passport, ni ara oro ‘Bambara’ ti won n pe ni ‘Kassi’ lo ti gba apeja re “Kasse’” eyi to tumo si pe ki eniyan sunkun.
”Ewe, ayeye ayajo odun márùndínlọ́gọ́rin ti igbeyawo won lo laye naa ko gbeyin ki oloogbe ohun o to jade laye.
sellapan ramanathan ( ; ojoibi 3 july 1924 ) je oloselu are singapore to je aare ile singapore kefa .
eniyan jankan-jankan ti o wa yẹ
pe won ya owo lati fi san owo osu yii tabi pe won tun da awon osise ijọba duro
Lẹ́yìn èyí ló pàsẹ kí àwọn 81 Brigade lọ sí ibi #EndSars Lekki Toll Gate.
Adebayo jẹ akọbi lọkunrin fun baba rẹ, Joseph Akanbi Faleti, o si jẹ eleti kan ṣoṣo lọwọ iya rẹ, Durowade Ayinkẹ Faleti nitori ko ni ẹgbọn niwaju, ko si ni aburo lẹ́yìn.
Ọ̀gá iléeṣẹ́ gbé £10 mílíọ̀nù ẹ̀bùn owó fún òṣìṣẹ́, èyí lohun tó pawọ́n pọ̀ Hisbah mú ọkùnrin mẹ́ta tó pín fídíò ìfipábánilòpọ̀ ọmọdébìnrin 16 tó fẹ́ ṣèyàwó lórí ayélujára Ìjọba Katsina ní kí àwọn iléèwé wà ṣì ní títìpa nítorí arùn Coronavirus Tí ìjọba bá gbé òfin kónílé-ó-gbélé ọlọ́jọ́ pípẹ́ míì kalẹ̀ nítori Covid-19, ǹkan yóò bàjẹ́ ní Naijiria- Dokita OPC láwọn mú afurasí agbébọn ajínigbé mẹ́rin l'Oyo, ọlọ́pàá ní àpapọ̀ òṣìṣẹ́ elétò aàbò ló ṣiṣẹ́ náa Bakan naa ni wọn tun fi owo kun owo ina ọba lasiko kannaa, to fi mọ owo ori awọn ọja gbogbo, eyi to nipa buruku lori owo ounjẹ atawọn ohun eelo fun igbaye-gbadun gbogbo osisẹ.
Ọpọlọpọ lo si ti n foya, nitori ipa ti isede ọlọsẹ mẹrin ọhun yoo ni lara ọrọ aje.
Ìfẹ́ tí kì í yẹ̀ ati òtítọ́ yóo pàdé;òdodo ati alaafia yóo dì mọ́ ara wọn.
Coronavirus: Ọmọ ilẹ̀ Amẹrika kú sí Ekiti Láì náání àjàkálẹ̀ àrùn coronavirus, Makinde ṣe ìpàdé ìtagbangba PDP ní Ibadan Ẹyin ilé ìjọsìn, ẹ tilẹ̀kùn ṣọ́ọ̀ṣì àti mọ́ṣáláṣí yín láti dènà àrùn Coronavirus - ìjọba Eko Ìjọ kò ní tilẹ̀kùn ilé ìjọsìn nítorí àrùn Coronavirus - Ondo PFN Ẹ wo ohun tí baba Adeboye sọ lórí ọ̀rọ̀ Coronavirus Wòlíì Sotitobire padà sílé ẹjọ́ lónìí Èyí ni ipa tí àdínkù owó epo bẹtiró yóò mú bá ọ̀rọ̀ ajé Nàìjíríà Lara awọn ti wọn ti wa lọhun ki ijọba to kede l'Ọjọru ṣalaye pe ajalu airotẹlẹ ni ikede ijọba apapọ Naijiria jẹ fawọn nitori awọn ni lati maa tete bọ wa si Naijiria ṣaaju ọjọ Satide ti ofin naa yoo di mimuṣẹ.
Sì sọ fún àwọn eniyan Israẹli pé, ‘Ẹ mú òbúkọ kan fún ẹbọ ìmúkúrò ẹ̀ṣẹ̀, ati ọmọ mààlúù kan ati ọ̀dọ́ aguntan kan fún ẹbọ sísun, kí àwọn mejeeji jẹ́ ọlọ́dún kọ̀ọ̀kan, wọn kò sì gbọdọ̀ ní àbààwọ́n.
Àwọn ọmọbinrin Selofehadi ṣe gẹ́gẹ́ bí àṣẹ tí OLUWA fún Mose; 
Bi o tilẹ jẹ pe awọn agbofinro naa ko kede ẹni to paṣẹ pe ki maṣe gba awọn asoju ijọba laye lati wọle, ṣugbọn lẹnu igba ti Ajimobi ti papoda ni aawọ ti n waye laarin mọlẹbi rẹ ati ijọba ipinlẹ Oyo.
"Olori Chanel Chin jẹ ọmọ orilẹ-ede Jamaica, baba rẹ si ni olorin takasufe ti ọpọ eeyan mọ si ""Bobo Zaro."
Iko Naijiria fagbahan Malaysia ati Belize ninu ifigagbaga akoko ti o waye lojoBo(Thursday).
Ojú kan la fí ń sùn, lẹ́yìn ilẹ̀ mímì tó wáyé Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí 2 sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 2:23 Fídíò, Water Generator: Ó leè ṣiṣẹ fún wákàtí mẹfà, kó tó sinmi, Duration 2,2310 Òkùdu 2020 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
Ofin ìmúnitì to wa ninu iwe ofin orilẹede Naijiria n daabo bo awọn to wa nipo iṣakoso ni Naijiria, eyi ti ko faaye gba gbigbe wọn lọ sile ẹjọ lasiko ti wọn ba wa n'ipo.
E̩nì kò̩ò̩kan ló ní è̩tó̩ sí ìsinmi àti fàájì pè̩lú àkókò tí kò pò̩ jù lé̩nu is̩é̩ àti àsìkò ìsinmi lé̩nu is̩é̩ láti ìgbà dé ìgbà tí a ó sanwó fún.
"O ni ""Wọn ko yin ibọn tabi tajutaju si awọn janduku ọhun, nitori naa, ẹmi ẹnikẹni ko sọnu nibi ti iwọde ọhun ti waye."
Oríṣun àwòrán, AFP Àkọlé àwòrán, Ikọ Al-Shabaab n gbimọran ati sefilọlẹ ijọba ẹsin Islam ni Somalia Ikọ ọmọ ogun ijọba lo n sakoso ilu Mogadishu, sugbọn awọn olugbe ilu naa bẹru awọn ikilọ ikọ alakatakiti yii eyi ti wọn sọ wi pe o ni ọpọlọpọ alami laarin awọn eeyan ilu naa.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù SERAP and Pension: Àjọ SERAP ké sí Buhari lórí èròngbà àwọn Gómìnà láti ná N17trillion nínú owó ìfẹ̀yìntì òṣìṣẹ́ 5 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 6 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Oríṣun àwòrán, @SERAPNigeria Ajọ ajafẹtọmọniyan kan ni Naijiria SERAP ti kesi aarẹ Buhari lati maa ṣe jẹ ki awọn Gomina ya triliọn mẹtadinlogun ninu owo ifẹyinti awọn oṣiṣẹ Naijiria.
Mi o si lero wi pe o tọ lati ma dẹyẹ si mi nitori ọjọ ori mi'' Bakan naa ni Atiku, ninu ibeere mi to jẹyọ lori eto aabo ṣalaye bi yoo ti ṣe dari ipenija to n koju awọn ọmọ ileeṣẹ ologun Naijria.
Wọ́n sì dá iná ńlá kan láti ṣọ̀fọ̀ rẹ̀.
Àwọn ará Ijipti yóo sì mọ̀ pé èmi ni OLUWA, nígbà tí mo bá nawọ́ ìyà sí Ijipti tí mo sì kó àwọn eniyan Israẹli jáde kúrò láàrin wọn.
Oríṣun àwòrán, Instagram/Emmanuel Amuneke Àkọlé àwòrán, AFCON 2019 Ṣaaju akoko yii, oloogbe Stephen Keshi lo gbe ikọ agbabọọlu Togo lọ si idije AFCON lọdun 2006.
00 lọdun kan lati le pese ilera ọfẹ fun awọn to ti kọja ọgọta ọdun,awọn ti ko to ọdun maarun ati awọn alaboyun.
Egbe osise so pe iro patapata  ni oro ti Chris Nigige so pe awon ko ti i fenuko lori ekunwo owo osu ti awon osise yoo maa gba.
Nígbà tí ìpàdè bá parí, ìwọ yóò gbó agogo, lẹ́hìn agogo ni ìwọ yóó maa rí ẹ̀fúùfù líle, ẹ̀fúùfù náà yóò lágbára ju èyí tí ó kọ́ fẹ́ lọ.
Scientific Reports: Ìgbẹ́ ọmọdé ní àǹfààní púpọ̀ lára
com/b9uDvzOjl9— Chelsea FC (@ChelseaFC) 19 April 2018Gege bi Antonio Conte se so,”A kopa ribiribi lo ni, bee si ni, a ni eto si ami meteeta ohun, ni papa julo, Moses se gudugudu meje ohun yaya mefa, leyin ti o gba ami-ayo kan wole t o si tun se iranwo ami-ayo kan.
Ọ̀dọ̀ fásitì jànkàn Oxford ló ti jáde Coronavirus cases in Africa- Ó tí lé ni mílíọ̀nù kan ènìyàn to ti lùgbàdì ààrùn Covid-19 Pẹlu afikun tuntun yii, o jasi pe iye awọn ti ayẹwo ti fihan pe o ni aarun yii lorilẹede Naijiria ti di ẹgbẹrun mẹrinlelaadọta ati ẹgbẹta o din mejila, 54, 588.
Mo kí gbogbo ẹni tó fi ìhà aríwá àgbáyé ṣe ibùgbé kú ìpalẹ̀mọ́ ọ̀gìnìntìn tó fẹ́rẹ̀ẹ́ dé o.
Ọdọọdun si ni wọn maa n se ọdun ibeji nilu naa, eyi to tun ko lọdun yii, ti ko si sẹyin ikọ iroyin BBC Yoruba.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Bí o bá fẹ́ darapọ̀ mọ́ ikọ̀ ọlọ́pàá SWAT tí yóò rọ́pò SARS, wo àmúyẹ tí o gbọ́dọ̀ ní Aisha Buhari polongo àwo orin tó ní Nàíjíríà ń ṣun ẹ̀jẹ̀ lásìkò ìwọ́de Lizzy Anjorin ń kiri àgọ́ ọlọ́pàá láti gba ọ̀dọ́ afẹ̀hónúhàn, tó wà láhàámọ́ sílẹ̀ 2015 ni mo ti ń kígbe pé gudugbẹ̀ máa já ní Nàíjíríà - Oyedepo Wo ohun tí ìwọ́de ENDSARS ṣé fáwọn akẹ́kọ̀ọ́ tó fẹ́ ṣèdánwò NECO Láàrin wákàtí mẹ́ta, wọ́n dá ₦4m fún àkàndá ẹ̀dá tó kópa nínú ìwọ́de Awọn eeyan tun wa n kọminu lori igbesẹ ologun lati bẹrẹ akanse eto naa lasiko yii ti arun Coronavirus si wa lode.
tesiwaju pe ,”Pupo ninu awon orile ede Afirika lo ti tesiwaju ti won si ti fi  orile ede Naijiria to je bi asiwaju wọn seyin.
sami ayeye si igba ti ijoba ologun gbe ijoba sile fun ijoba alagbada lodun 1999.
Lagos Lion: Kìnìhún ti jí lẹ́yìn abẹ́rẹ́ orun méjì tí wọ́n yìn lù ú
Oríṣun àwòrán, Gloria Yusuff O fi kun ọrọ rẹ pe, wọn tun maa n beere pe kin lo de ti oun ko ti fii lọ sile ọkọ nigba ti oun ba da wọn lohun pe, oun ko ti ṣe igbeyawo.
Wọ́n sin òkú rẹ̀, nítorí wọ́n ní, “Ọmọ ọmọ Jehoṣafati, ẹni tí ó fi tọkàntọkàn gbọ́ ti OLUWA ni.
Gẹgẹ bi ẹni to mọ ilu lilu, Oladele bẹrẹ si ni ba wọn lu ilu ninu ijọ naa.
Kíyèsára, nítorí pé OLUWA ti yàn ọ́ láti kọ́ ilé kan tí yóo jẹ́ ibi mímọ́, ṣe gírí, kí o sì kọ́ ọ.
Awọn meji miran ku lẹyin ti ẹnikan fun wọn Minisita Sisulu sọ pe ijọba ko faye gba iru iwa bẹẹ, bakan naa lo ke si awọn agbofinro lati mu awọn to n da wahala silẹ.
Kemi Afolabi: Mo mọ rírì àwọn olólùfẹ́ mi, àdúrà ti wọn náà yóò gbà
Ẹdọ̀ fóóró, ẹ̀dọ̀, kídìnrin, àti àwọ ara yóò maa fọ idọti wọn kuro.
Agbegbe ibi ti omiyale naa ti ṣọṣẹ Àkọlé àwòrán, Àwòrán atọ́ka àwọn ìlú tó wà ní Katsina Iyawo ọsingin ba omiyale lọ Ọjọ Ẹti to kọja ni awọn ara adugbo sọ pe ọmọbinrin naa ṣe igbeyawo, ko to dipe wọn gbe e wa sile ọkọ rẹ lọjọ Abamẹta.
Lara awọn eeyan naa to ba BBC Yoruba sọrọ ni Segun Paul to jẹ adẹrin poṣonu loju opo Instagram, ti ọpọ awọn ololufẹ rẹ mọ si Olukọni.
Wọn tun ni ko ṣe e fi ọkan tan ati pe o tun gba owo ati ẹbun lọna aitọ yatọ si aṣilo ipo ati agbara.
Èrè àwọn olódodo a máa fa ìyè,ṣugbọn èrè àwọn eniyan burúkú a máa fà wọ́n sinu ẹ̀ṣẹ̀.
Ẹni to bori: Egypt Ìpele to ṣaaju eyi to kangun si aṣekagba Senegal vs South Africa.
Ni a bá wọ̀ ọ́, ọkọ̀ bá ṣí.
Ẹ jẹ́ kí àwa ilẹ̀ Afirika bá arawa ṣòwò, kí a máa ra ọjà arawa kí ìlọsiwájú tó péye lè dé bá wa.
Owo ti ile ẹjọ ba sọ pe ki ẹ fi gba oniduro, kii se fun ile ẹjọ, o tumọ si pe iye owo ti o o san fun ile ẹjọ niyẹn ti ẹni to duro fun ba salọ.
Awọn ileewe giga ti ọrọ naa kan, ni ileewe ẹkọṣẹ olukọni agba to wa nilu Ila Ọrangun, ileewe ẹkọṣẹ olukọni agba to wa nilu Ilesa, ileewe gbogboniṣe poly ti ilu Iree ati ileewe imọ ẹrọ OSCOTECH, Esa oke.
ole, idi niyi ti aare Buhari se n gbogun ti iwa ibajẹ ni orile ede yii.
N óo wẹ̀ wọ́n mọ́ kúrò ninu gbogbo ẹ̀bi ẹ̀ṣẹ̀ tí wọ́n dá sí mi, n óo dárí gbogbo ẹ̀ṣẹ̀ ati oríkunkun tí wọ́n ṣe sí mi jì wọ́n.
 ti pada si ipinle Gombe bayii  lẹyin ofin wakati màrúndínlógún konile-gbele ti ijoba ipinle naa
O ni iye eeyan to wa lorile-ede Naijira gan an ti pọ si i.
Ọ̀rọ̀ tí Aisaya ọmọ Amosi sọ nípa Juda ati Jerusalẹmu nìyí:
Eeyan 59,634 lo ti jajabọ lọwọ aarun coronavirus bayii.
"Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Sex: Ìye ìgbà tóo ní ìbálòpọ̀ kọ́ ló ń jẹ́ kí abẹ́ obìnrin fẹ̀ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Sex: Ìye ìgbà tóo ní ìbálòpọ̀ kọ́ ló ń jẹ́ kí abẹ́ obìnrin fẹ̀ Oríṣun àwòrán, Yinka TNT/Facebook 2 Ògún 2020 ""O lereju abẹ ti ọkunrin maa n fẹ ba le, ti wọn ba ti wọle ti wọn ri i pe awọn ja lu Express, wọn a sa pada""."
“Ṣugbọn bí alufaa bá wá yẹ ilé náà wò, tí àrùn náà kò bá tàn káàkiri lára ògiri rẹ̀ lẹ́yìn tí wọ́n ti tún un rẹ́, alufaa yóo pe ilé náà ní mímọ́, nítorí àrùn náà ti san.
olubori , ni won ti n bẹrẹ si n fi idunnu won han.
Ọna miran tun ni pe ki ọkunrin tabi obinrin gbiyanju lati da itọ duro lasiko ti wọn ba n tọ lọwọ.
Amọ, ẹgbẹ oṣelu APC ni gomina ipinlẹ Edo lo kọ awọn janduku si Ile igbimọ aṣofin nitori ko fẹ ki wọn yọ oun kuro ni ipo.
Ai k;í ń le maa sun daadaa fun iye wakati to yẹ: Njẹ o tí ṣẹlẹ sí yin ri wípé ẹ gbagbe ibi ti ẹ fi kokoro ile yin sí tàbí kí ẹ tí ẹ gbagbe ona lati dé ilé pada.
Ikọ agbabọọlu Nasarawa ko tii sọrọ lori iku ojiji adilemu wọn to ti ṣoju ikọ agbabọọlu naa nigba mẹrin ọtọtọ ni saa bọọlu yii.
Ọjọru ni ajọ to n gbogunti ijẹkujẹ lorilẹede Naijiria, EFCC, pada gbe Fayoṣe lọ sile ẹjọ giga ti ijọba apapọ to wa ni adugbo Ikoyi nipinlẹ Eko.
Nígbà tí Peteru rí wọn, ó bi àwọn eniyan pé, “Ẹ̀yin eniyan Israẹli, kí ló dé tí èyí fi yà yín lẹ́nu?
Oríṣun àwòrán, Instagram Àkọlé àwòrán, Ọjọ kini, Osu Kini, ọdun 1978 ni wọn bi gbajugbaja oṣere, Mercy Aigbe ni ipinlẹ Edo.
 Obama bawon soro ni fafiti ti Cairo ni eyi to pe ni ibere otun nibi to ti fon rere Pataki nini ajosepo to rorun pelu awon elesin islaamu ni agbaye ati ona abayo lati gbogun ti ija esin.
Àwọn ìtàn Mánigbàgbé tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ìtàn ayé Taiwo Oredein rèé, ó kọ́ wa láti máa ni ìtẹ́lọ́rùn Ìtàn ìgbésí ayé Oshodi, ọmọ Tápà léǹpe tó di akọni ní ìlú Eko Ìtàn tó rọ̀ mọ́ òwe ‘aṣọ kò bá Ọ́mọ́yẹ mọ́.
Awọn ta n sọ yi ni agba ki fi gbogbo ẹnu sọrọ ati pe, bi o ti ṣe yẹ ki Tinubu sọrọ lo ṣe sọ.
Oríṣun àwòrán, @others Àkọlé àwòrán, Awọpn obinrin Madaka sọ pe aye wọn ninu ewu latari ọna ti ko si Hajara Kadamato, to jẹ ọkan lara awọn ti iṣẹlẹ ọhun ṣẹlẹ si sọ pe, oun padanu ọmọ nitori ọna ti ko si labule ọhun.
Kano Death: Àwọn Dókítà ní Kano ni irọ ni pé àwọn sá kúrò ní Kano nítorí ikú tó ń pa àwọn èèyàn Alaga ẹgbẹ awọn oniṣegun oyinbo ni ipinlẹ Kano ti ni ahesọ lasan ni iroyin ofege to gba igboro kan pe awọn dokita n sa kuro ni ipinlẹ Kano nitori arun to n fa iku ọwọọwọ.
Ni ìgbá ayé olóògbé Adébáyọ̀ Fálétí, ó jẹ́ ìkan ninú àwọn òṣìṣẹ́ àkọ́kọ́ ni ilé iṣẹ́ amóhùn-máwòrán àkọ́kọ́ ni ilẹ̀ Aláwọ̀dúdú ti wọn dá sílẹ̀ ni Ìbàdàn ti ó jẹ́ olú ilú ẹ̀yà Yorùbá ni ìwọ̀ oòrùn orílẹ̀ èdè Nigeria.
Ẹ̀sùn mẹ́tàdìnlógún ni àjọ EFCC fi kàn án, àti Fani-Kayọde, tó fi mọ́ alága nígbàkan rí fún ẹgbẹ́ àwọn ìjọba ìbẹ́lẹ̀ ní Nàìjíríà, Ọ̀gbẹ́ni Yusuf Danjuma.
Ohun tí ó mú kí n sọ̀rọ̀ báyìí ni pé kò sí ohun tí ó kàn mí ninu ọ̀rọ̀ a-jẹ́-aṣaaju tabi a-kò-jẹ́-aṣaaju.
Amọ awọn miran faramọ ọrọ ti o sọ, bi o tilẹ jẹ wi pe awọn ko ri ọkan rẹ ati idi ti o fi sọrọ naa.
O salaye pe, “ijoba orile-ede Naijiria niloo lati bere si n fun awon omo ile-iwe ni anfaani ati ko imo lori eto ogbin, imo ijinle igbalode lori ohun ogbin ati awon agbegbe miiran ti o je mo eto ogbin ni awon ile-iwe ijoba gbogbo”.
Ọpọ lo n ṣedaro Patrick Day lori ayelujara, wọn kẹdun pẹlu ẹbi rẹ ninu ọrọ ti wọn fi sita.
Nàíjìrìà ti ṣe tán láti f'ẹjọ́ sun EU, UN lórí àwọn akẹ́kọ̀ọ́ tí Croatia le lọ sí Bosnia Ọlọ́pàá bẹ̀rẹ̀ ìwadìí lórí ikú olùṣirò owo táwọn agbénipa pa ní Ikorodu Wo àwòràn ohun tó ṣẹlẹ̀ nílé ìjọsìn Sotitobire tí wọ́n sun ní àná O sọ pe ile ẹjọ Naijiria ti ṣaaju ni Adoke ko jẹbi ẹsun ti wọn fi kan an ati pe dide to pada de si Naijiria yii, yoo lọ yanju ara rẹ lọdọ awọn to yẹ.
Ìdí rèé táwọn ọmọ Nàíjíríà kan ṣe ń tako ìdásílẹ̀ ‘Ruga Settlement’ Ajọ to n risi ọrọ aàwọ ara ni orilẹ-ede Britain sọ pe, ''awọn ohun to ba ni hydroquinone ninu ṣe e lo lati ṣe iwosan awọn aarun aawọ ara kan, labẹ amojuto onimọ nipa àwọ ara, ti yoo si so eso rere.
Orílẹ́èdè Nàìjíríà ni ìtànkálẹ̀ òtútù ìgbá àyà tí pọ̀ jù lọ lágbàáyé Olùdásílẹ̀ Twitter bá wọn jó 'Soapy' ní Nàìjíríà , ó fi òǹtẹ̀ jan Tacha Ta ni Ken Saro-Wiwa tí ìjọba ológun sekúpa?
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Iná Ibadan: Gbogbo dúkìá tó wà lókè ilé alájà kan náà ló jóná tán Akọ̀wé ẹgbẹ́ CAN ní ìpínlẹ̀ Ebonyi nígbà kan ri tí wá rọ ọmọ Nàìjíríà láti fi ori jí òun ati pé òun yóò ma kíyèsára ní ìgbà míràn.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù 2019 elections: Ganduje ní òun yóò gba èsì yóòwù tó bá jáde ní ìdìbò gómìnà Kano 8 Ẹrẹ̀nà 2019 Oríṣun àwòrán, kabiru gaya Àkọlé àwòrán, Gandije ni oun gba pe Ọlọrun mọ̀ sí èsì yóówù tó bá jáde nínú ìdìbò náà.
Lọwọlọwọ, apapọ awọn to ti ni aarun naa ti pe 61,558, eyan 56,697 ti ri iwosan, 1,125 si ti ku.
Oríṣun àwòrán, Gboyega Akosile Àkọlé àwòrán, Aworan awọn ọkọ ti ijọba fẹ lu ni gbanjo Ṣaaju ni ijọba ipinle Eko ti kọkọ kede pe ẹnikẹni ti ọwọ ba tẹ pe o tapa s'ofin naa yoo ki ọkọ rẹ ni odigboṣe.
Awọn ti wọn ji gbe naa ni Fada Victor Adigboluja ti ẹkùn Ijebu Ode, Fada Anthony Otegbola ti ẹkùn Abeokuta, Fada Joseph Idiaye ti ẹkùn agba ti Benin ati Fada Obadjere Emmanuel ti ẹkùn Warri.
Kò yẹ kí òṣèlú ó jẹ́ ìdààmú fún wa.
 bí baba ń lọ , bí ń bọ ̀ , ẹnu rẹ ̀ kì í dákẹ ́ .
Asán ni kí á máa fi làálàá wá oúnjẹ;nítorí pé OLUWA a máa fún àwọn àyànfẹ́ rẹ̀ ní oorun sùn.
Aya gomina ipinle  Adamawa , Ahmadu Fintiri ati awon aya aare orile ede Ghana, Niger, Chad, Gambia ati Cote D’Ivoire pelu awon aya awon gomina  ipinle to wa lorile ede  Naijiria yii, ni won jo peju-pesẹ sibi eto naa.
Jakọbu sọ fún Simeoni ati Lefi pé, “Irú ìyọnu wo ni ẹ kó mi sí yìí?
O ni pé gómìnà ìpínlẹ̀ Ọyọ onímọ-ẹ̀rọ Seyi Makinde yóò yí ìpínnu rẹ̀ padà lóri gbígbẹsẹlé ẹgbẹ́ náà.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Jẹẹsí Super Eagles: N5,000, N3000, N2,500.
Amọ ile isẹ ipoogun naa ti ni awọn ko faramọ idajọ ile ẹjọ naa, nitori naa awọn n gba ile ẹjọ kotẹmilọrun lọ.
Loom Money Nigeria: Ṣáájú Loom Money Nigeria, àwọn ètò sogún-dogójì púpọ̀ ti ta pàù lórílẹ̀èdè
Nítorí pé nígbà tí mo wà ninu ẹ̀wọ̀n ati ìgbà tí mo ní anfaani láti gbèjà ara mi ati láti fi ìdí ọ̀rọ̀ ìyìn rere múlẹ̀, gbogbo yín ni ẹ jẹ́ alájọpín oore-ọ̀fẹ́ Kristi pẹlu mi.
Ẹ kú dédé àsìkò yìí gbogbo olólùfẹ́ ojú ìwé yìí, Èyí ni láti kéde wípé láti ọlá lọ a ó bẹ̀rẹ̀ si ká ìwé Ègún Aláré tí
Agbarijọpọ ẹgbẹ ajafẹtọ kan ti wọn pe ara wọn ni Coalition of Civil Society group ṣewọde lọ si olu ileeṣẹ ilẹ Gẹeṣi l'Abuja.
Kò sí Ààrẹ tàbí Gómìnà tó lè dá ìfẹ̀họ́núhàn àwọn Nàìjíríà lórí #EndSARS dúró- Monday Ubani Ẹ lo ìfẹ̀họ̀núhàn #EndSARS lati fí tún gbogbo ohun tó bàjẹ́ ṣe ní Naijiria- Pásítọ̀ Sam Adeyemi Buhari sọ pe ọga ọlọpaa ti gba aṣẹ lọwọ oun lati gbe igbesẹ lori awuyewuye to n waye lati ọdọ araalu lori iwakiwa to wa lọwọ awọn ọlọpaa SARS, ati lati ri i daju pe awọn ọlọpaa to hu iwa ti ko tọ foju wina ofin.
Alaafin ti ilu Oyo, Oba Lamidi Olayiwola Adeyemi kẹta ti fi ilumọọka olorin Fuji, Alhaji Wasiu Ayinde jẹ oye Mayegun ilẹ Yoruba.
”Àwọn eniyan náà dá a lóhùn pé, “Ṣe èyí tí ó bá dára lójú rẹ.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Lara awọn ohun ti gbogbo ọmọ igbimọ naa fẹnuko si ni iwọnyii: Eti fun irọwọrọsẹ idije naa ati abo ko peye lasiko ipele keji aṣekagba idije CAF Champions league to waye ni ọjọ kọkanlelọgbọn oṣu karun ọdun 2019 eyi ti ko fi aaye silẹ fun ifẹsẹwọnsẹ naa lati wa si opin gẹgẹ bi ofin ere bọọlu ṣe laa silẹ.
Ẹni tí ń wo ojú afẹ́fẹ́ kò ní fún irúgbìn kankan,ẹni tí ó bá sì ń wo ṣúṣú òjò kò ní kórè.
Ó lọ sí ilé wolii Ahija ní Ṣilo.
Òun ni ó mú kí gbogbo nǹkan dúró nípa agbára ọ̀rọ̀ rẹ̀.
Nítorí náà, ó na ọ̀pá tí ó mú lọ́wọ́, ó tì í bọ inú afárá oyin kan, ó sì lá a.
Alaye lori asiko ikẹyin Oriṣabunmi Oríṣun àwòrán, Instagram/standard_presenter Nigba to n tẹsiwaju ninu fidio naa, Baba Ijẹṣa ni ọpọlọpọ awọn oṣere ni inu wọn ko dun si bi ijọba lẹkajẹka gbogbo ṣe n ja awọn oṣere sinima kulẹ nipa aitọju wọn ati airi tiwọn ro.
Gbogbo ọrọ ẹ ku ara fẹraku ti awọn eeyan kakakiri agbaye ti n sọ nipa rẹ nikan kọ lo fi han pe eniyan ọtọ ni.
Olorì Gẹ̀ẹ́sì kan tí kò rí ọmọ bí lọ síbẹ̀, ó sì wẹ̀ nínú omi Sulis.
”Lara awon agbaboolu jankan-jankan ti yoo kopa ninu
Orúkọ wọn yóo máa jẹ́ ẹnubodè Simeoni, ẹnubodè Isakari ati ẹnubodè Sebuluni.
Won ko sun, won ko wo lati
Àlàyé rèé lórí ikú tó pa Ogun Majek O ni Aarẹ Buhari to fi ṣe ọrẹ ti sọ di ọta, ti gbogbo ero rẹ lori ẹgbẹ oṣelu APC si ti jasi pabo.
Nígbà tí àwọn olórí alufaa ati àwọn amòfin rí àwọn ohun ìyanu tí Jesu ṣe, tí wọ́n tún gbọ́ bí àwọn ọmọde ti ń kígbe ninu Tẹmpili pé, “Hosana fún Ọmọ Dafidi,” inú wọn ru.
O ni eyi yoo le jẹ ki wọn ba awọn akẹẹgbẹ wọn lagbaye pe, tawujọ agbaye yoo si maa gbe osuba fun awọn osere ni Naijiria pẹlu.
N óo gbà wọ́n ninu gbogbo ẹ̀ṣẹ̀ ìfàsẹ́yìn tí wọ́n ti dá.
Ṣugbọn laarin ọdun mẹrin ati oṣu mẹjọ, Abacha ti sọ owo ti Naijiria ko pamọ silẹ okeere di biliọnu mẹsan dọla, amọ gbogbo owo yii lo parẹ lẹyin oṣu mẹsan ti Abacha ku.
Jesu wá bi í pé, “Kí ni orúkọ rẹ?
Ọjọgbọn Yẹmi Osinbajo sọ ibanujẹ rẹ lẹyin abẹwo rẹ si ile ẹwọn kan n'ilu Port Harcourt, eyi ti ijọba kọ lati gba awọn ẹlẹwọn ẹgbẹrin, ṣugbọn nisisiyi o ni marun ẹgbẹrun ẹlẹwọn lọ.
Ranti mi, OLUWA, nígbà tí o bá ńṣí ojurere wo àwọn eniyan rẹ.
Awon onimo kan tile so pe iwa aito  si awon obinrin je eyi ti o lodi si ofin eto omoniyan lawujo, nibi yoowu ti won ba ti n hu iwa iwa bayii.
Nítorí ẹ ti gbúròó ìwà mi látijọ́ nígbà tí mo wà ninu ẹ̀sìn ti Juu, pé mò ń fìtínà ìjọ Ọlọrun ju bí ó ti yẹ lọ.
Kí lo mọ̀ nípa ìbẹta kan ṣoṣo tí Alaafin Oyo bí?
 johnston fúnra rẹ ̀ kú ní oṣù kẹjọ ọdún náà lẹ ́ yìn tí ó pé ọdún méjìdínlaadọrin .
Amọ ṣa, awọn onimọ nipa ọrọ ifẹ fi ikilọ sita pe, ki awọn eeyan fi ọgbọn ati oye lo loju opo ayelujara, ki wọn maa ba gbe eegun eleegun.
Alaga ẹgbẹ akọroyin ni ipinlẹ Ọyo, Kọmureedi Adewunmi Faniran lo sọ eyi fun BBC Yoruba, lasiko to n fesi si bi ile iṣẹ ologun Naijiria, ṣe yabo ile iṣẹ iroyin Daily Trust ni Maiduguri ati Abuja.
Gbajugbaja olorin Naijiria Afeez Fashola ti gbogbo eeyan mọ si Naira Marley ni orukọ rẹ leke ninu orukọ awọn ilumọọka ni Naijria tawọn eeyan n bere ọrọ nipa wọn.
Ní ọjọ́ náà, wọ́n mú ìròyìn iye àwọn tí wọ́n pa ní Susa wá fún ọba.
"Atawọn to n ti Oluomo lẹyin atawọn to jẹ ololufẹ Ronke ṣugbọn ti wọn ni o ja awọn kulẹ nitori wọn ni ""o ngbe lẹyin janduku oloṣelu to ti gba ẹmi ọpọ""."
Awon alamojuto eto idibo labe akoso ajo ECOWAS ati ajo AU se ipade, latari ati se agbekale ilana fun eto idibo ti yoo waye ni awon orile-ede naa.
Fun apẹrẹ, ọgẹdẹ ni eroja bi vitamin B1,C magnesium ati bromelain ti wọn n ṣiṣẹ takuntakun ni ara ọkunrin.
Yára wá, olùfẹ́ mi,yára bí egbin, tabi ọ̀dọ́ akọ àgbọ̀nrín,sí orí àwọn òkè turari olóòórùn dídùn.
Ní ọjọ́ kẹrinla oṣù Adari àwọn Juu tí wọ́n wà ní Susa tún parapọ̀, wọ́n sì pa ọọdunrun (300) ọkunrin sí i.
1 Ìdìde ti Ìjọ Krístì ní àwọn ọjọ́ tí ó kẹ́hìn wọ̀nyí, tíí ṣe ẹgbẹ̀rún kan ọgọ́rũn mẹ́jọ ati ọgbọ̀n ọdún lati ìgbà wíwá Olúwa àti Olùgbàlà wa Jésù Krístì nínú ẹran ara, òun náà ti a ṣe àkójọ rẹ̀ dáradára àti tí a gbé e kalẹ̀ ní ìbámu pẹ̀lú àwọn òfin orílẹ̀ èdè wa, nípa ìfẹ́ inú àti àwọn àṣẹ Ọlọ́run, ní oṣù ìkẹrin, àti ní ọjọ́ ìkẹfà ti oṣù náà èyí tí a npè ní Oṣù Kẹrin—
Ọládúpọ̀ - - Ọmọ Àkàngbé Orímóògùnjé ni òun náà.
S Badore - Five Cowries Badore - Ijede Baiyeku - Ajah Baiyeku - Victoria Island Ebute Ero - Ikorodu Ebute Ojo - Ijegun Egba - Marina C.
 gbogbo aáyan àwọn ifẹ ̀ láti mú kí Ọlọ ́ gbẹ ́ ńlá padà sí ifẹ ̀ lẹ ́ yìn tí ó ti ṣẹ ́ gun ní oǹdó ló já sí pàbó .
₦50 Duty Stamp: Iléẹjọ́ korò ojú sí CBN bó ṣe ń yọ owó táwọn báńkì olókoòwò fi pamọ́ sọ́dọ̀ rẹ̀
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ẹ̀tàn lásán ni ìkéde ìjọba àpapọ̀ lórí RUGA - Afenifere Ẹ̀yin tẹ́ẹ tako àgbékalẹ̀ àgọ́ Fulani, ìkórira ló ń yọ yín lẹ́nu - Ìjọba àpapọ̀ Ooni Ile ife, Ààrẹ Gani Adams fárígá lórí ikú ọmọ Fasoranti Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Ní ọjọ́ keji, wọ́n fi ẹgbẹrun akọ mààlúù rú ẹbọ sísun sí OLUWA, ati ẹgbẹrun àgbò, ati ẹgbẹrun ọ̀dọ́ aguntan, pẹlu ọrẹ ohun mímu ati ọpọlọpọ ẹbọ fún gbogbo àwọn ọmọ Israẹli.
Ó wí fún Dafidi pé, “Eniyan rere ni ọ́, èmi ni eniyan burúkú, nítorí pé oore ni ò ń ṣe mí, ṣugbọn èmi ń ṣe ọ́ ní ibi.
Ọpọ ọdọ lode oni si lo fẹ mọ ohun ti iran Yoruba ṣe fun Aole, to fi ṣẹ epe naa.
O ni ijọba ṣi n sọrọ pẹlu awọn alakatakiti ẹsin Islam, ISWA lori fifi Leah Sharibu silẹ.
N óo máa yìn ọ́ títí ayé mi;n óo máa tẹ́wọ́ adura sí ọ.
Ẹni tí ń fi baba rẹ̀ ṣe yẹ̀yẹ́,tí ó kọ̀ tí kò tẹríba fún ìyá rẹ̀,ẹyẹ ìwò àfonífojì ati àwọn igún ni yóo yọ ojú rẹ̀ jẹ.
Oríṣun àwòrán, Emmanuel Oyeleke Ijọba ni oun gbe awọn igbesẹ ọhun lati dẹkun bi ọwọja arun Coronavirus to n ja kiri eyi to ti mu ki awọn eeyan to ni arun naa lorilẹede Ghana di mẹfa, lati meji to wa tẹlẹ.
O jawe olubori ninu idibo sipo aṣofin lọdun 1946 ati 1947.
Lórí wọn ni àwọn ẹyẹ ń tẹ́ ìtẹ́wọn sí,àkọ̀ sì ń kọ́ ilé rẹ̀ sórí igi firi.
O ni o yẹ ki wọn maa dibo ni alafia ni ki esi si jade bi wọn ba ṣe n ṣe idibo tan.
OLUWA wí fún Samuẹli pé, “Ìgbà wo ni o fẹ́ káàánú lórí Saulu dà?
Buhari ba osinbajo sayẹyẹ igbeyawo ọmọ rẹ.
Tí ẹ bá rántí, aláṣẹ ìjọba lorílẹ̀-èdè Nàìjíríà ti kọkọ sọ pé o lé ni ọgọ́rún kan ènìyàn ló ti pàdánù ẹ̀mí wọn nípa àgbàrá omíyale àgbárá ya sọ́ọ̀bù tó ń ṣẹ̀lẹ̀ jákèjádò Nàìjíríà láàrín osẹ̀ méjì sẹ́yìn.
Nígbà tí Pirisila ati Akuila gbọ́ ọ̀rọ̀ rẹ̀, wọ́n mú un, wọ́n túbọ̀ fi ọ̀nà Ọlọrun yé e yékéyéké.
Bo tilẹj ẹ pe ọpọlọpọ eniyan lo ni coronavirus nibẹ - ilana títọ pinpin awọn to ni nkan ṣe pẹlu ẹni to ba ni aarun naa ni wọn n lo.
#Oshiomole: Àwọn aṣáájú APC kò mọ ohun ti wọ́n n ṣe lásìkò yí Ko pẹ si igba naa ni ikede miran wa lati ile ijọba pe wọn ti yọ akọwe ẹgbẹ naa ati pe wọn tun kọwe lọ fidimọlẹ fun alaga ẹgbẹ naa lapapọ Adams Oshiomole.
èèyàn mẹ́rin míràn móríbọ́ lọ́wọ́ Coronavirus l'Eko Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí 3 sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
Iwaadi ti fi han pe o ṣeeṣe ki awọn eeyan ni arun yi lara lalai mọ ti eleyi si ni ewu pupọ.
A kò lè ronú lọ́nà kan ṣoṣo, nítorí náà, ìjà àti asọ̀ máa ń jẹ́ àwọn nnkan tí a kò lè ṣàì má rì í níbi ti àwọn ènìyàn bá ń gbé.
Wọn ni ọpọ ero lo maa n fẹ fọwọ kan awọn ẹni mimọ yii tabi ki wọn fẹ mu nkan lara wọn lati fihan pe awọn pade wọn ni mọṣalaṣi nla.
Oríṣun àwòrán, Others Ki lo pa ọgagun Borgi to sẹsẹ se igbeyawo, iku ati ọrun wa ni, Boko Haram ni abi awọn ọta rẹ to n fi ara han bi ọrẹ?
"Ìyá ló lọmọ ní tòótọ ́ gẹ ́ gẹ ́ bí ohun tí àwọn yorùbá máa ń sọ , ìyá lalábàárò , ìyá jìjì tún tọ ọmọ rẹ ̀ lọ pẹ ̀ lú ọ ̀ pẹ ̀ lọpọ ̀ ẹ ̀ bẹ ̀ àti àròyé "" jọ ̀ wọ ́ ọmọ mi Àṣàkẹ ́ ."
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Nigerian Fraudsters: Ìwádìí BBC fihàn pé ìdajì àwọn gbájúẹ̀ lágbàyéé wá láti Nàíjíríà Wolii Ayodele ni gbogbo erongba Tinubu, Bukola Saraki, Aminu Tambuwal, Kayode Fayemi ati Amaechi lati dije fun ipo aarẹ Naijiria ni yoo ja si pabo ni 2023.
Lára àwọn dúkìá olówó iyebíye ọba alaye náà tó ṣòfò sínú làásìgbò ni ile alaja kan tó wà ní òpópónà Oludasa nilu Ọwọ èyí tí owó rẹ tó ẹgbẹ̀rún mẹta pọn-un, àwọn ohun èlò ara fún ọba alaye náà, towo wọn tó ẹgbẹ̀rún mẹ́fà ó lé díẹ̀ pọn-un.
Jẹfuta bá jẹ́jẹ̀ẹ́ kan sí OLUWA, ó ní, “OLUWA, bí o bá ràn mí lọ́wọ́ tí mo bá ṣẹgun àwọn ara Amoni, 
Kò ní sinmi títí yóo fi jẹ ẹran tí ó pa tán,tí yóo sì fi mu ẹ̀jẹ̀ rẹ̀ tán.
Ko si amojuto fun iwosan alabọde, eyi to fi jẹ ki gbogbo eniyan maa wa si awọn ile iwosan ikọṣẹ iṣegun.
“Nítorí náà, ìwọ ọmọ eniyan, sọ àsọtẹ́lẹ̀, kí o sápẹ́, fi idà lalẹ̀ léraléra, idà tí a fà yọ tí a fẹ́ fi paniyan.
"Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: ""Àlàyé rèé lórí bí mo ṣe fi ọsàn híhó fẹ́ ìyàwó mi"" Ọwọ́ tẹ ọkùnrin kan ní pápákọ̀ òfurufú l‘Eko tó ń kó ike ATM 2,886 lọ si Dubai Lẹ́yìn ọ̀pọ̀ ọdún, ìjọba Kwara fẹ́ sọ orúkọ Rashidi Yẹkini di mánigbàgbé Ọ̀kẹ àìmọye ẹ̀rọ àyẹ̀wò káàdì olùdìbò jóná mọ́lé l' Ondo Wo iye àwọn tó ti gbẹ̀mí ara wọn ní Nàìjíríà láàrin ọdún mẹ́rin ìjọba Buhari Lagbegbe Alasia bus stop ni Marosẹ Lekki si Epẹ; Ajọ LASEMA si jẹ ko di mimọ pe ijanu ọkọ akoyanrin lo sọ iṣẹ silẹ ti fi lọ kọlu ọkọ ayọkẹlẹ naa to si tẹ awakọ rẹ pa."
Kiakia ni akọwe ipolongo ẹgbẹ naa ti fi ọrọ sita loju opo Twitter nipa ọrọ yi.
    Emi náà fèsì mo ní, ‘Kábíyèsí’, à ń lọ sí òkè Ìrònú ti ń bẹ nínú Igbó Elégbèjè, kí ọgbọ́n bà túbọ̀ wọ inú [[ilú wa, kí òye ba túbọ̀ wọ ibẹ̀.
com/RPyoNgkLUC  Dusan Tadic70′Marco Asensio  1 – 3  72′1 – 4  Lasse Schoene90′Nacho Fernandez    90′Nacho Fernandez         Kaadi olomi osan Keji ati Kaadi pupa Bakan naa, iko agbaboolu Dortmund fori bale fun iko agbaboolu Tottenham leyin ti won padanu ifesewonse ikolu mejeeji pelu ami ayo merin sodo(0-4).
Mo ní kí ẹ̀yin àgbà sọ̀rọ̀,kí ọ̀rọ̀ yín sì fa ọgbọ́n yọ gẹ́gẹ́ bí ọjọ́ orí yín.
" Ọgbẹni Oyebode ṣalaye pe ofin tuntun naa ko yọ àwọn ẹbí paapaa, to le fẹ ba ẹjọ jẹ, silẹ.
Obasanjo ni arise ni arika, ati pe arika ni baba iregun pe ọpẹlọpẹ Oloogbe Walter Carrington lo fun oun ni aaye lati ribi sa asala fun ẹmi oun lati satipo oloselu nie America nigb anaa O ni lodun 1995 ti oun lọ si Copenhagen lati lọ si ipade agbaye World Social Summit as Human Development Ambassador of the United Nations Development Programme nigba naa.
”pataki ipade yii ni ka fi ohun gbogbo ti a ti ṣe ni Ile Igbimọ Aṣofin Ipinlẹ Eko to araye leti, ka dẹ gbọ ibi ti kudiẹkudiẹ to ba ku diẹ kaato si lọdọ awọn eniyan”Ọpọ awọn tọrọ kan to kopa ninu ipade naa, ni wọn sọrọ lori oriṣriṣi akoonu, bii ọrọ ayika, ilana iṣe-ofin, ojuṣe Ile naa lori amojuto awọn iṣẹ ijọba, aabo ilu, owo-ori nnkan ini to jẹ mọ ilẹ ati ile ati awọn nnkan miiran.
Nígbà tí ó dé ibẹ̀ ó wò bí wọ́n ti ṣe di òkú náà dáradára, lẹ́hìn èyí, ó tú u, ó sì kó egungun tí ó bá, ó sọ ọ́ nù lẹ́hìn náà wàyí, ó rọra fi aṣọ náà di ara rẹ̀.
Àwọn ìtàn mánigbàgbé tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ìtàn ayé Henry Fajemirokun, olówó tó fi owó mọ Olúwa àti ènìyàn Ìtàn ayé Taiwo Oredein rèé, àgbà òṣèlú tó parí ayé rẹ̀ sọ́gbà ẹ̀wọ̀n Ìtàn ìgbé ayé Bode Thomas rèé, ó kọ́ wa láti máa kó ẹnu wa ní ìjánu Ṣo mọ̀ pé J.
Babalawo kan niluu Ibadan, Oloye Idowu Olukunle Adewole, Akọda Awo nijọba ibilẹ Ọna Ara lo kin ọrọ ti Oloye Sunday Adeyemo lẹyin bẹẹ.
Iko ohun ti o sese gba igbega
Wọn bi ọmọ meji - Ama ati Kojo.
O tàn mí jẹ, o sì kó àwọn ọmọbinrin mi sá bí ẹrú tí wọ́n kó lójú ogun.
Ṣugbọn iye àwọn tí ó gbà á, ni ó fi àṣẹ fún láti di ọmọ Ọlọrun, àní àwọn tí ó gba orúkọ rẹ̀ gbọ́.
Amadi sọ pe bi a ba ni ofin, a o da abo bo awọn to nfara gba isẹlẹ yii ki wọn le sọrọ lai foya pe ẹnikẹni yoo pa wọn lara nitori ẹni to nfi ilọkulọ lọ wọn le lagbara ju wọn lọ."
"Àwọn fóònù ti WhatsApp kò bá ṣiṣẹ́ mọ́ yìí ni wọ́n pè ní ""legacy operating systems'', ti wọ́n ni àwọn kò lé ṣe wàhálà láti mú ko bá ìgbà mu mọ́."
Àwọn ọmọ Geriṣomu jẹ́ meji: Ladani ati Ṣimei; 
bari ni aṣa-iṣowo-iṣowo-iṣowo-iṣowo kan ati pe o ti jẹ ilọsiwaju ni iṣowo ati awọn olubasọrọ ti oselu-aṣa pẹlu middle east .
Ó fi omi kún inú ìkùukùu,ìkùukùu sì fọ́n mànàmáná rẹ̀ ká.
 Taribo West wa lara iko Super Eagles ti o gba ife-eye idije boolu agbaye tawon odo tojo ori won koju odun metalelogun lo, 1996 Atlanta Olympic, beesini O tun kopa ninu idije Africa Cup of Nations ati idije boolu agbaye.
Ó ní, “Ẹ pe akọrin kan wá.
Ìyàwó Ọ̀ọ̀ni Ogunwusi kò bímọ tuntun Fatai Rolling Dollar, Ọmọ ìdílé oyè tó gbé igbá orin tí Ebenezer Obey ń ṣiṣẹ́ lábẹ́ rẹ̀!
7 76036 Orilẹede Uzbekistan 611 1.
Bawo ni arun yii ṣe n tan kaakiri?
awon eniyan lati  ibikan lọ si ibomiran.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Stella Adadevoh tó dènà Ebola ní Nàìjíríà gba ìdálọ́lá lọ́wọ́ Ààrẹ Buhari 29 Òkùdu 2019 Oríṣun àwòrán, Muhammadu Buhari/ICIR Àkọlé àwòrán, Ọmọ oloogbe Adadevoh, Bamkole Cardoso lo ṣ'oju iya rẹ fun ami ẹyẹ naa Aarẹ Muhammadu Buhari ti fi aami ẹyẹ akọni da oloogbe, Dokita Stella Ameyoh Adadevoh lọla fun ipa to ko lati dena itankalẹ aarun Ebola l'orilẹede Naijiria.
Lọsẹ to kọja diẹ ni ọpọlọpọ aṣatipo dari pada wa sisle ni ẹkun yii pe ogun ti tan laimọ pe Boko haram n pada bọ.
Nígbà tí ó wo Amaleki, ó fi òwe sọ̀rọ̀ nípa wọn báyìí pé:“Amaleki ni orílẹ̀-èdè tí ó lágbára jùlọ,Ṣugbọn yóo ṣègbé níkẹyìn.
Wọ́n ti gba ibi ìsọdá odò,wọ́n ti dáná sun àwọn ibi ààbò,ìbẹ̀rùbojo sì ti mú àwọn ọmọ ogun.
 yíya àwọn èniyàn sọ ́ tọ ̀ ní awọn ìletò adẹ ́ tẹ ̀ ṣsì ń wáyé ní àwọn orílẹ ̀ -èdè bíi Índíánì , pẹ ̀ lú iye ju ẹgbẹ ̀ gbẹ ̀ rún lọ ; Ṣáínà , pẹ ̀ lú iye ní ọgọgọ ́ rùn ; àti ní Áfíríkà .
Lẹyin eyi ni ọkọọkan awọn eeyan to sisẹ ibi naa wa bura pe ki ilẹ gbe ẹnikẹni to ba tu asiri awo to wa laarin wọn mi.
A Adeboye ti sun ipade adura nla kan to yẹ ko waye lọjọ Satide, ogunjọ oṣu kẹta ọdun 2020 siwaju.
Ó gba obìnrin náà ní ọdún méjì gbáko nílé ẹjọ́ láti jà fún ìdádúró láì bá òfin mu ní ẹnu iṣẹ́.
Aare fikun oro re pe, isakoso egbe APC ti kopa ribiribi lati ri daju pe o mu gbogbo ileri re se fun awon omo orile-ede yii lateyin wa.
“Nígbà tí ẹ bá ń gbadura, ẹ má máa wí nǹkankan náà títí, bí àwọn abọ̀rìṣà ti ń ṣe.
Boris Johnson ni ikede yii yoo dola ẹmi to pọ nitori pe ẹni to ba wa laye lo maa n ṣọdun.
Èyí yóo jẹ́ ìwà òdodo lójú OLUWA Ọlọrun yín.
37 ti o wa ninu osu kejila odun 2017.
” “Asiko oorun la wa yii, bee si ni, oju ojo dara pupo.
Oríṣun àwòrán, Reuters Àkọlé àwòrán, L'ọjọ kannaa , Rebecca Palai n ba dokita kan sọrọ lori fonu nigba to n gba ogun lati ẹrọ ifunnilogun kan.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Kàyééfì Promo: Ìyá, ọmọ tuntun àti olubi ló wà níbùdó ìgbókùsí, àmọ́ òkú ọmọ di àwátì O ni o ya oun lẹnu wipe, pẹlu iru eniyan ti Busola ati ọkọ rẹ jẹ ni awujọ, o ya oun lẹnu wipe, wọn le fi iru ẹsun naa kan oun.
Àwọn eniyan ní, “Ìkórè ti parí,àsìkò ẹ̀ẹ̀rùn ti kọjá,sibẹ a kò rí ìgbàlà.
Bákan náà ni ó ṣe ní àwọn ìlú Manase, ati ti Efuraimu, ati àwọn ìlú ilẹ̀ Simeoni títí dé ilẹ̀ Nafutali, ati ní gbogbo àyíká wọn.
    “Oṣù keje ti mo ti kúrò ní ilé ni mo tó padà dé, lọ́jọ́ kẹta tí bàbá mi sì kú ni mo dé ilé bí wọ́n ti sin òkú rẹ̀ tán gan-an ni.
 idamu le wa , ipadanu akoso apo-ὶtợ tabi irora egungun ibadi ti o jọ ti pajapaja [ [ ile-ọmọ | niiṣe pẹlu ile-ọmọ ] ] .
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Duncan Mighty: Ọlọ́pàá fi pampẹ́ mú olórín tàkasúfèé lórí ẹ̀sùn jíbítí mílíọ̀nù mọ́kànlá 14 Ọ̀pẹ̀̀ 2019 Oríṣun àwòrán, @klassiQ2AT Àkọlé àwòrán, Ọlọpaa ti gbe Duncan Mighty ṣaaju akoko yii, to si jẹwọ pe lootọ ni oun gba owo naa Ajọ ọlọpaa ipinlẹ Imo ti fi pampẹ ofin mu gbajugbaja olorin takasufe Duncan Mighty, nipinlẹ ọhun lori ẹsun jibiti.
Oríṣun àwòrán, Instagram/ abiola ajimobi Ajọ amuṣẹya APC, NWC tun yan Hilliard Etta lati ma a ṣiṣẹ dele de Abiola Ajimobi to wa ni idubulẹ aisan, amọ Victor Giadom sọ wi pe apo ara wọn ni wọn sọ iyẹn si.
Alaga igbimọ awọn ọmọ ẹgbẹ Shiite ti wọn ti n ṣewọde, eyi ti wọn fi n sọ fun ijọba lati fun olori wọn ati iyawọ rẹ lominira, Abdurrahman Abububakar Yola ni, ẹgbẹ Shiite nigbagbọ ninu titẹle ofin ati lilepa alaafia lati yanju aawọ lai lo ipa bo tilẹ jẹ pe ijọba mọọmọ bi awọn ninu.
Ibi kan ṣoṣo ti wọn ti ri owo gbe lọ ni ibi ẹrọ igbalode to n pọ owo jade.
'Ọlọ́pàá Nàìjíríà ti dí agbẹnusọ ijọba Buhari' 'Logo Benz yóò lẹ́yìn fún àwọn ọ̀dọ́ tó bá ṣògùn owó' Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, New year message: Buhari, Jonathan, Atiku, kí àwọn ọmọ orílẹ̀èdè Nàìjíríà Oríṣun àwòrán, @Aishaofficial Àkọlé àwòrán, 2019 Elections: Àwọn òṣèré Yorùbá tó wà nínú ìgbìmọ̀ ìpolongo APC 27.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Water Theraphy: Àwọn àmi méje tó ń tọ́ka sí pé oò kí ń mu omi bí ó ti tó Yemisi Oyedepo Broadcast Journalist 26 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Oríṣun àwòrán, Getty Images Omi labuwẹ, omi labumu, omi naa ni wọn lo so aye ro, koda ọrọ Yoruba a maa sọ pe ẹnikan kii ba omi se ọta.
Orilẹede Israel yẹ ikọlu ṣugbọn ti ilẹ Sinai pada ko sọwọ Egypt.
 wọ ́ n tún ń sọ èdè yìí ní cote d ' lvoire àti tógò .
Kí OLUWA máa ranti ẹ̀ṣẹ̀ wọn nígbà gbogbo,kí á má sì ranti ìran wọn mọ́ láyé.
Aare Muhammadu Buhari  gbalejo ife-eye idije boolu agbaye, leyin ti ife-eye ohun bale silu Abuja ti n se olu-ilu Naijiria lojoRu(Wednesday).
Wo àwọn àwòràn tó làmìlaaka nílẹ̀ Adúláwọ̀ lọ́sẹ̀ yìí Pasitọ agba ijọ RCCG naa sọ ọrọ rẹ bi ẹna ati owe ni eyi to jẹ lowe-lowe ni a n lu ilu ogidigbo.
Lẹ́yìn náà, kí ó bọ́ aṣọ iṣẹ́ alufaa rẹ̀ kí ó sì wọ aṣọ mìíràn, kí ó wá ru eérú náà jáde kúrò ninu àgọ́ sí ibi mímọ́ kan.
Amọ, iroyin kan sọwipe, ti wọn ba si wa ni orilẹede Naijiria, igbo Sambisa lawọn ajinigbe naa yoo ko awọn ọmọ lọ, nitori wipe igbo yii nikan lo tobi to bẹẹ, ti wọn le ko awọn ọmọ naa pamọ si.
OLUWA tún sọ fún mi pé, “Kéde gbogbo ọ̀rọ̀ yìí ní àwọn ìlú Juda ati ní àwọn òpópó Jerusalẹmu, pé kí wọn fetí sí ọ̀rọ̀ majẹmu yìí, kí wọ́n sì ṣe bí ó ti wí.
Nípa àṣẹ rẹ̀ ni a óo ré odò Jọdani kọjá, a óo lọ jagun ní ilẹ̀ Kenaani, kí ilẹ̀ ìhà ìlà oòrùn Jọdani lè jẹ́ tiwa.
Atẹjade kan ti ijọba orilẹede Saudi Arabia fi sita lọjọ Abamẹta fihan pe, awọn ọmọ Naijiria yii wa lara awọn ti wọn mu ni papakọ ofurufu King Abdul-Aziz nilu Jeddah ati ti Prince Muhammad Bin Abdu-Aziz ni Madinah, laarin ọdun 2016 si 2017.
Lórí ikú olórí ilé aṣòfin ìpínlẹ̀ ọ̀yọ́ tó kú ní ọjọ́ ẹtì, Guru Maraji ni aṣòfin Adéyẹmọ kì bá tí kú kání ó mọ òun ni.
Iyanṣẹlodi lẹka epo rọbi ni Naijiria ti wọn gunle yii wa ni ajọṣepọ pẹlu awọn oṣiṣẹ awakọ epo rọbi, NUPENG, nitori naa, o ṣeeṣe ki awọn araalu ma ri epo bẹntiroo ra.
Wọn kò pọ̀ rárá tẹ́lẹ̀, ṣugbọn níbẹ̀ ni wọ́n ti di pupọ, wọ́n sì di orílẹ̀-èdè ńlá, tí ó lágbára, tí ó sì lókìkí.
Aarẹ ẹgbẹ naa lo fesi bẹẹ lẹyin ti NIS sọ pe awọn da awọn dokita wọnyi to fẹ lọ si London pada nitori pe wọn ko ni iwe aṣẹ irinna, fisa.
Ahasaya, ọmọ Jehoramu, ọba Juda, sì lọ bẹ̀ ẹ́ wò ní Jesireeli nítorí ara rẹ̀ tí kò yá.
 O tun ro awon to ni ito suga lati so ounje je ki won maa je ounje bii opolopo ewebe, ati eso to n sara lore ki won si dekun jije ounje ale leyin aago mefa si meje.
Ana yìí ni ó rí àwọn ìsun omi gbígbóná láàrin aginjù, níbi tí ó ti ń tọ́jú àwọn kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ Sibeoni, baba rẹ̀.
Àkọlé àwòrán, Eyi ni ẹlẹẹkẹta ti ina yoo jo ọja Binukonu lẹyin ti ọdun 2015 ati 2017.
Ẹ wo òpópónà dáradára, ẹ fiyèsí ọ̀nà tí ẹ gbà lọ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù UK: Ọjọ́ kejilelogun, oṣù keje, ọdún 2019 ni wọ́n yóò ṣe ìkéde 8 Òkùdu 2019 Àkọlé àwòrán, Ta ló máa gba iṣẹ́ lọ́wọ́ Theresa May?
Mo lè ka gbogbo egungun miwọ́n tẹjúmọ́ mi; wọ́n ń fojú burúkú wò mí.
Ẹ̀yin ẹlẹ́gbẹ́ òkùnkùn tẹ fẹ́ ṣe àjọ̀dún lónìí, lákọ la ń dúró dè yín - Iléeṣẹ́ ọlọ́pàá Ìjọba Akeredolu kò ní omi àánú lójú, a kò tọ́jú alárùn Coronavirus mọ́ - Dókítá Ondo Bí àwọn adarí ìjọba ṣe ń kó Coronavirus, ń kọ wá lóminú - Ìjọba àpapọ̀ Opeodu ni awọn fẹ sin oku naa gẹgẹ bi ilana ti awọn ma n gba sin ẹni to ba pa ara rẹ, nitori ẹbọ ati oro ti o yẹ ki wọn ṣe ki iru rẹ ma ba tun wa ye mọ.
O fikun-un pe, asekagba idije eka mejeeji, ti n se iko okunrin ati tobinrin, yoo waye ni ile iwe giga fafiti onimo-ero Yaba College of Technology  lojo kinni osu kesan an odun ti  a wa yii nilu Eko.
Oríṣun àwòrán, Dolapo osinbajo O ni eyi ni yoo jẹ ko rọrun fun wọn lati lee wa egbo dẹkun si ọwọja iwọkuwọ aṣọ ati oge aṣesodi pẹlu ogun oloro mimu lawujọ.
Yorùbá fẹ́ràn ayẹyẹ ṣi ṣe púpọ̀ pàtàki fún igbéyàwó.
Ṣùgbọ́n ẹ̀yán kan nínú mẹ́fà ni yóò ṣe àìsàn gidi ti yoo si nira fún wọn láti mi.
Esi rẹ fidiẹ mulẹ pe ṣuga apọju lara ni eyi to wa ninu ẹlẹrindodo n ṣokunfa arun jẹjẹrẹ lara eniyan.
Awọn to nifẹ fidio naa kọja ẹgbẹrun lọna ọgọrin.
Bakan naa ni gomina tun salaye fun awon igbimo ohun p,e
Adajọ Ekwo ní gbogbo àwọn ti ọ̀rọ̀ náà kan ní a wọn gbọdọ tẹ̀lé ìdájọ náà titi yóò fi pari ọ̀rọ̀ naa.
ohun naa ni, Gomina ipinle Eko, ogbeni  Babajide Sanwo-Olu, gomina ipinle Ondo ,
Ẹ máa pọ̀ sí i, ẹ má sì dínkù.
Inu ilera pipe ni awọn ibeji naa wa laisi wahala kankan.
Ninu osu Kesan an ni won da ise oko oju irin naa duro nitori opo omi ti o ba awon oju irinna oko oju irin naa je.
’ rèé Ọ̀rọ̀ǹpọ̀tọ̀niyùn, Aláàfin obìnrin àkọ́kọ́ rèé, tó ní nǹkan ọkùnrin Asòfin PDP Ondo fìdírẹmi torí ó jẹ́ ọmọ orílẹ̀èdè méjì Ṣaaju iwadii BBC Yoruba yii, ile ẹjọ to n gbọ ẹsun idibo ni ipinlẹ Ondo ti sọ wi pe oludije ni ẹgbẹ oselu APC, Albert Akintoye lo jawe olubori ni idibo sile asofin Naijiria, lẹyin to wogile idibo Ikengboju Gboluga to n soju ẹkun idibo Okitipupa/Irele ni ipinlẹ Ondo.
”Wọ́n dá a lóhùn pé, “Àwọn ohun tí ó ṣẹlẹ̀ sí Jesu ará Nasarẹti ni.
Bidemi Kosọkọ di ìyá ìkókó Oríṣun àwòrán, EPA Àkọlé àwòrán, Ọkan lara awọn to n sare fun idije agbaye ṣafihan bi eeyan ṣe le fo pẹlu ara rẹ.
N óo máa rìn láàrin yín, n óo jẹ́ Ọlọrun yín, ẹ óo sì jẹ́ eniyan mi.
"Mi ò kábàámọ̀ pé mo béèrè ìbéèrè tó fàbínú wá lọ́dọ̀ Femi Fani Kayode 'Sanwo-Olu kò ní ṣ'àyẹ̀wò covid-19 míì nítorí kọmíṣọ́nà ètò ìlera ṣẹ̀ṣẹ̀ k'árún náà' Ọkọ Funke Akindele kó eléré àti òṣìṣẹ́ jọ fi ṣe ""Surprise Pato"" fún un lọ́jọ́ ìbí rẹ̀ John Blake wà ní ICU, ọlọ́pàá tó yìnbọn fún un bẹ̀rẹ̀ ìsinmi tipá tipá Ẹ má rán ọmọ lọ ilé ìwé ní Cyprus mọ́ - Abike Dabiri Igbimọ naa wa rọ awọn gomina iha Ariwa Naijria, pẹlu gomina ipinlẹ Kwara ati Kogi lati kẹkọọ lara gomina ipinlẹ Benue, Samuel Otom, to ni ki awọn eeya ipinlẹ rẹ lọ gba aṣẹ lati ni ibọn fun abo ara wọn."
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù House on water: Ǹjẹ́ ìwọ lè gbé ilé tó wà lórí omi?
Wọ́n ṣe ogún àkànpọ̀ igi fún apá gúsù àgọ́ náà, 
À ń gbadura kíkankíkan tọ̀sán-tòru pé kí á lè fi ojú kàn yín, kí á lè ṣe àtúnṣe níbi tí igbagbọ yín bá kù kí ó tó.
, ti wọn si tẹdo seti odo naa, lọna ati gba awọn eeyan rẹ silẹ lọwọ iyan ati ebi.
Arabinrin Ọlayiwọla Abọsẹde sọ fun BBC Yoruba pe ''oju popo ni oun ti n ta ọja lati fi bọ ẹbi ki o to di pe oun ṣakiyesi pe oju oun n wo bayi-bayi.
Ní ọjọ́ kinni, oṣù kẹta, ọdún kọkanla tí a ti wà ní ìgbèkùn, OLUWA bá mi sọ̀rọ̀, ó ní, 
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Awọn ọmọ ìjọ sàtánì ń bínú sí Nàìjíríà Tinubu: Ọbasanjọ kò lè yan olùdíje fún wa Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ọdún 1940 ni wọ́n ti ń sin ọ̀ọ̀nì ilé Delesolu ní Ìbàdàn Wo diẹ lara awọn oniroyin lorilẹ-ede Naijiria ti awọn ọlọpaa ti mu tabi dunkoko mọ ri: Ibraheema Yakubu, ti oun naa jẹ oniroyin pẹlu Hausa DW radio lugbadi awọn ọlọpaa nibi ti o ti n kọroyin lori iwọde wọọrọwọ ẹgbẹ musulumi nilu Kaduna lọdun 2017.
Èmi ni mo ṣe ìtọ́jú yín nígbà tí ẹ wà ninu aṣálẹ̀, ninu ilẹ̀ gbígbẹ; 
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Dúkìá àti ọkọ̀ jóná, ọlọ́pàá mẹ́sàn-án fara gbọta lásìkò ìwọ́de Shiite Ìlú tí ọ̀daràn bá tí dẹ́ṣẹ̀ ló yẹ kí wọn tí gbẹjọ́ rẹ̀ -Agbẹjọ́rò Àgùnbánirọ̀ gbẹ́mìí mì látàrí 'Snipper' tó fi fọ irun rẹ̀ Ìjọba ló ń ṣe kóríyá fún àlàfo ńlá láàrin ọlọ́rọ̀ àti mẹ̀kúnnù - Oxfam Atẹjade naa, ti wọn fi sọwọ sawọn akọwe agba ati olori awọn ọọfisi to wa feto ẹkọ yika ipinlẹ naa tun kede pe lati ọjọ ti gomina Seyi Makinde ti di gomina ni owo gbigba lawọn ileẹkọ ijọba ti di eewọ.
Boss Mustapha to jẹ olori igbimọ to n gbogun ti arun Covid-19 ni Naijiria ni ọpọ igba ni ijọba ti kilọ fun awọn Gomina ariwa Naijiria sugbọn wọn keti ikun si ikilọ awọn.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ondo Assembly: Ejò da ìjókòó ilé rú , l'àwọn aṣòfin bá fẹsẹ̀ fẹ 25 Agẹmo 2019 Oríṣun àwòrán, MELITA VAMBERGER/SENCKENBERG RESEARCH INSTITUTE Ọrọ di bo o lọ, ya a mi nigba ti ejo afayafa deede jabọ pi lati ori aja sinu ile igbimọ aṣofin ipinlẹ Ondo lasiko ti ijoko ile n lọ lọwọ.
Ni bayii, o ti di didan fawọn ọdọkunrin ati ọdọbinrin ti wọn ba fẹ ṣegbeyawo lati ṣe ayẹwo ẹjẹ ki wọn to lọ sori pẹpẹ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Sunday Igboho: Fulani kò leè dúró, táa bá lo ohun ta jogún lọ́dọ̀ àwọ̀n bàbá wa O ni iwe ofin ilẹ wa faaye gba ipinlẹ kọọkan pẹlu aṣẹ lati da aabo bo awọn ara agbegbe rẹ labẹ iṣejọba alagbada.
Nbayii, awn lpaa ti n ko gbogbo wn lọ si olu ile iṣẹ wn ni Abeokuta nibi ti wọn yoo ti ba awọn oniroyin sọrọ fun ẹkunrẹrẹ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ajọ SERAP sọrọ lori owo ifẹhinti awọn oloselu kan Pataki abadofin yi ni Kwara Lọdun 2010 ni a atunyẹwo de ba ofin to risi sisanwo ifẹyinti fun awọn gomina lasiko isejọba Dokita Bukola Saraki.
Oríṣun àwòrán, @Ramdog1980 Àkọlé àwòrán, Pupọ lara wọn ti kuro nileewosan bayii Ajọ naa si ti gba awọn arinrinajo ni imọran lati yago fun rínrìn ninu oorun, ki wọn si maa mu omi daadaa, ki wọn o si maa wọ aṣọ to fẹlẹ.
Ibudo tuntun kan ti wọn ṣẹ̀sẹ̀ ṣe to n jẹ Zonal Mediation Centre nilu Ogbomosho yoo gba orukọ Justice Atilade Ojo Mediation Centre.
Ọkùnrin tí kò ríran kan rèé tó ń lọ ẹ̀rọ ata Ọọ̀ni obìnrin, Lúwòó Gbàgídà rèé, akọni tó ń gun ọkùnrin ní ẹṣin rìn Nigba to n sọ ero ọkan rẹ nipa awọn ojisẹ Ọlọrun to ni Oluwa lo sọ fun awọn lati dibo gẹgẹ bii aarẹ Naijiria, Abiara ni o seese ko jẹ ero ọkan wọn tabi ki Ọlọrun pasẹ fun wọn lootọ lati lọ dibo aarẹ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Coza Rape: Ọlọ́pàá ránṣẹ́ pe Timi Dakolo àti ìyàwó rẹ̀ lórí ẹ̀ṣùn ìfipábánilòpọ̀ 21 Agẹmo 2019 Oríṣun àwòrán, @timidakolo Ileesẹ ọlọpaa ti ti ẹsẹ ofin wọ ẹsun ifipabanilopọkan ti Timi Dakolo ati Busọla iyawo rẹ fi kan Pasitọ kan nilu Abuja, Tolu Fatoyinbo.
Ọ̀dọ̀ fásitì jànkàn Oxford ló ti jáde Bawo ló ṣe ṣẹlẹ nigbà tí ọlọjọ wọle de wẹrẹ wa mu Isa Funtua lọ?
Obinrin kan bá gbé ọmọ ọlọ kan, ó sọ ọ́ sílẹ̀, ọmọ ọlọ yìí bá Abimeleki lórí, ó sì fọ́ agbárí rẹ̀.
" Ijẹwọ rẹ naa jẹ eyi to yani lẹnu pupọ, paapa julọ, ti enyan ba mọ wipe Okina, to si jẹ ọdọ langba ti n ṣe oludari ajọ alaanu to n ran awọn ogunlọgọ awọn ọmọ to fi awọn oju opopona se ile jakejado ilu Calabar, ti se olu ilu Cross Rivers, llkun guusu guusu Naijiria lọwọ.
Naijiria lati tubo maa lo imo sayensi ati imo ero igbalode,lati pese ise ati ọrọ
Bọndu owo nla lo wa lọwọ Ọgbẹni Dino ninu eyi ti o ti n na olorin lowo nibi inanwo oku iya rẹ nipinlẹ Kogi ninu fidio naa Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Awọn ọdọ Ondo fẹ̀họ́nù hàn lórí ìṣekúpani Funke Olakunrin Ẹwẹ, ọjọ Abamẹta to kọ ja ni ọkan lara awọn ọga agba nile ifowopamọ Naijiria (CBN), Isaac Okorafor sọ pe ile ifowopamọ naa ti ṣetan lati fọwọ ofin mu ẹnikẹni to ba n ba owo naira jẹ nipa fifi ṣe imọri loju agbo.
ẹgbẹ Ile Igbimọ Aṣofin Ipinlẹ Eko
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Lagos: Àjọ iwádìí ọrọ̀ ajé àgbáyé, EIU ní Ilu eko wà lára àwọn ìlú tó gbọ̀pọ̀ jùlọ lagbaye 21 Ẹrẹ̀nà 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ọ̀pọ̀ olùgbé ìlú Eko ló ń pariwo pé kò rọrùn láti gbé níbẹ̀ Njẹ ẹ mọ pe ipinlẹ Eko wa lara awọn ilu mẹwa ti owo gbigbe e rẹ gba ọpọ julọ lagbaye?
O rọọ lati ṣe ohun gbogbo ni wọntunwọnsi.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Idi Amin Dada lo fun ara rẹ ni oye Field Marshal lọdun 1975 pẹlu ami irawọ marun un leti aṣọ rẹ Wo ohun to yẹ ki o mọ nipa Mohamed Hussein Tantawi to di 'Field Marshal' ni Egypt: Tantawi di aarẹ ilẹ Egypt lẹyin iṣubu ijọba Mubarak lọdun 2011, ṣugbọn o gbe ìjọba silẹ lọdun 2012.
Ọmọ Nàìjíríà ẹ ṣọ́ra fún ìrìn alẹ́ nítorí àwọn tó fẹ́ gbẹ̀san ikú Soleimani Irú kí lèyì!
Ọjọ́ karùn ún ni ti obìnrin.
akonimoogba mejeeji mo pe ko si ohun ti  ko le e waye ninu ere boolu afesegba lataari
Nítorí pé àwọn Juu kọ ìyìn rere, wọ́n sọ ara wọn di ọ̀tá Ọlọrun, èyí sì ṣe yín láǹfààní.
Àwọn Oniṣòwò á ri ọjà tà nitori àsikò yi ni Bàbá àti Ìyá ma nrán aṣọ ọdún fún àwọn ọmọdé àti oúnjẹ rẹpẹtẹ fún ipalẹ̀mọ́ ọdún.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ẹlẹ́wọ̀n, ẹni ọgọ́rùn ọdún n bẹ̀bẹ̀ fún òmìnira ‘Buhari gbà wá o, Seyi Makinde n fi jàǹdùkú halẹ̀ mọ́ wa láti kúrò lọ́ọ́fìsì’ Ẹ dákẹ́ àhesọ ọ̀rọ̀, n kò bí ìbẹta - Yinka Ayefẹlẹ Ọba Adesoji Aderemi, Ọọ̀ni Ifẹ̀ tó gba ipò ọba mọ́ tòṣèlú Celestine Egbunuche, ni ẹgbẹ kan ti kii se tijọba, eyi to n gbogun ti iwa ajẹbanu, Global Society for Anti Corruption (GSAC), ja fun idande rẹ rẹ ati ọmọ rẹ lọgba ẹwọn.
Josẹfu sọ fún àwọn eniyan náà pé, “Àtẹ̀yin, àtilẹ̀ yín, láti òní lọ, mo ra gbogbo yín fún Farao.
AAUA; Ọ̀pọ̀ ìgbà ni SARS ma ń lu àwọn akẹ́kọ̀ọ́ fásitì wa
 Wo bí ọwọ́ orílẹ̀-èdè Dubai ṣe tẹ Ramoni Igbalode tí gbogbo ayé ń pè ní Hushpuppi Ìgbé ayé Abiola Ajimobi nínú àwòràn pẹ̀lú àwọn ǹkan tó ṣẹlẹ̀ Ìtàn ìgbésí àyé olóògbé Isiaka Abiola Ajimobi Omijé bọ́ níbi ìsìnkú Ogun Majek Oríṣun àwòrán, @AdekunleOtun Adebayo Osinowo Ko to jade laye, oniṣowo ati oloṣelu ni Adebayo Osinowo jẹ."
Ìwádìí atọpinpin BBC fihàn pé iks agbésùnmọ̀mí Boko Haram,rán ènìyàn tó lé ní ẹ̀ẹ́dẹ́gbẹ̀wá s'ọ́run ní ọdún 2017.
" Àbẹ̀wò sí kóòtù Ikoyi, lógúnjọ oṣù kéjé fi han pé , ẹni tó bá wù nìkàn ló le mú ibi tó bá wùú ti yóò sì san ẹgbẹ̀rún lọ́nà ààdọ́ta náírà.
Ijọba orilẹede Burundi fi iroyin iku aarẹ naa sita loju opo twitter rẹ.
Lati igba yii ni Ayuba Wabba gẹgẹbi adari ẹgbẹ ti bẹrẹ si ni kopa ninu igbesẹ fun agbelarugẹ awọn osisẹ ati fifi owo kun owo osu wọn lorilẹede Naijiria, eyi to n mu iyansẹlodi lọwọ nigba miran.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Oyenusi ló mú mi wọ ẹgbẹ́ adigunjalè kó tó di pé mo b'Ólúwa pàdé' Oríṣun àwòrán, Others Lẹyin naa ni wọn ta soko ẹru fun oyinbo Brazil kan to n jẹ Williams, ẹni to gbe Seriki Abass lọ sorilẹede Brazil lati lọ se ọmọ ọdọ rẹ.
 mọ ́ ṣáláṣí yìí ní gílásì aláwọ ̀ àràbarà tí ó sí ṣe àfihàn àwọn èròjà ìbílẹ ̀ bíi  panj kāse "" ( "" marún tí ó tẹ ̀ "" ) ."
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Tomi Waziri: Kí n tó gbé fóònù lé wọn lọ́wọ́, wọ́n ti fi ìbọn fọ́ mi lójú Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Tomi Waziri: Kí n tó gbé fóònù lé wọn lọ́wọ́, wọ́n ti fi ìbọn fọ́ mi lójú 20 Bélú 2019 Nigba ti BBC Yoruba ṣe ibẹwo si ile ti Waziri ati iya rẹ n gbe, ọrọ naa kọja afẹnusọ.
  Àwọn kan a tún máa fi màrìwò ṣe òrùlé ilé.
Àjọ DSS ti fi Abdullahi si àtìmọ́le títí di àsìkò tí wọn yóò parí ìwádìí wọ̀n.
Ẹ̀ṣẹ̀ mi ti bò mí lórí mọ́lẹ̀;ó rìn mí mọ́lẹ̀ bí ẹrù ńlátí ó wúwo jù fún mi.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Demilade Adepegba: Mo má a ń gbàgbé fèrè ni, tí mo bá wà nílé ìwé Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Demilade Adepegba: Mo má a ń gbàgbé fèrè ni, tí mo bá wà nílé ìwé 20 Ẹrẹ̀nà 2019 Ohun iyalẹnu lo jẹ fun BBC Yoruba lati ri ọmọdekunrin kan, ọmọ ọdun mẹwa, Demilade Adepegba to n fọn fere ni ode ariya bii agbalagba.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Àgbàrá òjò gbé alága àdúgbò àti èèyàn méjì mìí lọ nílùú Ibadan 27 Ọ̀wàrà 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 28 Ọ̀wàrà 2020 Agbara ojo gbe alaga adugbo ati awọn eeyan meji mii lọ nilu Ibadan.
Ṣugbọn, ẹ pín ilẹ̀ náà láàrin àwọn ọmọ Israẹli gẹ́gẹ́ bí ìpín wọn, bí mo ti pàṣẹ fun yín.
Oríṣun àwòrán, SOLA ILESANMI Àkọlé àwòrán, Ajọ FRSC n parọwa fun awọn awakọ lati dẹkun ere asapajude Rauf wi pe ọpọlọpọ awọn oluraja ati onisowo ti o farapa ninu ijamba naa ni wọn ti ko lọ si ile-iwosan, ti awọn osisẹ ajọ FRSC ati ọlọpa si korajọ lati da alafia pada si agbegbe naa.
Ni bayii, ipo kẹta ni Chelsea wa lori tabili Premier League, nigba ti Man City tẹle wọn ni ipo kẹrin.
Ikanni BBC Yoruba ti lọ káàkiri àwọn ìpínlẹ̀ mẹ́rin ọ̀tọ̀ọ̀tọ̀ fún ìpàdé ìtagbagba yìí.
Nígbà tí Jehoiada dàgbà tí ó di arúgbó, ó kú nígbà tí ó pé ẹni aadoje (130) ọdún.
Lọ́wọ́lọ́wọ́, òǹkà iye ènìyàn tó wà lórílẹ́èdè Nàìjíríá ti sún mọ́ mílíọ̀nù lọ́nà igba.
Oríṣun àwòrán, @AkwaUnited_fc Àkọlé àwòrán, Ẹgbẹ agbabọọlu Akwa United gbẹyẹ mọ Hawks ti orilẹede Gambia lati de ipele yii Ni orilẹede Tunisia ni ẹgbẹ agbabọọlu Al-Ittihad ti n gba awọn ifẹsẹwọnsẹ rẹ nitori wahala eto aabo to mẹhẹ lorilẹede Libya ni lọwọlọwọ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Iléeṣẹ́ aṣọ́bodè gba àgbá ọjà tó kún fún ẹrù ogun 28 Agẹmo 2018 Oríṣun àwòrán, Nigeria Customs service Àkọlé àwòrán, opopona marosẹ Aba si Port Harcourt ni wọn ti gba ẹru ofin naa Ileeṣẹ aṣọbode orilẹede Naijiria ti gba awọn ohun elo ologun kan ti awọn eeyan kan fẹ ko wọ orilẹede Naijiria lọna aitọ.
won fi pa ogbeni Kolade Johnson.
Ọ̀pọ̀ àwọn arìnrìn-àjò afẹ́ jẹ́ akẹ́kọ̀ọ́ ilé-ẹ̀kọ́ gíga.
Ǹkan ẹyọ kan ni owó yìí wà fún, ǹkan náà si ni láti fi gbárùkù ti ìdókoowo ti ènìyàn bá fẹ́ ṣe tàbi láti fi ran ẹni to ni ẹ̀bùn kán tó sì nílò owó láti gbé ẹ̀bùn náà jáde, àti pé àwọn ọ̀dọ́ nìkàn ni ó wà fún.
Àwọn ti Korea máa ń fẹ láti ṣe Núdùlù wọn láti ara èdso igi apádò Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ohun ìwúri ni lílo èso igi apádò fún àwọn olùdáná ní Korea Ní Korea onírúurú núdùlù ní wọn máa ń ṣe láti ara èso igi apádò (Oak tree) Eso igi apádo tabi dotori guksu, ní wọn maa ń dapọ mọ àwọn eso onikóró míràn bíi wiiti lati fi ṣe núdùlù.
Amọ ko sọ ni pato iye ọjọ, ọsẹ tabi oṣu ti ilana ọhun yoo gba wọn.
Bẹ́ẹ̀ ni Dafidi ṣe jọba lórí gbogbo Israẹli, ó sì ń ṣe ẹ̀tọ́ ati òdodo sí gbogbo eniyan, nígbà gbogbo.
Ọmọ Risikat olójú búlúù méjèéjì jẹ̀bùn oríire àti ìfà ńlá Ta ni obìnrin tó fẹ́ bá Dino Melaye ṣe ìgbéyàwó lọ́jọ́ kejì Kérésì?
Ninu atẹjade kan to fi ran amugblẹgbẹ fun un lori eto ibanisọrọ, Bọlaji Tunji ni Gomina Ajimọbi ti ṣalaye eyi.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ìdẹ̀ra dé, Gẹnẹrátọ̀ tó ń lo omi dé, a bọ́ lọ́wọ́ òkùnkùn Wo ìgbéyàwó olówó iyebíye tí awakọ̀ Kabúkabú ti jẹ̀bùn ọkọ N3.
Bi awọn dokita ṣe n tiraka lati lo awọn irinṣẹ ti ko to lati gba ẹmi awọn eeyan la lọwọ iku, wọn ti bu ẹnu atẹ lu ijọba fun iṣẹ ajanbaku to ṣe si ẹka eto ilera ilẹ ọhun.
Àwọn ìjòyè orílẹ̀-èdè kó ara wọn jọpẹlu àwọn eniyan Ọlọrun Abrahamu.
Ajagun- fehinti Sambo Dansuki ati awon merin miiran ni won yoo foju bale-ejo ni ojo kẹ́rìndínlógún osu karun un nile ejo to wa niluu Abuja lori esun méjílélọ́gbọ̀n ti ajo to n ri si sise owo ilu kumo-kumo ( EFCC) fi kan won.
Àwọn kẹ̀kẹ́ ogun ń dà wọ ìgboro pẹlu ariwo,wọ́n ń sáré sókè sódò ní gbàgede;wọ́n mọ́lẹ̀ yòò bí iná ìtùfù,wọ́n ń kọ mànà bí mànàmáná.
Aare ana tun so pe aare Buhari ti kuna lati gbokun ti iwa ibaje ni eyi to si je pe iwa ibaje wa lara ohun Pataki  ti o pinnu lati gbokun ti,lasiko to n seleri fun awon omo orile ede yii pe, oun yoo se, nigba ti  o ba de ori aleefa.
Daniẹli bá lọ sí ọ̀dọ̀ Arioku, ẹni tí ọba yàn pé kí ó pa àwọn ọlọ́gbọ́n Babiloni run, ó sọ fún un pé, “Má pa àwọn ọlọ́gbọ́n Babiloni run, mú mi lọ sí ọ̀dọ̀ ọba, n óo sì túmọ̀ àlá rẹ̀ fún un.
Ìkéde tí àjọ náà fisíta sọ pé ìgbà kẹrìnÌdí rèé tí BBC Yorùbá se ń bèèrè pé ǹjẹ́ àwọn aráàlú mọ ipa àdínkù owó ọjà náà lára bí?
Wọ́n fi inú dídùn ṣe é, ó sì jẹ wọ́n lógún láti ṣe bẹ́ẹ̀.
Àwọn ìlú tí ó wà ninu ilẹ̀ tí wọ́n pín fún wọn nìyí: Beeriṣeba, Ṣeba, Molada; 
”Siba sọ fún ọba pé, “Kabiyesi, mo júbà, jọ̀wọ́, jẹ́ kí n máa bá ojurere rẹ pàdé nígbà gbogbo.
Johanani bá sọ fún Gedalaya ní ìkọ̀kọ̀ ní Misipa pé, “Jẹ́ kí n lọ pa Iṣimaeli ọmọ Netanaya, ẹnikẹ́ni kò sì ní mọ̀.
Múra láti ràn mí lọ́wọ́,nítorí pé mo ti gba ẹ̀kọ́ rẹ.
Amọṣa ajọ LASEMA ni awọn oṣiṣẹ alaabo ati adoola ẹmi tete de ibẹ lati pana naa ki o to ṣe ọṣẹ ju bo ṣe yẹ lọ.
Amọṣa o, nipasẹ ṣiṣe eyi, ọpọ wọn lo ti n darapọ mọ ibi ti ọpọ ero wa, ti wọn si ti n t'ipasẹ bẹẹ fi ara wọn sinu ewu ati ko arun Coronavirus.
Ni kete ti ohun gbogbo daru nibudo ikede esi idibo gomina ati awọn aṣojuṣofin ipinlẹ Rivers ni ajọ INEC ti sun ohun gbogbo siwaju.
Òfin Ọlọrun rẹ̀ wà ní ọkàn rẹ̀;ìrìn ẹsẹ̀ rẹ̀ kì í yà kúrò níbẹ̀.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù A kò fòfin de owó naira tó ti pẹ́ ní Naijiria- CBN 31 Ògún 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 24 Ọ̀pẹ̀̀ 2019 Àkọlé àwòrán, Owo tuntun lo dun lati na Ọpọ àwọn ọmọ Naijiria ni ẹru n ba lori iroyin to gba igboro kan pe banki apapọ Naijiria, CBN fẹ ko gbogbo owo atijọ nilẹ.
Ìwọ ọ̀rẹ́ mi ọ̀wọ́n, bí o bá tún rí ẹsẹ̀ mi ní ilé aládùúgbò rẹ̀ yìí mọ̀, wí pé bàbá mi kọ́ ló bí mi.
Amọ aarẹ Boubacar Keita ti wa kọwe fipo rẹ silẹ, to si tun tu ile asofin ati ijọba rẹ ka, amọ ọpọ orilẹede lagbaye lo ti koro oju si isẹlẹ naa.
Ẹ ṣe à yẹ̀ wò àlàyé àti pi pè ibáṣepọ̀ idilé ni ojú iwé yi.
Alukoro ileeṣẹ naa, Felix Ofulue lo kede bẹẹ ninu ofọrọwerọ pẹlu BBC Yoruba.
Ṣugbọn obinrin yìí fi omijé rẹ̀ fọ ẹsẹ̀ mi, ó sì fi irun orí rẹ̀ nù ún.
Oríṣun àwòrán, others Ni France, Olootu ijọba, Jean Castex, sọ pe wọn yoo fi ofin de awọn ile itaja, lati ma ta àwọn nkan to ṣe koko, bẹrẹ lati ọjọ Iṣẹgun, lati le doola àwọn onile itaja keekeeke to ti ko gba wọlé.
Raissa Feujio lati Cameroon ati Jill Scott lati ilẹ Gẹẹsi ni wọn lọpọ ninu ifẹsẹwọnsẹ fun ife ẹyẹ agbaye tawọn obinrin to n lọ lọwọ.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: 'Ayélujára la fi rí ọmọ wa tó sọnù!
Koda, wọn mu isẹlẹ naa to Ọba Alaaye tilu Efon Alaaye leti nigba ti aayan wọn lati wa ọmọ naa ni gbogbo arọko to sunmọ wọn ja si pabo.
Àjàkálẹ̀ àrùn ati ìyàn yóo pa ìdámẹ́ta lára yín, ogun tí yóo máa jà káàkiri yóo pa ìdámẹ́ta yín, n óo fọ́n ìdámẹ́ta yòókù káàkiri gbogbo ayé, n óo sì gbógun tì wọ́n.
Ekun ila oorun,Gusu– Amojuto eto inawo, igbakeji alaga egbe (SE), akowe agba fun amojuto eto, igbakeji alamojuto eto inawo, igbakeji oludari awon obinrin.
Ibrahim Chatta: Ó gba àwọn òṣèré tíátà nímọ̀ràn láti máa ṣaájò ẹgbẹ́ wọn
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù EndSARS: Olórí ilé aṣofín-ṣòfin ní ìṣúnà 2020 gbọdọ̀ pèsè owó fún ASUU bí bẹ́ẹ́kọ̀.
Ní àsìkò tí a wà yìí, mí ò jẹ́ kí ọ̀rọ̀ òṣèlú nípa ọdún 2023 jẹ mí lógún, mó rí eyi bi ǹkan ti kò bójú mu rárá, ó sì jẹ́ ìwà àìní ìmọ̀lára lásìkò ti ọ̀pọ̀ ń koju ìṣòro oníhà méjì, ètò ọ̀rs ajé tó nira àti ààrùn tó n kó ìpaya bá gbogbo ayé.
Aarẹ ile asofin agba, Sẹnatọ Saraki wa fun awọn ileesẹ ati lajọlajọ ti ọrọ kan ni ọsẹ kan lati fi se atunse gbogbo to ba yẹ bi bẹẹkọ, o ni awọn asofin agba yoo gbe awọn igbesẹ ti ofin la kalẹ fun un lati gbe.
Ǹkan ti àwọn ọmọ wọ̀nyìí yàn láàyò ni láti maa sín àwọn olókìkí ènìyàn jẹ, Muiz Sanni (14), Fawas Sanni (10) àti Malik Sanni (8) jẹ́ ọmọ ìyá kan náà ti wọ́n sì máa ń dẹ́rin pa àwọn ènìyàn.
Oludari ofiisi ajọ naa ni Naijiria, Ọgbẹni Patrick Areghan lo fi ikede naa soju opo Twitter ajọ WAEC.
Aare jabo oro naa lasiko ti o
Olorun fun orile ede yii ni gbogbo nnkan.
n óo kó àwọn eniyan ibẹ̀ jọ láti gbogbo orílẹ̀-èdè tí mo ti fi ibinu, ìrúnú, ati ìkanra lé wọn lọ; n óo kó wọn pada sí ibí yìí, n óo sì mú kí wọn máa gbé ní àìléwu.
Jẹ́ kí wọn máa ṣe onídàájọ́ fún àwọn eniyan náà nígbà gbogbo; àwọn ọ̀rọ̀ tí ó bá jẹ́ pataki pataki nìkan ni wọn yóo máa kó wá sí ọ̀dọ̀ rẹ, kí wọ́n máa parí àwọn ẹjọ́ kéékèèké láàrin ara wọn.
N óo tú ẹ̀mí mi lé àwọn ọmọ Israẹli lórí, n ko ní gbé ojú mi kúrò lọ́dọ̀ wọn mọ́.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Awọn gomina lawọn o le san ọgbọn ẹgbẹrun Naira f'oṣiṣẹ Igbimọ awọn gomina lorilẹede Naijria ti sọ wi pe awọn ko tako fifi owo kun owo awọn osisẹ, amọ awọn ko ni owo lati san an ni.
" Ní kété tí mo gbọ́ àwọn ọ̀rọ̀ yìí, ló rẹ̀ mí wá láti inú.
Nigba ti yoo wa tun un gbe jade lo pe ọmọ tia Burna Boy si i, lorin ba di gbua lori ayelujara to n ta wara wara.
Adesoji Aderemi, Ọọ̀ni Ifẹ̀ àti gómìnà Adúláwọ̀ àkọ́kọ́ láyé eèbó amúnisìn Bàbá Aláàfin ìlú Ọ̀yọ́, Elérúwà àti àwọn Ọba Ilẹ̀ Yorùbá míràn tí wọ́n rọ̀ lóyè Ẹ wo bí ọ̀rọ̀ òṣèlú, ẹ̀sìn àti ẹ̀yà ṣe fa ogun abẹ́lé Biafra Ọpọlọpọ awuyewuye lo si waye lori iyansipo rẹ lati ibẹrẹ pẹpẹ.
adari orile ede yii ati adari egbe oselu  APC  ti
Eeyan 51,304 ni apapọ ni arun naa ti fara kan labẹ ayẹwo, ti awọn 37,885 si ti ri iwosan gba lọwọ ajakalẹ arun ọhun.
Lọti tí ó bá Abramu lọ náà ní ọpọlọpọ ẹran ọ̀sìn ati agbo mààlúù ati ọpọlọpọ àgọ́ fún ìdílé rẹ̀ ati àwọn iranṣẹ rẹ̀.
Mo gbọ́ iye àwọn tí a fi èdìdì sí níwájú, wọ́n jẹ́ ọ̀kẹ́ meje eniyan ó lé ẹgbaaji (144,000) láti inú gbogbo ẹ̀yà ọmọ Israẹli: 
Orukọ wọn ni Bartholomew Owoh, Bernard Ogedemgbe, Alhaji Akanni Lawal Ojuolape, Sidikatu Tairu ati Ayisat Ajike Muhammed.
Èrèdí ọ̀rọ̀ rè é tí a fi jẹ ọmọ ẹgbẹ́ yìí.
Ilé ìjọsìn àti mọ́sálásí yóò máa tẹ̀lé ìlànà ti ìpínlẹ̀ kọ̀ọ̀kàn bá là sílẹ̀ fún wọ́n.
Gomina naa si fi ami ẹyẹ aworan ti wọn fi owo ya, da ajagunfẹyinti naa lọla.
Oríṣun àwòrán, LagosPoliceng Fatai ti inagijẹ rẹ n jẹ 'small' ni wọn sọ pe o n damu awọn eeyan Langbasa ladugbo Ajah.
Lákọ̀ọ́kọ́, àwọn eniyan mi lọ ṣe àtìpó ní ilẹ̀ Ijipti, lẹ́yìn náà, àwọn ará Asiria pọ́n wọn lójú láì nídìí.
Akẹ́kọ̀ọ́ mẹ́fà di ẹni àtìmọ́lé lọjọ́ Ìṣẹ́gun 12, oṣù Ẹrẹ́nà ní agbègbè Kirundo ní Àríwá Ìlà-oòrùn Burundi fún ẹ̀sùn-un kíkọ ìkọkúkọ sórí àwòrán Ààrẹ Pierre Nkurunziza nínú àwọn ìwé ìkọ́ni márùn-ún.
Èyí nìkan kọ́, àkókò ń bọ̀ tí ó jẹ́ pé ẹni tí ó bá ṣe ikú pa yín yóo rò pé òun ń ṣe iṣẹ́ ìsìn sí Ọlọrun ni.
Oríṣun àwòrán, Other Bí wọn ṣe gbọ ìlú yìí ni igbakeji Kurunmi ni kí wọn rekọja odò, ọwọ ọmọ ogun Ibadan si ni wọn bọ si, tí wọn si ge orí ọmọ Kurunmi to wa lójú ogun.
Àwọn ẹ̀yà Lefi kò ní ba yín pín ilẹ̀ nítorí iṣẹ́ alufaa OLUWA ni ìpín tiwọn.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Public Holiday: Ìjọba Nàìjíríà ya ọjọ́ méjì sọtọ̀ fún ìsinmi ọdún Iléyá 27 Èrèlè 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 28 Agẹmo 2020 Oríṣun àwòrán, Getty Images Ijọba Naijiria ti kede ọjọbọ ati ọjọ Ẹti gẹgẹ bi ọjọ isinmi fayajọ ọdun Eid-ul Adha lorileede Naijiria.
0 5576 Orilẹede Belize 183 47.
Lẹ́yìn tí ó rí òrùka ati ẹ̀gbà ọwọ́ lọ́wọ́ arabinrin rẹ̀, tí ó sì ti gbọ́ ohun tí Rebeka sọ pé ọkunrin náà sọ fún òun, ó lọ bá ọkunrin náà níbi tí ó dúró sí lẹ́bàá kànga pẹlu àwọn ràkúnmí rẹ̀.
Ó ní, “Ẹ̀yin eniyan wa, ẹ mọ̀ pé ninu iṣẹ́ yìí ni a ti ń rí èrè wa.
Sugbon Alukoro ile ise oloopa ni Ipinle Oyo, Ogbeni Gbenga Fadeyi so wi
Kalebu tún ní obinrin mìíràn tí ń jẹ́ Maaka.
Ajọ to n mojuto ajakalẹ arun lorilẹede Naijiria, NCDC ninu atẹjade toun fi sita loju opo twitter tirẹ ṣalaye pe awọn ami aisan naa to farahan lara awọdn eeyan ọhun ṣi mọ niwọnba, wọn si n gba itọju bi o ti tọ ati bo ti yẹ.
Ọjọgbọn kan ni fasiti lorileede Amerika ti o tun jẹ akoroyin naa fara kasa ninu a n gbe iroyin ayederu yi ka.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Mama Boko Haram: Alaafia ni akẹẹkọ Dapchi wa 2 Ẹrẹ̀nà 2018 Oríṣun àwòrán, Yobe state governmentt Àkọlé àwòrán, O le ni aadọfa akẹkọ Dapchi to tun bọ sọwọ Boko Haram Gbaju gbaja ajafẹtọ ẹni kan, Aisha Wakili, ti wọn tun ndape ni Mama Boko Haram ti ni awọn akẹẹkọ Dapchi ti ikọ Boko Haram ji gbe laipẹ yi wa ni alaafia pẹlu Habib, ẹni to pe ni ọmọ rẹ.
Ti a ko ba gbagbe, lẹyin ifẹhọnuhan EndSars ni awọn janduku yabo ile igbe ounjẹ si ati ileeṣẹ ijọba ti wọn si ko awọn ohun ini ijọba lọ nipinlẹ naa.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Yoruba: Báwo lo ṣe gbọ́ èdè rẹ sí?
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ondo State Election result 2020: Bí èsì ìdìbò gómìnà ìpínlẹ̀ Ondo ṣe ń jáde rèé.
Wò ó, òṣùpá pàápàá kò mọ́lẹ̀ tó,bẹ́ẹ̀ ni àwọn ìràwọ̀ kò mọ́ tó lójú rẹ̀;
Kání àwọn babańlá wa mọ̀n níjọ́ kìíní àná ni, bóyá àwọn Gẹ̀ẹ́sì ò bá tí múnwa sìn.
BBC pidgin lẹyin iwaadi ri wi pe ileesẹ ọlọpaa Tallahassee kede pe o di awati ni ọjọ Kẹsan osu Kẹfa 2020, sugbọn lẹyin ọjọ diẹ ni wọn kede pe awọn ri oku rẹ ni irọlẹ ọjọ Kẹẹdogun osu Kẹfa.
Ni oṣu keje, ọdun to tẹlee, 2012, o din diẹ ni irinwo eniyan ti omiyale ati agbara ojo pa kaakiri orilẹ-ede Naijira, ni paapaa, Ipinlẹ Eko nibi ti ọpọlọpọ eniyan ti ku.
Àkókò ìgbà tí àwọn Àkàrà-oògùn fi ń múra àti lọ sí òkè láńgbòdó gan-an ni bàbá mi rán mi lọ sí ìdálẹ̀ kan ní ijọ́sí.
Dybala kede loju opo Instagram rẹ pe oun ati ọrẹbunrin oun, Sabatini ti ko arun ko arun covid-19.
Sedekaya ọba bá dá wọn lóhùn, pé, “Ìkáwọ́ yín ló wà, n kò jẹ́ ṣe ohunkohun tí ó bá lòdì sí ìfẹ́ yín.
Awon yooku ni: Eni owo Efe
 Ọmọ bíbí ìlú yewa , Ìmẹ ̀ kọ ní ìpínlẹ ̀ Ògùn ni .
Oríṣun àwòrán, others Aṣọgba yii, Tanko Abdullateef nikan ni ọmọ ọdọ ti obinrin ẹni aadọta ọdun naa ni ninu ile rẹ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, coronavirus prevention badge update: Wo òótọ́ àti irọ́ tó wà nínú báàjì àyà náà Awọn yoku ni Ile Oluji/Okeigbo, Owo, Idanre ati Ondo East.
Aarẹ Buhari ṣe oniruuru ipade pẹlu aarẹ ilẹ South Africa, Cyril Ramaphosa lori ibaṣepọ laarin awọn orilẹede mejeeji.
Ẹ má ṣe gbàgbé wí pé bí ayé tí dùn tó bẹ́ẹ̀ náà ni ìṣsòro inú rẹ̀ pọ̀ tó.
Ninu ifọrọwerọ pẹlu awọn akọroyin,Mourinho ni alaga ẹgbẹ Tottenham Daniel Levy ti fi igba kan ba ohun sọrọ nipa gbigba iṣẹ ni Tottenham lọdun 2007.
Èyí ni pé wọn kì í tún ṣe ẹni meji mọ́, bíkòṣe ọ̀kan.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ẹni bá láyà kó wá wọ̀ọ́!
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Iyabo Ojo: Wọ́n gba N51,950 lọ́wọ́ mi ní pápákọ̀ òfurufú láì ṣe àyẹ̀wò Coronavirus fún mi 28 Owewe 2020 Oríṣun àwòrán, Instagram/iyaboojofespris Gbajumọ osere tiata lobinrin, Iyabo Ojo ti figbe ta lori iwa gbajuẹ tijọba Naijiria n hu lori ayẹwo arun Coronavirus.
Eli a máa súre fún Elikana ati Hana aya rẹ̀ pé, “OLUWA yóo jẹ́ kí obinrin yìí bí ọmọ mìíràn fún ọ, dípò èyí tí ó yà sọ́tọ̀ fún OLUWA.
Bí ó bá jẹ́ pé òfin tí a fi fúnni lè sọ eniyan di alààyè, eniyan ìbá lè di olódodo nípa òfin.
Amnesty International gba pé eyi n jẹ ki awọn agbofinro lọ laijiya ẹṣẹ wọn.
Liverpool fẹ gbiyanju lati di ikọ agbabọọlu keji ninu itan ti yoo gba ife ẹyẹ Premier League mọ ikọ to n siwaju lọwọ lọjọ ti idije naa pari.
Lẹ́yìn náà mo rí ìlú mímọ́ náà, Jerusalẹmu titun, tí ó ń ti ọ̀dọ̀ Ọlọrun sọ̀kalẹ̀ láti òkè wá.
Nígbà náà ni ọ̀gá àwọn ẹ̀ṣọ́ ati àwọn iranṣẹ lọ mú àwọn aposteli.
Ipa ribiribi to ko pẹu iṣejọba rẹ ninu idagbasoke ipinlẹ Eko kun ara ohun ti o mu ki ọpọ awọn ọmọ orilẹede Naijiria fẹran rẹ.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Mo fẹ́ kí àyẹyẹ ìgbeyàwó mi dùn ni mo se bú sẹ́kún - Ọkọ ìyàwó ẹlẹ́kún Mo fẹ́ ọkọ mi torí bó se ń kọrin, kìí se torí owó - Ìyàwó Aràrá Ìtàn tó wà nídi òwe ‘Sebótimọ Ẹlẹ́wà Sàpọ́n’ Hubert Ogunde rèé, baba àwọn òsèré tíátà Samuel Ladoke Akintọla jẹ́ Agbẹjọ́rò àti Akọ̀ròyìn tí ọ̀rọ̀ dá lẹ́nu rẹ̀ Wọn salaye pe ko si ohunkohun to lee ya awọn, tori Ọlọrun lo kọ awọn papọ lati ọrun, olúbi kansoso si lawọn gbe wa saye.
Tí a fiṣọwọ́ ní 12:33 29 Èbibi 201912:33 29 Èbibi 2019 Gómìnà Badaru Abubakar ti ipinlẹ̀ Jigawa bùrawọlé BBCCopyright: BBC Gomina Badaru AbubakarImage caption: Gomina Badaru Abubakar Article share tools Facebook Twitter ṢàpínlòView more share options Share this post Copy this linkKà síwájú síi nípa àwọn ìtọ́kasí wọ̀nyí.
Wò ó bí wọn ṣe parun lọ́gán,tí ìpayà sì gbá wọn lọ patapata.
5M ti pọ̀ jù fún owó fọ́ọ̀mù ìdìbò abẹ́lẹ́ sípò gómìnà APC - SERAP Àntí Korona ni wọ́n n pè mí l'ádùúgbò láti ìgbà tí mo ti ní Covid-19- Motosinoluwa Afolaranmi Ilé ẹjọ́ dá Ààfá dúró láti gbé ọmọ ọdun 16 sílé gẹ̀gẹ́ bí ìyàwó rẹ̀ kẹ́sàn án Òṣèré tíátà, Ọmọba Femi Oyewunmi tí ọ̀pọ̀ mọ̀ sí Laditi ti jáde láyé Ọlọ́pàá ti bẹ̀rẹ̀ ìwádìí láti mọ òkodoro bí wọ́n ṣe gbé ọmọ tuntun náà sin láàyè ní India Arákùnrin tó jí Ese Oruru gbé ti rí ẹ̀wọ̀n ọdún 26 he Ó ní títí di àsìkò yìí àjọ òun kò lọ́fììsì, gbogbo àwọn irinsẹ́ ọlọ́dani tí àwọn sì n lò ló wà ní títì pá títí di àsìkò yìí.
National Stadium Flyover, Ijọba ibilẹ Surulere 9.
Buhari sọ pe ti igbimọ naa ba ṣe iṣẹ rẹ bi iṣẹ, nnkan yoo yipada si rere fun awọn ọmọ Naijiria.
Nítorí ní ìgbà àtijọ́ irú ẹwà báyìí ni àwọn aya tí a yà sọ́tọ̀, àwọn tí wọ́n ní ìrètí ninu Ọlọrun, fi ṣe ara wọn lọ́ṣọ̀ọ́.
Ọmọ Nàìjíríà tó fẹ́ pa adájọ́ lọ ẹ̀wọ̀n gbére ní Amẹ́ríkà
Bí ẹni tí ó ya ilẹ̀ náà sọ́tọ̀ fún OLUWA bá fẹ́ rà á pada, yóo san iye tí ó bá tó, yóo sì fi ìdámárùn-ún owó rẹ̀ lé e, ilẹ̀ náà yóo sì di tirẹ̀.
Awọn akẹkọọ wọn keekeeke si wa ni ile ẹkọ.
O fi ẹsun kan awọn Obi Wasiu pe wọn maa n sọrọ nitori awọ buluu oju oun ati tọmọ ṣugbọn Wasiu ni irọ ni pe inu Obi oun dun si awọ oju rọ.
Àwọn agbébọn fọ́ ọgbà ẹ̀wọ̀n ni Minna nPDP jáwọ́ nínú ìjíròrò pẹ̀lú APC O ni akori ayajọ naa to fọnrere wahala ti ike n koba ayika jẹ ohun to pe akiyesi gbogbo eeyan si wahala to n lọ layika.
Pẹlu iyi lo fi maa n pọn orilẹede rẹ le nibikibi to ba wa, asia Naijiria ko le ma fẹ lẹlẹ nibi to ba ti n ja, koda aworan Afirika wa gbagada lapa rẹ.
 Oríṣun àwòrán, LASEMA Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!"
Jija fun owo oṣu to dọ́gba fun gbogbo oṣiṣẹ nilẹ America, ni afojusun rẹ.
Ẹgbẹ Afenifere ni yoo jẹ nkan to buru jai ti ijọba ba tun gunle eto atunṣe iwe ofin Naijiria lasiko yii lai ṣe amulo awọn eleyi to ti waye tẹlẹ.
“Èmi fúnra mi ni mò ń tù ọ́ ninu,ta ni ọ́, tí o fi ń bẹ̀rù eniyan tí yóo kú?
ati Ogu ọba Baṣani,nítorí pé ìfẹ́ rẹ̀ tí kì í yẹ̀ wà títí lae.
Bakan naa lo tun dupẹ lọwọ awọn ọrẹ rẹ miran ti wọn ti ṣe iranwọ kan tabi omiran fun un.
Bakan náà àwọn ìjìyà ti òfin Sharia mú daní lé jẹ́ sísọ ènìyàn ni okúta pa.
Aisan Ebola tún ti padà dé sí Goma!
Ọmọ ọdun mẹrindinlogun naa, Ajekigbe Ifeoluwa Martins sọ pe o jẹ iyalẹnu fun oun pe awọn obi oun ko le sọrọ, ati pe o ṣoro lati ba awọn obi oun sọrọ nigba ti oun wa ni kekere.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
Ìyàn ati àjàkálẹ̀ àrùn yóo wà ní ibi gbogbo.
Ní ọdún kẹjọ tí Josaya gorí oyè, bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé ọmọde ni, ó bẹ̀rẹ̀ sí sin Ọlọrun Dafidi, baba ńlá rẹ̀.
Irú nǹkan báyìí náà ni a wí pé kí àwọn ọmọ aráyé máa ṣe, ní dúdú, ni funfun, ni èyí tí kò dúdú tí kò funfun wí pé, kí ọmọdé fi ipò àgbà fún àgbà, kí àgbà náà fi ipò ọmọdé fún ọmọdé; kkí ìránńṣẹ́ fi ipò ọ̀gá fún ọ̀gá, kí ọ̀gá náà sì fi ipò ìrànńṣẹ́ fún iránńṣẹ́, kí ọkọ fi ipò aya fún aya, kí aya nàá sì fi ipò ọkọ fún ọkọ.
"Nitori pe awọn obi kan,kaka ki wọn foju odaran wo awọn ọmọ buruku wọn yi,nise ni wọn raga bo won"" Ẹgbẹ Pyrates ti Soyinka si yi jẹ ọkan lara wọn gẹgẹ bi o ti ṣe sọ si n ṣe igbelarugẹ awọn iṣẹ oloore f'ẹda moniyan."
Owó oúnjẹ ni mo lọ ọ gbà, oyún ọmọ tí mo jù sí àkìtàn ni mó gbé wálé- Dupe, ìyá Muiz Ènìyàn 156 míràn ló tún kó Coronavirus ní Nàìjíríà ní ọjọ́ Ẹtì Olórin Kano tí wọ́n dájọ́ ikú fún pe ẹjọ́ kòtẹ́milọ́rùn Nàìjíríà làwọn ní ìfẹ́ sí ìpèsè abẹ́rẹ́ àjẹsára Covid-19 tí Russia ṣe Wo ọ̀nà ìsanwó tuntun fún àwọn oníbárà iná mọ̀nàmọ́ná ní Eko (EKDC) Àwọn dókítà yóò bẹ̀rẹ̀ ìyanṣẹ́lódí lọ́jọ́ Ajé Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Fuel hike protest: Àwọn akẹ́kọ̀ọ́ ìpínlẹ̀ Oyo, Osun àti Ondo ṣe ìfẹ̀hónúhàn lórí èlé owó iná àti owó epo8 Owewe 2020 Fídíò, Akomolede ati Aṣa lori BBC: Mọ̀ si nípa oríṣìí ẹ̀ka ìsọ̀rí ọ̀rọ̀ àti ìwúlò wọn8 Owewe 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Awọn olugbe ile naa ṣe alaye fun ikọ BBC Yoruba wi pe, ina ọba to de lojiji si adugbo naa, lo ṣokunfa iṣẹlẹ agbọgbarimu ọhun.
27 Ògún 2020 Oríṣun àwòrán, OTHERS Àwọn gbájúgbajà òṣèré kan jẹ́ ilúmọ́ọ̀ká ni àsìkò kan, pàápàá jùlọ nínú àwọn eré àgbéléwò Yorùbá.
"Oríṣun àwòrán, From The Palace of Ooni of Ife ""A ko lee ni alaafia ati eto aabo to peye nigba ti a ko ni isejọba rere ati idajọ ododo."
 mo maa n gbo  aheso oro pe won ko iye awon olopaa bayii wa, leyin oreyin, ko ni si olopaa Kankan nibe, mo ti iru isele bayii ni ipinle Edo.
ṣiṣẹ lori alekun owo oṣu tuntun fawọn oṣiṣẹ.
OLUWA sọ fún Mose kí ó sọ fún àwọn ọmọ Israẹli pé, 
Akinjo ti fi igba kan jẹ igbakeji Mayor ilu Latherop, o si tun sisẹ gẹgẹ bi ọmọ ologun ilẹ America, laarin ọdun 1982 si 1989.
Dokita naa sọ pe ohun gbogbo lo wọn gogo lagbegbe naa, latari ọna ti ko si, bẹẹ si ni awọn aboyun maa n ri eemọ ki wọn to bimọ.
Alaye ree lori orukọ awọn oṣu kọọkan itumọ ati bi wọn ṣe n pe wọn: Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ọgọrọ awọn musulumi lo maa n kopa ninu isin Hajj ọlọdọọdun Muharram: Osu yi tumọ si oṣu eewọ lede larubawa.
Ẹ gbọ́ nígbà tí mo sọ fun yín pé, ‘Mò ń lọ, ṣugbọn n óo tún pada wá sọ́dọ̀ yín.
N kò nílò ìwé ẹ̀rí WAEC ní fásitì Amẹrika - Adeleke Oò nílò ìwé ẹ̀rí WAEC láti dí ààrẹ tàbí gómìnà - Keyamo APC yọ orúkọ Shittu kúrò láti kópa nínú ìdìbò abẹ́lé Ilé alájà méjì wó lu ọmọ mẹ́rin ni Bariga Ṣaaju ni ile ẹjọ giga ijọba apapọ nilu Abuja, ati ile ẹjọ kotẹmilọrun ti da ẹjọ wọn nu ninu idajọ kan lọjọ kejila, oṣu Keje, ọdun 2019.
 Àwọn olórí-ọmọ yìí ló máa ń kó àwọn ọmọ ìlú lẹ ́ hìn lákòókó ọdún Àgàdá náà láti jó yí ìlú káákiri àti láti máa ṣàdúrà fún ìlọsíwájú ni gbobgo ìkóríta ìlú .
Ọjọ ti pẹ ti àwọn èniyan ti ń siye meji lori ọ̀rọ̀ abẹ́rẹ́ àjẹsára fún oniruuru ìdí, láti ori ẹ̀sìn, àsà nítori wọ́n rò ó pé kìí ṣé ohun tó mọ àti pé ọ̀nà láti gba ẹ̀ta ominira ara ẹni lọ́wọ́ wọn ni.
"Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Oshisko twins, àwọn 'ìbejì' tó ń dẹ́rìn ín p'òṣónú Ìyá àgbà Ọlayinka, arúgbó tó ń ṣoge bí omidan World TB Day: ""Ó dùn mí jù pé ń kò rí ọmọ mi fún ọdún kan"" Baṣọ̀run Gáà, tó yan ọba mẹ́rin, pa ọba mẹ́rin àmọ́ ọba karùn-ún ló pa á Àràmọ̀ǹdà!"
Kashamu ṣì ni olùdíje PDP fún ipò gómìnà l'Ogun Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fọ́nrán ohùn, Akala lè ṣàtìlẹ́yìn fẹ́ni tó bá wù ú Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Diaspora: Ẹyin nikan kọ́ ni ọ̀rọ̀ idibo Naijiria kàn nílé Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
4 114 Orilẹede Montserrat 1 20.
Mi o sọ fun ẹnikẹni, bo tilẹ jẹ wipe awọn ọrẹ mi ṣakiyesi pe inu mi ko dun.
“Nítorí pé bí ẹnikẹ́ni ninu ẹ̀yin ọmọ Israẹli tabi ninu àwọn àlejò tí wọ́n wọ̀ ní ilẹ̀ Israẹli bá ya ara rẹ̀ kúrò lọ́dọ̀ mi, tí ó Kó oriṣa rẹ̀ lé ọkàn, tí ó sì gbé ẹrù ẹ̀ṣẹ̀ tí ń múni kọsẹ̀ ka iwájú rẹ̀, tí ó wá tọ wolii lọ láti wádìí ọ̀rọ̀ lọ́wọ́ rẹ̀ ní orúkọ mi, èmi OLUWA fúnra mi ni n óo dá a lóhùn.
Ipele keji ifẹwọnsẹ mejeeji yoo waye lọsẹ to mbọ.
Akẹ́kọ̀ọ́ mọ́kànlá ni wọ́n fẹ̀sùn ìtàbùkù bá adarí ìlú àti “ìhàlẹ̀ mọ́ ààbò ìlú” kàn, bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé wọ́n padà dá wọn sílẹ̀.
Ìfarahàn ògo OLUWA gbéra kúrò lórí àwọn Kerubu, ó lọ dúró sí àbáwọlé.
Alaafin Ọyọ bí ìbejì lẹ́ẹ̀mẹta láàrin oṣù mẹ́jọ
Doris Simeon Ọjọ meji ṣaaju ọjọ ibi Bimbọ Oshinn ni gbajugbaja oṣere miran, Doris Simeon ṣe ọjọ ibi.
Aṣọ funfun náà ni iṣẹ́ òdodo àwọn eniyan Ọlọrun.
 nípa ìtúmọ ̀ tí ó gbòòrò yí , lati ìgbà tí ènìyàn ti wà láyé ni tíátà ti wà to bẹ ́ ẹ ̀ gẹ ti ó se sajejuwe ìgbé ayé ènìyàn nítorí Ìfé àwọn ènìyàn si ìtàn sísọ .
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Aborisade: Mẹ̀kúnù gbọ́dọ̀ funra sí Obasanjo Ta ni Fairstein Linda yii?
Ni Brussels awọn igbimọ ijọba ti n fikulukun lojuna ati gbọ esi ti yoo ṣe anfani fun awọn ọmọ ẹgbẹ EU metadinlọgbọn to ku.
Ninu ọrọ tiẹ, Taiwo Adisa sọ pe ipinlẹ Ọyọ ko ni i kopa ninu eto naa, nitori pe ipinlẹ naa ko nilo eto naa.
Nigeria Bad roads: Àwọn obìnrin abúlé yìí ń pàdánù ọmọ látàrí òpópónà tó mẹ́hẹ
" Hajj: Ǹjẹ́ o mọ pàtàkì Ọjọ́ Àràfá fún àwọn mùsùlùmí?
Jonatani sì dáhùn pé, “Kí ló dé tí yóo fi kú?
Ọgbọ́n ń pe eniyan,òye ń pariwo.
iwadi lori ẹsun ti wọn fi kan ileeṣẹ Alpha Beta Consulting Limited ṣi n tẹsiwaju.
koju oṣuwọn ninu iṣẹ wọn, ki aabo si le wa fun awọn ẹṣọ yii funra
ati ogoji ìtẹ́lẹ̀ fadaka, meji meji sí àkànpọ̀ igi kọ̀ọ̀kan.
Ìyá mi, kí ló dé tí o bí mi, èmi tí mo di oníjà ati alárìíyànjiyàn láàrin gbogbo ìlú!
Àwọn ìròyìn míì tí ẹ lè nífẹ sí Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Tọkọ-taya Aràrá: Àwọn èèyàn máa ń wò wá, ta bá fa ọwọ́ ara wa ní títì Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Tabi, kí ni ó pa ìmọ́lẹ̀ ati òkùnkùn pọ̀?
Ipo karun un ni Messi wa.
To ba jẹ tootọ ni pe ile-onile ni ajo EFCC n ti pa, ṣe bi awọn ti o ni ile naa ko ti i ku?
Ijoba UAE ti o ti n se itoju awon omo ogun ohun, kuna lati tesiwaju latari awon iwa magogo ti won kofiri re.
Obaseki la Ize-Iyamu mọ́lẹ̀ wọlé ìbò gómìnà lẹ́ẹ̀kejì ní ìpínlẹ̀ Edo Omoni ṣalaye pe ileeṣẹ ọlọpaa ti gba ibọn lọwọ ọlọpaa naa, o si ti wa lahamọ ni ẹka ileeṣẹ ọlọpaa to n ṣewadii awọn ọdaran.
ipinle yii, ki e si wa ona abayo si awon idojuko won yii lai fi fale rara.
Eric ati Tochi ni wọ́n lé kúrò nílé ẹlẹ́gbọ̀n àgbà BBNaija lọ́sẹ̀ yìí Sanwo Olu ti mú ìlérí rẹ̀ ṣẹ, mo ṣèlérí pé máà jẹ́ ọmọ dáadáa- Ọmọ fídíò 'Mummy calm down' Mo ti buwọ́lu àdínkù owó orí nítorí ìrọ̀rùn àwọn èèyàn ìpínlẹ̀ Ogun lásìkò Covid 19- Dapo Abiodun Àwọn adarí lágbàyé ṣèpàdé láti ṣèrànwọ́ fún Lebanon lẹ́yìn ìbúgbàmù tó pa ènìyàn 158 Dokita Hadi Abdallar banujẹ lori iwadii yii lataari ọpọ ẹmi to ti sọnu nipasẹ iwa ika awọn alatẹnujẹ kan nilẹ Adulawọ.
Ogbeni Yakubu  soro yii leyin ti ile-ejo to ga julọ lorile
 Eyi le waye ti ẹni to ba jawe olubori ko ba bori lawọn agbegbe to se
O kọ ọkan lara awọn orin inu awo naa pẹlu Reminisce ati Chinko-Ekun.
Olatunji fí kún-un pé '' a ṣe àkíyèsí akitikyan àtí ipò bàbá ti ààrẹ Muhammadu Buhari láti ríi dájú pé ìṣèjọba awà-arawa tún gbilẹ̀ sí, àìfárí apákan dá apákan si àti ìwà aparò kàn o ga jú ìkan lọ ti ó fi kọ àwọn ọmọ ẹgbẹ́."
Ọlọ́wọ́ idán Houdini kò yè é o, ó bómi lọ!
Ikọlu awọn ọmọ Naijiria laipẹ yii jẹ ọka gbogii ninu ọrọ tawọn olori orilẹede mejeeji jọ sọ.
Díẹ̀ ló kù kí bàlúù arìnrìnàjò sílẹ̀ mímọ́ Hajj gbaná Láìpẹ́, ará ìlú rẹ ni ọlọ́pàá tí yóò máa ṣọ́ ìlú rẹ Ààbò tó péye wà fún àwọn okòwò ará South Africa ni Eko -Sanwo Olu Gẹgẹ bi a ṣe gbọ, ọkan ninu awọn mejeeji yii gbiyanju lati yọ ẹrọ ibanisọrọ alagbeka rẹ to jabọ sinu kọnga yii lasiko to fi n pọn omi lati fi jẹun lo ba di wọ ninu kọnga.
Ilana iṣẹ mẹrin ni ileeṣẹ ọlọpaa gbe sita fun awọn ọlọpaa ti yoo wa ninu ajọ SWAT Wọn yoo ma a gbogun ti idigunjale, ijinigbe Awọn ọmọ ikọ yii ni agbara lati lọ sibikibi ti iwa ọdaran ba ti n waye pẹlu ohun ija oloro Iṣẹ idoola ni ojuṣe wsn kẹta Eyi to kẹhin ni akanṣe iṣẹ, to ni i ṣe pẹlu awọn iwa ọdaran to lagbara pupọ.
Oríṣun àwòrán, Instagram/ushbebe comedian Ko tan sibẹ o, Ushbebe ni igbesẹ ijọba lati fofin de irinajo sawọn orilẹede mẹtala naa na oun owo lowo airotẹlẹ nitori oun ni lati ra tikẹti mii ki oun le pada sile.
- MC Oluomo Àròsọ àti ìgbàgbọ́ àwọn ènìyàn lórí gbígba ẹ̀jẹ̀ Ayinla Ọmọwura, orin èébú àti oríyìn lo fi di ọ̀rẹ́ àwọ̀n obìnrin Gani Adams: Iléèṣẹ́ ọlọ́pàá ti kàn sí OPC lórí ètò ààbò Sááju àsìkò yìí ni Aisha Buhari ti ba BBC Hausa sọ̀rọ̀ lọdun 2016 pe àwọn kan lo ń dari ọkọ òun nilé ìjọba.
Ọkan lara awọn ọkunrin naa sọ pe, oun lo kọndọmu ileeṣẹ Life Guard, ṣugbọn o ja lasiko ti oun n ni ibalopọ.
Àwọn ọkunrin Juda bá bèèrè pé, “Kí ló dé tí ẹ fi gbógun tì wá?
Ẹ dákẹ́ jẹ́ẹ́ níwájú OLUWA Ọlọrun!
Ẹgbẹ agbabọọlu rẹ, lorilẹede China, Shandong Luneng lo kede ọrọ naa laarọ ọjọ Aiku.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo 18 Èbibi 2020 Ṣe lootọ ni akudaaya wa?
Fayẹmi ni: “Aṣeyọri mi ninu eto idibo yii ni oore ofe lati wa tun Ekiti ṣe.
rẹ, eleyii ti wọn fi n wo awokọṣe rẹ kaakiri agbaye bayii.
Fayoṣe àti Fayẹmi dì mọ́ra wọn l'Eko Ó sọ pé òun kò jẹ̀bi ẹ̀sùn ti wọn fi kan òun kí wọn to yọ̀nda rẹ̀ lẹ́wọ̀n.
Iṣẹ́ tí ó fi rán wa, tí à ń jẹ́ fun yín nìyí: pé ìmọ́lẹ̀ ni Ọlọrun, kò sí òkùnkùn ninu rẹ̀ rárá.
Ẹbí àwọn èdè kan nìyí tí èdè tí ó wà nínú rẹ ̀ tó ọgọ ́ fà .
O ni oun n wẹ lọwọ ni nigba ti ipe pajawiri kan wọle wi pe atẹgun ojo ti ṣi paanu ile lọ ti o si rọ lu ile alaja kan to n bẹ ni iwaju ibi ti wọn fi n ṣe ile ẹkọ.
Bunkunmi kọ bi wọn ṣe rin irinajo ifẹ wọn soju opo rẹ afi bii episteli ni tori bi wọn ba gun ẹṣin ninu rẹ , wọn o le kọsẹ rara.
Awọn yoku ni Modupẹ Onitiri ati Rẹmi Abiọla.
Lonii Ọjọru nile yoo dibo lati fẹsun kan Trump pe o ṣokunfa ikọlu to waye nile aṣofin.
' Buhari wa gbadura ẹmi gigun ati ilera ninu ọrọ fun Jonathan ki o lee tubọ sin orilẹede Naijiria siwaju si.
Mo wí fún wọn pé,“Ẹ máa dẹtí sílẹ̀ sí fèrè ogun!
"Onuegbu ni ""Lọwọ lọwọ, awa si n ko awọn ọmọ ẹgbẹ wa jọ lati fi ẹhonu han lori owo tijọba fikun owo epo, eyi to n nipa to ko dara lori awọn osisẹ nilẹ yii."
A bí eniyan sinu wahalabí ẹ̀ta iná tí ń ta sókè.
Ṣugbọn ẹ sùn níbí ní alẹ́ yìí, kí n lè mọ ohun tí OLUWA yóo tún bá mi sọ.
Ninu ọrọ tiẹ nibi ipade naa, Oyinlola sọ pe asiko ti to lati ṣe atunto orilẹede Naijiria, o ni itanjẹ ẹgbẹ APC ti to gẹẹ.
N óo kọ́ ibùgbé mi sí ààrin wọn, n óo jẹ́ Ọlọrun wọn, wọn yóo sì jẹ́ eniyan mi.
Ìtàn lè pa wọ́n pọ̀ nipa àjọjẹ́ orúkọ, àjọṣe kankan lè má sí láàárin wọn nígbà kan ti rí ju wí pé orúkọ yìí, tó wu Ògbóni kìíní Ọba Ìjẹ̀bú-Jẹ̀ṣà nígbà tí ó bá àbúrò rẹ̀ Ajíbógun lọ bòkun, wọ́n gba ọ̀nà Ìjẹ̀bú-Òde lọ.
Lodun 2008, lo se ‘Abobaku’, ti Niji Akanni dari e to de gba ami eye fiimu to kere julo to dara ju lodun 2010 nibi eto Zuma Film Festival .
Àkọlé àwòrán, Ile wiwo bẹrẹ l'Eko Ninu fọnran fidio yi ti a ti ba awọn eeyan sọrọ wọn bẹnu atẹ lu bi awọn oṣiṣẹ eleto ile kikọ kan ti ṣe n gba abẹtẹlẹ lọwọ awọn ti wọn ba ti fagile ile wọn fun wiwo.
Ta ni ẹ rò pé mo jẹ́?
Nítorí pé ilẹ̀ náà kún fún àgbèrè ẹ̀sìn,ọ̀nà ibi ni wọ́n ń tọ̀,wọn kò sì lo agbára wọn ní ọ̀nà ẹ̀tọ́nítorí ègún, ilẹ̀ ti di gbígbẹgbogbo pápá oko ló ti gbẹ.
O tún ṣe àgbèrè lọpọlọpọ pẹlu àwọn oníṣòwò ará ilẹ̀ Kalidea, sibẹsibẹ, kò tẹ́ ọ lọ́rùn.
Irú kí ni ẹ dánwò yìí?
Ni aye ode oni, ẹkọ nla gidi ni itan igbe aye Alaafin obinrin akọkọ yii yẹ ko kọ wa, eyi to fi han wa pe ko si ohun ti ọkunrin lee se, ti obinrin ko lee se.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Oludamọran fun gomina salaye ọrọ yii ninu ọrọ apilẹkọ rẹ nibi ipade apero fawọn osisẹ alaabo adayeba nilẹ Yoruba, akọkọ iru ẹ, to waye nilu Ibadan.
Òkú rẹ yóo di ìjẹ fún àwọn ẹyẹ ati àwọn ẹranko tí ń káàkiri orí ilẹ̀ ayé, kò sì ní sí ẹnikẹ́ni tí óo lé wọn kúrò.
Ati pe ko si owo ni igboro ni eyi to maa mu ki igbese ijọba ipinlẹ Eko yii tubọ nira sii fun tẹrutọmọ.
), “Savannah Grass” yóò wà nínú àkópamọ́ orin soca gẹ́gẹ́ bí orin ìgbà-dé-ìgbà tí ó mú inú àwọn olólùfẹ́ẹ Ijó ìta-gbangba ní ibi gbogbo dùn.
Obìnrin náà sanra báyìí ó wà ní ìhòòhò gidigidi.
Bí mo bá pè é pé kó wá gbọ́,tí ó sì dá mi lóhùn,sibẹ n kò lè gbàgbọ́ pé yóo dẹtí sílẹ̀ gbọ́rọ̀ mi.
" Bakan naa ni awọn ọmọ orilẹede yii miran naa ti n bu ẹnu atẹ lu minisita naa.
Wọn ni owo naa wa fun awọn ọdọ to nilo iranlọwọ ṣugbọn ti ọjọ ori wọn ko ju ọdun mejidinlogun si ọdun marundinlogoji lọ.
Gbogbo aye lo n gbadura fun un lẹyin to bẹrẹ aisan ni bii ọjọ mẹta sẹyin ko to jade laye l'ẹni ọdun mẹrindinlọgọrin.
O si seese ki o pẹ lasiko yii nitori coronavirus.
Nítorí náà bí èmi, OLUWA àwọn ọmọ ogun, Ọlọrun Israẹli, ti wà láàyè, 
OLUWA kò ní wà pẹlu yín nítorí pé ẹ ti ṣe àìgbọràn sí i.
Bakan naa ni wọn fikun pe awọn ti ko awọn ọkọ meji yoku kuro loju ọna, ki sunkẹrẹ fakẹrẹ ọkọ le dinku.
Won ko i ti fenuko lori ojo ti ipade egbe People’s Party yoo waye .
Àwọn módẹ̀lì bi 4S, 5, 5S.
jawe olubori , ti won si ti kede won ninu eto idibo gomina ni won yoo gba iwe
Atamatase olukopa ti o dara julo lagbaye ninu ere idaraya boolu afibaati gba, Novak Djokovic se gudugudu meje ohun yaya mefa ninu asekagba idije ATP, leyin ti o fagba han akegbe re lati orile-ede Germany, Alexander Zverev, lojoRu(Wednesday).
Nígbà náà ni Simoni Peteru gòkè, ó fa àwọ̀n sí èbúté.
A ti kú sí ohun tí ó dè wá.
Baba Sala wọ káà ilẹ̀ lọ ní Ilesa Òṣìṣẹ́ OSCOTECH gb'òmìnira lọ́wọ́ ajínigbé darandaran Fulani Kashamu ní òfin kò dá Ladi tí PDP gbé àṣíá fún mọ̀ láti díje gómìnà Ko si si ibi ti o lọ ti kiiṣe ari-ma-lee-lọ awo pada sẹyin ni wọn n woo nitori ẹwa rẹ.
Ipele àṣẹ ninu ijọ Satani: Ọmọ ijọ to f'orukọ silẹ Ọmọ ẹgbẹ to n ṣe deede (Oye Akọkọ) Ajẹ/Oṣo (Oye keji) Alufaa ọkunrin/obinrin (Oye kẹta) Magistra/Magister (Oye kẹrin) Maga/Magus(Oye Karun un) Ilana Ijọsin wọn: Oríṣun àwòrán, GEMMA PURKISS Àkọlé àwòrán, Ijọ naa ma n ṣe isin 'Black Masses', to si ma n jọ ere ori itage Irubọ wọn akọkọ jẹ iṣọtẹ si ẹsin Kristiẹni.
O ti to osu kan  bayii ti awon osise eleto ilera ti gunle iyanselodi yii , lati  beere fun irinse , ekunwo  ati ajemonu won.
Mama to jẹ ẹni ọdun mẹtadinlọgọrin di ẹni ti ọgọọrọ eeyan n sọ nipa rẹ lori ayelujara lẹyin ti sọ ọpọ ọrọ nipa ẹgbẹ agbabọọlu to yan laayo.
Minisita fun iroyin ati asa, ogbeni Lai Mohammed ti fokan awon omo orile ede Naijiria bale pe, ijoba orile ede yii ko ni kaare lati sa gbogbo ipa re  lori bi eto aabo yoo se  tubo fese mule si I.
Ayẹwọ awọn dokita lo ṣafihan pe, arabinrin Mumbi ni awọn eroja ara homoonu kan lara rẹ, eyi to mu ko ni irungbọn bi ọkunrin.
Nibi ọsẹ kan sẹyin ni awọn ajinigbe gbe eniyan mẹẹrin; oṣiṣẹ ileewosan Federal Medical Centre to wa nilu Ọwọ, ati olukọ ileewe gbogboniṣe Rufus Giwa.
Lara awọn ayipada ati iṣẹlẹ ti o ti mu waye ree: Iwọde tako ẹlẹyamẹya, iwa ipa awọn ọlọpaa ati ijẹgaba leni lori.
Wọn ni o kere tan, eniyan meje lo paya ti wọn si fo bọ silẹ nigba ti ina naa bẹrẹ si ni jọ.
Ninu atẹjade naa, ile ijọsin naa ni awọn ko ''faaye gba iru iwa buruku bayi ati pe awọn ko lọwọ si iru iwa ti Pasitọ Boniface hu yi'' Oríṣun àwòrán, @others Àkọlé àwòrán, Four Square sọrọ lori olukọ fasityi Eko pe.
ní Òkè-igbó àti ifẹ ̀ ẹ ́ tẹ ̀ dó , àwọn àdúgbò wọ ̀ nyí ló wà níbẹ ̀ : ilé badà , oríyangí , kúwólé , aṣípa-afolúmọdi , mọ ̀ ọrẹ ̀ , balágbè , fáró , Ìta-akíndé , odò-odi , Òkè-Ẹ ̀ ṣọ ̀ , Òkèèsodà , olú-Òjá àti Ọdọ ́ .
Lai jẹ bẹẹ, aarun coronavirus maa ran ni kiakia de awọn ipinlẹ ti ko tii de ti ko ba si iṣede kaakiri orilẹede Naijiria.
Mo bá gbọ́ ohùn kan láti ara àwọn ìwo tí ó wà lára pẹpẹ ìrúbọ wúrà tí ó wà níwájú Ọlọrun.
Bakan naa ni ilana ẹ pada soko wa labẹ ofin yii, eyi to n ṣe iwuri fun eto ọgbin aladanla, ki ounjẹ le pọ yanturu ni Naijiria.
” Ṣugbọn Asaheli kọ̀, kò yipada kúrò lẹ́yìn rẹ̀.
Àwọn Farisi bá ń bá ara wọn sọ pé, “Ẹ jókòó lásán ni!
Kí oore-ọ̀fẹ́ ati alaafia wà pẹlu yín láti ọ̀dọ̀ ẹni tí ó ti wà, tí ó ń bẹ, tí ó sì tún ń bọ̀ wá, ati láti ọ̀dọ̀ àwọn ẹ̀mí meje tí wọ́n wà níwájú ìtẹ́ rẹ̀; 
Odion Ighalo di ọmọ Naijria àkọ́kọ́ tí yóò gbá bọ́ọ̀lù fún ikọ̀ Manchester United
Ninu oko tí ẹ tí ń retí pé ẹ óo rí ogún òṣùnwọ̀n ọkà, mẹ́wàá péré ni ẹ rí; níbi tí ẹ tí ń retí pé ẹ óo rí aadọta ìgò ọtí, ogún péré ni ẹ rí níbẹ̀.
Awọn ẹgbẹ ajafẹtọ sọwipe ko din ni aadọjọ eeyan to ku lasiko hilahilo to waye lẹyin idibo apapọ lorilẹede naa lọdun to kọja.
Bẹẹ lawọn ajijagbara ba sa asala ti wọn si wa ibi isadi lọ si bareke awọn ọmọ ogun oju omi ni ibẹru bojo ba walẹ wọọ.
O ni gbogbo awọn ti awọn oniṣẹ ibi yii ji gbe nijọba ni lọkan lati gab pada sile.
Ìwọ ni o fi Uraya fún ogun pa; tí o jẹ́ kí àwọn Amoni pa á.
Wọ́n f'ẹ̀sùn ọkọ̀ jíjí kan Naira Marley; Ó ní òun ni Buhari yóò gbé ìjọba fún Òkété bórù mọ àwọn ọjọgbọ́n méji lọ́wọ́, UNIABUJA jù wọ́n síta Oluwo: Chanel Chin rẹwà gidigidi lóbìnrin, ṣùgbọ́n.
 , èkíni nínú àwọn odù wọ ̀ nyìí a máa jẹ ogbeyẹ ̀ kú .
Jese di ẹrù burẹdi ru kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ kan, ati waini tí wọ́n rọ sinu ìgò aláwọ pẹlu ọmọ ewúrẹ́ kan, ó kó wọn rán Dafidi sí Saulu.
Lara awọn ti ọrọ naa kan ni Bukọla Saraki, Yakubu Dogara, Ike Ekweremadu ati Lasun Yusuf.
laarin orile ede mejeeji naa yoo tun fi tubo tesiwaju, ni eyi ti orile ede
Ayé ò fẹ́ á kú fi ilé ayé sílẹ̀
‘Ajimobi ko yọju si ibi isinku naa ti wọn ṣe laarin ọsẹ kan, ti ko si ran ẹnikẹni wa si ibi isinku naa.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Maryam Sanda pe ẹjọ́ kòtẹ́milọ́rùn lóri ìdàjọ́ ikú ''Láìpẹ́, ìjọba ìpínlẹ̀ Eko yóò fi ǹkan tó dára míì rọ́pò Kẹ̀kẹ́ àti ọ̀kadà'' Ìhàlẹ̀ lásán ní NURTW ń ṣe torí pé a dínà owó tí wọn ń kó sápò - Ìjọba Ọyọ Kìí ṣe torí gbígba àmì ẹ̀yẹ ni ọmọ wa ṣe kú, a dúpẹ́ lọ́wọ́ ìjọba tẹ rántí rẹ̀ - Ẹbí Adadevoh Ibà Lassa wọ ìpínlẹ̀ Èkó!
Wọ́n ṣe gẹ́gẹ́ bí agbára wọn ti tó.
O rọ awọn obinrin ti wọn ti ni iru iriri bayii lati sọ sita ki awọn eeyan mii le kọgbọn lara wọn.
Àwọn òṣìṣẹ́ ilé iṣẹ́ ìròyìn NAN wọ́de lórí ìlànà iṣẹ́ tó mẹ́hẹ
Gbogbo ayé ni ó sì ń wá sọ́dọ̀ Josẹfu ní Ijipti tí wọ́n wá ra oúnjẹ, nítorí pé ìyàn náà mú gidigidi ní gbogbo ayé.
O fi kun un wi pe, ọkọ ti oun fi silẹ, Kevin irabor lo fẹ ẹlomiran lẹyin ti awọn ṣe igbeyawo, ti oun si ti bimọ meji fun un.
Bayii Naijiria ti pegede lati kopa ninu idije oni ikẹrindinlogun ko mẹsẹ o yọ.
Farao bi Jakọbu pé, “Ẹni ọdún mélòó ni ọ́ báyìí?
Ọlọ́run ni mo gbẹ́kẹ̀ mi lé!
Amaechi, lasiko to n kopa lori eto ori mohun-maworan kan nilu Eko lo sisọ loju ọrọ yii.
O ní gbogbo àwọn orisa Sango, Ògun, kéré si òòdua ti Ọba yoruba ń ṣoju fún, nítori náà àwọn Ọba atijọ ti wọ́n ń bọ òrìsà, ìgbà aimọ ni.
Wọ́n wó gbogbo àgọ́ àwọn tí ń sin mààlúù, wọ́n sì kó ọpọlọpọ aguntan ati ràkúnmí wọn pada sí Jerusalẹmu.
Ẹ ti gbin ẹ̀ṣẹ̀, ẹ sì ti ká aiṣododo, ẹ ti jẹ èso ẹ̀tàn.
austria-hungary fún ilẹ ̀ serbia ní àwọn nǹkan tó le mu ogun yìí wọlè , ṣùgbọ ́ n ilẹ ̀ serbia kò tẹ ̀ lé àwọn nǹkan wọ ̀ nyí .
Akinwumi Adesina bọ́ lọ́wọ́ ẹ̀ṣùn jẹgúdújẹrá tí wọ́n fi kan - AFDB Ìjọba Nàìjíríà kéde ìsinmi ọlọ́jọ́ méjì f'ọdún Iléyá Ìyá Barakat fi ẹ̀mí ìmoore hàn sí gbogbo àwọn tó nawọ́ síi lẹ́yìn ikú ọmọ rẹ̀ O ni yatọ si gbigba owo ijọba ti awọn eeyan kan lu ni ponpo pada, ijọba to wa lode yii tun n ṣeto iyipada ọkan fun awọn ọmọ Naijiria ki iwa ajẹbanu lee di ohun igbagbe.
Gbajúmọ̀ nínú wọn ni Kami Sid, Bebo láti Sindh, Nadra láti KPK, Anmol láti Agbègbè Sahiwal, Nayab láti Okara, Sunaina Khan (Oníjó ìbílẹ̀), Naghma àti Lucky (Akọrin Coke Studio), Laila Naz àti Neeli Rana.
Refidimu ni wọ́n ti gbéra wá sí aṣálẹ̀ Sinai.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Bristow Helicopters: Awakọ̀ òfurufú tó lé ní ọgọ́rùn ún pàdánù iṣẹ́ toríi Covid-19 16 Ọ̀wàrà 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 5 Ògún 2020 Oríṣun àwòrán, OTHERS Ileeṣẹ ọkọ ofurufu Bristow ti kọ iwe lọ gbe ile rẹ fun awakọ ofurufu to le ni ọgọrun lorilẹede Naijiria.
Ipẹjọ rẹ da lorii pe ẹjọ Sharia ti wọn da fun un ko tọna rara ko si ba ofin mu.
Ogunlọ́gọ̀ eniyan ni àwọn tí yóo pada wá síbí.
Oríṣun àwòrán, LASEMA Àkọlé àwòrán, Ijamba yi waye ni itosi ile igbafẹ Oriental Ọgbẹni Tiamiyu ṣalaye wipe ọkọ ayọkẹlẹ Lexus kan ṣa deede ya si opopona awọn eniyan miran ti o si kọlu ọkọ akero kan ti o ṣẹṣẹ n kuro ni ẹnu ibode Lekki.
- Ọọ̀ni Ife Géndé ọkùnrin ẹni ọdún 32 yìí sọ bí àwọn òbí rẹ̀ adití ṣe tọ́ ọ dàgbà Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí 3 sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
Ọlọrun ni ó sì sọ fún mi pé kí n má jáfara, má ṣe dojú ìjà kọ Ọlọrun, nítorí pé ó wà pẹlu mi; kí ó má ba à pa ọ́ run.
“Ọmọ ni ẹ jẹ́ fún OLUWA Ọlọrun yín, nítorí náà, ẹ kò gbọdọ̀ fi abẹ ya ara yín lára tabi kí ẹ fá irun yín níwájú nígbà tí ẹ bá ń ṣọ̀fọ̀ ẹni tí ó kú.
Irufẹ bẹẹ tun le dena arun jẹjẹrẹ, arun ọkan ati itọ ṣuga pẹlu awọn arun miran gbogbo.
- Ìjọba àpapọ̀ N-Power jẹ ọna ti ijọba n gba pese isẹ fun awọn ọdọ, labẹ ẹka ijọba to n ri si eto amuludun ati irọkun sapa awọn ara ilu.
Lẹhin igbéyàwó ibilẹ̀, wọn yio pin ẹrù yi (yàtọ̀ si ẹrù fún Iyàwó), si ọ̀nà meji lati kó apá kan àti apá keji fún Idilé Bàbá àti Ìyá Iyàwó.
O fi kun oro re pe,” O je akinkanju eniyan, besini Mgbolu fi ara re jin fun ise, ti o si fi apere rere sile ki o to jade laye”.
Aláàfin - BBC News Yorùbá BBC News, YorùbáFò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Alaafin Oyo: Àwọn onílù mí ló ń tú àṣírí ìkà èèyàn tó bá wọ ààfin mi - Aláàfin 18 Ògún 2020 Oríṣun àwòrán, Alaafin Oyo Alaafin ilu Oyo, Ọba Lamidi Olayiwola Adeyemi kẹta ti sọ pe, awọn onilu ni afin oun lo maa n ta oun lologbo ti ẹni ibi tabi ọdalẹ ba wọle tọ oun.
Agbẹjọro to n ṣoju ijọba ipinlẹ Oyo lori ẹjọ ọhun, Adeniyi Farintọ to ba BBC Yoruba sọrọ ṣalaye pe, agbẹjọro awọn alaga ko yọju sile ẹjọ lonii ọjọ Iṣẹgun.
Ṣugbọn ko si ikankan lara wọn to bimọ fun.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Obateru Akinruntan: Wíwá ohun tá jẹ títí láé ló gbé wa kúrò nílé Ife Ta lo ti fẹ gba arẹwa obinrin Gloria, iyawo Bamiloye ri?
Ọdun 1952 ni Olatunji bẹrẹ ifẹhọnuhan tirẹ ni awọn ọkọ igboro ni Guusu ilẹ Amerika.
bayii, mo wa pelu omo mi Zainab, bi mo se n ba yin soro yii ile ni a n lo.
Nkan bii aago kan abọ ọsan ọjọ aiku lawọn akẹkọ naa gunlẹ silu dapchi ninu ọkọ bọọsi marun, ti awọn ologun si kọwọrin pẹlu wọn.
Láti bi ọjọ́ méjì ní gbómisi-omi-òto tí n lọ láàrìn àgbààgbà méjì, ti wọ́n tún jẹ́ gbájúgbajà olóṣèlú ní orílẹ̀-èdè Nàìjìríà.
Gẹ́gẹ́ bi ìṣe wọ́n àwọn méjèèjì tún wọ ànkoo bii tọkọtiyàwò ti wọ́n sí fọ́n fóto wọ́n ka sórí ayelujara bi ina wẹ́dà.
to wa ni  Okposi Umuoghara(07), ni Ariwa ijoba
 lẹ ́ yìn ìgbà tí ó ti ṣẹ ́ gun wọ ̀ nyí , ó sọ ara rẹ ̀ di emperor ní 1804 .
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ibadan Rape: Àjọ ọlọ́pàá, Ìjọba ìpínlẹ̀ Ọyọ jẹ́jẹ̀ẹ́ láti ṣàwárí òòsà tó ń mu ẹ̀jẹ̀ nílùú Ìbàdàn 26 Sẹ́rẹ́ 2018 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 14 Òkùdu 2020 Àkọlé àwòrán, Àjọ ọlọ́pàá, Ìjọba ìpínlẹ̀ Ọyọ jẹ́jẹ̀ẹ́ láti ṣàwárí òòsà tó ń mu ẹ̀jẹ̀ nílùú Ìbàdàn Ile iṣẹ ọlọpaa ipinlẹ Ọyọ ti ṣe abẹwo si adugbo Idi Ori ni agbege Ọjọọ nijọba ibilẹ Akinyẹle niluu Ibadan, nibi ti awọn olubi ẹda kan ti ṣekupa Arabinrin ẹni ọdun mọkanlelogun, Grace Oshiagwu ninu ile to n gbe pẹluu awọn ẹbi rẹ l'ọsan ọjọ Abamẹta.
Ileeṣẹ ọlọpaa ni ọwọ awọn ti tẹ arakunrin ti o ni ọkọ agbepo to ṣokunfa ijamba ina to waye lori afara Ọtẹdọla nilu Eko.
Yóo san ẹ̀san ibi fún àwọn ọ̀tá mi;OLUWA, nítorí òtítọ́ rẹ, pa wọ́n run.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: 'Àwa ò tẹ́ pẹpẹ ǹkan táa ní sórí ẹ̀rọ̀ ayélujára' Kí lẹ ò mọ̀ nípa àwọn obinrin Yollywood yìí?
Lara rẹ ni eyi to gba ni orilẹ-ede Germany nibi ajọdun isẹ ọna ti ilu Berlin lọdun 1964 ati ami ẹyẹ to gba ni ajọdun isẹ ọna Commonwealth lọdun 1965 Ere tiata mẹrindinlogoji ni Duro Ladipọ kọ, to si se jade, nigba to kọ ere mẹwaa, to si ko awo ere mẹsan an sita lori ẹrọ giramofonu, to si se ere fiimu mẹrin Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, SS3 ní mo wà báyìí, mo sì ti gba àmì ẹ̀yẹ̀ púpò nílé-lóko gẹ́gẹ́ bí onílù - Ayansike Lara awọn osere tiata ti wọn jẹ akẹẹgbẹ Duro Ladipọ ni Kọla Ogunmọla, Ọla Rotimi, Herbert Ogunde, Ayox Arisekọla, Ojo Ladipọ, Moses Ọlaiya Adejumọ ( Baba Sala), Oyin Adejọbi, Isọla Ogunsọla ( I show pepper) ati bẹẹ bẹẹ lọ Duro Ladipọ ni ọpọ iyawo, to si tun bi ọmọ pupọ, amọ eyi to jẹ aayo ninu awọn iyawo rẹ ti gbogbo aye mọ ni Mama Abiọdun Duro Ladipọ, to maa n se ere Ọya, nigba ti Duro ba se Sango Oríṣun àwòrán, Yomi Duro Ladipo Ọjọ nla ni ọjọ Kọkanla, osu Kẹta, ọdun 1978 ti Duro Ladipọ mi kanlẹ, to si ki aye pe o digbose Gẹgẹ bii orisa Sango ti gbogbo eeyan mọ si, apẹẹrẹ Sango lo jẹyọ lọjọ ti Duro Ladipọ jade laye, nitori ojo nla, to mu ara lọwọ lo rọ lọjọ naa, ti ara si n sana gidigidi.
Amọṣa o, kii ṣe aṣuwọn rẹ nikan ni wọn gbẹsẹ le bi ko ṣe pẹlu ti aburo baba rẹ Ademọla Adeleke to n du ipo gomina labẹ aṣia ẹgbẹ oṣelu PDP nipinlẹ Ọṣun.
Ọdun ti o kọja ni baba rẹ ku.
US Election 2020: Nígbà wo laó mọ èsì ìdìbò àti pé ṣé ó ṣeé figagbága?
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Akomolede ati Asa lori BBC: Olùkọ́ Kikelomo Ogunboye tan ìmalẹ̀ sí ìwà olè ọ̀gá ọlọ́pàá Andrew lọ si ati ti girama Government College Maiduguri ni Bornu lọdun 1971 si odun 1975.
pe yoo tun ran ile-ejo mejeeji lọwọ lati fimọ kun imọ won.
Da òróró sí i, kí o sì fi turari sórí rẹ̀.
Nítorí oun tó kọ iwájú sẹ́nìkan, ẹ̀yìn ló kọ sẹ́lòmíì.
Ṣùgbọ́n bí odò yìí ti ṣe rìn tí ó ibẹ̀, àti bí ẹja inú rẹ̀ ti ṣe yàtọ̀ sí àwọn ẹja mìíràn, ọ̀ràn yìí ta òye gbogbo ènìyàn yọ.
Gomina Oyetola sọrọ yii di mimọ ninu atẹjade ti akọwe iroyin rẹ, Adeniyi Adesina fi lede.
Ọdún kan kọjá, nínú oṣù Èrèlé ọdún 2015, a gbé e re ilé ẹjọ́ a sì rán an ní ẹ̀wọ̀n ọdún márùn-ún fún “àgbékalẹ̀” ìyíde kiri ìfẹ̀hànnúhàn lábẹ́ òfin ìyíde kiri ìfẹ̀hànnúhàn ọdún 2013 tí kò fi àyè gba ìyíde láìgbàṣẹ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Nollywood: Àwọn òsèré tíátà Nàìjíríà tó jẹ́ ọmọ Yorùbá 21 Èbibi 2018 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 13 Owewe 2018 Oríṣun àwòrán, Wale Akorede Okunnu/Facebook Àkọlé àwòrán, Òsèré Tíátà Wale Akorede Okunnu Wale Akorede Okunnu A bí i ní ìlú Ibadan ìpínlẹ̀ Ọyọ ní ọjọ́ karùn-ún osù kọkànlá ọdún 1967 sùgbọ́n ọmọ bíbi ìlú Ogbmọsọ ní ìpínlẹ̀ Ọyọ ni .
Nígbà tí ó ṣe, àgbàdo yìí hù, bí iré ó dàgbà ó sì yọ ọmọ, ó yọ ọmọ méjì ńláńlá.
Mo nigbagbọ pe laipẹ yii o ri pe ọpọ awọn orileede miran ti ni ẹya Covid-19 tuntun yii,"" Marc Van Ranst to jẹ onimọ nipa itankalẹ aarun lati ile iwe Raga Institute for Medical Research ni Belgium lo sọ bẹ fun oniroyin."
” Dafidi bá rán oníṣẹ́ lọ kí i kú àṣẹ̀yìndè baba rẹ̀.
” Àmọ̀ràn yìí dá yánpọnyánrin sílẹ̀ ní orílẹ̀-èdè Nàìjíríà nítorí wípé Ọbásanjọ́ jẹ́ alátìlẹ́yìn àgbà fún Buhari gẹ́gẹ́ bí òǹdíje nínú ìbò ipò Ààrẹ ni sáà àkọ́kọ́ ní ọdún 2015.
Lẹ́yìn náà ni òpin yóo dé, lẹ́yìn tí ó bá ti dá ìjọba pada fún Ọlọrun Baba, tí ó sì ti pa gbogbo àṣẹ, ọlá ati agbára run.
 Àwon tí ó ń so èdè yìí tó egbèrún lónà igba ní Ìráànù ( iran ) àti Ìráàkì ( iraq ) pèlú òpòlopò àwon mìíràn tí wón tún ń so ó ní Ààrin gbùngbùn ìlà-òòrùn àgbáyé ( middle tast ) .
Ìpele ikọ̀ mẹrindinlogun Zimbabwe vs Algeria.
" Ẹwẹ, agbẹnusọ fun Abiola Ajimobi, Bolaji Tunji ti sọ ninu atẹjade kan pe kii ṣe pe awọn mọọmọ le igbakeji gomina pada nibi adura ọjọ kẹjọ ọhun, ṣugbọn o wa lasiko ti ko yẹ ni.
ipade rampe ohun, ogagun Dambazau tun lo sabewo si aafin Sarkin Katsina Gusau, oba
Àwọn ọmọ Israẹli tí wọ́n wà ninu ìlú náà jáde sí wọn, àwọn ará Ai sì wà ní agbede meji àwọn ọmọ Israẹli, àwọn kan wà ní ẹ̀gbẹ́ kinni, àwọn kan wà ní ẹ̀gbẹ́ keji.
Ó wí fún gbogbo wọn pé, “Báyìí ni OLUWA Ọlọrun Israẹli wí, ‘Nígbà laelae, òkè odò Yufurate ni àwọn baba yín ń gbé: Tẹra, baba Abrahamu ati Nahori.
Lára ilẹ̀ ẹ̀yà Efuraimu ni wọ́n ti pín àwọn ìlú ńláńlá fún àwọn ìdílé kan ninu àwọn ọmọ Kohati.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: ''Bí mo ṣe borí àrùn asétọ̀ rèé'' Ìfipábánilòpọ̀ tó ń gogò láwùjọ, ẹ̀yin aráàlú ló ń fàá"" Akẹ́kọ̀ọ́ mẹ́fà tó lu akẹẹgbẹ́ wọn ní fásitì FUTA dèrò ilé Àṣírí tú!"
Lẹ́yìn ọjọ́ mẹta Paulu pe àwọn aṣiwaju àwọn Juu jọ.
Eyi si n fa wahala laarin eeyan atawọn ẹranko lojojujmọ nibẹ.
Samuẹli dá a lóhùn pé, “N kò ní bá ọ pada lọ.
Nítorí pé bí o bá kọ̀, tí o kò jẹ́ kí àwọn eniyan òun lọ, ó ní òun yóo mú kí eṣú wọ ilẹ̀ rẹ lọ́la.
ri omo mi gba layo ati alafia.
yii lọjọBọ nibi apejẹ asalẹ to waye ni gbongan Banquet nile aare to wa niluu
Ọ̀dọ̀ àwọn tí ń ni wọ́n lára ni agbára kọ̀dí sí,kò sì sí ẹni tí yóo tu àwọn tí à ń ni lára ninu.
Olu ilu orilẹ-ede Welsh ni Sala n lọ lẹyin to bowọlu iwe adehun
Láti inú ẹ̀yà Dani, ẹgbaa mẹrinla ó lé ẹgbẹta ọkunrin (28,600) tí wọ́n dira ogun ni wọ́n wá.
Saulu wí fún Samuẹli pé, “Bẹ́ẹ̀ ni, mo ti dẹ́ṣẹ̀.
Ọba yóo jọ́sìn ní ẹnu ọ̀nà àbájáde, yóo sì jáde; ṣugbọn wọn kò ní ti ìlẹ̀kùn náà títí di ìrọ̀lẹ́.
Ọmọlúàbì yóò máa rántí àwọn ènìyàn rere tó ti jẹ́ orúkọ rẹ̀ síwájú, yóò sì máa gbìyànjú láti máa hùwà rere kí ó má baà ba orúkọ náà jẹ́.
Ọ ni bi ìṣẹ́ òun òṣì ti peleke láàrin àwọn ará ìlú ko ṣẹyin bí ìjọba Fayoṣe tí kùnà láti san owó oṣù àwọn oṣiṣẹ.
"Ìbàlòpọ̀ pẹ̀lú ọ̀rẹ́kùnrin kìí ṣe ìfẹ́, bẹ́ẹ̀ ni ìfẹ́ kọ́ ni ìbálòpọ̀ - Genevieve Nnaji Wo ọ̀rọ̀ tí Asiwaju Bola Tinubu fi síta lórí ìṣòro ètò àbò Nàìjíríà Mi ò to iṣẹ́ Regina Daniels rárá kí n tó fẹ́ ẹ láàrin ọ̀sẹ̀ mẹ́ta, mo sì tún le fẹ́ ìyàwó míì - Ned Nwoko Ninu ọrọ ọhun ni Nkechi ti sọ pe ""ọrọ ti mo fẹ kọ gun pupọ ṣugbọn mo kan fẹ sare sọ fun yin loju koju pe mummy mi ẹdakun ẹ jeburẹ."
Àwọn ilé iṣẹ́ tó jọ bi ẹni pe kò fi bẹ́ẹ̀ hàn síta ní Minisita fun eto ọrọ araalu, ajalu ati idagbasoke awujọ.
Demeteriu wá pe àpèjọ àwọn alágbẹ̀dẹ fadaka ati àwọn tí iṣẹ́ wọn fara jọra.
Àwọn wọnyi ni àwọn ọmọ tí wọ́n bí fún Jakọbu ní Padani-aramu.
    Ní ọjọ́ kejì ni ọkùnrin yìí mu aṣọ náà lọ.
A gbọdọ gba ọwọjọ ṣe ni.
Àwọn ẹranko bi Ẹfọ̀n, Erin, Kìnìún, Ẹkùn ti dínkù nígbàtí ẹranko bi Àgbánreré ti parẹ́ ni ilẹ̀ Yorùbá.
Jẹ́ kí ojú ọ̀nà wọn ṣóòkùn, kí ó sì máa yọ̀,kí angẹli OLUWA máa lépa wọn!
Nítorí náà, yára ranṣẹ lọ kó gbogbo àwọn ẹran rẹ tí wọ́n wà ninu pápá síbi ìpamọ́, nítorí pé yìnyín yóo rọ̀ sórí eniyan ati ẹranko tí ó bá wà ní pápá, tí wọn kò bá kó wọlé, gbogbo wọn ni yóo sì kú.
22 Àti pé kí o dúró ṣinṣin nínú pípa àwọn òfin mọ́ pẹ̀lú èyítí èmi ti pàṣẹ fún ọ; bí o bá sì ṣe èyí, kíyèsíi, mo fún ọ ní ìyè ayérayé, àní bí wọn tilẹ̀ pa ọ́.
Pneumonia in Nigeria: Ó kéré tán ọmọdé 142,000 sí 160,000 ní àìsàn otútú àyà ń pa lọ́dọọdún ní Nàìjíríà
Wọn gbe aboyun naa Kamini Chachi wa si ile iwosan to ti n ṣiṣẹ nigba ti o n rọbi.
EKSU: Fásitì ìpínlẹ̀ Ekiti dá òṣìṣẹ́ 355 padà sẹ́nu iṣẹ́
Ẹfẹ tóun yèyé ní àwọn ọmọ Kenya tun fí da esi pada fún-un lórí Twitter .
Kí o sì kó owó náà fún Aaroni ati àwọn ọmọ rẹ̀.
Lọpọlọpọ igba gan an ni wọn maa tun n halẹ mọ wa wipe ti a ko ba san owo yii, orukọ wa o ni jade.
Ó sọ fún wọn pé, “Ó wà ní àkọsílẹ̀ pé, ‘Ilé adura ni ilé mi jẹ́,’ ṣugbọn ẹ̀yin ti sọ ọ́ di ibi tí àwọn ọlọ́ṣà ń sápamọ́ sí.
Oríṣun àwòrán, Others 5) Lekan Babalola: Ọjọ Kẹẹdogun, oṣu Karun un, ọdun 1960 ni Olalekan Babalola de ile aye nilu Eko, kekere si lo ti n lu ilu Konga ni ìjọ Kerubu ati Serafu tawọn obi rẹ n lọ.
Oun naa ni Aarẹ akọkọ fun ẹgbẹ naa.
Ipele arun yi a ma ran to ida mẹrinla ninu ida ọgọrun eeyan ti a ba fi iroyin ta ri gba lati China wo.
 wọ ́ n sọ pápá ìṣeré kan ní orúkọ rẹ ̀ ní ìlú adó-Èkìtì ní ìrántí rẹ ̀ .
Ọkan lara awọn agba ọjẹ sinima Yoruba ni Motunrayọ Adeoye, owurọ ọjọ kinni, oṣu kẹfa ọdun 2018 lo faye silẹ lẹyin aisan ọgbẹ inu.
Kí OLUWA bukun ọ láti Sioni!
Mo wí lánà-án pẹ̀lú bi èmi àti ìránṣẹ́ ọba yi gbogbo àgbègbè lọ tí à ń wá àwọn ènìyàn pàtàkì kiri, mo sì tún wi pẹ̀lú bí a ti ṣe rí abàmì ẹ̀dá kan mú bọ̀ orúkọ ẹni ti ń jẹ́ Ìbẹ̀ǹbẹ́-olókùnrùn ti ó jẹ́ ẹni ti o le jẹun júlọ lórí ilẹ̀ ayé.
Israel Adebajo: Ìlúmọ̀ọ́ká oníṣòwò tó fi òkò Stationery Stores pa ẹyẹ púpọ̀ O tun lọ si ile iwe girama ti ijọba Maiha Government Secondary school to ti ṣe idanwo iwe mẹwaa lọdun 2012.
Lẹnu ọsẹ meloo kan sẹyin, niṣe ni o wa laarin ida aadọta akojọ ero yii to si fi ami ayo mẹwa le waju lawọn asiko kan.
"ìyá ẹgbẹ́ àwọn eléwé ọmọ̀ - BBC News Yorùbá BBC News, YorùbáFò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Lassa Fever: Ṣe ẹ rí eku tí ẹ̀ ń pè yẹn, oúnjẹ tó dára ni - ìyá ẹgbẹ́ àwọn eléwé ọmọ̀ 18 Èrèlè 2020 Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Mo lè jẹ eku mẹ́wàá lọ́jọ́ kan' ""Ṣé ẹ rí ìwádìí tí wọn sọ pé lára eku ni wọ́n ti rí Lassa Fever yẹn, wọn ò tíí mọ ibi tí wọ́n ń lọ""."
Wèrédìran rọ̀ mi ki n jẹun ṣùgbọ́n n kò jẹun, n ko le jẹun ìbájẹ́ ilé Òmùgọ́parapọ̀.
Jesu sọ fún un pé, “O káre, Simoni, ọmọ Jona, nítorí kì í ṣe eniyan ni ó fi èyí hàn ọ́ bíkòṣe Baba mi tí ń bẹ lọ́run.
Pásítọ̀ gún ìyàwó rẹ̀ lọ́bẹ nínú ṣọ́ọ̀ṣì, ló bá tì í bọ ara rẹ̀ náà níkùn
24 Kọ́ sí orí àpáta mi, èyí tí ṣe ìhìnrere mi.
Niwọn igba to jẹ pe ole kii wa, bikose lati jale, lati pa ati lati parun, awọn adigunjale yii se akẹkọ meji lese, ko to di pe wọn na papa bora.
Ile igbimo asoju-asofin niluu Abuja ti fagile iwole won to ye ki o waye
Ó fẹsẹ̀ walẹ̀ ní àfonífojì,ó yọ̀ ninu agbára rẹ̀,ó sì jáde lọ sí ojú ogun.
ogunlogo eniyan pelu iye owo kekere ti won  n ri , ti a ba fiwe awon ijoba ti o ti wa tele
Ǹjẹ́ omi dídùn ati omi kíkorò lè ti inú orísun omi kan náà jáde?
Bí Zainab ṣe dèrò ẹ̀wọ̀n Saudi lórí ẹ̀sùn ògùn olóró tí kò mọ̀ Ìjọ̀ba Saudi ti tú Zainab tí wọ́n fẹ̀sùn òògùn olóró kàn sílẹ̀ ‘Bí ẹ se gba Zainab sílẹ̀, ẹ gba Leah Sharibu lọ́wọ́ Boko Haram’ Ọgbọnjọ oṣu Kẹrin ni o gba ominira kuro ni ẹwọn lẹyin ti ijọba Naijiria da si ọ̀rọ̀ naa.
Ìtan ẹya Hausa kò pe, lai si ọrọ Ọbabinrin Daurama ninu rẹ.
Ẹ wò ó, àwọn alágbára ń kígbe lóde,àwọn òjíṣẹ́ alaafia ń sọkún tẹ̀dùntẹ̀dùn.
Lagos building collapse: Ìjọba ìpínlẹ̀ Èkó bẹ̀rẹ̀ ilé wíwó ní Lagos Island
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Maina dákú fún ọ̀pọ̀ ìṣẹ́jú, iléejọ́ sáré so ìjókòó rọ̀ Ọlọ́pàá tún yìnbọn pa awakọ̀ Márúwá, ìwọ́de gba Portharcourt kan Wo ìròyìn tó pọ̀ jùlọ táwọn èèyàn ń wá ní Google lọ́dún 2020 Obasanjo àti Gani Adams tẹ́ mi pẹ̀lú bí wọn ṣe tahùn síra wọn - Adebanjo Buhari le sọ ipò ààrẹ́ nù tí kò bá yọjú sáwọn aṣòfin - Amòfin Ẹgbẹ́ òṣèlú alátakò takú láti gba èsì ìbò ààrẹ ní Ghana Ọ̀pọ̀ nkan tó n ṣẹlẹ̀ kò jẹ́ kí n gbàgbọ́ pé Naijiria wà ní abẹ́ ìdarí ẹnikẹ́ni - Wole Soyinka Ọmọ ẹgbẹ́ òkùnkùn ṣoro ní Ijebu Ode, ọ̀pọ̀ ẹ̀mí sọnù O ṣalaye pe, Gomina Seyi Makinde ti pasẹ fun awọn alaṣẹ ikọ naa lati ṣe eto gbogbo nipa riri daju pe, eto to fun awọn oṣiṣẹ ikọ Amotekun lati gba owo oṣu wọn, ki ọdun Keresimesi to waye.
Ondo State Election result 2020: Bí èsì ìdìbò gómìnà ìpínlẹ̀ Ondo ṣe ń jáde rèé.
Nítorí náà, ọba pàṣẹ pé kí wọ́n pe àwọn pidánpidán, ati àwọn aláfọ̀ṣẹ, àwọn oṣó ati àwọn ará Kalidea jọ, kí wọ́n wá rọ́ àlá òun fún òun.
Awọn mejeeji si ti ni awọn ko jẹbi awọn ẹsun yii rara.
Ọmọbinrin naa to wa ni ileẹkọ fasiti bayii ṣalaye wipe, ati igba ti oun ti wa ni ọmọ ọdun mẹrin ni baba iya oun naa, to jẹ eniyan kan pataki lawujọ, ti bẹrẹ si ni ba oun lo pọ.
Adajọ Okon Abang da ẹjọ naa lọjọ iṣẹgun ọsẹ lori ẹsun siṣe owo maku-maku ati yiyi owo da si tir ti gbogbo rẹ to irinwo miliọnu naira.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Habits that damage brain: Wo àwọn ìṣesí ojoojúmọ́ mẹ́wàá tó le ṣàkóbá fún ọpọlọ rẹ 16 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àwọn ìṣesí mẹwàá tó lè ṣakoba fún ọpọlọ wà ni a n gbe yẹwo ni oni.
Arteta ko ṣai gboriyin fawọn ọmọ ẹgbẹ agbabọọlu Arsenal yoku, o ni gbogbo wọn patapata lo ṣe gudugudu meje yaya mẹfa bi wọn ti fẹyin Liverpool gbalẹ.
Ronke lo n fi ika hanu pe, oun polongo ibo fawọn oloselu Naijiria lasiko ibo gbogbo gboo to kọja.
Yóo fi ajọ̀ ìparun jọ àwọn orílẹ̀-èdè,yóo sì fi ìjánu tí ń múni ṣìnà bọ àwọn eniyan lẹ́nu.
Biodun Fatoyinbo fi ipò sílẹ̀ lorí ẹ̀sùn ìfipábánilòpọ̀ COZA: Mi ò fípá bá obìrin lò pọ̀ rí láyé mi - Pásítọ̀ Fatoyinbo Ìjọ Satani dá MI lóhùn lórí ọ̀rọ̀ Fatoyinbo CAN kò rán ẹnikẹ́ni lọ ṣọ́ọ̀ṣì COZA, iṣẹ́ ara wọn ní wọ́n lọ jẹ́ -Samson Ayokunle O sọ ninu ifọrọweró naa pe: olusọ agutan Biodun Fatoyinbo kọ lati yọju si ibi iwadii ti ajọ naa gbe kalẹ, bi o tilẹ jẹ pe, Busọla Dakolo ti yọju nitirẹ.
O fi kun ọrọ rẹ pe, ofin to de ọja tita loju popo naa lo de agbo tita loju popo nipinlẹ Eko.
Bí mo ti n lọ ti mo fẹ́ wọlé, se ni mo rí ti ògiri ẹnu ọ̀nà ní apá ọ̀tún àti apá òsì súnmọ̀ ara wọn, tí wọ́n pade sinsin tí kò sì sí ojú ọ̀nà mọ́, mo bá padà, mo lọ dúró.
Filipi ati Batolomiu, Tomasi ati Matiu agbowó-odè, Jakọbu ọmọ Alfeu ati Tadiu.
Mo lòdì sí àwọn wolii tí wọn ń sọ ọ̀rọ̀ ti ara wọn, tí wọn ń sọ pé èmi OLUWA ni mo sọ bẹ́ẹ̀.
Ẹsùn ìpànìyàn ni wọn fi kan agbẹjọrò ọmọ ọdun mejidinlaadọta ọhún, ni eyi to ṣe lodi si ofin ilẹ yii.
Bakan naa ni wọn ni ile nigba naa, lodi si rira awọn ọkọ akero yii.
Ọjọ kẹfa oṣu kẹta ni ileẹjọ kọkọ paṣẹ pe ki Victor Giadom maa ṣe ojuṣe gẹgẹ bi alaga ẹgbẹ oṣelu APC.
Wọ́n ní, “Èso tí o fẹ́ràn kò sí mọ́, gbogbo ìgbé-ayé fàájì ati ti ìdẹ̀ra ti bọ́ lọ́wọ́ rẹ, o kò tún ní rí irú rẹ̀ mọ́.
Àkọlé àwòrán, Aworan afinimọna ìlú Ijegun Bakan naa wọn ni awọn ará Ijegun kọ́ ló ń bẹ́ ọ̀pá epo ní Ijegun, ita ni wọn ti n wa nitori naa wọn ke gbajare si ijọba pe ''o ti sú awọn, kí ìjọba wá gbà wọ́n!
'Báyìí la ṣe rìn ín láti pápákọ̀ òfurufú Abuja sí Eko bí ìrìnà òfurufú abẹ́lé ṣe bẹ̀rẹ̀' Ìṣòro mi ni pé mo tètè ṣe tàn, ṣùgbọ́n ó wù mí kí n ní ìbálòpọ̀ síi Ààrùn Coronavirus tún ti ran ènìyàn 664 l'órílẹ̀-èdè Nàìjíríà Ayé le!
Wọ́n ń gun orí ilé wọlé,wọ́n gba ojú fèrèsé bẹ́ sinu ọ̀dẹ̀dẹ̀ bí olè.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù BBC Debates: Àwòrán tí ẹ kò rò níbi ìpàdé ìfọ̀rọ̀wérọ̀ BBC Yorùbá l'Eko 27 Sẹ́rẹ́ 2019 Ó ṣeé ṣe kí ẹ má fọkàn síi pé àwọn ǹkankan wáyé níbi ìpàdé ìfọ̀rọ̀wérọ̀ náà.
Schools Resumption: Ohun tó yẹ kí o mọ̀ b'áwọn akẹ́kọ̀ọ́ ṣé fẹ́ wọlé padà ní Ogun,Èkó àtàwọn ìpínlẹ̀ míì
Ìdí tí ẹ kò fi gbọ́ ni èyí, nítorí ẹ kì í ṣe ẹni Ọlọrun.
Oríṣun àwòrán, Facebook/Nairobi Crime Free Àkọlé àwòrán, Oju opo ẹgbẹ́ naa nibi ti wọn ti n ṣe ayẹwo fun awọn ọmọ ẹgbẹ́ tuntun Awọn olugbe ilu Kayole sọ pe, oriṣiriṣi ẹgbẹ naa lo wa lori Facebook, ti wọn si maa n fi awọn aworan to banilọkan jẹ sibẹ lojoojumọ.
 Àjọ Ìlera Àgbayé lápapọ ̀ pé ní 2012 , àwọn ìṣẹlẹ ̀ 207 mílíónù ibà ni ó wáyé .
EFCC: Ibrahim Magu ní ìwá ìbàjẹ́ ló fa Coronavirus
ASUU ní ìjọba àpapọ̀ ni kò fẹ́ kí ìyanṣẹ́lódì àwọn o pari
Oríṣun àwòrán, Twitter/Dabiri-Erewa Abike Dabiri-Erewa ni arabinrin Peace Busari pada sile pẹlu awọn mọkandinlọgbọn miran ti wọn wa ni oko ẹru ni Lebanon naa.
Ṣugbọn kò sí ohun tí n kò mọ̀ nípa rẹ,mo mọ àtijókòó rẹ, àtijáde rẹati àtiwọlé rẹ, ati bí o ti ń ta kò mí.
Omo-odun marunlelogbon ohun ni ami ayo marun un pere ninu ifesewonse mokandinlogun ti o gba ni saa yii lati gba ife eye kejo idije Bundesliga.
Wọn óo wá mọ̀ nígbà náà pé èmi ni OLUWA nígbà tí mo bá sọ ilẹ̀ náà di ahoro ati aṣálẹ̀, nítorí gbogbo ìwà ìríra tí wọ́n ti hù.
Okechukwu ni “oun faramo ohun ti Ohaneze so ,nitori pe adura wa ni pe, ki orile ede yii maa se ojuse re”.
Ni bayii, o je ohun iyalenu ti o si ru ni loju pelu, idi ti iru eyi fi waye, bee si ni o seese ki o ro mo bi awon oloselu se n fi egbe won kookan sile lo sinu egbe miiran.
Ó ga ní ìwọ̀n igbọnwọ mẹfa ati ìbú àtẹ́lẹwọ́ kan.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Igbeyawo: Idapọ ọgbọn ọdun fori sanpọn 15 Ẹrẹ̀nà 2018 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Bi igbeyawo se ntuka lemọlemọ lode oni ti di ailasọ lọrun paaka, apero fawọn ọmọ eriwo.
musulumi lasiko Ummah losu mimọ yii.
Ǹkan tí a mọ̀ nípa kọ́lẹ̀jì olùdìbò tó ń fìdì ẹni ti yóò jẹ ààrẹ ilẹ̀ Amérika múlẹ̀ EFCC bẹ̀rẹ̀ ìwádìí lórí ẹ̀sùn ìwà jẹgúdújẹrá tí wọ́n fi kan Fowler tó jẹ́ Alága iléeṣẹ́ FIRS tẹ́lẹ̀ ''Àjọ NERC ti fún Disco láṣẹ láti padà sí owó tàríìfù tuntun iná mọ̀nàmọ́ná'' Kíní ọ̀nà àbáyọ sí ìjàmbá ọkọ̀ tó ń wáyé lemọ́lemọ́ ní Ọjà Akungba,ní Ondo?
Wọ́n jí ọmọ yìí gbé láti máa fi tọrọ bárà l'Eko Lẹ́yìn igbe Atiku, Ààrẹ Ilé Ẹjọ́ kòtẹ́milọ́rùn yọra rẹ̀ nínú ìgbẹ́jọ́ èsì ìdìbò ààrẹ 'Ẹ̀yin olùgbé ìlú Eko, kò séwu fún afárá Third Mainland' Ọ̀rọ̀ ń bọ́ lóríi fídíò Codeine Facebook fẹ da owo ori ẹrọ kọmputa silẹ eyi ti ko ni ga ju ara lọ ti yoo tun pese abo to peye fun awọn ina isanwo lori ayelujara lai naani boya ẹni bẹẹ ni aṣuwọn ifowopamọsi ni banki tabi ko ni.
Bí OLUWA tí ń bẹ láàyè, ẹyọ irun orí rẹ̀ kan kò ní bọ́ sílẹ̀.
Ni osu kẹwaa, ọdun 2019 lawọn mejeeji ṣe eto mọmi n mọ ọ ki wọn to ṣe igbeyawo bonkẹlẹ ki o to jade laye.
Ìwà mi kò yé èmi alára; nítorí kì í ṣe àwọn nǹkan tí mo bá fẹ́ ṣe ni mò ń ṣe, àwọn nǹkan tí mo kórìíra gan-an ni mò ń ṣe.
Oriṣiriṣi ere idaraya Kegel to wa Oriṣiriṣi ere idaraya yii lo wa - o le ṣe e lori iduro, ti o ba joko, tabi ki o sun si ilẹ Eyi to wọpọ ju ni ki o sun silẹ, ki o si kọ oju si oke.
Ọpọ eeyan ni iru isẹ bayi maa n ba lẹru, eyi to ni se pẹlu fifi ọwọ kan oku ati sise akọsilẹ nipa ohun to n waye pẹlu oku to n jẹra ni isẹju isẹju Àkọlé àwòrán, Awọn onisẹ iwadi kan n fajuro lori agbekalẹ oko oku Bi o tilẹ jẹ pe anfaani nla ni yoo ba iran ọmọniyan lọjọ iwaju lati ipasẹ isẹ iwadi yii, amọ ibeere ton gba ọkan awọn eeyan kan ni pe, se o yẹ ki oku maa rare nitori isẹ iwadi bi eyi?
Ẹ sọra lati farakan ẹni ti o ma ni aisan iba ti kosi tete lọ.
O tun je Orunta tilu Ifewara ni 1974 ati Obaloro tilu Ado Ekiti ni 1977 Bakan naa, lẹyin ọdun marun un to ti jade laye, ijọba apapọ tun fun un ni ami ẹyẹ CON (Commander of the Order of the Niger).
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Code of Conduct Tribunal: Adájọ́ Àgbà Nàíjíríà, Walter Onnoghen ní ẹjọ́ láti rò 29 Ẹrẹ̀nà 2019 Oríṣun àwòrán, Google Àkọlé àwòrán, Ìjọba àpapọ̀ fi ẹ̀sùn ìwà ìbàjẹ́ àti pípa irọ́ lóri ohun ìnì Walter Onnoghen láti ìgbà tí ó jẹ Adájọ́ Agba lórílẹ̀èdè Naijria.
 síbẹ ̀ síbẹ ̀ , wọ ́ n ṣì ń ráyẹ ̀ gbọ ́ ti ẹ ̀ sìn ìbílẹ ̀ yorùbá , bí ọ ́ tilẹ ̀ jẹ ́ pẹ ́ ó ní àwọn àdúgbò tí èyí múmú láyà wọn jù .
ti o wa lọkan abenugan ile igbimo asoju ni lati mu awon ileri ti o se sẹ.
Ẹwẹ, Dorathy ti jẹ ẹbun owo to ku diẹ ko to miliọnu mẹrin Naira, N3,926,000.
Kìnnìún ọba ẹranko bínú gidigidi nítorí ìbànújẹ́ ní ó jẹ́ fún wọn láti rí ènìyàn tí í ṣe ọ̀tá ẹranko inú igbó láàrin wọn.
Ṣùgbọ́n á ṣòro fún Obama nítorí pé àwọn olóṣèlú míràn gbàgbọ́ pé ẹ̀tọ́ àwọn ọmọ Amẹrika ni láti ní ìbọn.
ó tó àkókò wàyí, ẹ ṣe é parí.
Bakan naa, aare ajo NFF, PinnickAmaju ati okan lara agbaboolu teleri fun iko Super Eagles, Segun Odegbami, ro iko ohun lati kopa ti o joju ninu ifesewonse naa, bee si ni ki won ni afojusun pe won yoo jawe olubori, papaajulo fun awon omo Naijiria.
Nibayii ti Naijiria wa n sami ajọdun ọgọta ọdun to gba ominira, ọpọ eeyan n beere pe, se Naijiria yoo se ajọdun ọgọrun ọdun gẹgẹ bii orilẹede kan soso bi?
”Ijoba ti gbe igbimo oluwadii kan jade.
    Nígbà tí ó pẹ́ tí ọba tuntun yìí ti jẹ, ó bẹ̀rẹ̀ sí í lọ sí ìgbìmọ̀, ìgbà tí o sì di ọjọ́ kan tí mo lọ kì i, ó wí fún mi pé òun ń fẹ́ kí n wá wo bí wọn ti ń ṣe Ìgbìmọ̀ ìlú òun.
 Aare Muhammadu Buhari lo n dari eto ipade naa.
Kini ka ti pe ifarapa gbogbo igba yii?
Bí igi ápù ti rí láàrin àwọn igi igbó,ni olùfẹ́ mí rí láàrin àwọn ọmọkunrin.
Ẹ kò rí i pé gbogbo eniyan ni wọ́n ti tẹ̀lé e tán!
Ẹ̀yinná tí ń jó ń jáde,láti inú ìmọ́lẹ̀ tí ó wà níwájú rẹ̀.
“Ṣe ẹ mọ gẹgẹ bi awa ‘transporters’, ọna gan-an lounjẹ wa, ki ijọba gbiyanju ati ba wa tubọ ṣe awọn ọna to ti bajẹ, ki iṣẹ wa le maa lọ daradara.
Ati wi pe lọpọ igba wọn maa n lo ọgbọn ọtọtọ bii ọrọ awo ti yoo ṣoro lati mọ loju ẹsẹ nibi kara-kata kaadi idibo naa.
Ni ipari “Mo kẹdun pelu ebi, ara, ati obi i awon agunbaniro yii, ti o fi mo awon to n sakoso eto NYSC ati apapo ijọba ipinle Taraba, nibi ti isele buruku naa ti waye, ati ipinle  Edo, Enugu, Delta ati Imo ti n se ilu kookan ti awon agunbaniro naa ti wa ,”.
Wọ́n ní ọpọlọpọ ìdánwò nípa ìpọ́njú.
Ó ní, “Àwọn ọrọ̀ ilẹ̀ Ijipti ati àwọn ẹrù ilẹ̀ Etiopia,ati àwọn ọkunrin Seba tí wọn ṣígbọnlẹ̀,wọn óo tọ̀ ọ́ wá, wọn óo di tìrẹ,wọn óo sì máa tẹ̀lé ọ.
Eyi ṣeeṣe ko ribẹ nitori bi eto aabo ṣe ri l'orilẹede naa bayi, latari bi aarẹ orilẹede naa nigba kan, Mohammed Morsi ṣe ku nile ẹjọ lasiko to n jẹjọ, ti idije naa si n waye lẹyin ọjọ diẹ ti eyi waye.
Kete ti ẹni to n ṣe ọjọ ibi ri awọn ọlọpaa Hisbah lo fo iganna salọ'' O tun sọ pe ''wọn ti ṣe waasi fun wa, a si ti ki irun Rakaah ogoji lati igba ti wọn ti mu wa.
Nigba to n fesi si pe awọn kọlọrọsi ẹda kan n fi arun naa kowo sapo ara wọn, paapaa nipa awọn irinṣẹ idaabo ara ẹni, Ghebreyesus ni ohun to buru gba ni.
Oríṣun àwòrán, Osatuyi Àkọlé àwòrán, Fuel Price: Ẹ̀dínwó epo bẹntírò ti NNPC kede kò kan ará ilú Iroyin ni wamuwamu ni awọn ọmọ ologun, awọn oṣiṣẹ abo ararẹni labo ilu, NSCDC ati ajọ to n risi igboke gbodo ọkọ, FRSC ro lẹnu ibode ọhun.
Iwe ofin eto idibo Naijiria ti ọdun 2010 (Electoral Act 2010), sọ fun wa ni abala ọgọje (140) ni abẹ ipele kẹta wipe ti ile ẹjọ ba ti sọ wipe ẹni to wa lori aleefa kọ́ ni ojúlowo gomina nitori wipe ko ni iye ibo to pọ́ju, ile ẹjọ naa gbọdọ kede orukọ ẹni to ni idibo to pọju gẹgẹ bii gomina.
Nehemaya bá sọ fún wọn pé, “Ẹ máa lọ, ẹ jẹ ẹran ọlọ́ràá, ẹ mu waini dídùn, kí ẹ sì fi oúnjẹ ranṣẹ sí àwọn tí wọn kò bá ní, nítorí pé ọjọ́ mímọ́ ni ọjọ́ òní jẹ́ fún OLUWA wa, ẹ má sì banújẹ́, nítorí pé ayọ̀ OLUWA ni agbára yín.
Eleyi to sọ ọ d'ofin fun awọn ile iwe giga ni ilu Eko lati maa gba kirẹditi ninu esi idanwo Yoruba gẹgẹ bi ọkan lara awọn kirẹditi marun ti awọn akẹẹkọ nilo lati wọ ile-iwe giga.
Obinrin ni ògúná gbongbo ni oníṣòwò òkèèrè, eyi jẹ ki obinrin lè ni ọrọ̀ àti lati lè gba oyè ‘Ìyálóde’.
OLUWA dá gbogbo àwọn tí ó fẹ́ ẹ sí,ṣugbọn yóo pa gbogbo àwọn eniyan burúkú run.
ṣugbọn ẹni tí kò bá rí mi, ó pa ara rẹ̀ lára,gbogbo àwọn tí wọ́n kórìíra mi, ikú ni wọ́n fẹ́ràn.
Ọ̀gbẹ́ni Vincent Jack, tó jẹ́ ọ̀gá àgbà àjọ ẹ̀ṣọ́ aláàbò ojúupópó (FRSC) ní ìpínlẹ̀ Òndó ti jáde láyé.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Kìí ṣe ọmọbìnrin nìkan ni Ọlọ́run pàṣẹ fún láti pa ìbálé mọ́ Àgbáríjọ àwọn nọ́ọ̀sì fẹ́ gbé Olamide Baddo lọ sílé ẹjọ́ fún ìbanilórúkọjẹ́ Oríṣun àwòrán, @Olamide/Instagram/others Ẹgbẹ awọn nọọsi l'orilẹ-ede Naijiria ti koro oju si fidio orin ti gbajugbaja olorin takasufe, Olamide Adedeji, ti awọn eeyan tun mọ si Baddo, gbe sita ninu eyi to ti fihan pe awọn oṣiṣẹ olutọju alaisan maa n ṣere ifẹ pẹlu awọn alaisan ti wọn n tọju.
"Ṣé lóòtọ́ ni ọ̀gá ""pension"" tẹ́lẹ̀, Abdulrasheed Maina ra ilé sí Abuja, Dubai àti Amẹrika?"
Bakan naa ni wọn tun ke si ajọ ilanilọyẹ lorilẹede Naijiria, NOA lati polongo faraalu ki wọn si rọọ ko-ko-ko bi ifa aditi fun awọn eniyan wipe ara awọn banki sogundogoji ni idokoowo naa jẹ.
Trump tun so pe “A o ni opolopo aarẹ, ti won yoo jẹ anfaani yii.
OLUWA bá wí fún Mose pé, “Yóo ti pẹ́ tó, tí ẹ óo fi kọ̀ láti pa àṣẹ ati òfin mi mọ́.
Alufaa yóo fì wọ́n gẹ́gẹ́ bí ẹbọ fífì níwájú OLUWA, pẹlu burẹdi tí ẹ fi àkọ́so ọkà ṣe, ati àgbò meji náà, wọn yóo jẹ́ ọrẹ mímọ́ fún OLUWA, tí a óo yà sọ́tọ̀ fún àwọn alufaa.
Àwọn eniyan rẹ̀ gbọ́ pé ó wà níbẹ̀, gbogbo wọn bá wá rọ̀gbà yí i ká.
"Akori apero ọhun ni ""Next Level Work for people"" Ninu ọrọ tirẹ, Okechukwu Enelamah to jẹ minisita fun idaleeṣẹ silẹ, karakata ati idokoowo ni ijsba ti gbe eto kalẹ fun tita awọn ohun elo ti wọn ba ṣe lorilẹede Naijiria si oke okun eyi to pe ni MINE."
O tun rọ awon ọdọ lati ni ifọkansin pẹlu igbiyanju nipa ọjọ ọla wọn.
Ó ti ra ọkàn mi pada kúrò lọ́wọ́ isà òkú,mo sì wà láàyè.
Aare Muhammadu Buhari kedun pelu awon eniyan ti o fara kaasa ibugbamu gaasi, eyi ti o waye nipinle Kaduna, ila oorun orile-ede Naijiria.
Dokita Kayode Samuel Adebayo to jẹ onimọ nipa ile ọmọ obinrin ninlu Eko sọ fun BBC pe 'uterus didelphys' ko fi bẹ wọpọ ni Naijiria.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Megabite: Ilé-ìwé ni mo ti bẹ̀rẹ̀ orin kíkọ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Isẹ́ Tíátà tí mò ń se ti tó mi jẹun' Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fọ́nrán ohùn, Ọ̀gá Bello: Ikú Aisha Abimbọla ká wa lára Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Nígbà tí Adéforítì yọ sii ní ààfin rẹ̀, ṣe ni Èṣù ta gìrì bí o sì ti ń mu u kiri ọkàn rẹ̀ kò balẹ̀ rárá, bí igi kan bá dá, ayà èṣù á já, bí ẹnìkan bá fi ẹsẹ̀ kọ, àyà Èṣù ń là gààrà, ọkàn rẹ̀ kò balẹ̀ rárá, hílà hílo ni Èṣù ń bá kiri.
Lẹ́yìn tí gbogbo wọn ti gun òkè odò tan, àwọn alufaa tí wọ́n gbé Àpótí Majẹmu OLUWA gòkè odò tẹ̀lé wọn, wọ́n sì rékọjá lọ siwaju wọn.
"Nígbà ti wọ́n de sọ́ọ̀bu ti wọ́n ti ń ta fóònù, wọ́n ji ọ̀pọ̀ fóònu, ìgbà náà ni Iphone méji jábọ́ ni ẹ̀gbẹ́ ibi ti mo dúró sí, mo kó méjèèjì pamọ́ sábẹ́ aṣọ mi, mo si lọlé.
 moller-maersk group ní jìbìtì owó rọ ̀ gùrọ ́ gù mílíọnù dọ ́ là .
“Bí mo ti wà láàyè, n óo pa yín run.
Lójú ìran, mo rí agbọ̀n èso ìgbà ẹ̀ẹ̀rùn kan.
Awọn ara agbeegbe Ezeukwu ni ipinlẹ Abia wa kesi ijọba lati ran awn lọwọ fun ipese omi mimọ to ṣe e mu ni agbeegbe naa.
Bákannáà ni o tún ṣàlàyé rẹ̀ pé onírúurú ohun ìjà olóró ni ọwọ́ wọn tún bà.
Lasiko gbogbo ipade adura to ba waye lẹ o ti ri awn to n rin yika lati ba a yin ko gbogbo ike omi ati ti ẹlẹrindodo ti ẹ ba mu ko da ẹ lee ma nilo lati dide laye yin lọ ju u nu bẹẹ ba duro diẹ.
Mo rán àwọn arakunrin sí yín, kí ọwọ́ tí a fi ń sọ̀yà nípa yín lórí ọ̀rọ̀ yìí má baà jẹ́ lásán.
Gbogbo àwọn àrùn burúkú ilẹ̀ Ijipti, tí wọ́n bà yín lẹ́rù, ni OLUWA yóo dà bò yín, tí yóo sì wà lára yín.
Èyí ní ẹ̀rí tí ẹnìkan fi sọwọ́ sí ilé iṣẹ́ BBC Oríṣun àwòrán, BBC Sport Àkọlé àwòrán, Eri owó ti Lekan Fashakin san fún ọlọpàá Bótilẹ̀ jẹ́ pé àwọn míran gbà pé kìí ṣe gbogbo SARS ní ó ń hùwà ìbàjẹ́ bíkò ṣe àwọn àsáwọ kan tó wà lára wọn, nítorí pé láti ìgbà ti wọn ti bẹ̀rẹ̀ ní àwọn ìwà ọ̀daràn tí ń díkù láwùjọ, sùgbọn síbẹ àjọ ọlọ́pàá gbọdọ̀ wá wọ̀rọ̀kọ̀ fi sàdá kí àwọn ọ̀bàyéjẹ́ láàárin àwọn ọlọ́páà yìí leè tọwọ́ ọmọ wọn bọsọ.
Nítorí OLUWA ti ya ọjọ́ kan sọ́tọ̀ fún ẹ̀san,ó ti ya ọdún kan sọ́tọ̀ tí yóo gbèjà Sioni.
Èmi kò ní kí Shiite má ṣe ẹ̀sìn won o -Muhammadu Buhari Bẹẹ lawọn Shiite naa pariwo pe awọn ko fẹ wahala ju ki ijọba ṣe ohun to yẹ fun awọn lọ.
Makinde gba won niyanju pe ki won tun tesiwaju lati maa
Awọn eeyan si faake kọri pe ajọ eleto idibo, ti Humprey Nwosu lewaju rẹ, gbọdọ kede MKO Abiọla gẹgẹ bii ẹni to bori ibo aarẹ naa.
Ọbabinrin Elizabeth Keji, pé aadọrun ọdún láyé ni ọjọ́ kọkànlélógún, oṣù kẹrin ọdún Ẹgbàálémẹrindinlólgún.
Nitori idi eyi kii ṣe kayeefi pe lọpọ igba ati kaakiri ipinlẹ lorilẹ-ede Naijiria ni awọn araalu kii mọ ibi ti wọn lee wa awọn aṣoju wọn si.
Sọun ni orukọ ti wọn n pe ọba ilu Ogbomọsọ.
 Eleyii ni o jẹ gbongbo ti a fi n dari ọkọ aṣeyọri lati ọpọ ọdun sẹyin.
Ogbẹni Joseph Attah to jẹ agbẹnusọ fun ileeṣẹ aṣọbode Naijiria ni awọn ko ti bode Naijiria ati ti orilẹ-ede Benin Republic pa rara.
”Eli wá mọ̀ nígbà náà pé, OLUWA ni ó ń pe ọmọ náà.
yoo fi  gbe lẹyin egbe oselu  APC.
Orúkọ àwọn ọmọ Israẹli tí wọ́n fẹ́ obinrin àjèjì nìwọ̀nyí:Ninu ìdílé Paroṣi: Ramaya, Isaya, ati Malikija; Mijamini, Eleasari, Haṣabaya ati Benaaya.
Wọn kò sì yapa kúrò ninu ìlànà tí Dafidi fi lélẹ̀ fún àwọn alufaa ati àwọn ọmọ Lefi nípa àwọn ohun tí wọ́n gbọdọ̀ máa ṣe, ati nípa ilé ìṣúra.
Imú rẹ dàbí ilé ìṣọ́ Lẹbanoni,tí ó dojú kọ ìlú Damasku.
Oniroyin ọrọ aje fun ile iṣẹ iroyin CNN Richard Quest lọ si olu ilu Kenya, Nairobi ninu oṣu kẹwaa fun eto rẹ lori ẹrọ amohunmaworan.
Erongba mi si ni ki n wọ aṣọ obinrin wọ inu ibusun wọn ki n si fọwọ kan awọn obinrin.
O ti ṣe gomina ipinlẹ Ekiti ri laarin Ọjọ kẹrindinlogun, osu kẹwaa, ọdun 2010 si ọjọ kẹẹdogun, osu kẹwaa, ọdun 2014.
Ilé ìwòsàn l'Àbuja ti ya àwọn ìbejì tí wọ́n sọpọ̀ láyà lọ́fẹ̀ẹ́ Fásitì ìpínlẹ̀ Ekiti dá òṣìṣẹ́ 355 padà sẹ́nu iṣẹ́ Sááju àsìkò yìí ni ọ̀gá ọlọpàá orilẹ̀-èdè Naijiria ti ránsẹ si gbogbo àwọn ọ̀gá ọlọpàá jákèjádo Naijiria pé ojú ni alákan fi ń sọri, ati pé ki wọ́n moju to àyika wọ́n dáada.
Ohun tí mo sì ṣe nìyí: 
Awọn lọkọlaya yii ṣalaye idi ti awọn ṣe ni irufẹ ipinnu yii fun BBC Yoruba lẹkunrẹrẹ.
Ejò lé àwọn aṣòfin ìpínlẹ̀ Ondo kúrò nípàdé Wo àwọn tí gómìnà ìpínlẹ̀ Oyo fi orúkọ wọn sílẹ̀ fún ipò kọmísánnà EFCC kó akẹ́kọ̀ọ́ fásitì UNIOSUN Ẹ wo ọmọ ọdún méje tó di Gómìnà l'Ekiti Baba ọhun lo mu ẹni kan ti o pe ni Wolii wa lati maa wa dari wọn ninu ijọ.
Ohun tí wọ́n fi ń ṣe báàgì, bàtà ni wọ́n ń tà bíi ‘pọ̀ǹmọ́’— NAFDAC Zaynab ni Ẹ kuro lọna mo fẹ kọja; ero pọ a ko le ya lọna' ni o kọkọ bi ọrọ atimọle El Zakzakky yii."
Wọ́n ń fi tọkàntọkàn kọ́ ẹ̀kọ́ tí àwọn aposteli ń kọ́ wọn; wọ́n wà ní ìrẹ́pọ̀, wọ́n jọ ń jẹun; wọ́n jọ ń gbadura.
idibo aarẹ to waye ni ipinle Niger.
Won ni o duro gbọingbọin lẹyin ọkọ rẹ.
Mo tún gbọ́ ohùn mìíràn láti ọ̀run tí ó sọ pé,“Ẹ jáde kúrò ninu rẹ̀, ẹ̀yin eniyan mi,kí ẹ má baà ní ìpín ninu ẹ̀ṣẹ̀ rẹ̀,kí ẹ má baà fara gbá ninu ìjìyà rẹ̀.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Ẹgbẹ agbabọọlu Tottenham ti jawe olubori ninu ifẹsẹwọnsẹ mẹta ti wọn gba ninu idije Premier League lati igba ti Mourinho ti rọ pe Mauricio Pochettino gẹgẹ bi akọnimọọgba Spurs.
Sugbọn nigba to n ba BBC sọrọ, ọkunrin kan ta fi orukọ ati ohun bo ni aṣiri, amọ ta sọ ni Kalu salaye pe ẹẹmeji ọtọọtọ lawọn obinrin ti fi tipa ba ohun lopọ.
Olorì Aláàfin, Memunat Adeyemi, fohùn ránṣẹ́ sí ikú bàbá yèyé Buhari pàṣẹ lílo àgbo tí orílẹ̀-èdè Madagascar ṣe fún coronavirus fún ìtọ́jú ọmọ Nàìjíríà Ṣé ẹ lè kí Liverpool kú oríire báyìí?
Nítorí pé nígbà kan ẹ dàbí aguntan tí ó sọnù.
Mo dupẹ pe ẹnu n kun mi bayii tori nigba ti iya n jẹ mi, n ko ni ọrẹ, bi ogo ba si ṣe pọ si, naa ni ọta yoo pọ, orúkọ mi si lo gbayi ti wọn ṣe n pariwo mi mo ri oju rere Ọlọrun gba ni.
Adari ikọ ajọ irinna popo ni ipinlẹ Eko fikun ọrọ rẹ pe ‘ẹrọ speed limit’ yii n sisẹ pelu ẹrọ to n gbe epo bẹntirolu lọ si inu ọkọ ni.
OLUWA, gbà mí lọ́wọ́ àwọn èké,ati lọ́wọ́ àwọn ẹlẹ́tàn.
”Awon ajo tuntun marun un naa ni: Ajo ti yoo maa ri si akanse ise,
Ṣugbọn, ẹpa ko boro mọ, nitori pe awọn eeyan kan ti n lo o.
7 96812 Orilẹede Ghana 341 1.
O ni koda to ba wu ọ o le san owo atijọ naa si inu asunwọn rẹ ni banki tabi ki o tun fi ranṣẹ si ara rẹ pada.
N óo sọ ilẹ̀ yìí di ahoro ati aṣálẹ̀.
Àwọn ọ̀nà tí ó wà láàrin abúlé yìí ṣẹ tóóró-tóóró ni, wọn kò fẹ̀ rárá.
" Kàn sí BBC Yorùbá Ayẹyẹ ifilọlẹ ileeṣẹ BBC Yoruba Kà nípa ìròyìn mánigbàgbé tí BBC News Yorùbá ṣe láàárín ọdún kan Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Imperial Majesty ni Olubadadan, Royal Majesty làwa, òfin sì tẹ̀lé e - Ọtun Olubadan Awọn ọmọ igbimọ ti yoo mu ẹni to ba jawe olubori si ti wa; awọn ọmọ igbimọ naa wa lati awọn orilẹede to wa ni Iwọ oorun Afrika, ikọọkan wọn si jẹ yala olukọ, onkọwe, ati akọroyin ni ede Pidgin.
Ẹnu rẹ̀ ni wọ́n ti gbọ́ pé Bínpé àbúrò fìlísíà fẹ́ ṣe ìgbéyàwó ní Gbọ̀ngán.
Oríṣun àwòrán, others O ni oun nilo ẹni ti yoo maa ṣe akoso oju opo ayelujara oun lasiko aawẹ, ni oun fi gba sọdọ, lai mọ pe ọmọkunrin naa ti ṣe aidaa ri lọdọ ọga rẹ tẹlẹ.
Ṣé lóòtọ́ọ́ ni Adìyẹ Broiler ń fa àìsàn Coronavirus?
Ilu mooka akorin ni, Oliver Mtukudzi wa nibi isinku naa lati da awon eniyan lara ya.
Nítorí náà, nígbà tí o rí i pé mo wẹ̀ dé òdì kejì, tí emi wà ní apá ọ̀hún tí òun wà ni apa ìhín, ó pòṣé, ó ta ìkà sí mi, ó sì bá tirẹ̀ lọ.
Bi iru obinrin bẹẹ ba ni ibalopọ pẹlu ọkọ rẹ ni tooto igba ti isẹlẹ ifipanilopọ naa waye, o see se ko loyun, ko si jẹ pe ẹni to fipa ba lopọ lo ni oyun.
Ṣugbọn gbé pẹpẹ ìrúbọ idẹ tọ̀hún sọ́tọ̀ fún mi kí n lè máa lò ó láti wádìí ọ̀rọ̀ lọ́wọ́ OLUWA.
Osun: Gboyega Oyetola, Adeleke ń ṣe àríyànjiyàn lórí èyí tó dárajù nínú 'oníjó' àti 'akówójẹ'
Bakan naa, Shina tun ge ahọn ọgọrun eeyan, ó ṣe e jẹ, to si tun gbe ninu igi iroko fun ọpọlọpọ ọjọ, bakan naa lo n sun ni itẹ oku lati sọ ara rẹ di ọkùnrin.
16 Nítorí Olúwa Ọlọ́run ti sọ ọ́; àti pé àwa, tí a jẹ́ alàgbà nínú ìjọ, ti gbọ́ a sì ti jẹ́rìí sí àwọn ọ̀rọ̀ ti Ọlọ́lá nlá ológo níbi gíga, sí ẹnití a fi ògo fún láé ati títí láeláe.
Nigba ti awọn idile ọmọọba Osu wa kọwe pe awọn fẹ gba iyọnda lati ta ilẹ naa f'ẹlomiran, ileesẹ to n dari ọrọ ilẹ lawọn kọwe si ileesẹ orileede Naijiria ni Ghana lati pese iwe ẹri ti wọn ni ṣugbọn awọn ko gbọ nkankan lati ọdọ wọn.
Ìwọ, ati gbogbo àwọn ọmọ ogun rẹ, ati àwọn eniyan tí wọ́n wà pẹlu rẹ yóo kú lórí àwọn òkè Israẹli.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù ASUU Strike: Òtítọ́ wo ló wà nínú pé ASUU tún fẹ́ yanṣẹ́lódì?
”Eto ẹkọ to yanrantiAare Buhari wa lo anfaani yii
Awọn miran gboriyin fun Asiwaju pe ko ṣe ẹlẹyamẹya ninu ọrọ rẹ: Ninu ọrọ awọn miran adura ni Baba Fasoranti nilo ati pe idanwo nla ni eyi jẹ fun Tinubu gẹgẹ bi Asiwaju ati ẹgbẹ APC lapapọ: NBC fọwọ́ sí ìdásílẹ̀ ilé iṣẹ́ Fulani Radio Sanwo Olu yan kọ̀míṣọ́nnà 25 àtàwọn olùbádámọ́ràn Ṣìṣeṣìṣe Troost-Ekong ṣokùnfà ìyà àjẹsùn fún Nàìjíríà lọ́wọ́ Algeria Aago Naijiria ti kún àkúnwọ́sílẹ̀ - Tunde Bakare Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
 Oríṣun àwòrán, Seyi Makinde Gomina Makinde ni oun mọ riri atilẹyin ati igbẹkẹle awọn eeyan ipinlẹ Oyo ninu oun, oun si seleri lati ma ṣe ja wọn kulẹ."
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ọmọ ìyá méjì gé orí ọmọ ọdún mẹ́wàá l'Eko Oby Ezekwesili yan Ganiyu Galadima, gẹ́gẹ́ bíi igbákejì rẹ̀ Dokita Ọba ni oṣu kẹjọ ọdun 2018 ni awọn dokita ileewosan naa, titi to fi kan awọn dokita agba nibẹ gba owo oṣu kẹyin eyi to tumọ si pe owo oṣu mẹta ni wọn jẹ awọn Dokita nibẹ.
Ó bẹ̀rẹ̀ eré tíátà rẹ̀ ní kékeré nípa síse ẹ̀fẹ̀ nínú àwọn ere orí ìtàge ní ìjọ rẹ̀ nígbà náà lọ́hun.
Àṣẹ kan náà ni Ọlọ́run fún gbogbo ẹ̀dá láti fún àwọn ǹnkan wọ̀nyìí ní orúkọ ní èdè tí wọ́n ń sọ.
Iran Xhosa ni eya keji to tobi julo ni South Africa.
Eleyii lo mu wọn lọ si ile Oba ilu Eko, ti wọn si yabo ibẹ pe ọba naa pẹlu ijọba, nitori awọn ileeṣẹ ijọba ni awọn n ṣekọlu si.
" Lori ọjọ ọla Naijiria lẹyin arun Covid-19, Fayemi ni ọjọ ọla orilẹede yii yoo dara nitori ọgbọn tuntun ni arun naa fi n ko wa, to si yẹ ka gbajumọ amulo ayelujara bayii ju ti tẹlẹ lọ.
Nibi ọrọ de duro bayii, apapọ awọn to ti ni arun naa ni Naijiria je 101,331.
NCC: A ti ri owó ti Iléeṣé MTN sannáà gbà
Wọn ní àwọn ṣì n ''ṣé iwadi'' torí náà awọn kò ti le sọrọ nípa ìṣẹlẹ òun.
Gbogbo àwọn ènìyàn tí wọ́n ń rìn nílẹ̀ á wa dàbí i kòkòrò kékèké.
Oríṣun àwòrán, EPA Àkọlé àwòrán, Ẹlẹsin Aghori to gbe ori eniyan dani Ni ede Sanskrit, ohun ti orukọ Aghori duro fun ni ‘ẹni ti ki n ba eniyan lẹru’, amọ awọn ohun ti o n banilẹru ti wọn n gbọ nipa wọn maa n fa ibẹrubojo ati irira nipa wọn fun awọn eniyan.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Kara Bridge: Ó kéré tán, ọkọ̀ yóò lo wákàtí mẹ́ta kó tó bọ́ lójú ọ̀nà Kara tó dí pa 15 Sẹ́rẹ́ 2020 Ọpọ awọn eeyan to n gba opopona Berger si ori afara Kara nilu Eko lo ti n figbe ta bayii lori isoro sunkẹrẹ-fakẹrẹ ọkọ nla ti wọn n koju lagbegbe naa.
6 mílíọ̀nù ni-APC A gba ìwé ìpẹ̀jọ́ ₦200m lọdọ mọlẹbi Sugar - UCH Bakan naa ni Ọjọgbọn Shehu fikun pe awọn yoo pin awọn eroja idibo lọjọ Ẹti, ati wi pe awọn kọmisana ajọ INEC mẹta mi i lati ipinlẹ Ogun, Kebbi ati Zamfara yoo wa si ipinlẹ Kano lati ran an lọwọ̀ ninu iṣẹ naa.
Ẹni tí ó di eniyan sinu jẹ́ ẹlẹ́tàn eniyan,ẹni tí ó bá sọ̀rọ̀ ìbàjẹ́, òmùgọ̀ ni.
Ìfẹ̀hónú hàn ńlá ń bọ̀ ní Nàíjíríà lọ́jọ́ Aje láti bèèrè fún ìṣejọba rere Oríṣun àwòrán, @YeleSowore Iroyin kan to n ja rainrain lawọn oju opo ikansira ẹni lori itakun agbaye ti fi ye ni pe iporogan, ifẹhonu han ati iwọde alagbara kan n bọ lọwọ Aje, ọjọ Karun osu kẹjọ, ni orilẹede Naijiria.
Ọmọwe Okorie wa fi kun un pe awọn ṣi n ṣe iwadii lati mọ boya ẹya kokoro arun naa dọgba pẹlu ẹya tuntun ti wọn pe o n ṣe ọṣẹ lorilẹede Gẹẹsi atawọn orilẹede miran bayii.
Wo iye ìgbà mẹ́rin tí ìtàkùn ìpínná ní Nàìjíríà ti dákú lọ́dún 2020 nìkan Èèyàn 82 tún ti ní COVID-19 ní Nàìjíríà Níbo ni Ọ̀gbẹ́ni 'Emma', tíṣà tí wọ́n ní ó lu ọmọ pa ní Ikorodu wà bayìí?
 Awon ajo asatipo naa wa lati rii pe won gbe igbese imupadabosipo fawon asatipo.
, Duration 8,0016 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 2:23 Fídíò, Water Generator: Ó leè ṣiṣẹ fún wákàtí mẹfà, kó tó sinmi, Duration 2,2310 Òkùdu 2020 6:56 Fídíò, Wòlíì Kasali sọ̀rọ̀ nípa awuyewuye pé ó lé ìyàwó rẹ̀ jáde nílé, Duration 6,5628 Ọ̀pẹ̀̀ 2018 8:23 Fídíò, Deborah Adebola Fasoyin: Èmi kọ́ ló gbé orin ọdún ń lọ sópin kalẹ̀, CAC ló ni í ni mó n ṣe àkójọ orin- Fasoyin, Duration 8,2331 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 2:59 Fídíò, Paystack Shola Akinlade: Ìgbésẹ̀ 5 yìí ni mo gbé tíléeṣẹ́ Stripe fi dókòwò $200m pẹ̀lú mi, Duration 2,5916 Sẹ́rẹ́ 2021 BBC News, Yorùbá Ìdí tí ẹ fi le è nígbàagbọ́ nínú ìròyìn BBC Ìlànà Lílò Nípa BBC Òfin Àṣírí Cookies Kàn sí.
Aṣiri tu nigba ti arakunrin kan to jẹ ololufẹ tẹgbọn-taburo naa, Linda Roberts ati Mary-Beth Tomaselli, ta awọn ọlọpaa lólobó wipe ọkan lara wọn jẹwọ fun oun wipe awọn lo pa baba wọn.
Iwadii fihan pe nigba ti olukọ Madumere fawọn ọmọ kekeke ṣọ awakọ yii gan an lo fipa ba ọmọ ọdun mẹrin yii tage lọna aitọ.
“Kọ ìwé yìí sí ìjọ Tiatira pé:“Ọmọ Ọlọrun, ẹni tí ojú rẹ̀ dàbí ọwọ́ iná, tí ẹsẹ̀ rẹ̀ ń dán bí idẹ.
” Àwọn àgbààgbà náà sì dúró lọ́dọ̀ Balaamu.
Alaga Igbimọ tẹẹkoto lori ijiroro ọrọ owo oṣu naa, Sẹnetọ Francis Alimikhena, lo ka abajade ijiroro igbimọ naa niwaju ile.
Omo bibi orile-ede Argentina ti o n kopa ninu idije boolu afigigba French open, Juan Martin Del Potro kopa ribiribi lati pegede sipele keji si asekagba idije ohun lati odun mesan an seyin, leyin ti o fagbahan Marin Cilic pelu ami-ayo meje si mefa(7-6), marun un si meje(5-7), mefa si meta( 6-3) ati meje si marun un (7-5), ninu ifigagbaga ti o waye lojoBo(Thursday),Ni bayii, omo-odun mọ́kàndínlọ́gbọ̀n ohun, Juan yoo lo koju Rafael Nadal, leni ti o ti gba ife eye ohun fun igba mewa otooto teleri.
6 Àti nísisìyí, kíyèsíi, mo wí fún ọ, pé ohun tí yíó níye lórí fún ọ jùlọ ni lati kéde ironúpìwàdà sí àwọn ènìyàn yìí, kí ìwọ baà lè mú àwọn ọkàn wá sí ọ̀dọ̀ mi, kí ìwọ baà lè sinmi pẹ̀lú wọn nínú ìjọba Bàbá mi.
Ẹ̀rù ohun burúkú tí yóo ṣẹlẹ̀ sí baba mi, ń bà mí.
Bi foonu ba ṣe n tan ina si ni odiwọn batiiri to maa lo.
ní Ọ ̀ yọ ́ ní ọjọ ́ jímọ ́ ọ ̀ olóyin yìí , àwọn asunrárà náà yíò máa káàkiri ilé awọn Ọ ̀ yọ ́ mèsì àti àwọn ìjoyé ìlú yókù .
Akọroyin BBC to wa ni ilu Abuja jabọ pe awọn ọlọpaa ni awọn ti n gbiyanju lati rọ ọwọ iṣẹlẹ naa.
Ẹ ranti ohun tí ó ṣẹlẹ̀ ninu ìrìn àjò yín láti Ṣitimu dé Giligali, kí ẹ lè mọ iṣẹ́ ìgbàlà tí OLUWA ṣe.
Ori aga ijoko ni awọn mejeeji ti kọkọ bẹrẹ, ti wọn si n fi ọwọ pa ara wọn lara.
Mose bá jáde kúrò níwájú Farao, ó lọ gbadura sí OLUWA, 
Iléeṣẹ́ Ọlọ́pàá di ẹ̀bi rògbòdìyàin ní Kogi ru ìwà kòtọ́ àwọn olóṣèlú
    Nígbà tí a ṣe ìpàdé, àwọn tí o ní kí a kó ìbọn wa fún Onibode Igbo Elégbèje kò ju mẹ́wàá lọ, gbogbbo àwọn ìyókù ni ó wí pé kí a pinnu láti jagun.
Agbẹnusọ fun Olubadan, Adeola Oloko ko gbe ẹrọ ibanisọrọ rẹ, bakan naa ni oluwoye igbesẹ, Yanju Adegboyega naa ko gbe ẹrọ ilewọ rẹ.
Arinze ni awọn isoro kan wa to nii se pẹlu igbẹjọ awọn eeyan ti wọn fi ẹsun ibalopọ kan, ti awujọ ko ba si fọwọsowọpọ pẹlu ijọba, o lee soro pupọ lati sedajọ wọn, pẹlu afikun pe ti iwa ifipabanilopọ ba si n tẹsiwaju lawujọ, awọn araalu lo n faa.
Ọjọbọ ni ileeṣẹ ọlọpaa fi ofin gbe Marley ati alakoso ẹgbẹ akọrin rẹ, Seyi Awonuga.
Lati igba to ti ṣe ikede yii ni ero awọn ọmọ Naijiria ti ṣotọọtọ lori ikede naa.
Ẹwẹ nigba to de ibi ipade apejẹ alẹ ana, Lawal yi ẹnu pada o ni oun ko sọ bẹẹ lẹyin pe Sẹnetọ Bassey Akpan ti ipinlẹ Akwa Ibom mẹnu ba ọrọ idi to fi yẹ ki ijọba ti gbe e jade ki wọn to lọ fun isinmi ni oun, Ahmed fi da wọn loju pe o ṣeese ko jade lọsẹ yii gan.
Ẹsira yin OLUWA, Ọlọrun, tí ó tóbi, gbogbo àwọn eniyan náà gbé ọwọ́ wọn sókè, wọ́n dáhùn pé “Amin, Amin,” wọ́n tẹríba, wọ́n dojúbolẹ̀, wọ́n sì sin OLUWA.
Iṣọla Oyenusi rèé, ẹnití ìfẹ́ obìnrin ṣun dé ìwà ìdigunjalè Ẹfunroye Tinubu - Ògbóǹtagí oníṣòwò, olówò ẹrú àti afọbajẹ Samuel Ajayi Crowther, òjíṣẹ́ Ọlọ́run tó gbé èdè Yoruba lárugẹ Bó tilẹ jẹ́ pe awọn olùgbe Ipinlé naa kọ̀ ọ́, Ìgbìmọ̀ Àgbààgbà Yoruba (YCE) ti ní bí ìjọba àpapọ̀ bá dán irú rẹ̀ wò nílẹ̀ káàrọ̀ o jíire, yoo dan an tán.
 Basirat sọ pe oun fi ọrọ naa lọ awọn obi ati ẹbi oun."
Adé mẹ́wàá wà lórí ìwo rẹ̀.
Ibugbamu ado oloro naa ni wọn sọ wi pe, awọn ọdọkunrin meji naa se ni agbeegbe Mubi, eyi ti ko jinna si Yola, to jẹ Olu-iIu ipinlẹ Adamawa.
Minista fun sayensi ati imo ero
Wí fún un pé, mo ní, ibi tí ajá ti lá ẹ̀jẹ̀ Naboti gan-an ni ajá yóo ti lá ẹ̀jẹ̀ tirẹ̀ náà.
Idi si ree to fi da ẹwọn gbere fun wọn nibamu pẹlu ofin to ngbogun ti iwa sise owo ilu basubasu ati iwa ọdaran tọdun 2004, ori kẹẹdogun, ẹsẹ kinni ati ikeji.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Obafemi Awolowo University: Àwọn tó jí olùkọ́ wa gbé kò tíì sọ ohun tí wọ́n fẹ́ gbà 6 Èbibi 2019 Oríṣun àwòrán, oau Àkọlé àwòrán, Ní ọjọ Aiku ni wọn ji Ọjọgbọn Adegbẹhingbe gbe.
Níwọ̀n ìgbà tí ẹ ti yà lọ́dọ̀ èmi iranṣẹ yín, ẹ kúkú jẹ́ kí n tètè tọ́jú oúnjẹ díẹ̀ fún yín láti jẹ, bí ẹ bá tilẹ̀ wá fẹ́ máa lọ nígbà náà, kò burú.
Èyí ni ìdí tí coronavirus ṣe n pa àwọn kan, tí kò sì pa àwọn kan Coronavirus- Atọ́nà bí nkàn ṣe ń lọ ní Afirika Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí kan sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
A gbọ pe fitila ti wọn n tan yii ti le ni ẹẹdẹgbẹta ọdun.
Femi Adebayo - BBC News Yorùbá BBC News, YorùbáFò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Yoruba Films: Iṣẹ́ amòfin tí mo kọ́ ni Fáṣítì kò mú owó wọlé fún mi bíi iṣẹ́ tíátà - Femi Adebayo 28 Ọ̀pẹ̀̀ 2018 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 9 Èbibi 2020 Oríṣun àwòrán, @Loveranger18 Gbajumọ osere tíátà, Femi Adebayo tí sísọ lójú rẹ pé, isẹ agbẹjọro tí òun kọ nílé ìwé Fáṣítì kò mú owó wá fún òun, bíi isẹ tíátà.
Nígbà tí ó di ọjọ́ kejì, gbogbo iwájú orí rẹ̀ ti wú kọ́ńdú kọ́ńdú, orí rẹ̀ tóbi tó odì ẹyìn, ọmọ ojú rẹ̀ wọnú.
Oludari agba fun ajọ iṣakoso okoowo ẹkun iwọ oorun gusu Naijiria, DAWN, Ṣẹyẹ Oyelẹyẹ ti jẹ ko di mimọ pe ikọ alaabo ẹkun naa ti ọpọ mọ si Amọtẹkun ko ku o, bẹẹni ina rẹ ko parun.
Lagos-287 FCT-255 Kaduna-36 Akwa Ibom-29 Katsina-25 Rivers-25 Kwara-21 Bauchi-19 Kano-15 Ondo-14 Plateau-13 Yobe-12 Nasarawa-11 Ebonyi-9 Gombe-8 Abia-7 Delta-4 Imo-4 Osun-3 Anambra-2 Borno-2 Cross River-1 Edo-1 Ekiti-1 Jigawa-1 Ogun-1 Èèyàn tó lè ní ẹ̀gbẹ̀rún kàn,1,145 lùgbàdì àrùn Covid-19 ní ìgbà àkọ̀kọ̀ ní Nàìjíríà Oríṣun àwòrán, @NCDC Nigba akọkọ ti arun Covid-19 ti bẹrẹ, iye awọn eeyan to lugbadi arun Covid-19 ni Naijiria ti kọja ẹgbẹrun kan lojumọ.
Wo àwọn fọ́ran to jẹyọ nibi ayẹyẹ náà Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Akọkọ naa, Ọba ilẹ Yoruba ni Ọọni Ile ifẹ, Koda, kii ṣe Ọba lasan, olori ọba alaye nilẹ Yoruba ati lagbaye ni nitori naa ọdọ rẹ gan an ni orisun gbogbo awọn eewọ wọnyii ati bibọwọ fun wọn ti ṣẹ wa.
Afenifere, Soyinka korò ojú sí fídíò tó n dúnkokò mọ́ àwọn èèyàn ẹ̀yà Igbo tó wà nílẹ̀ Yoruba Ẹgbẹ Afenifere ti sọ pe oun ko lọwọ si fidio kan to n lọ kaakiri ori ayelujara, ninu eyi ti ọkunrin kan ti fun awọn eeyan ẹya Igbo ni gbedeke wakati mejidinlaadọta lati kuro ni ilẹ Yoruba.
Ninu ọrọ rẹ pẹlu akọroyin BBC Ayinde Soaga ni lati ọjọ Kẹsan osu Kẹrin ni awọn gbajuẹ ti gbakoso oju opo oun ti o si ni gbogbo ohun ti awọn eeyan ba ri nibẹ ko ti a ti ọwọ ohun wa.
A ti fi ọ̀nà Oluwa kọ́ ọ, a máa sọ̀rọ̀ pẹlu ìtara; a sì máa kọ́ àwọn eniyan lẹ́kọ̀ọ́ nípa Jesu ní àkọ́yé.
Mata sọ fún Jesu pé, “Oluwa, ìbá jẹ́ pé o wà níhìn-ín, arakunrin mi kì bá tí kú!
 Ki ijoba si setan lati ro osise  alaabo gbogbo lagbara ki ijoba si daabo bo
Wé lawani mọ́rí, sì wọ bàtà.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: INEC ní kíkùnà ààrẹ láti buwọ́lu òfin ìdìbò kò dí ìbò Ọ̀ṣun, 2019 lọ́wọ́ APC àti PDP takora wọn lórí Olùsirò owó àgba Ọsun tó fisẹ́ sílẹ̀ Òkú Kofi Annan balẹ̀ sí Ghana Amofin Mutiu Agboke gan an lo n lewaju eto naa eleyi ti wọn gbe kalẹ ni olu ileeṣẹ ajọ naa nipinlẹ Ọyọ.
Ṣugbọn sísun ni wọ́n ń sun ẹran ẹbọ wọnyi lẹ́yìn ibùdó.
Nígbà tó ń dá si ìjíròrò náà, igbakeji olórí ọmọ ẹgbẹ́ òṣèlú tó pọ̀ julọ, Sẹnatọ Ajayi Boroffice ni ifilọlẹ ẹ̀rọ alatagba 5G náà, tí ń mú awuyewuye tó pọ̀ lọ́wọ́.
Ní bò míràn ẹ̀wẹ̀, wọ́n má á ń lo inú akèǹgbè láti kówó pamọ́ sí.
Ẹni tí ó ṣiṣẹ́ fún tí ó san owó ọ̀yà HK$500 dollars (US$65) fún un ni ó pa a.
Agbẹnusọ fun Kabiesi ọhun, Alli Ibrahim fi idi ọrọ naa mulẹ fun BBC.
Awọn ọlọpaa ṣi n ṣewadii awn iroyin to sọ pe afurasi agbebọn ṣi ku ọkan ti wọn ko si ti mọ ibi ti o wa.
Wọn óo tan àwọn àyànfẹ́ pàápàá jẹ, bí ó bá ṣeéṣe.
Andrew Aniamaka to jẹ alukoro fun ile iṣẹ ọlọpa ni ipinlẹ Delta lo fidi ọrọ na mulẹ fun ile isẹ BBC pe lootọ ni awọn fada naa ti gba itusilẹ.
Ọba bèèrè lọ́wọ́ rẹ̀ pé, “Ṣé nǹkankan kò ṣe Absalomu ọmọ mi?
Bẹẹ naa ni olootu ijọba Greece Kyriakos Mitsotakis tawọn eeyan gbosuba kare fun bi o ti se seto ti awọn to ku ko fi ju mẹrinlelaadọfa lọ ninu awọn eeyan miliọnu mọkanla.
Ko si idunadura kankan lori iye owo tẹẹ maa wọ ọkọ lọ si ilu Mowe nibi ti ipagọ ijọ RCCG naa wa.
O ṣeeṣe o ki orilẹede Gẹẹsi o ni olootu ijọba tuntun laipẹ.
Lopin gbogbo ere, ibo ti awọn ololufẹ eto naa di ja Vee, Nengi, Neo ati Dorathy.
 Chibuzor fikun pe oun fẹ lu jibiti gba owo lọwọ ọlọpa ni, ọmọde ti wọn n wa naa ko si lọdọ oun, bẹẹ ni ẹnikẹni ko ran oun nisẹ lati parọ mọ pasitọ Babatunde.
Oun nikan ni oriṣa ti ọrọ wa ye.
Bakan naa ni Adewole ni oun ti jabo fun ijoba ibi ti ise de duro lori arun yirunyirun ni apa ibi kan ni Naijiria.
Bi Biden ṣe n lakaka naa ni Aarẹ Donald Trump naa ṣe n gbiyanju lati wọle fun saa keji.
Abileko Babalola ni oun ko lero pe fidio naa le tan kaakiri ayelujara bi eleyii.
"Wo àwọn ojúṣe àti èèwọ̀ fún ikọ̀ ọlọ́pàá SWAT tó gba iṣẹ́ lọ́wọ́ SARS Ọlọ́pàá mú afurasí 31 tó ń dúnkokò máwọn ọmọdé lórí ayélujára Pásítọ̀ Enoch Adeboye darapọ̀ mọ̀ #ENDSARS, ó fún ìjọba Nàìjíríà ní ìmọ̀ràn ọ̀nà àbáyọ Mọ̀ nípa iPhone 12, fóònù ológo 5G tí kìí lo ""Charger” tó ṣẹ̀ṣẹ̀ jáde Àṣé àṣírí wà nínú Hijabu tí Aisha Yesufu ń wọ̀ lọ ìwọ́de O ni: ""Ikọ SARS ti a da silẹ lọdun 1984 yatọ si ikọ SARS to wa nilẹ bayii nitori pe ohun kan ṣoṣo ti o lee mu ki ọlọpaa ikọ SARS o yọ ibọn jade nigba naa ni bi adigunjale ba yọ ibọn lati yin si wọn."
‘DJXgee lọ sòde eré lọ́jọ́ ọdún tuntun láìmọ̀ pé yóò gbẹ̀mí ara rẹ̀’ Awọn ti iṣẹlẹ naa ṣoju wọn tun ṣalaye pe bata ni arabinrin yii lọ ra ni ilu Eko ki o to kagbako awọn obinrin meji naa nibi ti wọn ti gbe irin kekere kan lee lọwọ ti wọn si gba ẹgbẹrun lọna ogoji naira lọwọ rẹ.
"Akọle ayẹyẹ na l'ọdun 2018 ni ""Ẹda fun Omi"", titọ ọna abayọ iṣẹda fun awọn ipenija omi ti o n koju wa l'ode oni."
Egbe osise lorile ede Naijiria tun wa ro ijoba
Má gbà fún ẹnikẹ́ni láti fojú tẹmbẹlu rẹ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Mori ara mi to funfun, mi o mọ pe ẹtẹ ni Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Obìnrin ló ni ilé àti àdúgbò fún ìdí èyí wọ́n lè ṣe ìlú dáadáa' Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
'Àwọn ti Micra ló jẹ̀bi rògbòdìyàn awakọ̀ tó wáyé lánàá n'Ìbàdàn' Seun Egbegbe lo ọdún méjì àti oṣù méje lẹ́wọ̀n láì tìí san béèlì rẹ̀ Mompha ti wọn fẹsun kan naa, lo ma n gbe igbe aye olowo pẹlu bii o se ma n fi aworan owo ilẹ okeere si ori ikanni Instagram rẹ, ati adura ni ọpọ igba.
Gomina ipinlẹ Ekiti, Dokita Kayọde Fayẹmi, ti fi ontẹ lu u pe ki ileeṣẹ igbohunsafẹfẹ ijọba ipinlẹ naa bẹrẹ iṣẹ pada lọjọ kinni, oṣu Kejila, ọdun 2019.
Oríṣun àwòrán, @BASHIRAHMAAD Àkọlé àwòrán, Ọrẹ atigba ewe ni Aarẹ Buhari ati Isa Funtua jẹ, wọn si jọ maa n jẹun ninu awo kan naa.
A fẹ́ bẹ̀rẹ̀ òfin má lo fóònù mọ́ fàwọn ọmọ wa -Òbí Iṣẹ́ ṣẹ̀ṣẹ̀ bọ́ lọ́wọ́ Seth Ator tó yìnbọn pa ọ̀pọ̀ èèyàn ní Texas ni- ọlọ́pàá Ìfẹ̀hónúhàn l'Abuja lórí ìdájọ́ ilẹ̀ Gẹ̀ẹ́sì tó gbẹ́sẹ̀ lé $9.
Kàkà bẹ́ẹ̀, ẹ máa sọ̀rọ̀ wọn ní rere ni.
O parowa fawon ti won jo se ipade naa lati bere ise lori awon igbese ti won jo fenuko le ki won jo fowosopo ki o le bi eso rere leyin ikolu to waye nipinle Benue atawon ipinle miran.
Ní ọdún kẹrin tíí Hesekaya jọba, tíi ṣe ọdún keje tí Hoṣea, ọmọ Ela, jọba lórí Israẹli, Ṣalimaneseri, ọba Asiria, gbógun ti Samaria, ó sì dó tì í.
Jesu ní, “Ẹ ní kí wọ́n jókòó.
Olanrewaju Adewusi, Titilayo Akinsola ati Abiodun Adewole salaye pe lootọ ni isẹ igbohunsafẹfẹ lori redio maa n mu iyi, apọnle ati ẹwa ba awọn, amọ isẹ la ri, ọwọ n kako lasan ni.
Lati iroyin ti o sẹsẹ tẹ wa lọwọ lori papa, sọ pe ajo
Finland maintain dia number one position from last year as di happiest kontri for di world.
"Osisẹ ologun kan, Onyema Nwachukwu, to ba awọn akọroyin sọrọ lọjọ Iṣẹgun ni olu ileeṣẹ ologun fidi rẹ mulẹ pe iwadii nlọ lọwọ , pẹlu afikun pe, ""abajade iwadii naa yoo di mimọ fun araalu ti asiko ba to."
Awọn obinrin to n bora jẹ ìdá mẹtadinlọgọrin.
Báwo ni ó ṣe lè lé ẹni tí ó kéré jù ninu àwọn olórí-ogun oluwa mi pada sẹ́yìn, nígbà tí ó jẹ́ pé Ijipti ni ó gbójú lé pé wọn óo fún un ní kẹ̀kẹ́ ogun ati àwọn ẹlẹ́ṣin?
Wo bí o ṣe le fi orúkọ sílẹ̀ láti gbà nínú N75b tí ìjọba fẹ́ ẹ̀ fún àwọn ọ̀dọ́ láti dá iṣẹ́ sílẹ̀ Ṣé o mọ̀ pé o leè forúkọ̀ iléeṣẹ́ rẹ̀ sílẹ̀ lọ́fẹ̀ẹ́?
"Awujọ wa kii se iwuri fun awọn eeyan ti wọn ba fi tipa lopọ lati jade sita wa fi ẹjọ sun, bakan naa ni ko si ilana atẹle lori iyara kankan lati gbe igbesẹ lori awọn ẹsun ifipabanilopọ ti wọn ba mu wa.
Ati pé kí n ṣe àlàyé nípa ètò àṣírí yìí, tí Ọlọrun ẹlẹ́dàá ohun gbogbo ti fi pamọ́ láti ìgbà àtijọ́, 
Ṣùgbọ́n, ṣe gbogbo ènìyàn ni o máa ń gbàdúrà kí òun máṣe bọ́ sínú ìdánwò!
Ẹ kéde ògo rẹ̀ láàrin àwọn orílẹ̀-èdè,ẹ polongo iṣẹ́ ìyanu rẹ̀ láàrin àwọn eniyan!
Ajọ to n mojuto iṣẹlẹ ajalu ati pajawiri nipinlẹ Eko, LASEMA ṣalaye pe ṣọọbu ti wọn ti n ta ibusun kan nibẹ ni ina naa ti kọkọ sọ ki o to ran de awọn ṣọọbu itaja miran to sun mọ ọ.
Òpin dé sórí igun mẹrẹẹrin ilẹ̀ náà.
Ko si ina ọba, ko si ẹrọ ibaraẹnisọrọ, bẹẹ si ni awọn oju popo kun fun opo ina ati waya ina ọba to ja silẹ.
Bí wọ́n ti ń gbọ́ ọ̀rọ̀ wọnyi, ó tún fi òwe kan bá wọn sọ̀rọ̀, nítorí ó súnmọ́ Jerusalẹmu, àwọn eniyan sí rò pé ó tó àkókò tí ìjọba Ọlọrun yóo farahàn.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Local Flight: Àyípadà tó bá pápákọ̀ òfurufú Abuja rèé bí ìrìnà òfurufú abẹ́lé ṣe bẹ̀rẹ̀ 12 Agẹmo 2020 Ẹ fójú lóunjẹ bi pápákọ̀ òfurufú Abuja olu ilu orilẹede Naijiria ṣe ri lasiko ti ijọba ni ki wọn bẹrẹ irina abẹle pada.
Jesu wọ inú ọkọ̀, ó rékọjá sí òdìkejì òkun, ó bá dé ìlú ara rẹ̀.
sc ) pẹ ̀ lú dókítọ ́ réti nínú ìmọ ̀ biochemistry lati yunifásítì ìlú port hacourt níbi tí ó tí padà di olùkọ ́ ìmọ ̀ biokẹ ́ mísìrì .
Yàrá àbáwọlé ilé ìsìn náà gùn ní ogún igbọnwọ, gígùn rẹ̀ ṣe déédé pẹlu ìbú rẹ̀, ó sì jìn sí ìsàlẹ̀ ní igbọnwọ mẹ́wàá níwájú.
Eyi fihan pe, ko si igba ti a fẹ ṣe nkan ti a ko ṣì le gbiyanju ẹ wo.
Amọ ifẹsẹwọnsẹ naa ko kọkọ sẹnu ire fun Naijiria, nitori ikọ Benin Republic lo kọkọ gba bọọlu si awọn Naijiria ni isẹju mẹta ti ifẹsẹwọnsẹ naa bẹrẹ.
Saraki àgbà ló kọ́ ilé yìí fáwa arúgbó kìí ṣe Bùkọ́lá- Arúgbó Ilọrin Bàbá akẹ́kọ̀ọ́ LASU tí ọ̀rẹ́kùnrin rẹ̀ àti pásítọ̀ fi ṣ'oògùn owó ń bèèrè fún ìdájọ́ òdodo Hawkins ni miliọnu meji abọ awọn ọmọde lo ṣalaisi laarin oṣu kan ti a bi wọn lagbaye.
Wò ó ọ̀nà láti mú ara rẹ dé ibi tó ga jùlọ nínú ìbálòpọ̀ pẹ̀lú ìlànà Tantra Ni ipari, igbagbọ la fi n rire gba lọwọ Olorun.
Ogagun Abdulla Khalifa Al Marri to n tukọ ileeṣẹ ọlọpaa gboriyin fun awọn ọlọpaa Dubai fun iṣẹ takuntakun ti wọn ti fi mu awọn mẹwaa naa.
Ṣaaju ni nkan bii oṣu diẹ sẹyin ni iroyin kan tan kalẹ pe o bimọ ti o si ni irọ ni awọn eniyan n pa, Ẹ dákẹ́ àhesọ ọ̀rọ̀, n kò bí ìbẹta - Yinka Ayefẹlẹ.
Bí ó ti rí i pé àwọn eniyan náà ń jáde bọ̀ láti inú ìlú, ó gbógun tì wọ́n, ó sì pa wọ́n.
Á jẹ́ bí ìrànlọ́wọ́ fún wọn láti ṣẹ́gun àwọn kòkòrò amúniṣàárẹ̀ tí wọ́n nbá jà.
Bo tile je pe ,lati odun 2009
A gbọ pe lati ile ẹkọ ni diẹ lara awọn olori naa ti n pohungbẹ lati di ayaba, ti wọn si n sunmọ awọn eeyan to wa ni aafin Ọyọ.
O kawe gba oye imọ ijinlẹ akọkọ ninu Philosophy, ni Fasiti ilu Eko lọdun 2016.
Lẹ́yìn náà, gbogbo àwọn ẹ̀yà Israẹli tọ Dafidi lọ ní Heburoni, wọ́n sọ fún un pé, “Ara kan náà ni wá, ẹ̀jẹ̀ kan náà sì ni gbogbo wa.
“Èmi ń wó ohun tí mo kọ́ lulẹ̀, mo sì ń tu ohun tí mo gbìn, bẹ́ẹ̀ ni ọ̀rọ̀ gbogbo ilẹ̀ náà rí.
Awọn aṣofin ni bi awọn sọja ṣe n foju ri oriṣiriṣi mabo lọwọ awọn jaguda kun lara idi to fi yẹ ki wọn fiṣẹ silẹ.
Ninu ọrọ tirẹ, igbakeji aarẹ, Yemi Ọsinbajo to ba gomina ipinlẹ Adamawa kẹdun, ni ki ajọ to n sakoso isẹlẹ pajawiri ( NEMA) tete pese ohun ti awọn to farapa ninu ikọlu naa nilo lasiko.
Kò sì sí ẹni tí ó là ninu wọn, àfi irinwo ọdọmọkunrin tí wọ́n gun ràkúnmí sá lọ.
Wọ́n ní, “Ọ̀gágun náà yẹ ní ẹni tí o lè ṣe èyí fún, 
Ọfà mi yóo tẹnu bọ ẹ̀jẹ̀,yóo sì mu àmuyó.
odun 1989,ti o si jẹ pe fun opolopo osu ni ko fi wa  lorile ede naa.
Ẹni tí ń fi talaka ṣẹ̀sín, ẹlẹ́dàá talaka ní ń tàbùkù,ẹni tí inú rẹ̀ dùn sí wahala ẹni ẹlẹ́ni kò ní lọ láìjìyà.
Ṣaaju ni ọdun yii, o kede pe oun ko ni dije fun ibo mọ lasiko idibo orilẹede naa ti wọn n fojusọna nigba naa pe yoo waye loṣu kọkanla ọdun yii.
O fi ero ijọba han nigba ti o gbalejo ààrẹ ẹgbẹ àwọn obinrin National Council of Women Society, Gloria Shoda, lọjọ Ẹti.
Oríṣun àwòrán, Channels Television Nigba to n ṣiṣọ loju awọn ẹri lati fidi ẹjọ naa mulẹ, Ofoma sọ pe ẹri to tẹ EFCC lọwọ lati ọdọ ajọ FBI fi han pe lootọ ni olujẹjọ naa lu jibiti ifẹ lori ayelujara.
Ti o ko ba jẹ ara ikọ ẹlẹsin Hakika, oye imọ yii ko lee ye ọ.
Iṣẹ́ àtúnṣe sí àwọn àjogúnbá ìgbàa Mughal ní mọ́ṣálááṣí Bangshal Mukim Bazar Jam-e àti mọ́ṣálááṣí Siddique Bazar Jam-e ti di ohun ìgbàgbé nítorí ojú àpá ò le è jọ ojú ara, ó ti yàtọ̀.
A kẹ̀yìn sí Atiku torí àtúntò Nàíjíríà tó fẹ́ ṣe - Árẹ̀wá Kò sí ilé ẹjọ́ kankan tó yọ mí - Gboyega Oyetọla 2019 Election: Bí Buhari ba le lọ Kóòtù ní ẹ̀ẹ̀mẹ́ta- Obasanjo Leah Sharibu ni wòlíì wa ní àgọ́ Boko Haram - Obìnrin tó jàjàbọ́ Ole ni ẹgbẹrun kan ibo ti Bala Mohammed fi bori atundi ibo gomina ipinlẹ Bauchi.
''Ìdí tí mo fi rin ìrìn 800 metres'' Serena kò gbọdọ̀ wọ aṣọ Black Panther mọ́ Oríṣun àwòrán, Instagram/Olanrewaju Malcolm Àkọlé àwòrán, Olanrewaju Malcolm kú lẹ́yìn àìsàn ọjọ́ pípẹ́ Eyi ni ọrọ asọkẹyin oloogbe lori opo Instagram rẹ ni yi pe, iyipada ti de ba oun.
N óo máa kọrin ìyìn sí Ọlọrun mi,níwọ̀n ìgbà tí ẹ̀mí mi bá ń bẹ.
Awọn amofin ijọba orilẹede Italy n fi ẹsun riba sisan kan awọn ileeṣẹ mejeeji nigba ti wọn fẹ ra kọnga ifapo OPL 245, to wa lori omi orilẹede Naijiria eyi ti wọn ni o n gbọn biliọnu mẹsan agba epo jade ti owo rẹ din diẹ ni ẹẹdẹgbẹta biliọnu naira.
Ẹ lọ ṣí gbogbo ilé ẹ̀kọ́ padà ní Nàíjíríà - Ìjọba àpàpọ̀ Nigeria schools reopening: October 4 làwọn ilé ẹ̀kọ́ yóò di ṣíṣí padà Minisita feto ẹkọ, Adamu Adamu ti kede pe ki awọn ile ẹkọ lorilẹ ede Naijiria di sisi pada.
Ojoojumọ ni iye eeyan to n ṣe iṣẹ abẹ ọyan ati idi n pọ si ni Naijiria.
to n wọle ju bi awọn ṣe lero rẹ lọ.
Ibinu OLUWA ru sí àwọn ọmọ Israẹli, ó sì mú wọn rìn kiri ninu aṣálẹ̀ fún ogoji ọdún títí gbogbo àwọn tí wọ́n ṣe burúkú níwájú OLUWA fi kú tán.
Tems ti gba ìtúsílẹ̀ lọ́gbà ẹ̀wọ̀n Uganda Òfin ìfipábánilòpọ̀ tuntun yóò fààye gba fífi kẹ́míkà tẹ ọkùnrin lọ́dàá Jide Kosoko forin sẹ́nu pé òun ni igi lẹ́yìn ọgbà Mr Latin lórí ipò ààrẹ TAMPAN tó wà Arábìnrin ẹni àádọ̀rún ọdún ló kọ́kọ́ gba abẹ́rẹ́ àjẹsára tí Pfizer ṣe síta Arabinrin ẹni aadọrun ọdun kan ti di ẹni akọkọ ti yoo gba abẹrẹ ajẹsara Covid-19 tuntun ni ilẹ Gẹẹsi.
Ṣiwaju eléyìí, Aisaya sọ bákan náà pé, “Bíkòṣe pé Oluwa alágbára jùlọ dá díẹ̀ sí ninu àwọn ọmọ wa ni, bíi Sodomu ni à bá rí, à bá sì dàbí Gomora.
N óo mú kí gbogbo ibi tí mo pinnu lórí wọn ṣẹ sí wọn lára ati sí ara àwọn tí ń gbé Jerusalẹmu ati àwọn ará Juda, nítorí pé wọn kò gbọ́ràn.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ọmọọba ilẹ̀ Gẹ̀ẹ́sì bí ọmọ ọkùnrin Ojú ń tì mí láti rí àwọn ọmọbìnrin Nàìjíríà tó ń ṣe aṣẹ́wó ní Italy"" Fashola fi orúkọ àwọn ilé isẹ́ tó jẹ́ àjẹbánu síta."
- Ìjọba àpapọ̀ Wo bi o ti ṣele ṣafikun iroyin nipa ara rẹ Kan si oju opo yii: http://www.
David Oyedepo pe Biodun Fatoyinbo si ìsìn Shiloh, ọmọ Nìíjíríà fárígá
Lati oṣu kẹta ọdun 2020 ni ileewe ti wa ni titi pa lorilẹ-ede Naijiria nitori ọwọja ajakalẹ arun COVID-19 to bẹ silẹ kaakiri agbaye.
Nítorí náà ni wọ́n Ṣe ń pe ibẹ̀ ní Sukotu.
Aare  Buhari tun ti gba iwe ẹ ku ori ire lati ọdọ awon aare  orile ede bi i aare Nana Koffi-Addo ti Ghana ati Macky Sall ti orile ede Senegal.
Òpin óo dé bá a bí àgbàrá òjò, ogun ati ìsọdahoro tí a ti fi àṣẹ sí yóo dé.
Bí àwọn ọba Filistini ti ń kọjá pẹlu àwọn ọmọ ogun wọn ní ọgọọgọrun-un ati ẹgbẹẹgbẹrun, Dafidi ati àwọn ọkunrin rẹ̀ tò sẹ́yìn ọba Akiṣi.
Igbo ẹran Gashaka Gumti wa lara awọn ohun amusagbara orilẹede yii sugbọn ti ọkan lara awọn isoro to n koju ni kiko awọn eranko inu rẹ lọ si awọn agbegbe miiran.
O ni paapaa julọ fun awọn obinrin, irufẹ idije bẹẹ yoo dara yoo si kun fun ọpọlọpọ ayọ ati idunnu.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Supplementary Election: Àwọn jàndùkú yìnbọn fún òṣìṣẹ́ Inec, Ọ̀jọ̀gbọ́n Tuluen, ní Benue 24 Ẹrẹ̀nà 2019 Oríṣun àwòrán, Twitter/Mahmood Yakubu Àkọlé àwòrán, Atundi ibo Ajọ eleto idibo orilẹede Naijiria ti sọ pe, lootọọ ni wọn yinbọn fun oṣiṣẹ rẹ kan, Ọjọgbọn C.
Otioto, ti o jẹ onidiri ti wa ninu irora ijamba ibọn lọwọlọwọ bayi.
”Lójú kan náà, afọ́jú náà bá ríran, ó bá ń bá Jesu lọ ní ọ̀nà.
Udaya Regmi, to je adari ajo arannilowo ti alagbelebu pupa Red Cross ni Paupua New Guinea, ni gbogbo ona ibanisoro ni Tari ni o baje nigba ti ko seese fun enikeni lati kan si enikeji re nipa lilo ona ibanisoro igbalode Kankan, O ni eyi ni ko je ki o le seese fun ajo Kankan lati le so ni pato odiwon isele naa ati iye awon nkan to baje.
Ilu Iwo ló yẹ kó kọ́kọ́ jẹ́ Sultan àkọ́kọ́ ní Nàìjíríà - Oluwo Iléeṣẹ́ ọmọ ogun dá Bashir tó ri owó he lọ́lá Etí ìjọba Buhari di sí ìmọ̀ràn àwọn ará ìlú -Jiti Ogunye WAEC gbé èsì ìdánwò WASSCE jáde Awọn ẹlẹsin Shia naa n beere fun itusilẹ adari wọn, El-Zakzakky to ti wa ni atimọle ijọba lati ọdun 2015 lori ẹsun pe wọn n da ilu ru.
Oṣere naa ko le pa idunnu rẹ mọra rara.
Ojelade gba ade Arẹkujaye ni gbogbo ilẹ Oyo nigba naa to si di olokiki to lowo, to lọrọ pẹlu iranlọwọ iyawo rẹ ti oun naa wa lati ile eleegun pẹlu.
Ọpọ orileede agbaye lo tin fi ofin de awọn arinrin ajo lati UK lojuna ati fopin si ẹya tuntun ti Coronavirus gbeyọ Orile-ede France fofin de awọn ero ati eru oju omi lati to n bọ lati UK, eyi si ti fa rukerudo ni awon enu ibode ori omi ni iha Guusu ile Geesi ti won pe ni 'British port of Dover'.
Oríṣun àwòrán, AFP Àkọlé àwòrán, Ọjọ Aje ni esi idibo naa jade lẹyin ti ile ẹjo gbe idina kuro lori esi idibo naa.
Elisha Abbo: Ẹ̀sìn àti ẹ̀kọ́ ilé tí mo ní kò gba ká na obìnrin
Àjẹsára náà wà gẹ ́ gẹ ́ bí èyí tó dá dúró fúnrarẹ ̀ àti bí èyítí a ṣe pọ ̀ pẹ ̀ lú àwọn àjẹsára mìíràn bíi àjẹsára rubella ( àjẹsára àrùn ìta jámínì ) , àjẹsára ṣegede , àti àjẹsára varicella ( àjẹsára àrùn ọfà ṣọ ̀ pọ ̀ nná tàbí ilẹ ̀ gbóná ) ( àjẹsára mmr àti àjẹsára mmrv ) .
Pásítọ̀ Fatoyinbo fi ipò sílẹ̀ fún ìgbà díẹ̀ nítorí ẹ̀sùn ìfipábánilòpọ̀ Damasus, Omotola, Ezekwesili, Funmi Iyanda dá sí ẹ̀sùn ìfipábánilòpọ̀ Fatoyinbo Ìjọ Satani dá MI lóhùn lórí ọ̀rọ̀ Fatoyinbo Ọkọ mi kò le f'ipá bá ẹnikẹ́ni lò pọ̀ láíláí - Modele Fatoyinbo Iwọde ṣe lodi si ẹsun ifipabanilopọ yii waye ni ilu Abuja to jẹ olu ilu Naijiria ati Ikeja ni ipinlẹ Eko.
Ọlọ́pàá fi páńpẹ́ ọba mú ọmọ ogun ilẹ̀ Naijiria Wo ohun tó yẹ kí o mọ̀ nípa àwọn obìnrin méje ti Buhari forúkọ wọn ránṣẹ Kò lè ṣééṣe kí Ruga wà lápá gúúsù Nàìjíríà fáwọn Fulani- Ganduje Èmi kò ní kí Shiite má ṣe ẹ̀sìn won o -Muhammadu Buhari Adedamola Kúti ní bí i kìlómítà kan ó lé ọwọ́ mẹ́rin tí wọ́n fẹ ṣe àtúnse rẹ̀ láti Berger si afára Kara bẹ̀rẹ̀ láti ọjọ́ Satide.
Lẹyin naa lo sọ pe awọn eeyan le lọ gba fọọmu naa lojo opo Amotekun to wa ni www.
O le ni miliọnu meji alalaaji to maa n kopa ninu Hajj ọlọdọọdun yi.
Ọga ọlọpaa ni ipo ti awọn to farapa gan wa nile iwosan bayii kọja afẹnusọ.
00) ni wọ́n ra ilẹ̀ náà.
Nisinsinyii ìwọ náà ti dàbí rẹ̀; o ti di ẹni yẹ̀yẹ́ lọ́wọ́ àwọn ọmọbinrin Edomu ati àwọn tí ó wà ní agbègbè wọn, ati lọ́wọ́ àwọn ọmọbinrin Filistini, ati àwọn tí wọ́n yí ọ ká, tí wọn ń kẹ́gàn rẹ.
Ènìyàn 226 ló ní àrùn Coronavirus ní Ọjọ Ìṣẹ́gun Eniyan okoolerugbaolemẹfa lo tun ṣẹṣẹ ni arun Coronavirus ni Naijiria ni Ọjọ Iṣẹgun.
Àwọn ọmọ Israẹli bọ́ sí ààrin òkun náà lórí ìyàngbẹ ilẹ̀, omi òkun wá dàbí ògiri ní ẹ̀gbẹ́ ọ̀tún ati ní ẹ̀gbẹ́ òsì wọn.
Onwoye naa ro pe awọn obi ni iṣẹ pupọ lati se nipa kikọ awọn ọmọ wọn lọna ti o tọ.
Ayo Akinwale ti jẹ adari patapata ẹka imọ ẹkọ Tiata, Performing Arts ni Fasiti Ilorin ati oludari agba ẹka isẹ ọna ni fasiti kan naa ko to jẹ Ọlọrun nipe.
Saulu ju ọ̀kọ̀ náà, ó ní kí òun fi gún Dafidi mọ́ ògiri, ṣugbọn Dafidi yẹ̀ ẹ́, ọ̀kọ̀ náà wọ ara ògiri, Dafidi bá sá lọ.
Ni se ni iro ibọn gbalẹ.
Ninu eyi, o lo igba ọjọ ole mẹtadinlogun ni Ilẹ Gẹẹsi nibi to ti lọ gba itọju.
Wọ́n to òkúta olówó iyebíye sí i lára ní ẹsẹ̀ mẹrin, wọ́n to òkúta sadiu ati topasi ati kabọnku sí ẹsẹ̀ kinni, 
miiran lati ilẹ Afirika lo si orile ede agbaye” .
Iyawo rẹ sọ fun awọn oniroyin wi pe nigba ti wọn mu ọkọ oun, oun ati ọmọ oun wa nibẹ.
Láti Tẹra wọ́n lọ sí Mitika.
A leè ṣe àpèjúwe rẹ bii oloselu to dantọ, onímọ̀ ìṣirò to pegede àti ojúlówó ọmọ Ibadan tó yanranti Ọjọ́ Kẹrìnlá, oṣù Kẹrin, ọdún 2020 ni Olunloyo pé ẹni ọdún marundinlaadorun lókè eepẹ.
Gẹ́gẹ́ bí ẹ̀ṣẹ̀ ṣe ti ipasẹ̀ ẹnìkan wọ inú ayé, tí ikú sì ti ipasẹ̀ ẹ̀ṣẹ̀ wọlé, bẹ́ẹ̀ náà ni ikú ṣe ran gbogbo eniyan, nítorí pé gbogbo eniyan ni ó ṣẹ̀.
apapọ tun lodi si awon ahesọ ọrọ ti won n sọ nipa aare Buhari pe yoo da si eto
Ogbeni Femi Odunsanya, ti o je onimo lori efo ni oja igbalode Mile 12 nipinle Eko so pe, gbogbo awon omo-egbe ajo ECOWAS ni inu won ko dun si bi won se n se ise naa, ni eyi ti won n mu ki eto kara-kata je isoro ni ekun naa.
Nigba tí Saulu gbọ́ èyí, ẹ̀mí Ọlọrun bà lé Saulu inú sì bí i gidigidi.
ti ko fi ni pa igbaye-gbadun awon omo orile ede Naijiria lara.
Lo ba bẹrẹ si ni ro o pe ta a ni oun ṣẹ to fi iru nkan bẹ kan ọmọ oun.
Asoju ajo UNICEF lorile-ede Naijiria, Mohamed Malick Fall, so pe, inu ako UNICEF dun pupo pe, awon omode-binrin ti won jigbe lojo kokandinlogun osu keji odun 2018 ti pada sodo awon ebi won.
Seyi Makinde: Ẹ̀kọ́ ọ̀fẹ́ tó pọn dandan ti bẹ̀rẹ̀ nílé ẹ̀kọ́ alákọ̀ọ́bẹ̀rẹ̀ àti girama ní Ọyọ
Fun 'ofofo' to ba jẹ mọ iwa ibajẹ, ẹni to ba tu aṣiri ọrọ naa yoo gba ida meji ataabọ owo ti ijọba ba ri gba.
Ó bẹ̀rẹ̀ síse eré gan ní ọdún 1991 ó sì gbé fíìmù àkọ́kọ́ rẹ̀ tó fọwọ́ kọ ní ọdún 1991.
O fin kun un pe ọdunrun o le ọgbọn miliọnu naira (N330m) ni wọn ti ko jọ bayii gẹgẹ bi owo fun imayedẹrun awọn eeyan ipinlẹ Ọyọ.
 iye tí ó ju ìwọ ̀ n ọgọsan nínú ọgọrun ( 80 % ) lọ lára àwọn ènìyàn wọ ̀ nyí ni wọ ́ n wà ní orílẹ ̀ -èdè olómìnira ti kongo .
O ti pe ọdun mẹjọ ti ẹlẹsẹ ayo, Rashidi to gba goolu sawọn julọ fun Naijiria di oloogbe.
Ṣugbọn o ṣalaye pe ile-ẹjọ ni yoo dajọ to yẹ fun Aafa ariran Hammed lẹyin ti ọrọ naa ti de ile-ẹjọ bayii.
Iroyin to tẹ wa lọwọ sọ wi pe ko si ẹni to dibo fun Nwosu ni wọọdu naa.
Eyi n waye lẹyin bi jiji ẹru ẹlẹru ko ṣe n waye laipẹ yii ni lemo lemo ni Naijiria lara rẹ ni awọn nkan to yẹ ko jẹ awọn nkan irọrun fun pinpin lasiko Covid 19, awọn ọja nile itaja nla nla ati awọn nkan ini awọn eeyan jankan jankan lawujọ.
Isegbe said that the UN listed Nigeria because “we travel a lot; and also because of our Isegbe salaye wi pe, ajo UN daruko orile-ede Naijiria toripe, “a je arin irinajo pupo ati pe, a tun po niye pelu olokan-o-jokan akitiyan wa”.
Wọn kò ròhìn mi fún ọ rí ni ndan?
Ó yà mi lẹ́nu láti gbọ́ pé ìwọ ssúnmọ́ òde ọ̀run tó bẹ́ẹ̀ tí ó fi jẹ́ pé ògiri kan ni ó pín ilé rẹ ní ìyà pẹ̀lú ọ̀run.
Oríṣun àwòrán, Facebook Àkọlé àwòrán, Onimọ ẹrọ ni Obafẹmi Hamzat Hamzat to jẹ ẹni ọdun mẹrinlelaadọta kẹkọ gboye imọ ẹrọ eto ọgbin ni fasiti Ibadan.
Leyin to ki wọn kaabọ tan lo lo sọrọ lori pataki ninawo si idagbasoke irinajo afẹ gẹgé bii ọna okowo tuntun ti oju ṣẹṣẹ n ṣi si bayii.
Oríṣun àwòrán, Screenshot/instagram/ronke odusanya Koda, o pe e ni 'baba to dara julọ ni agbaye'.
Bótilẹ̀ jẹ̀ pé, ní ẹnu lọ́lọ́ yìí ọ̀ps àwọn eléré orí ìtàgé lọ n fi àwọn irú ǹkan báyìí dá awọn olólùfẹ́ wọ́n lárayá.
O dabi ki gomina ipinlẹ Oyo lọ si Ekiti, lọ maa da si ọrọ oṣelu wọn, yoo gba eebu ati abuku bọ ni, tori aja kii roro, ko ṣọ ojule meji.
tí ewé rẹ̀ lẹ́wà, tí ó so jìnwìnnì, tí èso rẹ̀ jẹ́ oúnjẹ fún gbogbo ẹ̀dá, tí gbogbo àwọn ẹranko ń gbé abẹ́ rẹ̀, tí àwọn ẹyẹ sì ń sùn lórí àwọn ẹ̀ka rẹ̀.
Bawo ni awọn eniyan ṣe ri aarẹ Trump lagbaye?
Bakan náà lọmọ sori ní Zamfara, bi gomina àna nibẹ Ahmed Sani ṣe fẹ́ ọmọ ọdun mẹ́rindinlogun to jẹ́ ọmọ orilẹ̀-èdè Egypt gẹ́gk bi ìyàwo kẹta ko to kurò lori oye.
O wi pe ile-iṣẹ naa yoo yi oruko
Lẹ́yìn èyí, wọ́n kó àdá fún wa, a múra ó di inú igbó tí Ẹlẹ́dàá pa láṣẹ́ pé kí Adéforítì fi kọ ilẹ̀ ìgbéga-ọ̀run.
Amọ, ọpọ eniyan ni ero wipe, ọrọ Aarẹ Donald Trump nipa isekupani awọn Kristeni lorilẹede Naijira lee mu ki ija ẹlẹsinjẹsin gbilẹ si.
Oluwo ni Sultan tumọ si Ọba lede Yoruba.
1 Ọ̀pẹ̀̀ 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 1 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Ọjọ Kini, Osu Kejila, ọdọọdun ni Ajọ Agbaye fi silẹ lati maa fi se ayajọ ọjọ kokoro aarun HIV to lee sekupani.
Nítorí náà ẹni tí ó bá fi pẹpẹ ìrúbọ búra, ati pẹpẹ ati ohun gbogbo tí ó wà lórí rẹ̀ ni ó fi búra.
Ohun ti ẹgbẹ oṣelu PDP n sọ Ninu atẹjade kan to fi sita lori ikanni twitter rẹ, gbajugbaja olorin taka sufe naa ti ọpọlọpọ mọ si ọmọ baba olowo ti sọ pe, bi o ti wulẹ o ri, omimi kan ko lee tori eyi mi atilẹyin oun fun aburo baba oun lati di gomina nipinlẹ Ọṣun nitori ọmọ ẹni ko le ṣedi bẹbẹrẹ ka sin ilẹkẹ si idi ọmọ ẹlomiran.
Wọn lai jẹ bẹẹ, awọn to maa ṣegbe si inu omi okunyoo tubọ maa pọ si.
Texas Walmart shooting: Èèyàn ogún pàdánù èmi wọn ninu ìyibọ́npanìyàn El Paso
Iorapuu sọ pe awọn bisọbu n ṣe'pade lọwọ nigbati ikọlu awọn darandaran naa ṣẹlẹ ni ipinlẹ naa.
Nítorí pé Ọ̀sanyìnnínbí jẹ́ ọ̀gá fún àwọn olè wọ̀nyí, wọ́n mú un lọ sí Àgọ́ ọlọ́pàá tí ó wà ní Morèmi ní ilé-Ifè.
Báyìí ni wọn yóo fi ṣe ẹ̀kọ́ Ọlọrun Olùgbàlà wa lọ́ṣọ̀ọ́ ninu ohun gbogbo.
Nitori bi lilọ bibọ ti ṣe pọ nibẹ, ọpọ eeyan lo ma n ha si inu sunkẹrẹ fakẹrẹ ati pe awọn ọkọ nla a ma saba bajẹ si ọna naa ti o si jẹ idiwọ nla.
 moller-maersk group fọwọ ́ sí pẹ ̀ lú united states district court for the southern district of new york ní ọdún 2005 , àwọn kan tí wọ ́ n ń gbé ní kuwait lu a.
O ni ọrẹ oun kan lo ni ki oun ba oun san owo naa si apo àsùnwọ̀n kan, eyi ti ko tako isẹ oun gẹgẹ bi oṣiṣẹ banki.
Saraki pa Akpabio lẹ́nu mọ́, lọ̀rọ̀ bá di ariwo ‘Omo-Agege ló da ìjókòó ilé rú’ Lọjọ kọkanla oṣu Kaarun ni awọn ọmọ ile aṣofin agba yoo dibo yan ẹni ti yoo jẹ olori wọn.
Hemani wà pẹlu wọn, ati Jedutuni ati àwọn mìíràn tí a yàn, tí a sì dárúkọ, láti máa dúpẹ́ lọ́wọ́ OLUWA nítorí ìfẹ́ ńlá rẹ̀ tí kì í yẹ̀.
odun merin miiran, mo si tun  mo pe
O ní gbogbo ìgbà ni àwọn ènìyàn ń wá ti ǹkan tó n ṣe wọ́n sì jọ mọ́ ààrùn Covid-19 sùgbọ́n kò sí ẹrọ àyẹwó àti pé ni ọ̀pọ̀ ìgbà ni àwọn máa n dari wọ́n lọ si ilú Abuja.
COZA: Ìlú tí ọdaràn ba tí dẹṣẹ ló yẹ kí wọn tí gbẹ́jọ́ rẹ̀ -Agbẹjọ́rò
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Obateru Akinruntan: Wíwá ohun tá jẹ títí láé ló gbé wa kúrò nílé Ife Oyinkansola Abayomi ko tun gbẹyin ninu oselu, to si n rọ awọn araalu lati maa kopa ninu eto iselu labẹle, ki wọn si jija gbara fun ominira Naijiria.
Àwọn ọ̀tá Nàíjíríà tó fẹ́ dojú ìjọba bolẹ̀ ló wà lẹ́yìn ìwọ́de EndSARS Oríṣun àwòrán, @GovKaduna Awọn gomina lẹkun ariwa Naijiria ti sọrọ lori rogbodiyan to gbode kan lati ipasẹ iwọde EndSARS.
Laarin oṣu mẹta pere, Samuel ti bọ si kilaasi kẹrin lati ikinni.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ibùdó àyẹ̀wò àwọn ológun Iroyin sọ pe ni Ọjọru ni awọn sja fipa ba akẹkọ ẹka imọ nipa ẹsin ati ẹkọ ilẹ Afirika ni fasiti naa lo pọ ni ibudo ayẹwo awọn ologun to wa ni opopona Ikare Akoko.
Orilẹede naa ti polongo oogun ohun gẹgẹ bi oogun to n dena to si n ṣewosan fun arun naa, ti wọn si ti fun awọn akẹkọọ to wa nile iwe mu lati bi oṣu mẹrin ṣẹyin.
A to ni oju opo Twitter naa ti jade lati ṣalaye pe aimọọsọ oun ni ko jẹ kawọn eeyan mọọ gbọ nitori pe kii ṣe awọn ti wọn le lẹnu iṣẹ ọlọpaa nikan lo wa ninu orukọ ti oun gbe sita.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Làá hàn mí: Ètò yìí ló ń kìlọ̀ fún wa láti mú ìmọ́tótó ní pàtàkì láti dènà Coronavirus Coronavirus: Èèyàn mẹ́rin míràn ní àrùn Coronavirus ní ìpínlẹ̀ Èkó Oríṣun àwòrán, Getty Images Ẹẹdẹgbeje (1300) awọn eeyan lawọn ileeṣẹ eto ilera n wa bayii lori itankalẹ arun coronavirus ọhun.
Ó ṣe èyí láti yà á sọ́tọ̀.
Awọn ti wọn farapa ti le ni igba.
Ẹ̀yin ìran yìí, ẹ gbọ́ ohun tí èmi, OLUWA ń sọ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ojojúmọ ní mọ ń kẹ́kọ̀ọ́ lára ọmọ mi to jẹ akanda Ṣugbọn amofin Remi Adeoye ṣalaye pe labẹ ofin, idajọ ile ẹjọ giga l'Abuja ọjọ Iṣẹgun ti fagile idajọ igbimọ igbẹjọ eto idibo(Tribunal) to sọ pe Sẹnẹtọ Ademola Adeleke lo wọle ibo gomina Ipinlẹ Oṣun.
"Ilé ẹjọ́ pàṣẹ kí Sẹ́nétọ̀ Elisha Abbo san N50m fún obìnrin tó fìyà jẹ Mi o fi ìgbà kankan sọ pé Buhari ni yóò jẹ ààrẹ kẹ́yìn ní Nàìjíríà- Akintoye ""Lẹyin ti a gbọ iroyin yii, a lọ sibẹ, amọ awọn afurasi mẹrin naa ti ge ori oku, ti wọn si salọ, sugbọn bi a ṣe bẹrẹ iwadii lẹkunrẹrẹ niyẹn, eleyii to jẹ ki a ri tọkọ-taya naa mu pẹlu Muyideen Tolubi."
Ẹ̀bùn tí ó fún un ju èyí tí òun alára mú wá lọ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù UFC245: Kamaru Usman, f'ẹ̀ṣẹ́ borí ààyò Trump, Colby Covington ní ìjà UFC 15 Ọ̀pẹ̀̀ 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Bii bara ni abẹṣẹkubiojo ọmọ orilẹede Naijiria, kamaru Usman lu Colby Covington ti wọn jọ koju ija lowurọ ọjọ aiku lati ṣi wa nipo to ni akọle rẹ, welterwwight ni idje UFC 245.
Ilẹ naa tun sọ pe Etete ni ẹgbẹlẹgbẹ owo bi ọgọrun biliọnu owo dọla ti o ko pamọ.
Láti ànà ti oníruurú àwọn ọ̀dọ́ ní ìpińlẹ̀ Eko àti jákèjádò àwọn ìpínlẹ̀ kan ni Nàìjíríà ti bẹ̀rẹ̀ ìwọ́de ìfẹ̀hónú hàn, owúrọ òní ni àwọn míràn ṣẹ̀ṣẹ̀ lọ sí ilé wọ́n.
Lara awọn ipinlẹ naa ti yoo tun ni ipin ninu lilo ẹrọ Diroonu naa ni Kaduna, Anambra, Ebonyi, Benue ati Enugu.
 o je eni ti ko beru eniyan , ti o si maa n so otito oro.
 Àwọn tó ti ilẹ ̀ tápà wá ń bẹ ní Ọ ̀ ra , àwọn tó ti kàbbà wá sì ń bẹ níbẹ ̀ báyìí- àwọn ni ọmọ , olújùmú .
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Colorado ni Amẹrika àti odò Awaye ní Naijiria nikeji àdágún órí àpáta ní gbogbo àgbáyé!
Wọ́n dá a lóhùn pé, “A óo fi tayọ̀tayọ̀ kó wọn fún ọ.
Ẹwẹ, awọn eeyan ọọdunrun le ni mẹrindinlogun miran lo ri iwosan ti wọn si ti ni ki wọn maa lọ ile wọn layọ ati alaafia.
Samuel Eto'o ọmọ Cameroon naa gba ami ẹyẹ naa lẹẹmẹrin ṣugbọn kii ṣe lerawọn.
Iya Rainbow, Jide Kosoko, Ọga Bello, yóò polongo Buhari fún 2019 ASUU pahùndà, ó fẹ́ kópa nínú àkóso ìbò 2019 Bayii, Alao Akala ni oludije fun ipo gomina lẹgbẹ oṣelu ADP ni ipinlẹ Oyo.
N jẹ ẹ ti ri ibi ti olukọ ti fẹgba lu akẹkọọ pa ri?
" Mọrèmi Àjàṣorò, akọni obìnrin tó gba Ilé Ifẹ̀ sílẹ̀ lóko ẹrú Ọ̀rọ̀ǹpọ̀tọ̀niyùn, Aláàfin obìnrin àkọ́kọ́ rèé, tó ní nǹkan ọkùnrin Ṣé ìwọ mọ odò adágún Adó Àwáyè tí kò ní òpin ní ìsàlẹ̀?
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Nollywood: Bẹbẹ ń lọ ní ibùdó yíya sinimá Àgbésọrísùn Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Nollywood: Bẹbẹ ń lọ ní ibùdó yíya sinimá Àgbésọrísùn 4 Èbibi 2019 Sinima ṣiṣe lorilẹede NAijiria ti di itẹwọgba lagbaye, ṣugbọn bawo ni awọn sinima yii ṣe n parapọ di ohun ti araye n tẹwọgba?
Àwọn tí wọ́n kọlà ti ara, tí wọ́n fi ọwọ́ kọ sì ń pè yín ní aláìkọlà.
Ilé-isẹ́ Ológun gbọdọ̀ sèwádìí bí ọmọogun se pa ọlọ́pàá - Buhari Iṣẹlẹ to fa bi afurasi ajinigbe naa ti ṣe sa lọ mọ ofin lọwọ ni ọjọ kẹfa, oṣu kẹjọ, ọdun 2019 fa ọpọ arinyanjiyan laarin ile iṣẹ ọlọọpa ati awọn ọmọ ogun.
Ẹnikẹ́ni kò gbọdọ̀ jẹ ẹran tí ó bá kan ohun àìmọ́ kan, sísun ni ẹ gbọdọ̀ sun irú ẹran bẹ́ẹ̀.
Àwọn kan ń sọ pé, “Johanu Onítẹ̀bọmi ni ó jí dìde ninu òkú, òun ni ó jẹ́ kí ó lè máa ṣe iṣẹ́ ìyanu bẹ́ẹ̀.
Lootọ mejimeji l'Eduwa da eniyan, gẹgẹ bi awọn agba ṣe maa n sọ, ṣugbọn ọrọ yii ko pa olori lẹrin rara.
Kí alufaa jáde kúrò ninu àgọ́, kí ó sì yẹ̀ ẹ́ wò bí àrùn ẹ̀tẹ̀ náà bá ti san.
  Agbaje, sọ  pe ko si irọ patapata gbaa nip e awon janduku
“Arakunrin yóo fi arakunrin rẹ̀ fún ikú pa; baba yóo fi ọmọ rẹ̀ fún ikú pa.
Ẹgbẹ oselu PDP ti ke si adari ẹgbẹ oselu APC lorilẹede Naijiria, Aṣiwaju Ahmed Tinubu lati tọwọ ọmọ rẹ bọṣọ lori bi o ṣe n tẹnu bọlẹ lori ọrọ ẹgbẹ oṣelu PDP.
nígbà tí Gehasi, iranṣẹ Eliṣa, sọ ninu ara rẹ̀ pé, “Olúwa mi jẹ́ kí Naamani ará Siria yìí lọ láì gba ohun tí ó mú wá lọ́wọ́ rẹ̀.
Cure for coronavirus: Ìjọba ti sún wa kan ògiri ló jẹ́ kí a daṣẹ́ sílẹ̀
RCCG Oríṣun àwòrán, RCCG Àkọlé àwòrán, Pasitọ Enoch Adeboye.
Àánú rẹ̀ ṣe ni ṣùgbọ́n Èṣù ko tilẹ̀ sọ pé òun gbọ́ nǹkan tí ó ń sọ, o wí fún Adéforítì pe ẹni tí o ri yìí ti rán àwọ̀ ẹranko mọ́ ènìyàn lára lóde ayé ó sì ti fa ẹni náà fún kìnìhún pa jẹ, o ti gbé ènìyàn sínú pósí láàyè, ó sì ti ní kí wọ́n so okún mọ́ ẹnìkan lápá àti lẹ́sẹ̀ àwọn ìránṣẹ́ ès]u méjì fà á, wọ́n ń fi í ra iná ìléru tí ó tóbi tí o ń jo tí ó gba gbogbo àgbègbè ibẹ̀ lọ, ọkùnrin yìí ń ké ṣùgbọ́n wọn kò fi í sílẹ̀ bẹ́ẹ̀ ni kò kú.
Ọpọlọpọ orilẹ-ede fofin de awọn ti fifi ẹjẹ wọn silẹ lewu pupọ.
“Nígbà tí ẹ bá rí i tí ogun yí ìlú Jerusalẹmu ká, kí ẹ mọ̀ pé àkókò tí yóo di ahoro súnmọ́ tòsí.
Ó lọ sí ilé-ẹ ̀ kọ ́ alákọ ̀ ọ ́ bẹ ̀ rẹ ̀ ti Ìjọ elétò àti ilé-ẹ ̀ kọ ́ mọdá ti Ìjọ yìí kan náà ní ìlú Ìgàngàn .
Èmi fúnra mi ni n óo wá àwọn aguntan mi, àwárí ni n óo sì wá wọn.
Ninu atẹjade ti Adari ikọ Iroyin Gomina Seyi Makinde, Taiwo Adisa fi lede fihan pe kii ṣe igba akọkọ ni yii ti gomina naa n ṣe ayẹyẹ yii.
Mercy ni Luminee gba adura fun oun pe ki ọdun yii to pari, oun naa yoo ni ile ti ara oun, ti oun si fesi pada pe ko fi oun silẹ, nitori ile ti oun n kọ lọwọ, oun ko tii pari rẹ.
Atamatase iko agbaboolu FC Barcelona, Lionel Messi ko ni gba boolu fun ose meta gbako lataari ifarapa owo ti o ni ninu ifesewonse iko ohun to waye lojo abameta(Saturday) pelu iko agbaboolu Sevilla.
Omi bo gbogbo àwọn erékùṣù, a kò sì rí ẹyọ òkè kan mọ́.
Agbẹ́sùnmọ̀mí ni ẹni to pa ẹ̀nìyàn méjì ní ìlú London!
Peter Mutharika di ààrẹ ilẹ̀ Malawi lẹ́ẹ̀kejì
Lara awọn mii ti wọn tun jọ kopa ninu ere ọhun ni Yemi Blaq, Nkechi Blesssing, Bolanle Ninalowo, Peters Ijagbemi ati awọn mii.
Ni tirẹ, Aarẹ Donald Trump kede loju opo Twitter rẹ lẹyin to gbọ iroyin ikọlu naa pe, 'Ko si giri'ati pe awọn ko ti i ṣe ayẹwo ọwọja ọṣẹ ti ado oloro naa ṣe.
 Igbora -eniye ati ifowosowopo nipa pipese  alaafia ni a  nilo lati ni  awujo to se e gbe.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù 2019: Marlian, òfégè ìgbéyàwó Buhari, Fatoyinbo àtàwọn ìṣẹ̀lẹ̀ ńlá tó mi ìgboro tìtì ní 2019 Busayo Akogun Broadcast Journalist, BBC Yoruba 29 Ọ̀pẹ̀̀ 2019 Oríṣun àwòrán, OTHER Oriṣiriṣi iṣẹlẹ apanilẹrin, arikọgbọn, ibẹru, ati bẹẹbẹ lọ lo ṣẹlẹ ni orilẹede Naijiria ni ọdun 2019.
Ni ipari, Salami ki ijoba apapo fun akitiyan re lati so oko oju irin ji ni Naijiria lati fi ja ekun guusu mo ekun ariwa ni eyi ti o gba pe yoo je ki kiko eran osin lati ibi kan si ikeji tubo rorun sii.
 Ó jẹ ́ sáyẹ ́ nsì àwùjọ ( a term with which it is sometimes synonymous ) tó únlo oríṣi ọ ̀ nà ìwádìí oníìrírí and critical analysis láti ṣàgbédìde àpapọ ̀ ìmọ ̀ nípa àgbéṣe àwùjọ ọmọnìyàn .
Bi o tilẹ jẹ pe ọrọ aje Naijiria lo dagun nigba naa ti ijọba rẹ ko fi ri owo oṣu san, amọ eyi ko ni ki ẹnu ma kun Ajimobi.
Ẹ máa lépa àwọn ohun tí ó wà lọ́run, ẹ má lépa àwọn ohun tí ó wà láyé.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ọlọ́pàá Ìpínlẹ Ondo: Egúngún tó pa ọ̀dọ́kùnrin yóò fojú ba Ilé- Ẹjọ́ 6 Ọ̀wàrà 2018 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 10 Ọ̀wàrà 2018 Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Femi Joseph: Egungun to pa ọdọkunrin yoo foju ba Ile- Ẹjọ Ile-Isẹ Ọlọ́pàá Ìpínlẹ Ondo ti fi panpẹ ọba mu eleegun kan ti wọn pe orukọ rẹ ni Olu Olowokere lori ẹsun pe o gun arakunrin kan to sẹsẹ ri isẹ pa.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Lamidi Adeyẹmi: Ọmọọba mẹ́wàá ló du òyè pẹ̀lú Adeyẹmi, tó sì já mọ́ ọ lọ́wọ́ 26 Èbibi 2018 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 15 Ọ̀wàrà 2020 Oríṣun àwòrán, @Alaafinofoyo Àkọlé àwòrán, Ọba Adeyẹmi gbafẹ, o gboge, to si rẹwa lọkunrin Ọba Lamidi Ọlayiwọla Adeyẹmi Kẹta, ti pe ẹni ọdun mejilelọgọrin loke eepẹ bẹẹ lo ti lo ọdun mọkandinlaadọta lori itẹ awọn baba nla rẹ.
Má ṣe jẹ oúnjẹ ahun,má ní ìfẹ́ sí oúnjẹ aládìídùn rẹ̀;
Rebeka jẹ́ ọmọ Betueli, ará Aramea, tí ń gbé Padani-aramu, ó sì tún jẹ́ arabinrin Labani, ara Aramea.
Jẹ́ kí n sọ ìtàn mẹ́ta fun yín tí a gbọ́ lẹ́nu Ìtándìran.
Ẹ̀yin ará mi, kò yẹ kí èyí rí bẹ́ẹ̀.
Ọna lati wa ibudo ti yoo ti gba itọju, eyi ti owo rẹ ko wọn lo gbe pada si orilede South Afrika, to si ri iwosan nibẹ.
“Ìbànújẹ́ àwọn tí ń sá tọ ọlọrun mìíràn lẹ́yìn yóo pọ̀:Èmi kò ní bá wọn ta ẹ̀jẹ̀ sílẹ̀ fún ìrúbọ,bẹ́ẹ̀ ni ẹnìkan kò ní gbọ́ orúkọ wọn lẹ́nu mi.
Awọn mẹrin miran ti awọn ajinigbe naa jigbe lọ ni Oludije sipo sẹnetọ lẹkun idibo ariwa ni ipinlẹ Ondo lẹgbe oṣelu ADC, Jide Ipinsagba, Ọmọọbabinrin Funmilayo Abdulraman to jẹ aṣaju awọn obinrin ni Guusu Ondo, Abẹsinkawọ Alaga, Arakunrin Idowu ati awakọ wọn.
very feminine : n ; ) ( the teacher taught the student feminine gender .
Dr Gomba Fortune jẹ Ọlọrun nipe, a ko mọ ṣugbọn ọrọ naa gbode kan.
Láti ìgbà náà ni iṣẹ́ ti ń lọ níbẹ̀ títí di ìsinsìnyìí, kò sì tíì parí.
Ó wá bi í pé, “Kí ni o ní sọ fún mi?
Ó fi wọn ẹgbẹrun igbọnwọ, (mita 450).
Wọn yóo bèèrè ọ̀nà Sioni, wọn yóo kọjú sibẹ, wọn yóo sì wí pé: ‘Ẹ wá, ẹ jẹ́ kí á darapọ̀ mọ́ OLUWA, kí á sì bá a dá majẹmu ayérayé, tí a kò ní gbàgbé mọ́ títí ayé.
Iku o dọjọ, bẹẹni ko doṣu, gbogbo wa la dagbada iku' Ni ọjọ Aje, ọjọ karundinlogun ni Sẹnetọ Adebayọ Oṣinọwọ jade laye lẹyin aisan ranpẹ.
Àrà ọ̀tọ̀ inú orin tó jáde lọ́dún 2018 ní Nàìjíríà Àwọn òṣèré tíátà Yorùbá ọkùnrin tí ó rẹwà Ni kete ti wọn kede rẹ pe oun ni omidan tuntun fun ilẹ Afrika, to si n rin, yan fanda lori itage ni ina dede gba mọ irun ori rẹ.
Inu ijọ 'Redeemed' kan ni wọn pa Uwaila Vera Omozuwa si, nitosi ile awọn obi rẹ.
Ǹ bá gba ọ̀dọ̀ yín lọ sí Masedonia, ǹ bá sì tún gba ọ̀dọ̀ yín lábọ̀.
Saraki wa bu ẹnu atẹ lu bi awon osise eleto
O ni awọn janduku naa pa ọlọpaa meji ni agọ wọn to wa ni Orile, bẹẹ ni wọn tun ṣe ogunlọgọ ọlọpaa leṣe, ki wọn to dana sun awọn agbegbe mẹwaa mii, ti awọn ọlọpaa maa n korajọ si.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Owu Water Fall: Ọba Oyewole ni ibùdó ìrìn àjò afẹ́ gidi ni àmọ́ ọ̀nà ibẹ̀ burú jáì Fidio ọhun si lo safihan bi Abbo se n rọjo igbaju lu obinrin kan nile itaja nilu Abuja.
Wo bí ètò ìsìnkú Tolulope Arotile ṣe lọ nílùú Abuja Ilé ẹjọ́ wọ́gilé ìgbẹ́jọ́ Olalekan 'Woodberry' Pọnle Bí o bá ń se N-Power tóo sì ti ríṣẹ́ sí ibòmíràn, olè ni ọ́!
BBC 100 Women 2019: Wo ọmọ Nàíjíríà kan tó wà nínú wọn Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Painter: Samuel ni ìdàgbàsókè Nàìjíríà ló jẹ òun lógún!
Olùrànlọ́wọ́ pàtàkì fún Gómìnà ìpínlẹ̀ Edo, Godwin Obaseki lórí ìfàyàwọ́ ọmọnìyàn àti ìrìnàjò kúrò nílùú lọ́nà àìtọ́, Solomon Okoduwa, sọ pé, ọ̀gá kan nílé ẹ̀kọ́ náà ló sọ bẹ́ẹ̀ fún òun.
Mubaraq dáhùn ìbéèré yìí Ìkọlù agbébọn tó ṣékú pá ọmọ ogún Niger 89, iṣẹ́ bọ lọ́wọ́ Ọgágun àgbà Kano Governorship: Ilé ẹjọ sún ìgbẹ́jọ Ganduje sí ogunjọ oṣù kíní Abdularahaman, Ọmọ ọdún 17 kó sí páńpẹ́ EFCC lórí ẹ̀sùn yahoo-yahoo ní Ibadan Baba Aladejẹbi sọ nipa awọn ẹmi, dukia ati ohun ti o ba ogun Biafra rin nigba naa ati ero awọn eniyan to kopa ninu ogun ọhun Naira Marley ti tèṣù mọ́lẹ̀ nílé ẹjọ́ májísíréètì lórí ẹ̀sùn ìjọ́kọ̀gbé Aláàfin Ọyọ: Ọba tó bá n mú ọtí ní ìta kò yẹ ní ẹni tàá bọ̀wọ̀ fún Idásilẹ̀ Amotekun ko ba òfin ọdún 1999 mu- Malami Ọ̀gá mi fẹ́ fi tipá bámi lòpọ̀ ní Lebanon àmọ́ ìjọba yọ mí l'óko ẹrú - Ọmọ Nàíjíríà míì Aladejẹbi sọ nipa iya ati ipenija ti awọn ọmọ ogun fẹyinti n koju ni isinyi ni eyi ti ijọba ko pese iranlọwọ bi o ti yẹ.
Ṣugbọn balogun ọ̀rún kò jẹ́ kí àwọn ọmọ-ogun ṣe ìfẹ́ inú wọn, nítorí pé ó fẹ́ mú Paulu gúnlẹ̀ ní alaafia.
Cardless Withdrawal: Èyí ni àwọn ìlànà tí o le fi gbowó ní ATM láì lo káàdì
Nígbà tí mo wo apá ibi tí ó wà tí mo rí i, mo pè é mo ní, Ọ̀rẹ́ mi, Ọ̀gbẹ́ni Olóhùn-un-dùùrù, o kú àtijọ́ o.
Oríṣun àwòrán, NPF Oriṣiriṣi ibeere lo n waye lori eto igbani sisẹ ileesẹ ọlọpaa Naijiria fún ọdun 2020 eyi to n waye lọwọ lọwọ.
 Lẹyin eyii ni ero ọkọ naa sa jade to si pe fun iranlọwọ, ko to di pe awọn ọlọpaa jade si wọn."
Mo ti wo gbogbo nǹkan tí eniyan ń ṣe láyé, wò ó, asán ati ìmúlẹ̀mófo ni gbogbo rẹ̀.
Orúkọ ìyá rẹ̀ ni Sibaya, ará Beeriṣeba.
Aare so pe eto oro aje
Tolanibaj, Wathoni àti Brighto dé òpin ìrìnàjò ní ilé ẹlẹ́gbọ́n àgbà BBNaija Oríṣun àwòrán, BBNaija/twitter Tolanibaj, Wathoni ati Brighto ni wọn le kuro nile Big Brother Naija l'ọsẹ yii.
Adeyẹye ni Ọọni kọkanlelaadọta ti yoo jẹ; bẹẹni onimọ nipa iṣiro owo ti o dantọ si ni.
 dillingham , kent ni wọ ́ n ti bí i ní ilẹ ̀ gẹ ̀ ẹ ́ sì .
Ṣùgbọ́n, àjọ elétò ìlera ní àgbáyé (WHO) ti bẹ àwọn ọmọdé láti má rí ara wọn bí ẹni tí kò lè ní aarun náà.
Bí ó bá ti kú ni n óo pa Jakọbu, arakunrin mi.
Ileẹkọ girama Ikeja, to wa ni Bọlade-Osodi nilu Eko si ni ayẹyẹ naa ti waye, akori ajọdun naa si ni ‘Isamulo ede abinibi fun idagbasoke, ibomirin, alaafia ati ibalaja.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Obateru Akinruntan: Wíwá ohun tá jẹ títí láé ló gbé wa kúrò nílé Ife Eyi lo mu ki ẹgbẹ awọn oṣiṣẹ tiraka lati gunle iyanṣẹlodi, amọ wọn gbegile iyanṣẹlodi naa lẹyin ti ijọba paṣẹ pe ki ina ọba pada si bo ṣe wa tẹlẹ ki wọn to fi owo kun un.
Ẹgbẹ alajẹsẹku yii si ni ijọba gbọkan le lati lo fun gbigba afikun owo ori naa.
 O ni ewu pupo lo ro mo dida idoti soju agbara.
9 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Akure shooting: Àlááfíà ti padà sí ìlú Akure, ẹnikẹ́ni kò kú - Deji ilu Akure7 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 EndSars in Portharcourt: Ọjọ́ méjì sẹ́yìn ni aya awakọ̀ Márúwá tí ọlọ́pàá pa bímọ tuntun10 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Ondo 2020 Tribunal: Ìgbìmọ̀ olùgbẹ̀jọ́ ìbò gómìnà yóò gbérasọ lọ́jọ́ Iṣẹgun7 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Oyo physically challenged protest: Ìdí rèé táwọn àkàndá ẹ̀dá fi dí iwájú iléeṣẹ́ ìjọba ìpínlẹ̀ Oyo pa l'Agodi n'Ibadan7 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 D.
Aya kò gbọdọ̀ kọ ọkọ rẹ̀.
A o maa jabo awon esi miran fun yin ti o ba se n tewa lowo.
Ijọba rẹ gbagbọ pe awọn ti bori ikọlu Boko Haram ni iha Ila Oorun Ariwa ṣugbọn eyi ti wa di ọna adọgbn kọlu ẹgbẹ ati awọn eniyan agbegbe naa.
Gbẹ́kẹ̀ rẹ lé Ọlọrun, nítorí pé n óo tún yìn ín,olùrànlọ́wọ́ mi ati Ọlọrun mi.
sọ fún àwọn eniyan Israẹli pé, “Nígbà tí nǹkan bá dà jáde lára ọkunrin, nǹkan tí ó jáde lára rẹ̀ yìí jẹ́ aláìmọ́.
ṣugbọn Kalebu ọmọ Jefune ni wọ́n fún ní ìgbèríko ati ìletò tí ó yí ìlú Heburoni ká.
A-purọ́-mọ́ni a máa kórìíra àwọn tí ń parọ́ mọ́,ẹni tí ń pọ́nni sì lè fa ìparun ẹni.
Lọdun 2000, ajọ to n ṣagbatẹru ere bọọlu lagbaaye, FIFA fi ẹbun agbabọọlu to dantọ julọ ninu iwe itan fun Maradona ati Pele orilẹede Brazil.
Manase pa ọpọlọpọ àwọn eniyan aláìṣẹ̀ títí tí ẹ̀jẹ̀ fi ń ṣàn ní ìgboro Jerusalẹmu.
Ninu àwọn ọmọ Pahati Moabu, Eliehoenai, ọmọ Serahaya, ni olórí;orúkọ igba (200) eniyan ni wọ́n kọ sílẹ̀ pẹlu rẹ̀.
Oluwatobi Adeigba, Ọkọ mi ń lọ siṣẹ́ fún àjọ INEC ló kàgbákò ikú - Opó Adeigba Ìdí tí a fi pa àwọn àgbẹ̀ onírẹ̀sì ní Borno, Boko Haram ṣàlàyé nínú fídíò tuntun Èèyàn 281 ló kó covid-19 lọ́jọ́ Ìṣẹ́gun, 123 wá láti ìpínlẹ̀ Eko nìkan Wọ́n ti rẹ ipò ọ̀gágun Olusegun Adeniyi sílẹ̀ lẹ́yìn tó jẹ̀bi títú àṣírí kùdiẹ-kudiẹ iléeṣẹ́ ológun lórí ayélujára Iwadii fihan pe o fẹ ta ọmọ naa fun arabinrin Chinwindi Omeh to n gbe ni ilu Anambra.
Kemi Afolabi di màmá olóyè nínú ẹ̀sìn, oyè ìmọ́lẹ̀ Àdínnì ni wọ́n fi jẹ
Nítorí náà, n óo jẹ́ kí ibi bá ìdílé rẹ, n óo sì pa gbogbo ọkunrin inú ìdílé rẹ run, àtẹrú àtọmọ.
“Àwọn ìwo mẹ́wàá tí o rí jẹ́ ọba mẹ́wàá.
Ní agbègbè Nyanya-Mararaba tí ọ̀pọ̀ òṣìṣẹ́ ń gbé, ṣe ni àwọn agbofinro gbé igi dabu ọna, láti tọpinpin lílọ bibọ ọkọ sí Ìpínlẹ̀ Nasarrawa, tíì ṣe Ìpínlẹ̀ miran to mule tí Abuja, tí wọ́n si ń rí dájú pé àwọn èèyàn náà wọ aṣọ ìbòjú.
Lawọn ikorita kaakiri orileede bi Singapore,Taiwan ati Hong Kong awọn aye wa ti wọn fi omi ati osẹ ifọwọ si fawọn eeyan ti lilo ibomu si jẹ nkan to kari laarin awọn eeyan wọn.
Amọṣa, Ijọba apapọ orilẹede Naijiria ti wa bọ sigboro aye bayii lati da omi tutu si iroyin naa eyi ti wọn pe ni iroyin ẹlẹjẹ.
Apá ibi tí ó ń kà nìyí:“Bí aguntan tí a mú lọ sí ilé ìpẹran,tí à ń fà níwájú àwọn tí ń rẹ́ irun rẹ̀,kò fọhùn, bẹ́ẹ̀ ni kò ya ẹnu rẹ̀.
Fasiti ti gbe igbimọ kan kalẹ lati ṣewadii iṣẹlẹ ọdun wọn yoo si gbe esi wọn jade laarin ọjọ perete.
Yọ mí kúrò ninu àwọ̀n tí wọ́n dẹ pamọ́ dè mí,nítorí ìwọ ni ẹni ìsádi mi.
Ìgbà ti ọjọ ́ àjò ń pe bọ ̀ Ọ ̀ rúnmìlà lọ bi ifa léèrè bí ọjọ ́ àjọ yoo ṣe rí nítorí ó tí mọ bi obinrin se jẹ ́ .
Ohun tí OLUWA àwọn ọmọ ogun sọ nípa Edomu nìyí: Ó ní,“Ṣé kò sí ọgbọ́n ní Temani mọ́ ni?
Ọpọ awọn eeyan lo n fara kaasa arun yii kaakiri agabye, ṣugbọn ọpọ awọn mii to n ko arun naa ni awọn eleto ilera ko mọ nitori wọn ko fi to wọn leti.
Nilẹ Zimbabwe, iye awọn to ti fẹjọ sun ijọba lori iwa ipa akọ si abo ti le ni ida mẹta.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, End SARS, End SWAT: Ó pé mi bí SARS kò ṣe sọ mí dolówọ́- Fulani Kwajafa Ki lo ti ṣẹlẹ sẹyin?
 o tako ofin orile ede yiiOjogbon Yemi Osinbajo ti salaye pe iwa ibajẹ ati pe o tako ofin orile ede Naijiria ati ofin to rọ mọ ọn.
wa se ni osu kefa , ojo kejila, odun yii lati fi sami ayeye eto ijoba
“Ní àkókò tí a ti pinnu, yóo tún gbógun ti ilẹ̀ Ijipti, ṣugbọn nǹkan kò ní rí bíi ti àkọ́kọ́ fún un; 
Mo gbà yín lọ́wọ́ àwọn ará Ijipti, ati gbogbo àwọn tí wọn ń ni yín lára.
Ìdíje Champions league: Salah dá iná ayò sára Roma
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ekiti state: Nítoríi fóònù ìbánisọ̀rọ̀, géńdé méjì kú sínú u kọ̀ǹga l'Ékìtì 9 Owewe 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Nítoríi fóònù ìbánisọ̀rọ̀, géńdé méjì kú sínú u kọ̀ǹga l'Ékìtì Ibanujẹ dori agba kodo, bẹẹni awọn ọmọ wẹwẹ ko si lẹnu ọmu ni ileto Anaye nijọba ibilẹ Emure Ekiti bayii nigba ti awọn gende meji jabọ sinu kọnga kan nibẹ ti wọn si dagbere f'aye.
Nigbati ìnira pọ̀ fún Moṣétán, ó jẹ́wọ́ wi pé adiẹ lohun jẹ, ṣùgbọ́n wọn ko gba a gbọ pé kò jẹ Igun, titi ti ó fi ṣubú ti ó si kú.
Igba akọkọ lo jẹ eyi to tobi, ti ẹnu rẹ si fẹ, eyi ti wọn yoo doju rẹ bolẹ.
''A ti fi ami si oju popo ki ẹnikẹni ma gba ibẹ kọja ni asiko yii nitori iwadii ṣi n lọ lọwọ lori iṣẹlẹ naa.
Revolution Now: Àwọn èèyàn tó ń ṣèwọ́de ní ẹ̀rù kò bà àwọn, awọn ṣetan láti wà ní àtìmọ́lé
End Sars Police shooting: Babajide Sanwo Olu ti pàṣẹ pé kí Ọ̀gá Ọlọ́pàa tú àwọn afẹ̀hónúhàn sílẹ̀ ní kíákíá Lori ọrọ iwọde fifopin si ifiyajẹni ati iṣekupani lọna aitọ lati ọdọ awọn agbofinro Naijiria ni gomina ipinlẹ Eko, Babajide Sanwo Olu naa ti paṣẹ.
Kò sí pé à ń wa nǹkan, a kò rí rárá.
Láti inú ilẹ̀ ni OLUWA Ọlọrun ti mú kí oríṣìíríṣìí igi hù jáde ninu ọgbà náà, tí wọ́n dùn ún wò, tí wọ́n sì dára fún jíjẹ.
Gomina  ipinle Oyo Abiola Ajimobi ti  bura fun awon akowe ile-ise ijoba  mọ̀kànlá ni ipinlẹ Ọyọ .
5 owó naira ni ọọfiisi àjọ INEC ni Zamfara Wo àwọn orílẹ̀-èdè márùn ún tó fún àwọn obìnrin làńfàní tuntun sí ẹ̀tọ́ wọn Nàìjíríà kò nílò sénétọ̀ kankan- Fayemi Ọgbẹni Uwem kin ọrọ rẹ lẹyin pe, bi idajọ iku ko ṣe dẹkun iwa ipaniyan, bẹ naa ni titẹ awọn afipabanilopọ lọdaa ko le dẹkun iwa ifipabanilopọ.
Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí 1:58 Fídíò, Alapinni Oosa ṣàdúrà fún gbogbo ọmọ kúoótù, oò jíire bí?
" Itan rẹ̀ jẹ́ èyí tó kọni lóminú, ó sì ṣeni láànú.
O ṣe orin yii bi ẹni n pe ọgọọrọ awọn irumọlẹ Yoruba jade ni.
Ètè mímú ati inú burúkú,dàbí ìdàrọ́ fadaka tí a yọ́ bo ìkòkò amọ̀.
Ó wó àwọn òpó oriṣa Aṣera, ó sì fọ́ àwọn ère gbígbẹ́ ati èyí tí wọ́n rọ.
Liverpool pègúnrẹ́, wọ́n gbé ife ẹ̀yẹ̀ Premier league lẹ́yìn ọgbọ̀n ọdún Chelsea fún Man United lóúnjẹ ẹ̀tẹ́ jẹ, Cuppy bínú yí jọ̀lọ́ọ̀fù dànù Ohun mẹ́fà tí ọ̀pọ̀ kò mọ̀ nípa ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ Arsenal àti Machester City Wo ohun tí Adájọ́ sọ nípa ìgbẹ́jọ́ Wòlíì Sotitobire l'Ondo Ṣẹ ẹkọ ẹlẹkọ kuku ni ẹgba ẹlẹgba ni Yoruba maa n wi Ni oṣu kọkanla ọdun 2019 ni awọn alaṣẹ Arsenal gba iṣẹ lọwọ rẹ lẹyin to lo ọdun kan abọ gẹgẹ bii akọnimọọgba nibẹ.
Àkọlé àwòrán, Wámúwámú ni àwọn ọlọpàá dúró láti mójú tó àbò gbogbo àwọn akópa àti agbègbè ìpàdé Àkọlé àwòrán, Muyiwa Fafowora ni ijọba oun ṣe tan láti ṣe metro line ni ìpínlè Eko, o ni ènìyàn 22m lo wà ní ìpínlè Eko bẹẹ si ni ohun irina bii metro line ti New York Experience ni won maa lo tí oun ba ti dé bẹ.
FIFAWWC: Super Falcons fi South Korea ṣ’ẹ̀bùn June 12 fún Nàìjíríà
Ondo state: Bàbá ọlọ́mọ méjì kú sínú àgbàrà òjò nílùú Akure
Nibayii, gomina Ikpeazu naa ti bẹrẹ iyasọtọ labẹ akoso awọn eleto ilera akọsẹmọṣẹ o si ni ki igbakeji rẹ maa dele de oun ko to de.
 Àwọn ẹ ̀ dá pàtàkì inú wọn ni ẹranko , òrìṣà àti àwọn akọni nínú àṣà tí wọ ́ n ti kópa tó jọjú ní ayé àtijọ ́ tàbí ayé mìíràn gẹ ́ gẹ ́ bí ojú ọ ̀ run tàbí ìsàlẹ ̀ ilẹ ̀ ) .
Oríṣun àwòrán, Oyo Àkọlé àwòrán, Seyi Makinde, jọ̀ọ́ fi ewé ọmọ mọ Auxiliary létí, ìwà ìjẹgàba rẹ̀ le da omi àlàáfíà ìlú rú - Sunday Igboho Folaranmi fikùn pé eekan àwùjọ kan, Oloye Sunday Adeyemo, tí ọ̀pọ̀ èèyàn mọ sí Sunday Igboho kò sì lọ́wọ́ sí ìṣẹ̀lẹ̀ náà rárá, lòdì sí ahesọ ọ̀rọ̀ tó gba ilẹ̀ kan.
“Omi tí eniyan bá jí mu a máa dùn,oúnjẹ tí a bá jí jẹ, oyinmọmọ ni.
Ènìyan tó lé ní ogojì ló farapa ninu isẹlẹ ibugbamu naa.
Ikọ Supper Eagles Nigeria lo kọkọ sọ bọọlu sinu awọn ilẹ Brazil, nigba ti Joe Aribo to n gba bọọlu fun Glasgow Rangers nilẹ Gẹẹsi ṣo ayo kan wọle, ni igabti idije naa wọ iṣẹju marundinlogoji.
léyìn tí muyideen dé òdò àbúrò bàbá rè , ó bèrè ilé iwé alákòó-bèrè níbàdàn , tí o sì tún n fojú sékòó Àlùkùránì ní ìròlé tí ó bá dé láti ilé iwé rè .
Arabinrin Meng - to jẹ ọmọ oludasilẹ Huawei- ni oun ko jẹbi ẹsun naa.
”Ṣugbọn Joabu dá a lóhùn, ó ní, “Rárá, níhìn-ín ni n óo kú sí.
Iṣẹ́ darandaran ni Abeli ń ṣe, Kaini sì jẹ́ àgbẹ̀.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Wo àgbáríjọpọ̀ àwọn Arugbá Ọ̀ṣun Òṣogbo látìgbà tó ti bẹ̀rẹ̀ Kí ní Khafi BB Naija yóò pàdánu tí iṣẹ́ ba bọ́ lọ́wọ́ rẹ̀?
38 Ohun tí èmi Olúwa ti sọ, mo ti sọ, èmi kò sì tọrọ gáfárà fún ara mi, ati pé bí àwọn ọ̀run àti ilẹ̀ ayé bá tilẹ̀ kọjá lọ, ọ̀rọ̀ mi kì yíò kọjá lọ, ṣùgbọ́n gbogbo rẹ̀ yíò wá sí ìmúṣẹ, bóyá nípa ohùn tèmi tàbí ohùn àwọn ìránṣẹ mi, ọ̀kan náà ni.
Mo dàbí ọ̀mùtí tí ó ti mu ọtí yó,mo dàbí ẹni tí ọtí ń pa,nítorí OLUWA, ati nítorí ọ̀rọ̀ mímọ́ rẹ̀.
ti won gba ami eye naa, lati ma rẹwẹsi ninu ojuse won, ki won si tun tesiwaju
N óo da òkú ẹ̀yin ọmọ Israẹli sílẹ̀ níwájú àwọn oriṣa yín, n óo sì fọ́n egungun yín ká níbi pẹpẹ ìrúbọ yín.
Agbẹnusọ fun un, Onogu Muhammed ni Gomina Bello ko mọ ni pa oun to waye nile aṣofin ipinlẹ naa nitori awọn n bọwọ fun eto konko jabele kaluku lo mi ṣe ti ẹ laarin awọn ẹka ijọba gbogbo nibẹ.
O óo sùn, láìsí ìdágìrì,ọpọlọpọ eniyan ni wọn óo sì máa wá ojurere rẹ.
Ẹ wo àwọn aṣebi níbi tí wọ́n ṣubú sí;wọ́n dà wólẹ̀, wọn kò sì le dìde.
Nígbà náà OLUWA Ọlọrun kun ọkunrin yìí ní oorun àsùnwọra, nígbà tí ó sùn, Ọlọrun yọ ọ̀kan ninu àwọn egungun ìhà rẹ̀, ó sì fi ẹran dípò rẹ̀.
Abbo ni awọn ọta oun ninu oṣelu lo faa, ti fidio naa fi jade ni akoko yii lẹyin to ti pẹ ti iṣẹlẹ naa ti waye sẹyin.
Nigerian Army: Lóòtọ́ ni Boko Haram pa àwọn ológun ní Metele Iléesẹ́ ológun: Àwọn ọmọ-ogun ṣi wá gbọ́ lórí ìsípò-rọpò wọn ni Agbègbè Diffa ní orílẹ̀èdè Niger ti ń rí ìkọlù Boko Haram, láti osù kejì ọdún 2015 ti wọ́n ti bẹ̀rẹ̀ sí kolu agbègbè náà.
ọlọpaa, tun pe fun sisan owo to jọju fun awọn ọmọ ẹgbẹ Igbimọ Alaṣẹ
Shehu sọrọ yii lọjọ abamẹta nilu Abuja.
Ko ti i ju ọjọ kan lọ ti ajọ naa kede eeyan mọkandinlọgọrin pere to ṣẹṣẹ ni aarun naa, eyi to ti i kere julọ lẹyin ọpọlọpọ oṣu.
Wọ́n kó wọn wá siwaju àwọn aposteli; wọ́n gbadura, wọ́n bá gbé ọwọ́ lé wọn lórí.
Ni ọjọ aje to kọja ni Gomina Makinde gbee jade loju opo twitter rẹ pe ayẹwo ti fihan pe oun ni arun Coronavirus lara to si ṣe bẹẹ wọ igbele iyasọtọ lọ gẹgẹ bi ilana aatẹẹle ti awọn onimọ nipa kokoro arun ati ilera ṣe laa kalẹ fun un.
Vincent àti Grenadines, òfin sọ wípé bí “ọ̀pọ̀ àwọn akọrin tí ó ń lé orin” yẹ kí “ó jẹ́ ṣíṣe láti ọwọ́ọ ọmọ bíbíi Trinidad àti Tobago”, orin náà lè jẹ́ afigagbága – eléyìí sì jẹ́ ọ̀kan.
Wo nnkan tawọn eeyan miran n sọ.
Aare Buhari wa gbadura pe Olorun yoo te oloogbe si afefe rere, yoo si wa pelu ebi ati ara oloogbe naa.
Yẹ̀ẹ̀pẹ̀ ni kí ẹ fi tẹ́ pẹpẹ fún mi, kí ẹ sì máa rú ẹbọ sísun yín ati ẹbọ alaafia yín lórí rẹ̀, kì báà ṣe aguntan tabi mààlúù.
05 ti ohun naa si pajude si N21.
Wọn si ni awọn kọ lawọn ṣe onigbọwọ awọn janduku to ṣaadede ya wọ ibẹ lati da iwọde ti awọn ọdọ n ṣe lodi si iwa aburu ti awọn ọlọpaa Naijiria n hu.
Akinbinu ni o daju pe igbakeji gomina naa n lepa lati dije si ipo gomina ni ipinlẹ Ondo ni, bi bẹẹ kọ, o yẹ ko yẹ ko jẹ asiko yii ni Agboola Ajayi yoo fi ẹgbẹ to gbee wọle silẹ.
Jẹ́ kí àwọn eniyan ó máa yìn ọ́, Ọlọrun;jẹ́ kí gbogbo eniyan máa yìn ọ́!
OLUWA ní, “N óo wá ba yín láti ṣe ìdájọ́; n óo wá jẹ́rìí mọ́ àwọn oṣó ati àwọn alágbèrè, àwọn tí wọn ń búra èké ati àwọn tí wọn kì í san owó ọ̀yà pé, àwọn tí wọn ń ni àwọn opó ati àwọn aláìníbaba lára, ati àwọn tí wọn ń ṣi àwọn àlejò lọ́nà, tí wọn kò sì bẹ̀rù mi.
92, eyi ti o wa ni ipo idagbasoke ohun, latigba tie to oro aje naa ti kuro ninu idenu-kole re”.
Bẹ́ẹ̀ náà ni Maaseaya, ọmọ Baruku, ọmọ Kolihose, ọmọ Hasaya, ọmọ Adaya, ọmọ Joiaribu, ọmọ Sakaraya, ọmọ ará Ṣilo.
5m) fun iko agbaboolu mọ́kànlélógójì ti won fi ipinle naa se ibugbe.
Nítorí náà OLUWA Ọlọrun lé e jáde kúrò ninu ọgbà Edẹni, kí ó lọ máa ro ilẹ̀, ninu èyí tí Ọlọrun ti mú un jáde.
Oríṣun àwòrán, Instagram/acupofkhafi Ni abala akọkọ, gbogbo oludije to wa nile lo sọrọ lọpọlọpọ nipa Naijiria, amọ Khafi, Mercy, Cindy ati Jackye nikan lo pegede de abala to kẹyin.
Ọ̀rọ̀ náà jẹ́ ohun tí ó kanni gbọ̀ngbọ̀n ati àtẹ̀mọ́ ti ara ẹni nítorí pé Olúwa sọ ohun tí ó jẹ́ mímọ̀ sí John Whitmer nìkan àti òun Tìkára Rẹ̀.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'O yé kí ìbáṣepọ̀ Nàìjíríà àti UK dán mọ́rán síi lẹ́yìn àbẹ̀wò May' Wọn gba pe ohun ikunna nla ni ki ọrọ Brexit ma yanju.
Dino Melaye: Mí ò sí lára àwọn aṣòfin tó bú Buhari
Mo ti ṣe àlàyé ọ̀rọ̀ yìí rí níbìkan.
Nígbà tí iranṣẹ Abrahamu gbọ́ ohun tí wọ́n sọ, ó wólẹ̀ ó sì dojúbolẹ̀ níwájú OLUWA.
Ta lo gba ìtumọ̀ 'àrìnfẹsẹ̀sí' jù nínú àwọn ọ̀dọ́ yìí?
Wọ́n ní, “Eléyìí ní agbára Ọlọrun tí à ń pè ní ‘Agbára ńlá.
Wọ́n sì jíṣẹ́ fún angẹli OLUWA, tí ó dúró láàrin àwọn igi mitili náà pé, “A ti lọ rin ilẹ̀ ayé wò jákèjádò, a sì rí i pé wọ́n wà ní alaafia ati ìdákẹ́rọ́rọ́.
Hesekaya bá gbadura sí OLUWA, ó ní: 
New Emirates: Ilé ẹjọ́ dá Gómìnà Ganduje dúró yíyan àwọn Emir tuntun ní Kano
ti won yoo fi seto ijoba tiwa-n-tiwa .
”Ewe, Nadal darapo mo Margaret Court omo ile Australia gege bi ondiije ti o ti gba ife-eye ohun igba mokanla bayii.
Trump so pe ;” o ni o dara ki baalu tuntun Boeing wa ni ọda pupa, funfun ati buluu.
Onnoghen: PDP so ìpolongo ìbò rọ̀ Kíni igbimọ NJC fẹ́ jíròrò lè nípa Onnoghen?
Ó jẹ́ olódodo eniyan ati olùfọkànsìn, ó ń retí àkókò tí Ọlọrun yóo tu Israẹli ninu.
Bolanle Sarumi Aliyu: Nígbà tó bá di àsìkò tèmi, èmi náà á dé 'bẹ̀
Nítorí náà Jesu sọ pé, “Kí ni à bá fi ìjọba Ọlọrun wé?
Wọ́n ti ìlẹ̀kùn odi Jẹriko ninu ati lóde, nítorí àwọn ọmọ Israẹli.
Ó yọ Maaka, ìyá baba rẹ̀, kúrò lórí oyè ìyá ọba, nítorí pé Maaka yá ère tí ó tini lójú kan fún oriṣa Aṣera.
Bi a ko ba gbagbe wi pe, Mikel
Ile-ise to n pese  irinna oko oju irin lorile ede Naijria lo ti seleri pe awon ko ni ja awon eniyan kule lati maa wo oko oju irin lati ilu Eko si Ipinle Kano.
Ó kọ́ pẹpẹ ìrúbọ kan sí orí òkè ní ìhà ìlà oòrùn Jerusalẹmu fún oriṣa Kemoṣi, ohun ìríra tí àwọn ará Moabu ń bọ, ati fún oriṣa Moleki, ohun ìríra tí àwọn ará Amoni ń bọ.
''Eyi a maa je aburu ti a ba joko sinu ile ti wọn ṣẹṣẹ kun tan ti a si n fin eefin rẹ simu'' Kemika kan wa ninu oda tuntun to jẹ wi pe o le fa iku ti eeyan ba fa si imu.
ọ̀dọ́ 47,000 fẹ́ di Amotekun, agbófinró yẹ̀ wọ́n wò yẹ́bẹ́yẹ́bẹ́ Aáwọ̀ oyè PDP gbé Fayose àti Seyi Makinde kọlu ara wọn, ìjà ń bọ̀ Arabinrin Halima Adamu to lewaju igbesẹ naa ṣalaye fun BBC pe, wọn bẹrẹ pẹlu eto ẹdawo laarin ọkọọkan awọn obinrin ni ileto naa.
to jade lati wa dibo lasiko eto idibo ni agbeegbe ti wọn ti n dibo.
Akọṣẹmọṣẹ nipa itọju oju, Ọjọgbọn Feyi Adepoju tun ti tan imọlẹ si ohun to le mu ki eeyan ni irufẹ oju buluu.
Gẹgẹ bi ohun ti awọn oṣiṣẹ ọ́fíìsì Amẹrika ni Nàìjíríà fi sita loju opo Facebook wọn, wọn ni ohun to de ba orileede awọn losokunfa titi ile iṣẹ wọn pa .
Ọdun mọkandinlọgbọn ti o faye silẹ, niṣe ni awọn ọmọ Naijiria n ṣele de pẹlu itu to maa n pa pẹlu apejuwe to munadoko nipa ohun to n ṣẹlẹ lori papa.
Lojo-Isegun ni Iko kan ninu awon omo ile-igbimo asofin egbe oselu to wa lori alefa lorile-ede South Africa, National Congress (ANC), gba lati satileyin fun abadofin pelu mimu atunto ba iwe ofin kan, eyi ti awon egbe ti o ja fun ominira eto oro aje, ti a mo si Economic Freedom Fighters (EFF) gbe siwaju ile-igbimo asofin, lati yan igbimo ti yoo seto ijiroro, ati lati pari atunse  si iwe ofin, eyi ti yoo faye gba gbigba ile lowo awon oyinbo alawo-funfun lai san owo gba mabinu, fun anfaani awon ara-ilu.
Ìròyìn dé sí etí ìgbọ́ ọ̀rẹ́ kejì pé ọlọ́jọ́ ti dé bá ọ̀rẹ́ tí wọ́n jọ ń ṣòwò.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Coronavirus: Èyí ni àwọn irọ́ bàǹtà-banta tí a ń pa fún ara wa nítorí Coronavirus 17 Ẹrẹ̀nà 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 17 Ìgbé 2020 Oríṣun àwòrán, Getty Images Awọn ibeere mẹta to yẹ ko bi ara rẹ ki o to pin iroyin nipa coronavirus niyii Njẹ iroyin yii jọ jinlẹ, tabi o wa lati ọdọ ọrẹ ti mi o mọ ibi to ti wa?
Ọgbẹni Jimoh Sọliu to jẹ olori gaa Eleesun ṣalaye pe ọfọ nla ni iku awọn maluu ati aguntan naa jẹ fun wọn.
igbimo lo ni kaadi idanimo ti egbe oselu APC ,kii se iyẹ nikan awon omo egbe gbọdọ  mọ wọn , won si tun gbodo lee jẹ akinkanju ni
Ó já sí pé àwọn orílẹ̀-èdè tí kò bìkítà rárá láti wá ojurere Ọlọrun, àwọn náà gan-an ni Ọlọrun wá dá láre, ó dá wọn láre nítorí wọ́n gbàgbọ́; 
Arabinrin Idowu ṣalaye fun ile ẹjọ naa pe ọkọ oun ko ṣe e fi ọkan tan ati wi pe ni kete ti oun bi ọmọ ni ọkọ oun ti sọ fun oun pe oun ti fẹ iyawo keji ti awọn ẹbi rẹ fara mọ julọ nitori pe ọmọ ilu kan naa ni wọn.
6m lórí ètò BBNaija torí pó sọ̀rọ̀ ìwúrí nípa Nàíjíríà Bí mo ṣe dúró ti Toyin nílé ìgbẹ̀bí jẹ́ kí ń mọ̀ pé ó yẹ kí ọkùnrin máa bọ aya wọn - ọkọ Toyin Abraham Iṣẹ́ ọpọlọ ló yẹ ká ṣe nínú tíátà, kìí ṣe àfihàn ara bíbó àbí ìhòòhò wa - Binta Mọgaji Ìjọba, ẹ yé fi ọlọ́pàá àtàwọn ológun dúnkokò máwọn èèyàn- Ṣoyinka Sise afihan ounjẹ yii yoo fi agbara fun ero awọn eniyan wi pe, ohun to kọju si ẹnikan, ẹyin lo kọ si ẹlomiran.
Nígbà tí wọ́n dé ọ̀dọ̀ Jakọbu baba wọn ní ilẹ̀ Kenaani, wọ́n kó gbogbo ohun tí ó ṣẹlẹ̀ sí wọn, wọ́n rò fún un, wọ́n ní, 
ó ní, “Ẹ̀yin ni n óo fún ní ilẹ̀ Kenaani,bí ohun ìní yín, tí ẹ óo jogún.
Lẹ́yìn náà, n óo ká ọwọ́ mi kúrò, o óo sì rí àkẹ̀yìnsí mi, ṣugbọn ẹnikẹ́ni kò lè rí ojú mi.
Olupẹjo agba fun ijọba, Tarek Saab ni, iwadi yoo bẹrẹ ni kia kia lati tọpinpin ohun to fa ijamba naa.
Amọ lọwọ-lọwọ bayi, asofin agba mọkanlelaadọta lo jẹ ọmọ ẹgbẹ oselu Republic ti aarẹ Donald Trump ti wa, nitorinaa, wọn nilo atilẹyin awọn asofin latinu ẹgbẹ oselu Democrat, ki wọn to lee ri ọgọta asofin ti yoo buwọlu aba naa.
Ǹkan mẹ́jọ tó máa kọ́kọ́ ṣẹlẹ̀ kí olólùfẹ́ méjì tó pa ara wọn Báwo ni mo ṣe lè sọ̀rọ̀ ìtùnú fún ẹni tí ọ̀kan rẹ̀ dàrú?
Ṣugbọn nisinsinyii, a ti pa ìrandíran wọn run,láti Heṣiboni dé Diboni,láti Naṣimu dé Nofa lẹ́bàá Medeba.
Kíni ìyàtọ̀ tí yóò wà láàrin SARS àti SWAT?
Jeremaya pàṣẹ fún Baruku pé, “Wọn kò gbà mí láàyè láti lọ sí inú ilé OLUWA; 
Àwọn ìròyìn mìíràn tí ẹ lè nífẹ̀ẹ́ sí: Wọ́n jí ọmọ yìí gbé láti máa fi tọrọ bárà l'Eko Ọwọ́ ọlọ́pàá tẹ ọmọ Britain tó ń ta kẹ́míkà gẹ́gẹ́ bi omi ìyanu Ọlọ́pàá Adamawa ni #30,000 ni wọ́n fi bọ́ igún látìmọ́lé Ọwọ́ ọlọ́pàá tẹ ọmọ Britain tó ń ta kẹ́míkà gẹ́gẹ́ bi omi ìyanu Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Kò sí ààbò, kò síṣẹ́; Àwọn dókítà LUTH bínú tán Ilé alájà mẹ́ta wó pa onímọ̀ ẹ̀rọ́ tó ń kọ́ ọ lọ́wọ́ Lẹ́yìn igbe Atiku, Ààrẹ Ilé Ẹjọ́ kòtẹ́milọ́rùn yọra rẹ̀ nínú ìgbẹ́jọ́ èsì ìdìbò ààrẹ Kíni o túmọ sí pé kí orílè-èdè rẹ má ní ilé iṣẹ tó n sójú rẹ n'ilẹ ókéré mìíràn?
Iroyin sọ nigba naa pe ọkọ ayọkẹlẹ, kẹẹkẹ 'maruwa', ati ọkada ni awọn janduku naa gùn wọ adugbo ni alẹ ọjọ buruku, eṣu gbomi mu ọhun.
Bí kò bá ní lè kò ó lójú, kí ọ̀tá rẹ̀ tó dé ìtòsí, yóo tètè rán ikọ̀ sí i pé òun túúbá.
Wọ́n ní: ọba mìíràn wà, ìyẹn ni Jesu!
Ìwé náà kà báyìí pé, “Fi Uraya sí iwájú ogun, níbi tí ogun ti gbóná girigiri.
Ṣugbọn ọna ati mọ awọn eyi to jẹ ayederu too ba ri i lori igba ṣe pataki lasiko yii nitori pe ileeṣẹ awọn apoogun orilẹede Naijria to n ṣe iwadii ati idagbasoke (NIPRD) ni ida mẹtalelọgọta oogun apakokoro to wa ni ilu Abuja nikan tii ṣe oluulu orilẹede yii ni kii ṣe ojulowo.
Bẹẹ, ti a kò ba ri ẹni ba la ni ọrọ iṣelu ni Naijiria, ọ̀là kìí yá.
Ẹ wò ó, mo gbọ́ pé ọkà wà ní Ijipti, ẹ lọ ra ọkà wá níbẹ̀ kí ebi má baà pa wá kú.
lati  ila oorun si iwọ oorun, maa satunse
Awọn orilẹede to mu ile ti i, Namibia ati Mozambique si n tọ ọ lẹyin gbagbaagba, ti Brazil naa si ti fẹ ẹ wa ni awujọ awọn mẹẹrin to wa l'oke.
Nígbà náà ni OLUWA Ọlọrun bù ninu erùpẹ̀ ilẹ̀, ó fi mọ eniyan.
Igbona ti pada wa Awọn orilẹede ti wọn ti n sunmọ ati pa arun igbona run ni wọn tun ti n ri ọwọja arun naa bayii.
To si sọ fun un pe ko ye e beere iru nkan bẹ ẹ mọ.
Àwọn olórí ninu ìdílé ẹ̀yà Juda ati ẹ̀yà Bẹnjamini, ati àwọn alufaa, ati àwọn ọmọ Lefi sì dìde, pẹlu àwọn tí Ọlọrun ti fi sí lọ́kàn láti tún ilé OLUWA tí ó wà ní Jerusalẹmu kọ́.
Òkú ọmọ tuntun pòórá nílé ìgbókúpamọ́sí nílùú Akurẹ Ṣugbọn ofin ti ajọ NFIU wa gbe silẹ sọ wi pe gbogbo owo yii ko maa lọ si apo ijọba ibilẹ kọọkan taara lati ọwọ ijọba apapọ eyi to lodi si ofin ijọba apapọ""."
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Nigeria models: Ẹ má bóra mọ́, ọmọ dúdú dùn lọ́mọbìnrin Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Nigeria models: Ẹ má bóra mọ́, ọmọ dúdú dùn lọ́mọbìnrin 2 Owewe 2019 Mo fẹran bi Adẹda ṣe da mi -Arinrin oge Idowu Olutosin, onidiri arinrin oge to jẹ ọkan lara awọn to ṣagbekalẹ eto Ẹwatomi ba BBC Yoruba sọrọ nipa ẹwa obinrin.
Ìdí rèé táa fi fọwọ́ òsì júwe ilé fún òṣìṣẹ́ àádọ́rin ọkọ̀ bààlú - Air Peace Ṣé òótọ́ ni pé Tayo Amusan ni yóò gba ìṣàkóso ilé ìtajà Shoprite?
Ṣugbọn, awọn ara abule naa n fura pe o ṣeeṣe ko jẹ latara igi nla kan to wa nitosi abule naa ni awọn oyin naa ti jade.
 dietrich ii ati princeton environmental institute .
Mo tú turari olóòórùn dídùn ati òjíá, aloe ati sinamoni, sórí ibùsùn mi.
Bi awọn ipinlẹ to ni Coronavirus ṣe lọ ni yii: Eko-156 Kano-65 Ogun-57 Plateau-54 Oyo-53 Benue-43 FCT-30 Ondo-18 Kaduna-16 Akwa Ibom-13 Gombe-13 Rivers-12 Ekiti-9 Osun-8 Cross River-3 Borno-2 Edo-2 Bayelsa-1 Oríṣun àwòrán, Twitter/NCDC Èèyàn 11 kú, èèyàn 438 míràn tún kó COVID-19 ní Nàìjíríà l'Ọ́jọ́ Àbámẹ́ta Eeyan 438 ni wọn tun kede pe ayẹwo tun ti fihan pe o laarun COVID-19 lorilẹede Naijiria bayii.
“Mo pàṣẹ jákèjádò ìjọba mi pé bí ẹnikẹ́ni ninu àwọn ọmọ Israẹli tabi àwọn alufaa, tabi àwọn ọmọ Lefi bá fẹ́ bá ọ pada lọ sí Jerusalẹmu, kí ó máa bá ọ lọ; 
Dúpẹ́ lọ́wọ́ Ọlọ́run Ọ̀gá Ògo bí a bá kà ọ́ yẹ láti ran ẹlòmíràn lọ́wọ́, ìwọ ọ̀rẹ́ mi.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Atunto Naijiria la n fẹ - Aarẹ Onakakanfo, Gani Adams Adams wa n kede pe yoo dara kijọba tete wa egbo dẹkun fáwọn eeyan naa ko to pẹ ju, ki eto aabo nilẹ Yoruba ma baa mẹhẹ bii ti Oke Ọya.
Aare Weah gba ami-eye agbaboolu ti o dara julo lọdun 1995, ti O si tun gba ami-eye Ballon d’Or  lọdun kan naa, eleyi ti o so di agbaboolu kan soso nile Afrika ti o gba ami-eye ajo FIFA mejeeji ti o lamilaaka julo.
se lati  le je ki eto idibo waye ni
3 Àti pé èmi yíò sọ àwọn nkan fún ọ tí èniyàn kankan kò mọ̀ àfi èmi àti ìwọ nìkan—
Ewe, asekagba idije boolu agbaye ohun yoo waye lojo Aiku(Sunday).
O kú wàhálà Igbó Olódùmarè, ibùgbé ohun àràmọ̀dà ayé gbogbo.
Alhaji Lai Muhammed fi sita pe bi kii ba ṣe ti aarẹ Buhari ni, orilẹede Naijiria o ba ti fori sanpọn.
Nkan bí ọdún méjì sẹ́hìn ni mo ya àwòrán yìí ní àdúgbò Èbúté Mẹ́ta ní ìlú Èkó.
Awon eniyan ti iye won je
Won ki Wizkid fun anfani fifun ile Afrika loruko tuntun yii pe o tun itan ile naa ko.
Ara rẹ̀ yá gágá, inú rẹ̀ dùn láti ṣe alábàpàdé àwọn ọ̀rẹ́ tí ó wá láti ilẹ̀ẹ rẹ̀, bẹ́ẹ̀ ló mọ̀ pé ó lé sọ èdè Tibet.
Àtàrí àjànàkú ni wọ́n pè é fún wa, wọn ní kìí ṣe ẹrù ọmọdé o.
 10,000km / hr irú eré tí àwọn móto má ń sá lọ ́ nà ẹ ́ spùrẹ ̀ sì irú eré yìí lọ ́ nà ẹgbẹ ̀ rún kan leré tí rọ ́ kẹ ́ ẹ ̀ tì yìí bá lọ sínú òfurufú lọhun .
m ni ojú mi déédé fọ́ níbi tí mo ti ń darí ọkọ̀ ni Ọrẹgun Ikẹja -LASTMA Yesufa Mamora, Lai Mohammed, Gbemi Saraki wà lára minista Buhari tuntun Òkìtì iyanrìn wó pa èèyàn méjí nílùú Ibadan Àgùnbánirọ̀ akọ̀ròyìn Channels náà ti dágbére fáyé látààrí ìkọlù Shiite l'Abuja Bẹẹ lọrọ ri pẹlu ọkunrin kan ti wọn n pe ni Adegbọrọ to n gbe ni ilu Ibadan.
Bí ó bá yẹ kí èmi náà lọ, wọn yóo bá mi lọ.
Ṣugbọn ṣá, kì í ṣe Jesu fúnrarẹ̀ ni ó ń ṣe ìrìbọmi fún àwọn eniyan, àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ ni.
Nígbà tí Aláàfin Atiba sì waja lọ́dún 1859, Adelu lo jọba lẹ́yìn rẹ lóòótọ́, tí Kurunmi kò sì lọ síbi ayẹyẹ iwuye rẹ tàbí fún ní ọwọ gẹ́gẹ́ bíi Aláàfin.
Kí irú ẹni bẹ́ẹ̀ pada sí ilé, kí ó má baà kó ojora bá àwọn ẹlẹgbẹ́ rẹ̀.
Ṣùgbọ́n èmi bẹ̀ yín tọkàntọkàn, ẹ má sàì sọ ẹni tí ẹ̀yin jẹ́, ẹ ma sì sàì sa ipá yín fún wa lọ́nàkọnà tí ẹ bá mọ̀ tí o lè jẹ́ ìrànlọ́wọ́ fún wa.
Nicholas ni awọn ti foju ikọ Shekau gbolẹ̀, ati pe awọn ti le ikọ Bokoharam jinna, awọn si ti tu ìpàgọ́ wọn ka.
O ni ṣugbọn o jọ gate ko jọ gate ni ọrọ naa.
Leyin iṣẹju diẹ l'awọnọmọde kan to sare wọle pẹlu aruwo pe ejo ti bu u ṣan.
Ogbontagi olorin raggae to di ilumọọka lẹyin to kọ orin tii akọle rẹ ''Send down the rain'' ṣiṣẹ pẹlu awọn gbajugbaja olorin bii Jimmy Cliff, Tracy Chapman and Snoop Dogg nigba aye rẹ.
Fun ọpọlọpọ wakati ni odiwọn ọrọ rẹ gan an fi kọja ti Bill Gates.
Ẹ máa wo aláìsàn sàn; ẹ máa jí àwọn òkú dìde; ẹ máa sọ àwọn adẹ́tẹ̀ di mímọ́; ẹ máa lé àwọn ẹ̀mí èṣù jáde.
"'Àwọn agbébọn tó pá Olufon ti Ifon ti ṣe ohun èèwọ̀ ní ilẹ̀ Yoruba' Awakọ̀ agbókùú, ọlọ́pàá, ológun, oníròyìn ló máa ń kọ́kọ́ dìbò ní Ghana, bó ṣe ń lọ rèé Olorì Aláàfín tẹ́lẹ̀, Anuoluwapo Adeyemi gba àmì ẹ̀yẹ lórí ipa tó kó nínú oge ṣíṣe 'Ẹ sọ́ra fún ""Christmas Carol"", ẹ̀yin tẹ́ẹ sì wà lókè òkun ẹ má wálé o!"
Aaroni dúró ní ààrin àwọn òkú ati alààyè, àjàkálẹ̀ àrùn náà sì dáwọ́ dúró.
Ìgbà tí ayẹyẹ bẹ̀rẹ̀ ni ó tó sọ fún àwọn àlejò rẹ̀ pé kò sí ọkọ kankan.
58 Ṣùgbọ́n kò sí olùkọ́ni tàbí diakonì tí ó ní àṣẹ láti ṣe ìrìbọmi, ṣe àkóso ouńjẹ alẹ́ Olúwa, tàbí gbé ọwọ́ lé ni lórí;
Ṣugbọn Ọlọrun ti fi ìpìlẹ̀ yìí lélẹ̀, tí ó dúró gbọningbọnin.
Arọwa arabinrin yii si ijọba ni pe ki wọn ja owo epo pada wa silẹ nitori pe o ti pọ ju.
27 Àti pé níwọ̀nbí wọn bá dẹ́ṣẹ̀ kí á lè bá wọn wí, kí wọn lè ronúpìwàdà.
Àbúrò-ò mi Yínká Adébóyè kò tilẹ̀ jẹ́ kí nfi ẹ̀dọ̀ lórí òróṅro nítorí ìlérí náà.
Minisita fun eto isuna ati eto ilana lorile-ede Nigeria, asofin Udo Udoma so pe, ijoba koi-ti ni aseyori ninu erongba ti won la kale naa.
Nígbà tí mo wo háhá náà n kò rí àmì kan ṣoṣo láti fi hàn mí pé ibi tí ó ti wá sún mọ́ mi rárá nítorí gbogbo àkíyèsí tí mo ṣe ni ó fihàn mi pé ọ̀nà ibi tí háhá àgbàdo náà ti wá jìnnà, nítorí ibi tí mo mọ̀ tí àgbàdo bẹ́ẹ̀ wà pàápàá jjìnnà ssí Igbó Olódùmarè gidigidi.
BBC OSUN DEBATE: Àwọn olùdíje sípò gomina sọ̀rọ̀ lórí ètò Èkọ́
Asiko ti to ki gbogbo eeyan kiyesi i awọn ihuwasi to le ṣakoba fun ọpọlọ wa.
Igba gbogbo ni awọn eeyan ẹkun rẹ maa ń fi ẹsun rẹ lọ niwaju ile lọpọ igba ṣugbọn ko yipada.
Mercy Aigbe Ọdun 2001 ni gbajugbaja osere yii bẹrẹ isẹ tiata.
Awọn olujẹjọ naa ni awọn ọlọpaa SARS ni wọn gbe awọn lati ofisi wọn to wa nilu Ilorin lo si ile iṣẹ ọtẹlẹmuye Intelligent Response Team to wa labẹ akoso ọga ọlọpaa, Abba Kyari.
Khafi bu sẹ́kún 26 Ògún 2019 Oríṣun àwòrán, khafibbn_officialfanpage Gedoni Ekpata ati Jackye Madu ni wọn ti yọ kuro lori eto BBNaija 2019 to n lọ lọwọ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ẹ̀dá ò láròpin, Super Eagles ṣẹ́só ìyá fún Cameroon 6 Agẹmo 2019 Oríṣun àwòrán, JAVIER SORIANO Àkọlé àwòrán, Ikọ Super Eagles ti tẹsiwaju lọ abala to kan ninu idije Afcon 2019 Ikọ agbabọọlu Super Eagles Naijiria ti gbewuro soju ikọ Cameroon lati tẹsiwaju ninu idije Afcon 2019.
Agbabọọlu orilẹede South Africa, Thembi Kgatlana lo gba ami ẹyẹ gẹgẹ bi agbabọọlu obinrin to tayọ ju ni Afrika.
Secret Cults in Nigeria: Iléèṣẹ́ ọlọ́pàá ní kò sí ààyè fún àjọ̀dún 7/7 ní ìpínlẹ̀ Oyo, Ogun
Òfin ìfipábánilòpọ̀ tuntun yóò fààye gba fífi kẹ́míkà tẹ ọkùnrin lọ́dàá Ìjọba ìpínlẹ̀ Zamfara ti gbé iléèwé mẹ́wàá tìpa lkyìn tí wọ́n jí àwọn akẹ́kọ̀ọ́ iléèwé Kankara gbé Ṣé lọ́òtọ́ ni ọlọ́pàá dàwátì torí àti dóòlà ọmọ India méjì tí wọ́n jígbé?
iye iku ti dinku laarin awọn ọdun 1970 ati 2000 .
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Oyinkan Abayomi: Ajàfẹ́tọ̀ọ́ ẹni tó dá ẹgbẹ́ òṣèlú obìnrin àkọ́kọ́ sílẹ̀, tó tún jà fún ètò ẹ̀kọ́, ìṣèlú àti òmìnira obìnrin 5 Bélú 2020 Oríṣun àwòrán, @Oyinkansola Lati igba laelae ni awọn akọni obìnrin ti wa, awọn akinkanju obinrin bii ọkùnrin.
Joshua Olusola Eleka ati Eunice Ademolabi Ojo Eleka bi Ọjọgbọn Kọlapọ Olubunmi Oluṣola lọdun 1968 ni Ikẹrẹ-Ekiti nipinlẹ Ekiti.
Ìtùmọ kọ́lẹ̀jì níbí ni àwọn ènìyàn tó parapọ̀ fún ìdí kan náà, iṣẹ́ wọn ni láti yan ààrẹ àti ìgbákejì ààrẹ Ọdún mẹ́rìn mẹ́rin ni àwọn kọ́lẹ̀jì ìdìbò yìí máa ń pàdé láti ṣe iṣẹ́ wọn lẹ́yìn ọ̀sẹ̀ díẹ̀ ti ará ìlú bá ti dìbò tán.
"Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Fayose: Àwòrán ìgbeyàwó ọmọ Fayose táwọn èèyàn ń kẹ́kòó nípa òṣèlú lára rẹ̀ 17 Bélú 2019 Oríṣun àwòrán, Twitter/ekitistategov Àkọlé àwòrán, Tẹrin tayọ lawọn mejeeji fi pade ara wọn nibi igbeyawo ọmọ Fayose ""Ẹ ma gbe ọrọ oloṣelu lori, ṣe ẹ ri Fayemi ati Fayose nibi iyawo ọmọ Fayose abi ẹ ko ri wọn?"
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Car Race: Elizade àti Akeredolu kópa nínú ìdíje eré sísá ni Ondo Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Bí mo bá gbà fún wọn, kò ní sí ẹni tí yóo jogún ọkọ mi, wọn yóo já ìrètí mi kan tí ó kù kulẹ̀, kò sì ní sí ọmọkunrin tí yóo gbé orúkọ ọkọ mi ró, tí orúkọ náà kò fi ní parun.
Ọpọlọpọ awọn eniyan ni o bu ẹnu ate lu oju opo Facebook gẹgẹ bi oju opo ti o ni ayederu iroyin to gajulọ.
Coronavirus ti orukọ rẹ n jẹ Sars-CoV-2,sunmọ kokoro aifojuri to n ba awọn adan finra amọ igbabọ ni pe lati ara adan si ẹrank miran lo gba ki o to de ara awọn eeyan.
Ààrùn Coronavirus tún ti ran ènìyàn 595 l'órílẹ̀-èdè Nàìjíríà Ọlọ́pàá kọ́ lo pa olórí àwọn ''One Million Boys'' Ebila n'Ibadan- Ọ̀gá ọlọ́pàá Oyo Kí ló fa ìjà láàrin Wunmi Toriola àti Seyi Edun?
Bí o bá rí ènìyàn kan tí ó ṣe ìlérí tí kò mó un ṣẹ mo fẹ́ kí o mọ̀ dájú pé olúwaarẹ̀ kò ṣeé gbẹ́kẹ̀lé.
Ìjà ìgboro rèé o, ṣe bí ọkùnrin ni Bobrisky ṣe bá ọkùnrin ẹgbẹ́ rẹ̀ jà ní?
Jonathan, ẹni to sọ idi ti oun fi n se atilẹyin fun Atiku Abubakar lati di aarẹ orilẹede yii ni, isoro to n ba Naijiria finra, taa ba tete mojuto, o lee tu orilẹede yii ka, ti ọpọ eeyan yoo si fọn ka lọ sawọn orilẹede miran.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Anger: Onínúfùfù máa ń ní ẹ̀mí gígùn ju Oníwàtútù lọ 16 Ìgbé 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Lati ọwọ awọn baba nla wa, lati ri ibinu Ọpọlọpọ awọn eniyan lagbaye ni igbe aye wọn rọrun, ti wọn si n fi ayọ lo igba, amọ kini o fa a, ti ọpọlọpọ eniyan n binu lode oni ju aye atijọ lọ?
Èyí máa n dènà àìsàn ẹ̀jẹ̀ ríru pẹ̀lú.
Àkọlé àwòrán, ọpọ ile lo ti di ẹgẹrẹmiti ni ipinlẹ Eko ti ijọba si ti fẹ ṣe ayẹwo lori wọn Omọwe Olufẹmi Oke- Osanyintolu to jẹ adari agba ajọ LASEMA ti parọwa fun baba onile naa lati jẹ ki ajọ LABSCA to n yẹ ile wo nipinlẹ Eko ṣiṣẹ wọn bi o ti yẹ.
 Buhari le sọ ipò ààrẹ́ nù tí kò bá yọjú sáwọn aṣòfin - Amòfin Àlàyé rèé lórí ìdí tí mo fi lọ sílé Tinubu - Rashidi Ladoja Ẹgbẹ́ òṣèlú alátakò takú láti gba èsì ìbò ààrẹ ní Ghana Ọ̀pọ̀ nkan tó n ṣẹlẹ̀ kò jẹ́ kí n gbàgbọ́ pé Naijiria wà ní abẹ́ ìdarí ẹnikẹ́ni - Wole Soyinka Ofoma tẹsiwaju pe iwadii ti a ṣe lori ẹrọ ibanisọrọ ati kọmputa rẹ fi han pe o lu awọn eeyan ni jibiti iye owo to to $15,000.
Wò ìdí tí téélọ̀ rẹ fi já ọ kulẹ̀ lásìkò ọdún Kérésìmesì Wo àwòràn ohun tó ṣẹlẹ̀ nílé ìjọsìn Sotitobire tí wọ́n sun ní àná Woli Arole, Gbenga Adeyinka àtàwọn míràn kẹ́dùn 'Sweet Steve' CBN dín owó sísan lóri lílo ATM kù Igun mẹrin ni iwe idibo naa ni.
Ní ọjọ́ tí ẹ bá kọjá odò Jọdani, tí ẹ bá ti wọ inú ilẹ̀ tí OLUWA Ọlọrun yín yóo fun yín, ẹ to òkúta ńláńlá jọ kí ẹ fi ohun tí wọ́n fi ń rẹ́ ilé rẹ́ ẹ.
Saaju ni Aare Muhammadu Buhari ti gbe igbimọ kan dide, eyi ti Ayo Salami jẹ alaga rẹ.
Wo bí ìwọ́de #ENDSARS tí Toyin Abraham ṣe nípínlẹ̀ Oyo ṣe lọ Wo oríṣi inú rírun márùn-ún tí o kò gbọdọ̀ pa mọ́ra Akeredolu lo moke ninu ijọba ibilẹ to pọ julọ ni ipinlẹ Ondo nigba ti Jegede oludije PDP atawọn to ku si tẹ le e.
Ṣùgbọ́n bàbá mi kò jẹ́wọ́ níwájú oníbodè, nítorí ọmọ ènìyàn kì í jẹ́wọ́ níwájú ọ̀tá, ìgbà tí ọmọ aráyé bá ti gbé ẹ̀wù ìbàjẹ́ wọ̀ tán, wọ́n á fi ìgbójú bo ara wọn ní àṣírí ìtìjú, ọ̀rọ̀ pẹ̀lẹ́ á sálọ kúrò lọ́dọ̀ ènìyàn, ohun gbogbo á di jàgídíjàgan.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Kunle Afolayan: èmi kò fẹ́ fi ogún sílẹ̀ fún ọmọ mi Awọn olukọni naa, labẹ aṣia ẹgbẹ olukọni ileewe giga nipinlẹ Ọṣun, CASUOSTI, wa fun ijọba ni gbedeke ọjọ meje lati pe awọn olukọni naa si ajọ ijiroro, lori ọrọ naa bibẹẹkọ awọn yoo bẹrẹ iyanṣẹlodi ni pẹrẹu.
Àwọ̀n àgbà Gẹ̀ẹ́sì bọ̀ wọ́n ní “Ìrìnàjò ńlá bẹ̀rẹ̀ pẹ̀lú ìgbésẹ̀ kan ṣoṣo”.
Iroyin sọ pe, ẹgbẹrun meji le díẹ̀ tọọnu ammonium nitrate to gbana yii jẹ ti ẹnikan, to fẹ ẹ ko ranṣẹ si ilẹ okeere lọdun 2014, ṣugbọn tí ijọba gbẹsẹ le e.
Ìríwísí àwọn aráàlú bí EFCC ṣe kó afurasí ọmọ yahoo 49 ní Ibadan Ajọ to n gbogun ti iwa ibajẹ lorilẹede Naijiria, EFCC ti fi panpẹ ọba mu awọn afurasi awọn ọmọ yahoo mọkandinlaadorun ni ilu Ibadan.
Lagos Lockdown: Ìgbésẹ̀ ìjọba lórí Twitter tì mí lójú- Jimi Disu
Ijọba wa rọ ẹka ilera lorilẹede Naijiria lati la awọn eniyan lọyẹ nipa ewu to wa ninu lilo yara igbọnse kan naa pẹlu Bobrisky.
Aare Muhammadu Buhari ti kẹdun pelu awon omo orile-ede Naijiria, papaa julo awon ipinle ti o n koju ikolu omiyale.
 Fun idi eyi, ile igbimo yii ko ni faaye gba enikeni tabi igbimo kankan lati tabuku ba bi o se le wu ko mo.
Bẹẹ lo kesi Aarẹ orilẹ-ede Niajiria lati maṣe foju kekere wo iṣẹlẹ to n waye ninu ẹgbẹ oṣẹlu APC, amọ ki o pẹẹtu saawọ naa, ki eto iṣejọba tiwantiwa ba le kẹsẹjari.
Nítorí náà, n óo fi aya wọn fún ẹlòmíràn,n óo fi oko wọn fún àwọn tí yóo ṣẹgun wọn.
“Nígbà tí ẹ bá ń gbẹ̀bí fún àwọn obinrin Israẹli, tí ẹ sì rí i pé ọmọ tí wọ́n fẹ́ bí jẹ́ ọkunrin, ẹ pa á, ṣugbọn bí ó bá jẹ́ obinrin ni, ẹ dá a sí.
Asofin tuntun lati ila Ariwa ni
Wọn gbe ọrọ naa lọ sile ẹjọ, ẹjọ naa si wa ni kootu titi di asiko ti ibugbamu waye ni nnkan bi aago mẹta ọsan lọjọ Iṣẹgun.
 fíìmù yìí jáde ni ọdún 1980 .
Oríṣun àwòrán, Others Ere Ayo: Ati ọmọde ati agba ni o ma n ṣe ere ayo.
Iye ìgbà tí ọrọ̀ ajé Nàìjíríà ti dẹnukọlẹ̀ lábẹ́ ìjọba ààrẹ Buhari Àwọn ìwàásù akọnilẹ́nu hàà tí Prophet Israel Oladele CCC Genesis Global ti ṣe rèé Wo àwọn èèkàn, ìlúmọ̀ọ́ka olórin tó ṣàbẹ̀wò sí ijọ Celestial Church ti Genesis Global Saka ń wá ọ̀rẹ́ rẹ̀ kan nítorí aṣọ kóòtù ọdún 34 sẹ́yìn Ọ̀kan nínú àwọn ọlọ́pàá náà sọ̀kalẹ̀ nínú ọkọ̀ wọ́n tó sì yìnbọ́n síbi táwọ̀n ènìyàn péjọ sí.
Ènìyàn 643 ló tún ṣẹ̀ṣẹ̀ lùgbàdì ààrùn Coronavirus ní Nàíjíríà Ọmọ Yorùbá mẹ́wàá tó jẹ́ àmúlùúdùn ní Amẹ́ríkà àti Yúróòpù Amojuẹrọ Arotilẹ ni ọdọ akọbi ọmọ awọn obinrin ni Tolulope n gbe Ni Kaduna.
Àwọn erékùṣù ń retí òfin rẹ̀.
Lootọ lo ti ku, awọn eniyan ṣi n fi ọrọ iranti si oju opo Twitter rẹ.
Agbẹnusọ ileeṣẹ ọlọpaa ipinlẹ naa, Abimbola Oyeyemi sọ wipe oloogbe naa lo fa ada yọ lati fi dẹrun ba ọmọ rẹ.
Leyin ti mo ribi bọ labere si ni wa.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ìjà ọlọ́pàá àti alápatà ni Bodija gbẹ̀mí Sulia aláìṣẹ̀ ni UCH ''A gbaa ko maa dana ounjẹ fun ẹbi, amọ oṣeni laanu pe a ko ṣayẹwo rẹ, ka to gbaa s'iṣẹ nitori pe a niloo rẹ ni kiakia.
Eliṣa Ran Opó Aláìní Kan Lọ́wọ́.
Bi ọpọ awọn eeyan ṣe n ki Onirisa ayọ abara tintin, lawọn miran n sọ pe Ọba lọla lo de yẹn.
OLUWA, o ò jẹ́ kí n dijú wò ní gbogbo òrumo dààmú tóbẹ́ẹ̀ tí n kò le sọ̀rọ̀.
Nítorí náà a máa bọ àwọ̀n rẹ̀.
Ṣugbọn Oluwa Jesu yóo fi èémí ẹnu rẹ̀ pa á, yóo sọ ìfarahàn rẹ̀ di asán.
"Sanwo-Olu kéde ìgbésẹ̀ rẹ̀ lórí ìrìnnà ọkọ̀ àjàgbé l'Eko Asa ""Ẹ dákun mo jẹbi ẹsún ẹ jẹ́ki a jọ ṣe adéhùn"" jẹ ǹkan to máa n wáye lásìkò ìgbéjọ ti olùjẹ́jọ ba gbà pe òun jẹ̀bi ẹsùn ti wọ́n fi kan òun."
Dájúdájú o mọ gbogbo ibi tí o ṣe sí Dafidi, baba mi; OLUWA yóo jẹ ọ́ níyà ohun tí o ṣe.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ẹbi yóò sèwádìí ohun tò pa Michael Adéyẹmọ 27 Ìgbé 2018 Oríṣun àwòrán, @Micadeyemo Àkọlé àwòrán, Kí ó tó kú, ẹkùn ìdìbò ìlà oòrùn Ìbàràpá ni aṣòfin Adeyẹmọ ṣojú fún Àyẹ̀wò yóò wáyé lórí òkú Olori ile aṣofin ipinlẹ Ọyọ, aṣofin Michael Adeyẹmọ tó dagbere fáyé lówúrọ̀ ọjọ́ ẹtì.
Bẹ́ẹ̀ ni yóo ṣe fi ẹ̀jẹ̀ ẹyẹ náà ati omi tí ń ṣàn, ati ẹyẹ tí ó wà láàyè, ati igi Kedari, ati ewé hisopu, ati aṣọ pupa tẹ́ẹ́rẹ́ náà sọ ilé náà di mímọ́ pada.
’ Wọ́n kó wọn fún mi, ni mo bá dà wọ́n sinu iná, òun ni mo sì fi yá ère mààlúù yìí.
Ní gbogbo ibi tí ó ti jagun ni ó ti pa wọ́n ní ìpakúpa.
Ẹni ọdun mẹtalelogoji ohun ni aisan ẹjẹ riru lo ni to si ti ṣe akoba fun isọrọ rẹ.
Nítorí náà, eniyan kò lè mọ ohun tí ń bọ̀ wá ṣẹlẹ̀ lẹ́yìn ọ̀la.
Minista wa lo asiko naa lati ki gbogbo omo orile ede
Irun tí ó hù sí orí ètè òkè ní ìsàlẹ̀ ibi tí imú wà ni ó ń jẹ́ túbọ̀mu.
O bẹ̀rẹ̀ sí fọ́nnu pẹlu ìgbéraga pé o ti ṣẹgun àwọn ará Edomu, ṣugbọn, mo gbà ọ́ ní ìmọ̀ràn pé kí o dúró jẹ́ẹ́ sí ilé rẹ.
 lámilámi gbọ ́ dọ ̀ jẹ wọ ́ n ṣáájú èyí .
Jerameeli tún ní aya mìíràn, orúkọ rẹ̀ ń jẹ́ Atara, òun ni ìyá Onamu.
Wo àwọn ìṣesí ojoojúmọ́ mẹ́wàá tó le ṣàkóbá fún ọpọlọ rẹ Ìyàwó mi fi mí sílẹ̀ kó lọ sílé ọkùnrin míì nínú báráàkì kan náà, àmọ́ mò sí tún fẹ́ràn rẹ̀- Sọ́jà Coronavirus: ''Ìjọba kò tíì pàṣẹ ìlànà ìtakété-síra-ẹni padà nínú BRT la ò ṣe máa tẹ̀le'' Ìjọba gbé ilé ijó oníhòhò tì pa lórí ẹ̀sùn títàpá sí ìlànà àti dẹ́kun coronavirus Wo àwọn Adelé-Ọba aládé méje tó jẹ́ obìnrin nílẹ̀ Yorùbá Jide Kosoko forin sẹ́nu pé òun ni igi lẹ́yìn ọgbà Mr Latin lórí ipò ààrẹ TAMPAN tó wà Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí How to get your National Identification Number: Àwọn ọ̀nà tí o le gbà rí fọ́ọ̀mù ìforúkọsílẹ̀ fún NIN rẹ gbà àti àwọn ibùdó ìforúkọsílẹ̀ lágbáyé nìyí22 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 NIN: Ohùn mẹ́ta pàtàkì tó yẹ kí o mọ nípa nọ́mbà ìdánimọ̀ Nàìjíríà16 Ọ̀wàrà 2019 NIMC registration portal: Ìjọba Nàìjíríà fọjọ́ mọ́kànlélógún gbako kun ọjọ́ láti so NIN rẹ̀ mọ́ síìmù21 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
"Bí ẹgbẹ́ One Million Boys ṣe bẹ̀rẹ̀ rèé àti ọṣẹ́ tó ṣe n'Ibadan Wo ohun tó yẹ kí o mọ̀ nípa Laycon, akẹ́kọ̀ọ́jáde UNILAG tó ń kópa nínú BBNaija 2020 Kanye West ti bẹ̀rẹ̀ ìpolongo àti díje dupò aàrẹ ilẹ̀ Amẹrika Ohun tí o kò mọ̀ nípa Ebila ""One Million Boys"" àti Ekugbemi, olórí ẹgbẹ́ òkùnkùn méjì tó da ìlú Ibadan rú Bakan naa, iroyin ti n jade bi awọn ologun ṣe n sọrọ pe awọn nkan ijagun ko to awọn ja ogun nla nla bii eyi ti awọn ajijagbara n ko."
” Rebeka bá mú ìbòjú rẹ̀, ó dà á bojú.
Ninu atẹjade kan ti Aarẹ ẹgbẹ naa, Arẹmọ Ọladọtun Hazzan fi ọwọsi lọjọ Aiku, ẹgbẹ naa ni, isẹlẹ naa jẹ iwa aṣilo agbara, ọtẹ oselu ati titẹ ẹtọ ẹni loju, nitori pe o yẹ ki ijọba duro de idajọ ileejọ na, ko to lọ wo ileesẹ redio naa.
''Ojuṣe wa ni lati daabo bo awọn ọdọ papaa julọ lọwọ awọn ti ijọba n sanwo fun un lati daabo bo wọn,'' Ọjọgbọn Osinbajo lo woye bẹẹ.
Ọjọ́ ayé mi ń lọ bí òjìji àṣáálẹ́,mo sì ń rọ bíi koríko.
Gẹgẹ bi agbẹnusọ ajọ EFCC, Tony Orilade ṣe sọ, owo naa, N9,927,714,443.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ọdọ kan sọrọ lori ipalara aibuwọlu abadofin Peace corps 2 Ẹrẹ̀nà 2018 Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ọdọ kan sọrọ lori bi Buhari se da abadofin Peace corps nu Pẹlu bi aarẹ orilẹede Naijiria, Muhammadu Buhari ti se da abadofin idasilẹ ajọ Peace Corps silẹ nu bayii, oniruuru iroyin to n jade bayii ni ti awọn ọdọ to wa ni ajọ naa ti wọn ti n mi imi ẹdun bayii lori igbesẹ naa ti wọn ni o jasi wi pe owo awọn wọgbo.
Awọn ọmọ eniyan mọ pe awọn ti ṣe nkan ti ko tọ ọ, eyi to mu wọn lọ ke ba awọn ti yoo gba wọn silẹ.
Ẹ máa dá ẹjọ́ ẹ̀tọ́ ní òwúrọ̀,ẹ máa gba ẹni tí a jà lólè lọ́wọ́ aninilára,kí ibinu èmi OLUWA má baà ru jáde, nítorí iṣẹ́ ibi yín,kí ó sì máa jó bíi iná,láìsí ẹni tí yóo lè pa á.
Ebi pa agbára mọ́ ọn ninu,ìṣòro sì ti ṣetán láti gbé e ṣubú.
Bí a bá bí ìbejì ní ìdílé wọ̀nyìí, tí àwọn méjéèjì sì jẹ́ obìnrin, ọjọ́ keje la ó sọ wọ́n lórúkọ.
Marriage Certificate: Bí o ṣe lè mọ ìgbéyàwó tí kò bá òfin mu
idagbasoke ba ile Afirika ati agbaye.
Aposteli èké ni irú àwọn bẹ́ẹ̀.
Asofin Temitope Olatoye Sugar to n soju fun  ekun Lagelu/Akinyele ni ilu Ibadan , ni ekun
Eto tuntun ti BBC Yorùbá já lójú loni ni a pè ni: Ìròyìn Kàyééfì ti BBC Yorùbá.
Nítorí náà, Dafidi ati ẹgbẹta (600) àwọn ọkunrin tí wọ́n wà pẹlu rẹ̀ kúrò ní Keila lẹsẹkẹsẹ.
" Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ọpọ awọn eeyan to faramọ pe ki ilẹ Gẹẹsi kuro ninu ajọ isọkan apapọ Yuroopu gbagbọ pe, awọn ko ni pẹ bori ipenija to lee yọju lori ọrọ aje ti Gẹẹsi ba kuro laisi adehun kankan O ni oun yoo wọgile adehun kikuro ti Theresa May se, ti oun yoo si beere fun ilana adehun miran to yatọ patapata ko to di ọjọ kọkanlelọgbọn osu Kẹwa, nitori ayipada ranpẹ ko lee tẹ oun lọrun.
 Àwọn ipa láti ṣàmúkúrò aarùn yíì nípa ìtọjú àwọn ọ ̀ wọ ́ ènìyàn lẹ ́ ẹ ̀ mejì lọ ́ dún ni o ńlọ lọ ́ wọ ́ ní ọ ̀ pọ ̀ agbegbè ní àgbayé .
Ṣelomiti ati àwọn arakunrin rẹ̀ ni wọ́n ń ṣe ìtọ́jú ẹ̀bùn tí àwọn eniyan bá mú wá, ati àwọn ohun tí wolii Samuẹli, ati Saulu ọba, ati Abineri, ọmọ Neri, ati Joabu, ọmọ Seruaya, ti yà sọ́tọ̀ ninu ilé OLUWA.
Ó bi àwọn ọkunrin kan, ará ìlú náà pé, “Níbo ni obinrin aṣẹ́wó tí ó máa ń jókòó ní gbangba lẹ́bàá ọ̀nà Enaimu yìí wà?
Àwọn igi àti ewéko kan díwa lójú díẹ̀ tí a kò sì rí nkan náà dáadáa.
Itai, ọmọ Ribai, ará Gibea, láti inú ẹ̀yà Bẹnjamini, ati Bẹnaya, ará Piratoni; 
O ni oun ti o han si oun ati ọpọ ọmọ ipinlẹ naa ni pe awọn oniṣẹ ibi ti gbajọba ni ipinlẹ naa de ibi pe awọn olugbe ibẹ ko lee di oju sun mọ.
Ọmọ bíbí Ijẹbu Ode, ìjọba ìbílẹ̀ kan ní ìpínlẹ̀ Ogun ni Eniola Badmus.
O dára, o wuni gan-an,olùfẹ́ mi, ẹlẹgẹ́ obinrin.
Ó ní kí n dìde, kí n ṣe ìrìbọmi, kí n wẹ ẹ̀ṣẹ̀ mi nù, kí n pe orúkọ Oluwa.
Dokita naa ni kii se aarin awọn ti kii se lọkọlaya ni isẹlẹ yii ti maa n waye nikan, amọ o tun maa n waye laarin tọkọ-taya pẹlu.
Wọn ti fi ẹsun kan ọmọ ọdun mẹtadinlọgbọn kan Nathan Harewood, 27 wipe o mọ nipa ọrọ naa.
Ṣé o lè pe mànàmáná pé kí ó wá kí o rán an níṣẹ́kí ó wá bá ọ kí ó wí pé, ‘Èmi nìyí?
Ayinla Ọmọwura, orin èébú àti oríyìn lo fi di ọ̀rẹ́ àwọ̀n obìnrin Ọmọ Isaac Adewọle gba ìdáǹdè lọ́wọ́ ajínigbé Agbekoya: Bí a bá na oògùn abẹnugọ̀ngọ̀ s'ókè, ìjínigbé á d'ópin!
“Jobu, n óo dá ọ lóhùn,nítorí pé bí o ti wí yìí, bẹ́ẹ̀ kọ́ lọ̀rọ̀ rí.
Àkọlé orí agbelebu tí wọ́n kọ, tí ó jẹ́ ẹ̀sùn tí wọ́n fi kàn án ni: “Ọba àwọn Juu.
OLUWA ní kí n sọ fún Ṣemaaya tí ń gbé Nehelamu pé, 
Saaju ni o je elere ori papa to kopa ninu idije asafogi ‘hurdles’ Summer Olympics lodun 2012 nilu London.
Ife mẹrin ni ó ṣe sórí ọ̀pá fìtílà náà gan-an, ọ̀kọ̀ọ̀kan wọn dàbí òdòdó alimọndi pẹlu ìrudi ati ìtànná rẹ̀.
Nígbà tí Mahalaleli di ẹni ọdún marundinlaadọrin, ó bí Jaredi.
Odò Jọdani ni ààlà rẹ̀ ní apá ìlà oòrùn.
fiwe  ipe  ranse si aare lati wa nibi ipade apero naa ,
Nítorí agọ̀ ni ọgbọ́n ayé yìí lójú Ọlọrun.
Nipa ti ounjẹ, Adamu to ribi moribọ sisọ loju rẹ pe okele tuwo kọọkan ni wọn n fun awọn lọsan ati alẹ.
Ọjọgbọn Oṣinbajo sọrọ lori akori to pe ni 'Ọgọta ọdun Naijiria gẹgẹ bii orilẹ-ede, Naijiria ṣi ni ilẹkun fun idagbasoke Afirika'.
Awọn miran sọ pe bi ọkọ Kabiesi ṣe n lọ, ni awọn afurasi ajinigbe naa da ọkọ duro, amọ awakọ rẹ to fura si wọn gbiyanju lati salọ.
Ọ̀rọ̀ dùn lẹ́nu rẹ̀, ó sì mọ Ìwé Mímọ́ pupọ.
Awọn fada mejeeji naa ni orukọ wọn n jẹ Cajethan Obiekezie ati igbakeji rẹ, Solomon Orakam Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Amotekun yóò gba owó oṣù kẹtàlá ní ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́ - Seyi Makinde Maina dákú fún ọ̀pọ̀ ìṣẹ́jú, iléejọ́ sáré so ìjókòó rọ̀ Ọlọ́pàá tún yìnbọn pa awakọ̀ Márúwá, ìwọ́de gba Portharcourt kan Wo ìròyìn tó pọ̀ jùlọ táwọn èèyàn ń wá ní Google lọ́dún 2020 Obasanjo àti Gani Adams tẹ́ mi pẹ̀lú bí wọn ṣe tahùn síra wọn - Adebanjo Buhari le sọ ipò ààrẹ́ nù tí kò bá yọjú sáwọn aṣòfin - Amòfin Ẹgbẹ́ òṣèlú alátakò takú láti gba èsì ìbò ààrẹ ní Ghana Ọ̀pọ̀ nkan tó n ṣẹlẹ̀ kò jẹ́ kí n gbàgbọ́ pé Naijiria wà ní abẹ́ ìdarí ẹnikẹ́ni - Wole Soyinka Ọmọ ẹgbẹ́ òkùnkùn ṣoro ní Ijebu Ode, ọ̀pọ̀ ẹ̀mí sọnù Fada Obiekezie, to se agbatẹru eto ifọrọwanilẹnuwo naa, lo lewaju ikọ iroyin BBC lọ sinu ijọ Adoration Ministry ti Mbaka n lewaju rẹ ni deede aago mẹwa owurọ.
ba gomina ipinle Sokoto Aminu Tambuwal ati awon omo ipinle Sokoto kedun nipa
Oyedepo, eni ti o seto adura yii lasiko abewo olojo kan si ilu Jos so pe, alaafia yoo bere si ni joba ni ipinle ohun lati sinsin yii lo.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù 8th National Assembly: Ilé ìgbìmọ̀ aṣòfin kẹ̀jọ kógbá sílé lónìí 6 Òkùdu 2019 Oríṣun àwòrán, Twitter/The Senate President Àkọlé àwòrán, Ile Igbimọ aṣofin kẹjọ Oni ọjọ kẹfa, oṣu kẹfa, ọdun 2019 ni ile igbimọ aṣofin agba ikẹjọ l'Abuja yoo kogba sile.
Àwa gan-an ni ìdílé rẹ̀ náà, bí a bá dúró pẹlu ìgboyà tí à ń ṣògo lórí ìrètí wa.
“Àwọn tí wọ́n wà ní ọ̀nà jíjìn réré yóo wá láti ba yín kọ́ ilé OLUWA.
Ijọba apapọ Naijiria lo se agbekalẹ eto iranwọ isẹ N-Power labẹ ileesẹ to n risi idagbasoke awujọ ni Naijiria fawọn ọdọ ti ko ba nisẹ lọwọ.
Ẹni tí ó bá ti kéde láti ìbẹ̀rẹ̀, nípa àwọn nǹkan tí yóo ṣẹlẹ̀,kí wọn sọ ohun tí yóo ṣẹlẹ̀ fún wa.
Wọn óo dàbí ìràwé tí afẹ́fẹ́ ń gbé lọ lórí òkè,ati bí eruku tí ìjì líle ń fẹ́ kiri.
Wọ́n fi ọ̀pá ìdábùú kan la àwọn àkànpọ̀ igi náà láàrin, ọ̀pá náà kan igun kinni-keji àgọ́ náà.
Coronavirus ti di ara wa, kò le è kúrò mọ láéláé - WHO Coronavirus cases in Africa- Atọ́nà bí nkàn ṣe ń lọ ní Afirika Ènìyàn 226 ló ní àrùn Coronavirus ní Ọjọ Ìṣẹ́gun Inú jìn!
Ẹ̀yin àgbèrè, ẹ kò mọ̀ pé ìbá ayé ṣọ̀rẹ́ níláti jẹ́ ìbá Ọlọrun ṣọ̀tá?
Lagos: Olùkọ́ fipá bá akẹ́ẹ̀kọ́ girama lòpò nítorí máàkì
 Ọba alaye lobinrin ọhun, to ni oun ko tii ni afẹsọna kankan, wa rọ ijọba lati maa ran awọn ọba alaye ati adele lọwọ."
Àwòrán ìgbeyàwó ọmọ Fayose dùn, ó lárinrin Rẹ́díò Fayose di títìpa l'Ekiti Ìgbẹ́jọ́ EFCC kò ní jẹ́ kí ń péjú sí ìbúra Fayemi - Fayose Ninu atẹjade kan ti Kọmisana feto Iroyin, irinajo igbafẹ ati ilanilọyẹ Muyiwa Olumilua fi sita, o ni a igbaniṣisẹ to waye lẹyin idibo Gomina losu Keje ọdun 2018 ko tẹle ilana to yẹ.
O ṣeese ki orilẹ-ede Amẹrika o gbe igbesẹ to le tako Naijiria atawọn orilẹede wọnyii bi wọn ko ba ṣe atunṣe lasiko.
Àwọn àgbààgbà Jabeṣi dáhùn pé, “Fún wa ní ọjọ́ meje, kí á lè ranṣẹ jákèjádò ilẹ̀ Israẹli.
Abẹnugan fun awọn dokita naa ni fasiti ẹkọṣẹ iṣẹgun ipinlẹ Ondo, UNIMEDTH, Olagbe Taiwo Paul sọ fun BBC Yoruba pe, ijọba atawọn alaṣẹ fasiti ọhun kọ lati mu gbogbo ileri ti wọn ṣe fun awọn ṣẹ.
Oríṣun àwòrán, @followlasema Ileesẹ o kere tan, ibudo itaja mẹsan miran lo fara gba ninu isẹlẹ ọhun, tii wọn si jona kanlẹ.
Agbenusoro ile-ise aare orile-ede Sudan soro naa di mimo ninu atejade
’’ Titi enu ona ile-ijọba pa.
Koko ẹhonu marun un lawọn oluwọde naa gbe kalẹ pe awọn fẹ ki ijọba mojuto ki wọn si tete gbe igbesẹ to tọna lori rẹ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Buhari: Òpùrọ́ àti òjòwú ni Olusegun Obasanjo 21 Sẹ́rẹ́ 2019 Oríṣun àwòrán, Google Àkọlé àwòrán, Ìjọba fèsì lẹ́yìn tí Ọbasanjo fi léde wí pé ìjọba Buhari kò yàtọ̀ sí tí Abacha pẹ̀lú ìmọ̀ràn pé kó lọ sinmi.
Nígbà tí ó bá di ọjọ́ kẹfa, kí wọ́n kó oúnjẹ wálé kí ó tó ìlọ́po meji èyí tí wọn ń kó ní ojoojumọ.
Ilana ijinasiraẹni jẹ ọkan gboogi lara awọn igbesẹ ti ajọ eto ilera agbaye, WHO gbe kalẹ gẹgẹ bi ara ọna ti a le gba dena itankalẹ aarun Coronavirus.
Watford da iyanrìn sínúu gaàrí Arsenal Òfò ṣ'ẹ̀dá: Ẹ̀fọn Norwich já bàálùu Man City Ronaldo, Messi ẹ yàgò lọnà fagbábọ́ọ̀lù Nàìjíríà tó n gbowò julọ!
Amugbalẹgbẹ fun aare lori ọrọ iroyin, Fẹmi Adesina lo sọ eyi.
Yorùbá dùn lẹ́nu àwọn ọmọ yìí níbi ìdíje ẹgbẹ́ Àtúnbí Yorùbá
 bákan náà , ní oṣù karùún ( may , 2011 ) , bádérìnwá di amúgbá-lẹ ́ gbẹ ̀ ẹ ́ ìròyìn alágo mọ ́ kànlá ( 11 p.
Wọn ni ko si ''ifarajin to pọju lati wa ọna idẹkun ajakalẹ yi patapaa'' CAN wa parọwa sawọn ile ijọsin gbogbo nipinlẹ ti ijọba ti wọgileisin yi lati se isin wọn ki ọjọ to lọ ki wọn si palẹmọ o pẹ ju ago mọkanla alẹ.
Bí iná bá kú a fi eérú bó ojú, n ó bo ojú rẹ dáradára; bí ọ̀gẹ̀dẹ̀ bá kú a fi ọmọ rẹ̀ rọ́pọ̀, n óò jẹ́ “Adérọ́pò” rere fún ọ; bí òṣùpá sì ti ń tàn káà kiri ayé bẹ́ẹ̀ ni n ó tan orúkọ rẹ káà kiri orílẹ̀-èdè ayé.
com Àkọlé àwòrán, Gbogbo ẹ di mimọ lataari fidio to jade lori ayelujare Awọn oṣiṣẹ kan ti wọn jọ pé ilé-iṣẹ́ àtúnṣe ilé ni ìlú Guizhou ni wọn n bá ṣiṣẹ ni ó jọ lori bí wọn ṣe n mu omi tó jọ itọ ninu kọọpu ati bi wọn ṣẹ n di imu wọn fun oorun.
Oríṣun àwòrán, Bose Àkọlé àwòrán, Fásitì OAU ṣàlàyé pé àìgbọ́raẹniyé láàárín fásitì àti ìjọba ló fa ìṣẹ̀lẹ̀ náà Àjọ náà gbé ìloro ọgbà fásitì náà tì pa lẹ́yìn tí gbèdéke ọjọ́ méje tí wọn fún OAU làti san owó orí ọ̀hun forí sánpọ́n.
" Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Kí lo tíì rí nípa Amotekun?
Iko agbaboolu odo Guingamp to n kopa ninu idije orile-ede Faranse, tojo ori won koju mokandinlogun lo, Guingamp U19 ti ra Isaac Drogba, omo atamatase iko agbaboolu Chelsea teleri, ti o tun je omo-orile-ede Cote d’Ivoire, Didier Drogba wa sinu iko naa bayi.
Ẹwẹ, minisita eto ilera, Dokita Osagie Ehanire ti sọ pe ijọba ti yanju ọrọ aṣọ idaabobo(PPE) tawọn oṣiṣẹ eleto ilera maa n wọ lẹnu iṣẹ.
Muhammed Alkali; Iléèṣẹ́ ológun ti ri òkú rẹ̀ nínú kànga
Wọ́n ti mu aṣojú ọmọ Britikó ní orílẹ̀-èdè Iran Serena Williams gba ife ẹ̀yẹ àkọ́kọ́ láàrin ọdún mẹ́ta sẹ́yìn Ṣaaju, oni ọjọ Aje lo yẹ ki ile-ẹjọ to ga ju lọ ni Naijiria dajọ awuyewuye to jẹyọ nibi ibo gomina awọn ipinlẹ naa.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Samuel Okwaraji: Kíni ẹ̀yín mọ nípa akọni yìí?
bí a ò bá dé adé, adé tèmi lẹ rí yẹn o!
Ninu ifigagbaga apapo olukopa meji (men’s team doubles), bi o ti le jepe, Azeez Jamiu ati Olajide Omotayo fagbahan Terry Su ati Devesh Hukmani ti won wa lati orile-ede Belize pelu (11-6), (11-4), (11-5), sugbon omi poju oka lo leyin ti won padanu ifigabaga elekeji sowo Javen Choong ati Chee Feng Leong lati Malaysia pelu ami-ayo (4-11), (9-11),(7-11).
Isìn ń tesiwaju pelu pé kò sí Àlùfáà Babatunde ni itosi, amọ lóòótọ́, kò dabi ìgbà tí bàbá wá nílé, kò sì ìlú lílu nítorí pe gbogbo àwọn èròjà wonyii ni wọn ti jo nina."
Ninu èyí tí ó dára jù ninu àwọn ohun tí ẹ bá gbà ni kí ẹ ti san ìdámẹ́wàá yín.
maa mojuto oro ile okeere , ẹ fọwọsowọpọ pẹlu ajo naa, ki a le mu ipinnu wa wa
Awọn agbabọọlu Mali gba pẹnariti marun un wọn wọ le nigba ti Argentina si le gba mẹrin pere sawọn.
Ọpọ awọn eeyan pẹlawọn ẹgbẹ alatako gbogbo ni wọn ti tako iyansipo Amina Zakari ti o jẹ ana fun Buhari.
kíndìnrín rẹ̀ mejeeji, pẹlu ọ̀rá tí ó bò wọ́n níbi ìbàdí, ati ẹ̀dọ̀ rẹ̀.
Àwọn ǹkan ti a mọ̀ nìyìí.
Sugbọn ile ẹjọ ni gbogbo ẹsun naa ni ko ri ẹsẹ walẹ nitori aisi ẹri aridaju.
8 515 Erekusu Bermuda 9 14.
Yóo dáná sun àwọn ilé àwọn oriṣa ilẹ̀ Ijipti; yóo jó wọn níná; yóo sì kó àwọn ará ìlú lọ sí ìgbèkùn; yóo fọ ilẹ̀ Ijipti mọ́ bí darandaran tíí ṣa eégbọn kúrò lára aṣọ rẹ̀, yóo sì jáde kúrò níbẹ̀ ní alaafia.
Baba Wande: Oríṣun àwòrán, Babawande/instagram Àkọlé àwòrán, Manigbagbe ni sinima 'Ti Oluwa nilẹ' pẹlu ipa ti Baba Wande ko gẹgẹ bii Oloye Ọtun Ara awọn agba ọjẹ ere sinima ede Yoruba ni Alhaji Kareem Adepọju, ti ọpọ mọ si 'Baba Wande' , o si ti lo to ọdun marunlelaadọta ninu ere itage ati sinima.
tí Hiramu, ọba Tire sì ti fún un ní ìwọ̀n igi kedari, igi sipirẹsi ati wúrà tí ó fẹ́, fún iṣẹ́ náà, Solomoni fún Hiramu ní ogún ìlú ní agbègbè Galili.
Irú ẹbọ yìí ni inú Ọlọrun dùn sí.
Lẹyin eyi ni o fẹ olorin takasufe ọmọ Naijiria Abdul Rasheed Bello niluu London.
Idi owo ẹrú si ni akọni obinrin naa ti ri taje ṣe bii Efunroye Tinubu, oun naa lowo, o lọla, o gbajumọ, to si n dari ọpọlọpọ ọkùnrin labẹ rẹ.
Ajọ isọkan pe fun iranwọ fun ariwa Naijiria Siga tita d'eewọ lẹba ile ẹkọ Wọn sọ wipe awọn to wa ni agbegbe ti wọn tin sọ edẹ Faranse nfun awọn ni wahala lati ri isẹ se ati nidi iwe kika, to fi mọ ipese eto ilẹra, iselu ati didi ipo asaaju mu.
Ile ẹjọ Crown Court to wa ni Birmingham sọ pe tọkọ-taya naa sọ ọmọ wọn ni Adolf lati fi bu ọlá fun olori ikọ̀ NAzi to ti papoda.
Igba ṣílè, eyiun dọ́là márùn-ún àbí pọ́ùn mẹ́rin, làwọn èèyàn tó bá ń lo àwọn ojú òpó wọ̀nyí lórí ìtàkùn àgbáyé yóò máa san lójoojúmọ́, tí wọn bá sí Facebook, Whatsapp, Viber àti Twitter.
O ni igbo kijikiji to wa ni agbegbe yii ni awọn kan ti sọ di ibuba wọn fun iṣẹ ibi.
"Oríṣun àwòrán, Seyi Makinde ""Mo gba gbogbo ẹbi mọra lori bi awọn osisẹ panpana se kuna lati tete bomi pa ina ọhun ko to bọwọ sori, ijsba mi yoo si se atunse to yẹ nipa isẹlẹ naa."
Asọ́ ń pe aṣọ ránsẹ́ níbi ayẹyẹ ojúde Ọba ní'lùú Ijẹbu Pàtàkì ọdún Ojúde Ọba fún ìran Yorùbá Khafi wọ gàu lẹ́nu iṣẹ́ lórí ẹ̀sùn ìbálòpọ̀ ní BB Naija Àlàyé rèé lóríi ìdí tí wọ́n fi ń pe aya ní ìyàwó Ọdún Orò ń sọ àwa obìnrin sí ìgbèkùn, ẹ̀wọ̀n, tó sì ń tẹ ẹ̀tọ́ wa lójú - Àwọn obìnrin Ikorodu faraya Gẹgẹ bi awọn obinrin to ba BBC sọrọ ti wi, o dara ni ẹkọọkan bayii lati maa fi ọwọ lile mu awọn ọkunrin, ti awọn obinrin nikan yoo ti da wa laisi awọn ọkunrin nibẹ.
Bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé, ó dẹ́ṣẹ̀ sí OLUWA, ṣugbọn ó wó òpó oriṣa Baali tí Baba rẹ̀ mọ, ẹ̀ṣẹ̀ rẹ̀ kò sì pọ̀ tó ti baba rẹ̀ tabi ti Jesebẹli ìyá rẹ̀.
Wọn ni àwọn ṣi n ṣe iwadii lori ohun to fa ijamba ọkọ naa.
ifọwọsowọpọ se nilo laarin awon oloselu ti ọrọ kan ni apa iwọ oorun gusu ki
 Eleyii ni o si n foju han ninu awọn iṣẹ idagbasoke ti a n foju ri kaakiri ni Ipinlẹ Eko bayii”.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Bobrisky: Olusegun Runsẹwẹ, o kéré sí nọ́mbà àwọn tí mò ń bá se!
Bí ẹnikẹ́ni bá jẹ́ ẹni tí ó kọlà nígbà tí a pè é, kí ó má ṣe pa ilà rẹ̀ rẹ́.
GDP ni àpapọ̀ owó tàbi odiwọ̀n ọjà ti orílẹ̀-èdè kan ń pèsè lábẹ́lé láti tà fún orílẹ̀-èdè míràn Bí ọ̀rọ̀ ajẹ Naijiria se wá dẹnukọlẹ̀ yìí, ó túmọ sí pé owó tí yóò máa wọlé fún ọjọ́ ti wọ́n tà síta óò maa kéré jọjọ.
6 Èbibi 2019 Lẹ́yin ti Gomina Ipinlẹ Kaduna Nasir El-Rufai ni awọn ara ipinlẹ Eko le yọwọ awọn baba isalẹ kuro ninu oṣelu Ipinlẹ Eko, onimọ kan, Ọjọgbọn Tunde Fatunde ti ṣe alaye bi iru igbesẹ yii ṣe le yọri si rere.
Ni Naijiria ko si agbelewọn to yatọ lori owo ori awọn elere idaraya tabi awọn to n ṣe iṣẹ amuludun.
Aarẹ Obasanjọ lo ya ọjọ yii sọto lọdun 2000 lasiko to ṣi wa ninu ijọba.
Ipinlẹ OgunIpinlẹ yii ni wọn ti ri ẹni to kọkọ ni aarun coronavirus ni orilẹ-ede Naijiria.
Túnde Atọ̀pinpin náà kọ lẹ́tà sí Olófìn-íntótó.
Nígbà tí ọtí tán, ìyá Jesu sọ fún un pé, “Wọn kò ní ọtí mọ́!
Lhamo ò fi ìgbà kan bẹ̀rù láti sọ èrò ọkàn-an rẹ̀ jáde rí tàbí fi ara rẹ̀ hàn gẹ́gẹ́ bí ọmọ Tibet- ó má ń wọ Chuba, aṣọ ìbílẹ̀ àwọn ọmọ Tibet, ní gbogbo ọjọ́ Ọjọ́rú.
Yipada sí wa, OLUWA; yóo ti pẹ́ tó tí o óo máa bínú sí wa?
Theresa May ti gúnlẹ̀ sí South Africa Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Orilẹ-ede South Africa, Nigeria ati Kenya ni olootu ijọba ilẹ Gẹẹsi naa yoo maa bẹwo pẹlu ireti ati tubọ fi idi iṣakoso rẹ mulẹ gẹgẹ bii olootu ijọba Olootu ijọba ilẹ Gẹẹsi, Theresa May ti gunlẹ si ilu Cape Town bi o ṣe n bẹrẹ abẹwo rẹ si orilẹede South Africa.
Ó tún fi kun fún mi pé, “Ìwọ ọmọ eniyan, n óo mú kí oúnjẹ wọ́n ní Jerusalẹmu tóbẹ́ẹ̀ tí ó fi jẹ́ pé ìbẹ̀rù ni wọn óo máa fi wá oúnjẹ tí wọn óo máa jẹ, wíwọ̀n ni wọn óo sì máa wọn omi mu pẹlu ìpayà.
@_MrAwaji ati @ayanbaba1 tako ara wọn lori ọrọ Tinubu, @_MrAwaji lo kọkọ sọ pe ẹru lo n ba Tinubu lo jẹ ko sọrọ bẹẹ ṣugbọn @ayanbaba1 ni irọ nio wipe ko si ẹru kankan fun Tinubu ati ẹgbẹ APC.
“ile ifowopamo agba CBN yoo ro awon olokoowo lati maa samulo owo China-yuan dipo dola,”Ewe, ti a ba ranti pe orile-ede Naijria ati People’s Bank of China (PBOC) towo bo iwe adehun bilionu lona meji abo owo dola($2.
Ọwọ́ mi mọ́, n kò ní ẹ̀bi, OLUWA,mo sì ń jọ́sìn yí pẹpẹ rẹ ká.
82% ọkùnrin ní kó mọ̀ pé òun ní àìsàn jẹjẹrẹ asẹtọ ní Naijiria Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Footballers: ìkà láwọn aṣojú agbábọ̀ọ̀lù míì lágbàyé Offia sọ di meji ni iṣẹju kẹtalelogun, ti Tomiwa Dele Bashiru to n gba fawọn ọjẹ wẹwẹ Manchester City ati Aliu Salawudeen si de lade pẹlu goolu Kẹta ati ikẹrin ni abala keji.
Oríṣun àwòrán, Reuters Lati ipinlẹ New York de awọn ipinlẹ miran ni awọn eniyan ti fa rogbodiyan lasiko ifẹhọnu han naa, ti wọn si jo aago ọlọpaa pẹlu.
Gbogbo nǹkan yòókù tí Asa ọba ṣe, ati àwọn ìwà akin tí ó hù, ati àwọn ìlú tí ó mọ odi yípo, ni a kọ sinu Ìwé Ìtàn Àwọn Ọba Juda, ṣugbọn ní ọjọ́ ogbó rẹ̀, nǹkankan mú un lẹ́sẹ̀.
Ọpọ awọn eeyan ni wọn n gbadura fawọn to padanu ọja pe Oluwa a fofo ra ẹmi fun wọn ati pe ki ijọba pese ohun to yẹ ni amayedẹrun fawọn eeyan.
Ìgbà tí mo sì ri ì bí àwọn mẹ́tẹ́ẹ̀ta ti ṣe, mo fèsì fún èyí tí ó pè wa ni alákọrí, mo ní, ‘orí rẹ alákọrí, àyà rẹ alákọrí, ìwọ ẹbọra abi eyin bí eyín òkété yìí.
Ondo Regent: Ó dùn mí pé mi ò lè wọ aṣọ obìnrin mọ́ gẹ́gẹ́ bí adelé ọba
Nítorí kí ni ohun tí mò ń sọ fun yín kò fi ye yín?
O ni ijọba ipinlẹ Carabobo n topinpin isẹle naa.
Bí ọfà ti rí lọ́wọ́ jagunjagun,bẹ́ẹ̀ ni àwọn ọmọ ìgbà òwúrọ̀ ẹni.
Awọn olori ileesẹ aabo tẹdo si Dapchi Awọn ọmọbinrin Dapchi de s'Abuja Ijinigbe Dapchi: Bo ṣe ṣẹlẹ Ibeere mẹfa lori ijinigbe Dapchi 6.
Pẹlu owo osu rẹ, yoo gba ọ ni odun 65, ati osu mẹjo lati gba iye owo ti sẹnatọ kan n gba lọdọọdun.
Nígbà tí Jesu sọ̀kalẹ̀ láti orí òkè, ọ̀pọ̀ àwọn eniyan ń tẹ̀lé e.
Yóo pa wọ́n run, yóo sì tẹ orí wọn ba fun yín, nítorí náà, kíá ni ẹ óo lé wọn jáde, tí ẹ óo sì pa wọ́n run, gẹ́gẹ́ bí OLUWA ti ṣe ìlérí fun yín.
Wí fún ọba ati ìyá ọba pé,“Ẹ sọ̀kalẹ̀ lórí ìtẹ́ yín,nítorí adé yín tí ó lẹ́wà ti ṣí bọ́ sílẹ̀ lórí yín.
Iṣẹ́ bọ́ lọ́wọ́ ọlọ́pàá mẹta tó yabo ilé Clark Orin awa o ran yin niṣẹ ni ile iṣẹ ọlọpaa orilẹede Naijiria fi bọ ẹnu lẹyin ti wọn da mẹta lara awọn ọlọpaa to yabo ile ọtọkulu Edwin Clark duro.
Ni oṣu kẹrin ọdun yii ni ijọba Pakistan gba awọn to ba ti ṣe iyipada lati akọ si abo tabi abo si akọ lati le darapọ mọ ajọ ọlọpaa ilẹ ọhun.
" Awọn afurasi darandaran pa agbẹ l'Ekiti Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Gulegule awọn darndaran fulani ti da oniruuru ipaya silẹ kaakiri orilẹede Naijiria Awọn daradaran kan ti wọn funrasi gẹgẹbi fulani ti pa rakunrin ọmọ ọdun mejilelọgbọn kan ti orukọ rẹ n jẹ Tunde Ọlayẹmi ni ilu Ipao Ekiti ni ipinlẹ Ekiti.
Àwọn ọmọ rẹ̀ sì wí fún un pé olóko pàápàá ti pinnu láti wá ṣisẹ́ rẹ̀ ni ọjọ́ kejì.
''Saraki farada ìnira púpọ̀ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Olóṣelú máa ń wá ẹgbẹ́ ti wọn lè lò láti mu ìpinu wọn ṣẹ Saraki ni ala lasan ni awọn to ni ki oun kọwe fipo silẹ n la."
Obinrin náà bá sáré lọ sọ fún ọkọ rẹ̀, ó ní, “Ẹni tí ó wá sọ́dọ̀ mi níjọ́sí tún ti fara hàn mí.
Ọba Èdìdàrẹ́, màlúù ni ẹ̀ ń pè ní ẹṣín!
Ọpọ ni ko mọ oruk abisọ rẹ tootọ Diẹ lara ohun ti ẹ le ma mọ nipa olorin to tun ti n di gbaju gbaja latari ẹsun ti wọn fi kan an niyii.
Ipe yi ko ṣẹyin iwadi kan ti ajọ naa gbejade to ti sọ wi pe o le ni ẹgbẹrun mẹta eeyan ti wọn ti lugbadi iku latari aawọ laarin awọn agbe ati darandaran ni Naijiria.
Oludari agba ile-ise NIWA, ogbeni Olorunibe Mamora, lo jabo oro ohun nipinle Eko lojo.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Fuoye: NANS késí ẹ̀ka ẹ́gbẹ́ l‘Osun, Ondo, Kogi láti máa bọ̀ ní Ekiti 15 Owewe 2019 Oríṣun àwòrán, @jimidisu Yoruba ni ojo to ba pa ikan ọrẹ, gbogbo ọrẹ ni eji n pa, bẹẹ si ni iku to n pa ojugba ẹni, owe nla lo n pa fun ni.
Hate speech: Ero wa kò yípadà lórí àbádòfin ìṣàkóso ẹ̀rọ ayélujára
nile igbimo asofin kekere lorile ede Naijiria ti yan awon asoju ti yoo maa dari
O ni ileesẹ naa yoo ma a ran awọn ileesẹ ìjọba yooku lọwọ lati ma a mu inu ara ìlú dùn.
Yatọ si Abidoun, Aarẹ Muhammadu Buhari naa ti ki Joshua ku orrire aṣeyọri ọhun.
Nígbà tí ó ṣe tí mo ronú mo rí i pé kì í ṣe nítorí kí ènìyàn baà rí ni ni a ṣe ń tọ́jú ara ẹni bí kò ṣe wí pé kí alára pàápàá baà gbádùn ara rẹ̀; ẹni tí ó tọ́jú ara rẹ̀ nítorí kí ènìyàn baà rí òun nìkan, ọ̀bùn ni eléyìínì.
O sì fi òmíràn pààrọ̀ rẹ̀, eléyìí ni náa ni ahọ́n gbọọrọ tí ìwọ rí yìí, tí ó tayọ ẹnu tí ó sì gùn dé ìyàwó mi ní dodo.
Wọn kò mọ̀ pé ọ̀rọ̀ Baba ni ó ń sọ fún wọn.
Ti a ba ni ki a ma ka wo o ni eni eji,o kere tan oludije maarun to jẹ ọmọlẹyin Aarẹ ile asofin agba Bukola Saraki lo ti fi erongba silẹ lati soju ẹgbẹ PDP.
Run-off election (Atundi idibo) : Idibo eyi maa n waye ti
"Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Benue: ‘Operation Cat Race’ ko lee yanju ikọlu darandaran 9 Èrèlè 2018 Oríṣun àwòrán, AFP Àkọlé àwòrán, Ọpọlọpọ ẹmi ti sọnu nitori ija Fulani darandarn ati agbẹ ni Naijiria Laipẹ yi ni ileesẹ ologun Naijiria ṣe ifilọlẹ ikọ ọmọ ogun kan to pe ni ""Operation Cat Race"" lati wa ojutu si wahala to n waye laarin awọn agbẹ ati daran-daran lawọn ipinlẹ kan l'orilẹede Naijiria."
Igbo Olodumare rèé, níbi tí Ìgbín ti tóbi ju Ìjàpá lọ Èyí ni bí gómìnà Babajide SanwoOlu ti ìpínlẹ̀ Eko ṣe kó COVID-19 Mi ò le tòṣì láéláé!
Amọ nigba to n fesi si abẹ ọrọ ti Oyedepo sọ naa, Daddy Freeze ni itẹriba funra ẹni ko gbọdọ mọ lọdọ obinrin nikan, amọ o wa laarin awọn mejeeji.
Ẹnu ọjọ mẹta yii lawọn eeyan bẹrẹ si n jẹ orukọ Joy Nunieh lẹnu lori ayelujara.
FIFA yan Infantino gẹ́gẹ́ bí ààrẹ fún sáà kejì Mi ò ní gbà!
"Awọn fọto yii da wahala silẹ gẹgẹ bi awọn eeyan ṣe ni o lodi si ilana ""Prophet Mohammed"" ti awọn mii si ni awọn o rohun to buru nibẹ."
OLUWA Ọlọrun ní, “N óo fọ́ àwọn ère tí ó wà ní Memfisi, n óo sì pa wọ́n run.
Àwọn àrá ìlú fi èrò wọn hàn lórí afárá 3rd Mainland tí ìjọba tì Awọn awakọ ati awọn arinrinajo ti bẹrẹ si ni fi ero wọn han lori ẹrọ ayelujara nitori inira ti wọn la kọja lori afara Third mainland ti ijọba ti.
Ìfihàn yìí ni a fi fúnni nípasẹ̀ Urímù àti Túmímù.
Wọn si n fẹ ki ijọba fi ofin de kiko kọndọmu naa wọ Uganda, tabi ta a.
Àwọn àṣàyàn orin tí wọ́n máa ń jó sí máa ń jẹ́ àkójọpọ̀ orin soca tí ó mi ìgboro títì nínú ọdún yẹn, àmọ́ Ìwọ́de Ojúnà  orin náà tí máa ń jẹ́ jíjó jù lọ ní àwọn ibi kọ̀ọ̀kan ní ojú ọ̀nà ìyíde  jẹ́ oyè tí ó mú ẹ̀bùn àti iyì ìgbélárugẹ àjogúnbá ohun àtijọ́.
Nigeria Police: Àwòrán àwọn afurasí tí a fi léde kìí ṣe ayédèrú, a kàn dọọ́gbọ́n síi ni
Wọn óo fi ṣe ẹ̀sín, wọn óo fi àbùkù kàn án, wọn óo tutọ́ sí i lára.
Olori naa si jẹ ara awọn apọnbeporẹ Alaafin to gbajumọ ni aafin Ọyọ, paa paa nitori pe o tun bi ibẹta fun ọba Lamidi Olayiwola Adeyemi Kẹta.
Tafàtafà ni wọ́n, wọ́n sì lè fi ọwọ́ ọ̀tún ati ọwọ́ òsì ta ọfà tabi kí wọ́n fi fi kànnàkànnà.
Inú mi kò dùn si yín, n kò sì ní gba ọrẹ tí ẹ mú wá.
Ní 2019 yìí, ayé kò ní ká pátá wa lọ o.
Bo tilẹ jẹ pe aarẹ America nigba kan, Barack Obama, sọ pe Biden, ni igbakeji aarẹ to dara ju ti America ti i ni, ẹnu n kun akọsilẹ nipa ogoji ọdun to fi jẹ oṣiṣẹ ijọba.
Àkókò ń bọ̀ nígbà tí a óo gba ọkọ iyawo lọ́wọ́ wọn; wọn yóo máa gbààwẹ̀ nígbà náà.
Lẹ́yìn náà alufaa yóo pè é ní mímọ́, yóo sì jẹ́ kí ẹyẹ keji tí ó wà láàyè, fò wọ igbó lọ.
inu wa dun pe, ipa pataki ti e ko, lati  je ki alaafia ati eto ijoba tiwa-n-tiwa tun fese mule si I lorile ede Gambia.
Loni ayajọ ọjọ ounjẹ ni gbogbo agbaye, BBC sọ anfani jijẹ awọn ounjẹ aṣaraloore ati ipa awọn eroja isebẹ bii ti ninu ila alasepọ yii ti Dayo Amusa se fun wa.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 2020 in Retrospect: Ìjàmbá iná, ilé tó dàwó, ìwọ́de àti àrùn Covid-19 wà lára ìṣẹ̀lẹ̀ 2020 Aarẹ tẹlẹ ni Naijira naa wa fikun pe, awa ara wa lo yẹ ka bu nitori ipo ti orilẹede wa wa bayii, kii se Ọlọrun, ohun tawọn alasẹ ati ero ẹyin ni Naijiria yan ree.
Ní Ọjọ́bọ, àwọn agbébọn kan kolu ìlú Toumour ọ̀hún tí wọ́n sì pa èèyàn mẹ́jọ nínu àwọn òṣìṣẹ́ ará ilẹ̀ Faransé kan tí wọ́n ṣe ẹ̀rọ omi ọlọ́wọ́ fún àwọn àtìpọ́ tó sá àsálà kúrò níbi ìjà Boko Haram ní agbègbè náà.
Àwọn kan ni, ìjọba ló fàá ti irú èyi fi n ṣẹlẹ nítori pe wọ́n ko ṣe ètò ti o yẹ fun ará ilú ki wọ́n to ni ki wọ́n gbélé jòkó.
Lẹyin ọjọ diẹ si ti isẹlẹ naa waye, awọn ibere ti ọpọ eeyan n bere bayii ni pe, kini ohun to ṣokunfa ibugbamu ọhun gan?
Bí ẹ bá pada sọ́dọ̀ OLUWA, àwọn arakunrin yín ati àwọn ọmọ yín yóo rí àánú lọ́dọ̀ àwọn tí ó kó wọn lẹ́rú, wọn yóo sì dá wọn pada sí ilẹ̀ yìí.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Naijiria wa lara orilẹ-ede ilẹ Adulawọ ti ọrọ kan julọ Aàrun náà ń rú gẹgẹ sí i ni láti àárín oṣu karùn-un, sùgbọ́n, o jọ pé o ti de ténté báyìí pẹlu bi aàrùn náà ṣe n dẹnu kọle ni ìbẹ̀rẹ̀ oṣù kẹfa báyìí.
Ọ̀ọ̀nì wa máa ń gba adìyẹ ní Òjé ìlú Ìbàdàn.
ṣugbọn Samuẹli sùn ninu ilé OLUWA, níbi tí àpótí Ọlọrun wà.
orukọ silẹ lati le dibo, ki awọn eniyan ti ko ba tẹ lọrun le pe akiyesi Ajọ
Ni bayii, aare George Weah ni yoo so boya ogbeni Fahngon yoo si maa sise labe isakoso ijoba re.
Ọgbẹni Ojijeogu ṣalaye pe, awọn eeyan lo fẹ fi iwe idanwo naa lu awọn akẹkọọ ni jibiti.
Ma a pa ara mi si Cute Abiola lọrun bo ṣe já mi silẹ tori afẹsọna miran O ni ṣugbọn bi epo ti didakẹ awọn le ta si aṣọ ala awọn lara lo mu ki awọn pada fi atẹjade tuntun yii sita.
Àkọlé àwòrán, Iwe yii lo ti jade fun lilo bayii, ki gbogbo omo Oodua lo ra ki a le tun ni imo kun imo nipa eya ara eniyan ati ti eranko ni ede abinibi wa gege bi awon ojogbon onimo kikun ninu ilera eda ati ede Yoruba ni fasiti Ibadan se gbee jade loni Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Esi ifesewonse ohun lofun iko agbaboolu Arsenal nigboya pe awon yoo tesiwaju ninu idije naa, leyin ti iko agbaboolu AC Milan ba wa si papa isere Emirate lati gba esekeji ifesewonse naa.
O fi kun un wipe ọkunrin mẹta ati obinrin kan ni awọn ti o j'ọlọrun nipe lẹsẹkẹsẹ, ti awọn obinrin mẹrin ati ọkunrin mejila miran si ti wa ni ile iwosan ti ijọba ni Marina.
Owó ounjẹ El-Zakzaky lósù kan nijọba lè fi bọ́ ẹlẹ́wọ̀n 208
O ni iyawo oun atawọn ọmọ ni wọn n ṣe itọju oun lati igba ti aisan yii ti bẹrẹ.
"Ilé ẹjọ sún ìgbéjọ Maina síwájú lati fi okodoro àìlera rẹ hàn ""Fasola, Nàíjíríà tó ǹ gbé yàtọ̀ sí tiwa lo ṣe ní àsọdùn ni pé ọ̀nà wa kò dára"" Ìlú Kano ni ẹ̀gbin afẹ́fẹ́ rẹ̀ pọ̀jù nílẹ̀ Áfíríkà- Ìwádìí Ìhàlẹ̀ Agbaṣẹ́ṣe láti gbé ìjọba lọ sílé ẹjọ́ fẹ tàbùkù ará Ọyọ ni- Ilé Aṣòfin Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Èmi gan máa ń béèrè lọ́wọ́ ara mi pé ta ni Wole Soyinka gangan' Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?"
Ìjàmbá bàálú Cuba; Ọ̀pọ̀lọpọ̀ ẹ̀mí sọnú ní Havana
Ṣùgbọ́n òdodo kì í ṣe nnǹkan yẹpẹrẹ nítorí bí ẹ kò bá múra dáadáa àti ṣe òdodo á jẹ́ ìṣòro: nítorí bí ẹ bá ti ń yọ ẹlòmíràn kúrò nínú kòtò,ẹni tí ẹ ń yọ ‘tun lè máa gbìyànjú àti tí yín sí inú ọ̀gbun.
Ẹ ṣé mo dúpẹ́ fún àdúrótì àti ìfẹ tí ẹ ní sí mi - Toyin Abraham Ṣé ẹ mọ̀ pé olóògbé Ìjàpá tó kú lẹ́ni ọdún 344 yìí kò gba abẹ́rẹ́ rí?
Ṣugbọn Ẹ̀mí Jesu kò gbà fún wọn.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Bisi Alimi: Ìyà mi rò pé n kò leè ṣe ni àmọ́ n kò ní ìfẹ́ abo ni mo ṣe fẹ́ akọ Ṣe ni orilẹede naa kọ ofin to sọ pe ki wọn mu ẹni to ba n ṣe ibalopọ akọs'akọ tabi abos'abo ko si lọ ẹwọn ọdun meje eyi ti wọn ni bo ri labẹ ofin tẹlẹ niyii.
Ṣugbọn òfin kò lè sọ àwọn tí ń wá siwaju Ọlọrun di pípé.
Ẹrin kò yatọ nipinlẹ Rivers nibi ti Buhari ti ni ibo 388, 653 àti nipinlẹ Imo to ti ni 697, 532 ìbò ninu àwọn 944, 843 to forukọ silẹ titi lọ ba àwọn ipinlẹ bii Bauchi, Borno, Bayelsa.
Mo kọ ọ̀rọ̀ àgbà, mo fi etí pa ìşítí àgbà, mo wu ìwà tó tọ́ ní ojú mi, bẹ́ẹ̀ ni mo şe fi etí gún lágídi ọ̀rọ̀ ẹbí pàápàá.
Òmùgọ̀ sọ lọ́kàn ara rẹ̀ pé, “Ọlọrun kò sí.
’’“To ba je pe oooto ni ni ohun  ti a gbo , pe fun bi  opolopo wakati ti isele buruku naa  se n lo lowo , ko si awon eso alaabo Kankan to da si isele naa, a je pe eto aabo oirle ede yii , nilo amojuto.
Èyí ni bí ogun abẹ́lé Biafra ṣe bẹ̀rẹ̀ ní Nàìjíríà Ọ̀pọ̀ àwòrán tó ń ṣeni láàánú rèè nípa ogun abẹ́lé Nàíjíríà Ǹjẹ́ o mọ ipa tí ẹja Panla kó lásìkò ogun abẹ́lé Biafra?
Ọgbà ẹ̀wọ̀n ni mo ti s‘orí re - Ẹlẹ́wọ̀n 'Mi ò mọ̀ pé mo lóyún àfìgbà t'ọ́mọ ń rún'ra' Wo ikọ̀ ọlọ́pàá tí àwọn ọ̀daràn ń sá fún Aáwọ̀ ilẹ̀ mú ẹ̀mi márùn-ún lọ ní Makoko Onímọ̀ nípa iṣẹ́ òbi ati itọju ọmọ yii ṣalaye awọn nkan to yẹ ki obi woye ti wọn lè fi mọ ti ọmọ wọn ba wà ninu ewu kankan.
Ọ̀pá fìtílà meje ni àwọn ìjọ meje.
Coronavirus tún ti ṣe ọṣẹ́ lórí iṣẹ́ líla ojú ọ̀nà relùwe láti Eko sí Ibadan - Ìjọba àpapọ̀ Àrùn Coronavirus fa'lẹ̀ya láwọn ìletò aláwọ̀dúdú ní Amẹ́ríkà New symptoms of coronavirus: Ọwọ́ tẹ̀ èèyàn 65 tó tàpá sí òfin gbéléẹ níbi ayaẹyẹ ọjọ́ ìbí Oríṣun àwòrán, others Ìgbìmọ̀ amúṣẹ́yá ìpínlẹ̀ Eko lóríi Covid-19 ti mú àwọn aláríyá márùndínláàádọ́rin (65) lóríi ẹ̀sùn ìtàpá sí òfin gbéléẹ láti dẹ́kun àj]akálẹ̀ ààrùn Coronavirus ní ìpínlẹ̀ náà.
Ṣe ọpọlọpọ oore fún èmi iranṣẹ rẹ,kí n lè wà láàyè,kí n sì máa tẹ̀lé ọ̀rọ̀ rẹ.
O tun so pe ”Nigba ti,orile ede Nijiria jẹ milionu mẹ́rìndínláàdọ́ta eniyan lasiko igba ti a gba ominiria lọdun 1960.
Oríṣun àwòrán, Joshua Mike Bamiloye/instagram Àkọlé àwòrán, Bayii ni awọn ẹgbọn iyawo, idile wọn, ati idile ọmọ Alufaa ijọ Redeem, Leke Adeboye ṣe ro dẹdẹ fun ayẹyẹ naa Diẹ lara aworan ayẹyẹ naa ti BBC Yoruba ri lori ayelujara fihan pe, o larinrin.
"Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Èmi àti Saheed kìí ṣe ọmọdé, a ti jọ ṣe Sinimá papọ̀, èyí túmọ̀ sí pé ìjà ti parí - Fathia Balogun ""Mo fẹ́ pa ara mi torí ojú àbùkù tí wọn ń fi wò mí pé mo fi iṣẹ́ abẹ bímọ"" Fulani kò leè dúró, táa bá lo ohun ta jogún lọ́dọ̀ àwọn bàbá wa - Sunday Igboho Ọjà Àgbáláta ní Badagry rèé, níbití ẹran ejò ti dùn ju ẹran adìẹ lọ Amọ lasiko to n gbe idajọ rẹ kalẹ lori ẹjọ kanmọ n kia ti ajọ ọtẹlẹmuyẹ naa pe, Adajọ Taiwo Taiwo salaye pe ajọ agbofinro naa lee pada wa beere afikun ọjọ to fẹ fi fi Sowore si ahamọ rẹ, lẹyin asẹ ọjọ marundinlaadọta ti oun pa fun."
Aare Buhari ti so pe o jẹ iyalẹnu fun un nipa awon to padanu emi won
Famakinwa ni ida alaafia ni Kabiesi tuntun mu lasiko etutu rẹ, eyi to tumọ si pe alaafia yooo jọba nilu Ọwọ lasiko ti Ọba naa ba fi wa lori itẹ.
Orí pẹpẹ náà ní igun mẹrin, òòró rẹ̀ jẹ́ igbọnwọ mejila (mita mẹfa) ìbú rẹ̀ sì jẹ́ igbọnwọ mejila (mita mẹfa).
Kí gígùn ọ̀kọ̀ọ̀kan ninu aṣọ náà jẹ́ ọgbọ̀n igbọnwọ, kí fífẹ̀ rẹ̀ sì jẹ́ igbọnwọ mẹrin, kí àwọn aṣọ mọkọọkanla gùn bákan náà, kí wọ́n sì fẹ̀ bákan náà.
Ahasu-erusi ọba dá Ẹsita Ayaba ati Modekai Juu lóhùn pé, “Mo ti so Hamani kọ́ sórí igi, nítorí ète tí ó pa lórí àwọn Juu, mo sì ti fún Ẹsita ní ilé rẹ̀.
Ọjọ kẹta to de si Naijiria ti lo ṣaisan rampẹ, ti ayẹwo si fi han pe arun Coronavirus lo n ba finra.
Ẹ wá ra ọtí waini láì mú owó lọ́wọ́,kí ẹ sì ra omi wàrà, tí ẹnikẹ́ni kò díyelé.
chanda rubin ( ojoibi february 18 , 1976 ) je agba tenis ara amerika to ti feyinti .
Wọn de Tinuade lade loṣu Keji, ọdun 2015, lẹyin ti baba rẹ Ọba Emmanuel Ayowole Adejuyigbe waja.
Bíótilẹ̀jẹ́pé gbogbo èèyan tí wọ́n ń kọjá níbẹ̀ ò tilẹ̀ kíyè sí i, tàbí kí wọ́n rí i ṣùgbọ́n kí wọ́n má kà á kún nkankan.
O ti le ni ẹgbẹ̀run mẹ́ẹ̀dọ́gọbọ̀n eniyan ti wọ́n ti pa.
Ajá dóòlà ọmọ tuntun tí ìyá rẹ̀ bò mọ́lẹ̀ láàyè ni Thailand
Ohun Tí Sedekaya Bèèrè lọ́wọ́ Jeremaya.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Afenifere: Ọ̀rọ̀ tó ń jáde lójú òpó ayélujára 13 Agẹmo 2019 Oríṣun àwòrán, Google Àkọlé àwòrán, Funke Ọlakunrin Pẹlu iroyin ojiji ti ọpọlọpọ n sọ nipa iku ọmọ alaga ẹgbẹ Afenifere ti ilẹ Yoruba, ọpọ gbọ yii sọ yii lo ti n jẹ jade lori boya Fulani daran daran tabi awọn agbebọn lo pa Funkẹ Ọlakunrin.
Ó ti kó sí mi lórí.
Nítorí náà, wọ́n bẹ̀rẹ̀ sí fi iṣẹ́ àṣekára ni àwọn ọmọ Israẹli lára, 
Ninu ilẹ̀ ẹ̀yà Gadi, wọ́n fún wọn ní: Ramoti ní Gileadi.
ó tẹjú mọ́ Jesu bí ó ti ń kọjá lọ, ó ní, “Wo ọ̀dọ́ aguntan Ọlọrun.
Ọjà ilú, ilé-ìfìwé rànṣẹ́ àti gbàngàn ìlú ti o nà wọn tó àádọ́ta àbọ̀ ọ̀kẹ́ naira: Àwọn ọ̀nà títí tí wọ́n bójú mu tí wọ́n sì bá ti òde òní mu náà ni wọ́n ti fi òógùn ojú wọn là láìsí ìrànlọ́wọ́ ìjọba kankan.
Ní [[akókò tí iwin burúkú kan ni etí òde ọrun bá ọmọ rẹ̀ jà, tí kò sí ẹni tí ó lè la ìjà náà, èmi ni mo parí ìjà wọn.
Pagieli ọmọ Okirani ni yóo jẹ́ olórí láti inú ẹ̀yà Aṣeri.
okowo brasil ni ikefa totobijulo lagbaye gegebi gdp oloruko ati ikeje totobijulo gegebi osuwon agbara inawo ( titi de 2011 ) .
Iye awọn to ti ri iwosan ti jẹ 3329, ti awọn to si ti ku nitori arun naa lorileede Naijiria ti jẹ 315.
Diẹ lara awọn ojisẹ Ọlọrun ti wọn si ti kede pe awọn ti sọ asọtẹlẹ nipa iwọde EndSARS ati ipaniyan to tẹle ree: Wolii TB Joshua: Oríṣun àwòrán, Twitter/tbjoshua Ọkan lara awọn wolii lorilẹede Naijiria to maa n sọ asọtẹlẹ loore-koore ni oludasilẹ ijọ Synagogue lagbaye, TB Joshua.
"Eto naa to pe akọle rẹ ni ""Aim High"" lo fi lọlẹ lẹyin awọn idanilẹkọọ to waye nigba to ṣabẹwo si ẹka ileeṣẹ naa to wa lorilẹ-ede Kenya."
iwe idibo aare ati fun ile igbimo asoju ati asofin lasiko eto idibo.
Busola Dakolo Vs Biodun Fatoyinbo Gbajugbaja ayaworan, to tun jẹ iyawo gbajugbaja akọrin, Timi Dakolo, Busola Dakolo, fi ẹsun kan pasitọ ijọ Commonwealth of Zion Assembly, Biodun Fatoyinbo, ninu ifọrọwanilẹnuwo kan pe o fi ipa ba oun lopọ lọdun diẹ sẹyin.
Ọ̀rọ̀ ọgbọ́n níí máa ń jáde lẹ́nu ẹni tí ó ní òye,ṣugbọn kùmọ̀ ló yẹ ẹ̀yìn ẹni tí kò gbọ́n.
Wọ́n lọ ṣe aṣẹ́wó ní ilẹ̀ Ijipti nígbà tí wọ́n jẹ́ ọmọge.
N kò ní fa ibinu yọ mọ́,n kò ní pa Efuraimu run mọ́,nítorí pé Ọlọrun ni mí,n kì í ṣe eniyan,èmi ni Ẹni Mímọ́ tí ó wà láàrin yín,n kò sì ní pa yín run.
“Mo ti bá ojú mi dá majẹmu;n óo ṣe wá máa wo wundia?
Àwọn tí wọ́n wá láti àwọn erékùṣù Caribbean (tí wọ́n jẹ́ ìran adúláwọ̀ tí àwọn òyìnbó kó lọ sóko ẹrú láíyé àtijọ́) ní wọ́n dáa sílẹ̀.
" Ohun ti mo n ṣe ni pe ki ilẹ Yoruba maa bajẹ, amọ a n jekuru ko tan lawo, wọn tun gbọn ọwọ sabọ ni ọrọ yii o,"" baba Adebanjo lo wí bẹẹ."
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Black women live matters: Ọdún 2015 ní àwọn ọlọ́pàá pa India Kager láìní ìdí- Gina Best Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Ó wó pẹpẹ ìrúbọ tí ó wà ní ẹnubodè, tí Joṣua, baálẹ̀ ìlú kọ́, tí ó wà ní apá òsì, bí eniyan bá ti fẹ́ wọ ìlú.
Kola Ologbondiyan to jẹ akọwe ipolongo fẹgbẹ oṣelu PDP sọ pe rẹgi ni igbeṣẹ naa ba ẹgbẹ awọn lara mu nitori pe awọn ko lọwọ ninu iwa to kọdi si eto ijọba awarawa.
Oríṣun àwòrán, others Laarin ọdun 1950, ijọba amunisin to n dari Naijiria nigba naa ṣe agbekalẹ ibudo ti wọn n ko eso kòkó, tijọba ba ra lọwọ awọn agbẹ, pamọ si.
Duyile sọ pe asa ati ise ti ẹgbẹ Afenifere dirọ mọ fayegba ki ọmọ ẹgbẹ o bere imọran lọwọ awọn adari ẹgbẹ lori ọrọ to ba niise pẹlu gbogbo ọmọ Yoruba.
Ṣugbọn kí ẹ lè jẹ́ eniyan mi, kí n sì jẹ́ Ọlọrun yín.
Gẹgẹ bi ohun ti awọn iwe iroyin abẹle kan sọ, ọpọ igba atẹyinwa ni wọn ti ṣekilọ fun un pe ko jinna si agbegbe ti wọn ti n na owo wọn nigbakugba to ba ti n waasu.
Orúkọ àwọn ọmọbinrin Selofehadi ni Mahila, Noa, Hogila, Milika ati Tirisa.
Ní ọjọ́ tí OLUWA bá Mose sọ̀rọ̀ ní ilẹ̀ Ijipti, 
Gẹ́gẹ́ bíi fìlísíà, Ọ̀gá ni ó jẹ́ fún Kọ́lá Òwú ara súwẹ́tà rẹ̀ tí ó já bọ́ síbi séèfù wà lára ohun tí ó ran Akin Olúṣínà lọ́wọ́ láti rí i mú.
Ṣé àwọn ìjayà ajaguntà ilẹ̀ òkèrè leè bá Nàìjíríà fòpin sí ìṣòro àbò?
Nígbà tí Òjòlà-ìbínú gbọ́ eléyìí ó kígbe ńlá ohùn rẹ̀ sì kù bí òjò, ó ní, ‘Ta ni Ọlọ́run náà tí ó lè gbà yín nínú pàkúté mi, ẹ̀yin ọmọ ènìyàn!
(Àwọn ọmọ tí Biliha bí fún Jakọbu ati àwọn ọmọ ọmọ rẹ̀ jẹ́ meje), Biliha ni iranṣẹbinrin tí Labani fún Rakẹli, ọmọ rẹ̀ obinrin.
nnkan ti igbakeji aare orile ede Naijiria ,Yemi Osinbajo yoo maa ba akegbe re jiroro
Aarẹ ma n sọ inira ti aini baba laye mu ba a nigba to wa ni èwe.
Gomina Samuel Ortom wọle fun saa keji ni Benue Gomina Samuel Ortom, to jẹ oludije ẹgbẹ oṣelu PDP ti wọle fun saa keki gẹgẹ bi gomina ipinlẹ Benue lẹyin atundi ibo gomina nipinlẹ naa.
 Àwọn nǹkan wọ ̀ nyí tó máa ń bí ogun , nígbà tí elòmírà bá ta ko irúfẹ ́ èèyàn bẹ ́ ẹ ̀ tàbí kí ó jẹ gàba lé òun lórí .
"- CAN Ẹ wo àwọn ìlúmọ̀ọ́ká ọmọ Nàíjíríà tó jáde láyé lọ́dún 2020 Ìtàn ìgbé ayé Isola Ogunsola, akọni mánigbàgbé òṣèré tíátà, olórin àti onílù ""Ma a pa ara mi si Cute Abiola lọrun bo ṣe já mi silẹ tori afẹsọna miran"" ""Àwọn akẹ́kọ̀ọ́ àgbà fipá bá ọmọkùnrin mi lòpọ̀ níléèwé Deeper Life, mò ń fẹ́ ìdájọ́"" Wo ọ̀pọ̀ àsọtẹ́lẹ̀ igba tí Primate Ayodele gbé síta fọ́dún 2021 Laarin bi ọsẹ diẹ sẹyin bayii, ko din ni eeyan mẹfa ti awọn eeyan ti dana sun ninu isẹlẹ ọtọọtọ, tori pe wọn fura iwa aidaa kan tabi omiran si wọn."
Lẹ́yìn ọdún díẹ̀, Jehoṣafati lọ sí ìlú Samaria láti bẹ Ahabu wò.
Ninu ọrọ tiwọn, ajọ awọn oniroyin nilẹ Kenya, sọ pe igbese ijọba Kenya naa kọjumọ, ti kosi lẹtọ labẹ ofin to faaye gba ominira awọn oniroyin.
Bakan naa, Aare ile-igbimo asofin teleri, asofin David Mark tun tenumo idi ti o fi ye ki awon omo orile-ede Naijiria maa gbe ninu ife ati irepo.
Ki se igba akọkọ re e ta o ri ti baba isalẹ ati ọmọ lẹyin to fa si ipo yoo ma doju ija kọ ara wọn.
O sì sọ èrò gbogbo gba nípa àwọn ìjòyè rẹ láì ku ẹyọ kan nínú wọn.
Ekiti Shooting: A ò ni farapamọ́ fún ará ìlú lórí ìwádìí ọlọ́pàá to pa ènìyàn ni Ekiti
Eni kan lo rii to yaa ni fọto ti o di gbajugbaja ni eyi ti ọpọlọpọ fi bẹre si ni pee si iṣẹ arinrin oge ati yiya fọto rẹ si oju awọn iwe atigbadegba.
Nígbà náà ni ẹ̀yin tún wá fi àlá yín dẹ́rù bà mí,tí ẹ sì fi ìran pá mi láyà,
Oríṣun àwòrán, Getty Images Ẹni ti kò bá wá fẹ́ pàdánù lílo tirẹ̀ yóò ni láti lọ wá èròjà ti yóò fi gbé fóònù tirẹ̀ lárugẹ síi, láti le tẹ̀síwájú ninu lílò rẹ̀.
Atawẹwẹ fọrọ yii lede ninu ifọrọwerọ rẹ pẹlu BBC Yoruba nile rẹ niluu Ikorodu l'Ọjọru.
Arọmọdọmọ rẹ̀ ni yóo máa jọba títí lae;ìtẹ́ rẹ̀ yóo sì máa bẹ níwọ̀n ìgbà tí ojú ọ̀run bá ń bẹ.
Odion Ighalo lo gba bọọlu kan ṣoṣo ọhun wọle fun Super Eagles nigba ti idije na wọ iṣẹju mejidinlọgọrin.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Mike Bamiloye ti Mount Zion fi ọmọbìnrin rẹ̀ kan ṣoṣo, Darasimi fún ọkọ nílùú Ibadan 25 Owewe 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 11 Ọ̀wàrà 2020 Oríṣun àwòrán, Joshua Mike Bamiloye/instagram Ariwo ayọ tun sọ nile gbajugbaja osẹre ẹsin Kristiẹni, Mike Bamiloye, lasiko ti abigbẹyin rẹ, Darasimi, lọ sile ọkọ.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ọmọ ilẹ̀ Gẹẹsi gbẹ́mi mi torí pé o fẹ́ ki ìdí òun tóbi síi Baaps ṣalaye fun Victoria Derbyshire ti BBC pe o keere tan, ẹni kan ninu ẹgbẹrun mẹta lo n ku lagbaye lataari nkan to n tẹyin iṣẹ abẹ naa jade.
 nínú ọ ̀ rọ ̀ kejì , olùsọdipúpọ ̀ , ìgbénọ ́ mbàga jẹ ́ ókan .
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Yinka Ayefele: Oṣù àwọn ìbẹ́ta mi kò pé ní kò jẹ́ kí n kọ́kọ́ kéde ìbí wọn Sophie ti wa pinnu ninu ọkan rẹ lati ṣe isẹ abẹ naa pẹlu Dokita to mọṣẹ lati din ẹru ẹyin rẹ ku si kekere ti ara rẹ yoo le gbe.
Lara awon omo egbe to wa nibii eto idibo naa so pe awon yoo fowosowopo lati le je ki  awon se aseyori nibi eto idibo  odun 2019  to n bo.
Adeleke fi kun ọrọ rẹ wi pe ẹmi eeyan meji ọtọọtọ (ọkunrin kan ati obinrin kan) lo ba iṣẹlẹ naa lọ.
“À bá lè kọ ọ̀rọ̀ mi sílẹ̀!
Lọ́jọ́ òní, àti lọ́jọ́dọ́gba ìgbà ìwọ́wé, ìlànà tí oòrùn tọ̀ láti ilà dé ìwọ̀ lókè ọ̀run bá ti Stonehenge mu rẹ́gí-rẹ́gí nílẹ̀.
Akano tẹ́ siwaju wipe, lara ohun ti o tun sokunfa iyansẹ̀lodi naa ni bi ijọba ipinlẹ̀ Ọ́yọ̀ se kọ́ lati sanwo ifeyinti ati owo ajemọ́nu awọn osisẹ̀feyinti ni Ile-Ekọ̀ Alakọ́bẹ́rẹ́, eleyi ti o n lọ si bi osu mẹ̀rindinlaadọ̀ta.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Eji Gbadero: Ó pa Raji Oba nítorí ilẹ̀ nìjọba bá yẹgi fún un 25 Òkùdu 2020 Oríṣun àwòrán, Others Yoruba ni aye ko tọ lọ bii orere, igba ko si tọ lọ bii ọpa ìbọn, gbogbo alagbara aye si lo yẹ ko rọra ṣe nitori ilẹ n yọ.
Egbe APC  fi iye ibo  402,961 gbe  egbe  People’s Democratic Party (PDP)  ti o ni iye ibo 138, 484  subu.
Ara àwọn ará Amori tí wọ́n ṣẹ́kù ni wọ́n.
Bojúwolẹ̀ láti ọ̀run, kí o sì wò ó;kí o sì tọ́jú ìtàkùn àjàrà yìí,
"Iṣẹ́ fẹ́ bọ́ lọ́wọ́ ọlọ́pàá tó gba N100k lọ́wọ́ awakọ̀ tó gba""One way"" l'Eko Ìjọba Naijiria faraya nínú lẹ́tà tó kọ sí CNN lórí ìwádìí rẹ̀ nípa ìṣẹ̀lẹ̀ Lekki Toll Gate Omotara pàdánù isẹ́ olówó ńlá nítorí ó fi ọtí ẹlẹ́rìndòdò sódà lá ọmọ alágbe lójú Jemila dáná sún ilé ọ̀rẹ́kùnrin rẹ̀ àti ọ̀rẹ́bìnrin tó bá nílé Atẹjade naa tun jẹ ko di mimọ pe, awọn etutu gbogbo to yẹ n lọ lọwọ fun Arẹmọ gẹgẹ bi iṣẹṣe ṣe laa kalẹ, Ati pe, o si di igba ti wọn ba pari awọn etutu wọnyi ki ẹnikẹni to lee ri Arẹmọ Ọọni naa."
David lo dije dfupo gomina labẹ ẹgbẹ oṣelu APC ni ipinlẹ Bayelsa pẹlu Senetọ Biobarakuma Degi-Eremienyo to jẹ igbakeji rẹ.
”Saulu bá sọ fún Dafidi pé, “Máa lọ, OLUWA yóo wà pẹlu rẹ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ògidì ọmọ Yorùbá gbọ́dọ̀ mọ 'áayan ògbufọ̀' dáadàa Lẹyin eyi ni olori ile naa ti wọn ys nipo, Bamidele Oloyelogun atawọn to jẹ tirẹ ni ile aṣofin naa lọ ko ara jọ pọ ni ile rẹ nibi to ti ba awọn oniroyin sọrọ pe oun ṣi ni olori ile naa ati pe ohun ti ko lẹsẹ nlẹ ni igbesẹ naa.
Bi ori ba le jẹ ki Adesanya fagba han Whittaker, a jẹ pe o ti gba ami ẹyẹ abẹṣẹ-kubi-ojo ni yẹn.
lati fafiti ti won je anfaani eto yii.
"Ọdọọdún lo ma n ṣe iṣẹ oko, o si má n fi owo to ba gba ran ẹbí ati iya rẹ lọwọ, nitori pe oun ni àkọ́bí rẹ.
O ní, ""àwọn àlàyé ti Oloye Olusegun ṣe nipa ara rẹ̀ àti àwọn amuyẹ adarí to ni, máà ń fún àwọn ọmọlẹ́yìn rẹ̀ ni ìwúrí."
Mo ká ayé mi bí aṣọ tí wọn ń hun.
Ife Àgbáyé 2026: Ọjọ́ 13, Osù Kẹfà la o mọ olùgbàlèjò
Yollywood: Toyin Abraham ṣe àjọ̀dún ogójì ọdún, èyí láwọn mánigbàgbé ìrìnàjò ayé rẹ Oríṣun àwòrán, Instagram/toyin abraham Gbajugbaja oṣere sinima Yoruba, Toyin Abraham ti ṣe ọjọ ibi ogoji ọdun laye.
Wọ́n kọ̀ wọn kò gbọ́ràn, wọn kò sì ranti àwọn ohun ìyanu tí o ṣe láàrin wọn, ṣugbọn wọ́n ṣoríkunkun, wọ́n sì yan olórí láti kó wọn pada sinu ìgbèkùn wọn ní Ijipti.
Ibi ti a ti n ṣe eléyìí ti à ń kí ọba ni ọ̀kan nínú àwọn ìjòyè rẹ̀ ti dáhùn tí ó ni, ‘Kábíyèsí, kò nà yín tó ti ijọ́sí lónìí.
Oríṣun àwòrán, others Wo awọn nkan ti a le fi ẹgẹ, iṣu ati eree ṣe sii nibi.
Wike, má gbé jàgídíjàgan wá sí Ondo, APC kò ní ṣ'èèrú nínú ìdìbò gómìnà tó ń bọ̀- Kalejaye Ẹgbẹ FIBAN fi kun un wi pe awọn yoo ṣewode lọ si aafin ti Alaafin Oyo lati fi aidunnu wọn han si iwa ifiyajẹni ti Kwam 1 n wu lawujọ.
Máa lọ fi tayọ̀tayọ̀ jẹ oúnjẹ rẹ, sì máa mu ọtí waini rẹ pẹlu ìdùnnú, nítorí Ọlọrun ti fi ọwọ́ sí ohun tí ò ń ṣe.
Nigba ti ọwọ wọn ko tete tẹ wọn, awọn ọlọpaa yinbọn lu wọn.
Kete ti okun to fi n fo ba ti kọọ lẹsẹ, to ba ti kuna, ni ẹlomiran yoo bẹrẹ ti rẹ.
 Bẹẹ naa si lo ka iwe kun iwe sii loke okun.
OLUWA wí pé,“Mo ti kọ ilé mi sílẹ̀;mo ti kọ ogún tí a pín fún mi sílẹ̀.
Mose bá dá àwọn eniyan náà lóhùn, ó ní, “Ẹ má bẹ̀rù, ẹ dúró gbọningbọnin, kí ẹ wá máa wo ohun tí OLUWA yóo ṣe.
"Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ija laarin awon ọmọ ẹgbẹ awakọ NURTW ni Idumọta ti gbẹmi eeyan kan 24 Sẹ́rẹ́ 2018 Àkọlé àwòrán, Awọn eniyan sọ pẹ Alnold Swagger ti won npe ni ""Pero"" faragbabon loru ojo isegun Nnkan o rọgbọ ni agbegbe Idumọta ni Lagos Island nipinlẹ Eko lẹhin ti awọn apaniyan dẹmi ọmọkunrin kan ti wọn n pe orukọ rẹ ni Alnold Swagger aka ""Pero"" legbodo."
OLUWA bá Jeremaya wolii sọ̀rọ̀ nípa Filistini kí Farao tó ṣẹgun Gasa, 
Oríṣun àwòrán, Kayọde Fayẹmi Àkọlé àwòrán, Ẹwẹ, ijọba n gbero lati ṣe afihan ipo ti apo aṣuwọn ijọba ipinlẹ Ekiti wa l'ọjọ to ba ṣe ajọyọ ọgọrun ọjọ lori oye.
"Gẹgẹ bi David Meade to jẹ onkọwe ẹsin Kristẹni ṣe sọ tẹlẹ, o ni ọjọ naa ni ọjọ ti aye mii to wa loke aye yii to pe ni ""Planet X"" yoo wo lulẹ sori aye gẹgẹ bo ṣe ni bibeli sọ ọ."
ti won ti se gudu gudu meje yaya mefa 
Nítorí àkókò tí yóo ṣẹlẹ̀ súnmọ́ tòsí.
OLUWA, tọkàntọkàn ni n óo fi dúpẹ́ lọ́wọ́ rẹ;n óo ròyìn gbogbo iṣẹ́ ìyanu rẹ.
Kò sí ohun tí ẹ̀dá lè fi kún un, tabi tí ẹ̀dá lè yọ kúrò níbẹ̀, Ọlọrun ni ó dá a bẹ́ẹ̀ kí eniyan lè máa bẹ̀rù rẹ̀.
Èyí ni àwọn arẹwà ‘ẹ̀lẹ̀ Daddy’, àfẹ́fẹ́ tí Aláàfin fi ń mí Kí ló mú Olorì Badrat Ajoke kúrò ní ààfin Oyo lọ́jọ́ Iléyá?
Ṣugbọn a kó àwọn ẹran ọ̀sìn wọn, ati àwọn ohun tí a rí ninu ìlú wọn bí ìkógun.
Oríṣun àwòrán, Idris Ibrahim Wo ohun tí àwọn ọmọ Nàìjíríà ń sọ lórí dájọ́ ikú Yahaya Sharif-Aminu tó gba ìdájọ́ ikú lórí ẹ̀sùn ọ̀rọ̀ òdì sí Ànọ́bì Awọn ọmọ Naijiria ti bẹrẹ si n fi erongba wọn lede lori itakun agbaye lẹyin ti ile ẹjọ Sharia kan ni ipinlẹ Kano ṣedajọjọ iku fun Yahaya Sharif-Aminu lori ẹsun pe o sọrọ odi si Anọbi.
Awọn alaṣẹ lorileede Naijiria sọ pe awọn ti mu eeyan meje to lọwọ ninu bi ogun oloro ṣe de inu ẹru Zainab.
Ọpa ifami mẹrinlelọgbọn ti wọn ka jọ pọ soju kan lati orilẹede China.
 Aare wa so pe oun ti pasẹ fun ajọ to n mojuto ise ọgbin
Akitiyan lati gbọrọ lẹnu Ọgagun agba Charles Ekeocha to jẹ olori ileeṣẹ olọgun 6 Division Nigerian Army ni Port Harcourt lori ẹsun pe awọn sọja n mu awọn araalu ni Oyigbo ja si pabo.
Àwọn ará Nebo keji jẹ́ mejilelaadọta.
"Ti ẹ ba pade SARS tabi oṣiṣ alaabo kankan lọjọ Aje, ẹ ma ṣe ba wọn ja.
Ninu fọnran fidio kan ti wọn fi sita, aarẹ ẹgbẹ oṣere tiata Yoruba Ọgbẹni Bọlaji Amuṣan ati ọkan lara awọn agba ọjẹ ninu ere tiata lorilẹede Naijiria, Alhaji Yinka Quadri ti ti paṣẹ ki gbogbo awọn mejeeji lọ ree gbẹnu dakẹ tabi ki wọn fi kele ẹgbẹ gbe wọn.
Loju Garba Shehu, ijọba Buhari paṣẹ yii ki agbara òfin lè fi di mimuṣẹ ni Kí ló ṣelẹ̀ sẹ́yìn?
kan Iye awon eniyan to n gbe ilu Goma,to wa lẹgbẹẹ omi.
Keyamo ni iwe ẹri ile iwe alakọbẹrẹ ni iwe ofin Naijiria sọ pe o tun dabi iwe ẹri girama.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Seyi Makinde làwa ń bá lọ lọ́jọ́ Satide - Ladọja Bí mo ṣe ń tako Buhari bá ìjọba tiwantiwa mu - Ọbasanjọ Ìbò sáà kẹta fún Ajimọbi ni ìbò Adelabu, ẹ yàgò fun - Seyi Makinde Níbo lowó ìrànwọ́ ẹ̀kọ́ wa wà - Àwọn akẹ́kọ̀ọ́ Kwara ń bèèrè?
Oríṣun àwòrán, Twitter/Osagie Ize-Iyamu Idibo sipo gomina ni ipinlẹ Edo naa yoo waye ni Ọjọ Kọkandinlogun, Oṣu Kẹsan, ọdun 2020.
Lati ọdun 2011 lo ti wa ni ile gẹgẹ bi Sẹnẹtọ labẹ asia ẹgbẹ PDP.
Oríṣun àwòrán, @AkinwunmiAmbode Olori ile aṣofin ipinlẹ Eko, Mudaṣiru Ọbada gbe igbimọ ẹlẹni mẹrindinlogun kan kalẹ, lati tan ina wo eto inawo ra ọkọ akero nlanla BRT atawọn akanṣe iṣẹ miran.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Premier League: Man City ti fàgbà han Fulham pẹ̀lú 2-0 30 Ẹrẹ̀nà 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Man City ti fàgbà han Fulham pẹ̀lú àmì ayò méjì sódo nínú ìlépa rẹ̀ láti gba ife Ẹyẹ Premiership tọdún yìí.
Gẹ́gẹ́ bi ìròyìn ṣe sọ, abúlé Okebi ni ìjà náà ti bẹ̀rẹ́ ni òwúrọ̀ ọjọ́ Àbẹ́mẹ́tà, sùgbọ́n kò sí ẹni to le fi ìdí ǹkan to fa èdè àìyedè náà títí di àsìkò tí à ń kọ ìròyìn yìí.
Bí wọ́n ti wọlé, wọ́n rí ọmọ náà pẹlu Maria ìyá rẹ̀, wọ́n kúnlẹ̀, wọ́n sì júbà rẹ̀.
Bo ba ṣe wu ki eeyan ko pẹ titi lori erupẹ, lọjọ ọjọ kan ni yoo di ero ọrun.
Ọmọbinrin naa sọ wi pe ẹru ba oun nigba ti oun gbo gbogbo iroyin naa.
Ọna papakọ ofurufu LASTMA ti ni awọn ọna wọnyii yoo wa ni titi nigba ti aarẹ ba n kọja tabi to ba duro lati ṣi iṣẹ akanṣe.
Obasa so oro iyanju yii nibi ipade lori abadofin lati da ile ise ti yoo maa mojuto irinajo afe ni Naijiria sile eyi ti igbimo teekoto lori asa, ise ona ati irinajo afe se ni Alausa ni Ikeja.
Ǹjẹ́ o tilẹ̀ mọ Samuel Okwaraji, agbábọ́ọ̀lù Nàìjíríà tó 'ṣubú lójú ìjà' Agbẹjọ́rò àgbà mẹ́fà, òdú amòfin mẹ́tàdínlógún míràn yóò ṣojú Sẹ́nétọ̀ Adeleke níléẹjọ́ tó ga jùlọ Atiku fẹ́ fa Lauretta Onochie, amúgbálẹ́gbẹ́ Buhari lọ ilé ẹjọ́ Ni gbogbo akoko to fi wa wọn, ko si eyi ti ko ranti ninu wọn to fi mọ igba ti awọn adari orilẹede mii lagbaye naa ba wa ṣe ibẹwo si awọn ti Naijiria.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Kamaru Usman: Ọmọ Áfíríkà àkọ́kọ́ tó gba ìgbànú ẹ̀yẹ ẹ̀ṣẹ́ kíkàn UFC 3 Ẹrẹ̀nà 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Kamaru Usman borí Tyron Woodle ní ìpele Welterweight.
Baba Nazanin kọkọ lra tikọ ṣugbọn emi ni mo mu ọkọ mi lọkan le pe ko gba owo naa lati ta ọmọ wa obinrin."
 orúkọ oyè rè ni Ọ ̀ gbọ ́ ni .
"Sugbọn nibayii, ""ijọba ipinlẹ Oyo gan an lo rufin, ta ni yoo wa gbe Gomina Seyi Makinde lọ si ile ẹjọ bayii, lẹyin ti wọn fun ẹbi Abiola Ajimobi laaye lati sin oku si GRA, to wa ni ipinlẹ naa?"
”Ni bayii, orile-ede Senegal, ti o je orile-ede ile adulawo kan soso ti o ku, yoo Columbia ninu ifesewonse keyin nipele kejo(group H), lojobo(Thursday).
Lakotan igbẹjọ naa, Owodunni pa laṣẹ pe aarin oru titi di aago mẹẹrin idaji ni wọn gbọdọ maa ṣe ọdun oro tabi gbe ẹbọ kankan, iyẹn ti awọn alaṣẹ toyẹ ba buwọlu.
Jide Sanwoolu Oloselu yii jẹ kọmiṣọna ipo mẹta ọtọtọ ni Ipinlẹ Eko nigba kan ri.
Ó bá pè é, ó ní, ‘Abrahamu, Baba, ṣàánú mi.
O fi idi rẹ mulẹ lori Instagram pe irọ ni iroyin to n lọ kaakiri igboro pe oun fi ọwọ si iwe naa.
Lọdun 1993, Aarẹ America, Bill Clinton, yàn-án lati ṣoju ni Naijiria titi di ọdun 1997.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: 'Fashọla, o ò dẹ̀ bẹ̀rù Ọlọ́run!
Adari ajọ naa, Antonio Guterres, sọ ninu atẹjade kan wipe ijọba awa-arawa ko le muna doko ti ko ba si iroyin ti ko labawọn.
Nítorí pé ní ìgbà tí mo bá jẹ ìran Esau níyà, n óo mú kí ibi dé bá wọn.
Ẹ wo ẹkunrẹrẹ fidio yii fun igbese ti awọn eniyan n gbe lati kapa arun Coronavirus.
Senate Hearing: Iléeṣẹ́ epo rọ̀bì ná ₦14.
Kì í ṣe pé a ní agbára tó ninu ara wa, tabi pé a ti lè ṣe nǹkankan fúnra wa.
Bẹẹ ba gbagbe, Aarẹ Buhari bẹrẹ saa keji iṣejọba rẹ ni ọjọ Kọkandinlọgbọn, oṣu Karun un, ọdun 2019, amọ ti ko ba awọn ọmọ Naijiria sọrọ lẹyin ti wọn bura fun un tan.
Ìmọ̀ràn wa ni pé, kí ọba pàṣẹ láti lọ wá àkọsílẹ̀ tí àwọn baba ńlá yín ti kọ.
O tun sọ pe ọrọ awọn ọlọpaa lorilẹede Naijiria pe fun ọgbọn, o ni kii ṣe agidi rara bibẹẹ kọ, eeyan le kabaamọ igbesẹ rẹ.
Àjọ ọlọ́pàá, Ìjọba ìpínlẹ̀ Ọyọ jẹ́jẹ̀ẹ́ láti ṣàwárí òòsà tó ń mu ẹ̀jẹ̀ nílùú Ìbàdàn Bí wọ́n ṣe kó mi mọ́ rògà ìròyìn òfégè kan tó leè kóbá olùdíje Ààrẹ ẹgbẹ́ alátako Ẹ wo ohun tó sàkòbá fún ọ̀kùnrín tó sọ owó ìyebíyé nù lásìkò Coronavirus Àwọn tó ṣiṣẹ́ pẹ̀lú Abacha ní kò kówó jẹ, ó fi pamọ́ fún ìdí kan ni- Sadik Abacha Àwọn olùfẹ̀hònúhàn kọ etí ikún s'íkìlọ̀ ọlọ́pàá ṣe ìwóde ní London 'Ọlọ́pàá ló ń pa wá, kìí ṣe coronavirus' Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí kan sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
Ibi ti ọrọ de duro bayii ni pe, boti lẹ jẹ pe wọn ti yọ Trump nipo, oun si ni aarẹ titi di igba ti ile aṣofin agba yoo ṣe idibo tiwọn.
Wọ́n rẹ́ àwọn talaka jẹ, wọ́n sì yí ẹjọ́ àwọn tí ìyà ń jẹ po.
Onimọ nipa ihuwasi ọmọniyan, Abileko Racheal Ọlaniyan, nigba to n sọrọ pẹlu BBC Yoruba gẹgẹ bi onimọ nipa iru isẹlẹ bẹẹ ni ibi ti eniyan gbe nigba to n dagba nii sẹ pẹlu ihuwasi rẹ nigba to ba dagba.
Gẹ́gẹ́ bí ó ti rí ninu gbogbo ìjọ eniyan Ọlọrun, 
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Arun Iba: Naijiria gbaradi fun eto ajẹsara to pọ julọ 24 Sẹ́rẹ́ 2018 Oríṣun àwòrán, AFP Àkọlé àwòrán, Orilẹ ede Naijiria ti setan la bẹrẹ eto ajesara to pọ julọ Ni ọjọru, orilẹ ede Naijiria yoo bẹrẹ ipolongo ati isẹ ajesara lati daabo bo awọn eniyan ti o to bii miliọnu mẹẹdọgbọn.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Kemi Afolabi: Mo mọ rírì àwọn olólùfẹ́ mi, àdúrà ti wọn náà yóò gbà 2 Ògún 2019 Oríṣun àwòrán, kemiafolabiadesipe Gbajugbaja osere lobinrin nni, Kẹmi Afọlabi ti fi fọnran aworan kan ransẹ lati ilu Meccah eyi to fi n fi ẹmi imoore rẹ han si awọn ọmọ Naijiria ti wọn gbarata lasiko to wa lori idubulẹ aisan nilu Meccah.
Ó gbọ́ ohùn mi láti inú ilé mímọ́ rẹ̀,ó sì tẹ́tí sí igbe mi.
Nígbà tí a rii, ṣe ni nǹkan náà la gbogbo ara wa já pátápátá tó bẹ́ẹ̀ tí ẹnikẹ́ni kò lè gbé apá tí ẹnikẹ́ni kò lè gbé ẹsẹ̀ tí á kò tilẹ̀ lè la ẹnu wa sọ̀rọ̀ jáde lẹnu.
CP Undie Andie - CP Ondo Command l.
Ike Ekweremadu, igbákejì ààrẹ ilé aṣòfin àgbà tẹ́lẹ́ rí èèmọ̀ he nilùú Germany!
Ewe, iseju die ki ifesewonse ohun ko wa si ipari, Al Dawsari gba ami ayo miiran wole, eleyi ti o ran Saudi Arabia lowo lati jawe olubori, ti won si pari sipo keta nipele naa.
Ọrọ yii ni wọn lo jẹyọ lasiko ti ẹgbẹ NANS lọ se abẹwo si aarẹ Buhari nile ijọba Aso Rock nilu Abuja.
Ìjọba ìpínlẹ̀ Ògùn ti kéde ọjọ́ kejìlá, oṣù Kẹfà, gkgẹ́ bí ọjọ́ ìsinmi lẹ́nu iṣẹ́.
Oríṣun àwòrán, EPA Ibẹrubojo ni ọpọ orile-ede lagbaye nitori ẹya aarun Coronavirus tuntun to tun bẹ silẹ ni Ilẹ Gẹẹsi ti ọpọ orileede si ti n fi ofin de irinajo lati ilẹ okere .
Àkọlé àwòrán, #BBCGOVDEBATE: Awọn àrá ipínlẹ̀ Ogun ti bẹ̀rẹ̀ ìjíròrò GNI ní òun ni ẹmio òòtọ́ àti ẹmi ìfọkansìn, ọmọ ìmẹkọ Afọn ni wọn Kosi ilé ẹkọ to yanranti Ijọba to wa lóde ko ṣe ohun ti o tọ nítori naa ètò ẹkọ ofẹ ṣe pataki Ademola Ogunbanjọ Àkọlé àwòrán, #BBCGOVDEBATE: Èrò àwọn oludije ṣe ọtọ̀ọ̀tọ lóri ètò ẹkọ Ofẹ Iberu olorun ni mo gbé dáni fún àwọn ènìyàn ìpínlẹ̀ Ogun Lóri ètò Ẹto ẹkọ ò lé dara kó tun jẹ pọ́ọ́kú lówó, ó ṣe pàtàkí kí wọn san owọ Gbogbo ǹkan to n fun wa ni wahala ni afe pada si.
Academy naa ni eka metadinlogun kaakiri awon osere, onkowe atiele re idanilaraya miran.
Ajayi ni opopona marosẹ Ogbomọsọ si Ilọrin ni isẹlẹ ikọlu naa ti waye, ti Kọmisana ọlọpa nipinlẹ Kwara, Kayode Ẹgbẹtokun si pasẹ pe ki awọn ọlọpa tete dide si isẹlẹ naa.
Alukoro ile-ise ologun tun so pe, gbogbo awon ara-ilu ti won bowo fun ofin ni won leto si eto abo ti o peye fun emi ati dukia, laifi ipo tabi aye ti won wa se.
Èèyàn 221 ní àrùn Coronavirus tún ṣẹ̀ṣẹ̀ ràn ní Nàìjíríà Ajọ to n gbogun ti ajakalẹ aarun lorilẹ-ede Naijiria, NCDC ti kede pe eeyan 221 miran ti kun iye awọn to ti ni aarun COVID-19 ni Naijiria.
Eyi tumọ si pe awọn ọmọde toto okoolelọọdunrun (340), lawọn obi wọn n sekupa pa laarin ọdun kan soso.
''Emi ni mo paṣẹ pe ki wọn ko gbogbo oriṣa to wa laafin Iwo kuro nigba ti mo jọba tan,'' Oluwo lo sọ bẹẹ.
lati wa pade aare Muhammadu Buhari , so fun awon oba alayeluwa ati awon omo
Kumuyi Bible: Ọdún mẹ́ẹ̀dógún ni òun àtàwọn onímọ̀ Yorùbá fi ṣe ìwádìí nípa Bíbélì náà
Aṣa wọn si ni pe o le bimọ lati ara arabinrin iyawo rẹ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ọ̀gá ọlọ̀pàá: Saraki gbọdọ̀ wá sọ àsọyé lórí lẹ́tà tó kọ 24 Agẹmo 2018 Àkọlé àwòrán, Idris ni o pọn dandan fun aarẹ ile asofin agba ilẹ wa naa lati wa yọju si ileesẹ ọlọpaa ni Abuja.
 Àrùn yìí kò ní àmìn ṣùgbọ ́ n a lè rí ìwami lójú àti ipin .
Ajibade Ogunoye di Ọlọ́wọ̀ tuntun fún ìlú Ọwọ Olè wọ ilégbèé obìnrin ní fásitì Ibadan, àkẹ́kọ̀ọ́ méjì farapa Ẹ fọkànbalẹ̀, kọ́bọ̀ kò ní gun owó epo pẹtiró - NNPC Olukọni ikọ Super Eagles nigba naa, Manfred Hoener wa fi eeni ko eeji, lo ba ni ki Omokharo o wọle.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Kunle Afolayan: èmi kò fẹ́ fi ogún sílẹ̀ fún ọmọ mi Oduyọye wa kesi Sẹnetọ Lanlẹyin pe, ko mase wọ orukọ gomina Seyi Makinde sinu ijakulẹ to n koju ninu ẹgbẹ oselu ADC, nitori adehun ajumọse naa ko wa fun ifẹ ẹnikẹni, bikose fun ifẹ awọn olugbe ipinlẹ Ọyọ.
Àṣẹ àwọn gómìnà là ń retí, àwa ti ṣetán láti dáàbò bo ilè Yorùbá- Gani Adams Orílẹ̀-èdè Naijíríà pàdánú onímọ tí kò lẹ́gbẹ́- Ayo Adebanjo 'Ohun ẹ rí, ẹ wí, ẹ ò lè fipá mú wa fáwọn darandaran nílẹ̀ ní ìpínlè wa' Àgbẹdọ̀!
" Bẹ́ẹ̀ bá sì gbàgbé, ọ̀pọ̀ àwọn òsèré orí ìtàgé ni wọ́n fi dúkìá tí wọn sẹ̀sẹ̀ rà se yàǹnga lórí ayélujára.
Yóo kó ọrọ̀ rẹ ati àwọn ọjà tí ò ń tà ní ìkógun.
sagbakale labe isakoso re mule gidi si.
Ẹ gbin òdodo fún ara yín, kí ẹ sì ká èso ìfẹ́ tí kì í yẹ̀; ẹ lọ dá oko sí ilẹ̀ tí ẹ ti kọ̀ sílẹ̀, nítorí ó tó àkókò láti wá OLUWA, kí ó lè wá rọ ìgbàlà le yín lórí bí òjò.
Mi o loye ohun to ṣẹlẹ - mo ba wo oju opo ikansiraẹni Facebook ati Twitter mi, ọpọ lẹta ni mo ti gba ti gbogbo wọn n bere ọrọ kan naa lọwọ mi pe ṣe emi ni Michelle Damien"", akọroyin iroyin aburu kan to n da wahala silẹ ni gbogbo Senegal?"
 O to eemetala ti ile naa n ri lojo naa ni eyi ti ko fu won lara rara ko to sele.
Eṣẹ si ofin ni oyun ṣiṣẹ ni ilẹ Morocco ati iwa agbere ṣiṣẹ.
Cesc Fabregas je góòlù àádọta rẹ láti ìgbà tó tí wá ni Premiership nínú ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ Chelsea àti Tottenham.
N ò wé gèlè dúdú rí ṣùgbọ́n a ṣe bí wọn ṣe wí.
Wọn kì í fi oúnjẹ kankan sílẹ̀ rárá ní ilẹ̀ Israẹli, bẹ́ẹ̀ ni wọn kì í fi aguntan tabi mààlúù tabi kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ kankan sílẹ̀.
Insecurity: Buhari ní ẹ̀ka aláàbò Nàíjíríà tiraka àmọ́ ó yẹ kí wọn ṣe jù bẹ́ẹ̀ lọ
koda awọn to ba ṣẹṣẹ lo oogun apa kokoro ara tan gbọdọ duro fun ọjọ meje ki wọn fi sinmi ki wọn to le fi ẹjẹ silẹ.
ASUU, CONUA tako ara wọn lórí iyansẹ́lódì Oríṣun àwòrán, @OfficialOAU Àkọlé àwòrán, Lọjọ aiku ni ASUU paṣẹ ki gbogbo awọn olukọ fasiti lorilẹede Naijiria o gunle iyanṣẹlodi Ede aiyede diẹ bẹ silẹ lọgba fasiti Ọbafẹmi Awolọwọ to wa nilu Ilẹ Ifẹ lori iyanṣẹlodi ẹgbẹ olukọni fasiti, ASUU to n lọ lọwọ.
Iroyin sọ pe, aarẹ Trump paṣẹ fun adele olori oṣiṣẹ ile ijọba rẹ Mick Mulvaney, lati dawọ iranwọ naa duro titi di igba ti ohun yoo ba aarẹ Ukraine sọrọ tan lori ago.
"Ki ede Yoruba ma baa parun ni BBC Yoruba ṣe jade lọ beere lọwọ awọn ọkunrin, ohun ti Yoruba n pe "" Necklace'."
Oríṣun àwòrán, Getty Images Awọn orilẹede re e ti wọn ti ṣi papakọ ofurufu wọn fun irinajo si orilẹede miran: Yuroopu: Ọjọ Kini, Oṣu Keje ni wọn ṣi papakọ wọn fun awọn arinrinajo lati orilẹede marundinlogun, eleyii ti Canada, Morocco ati Australia wa lara wọn, Amọ wọn ko fun orilẹede Naijiria, Amerika, Brazil ati Russia laaye lati wọle sọdọ wọn.
Gbogbo àwọn tí wọ́n kú ninu àwọn ọmọ Bẹnjamini ní ọjọ́ náà jẹ́ ọ̀kẹ́ kan ó lé ẹẹdẹgbaata (25,000); gbogbo wọ́n jẹ́ akikanju jagunjagun tí ń lo idà.
”O fikun un oro re pe: “Yiyan
Adeoti ki gomina Fayemi ku oriire Tesiwaju si, oludije gomina labe asia egbe oselu Action Democratic Party (ADP) nipinle Osun, Alhaji Moshood Adeoti ki dokita Kayode Fayemi ku oriire iyansipo re.
" Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Christmas & Border Closure: ìrẹsì dí góòlù fún Kérésì 2019 Lẹyin naa ni wọn yoo kede orukọ rẹ, poopu tuntun naa yoo si jade si gbangba fun igba akọkọ.
 Gege bi iroyin lati ile-ise akoroyin Voice of Nigeria,  Akori ipade ohun ni: ‘Eto ise akanse ipele to kan: Oro Eto isuna.
16 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Pakistan new rape law: Ìjọba yóò fààye gba fífi kẹ́míkà tẹ ọkùnrin lọ́dàá15 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Yoruba Nollywood: Jide Kosoko ní Mr Latin ò lè dá a ṣe gẹ́gẹ́ bí ààrẹ TAMPAN16 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Ooni sọ pe irin ajo oun kun fun oriṣiiriṣii iṣẹlẹ nla, ati pe ọpọ ni ko gbagbọ pe oun le de ori ọtẹ gẹgẹ Ooni Ile Ife.
Gẹ́gẹ́ bí Joṣua ti pàṣẹ fún àwọn eniyan náà, àwọn alufaa meje mú fèrè ogun tí wọ́n fi ìwo àgbò ṣe lọ́wọ́ níwájú OLUWA, wọ́n ṣáájú, wọ́n ń fọn fèrè ogun wọn; àwọn tí wọ́n gbé Àpótí Majẹmu OLUWA sì tẹ̀lé wọn.
O sọ pe ni nkan bi ọgbọn isẹju ti baalu gbera lo fẹsẹ tẹlẹ ti o si sọ layo.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Nigba naa lo sa kuro lorilẹede to si dara pọ mọ ikọ awọn olugbẹsan lati koju ija si ijọba ti ẹya Tutsi n dari nigba naa.
Ó tún lóyún mìíràn, ó tún bí ọkunrin bákan náà, ó bá sọ ọmọ náà ní Ṣela.
Bourdain bẹrẹ pẹlu CNN lodun 2013 pẹlu iṣe iroyin nipa irin ajo afé, itan iwaṣẹ ilu kookan, ounjẹ agbegbe kọọkan ati bee bee lo.
OLUWA wí fún Mose pé, “Ọkàn Farao ti le, kò sì jẹ́ kí àwọn eniyan náà lọ.
Arakunrin ẹni ọdun aadọta naa wa lati idile awọn apẹẹja,nitori naa ni awọn eniyan se bọwọ fun gẹgẹ bi omuwẹ ni ipinlẹ Eko.
A ó ṣèwádíi òṣìṣẹ́ LASTMA tó ń ka owó àbẹ́tẹ́lẹ̀ nínú fídíò - LASTMA Ọjọ Aje ni ijọba orilẹ-ede Saudi Arabia kede pe irinajo mimọ Hajj ko ni waye fun ọpọ eero lọdun 2020.
” Wọ́n bẹ̀rẹ̀ sí ti Lọti mọ́ ara ìlẹ̀kùn títí ìlẹ̀kùn fi fẹ́rẹ̀ já.
Láìpẹ́ ọ̀tá yóo dà á wó, yóo sì di àtẹ̀mọ́lẹ̀.
Nigba ti yoo fi di ọgbọn iṣẹju ti idije naa bẹrẹ, Chelsea ati Arsenal ti ku eruku ami ayo kọọkan si ara wọn l'oju.
Ọrọ yii si ni awọn eeyan ti n gba bii ẹni gba igba ọti loju opo Twitter, ti ọpọ abikẹyin ti ọrọ naa kan julọ, si n sọ awọn iriri tiwọn naa, eyi to pa ni lẹrin pupọ.
PDP fi pẹjọ  lati fi tako abajade esi ibo
Nítorí náà, Ẹsira alufaa yan àwọn olórí ninu ìdílé wọn, wọ́n kọ orúkọ wọn sílẹ̀.
Igbimọ tẹẹkoto ile asofin agba lori ọrọ epo rọbi lo sọ eyi di mimọ nibi ijoko ita-gbangba to nse lọwọ lori lori wahala to n suyọ lori ọrọ owo iranwọ lori eroja epo rọbi.
Atejade ohun ni oga agba eka ti o n samoju to ilana eto owo-na Kevin Amugo fowo si, eyi ti o salaye pe, ile-ifowopamo CBN ti kowe si awon ile-ifowopamo kaakiri orile-ede Nigeria lati je ki won mo pe, ko si ajo to samojuto oja kara-kata owo takada lorile-ede Nigeria ati ni gbogbo agbaye.
OLUWA àwọn ọmọ ogun ní, “Ìwọ idà, kọjú ìjà sí olùṣọ́ àwọn aguntan mi, ati sí ẹni tí ó dúró lẹ́gbẹ̀ẹ́ mi.
Oríṣun àwòrán, oluwo Nígbà tó ń ṣàlàyé ìdí tó fi sọ ọmọ rẹ ni Odùduwà, Oluwo ni kí ló burú nínú kí èèyàn sọ ọmọ rẹ ni orúkọ Baba ńlá rẹ, o ni, ohun tó dára gbaa ni.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Osun Election Results 2018: Adeleke ní òun yóò gba ipò gómìnà padà, ó sì rí bẹ́ẹ̀ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Osun Election Results 2018: Adeleke ní òun yóò gba ipò gómìnà padà, ó sì rí bẹ́ẹ̀ 28 Owewe 2018 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 22 Ẹrẹ̀nà 2019 Oludije fun ipo gomina labẹ ẹgbẹ oselu PDP nipinlẹ Ọsun, Ademọla Adeleke, ti ilé ẹjọ́ ti kéde pe oun lo gbe igba oroke ninu idibo gomina Oṣun to kọja se apejuwe bo se fidi rẹmi ninu eto idibo naa gẹgẹ bii ifasẹyin ranpẹ, eyi ti yoo ni atunse laipẹ.
Ọba Ilorin ló pàṣẹ pé kí ń padà sọ́dọ̀ ọkọ mi - Risikat olójú búlúù Ẹfunroye Tinubu - Ògbóǹtagí oníṣòwò, olówò ẹrú àti afọbajẹ Samuel Ajayi Crowther, òjíṣẹ́ Ọlọ́run tó gbé èdè Yoruba lárugẹ Mọrèmi Àjàṣorò, akọni obìnrin tó gba Ilé Ifẹ̀ sílẹ̀ lóko ẹrú Ọ̀rọ̀ǹpọ̀tọ̀niyùn, Aláàfin obìnrin àkọ́kọ́ rèé, tó ní nǹkan ọkùnrin O ṣalaye pe, Ifa lo n ka oun lọwọ ko tẹlẹ lori ọrọ naa, bi bẹẹ kọọ, oun mọ ohun ti oun le ṣe lati wa owo naa rii ni kiakia.
Ilé iṣẹ́ BBC kò ní bàbá ìsàlẹ̀, à kìí parọ, a sí ní òótọ́.
Ojúewé tí ó ṣe é tẹ̀ ṣ'íwèé 
 Òògùn tí à nlò ni albendazole èyítí ènìyàn lè nílò fún ọ ̀ pọ ̀ lọpọ ̀ ọdún .
Lójú mi, ìwà wọn dàbí ìríra obinrin tí ń ṣe nǹkan oṣù rẹ̀ lọ́wọ́.
Ọpọlọpọ ní ń fọ́nnu nípa nǹkan ti ara, ẹ jẹ́ kí èmi náà fọ́nnu díẹ̀!
Ìgbìmọ aláṣẹ bákan náà tún fọwọ sí yíyàn Ọgbẹni Tunde Adedeji gẹ́gẹ́ bí alaga àjọ tó ń mójú to ìjọba ìbílẹ̀.
Egbé agbábọọlù Super Eagles gbàgbé ohun eèlò wọn - Ọlajiire Ṣé lóòtọ́ ni PDP fẹ́ kẹ̀yìn sí Gómìnà Seyi Makinde nípínlẹ̀ Oyo?
Idris so oro ohun di mimo fun awon akoroyin nile ipinle naa lojo isegun(Tuesday), O so pe, won yoo ko iko omo-ogun ẹgbẹ̀wàá lo si ipinle Zamfara lati lo mojuto idojuko naa, ni papaajulo lati da igbe aye alaafia pada sipinle ohun.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, #JusticeforTina: Àwọn obi Tina Ezekwe ń bèrè fún ìdájọ́ òdodo pẹ̀lú omijé lójú Pierre Nkurunziza, Ààrẹ orilẹede Burundi ti jáde láyé lẹ̀ni ọdún 55 Aarẹ orilẹede Burundi, Pierre Nkurunziza ti jade laye.
“Bí ẹ bá rí ìtẹ́ ẹyẹ lórí igi tabi ní ilẹ̀, tí ẹyin tabi ọmọ bá wà ninu rẹ̀, tí ìyá ẹyẹ yìí bá ràdọ̀ bò wọ́n, tabi tí ó bá sàba lé ẹyin rẹ̀, ẹ kò gbọdọ̀ kó àwọn ọmọ ẹyẹ náà pẹlu ìyá wọn.
Lara awọn ti wọn wa nibi ipade yi ni: Dr Kole Shettima-MAC Arthur Foundation Innocent Chukwuma -Ford Foundation Jude Ilo-OSIWA Segun Awosanya(segalinks)-End Sars Movement Yemi Adamolekun-Enough is Enough Folarin Falana Falz Auwwal Rafsanjani- CISLAC Kemi Okonyedo- PWAN Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ènìyàn 17 kú nínú ìjàmbá ọkọ̀ mẹ́ta tó ṣẹlẹ̀ ní Osun, òpópónà Ibadan sí Eko àti Delta Wo ìdí tí Tẹni, ọ̀dọ́mọdé olórin obìnrin kìí fi ń ṣí ìhòhò rẹ silẹ̀ Wo ìgbà mẹ́rin tí ìjọba ti tú ikọ̀ ọlọ́pàá SARS ká sẹ̀yín ṣùgbọ́n.
”Ṣugbọn Jesu wí fún wọn pé, “Ninu irú ife ìrora tí n óo mu ẹ̀yin náà yóo mu, irú ìṣòro tí ojú mi yóo rí, tiyín náà yóo sì rí i.
Ta ni ẹlẹ́sẹ̀ ayò Megan Rapinoe tó gba ife ẹyẹ àgbáyé tàwọn obìnrin?
Ọ̀pọ̀ àwọn èèyàn láti Hong Kong ní ìgbàgbọ́ pé China tí ń lo agbára tìkúùkú, wọ́n sì ń lo ètò ìlú láti ṣẹ́ àwọn ọ̀tá àti àwọn ẹ̀yà tí kò pọ̀ lẹ́yìn.
Adamawa kẹdun lori iku ogagun , onirawo merin naa.
Ajọ Law Enforcement Conduct Commission to fi iwadii naa lede rọ ileeṣẹ ọlọpaa lati tọrọ aforijin ni ọwọ obinrin ti wọn ni ko yọọ nkan oṣu rẹ naa.
Mú ọ̀pá yìí lọ́wọ́, òun ni o óo máa fi ṣe iṣẹ́ ìyanu.
awon odo miiran ko eti ikun si isiti ohun.
Vaccine rumours debunked: Àwọn ìròyìn òfegè nípa abẹ́rẹ́ àjẹsára Covid-19
Ará Amori ni baba rẹ ará Hiti sì ni ìyá rẹ.
Ni ọdun 2015, Boko Haram gba idanimọ gẹgẹ bii ẹgbẹ agbesunmọmi to buru julọ lagbaye, gẹgẹ bi ajọ to wa fun ọrọ aje ati alaafia lagbaye ṣe sọ.
Ta ba ni ka maa ka ni eni, eji, ilẹ kun nidi ọpọ aseyọri ti Alaafin ti gbe se ori oye, amọ diẹ lara awọn aseyọri naa ree, se bi ọmọ ko ba ba itan, yoo ba arọba.
Wọn ni ẹtọ ọmọ ko faaye gba ki aṣiṣe iya tabi baba maa dá ẹmi ọmọ ọwọ́ légbodò lọdun 2019.
Orí rẹ̀ ni yóo sì fi ru ẹ̀bi ẹ̀ṣẹ̀ rẹ̀.
Lọti bá yan gbogbo agbègbè odò Jọdani fún ara rẹ̀, ó sì lọ sí ìhà ìlà oòrùn.
Ọ̀kọ̀ọ̀kan wọn gba ìdájọ́ ìgbà ọdún mẹ́ta ní ẹ̀wọ̀n pẹ̀lú ìdádúró ọdún mẹ́rin sí márùn-ún.
Yan eto ilé ti o fẹ Pa oju aye bo ti ṣe yan awọn agbabọọlu rẹ(formation) de Paádé X Yan bo aaye ti o fẹ ki awọn agbabọọlu rẹ gba(formation) 4-4-2 Yan bo aaye ti o fẹ ki awọn agbabọọlu rẹ gba(formation) 4-2-3-1 Yan bo aaye ti o fẹ ki awọn agbabọọlu rẹ gba(formation) 5-3-2 Yan bo aaye ti o fẹ ki awọn agbabọọlu rẹ gba(formation) 4-5-1 Yan bo aaye ti o fẹ ki awọn agbabọọlu rẹ gba(formation) 4-3-3 Yan bo aaye ti o fẹ ki awọn agbabọọlu rẹ gba(formation) 3-4-3 Yan bo aaye ti o fẹ ki awọn agbabọọlu rẹ gba(formation) 5-4-1 Yan bo aaye ti o fẹ ki awọn agbabọọlu rẹ gba(formation) 3-5-2 Yan bo aaye ti o fẹ ki awọn agbabọọlu rẹ gba(formation) 4-3-2-1 Yan bo aaye ti o fẹ ki awọn agbabọọlu rẹ gba(formation) 4-1-2-1-2 Yan bo aaye ti o fẹ ki awọn agbabọọlu rẹ gba(formation) 3-3-3-1 Yan bo aaye ti o fẹ ki awọn agbabọọlu rẹ gba(formation) 3-4-1-2 Yan adiẹ̀yìnmú Pa oju aye orukọ awọn agbabọọlu rẹ de X Ri aridaju pe ikọ agbabọọlu naa lo yan Iyatọ ti de ba eto iṣẹ rẹ.
gege bi awon higher primates , adanida awon eniyan je alawujo .
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 9th Assembly: Aráàlú ní àwọn ń fẹ́ ìpèsè àwọn ohun èèlò amáyédẹrùn Ẹwẹ, iroyin to tẹ wa lọwọ sọ pe aarẹ tuntun funrarẹ, Lawan ni ohun yoo ṣe daadaa si awọn ẹlẹgbẹ oun lai fi ti oṣelu ẹya tabi ẹsin ṣe.
Amusan tun jẹ ọkan lara ikọ adari awọn miran ileeṣẹ bii Garages Limited ati Southern Petroleum Limited.
Yóo dáàbò bò wọ́n lọ́wọ́ oòrùn lọ́sàn-án, yóo jẹ́ ibi ìsásí ati ààbò fún wọn lọ́wọ́ ìjì ati òjò.
Nítorí náà, n óo pa ìwọ ati ìdílé rẹ rẹ́.
Ninu ọrọ idupẹ rẹ, Minisita naa ni ọpọ igba ni awọn kọ lẹta si ipinlẹ Kwara, lati gbe igbesẹ ti ko ni jẹ ki orukọ gbajugbaja elerebọọlu naa parẹ lailai.
Akeredolu parọwa si awọn eniyan lati fun awọn agbofinro ni anfaani lati ṣe iwadii ni ẹkunrẹrẹ lori ohun to sẹlẹ.
Orilẹede Togo ni orilẹede kẹsan ti arun Coronavirus yoo ti suyọ lẹyin Algeria to jẹ orilẹede akọkọ l'Afirika ti yoo kede arun ọhun lọjọ karundinlọgbọn oṣu keji ọdun 2020; Egypt, Morocco, Nigeria, Senegal, South africa, Tunisia ati Cameroun.
Nípasẹ̀ Mose ni a ti fún wa ní Òfin, ṣugbọn nípasẹ Jesu Kristi ni oore-ọ̀fẹ́ ati òtítọ́ ti wá.
 “Zenit ati Roberto Mancini fenuko lati fopin si ibasepo won,.
kì báà ṣe òkú baba, tabi ti ìyá rẹ̀; bẹ́ẹ̀ ni kò gbọdọ̀ súnmọ́ òkú arakunrin tabi arabinrin rẹ̀, nígbà tí wọ́n bá kú.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Àwọn bísọ̀ọ̀bù Aguda rọ ààrẹ Buhari lati kọ̀wé fipò sílẹ̀ 4 Agẹmo 2018 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Àwọn ẹgbẹ bísọ̀ọ̀bù ijọ àgùda Ẹgbẹ́ àwọn Bísọ̀ọ̀bù ìjọ páàdì Catholic Bishop conference of Nigeria (CBCN) tí ke pe ààrẹ Muhammadu Buhari láti kọ̀wé fipò sílẹ̀ tí kò bá le fòpin sí ìpànìyan tó ń lọ lọ́wọ́ lórílẹ̀-èdè Nàìjíríà.
OLUWA bá wolii Jeremaya sọ̀rọ̀ nípa Babiloni ní ilẹ̀ àwọn ará Kalidea pé:
Oríṣun àwòrán, AFP Àkọlé àwòrán, Onkọrin lati ọkan wa ni Fun bi aadọrin ọdun ni obinrin naa fi kọrin.
Agbenuso fun awon asojusofin lori oro kebi-ma-pa-ilu nile igbimo asojusofin agba nilu Abuja, Omowe Aliyu Sabin aa soro lori pataki fifon rere awon ise akanse to n to n lo lowo fun gbigbogun tri ise ati osi.
Márosẹ̀ Kaduna di ìbùba fáwọn ajínigbé Wahala Kaduna: Ọwọ ọlọpaa tẹ eeyan mẹwa Ìpínlẹ̀ Kaduna dá àwọn olùkọ́ tuntun dúró Wọ́n ti sin ológun Naìjíríà 11 ní Kaduna Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Kaduna ni àjọ NYSC pín mi sí sùgbọ́n.
naa lati maa se fi oju aanu wo awon ọdaran ti o se ikọlu yii.
Bakan naa, awon olopaa fi owo sinkun mu egbe oselu alatako ti won n gbero lati tako iwe abadofin ijoba.
 Lara awọn eyi lo nii ṣe pẹlu ayika, eto irinna-ọkọ, ina mọnamọna, aṣa ati iṣe, pẹlu awọn miiran.
Mo mọ èyí, ó sì dá mi lójú nípa àṣẹ Oluwa Jesu pé kò sí ohunkohun tí ó jẹ́ èèwọ̀ ní jíjẹ fún ara rẹ̀.
Awọn ileewe wọle pada fun saa igbẹkọ tuntun lẹyin igbele isede ajakalẹ aarun coronavirus.
Ọ̀rọ̀ǹpọ̀tọ̀niyùn, Aláàfin obìnrin àkọ́kọ́ rèé, tó ní nǹkan ọkùnrin Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Mama Arsenal: Màmá àgbà yìí máa ń lọ sí ìbùdó tí wọ́n ti ń wo bọ́ọ́lù láti wòran Bakan náà ni àwọn alaṣẹ ni Mumbai ti fi akọlé si ẹnu ọ̀nà ilé Bachchan gẹ́gẹ́ bi ibi ti ẹnikẹ́ni kò gbọdọ̀ dé (Containment Zone)"" Amitabh Bachchan: Gbajúgbajà òṣèré India àti ọmọ rẹ̀ lùgbàdì ààrùn Coronavirus Oríṣun àwòrán, others Gbájúgbajà òṣèré ní orílẹ̀-èdè India, Amitabh Bachchan àti ọmọ rẹ̀ Abhishek Bachchan ti kéde lójọ́ Ẹti, ọjọ́ kọkànlá, oṣù keje, ọdun 2020, pé àyẹwò tí gbé e jáde pé àwọn ti lùgbàdì ààrùn Covid-19."
Àjọ NCDC tún ti kéde ènìyàn 245 míràn tó ní ààrùn Covid-19 l'órílẹ̀-èdè Nàìjíríà Bí Eko ati Abuja ṣe rí rèé lọ́jọ́ àkọ́kọ́ tí wọ́n dẹ ọwọ́ igbele Coronavirus Ọwọ́ tẹ báàlẹ̀, Ṣinkó mẹ́tàdínlógún tó ń jí kùsà wà ní ìpínlẹ̀ Ọ̀ṣun Duro Ladipọ, ìlúmọ̀ọ́ká òṣèré tíátà àti ọmọ àlúfà tí kò gbàgbé àṣà ìbílẹ̀ Ilé ẹjọ́, tó ní Ogungbeje jàre ẹjọ́ ọhun, tún pàṣẹ fún ìjọba àpapọ̀ láti tọrọ aforijin lọ́wọ́ olupẹjọ náà, lójú ewé ìwé ìròyìn mẹta nilẹ wá.
"Àjọ aláàánú Para Foundation ń rawọ ẹ̀bẹ̀ si ọkàn àánú yín láti ṣètò iranlọwọ fún baba Ogun Majek, kò lè e bọ nínú ipò ikaanu tó wa.
 Won gba mi mora, inu mi si dun pupo,”Ronaldo ti pinnu lati ran iko agbaboolu Juventus lowo lati gba ife-eye lolokan-o-jokan nile Europe.
 O tun seleri lati maa se atileyin fun awon alaini.
gbigbe awon osise ijoba ajo eleto idibo INEC salọ, didana sun iwe idibo ati iwe
Bí ènìyàn bá rẹ́ ọ jẹ, tí ìwọ sì ṣe bí ẹni pé ìwọ kò tilẹ̀ mọ̀, ìwọ ti gbé eléyìínì sí inú ìkòkò gbígbóná, èrí-ọkàn rẹ̀, yóò sì máa ko iná mọ́ ọn.
“Ẹ̀mí OLUWA ń gba ẹnu mi sọ̀rọ̀,ọ̀rọ̀ rẹ̀ wà ní ẹnu mi.
Ọmọ Yorùbá tó bá ti rú òfin, ẹ gbé e jàntò - Oluwo Ọlọ́pàá Kwara ti rí ọmọ orílẹ̀-èdè Turkey mẹ́rin gbà padà lọ́wọ́ ajínigbé!
Oṣu meloo kan sẹyin ni ile aṣofin Egypt fun awọn alaṣe ẹgbẹ omoogun orilẹede naa ni aabo labẹ ofin fun ẹṣẹ ti wọn ṣẹ nigba ifẹhonuhan naa ati awọn laabi miiran ti wọn ṣe laarin oṣu keje 2013 si oṣu kinni 2016 Oríṣun àwòrán, EPA Àkọlé àwòrán, Ọpọ̀lọ́pọ̀ ènìyan ni àwọn olóógun yínbọn pa ni oríta Rabaa al-Adawiya ní 2013 Awọn ti wọn ran l'ẹwọn naa ni wọn fi ẹsun idaluru, ipaniyan ati fifa jagidijagan laarin ilu kan.
Ṣe ni iyanṣẹlodi yii ka ijọba niṣan ko tori o jẹ ọkan lara awọn iyanṣẹlodi awọn oṣiṣẹ ileeṣẹ epo bẹntiroo to gun ju ninu itan Afirika.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Amotekun Recruitment: Ìròyìn ayọ̀ fún gbogbo àwọn tó forúkọ sílẹ̀ fún ikọ̀ Amotekun ní ìpínlẹ̀ Oyo 29 Ọ̀wàrà 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 1 Bélú 2020 Ijọba ipinlẹ Oyo ti kede pe orukọ awọn to yege lati darapọ mọ ikọ alabo Amọtekun ti jade.
Àwọn ọmọ ikọ Boko haram tún ti s'oro ni Maiduguri, olú ìlú ìpínlẹ Borno, èyí tó ṣ'okùnfà ikú èèyàn mẹ́ẹ̀dógún tí àwọ̀n míràn tó dín díẹ̀ ni àádọ́rin sì farapa.
Oríṣun àwòrán, Davido/@SeyiTunbi Ki lo ti ṣẹlẹ sẹyin?
Arakunrin Verney to ni akukọ naa ni eyi ko lee di ofo to ṣe oun.
Àwọn ọmọ Israẹli bá tún ké pe OLUWA, wọ́n ní, “A ti sẹ̀ sí ọ, nítorí pé a ti kọ ìwọ Ọlọrun wa sílẹ̀ a sì ń bọ àwọn oriṣa Baali.
Iru igbẹ yii lo maa n fọn jade tẹ o maa gbọ prẹẹẹrẹrẹ.
Ọgbẹni Okoye sọ pe esi ibo aarẹ ko si ninu ''server'' INEC tabi ẹrọ kọmputa nibi kankan.
kò ní sí òkùnkùn, kò ní sí ọ̀sán, kò ní sí òru bíkòṣe ìmọ́lẹ̀ nígbà gbogbo.
Lasiko to n salaye bi ọrọ ifẹ oun ati ọkọ rẹ, Mike Adeyẹmi se bẹrẹ loju opo Instagram rẹ, lasiko ti wọn n bawọn ololufẹ wọn jẹwọ loju koroju, Nkechi ni ọrọ naa dabi ti Romeo ati Juliet ni.
Eyi waye lẹyin ti WhatsApp fa awọn to n lo o leti lori foonu oni Windows pe wọn le dede ri awọn nkan amuy kọọkan ti ko ni ṣiṣẹ mọ.
Àwa nìkan ni a óo kọ́ ọ gẹ́gẹ́ bí Kirusi, ọba Pasia, ti pa á láṣẹ fún wa.
laarin odun meta ijoba yii , awon omo orile ede Naijiria ati ajo gbaye ti bere si n kan saara si wa lori awon igbese ati eto ilana ti a n gbe lati gbokun ti iwa ibaje.
gba ara rẹ là, sọ̀kalẹ̀ láti orí agbelebu.
“Ise ti a n se yii, nitori olorun ni, bee si ni,  tori orile-ede yii ni ati awon omo orile-ede yii.
Ìtẹ́ náà ní àtẹ̀gùn kan tí ó ní ìṣísẹ̀ mẹfa ati àpótí ìtìsẹ̀ kan tí a fi wúrà ṣe, tí a kàn mọ́ ìtẹ́.
“Nígbà tí o bá dé orí ilẹ̀ tí OLUWA Ọlọrun rẹ fún ọ, tí o gbà á, tí o sì ń gbé inú rẹ̀, 
Báyìí ni 50kobo ṣe dá ìfẹ̀hónú Ali Must go"" sílẹ̀ tó mú ọ̀pọ̀ ẹ̀mí akẹ́kọ̀ọ́ lọ Bọ́ọ̀sì ìrìnà 106 tuntun yóò máa ná Ibadan sí Eko àtàwọn ìpínlẹ̀ míì - Seyi Makinde Wo ìdí tí orílẹ̀-èdè America ṣe tako ìyànsípò Okonjo-Iweala gẹ́gẹ́ bi olórí ajọ WTO Àkùkọ dojú ìjà kọ ọlọ́pàá, ikú ló já sí fún agbófinró Ẹ̀kọ́ ọ̀fẹ́ déé fáwọn ọmọ Ọlọ́pàá tó kú lásìkò EndSARS, Gómìnà ìpìnlẹ̀ Eko kéde ''Awọn awakọ ati ọlọkada ko ni ṣiṣẹ ju asiko isẹde naa lọ, paapaa ti wọn ba kasẹ isẹde naa kuro nilẹ'' Gomina Oyetọla dupẹ lọwọ awọn araalu fun atilẹyin wọn lasiko yii titi alaafia yoo fi pada si ipinlẹ naa."
Oríṣun àwòrán, TWITTER Àkọlé àwòrán, Lọjọ Aiku ni Aarẹ Buhari ṣe ifilọlẹ iwe eto ijọba ohun ti o pe akori rẹ ni Next Level.
" nam , tí ó lọ sí yunifásítì faransé , paoda tí ó léfó sí ojú omi sílẹ ̀ ní "" ilú àgbọn "" ti gúúsù vietman , ní agbèègbè bến tre ."
Mide náà ti kópa nínú àìmọye eré tó ti hùwà kògbérégbé gẹ́gẹ́ bí obìnrin.
Ti wọ̀n ko ju ki wọ̀n jẹ́un, ki wọ̀n sun tabi yagbẹ lọ.
Ìdílé kọ̀ọ̀kan ní ilẹ̀ náà yóo ṣọ̀fọ̀ lọ́tọ̀ọ̀tọ̀; ìdílé Dafidi yóo dá ọ̀fọ̀ tirẹ̀ ṣe, bẹ́ẹ̀ sì ni àwọn iyawo wọn yóo ṣọ̀fọ̀ tiwọn lọ́tọ̀.
Wọn fi ẹsun kan an pé o kowo jẹ ni eyi ti ajọ to n gbogun ti iwa ṣiṣe owo ilu baṣubaṣu EFCC n ṣe iwadii rẹ lọwọ lati oṣu keji, ọdun 2016.
Minisita to n ri si oro awon osise, dokita Chris Ngige jabo oro naa fun awon akoroyin lojoBo(Thursday), niluu Abuja.
Eléyìí mú kí n lọ wo òkè àjà wò bòyà òótọ́ ni ọ̀rọ̀ náà, nígbà tí mo sì máa dé ọ̀hún ńkọ́, mo bá ọkùnrin náà níbi tí ó lé góńgó sí, mo bá gba àwọn oòg[pun, mo ku àpò oògùn wa mọ́ ọn ní àtàrí, mo bá ń lọ tí mo ń pòṣé lọ ní tèmi, òun náà bá fi ìtìjú tẹ̀lé mi.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù PDP Kogi Primary: PDP yóò yan olùdíje tí yóò gbé àsíá ẹgbẹ́ fún ipò gómìnà 3 Owewe 2019 Oríṣun àwòrán, Google Àkọlé àwòrán, Sẹnatọ Dino Melaye wà lára àwọn tó ń díje dupò láti gbé àsíá ẹgbẹ́ náà nínú ìdìbò sípò gómìnà ní Kogi.
Mo fẹ́ kí ẹ máa tẹ̀lé ọ̀rọ̀ irú wọn ati gbogbo àwọn tí wọn bá ń bá wọn ṣiṣẹ́ pọ̀, tí wọn ń ṣe làálàá níbi iṣẹ́ kan náà.
Kí o tún máa bèèrè pé, ‘Anfaani wo ni mo ní?
Gege bi Edmund se so,“ohun iwuri ni o je fun mi lati fagbahan okan lara ondije ti o darajulo ninu ere idaraya yii”Edmund ti o wa ni ipo kéjìlélógún lori tabili apapo awon ondije ohun, ni ireti wa bayii pe yoo koju ondije omo orile-ede Belgium David Goffin ninu ipele keta idije naa.
Idi ni pe agbarijọpọ ẹlẹgbẹjẹgbẹ osisẹ nipinlẹ Ondo naa ti n kọrin owe pe, awọn yoo maa wo isẹ niran nipinlẹ naa.
Rape Case: Tó o bá ṣàdéhùn ìfẹ́ tó ò mú u ṣẹ, ẹ̀wọ̀n lo fi ń ṣeré
Ninu awọn to n hu iwa buruku ifipabanilopọ lọwọ rẹe gẹgẹ bo ti se jẹwọ fawọn ọlọpaa.
Àbí mààlúù a máa dúntí ó bá ń wo oúnjẹ rẹ̀ nílẹ̀?
Tí Ikú Ẹnìkan Bá Rúni lójú.
OLUWA àwọn ọmọ ogun, Ọlọrun Israẹli, pẹlu ìgboyà ni mo fi gbadura mi yìí sí ọ, nítorí pé o ti fi gbogbo nǹkan wọnyi han èmi iranṣẹ rẹ, o sì ti ṣèlérí pé o óo sọ ìdílé mi di ìdílé ńlá.
 Ìgbà tí ó dé , ó bu omi òkun bọ ̀ , wọ ́ n lo omi yìí , bàbá wọn sì ríran .
Ogbẹni Bolaji Tunji to jẹ oluranlọwọ pataki fun oloogbe Ajimọbi lori eto iroyin nigba aye rẹ lo ṣalaye bi eto isinku naa yoo ṣe waye lorukọ mọlẹbi Ajimọbi.
"Oríṣun àwòrán, @MBuhari ""Se to ba jẹ Jubril ti Sudan ni, se yoo ranti ọrẹ rẹ ati ibi ti wọn ti pade loju ogun lọdun 1968, ẹ gbe irọ da sọhun, ko jẹ wa."
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'A ò tíì rí omi mu, ẹ ní ká máa fọwọ́ tóríi Coronavirus' Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Ó fún wọn ní etígbọ̀ọ́,ó sì pàṣẹ pé kí wọ́n yipada kúrò ninu ẹ̀ṣẹ̀.
Igbakeji ọga ọlọpaa Mba sọ pe wọn ti ko wọn si atimọle ọlọpaa to wa ni Panti, Yaba ni ipinlẹ Eko.
Ìpele ikọ̀ mẹrindinlogun Uganda vs Senegal.
OLUWA, dákun gbà mi;yára, OLUWA, ràn mí lọ́wọ́.
O ni bi oun se gbọ́ iroyin iku Mavrodi, n se ni ọkan oun baje nitori owo oun ba ilana sogúndogójì MMM lọ̀.
Bákan náà ni Adájọ́ rọ olùjẹ́jọ́ náà láti máa hùwà rere kí ó sì jìnà réré sí ìwà ọ̀dáràn, nítorí tí ẹjọ́ rẹ̀ bá tun padà sí ilé ẹjọ́, ilé ẹjọ́ le máa ṣíjú àaǹú wòó mọ́.
Akọnimọọgba Lesotho ni Osihmen ati Aribo ti fakọyọ fẹgbẹ agbabọọlu wọn loke okun, idi niyii ti fi gbọdọ mu wọn daadaa.
Aare Muhammadu Buhari n se ipade lowo-lowo pelu apapo awon gomina jake-jado orile-ede Naijiria, ipade ohun n waye nile-ise aare niluu Abuja.
Àjọ EFCC ló gbé Sẹ́nétọ̀ náà lọ sile ẹjọ́ lórí ẹ̀sùn ikowo ìlú pamọ́.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Sotitobire: Ọkọ mi kò mọ̀ Jegede PDP rí, kódà kò fa ẹnikẹ́ni kalẹ̀ dípò Akeredolu- Bisola Nilu Abuja awọn oluwọde fi imoore han plu bi wọn ti ṣe fi aworan arakunrin kan ti wọn lo fun awọn ni ounjẹ lasiko iwọde naa han lori ayelujara Yatọ si eyi, awọn oluwọde tun fun awọn agbofinro ni omi mu laibikita pe wọn n koju awọn.
Njẹ ọmọ yii le jẹ ọmọbibi ilẹ Amẹrika?
Adájọ́ Olusegun Odusola to gbọ́ ẹjọ́ náà gbà pé ẹ̀rí ni ọ̀rọ̀ Temitope Kolawole jẹ́ níwájú ilé ẹjọ́ èyí tó ti fi lélẹ̀ lásìkò ti àwọn ẹka ọlọ́pàá tó n rí sí ijínigbé fọ̀rọ̀ wáa lẹ́nuwò.
Yemi Alade lo kọkọ fi ọrọ sita pe ki Tiwa Savage ye ma paro tan awọn eeyan pẹlu bi o ti ṣe n ṣe afikun idi rẹ ninu aworan.
Minisita fun iwakusa, Olamilekan Adegbite naa wa nibẹ.
Nigbati awọn adari mejeeji n ba awọn akọroyin sọrọ, Aarẹ Trump sọ wipe ijọba oun setan lati sisẹ pọ pẹlu ijọba orilẹede Naijiria lati gbogun ti awọn agbesunmọmi.
Kí OLUWA onídàájọ́ dájọ́ lónìí láàrin àwọn ọmọ Israẹli ati Amoni.
Iwadii naa fi ẹsun kan Atiku wi pe o fi owo to le ni miliọnu mẹwa dọla ( USD 10 million) ranṣẹ si oke okun labẹ ileeṣẹ GTCN.
Òwò mẹ́wàá tí yóò pàdánù àìsí ìpéjọpọ̀ ńlá RCCG lọ́dún yìí Àgbáríjọ àwọn nọ́ọ̀sì fẹ́ gbé Olamide Baddo lọ sílé ẹjọ́ fún ìbanilórúkọjẹ́ Ṣọ́ọ̀ṣì tí wọ́n ti ń fi ọtí àmupara bá Ọlọ́run sọ̀rọ̀ ní kí ìjọba dẹwọ́ọ òfin títà ọtí lásìkò Covid-19 Ọkọ kọ àwọn ọmọ méjì lé ìyàwó lọ́wọ́ nítorí ìrísí ojú wọn ní Ilorin 'Ọkọ mi mú ọ̀bẹ jáde lápò, ó sì gé imú mi jábọ́.
Kìí ṣe ààrùn Covid-19 ló pa adájọ́ àgba ìpínlẹ̀ Kogi-Kọmísọ́nà ìlera 'Rọ́bọ́ọ̀tì ni yóò máa yẹ̀ yìn wò kẹ́ẹ tó rìnrìnàjò òfurufú ní Nàìjíríà' Ìgbà mẹ́jọ tí awuyewuye wáyé lórí ìṣèjọba Ajimobi!
Amọ ṣa ni Naijiria nikan kọ ni ijiya ti wa fẹnikẹni to ba bu aarẹ.
Oríṣun àwòrán, @Jane Àkọlé àwòrán, Onimọ yii ṣalaye kikun ohun to n ṣaju ipaniyan nitori ifẹ yii O ṣalaye fun BBC pe ọpọ igba ni awọn onimọ maa n pe iru iwa ọdaran yii ni: iwa ọdaran ipaniyan nitori ifẹ (Crime of passion) Kí ni ó gbé ọlọ́pàá dé ibi àjọ̀dún ọjọ́ ìbí i Bobrisky?
3) Oríṣun àwòrán, Getty Images Sùgbọ́n ní Githinji Gitahi, olórí Amref Health Africa to jẹ àjọ kan tí kìí ṣe ti ìjọba ti wọ́n sì máà ń mójú tó ọ̀rọ̀ ìlera, sàlàyé pé tí iye ènìyàn tó kú ba pọ̀, ó túmọ̀ si pé iye ènìyàn to ni aàrùn náà pọ̀ ju iye ènìyàn ti wọ́n ni àkọsilẹ̀ rẹ̀ ni.
Àwọn ìṣẹ̀lẹ̀ mánigbàgbé tó wáyé nínú oṣù Kẹ́wàá ọdún 2020 Seyi Makinde fún olórin Fuji Taye Currency lẹ́bùn ọkọ̀ bọ̀kìnnì Toyota Prado 2020 Ẹ jọwọ, ẹ ba mi bẹ ìyàwó mi kí ìgbéyàwó mi ma baà túká - 9ice Ọrọ̀ ajé Naijiria gbá rìfáàsì tó burú jùlọ láti ọdún 1987 Wo bi wọ́n ṣe n ṣe àmójútó ilé ìjọsìn Prophet Israel Oladele, CCC Genesis Global Fasola ṣalaye pe sisọ opopona di ibudo igbe ọkọ si yii ti ṣakoba to pọ fun eto ọrọ aje Naijiria lapapọ.
Ṣugbọn tí ẹ kò bá jẹ́jẹ̀ẹ́ rárá, kì í ṣe ẹ̀ṣẹ̀ fun yín.
Bakan naa ni Aarẹ Ọna Kakanfo ilẹ Yoruba, Gani Adams naa ti kede bẹ ẹ laimọye igba pe, awọn agbebọn ti n wọle si ilẹ Yoruba.
Ṣugbọn iroyin ti a gbọ ni pe awọn ọkunrin ti juba ehoro.
N óo láyọ̀ ninu àwọn ìlànà rẹ,n kò ní gbàgbé ọ̀rọ̀ rẹ.
Èèyàn 390 ló tún ti ní covid-19 ní Naijiria Eeyan irinwo din mẹwa lo tun ṣẹṣẹ ni Covid-19 ni Naijiria.
Saaju asiko yii ni FIFA ti fun Naijiria ni gbedeke di aago mejila ọsan ọjọ Aje, ogunjọ, oṣu Kẹjọ, 2018, lati yanju wahala to n koju ajọ NFF, lori taani yoo jẹ aarẹ ẹgbẹ.
Agbẹnusọ ẹgbẹ onwoye naa to jẹ eto pataki kan labẹ Yiaga Afrika, Moshood Issa sọ fun BBC Yoruba ninu ifọrọwanilẹnuwo kan pe ọrọ ti Gomina El Rufai sọ ku diẹ kaato.
N óo lé àwọn ará Hamori ati àwọn ará Kenaani, àwọn ará Hiti ati àwọn ará Perisi, àwọn ará Hifi ati àwọn ará Jebusi, jáde kúrò níwájú rẹ.
Níbi tí odi ti ya ni wọn óo ti fà yín jáde, tí ẹ óo tò lẹ́sẹẹsẹ; a óo sì ko yín lọ sí Harimoni.
Ogun ti kó àwọn ọmọ ogun rẹ̀,àwọn ọ̀tá ti rún àwọn ọfà rẹ̀ jégéjégé,nítorí pé Ọlọrun ẹ̀san ni èmi OLUWA,dájúdájú n óo gbẹ̀san.
Nígbà tí mo mú wọn dé ilẹ̀ tí mo búra pé n óo fún wọn, bí wọ́n bá ti rí òkè kan tí ó ga, tabi tí wọ́n rí igi kan tí ewé rẹ̀ pọ̀, wọn a bẹ̀rẹ̀ sí gbé ẹbọ wọn kalẹ̀ sibẹ.
Eyi to tumọ si pe, ikoko ti yoo jẹ ata, idi rẹ yoo kọkọ gbona, ti a ko ba si jiya to kun agbọn, eeyan ko ni jẹ aye to kun aha.
O ni odiwọn iye àwọn oludibo to forukọ silẹ jẹ 775, 675.
Àwọn tí wọ́n wà lẹ́bàá odi níbi tí ó ń gbà lọ sì rí i pé ó wọ aṣọ-ọ̀fọ̀ sí abẹ́ aṣọ rẹ̀.
Eto yii waye ni papa isere Samuel Doe to wa nitosi Monrovia tii se olu ilu orilẹede Liberia.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Báwo lo se gbọ́ èdè Yorùbá sí ?
eyi ti o si n se isẹ gidigidi.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Child Labour: Òbí mi kú nígbà ti mo wà lọ́mọ́ ọdún kan' Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Child Labour: Òbí mi kú nígbà ti mo wà lọ́mọ́ ọdún kan' 15 Òkùdu 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 2 Èbibi 2020 Emi ati ọrẹ mi la jọ n tọrọ owó fún ìyá àgbà -ọmọde Fifi ọmọde ṣowo wọpọ ni ilẹ Afrika ṣugbọn tilẹ Naijiria lo pọ ju.
Ó bá sọ ìdámẹ́ta òkun di ẹ̀jẹ̀.
"Wọn jẹ ko di mimọ pe ""ẹni to fẹ wa ba ẹ tọju ọmọ rẹ kan fẹran lati wa ran lọwọ ni""."
Baale Apese d'àwátì, ó bọ́ sọ́wọ́ ajínigbé!
Wúrà ni gbogbo ìlú náà tí ó mọ́ gaara bíi dígí.
Oṣu mẹrin ni anfaani iwe aṣẹ igbelu.
9 Kíyèsíi, èmi ni ìmọ́lẹ̀ àti ìyè ayé, tí ó ńsọ àwọn ọ̀rọ̀ wọ̀nyí, nítorínáà fi etí sí ọ̀rọ̀ mi pẹ̀lú agbára rẹ, nígbànáà ìwọ ni a pè.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Coronavirus: Borussia Dortmund fẹ̀yìn Schalke 04 gbolẹ̀ bí Líìgì ilẹ̀ Germany ṣe padà bẹ̀rẹ̀ 18 Ẹrẹ̀nà 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 16 Èbibi 2020 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ifẹsẹwọnsẹ naa waye laisi ero iworan.
Nítorí bí a bá gbàgbọ́ pé Jesu kú, ó sì jinde, bẹ́ẹ̀ gan-an ni Ọlọrun yóo mú àwọn tí wọ́n ti kú ninu Jesu wà pẹlu rẹ̀.
Gbogbo àwọn agbéraga láyé ni yóo wólẹ̀ níwájú rẹ̀;gbogbo ẹni tí yóo fi ilẹ̀ bora bí aṣọni yóo wólẹ̀ níwájú rẹ̀,àní, gbogbo àwọn tí kò lè dá sọ ara wọn di alààyè.
O jẹ́ kí á bọ́ sinu àwọ̀n;o sì di ẹrù wúwo lé wa lórí.
Òmùgọ̀ sọ lọ́kàn ara rẹ̀ pé,“Kò sí Ọlọrun.
Ki wọn rii pe awọn akékọọ ati Olukọ ati awọn osiṣẹ to ku n tẹlẹ awọn ilana ti ijọba ti la kalẹ naa.
Nígbà tí Absalomu, ẹ̀gbọ́n Tamari, rí i, ó bi í léèrè pé, “Ṣé Amnoni bá ọ lòpọ̀ ni?
Iko Mokanla Naijiria(Potential Nigeria XI): Uzoho, Shehu, Ekong, Balogun, Aina, Obi, Ndidi, Onazi, Iheanacho, Moses, Ighalo Iko Mokanla Poland(Potential Poland XI): Szczesny,  Bereszynski, Glik, Piszczek, Cionek, Krychowiak, Rybus , Zielinki, Milik, Lewandowski.
Pàápàá jùlọ iPhone àti àkójọpọ̀ àwọn ẹ̀rọ ìbánisọ̀rọ̀ alágbèéká tí irúfẹ àìrídìmú inú wọn jẹ́ Android.
Omololu Olunloyo Kọmíṣọnnà lẹẹmẹfà tó gbé ọpá àṣẹ fún aláàfin Oyo àti Ṣọun Ogbomọṣọ N1000 tí Ọlọ́pàá ń gbà lẹ́nubodè wa làrùn Coronavirus fi ráyè wọlé-Ìjọba ìpínlẹ̀ Oǹdó Gómìnà Makinde, pe Sunday Igboho àti Auxilliary kóo parí ìjà wọn, àwọn ọmọ Nàìjíríà sọ̀rọ̀ jáde Akojọpọ ǹkan amáyedẹrùn tí ijọba ti fun awọn ọmọ Naijiria nitori aarun coronavirus Ṣugbọn ṣe o ṣeṣe ki arun naa wọle si eeyan lara lẹyin to ba ti bọ lọwọ rẹ tan?
Oluṣọ agutan ati oniwaasu nibi idupẹ naa, Simeon Borokini, wa rọ gomina Makinde lati mojuto ọrọ ọgbin, lọna lati gbogun airiṣẹ awọn ọdọ.
Ṣe ni ọpọlọpọ ti n gbiyanju lati Sọ àsọtẹ́lẹ̀ orílẹ̀èdè tí yóò borí ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ t'òní Bí eṣinṣin bá kọ́já, wíwọ́n ní, lásìkò ìṣíde AFCON 2019 Egypt ṣíná fún Zimbabwe, ẹ̀kọ́ mẹ́rin tó yẹ ní kíkọ́ Rohr já Iheanacho àti Semi jùú lẹ̀ lọ Egypt fún AFCON 2019 'Kí ni alága NFF, Amaju Pinnick ń wá ní Egypt fún AFCON?
Ò ń ṣìkẹ́ ayé, o sì ń bomi rin ín,o mú kí ilẹ̀ jí kí ó sì lẹ́tù lójú;o mú kí omi kún inú odò ìwọ Ọlọrun,o mú kí ọkà hù lórí ilẹ̀;nítorí pé bẹ́ẹ̀ ni o ṣe ṣètò rẹ̀.
Nigeria Elections 2019:Muhammadu Buhari, olùdíje ẹgbẹ́ òṣèlú APC
Mercy Aigbe bu èpè jó àwọn tó ní gómìnà kan ló ra ilé fún-un Afurasí méjì fi áńbúláǹsì kó Tramadol N60m wọlé l'Apapa Olólùfẹ́ méjì jábọ́ láti àjà kẹsàn án lásìkò tí wọ́n n ṣe kerewà Ẹrọ FaceApp le mu ẹni ti o ba le oju koko, ki o dabi ẹni to ba n rẹrin, bakan naa ni o le mu ẹni ti o ba darugbo, jọ ọdọ.
Báyìí ni orúkọ àwọn tí wọ́n ti jẹ Báálẹ̀ ṣe lọ, àti àwọn Elétù Òdìbo tí wọ́n fi wọ́n jẹ:
Iwadii awọn onimọ sọ wipe, atẹgun awọn ilu bii Eko, Port Harcourt, Abuja ati Kano lọpọ gbedeke ti WHO gba laaye ni ilọpo ọna, eyi to si n ṣe iku pa awọn ara ilu.
Nkan bii oludibo 109,577 lo n dibo bayii jakejado orilẹede naa kaakiri igun bii mejila ti ajọ eleto idibo fun laṣẹ lati kọkọ dibo eto idibo toni bẹr ni agogo meje owurọ eyi ti yoo si pari ni nkan bii ago marun irọlẹ oni.
Ẹ ma lo si ile iwosan fun abere aje sara lati dena aisan bii Hepatitis B ati bee bee lo.
Oríṣun àwòrán, Ooni ife Àkọlé àwòrán, Adeyẹye ni Ọọni kọkanlelaadọta ti yoo jẹ Ni ọjọ kẹtadinlogun, oṣu kẹwa, ọdun 1974 ni wọn bi Ọọni Ogunwusi ni idile Ọba Giesi ni ile ifẹ.
Ọlọrun Abrahamu, Ọlọrun Isaaki ati Ọlọrun Jakọbu, Ọlọrun àwọn baba wa ni ó dá Ọmọ rẹ̀, Jesu lọ́lá.
Jijawe olubori Joe Biden jẹ ibori imọlẹ lori okunkun - Obasanjo Oríṣun àwòrán, Reuters Aarẹ ana lorileede Naijira Olusegun Obasanjo ti pẹlu awọn olori kọọkan lagbaye to n fi ikini ku oriire ranṣẹ si Joe Biden to jaweolubori ninu idibo Amẹrika.
Ilé ẹjọ́ kọ̀ láti tú Omoyele Soworẹ sílẹ̀ Sibẹ ọpọ arugbo ati ọmọde lo fi ayọ han si ayajọ ominira China pe aadọrin ọdun kuro ni keremi ninu ominira.
Dabiri ti o jẹ oluranlowo aare lori ọrọ 
Adajọ Odusola wa sun igbẹjọ náà siwaju di ọjọ́ Kẹrìnlá, ikẹẹdogun àti ìkẹrin dínlógún oṣù keje ọdún 2020.
Femi ni o kan jẹ pe adanwo to wa ninu iṣẹ tiata pọ ni fun apẹrẹ awọn ololufẹ ipa ti mo n ko ninu ere to jẹ obinrin maa n gbe adanwo wa.
Kini Lisa ṣe lẹyin to ri fidio to tu aṣiri rẹ yii?
@OsaAOsula, o dup pupọ lọwọ Shogunlẹ fun alaye to se lori ọrọ yii, amọ o wa n beere pe ki wa ni itumọ sisi ara silẹ lọna aitọ?
Sugbọn ile iwe yoo si wa ni sisi ki wọn si maa tẹle awọn ofin itankalẹ arun Covid 19.
Bí Aaroni ti ń bá gbogbo ìjọ eniyan Israẹli sọ̀rọ̀, wọ́n wo apá aṣálẹ̀, wọ́n sì rí i pé ògo OLUWA hàn ninu ìkùukùu.
"Ko si ọmọ ẹgbẹ APC kankan ti ọlọpa gbe lasiko ibo naa, amọ se ni wọn n dunkoko mọ awọn asaaaju ẹgbẹ PDP lasaiko atundi ibo naa.
Klopp ko na ẹgbẹ ẹgbẹ agbabọọlu ti Mourinho n dari gẹgẹ bi akọnimọọgba ri.
Ẹ kí Filologu ati Julia, Nerea ati arabinrin rẹ̀, ati Olimpa ati gbogbo àwọn onigbagbọ tí ó wà lọ́dọ̀ wọn.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Falz tó jẹ́ olórin tàka-súfèé ti kéde pé òun ń wá obìnrin rere lọ́ọ̀dẹ̀ òun Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Falz tó jẹ́ olórin tàka-súfèé ti kéde pé òun ń wá obìnrin rere lọ́ọ̀dẹ̀ òun 10 Ẹrẹ̀nà 2018 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 26 Ọ̀pẹ̀̀ 2019 Falz sọ orisirisi nkan nipa ara rẹ, ati wipe oun n wa iyawo.
Agbẹnusọ rẹ kan, Gideon Ayọdele fidi rẹ mulẹ fun BBC ninu ifọrọwanilẹnuwo wipe Asofin Melaye funra rẹ lo fi fidio naa sori opo rẹ.
Nwachukwu ni iṣẹlẹ naa ko dun mọ awọn ninu nitori pe ki i ṣe igba akọkọ ni yii ti Kwam 1 yoo ma hu iru iwa bayii ni igba de igba.
EndSARS, EndSWAT Protests: Òbí agbábọ́ọ̀lù Kazim Tiamiyu Kaka àtàwọn míì tí ọlọ́pàá pa sọ̀rọ̀, omijé bọ́ lójú ''Àjọ NERC ti fún Disco láṣẹ láti padà sí owó tàríìfù tuntun iná mọ̀nàmọ́ná'' Ẹ dẹ̀kun lílo Sniper àti Dichlorvos fún ìtọ́jú oúnjẹ- NAFDAC kìlọ̀ Ajọ WAEC gbé èsì ìdánwò ọdun 2020 jáde Tee-Leo Ikoro ni kii ṣe iṣẹ awọn lati ko ọja kuro ni oju popo, amọ o ni o dara kii ijọba ko awọn ọja kuro ni oju popo ki adinku ba ijamba ọkọ ojojumọ.
WHO sọ pe abẹ́rẹ́ ajẹ sara ń dóòlà ẹmi àwọn ọmọ mílíọnu méji si mẹta kákìri àgbáye ní ọdọọdun.
Auxiliary ni A ti n gbadun alaafia nipinlẹ Oyo lati igba ti mo ti n dari igbimọ Alakoso gareeji, mo si n rọ awọn ọmọ igbimọ mi lati lati ri daju pe alaafia naa n tẹsiwaju."
Ẹkún àti ìbànújẹ́ láwọn mọ̀lẹ́bí fi sìnkú ọmọ méje ní Kumba, Cameroon lónìí
Ọkàn mi kò balẹ̀ rárá,yóo ti pẹ́ tó, OLUWA, yóo ti pẹ́ tó?
Ṣugbọn olórí-ogun kan yóo ṣẹgun rẹ̀, yóo sì pa òun náà run.
Ọgbẹni Mohammed gba oye akọkọ nile ẹkọ giga fasiti ninu ẹkọ nipa ile aye(Geography).
Ìran mi ni ó rẹ̀yìn jùlọ ninu ẹ̀yà Manase, èmi ni mo sì kéré jù ní ìdílé wa.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Sunday Igboho: Ẹ fi Ògún búra fún wa láti jà fún ilẹ̀ Yorùbá láì gbé Amotekun sábẹ́ ìjọba Osikoya wipe awọn ile-iwe Girama ti ijọba ati ti aladani wa ninu awọn ile-iwe ti wọn f'ofin de naa kaariri ipinlẹ Kogi.
Makinde fẹ́ san ₦30,000 fáwọn òṣìṣẹ́ l’Oyo, yóò tún kọ́ ọjà ìgbàlódé sí Akẹ̀sán Nkechi ni ifẹ awọn mejeeji bẹrẹ ni kete ti awọn fi oju kan ara awọn, to si ti n gbinlẹ si lati igba naa wa.
Eyi ni iroyin itan ọmọ orilẹede Naijiria kan to ri ifẹ ni orilẹede Kẹnya.
Lati kekere ni awn kan ti n tọju rẹ ti wọn si dagba sẹ́nu ẹ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Minimum wage: Àwọn gómìnà PDP láwọn yóò san #30,000 owó oṣù fáwọn òṣìṣẹ́ 7 Òkùdu 2019 Oríṣun àwòrán, Facecook/Seriake Dickson Awọn gomina labẹ asia ẹgbẹ oṣelu PDP lawọn ti ṣetan lati san ọgbọn ẹgbẹrun un naira owo oṣu to kere julọ fawọn oṣiṣẹ.
Ẹkọ miran ni pe ko yẹ ka maa fi ibi san oore fun alaanu wa ati ọmọ rẹ, boya loju aye rẹ ni abi lẹyin to ku.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ààrẹ Muhammadu Buhari Laarin ọjọ Kinni Oṣu kẹjọ ọdun 1975 si ọjọ Kẹta Oṣu keji ọdun 1976, Ọgagun Murtala Muhammed yan Buhari gẹgẹ bi Gomina awọn ipinlẹ ila Oorun Ariwa papọ ti pe ni North-Eastern States nigba naa lọhun.
Èkó ni olú ilú Nigeria fún ọ̀pọ̀lọpọ̀ ọdún ki àwọn Ijọba Ológun tó kó Olú Ilú Nigeria lọ si Abuja ni bi ọdún mẹrinlélógún sẹhin.
Ọjọ keji ọdun tuntun ni ọkunrin naa ge okun ẹmi ara rẹ kuru, to si gbe oogun apakokoro jẹ.
Àwọn ni ìlànà ati òfin tí OLUWA ti pa láṣẹ fún Mose fún àwọn ọmọ Israẹli, ní pẹ̀tẹ́lẹ̀ Moabu ní ìhà ìlà oòrùn Jọdani, ní òdìkejì Jẹriko.
Ẹ̀ wo àwọn ìgbéṣẹ̀ tí ó ṣeeṣe kí ìjọba àpapọ̀ gbé lórí òfín kónílé ó gbélé ní Eko, Abuja, Ogun AjọAmuṣẹya ti Aarẹ Buhari gbekalẹ lori arun Coronavirus,PTF yoo ṣe ipade lọni lati ṣe agbeyẹwo ofin konile-o gbele ni Naijiria.
Ileeṣẹ to n soju Amerika ni orilẹede Naijiria lo fi ikilọ naa lede ni oju opo ikansiraẹni Twitter wọn.
 ní ìsojú gama ni ilé jíjó , èèyàn pípa ati bẹ ́ ẹ ̀ bẹ ́ ẹ ̀ lọ ṣe sẹlẹ ̀ ní àsìkó rògbòdìyàn yìí .
Ninu idibo gbogbogbo to lọ ni Naijiria ni wọn ti dibo yan Pepperito gẹgẹ bi sẹnẹtọ to n ṣoju ẹkun ila oorun ipinlẹ Eko nile aṣofin agba nilu Abuja.
O wa ninu ibanujẹ latari isẹlẹ yi pẹlu.
Tí a fiṣọwọ́ ní 14:24 11 Òkùdu 201914:24 11 Òkùdu 2019 Ìdìbò ń lọ lọ́wọ́ láti yan olórí ilé aṣojú-ṣòfin Ibo ti n lọ lọwọ bayii lati yan ẹni ti yoo maa dari ile asoju-sofin nile asofin apapọ ile wa.
Ibùdó Amúnáwá kọsẹ́ lẹ́ẹ̀mejì lọ́jọ́ márùn ùn Banki agbayẹ pẹsẹ iranwọ fun Naijiria Òkùnkùn biribiri ni ìjìyà ẹ̀ṣẹ̀ ìjọba ìbílẹ̀ mẹ́fà nílẹ̀ Ìjẹ̀ṣà tó na òṣìṣẹ́ àjọ amúnáwá Ìjọba àpapọ̀ buwọ́lu $1.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Didier Drogba: Agbabọọlu to fí okiki dáwọ ìjà ogun abẹ́lé dúró n'ilẹ baba rẹ 2 Ìgbé 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 27 Ìgbé 2020 Oríṣun àwòrán, others Ni papa isere Al-Merrikh Stadium ní orile-ede Sudan ní iṣẹlẹ kan to mí agbo ere bọọlu n'ilẹ Afrika ti waye.
 awọn òpìtàn yìí lè rò pé bóyá nítorí tí a ti ń pe àwọn Ọba ilẹ ̀ yorùbá ni ìgbákejì òrìṣà ni àwọn náà ṣe rò pé aláayè àkọ ́ kọ ́ rọ ̀ sílẹ ́ ayé lati ọ ̀ run .
Ọmọ ẹgbẹ Afenifere ọhun sọ pe iya n jẹ awọn eeyan, nitori naa o yẹ ki ijọba wa gbogbo ọna lati tan ijiya wọn dipo ko maa ṣina ibọn bo wọn.
Paulu mú Sila ó bá ọ̀nà tirẹ̀ lọ lẹ́yìn tí àwọn onigbagbọ ti fi í lé oore-ọ̀fẹ́ Oluwa lọ́wọ́.
eto aabo to peye fun emi ati dukia awon ara ilu jake-jado orile-ede Naijiria.
Lara awon ti o wa pade aare Muhammadu Buhari ni  asoju orile ede Naijiria fun ilẹ Amerika , Sylvanus Adiewere, Minisita fun oro okeere, Geoffrey Onyama ati minisita fun eto ilera,Osagie Ehanire .
Ọba sì rán ọkunrin meji pẹlu kẹ̀kẹ́ ogun meji láti lọ wo ohun tí ó ṣẹlẹ̀.
Ìwọ̀nyí ni àwọn ìpín 137 àti 138, tí ó gbé àwọn ìpilẹ̀sẹ̀ ìgbàlà fún àwọn òkú kalẹ̀; àti Ìkéde Lábẹ́ Àṣẹ 2, ní kíkéde pé gbogbo ọkùnrin ọmọ Ìjọ tí wọ́n bá yẹ le jẹ́ yíyàn sí oyè àlùfáà láì ka ẹ̀yà tàbí àwọ̀ ara sí.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Àráàlú yarí fún fásitì Babcock fún bo ṣe lé akẹ́kọ̀ọ́ tí wọn bá lòpọ̀ nínú fídíò Àwọn iròyin ẹlẹ́jẹ̀ márùn ún tó fẹ́ẹ̀ tú Nàìjíríà ká Bó ṣe ń wáyé ní Oyo, ló tún ń ṣẹlẹ̀ ní Kano, ilé ẹjọ́ júwe ilé fún Emir mẹ́rin tí Ganduje yan Ẹ wo àwọn ọ̀dọ́mọdé Naijiria tó ń ṣe bẹbẹ nínú isẹ́ aládaní nílé Àwọn agbébọn kọlu Kọmísánà fọ́rọ̀ ilẹ̀ àti ilégbèé ní Ọyọ, awakọ̀ dèrò ọ̀run Èwo nínú àwọn amóhùnmáwòrán yìí lẹ rántí?
"Buhari fi ọ̀kadà, ọkọ̀ àti $500,000 ta orílẹ̀èdè Guinea Bissau l'ọ́rẹ Arsenal ṣẹ́ṣó ìyà, búlálà ẹlẹ́nu mẹ́ta ni Leicester City fi lù wọ́n lálù bami Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Àwọn òbí mi rò pé ẹ̀jẹ́ ti ta sí ọpọlọ mi nígbà tí mo bẹ̀rẹ̀ sí ba ẹranko igbó ṣọ̀rẹ́ ""Àbádofin ọ̀hún kìí ṣe èyí tó tọ̀nà, ó si tún jẹ ṣíṣe àṣojú ará ìlú lọ́nà ti kò tọ, àti pé àṣìlò ìpò gbáà ni."
APC àti PDP takora wọn lórí Olùsirò owó àgba Ọsun tó fisẹ́ sílẹ̀ Májèlé ni àdí-àgbọn, ẹ yàgò fun - Dókítà Àwọn obìnrin tí kò lọ́kọ ń kojú ìsòro ilé gbígbà Ìjì líle pa arẹ̀wà fasiti tó ń ya fọ́tò létí òkun Awọn èèkàn nibi ọdun ijẹṣu naa ṣalaye fun BBC Yoruba lori igbesẹ ọdun naa àti àwọn èèwọ̀ inu rẹ̀ bii bíbẹ́ orí fun ọlọsin to ba gbe imọlẹ to ba ṣubu lasiko ti imọlẹ naa ṣì wà lọwọ rẹ̀.
soro yii  lori ero Twitter  pe ‘‘A gbodo lee  jẹ ki awon omo orile ede Afirika lee maa  rin lati orile ede kan si ekeji laini wahala
Gbogbo ọmọ Israẹli yóo di ẹni àmúpòwe ati ẹlẹ́yà láàrin àwọn orílẹ̀-èdè yòókù.
Gideoni bá kó àwọn eniyan náà lọ sí etí odò, OLUWA bá wí fún Gideoni pé, ẹnikẹ́ni tí ó bá fi ahọ́n lá omi gẹ́gẹ́ bí ajá, yọ ọ́ sọ́tọ̀ sí ẹ̀gbẹ́ kan, bákan náà ni kí o ṣe ẹnikẹ́ni tí ó bá kúnlẹ̀ kí ó tó mu omi.
Àfonífojì tí ó gbòòrò yóo sì wà láàrin rẹ̀ láti apá ìlà oòrùn dé apá ìwọ̀ oòrùn.
’ OLUWA bá dá a lóhùn pé, ‘Ìwọ ni kí o lọ tàn án jẹ, o óo sì ṣe àṣeyọrí, lọ ṣe bí o ti wí.
Ogbeni Atanda fi oro naa mule pe, idije ohun yoo kun fun iko okunrin ati obinrin merindinlogun ti yoo kopa ninu idije naa.
Ṣugbọn àwọn kan wà tí wọn kò lè bá wọn ṣe ọdún náà nítorí pé wọ́n jẹ́ aláìmọ́ nípa fífi ọwọ́ kan òkú.
 folúkẹ ́ ni ó sọ fún ìyá rẹ ̀ pé Àṣàké ń fi kọ ́ kọ ́ rọ ́ dán séèfù wò .
Ẹ̀yin baba, mo kọ ìwé si yín, nítorí pé ẹ ti mọ ẹni tí ó wà láti ìṣẹ̀dálẹ̀ ayé.
Ibikíbi tí ẹ bá wà, tí ẹ bá ti gbọ́ fèrè, ẹ wá péjọ sọ́dọ̀ wa.
Tó bá di ìgbà náà, àwọn ìlú olódi ńláńlá wọn yóo dàbí àwọn ìlú tí àwọn ará Hifi ati àwọn ará Amori sá kúrò níbẹ̀, nígbà tí àwọn ọmọ Israẹli gbógun tì wọ́n; gbogbo rẹ̀ yóo di ahoro.
 O si gboriyin fun ijọba fun ṣiṣe agbekalẹ
Ó ń kó ọ̀wọ́ eṣú jọ ní àkókò tí koríko ìkẹyìn bẹ̀rẹ̀ sí yọ sókè, lẹ́yìn tí wọ́n ti gé koríko ti ọba tán.
Lataari ababo ipade ohun, egbe awon osise kede ojo merinla fun ijoba lati tun sepade lori oro naa eleyi ti yoo pari ni asale ojoRu(Wednesday), ti n se ale oni.
Lorilẹede India, ọmọ ọdun meje ti gbe baba rẹ lọ agọ ọlọpaa nitori pe ko kọ ile igbọnsẹ fun wọn ninu ile.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ìdílé tí ọkọ da ọmọ síta tóríi ojú Búlùú tí wọ́n ní bá BBC sọ̀rọ̀ Bẹẹ ba n fọkan tẹle wa bọ lati bii ọsẹ meji sẹyin, la ti n mu iroyin wa fun yin nipa ipo ti Risikat ati ọmọ rẹ obinrin mejeeji wa lẹyin ti to kuro nile ọkọ rẹ nitoriidẹyẹsi pe o n i oju buluu.
Ewé obì, ewé ọ̀gẹ̀dẹ̀, ewé kókò, àti àwọn ewé yókù ni iwúlò wọn ni ilé tàbi lóko.
Ọpọ lo bẹrẹ si ni fi West to jẹ adilemu ẹgbẹ agbabọọlu Super Eagles ṣe lẹyin ti oludije ẹgbẹ oṣelu Democrat, Joe Biden wọle ibo ọhun tan.
Sugbọn ninu ifọrọwerọ rẹ pẹlu wa ni aarọ ọjọ Ẹti, Risikat ni oun ati baba Kaosara dijọ ya fọto papọ ni, ile awọn si ni oun si wa.
5 5838 Orilẹede Guyana 153 19.
Níbo ni kí n ti rí ẹran tí yóo tó fún àwọn eniyan wọnyi?
”OLUWA rí i pé kò sí ìdájọ́ òdodo,ó sì bà á lọ́kàn jẹ́,
To fi mọ ajọ adojutofop ilera, National Health Insurance Scheme.
Bí oní ṣe wá jẹ́ ọgbọ̀n ọdún gééré gé ti Samuel Okwaraji papo dà ajọ NFF náà ń selédè lẹ́yin rẹ̀.
Nigba ti o lọ sile iwe ni England, ni oju rẹ ṣi si bi àwọn oyinbo kan ṣe n huwa ìdẹ́yẹsí si àwọn alawọ dudu.
Wọ́n bá bẹ̀rẹ̀ sí wí láàrin ara wọn pé, “Nítorí a kò mú oúnjẹ lọ́wọ́ wá ni ó ṣe sọ bẹ́ẹ̀.
Nígbà náà ni OLUWA la kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ náà lóhùn ó sì sọ̀rọ̀ bí eniyan, ó sì sọ fún Balaamu pé, “Kí ni mo fi ṣe ọ́ tí o fi lù mí nígbà mẹta?
Aarẹ orilẹede Naijiria, Muhammadu Buhari ti sọ fun awọn ẹbi awọn ọmọ ile iwe awọn obinrin Chibok ni ilu Borno wi pe oun ko gbagbe awọn ọmọ naa to wa ni igbekun Boko Haram.
Ẹ̀mí rẹ̀ yóo gùn,a óo máa fi wúrà Ṣeba ta á lọ́rẹ,a óo máa gbadura fún un nígbà gbogbo;a óo sì máa súre fún un tọ̀sán-tòru.
Àlàáfíà kọ́ ni ìyàwó rẹ wà?
Obinrin naa tẹ siwaju pe, lara apẹẹrẹ ti oun n ri pe oun ni arun ikọ ife ni pe oun n wukọ lemọlemọ, oun kii sun loru tori ikọ wiwu, oun n laagun pupọ, ounjẹ kii wu oun jẹ, ti oun si n ru.
Beauty tips: Ṣé ẹ gbà pé obìnrin lè kun ojú láàrín ìṣẹ́jú mẹ́ta?
Ìmáámù tó gbẹ̀mí èèyàn là yóò bọwọ pẹlú Buhari Ìpínlẹ̀ Kaduna dá àwọn olùkọ́ tuntun dúró Ọwọ́ ikọ̀ aláàbò STF tẹ afurasí mẹ́jọ tó lọ́wọ́ nínú ìpànìyàn lemọ́-lemọ́ọ Gúúsù Kaduna Gómìnà ìpínlẹ̀ Kaduna, El-Rufai fi ipò míì dá Sanusi lọ́lá Ǹ jẹ́ o mọ̀ pé oṣù ojú ọ̀run táwọn Mùsùlùmí ń lò ti wà saájú Ànọ́bì?
Èèyàn 13 mííràn tún ti lùgbàdì ààrùn Coronavirus ní Naijiria Ń ko tọrọ agbe fún ìyá Awero, Larry àti bàbà Feyikọgbọn, ẹ má sọ ire di ibi mọ́ mi lọ́wọ́ - Foluke Daramola 82% ọkùnrin ní kó mọ̀ pé òun ní àìsàn jẹjẹrẹ asẹtọ ní Naijiria Àwọn Alákòso gárèjì ló kó ìbọn àti àdá tọ ọlọ́kadà wá ní Soka-Alága ẹgbẹ́ ọlọ́kadà Ọyọ Ilẹ Yuroopu ni ajakalẹ yi ti gbogo julọ ti o si jẹ wi pe ni Latin Amẹrika orileede Amẹrika ati ilẹ larubawa,iye awọn to n ko arun naa pọ si.
Níbẹ̀ ni ó wà lábẹ́ ìtọ́jú fún ẹgbẹfa ọjọ́ ó lé ọgọta (1260).
Sowore ni awọn oloye ẹgbẹ oṣelu ZLP ni apapọ ti fun Agboola ni anfaani lati dije sipo gomina labẹ ẹgbẹ naa.
Awọn orilẹ-ede kan to kogba wọle nigba ti awọn to yege n tẹsiwaju ninu ipele Komẹsẹ- o- yọ-danu.
Ti Ọlọrun ni àwa; Ẹni tí ó bá mọ Ọlọrun ń gbọ́ tiwa; ẹni tí kì í bá ṣe ti Ọlọrun kò ní gbọ́ tiwa.
Laye atijọ, alẹ ọjọ igbeyawo jẹ ọjọ ti ọmọbinrin maa n fi sọkan, ti yoo si maa fi oju sọna fun pẹlu awọn obi ati ẹbi rẹ lapapọ.
Ẹ wá sanra bíi mààlúù, bẹ́ẹ̀ sì ni ọjọ́ tí wọn yóo dumbu mààlúù ló kù sí dẹ̀dẹ̀ yìí.
Ileeṣẹ ologun ninu atẹjade kan lati ọdọ ọgagun Sani Usman to jẹ gabẹnusọ wọn ni niṣe ni ajọ naa n gbero lati tu Naijiria ka.
Asán a máa pọ̀ ninu ọ̀pọ̀ ọ̀rọ̀; kì í sì í ṣe eniyan ní anfaani.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Iléẹjọ́ fi Ọ̀jọ̀gbọ́n tó bèérè fún ìbálòpọ̀ ní fásitì OAU pamọ́ sọ́gbà ẹ̀wọ̀n Ìyanṣẹ́lódì òṣìṣẹ́ ilé aṣòfin bẹ̀rẹ̀ ní pẹrẹwu nílé aṣòfin Nàìjíríà Amnesty International fẹ́ tú Nàìjíríà ká —iléesẹ́ ológun Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Ṣugbọn àwọn eniyan yóo máa gbé ilẹ̀ Juda títí lae,wọn óo sì máa gbé ìlú Jerusalẹmu láti ìrandíran.
Orìlẹ-èdè mẹrindínlọgbọn tí ọmọ Nàìjíríá lè wọ̀ láì ní àṣe ìwé ìgbélùú O wa parọwa si gbogbo awọn ololufẹ rẹ pe ki wọn ma ṣe sọrọ alufanṣa pada si ẹnikẹni to ba sọ iru ọrọ bẹẹ.
Sanwo-Olu ni iṣẹlẹ naa ṣeni laanu pupọ, o ni niṣe lo dabi ẹni pe ogun ṣẹṣẹ ja tan nibi ti iṣẹlẹ ti ṣẹlẹ.
Mò ń bọ̀ wá gbá gbogbo orílẹ̀-èdè ati ẹ̀yà jọ.
Wọ́n dínwó rẹ̀ kù níbi tí mo ti ràá ni.
Ni wọn ba jọ n fa a.
bẹ́ẹ̀ ni kò sì ní sí ìgbà kan tí ẹnìkan ninu àwọn alufaa, ọmọ Lefi, kò ní máa dúró níwájú òun láti rú ẹbọ sísun ati ẹbọ ohun jíjẹ, láti máa rú ẹbọ títí lae.
Ṣugbọn ki ajakakẹ aarun covid-19 to de ni gbogbo eleyi.
Kora ọmọ Iṣari láti inú ìdílé Kohati ọmọ Lefi, pẹlu Datani ati Abiramu àwọn ọmọ Eliabu, pẹlu Ooni ọmọ Peleti láti inú ẹ̀yà Reubẹni gbìmọ̀ pọ̀, 
Shehu fikun pe, ko si aniani pe aseyọri nla naa yoo mu ilọsiwaju ba eto ayẹwo fawọn araalu, lati mọ awọn ti ina arun Coronavirus ti bọ si abẹ asọ wọn.
Ọ ̀ rọ ̀ tí a pè ní soṣiọ ́ lọ ́ jì lítíṛọ ̀ jẹ ́ ọ ̀ rọ ̀ tí onímọ ̀ èrò ìjìnlẹ ̀ kan ti à ń pè ní taine ọmọ orílẹ ̀ èdè faranse rọ fúnra rẹ ̀ .
Gomina Ipinlẹ Ondo, Oluwarotimi Akeredolu ti pasẹ fun ile-isẹ ọlọpaa ni ipinlẹ Ondo latiri wi pe wọn wa awọn ẹni to pa ọmbinrin ogun ọdun ni ipinlẹ Ondo.
Tí àwọn ìyá wá méjèèjì bá sì ń sọ̀rọ̀, Tinubu yóò rán mi láti lọ ra èédú tí yóò fi lọ aṣọ.
O jọ bi ẹní pe àwọn olólùfẹ́ Manchester United ko ni fi bẹ́ẹ̀ ba Chelsea kẹ́dùn bí ìdíje yìí ṣe jẹ èsì tó tíì dára júlọ ni old Trafford pẹ̀lú Chelsea láti ọdun 1965 Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Man Utd sign defender Maguire from Leicester hand for £80m5 Ògún 2019 Lukaku: Inter Milan don sign Belgium striker from Manchester United for £74m8 Ògún 2019 Alex Iwobi: Di midfielder transfer from Arsenal make Nigerians squeeze face9 Ògún 2019 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Ìjọba orílẹ̀-èdè Naijiria tí kéde àwọn ènìyàn tuntun tó tún ṣẹ̀ṣẹ̀ kó ààrùn coronavirus, ní báyìí, ènìyàn ẹgbẹ̀rún mẹ́rin lé ni ọ̀kànléláàdọ́jọ (4151) to ti ni ààrùn náà ni Nàìjíría.
O ni ile oun to wa ni Ikoyi ni oun ṣi wa titi di asiko yii ati pe ile oun ko si ni agbegbe Banana Island rara bikoṣe Ikoyi.
Ni ibere pepe osu kewaa yii ,ni won ta ile-ise Ologun lolobo pe  won ri oku ogagun naa ninu koto kan to wa ni Dura ni ijoba ibile Jos, nibi ti won ti ri oko ogagun naa ati awon oko merin miiran.
Ọjọ ti wọn ba lọ si ojubọ Ọṣun Oṣogbo yii ni asekagba, ti ọpọ eeyan jakejado Naijiria ati loke okun yoo si pejọ si ojubọ Ọsun lati beere ohun kan tabi omiran tabi lati gbe bi ayẹyẹ naa se n lọ fun araye.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Child Education: Mílíọ̀nù mẹ́rìndínlógún ọmọdé ni kò sí níléèwé lórílẹ̀èdè Nàìjíríà 25 Agẹmo 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Ninu igba miliọnu awọn eeyan to n gbe lorilẹede Naijiria loni, njẹ o mọ pe miliọnu mẹrindinlogun awọn ewe ni ko ri ileewe lọ bayii?
"Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Yoruba Taboo: Èèwọ̀ ni fún ọba láti gbé Bibeli tabi Kurani dání dípò ifá- Elebuibon, Agẹṣin Àdìmúlà 29 Bélú 2020 Oríṣun àwòrán, Alaafin of Oyo oba adeyemi lamidi III ""Ọpọlọpọ ọba ti a n pe ni ọba ni ilẹ Yoruba bayii ni ko ba"" iyẹn ni pe wọn kii ṣe ọba."
Ní àkókò ìgbà tí igi ń rúwé, tí ó jẹ́ àkókò tí gbogbo àwọn ọba máa ń lọ sójú ogun, Dafidi rán Joabu ati àwọn ọ̀gágun rẹ̀ ati àwọn ọmọ ogun Israẹli jáde.
 Matt Grimes gba ami-ayo akoko wo le ni ogun iṣẹju ti wọn bẹrẹ ifesewonse
" Wo ẹ̀bùn àti owó tí àwọn olùkópa ti jẹ lórí ètò BBNaija season 5 Wo ọ̀nà àbáyọ sí bo ṣe ń han‘run Mi o fi ìgbà kankan sọ pé Buhari ni yóò jẹ ààrẹ kẹ́hìn ní Nàìjíríà - Akintoye Lori bi oun ati ọkọ rẹ ṣe jẹ ẹlẹsin ọtọọtọ, Sẹnetọ Tinubu sọ pe oun ko ri bi nkan babara nigba ti oun ati ọkọ rẹ pade.
 Bẹẹ naa lo tun kan sara si awọn ibatan rẹ fun aduroti wọn."
Fatomilọla, tii se onimọ nipa asa ati ede Yoruba sọ pe, bi igba ti eeyan tasẹ agẹrẹ ni igbesẹ alaafin naa.
Gbogbo irú ẹ̀ṣẹ̀ tí baba Abijamu dá, ni òun náà dá.
Àwọn ọmọ tí Dafidi bí ní Jerusalẹmu nìwọ̀nyí:Batiṣeba, ọmọbinrin Amieli, bí ọmọ mẹrin fún un: Ṣimea, Ṣobabu, Natani ati Solomoni.
O ba ajọ naa ṣe dunadura lodun 2008 lati san lara owo to ko jẹ pada ki o si maa.
“Tí ẹ̀yin ọmọ Israẹli bá yá ara yín lówó, tabi oúnjẹ tabi ohunkohun, ẹ kò gbọdọ̀ gba èlé lórí rẹ̀.
Dafidi kò ka àwọn tí wọn kò tó ọmọ ogún ọdún, nítorí Ọlọrun ti ṣe ìlérí pé òun yóo mú kí àwọn ọmọ Israẹli pọ̀ bí ìràwọ̀ ojú ọ̀run.
Ǹjẹ́ kùmọ̀ lè mú ẹni tí ó ń lò ó lọ́wọ́,tabi kí ọ̀pá mú ẹni tí ó ni í lọ́wọ́?
Azeez Ijaduade: Oríṣun àwòrán, Azeez ijaduade Azeez ni ọmọkùnrin Dimeji Ijaduade, tíì ṣe ilumọọka osere tíátà láti Abeokuta.
Farao bá pàṣẹ fún àwọn iranṣẹ rẹ̀ nípa Abramu, wọ́n sì rí i pé Abramu jáde kúrò nílùú, ati òun ati aya rẹ̀, ati ohun gbogbo tí ó ní.
Ọjọbọ ni ileeṣẹ eto ilera Naijiria fidirẹmulẹ pe ẹnikan ti gbe aarun naa wọ ipinlẹ Eko.
Agbára ati ipá wà ní ìkáwọ́ rẹ, kò sì sí ẹni tí ó tó dojú kọ ọ́.
nítorí pé ẹ̀mí eniyan níye lórí pupọ.
Eyi ni awọn Aarẹ ọna kakanfo marun to jẹ kẹyin: Àkọlé àwòrán, O le ni irinwo ọdun sẹyin ti aarẹ kakanfo akọkọ jẹ nilẹ Yoruba Ojo Aburumaku Ojo Aburumaku ni Aarẹ Ọna kakanfo kọkanla.
Ribery so pe,“inu mi dun pe maa tun kopa fun iko agbaboolu yii fun saa kan si,”“Munich ti je ile fun emi ati ebi mi lati ojo pipe, bee si ni  o je iwuri fun mi pe ma tun.
BBC Yorùbá: Ọ̀pọ̀ òjò ti rọ̀, ilẹ̀ ti fimu láàrin ọdún kan BBC Yorùbá
O Tokode, tileẹjọ giga apapọ to wa nilu Benin, ti wọn yọ kuro lẹnu isẹ.
Ikechukwu Ogah Mohammed Musa Bello Sharon Ikeazor Adamu Adamu Ambassador Maryam Katagun George Akume Mustapha Baba Shehuri Goddy Jedy Agba Ogbonnaya Onu Osagie Ehanire Clement Ike Richard Adeniyi Adebayo Geoffrey Onyeama Ali Isa Pantami Emeka Nwajiuba Suleiman Adamu Zainab Ahmed Muhammad Mahmood Sabo Nanono Major General Bashir Salihi Magashi Abubakar Malami Ramatu Tijjani Mohammed H.
“Ọdọmọkunrin kan wà níhìn-ín tí ó ní burẹdi bali marun-un ati ẹja meji, ṣugbọn níbo ni èyí dé láàrin ogunlọ́gọ̀ eniyan yìí?
"Tí a fiṣọwọ́ ní 10:58 29 Èbibi 201910:58 29 Èbibi 2019 Àwọn ará Kwara ni ""Idẹra dé"" Lara awọn esi ẹyin ololufẹ wa rèé lójú opo Facebook bbcnewsyoruba BBCCopyright: BBC Esi awọn ara KwaraImage caption: Esi awọn ara Kwara Article share tools Facebook Twitter ṢàpínlòView more share options Share this post Copy this linkKà síwájú síi nípa àwọn ìtọ́kasí wọ̀nyí."
Bẹẹ lọrọ ri fun gbajugbaja osere tiata lobinrin, Kẹmi Afọlabi Adesipẹ, ẹni to dubulẹ aisan nilu Mecca lasiko to n kopa ninu isẹ Hajj fun tọdun yii.
O kẹkọọ jade nile iwe Obafemi Awolowo to wa ni ilu Ile Ife, nibi to ti darapọ mọ ẹgbẹ awọn to n ja fun ẹtọ awọn akẹkọọ.
Lodun 2010 ni won da egbe alajeseku HAAB sile lati fi maa ran awon obinrin lowo nipa ipese owo yiya ti ko ni ra fawon obinrin ninu okowo eto ogbin.
Kí ló pa obìnrin àkọ́kọ́ tí ó wa ẹlikọ́pítà Iléesẹ́ ọmọogun òfúrufú ní Nàìjíríà?
Ààrẹ Buhari ṣí ilé iṣẹ́ àti afára ní ìpínlẹ̀ Ondo
Ki aarẹ gba awọn ọdọ ipinlẹ Borno si ileeṣẹ ologun lati lee kun wọn lọwọ.
Nígbà tí Esau di ẹni ogoji ọdún, ó fẹ́ Juditi, ọmọ Beeri, ará Hiti ati Basemati, ọmọ Eloni, ará Hiti.
Amọ ijọba sọ pe ọna aitọ ni Oloye Olusola Saraki fi gba ilẹ naa nigba naa nitori ko si akọsilẹ kankan to ṣafihan pe o sanwo fun ijọba.
Oríṣun àwòrán, other Àkọlé àwòrán, Falz ni ki araye wo Naijiria ti a n gbe loni ninu awo rẹ kan 6) Olamide - Science Student Orin yii wà lára orin to kọkọ jade ni 2018 ni eyi to da wahala nla silẹ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, The Polytechnic Ibadan: Ẹ̀rọ abẹ́lé tó ń fọ ọwọ́ àti ‘Ventilator’ ló ṣẹ̀ṣẹ̀ gbé jáde Minisita feto idajọ ati agbẹjọro agba, Abubakar Malami lo sisọ loju ọrọ yii fun ileesẹ akoroyinjọ Reuters.
0 100489 Orilẹede Kuwait 910 22.
Mo fẹ́ fi àkàrà òyìnbó ọjọ ìbímí tọrẹ- Bobrisky Àjọ Commomwealth gbọ̀dọ pé ìpáde pàjáwìrì lori ọ̀rọ̀ Brexit- Wole Soyinka Lily wa parọwa pe ki awọn eeyan fọwọ wọnu lori isẹlẹ naa, tori ta ba ro didun ifọn, a họra de egungun.
Ààrẹ Muhammadu Buhari buwọ́lu owó ìṣúná ọdún 2019 Bóò ṣe lè yẹra fún ikú nígbà òjò - Onímọ̀ Ehi Iden Kò sí àyè fún fíìmù eré ìfẹ ṣíṣe ni Kannywood mọ́ Aisha Buhari ké gbàjare pé ètò ìjọba Buhari kò ṣànfàní f'óbìrin @Ezbaronkings sọrọ loju opo Twitter rẹ wi pe ki wọn bu ajọ ọtẹlẹmuyẹ ilẹ Amẹrika FBI gbọ ki wọn le f'ofin de minisita lati lọ si orilẹede Amẹrika.
 ' awon ' ti kọrin pẹ ̀ lú ọ ̀ pọ ̀ lọpọ ̀ àwọn olórin hip hop ilẹ ̀ ̀ amẹ ́ ríkà bíi : little brother , common , epmd , mc lyte , ati oddisee .
Bo ṣe yẹ ko jẹ gangan ni wipe ẹnikẹni to ba ru ofin irina gbudọ san faini si asuwọn ijọba ki wọn si gba iwe 'mo sanwo' ṣugbọn Ibukun ni wọn kan gba owo lọwọ awọn ni lai si akọsilẹ.
 ju 99 % ìṣẹ ̀ lẹ ̀ dìgbòlugi ní àwọn orílẹ ̀ èdè tí ajá ti ń ní dìgbòlugi , ìbùjẹ ajá ni o ń fà .
 Ọkọ ̀ náà kọ lu kòtò , ó sì tàkìtì sí òdìkejí , ni ẹsẹ bàtà ọdúrún ( 91m ) kí ó tó dé àlìkámà ààyè tó ti dúró .
Taní Ibidunni Ighodalo tí gbogbo ọmọ Nàìjíríà ń selédè lẹ́yìn rẹ̀ 'Ọlọ́pàá ló ń pa wá, kìí ṣe coronavirus' Èèyàn 403 ló lùgbàdì àrùn Coronavirus ní Naijiria ní Ọjọ́ Isinmi Àwọn olùfẹ̀hònúhàn kọ etí ikún s'íkìlọ̀ ọlọ́pàá ṣe ìwóde ní London Wolii Alfa Babatunde Sọtitobirẹ atawọn oṣiṣẹ ẹka ileejọsin awọn ọmọde ni ileejọsin naa ni wọn n jẹjọ ti ile ẹjọ si n gbọ awijare awọn olupẹjọ fun ijọba lọwọ bayii.
Ọjọ Kẹẹdọgbọn osu kẹfa ọdun 2020 si ni Akanji ‘ọmọ ọlọdun mẹjọ’ ki aye pe o digbose, Ajimobi si wa lara awọn eeyan jankan-jankan ti wọn tẹri gbaṣọ lọdun 2020.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Human trafficking: Ààrẹ Buhari, ẹ̀yin gómìnà ìpínlẹ̀ Yorùbá, ẹ rántí wa ní Oman, àwọn ọmọ Gbajabiamila fẹsun kan Akpabio pe ọgbọn olumọkọrọyi lo n lo lati moribọ ninu awọn ẹsun ti wọn fi kan an, bi bẹẹ kọ, ko fi orukọ awọn to n naka si lede.
Kò sí ọkùnrin tí yóò fún obìnrin tó halẹ̀ bíi tèmi lówó - Lizzy Anjorin Ọ̀jọ̀gbọ́n fásitì OAU pàdánù ẹ̀mí lópoópónà Benin sí Auchi.
chidume Àkọlé àwòrán, Ohun to ṣẹku ree lara ẹrọ ikọlẹ (Tractor) lẹyin ti awọn alaburu ṣe apata rẹ tan ni Yola Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Apo iresi,semo, ati pali indomie wa lara ohun ti wọn fi bẹrẹ ki ọpọn tosun siwaju Oríṣun àwòrán, ejiofor.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Serena Williams gba ife ẹ̀yẹ àkọ́kọ́ láàrin ọdún mẹ́ta sẹ́yìn 12 Sẹ́rẹ́ 2020 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Serena Williams na Jessica Pegula ni Auckland pẹlu 6-3; 6-4 Ife ẹyẹ akọkọ ni yii ti Serena Williams maa gba laarin ọdun mẹta.
'Ọ̀rọ̀ Amotekun ti dàrú bíi ẹsẹ̀ télọ̀ ní ìpínlẹ̀ Oyo' Tinubu kò ṣékú, kò ṣé ẹyẹ, o n dibọn ní lórí ọ̀rọ̀ ikọ̀ Amotekun - Fani Kayode Bí òṣìṣẹ́ Amotekun bá fi orúkọ sílẹ̀ lórí ayélujára, àwọn ọ̀daràn yóò tètè fojú hàn - Oludari Amotekun l'Oyo Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'ìjà ṣẹlẹ̀ láàrín èmi àti ọ̀gá mi ní Lebanon tórí mi ò lè dá N300K padà' Ẹ̀yin gómìnà, Ifá nìkan ló le tọ yín sọ́nà láì kùnà lórí Amotekun - Babaláwo Akoda Awo kin Sunday Igboho lẹ́yìn pé ìṣẹ̀ṣe nìkan ló le ṣe ètùtù láti dẹ́kun ọ̀dàlẹ́ nínú Amotekun Dandan ni pe ki ijọba beere lọwọ awọn babalawo lori ọrọ Amọtẹkun, bii bẹẹ kọọ, eto naa ko le kẹsẹjari.
William O’Loughlin ti o je onimo lori eto idokowo nile-ise Rivkin Securities so pe, “iduro deedee ati akosile ise to yanranti seese ko satileyin fun owo ori oja naa”.
Ọrọ yi ko ṣyin bi fidio kan to ṣafihan bi o ṣe n fi ohun mimu naa la ọmọ alagbe kan to n tọrọ jẹ lọwọ rẹ loju ninu ọkọ lasiko sunkẹrẹ fakẹrẹ ṣe gbode.
Obasanjo bẹ̀rẹ̀ ọ̀sìn ẹja 50,000 ní oko rẹ̀ láti dènà ebi Yoruba ni ati okeere ni oloju jinjin ti n mu ẹkun sun, bẹẹ si ni igi gogoro ma gun mi loju, ati okeere la ti n lọ ọ.
Òun alára wà pẹlu àjàgà mààlúù tí ó kẹ́yìn, ó ń fi í kọ ilẹ̀.
 fún àpeere omo ni olórí fún ( 7a ) àti ( 7b ) àpólà orúko sì ni méjèèjì .
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ajimobi: Obaseki, Ambode àtàwọn gómìnà míràn tí tírélà gba ààrín àwọn àtàwọn bàbá ìsàlẹ̀ wọn kọjá 18 Òkùdu 2020 Oríṣun àwòrán, Twitter/APC Àkọlé àwòrán, Idibo aarẹ ọdun 2023 Awọn ‘Baba Isalẹ’ ni eto oṣelu Naijiria ni ọpọlọpọ eniyan gbagbọ wi pe wọn kii dije dupo fun ara wọn, Amọ awọn ni o maa n sọ nipa ẹni ti yoo bori tabi ti yoo kuna ni idibo sipo lagbegbe wọn.
Àwọn orílẹ̀-èdè yóo dààmú nígbà tí wọ́n bá gbọ́ tí òkun ń hó, tí ó ń ru sókè.
Oshoala fi idunnu re han lori ero ayelujara(Twitter) re, leyin
Kí ẹ rí i pé ẹnikẹ́ni kò fi burúkú gbẹ̀san burúkú lára ẹnikẹ́ni.
Awọn ọrẹ iyawo mẹwa pẹlu ọmọ iyawo lọkunrin ti ọjọ ori gbogbo wọn ko ju ọdun mẹjọ lọ ni yoo duro ti iyawo tuntun Oríṣun àwòrán, OLI SCARFF Àkọlé àwòrán, baba ọkọ ni yoo fi iyawo fun ọmọ rẹ dipo baba iyawo Lara awọn wọnyii ni Ọmọọbakunrin Goerge ati Ọmọọbabinrin Chalotte yoo wa.
Ẹlomiiran to n jẹ orukọ kan naa ti ọjọ ori wọn ko jina si ara wọn ni wọn fẹ parọ kindirin rẹ kawọn dokita naa to lọ fun ẹni ko ni aarun kindirin.
Ọwọ́ Interpol àti ọlọ́pàá Nàìjíríà ti tẹ ọmọ Nàìjíríà mẹ́ta tó lu èèyàn 50,000 ní gbájúẹ̀ Iléeṣẹ́ ọlọ́pàá palẹ̀ òkú ọmọ ọjọ́ kan mọ́ lẹ́yìn t́i wọ́n jùú sórí ààtàn Fatai Rolling Dollar, Ọmọ ìdílé oyè tó gbé igbá orin tí Ebenezer Obey ń ṣiṣẹ́ lábẹ́ rẹ̀!
Nigba ti o n soro loruko awon igbimo Olubadan leyin
Nígbà tí ó ṣe, àwọn ará Filistia kó ara wọn jọ láti bá Israẹli jagun.
" Ninu ọrọ rẹ, Aarẹ ileegbimọ aṣofin agba, lorilẹede Naijiria.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: 'Ó wu ìyá mi láti kú lásìkò Ramadan ni' Orí kó Ọ̀sinbajo yọ lọ́wọ́ ìjàmbá bàálù Zuma fojú ba ilé ẹjọ́ lórí ẹ̀sùn ìwà ìbàjẹ́ Ọbasanjọ figbe ta pé Buhari fẹ́ gbé òuń Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí kan sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
Àkọlé àwòrán, Onaiyekan rọ ijọba lati 'tun Naijiria ṣe'  Ma jẹ ki n pe aja lọbọ, oju n gba mi ti, oju n timi- emi iranṣẹ Ọẹọrun lati ilu nla bii Abuja, mo n lọ ni oju popo ni ilu Rome, Milan, Naples, ki n si maa ri awọn ọmọ mi ni oju popo fun tita,"" Ẹniọwọ naa fi to BBC leti lẹyin ipade oniroyin wọn naa."
Idẹ ni wọ́n fi ṣe gbogbo àwọn èèkàn àgọ́ náà, ati ti gbogbo àgbàlá rẹ̀.
Àwọn ìpińlẹ̀ to kù ni orílẹ̀-èdè Nàìjíríà jẹ́ Oyo to ni ènìyàn mọ́kandinlógún, Ondo ènìyàn mẹ́rìnlá, Abia, Enugu àti Kaduna ni ènìyàn mẹ́tàlá.
Widada bimọ fun ọkọ rẹ tẹlẹ to ku sinu ijamba ọkọ baalu kan ki Al-Bashir to fẹ.
•Ipinlẹ Cross Rivers •Ipinlẹ Kogi Lati igba ti Covid-19 ti bẹrẹ ni Naijria awọn ipinlẹ mejeeji wọn yi gbe awọn igbesẹ kan lati ma se jẹ ki o wọ ọdọ wọn ti wọn si ti n gbaradi de bi o ba fi le wọ ọdọ wọn.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ifọrọwanilẹnuwo pẹlu Ọjogbọn Wọle Soyinka Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Aarẹ Donald Trump to n dari ilẹ Amerika ati iyawo rẹ, Melania Trump ni wọn jọ de si UK bayii.
Ilé oúnjẹ ni Akin àti Ilésanmí ti kọ́kọ́ pàdé rẹ̀.
Wọn bi Idi Amin ni ọdun 1925, o si darapọ mọ ẹgbẹ ọmọ ogun labẹ iṣejọba ilẹ Gẹẹsi lọdun 1945.
 inú n rògbodìyàn yìí ni ó ti wá ìyá rẹ ̀ tì , tí bàbá rẹ ̀ náà si báa run .
Oríṣun àwòrán, Nike/Twitter Àkọlé àwòrán, Asọ olomi aro yi dara pupọ lọrun Mikel Obi Ileesẹ Nike lo gba ipo Adidas, to n ran asọ fun Super Eagles tẹlẹ Orilẹede Naijiria nlo ileesẹ aransọ Nike lati pese asọ ere bọọlu fun Super Eagles lẹyin ti ileesẹ aransọ Adidas ti pese asọ jẹẹsi fun ẹgbẹ agbabọọlu ilẹ wa naa fun ipolongo idije ife ẹyẹ agbaye meji gbako, eyiun lọdun 2010 ati 2014.
Iroyin so pe, awon ina ti won pese nipase eedu ni wakati kookan je egberun lona merinlelogorin 84,026 MWh, nigba ti eyi ti won fi omi pese je egberun lona mokanlelogun 21, 126 MWh ni wakati kookan.
OLUWA ti sọ ìṣẹ́gun rẹ̀ di mímọ̀,ó ti fi ìdáláre rẹ̀ hàn lójú àwọn orílẹ̀-èdè.
Ewe, iko agbaboolu Pleateau United ti won wa lori oke tente tabili idije NPFL bayii, ni ajo CAF ti fofin de lati ma se gba ifesewonse Kankan lori papa naa, latari ipo ti o boju mu ti papa isere ohun wa bayii, ayafi bi won ba satunse si papa isere naa, ni eyi ti ise si tin lo lori re bayii.
Àní, o ti ba gbogbo ohun ìjà rẹ̀ jẹ́,o kò sì ràn án lọ́wọ́ lójú ogun.
Bayii, Joshua ti ṣetan nile ẹkọ giga fasiti Oxford.
Eeyan to ba ti lo ọkọ ri tabi to jẹ olowo nigba aye rẹ ni wọn maa n fi posi ọbọkun ọlọyẹ sin.
Ọrọ naa di awuyewuye, ti wọn si ri iwa gomina naa bii ọyaju si Olubadan, ti igbesẹ naa si pin igbimọ Olubadan si meji di oni oloni.
Bi a ko ba gbagbe, awọn adigunjale naa ko ibọn ati awọn ohun ija oloro miran lọwọ, ti wọn si yabo ile ifowopamọ First Bank to wa ni Idoani lọjọ Kẹjọ osu Kerin ọdun 2019.
A ko ri arigbamu ohunkohun lori ayelujara Instagram rẹ.
Akitiyan ọmọ'ṣẹ́ mi tó wà lára àwọn tó jí ìbejì mi gbé kò kéré nígbà tí á n wá wọn- Akeugbagold Ọlọ́pàá ṣ'orò alẹ́ ẹrẹbẹ̀ fáwọn akọ̀ròyìn, dókítà Ko din ni aadọta awọn dokita , oniroyin atawọn oṣiṣẹ ẹka to ṣe koko miran lasiko ajakalẹ arun coronavirus yii ni awọn ọlọpaa ni ipinlẹ Eko ti fi panpaẹ ofin mu bayii lọjọ Iṣẹgun ni ibamu pẹlu aṣẹ kan ti ọga ọlọpaa lorilẹede Naijiria pa.
Kí àwọn ọ̀pá yìí máa wà ninu àwọn òrùka tí ó wá lẹ́gbẹ̀ẹ́ àpótí yìí nígbà gbogbo, kí ẹnikẹ́ni má ṣe fà wọ́n yọ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Njẹ ọ mọ̀ pé mímí afẹ́fẹ́ tí kò dára lè fa àìsàn?
"Wọ́n fún obìnrin kan lọrùn pa, awuyewuye ti ń wáyé Àlàyé rèé lórí bí wọ́n ṣe pa Ebila, olórí àwọn ""One million boys"" n'Ibadan Sotitobire: Ẹlẹ́rìí mẹ́rìn ló tẹ̀lé Alfa Babatunde wá síwájú ilé ẹjọ́ lonìí Ààrẹ Muhammadu Buhari gbè sẹ́yìn Keyamo lórí ètò ìṣẹ́ 774,000 Ọkan lara awọn ọmọ orilẹede Naijiria kan loju opo Twitter @Mochevious kọọ soju opo naa pe, baba Adeboye i ba ti sọ pe "" Ku ọjọ ibi ẹran ninu ẹran ara mi"" ko si fi mọọ bẹẹ."
Ìpínlẹ̀ Oyo àti Eko kò nífẹ̀ẹ́ láti gba 'Ruga Settlement' láyè Ìdí rèé táwọn ọmọ Nàíjíríà kan ṣe ń tako ìdásílẹ̀ ‘Ruga Settlement’ Ẹ má dá NEF lóhùn, kò síbi t'ọ́mọ Nàìjíríà kò lè gbé nílẹ̀ yìí - Buhari Ṣugbọn lẹyin ti awọn gomina kan ti ni ko saaye fun eyi ti awọn kan si nawọ soke paapaa ni iha ariwa pe awọn nifẹ si eto RUGA, Ẹ wo ìpínlẹ̀ 15 tó faramọ́ ìdásílẹ̀ àbúlé Ruga.
"Nkan ti o dára jù ni pé ṣókí ni, ìwọ àti ẹbi rẹ lọ ṣe pàtàkì jù kii se àkókò láti máa jẹ ki àwọn àlejò wò "" Tí ó bá ti ní àwọn ọmọ nílé, má ṣe gba wọn láàyè láti bá àwọn míràn ṣeré."
nipa iwa ọdaran lawujọ, nipa eyi, o daju pe, iwa odaran  yoo di ohun afisẹyin ti eegun n fi asọ lorile
“Ó fa ìkán omi sókè láti inú ilẹ̀,ó sọ ìkùukùu di òjò,
Wọn ko sì fẹ́ràn irú àwọn ènìyàn bẹ́ẹ̀ ràrá.
”Gbogbo àwọn eniyan sì dáhùn pe, “Amin”, wọ́n sì yin OLUWA.
US presidential election 2020: Bí ààrẹ Trump kò ṣe gbé ipò sílẹ̀ yóò ṣe àkóbá fún ọ̀pọ̀ ènìyàn
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ilé orin wa tí Ajimobi tun kọ́ dára púpọ̀, ṣùgbọ́n a kò ní dẹ́kun òtítọ́ Ẹ o ranti wi pe oṣu kẹjọ ni Ipinlẹ Oyo wo ileeṣẹ orin naa latari pe ko gba iwe to tọ.
Saere Mekonnen ni olori gbogbo ọmọ ogun orilẹ-ede Ethiopia nilẹ Adulawọ.
Samuẹli pe àwọn eniyan náà jọ siwaju OLUWA ní Misipa.
Ikọ asẹrubalu Boko Haram naa ni ọmọ ogun mẹta ni oun gbẹmi wọn, toun si ti mu awọn olujọsin tọwọ oun ba lawọn ile ijọsin ni igbekun, to fi mọ awọn olugbe abule naa.
 kọjú sí ọ̀ná wa, à ń lọ, a kò sì rí nǹkan kan jù bẹ́ẹ̀ lọ títí ó fi fi òwúrọ̀ ọjọ́ kan báyìí, ní nǹkan bí agogo mẹ́wàá, tí a rí ọ̀nà kan tí ó yà bá a pá ọ̀tún lọ.
Ajọ IFJ ni awọn ti wọn ko le fara da awọn oun to wa ninu iroyin, pẹlu iwa jẹgudujẹra lo n fa ti awọn akọroyin fi wa ninu ewu.
" O ni ohun to da oun l'oju ni pe orilẹede Naijiria yoo dun n gbe ti ijọba ba le tẹle awọn nkan ti igbimọ amuṣẹya naa gba a nimọran.
Ti Aisha si bẹrẹ si ni pariwo si iyalẹnu gbogbo wọn.
Àkọlé àwòrán, Aarẹ Donald Trump ti gunlẹ si UK Papa iṣere Stansted lo balẹ si ti wọn ti lọ kii kaabọ.
O ni torii oju buluu ọhun gan an ni oun ṣe fẹ ẹ oun ko si kabamọ pe awọn ọmọ awọn naa ni oju buluu.
“Gbogbo ẹbí rẹ̀ ní agboolé baba rẹ̀ yóo di ẹrú rẹ̀, ati àwọn ọmọ ati àwọn ohun èlò, láti orí ife ìmumi, títí kan ìgò ọtí.
9 5135 Erekusu Bahamas 163 42.
Bí wọ́n ṣe pa Funke Olakunrin, ọmọ bàbá Fasoranti nìyí Fulani DaranDaran di fà kí n fà láàrin Gómìnà Ganduje àtàwọn Gómìnà ilẹ̀ Yorùbá Dálémoṣú ni mí ṣùgbọ́n ó ní ìdí - Adaku inú eré Jẹnifa Ẹ má dá NEF lóhùn, kò síbi t'ọ́mọ Nàìjíríà kò lè gbé nílẹ̀ yìí - Buhari Bi o tilẹ jẹ wi pe idibo apapọ ti lọ, sibẹ Dele Mọmọdu ni ironu awọn eeyan to wa nidi eyi ba oun ninu jẹ lọpọlọpọ, o si mu ẹnu le alaye ninu ifọrọwanilẹnuwo yii pẹlu BBC News Yoruba.
8 wọlé lójúmọ́ lẹ́yìn tíjọba ti ẹnu bodè -Ali Àgùnbánirọ̀ gbẹ́mìí mì látàrí 'Snipper' tó fi fọ irun rẹ̀ Buhari ti fòfin de àwọn mínísítà láti rìnrìn àjò lọ sí ilẹ̀ òkèrè Hammed ni ọja ti wọn ti gbẹsẹ le lati igba ti wọn ti ti ibode Naijiria ni iye rẹ le ni biliọnu kan ati irinwo, ti ajọ ọhun si ti n pa owo ti ko din ni biliọnu marun un naira wọle sapo ijọba lojoojumọ Ilééṣẹ́ Aṣọ́bodè Naijiria n pa bílíọ̀nù N5.
Wọn ni yatọ si arakunrin yi,awọn ọkunrin meji miran ati obinrin kan lo wa ni ahamọ ti awọn si gba ohun ija oloro lọwọ wọn.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Lágbo tíátà lọ́sẹ̀ yìí, Femi Adebayo di àgbà àáfà òníláwàní, Iyabo Ojo fi sìgá dárà, Allwell Ademola di ọmọdé padà, tí Wazo si bímọ tuntun.
Ajọ naa ni, oludari agba NNPC, Mallam Mele Kyari fara han niwaju ile igbimọ́ asofin apapọ Naijiria lọjọ iṣẹgun, ko si sọ ohunkohun nibẹ to lee tọka si pe, afikun fẹ de ba owo epo bẹntiroolu.
Ọ̀jọ̀gbọn Ogunṣola ni ọna iyọni nipo naa kudiẹ kaato nitoripe wọn ko téle ilana ofin bi o ṣe yẹ.
Bakan naa, ni a tun n pe awon
5 million naira), lati wo ayeye igbeyawo aremo oba, Prince Harry ati omidan Meghan Markle, eleyi ti yoo waye lopin ose to n bo lori ero amohunmaworan Nairobi.
Iwaju ile ijọsin nla Cathedral Church of Saint David, ni Kudeti, ni awọn janduku naa ti fa rogbodiyan kan to waye lọjọ kọkandinlogun, oṣu Kejila, ọdun 2016.
Arsenal bọ́ mọ́ Dangote lọ́wọ́ láti rà Dangote: Buhari ti sọ àgbẹ̀ d'ọba O salaye pe ohun ṣadede lọ ile ifowopamọ lati lọ gba miliọnu mẹwa dọla ti oun si gbe si ẹyin ọkọ.
OLUWA àwọn ọmọ ogun, ìwọ tíí dán olódodo wò,ìwọ tí o mọ ọkàn ati èrò eniyan.
Ẹnikẹ́ni tí kò bá gbé agbelebu rẹ̀, kí ó máa tọ̀ mí lẹ́yìn kò lè jẹ́ ọmọ-ẹ̀yìn mi.
Agbẹ́gilére ń gba alágbẹ̀dẹ wúrà níyànjúẹni tí ń fi òòlù lu irin ń kí ẹni tí ń dán irin tí wọ́n ti rọ,Ó ń wí pé: ‘Òjé tí a fi jó o dára.
''Oriṣii mẹta irufẹ iwe idanwo naa ni mo ri fun ra mi, irọ lasan ni gbogbo rẹ,'' Ojijeogu lo sọ bẹẹ.
N óo gbẹ̀san lára àwọn ọ̀tá mi,n óo sì jẹ àwọn tí wọ́n kórìíra mi níyà.
Oríṣun àwòrán, Reuters Adajọ Gustavo Amarilla ara gbedeke to wa ninu beeli awọn mejeeji ni pe wọn ko gbọdọ sa lọ.
''Ẹiyele Mimiko ba onile wa jẹ o ba wa mu,sugbọn nigba ti o di ọjọ iku nise ni o yẹri.
Lọjọ kẹrindinlogun, oṣu kẹjọ, ọdun yii ni ajọ to n mojuto ọrọ ere bọọlu ni agbaye FIFA fi ofin de SiasiaSiasia ń gbèrò àti gbé FIFA lọ sí ilé ẹjọ́ .
Wọn ni o tun ṣabẹwo sawọn ibomii.
Ilé ẹjọ́ ti sún ìgbẹ́jọ́ pásítọ̀ ìjọ Sotitobire si Ọjọ́bo̩ Nítorí coronavirus, Mikel Obi sá kúrò ní ikọ̀ Trabzonspor Nigba to n sọrọ lori pe ti ijọba ba paṣẹ pe ki wọn ti awọn ile ijọsin, Opayinka sọ pe ijọ yoo tẹlẹ aṣẹ ti ijọba ba pa lori arun naa.
Pọtifari mú un sọ́dọ̀ pé kí ó máa ṣe iranṣẹ fún òun, ó fi ṣe alabojuto gbogbo ilé rẹ̀, ó sì fi ohun gbogbo tí ó ní sí ìkáwọ́ rẹ̀.
Ngige salaye pe ijọba n gbero lati maa san ẹgbẹrun mẹrinlelogun gẹgẹ bi owo oṣiṣẹ to kere julọ, nigba ti awọn ile iṣẹ aladani n gbero mẹrindinlọgbọn.
Olùdarí BBC: Èyí ní àwọn ọ́gá àgbà aláṣẹ ẹka ìròyìn BBC News Board.
OLUWA yọ jáde lọ bí alágbára ọkunrin,ó ru ibinu rẹ̀ sókè bí ọkunrin ogun,ó kígbe, ó sì bú ramúramù.
Alaafin: Lẹ́yìn rògbòdìyàn ààfin Ọyọ, ẹ wo bẹbẹ tí Olorì Badra ń ṣe
Gege bi iroyin orile-ede ohun se so pe, awon olugbe ti bu enu-ete lu ijoba, latari bi o se kuna lati mura sile di akoko ojo naa.
Aare soro yii nibi isami ayajo ojo ogo weere lagbaye fun todun 2018.
A óo sọ fún wọn pé,“OLUWA ti fi ìdí Sioni sọlẹ̀àwọn tí à ń pọ́n lójú láàrin àwọn eniyan rẹ̀yóo fi ibẹ̀ ṣe ibi ààbò.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ibalopọ lati ri ojurere lọdọ awọn okunrin je idojukọ nla fun awọn agbabọọlu Super Falcons 27 Sẹ́rẹ́ 2018 Oríṣun àwòrán, ANDY CLARK/AFP/GETTY Àkọlé àwòrán, Ohun oju awọn obinrin agbabọọlu nri lọdọ awọn ọkunrin kii se die Arabinrin agbabọọlu orilẹede Naijiria tẹlẹri kan (ko fẹ ka da orukọ rẹ) sọ fun ile isẹ iroyin BBC wipe ọrọ fifi ilọkulọ ibalopọ lọ ni ati awọn elere ori ọdan orilẹede Naijiria tẹle 'ra wọn bii satide ati sunde ni.
Nígbà tí bàbá mi dé ilé; ó wí fún ìyàwó rẹ̀, nígbà tí àwọn méjéèjì sì rò ó wò, wọ̀n pinnu pé àwọn óò dúró fún ìgbà pípé ní ọ̀dọ̀ ọba náà àti pẹ̀lú pé bí ó bá ṣeé ṣe àwọn lè kúkú fi ibẹ̀ ṣe ibùgbé àwọn.
Nígbà tí Jesu gbọ́, ó sọ fún un pé, “Nǹkankan ló kù ọ́ kù.
Awọn koko ọrọ min ti Fasọla tun sọ nile asofin: Ilana idokowo laarin ijọba ati ẹka adani to wa nilẹ lat'ọdun 2015 ko muna doko.
O wá bá àwọn tí ó wù ọ́ da ọ̀rọ̀ pọ̀,ẹ̀ ń bá ara yín lòpọ̀.
Ó fi igi akasia ṣe àwọn ọ̀pá, ó sì yọ́ idẹ bò wọ́n.
O sá mọ gbogbo ìdààmú mi;ati bí omijé mi ti pọ̀ tó,wọ́n ṣá wà ní àkọsílẹ̀ ninu ìwé rẹ.
Wo Ọ̀jọ̀gbọ́n Ẹlẹka tó ń díje fún ipò gómìnà Sé ìwọ mọ Kayọde Fayẹmi tó ń díje ni APC?
Yoruba bọ wọn ni afẹfẹ fẹ, a ri furọ adiyẹ ohun lo difa fun arẹwa Lisa Li, to jẹ obinrin kan pataki lori ayelujara lorilẹ ede China sugbọn to jẹ ọbun.
Wọ́n fún un ní ọtí tí wọ́n ti po òjíá mọ́, ṣugbọn kò gbà á.
Oke sọ wi pe ohun to jẹ Yoruba logun ju ni ki atuntọ o waye lorilẹede Naijiria, ki ipinlẹ kọọkan ko fun ra rẹ seto bi ipinlẹ awọn yoo se tẹsiwaju.
“Ṣugbọn bí ó bá jẹ́ pé ninu igbó ni ọkunrin kan ti ki ọmọbinrin kan tí ó jẹ́ àfẹ́sọ́nà ẹnìkan mọ́lẹ̀, tí ó sì bá a lòpọ̀, ọkunrin nìkan ni kí wọ́n pa.
Ohun tí ó sọ talaka ati aninilára di ọ̀kan náà ni pé,OLUWA ló fún àwọn mejeeji ní ojú láti ríran.
Travel Ban List: Muhammed ní Amẹ́ríkà kò bùn Nàíjíríà gbọ nípa ìgbésẹ̀ náà
Wọ́n ti ara wọn mọ́ inú rẹ̀, wọ́n sì gun òkè ilé ìṣọ́ náà lọ.
Hana bèèrè lọ́wọ́ Eli pé, “Oluwa mi, ǹjẹ́ o ranti mi mọ́?
Hosia bá lọ fẹ́ iyawo kan tí orúkọ rẹ̀ ń jẹ́ Gomeri, ọmọ Dibulaimu.
Àjọ NAFDAC ti bẹ̀rẹ̀ àyẹ̀wò àgbò mẹ́rin tí wọ́n ṣe ní Nàìjíríà fún Covid-19 ''Olóde'' ni Yorùbá ń pe coronavirus, iléeṣẹ́ Yemkem ti rí òògùn rẹ̀ báyìí- Olùdásílẹ̀ Yemkem Ǹjẹ́ òògùn vitamin C lè pa coronavirus?
Ṣugbọn pataki ni pé, ǹjẹ́ o tilẹ̀ bẹ̀rù Ọlọrun?
Bakan naa ni alukoro fun ẹka kan lara OPC ọgbẹni Ṣina Akinpelu ṣalaye wi pe lootọ ni OPC yoo kopa ninu eto naa.
Ẹlẹsẹ ayo, Victor Osimhen eleyi tawọn Lesotho bẹru ki ifẹsẹwọnsẹ naa to bẹrẹ lo gba goolu ẹlẹẹkẹta wọle.
Pupọ awọn to nfi kan ba ere bọọlu bọ ni esi naa j iyalẹnu fun ti onikaluku si n bere pe ki lo ṣẹlẹ si Man City.
Ọna lati fi idi otitọ mulẹ nipa iroyin yii, lo mu ki BBC Yoruba kan si MC Murphy, ka le mọ bi isẹlẹ naa se waye.
Nítorí Òfin Mose jẹ́ òjìji àwọn ohun rere tí ń bọ̀, kì í ṣe àwòrán wọn gan-an.
Gbèsè niye èèyàn tó pọ̀ ní Nàìjíríà kìí ṣe dúkìá- Emir Sanusi Kí ló mú kí Adájọ yin ìbọn lu ará rẹ láyà nílé ẹjọ́?
Ninu ọrọ rẹ, ọkan lara awọn amugbalẹgbẹ fun aarẹ, Lauretta Onocjie ṣalaye penigba ti aarẹ kọ yan Okuru, ko tii ku nigba naa koda, 'o funra rẹ mu iwe ẹri rẹ wa ni imurasilẹ fun ifọrọwanilẹnuwo ti yoo waye ni ileegbimọ aṣofin agba.
Adebayo to n ṣiṣẹ oko alagbaṣe fi ran ara rẹ nile iwe titi to fi kawe de ile iwe giga Owo Poly lo ko sọwọ agbofinro lori ẹṣẹ aimọdi to si ti ibẹ gba idajọ iku.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ọkùnrin tó fẹ́ fipábámilòpọ̀ fín ǹkan sí mi lójú ló ṣe rọ́nà wọlé sí mi lára Ìjọba ààrẹ Buhari ti sú àwọn ọmọ Nàìjíríà lórí àìsí àbò Ooṣa boo le gbe mi, ṣe mi boo ṣe ba mi.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Iriwisi àwọn ará ìlú ṣe ọtọtọ lórí èsì ìdìbò Osun Kíni òdiwọ̀n iye ìbò ìpínlẹ́ Ọṣun?
bright : adj ; ( the sun is very bright .
Lẹ́hin ìgbà tí bàbá mi si ti bá ìrìnkèrindò rẹ̀ kiri fún ìgbà díẹ̀ nínú aginjù ńlá yìí tán òun àti ẹbọra kékeré inú ọ̀gàn fi ojú gán-ánní ara wọn.
Ọpọ awon omo orile ede Britain lo ni okoowo niluu Eko.
Ghana: Nurudeen Adam ní a jẹ́ bíi idán ni
Wọ́n fi ọ̀yàyà gba gbogbo wa.
Ninu idibo naa to waye ni ọjọ Kẹwaa, oṣu Kẹwaa, ọdun 2020 ti Gomina Rotimi Akeredolu ti ẹgbẹ oṣelu APC lo gbegba oroke.
Kiniun pa olusọ ọgba ẹranko Ọ̀bọ lé àwọn ènìyàn kúrò nílè Asiri ibudo igbafẹ ẹranko ni Naijiria O ní erin náà lọ sí Gwartanbali níbi ti àwọn ará ìlú ti pé bòó tí wọn si ń ya fọto pẹ̀lú rẹ̀.
“Bẹ́ẹ̀ ni n óo ṣe tẹ́ ibinu mi lọ́rùn lára odi náà ati àwọn tí wọn ń kùn ún lẹ́fun.
Oríṣun àwòrán, Olusina Olabode Ijọba Ọyọ mu ipinnu wiwo ileesẹ redio Ayefẹlẹ sẹ Lẹyin ọpọlọpọ awuye-wuye to ti waye lori iwe kan ti ijọba ipinlẹ Ọyọ fi sita pe, oun yoo wo ileesẹ redio Fresh Fm, ti gbaju-gbaja olorin juju n ni, Yinka Ayefẹlẹ da silẹ, ijọba ipinlẹ Ọyọ ti mu ipinnu rẹ sẹ, to si ti bi ile naa wo.
25 Ìgbé 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Oriísirísi ǹkan ni àwọn ènìyàn gbà wí pé o ma ń fa àìsàn ibà sí ara ènìyàn, àmọ́ tí kìí se òtító.
Wọn gab asia ilẹ European Union ati ti UK.
Mo sọ fún orílẹ̀-èdè tí kì í gbadura ní orúkọ mi pé,“Èmi nìyí, èmi nìyí.
Gbogbo ìdílé Ahabu ni yóo ṣègbé, n óo sì pa gbogbo àwọn ọmọkunrin tí wọ́n wà ninu ìdílé náà, ati ẹrú ati ọmọ.
Ọga ajọ ẹṣọ alaabo Amọtẹkun nipinlẹ Ekiti, Brig.
Má sọ àsọtẹ́lẹ̀ ní Bẹtẹli mọ́, nítorí ibi mímọ́ ni, fún ọba ati fún gbogbo orílẹ̀-èdè.
Joẹli, arakunrin Natani, ati Mibihari, ọmọ Hagiri, 
yii lasiko ayeye ti ile-asoju orile ede India se lati fi sami ayeye odun
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Èmi àti Saheed kìí ṣe ọmọdé, a ti jọ ṣe Sinimá papọ̀, èyí túmọ̀ sí pé ìjà ti parí - Fathia Balogun Àrà méèrírí!
Nígbà tí gbogbo àwọn eniyan gbọ́, tí ó fi mọ́ àwọn agbowó-odè pàápàá, wọ́n fi ìyìn fún Ọlọrun, wọ́n lọ ṣe ìrìbọmi gẹ́gẹ́ bí ètò ìrìbọmi Johanu.
Isele ijamba oko epo naa lo waye lataari ohun idakoduro oko naa ti o kuna lori ere.
 Èyí mú kí ilẹ ̀ germany bínú , wọ ́ n sì pínú láti gbógun tí ilẹ ̀ belgium .
osu kejila odun yii,lasiko ti won n seto aabo ni agbegbe Kubtara ni ijoba ibile
 Wọn tẹnu mọ ọn pe nipa isin ati orin iyin si Oluwa, eyi yoo jẹ korioya fun Ọlọrun lati tubọ da si gbogbo iṣoro wa lorilẹ-ede yii.
Fibroid: Ǹjẹ́ o mọ pé o le ní oyún ìju tí o kò bá tètè bímọ?
“ gbogbo ona lo ye ki awon orile-ede  maa gba je  anfaani  eto ilera agbaye.
Adeola ni ẹyin ni wọn fi n gba ibale obinrin ti wọn ba fẹ fi ṣowo nabi, a ko si ri ounjẹ asaara loore kankan jẹ nibẹ."
Odu agbabọọlu orilẹede Naijiria ni Samuel Sochukwuma Okwaraji jẹ ni igba aye rẹ, o si ṣoju orilẹede Naijiria fun ọpọ ifẹsẹwọnsẹ.
Bí a kò bá ní jí àwọn òkú dìde, kí ni ìdí rẹ̀ tí wọ́n fi ń ṣe ìrìbọmi nítorí wọn?
o kò gbọdọ̀ foríbalẹ̀ fún àwọn oriṣa wọn, o kò sì gbọdọ̀ bọ wọ́n, tabi kí o hu irú ìwà ìbọ̀rìṣà tí àwọn ará ibẹ̀ ń hù.
Àwọn aguntan mi a máa gbọ́ ohùn mi, mo mọ̀ wọ́n, wọn a sì máa tẹ̀lé mi.
Bí Jesu tí ń sọ ọ̀rọ̀ yìí fún wọn, ìjòyè kan wá, ó kúnlẹ̀ níwájú rẹ̀, ó ní, “Ọmọdebinrin mi ṣẹ̀ṣẹ̀ kú nisinsinyii ni, ṣugbọn wá gbé ọwọ́ rẹ lé e, yóo sì yè.
Esi ti awọn eeyan fun un pada wi pe awọn kii ṣe ọlẹ lori Twitter ko rẹrin rara.
Ohun gbogbo ti n kò ṣe rí ni mo di ẹni tti ń ṣe, èyí tí kò kàn mí rí di tèmi pàtàk[pi, mo di ẹni tí ń parí ìjà fún àwọn ará ilé wa.
ó ní ilé tí wọn ń kó nǹkan pamọ́ sí ní àwọn ìlú ńláńlá Juda.
Norway Lọjọ Kẹtadinlọgbọn, osu Kẹrin ni awọn ileewe alakọbẹrẹ si pada ni Norway ti awọn ileewe jẹle o sinmi si pada ni ogunjọ, osu Kẹrin.
Akpata di aàrẹ àjọ àwọn agbẹjọ́rò ní Nàìjíríà, ọ̀pọ̀ èèyàn kíi kú oríire Gomina salaye siwaju si pe wọn sagbekalẹ ofin tuntun yi lati fi dena ija lori ilẹ ati awọ̀n ohun ini to ku.
Awọn marun ti wọn fẹsun kan naa ni wọn ni wọn tun gbe miliọnu mẹrin Naira owo ajọ naa lai gba asẹ lati gbe owo naa kuro ni apo ijọba lọ si ibomiran.
Torí ìdí èyí, èmi a máa tètè jí ṣe oun tí mo ní ṣe lóòjọ́.
Ìwé yìí wà fún tọmọdétàgbà lọ́kùnrin lóbìnrin ní ilẹ̀ ènìyàn dúdú, àti pàápàá ní ilẹ̀ Yorùbá, ti wọ́n jẹ́ ìbílẹ tí wọ́n sì mọ èdè Yorùbá a kà dáadáa, àti fún àwọn ilé-ẹkọ́ kékeré  pẹ̀lú.
 lílo Àjẹsára yíi kò léwu nígbà oyún àti nìgba fífún ọmọ lọ ́ yàn .
 Nigba ti gomina Rick Scott to n tuko ipinle Florida ni isele agbako ibi gbaa ni oro ohun je mi ko si setan lati dahun ibeere kankan lori ofin ibon lilo bayii.
Àwọn eniyan yóo máa gbé àwọn ìlú Juda ati àwọn agbègbè rẹ̀ pẹlu àwọn àgbẹ̀ ati àwọn darandaran.
Ileeṣẹ ọlọpaa sọ wi pe awọn oni jagidijagan yii n ṣe ohun gbogbo ti wọn le ṣe lati jẹ ki awọn araalu gbagbọ ninu ọrọ ti wọn sọ.
Bí ẹlẹ́rìí èké kan bá dìde láti jẹ́rìí èké mọ́ ẹnìkan, tí ó bá fi ẹ̀sùn kàn án pé ó ṣe nǹkan burúkú, 
Bí Buhari wọ́gilé wíwọ bàálù olówó gọbọi fún òṣìṣẹ́ ìjọba kó ṣe aráàlú láǹfàní - SERAP Ẹbí Buhari lásán ni Mamman Daura kò nípò òṣèlú kankan Èrò yapa ní mọ́ṣáláṣí Jimọ̀h láti wá fójú lóúnjẹ lórí ìgbéyàwó òfegè Buhari.
saa keji ifesewonse naa lati so ami ayo ohun di meta lai labula.
"O ní ní kété ti àwọn dé àgọ́ ọlọ́pàá náà ni wọ́n bẹ̀rẹ̀ si ni tú inú fóònù òun àti ti àwọn ọ̀rẹ́ rẹ náà tó wà nínú mótò, wọ́n fi àwọn to kù silẹ̀, ṣùgbọ́n wọ́n ṣe alábàpàde ìfọ̀rọ̀wérọ̀ kan lórí fóònù òun ti òun kọ pé ""Gay men dey pay"" iyẹn ni pe awọn ọkunrin to maa n ba ara wọn lopọ n pawo wọle gidi gan."
fi ọrẹ rẹ sílẹ̀ níbẹ̀ níwájú pẹpẹ ìrúbọ, kí o kọ́kọ́ lọ bá arakunrin rẹ, kí ẹ parí ìjà tí ó wà ní ààrin yín ná.
Máa yan lọ, ìwọ ọkàn mi, máa fi agbára yan lọ.
'Ìbọn dún láàfin Ọ̀ọ̀ni ilé ifẹ̀ lóòtọ́, ṣùgbọ́n kò séwù' Àwọn ohun tó yẹ kí o mọ̀ nípa Ọ̀ọ̀ni Ilẹ̀ ifẹ̀ Àwọn ọbá aláye ilẹ̀ Yorùbá márùn-ún pẹ̀lú ọ̀pá àṣẹ wọn Elebuibọn ni, pe Ooni bi ọmọ ọkunrin ko tumọ si pe ọmọ naa ni yoo gori itẹ lọjọ iwaju.
O tun rọ gbogbo awọn olugbe Ipinlẹ Eko lati gbaruku ti oun, ki iṣẹ ilu baa le tẹsiwaju.
Àràmọ̀ǹdà àwòràn láti ilẹ̀ àdúláwọ̀ lọ́sẹ̀ yìí
Àwọn ọba tó wà lábẹ́ mi ń talẹ̀ nítàkutà- Oluwo Oyè Ibadan kò sí fún títà - Otun Olubadan, Lekan Balogun Eyi ni igba akọkọ ti Anthony Joshua yoo maa yọju si orilẹede Naijiria lẹyin to gba igbanu ẹyẹ agbaye rẹ, WBA, WBO, IBF ati IBO pada lọwọ Andy Ruiz.
Awọn ọmọ alimajiri ti a n wi yii lo pọju ninu wọn.
Wọ́n fi aṣọ aláwọ̀ aró, ti elése àlùkò, ati aṣọ pupa ati aṣọ funfun onílà tẹ́ẹ́rẹ́tẹ́ẹ́rẹ́ ṣe àwòrán èso Pomegiranate sí etí ẹ̀wù àwọ̀kanlẹ̀ náà nísàlẹ̀.
Bẹ́ẹ̀ ni Abineri ṣe kú, nítorí pé ó pa Asaheli arakunrin Joabu.
Nítorí ẹnikẹ́ni tí ó bá gbé ara rẹ̀ ga ni a óo rẹ̀ sílẹ̀, ẹnikẹ́ni tí ó bá sì rẹ ara rẹ̀ sílẹ̀ ni a óo gbé ga.
Ẹ̀yin ará mi, kí ọpọlọpọ yín má máa jìjàdù láti jẹ́ olùkọ́ni, kí ẹ mọ̀ pé ìdájọ́ ti àwa olùkọ́ni yóo le.
Tani Kingsley Moghalu tó ń duipò ààrẹ?
Adari ajo orile ede Britain tun so pe ifowosowopo lori eto aabo yoo je ki eto aabo orile ede mejeeji naa tun fese mule sii.
"Èsì tí o fún BBC ni pé""Gbogbo rẹ lo ti wa lóri ayélujára ki a lọ wòó níbẹ̀ àti pé kò síi ọ̀rọ̀ ti òun fẹ́ sọ síi Oluwo kọ̀ láti sọ̀rọ̀ lórí àwọn afọbajẹ tó fẹ́ yọ ọ́ nípò, aráàlú fọ́n síta láti fẹ̀hónú hàn Oba AbdulRasheed Akanbi, Oluwo ti fesi sawọn Afọbajẹ mejila ti wọn kọwe si Gomina Gboyega Oyetola pe ko rọ Oluwo loye."
Aarẹ BUhari fun ra rẹ lo dari ipade ọhun.
Ibugbamu ohun, ni ijoba ti ni o waye lati owo awon omo ogun olote, bio tile jepe, ijoba orile-ede naa so pe, awon yoo mu igberu ba ile ise aabo latari irufe ibugbamu ohun ti o waye ninu osu kinni odun ti a wa yii, ti o si gbemi ogorun eniyan.
 Adamu ni gbogbo awon toro eto aabo
Kọmiṣọna eto ilera, Bashir Bello ni ijọbaa ti ṣayẹwo ẹni kan to ṣẹṣẹ de lati ilẹ Gẹẹsi, ti wọn si ti fi ayẹwo naa ranṣẹ si yara ayẹwọ to wa ni fasiti ẹkọṣẹ iṣegun to wa ni ilu Eko, LUTH.
O yan Aarẹ Ọna Kakanfo meji sipo Ọba Adeyẹmi lo yan oloogbe, Oloye MKO Abiola gẹgẹ bi Aarẹ Ọna Kakanfo ilẹ Yoruba l'oṣu Kinni, ọdun 1988.
Eyi lo mu ki awọn kan maa sọ pe, o ṣeeṣe ki iyawo Ọọni ti bimọ ni ṣugbọn nibayii, aafin ti tako iroyin naa.
Ọgbẹni Joshua Kaputah ni iṣẹ ati bi ijọba ti gbe ileewe tipa nitori ajakalẹ aarun coronavirus ti jẹ iṣẹlẹ ṣiṣe igbeyawo tipatipa fawọn ọmọde pọ sii.
Kí ọkọ iyawo jáde láti inú yàrá rẹ̀,kí iyawo àṣẹ̀ṣẹ̀gbé náà jáde ninu yàrá rẹ̀.
Oríṣun àwòrán, Foluke/instagram Àkọlé àwòrán, Ń ko tọrọ agbe fún ìyá Awero, Larry àti bàbà Feyikọgbọn, ẹ má sọ ire di ibi mọ́ mi lọ́wọ́ - Foluke Daramola Gbajúmò osere orí ìtàgé lobinrin, Foluke Daramola, ẹni tó máa ń béèrè àánú fún àwọn akẹẹgbẹ rẹ tó nílò iranlọwọ, ti ń rawọ ẹ̀bẹ̀ sáwọn aráàlú pé kí wọn má ṣe sọ isẹ àánú tí òun ń ṣe di ibi mọ òun lọ́wọ́.
Nichole Ozioma Banna – Icheke Oku
N)  so lojo-Eti pe, ni oja epo-robi, awon ile-ise ohun amusagbara lorile-ede America se adinku ipese epo-robi won lose to koja fun igba akoko lati bi osu meji months RIG-OL-USA-BHI, pelu sise adinku re ni ilopo merin.
Igbesẹ awọn asofin lati ransẹ pe Buhari waye lẹyin ti ikọ Boko Haram pa awọn agbẹ kan nipinlẹ Borno.
Rasheed Tijani ko riran ṣugbọn o n lọ ata Bakanna lo ni atunṣe yoo ba iye akẹkọ to gba ominira ninu awọn ọmọbinrin naa lẹyin ti awọn yooku wọn ba ti ni akọsilẹ, paapa nitori pe wọn ko yọnda awọn ọmọ naa fun ẹnikẹni, wọn kan ja wọn da silẹ ni Dapchi ni.
Olorì Anu Adeyemi ń ṣe ọjọ ìbí, ẹ gbọ́ ǹkan tò sọ sí Kábíyésì Ẹ wo àwọn gbajúmọ̀ òṣèré tíátà tó jogún eré ṣíṣe lọ́dọ̀ òbí wọn Nàìjíríà kò ní olórí, ẹ pín sí ẹlẹ́kùnjẹkùn - Soyinka Ninu fidio to gbe jade ọhun ni Ajikanle, ẹni to ko ipa ribiribi ninu sinima Mufu Olosha Oko ati Olosha Molete, ti n bẹbẹ si araalu pe ki wọn saanu oun pẹlu iranwọ owo.
 O salaye bi arun jejere se ti di opo kariaye laisko yii pelu awon ireti ati ayo ti lilo oko alagbeka yii yoo mu wa fawon to ti lugbadi arun yii.
Ko fi bẹẹ si akọsilẹ nipa rẹ, sugbọn a le sọ pe ọdun 2014 ni orúkọ rẹ kọkọ jade sita lasiko ti àṣírí ibuba awọn ajinigbe kan tú ni agbegbe Soka niluu Ibadan.
Ko pẹ pupọ ni ẹka ẹgbẹ oṣelu APC nilẹ Gẹẹsi APC UK chapter gbe iroyin kan jade loju opo ayelujara wọn ti wọn fi n ki agba oṣelu naa pe ko maa faraalẹ o.
Awọn onimọ sọ pe o ṣoro ki eeyan to ba gba ọna yi rọ lapa ko ku ṣugbọn eeyan le rọ lapa nipa ibalopọ.
Báwo ní ẹ ṣe lè wí pé ẹ kì í ṣe aláìmọ́;ati pé ẹ kò tẹ̀lé àwọn oriṣa Baali?
Gómìnà Kẹfà – Ọ̀gágun Òfúrufú – Gbọ́láhàn Múdàṣírù – Gómìnà fún ọdún meji – ọdú́n mẹ́tàlélogbon di ọdún mọ́kànlélọ́gbọ̀n
pe awon ti n jiroro pelu ijoba orile ede Sudan leyin wahala to sele lorile ede
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, World Diabetes Day: Ọdún kọkandinlogun ti mo ti wà lẹ́nu itọ ṣúgà nìyí Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Àjọ Ọlọ́pàa Naijiria: A ó fi òsìsẹ́ SARS tó se isẹ́ ibi náà jófin Amọ nibayii, alafia ti pada si agbeegbe naa.
Bayii ni bi igbẹ rẹ ṣe ri ṣe le sọ nipa ilera rẹ.
O kẹkọọ siwaju si ni fasiti miran ni oke okun ki o to gboye ọmọwe ko to bẹrẹ si ṣiṣẹ ni orilẹede Amerika.
Oríṣun àwòrán, Twitter/Premier League Ọkan lara awọn ọjẹwẹwẹ agbabọọlu Chelsea, Mason Mount lo gbayo ẹlẹẹkeji wọle fun Chelsea.
N kò ní fi ọ̀kankan ninu wọn sílẹ̀ sí ààrin orílẹ̀-èdè mìíràn mọ́.
22 Bélú 2018 Black Friday: Africa suppose dey do dis one?
Naijiria, ti o waye lojo aje(Monday), (10th General
China fi ọwọ́ọ ṣìnkún òfin mú ayàwòrán eré orí ìtàgé nítorí pé ó tún àwòrán ìgò ọtí-líle kan tí ó ń tọ́ka sí Ìpanìyànnípakúpa Tiananmen pín
leyin ogun ọdun nidi ere bọọlu rẹ pe, o
Wo ọ̀nà tí o fi lè dáàbò bo ọmọ rẹ lọ́wọ́ COVID-19 níléèwé Kò sí iléẹjọ́ tó le dá wa dúró, ìyanṣẹ́lódì yóò bẹ̀rẹ̀ ní Ọjọ́ Ajé - NLC Ǹjẹ́ o ti gbọ́ nípa Da Rocha?
"Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Láàrín ìṣẹ́jú díẹ̀, ẹ ka ìwé Akinwumi Ishola, ""Nítorí Owó"" lórí Akomolede Yoruba Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Fídíò, Akomolede àti Asa lórí BBC Yorùbá: Mọ̀ síi nípa ẹ̀kún ìyàwó níbí3 Bélú 2020 Fídíò, Soyinka Cancer: Àṣe ara mi ni iso ti n run gbogbo bí mo ṣe n ṣèrànwọ́ lórí jẹjẹrẹ27 Bélú 2019 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 3 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 5 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!"
Gbogbo àwọn eniyan wà ní èbúté, wọ́n jókòó lórí iyanrìn.
NCDC ti kede pe eniyan marun un miran tun ti ni arun Coronavirus lorilẹede Naijiria Ajọ to n risi idẹkun itankalẹ arun lorilẹede Naijiria, NCDC ti kede pe eniyan marun un miran tun ti ni arun Coronavirus lorilẹede Naijiria.
 wọ ́ n dá ilé iṣẹ ́ náà kalẹ ̀ ní ojọ ́ kejì oṣù kejì , ọdún 1977 ( february 2 , 1977 ) gẹ ́ gẹ ́ bí ilé isẹ ́ rédíò ti ìjọba .
Adugbo yi jẹ ibi tawọn eeyan pọ si ti aaye tawọn kan ti n ta ọkọ si farako pupọ ninu ibugbamu yi.
Amọ, o ni ibanujẹ lo jẹ fun awọn, nitori pe ijọba ipinlẹ Kaduna kọ lati gbe igbesẹ to yẹ lati pese aabo fun wọn.
Ṣé ọjọ́ Ajé kúkú ti jẹ́ ọjọ́ odún kan tẹ́lẹ̀, gbogbo ẹ̀ wá jẹ́ ọjọ́ mẹ́rin – Àbámẹ́ta, Aìkú, Ajé àti Iṣẹ́gun – tí àwọn ọ̀pọ̀lọpọ̀ èyàn r’áàyè jáde wòran dáadáa.
Oríṣun àwòrán, kolawoleajeyemi Àkọlé àwòrán, Kolawole Ajeyemi, ọkọ Toyin Abraham Ọmọ Naijiria tó lé ní 300 ti padà wálé láti South Africa Àwọn olólùfẹ̀ Toyin Abraham ati Liz Anjorin ti gbé ọ̀rọ̀ wọn rù sórí, ẹ wo òjò òkò ọ̀rọ̀ Ọmọ iná làá rán síná, Angel Maria fojú ọlá Real Madrid gbolẹ̀ Ọmọdé 27 jóna ráuráu mọ́'le níléèwè Liberia Bẹẹ lo tun woye pe, ẹka ileeṣẹ sinima agbelewo jẹ ibi ti awọn eeyan ti le kọ ọgbọn, to si yẹ ki awọn osẹre maa lo oju opo ẹrọ ayelujara wọn lati kọ awọn ololufẹ wọn lẹkọ, kii sẹ lati ma ṣi awọn eeyan lọna.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: 'Wọ́n pa ènìyàn mẹ́jọ nínú ẹbí mi' Ìgbà wo ni Buhari yóò simi àwáwí?
Bi ẹ ko ba gbagbe, iroyin jade rẹpẹtẹ nigba ti ọwọ kọkọ tẹ Shodipe to jẹ ọmọ ọdun mọkandinlogun koda ati igba to tun sa lọ mọ ọlọpaa lọwọ, iroyin ko tii tan nilẹ titi di akoko yii.
Oun naa ni oludasilẹ ẹgbẹ oṣelu NAC.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Saudi Arabia: Ìjọba ti fàyé gba òbinrin lati rìnrinajo lọ orilẹ̀-èdè to wù wọ́n 2 Ògún 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, A o ni topinpin obinrin Saudi to ba rìrìnàjò mọ́- Ìjọba Saudi Ṣe mo le lọ?
Ọlọrun, àwọn agbéraga dìde sí mi;ẹgbẹ́ àwọn ìkà, aláìláàánú kan ń lépa ẹ̀mí mi;wọn kò sì bìkítà fún ọ.
Ẹ yìn ín gbogbo ẹ̀yin eniyan,
lati fi tako gomina naa ko lẹsẹ nilẹ, nitori naa ko lee fidii mulẹ.
Bótiwù kó roni lójú láti rẹ́ ilá, tàbí láti ro àmàlà, tí oúnjẹ bá dé’lẹ̀ tán ìgbádùn dé!
Ọ̀kan ninu àwọn ọmọkunrin Jehoiada, ọmọ Eliaṣibu olórí alufaa, fẹ́ ọmọ Sanbalati ará Horoni kan, nítorí náà mo lé e kúrò lọ́dọ̀ mi.
Ẹ̀rù ba àwọn àjèjì,wọ́n gbọ̀n jìnnìjìnnì jáde ní ibi ààbò wọn.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ọmọbíbí orílẹ́èdè Brazil ni Diego Costa ṣùgbọ́n ó pinu láti máa ṣojú ilẹ̀ Spain Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 3 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 5 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Mo bẹ Titu kí ó wá sọ́dọ̀ yín.
Lílo oògùn Sniper fún ìtọ́jú oúnjẹ leè yọrí sí ikú àìtọ́jọ́
Àkọlé àwòrán, Awon oludije to ni àmì yii ni won n je ki won wole dibo fun oludije to wu won ni Enugu Awọn agbatẹru ibo ni Enugu ti ya awọn oludibo si ọtọọtọ nipa wiwo iru ààwọ̀ kaadi idbo ti won ba muwa sibudo idibo.
"Wí pé, kọ ìtan tìrẹ láyé kí o sì ṣe ohun tó le mú inú ara rẹ̀ dùn.
n óo fún wọn ní ipò láàrin àgbàlá mi,ati ìrántí tí ó dára, ju ọmọkunrin ati ọmọbinrin lọ.
Bótilẹ̀ jẹ́ pé ìròyìn kan sọ pé, ọdọmọkunrin kan ti orúkọ rẹ̀ jẹ́ Isaac Bamidele lo fí ibúdó rẹ̀ sílẹ̀ ni ìlú Akure tí o si wá fi ilú Ibadan ṣe ibùgbé láti ri ọmọkùnrin náà mú.
Látàrí ìṣẹ̀lẹ̀ ìpànìyàn tó wáyé ní Kaduna, àjọ àgùnbánirọ̀ (NYSC) tí kéde sísun ètò ìgbaniwọlé àgùnbánirọ̀ ní ìpínlẹ̀ náà.
Àwọn ọ̀nà tí obìnrin fi le gbádùn ìbálòpọ̀ Láìpẹ́ yìí ni Mercy Aigbe ra ilé àwòdami-ẹnu tí iye owó rẹ̀ tó igba mílíọ̀nù.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Adamawa: Ọlọ́pàá mú ẹyẹ igún sí àtìmọ́lé ní ìpínlẹ̀ Adamawa 20 Èbibi 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ileeṣẹ ọlọpaa ni awọn ṣi n ṣewaadi ẹsun ti wọn fi kan ẹyẹ igunnugun naa Kayefi nla leyi ṣugbọn ododo ọrọ ni.
Bakan naa si ni ọmọ ṣe ori ni ibudo idibo miran ni ijọba ibilẹ Dala.
Bada Maruf Mathew, ẹni to fi aworan Dele sori Twitter to si gbilẹ kaakiri ni nini imọlara ohun ti ọmọde yii n la kọja gẹgẹ bi baba ẹlomiran lo wu oun lori.
Idibo naa waye ni ile ẹkọ alakọbẹrẹ Unity Primary School, Umuchoke Amaigbo ni ipinlẹ Imo.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù BBC Africa Eye: Akọroyin fẹ ìdí àwọn oníṣẹ́ ibi ọmọ ogun síta Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ BBC Africa Eye: Akọroyin fẹ ìdí àwọn oníṣẹ́ ibi ọmọ ogun síta 8 Òkùdu 2019 Iwadii yii bí igbesẹ akọni loriṣiiriṣii káàkiri agbaye.
Ogbeni Stuart Symington, gba awon omo orile-de Naijiria nimoran yii lakooko to se abewo si alamojuto agba ile-ise International Institute of Tropical Agriculture (IITA) ti o fidi kale si ilu Ibadan ni ipinle Oyo.
Máa gbé kẹ̀kẹ́ rẹ lọ, àwọn akọròyìn kọ̀ ìpàkọ́ sí Femi Fani Kayọde Nibayii, awọn ọlọpaa to n ṣiṣẹ loju omi ati Ajọ oṣiṣẹ pajawiri ni ipinlẹ Eko, Lasema n ṣiṣẹ papọ lọna ati sawari ẹni to sọnu ninu ijamba ọkọ naa.
Ṣugbọn wọ́n rán eniyan lọ bá a níbẹ̀, wọ́n sì pa á.
Ọjọ kẹjọ, oṣu Kẹrin, ọdun 2010 lo lo ayelujara Twitter gbẹyin.
Oloye Adeyemi Soladoye, aarẹ ẹgbẹ ni awọn ọmọ Ibadan ti ṣe suuru to lati igba ti wọn ti da fasiti naa silẹ ati pe aika nkan kun awọn ti to gẹ bayi.
ti yoo sọ esi idibo lẹyin ti wọn ba ti ka a.
Èmi a máa fún àwọn tí wọ́n fẹ́ mi ní ọrọ̀,n óo máa mú kí ìṣúra wọn kún.
ti won lo lati  fi kọ ile naa lo jẹ pe
Agbenuso fun ile-ise ologun naa, ogagun agba Texas Chukwu so ninu atejade kan pe, “ile-ise ologun ko ni gba oro pelu agbalagba bi eni gbagba otin’, amo, a ni lati wa yanju si awon oro kan fun anfaani awon omo ipinle Taraba ati awon omo orile-ede Naijiria lapapo.
Hamani lọ mú ẹ̀wù ati ẹṣin náà, ó ṣe Modekai lọ́ṣọ̀ọ́, ó gbé e gun ẹṣin, ó sì ń ké níwájú rẹ̀ bí ó ti ń fà á káàkiri gbogbo ìlú pé, “Ẹ wo ohun tí ọba ṣe fún ẹni tí inú rẹ̀ dùn sí láti dá lọ́lá.
Nigba aye rẹ, iwe mẹrindinlọgbọn ni Oyebola kọ.
Akowe agba lorile-ede America Rex Tillerson ti se adinku irinajo abewo alakoko re nile-Africa, eyi ti yoo pada sorile-ede America saaju gbedeke ojo ti o da, lati le tete yanju awon ise kan ni kiakia.
Toyin Abraham jọ̀wọ́ dáríjì mí - Yomi Fabiyi Ooni Ile ife, Ààrẹ Gani Adams fárígá lórí ikú ọmọ Fasoranti Kí ni Obasanjo sọ lórí ikú ọmọ aṣíwájú Afenifere, Rueben Fasoranti?
 Pasitọ Ajifowowe ni ko sí ohun kan ti yoo yipada fun ẹnikẹni ti ko ba ni ipinnu tabi eto fun ọdun tuntun."
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù World Food Day: Oúnjẹ àràmọ̀ǹdà mọ́kànlá tí wọ́n ń jẹ lágbààyé rèé 17 Ọ̀wàrà 2018 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Turkey n fi omi ara ọpọlọ ti wọn ti rẹ se ara rindin Ounjẹ jijẹ jẹ ọrẹ ara, amọ jijẹ idin ninu burẹdi jẹ ohun to so si ni lẹnu, to si bu iyọ si.
Pẹlu owo osu yii, o ma gba ọ ni odun mejilelogunlelẹẹdẹgbẹrin(722 years) ati osu meta lati gba iye owo ti sẹnatọ kan n gba lọdọọdun.
"Àpanisáyé ni ẹ̀wà tí wọ́n n fí 'sniper' sí Báyìí ni o ṣe lè fi orúkọ oògùn tàbí àgbo rẹ sílẹ̀ lábẹ́ àjọ NAFDAC Ohun tí wọ́n fi ń ṣe báàgì, bàtà ni wọ́n ń tà bíi ‘pọ̀ǹmọ́’— NAFDAC Òjò ló lè mú kí ìtànkálẹ̀ àrun ìgbẹ́ ọ̀rìn má tètè dópin ni Eko- Iléeṣẹ́ ìlera ""Bi ọjọ ba ṣe n lọ si lori rẹ, ni ewu to rọ mọ lilo iru nkan bẹ n pọ si."
Na ọwọ́ rẹ sílẹ̀ láti òkè,kí o yọ mí ninu ibú omi;kí o sì gbà mí lọ́wọ́ àwọn àjèjì,
Alubami ni Fury, to jẹ ọmọ orilẹ-ede Gẹẹsi lu Deontay, to jẹ ọmọ ilẹ Amẹrika ninu idije ife agabaye ọhun.
Lati saami aadọta ọdun àṣeyọrí náà, Chelsea wọ jẹsi to jọ ọ idije kan pẹlu Nottingham Forest lọdun 2020.
"Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Àjẹ́, eégún, kí ni wọn ò pè mí tán tórí Vitiligo lára mi' Eyi ti mu ki ọpọlọpọ abule ni agbegbe naa o di ""abule awọn obinrin ti ko ni ile ọmọ''."
tóbẹ́ẹ̀ tí àwọn alufaa kò fi lè ṣe iṣẹ́ ìsìn wọn, nítorí ògo OLUWA tí ó kún ilé Ọlọrun.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Nigerian Recession: Ọ̀rọ̀ ajé Naijiria tó dẹnu kọlẹ̀ yóò kan gbogbo èèyàn 21 Bélú 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 23 Bélú 2020 Ọjọ kọkanlelogun, oṣu Kọkanla, ọdun 2020, ni ijọba Naijiria kede pe eto ọrọ aje ti dẹnu kọlẹ.
Ohun ija lorisirisi ni wọn ka mọ awọn afunrasi naa lọwọ.
 Bẹẹ ṣe wa sọ yii a o tun fọwọ ọkundun mu ọrọ naa.
Ìròyìn tó tẹwa lọwọ sọ pé àwọn oṣiṣẹ ileese ọtẹlẹmuyẹ àpapọ ló kókó gbé ti wọn sì fa le àwọn agbofinro lọwọ.
O ni ko pẹ ti a bẹrẹ ipalẹmọ ni Aisha Buhari yabo ile awọn ti o si fi aga ja ilẹkun, ti o si fẹrẹ kọlu ẹgbọn oun nibi ti o ti n huwa ipa si wọn.
Ọ̀rọ̀ náà ṣòro láti túmọ̀ nígbà tí ọkàn yín ti le báyìí.
Ó ní fún àpẹẹrẹ ila kíkọ kò bá ìgbà mú mọ, tó fi mọ sise oogun owó àti lilo ẹ̀yà ara èèyàn fún òrìṣà bíbọ nítorí gbogbo ohun tó bá ń mú ẹ̀mí lọ kò dára, ó yẹ ká mú kúrò nínú àṣà wá.
òun nìkan ni majẹmu tí mo bá Dafidi iranṣẹ mi dá ṣe lè yẹ̀, tí ìdílé rẹ̀ kò fi ní máa ní ọmọkunrin kan tí yóo jọba; bẹ́ẹ̀ náà ni majẹmu tí mo bá àwọn alufaa, ọmọ Lefi iranṣẹ mi dá.
O tíí ẹsẹ mi kúrò lára igi o sì gbé mi jù sílẹ̀ ó ṣebí mo ti kú ni.
Awọn rẹkọọdun orin ti Sikiru Ayinde Barrister gbe jade nigba aye rẹ ni Ejeka Gbo T'Olorun (1966) Vol.
Bẹẹ ba gbagbe, Leah Sharibu ni awujọ agbaye ti n pariwo fun idande rẹ lọwọ ikọ Boko Haram, lẹyin ti wn ji gbe pẹlu awọn akẹkọ ileewe girama kan nilu Dapchi, nipinl Yobe.
Mo lero wipe owo oṣu to kere ju tuntun yii yoo jẹ ki awọn oṣiṣẹ jara moṣẹ daradara si.
Ka ẹkúnrẹ́rẹ́ rẹ̀ níbi history of the BBC.
Day 23: Àwọn nkan márùn ún tó gbajúmọ̀ nípa Daura #BBCNigeria2019 Ohun márùn ún tí o kò mọ̀ nípa òfin tó dáàbò bo àwọn àkàndá Day 25: Àwọn àkànlò èdè lásìkò ìdìbò #BBCNigeria2019 Àwọn onímọ̀ Islam àti Oluwo takora lórí oyè Wàzírì Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ọ̀tọ̀ ni nkan tí wọ́n sọ fún ẹbí rẹ̀, iṣẹ́ aṣẹ́wó ni wọ́n fi n ṣe Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Osinbajo: Ikẹnnẹ yẹ kó jẹ́ Mẹ́kà òṣèlú ni Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Lootọ ni Akpabio pada si ibi aaye ijoko rẹ, ṣugbọn o sọ pe, Saraki gbọdọ tọrọ aforiji lọwọ oun fun iwa ifini se ẹlẹya to hu si oun.
Ewe, balogun iko ohun Mikel John Obi ni koi ti wa pelu awon akegbe re ni Wroclaw latari ise to n se lowo latii so iwe isise re ni China di tuntun ninu iko agbaboolu re Tianjin Teda.
Láìpẹ́, wọ́n yọ sókè nítorí erùpẹ̀ ibẹ̀ kò jinlẹ̀.
Sugbon lataari ise akinkanju awon oloopa eka ipinle Enugu ti o koju awon agbesunmomi ohun lojukoju, eyi lo sokunfa bi won se gba baba re sile lowo awon agbebon ohun lojo Aje(Monday).
Awon eniyan marun un naa wa, lati ekun maraaarun ti orile ede yii.
Nígbà tíó di ojú  alẹ́, gbogbo wa di ẹrù wa a gbé e lé orí àwọn tí ó kéré díẹ̀ nínú wa, nítorí a ti pọ̀ díẹ̀ ju bí a ti ṣe kúrò ní ilé Baba-onírùngbọ̀n-yẹ́úkẹ́ lọ.
Salah gbẹyẹ mọ Kevin de Bruyne, ( Manchester City), Harry Kane (Tottenham), Leroy Sane (Manchester City), David Silva (Manchester city) àti David de Gea (Manchester United) lọwọ, láti gba àmì ẹyẹ PFA náà.
Idiwo yii waye nigba ti ẹrọ to
Abikẹ Dabiri ati Kabiru Bala to jẹ asoju Naijiria si South Africa ni fifi oro ya oro ni Naijiria ko ni yanju ọrọ to wa nilẹ yii.
Àwọn òbí fárígá lórí sísan N25, 000 owó àyẹ̀wò COVID-19 fáwọn akẹ́kọ̀ọ́ kí wọ́n tó wọ iléèwé Àkójọ́pọ̀ àwòrán rèé lórí bí ìwọlé akẹ́kọ̀ọ́ ṣe lọ sí ní Oyo Ibi ọ̀rọ̀ dé dúró lórí ṣíṣí àwọn ilé ìwé padà ní Naijira rèé àti nílẹ̀ Afrika Kọmíṣọ́nà mẹ́ta lùgbàdì àrùn Coronavirus l'Ọyọ Ipinlẹ Oyo ti kọkọ fi orukọ silẹ gẹgẹ bi ipinlẹ to bẹrẹ ẹkọ pada loṣu Keje.
Kin lo fa ikunsinu laarin awọn asofin yi?
Nígbà tí ó wọ inú ilé, àwọn afọ́jú náà tọ̀ ọ́ lọ.
Ní Kaduna, Ẹ̀mí 55 sọnù sínú ìjà ẹ̀sìn Ìdájọ́ ikú ń dínkù, àmọ́ orílẹ̀-èdè mélòó ló sì ń pa ẹlẹ́sẹ̀?
 Èdùmàrè fún gbogbo àwọn tó fi ara pa ni ìwòsàn to péye
Nígbà tí Ìjàǹbáforítì jókòó lẹ́ẹ̀kejì yìí, èmi náà tún dìde mo kín ọ̀rọ̀ rẹ̀ lẹ́hìn, ìgbà tí mo sì jókkòó tán Oóhùn-ún-dùùrù dìde òun náà bẹ̀rẹ̀ sí ọ̀rọ̀ í sọ, ohùn Olóhùn-un-dùùrù sì dún tó bẹ́ẹ̀ tí ó jẹ́ pé nígbà tí ó jókòó Baba-onírùngbọ̀n wò ó lójú, ó wí pé: ‘Olódùmarè fi iyọ̀ sí ètè rẹ.
Èèyàn 64 míràn tún ti ní àrùn Coronavirus ní Nàíjírìa Gbogbo ìgbésẹ́ to yẹ ni a gbé nígbà ti àwọn ọ̀daràn dé ọgbà wa- Agbẹnusọ ọgbà ẹ̀wọ̀n Àwọn òṣìṣẹ́ ìjọba ìpínlẹ̀ Oyo láti ipele kẹtàlá ti padà sí ẹnu iṣẹ́ lọ́jọ́ ajé Mo ṣetán láti ta ilé tí mo ń gbé, kí n le rí àwọn ìbejì mi padà - Akeugbagold Amọṣa, lẹyin-o-rẹyin awọn nnkan kan wa eleyi ti aarẹ ko mẹnule, eyi ti ọpọ si ti n reti boya yoo sọrọ lori rẹ.
Gẹgẹ bi Punch ti wi, obinrin kan ti wọn pe ni iya Dada ni ohun idana sitofu rẹ gbina mọ lọwọ, lo ba sọ si ita, pẹki ni sitoofu naa se alabapade kẹẹgi epo petiroolu ti eeyan kan n gbe kọja lọ, ni ina ba sọ.
O ni tẹlẹ gan an kii ṣe Sanusi lo tọ si ipo naa, awọn alagbara ijọba nigba naa lo kan fi iyansipo rẹ ṣe ọna ati fi la aarẹ igba naa, Goodluck Jonathan loju.
Asiko Aisan ranpẹ Nkan ti ọpọ awọn eeyan yoo ri re nipa arun yi.
 “Ifojusun aare Trump ni lati jiroro lori eto ilana ti wọn yoo lo lati le jẹ ki ibasepo orilẹ ede mejeeji naa tun tẹsiwaju , lara ohun ti won yoo  jo maa jiroro le lori ni: “Idagbasoke ati atunse  lori eto oro aje , gbigbokun ti iko olote ati awon ohun to le pa alaafia ati eto aabo lara ati ona ti orile ede Naijiria yoo se je adari ninu eto ijoba tiwa-n-tiwa  ni ekun ti won wa”.
OLUWA pàṣẹ pé, a óo wó àwọn ilé ńlá, ati àwọn ilé kéékèèké lulẹ̀ patapata.
 Ìlú ọba aládé sì ni ìlú méjèèjì Ọ ̀ ra àti Òkèwù .
Àwọn tí ó ṣì ń dúró ti di ẹgẹrẹmìtì, èyí á mú kí àwọn kan ó máa lọ (ṣe ayédèrú ìwé láti) gbẹ́sẹ̀ lé ilé wọ̀nyí.
Tọdun 2015 ni akọsilẹ wọn ni apa Durban ati ni Johannesburg.
” Àwọn mejeeji tún ń bá ìrìn àjò wọn lọ.
Aarẹ Buhari ni orilẹede Naijiria ko ni wa ọwọ ajọsepọ rẹ pẹlu orilẹede South Africa ku.
Yemi Osinbajọ sọ ọrọ yii loju ọpọ ikansiraẹni Twitter rẹ ni Ọjọ Aiku.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Tunde Braimoh: Itẹ́ òkú ní Vault Garden ní wọ́n sin Aṣòfin náà sí ní ìlànà ẹ̀sìn Musulumi 10 Agẹmo 2020 Oríṣun àwòrán, @GiwaMoore Awaye ku ko sin, ọrun ma kanju, gbogbo wa la n bọ.
Awọn mejeeji gbéná wojú ara wọn ninu ilé nigba ti ọkọ sọ pe o dara ki Buhari maa ṣe ijọb alọ ti iyawo dẹ ni rara, eyi ti Buhari ṣe to, ko pada si Daura.
O ni o se ni laanu pe awa taa wa lẹyin wọn ko wo awokọse awọn agbaagba yii lati le sọ pe nnkan ti awa naa ti gbe se ni eleyi.
Aarẹ CAN Samson Ayokunle sọ fun gbogbo awọn ile ijọsin Naijiria lati bọwọ fun ofin ki wọn si tẹle ilana ijọba nipa isin ọjọ aisun ọdun.
Tọkọtaya, ọmọ mẹ́ta àti àlejò kú sínú ilé l'Oshodi Ọba Ogunwusi gbe imọran ọhun kalẹ lasiko to n gbalejo awọn osisẹ agba ajọ EFCC ni aafin rẹ nilu Ile Ifẹ.
Lasiko to n ba awọn Gomina ipinlẹ sọrọ ni Aarẹ Uhuru kede ọrọ yi.
Oríṣun àwòrán, Instagram/odumeje_dlion Indaboski ni nibẹrẹ ọdun 2020 ni oun ti sọ asọtẹlẹ pe ki olori di ori rẹ mu ni nitori ọdun yii kii se ọdun awada tabi ẹfẹ rara, ọdun ija ati wahala gbaa ni.
Ẹ̀yin ọmọbinrin Jerusalẹmu,òun ni olùfẹ́ mi, òun sì ni ọ̀rẹ́ mi,
Nitori naa ni oun gbogbọ ṣe iwadii daradara lati mọ ewu to wa ninu ṣiṣi awọn ile ijọsin pada.
Ni nkan bi aago mẹjọ alẹ ni ìró ìbọn bẹrẹ si ni i dún, eyi to mu ki ọpọ eeyan o fi ile, sọọbu wọn silẹ, koda awọn kan fi ara pa.
Saulu náà kó àwọn ọmọ ogun rẹ̀ jọ, wọ́n pa ibùdó sí Giliboa.
“Ẹ ti gbọ́ tí a ti sọ fún àwọn baba-ńlá wa pé, ‘Ìwọ kò gbọdọ̀ pa eniyan; ẹni tí ó bá pa eniyan yóo bọ́ sinu ẹjọ́.
"Wọn ò tí rí kòkòrò Covid-19 ni ojú ara ìyá, tàbí lára ìwọ́ ọmọ tàbí láti inú omi ọyàn abiyamọ"" , ìwádìí ń lọ lọ́wọ́ lórí èyí ṣùgbọ́n àwọn onímọ̀ kò tíì salábàpàdé Covid-19 nínú olubi ọmọ nínú ẹ̀jẹ̀ ."
Dauda sọ wi pe ọgbẹ ọkan nla ni iku ọmọbinrin naa da silẹ nitori o jẹ daadaa ti gbogbo eeyan fẹran nigba aye rẹ.
Alhaji Ayinde kọ ninu orin nibẹ pe ayọ ni fun gbogbo awọn ijọ Genesis ati fun oun naa to fi mọ idile oun.
5m ni ilẹ̀ Ireland fẹ́ fún Nàíjíríà lára owó tí olórí ológun tẹ́lẹ̀ jí kó 4 Òkùdu 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 16 Ògún 2020 Oríṣun àwòrán, Nigeria High Commision Àkọlé àwòrán, Owo Abacha Ko si ibi ti iranwọ ko ti lee dide fun ẹda, koda, oku gan n se iranwọ owo fun orilẹede Naijiria.
Díẹ̀ lára àwọn ìṣẹ̀lẹ̀ tí yóò mi ìgboro tìtì l'ọ́dún 2020 rèé Gómìnà mẹ́ta àtí ènìyàn 1,242 ló kó sí panpẹ EFCC ni ọdún 2019 Ilé ìwòsàn l'Àbuja ti ya àwọn ìbejì tí wọ́n sọpọ̀ láyà lọ́fẹ̀ẹ́ Wo àwọn mẹ́ta tí Buhari ti dá padà rí lẹ́yìn tí wọ́n yọ wọ́n lóyè Amọ awọn ọmọ Naijiria ati ẹgbẹ oṣelu PDP ko fi ara irẹ gba ọrọ yii, ti wọn si fikun un wi pe owo goboi ni ijọba n gba lọwọ araalu lati tun awọn ọkọ ofurufu yii ṣẹ.
Ẹgbẹ naa ṣalaye pe awọn eeyan bi ọgọrun un mẹfa lo ti kọwọ bọwe pe ki Emery dagbere fun Arsenal.
Joshua naa fẹ ṣe bi agbọjẹ ninu ẹṣẹ kikan, oloogbe Muhammad Ali to ba George Foreman ja ni Zaire lọdun 1974.
Oríṣun àwòrán, Twitter/@aaajimobi Ṣugbọn ṣa, wọn ni awọn araalu yoo ni anfaani lati wo bi eto adura naa ba ṣe n lọ lori amohunmaworan ati lori ayelujara.
Eyi ri bẹẹ lẹyin ti ile ẹjọ kotẹmilọrun kan fi àṣẹ sii.
Ohun tí ó lọ́lá ni igbeyawo.
Ile Igbimọ fẹ gba owo ipolongo ibo lọwọ Gomina to kọ lati fun wọn ni wọn
Ahmed Musa gbàmì ẹ̀yẹ agbábọ́ọ̀lù tó pegede ní ọdún 2018 Liverpool fàgbà han Tottenham pẹ̀lú àmì ayò 2-1 Ilé ẹjọ́ kòtẹ́milọ́rùn yá lórí ọ̀rọ̀ Adeleke- PDP Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ayekofẹnifọrọ: Ó yá, ẹ fi àmì sórí ọ̀rọ̀ náà.
Oríṣun àwòrán, Facebook/govborno Boko Haram kọlu Gomina ipinlẹ Borno O ti le ni eniyan ẹgbẹrun lọna mẹrindinlogoji ti ikọ Boko Haram ti pa lati igba ti wọn ti n ṣọṣẹ lorilẹede Naijiria, ti wọn si ti sọ miliọnu meji eniyan di alairile gbe.
lati ni awon ọkọ oju irin ti a lee lo bayii ki awon oko oju irin
Gege bi iroyin naa se so,“ Ijoba orile-ede Naijiria fi opolopo owo gba awon omo mọ́kànléláàdọ́fà ti o di awati nile iwe alakobere ni agbegbe Dapchi sile, lojo kejidinlogun osu keji odun ti a wayii, eyi ti igbimo Islamic State West Africa Province (ISWAP) lowo si itusile awon omo naa, lojo kokanlelogun osu keta odun ti a wayii,”Alhaji Lai Mohammed fi mule pe, aheso oro lasan-lasan ni eyi je.
Oríṣun àwòrán, Wacol Ọmọ ọhun ti wa nile iwosan Parklane ni ilu Enugu bayii, nibi to ti n gba itọju lọwọ.
níwájú OLUWA, nítorí pé ó ń bọ̀;ó ń bọ̀ wá ṣe ìdájọ́ ayé.
Oríṣun àwòrán, iyaboojofespris Àkọlé àwòrán, Madam Saje atawọn oṣere miran ko gbẹyin nibẹ.
Ogunlọ́gọ̀ ràkúnmí yóo yí ọ ká,àwọn ọmọ ràkúnmí Midiani ati Efa.
Ọ̀jọ̀gbọ́n Richard Akindele tilééwé fásitì OAU Ile-Ife, ni ariwo rẹ̀ gbòde kan pé ó bèèrè láti bá akẹ́ẹ̀kọ́ obìnrin lájọṣepọ̀ fún ìgbà máàrún ọ̀tọ̀ọ̀tọ̀ láti fún ní máàkì.
Bá mi pada lọ, kí n lọ sin OLUWA Ọlọrun rẹ.
Penina bímọ, ṣugbọn Hana kò bí.
Kí ló dé tí Ilẹ̀-Adúláwọ̀ kò ní ẹ̀tọ́ láti ṣẹ̀ gẹ́gẹ́ bí ẹ̀ka tí ó ṣe pàtàkì nínú òmìnira ọ̀rọ̀ sísọ?
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Roman Abramovich ati Cesar Azpilicueta Ki ni akọnimọọgba Chelsea ni lati ṣe ki wọn ma le?
da si ohun to n sẹlẹ ni orile ede Algeria,ni eyi ti won ti n tako ijoba aare
Ìṣọdẹ-àjẹ́ ṣì ń gba ẹ̀mí àwọn ènìyàn ní ìgbèríko India
Akori idanlekoo ohun dale: Awon akoroyin, ojuse ati iroyin eka eto-ilera lorile-ede Naijiria, eyi ti ojogbon Pate ti ile eko giga fafiti Bayero  safihan awon ipenija ti o n koju  awon akoroyin, lara eyi ti a ti ri: ainimo ijinle nipa ise won to, ipolowo-oja, aisi amojuto to peye, aini ife si oro to n sele leka eto-ilera ati awon oro miiran gbogbo.
re pe, iko omo ogun Naijiria n jawe olubori ninu ikolu pelu awon omo ogun olote
Ìjábọ̀ pàtàkì ti àjọ ajàfẹ́tọ̀ọ́ ènìyàn ṣe ní oṣù Èbìbí 2018 rí i pé àwọn èṣọ́ aláàbò ní Burundi, àwọn afòyeṣiṣẹ́ àti àwọn ọmọ ẹgbẹ́ òṣèlú tí ó wà nípò, àwọn ẹgbẹ́ Imbone… ń kọlu àwọn alátakò àti àwọn ẹni tí wọ́n fura sí gẹ́gẹ́ bí alátakò pẹ̀lú ajàfẹ́tọ̀ọ́ ènìyàn àti akọ̀ròyìn.
 Kimono jẹ onkọrin to yatọ nitori o ni arojinlẹ ninu orin rẹ”.
ere asapajude lai bọwọ fun gbendeke kilomita aadọta ere sisa lo tun ṣakoba to pọ ninu ijamba naa.
Eyi si ni ipade akọkọ laarin awọn oloselu mejeeji yii ni gbangba lẹyin igba naa.
Bẹnaya yìí jẹ́ ọ̀kan ninu àwọn ọgbọ̀n akọni jagunjagun, òun sì ni olórí wọn.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Jide Kosọkọ: Isẹ́ tíátà yóò gòkè tíjọba bá gbówó kalẹ̀ láti seré Ile ẹjọ kotẹmilọrun ti kọkọ dajọ pe ko si ẹri to daju to fidi rẹ mulẹ pe magomago wa ninu eto idibo to gbe Ganduje wọle.
Èyí ni apá ìwọ̀ oòrùn ilẹ̀ náà.
Ọwọ́ tẹ babaláwo àti adigunjalè márùń ni Imo - Olọpàá Nigba ti o to asiko kan, o tọrọ aforiji lọwọ iya onile rẹ ti o ṣalaye pe iṣẹ lo faa ti iru iṣẹlẹ bẹẹ ṣe waye pe atunṣe yoo wa.
Bàbá mi sùn lójú ọ̀nà ni ọjọ́ kìíní tí ó kúrò ni ilé, nígbà tí ó sì máa di ọ̀sán ọjọ́ kejì díẹ̀ ló kù kí ó dé ibi tí ó ń lọ.
Ènìyàn mọkanlá lókú tí tí ọ ̀ kànlélọ ́ gọta farapa , mẹ ́ tàlélọ ́ gbọ ̀ n sí dèrò ilé ìwòsàn láìrò tẹ ́ lẹ ̀ .
Bi a ko ba maa ṣe wawu lori ikọlu awọn oluwọde, awọn ara ilu a si maa ṣeemọ lori ọrọ tabi iṣesi awọn oloṣelu ni idahun sawọn iṣẹlẹ to n waye.
 ) fún ní ìwúrí ; kì laya .
Bí aiṣotitọ mi bá mú kí ògo òtítọ́ Ọlọrun túbọ̀ hàn, kí ni ṣe tí a tún fi ń dá mi lẹ́bi bí ẹlẹ́ṣẹ̀?
Pondei daku aasiko to n ṣalaye iye owo ti ajọ NDDC na labẹ iṣakoso rẹ.
Ẹni tó bá ń bá Amotekun jà, ló fẹ́ bá Yorùbá jà - Yoruba World Congress Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Amotekun: Ikọ̀ aláàbò yíì kọjá ọ̀rọ̀ ẹ̀sìn, àwọn ọdẹ àti Àgbẹ̀kọ́yà ló pọ̀ nínú rẹ̀ Kaakiri awọn olu ilu ipinlẹ to wa nilẹ Yoruba lawọn eeyan ti jade lọjọ Aje lati se iwọde alaafia fun itẹwọgba ikọ alaabo alajumọse lẹkun iwọ oorun guusu Naijiria, taa mọ si Amotekun.
Amọṣa, ṣe awọn agba bọ, wọn ni baoku iṣe o tan.
Ṣugbọn bi awọn oluwadii kan ni London School of Hygiene and Tropical Medicine, ṣe sọ, aarun coronavirus ti tan de gbogbo agbegbe ti ajọ eleto ilera l'agbaye, WHO, n mojuto.
Kaka ki wọn ranti ipilẹṣẹ pupo a ma seku pani ti wọn a si ma bani lopo lọna aitọ.
Bakan naa o lọ si ile iwe awọn ọmọ ogun alaabo ti Defence Services Staff College, Wellington ni India lọdun 1973.
Ṣugbọn Ọlọrun ṣàánú rẹ̀, kì í sìí ṣe òun nìkan ni, Ọlọrun ṣàánú èmi náà, kí n má baà ní ìbànújẹ́ kún ìbànújẹ́.
Ọwọ́ tẹ ọmọ ẹgbẹ́ ISIS 2 ní Abuja Olórí ẹgbẹ́ agbẹ́sùnmọ̀mí IS ku bi ajá - Donald Trump Gbàjarè!
àfi igi tí ó wà láàrin ọgbà nìkan ni Ọlọrun ní a kò gbọdọ̀ jẹ ninu èso rẹ̀, a kò tilẹ̀ gbọdọ̀ fọwọ́ kàn án, ati pé ọjọ́ tí a bá fọwọ́ kàn án ni a óo kú.
bàbá wọn rí i pé inú bí i, ó sì pàrọwà fún un.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù 2019 Election: Ọbasanjọ ní ìrètí wà pé Nàíjíríà kò ní pẹ́ ní ààrẹ tuntun 29 Sẹ́rẹ́ 2018 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 13 Ọ̀wàrà 2018 Oríṣun àwòrán, @MBuhari Aarẹ ana ni orilẹ-ede Naijiria, Oloye Olusẹgun Ọbasanjọ ti kede ni pe ọwọ aarẹ orilẹ-ede yii, Muhammadu Buhari ko ni agbara to lati buwlu iwe adehun okoowo ọfẹ nilẹ Afrika.
Lẹ́yìn ọjọ́ mélòó kan tí a kéde èsì ìdìbò ọ̀hún, ogunlọ́gọ̀ àwọn ọmọ China tí wọ́n ń kẹ́kọ̀ọ́ l'ókè òkun fi òǹtẹ̀ lu àpilẹ̀kọ ìfi-èhónú kan ní orí ẹ̀rọ-ayélujára, tí wọ́n sì ń t'ọ́ka àbùkù sí Lhamo pé ó ń l'ẹ̀díàpòpọ̀ pẹ̀lú àwọn àjọ tó ń jà fún òmìnira Tibet.
" bakanna won tun unpe ni "" "" olori wa owon "" "" , "" "" baba wa "" "" , "" "" ologun "" "" ati "" "" generalissimo "" "" ."
Hilahilo lori ọgọrọ ero to n wọ lu ileeṣẹ ajọ iforukọsilẹ kaadi idanimọ lorilẹede Naijiria, NIMC ti mu ki ọpọlọpọ awọn ọmọ Naijiria to wa loke okun ti ko tii gba nọmba naa o maa ko aya soke.
Awo Jogodo ni awọn ijọba nilo lati tubọ ṣe atilẹyin fun ọdun iṣẹṣe naa nitori ohun ni o n mu iranti wa fun awọn ọmọ karọ o jiire lati mọ pataki wọn ni orilẹ agbaye.
Agbẹnusọ Hisbah tí a mọ si ọlọpaa Sharia Adamu Yahaya sàlàyé fún BBC pé ìgbésẹ̀ náà jẹ òhun ti wọn máa ń ṣe ni gbogbo ìgbà gẹ́gẹ́ bi imúrasilẹ̀ de osù ramadani pàápàá jùlọ àwọn agbegbe ti àwọn ǹkan burúkú ti máa ń ṣẹlẹ̀ láti lé ri pé àwọn ènìyàn Kano gbé aradi dé ààwẹ.
O kò gbọdọ̀ bá obinrin kan lòpọ̀ tán, kí o tún bá ọmọ rẹ̀ obinrin lòpọ̀ tabi ọmọ ọmọ rẹ̀, kì báà jẹ́ ọmọ ọmọ rẹ̀ ọkunrin tabi ọmọ ọmọ rẹ̀ obinrin, nítorí pé, ẹbí rẹ̀ ni wọ́n jẹ́, ìwà burúkú ni èyí jẹ́.
 eyi jẹ pe jésù rán jésù lati ṣẹgun iku ati satani .
Iṣimaeli pa gbogbo àwọn Juu tí wọ́n wà pẹlu Gedalaya ní Misipa, ati gbogbo àwọn ọmọ ogun Kalidea tí wọ́n wà níbẹ̀.
Ó máa ń jobì tó fi ataa sínú rẹ̀.
Ìtura ọ̀pọ̀ yanturu (Multiple Orgasms) Eyi ni pe ti o ba gba itura kan, ti o sinmi diẹ, ti o tun gba itura mi lera-lera lai dawọ duro.
Ẹ̀yin ará mi, bí ẹnikẹ́ni ninu yín bá ṣìnà kúrò ninu òtítọ́, tí ẹnìkan bá tọ́ ọ sọ́nà, 
Dafidi rí angẹli náà tí ó dúró ní agbede meji ayé ati ọ̀run, tí ó na idà ọwọ́ rẹ̀ sí orí Jerusalẹmu.
Ẹ̀yin ará Dedani, ẹ pada kíá, ẹ máa sálọ.
Wo òfín tuntun tí INEC ṣe fún ìdìbò 2019 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
“Mo dupe pupo lowo Olorun fun aseyori ise akanse yii, bee si ni Mo tun dupe lowo ijọba apapo, nitori pe, eyi je ohun ti a ti n lero lojo pipe pe ijọba yoo ba wa se.
8 24752 Orilẹede Finland 415 7.
Ṣugbọn igbakeji ikọ Cameroon naa Bernadette Anong sọrọ, o ni gbogbo agbara lawọn o sa lati rii pe awọn fẹyin Naijiria gbolẹ ninu ifẹsẹwọnsẹ ọhun to kangun si aṣekagba.
Ṣugbọn n kò fẹ́ dá nǹkankan ṣe láìjẹ́ pé o lọ́wọ́ sí i, n kò fẹ́ kí ó jẹ́ pé túlààsì ni oore tí mo fẹ́ kí o ṣe.
Nàíjíríà kò gba gbẹ̀rẹ́ lórí Coronavirus, wo itú tà ń pa láti dènà alárùn ní pápákọ̀ òfurufú wa Ìdí tí ìjóba ìpínlẹ̀ Eko fí ṣí àwọn ilé ìwé kan padà Mọ síi nípa ohun tó ṣẹlẹ ní àwọn ibi tí wọn ti ṣilẹkùn ilé ìwé padà lẹyìn Covid 19 Pupọ awọn eeyan ni ko ribi ṣe ayẹwo yi tawọn to si ti ṣe kii tete ri esi ayẹwo wọn gba Ìrìnna ọkọ́ òfúrufú s'ílẹ̀ òkèèrè bẹ̀rẹ̀ padà ní Nàìjíríà Ijọba apapọ orilẹede Naijiria ti kede pe irinna ọkọ ofurufuru si ilẹ okeere yoo bẹrẹ pada ni ọjọ kọkandinlọgbọn oṣu kẹjọ ọdun 2020.
Bayi ti wọn yọ, ko sẹni to le sọ ibi ti yoo ja si.
Fani-Kayode sọ lórí Twitter ní Ojoru wí pé bí Melaye ṣe hùwà nínú fídíò ìṣẹ̀lẹ̀ náà kò fi akin àti iyì hàn.
A jẹ́ aláìní, sibẹ a ti sọ ọpọlọpọ di ọlọ́rọ̀.
Lẹ́yìn tí mo bá kó wọn kúrò tán, n óo pada ṣàánú wọn, n óo dá olukuluku pada sí ilẹ̀ ìní rẹ̀.
Ninu eto tuntun yii, gbogbo ile iṣẹ ijọba ni lati jẹ ki ọfiisi akọwe ijọba apapọ mọ nipa irin ajo ti wọn ba fẹ gun le lọdọdun.
 O wa rọ awọn musulumi lati ma se gegi dina ẹnikẹni to ba fẹ kirun ninu mọṣalaṣi to
O ni “Awọn ẹka ijọba mẹtẹta ni awọn ipinlẹ gbọdọ ṣiṣẹ pọ dardara lojuna ati mu igberu ba ọrọ aje awọn ara ilu.
Kanye West, Ozil, Boyega, àti àwọn gbajúmọ̀ ilẹ̀ ilẹ̀ okèèrè tó ṣàtìlẹyìn fún ìpolongo #ENDSARS Ọba Lamidi Adeyẹmi, òṣìṣẹ́ adójútòfò àti Abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò kó tó jọba Kí ló ń ṣẹlẹ̀ láàfin Oyo táwọn èèyàn fi ń ki Alaafin ní mẹ́sàn án mẹ́wàá?
"Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, International Day Against Drug Abuse and Trafficking: ìdí ti mo fi ń mu oògùn olóró ""Ta ba wo, a lee ni ootọ ọrọ ni aarẹ ile asofin agba n sọ nipa owo osu awọn asofin agba naa, amọ eelo ni apapọ owo ti wọn n mu ls sile losu, o to miliọnu mẹẹdogun naira."
Gbigba ti wọn gba ijọba lọwọ aarẹ Omar al Bashir loṣu kẹrin ati ọrọ dida ijọba pada fawọn alagbada lo n fa wahala ni Sudan bayii.
Theresa May ti gúnlẹ̀ sí South Africa 'Ìpòrúuru bá ìyàwó mi bó ṣe gbọ ohun ọmọ wa' Kíni iyatọ tó wà láàrin FSARS àti SARS?
Irinajo Adebayo Ojo lati ilu Ọgọtun Ekiti ni BBC Yoruba mu wa loni.
ẹni tí ó kú nítorí ẹ̀ṣẹ̀ wa, tí a sì jí dìde fún ìdáláre wa.
Àkọlé àwòrán, Ìyá Leah Sharibu Ẹwẹ, oluranlọwọ pataki fun aarẹ lori ọrọ to kan araalu, Garba Shehu ni ifọrọwerọ ti n lọ lori bi wọn yoo ṣe tu gbogbo awọn to wa ni igbekun Boko Haram silẹ.
Irun ràkúnmí ni wọ́n fi hun aṣọ tí Johanu wọ̀, ọ̀já ìgbànú aláwọ ni ó gbà mọ́ ìdí, eṣú ni ó ń jẹ, ó sì ń lá oyin ìgàn.
“Ìjọba ọ̀run dàbí baálé ilé kan tí ó jáde ní òwúrọ̀ kutukutu láti lọ wá àwọn òṣìṣẹ́ sinu ọgbà àjàrà rẹ̀.
Adebola Ademilua gba awọn ọdọ nimọran lati wa iṣẹ ara wọn ṣe .
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ààrẹ Túnisia kú sẹyin odi lẹ́ni ọdun mẹtalélọ́gọ́rin 19 Owewe 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ààrẹ Túnisia kú sẹyin odi lẹ́ni ọdun mẹtalélọ́gọ́rin Ààrẹ Tunisia nígbà kan rí President Zine el-Abidine Ben Ali tí kú sí ẹ̀yin odi lẹ́ni ọdun mẹ́tàlélọ́gọ́rin.
Awọn ijọba ipinlẹ ti wọn n na owo to yẹ fun eto abo fun ara wọn.
babaloja ati gbogbo ara ilu lapaapo lati sapa won ki won maa pa idoti mo si ibi
Eyi lo si sun awọn ara adugbo lati dide si iya arugbo naa, wọn fi oniruuru iya jẹ ẹ titi to fi gbe ẹmi mi.
Sibẹsibẹ ẹ tún kọ̀ mí sílẹ̀, ẹ sì ń bọ oriṣa.
Ẹni Mímọ́ Israẹli ni Olùràpadà yín.
Ẹni tí ọwọ́ rẹ̀ mọ́, tí inú rẹ̀ sì funfun,tí kò gbẹ́kẹ̀lé oriṣa lásánlàsàn,tí kò sì búra èké.
Nítorí náà, ìwọ aṣẹ́wó yìí, gbọ́ ohun tí OLUWA wí.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Rape: Oríṣí ìjìyà ní àwọn bíi Gómìnà El Rufai àti Fayemi ń bèèrè f'àwọn afipábánilòpọ̀ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Rape: Oríṣí ìjìyà ní àwọn bíi Gómìnà El Rufai àti Fayemi ń bèèrè f'àwọn afipábánilòpọ̀ 2 Agẹmo 2020 Nibo ni ọrọ ile aye n lọ bayii lori ifipabanilopọ?
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fọ́nrán ohùn, Inú mi dùn pé ọmọ obinrin nìkan ni mo bi Ṣaaju awọn oluranlọwọ fun Aisha Buhari nileeṣẹ Aarẹ ti sọ fun BBC tẹlẹ pe irọ to jina si ootọ ni iroyin naa.
Awon ọdọ tun kilọ pe awọn yoo jo agọ ọlọpaa, ti kii ba ṣe ọwọ agbara ofin ti wọn lo.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ṣé ẹ mọ̀ pé àṣà nílẹ̀ Yorùbá ni ìwà ọmọlúàbí?
Coronavirus: Àwọn ohun tí a kò tíì mọ̀ nípa àrùn Covid-19 Àrùn Coronavirus fa'lẹ̀ya láwọn ìletò aláwọ̀dúdú ní Amẹ́ríkà Kí lo mọ̀ nípa fẹntilétọ̀, ohun èlò aṣèrànwọ́ èémí Èyí ni ìdí tí coronavirus ṣe n pa àwọn kan, tí kò sì pa àwọn kan Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Yoo tun ṣe ọdun meji miran fun fun lilo owo ilu nilokulo; ọdun meje miran fun lilo owo ilu fun ifẹkufẹ ara a rẹ; ati ọdun meji miran fun jibiti lilu.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Osun Supreme Court: PDP ní iléẹjọ́ ti sọ tirẹ̀, kò sí ohun tí ẹnikẹ́ni leè ṣe si 5 Agẹmo 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 6 Agẹmo 2019 Oludije fun ipo aarẹ labẹ ẹgbẹ oṣelu PDP Atiku Abubaka, ti fesi si idajọ ile ẹjọ ga julọ nilẹ wa, eyi to ni Gboyega Oyetola ti ẹgbẹ APC ni ojulowo gomina Ipinlẹ Osun, Atiku loju opo Twitter rẹ ni, ipa Adeleke ninu oṣelu ko ti i dopin bo tilẹ jẹ pe o ja kulẹ niwaju ile ẹjọ.
Nínú ìwádìí BBC láti mọ bóya àwọn ikọ̀ agbábọọlù Super Eagles ti gba owó ajẹmọnú wọ́n, BBC ò le fìdí ọ̀rọ̀ múlẹ̀ bóyá wọ́n ti rí àwọn ajẹmọnu náà gbà sùgbọ́n àwọn ayọlo ti wọ́n sọ ko jẹ ki a le sọ pato ibi ti ọ̀rọ̀ dé.
6m lórí ètò BBNaija torí pó sọ̀rọ̀ ìwúrí nípa Nàíjíríà Nigba ti wọn mẹnu le ọrọ oriṣiriṣi nkan to tẹyin awọn idije to waye ninu ile, itakurọsọ, ede aiyede, tawọn araale si n jẹwọ ẹni ti wọn fẹ gbaruku ti tabi bi wọn ṣe n ṣi kuro lẹyin ẹnikan bọ sẹyin ẹlomiiran tawọn eeyan wa n jẹ ọrọ Tacha ati Seyi lẹnu, Seyi fesi pe ọrẹ oun ni Tacha.
Òkú rẹ̀ wà ní ojú ọ̀nà níbẹ̀, kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ ati kinniun náà sì dúró tì í.
yoo maa soju fun won nile igbimo asofin.
Oyetola to je olori awọn osisẹ ni ọfiisi Gomina Aregbesọla lo pegede pẹlu ibo 127,017 láti fi ẹ̀yìn ìgbà kejì olórí ile asofin kékeré l'Abuja Lasun Yusuf tó ní 21,975 àti àwọn Olùdíjé mìíràn na le lẹ̀.
"Ṣugbọn, gbogbo igbiyanju wa lati da wọn lẹkun, to fi mọ awọn ikede ti a ṣe lori rẹdio, ni ko wọ wọn leti.
Oòrùn, òṣùpá, ati àwọn ìràwọ̀ yóo gbọ̀n dànùa óo ká awọsanma bí ẹni ká ìwé.
Ọlọrun tíí ṣí ọ̀nà ni yóo ṣáájú wọn; wọn yóo já irin ẹnubodè, wọn yóo sì gba ibẹ̀ jáde.
Èmi ò mọ̀ pé ikú á máa dá oró lóòótọ́
Ileesẹ ijọba Naijiria sọ pe oun ni gbogbo iwe ẹri pe wọn san owo to yẹ fun akọwe agba ileesẹ to n dari ọrọ ilẹ ni Ghana.
Ní gbogbo àkókò yìí, Josẹfu ni gomina ilẹ̀ Ijipti, òun ni ó ń ta ọkà fún àwọn eniyan láti gbogbo orílẹ̀-èdè.
Ẹro awọn ọmọ Naijiria se ọtọọtọ lori lẹta ti Baba Ọbasanjo ko si Aarẹ Muhammadu Buhari lori isejọba rẹ ọdun mẹrin ati eto idibo osu to n bọ.
 túnde atọ ̀ pinpin náà kọ lẹ ́ tà sí olófìn-íntótó .
Lóòótọ́, fún àwa obìnrin ọ̀pọ̀lọpọ̀ ọjọ́ ni ó le tí ó sì ń dùn èèyàn nítorí pé a ṣì wà ní ipò tí ó jẹ́ pé a máa ń yẹra fún ìjìyà lọ́nà kan tàbí òmíràn.
Atẹjade naa ni eto abo yika ile ijọba ipinlẹ naa ti gbopsn sii lati lee daaboobo dukia ati ẹmi gbogbo.
ti o kowo rin pelu minisita lati ri oludari eka irinna oko ojurin nile-ise
Mo n lọ ra ǹkan ìṣeré ìbálòpọ̀ ti mo ti n la ala rẹ tipẹ.
Ogagun Tukur Buratai to ti ṣiṣẹ ologun fun o le ni ọdun marundinlogoji paapaa ti ki àwọn ọgagun wọnyii ku oriire.
Gẹgẹ bii baba, awọn ọba alaye wa n gba gomina Fayemi nimọran, lorukọ Oduduwa ati awọn alalẹ yoku nilẹ Yoruba, lati tẹẹ jẹjẹ ninu ibasepọ rẹ pẹlu igbimọ awọn lọbalọba, ko si lo ọgbọn agba lati yanju ọrọ naa nitori Yoruba ni ọgbọn isẹdalẹ ti wọn fi n yanju aawọ nilana ibilẹ.
O lede ọrọ naa nigba to'n ba agbarijọpọ awọn ọmọ ẹgbẹ Democrat ati Republican sọrọ ninu ipade kan ti wọn ṣe afihan rẹ lori ẹrọ amohunmaworan.
Nígbà tí àwọn eniyan náà mọ̀ pé Aaroni ti kú, wọ́n ṣọ̀fọ̀ rẹ̀ fún ọgbọ̀n ọjọ́.
Agbára Oṣó àti Àjẹ́ yóò mú àgbéga bá ìmọ̀ ẹ̀rọ Nàíjíríà - Elebuibon Gbajugbaja onimọ nipa iṣegun ibilẹ nilẹ Yoruba, to tun jẹ Araba nipinlẹ Oṣun, Ifayemi Elebuibon, ti gba ipade nla ajọdun ayẹyẹ apapọ ẹgbẹ awọn oṣo ati ajẹ.
Ati pe kii ṣe ohun ti ko wọpọ bi awọn eniyan ṣe lero.
Títí di àsìkò yìí, àwọn ti àwọn ènìyàn yìí ń pé ni ọmọde náà ló n sá sóke sódo fun ìlọsíwáju ẹgbẹ́"" ""Àwá ti di àgbà, ìgbaagba mí si ni láti fún wọ́n lóóre ọ̀fẹ́ láti jẹ́ ki ìtẹ́síwájú wà."
Àwọn agbébọn kan tí gbẹ̀mí Ọ̀gágun àgbà tẹ́lẹ̀ fún iléeṣẹ́ ọmọ ogun òfúrufú Nàìjíríà, Alex Badeh.
Bakan naa ni wọn fikun wi pe iwadii ṣi n tẹsiwaju lori iṣẹlẹ naa.
Gbogbo ohun tí ènìyàn nílò láti dári ni Tinubu ní - APC Ìpínlẹ̀ Osun yóò mú àyípadà bá àwọn ilànà ìṣèjọba Rauf Aregbesola Oluwo yí ìpinnu padà,Telu lóun yóò tẹlé àṣẹ lọ rọọ́kún nílé ṣùgbọ́n.
Ó fi igi Kedari ranṣẹ sí i, pẹlu àwọn gbẹ́nàgbẹ́nà, ati àwọn tí wọn ń fi òkúta kọ́ ilé, pé kí wọ́n lọ kọ́ ààfin Dafidi.
" Ninu ọrọ rẹ igbakeji aarẹ, Yẹmi Oṣinbajo ṣe akawe Gomina Rochas gẹgẹ bii ẹni to ṣe ọpọ aṣeyọri, amọ ti ko pariwo aṣeyọri rẹ sita fun aye ri.
  Aare Buhari panupo pelu ijoba apapo lati kẹdun pelu ebi, ore ati awon ara ipinle Nasarawa fun iku oloogbe naa.
2 bílíọnù fi tún wáyà iná àti inú ilé Aso Rock ṣe- Buhari Tani Akeredolu tó wọlé láti tukọ̀ ìṣàkóso ípìnlẹ̀ Ondo lẹ́ẹ̀kejì yìí?
Ibeere lati ẹnu àwọn ará ilé Àkọlé àwòrán, #BBCOGUNDEBATE: O ṣe pataki láti yan àwọn akanda ẹda si ipò kọmisọna.
Ọba Siria yóo wá gbógun ti ọba Ijipti, ṣugbọn yóo sá pada sí ilẹ̀ rẹ̀.
Bẹẹ si ni aisan kokoro oju ara yii le mu ki eniyan to si ara rẹ ni oru tabi ni ọsan paapaa pẹlu.
O ni awọn ẹkun bii aringbungbun gusu orilẹede Naijiria, ila oorun gusu ati aringbungbun ariwa orilẹede Naijiria naa yoo nilo lati tun ya a lo nitori ikọ alaabo tuntun naa yoo gba ẹkun Yoruba pada lọwọ awọn janduku ati ọdaran to n ṣọṣẹ nibẹ.
Alaga igbimo awon gomina,Abdulaziz Yari ti ipinle Zamfara, ni ila iwo oorun orile ede Naijiria , so lojoBọ pe gbigbẹsẹ le iwe-owo ipinle Benue ko bofin mu.
Èyí ló fà á tí ọ̀kan nínú wọn tì í síta látojú fèrèsé àjà kejì náà.
Wabara so pe ipade ti awon
Ọba Asiria ti rán Rabuṣake, olórí ogun rẹ̀ kan, láti sọ̀rọ̀ ẹ̀gàn sí Ọlọrun alààyè.
Ọmọ Yorùbá mẹ́wàá tó jẹ́ àmúlùúdùn ní Amẹ́ríkà àti Yúróòpù Ènìyàn 653 míràn tún kún iye àwọn tó ní COVID-19 ní Nàìjíríà Àwọn alágbára ni mo bá díje ṣùgbọ́n mo ti gbà f'Olọrun- Agboola Ajayi Ta ni Yusuf Satia ti iku mu lọ?
Nígbà tí ó bá ń ṣe fáàrí, kò ní í sá fún mọ́tò, kò ní yàgò fún klkẹ́, kò ní í fi ọ̀nà sílẹ̀ fún alùpùpì, a wí pé kí aráyé má baà fi òun ṣe yẹ̀yẹ̀, a máa rìn lójú ọ̀nà rélùwé, a dúró sí ojú ọ̀nà de gẹdú, á sì máa fi ejò olóró ṣiré, bẹ́ẹ̀ ni kò ṣọ́ra pẹ̀lú àkeekèé, ó ń rìn kiri ní ọ̀gànjọ́ òru, ó ń káàkíri láàrin ẹ̀fúùfù, bí ó si tílẹ̀ jẹ́ pé kò mọ̀ ìwẹ̀, síbẹ̀ a máa siré ní ibi omi jíjìn, a máa jẹ ìjẹkújẹ káà kiri òde, a máa mu ìmukúmu káà kiri ilé onílé, a sì máa hu onírúurú ìwà àfara káàkiri orí ilẹ̀ ayé, bẹ́ẹ̀ ni ẹni tí ó bá ń ṣe nǹkan wọ̀nyí, olúwaarẹ̀ ń dán Ọlọ̀run Ọba wò, ó ń fi Olódùmarè ṣe yẹ̀yẹ́, ó ń pèsò sílẹ̀ de ọjọ́ ìparrun.
Ilé iṣẹ́ márùn ún tí wọ́n dárukọ kìí ṣe túntun- Garba Shehu Tolani ṣiṣẹ gẹgẹ bi ayaworan fun gomina Ajimobi to tukọ ipinlẹ Oyo lati oṣu kejila lọdun 2014 to fi kuro nipo.
Jagunjagun ni OLUWA, OLUWA sì ni orúkọ rẹ̀.
O ṣalaye pe, ewu to wa ninu iroyin ori ayelujara pọ nitori ni iṣẹju akan ni yoo tan kalẹ kaakiri.
Àwọn èèyàn fi ìtara ba ilé ìjọsìn jẹ́ Ọwọ́ tẹ babaláwo àti adigunjalè márùń ni Imo - Olọpàá Ọ̀nà tó fi le è mọ gbájúẹ̀ babaláwo - Ẹlẹ́buìbọn Iwe iroyin O Globo ni Brazil naa sọ pe awọn alaṣẹ fura si ipe o fẹ na papa bora nigba ti o gba owo to to miliọnu dọla mẹjọ lakoto owo rẹ meloo kan.
Agbẹjọro naa gbiyanju lati ge ẹjọ ti wọn da fun Onyeri si ọgbọn ọdun l'ẹwọn.
Ẹni tí ó bá ṣẹ̀ ni yóo kú: ọmọ kò ní jìyà ẹ̀ṣẹ̀ baba rẹ̀; baba kò sì ní jìyà ẹ̀ṣẹ̀ ọmọ rẹ̀.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Orísi ọ̀gẹ̀dẹ̀: Sàró lo mọ̀ ni àbí Pàǹbo?
Koda awọn ololufẹ Naira Marley kan tilẹ kọlu Ruggedman ni ilu Gẹẹsi lori ọrs yii gẹgẹ bi iroyin ṣe sọ.
Bi o ba ni iṣoro kankan ni o le e tọ oju opo ileeṣẹ ina mọnamọna ẹkun Eko lọ ki o si kọ bi ipenija ti o n koju ba ṣe jẹ sibẹ.
Ẹ kò gbọdọ̀ jẹ ajá mọ́' Dandan kọ́ ni kí Ààrẹ Buhari wọ ìbòmú - ìjọba àpapọ̀ Ìdí táwọn apòògùn Nàìjíríà fi tako oògùn Coronavirus láti Madagascar Ẹgbẹ awọn apoogun lorilẹede Naijiria, PSN ti ni ijọba orilẹede Niajiria ko kọ ibi ara si awọn ogun abẹle ti awọn eniyan n ṣe lati koju arun Coronavirus.
A wò ráràrá bóyá a ó rí ẹnìkan níbẹ̀, ṣùgbọ́n ibẹ̀ dákẹ́ rọrọ ni.
Nigeria Air Force: Mo mọ̀ọ́mọ̀ dá €37,000 ti mo rí he padà ni -Ọmọ ogun Bashir
Ṣaaju ko to du ipo gomina to ṣẹṣẹ ṣe saa rẹ tan lọdun 2019, o ti ṣe sẹnetọ fun saa kan laarin ọdun 2004 si 2007.
Èèyàn 409 míì ti lùgbàdì àrùn Coronavirus ní Naijiria Olu Jacobs: Ipò wo ni gbajúmọ̀ òṣèré tíátà yìí wà?
Dikita naa pari ọrọ pe ki awọn ara ilu joko sile wọn lọna ati dabo bo ara wọn ati awọn ololufẹ wọn."
Ṣugbọn ọ̀rọ̀ tí àwọn gbọ́ kò ṣe wọ́n ní anfaani, nítorí wọn kò ní igbagbọ ninu ohun tí wọ́n gbọ́.
Ọmọ Ọgọta Ọdún kú sórí obínrin ní ilé ìtura ní Èkó
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Kayode Williams ọmọ lẹyin Oyenusi, ògbóǹtarìgì adigunjalè tó ń fi àyípadà rẹ̀ ran àwọn ẹlẹ́wọ̀n lọ́wọ́ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Kayode Williams ọmọ lẹyin Oyenusi, ògbóǹtarìgì adigunjalè tó ń fi àyípadà rẹ̀ ran àwọn ẹlẹ́wọ̀n lọ́wọ́ 28 Ògún 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 1 Owewe 2020 Oyenusi ló mú mi wọ ẹgbẹ́ adigunjalè kó tó di pé mo b'Ólúwa pàdé - Kayode Williams Kayode Williams ni igbe aye ọtọọtọ gba a ni ki eeyan lọ sẹwọn ati ki o tẹwọn de eyi to si nilo ilanilọyẹ akọtun.
A máa tọ́ àwọn onírẹ̀lẹ̀ láti ṣe ohun tí ó tọ́,a sì máa kọ́ wọn ní ìlànà rẹ̀.
Ramoti yìí ni ìlú ààbò fún àwọn tí wọ́n bá ṣèèṣì pa eniyan.
Baba fẹ́ràn Ọmọ, ó sì ti fi ohun gbogbo sí ìkáwọ́ rẹ̀.
Oba Alaye yi ni ti iru eleyi fi le ṣẹlẹ si ọmọ oun, aimọye ọdọ ni iru rẹ yoo ti ṣẹlẹ si.
    Ìgbà tí ilẹ̀ ṣú, a lọ aíle oúnj, ìyàlẹ́nu ló sì jẹ́ ti a ri tí wọ́n tẹ́ tabili lọ gbọọrọ, tí wọ́n ko ṣíbí fàdákà àti àwo fàdákà sílẹ̀ fún ni láti jẹun.
Gbogbo eyín rẹ̀ ni ó kún fún ẹ̀rù.
Bakan naa lo fi kun un wi pe ibọwọ fun ara wa gbọdọ jẹ awọn ọmọ Naijiria logun fun itẹsiwaju orilẹ-ede Naijiria.
Lasiko ti o n dari pada si Maiduguri lati ilu Baga ni iṣẹlẹ yii waye.
Ẹsun to fi kan wọn fa awuyewuye laarin awọn ọmọ Naijria.
Awakọ naa, Isiaka Yinus, to ṣi wa ni ileewosan ijọba sọ pe owurọ ọjọ Ẹti ni ọga oun to ni ọkọ akẹru naa pe oun lati ko ẹru kan to wa ninu ọkọ akẹru miran to bajẹ si ilu Oṣu nipinlẹ Ọṣun lọ si ilu Auchi nipinlẹ Edo.
Ọlọ́pàá ejò yìí gbé ọ̀rọ̀ mi lọ sí iwájú Òjòlà-ìbínú, ó ní mo fi í lé Ọlọ́run Ọba lọ́wọ́.
nítorí kò sí ìyàtọ̀ láàrin òpin eniyan ati ti ẹranko.
Kí ló yẹ kí Àyájọ́ ọjọ́ àwọn èwe Nàìjíríà lọ́dún yìí dá lé lórí?
Awọn ẹbi naa gbiyanju lati mu u wọ inu yara kan ni kọọrọ, eyi to fun ni anfaani lati nawọ si awọn to pe ni ẹbi rẹ.
Ẹgbẹ ajijangbara ti Ken Saro-Wiwa naa bu ẹnu atẹ lu ijọba Sani Abacha fun ipa ti wọn nko pẹlu awọn ile isẹ iwa epo lati ilẹ okeere ti wọn ko fi ofin de wọn.
Awọn onimọ nipa eto abo gbagbọ wipe lilo awọn ologun ilẹ okere ko lee laye laye wa ojutu si iṣoro abo to n doju kọ orilẹede Naijiria lọwọ lọwọ.
Ṣugbọn bí ẹ bá rọ́ àlá náà, tí ẹ sì sọ ìtumọ̀ rẹ̀, ẹ óo gba ẹ̀bùn, ìdálọ́lá ati ẹ̀yẹ ńlá, nítorí náà ẹ rọ́ àlá náà fún mi, kí ẹ sì sọ ìtumọ̀ rẹ̀.
“Erongba wa ni lati jawe olubori ninu ifesewonse yii, sugbon a gba oomi ayo, ni eyi ti o si tun je esi ti o se faramo.
ó pe àwọn ọkunrin tí wọ́n wà ninu ilé rẹ̀, ó sọ fún wọn, ó ní, “Ẹ wo nǹkan, ọkọ mi ni ó mú Heberu yìí wá láti wá fi ẹ̀gbin lọ̀ wá.
"Ṣugbọn ṣa, agbẹjọro kan, Amofin Sali Adebayo sọ fun BBC Yoruba pe ""awọn ofin fi aaye gba awọn aṣofin, lati ranṣẹ pe aarẹ lori ohunkohun ti wọn ba n fẹ alaye lori rẹ""."
"Mo ti gbiyanju lati pa a mọra, ki n si gbe ọrọ naa kuro l'ọkan mi, ṣugbọn, ko rọrun.
Àwọn odi wọ̀ nyí jẹ́ gẹ́ gẹ́ bíi ìfàlà sílẹ̀ tí àwọn onílẹ̀ yìí fi dá ilẹ̀ tiwọn yàtọ̀ sí ti ẹlòmíràn.
Nígbà náà ni ọba sọ fún Joabu pé, “Mo ti pinnu láti ṣe ohun tí o fẹ́ kí n ṣe.
Amọṣa ọrọ yi pada ni ọjọru nigba ti ile ẹjọ naa tẹti si ẹbẹ awọn igun mejeeji lati yanju aawọ naa ni tubiinubi laarin ara wọn APC kò ní olórí tí yòó tọwọ́ bọ̀wé, INEC yarí fún ìbò abẹ́nú l‘Ondo Ọ̀dàlẹ̀ ni Igbákejì Gómìnà, kìí ṣe pé a dẹ́yẹ si - ìjọba Ondo Ìhòhò ọmọlúàbí ni mo má a ń bá àwọn ọmọkùnrin mi wí - Elesho Èyí ni àwọn arẹwà ‘ẹ̀lẹ̀ Daddy’, àfẹ́fẹ́ tí Aláàfin fi ń mí Obaseki: Kí ló dé tí Aàrẹ Buhari kìí fí í dá sí aáwò àwọn ọmọ ẹgbé APC?
Ijọba orilẹ-ede Canada ti ni ọpọlọpọ ijiroro gbọdọ waye lori igbeṣẹ Ọmọọba Harry ati Meghan lati wa bẹrẹ si ni gbe ni Canada.
Nigbati àwọn Òṣèlú gba Ìjọba ni igbà keji lọ́wọ́ Ìjọba Ológun, inú ará ilú dùn nitori wọn rò wi pé Ológun kò kọ iṣẹ́ Òṣèlú.
Ẹ̀wẹ̀, agbẹjọrò fún ìjọba ìpínlẹ̀ Oyo, Ọgbẹ́ni Oluwaseun Dada sọ fún ilé ẹjọ́ pe, iwé ìpẹ̀jọ pe ki Makinde ma tú ilé ka kò ti dé ọdọ àwọ̀n, nítori náà ko tíi yẹ fún ìgbẹ́jọ.
Ayinla Ọmọwura, orin èébú àti oríyìn lo fi di ọ̀rẹ́ àwọ̀n obìnrin Ẹrí rè é, Sanwo-Olu ṣèlérí lóòtó lórí súnkẹrẹ-fàkẹrẹ Apapa Àwọn àṣà àti ìse tó yọ obìnrin sílẹ̀ nílẹ̀ Yorùbá Ènìyàn 721 fi ayédèrú ìwé ẹ̀rí gba iṣẹ́ ìjọba àpapọ̀ - ICPC Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Fún ọjọ́ meje tí ẹ óo fi ṣe àjọ̀dún yìí, yóo mú ọ̀dọ́ akọ mààlúù meje ati àgbò meje tí kò ní àbààwọ́n wá fún ẹbọ sísun, ati òbúkọ kọ̀ọ̀kan fún ọjọ́ kọ̀ọ̀kan fún ẹbọ ìmúkúrò ẹ̀ṣẹ̀.
 fún ìdí èyí , ó ṣe pàtàkì kí ọ ̀ pọ ̀ ènìyàn tí ó ju bíi 80 % gba abẹ ́ rẹ ́ àjẹsára .
Kí á sì lọ sí ibi tí Àpótí Majẹmu Ọlọrun, tí a ti patì láti ayé Saulu wà, kí á gbé e pada wá sọ́dọ̀ wa.
Bi igbesẹ naa se waye ko dun mọ
Laarin asiko ti wọn fi n ko awọn ọmọ naa pada, idaduro ba awọn nkankan l'awọn agbegbe kan lati le ri daju pe ko si idiwọ kankan, ati pe ko si ẹmi to s'ofo."
Ní ọjọ́ kẹrinla oṣù yìí, láti àṣáálẹ́ ni àwọn ọmọ Israẹli yóo ti máa ṣe Àjọ̀dún ìrékọjá gẹ́gẹ́ bí òfin ati ìlànà rẹ̀.
Ko si eto idibo to pe nibiki lagbaye, koda titi de orilẹ-ede Amẹrika pẹlu.
Oríṣun àwòrán, @not_oyedepo 2015 ni mo ti ń kígbe pé gudugbẹ̀ máa já ní Nàíjíríà - Oyedepo Oyedepo ní àwọn ọ̀dọ́ lẹ́tọ̀ọ́ láti tako bí ọlọ́pàá ṣe ń pa wọ́n ní ìpakúpa Biṣọọbu Oyedepo jẹ ọkan pataki lara awọn ojiṣẹ Ọlọrun ni Naijiria ti kii fi ọrọ sabẹ ahan sọ lori ojuṣe tabi aṣiṣe ijọba Pasitọ agba ninu ijọ Living Faith lagbaye, David Oyedepo ti da si ọrọ iwọde End SARS to n lọ kaakiri awọn ilu nla nla ni Naijiria.
  Pelu ile ti o kun fun awon agbaboolu lolokan-o-jokan, awon aworan yii safihan bi won se n gbafe leyin igbaradi ni kikun saaju ifigagbaga naa.
Benhadadi ọba gba ohun tí Asa wí, ó sì rán àwọn ọ̀gágun rẹ̀ láti lọ gbógun ti àwọn ìlú ńláńlá Israẹli.
Jeremaya wolii bá dá Hananaya wolii lóhùn níṣojú àwọn alufaa ati gbogbo àwọn ará ìlú tí wọn dúró ní ilé OLUWA, 
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ajọ asọbóde ṣe agbéga fun osiṣẹ̀ rẹ̀ tó kọ̀ rìbá O ní onífàyàwọ́ ọ̀hún tún jẹ́ẹ̀jẹ́ pé òun yóò sàn rìbá tó tún pọ̀ jùbẹ́lọ ti tí àkọ́kọ́ yìí ba ṣe dáradára.
Ó lè gé igi kedari lulẹ̀, tabi kí ó gbin igi Sipirẹsi, tabi igi Oaku, kí ó jẹ́ kí ó dàgbà láàrin àwọn igi inú igbó.
Ìlú kò mọ ohunkóhun nípa iṣẹlẹ màálù tó kú nilu Ikarẹ- Oba Olukarẹ Wọ́n ti ṣí ilé oúńjẹ oní ọgbọ̀n náírà (N30) ní Kano Ẹ wo ojú owó ìrẹ̀sì báyìí lẹ́yìn tí ìjọba ti ibodè pa Ìdí tí mo ṣe fẹ́ yọ ayédèrú ìdí ńlá tí mo ní- Sophie Bakan naa wọn ni awọn yoo ṣe ohun to tọ lati da awọn ti wọn ri itusilẹ yii pada sọdọ awọn mọlẹbi wọn lalafia.
3 7585 Orilẹede Nicaragua 162 2.
Oríṣun àwòrán, Twitter/Nigerians in Diaspora Comm Ni nnkan bi ọjọ meji sẹyin ni ọta le lugba ọmọ Naijiria o din meje balẹ si Naijiria lati ilẹ Gẹẹsi.
Bi awọn ìyà mi gba aṣẹ niyi, ti wọn si bẹrẹ si i da ọmọ eeyan laamu - ori ffiọ, inu rirun, iṣẹ ti ko lọ deede, wọn n mu ẹjẹ wọn, ati bẹẹbẹẹ lọ.
 Ṣùgbọ ́ n , àwọn náà kò rọ ́ mọ bí , nìyá wọn bá tún gboko aláwo lọ ̀ .
Wabba tun ni  ki won so fun gbogbo omo orile ede Naijiria boya won ti fenuko lori iye kan.
Blessing ni gbogbo eeyan lo mọ pe Ọlọrun pari iṣẹ si ẹyin oun, o ni awọn to ni ipenija oju kan to ba sun mọ oun le mọ bi ikebe oun ṣe tobi to.
pẹ̀lú àmì ayò méjì sí òdo.
Sanwo-Olu fẹ́ fojú-rinjú pẹ̀lú ọmọ tó ní kí ìyá òun ‘Calm down’ Keisha sàlàyé ìdí tó fi sunkún ní ìyàrá ìrántí nílé ẹlẹ́gbọ̀n ọ́n àgbà, ayé pariwo Wo ìyàtọ̀ tó wà láàrin Bíbélì Yorùbá tí Kumuyi kọ sí èyí tó wà ńlẹ̀ Ìjọba Èkó yóò fi òfin dè títà afẹ́fẹ́ gáàsì létílé láti dènà ìbúgbàmú láwùjọ Ninu atẹjade kan ti alukoro ileeṣẹ to n ri si eto ẹkọ, Ben Goong, fi lede, wọn ni idanwo aṣewọle si awọn ile iwe ijọba apapọ, Unity Schools naa yoo waye lọjọ kẹtadinlogun oṣu kẹwaa.
"Ko si dara ki awọn asaaju nilẹ Yoruba, ti a ko asa le lọwọ, maa ba asa jẹ, eyi ko bojumu to.
Èmi ni mo sá mu yín jáde láti ilẹ̀ Ijipti, tí mo rà yín pada kúrò lóko ẹrú; tí mo rán Mose, Aaroni ati Miriamu láti ṣáájú yín.
Pẹ̀lú bí gbogbo nǹkan ṣe ń lọ, yóò fẹ́rẹ̀ẹ́ pẹ́ díẹ̀ kí orílẹ̀-èdè Nàìjíríà ó tó le è ní Ààrẹ tí kò ní nǹkan ṣe pẹ̀lú, tàbí tí kò ní àtìlẹ́yìn ‘ẹgbẹ́’ àwọn ọ̀gágun ajagun fẹ̀yìntì.
Abenugan ile igbimo asofin orile ede Naijiria, Dokita Bukola Saraki yoo saaju awon asoju lati ile igbimo asofin lo sorile ede Russia lojo Isegun , lati se ipade pelu ile igbimo asofin orile ede Russia , lati  jiroro  nipa oro to je mo ile igbimo asofin ati bi ibasepo orile ede mejeeji naa yoo se tun munadoko si i.
” Ṣugbọn ọ̀rọ̀ tí Juda sọ yìí kò dé inú rẹ̀ nítorí ẹ̀rù ń bà á pé kí Ṣela náà má kú bí àwọn arakunrin rẹ̀, Tamari bá pada lọ sí ilé baba rẹ̀.
Lẹ́yìn tí Judasi ti gba òkèlè náà, Satani wọ inú rẹ̀.
O fi ọna kan báyìí hán wa, òun ni a sì gbà títí a fi fi ìlú àwọn ẹyẹ sílẹ̀ ní ibi tí ògòǹgò ti ń ṣe ọba wọn.
Nigeria Population: Báwọn ọmọ Nàíjíríà ṣe ń pọ̀ si jẹ́ ìpèníjà fún Buhari
 Gomina Dapọ Abiọdun (Ogun): Ẹ jẹ ki ifarajin ti ẹ ṣe lasiko Ramadan tubọ fa yin sunmọ Ọlọrun."
O ni ailọ sileewe awọn ọmọ naa, to jẹ iṣẹ maalu dida kiri nikan ni wọn fi nkọ wọn, jẹ ara nkan to n fa iwa jagidijagan.
Àìgbọ́ran sí igbákejì ààrẹ Yemi Osinbajo lẹ́nu ló fa ìdàmú mi-Okorocha Kí ló sọ Okorocha di Wòlíì àgbà tuntun?
Awọn ara orilẹede Iran, Afghanistan ati Iraq ko fi oju abo àgbò sere rara ati ọpọlọ rẹ.
Awọn ọmọ ikọ amuṣẹya ẹgbẹ naa to lọ ko awọn obinrin naa sọ pe awọn yabo awọn ile-ijo ati ile ọti nibi ti awọn ti ko awọn obinrin nikan nitori pe aṣọ pempe ni ọpọlọpọ wọn wọ.
Fẹstu bá pàṣẹ kí wọ́n mú Paulu wá.
Gomina Masari sọ pe afojusun Aarẹ Buhari ni lati ṣawari awọn ọmọ ọhun.
Nítorí yóo mú kí àṣírí èrò ọkàn ọpọlọpọ di ohun tí gbogbo eniyan yóo mọ̀.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Zidane: Ọjọ́ ọ̀la mi kò nìí se pẹ̀lú ife ẹ̀yẹ UCL 1 Èbibi 2018 Oríṣun àwòrán, EPA Àkọlé àwòrán, Real Madrid wàákò pẹ̀lú Bayern Munich nínú ìdíje Champions League.
Lai Mohammed ni oun gbe igbesẹ naa lẹyin ti oun gba aṣẹ lọwọ Aarẹ Muhammadu Buhari to paṣẹ atunṣe naa lẹyin gbogbo ọrọ kubakugbe to waye ni Naijiria saaju idibo gbogboogbo ti ọdun 2019.
A kò gbọ́ tìrẹ OLUWA Ọlọrun wa, bẹ́ẹ̀ ni a kò pa òfin rẹ tí o fi rán àwọn wolii, iranṣẹ rẹ sí wa mọ́.
"A ni lati kọ awujọ ti yoo mu ki awọn ọmọ Naijiria ni ifọkanbalẹ pe ko si ewu fun wọn.
Global Vaccine crisis: Ìgbẹ́kẹ̀lé nínú abẹ́rẹ́ àjẹsára ń di òkú l'ágbáyé!
Ìfẹ́ àìlópin ni mo ní sí ọ,nítorí náà n kò ní yé máa fi òtítọ́ bá ọ lò.
Ọrọ naa da awuyewuye silẹ ti Toyin si sọ pe oun fi ọrọ yii lọ agbejẹro rẹ, Legal House Solicitors.
Lẹyin ti ijọba apapọ paṣẹ wi pe ki awọn ile ẹkọ di titi pa ni Barakat kuro ninu ọgba ile ẹkọ ti a ti n kọ nipa ilera ohun ọsin ati ohun ọgbin, Federal College of Animal Health and Production"", ni agbegbe Apata nilu Ibadan gẹgẹ bi akẹkọọ to n bẹ ni ipele akọkọ."
44 fún lítà kan Ìdí rèé táwọn àkàndá ẹ̀dá fi dí iwájú iléeṣẹ́ ìjọba ìpínlẹ̀ Oyo pa l'Agodi n'Ibadan A kò ní padà sílé ìwé àyàfi t́i ìjọba bá san owó oṣù tó jẹ wá - ASUU Ohun tó yẹ kí o mọ̀ nípa ìgbésẹ̀ tí Amẹ́ríkà fẹ́ gbé lórí Nàìjíríà nítorí ọ̀rọ̀ ẹ̀sìn Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ojú mi ti rí lọ́pọ̀ lọpọ̀, àmọ́ mo dúpẹ́ pé mo ti pé ọdún márùn ún lórí oyé- Ooni Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Akure shooting: Àlááfíà ti padà sí ìlú Akure, ẹnikẹ́ni kò kú - Deji ilu Akure7 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Ondo 2020 Tribunal: Ìgbìmọ̀ olùgbẹ̀jọ́ ìbò gómìnà yóò gbérasọ lọ́jọ́ Iṣẹgun7 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Aisha Buhari: Aya Ààrẹ Buhari ké sí àwọn aya gómìnà pé kí wọ́n lọ paná ìdàrúdàpọ̀ ágbègbè kóówá7 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Fídíò, Soyinka Cancer: Àṣe ara mi ni iso ti n run gbogbo bí mo ṣe n ṣèrànwọ́ lórí jẹjẹrẹ27 Bélú 2019 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Minisita feto abo ilẹ Naijiria wa fi kun-un pe, igbimọ naa ti fọwọ sii ki awọn osisẹ ileesẹ eto abo nijọba apapọ o lọ fikuluku pẹlu asoju ijọba ilẹ Amẹrika ni ilẹ Naijiria, ọgbẹni Stuart Syminton lati yannana ọrọ naa.
Awọn ọdaran yi ko sẹsẹ ma sọsẹ laaye ibi ti wọn ti ji Kọmisana gbe.
Ọwọ́ wọn tẹ Sedekaya, wọ́n bá mú un lọ sọ́dọ̀ ọba Babiloni ní Ribila, ó sì dá ẹjọ́ fún un.
Kọmiṣọnna fun eto aabo ni Kaduna, Samuel Aruwan gboṣuba fawọn oṣiṣẹ iṣẹlẹ pajawiri ninu iṣẹ ibanikẹdun to fi ṣọwọ si ẹbi awọn ti iṣẹlẹ naa mu ẹmi wọn lọ.
Awon agbofinro atawon osise eleto aabo gbogbo lo n rirn irin oju lalakan fi n sori kiri.
Da Ògì sinú àpò ki ó lè gbẹ fún ìtọ́jú
mọ laasigbo ti a n koju gẹgẹ bi ẹkun kan ninu eyi ti iwa
Zarka ni ọkọ oun ko jẹri oun, nitori igbagbọ rẹ pe oun maa n ṣe agbere.
waye laarin rẹ ati aare orile ede naa ,Mohamed Abdullahi Mohamed Farmaajo.
Wọn fifọnran kan sita loṣu to kọja eyi to fi oju awọn ti wọn ji gbe ọhun han.
Awọn ti eyi kan julọ ni awọn osisẹ ile itura, ile iwe, ibudo igbafẹ, ati bẹẹ bẹẹ lọ to yẹ ki wọn ti seto sisan owo ori wọn saaju ọjọ kọkandinlọgbọn, osu kẹjọ, ọdun 2020.
Bi iye awọn eeyan to ṣẹṣẹ ko arun naa kaakiri Naijiria ṣe lọ ree: Lagos-653 Plateau-63 Benue-48 Zamfara-45 FCT-42 Rivers-27 Ondo-26 Adamawa-26 Kaduna-22 Edo-18 Ogun-16 Imo-12 Kano-9 Yobe-6 Ekiti-5 Jigawa-4 Osun-2 Lọ́jọ́ Àbámẹ́ta èèyàn mẹ́jọ mìíràn ló pàdánù ẹ̀mí wọ́n lọ́wọ́ ààrùn COVID-19 ní Nàìjíria Oríṣun àwòrán, Twitter/ncdc Nilẹ ọjọ Abamẹta to ṣu ni Naijiria, iye eeyan to dagbere faye gba tọwọ aarun Covid-19 ni Naijiria tun ti lekun si.
O óo rí i bóyá ohun tí mo sọ fún ọ yóo ṣẹ, tabi kò ní ṣẹ.
6m ni mo fi borí Buhari, ojú òpó INEC gan leè jẹ́rì si - Atiku Owó dé!
ipinle Kaduna,  Nasiru El-Rufai naa tun
Àkọlé àwòrán, Iku ba ọla Abiola jẹ́ L'ọdun 1994 lo kede ará rẹ gẹgẹ bii aarẹ Naijiria ni eyi ti wọn fi fi Abiọla satimọle nibi to ti pada jẹ Olorun nipe.
 Ṣùgbọ ́ n ní ìgbà tí ọ ̀ rùnmìlà fi wà láyé yìí naa , a tún maa lọ sí òde ọ ̀ run lẹ ́ ẹ ̀ kọ ̀ ọ ̀ kan tí olódùmarè bá pèé láti wá fi ọgbọ ́ n rẹ ̀ bá òun tún òde-ọ ̀ rùn ṣe .
Ojogbon Oyewusi Ibidapo-Obe ti o je oga agba ile-eko fafiti teleri, University of Lagos, ti o tun je alaga ayeye naa ro awon omo orile-ede Nigeria lati tunbo kowo lori oja idokowo.
Nígbà tí àwọn ọkunrin marun-un náà pada dé ọ̀dọ̀ àwọn eniyan wọn ní Sora ati Eṣitaolu, àwọn eniyan wọn bi wọ́n léèrè pé, “Báwo ni ọ̀hún ti rí?
O ni ko ba ofin mu bi wọn se tii Sowore mọle, ti Ajọ ọtẹlẹmuyẹ DSS si kọ lati fi silẹ nitori pe Sowore n pe fun atunto Naijiria lọna to ba ofin mu.
” Ó ní kí wọ́n máa lọ, wọ́n sì lọ; ó bá so okùn pupa náà mọ́ fèrèsé rẹ̀.
Fi ìtẹ́ àánú sórí àpótí ẹ̀rí ninu ibi mímọ́ jùlọ.
Jesu tún sọ fún àwọn eniyan pé, “Nígbà tí ẹ bá rí i tí òjò ṣú ní ìwọ̀ oòrùn, ẹ óo sọ pé, ‘Òjò yóo rọ̀.
Obinrin to ni ominira Yoruba ni bi a ṣe n dagba, la n gbọn si.
ó rán Joramu ọmọ rẹ̀ láti kí Dafidi ọba kú oríire, fún ìṣẹ́gun rẹ̀ lórí Hadadeseri, nítorí pé Hadadeseri ti bá Toi jagun ní ọpọlọpọ ìgbà.
Opolopo awon omo ipinle Osun  lo  si n tu yaya-yaya lati dibo ninu eto idibo gomina to  n lo lọwọ bayii.
Ẹ̀wẹ̀, fónrán iṣẹ́jú meji kan ṣẹ́yọ lórí ayélujára, èyí tó sàfihàn ìtiràka rẹ̀ lórí bi yóò ṣe gba ìwòsàn lórí ìṣòro ẹsẹ̀ tó n bá fíra lásìkò ọ̀ún.
Yan àwọn tí o fẹ̀ fún ẹgbẹ agbábọ́ọ́lù ààyò rẹ Orin kíkọ kò dí ìwé mi lọ́wọ́ rárá -Hameen School Boy Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí 2 sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 2:23 Fídíò, Water Generator: Ó leè ṣiṣẹ fún wákàtí mẹfà, kó tó sinmi, Duration 2,2310 Òkùdu 2020 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
Omi yìí ni Aaroni ati àwọn ọmọ rẹ̀ yóo fi máa fọ ọwọ́ ati ẹsẹ̀ wọn.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù 2020 Public Holidays: Àwọn ọjọ́ ìsìnmi tó máa wà nínú ọdún 2020 ní Nàìjíríà 13 Sẹ́rẹ́ 2020 Oríṣun àwòrán, @others Àkọlé àwòrán, Isinmi dun pupọ lẹyin iṣẹ!
'Ààrùn sickle cell ti lóògùn báyìí' Buhari: Ipa pàtàkì ni Fasheun kó nínú ẹgbẹ́ NADECO Ààrẹ Ethiopia tẹ́lẹ̀ Giorgis papòdà lẹ́ni ọdún 94 Stephen Hawkins to jẹ Ogbontarigi onimọ sayẹnsi naa lọ loṣu kẹta ọdun lẹyin to koju arun iṣan ara fọdun mejilelogun.
Sola Sobowale gbàmì ẹ̀yẹ òṣèré tíátà obìnrin tó dáńtọ́ jùlọ Olóṣèlú tó nílé kiri, tó tún fẹ́ jẹ ààrẹ Nàíjíríà, ẹ kò ní lọ láì pọ ohun tí ẹ jí - Tunde Bakare Awọn adoola ẹmi naa fi atẹgun inu igo si ara ọmọ naa ti o wa ninu kọnga ọhun, bo tilẹ jẹ pe wọn ko le sọ pato ipo ti ọmọ naa wa.
Pilatu tún bi wọ́n pé, “Kí ni ẹ fẹ́ kí n ṣe sí ẹni tí ẹ̀ ń pè ní ọba àwọn Juu?
awon oluko ti  ijoba apapo ni Kano (Federal
Nígbà tí wọ́n rí i pé kò sí nǹkan kan tí ó ṣe wá wọ́n wọ́n mú wa ó di ilé Òjòlá-ìbínú tí í ṣe olórí ejò ayé gbogbo.
’ Bakan naa ni iya Tolulope ṣe apẹjuwe ọmọ rẹ gẹgẹ bi ẹni ti o fẹran lati gbadura ati awe.
Àwọn obìnrin ló pọ̀ níbẹ̀ jù lákòókò yìí, etí ènìyàn gbọ́ nǹkan.
igbé aye wa ṣẹ̀ṣẹ̀ bẹ̀rẹ̀ papọ̀ ni, o ti di ara wa bayìí ọmọ mi jòjòló.
 Lẹyin eyi ni ọkan lara awọn ọlọpaa to fi ara pa ṣẹṣẹ sọ pe ọlọpaa ni awọn, ati pe, lati olu ileeṣẹ ọlọpaa l'Abuja ni wọn ti ran awọn niṣẹ ikọkọ naa lati lọ gbe balogun ikọ ajinigbe kan.
Àwọn òṣèlú UK fi yé aráyé pé àwọn ọmọ orílẹ̀èdè tí àwọn kà sílẹ̀ nì, wọn kò kí ń ṣábàá fẹ́ padà sílé lẹ́hìn tí àkókò tí a fún wọn ba tán.
"Aare Muhammadu Buhari sọ pe o jẹ ""ajalu nla fun orilẹede Naijiria"" ati fun awọn obi ati ẹbi awọn ọmọbirin naa."
Ó yàtọ̀ láti èdè kan sì òmíràn.
Oga agba eka awon to n pin oogun arun naa, Dokita Margaret Ekpenyong  lo so eyi di mimo lasiko to n soro lori idojuko ti won n ri lati ri oogun naa lasiko ni Naijiria.
Papakọ ofurufu ti Nmandi Azikwe ni ipinlẹ Eko ni Ajọ EFCC ni awọn ti mu Mompha, lẹyin ti ile isẹ ọlọpaa ilẹ okeere Interpol tawọn lolobo nipa igbe aye Mompha.
Ó gun òkè gíga,ó kó àwọn eniyan nígbèkùn;ó gba ẹ̀bùn lọ́wọ́ àwọn eniyan,ati lọ́wọ́ àwọn ọlọ̀tẹ̀ pàápàá.
Ó tún tẹnu mọ́ ọn dáadáa pé kí á má ṣe ńi èrò àtilọ rárá nítorí pé bí a bá lọ, kò sí àníàmí pé ọ̀pọ̀lọpọ̀ yóó ṣègbé sí ọ̀nà láàrin wa.
Osun Election Results: Wọ́n ti ka ìbò Ọṣun tan, ìkéde INEC lo kù
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Sudan coup: Ṣé ìfipágbàjọba àwọn ológun kò maa pọ̀ si l'Afirika?
Àjọ àgbáyé tọ ń rí sí ọ̀rọ̀ oúnjẹ (FAO) sọ wípé, Naijiria jẹ́ ọ̀kan lára àwọn orílẹ̀ède tó ń jẹ ìrẹsì jú ní àgbáyé, Báwo ni ẹ ṣe ń jẹ ìrẹsì tó nínú ilé yín?
Oyo wa bayii ko lee faaye gba ijoba lati bẹrẹ sisan ẹkunwo naa.
"Wọ́n ṣe èyí lóòni nígbà tó ràn àwọn amúgbálẹ́gbẹ̀ẹ́ rẹ̀ Patricai Komolafe àti àwọn adari ẹgbe rẹ ni Kwara lọ láti lọ fi owo náà jíṣẹ́ Oríṣun àwòrán, Rafiu Abdul Ilorin Blue Eyes Family: Ìyá àwọn ọmọ tí bàbá kọ̀ sílẹ̀ torí àwọ̀ ojú wọn bá BBC sọ̀rọ̀ ""Abi ṣe oju buluu yii kan naa kọ ni baba Kausara ri lara iya rẹ nigba to yofẹẹ rẹ to fi ṣe ""Wos fáín gẹẹ̀lì""?"
O fikun un pe ajọ NAFDAC ko fi ontẹ lu oogun kọlẹra Dukoral lorilẹ-ede Naijiria.
Iru awọn iroyin ti ẹ le nifẹ si: Ishaq Oloyede: Jamb ko nii fi esi idanwo silẹ ni kiakia Saraki pe fun ajọṣepọ Ghana ati Naijiria Abẹwo Buhari si Taraba Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Òun náà sì dáhùn, ó ní, ‘Ọgbà bàbá mi, Èmi náà tún béèrè, mo ní, Ta ni baba tí ó bí ọ?
Oko ofurufu aare Buhari ati awon ti o tẹle
Mo mu ago owo goolu to jẹ ti Baba mi, mo wọ ọ lọ sileewe lati fi ṣe fọri fọri fawọn ọrẹ mi.
Ẹni to ba fẹ lọrọ ninu Oluwa ko gbọdọ fi idamẹwa ati ififunni ṣere,'' Oyedepo lo sọ bẹẹ.
Amọ, Ọgbẹni Lawal ni ko si ewu kankan lori ọrọ naa, o ni gbogbo rẹ ni yoo ni iyanju laipẹ.
Ó ní,“Èmi óo pe orúkọ rẹ ní gbangba fún àwọn arakunrin mi.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ile aṣofin Kwara da'ba fif'opin s'owo osu ọna meji 28 Èrèlè 2018 Oríṣun àwòrán, TWITTER/ALI AHMAD Àkọlé àwòrán, Ile igbimo asofin Kwara ni akọkọ ti yoo gba abadofin yi wole Ile igbimọ asofin nipinlẹ Kwara ti fọwọ si aba ofin kan ti yoo dẹkun sisanwo ifẹyinti fun awọn to ba jẹ gomina tabi igbakeji gomina nigba kan ri nipinlẹ naa.
Ẹ̀rọ ayélujára wa, Móhùnmáwòràn àti Rẹdíò, ìròyìn tó pé ti ko sì ní ẹja ń bákan nínú, ti ó dádúró tí ó sì wà fún òótọ́ ní BBC ń ṣe.
" Nitori ile mi sun mọ ẹgbẹ titi mọ maa n gbọ fere awọn Tutsi bi wọn se n ko awọn eniyan lo si ileijọsin gẹgé bi Mukamushinzimana ṣe sọ nibi to joko si ni kọrọ ọgba ẹwọn pẹlu omije lọwọ.
Ọ̀pọ̀ gèlè lati òkè òkun ṣòro lati wé nitorina bi enia ò bá we dáadáa, kò ni yẹni.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Cameroon wa ìyà mu bíi gaàrí lọ́wọ́ England, 3-0 ló bá dé 23 Òkùdu 2019 Oríṣun àwòrán, Reuters Àkọlé àwòrán, Niṣe ni ẹkun gba ẹnu awọn agbabọọlu Cameroon lẹyin ti VAR fagile goolu ti wọn jẹ Wọn ṣe iwọn ti wọn le ṣe amọ, ikọ agbabọọlu obinrin orileede Cameroon ti fidirẹmi lọwọ England pẹlu ayo mẹta si odo.
Àwa mọ̀ pé Ọlọrun ti bá Mose sọ̀rọ̀, ṣugbọn a kò mọ ibi tí eléyìí ti yọ wá.
Ìbẹ̀rù eniyan a máa di ìdẹkùn fún eniyan,ṣugbọn ẹni bá gbẹ́kẹ̀lé OLUWA yóo wà láìléwu.
O ní ǹkan ìtìjú ní láti rí irú ǹkan bẹ́ẹ̀ lórí Twitter.
Awọn to ṣoju wọn koro ni kan ni o jọ bii pe alawọfunfun ni to wa ni nkan bii ẹni ọgbọn ọdun o ṣẹ le diẹ.
Ó ní tí eyí bá wáye ǹkan yóò túbọ̀ rọrùn ni Nàìjíríà ní.
Osu kẹta ọdun 2019 lo bi ọmọkunrin kan ti wọn sọ orukọ rẹ ni Khalid, ti ayaba yii kii si na oju opo ayelujara to bẹẹ.
Ninu osu kesan ọdun to koja, kiniun kan pa ọkunrin kan ton fun ni ọunje nigboro ilu Ibadan.
Oòrùn ti yọ nígbà tí Lọti dé Soari.
Ọlọ́run kò ní í jẹ́ k’a r’írú rẹ̀ mọ́.
Oríṣun àwòrán, Others Ẹkọ ti itan manigbagbe yii kọ wa: Itan manigbagbe yii lo n ran wa leti pe bi aye ba yẹ wa tan, ka mase hu iwa ibajẹ nitori igba ko tọ lọ bii orere, aye ko tọ lọ bii ọpa ibọn Ninu itan yii, o to sba meji ti wọn padanu itẹ wọn nitori aawọ obinrin, eyi si yẹ ko kọ awọn eeyan nla nla, olowo, ọlọrọ, gbajumọ ati awọn ọdọ lọgbọn pe obinrin ko see foju kere nitori agbara to wa lọwọ wọn lee fa isubu ọkunrin Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Brain Squad: Àwọn ọmọdébìnrin Nàìjíríà ṣe App"" ìrànwọ́ owó iléèwè Bakan naa la kọgbọ pe ọpa ẹru, wọn maa n fi ni, ko si yẹ ki awọn ọba alaye ati awọn asaaju wa ro pe awọn ni alagbara to ga julọ nitori oni la ri, ko sẹni to mọ ọla, Ọlọrun nikan ni alagbara Itan yii tun kọ wa gbe obiri laye, to ba lo siwaju, o tun lee lo sẹyin, saa si ni ẹda ni, ẹnikan ko nile aye."
    Èṣù náà bá mú u lọ, ṣùgbọ́n ìyàlẹ́nu ló jẹ́ fún wa nígbà tí a dé ibẹ̀ tí ó jẹ́ pé àwọn ẹranko ni a bá, kìnìhún, àgbọ̀nrín, ẹkùn, ìkóòkò, ẹfọ̀n, erin, màlúù, ràkúnmí, esin, àgùnttàn, ewúrẹ́, kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́, ajá, ológbò, èkúté, òkétá àti àwọn bẹ́ẹ̀ lọ.
"Innocent Mburanumwe, tii se igbakeji oludari ibudo igbafẹ naa ni ""awọ̀n inaki yii n sin eeyan adarihunrun jẹ ni, ti wọn yoo si duro lori ẹsẹ wọn mejeeji bii eeyan lati yan fọto, bẹẹ ni wọn yoo gan pa."
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Funke Olakunrin Burial: Ọ̀gọ̀rọ̀ èèyàn péjú síbi ìṣẹ̀yẹ ìkẹyìn f'ẹ́ni re tó lọ 22 Agẹmo 2019 Àkọlé àwòrán, Isinku Funke Olakunrin Àkọlé àwòrán, Eto isinku Funke Olakunrin Àkọlé àwòrán, Eto isinku Funke Olakunrin Àkọlé àwòrán, Eto isinku Funke Olakunrin Àkọlé àwòrán, Ọkọ ati awọn ọmọ oloogbe nibi eto isinku fun Funke Olakunrin Àkọlé àwòrán, Eto isinku for Funke Olakunrin Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Ebi, ara ati awọn ojulumọ ni gbogbo wọn n ṣe idaro ẹni rere to lọ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fọ́nrán ohùn, Pius Adesanmi ní Wole Soyinka ìran yìí - ọmọ Naijiríà Diẹ lara awọn ibi ti Pius ti ṣiṣẹ ni fasiti Pennsylvania ni America, French Institute for Research in Africa ati ti South Africa ko to wa di ọjọgbọn ni fasiti Carleton ni Ottawa, ni orilẹ-ede Canada.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Olólùfẹ́ mi ṣèèsì fi ọkọ́ gbá mi sí gọ́tà, mo rò pé ọlọ́jọ́ dé ni - Iya Osogbo Torí ₦300, awakọ̀ ojú omi ṣokùnfà ikú èèyàn méjìlá l‘Eko - Ọlọ́pàá Láì san owó oṣù tẹ jẹ wá, kò sọ́rọ̀ kankan - ASUU sọ fún ìjọba Ìjọ́ mí ní Italy ni mo fi ń ṣèrànwọ́ fáwọn aṣẹ́wó ọmọ Nàíjíríà tó há - Taribo West Àwọn òṣèré tíátà Yorùbá kọjú ìjà síra wọn lórí ìdárò akẹẹgbẹ́ wọn tó kú Ìpàkọ́ kò gbọ́ sùtì ní ọ̀rọ̀ ẹ̀yin tí ẹ̀ ń bú mi- Oyedepo Mo kọ̀ láti pín ọkọ mi pẹ̀lú ẹnikẹ́ni, nítorí náà ẹ tú wa ká- Abílékọ Idowu faraya ní kóòtù kọkọ-kọkọ Keita ni iyawo, Aminata Maiga, wọn si bi ọmọ mẹrin.
Nigeria gba Òmìnira ni bi ọdún mẹrindinlọgọta sẹhin.
Wọ́n kúrò ní Òkè Hori wọn lọ sí Salimona.
Orilẹede South Africa ni wọn ti bii, igba to ta oju opo isanwo ori ayelujara, Paypal fun ileeṣẹ eBay lo fi pa owo to le ni ọgọjọ biliọnu dọla ($160m) Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Oba Adedokun Abolarin ti Oke Ila: Ó ya ọ̀pọ̀ tó súnmọ́ mi lẹ́nu bí mo ṣe ń kọ́ Yatọ si ileeṣẹ SpaceX, o lowo ninu idasilẹ ileeṣẹ miran bii Tesla, ileeṣẹ to n ṣe ọkọ to n lo ina ẹlẹntiriki dipo epo rọbi, Hyperloop ati bẹẹ bẹẹ lọ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Auxilliary : Sunday Igboho kìí ṣe ọmọ ìbàdàn, òun gan ló ń dá Ibadan ru Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Auxilliary : Sunday Igboho kìí ṣe ọmọ ìbàdàn, òun gan ló ń dá Ibadan ru 13 Ìgbé 2020 Sunday Igboho kìí ṣe ọmọ ìbàdàn, òun gan ló ń dá Ibadan ru, Auxilliary fún Sunday Igboho lésì Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí 3 sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 2:23 Fídíò, Water Generator: Ó leè ṣiṣẹ fún wákàtí mẹfà, kó tó sinmi, Duration 2,2310 Òkùdu 2020 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Mò ń fi lẹ̀kẹ̀ ya àwọnran láti jèrè ǹkan méjì - Olaniyi Olaniyan Aarẹ Buhari rọ awọn ọmọ Naijiria ni gbogbo ipinlẹ lati yago fun iwa bi adiẹ ba dami loogun nu, maa fọ lẹyin ti ede-aiyede ba bẹ silẹ laarin wọn.
Oríṣun àwòrán, unilag Ẹwẹ, ajọ eto ẹkọ ni Abuja ti kilọ fawọn ileeẹkọ lati ma se bẹrẹ isẹ pada nitori pe awọn ko ti pasẹ eyi to faye gba iru igbesẹ bẹ.
 Àwọn ọ ̀ rọ ̀ náà ní nọ ́ mbà adúróṣinṣin ( tó únjẹ ́ olùsọdipúpọ ̀ ọ ̀ rọ ̀ náà ) tó le jẹ ́ sísọdipúpọ ̀ pẹ ̀ lú nọ ́ mbà adópin kan ti àwọn ayípadà ( tó únjẹ ́ ṣíṣojú pẹ ̀ lú lẹ ́ tà ) .
Igbo Olodumare rèé, níbi tí Ìgbín ti tóbi ju Ìjàpá lọ Wo oríṣìí àrùn márùn ún tí ìgbéyàwó láàrin ìbátan si ìbátan máa ń fà Adeboye ló sọ àsọtẹ́lẹ̀ pé màá wọlé ìbò gómìnà lẹ́ẹ̀kejì, ó sì rí bẹ́ẹ̀ - Obaseki Iléeṣẹ́ epo rọ̀bì ná ₦116m lórí báírò, ìwé ìkọ̀wé, àwọn aṣòfin fìka hánu Dapọ jẹ ọkan lara awọn ọmọ gbajugbaja oniṣowo nni, Otunba Kunle Ojọra; oun si tun ni aburo fun Toyin Saraki to jẹ iyawo aarẹ ile aṣofin agba tẹlẹ, Sẹnetọ Bukọla Saraki.
Gíga àgbékà kọ̀ọ̀kan ilé náà jẹ́ igbọnwọ marun-un; 
“Ẹnikẹ́ni tí ó bá sọ ọ̀rọ̀ kan lòdì sí Ọmọ-Eniyan, a óo dáríjì í.
Ọpọlọpọ awọn to fesi lori ẹrọ ayelujara bu ẹnu atẹ lu igbesẹ ijọba saaju ifẹhọnu awọn ọmọ Naijiria, eleyii ti Sowore jẹ asaaju fun.
    Bí a ti dé ibi ìlẹ̀kùn yìí ni ìlẹ̀kùn sí fúnrarẹ̀ tí gbogbo wa sì wọlé.
Wọ́n so aṣọ aláwọ̀ aró tẹ́ẹ́rẹ́ kan mọ́ ọn, láti máa fi so ó mọ́ etí adé náà gẹ́gẹ́ bí OLUWA ti pàṣẹ fún Mose.
”Alakoso naa tun so pe ijọba ibilẹ  merin tuntun naa ni  yoo je ipele kerin  ti yoo wa ni Gusu ilu Abuja, eyi tun jẹ ilana to ti wa tele fun idagbasoke  fun ilu Abuja.
Tó bá jẹ́ lóòótọ́ ni àwọn èròjà náà dùn tó bẹ́ẹ̀, kí ló ṣe tí àwọn ilé-oúnjẹ ìyókù ò ṣe máa lò wọ́n se oúnjẹ tiwọn?
Aadọrin péré ni àwọn baba ńlá yín nígbà tí wọn ń lọ sí ilẹ̀ Ijipti; ṣugbọn nisinsinyii, OLUWA Ọlọrun yín ti sọ yín di pupọ bíi ìràwọ̀ ojú ọ̀run.
Ṣugbọn nítorí àánú rẹ ńlá, o kò jẹ́ kí wọ́n parun patapata, bẹ́ẹ̀ ni o kò pa wọ́n tì, nítorí pé Ọlọrun olóore ọ̀fẹ́ ati aláàánú ni ọ́.
Abẹnugan ile igbimọ asofin naa, to wọ aṣọ amọtẹkun sọ wi pe ni kete ti gomina ipinlẹ Ondo, Rotimi Akeredolu ba ti buwọlu abadofin naa, ni iwa ọdaran yoo dẹkun ni ipinlẹ naa.
11 Àti kíyèsíi, mo wí fún ọ, pé nítorí tí wọn ti pààrọ̀ àwọn ọ̀rọ̀ wọ̀nyí, wọn kà lòdì sí ohun tí ìwọ túmọ̀ àti tí o mú kí a kọ;
Oun ìní díẹ̀ tí wọ́n tún ni, àti iṣẹ́-òòjọ́ wọn náà sì ni wọ́n ti bá iná lọ.
“Ẹ ṣe kíá, ẹ wá lọ sọ́dọ̀ baba mi kí ẹ wí fún un pé, Josẹfu ọmọ rẹ̀ wí pé, Ọlọrun ti fi òun ṣe olórí ní gbogbo ilẹ̀ Ijipti, ẹ ní mo ní kí ó máa bọ̀ lọ́dọ̀ mi kíákíá.
Aarẹ Buhari n lọ sinmi ni London fun ọjọ mẹwa
 Àwọn tí ó ń sọ èdè yìí ní baluchistan tó múlíọ ̀ nù ( iran ) , afuganíísítáànù ( afghanistan ) àti in-índíà ( india ) .
Àyipadà burúkú yi ni obìnirin Trudy Alli-Balogun gbé dé ẹnu iṣẹ́ lati ja ilé iṣẹ́ rẹ ni olè ọ̀kẹ́ aimoye, ti ó si na owó bẹ́ ẹ̀ ni ìná àpà lai ronú orúkọ burúkú ti ó rà fún Yorùbá àti gbogbo orilẹ̀ èdè Nigeria ni Ilú-Ọba àti pé irú iwà ibàjẹ́ yi ló ba ohun amáyédẹrùn jẹ ni Nigeria.
Wọ́n mú ọkunrin tí ó ṣépè náà jáde kúrò láàrin ibùdó, wọ́n sì sọ ọ́ ní òkúta pa.
Wọ́n tún bi ọkunrin afọ́jú náà pé, “Kí ni ìwọ alára sọ nípa lílà tí ó là ọ́ lójú?
Ẹwẹ, iroyin s pe ọlọpaa kan lati agọ Ajiwe ti ko fẹ fi oju han sọ pe ọwọ ti tẹ awọn afurasi kọọkan ti iwadii si ti n lọ lọwọ lati igba ti wọn ti wa fi ọrọ naa to wọn leti.
"Dangote, Fayemi pari ìjà láàrin Ganduje àti Emir Sanusi Italy dá àwọn aboyun àt'ọmọ wẹ́wẹ́ pada Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Àìríṣẹ́ṣe ló mú àwọn ọ̀dọ̀ fẹ̀mí wọn wéwu Akintola ni ajọ to n ri si iwọle wọde Naijiria ni ipinlẹ Oyo sọ pe laarin ọmọde mẹfa si mẹwaa lawọn ti gba silẹ, ""ọjẹ wẹwẹ si lawọn wọnyi o; awọn mii t'ọjọ ori wọn ko tii to mejidinlogun naa la tun ti gba silẹ lagbegbe yii."
” Jakọbu bá gbé oúnjẹ náà súnmọ́ ọn, ó jẹ ẹ́, ó bu ọtí waini fún un, ó sì mu ún.
Laipẹ yii ni ijọba ilẹ naa kede pe awọn eeyan lati ilẹ mii ko ni lanfaani lati ṣiṣẹ Hajj fun ti ọdun 2020.
El Helicoide lo yẹ ko jẹ ile itaja to lokiki ju lagbaye plu ọṣọ rẹ to ga lọ soke roo ro to fi to iwọn iye ile itaja ọọdunrun eleyi ti wn la kalẹ pe yoo wa ninu ile naa.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ondo Elections 2020: Ọgọ́rùn-ún ọdún tí a máa lò lórí oyè l'Ondo, ẹ ó rí àrà - Ojon YPP Oníṣẹ́ ọwọ́, oníṣẹ́ àdáni, awakọ̀, ẹ wo ọ̀nà láti gba lára owó ìrànwọ́ Covid-19 tí ìjọba gbékalẹ̀ Wo ọ̀nà àbáyọ sí bo ṣe ń han‘run Dapo Abiodun yan Laycon ní aṣojú pẹ̀lú ẹ̀bún ₦5m àti ilé oníyàrá mẹ́ta ENDSARS: Ẹ̀yin ọmọ Nàìjíríà, ẹ ṣè ìrànwọ́ irinṣẹ́ fáwọn ọlọ́pàá- Naira Marley bẹ̀bẹ̀ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Àwọn kan ṣónú bí wọ́n bá di gómìnà, ẹ fún wa láyè láti wá parí iṣẹ́ táa bẹ̀rẹ̀ - Akeredolu Adájọ́ sọ wòlíì Sotitobire àtàwọn márùn-ún míì sẹ́wọ̀n gbére!
Ọjọ Iṣẹgun si ni ijọba kede iyọnipo rẹ Awọn onimọ kan ni Naijiria ti ẹ sọ pe , ti iwadii ba fi fidirẹmulẹ pe lootọ ni alaga ajọ EFCC, ti wsn ṣkṣẹ gba iṣẹ lọwọ rẹ, Ibrahim Magu, ba fi jẹ ootọ, pe yoo ta ẹrẹ si awọn aṣeyọri ti ijọba sọ pe oun ti ṣe lori igbagun ti iwa ibajẹ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù UEFA Champions League 2019: ilé ló máa bọ́sí fàwọn ọmọ Afrika loni 1 Òkùdu 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ọmọ Afirika mẹfa lo wa ninu ẹgbẹ agbabọọlu mejeeji yii Agbábọ́ọ̀lù ọmọ Áfíríkà mẹ́fà tó ṣeéṣe kó gba ife ẹ̀yẹ UEFA Champions league lónìí.
Wọ́n gba fóònù afurasí náà, títí di ìgbà ti ọwọ́ òfín ba wọ́n, fóònù méjèèjì ti wọ́n gbà ni wọ́n ti sọ di ti àra wọ́n ti wọ́n ń lò.
[Ìròyìn tó tẹ̀wá lọ́wọ́] Luz Mely Reyes tí ìṣẹ̀lẹ̀ náà ṣe ojúu rẹ̀, fi tó wa létí nípa bí àwọn Agbófinró SEBIN ṣe yẹ ilée Díaz pẹ̀lú ilée Soto náà wò.
Awọn ara agbegbe naa ti n figbe sita loju opo ayelujara pe ki awọn alaṣẹ tọrọ kan tete wa seranwọ lati pa ina ọhun.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ganduje: Gòmìna Ganduje ni yíyọ Sanusi nípò Emir Kano wà fún àtúnṣe ètò oyè jíjẹ ní ìlú Kano 16 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Oríṣun àwòrán, Twitter/Maigaskiya Gomina ipinlẹ Kano, Ganduje ti sọ pe oun ko kabamọ bi oun ṣe rọ Emir ilu Kano tẹlẹ, Sanusi Lamido Sanusi loye.
yorùbá ní ìlànà tí wọ ́ n ń tẹ ̀ lé láti fi ọmọ fọ ́ kọ tàbí gbé ìyàwó .
 “eleyii jẹ anfani lati jẹ ki ijọba ati awọn ara ilu fikunlukun jiroro lati mọ okan wọn, ki wọn si le mọ ona abayọ.
Wọ́n gbẹ́ igi ọ̀pẹ, ati òdòdó, ati àwọn kerubu sí ara àwọn ìlẹ̀kùn náà, wọ́n sì fi wúrà bo gbogbo wọn.
Ọpọlọpọ orílẹ̀-èdè yóo wá, wọn yóo sì wí pé,“Ẹ wá, ẹ jẹ́ kí á lọ sórí òkè OLUWA,ẹ jẹ́ kí á lọ sí ilé Ọlọrun Jakọbu,kí ó lè kọ́ wa ní ọ̀nà rẹ̀,kí á sì lè máa tọ̀ ọ́.
Olukọni kan ti o ba awọn oniroyin sọrọ lẹyin ikọlu naa pe wọn o ji ẹnikankan gbe.
Ẹ máa pa á nítàn fún àwọn ọmọ yín ati àwọn ọmọ ọmọ yín, 
Lẹ́yìn náà wọ́n kó ohun ìní rẹ̀.
Awọn papakọ ofurufu bi i ti ilu Eko, ati Abuja ni yoo kọkọ bẹrẹ iṣẹ, ko to o kan awọn ilu yooku.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Olúbàdàn: Ìgbésẹ̀ Ajimọbi tako ìsèjọba ìsẹ̀ǹbáyé 8 Èbibi 2018 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 22 Ògún 2018 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Olúbàdàn àti gómìnà Ajimọbi wojù ara wọn lórí oyè jijẹ nilú Ìbàdàn Osi Olubadan ti ilẹ Ibadan, Rashidi Ladoja lo pe ọkan lara awọn ọba alade tuntun naa lẹjọ.
Amọ ṣa iwaadi naa kan na lero wi pe o le ni mẹjọ ninu awọn mẹwa to fara kasa iku lọwọ ololufẹ wọn jẹ obinrin.
Iléẹjọ́ gíga Akure kọ̀ láti gba onídùróó olórí ìjọ Sotitobire Ọwọ́ ọlọ́pàá tẹ afurasí tó ní òun ló jí ọmọ gbé láti parọ́ mọ́ pásítọ̀ ìjọ Sotitobire Ẹ má gbàbọ̀de kankan láti tú Wolii ìjọ Sotitobire sílẹ̀ o!
Amọ ṣa, ifaraṣeṣe rẹ lọpọ igba ko jẹ ki o da bi ẹdun, kó rọ̀ bi òwè fun Arsenal lati nnkan bii ọdun kan abọ sẹyin, eyi si ni ọpọ n wo gẹgẹ bii idi ti o fi n fẹyinti ni Arsenal.
Oríṣun àwòrán, @nassnigeria Àkọlé àwòrán, Ọpọ ọmọ Naijiria lo ti n pariwo lori ohun to faa ti aṣiri ayederu iwe ẹri agunbanirọ minisita feto iṣuna tẹlẹ ṣẹṣẹ n foju han.
ede Naijiria nilo awon adari ti yoo le ko gbogbo awon eniyan mọra, ni eyi ti
Seyi Makinde: Àwọn iléẹkọ́ àdáni le è lọ fún ìsinmi ìdajì táámù
O tun kede pe awọn oṣiṣẹ oju popo LASTMA aadọta ati ọgọrun un mẹfa ni yoo wa nibẹ lati maa ri si lilọ bibọ ọkọ.
Kí ló dé tí ikọ̀ ìjọba Oyo kò fi ráyè wọ́lé síbi àdúrà ọjọ́ kẹjọ fún Ajimobi?
ṣagbekalẹ aba eto iṣuna-owo odun 2019.
Ṣugbọn ta ni arakunrin ti awọn ọlọpaa ilẹ Dubai ati ọtẹlẹmuyẹ Amẹrika gbe, fun ẹsun gbajuẹ olowo iyebiye yii?
Nítorí wọn kò ṣe eniyan ní anfaani, wọn kò sì wúlò rárá.
Aisaya bá sọ fún àwọn iranṣẹ ọba pé kí wọ́n fi èso ọ̀pọ̀tọ́ sí orí oówo rẹ̀, kí ara rẹ̀ lè dá.
''Ohun to tun yẹ ki a gboriyin fun ni ajọsepọ laarin Amọtẹkun ati awọn fijilante ọlọdẹ ati Miyetti Allah.
Ṣugbọn n kò gbàgbọ́ títí tí mo fi wá, tí mo sì fi ojú ara mi rí i.
Ọbasanjọ ni bi o tilẹ jẹpe awọn obi oun jiya pupọ lori oun sibẹ, o ba oun ninujẹ, to si se oun laanu pe wọn ko duro lati foju ri itan aye oun to ja si rere.
Ti a ba n kàá ni meni meji, o yi ku ipele bii mẹta ki aarẹ to buwọlu abadofin yi ko si daju pe wọn yoo rii ṣe ki saa ijọba yi to pari.
Alaga egbe Peoples Party of Nigeria , Razak Eyiwumi,ni egbe awon faramọ
1 2150 Erekusu Reunion Island 41 4.
Nigba ti , iye eniyan to ti ni arun Coronavirus ni ipinlẹ Eko kaakiri ti le ni ẹgbẹrun mejidinlogun.
Ọmọ mi, má ṣe kẹ́gàn ìtọ́ni OLUWA, má sì ṣe jẹ́ kí ìbáwí rẹ̀ sú ọ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù James Bond: Gbajúgbajà òṣèré, Sean Connery tó ṣe fíìmù James Bond tí jáde láyé lẹ́ní ọdún 90 31 Ọ̀wàrà 2020 Oríṣun àwòrán, PA Media Gbajugbaja oṣere, Sean Connery ti gbogbo eniyan mọ si James Bond gẹgẹ bi orukọ ere to ṣe ti jade laye ni ẹni aadọrun ọdun.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Secret Cults in Nigeria: Ọwọ́ ọlọ́pàá tẹ àwọn ọmọ ẹgbẹ́ òkùnkùn tó yìnbọn 12 Owewe 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 28 Owewe 2020 Oríṣun àwòrán, Nigeria Police Ogun State Awọn ọmọ ẹgbẹ okunkun Black Axe kan to n ṣe idaro akẹgbẹ wọn ni ọwọ awọn agbofinro ti tẹ nilu Ogijo, nipinlẹ Ogun.
Agbẹnusọ fun Oba Saliu Adetunji, Oloko Adeola lo sọ bẹẹ lasiko to n ba BBC Yoruba sọrọ lori igbesẹ awọn ọba yii.
Ó bi wọ́n pé, “Ṣé kí á lọ gbógun ti Ramoti Gileadi tabi kí á má lọ?
O ni ọda owo, ohun eelo ati irinsẹ lo n da oun laamu, erongba oun si ni lati maa se mọto fun lilo awọn ọmọ Naijiria.
“Èmi Jesu ni mo rán angẹli mi láti jíṣẹ́ gbogbo nǹkan wọnyi fún ẹ̀yin ìjọ.
Iyawo rẹ naa, atawọn ọmọ rẹ mẹta ni wọn bẹ ẹ wo nibi ti gomina ipinlẹ Nasarawa, Abdullahi Ganduje le si ni ipinlẹ nasarawa.
Ní àkókò náà, rògbòdìyàn bẹ́ sílẹ̀, tí kì í ṣe kékeré, nípa ọ̀nà Oluwa.
Àkójọ́pọ̀ àwòrán rèé lórí bí ìwọlé akẹ́kọ̀ọ́ ṣe lọ sí ní Oyo Bí Hushpuppi ṣe tiraka rèé l‘Eko, kí ọlà ‘òjijì’ tó dé Akẹ́kọ̀ọ́ wọlé padà, ìjọba Oyo kò pèsè ìbòmú lòdì sí ìlérí rẹ̀ Ẹ wo bí ọ̀rọ̀ òṣèlú, ẹ̀sìn àti ẹ̀yà ṣe fa ogun abẹ́lé Biafra Kàkà k‘éwé àgbọn dẹ̀ lágbo òṣèlú l‘Ondo, akọ̀wé ìjọba tún kọ̀wé fipò sílẹ̀ Ẹ wo bí ọ̀rọ̀ òṣèlú, ẹ̀sìn àti ẹ̀yà ṣe fa ogun abẹ́lé Biafra Bẹẹ ba gbagbe, laipẹ yii ni igbakeji gomina nipinlẹ Ondo kuro ninu ẹgbẹ oselu APC, to si dara pọ mọ ẹgbẹ oselu alatako, PDP.
Ó fún wọn ní ohun tí wọ́n bèèrè,ṣugbọn ó fi àìsàn ajẹnirun ṣe wọ́n.
Fidio bi nkan ṣe ri ni aafin Emir ilu Kano, Sanusi Lamido Sanusi lẹyin ti ijọba ipinlẹ Kano rọ ọ l'oye.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Losu kẹrin ọdun 2014 ni ikọ Boko Haram ji akẹkọbinrin to din diẹ ni ọọdunrun gbe lọ nilu Chibok lkun ariwa Naijiria.
Nengi tun jẹ owo Bitcoin to to ẹẹdẹgblta Dọla, ati aṣoju ileeṣẹ.
Fatai Owoseni to je kòmisónnà ajo ọlọ́pàá tẹ́lẹ̀ ní ìpínlè Èkó àti Benue ni Seyi Makinde kede pe ko bẹre iṣẹ loṣu kẹjọ ọdun yii.
Ẹwẹ, abẹnugan ile aṣofin nipinlẹ Edo, Marcus Onobum ti ni lootọ ni awọn aworan to n ja ranyin lori ayelujara wi pe awọn ẹlẹwọn gbiyanju lati sakuro ni ọgba ẹwọn amọ wọn ko ṣe aṣeyọri.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Òndó: Ọ̀gá àgbà àjọ ẹ̀ṣọ́-aláàbò ojúupópó (FRSC) dolóògbé 2 Èbibi 2018 Oríṣun àwòrán, @FRSC AKURE/ FACEBOOK Àkọlé àwòrán, Ọ̀gbẹ́ni Jack jáde láyé lẹ́yìn àìsàn ránpẹ́.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Minimum wage: Buhari ti buwọ́lu sísan ẹ̀kúnwó oṣù tuntun fáwọn òṣìṣẹ́ àpapọ̀ 17 Agẹmo 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Iroyin ayọ sọkalẹ fawọn oṣiṣẹ bayii paapaa awọn ti wọn ko gba ju ẹgbẹrun lọna ọgbọn naira lọ tẹlẹ.
Ọ̀ràn aya-eré-ìtàgé Min Htin Ko Ko Gyi tún fi ìrísí ìhámọ́ tí a há àwọn akọrin pàtàkì mọ́.
Lati ọdun 2006 ti ina ti jo ile aarẹ ni wọn ti gbe ọfisi aarẹ lọ si ọfisi alaja mẹfa ti ileeṣẹ to n ri si ọrọ ilẹ okere n lo.
Fi ojúlówó wúrà ṣe ẹ̀wọ̀n tí a lọ́ pọ̀ gẹ́gẹ́ bí okùn fún ìgbàyà náà.
Ṣugbọn nigba ti ọjọ kẹtadinlogbọn, osu Kẹta kọja ti coronavirus ko ti i ko ẹrù rẹ pada sibi to ti wá, awọn eniyan fi pasitọ naa ṣe ẹléya.
Elikana dá a lóhùn pé, “Ṣe bí ó bá ti tọ́ ní ojú rẹ.
A ti kọwé sí ìjọba àpapò làti pe agbaṣèṣe odò Asa padà- Gomina Kwara Àwòrán bí ẹ̀kún omi ti ṣọṣé l'Eko àtàwọn ìlú míì nílẹ̀ Yorùbá rèé Aisha Buhari, ohun mẹ́fà tò fi yàtọ̀ sí àwọn aya ààrẹ tó ti jẹ kọjá!
Ẹgbẹ́ alágbèlébù pupa ní ìsẹ̀lẹ̀ náà ká wọn lára bẹ́ẹ̀ sì ni wọ́n ní ìmọ̀lára rẹ̀.
Nígbà tí ẹ bá rí i, ẹ wá ròyìn fún mi kí èmi náà lè lọ júbà rẹ̀.
"Nínú ìwádìí tí ilé ìṣe BBC Yoruba ṣe, ojo náà pọ gidigidi tí ó wà di ti ""boolo - ó- yàgò"" èyí tí ó mú kí ọmọbìnrin náà sá fún ojo náà lai mọ wípé, ibi tí ólọ́jọ́ yóò ká òhun mọ ní yìí."
Lẹ́yìn èyí, Absalomu wá kẹ̀kẹ́ ogun kan, ati àwọn ẹṣin, ati aadọta ọkunrin tí wọn yóo máa sáré níwájú rẹ̀.
Pada sinu àkọ̀ rẹ, máa sinmi kí o sì dúró jẹ́ẹ́.
Ìpèníja to ga jùlọ, àti àwọn orilẹ̀ -èdè tó kéré jùlọ ninú gbígba abẹ́rẹ́ ajẹ sára, ti ìja ìdámu àti iyàn si kún ibẹ̀ mi Afghanistan, Angola, àti DR Congo.
Bàbá Wande, lásìkò to ń bá BBC Yoruba sọ̀rọ̀ ni, ọmọ bibi ìlú Osogbo ni òun, tí òun sì lọ sile ẹ̀kọ́ alakọbẹrẹ Ansardeen àti ilé ẹ̀kọ́ mọda.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Buhari: Ẹ̀rù ìdìbò tó yanrantí kò bà mí APC pàdánù aṣòfin míràn ní'pínlẹ̀ Osun 'Ààrẹ Buhari kò náání àwọn ọmọ Nàìjíríà tó fọkàn tán an' Awọn akanṣe iṣẹ ti ọrọ kan ni opopona marosẹ Eko si Ibadan, afara keji ori odo Niger pẹlu opopo alasopọ ẹkun ila oorun si iwọ oorun orilẹede Naijiria.
 “Erongba orile-ede Islamic Republic of Iran ni lati fese ajosepo mule pelu awon orile-ede ile Africa ni paapaa, awon orile-ede ti won je omo-egbe ajo isokan ile Africa, Nipa mimu igberu ba eto oro-aje laarin orile-ede mejeeji, asoju Zarchi fi mule pe, awon asoju oludokowo ti n ba ara won soro, lati le bere okowo fun idagbasoke orile-ede mejeeji naa.
Geriṣoni bí ọmọ meji: Libini ati Ṣimei, wọ́n jẹ́ olórí àwọn ìdílé wọn.
Kí nìdí tí Ooni Adeyeye Ogunwusi fi gbé Àrẹ̀mọ ilẹ̀ Oodua wọ ṣọ́ọ̀ṣì?
O si tun s'ọrọ nipa kikan titun ilẹ pin l'oju, pẹlu sise apejuwe bi yoo ti mu idagba s'oke ba oro aje orilẹede naa ati bi yoo ti pese ise.
Ṣùgbọ́n ẹ gbọ́ o, ṣèbí bí a ó ba wọ fìlà, dandan ni kó bá aṣọ mu.
Osu Kẹfa ọdun 2010 ni ijọba ipinlẹ Ondo rọọ loye gẹgẹ bii Deji tilu Akure nitori pe o n aọkan lara awọn olori rẹ nita gbangba Orukọ Olori naa ni Bolanle Adepoju Adesina, ẹniti aawọ waye laarin oun ati ọkọ rẹ, ti Deji naa si ni ki awọn ẹsọ to wa ni aafin naa ni anadojubolẹ, ta si gbọ pe oun gan da eroja olomi kan si lara, ti wọn pe ni asidi, eyi to mu ki ara obinrin naa bo yanna-yanna Idi ree ti awọn afọbajẹ ilu Akurẹ fi pinnu pe oriade naa ko yẹ ni ipo ọwọ naa, ti wọn si le kuro lori itẹ.
Ẹni to bori: Kenya South Africa vs Tunisia.
Eyi ni ipele kẹrin ti orile ede mejeeji  naa yoo ti maa fagba han ara wọn.
Oríṣun àwòrán, Facebook/Oyo state house of Assembly Awọn miiran ni Oloye Bayo Ojo, Dokita Bashir Abiodun Bello, Ọjọgbọn Oyelowo Oyewo, Ọjọgbọn Dawud Sangodoyin, Ọgbẹni Olasunkanmi Olaleye ati Ọgbẹni Adeniyi Olabode AdebisiAdebisi.
O ni o to gẹ bi wọn ti ṣe n dana sun awọ́n ile itaja ọmọ Naijiria lorileede South Afrika.
Arabinrin Richards sọ fun awọn oniroyin pe, ''mo joko lori awo ile igbọnsẹ ni mo deede ri ti nkan jami jẹ, kia ni mo fo dide t'ohun ti pata mi nilẹẹlẹ, ki n to o ri kinni kan to jọ ijapa, pẹlu ọrun gùn to n sa pada sinu omi.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù #ENDSARS: Àṣìta ìbọn ọlọ́pàá ló sọ mọ̀lẹ́bí mi, Adenike di báyìí, wọn ò bí i bẹ́ẹ̀, EndSARS ni dandan o- Toyin Abraham 15 Ọ̀wàrà 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 16 Ọ̀wàrà 2020 Oríṣun àwòrán, Instagram/toyin abrahams Ọpọ eeyan lo ti n sọ ọpọ iriri wọn pẹlu awọn agbofinro SARS atawọn ọlọpaa Naijiria.
Sihoni bá jáde sí wa, òun ati àwọn eniyan rẹ̀, láti bá wa jagun ní Jahasi.
Alaga ajọ Oyo SUBEB, Dokita Nureni Aderemi Adeniran lo sọ eyi ninu atẹjade kan ti wọn fi lede ni ipinlẹ naa.
Loju ẹsẹ naa lawọn eeyan ti han wọn ti wọn si n fesi nipa didarukọ adugbo wọn lọkọọkan pe ọrọ aisina kii ṣe ọrọ oni tabi ana ti wọn si n fesi pe titi di asiko ti Ikeja Electric n fi ọrọ wọn sita, ko tii si ina ladugbo awọn.
OLUWA, Ọlọrun mi, mo bẹ̀ ọ́, èmi ati ilé baba mi ni kí o jẹ níyà, má jẹ́ kí àjàkálẹ̀ àrùn yìí wá sórí àwọn eniyan rẹ.
1983 lo bẹrẹ orin tirẹ gangan.
Arlene ni, ka to wi ka to fọ ni ipe bẹrẹ si ni ja lu ipe lori ẹrọ ilewọ oun ati gbogbo oju opo ikansiraẹni, ti awọn eniyan si n ki oun ku orire igbeyawo ati wi pe ọjọ wo gangan ni igbeyawo ọhun, ki awọn ba le wa yẹsi.
O dojú ibinu kọ mí,o fi agbára rẹ bá mi jà.
Ẹ má pa ìyàwó mi bí ẹ ṣé pa màmá mí-Prince Harry Má ṣé tọrọ aforijin lọ́wọ́ Buhari lásìkò àbẹwò rẹ- South Africa Ǹ jẹ́ o mọ àwọn èèyaǹ wọ̀nyí tó jà fún òmìnira Nàìjíríà?
Ẹka ẹkunrẹrẹ rẹ nibi Ọjọ 20, Osu Keji Ijọba orilẹede Naijiria fi idi rẹ mulẹ wipe aadọfa awọn ọmọbinrin Dapchi lo sọnu Ẹka ẹkunrẹrẹ rẹ nibi Ọjọ 21, Osu Keji Ijọba ipinlẹ Yobe kede wipe awọn ọmọogun Naijiria ti gba lara awọn ọmọ naa silẹ atiwipe wọn wa lọdọ ikọ awọn ọmọogun naa.
Awọ pupa ni aṣọ ọhun pẹlu fila pipa naa lori rẹ, bata alawọ funfun ni Femi Adebayo fi wọ si ori aṣọ naa.
Owu Water Falls: Ọba Oyewole ni ibùdó ìrìn àjò afẹ́ gidi ni àmọ́ ọ̀nà ibẹ̀ burú jáì
Mohammed Yusuf: Irú èèyàn wo ní olùdásílẹ̀ Boko Haram?
Ohun adojuti ni ki awọn ọkunrin maa hu iru iwa ka maa mura bi obinrin'' O fẹ́ yọ́ wọ ààyè ibùsùn àwọn obìnrin lọwọ́ ọlọ́pàá bá tẹ̀ ẹ!
Ẹkọ kẹta ni pe o yẹ ka mọ pe bo pẹ, bo ya ewe yoo sunko nitori oogun lo ni ọjọ kan ipọnju, ori ẹni lo ni ọjọ gbogbo.
Aṣagbeyẹwo iṣuna owo Agba ni Ipinlẹ Eko, Arabinrin Morenikẹ Helen Deile,
" O ni o ṣe pataki lati fi ye awọn eniyan pe, miliọnu mẹwaa naira ti awọn oniroyin n sọ jẹ owo iṣẹ ti awọn agbẹjọro n ṣẹ lori ipẹjọ naa.
Ọjọ Abamẹta ni iroyin gba ori ayelujara pé iyawo marun un ati ọpọlọpọ ọmọ ni ọkọ Lizzy Anjọrin kọ silẹ, nitori ko le fẹ ẹ.
Wọ́n fẹ́ràn àga iwájú ní ilé ìpàdé.
Wọ́n bi Jẹfuta léèrè pé, “Kí ló dé tí o fi rékọjá lọ sí òdìkejì láti bá àwọn ará Amoni jagun tí o kò sì pè wá pé kí á bá ọ lọ?
Èrò àwọn gómìnà lórí ' minmum wage': Alága ìgbìmọ̀ àwọn gómìnà náà tó jẹ́ gómìnà ìpínlẹ̀ Zamfara, Abdulaziz Yari fi èyí léde lásìkò tó ń bá àwọn oníròyìn sọ̀rọ̀, lẹ́yìn ìpàdé tí wọ́n ṣe ní ìlú Abuja.
Atamatase agbaboolu owo iwaju fun iko agbaboolu Atletico Madrid, Antoine Griezmann ti ran iko re lowo lati gba ife eye idije Europa League fun igbaketa bayii, leyin ti won fagbahan iko agbaboolu Olympique de Marseille pelu ami-ayo meta sodo(3-0), lojoRu (Wednesday).
Orisun: Ẹgbẹ ẹka asofin kan si ekeji, ida obinrin to wa nile titi di ọjọ kinni, oṣu keji ọdun 2019.
Ikolu si awon agbegbe naa waye
Oríṣun àwòrán, Pastorfoluadeboye Ọna ti Baba Adeboye gba ṣe ayẹsi ọjọ ibi iyawo rẹ, Folu Adeboye lọtẹ yii to pe ọdun mejilelaadọrin ma nii- ni awọn ọdọ Naijiria ba tu sita loju opo Twitter Adeboye lati da si ọrọ naa yala ni ti ṣiṣi fila fun ohun ti Pasitọ yii ẹni ọdun mẹtalelọgọrin funrararẹ sọ nipa iyawo rẹ, Folu Adeboye.
Ọlọpaa ninu atẹjade ti wọn fi lede sọ wi pe awọn ọmọ kilasi SS2 ati SS3 ti wọn ni ija ti tẹlẹ ni wọn fẹ sọsẹ fun ara wọn.
O fikun oro re pe, awon ti o farapa ti wa labe itoju nile iwosan Specialist, niluu Maiduguri.
Kò sí òfin kan tí ó lòdì sí irú nǹkan báwọ̀nyí.
0 32 Orilẹede Geenlande 0 0.
Nígbà tí àgbà dé sí Samuẹli, ó fi àwọn ọmọ rẹ̀ ṣe adájọ́ ní ilẹ̀ Israẹli.
Ezekwesili, obìrin kan ṣoṣo tí ó ń du ipò nínú eré ìbò sísá ti ọdún tí a wà yìí, ti ṣe mínísítà ọrọ̀ líle inú-ilẹ̀ àti ètò ẹ̀kọ́ ní àsìkò ìjọba Olusegun Obasanjo ní àárín ọdún 1999 sí 2007.
Fún Lhamo, ayé tí ó pé pérépéré ni èyí tí kò sí ìdálọ́wọ́kọ́ tàbí ìyàsọ́tọ̀  Òmìnira Tibet àti ìdádúróo rẹ̀ kọ́ ni ohun tí ó hún jẹ wá lẹ́sẹ̀.
Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Covid 19 update: Wo ǹkan mẹ́wàá tó yẹ kí o mọ̀ tí o bá fẹ́ lọ fún ìsinmi lẹ́yìn Covid 1923 Bélú 2020 Fídíò, Akomolede Yoruba: Kí ni ìdí tí aṣọ fi máa ń pọ̀ lára Egúngún ju Orò lọ́?
Ni àwọn ọmọ-ogun ati ọ̀gágun ati àwọn ẹ̀ṣọ́ àwọn Juu bá mú Jesu, wọ́n dè é, 
O ni ibo awọn ọmọ Naijiria lo ṣi jẹ ko wa nibẹ.
Bí a bá tà á, ìbá tó nǹkan bí ọọdunrun (300) owó fadaka, à bá sì fún àwọn talaka.
Laisi NIN, o ko ni le gba iwe aṣẹ fun ọkọ wiwa.
Wo àwọn oúnjẹ márùn ún tó ń mú kí àtọ̀ ọkùnrin dára síi Wo ibi fún èsì ìdìbò yíyan aàrẹ tuntun ní orílẹ̀-èdè Ghana Ọlọ́pàá, sójà yabo Lekki Toll Plaza láti dènà ìfẹ̀hónúhàn míràn Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Akomolede ati Asa lori BBC: Olùkọ́ Kikelomo Ogunboye tan ìmalẹ̀ sí ìwà olè ọ̀gá ọlọ́pàá Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Iroyin sọ pe Kọmiṣana Ọlọpaa ipinlẹ Ondo, Salami Bolaji ko awọn ọlọpaa rẹ sẹnu ọna ọfiisi ijọba ki igbakeji gomina, Agboola Ajayi ma lee jade sita tabi gbe ọkọ ijọba to n lo jade.
Ni ti ijọba ipinlẹ Osun, o ti kọkọ wọgile isin yii sugbọn wọn tun ipinu wọn da ro.
Amọṣa Taye kọrẹnsi ti sọ pe lootọ ọmọ ilu kan naa ni awọn mejeeji, sibẹ Pasuma Ọganla loun yoo ba lọ lọjọkọjọ.
Lẹyin eyi ni May yoo tẹkọ leti lọ si orilẹ-ede Naijiria.
Falz ti ní òun kò ní yọ fídíò orin náà tí ó fi gbogbo àléébù orílẹ̀èdè Naijiria han láfẹ́fẹ́.
Nítorí kì í ṣe ọ̀rọ̀ ti ara mi ni mò ń sọ, bíkòṣe ti Baba tí ó rán mi níṣẹ́, tí ó ti fún mi ní àṣẹ ohun tí n óo sọ ati ohun tí n óo wí.
Peteru bá dìde, ó ní, “Ẹ̀yin arakunrin, ẹ̀yin gan-an mọ̀ pé ní àtijọ́ Ọlọrun yàn mí láàrin yín pé láti ẹnu mi ni àwọn tí kì í ṣe Juu yóo ti gbọ́ ọ̀rọ̀ ìyìn rere, kí wọ́n lè gba Jesu gbọ́.
Abimeleki bá dá a lóhùn pé, “Irú kí ni o dánwò sí wa yìí?
”Ipade naa yoo  waye LojoRu ojo kewaa, nigba ti egbe oselu naa yoo ti pari gbogbo eto idibo inu egbe fun awon oludije won.
O ni lati ro nkan too nilo gangan.
Ọjọgbọn naa wa woye pe kii ṣe aarẹ Buhari lo n dari Naijiria, to si n rọ ọ lati mase fi ọwọ yẹpẹrẹ mu ọrọ lẹta naa."
BBC tun gba wọn nimọran lati yẹra fawọn onijibiti ẹda to lee fẹ maa gbe wọn mọra lati gba owo iforukọsilẹ lọwọ wọn.
Gege bi iye pasipaaro lati ile
Angẹli Ọlọrun tí ó ti wà níwájú àwọn eniyan Israẹli bá bọ́ sẹ́yìn wọn, ọ̀wọ̀n ìkùukùu tí ó wà níwájú wọn náà bá pada sí ẹ̀yìn wọn.
1 955766 Orilẹede Ukraine 15278 34.
Gẹgẹ bi ọrọ rẹ, ọjọ marun ni iyanṣẹlodi naa yoo fi waye nitori wọn fẹ fi fa ijọba leti ni lẹyin ti wọn ti fun ijọba ni gbede ọjọ mẹrinla lori ibeere wọn naa ṣaaju asiko yii eleyi to ni ijọba kọ eti ọgbin si.
Níwọ̀n ìgbà tí a ti dá ọjọ́ fún un,tí o mọ iye oṣù rẹ̀,tí o sì ti pa ààlà tí kò lè rékọjá.
 Eto igbaninimoran di dandan sugbon a si n tepeple mo ifokannsin awujo eni.
Wá, jẹ́ kí á ṣeré ìfẹ́títí ilẹ̀ yóo fi mọ́,jẹ́ kí á fi ìfẹ́ gbádùn ara wa.
Oríṣun àwòrán, @BashirAhmad Àkọlé àwòrán, Muhammadu Buhari ni inu oun dun si bi wọn se yan oun ni alaga ajọ Ecowas O ni ni kete ti awọn olori orilẹ-ede lẹkun iwọ oorun Afrika pari ipade ajọ Ecowas naa, ni wọn kede Buhari gẹgẹ bii alaga wọn tuntun.
Amọ, Baba Wande nigba to n ba BBC sọrọ wi pe oun ko ni ija pẹlu Tunde Kelani, sugbọn otitọ ni wi pe Kelani yan oun jẹ lori filmu naa.
"Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ọkọ mi kò le f'ipá bá ẹnikẹ́ni lò pọ̀ láíláí - Modele Fatoyinbo Àdúrà kò le pa ìfipábánilòpọ̀ rẹ́, àtàwọn àkọlé mìí tó jẹyọ lórí ọrọ Fatoyinbo Ìjọ Satani dá MI lóhùn lórí ọ̀rọ̀ Fatoyinbo Damasus, Omotola, Ezekwesili, Funmi Iyanda dá sí ẹ̀sùn ìfipábánilòpọ̀ Fatoyinbo ""Mo ti gba adura, mo si ti beere itọni lọwọ awọn aṣiwaju ninu irinajo igbagbọ kaakiri agbaye lori ọrọ to n ja ranyinranyin lori afẹfẹ."
O rọ awọn ara'lu pe ki wọn ma a sọra pẹlu awọn ẹrọ to'n ba ina sisẹ paapa julọ lasiko ọyẹ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Kid boxer: Ọmọọba 'The Buzz' Larbie rèé, ọmọ ọdún méje tó ń fi ẹ̀ṣẹ́ dá bírà Ize-Iyamu borí ìbò abẹ́nú fún idíje gómìnà l'Edo Oríṣun àwòrán, others Iroyin to n tẹ wa lọwọ n fiyeni pe Ize-Iyamu ti jawe olubori gẹgẹ bii oludije ti yoo gbe aṣia ẹgbẹ oṣelu APC ni idibo sipo gomina ni ipinlẹ Edo.
Ṣùgbọ́n a ti kọjá ọjọ́dọ́gba tó síwájú ìgbà-ìwọ́wé (ẹ̀kúnrẹ́rẹ́ rẹ̀ rèé).
Kogi Prison: Aráàlù tẹ́ẹ bá ní ìròyìn nípa àwọn ẹlẹ́wọ̀n tó sá lọ, ẹ jọ̀wọ́ ẹ fún wa Ìjọba ìpínlẹ̀ Èkó ṣàwárí agolo akẹ́rù tó kún fún ẹja àti oúnjẹ tó ti díbàjẹ́ Bìlísì wáyé nígbà táwọn ṣọ́jà ya bo olú iléeṣẹ́ ọlọ́pàá l'Osogbo À ń ṣọ́ọ yín lórí ayélujára yín bàyìí o!
Ogbeni Mohammed tun so pe, bo tile je pe awon igara olosa yii pa awon eniyan , ti won si tun se awon miiran ni ijamba sibe ,won o pa emi isokan  ati  iwa akinkanju awon omo ilu offa.
Awọn iroyin kan ti ẹ tun sọ pe oludari ileeṣẹ eto irinna kan ni ọkunrin naa, to si jẹ pe ọga rẹ sọ pe iṣẹ yoo bọ lọwọ rẹ ti ko ba ri ọkọ naa gba pada.
" Ibẹrẹ ijọ Satani: Lati nkan bi ọdun 1950, ni awọn to faramọ erongba LaVey ti n sun mọ ọ, nipa kikorajọ pọ si ile rẹ Black House"" nilu San Francisco."
ikolu maa n waye lati ọdọ  awon ikọ ọlọtẹ.
Bayii o ti di awokọṣe obinrin ti awọn eniyan Algeria n ya aworan rẹ kaakiri ogiri ni gbangba ti wọn si ti sami ayẹyẹ ọdun rẹ nipa ere oniṣe lati ọdun 2003.
#BBCNigeria2019 Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 2019 Elections: Èrò àwọn ọmọ Nàíjíríà se ọ̀tọ̀ọ̀tọ̀ lóri ètó àlùfáà tàbí ìmámù lásìkò ìbò Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ọ̀tọ̀ ni nkan tí wọ́n sọ fún ẹbí rẹ̀, iṣẹ́ aṣẹ́wó ni wọ́n fi n ṣe Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 3 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 5 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Lebanon: Iṣẹ́ tí kòsí ní Naijiria, la ṣe lọ ṣe ọmọ ọ̀dọ̀ ní Lebanon Wọn ni ọrọ Abubakar Malami yii kudiẹ kaato nitori pe o dabi i ti ẹni to fẹ ṣe aṣilo ipo tabi ọọfiisi rẹ ni.
Agbẹjọro rẹ ni irẹwẹsi ọkan de ba Onyeri fun oun to ṣẹlẹ si adajọ Kocurek.
Musa Ahmad Tijjani Oniroyin ni Oloogbe Musa Ahmad Tijjani to si ti fi igbakan ri jẹ olotu iwe iroyin Leadership Sunday ati Triumph ni Kano.
Ọ̀nà àbáyọ fún olóyún lásìkò àjàkálẹ̀ ààrùn Covid-19 Ẹnìkan ṣoṣo nínú ìdílé kan ni yóò gbà N20, 000 owó ìdẹ̀rùn igbele Covid-19 - ìjọba àpapọ̀ Ikú Dagrin pé ọdún mẹ́wàá, wo àwọn nǹkan mánigbàgbé nípa rẹ̀ Ẹnìkan ṣoṣo nínú ìdílé kan ni yóò gbà N20, 000 owó ìdẹ̀rùn igbele Covid-19 - ìjọba àpapọ̀ Ọgbẹni Opeyemi tun sọ pe iṣoro to n koju ọpọ awọn agbẹ gan an bayii ni ai ri ibi ti wọn ti le ta nnkan oko wọn.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Osun Kidnap: Òṣìṣẹ́ àjọ FRSC méjì bọ́ sọ́wọ́ àwọn ajínigbé l'Ọsun 21 Èbibi 2019 Oríṣun àwòrán, FRSC Àkọlé àwòrán, FRSC ni wọn ji wọn gbe ni agbegbe Iwaraja ni ijba ibilẹ Oriade lọjọ aje ọsẹ yii.
Eyi kii ṣe akọkọ igbesẹ bayii.
Bi o tilẹ̀ jẹ́ pé àwọn èèyàn yìí ló aṣọ ibomu tó jẹ́ atọwọda, àmọ́ àwọn òṣìṣẹ́ eleto ìlera ti kede tẹ́lẹ̀ pé èyí kò tó láti dáàbò bo ara ẹni lọ́wọ́ Coronavirus.
Nítorí náà, fi Ọlọrun búra fún mi níhìn-ín yìí, pé o kò ní hu ìwà ọ̀dàlẹ̀ sí mi, tabi sí àwọn ọmọ mi, tabi sí ìran mi, ṣugbọn bí mo ti jẹ́ olóòótọ́ sí ọ, bẹ́ẹ̀ ni ìwọ náà yóo jẹ́ olóòótọ́ sí mi ati sí ilẹ̀ tí o ti ń ṣe àtìpó.
lẹ ́ yìn tí àwọn òṣèrè yìí ṣe fíìmù yìí tán , àwọn òṣèrè mìíràn bẹ ̀ rẹ ̀ sí í gbé fíìmù tiwọn náà jáde .
Salah àti Mane ti sọ ara wọn di ògúnnágbòǹgbò nínú ikọ̀ agbábọ́ọ̀lù Liverpool.
Ìmọ ̀ tàbí ìwádìí ohun tí ń mú àìsàn wá , ìtọ ́ jú àti ìlòsí rẹ ́ , tàbí ìdí-lọ ́ wọ ́ àrùn àti àwọn ìbàjẹ ́ sí inú ara Ẹ ̀ ka .
N óo fún ọba Babiloni lágbára, ṣugbọn ọwọ́ Farao yóo rọ.
Ṣùgbọ́n inú Èṣù pàápàá kìí dùn láti ṣe ibi ko si ń le ṣe ibi láì jẹ́ pé ọmọ ènìyàn fún un ní ààyè.
Wọ́n fi òkúta kọ́ igun mẹrẹẹrin, ọ̀kọ̀ọ̀kan wọn yípo.
Iranṣẹ tí ó lọ pe Mikaya sọ fún un pé, “Àsọtẹ́lẹ̀ kan náà ni gbogbo àwọn wolii ń sọ, pé ọba yóo ṣẹgun, ìwọ náà sọ bẹ́ẹ̀.
Andy Ruiz já ìràwọ̀ Anthony Joshua 2 Òkùdu 2019 Oríṣun àwòrán, Al Bello Àkọlé àwòrán, Ẹẹmẹrin ọtọọtọ ni Ruiz fi ẹsẹ kan Joshua mọlẹ lai le dide.
Sugbọn sa, olupẹjọ, Femi Onipede sọ pe ijọba ko sẹsẹ maa kede lori redio ati ọna ibaraẹnisọrọ miran saaju asiko lori pataki wiwọ ibomu yi.
Bí ìgbéraga rẹ̀ tilẹ̀ ga, tí ó kan ọ̀run,tí orí rẹ̀ kan sánmà,
Oríṣun àwòrán, Instagram Olori naa ni asiko arun Coronavirus yii pe fun ironujinlẹ, ti kii si ṣe fun afẹfẹ yẹyẹ nitori ọpọ ẹmi lagbaye lo n lọ si iṣẹlẹ yii.
N óo sọ Patirosi di ahoro, n óo sì dáná sun Soani, n óo sì ṣe ìdájọ́ fún ìlú Tebesi.
Wọn kọ lẹta yii ní ìdáhun si ibéèrè BBC Yoruba lójú òpó facebook rẹ̀ pé ti wọ́n ba ni ànfani lati kọ lẹ́ta si ààrẹ Buhari kíní wọ́n yoo kọ?
Wọ́n pa wọ́n ní ojú òpópó ọ̀nà tí ó lọ sí Bẹtẹli ati Gibea ati ninu pápá.
NBC kilọ fun awọn ileeṣẹ igbohunsafẹfẹ lori isọrọ odi
Láti inú aṣálẹ̀ ati òkè Lẹbanoni yìí lọ, títí dé odò ńlá náà, odò Yufurate, gbogbo ilẹ̀ àwọn ará Hiti, títí dé Òkun Mẹditarenia ní apá ìwọ̀ oòrùn, ni yóo jẹ́ ilẹ̀ yín.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ṣeyi Makinde ṣèdánrawò fún ayẹyẹ ìbúra Bidemi Kosọkọ di ìyá ìkókó Ọ̀tá Nàíjíríà ni Saraki àti Dogara - Buhari Olùdásílẹ̀, akẹ́kọ̀ọ́ iléẹ̀kọ́ Yahoo-Yahoo wọ gàù EFCC Atẹjade naa tun n fi ewe ọmọ mọ igun ẹgbẹ ọlọkọ ero NURTW to ba gbero lati da omi alaafia ipinlẹ Ọyọ ru ki wọn to se ibura, lasiko ibura ati lẹyin rẹ, yoo ge ika abamọ jẹ.
 Lasiko ipade naa, ni won fi mule pe ile igbimo asoju ilu
Ìbátan Saraki ní APC ló ni Kwara lọ́jọ́ Abamẹta tó m bọ̀ Ìjọba pàṣán ni ìjọba Buhari yóò jẹ́ fún Nàìjíríà ní sáà kejì- Ṣoworẹ Ó tó gẹ́, Atikulated àti àwọn àṣà ìpolongo tó gbòde lásìkò ìbò 2019 Kamaru Usman: Ọmọ Áfíríkà àkọ́kọ́ tó gba ìgbànú ẹ̀yẹ ẹ̀ṣẹ́ kíkàn Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Jimi Agbaje: èmi kò faramó owó ẹnubodè Toll Gate Eko rárá Wolii Austin Moses ati Omoyele Sowore Omoyele Sowore ni wolii yi riran si wi pe yoo jẹ aarẹ Naijiria ti o si ni Olorun ni o fi iran naa han oun.
Gbogbo nǹkan yòókù tí Asaraya ṣe ni a kọ sinu Ìwé Ìtàn Àwọn Ọba Juda.
Oríṣun àwòrán, Obasanjo/instagram Ìfọwọ́sowọ́pọ̀ nìkan ni ọ̀nà abáyọ sí ìṣòro Nàìjíríà- Olusegun Obasanjo Ààrẹ àná lórílẹ̀-è[de Nàìjíríà Olusegun Aremu Obasanjo ni ipa pàtàkì ni ọ̀rọ̀ ọlórí àti àwọn adarí lórílẹ̀-èdè Nàìjíríà ni láti kó kí wọ́n tó borí ètò ààbò tó mẹ́hẹ, ètò ọrọ̀ ajé tó dojúdé àti ètò òṣèlú ti kò rọgbọ̀.
Jesu tún bi í lẹẹkeji pé, “Simoni ọmọ Johanu, ǹjẹ́ o fẹ́ràn mi?
Access Bank ti gba ilé ìfowópamọ́sí Diamond Bank Oríṣun àwòrán, FACEBOOK Àkọlé àwòrán, Ẹ̀rọ̀ àwọn ọmọ Naijiria se ọ̀tọ̀ọ̀tọ̀ lórí bí ilé ìfowópamọ́sí Diamond se darapọ̀ mọ́ ile iilé ìfowópamọ́sí Access.
A béèrè fún ìtọ́sọ́nà nípa mímọ ibi tí ó wà, àti ìbọ̀wọ̀ fún ẹ̀tọ́ ọmọnìyàn-an rẹ̀.
'A ò kí ǹ fún ènìyàn ní ìwé ẹ̀rí lẹ́ẹ̀méjì' Oríṣun àwòrán, @BashirAhmaad Àkọlé àwòrán, Àjọ WAEC ṣàfihàn ìwé ẹ̀rí girama Ààrẹ Muhammadu Buhari Ajọ to n ri si idanwo aṣekagba ile iwe girama, WAEC ti ṣalaye wi pe kii ṣe pe awọn ṣẹṣẹ fun Aarẹ Buhari ni iwe ẹri tuntun lọjọ ẹti.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Xenophobia: Ohun tójú àwọn ọmọ Nàìjíríà ń rí ní South Africa kọjá àfẹnusọ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Xenophobia: Ohun tójú àwọn ọmọ Nàìjíríà ń rí ní South Africa kọjá àfẹnusọ 3 Owewe 2019 Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí 2 sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
ifesewonse olorejore pelu Egypt ni, Mohammed Salah, Mohammed
Eyi to mu ki ọpọ o sọ nigba naa pe boya o ti mọ pe oun fẹ ẹ ku lo ṣe kọ orin naa.
Ìbànújẹ́ sọ ojú mi di bàìbàì;àárẹ̀ sì mú ọkàn ati ara mi.
Ìjàmbà ọkọ̀ akẹ́rù ní Ikòròdú fa súnkẹrẹ-fàkẹrẹ ọkọ̀ ní Márosẹ̀ Irọ̀ ni ìjọba ń pa, Ikọ Amọtẹkun ba ofin Naijiria mu- Ìgbìmọ̀ Yoruba Wo ohun tó yẹ kó mọ̀ nípa Gomina Imo ti ilé ẹjọ́ giga ye àga mọ́ nídí Ọ̀pọ̀ àwòrán tó ń ṣeni láàánú rèè nípa ogun abẹ́lé Nàíjíríà EFCC ni Akapo ijọ naa fun igbakeji rẹ ni $ 500,000.
Gbogbo àwọn ará Hiti tí wọ́n wà níbẹ̀ jẹ́rìí sí i pé ilẹ̀ náà di ti Abrahamu.
Bí ẹ ti ń ṣe sí ọmọ onílé ni kí ẹ máa ṣe sí àlejò tí ó wọ̀ sọ́dọ̀ yín, ẹ fẹ́ràn rẹ̀ gẹ́gẹ́ bí ara yín, nítorí pé ẹ̀yin pàápàá ti jẹ́ àlejò rí ní ilẹ̀ Ijipti.
Ọ̀rọ̀ yìí kò dùn mọ́ Abrahamu ninu nítorí Iṣimaeli, ọmọ rẹ̀.
Mo fẹ́ kí Ọlọ́run fún wa ní ọmọ olójú búlúù si lẹ́yìn yìgì - Ọkọ olójú búlúù Ẹ̀yin gómìnà, Ifá nìkan ló le tọ yín sọ́nà láì kùnà lórí Amotekun - Babaláwo Ilé ẹjọ́ yá lórí òfin CAMA tó fẹ́ gba àkóso ilé ìjọsìn, tẹ ẹ̀tọ́ aráàlú mọ́lẹ̀ - SERAP Kí ló ń ṣẹlẹ̀ lọ́wọ́ sí Mamman Daura àti ìlera rẹ̀?
O ni awọn a jọ maa ṣe iṣelu lọ ni.
Diaz ni ipinnu oun ni lati tẹsiwaju ninu ẹkọ oun, ki o le tubọ kọ awọn ọmọ abule rẹ ni ẹkọ iwe sii.
Ẹ wá ọkàn tuntun ati ẹ̀mí tuntun fún ara yín.
Lẹyin naa lo kede pe apapọ awọnj to ti ni arun naa ti di mẹtalelogoji bayii.
Mo sọ èyí kí ẹ lè mọ̀ pé mo yọ̀ǹda fun yín pé kí ẹ ṣe bẹ́ẹ̀ ni; kì í ṣe pé mo pa á láṣẹ.
Juda dáhùn, ó ní, “N óo fi àwọ́nsìn ewúrẹ́ kan ranṣẹ sí ọ láti inú agbo ẹran mi.
Nǹkan tí ó n pa wọ́n lẹ́kún nì yí;
 Ko si ohun ti yoo ṣẹlẹ ti wọn ba gbe ọpa aṣẹ ile igbimọ aṣofin lọ nitori ko si ibi to wa ninu ofin pe ti wọn ko ba ti ri ọpa aṣẹ, pe ijoko ko ni wa ninu ile aṣofin.
"Ajẹ ke lana, ọmọ ku loni, tani o mọ pe ajẹ to ke lana lo pa ọmọ jẹ.
Àwọn ẹlẹ́sin tí wọ́n jọ́ arẹwà ti wọ́n ṣe ẹsin wọn ni ọ̀sọ́, àti àwọn wúndíá tí wọ́n to ara wọn sínú mọ́tò ayọ́kẹ́lẹ́ pẹ̀ú ogunlọ́gọ̀ àwọn ẹ̀dá tí wọ́n wà lórí alupùpù tuntun, ni wọ́n to ara wọn jọ síwájú ọkùnrin náà bí òun ti ń bọ̀ nínú mọ́tò ayọ́kẹ́lẹ́ gbọ̀lọ̀kù kan bí àtàtà ọba.
O ni obinrin yii lo se akiyesi pe oun mọ ọsan ho daadaa, to si joko ti oun, nibẹ si ni awọn ti di ọrẹ titi di oni.
Omi fẹ́ máa bọ́ lójú rẹ̀ bí ó ṣe nṣe ìkéde náà.
A máa yọ ọ́ kúrò ninu ìpọ́njú,bọ́ sinu ìdẹ̀ra níbi tí kò sí wahala,oúnjẹ tí a gbé kalẹ̀ níwájú rẹ̀ a sì jẹ́ kìkì àdídùn.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ìpolongo fífòpin sí SARS ti lágbára si Lai Mohammed fèsì sí ọrọ Obasanjo Small Doctor, Afolayan bá Buhari ṣínu ààwẹ̀ Gwandu to jẹ kọmisọna ọlọpaa ni Edo ni lootọ ojuṣe ọlọpa labẹ ofin ni lati daabo bo araalu, ṣugbọn eredi idasilẹ ikọ kogberegbe FSARS ni lati da si ipe 'gbami-gbami' araalu.
Umar tun so pe, woo yoo nilo egberun marun awon agbe, besini agbe kookan yoo gbin ekta mejii egbon-owu.
Ara: Láti kékeré ni mo ti ń lu ìlú pẹ̀lú ayọ̀
Europe: Yúrópùù ní ọmọ Nàìjíríà àti orílẹ̀-èdè Áfíríkà 43 míì kò ni wọ ilẹ̀ òun
 Orile ede naa ko ni pe bere eto idibo won , o si wu wa lati pese eto aabo lasiko eto idibo fun orile ede naa.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ogundiya: Àṣìṣe Dókítà ló sọ mi di aláàbọ̀ ara lórí kẹ̀kẹ́ Day 30: Ṣé o mọ Ààrẹ Buhari délé délé?
Ṣugbọn nítorí ìfẹ́ ńlá tí Ọlọrun tí ó ní àánú pupọ ní sí wa, 
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Brighton vs Tottenham: Aṣọ́lé Tottenham, Hugo Lloris dèrò ilé ìwòsàn lẹ́yìn ìyà àjẹtúnjẹ lórí pápá Brighton 5 Ọ̀wàrà 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Kaka ki ewe agbọn dẹ, niṣe lo n le koko sii.
Ọ̀pọ̀ àwọn ọmọ Nàìjíríà ní ìjọba ti dá pádà wále láìpẹ́ yíì nítorí iṣekú-pani to ń waye níbẹ̀ láti ọwọ́ àwọn orílẹ̀-èdè Libya.
Oríṣun àwòrán, AFP Tolori tẹlẹmu ni ko ni gbagbe ilumọọka agbabọọlu elege ara yi to ṣe pe o ko ipa ribi ribi ninu ere bọọlu lagbaye.
obinrin kan wọlé tọ̀ ọ́ wá tí ó ní ìgò òróró iyebíye olóòórùn dídùn, ni ó bá bẹ̀rẹ̀ sí tú u sí orí Jesu níbi tí ó ti ń jẹun.
Mo sì mú wọn búra ní orúkọ Ọlọrun wí pé: “Ẹ kò gbọdọ̀ fi àwọn ọmọbinrin yín fún àwọn ọmọ wọn, tabi kí ẹ fẹ́ àwọn ọmọ wọn fún àwọn ọmọkunrin yín tabi kí ẹ̀yin pàápàá fẹ́mọ lọ́wọ́ wọn.
O tun sọrọ lori ede-aiyede aarin oun ati Liz Anjọọrin to jẹ oṣere Yorùbá pe ti inu wọn ba rọ tan, ohun gbogbo a yanju fun onikaluku.
Tọmọde tagba lo n jẹẹ ninu ile, nibi ase ati nibi gbogbo.
Ẹfunsetan Aniwura, obìnrin tó ju ọkùnrin lọ Ọ̀rọ̀ǹpọ̀tọ̀niyùn, Aláàfin obìnrin àkọ́kọ́ rèé, tó ní nǹkan ọkùnrin Taiwo Akinkunmi, ọmọ Ibadan tó ya àsìá Nàíjíríà Gbogbo ìwọ̀n rẹ̀ kò ju èso Apple lọ lọjọ ti wọn bi i.
Nítorí OLUWA Ọlọrun ní, “Báwo ni yóo ti wá burú tó nisinsinyii tí mo rán ìjẹníyà burúkú mẹrin wọnyi sí Jerusalẹmu: ogun, ìyàn, ẹranko burúkú ati àjàkálẹ̀ àrùn láti pa eniyan ati ẹranko run ninu rẹ̀.
Gbajugbaja onkọwe Kongi ni ẹsun ti wọn fi kan Sowore pe o fẹ ditẹ gbajọba yii ku diẹ kaato.
– Seyi Makinde 2019 Election: Àwọn oloṣelu tó yege àti àwọn to fidirẹmi Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, #NigeriaDecides: BBC ti wa ni gbogbo ìpínlẹ̀ Naijiria láti firoyin gbogbo tóo yin létí Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 3 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 5 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
    Èmi, Ìfẹ́pàtàkì, ọmọ Ajédùbúlẹ̀, iwin, tí ń gbé odò Ìránti’, àbúrò olókun, ti i ṣe alákòóso omi, gba Ìrìnkèrìndò, ọmọ Ìfẹ́dayépọ̀, ọmọ ènìyàn, ti ń gbé ilú Alárìnkiri, tí o ń lọ sí òkè Ìrònù, ti ń bẹ nínú Igbó Elégbèjè, bí ọkọ mi.
Obìnrin kò gbọdọ̀ jáde alẹ́ mọ́ ní Kano NAFDAC ti parí ìwádìí lórí codeine Ìjọba gbẹ́sẹ̀ lé 2.
Ibe ṣalaye ninu atẹjade naa pe Atiku ko tapa si ofin kankan yala ni Naijira tabi loke okun, o ni irọ nla lawọn kan n gbe kiri nipa Atiku.
 orúkọ rẹ ̀ wá láti ọ ̀ rọ ̀ èdè grííkì tó túmọ ̀ sí  ohun tuntun "" ."
Iya Rainbow gbe imọran naa kalẹ, lasiko ti ileesẹ Gulf Platform n side ayẹyẹ ti wọn fi n sami ọjọ ibi ọdun kẹtadinlọgọrin rẹ ni olu ileesẹ naa to wa nilu Ibadan nigba naa.
" APC tàpá sí ìdájọ́ ilé ẹjọ́ lórí olùdíje ipò Gómìnà Kwara Gómìnà tí wọ́n yàn ní Kwara, Abdulrazaq ní òun yóò tún ìdigunjalè Offa yẹ̀wò #BBCNigeria2019: Ohun ti mo gbé dání fún Kwara ju ti APC àti PDP lọ -Yinka Ajia Abdulfatah ni oun to ṣẹlẹ ni pe awọn eniyan Kwara ro pe o ni ipa miran to yẹ ki igbimọ ẹgbẹ to n fa ijọba kalẹ ni Kwara gbe ni.
O fikun ọrọ rẹ pe, ijọba ti yan awọn amofin to dantọ lati ṣoju rẹ, ti ọrọ naa ba dọrọ ileẹjọ.
Ọkà àti àkàṣù ẹ̀kọ pẹ̀lú ọbẹ̀ ẹ̀fọ́ tí ó kún fún ẹran.
Ti a ko ba gbagbe, laipẹ yii ni Ọmọọba Harry ati iyawo rẹ sọ wi pe awọn fẹ ṣiṣẹ aje lati fi tọju ara wọn.
”Oludari ajo naa tun so pe awon ipinle bi i Kebbi, Kwara, Bayelsa, Rivers, Benue, Adamawa ati Taraba ni won tun wa nibi ewu omiyale bayii.
NFF ti san owó àjẹ́mọ́nú Super Eagles Àwọn orílẹ̀èdè tó ń ṣe bẹbẹ nínú ìdíje AFCON 2019 tó ń lọ ní Egypt Wo àwọn ẹranko tí wọ́n máa figagbaga ni Egypt nínú AFCON 2019 Àwọn orílẹ̀èdè àjọ ECOWAS yóò máa ná owó kan nàá l'ọ́dún 2020 Rohr ni oun ni idaniloju pe awọn adiẹyin mu mejeeji yii yoo wulo ninu idije ipele ẹlẹni merindinlogun ti o m bọ lọna.
Nigba ti Dogara n soro nibi atejade kan to gbe jade lati odo oluranlowo re, lori iroyin ati ipolongo, Turaki Hassan, o wa ro ijoba apapo ati ijoba ipinle lati tete pese eto iranwo fun awon ti iji lile naa kolu , ni eyi ti yoo din wahala to n dojuko won ku.
Bí wọn ṣe bí ọ nìyí: nígbà tí wọ́n bí ọ, wọn kò dá ìwọ́ rẹ, bẹ́ẹ̀ ni wọn kò fi omi wẹ̀ ọ́.
Èyí jẹ́ nǹkan tí kò ṣe é ṣe lábẹ́ Òfin, nítorí eniyan kò lè ṣàì dẹ́ṣẹ̀.
Ààrẹ Muhammadu Buhari ni àwọn alasilẹ ti ijọba yoo gunle ree lasiko yii a.
Kí ló dé tí ó fi fún mi lọ́mú?
Ko ṣe e ṣe ki Naijiria o jà ni Ghana, bi awọn kan ṣe n beere fun."
Nítorí ẹni tí o ti kọlù ni wọ́n tún gbógun tì;ẹni tí o ti ṣá lọ́gbẹ́ ni wọ́n sì tún ń pọ́n lójú.
Oníròyìn Orí ẹ̀rọ-alátagbà Luis Carlos Diaz di àwátì ní Venezuela
OLUWA ti kéde títí dé òpin ayé.
Olùkọ́ fásitì méjì ń bèèrè ìbálòpọ̀ lọ́wọ́ akẹ́kọ̀ọ́ fún máákì Fídíò rèé nípa bí Aláké tuntun ṣe ń gba ìwúre lábẹ́ Olúmọ kó tó gba adé Ọdún ìbejì sọkutu-wọ̀wọ̀ ní Igboọrà, àṣírí bí wọn ṣe ń bí ìbejì tú Sanusi Adebisi Idikan rèé, olówó tó ń san owó orí fún gbogbo ọkunrin ilẹ̀ Ibadan Ṣé ìwọ leè wa kẹ̀kẹ́ lórí ìgò?
Ọba sọ fún wọn pé, “Mo lá àlá kan tí ó bà mí lẹ́rù pupọ, mo sì fẹ́ mọ ìtumọ̀ rẹ̀.
Àwọn tí wọ́n ń bá a jẹ oúnjẹ àdídùn pọ̀ gan-an ni yóo dìtẹ̀ mọ́ ọn; gbogbo ogun rẹ̀ ni yóo túká, ọpọlọpọ yóo sì kú.
3 Ògún 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 13 Bélú 2020 Orin o tiṣe fun mi, oti ṣe fun mi, oun baba, iya ko le ṣe, o ti ṣe fun mi lo gbẹnu ọkọ iyawo ori Zoom.
Àgbárá òjò bà'lú jẹ́ n'Ípínlẹ̀ Ogun Olórí ilé asòfin l‘Ọ́sun pàdánù N38m sọ́wọ́ gbájúẹ̀ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, OsunDecides: Omisore ní ẹni tó bá fẹ́ ra ìbò, àwọn yóò lọ lásọ mú ni Abajade naa ni nigba to ba fi maa di ọdun 2050, awọn akuuṣẹ eniyan bi miliọnu mejilelaadọjọ (152 million) ni yoo wa ni orilẹede Naijiria ninu awọn eniyan bi ọgbọnlenirinwo miliọnu (429 million) ti yoo maa gbe orilẹede yii ni ọdun naa.
Ayariga tun so pe “Nitori isele yii ni ijoba se so fun awon onisowo okeere lati fi awon iwe igbelu, iwe to gba won laaye lati fi se ise, ati iwe lati da ise sile, ki won si ko fun ajo teekoto.
Ronú jinlẹ̀ kí o tó jẹ́jẹ̀ẹ́ fún OLUWA,kí o má baà kábàámọ̀ rẹ̀.
Awọn ohun to n ṣokufa igbẹ rẹ ree: Ounjẹ Ounjẹ bii ẹwa tabi ewebẹ ati eso yoo jẹ ki igbẹ rẹ wa wọọrọwọ.
Nígbà tí Jesu rí bí inú rẹ̀ ti bàjẹ́, ó ní, “Yóo ṣòro fún àwọn olówó láti wọ ìjọba Ọlọrun.
Agbenuso fun ile-iwosan Kisubi Edward Zabonna so fun ile-ise iroyin BBC pe, osise oko oju ofurufu ohun “ti fi oju sese ati ni orokun re”.
Isoro pẹlu ọpa ẹyin Ẹni to ba ni iṣoro pẹlu ọpa ẹyin rẹ, Spine, o ṣeeṣe ko bẹrẹ si ni tọ si ara.
Oríṣun àwòrán, @hubertogunde Àkọlé àwòrán, Ọpọ igba lawọn obinrin n pagbo yi awọn oṣere ka Bi Hubert Ogunde tilẹ ṣilẹ bora, sibẹ ko yẹ ka gbagbe awọn iṣẹ takun-takun to ti gbe ṣe lati ṣeranwọ fun aṣa, iṣe ati ede Yoruba ko ma baa parun, idi si ree taa fi gbọdọ mọ ohun kan tabi meji nipa irufẹ eeyan ti Ogunde jẹ.
Ó pa akọ mààlúù ati àgbò ẹbọ alaafia fún àwọn eniyan, àwọn ọmọ rẹ̀ gbé ẹ̀jẹ̀ rẹ̀ tọ̀ ọ́ wá, ó sì dà á sórí pẹpẹ náà yípo.
Wo ohun márùn-ún tó ń fa ìjàmbá iná nínú ilé Day 25: Àwọn àkànlò èdè lásìkò ìdìbò #BBCNigeria2019 Lẹ́yìn òkò ọ̀rọ̀, Buhari àti Ọbasanjọ fẹ̀rín pàdé ara wọn l‘Abuja Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ọ̀tọ̀ ni nkan tí wọ́n sọ fún ẹbí rẹ̀, iṣẹ́ aṣẹ́wó ni wọ́n fi n ṣe Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Bukunmi tun fikun pe ọkan lara ala ọjọ pipẹ oun, lo wa si imusẹ wẹrẹ yii, to si seese ko jẹ pe osere-binrin naa ti n da ọfun tolo lati kopa ninu ere tiata pẹlu Funke Akindele tii se agba ọjẹ ninu isẹ naa.
Laarin ọdun kan ti ogun naa bẹrẹ, ijọba Naijiria fi awọn ọmọ ogun yi agbegbe Biafra ka, ti wọn si gba awọn ileeṣẹ ifọpo wọn, ati ti ilu Port Harcourt.
Kò lò ju bí ọjọ́ mẹjọ tabi mẹ́wàá lọ pẹlu wọn, ni ó bá pada lọ sí Kesaria.
Funke Akindele Ọna ti Funke Akindele fi ṣe ọdun Keresi ni lati ṣe awọn ololufẹ rẹ loore.
 Èèyàn 7 kú, 21 di àwátì lásìkò tí ọkọ̀ ojú omi dojúdé ní Eko àti Benue Ìjọba àpapọ̀ yóò ti afárá Third Mainland pa fún oṣù mẹ́fà láti ṣe àtúnṣe Bí Hushpuppi ṣe tiraka rèé l‘Eko, kí ọlà ‘òjijì’ tó dé Akẹ́kọ̀ọ́ wọlé padà, ìjọba Oyo kò pèsè ìbòmú lòdì sí ìlérí rẹ̀ Lẹyin ti mo lo ọjọ diẹ ni idanikanwa ni mo ṣe ayẹwo miran gẹgẹ bi agbekalẹ ajọ NCDC, iṣẹju diẹ sẹyin ni mo gba esi ayẹwo naa, to si fi han pe mi o ni arun ọhun mọ.
Ẹ̀yin tí ẹ kórìíra ohun rere, tí ẹ sì fẹ́ràn ibi, ẹ̀yin tí ẹ bó awọ lára àwọn eniyan mi, tí ẹ sì ya ẹran ara egungun wọn; 
Olórí ogun kẹta ni Amasaya, ọmọ Sikiri, ẹni tí ó yọ̀ǹda ara rẹ̀ fún iṣẹ́ OLUWA, ó ní ọ̀kẹ́ mẹ́wàá (200,000) akọni ọmọ ogun.
Nígbà tí Toi, ọba Hamati gbọ́ pé Dafidi ti ṣẹgun gbogbo àwọn ọmọ ogun Hadadeseri, ọba Soba, 
Aṣofin Ọbasa ti o tun jẹ alaga igbimọ awọn
O ni o yẹ ki ijọba fi ọrọ naa lọ awọn ọmọ ilẹ Yoruba ati ẹ̀yà to ku, lati gba akọsilẹ orukọ awọn eeyan to ṣe pataki si ẹ̀yà wọn, lati fun ni iru ọlá bẹ ẹ.
Nígbà tí a kí i tán, a lọ kí àbúrò Òmùgọ́dimẹ́ta ẹni ti orúkọ rẹ ń jẹ́ Dánásungbó.
Manchester United dáná sun Chelsea bi ẹràn àgbò iléyá Àṣìta ìbọn ló pa obìnrin nílùú Eko lọ́jọ́ Satide- Ọlọ́pàá Kí ní Khafi BB Naija yóò pàdánu tí iṣẹ́ ba bọ́ lọ́wọ́ rẹ̀?
Ọ̀sẹ̀ kini oṣù keje ọdún Ẹgbàálémẹ́rìndínlógún ṣòro fún àwọn Àméríkà.
Dafidi bá rán oníṣẹ́ lọ, láti wádìí aya ẹni tí obinrin náà í ṣe.
”Asán ni èyí pàápàá ati ìmúlẹ̀mófo.
Njẹ ìṣẹ́ ti buru jai si?
O ni ijọba ti ṣetan lati ṣe ohun gbogbo tawọn ọdọ n beere eyi to mu wọn ṣe iwọde EndSARS.
00 to je bilionu mẹ́rìndínlọ́gọ́fà ati ogorun milionu naira lo je.
Oríṣun àwòrán, @NGRSenate Àkọlé àwòrán, Awọn ipenija to n ba ibagbepọ alaafia ati eto abo orilẹede Naijiria finra lo sokunfa apero ọrọ abo ti awọn asofin se nilu Abuja Ohun ti Aarẹ ileegbimọ asofin orilẹede Naijiria, Bukọla Saraki sọ.
Àwọn tí wọ́n jẹ́ baálé baálé pọ̀ ninu àwọn ọmọ Eleasari ju ti Itamari lọ, nítorí náà, wọ́n pín àwọn ọmọ Eleasari sí abẹ́ àwọn baálé baálé mẹrindinlogun, wọ́n sì pín àwọn ọmọ Itamari sí abẹ́ àwọn baálé baálé mẹjọ.
Mo mú ọ̀pá meji, mo sọ ọ̀kan ní “Oore-ọ̀fẹ́,” mo sì sọ ekeji ní “Ìṣọ̀kan.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Rape Case: Tó o bá ṣàdéhùn ìfẹ́ tó ò mú u ṣẹ, ẹ̀wọ̀n lo fi ń ṣeré 19 Ìgbé 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Ṣe ti ọkunrin ba kọ lati fẹ obinrin to ti ṣeleri fun pe oun yoo fi ṣ'aya, ṣe a le pe ibalopọ to ti waye laarin wọn lasiko ti wọn n rinrinajo ifẹ ni ifipanilopọ?
6 mílíọ̀nù ni-APC 20 Ẹrẹ̀nà 2019 Oríṣun àwòrán, Lanre Issa-Onilu Ẹgbẹ oselu All Progressives Congress ti fesi si ọrọ oludije ẹgbẹ oselu Peoples Democrativc Party,PDP Atiku Abubakar to ni ohun fi ibo 1.
Àkọlé àwòrán, ọdun Keresi jẹ ti ọjọ ibi Jesu Kristi Ọdun Keresimesi: ọjọ kẹẹdọgbọn, oṣu kejila: Ni gbogbo agbaye ni wọn ti n sami ọjọ keresimesi ni asiko yii.
Orí kó Ààrẹ yọ lọ́wọ́ àdó olóró Ìwádìí BBC: Àwọn ará Èkìtì ń sáré gba N4,000 sáájú ìbò Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ọdunlade Adekọla gbóṣùbà fáwọn ọkùnrin tó ń ran ìyàwó wọn lọ́wọ́ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Obìnrin tí kó ba fẹ́ òṣìṣẹ́ Mọ́ṣúárì, ìpinu rẹ̀ mẹ́hẹ' Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Fẹla Durotoye: ọ̀rọ̀ ìṣọ̀kan Nàìjíríà tó àpérò ọmọ eríwo Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Lẹ́yìn tí Mose bá wọn sọ̀rọ̀ tán ó fi aṣọ ìbòjú bo ojú rẹ̀.
Àwọn ìtàn mánigbàgbé tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ìtàn Àrọ̀gìdìgbà jẹ́ kí ń rò pé bàbá mi yan Yemọ̀ja ní àlè - Ọmọ Fagunwa Ó pé ọdún mẹ́rìnlélàádọ̀ta tí Akintola kú, ìdí abájọ ìja rẹ̀ pẹ̀lú Awolowo rè é Ìtàn Gbọnka àti Timi, akọni méjì tó borí Aláàfin Ṣango Wo ìṣẹ̀lẹ̀ márùn-ún tí kò bá pín Nàíjíríà sí yẹ́lẹ-yẹ̀lẹ Eji Gbadero, ọmọ Ibadan àti jayé-jayé ọmọ ónílẹ̀ ti wọn yẹgi fun l'Eko Lisabi Agbongbo Akala rèé, ẹni tó fi ìfẹ́, ìṣọ̀kan àti ìrẹ́pọ̀ gba ilẹ̀ Ẹ̀gbá lọ́wọ́ ìmúnisìn Bakan naa lo tun maa n lọ ẹrọ ata ni owurọ fun iya rẹ to ni ẹrọ ata to fi n pawo wọle, ko to ls sile ẹkọ.
Iṣẹ orin kíkọ si loun naa yan laayo ni Kentucky lorilẹ-ede Amẹrika, to si ti gba ami ẹyẹ Grammy ni ẹẹmẹta ọtọọtọ.
O fi kun wi pe Ilẹ Gẹẹsi ti se atilẹyin imọ oye fun ọmọogun to to ẹgbẹrun lọna ọgbọn lati fi atilẹyin wọn han fun orilẹede Naijiria.
Ẹ̀yà Bẹnjamini ni yóo pàgọ́ tẹ̀lé ẹ̀yà Manase; Abidoni, ọmọ Gideoni ni yóo sì jẹ́ olórí wọn.
1 368 Orilẹede Fiji 2 0.
Ó fi bàbà ṣe òpó meji; gíga ọ̀kọ̀ọ̀kan jẹ́ igbọnwọ mejidinlogun, àyíká rẹ̀ sì jẹ́ igbọnwọ mejila, ó ní ihò ninu, nínípọn rẹ̀ sì jẹ́ ìka mẹrin.
Ẹni tí ó ń wá owó kí Olódúmarè fún un ní owó àǹfààní; ẹni tí ó ń wá ọmọ kí Ẹlẹ́dàá fún un ní ọmọ àlàáfíà; ẹyí tí ó wá iṣẹ́ kí Ọ̀g;a Ògo fún un ní iṣẹ́ tí yóó ṣe é ní rere.
Àwọn ọmọ Merari láti inú ìdílé Jaasaya ni Beno ati Ṣohamu, Sakuri ati Ibiri.
odo obinrin tojo ori won koju ogun odun lo (2020 FIFA U-20 Women’s World Cup).
Banaba bá wá Paulu lọ sí Tasu.
Oríṣun àwòrán, Abiola Ajimobi Akọroyin wa to lọ si mọsalasi Ansarudeen to yẹ ki eto isinku naa ti waye lonii tẹlẹ jabọ pe se ni ibẹ da paro paro.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Afurasi ọmọ ẹgbẹ Boko Haram lọwọ ti te ni ilẹ Germany 26 Sẹ́rẹ́ 2018 Oríṣun àwòrán, EPA Àkọlé àwòrán, Boko Haram ti jin ogunlọgo ẹniyan gbe lati ọdun 2009 Páńpẹ́ ọba ti mú ọmọ ọdún mẹ́tàdínlọ́gbọ̀n afurasí Boko Haram kan tó tun jẹ́ ọmọ Naijiria ni orilẹ́ede Germany.
Jesu wí fún un pé, “Ṣebí mo ti sọ fún ọ pé bí o bá gbàgbọ́ ìwọ yóo rí ògo Ọlọrun.
Lara awọn to ba BBC Yorua sọrọ ni nkan ko rọgbọ fun wọn lati igba ti igbele naa ti bẹrẹ.
Oríṣun àwòrán, Mario Tama/Getty Images Vanuatu Lootọọ ni pe ibode ti wọn ti pe sọ ọpọ di alaini ni Vanautu, ọpọ eeyan ilẹ naa ni ko si fẹ ki wọn ṣi ibode naa pada laipẹ.
Lanre Issa Onilu, tii se akọwe ipolongo apapọ fun ẹgbẹ APC salaye pe, ọrọ Wadume dabi afomọ to n wa gbongbo ti yoo so mọ ni lasiko to fẹ subu sinu odo, o si di dandan ki Wadume to n koju idajọ fẹ wa awọn ti yoo fẹyin ti ni.
Wọn ko tako ṣiṣe ọdun Keresimesi: Iyalẹnu nla ni eyi jẹ lati ri i pe wọn faramọ ṣiṣe ajọyọ ọjọ ibi Jesu.
votes), ti egbe oselu PDP si ni, apapo ibo (283,847 votes).
Kenya gbona lori ikọlu awọn ọlọọpaati oluwọde
"Igba ti o ba si wu mi ni mo le ṣe abẹwo si ana mi"" Fayẹmi ko sọ ohunkohun ti o jọ mọ atundi ibo gomina ipinlẹ lasiko to n dahun ibeere awọn oniroyin nibi abẹwo naa."
"Nkan tí a mọ̀ nìyíì Mo ti kúrò ní ààfin Oyo, kí ìròyìn tó ò jáde pé èmi àti Wasiu Ayinde n fẹ́ ara wa - Olori Badirat Gẹgẹ bi google ṣe sọ ọ, Maryam Sanda ni ẹni ikẹẹsan lori ayelujara ni Naijiria lọdun yii, tawọn eeyan fẹ mọ nipa rẹ Wo ẹkunrẹrẹ oniruuru isọri ohun tawọn eeyan n wa ati awọn to gba ipo kinni gẹgẹ bi google ṣe gbe e jade: Awọn eeyan ti wọn n wa nipa wọn ju (Nigeria): Joe Biden Rema Naira Marley Rahama Sadau Hushpuppi Laycon Kamala Harris Omah Lay Maryam Sanda Kai Havertz Nkan gboogi mẹwa tawọn eeyan n wa lọdun yii ni Naijiria lorii Google: Coronavirus US election Joe Biden Google Classroom ASUU Zoom Live Rema Naira Marley Rahama Sadua Hushpuppi Iru ounjẹ, nkan mimu ati ipanu tawọn eeyan n beere ju nipa rẹ ni Naijiria lorii Google: Pornstar martini recipe Puff puff recipe Pancake recipe Red velvet cake recipe Meat pie recipe Chin chin recipe Bread recipe Chocolate cake recipe Oha soup recipe Egusi soup recipe Awọn orin mẹwaa tawọn eeyan tẹ soju opo Google lọdun 2020: Davido - Fem Simi - Duduke XXXTentacion - Bad Betty - Butter Rema- Ginger me Rema - Woman Burna Boy - Wonderful Patoranking - Abule Naira Marley - Tesumole Davido ft Nicki Minaj - Holy Ground Awọn ibeere bii ""bawo ni wọn ṣe n ṣe burẹdi jẹ ọkan lara ibeere to wa loke ohun tawọn eeyan n bi Google ju lọdun 2020."
Ẹ má ṣe jẹ́ ohun ìkọsẹ̀ fún àwọn Juu tabi fún àwọn tí kì í ṣe Juu tabi fún ìjọ Ọlọrun.
Ninu ọgọrun-un tí ìlú mìíràn bá rán jáde, mẹ́wàá péré ni yóo kù.
Àyìndé ọwọ́ ti tẹ àgádágodo wọn
Orukọ awọn ibeji Femi Adebayo ni Fadlullah ati Fadlulrahman Adebayo, awọn mejeeji jọ ara wọn bii imumu, ti wọn si rẹwa ni ọmọkunrin.
Lẹyin iku iyawo rẹ, Barbara ni oṣu kẹrin ọdun yii ni wọn gbe e lọ sile iwosan fun itsju aisan kokoro kan .
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ọlọpa:Ọwọ palaba adigunjale mẹrin segi nipinlẹ Ọsun 30 Sẹ́rẹ́ 2018 Oríṣun àwòrán, Baba Oloye Àkọlé àwòrán, Ọpọ araalu lo ti padanu ọkọ wọn si ọwọ awọn ọlọsa ti ọwọ ba yii Ọkọ ayọkẹlẹ mọkandinlogun lawọn ọlọpa ti gba lọwọ awọn adigunjale nipinlẹ Ọsun.
" Ni ṣe ni Christina pa isẹ oko ti, ko le ri aaye gbajumọ iwe kika, ni imurasilẹ fun idanwo.
NFF: Ilé ẹjọ́ ní k'ọ́lọ́pàá ó wọ́ Amaju Pinnick wá síwájú òun lórí ẹ̀sùn ìkówójẹ
O ni ara oun ti wọn fi n bu oun naa ni oun pa owo wọle fun oun.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ogun Flood: Ọ̀pọ́ Dúkìá ló sọnù ní 2019 lásìkò tí ìjọba ṣí dáàmù Ọyan Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Ogun Flood: Ọ̀pọ́ Dúkìá ló sọnù ní 2019 lásìkò tí ìjọba ṣí dáàmù Ọyan 1 Agẹmo 2020 Awọn ara agbegbe Iṣheri ti ke gbajare si ijọba lati dawọ duro lori igbese wọn lati ṣi daamu Oyan laipẹ.
1 514338 Orilẹede Sweden 10323 103.
Ó fi ẹnu kò ó lẹ́nu, ó sì wí fún un pé, “OLUWA fi àmì òróró yàn ọ́ ní olórí àwọn eniyan Israẹli.
O fi ye wa pe agbara wa ninu fifohunṣọkan.
Sọ èyí tí o bá fẹ́, kí n lè mọ ohun tí n óo sọ fún ẹni tí ó rán mi.
Mamora sọ pe Naijiria gba awọn agbo naa lati ṣe atilẹyin fun akẹẹgbẹ rẹ nilẹ Africa to kede pe oun ti ri iwosan fun Covid-19.
Ṣugbọn ẹni tí Ọlọrun jí dìde kò ní ìrírí ìdíbàjẹ́.
Wo àwọn ọmọ ilé ìgbìmọ̀ aṣòfin l'Abuja tó sùn fọnfọn lásìkò ìjókòó ilé 'Ó tẹ́mi lọ́rùn kí n pàdánù ẹsẹ̀ mi, ju kí ǹkan ṣe oyún inú mi' Ọkọ Funke Akindele kó eléré àti òṣìṣẹ́ jọ fi ṣe Surprise Pato"" fún un lọ́jọ́ ìbí rẹ̀ Kọmísọ́nà ètò ìlera ìpińlẹ̀ Eko ọjọ̀gbọ́n Akin Abayomi lùgbàdì ààrùn Covid-19 Oríṣun àwòrán, Others Kọmísọ́nà ètò ìlera ní ìpińlẹ̀ Eko, ọ̀jọ̀gbọ́n Akin Abayomi ti lugbàdì ààrún."
Àwọn nǹkan mẹfa kan wà tí OLUWA kò fẹ́:wọ́n tilẹ̀ tó meje tí ó jẹ́ ohun ìríra fún un:
Àwọn tí wọ́n ń tọwọ́ b'àpò mú owó ọkọ̀ jáde san fún ilé-iṣẹ́ ọkọ̀ òfurufú.
“Erongba wa ni pe, ni ipari ijiroro yii, awon ti oro kan gbodo duro sinsin, ki ajosepo ti o fese mule si wa”.
Àkọlé àwòrán, Abeokuta, Ogun A o maa mu ẹkunrẹrẹ iroyin naa wa fun yin bo ṣe n lọ jakejado Naijiria.
Ajimobi ni ile orin naa lo wa lẹba oju popo, ti Ayefele ko si tun ni iwe onilẹ to yẹ nipa ilẹ to kọ ile le lori.
Ọpọ gbagbọ pe awọn kan lara wọn ti dagba ju fun idije naa.
Awọn kan sọ pe ado-oloro lo bu gbamu ni agbegbe naa.
ti adari iko omo ogun ẹkun naa  Brigade
Kọmísọ́nà ètò ìròyìn àti ọ̀rọ̀ tó n lọ ní ìpínlẹ̀ Eko Gbenga Omotoso lo fi ọ̀rọ̀ náà léde nínú àtẹ̀jáde kan lójú òpó twitter rẹ̀.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Russia 2018: Aare Buhari pase ki wọn lọ ko awọn alátilẹyin àgbabọọlu pada sílé Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Russia 2018: Aare Buhari pase ki wọn lọ ko awọn alátilẹyin àgbabọọlu pada sílé 14 Agẹmo 2018 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 16 Agẹmo 2018 Aarẹ Muhammadu Buhari ti pasẹ fun Minisita fun ọrọ ilẹ okeere, Geoffery Onyeama lati ko gbogbo awọn to lọ se atilẹyin fun Super Eagles nibi Idije Ife Ẹyẹ Agbaye, Russia 2018 pada wale.
Yóo bukun àwọn tí ó bẹ̀rù rẹ̀,ati àwọn ọlọ́lá ati àwọn mẹ̀kúnnù.
Rutu bá sùn lẹ́bàá ẹsẹ̀ rẹ̀ títí di òwúrọ̀ ọjọ́ keji, ṣugbọn ó tètè dìde ní àfẹ̀mọ́jú, kí eniyan tó lè dá eniyan mọ̀.
tí ẹ bá dúró ninu igbagbọ, tí ẹ fi ẹsẹ̀ múlẹ̀, tí ẹ dúró gbọningbọnin, tí ẹ kò kúrò ninu ìrètí ìyìn rere tí ẹ ti gbọ́, tí èmi Paulu jẹ́ iranṣẹ rẹ̀, tí a ti waasu rẹ̀ fún gbogbo ẹ̀dá ayé.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ọyọ: Alaafin bi ibeji l‘ẹẹmeji lọsẹ kansoso 24 Òkùdu 2020 Oríṣun àwòrán, Olubunmi Labiyi Àkọlé àwòrán, A ku oriire ibeji obirin ni aafin Ọyọ Alaafin tilu Ọyọ, Ọba lamidi Ọlayiwọla Adeyẹmi kẹta ti bi ibeji ni ẹẹmeji ọtọọtọ laarin ọsẹ kansoso.
Nibayii, eeyan 950 lo ti dero ọrun nitori ajakalẹ arun ọhun ni Naijiria.
Ṣugbọn àwọn alágbàro náà wí láàrin ara wọn pé, ‘Àrólé rẹ̀ nìyí, ẹ jẹ́ kí á pa á, kí ogún rẹ̀ jẹ́ tiwa.
Nígbà tí Ahabu rí Elija, ó wí fún un pé, “Ojú rẹ nìyí ìwọ tí ò ń yọ Israẹli lẹ́nu!
Nítorí èmi náà jẹ́ ẹni tí ó wà lábẹ́ àṣẹ.
Afẹnifẹre ni ko si ninu ofin Naijiria pe ki gomina kọkọ lọ maa gba aṣẹ lọwọ agbẹjọro agba fun Naijiria ko too pese eto aabo to peye fun awọn eniyan rẹ.
 Ẹwẹ, ni ẹkun idibo keji Ikẹja, Aṣofin
Bí o tí ń yí ninu ẹ̀jẹ̀, mo bá sọ fún ọ pé kí o yè, 
Awọn onimọ sayẹnsi ni orilẹ-ede Faranse ṣẹṣẹ fi abajade esi iwadii wọn kan sita bayii.
Kódà wọ́ tún ta okùn mọ́ abẹ́ ilé náà níbi to ti léfò, tí wọn sì ṣe ìjókòó olókùn sí i!
27 Ìgbé 2020 Láti ìgbà ti ààrùn Corornavirus ti bẹ̀rl lórílẹ̀-èdè Naijiria ni oníruuru iroyin ti n tan kalẹ.
Kò lè ṣe iṣẹ́ ìyanu níbẹ̀ àfi pé ó gbé ọwọ́ rẹ̀ lé àwọn aláìsàn bíi mélòó kan, a sì wò wọ́n sàn.
53) si ẹgbẹrun mẹsan o le diẹ naira (N9,387.
Ẹ máa yọ̀ nítorí ìrètí tí ẹ ní.
Jesu bá sọ fún un pé, “N óo wá, n óo sì wò ó sàn.
Losu to koja ni ile-ejo pase fun aare orile ede naa lati yan adari ijoba ti yoo yan awon igbimo, ti gbogbo awon oloselu egbe yoo wa nibe.
Winter Olympics: Buhari ransẹ oriire sikọ Naijiria
Ṣugbọn, awọn kan lara awọn to ṣe akoso eto naa ti sọ wi pe irun agbebọ ori, wiigi, to de sori lo gbina, kii ṣe irun rẹ gan n gan.
Nígbà tí mo wà lọ́dọ̀ wọn, mo fi agbára orúkọ rẹ pa àwọn tí o ti fi fún mi mọ́.
Ta ni ẹni tí ó ń sọ bóyá ọ̀rọ̀ kan jẹ́ àfojúdi?
Àwọn atọmọdọmọ Peresi nìwọ̀nyí: Peresi ni baba Hesironi; 
 ni 1968 , o di obinrin alawodudu akoko to je didiboyan si ile asofin amerika .
“Emi o lọ gege bi eni ti inu re n baje, mo ti se ohun to ye ki n se.
jẹ́ ẹgbaa mọkandinlọgbọn ó lé eedegbeje (59,300).
”Mikaaya dáhùn pé, “Lọ gbógun tì í, OLUWA yóo fún ọ ní ìṣẹ́gun.
BBCCopyright: BBC Ovie Omo-AgegeImage caption: Ovie Omo-Agege Article share tools Facebook Twitter ṢàpínlòView more share options Share this post Copy this linkKà síwájú síi nípa àwọn ìtọ́kasí wọ̀nyí.
Èrò burúkú àti ba oyún jẹ́ ni í máa ń wà l’ọ́kàn obìnrin tí ó ní oyún àìròtẹ́lẹ̀.
Àwọn tí ń ṣiṣẹ́ ninu ọkọ̀ati àwọn tí ń darí ọkọ̀yóo dúró ní èbúté.
Ẹ̀mí ológun kan bọ́, ọ̀pọ̀ arìnrìn àjò bọ́ sọ́wọ́ ajínigbé Àkọlé àwòrán, Awọn iròyin ẹlẹjẹ marun to ti fẹ́ tu Naijiria ka Ìrọ̀yìn òfégé náà gbalẹ̀ de bi pé wọ́n ṣe ìyàwò náà lóri ayelujára ni eyi ti ayé gbọ́ ti ọ̀rún náà mọ̀.
Oríṣun àwòrán, @AfricaFactsZone Ìpínlẹ̀ Ogun fẹ́ fi òfin wọ́gilé ìsìnkú ọba lọ́nà ìṣẹ̀mbáyé Mi o tíì rí olórí tó fẹ́ràn Naijiria tó Baba Obasanjo- Yoruba Council of Elders Lẹ́yìn ò rẹyìn, Amotekun dòhun, gbogbo ilé aṣòfin nílẹ̀ Yorùbá fòǹtẹ̀ lu Oshiomole: irọ́ ni wọ́n ń pa,èmi ṣí ní Alága APC!
Ẹ má sì gbé ara yín sílẹ̀ bí ohun èèlò fún ẹ̀ṣẹ̀.
Nǹkan yan, àwọn aṣẹ́wó fẹ́ daṣẹ́ sílẹ̀ nítorí ẹ̀kúnwó epo ní Nàìjíríà Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Èmi gan máa ń béèrè lọ́wọ́ ara mi pé ta ni Wole Soyinka gangan' Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Bíbẹ́ẹ̀kọ́ gbogbo àwọn eranko ìsìn wọn, ti àgùntàn ti màlúù, ò bá sálọ tán.
Labẹ ofin to de eto owo ifẹyinti ni Naijiria, awọn alakoso owo ifẹyinti yi ni wọn lẹtọ lati fi owo yi dokowo lọna ti yoo pawo wọle fawọn to ni.
 díẹ ̀ díè àwọn olórí ibẹ ̀ gba àpẹrẹ àṣà , ẹ ̀ sìn àti olóṣèlú láti òkèrè láti ìbẹ ̀ rẹ ̀ àwọn ọ ̀ rúndún ce , bẹ ́ ẹ ̀ sìni àwọn ilẹ ̀ ọba hindu àti buddhisti gbòòrò .
“Lọ kéde sí etígbọ̀ọ́ àwọn ará Jerusalẹmu, pé èmi OLUWA ní, mo ranti bí o ti fi ara rẹ jì mí nígbà èwe rẹ, ìfẹ́ rẹ dàbí ìfẹ́ iyawo àṣẹ̀ṣẹ̀gbé; mo ranti bí o ṣe ń tẹ̀lé mi ninu aṣálẹ̀, ní ilẹ̀ tí ẹnikẹ́ni kò gbin nǹkankan sí.
Ìgbésẹ̀ Boris Johnson gẹ́gẹ́ bí àwọn kan ṣe ríi dàbi ọ̀nà láti ka àwọn ọmọ ilé ìgbìmọ aṣòfin lápákò kí wan baa le dá ilẹ̀ gẹẹsì dúro láti kurò ni àgbájọ Yúróòpù lábẹ àwọn àyàfi kan ti wọ́n lè gbe sílẹ̀.
O ni ijọba ko tii fi to ẹgbẹ ọhun leti pe o ti wọgile ijọsin ti eeyan rẹ ju aadọta lọ.
Nigba ti akọroyin BBC de ilé ti Idris to yinbọn fun awọn to n fi ẹṣin sare ije n gbe ni Kano ni a gbọ ọrọ kikun nipa rẹ.
“Nítorí náà mo rán àwọn oníṣẹ́ láti aṣálẹ̀ Kedemotu, sí Sihoni, ọba Heṣiboni.
Tinubu, yé é sọ̀rọ̀ abẹ́lẹ̀, bọ́ sí gbangba láti bèèrè àtúntò Nàíjíríà lọ́dọ̀ Buhari - Afẹnifẹrẹ Wo àwọn ìlànà tuntun ti o gbọdọ tẹlèé rèé ki ó to le wọkọ̀ òfurufú lọ sókè òkun Ẹ̀rọ CCTV tú àsírí ọkùnrin ẹni ọgbọ̀n ọdún tó fi ipá bá ọmọ ọdún mọ́kànlá lòpọ̀ Toyin Abraham pé 40, wo ohun márùn ún tó mú dá yàtọ̀ láàrín ogójì ọdún Nengi fún Erica lésì pé, kìí ṣe pé Kiddwaya fi bẹ́ẹ̀ wu òun lọ́mọ́kùnrin, sùgbọ́n kìí ṣe inú ilé BB Naija ni òun ti ṣẹ̀ṣẹ̀ mọ Kiddwaya, àti pé àwọn ti mọra tipẹ́.
Obesere sọ pe oun gan an ni ipo agba ninu orin Fuji kan lẹyin oloogbe Barrister ati Kollington.
Oríṣun àwòrán, BBC Sport Àkọlé àwòrán, Ni ọjọ yii, wọn a maa ṣe agbeyẹwo ipa ti awọn to wa ni ilẹ okere le ko lati mu idagbasoke ba Naijiria.
Má wá sí Nàìjíríà láti ṣe ère orí itage lákòókò naa, má tún kó ọjà wá láti tá nile, orí kò si ní òun yoo bá ọrùn dúró nígbà náà.
Ninu ọrọ rẹ to sọ lati pe fun ki wọn dibo yan an fun saa keji, Adesina ni oun n lo oun gbogbo ti oun ni lati sin ilẹ Afirika lai lẹ́ja n bákàn ninu.
Oríṣun àwòrán, @apple Lawọn orilẹede kan, 5G ko tii di kari ile kari oko.
"Kọmísọ́nà ọlọ́pàá tí fí ìwé ẹ̀dùn ọlọ́pàá ṣọwọ́ sí ìjọba, àtàwọn ǹkan ti yóò mú ìwúrí bá àwọn ọlọ́pàá lásìkò yiì.
Ẹ̀rín ni wọ́n fi wá rín nígbàtí wọ́n ṣàkíyèsí pé ó bàwá lẹ́rù díẹ̀.
Òun ni ó mú kí ẹ máa ní ẹ̀sùn sí ara yín.
BBCCopyright: BBC Babajide SanwooluImage caption: Babajide Sanwoolu Article share tools Facebook Twitter ṢàpínlòView more share options Share this post Copy this linkKà síwájú síi nípa àwọn ìtọ́kasí wọ̀nyí.
Bákan náà, Dafidi ọba kó ọpọlọpọ idẹ láti Bẹta ati Berotai, ìlú meji ninu àwọn ìlú tí ó wà lábẹ́ ìjọba Hadadeseri.
 Nigba to n salaye ohun to gbe de orile-ede south Africa to tẹdo si bayii, agba Inaki ṣalaye pe ""Bi mo ṣe pari ẹkọ Fasiti, ti mo lọ sinru ilu ni iya mi ku, ba si ṣe sin oku tan, ti mo pari agunbanirọ, ni mo tẹle ọrẹ mi lọ si orílẹ̀ ede south Africa, lati pa ironu rẹ"" ""A bẹrẹ si ran aṣọ ta, sugbọn a ti pa iṣẹ naa ti bayii, ta si tun mu orin kikọ ni ibaada, ede Yoruba ni emi n lo, ti awọn eeyan si tun maa n gbadun mi."
Oríṣun àwòrán, Getty Images Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Buhari yóò mú gbogbo ìlérí rẹ̀ ṣẹ Oríṣun àwòrán, Facebook/Femi-Adesina ''Igbonara wa ti pọju, ikunsinu pọ fun wa, a fẹran ka maa sọ ijọba lorukọ buruku, awọn to ba n gbiyanju ati tun ilu ṣe orukọ ti ko da laa n sọ wọn'' Bi ẹ ba gbọ bi awọn eeyan kan ti ṣe n sọrọ, awọn ọdọ tara wọn n gbona, awọn olori ẹlẹsin,awọn onwoye agbo oṣelu to fi mọ awọn ti wọn pe ara wọn lajafẹtọmọniyan, wan kii ri nkan daada kan ninu ijọba yi'' Adesina wa ṣe akawe awọn iṣẹ ti ijọba ti sẹ to fi mọ ipese awọn ohun amayederun fara ilu lẹka orisirisi.
tele aare ni minisita fun ọrọ ilẹ okeere , Geoffrey Onyeama; oludamọran fun
Nígbàkúùgbà tí ọba bá lọ sí ilé OLUWA, olùṣọ́ ààfin á ru apata náà ní iwájú rẹ̀, lẹ́yìn náà yóo kó wọn pada sí ibi tí wọ́n kó wọn pamọ́ sí.
"màríà ( èdè aramaiki , èdè heberu : מרים , "" maryām "" "" miriam "" ; èdè arabu : مريم , "" maryam "" ) , ti awon omo leyin kristi n pe ni mariamo , maria wundia tabi maria mimo ati nigba miran madonna , je obinrin ju ara nazareth ni galilee , ti majemu tuntun tokasi gege bi iya jesu kristi ."
8%) Amọṣa lorilẹede Amẹrika, ilana ti wọn fi n yan aarẹ wọn yatọ si bi wọn ṣe n ṣe lọpọ orilẹede jakejado agbaye.
Ẹgbẹ́ àwọn òṣìṣẹ́ elétò ìlera, JOHESU bẹ̀rẹ̀ ìyanṣẹ́lódì káàkiri Nàìjíríà Ṣé Fulani daran-daran ni àwọn tó n jí ènìyàn gbé ní ìpínlẹ̀ Ondo?
Ọ̀kọ̀ọ̀kan ninu wọn ní iwájú mẹrin mẹrin.
O ṣalaye pe awọn n sọja n mu awọn ọdọ kaakiri, eyi lo jẹ ki ọpọ maa bẹru lati jade nile.
Ibadan Market looting: Ọjà ẹgbẹ̀lẹ́gbẹ́ mílíọ̀nù ni jàǹdùkú kó lọ́jà Agbeni, wọ́n tún sọná sun ṣọ́ọ̀bù
eniyan ti o farapa nibi isẹlẹ naa.
Awọn ọmọ Naijiria ko ti i dakẹ lori ipe wọn si ijọba apapọ lati wa atunṣe ti yoo wa lailai si iṣẹlẹ iṣekupani to n waye nipinlẹ Zamfara.
A fún un ní ẹnu láti fi sọ̀rọ̀ tí ó ju ẹnu rẹ̀ lọ, ọ̀rọ̀ àfojúdi sí Ọlọrun.
Àwọn pidánpidán náà gbìyànjú láti mú kí iná jáde pẹlu ọgbọ́n idán wọn, ṣugbọn wọn kò lè ṣe é.
Ọkàn OLUWA sì bàjẹ́ pé òun fi Saulu jọba Israẹli.
Òògùn ẹ̀fọn pa ọmọ mẹ́ta ní Ghana Naijiria bẹ̀rẹ̀ abẹ́rẹ́ àjẹsára Ọ̀nà àbáyọ dé fún àìsàn ibà Ìròyìn ta gbọ ni pe, Iya wọn fin ogún oloro náà silẹ̀, lati dẹkùn bi ááyán ṣe n daamu wọn.
"Àwọn ìròyín mìíràn tí ẹ lè nífẹ̀ẹ́ sí: Njẹ o mọ oju yi ni ""Yollywood""?"
Bí wọ́n ti wọ inú ilé Ọlọrun lọ, tí wọ́n sì jẹ burẹdi tí ó wà lórí tabili níwájú Oluwa, èyí tí ó lòdì sí òfin fún òun ati àwọn tí ó wà pẹlu rẹ̀ láti jẹ bíkòṣe fún àwọn alufaa nìkan?
"Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: ""APC àti PDP ń dìtẹ̀ láti yọ Seyi Makinde ní 2023, ẹ gbàdúra fun kó gúnlẹ̀ ayọ̀"" Ìwọ́de ńlá míì ń bọ̀ ní March, tí December 2021 yóò sì gbóná fáwọn ọ̀jẹ̀lú olóṣelú - Alfa sọ àsọtẹ́lẹ̀ Njẹ́ ẹ ti gbọ́ nípa àríyá oníhòhò àti ìbálòpọ̀ tó fẹ́ wáyé ní Kaduna lásìkò ọdún?"
 jésú sẹ ọ ̀ pòḷòp ̣ ọ ̀ iṣẹ ́ ìyanu láti fi ìfé olódùmarè hàn sí àwọn ọmọ ènìyàn .
Ọkọ̀ ọ̀fẹ́ ní ọmọ tuntun jòjòlò tí wọ́n bí sínú ọkọ̀ òfurufú yóò máa wọ̀ títí ayé rẹ̀- Egypt Air Ẹ lọ ṣí gbogbo ilé ẹ̀kọ́ padà ní Nàíjíríà - Ìjọba àpàpọ̀ Irọ́ ni o!
” Nígbà tí ó sọ báyìí tán, ó kú.
Ilẹ̀-ìní ẹ̀yà kan kò gbọdọ̀ di ti ẹ̀yà mìíràn, ilẹ̀ ẹ̀yà kọ̀ọ̀kan gbọdọ̀ wà ní ìkáwọ́ rẹ̀.
Atari ajanaku lọrọ to wa nilẹ yi Lati ọdun 2009 ni ọrọ iwadi owo agbaṣe lẹka yi ti n mẹhẹ.
" Iwe naa, ti asofin agba nilẹ Amẹrika, Sẹnetọ Robert Menedez ati ọmọ ile asoju sofin kan, Josh Gottheimer dijọ fọwọsi lo tun bu ẹnu atẹ lu ijọba Naijiria fun bo se n huwa ọyaju, to si tun ti Sowore atawọn eeyan miran mọle, awọn to sọ pe wọn n sewadi, ti wọn si n sọrọ sita lati tako awọn isoro ti wọn kẹẹfin nidi eto isejọba, to fi mọ iwa ajẹbanu ati aisi eto aabo to peye.
Ninu ọrọ kan ti ọga ọlọpaa fi sita loju opo Twitter ile iṣẹ ọlọpaa lọjọ Abamẹta, o sọ pe ẹsun iditẹ gbajọba ati igbesunmọmi lawọn yoo fi kan ẹnikẹni to ba kopa ninu ifẹhonu han gbogbogbo naa.
Amọ, akọnimọọgba Super Falcons, Thomas Dennerby sọ pe ẹgbẹ agbabọọlu Naijiria ṣe tan lati gbo ewuro soju South Korea lonii.
Aare  egbe ICAO , ogbeni  Bernard Aliu,ni ilẹ Afirika ko ida merin ninu ọgọ́rùn ún ninu
 Bee si ni, ki Russia lo ipo won silu Syria lati fi da ikolu miiran bi o ti le wu ko mo duro.
OLUWA sọ Asaraya ọba di adẹ́tẹ̀, ó sì wà bẹ́ẹ̀ títí di ọjọ́ ikú rẹ̀, ó ń dá gbé.
UTAS, ASUU, IPPIS, FGA kó ní sanwó oṣú ASUU láìjẹ́ pé wọ́n gba IPPIS- Ìjọba Àpapọ̀
Aṣofin Ọbasa fi da awọn ọmọde lorilẹ-ede Naijiria loju pe ijọba ẹgbẹ oṣelu ‘All Progesives Congress (APC)’ to wa lori aleefa yoo tẹ siwaju lati fọwọ ọkunkundun mu awọn ọrọ to nii ṣe pẹlu awọn ọmode nipasẹ awọn eto ati liana iṣakoso ijọba loriṣiriṣi, ti yoo fi mu igbe-aye rọrun fun wọn siwaju.
Filipi lọ sí ìlú Samaria kan, ó waasu fún wọn nípa Kristi.
Aare Buhari, eni ti igbakeji re,ojogbon Yemi Osinbajo soju fun so pe, ise-akanse etikun ohun yoo je eyi ti o tobi ju ni ekun naa, ni eyi ti yoo je ibi-ise kan gboogi ni ile Afrika.
Ọ̀pọ̀ èèyàn bẹnu ẹ̀tẹ́ lu Mercy Aigbe lórí bó ṣe ki Adeniyi Johnson O dìgbà tí mo bá dórí àgá kí ń tó sọ ìpinnu mi - Fatai Owoseni Falana àtàwọn míì péjú síbi àpérò #RevolutionNow l'Eko O tó gẹ́; A kò fẹ́ ìwòkuwò mọ́ ní Nàijíríà- Runsewe (NCAC) Fayẹmi ni ohun kan to jẹ ijọba oun logun ni gbigbe aṣa ati iṣe ga ni ipinlẹ naa pẹlu gbigbe ede Yoruba ati ede Ekiti larugẹ.
Saaju ni isede naa wa l;ati aago mẹfa irọle si aago mẹjọ aarọ ṣugbọn ijọba ti dẹwọ rẹ bayii si aago mẹjọ alẹ si aago mẹfa idaji.
Gbogbo ilẹ̀ tí ó ti jẹ́ ti Saulu baba baba rẹ rí, ni n óo dá pada fún ọ, a óo sì jọ máa jẹun lórí tabili mi nígbà gbogbo.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ọgbà ẹ̀wọ̀n ni wọ́n ti já àbálé Esra lábẹ́ àwáwí àyẹ̀wò wúndíá Awọn nkan miiran to tun le ṣakoba fún ọpọlọ ni wọnyi: 6.
Oríṣun àwòrán, Seyi Makinde Bẹẹ ba gbagbe, ọjọru, ọjọ Kọkandinlọgbọn, oṣu Karun un ọdun 2019, to jẹ ọjọ ti wọn bura fun un gẹgẹ bi gomina tuntun ni ipinlẹ Ọyọ, ni Gomina Seyi Makinde paṣẹ pe ki gbogbo awọn alaga ijọba ibilẹ nipinlẹ naa fi ipo wọn silẹ ni kiakia.
Ó wí fún obinrin yìí pé, “Jọ̀wọ́ lọ bá mi bu omi wá kí n mu.
Ó sì wí pé, “OLUWA, kò yẹ kí n mu omi yìí, nítorí pé, yóo dàbí ẹni pé ẹ̀jẹ̀ àwọn ọkunrin mẹta yìí, tí wọ́n fi orí la ikú lọ ni mò ń mu.
Ẹnìkan tí ó ní àrùn ẹ̀tẹ̀ sì wá, ó kúnlẹ̀ níwájú rẹ̀, ó ní, “Alàgbà bí o bá fẹ́, o lè sọ ara mi di mímọ́.
Nítorí náà káwọ́ lérí kí o sì máa hu.
Bí Peteru ti fẹ́ wọlé, Kọniliu lọ pàdé rẹ̀.
Bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé OLUWA ga lọ́lá,ó ka àwọn onírẹ̀lẹ̀ sí,ṣugbọn ó mọ àwọn onigbeeraga lókèèrè.
Àwọn ẹgbẹ́ iléeṣẹ́ oníròyìn àti ajà-fún-ẹ̀tọ́ ọmọnìyàn ń ṣe àjọyọ̀ọ ti ìdásílẹ̀ lẹ́wọ̀n-ọn akọ̀ròyìn Reuters Wa Lone àti Kyaw Soe Oo tí ó lò ju ọjọ́ 500 ní àtìmọ́lé fún ipa tí wọ́n kó nínú ìwádìí òfíntótó ìṣẹ̀lẹ̀ ìpanípakúpa àwọn olùgbée Rohingya kan ní gúúsù Myanmar.
Gẹgẹ bi Adesina ṣe sọ, ọjọ Ẹti, ọjọ kẹtadinlogun, oṣu Kẹrin ni Kyari ku.
Ó kígbe lọ sí ààrin ìlú, ó ń pohùnréré ẹkún.
Sì sọ fún àwọn ọmọ Israẹli pé nígbà tí ẹnìkan bá kú láìní ọmọkunrin, àwọn ọmọbinrin rẹ̀ yóo jogún ilẹ̀ ìní rẹ̀.
'Kò sí ìyàtọ̀ nínú ọ̀kùnrin olóòtọ́ àti èyí tí kò sòótọ́ mọ́' Àlàyé rèé lórí ìdí tí ìyá mi fi sọ fáráyé pé mo ti kú Iṣọla Oyenusi rèé, ẹnití ìfẹ́ obìnrin ṣun dé ìwà ìdigunjalè Iwa nabi tu igbeyawo ọgbọn ọdun ka Igbesẹ mẹjọ to hande ninu ipaniyan mejilelaadọrin o le ni ọọdunrun iku ololufẹ: 1) Iṣẹlẹ nína ara ẹni a ti maa waye diẹdiẹ latẹyinwa ninu ajọṣepọ ololufẹ mejeeji.
Bakan náà ni Gomina ni ìjọba ti ṣe àfikún àwọn ilé iwosan ti wọ́n le ko àwọn ènìyàn si.
Ẹ wo Daniel tí wọ́n fẹ́ yẹgi fún lẹ́yìn tí US kò ṣe irú ẹ̀ fún odidi ọdún 17 Oya, wo ilana ti wa tẹle lẹsẹẹsẹ fun igbani sisẹ ọdun 2020 O gbọdọ ni imeeli to n sisẹ, ati nọ́mbà NIN, ki o to bẹrẹ iforukọsilẹ.
Wọ́n bẹ̀rẹ̀ sí bá obinrin mi lòpọ̀ títí tí ó fi kú.
Ẹya ara 'pelvis' yii kan naa lo gbe awọn ẹya ara to gbe nkan smọkunrin ati oju ara obinrin duro.
O ni ẹgbẹ APC ko nilo lati ṣe eeru ninu ibo ni ipinlẹ tawọn araalu ti gba ẹgbẹ naa tọwọ teṣẹ lọdun mẹrin sẹyin.
Kishi sile ni pe won se akiyesi pe awon eniyan agbegbe Kishi ko faaye gba osise
Òun àti èkejì-i rẹ̀ Àbùkù lọ jόkòό sí ìta níbi tí wọn ti le-è tètè rí ońjẹ jẹ.
Wọ́n jẹ ko di mimọ pe ẹni ti tara ile tara oko fẹran gan ni Oba Olayode bo tilẹ jẹ pe ija oye wa lori didi Soun Ogbomoṣo.
Kii ṣe ana ni ariyanjiyan laarin awọn eeyan, paapaa julọ, awọn ọmọ orilẹede Naijiria ati Ghana ti n waye lori irẹsi jọlọọfu ẹni to dun julọ ninu ti orilẹede mejeeji.
Awọn ọlọpaa wu oku ọmọbinrin kan, Ozigie Wovueze jade loṣu Kejila, ọdun 2018, ninu yaara ọrẹkunrin rẹ, Ndema Owabie lagbegbe Rumuepirikom.
Bakan naa lo dunkoko pe ti oun ba gbẹmi ara oun, Abdulrazak Abiola lo faa, oun si ni ki wọn mu pe o pa oun nitori bo se kede pe oun ti ni afẹsọna ti ba oun lọkan jẹ lọpọlọpọ.
OLUWA tún sọ fún mi lẹẹkeji pé, 
O tun je ki wọn si lee da awọn ibusun ile iwosan si fawọn alaisan Coronavirus nikan.
Olukolu tun fi asiko ohun da awon eniyan Ipinle Oyo loju
Awọn ọmọ ẹgbẹ Ologun rẹ, gẹgẹ bii ajọsọ wọn, naa kọlu awọn Ajẹlẹ ati Ilari to n gbe ni adugbo ikọọkan wọn, ti gbogbo wọn si fi iya nla jẹ awọn iriju Ọlọyọ ọhun Onisẹ kan Ọlọyọ lara nilu Ọyọ pe awọn Ẹgba ti siwọ lu imi, wọn ti tẹ ofin oun loju mọlẹ, ti inu si bi i gidigidi pe wọn fi ori ade wọlẹ bii eyi, ẹni to ba si ri ọba fin, ni ọba n pa Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Èmi gan máa ń béèrè lọ́wọ́ ara mi pé ta ni Wole Soyinka gangan' Ọlọyọ ransẹ pada silu Ẹgba pe ki wọn lọ jẹ wọn run amọ gudugudu awọn ọmọ Ẹgba Ologun Lisabi ko fi igba kankan tura silẹ, Koda ajẹkun iya ni awọn ọmọ ogun Ọyọ tun jẹ nilu Ẹgba lati ọwọ awọn Lisabi, ti wọn si gba itusilẹ fun awọn Ẹgba lọwọ igbekun Ọlọyọ tilu Ọyọ.
Bakan naa ni ijọba wa rọ awọn adari ileewe lati tẹle ofin ati ilana ti ijọba gbe kalẹ lati le bọ lọwọ arun Coronavirus nipinlẹ naa.
Iran ti jáwọ nínú ìlù ogun tó n lù -Trump
’’O wa ro awon oloselu lati yago fun iwa “Bi o
Oríṣun àwòrán, ỌLLABỌ̀DÉ AKAMỌ Àkọlé àwòrán, Lọjọ kejidinlọgbọn oṣu kẹfa lọkọ elepo kan da ijamba ina silẹ lori afara Ọ̀tẹdọla nilu Eko to si gba ẹmi ati dukia Gẹgẹ bii ọgbẹni Chike Oti to jẹ alukoro ileeṣẹ Ọlọpaa ipinlẹ Eko ṣe sọ, 'oju kẹrindinlogun, opopona Hitoro Limawa ni wọn ti mu arakunrin Hassan Maiwake ni ipinlẹ Kano, o si ti n ran awọn ọlọpaa lọwọ ninu iwadi wọn lati ṣawari awakọ to wa ọkọ ajagbe yii lọjọ ti iṣẹlẹ naa ṣẹ.
tuntun ti won se ni ijo Peteru ati Paulu to wa ni Nyanya niluu Abuja to je olu
Wo àwọn tó ṣeéṣe kí Ṣeyi Makinde ti kó Coronavirus ràn Máfọ́, mo wà pẹ̀lú ẹ, Ajimọbi kàn sí Makinde lóri Coronavirus to ni Ó ṣe é ṣe kí o ti ní coronavirus kí ó má mọ̀ nítorí pé ó kò rí àpẹẹrẹ Ǹjẹ́ fífi omi àti iyọ̀ yọnu leè dènà àrùn Coronavirus?
Èèyàn 2,040 làwọn agbésùnmọ̀mí ti pa ní Nàìjíríà lọ́dún yìí- Ìwádìí Àbá ìsúná N1.
Abimeleki ati àwọn ẹgbẹ́ ọmọ ogun tí wọ́n wà lọ́dọ̀ rẹ̀ sáré, wọ́n lọ gba ẹnu ọ̀nà bodè ìlú.
Nígbà tí Baali Hanani ọmọ Akibori kú, Hadadi gorí oyè, orúkọ ìlú tirẹ̀ ni Pau, orúkọ aya rẹ̀ ni Mehetabeli, ọmọ Matiredi, ọmọbinrin Mesahabu.
Ẹ̀yin tí ẹ̀ ń sọ fún ohun tí a fi igi gbẹ́, pé kí ó dìde; ẹ̀yin tí ẹ̀ ń sọ fún òkúta tí kò lè sọ̀rọ̀, pé kí ó gbéra nílẹ̀.
Ijamba baalu Syria: Ẹmi ọmọ Russia mejilelọgbọn sọnu
Okiki to kan kii ṣe nipa awọn eekan atawọn eeyan jankanjankan to peju-pesẹ sibẹ ṣugbọn pẹlu bi ọgọrọ ọlọpaa tun ṣe ya bo ibi ayẹyẹ naa.
kí ó tó já Àwọn olùgbé Fiditi pé fún ìrànlọ́wọ́ lórí àwọn òrùlé tí atẹ́gùn ojó ṣí lọ Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Ehudu bá fi ọwọ́ òsì fa idà tí ó so mọ́ itan rẹ̀ ọ̀tún yọ, ó sì tì í bọ ọba Egiloni níkùn.
6 27972 Orilẹede Albania 905 31.
Nítorí nígbà kan, ninu òkùnkùn patapata ni ẹ wà.
dibo wọn ni ikọkọ lai si iranwọ ẹnikẹni (i.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Àwọn t'Ojuẹlẹgba l'Eko sọ̀rọ̀ nípa iṣẹ́ oògùn olóró lára Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àwọn t'Ojuẹlẹgba l'Eko sọ̀rọ̀ nípa iṣẹ́ oògùn olóró lára 30 Òkùdu 2018 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 30 Owewe 2018 Wo bí oògùn olóró ṣe ń fèèyàn dábírà!
Ní ọjọ́ kẹta oṣu kinni ọdun 2019, ni ọwọ awọn agbófinró tẹ awọn ọmọdekunrin mejì tí wọ́n fẹ̀sun kan pe, wọn ji pata awọn obinrin mẹ̀wàá ká lórí okùn níbi tí wọ́n sá wọn si nílu Agbarha, nijọba ibilẹ̀ Ukwuani ni Ipinlẹ̀ Delta.
Mo dupẹ pe mo ba ọ sọrọ igbeyawo lọdun marundinlogoji sẹyin; mo dupẹ pe o gbọran si àṣẹ Oluwa lati fẹ mi."
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Òṣìṣẹ́ Bánkì ni mí l'Amẹ́ríkà kí n tó bẹ̀rẹ̀ Tíátà' Oníruuru àwọn afara to fi mọ ti 2nd Niger Bridge, àṣe pari ilé igbé ọlọpọ yanturu lagbegbe mẹ́tàlá lábẹ ètò ijọba apapọ to n kọle ọlọpọ̀ yanturu fun ará ilú.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìtàn Mánigbàgbé: Kí ni ẹ rántí nípa Israel Adebajo, gbajúmọ́ oníṣòwò tó dá 'Stationery Stores' sílẹ̀?
Òpin nǹkan sàn ju ìbẹ̀rẹ̀ rẹ̀ lọ, sùúrù sì dára ju ìwà ìgbéraga lọ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, APC Primaries: A ṣi n lọ sílé ẹjọ́ lóṣù tó m bọ̀ lórí ọ̀rọ̀ yìí Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, #Oshimole: Àwọn aṣáájú APC kò mọ ohun ti wọ́n n ṣe lásìkò yí Lootọ ni pe idibo ko ni waye ni gbogbo ipinlẹ naa sugbọn awọn amoye ni esi rẹ yoo sẹ atọna ibi ti ọpa ẹbiti idibo 2019 yoo re si.
Awon gomina mefa ni ekun iwo-oorun orile-ede Naijiria yoo ma a se ipade pelu oga ajo olopaa, ati awon eleto aabo lati wa ona abayo si isoro eto aabo to mehe ni agbeegbe naa.
Ó ní, “Báyìí ni ìjọba ọ̀run rí.
 Àrùn náà le ṣòro láti sọ yatọ ̀ sí àwọn aisàn míìràn , pà ́ apáà nígbà ìpinlẹ ̀ àkọkọ ́ bẹ ́ rẹ ̀ .
Awon osise naa sọ pe ẹru n ba wọn ki aarun Ebola naa ma se tan lọ
Ní ọjọ́ karun-un oṣù kẹrin, ní ọgbọ̀n ọdún, èmi, Isikiẹli, ọmọ Busi, wà láàrin àwọn tí wọ́n kó ní ìgbèkùn lọ sí ilẹ̀ Babiloni.
Abẹwo Aarẹ Buhari si Plateau Buhari ṣ'eleri iṣẹ f'awọn ọdọ Lẹyin ti awọn adari mejeeji sepade, aarẹ Kenyatta nigba to n ba awọn akọroyin sọrọ, pe fun ifọwọsowọpọ laarin awọn ọmọ ilẹ Kenya fun idagbasoke orilẹede naa.
Timoti ba Paulu ati Sila lọ.
Awọn atipo kan ti wọn nlọ lori okọ oju omi lo ran wọn lọwọ, ti wọn si gbe wọn wọ orilẹede Naijiria.
reti ilke igbimo asofin agba lati gbe igbese tiwon naa lori rẹ, ki o to dip e won
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Human trafficking: Ọlọpàá Spain mú ènìyàn mọkànlá tó ń fi àwọn obìnrin Nàìjíríà ṣòwò aṣẹwó 1 Èrèlè 2018 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 30 Èbibi 2020 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ọpọ ọmọbinrin Naijiria ni wọn fi n sowo nabi ni Spain Ọwọ awọn agbofinro lorilẹ-ede Spain ti tẹ eniyan mokanla lori ẹsun pe wọn n ko awọn ọmọbinrin Naijiria wa sorilẹ-ede naa lati fi se owo aṣẹwo.
 bẹ ́ ẹ ̀ gẹ ́ gẹ ́ ló ṣe rí fún àwùjọ-ẹ ̀ dá .
Àjọ tó ń mójútó àyíká l'Eko mú 123 ọlọ́kadà tó ń bọ̀ láti Jigawa Ọkọ̀ òfúrufú ọlọ́pàá yóò bẹ̀rẹ̀ sí ní káàkiri Naijiria - Ọgá Ọlọ́pàá ‘Àwọn jàǹdùkú pa fadá ní Taraba’ Olugbodi jẹ ọkan alara orukọ Amutọrunwa ti iran Yoruba maa n sọ ọmọ wọn.
Yala ile-ise olopaa tabi ijoba orile-ede Ivory Coast, ko si eni ti o wa larowo to lori isele naa.
Page 1 nínú 8 rewind previous Navigate to the next page nextNavigate to the last page forward Padà sí òkè ÀkọléÀkọlé abala Àkọlé abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Rìn káàkiri BBC News Sport Weather Radio Arts Ìlànà Lílò Nípa BBC Òfin Àṣírí Cookies Ìrànlọ́wọ́ Ìwọlé Ìtọ́ni Òbí Kàn sí BBC Get Personalised NewslettersCopyright  2020 BBC.
Ikọ Tottenham naa ko ni gbéyin, ni bi ikọ naa ti kẹkọọ lẹyin ti ikọ Liverpool fẹyin wọn janlẹ ni saa to kọja.
Ọrọ ti Ebuka atọkun eto sọ nipa Laycon ati Erica ati bi o ti ṣe doju ọrọ kọ Vee.
Ta ni ki ń bá sọ̀rọ̀ lọ́gànjọ́ òru!
Ó fi tọkàntọkàn gbadura pé kí òjò má rọ̀.
Ẹ kò wá fi aguntan rúbọ sí mi,tabi kí ẹ wá fi ẹbọ rírú bu ọlá fún mi.
Ò̀we Yorùbá sọ wi pé, “Iwà jọ iwà, ni ọ̀rẹ́ jọ ọ̀rẹ́”, ṣùgbọ́n ninú itàn yi, iwà Ìjàpá àti Ọ̀bọ kò jọra.
È tẹti kí ẹ ma bawa kalọ.
Tọwọ́ tẹsẹ̀ laá fi gba ìrànwọ́ owó ẹ̀kọ́ Almajiri ní ìpinlẹ̀ Oyo- Alága Subeb Buhari kàn ń kọwọ́ bọ̀wé nílẹ̀ òkèèrè kiri ni, a ò rí ipa ní Nàijíríà- Onímọ̀ ọrọ̀-ajé Ijọba ipinlẹ Ọyọ wa rọ awọn eeyan ti eto yii gberu lawọn ileẹkọ ijọba lati lo owo naa bo se yẹ .
 Àwọn ìpìlẹ ̀ mẹ ́ rẹ ̀ ẹ ̀ rin tó wà nínú dna ni adẹnínì ( kíkékúrú sí a ) , sitosínì ( kíkékúrú sí c ) , guanínì ( kíkékúrú sí g ) àti timínì ( kíkékúrú sí t ) .
Awọn iroyin ti ẹ lee nifẹẹ si: Tẹgbọn-taburo se igbeyawo ni Anambra Ọmọbinrin kan ku si sọọsi lasiko ijẹri O ni Alaafin kii jẹ ounjẹ amọga, bẹẹ ni kii mu ọti tabi ohun mimu ẹlẹrindodo, kii jẹ obi tabi mu kọfi, ti ko si tun kundun awọn ounjẹ oyinbo.
Ẹgbé agbábóólù orílẹ-èdè Naìjíríà gba ẹbuǹ wúrà ilẹ Afrika Bàbà ọmọ ọdún 75 kó HIV ran ọmọ ọdún 14 lẹ́yìn tó fi ipá báa lò Gbogbo ọjà di títì pa nílùú Akure, ṣugbọ́n nítorí kí ni?
Ìpànìyàn, ìjínigbé ti gbàkóso ilẹ̀ Yorùbá, Buhari, tètè kéde pé ètò ààbò kò fararọ - Soyinka Wọn ni eyi ko sẹyin ilana ti Bọla Tinubu fi lelẹ, lasiko to jẹ gomina ni ọdun 1999 si ọdun 2007, eyi ti wọn ni ọpọ awọn gomina si n tẹle.
Wòlíì Kasali ní Dolapo Awosika kò lé ìyàwó òun jáde 'Alífábẹ́ẹ́tì Ohùn Oduduwa di ìtẹ́wọ́gbà ni Ajaṣẹ' Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Orile ede China lo ti ta “Black Panther” julo nita pelu pipa milionu marunlelogorun owo dola ko to kan U.
1–7, Ohùn ìkìlọ̀ yíó wà fún gbogbo ènìyàn; 8–16, Ìṣubú kúrò nínú òtítọ́ àti ìwà búburú síwájú Bíbọ̀ Ẹ̀ẹ̀kejì; 17–23, Joseph Smith ni a pè lati mú òtítọ́ àti agbára Olúwa padà bọ̀ sípò lórí ilẹ̀ ayé; 24–33, Ìwé Ti Mọ́mọ́nì ni a mú jade tí a sì fi ìjọ òtítọ́ kalẹ̀; 34–36, A o mú àlàáfíà kúrò lórí ilẹ̀ ayé; 37–39, Wádìí àwọn òfin wọ̀nyi.
Àwọn tí wọ́n kú lára wọn jẹ́ ọ̀kẹ́ kan (20,000).
Iṣẹ́ tí OLUWA Rán sí Àwọn Ará Filistia.
#FIFAWWC : Chile fi àmì àyo méjì gbógo fún Naijiria
Oriyin yi si lo ni yoo mu ko tubọ se aseyọri pupọ sii fun anfaani awọn eeyan ipinlẹ naa.
”Kompany kopa ninu iko re ti o fagbahan iko agbaboolu Arsenal pelu ami-ayo meji sodo, bee si lo tun bere fun iko re ti o fagbahan iko agbaboolu Huddersfield Town pelu ami-ayo mefa sookan(6-1) nipari ose ti o koja.
Onímọ̀ nípa ẹṣin Islam náà, lásìkò tí ń sọ̀rọ̀ lórí ibi tí ìṣẹ̀lẹ̀ náà dé dúró, tún sísọ lójú rẹ pé, àwọn ajinigbe ọhún tún ti ya fọto àwọn ìbejì náà ranse si òun, tí àwọn ọmọ náà sì ń wo pẹ̀lú ibanuje.
OLUWA yóo lé àwọn orílẹ̀-èdè wọnyi jáde fun yín, ẹ óo sì gba ilẹ̀ àwọn orílẹ̀-èdè tí wọ́n pọ̀ jù yín lọ, tí wọ́n sì lágbára jù yín lọ.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: ‘A nílò ọdún kan láti sinmi lẹ́yìn ìbímọ’ 'Èrò ọ̀dọ́ Kwara ṣọ̀tọ̀ọ̀tọ̀ lórí ọ̀rọ̀ Saraki' 'Ọlọ́run kómiyọ lọ́wọ́ ìbọn l'Ékìtì' Nigeria àti Ghana jẹ́ orílẹ̀-èdè méjì tí ìwádìí nipa òògùn ìṣẹ́yún Misoprostol lórí ayélujára tí gbilẹ̀ jùlọ, gẹ́gẹ́ bíí goggle ṣe sọ.
Ileeṣẹ ọlọpaa yabo gbọngan naa lẹyin tawọn ara ilu kan tawọn lolobo lori ohun to n ṣẹlẹ lagbegbe naa.
Ó dà bí ẹní pẹ́ gbogbo ńǹkan abẹ̀mí - àti kòkòrò àìf'ojúrí (bacteria) - ní agogo ara (circadian cycle): tó tó bíi wàkàtí mẹ́rìnlélógún tó sì ń ṣẹ atọ́kùn fún ìṣẹ̀mí wa.
Koko ija to n waye laarin Ethiopia ati Egypt da lori ọjọ iwaju ti odo yii to jẹ ibudo akanṣe iṣẹ ipese agbara eyi to bẹrẹ lọdun 2011.
Ṣugbọn wọ́n sá níwájú àwọn ará Ai.
Iroyin naa tun sọ pe Daura ko ni lanfani lati rinrin àjò lọ silẹ okeere lẹyin ti wọn ti gba iwe irinna rẹ bayii.
Nítorí náà Johanani, ọmọ Karea, ati gbogbo àwọn olórí ogun ati gbogbo àwọn ará ìlú kò gba ohun tí OLUWA sọ, pé kí wọ́n dúró ní ilẹ̀ Juda.
Ilé aṣòfin Èkìtì lé aṣofin Akinniyi fún ẹ̀sùn oorun sísùn
Wọ́n gbà á ní ìmọ̀ràn pé, “Bí o bá ṣe dáradára sí àwọn eniyan wọnyi, tí o bá ṣe ohun tí ó tẹ́ wọn lọ́rùn, tí o sì sọ̀rọ̀ dáradára fún wọn, wọn yóo máa sìn ọ́ títí lae.
Ni aarọ ọjọ isinmi ni awọn ololufẹ meji to gbajumọ bii isana ẹlẹẹta ninu ile naa, Vee ati Neo, tun ti da ara miran tuntun.
Nígbà tí ọ̀kan ninu wọn rí i pé ara òun ti dá, ó pada, ó ń fi ìyìn fún Ọlọrun pẹlu ohùn gíga.
Ẹ ronupiwada, kí ẹ gba ìyìn rere gbọ́.
Lẹ́yìn tí o ti wí báyìí fún mi tán, o ki mi pé ó dìgbà, n kò sì ri i mọ.
    Nígbà tí ìgbéyàwó ku ọ̀la, díẹ̀ nínú awa tí à ń lọ sí òké Ìrònù lọ sí ilé ọ̀gbẹ́ni Ajébúlẹ̀ tí o ń gbé etí odò Ìrántí tí ó jẹ́ àná mi.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Osun state lockdown update: Ìpínlẹ̀ Osun ṣòfin ẹ̀wọ̀n gbére fún ẹnikẹ́ni tó bá jẹ̀bi ẹ̀sùn ìfipábánilòpọ̀ 31 Èbibi 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 4 Òkùdu 2020 Oríṣun àwòrán, BBC/others Ẹwọn gbere ni fun ẹnikẹni to ba ti jẹbi ẹsun ifipabanilopọ bayii ni ipinlẹ Ọṣun.
Iroyin ni Ede Gẹẹsi ko bawọn lara mu rara, bẹẹ ni wọn fẹran lati ma a bu eebu ni Comment Box.
Eniyan lásán, ìkà eniyan, a máa rìn káàkiri,a máa sọ̀rọ̀ àrékérekè,
Kí ló fa ìjà láàrín ìlú mẹ́ta tó ń jà sí odò Nile?
Oríṣun àwòrán, María Conejo/BBC Idi ni pe ko fi bẹẹ si iroyin to fidi mulẹ nipa ẹya ara obinrin gẹgẹ bo se wa fawọn ọkunrin, bẹẹ si ni akọsilẹ awọn onimọ ijinlẹ nipa isẹda abo gan maa n tako ara wọn nigba miran, eyi ti ko see tẹle.
Minista nijoba ti sagbekale igbimo ebola eyi ti Onisegun oyinbo Basanyi je alaga re.
Ọjọgbọn Aliyu Umar Dikko (1953-2020) Oríṣun àwòrán, dikko's family Ọmọ ilu Kano ti a bi ni ọdun 1953 ni Ọjọgbọn Dikko.
Stanley to rojọ fun ọkọ iyawo gan-an ko si nile lasiko ti ede aiyede naa waye.
O gbà bẹ́ẹ̀, o sì ṣèlérí fún mi pé o óo pa òfin náà mọ́.
Wọ́n ṣe ojú ìdè wúrà meji, ati òrùka wúrà meji, wọ́n fi òrùka wúrà mejeeji sí etí kinni keji ìgbàyà náà.
Akọ mààlúù kékeré kan, àgbò kan ati ọ̀dọ́ àgbò ọlọ́dún kan fún ẹbọ sísun.
Bakan naa ni orisirisi ede nile-ise VON n lo lati fi gbohun safefe bi:,“ Yoruba, Arabic, Hausa, Igbo, Kiswahili ati Fulfulde, eyi si waye lojuna ati le ba awon eniyan soro ni ede ti won gbo, bee si ni lati mu igberu ba awon ede won yii lawujo.
Nibi ipade kan to waye lọjọ Ẹti ni wọn ti gbe afẹnuko yii kalẹ bi o tilẹ jẹ pe wọn ko sọ igba kan ni pato ti wọn yoo pada bẹrẹ gbigba iyoku rẹ.
O ni afojusun oun ni lati ni ọgba ẹran maalu, ogunfe ati agbo ti ara oun.
Tí a fiṣọwọ́ ní 17:38 11 Òkùdu 201917:38 11 Òkùdu 2019 Ta ni Femi Gbajabiamila tó di Olórí tuntun nílé Asojú-sòfin Nàìjíríà?
Àwọn ni àwọn tí kò fi obinrin ba ara wọn jẹ́, nítorí wọn kò bá obinrin lòpọ̀ rí.
Oríṣun àwòrán, Idile Adcock Àkọlé àwòrán, Jack ku si Leicester Royal Infirmary ni 2011 Dokita Hadiza dupe lọwọ awọn alabasisẹ to gbaruku tii nigba igbẹjọ re.
Wọ́n rò pé bóyá àwọn lè tukọ̀ dé èbúté ibẹ̀.
Ẹ kò fẹ́ ìmọ̀ràn mi,ẹ sì kẹ́gàn gbogbo ìbáwí mi.
Ọ̀kan ni ẹni tí ó ń gbin irúgbìn ati ẹni tí ó ń bomi rin ín.
" wọn a pe "" owó "" , "" Òwírọ ̀ ' "" Àwòrò "" ni "" eó "" , "" ọ ̀ úrọ ̀ "" , "" Àòrò "" ."
Àwọn ọmọ Iyabọ Ojo rí bàbá wọn fún ìgbà àkọ́kọ́ ní ọdún mẹ́fà
Ẹ̀yìn rẹ̀ kún fún ìpẹ́ tí ó dàbí apata,a tò wọ́n lẹ́sẹẹsẹ, wọ́n súnmọ́ ara wọn pẹ́kípẹ́kí bí èdìdì.
Eyi ko ṣẹyin bi iroyin ṣe jade sori ayelujara pe Fatoyinbo yoo ṣe iṣẹ iranṣẹ ninu eto Shiloh to n lọ lọwọ ninu ijọ Living Faith 'Winners Chapel', to jẹ ti Pasitọ David Oyedepo.
Ṣugbọn ẹ kó ìṣúra jọ fún ara yín ní ọ̀run, níbi tí kòkòrò kò lè bà á jẹ́, bẹ́ẹ̀ ni kò lè dógùn-ún, àwọn olè kò sì lè wá a kàn kí wọ́n jí i lọ níbẹ̀.
Ọgagunfẹyinti Ọladipọ Ajibọla ni ara igbesẹ lati dẹkun iwa ọdaran awọn ẹgbẹ ọdaran abi ẹgbẹ okunkun to n da họwuhọwu silẹ ni ipinlẹ Ọyọ ni o ṣokunfa iku Ebila.
Gomina ti buwọlu aṣẹ fun sisan owo na wọn si ti jẹ ko di mimọ pe nigba ti a o ba fi ri ọla (ọjọbọ) awọn oṣiṣẹ yoo bẹrẹ si ni gba owo naa lori aṣuwọn ifowopamọ si wọn.
Ọba a máa lọ sí Gibeoni láti rúbọ, nítorí pé níbẹ̀ ni pẹpẹ tí ó lókìkí jùlọ nígbà náà wà.
Coronavirus: Togo di orílẹ̀èdè kẹsàn án tí àrùn Coronavirus dé ní Afíríkà
Ó sì wà lórí oyè fún ọdún mejila.
  Ayé ń yí lọ biribiri bí òkúta, àwa ẹ̀dá ń tọ̀ ọ́.
Iṣẹ alapata ẹran ni baba rẹ n ṣe, iya rẹ si jẹ oniṣowo.
Lórí ìmọ̀ràn Sunday Igboho, Ẹlẹbubọn ní yóò dára kí Yorùbá padà sí àmúlò èròjà ìbílẹ̀ fún ààbò Buhari yóò búra wọle fún àwọn mínísítà Sowore takú, kò jẹun ní àgọ́ ọlọ́pàá torí májèlé - Deji Adeyanju Òṣùká kékeré kò rẹrùn àgbà, orílẹ́èdè Nàìjíríà ṣòro púpọ̀ láti darí - Ibrahim Babangida Ìjọba Buhari ń wùwà bíi ìjọba Abacha lórí ọ̀rọ̀ Ṣoworẹ- Ṣoyinka Mẹrin lara awọn eeyan to fẹ jẹ kọmiṣọna naa ti jẹ asofin ri, awọn eeyan naa ni Ọgbẹni Kehinde Ayoola (adari ile tẹlẹ ri), Amofin Adeniyi Farinto, Iyaafin Funmilayo Orisadeyi (oun nikan lobinrin) ati Ọgbẹni Muyiwa Jacob Ojekunle.
Orin tí Hesekaya ọba Juda kọ sílẹ̀ nígbà tí ó ṣàìsàn tí Ọlọrun sì wò ó sàn nìyí:
Ogúnlọ́gọ̀ àwọn ọ̀dọ́ náà ló yarí kanlẹ̀ sójú pópó, tí wọ́n sì ń sun iná láwọn òpópónà kan ní ìlú Makurdi, tíí se olú ìlú ìpínlẹ̀ náà.
Atẹjade kan ti akọwe eto iroyin gomina Ahmed, Abdulwahab Ọba fisita wa se apejuwe iku awọn eeyan naa bii adanu ati ofo nla fawọn ẹbi wọn, ati ipinlẹ Kwara lapapọ.
O mọ ìgbà tí mo jókòó, ati ìgbà tí mo dìde;o mọ èrò ọkàn mi láti òkèèrè réré.
Wọ́n ní kí ó jókòó, kí ó kà á fún àwọn, Baruku bá kà á fún wọn.
Àti pé wọ́n ní ìmọ̀jinlẹ̀ gan-an ni nípa ojú ọ̀run.
akori ’’E lo ero igbalode fun ibasepo”Ipade yii yoo tun je ki idagbasoke ba imo ero igbalode ati
Bí àwọn ọ̀tá bá kó wọn lẹ́rú, tí wọn ń kó wọn lọ, n óo pàṣẹ pé kí àwọn ọ̀tá pa wọ́n.
 } ( èyun nọ ́ mbà odidi rere ) tàbí òkan nínú àkójopò { 0 , 1 , 2 , 3 , .
Alaga ẹgbẹ awọn obi awọn ọmọ ile iwe Chibok fikun un wi pe ipa awọn ti pi.
EndSars Protest;Oluwapọ̀nmile sọ ìrírí rẹ̀ lọ́wọ́ àwọn sójà tó fìyàjẹ́ ní Ibadan
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, EndSars, EndSwat: Ọlọ́pàá ti fi ìbọn lù mí láyà rí torí mó ní 'extra tyre' méjì- afẹ́hònúh Wọnyii ni awọn aworan bi iwọde #endSARS ṣe n lọ niluu Ibadan.
Nítorí náà ẹ gbọ́n bí ejò, kí ẹ sì níwà tútù bí àdàbà.
Ìjọba Nàìjíríà ní ó di dàndàn láti fẹ̀sì lóri awuyewuye tó n lọ lóri ọga ọmọ IMN Ibraheem El-Zakzaky to pada de láti orilẹ̀-èdè India níbi tó yẹ kí òun àti ìyàwó rẹ̀ ti lọ gba ìtóju.
Indeed, Africa gained a friend who cared about its well-being.
"Ipese owona fun ikọ Amotekun lee gbe pẹẹli nipinlẹ kan ju ọkan lọ tabi ko dinkun si ara wọn, eyi to wa lọwọ bi ipinlẹ kọọkan se lowura si.
Bi o tilẹ jẹ pe awọn akinkanju ọmọ Oodua to n ṣe bẹbẹ loke okun pọ lọ jantirẹrẹ, amọ ninu akọsilẹ wa, mẹwaa pere ni BBC Yoruba ṣe akojọpọ iroyin nipa wọn ni ẹka amuludun.
naa tun jawe olubori gege bi igbakeji abenugan ile igbimo asoju .
Nítorí pé àṣẹ tí ọba pa yìí burú lójú Joabu, kò ka àwọn ẹ̀yà Lefi ati ti Bẹnjamini.
Ẹkùn kò mọ iyì ara rẹ̀, ẹ kò mọ̀ bí ẹ ti n’iyi tó lójú àwọn ọmọ aráyé, nítorí n kò mọ̀ bí mo ti le ṣe àpèjúwe yín jù wí pe nígbà tí mo fi ojú inú wò yín láti òkè dé ìsàlẹ̀, ẹ dàbí ìgbà tí òòrùn bá ṣẹ̀ṣẹ̀ yọ ní òwúrọ̀ ní ìgbà ẹ̀ẹ̀rùn, ìmọ́lẹ̀ ológo rẹ̀ sí ara onírúurú àwọn nǹkan tí ń bẹ ní orí ilẹ̀ ayé, àwọn arẹwà kòkòrò, àwọn ẹranko dídára, àwọn ẹyẹ tí ó wu ni àti onírúurú gbogbo ẹ̀dá alààyè, àwọn ẹlẹmìí àwọn aláìní ẹ̀mí – bẹ́ẹ̀ ní ẹ rí, ọ̀rẹ́ mi tòótọ́, Ìfẹ́pàtàkì tí ó gbin ifẹ́ sí mi lọ́kàn, tí ìfẹ́ ń gùn mi ká bí kẹ̀kẹ́, tí o ń gbé mi kiri bí mọ́tò, tí o ń ti mí síhin-ín, tí mí sọ̀hùn-ún bí ìgbà tí ẹ̀fúùfù bá ń fẹ́ igi oko.
eré yìí sọ ìtàn àwọn ọ ̀ ré méjì tí wọ ́ n rí ère alágbára ní ojúbọ tí wọ ́ n ti pa tì nínú igbó nígbà tí wọ ́ n ń ṣàgùnbánirọ ̀ , tí ìkan nínú wọn gbé ère yìí lọlé .
Àbí kí n má jẹ ìrora ńlá tí Baba ti yàn fún mi ni?
Ní àkókò náà, Dafidi ati àwọn ọmọ ogun rẹ̀ gbógun ti àwọn ará Geṣuri, ati àwọn ará Girisi ati àwọn Amaleki, tí wọ́n ti ń gbé ibẹ̀ fún ìgbà pípẹ́, títí dé Ṣuri ati ilẹ̀ Ijipti.
Irọ to jinna si ootọ leleyi."
Àwọn tí wọ́n jẹ́ eniyan burúkú ati òǹrorò láàrin àwọn tí wọ́n bá Dafidi lọ ní, “Nítorí pé wọn kò bá wa lọ, a kò ní fún wọn ninu ìkógun wa tí a gbà pada, àfi aya ati àwọn ọmọ wọn nìkan ni wọ́n lè gbà.
Láti ìgbà tí Amnoni ti fi ipá bá Tamari, arabinrin rẹ̀ lòpọ̀, ni ó ti pinnu láti ṣe ohun tí ó ṣe yìí.
Ètò sogúndogójì 'MMM' tún ti padà dé, rọ́bọ́ọ̀tì ni yóò maa ṣàkóso Àwọn àṣà àti ìse tó yọ obìnrin sílẹ̀ nílẹ̀ Yorùbá Ọọ̀nì àléégbà dé bá ọ lálejò, kí ló máa ṣe?
Saaju ifẹsẹwọnsẹ yi ni akọnimọọgba Norwhich ti ni agbabọọlu ohun mẹwa lo farapa.
Onidajọ Ademọla Bọla ni arakunrin naa ku ni ileewosan lẹyin ti o ṣa a lada ni ileto Gberinlegi.
"Ẹka ileeṣẹ naa ti wa ni titi pa , bẹẹ ni yoo si wa tiit ti ajọ FCCPC ati NAFDAC yoo fi gbẹsẹ le awọn ọja ti ọjọ ti lọ lori wọn.
 igi àbà po ni àdúgbò yìí nìgbà náà .
Yollywood: Odunlade fijó bẹ́ẹ, Lizzy padà sọ́dún 2012, Lateef gbàmì ẹ̀yẹ tuntun
Lara awọn nnkan ti mo n ri ṣa kiri lati igba ti arun naa ti bẹrẹ ni ibomu, ibọwọ, igo ọṣẹ apakokoro Sanitaisa atawọn ohun eelo idaabobo ṣugbọn mi o ni idaabobo kankan."
"O ni, ""bi a ṣe n sọrọ lọwọlọwọ, ko tii si ogun ti o le wo aarun Corona."
O ṣe apejuwe iwa ọkunrin naa gẹgẹ bi ti ẹni ti ọpọlọ rẹ ko pe e.
Ṣugbọn isẹ orin lo yan laayo ni kete to de ilu Ọba, lẹyin naa lo lọ kawe nipa sinima ṣíṣe, to si gba oye imọ ijinlẹ keji ninu rẹ.
Ó bá wí fún wọn pé, “Ẹ wá kí á lọ sí ibìkan níkọ̀kọ̀, níbi tí kò sí eniyan, kí ẹ sinmi díẹ̀.
“Ẹ kò gbọdọ̀ fi ẹran rúbọ sí mi pẹlu ìwúkàrà, bẹ́ẹ̀ ni ohunkohun tí ẹ bá sì fi rú ẹbọ àjọ̀dún ìrékọjá kò gbọdọ̀ kù di ọjọ́ keji.
Ta nìyí tí ń fi ìmọ̀ràn pamọ́ láìní òye?
Ati fi kun awọn ọlọpa to n duro loju ọna.
Oríṣun àwòrán, Olayomi Koiki Bi iran Yoruba se n beere fun idasilẹ orilẹede Oduduwa, ni Igbo n beere fun idasilẹ orilẹede olominira Biafra.
Ìyapa tún bẹ́ sáàrin àwọn Juu nítorí ọ̀rọ̀ yìí.
Awọn ajọ aseranwọ lagbaye kọ lati fun Burundi lowo fun eto idibo lọdun 2020 lẹyin igba ti aarẹ Pierre Nkurunziza so pe oun yoo du ipo aarẹ fun igba kẹta lọdun 2015.
Nibi ipade naa ni ,won yoo tun maa jiroro nipa erongba, imoran ati irawo lati odo awon ile-ise ti ki I se ti ijoba ati ona ti won yoo gba lati maa fowosowopo pelu awon orile ede ti ajalu naa kọlu ati awon egbe ti won ti n pese eto irawo fun awon orile ede wonyi.
Kò sí ẹni tí yóo máa bá mi pa àgọ́ mọ́,bẹ́ẹ̀ ni kò sí ẹni tí yóo máa bá mi ta aṣọ àgọ́ mi.
Angẹli náà kìlọ̀ fún Joṣua pé, OLUWA àwọn ọmọ ogun ní, 
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Oluremi Adeleye: Ilẹ̀ Amẹríkà rán ọmọ Nàìjíríà lẹ́wọ̀n nítorí ó fọ́mọ lóunjẹ 7 Èbibi 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images, Goolge Àkọlé àwòrán, Arábìnrin Oluremi Adeleye Arábìnrin Oluremi Adeleye ti di èrò ẹwọ̀n ọdún mẹ́ẹ̀dógun nítori ó dá ọmọ oṣù mẹ́jọ kilẹ̀ láti rọ ọ́ ní ounjẹ ni Maryland ilẹ Amẹríkà.
Àwọn ọ̀dọ́ Benue fọnmú nítorí ìkọlù darandaran Agbébọn yabo àgọ́ ọ́lọ́pàá, wọ́n pa DPO àti ọlọ́pàá mẹ́ta míràn Alufaa samson Ayokunle ni Ìkọlù àwọn Fulani darandaran àti ajínigbé ti ń gba ẹbọ lọwọ tẹru tọmo bayii ni Naijiria.
Iyalẹnu ni adura Eid ti ko ni i waye jẹ fun awọn kan nilu Kano, nitori pe ko si isede mọ, ati pe ọdun ileya akọkọ niyii ti Emir ilu Kano, Alhaji Aminu Ado Bayero, yoo ṣe lori itẹ.
Nígbà tí àwọn Farisi rí i, wọ́n bi àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ pé, “Kí ní ṣe tí olùkọ́ yín fi ń bá àwọn agbowó-odè ati àwọn ẹlẹ́ṣẹ̀ jẹun?
Kó wúlò fún oko tabi fún ààtàn mọ́ àfi kí á dà á sóde.
Malam Isa ni oludasilẹ Iwe Iroyin Democrat Newspaper, ti o si tun jẹ Aarẹ tẹlẹri fun ẹgbẹ Newspaper Proprietors Association of Nigeria (NPAN).
ati ẹmi isokan , ki won si yago fun iwa bi –o- ba-paa,bi o ba- buu-lẹsẹ.
Ọmọ ilu Ondo ni oloogbe naa, nibẹ lo si ti mu ọmọ orilẹ-ede Togo naa wa si Eko, lati maa dana ounjẹ fun idile rẹ.
fún àwa iranṣẹ rẹ tí a wà níwájú rẹ láṣẹ láti wá ọkunrin kan tí ó mọ hapu ta dáradára.
Babalawo Adewole ni awọn babalawo lo mọ itumọ aye, o ni ilana ẹsun musulumi ati kristẹni ko le mu eto naa kẹsẹ jari.
Ṣugbọn wọn n fi idaro han lẹyin ti wọn rii pe Kabiesi Adegbitẹ ti re ibi agba n re.
Àwọn àṣà tó ń jẹ́ kí Yorùbá hùwà bíi ẹranko àti ajẹ̀nìyàn, ẹ pa wọ́n run - Oluwo Oluwo tilu Iwo, Ọba Abdulrosheed Adewale Akanbi, Telu Kinni, ti kede pe o yẹ kawa ọmọ Yoruba se ipade apero lori ọna ta gba pa awọn asa ati ise awujọ wa kan rẹ, ti ko ba igba mu mọ.
Bi aarẹ Moon Jae-in South Korea ti se seto ipenija yi mu ki ẹgbẹ rẹ gbegba oroke ninu idibo ile asofin to waye lọjọ kẹẹdogun, osu Kẹrin.
Bakan naa, lo digi lati fi pese iansan imọlẹ sinu yara too wa koo si kun yara naa ni ọda funfun tabi awọ ina ki imọlẹ le pọ.
Iya Otubusin fikun wi pe oun paapaa ko kọkọ gbagbọ nigba ti ayẹwo fihan pe oun ti loyun, yàtọ̀ sí ọpọlọpọ ipenija ti òun ti kojú ninu ìlera ara oun lati ọdun marundinlogoji sẹyin.
Ẹ jẹ́ kí á lọ sọ́dọ̀ rẹ̀.
 O ni bi wọn ba sọ Abadofin naa di Ofin, yoo jẹ ki wọn mọ riri awọn iṣẹ aṣeyọri, iṣẹ akin ati iṣẹ takuntakun laarin ilu.
Trump soro yii ni Scotland lojo isinmi ose yii pe, baalu naa yoo tun wulo fun awọn’’ aarẹ lọjọ iwaju’’’nitori opolopo odun ti yoo lo.
Aarọ Ọjọru ni ariwo ta pe ọkọ ọrẹ Tolulope kan lo sadede kọ lu ọmọbinrin naa, nigba to n tara lati ki i.
Àwọn kan ninu àwọn Farisi sọ pé, “Kí ló dé tí ẹ fi ń ṣe ohun tí kò tọ́ ní Ọjọ́ Ìsinmi?
ọ̀án pọ́n gidigidi; àwọn àgbẹ̀ pàápàá ti sá kúrò nínú oko, wọ́n n rẹ́rìn-ín nínú ahéré; aláàárù kò le sọ̀rọ̀ mọ́, wọ́n ń mi hẹlẹ bí wọ́n ti ń gun orí òkè; ojú ọ̀nà le bí òkúta; gbòǹgbò le bí ìdàrọ́, ilẹ̀ pupa bí epo, etí ṣòkòtò funfun bàjẹ́, etí ẹ̀wù agbádá di pupa; àánú àwọn oní mọ́tò ṣe mí, ara wọn kún fún èéri, ó dà bi ewéko ojú ọ̀nà, àwọn tíó sì jókòó sí ẹhin ọkọ̀, àwọn wọ̀n-ọnnì kun àtíkè ìjàngbọ̀n, wọ́n pupa bi ẹ̀gbẹ́ ògiri, eruku bo ọmọ aráyé gbogbo; ogunlọ́gọ̀ àwọn ẹ̀dá alààyè ni wọ́n mọ̀ pé òòrùn náà mú, àwọn aláǹgbá ń sáré, ara wọn ń dún hánrán-hánrán lórí ewé gbígbẹ; àwọn ẹyẹ ńlá kò sì ké mọ́, nítorí  mo ti gbọ́ igbe ẹ̀lúùlu, mo ti gbọ́ ohùn àdàbà, ẹyẹ agbe ti ké, àlùkò ti sọ̀rọ̀, olúkúlùkù wọn sì ti dákẹ́ minimini sí ibi tí Olódùmarè sọ wọ́n lọ́jọ̀ sí, àfi àwọn ẹyẹ kékeré gbogbo tí wọn kò tóbi ju alápàáǹdẹ̀dẹ̀ ni wọ́n ń fò síhìn-ín sọ́hùn-ún, tí ara wọn kò balẹ̀ bí ewé oju omi, wọ́n ń ti orí igi dé orí igi bí wọ́n ti ń ké bí ọmọ adiẹ.
Wọ́n ń sọ ìsọkúsọ sí àwọn ẹ̀dá ọ̀run tí ó lógo.
Nítorí náà ni OLUWA ṣe san án fún mi gẹ́gẹ́ bí òdodo mi;ati gẹ́gẹ́ bí ọwọ́ mi ṣe mọ́ lójú rẹ̀.
15 Kíyèsíi, ìwọ mọ̀ pé ìwọ ti béèrè lọ́wọ́ mi èmi sì fi òye yé ọkàn rẹ; àti pé nísisìyí èmi sọ àwọn nkan wọ̀nyí fún ọ kí ìwọ lè mọ̀ pé ati fi òye yé ọ́ nípasẹ̀ Ẹ̀mí òtítọ́;
‘Kò sí ohun tó lè yẹ ìfèhọnú ọjọ karun un Oṣu Kẹsan lórí àtìmọ́lé Omoyele Sowore’ Amẹrika ń gbẹ̀san lára Nàíjíríà, owó ‘Visa’ di ọ̀nà méjì láti wọ Amẹrika Ambode ti tako ọrọ yi pe oun ko ni nkankan ṣe pẹlu akoto naa tabi owo to wa ninu rẹ.
Láti ibẹ̀, mo lè rí ìsàlẹ̀ kedere, àwọn igi ìtàkùn tí ó hù sí orí àpáta náà sì dáàbòbò mi, mo sá pamọ́ sí ẹ̀yìn wọn, àwọn dúró bí awọ́n fún ojú mi.
Bákan náà ni ẹ níláti ṣe, tí ó bá jẹ́ pé kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ rẹ̀ ni ó sọnù, tabi aṣọ rẹ̀, tabi ohunkohun tí ó bá jẹ́ ti arakunrin yín, tí ó bá sọnù tí ẹ sì rí i.
O ni yatọ si pe iwa ọhun jẹ ohun to buru jai, o tun jẹ ohun to lodi si ẹtọ awọn ọmọ wẹwẹ labẹ ofin.
Ṣugbọn akiyesi wa ni pe awọn ọkọ akero to fi mọ ọkọ akero ijọba BRT ko tẹle ilana itakete sira ẹni ti ajọ NCDC la kalẹ mọ.
– Seyi Makinde 2019 Election: Àwọn oloṣelu tó yege àti àwọn to fidirẹmi Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, #NigeriaDecides: BBC ti wa ni gbogbo ìpínlẹ̀ Naijiria láti firoyin gbogbo tóo yin létí Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Gíga pẹpẹ láti pèpéle tí ó wà nílẹ̀ títí dé ìtẹ́lẹ̀ ìsàlẹ̀ jẹ́ igbọnwọ meji (mita kan).
Àwàdà kẹríkẹrì nígbà táwọn olùdíje ààrẹ́ Amẹ́ríkà méjì kọjú ìjà síra wọn Ṣé Biden lè fẹ̀yìn Trump kó di ààrẹ America tó kàn?
Wòlíì Kasali ní Dolapo Awosika kò lé ìyàwó òun jáde Àrà méèrírí, ọkùnrin kan ń fi ìyarun fọn fèrè tó ń dún bíi gìtá Ṣẹ gbọ́ nípa Alájọ Ṣómólú, tó ta mọ́tò ra kẹ̀kẹ́?
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Osun state: PDP ní nítorí ẹjọ́ lórí ìbò gómìnà Ọ̀ṣun ni Ọlọ́pàá fi mú Sẹ́nétọ̀ Ademọla Adeleke sí àhámọ́ 6 Èbibi 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 7 Èbibi 2019 Oríṣun àwòrán, @IsiakaAdeleke1 Àkọlé àwòrán, Ọlọpaa ti n n fi ẹsun lilo ayederu iwe ẹri kan Sẹnetọ Adeleke fun igba diẹ bayii Ileeṣẹ ọlọpaa ti fi panpẹ ofin gbe oludije fun ipo gomina ipinlẹ Ọṣun labẹ aṣia ẹgbẹ oṣelu PDP nibi idibo gomina ipinlẹ naa to waye ni ọdun 2018.
Penis Captivus: Nǹkan márùn-ún tí obìnrin àti ọkùnrin tó lẹ̀pọ̀ yóò ṣe láti yọ rèé
– Baba-onírùgbọ̀n, dé ilé ta ni sẹ́ẹ̀?
Ẹsun ti wọn fi kan an ni wi pe owo ilẹ okeere naa ni Ajọ FIFA san fun orilẹede Naijiria fun afarahan ninu idije ife agbaye ti Brazil lọdun 2014.
Ọmọ atàpátadìde ni mí, télọ̀ ni bàbá mi- Abiola Ajimobi Ayefele fi orin ẹ ṣeun sẹ́nu kí Ajimobi Iléẹjọ́ kòtẹ́milọ́rùn ti ní Ajimobi létọ̀ọ́ láti yan ọba l’Ọyọ Kọmisana eto iroyin, Toye Arulogun ni igbimọ alaṣẹ ipinlẹ ti fọwọ si igbesẹ fifun awọn adugbo naa ni orukọ tuntun.
Oríṣun àwòrán, @opetodolapo Awọn ọlọpaa ti fa ọmọ yii, tii se ọmọ orukan naa, le ijọba ipinlẹ Eko lọwọ.
Europa League Semi-final: Chelsea rọ́ Eintracht Frankfurt lágbo dà sí iná ni Stamford Bridge
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Kò sí ǹkan tó ń jẹ́ ọ̀rọ̀ ìgbàgbọ́ tàbí ìmọ̀le nínú àgbékalẹ̀ Amotekun - Alake ti Egba Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Wo àwọn oúnjẹ márùn ún tó ń mú kí àtọ̀ ọkùnrin dára síi Wo àwọn Adelé-Ọba aládé méje tó jẹ́ obìnrin nílẹ̀ Yorùbá Ọmọ ẹgbẹ́ òkùnkùn ṣoro ní Ijebu Ode, ọ̀pọ̀ ẹ̀mí sọnù Gomina naa ṣalaye pe 849 ni gbogbo akẹkọọ to wa ni ile ẹ̀kọ́ naa.
Fún ọdún mejila gbáko ni àwọn ọba maraarun yìí fi sin Kedorilaomeri, ṣugbọn ní ọdún kẹtala, wọ́n dìtẹ̀.
    ‘Ofin kín-ín-ní: Ẹnikẹ́ni tí ó bá rí Ìrìnkèrindo nílati nà án ní kùmọ̀ lẹ́yìn ọrùn, ẹni tí ó bá rí ọkùnrin náà tí kò fọ ọ ni kùmọ̀ dáadáa, olúwarẹ̀ ìbáà ṣe ọkùnrin, ìbáà ṣe obìnrin nílati san kọ́bọ̀ márùn-ún.
O ni ọkan lara wọn ọdẹ to n ṣọ ibi ti wọn ti n kọ ile naa, Adamu Ibrahim lo ji simẹnti naa.
Àwọnn ǹkan tó yàtọ̀ nínú abá ìsúnà tí ọdún 2019 Ètò àbò, ètò ẹ̀kọ́, gbégbá orókè nínú àbádòfin 2019 Onilu salaye pe ẹgbẹ APC le Ishola Balogun Fulani ati awọn ọmọ igbimọ kuro ninu ẹgbẹ lẹyin iwadi to safihan wi pe o n gbe igbesẹ to tako ẹgbẹ.
Lára àwọn ìlànà àyẹwò kí èèyàn tó lè di ipò mú ní Nàìjíríà pàápàá jùlọ ipò Mínísítà ni pé o gbọdọ ní ìwé èrí tó péye.
Àwọn olódodo yóo yí mi ká,nítorí ọpọlọpọ oore tí o óo ṣe fún mi.
ijoba ati omo orile ede Naijiria, aare 
Ileeṣẹ ọlọpaa wa bu ẹnu atẹ lu bi awọn eeyan ṣe n fi idajọ si ọwọ ara wọn bayii, eyi ti wọn ni o ti wa n di lemọlemọ, paapaa ni ilu Ibadan ati ipinlẹ Ọyọ lapapọ.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ọ̀pọ̀lọpọ̀ adarí ní Naijiria ló ti bu ẹnu àtẹ́ lu ìpànìyàn nítorí ẹ̀yà, pàápàá àwọn ọmọ Naijiria ní South Africa.
"Tí a fiṣọwọ́ ní 13:05 29 Èbibi 201913:05 29 Èbibi 2019 Sowore: Ìjọba pàṣán ni ìjọba Buhari Oludije ipo aarẹ labẹ asia ẹgbẹ oṣelu AAC ninu idibo to kọja ni ""bi ẹ ba wo o dadaa, inu awn ọmọ Naijiria ko dun si eto to n lọ lonii""."
“Ẹ pa orúkọ Farao, ọba Ijipti dà,ẹ pè é ní, ‘Aláriwo tí máa ń fi anfaani rẹ̀ ṣòfò.
"Ohun to ba tọ si baba yii la o ṣe fun un gẹgẹ bi obi.
Ojọgbọn Oye ṣalaye nipa eto oloṣu meji, mẹta ati mẹsan an nibi ti wọn ti le da duro ti awọn ọmọ oyinbo yii si n fi imọ ede Yoruba jẹun.
Ebola tun ti pada si ilé Adulawọ.
Nígbà tí ó di ọ̀sán, Elija bẹ̀rẹ̀ sí fi wọ́n ṣe yẹ̀yẹ́ pé, “Ẹ kígbe sókè, nítorí pé Ọlọrun ṣá ni.
Kolokuma/Opokuma LGA, Yenegoa LGA, Southern Ijaw LGA, Ekeremor LGA, Sagbama LGA lawọn ijọba ibilẹ tọrọ kan.
Ẹ yin Ọlọrun nítorí Oore Rẹ̀ .
9 74053 Orilẹede United Arab Emirates 594 6.
Jẹ́ kí inú òkè Sioni kí ó dùn,kí gbogbo Juda sì máa yọ̀nítorí ìdájọ́ rẹ.
Tinubu: Ọsinbajo ko gberaga pẹlu ipo giga to wa
Wo ohun tí Ọọ̀ni, Sultan Sokoto sọ nípa ọta ìbọn tó gbẹ̀mí Ọba Olúfọ́n Awọn ọbalaye kanrinkanrin meji lorilẹede Naijiria ti bu ẹnu atẹ lu bi ọrọ abo ṣe dẹnukọlẹ lorilẹede Naijiria eyi to ṣokunfa iṣekupa ọbaalaye, Olufọn ti ilu Ifọn-Owo ni ipinlẹ Ondo.
Akomolede: Bolaji Faleke ni Olùkọ́ tó ń kọ́ wa ní àṣà oge ṣiṣe lórí BBC Yorùbá Ìwọ tó ń ṣí ara sílẹ̀ lọ ṣọ́ọ̀ṣì, ṣé apàyàn kọ́ ni ẹ́ báyìí?
Ẹ̀yin olólùfẹ́ mi àti ẹbí ni mo bẹ̀ Mr Latin, Jide Kosọkọ àti Mama Rainbow sọ̀rọ̀ lórí ìjà Toyin ati Lizzy Mi ò fẹ́ dá sí ìjà Toyin ati Lizzy!
Yóo wá fi ìmọ́lẹ̀ fún gbogbo ẹni tí ó wà ninu ilé.
Ojoojumọ lo n jade wa yọju si awọn eeyan."
Mose tún bi Ọlọrun pé, “Bí mo bá dé ọ̀dọ̀ àwọn eniyan Israẹli, tí mo sì wí fún wọn pé, ‘Ọlọrun àwọn baba yín ni ó rán mi sí i yín,’ bí wọ́n bá wá bi mí pé ‘Kí ni orúkọ rẹ̀?
Igí wó pa akẹ́kọ̀ọ́ Nàìjíríà ni Cameroon Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí 2 sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 2:23 Fídíò, Water Generator: Ó leè ṣiṣẹ fún wákàtí mẹfà, kó tó sinmi, Duration 2,2310 Òkùdu 2020 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
Alaga ẹgbẹ osisẹ National Union of Air Transport Employee (NCAA), Paul Igene ni awọn da iyansẹlodi naa duro nitori pe awọn adari ẹka eto irina ofurufu pẹtu si wọn ninu wi pe awọn ti kọ iwe ransẹ si ile-isẹ irina, pẹlu adehun wi pe awọn yoo da wọn lohun laarin osẹ meji.
Ṣoworẹ sọ fun BBC News Yoruba pe ohun to ṣẹlẹ si Oby Ezekwesili ti awọn ẹgbẹ oṣelu rẹ ACPN fi kọ ẹyin sii le ṣẹlẹ si Kingsley Moghalu ati Fela Durotoye to jẹ oludije YPP ati AAN, ṣugbọn ko le ṣẹlẹ si oun.
"Tinubu wa n beere pe, ""Ti wọ̀n ba n sọ̀ pe Jagaban, Asiwaju wa fi eeyan kan jẹ́ gaba l‘Ọsun lati maa ko owo yin, mo wa n beere pe eelo gan lk ni lọwọ ?"
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Yinka Ayefele: Oṣù àwọn ìbẹ́ta mi kò pé ní kò jẹ́ kí n kọ́kọ́ kéde ìbí wọn Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Àsìkò tó láti fi ìwọ́de gba ara wa sílẹ̀ lọ́wọ́ ebi àti oko ẹrú - Sowore Lati ìgbà ti wọ́n ti fi Soworẹ sí àhàmọ, ọ̀pọ̀ àwọn ọmọ Nàìjíríà ló ti bu énu àtẹ́ lu ìgbéṣẹ̀ ìjóba Nàijiria, bẹ́ẹ̀ ni àwọn kan ni dandan ìwọ́de náà gbọdọ wáyé.
“Bí arakunrin rẹ bá ṣẹ̀ ọ́, bá a wí; bí ó bá ronupiwada, dáríjì í.
Wọ́n wá gba Pisidia kọjá lọ sí Pamfilia.
Kete si ni ọ̀kan nínú àwọn tó ń gbèrò láti díje sípò ààrẹ orilẹ̀-èdè Nàìjíríà Christmas Akpodiete nínú ẹgbẹ́ òṣèlú All Progressive Congress wọ ẹgbẹ́ òṣèlú APC lọ sílé ẹjọ kan l'Abuja lóri bí owó fọ́ọ̀mù ìfèróngbà hàn ṣe ṣe gọbọi.
"Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Homosexualism: Ofin ti f'àyè gba ìbálòpọ̀ Akọs'akọ, Abos'abo ní Botswana 12 Òkùdu 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ibaṣepọ abo s'abo Kii ṣe ẹṣẹ ki ọkunrin ati ọkunrin tabi obinrin si obinrin maa jọ lo pọ ni Botswana, ""Ìbálòpọ̀ ọkùnrin sí ọkùnrin kò lòdì s'ofin""."
Wọ́n ré odò Jọdani kọjá, wọ́n pàgọ́ sí ìhà gúsù Aroeri, ìlú tí ó wà ní ààrin àfonífojì, ní agbègbè Gadi.
 Ère yìí ló dúró bí olúgbàlà wọn .
Nítorí pé, OLUWA Ọlọrun yín wà pẹlu yín ninu àgọ́ láti gbà yín là, ati láti jẹ́ kí ọwọ́ yín tẹ àwọn ọ̀tá yín.
Ọdun 1993 yii ni aarẹ ologun, Ibrahim Badamọsi Babangida wa lori aleefa, ti gbogbo ọmọ Naijiria si n ke boosi fun agbekalẹ ijọba alagbada lẹyin ti Babangida ti lo ọdun mẹjọ lori aleefa.
Má sọ pé o fẹ́ fi burúkú san burúkú,gbẹ́kẹ̀lé OLUWA, yóo sì gbà ọ́.
Aṣidodu, pẹlu àwọn ìlú ati àwọn ìletò rẹ̀; Gasa, pẹlu àwọn ìlú ati àwọn ìletò rẹ̀ títí dé odò Ijipti, ati etí òkun Mẹditarenia, pẹlu agbègbè rẹ̀.
Lara awọn ti ofin naa kan ni enikẹni to ba je gomina tabi igbakeji gomina nigba kan ri ti o si tun di ipo ijọba tabi oṣelu mu lọwọlọwọ.
Lilo oogun apẹfọn jẹ fi fi iru oogun bẹ fin ile lẹẹkan tabi ẹẹmeji l'ọdun.
O ni oun ati Ajimọbi ko jọ tọwọ bọ iwe adehun ìlérí kankan nigba ti awọn jọ n ṣe ẹgbẹ kan naa papọ.
Nítorí náà mo sọkún fún ọgbà àjàrà Sibumabí mo ṣe sọkún fún Jaseri;mo sì sọkún nítorí Heṣiboni ati Eleale,mo sọkún, omi ń dà lójú mi pòròpòrònítorí gbogbo ìkórè yín, ati èso oko yín ni ogun ti kó lọ.
Bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé Ọmọ ni, ó kọ́ láti gbọ́ràn nípa ìyà tí ó jẹ.
Collapsed Building: Ilé alájà mẹ́rin wó l'Eko
Kamaru Usman ti wọn tun ma n pe ni ‘Nigerian Nightmare’ lo wọ gbagede ifẹsẹkubiojo pẹlu igboya to si lu akẹgbẹ rẹ ni alubami.
Àṣẹ ilé-ẹjọ́ ilẹ̀ òkèrè nìkan ni ìjọba lè pamọ́ ṣùgbọ́n tàpá sí ti Nàìjíríà lórí Sowore àbí?
Kí Mose yan àwọn ọmọ Geriṣoni sí ìtọ́jú àwọn ẹrù, kí ó sì rí i pé wọ́n ṣe gbogbo ohun tí Aaroni ati àwọn ọmọ rẹ̀ bá pa láṣẹ fún wọn nípa iṣẹ́ wọn.
Yóo di aláṣẹ lórí wúrà, fadaka ati àwọn nǹkan olówó iyebíye ilẹ̀ Ijipti; àwọn ará Libia ati Etiopia yóo máa tẹ̀lé e lẹ́yìn.
Otinieli, ọmọ Kenasi, àbúrò Kalebu, ṣẹgun ìlú náà, Kalebu bá fi Akisa, ọmọbinrin rẹ̀ fún un kí ó fi ṣe aya.
Aare Kagame soro yii ninu oro iside re leyin ti won dibo yan an nibi apero awon Olori Ile Adulawo to waye ni Addis Ababa ni Ethiopia.
Èyí tí ó dùn wọ́n jù ni ọ̀rọ̀ tí ó sọ, pé wọn kò tún ní rí ojú òun mọ́.
'- Joy Ogaji asojú Gencos Ikú ni fífi oògùn 'Paracetamol' bọ ẹran tàbí se ẹ̀wà- Iléeṣẹ́ ìlera Wada: Alága àjọ ìdìbò INEC àti ọgá ọlọ́pàá, mò fà yín lè Ọlọrun lọ̀wọ́ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Kogi vs Bayelsa: Primate Ayodele sọ àsọtẹ́lẹ̀ Adajọ Lateefa Okunnu ti ilé ẹjọ giga ìlú Eko to wà ni Ikéja lo dájọ rẹ ninu osù kini ọdun 2016 láti ṣẹ̀wọ̀n ọdun mẹ́rìlélógun fun gbájuẹ̀ ori ayélujára lórí owó mílíọnù márundinlọ́gbọ̀n.
Wọn fi ọrọ yi sita gẹgẹ bi idahun si ihalẹ ti aarẹ Buhari ṣe nibi ipade bonkẹlẹ ẹgbẹ APC to waye l'Abuja lọjọ Aje.
EFCC 2019 in Retrospect: Gomina mẹ́ta wà láàrín ènìyàn 1,245 tó kó sí panpẹ wa ni 2019
’’Minisita fun eto eko lorile ede Naijiria lo pe ipade naa nitori iyanselodi ti egbe ASUU gunle.
Oríṣun àwòrán, others Bi Oshodi ṣe wa ni owo to yii, ko gbagbe ibẹrẹ rẹ, to si tun sun mọ ọba Eshinlokun tipẹ-tipẹ bii ti tẹlẹ, eyi to mu ki ọba fi ṣe akoso káà awọn olori.
 kòsí egbògi tàbí òògùn ìtọjú tí o ṣiṣẹ ́ lòdì sí àrùn náà .
Àwọn aṣòfin 26 fi ẹgbẹ́ òṣèlú APC 26 sílẹ̀ lọ sí APM Oríṣun àwòrán, APc Àkọlé àwòrán, Èyí ni ara àwọn ìgbésẹ̀ tí ó ń ṣàfihàn èdèaìyedè nínú agbo ẹgbẹ́ òṣèlù APC ní ìpínlẹ̀ Ògùn.
N30,000 minimum wage: Ṣé N30,000 mú ìyàtọ̀ gorí N18,000 owó oṣù òṣìṣẹ́?
Àwọn ọmọ Lefi ni yóo máa ṣe ìtọ́jú Àgọ́ Ẹ̀rí náà.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Minisita f'eto ilera wipe ni awọn ipinlẹ ni iṣẹ lati ṣe lori iba lassa 20 Èrèlè 2018 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Minisita feto ilera ni ajumọse ni igbesẹ lati gbogun ti iba ọrẹrẹ Awọn ijọba ipinlẹ ni lati tun ero wọn pa lori idagbasoke eto ilera bi orilẹede Naijiria ba fẹ ṣẹgun iba lassa to n fi ojojumọ gbalẹ gba oko bayii.
GRIDCo: Àpọ̀jù iná mọ̀nàmọ́ná ló sọ Ghana sí òkùnkùn birimù
6 139908 Orilẹede Haiti 233 2.
Tony iwobi, ẹniti wọn fẹsun kan ẹgbẹ oselu rẹ pe oun lo ru eefin iwa gbigbe oju agan sawọn ajeji soke nilẹ Italy, ni wọn dibo fun nilu Brescia tileesẹ nlanla pọ si julọ lẹkun ariwa orilẹede Italy, tawọn ajeji naa tun tẹdo si julọ.
"Báyìí ni 50 Kobo ṣe dá ìfẹ̀hónú ""Ali Must go"" sílẹ̀ tó mú ọ̀pọ̀ ẹ̀mí akẹ́kọ̀ọ́ lọ Àṣírí tó ń bẹ láàrín Oluwo àtàwọn ọ̀dọ́ Iwo tí wọ́n fi fi ẹ̀mí wọn lélẹ̀ dáàbò bo ààfin rẹ̀ N kò ni nkan kan sọ lórí fídíò to gba ayélujára kan pé mo ń we igbó, ẹ mú ẹnu kúrò nibẹ - Oluwo Èèwọ!"
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Wo àwọn òrílẹ̀ èdè Mẹ́wàá tó láyọ̀ jùlọ Lágbàyé Finland: Ìgbà keji rèé léra wọn ti Finland yóò gba ipo kinni ninu awọn orilẹ̀-èdè to ní ìdùnú jùlọ, ìdí ni pé wọn ni ọ̀pọ̀ àwọn ènìyàn tó ni ìmọ̀ àtinudá Awọn orilẹ yoku to ri ipo mu ni Denmark, Norway, Iceland, Nertherland, Switzerland, Sweden, New Zealand, Canada, Austria Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ìgbà keji rèé ti Finland yoo gba ipò yìí Ǹkan mẹ́fà ni wọn ṣe ìgbéléwọ̀n fún àwọn orilẹ̀-èdè yìí, tó fi mọ bí owo ṣe ń wọlé sí, òmìnira, ìgbẹ́kèlé, ẹmi gígùn àti aláfià, ìrànwọ́ fún ìgbé àyé amúlùdùn àtí bí àwọn ará ìlú ṣe ń fẹ́ràn àra wọn sí.
Àkókò nìyí láti ṣe ohun tí ẹ ti fẹ́ ṣe, nítorí pé OLUWA ti ṣe ìlérí fún Dafidi pé Dafidi ni òun óo lò láti gba àwọn ọmọ Israẹli kúrò lọ́wọ́ àwọn ará Filistia ati gbogbo àwọn ọ̀tá wọn yòókù.
"Awọn ọmọ orilẹede Naijiria n di ẹbi ru aarẹ Buhari ati ijọba rẹ̀ pé wọn lọwọ ikọ̀lu awọn darandaran lorilẹede yii, ṣugbọn ohun ti aarẹ ri lati fi fesi si ẹhonu araalu ni ko di ẹ̀bi ru Ghadaffi to di oku ni ọdun meje sẹyin.
“All-Time Legendary Awards” Chiejine, Christian Chukwu, Uche Okechukwu, Austin Eguavoen, Felix Owolabi, Austin Okocha, Nwankwo Kanu, Segun Odegbami, Adokie Amaesimaka, Mercy Udoh ati Thompson Usiyen.
Orilẹede Amerika tilẹ ti fofin de e ki enikeni ma sin iru aja bẹẹ nitori o ti pa, o kere tan, eniyan merindinlogun lorileede naa.
Oro yii ya orile-ede America lenu nigba naa, ni paapaa julo, leyin  ose die ti orile-ede America gbe ofin ti won fi de orile-ede Sudan lati bi ogun odun kuro.
Agba Inaki sọ pé làásìgbò to ń wáyé ní South Africa pẹ̀lú àwọn ẹ̀yà mìí kò tó bí wọ́n ṣe ń pariwo rẹ̀
Tyson Fury d'ẹ̀ṣẹ́ bo Deontay Wilder lórí, ó gbadé WBC mọ́ ọ lọ́wọ́ Otedola Bridge: Àwọn ẹ̀ṣọ́ ojú pópó ti gbé Ọkọ̀ agbépo tó dànù kúrò lọ̀ná ₦400 péré ni àfẹ́sọ́nà mi nílò, ìfẹ́ obìnrin yìí sì ló sọ mi di adigunjalè - Iṣọla Oyenusi Awọn to wa ninu igbiimọ naa ni; ijọba Naijiria, ijọba Benin ati ijọba Niger Republic.
“Bí ẹnìkan bá fún aládùúgbò rẹ̀ ní ẹran sìn, kì báà ṣe kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ tabi mààlúù, tabi aguntan, bí ẹran náà bá kú tabi kí ó farapa, tabi tí ó bá rìn lọ tí kò sì sí ẹni tí ó rí i, 
Aarẹ ẹgbẹ awọn dokita ni Naijiria fikun ọrọ rẹ pe ko yẹ ki ipejọpọ nibi kibi ju ogun eeyan tabi eeyan mẹẹdọgbọn lọ lasiko ti coronavirus wa lode yii.
Ẹ̀mí èṣù ní ń da ọdọmọbinrin mi láàmú.
Bakan naa ni ijọba ni ki awọn araalu fọkanbalẹ nitori otitọ ni yoo jọba ninu iṣẹlẹ yii, ati wipe awọn ọmọ naa yoo di awari, ti wọn yoo si pada sile ni ayọ ati Alaafia.
Ẹlẹ́gbára ti fa ọkùnrin náà ya pẹ́rẹpẹ̀rẹ, báyìí ni a sì ń wò ó tí o ń fọ́n egungun agbárí Ìgbín-ènìyàn bí ẹni fọ́n fèrè.
Wọ́n ṣe ìsìn Ọlọrun ati ìsìn ìyàsímímọ́ bí àwọn akọrin ati àwọn olùṣọ́ ẹnu ọ̀nà tí ṣe, gẹ́gẹ́ bí òfin Dafidi ati ti ọmọ rẹ̀, Solomoni.
Sunday Igboho ni o yẹ kawọn baba Yoruba naa bẹru Ọlọrun, ilẹ Yoruba yoo si bi gbogbo wọn, awọn alalẹ yoo si bi gbogbo awọn to salọ.
Gehasi dáhùn pé, “Rárá, kò sí nǹkan.
Ó pa àwọn akikanju ọmọ ogun ará Moabu meji ní àkókò kan.
A bi Wolii Olapade Agoro lọjọ kẹsan an, oṣu kẹwaa, ọdun 1943 ni abule Ajibabi ni ilu Ibadan to jẹ olu ilu ipinlẹ Oyo ni guusu Iwọ oorun Naijiria Olapade jẹ ọmọ ile ori ade nitori pe baba rẹ jẹ ọmọ Ọba Atapami ni ilu Itapa Ijesha.
Ó ní láti ri dájú pé ìdìbò yìí kò dàbí àwọn èyí tó ti ṣẹ̀lẹ̀ láti ẹyìn wá, àjọ elétò ìdìbò gbọdọ pèsè ètò ààbò tó péye ni àwọn ibùdó ìdìbò tó wà ní eti omí, lásìkò tí wọn bá n pín nǹkan ìdìbò àti lásíkò ìdìbò gan.
A gbọ́dọ̀ ṣewàdìí ìròyìn ayélujára kí a tó pin in- OloriSuperGal Mi ó lè na apá mi àmọ́ mo lè lo ọpọlọ mi fí kọrin-Ayeyi Ò bá mi lójijì bí wọ́n ṣe yọ Sẹnetọ Adeyeye bÍi jìgá- Gomina Fayemi Ọmọ ogun Nàìjíríà mẹ́wàá dèrò ọ̀run lẹ́yìn ìkọlù ẹgbẹ́ Boko Haram 'Màálù tó bá tàsẹ̀ àgẹ̀rẹ̀ níwájú ilé mi, ó dẹran àsun!
Awọn asọju ileeṣẹ ijọba ijọba to n ri si iṣẹlẹ pajawiri to wa lojuko ti iṣẹlẹ naa ti waye ni iwadii ti bẹrẹ lati ohun gan pato to fa iṣẹlẹ'naa.
Àjọ ajàfẹ́tọ̀ọ́ Amnesty International ni àwọn aṣàtìpó ń ṣe èyí ní àwọn aṣatipo ń fi ṣe pàṣípààrọ̀ pèlú ounjẹ̀ àti àti àwọn ohun èlò mííràn tókù ni ibùdó ní.
Saudi Arabia Saudi Arabia ni awọn faramọ́ bi Amerika, France ati ilẹ̀ Gẹ̀ẹ́sì se kọlu Syria, nitori pe ikọlu ọun |jẹ́ ìdáhùn si awọn ìwà ọ̀daràn ti ìjọba Bashar al-Assad n hù."
bahrain tabi ile-oba bahrain ní ọdún 1995 , àwọn ènìyàn tí ó ń gbé orílẹ ̀ -èdè yìí tó ẹgbẹ ̀ rún lọ ́ nà ẹ ̀ ẹ ́ dégbẹ ̀ ta àti ààbọ ̀ ( 555,000 ) .
Nítorí pé ìyọlẹ́nu ni àwọn akéde meji wọnyi jẹ́ fún àwọn tí wọn ń gbé orí ilẹ̀ ayé.
Sáájú ní ilé iṣẹ́ ààrẹ ti kédé Aisha Buhari àti aya igbákeji ààrẹ Dolapo Osinbajo láti jọ jumọ ṣe alága iṣẹ́ ìpólngo náà pọ̀, nígbà ti Adejoke Adefulure àti àya gómìnà Nasarawa Mairo Almakura yóò jẹ igbákeji.
Jesu tún ń bá ọ̀rọ̀ rẹ̀ bọ̀, ó ní, “Ta ni èmi ìbá fi àwọn eniyan òde òní wé?
Jọ́wọ̀ Ẹlẹ́dàá mi, má ṣe ṣe mi bi gbogbo àwọn wọ̀nyí.
Ọ̀wọ́ngógó búrẹ́dì gbòde kàn lẹ́yìn tí àwọn oníbúrẹ́dì da iṣẹ́ sílẹ̀ Èèyàn mẹ́jọ jónà ráúráú nínú ìjàmbá ọkọ̀ akérò tó ṣẹlẹ̀ ní mọ́rosẹ̀ Eko sí Ibadan Ọlọ́jọ́ Festival 2020:Ọ̀ọ̀ni ti Ilé Ifẹ̀ tí wọ ìléèdí ọlọjọ méje tí kò ní rí ẹnikẹ́ni sójú Ẹ̀yin òṣìṣẹ́ elétò ìlera, ẹ padà sẹ́nu iṣẹ́- JOHESU Bí PDP ṣe na APC lálùbami ní Edo, bẹ́ẹ̀ ni yóò ṣẹlẹ̀ ní Ondo- PDP Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí 5:52 Fídíò, Akomolede àti Aṣa: Ọ̀rọ̀ Ẹ̀yán ni Bunmi Femi Amao ń kọ́ wa lórí ètò Akọ́mọlédè àti Àṣà lórí BBC Yorùbá, Duration 5,5224 Owewe 2020 Fídíò, Akomolede: Bolaji Faleke ni Olùkọ́ tó ń kọ́ wa ní àṣà oge ṣiṣe lórí BBC Yorùbá1 Owewe 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Idajọ naa waye nibi igbẹjọ aṣepọ to n lọ lọwọ nibudo awọn ologun kan nilu Kainji lori awọn afurasi to le ni ẹgbẹrun kan.
Ṣugbọn ìwọ Ọlọrun rí gbogbo nǹkan,nítòótọ́, o kíyèsí ìṣòro ati ìyà,kí o baà lè fi ọwọ́ ara rẹ gbẹ̀san;nítorí ìwọ ni àwọn aláìṣẹ̀ gbẹ́kẹ̀lé,ìwọ ni olùrànlọ́wọ́ àwọn aláìníbaba.
Ọjọ́ kejì tí àwọn ará ilé Òmùgọparapọ̀ ti ń retí ìyàwó wọn ni mo dé ibẹ̀.
Bákan náà, wọ́n ṣẹgun àwọn Susimu tí wọ́n wà ní Hamu, àwọn Emimu tí wọ́n wà ní Ṣafe-kiriataimu, 
August 15, 2019 Suhaila Zakzak, ọmọ El- Zakzaky ṣàlàyé fún BBC pé àwọn àyèwò ara tí Zakzaki ṣe ni Medanta Hospital fihàn pé májèlé ọta ìbọn tí àwọn ológun yìn lùú ní ọdún 2015 ń dàá láàmú.
Iru awọn iroyin ti ẹ le nifẹ si: Isẹ asayẹyẹ f'oku Awọn aworan awodamiẹnu latilẹ Afrika lọsẹ yi Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí 3 sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 2:23 Fídíò, Water Generator: Ó leè ṣiṣẹ fún wákàtí mẹfà, kó tó sinmi, Duration 2,2310 Òkùdu 2020 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
Gbogbo igbiyanju BBC lati ri Owa ba sọrọ jasi pabo titi di asiko yii Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, John Amanam: Ìfẹ́ tí mo ní sí àbúrò mi ló sọ mi dí ẹni tó ń ṣe 'Prosthetic' báyìí Ki lo ti ṣẹlẹ sẹyin?
Chelsea: Chelsea dun DJ Cuppy nínú lẹ̀yìn tí Arsenal gba omijé lójú rẹ̀
idibo pe, ti ọwọ  ofin ba mu won , won
Glover beere agbegbe Epetedo lọwọ idile Aromire fun Oshodi ati idile rẹ lati tẹdo si ni kete to de lati ilu Epe, to si di asoju gomina.
Oríṣun àwòrán, Other Ọgbẹni Azeez ṣalaye siwaju sii pe igbesẹ igbimọ alaṣẹ naa wa ni ibamu pẹlu ofin to gbe e kalẹ.
Arakunrin ẹni tí a pa ni yóo pa apànìyàn náà nígbà tí ó bá rí i.
Aare fi idunnu re han pupo lataari ise akinkanju, afojusun iko naa, eleyi ti o ron won lowo lati gba ife-eye idije ohun wa sile.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ifa Priest: ọdún mọ́kànlá ni mo fi ṣe iṣẹ́ agbejọ́rọ̀ kí n tó gbọ́ràn si Ifá lẹ́nu Nitori eyi, ileeṣẹ ọlọpaa ni awọn ti fi ẹsun ki eeyan dibọn bii ẹlomiran, ole jija ati kiko nkan pẹlu idanimọ ẹlomiran.
Timi Agbale n fi isakọlẹ ransẹ si Alaafin Sango fun igba diẹ, nigba to ya, lo ba faake kọri pe oun ko ni fi isakọlẹ kankan ransẹ mọ si Alaafin.
Eniyan rere a máa ní ojurere lọ́dọ̀ OLUWA,ṣugbọn ẹni tí ń pète ìkà ni yóo dá lẹ́bi.
com/xvfqpYsl2T — En Avant de Guingamp (@EAGuingamp) February 19, 2018Omo odun metadinlogun ohun, Isaac Drogba  yoo tun lo kopa fun iko agbaboolu Guingamp, ti baba re ti kopa fun lodun merindinlogun seyin.
Ọrọ naa di fa ki n fa a laarin Kemi ati ẹni kan to pe orukọ rẹ ni Gloria Johson tori pe Kemi ni o fi nọmba kan dẹru ba oun.
Nígbà tí ó di ìrọ̀lẹ́, wọ́n gbúròó OLUWA Ọlọrun tí ń rìn ninu ọgbà.
“Ẹ kò gbọdọ̀ kó ọ̀rọ̀ yín lọ sí ọ̀dọ̀ àwọn aláyẹ̀wò tabi àwọn abókùúsọ̀rọ̀, kí wọ́n má baà sọ yín di aláìmọ́.
Nítorí náà, gbogbo àwa tí a ti dàgbà ninu ẹ̀sìn kí á máa ní irú èrò yìí.
Aare Buhari fi ikede naa sita lati gba ọwọ agbẹnusọ rẹ, Garba Shehu.
 Àìsàn náà a máa lọ fúnrarẹ ̀ ní ara ìdá mẹ ́ wàá sí àádọ ́ ta ninu ọgọ ́ rùn ún àwọn ènìyàn tí ó bá mú , tí ó sì máa n tètè kúrò lára àwọn ọ ̀ dọ ́ mọbìnrin ju àwọn yooku lọ .
Wọ́n ká ninu èso ilẹ̀ náà bọ̀, wọ́n sì jábọ̀ fún wa pé ilẹ̀ dáradára ni OLUWA Ọlọrun wa fi fún wa.
Mínísítà fún ètò ìròyin àti àsà Lai Mohammed lo sọ̀rọ̀ náà, lásìkò tó ń gba àlejo àwọn ọmọ ẹgbẹ́ tó ń ri si akoso igbóhùn sáfẹ́fẹ́ (BON) nílú Abuja.
Oríṣun àwòrán, Abba Kyari Àkọlé àwòrán, Lara ohun ti wọn ka mọ awọn afurasi naa lọwọ ni awọn Garawa to kun fun oriṣiriṣi ayederu oogun to fi mọ awọn kẹmika loriṣiriṣi ti wọn fi n ṣe awọn oogun naa.
Ó tún pada lọ sí òdìkejì odò Jọdani níbi tí Johanu tí ń ṣe ìrìbọmi ní àkọ́kọ́, ó bá ń gbé ibẹ̀.
Ẹ jẹ ka wo bi wọn ṣe sọ ọ lọkọọkan, ejeeji.
O sọrọ ilẹ kun lori ohun to ti ṣẹlẹ ninu SARS lẹyin ti oun fẹyin ri lọdun 1989.
agbaboolu Manchester City ati Liverpool ti setan lati tun waako fun ife-eye naa.
O ni lasiko ifọrọwanilẹnuwo, Woli Sotitobirẹ sọ wi pe aago mẹta ọsan ni oun to gbọ wi pe wọn n wa ọmọ to sọnu ni ile ijọsin oun.
Baba wa náà ni ó gbà wá lọ́wọ́ agbára òkùnkùn, ó sì mú wa wá sinu ìjọba àyànfẹ́ Ọmọ rẹ̀.
Freixa ni ''ọdun 2015 ti Barcelona ti gba ife ẹyẹ Champions League kẹyin, eyi si lo n kọ Messi lominu nitori o tun fẹ gbade Champions League sii.
Lootọ ni isu ni eroja afaralookun taa mọ si Starch ninu, amọ to ba fẹ jẹ isu, mase jẹ ki isu to jẹ kọja odiwọn ikuuku tabi ẹsẹ rẹ nigba kuugba to ba n jẹ isu.
"Iha ti Ijọba Naijiria kọ si ipenija abo Oríṣun àwòrán, Oluwo/instagram Àkọlé àwòrán, Oluwo ṣalaye pe inu igbo rere nile Fulani koda, wọn mọ igbo wa ju wa lọ""."
Aṣeyọri ninu eto idibo Edo ati Ondo Nkan pataki ti igbimọ alamojuto tuntun naa gbọdọ mojuto ni ipalẹmọ fun idibo gomina ipinlẹ Edo ati Ondo.
Mo nawọ́ kó ọrọ̀ àwọn orílẹ̀-èdè,bí ẹni nawọ́ kó ọmọ ẹyẹ.
Bi awọn kan ṣe n sọ pe atọhunrinwa lati ilẹ Singapore ni abadofin naa, lawọn mii n sọ pe yoo fun ọga agba ajọ to n gbogun ti itankalẹ ajakalẹ arun ni Naijiria, NCDC, ni agbara to pọ ju ẹni ti wọn dibo yan lọ.
Abdulmumin,lo soro yii lasiko to n ba awon akoroyin soro nile –aare to wa niluu
”Ọkunrin náà sì fi ibẹ̀ hàn án.
wọn fi kan adajọ Walter pe ko kede awọn dukia rẹ gẹgẹ bi ọkan lara awọn to dipo
Àjọ tó n mójútó ìpèsè òògùn ní America ti fọ́wọ́ sí lílo òògùn Ebola fí tọ̀jú Coronavirus Àyájọ́ òṣíṣẹ́ àti ìpèníjá ọjọ́ ọ̀lá f'óṣìṣẹ́ Nàìjíríà lẹ́yìn COVID-19 Wo àwọn nkan tí o le ṣe gẹ́gẹ́ bi aláboyún lásìkò àjàkálẹ̀ ààrùn Covid-19 Òfìfo ṣọ́ọ̀ṣì pa aṣọ dà fún àwọn Páṣítọ̀ Nàìjíríà Mikel Obi fi ẹgbẹ́ agbábọ́ọ̀lù rẹ̀ sílẹ̀ ní Turkey nítorí coronavirus Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, John Mikel Obi jẹ agbabọọlu pataki ninu aṣeyọri Trabzonspor ninu liigi orilẹ-ede Turkey Balogun ẹgbẹ agbabọọlu Naijiria nigba kan, to tun jẹ agbabọọlu Chelsea tẹlẹ, John Mikel Obi ti finu-findọ fi idije Turkish Super Lig leaders Trabzonspor, silẹ lẹyin ọjọ diẹ to fi ero ọkan rẹ han si bi liigi naa ṣe n tẹsiwaju lai fi itankalẹ arun coronavirus ṣe.
Iwadii naa ti ajọ Development and Peace Initiative (IEP) ni ilu Sydney lorilẹ-ede Australia gbe jade ṣalaye pe ti a ba n sọrọ iwa igbesunmọmi lagbaye.
3 Bélú 2020 EFCC: Ìwádìí lórí ẹ̀sùn ìwà jẹgúdújẹrá tí wọ́n fi kan Babatunde Fowler tó jẹ́ àdàrí iléeṣẹ́ FIRS tẹ́lẹ̀2 Bélú 2020 5:55 Fídíò, Soyinka Cancer: Àṣe ara mi ni iso ti n run gbogbo bí mo ṣe n ṣèrànwọ́ lórí jẹjẹrẹ, Duration 5,5527 Bélú 2019 Èyí tí a wò jùlọ 5:03 Fídíò, Omolola Arohunmolase Welder: Mo ti fí iṣẹ́ 'Welder' gbayì láwùjọ, tó mo fi tọ́ ọmọ yanjú, Duration 5,039 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 5:39 Fídíò, Akomolede ati Asa lori BBC: Olùkọ́ Kikelomo Ogunboye tan ìmọ́lẹ̀ sí ìwà olè ọ̀gá ọlọ́pàá Audu gẹ́gẹ́ bí àwòkọ́ṣe àsìkò yìí, Duration 5,398 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 4:11 Fídíò, Oba Adeyeye Ogunwusi: Ojú mi ti rí lọ́pọ̀ lọpọ̀, ọ̀pọ̀ èèyàn ni kò tilẹ̀ gbàgbọ́ pé mo lè jọba- Ooni, Duration 4,117 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 4:43 Fídíò, Promise Akinlade: ọmọ ọdún mọ́kànlá tó ń fi ìlù dárà bíi àgbàlagbà sọ̀rọ̀ nípa tálẹ́ǹtì rẹ̀, Duration 4,437 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 0:59 Gbọ́, Ìsẹ̀lẹ̀ jákèjádò orílẹ̀èdè àgbáyé láàárín ìṣẹ́jú kan, Duration 0,59wákàtí 6 sẹ́yìn 4:45 Fídíò, Yoruba Films: Ẹ̀ẹ́ bẹ̀ mi kúrò láyé ni, mi ò lè kú - Fadeyi Oloro, Duration 4,4526 Èrèlè 2020 7:03 Fídíò, Olumuyiwa Bolade Adedeji Military Bruitality: Bí arákùnrin onípèníjà ara tí sọ́jà lù ṣe dé, Duration 7,035 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 2:48 Fídíò, Esther Ajayi: Èmi náà ti borí ìṣòro rí ló ń mu mi ṣojú àánú, Duration 2,481 Ògún 2019 6:08 Fídíò, Adebola Ademilua: Àìrísẹ́ ṣè lẹ́yìn ìwé kíkà ló sọ mi dí ìyá onírú, mo dúpẹ́ tèmi, Duration 6,0827 Bélú 2020 5:55 Fídíò, Soyinka Cancer: Àṣe ara mi ni iso ti n run gbogbo bí mo ṣe n ṣèrànwọ́ lórí jẹjẹrẹ, Duration 5,5527 Bélú 2019 BBC News, Yorùbá Ìdí tí ẹ fi le è nígbàagbọ́ nínú ìròyìn BBC Ìlànà Lílò Nípa BBC Òfin Àṣírí Cookies Kàn sí.
Oríṣun àwòrán, Ololufe BBC Àkọlé àwòrán, Arun Coronavirus ti rogo, ẹwu ogun ni wọn fi ṣe.
Bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé ọjọ́-orí àwọn ọ̀daràn náà lè jẹ́ ìdí fún ṣíṣe àdínkù ìjìyà ẹ̀sẹ̀ nínú ìgbẹ́jọ́ àwọn akẹ́kọ̀ọ́ yìí.
Gbogbo nkan ti a n ri ninu awuyewuye oselu ipinlẹ Edo n jẹki ọrọ yi rinlẹ si lọkan gbogbo ẹni to ba n fi ọgbọn ati oye ba a bọ wi pe awọn oloselu kii ba ara wọn se ọrẹ timọtimọ.
Siba, iranṣẹ ìdílé Saulu, náà wá pẹlu àwọn ọmọ rẹ̀ mẹẹdogun, ati ogún iranṣẹ.
Lagos-Ibadan Express: Ènìyàn mẹ́rin ti kú nínú ìjàmbá ọkọ̀ Ṣé ẹ ti rí kí èèyàn ní àwọ̀ ara tó ń ṣí bíi ìpẹ́pẹ́ ẹja rí?
Dafidi fi Asafu ati àwọn arakunrin rẹ̀ sí iwájú Àpótí Majẹmu OLUWA láti máa ṣe iṣẹ́ ìsìn wọn níbẹ̀ lojoojumọ, 
Ni papa iṣere Stamford Bridge ni ifẹsẹwọnsẹ toni yoo ti waye ninu idije ife Carabao Cup.
Cardi B ti pín yà pẹ̀lú ọkọ rẹ̀ Offset lẹ́yìn ọdún kan Inú mí dùn láti kọrin pẹlú Beyonce nílẹ̀ Amerika- Ìyá àgbà láti Nàíjíríà Tiwa Savage tọwọ́ bọ'wé àdéhùn pẹ̀lú àwọn onígbọ̀wọ́ orin lágbàyé Wo ìdí tí Tẹni, ọ̀dọ́mọdé olórin obìnrin kìí fi ń ṣí ìhòhò rẹ silẹ̀ Lẹyin naa lo sọ pe oun ko ni i gbe ẹnikẹni lọ sile ẹjọ lori fidio ihoho naa, nitori pe ọwọ oun ni aṣiṣe naa ti wa.
Ẹ kígbe pé, “Gbà wá, Ọlọrun, olùgbàlà wa,kó wa jọ, sì gbà wá láàrin àwọn orílẹ̀-èdè,kí á lè máa dúpẹ́, kí á máa yin orúkọ mímọ́ rẹ,kí á sì máa ṣògo ninu ìyìn rẹ.
Àwọn tí wọ́n mọ oríṣìíríṣìí iṣẹ́ yóo wà pẹlu rẹ, bákan náà, àwọn olórí ati gbogbo eniyan Israẹli yóo wà lábẹ́ àṣẹ rẹ.
Àgbéré kí lò ń ṣe,tí o sì ń fi ojú burúkú wò wá.
Mò ń retí rẹ, OLUWA,ju bí àwọn aṣọ́de ti máa ń retí kí ilẹ̀ mọ́ lọ,àní, ju bí àwọn aṣọ́de, ti máa ń retí pé kí ilẹ̀ mọ́.
Inú bí àwọn ìjòyè sí Jeremaya, wọ́n lù ú, wọ́n sì jù ú sẹ́wọ̀n ní ilé Jonatani akọ̀wé, nítorí pé wọ́n ti sọ ibẹ̀ di ọgbà ẹ̀wọ̀n.
Lẹ́yìn tí àwọn arakunrin Jesu ti lọ sí ibi àjọ̀dún náà, òun náà wá lọ.
Ṣugbọn ẹ̀yin mọ̀ ọ́n, nítorí ó ń ba yín gbé, ó sì wà ninu yín.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù NUT ní àìsí àbò ń ṣàkóbá fún àwọn olùkọ́ ní Nàìjíríà 4 Èbibi 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ọpọ igba lo jẹ pe awọn ileewe ni awọn agbebọn ati agbesumọmi maa n kọlu lasiko iṣigun wọn Ko din ni ẹgbẹta olukọ ti wahala aabo to mẹhẹ ni apa ila oorun ariwa orilẹede Naijiria ti ran lọ sọrun ọsan gangan.
Àkọlé àwòrán, Akọroyin nigba kan ri ni yoo ṣoju APC dupò gomina Kwara O ti ṣiṣẹ pẹlu ileeṣe iwe iroyin THISDAY ri, ko to wọle di olori awọn ọmọ ile igbimo asofin to kere ju nipinlẹ Kwara.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù UN: Orílẹ̀èdè 170 ló ti fi àjàkálẹ̀ àrun Ẹ̀yi tó wa létí ní 2019 16 Ìgbé 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Amọ ajọ isọkan orilẹede agbaye ( United Nations) ti keboosi fun araye pe ajọ eleto ilera lagbaye, WHO ti fi iroyin sita pe, ọwọja arun Ẹ̀yi taa mọ si Measles ti le kankan si ni aarin osu mẹta akọkọ lọdun 2019 pẹlu ida mẹta ju bo se wa ni esin lọ.
Childbirth in Nigeria: Dokita àti Nọ́ọ̀sì ń fìyà jẹ àwọn alaboyún lásìkò ìbímọ!
 Won ni won ti bere iwadii lori ero alatagba re ti o safihan awon ohun to buru jai.
S, Canada ati Mexico, eyi ti igbimo to n ri si boolu afesegba lagbaye FIFA yoo se ipade apero re ninu osu kefa odun ti a wayii, ni Moscow lati mo orile-ede ti o kaju osuwon julo lati sagbateru idije naa.
Eji Gbadero, ọmọ Ibadan àti jayé-jayé ọmọ ónílẹ̀ ti wọn yẹgi fun l'Eko Saudi Arabia kéde ìlànà tuntun fún Hajj nítorí coronavirus Ajọ to n ṣeto irinna Hajj l'orilẹ-ede Naijiria sọ pe oun yoo ṣe ipade lọjọ Iṣẹgun, lati le mọ igbesẹ to ku ti wọn yoo gbe lori bi ijọba Saudi Arabia ṣe f'ofin de Hajj f'awọn ọmọ ilẹ okeere.
Campbell, sabewo wa si orile ede Naijiria ni ilu Eko nigba ti o n kopa ninu eto afihan aso igbalode wiwo olose kan ti won pe ni: Arise Fashion Week.
O dèèwọ̀ lati ti ojú pópó pa nipinlẹ Ondo 'Màálù tó bá tàsẹ̀ àgẹ̀rẹ̀ níwájú ilé mi, ó dẹran àsun!
Amọ Sara ni inu oun dun pe oun bọ lọwọ ero buruku yii lati igba ti oun ti de si Afirika.
Ǹjẹ́ kabiyesi ha lè lọ́wọ́ sí irú nǹkan báyìí; kí ó má tilẹ̀ sọ ẹni tí yóo gun orí oyè lẹ́yìn rẹ̀ fún àwọn iranṣẹ rẹ̀?
Sagay fikun pe, irọ diẹ, ootọ diẹ ni Lawan sọ, nitori gbogbo aye lo ti mọ pe inu ajẹmọnu awọn asofin ni wọn di owo to lorukọ si.
O wa ṣeleri lati mu ki iṣẹ ajọ naa gbooro sii nipa ṣiṣe iṣẹ pọ pẹlu awọn agbofinro ati awọn ẹṣọ eleto abo miran.
Titi di asiko yii, eniyan marun ni wọn ri yọ laaye, eniyan mejila ku nigba ti ko si ẹni to ri awọn eniyan mẹta to ku.
Yahaya ni ipinlẹ Kano ti kanju da oun lẹbi ti wọn ko si faaye gba oun lati sọ toun pẹlu bo ṣe jẹ pe ilana ofin wa nipinlẹ Kano.
Bi owo epo rọbi ṣe walẹ lọja agbaye lo jẹ ki adinku ba owo tawọn alagbata epo fi n gbepo wọ Naijiria lati oṣu kẹta ọdun 2020 nitori ajakalẹ aarun coronavirus.
Aarẹ tun sọ pe ijọba oun ko ni foju re wo ẹnikẹni to ba fẹ da rogbodiyan silẹ nibi kibi kaakiri orilẹede Naijria ati awọn to ba kowo ilu jẹ.
ninu eto idibo  atundi to waye ni ọjọ
Adájọ gbà ìdájọ ikú lọ́wọ́ ejò A fi ki Olorun maa ṣo wa nibi ogun ni iṣẹlẹ yii jẹ.
Nígbà tí àwọn arakunrin rẹ̀ yòókù rí i pé baba wọn fẹ́ràn Josẹfu ju àwọn lọ, wọ́n kórìíra rẹ̀, wọn kì í sì fi sùúrù bá a sọ̀rọ̀.
Bí gbogbo rẹ̀ se ṣẹlẹ̀ gan-an lẹ gbọ́ ní ṣókí yẹn.
Naijiria ati ijoba fi aidunnu won han , won si tun ba ẹbi  awon ti o padanu ẹmi won lasiko ikọlu naa.
Ẹ wọn ibòmíràn tí òòró rẹ̀ yóo jẹ́ ọ̀kẹ́ kan ati ẹẹdẹgbaata (25,000) igbọnwọ (kilomita 12½), tí ìbú rẹ̀ yóo sì jẹ́ ẹgbaarun (10,000) igbọnwọ (kilomita 10).
Ẹ̀yin ará Jerusalẹmu, ati ẹ̀yin ará Juda,mo bẹ̀ yín, ẹ wá ṣe ìdájọ́ láàrin èmi ati ọgbà àjàrà mi.
Lẹ́yìn ìṣẹ́jú mẹ̀wàá ni Asisat tún jẹ góòlù rẹ̀ kẹẹ̀ta tó sọ góòlù Nàìjíríà di mẹ́rin.
Bí ó ti ń bọ̀ ni mmò ń ronú ohun tí mo máa ṣe.
Trump impeachment: Àṣírí tùú, àkọsílẹ fihàn bí Trump ṣé béèrè iranwọ lọ́wọ́ ààrẹ Ukraine
Ohun tí ó bá hù kì í rí bí ohun tí a gbìn ti rí, nítorí pé irúgbìn lásán ni, ìbáà ṣe àgbàdo tabi àwọn ohun ọ̀gbìn yòókù.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Kemi Dairo: Iṣẹ́ abẹ nínú ọpọlọ àti ẹ̀rọ ni mo fi ń gbọ́ ọ̀rọ̀ báyìí Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Ogeadiro_official, @ogeadiro1 naa kin Jikan lẹyin pẹlu afikun pe Naijiria yoo maa bajẹ si ni.
Ilé ẹjọ́ rán àwọn mérìndínlógún lẹ́wọ̀n gbére fún dídáná-sun Nusrat EFCC gbé ọ̀gá owó ìfẹ̀yìntì tẹ́lẹ̀ lọ sÍ ilé ẹjọ́ fún ìwà ìbàjẹ́!
Mò ń tẹ̀lé e lẹ́yìn, mo súnmọ́ ọn pẹ́kípẹ́kí,n kò tíì yipada kúrò ní ọ̀nà rẹ̀.
(Express) Bakan naa ni o ṣeeṣe ko di dandan fun Manchester United lati wa ọgọrin miliọnu Pọnun ti wọn yoo fi ra agbabọọlu England, Harry Maguire lẹyin ti Eric Bailly fi orunkun ṣeṣe lasiko idije ọlọrẹsọrẹ pẹlu Tottenham ni Ọjọbọ.
Labẹ aṣẹ tuntun yii, eleyi to fi sita lori ẹrọ amounmaworan, Trump ni awọn ti so irinajo awọn eeyan lati Yuroopu si Amẹrika rọ fun ọgbọn ọjọ gbako.
Ọgbẹni Gbadamosi Olusola ṣalaye pe ko si anfaani kankan ti Naijiria jẹ lara titi awọn ẹnu ibode, nitori pe iṣẹ fayawọ lọ soke si, ti ko si tun si ayipada lori ọrọ eto aabo.
Kí ló dé tí àwọn orílẹ̀-èdè fi ń bínú fùfùtí àwọn eniyan ń gbìmọ̀ asán?
Ẹ̀ṣẹ̀ wo ni mo ṣẹ baba rẹ tí ó fi ń wọ́nà láti pa mí?
" wón máa ń sàbà pèé ní "" mọ ́ ṣáláṣí aláwọ ̀ pupa fẹ ́ ẹ ́ rẹ ́ "" , nítorí lílo áwọ ̀ pupa fẹ ́ ẹ ́ rẹ ́ sílẹ ̀ fún ẹ ̀ ṣọ ́ inú rẹ ̀ ."
Burna Boy Twice as Tall: Ǹkan tí ó yẹ ki o mọ̀ nípa Damini Ebunoluwa Ogulu Rex (Burna Boy) ti orin rẹ̀ lu ìgboro pa báyìí
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Black women live matters: Ọdún 2015 ní àwọn ọlọ́pàá pa India Kager láìní ìdí- Gina Best Ọsẹ to kọja ni igbakeji Gomina ipinlẹ Ondo, Agboola Ajayi pe fun ki wọn yọ Abẹnugan Ile Aṣofin ni ipinlẹ Ondo, David Oloyelogun.
OLUWA ní, “Àwọn ọmọ Efuraimu parọ́ fún mi, ilẹ̀ Israẹli kún fún ẹ̀tàn, sibẹsibẹ mo mọ ilé Juda, nítorí pé ó jẹ́ olóòótọ́ sí èmi, Ẹni Mímọ́.
Eyi lo mu ki a se atupale awọn nnkan to sẹlẹ nigba ti Aarẹ orileede Naijiria Muhammadu Buhari se irinajo lọ si China.
Bakan naa lo mọ orukọ awọn aarẹ orilẹede kaakiri agbaye, to fi mọ awọn nkan pataki mi i to n ṣẹlẹ l’agbaye ti ko yẹ ki ọmọ ọdun meji bi tiẹ o mọ.
Nínú oṣù Belu ọdún tí ó ré kọjá, àwọn òṣìṣẹ́ Ìgbìmọ̀ tí ó ń Dáàbò bo Oníṣẹ́-ìròyìn, Angela Quintal àti Muthoki Mumo di ẹni àtìmọ́lé fún ọ̀pọ̀ wákàtí ní Dar es Salaam, Tanzania, tí ìwé ẹ̀rí ọmọ-ìlú-fún-ìrìnnàa wọ́n di gbígbà lọ́wọ́ọ wọn.
Iroyin ti jade laimọye igba pe, Lateef ati oṣerebinrin miran, Bukunmi Oluwashina, n fẹ ara wọn.
Nítorí náà, inú ilé Absalomu ni ó ń gbé, kò sì dé ọ̀dọ̀ ọba rárá.
Yemi Osinbajo: Ẹgbẹ́ Arewa ní ọ̀rọ̀ ìgbákejì ààrẹ tún dákún ìṣòro Nàíjíríà ni
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, WORLD AIDS DAY 2018: HIV/ AIDS kìí ṣe ìdájọ́ ikú mọ́ Laarin ọdun 1989 si 1993 ni o fi jẹ aarẹ, ṣugbọn ilepa rẹ fun saa keji foriṣanpọn nigba ti aarẹ Bill laa mọlẹ ninu idibo aarẹ to waye lọdun 1992.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Mohammed Umar: Ta ni ọ̀gá àgbà tuntun fún EFCC?
Dandan ni wiwọ ibomu-bo ẹnu nipinlẹ naa.
Ofin naa fi aye silẹ ki wọn maa san iye owo osu ti awọn gomina tẹlẹ ba n gba lasiko ti wọn wa lori oye fun wọn gẹgẹ bi owo ifẹyinti leyin ti wọn ba kuro lori oye.
Ìsèjọba ìgbìmọ̀ asòfin dára ju ìsèjọba ààrẹ lọ -Femi Okunronmu Àpótí ìkẹ́rùsí jálu ọkọ̀ méjì lórí l'Eko 'Tàpá sófin ojú pópó kóo ṣọdún lẹ́wọ̀n' Wo ojú àwọn ọmọ Nàìjíríà tó ń dá bírà rere ní àgbáyé Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, ''Ẹ̀mí ọ̀pọ̀lọpọ̀ ṣì n sọnù ni orilẹ̀-ede Burundi' Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Ó ní, “Ǹjẹ́ OLUWA Ọlọrun yín kò ha wà pẹlu yín?
Bakan naa lo ni lilo awọn nọmba ibanisọrọ lati mọ awọn ti iye owo ipe to wa lori ẹrọ ibanisọrọ wọn ko ba ti ju ọgọrun naira lọ.
Dokita Onu tun yanana ogunlogo tirilionu naira ti orile-ede Naijiria na seyin lori kiko awon ohun ipese ile okere wole.
Bẹ́ẹ̀ ni wọ́n ṣe fún ọjọ́ mẹfa.
Aare yo pelu awon ebi, ara, ore ati awon omo egbe oselu APC, bee si ni o tun gboriyin fun akitiyan ati ise takun-takun re ninu egbe oselu APC, paapaa julo fun atileyin re to n sa lore-koore lati polongo egbe naa fun awon ara ilu saaju idibo gbogbo-gboo to n bo lona.
O di dandan fun nikẹni to ba wa ninu ọkọ lati wọ bẹliti yi,o wa fun awakọ ati gbogbo ero to ba gbe.
Àwọn èèyan kàn ni ko ri bẹẹ.
Gbogbo ìròyìn lati Nigeria kò ri ọ̀rọ̀ àti ìṣò̀ro ti ó dojú kọ ilú ti wọn sọ mọ, ju ọ̀rọ̀ èsi ibò ni Amẹ́rikà.
billion), bee si ni lodun 2022 yoo je bilonu mẹ́tàdínláàdọ́rùn ún owo
Lọjọ kọkanlelogun oṣu kẹwaa to lọ yii ni ijọba ipinlẹ kede ofin konle o gbele nijọba ibilẹ Oyigbo atawọn ibomiiran niluu Port Harcourt lẹyin tawọn afurasi ọmọ ẹgbẹ IPOB da rogbodiyan silẹ nibi iwọde EndSARS.
Ẹgbẹ agbabọọlu Newcastle lo ṣina iya fun Man U ni tiwọn ni papa iṣere St.
 wọ ́ n jẹ ́ ẹgbẹ ̀ rún méjìlá ènìyàn níye .
 Ó ṣe é ṣe kí irú ìyàtọ ̀ -sára èdè yìí ṣẹlẹ ̀ nípa oríṣìíríṣìí ogun abẹ ́ lé tí ó ṣẹlẹ ̀ ní ilẹ ̀ yorùbá láyé àtijọ ́ nítorí èyí mú ọ ̀ pọ ̀ lọpọ ̀ ènìyàn láti oríṣìíríṣìí ẹ ̀ yà tẹ ̀ dó sí agbègbè yìí tí ó sì fa sísọ oníruurú èdè tó yàtọ ̀ sí ara wọn nítorí agbègbè yìí jẹ ́ ààlà láàárín Ìpínlẹ ̀ oǹdó , kwara àti bendel lóde òní .
OLUWA rán Mose pé, kí ó sọ fún Aaroni pé kí ó na ọ̀pá rẹ̀ jáde, kí ó sì fi lu erùpẹ̀ ilẹ̀, kí gbogbo rẹ̀ sì di iná orí ní gbogbo ilẹ̀ Ijipti.
TONY ELUMELU AMAA 2018 Ami eye fun ere apanilerin to dara ju Sidechic Gang – Ghana
Emi gẹgẹ bi ẹnikan ti lọ fun idanilẹkọọ lorisirisi bi mo ṣe le bori awọn ipenija mi.
Lagos-111 FCT-16 Akwa Ibom-10 Oyo-8 Kaduna-6 Delta-6 Rivers-5 Ogun-4 Ebonyi-4 Kano-3 Plateau-2 Gombe-2 Kebbi-1 Kwara-2 Bauchi-1 Borno-1 Nibayii, eniyan 8915 lo ti ni, 2592 ti ri iwosan, 259 si ti ku.
Ẹnìkọ̀ọ̀kan tí ó bá jẹ́ olórí láti inú ẹ̀yà kọ̀ọ̀kan ni kí o rán.
“Ẹkẹta dé, ó ní, ‘Alàgbà, owó wúrà rẹ nìyí, aṣọ ni mo fi dì í, mo sì fi pamọ́, 
O fikun pe ọkunrin takuntakun ni Baba Obasanjọ, ti o laya ti kosi bẹru lati sọ otitọ fun ẹnikẹni.
Òkìkí Dafidi kàn káàkiri, OLUWA sì jẹ́ kí ẹ̀rù rẹ̀ máa ba gbogbo àwọn orílẹ̀-èdè.
Lẹ́yìn ọdún díẹ̀ sí i,n óo lọ àjò àrèmabọ̀.
Ọkọ̀ ojú omi dànù ní Kwara, ọmọ́dé 9 ba rìn Ìjàmbá Kwara: Isẹ́ ìdárò ń wọlé sọ́dọ̀ ìjọba Kwara Ilu Lafiagi, nijọba ibilẹ Edu nipinlẹ Kwara ni ọkọ oju omi to ko ero mejilelogun naa ti danu lagbami.
Ni Jigawa, àwọn obìnrin dáwó ra ọkọ̀ N1m láti máa fi gbé aláboyún ní iletò kan
Bi awọn to ni i ṣe n pọ si, to si n tan kaakiri agbaye fihan pe a ko gbọdọ ni ìrètí pe ara yoo tu wa ni asiko ooru.
Ẹ sá kúrò láàrin Babiloni,kí olukuluku sá àsálà fún ẹ̀mí rẹ̀!
 O ni “Kosi ohun to dara julo pe ki inu awon eniyan to n gbo wa lati ile akede dun lati maa tẹti si won.
Oríṣun àwòrán, Garba Shehu Ileeṣẹ aarẹ lorilẹede Naijiria pẹlu ti da si ọrọ naa gẹgẹ bi awọn iwe iroyin abẹle kan ti gbe e sita.
Idajọ awọn adajọ idije ẹṣẹ kikan naa to fi ni ami 50-44, 50-44 ati 50-45 lo fi bori.
Ó wípé ọjọ́ ti pẹ́ tí òun ti wà ládùúgbò náà.
Nígbà tí ọkùnrin yìí wà ní òdé  ayé èdè Ẹlẹ́dàá kò yẹ àwọn ọmọ ènìyàn, nítorí Ọlọ́run fún un ní owó, Ó fún un ní ọmọ, Ó  sì fún un ní ọ̀pọ̀lọpọ̀ ìṣúra inú ayé.
Atiku sọ pé tí ó bá jẹ́ pé ó pọn dandan ni, òun kò bá má gbà rárá fún M.
Iru iṣẹlẹ bayii ko ṣẹṣẹ ma a waye l'orilẹ-ede Naijiria laarin ololufẹ.
omo orile ede Naijiria ninu sibe ,awon omo orile ede Naijiria ti ni kaka ki eku
Ṣugbọn mo ní ìrètí pé ẹ mọ̀ pé ní tiwa, àwa kò kùnà.
Oríṣun àwòrán, George Wafula/BBC Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Oríṣun àwòrán, AFP Awọn agbabọọlu naa yari nitori pe wọn ko ti i gba awọn ajẹmọnu wọn.
awa naa” O wa fi asiko naa ran Oba Saliu Adetunji leti pe ko ma se
Mo sì ní ìrètí pé yóo ye yín jálẹ̀.
Ó sọ fún wọn pé, “Ó ti mú mi lọ́kàn pupọ láti jẹ àsè Ìrékọjá yìí pẹlu yín kí n tó jìyà.
Ẹjọ́ òfo ni ẹ gbójú lé.
 lati maa je ki awon asofin , akoroyin ati osise ile igbimo asofin wole si ile igbimo asofin.
A wo arawa pé àbí irọ́ ni, kò jẹ́ jẹ́ bẹ́ẹ̀.
Olórin tàkasúfèé pàdánù mílíọ̀nú náìrà kan lori ìfẹsẹ̀wọsẹ̀ Liverpool Vs Barcelona
Magu,'estimated billing' àti àwọn ohun míràn tí ilé aṣòfin Nàìjíríà kò rí yanjú Ilé ẹjọ́ kòtẹ́milọ́rùn yá lórí ọ̀rọ̀ Adeleke- PDP Ìpànìyàn Zamfara: Kò gbọdọ̀ sí ìwakùsà ní Zamfara Kini ọ̀nà àbáyọ sí ooru tó mú lásìkò yìí ní Nàìjíríà?
Ó tún dé fìlà gbọọrọ kan báyìí, kò wọ ṣòkòtò, kò wọ ẹ̀wù bẹ́ẹ̀ ni kò wọ bàtà rárá.
Ewe, adari egbe oselu APC, Bola Tinubu, jabo lasiko to n ba awon akoroyin soro pe, fi erongba re han pe egbe oselu APC yoo jawe olubori ninu idibo ohun to n bo lona.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Akomolede ati Asa: Mọ̀ si nípa àwọn ọ̀nà tí Yorùbá ń gbà ran ara wọn lọ́wọ́ Ori awọn onisẹ ọwọ lati ti kọkọ bẹrẹ, eeyan ẹgbẹrun mẹrin ati aabọ si ni yoo jẹ anfaani owo iranwọ naa nipinlẹ kọọkan.
Èmi ò kúkú dá àjèjì yìí l’ẹ́bi.
Francis Uzoho (Anorthosis Famagusta, Cyprus); Ikechukwu Ezenwa (Katsina
Óyá fi ààmì sórí 'Bobajiroro' 10 Èbibi 2019 Ede Yoruba jẹ ọkan gboogi ni agbaye ti aami ori rẹ jẹ kọkọrọ ti ẹnikẹni le fi tumọ rẹ.
Ẹni to bori: Mauritania Tunisia vs Namibia.
Angẹli tí ń bá mi sọ̀rọ̀ bá jáde, ó ní, “Gbé ojú rẹ sókè kí o tún wo kinní kan tí ń bọ̀.
John Onaiyekan: Ìtìjú ni fún mi láti rí àwọn ọmọbìnrin Nàìjíríà tó ń ṣe aṣẹ́wó ní Italy
Ninu atejade kan ti aare Buhari gbe jade lati ba awon mọlẹbi , ọrẹ  , akẹgbẹ rẹ ninu ise ati oselu kẹdun lori iku oloogbe naa ati ọmọ rẹ , ti won padanu emi won ninu ijamba oko.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ladoja: Àwọn èèyàn Oyo fì ìbò sọ̀rọ̀ pé ìjọba Ajimobi kò dára Ọdẹyẹmi, lasiko to n sọrọ lori bi awọn ọmọ ẹgbẹ oselu PDP kan se pọn lẹyin Ahmed Lawan dipo Alli Ndume, ti ẹgbẹ PDP fẹ lati se atilẹyin fun lasiko idibo naa, igbakeji akọwe ipolongo fẹgbẹ PDP ni, ko si ohun to buru ninu ohun ti awọn asofin PDP naa se nitori o pẹ diẹ ki ẹgbẹ PDP gan to sọ ẹni ti wọn yoo dibo fun, fun wọn.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Iléeṣẹ́ ọmọogun sáwọn olóṣèlú: Ẹ má t'ọwọ́ òṣèlú b'ọ̀rọ̀ ológun mọ́ 19 Ìgbé 2018 Oríṣun àwòrán, Nigeria Army Àkọlé àwòrán, Ọ̀pọ̀ nǹkan ìjà olóró ati afunrasí ni àwọn ọmọogun ti gbà Iléeṣẹ́ ọmọogun Nàìjíríà ti ké sáwọn olóṣèlú láti yéé ti owọ́ òṣèlú bọ ọ̀rọ̀ àwọn ọmọ ogun mọ́.
Ati ri owo na nira fun wọn ṣugbọn wọn n ri iranwọ lẹẹkọọkan latọdọ awọn mọlẹbi ati ọrẹ Abiola.
Ọmọ Naijiria ko le maa jiya ki awọn oloṣelu maa bu owo fun ara wọn bo ṣe wu wọn.
Nígbà tí ayaba gbọ́ ohun tí ó ṣẹlẹ̀ sí ọba ati àwọn ìjòyè rẹ̀, ó wọ inú gbọ̀ngàn àsè náà, ó sọ fún ọba pé, “Kabiyesi, kí ọba kí ó pẹ́, má jẹ́ kí ọ̀rọ̀ yìí dààmú rẹ tabi kí ó mú kí ojú rẹ fàro.
Ati gara nítorí pé ó ń jẹ àpọ̀jẹ, ṣugbọn pátákò ẹsẹ̀ rẹ̀ kò yà, ó jẹ́ ohun àìmọ́ fun yín.
Amọ, ọpọlọpọ awọn ọmọ Naijiria to fi ẹrọ wọn lede loju opo BBC Yoruba lori Facebook ti kesi aare lati tu awọn silẹ lọwọ ofin konile-o-gbele ti yoo pari loni.
Níbi oòrùn ti ń yọ lóru gànjọ́, gbogbo rẹ̀ ló sojú èmi kinní yìí.
Nigeria Labour Congress, NLC ,fun atileyin won lori aseyori eto idibo , ni eyi
Mo bá súnmọ́ Saulu, mo sì pa á.
Egbe oselu alatako lorile-ed Zimbabwe ti yan adele Aare, eyi waye latari iku olori egbe naa, Morgan Tsvangirai, eni ti o di ologbe leyin aisan ti o ti n ba finra.
Yarchida, Bombula, Tshata ati Bamzir .
Iyaloja Oyo state: Àwọn ọlọ́jà ń sèdárò Ìyálọ́jà ìpínlẹ̀ Oyo, Wuraola aya Kola Daisi tó dolóògbé, wọ́n yan asojú míràn
ọrọ ilẹ abẹle, Abdulrahman Dambazau gbe jade ti alakoso lle-ise to n mojuto bi
Oríṣun àwòrán, @stella_immanuel Lọpọ awọn fọnran fidio to fi sita, o ma n ṣe iwaasu lori bi awọn eeyan ti ṣe yago kuro lọna Kristi nipa kikopa ninu awọn iwa ẹṣẹ bi ibalopo laarin akọ si akọ ati abo si abo.
Àwọn ọmọ Kohati yóo pàgọ́ tiwọn sí ẹ̀gbẹ́ Àgọ́ Àjọ ní ìhà gúsù.
Ọlọrun sé orísun omi tí ó wà lábẹ́ ilẹ̀, ó ti àwọn fèrèsé ojú ọ̀run, òjò náà sì dá.
Nǹkan mẹ́sàn án tí Mùsùlùmí gbọdọ̀ ṣe nínú oṣù Dhual- Hijjah Èmi Ọba tí wọ́n ń kó jẹ nígboro- Oluwo ti ilú Iwo Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
 Ọ ̀ pọ ̀ dìgbòlugi nínu àwọn ènìyàn jẹ ́ òkùnfà ìgéjẹ ajá .
Canada: Kò sí ẹ̀sẹ̀ nínú igbó mímu àti títà, ẹ tẹ́síwájú
Akẹ́kọ̀ọ́ ìmọ̀ òfin kọ̀ọ̀kan yóò gba ₦500,000 owó ìrànwọ́ l‘Oyo Ni bayii, ileeṣẹ ọlọpaa sọ pe iwadii ti n lọ lori nkan to fa iṣẹlẹ iṣekupani ọhun.
Oun naa kepe ijọba lati fopin si iwa ifiyajẹni awọn ọlọpaa SARS.
tabi pé kí ẹ fi orí yín búra, nítorí ẹ kò lè dá ẹyọ irun kan níbẹ̀, ìbáà ṣe funfun tabi dúdú.
Wọ́n ń fi fadaka ati wúrà wọn yá ère fún ìparun ara wọn.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù 137 ni iye àwọn obìnrin tí ikú ń pa lójúmọ́ lágbàáyé 26 Bélú 2018 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ko din ni obinrin mẹ́tàdínlógóje kaakiri agbaye ni awọn ololufẹ wọn tabi mọlẹbi wọn maa n ṣe iku pa wọn lojumọ Iwadi kan ti ajọ to n ri si ọrọ oogun oloro ati iwa ọdaran ti ṣe afihan wi pe o to obinrin mẹ́tàdínlógóje kaakiri agbaye ni awọn ololufẹ wọn tabi mọlẹbi wọn maa n ṣe iku pa wọn lojumọ.
ti awọn ọmọ orilẹ-ede yii le lo anfani rẹ lati fi igbagbọ wọn ninu
Amọ ṣa ẹgbẹ ọmọ Kristẹni ipinlẹ naa fẹ ki ijọba gbẹsẹ kuro lórí òfin yii.
Ẹ̀yin ará Juda,ẹ má sọkún nítorí ọba tí ó kú,ẹ má sì dárò rẹ̀.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Akure Anglican Bursar: Àwọn agbébọn gbé owó sálọ lẹ́yìn tí wọ́n pa akápò ìjọ Anglican 4 Ìgbé 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 5 Ìgbé 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Awọn agbebọn naa tẹle akapo ijọ naa lati ile ifowopamọ nibi ti o ti lọ gba owo Awọn agbebọn kan ti yinbọn pa akapo ijọ Anglican lẹkun Akure, Gabriel Abiodun ti wọn si gbe owo ti o lọ gba ni ile ifowopamọ salọ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Gbara ti o kan wa kuu bayii ni ẹlẹha ti figbe bọnu laarin ọja, ti ọkan ninu awọn obinrin mejeeji yi si juba ehoro.
com Yatọ si ile oludasilẹ rẹ, ti wọn ti bẹrẹ ijọ naa, wọn ti fi igba kan ni awọn ẹka ile ijọsin , ṣugbọn wọn ti tu wọn ka, nigba ti wọn ro o pe ko ba oju mu.
Oríṣun àwòrán, Others N ṣe ni awọn oṣiṣẹ ati ojulumọ naa duro sita lẹyin igbesẹ Baba Obasanjo, ti wọn si lọ sin oku ohun lẹyin isin.
Ahinoamu ọmọ Ahimaasi ni aya Saulu.
Ó bá sọ fún un pé, “O kò ní so mọ́ laelae.
Buhari kò leè ṣàtìlẹyìn fún olùdíje Amosun l'Ogun Gómìnà Amosun f'ohùn sílẹ̀ láti kúrò ní APC Ogun: Amosun, ẹgbẹ́ òṣìṣẹ́ NLC fẹ́ forígbárí l'Ógùn Sìgá mímu ń di èèwọ̀ oògùn ìlera pípé lagbaye Bakan naa ni wọn tun buwọlu ofin to tu gbogbo awọn alaga ijọba ibilẹ atawọn adari ajọ ile iṣẹ ijọba ipinlẹ Ogun gbogbo ti Amosun yan ká nitori wọn ti gba owo to tọ si wọn lọdọ ijọba to kogba wọle.
Wọ́n sọ fún ara wọn pé, “A kò ní rí ẹ̀sùn kà sí Daniẹli lẹ́sẹ̀, àfi ohun tí ó bá jẹmọ́ òfin Ọlọrun rẹ̀.
Ọ̀rọ̀ ojisẹ Ọlọ́run náà sì lo tí ń fa awuyewuye làwọn ojú òpó ikansiraẹni lórí itakun àgbáyé , bí àwọn èèyàn kan sì ṣe tako èrò rẹ, ni àwọn míràn fara mọ.
Ifa ni olugbala wọn, nitori ẹ si ni wọn ti ma n pe ifa ni Ọdundun, ti i du ori elemere.
Ti a ko ba gbagbe, Aarẹ Muhammadu Buhari ti sọ ero rẹ lati dije du ipo aarẹ lẹlẹẹkeji ninu idibo gbogboogbo tọdun 2019.
Ohun tó ti yá kan kìí pẹ́ mọ́, fọ́ọ̀mù ìgbaniṣíṣẹ́ fún Àmọ̀tẹ́kùn dé!
Rogbodiyan to bẹ silẹ lojuko iwọde naa mu ẹmi eeyan meji lọ, koda ori lo ko gomina Oyetola ati awọn ẹmẹwa rẹ yọ nibi iwọde lọwọ oko ti awọnj eeyan ọhun n sọ si wọn.
Awọn miiran ni titapa si ofin to wa nilẹ gbaa ni bi awọn eeyan ti pejọ sibi eto isinku Abba Kyari l'Abuja nigba ti konile-o-gbele wa lode.
Oríṣun àwòrán, Other Àkọlé àwòrán, Gbajugbaja osere Nollywood, Ibinabo Fiberesima ni wọn fi ẹsun ipaniyan kan lẹyin ti o wa ọkọ pa dokita kan ni ilu Eko ni ọdun 2006.
Sùúrù ni bàbá àti ìyá aǹfààní, òmùgọ̀ ènìyàn ní í wí pé sùúrù òun pọ̀ jù nítorí sùúrù kò ní òpin.
Tinubu parí aáwọ̀ Ambode àtàwọn aṣòfin ìpínlẹ̀ Eko #BBCNigeria2019 Bààlú Sala tó pòórá ti di àwárí nínú òkun Ọ̀rọ̀ LAUTECH gba àpérò f'áwọn Olúdíje Ọṣun Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'A ni òfin púpọ̀ ní Naijiria ṣùgbọ́n a kò bọ́wọ́ fún un ni' Ajọ naa fikun wi pe o ṣeeṣẹ ki o peleke si ninu ọdun yii pẹlu bi oju ọjọ ṣe n bajẹ si, ti igbe aye awọn eniyan o gbe pẹẹli si ati iru ounjẹ ti awọn eniyan n jẹ.
Goliati dúró, ó sì kígbe pe àwọn ọmọ Israẹli, ó ní, “Kí ló dé tí ẹ fi kó ara yín jọ láti jagun?
Ẹẹmẹta ni a fi ọ̀pá lù mí.
Laipẹ yi ti Minisita sọ fara ilu pe o di dandan lati fofin de itankalẹ iroyin ofege ni Naijira niṣe lawọn eeyan tako.
”O gboriyin fun gomina ijoba ipinle Akwa Ibom, Udom Emmanuel fun anfani ti o fun awon odo lati febun won han nipase ayeye ohun.
Oríṣun àwòrán, @inecnigeria Àkọlé àwòrán, INEC ni ètò náà lọ ní irọwọrọse.
L’ọ́jọ́ tí wọ́n fẹ́ ṣoró n’íhò ọ̀run.
"Mo kọ lẹta naa gẹgẹ bii Alaafin Ọyọ, ohun mi si ni ohun gbogbo ọmọ Yoruba.
 Ṣaaju ni ajọ NCDC ti kede pe eeyan mẹrinlelogoji lo fara kasa arun Covid-19 ni ipinlẹ ọhun ni Ọjọbọ, eyi to jẹ iye eeyan to pọ ju ti yoo ni arun naa lọjọ kan ṣoṣo ni ipinlẹ ọhun."
Adeleke sọ pe Omisore kosi pẹlu PDP nigba ti awọn jawe olubori ninu idibo ọjọ Abamẹta to lọ, o fi kun ọrọ rẹ pe ẹgbẹ PDP ko ba ni bi ibo ẹgbẹrun marun un si ṣugbọn mọgomọgo ni ko jẹ.
” He saidFarah bere si ni fakoyo ni olokan-o-jokan ere-ije lati igba ti o ti gba ami-eye goolu nigba meji otooto lodun 2012 ati odun 2016 ninu idije Olympic.
Lóòótọ́ ó yẹ kí ènìyàn máa làkàkà láti ṣe nǹkan ńlá, kí olúwaarẹ̀ máa wá ìlọsíwájú fún ara rẹ̀, nítorí ẹni tí ó dúró sí ojú kan bí adágún omi kò sí láàárin àwọn alààyè, òkú ni eléyìínì láàárin wọn.
Chidoka ni Sẹnẹtọ Ekweremadu siwaju awọn igbimọ ti wọn lọ ba arẹẹ Muhammadu Buhari pe ko fi olori ẹgbẹ IPOB, Nnamdi Kanu silẹ.
’ Mú igi mìíràn kí o kọ sí ara rẹ̀ pé, ‘Ti Josẹfu, (igi Efuraimu) ati gbogbo àwọn ọmọ Israẹli tí wọ́n wà pẹlu rẹ̀.
Atẹjade kan ti Ọmọwe Umar Jibrilu Gwandu, tii se igbakeji osisẹ alarena, nileesẹ agbẹjọro agba ati Minisita feto idajọ ilẹ wa fọwọ si lo kede iyansipo tuntun naa.
Ninu oro minista fun eto isuna ati ilana aatele, iyen, asojusofin Udoma Udo Udoma lo ti ran won leti pe ijoab Buhari ba eto oro aje to ti mehe nile nigba ti o de ori aleefa sugbon ti ohun gbogbo ti n yato bayii lataari awon ilana ofin to poju owo tuntutn ti won n gbe kale.
aya awon oloselu, ati awon obinrin to n ba iyawo aare se ise papo.
Oríṣun àwòrán, Reuters Amọ, Aarẹ Lukashenko to ti wa ni ipo lati ọdun 1992 sọ wi pe awọn ijọba lati oke okun lo n ṣe agbatẹru fun awọn alatako oun ati awọn afẹhọnuhan.
Òun ni ó wà pẹlu Ọlọrun ní ìbẹ̀rẹ̀, kí á tó dá ayé.
Sẹnetọ Ben Murray-Bruce ati Alagba Ayọ Adebanjọ to jẹ eekan ninu ẹgbẹ Afẹnifẹre.
Ọlafare sọ wipe o jẹ ojiji lati gbọ iru ohun to le si ni lọkan bayii nitori pe ko si ootọ kankan ninu rẹ.
    Inú mi dùn rékọjá nígbà tí mojí, nítorí gẹ́gẹ́ bí ìtumọ̀ tí àwọn ènìyàn mi ti ń ṣe, àlá eléyìí nì dára, èyí nì ni pé a o jọ bá ara wa rẹ.
"APC yọ orúkọ Shittu kúrò láti kópa nínú ìdìbò abẹ́lé "" Ìwé ẹrí tó tẹ̀lé èyí tó tayọ jù ni mo gbà, tí òun ṣì wà lára àwọn akẹ́kọ̀ọ́ tó ṣe dáadáa jùlọ"" ''Níbi ọrọ ti mo n bá àwọn ọ̀dọ́ sọ níbi ayẹyẹ ilé ìjọsìn Commonwealth of Zion,ohun ti mo sọ ni wí pé mo wà lára àwọn tó l'eke."
eto irinna ofurufu , bakan naa, eto irinna ofurufu tun le je irinse ti o le
Jibowu/Yaba flyover Bridge, Ijọba ibilẹ Ikeja Lagos Mainland 29.
"Ẹwẹ, alukoro ile isẹ ogun oju ofurufu, ọgagun Olatokunbọ Adesanya sapejuwe ija inu ofurufu naa gẹgẹ bi ""ibọn fun ikilọ, kii se fun ipaniyan."
 Òrìsà Àdáátán , ọ ̀ tọ ̀ ni .
Ẹkunrẹrẹ orukọ ọmọ naa ni Tadenikawo, Adesoji, Aderemi, Eri-Ifeoluwasimi, Adeiwa, Inioluwa, Ademide, Adegbite, Diekoloreoluwa, ọmọ Ogunwusi.
Ìdí nìyí tí mo fi sọ fun yín pé gbogbo ẹ̀ṣẹ̀ ati gbogbo ìsọ̀rọ̀ òdì ni a óo dárí rẹ̀ ji eniyan; ṣugbọn ẹni tí ó bá sọ̀rọ̀ òdì sí Ẹ̀mí Mímọ́ kò ní rí ìdáríjì.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ilẹ̀ UAE ti n fún àwọn arìnrìnàjò ní ìwé ìrìnnà ọlọ́dún márùn ún Ọwọ́ EFCC tẹ káńsẹ́lọ̀ olórí adigunjalè tó ń jí ọkọ̀ ní Kwara Fọwọ́ kan obìnrin lọ́nà àìtọ́, kí o rẹ́wọ̀n ọdún mẹ́rìnlá he- Àwọn aṣòfin yarí Ọwọ́ ọlọ́pàá ìpínlẹ̀ Oyo tẹ àwọn afurasí lórí ìpànìyàn tó wáyé ní Akinyele Bawo lo ṣe ṣẹlẹ?
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Wàhálà Boko Haram ló lé mi wá sí Eko tí mo fi di èrò abẹ́ afárá' 11) Daphne - My Lover Daphne jẹ ọkan lara awọn onkọrin ọmọ Cameroon ti Ọlọrin gab fun lọwọlọwọ ni Cameroon.
Ó wà ninu àkọsílẹ̀ pé, “Adamu, ọkunrin àkọ́kọ́ di alààyè;” ṣugbọn Adamu ìkẹyìn jẹ́ ẹ̀mí tí ó ń sọ eniyan di alààyè.
Olukọ mọkanla lo ṣi wa ni ihamọ ajinigbe.
"Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Kini Yoruba n pe ni ""pen""?"
 Àjọ kan wà tí wọ ́ n ń pè ní baluchi academy tí ó ń ń sí pé àkọsílẹ ̀ èdè yìí páye .
Àwọn ọmọ tí wọn bá gbẹ̀yìn rẹ̀,àjàkálẹ̀ àrùn ni yóo pa wọ́n,àwọn opó wọn kò sì ní ṣọ̀fọ̀ wọn.
Oni lonii jẹ, ẹ ni a bẹ lọwẹ lọrọ gbankọgbi ifẹsẹwọnsẹ Premier League toni.
" Ọmọkunrin naa to jẹ gẹri-gẹri nigba kan sọ pe ẹru ba oun diẹ lẹyin ti awọn ọlọpaa Sharia, Hisbah, ati ajọ ọlọpaa ọtẹlẹmuyẹ DSS pe e si ọọfisi wọn.
 Àwọn ẹ ̀ pọ ́ n ni à n pè ní Àwọn Àfikún .
Bakan naa ni wọn tun kede iku Ambachew Meckonnen to jẹ gomina ẹkun Amhara ati olubadamọran rẹ ti wọn ba iṣẹlẹ iditẹ-gbajọba naa rin.
Ṣaaju asiko yi ni ajọ eleto idibo Ghana ti ni awọn yoo ri pe idibo ti ko laahẹ ninu waye koda wọn tun pese nọmba ibaraẹnisọrọ tawọn eeyan le pe si ti wọn ba ri aiṣedede kankan.
Àpótí Majẹmu Ọlọrun náà wà ní ilé Obedi Edomu yìí fún oṣù mẹta, OLUWA sì bukun ilé Obedi Edomu ati gbogbo ohun tí ó ní.
Oríṣun àwòrán, Others Ẹjọ yi mu iriwisi wa ti awn eeyan si n ṣe emo bi ẹni to pe ara rẹ lẹni Ọlọrun ṣele hu iru iwa bayi.
5 owó naira ni ọọfiisi àjọ INEC ni Zamfara Ǹkan mẹ́jọ tó máa kọ́kọ́ ṣẹlẹ̀ kí olólùfẹ́ méjì tó pa ara wọn Dokita àti Nọ́ọ̀sì fìyà jẹ mí lásìkò tí mò ń rọbí- Alaboyún Kini Okorocha sọ lori awọn sẹnetọ?
Wọn lawọn ri fọnran fidio kan lori ẹrọ alagbeka ọkọ rẹ nibi ti o ti jẹwọ wi pe oun loun pa iyawo rẹ.
Awọn ti ọrọ kan ti wa wọrọko fi ṣada ni bi wọn ṣe gbe igbesẹ lati ṣe ipade naa lori itakun agbaye dipo ki wọn ṣe loju koju.
Ṣé lóòtọ́ ni Ọọ̀ni ilé ifẹ̀ ti parí aáwọ̀ lọ́balọ́ba l'Ékìtì?
Orile-ede Amerika ti yan akonimoogba iko Columbus Crew teleri, Gregg Berhalter gege bi akonimoogba tuntun fun iko agbaboolu orile-ede naa.
Mo gbọ́ ohun tí àwọn wolii tí wọn ń fi orúkọ mi sọ àsọtẹ́lẹ̀ èké ń sọ, tí wọn ń sọ pé, àwọn lá àlá, àwọn lá àlá!
'A sinmi ìwádìí lóri Kemi Adeosun' Kíni àmúyẹ àyẹ̀wò fún ipò lórílẹ̀-èdè Nàìjíríà?
Ọlọ́pàá Ogun gb'ọmọ Ìmáàmù lọ́wọ́ ajínigbé, ṣùgbọ́n wọ́n gbé ọkọ̀ ojú omi ọlọ́pàá lọ Wo àwọn eléré ìdárayá mẹ́ta tí àjọ FIFA ti fòfin dè títí ayé Yàtọ̀ sí Ọ̀ṣun Òṣogbo, Ṣàǹgó pẹ̀lú a máa ní arugbá lóde Ọ̀yọ̀ Ìpínlẹ̀ Ọ̀ṣun kéde ìsinmi lẹ́nú iṣẹ́ nítorí ọdún Ìṣẹ̀ṣe Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Idahun si eyi wa ninu atẹjade kan eleyii ti ileeṣẹ ijọba apapọ to n ri si idiyele owo epo rọbi lorilẹede Naijiria, (PPPRA) tẹ jade ni Ọgbọn ọjọ, oṣu kẹta ọdun 2020 Ṣugbọn ti o bọ si gbangba iwoju araalu ni ọjọ kẹrin, oṣu karunun, ọdun 2020 yii kan naa eleyii ti wọn pe akọle rẹ ni Ofin lilo idunadura oju ọja epo lati fi diyele epo bẹntiro t'ọdun 2020""."
Eyi waye lẹyin ti awọn alatako rẹ bi i Joseph Tegbe, ti awọn kan gbagbọ pe oun ni ẹni ami ororo Gomina Abiọla Ajimọbi, ati awọn oludije mi i finu-findọ jawọ ninu eto idibo naa, ayafi Amofin Adeniyi Akintọla to ni dandan ni ki wọn jẹ ki eto idibo waye fun gbogbo oludije.
Bàbá mi náà si tún dá a lóhùn ó ní, N kò dé Igbó Olódùmarè ri ṣùgbọ́n mo gbúròó Igbó Olódùmarè rí.
Ninu ọrọ asọtẹlẹ rẹ fun ọdun 2019, o ni idaamu ati iṣoro nlanla lo wa lọna fun orilẹ-ede Naijiria ni ọdun 2019.
Ẹ má wá fún ìwòsàn ní Ọjọ́ Ìsinmi mọ́!
Operation Amotẹkun: Ẹ̀ṣọ́ ilẹ̀ Yorùbá 'Àmọ̀tẹ́kùn' ṣetán láti bẹ̀rẹ̀ iṣẹ́ káàkiri ilẹ̀ káàrọ́ọ̀ oò jíire
Tẹ àwọn tí ó fẹ́ràn owó mọ́lẹ̀;fọ́n àwọn orílẹ̀-èdè tí ó fẹ́ràn ogun ká.
 Ìrètí ni pé lhc yíò wá ìdáhùn is expected to address some of the ọ ̀ pọ ̀ àwọn ìbérè inú físíksì , nípa èyí láti mú ìlọsíwájú bá òye àwọn òfin àdánidá jínjnlẹ ̀ .
N kò ní sọ yín di ẹni ẹ̀gàn láàrin àwọn orílẹ̀-èdè yòókù mọ́.
Nítorí náà, ìṣẹ́gun ọjọ́ náà pada di ìbànújẹ́ fún gbogbo àwọn eniyan; nítorí wọ́n gbọ́ pé ọba ń ṣọ̀fọ̀ ọmọ rẹ̀.
Ṣugbọn nígbà tí ó gbọ́ gbogbo ohun tí Josẹfu wí fún wọn, tí ó tún rí kẹ̀kẹ́ ẹlẹ́ṣin tí Josẹfu fi ranṣẹ pé kí wọ́n fi gbé òun wá, ara rẹ̀ wálẹ̀.
Iroyin gbe e pe, arabinrin Alokha ku lẹyin to doola ẹmi awọn akẹẹkọ ileewe naa lasiko ti ibugbamu waye ladugbo Festac nilu Eko.
Bàbá ni Ìmọ́lẹ̀ jẹ́ fún mi ṣùgbọ́n ìyá mi ni òkùnkùn.
Ọgbọn ọdun to lo lori alefa wa sopin lọdun 2011 nigba ti wahala nla kan ṣẹlẹ to si ko o ni papa mra kuro lori itẹ.
"athan Sharibu - BBC News Yorùbá BBC News, YorùbáFò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Leah Sharibu: Mo gbàgbọ́ pé ọmọ mi ṣì wà láàyè - Nathan Sharibu 26 Agẹmo 2019 Oríṣun àwòrán, OTHER Àkọlé àwòrán, Leah Sharibu ""O da mi loju pe ọmọ mi ko ku, o ṣi wa laaye""."
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Wo bí Sunday Orimola ṣe gba ikú ẹranko kú ní Ifon ni Ondo lórí ọ̀nà àtijẹ Atẹjade naa tun fi kun un pe isinmi ranpẹ miran yoo tun waye bẹrẹ lati ọjọ kẹrinlelogun, oṣu kejila nitori pọpọṣinṣin ọdun ti yoo maa waye nigba naa.
Oloye Lai Mohammed to je minista fun ifitonileti, asa ati irin ajo afe fun Naijiria lo gbe atejade naa sita leyin to ti saaju iko ijoba apapo lo sabewo si Dapchi leemeji leyin ti oro naa ti sele.
3 543 Antigua and Barbuda 6 6.
Wọn si tun fun wọn ni alupupu ọfẹ.
Pẹlu idunnu ọkan ni Madam Saje fi sọ wi pe, awọn fẹran Dagunro, amọ Ọlọrun fẹran rẹ ju awọn lọ.
Okùn igi ńlá kan ni ó fi ṣe ìgbànú tí ó sán mọ́ ara rẹ̀ ni ẹ̀gbẹ́ bẹ́ẹ̀ ni irun orí rẹ̀ kún tí ó dà bí irun orí aṣiwèrè tí oríṣiríṣi ìpàǹtí sì kún ibẹ̀ kítikìti.
Ibi tí àwọn èkúté náà ti ń sọ báyìí ọkùnrin náà bú si ẹ̀rin, ṣùgbọ́n ó fẹ́rẹ́ má ì tí ì parí ẹ̀rín rẹ̀ tán tí ìyàwó burúkú yìí ti ta pẹẹrẹ wọlé tí ó bẹ̀rẹ̀ sí kígbe ńlá tí ó ń pariwo wí pé òun nni ọkùnrin yìífi ń ṣe yẹ̀yyẹ̀.
Nínú ọ̀rọ̀ tirẹ̀ Agbénusọ ọlọpàá ìpinlẹ̀ Eko DSP Bala Elkana sọ pé àwọn yóò gbé afurasí náà lo si ẹka to n ṣe iwadii ọdaran fún itẹsiwáju ìwádìí.
ati ise akanse lorile ede Naijiria, Udo Udoma n soju fun aare Muhammadu Buhari
Awọn aworan mẹta ọhun di awati lẹyin iku rẹ lọdun 1994.
OLUWA sì lé gbogbo àwọn orílẹ̀-èdè náà kúrò níwájú wa ati àwọn ará Amori tí wọn ń gbé ilẹ̀ náà tẹ́lẹ̀.
O tẹ̀síwájú pé ìdá marun-un nínú ọgọrùn ní ìjọba yóò ní nínú ilé iṣẹ ọkọ òfurufú náà àti pé ìjọba yóò yọwọ kúrò nínú iṣẹ àkóso ọkọ òfurufú náà.
 Ninu orin, ninu iyin, ohun ni Paul ati Selia fi ri itusilẹ ninu ọgba ẹwọn.
"Oríṣun àwòrán, @doubleblessin ""Eeyan pataki to gbe Naijiria de ipo giga, to si mu agbega ba eto aabo ati oju ti awujọ agbaye fi n wo Naijiria, lo wa di ẹni ti awọn eeyan kan n fi ẹnu saata rẹ, sugbọn awọn eeyan to pin owo ti Abacha fi silẹ si wa laye lai si ẹni to fi ọwọ kan wọn."
 agígírì rìn díẹ ̀ síwájú kí ó tó dúró .
Olódùmarè ló pa á láṣẹ fún òbìrìkìtì ayé kó máa yí oòrùn po láìdúró.
Aarẹ Muhammadu Buhari ti ransẹ ayọ sawọn oludije ọmọ ilẹ Naijiria nibi idije ere idaraya olimpiiki ori yinyin, Winter olympics to bẹrẹ lọjọ ẹti nilu Pyeong Chang, lorilẹede South Korea.
''Ẹgbẹ oṣelu APC lawọn to to gba NURTW ipinlẹ Oyo tẹ le, wọn o si ke si mi nigba ti wọn lo ọdun mẹjọ ti wọn naa lasiko ti APC wa ni ijọba,'' Auxiliary lo ṣalaye bẹẹ.
O se afikun ọrọ wipe ile iṣẹ redio naa yoo duro de idajo ile ẹjọ lori ọrọ ọhun.
Water Generator: Ó leè ṣiṣẹ fún wákàtí mẹfà, kó tó sinmi
Gbogbo ẹ, ati kikọ ati aaye ko gbudọ ju aaye alifabẹti mejindinlọgbọn lọ (38 characters) bẹẹ si ni aaye gbudọ wa laarin ọrọ meji.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Lagos State Task Force: Lóòótọ́, a tí mú Ọlọ́páà to f'ọ̀nà ẹ̀bùrú gba owó ẹ̀yìn N100k lọ́wọ́ awakọ̀ 23 Bélú 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 24 Bélú 2020 Oríṣun àwòrán, TWITTER/Taskforce112 Ọwọ palaba ọga ọlọpaa kan ti ṣegi lẹyin to gba owo abẹtẹlẹ ẹgbẹrun lọna ọgọrun Naira lọwọ awakọ to tapa sofin oju popo nilu Eko.
Adeagbo ni ọmọ orilẹẹde Nigeria ti yoo kọkọ kopa ninu idije ti wọn pẹ ni ‘’skeleton’   Ẹ le ka nipa rẹ si nibi Connor Wilson Ọjọ ori: Mọkanlẹlogun Orilẹẹde: South Africa  Ere idaraya: Alpine skiing Connor Wilson kẹko gboye nipa itọju ẹranko ni ile ẹko fasity Vermont ni orilẹẹde Amerika.
Bákàn náà ni, wọ́n ní àwọn ń fẹ́ ki ìwé ìròyìn SUN UK tọrọ àforíjí nítori pe wọ́n kò gbọ́ ìhà ti Khafi, ki wọ́n tó gbé ìròyìn náà jáde.
Toyin jẹ ọkan lara awọn wọ kilu o mọ akọkọ ti yo mẹnu le ọrọ lori arun yii.
Níbo ni wọ́n wà kí wọ́n sọ fún ọ,kí wọ́n sì fi ohun tí OLUWA àwọn ọmọ ogun pinnu láti ṣe sí Ijipti hàn ọ́.
Mó ń tọrọ pẹ̀lú ìrẹ̀lẹ̀ lónìí, pé kí ó ṣe dídǹ inú Rẹ, ki emi le da bi àwọn wọ̀n-ọnnì ti wọ́n wá si inu ayé tí wwọ́n si da bi oṣupa ti ń ṣoore fún àtọmọdọ́mọ.
Àwọn ọkunrin kan, ará Sifi lọ sọ fún Saulu ní Gibea pé, “Dafidi farapamọ́ sí òkè Hakila tí ó wà ní apá ìlà oòrùn Jeṣimoni.
Ẹ wo bí ìsìnkú Adegbenro, Kọmíṣọ́nnà l‘Ondo ṣe lọ.
Kos i ẹni ti ọrọ naa ye boya iku coronavirus lo pa Aramide naa abi bẹẹ kọ.
OLUWA àwọn ọmọ ogun nìkan ni kí o kà sí mímọ́, òun ni kí ẹ̀rù rẹ̀ máa bà ọ́.
Ẹ yin OLUWA, Ọlọrun wa,kí ẹ sì jọ́sìn níbi òkè mímọ́ rẹ̀;nítorí pé mímọ́ ni OLUWA Ọlọrun wa.
Beckham yii, lo n sọrọ ninu fidio ranpẹ naa, ni wọn lo imọ ẹrọ igbalode fun, to si n sọ ede Swahili, Kinyarwanda, Arabic, Yoruba, Faranse, Spanish, Hindi, mandarin àti bẹ́ẹ̀ bẹ́ẹ̀ lọ.
Daniel gba lati wa a lọ sile; o si ṣeleri pe iya oun yoo mu oun wa.
Jẹ́ kí ojú tì wọ́n, kí ìdààmú dé bá wọn títí lae,kí wọn sì ṣègbé ninu ìtìjú.
O ni ṣugbọn aṣẹ yii ko ye awọn eniyan to ni.
Kọmiṣọnna fun Eto Ilẹra ni ipinlẹ naa, Mojisola Yaya-Kolade to fi idi iroyin yii mulẹ ni wọn n gba iwosan ni ileewosan ẹkọsẹ ti ijọba apapọ to wa ni Ido-Ekiti.
Lara awọn ounjẹ yii la ti ri eso Carrot, ewe Lettuce, eso Cucumber ati Avocado pear eyi ti wọn ni eroja asaloore ti wọn n pọ sinu agọ ara wa kii se kekere ta ba jẹ wọn.
Awọn agbebọn ti pa mọlẹbi rẹ kan; wọn si tun ti ji orogun iya rẹ kan gbe lọ lasiko ti wọn kọlu ilu rẹ nipinlẹ Adamawa lọjọ satide.
Gẹgẹ bi Dokita Sheila Poddar to ṣe iṣẹ abẹ fun ṣe sọ, o ni iyalẹnu nla ni ọrọ obinrin naa jẹ fun awọn nileewosan.
Samuel Ladoke Akintọla jẹ́ Agbẹjọ́rò àti Akọ̀ròyìn tí ọ̀rọ̀ dá lẹ́nu rẹ̀ Hubert Ogunde rèé, baba àwọn òsèré tíátà Ìyàtọ̀ wà nínú ìlépa àwọn òṣèré tíátà ayé àtijọ́ àti ìsisìnyí-Papalolo Tẹ̀gbọ́n-tàbúrò gé orí ọmọ aládùúgbò torí ₦200,000 owó ìkómọ Akọsilẹ oju opo Wikipedia ni a lo, lati se akojọpọ itan nipa igbe aye Ẹfunsetan Aniwura yii.
Nítorí mo mọ̀ pé alágídí ni yín,olóríkunkun sì ni yín pẹlu.
oríṣiríṣi ibi ni wọ ́ n rò wípé òwe yìí ti jẹyọ .
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Kwesi gbòmìnira lọ́wọ́ ọlọ́pàá lẹ́yìn ìfọ̀rọ̀wánilẹ́nùwò 25 Èbibi 2018 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ohun tó ṣẹlẹ̀ ní Ghana yíì tí kóbá ẹgbẹ́ àgbábọ́ọ̀lù ibẹ̀ láti rí onígbọ̀wọ̀ fún eré bọ́ọ̀lú Wọ́n ti kìlọ̀ ìṣọ́ra fún ààrẹ ẹgbẹ́ agbábọ́ọ̀lù orílẹ̀-èdè Ghana àti igbákejì àjọ CAF, Kwesi Nyantekyi Bákan náà ní wọn ti gba ìdúró rẹ̀ lẹ́yìn tí wọn ṣe ìfọ̀rọ̀wánilẹ́nùwò fún un tán lóri lílo ọ̀nà àlùmọ̀kọrọ́yí lu jìbìtì.
Nitori pe mo jẹ gbajumọ, dandan ni fun mi lati jẹ awokọṣe ninu iwa, iṣe ati irin mi.
OLUWA sọ fún Mose ní ọjọ́ náà gan-an pé, 
Ẹni ti gbogbo aye n bọ̀wọ̀ fun ni Obasanjo nitori awọn nkan to ṣe nigba to fi jẹ aarẹ ológun, ati alagbada.
Awọn Iroyin mii ti ẹ le nifẹ sii Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Kayeefi: Facebook ni Wolii Arole Jesu fi tàn an wọ agbo, orí rẹ̀ ni wọ́n fi s'owó Gbogbo igbiyanju BBC lati kan si awọn ile iṣẹ aarẹ ko fi bẹẹ́ bimọ ire ayafi Bashir Ahmad to jẹ oluranlọwọ pataki fun aarẹ ni ko si ohun to jọ bẹẹ o.
Òjò rọ̀; àgbàrá dé, ẹ̀fúùfù sì kọlu ilé náà; ṣugbọn kò wó, nítorí ìpìlẹ̀ rẹ̀ wà lórí àpáta.
Amọ agbebọn naa ko ye e tori awọn ọlọpaa naa doju ibọn kọ lẹyin to ṣina ibọn tirẹ bolẹ.
Àìsàn tí kò tó nkan ní í ránni lọ s'álákeji.
Oloogbe Ọṣuntoun funrarẹ naa gbe awọn ere kan jade bii 'Omi Ipin,' 'Imi Esin' ati 'Ogun Omo Iya le', to jẹ ere ti o ṣe gbẹyin, gẹgẹ bi ọgbẹni Adedokun ṣe sọ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo Éníyán la n pe awọn ìyà mi, ènìyàn ni a n pe ọmọ ènìyàn.
Lẹ́yìn wọn, Sadoku, ọmọ Imeri, ṣe àtúnṣe ibi tí ó kọjú sí ilé tirẹ̀.
Ẹ̀gún ti hù níbi gbogbo,igbó ti bo gbogbo rẹ̀ mọ́lẹ̀,ọgbà tí ó fi òkúta ṣe yí i ká sì ti wó.
Kò sí ọba ní ilẹ̀ Israẹli ní gbogbo àkókò náà, olukuluku bá bẹ̀rẹ̀ sí ṣe bí ó ti tọ́ ní ojú ara rẹ̀.
Bí mo ṣe ń dàgbà ni ǹkan ọmọkùnrin mi ń tóbi síi àmọ́ obìnrin ni mi' Ìdájọ́ ẹ̀wòn gbére kò ní kí Wòlíì Sotitobire má lọ sí ilèẹjọ́ kòtẹ́milọ́rùn - Agbẹjọ́rò Pásítọ̀ Alfa Babatunde Agbẹjọro to n ti n gba waju gba ẹyin fun Pasitọ Alfa Babatunde ti ijọ Sotitobire Praising Chapel, Akinyemi Omoware ti ṣalaye ọrọ fun araye gbọ pe onibara oun ṣi lanfani ati gbà ile ẹjọ kotẹmilọrun lọ lẹyin idajọ.
" "" Ó sì tún ṣiṣẹ ́ ní star 101."
Ìwọ yóo rí ohun tí ó jù yìí lọ.
O ṣalaye pe ọkọ ojuurin ti ilu Eko si Ibadan ti ijọba Muhammadu Buhari fẹ ṣi gan an, ẹgbẹ PDP naa lo bẹrẹ rẹ.
Ààrẹ Buhari kí Akeredolu kú orííré bí ó ṣe jáwé olúborí nínú ìdìbò sípò gómínà Akeredolu ti mókè nínú ìbò gómìnà níjọba ìbílẹ̀ méjìlá l‘Ondo, PDP gba mẹ́ta Bí èsì ìdìbò gómìnà ìpínlẹ̀ Ondo se ń jáde rèé.
Ọrọ naa fẹ ṣe bi ẹni lọ to si ti di bíi ere tiatia nile igbimọ aṣofin gẹgẹ bi Ovie Omo-Agege ati Ike Ekweremadu ṣe jọ n waa ko lati dori aga igbakeji aarẹ ile igbimọ aṣofin kẹsan Igbakeji aarẹ ile aṣofin agba ikẹjọ ni Ike Ekweremadu.
Ọgbọ́n rẹ̀ jinlẹ̀,agbára rẹ̀ sì pọ̀.
Adajọ Kurada wa sun igbẹjọ naa si Ọjọ Karundinlọgbọn, Osu Kẹta ,ọdun 2019.
Ọga ajọ naa ni iwo oorun Guusu to n mojuto awọn ilẹ kaarọ ojiire eleyi ti Ibadan wa labẹ wọn Slakku Luggard lo sọrọ yi fun BBC.
Ohun tí Ìwé Mímọ́ sọ ni pé, “Abrahamu gba Ọlọrun gbọ́, Ọlọrun sì kà á sí ẹni rere.
Ohun to bẹrẹ gẹgẹ bi iwọde awọn ọmọogun lowurọ oni ṣe kẹrẹkẹrẹ di iditẹgbajọba.
Ìpínlẹ̀ Osun kéde ọjọ́ táwọn iléèwé yóò ṣí padà Máa gbé kẹ̀kẹ́ rẹ lọ, àwọn akọròyìn kọ̀ ìpàkọ́ sí Femi Fani Kayọde Èèyàn mẹ́tàlélógóje míì ṣẹ̀ṣẹ̀ kó COVID-19 ní Nàìjíríà Ọkùnrin kan di èrò ọ̀run nítorí pé o fi ẹ̀sùn kan alájọgbélé rẹ̀ pé o n yan ìyàwó ẹnìkan lálè Wo àwọn orílẹ́-èdè mẹ́wàá tí kò ní coronavirus lágbàáyé, bá wo ni wọ́n ṣe ṣe é?
Pópóọlá tí ó jẹ́ ọlọ́pàá ni ó pàṣẹ pé kí wọn dá ọwọ́ ìjà dúró tí wọ́n sì ṣe bẹ́ẹ̀.
Kí ó fi ìfarabalẹ̀ bá àwọn tí ó bá lòdì sí i wí, bóyá Ọlọrun lè fún wọn ní ọkàn ìrònúpìwàdà, kí wọ́n lè ní ìmọ̀ òtítọ́, 
Bi ẹrọ to lee tu iyẹ lara adiyẹ ṣe wa de'lẹ latọwọ Akanbi, aramanda ni.
Gomina wa ro  awon osise ti won ba ko firi awon eniyan kan
Ọgbẹ́ ati àbùkù ni yóo gbà,ìtìjú rẹ̀ kò sì ní kúrò lára rẹ̀ laelae.
"Oríṣun àwòrán, @Austynzogs Baba Suwe ni ""n ko tii ni iyawo miran tabi ọrẹbinrin kankan rara lẹyin iku Moladun aya mi titi di akoko yii, kii si ṣe pe o wu emi naa lati da duro."
Àwọn ará Amoni jáde sí àwọn ọmọ ogun Israẹli, wọ́n tò sí ẹnubodè wọn ní Raba, tíí ṣe olú ìlú wọn.
Wọ́n bá tọ alabojuto ilé Josẹfu lọ lẹ́nu ọ̀nà, 
“Ó tó àkókò fún mi, láti lọ sí ibi tí àgbà ń rè.
Bí o bá́ gbójú lé wọn, o tẹ́ tán ni mo sọ fún ọ
Awọn igi elewe tutu ati ẹwa didara ti o yii ka kii jẹ ki ẹni to ba wa ni ibi orisun omi Olumirin o mọ ala pe oorun n mu rara.
"Bákan náà ni ẹni tó sún mọ́ ọkọ olóògbé náà fìdi ìṣẹ̀lẹ̀ aburu náà múlẹ̀ fún ìwé ìròyìn ""The Nation"", sùgbọ́n kò sọ bóyá o ti ṣe àìsàn tẹ́lẹ̀."
Ko si fẹ ẹ si akọsilẹ nipa ọdun to di iyawo Aarẹ Buhrai, ṣugbọn awọn kan sọ pe ni nkan bi ọdun 1930 ni.
Santes nikan kọ lo jin si panpẹ ofin owo ori Sanches yi si jẹ ọkan lara awọn gbajugbaja agbabọọlu to ti ko si panpẹofin owo ori lorilẹede Spain.
Dá mi láre, OLUWA, Ọlọrun mi, gẹ́gẹ́ bí òdodo rẹ;má sì jẹ́ kí wọ́n yọ̀ mí!
Lẹyin naa ni Eniola lọ si ile iwe girama tawọn ologun ni Epe kan naa.
#ShoMoAgeMiNi# Àṣà tó ń dá ìgboro rú 'Obinrin lo mu mi fẹran orin kikọ' Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí kan sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
Ajọ to n risi ajakalẹ arun lorilẹede Naijiria, NCDC ti fi lede wi pe awọn to tii fi idi ẹ mulẹ pe oogun Dexamethasaone n ṣiṣẹ fun arun Coronavirus.
" Oríṣun àwòrán, @JAMB Àkọlé àwòrán, Iroyin fidirẹmulẹ pe ejo ajoji kan mi miliọnu mẹrindinlogoji naira lọọfisi ajọ JAMB Ìròyin fi idi rẹ mulẹ pe Chieshe sàlàyé pé ejo ajoji kan deede wọ inu ọọfisi ti ajọ JAMB n ko owo si, to si ko miliọnu mẹrindinlogoji naira lọ.
Síṣé àfilọlẹ̀ pápákọ̀ òfurufu Eko, Kano, Maiduguri, ati Enugu lọ́dun yìí (2020) Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Mí ò ya wèrè, mí ò burú, ọ̀nà àtijẹ là ń wá' Síṣe àfilọ́lẹ̀ lílo ẹrọ fun iṣẹ́ ọ̀gbìn nigbèríko, èyí ti yoo kalekako àwọn ìjọba ìbílẹ̀ ẹẹdẹgbẹrin (700) láàrin ọdun mẹ́ta Ààrẹ ni ìjọba òun yóò dáwọlé sísé ojú irin Ibadan-Abjua -Kano- Kaduna láarin osù mẹ́ta àkókó ọdun yìí.
Àwọn ará Filistia ti dé sí àfonífojì Refaimu, wọ́n bẹ̀rẹ̀ sí gbógun ti àwọn ìlú tí ó wà níbẹ̀, wọ́n sì ń kó wọn lẹ́rú.
Children's Day: Àwọn ọmọdé tó ń ṣe bẹbẹ láwùjọ Afíríkà Wo òtítọ́ nípa oúnjẹ Nódùùlù táwọn ọmọde ma ń jẹ Fayemi fojú Alufa to fipa bá ọmọde lòpọ̀ síta l'Ekiti Kíni ìjọba ń ṣe lórí ewu ẹkọ Almajiri àti covid 19 ní Nàìjíríà?
Ṣùgbọ́n Ọlọ́run tó ṣe tàná ni yóò tún ṣe tòní.
Alaga ẹgbẹ awọn onisegun oyinbo (NMA) nipinlẹ Ọsun, Dokita Tokunbọ Ọlajumọkẹ lo salaye ọrọ yii lasiko tawọn dokita onisegun oyinbo lọ kaakiri lati seto itaniji fawọn araalu kaakiri awọn ọja to wa ni ilu Osogbo.
Wọn ti ṣe e si fiimu agbelewo lọdun 1997, lati ọwọ ileeṣẹ MainFrame eyi ti Tunde Kelani dari rẹ to si ti di awogbadun sinima.
Oríṣun àwòrán, @tundefashola Ninu ọrọ tirẹ minisita fun iṣẹ ode ati ilegbe, ọgbẹni Babatunde Fashola ni ki awọn ọmọ Naijiria kọju si ijọba ipinlẹ ati ibilẹ, fun ọna abayọ si isoro wọn, kaka ti wọn yoo fi maa di gbogbo rẹ le ijọba apapọ lọrun.
Bó tilẹ̀ jẹ́ pé àwọn kan ní ìhà ìwọ̀-òòrun rí i pé ìtẹ̀síwájú ni èyí jẹ́ fún òbìnrín Saudi, síbẹ̀ àwùjọ àwọn musùlùmí kan nínú àtí lẹ́yìn odi Saudi rí i gẹ́gẹ́ bi ǹkan ti ko tọ̀nà.
Magu,'estimated billing' àti àwọn ohun míràn tí ilé aṣòfin Nàìjíríà kò rí yanjú Ààrẹ Abdulaziz Bouteflika ti kowe fipo silẹ Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Okei-Odumakin: Awọn obinrin Naijiria nilo ajọ iranwọ fun oṣelu'8 Ẹrẹ̀nà 2018 1:40 Fídíò, Wo imọran Fọlọrunṣọ Alakija fun awọn ọdọ adulawọ, Duration 1,409 Ẹrẹ̀nà 2018 Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí kan sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Mistura Oseni Akintunde: Ara múmú kìí ṣe oríṣun ìfipábánilòpọ̀, ìran àwòjù ló ń fà á Idi ree ti BBC Yoruba fi tọ awọn onisẹse lọ lati mọ boya wọn nigbagbọ ninu ọrọ dokita yii, bi ko ba si ri bẹẹ, ki lo n fa ki ololufẹ meji lẹpọ lasiko ere ifẹ, ninu igbagbọ awọn baba wa.
“Òṣùnwọ̀n eefa ati ti bati tí ó péye ni kí ẹ máa lò.
Ẹlẹ́wọ̀n 44 kú sọ́gbà ẹ̀wọ̀n nítorí ooru tó mú púpọ̀ Àwọ̀ ojú pọ̀ bíi àwọ̀ òṣùmàrè, àmọ́ ojú búlúù Risikat kò nílò àtúnṣe- Dókítà Feyi Wo àwọn iléèwé gíga tó ti bẹ̀rẹ̀ sí ní ta fọ́ọ̀mù JAMB post UTME screening ní Naijiria Ìdí rèé tí a ṣe fẹ́ sin Majek Fashek sílẹ̀ Amerika- Randy Fashek Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Alaafin: Olori Aanu Adeyemi ṣàlàyé ìdí tó ṣe gẹ́ Oba Lamidi Adeyemi ti ìlú Oyo Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ọjọgbọn Akinwunmi Ishola pa'poda lẹyin ọdun mọkandinlọgọrin 17 Èrèlè 2018 Oríṣun àwòrán, @MobilePunch Àkọlé àwòrán, Oloogbe Ishọla lo kọ iwe Ẹfunsetan Aniwura Ọjọgbọn Akinwunmi Ishola ti d'oloogbe, ọmọdun mọkandinlọgọrin ni wọn.
Flora, lasiko to n ba BBC Yoruba sọrọ ni oun ti sa gbogbo ipa oun lati wa ibi ti ọkọ rẹ wa, ti o si fi to gbogbo awọn ẹsọ alaabo to wa ni Naijiria leti.
Sáájú ìdìbò náà ní ààrẹ Muhammadu Buhari ti rán àwọn asojú ìjọba àpapọ̀ lọ láti lọ gbárùkù tí Muhammadu Bande.
Tabi ta ni mo ni lára rí?
Wọn tun ni ọpọ ẹlẹwọn ni ebi n pa ni Chad ti wọn ko si tun ri omi to mọ geere mu.
Àyè àti ni owó ojiji nipa ifi owó epo-rọ̀bì ṣòfò, ki kó owó ìpèsè ohun amáyédẹrùn jẹ, gbi gba àbẹ̀tẹ́lẹ̀ àti iwà ìbàjẹ́, ló pa ilé-iwé giga, ilé-ìwòsàn, pàtàki ìpèsè iná-mọ̀nàmọ́ná, ìdájọ́ àti bẹ ẹ bẹ lọ.
Oríṣun àwòrán, @FedfireC Agbẹnusọ ileeṣẹ panapana to wa ni ilu Osogbo, Adijat Basiri, sọ fun awọn akọroyin pe, ni kete ti awọn ara ilu fi ọrọ naa to wọn leti ni awọn oṣiṣẹ ileeṣẹ ọhun lọ sojuko naa ti wọn si pa ina ọhun.
Ẹ wo òtítọ́ ọ̀rọ̀ nàá Ó pé ọdún mẹ́wàá tí Barrister kú; wo ǹkan tó yẹ láti mọ̀ nípa rẹ̀ gẹ́gẹ́ bíi olórin, tẹ̀wé-tẹ̀wé, akọ̀wé àti sọ́jà Wọ́n ti dí ọ̀pá afẹ́fẹ́ gáàsì tó bẹ́ lópópónà márosẹ̀ Ibadan sí Eko pa Jide Kosoko forin sẹ́nu sọ pé òun ni igi lẹ́yìn ọgbà Mr Latin lórí ipò ààrẹ TAMPAN tó wà Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsèjẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọ Lara awọn to doju ija kọ ijọba Jonathan ni idibo ọdun 2015 ni Melaye wa to si polongo takuntakun lati tako Aarẹ ana naa ati awọn igbesẹ ti ijọba rẹ gbe paapa julọ nipa aabo ati eto ọrọ aje.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù June 12: Ìtàn bí Alhaja Kudirat Abiola ṣe dojúkọ ohun t'ọ́kùnrin kò leè dojúkọ fún ìjọba àwaarawa 12 Òkùdu 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 13 Òkùdu 2020 Oríṣun àwòrán, @EiENigeria Àkọlé àwòrán, Kudirat Abiola (1951 - 1996) Ajafun ijọba awa ara wa, ọmọ Naijiria ni Kudirat Abiola.
Ìgbáradì yóò gbérasọ ní ìpínlẹ̀ Ekiti lọ́jọ́ Àìkú tó ń bọ̀ Adà ní bàbá mí yọ sí mí nígbà tí mo ní mò fẹ̀ máà kọrin-Popular Jingo Èèyàn 111 ní àrùn Coronavirus tún ṣẹ̀ṣẹ̀ ràn ní Nàìjíríà ní Ọjọ́ọ̀rú Ìtumọ̀ àbàdòfin lórí omi tí ìjọba tẹramọ́ tó n bí àwọn ọmọ Nàìjíríà nínú rèé Mo ti ṣe afikun ilu marun miran kun ilu meji to n jẹ anfaani eto itọju tiya-tomo, ti inu ọpọ eeyan si dun sì.
Coronavirus prevention tips: Ọ̀nà àbáyọ fún olóyún lásìkò àjàkálẹ̀ ààrùn Covid-19
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, BIAFRA at 50: Ìhàlẹ̀ ológun ni Gowon ni ká kọ́kọ́ fi bẹ̀rẹ̀- Aladejẹbi Kuti fikun pe ti yoo ba fi di idaji osu Keji shun 2020, o seese ki awọn isẹ atunse oju ọna Ibadan si Eko ti buse ki ojo too bẹrẹ.
Àwọn ọ̀rọ̀ iko rira wọnyi lòdi si àwọn obinrin, ẹ̀yà miran ti ó yàtọ̀ si ẹ̀yà rẹ, àlejò, ẹlẹ́sin Mùsùlùmi àti bẹ́ ẹ̀ bẹ́ ẹ̀ lọ.
Awọn to fara kaasa iku ninu ijamba naa jẹ awọn ero inu agba ikẹrusi taa mọ si container, to dabi ọkọ akẹru naa.
Eji Gbadero, ọmọ Ibadan àti jayé-jayé ọmọ ónílẹ̀ ti wọn yẹgi fun l'Eko Lisabi Agbongbo Akala rèé, ẹni tó fi ìfẹ́, ìṣọ̀kan àti ìrẹ́pọ̀ gba ilẹ̀ Ẹ̀gbá lọ́wọ́ ìmúnisìn A jọ ṣe ìyàwó pọ̀, a jọ bímọ ní ọjọ́ kan náà, a tún jọ máa ń ṣàìsàn pọ̀ ni Ìyàwó mi fẹ́ràn ìrìnàjò òfurufú ni mo ṣe kọ́ ilé Bàálù yìí fún un Omi ìṣẹ̀ńbáyé tó ń dà ní Ówù rèé, èyí tó ga jùlọ ní Afirika Adu ni awọn orilẹede yoku ni iwọ oorun Afirika wa ọna lati gbe awọn asoju wọn nibi idije naa amọ Naijria ko tiẹ ranti oun, tawọn mẹta yoku ti wọn jọ soju Naijiria si ti pada sile.
Déédéé aago mẹ́jọ alẹ ọjọ́ Satide, ni àwọn agbebọn náà jí àwọn ìbejì ọhun, tí wọn jẹ takọtabo, gbé lọ nínú ilé Akeugbagold tó wà ládùúgbò Ọjọọ n'ilu Ibadan.
Àkọlé àwòrán, Iwe naa da lorii orukọ ti gbogbo ẹya ara kọọkan ti eeyan ati ẹranko n jẹ lede Yoruba pọnbele Àkọlé àwòrán, Afojusun awọn ọjọgbọn naa ni lati tẹsiwaju ninu itumọ ede fun igbayegbadun gbogbo akẹkọ Àkọlé àwòrán, Igbagbọ awọn ọjọgbọn ni wi pe ko tọ ki a maa fi ede gẹẹsi kọ ogidi ọmọ Yoruba ni eto ẹkọ, paapaa julọ awọn to n kẹkọ lẹka imọ iṣegun oyinbo Àkọlé àwòrán, Opolopo ogidi omo Yoruba lo ti n fi idunnu won han lori iwe tuntun to jade lati odo awon agba ti ko fe je ki ede Yoruba parun.
Ọgọọrọ awọn to n ṣe ajọyọ lo kun ojude ilu.
Gẹ́gẹ́ bí ó ti jẹ́ pé ẹ kò ì tíì mọ̀ wá dáradára, ẹ óo rí i pé a óo jẹ́ ohun ìṣògo fun yín gẹ́gẹ́ bí ẹ̀yin náà yóo ti jẹ́ fún wa ní ọjọ́ tí Oluwa wa, Jesu, bá dé.
Ṣugbọn àwọn mìíràn ń sọ pé Elija ni ó fara hàn.
Oríṣun àwòrán, Omoyele Sowore Àwọn àwòrán ẹ̀yìn ìtàgé níbi ìpàdé ìfọ̀rọ̀wérọ̀ BBC Yorùbá l'Eko Link Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Falana: Awọn to n dije dupo ìdìbò 2019 fẹ́ fa ogun si Naijiria Ki wa ni Sowore n sọ to le mu ki awọn ara ilu gba ti ẹ?
71 A kò lè gba ẹnikẹ́ni sínú ìjọ ti Krístì bíkòṣepé òun ti dàgbà dé awọn ọdún ṣíṣe ìṣirò níwáju Ọlọ́run, àti tí ó ti lè ṣe ìrònúpìwàdà.
Ó pàṣẹ fún oòrùn,oòrùn kò sì yọ;ó sé àwọn ìràwọ̀ mọ́lé;
Àwọn kan wá, wọ́n ń bi Jesu pé, “Kí ló dé tí àwọn ọmọ-ẹ̀yìn Johanu ati àwọn ọmọ-ẹ̀yìn àwọn Farisi a máa gbààwẹ̀ ṣugbọn àwọn ọmọ-ẹ̀yìn tìrẹ kì í gbààwẹ̀?
Ó fi ọgbọ́n àgbà pògì mú fún àlejò
Joṣua Ṣẹgun Jabini ati Àwọn tí Wọ́n Darapọ̀ Mọ́ ọn.
eyi ti o tako ofin awon osise lagbaaye, o tun wi pe “Iye ekunwo ti awon fenuko le
Tọ́ ọmọ rẹ, yóo sì fún ọ ní ìsinmi,yóo sì mú inú rẹ dùn.
Bakan naa lo rọ awọn eeyan ki wọn dékun ìdẹ́yẹsí àwọn akanda ẹda ati pe ki wọn fopin si titabuku wọn lawujọ nitori ko wu àwọn naa lati ri bẹẹ.
Bí bẹ́ẹ̀ sì kọ́, mo níláti san ìwọ̀n talẹnti fadaka kan gẹ́gẹ́ bí owó ìtanràn.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Kenya gbona lori ikọlu awọn ọlọọpaati oluwọde 5 Èrèlè 2018 Oríṣun àwòrán, Reuters Àkọlé àwòrán, Ile isẹ amohunmaworan NTV,KTN ati Citizen TV wa lara awọn ile isẹ ti ijoba ko lati si Awọn olopaa nilu Kenya ti yin afẹfẹ tajutaju lu awọn to'n fi ehọnu han pẹ ki ijoba si awọn ile isẹ amohunmaworan ti wọn ti pa lati ọse to koja.
Bi alara ti n da sii naa ni Ajero n da sii titi to fi kan Ọwarangun aga.
OLUWA bẹ Sara wò gẹ́gẹ́ bí ó ti wí, ó sì ṣe fún un gẹ́gẹ́ bí ìlérí rẹ̀.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù US election 2020: Olórí àwọn òṣìṣẹ́ Trump sọ pé ìjọba ilẹ̀ America kò le kápá coronavirus 26 Ọ̀wàrà 2020 Oríṣun àwòrán, Donald Trump/Twitter Ọkan Pataki lara awọn amugbalẹgbẹ Aarẹ Donald Trump ti sọ pe orilẹ-ede Amẹrika ko lagbara lati koju ajakalẹ arun Covid-19.
“Gbogbo yín, ẹ péjọ, kí ẹ gbọ́,èwo ninu wọn ni ó kéde nǹkan wọnyi?
 ní ìgbà yìí , ọ ̀ pọ ̀ lọpọ ̀ Ìdàpọ ̀ yúróòpù kò gbàá .
 Ọ ̀ pọ ̀ lọpọ ̀ àwọn tí ó ń dábẹ ́ fún obìrin ní orílè èdè nàìjíríà jẹ ́ obìrin tí kò ní ìmọ ̀ púpọ ̀ tàbí ìmọ ̀ rárá nípà abẹ ́ dídá .
Ṣáájú àkókò yìí, ọba Jehoiakini ati ìyá ọba ti kúrò ní Jerusalẹmu, pẹlu àwọn ìwẹ̀fà ati àwọn ìjòyè Juda ati ti Jerusalẹmu, ati àwọn oníṣẹ́ ọwọ́ ati àwọn oníṣẹ́-ọnà.
Lẹ́yìn náà ni ọjọ́ ìyàsọ́tọ̀ rẹ̀ ṣẹ̀ṣẹ̀ bẹ̀rẹ̀, a kì yóo ka àwọn ọjọ́ tí ó ti lò ṣáájú nítorí pé ìyàsọ́tọ̀ rẹ̀ ti bàjẹ́ nítorí pé ó fi ara kan òkú.
Akomolede Yoruba: Ìtàn ọ̀rẹ́ tó fi ògùn gba ọkọ ọ̀rẹ́ rẹ̀ nílùú òyìnbó rèé
A gbìn ín pẹlu àìlera: a jí i dìde pẹlu agbára.
Ọpọlọpọ igba si ni Wenger ati Mourinho maa n kọlu ara wọn lori papa.
Tẹlẹ, ọjọ ikọkanlelogun, oṣu kẹsan an lo yẹ ki atimọle rẹwa sopin.
Lẹ́yìn tí wọ́n bá wọn owó náà, wọn yóo gbé àpò owó náà fún àwọn tí wọn ń ṣe àkóso ilé OLUWA.
Èrò mi ni èyí, Olówó-ayé, jókòó sí inú Igbó Olódùmarè níhìn-ín nínú ààfin mi ki a máa gbádun ara wa.
Igba akọkọ ree ti Tinubu yoo da sí iwọde to gba ile, gba oko ni Naijiria.
Ti ẹnikẹni ba ri alejo ti irin rẹ jọ ti afurasi, ki iru ẹni bẹẹ tete kansi ile iṣẹ ọlọpaa lapapọ lori aago 112, bakan naa awọn olugbe ilu Eko le pe 727.
O fi kun un pe ko gbọdọ si aaye fun ẹnikẹni lati gba owo to ju ẹgbẹrun lọna ẹẹdẹgbẹta naira lojumọ.
Wọn fi ọrọ̀ ajé àti iṣẹ́ àgbẹ̀ ni ipinlẹ̀, pèsè ohun amáyédẹrùn fún ilú, ilé-ìwòsàn ọ̀fẹ́, ilé-iwé ọ̀fẹ́, àwọn tó jade ni ilé-iwé giga ri iṣẹ́ gidi àti pé àwọn ará ilú tẹ̀ lé òfin.
Bákan náà ibẹ ni wọ́n kò àwọn sójà to n dá ààbò bo ara síi, ni kété to bá sì ti ri àjòjì tó bá ara jà rí, kía ni yóò ti kòjú ìjà síi.
Minisita Jim Mattis ni bakannaa ni awọn miran n yiira ninu eefọ igo ti wọn se gẹgẹbi ara afihan iwa akin awọn ọmọogun ilẹ Indonesia.
 Eyi ni o munu mi dun pupo pe, Ma a fi ara mi han ninu ifigagbaga nla yii.
Ó yàn án láti jẹ́ ọba lẹ́yìn tí òun bá kú.
Awọn onimọ sayẹnsi ti sọ wi pe, abẹrẹ ajẹsara tabi oogun oyinbo to lagbara ni awọn lero wi pe o le koju arun Coronavirus lagbaye.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Èwo nínú àwọn amóhùnmáwòrán yìí lẹ rántí?
Bákan náà, wọ́n tún jẹ́ oníṣowò gidi.
Nítorí tí àwọn obìnrin méje wọn-ọnnì jẹ́ olóríkunkun, Ọlọ́run Ọba fi wọ́n bú ó sì wí ní ìbínú rẹ̀ pé: ‘Ẹ̀yin aláìgbọ́ràn ẹ̀dá, mo dá yín tán ẹ gbàgbé Mi, ẹ lọ fún àwọn ènìyàn Mi ní èèso Tèmi-nìkan jẹ, ẹ si sọ ayé wọn di ewúro!
Owó tí o yà lọ́wọ́ mi nígbà òkú ìyá rẹ, ọ̀rọ̀ náà bí àwọn àbúò ọkọ mi nínú nígbà tí mo rò fún wọn, mo sì gba ọ níyànjú wí pé kí ó tètè fi owó náà sọwọ sí mi, nítorí kí ó má ba jẹ pé iwọ yóò déédéé rí àwọn ara ilé ọkkọ mi láìròtẹ́lẹ̀, kí wọn sì gba owó náà tagbára.
O le ni ogoje awon olukopa lati ipinle merindinlogbon kaakiri Naijiria ni won kopa nibi eto naa ti won se lati fi ko won nipa aabo fun ohun jije ati ona amojuto okowo ohun jije.
Ọpọlọpọ awọn ọmọ orilẹ-ede Naijiria ti fi èrò ọkan wọn han lori ohun ti wọn yoo ba Aarẹ Muhammadu Buhari sọ ti wọn ba ni anfaani iṣẹju meje pere lati ba a sọrọ.
Ṣé òkú ni o óo ṣe iṣẹ́ ìyanu hàn?
O ni awọn orileede bi Taiwan ati Singapore ko lọra nipa wiwa awọn to ni arun yi ati yiya wọn sọtọ.
” Wọ́n sì bá a di kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ rẹ̀ ní gàárì.
Nígbà tí wọ́n dé ibi odi ìlú, Samuẹli wí fún Saulu pé, “Sọ fún iranṣẹ rẹ kí ó máa nìṣó níwájú dè wá.
 Ète láti sọ àgbéyẹ ̀ wò iṣẹ ́ ọnà dàbí ti ìmọ ̀ sáyẹ ́ nsì ló fa ìṣẹ ̀ dá soṣiọ ́ lọ ́ jì lítíréṣọ ̀ .
Lẹ́hìn ìgbà díẹ̀, òkìkí Aquae Sulis kàn káàkiri gbogbo ìlẹ̀ Róòmù ìgbà náà.
Wọ́n bá fa kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ náà wá sí ọ̀dọ̀ Jesu, wọ́n tẹ́ aṣọ wọn sí orí rẹ̀, Jesu bá gùn un.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ayẹyẹ ìgbaniwọlé sínú ẹgbẹ́ òkùnkùn bẹ́yìn yọ, wọ́n lu ọmọ ẹgbẹ́ tuntun pa Akeredolu yan ọmọ Ilajẹ gẹ́gẹ́ bíi igbákejì rẹ̀ tí wọ́n yóò jọ díje dupò ní Ondo Ìjọba àpapọ̀ ti gba 800 bílíọ̀nù padà lọ́wọ́ àwọn tó jí owó ìlú kó, àwọn 1,400 ti wà nínú ẹ̀wọ̀n -Lai Mohammed Toke Makinwa ti sọ̀rọ̀; Amcon náà dá a padà fún un pé.
tun wa ki aare Bubari ku ori-ire fun aseyori saa keji gege bi aare orile ede
”Fẹstu dáhùn ó ní, “Ẹ óo gbọ́ ọ̀rọ̀ lẹ́nu rẹ̀ lọ́la.
Ninu ọrọ to fi sita, o ni ọkunrin naa sọ pe ohun yoo fi ọkọ gbe oun pada lọ si sọọsi kan tohun fori pamọ si.
Gbogbo ẹ, gbogbo ẹ lati dẹkun itankalẹ arun naa ni.
Ikọ Falconets ti wọ ipele aṣekagba FIFA Under 20 World Cup lẹẹmeji otọọtọ ṣugbọn wọn kuna lati gba ife ẹyẹ naa.
kí ó tó já #Mothersday2019: Àwọn ìpèníjà obìnrin láwùjọ Abẹ̀sẹ́kù bí òjò wọ gàù lẹ́yìn tó fẹnu ko ''Jennifer'' lẹ́nu Gbajabiamila sọ pe oun yoo ṣakitiyan lati ri wi pe awọn aṣofin ṣe ofin lati jẹ ki awọn ọmọ orilẹede Naijiria gbaye gbadun ti ile ba yan oun gẹgẹ adari.
Myanmar: kékeré ni wọ́n ti n kọ́ àwọn ọmọ nípa ọ̀nà oge ṣiṣe
Ǹjẹ́ bí ẹnìkan bá mú ẹran tí a fi rúbọ, tí ó ti di mímọ́, tí ó dì í mọ́ ìṣẹ́tí ẹ̀wù rẹ̀, tí ó sì fi ẹ̀wù náà kan burẹdi, tabi àsáró, tabi waini, tabi òróró, tabi oúnjẹ-kóúnjẹ, ṣé ọ̀kan kan ninu àwọn oúnjẹ yìí lè tipa bẹ́ẹ̀ di mímọ́?
Oríṣun àwòrán, FUNTUA PAGE/ FACEBOOK Samaila Isa Funtua Iku doro, iku mu amugbalẹgbẹ Aarẹ Muhammadu Buhari lọ ni Abuja Ọkan gboogi ninu iṣejọba Aarẹ Buhari, Malam Ismaila Isa Funtua ti jade laye ni ẹni ọdun mejidinlọgọrin.
ki o to fipo naa sile lọdun 2015.
Anthony Joshua ni ìwúrí ọmọ ọdún méje yìí Obìnrin awakọ̀ Bàálù àkọ́kọ́ láti Ọffa rèé Fun ẹni ti ko ba mọ lara,awẹ a ma muinira wa ṣugbọn lọdọ ọmọdebinrin Nadia lati ilu Mombassa lorileede Kenya,o ni yatọ si awẹ akọkọ to mu inira wa diẹ,ohun kii m ala awẹ lara.
Àwọn ará Bẹnjamini bá jáde sí wọn láti ìlú Gibea, wọ́n sì pa ọ̀kẹ́ kan (20,000) ninu àwọn ọmọ ogun Israẹli ní ọjọ́ náà.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Say no to rape: Àwọn òṣèré tíátà Yorùbá pariwo síta lórí wàhálà ìfipábánilòpọ̀ A kaa pe ọpọ iṣẹlẹ iditẹ gbajọba to waye ni Naijiria lo n lọwọ Abacha ninu nigba to si wa ni ipo 'second lieutenant' lasan, ibẹrẹ pẹpẹ si lo ti bawọn kopa ninu iditẹ gbajọba to waye losu keje ọdun 1966, to fi mọ eyi to waye lọdun 1983, to gbe ọgagun Ibrahim Babangida sori aga akoso.
Ahmed Taiwo ṣalaye pe awọn sọja gbe ibọn pẹlu ọta gidi ninu rẹ dani lati baado bo ara wọn.
Àkọlé àwòrán, Ìtàn Manigbagbe: Ẹ fokan balẹ, àwọn ajakale àrùn kan rèé to burú ju Coronavirus lọ Bákan náà, láàárín ọdún 2005 sì 2012, tíì ṣe ọdún méje sì ara wọn, kòkòrò HIV àti AIDS tí pá mílíọ̀nù lọ́nà mejidinlogoji èèyàn, taa sì leè sọ pé ó burú ju Coronavirus lọ.
Ninu ọrọ ikini kaabọ rẹ, olugbalejo pataki nibi ayẹyẹ ifilọlẹ ọhun, gomina Ṣeyi Makinde ti ipinlẹ Ọyọ ni, asiko ti to fun ilẹ Yooba lati dẹruba ẹru gangan funra rẹ.
Bí wọn bá ń lọ àwọn àgbá náà a máa yí lọ pẹlu wọn.
INEC: Raheem Olawuyi ti APC mókè nínú àtúndì ìbò Ajọ Eleto idibo lorilẹede Naijiria, INEC ti kede Raheem Olawuyi ti ẹgbẹ oselu APC, gẹgẹbi ẹni to jawe olubori ninu atundi ibo si ipo asojusofin lẹkun idibo Ekiti/Irepodun/Isin/Oke-Ero ni ipinlẹ Kwara.
A máa ṣàánú àwọn eniyan lọpọlọpọ, a sì máa gbadura sí Ọlọrun nígbà gbogbo.
Awon omo orile ede Naijiria je akinkanju , ti won ko gbodo kuna
17 Agẹmo 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 17 Ọ̀wàrà 2019 Ẹ wo oriṣii ìkíni ti awọn èèyàn fún onidiri.
Àṣá ati òòrẹ̀ ni yóo fi ibẹ̀ ṣe ilé,òwìwí ati ẹyẹ kannakánná ni yóo máa gbé ibẹ̀.
Inec: Èsì ìbò ko tó làti yọ Dino Mélayé
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Abayọmi Aranmọlatẹ, Dr Laser: Vagino Plasty àti iṣẹ́ abẹ ẹwà Obìnrin ló jẹ mí lógún Saaju ni ijọba ti kọkọ kede ifopin si SARS ENDSARS: Wo ohun márùn-ún tí yóò ṣẹlẹ̀ bí ìjọba ṣe tú SARS ká Ọga agba ajọ ọlọpaa ni wọn yoo gbe gbogbo awọn agbofinro naa to n ṣiṣẹ ni ikọ SARS lọ si ẹka mii nileeṣẹ ọlọpaa kan naa.
Coronavirus Lockdown: À ń gbáradì láti pàṣẹ òfin kóníléógbélé tó bá dójúẹ̀ tán
Kọmiṣọna fun ileeṣẹ ọlọpaa ní Ipinlẹ Eko Edgal Imohimi ti paṣẹ fun ẹka ọtẹlẹmuyẹ lati bẹrẹ iwadi kikun lori ọrọ naa.
Wo fọ́tò àrà MC Oluomo, Pasuma àtàwọn òṣèré tíátà míì níbi ìṣílé Iyabo Ojo Ọ̀dọ́ Nàíjíríà fèsì padà fún Buhari lórí ìkéde pé kí wọn padà sóko Iṣẹ́ jìbìtì ni INEC fi ọ́ọ́fìsì rẹ̀ tó jóná l‘Ondo ṣe - Eyitayo Jegede Wo àmì márùn-un tí o fi le mọ ẹni tó fẹ́ gbẹ̀mí ara rẹ̀ Akọbi rẹ wa ni ipele keji ni fasiti to ti n kọ nipa imọ iṣegun oyinbo.
Àwọn ọmọ Kohati yòókù sì gba ìlú mẹ́wàá lọ́wọ́ àwọn ẹ̀yà Efuraimu, ẹ̀yà Dani, ati ìdajì ẹ̀yà Manase.
Mo fi Ọlọrun ṣe ẹ̀rí pé àárò gbogbo yín ń sọ mí, pẹlu ọkàn ìyọ́nú ti Kristi Jesu.
Láti àtẹ́lẹsẹ̀ yín títí dé àtàrí yín kìkì oówo ni yóo jẹ́.
Àrà ọ̀tọ̀ inú orin tó jáde lọ́dún 2018 ní Nàìjíríà Zlatan sọ ìtumọ̀ òrin rẹ̀ tó gbòde kan Kéere o!
Olówó yalumọ àkọ́kọ́ nílẹ̀ Yorùbá Oríṣun àwòrán, dailypost.
Olori ijọ Winners naa ni ọpọ ẹtan lo wa ninu aye loni, amọ emi duro fun otitọ, agbara nla ti Ọlọrun yoo si gbe wọ ijọ rẹ lọrun yoo pọ to bẹẹ gẹ, ti yoo mu owu jijẹ dani."
O so pe, “o-lokan-o-jokan idanilekoo bi: ‘Shirin Harbi,’ ‘Harbin Kunama 2’ and ‘Crocodile Smile 2’ ni won ti lo, ti o si ti yori sir ere jake-jado orile-ede Naijiria ni odun 2017.
Lasiko naa ni wọn ni obinrin naa sọ fun ikọ naa wipe oun o le salaye kankan nipa miliọnu mẹrindinlogoji ti wọn pa wọle lawọn ọdun to diẹ sẹyin saaju ki wọn o to dawọ tita kaadi naa duro.
Àwọn ọba ayé kó ara wọn jọ,àwọn ìjòyè fohùn ṣọ̀kan,láti dìtẹ̀ sí Oluwa ati sí Mesaya rẹ̀.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù AFCON 2019: Nàìjíríà wà ní ìsọ̀rí kan náà pẹ̀lú Burundi, Madagascar àti Guinea 12 Ìgbé 2019 Oríṣun àwòrán, Twitter/Super Eagles Super Eagles yoo koju Burundi, Madagascar àti Guinea nínú ìdíje ife ẹ̀yẹ Afrika AFCON 2019.
Stella Adadevoh tó dènà Ebola ní Nàìjíríà gba ìdálọ́lá lọ́wọ́ Ààrẹ Buhari
Ìbà lọ́wọ́ yín, atìdí mùjẹ̀ èèyàn
O tun menuba awọn iṣẹ akanṣe ti ijọba rẹ fẹ ṣe ni 2020 pe Ó ti tán fún mí lọ́dún 2023- Ààrẹ Muhammadu Buhari Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, #Queen Dihya: Obinrin tó gbógun tàwọn agbésùnmọ̀mí ni Algeria Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Igba ti awọn ayaba n ti naa, lo duro fun ilu ti wọn n lu si orin abi oriki Alaafin ti wọn n kọ, bi gbogbo awọn ayaba yii si ṣe da ọwọ bo igba, ti wọn n lu u, ati asaaju wọn to n fi igi gigun meji na igba kekere to wa niwaju rẹ, ni yoo mu kawọn igba ọhun maa ro bii ilu, ni eti awọn to n gbọ.
Lẹ́yìn náà ni àwọn olórí ogun àwọn olórí ẹgbẹẹgbẹrun ati ọgọọgọrun-un tọ Mose wá, wọ́n wí pé, 
Àwọn alufaa rẹ̀ wà níhìn-ín láti fun fèrè láti pè wá kí á gbógun tì yín.
Dani yóo dàbí ejò lójú ọ̀nà,ati bíi paramọ́lẹ̀ ní ẹ̀bá ọ̀nà,tí ń bu ẹṣin ní gìgísẹ̀ jẹ,kí ẹni tí ó gùn ún lè ṣubú sẹ́yìn.
Àpapọ̀ gbogbo àwọn ọmọ Bẹnjamini wá jẹ́ ẹẹdẹgbẹrun ó lé mejidinlọgbọn (928).
Nítorí pé ọpọlọpọ ọgbọ́n a máa mú ọpọlọpọ ìbànújẹ́ wá, ẹni tí ń fi ìmọ̀ kún ìmọ̀ rẹ̀, ó ń fi kún ìbànújẹ́ ọkàn rẹ̀ ni.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Oluwo: Mo lè jẹ Ọba ní Ile Ife Ọba alaye naa fikun pe aisi ẹkọ iwe lo maa n se okunfa iwa jagidi-jagan.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Baruwa Gas Explosion: Àwọn tó forí sọta ìjàmbá iná ń bẹ ìjọba láti dìde ìrànwọ́ ''Mo ranti igba ti ọrọ pa wa pọ, to sọ fun mi pe oun dije lọdun 1954 pẹlu baba ẹni to fẹ du ipo Gomina lọdun 2003.
Màmá Guardiola d'olóògbé lẹ́yìn tó lùgbàdì Coronavirus Páro-páro ni àwọn mọ́ṣálááṣí dá káàkiri Nàìjíríà lásìkò ìrun Jímọ̀ nítorí coronavirus Ohun ti Ajọ Eleto Ilera lagbaye, WHO n sọ tẹlẹ ni pe omi ara eniyan lo n fa itankalẹ arun naa.
Awọn alatilẹyin rẹ n ke dansaaki rẹ ti awọn alatakọ si n ṣe ọọbi fun un.
  Ọpọ̀ lọpọ̀ abúlé àti ìgbèríko ni wọ́n yí igbó àti òkúta yìí ká.
Oríṣun àwòrán, Taribo/ twitter O tun sọ ninu fọ́nrán naa pe asọtẹlẹ jade lẹnu oun pe Rotimi Akeredolu ni yoo wọle ibo gomina Ondo, ṣugbọn ko si ẹni to sọ nipa awọn asọtẹlẹ yii lori ayelujara.
Wọ́n rí bí àwọn yàrá ti ìhà àríwá, òòró ati ìbú wọn rí bákan náà.
Arabinrin naa wi pe ti obi ba ti na ọmọ ti ara rẹ si bẹ ẹjẹ lọna ati ba a wi, o ti da ẹṣẹ ifiyajẹni to lodi si ofin.
Ẹ̀mí gígùn wà ní ọwọ́ ọ̀tún rẹ̀,ọrọ̀ ati iyì sì wà ní ọwọ́ òsì rẹ̀.
Ọ̀rá ẹran náà pẹlu àyà rẹ̀ ni yóo mú wá.
"Ọwọ́ pálábá ségi fún gbajúgbajà olè méjì tó ń ṣọṣẹ́ lọ́wọ́ l‘Eko Seyi Makinde figbe ta lórí bí Ajimobi ṣe ń ná owó ìlú Gerald Bourke, latinu aj to n risi ipese ounjẹ labẹ ajọ isọkan agbaye ni ""Ko si ile ti afẹfẹ lile naa ko fi ọwọ ba."
Marvel Universe lo gbe e sita ti olu ẹda itan rẹ jẹ eniyan dudu ti ibudo itan si jẹ afihan ilẹ Adulawọ ati ilẹ Gẹẹsi.
“Kí ló dé tí a kò ta òróró yìí ní nǹkan bí ọọdunrun (300) owó fadaka, kí á pín in fún àwọn talaka?
Ṣugbọn bí o bá kọ̀, tí o kò jẹ́ kí wọ́n lọ, n óo da ọ̀pọ̀lọ́ bo ilẹ̀ rẹ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Igbakeji gomina Eko sọrọ nipa obinrin Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Igbakeji gomina Eko sọrọ nipa obinrin 9 Ẹrẹ̀nà 2018 Arabinrin Idiat Adebule to jẹ igbakeji gomina ipinlẹ Eko so wipe amuludun ni obinrin jẹ.
Atẹjade kan eyi ti minisita f'ọrọ ilẹ okeere l' Amẹrika, Mike Pompeo fi sita lọjọ keje oṣu kejila ọdun 2020.
Àwọn mìíràn wà tí wọ́n ti fa apá wọn kan ya kúrò lára wọn ti wọn ń gbé kùkùté tí ó kù kiri ti ẹ̀jẹ̀ wà bálabàla lójú apá tí wọ́n faya lọ tí ojú egbò kò san tí ẹ̀jẹ̀ kò dáwọ́ dúró tí wọn ń rìn bẹ́ẹ̀ kiri.
 Ijọba ko sọrọ, awọn oluwọde ko sọrọ nitori naa eleyi n ṣe ipalara nla fun idanwo NECO, ipalara nla ni iwọde n ṣe fun idanwo NECO O ni adura ati ọrọ iyanju láwọn n ṣe fawọn akẹkọọ nitori o ti ṣu ọpọ ninu wọn.
 “A n fi ye awon igbimo ipinle pe,
Oshiomole, alaga egbe APC  ti ni ki wọn yọ
Ogbeni Nuhu tun so pe igbimo awon
Òun ati Jehieli, ọmọ Hakimoni, ní ń ṣe àmójútó àwọn ọmọ ọba.
Ta ni ó sì lè sọ, bóyá nítorí irú àkókò yìí ni o fi di ayaba?
Ọrọ yii ti n mu awuyewuye dani lori ayelujara, ti ọpọ eeyan si koro oju si ihuwasi Erica naa, lẹyin ariya alẹ ọjọ Satide.
Koda, Hush lọ sibi ayẹyẹ igbeyawo ẹgbọn Davido, Adewale, to waye nilu Dubai nibẹrẹ ọdun 2020.
"Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Cerebral Palsy: Ìyá Najeebah ní oyún oṣù mẹ́rin ààbọ ni wọn gbe jáde kúrò nínú òun ""Bi wọn se n ko oogun oyinbo ninu ọpọ sọọbu, ni wọn n fọ ilegbe ati ibudo itaja fun eroja ounjẹ lai si ẹni ti yoo yẹ wọn lọwọ wo."
Nígbà tí Joabu gbọ́ ohun tí ó ṣẹlẹ̀, ó sá lọ sinu Àgọ́ OLUWA, ó sì di ìwo pẹpẹ mú, nítorí pé lẹ́yìn Adonija ni ó ti wà tẹ́lẹ̀ rí, bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé kò sí lẹ́yìn Absalomu.
Ilà tí o kọ ní anfaani, bí o bá ń pa Òfin mọ́.
Iroyin fi lede pe awọn eniyan to wa ni agbeegbe naa fi ara pa, ki o to di wi pe iranwọ de.
Alakoso ajo NAQS, dokita Vincent Isegbe, ni o se ikinlo yii lasiko iforo-wani-lenu wo pelu awon oniroyin lojo-Isegun nilu Abja.
Ki nijọba n gbero pẹlu Ruga ti wọn fẹ da silẹ: Aawọ laarin darandaran ati agbẹ ni ijọba lawọn fẹ dẹkun pẹlu idasilẹ aagọ fawọn to n da ẹran.
Nípa aṣọ tí ó wọ̀ ní ọjọ́ tí ó wá sí ọ̀dọ̀ Orímóògùnjẹ́, ẹni kan sọ pé aṣọ sáfẹ́ẹ̀tì pẹ̀lú aṣọ òfì ni ó wọ̀.
O ni igba de igba ni mo n fi owo ranṣẹ si Adebimpe, amọ mi o le gbe iru igbeaye olowo ti Adebimpe n gbe.
Olapade Agoro: Olùdíje dùpo aàrẹ Nàìjíríà rí, Owatapa ti Itapa Ijesha, Wolii Olapade Agoro jáde láyé
Ki a ma si parọ, ọpọ omidan ladugbo ni o mọ pe ọmọ daa sibẹ.
Gbogbo àwọn tí Mose, Aaroni ati àwọn olórí àwọn ọmọ Israẹli kà ninu àwọn ọmọ Lefi ní ìdílé-ìdílé gẹ́gẹ́ bí ilé baba wọn, 
ibasepo ati ifowosowopo pelu awon ile-ise alaabo akegbe re lorile-ede yii
Abrahamu fẹ́ aya mìíràn, tí orúkọ rẹ̀ ń jẹ́ Ketura.
“Ọkunrin tíí ṣe alákòóso ilẹ̀ náà sọ̀rọ̀ líle sí wa, ó ṣebí a wá ṣe amí ilẹ̀ náà ni.
"O ni ""ko pẹ to de ile itura naa, ni nkan bi aago kan oru, to si n wa awọn ọrẹ rẹ, ni awọn ọlọpaa wọle."
Ọjọ kọkanlelogun, Oṣu Ebibi (May), ọdun 2011: Asọtẹlẹ eyi ti gbaye kan ju nipa igba ti aye yoo parẹ ni eyi ti Harold Camping sọtẹlẹ pe ọjọ kọkanlelogun, oṣu karun un, ọdun 2011 ni opin aye yoo de.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: ADC, ADP, APC, SDP fakọyọ níbi ìpàdé ìtagbangba l'Ọṣun Ará Kwara soríre bí mo se jáwé olúborí - Ọlawuyi MC Oluọmọ, fara gb'ọ̀bẹ níbi ìpolongo ìbò APC l'Eko ASUU strike: Ẹ wo ohun t'áwọn akẹ́kọ̀ọ́ ńṣe lásìkò ìyanṣẹ́lódì?
Lọdun to kọja, Aarẹ Paul Biya ṣe ijiroro gbogboogbo, ati awọn nkan miran to tun ṣe lati ri pe alaafia jọba ni agbegbe naa.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù WAEC 2020 result checker: Wo nkan tí yóò ṣẹlẹ̀ sí àwọn akẹ́kọ̀ọ́ tí àjọ WAEC gbẹ́sẹ̀ lé èsì ìdánwò wọn 2 Bélú 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 3 Bélú 2020 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Miliọnu kan abọ awọn akẹkọọ to pegede ninu idanwo naa Wo nkan tí yóò ṣẹlẹ̀ sí akẹ́kọ̀ọ́ tí àjọ WAEC gbẹ́sẹ̀ lé èsì ìdánwò wọn.
Bákan náà ni wọ́n bu ẹnu atẹ́ lu àbájáde ìwádìí EU lóri bi ètò ìdìbò ṣe lọ ni Nàìjíríà, tí wọ́n si sàpèjúwe rẹ̀ gẹ́gẹ́ bii èyí ti kò jágara tó, ti kò si tọ ìlànà òfin ìdìbò.
Jeroboamu ọmọ rẹ̀ sì jọba lẹ́yìn rẹ̀.
Gomina Ahmed so pe iko omo ogun naa
Láìsí igi, iná óo kú,bẹ́ẹ̀ ni, láìsí olófòófó, ìjà óo tán.
Aarẹ orilẹede Naijiria, Muhammadu Buhari lo ti lọ si Ilẹ Gẹẹsi ni London lati lọ lo isinmi ọlọjọ mẹwaa, eleyi ti yoo bẹrẹ ni Ọjọ Kẹta, Osu Kẹjọ ti a wa yii.
N óo sọ ọgbà rẹ̀ di igbó, àwọn ẹranko ìgbẹ́ yóo sì jẹ wọ́n ní àjẹrun.
O ni kii ṣe pe awọn le e dari ijọba apapọ lori rira agbo lọwọ orilẹede Madagascar, amọ awọn fẹ ki ijọba ṣe ayẹwo awọn oogun ti wọn ti ṣe abẹle naa lati koju arun Coronavirus.
Gbójú sókè kí o wo ojú ọ̀run,ati àwọn ìkùukùu tí ó wà lókè.
A kò fẹ́ mọ òfin rẹ.
Ní àfikùn sí panchayat tí ìbó yàn, àwọn kan ńbẹ tí wọ́n pe ara wọn ní panchayat ipò-ìsàlẹ̀ láì ní àṣẹ kankan tí ó fún wọn lágbara níbikíbi ní orílẹ̀-èdè.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìtàn Mánigbàgbé: Kuti ni akọni Obìnrin Ẹ̀gbá tó di àwòkọ́ṣe rere f'áwọn ọ̀dọ́bìnrin ìwòyí 21 Owewe 2018 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 10 Ọ̀pẹ̀̀ 2019 Oríṣun àwòrán, @NzekweGerald Àkọlé àwòrán, Ọmọ ju ọmọ lọ, agbára ju agbára lọ ni ọrọ Funmilayọ Kuti tí Ilééṣẹ́ Google ń ṣe ìrántí rẹ̀.
Kò wá sí ẹni tí yóo pada wá dúpẹ́ lọ́wọ́ Ọlọrun, àfi àlejò yìí?
ní Rakali, ní àwọn ìlú Jerameeli, àwọn ìlú Keni, 
"Nàìjíríà bèèrè ìrànwó lọ́wọ́ àjọ àgbáyé láti kápá Coronavirus ""Owó oṣù òṣìṣẹ́ yóò di gbèsè, oúnjẹ yóò wọ́n, ìlú yóò le, bí ọrọ̀ ajé Náíjíríà bá dagun"" Lorilẹede Gabon n tiẹ, ẹni to ni kokoro naa lara jẹ ọmọ orilẹede naa amọ to sẹsẹ de lati orilẹede Faranse."
OLUWA a máa gba olódodo lọ́wọ́ ìyọnu,ṣugbọn ẹni ibi a bọ́ sinu wahala.
Ifeoma ṣalaye fun BBC pe niṣe ni ẹnu ya gbogbo eeyan nile iwosan ni America ti oun lọ bimọ si nigba ti wọn kọkọ gbe ọmọ mẹrin ti fọto 'Scan' sọ pe o wa nibẹ tẹlẹ sita, ti wọn tun ri mii sii.
Ajakaye tun fikun wi pe ,awọ̀n ko mọ igba tabi akoko ti ipade laarin ijọba ati osisẹ yoo waye, amọ laipẹ awọn yoo sọ ipinnu wọn lori ọrọ naa.
ẹlẹsin, awon alasẹ ,lona lati je ki eto aabo tubo fẹsẹ  mulẹ lorile ede NaijiriaOgagun Otiki  wa gbosuba fun adari ile-ise ologun orile ede
ó yanu, ó sì gbé wọn mì, ati àwọn ati ìdílé wọn, ati ohun ìní wọn.
Wọn tun ni ọrọ ẹnu DJ Switch ni CNN n gbagbọ, eyi to jẹ pe o ti yipada lọpọ igba.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ṣó yẹ kí akẹ́kọ̀ọ́ tàbùkù mi torí mo ya ‘Tatoo’ sí gbogbo ara?
’’“iriri mi  ni ipinle Edo ni pe .
Muhammadu Buhari ti gbosuba fun ọjọgbọn Yemi osinbajo fun ipa pataki ti o ko
Ó wá bi wọ́n pé, “Ǹjẹ́ ẹ mọ ohun tí mo ṣe si yín?
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Oronpoto Animation: Akin Alabi ní kò dára bí eré aláwòrán fáwọn ọmọdé ṣe jẹ́ aláwọ̀ funfun Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Oronpoto Animation: Akin Alabi ní kò dára bí eré aláwòrán fáwọn ọmọdé ṣe jẹ́ aláwọ̀ funfun 29 Agẹmo 2020 Ni ọpọ igba ta ba ri ere alaworan to wa fun awọn ọmọde lori ayelujara tabi mohun maworan, awọn alawọ funfun lo maa n se jade.
Ṣugbọn àwọn eniyan ń bá ìwà burúkú wọn lọ.
Ninu atejade kan ti ile –ise aare gbe jade pe“Lẹyin irinjo naa ni aare Buhari yoo gunle irinajo lọ si orile ede UK .
"Owo ifẹyinti ko tọ si ẹni ti o sisẹ gẹgẹ bii gomina ilu fun patapata ọdun mẹjọ.
Buhari ko sai fi dawọn ọmọ Naijiria loju pe ijọba oun n ṣiṣẹ takuntakun lati fopin si Boko Haram, iṣẹlẹ ijinigbe ati awọn iwa ọdaran mii to gbode kan ni Naijiria.
Ijọba apapọ lo ṣalaye pe owo iranwọ ti awọn n pin lati bomi pa inira arun coronavirus lorilẹede Naijiria ko si fun ẹnikẹni to ba ni owo to pọ ju ẹgbẹrun marun naira ninu aṣuwọn ifowopamọsi rẹ.
Oludije si ipo gomina ni abe ẹgbẹ oselu PDP, Olusọla Eleka ni oun n gba ileẹjọ to n dajọ ọrọ eto idibo ni Naijiria lọ lati koju esi idibo to gbe Kayde Fayemi wọle.
Mo lero pe, orile-ede Netherland ye ko pegede besini, o ye ki o maa kopa fun olokan-o-jokan idije, mo ri apere ti o dara fun ojo iwaju, eleyi ti o sokunfa idi ti mo fi gba ise yii.
Fún àwọn tí wọn ń ṣègbé, a dàbí òórùn tí n pani, ṣugbọn fún àwọn tí à ń gbàlà, a dàbí òórùn dídùn tí ó ń fún wọn ní ìyè.
O ṣalaye ọrọ yii lasiko ti o fi n ba awọn oniroyin sọrọ ni ile rẹ to wa nilu Iragbiji tii ṣe ilu rẹ.
'Buhari, máa múra sílẹ̀ láti fẹ̀yìntì' Ninu ọrọ Femi Fani Kayode lo ti ni ọmọ ijọ Satani ni Linda yii jẹ fun iwa idẹyẹsi to hu sawọn ọdọ ti kii ṣe alawọ funfun yii.
Láti Risa wọ́n lọ sí Kehelata.
Mo si sọ fun wọn nigba naa lọhun pe ifẹ inu mi ko ṣe pataki to ipenija aabo tawọn eeyan wa n koju to bẹẹ to di igba kan ti ẹru n ba awọn eeyan lati rinrinajo""."
Yemi Adewetan wa parọwa si awọn ọmọ bibi ilu Ondo lati fọwọwọnu lori bi wọn se fagile ọdun Ekimogun ti ọdun yii.
Lọjọ Aiku yii ,ni agbẹjọro fun ijoba sọ pe, aare orile ede Sudan, Al-Bashir ti wọn yọ kuro lori aleefa bii jiga, ti n kawọ sẹyin rojọ lori sise owo ilu kumọ-kumọ ati sise atilẹyin fun awọn ọlọtẹ nipa owo iranwọ to n fun wọn.
Wọn a sì máa mú ọkà baali ati koríko wá fún àwọn ẹṣin tí ń wa kẹ̀kẹ́ ogun ati àwọn ẹṣin tí wọ́n fi ń ṣiṣẹ́.
Dáwọ́ ẹgba rẹ dúró lára mi,mo ti fẹ́rẹ̀ kú nítorí ìyà tí o fi ń jẹ mí.
Láti Harada wọ́n lọ sí Makihelotu.
Bakan naa ni awọn alejo miran tun jẹ ẹbun aago ọwọ olowo iyebiye, eyi ti wọn fi se ẹbun hiha nibi igbeyawo naa.
Oluwo Ìwo ṣ'àlàye lori oye Emir Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fọ́nrán ohùn, Oluwo Ìwo ṣ'àlàye lori oyé oba oni lawàni Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Oba Samuel Adeniran Asusumasa Atewogboye II: Alaaye ti Efon Alaaye tí wọ́n yẹgi fún lọ́dún 19498 Ògún 2020 Fídíò, Oba Olayode: Egbo to ti fẹẹ́ jiná ni ẹ tún ń fi èékáná te yìí - Omo Soun Ogbomoso II26 Ọ̀wàrà 2020 Fídíò, Ìròyìn Kàyééfì BBC Yorùbá: Ẹ̀kúnrẹ́rẹ́ àlàyé lórí ááwọ̀ tó wáyé láárin Oluwo ati Agbowu27 Ẹrẹ̀nà 2020 Saudi Arabia: Ìtàn kíkùn lórí Mọ́ṣáláṣí Anabi tí wọ́n dá sílẹ̀ lọ́dún 1440 sẹyin.
Bẹ́ẹ̀ ni wọ́n óo ṣe tẹ̀léra wọn níbi iṣẹ́ ṣíṣe ninu ilé OLUWA, gẹ́gẹ́ bí ìlànà tí Aaroni, baba wọn, ti là sílẹ̀ fún wọn, gẹ́gẹ́ bí àṣẹ tí OLUWA Ọlọrun pa fún Israẹli.
Sibẹ wọn ko tii sọrọ ni pato lori bi iṣẹlẹ naa ṣe ṣẹlẹ ati ọna lati wa ọmọ naa ri.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Boko Haram: igba marun un ti Shekau ku ti ko tun ku mọ 30 Agẹmo 2019 Oríṣun àwòrán, AFP Àkọlé àwòrán, Boko Haram: igba marun un ti Shekau ku ti ko tun ku mọ Boko Haram ko deede ṣẹlẹ ni Naijiria.
Awọn awọran mẹta ohun di awati lẹyin iku rẹ lodun 1994.
Ṣugbọn mo fẹ́ rí i pé ẹ kò ní ìpayà kan tí yóo mú ọkàn yín wúwo.
Fi ààmì sórí 'Bobajiroro Ti ẹ ko ba gbagbe, ni ọse yii ni gbajugbaja olorin Ruggedman fi fidio sita pe onijibiti to n se yahoo yahoo ni Naira Mailey.
Ọ̀kan ninu àwọn ilé tí ó kọ́ sí ààfin náà ni Ilé Igbó Lẹbanoni.
Ajo INEC ti fẹ bẹrẹ lati maa  kede abajade esi idibo odun 2019 ,Abajade esi idibo ti aarẹ ati ile igbimo asoju sofin ti
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù EFCC kó akẹ́kọ̀ọ́ fásitì UNIOSUN làwọn akẹ́kọ̀ọ́ náà bá fọ́n sígboro 25 Agẹmo 2019 Oríṣun àwòrán, Efcc Awọn oṣiṣẹ ajọ EFCC ti ko awọn akẹkọ ileewe fasiti ipinlẹ Ọṣun University of Osun State lori ẹsun pe wọn n ṣe owo gbajuẹ ati Yahoyahoo.
A ṣetán láti ran àjọ aláàbò alájùmọ̀ṣe lọwọ fún ààbò tó péye nílẹ Yorùbá - Ọlọ́pàá Ogun Buhari, pe ìpàdé àpérò ọmọ Nàíjíríà fún àgbékalẹ̀ òfin tuntun - Afe Babalola Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
ajo eleto idibo ,Independent National Electoral Commission (INEC) tun gbe jade
A kò lè pe èrè tí òṣìṣẹ́ bá gbà ní ẹ̀bùn; ẹ̀tọ́ rẹ̀ ni.
Ṣé yóo gbéjà kò mí pẹlu agbára ńlá rẹ̀?
Ọlọpaa wa ni pe ijiya nla n bẹ fun ẹnikẹni ti ade ori ọrọ naa ba ṣimọ.
Awọn ti iṣẹlẹ naa ṣoju wọn ṣalaye fun BBC pé awọn oniṣẹ ibi yii tun jo ọpọlọpọ ilé ni ina.
Ṣugbọn ẹ̀yin, àyànfẹ́ mi, ẹ fi igbagbọ yín tí ó mọ́ jùlọ ṣe odi fún ara yín, kí ẹ máa gbadura nípa agbára tí ó wà ninu Ẹ̀mí Mímọ́.
Àfàìmọ̀ kí Naira Marley má fi ẹ̀wọ̀n bẹ̀rẹ̀ ọdún 2020 Àwọn orílẹ̀èdè tó ti ṣáájú Nàìjíríà wọ ọdún 2020 Wo àwọn èèyàn jáńkán tí yóò ṣe ọdún tuntun ní ọgbà ẹ̀wọ̀n Àlùfáà ìjọ Redeem àti ọmọ rẹ̀ méjì kú sílé ìgbafẹ́ kan lásìkò Kérésì Ninu ikede ti Ijọba fi sita soju opoTwitter, wọn sọ pe awọn gbẹsẹ le ilẹ naa nitori pe ko ni iwe aṣẹ to yẹ.
    N o máa retí ìwé yín
, Duration 2,1522 Bélú 2020 Fídíò, Akomolede Yoruba: Kí ni ìdí tí aṣọ fi máa ń pọ̀ lára Egúngún ju Orò lọ́?
“A wo bi a sele ra opolopo awo, nitori ile-ise to n pese bata eyi ti ijoba ipinle Abia ngbero lati ko lai pe (Automated Shoe Factory), ni erongba lati tun mu igberu ba oja awo lorile-ede yii,” Tobi Sangotola.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Schools Resumption: Ohun tó yẹ kí o mọ̀ b'áwọn akẹ́kọ̀ọ́ ṣé fẹ́ wọlé padà ní Ogun,Èkó àtàwọn ìpínlẹ̀ míì Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Schools Resumption: Ohun tó yẹ kí o mọ̀ b'áwọn akẹ́kọ̀ọ́ ṣé fẹ́ wọlé padà ní Ogun,Èkó àtàwọn ìpínlẹ̀ míì Àkọlé àwòrán, Ipinlẹ Oyo ni ipinlẹ akọkọ ti awọn akẹkọọ yoo wọle pada sile ẹkọ ni Naijiria 8 Agẹmo 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 3 Ògún 2020 Ni ibamu pẹlu aṣẹ ileeṣẹ eto Eko ni ipinlẹ Eko, Ogun ati Kwara awọn akẹkọọ yoo pada sileewe lọjọ Iṣẹgun tii ṣe ọjọ Kẹrin oṣu Kẹjọ ọdun 2020.
 Aare Buhari menuba awon ise akanse ijoba apapo nipinle Plateau bii ti sise opopona Pankshin- Tapshin-Gambrar-Sara- Kai-Gindiri pelu owo iranwo epo ronbi TETFUND, owo iranlowo iyonikuro lahamo ati eto igbanisese N Power atawon miran pelu ileri pe ise ko ni pe bere loju ona Jos si Abuja lo si ila oorun ariwa Naijiria.
Palau jẹ ọkan lara orilẹede mẹwaa ti ko ni akọsilẹ coronavirus kankan lati igba ti aarun naa ti ba gbogbo aye finra(awọn orilẹede to jẹ ọmọ ẹgbẹ ajọ iṣọkan agbaye, UNO la n sọ nibi yatọ si North Korea ati Turkmenistan).
Ki ni idi ti ìsìnrú ìlú se se pàtàkì?
"ko si si ohun to jọ bẹ'' ""Ọrọ ti wọn n sọ yi ti waye saaju ki Jonathan to d'ori alefa o ṣi yi tẹsiwaju lẹyin to kuro."
Iroyin so pe, bio tile je pe, ipinnu Russia ni lati koju awon omo-ogun olote naa fun wakati marun-un pere lojoojumo, ti won yoo fi reyin won, sugbon ipinnu ohun yipada latari bi ikolu naa se lagbara koja bi won se lero.
Ẹ gbọ́ ǹkan ti àwọn òṣèré tíátà sọ nípa Pa Kasumu A dúpẹ́ o!
Wọn pa ọlọ́pàá kan níbi tí wọ́n ti dáná sun ìjọ Sotitobire l'Akurẹ - Police PRO Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Sotitobire church: Àwọn ọ̀dọ́ ilu dáná sun ilé ìjọsìn Nígba ti ọ̀rọ̀ de agọ ọlọpàá, nínú àwọn aṣọ́na mẹrinla to wà nilé ijọsin lọ́jọ́ ìṣẹ̀lẹ̀ náà, meji péré lo yọju si agọ ọlọpàá.
“lopo igba ni mo ti maa n so pe, a ko ni orile ede miran , yato si orile ede Naijiria, nitori naa a o jo tun orile ede yii se ni.
Ìloro ẹnu ọ̀nà náà wà ninu patapata.
bí o bá kígbe tí o tọrọ òye tí ó jinlẹ̀,tí o gbóhùn sókè tí o bèèrè ìmọ̀,
Ó tún lóyún ó sì tún bí ọkunrin, ó ní, “Wàyí o, n óo yin OLUWA,” ó bá sọ ọ́ ní Juda.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Boko Haram ta taba cewa ta musuluntar da 'yan matan wadanda mafi yawansu Kiristoci ne Ijinigbe wọn lọdun 2014 mu ki awọn eeyan jankanjankan kaakiri agbaye pe fun itusilẹ wọn.
Àwọn Ogun tí Dafidi Jà ní Àjàṣẹ́gun.
Kí ogbó tó dá ikooko Osuolale lára, ó ṣiṣẹ agbẹjọro débi pé ó gbà òye àgbà amofin taa mọ si SAN, tó sì tún jẹ́ òye n'ilu Ibadan, tíì ṣe ikú abinibi rẹ.
Akẹgbẹ rẹ, Oshoala naa sọ pe ko le sẹeṣe ki France na Naijiria ni 8-0 lọdun 2018, ki wọn tun wa tun wọn na lalẹ ọjọ je.
Mo dá iná mo sun ọ̀kan náà mo sì jẹ ẹ́ tán pátápátá.
Ilumọọka osere tiata kan, Funmilayo Ogunsola, ti gbogbo eniyan mọ si Mama Ijẹwuru, ti papoda lẹyin aisan ranpẹ ni ile rẹ ni Ibadan.
Oluwo: Ọ̀pọ̀ ọ̀dọ́ láwọn aṣíwájú orílẹ̀èdè Nàìjíríà ti fi ìwà àjẹbánu àti ìjẹkújẹ lé dànù sí òkè òkun
Messi ló gb'àmì ẹ̀yẹ Ballon D'or lóòtọ́ọ́, àmọ́ Ronaldo ló dára jùlọ (GOAT)- Mendes Mọ̀ síi nípa Oyedele Adedokun tó ya àwòràn Donald Trump tó lu ayélujára pa Wo bí àwọn àkàndà ẹdá ní Akurẹ ṣe sàmì àyájọ́ ọjọ́ wọn LASTMET kọ́ ló kó Opay nílẹ̀ ṣùgbọ́n ọlọ́kadà kò láṣẹ látigba ọ̀nà mọ́rosẹ̀ l'Eko- Opeifa Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Òwe Yorùbá: Mélòó lo lè parí nínú òwe Yorùbá yìí?
òrùka ọwọ́ wọn ati òrùka imú, 
Olayinka sọ pe agba ẹgbẹ PDP ni Fayose nitori naa ko si iru ọrọ ti ara rẹ kọ.
Lojiji ni ọkada naa ja sinu koto nla kan, tawọn adigunjale naa si jabọ, bẹẹ ni ọkan ninu wọn dagbere faye loju ẹsẹ nigba ti ekeji fara gbọgbẹ, ti ara rẹ si bo falafala.
Kàkà bẹ́ẹ̀, ẹ̀ ń tẹ̀lé ìlànà àwọn orílẹ̀-èdè tí ó yí i yín ká.
Ẹ̀wẹ̀, agbẹ́jọ́rò láti ọ́fíìsì agbẹjọ́rò àgbà ìjọba Labaran Magaji tó péjú sílé ẹjọ́ fún ìgbà àkọ́kọ́ lónìí sàlàyé pé, àwọn ti gba, ẹjọ́ náà lọ́wọ́ àjọ ọl\\apàá lánàá ọjọ́ ìṣẹ̀gún.
Awon egbe oselu alatako ti won fowo sinkun mu ohun ni ogbeni Idrissa Seck, Malik Gakou ati Thierno Bokoum.
"Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ìdílé tí ọkọ da ọmọ síta tóríi ojú Búlùú tí wọ́n ní bá BBC sọ̀rọ̀ ""Jẹjẹ ni emi ati ọkọ mi wa ninu ile, ta n gbadun akoko isera ẹni igbeyawo, 'Honeymoon' wa lọwọ, ni Olori Memunat ati iya mẹta pe mi."
Mo kọ̀ láti yí ọ̀rọ̀ mi padà lórí ètò ẹ̀kọ́ ọ̀fẹ́ - Gómìnà Dapo Abiọdun A fẹ́ ìdájọ́ òdodo lórí ìsẹkúpani- àwọn akẹ́kọ̀ọ́ FUOYE Gbàgbé ẹ̀sọ́ ara $40m rẹ pátápátá - Ilé ẹjọ́ sí Dienzani Ẹ wo márùn ún lára àwọn tí ilé ẹjọ́ ti yọ kúrò nípò lẹ́yìn ìdìbò ọdún 2019 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 3 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 5 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
"IAAF World Championships: Abiyamọ kan di lobìnrin tó leè sáré ""100 meters"" jùlọ l'àgbáyé"
JAMB: Ǹjẹ́ o ma ń bẹ̀rù láti ṣe ìdańwò?
ìbẹ̀rùbojo mú mi,gbogbo ara mi sì ń gbọ̀n rìrì.
OLUWA a máa gbẹ̀san lára àwọn ọ̀tá rẹ̀,a sì máa fi ìrúnú rẹ̀ pamọ́ de àwọn ọ̀tá rẹ̀.
ìjọba àpapò tí fẹ̀sùn kán àjọ àwọn òṣìṣẹ́ pé, àwọn ni wón ń fà ifaseyin bá ṣíṣe àfikún sí owó àwọn osise lórílẹ̀ èdè Naijiria.
Ọmọ Amẹrika Tyron Woodley ni Usman din dundun iya fun to fi di ilumọọka akeṣẹ.
Ọba Asiria yìí kọ àwọn ìwé àfojúdi kan sí OLUWA Ọlọrun Israẹli, ó ní, “Gẹ́gẹ́ bí àwọn oriṣa àwọn orílẹ̀-èdè yòókù kò ti lè gba àwọn eniyan wọn kúrò lọ́wọ́ mi, bẹ́ẹ̀ ni Ọlọrun Hesekaya náà kò ní lè gba àwọn eniyan rẹ̀ lọ́wọ́ mi.
akowe agba fun ajo to n ri si iroyin , naa tun salaye nipa iriri rẹ gege bi ohun
Àgọ́ tí a pa tó ìṣẹ́jú mẹ́ẹ̀dógún sí ìlú yìí, nítorí etí ibẹ̀ kò wu wa láti pa àgọ́ sí.
“Ẹ kò gbọdọ̀ jẹ ẹran pẹlu ẹ̀jẹ̀ rẹ̀, bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò gbọdọ̀ lọ máa woṣẹ́, tabi kí ẹ gba àjẹ́.
Àwọn ọ̀dọ́ ya bo ààfin Akire láti jí oríadé gbé Agbára wa kò ká àrùn Covid-19 mọ́ - Ìjọba ilẹ̀ Amẹrika Taa gan ló ni Lekki Toll gate láàrin aráàlú àti Asiwaju Tinubu?
Nítorí kì í ṣe èmi ni mo rán ara mi wá, ṣugbọn òun ni ó rán mi.
Gege bi oro re, ijoba ipinle Edo yoo satileyin fun ile-ise iwadii lati mu irorun ba eto ogbin ati imo ijinle nipinle naa.
Wọ́n fí ìdi èyí múlẹ̀ lásìkò tí wọ́n ń wáde lọ́jọ́ ajé pé kí Buhari ko gbogbo àwọn sẹ́wọ̀n, súgbọ̀n kíi ààrẹ mọ pé ẹ̀yin ìgbẹ́sẹ̀ náà kò ní fararọ.
SARS: Awọn ará ìlú fi ẹ̀rí síta nípa ìrírí wọn
Ile-ifowopamo agba  Central Bank of Nigeria (CBN), ti se alekun owo ti iye re le nigba milionu owo dollars $210 fun awon ile-ifowopamo ti won se kara-kara owo ile-okeere.
Wọn lero wi pe iṣẹ ọna naa yoo mu ẹgbẹrun lọna ọọdunrun pọun wa ṣugbọn wọn ti san miliọnu kan le diẹ fun un nigba ti wọn lu u ni gbanjo.
A tun fẹ ki ilẹ Afirika mọ nipa  soya ti Kebbi , tomato, asọ ati awon ohun elo
Malami, ni titẹle iwe abajade naa yoo tun jẹ ki eto ofin, eto ijoba tiwa-n-tiwa
Báyìí ni Àrẹ̀mọ Ooni Adeyeye Ogunwusi ṣe wọ ṣọ́ọ̀ṣì fún ìgbà àkọ́kọ́ láti bá bàbá rẹ̀ ṣe ìdúpẹ́ ìwúyè Àìmọ̀kan ló mú mi hu ìwà tí mo hù kọjá sẹ́yìn, Jonathan dárí jì mí - Dino Melaye Dino Melaye tun k'ọrin miran Dino Melaye bẹnu àtẹ lù Buhari Àwọn agbófinró tún ti'mú Dino Melaye Dino Melaye yóò f'ojú balé ẹjọ̀ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Pásítọ̀ ló sọ fún mi pé Ọlọ́run pè mí láti di Olokun tó ń bọ omi' Bí wákati díẹ̀ sẹyìn ni ìwé ìpè síbi wẹ̀jẹ-wẹ̀mu àti ayẹyẹ ìgbéyàwó Dino jẹyọ lórí ayélujara, níbi ti wọ́n ti ń pe àwọn ènìyàn sí ilé ìjọsin kan ni àgbègbè Ogudu nípìnlẹ̀ Eko.
O wa rọ awọn ọmọ Naijiria lati gbaradi fun abala keji ọwọja arun Coronavirus, ki wọn si maa daabo bo ara wọn ki ọwọja arun naa maa ba kọja afarada.
Iwọde ẹbẹ kan ti a mọ si Revolution Now ni agbẹnusọ fun aarẹ Buhari, Fẹmi Adeṣina n sọrọ nipa rẹ ninu fidio naa, oṣu meji sẹyin ki iwọde #EndSARS Now to waye ni iwọde ti a n sọrọ rẹ yii ti waye, ti ọrọ naa si ti jade.
Ó tún ń wo àwọn tí ẹ̀mí Èṣù ń dà láàmú sàn.
Nípa gbolohun yìí, ẹ̀ ń jẹ́rìí sí ara yín pé ọmọ àwọn tí ó pa àwọn wolii ni yín.
Ṣugbọn ó rọ̀ wọ́n pé kí olukuluku wọn fún òun ní yẹtí tí ó wà ninu ìkógun rẹ̀, nítorí pé àwọn ará Midiani a máa lo yẹtí wúrà gẹ́gẹ́ bí àwọn ará ilẹ̀ Iṣimaeli yòókù.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Elisha Abbo: kí ẹnikẹni ma halẹ̀ mọ Kayọde mi, ẹjọ wà nile ẹjọ́ 10 Agẹmo 2019 Oríṣun àwòrán, @others Àkọlé àwòrán, E ma halẹ Kayọde mi o -Abbo Ohun to ṣẹlẹ nigba ti awọn aṣoju senetọ ti wọn yan fun iwadii nkan ti aṣojuṣofin Elisha Abbo ṣe pade ti n ja lori ayelujara bayii.
Ó bá dá wọn lóhùn pé, ‘Rárá o!
 o di alakoso agba britani lati 1940 de 1945 ati lekansi lati 1951 deo 1955 .
Iná ẹ̀lẹ́ńtíríkì pa ẹlẹ́wọ̀n mẹ́ta lọ́gbà ẹ̀wọ̀n l'Eko Ọlọ́pàá South Africa rí ẹ̀wọ̀n ọgbọ̀n ọdún re torí ikú ọmọ Nàìjíríà Àwọn agbébọn pa ènìyàn mẹ́rinlá lásìkò ìjọsìn Èrò ọmọ Nàìjíríà ṣé ọ̀tọ̀ọ̀tọ̀ lóríi ìkéde Rélùwéè ọ́fẹ́ Èkó sí Ìbàdàn Wọn yi lawọn nkan mẹwaa to yẹ ni mimọ nipa fasiti tuntun yi : Ni oṣu Kẹwaa, ọdun 2018 ni ijọba apapọ buwọlu owo ti wọn yoo fi kọ ile ẹkọ yi ni ibamu pẹlu ilana ajọ to n ṣakoso fasiti ni Naijiria (NUC) Fasiti yi yoo gbajumọ iwadii ati idagbasoke ohun amuṣagbara ti yoo mu idagbasoke ba ẹka irinna ni Naijiria.
Emir of Kano: Èyí ni àwọn ohun márùn ún tó yẹ kí o mọ̀ nípa Sanusi tí wọ́n yọ nípò Emir
Olusegun Obasanjo: Ẹ máṣe bú Ọlọ́run torí ọrọ̀ ajé tí kò dára àti òṣì tó gbalẹ̀ ní Nàíjíríà
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Mamman Daura: Ọmọ Nàíjíríà ní ọgbọ́n àti gbé ààrẹ fún ẹ̀kùn àríwá ni 29 Agẹmo 2020 Oríṣun àwòrán, Others Awọn eniyan ti bẹrẹ si ni fi ero wọn han lori ayelujara nipa ohun ti ọrẹ timọ-timọ aarẹ Buhari, Mamman Daura sọ.
Igbese ileeṣẹ Bristow naa tẹle eleyii ti ileeṣẹ ọkọ ofurufu Air Peace naa gbe pẹlu bi wọn ṣe le awọn awakọ ofurufu to le ni aadọrin, ti wọn si ge owo oṣu awọn oṣiṣẹ kuru.
ikunsinu dani laarin awon ololufe iko agbaboolu mejeeji jake-jado agbaye.
"All For Love - Wizkid ati Bucie (2017) Ninu awo orin yii, Wizki ọba orin Afro tun gbe tuntun yọ pe oun to gbangbaa sun lọyẹ pẹlu ọmọbabinrin nile orin eyi ti wọn fi jọ gbe orin ""All For Love"" jade pẹlu ede Yoruba, Xhosa ati Gẹẹsi ti Maphorisa tun wa sa awọn ohun elo orin bii duru, gita ati woroworo xylophone si i."
Àwọn ìròyìn míì tí ẹ lè nífẹ sí Segun, Máàkì tóo ní kọ́ ni yóò ṣé atọ́nà oríire rẹ láyé A ò tì ilé Saraki pa ní'lú Eko - EFCC Sowore: olùdíje Ààrẹ tó fẹ gbà Nàìjíríà padà fún àwọn ọdọ Ohun tó yẹ kí o mọ̀ nípa OIC rèé Alhaji Wasiu Ayinde ni bi oun ba tilẹ wa jẹ alagbafọ fun Alhaji Sikiru Ayinde Barrister, oriire lo jẹ fun oun tori oun sin in tọkan tọkan.
Orile-ede Egypt fofin de egbe Brotherhood ni odun 2013, nigba ti ogagun agba ti o di Aare Abdel Fattah al-Sisi fipa gbajoba lowo Mursi Sisi leyin odun kan ti o gori alefa, ni eyi ti ogoro awon alatileyin Aare ti won yo kuro nipo naa ti wa latimole latigba naa.
Aare wa n ro awon omo orile ede yii lati fowosowopo pelu re ni ona ti won yoo se mu ipinnu yii wa si imuse.
èmi gan-an yóo wá kẹ̀yìn si yín, n óo sì jẹ yín níyà ní ìlọ́po meje, fún ẹ̀ṣẹ̀ yín.
N kò rán ọ sí àwọn orílẹ̀-èdè tí wọn ń sọ èdè mìíràn tí yóo ṣòro fún ọ láti gbọ́.
Lopetegui sapejuwe ifopin si ise re ohun gege bi ohun ti o ba oun ninu je lopolopo, leyin iku iya re.
" Aṣiṣe ti ko dara gba a ni yoo jẹ ti ọba ko ba ṣe etutu ki o to jọba, abi ki wọn ma bọwọ fun asa ti wọn ba fẹ sin ọba"" Oríṣun àwòrán, @ObatAkinruntan Onimọ nipa eto ati asa ilẹ Yoruba naa ni oro ati etutu ti wọn n ṣe fun awọn ọba lo ya ọba sọtọ, nitori ẹlomiran ni owo amọ wọn ko le e pe e ni ọba, nitori ko le e ṣe oun ti ọba n ṣe."
Gege bi akonimoogba iko Yobe Stars’, Ganaru Mohammed se so,”Esi ifesewonse yii bami ninu je pupo.
Lẹ́yìn tí aṣojú iléeṣẹ́ náà fún ìbánisọ̀rọ̀ pẹ̀lú àwùjọ, Sergey sọ fún olóòtú ètò náà pé kò sí alámọ̀dájú ọkùnrin kankan ní iléeṣẹ́ naa, ó ní olóòtú ètò náà ṣe ìlérí láti padà wá lẹ́yìn tí ó bá ti bá olóòtú àgbà ètòo wọn sọ ọ́.
Ojú tí n óo gbé sókè, mo rí i pé ẹ ti ṣẹ̀ sí OLUWA Ọlọrun yín, ẹ ti yá ère wúrà tí ẹ fi iná yọ́, ẹ ti yára yipada kúrò ní ọ̀nà tí OLUWA Ọlọrun yín pa láṣẹ fun yín.
 Ìnira tí ó rọ mọ ni eéwo.
 kóòdù ìfìwéránṣé agbègbè yí sì jẹ ́ 233 .
Amugbalẹgbẹ fun Jegede to ba BBC Yoruba sọrọ, Kunle, sọ pe awọn gbe igbesẹ yii lẹyin ọpọlọpọ ifarabalẹ.
Bee si ni, O fikun un pe, igbe aye alafia agbegbe ohun ro mo ibasepo ti o donmonran ti o wa laarin awon ara ilu ati iko omo ogun naa.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ẹ máà fi Eko wé Ghana lórí dídẹ okùn ìgbélé, ìyàtọ̀ wà níbẹ̀-Hamzat, igbákejì gómìnà Eko Ìjọba Osun dẹkùn lọrun àṣẹ konile ó gbélé Koko ohun mẹ́wàá tí Gomina Oyetola báwọn èèyàn Ìpínlẹ̀ Osun sọ Ìjọba Ìpínlẹ̀ Osun tí dẹkùn àṣẹ konile ó gbé lé ọlọsẹ méjì ni ọrùn àwọn èèyàn jákèjádò Ìpínlẹ̀ náà.
Idi ree tawọn ipinlẹ kan fi kede ofin konile o gbele lọna ati fopin si ifẹhonuhan awọn ọdọ yii.
Lọ́gán ti a ba ti ba ara India ọhun ni gbolohun tan la o gbe ẹjọ naa kuro lọdọ tiwa sọwọ awọn agbofinro tọrọ̀ kàn.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Mourinho kò ọ́rọ́ rẹ̀ jẹ,o padà wá dì akọ́nimọ̀ọ́gbá tuntun fún ikọ̀ Tothenham 20 Bélú 2019 Oríṣun àwòrán, SpursOfficial Aya bẹ silẹ o bẹ sare lọrọ Jose Mourinho to gba iṣẹ akọnimọọgba tuntun Tottenham fẹ jọ.
Lẹ́yìn náà Rebeka mú aṣọ Esau, àkọ́bí rẹ̀, tí ó dára jùlọ, tí ó wà nílé lọ́dọ̀ rẹ̀, ó wọ̀ ọ́ fún Jakọbu ọmọ rẹ̀.
Bí OLUWA ti pàṣẹ fún Mose.
Ipolongo idibo ọdun 2015 bẹrẹ lọjọ kẹrinlelogun, oṣu keje, ọdun 2015 ni eyi to pari lọjọ kọkandinlogun, oṣu kọkanla ọdun 2015.
Bí obinrin bá tọ ẹranko lọ, tí ó sì tẹ́ ara rẹ̀ sílẹ̀ fún un láti bá a lòpọ̀, pípa ni kí ẹ pa òun ati ẹranko náà, ẹ̀jẹ̀ wọn yóo wà lórí ara wọn.
 a ṣe àdàkọ àwọn orin tí a gbà jọ , a sì ṣe àgbéyẹwò àwọn iṣẹ ́ tí wọn ti wà nílẹ ̀ lórí orin ní àwọn agbègbè mìíràn .
Nitori naa ,a n ro awọn ọmọ ẹgbẹ  wa lati mu suuru fun wa gege bi a se n lakaka lati yanju awọn ipenija to wa ninu ẹgbẹ  yii ati lati tun fidi ẹgbẹ  yii mule si lona ti yoo fi jawe olubori ninu eto idibo odun to n bo.
Eka ileesẹ naa to wa ni Sokoto ni o gba awọn mejeeji yi mu ti wọn si ti safihan owo naa ati awọn afunrasi yi loju opo Facebook ajọ EFCC.
Òògùn araríro míì, Tramadol, náà sì ń tàn kálẹ̀, bíi òògùn táwọn èèyàn ń sì lò - gẹ́gẹ́ bi akọ̀ròyìn BBC, Stephanie Hegarty se sàwárí rẹ̀, èyí tún leè ta epo pẹtiroolu sí ina ìgbésúnmọ̀mí tó ń jó ní ìlú Maiduguri.
O kò gbọdọ̀ bá ọmọ ọmọ rẹ lobinrin lòpọ̀, kì báà jẹ́ ọmọ ọmọ rẹ obinrin tabi ọmọ ọmọ rẹ ọkunrin, nítorí ohun ìtìjú ni ó jẹ́ fún ọ, nítorí pé, ìhòòhò wọn jẹ́ ìhòòhò rẹ.
Lóòótọ́ àwa ọmọ Nàìjá a fẹ́ran ata, àgàgà àwa ti ilẹ̀ Oòduà.
Ńjẹ́ ìwọ ni ọkùnrin náà tí ó pa Àǹjànnú-ìbẹ̀rù bẹ́ẹ̀?
Charles Okah gba'dajọ ẹwọn gbere Lush beauties: Ara sisan kii n ṣe arun Ajafẹtọ naa ni bi o tilẹ jẹ wi pe nkan ti n yi pada lori pipese eto ẹkọ fun awọn obinrin ṣugbọn aabo fun wọn si n mẹhẹ patapata.
Àwọn géńdé bá dìde, wọ́n fi aṣọ wé e, wọ́n gbé e lọ sin.
ọmọ Joṣua ọmọ Elieseri, ọmọ Jorimu, ọmọ Matati, ọmọ Lefi, 
’’Aare Buhari tun so pe , ijamba ina ti o sẹlẹ ni ọja Jos yii,  je iketa iru re  ti yoo waye laarin odun mewaa lorile ede Naijria.
Iṣẹ́ bọ́ lọ́wọ́ ọ̀gá ilé iṣẹ́ tó bẹ́nu àtẹ̀ lu Obinrin Wo ohun tó yẹ kí o mọ̀ nípa ikọ̀ Burundi Lẹ́yìn ò rẹyìn Seyi Makinde búra fún ìgbìmọ̀ olùgbaninímọ̀ràn Bí eṣinṣin bá kọ́já, wíwọ́n ní, lásìkò ìṣíde AFCON 2019 Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, AFCON 2019: Inú mi dùn pé mo jẹ́ ẹni àkọ́kọ́ tó ṣojú Nàíjíríà fún ìgbà 100 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Irú nǹkan bẹ́ẹ̀ kò ṣẹlẹ̀ rí, bẹ́ẹ̀ ni kò ní ṣẹlẹ̀ mọ́.
Nítorí wọ́n ronupiwada nígbà tí Jona waasu fún wọn.
Merari ni baba ńlá àwọn ọmọ Mahili, ati ti àwọn ọmọ Muṣi.
O ti pe ọdun kan ti wọn ni ki Mugabe fi ipo silẹ nitori ailera rẹ.
Ni ipari, O salaye pe won yoo se agbekale eto idanileko lati tun mu awon ohun otun miiran wa siwaju awon adajọ naa.
Ajulo lọ sọ eyi lasiko to n ba BBC Yoruba sọrọ lori igbesẹ Igbakeji Aarẹ Yemi Osinbajo lati ṣe ẹjọ pẹlu ẹsun wi pe awọn kan n ba orukọ oun jẹ.
Ninu ikede kan ti ajọ naa fi sita l'oju opo Facebook rẹ̀ lo ti sọ pe ajọ naa ta kété si oṣelu, ti ko si ko ipa kankan ninu idibo to waye laipẹ nipinlẹ Ekiti.
"ni awọn mark ati matthew àpamọ , awọn balogun ọrún ni idiyele comments lori awọn iṣẹlẹ : "" lóòótọ ni ọkunrin yi Ọmọ Ọlọrun !"
Mo ti pàṣẹ fún opó kan níbẹ̀ láti máa fún ọ ní oúnjẹ.
Lọjọ kẹtala Osu yi ni ile alajamẹrin kan dawo ladugbo Ita Faji nibi ti eeyanogun ti padanu ẹmi wọn.
"O ni ""Adupẹ fun aṣeyọri ti a ri ninu idibo abẹlẹ ti a ṣe kọja, ṣugbọn oun to wa niwaju wa ṣi ju iṣẹgun ti a ti ni sẹyin lọ."
pe ikọ naa lo pa Tiyamiyu Kazeem, to jẹ ọkan lara ọmọ ikọ ọhun.
Àkọlé àwòrán, MKO Abiola Stadium Lọdun 2003 ni wọn bẹrẹ si ni lo papa iṣere yii nilu Abuja.
    Bí mo ti wí lẹ́ẹ̀kan, aṣọ kò wọ́pọ̀ ní ìlú náà, nínú agbo ilé ìbẹ̀, púpọ̀ ló jẹ́ pé aṣọ kan ṣoṣo ni ó wà fún gbogbo wọn, wọ́n a si ṣe èetò bí awọn ó ti ṣe lò ó.
Nibi ọrọ de duro bayi, eeyan mọkandinlogoje (139) lo ti fara kaasa arun na lorilẹede yii, awọn meji lara wọn ti jẹ Ọlọrun nipe, ti mẹsan an si ti ri iwosan.
"Awọn orukọ miran ti wọn tun maa n a pe ni ""Lion"", ""Liquid Metal"", ""Indaboski Pahose"" ati orukọ míràn bẹẹ."
Iwadii fihan wi pe ile isẹ to gbe ẹro naa jade ko sọ fun awọn eniyan lẹkunrẹrẹ wi pe awọn fọto wọn ti wọn ba fi sori ẹrọ FaceApp yoo wa lọwọ wọn fun igba pipẹ.
Àwọn ọmọ ti Bẹnjamini ni: Bela, Bekeri, Aṣibeli, Gera, Naamani, Ehi, Roṣi, Mupimu, Hupimu, ati Aridi, 
Wọ́n gba ìlú Ijoni ati Dani, Abeli Beti Maaka, ati gbogbo agbègbè Kineroti, pẹlu gbogbo agbègbè Nafutali.
Oun ni olori awọn obinrin ninu ẹgbẹ oṣelu APC ti aarẹ Buahri lo fi n tukọ Naijiria bayii.
Lara awọn iroyin ofege naa ni pe awọn eleto ilera fẹ lo ẹrọ kọmputa ti wọn ko le foju ri si ara eeyann, ati bẹbẹ lọ.
Òǹlò Mohammad Mynuddin jábọ̀ ìfàsẹ́yìn láti ọwọ́ àwọn òṣìṣẹ́ ìjọba láti kápá àjàkálẹ̀ náà:
Ninu gbogbo ìyà tí wọ́n jẹ, òun pẹlu wọn ni,angẹli iwájú rẹ̀ sì gbà wọ́n là.
Amaechi sọ pé, ile iṣẹ́ ọkọ oju irin (NRC) yóò gbe yàrá ìkérò si méjì míràn láti Itakpe si Warri, wá si ti Kaduna-Abuja.
Iṣọkan ẹgbẹ Ajeje ọwọ kan ko gbẹru d'ori, agbajọws la fi n sọya.
nítorí pé a ti ṣetán láti pa ìlú yìí run, nítorí ẹ̀sùn tí wọ́n fi ń kan àwọn ará ìlú yìí ti pọ̀ níwájú OLUWA, OLUWA sì ti rán wa láti pa á run.
Labẹ ofin tuntun naa, ileeṣẹ to ba jẹbi ẹsun fifi iya jẹ akanda ẹda kankan yoo san miliọnu kan Naira gẹgẹ bi owo itanran, ti ẹnikan yoo si san ọgọrun un ẹgbẹrun Naira tabi lọ si ẹwọn oṣu mẹfa pẹlu rẹ.
Jesu dá a lóhùn pé, “ ‘Fẹ́ Oluwa Ọlọrun rẹ pẹlu gbogbo ọkàn rẹ, ati gbogbo ẹ̀mí rẹ, ati ní gbogbo èrò rẹ.
Gbajúgbajà òṣèré “Blue film'' wọ gàù ẹ̀sùn fífipá bá obìrin 13 lòpọ̀ Ọ̀kọ̀ ojú omi dànù, ènìyàn méjì kù, ẹnìkan di àwátì Àṣírí tú!
"Ẹwẹ, o ni ""loju na wa pada, ọkọ baalu awọn ọmọ ogun ofurufu ri idamu nla ninu ofurufu ṣugbọn awakọ atawọn oṣiṣẹ inu baalu naa ṣe iṣẹ takun takun lati da a pada sọna rẹ""."
 Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Ìgbà tí mo máa fi lajú sáyé padà, ọ̀fọ̀ ikú mi ní wọ́n ń kígbe' Orílẹ̀-èdè náà kìí ṣe eyí ti àjọ iṣọkan agbáyé rí gẹ́gẹ́ bi orílẹ̀-èdè, kò sì sí orílẹ̀-èdè to rí Ariwa Cyprus bi orilẹ̀-èdè to dá dúró.
Èyí ni ọ̀nà tí àwọn obìnrin n gbà kó ara wọn sí wàhálà nítorí ara bíbó Gbọ́ àsọtẹ́lẹ̀ látẹnu Small Mummy Ọjọ́ mẹ́fà ni mo lò lọ́dọ̀ àwọn Fulani Ajinigbe - Hamzat Àbàwọ́n funfun ló sún Temilola di arìnrìnoge Vitiligo Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí 2 sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 2:23 Fídíò, Water Generator: Ó leè ṣiṣẹ fún wákàtí mẹfà, kó tó sinmi, Duration 2,2310 Òkùdu 2020 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
 a lè fi àwòrán-atóka igi fi èyí hàn báyìí .
“Nígbà tí àwọn eniyan rẹ bá lọ sójú ogun, níbikíbi tí o bá rán wọn, láti lọ bá àwọn ọ̀tá wọn jà, tí wọ́n bá kọjú sí ìhà ìlú tí o ti yàn yìí ati sí ìhà ilé tí mo kọ́ fún ìjọ́sìn ní orúkọ rẹ yìí, 
Lóòótọ́ èmi ni ọmọbìnrin náà ti orúkọ rẹ̀ ń jẹ́ àjẹ́dìran, ẹni ti ń gbe ilé alágbẹ̀dẹ.
Èèyàn 1096 ló ti ni àrùn Coronavirus ní Nàíjírìa báyìí Oluwo sọ̀rọ̀ lórí fídíò to gba ayélujára kan pé ó ń we igbó Èèyàn 114 míràn tún ti ní àrùn Coronavirus ní Nàíjírìa Bakan naa ni wọn fikun wi pe awọn ko binu si ijọba apapọ amọ ti wọn ba ni irẹsi miran to dara awọn yoo gba lọwọ wọn Ẹkunrẹrẹ fidio naa ni eyi; Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí kan sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
Ajakalẹ aarun tun mọ si pe arun naa n kaakiri orilẹede pupọ ni ẹẹkan naa.
Bó ti wà láti ìpilẹ̀ṣẹ̀ ayé nìyẹn.
Ibeere nla re e ti ko si si ẹni to mọ esi rẹ bayi.
Ní ọ̀la ni ìwọ ati àwọn ọmọ rẹ yóo kú; OLUWA yóo sì fa àwọn ọmọ ogun Israẹli lé àwọn ará Filistia lọ́wọ́.
Ìwádìí BBC: Àwọn ará Èkìtì ń sáré gba N4,000 sáájú ìbò Nàìjíríà bá RCCG, ìyá Folu Adeboye yọ ayọ̀ 70 Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ekiti Decides: Abiọdun Aluko ní báwọn se kàwé tó l‘Ekiti, ìyà sì ń jẹ àwọn Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Ewe, Juventus di iko agbaboolu akoko ti yoo gba ife eye ohun lai fayegba ki ami ayo Kankan wonu agbon won, bee si ni odaju pe iko naa yoo tun gba ife eye idije Serie A, eleyi ti yoo di igba kerin lera bayii.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ajax k'ógun ja Tottenham, àlù mọ́lé ni wọ́n nà wọ́n 30 Ìgbé 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 1 Èbibi 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ajax n koju Tottenham Ẹkọ ko ṣ'oju mumu fun ikọ agbábọ́ọ̀lù Tottenham, bi ikọ agbabọọlu Ajax ṣe fi ìya jẹ wọn mọle pẹlu ami ayo 0-1.
"Eton College: Awọn ọhun to yẹ ni mimọ: Orisun: Eton College ati BBC Olukọ agba ile ẹkọ naa sọ pe oun yoo fiwe pe Onyeama lati le tọrọ aforijin lọdọ rẹ ""ki oun si jẹ ko mọ pe ko si igba ti ko le pada wa si ile ẹkọ Eton'' ""Gbogbo wa la gbọdọ sọrọ sita, ki a si mọkan pe a fẹ se daada - mo setan lati samulo anfaani asiko yii lati fi sokunfa iyipada tootọ, tọkan-tọkan'' Ki wa ni Onyeama sọ?"
Ní ìparí, ẹ jẹ́ alágbára ninu Oluwa, kí ẹ fi agbára rẹ̀ ṣe okun yín.
He met Nigeria under the military rule which had run consecutively for over a decade and bred a culture of arbitrariness, flagrant abuse of human rights and disdain for the rule of law all of which relegated our dear country, Nigeria, to the unenviable league of pariah states in the comity of nations.
Mo gbẹ́ kànga ní ilẹ̀ àjèjì,mo sì mu omi rẹ̀;ẹsẹ̀ àwọn jagunjagun mi ni ó sì gbẹ́ àwọn odò Ijipti.
Gégé bí ìlànà tó, ìwòye ni pé kí àwọn kòkòrò aifojuri yìí kò dinku nínú agbára rẹ kì í sì má lè pá ènìyàn mo ti bá ya ṣùgbọ́n kò sí afọwọ́sọ̀yà pé.
Ẹ óo fi ààyè sílẹ̀ ninu ilẹ̀ yìí fún Tẹmpili mímọ́, ìbú ati òòró rẹ̀ yóo jẹ́ ẹẹdẹgbẹta (500) igbọnwọ, ẹ óo sì tún fi aadọta igbọnwọ ilẹ̀ sílẹ̀ yí i ká.
“Bí àwọn arakunrin meji bá jùmọ̀ ń gbé pọ̀, tí ọ̀kan ninu wọn sì kú láìní ọmọkunrin, aya ẹni tí ó kú kò gbọdọ̀ lọ fẹ́ ará ìta tabi àlejò.
Àwọn alágbára ńkọ́ àwọn ọmọ ẹnití kò ní agbára bí ti wọn tà.
Ìṣẹ̀lẹ̀ ọ̀hún tó wáyé ní Okpoko, ní ẹgbẹ́ Onisha, ìjọba ìbílẹ̀ Ogbaru, ìpínlẹ̀ Anambra bẹ́ẹ̀ sì ni àwọn ọlọ́pàá ti mú u ti wọ́n sì ti bẹ̀rẹ̀ ìwádìí wọ́n lórí ọ̀rọ̀ náà.
 Àwon èka èdè tí ó wà ní abẹ ́ rẹ ̀ ni okene ( hima , ihima ) ìgbàrà ( etunno ) Èbìrà ní ìsupò èka èdè , wón ń lò ó ní ilé ìwé .
Ishaq Oloyede: Jamb ko ni fi esi idanwo silẹ lẹsẹkẹsẹ
"Ọkan lara wọn sọ fun BBC pe too ba ri ilu kan ti wọn ti pa gbogbo eeyan ti wọn si n ji wọn gbe, igba mii too ba san owo itanran gan O ni: ""Ki n ma parọ, ijọba ti kuna, wọn ti ja wa kul tori lati ọdun marun sẹyin ni iṣoro ati wahala ti n wa""."
"Oríṣun àwòrán, @AdedejiKenny16 Gẹgẹ bo ṣe sọ, o ni ""bo tilẹ jẹ pe arun naa n dun mọhuru mọhuru, ẹgbẹrun mẹwaa ẹka tuntun ni ijọ yii ṣi lai gba owo ọrẹ kankan, a o fi oju imu eṣu danrin."
Ogún ọdún ni mo fi gbáradì fún àjàkálẹ̀ ààrùn coronavirus
Awọn ounjẹ ti wọn fi iyẹfun ṣe bii Pọfu Pọọfu, Shin Shin, Bisiki Panbolabola atawọn jijẹ ati eso mii to ba wa lode.
Ìròyìn ti o jade ni ọjọ́ Ìṣẹ́gun, ọjọ́ kẹwa, oṣú karun, ọdún Ẹgbàá-le-mẹ́rìndínlógún, sọ wi pé Olóri Òṣèlú Ilú Ọba, David Cameron pe orilẹ̀ èdè Nigeria ni ilú ti ó hu iwà ibàjẹ́ jù ni àgbáyé.
Àwọn ọkùnrin mẹ́fà, tí a ti ṣe ìrìbọmi fún tẹ́lẹ̀, ni wọ́n kópa.
Sugbọn o sọ fun awọn ọlọpaa pe bi awọn ṣe de agbegbe fasiti Baze ti o wa ni Abuja ni oníbàárà naa duro l'ẹgbẹ ọna ti o si fa ọbẹ yọ ti o gba gbogbo nkan to wa lọwọ oun.
Atẹjade kan lati ileeṣẹ ọlọpaa ni ipinlẹ ṣalaye pe, kọmiṣọna ọlọpaa ni ipinlẹ naa ti jawe ikilọ ranṣẹ sawọn to kundun idajọ ọwọ nibẹ ati pe ẹnikẹni ti ọwọ ba tẹ yoo kabamọ ṣiṣe bẹẹ.
 O ni “Nitori naa, won ko ni da egbe
Elija tún sọ fún Eliṣa pé, “Dúró níhìn-ín, nítorí pé OLUWA rán mi sí Jẹriko.
Lẹyin naa lọ si ikọ agbabọọlu Southampton nibi to ti lo ọdun kan ati abọ ki o to darapọ mọ Tottenham lọdun 2014.
17 Bélú 2020 EndSARS Protest: Wo bí olùwọ́de EndSARS, Eremosele Adene ṣe gba òmìnira lọ́wọ́ ọlọ́pàá20 Bélú 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
"Bi ọrọ ṣe ri bayii buru pupọ ni iwoye temi.
Wọn ni eyi yoo le dena ki APC o ma ni iriri ohun to ṣe PDP l'ọdun 2015.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù PDP: Buhari gbọdọ̀ tọrọ àforíjìn lọ́wọ́ ọmọ Nàíjíríà fún èdè àbùkù tó pè 5 Òkùdu 2019 Oríṣun àwòrán, @Buhari official Àkọlé àwòrán, Irú ọ̀rọ̀ báyìí kò yẹ kó tí ẹnu ààrẹ jáde- Kola Ologbodiyan Ìsọ̀rọ̀ ní ìgbèsì, ẹgbẹ́ òṣèlú People's Democratic Party (PDP) ti fẹ̀sì si ọ̀rọ̀ ààrẹ Muhammadu Buhari to ni Eni ibi ti kò ṣe máà nìí ni àwọn ènìyàn Abuja""."
Tani ẹ rò pé yóò lọ nílé ẹlẹ́gbọ̀n ọ́n àgbà BigBrotherNaijia lálẹ́ òní?
Ṣe ni gbogbo iṣan yóò dì pọnpọn tí obìnrin kò sì ní lágbára lórí rẹ̀.
Iroyi tun so pe wahala to sele ni opolopo ibudo idibo to
Gomina Akeredolu ni bi oun ba tun gbọ pe eeyan kan ni ipinlẹ naa tun ko arun naa, oun yoo ti gbogbo ipinlẹ Ondo pa ni.
Gọngọ sọ, ẹlẹ́há pàdé àwọn tó lùú ní jìbìtì nílùú Eko lọ́jà Ibadan
Gomina lpinle Osun naa yoo tun kọ si ile iwe, ati lati tun ọpọlọpọ ṣe.
Ìletò kan ní ẹ̀báa Jamshedpur ní Jharkhand.
Ènìyàn 829 ló ní ààrùn Covid-19 ní Nàìjíria nínú èsì àyẹ̀wò tó jáde lọ́jọ́ sátidé Èsì àyẹ̀wò Coronavirus tuntun to jáde lọ́jọ́ satide lórílẹ̀-èdè Naìjíríà fi han pé ènìyàn ẹgbẹ̀rin àti mọ́kandinlọ́gbọ̀n tún ṣẹ̀ṣẹ̀ lùgbàdì ààrùn Covid-19 ni Nàìjíríà.
Awọn olujosin to wa nile ijọsin lọjọ naa sọ fun awọn akọroyin pe Pasitọ naa, Elisha Misiko jokoo niwaju ninu ijọ Nibi to joko si nibẹ si lo ti dide lọ ba iyawo rẹ lori pẹpẹ to si gun un pẹlu ọbẹ to fi pamọ sabẹ ẹwu to wọ.
”Ọdọmọkunrin náà bá dáhùn pé, “Ìwọ ni, Balogun.
Lara awọn to wa ninu ile naa, eeyan kan fara pa.
4%) ni iwa riba gbigba ti gogo julọ.
Má gba ọ̀rọ̀ òtítọ́ rẹ lẹ́nu mi rárá,nítorí ìrètí mi ń bẹ ninu ìlànà rẹ.
Ọpọ ọmọ ilẹ Yoruba lo maa n tiraka lati ri ti aje se, ti ara wọn kii si balẹ ti buruji ko ba si lọwọ wọn.
Gẹgẹ bo ṣe sọ, o ni obinrin naa ko bere owo lọwọ ohun, ṣugbọn oun gbe igbesẹ naa nitori oun ti ṣe alaini ri, ati pe Oluwa lo ni ki oun ṣe bẹẹ.
“Yóo bá ọ ṣẹgun àwọn ọ̀tá tí ó bá dìde sí ọ.
Àwọn mẹ́ta tó ti pegede fún ipele ẹlẹ́ni mẹ́rìndínlógun Morocco àti Ivory Coast yoo gbẹ́na wóju ara wọ́n ní ààgo mẹ́fà ìrọ̀lẹ́, South Africa àti Namibia yoo figagbága ní ààgo mẹ́sàn alẹ́, nígbà ti Tunisia ati Mali náà kò ni gbẹ́yìn ni ààgo mẹ́ta ààbọ ọsán òní.
Ìyàn tí ó mú ní ilẹ̀ Kenaani ṣá túbọ̀ ń pọ̀ sí i ni.
Awon eleka-jeka ohun ni a ti ri: eto abo, ilana ofin, kikopa ninu oro eto omo eniyan, fifi ese eto oro-aje mule, ati mimu igbe aye rorun fun awon ara-ilu.
Oríṣun àwòrán, @NigerianPolice Ẹwẹ, Dokita Sule ni ọkan oun gbọgbẹ, ti inu oun si bajẹ gidigidi lori isẹlẹ naa nitori oogun lawọn eeyan mẹtẹẹta ti wọn ji gbe naa lọ ra fun ile iwosan naa nilu Eko, asiko ti wọn si n pada bọ lọwọ alẹ ni wọn ko sọwọ awọn ajinigbe.
NCDC lo kede bẹẹ loju opo Twitter rẹ, ipinlẹ Eko si ni iye eeyan to pọ ju to ṣẹṣẹ ni arun ọhun ti wa.
Coronavirus tún ti ṣe ọṣẹ́ lórí iṣẹ́ líla ojú ọ̀nà relùwe láti Eko sí Ibadan - Ìjọba àpapọ̀ Bakan naa ni o sọ wi pe eto isinku ọba ilẹ Yoruba ti yipada nitori wọn kii sin ẹnikẹni mọ ọba mọ, bẹẹ ni wọn kii yọ ẹya ara kankan lara ọba mọ to ba waja, nitori wọn ti fi ẹran rọpo awọn etutu ti wọn ma n ṣe.
Ọkunrin kan wà ní Kesaria tí orúkọ rẹ̀ ń jẹ́ Kọniliu.
N kò ní jẹ́ nǹkankan lójú rẹ, ṣugbọn àwọn iranṣẹbinrin tí o sọ nípa wọn yìí, yóo bu ọlá fún mi.
Nígbà tí Jakọbu gbọ́ pé ọkà wà ní ilẹ̀ Ijipti, ó wí fún àwọn ọmọ rẹ̀ pé, “Kí ni ẹ̀ ń wo ara yín fún?
Ijọba apapọ lori itakun ikansiraẹni, Twitter ni, awọn ti pasẹ fun awọn ẹsọ alaabo lati gbe igbesẹ to peye ki aabo to kun ojuwọn lee wa ni agbegbe Mubi.
Láti ìgbà tí mo ti mọ̀ yín, kò sí ìgbà kan tí ẹ kò ṣe orí kunkun sí OLUWA.
ti n sa gbogbo ipa wa,a ti mu awon afurasi  to lowo nibi isele naa, a si mo pe laipe, a o
“Ẹ̀yin nìkan ni mo mọ̀ láàrin gbogbo aráyé, nítorí náà, n óo jẹ yín níyà nítorí ẹ̀ṣẹ̀ yín.
AMAA 2018 Ami eye fawon asaraloge to dara julo
Ṣùgbọ́n mo ṣe àkíyèsí ibi tí ọkùnrin náà bá lọ nígbà tí ó sì ṣe díẹ̀ tí mo wo àgbègbè yíká mo rí i pé òjò tún ṣú, láìpẹ́ mo bẹ̀rẹ̀ sí gbọ́ ariwo, àṣé ariwo ẹ̀fúùfù ni.
Àní sẹ́, Ọlọrun rán Ọmọ rẹ̀ wá gẹ́gẹ́ bí eniyan ẹlẹ́ṣẹ̀ láti pa ẹ̀ṣẹ̀ rẹ́.
Nígbà tí Balaki gbọ́ pé Balaamu ń bọ̀, ó jáde lọ pàdé rẹ̀ ní ìlú Moabu tí ó wà létí odò Arinoni ní ààlà ilẹ̀ Moabu.
Aarun yii maa n ba awon agba ja, awon ti ara won ko pe to, awon alaboyun ati awon omo tuntun jojolo.
Ẹ̀rù OLUWA ba àwọn tí wọ́n wà ninu ọkọ̀ lọpọlọpọ, wọ́n rúbọ, wọ́n sì jẹ́ ẹ̀jẹ́ fún OLUWA.
"Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Helen Paul sọ idi tó fi gba orúkọ ní kékere ""Aafin ni awọn ọdọ wa ti ọba n ba wọn sọrọ."
Minisita to n ri si imo ijinle ati imo-ero lorile-ede yii, Dokita Ogbonnaya Onu lo jabo oro ohun lasiko to n se ifilole igbimo alabesekele kan niluu Abuja ti yoo maa majuto sise amulo kemika epo robi ohun.
Champions League: Ṣé Liverpool ò wọ gàu lọ́wọ́ Messi báyìí?
Gbogbo ọkùnrin tó bá ti bàlágà, tó sí lé mu ọwọ́ lọ sẹnu láì woju olójú, náà ni ìyàwó yẹ kó wà lẹ́ẹ̀dẹ̀ rẹ̀.
Nítorí pé ìwà wèrè wọn yóo hàn kedere sí gbogbo eniyan, gẹ́gẹ́ bí ti Janesi ati Jamberesi ti hàn.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù AFCON 2019: Cameroun yọ Seedorf nípò gẹ́gẹ́ bíi olùkọ́ni Indomitable Lions 16 Agẹmo 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ajọ ere bọọlu ni Cameroun ṣalaye pe Seedorf ko lee mu ẹjẹ to wa ninu iwe adehun igbanisiṣẹ rẹ ṣẹ ni wọn fi yọọ nipo Ajọ ere bọọlu lorilẹede Cameroun ti rọ olukọni ẹgbẹ agbabọọlu orilẹ-ede naa, Clarence Seedorf loye lẹyin to kuna lati gba ife ẹyẹ AFCON lọdun yii.
”Jesu dá wọn lóhùn pé, “Mo ti sọ ẹni tí mo jẹ́ fun yín láti ìbẹ̀rẹ̀.
Ọjọ kẹtadinlọgbọn oṣu keji ọdun 1977 ni Maradona bẹrẹ si ni ṣoju orilẹede Argentina.
 Ó ní ìdí tí òun fi jí owó náà gbé nip é òun kò bímọ fún orímóògùnjẹ ́ òun kò sì fẹ ́ kì tòun ó gbé sílé rẹ ̀ nítorí pé ọmọ tì obìnrin bá bí fún ọkọ ni wọ ́ n fi máa ń pín ogún ọkọ náà ní ilẹ ̀ yorùbá .
Bí eniyan bá gbìyànjú láti fi gbogbo nǹkan ìní rẹ̀ ra ìfẹ́,ẹ̀tẹ́ ni yóo fi gbà.
Gbogbo àwọn tí ó rí mi ní ń fi mí ṣe yẹ̀yẹ́;wọ́n ń yọ ṣùtì sí mi;wọ́n sì ń mi orí pé,
Ó wá ninu ọlá ńlá rẹ̀.
Oludasilẹ ijọ Sọtitobirẹ Miracle center nilu Akurẹ, Woli Alfa Babatunde pada si ile ẹjọ lori iṣẹlẹ ọmọdekunrin kan to sọnu ni ileejọsin naa loṣu kọkanla ọdun to kọja.
Agbẹnusọ Gomina ipinlẹ naa, Taiwo Adisa sọ fun BBC pe kii ṣe gbogbo ile iwe ni yoo di ṣiṣi O ni ayafi awọn ile iwe to ba tẹlẹ ilana ti ajọ eleto ilera gbe kalẹ lati dabo bo awọn akẹkọ.
Nitori naa iṣejoba oun yoo pese ileewosan alabọde kaakiri wọọdu.
Awọn alaṣẹ ẹgbẹ oṣelu APC pe ipade fun awọn aṣofin to jẹ ọmọ ẹgbẹ wọn lati jiroro lori bi wọn yooo ṣe yan awọn olori ile aṣofin, ti awọn ọmọ ẹgbẹ PDP si lo anfaani naa lati sẹto idibo.
Ẹkùn kò kọ́kọ́ gbàgbọ́, ó ni ọjọ́ ti òhun ti njẹ ẹran oriṣiriṣi, kò si ẹranko ti inú rẹ dùn bi eyi ti Ìjàpá gbé wá.
Bóò ṣe lè yẹra fún ikú nígbà òjò - Onímọ̀ Ehi Iden Kò sí àyè fún fíìmù eré ìfẹ ṣíṣe ni Kannywood mọ́ Aisha Buhari ké gbàjare pé ètò ìjọba Buhari kò ṣànfàní f'óbìrin Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Asa Trokosi nibi ti ọmọde ti n jiyan ẹsẹ mọlẹbi rẹ , wọpọ ni Ghana, Togo ati Benin.
O sọ pe, agbẹjọro awọn alaga ìjọba ibilẹ naa bẹbẹ pe ki adajọ sun igbẹjọ naa di oṣu kẹwaa, ṣugbọn agbẹjọro ipinlẹ Oyo tako ẹbẹ naa.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Oyo 2020 Budget: Èyí ni àtúpalẹ̀ abá ìṣúná 2020 tí Seyi Makinde gbé kalẹ̀ 27 Bélú 2019 Gomina Seyi Makinde gbe aba eto isuna ọdun 2020 kalẹ siwaju awọn asofin lọsan ọjọru eyi ti apapọ rẹ le diẹ ni igba biliọnu naira (208,802,972,878.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Àlàyé rèé lórí ikú tó pa Ogun Majek Abisola, aya wòlíì Babatunde ti ń jẹrìí nípa bí ọmọ ọdún kan ṣe sọnù Eji Gbadero, ọmọ Ibadan àti jayé-jayé ọmọ ónílẹ̀ ti wọn yẹgi fun l'Eko Èyí ni àwọn arẹwà ‘ẹ̀lẹ̀ Daddy’, àfẹ́fẹ́ tí Aláàfin fi ń mí Mùjẹ̀-mùjẹ̀ ní Akinyele tún ti mu ẹ̀jẹ̀ obìnrin míràn lónìí Oyè adelé alága APC bọ́ lọ́wọ́ Ajimobi, Buhari fòǹtẹ̀ lu Giadom Ọkùnrin kan bá ọmọ oṣù mẹ́ta lòpọ̀, ìfun ọmọ tú jáde!
Berekaya ati Elikana ni wọ́n ń ṣọ́ ẹnu ọ̀nà ibi tí wọ́n gbé Àpótí Majẹmu sí.
Gẹ́gẹ́ bí àṣà, nígbà tí a bá ti ṣe majẹmu tán, kò sí ẹni tí ó lè yí i pada tabi tí ó lè fi gbolohun kan kún un.
Ó fún tálákà yìí ní owó tí yóó fi ra akèǹgbè àti gbogbo nǹkan fífí dá ẹmu.
Bí Ọlọrun bá wà lẹ́yìn wa, ta ni lè lòdì sí wa?
Ọkàn mi wà ninu ìrora,ìpayà ikú ti dé bá mi.
"Ki awọn eeyan yee naka ẹsun si wa lọna aitọ"" O ni ""ṣe ẹwu NURTW lawọn janduku naa wọ ni?"
    “Ọ̀rọ̀ mi kò ní jù báyìí lọ, mo fi ọ́ sí abẹ́ ìtọ́jú Ọlarun ọba, Ẹlẹ́dàá rẹ yóò máa bá ọ gbé ẹrù rẹ, Olódùmarè yóò taari bìlísì síwájú, Ọlọ́run yóò gbà ọ lọ́wọ́ àwọn abínúkú ẹni, bí o sì ti ń lọ, o kò ní bá eléṣù rìn, o kò ní bá akó-tirẹ̀-bá-tẹni ṣe àjọpín, Olódùmarè yóò gbà ọ́ lọ́wọ́ àgbákò, o kò ní bọ́ sọ́wọ́ tẹ̀ǹbẹ̀lẹ̀kùn, o kò ní pàdé ìjaǹbá, o kò sì níí rìn lọ́jọ́ tébi ń pa ọ̀nà láéláé.
Ẹ̀yin èèyàn àtàtà: Mi ò rí LuisCarlos bá sọ̀rọ̀ láti aago 5:30 lọ́sàn-án yìí, ó sì sọ fún mi pé òun ń bọ̀ nílé láti sinmi nítorí pé òun ní ìkéde pàtàkì kan láti se lórí Unionradionet láti aago 10:00 alẹ́ sí 5:00 ìdájí DóndeEstáLuisCarlos
Lẹyinorẹyin, inu ahamọ ni Adoke wa bayii ti awọn agborinro si sọ pe o n fọwọsowọpọ pẹlu wọn ninu iwaadi ti wọn ṣe.
Gbogbo wọn wá ń játùbú nínú omi ata, wọ́n ṣe àwọ̀ kàlákìní.
Wọ́n pa ọ̀dọ́ aguntan Àjọ Ìrékọjá fún àwọn tí wọ́n pada dé láti oko ẹrú, wọ́n pa fún àwọn alufaa ẹlẹgbẹ́ wọn, ati fún àwọn tìkara wọn.
Sheikh Tijjani Tukur Yola Gbajugbaja onimọ nipa ẹsin Islam ni Sheikh Tijjani to si da ileewe Tijjaniya silẹ.
Nigba ti ile iṣẹ BBC kan si alakoso ile iṣẹ Air Peace, o ni oun ko tii le sọ nkankan lori ọrọ naa, amọ ile iṣẹ iroyin Punch sọ pe Onyema ni irọ ni wọn n pa mọ oun.
Iwa ọmọluabi gbọdọ wa lara wa.
Jijẹ eso pupọ loriṣiriṣii bii ọsan, ibẹpẹ, ọpẹ oyinbo, ọgẹdẹ ọmini a maa fi kun agbara lasiko ibalopọ sii.
) Gbogbo àwọn ọmọ rẹ̀ lọkunrin ati lobinrin jẹ́ mẹtalelọgbọn.
Bí ó ti jé̩ pé àìka àwo̩n è̩tó̩ o̩mo̩nìyàn sí àti ìké̩gàn àwo̩n è̩tó̩ wò̩nyí ti s̩e okùnfà fún àwo̩n ìwà búburú kan, tó mú è̩rí‐o̩kàn è̩dá gbo̩gbé̩, tó sì jé̩ pé ìbè̩rè̩ ìgbé ayé titun, nínú èyí tí àwo̩n ènìyàn yóò ti ní òmìnira òrò̩ síso̩ àti òmìnira láti gba ohun tó bá wù wó̩n gbó̩, òmìnira ló̩wó̩ è̩rù àti òmìnira ló̩wó̩ àìní, ni a ti kà sí àníyàn tó ga jù lo̩ ló̩kàn àwo̩n o̩mo̩‐èniyàn,
Ṣugbọn àwọn iranṣẹ tẹmpili ń gbé ilẹ̀ Ofeli, Siha ati Giṣipa sì ni olórí wọn.
Nígbà tí o ṣe, mo rí ìmọ́lẹ̀ ǹlá kan tí kò yàtọ̀ sì òòrùn gangan tí o ràn yí ibi ribiti kan báyìí yípo, ẹnu ibi tí òòrùn èèmọ̀ yìí ràn sí to ẹsẹ̀ bàtà méjìlá ní ìbú ó sì tó bẹ́ẹ̀ ní gígùn, gbogbo ìyókù lẹ́yìn òòrùn birikiti yìí wà ní òkùnkùn biribiri.
" 1990 Ọgbẹni Mandela gba ominira kuro l'ọgba ẹwọn lẹyin ọdun mẹtadinlọgbọn.
opolopo nnkan ni awọn ọmọ orile ede Naijiria n reti lati odo   wọn, ki   wọn to yan   wọn, idi niyi ti a fi tete se isẹ wa bi isẹ.
Oríṣun àwòrán, @Osinbajo Àkọlé àwòrán, Etò NPower jẹ́ ọ̀nà tí ìjọba Nàìjíríà fi ń pèsè iṣẹ́ àti ìgúnpá fún ọ̀pọ̀ ọ̀dọ́ tí kò rí iṣẹ́ ṣe.
Akọroyin Punch ti ayẹyẹ igbeyawo naa soju rẹ salaye pe awọn ile ijọsin naa se atunṣe ranpẹ si ilana eto igbeyawo naa nigba ti wọn ri bi nkan ṣe ri, ati pe o dabi ẹni pe nkan ko ni fararọ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Ọ̀lọ́pàá shátà mi láti Mowe dé Magboro dé Shagamu, wọ́n ní ṣé mi ò mọ̀ pé ìjọ́ba ni mo ṣiṣẹ́ fún' Amọṣa o, ajọ NIMC ti fi wọn lọkan balẹ pe ko si ewu ati pe awọn ti ṣeto awọn ibudo iforukọsilẹ kan loke okun ti wọn ti lee lọ gba nọmba idanimọ apaps ilẹẹwa , NIN tiwọn lẹyin ti wọn ba forukọsilẹ.
Awọn asofin ẹgbẹ Republican ntiwọn nfẹ ki ijọba pese owona lati fi gbọ bukata lori eto aabo lawọn lẹnu bode ilẹ Amẹrika, to fi mọ igbesẹ mimọ odi lẹnu bode ilẹ Mẹxico ati atunse ofin irinna to fi mọ afikun owona fun ileesẹ ologun.
Ikoyi Ile ni ṣọọṣi Wolii Phillips to jẹ Pasitọ ijọ ti Owolabi ọrẹkunrin Favour mu u lọ wa.
Ṣugbọn nigba ti Ajebori tẹnu bọrọ fun BBC Yoruba, o ni kí n tó bẹ̀rẹ̀ orin tèmi, mi ò m'ẹni tó ń jẹ́ Ayuba"", síbẹ̀, bí ẹ̀pà l'ohùn àti ijó Ajebori àti Adewale Ayuba jọ ara wọn ti ọpọlọpọ si n beere pe taa gan lo n ji orin ati ohun ara wọn lo ninu awọn mejeeji."
ede Naijiria ti gbera lo siluu Makkah lorile ede Saudi Arabia fun ipade apero
O ni wọn maa dibo abẹle yan ẹni to wu wọn gẹgẹ bii gomina ipinlẹ Eko ni ti asiko ba tó pẹlu ileri pe àwọn to se daadaa ninu oloye ẹgbẹ yoo ni anfani lati lọ leekeji.
Inu omije lawọn obinrin mẹtẹta wa pẹlu aṣọ idọti aṣọ ẹlẹwọn ti wọn wọ ninu gbaga apoti ijẹjọ nile ẹjọ majisireeti ni olu ilu orilẹede Zimbabwe, Harare ti wọn n duro de idajọ boya wọn yoo jẹ ki wọn gba beeli wọn.
Ẹ óo mú ọrẹ náà wá bí OLUWA Ọlọrun yín bá ti bukun yín.
'Ọwọ́ wa tún tẹ ojúkòó tí wọ́n tí ń bá àwọn ọmọdékùnrin lò pọ̀ ní Daura' Ọkan lara awọn agba oniṣẹ iroyin ni Daura to di alabojuto iwe iroyin 'New Nigeria' lẹyin oṣu diẹ to pari ikẹkọọgboye rẹ ni Trinity College, Dublin.
Zlatan Ibrahimovic ti pinnu lati fi iko Manchester United sile lati darapo mo iko agbaboolu LA Galaxy.
Oluronbi tó ṣe apoogun gẹ́gẹ́ bi iṣẹ́ tó yàn láàyò jẹ́ ọkan lára ẹni ti ẹsun iyé ènìyàn to fi ipá bálòpọ̀ ga júlọ nínú ẹjọ́ tó ti wá silé ẹjọ́ gẹ́gẹ́ bi adájọ ṣe sọ.
Ewe, Djokovic ti gbo lojoRu(Wednesday) pe, o seese ki oun bo sori oke tente tabili gege bi olukopa ti o darajulo lagbaye ninu ere idaraya ohun, leyin ti akegbe re Rafa Nadal kuro ninu idije ohun lataari ifarapa kan naa.
Akekoo mejilogbon ati oluko meji pelu awako oko naa lo gbemi mi nigba ti oko naa yi kuro loju popo ni agbegbe Karatu ni ariwa ile Tanzania lasiko ti won n ko awon akekoo na a lo se idanwo.
Nígbà tí Atalaya rí nǹkan tí ń ṣẹlẹ̀, ó fa aṣọ rẹ̀ ya, ẹ̀rù bà á, ó sì kígbe lóhùn rara pé, “Ọ̀tẹ̀ nìyí!
Nítorí OLUWA Ọlọrun àwọn ọmọ ogun ti ya ọjọ́ kan sọ́tọ̀,ọjọ́ ìrúkèrúdò ati ìdágìrì ati ìdàrúdàpọ̀, ní àfonífojì ìran.
Yóo ti pẹ́ tó kí á tó wẹ̀ yín mọ́?
Àwọn ọmọ Paṣuri jẹ́ ẹgbẹfa ó lé mẹtadinlaadọta (1,247)
"Àkọlé àwòrán, ""A o ni gba kẹẹ tun mu wa lẹru lẹẹkan sii""."
O se ipade pelu aare lori ile-ise ti yoo maa
Òkítì yìí ati ọ̀wọ̀n yìí sì ni ẹ̀rí pẹlu pé n kò ní kọjá òkítì yìí láti wá gbógun tì ọ́, bẹ́ẹ̀ sì ni ìwọ náà kò ní kọjá òkítì ati ọ̀wọ̀n yìí láti wá gbógun tì mí.
won,ati lati maa gbe ni alaafia.
Ni Ọjọ Isẹgun ọsẹ yii ni Aarẹ Muhammadu Buhari ni Ọjọru, ọsẹ to n bọ ni oun yoo wa salaye bii eto isuna ọdun 2019 yoo se ri.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù EndSARS Protest: Àwọn olùwọ́de ní ''májèlè ni oúnjẹ tí MC Oluomo gbé wá fún wa, a ò jẹ'' 9 Ọ̀wàrà 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 17 Ọ̀wàrà 2020 Oríṣun àwòrán, Instagram/MC Oluomo Awọn oluwọde fi ẹsun kan pe MC Oluomo lo ran awọn janduku to lọ ṣe ikọlu si awọn to n wọde ṣugbọn agbẹnusọ MC, Jimoh Buhari ni awọn ko mọ nkankan nipa ikọlu naa.
Awon agbaagba naa wa ba Aare kedun iku ebi re meji ati lati dupe lowo Olorun fun alaafia omo re Yusuf omo re.
Aarin ile ni agbegbe Salvation road ni Opebi naa ni ọkọ ofurufu hẹlikọpita wo si, to si ṣe ọpọlọpọ ipalara fun awọn to wa ni agbegbe naa.
Nítorí náà, ẹ máa ṣe ìrántí ìlànà yìí ní àkókò rẹ̀ ní ọdọọdún.
Bí ẹnikẹ́ni bá wá dẹ́ṣẹ̀, a ní alágbàwí kan pẹlu Baba tíí ṣe Jesu Kristi olódodo.
O fi idi ẹ mulẹ pe agbara wa lọwọ awọn mejeeji ati pe awọn nikan lo le sọ ǹkan ti wọ́n fẹ́, àti pé àwọn níkan ló lé pasẹ ibi ti ọ̀rọ̀ yóò dúró lé.
A fi ọwọ́ọ ṣìnkún òfin mú àwọn ọmọkùnrin orílẹ̀ èdèe China mẹ́rin, Fu Hailu, Zhang Jinyong, Luo Fuyu àti Chen Bing, ní ọdún-un 2016 fún ìṣẹ̀lẹ̀ ìgò ọtí-líle tí a sì fi ẹ̀sùn-un “rírú ìṣẹ́po agbáraiìlú sókè”.
Ṣé bíríkì ni wọ́n fi kọ́ àwọn ilé tí ó wó lulẹ̀?
Lọjọ Iṣẹgun ni Ilé ìgbìmọ̀ aṣòfin àgbà l'Abuja ké si ìjọba àpapọ pe ko fi sínú ero rẹ láti fi ofin de àwọn arinrin ajò ti kìí ṣe ọmọ Naijíríà láti àwọn orilẹ̀-èdè ti àrun (COVID-19) náà n bá fíra láti ma wọ Naijiria mọ́.
Lórí ìpèsè ohun ìdẹ̀rùn fún aráàlú lásìkò igbele Coronavirus, Akeredolu ni òun kò ní kí ẹnikẹ́ni mase tá ọjà, àwọn wọn kan ni kí wọ́n má sú pọ ni.
Ṣugbọn nígbà tí Israẹli na ọwọ́ rẹ̀ láti súre fún wọn, ó dábùú ọwọ́ rẹ̀ lórí ara wọn, ó gbé ọwọ́ ọ̀tún lé Efuraimu lórí, ó sì gbé ọwọ́ òsì lé Manase lórí, bẹ́ẹ̀ ni Efuraimu ni àbúrò, Manase sì ni àkọ́bí.
Sanwo Olu funra rẹ gba pé awọn ti oun yan yoo ran oun lọwọ lati wakọ ipinlẹ Eko de ebute ogo laipẹ Ààrẹ Muhammadu Buhari bẹ̀rẹ̀ ìbúra f'àwọn mínísítà tuntun Wo ohun tó yẹ kí o mọ̀ nípa àwọn obìnrin méje ti Buhari fẹ́ yàn sípò minista Ajínigbé ń bèèrè fún epo, iṣu àti ọ̀tí Schinap gẹ́gẹ́ bí owó ìtanràn O dìgbà tí mo bá dórí àgá kí ń tó sọ ìpinnu mi - Fatai Owoseni Awọn eniyan ipinle Eko kan parọwa fun gomina Sanwo Olu pe eebu alọ ni tahun ni ọrọ naa yoo di ti awọn to yan sipo ko ba ṣiṣẹ bi o ti yẹ.
Oríṣun àwòrán, @raufaregbesola Awọn Oṣiṣẹ́ fẹyinti ti ko dunnu si Aregbesola: Ara ko rọ̀ okun, bẹẹ ni ko rọ adiẹ fawọn osisẹ fẹyinti lawọn akoko kan lasiko isejọba Rauf Arẹgbẹsọla, to si jẹ pe ija loni, asọ̀ lọla ni ijọba atawọn osisẹfẹyinti n se titi ti ijọba naa fi wa sopin.
Lẹyin naa ni adajọ ọhun paṣẹ pe ki wọn da awọn memeji pada si ahamọ DSS titi di ọjọ Ẹti, ti yoo fi gbọ ẹjọ beeli awọn olujẹjọ ọhun.
Akitiyan ọmọ'ṣẹ́ mi tó wà lára àwọn tó jí ìbejì mi gbé kò kéré nígbà tí á n wá wọn- Akeugbagold Wo ìgbà márùn ún tí àwọn ọmọ ọ̀dọ̀ ti gé ẹ̀mí ọgá wọn kúrú Àgbo Madagascar ti wà ní Nàìjíríà ṣùgbọ́n kìí ṣe ọ̀fẹ́, a ní láti sanwó-Mínísítà Ọbalaye naa sọ eyi lasiko to fi n gba alejo kọmiṣọna feto Ẹkọ ni ipinlẹ Ọṣun, Ọgbẹni Ọlayinka Ọladoyin Fọlọrunshọ ati igbimọ rẹ ti wọn wa ṣe abẹwo si ibudo ileẹkọ giga fun ẹkọṣẹ olukọ apapọ ni ilu Iwo.
OLUWA, ranti pé àwọn ọ̀tá ń fi ọ́ ṣe yẹ̀yẹ́;àwọn òmùgọ̀ eniyan sì ń fi orúkọ rẹ ṣe ẹlẹ́yà.
Lọwọlọwọ, ami ayo kan ni Liverpool fi n lewaju Manchester City ti o si jẹ wi pe ti Man City ba fi le bori Man United, awọn ni yoo di ipo kini mu saaju Liverpool.
O ni lẹyin ti wọn ba fi ija ẹlẹmẹya ati ẹsin de ipo ijọba tan, wọn maa bẹrẹ si sin ilu nibamu pẹlu ifẹ ọkan wọn.
“Sibẹsibẹ ẹ̀ ń sọ pé, ‘Ọ̀nà OLUWA kò tọ́.
"Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ibadan: Oluwapọ̀nmile sọ ìrírí rẹ̀ lọ́wọ́ àwọn sójà tó fìyàjẹ́ ní Ibadan 2 Bélú 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 3 Bélú 2020 Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, EndSars Protest;Oluwapọ̀nmile sọ ìrírí rẹ̀ lọ́wọ́ à Arakunrin Ẹmiọla David Oluwapọnmile ṣe alabapade ikọ ologun ""Operation Burst"" ni agbegbe Bẹẹrẹ nilu Ibadan ti wọn si fi abẹ ṣekele fa irun ori rẹ."
“Eleasari ọmọ Aaroni Alufaa ni yóo ṣe ìtọ́jú òróró fìtílà, ati turari olóòórùn dídùn, ẹbọ ohun jíjẹ ati òróró ìyàsímímọ́, ati gbogbo Àgọ́ náà.
Olùṣọ́, Ẹni Mímọ́ tí ọba rí tí ó sọ̀kalẹ̀ láti ọ̀run, tí ó ń wí pé, ‘Gé igi náà lulẹ̀ kí o sì pa á run, ṣugbọn kí ó ku kùkùté ati gbòǹgbò rẹ̀ ninu ilẹ̀, kí ó wà ninu ìdè irin ati ti idẹ, ninu pápá oko tútù, kí ìrì sẹ̀ sí i lára, kí ó máa bá àwọn ẹranko jẹ káàkiri fún ọdún meje.
Amọ ti wọn ko ba daba pe ko ma di ipo miran mu lọjọ iwaju,ko le si nkankanti yoo di lọwọ lati du ipo aarẹ lọdun 2020 ti o si le pada sile ijọba White House.
Nǹkan márùn ún tí awuyewuye òṣèlú ìpínlẹ̀ Edo kọ́ wa nípa òṣèlú Nàìjíríà Igbákejì gómìnà ìpínlẹ̀ Ondo Agboola Ajayi ti fẹgbẹ́ APC sílẹ̀ lọ PDP Báwó ni òògùn dexamethasone ṣe ń ṣiṣẹ́ lára Wo orin l'édè Yoruba àti Zulu tí Burna Boy fi fa ayélujára ya Ìdílé márùn-ún tó gbajúmọ̀ fún òwò ẹrú nílẹ̀ Yorùbá Wo obìnrin tó ń fi táyà ọkọ̀ ṣe àga àti àwọn ẹ̀ṣọ́ ilé Ẹ wo bí àwọn ọmọ Yoruba ṣe làlùyọ nídìí iṣẹ́ àgbẹ̀ ní Amerika Èyí tí a wò jùlọ 5:03 Fídíò, Omolola Arohunmolase Welder: Mo ti fí iṣẹ́ 'Welder' gbayì láwùjọ, tó mo fi tọ́ ọmọ yanjú, Duration 5,039 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 5:39 Fídíò, Akomolede ati Asa lori BBC: Olùkọ́ Kikelomo Ogunboye tan ìmọ́lẹ̀ sí ìwà olè ọ̀gá ọlọ́pàá Audu gẹ́gẹ́ bí àwòkọ́ṣe àsìkò yìí, Duration 5,398 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 4:11 Fídíò, Oba Adeyeye Ogunwusi: Ojú mi ti rí lọ́pọ̀ lọpọ̀, ọ̀pọ̀ èèyàn ni kò tilẹ̀ gbàgbọ́ pé mo lè jọba- Ooni, Duration 4,117 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 4:43 Fídíò, Promise Akinlade: ọmọ ọdún mọ́kànlá tó ń fi ìlù dárà bíi àgbàlagbà sọ̀rọ̀ nípa tálẹ́ǹtì rẹ̀, Duration 4,437 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 0:59 Gbọ́, Ìsẹ̀lẹ̀ jákèjádò orílẹ̀èdè àgbáyé láàárín ìṣẹ́jú kan, Duration 0,59wákàtí 5 sẹ́yìn 7:03 Fídíò, Olumuyiwa Bolade Adedeji Military Bruitality: Bí arákùnrin onípèníjà ara tí sọ́jà lù ṣe dé, Duration 7,035 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 4:45 Fídíò, Yoruba Films: Ẹ̀ẹ́ bẹ̀ mi kúrò láyé ni, mi ò lè kú - Fadeyi Oloro, Duration 4,4526 Èrèlè 2020 2:48 Fídíò, Esther Ajayi: Èmi náà ti borí ìṣòro rí ló ń mu mi ṣojú àánú, Duration 2,481 Ògún 2019 6:08 Fídíò, Adebola Ademilua: Àìrísẹ́ ṣè lẹ́yìn ìwé kíkà ló sọ mi dí ìyá onírú, mo dúpẹ́ tèmi, Duration 6,0827 Bélú 2020 5:55 Fídíò, Soyinka Cancer: Àṣe ara mi ni iso ti n run gbogbo bí mo ṣe n ṣèrànwọ́ lórí jẹjẹrẹ, Duration 5,5527 Bélú 2019 BBC News, Yorùbá Ìdí tí ẹ fi le è nígbàagbọ́ nínú ìròyìn BBC Ìlànà Lílò Nípa BBC Òfin Àṣírí Cookies Kàn sí.
Adura wa ni pe ki Ọlọrun tẹ Agagunfẹyinti Tunde Idiagbon si afẹfẹ rere, ko si duro ti ẹbi to fi silẹ.
Ìtàn Mánigbàgbé: Samuel Ladoke Akintọla jẹ́ olóṣèlú pàtàkì tó tako Awolọwọ
Jabesi gbadura sí Ọlọrun Israẹli pé, “Ọlọrun jọ̀wọ́ bukun mi, sì jẹ́ kí ilẹ̀ ìní mi pọ̀ sí i.
Nàìjíríà kò fararọ fún ẹ̀yà Yorùbá, Buhari ń dọdẹ àwọn ọmọ ẹgbẹ́ mi - Akintoye Ebenezer Obey ń wá ìyàwó , wo àmúyẹ tí o gbọdọ̀ ní tí o bá fẹ́ ẹ́ di aya lọ́ọ̀dẹ̀ baba Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí 2 sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
Nigeria 2019 Elections: Èwo nínú ìlérí tí Buhari ṣe ní 2015 ló ti mú ṣẹ?
'Oríṣíiríṣi orúkọ ni wọ́n sọ ọmọ tuntun yìí’ Ọmọ igboro to di ayaworan pataki lawujọ #BBCGOVDEBATE: Ọgbọ́n ìmọ̀ àti òye ní ń ò fi ṣe ìjọba- GNI Bẹẹ, orukọ ọmọ ni ìjánu ọmọ ni Yoruba kìí fi ṣàà déédé sọ ọmọ lorukọ ki orukọ.
City gbá bọ́ọ̀ù àkọ́kọ́ sínú àwọn Watford ní àáyá ìṣẹ́jú méjìléláàádọ́ta (52 seconds) sí ìgbà tí wọ́n bẹ̀rẹ̀ eré nígbà tí láti ẹ̀sẹ̀ David Silva kí Sergio Aguero ó tó fi kú un.
Ọtí ti pọ̀jù ọ̀kà wọn lọ
Eyi kii ṣe igba akọkọ ni ilẹ China ti iru rẹ yoo waye, iru rẹ waye ni Osu keje nipa ọmọ obinrin kan laimọ pe arugbo ni.
O Abiola lo àkọlé 'Ìrètí fún ìpolongo ìdìbò lọ́dún 1993 èyí ti ààrẹ àna orílẹ̀-èdè Amẹríkà Barrack Obama náà mú lò ní ọdún 2008.
’ ‘Ẹyin ará Ondo, Eko, Ogun, Osun, Ọyo, ẹ gbàdúrà ò!
FIFA ni lati ọdun 2017 ni wọn ti n ṣe iwadii naa titi di ọdun 2019.
Lẹyin iku Kudirat, wọn ko ṣi tu ọkọ rẹ silẹ kuro lẹwọn.
Àwọn kan ninu àwọn ọmọ Lefi ni alabojuto àwọn ohun èlò ìjọ́sìn, iṣẹ́ wọn ni láti máa fún àwọn tí wọ́n ń lò wọ́n, ati láti gbà wọ́n pada sí ipò wọn, kí wọ́n sì kà wọ́n kí wọ́n rí i pé wọ́n pé.
Àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ sọ fún un pé, “Níbo ni a óo ti rí oúnjẹ ní aṣálẹ̀ yìí tí yóo yó àwọn eniyan tí ó pọ̀ tó báyìí?
Bakan naa ni wọn lo fun awọn ileeṣẹ elepo Shell, Eni ati awọn ileeṣẹ to n wa epo rọbi miran laaye, lati lu owo ilu ni ponpo lai san owo ori.
Dokita ọhun ni ijọba gba awọn ara ilu lati jinna rere si ẹni ti wọn ba funra sip e o ni arun Coronavirus lara, ṣugbọn awọn to n ṣiṣẹ nile iwosan n fẹgbẹkẹgbẹ pẹlu alarun naa laisi ohun idabo bo ara ẹni to kun oju oṣuwọn.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Janduku yinbọn nilu Iwara Dino fẹ́ fún èèyàn mẹwa ní ₦10m tí Atiku bá wọlé kẹ̀?
Ṣé kò ṣá sí ẹnikẹ́ni ninu àwọn aláṣẹ ati àwọn Farisi tí ó gbà á gbọ́?
" Ohun marun t'ejo n jẹ O ni bi o tilẹ jẹ wipe iroyin nipa oṣiṣẹ ajọ naa, Philomena Chieshe to sọ fun igbimọ oluwadi pe ejo airi kan lo deede wọ inu ọọfisi oun, to si gbe miliọnu mẹrindinlogoji mi lo jade sita, Benjamen ni awọn meje ni wọn ṣe magomago owo ti ajọ naa pa wọle lati ara awọn kaadi ti o ta fun awọn akẹkọọ saaju ki wọn o to dawọ tita kaadi naa duro.
Ṣaaju ni ijọba ilẹ Canada ti sọ pe oun ko ni gba ki ẹnikẹni wọ orilẹ-ede ọhun lati oke okun titi di Ọjọ kọkanlelọgbọn, oṣu Keje ọdun 2020 nitori ajakalẹ arun Coronavirus.
 Ìrora lè wáyé níbi tí a gba abẹ ́ rẹ ́ sí.
Àwọn olórí lára àwọn òṣìṣẹ́ Solomoni jẹ́ igba ati aadọta (250), àwọn ni wọ́n ń ṣe àkóso àwọn tí wọn ń ṣiṣẹ́.
Nigeria Borders open: Onímọ̀ ọrọ̀ ajé ní ìlànà tẹ́tẹ́ títa ní ìjọba ń lò fétò ọ̀rọ̀ ajé
Toyin Abraham kìí bá èmi náà yọ̀, ni kò jẹ́ kí ń gbé e lárugẹ fún ayọ̀ ọmọ - Lizzy Anjorin Iṣẹ́ ọpọlọ ló yẹ ká ṣe nínú tíátà, kìí ṣe àfihàn ara bíbó àbí ìhòòhò wa - Binta Mọgaji Èmi àti Saheed kìí ṣe ọmọdé, a ti jọ ṣe Sinimá papọ̀, èyí túmọ̀ sí pé ìjà ti parí - Fathia Balogun Ọ̀pọ̀ èèyàn bẹnu ẹ̀tẹ́ lu Mercy Aigbe lórí bó ṣe ki Adeniyi Johnson Àjẹ́ àti Aṣẹ́wó ní ìyá Rainbow - Òjòpagogo N30,000 ni mo gbà fún orí, ọwọ́ àti ẹran ara wòlíì Bosede - Kayeefi O ni wiwa pẹlu aya oun, Toyin lasiko to wa nile igbẹbi, to si n rọbi lọwọ, ti jẹ ki oun mọ ohun to maa n jẹ ki awọn ọkunrin kan maa n kẹ iyawo wọn gẹgẹ, toju-timu.
O kepe ijọba apapọ lati fi orukọ awọn gomina to n dari owo ijọba ibilẹ si ibo miiran.
Bakan naa ni wọn ti gbe akẹkọọ naa lọ sile iwosan fun itọju.
Ní ọjọ́ kẹjọ wọ́n pe àpéjọ mímọ́.
ṣugbọn wọ́n dara pọ̀ mọ́ àwọn orílẹ̀-èdè náà,wọ́n sì kọ́ ìṣe wọn.
nítorí náà, ẹ gbọ́ ohun tí èmi OLUWA wí, kí ẹ̀yin òkè ńláńlá ati ẹ̀yin òkè kéékèèké Israẹli, ẹ̀yin ipa odò ati ẹ̀yin àfonífojì, ẹ̀yin ibi tí ẹ ti di aṣálẹ̀ ati ẹ̀yin ìlú tí ẹ ti di ahoro, ẹ̀yin ìlú tí ẹ di ìjẹ ati yẹ̀yẹ́ fún àwọn orílẹ̀-èdè yòókù tí wọ́n yi yín ká.
Ṣugbọn Mose kò pín ilẹ̀ fún àwọn ẹ̀yà Lefi, OLUWA Ọlọrun Israẹli ni ìpín tiwọn, gẹ́gẹ́ bí ó ti wí fún wọn.
Góòlù pọ̀ ní ìlú Madaka ṣùgbọ́n wọn kò ní ọ̀nà fún ọgọ́rùn ún ọdún ‘Ilé ẹjọ́ kò gbé ẹ̀sùn ìfipánílòpọ̀ yẹ̀wò, à ń lọ sí ilé ẹjọ́ - Busola Dakolo Ẹ̀yin ẹ̀ṣọ́, ẹ kò gbọdọ̀ fààyè gba jíjí àpótí ìdìbò ní Kogi àti Bayelsa- Buhari Èèyàn méjì farapa nínú ilé tó jóná ní Tejuoso l‘Eko Omọọba Abubakar Audu ti APC ni INEC kede 240, 867 fun nigba ti Captain Wada Idris to jẹ gomina tẹlẹ ni PDP ni 199, 514 nipo keji.
Ohun tó yẹ kí o mọ̀ nípa ìbòmú tí ń lò yẹ́n Coronavirus ti di ara wa, kò le è kúrò mọ láéláé - WHO Ni bayii, oun ni obinrin alawọdudu akọkọ, to jẹ musulumi to tun n wọ hijab, to jẹ adari ere bọọlu nilẹ Gẹẹsi.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Peers of Heaven: Ààrẹ ẹgbẹ́ Emèrè ní àwọn ti wà tipẹ́, wọn kò pariwo síta ni 14 Ògún 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 18 Ògún 2020 Oríṣun àwòrán, Others Ẹgbẹ Emere ti wa tipẹ, a ko kan pariwo sita ni, paapa laarin awọn oniṣẹ'ṣe."
Oríṣun àwòrán, AFP Àkọlé àwòrán, Awọn eeyan ti iji Cyclone Idai ṣe akoba fun ko tii bọ lẹyin iṣẹlẹ ọhun.
Aadọta ìwọ̀n ṣekeli wúrà ni ó fi ṣe ìṣó, ó sì yọ́ wúrà bo gbogbo ara ògiri yàrá òkè.
Iwadi Oxfam lo gbe e jade bẹẹ wi pe, agbeegbe Iwọ Oorun Ilẹ Afirika lo ni aidọgba to pọ julọ laarin awọn talaka ati olowo julọ ni agbaye.
“Ìwọ ọmọ eniyan, ààrin àwọn olóríkunkun ni o wà: àwọn tí wọ́n ní ojú, ṣugbọn tí wọn kò fi ríran.
“N óo fi ẹ̀mí àánú ati adura sí ọkàn àwọn ọmọ Dafidi ati àwọn ará Jerusalẹmu, tóbẹ́ẹ̀ tí yóo jẹ́ pé, bí wọ́n bá wo ẹni tí wọ́n gún lọ́kọ̀, wọn yóo máa ṣọ̀fọ̀ bí ẹni tí ń ṣọ̀fọ̀ ọmọ rẹ̀ kanṣoṣo.
Kamilu, ẹni tó kéde pé òun ti ṣètò iranwọ fáwọn olólùfẹ́ òun lásìkò igbele Covid-19 náà, tún rọ wọn láti máa tẹle àwọn ìlànà tó ń dènà itankalẹ àrùn bíi fífi ọ̀sẹ̀ fọ ọwọ, lilo ìbòjú àti títa kété síra ẹni.
tí gbólóhùn kò bá ní ju ẹyọ ọ ̀ rọ ̀ -ìṣe kan lọ nínu àpólà-ìṣe .
Amẹrika ń gbẹ̀san lára Nàíjíríà, owó ‘Visa’ di ọ̀nà méjì láti wọ Amẹrika Ọkọ̀ akẹ́rù Dangote rọ́lu BRT lọ́nà Ikorodu, èèyàn kan kú, 59 farapa, ẹsẹ̀ dẹ́rẹ́bà gé Oludari fun alakoso egbẹ ajafẹtọ Coalition of Human and Civil Rights Organizations(COHCRO) fikun pe ara lo n ta ijọba apapọ nitori aiṣe deede wọn pelu ara ilu, nipa pipese ohun to tọ, to si yẹ fun mutumuwa.
Ìlú ńlá náà bá pín sí mẹta.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù BBC Pidgin Essay Competition 2019: Njẹ́ ìwọ le kọ àròkọ̀ ní èdè Pidgin?
 rí ẹni tí ó gbé owó ṣùgbọ ́ n òun kò rí ojú rẹ ̀ tí òun fi ta jí .
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìdìbò 2019: Fani-Kayode ní kí Buhari gbáradì fún ìfẹ̀yìntì 20 Èbibi 2018 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 8 Ọ̀wàrà 2018 Àkọlé àwòrán, ọ̀rọ̀ ń bọ́ mokó morò bọ̀ lórí ìdìbò ààrẹ ọdún 2019 Minisita tẹlẹ ri fun ile iṣẹ ọkọ ofurufu lorilẹede Naijiria Femi Fani-Kayode ti sọ fun Aarẹ Muhammadu Buhari pe ko mura silẹ fun ifẹyinti lọdun 2019.
Gbogbo àwọn ọjà , ilé ìfowópamọ́ àti ilé ẹ̀kọ́ ní ìlú ọ́hùn ni wọ́n tì pa, táwọn òbí sì ń sáré lọ mú àwọn ọmọ wọn nílé ẹ̀kọ́ nítorí kí ojú má rí ibi, ẹsẹ̀ ni òògùn rẹ̀.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Àtúndì ìbò Kwara: Raheem Ọlawuyi ní èsì ìbò náà jẹ́ àseyọrí ire tó ń bọ̀ 14 Bélú 2018 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 18 Bélú 2018 Oríṣun àwòrán, Olawuyi Facebook Raheem Ọlawuyi, to jawe olubori ninu atundi ibo si Ile Asojusofin lẹkun idibo Ekiti/Irepodun/Isin/Oke-Ero ni ipinlẹ Kwar, ti kede pe awọn eeyan ipinlẹ Kwara ti se oriire nitori bi wọn se dibo yan oun.
Ọmọ ìyá wa Yakubu Adesokan ló mà fúnwa láyọ̀ o.
Humphrey Okorie sọ pe Ipinlẹ Eko ti n ṣiṣẹ ni ibamu pẹlu ilana agbayẹ ni
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, EndSars, EndSwat: Ọlọ́pàá ti fi ìbọn lù mí láyà rí torí mó ní 'extra tyre' méjì- afẹ́hònúh Ọjọgbọn Akande ni anfaani lo jẹ fun oun pe oun naa bu mu ninu omi ọgbọn Alaafin.
Àyájọ́ òṣìṣẹ́: NURTW gba ẹ̀jẹ̀ lára àwọn òsìsẹ
Ọdun mẹwa lẹyin rẹ, mo lọ sileewosan naa, wọn ṣe iṣẹ abẹ fun mi, o ṣi yọri sirere.
Oye miran to tun jẹ iyalẹnu ni agbo oṣelu Naijiria ni oye oluranlọwọ pataki lori ọrọ awọn ina ti ijọba n tàn si adugbo, 'street lights'.
Rògbòdìyàn bẹ́ sílẹ̀ láàrin àwọn ọlọ́kadà àti àwọn òṣìṣẹ́ ọgbà ẹ̀wọ̀n ní Ibadan Èyí ni ohun tí Ọọ̀ni sọ nípa Àrẹ̀mọ rẹ àti ètùtù tó ń ṣe lọ́wọ́ O si gbọdọ ni aridaju pe yoo wa sile ẹjọ lọjọkọjọ ti ile ẹjọ ba sọ pe ko wa, ti ko ni salọ.
28 Lõtọ́, lõtọ́, ni mo wí fún ọ, ègbé ni fún ẹnití ó parọ́ láti tan ni jẹ nítorí òun rò pé ẹlòmíràn ti parọ́ láti tan ni jẹ, nítorí a kì yíò dá irú ẹni bẹ́ẹ̀ sí nínú ìdájọ́ Ọlọ́run.
Ṣé wọ́n ní “igi gogoro má gúnmi lójú, àtòkèrè làá tí í wòó” àbí?
Ni ipari, a o jabo ipade naa fun yin bi iroyin miiran ba se n te wa lowo….
Oloye Osita Okeke to je olootu fiimu agbelewo ti won maa n pe loruko inagije Ossy Affason naa pe fun atileyin ti o ye fun ilosiwaju ede ati asa Igbo fun iran to m bo yii.
Ẹgbẹrun (1,000) eniyan, láti inú ẹ̀yà Bẹnjamini, ni ó kó lọ́wọ́.
Eyi ri bẹ ẹ lẹyin ti ajọ to n gbogun ti ajakalẹ aarun, NCDC, tun kede ọọdunrun ati mẹtalelaadọrin to tun ṣẹṣẹ ni i.
ati  osisẹ  wọn ati ajọ to wa labẹ wọn , a n ki gbogbo
Lẹyin naa lo wa fikun pe ijọba ilẹ naa ti bẹrẹ igbesẹ lati ṣawari gbogbo awọn eeyan ti obinrin ọhun ṣalabapade ninu irin ajo rẹ lati Belgium si Tanzania lati le ṣayẹwo wọn.
Afurasi ti Àmọ̀tẹ́kùn bá lu lálù bẹ́, ilé iṣẹ́ ọlọ́pàá ò ni gbàá sátìmọ́lé Pásítọ̀ Adeboye kéde ààwẹ̀ ọjọ́ 63 fọ́mọ ìjọ rẹ̀, ariwo sọ lórí ayélujára Ìwádìí BBC rèé lórí ìjà APC tó fẹ́ gbẹ̀mí Sẹ́nátọ̀ l‘Osun Ìlú tuntun tó kún fún ohun àdáyébá láìsí ọkọ̀ tàbí òpópónà ń bọ̀ ní Saudi Arabia Ẹwẹ, ajọ NCDC tun ti kede eeyan 1,244 miran to ṣẹṣẹ lugbadi arun naa ni Naijiria.
ipe yii  lasiko to n ba awon akoroyin
10 Títí di ọjọ́ tí Olúwa yíò dé lati san fún olúkúlùkù ènìyàn gẹ́gẹ́bí iṣẹ́ rẹ̀, àti lati wọ̀n fún olúkúlùkù ènìyàn gẹ́gẹ́bí òsùnwọ̀n tí òun ti fi wọ̀n fún arákùnrin rẹ̀.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ìjọba àpapọ̀ ní òun ń sa ipá gbogbo láti wawọ́ ìkọlù iléèwé bọlẹ̀ Mínísítà fétò ẹ̀kọ́ ni yàtọ̀ sí èyí, ẹ̀ẹ́dẹ́gbẹ̀jọ iléèwé làwọn agbébọn Boko Haram ti bà jẹ́ láàrín ọdún 2014 sí àsìkò yìí.
BBNaija 2020: Trikytee àti Ozo ní wọ́n fọ́wọ́ òsì júwe ile fún ni bbnaija lọ́sẹ̀ yìí
Nígbà tó ń bá BBC Yoruba sọ̀rọ̀ láti sàmì ayajọ ìrántí ikú olóògbé náà, Oluwadamilola ni bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé òun kéré pupọ nígbà tí bàbá òun kú, àmọ́ òun leè ṣe àpèjúwe rẹ bíi ẹni tó gbé aye ṣe rere.
nígbà tí Ọ ̀ rànmíyàn dé , aláyẹ ́ mọrẹ sá kúrò lórí oyè nítorí pé ní ayé àtijọ ́ wọn kì í fi ẹni ìṣááju sílẹ ̀ láti fi àbúrò joyè .
”O tun salaye nipa bi ajo NCC  se gba iwe ase lati yo awon ile-ise kan to n
Wọ́n á kọ́kọ́ fi àwọn èròjà kan pa á lára kí wọ́n to sọ ọ́ sínú agbada òróró gbígbóná.
Charles Okah gba'dajọ ẹwọn gbere Lush beauties: Ara sisan kii n ṣe arun Ni ọsẹ meji meji sẹyin ni awọn ikọ Boko Haram ji awọn akẹkọbinrin to le ni ọgọrun gbe ni ileewe wọn to wa ni ilu Dapchi, ipinlẹ Yobe lẹkun ila orrun ariwa orilẹede Naijiria.
"Libya: Ọmọ Naijiria mejilelaadoje miran pada sile Aadọrun atipo ri s'omi ni Libya ""A gbọ ti awọn iro ibọn ndun ni akọkọ,"" Wilson rántí."
Bo tilẹ jẹ pe o ni oun ko le fi idi rẹ mulẹ pe awọn oluwọde naa n jo ṣoọbu lagbegbe Arakalẹ ni Akure, ṣugbọn ori alupupou ni oun wa, ti oun si n kaakiri ilu naa lati woye bi ohun gbogbo ṣe n lọ.
Nítorí pé, dájúdájú n óo gbà ọ́ sílẹ̀, o ò ní kú ikú idà, ṣugbọn o óo sá àsálà, nítorí pé o gbẹ́kẹ̀lé mi.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Sex For Marks: Ọwọ́ ọlọ́pàá tẹ olùkọ́ tó n fipa bá akẹ́kọ̀ọ́ tó n ṣe ìdánwò WAEC sùn' l'Ogun 11 Ọ̀wàrà 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 12 Owewe 2020 Oríṣun àwòrán, Others Ọwọ ileeṣẹ ọlọpaa ti tẹ olukọ ileewe girama aladani kan, Matthew Adebayo to n fi ipa ba akẹkọọ rẹ kan ni ibalopọ, ni agbegbe Sango nipinlẹ Ogun.
kí ó fa àjẹsí rẹ̀ yọ, kí ó sì tu ìyẹ́ rẹ̀, kí ó dà á sí apá ìhà ìlà oòrùn pẹpẹ náà, níbi tí wọn ń da eérú sí.
Òsìṣẹ́ ní bàbá rẹ̀ nílé iṣẹ́ BCOS ati OSBC, kó tó fẹ̀yìn tì.
“Kò yẹ kí wọ́n di èrò ẹ̀wọ̀n ní ìbẹ̀rẹ̀.
Ṣugbọn ti ẹni tí wọn kò tíì bí rárá,sàn ju ti àwọn mejeeji lọ,nítorí kò tíì rí iṣẹ́ ibití àwọn ọmọ aráyé ń ṣe.
Ajọ naa ni Metuh gba owo yii lati fi ṣe iṣẹ ijọba kan ni, ṣugbọn ko ṣe nkan kan lẹyin to gba owo naa tan.
Kò sí bí eniyan ti lè ṣe làálàá tó, kò lè rí ìdí rẹ̀.
Oun naa si gbọdọ gbe gbogbo igbesẹ lati da awọn nkan naa pada.
Ọkan lara awọn olori kabiyesi iku baba yeye, Adeyẹmi, iyẹn olori Memunat ti fohun ranṣẹ si kabiyesi Ọba Lamidi Adeyẹmi kẹta to si n kii ni mẹsan mẹwaa pe lootọ oun ko pe ṣugbọn Alaafin duro ti oun.
akọ mààlúù kékeré kan, àgbò kan, ọ̀dọ́ àgbò ọlọ́dún kan fún ẹbọ sísun, 
Èèyàn 163 ló tún ṣẹ̀ṣẹ̀ ní àrùn coronavirus ní Nàìjíríà Ààrẹ Buhari kí Akeredolu kú orííré bí ó ṣe jáwé olúborí nínú ìdìbò sípò gómínà Gomina Kano tí ní kí olùrànlọ́wọ́ rẹ̀ lọ rọ́kún nílé nítori o bu Ààrẹ Buhari lórí #EndSars Bí èsì ìdìbò gómìnà ìpínlẹ̀ Ondo se ń jáde rèé.
Ó tún pàṣẹ pé, “Ẹ lọ sí ààrin àwọn eniyan, kí ẹ sì wí fún wọn pé, kí wọ́n kó mààlúù wọn ati aguntan wọn wá síhìn-ín.
''Nitori naa, mo fẹ kẹ gba alaafia laaye, ki a si duro de ijọba lati sọrọ lori ibeere ti awọn ọdọ bere lọwọ wọn.
Lẹ́yìn ọjọ́ pípẹ́, ní ọdún kẹta tí ọ̀dá ti dá, OLUWA sọ fún Elija pé, “Lọ fi ara rẹ han Ahabu ọba, n óo sì rọ̀jò sórí ilẹ̀.
" Ọrọ ti Lawal sọ yii ti n fa ariyanjiyan laarin awọn ọmọ orilẹ-ede Naijiria kan lori ayelujara.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Olusegun Obasanjo sọ̀rọ̀ síta pé ọpẹ́lọpẹ́ Walter Carrington láyé òun nígbà tí Sani Abacha ń lé òun kíri 13 Ògún 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 18 Ògún 2020 Oríṣun àwòrán, others Oloye Olusegun Obasanjo to ti figba kan dari orilẹ-ede Naijiria ri sọrọ nipa Oloogbe Walter Carrington.
’Olukuluku tẹ̀ sí ọ̀nà tí ó wù ú,bí ẹṣin tí ń sáré lọ ojú ogun.
Won bi Rohr lojo kéjídínlọ́gbọ̀n osu kefa, odun 1953 silu Mannheim, lorile-ede Germany.
Ṣugbọn, nigba ti ilẹ ṣu ti Joe ko pe gẹgẹ bi iṣe rẹ ni wọn to bẹrẹ si ni bẹru pe boya nkan ti ṣẹlẹ si.
“Ẹnìkan yóo wí pé,‘OLUWA ló ni mí.
 Ijoba tun n gbiyanju lati pese awon eto alaafia ati idagbasoke fun awon eniyan naa.
gẹ ́ gẹ ́ bí ìtàn tí gbọ ́ , ifẹ ̀ ni àwọn ará ifẹ ̀ wàrà ti ṣí lọ sí ìlú náà láti agboolé arùbíìdì ní òkè mọ ̀ rìṣà ní ilé-ifẹ ̀ 1 .
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Sùúrù àwọn ará Ọṣun ti tó gẹ́ - Saraki Ìpínlẹ̀ Oṣun kò nílò Gómìnà oníjó - Oshiomole Àṣìlò òògùn burú, ṣùgbọ́n ṣé ẹ̀bi ará ìlú nìkan ni?
Lati ọdọ ni Ayinde Barrister ti bẹrẹ orin kikọ pẹlu ẹka ori 'Were'.
Kí wọn má baà fi ojú wọn ríran,kí wọn má baà fi etí wọn gbọ́ràn,kí wọn má baà mòye,kí wọn má baà yipada,kí n wá gbà wọ́n là.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Widows Day 2019: Mo máa ń sá kiri wá owó ilé ni -Opó Ninu oṣu kejila, ọdun 2018 ni awọn igbimọ oluwadii yii ti gba aarẹ Buhari nimọran pe ko da ọjọgbọn Yusuf duro lẹnu iṣẹ rẹ.
Ẹ̀yin lẹ kọ́ Sínétọ̀ kọ́ Olórí-oko.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Kidnapped Girl: Iyá Ikimot ní lẹ́yìn ọ̀pọ̀ ìdààmú àti owó láti wá ọmọ náà, òun sọ ìrètí nù Lọjọ Ajé ni Oshimole ṣe ìpàdé pẹ̀lú àwọn ọmọ ilé ìgbìmọ̀ asoju-sofin ti wọn dibo yàn pẹ́lú àṣẹ pé, dàndàn ni kí ẹgbẹ́ APC ṣe agbédide ẹni ti yóò dari láàrin ẹgbẹ́.
Enikeni ti oruko ba wa lara iwe awon adunkoko-moni, ijoba yoo gbese le dukia re, bakan naa ni won yoo fofin irinajo de, amo o le pejo kotemilorun laarin ogota ojo.
Oba Akinruntan wa gbadura fun awọn iyawo, ẹbi ati ọrẹ ti Ọba Olufon fi silẹ, wi pe iru ibanujẹ bẹẹ ko ni kangun si wọn mọ.
rẹ pada si ile-ise  Buhari .
Oun to ṣaa ṣe koko ni wipe, iru ẹni ti yoo gbe iṣẹ Sarri ru ni yoo tọka ibi ti Abramovich yoo ya si.
Ní báyìí, páro-páro ni agbègbè nàá dá, tí àwọn onílé ìtajà sì ti gbé ilẹ̀kùn wọn tì pa.
com/gAAK89Q1XfAsemase agbaboolu  eyin Super Eagles, Leon Balogun lo sokunfa  ami ayo akoko, ki Carolus Andriamahitsinoro o to gba ami ayo keji sagbon niseju die ti saa keji bere .
Ògo rẹ̀ yóo dẹ́rùbà yín,jìnnìjìnnì rẹ̀ yóo dà bò yín.
 kongreesi unse ipade ni kapitoli to wa ni ilu washington , d.
Ẹ jẹ́ kí ọkàn yín ṣe ọ̀kan, kí èrò yín sì papọ̀.
 ká tó rérin ó digbó , ká tó rèfon ó dò dàn , ká tó réye bí òkín murtala ramat mohammed ìyén di gbére .
10 Ògún 2019 Oríṣun àwòrán, Google Àkọlé àwòrán, Àwọn gómìnà ní ẹkùn Ìwọ̀-oorun Naijiria ti késí àwọn ọmọ Naijiria lati lo asiko ọdún yìí láti fi gbàdúrà fún orílẹ̀èdè Naijiria.
Liverpool to n tele Manchester City pẹlu ami ayo kan yoo gbalejo Wolves ni papa iṣẹre Anfield nigba ti Man City yoo waako pẹlu Brighton ni deedee aago mẹta ọsan ọjọ Aiku.
Àmọ́ àtẹ́jáde ti Femi Fani-Kayode kọ náà, tó si fí ẹ̀dà rẹ̀ sójú òpó twitter rẹ̀ @realFFK, ni kò sí mọ́ lójú òpó twitter náà báyìí, sùgbọ́n ó sí wà lójú òpó Facebook rẹ̀: FFK ni àyípadà ọkàn Bakare kò ni sàì ṣẹ̀yin ọ̀rọ̀ ilé ifówópamọ́ tí orúkọ ẹni tó ni yí pada láìpẹ́ yìí, àti àwọn ǹkankan tọ ṣẹlẹ̀ lọ́dún 1990 ní ìgbésí ayé Tunde Bakare, bóyá àwọn ọmọ lẹ́yìn Tinubu si ti ń pinu láti tú àṣírí náà síta ló fàá, tí Bakare fi yi bìrí.
mo fi ọ́ gégùn-ún lórí ilẹ̀ tí ó mu ẹ̀jẹ̀ arakunrin rẹ tí o pa.
Papakọ ofurufu Murtala Muhammed (Murital Muhammed International Airport) Ilu Eko Papakọ ofurufu ilu Eko jẹ ọkan lara awọn papakọ ofurufu ti igbokegbodo baluu ti n waye julọ ni ilẹ Afirika.
37% Eyi ni Gomina Seyi Makinde lo kọja iye ida ti ajọ UNESCO n beere ninu aba eto isuna ipinlẹ kan Gomina ni eto ẹkọ ọfẹ ti gberasọ nipinlẹ Ọyọ, tijọba si ti pin iwe kika ati iwe ajakọ fawọn akẹkọ lọfẹ Bakan naa ni o ti pin iwe idanwo tẹlẹri fawọn akẹkọ lati fi gbaradi, to si n fọwọ sọya pe ipinlẹ Ọyọ yoo kuro ni ipo kẹrindinlọgbọn to wa ninu esi idanwo WAEC to kọja Ijọba tun ti n wọna abayọ lati tan ọpọ isoro to n koju awọn ileẹkọ nipinlẹ Ọyọ bii aito awọn olukọ, to si n gba awọn olukọ tuntun sẹnu isẹ, to fi mọ ipese eto aabo to peye sawọn ileẹkọ, paapa awọn ti wọn ko mọ odi yika wọn.
Iya naa ati ọmọ rẹ ọkunrin to jalaisi yi ni wọn ero inu ọkọ akero kan ko to di pe ijamba naa waye.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Olólùfẹ́ méjì jábọ́ láti àjà kẹsàn án lásìkò tí wọ́n n ṣe kerewà Ẹ wo ohun tó fàá tí àwọn òbí fi ń pa 340 ọmọ bíbí wọn lọ́dọọdún Buhari gbà wá, àwọn àjèjì ti gbàkóso ilẹ̀ Yorùbá - Ọọ̀ni figbeta Afọnja, ẹni tó finú wénú ní Ilọrin, àmọ́ tó jẹ iwọ Oluwo ni o ṣe pataki ki ijọba ṣe ofin pe, ki awọn ọmọ Fulani maa lọ si ileewe, bi ko tilẹ kọja ileewe girama, lati le ṣe eto ọjọ iwaju to dara fun ẹya naa.
Nítorí láti ìgbà àtijọ́ ni wọ́n ti ń ké òkìkí Mose láti ìlú dé ìlú tí wọn sì ń ka ìwé rẹ̀ ninu gbogbo ilé ìpàdé lọ́sọ̀ọ̀sẹ̀.
Dino Melaye, olùdíje sípò kẹẹ̀ta lábẹ́ àsìá PDP tó gba fọ́ọ̀mù ipò Gómìnà Kogi
Ní àkókò náà, àwọn Farisi kan wá sọ́dọ̀ Jesu, wọ́n sọ fún un pé, “Kúrò níhìn-ín nítorí Hẹrọdu fẹ́ pa ọ́.
Ó sọ òtítọ́, kò parọ́, ó ní, “Èmi kì í ṣe Mesaya náà.
Nígbà tí ó di ìrọ̀lẹ́ ọkunrin náà ati obinrin rẹ̀ ati iranṣẹ rẹ̀ gbéra, wọ́n fẹ́ máa lọ; baba ọmọbinrin náà tún wí fún un pé, “Ṣé ìwọ náà rí i pè ilẹ̀ ti ń ṣú lọ, jọ̀wọ́ dúró kí ó di ọ̀la.
wọ ́ n pinu pé roof le dúró fún ìgbẹ ́ jọ ́ ní ilé-ẹjọ ́ ìjọba àpapọ ̀ , ni oṣù kejìlá ọdún 2016 wọ ́ n dá roof lẹ ́ bi ẹ ̀ sùn 33 tí wọ ́ n jẹ ́ ọ ̀ ran ikorira lábẹ ́ ìjọba àpapọ ̀ àti ẹ ̀ sùn ìpànìyàn tó ṣe pẹ ̀ lu ìyìnbọn náà .
 Oríṣun àwòrán, @SegunAde88 Nigba to n bawọn eeyan sọrọ lẹnu abẹwo rẹ naa, aarẹ Muhammadu Buhari ni ole kii ja agba, ko ma se loju firi, nitori naa lai si atilẹyin awọn araalu, ko seese fun ẹnikẹni lati wa kọlu agbegbe kankan."
Kọmiṣọnna fun ifitonileti ni ipinlẹ Delta, Charles Aniagwu lo kede asiko tuntun naa lẹyin to dupẹ lọwọ awọn olugbe ibẹ si bi wọn ṣe tẹle ofin isede fun aabo ẹmi ati dukia.
Amọṣa lọtẹ, olori Mẹmunat Adeyẹmi, to ti bi ọmọ mẹta fun Kabiyesi ṣalaye ninu ọrọ iwuri to kọ soju opo ikanni Instagram rẹ pe eekan sọrọsọrọ, olukọ ati awokọṣe rere to mu ayipada rere ba igbe aye oun ni kabiyesi Alaafin.
Ẹ ti gbọ́ nípa Jobu, bí ó ti ní ìfaradà, ẹ sì mọ bí Oluwa ti jẹ́ kí ó yọrí sí fún un.
Gbẹ́kẹ̀ rẹ lé Ọlọrun; nítorí pé n óo tún yìn ín,olùrànlọ́wọ́ mi ati Ọlọrun mi.
Wọ́n bá àwọn ọmọ-ẹ̀yìn mọkanla ati àwọn tí ó wà pẹlu wọn níbi tí wọ́n péjọ sí, 
Ẹsira bá dáhùn pé, “Ìyìn ni fún OLUWA, Ọlọrun àwọn baba wa, tí ó fi sí ọba lọ́kàn láti ṣe ọ̀ṣọ́ sí tẹmpili Ọlọrun ní Jerusalẹmu, 
O ni irọle ọjọ Abamẹta ni oun fi ara oun silẹ fayẹwo amọ bayi esi ti fi han pe oun ni Coronavirus.
Mercy Aigbe: Èmi ni ìyá onílé tuntun 'Fayẹmi ṣì ní ẹ́jọ́ láti jẹ́ ní Ékìtì' Ìmáàmù yiì dóólà ẹ̀mí 262 Krìstìẹ́nì ni Plateau Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ìjà ọlọ́pàá àti alápatà ni Bodija gbẹ̀mí Sulia aláìṣẹ̀ ni UCH Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Plateau: Àsìkó tó láti fi káádì ìdìbò yanjú ọ̀rọ̀ Buhari Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Àyàn: Ti mo bá ti gbọ́ ohùn ìlù ni àárẹ́ mi ma ń lọ!
Ẹni tí í bá máa ń sọ̀rọ̀ jàbùjàbù láìronú,ọ̀rọ̀ rẹ̀ dàbí kí á fi idà gún eniyan,ṣugbọn ọ̀rọ̀ ọlọ́gbọ́n dàbí ẹni wo ọgbẹ́ sàn.
Ó mú kí ẹsẹ̀ kẹ̀kẹ́ ogun wọ́n há, tí ó fi jẹ́ pé àwọn kẹ̀kẹ́ náà wúwo rinrin.
Aarẹ ẹgbẹ naa to ba BBC Yoruba sọrọ, Ọjọgbọn Adedayo Faduyile sọ pe gbigba oye ninu eto iṣegun ibilẹ ni nileewe giga yoo ṣeranwọ ni ẹka eto ilera.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Independence Day Nigeria: Ọ̀kọ̀ọ̀kan àwòrán mẹ́fà yìí ló dúró fún ọdún mẹ́wàá ìtàn ilẹ̀ wa 1 Ọ̀wàrà 2020 BBC Se akojọpọ itan nipa Naijiria pẹlu aworan mẹfa pere, eyi to n salaye awọn igba manigbagbe ninu ọgọta ọdun ti Naijiria gba ominira.
Awọn ọlọkọ ero ati ọlọkada to ba wa sọrọ ṣe alaye wi pe aṣẹ ti ijọba pa ko tii fi bẹẹ fi ẹsẹ mulẹ nitori naira marundinlaadọjọ ṣi ni awọn onile epo kan n taa, bẹẹ sini awọn kan gbe ilẹkun ile itaja epo wọn ti pa.
Amọ ajọ eleto ilera lagbaaye, WHO ti ṣalaye pe ko si ohun to jẹ bẹẹ rara.
 Gbogbo ohun ti a ba gbin la o ka, ti ko ni ku ikan sile.
Oríṣun àwòrán, @PDPOfficialNIG Àkọlé àwòrán, Kiko ọpọ ọmọ ogun lọ si tibu-tooro ipinlẹ Ekiti ko ba PDP lara mu PDP ni aimọye igba ni ijọba aarẹ́ Muhammadu Buhari ti n dun kooko mọ eto isejọba awa ara wa, to si n tubọ̀ fẹju si ni ojoojumọ, paapa ni bayii ti eto idibo gomina ni ipinlẹ Ekiti n sunmọle.
Amọ Gomina Makinde la gbọ pe o fi apa janu pe nibo ni oun yoo ti ri alekun biliọnu mẹwa naira lati fi gbọ bukata isuna ọhun lasiko ọda owo to n ba ilẹ wa finra yii.
Daddy Freeze ni Jesu tabi awọn ọmọ ẹyin rẹ ko gba ida mẹwaa nigba aye rẹ, ofin atijọ ni sisan ida mẹwaa jẹ, idi si ree ti Kristẹni fi n pe ofin majẹmu laelae ni ofin ẹsẹ ati iku.
Sẹnẹtọ Shehu Sani naa sọrọ iwuri nipa Yar'Adua, o ni aarẹ to lọ jẹ olotitọ eniyan ati oloṣelu ti kii figba kan bọkan ninu.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù EFCC- Diezani: Ilé ẹjọ́ ti gbéjilé ẹ̀ṣọ́ ara Diezani tó tó $40m pátápátá 11 Owewe 2019 Oríṣun àwòrán, WOLE EMMANUEL Àkọlé àwòrán, Ilé ẹjọ́ tó ń gba ẹjọ́ ẹ̀sùn ìwà àjẹbánu tí Àjọ EFCC pé mọ Diezani Allison-Madueke ti gbẹ́ṣẹ̀ lé ohun ẹ̀ṣọ́ ara rẹ̀.
Bisi Alimi ni oun ti segbeyawo pẹlu ọkunrin miran ni ilu London, ti awọn si jọ n gbe papọ, nitori oun ko lee gbe obinrin ti oun ko ni ifẹ kankan si, sinu ile.
 Ìlú tí wọ ́ n ti n sọ èka-èdè igbómìnà ni ìjọba Ìbílẹ ̀ Ìfẹ ́ lódun ni Ìgbàjà , Òkèyá , Òkè-Ọdẹ , babáńlá , Ṣàárẹ ́ àti bẹ ́ ẹ ̀ bẹ ́ ẹ ̀ lọ .
Iwobi (Arsenal FC, England); Samuel Kalu (Girondins Bordeaux, France); Paul
"Oríṣun àwòrán, AFP Àkọlé àwòrán, Awọn to n kẹdun fi ifunni ni ""Agbara dudu"" fun Winnie Madikizela-Mandela."
Banki Nàìjíríà, CBN ṣàlàyé nípa àwọn tó máa rí gbà nínú owó ìrànwọ́ N75b tíjọba gbé kalẹ̀ Ọkùnrin kan rí ẹ̀wọ̀n ọdún mẹ́rin he lẹ́yìn tó jí ẹ̀rọ ìléwọ́ iPhone ní ìpínlẹ̀ Ogun ₦50 bílíọ́nù ni a pín fún gbogbo ìpínlẹ̀ ní Naijiria láti kojú àrùn Covid-19- Ìjọba àpapọ̀ Àwọn ọ̀dọ́ dáná sun ọkọ̀ akérò tó ṣekúpa ọlọ́kadà ní Ibadan Oṣú mẹ́fà ni òṣìṣẹ́ ìjọba tó bá bímọ yóò máa lò nílé kó tó wọṣẹ́ padà- Seyi Makinde Koda, ọjọ mọkanla lẹyin ti wọn pa ọmọde meje ni Kumba, ni iṣẹlẹ naa waye.
Àwọn èèyàn London ya bo ilé ìtajà lórí òfin kónílé-ó-gbélé Èèèyàn márùn ún péré ló leè lọ ayẹyẹ ìgbéyàwó ní Australia báyìí nítorí Coronavirus 'Akonimu BBC' 'Màálù tó bá tàsẹ̀ àgẹ̀rẹ̀ níwájú ilé mi, ó dẹran àsun!
NUJ: A fẹ mọ ẹsẹ awọn akọroyin tẹ da duro
O ni orile-ede Tanzani, nilẹ Afrika ni oun ti ni ifọkanbalẹ ti oun n fẹ tọmọ-tọmọ.
Bakan naa , ni ijoba ko ni rẹyin lati maa se ojuse won latimu  erongba ati igbaye-gbadun awon osise ni ọkunkundun.
Àkókò náà súnmọ́ tòsí tí a óo fi Ọmọ-Eniyan lé àwọn ẹlẹ́ṣẹ̀ lọ́wọ́.
Gbogbo ìlú tí ẹ óo fún wọn yóo jẹ́ mejidinlaadọta pẹlu ilẹ̀ pápá tí ó yí wọn ká.
"Ohun to sọ ni agbekalẹ iwe Ẹkun Jerimaya, ori kẹta, ẹsẹ kejilelogun ati ikẹtalelogun ninu Bibeli mimọ eyi to ka pe: ""22."
OLUWA, o tàn mí jẹ, mo sì gba ẹ̀tàn;o ní agbára jù mí lọ, o sì borí mi.
Mo ra agbórisétí tuntun tí wọ́n ṣẹ̀ṣẹ̀ gbé jáde tí wọ́n npè ní EarPod.
Pabo ni gbogbo akitiyan Swansea láti pa odo rẹ jasi.
Nígbà tí Absalomu ati àwọn ọmọ Israẹli yóo fi ré odò Jọdani kọjá tán, Dafidi ti dé ìlú tí wọn ń pè ní Mahanaimu.
Gégé bí òwe tí mo pa níbẹ̀rè, èdè àyálò náà lókù nítorípé “ọgbọ́n ọlọ́gbọ́n ni ò jẹ́ ká pe àgbà ní wèrè”
Wọ́n gba aṣọ lára rẹ̀, wọ́n lù ú, wọ́n bá fi í sílẹ̀ nígbà tí ó fẹ́rẹ̀ kú tán.
Hamori baba Ṣekemu tọ Jakọbu wá láti bá a sọ̀rọ̀.
Okoduwa wá kìlọ̀ fáwọn ọmọ ilé ẹ̀kọ́ òhún láti kíyèsára kí wọn máà bọ́ sọ́wọ́ ìtànjẹ àwọn fàyàwọ̀ ọmọnìyàn láti rínrin àjò to léwu nínú lilọ sí orílẹ̀-èdè Libya Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
A bẹ̀rẹ̀ ẹ rẹ̀ gẹ́gẹ́ bíi ètò Halowíìnì láti kó owó jọ fún ilé-iṣẹ́ ìbílẹ̀ kan.
Ninu fidio, nise ni Gomina Ganduje n ri owo dolla to gba lọdọ ẹnikan bọ inu apo rẹ.
Èèyàn 114 míràn tún ti ní àrùn Coronavirus ní Nàíjírìa Àkọlé àwòrán, Àjọ NCDC lo fi ikede naa si kita loju opo ikansiraẹni Twitter rẹ.
Petri Sipilä; oba orile ede Austria, alaye julo, Sebastian Kurz; ati minisita
Wọ́n bá bẹ̀rẹ̀ sí bú u pé, “Orí rẹ dàrú!
Ojo arọọrọ da naa bẹrẹ ni alẹ ọjọ Aiku, to si rọ titi di ọjọ keji.
Ẹgbẹ́ IPOB ò tako Ààrẹ Buhari ní Japan- Iléeṣẹ́ Ààrẹ Òfin nìkan ló lè gbadé lórí àwa Ọba ìlú lbadan- Oba Lekan Balogun Irọ́ ló pa, a kò mọ̀ ọ́ rí tàbí fún ọ ní ₦13m - APC tako afurasí ajínigbé Àlàyé rèé lórí bí wọ́n ṣe mú mi lẹ́rú ní 1837 - Ajayi Crowther Fakorede ní ọ̀rọ̀ náà dàbi ẹni ti wọ́n fi ọ̀pá àṣẹ ọba rán níṣẹ́ ni, ọ̀wọ̀ ọpá àṣẹ́ ọba ni wọ́n gbọdọ̀ máa fi wọ òun.
Aya aare orile ede Naijiria ,iyaafin Aisha Buhari  ro awon obinrin ẹgbẹ̀wàá  niluu Yola ni ipinle Adamawa lagbara.
Iya rẹ, Deborah Okezie lo fi fidio kan sita ni ọsẹ to kọja, nibi to ti fi ẹsun kan pe awọn akẹkọọkunrin kan to wa ni kilaasi Agba fi ipa ba ọmọ oun ni ibalopọ, lai ti ju oṣu meji to de ileewe naa lọ.
Oluwo: Ó dàbí ẹni pé ọ̀tá pọ̀ fún mi, inú wọn kò dùn sí bí mo ṣe ń ṣakọ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fọ́nrán ohùn, iyonipo Oluwo tilẹ Iwo, Ọba Abdulrasheed Akanbi ti fesi lori ipinnu igbimọ lọbalọba nipinlẹ Ọsun to ni ko lọ rọọkun nile fun osu mẹfa.
Bi obinrin naa ba wa loyun pẹrẹ, o ṣeeṣe ko ṣokunfaa bibi ọmọ ti ko tọjọ.
mo igbiyanju lati se ironilagbara fun awon odo orile ede Naijiria .
O ni èyí ṣe pàtàkì láti lè fòpin sí ìkọlu àwọn daran-daran kaakiri ipinlẹ Oyo tó fi mọ ojú popona marose káàkiri ipinle naa.
Ninu ọrọ to ba BBC News Yoruba, Babalawo Idowu Olukunle, Akoda Awo ṣalaye pe, ko si ootọ ninu ọrọ ti awọn dokita iṣegun Oyinbo sọ naa.
N óo rán àyànfẹ́ ọmọ mi, bóyá wọn yóo bọlá fún un.
Wọ́n ti mu aṣojú ọmọ Britikó ní orílẹ̀-èdè Iran Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Bí ó bá jẹ́ ẹ̀bùn láti darí ètò ni, kí á lò ó láti darí ètò.
ṣugbọn lẹ́yìn náà ìyàn yóo mú fún ọdún meje, ìyàn náà yóo pọ̀ tóbẹ́ẹ̀ tí ọdún meje tí oúnjẹ pọ̀ yóo di ìgbàgbé ní ilẹ̀ Ijipti, ìyàn náà yóo run ilẹ̀ yìí.
Fuel hike protest: Àwọn akẹ́kọ̀ọ́ ìpínlẹ̀ Oyo, Osun àti Ondo ṣe ìfẹ̀hónúhàn lórí èlé owó iná àti owó epo
Oríṣun àwòrán, Twitter/Manchester City Àkọlé àwòrán, Manchester City vs Chelsea: Ṣé kìnìhún Manchester City tó bú ramúramù kò ní pa Chelsea jẹ lónìí?
Bí ọkàn àgbọ̀nrín tií máa fà sí odò tí omi rẹ̀ tutù,bẹ́ẹ̀ ni ọkàn mi ń fà sí ọ, Ọlọrun.
Egbe to n ri si ere idaraya lorile-ede South Africa, (SAFA), ti ni akonimoogba agba tuntun fun iko egbe agba-boolu orile-ede ohun, Stuart Baxter, yoo kede awon agba-boolu re lojo karundinlogbon, osu karun un odun yii, lataari ifesewonse ipegede fun idije boolu awon Adulawo ti yoo waye lodun 2019, laarin iko egbe agba-boolu South Africa ati iko egbe agba-boolu orile-ede Naijiria.
Èyí sọ yín di alábàápín ninu ìjìyà Kristi.
Wò ó, ìparun náà ti dé tán.
Oríṣun àwòrán, @dabiodunMFR Gomina Abiodun ti wa parọwa si awọn awọn ọmọ ikọ Remo Stars atawọn ọmọ ipinlẹ Ogun lati ma tẹ oju ofin mọlẹ nitori wọn n fẹ idajọ ododo fun arakunrin wọn to d'ologbe.
Aare egbe to n se  polongo ifetosomo-bibi lorilede Naijiria
Nítorí náà ni mo ṣe sa gbogbo ipá mi láti sálọ sí Taṣiṣi; nítorí mo mọ̀ pé Ọlọrun onífẹ̀ẹ́ ati aláàánú ni ọ́, o ní sùúrù, o kún fún ìfẹ́ tí kì í yẹ̀, ò sì máa yí ibi tí o bá ti pinnu láti ṣe pada.
"O ni ""ọpọ èèyàn ti ko ni isẹ lọ́wọ́ lo ń fi ọtí pa ìrònú rẹ, dípò kí wọn lo oogun oloro, tó sì tún daba pé, tí ìjọba bá fi ààyè gba títa ìwọ̀nba ọtí díẹ̀, èyí kò ní jẹ́ kí oko-owo òun dẹnu kọlẹ."
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Oba Adedokun Abolarin ti Oke Ila: Ó ya ọ̀pọ̀ tó súnmọ́ mi lẹ́nu bí mo ṣe ń kọ́ Ohun mẹwaa pataki to yẹ ki o mọ ree nipa Diego Maradona 1.
"Ninu ọrọ to ba awọn ololufẹ rẹ sọ nibẹ, Họnọrebu Debọ Akanbi ṣalaye wí pé, "" A mọ ipilẹṣẹ APC nipinlẹ Ọsun, a si ni adehun pẹlu gomina Arẹgbẹṣọla lati lo ọdun mẹjọ rẹ nipo, kii ṣe lati wa yan eeyan kan le wa lọwọ nigba ti o ba ṣetan ati lọ."
OLUWA, nígbà tí o bá jí gìrì, wọn óo pòórá.
OLUWA wí pé: “Mo rí Israẹli he bí ìgbà tí eniyan rí èso àjàrà he ninu aṣálẹ̀.
Wọ́n farahàn ninu ògo, wọ́n ń bá a sọ̀rọ̀ nípa irú ikú tí yóo kú láìpẹ́, ní Jerusalẹmu.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ọjọ kẹrinlelogun ati ikarundinlọgbọn oṣu kẹrin ni ifẹsẹwọnsẹ akọkọ ni ipele yii yoo waye Ọjọ kẹrinlelogun ati ikarundinlọgbọn oṣu kẹrin ni ifẹsẹwọnsẹ akọkọ ni ipele yii yoo waye.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Dino Melaye: Mi o du ipo aarẹ ni 2019 4 Ẹrẹ̀nà 2018 Oríṣun àwòrán, TWITTER.
tabi kí n dá oúnjẹ mi jẹ,láìfún ọmọ aláìníbaba jẹ
Ó súnmọ́ ẹnu ọ̀nà ilé ìṣọ́ náà láti dáná sun ún.
Lẹ́yìn ogoji ọjọ́, Noa ṣí fèrèsé ọkọ̀ tí ó kàn.
Lai si aniani, eeyan nilo hand sanitizer lati le jẹ ki ọwọ rẹ wa ni imọtoto nitori ohun ipawọ ọhun lagbara lati pa awọn kokoro aifojuri.
Ní ọdún 2020, ìjóba ìbílẹ̀ yìí ni yóò fi ìdí rẹ̀ múlẹ̀, ẹni ti yóò jáwé olúborí gẹ́gẹ́ bi gómìnà ìpínlẹ̀ Ondo Ẹ̀wẹ́, ìjọba ìbílẹ̀ yìí gan ni olùdíje dupò lábẹ́ ẹgbẹ́ òṣèlú People's Democratic Party, (PDP) Eyitayo Jegede ti wá.
Kunle Afolayan, Gabriel Afolayan ati Moji Afolayan.
naa wa seleri pe awon yoo mu  odaran naa,
Lara awọn eniyan jankanjankan ti wọn wa nibi Ipade Apero Awọn Alẹnulọrọ, ẹlẹẹkẹrin iru rẹ yii ni awọn lọbalọba, olori ẹlẹsinawọn aṣiwaju ẹgbẹ oṣelu, awọn ẹgbẹ ọlọja, awọn oniṣẹ ọwọ, awọn olori ẹya Hausa ati Igbo, awọn ọdọ ati awọn miiran bẹẹ.
Lẹ́yìn náà, da ẹ̀jẹ̀ yòókù sí ara pẹpẹ yíká.
 A ni lati ri i daju pe a ko gba awọn oṣiṣẹ to le pa wa lara sinu ile.
O ni omii wa lati idije pẹlu Gambia ati Senegal lọdun meji sẹyin.
India: Ó lé ní mílíọ́nù ènìyàn tí wọ́n kó kúrò lágbèègbè Orissa
Obama gboriyin fun arabinrin Sherald fun bi o ṣe safihan ẹwa iyawo oun ninu aworan rẹ to ya.
ati beebe lo ni ede Faranse ni won se lose yii lati fi ran awon eniyan leti nipa ede ati asa ile Faranse.
’ Ìtànjẹ ẹẹkeji yóo wá burú ju ti àkọ́kọ́ lọ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, #EndSARS : Àwọn ọ̀dọ́ dáná sun tírélà akẹ́rù tẹrùtẹrù ní Ekiti Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Idi niyi ti kabiyesi Ọọni fi kede pe ki gbogbo awọn olugbe ilu ifẹ o wa ninu ile wọn nitori oro fẹ jade lati fọ ilu mọ lọwọ arun Corona.
Asaraya, olórí alufaa, láti ìdílé Sadoku dá a lóhùn pé: “Láti ìgbà tí àwọn eniyan ti bẹ̀rẹ̀ sí mú ẹ̀bùn wá sí ilé OLUWA ni a ti ń jẹ àjẹyó, tí ó sì ń ṣẹ́kù, nítorí pé OLUWA ti bukun àwọn eniyan rẹ̀, ni a fi ní àjẹṣẹ́kù tí ó pọ̀ tó yìí.
Iṣẹlẹ ọhun lo ṣẹlẹ lọjọ Iṣẹgun lẹba ile itaja nla kan ni Millenia ni Orlando lorilẹ ede Amẹrika.
Gege bi Buratai seso “Awon eto ti a pese sile bayii lati koju isoro to n dojuko eto aabo lorile-ede yii, laipe-laijina yoo so eso rere.
Nítorí náà, Mose ati Aaroni lọ, wọ́n sì wí fún Farao pé, “OLUWA Ọlọrun àwọn Heberu ní kí á bèèrè lọ́wọ́ rẹ pé, yóo ti pẹ́ tó tí o óo fi kọ̀ láti rẹ ara rẹ sílẹ̀ níwájú òun Ọlọrun?
Ìkọlùkọgbà ńrúgbó bọ̀ pẹ̀lú ènìyàn 200m Wo àwọn olórí orílẹ́-èdè tó sọ̀rọ̀ fẹnu kọ pẹ̀lú ẹ̀rọ gbohùngbohùn Àjọ DSS tọrọ àforíjìn lórí ìwà ti wọ́n hù nílé ẹjọ Ẹwẹ iwadii naa tun fi kun un pe riba gbigba ti sọ eto igbanisiṣẹ lorilẹ-ede Naijiria di toni owo ree, iṣẹ ree.
Kọmísọ́nà àjọ INEC, tó tún jẹ́ alága ìròyìn àti ìtanijí Festus Okoye ni àwọn ti kàn si ilé iṣẹ́ ọmọogun ojú omi àti àwọn ọlọpàá inú omi, láti sin àwọn èròjà tí wọ́n yóò lò fún ìdìbò lágbègbè náà.
Ọwọ́ ọlọ́pàá tẹ afurasí olóògùn owó tó fẹ́ gé ọmú obìnrin kan nílé ìtura Àwọn èèyàn ìpínlẹ̀ Oyo gbarata lórí àlékún owó epo bẹntiróò Ọ̀la òde yìí ni ìrìnàjò sí ilẹ̀ òkèèrè yóò padà bẹrẹ ní Nàìjíríà Wo ohun tí ilé ẹjọ́ ní kí wọ́n ṣe fún Sunday Shodipe, afurasí ìṣekúpani l'Akinyele E wo ọmọ Yorùbá àkọ́kọ́ tó jà fún ẹ̀tọ́ àwọn aláwọ̀dúdú ní America!
Aare Muhammadu Buhari ti bowolu iwe itesiwaju lenu ise oga agba to n mojuto ile-ise ogba ewon lorile-ede Naijiria,   Ja’afaru Ahmed.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Lekki free toll: Àwọn ará ìpínlẹ̀ Eko kan sárá sí Sanwoolu 11 Agẹmo 2019 Àkọlé àwòrán, Ibodè Lekki Lẹyin ti gomina ipinlẹ Eko, Babajide Sanwoolu ti kede pe ọfẹ ni awọn awakọ yoo kọja lẹnu ibode Lekki si Ikoyi, bi inu awọn eeyan ṣe dun ko ṣee fẹnu sọ.
" Gbogbo wa n to lati yan niwaju gomina nigba ti wọn ṣa dede gba ẹburu lai fẹ to.
O salaye pe,”a ti wa loju ona bayii, a ti  bere nilu Jos nipinle Plateau ni osu kerin odun 2016, eyi ti ipolongo sise amulo ero igbalode naa ti de ilu Abuja, Ilorin, Kaduna, eyi ti o gunle si ipinle Enugu bayii.
Ó ní, “Ní ti ibukun, n óo bukun ọ.
Ṣugbọn Mose bẹ OLUWA Ọlọrun rẹ̀, ó ní, “OLUWA, kí ló dé tí inú fi bí ọ tóbẹ́ẹ̀ sí àwọn eniyan rẹ, àwọn tí o fi agbára ati tipátipá kó jáde láti ilẹ̀ Ijipti?
- Àjọ ajàfẹ́tọ̀ọ́ ọmọdé Ó ṣeésẹ kí ọkùnrin tó n mu àmujù ọtí ó maa lo ìwà ipá pẹ̀lú ìyàwó rẹ̀ Al Shabab ṣe ìkọlù sí ibùdó ogun America ní Kenya, ẹ̀mí mẹ́ta lọ síi O ni ijọba pẹlu gbọdọ ṣetan lati doju ija kọ awọn ọta orilẹ-ede Naijiria gangan ki wọn lee gba awọn ọmọ Naijiria lọwọ wọbia awọn amunisin to n jẹ gaba lori wọn.
A si fẹnu ko pe asise kankan ko gbọdọ waye, amọ ni kete ta pẹyinda tan, ni minisita feto ẹkọ sọ nnkan miran sita.
Ìdí ẹ̀ lèyí tó fi jẹ́ pé ọjọ́ tí oòrùn bá yọ, tí ojú-ọjọ́ bá fẹ́ ṣe bí ẹní mọ́n díẹ̀, kíà-kíà ni gbogbo wa má jáde síta láti gbádùn ìmọ́lẹ̀ àti lílọ́wọ́rọ́ oòrùn.
kí wọ́n wá kíá,kí wọ́n wá máa sọkún tẹ̀dùntẹ̀dùn lé wa lórí,kí omi sì máa dà lójú wa pòròpòrò.
Alaga àjọ LMC, Shehu Dikko, nínú àtẹjáde kan to fi ba Nasarawa United àti ẹbi olóògbé náà kẹ́dun.
Bakan naa lo jẹ ọkan lara awọn oludasilẹ Boddiemax Online Premium Fashion Brand.
Bí ọlọ́pàá ṣe bọ́ aṣọ mi tí wọ́n lù mi, wọ́n tún gba #260, 000 lọ́wọ́ mi - Olumide Wo ilé ìwòsàn kan ti tọmọ-tìyà ti ń kú lẹ̀yìn tí Covid-19 búrẹ́kẹ Ìhà wo ni àwọn aláṣẹ kọ si?
Jìnnìjìnnì bá dàbo gbogbo àwọn ọmọ ogun wọn.
Wọn fikun wi pe lẹyin ti iya naa ri wi pe ọmọ oun ji owo naa, o pe ọkọ rẹ to jẹ ọlọpaa lati fi ẹjọ ọmọ naa sun, ti baba ọmọ naa si pasẹ wi pe ki wọn na ọmọ naa.
Àwọn ni ìlú olódi ní Juda ati Bẹnjamini.
Àwọn ọlọ́ṣà yóo wọnú rẹ̀, wọn yóo sì sọ ọ́ di eléèérí.
Ifiposilẹ ọgbẹni Desalegn sokunfa bi ijọba ti se kede ilu ofara rọ jakejado orilẹẹde naa.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Operation Amotẹkun: Ẹ̀ṣọ́ ilẹ̀ Yorùbá 'Àmọ̀tẹ́kùn' ṣetán láti bẹ̀rẹ̀ iṣẹ́ káàkiri ilẹ̀ káàrọ́ọ̀ oò jíire 2 Sẹ́rẹ́ 2020 Oríṣun àwòrán, Facebook/Dr Kayode Fayemi Àkọlé àwòrán, Ẹ̀ṣọ́ ilẹ̀ Yorùbá 'Àmọ̀tẹ́kùn' ṣetán láti bẹ̀rẹ̀ iṣẹ́ káàkiri ilẹ̀ káàrọ́ọ̀ oò jíire Gomina ipinlẹ Ekiti, Kayode Fayemi ti kede pe gbogbo eto ti to bayii fun ile iṣẹ eto aabo ilẹ Yoruba ''Amọtẹkun'' lati bẹrẹ.
teleri ,Abiola Ajumobi, nigba ti gomina ipinle Eko  Babajide Sanwo-Olu ati igbakeji re Obafemi
Eyi si gbọdọ wa pẹlu iwe aṣẹ ati ominira lati le lo ibọn.
Ipa tí ìyànsípò Olóòtú ìjọba Gẹ̀ẹ́sì tuntun yóò mú bá ‘Brexit’ Òkìtì iyanrìn wó pa èèyàn méjí nílùú Ibadan Àgùnbánirọ̀ akọ̀ròyìn Channels náà ti dágbére fáyé látààrí ìkọlù Shiite l'Abuja Ààrẹ orílẹ̀èdè Tunisia dágbére fáyé Ta ló ni $1.
Wọ́n ru ẹrù títí orí gbogbo wọn pá, èjìká gbogbo wọn sì di egbò.
Oríṣun àwòrán, Reuters Sextuplet: Àdúrà Ìbùkún ló kú lẹ́yìn ọmọ mẹ́fà yìí- Ifeoma Thelma àti Onyemaechi Chiaka Joe Biden kéde Kamala Harris, obìnrin aláwọ̀ dúdú gẹ́gẹ́ bí igbákejì rẹ̀ nínú ìdíje sípò Ààrẹ Amẹrika Wo ìdí tí Risikat Moromoke Azeez n'Ilorin fi ní Blue Eyes"" - Dókítà NCDC kéde èèyàn 423 míràn tó ṣẹ̀ṣẹ̀ lùgbàdì Covid-19 ní Nàìjíríà, 263 gbàwòsàn Ohun tí a mọ̀ nípa òògùn 'Sputnik V' tí Russia tó ń wo àrùn Coronavirus Ọsẹ to kọja ni ijọba orilẹ-ede Russia fi lede wi pe awọn n pese abẹrẹ ajẹsara ọlọgọọrọ lati koju arun Coronavirus, bẹrẹ lati Oṣu Kẹwaa."
Ṣé ìwọ náà rí i pé àbúrò rẹ̀ lẹ́wà jù ú lọ, jọ̀wọ́ fẹ́ ẹ dípò rẹ̀.
Apero naa bere ni ojo kerin osu kesa an si ojo kefa osu kesan an ni eyi ti yoo je elekewaa iru re fun NFELTP.
Ìlànà yìí yóo wà títí lae ní ìrandíran yín.
Ẹgbẹ agbabọọlu Manchester city ti fi agba han ẹgbẹ agbabọọlu Chelsea lẹyin ti wọn na wọn pẹlu ami ayo mẹfa si odo.
Àwọn ọba ayé kó ara wọn jọ,àwọn ìjòyè gbìmọ̀ pọ̀,wọ́n dojú kọ OLUWA ati àyànfẹ́ rẹ̀.
Nàìjíríà bí ìkókó 26, 039 lónìí ọjọ́ kíní, oṣù kínií, ọdún 2020- UNICEF Bàbá akẹ́kọ̀ọ́ LASU tí ọ̀rẹ́kùnrin rẹ̀ àti pásítọ̀ fi ṣ'oògùn owó ń bèèrè fún ìdájọ́ òdodo Ó ti tán fún mí lọ́dún 2023- Ààrẹ Muhammadu Buhari Wo àwọn èèyàn jáńkán tí yóò ṣe ọdún tuntun ní ọgbà ẹ̀wọ̀n Elkana ni nígbà ti ìwádìí bẹ̀rẹ̀ ni àwọn tọpasẹ àwọn ajílẹ̀ náà de ọja Dalekọ ni àgbègbè Mushin, eyi ti ko ṣẹyin awọn afurasi ibẹ.
O tun salaye pe, apọnle ti wọn ba n fun Fela lo yẹ ki wọn maa fun Barrister kaakiri gbogbo agbaye.
Kí ló dé tí ẹni tí ó bá ní ẹ̀sùn sí ẹnìkejì rẹ̀ fi ń gbé ẹjọ́ lọ siwaju àwọn alaigbagbọ?
Gomina ipinlẹ Ekiti tẹlẹ, Ayọdele Fayose ṣalaye pe lẹyin Ọṣun, Ekiti lo kan lati bọ si ọwọ ẹgbẹ oṣelu PDP.
Adeoti ní aiṣedeede nínú ìdìbò abẹnu APC ló sún òun débi a n kowefiposilẹ àti wí pé òun ṣetan láti dije ipò Gómìnà nínú ìdìbò tó n bọ lónà lábé àsìá ẹgbẹ ADP.
Nítorí náà Tigilati Pileseri, ọba Asiria gbógun ti Ahasi, ó sì fìyà jẹ ẹ́, dípò kí ó ràn án lọ́wọ́.
"O ni: ""Mi o ro pe awọn eniyan mọ nkan to ṣẹlẹ si mi gan-an."
Opọ ẹmi lo ti sọnu si iwọde wọnyii ni Abuja lai yọ ọga agba ọlọpaa silẹ ati agunbanirọ pẹlu awọn ẹlẹsin Shiite silẹ.
'Títẹ àwọn afipábánilopọ̀ lọ́dàá kọ́ ni ọ̀nà àbáyọ sí ìwà ìfipábánilopọ̀' Jessica Nabongo ni obìnrin àkọkọ nílẹ Adúláwọ tó rin gbogbo àgbáyé.
bí ó bá ti gbóòórùn omi, yóo sọ,yóo sì yọ ẹ̀ka bí ọ̀dọ́ irúgbìn.
De Bruyne gba goolu mẹtala sawaọn fun Man City bo tilẹ jẹ pe ipo keji ni wọn gba ti Liverpool si gba ife Premier League.
Bẹẹ ba gbagbe, ọjọ Aje ni iroyin tan kalẹ pe ileesẹ ọtẹlẹmuyẹ DSS ti gbe Magu, ti wọn si n fi ọrọ wa lẹnu wo.
Awọn dokita naa ṣ'alaye ọrọ ni iwaju ipade ara ilu ti wọn ṣe wi pe ọkẹ aimọye oloyun ti o ti mu ọti amupara ni awọn ṣe itọju wọn to fi mọ awọn eniyan ibilẹ to jẹ wi pe wọn ṣe ikọlu wọn tabi ti wọn gbiyanju ati gba ẹmi ara wọn.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Awọn ara Sudan atawọn ologun gbe ọwọ ami iṣẹgun wọn, V for Victory.
Ọga ọlọpaa patapata ran ẹni naa lati ṣe ipade pẹlu OPC pe oun nilo iranlọwọ ẹgbẹ naa.
Àjọ ọlọpàá Eko kédé pé ìbalòpọ̀ nítà kò bójúmu Njẹ́ ẹ mọ̀ pé orílẹ̀-èdè Nàìjíríà ló n wo 'Blue film' jù?
O ni osu meta ni ijoba
“Mú ẹ̀yà Lefi wá siwaju Aaroni alufaa, kí wọ́n sì máa ṣe iranṣẹ fún un.
Ìtàn ayé Alájọ Ṣómólú rèé, tó ta mọ́tò ra kẹ̀kẹ́?
Gẹgẹ bi ọba Badmus ti wi, o ti to aadọta ọdun sẹyin ti ilu Igboọra ti gbajumọ nipa bibi ibeji abi ibẹta, ohun to si tun jẹ pataki ni pe, wọn kii fi ibeji tọrọ owo nilu Igboọra.
Ọkùnrin náà sì dá a lóhùn, ó ní, bẹ́ẹ̀ ni, bí ó bá mo bí ọ̀rọ̀ mi ti rí, o kò bá tí sọ bẹ́ẹ̀.
A fẹ̀sọ̀ dá ìjọba l'ẹ́kun ìwà ìbàjẹ́
Ààlà àwọn ọmọ Manase tún lọ sí apá àríwá odò náà, ó sì pin sí Òkun Mẹditarenia.
Agbẹnusọ fun ile iṣẹ ọlọpaa ni Ipinlẹ Oṣun SP Folasade Odoro fidi ọrọ naa mulẹ laarọ ọjọ Ẹti.
O ni ohun kan to ku ni lati kede orukọ ẹni to jawe olubori ninu ibo ki wọn to ko ibọn wọ le.
Ọrọ ibalopọ ko ṣẹṣẹ ma a waye laarin awọn olukopa ninu eto naa lati igba to ti bẹrẹ.
lati maa dari eto oro aje orile ede Naijiria.
Awọn eeyan ro pe a n fẹ ara wa ni, idi ree taa fi sun sẹyin funra wa, awọn aye lo tu wa ka.
O fi kun un pe egbeje eeyan lo ti n faṣọ penpe roko ọba bayii lẹyin ti aje iwa ajẹbanmu ṣi mọ wọn lori.
Tí wọ́n bá sọ fún wá ni ọjọ́ àìkú tó kọjá wipe àó wá sòkú Ayodeji ènìyàn yóò jiya Ọdún kẹtalá rẹ̀ẹ́ tí Ituah àti Ibidunni ti wà bíi tọkọtaya kí ó to dédé dolóògbé ní ilú Port harcourt láàrọ̀ kùtù ọjọ́ àìkí Oríṣun àwòrán, others Àkọlé àwòrán, Ibidun Ituah Ighodalo fayé silẹ̀ ìlúmọ̀ọ́ká arẹwà tí fáyésilẹ̀ Wo àwọn òṣèré tíátà Yorùbá tó bí ìbejì Ẹ̀kọ́ mẹ́jọ tó yẹ kí ilẹ̀ Afirika kọ́ lára àjàkálẹ̀ aàrùn coronavirus Alhaja Kudirat Abiola: Odindi géńdé ọkunrin mẹ́fà ni wọ́n gbé iṣẹ́ ikú rẹ̀ fún Mo kábámò pé mo fipá bá Ìyá ẹni ọgọrin ọdún sún ní Kano- Muhammad Zulfara'u Oríṣun àwòrán, @prettypearl Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Ọ̀gbẹ́ni Abíọ́dún Ọláńrewájú ni àwọn aláṣẹ fásitì náà yóò gbé ìgbésẹ tó bá yẹ lẹ́yìn tí ìgbìmọ̀ tí wọ́n gbé kalẹ̀ bá ti jáde pẹ̀lú àbọ̀ ìwádìí rẹ̀.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù FIFAWWC: Super Falcons fi South Korea ṣ’ẹ̀bùn June 12 fún Nàìjíríà 12 Òkùdu 2019 Ikọ agbabọọlu obinrin Naijiria, Super Falcons naa ko gbẹyin bi orilẹede Naijiria ti bẹrẹ si sẹ ayajọ ọjọ ijọba awa arawa loni ọjọ kejila, oṣu kẹfa.
Ajamu ni ijapa naa ti gbe ni afin Ṣọun fun ọpọlọpọ ọdun, to si ni awọn osiṣẹ afin Ogbomọṣọ to ma n toju rẹ ki ọlọjọ to de.
Ọlọrun fun Iya Rainbow ni ọmọ marun un.
Bẹ́ẹ̀ ni ẹni tí ó bá ń ṣe ohun ẹ̀gbin tabi èké kò ní wọ ibẹ̀.
Kí o mọ èyí pé àkókò ìṣòro ni ọjọ́ ìkẹyìn yóo jẹ́.
Fafiti Bayero  ni ipinle Kano,iyaafin Pauline
Oniwaasu ni, bakan naa lọ jẹ oṣere tiata.
Laipẹ yii ni iroyin gbe iṣẹlẹ kan to waye niluu Ibadan nibi ti awọn araalu ti lu arakunrin kan ni adugbo Dugbẹ nitori pe wọn ri t'oun gba owo lẹnu ẹrọ 'ATM' lai lo kaadi.
O mẹnuba awọn ọrọ rẹ kọokan ti awọn eniyan ti fun ni itumọ mii ti wọn si ti fi pa oun lẹkun sẹyin.
Owo ajẹẹlẹ owo oṣu fun awọn olukọ fasiti kan, owo fun atunṣe awọn fasiti, ati owo ajẹmọnu ti wọn pe earned Allowance.
O ṣe iṣẹ ni ileeṣẹ wọlewọde naa titi di ọdun 1978 to darapọmọ ileeṣẹ to n ṣe ohun eelo ataraṣe.
Àwọn ohun tí a ń lò bí ìlù nínú eré àpíìrì láti ìbẹ ̀ rẹ ̀ pẹ ̀ pẹ ̀ wá ni agbè tí ajé wà lára rẹ ̀ .
Nítorí náà, bí a bá ti ń rí ààyè kí á máa ṣe oore fún gbogbo eniyan, pàápàá fún àwọn ìdílé onigbagbọ.
Ilu Abidjan nilẹ Cote D'ivoire si ni Henry Fajemirokun ku si lasiko to lọ se ipade okoowo kan nibẹ.
Àwọn ọmọ Ṣaṣaki nìwọ̀nyí: Iṣipani, Eberi, ati Elieli; 
gba , ati pe oba meji ko lee wa laafin.
Ọmọdé méjì àtàgbà kan ló kú nílé alájà mẹ́ta tó wó l'Eko pátápátá - LASEMA FBI jí Hushpuppi gbé ní Dubai ni- Agbẹ́jọ́rọ̀ Ramọni Igbalode Kí ló mú Obasanjo ti ilẹ̀kùn mọ́ ẹbí, òṣìṣẹ́, ojúlùmọ̀ ní ibi òkú àna rẹ̀?
Ọmọ meje ni Hodeṣi bí fún un: Jobabu, Sibia, Meṣa, ati Malikami, 
Shehu ni alakalẹ ọga ọlọpaa ni Naijiria ni ìkọ Amotekun yoo duro le lori.
Kọ́ńdọ̀mù tó bẹ́ gbé iléèṣẹ́ ìjọba àti aládáni kan dé ilé ẹjọ́ Ipa tí Fathia Balogun kó nínú bí mo ṣe dèèyàn lágbo òṣèré fíìmù Yorùba rèé - Baba Ijesha Èèyàn 16 kú lẹ́yìn tí bàálù Air India já lulẹ̀ , tó sì kán sí méjì ní Kerala Àgbáríjọ àwọn nọ́ọ̀sì fẹ́ gbé Olamide Baddo lọ sílé ẹjọ́ fún ìbanilórúkọjẹ́ Inú odò ni wọ́n ti rí òkú ọmọ ọdún méjì tó sọnù l'ọ́jọ́ ọdún Eid nílùú Ibadan Sugbọn iyalẹnu lo jẹ pe ibeere to gba ẹnu ọpọ ololufẹ Ọba Adeyemi lasiko ti wọn foju kan aworan naa ni pe: Ki lo mu Olori Badra kuro l'Alaafin Oyo lọjọ Ileya, ti ko fi ba awọn ayaba yoku ya aworan pẹlu ọkọ wọn lọjọ ọdun?
Ọlọ́pàá fi páńpẹ́ ọba mú ọmọ ogun ilẹ̀ Naijiria Igba ikeji ti Shekau di oloogbe: Lọdun 2013 ni awọn ọmọ ogun ilẹ Naijiria tun kede pe awọn ti ṣe Abubakar Shekau leṣe lasiko ti wọn kọlu Boko Haram ni ariwa Naijiria.
Mo n ro yin lati maa gbadura fun alaafia awon omode wonyii”.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Chelsea na Swansea 1-0 mole.
Mínísítà fún ètò ìròyìn,Alhaji Lai Muhammed, lo fèsì naa pada pé ''àhesọ ọ̀rọ̀ ni Ọbasanjọ n sọ, àti pé ìjọba Buhari kò ráàyè a n dìràn mọ́ni lẹ́sẹ̀'' Ọrọ náà jẹyọ nínú aàtẹ̀jáde kàn tó fí ṣọwọ́ s'awọn akọ̀ròyìn lọ́jọ́ Ẹtì nílùú Èkó.
Ijinigbe lawọn oju popo Naijiria ti wa peleke si lẹnu ọjọ mẹta yi ti ọpọ si ti padanu ẹmi wọn lọwọ awọn alaburu ẹda ajinigbepawo Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 3 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 5 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
ipenija to n dojuko ipinle naa, wa siwaju igbimo alase yii ni ibamu pelu  eto ati ilana ti a ti la sile.
Lẹ́yìn náà, afẹ́fẹ́ fẹ́ wọn lọ, a kò sì rí wọn mọ́ rárá.
Níbo lo wà, nígbà tí mo fi ìpìlẹ̀ ayé sọlẹ̀?
Isọri B: Awọn wọnyii yoo maa lanfani siina manamana laarin wakati mẹrindinlogun si ogun wakati.
Ẹ wo ọ̀nà márùn ùn tí ọkùnrin ṣì fi ń jẹ gàba lé obìnrin lórí Harvey Weinstein tó jẹ̀bi ẹ̀sùn ìfipábánilòpọ̀ ti rí ẹ̀wọ̀n ọdún mẹ́tàlélógún he!
Abẹ kò gbọdọ̀ kan orí rẹ̀, nítorí pé, Nasiri Ọlọrun ni yóo jẹ́ láti ọjọ́ ìbí rẹ̀; òun ni yóo sì gba Israẹli sílẹ̀ lọ́wọ́ àwọn ará Filistia.
Atẹjade kan ti alukoro ileeṣẹ ọlọpaa nipinlẹ Eko, Bala Elkana fi sita ni, ọwọ tẹ afurasi naa, Ojo Adeṣọla, ni ọjọ kọkanlelogun, oṣu Kẹfa, ọdun 2019, ni nkan bi aago mẹjo owurọ ni adugbo Alagbado nipinlẹ Eko.
Ọmọ ẹya Oromo nii se, eleyi to jẹ ẹya to wa nidi iwọde ifẹhonu alatako ijọba fun ọdun mẹta sẹyin.
 obìnrin ló pò jù nínú àwon tí ó n yáwó lówó rè .
Omiri mọ odi yí òkè náà ká, ó sì sọ orúkọ ìlú tí ó kọ́ náà ní Samaria, gẹ́gẹ́ bí orúkọ Ṣemeri, ẹni tí ó ni òkè náà tẹ́lẹ̀.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Lockdown updates: Naira Marley gbóríyìn fún Jude Chukwuka pẹ̀lú #1 míliọnù Ki lo ti ṣelẹ sẹyin?
 Ẹ ̀ gbá òkè- ọnà ló ń yan ọ ̀ tún ọba .
Nítorí èyí, ẹ gbé gbogbo ihamọra Ọlọrun wọ̀, kí ẹ lè dìde dúró láti jà nígbà tí ọjọ́ ibi bá dé.
N óo kó àwọn tí wọ́n kù ninu àwọn aguntan mi jọ láti gbogbo ibi tí mo lé wọn lọ.
Ẹ kí Nimfa ati ìjọ tí ó wà ní ilé rẹ̀.
Ṣugbọn ìwọ, Ọlọrun, o óo sọ àwọn apaniati àwọn alárèékérekè, sinu kòtò ìparun;wọn kò ní lo ìdajì ọjọ́ ayé wọn.
Oríṣun àwòrán, others Ninu waasi ti wọn gbe kalẹ lati gba awọn eeyan niyanju níbi eto naa, Sheikh Muideen Ajani Bello atawọn agba Alfa to wa nibẹ gba awọn ololufẹ Ajimobi nimọran lati mase jẹ ki ogun rere to fi silẹ parun.
BBC Gist Naija ṣe iṣẹ iwadii lori awọn ti wọn ti bọ sọwọ agbewiri, o jẹ ohun to yanilẹnu pe ọpọlọpọ ni wọn ti kagbako awọn aṣoju agbabọọlu ti wọn jẹ gbajuẹ.
Oríṣun àwòrán, Facebook/Kamilu Adewole Nigba to n fidi isẹlẹ iku baba Oniluola mulẹ fun BBC Yoruba, ilumọọka osere tiata kan, Tunke Kelani salaye pe aago mẹrin irọlẹ oni Ọjọru ni oloogbe naa yoo wọ kaa ilẹ sun.
Ifeanyi Okowa ti ro awon akegbe re  ni
O tun ṣalaye pe awọn ẹgbẹ okunkun yii lo n fi atẹjise yii sita lati fi da ipaya si ara awọn eniyan.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Sri Lanka áti India níkan ni irù ològbó yì wá Lọdun 2014 ni ẹgbẹ BJP bori pẹlu ijoko mejilelọgọrin o le nigba eyi to jẹ ipo to pọ ju ti ẹgbẹ kankan tii ni lati ọgbọn ọdun sẹyin ni India.
Asoju Ajọ INEC ninu eto idibo ni ipinlẹ Kwara, Ọjọgbọn Abimbola Adesoji, lasiko to n kede esi ibo naa ni, Olawuyi jawe olubori pẹlu ibo ẹgbẹrun lọna mọkanlelelogun ati ojilerugbadinmẹrin(21,236), nigba ti oludije fun ẹgbẹ oselu PDP ni ibo ẹgbẹrun lọna mejidinlogun ati marundinlọgọrun(18,095).
Ibi tí OLUWA Ọlọrun yín bá yàn pé kí ẹ ti máa sin òun ni kí ẹ ti jẹ ìdámẹ́wàá ọkà yín, ati ti ọtí waini yín, ati ti òróró yín, ati àkọ́bí àwọn mààlúù yín, ati ti agbo ẹran yín; kí ẹ lè kọ́ láti bẹ̀rù OLUWA Ọlọrun yín nígbà gbogbo.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Awọn ọmọ ogun Biafra n yẹ awọn ibọn wọn wo ni imura silẹ Amọ ṣa, awọn ọmọ ogun Biafra naa fi ija da orilẹ-ede Naijiria lohun nigba ti wọn wọ Iwọ-oorun Naijiria lọjọ kẹsan an, oṣu Keje.
naa tẹlẹ, eleyii ti yoo fun ikọ ẹṣọ allabo abẹle yii lagbara lati le wọ
Nítorí pé àwọn Amaleki ati ará Kenaani ń gbé àfonífojì, ní ọ̀la, ẹ gbéra, kí ẹ gba ọ̀nà Òkun Pupa lọ sinu aṣálẹ̀.
Wọ́n ní kí emi àti ẹ̀gbọ́n mi wọ aṣọ funfun kan tí a máa ń wọ̀ lọ sí ilé- ìsìn.
Sugbọn sa, eeyan gbọdọ lọ sileewosan fun ayẹwo, ti irora nkan oṣu ba kọja bose yẹ.
Ṣùgbọ́n ìwọ ọ̀rẹ́ mi, ó yà mi lẹ́nu láti gbọ́ orúkọ àwọn aládùúgbò rẹ, mo sì ní ìrètí wípé nígbà tí mo bá rí àyè n ó lọ mọ̀ wọ́n ṣùgbọ́n n kò rò pé mo lè rí wọn lónìí mọ́ nítorí ilẹ̀ ń ṣú lọ, mo sì rò pé ó kúkú yẹ kí ìwọ àti èmi jọ máa gbádùn ara wa lónìí, bí ó bá di ọ̀la a ó lọ kí àwọn aládùúgbò rẹ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Kelechi Iheanacho ẹlẹ́sẹ̀ ayò tún ti dábírà fún Leicester City 28 Agẹmo 2019 Oríṣun àwòrán, @Leisecter Àkọlé àwòrán, Eyi ti mo fẹ sọ bọọlu sawọn lẹẹmeji Kelechi Iheanacho, ogbontarigi ninu awọn ọdọ agbabọọlu Naijiria tun ti jẹwọ orukọ rẹ.
Kamala yoo koju igbakeji Donald Trump, iyẹn Mike Pence lọjọ keje, oṣu Kẹwaa, ọdun 2020 kan naa ninu itakurọsọ awọn oloṣelu ti yoo waye ni ilu Salt Lake, ni Utah.
Bí o ṣe wá ku dẹ̀dẹ̀ tí àyẹyẹ eegun kan pàtàkì nílùú Ibadan egúngún oloolu yóò wáyé, BBC bá olóye Ojegboyega Adepoju to jẹ́ aláàgbàá agúngù àti akọ̀wé gbogbo eléégún nílẹ̀ Ibadan, ó sì tún jẹ́ ìgbákeji ààrẹ gbogbo ẹlẹsin ibílẹ̀ ni ìpínlẹ̀ Oyo sọrọ láti mọ igbẹ́sẹ̀ wọ́n nípa àṣe olubadan àti ìjọba.
Awọn agbarijọ aja fẹtọ náà tun ní ki wọ́n pa ẹka Eagle Squad naa rẹ patpata.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Yoruba Movies: Àwọn òṣèré Yollywood tó ń pàrònú rẹ́ 24 Òkùdu 2019 Nínú àwọn apanilẹ́rìín òṣèré Yorùbá yìí, èwo ló ń pa ìrònú rẹ́ fún un yín jù?
Aare Buhari gba alejo pataki ohun, Merkel ni agogo mesan an owurọ yii niluu Abuja.
Nigba ti awọn adajọ mẹtẹẹta yoo gbe idajọ wọn kalẹ, meji ninu wọn dajọ pe oludije PDP Ademọla Adeleke ni ẹni ti ilu dibo yan.
To ba jẹ́ ọ́fíìsì gbayawu ni o ti n siṣẹ́ pẹ̀lú àwọn ènìyàn péréte, ewu bíntín ni ṣùgbọ́n ti èrò ba pọ̀ nibẹ̀, o ní láti gbé e yẹ̀wò dáadáa.
Ó ṣeéṣe kí wọn mú ẹ̀bẹ̀ wọn wá siwaju OLUWA, kí olukuluku sì yipada kúrò lọ́nà ibi rẹ̀ tí ó ń rìn, nítorí pé ibinu OLUWA pọ̀ lórí wọn.
“Nígbà tí Alátìlẹ́yìn tí n óo rán si yín láti ọ̀dọ̀ Baba bá dé, àní Ẹ̀mí tí ń fi òtítọ́ Ọlọrun hàn, tí ó wá láti ọ̀dọ̀ Baba, yóo jẹ́rìí nípa mi.
Ewó ninu àwọn wọ̀nyí ni yóò wà níní ẹgbẹ́ agbábọ́ọ́lù ààyò rẹ?
"Wo àfipábánilòpọ̀ ẹni ọdún 51 tí ìjọba ìpínlẹ̀ Ekiti tú làṣirí ní gbangba ""Àwọn sójà ní mo káàbò sí ilé ìṣerun àgbáyé tí wọ́n tí ń ṣerun bó ṣe wu wọ́n"" Sanitáísa leé ba ìwé ìtẹ̀ka ìbò jẹ́ - Àjọ CDC kìlọ̀ Ẹ fún wa lówó oṣù wa tàbí kí a gùnlé ìyanṣẹ́lódì ọlọ́jọ́ gbọọrọ- Àwọn dokita ìpínlẹ̀ Ondo Ọkùnrin kan rí ẹ̀wọ̀n ọdún mẹ́rin he lẹ́yìn tó jí ẹ̀rọ ìléwọ́ iPhone ní ìpínlẹ̀ Ogun Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Fídíò, Soyinka Cancer: Àṣe ara mi ni iso ti n run gbogbo bí mo ṣe n ṣèrànwọ́ lórí jẹjẹrẹ27 Bélú 2019 Ekiti rape: Ẹni ọdún 51 fipá bá ọmọ ọdún 12 lòpọ̀, ìjọba ìpínlẹ Ekiti lẹ awòrán rẹ̀ gbangba sí àárín ìlú4 Bélú 2020 Ibadan Tailor: Ilé-ẹjọ́ dá ẹjọ́ lòdì sí ìwà ọ̀gá ọlọ́pàá sí télọ̀ rẹ̀18 Bélú 2020 Fídíò, Orlando Owoh: Ayé ti sú mi, àdúrà ikú ìrọ̀rùn ló wù mí- Christiana, Ìyá Orlando Owoh tó ti pé ọdún 1105 Bélú 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 3 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 5 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!"
ó sì rọ òjò sílẹ̀ láti ojú ọ̀runsórí ọmọ eniyan lọpọlọpọ.
Oríṣun àwòrán, Ademola Adeleke/Facebook Àkọlé àwòrán, Adeleke ni oludije ẹgbẹ òṣèlú PDP nínú ìdìbò Gómìnà ìpínlẹ̀ Osun Ọdun ti orileede Naijiria gba ominira, 1960 ni wọn bi i ni ilu Enugu.
Ṣugbọn ọba dá wọn lóhùn, pé, “Ohun tí mo bá sọ abẹ ni ó gé e; bí ẹ kò bá lè rọ́ àlá náà fún mi, kí ẹ sì sọ ìtumọ̀ rẹ̀, n óo fà yín ya ní tapá-titan, ilé yín yóo sì di àlàpà.
Èèyàn mọ́kànléláádọta ló wá láti ìpínlẹ̀ Eko nínú èèyàn 72 tó kó ààrùn covid-19 lọ́jọ́ Ajé Ipinlẹ Eko lawọn to lugbadi aarun coronavirus lọjọ Aje ọjọ kẹta oṣu kọkanla ọdun 2020 ninu awọn mejilelaadọrin ti ajọ NCDC kede.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fọ́nrán ohùn, Ọrọ gbenga Adeyinka lori Wenger to fẹ fipo silẹ Bakannaa, ilumọ̀ọ̀ka akọ̀rin takasufe ni, Sound Sultan ṣalaye pe ifẹyinti Arsenal yoo fun ẹgbẹ̀ agbabọ̀ọ̀lu Arsenal lanfani ati yẹ ọ̀na ayò miran wo.
Akẹ́kọ̀ọ́ mẹ́fa, olúkọ̀ méjì ni wọ́n jígbé ní Kaduna A padà san owó ìtanràn fáwọn ajínigbé kí wọ́n to fi àwọn mẹ́tẹ̀ẹ̀ta sílẹ̀- Ẹbí Èèmọ̀ rèé!
Iwin náà ni irun lára bi ti ẹranko gan-an ni, irun wọ̀nyí ni mo si di mọ́ pẹ̀lú iké ẹ̀yìn rẹ̀ tí kò jẹ́ kí n já ṣubú.
Eeyan mẹrin ku ninu ijamba ọkọ l'Eko Jẹgudu jẹra ni ijọba ẹgbẹ APC - PDP Ọgbẹni Bello ti kọkọ kede idaduro lẹnu iṣẹ fun gbogbo awọn ọmọ igbimọ alaṣẹ ipinlẹ mẹẹdogun ati awọn alaga ibilẹ mọkanlelogun ninu ipade kan pẹlu awọn oloṣelu ni ileeṣẹ ijọba ni ilu Lọkọja lọjọ aiku.
Nilu Madinah ni wọn ti mu Zainab niṣoju iya rẹ ati ọmọ iya rẹ ninu ile itura ti wọn de si.
Ọdun 2015 ni Biya ti se ipade igbimọ alaṣẹ kẹhin, ko to o tun ṣe ni 2018.
Yatọ si pe oun lo ṣokunfa meji ninu goolu mẹta ti Manchester city fi gbẹyẹ mọ Arsenal lọwọ, oun naa ni agbabọọlu Arsenal to gba kaadi pupa eyi to tums si pe rẹfiri ni ko wabigba kuro lori papa.
Díẹ̀díẹ̀ ni n óo máa lé wọn jáde fún yín, títí tí ẹ óo fi di pupọ tí ẹ óo sì gba gbogbo ilẹ̀ náà.
Bẹẹ ni wọn ni konileogbele yoo wa lalẹ ọjọ meji, iyẹn ọgbọnjọ oṣu Kẹsan ati ọjọ Kini oṣu Kẹwa Ninu awọn to n palẹmọ lati ṣe iwọde lọjọ ayajọ ominira Naijiria ni Omoyele Sowore ati awọn ajafẹtọ ominira mii, labẹ akori RevolutionNow.
5 1629 Orilẹede New Zealand 25 0.
" Igbakeji gomina Eko sọrọ nipa obinrin Obi awọn akẹkọ Dapchi nbeere ọmọ wọn O gboriyin fun ijọba Plateau fun bi wọn ṣe gbaruku ti ilana ọgbin ijọba apapọ.
Famalay kì í bẹ̀rù láyé láti tì ọ́ lẹ́yìn ní ìgbà gbogbo…
Tí Mágà ẹ bá ti lè yó ìfẹ́, kò kọ̀ kí ọ́mọ tirẹ̀ kú - Yahoo Boy 'Buns ni ọmọ mi jẹ tán ní ṣọ́ọ̀ṣì, ló bá di àwátì' Kó tó wa di pé ẹ̀pa ò bóró mọ́, Ọ̀jọ̀gbọ́n lo ọgbọ́n láti mú ìkìlọ̀ àti ìmọ̀ràn dókìtà akọ́ṣẹ́mọsẹ́ lò.
Ṣugbọn ní ti jíjókòó ní ẹ̀gbẹ́ ọ̀tún ati ẹ̀gbẹ́ òsì mi, kì í ṣe tèmi láti fún ẹnikẹ́ni, ipò wọnyi wà fún àwọn tí Ọlọrun ti pèsè wọn sílẹ̀ fún.
Ní Ọjọ́ Ìsinmi kan, bí Jesu ti ń la oko ọkà kan kọjá, àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ bẹ̀rẹ̀ sí já ọkà, wọ́n ń fi ọwọ́ ra á, wọ́n bá ń jẹ ẹ́.
Toyin Abraham bí ọmọkùnrin jòjòló Ariwo Allahu Akbar"" kò tọ́ sawọn Agbébọn àti Boko Haram - Buhari Facebook fi kọ́kọ́rọ́ ti àwọn ojú òpó ayédèrú ìròyìn léde Yorùbá àti Igbo Akọroyin BBC to wa ni papakọ ofurufu naa salaye pe, aago mejila ọsan yii lo seese ki baalu Ethiopia to gbe Zakzaky balẹ si papakọ ofurufu naa, ti igbaradi si ti doju ọgbagade lati ọdọ awọn agbofinro fun abọ asaaju ẹsin Shiite naa ati aya rẹ."
Ewe, latari didarapo mo igbimo isakoso DW sport ohun, eyi lo fopin si ibasepo Musa ati Tony Harris, leni ti isakoso katakara Ahmed Musa lati darapo mo iko agbaboolu lorisirisi wa lowo re, bere lati igba ti o kuro ninu iko agbaboolu Kano Pillars losi ile okere.
Iroyin ayọ yi ni Minisita idagbasoke ọrọ ọdọ Naijiria Sunday Dare fi sita loju opo Twitter rẹ lỌjọbọ to si ni eto agunbanirọ yoo gberasọ lọjọ Kewaa, oṣu Kọkanla.
Ọjọ kẹtadinlọgbọn oṣu kọkanla tii ṣe ọjọ ibi rẹ ni ayẹyẹ alujo náà yóò sì waye.
Odò kan wà tí omi rẹ̀ ń mú inú ìlú Ọlọrun dùn,ìlú yìí ni ibùgbé mímọ́ Ọ̀gá Ògo.
O menuba ise tijoba ti se lati tun ile awon ohun osin abiye se ni Mbiaya to ti to ijoba ibile Uruan ni eyi to n pese oromodiye egberun mewaa loojo.
Oríṣun àwòrán, Others Awọn agbegbe naa ni Rano, Gaya, Karaya ati Bichiin Igbesẹ yii ti Gomina Ganduje gbe, lawọn eeyan kan woye o wa lati fi ge iyẹ Emir Sanusi Lamido, to si mu ariwisi ọtọọtọ wa nigba naa.
Bí ohunkohun bá ṣẹlẹ̀ sí i ní ìrìn àjò tí ẹ fẹ́ lọ yìí, mo ti darúgbó, ìbànújẹ́ rẹ̀ ni yóo rán mi sọ́run.
Bakan naa ni ijọba tun fun mọmọ Yekini ni ẹgbẹrun lọna aadọta naira gẹgẹ ẹbun fun awẹ Ramadan to n lọ lọwọ.
Wọ́n sọ̀rọ̀ tóbẹ́ẹ̀ tí ọpọlọpọ ninu àwọn Juu ati àwọn Giriki fi gba Jesu gbọ́.
“Sọ fún àwọn ọmọ Israẹli pé kí wọ́n yipada, kí wọ́n sì pàgọ́ siwaju Pi Hahirotu, láàrin Migidoli ati Òkun Pupa, níwájú Baali Sefoni; ẹ pàgọ́ yín siwaju rẹ̀ lẹ́bàá òkun.
‘Ọlọ́pàá ló ti Dino kúrò nínú ọkọ̀’ 'Kélé á gbé ẹni bá fi nǹkan ṣe Dino Melaye' Ọwọ́ òfin ti tẹ ọ̀pọ̀ ọmọ Nàìjíríà lórí ẹ̀sùn jìbìtì l'Amẹrika- FBI Ta ni Ọjọgbọn Adebanji Akintoye tó borí Tinubu láti di olórí àwọn Yoruba?
Oríṣun àwòrán, @battravels Ere Baba Onirungbọn yẹukẹ to n gbe ibi gegele okuta: Ere baba onirungbọn yẹukẹ naa wa ninu igbo olodumare yii.
Ṣugbọn Jesu kò dá a lóhùn gbolohun kan ṣoṣo, tí ó fi jẹ́ pé ẹnu ya gomina pupọ.
Ọpọlọpọ ohun to si korira nigba naa, lo ti wa fẹ oju mọ wa lọwọ ni Naijiria bayii, ti ọkọ Naijiria si n rin loju omi lai mọ ẹni ti yoo ti de ebute ayọ.
’’Tesiwaju si, aare Buhari tun gba leta o kare lai lati owo ogagun teleri,  Waqar Kingravi, to je komisona ile Pakistan si Naijiria, ogbeni Babacar Ndiaye, to je komisona ile Senegal si Naijiria ati ogbeni Vyacheslav Beskosky, komisona tuntun ile Belarus si Naijiria, aare jabo oro re pe orile-ede Naijiria mo riri ibasepo ti o wa laarin orile-ede won kookan.
 Ẹ jẹ ́ kí á tún wo àpẹẹrẹ orin òkè yìí wò lẹ ́ ẹ ̀ kan sí i .
Inú eléyìí ni mo wà títí igi tí mo dúró lé lẹ́ẹ̀kan fi foríbalẹ̀ tán ṣùgbọ́n mo ń retí ìgbà tí yóó tún dídé wáá bá mi.
Èèyàn 789 gbèkuru jẹ lọ́wọ́ ẹbọra nítorí COVID-19 ní Nàìjíríà Eeyan ọtalelẹẹdẹgbẹta o din mẹrin lo tun kun iye awọn to ni aarun coronavirus lorilẹ-ede Naijiria.
"O sọ pe ijọba ""ko ṣetan lati fi awọn ọmọ wa tọrẹ fun aarun yii""."
odun ti a wayii, saaju ifesewonse olorejore ti won yoo gba pelu iko agbaboolu
Tinubu - BBC News Yorùbá BBC News, YorùbáFò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Kankara Abduction: Ohun ìbànújẹ́ ni bí wọ́n ṣe jí akẹ̀kọ̀ọ́ t'o le ni 300 gbé - Tinubu 18 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 20 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Oríṣun àwòrán, @NextEditionNews Eekan ẹgbẹ oṣelu APC, Bola Ahmed Tinubu ti gbe oṣuba kare fun Aarẹ Muhammadu Buhari lori akitiyan rẹ lati doola ẹmi awọn akẹkọọ ti awọn agbebọn ji gbe ni Kankara.
Ìgbà ti àwọn wọ̀nyí máa padà dé, tti ń ṣe ọdẹ ki ìyá mi tó wọlé ọkọ àwọn arìnrìn àjò ti wọ́n ti rin tí ojú wọn ti dá ṣákáṣáká, àwọn arúgbó tí ojú wọn ti rí abàmì nǹkan nínú ayé, àwọn amòye tí ọgbọ́n ti fi agbárí wọn ṣe ibùjójòó, àwọn jagun jagun àti alágbára gbogbo, adáhunṣe àti ẹlẹ́bọlóògùn, gbajúmọ̀ àti bbọ̀rọ̀kìnní, àwọn ọmọ tálákà àti àwọn ọmọ olówó- gbogbo wọn ni wọ́n pé sí ìlú wa; àkókò pàtàkì ni.
" kí ó tó darapọ ̀ mọ ́ yunifásítì ìlú port hacourt , Ó ṣiṣẹ ́ ilẹ ́ "" shell oil "" fún odún kan péré ."
 Òdo fun ra re ki se odi tabi odaju .
Sẹnẹtọ to n ṣoju aarin gbungbun Ipinlẹ Kaduna, Shehu Sanni naa sọrọ loju opo Twitter tiẹ pe, kii ṣe dandan fun aarẹ Buhari lati kopa ninu ijiroro to waye lalẹ ọjọ Abamẹta naa.
Oniruuru awọn onimọ, paapaa julọ awọn onimọ nipa ofin ni wọn ti jade ṣalaye pe o ku diẹ kaato, bẹẹni awọn onwoye miran n wii lẹnu pe ko sẹni to kọja ofin.
 Ẹ ̀ rí iṣẹ ́ rẹ ̀ lára àgbàlagbà tí ọjọ ́ -orí rẹ ̀ ti ju ọdún 65 lọ kò fi bẹ ́ ẹ ̀ wọ ́ pọ ̀ .
Indeed, I recall, sometime in 1995, that on one of my trips to Copenhagen to attend World Social Summit as Human Development Ambassador of the United Nations Development Programme, I received the most touching of the warnings, pieces of advice and offers to me from Amb.
Eledua ma jẹ ka rinrin arinfẹsẹkọ.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Lọwọ yii obitibiti iwe ti awọn eeyan fi ranṣẹ ni ko tii tẹ awọn ti wọn fi ranṣẹ si lọwọ nitori ajakalẹ arun Coronavirus.
17 Ìgbé 2020 Fídíò, Afeez Agoro: O ṣòro fún mi láti wọ Danfo jáde16 Ìgbé 2020 Fídíò, Hakeem: Idán inú eré sinimá ti gbàràdá ní Nàìjíríà14 Ìgbé 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
"Èyí jẹyọ nínú àtẹ̀jáde kan ti àkọlé rẹ̀ ni ""Gómìnà Yahaya Bello gẹ́gẹ́ bi alága ìdìbò abẹ́lé ìpínnlẹ̀ Ondo"" tí ìgbákejì akọ̀wé ìpolongo apapọ̀ ẹgbẹ́ buwọ́lù, Yekini Nabena nílùú Abuja lọ́jọ́rú."
2 163992 Orilẹede Japan 2419 1.
Ọpọ gbagbọ wipe, ko ṣeeṣe ki olorin dárà lai mu igbo tabi ọtin.
Oríṣun àwòrán, lizzy anjorin/instagram sceenshot Lizzy Anjorin sọ ìdí tó fi ṣe ìgbéyàwó lẹ́yìn ọdún mẹ́rìnlá tó ti pàdé ọkọ rẹ̀.
Ọjọ náà ni mo sì tó wá mọ̀ pé òmùgọ̀ tí ó ta gbogbo òmùgọ̀ yọ ni kí ẹni tí ó gọ̀ rò pé òun gbọ́n, nítorí ìgbà tí ènìyàn kò bá gbọ́n ṣùgbọ́n tí kò mọ̀ pé òun kò gbọ́n, àti gbe ọgbọ́n ẹlòmiràn kò ní ṣàì jẹ́ iṣoro.
Ẹ̀ ń jẹ èso àjàrà ati ti igi olifi tí kì í ṣe ẹ̀yin ni ẹ gbìn.
Láti ìgbà èwe mi ni mo ti jẹ́ olórí fun yín títí di àkókò yìí.
Bẹẹni ọ̀pọ̀ géndé (youth) ń sọnù, tí à nfi wón ṣe àwárí.
Gbajumọ oṣere naa ni adura ti onikaluku maa n gba naa ni pe, ki aburu maa ṣẹlẹ si ẹnikọọkan, ṣugbọn o ni ko si ẹni ti iru iṣẹlẹ bẹẹ ko le ṣẹlẹ si i.
Jẹ́ kí n sọ fún ọ, mo ti ń pérò nínú ara mi nísisìyí láti se àsè ńlá kan láti fi ṣe àjọyọ̀ nítorí rẹ, kí n sì pe àwọn ẹbọra Igbó Olódùmarè sì ibi àsè náà, mo sì tànmọ́ọ̀ lọ́kàn mi láti fi ikú jẹ alága, àti láti fi àrùn jẹ igbá kejì rẹ̀, kí n sì fi ìwọ sí ipò ẹni í ń ṣe ọdún láàrin wọn.
Ẹ má gbìyànjú àti bo àṣírí ǹkan tó ṣẹlẹ̀ ní Lekki, a ní ẹ̀rí tó dájú Ajọ ajafẹtọ ẹni kan l'agbaye, Amnesty International, ti kilọ fun ijọba orilẹ-ede Naijiria, lati ma bo aṣiri bi awọn kan ṣe yinbọn mọ awọn oluwọde ni Lekki, nipinlẹ Eko.
Idi ree ti ileeṣẹ iroyin BBC Yoruba ṣe kan si Araba awo ilu Oṣogbo, Ifayemi Elebuibọn lati tanj imọlẹ si ọrọ naa.
Oríṣun àwòrán, @GarShehu Àkọlé àwòrán, Ero ọkan ọpọ ọmọ Naijiria ni wi pe Aarẹ Buhari yoo buwọlu ẹkunwo owo oṣu tuntun Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
- Ẹ̀yin ọmọ ẹnìyàn, bí ẹ bá ń múra àti lọ síwájú nǹkan rere ni; ṣùgbọ́n bí ẹ bá ń sọ̀rọ̀ bí ẹni pé ẹ ń pẹ̀gàn Olódùmarè ẹ dàbí iṣẹ́ ọwọ́ gbẹ́nàgbẹ́nà tí ó ní ojú tí kò lè fi ríran, tí ó ní imú tí kò lè fi gbóòórùn, tí ó ní etí tí kò lè gbọ́ràn.
Oríṣun àwòrán, LIB Àkọlé àwòrán, Ọmọ ọ̀dọ̀ ni wọ́n fi ẹ̀sùn kàn pé ó pa Oloye Bademosi Gẹgẹbi ọrọ afurasi naa, lẹyin ọjọ kẹta ti wọn gba a si ibisẹ ni o pinu lati ja ọga re lole, ti o si wo ibusun ti ọga rẹ lati bere owo lọwọ rẹ, lẹyin ti iyawo rẹ jade kuro ni ile laarọ kutu, amọ ti o sọ wi pe oun koni owo nile lati fun ọmọ ọdọ naa.
Oṣu meji ṣaaju igba naa, arabinrin naa gba Joel sile lati di alase rẹ lai mọ pe iku ni oun gba sinu ile.
Ìwọ aláìgbédè ọkùnrin, ìwọ kò mọ̀ pe kìnnìún àti agbọnrin kì í fi ojú ri ara wọn, àti pé ẹkùn òun mààlúù kì í ṣe ọ̀rẹ́ pọ̀, bẹ́ẹ̀ ni ọjọ́ ti ológbò bá fi ojú kan èkúté ni ayé èkúté yóó pin!
“Gbogbo àwọn tí wọ́n fẹ́ pa ọ́ runni n óo dójú tì, wọn óo sì dààmú.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ǹ jẹ́ o mọ̀ pé iṣẹ́ ń dúró de akẹ́kọ̀ọ́ tó yan iṣẹ́ olùkọ́ láàyò ní fásitì?
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Mike Bamiloye, adarí Mount Zion bèrè bóyá àpaàyàn kọ́ ní ẹni tó ń ṣí ara sílẹ̀ lọ ṣọ́ọ̀ṣì, ṣé apàyàn kọ́ ni ẹ́ báyìí?
Lẹ́yìn tí ó bí Enọku, ó gbé ẹgbẹrin (800) ọdún láyé, ó sì bí àwọn ọmọ mìíràn lọkunrin ati lobinrin.
Ilé tí ẹ bá ti se oúnjẹ yìí ni ẹ ti gbọdọ̀ jẹ gbogbo rẹ̀, ẹ kò gbọdọ̀ mú ninu ẹran rẹ̀ jáde, ẹ kò sì gbọdọ̀ fọ́ egungun rẹ̀.
Igbes yi waye lẹyin tara ilu faraya lori gbedeke ọlọjọkukuru ti ijọba ṣaaju gbe kalẹ.
" Oríṣun àwòrán, Oluwo/Instagram Oloye Bello tẹsiwaju pe ọpọ igba lawọn ti gba Oluwo nimọran, ti ko gbọ, awọn ko si le tẹsiwaju lati maa fara daa mọ nitori idojuti nla ni Oluwo n ko ba awọn.
Bí o bá bá wa lọ, OLUWA yóo fún ìwọ náà ninu ibukun tí ó bá fún wa.
Oríṣun àwòrán, Oyo state govt Odumakin, ẹni ti isẹlẹ naa ba lojiji fikun pe, igba keji ree ti alagba Fasoranti yoo padanu ọmọ rẹ, eyi to ba eeyan ninu jẹ pupọ.
Orisirisi ohun igbalode pipana lati ko lo sibe lati dekun owo ina ohun.
Bí Ọlọrun bá gba ẹ̀mí rẹ̀ sọ́dọ̀ ara rẹ̀,tí ó sì gba èémí rẹ̀ pada sọ́dọ̀,
PDP ní Ọlọ́pàá ti mú Sẹ́nétọ̀ Ademọla Adeleke sí àhámọ́ APC, PDP di ẹgbẹ́ aládúrà nítorí ìdájọ́ èsì ìdìbò Ọṣun Àwọn ọmọge wọ gàù l'Abuja nítorí asọ péńpé Ajimobi figbe ta, ó ní 'èmi kọ́ ló pa Ṣugar o!
Bimbo gba awọn eeyan niyanju lati ma pa ọmọ ọlọmọ tori ati mu igbeyawo duro.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Bisi Alimi: Ìyà mi rò pé n kò leè ṣe ni àmọ́ n kò ní ìfẹ́ abo ni mo ṣe fẹ́ akọ Lero tawọn eeyan kan, wọn gbe si oju opo Twitter wọn pe ọpọ isẹ ti aarẹ Muhammadu Buhari n bọ wa si naa ni isẹ ko tii pari lori wọn, amọ ti gomina Akinwunmi Ambọde fẹ fi iwanwara si awọn isẹ naa.
Akọtun rògbòdìyàn náà sì lo mu kí Ọgagun Adeyinka Adebayo gbé igbimọ kan dìde láti ṣèwádìí ohun tó ń ṣe idiwọ fún ípadabọ ọba alaye náà si ori ìtẹ́.
Amọ, iroyin ni Olootu ijọba Dominica, Roosevelt Skerrit ti yan Dieziani Alison-Madueke gẹgẹ bi kọmisọnna fun eto oro ajẹ lorilẹ-ede naa, ti wọn si fun un ni iwe igbelu.
Lakọkọ, lati ibẹrẹ ni ara ọtọ eyi ti BBC Yoruba ṣe - fifi ọrọ wa awọn akopa lẹnu wo nibi iforukọ silẹ lori ki ni wọn wa ṣe ati ireti wọn latọdọ awọn oludije ti yoo kopa nibi eto naa.
 Kini o wa ń ṣẹlẹ bayii?"
Eyi tilẹ ti mu ki minisita ana, Ọjọgbọn Isaac Adewole ge irinajo rẹ lo soke okun kuru lojiji.
Kó ẹgbaarun (10,000) eniyan ninu ẹ̀yà Nafutali ati Sebuluni jọ.
Makinde fi owó lọ̀ wá àmọ́ a kò fẹ́, sáà wa tó kù ni kẹ jẹ ká parí - ALGON Ọyọ yarí O ni asiko to fun awọn gomina lati dẹkun aṣa pe awọn ko lee ba alaga kansu ti ko ba ti wa lati ẹgbẹ oṣẹlu wọn ṣiṣẹ.
Àwọn olórí ninu ìdílé àwọn ọmọ Lefi yòókù nìwọ̀nyí: Ṣubaeli láti inú ìdílé Amramu,Jedeaya láti inú ìdílé Ṣubaeli.
igberiko kan si omiran lati se idanilẹkọọ, ayewo ati itoju oju fun awon omode
Ìjọba òyìnbó amúnisìn náà la ò bá gbọ́njú bá, ọpẹ́lọpẹ́ àwọn ènìyàn pàtàkì tí wọ́n ṣe làálàá, tí wọ́n ja ìjà òmìnira takun-takun.
Nkan tí a mọ̀ nìyíì Mo ti kúrò ní ààfin Oyo, kí ìròyìn tó ò jáde pé èmi àti Wasiu Ayinde n fẹ́ ara wa - Olori Badirat O ni o ṣe pataki fun awọn onibara lati maa tẹle alakalẹ ti wọn yoo maa fi sita titi ti ajọ naa yoo fi pari ayẹwo iwe owo naa.
O ni, “mo fẹ fi da yin loju pe gbogbo eyi ni ijọba ni gbogbo ipele yoo ṣe pẹlu awọn eto wa gbogbo ti yoo fi mu ilọsiwaju rere ba igbesi-aye yin.
Oríṣun àwòrán, Bashir ahmad Saaju ki aarẹ to ba awọn ọmọ Naijiria sọrọ ni alẹ ọjọ Aje ni ọpọlọpọ ti fi ireti ohun ti wọn n reti lati ọdọ aarẹ hàn nikete ti ikede jade pe aarẹ Muhammadu Buhari yoo tun sọrọ l'ori itankalẹ aarun coronavirus.
Afurasí tí Ọlọ́pàá ní ó pa Barakat, Grace àtàwọn míì l'Akinyele ti sọ̀rọ̀ pé.
Ipa wo ni abẹrẹ yi yoo mu wa?
Wọ́n bá ranṣẹ lọ sí Ṣilo láti gbé àpótí ẹ̀rí OLUWA tí ó gúnwà láàrin àwọn Kerubu.
Lai Mohammed ni ori ayelujara lasan lawọn ọmọ Naijiria ti n pariwo pe sja paayan, ko sẹni to ni aridaju.
RCCG: Adeboye ní ó sàn láti sọ̀rọ̀ ìgbéyàwó f'àlúfà ju òbí lọ
Ọkàn mi dàrú, ara mi kò balẹ̀,ọjọ́ ìpọ́njú dé bá mi.
Fi igi akasia ṣe ọ̀pá pẹpẹ, kí o sì yọ́ idẹ bo ọ̀pá náà.
Dino Melaye lọ si ile-ẹjọ pẹlu ogunlọgọ awọn eniyan ti wọn n kin lẹyin.
Po iyọ̀ àti iyọ̀ igbàlódé, ata gigún tàbi rẹ́ atarodo tútù, rin tàbi rẹ àlùbọ́sà si ewùrà rí-rin yi
Ohun tí a jẹ́, á kúkú jẹ, ká sá máse kánjú.
N kò ní pa orúkọ rẹ̀ rẹ́ kúrò ninu ìwé ìyè.
Bo tilẹ jẹ pe ọga NDLEA pẹtu si ninu, sibẹ o sọ fun pe, igbogun ti egboogi oloro jẹ eyi to pataki ni Naijiria.
Inú Paulu Dùn Nígbà Tí Ìjọ Ronupiwada.
B Joshua-Angel Gomes Sáájú ni Oshiomhole ti pe ẹjọ́ kòtẹ́milọ́rùn lórí ìdájọ́ tí àdájọ Abubakar Yahaya sì dájọ pé kí ìdájọ́ náà dúró náà kí ó ṣì maa ṣe alága lọ́ títí ìdájọ́ ilé ẹjọ́ kòtẹ́milọ́rùn yóò ṣe fìdímúlẹ̀.
"Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Awọn oludibo kọ kaadi silẹ l'Ekiti Inec kede ọjọ idibo titi di 2055 Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, INEC yoo sun miliọnu meje kaadi idibo ""Láàárín ọdún 2015 sí àsìkò yìí, ìdìbò ọ̀rìnlélúgba ó lé mẹ́fà ni àjọ yìí ti ṣe nínú èyí tí wọ́n ti wọ́gilé méjìdínlọ́gbọ̀n nítorí àìkìí fààyè gba ètò ìṣèlú àwarawa labẹ́nú láàrin áwọn ẹgbẹ́ òṣèlú."
Ọmọ tí kò bá ronú jinlẹ̀ kí ó tóó jẹ́ kí ìfẹ́ gun òun bi ẹṣin, nígbà tí ìfẹ́ bá tì í sí kòtò tán, tapátẹsẹ̀ rẹ̀ ni yóò kún inú kòtò bámúbámú!
"Lanre Kuti ni mo fẹ́ - Jaiye Kuti Onínúfùfù ni Saheed Oṣupa, ṣùgbọ́n èèyàn dáradára ni-Taye Currency Mi ò ní ìyàwó nílé, àmọ́ mo ní ọmọ tó pọ̀ -Saheed Oṣupa Kìí ṣe emí ni mó ràn amúgbálẹ́gbẹ̀ẹ́ mi tó sọ̀rọ̀ abùkù sí FIBAN níṣẹ́- Wasiu Ayinde O ni ""Ajakalẹ aarun naa kọ mi lati ma a ṣọ owo na, ati lati ṣe eto ọna abayọ silẹ ninu okoowo to wu ki eeyan ma a ṣe."
Lórí ìmọ̀ràn Sunday Igboho, Ẹlẹbubọn ní yóò dára kí Yorùbá padà sí àmúlò èròjà ìbílẹ̀ fún ààbò Ìpànìyàn, ìjínigbé ti gbàkóso ilẹ̀ Yorùbá, Buhari, tètè kéde pé ètò ààbò kò fararọ - Soyinka Ààrẹ Buhari ti lọ sí ìlú Daura fún ọdún Sallah Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, ''Ọjà ẹran àgbò kò yá bí ti ọdún tó lọ'' Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Sunday Igboho: Fulani kò leè dúró, táa bá lo ohun ta jogún lọ́dọ̀ àwọ̀n bàbá wa Adajọ A.
Ajọdun ayajo awọn ewe (ọmọde) lagbaaye bayii lo maa n waye ni ọjọ kẹtadinlọgbọn oṣu karun-un ọdọọdun.
Kidnapping: BBC ṣe ìwádìí bí ikọ̀ IRT ṣe ń gbéjà ko awọn ajinigbe lójú
Awọn akinkanju ọkunrin, olowo, ọlọrọ ati ọkunrin to jẹ oju ni gbese lo n nawọ ifẹ si Wuraọla, ti wsn si n wa lati ilu odikeji.
Adigunjalè pa ọlọ́pàá mẹ́jọ àti obìnrin kan ní Kogi 'Títẹ àwọn afipábánilopọ̀ lọ́dàá kọ́ ni ọ̀nà àbáyọ sí ìwà ìfipábánilopọ̀' Ìjọba dẹwọ́ kónílé ó gbélé ní ìpínlẹ̀ Osun Wọnyi ni awọn nnkan mẹwaa to yẹ ki o mọ nipa oloogbe George Floyd: Houston ni George ti dagba ko to lọ si Minneapolis Oríṣun àwòrán, @LITE_III Ni agbegbe Third Ward ni Houston ni George Floyd dagba si.
China ti kọkọ kilọ pe o ṣeeṣe ki aarun naa ran lati ẹnikan si ẹlomiran.
29 Lõtọ́, lõtọ́, ni mo wí fún yín, bí wọ́n bá kọ àwọn ọ̀rọ̀ mi, àti apákan ìhìnrere mi àti iṣẹ́ ìránṣẹ́ yìí, alábùkúnfún ni ẹ̀yin, nítorí wọn kò le ṣe síi yín mọ́ ju sí mi lọ.
Tyson Fury d'ẹ̀ṣẹ́ bo Deontay Wilder lórí, ó gbadé WBC mọ́ ọ lọ́wọ́ Boko Haram tún ṣọṣẹ́ ní Adamawa, ọ̀pọ̀ òkú ṣùn, àìmọye dúkìá jóná Awọn oṣiṣẹ pajawiri ati ajọ awọn òṣìṣẹ́ àjọ ojú pópó fi lede wi pe ohun gbogbo ti pada si ipo lẹyin ti wọn gbe ọkọ naa kuro loju popo, ti awọn ọkọ si ti bẹrẹ si ni rin loju ọna naa pada.
nígbà tí wọ́n dé òdìkejì odò Jọdani, ní àfonífojì tí ó dojú kọ Betipeori, ní ilẹ̀ Sihoni, ọba àwọn ará Amori tí ń gbé Heṣiboni.
Oríṣun àwòrán, Hammed Ali Hammed Ali Hammed Ali ni Adari ileeṣẹ aṣọbode lorilẹede Naijiria.
Wọn ti lee lẹnu iṣẹ́ ọlọ́pàá tẹlẹ lọdun 2012 nitori pe, o pàdí àpò pẹlu awọn adigunjale ni Kwara ki wọn to fi sẹwọn di ọdun 2015.
Ninu àwọn ọmọ Bani, Ṣelomiti, ọmọ Josifaya, ni olórí;orúkọ ọgọjọ (160) eniyan ni wọ́n kọ sílẹ̀ pẹlu rẹ̀.
Ṣọ́ra pẹlu èrò ọkàn rẹ,nítorí èrò ọkàn ni orísun ìyè.
abẹ ́ rẹ ́ -àjẹsára hepataitisi a lágbára tó láti dènà àìsàn yìí .
 níbẹ ̀ , wọn jẹ okanlelogun nínú ọgọ ́ rùn-ún àwọn ará nàìjíríà .
Ẹ́ni ọdun mọkandilọgbọn ni Seyi Makinde nigba to kọkọ da ile iṣẹ
Ayẹwo to n lọ lọwọ ni yoo sọ ipo ti wọn o gba onikaluku si.
Ó pe ọmọde kan, ó wádìí ohun tí ń ṣẹlẹ̀.
"O salaye, ""O yẹ ki a ni"" federal Character, sugbọn ki lo de ti a ni minisita, to mọṣẹ rẹ doju ami, to si n mu esi jade, sugbọn ti a tun ni minisita miran ti ko le gbe nkan tuntun ṣe?"
Ẹkẹta ni Absalomu, ọmọ Maaka, ọmọbinrin Talimai, ọba ìlú Geṣuri; lẹ́yìn náà Adonija ọmọ Hagiti.
A fẹ́ àwùjọ tí ẹ̀rù àtijáde ò ti ní bà wá!
Owó yóò di àwátì lọ́wọ́ àwọn onímọ̀- owó àti ọrọ-ajé bẹ́ẹ̀.
Ẹ sọ pé, ‘Kí eniyan máa sin Ọlọrun kò jámọ́ nǹkankan.
Ẹ jẹ́ kí á fi ọgbọ́n bá wọn lò, nítorí bí wọ́n bá ń pọ̀ lọ báyìí, bí ogun bá bẹ́ sílẹ̀, wọn yóo darapọ̀ mọ́ àwọn ọ̀tá wa láti bá wa jà, wọn yóo sì sá kúrò ní ilẹ̀ yìí.
Ọpọlọpọ awọn to faraya ninu awọn eniyan naa sọ wi pe owo ọkọ wọn, ati wi pe awọn ibi ti wọn n gbe ni igba Naira tẹlẹ, awọn awakọ ti sọ di ẹgbẹrun Naira kan.
O ni wọn yoo wo bi nnkan yoo ṣe ri lọjọ Ẹti, ọjọ kẹtalelogun oṣu kẹwaa lati mọ boya aṣẹ naa yoo tẹsiswaju abi kawọn akẹkọọ pada sẹnu ẹkọ wọn.
Aarẹ ajọ liigi orilẹede Spain, Javier Tebas ni afaimọ ko maa di ọjọ kejidinlọgbọn ki wọn to bẹrẹ liigi pada nibẹ.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Liverpool bori ifẹsẹwọnsẹ àwọn àti Bournemouth pẹlu ami ayo mẹta si odo Ki o to di asiko yii, gbajugbaja agbabọọlu orilẹede Ivory Coast ni, Didier Drogba lo gba goolu wole ju pẹlu goolu mọkandinlọgbọ to gba wọle ni saa liigi ọdun 2009/2010 fun ẹgbẹ agbabọọlu Chelsea Kaakiri gbogbo ifẹsẹwọnsẹ ti Salah ti gba fun Liverpool ni saa yii, ogoji goolu lo ti wa ni ikawọ rẹ Bakanaa ni Sadio Mane, agbabọọlu orilẹede Senegal pẹlu to n gba bọọlu jẹun ni Liverpool gba goolu tirẹ wọle pẹlu.
Tí a fiṣọwọ́ ní 18:47 10 Ọ̀pẹ̀ 202018:47 10 Ọ̀pẹ̀ 2020 Ọ̀gá àgbà àwọn ológun fò ṣànlẹ̀ kú l'Abuja látàríi Covid-19, àwọn ológun fagilé ìpàdé Covid Death: Àlàyé bí Ọ̀gá àgbà àwọn ológun ṣe kú ikú Covid l'Abuja rèé @SagirMu56500360Copyright: @SagirMu56500360 Ọgagun agba to n ṣakoso 6 Division nileeṣẹ ọmọ ogun Naijiria, Ọgagun Irefin ti ba ọlọjọ lọ lasiko ti wọn n ṣepade idanilẹkọ ọlọdọọdun ti ile iṣẹ ologun Naijiria.
OLUWA bojúwo ilẹ̀ láti ọ̀run,ó rí gbogbo eniyan;
bi orile ede kan sugbon anfaani wa ti a ba wa ni isọkan .
O tun wa ki awon osise ku ayeye ajodun osise.
Wọn kò ríran wọn kò gbọ́ràn, bẹ́ẹ̀ ni wọn kò mọ ohun tí ó ń ṣẹlẹ̀.
Nígbà tí àwọn ará Ijipti náà gbìyànjú láti kọjá, rírì ni wọ́n rì sinu omi.
Sáájú àsìkò yìí tí àjàkálẹ̀ ààrùn kan bá ti bẹ́ sílẹ̀, tó sì jẹ́ pé ààrùn náà sábà máa n ràn láti ọ̀dọ̀ ẹnìkàn si ẹlòmíràn, àwọn àjọ tó ń gbógun ti àjàkálẹ̀ ààrùn jákèjádò àgbàyé a máa ṣètò àwọn ibi ìyàsọ́tọ̀ fún àwọn tó ba ni ààrùn náà.
Mikaya ní, “OLUWA ni ó mú kí àwọn wolii rẹ wọnyi máa sọ àsọtẹ́lẹ̀ èké, ṣugbọn àjálù burúkú ni OLUWA ti pinnu pé yóo dé bá ọ.
Iṣẹ́ ẹ̀mí ẹ̀tàn ló bàlemi lasiko tí mo sọ àṣọtẹ́lẹ̀-Simeon Ononogbu Mo gbàgbé sùnlọ sìnú ọkọ̀ òfurufú, ẹ̀rù ikú bà mí -Tiff Ìdí tí ilé fi wó lu ènìyàn méjì ní Oshodi -LASEMA EFCC: Ẹ yàgò fún MMM, àwa ké fún un yín tó o!
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù CAF: Wo ohun tuntun tó n ṣẹlẹ̀ lágboolé CAF 21 Òkùdu 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Fatma, akọwe FIFA; Infantiano aarẹ FIFA ati Ahmad, aarẹ CAF Ajọ agbaye to n risi ọrọ idije bọọlu alafẹsẹgba ti yan aṣoju tuntun.
nickelodeon ká itan ọjọ pada si december 1 , 1977 , nigbati warner cable communications igbekale akọkọ meji-ọna ibanisọrọ usb eto , qube , ni columbus , ohio .
Àkọlé àwòrán, Oludari agba BBC ni ẹkun iwọ oorun Afirika, Toyosi Ogunṣẹyẹ pẹlu oludari BBC ni orilẹede Naijiria, Aliyu Tanko n ṣe gbogbo akitiyan bi eto yoo ṣe yọri si rere plu awọn akẹgbẹ wọn lẹnu iṣẹ Àkọlé àwòrán, Arabinrin Ọmọlara Adesanya dúró déédé lati ya fọ́tò ko to lọ we gele rẹ sori ni kete bo ṣe n de gbọngan ipade.
Sotunde, ti baba rẹ jẹ atọkọse, ti iya rẹ si n ta ọja ke ke ke ninu sọọbu kan, fikun pe oun maa n lọ ran baba oun lọwọ lati tun ọkọ se ni sọọbu rẹ.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Iléeṣẹ́ ààrẹ pàrọwà sáwọn aṣòfin àpapọ̀ Secondus pẹtu saawọ nínú PDP Ọ̀sun Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Buhari, Saraki, Dangote, abẹ́ mi ni wọ́n wà' Awọn ohun elo iṣẹ alabọde bii ẹrọ ilọta, ẹrọ guguru, ẹrọ iṣerun, ẹrọ iranṣọ, ati owo lati fi bẹrẹ iṣẹ kereje-kereje ni awọn opo naa tẹwọ gba nibi eto kan ti ajọ kan ti kii ṣe tijọba gbe kalẹ ni ilu Iwo.
Ewe, iroyin ti o siji bo awon ayeye ohun ni iroyin ti o wa nile, eyi ti o ni I se pelu ikowe fipo Aare Ameenah Gurib-Fakim obinrin akoko lorile-ede ohun.
 akọ àti abo rẹ ̀ ní ìho méjì tí ó yípo sẹ ́ yìn .
 Gbogbo awọn eeyan to n pariwo pe agbekalẹ eto alaabo ti ko mu ewu lọwọ yii , to si tun ni gbedeke ibi to lee sisẹ de lo n dẹru ba isọkan Naijiria ni ko ni arojinlẹ.
" Awọn ọmọ orileede Liberia ni awọn o maa ranti aarẹ Johnson Sirleaf gẹgẹbi ẹni to mu alafia jọba lorileede naa lẹyin ogun abẹle to waye laarin ọdun 1989 si 2003.
 káyọ ̀ dé ni orúkọ akọ ̀ wé rẹ ̀ .
- Bode George Ǹjẹ́ ẹ mọ pé kìí ṣe ènìyàn nìkàn ló ń ṣe òfin ìyàsọ́tọ̀ social distance"" lásìkò àìsàn?"
Kí ló pa bàbá Adeboye, bàbá Davido àti Ọ̀ọ̀ni Ifẹ̀ pọ̀ lásìkò ìgbélé l'Ọ́ṣun?
Wọ́n a dàá sí inú àwo, wọ́n a sì da wàrà tútù lée.
A ó sanwó ìdánwo aṣewọlé ìwé gíga fásitì fawọn àkàndá Oun ti Eyitayo Jegede ni iṣejọba oun yoo ṣe fun awọn akanda ẹda ni wipe ileewe awọn akanda yoo ri iranlọwọ lọdọ ijọba oun paapaa lori irinṣẹ ti wọn fi n kawe.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù George Floyd: Ẹ̀rọ ayàwòrán ara ọlọ́pàá ṣàfihàn bí George Floyd ṣe ni òun kò le mí mọ́ 13 Òkùdu 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 9 Agẹmo 2020 Oríṣun àwòrán, Twitter/Ruty Richardson Iwadii tuntun ti fihan pe, ọlọpaa ti wọn fẹsun kan pe o pa George Floyd sọ fun un pe, ko gbẹnu dakẹ ni gbogbo igba to fi n pariwo pe oun ko le mi mọ.
Ẹni tí ó ń kọ́ ẹ̀kọ́ ìyìn rere gbọdọ̀ máa pín olùkọ́ rẹ̀ ninu àwọn nǹkan rere rẹ̀.
ni ọjọ kọ́kàndínlọ́gbọ̀n , osu keta,leyin igba ti won ba ti gbe eto  ilana 
“Má jẹ́ kí Ọlọrun tí o gbẹ́kẹ̀lé tàn ọ́ jẹ pé ọba Asiria kò ní fi ogun kó Jerusalẹmu.
 Amusa wa n beere pe ṣe bi a o ṣe ma a ba lọ ni yii?
Tyson Fury d'ẹ̀ṣẹ́ bo Deontay Wilder lórí, ó gbadé WBC mọ́ ọ lọ́wọ́ Anthony Joshua na Joseph Parker Kamaru Usman: Ọmọ Áfíríkà àkọ́kọ́ tó gba ìgbànú ẹ̀yẹ ẹ̀ṣẹ́ kíkàn Ibanuje d'orí agbà k'odò, Ruiz fi ẹ̀ṣẹ́ sọ Anthony Joshua di ọmọ ológo àná Ìròyin so pé láti igbà ti Yoel Romero ti n kopa nínú eré ìdaáraya abẹsẹ́ kù bi ojo, ko si ẹni to fi ojú rẹ̀ gbòlẹ̀ rìí, Sugbọ́n ní báyìí Isreal Adesanya fẹ́ tún ìtàn náà kọ.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ajọ LASEMA sọ̀rọ̀ lórí okùnfà iná to jó l'Abule Ẹgba.
Ẹ jẹ́ kí olukuluku pinnu lọ́kàn ara rẹ̀ nípa irú ọ̀ràn báwọ̀nyí.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Oxfam: Ìjọba kìí gba owó orí púpọ̀ lọ́wọ́ àwọn olówó tàbí fìyà jẹ àwọn alájẹbánu 9 Agẹmo 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ìwádìí fihàn wí pé yóò tó ọdún 46 kí ẹni tí ó ní owó jùlọ ní Naijiria fi ná owó rẹ̀ tán, bí ó tiíẹ̀ ń ná owó tó tó mílíọ́nù dọ́là kan ní ojoójúmọ́.
    Kò sí ẹni tí ó wà ní òde ayé yìí tí kò ní àgbélèbú tirẹ̀.
Bẹ́ẹ̀ ni gbogbo Israẹli ṣe gbé Àpótí Majẹmu OLUWA pẹlu ìró orin ayọ̀, tí wọn ń fi oríṣìíríṣìí ohun èlò orin bíi ipè, fèrè, aro, hapu ati dùùrù kọ.
Ikú ọkọ mi ṣì n dàbí àlá l'ójú mi àtawọn ọmọ Reno Omokri loju opo Twitter tiẹ sọ pe o ṣẹṣẹ han gbangba idi ti Ọjọgbọn Sagay fi n satilẹyin fun Aarẹ Buhari.
kopa ninu ifesewonse ikolu keji naa lataari kaadi olomi osan ti o gba ninu
Ọga Agba fun le Ẹkọ fun Agbeyẹwo Iṣuna Owo ninu Ile-iṣẹ, Ọgbẹni
Ìjà wẹ̀ láàrín èmi àti Ọọ̀ni, ká má ri!
Ọmọogun Naijiria ni ọna yii yoo fun ikọ ọmọ ogun laaye lati mọ awọn ti wọn jẹ agbesunmọmi ati janduku ni agbeegbe naa.
 Ṣugbọn awọn ile iwe ti ko ba ṣe awọn ohun to tọ bii ibi ti awọn ọmọ ile iwe yoo ti maa fọ ọwọ wọn pẹlu aridaju pe awọn akẹkọọ naa yoo ma lo ibomu, ko tii ṣetan lati di ṣiṣi.
Ẹ rú ẹbọ alaafia, kí ẹ jẹ ẹ́ níbẹ̀, kí ẹ sì máa yọ̀ níwájú OLUWA Ọlọrun yín.
com/Postsubman O kere tan ẹlẹwọn to le ni igba lo salọ kuro ni ọgba ẹwọn to wa ni ilu Benin, nipinlẹ Eko lasiko ifẹhọnuhan EndSars.
Lasiko ti ọrọ naa di ija ni Stanley fi èdè Igbo sọ fun iyawo rẹ pe ko mu ọ̀bẹ wa fun oun, nigba to ri pe Adekunle ti n bori.
Yóo pa mí jẹ lójú pópó!
Amọ, iroyin ti a ko le fi idi rẹ mulẹ sọ wi pe wọn ti da ọpa aṣẹ pada lẹyin ti Ọba Akiolu pada si afin.
Olóri ẹbi lè din oye ẹrù ku lati din ìnáwó ọkọ iyàwó kù.
Ọ̀rẹ́ méjì kan wà láyé àtíjọ́; kòríkòsùn gbáá ni wọ́n.
Ìjọba-àpapọ̀ sọ Èkó di ìpínlẹ̀ ni àádọ́ta ọdún sẹhin.
Kí ló wà nínú Tea tí Abiola mu?
Ètò àgùnbánirọ̀ yóò bẹ̀rẹ̀ padà jakejado Nàìjíríà Ijọba apapọ Naijiria ti kéde pe ki wọn ṣí gbogbo Ibudo akojọ eto agunbanirọ pada keto gbogbo si maa waye nibẹ.
Baba agba, ẹni ọdun marundinlaadọrin kan ni ọlọjọ ti de fun lataari igbesẹ ọmọ rẹ sii.
Trump sọ eyi saaju eto idibo ti yoo waye ni ọsẹ kan si isinyin lati yan awọn asofin si Ile Igbimọ Asofin Agba ati Kekere lorilẹede naa.
Aarẹ Buhari kede pe ijọba orilẹede Naijiria ko ṣa dede ti awọn ẹnubode naa bikoṣe lati dẹkun awọn fayawọ ohun ija oloro ati ogun nigba naa lẹyin ipade pẹl'awọn gomina ipinlẹ mẹrindinlogoji to wa lorilẹede Naijiria.
Láti ìgbà tí mo ti wà ní kékeré ni mo ti pinnu lọ́kàn mi pé nkò ni ní ọkọ títí ọjọ́ ayé mi.
O ni lẹyin eyi ni awọn oṣiṣẹ oun wa pe pe awọn eeyan kan naa fẹ ba awọn rirnirn ajo ki awọn kuku lo aṣẹ ti wọn fun wọn fi gbe.
O Fagunwa kú, dúkìá rẹ̀ sì ń fọhùn síbẹ̀, ilé rẹ̀ rèé Jonathan gba ijọba Buhari ni imọran lati tẹti si ohun ti awọn ara ilu n fẹ.
    Báyìí ni mo yọ nínú ẹjọ́ náà, kò sì pẹ lẹ́yìn èyí tí a dé odó ẹjẹ̀.
Òun ni kò fi lè wá síbi àsè ọba.
Lẹ́yìn náà, ó pàṣẹ fún Aṣipenasi, olórí àwọn ìwẹ̀fà rẹ̀ pé kí ó lọ sí ààrin àwọn ọmọ ọba ati àwọn eniyan pataki pataki ninu àwọn ọmọ Israẹli, 
Fatima ni oun lo ya fidio naa lasiko ti Aisha Buhari yabo Ile Glass House ti Aarẹ ti ni ki wọn kuro lati fi aaye gba itọju Yusuf, ọmọ Aisha ti o ṣubu lori kẹkẹ lasiko naa.
"Àkọlé àwòrán, Lati ìgbà pípẹ́ sẹ́yìn wá, Liliya kìí jẹ́ ki ẹni kẹni ri ori rẹ̀ lai lo wíìgì Kaní pe mo ni òòre ofẹ́ láti yíi ọwọ́ aago sẹ́yìn ni mí o ba gba ara mi ni ìmọ̀ràn láti gbadun ara mi jú ìgbà náà lọ, ti mi o si ni bìkítà lóri wíígì"" Ọ̀pọ̀ àwọn tí wan ti gbà láti maa gbé orí pípa wọ́n bẹ́ẹ̀ ni àwọn ènìyàn máá ń sọ ọ̀rọ̀ alùfànsá sí yálà lóri ayelujara tàbi lóju kòroju."
Nigba ti yoo fi di ọdun 1980, Ayinde Barrister ati orin Fuji ti di itẹwọgba laarin gbogbo ẹsin to wa ni Naijiria.
Ni arabinrin yii fesi fun awọn aburo rẹ to ba a wa iṣẹ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Àwọn olórin Naijiria pọ̀ tó fakọyọ nilẹ̀ Adulawọ ni 2018 24 Ọ̀pẹ̀̀ 2018 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 30 Ọ̀pẹ̀̀ 2018 Oríṣun àwòrán, others Àkọlé àwòrán, Wizkid ati Tiwa da igboro ru p#elu fidio orin yii Àwọn olórin Naijiria, Ghana àti Cameroon da bira ninu ọdun 2018.
“N óo fi ìtara sọ̀rọ̀ sí àwọn orílẹ̀-èdè yòókù ati gbogbo Edomu, tí wọ́n fi tayọ̀tayọ̀ pẹlu ọkàn ìkórìíra sọ ilẹ̀ mi di ogún wọn, kí wọ́n lè gbà á, kí wọ́n sì pín in mọ́wọ́, nítorí wọ́n rò pé ilẹ̀ mi ti di tiwọn.
Nisinsinyii, bojú wo ohun tí ń ṣẹlẹ̀ sí wa; kí o sì gbọ́ bí Senakeribu ti ń sọ̀rọ̀ ẹ̀gàn sí ìwọ Ọlọrun alààyè.
“Bí ẹnìkan bá fẹ́ wá sọ́dọ̀ mi, bí kò bá kórìíra baba rẹ̀ ati ìyá rẹ̀, ati iyawo rẹ̀, ati àwọn ọmọ rẹ̀, ati ẹ̀gbọ́n, ati àbúrò rẹ̀, lọkunrin ati lobinrin, tí ó fi mọ́ ẹ̀mí òun pàápàá, kò lè jẹ́ ọmọ-ẹ̀yìn mi.
Awon alase orile-ede Kenya ti le kuro tele, latari  ojuse re nipa fifi adari egbe oselu alatako Raila Odinga se yeye, gege bi “Aare gbogbo eniyan”Won so pe, ogbeni Miguna ko ni iwe eri omo bibi orile-ede Kenya, amo o ni iwe eri omo bibi orile-ede Canada.
Bakan naa ni ileeṣẹ ọlọpaa ni awọn ri iye to to ẹgbẹrun lọna marundinlaadosan to jẹ owo to ṣẹku lara owo ti wọn gba lẹyin ti wọn ta ọmọ naa.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Period party: Àwọn obìnrin kan ṣe ayẹyẹ nkan oṣù l'órí ayélujára Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Ó bá angẹli jà, ó ja àjàṣẹ́gun, ó sọkún, ó sì wá ojurere rẹ̀.
Yatọ si pe o jẹ Dokita,oniwaasu Kristẹni ni Dokita Stella ''Dokita nikan kọ ni mi.
 ile-iṣẹ isakoso ti naijiria ( fmin ) 1985 ati awọn alakoso oludari british .
Àwọn rèé 14 Agẹmo 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 19 Agẹmo 2020 Oríṣun àwòrán, Others Àkọlé àwòrán, Bi Ọba Adeyemi si ti n ṣetọju awọn ẹlẹyinju ẹgẹ, naa ni ko gbagbe awọn aya igba ọdọ rẹ, to si n bu ọla ati iyi fun wọn pẹlu.
Lomana Lualua, Seydou Keita ati agbamieye agbaboolu ti o darajulo nile Afrika
" Ọmọ oniwaasu ati ajinhinrere ni Ọgbẹni Chakwera.
Olu ilu orilẹede Naijiria, Abuja lo ṣe ipo keji pẹlu ọgbọn eeyan to ṣẹṣẹ fara kaasa aarun naa.
Gẹgẹ bi ile-isẹ to mojuto eto ilera se sọ pe
Ọ̀kọ̀ọ̀kan ninu àwọn ìyẹ́ kerubu kinni keji jẹ́ igbọnwọ marun-un (mita 2¼), ọ̀kan ninu àwọn ìyẹ́ kerubu kinni nà kan ògiri ilé náà lẹ́gbẹ̀ẹ́ kan, ìyẹ́ rẹ̀ keji tí òun náà jẹ́ igbọnwọ marun-un (mita 2¼), nà kan ìyẹ́ kerubu keji.
Gbogbo àwọn ọkunrin Juda dúró níwájú OLUWA pẹlu àwọn ọmọ wẹ́wẹ́ wọn, àwọn aya wọn ati àwọn ọmọ wọn.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Lẹyin eyi ni Somayaa wa pinnu pe oun yoo kọ Ibrahim silẹ nitori o ti di ajeji si oun, ti oun ko si fẹ maa pe ẹni to n tẹle asa lati ni ifẹ oun, gẹgẹ bii ọkọ.
Gege bi O se so, O ni, pipadanu ifesewonse naa se afihan awon kudie-kudie to ku fun akonimoogba iko naa ati awon osise ajo NFF ni lati se saaju idije agbaye ohun to n bo lona.
Eyi lo bi orin Fuji Garbage.
Bakan náà ni òfin tun sọ pé, olori ilé iṣẹ́ Amotẹkun gbọdọ jẹ́ oṣìṣẹ́ fẹ̀yìnti lẹ́nu iṣẹ́ ologun tabi agbofinro.
Gbogbo àwọn ọba wọnyi parapọ̀, wọ́n kó gbogbo ọmọ ogun wọn jọ láti bá Israẹli jagun.
Àfikún owó ilé ìwé leè dákún ìsòro Nàíjíríà Fásitì Ìbàdàn, UI gbé owó àkànṣe ìdánilẹ́ẹ̀kọ́ f'áwọn akẹ́ẹ̀kọ́ rẹ̀ sókè láti ẹgbẹ̀rún márùndínláàdọ́ta, (75, 000) sí ẹgbẹ̀rún lọ́nà ọgọ́rún, (100, 000), tí owó iléègbé sì kúrò ní ẹgbẹ̀rún mẹ́rìnlá sí ẹgbẹ̀rún lọ́nà ogójì, (40,000) Fún fásitì ìpínlẹ̀ Oǹdó ní tirẹ̀, ẹgbẹ̀rún márùndínlógójì làwọn akẹ́ẹ̀kọ́ ń san tẹ́lẹ̀ kí wọ́n tó sún un sí ọgọ́fà ẹgbẹ̀rún àti ẹgbẹ̀rún lọ́nà igba.
“Níbo ni ọ̀nà ilé ìmọ́lẹ̀,ibo sì ni ibùgbé òkùnkùn,
Ìsòrò àìríná lò jẹ́ ọ̀kan pàtàkì ni orílẹ̀ yìí, èyí sí nń pa àwọn ilé iṣẹ́ míràn to yẹ kí o ti mú ìdàgbàsoke ba orílẹ̀-èdè yiìí.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, CAN: Samson ni ọrọ awọn ajinigbe ti gba àpérò ní Naijiria Bakan naa lo fikun pe itọni ti oun gba ninu ile ati ijọ Ọlọrun ko fọwọsi iru iwa yii, nitori idi eyi, oun tọrọ idarijin niwaju Ọlọrun ati awọn eeyan ti iwa oun yii ti jẹ ẹdun ọkan fun.
 ọrun re rẹ ẹgbọn mi ati ọrẹ mi tootọ”Austin Peter,  olorin reggae ti a mo si ‘King Wadada’, naa kẹdun iku Ekulele Elumelu to doloogbe lomo ogota odun nile iwosan Lagoon Hospital nilu Eko.
Ẹ fetí sí orin arò tí mò ń kọ le yín lórí, ẹ̀yin ìdílé Israẹli:
Link Governorship Election Results: Àgbùnbánirọ̀ tó bá INEC ṣiṣẹ́ kú nínú ìjàmbà ọkọ̀ ojú omi l'Ondo Arsenal lo fi o to gẹẹ si irinajo olubori ti Manchester United ti bẹrẹ si nii rin lati igba ti olukọni wọn, Ole Gun Solkjaer ti gba iṣẹ ni ọjọ kọkandinlogun oṣu kejila ọdun to 2018.
Adari  egbe osise lapapo (The Nigeria
Cardee ni èyí dálé ipò tí obìnrin náà wà, irú ìdojúkọ rẹ̀ àti bí ilé ìwòsàn ètò ìlera àgbègbè rẹ̀ bá ṣe rí Ṣe àwọn ẹbí mi le wà pẹ̀lú mi ti mo bá fẹ́ bímọ?
O ni ẹka to n ṣeto owo oṣu oṣiṣẹ (Salaries and Wages Commission) lawọn reti ki wọn ṣe atunṣẹ to yẹ, ni ibamu pẹlu aṣẹ lati ọdọ akọwe agba fun ijọba apapọ (SGF).
Ipa meji ti ipaniyan naa jasi Martha Mukamushinzimana ọlọmọ marun, ti oun nikan da ẹru ẹṣẹ gbe fun ọdun marundinlogun, ki o to lọ salaye ara rẹ fun ile ẹjọ lọdun 2009 nigba ti ko le koju isoro ẹdun ọkan yii.
Rehoboamu ọba bá yára bọ́ sinu kẹ̀kẹ́ ogun rẹ̀, ó sá àsálà lọ sí Jerusalẹmu.
Nítorí OLUWA ti fi ẹ̀mí oorun àsùnwọra si yín lára Ó ti di ẹ̀yin wolii lójú;ó ti bo orí ẹ̀yin aríran.
Ẹwẹ, ẹgbẹ oselu The African Action Congress ti le Sowore ati awọn mejidinlọgbọn miran fun ẹsun wi pe wọn dojuti ẹgbẹ oselu naa.
Osun tribunal: Ilé ẹjọ́ sọ Adeleke di gómínà, ṣùgbọ́n kò tó bẹ́ẹ̀ kó kó lọ ilé ìjọba
Ṣugbọn OLUWA wí fún mi pé, ‘Má bẹ̀rù rẹ̀, nítorí pé mo ti fi òun ati àwọn eniyan rẹ̀ ati ilẹ̀ rẹ̀ lé ọ lọ́wọ́, ohun tí o ṣe sí Sihoni, ọba àwọn ará Amori, tí ń gbé Heṣiboni ni kí o ṣe sí òun náà.
 ""Oṣerebinrin to ba foju wina iru nkan bẹẹ, gbọdọ sọ sita lati ran awọn miran lọwọ."
Àìsọ̀rọ̀ Buhari lórí ìṣẹ̀lẹ̀ Lekki, ìkọjú ìjà sí Yoruba ni - YWC Kò sọ́rọ̀ nínú ọ̀rọ̀ Buhari, àtúntò Nàíjíríà nìkan lọ̀nà àbáyọ - Àgbà Yorùbá O ni lara awọn to ku ni ara ilu mọkanlelaadọta, ọlọpaa mọkanla ati ṣọ́ja meje.
Ẹgbẹ̀rún márùn ún náírà ni àwọn olóṣèlú san fún ìbò kọ̀ọ̀kan ní ìpínlè Òǹdó àti Anambra.
Agbábọ́ọ̀lù Super Falcons tẹ́lẹ̀, Chiejine jáde láyé lẹ́ni ọdún 36 Ilé iṣẹ́ márùn ún tí wọ́n dárukọ kìí ṣe túntun- Garba Shehu FRSC dá N443,180 padà fún ẹbí ẹni to ní ìjàmbá mọ́tò Súnkẹrẹ fàkẹrẹ ọkọ̀ ló sún wa dé ìdí kẹ̀kẹ́ gígùn -Awa Bike Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí 2 sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 2:23 Fídíò, Water Generator: Ó leè ṣiṣẹ fún wákàtí mẹfà, kó tó sinmi, Duration 2,2310 Òkùdu 2020 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
Lẹyin naa ni o tun lọ si St Agnes College, ti o wa ni Maryland, Ikeja, ilu Eko, laarin ọdun 1955 si 1956.
Aare Muhammadu Buhari ti darapo mo awon adari orile ede lagbaaye lati ba orile ede Amerika kẹdun lori iku  aare ana George H.
OLUWA bá sọ fún mi pé: “Ìwọ ọmọ eniyan, ṣe akiyesi dáradára, ya ojú rẹ, kí o sì fi etí sílẹ̀ kí o gbọ́ gbogbo ohun tí n óo sọ fún ọ nípa àṣẹ ati àwọn òfin tí ó jẹ mọ́ tẹmpili OLUWA.
Ò- gbé- kọ̀nkọ̀ṣọ̀- fọhùn - ọmọge;
Eyí tó ṣẹ̀lẹ̀ gbẹ̀yìn yìí lo wáye ni ogúnjọ́ oṣù kẹ́jọ ọdun yìí, àsìkò yìí ni ẹjọ́ bẹ̀rẹ̀ pé ìjọba ìpínlẹ̀ Rivers wo mọsálásí Trans-Amadi Góminà Wike náà si ti sàlàyé pe wọ́n ti fi ofin de ilẹ náà pé wọ́n o lé kọ ǹkankan sóri rẹ̀.
Mo fẹ́ kí o mọ̀ dájúdájú pé, kí àkùkọ tó kọ ìwọ óo sẹ́ mi lẹẹmẹta.
Lagos missing children: Ọ̀kan lára ìyá àwọn ọmọ tó sọnù náà ti ń sínwín
Mo bá tún rí angẹli mìíràn tí ó gòkè wá láti ìhà ìlà oòrùn, tí ó mú èdìdì Ọlọrun alààyè lọ́wọ́.
 Ẹ ̀ rù sì ń yọ ́ mi bà láìjẹ gbèṣè .
 ní ìgbà kan rí , aymara jé èdè kan tí ó se pàtàkì ní ààrin gbùngbùn andes tí wón jé apá kan Énípáyà inca ( inca empire ).
Àbí o kò gbàgbọ́ pé mo wà ninu Baba ati pé Baba wà ninu mi ni?
Delila bá mú okùn titun, ó fi dè é, ó sì wí fún un pé, “Samsoni, àwọn ará Filistia dé!
#BBCNigeria2019 Ní ìbò kọ̀la, àwọn agbébọn gbẹ̀mí èèyàn 66 ní Kaduna INEC sún ọjọ́ ìdìbò síwájú: PDP, APC fárígá!
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Equality; Ẹ wo ọ̀nà márùn ùn tí ọ̀kùnrin ṣì ń jẹ gàba lé obìnrìn lórí 11 Ẹrẹ̀nà 2020 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Àjọ Ìṣọ̀kan Àgbayé, UN ti kéde ọ̀nà mọ́rùn ún tí orílẹ̀èdè Naijiria ṣì ń rẹ̀yìn nípa ìdọ́gba láàrín ọkùnrin àti obìnrín.
Ẹ̀yin ẹlẹ́gbẹ́ òkùnkùn tẹ fẹ́ ṣe àjọ̀dún lónìí, lákọ la ń dúró dè yín - Iléeṣẹ́ ọlọ́pàá Kòṣẹlẹ̀rí ni Hajj ọdún 2020, wo ìyàtọ̀ tó wà nínú rẹ̀ sí ti tẹ́lẹ̀ Ṣé lóòtọ́ ni Lateef Adedimeji àti Adebimpe Oyebade ṣe ìgbéyàwó?
Ọọni, Aláàfin, Ojisẹ Ọlọ́run àti oniṣẹ ìwádìí fi Ògún gbari pé òògùn ìbílẹ̀ le wo Covid-19 Àwọn alárùn coronavirus ṣe ìwọ́de ní Gombe, wọ́n ní ìjọba n febi pa wọ́n Ajọ naa sọ pe oun n ṣiṣẹ kara-kara lati ṣe eto ti yoo daabo bo awọn arinrinajo, ti papakọ ofurufu ba ṣi pada.
Ṣugbọn Ahikamu ọmọ Ṣafani fọwọ́ sí ọ̀rọ̀ mi, kò sì jẹ́ kí á fà mí lé àwọn eniyan lọ́wọ́ láti pa.
Ọrọ̀ tí a kójọ lọ́nà èrú kò lérè,ṣugbọn òdodo a máa gba eniyan lọ́wọ́ ikú.
Bakan naa lo ko awọn ọmọ mejeeji fun Basirat.
Ahasi kó ohun ìṣúra inú ilé OLUWA, ati ti ààfin, ati ti inú ilé àwọn ìjòyè, ó fi san ìṣákọ́lẹ̀ fún ọba Asiria, sibẹsibẹ ọba Asiria kò ràn án lọ́wọ́.
Iroyin sọ pe Okikiola lọ si ile ọti Avid ni Alagbado lọjọ Eti, ọjọ kọkanla lati ra Sharwama to si pe Oloruntoba lati sin oun lọ.
Aṣofin Baffa Dan Agundi sọ fun BBC pe ko tọ si awọn lati ṣaigbọran si aṣẹ ti ile ẹjọ pa pe ki wọn jawọ ninu iwadi naa patapata.
 O ni iroyin ti awon gbo nipa
”  Aare wa sapejuwe ise gege bi ipenija to
Ẹ dákun, e má jẹ́ ki tilẹ̀ ó pọ̀jù ti tẹnu lọ
O ni ohun ti yoo gba aaye to lapẹrẹ ninu eto iṣejọba oun bayii ni ipese ohun amayedẹrun fun araalu.
Àkọlé àwòrán, Tọkunrin-tobinrin lo yọ ayọ ayajọ awọn ewe tọdun 2019 laafin Ojaja 11 nile Ifẹ.
Issa Onilu fi ọrọ rẹ to tako idajọ yi sita ninu atẹjade kan.
“O je olori-ire ati eni to maa n bowo fun ofin orile ede United Kingdom , o tun  ti se osise ile ise to n mojuto idagbasoke ere idaraya fun osu mefa ni ilu Bristol”.
O kede pe gbogbo ọmọ ti wọn maa bi lagbaye jẹ mejidinlọgọrin o le ni irinwo ẹgbẹrun o din mejọ.
‘A óo kó ninu àwọn ọmọ bíbí inú rẹ lọ, a óo sì fi wọ́n ṣe ìwẹ̀fà láàfin ọba Babiloni.
Lasiko to n kopa nibi ijọsin Keresimesi ni ṣọọsi Cathedral Church of Christ, ni Marina nilu Eko lo ti lede ọrọ yii.
Ṣugbọn eyi ko ya awọn onimọ sayẹnsi lẹnu o.
tun kede pe ile-ise ajo agbaye to n mojuto ohun ogbin lorile ede Naijiria  ( International Institute of Tropical
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Afeez Agoro: O ṣòro fún mi láti wọ Danfo jáde Ṣugbọn ọgọọrọ eeayan lori ayelujara ni ko kọrin 're ki minisita lori ọrọ yii, @biolakazeem sọrọ loju opo Twitter rẹ pe oun fẹ ki ajọ IAAF f'ofin de Naijiria.
n óo kó gbogbo orílẹ̀-èdè jọ sí àfonífojì Jehoṣafati,n óo sì dá wọn lẹ́jọ́ níbẹ̀;nítorí ohun tí wọ́n ti ṣe sí Israẹli, àwọn eniyan mi.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ngendera Albert: Mi ò fẹ́ kí wọ́n máa pa ọ̀ọ̀nì ni mo ṣe ń rà wọ̀n Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Ngendera Albert: Mi ò fẹ́ kí wọ́n máa pa ọ̀ọ̀nì ni mo ṣe ń rà wọ̀n 9 Sẹ́rẹ́ 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 19 Ìgbé 2020 Ijẹlọkan ki ẹmi awọn ọọni ma nu mọ lo mu ki Ngendera Albert máà kó wọn ya sọtọ ni orilẹede Burundi lati maa ṣe itọju wọn.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Àgbàrá omíyalé ba ilé 500 jẹ́ ní Nàìjíríà 'Eyi ni bi àgbàrá omíyalé sẹ ru ìyàwó mi lọ' Ọdún wo ni Nelson Mandela gba ÀmÌ Ẹ̀yẹ Nobel Peace prize?
Bẹ́ẹ̀ ni àwọn mejeeje ṣá ṣe kú láì ní ọmọ.
'À ń fẹ́ epo ọ̀fẹ́ tàbí gbà má bínú lọ́wọ́ ìjọba' Ihalẹ Buhari: PDP na ìká àbuku sí Buhari lẹyìn ìpàdé wọn INEC kéde pé àwọn ẹgbẹ́ òṣèlú lé tẹ̀síwájú pẹ̀lú ìpolongo ìbò Ni akoko to fi n ba awọn oniroyin ati alẹnulọrọ lori eto idibo sọrọ nilu Abuja.
Ko ti i pe oṣu kan ti aṣofin to n ṣoju ẹkun idibo Kosofe, nile aṣofin agba Naijiria, Bayo Osinowo jade laye.
031trn) 2019 Budget: Ààrẹ Buhari gbé àbádòfin N8.
O fi kun ọrọ rẹ pe, iru igbesẹ bẹẹ maa n ṣe adinku eeyan gẹgẹ bi ẹlẹran ara nitori o fihan pe, ijọba ko fẹ gbọ ohun ti ara ilu n wi ni.
6 71344 Orilẹede El Salvador 1186 18.
“ Awọn ọdọ ati gbogbo omo
Kilode ti won ko tii ri awon omo dapchi yii?
Dafidi ní, “OLUWA, Ọlọrun Israẹli, èmi iranṣẹ rẹ gbọ́ pé Saulu ti pinnu láti wá gbógun ti Keila ati láti pa á run nítorí mi.
Ẹ máa ta gbọ̀n-ọ́n-gbọ̀n-ọ́n láì mu ọtí líle.
O sọ ọrọ naa nibi eto kan kan to waye nilu London.
Gbogbo nǹkan yòókù tí Jehoṣafati ṣe, gbogbo iṣẹ́ akikanju rẹ̀, ati gbogbo ogun tí ó jà, wà ninu àkọsílẹ̀ Ìwé Ìtàn Àwọn Ọba Juda.
mejidinlogun naa ni wọn ka ni igba ẹkẹta ninu gbongan Ile Igbimọ Aṣofin
mẹta (14,533), nigba ti akẹgbẹ rẹ lati ẹgbẹ oṣelu PDP, Ọgbẹni Alani
Bí ọrọ̀ bá ti ń pọ̀ sí, bẹ́ẹ̀ ni iye àwọn tí yóo máa lò ó yóo máa pọ̀ sí i.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Akomolede ati asa Yoruba: Ẹ wá kọ́ nípa àpòtí ìṣura èdè wa lórí BBC Yorùbá Oyetunji salaye pe: lẹyin ẹgbẹrun lọna ọgbọn naira to fi ranṣẹ fun owo idanwo aṣekagba girama WAEC rẹ, ko mọ bi ọmọ naa ṣe joko ṣe awọn idanwo gbogbo to ku ati bi o ṣe wọ ile iwe giga fasiti.
Má jẹ́ kí ọkàn mi fà sí ibi, má sì jẹ́ kí n lọ́wọ́ sí iṣẹ́ ìkà.
Bẹ́ẹ̀ sì ni àdàbà, ati lékèélékèé, ati alápàáǹdẹ̀dẹ̀;wọ́n mọ àkókò tí ó yẹ láti ṣípò pada.
Ṣé wọ́n ni bí kò bá ní ìdí obìnrin kìí jẹ́ Kúmólú.
 Àìṣọ ̀ kan tó wà láàrín òun àti samuel ládòkè akíntọ ́ lá tó dipò rẹ ̀ gẹ ́ gẹ ́ ́ bí fìdí hẹẹ ́ olórí Ìjọba ní agbègbè Ìwọ ̀ oòrùn mú ni ó dá fàá ká ja tí ó ṣẹlẹ ̀ ní ọdún 1962 .
Ati pe gbogbo ẹsun ti wọn fi kan Magu, ni yoo ma wí àwíjàre rẹ le lori ni gbangba bayii.
O ṣalaye pe eṣu jẹ kokoro to maa n jẹ oko run ti awọn oloyinbo n pe ni 'Locust' Ati pe irufẹ owe yii wa fun awọn olowo, ẹni to ri jajẹ lawujọ, ọlọla, oloṣelu ati ẹni to wa nipo nla ti ọpọ eeyan maa n wari fun.
Sanwo-olu gbé ìwé ẹ̀dùn ọkàn olùwọ́de ENDSARS lé Buhari lọ́wọ́ Ìwọ́de 'End SARS' lè tan àjàkálẹ̀ arùn coronavirus lẹ́ẹ̀kejì ní Nàìjíríà- Ọjọ̀gbọ́n Faduyile Ṣé lóòtọ́ ni gómìnà Seyi Makinde fún Soun Ogbomoso ní N100M láti tún ààfin ṣe?
lorisirisi ọna , ‘Dibo maa se ja tabi idibo si i se ogun’.
Ìlú Ilẹ́ṣà ti ó jẹ́ olú ìlú fun gbogbo ilẹ̀ jẹ̀ṣà jẹ́ nnkan ibùsọ̀ mẹ́rìnléláàádọ́rin sí ìlú Ìbàdàn tí jẹ́ olú ìlú ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́.
Oludije fun ipo gomina labẹ asia ẹgbẹ oṣelu PDP, Abba Kabir Yusuf lo pe oludije ẹgbẹ oṣelu APC, Abdullahi Umar Ganduje to jawe olubori ninu ibo gomina ipinlẹ Kano lẹjọ.
” Nigige so pe egbe APC yoo kopa ninu eto idibo gbogbogboo to n bo, o wa ro gbogbo omo egbe lati se ise gidi-gidi ni eyi ti egbe APC yoo se tun jawe olubori pelu ami to lapare ni ipinle Anambra.
Sugbọn sa iru igbesẹ bayi ni wahala ti o maa n mu wa paapa julọ lagbami oselu gẹgẹ bi ọjọgbọn Campbell ti se salaye.
Ṣugbọn ẹnu ni a fi ń jẹ́wọ́ láti rí ìgbàlà.
ọkọ Ìparun ni Jàgùdà páálí tí obìnrin kan báyìí tí orúkọ rẹ̀ ń jẹ́ Ẹ̀fẹ́-ilé bí fún Bìlísì.
 Eyi ni Aṣofin Ọbasa fi kasẹ ọrọ ikini rẹ nilẹ.
Bí bẹ́ẹ̀ kọ́, tẹ́tí sí mi;farabalẹ̀, n óo sì kọ́ ọ lọ́gbọ́n.
Wọ́n ń kígbe pé, “Àwọn tí wọn ń da gbogbo ayé rú nìyí; wọ́n ti dé ìhín náà.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, SARS: Awọn ará ìlú fi ẹ̀rí síta nípa ìrírí wọn Èyí wáyé nípa ìwà ìjẹkujẹ àti ìwà ọ̀daran tí àwọn kọ̀rọ̀wọ̀sí tó wà láàárín wọn ń wù fún ará ìlú.
Eyi si maa n mu ki awọn sẹẹli ṣiṣẹ kiṣẹ.
Ẹni tí OLUWA bá sì yàn ni yóo mú kí ó súnmọ́ òun.
“Baba mi ti fi ohun gbogbo lé mi lọ́wọ́.
Kú iṣẹ́ ńlá ìwọ ọmọ ènìyàn, kú u làálàá.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Mo máa n forin mi kìlọ̀ ìwà ìbàjẹ́ láwùjọ ni -Hameen Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
isere Old Trafford yoo gbalejo iko agbaboolu Fulham lojo Abameta(Saturday), nibi
Fun apẹrẹ, ni Zimbabwe lọdun 2017 nigba ti awọn ologun gbajọba ọdun mẹtadinlogoji Robert Mugabe, ọgagun agba Sibusiso Moyo nigba naa sọrọ lori ẹrọ amuhunmaworan pe ko si ohun to jọ idtẹgbajọba.
Oríṣun àwòrán, Facebook/Rose Oko Saa keji ni Sẹnẹtọ Oko n ṣe lọwọ nile igbimọ aṣofin agba niluu Abuja ki iku to mu un lọ.
Awọn ọmọogun Indonesia n mu ẹjẹ ejo Àwọn mọ̀lẹ́bí ajínigbé tó pàdánù ẹ̀mí l'Ondo kò tí ì yọjú Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí kan sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
Ọ̀pọ̀lọpọ̀ ti fọ́jú nitori iwà burúkú ẹni kan tàbi itàn burúkú.
Adegbenro ni arun yii ti di itankalẹ aarun nitori pe ọdọọdun ni iba Lassa yii ma n waye ni agbeegbe ijọba ibilẹ mẹta nipinlẹ naa.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Àlàyé rèé lórí bí wọ́n ṣe mú mi lẹ́rú ní 1837 - Ajayi Crowther Mo nífẹ̀ẹ́ Khafi torí kìí díbọ́n tàbí hùwà oníwà - Gedoni sọ̀rọ̀ ìdágbére Wo iléeṣẹ́ ìjọba tí Kọmísánà tuntun kọ̀ọ̀kan ní Ọyọ yóò dìmú Àwọn alálẹ̀ kò ní forí jìn mí tí ń kò bá ṣe ọdún Ṣàngó - Alaafin Kíni ẹ mọ̀ nípa Tolani Alli, ayàwòrán tí igbákejì ààre Osinbajọ ṣẹ́ṣẹ́ yàn?
Ọ̀kan jẹ ẹ́ ní àpò marun-un owó fadaka, ekeji jẹ ẹ́ ní aadọta owó fadaka.
Olatoye, ti awon agbebon sekupa nirole ojo Abameta Satide.
O ṣalaye pe ni nkan bi agogo maarun abọ idaji ọjọ isinmi ni wn yọnda awọn ọmọ naa fun oun lẹgbẹ igbo kan ni agbegbeti oun ko mọ.
Gbogbo aye lo si n fẹran rẹ eleyi ti o farahan ninu awọn ami ẹyẹ to ti n gba nihin ati lọhun.
Ó dé ibùdó ogun ní àkókò tí àwọn ọmọ ogun ń lọ sójú ogun, wọ́n ń hó ìhó ogun.
O tun sọ pe ki wọn fi akoko igbele ati Ramadan ọhun gba adura ki wọn si tun fi ṣetọju awọn alaini.
Iwadii abẹrẹ ajẹsara tuntun yii fihan wi pe, awọn eniyan yoo nilo ati ma a gba ni ẹẹmeji laarin ọsẹ mẹta, ki o le ṣiṣẹ daradara lara.
Gómìnà Seyi Makinde bá ẹbí Isiaq Jimoh tó kàgbákò ikú òjijì dárò Ẹ gbọ́ òhun tí àwọn olùdíjé sípò gómìnà nípínlẹ̀ Ondo sọ nípa Bàbá ìsàlẹ̀.
Bobrisky: Ẹ má ṣe ìdájọ́ mi, mo ṣún mọ́ Ọ́lọ́run, máà sì lọ sí Mecca láìpẹ́
Inu ile mi ni mo wa, ọrẹbinrin mi si nikan ni mo le ko o ran.
Awọn mọlẹbi rẹ kankan ko ti i yọju.
Ojú rẹ̀ wá ń tàn bí oòrùn.
Irọ́ lásán ni ìdìbò tó wáyé ní ẹkùn Ìwọ̀-òòrùn Kogi - Dino Melaye A maa mu bi iroyin naa ba ṣe n lọ wa fun un yin laipẹ.
Akọwe agba ẹgbẹ awọn ẹlẹsin ibilẹ l'Oyo, Ọmọwe Fayemi Fakayode ṣalaye pe iha ti ijọba Gomina Seyi Makinde kọ si awọn ẹlẹsin ibilẹ lo jẹ k'awọn ṣewọde lati fi ẹhonu han.
Ìrántí àwọn tí wọ́n ti di olóògbé nípasẹ̀ àrùn Kògbóògun, àti àwọn tí wọ́n ngbé pẹ̀lú kòkòrò àrùn náà nínú ara wọn.
Oríṣun àwòrán, Twitter/Super Falcons Dennerby ni pẹlu igboya lawọn agbabọọlu Naijiria yoo fi koju akẹgbẹ wọn, bo tilẹ jẹ pe wọn fidi rẹmi ninu ifẹsẹwọnsẹ wọn pẹlu Norway.
Ileeṣẹ Pfizer dan oogun kan wo lara awọn eeyan ni ipinlẹ Kano ni ariwa Naijiria lọdun 1996.
Ni ọdun 1952 ni Olatunji bẹrẹ ifẹhọnuhan tirẹ ni awọn ọkọ igboro ni Guusu agbegbe naa.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Naomi Adamu se àkọsílẹ̀ ìgbé ayé rẹ̀ ni àgọ́ Boko Haram 30 Agẹmo 2019 Oríṣun àwòrán, AFP/BOKO HARAM Àkọlé àwòrán, Mo ní ìwé àkọsílẹ̀ ìgbé ayé mi ni àgọ́ Boko Haram- Naomi Adamu Ó pé ọdún mẹ́wàá gbáko tí ọ̀gá àwọn alakatakiti ẹsin Islam Boko Haram ti gbogbo ènìyàn mọ̀ si Mohammed Yusuf kú Yusuf kú nígbà ti ó wà ní àhámọ́ ọlọ́pàá ní ìlú Maiduguri, sùgbọ̀n láti ìgbà tí ìṣẹ̀lẹ̀ yìí ti ṣẹ́ ní omi àláfíà ìhà árèwá Nàìjíríà àti orílẹ̀-èdè Nàìjíríà lápapọ ti dàrú.
Joseph ni o ti to ọsẹ mẹta ti awọn obi ọmọbinrin naa ti n wa lẹyin to kuro ni ile iwe giga fasiti Adekunle Ajasin University (AAUA) ti o n ti n lo si ile iwe lati lo ki ọrẹkunrin rẹ.
Ó ti di ọjọ́ mẹ́rin lérawọ́n báyìí ti àbájade ìye ènìyàn to ni ààrùn Covid-19 ti ń já wálẹ̀ lójoojúmọ.
Jàńdùkú olóṣèlú gbàkóso ilé aṣòfin l‘Ondo Wo àmì márùn-un tí o fi le mọ ẹni tó fẹ́ gbẹ̀mí ara rẹ̀ Wo ìyá ọlọ́mọ mẹ́ta tó ti pé ọdún 48 tó ń ṣe ìdánwò WAEC, kó le di nọ́ọ́sí Wo fọ́tò àrà MC Oluomo, Pasuma àtàwọn òṣèré tíátà míì níbi ìṣílé Iyabo Ojo Iṣẹ́ jìbìtì ni INEC fi ọ́ọ́fìsì rẹ̀ tó jóná l'Ondo ṣe - Eyitayo Jegede Àwọn olùdíje dupò gómìnà ní ìpínlẹ̀ Ondo ń fapájánu lórí ilé iṣẹ́ INEC to jọ́ná Ó ṣeni laanu pe iru iṣẹlẹ yìí ṣẹlẹ nítori pe o fi han pe, awọn kan ko fẹ́ ki idije yiìí yọri si rere, àwọn èèyàn mu ero ọkan wọ́n ṣẹ ni.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Gun control in Nigeria: Wo ọ̀nà márùn ún tí o lè gbà dábòbò ara rẹ lọ́wọ́ ìjàmbá!
 Oun ni yoo soju orile-ede South Africa nidije omidan agbaye.
Opọ ni wọn n woye nipa arabinrin Sadiya ati oun to n ṣẹlẹ ni Aso Rock Èmi kò sí nílé, ọkọ́ mi ló leè sọ bóyá lóòtọ́ọ́ ló fẹ́ gbéyàwó àbí bẹ́ẹ̀ kọ́ - Aisha fèsì .
Dokita Thomas-Wilson Ikubeseto jẹ oniṣegun eto ilera ni, titẹ okunrin lọdaa jẹ ọna ti wọn fi n yọ koropọn okunrin kuro ni ipo to wa.
Nígbà tí Jesu dé ọ̀gangan ibẹ̀, ó gbé ojú sókè, ó sọ fún un pé, “Sakiu, tètè sọ̀kalẹ̀, nítorí ọ̀dọ̀ rẹ ni mo gbọdọ̀ dé sí lónìí.
Gbogbo wa ni a óo jọ pín ìkógun náà dọ́gba-dọ́gba, ati àwọn tí ó lọ ati àwọn tí ó dúró ti ẹrù.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Mo fẹ́ gbé ògo ìdílé ìyá àti bàbá mi ga pẹ̀lú iṣẹ́ Mọkálìíkì' Gẹgẹ bi o ṣe sọ, 'gbogbo awọn to lee ṣe iṣẹ ti a la kalẹ fun ikọ Amọtẹkun kii ṣe awọn to lee ṣe ohunkohun lori ayelujara.
' eyi to mu ki awọn eeyan maa woye pe o seese ki wọn fẹ bẹrẹ si ni tanna wadi Gomina Ayọdele Fayose to da awọn ile adiyẹ naa silẹ nigba to fi kọkọ ṣe gomina l'Ekiti.
Ninu itan ilẹ Yoruba, aafin Iwo lasiko temi ni awọn ẹleṣin musulumi ati kristẹni wa gbadura laafin fun igba akọkọ.
October 29, 2018 Àwọn olùfẹ̀hónú hàn tún pada fìjà pẹ́ẹ́ta pẹ̀lú àwọn ọmọ ológun àti ọlọpàá.
Ìtàn Aláàfin Aole rèé, tó gbé ìran Yòrùbá ṣépè Kí ló fa ááwọ̀ láàrín ìjọba àti Alaafin, tí Makinde fi ń bẹ̀bẹ̀?
Mo ti gba amọran yin bayii, igbakeji aarẹ.
Ọmọ mi, má ṣe gbàgbé ẹ̀kọ́ tí mo kọ́ ọ,sì pa òfin mi mọ́ lọ́kàn rẹ,
Awon dokita tun tesiwaju pe ti Joy ko ba tete ri owo lati fi
Kí olukuluku yẹ iṣẹ́ ara rẹ̀ wò, nígbà náà yóo lè ṣògo lórí iṣẹ́ tirẹ̀, kì í ṣe pé kí ó máa fi iṣẹ́ tirẹ̀ wé ti ẹlòmíràn.
Òwú aláǹtakùn yín kò lè di aṣọ,eniyan kò ní fi iṣẹ́ ọwọ́ yín bora.
’Bakan naa, aare egbe ASUU, ojogbon Biodun Ogunyemi naa so pe ipade yoo waye laarin won pelu ijoba apapo lose to n bo.
Awọn to sun mọọ ṣalaye pe ko fi igba kọọkan rin irinajo lẹnu lọwọlọwọ yii.
Alágbára ati akọni eniyan ni wọ́n, wọ́n jẹ́ mejidinlaadoje (128).
Oṣiṣẹ orilẹede Amẹrika kan ti ṣalaye ọrọ pe igbesẹ tuntun yii waye nitori pe orilẹede mẹfẹfa yii kọ lati ṣe ohun to tọ ni ibamu pẹlu ofin Amẹrika nipa aabo ati pinpin iroyin.
Man City naa lo gba ife ẹyẹ Premier League Liverpool lọwọ ni saa bọọlu to lọ.
Àkókò ń bọ̀ tí àwọn eniyan kò ní fẹ́ fetí sí ẹ̀kọ́ tí ó yè.
Oludije fun ipo aarẹ labẹ asia ẹgbẹ oṣelu AAC, Omoyele Ṣowore lo sọ bẹẹ nigba to gba BBC Yoruba sọrọ lori ifẹhonu han ''Days of Rage'' ti yoo bẹrẹ lọjọ Aje, ọjọ Karun un oṣu kẹjọ.
Ọlọ́run kò ní í jẹ́ kí ẹ kú àkúrun mọ́ o.
Máṣe hùwà àbùkù bí irú ìwọ̀nyí mọ́, kí ìwọ bà rí obìnrin fẹ́ ọ.
Wo pataki igbesẹ to yẹ ni gbigbe koo too fi ẹjẹ rẹ silẹ Àròsọ àti ìgbàgbọ́ àwọn ènìyàn lórí gbígba ẹ̀jẹ̀ Ọ̀pọ́ jàǹdùkú l‘Ọṣun bọ́ sí gbaga ọlọ́pàá lórí ìwà ọ̀daràn Ṣé ìnàkí tún gbé owó tó lé ní mílíọ̀nu mẹ̀fà Náírà mì ni?
Olu ilu orilẹede Argentina, Buenos Aires ni wọn sin Maradona si nibi ti ọpọ ti pejọ lati ṣe ẹyẹ ikẹyin fun elege ara to filẹ ṣaṣọ bora.
Awo orin rẹ, Chief Executive Omota, gba ami ẹyẹ Hip hop World Award fun orin 'rap' lọdun 2010.
bí ó bá jẹ́ pé nínà ni ó yẹ kí wọ́n na ẹni tí ó jẹ̀bi, ẹni náà yóo dọ̀bálẹ̀ níwájú adájọ́, wọn yóo sì nà án ní iye ẹgba tí ó bá tọ́ sí i gẹ́gẹ́ bí ẹ̀ṣẹ̀ rẹ̀.
Ó sọ fún àwọn iranṣẹ wọnyi pé, “Ẹ máa lọ ṣáájú mi, kí ẹ sì jẹ́ kí àlàfo wà láàrin agbo ẹran kan ati ekeji.
Ààrẹ ní kí wọ́n wádìí oun tó ti bààlú Osinbajo fi já lulẹ̀
1 999 Ọkọ oju omi Diamond Cruise 13 712 Orilẹede Mauritius 10 0.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Yaa Asantewaa: Ti ẹyin ọkunrin Ashanti kò bá tẹsiwaju, awa obinrin yóò lọ Irora ni ẹyin, ọrun ati orunkun, to fi mọ ọwọ, ẹsẹ ati oju wiwu ni obinrin kan sọ pe o maa n ṣe oun.
Seruaya yìí ló bí Abiṣai, Joabu ati Asaheli.
Ẹ kò mọ̀ pé ẹrú ẹni tí ẹ bá ń gbọ́ràn sí lẹ́nu lẹ jẹ́, ẹnikẹ́ni tí ẹ bá fara yín ṣẹrú fún, tí ẹ sì ń jíṣẹ́ fún?
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Yetunde Bakare dárà lórí ètò Ṣé o láyà, ẹ ràn án lọ́wọ́ nínú ìbéèrè tó ṣì Ipinlẹ Borno lorilẹ-ede Naijiria, orilẹ-ede Chad, Niger, Mali, Burkina Faso, ati Cameroon.
26 Lõtọ́, lõtọ́, ni mo wí fún ọ, pé àwọn àkọsílẹ̀ wà èyítí ó ní púpọ̀ lára àwọn ìhìnrere mi nínú, èyí tí a ti pamọ́ sẹ́hìn nítorí ìwà búbúrú àwọn ènìyàn.
“Mo fẹ́ kí ẹ mọ̀ dájúdájú pé ẹni tí kò bá gba ẹnu-ọ̀nà wọ àgbàlá ilé tí àwọn aguntan ń sùn sí, ṣugbọn tí ó bá fo ìgànná wọlé, olè ati ọlọ́ṣà ni.
Ǹjẹ́ èyí tí ó kọ sẹ́yìn yìí kò fi ìfẹ́ hàn tó, ‘Nǹkan tí ẹ bá jẹ́ kù kí ẹ máa fi tiwa ránṣẹ́ sí wa o’?
Kí oore-ọ̀fẹ́ ati alaafia máa wà pẹlu yín.
Ajọ campaigners ni wọn gbọdọ fagi le adehun kankan to ba tiẹ wa laarin orilẹede Naijiria ati ile iṣẹ epo mejeeji.
Ẹwẹ, igbimọ naa ti pari ayẹwo ohun ti kamẹra CCTV ka silẹ logunjọ oṣu kẹwaa ti iṣẹlẹ ọhun ṣẹlẹ.
“A ni ibasepo pelu ajo to n pese eto ilera ati ajo to n mojuto eto idajo lati ri daju pe a da ile itoju ohun sile.
Àṣé ìyá yìí ntọọrọ owó ni.
    Kò pẹ́ tí iwin yìí fi wá sílẹ̀ tán tí a pàdé àwọn mẹ́ta kan.
Abalọ ababọ, wọn ri awọn ibọn atamatase mẹfa gba, ibọn ẹtu mẹrindinlogun ati ọta'' ''Wọn mu awọn afurasi naa.
Eeyan kan to ku, to jẹ alaga igbimọ naa, Onidajọ Ibrahim Sirajo ni tirẹ dajọ gbe Oyetọla ti ẹgbẹ oṣelu APC lẹyin.
Fi idẹ ṣe aadọta ìkọ́, kí o sì fi wọ́n kọ́ àwọn ojóbó náà, láti mú àwọn àránpọ̀ aṣọ mejeeji náà papọ̀ kí wọ́n lè jẹ́ ìbòrí kan.
fi asiko naa dupe lowo awon ara ipinle naa fun atileyin  ati adura fun  itesiwaju ipinle ohun.
Ilé ìwòsàn l'Àbuja ti ya àwọn ìbejì tí wọ́n sọpọ̀ láyà lọ́fẹ̀ẹ́ Gómìnà mẹ́ta àtí ènìyàn 1,242 ló kó sí panpẹ EFCC ni ọdún 2019 Ṣugbọn awọ ko tii ka oju ilu nitori ọgọrun un miliọnu kii ṣe owo ọmọde owo.
Aare Buhari wa gbadura fun  Oloye Olusegun Obasanjo pe ajinde ara a maa jẹ,
Ni Michigan ida mẹrinla lawọn to jẹ alawọdudu nibẹ, ṣugbọn awọn gan an lo ko ida mẹtalelọgbọn lara awọn ti arun coronavirus ti kan; bẹẹni ida mọkanlelogoji awọn to ti ku lo jẹ alawọ dudu gẹgẹ bi ileeṣẹ eto ilera nibẹ ti ṣe sọ.
”OLUWA, tẹ́tí sí ohùn ẹ̀bẹ̀ mi.
Iye àwọn tí Mose ati Aaroni kà ninu àwọn ọmọ Kohati nìyí, àwọn tí wọ́n lè ṣiṣẹ́ ninu Àgọ́ Àjọ gẹ́gẹ́ bí OLUWA ti pàṣẹ fún wọn.
Asiko to fi n gberu lara Asiko yi ni kokoro naa fi n fẹsẹ mulẹ ninu ara.
Ajọ ọlọpaa Ipinlẹ Eko ti kede orukọ awọn ọlọpaa to lọwọ si bi wọn ṣe yinbọn lu awọn ololufẹ meji ni Ajegunlẹ ni ipinlẹ naa, ti arabinrin naa si gbẹmii mi.
Nípa ẹ̀mí, ó lọ waasu fún àwọn ẹ̀mí tí ó wà lẹ́wọ̀n.
wọ́n bá gbógun ti àwọn ẹ̀yà Bẹnjamini, wọ́n fi ìlú Gibea ṣe ojú ogun wọn.
Nítorí ẹ̀ṣẹ̀ tí wọ́n fi ẹnu wọn dá,àní, nítorí ọ̀rọ̀ tí wọ́n fi ẹnu wọn sọ,jẹ́ kí ìgbéraga wọn kó bá wọn.
Ronaldo ya ẹro ibanisọrọ dokita lati yẹ oju rẹ to bẹjẹ wo lori papa
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Àwọn ará àdúgbó Lekki rí orí àti ara ọkùnrin mẹ́ta ní àdúgbo wọn 14 Ìgbé 2019 Oríṣun àwòrán, Minkail Adesoji/Twitter Àkọlé àwòrán, Ibeere ti gbogbo ara adugbo to lọ ibi iṣẹlẹ naa ni pe ta lo pa wọn.
"Oríṣun àwòrán, @tokstarr Gbolohun kan to kọ sori ayelujara Twitter rẹ lati igba ti ariwo naa ti bẹrẹ ni pe ""We move"" - eyi ti a le sọ pe o tumọ si pe, ohunkohun to wu ko ṣẹlẹ, igbe aye n tẹsiwaju naa ni."
Air Marshal Abubakar wa ro awon
Boya eyi lo mu ki ọkunrin kan, Abdullahi Bashir fi n fi ẹsẹ tọ igboro ilu Abuja kiri, lati se alabapade, Hanan, ọmọbinrin aarẹ Muhammadu Buhari.
Ní ọjọ́ kan náà, àwọn meji ninu àwọn ọmọ-ẹ̀yìn ń lọ sí abúlé kan tí ó ń jẹ́ Imausi.
Ko dawọ duro nibe ti o si tẹsiwaju lati ra ọkọ ologun kan ti o yi pada si eleyi ti wọn le dari lọna meji-iwaju ati ẹyin.
Lẹyin to pari saa akọkọ naa, igbimọ alaṣẹ fasiti naa tun fi orukọ rẹ silẹ fun saa keji.
N ko ni ifẹ ikọkọ pẹlu ọkunrin kankan nitori owo ara mi ni mo fi ra ile ti mo n gbe ati mọto mẹta ti mo n lo.
waye ni ipinlẹ Borno ti o jẹ Ila oorun Ariwa , orile ede yii.
Akeredolu ni ijọba oun ti ṣe adinku si owo ile ẹkọ fasiti naa lẹyin ti awọn akẹkọọ fasiti naa ṣe iwadi kaakiri ẹkun ìwọ oorun Naijiria lati mọ fasiti to n sanwo ile ẹkọ to kere julọ.
Asoju orile ede Congo si orile ede Naijiria so pe oun  yoo sa ipa lati je ki ibasepo laarin orile ede Naijiria ati orile ede Congo tun dan monra si I paapaa julo lori eto oro aje, o tun tesiwaju pe awon onisowo bi Alhaji Aliko Dangote ati awon onisowo miiran ti da ile-ise won sile ni orile ede Congo.
O ni opin gbọdọ de ba ọlọpaa SARS ati SWAT ti ijọba ṣẹṣẹ yi orukọ wọn pada si.
Sọ àsọtẹ́lẹ̀ orílẹ̀èdè tí yóò borí ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ t'òní Presidential Election Tribunal: Láyé, a ò lè gba ẹ̀bẹ̀ PDP láti yẹ ojú òpó ayélujára INEC wò Ta ni awàdà rẹ̀ wúu yín lórí jù ní Yollywood?
Ẹ ṣọ́ra, ẹ máa fojú sọ́nà nítorí ẹ kò mọ wakati náà.
Ọkàn àwọn eniyan ti dàrú,orúnkún wọn ń gbọ̀n pẹ̀pẹ̀,ìrora dé bá ọpọlọpọ,gbogbo ojú wọn sì rẹ̀wẹ̀sì.
”“orile-ede Croatia ko fi be jina sibi, ti o si dawa loju pe, ogoro awon ololufe won ni a o ri nibi.
John Ogu, Etebo Ogenekaro, Francis Uzoho, Victor Osimhen and Henry Onyekuru have arrived in camp ahead of the #AFCON2019Q vs Seychelles 🇸🇨.
Lonii naa ni adajọ yoo sọ bo ya ileẹjọ yoo gba oniduro Alfa Babatunde.
Èèyàn tó tó egberun mẹta ló bá ija yi lọ.
Nibẹ, wọn a yọ ibomu-boju wọn silẹ, wọn a maa parọ foonu, wọn a ti gbagbe iṣẹ ti wọn n ṣe ninu wọọdu.
Idi ree ti ọba Eshinlokun fi gba Oshodi Tapa sọdọ rẹ, to si fi ṣe alakoso eto aabo ni awọn abala kan ninu aafin rẹ, ti ọba si fi si abẹ amojuto Fagbemi.
Mercy gba ami ẹyẹ Africa Magic Viewers Choice gẹgẹ bi ẹni to n mura daradara julọ ni ọjọ kẹrinla oṣu kẹta ọsun 2020.
Pẹ̀lú iṣẹ́gun lórí àwọn arákùnrin rẹ̀ yìí, kò ní ìtẹ́lórùn, òun náà fẹ́ ní ibùjókòó tí yóò ti máa ṣe ìjọba tirẹ̀.
Ninu idije AFCON tọdun 1990 ti Algeria gbalejo rẹ, ami ayo marun un si ookan ni wọn fi ṣina fun Naijiria ki wọn to gba ife lọ nigbẹyin.
Lọjọọjọ Aiku ni wọn ṣi maa n ṣe isin ninu ilé ijọsin naa.
Èyí yóo jẹ́ kí gbogbo eniyan mọ̀ pé kò sí òótọ́ ninu gbogbo nǹkan tí wọn ń sọ nípa rẹ.
Nígbàq tí mo wo inú àpò mi, tọ́rọ́ péré ni mo rí, ojú sì ń tì mí àti fi eléyìí tọrẹ fún àwọn ọmọ ibẹ̀, ṣùgbọ́n síbẹ̀ náà mo fi tọ́rọ́ yìí fún wọn; nígbà tí mo sì tún wo nínú àpò mi, mo rí àkàrà tí ìyá mi fún mi ní ijọ́sí mo sì bu díẹ̀ fún wọn nínú rẹ̀.
Àkọlé àwòrán, Awọn abanikẹdun si ti n bọwọlu iwe iforukọsilẹ ikẹdun nile Oloogbe to wa ni agbegbe Park view, Ikoyi niluu Eko.
“Ní ìgbà Hesekaya ọba Juda, Mika ará Moreṣeti sọ àsọtẹ́lẹ̀ fún gbogbo àwọn ará Juda pé OLUWA àwọn ọmọ ogun ní, ‘A óo kọ Sioni bí ilẹ̀ oko,Jerusalẹmu yóo di òkítì àlàpà;òkè ilé yìí yóo sì di igbó kìjikìji.
“Mose iranṣẹ mi ti kú, nítorí náà, ìwọ ati gbogbo àwọn ọmọ Israẹli, ẹ múra kí ẹ la odò Jọdani kọjá, kí ẹ sì wọ ilẹ̀ tí n óo fun yín.
eniyan yoo se maa rin ku , paapaa julo lasiko ojo eto idibo , o wa ro gbogbo
Ṣugbọn sibẹ, irufẹ Ọba bẹẹ ko lee fọwọ kan ọmọ naa.
Àṣìṣe ní orílẹ̀èdè Iran fi já bàálù Ukraine wa silẹ̀ - Iléeṣẹ́ ìròyìn Amẹrika kéde Amotekun dé!
Nítorí ìlérí ati ìfẹ́ ọkàn rẹ ni o fi ṣe gbogbo nǹkan ńlá wọnyi, kí iranṣẹ rẹ lè mọ̀ nípa wọn.
Nígbà tó ń gbàlejò Bíṣọ́ọ̀bù àgbà ìjọ Anglican ní Canterbury, Ẹniọ̀wọ̀ Justin Welby ní ìlú London.
A ṣe agbeyẹwo awọn kan ati asọtẹlẹ wọn nipa ẹni ti yoo jẹ oye nijọba ,njẹ wọn jana abi wọn kuna ni?
Aare orile ede Naijiria ,Muhammadu Buhari  ti wa pasẹ fun ile-ise ologun ati gbogbo awon
Wọn bi i bi wọn ṣe n bi gbogbo ọmọ to ku to si dagba gẹgẹ bi ọdọ to ja fafa ninu iṣẹ ṣiṣe.
Minisita fun ọrọ isẹ ode, ọrọ ilẹ ati ilegbe, Arakunrin Babatunde Fashola lo se ikede iyipada ọjọ atunse afara naa ninu atẹjade kan to fun awọn oniroyin.
Ẹ pohùnréré ẹkún, nítorí pé ọjọ́ OLUWA súnmọ́lé,yóo dé bí ìparun láti ọwọ́ Olodumare.
Oladapo Otiki naa tun tepele mo oro idaniloju rẹ pe iko omo ogun oun yoo ri i pe
Ó wí pé, “Balogun, wọ́n rán mi níṣẹ́ sí ọ.
O ni: ''Lilo iwa ipa, ija ati jijo ohun ini ijọba ati ti awọn eniyan ko ni wa ọna abayọ si iṣoro to doju kọ orilẹede Naijiria.
Dokita Obinnaadigo sọ pe irora naa yoo wa fun igba diẹ, ko tun to o lọ silẹ.
Ọba maa n jẹ ẹdọ eeyan ko to de ipo ọba, ṣe ootọ ni ọrọ yii?
"Sẹnẹtọ Shehu Sani ninu ọrọ ti ni ti awọn ẹṣọ Amọtẹkun ba fi iṣẹ eto aabo ilu silẹ bẹrẹ sí ni dọdẹ awọn to n wọ iwọkuwọ kiri, a jẹ wi pe orúkọ wọn ti di ""Hisbahtekun"" nìyẹn."
Ọkùnrin kan di èrò ọ̀run nítorí pé o fi ẹ̀sùn kan alájọgbélé rẹ̀ pé o n yan ìyàwó ẹnìkan lálè Máa gbé kẹ̀kẹ́ rẹ lọ, àwọn akọròyìn kọ̀ ìpàkọ́ sí Femi Fani Kayọde Victoria Rubadir ọmọ Kenya ló gba àmì ẹ̀yẹ Komla Dumor BBC World News.
Bákan náà ni wọn ti pé fún rírà lati ọdọ Luton Smith group èyí yóò sí jẹ eya kelebe.
Naijiria gbe ile-ẹkọ giga fasiti ti Alabama re ile-ẹjọ
Itán sọ pé Ibòkun ni wọ́n kọ́kọ́ dó sí kí wọn tó pínyà.
Laipẹ ni iya Joe wa sọ fun un pe ọkọ oju omi kan danu sinu odo ni Bakana, ti ọkọ rẹ si wa lara awọn ti o wa ninu rẹ, sugbọn wọn ṣi n wa.
eto amusẹya – Onari BrownIgbakeji  oludari kinni- Chris HassanIgbakeji oludari
"Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìjọba Buhari: Orúkọ Adeọsun tún wà lórí òpó ayélujára lẹ́yìn tó fipò sílẹ̀ 14 Owewe 2018 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 30 Ọ̀wàrà 2018 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, ""Iwe ofin ko sọ pe ki wọn maa lẹ orukọ eeyan kan mọ ipo kan ni pato"" Lẹyin ọjọ merindinlaadọta ti minisita eto inawo tẹlẹ ri, Kemi Adeọṣun kọwe f'ipo silẹ, orukọ rẹ si tun wa lori oju-opo ayelujara ijọba apapọ."
Agboolé Aperin jẹ ìdílé àwọn akíkanjú jagunjagun láyé atijọ, a sì leè ni ẹ̀jẹ̀ lọ ro Osuolale, tí òun náà fi jẹ akíkanjú ẹ̀dá lókè eepẹ.
Ile igbimo asoju sofin ni Naijiria ti ro ijoba apapo lati mu igberu ba awon ile-iwosan akeko ni Naijiria ati ile-iwosan National Hospital Abuja (NHA), lati mu adinkun ba irin-ajo ilu okere lo gba iwosan.
“ ‘Ẹni ìfibú ni ẹnikẹ́ni tí ó bá gba àbẹ̀tẹ́lẹ̀ láti pa aláìṣẹ̀.
Ìròyìn sọ pé ọ̀pọ̀ àwọn tó ń gba ìgbòro ló ti pàdánù àwọn ẹbí wọ́n nínú wàhàlá tí àwọn ará South Africa ń dásílẹ̀.
Láti inú ẹ̀yà Isakari, àwọn igba (200) olórí ni wọ́n wá, àwọn tí wọ́n mọ ohun tí ó bá ìgbà mu, ati ohun tí ó yẹ kí Israẹli ṣe; wọ́n wá pẹlu àwọn tí wọ́n wà lábẹ́ wọn.
Láti ẹni ọgbọ̀n ọdún títí dé ẹni aadọta ọdún, àwọn tí wọ́n lè ṣiṣẹ́ ninu Àgọ́ Àjọ.
Gege bi atejade naa pe, awon omobinrin ohun yoo le pada sodo awon molebi won, ati anfaani lati bere igbe aye otun.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Njẹ Chloroquine nipa kankan lati le koju Coronavirus CoronaUpdate: Gómìnà ìpínlẹ̀ Kaduna,Nasir El Rufai nàá ti ní àrùn Coronavirus Oríṣun àwòrán, @elrufai Gomina ipinlẹ Kaduna Nasir El Rufai ti kun awọn Gomina to lugbadi arun Coronavirus ni Naijiria.
Ọlọrun ti pèsè ọ̀gbun tí ó ṣókùnkùn biribiri fún wọn.
Nigba ti ile-ifowopamo Access, Learn Africa Plc, AG Leventis Nigeria, ati May and Baker Nigeria Plc gba ami eye Bronsi (Bronze), latari bi won se n sanwo owo-ipin idokowo fun awon onibara won lati bi odun mewaa.
Ọmọ Yorùbá tó bá ti rú òfin, ẹ gbé e jàntò - Oluwo Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Oluwo: Mo lè jẹ Ọba ní Ile Ife Nibi ipade awọn lọba lọba lati iha Guusu-Ila Oorun Naijiria iyẹn awọn ọba Yoruba pẹlu aarẹ Muhammadu Buhari, Oluwo tunbọ ṣe afikun ọrọ to fi ranṣẹ si aarẹ nipa ṣiṣe adura fun un.
Ẹ máṣe gbàgbé pe Àjùlé ọ̀run ni àwa wà yìí o, nítorí ibẹ̀ ni ilé Adéforítì.
Àwọn ará Damasku bá ọ ṣòwò nítorí ọpọlọpọ ọjà ati àwọn nǹkan olówó iyebíye tí ò ń tà, wọ́n mú ọtí waini ati irun aguntan funfun wá láti Heliboni.
Wọ́n kó gbogbo aguntan wọn, gbogbo mààlúù wọn, gbogbo kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ wọn, ati gbogbo ohun tí ó wà nílé ati èyí tí ó wà ninu pápá.
Ohun tí mo ní lọ́kàn nìyí.
Lójijì, OLUWA sọ fún Mose, Aaroni, ati Miriamu pé, “Ẹ wá sí ẹnu ọ̀nà Àgọ́ Àjọ.
" Oríṣun àwòrán, emperortelu1 Oluwo tun tẹsiwaju pe asa Yoruba yaayi lootọ, ko si si ohunkohun taa fẹ gba ninu ka ba asa wa jẹ, amọ ta ba ba aye yi nidi awọn asa to ti di ogbo, a ti kuna niyẹn, iyipada maa n duro titi lae ni.
iwe adehun pelu iko ọlọtẹ ti Gusu , ko to di pe won ya lọ da orile ede South
Ó ń lọ gbé ilẹ̀ Midiani.
Ibẹ̀ ni wọn óo ti máa sìn mí títí lae.
Motara ṣalaye fun BBC pe lojojumọ, lọsọọsẹ ti oun n ro pe ọrọ naa yoo rọlẹ ṣugbọn kaka kewe agbọn dẹ, pipele lo n pele sii ti mo n gbọ kaakiri pe awọn kan nibi lọhun tun ti n sọrọ nipa rẹ.
“Ìwọ ni o gbà mí lọ́wọ́ ìjà àwọn eniyan mi,o sì mú kí ìjọba mi dúró lórí àwọn orílẹ̀ èdè;àwọn eniyan tí n kò mọ̀ rí di ẹni tí ó ń sìn mí.
Fẹ́mi Gbàjàbíàmíà, olórí ọmọ ẹgbẹ́ òsèlú tọ pọ̀ jùlọ nílé asojú sòfin ilẹ̀ wa, nínú àtẹ̀jáde kan tó fi síta ní Àbújá rọ àwọn asòfin yòókù láti tu mọ̀lẹ́bí náà nínú.
Nǹkan kan ṣo tí mo gbọ́ ni “Ìyá àgbà Saray”.
Oríṣun àwòrán, other Àkọlé àwòrán, Ọdun 1942 ni wọn bi Aarẹ Muhammadu Buhari sinu idile Baalẹ Fulani l'abule Dumurkol nitosi Daura, Hando Adamu ati Hajia Zulhatu Musa lorukọ obi rẹ Oríṣun àwòrán, other Àkọlé àwòrán, Buhari ni ilu Owerri lasiko oogun Biafra to waye ni Naijiria laarin ọdun 1967 si 1970 Oríṣun àwòrán, Muhammadu Buhari Àkọlé àwòrán, Ẹ jẹ ki awọn ọmọde ki o wa s'ọdọ mi.
Nítorí àwọn tí wọ́n dúró ṣinṣin ni wọn yóo máa gbé ilẹ̀ náà,àwọn olóòótọ́ inú ni yóo máa wà níbẹ̀,
Ni àpapọ̀, ọyẹ́ jẹ́ ki ẹni ti ó bá nti Òkè-Òkun bọ̀ gbádùn nitori ooru din kù.
Fayemi ṣetán láti ṣáájú àwọn gomina láti mójútó ètò ààbò ‘Bi Gomina Ajimobi se yan adarí òsìsẹ́ tuntun ní Oyo kò dí wa lọ́wọ́’ Wọ́n jí ọmọ yìí gbé láti máa fi tọrọ bárà l'Eko 'Fún ìtẹ̀síwájú ìpínlẹ̀ Kwara ni wọ́n ṣe ni Ó tó gẹ́!
Oríṣun àwòrán, @jidesanwoolu Sanwo-Olu ni igbimọ naa wa lati gba ẹri lọwọ ẹnikẹni tabi ẹbi wọn to ba iriri ifiyajẹni lọwọ ọlọpaa SAR.
Àkọlé àwòrán, Ìpínlẹ kọ̀ọ̀kan ní àṣẹ láti dá ààbò bo àwọ̀n ènìyàn wọn Amotekun: Igboho ṣe káre fáwọn gómìnà Yorùbá pé wọ́n fi ohùn kan sọ̀rọ̀ fún ìgbà àkọ́kọ́ Akọni ọmọ Oodua kan, Sunday Majasọla Adeyẹmọ, ti gbogbo eeyan mọ si Sunday Igboho ti fọwọ gbaya pe oun yoo se atilẹyin fun eto Amotekun.
Ronke Oshodi Oke ṣe àwo orin jáde fún MC Oluomo fún ọjọ́ ìbí rẹ̀ Oni ọjọ Abamẹta ni ayẹyẹ ọjọ ibi alaga ẹgbẹ ọlọkọ ero nipinlẹ Eko, Musiliu Akinsanya, ti ọpọ eeyan mọ si MC Oluomo.
Ng kò lè s’àì mẹ́nuba oúnjẹ oní kíakía tí ó wọ́pọ̀ láti jẹ lọ́jọ́ ọ̀sẹ̀.
Olomidé sá lọ si DR Congo lọdun 2009 pẹ̀lú ìléri pé òun yóò gbèjà ara òun sùgbọ́n ó kọ̀ láti farahan nílé ẹjọ́ ni France.
Alabi Pasuma Ọ̀gáńlá pé ẹni ọdún 51 Olóòtú ìjọba Gẹ̀ẹ́sì yan ọmọ Yorùbá ní Mínísítà Mohammed Yusuf: Irú èèyàn wo ní olùdásílẹ̀ Boko Haram?
Nigba to n dahun awọn ibeere yii fun BBC Yoruba, Onimọ kan nipa eto ilera ara, Chidinma sọ awọn nkan to n fa iku ojiji lawujọ ati ọna abayọ.
A ṣe ọ̀ṣọ́ sí gbogbo igun ìtẹ́lẹ̀ náà, 
naa sipo , lati dẹkun iwa aparo kan, ga ju okan lọ lorile ede Naijiria.
Ó pàṣẹ fún ọkunrin náà, ó ní, “O lè jẹ ninu èso gbogbo igi tí ó wà ninu ọgbà yìí, 
Ìfẹ́pàtàkì, Ìfẹ́pàtàkì ni ọ̀wọ́n, ṣe ẹ kò fẹ́ ki n kú láìròtẹ́lẹ̀?
Gẹ́gẹ́ bi ìtàn àtẹnudẹ́nu, oríṣìíríṣìí ọ̀ná ni a máa ń gbà láti fi ìdí òótọ́ múlẹ̀, Ṣùgbọ́n ó kù sọ́wọ́ àwọn onímọ̀ òde òní láti ṣe àgbéyẹ̀wò àwọn ìtàn wọ̀nyí kí a sì mú eléyìí tí ó bá fara jọ ọ̀ọ́tó jù lọ nínú wọn.
O fikun un oro re wipe, bi a ba ko lati se eyi, o seese ki orile-ede Naijiria padanu olaju re.
Ẹwẹ, ijọba ipinlẹ Eko ti sọ pe oun yoo ṣepade pẹlu awọn dokita naa lati wa ojutu si ọrọ wọn.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ibadan Murder: Oyún oṣù méje ló ń bẹ nínú Azeezat, kí wọ́n tó f'òkúta fọ́ ọ lórí Iṣẹ Alhaja Kudirat ko parẹ Ninu gbogbo iwadii, a o rẹni to sọrọ lodi si Alhaja Kudirat Abiola ri dipo bẹẹ kiki awọn to n kan sara si igbesẹ rẹ ati iṣẹ takuntakun to ṣe gẹgẹ bi akọni obinrin fun orilẹ-ede Naijiria ni.
Oholibama bí Jeuṣi, Jalamu ati Kora.
tí wọ́n bá ronupiwada tọkàntọkàn ní ilẹ̀ àwọn ọ̀tá wọn tí ó kó wọn lẹ́rú, tí wọ́n bá kọjú sí ilẹ̀ tí o fi fún àwọn baba ńlá wọn, ati ìlú tí o yàn yìí, ati ilé ìsìn tí mo kọ́ ní orúkọ rẹ, tí wọ́n bá gbadura sí ọ; 
Ẹni to bori: Benin Ìpele to kangun si aṣakagba Namibia vs Morocco.
Bi o tile se pe ọpọlọpọ lo n sọrọ nipa fiimu Game of Thrones, ti eniyan to ju miliọnu mẹtadinlogun tilẹ wo ‘season 8’ lọjọ ti fiimu naa kan oju opo ayelura.
” Hagari dáhùn pé, “Mò ń sálọ fún Sarai, oluwa mi ni.
Ṣé ohun tí Kemoṣi, oriṣa rẹ fún ọ, kò tó ọ ni?
 Àwọn àmì àìsàn lè yàtọ ̀ sí ara wọn nítorí ara ẹranko tí wọ ́ n ti wáyé a má a yàtọ ̀ .
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Adeyeye Ile Ife: Kílódé tí Ọọni Ife, Oba Ogunwusi kò fi gbọdọ̀ rí ọmọ rẹ̀ tuntun títí di ẹ̀yìn oṣù mẹ́fà?
Ìwọ ni o mú kí gbogbo wọn wà láàyè, ìwọ sì ni àwọn ogun ọ̀run ń sìn.
 Ipade naa lo da lori agbekalẹ Abadofin kan ti wọn fi n ṣeto lati maa fun awọn ara ilu ni aami ẹyẹ lori iṣẹ takuntakun wọn fun idagbasoke ipinlẹ Eko lapapo, eleyii ti yoo nii ṣe pẹlu iṣẹ ati ojuṣe olukuluku.
Awọn aṣofin n beere ibeere yii nitori iṣoro aabo to wa lorilẹede Naijiria, paapaa eyi to ṣẹ ṣẹlẹ ti awọn Boko Haram dumbu awọn agbẹ ni ipinlẹ Borno.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù New Minimum Wage: Òṣìṣẹ́ ń fẹ́ kí ìjọba bẹ̀rẹ̀ sí san owó oṣù tuntun kíákíá 20 Ìgbé 2019 Oríṣun àwòrán, @NLCHQ_ABUJA Awọn adari ẹgbẹ oṣiṣẹ ni Naijiria ti gboriyin fun Aarẹ Muhammadu Buhari fun bo ṣe buwọlu sisan ẹgbẹrun lọna ọgbọn Naira owo oṣu tuntun fun oṣiṣẹ.
Buhari ti pe ṣaaju fun asọyepọ laarin ọlọpaa ilẹ yii ati ti South Africa lati daabo bo dukia ati ẹmi awọn ọmọ Naijiria sugbọn ti o ja si pabo.
Ẹgbẹ́ àwọn awakọ̀ epo rọ̀bì NUPENG so ìyanṣẹ́lódì tí wọ́n gùnlé l'Eko rọ̀ Ìdí rèé tí igbákejì Gómìnà Ondo Agboola Ajayi tún ṣe fi ẹgbẹ́ òṣèlú PDP sílẹ̀ Baba Obasanjọ kò ní àrùn Coronavirus- NCDC Oríṣun àwòrán, others Ṣaaju ni Kaduna lẹyin ipaniyan awọn eeyan Guusu ni ibẹrẹ: Awuyewuye ń wáyé lórí bí ìjọba Ìpínlẹ̀ Kaduna ṣe kó àwọn oníbárà sí àhámọ́ Ede aiyede ti n waye laarin ijọba ipinlẹ Kaduna, ati awọn ẹlẹgbẹjẹgbẹ, nitori bi ìjọba ṣe mu àwọn onibara kuro ni titi.
AMAA 2018 Ami eye fun fiimu asotan to dara julo
Ninu atẹjade naa ni ajọ JAMB ti fi lede wipe idanwo naa ṣeeṣe ki o waye lọjọ kẹsan si ọjọ kẹtadinlogun, osu kẹta, ọdun 2018.
Nítorí ó ti pẹ́ tí ó ti fẹ́ rí i, nítorí ìró rẹ̀ tí ó ti ń gbọ́.
Ogbẹni Ibidokun sọ eyi lẹyin ti komisọnna fun eto Eko ni ipinlẹ Oyo, Ọjọgbọn Kehinde Sangodoyin fi ikede naa lede ni ilu Ibadan, ni ipinlẹ Ọyo.
Ṣugbọn ẹ tún máa tiraka láti ní Ẹ̀mí Mímọ́, pàápàá jùlọ, ẹ̀bùn ìsọtẹ́lẹ̀.
3) Awọn aṣiri ohun ikọkọ ti eti ko gbọri yoo jade.
Bẹ́ẹ̀ náà ni àwọn ọkunrin wọn.
Lálẹ́ ọjọ Aiku ní wọn gbé fọ́nrán tí ẹnikan yọ́lẹ̀ ya, níbi ti gómìnà ń kó dọ́là tó tó mílíọ̀nù márùn sínú àpò agbádá rẹ̀, èyí ti wọn ni owó àbẹ̀tẹ́lẹ̀ tó ń gbà lọ́wọ́ kọngilá tó fẹ gba iṣẹ́ lọ́wọ́ rẹ̀ ní.
Àwọn aṣòfin Republican ti ń darapọ̀ mọ́ Democrat lórí àti yọ Trump nípò Kinni Trump sọ?
Ó jẹ́ àṣẹ tí mo pa fun yín.
Gbigbe ogun ti iwa ibajẹ: Aarẹ Donald Trump ni, ijọba Aarẹ Buhari se gudugudu meje ati yaya mefa lati gbogun ti iwa ibajẹ to wọpọ laarin awọn ọmọ Naijiria, ati wipe, awọn ti setan lati ran ijọba Naijiria lọwọ lati gbogun ti iwa ibajẹ ni gbogbo ọna.
Àwòran bí Yorùbá ṣe gbayì ní Austria Kò sí àjòjì darandaran kankan ní Nàìjíríà -NIS Kakaki jẹ ololufẹ awọn nkan elo orin ilẹ Afirika eyi lo si mu ko maa lo wọn ninu gbogbo awo orin to ba gbe sita bo tilẹ jẹ wi pe oke okun lo ngbe, awọn ọmọ Naijiria to wa nibẹ naa tẹwọ gba aṣa ilu wọn ninu iṣẹ to n ṣe.
Oko Oloyun: Ta ló pa Àlhájì Fataì Yusuf?
Wọn ni ipe naa ṣe pataki ki ilu naa le jaja bọ lọwọ bi ọti mimu ti ṣe'n ṣ'okunfa alekun iwa ipa ati gbigba ẹmi ara ẹni.
Saraki fi kun ọrọ rẹ pe oun fi ẹgbẹ naa silẹ lẹyin ti oun ti ro o daadaa fun igba pipẹ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Border Closure reoppening: Àarẹ Buhari ní àti dẹ́kun fàyàwọ́ ogun ati ìbọn ló fa títi ẹnubodè pa, ṣùgbọ́n yóò di ṣíṣí padà láìpẹ́ 9 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Oríṣun àwòrán, Others Wo ìgbà tí Ààrẹ Buhari yóò ṣí 'bọ́dà' padà Aarẹ Muhammadu Buhari ni ijọba apapọ ti n ronu ṣiṣi awọn ẹnubode orilẹede Naijiria ti wọn ti pa tẹlẹtẹlẹ.
Ondo APC: Irọ̀ ni Ayiloge ń pa mọ gómìnà Akredolu, kìí ṣe ọmọ ẹgbẹ́ wa
Minisita fun eto oro-aje lorile-ede Germany Peter Altmaier so fun radio Deutschlandfunk pe, “ Inu mi dun lati ri pe, a ti dena awon ohun ti o le sokunfa ki ile-ise ipese irin lorile-ede Germany ati awon osise re ni aawopelu orile-ede America”.
ibagbepọ alaafia si ṣe pataki fun idagbasoke ati igbayegbadun awujọ yoowu.
Iwọde ọhun ni wọn ṣe nitori bi aarẹ Macron ṣe satilẹyin fun atẹjade aworan ẹranko to jọ anabi Muhammed.
BBC Yoruba kan si alukoro ile iṣẹ ọlọpaa ipinlẹ Ogun, Abimbola Oyeyemi to fi aridaju han pe lootọ ni awọn ti doola ẹmi gbogbo wọn.
Gomina Greg Abbott to n tukọ ipinlẹ Texas ni: A ko ni faaye gba awọn ẹlẹtanu ati oni ikorira ni Lone Star State ti a wa yii, irẹpọ ati iṣọkan ni a maa fi bori iṣẹlẹ yii ni Texas.
Eyi lo mu ki awọn ilumọọka oloselu, awọn akọsẹmọsẹ ati awọn ẹlẹgbẹjẹgbẹ fi n kọrin re ki gomina tẹlẹ nipinlẹ Eko, Lateef Kayọde Jakande, ẹni to pe ẹni aadọrun ọdun loke eepẹ lọjọ Isẹgun.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ayò mẹ́ta ni Giroud fi fakọyọ fún ikọ̀ Chelsea nínú Europa League 14 Ẹrẹ̀nà 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Igba akọkọ re e ti Giroud yoo jẹ goolu mẹta ninu idije Europa fun Chelsea Ẹgbẹ agbabọọlu Chelsea ti pegede lati kopa ninu abala komẹsẹoyọ Idije Europa League lẹyin ti wọn da bantẹ iya ayo mẹrin sodo fun Dynamo Kiev.
Alaafin: Ọ̀pọ̀ èèyàn ń bèèrè pé kí ló dé tí Olorì Badra kò fi sí nínú fọ́tò ọdún Ileya
Kò jẹ́ kí àwọn ẹ̀mí èṣù náà sọ̀rọ̀, nítorí wọ́n mọ ẹni tí ó jẹ́.
ninu eto idibo ti yoo waye lojo kẹ́rìndínlógún, Abameta , o fi da
Chinedum Aranato sọ pe ẹnikẹni to ba n jẹun lojoojumọ gbudọ ya idọti jade lojoojumọ.
ọjọ krindinlọgbọn, oṣu Kọkanla, fihan pe, eeyan mọkandinlaadọsan tun ti ni aarun naa ni Naijiria.
Bakan naa ni igbimọ NEC buwọlu agbekalẹ igbimọ alaṣẹ to ti di tutuka tẹlẹ.
Lẹ́yìn ọdún mẹ́wàá tí Abramu ti dé ilẹ̀ Kenaani ni Sarai, aya rẹ̀ fa Hagari, ará Ijipti, ẹrubinrin rẹ̀ fún un, láti fi ṣe aya.
Ijọba Naijiria tapa si jijẹ ọmọ ẹgbẹ okunkun ti wọn si ti n fi panpẹ ofin mu ogunlọgọ awọn to darapọ mọ awọn ẹgbẹ yi.
Bi obinrin kankan ba si gbe oyun wa fun mi lasiko yii, n ko ni pariwo sita, ko maa ba ko okuta ba ọja mi.
Ọlọrun kó wọn ti Ijipti wá,ó jà fún wọn gẹ́gẹ́ bí àgbáǹréré.
Gbogbo agbegbe lo dudu raki raki ni awọn ara adugbo fi bọ ẹnu ti wọn si n kigbe pe agbara ojo ti wọ ọmọ meji lọ."
Ẹwẹ, lẹ́yìn tí ilé ẹ́jọ to gá jùlọ n'9i Nàìjíría ti yí ẹ̀sùn ẹgbẹ́ òṣèlú People's Democratic Party (PDP) tó pe All Progressive Party (APC) lórí àbájáde èsì ìdìbò ọdún 2019 dànù tán, ní agbẹnusọ ẹgbẹ́ òṣèlú APC Mallam Lanre Issa Onilu ba BBC sọ̀rọ̀.
Jonatani ati Ahimaasi bá sáré lọ fi ara pamọ́ ní ilé ọkunrin kan ní Bahurimu.
ẹni tí ó wà ní ọwọ́ ọ̀tún Ọlọrun, tí ó ti kọjá lọ sọ́run, lẹ́yìn tí àwọn angẹli ati àwọn aláṣẹ ati àwọn alágbára ojú ọ̀run ti wà ní ìkáwọ́ rẹ̀.
Ni ọsẹ to lọ niroyin sọ pe, ileeṣẹ ọlọpaa ilẹ Gẹẹsi n ṣewadii fọnran kan lori ayelujara eyi ti ọpọ gbagbọ pe Khafi n ni ibalopọ pẹlu akẹgbẹ rẹ, Gedoni ninu rẹ.
Ẹni to bori: Namibia Morocco vs Ghana.
Won ti ro ijoba orile-ede Naijira lati se amulo ilana igbedo odo Benue, latari ati se agbekale etikun, ni iyanju ati mu idagbasoke ba eto oro-aje ati amugberu awon ile-ise.
Wọ́n wó àwọn ère ati ilé ìsìn Baali lulẹ̀, wọ́n sì sọ ibẹ̀ di ilé ìgbẹ́ títí di òní yìí.
Olóri Òṣèlú Nigeria Muhammadu Buhari àti Àtẹ̀lé rẹ Ọ̀jọ̀gbọ́n Yẹmi Oṣinbajo pé Ọgọrun Ọj̀ọ́ lori oye
Mika bá dáhùn pé, “Mo mọ̀ nisinsinyii pé OLUWA yóo bukun mi, nítorí pé, ọmọ Lefi gan-an ni mo gbà gẹ́gẹ́ bí alufaa.
Ni eyi to ṣeeṣe lati gbadun lai lọ fun itọju àrà ọtọ kankan Awọn arugbo ati awọn to ni ailera ni ara wọn tẹlẹ biiaisan ọkan, itọ ṣuga, arun jẹjẹrẹ lo ṣeeṣe ki o pa lára julọ Ṣe ti o ba ti ni coronavirus lẹẹkan ko ni mu ẹ mọ?
A gbọ pe aṣẹwo naa sọ fun awọn ọlọpaa pe oun pade ẹni to ja oun l'ole naa nile igbafẹ kan ni Abuja, ti ìná si wọ̀ laarin wọn.
Amọ, ao le sọ boya ẹjọ ti pari lori awọn ẹsun naa.
Amugbalegbe ati Oludari eto ati oro ara ilu, Ogbeni
Ile bii mẹfa, ile itaja mẹtadinlogun ati ọkọ akoyanrin mẹtalelọgbọn, ọkọ ayọkẹlẹ mẹta ati kẹkẹ NAPEP alupupu mẹta naa ba iṣẹlẹ naa lọ.
Ogagun  Jonah Danjuma, ti o jẹ agbẹnusọ iko omo ogun 16
Ijọba ní nígbà ti El-Zakzaky de India ló bẹ̀rẹ̀ si ni hú àwọn ìwà tó ti ni ọkàn tẹ́ll ti kò si hàn si ìjọba ki wọ́n to kuro lorilẹ̀-èdè Nàìjíríà, èyí ló fa sábàbí ìdí tí wọ́n fi dáá pada si orilẹ̀-èdè yìí.
Nítorí náà, ní ìhòòhò, pẹlu ebi ati òùngbẹ, ati àìní ni ẹ óo fi máa sin àwọn ọ̀tá tí OLUWA yóo rán si yín, yóo sì la àjàgà irin bọ̀ yín lọ́rùn títí tí yóo fi pa yín run.
Àwọn nǹkan wọnyi ni kí o máa fi kọ́ àwọn eniyan, kí o sì máa fi gbà wọ́n níyànjú.
Shehu Garba, tí ó jẹ́ olùrànlọ́wọ́ pàtàkì fún Ààrẹ Buhari lórí gbígbé ìròyìn jáde, bu ẹnu àtẹ́ lu ìwé àpilẹ̀kọ Ọbásanjọ́:
Ṣùgbọ́n ohun tí mo lè sọ ni pé oṣù kẹfà tí mo ti rí ìwé ọ̀rẹ́ mi yìí gbà, ìwé Baba-onírùngbọ̀n-yẹ́úkẹ́, ni mo tóó dé ibib tí Ọba Igbó Olódùmarè fi ṣe ibùgbé.
Wọn ni àmọ́ ni ọrọ Aarẹ Donald Trump, ko mọ ara ẹran rara.
Ajọ NCDC ni ipinlẹ ogun ni wọn ti ri awọn alekun awọn to laarun naa.
Pẹlu esi yii, ifẹsẹwọnsẹ meji pere ni Chelsea ṣi bori ninu mẹfa ti wọn ti gba ninu liigi saa yi labẹ akoso olukọni wọn tuntun, Frank Lampard.
Igbakeji aare, Yemi Osinbajo, lo n dari igbimọ naa.
Ṣugbọn ko ni i ya mi l'ẹnu ti awọn ọmọ ijọ naa kan ba pari rẹ laarin ọjọ mẹrinla ti igbele yoo fi wa.
Wọn óo sẹ́ Oluwa wọn tí ó rà wọ́n pada, nípa ṣíṣe bẹ́ẹ̀ wọn óo mú ìparun wá sórí ara wọn kíákíá.
Ẹ lọ sí ilẹ̀ ọlọ́ràá náà, tí ó kún fún wàrà ati oyin; n kò ní sí ní ààrin yín nígbà tí ẹ bá ń lọ, nítorí orí kunkun yín, bí bẹ́ẹ̀ kọ́ n óo pa yín run lójú ọ̀nà.
Àwọn tí wọn ń lépa wa ti bá wa,ó ti rẹ̀ wá, a kò sì ní ìsinmi.
Mo bá dá ọba lóhùn pé, “Kí ẹ̀mí ọba gùn!
Ó ṣeéṣe kí ènìyàn 12,000 máa kú lójoojúmọ́ lẹ́yìn Covid-19 Orílẹ̀-èdè mẹ́wàá tí ẹgbẹ́ alákatakítí Islamic State n fínna mọ́ ní àgbáyé N kò gba ₦4bn lọ́wọ́ Magu, ẹ má ró àjẹbánu mọ́ mi láṣọ - Osinbajo pariwo Mi ò tíì gba ìwé ìfitónilétí pé wọ́n fẹ́ yọ mí nípò igbákejì gómìnà ìpínlẹ̀ Ondo- Agboola Ajayi Isẹlẹ naa ni ti ẹkun omi to maa n wọnu ile rẹ to kọ si adugbo Ikorodu nilu Eko, eyi to maa n daa laamu ni ọdọọdun.
 nígbà míìran , Èṣú jẹ ́ ìrán ńṣé fún ifá .
Ọ̀nà òmùgọ̀ níí dára lójú tirẹ̀,ṣugbọn ọlọ́gbọ́n a máa fetí sí ìmọ̀ràn.
Najim Yasin, ẹni to ni orilẹ-ede Saudi Arabia ni oun wa fun haji, wa se apejuwe oloogbe Oyerinde Fẹlẹ bii ololufẹ alaafia, to si gbadura pe ki Ọlọrun gba abọ rẹ.
Fayemi: Gbèsè tí mo bá nílẹ̀ ni kò jẹ́ kí n ti yan kọmíṣọ́nà
Ẹwẹ, àwọn miran ni àwọn sí ń retí oúnjẹ tí ìjọba ń pín nítorí kò tií de àdúgbò wọn rárá.
Bàbá ọmọdé yìí ní bàntẹ́ kan, bàntẹ́ jẹ́ aṣọ kékeré tí àwọn àgbàlagbà máa ń wọ̀ sí abẹ́ aṣọ.
Ìjọba ti buwọ́lu lílo hijab láwọn iléèwé ní ìpínlẹ̀ Osun Ọwọ́ ọlọ́pàá ti tẹ afurasí mẹ́ta tó lọ́wọ́ nínú ìjínigbé alága Iganna l'Oyo Wo ọ̀nà àbáyọ fún àwọn akẹ́kọ̀ọ́ tí àjọ WAEC gbẹ́sẹ̀ lé èsì ìdánwò wọn A ó ṣèrànwọ́ fáwọn ẹbí ọlọ́pàá tó bá rògbòdìyàn EndSARS lọ láti inú N500m tí a yà sọ́tọ̀- Makinde Awọn dokita naa korajọ, wọn si ṣe ifẹhonuhan niwaju ọọfisi adari UNIMEDTH ni ilu Akure, ti wọn si n bii eredi ti ijọba yoo ṣe jẹ wọn lowo oṣu mẹrin.
Tí a bá pè é ní Ìlúmọ̀míka, bí ẹní tẹ́mbẹ́lú rẹ̀ ni.
Nigba ti gbogbo ibo ti wọn fagile jẹ́ 47, 874.
Buhari yoo lọ sibi ayẹyẹ ọdun kọkanlelọgọta ni Ghana
Jíjáwé oluborí Joe Biden jẹ ìborí ìmọ́lẹ̀ lórí òkùnkùn-Obasanjo US Election 2020: Nígbà wo laó mọ èsì ìdìbò àti pé ṣé ó ṣeé figagbága?
Oríṣun àwòrán, NBS NIGERIA Àkọlé àwòrán, Owo ipin osoosu ti ipinle Osun ti ajo to'n risi ounka oun isiro Sibẹ sibẹ owo naa yoo sẹku.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ sí Àwọn olórin Nàìjíríà kẹ́dùn ikú ọmọ DBanj Ẹbí D'banj sọ̀rọ̀ lórí ikú ọmọ ọdún kan rẹ̀ Láti ìgbà náà, ìdílé D'Banj kọ̀ láti bá àwọn oníṣẹ́ ìròyìn sọ̀rọ̀ tábi tẹ ohunkóhun jáde sórí ẹ̀rọ ayélujára.
ibi to yẹ ki agbara atbi omi maa gba kọja;  a wa sibi lati ko awon obitibiti idoti wonyi;
Nígbà náà ni wọ́n mú un, wọ́n pa á, wọ́n bá wọ́ ọ jù sẹ́yìn ọgbà àjàrà.
Ni Naijiria, milionu meji ni akosile fihan pe o n ba arun yii ja ti ogota leni oodunrun si ti fo loju patapata nigba ti o le ni ida aadorun ninu ogorun un eniyan ko mo pe arun yii n ba won finra”.
Wọn ni ọrọ agba bi ko sẹ lowurọ, yoo sẹ lọjọ alẹ.
Alaafia Ọlọrun, tí ó tayọ òye eniyan yóo pa ọkàn ati èrò yín mọ́ ninu Kristi Jesu.
Aloe Vera dara fun itọju ara
Gẹ́gẹ́ bàa ṣeé rí gbọ́, àwọn jagunjagun ilẹ Rome lọ ń ti ojú ogun bọ láti agbègbè ìwọ oòrùn Asia tí wọn tí lọ jagun, wọn kẹru, wọn kẹru laimọ pé wọn tí kò àrùn sanponna taa mo sì small pox mọ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Akomolede ati Aṣa lori BBC:Wo ìrúfẹ́ ìgbeyàwó méje tó wà nílẹ̀ Yorùbá àti ojúṣe Alárinà Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Fídíò, Grandma Maruwa: Ó yẹ kí obìnrin sisẹ́ láì wojú ọkọ kó tó jẹun11 Bélú 2020 Fídíò, Soyinka Cancer: Àṣe ara mi ni iso ti n run gbogbo bí mo ṣe n ṣèrànwọ́ lórí jẹjẹrẹ27 Bélú 2019 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Amofin Abiade ṣalaye igbesẹ to yẹ ni gbigbe ni kikun fun ikọsilẹ labẹ ofin Naijiria.
Ẹwẹ, Wole Olanipekun to ṣoju ẹgbẹ oṣelu APC lori ẹjọ yii sọ pe ile ẹjọ lo lagbara lati ṣe agbeyẹwo ẹjọ wọn o si ni ki wọn ma ṣe da ẹjọ ọjọ kẹtala oṣu keji dun 2020 naa nu.
Ẹwẹ, Ọgbẹni Kalu ti pada sile aṣofin agba l'Abuja nibi o ti n ṣoju ipinlẹ rẹ gẹgẹ bi sẹnẹtọ.
Bayii, ẹka ti o n ri si ilera ara ilu ati awujọ ti fi panpẹ ọba mu awọn alapata ti o n ta eran ti ara pa yii fun ara ilu lẹyin ti wọn sun wọn ti wọn ṣeto rẹ daadaa.
ni ẹni tó ṣi ẹlòmíràn lọ́nà,tí ó wá ń sọ pé “Mo kàn ń ṣeré ni!
" Aarẹ Buhari gunle abẹwo lọ si ipinlẹ Nasarawa nibi to ti se ifilọlẹ eto awọn majẹobajẹ ilera alabọde, CHIPS atawọn akanse isẹ kan nibẹ.
 samuel joseph cookey jẹ ́ adarí rẹ ̀ .
Èrè wo ni ó wà níbẹ̀ fún wa bí à ń gbadura sí i?
Ko pe pupo ti awọn eeyan pe akiyesi rẹ si aworan naa wi pe aworan awọn osere Kannywood lofi sita to pe ni aworan awọn ọmọ ogun Naijiria.
Ní ọjọ́ keji, àwọn tí wọ́n dúró ní òdìkejì òkun rí i pé ọkọ̀ kanṣoṣo ni ó wà níbẹ̀.
Lilo ẹrọ abanigbọrọ ori foonu lee ṣeranwọ nigbamii too ba si fẹ da kun iranwọ yii.
Oríṣun àwòrán, Thisdaylive Femi Fani-Kayode atawọn eekan ilu mii n daro Dapo Ojora Niwọn igba to jẹ pe bi ọdẹ ba ku, ọdẹ lo n ṣoro lẹyin ọdẹ, awọn eekanlu lorisirisis ti bọ soju opo ayelujara wọn lati daro Dapo Ojora to di oloogbe.
Awọn ile-iṣẹ ti ofin naa kan ti padanu aimọye milionu dọla nipa aile gbohunsafẹfẹ won.
Ṣé àkókò yìí ni ó yẹ láti gba fadaka tabi aṣọ tabi olifi tabi ọgbà àjàrà tabi aguntan tabi mààlúù tabi iranṣẹkunrin tabi iranṣẹbinrin?
Wọ́n ní ẹsẹ̀ méjì-méjì tí ó kúrú tí wọ́n sì fi ń rìn dáradára, ìrù wọn gùn ara wọn sì ní ìpẹ́ tí ó tóbi.
Wọ́n bá mú un lọ láti kàn án mọ́ agbelebu.
Àbí ojú ọ̀run ní ń fúnrarẹ̀ rọ ọ̀wààrà òjò?
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Akin Oyebode: ohun tí wọ́n fẹ́ jẹ ni wọ́n ń wá Bi a ko ba gbagbẹ lasiko ti olootu ijọba Merkel n gba alejo Aarẹ Ukraine Volodymyr Zelensky lo kọkọ bẹrẹ si ni gbọn nita gbangba.
A ṣẹ̀ṣẹ̀ ń mú ẹyẹ bọ̀ lápò ni pẹ̀lú títú FSARS ká, àtúntò ọlọ́pàá ń bọ̀- Buhari Àìbìkítà yíì gbọ́dọ̀ dópin, ìjọba gbọdọ̀ mú ẹ̀dùn ọkàn àwọn aráàlú lọ́kùnkúndùn- Agbẹjọ́rò Àgbà Wo àwọn kọ̀ndísàn tuntun tí àwọn olùwọ́de #ENDSARS gbé jáde lẹ́yìn tí wọ́n tú SARS ká Wọ́n kò pa ẹnikẹ́ni sí ààfin Ṣọun Ogbomosọ, òkú tí àwọn ọdọ́ gbé wa ni ọlọ́pàá wọ́ jáde- Agbẹnusọ Ṣọ̀un Wo ìgbà mẹ́rin tí ìjọba ti tú ikọ̀ ọlọ́pàá SARS ká sẹ̀yín ṣùgbọ́n.
Nibayii, apapọ iye awọn ti ayẹwo ti fihan pe o laarun naa ni Naijiria bayii ti di ẹgbẹrun mẹtadinlogoji ati mọkanlelẹgbẹrin, 37, 801.
AFDAC kìlọ̀ - BBC News Yorùbá BBC News, YorùbáFò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Lílo oògùn Sniper fún ìtọ́jú oúnjẹ leè yọrí sí ikú àìtọ́jọ́ - NAFDAC kìlọ̀ 2 Bélú 2020 Oríṣun àwòrán, @DailyPostNGR Ajọ to n mojuto ipese ounjẹ ati oogun lilo ni Naijiria, NAFDAC, ti kilọ fun awọn eeyan lati ṣora fun lilo oogun Sniper"" atawọn oogun miran to wa labẹ ""Dichlorvos,"" DDVP, fun ṣiṣe itọju ounjẹ."
Congress (APC) wipe o jawe olubori pelu apapo ibo ti o le ẹ̀gbẹ̀rún méjìléláàdọ́jọ(152,546),
Yatọ si apero yii, ile jiroro lọsọọsẹ lori bi eto aabo yoo ṣe gbopọn si lorilẹedee Naijiria bo tilẹ jẹ pe diẹ ninu aba wọn ni igbimọ alaṣẹ ṣiṣẹ le lori.
"'Mo kabamọ pe mo fii fọkọ ṣugbọn mo ṣi ni ireti ọjọ ọla to dara""."
Ọ ̀ fọ ̀ ni ó máa ń jẹ ́ tí ìyàwó ilé bá sáájú ọkọ rẹ ̀ kú .
Bíbéèrè fún ìbálòpọ̀ gbogbo ìgbà sọ ìyàwó ilé dèrò ilé ìwòsàn Wo àfipábánilòpọ̀ ẹni ọdún 51 tí ìjọba ìpínlẹ̀ Ekiti tú làṣirí ní gbangba Wo àfipábánilòpọ̀ ẹni ọdún 51 tí ìjọba ìpínlẹ̀ Ekiti tú làṣirí ní gbangba Àlàyé rèé lórí ìdí tí Sẹnẹtọ Ishaku Abbo fi kọ̀wé fi PDP sílẹ̀ Oríṣun àwòrán, The Nation Kọmiṣonna ni o buru ju ajakalẹ aarun lọ.
Laarin Liverpool ati Manchester City ni dugbẹ dugbẹ yi n fi si amọ ko ti daju ibi ti yoo ja si.
Kii ṣe Liverpool nikan ni Manchester United ko nifẹ.
Wo bí ètò ìsìnkú Tolulope Arotile ṣe lọ nílùú Abuja Ìjọba ìpínlẹ̀ Kano tí wọ́gilé ayẹyẹ lẹ́yìn ìrun ọdún Iléyá!
Albert Einstein: 'Ọ̀rọ̀ lọ́kọláya kọjá ọ̀rọ̀ orí ahọ́n lásán'
Ṣebí ogun Etiopia ati Libia lágbára gidigidi?
Oríṣun àwòrán, @mavel Idi ree ti BBC Yoruba fi wọ inu itan lọ lati se agbeyẹwo igba meje ọtọọtọ ti ẹpọn agbo Naijiria ti mi, amọ ti Ọlọrun ko jọ ko ja.
Gbogbo eni tí ó bá mú,gbé, tàbí yo ohun tí kìí se tirè láìgbàase ni olè nígbàtí adigunjale jé eni tí ó fi ipá gba,mú tàbí gbé ohun tí kìí se tirè.
" O ni nibi ti ọrọ de duro yii, awọn ẹkọ ti Jegede kọ ninu eto idibo ọdun 2016, lo n ṣamulo bayii.
Oja owo Naira duro gbari ninu oja idokowo lojo-Aje, ni eyi ti won n ta dollars kan din die nirinwo naira N363 ni awon ile-itaja owo, ti a mo si Bureau De change (BDCs) ni oja ifarawe lojo-Aje nipinle Eko.
 Wo àwọn èèkàn, ìlúmọ̀ọ́ka olórin tó ṣàbẹ̀wò sí ijọ Celestial Church ti Genesis Global CCC Genesis Global: Ǹkan mẹ́wàá tí ẹ ò gbọ́ rí nípa Israel Oladele, Woli ìjọ Genesis Global Ẹ̀tanú pé Olùṣọ́ Genesis kò fẹ́ Laide Williams-Oni ló ṣe rán an lọ́ sí ẹ̀wọ̀n ọdún kan - CCC Genesis Global Saka ń wá ọ̀rẹ́ rẹ̀ kan nítorí aṣọ kóòtù ọdún 34 sẹ́yìn Ọkùnrin tó pe ìyàwó rẹ̀ lájẹ̀ẹ́ tì í mọ́lé fọ́dún mẹ́rin, fún un lóyún nígbà mẹ́ta!"
Oluwatoyin Kembi to jẹ baba akẹkọọ naa sọ fawọn akọroyin pe awọn tiẹ ro pe ọmọ naa ti sọnu ni nigba ti ko pada wale lọjọ naa lai mọ pe awọn oniṣẹ ibi ti gee wẹlẹ wẹlẹ.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ìtàn ayé Ọba Seriki Abass ti Badagry, tó ní aya 128, ọmọ 144 Ìtàn rèé nípa bí Ogbomoso ṣe pa ọba, yọ nǹkan ọkùnrin rẹ jó kiri ìlú Àwọn ọba Yorùbá kan rèé tí wọ́n rọ̀ lóyè, tí ọba míràn jẹ lójú ayé wọn Kí ló fà ogun Ìjàyè àti ìṣubú Kurunmi, ìfẹ́ ìlú ni àbí orí kunkun?
14 Àti pé nípa agbára mi títóbi jùlọ ni ìwọ fi gbà wọ́n.
" Lasiko ti a fi n kọ iroyin yii, awọn agbẹjọro rẹ ko tii ri ilana beeli rẹ muṣẹ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ministerial List: Mo setan lati yan ise fun awon minista mi- Aare Buhari 31 Agẹmo 2019 Oríṣun àwòrán, @Presidency Àkọlé àwòrán, Aare Muhammedu Buhari ti seatn lati yan ise fun awon minisita tuntun Aare orile-ede Naijiria Muhammedu Buhari ti dupe lowo awon omo ile igbimo asofin Naijiria lori titete pari iforowanilenuwo fun awon minisita ti won fi sowo si won Awon omo ile igbimo asofin agba lo ojo ise marun gbako lati ri si iforowanilenuwo awon minisita, eyi ti won ti bere lati ojo ojoru, ojo kerinlelogun osu keje si ojo isegun ogbon ojo osu keje lati pari ioforwanilenuwo fun awon minisita metalelogoji ti won ti fi oruko won ranse si ile asofin lojo ketaleogun osu keje.
Gbogbo wọn jẹ́ ọ̀kẹ́ mẹẹdogun (300,000) akọni ọkunrin tí wọ́n tó lọ sójú ogun, tí wọ́n sì lè lo ọ̀kọ̀ ati apata.
Gaddafi ló l‘ẹ̀bi ìkọlù darandaran - Bùhárí Ọọ̀ni : Oluwo lorukọ oyè tí ọba Ìwó ń jẹ́ Awọn ajinigbepawo naa ti kan si awọn mọlẹbi rẹ ti wọn sì ń bèèrè Mílíọnù máàrún naira kí wọn tó leè túu sílẹ.
Wọn sọ fun mi pe lati ọdọ ọga agba ọlọpaa ni Abuja lawọn ti wa, ti wọn si ni mo ni lati buwọ lu iwe tawọn mu wa.
Àgbàrá omíyalé Katsina ru ìyàwó mi lọ si orílẹ̀-èdè Niger
Baba Kaosara, ninu ifọrọwerọ rẹ pẹlu BBC Yoruba lori isẹlẹ yii fi ẹmi imoore rẹ han pupọ fun awọn eeyan to se idile naa laanu.
Lara awon to wa ki aare naa ni
ti ma dunnu  tabi banujẹ  nitori pe ko ti si eni to jawe olubori tabi
Awọn kan kii fẹ ki eeyan mọ pe awọn maa n yagbẹ; sibẹ, pataki ni igbẹ yiya nigbesi aye wa tori o pọ ohun ti ko dara kuro lara.
New Variant: Kí ni ìbẹ̀rù tó gbọkàn àwọn èèyàn lágbàáyé nítorí ẹ̀yà ààrùn Covid-19 tuntun?
Nitori naa lo fi ni ohun bẹrẹ si ni kọ nipa iriri yi soju opo Twitter-ibẹ lawọn eeyan ti bo bi igba ti eera bo ṣuga ti wọn si n pin kaakiri.
  hindustan "" ( ) , ni berebere to je oro persia fun "" ile hindus "" lati toka si apaariwa india , bakanna tun lilo gege bi oruko gbogbo india ."
Sugbọn a gbọ pe oṣiṣẹ alaabo to n sọ ile naa, to jẹ pe ọjọ kan naa l'oun ati alase ọhun jọ bẹrẹ iṣẹ lọjọ kan naa, ti wa lagọ ọlọpa lori ọrọ naa.
eyi to waye  ni gbogan International Conference
pẹlu orin, lórí ohun èlò orin olókùn mẹ́wàá,ati hapu.
eyi ti  Alhaji Umaru Dembo, dari rẹ.
Oríṣun àwòrán, @others Kini BBC ri nile iwosan LUTH?
Amọ a gbọ pe ori ko gomina naa yọ.
O dára gan-an ni, olólùfẹ́ mi,ẹwà rẹ pọ̀.
Iwọde End SARS bẹrẹ lati pe fun opin si ẹka ileeṣẹ ọlọpa to n ri si iwa idigunjale, SARS, lori iwa aṣemaṣe ti wọn n wu ati bi wọn ṣe n tẹ oju ẹtọ awọn eeyan mọlẹ.
Èmi kò forí ṣọta ìjàmbá ọkọ̀ òfúrufú kankan - Obasanjo Aṣọ ń pe aṣọ ránṣẹ́ ni lásìkò ìbúra gómìnà àti ààrẹ Ìtàn ayé Seyi Makinde, gómìnà tuntun ní Ọ̀yọ́ Èèyàn 5 farapa, ọ̀pọ̀ ọkọ̀ jóná nínú ìjàmbá iná márosẹ̀ Ibadan sí Eko O ṣe alaye wi pe, ko bojumu ki awọn obi maa lakaka ki wọn to ri owo san fun awọn ọmọ wọn to n bẹ nile ẹkọ girama to jẹ ti ijọba.
O gba pe  wiwa eka irinajo afe ninu ajo isokan agbaye yoo pese iranlowo to ye fun Naijiria pelu ise ti won n se po pelu awon eka to ku.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Dino gba àgọ́ Ọlọ́pàá ré sílé ìwòsàn 4 Sẹ́rẹ́ 2019 Àkọlé àwòrán, Dino Melaye Sẹnetọ Dino Melaye tó ṣẹṣẹ yọju si agọ Ọlọpáà lati yọju si ọga agba awn ọlọpaa ti di ero ile iwosan.
 ilé atóbatélè : Ìwàdìí fi yé mi pé enití ó pilèsè ìlè yìí eni pàtàkì àti alákíkanjú tí ìsesí àti ìhùwàsí rè láàrin àwùjo fi ara jot í oba ìlú .
Láti ibẹ̀ ààlà ilẹ̀ náà gba apá ìhà gúsù, ní ọ̀nà Lusi, kọjá lọ sí ara òkè, (Lusi ni wọ́n ń pè ní Bẹtẹli tẹ́lẹ̀) ààlà náà tún yípo lọ sí apá ìsàlẹ̀, sí ọ̀nà Atarotu Adari, sí orí òkè tí ó wà ní apá ìhà gúsù, ni ìsàlẹ̀ Beti Horoni.
Awọn iròyìn mìíran tí ẹ lè nífẹ̀ẹ́ si: ‘Ọ̀mọ́ ọdún 15 ló yẹge jùlọ ní ìdánwò JAMB’ Jamb ni kawọn akẹkọ duro de esi idanwo JAMB f'ọjọ kun asiko iforukosilẹ Àwọn akẹ́ẹ̀kọ́bìnrin fakọyọ ju akẹ́kọkùnrin ní'dánwò WAEC Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí 3 sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 2:23 Fídíò, Water Generator: Ó leè ṣiṣẹ fún wákàtí mẹfà, kó tó sinmi, Duration 2,2310 Òkùdu 2020 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
Abba Kyari: Àwọn ojúṣe olórí àwọn òṣìṣẹ́ fún ààrẹ Nàìjíríà
Ki wọn gbe oku rẹ wa ki wọn si gbe sin o ya ju kin ma le ri lọ.
O wa rọ awọn araalu lati mase tabuku awọn ileewe tawọn ijọ ẹlẹsin da silẹ pe owo wọn ti wọn ju, o ni ọbẹ to dun, owo lo paa, bẹẹ si ni ọpọ awọn ileewe ẹlẹsin naa lo n se iranwọ ẹkọ ọfẹ fun awọn ọmọ alaini.
silẹ fun eto idibo lọjọ Abamẹta lati yan aarẹ tuntun ati awon ti yoo soju fun
Ìròyìn náà ní, lásíkò tí ìjókòó ilé ń lọ lọ́wọ́, lawọn jàǹdùkùú yìí ya wọnú ilé, tí wọn sì gbé ọ̀pá àsẹ ilé.
2018 nile ise naa ,iba maa ti se e se, ti ko ba si awon omo ogun ofurufu
Mo sì sọ fún àwọn ọlọ́lá ati àwọn ìjòyè ati àwọn eniyan yòókù pé, “Iṣẹ́ náà pọ̀ gan-an, odi yìí sì gùn tóbẹ́ẹ̀ tí ó mú kí á jìnnà sí ara wa.
"Ìdáhùn nìyíì Ẹ wo bí ẹ ṣe lè ṣe ""hand sanitizer"" nínú ilé yín láàrín ìṣẹ́jú díẹ̀ Coronavirus: Àwọn ohun tí a kò tíì mọ̀ nípa àrùn Covid-19 Bawo ni nnkan ṣe ri lorilẹede Amẹrika lapapọ?"
Pupọ awọn to n ko ero oludibo jọ ti ṣe atunṣe aṣiṣe yi bayi.
Ṣé ẹ kò sì tíì gba ẹ̀rí wọn, pé,
"Lara awọn isẹ ti Tolani Alli ti se tẹlẹ ri ni "" Code Girl Magic"" eyi o se ni osu kankanla, ọdun 2018."
Níbo lórí n gbé Zlatan Ibrahimovic lọ nínú ìrìnàjò eré bọ́ọ̀lù
Magun Majẹ-ibẹpẹ: Ọkunrin to ba ba obinrin ti wọn ba le iru Magun yii si lara laṣepọ, yoo maa pongbẹ lati jẹ ibẹpẹ ni.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Àbá ìsúná N1.
"Iku Ajimọbi jẹ́ ǹkan ìjayà nítori kò só sí ẹnìkan tó ń reti irúẹ̀ lásìkò yii"" Mí ò tíí ní ìpinnu lóri ìdíje ààrẹ ọdún 2023 Yàtọ̀ sí coronavirus, wo ìgbà mẹ́wàá míì táwọn mùsùlùmí kò lè ṣiṣẹ́ Hajj Wo àwọn èèyaǹ jàǹkàn mérin tí àrùn Coronavirus ti sọ dèrò ọ̀run ní Naijiria Nínú ọ̀rọ̀ rẹ̀ ó ní : Sí gbogbo ẹyin ti ẹ ti n kù pé ìgbésẹ̀ ààrẹ Buhari àti ìpáde àwọn ìgbìmọ tuntun nínú ẹgbẹ́ òṣèlú APC ṣe ṣe fi òpin sí ìpínnu mí láti di ààrẹ lọ́dún 2023, ó ṣe mi láànú fún yín"" ""Ènìyan ẹlẹ́ràn ara lásán ni mí tí kò sì ni oye ọjọ́ iwájú tàbí ọgbọ́n òṣèlú tí ẹ ń fi ẹnu jẹ́ pé ní, ẹ tí n yọ ayọ lórí ikú ìpínnu ìjákulẹ oyé ààrẹ tí kò ti wáye rárá."
Osinbajọ: Ọlọrun ṣetán láti mú Nàìjíríà d'élẹ̀ ìlérí, TUC ní Nàìjíríà ti kùnà lẹ́ni ọdún 59 Irọ́ ni, mi ò sọ pé mọ fẹ di Ààrẹ ní 2023- Tunde Bakare Ẹ wo ìyá ẹni ọdún 81 tó sẹ̀sẹ̀ parì ilé iwé alákọ̀bẹ̀rẹ̀!
Lẹ́yìn náà, ó to igi sórí pẹpẹ, ó gé akọ mààlúù náà sí wẹ́wẹ́, ó sì tò wọ́n sórí igi.
Nibayii, ẹ jẹ ka wọ awọn igbesẹ ti Ile Aṣofin Ipinlẹ Ondo gbọdọ tẹle lati yọ Agboola Ajayi ni ipo, gẹgẹ bi ofin Naijiria se laa kalẹ.
Agbẹnusọ fun ajọ WAEC ni akẹkọọ to ba tẹ le awọn iwe idanwo yii yoo fidi rẹmi ninu idanwo ọhun.
Apapọ awọn to ti ni arun naa kaaakiri orilẹ-ede Naijiria ti wa di 15,682 bayii.
Ìlé iṣẹ ti kẹde láti gba àwọn òṣiṣẹ ẹgbẹrún lónà ogójì tí yóò maa ṣe ọlọpàá àdúgbò tí àwọn ọmọ Nàìjíríà tí ń pè fún kí ọrọ ètò ààbò òrílẹ-èdè yìí tó dé ibi ti ó de dúró yìí.
orin ni èso àṣà ìsẹ ̀ ǹbáyé àti ìtàn àwùjọ ènìyàn .
Ìdí tí mo fi ń ṣe ayẹyẹ ọjọ́ ìbí 35 lọ́dọọdún rèé- Allwell Ademola Wo ojú Akeem t'Ọlọ́pàá mú pé ó fipá bá ọ̀dọ́mọbìnrin kan sùn létí odò l'Oṣun Yàtọ̀ sí Eko, wo ohun t'áwọn ìpínlẹ̀ meje míràn ń sọ nípa ìwọlé àwọn akẹ́kọ̀ọ́ Iléẹjọ gíga jùlọ da ẹjọ́ SDP àti PDP nù, wọ́n ní Yahaya Bello ló wọlé ìbò gómìnà Kogi Ìjọba Ghana ṣí iléeṣẹ́ àwọn ọmọ Nàìjíríà padà.
Ọgbẹni Teixeria ti kii ṣe onimọ iṣegun ni wọn ti ṣaaju ni ko san owo itanran ti o si ṣẹwọn tori pe o n ṣe itọju awọn eeyan lai ni iwe aṣẹ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Collapsed Building: Ayálégbé ló dára bí ìjọba ṣe wólé àmọ́ wọ́n fẹ́ ìrànwọ́ ilé míràn O ni bakan naa lawọn ni ki wọn lọ gbe ounjẹ́ wa fun.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ooni Adeyeye Ogunwusi: Fani-Kayode ní ìwà àbùkù Tinubu yìí ta bá gbogbo ọmọ Oodua 10 Owewe 2020 Oríṣun àwòrán, Others Awuyewuye to n waye lori ikinni laarin Ọọni tilu Ile Ifẹ, Ọba Adeyeye Enitan Ogunwusi ati asaaju ẹgbẹ oselu APC, Asiwaju Bola Ahmed Tinubu, si n tẹsiwaju lori ayelujara.
Ó dájú pé a jí àwọn òkú dìde nítorí ohun tí Mose kọ ninu ìtàn ìgbẹ́ tí ń jóná, nígbà tí ó sọ pé, ‘Oluwa Ọlọrun Abrahamu, Ọlọrun Isaaki, ati Ọlọrun ti Jakọbu.
Ní ìgbà àtijó, Oba olórò kan wà, ó ní oko beere, ó ní ilé nlá púpò, ó ní orò jántirere bákannáà ni erú rè kò mo níwòn.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Obìnrin tí kò bá rẹwà ló ń ṣí ara sílẹ̀ - Ṣọla Allyson Kí lo fẹ́ mọ̀ nípa D.
Idanwò WAEC ni ọdun 2019 fi han pé nínú àwọn ọmọ to dín díẹ̀ ńi ẹgbẹ̀run mejilà to kọ ìdánwo náà, agbara káká ni a fi ri eniyan ẹgbẹ̀run mẹta to gba àmì Krediiti marun to si ni Isiro àti èdè Gẹẹsi nínú.
Ní alẹ́ ọjọ́ Satide, a péjọ láti jẹun; Paulu wá ń bá àwọn onigbagbọ sọ̀rọ̀.
 kàkà kí ó lọ , ó lọ sí ayẹyẹ ní ilé Ìturà orilẹ ̀ èdè wọn , ní ibi tí àwọn ológun ti 142nd indiana infantry ti ṣe àfikalẹ ̀ gómìnà oliver morton pẹ ̀ lú àsíá ogun ìṣọ ̀ kan .
" 'Dokita ilé ìwòsàn ló gba ẹsẹ̀ lọ́wọ́ mi' Dánáfojúrà nìyí, abàmì eégún tí ń gbé inú iná ṣọlá Baba Latin ṣe bẹbẹ lori èto Se o láya, sùgbọ́n.
Kọmiṣọnna fun ile iṣẹ idagbasoke awujọ Deborah Bose Aremu ni gomina yan kọmiṣọnna fun ile iṣẹ to n ri si idagbasoke awujọ ni ipinlẹ Kwara.
“Kò gbọdọ̀ gé irun orí rẹ̀ tabi kí ó fá a títí tí ọjọ́ tí ó fi ya ara rẹ̀ sọ́tọ̀ fún OLUWA yóo fi pé, kí ó jẹ́ mímọ́, kí ó sì jẹ́ kí ìdì irun orí rẹ̀ máa dàgbà.
Inu rirun ati inira ni isalẹ ikun Oríṣun àwòrán, other Àkọlé àwòrán, Aworan oyun iju Kindinrin obinrin naa yoo wu, tabi ki inu rẹ kún Inira lasiko ti obinrin ba ṣẹṣẹ loyun Obinrin naa yoo ma a tọ loorekoore, inira lasiko to ba n tọ tabi ṣe igbọnsẹ.
Ẹ óo wá mọ̀ pé èmi ni OLUWA Ọlọrun.
Lẹyin iku Barbara, Wole fẹ ara orilẹ-ede Naijiria mọ Liberia, Olaide Idowu lọdun 1963.
Ní ọdun 2018 ọfíísì agbẹjọrò àgbà fún ìpínlẹ̀ California fí àbájade ìwádìí kan nípa òṣìṣẹ́ ilé iṣẹ́ mọ́tò kan to ń sún oorun wákàti mẹ́ta lójòòjúmọ lẹ́nu iṣẹ́ sita.
Oríṣun àwòrán, Oluwo Igbimọ kan ti igbimọ lọbalọba naa gbe kalẹ, eyi ti Ọrangun ile Ila, Ọba Wahab Adedọtun ko sodi, lati sewadi awọn isẹlẹ to nii se pẹlu Oluwo, gbe abọ wọn kalẹ lọjọ Ẹti.
OLUWA Ọlọrun wa bá wa dá majẹmu kan ní òkè Horebu.
 ni ọdun 2006 , matthew w.
Adisa pari ọrọ rẹ pe ijọba ti kọwe ranṣẹ si awọn olori ile iwe lori igbesẹ to yẹ ki wọn gbe, ṣugbọn ti wọn ba kọ lati tẹle awọn igbesẹ yii, ko ni si aye lati ṣi irufẹ ile iwe bẹẹ.
O gbadura wi pe arun naa yoo kaṣẹ̀ nilẹ ni kia, ki awọn eniyan ma ba a ni idiwọ idena pipa jijade ati iwọle si awọn ibi adura.
ipade ti o se pelu igbakeji aare Yemi Osinbajo 
Ẹni to ba bori ninu idije Big Brother Naija ti ọdun yii fi biliọnu marundinlaadọrun fi ṣe ara rindin.
Lọwọlọwọ, ẹgbẹ agbabọọlu Madagascar lo wa ni oke tente atẹ igbelewọn ninu idije Afcon 2019.
Mo lè fún ọ tí ó bá dá ọ lójú pé àwọn ọkunrin tí wọ́n wà pẹlu rẹ ti pa ara wọn mọ́, tí wọn kò sì bá obinrin lòpọ̀.
Gomina Akeredolu parọwa si awọn eeyan ilu lati fi ọwọ sowọpọ pẹlu ijọba ati awọn agbofinro, lati le wa ojutu si awọn ipenija to n ba eto aabo wọya ija.
Ẹ jẹ ki a yẹ ẹ wo.
Nígbà tí Pilatu gbọ́ gbolohun yìí, ẹ̀rù túbọ̀ bà á.
Lẹyin ifilọlẹ naa ni wọn wa pe orukọ rẹ ni Iwe Irohin""."
"Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Á rọ̀ wá lọ́rún tí wọ́n bá lè ṣí ibodè Lekki lọ̀fẹ̀ẹ́ láàrọ̀' ""O yẹ ko ye wọn pe eṣinṣin wọn n jẹ elegbo bayii ni imura silẹ fun igba ti elegbo pẹlu yoo yiju pada lati jẹ eṣinṣin"" ""Ki ẹnikẹni maa da wa lẹbi o nigba ti a ba bẹrẹ tiwa."
Eyi ni ọna ti o lee gba daabo bo ara rẹ atawọn miran lọwọ arun Coronavirus: Maa fọ ọwọ rẹ loorekoore pẹlu ọṣẹ ati omi to mọ gaara: Oríṣun àwòrán, Getty Images Rii daju pe o n fọ ọwọ rẹ loorekoore pẹlu ọṣẹ ifọwọ ati omi to mọ.
Àjẹsára àrùn ìta jẹ ́ àjẹsára tó ní agbára púpọ ̀ láti dènà àrùn ìta .
Ṣafani jíṣẹ́ ọba fún Hilikaya; Hilikaya olórí alufaa, sì sọ fún un pé òun ti rí ìwé òfin ninu ilé OLUWA.
Àwọn wolii wọn ń tàn wọ́n, wọ́n ń ríran irọ́, wọ́n ń woṣẹ́ èké.
Lẹ́yìn náà wọ́n bèèrè fún ọba; Ọlọrun bá fún wọn ní Saulu ọmọ Kiṣi, láti inú ẹ̀yà Bẹnjamini.
 Ọbalùfọ ̀ n aláyémọrẹ yìí jẹ ́ ọmọ Ọbàlùfọ ̀ n ogbógbódirin tí í ṣe àkọ ́ bí odùduwà tí ó jẹ ́ Ọọ ̀ ni ti ilé-ifẹ ̀ ni àkókó ìgbà kan .
O gba awọn oṣiṣẹ FRSC kaakiri Naijiria nimọran lati maa fi ootọ inu ṣiṣẹ bii ti awọn ọmọ abẹ oun.
Oríṣun àwòrán, Joshua Paul for the BBC Àkọlé àwòrán, Nenney Shushaidah ati awọn oṣiṣe ile ẹjọ rẹ.
asoju  ati ile igbimo asofin lapapọ.
awon osise ku ayẹyẹ ayajọ ọdun awon osise ti odun 2019 yii, ni eyi ti oluranlọwọ
“Bí o bá gbọ́ ti OLUWA Ọlọrun rẹ, tí o sì farabalẹ̀ pa gbogbo òfin rẹ̀, tí mo ṣe fún ọ lónìí mọ́, OLUWA Ọlọrun rẹ yóo gbé ọ ga ju gbogbo orílẹ̀-èdè yòókù láyé lọ.
ba pa, bi o baa, buu lẹsẹ.
Ni ọjọ Aje ni ijọba ipinlẹ Ekiti kede pe ko saye oyinbo sisọ mọ lawọn ibi eto to ba jẹ abinibi abi ti ibilẹ.
Ajọ to n risi ọrọ oju ọjọ ti ni ọpọlọpọ ipenija lo wa ninu ki orilẹ-ede kọ lati maa lo ike nigba gbogbo lati daabo bo ayika.
Jesu kan náà, tí a mú kúrò lọ́dọ̀ yín, lọ sí ọ̀run yìí, yóo tún pada wá bí ẹ ṣe rí i tí ó ń lọ sí ọ̀run.
Ẹ̀ gbọ́ ọ̀rọ̀ lẹ́nu Adelé Ọba Alade Idanre ló rí ohun tó ṣẹlẹ̀ láàárín òun àti Ọba Aroloye 2) Ọgbẹni Yomi Faparusi: Ẹlomiran to tun n dije fun ipo ninu ijọba apapọ ni Ọgbẹni Yomi Faparusi.
Lẹyin oṣu mẹfa, wọn yi ipẹjọda.
"Obianinwa ni ikọlu naa dawọ duro nigba ti oun pariwo pe ""Gbogbo aye ni yoo mọ pe ile Fada Mbaka ni wọn ti pa awọn."
Aarẹ ni gbogbo ọmọ Naijiria gbọdọ mọ wi pe wọn yoo jiyin ohun gbogbo ti wọn ba ṣe, paapaa awọn to di ipo mu lorilẹede Naijiria.
Ààrẹ Akufo-Addo sọ pé Òun kò ní sati lẹ́yìn òfin fún ìbálòpọ̀ láàárín akọ ṣákọ tàbí abo sábo lásìkò ìṣèjọba òun.
Oríṣun àwòrán, PA Media Ní báyìí wọ́n ti tí orí afára náà pa ti wọ́n si pa ọkùnrin kan to n gún àwọn ènìyàn lẹ́gbẹ̀ẹ́ afárá náà Aàrẹ Trump kọ̀ láti jẹ Tòlótòló ìsìn ìdúpẹ́ 2019 nílé, ó gba Afghanista lọ!
"Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Eégun àti orò, bí wọ́n ṣe jọ bí Ẹ̀ṣà Egúngún nílẹ̀ Yorùba rèé Kabiesi naa tẹsiwaju pe ""aafin Ọba jẹ aafin Ọlọrun nile aye, eyii to n tumọ si Ọlọrun Iwo."
Okoowo naa si ti gbalẹ bayii ni orilẹ-ede Ghana Oríṣun àwòrán, Fellipe Abreu Àkọlé àwòrán, Ọwọ lo n tun ara se.
"Kíni ẹ̀yin rántí nínú ǹkan ti o ti ṣẹlẹ lọ́dun díẹ̀ sẹ́yìn àti nísìnyìí Ilé aṣọ̀fin Nàìjíríà ń gbèrò ẹ̀wọ̀n f'áwọn olùkọ̀ tó bá dẹnu ìfẹ́ kọ akẹ́kọ̀bìnrin Ìṣòro Nàíjíríà kọjá kí Bobrisky àtàwọn ẹlẹgbẹ́ rẹ̀ dá ní ilé ìgbọ̀nsẹ̀ lọ́tọ̀"" Ọdun 2003 ni arakunrin naa ti bẹrẹ si ni yo ọmu ni aya, lẹyin ti o bẹrẹ si ni lo oogun Risperdal to n gbogun ti aisan ‘autism’."
tí kò bá mú ẹran tí yóo fi rú ẹbọ náà wá sí ẹnu ọ̀nà Àgọ́ Àjọ láti fi rúbọ sí OLUWA, a óo yọ ẹni náà kúrò láàrin àwọn eniyan rẹ̀.
Àwọn apànìyàn kórìíra olóòótọ́ inú,wọ́n sì ń wá ọ̀nà láti pa á.
LASEMA Lagos: Ọkọ̀ méjì jóná ráùráú níbi tí ọkọ̀ tó gbé bẹntiróò ti gbiná
Wọ́n bá mú un lọ sí ọ̀dọ̀ rẹ̀.
Bee sini, Bode Abiodun naa tun fagbahan Mohammed Rizal  lati Malaysia pelu ami-ayo (11-5), (11-7),(13-11) ninu ifigagbaga keji re, leyin ti o ti fagbahan Devesh Hukmani torile-ede Belize ninu ifigagbaga akoko pelu ami-ayo (11-5), (11-3), (11-2).
O sọ pe oun ṣetan lati ya ara oun sọtọ fun ọjọ mẹrinla bayii gẹgẹ bi alakalẹ ijọba fawọn to ba ṣeṣẹ rinrin ajo de lati awọn orilẹede mẹtala ti ijọba apapọ fofin de.
Aṣòfin Karimi ni àwọn alágbára kan ni ìjọba ló ń dùn mọ̀huru mọ́ Dino nitori iha tó ń kọ sí ìjọba.
Nítorí ohun tí eniyan lè mọ̀ nípa Ọlọrun ti hàn sí wọn, Ọlọrun ni ó ti fihàn wọ́n.
pelu gomina fun ilosiwaju ati idagbasoke Ipinle Oyo.
Iroyin naa ni isẹlẹ ọhun waye ni agbegbe ti ko jinna si ileekọ fasiti Ambrose Ali ni ilu Ekpoma.
Blessing ni aṣiṣe nla lawọn to n sọ pe oun ju idi kiri ki awọn aye le maa sọrọ ṣe nitori iṣu Ọlọrun ti ko ṣe fọwọ bo ni ikebe naa jẹ foun.
"Mo ri, o wu mi, a si ṣe igbeyawo laarin ọsẹ mẹta.
Ohùn rẹ̀ dàbí híhó omi òkun.
Ni ijoko ipade naa to waye kẹyin, n ṣe ni ọgagun to n ṣoju ileeṣẹ ologun niwaju igbimọ naa ṣalaye pe, awọn ko yinbọn pa oluwọde kankan ni Lekki.
Oríṣun àwòrán, @GEJonathan Jonathan ni orilẹede yii ti yapa to bẹẹ gẹ, debi pe taa ba tete pana rẹ, ọpọ ẹmi ni yoo ba rin, to si seese ki ọpọ eeyan sa kuro nilẹ yii.
Ẹni ọdun mẹrindinlaadọta ni nigba to jade laye ni ọjọ Iṣẹgun, ọjọ Karundinlogun oṣu Karun ọdun 2018 ni ilu Toronto.
Bí irun ọ̀gangan ibẹ̀ bá funfun, tí ó sì jìn ju awọ ara rẹ̀ lọ, àrùn ẹ̀tẹ̀ ni; ẹ̀tẹ̀ ni ó jẹ jáde níbi tí iná ti jó olúwarẹ̀.
 Sẹnatọ Ike Ekweremadu, igbakeji aarẹ ile asofin agba lorilẹede Naijiria."
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Theresa May ni ijọba oun yoo fún Nàìjíríà ní £70-million láti pèsè isẹ́ MTN, Banki mẹ́rin wọ gàù CBN Ondo, Zamfara ya ọjọ ìsinmi sílẹ fún PVC Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ìjẹ̀bú: Àgbàlàgbà ni mo máa ń ṣe nínú eré tẹ́lẹ̀ Laipe yii, ni Olootu Ilẹ Gẹẹsi naa sọ ni orilẹ-ede South Africa wi pe Naijiria lo ni awọn talaka julọ ni agbaye.
Ẹ wò bóyá ilẹ̀ náà jẹ́ ilẹ̀ ọlọ́ràá tí ó lẹ́tù lójú, ẹ wò ó bóyá igi wà níbẹ̀ tabi kò sí.
Láti Kinereti títí dé Òkun Araba tí wọn ń pè ní Òkun Iyọ̀, ní ẹsẹ̀ òkè Pisiga ní apá ìlà oòrùn.
Sanusi ni ara awon agboolu yii ya gaga , ti won si ti setan lati fagba han akegbe won ninu idije ti orile ede Afirika.
Lagos Beggars: Bí wọ́n ṣe jí ọmọ yìí gbé láti máa fi ṣiṣẹ́ bárà l'Eko
Ojuṣaaju kò dára,sibẹ oúnjẹ lè mú kí eniyan ṣe ohun tí kò tọ́.
Aare tun so pe “Ki i se dandan ki o je omo oloogun, ki o to je olooto eniyan.
Kẹ̀kẹ́ ogun ati àwọn ẹlẹ́ṣin bá a lọ pẹlu, àwọn eniyan náà pọ̀ lọpọlọpọ.
Ile itaja Walmart kan to wa ni Cielo Vista Mall lẹgbẹ ibode ilẹ Amerika ati Mexico lo ti ṣẹlẹ.
Àwọn ọmọ Sakai jẹ́ ẹẹdẹgbẹrin ó lé ọgọta (760)
Àwọn wo gan an ló wà nínú bàálù Ethiopia tó já ni Nairobi?
Àkọlé àwòrán, Àwọn adarí orílẹ̀èdè Amọ, Ọjọgbọn Akin Oyebode wa fikun wipe oseese ki wiwa ti awọn adari Ilẹ Europe yii n wa si Naijiria o fi agbara fun Aarẹ Muhammadu Buhari saaju idibo gbogboogbo ọdun 2019.
Ijakulẹ ọrọ aje Naijiria di dandan Onimọ kan nipa eto ọrọ aje ọmọwe Chijioke Ekechukwu ni iru nkan bayi ko ṣẹṣẹ ma ṣẹlẹ.
Kàkà bẹ́ẹ̀ kí á kọ ìwé sí wọn pé kí wọ́n takété sí ohunkohun tí ó bá ti di àìmọ́ nítorí pé a ti fi rúbọ sí oriṣa; kí wọn má ṣe àgbèrè, kí wọn má jẹ ẹran tí a lọ́ lọ́rùn pa, kí wọn má sì jẹ ẹ̀jẹ̀.
Yóo ti pẹ́ tó, tí ilẹ̀ náà yóo máa ṣọ̀fọ̀,tí koríko oko yóo rọ?
pelu awon akoroyin: “Oni yii je ojo ti mi o lero pe yoo
“Ẹ ti tún gbọ́ tí a sọ fún àwọn baba-ńlá wa pé, ‘Ìwọ kò gbọdọ̀ fi ìbúra jẹ́jẹ̀ẹ́ láì mú un ṣẹ.
Fada Anselm ni òògùn ìbílẹ̀ náà lo dára julọ fún ìwòsàn àrùn Coronavirus, tá sì tún leè pèsè òògùn naa ni irọrun ni abẹle, ká sì pín kàkàkí.
Owe yii lo ṣalaye gẹlẹ bí awọn alagbatọ ninu fọnran yii ṣe ṣalaye bi awọn naa ṣe jẹ eeyan ti Ọlọrun da bii ẹlomiiran ṣugbọn ti awọn to gba wọn si iṣẹ maa n saba yi ero pada nipa wọn.
 Ọdún kan ni ó kù kí ó jáde .
Oríṣun àwòrán, Nigeriagalleria Àkọlé àwòrán, Lalong ni ọkan lara awọn ẹkun to wa ni ọgba naa ku ni ọdun meji sẹyin.
Ọmọ Ààrẹ lẹ́tọ̀ọ́ láti ṣe ìgbéyàwó yálà àwọn ará ìlú fẹ́ràn ìjọba bàbá rẹ̀ tàbí bẹ́ẹ̀ kọ́ - Aisha Buhari Ó yẹ kí Buhari dá owó epo padà sí ₦97 tàbí kó kọ̀wé fipò sílẹ̀ - Àwọn akẹ́kọ̀ọ́ Owó lítà epo ní Nàíjíríà ló kéré jùlọ l‘Áfíríkà - Lai Muhammed Ìjà ẹgbẹ́ òṣèré TAMPAN àti ANTP ni kò jẹ́ kí wọ́n pe Baba Legba sínú eré mọ́, kó tó kú - Owolabi Ajasa Wo ọ̀nà ìsanwó tuntun fún àwọn oníbárà iná mọ̀nàmọ́ná ní Eko (EKDC) Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Nigeria-China Loan: Afenifere korò ojú sí ìjọba Buhari, bó ṣe ń yáwó kiri1 Ògún 2020 6:30 Fídíò, Akomolede ati Aṣa lori BBC: Mọ̀ si nípa oríṣìí ẹ̀ka ìsọ̀rí ọ̀rọ̀ àti ìwúlò wọn, Duration 6,308 Owewe 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Awọn ọtẹlẹmuyẹ ṣi n wadii bi iṣẹlẹ mejeji naa ṣe so pọ mọ ara wọn.
Oríṣun àwòrán, Wumi toriola Amọ laipẹ yii la gbọ pe ija ti tan, ogun si ti dopin laarin Toyin Abraham ati Wunmi Toriola, bẹẹ ni Wunmi gan fi idi ọrọ naa mulẹ ninu ifọrọwerọ kan to ṣe laipẹ yii.
Fi ewé hisopu fọ̀ mí, n óo sì mọ́;wẹ̀ mí, n óo sì funfun ju ẹ̀gbọ̀n òwú lọ.
Igbakeji aare lorile ede Naijiria lo soro yii nigba to n se abewo olojo meji si awon atipo ti won awon eniyan ti ijamba kolu si wa  ni ipinle Benue.
Bakan naa, ẹgbẹ agbabọọlu Liverpool sọrọ loju opo Twitter pe, ikọ naa ti gbiyanju ni saa ohun kohun to wu ko ṣẹlẹ lonii Man City yoo di ikọ agbabọọlu akọkọ ti yoo gba ife ẹyẹ Premier League lera wọn laarin ọdun mẹwaa sẹyin ti wọn ba gba ife naa mọ Liverpool lọwọ lonii.
Ọjọ kẹrinlelogun, oṣu Kẹta, ọdun 2020, ni ajọ to n mojuto itankalẹ aarun ni Naijiria, NCDC, kede pe Kyari ni Covid-19.
Ìjọba Alaafia OLUWA Tí Ó Kárí Ayé.
 eto ayeye ọdun naa ni won pe ni ‘ ọgọ́rùn ún odun
Ogbeni Akufo-Addo  salaye ipa Pataki to wa laarin orile ede  Ghana ati Jamaica , nipa ibasepo to monyan
Wo ewu tó rọ̀ mọ́ tí o kò bá bẹ̀rẹ̀ sí ní jẹ oúnjẹ́ aṣaralóòre lẹ́yìn ti oyún ti dúró sí ọ lára
Unilag VC: Folasade Ogunsola ni obìnrin àkọ́kọ́ tó jẹ ọ̀gá àgbà fún ibùdó ẹ̀kọ́ṣẹ́ ìṣègùn Fáṣítì Eko
Koda, aisan yii wọpọ ni Naijiria, paapa laarin awọn ọmọde, ti ajọ Unicef si ti kede pe orilẹede Naijiria wa lara awọn ti aisan naa ti wọpọ lagbaye.
Eyi si waye labẹ iṣakoso Aarẹ Olusegun Obasanjo.
Kí ni ẹ fẹ́ fi ọjọ́ OLUWA ṣe?
Eyi ni awọn diẹ lara iṣẹlẹ to sọ gbajugbaja akọrin naa di oriṣa akunlẹbọ lọdun 2019.
Pásítọ̀ fẹsẹ̀ fẹ lẹ́yìn tọ́mọ ijọ rì sọ́mi Ọmọ ọdun méje gbé bàbá rẹ̀ lọ àgọ́ ọlọ́pàá Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí kan sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
Oríṣun àwòrán, Google Lo ba n rọ lu oniruuru isẹ lati lee bọ ilé sugbọn lọdun 2002, gbajugbaja olorin àti adari orin Steve Rhodes, ṣàwárí rẹ o si wu u jade pada eyi to mu un bẹ̀rẹ̀ si ni ṣíṣe pẹlu Tony Allen.
Ìyà n bọ̀ fọ́mọ tí kò gbọ́n, ẹkún n bẹ fọ́mọ tó n sá kiri
Láàrin rẹ̀ ni ìlú yóo wà.
Oríṣun àwòrán, Facebook/Grace Adejoh Àkọlé àwòrán, Obinrin kan soso to wa lara awon oludije Ibrahim Wada to ti jẹ Gomina tẹlẹri jẹ ẹya Igala lati Dekina ti o si fidirẹmi lọwọ Abubakar Audu ẹgbẹ PDP ninu idibo gomina to kọja.
Ó kó àwọn kan sí àwọn ìlú tí ó kó kẹ̀kẹ́ ogun rẹ̀ sí, ó kó ìyókù sí Jerusalẹmu, níbi tí ọba ń gbé.
47 billionpelu aseyori ti o je 4,774.
"Baba ṣe apẹlrẹ ilu ile ifẹ nigba ti awọn ijoye Ọọni ba fẹ kii, wọn a ni ""eku a jiṣẹ, ẹja a jiṣẹ, ẹran a jiṣẹ, owo a jiṣẹ"" Riran ni wọn n ran awọn nnkan wọnyii ni iṣẹ gẹgẹ bi iwure ni."
tabi owo lowo lati fi setoju ara rẹ.
Angelique kidjo pe fun anfani f'awọn obinrin Obinrin kan rèé tó borí ogun Gẹ̀ẹ́sì Kíni ìdí ti wọn fi ń lọ ọmú obinrin Ọlọpa kan yinbọn mọ ọga rẹ nitori obinrin Iwadii fihan pe irufẹ sitaili irun ti awọn ọdọmọbinrin wọnyii ba ṣe ni yoo fihan boya wọn n wa ọkọ tabi bẹẹ kọ.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Chelsea ni tirẹ ta ọmi pẹlu Eintranct frankfurt ni orilẹede Germany Chelsea, ni tirẹ, ta ọmi pẹlu Eintranct frankfurt ni orilẹede Germany.
Ileẹjọ f'ofin de ṣiṣe ọdun oro laigba'ṣẹ nipinlẹ Ogun
Saaju eyi ,ni awon asofin inu egbe oselu APC ti koko fenuko lati yan Ahmad gege bi abenugan won .
Olorì Anu Adeyemi ń ṣe ọjọ ìbí, ẹ gbọ́ ǹkan tò sọ sí Kábíyésì Òṣèré tíátà míì ń ṣàìsàn láti ọdún kẹta, ó bẹ̀bẹ̀ f'ówó Nàìjíríà kò ní olórí, ẹ pín sí ẹlẹ́kùnjẹkùn - Soyinka Nǹkan oṣù obìnrin le jáde ní imú tàbí ìdodo yàtọ̀ sí ojú ara - Dókítà Oluwo bẹ Ìjọba àpapọ̀ láti ṣe òfin tí yóò mú àdínkù ba ìwà ìfipá báni lòpọ Onírù tuntun Oba Abdulwasiu Gbolahan Lawal gba ọ̀pá àṣẹ Ẹwẹ, sisa ipa ara ẹni ko yọ awọn oṣerebinrin Yollywood silẹ gẹgẹ bi wọn ṣe tu sita loju opo ayelujara wọn lọkọọkan pẹlu fidio, ọrọ, aworan ati bẹẹ bẹẹ lọ lati lodi si iwa ipa naa.
Oríṣun àwòrán, @BashirAhmaad Dogara ni adari ile igbimọ aṣoju-ṣofin nigba naa.
Ese Oruru: Arákùnrin tó jí Ese Oruru gbé gba ìdájọ́ ẹ̀wọ̀n ọdún mẹ́rìndínlọ́gbọ̀n
Dìde, ìwọ afẹ́fẹ́ ìhà àríwá,máa bọ̀, ìwọ afẹ́fẹ́ ìhà gúsù!
Ahmadu Bello ja fitafita lati ri i pe Naijiria gba ominira lọwọ oyinbo alawọ funfun leẹyin to pada de lati orilẹ-ede Gẹẹsi.
Kò pẹ́ pupọ ni Boasi náà dé láti Bẹtilẹhẹmu.
Mo rántí wí pé mo ṣe ìlérí kan fún-un yín láìpẹ́ ọjọ́.
Abegunde ni oun gbero pe ki awọn eniyan le ri sinima wo lasiko ajakalẹ arun Coronavirus yii, ti ipinlẹ Eko si ti gba ki awọn eniyan ma a jade lo si ibi ise.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Chloroquine for coronavirus: Àjọ NAFDAC fọwọ́ sí pípo ògùn chloroquine fún àyẹ̀wò ìtọ́jú coronavirus ní Nàìjíríà 30 Ẹrẹ̀nà 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 31 Ẹrẹ̀nà 2020 Oríṣun àwòrán, Getty Images Ajọ to n mojuto ṣiṣe, lilo ati tita ogun oyinbo ni Naijiria, NAFDAC, ti fun ileeṣẹ apoogun oyinbo kan ni aṣẹ lati ṣe ogun Chloroquine fun itọju coronavirus.
Ojogbon Osinbajo ni o soro yii nilu Abuja lojo-isegun  pe, erongba akotun ifilole ohun ni lati mu igberu ba eto oro-aje, ati lati ri daju pe, orile-ede Nigeria tesiwaju ninu erongba ati seto oro-aje ifiga-gbaga.
Omi náà ń ṣàn láti apá gúsù ibi ìlẹ̀kùn àbájáde tí ó wà ni ìhà gúsù pẹpẹ ìrúbọ.
Nitori bi ọmọ kekere kan, Gold Kolawole se dede poora ni Sọọṣi Wolii yii ni Akure ninu oṣu kọkanla ọdun 2019 ni ẹjọ ti wọn ṣi wa lori rẹ bayii.
 abuja ni olúìlú rẹ ̀ .
Ibi tí mo tí ń simi yìí ní\i mo ti gbé ojú sókè tí mo rí àwọn ẹyẹ ńlá gbogbo ti wọ́n ń fò káà kiri mo sì pa ọ̀kan nínú wọn.
Amọ o jọ bi ẹni pe awọn ọmọ Naijiria n dunnu si ohun to de ba Ghana yi.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù 'Ọmọdé tó fẹ̀ràn sínsín èèyàn jẹ ní Ikorodu ni wá' Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ 'Ọmọdé tó fẹ̀ràn sínsín èèyàn jẹ ní Ikorodu ni wá' 1 Sẹ́rẹ́ 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 7 Sẹ́rẹ́ 2019 Ọpọ ìgbà ni wọn maa n múra bíi obìnrin láti sín wọn jẹ.
Lọwọlọwọ bayii, ajọ ọlọpaa nipinlẹ Ọyọ ti bẹrẹ iṣẹ iwadii lori awọn olubi ẹda to da idile naa loro.
Ọ̀pọ̀ yóo rí i, ẹ̀rù óo bà wọ́n,wọn óo sì gbẹ́kẹ̀lé OLUWA.
46 Àti, kíyèsíi, gbogbo ìyókù iṣẹ́ yìí ní gbogbo àwọn abala ìhìnrere mi nínú, èyí tí àwọn wòlíì mímọ́ mi; bẹ́ẹ̀ni, ati bákannáà àwọn ọmọ ẹ̀hìn mi, ti fẹ́ nínú àdúrà wọn pé kí wọ́n lè jáde wá sí àwọn ènìyàn wọ̀nyìí.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Porn Sites 2019 in Retrospect: Njẹ́ ẹ mọ̀ pé orílẹ̀-èdè Nàìjíríà ló n wo 'Blue film' jù?
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Flood: Ọ̀pọ́ Dúkìá ló sọnù ní 2019 lásìkò tí ìjọba ṣí ’dáàmù Ọyan’ Iṣẹ ilẹ gbígbá, fifọ gọ́tà, didari ọkọ̀, ati oju ọna sise, ni diẹ lara isẹ ti awọn ọdọ naa yoo ṣe fun oṣu mẹta.
ofurufu naa to poora ati awọn to wa ninu rẹ, lojo ọjọru(Wednesday).
 Ti won ko ba ko oko
A kọ òfin gígé nǹkan ọkùnrin tó bá fipá bá obìnrin lòpọ̀ - Àwọn Alfa yarí Ewé ṣunko!
Bí ó ti ń rọbí lọ́wọ́, agbẹ̀bí tí ń gbẹ̀bí rẹ̀ ń dá a lọ́kàn le pé, “Má bẹ̀rù, ọkunrin ni o óo tún bí.
kopa pataki lati lee gbin iresi lopo janturu.
Ṣugbọn ta ni ọ́, ìwọ ọmọ-eniyan, tí o fi ń gbó Ọlọrun lẹ́nu?
Àwón Oníbúrẹ́dì ń gbé ìgbésẹ̀ láti fi kún owó Búrẹ̀dí ní Nàìjírià Ẹgbẹ awọn oniburẹdi ni Naijiria ti apẹjẹ wọn n jẹ Premium Breadmakers Association of Nigeria (PBAN) ati ẹgbẹ awọn alase ti wọn n jẹ Association of Master Bakers and Caterers of Nigeria ti yari fun ijọba Naijiria lori ọwọngogo ohun jijẹ laisko yii.
 wọ ́ n tún tẹnu mọ ́ ọ dáradára pé ibẹ ̀ ni àwọn ti gbé adé ọba wọn wa .
Iya ati ọmọ n ku Ibanujẹ ti dori awọn dokita kan kodo lẹyin ti wọn ri bi awọn obinirin ati ọmọ wọn ṣe dagbere faye laipẹ yii latari bi wọn ko ṣe ri oṣiṣẹ ti yoo ṣetọju wọn nitori pe awọn alaisan pọ ju olutọju lọ nile iwosan Dora Nginza ni Port Elizbeth.
“Bí o bá lè dá mi lóhùn, dáhùn.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Funmi Adewara: Tele Medicine' ní a fi ń ṣàyẹ̀wò èèyàn ìdá ọgọtá láti dènà ìtànkálẹ̀ Covid Lizzy Anjọnrin ti sọ̀rọ̀ lórí ẹ̀sùn pé ìyàwò kẹfa ni nílé ọkọ tó fẹ́ Awuyewuye ko ti i dawọ duro lori ọrọ igbeyawo Lizzy Anjorin.
Ọkan lara wọn, Nkiru Obasi to wa lati ipinlẹ Ebonyi nila oorun guusu lorilẹ-ede Naijiria to n ṣiṣẹ ọmọ ọdọ ni Lebanon.
Ìwọ ọgbà àjàrà Sibima,ọ̀rọ̀ rẹ pa mí lẹ́kún, ju ti Jaseri lọ!
Awọn ile ti laarinlọọdu ba n gbe, ti wọn tun fi n pese awọn ohun eelo lawujọ, ni wọn ti din ida marundinlọgbọn kuro lara owo ori ilẹ wọn, dipo ki wọn san ẹgbẹrun lọna ọgbọn ati okoolelẹẹdẹrin naira (N30,720) tẹlẹ, wọn yoo maa san ẹgbẹrun lọna mẹtalelogun ati ogoji naira (N23,040) bayi lọdọọdun.
nítorí pé mò ń bẹ̀rù ọpọlọpọ eniyan,ẹ̀gàn ìdílé sì ń dẹ́rùbà mí,tóbẹ́ẹ̀ tí mo fi dákẹ́, tí n kò sì jáde síta.
Nígbà tí wọ́n bá ń se ẹran náà lọ́wọ́ lórí iná, 
Lọsẹ yii, ìlú Igbódìgò ni Okiti Pupa nipinlẹ̀ Ondo ni BBC Yoruba ti ri Kayeefi yii o.
Tiwa Savage gba akọrin obirin ti ko lẹlẹgbẹ lẹkun iwọ oorun Afirika pẹlu.
Bí a kò bá jí àwọn òkú dìde, bí wọ́n ti máa ń wí, wọn á ní:“Ẹ jẹ́ kí á máa jẹ, kí á máa mu,nítorí ọ̀la ni a óo kú.
Ni ṣoki, ọrọ yi niṣe pẹlu ẹni ti yoo di aarẹ ilẹ Amẹrika Nibo ni ọrọ yi ti wọwa?
isokan, alaafia ati idagbasoke orile ede Niajiria.
- Ooni Ile Ife Ilé ìgbọ̀nsẹ̀ kan ṣoṣo ni aṣòfin mẹ́rin ń pín lò!
Ẹgbẹẹgbẹrun ọmọ ni aisan naa sọ di arọ ni orilẹ-ede Naijiria, ati kaakiri ilẹ Africa.
orile-ede France pelu ami mefa si meta(6-3),mefa sookan(6-1).
Iwadii fihan pe, ẹlẹsin Musulumi ni ọkunrin naa, amọ awọn ẹlẹsin ibilẹ wa gbe oku rẹ lẹyin ti iroyin iku rẹ jade sita.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Obateru Akinruntan: Wíwá ohun tá jẹ títí láé ló gbé wa kúrò nílé Ife Kọmisana ọlọpaa ipinlẹ Ogun, Edward Awolowo Ajogun ti wa paṣẹ pe ki wọn ko awọn afurasi naa lọ si ẹka ọtẹlẹmuyẹ ileeṣẹ ọlọpaa.
Ipinlẹ Eko, Gombe ati Plateau, lo wa ni ipo kinni si ipo kẹta ninu esi tuntun naa.
Àkọlé àwòrán, Aarẹ Donald Trump ni ikede yi ko kan awọn Amẹrikato ba n bọ lati Yuroopu Ṣugbọn, o ni igbesẹ naa ko ni kan ilẹ Gẹẹsi nibi ti eeyan ẹtalelọgọtalelenirinwo ti ko aisan naa.
Oríṣun àwòrán, Abdinoor Aden Àkọlé àwòrán, Ọ̀pọ̀lọpọ̀ àwọn eléré ìdárayá ní kò tí ì rí ààyè kúró ní pápákọ̀ òfurufú láti bí ọjọ méjì Bi o tilẹ jẹ wipe, igbimọ to n mojuto idije naa ni Naijiria, to fi mọ gomina ipinlẹ Delata to n gbalejo idije naa, Ifeanyi Okowa, ni gbogbo eto lo ti to fun idije naa lati jẹ ko yọri sirere, sibẹ, ero awọn elere idaraya ati awọn alamojuto to wa lati orilẹede mi i yatọ si ti wọn.
Ọlọrun ba yín sọ̀rọ̀ láti inú iná náà wá, ẹ gbọ́ ohùn rẹ̀, ṣugbọn ẹ kò rí i.
 Iko Super Eagles fagbahan Iceland pelu ami-ayo meji sodo(2-0), ninu ifesewonse keji lojo eti(Friday), eleyi ti o je esi ti o si oju ayo ohun sile fun iko naa lati tun tesiwaju ninu idije ohun.
Awọn ile ti wọn ni o jẹ ti Osinbajo nigba naa ni wọn ka silẹ pe ile oniyara mẹrin ni Victoria Garden City nipinlẹ Eko, ile oni yara mẹta ni Mosley Road, Ikoyi l'Eko, ile oni yara meji ni Redemption Camp lopopona Eko si Ibadan ati ile oni yara meji to latọwọ eto san an diẹ diẹ ni Bedford, England.
Joahasi jẹ́ ẹni ọdún mẹtalelogun nígbà tí ó jọba, ó wà lórí oyè fún oṣù mẹta.
“Nígbà tí OLUWA Ọlọrun yín bá mú kí ilẹ̀ yín pọ̀ sí i gẹ́gẹ́ bí ó ti ṣèlérí fun yín, tí ẹran bá wù yín jẹ, ẹ lè jẹ ẹran dé ibi tí ó bá wù yín.
Oríṣun àwòrán, iyaboojofespris Àkọlé àwòrán, Inu ile naa dun wo loju.
Awọn ẹsun yoku ni kiko dukia jọ pẹlu owo ti wọn ri lọna aitọ ati fifi irufẹ awọn dukia yii pamọ laijẹ ki araye mọ pe awọn lo nii ati bẹẹ bẹẹ lọ.
Ọdọmọkunrin ayaworan ọmọ Naijiria kan, Isaac Oyedele Adedokun to ya aworan aarẹ ilẹ̀ America, Donald Trump ni iroyin nipa rẹ ti lu ayelujara pa.
Ṣugbọn ìwọ wà nítòsí, OLUWA,òtítọ́ sì ni gbogbo òfin rẹ.
Iroyin fi mule pe, awon omo ogun Somalia ti o n lo ipago naa fun olokan-o-jokan igbaradi ni o ta awon ohun elo ija naa sita.
” Arioku bá sọ bí ọ̀rọ̀ ti rí fún un.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Sotitobire: Ọkọ mi kò mọ̀ Jegede PDP rí, kódà kò fa ẹnikẹ́ni kalẹ̀ dípò Akeredolu- Bisola Bi ẹ ko ba gbagbe, igba keji ree ti gomina Sanwoolu yoo yọju si awọn oluwọde koda o tun ba gbe patako soke.
Mo fẹ́ kí Ighalo gba ife pẹ̀lú Manchester United kó tó kúrò lọ́dún 2021- Solskjaer Mò ń ronú láti padà sí ẹgbẹ́ agbábọ́ọ̀lù Nàìjíríà, Super Eagles láìpẹ́- Odion Ighalo Ohun mẹ́wàá pàtàkì tí Ṣẹnetọ Osinowo fi ta yọ Kí ló kàn fún Godwin Obaseki lẹ́yìn tó kúrò lẹ́gbẹ́ òṣèlú APC?
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Baby abandoned on dunmpsite: Mo ti bímọ mẹ́rin tẹ́lẹ̀ fún bàbá méjì nínú òṣí- Dupe Ogbomos Wọ́n a maa hu àwọn ìwà to léwu: Ìwà àwọn ti ayé bá ti sú máa n yí ìwà pada, yóò maa ṣe àwọn nńkan to le kó o sínú ewu.
 nitori idawaloto oloselu ati ede ati aisi okowo to fa isodi awon araalu si iwoorun pakistan , to fa ogun fun ilominira ni 1971 ati idasile orile-ede bangladesh .
''Ikede yatọ si ki ijọba sọ da ofin nipa ki aarẹ Buhari buwọlu iwe ofin pe ko ni si ikọ ọlọpaa SARS mọ ni Niajiria.
re ni nawo sori eto agbe ati asa lojuna ati mu igberu ba igbaye-gbadun awon omo
Ninu ìdílé Haṣumu: Matenai, Matata, ati Sabadi; Elifeleti, Jeremai, Manase, ati Ṣimei.
Ni bi a ṣe n sọrọ yii, ileewosan kan ni ilu Akurẹ ni Ọgbẹni Daniel wa to ti n gba itọju.
Ọpọlọpọ igba lo si ti kọ lẹta si awọn olori ijọba bi gomina ipinlẹ Ekiti, Kayọde Fayẹmi, lasiko ti Fayẹmi ba awọn mẹrindinlogun wi nipinlẹ rẹ, fun pe wọn ko fọwọsowọpọ pẹlu ijọba.
Oluwa Ọlọrun yóo fún un ní ìtẹ́ Dafidi, baba rẹ̀.
 Okonjo-Iweala kawe gboye lati ile-iwe giga onimo ero Massachusetts Institute of Technology, ti o si tun ni iwe eri A.
Yàtọ̀ sí coronavirus, wo ìgbà mẹ́wàá míì táwọn mùsùlùmí kò lè ṣiṣẹ́ Hajj Ọmọ rẹ, Abdulaziz bin Fahad, naa jẹ ọkan lara awọn to yọ kuro nipo gẹgẹ bi igbakeji Gomina.
Egypt, Morocco, Nigeria ati Tunisia ti padanu ninu awọn idije akọkọ wọn.
’ Ọlọrun kì í ṣe Ọlọrun àwọn òkú, Ọlọrun àwọn alààyè ni.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Oba Adedokun Abolarin ti Oke Ila: Ó ya ọ̀pọ̀ tó súnmọ́ mi lẹ́nu bí mo ṣe ń kọ́ A ò ni farapamọ́ fún ará ìlú lórí ìwádìí ọlọ́pàá to pa ènìyàn ni Ekiti Àwọn lánàá, àwọn lónìí bí ẹkún apọkọjẹ, bí a ṣe ń pàkan ní ọ̀kán ń rú ni ọ̀rs àwọn ọlọ́pàá orílẹ̀ -èdè Nàìjíríà.
Ṣugbọn ọmọkunrin kan rí wọn, ó sì sọ fún Absalomu.
Bill Gates ni oludasilẹ ileeṣẹ imọẹro kọmputa Microsoft ti odinwọn ọrọ tirẹ jẹ aadoje biliọnu o din ọdunrun miliọnu dọla, ($127.
Ẹ̀sín tí ẹnikẹ́ni kò ní gbàgbé yóo dé bá wọn títí lae.
Bii ti Rinuola, Temitope naa jẹ ọdọ ti o mu jijafẹtọmọniyan ni ọkunkundun.
Ohun ni afara to gun julọ nipinlẹ Eko to jẹ olu ilu Naijiria tẹlẹ ki wọn to koo lọ si Abuja.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Aarẹ ilẹ Amẹrika ni oun yoo koju agbebọn to pa ọmọ ile-iwe mẹtadinlogun ni Florida.
"Ao mọ nkan to kọlu ọmọkunrin naa.
Orile-ede Ethiopia ti setan lati gbalejo ipade ijiroro laarin akowo agba orile-ede America Rex Tillerson ati minisita fun oro ile-okere lorile-ede Russia Sergei Lavrov.
 Ǹjẹ́ ìwọ ṣe irúfẹ́ ère yìí nígbà èwe rẹ.
 Ile-ise to n ri si ipolongo lorile-ede yii je anfani lopolopo ninu ebun olokan-o-jokan oloogbe ohun.
''Mo le bura pe were kan lo kilọ fun mi lọjọ ti mo fẹ gba pe ẹni to wa lẹyin mi ju mi lọ.
Ni bayii, ọmọbinrin yii wa n fẹ ki ọpọlọpọ ojugba rẹ lati ilẹ Adulawọ naa gbiyanju lati mu ala ati ero wọn ṣẹ bii ti oun.
Mowe ni Favour n gbe pẹlu awọn obi rẹ, Alagba ati iyaafin Dale David Oladele.
Eeyan 47,290 ni apapọ ni arun naa ti fara kan labẹ ayẹwo, nigba ti eeyan 33,609 lapapọ ti ri iwosan gba.
    Báyìí ni Ìnàkí-ìbẹ̀rù n bọ̀ lọ́jọ́ tí à ń wí yìí, òun àti àwọn iwin.
Níṣe ni Lulu dájọ́ ayédèrú ìgbéyàwó, àmọ́ ó fún àwọn ọ̀rẹ́ rẹ̀ ní ojúlówó ìwé ìpè.
Ọkunrin yìí kò fẹ́ alaafia àwọn eniyan wọnyi, àfi ìpalára wọn.
Oni loni n jẹ ẹni a bẹ lọwẹ, ṣaaju, akọnimoọgba ikọ Super Falcons Thomas Dennerby fọwọ sọya pe Naijiria yoo fagba han Cameroon lonii ninu idije ere bọọlu awọn obinrin ilẹ Afirika AWCON to n lọ lọwọ lorilẹede Ghana.
Laarọ kutu owurọ oni ni ọfọ ṣe to mu ẹmi mẹrin dani ti awọn miran wa nile iwosan.
Ó ké sí ọ̀run lókè;ó pe ayé pẹlu láti gbọ́ ìdájọ́ tí yóo ṣe fún àwọn eniyan rẹ̀.
Emi yoo fẹ lati duro ni Italy, ko da fun igba iyoku aye mi."
Àwọn èrò nígboro Eko fẹ́ lu obìnrin kan pa, pé ó mú nǹkan ọmọkùnrin pòórá Olùkọ́ àgbà tó fipá bá ọmọ ọdún 13 lò yóò fojú ba ilé ẹjọ́ ni Benue Ìpéníjà owó jẹ́ ọ̀kan pàtàkì nínú ìṣòro àwá òṣèré- Kemi Lala Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí 2 sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 2:23 Fídíò, Water Generator: Ó leè ṣiṣẹ fún wákàtí mẹfà, kó tó sinmi, Duration 2,2310 Òkùdu 2020 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
Ìkà eniyan tan aládùúgbò rẹ̀,ó darí rẹ̀ lọ sọ́nà tí kò tọ́.
Tọwọ́ tẹsẹ̀ laá fi gba ìrànwọ́ owó ẹ̀kọ́ Almajiri ní ìpinlẹ̀ Oyo- Alága Subeb Buhari kàn ń kọwọ́ bọ̀wé nílẹ̀ òkèèrè kiri ni, a ò rí ipa ní Nàijíríà- Onímọ̀ ọrọ̀-ajé Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Small Doctor: Mo kórira igbó, ọtí àti sìgá nítorí màmá mi lòdì si Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Gbogbo eniyan ayé ni yóo rí i pé orúkọ OLUWA ni wọ́n fi ń pè ọ́, wọn yóo sì máa bẹ̀rù rẹ.
Awọn ẹbi oloogbe ọhun sọ fun awọn akọroyin pe aisan kọ lo pa Blom.
ati Alugbo Comprehensive High School, Egbeda ni ilu Ibadan.
O salaye siwaju pe, igbimo to n sakoso ajo  naa ni agbara lati da awon oludari eka ajo ati awon osise duro ti won ba tapa si ofin.
ati sí àwọn ọba tí wọ́n wà ní àwọn ìlú olókè ti apá ìhà àríwá, ati sí àwọn tí wọ́n wà ní Araba ní ìhà gúsù Kineroti, ati sí àwọn tí wọ́n wà ní ẹsẹ̀ òkè, ati sí àwọn tí wọ́n wà ní Nafoti-dori ní apá ìwọ̀ oòrùn.
Nítorí náà, inú mi yóo ru sí ibí yìí, kò sì ní rọlẹ̀.
    “Ọmọ mi, Ìrìnkèrindò, mo fẹ́ sọ fún ọ lónìí pé ko sí ènìyàn náà nínú ayé yìí tí ó fẹ́ràn ọmọ rẹ̀ ju bí mo ti fẹ́ràn rẹ lọ.
Gbọ̀ngàn Mapo, ọ̀kan lára ibi àmúyangàn n'Ibadan rèé Àgbálùmọ̀, ohun mẹ́fà tó ń ṣe lára tí o kò mọ̀ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, BBC Gov Debates: Ètò ẹ̀kọ́ ọ̀fẹ́ ni àwọn olùdíje yóò ṣe Àkọlé àwòrán, ìfọ̀rọ̀wérọ̀ BBC Yorùbá Bakan naa ṣaaju eto ni wọn wọ inu ibi igbalejo ti gbogbo awọn oludije naa wa ki eto to bẹrẹ lati bere iwoye wọn nipa ipade ifọrọwerọ yii paapaa ti yoo ko atọrẹ ati alatako pọ soju kan naa leyii to jẹ wi pe loriṣiriṣi ọna ni wọn ti fi ọ̀rọ̀ ati iṣe ta ko ara wọn tẹlẹ nitori idibo.
Minista naa ni asoju ijoba apapo lo si Dapchi lojo Bo lati funr a won moju de ibe lati mo ohun to n sele.
 nítorí náà ẹ gbé àga , mo ni ẹ jòkó , kí ẹ gbọ ́ mi gbóhùn ẹnu mi .
Ẹ wá, ẹ jẹ́ kí á jọ́sìn, kí á tẹríba,ẹ jẹ́ kí á kúnlẹ̀ níwájú OLUWA, Ẹlẹ́dàá wa!
Ọpọlọpọ àwọn alufaa ni wọ́n wá, tí wọ́n sì ya ara wọn sí mímọ́.
Ìlú mẹtala ni wọ́n pín fún àwọn ọmọ Geriṣomu ní ìdílé ìdílé lára àwọn ìlú ẹ̀yà Isakari, Aṣeri, Nafutali, ati ìdajì ẹ̀yà Manase, tí wọ́n wà ní ilẹ̀ Baṣani.
Ǹjẹ́ orílẹ̀-èdè kan gbọ́ kí oriṣa kan sọ̀rọ̀ láti ààrin gbùngbùn iná rí, gẹ́gẹ́ bí ẹ ti gbọ́, tí ẹ sì tún wà láàyè?
Àyẹ̀wò DNA ti fẹ́ bẹ̀rẹ̀ fún àwọn àlùfá Kátólíìkì tó bímọ Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Fídíò, Oba Adedokun Abolarin ti Oke Ila: Ó ya ọ̀pọ̀ tó súnmọ́ mi lẹ́nu bí mo ṣe ń kọ́ àwọn akẹ́kọ̀ọ́ pẹ̀lú ipò Ọba23 Bélú 2020 Fídíò, Akomolede ati Aṣa lori BBC:Wo ìrúfẹ́ ìgbeyàwó méje tó wà nílẹ̀ Yorùbá àti ojúṣe Alárinà10 Bélú 2020 Fídíò, The New Pandemic: Kíni àwọn onímọ̀ sáyẹ́ńsì ń sọ nípa rẹ̀?
Iṣẹ́ abẹ láti ya ìbejì tó lẹ̀pọ̀ yọrí sí rere l'Abuja
' Afurasí kan yin Oloruntoba níbọn nítorí èdèàìyedè nílé oní Sharwama Afurasi kan ti ko si ẹni to tii mọ ọ ni wọn fẹsun kan pe o yin ọkunrin kan to n jẹ Kayode Oloruntoba nibọn ni ikun nile oni Shawarma kan lagbegbe Alagbado nipinlẹ Eko.
Ààrẹ Buhari kẹ́dùn pẹ̀lú ẹbí àwọn èèyàn 207 tí wọ́n pa lọ́jọ́ Àjíǹde Àkójọpọ̀ àwòrán ọdún ọdún Àjínde l'Afrika Ẹlẹ́wọ̀n bí ìbejì làǹtì lànti!
"Ẹjọ́ náà ti wà ni ẹ̀ka tó ń ri si ìwà ọ̀daran ní ìpínlẹ̀ Oyo.
 Awon akeeko naa lati ilu Cape Town lo ito lati ile igbonse awon okunrin pelu iyepe ,ti o ni kokoro ninu pelu erongba lati je ki o di bi okuta lailo orun.
N óo rọ òjò yìnyín, iná, ati imí ọjọ́ lé òun, ati àwọn ọmọ ogun rẹ̀, ati ọpọlọpọ eniyan pupọ tí wọ́n wà pẹlu rẹ̀ lórí.
L'ọsẹ to kọja, Giwa ati awọn alatilẹyin rẹ gba iṣakoso ọọfisi ajọ NFF to wa ni ilu Abuja, lẹyin ti ile ẹjọ kan to wa ni ilu Jos, fa igi le esi idibo to gbe Amaju Pinnick wọle gẹgẹ bi aarẹ.
Ọlọ́pàá àti àwọn olùfẹ̀hónúhàn gbéná wojú ara wọn níbi ìwọ́de Revolution Now Ìwọ́de #RevolutionNow forí ṣánpọ́n ní Ibadan, àgbófinró gbàkóso ojú pópó Bẹẹ ba gbagbe, awọn ọmọ ẹgbẹ Shiitee lo ti gun le iwọde alagbara eyi to la ẹmi lọ lati bii ọjọ melo kan, ti wọn si n beere fun itusilẹ asaaju wọn to wa ni ahamọ naa.
Ọgbọ́n ti kọ́lé,ó ti gbé àwọn òpó rẹ̀ mejeeje nàró.
 Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Akomolede ati asa Yoruba: Ẹ wá kọ́ nípa àpòtí ìṣura èdè wa lórí BBC Yorùbá Ọba alaye naa pari ọrọ rẹ pe o yẹ ki awọn ọmọ ilẹ Yoruba ṣe ara wọn ni oṣuṣu ọwọ gẹgẹ bi ọmọ iya kan , ki wọn ma si jẹ ki eto oṣelu oin wọn niya."
Ọdọ oloogbe Sikiru Ayinde Barrister ni Wasiu Ayinde ti bẹrẹ isẹ gẹgẹ bi ẹni to maa n ba ẹgbẹ akọrin rẹ ko irinṣẹ.
Àkọlé àwòrán, Ni ọdun 1930 ni idije ife ẹyẹ agbaye kọkọ waye Àkọlé àwòrán, Orilẹede Uruguay lo kọkọ gbalejo idije yii ni ọdun 1930 Àkọlé àwòrán, Orilẹede Egypt ni orilẹede Afirika to kọkọ kopa ninu idije ife ẹyẹ agbaye Àkọlé àwòrán, Ọdun 1994 ni orilẹede Naijiria kọkọ kopa ninu idije ife ẹyẹ agbaye Àkọlé àwòrán, Saaju idije ti yoo waye ni orilẹede Russia lọdun 2018, igba marun ọtọọtọ ni orilẹed4e Naijiria ti lọ si idije ife ẹyẹ agbaye Àkọlé àwòrán, Naijiria ko kọja ipele keji idije yii ri lati ọdunmẹrinlelogun ti o ti n lọ si idije yii Àkọlé àwòrán, Fẹmi Ọpabunmi ni agbabọọlu to kere julọ lati orilẹede Naijiria ti yoo kopa ni idije ife ẹyẹ agbaye Àkọlé àwòrán, Orilẹede Brazil lo tii gba ife ẹyẹ agbaye ju lọ ni igba marun ni wọn si ti gba a Àkọlé àwòrán, Orilẹede meji ni ilẹ Afirika lo tii bọ si ipele ko mẹsẹ o yọ quarter finals, awọn si ni Cameroun ati Ghana Àkọlé àwòrán, Orilẹede mejilelọgbọn ni yoo kopa ninu idije ife ẹyẹ agbaye ti ọdun 2018 Awọn aworan yii wa lati ọwọ Ile-ise iroyin BBC.
Gege-bi oro re, ikede awon ti iwa ibaje si mo lori ko ye ko je omo egbe oselu alatako (PDP) nikan sugbon gbogbo awon omo egbe oselu Pataki julo egbe oselu to wa lori aleefa bayi,ti isakoso ti o wa lori aleefa ba fe gboogun ti iwa ibaje lotito ati lododo.
Atẹjade naa sọ siwaju si pe, o ti wa ninu ofin ati ilana ileeṣẹ ọlọpaa Met pe, wọn gbọdọ huwa bi ọmọluabi nibi kibi ti wọn ba wa.
Ni ọjọ́ Ẹti, Oṣù kẹfà, ọjọ́ Kẹrindinlọ́gbọ́n, ọdún Ẹgbãlemẹdógún, Ilé Ẹjọ́ Àgbà ti ilú Àmẹ́ríkà ṣe òfin pé “Kò si Ìpínlẹ̀ Àmẹ́ríkà ti ó ni ẹ̀tọ́ lati kọ igbéyàwó laarin ọkùnrin pẹ̀lú ọkùnrin tàbi obinrin pẹ̀lú obinrin”.
ó sì fi àwọn ìlànà ati àṣẹ lélẹ̀ fún wọn nígbà tí wọ́n jáde kúrò ní Ijipti, 
Gbogbo ìgbà tí mo bá ti sọ̀rọ̀, ni mò ń kígbe pé,“Ogun ati ìparun dé!
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Awọn Ibẹẹta pẹlu ọmọ iya wọn jona mọle ni jigawa 22 Sẹ́rẹ́ 2018 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Irin igbomikana lewu lasiko ọyẹ Awọn ibẹta kan ati ọmọ iya wọn lọkunrin ti jona mọle nilu Hadejia nipinlẹ Jigawa.
Nígbà tí wọ́n súnmọ́ ẹnu odi ìlú náà, wọ́n rí òkú ọmọ kan tí wọn ń gbé jáde.
Eyi ni ohun ti akọwe ikọ alaabo Chad Wolf sọ lọjọ ẹti.
O ni awọn araalu Iwo fihan pe awọn mọ riri iṣẹ iranwọ, itọju ilu ati mimojuto igbayegbadun wọn ni wọn fi dide lati daabo bo oun ati aafin.
Ọkàn ọlọ́gbọ́n eniyan a máa darí rẹ̀ sí ọ̀nà rere,ṣugbọn ọ̀nà burúkú ni ọkàn òmùgọ̀ ń darí rẹ̀ sí.
Muhammad Ali yi orúkọ ẹrú “Cacius Clay’’àti ẹ̀sìn padà lati kọ ẹ̀hin si iwà burúkú ti Aláwọ-funfun hù si enia rẹ.
Lẹsẹkẹsẹ, ọwọ́ kan bẹ̀rẹ̀ sí kọ̀wé sí ara ògiri ààfin níbi tí iná fìtílà tan ìmọ́lẹ̀ sí, ọba rí ọwọ́ náà, bí ó ti ń kọ̀wé.
Àwọn ará Didani ń bá ọ ṣòwò, ọpọlọpọ etíkun ni ẹ tí ń tajà, wọ́n ń fi eyín erin ati igi Ẹboni ṣe pàṣípààrọ̀ fún ọ.
Nínú ìfọ̀rọ̀wérọ̀ kan pẹ̀lú àwọn oníròyìn, ó ní, gẹ́gẹ́ bíi ara ìlàkàkà rẹ̀, àwọn jàǹdukú mẹ́tàlélọ́gọ́sán ni ọwọ́ ti bà lábẹ́ ètò kògbéégbè operation AYEM AKPATUMA.
ogbeni Nasiru El-Rufai so pe, ile-ise naa tun ni eka ti yoo maa mojuto oniruuru
Ẹ mú ọrẹ wá fún OLUWA lára àwọn àkàrà tí ẹ kọ́kọ́ ṣe gẹ́gẹ́ bí ọrẹ láti ibi ìpakà.
Omotola Ekehinde, Ezekwesili, Funmi Iyanda dá sí ẹ̀sùn ìfipábánilòpọ̀ Fatoyinbo COZA: Mi ò fípá bá obìrin lò pọ̀ rí láyé mi - Pásítọ̀ Fatoyinbo Seyi Makinde yan obìnrin míràn sípò akọ̀wé ìjọba SSG Àwòrán apanilẹ́rìn-ín fún ọ̀sẹ̀ yìí, ìtọ́wò rèé Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí 2 sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 2:23 Fídíò, Water Generator: Ó leè ṣiṣẹ fún wákàtí mẹfà, kó tó sinmi, Duration 2,2310 Òkùdu 2020 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
Awọn ẹya Yoruba, Igbo, Efik atawọn ẹya ke ke ke miran lo gba pe ẹya Hausa/Fulani n jẹ gaba le awọn lori, ti wọn si n pariwo pe ki ipinya wa.
Nítorí pé ẹnìkọ̀ọ̀kan ninu yín níí máa kánjú jẹun, ebi a máa pa àwọn kan nígbà tí àwọn mìíràn ti mu ọtí lámuyó!
Gómínà Kogi pàṣẹ kóníléógbélé ní ìjọba ìbílẹ̀ kan ní Kogi Ó ṣeéṣe kí ilé ìjọsìn, mọ́sálásí àti ọkọ òfurufú ṣí, Ẹ wo àwọn ìlànà tuntun tí ìjọba là sílẹ̀ Ọ̀pọ̀lọpọ̀ dúkìá ṣòfò lásìkò ìfẹ̀họ́nú hàn nítorí ìṣèkúpani George Floyd Inú káàdì ìránti tí mo rí he ní mó tí rí fọ́tò ìhòhò Salawa, mó kàn fẹ́ gbà owó díẹ̀ ni- Afurasí Ọ kan nínú àwọn olùfẹ̀hónú hàn náà ati ẹgbọ́n ọmọ tí ìṣẹ̀lẹ̀ yìí sẹlẹ̀ sí sàlàyé pé oríṣiríṣi irú ìṣẹ̀lẹ̀ yii ló ti n wáyé látẹyinwá to fi mọ ìyá àgbàlagbà tọ n lọ si ilé rẹ̀ jẹjẹ ti wọ́n sì fi ipá bálòpọ̀ láàrín ọ̀nà Justice for Uwa: Pásítọ̀ Adeboye, Amnesty International fárígá lórí àwọn aṣebi tó pa omidan Omozuwa Oríṣun àwòrán, PAstor adeboye/ facebook Pasitọ agba fun ijọ Redeemed lagbaye, Enoch Adeboye ti ṣeleri ati rii daju pe awọn leṣebi-leṣeka ẹda to ṣekupa akẹkọọ ipele kinni ni fasiti Benin, Uwaila Omozuwa lẹyin ti wọn fipa baalopọ ko sa mọ ofin lọwọ.
Mo kọlù yín, mo sì mú kí atẹ́gùn gbígbóná ati yìnyín wó ohun ọ̀gbìn yín lulẹ̀, sibẹsibẹ ẹ kò ronupiwada, kí ẹ pada sọ́dọ̀ mi.
awon eniyan , ni eyi ti eto idagbasoke yoo se tubọ fẹsẹ mulẹ si ni ipinle naa.
Latẹnu Aarẹ Apapọ ẹgbẹ́ naa, Ọjọgbọn Biọdun Ogunyẹmi, ni ASUU gba kede iyanṣẹlodi ọhun, lopin ipade igbimọ alaṣẹ gbogboogbo to waye lọjọ kẹrin, oṣu Kọkanla, ọdun 2018, ni Fasiti Imọ Ẹrọ, FUTA, to wa niluu Akurẹ, nipinlẹ Ondo.
ti o ki aare kaabo ni papako ohun lati ri minisita FCT,  Mohmammed Bello, oga agba awon osise, Abba
Kete ti Jaiye fi ọrọ aridaju pe oun ati Pasuma ko fẹ ara wọn sita lawọn eeyan n fesi loju opo rẹ pe awọ́n dupẹ pupọ pe o ẹkunrẹrẹ alaye ọrọ naa sita.
Ẹni tí OLUWA kò gbé ṣépè,báwo ni mo ṣe lè ṣépè lé e?
Loni ni igbẹjo naa waye nile ẹjọ ọhun.
Ẹ̀jẹ̀ yóò sàn pẹ̀lú bí Amerika se pa Ọ̀gáagún wa - Iran Oṣù Kínní ọdún 2020 ti pẹ́ jù, ẹ ṣe ìgbẹ́jọ́ mi kíákíaá - Donald Trump Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Trump impeachment: Trump kò fìdí janlẹ̀ tán, àmọ́ níbo ni yóò jásì?
Jakọbu bá jẹ́ ẹ̀jẹ́ kan, ó ní “Bí Ọlọrun bá wà pẹlu mi, bí ó bá sì pa mí mọ́ ní ọ̀nà ibi tí mò ń lọ yìí, tí ó bá fún mi ní oúnjẹ jẹ, tí ó sì fún mi ni aṣọ wọ̀, 
Bakan naa fun igba akọkọ, idije naa to maa n waye laarin oṣu Kinni ọdun si oṣu Keji yoo waye, laarin oṣu Kẹfa ọdun si oṣu Keje.
Omowe Onu tun salaye fun awon asofin nipa awon odo ẹ̀ẹ́dẹ̀gbẹ̀rin le ni mẹ́rìnléláàdọ́rin  ti ajo naa fun ni  ami eye, o so pe ajo naa ko ni rewesi lati tun tesiwaju nipa mimu iwuri ba awon odo orile ede yii ti won nifee si eko  sayensi , ni eyi ti idagbasoke yoo se de ba imo sayensi, imo ero ati ogbon atinuda lorile ede Naijria.
Ibẹ̀ ni ọkọ̀ ojú omi ń gbà lọ,ati Lefiatani tí o dá láti máa ṣeré ninu òkun.
Emir of Kano: Lamido Sanusi pe Ọ̀gá ọlọ́pàá àti Ọ̀gá DSS lẹ́jọ́ Oríṣun àwòrán, Getty Images Emir ipinlẹ Kano tẹlẹ, Lamido Sanusi ti pe ẹjọ ni ile ẹjọ giga ni Abuja lati pe fun itusilẹ oun ni ahamọ.
À ń gbọ́ ohùn OLUWA lójú omi òkun,Ọlọrun ológo ń sán ààrá,Ọlọrun ń sán ààrá lójú alagbalúgbú omi.
din mẹsan-an (16, 891) nigba ti akẹgbẹ rẹ lati ẹgbẹ oṣelu PDP ni ẹgbẹrun
owo awon ku, ti o si tun fun awon ni ibale okan lati mo ipo ti ilera ara won
Oríṣun àwòrán, @juliana Àkọlé àwòrán, Iku doror ni ipinlẹ Osun Nigba ti BBC kan si ajọ to n mojuto ọrọ awọn agunbanirọ ni Oṣogbo to jẹ olu ilu ipinlẹ Oṣun, ni wọn fidi iṣẹlẹ yii mulẹ.
Gege bi Purity Akuh, ti o je akonimooja ikon aa,”Inu mi dun pupo pe, iko mi ti pe bayii.
Olórin, Small Doctor, gba ìtúsílẹ̀ nínú àhámọ́
"Ọjọgbọn ni ""àwọn ọmọ ẹgbẹ́ òkùnkùn òde òní kàn ń ba orúkọ ẹgbẹ́ tí àwa dá sílẹ̀ ní 1952 jẹ́ ni""."
O Fagunwa Àkọlé àwòrán, Ọpọ awọn itan adiitu ti Orowọle kọ, lo n mu ki ọpọ eeyan maa ro pe Iwin tabi ẹmi airi kan ni Bi ina ba ke, a fi eeru boju, bi ọgẹdẹ ba ku, yoo fi ọmọ rẹ rọpo, bi oloye ba ku, yoo fi oloye silẹ ni, bi eeyan ba si ku, ọmọ ẹni ni selede ni.
” OLUWA sì gbọ́ ọ̀rọ̀ tí wọn ń sọ.
Ile ẹkọ The Vale College ni agbegbe Iyaganku ni Ibdan ni Alagba Niyi ti n fi ẹkọ Yoruba dara.
Lilo eyikeyi ninu awọn wọnyii nii ṣe pẹlu asiko ati iru ipo ti a ti loo ninu gbolohun Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí 2 sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 2:23 Fídíò, Water Generator: Ó leè ṣiṣẹ fún wákàtí mẹfà, kó tó sinmi, Duration 2,2310 Òkùdu 2020 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Elebuibon: Àwọn àṣà àtọ̀húnrìnwá ló fa títa ẹ̀jẹ̀ nítorí ògùn owo Ṣaaju asiko yii, ijọba Naijria ti pinnu lati ya owo to le ni biliọnu mejilelogun Dọla lati fi gbọ diẹ lara bukata iṣuna ọdun 2020.
Ikọ̀ aláàbò Nàìjìríà dojú kọ Shiite Èmi kò ní kí Shiite má ṣe ẹ̀sìn won o -Muhammadu Buhari Àgùnbánirọ̀ akọ̀ròyìn Channels náà ti dágbére fáyé látààrí ìkọlù Shiite l'Abuja Dúkìá àti ọkọ̀ jóná, ọlọ́pàá mẹ́sàn-án fara gbọta lásìkò ìwọ́de Shiite Awọn onwoye ni aifẹ idojukọ pẹlu awọn ọlọpaa lo mu ki wọn tete ṣẹwe le irin naa eleyii ti o ti da ọpọ ipaya si ọkan awọn olugbe ilu Abuja lati igba ti wọn ti kede pe awọn yoo ṣee.
Amọ ọna kan wa ti eeyan fi le ri taje se lai se laala pupọ, ọna yii si ni amulo awọn oju opo kan lori ayelujara fun okoowo.
Laipẹ yii ni ile igbimọ aṣofin agba mejeeji l'Abuja fi abadofin naa ranṣẹ si Aarẹ Buhari.
 Awọn  ọmọ   igbimọ  naa ni; Justice Clara Ogunbiyi  to n soju fun  Ila oorun Ariwa ati igbakeji oga awọn   ọlọpaa teleri  ogbeni Lawal Bawa to n soju fun Ila- Iwo oorun , ati awọn  komisona to tun wa lenu isẹ.
Ṣugbọn ṣa, Ọgbẹni Enwonwu sọ pe ileeṣẹ ọlọpaa ti wa l'akọ bi ibọn, lati gbogun ti awọn ipejọpọ ti ko ba ofin mu.
Ẹ kò sì ní fojú kan ilẹ̀ yìí mọ́.
Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Nigerian Youth Investment Fund: Ijọba àpapọ̀ yóò kó bílíọnù 75 owó ẹyá fún àwọn ilé ìfowópamọ́ kéékèké fún ìṣòwò àwọn ọ̀dọ́25 Agẹmo 2020 Delta petrol tanker explosion: O ti lé ní ènìyàn mẹ́wàá tí ina jó gúrúgúrú nínú ìjàmbá tó wáyé ní Delta23 Agẹmo 2020 Fídíò, Peters Ijagbemi dá àrá lórí ètò 'Ṣé o láyà' ti BBC Yorùbá lọ̀sẹ̀ yìí25 Agẹmo 2020 Iya Jogbo Dead: Ọ̀pọ̀ olólùfẹ́ Emmanuella Pobeni Adepoju kẹ́dùn ikú rẹ̀25 Agẹmo 2020 Marina-Eko Bridge: Ìjọba gbóṣùbà fún àtìlẹyìn aráàlú lásìkò tí wọn ti afárá méjèèjì pa18 Ọ̀wàrà 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Oríṣun àwòrán, Ogun State Governor's office Àkọlé àwòrán, Gomina Amosun sọ pe yatọ si ipinlẹ mẹrindinlọgbọn ni Naijiria ti yoo kopa nibi ajọdun naa l'ọdun yii, orilẹede ilẹ Afrika mọkanlelogun, to fi mọ orilẹede UK ati China ni yoo kopa.
Egungun to kọkọ jo iran ni yoo wo gbẹyin ni Tottenham fi ṣe fún Man United lẹyin ti Bruno Fernandez gba goolu akọkọ ninu ifẹsẹwọnsẹ ọhun ṣawọn.
Awọn Iroyin mii ti ẹ le nifẹ sii Barrister ló sọ mí di èèyàn ńlá - Ayinla Kollington Ìtàn tó wà nídi òwe ‘Sebótimọ Ẹlẹ́wà Sàpọ́n’ Ilu Iwo ló yẹ kó kọ́kọ́ jẹ́ Sultan àkọ́kọ́ ní Nàìjíríà - Oluwo WAEC gbé èsì ìdánwò WASSCE jáde Etí ìjọba Buhari di sí ìmọ̀ràn àwọn ará ìlú -Jiti Ogunye Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Awọn nkan miran to tun wa ninu ilana tuntun naa Ajọ NCAA sọ pe awọn ileeṣẹ baalu to n ko eero lati Naijiria lọ si orilẹ-ede miran gbọdọ tẹle awọn ilana yii: Wọn gbọdọ da awsn oṣiṣẹ wọn l'ẹkọọ nipa aarun, idena rẹ, ati amojuto rẹ Wọn gbọdọ ri i daju pe wọn ra aṣọ idaabo bo ara ẹni lọwọ aarun, sanitaisa, ki baalu o to gbera.
Wọn yóo sì ti igi tí a fi ń gbé e bọ̀ ọ́.
Lasiko to n bawọn akọroyin sọrọ lori abajade ibo abẹnu PDP nipinlẹ Ọsun, eyi to se ni ilu Ile-Ogbo, tii se ilu abinibi rẹ, Ogunbiyi ni bi wọ́n se se ayẹwo orukọ awọn asoju to dibo, eto idibo ati kika esi ibo ni wọn se lati gbe lẹyin alatako oun, Senatọ Ademọla Adeleke.
"Ìgbà míì, àwọn báábà ò kí ń béèrè pé ṣé ẹ fẹ́ gẹrun orí, irun àgbọ̀n nìkan la máa ń gẹ̀ nígbà tí kò sí ǹkankan lórí, kondoro ni""."
Kí OLUWA fún ọ ní ọgbọ́n ati làákàyè kí o lè máa pa òfin OLUWA Ọlọrun rẹ mọ́ nígbà tí ó bá fi ọ́ jọba lórí Israẹli.
Didier Drogba kopa fun iko agbaboolu Guingamp fun saa kan, ki o to lo darapo mo iko agbaboolu Le Mans lodun 2002.
Ẹ̀wà Soya ( Soya Beans) Oríṣun àwòrán, Getty Images Gbogbo ènìyàn ló gba pé òunjẹ to dára ni ẹwà jẹ́ sùgbọ́n ọkàn wá ti ènìyàn ko ba sọ́ra ó le di àìsàn si ni lára.
Lẹ́yìn náà, ó yipada, ó wọn apá ìwọ̀ oòrùn, ó jẹ́ ẹẹdẹgbẹta (500) igbọnwọ (mita 250), gẹ́gẹ́ bí ọ̀pá rẹ̀.
Sibẹ nítorí tiwa, Ọlọrun sọ ọ́ di ọ̀kan pẹlu ẹ̀dá ẹlẹ́ṣẹ̀, kí á lè di olódodo níwájú Ọlọrun nípa rẹ̀.
Murder In Ibarapa: Aborode tó tún jẹ́ olóṣèlú kàgbákò ikú òjijì lọ́nà oko
" Eyi gan an lo n fa awuyewuye lori ayelujara lori bi awọn eeyan ṣe n sọrọ pe ohun ti iranṣẹ Ọlọrun yii sọ ninu fidio naa ko tọna.
AFCON 2019: Èmi ò lè fi dáa yín lójú pé a máà bórí o
Nígbà tí ẹ bá rí i, tí wọ́n bá rúwé, ẹ̀yin fúnra yín mọ̀ pé àkókò ẹ̀ẹ̀rùn dé.
Aifagba fun ẹnikan ni o n fa wahala laaarin awọn ọbalaye ilẹ Yoruba."
Olóríkunkun ati ọlọ́kàn líle ni gbogbo wọn.
Bakan naa lo lọ si ileewe Kaduna College laarin ọdun 1941 si 1944.
Ọlọ́pàá fi afẹ́fẹ́ tajú-tajú àti omi tú àwọn tó fẹ́ ṣun ilé ìtajà ShopRite l‘Abuja ká ShopRite Ibadan gbé ìlẹ̀kùn tìpa torí ìkọlù àwọn tó ń fẹ̀hónú hàn Xenophobic Attack: 'Nàìjíríà ló máa forí kó kíkọlu iléeṣẹ́ South Africa jùlọ' Xenophobic Attack: Àwọn ọmọ Nàìjírìá bínú kọlu Shoprite l'Eko Orí mi wú pé àwọn àgbà ìjòyè kọ́wọ̀rín-ìn tẹ̀lé Olúbàdàn, ìjà parí - Makinde Bakan náà ní ìjọba ti ń ròó pé ki asoju ijọba ni orílẹ̀-èdè South Africa Kabir Bala ó pada sílé, gẹ́gẹ́ bí ìròyìn NAN ṣe sọ Ààrẹ Buhari ń gbe yẹ̀wò boyá yóò bọ̀wọ̀ fún ìpè ààrẹ South Africa ààrẹ Cyril Ramaphosa lọ́ri àkọlu tó n wáye.
" Bo tilẹ jẹ pe Oyetola ni ootọ ni pe ẹmi eeyan meji bọ lọjọ naa, ṣugbọn o fi kun pe, ko si otitọ ninu iroyin to sọ pe eeyan meji ku nibi iwọde ti wọn ti kọlu oun.
”Asaheli sì dá a lóhùn pé, “Èmi ni.
Estimated Billing: Wo ọ̀nà tí àṣẹ tuntun tí Ààrẹ Buhari pa nípa owó iná gbà kàn ọ
David West ṣalaye ninu fọnran naa bi o ti gbe obirinrin kan kuro ni ile ijo to si lọ paa nile itura kan.
Gbogbo àwọn tí wọ́n ń gbé àwọn ìlú tí ó wà ní orí òkè, láti Lẹbanoni, títí dé Misirefoti Maimu, ati gbogbo àwọn ará Sidoni ni n óo lé jáde kúrò níwájú àwọn ọmọ Israẹli.
Iṣẹ́ ìsìn ti àwọn ọmọ Geriṣoni nìyí: 
OLUWA bá Jeremaya sọ̀rọ̀ ní ọdún kẹwaa tí Sedekaya jọba ní Juda, tí ó jẹ́ ọdún kejidinlogun tí Nebukadinesari jọba.
(GOC) 7 ti eka akọkọ Lafiya Dole,sọrọ yii nibi  apejẹ ti won seto lati fi sami ayẹyẹ igbaye-igbadun, ile-ise omo ogun orile ede
Bakan naa ni Sikiru Aliu ẹni ọdun mẹẹdọgbọn, Fasasi Fatai, ẹni ọdun mẹrinlelogun, Isiaka Olaniyi, ẹni ọdun mejilelọgbọn, Raheem Toheeb, ẹni ọdun mejidinlọgbọn Ati Adeleke Akeem, ẹni ọdun mejilelogoji.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Iba Gani Adams: Bẹ́ẹ gbé màláíkà kan lọ sí Aso Rock, kò lè ṣàṣeyọrí Ṣugbọn nibayii ti ọga ileeṣẹ ọlọpaa ti kan si olori ẹgbẹ naa, kini yoo jẹ ṣiṣe?
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Oba Adedokun Abolarin ti Oke Ila: Ó ya ọ̀pọ̀ tó súnmọ́ mi lẹ́nu bí mo ṣe ń kọ́ Gbogbo igba ni Olori Folashade mAa n yangan lori ayelujara pe, oun nikan ni olori to bi ibẹta fun Alaafin.
Wọn á ṣe waja-waja ńláńlá sí etí aṣọ wọn.
Yago fun awọn to ba n wukọ tabi sin Oríṣun àwòrán, Getty Images Rii daju pe o rin jina fun bi iwọ ẹsẹ bata mẹta si ẹnikẹni ti o ba kẹẹfin pe o n wukọ tabi ṣe ọfinkin.
Ajo UNICEF tun salaye pe, aisi omi to mo gaara mu ati ayika ti ko dun n wo fun awon omode n sokunfa ailera ara fun won.
Ile-iwosan ijọba ni awọn ibeji naa ti gba iwosan fun osu meedogun, ti okun wọn si ti le daadaa, ki wọn to le ṣe iṣẹ abẹ naa.
Onírúirú àrà ní wọ́n dá o!
Gege bi awon ti isele ohun soju won: Eniyan mesan padanu emi won sinu ijamba ina naa, bee si ni oko irinna mẹ́rìnlélógójì jona deeru, eleyi ti ijamba oko epo robi sokunfa re.
Eyi lo mu ki ajọ SERAP lọjọ Aiku kọ iwe ipẹjọ si ajọ ICPC lati rii daju pe wọn tọpinpin awọn iṣẹlẹ yii ki wọn si fi ẹnikẹni ti igba rẹ ba ṣi mọ lori jofin ti wọn ba fidi rẹ mulẹ pe lootọ ni awọn kan n ko gbogbo nkan iranwọ to yẹ ki wọn pin lasiko Covid-19.
Nuhu to ni ile iṣe to n gbe fiimu jáde FKD yóò ṣe àgbéjade fiimu tó ṣẹṣẹ ṣe ti àkọlé rẹ̀ jẹ 'Ki yarda da ni' tósi jẹ fíìmù ìfẹ́ lósù tó n bọ, èyí ni Maikaba ń pinu láti fofinde.
Àrà méèrírí , ẹ wo ọkùnrin tí eegun rẹ̀ rọ̀ bíi rọ́bà, tó ń ká bíi ẹja Day 24: Ǹjẹ́ O lè dìbò fún olùdíje tí àlùfáà tàbí ìmámù rẹ́ bá yàn?
Due to revisions in the number of cases, an average cannot be calculated for this date.
Nítorí ẹni tí ó bá fẹ́ gba ẹ̀mí ara rẹ̀ là yóo pàdánù rẹ̀.
“Tèmi ni gbogbo ohun tí ó bá jẹ́ àkọ́bí, gbogbo àkọ́bí ẹran: kì báà jẹ́ ti mààlúù, tabi ti aguntan.
Nigba to n fidi otitọ ọrọ mulẹ nipa ipo ti ọkọ rẹ wa, Joke Silva, to tun n jẹ Joke Jacobs, tii ṣe aya oṣere tiata naa ni ko ko ko bii okuta ni ara ọkọ oun le, ko si si iku kankan loju rẹ.
Basilai ará Gileadi náà wá láti Rogelimu.
Idà ni yóo fọ́ àwọn ilé ìṣúra wọn,kí wọ́n lè di ìkógun!
Nítorí a mọ̀ pé bí àgọ́ ara tí a fi ṣe ilé ní ayé yìí bá wó, a ní ilé kan lọ́dọ̀ Ọlọrun, tí a kò fi ọwọ́ kọ́, tí yóo wà lọ́run títí laelae.
Gẹgẹ bi iyalode, oun ni oloye Obinrin ti o ga julọ ni igbimọ lọbalọba ilẹ Ibadan ni igba aye rẹ.
com ati islamicfinder Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Àwọn ìtàkùn àti igbó dúdú kan báyìí wà ní ìsàlẹ̀ àpáta ní apá òdìkejì ibi tí òun ń bá gun òkè bọ̀, mo sì ti rọra yọ́ sọ̀kalẹ̀ lẹ́yìn tí wọ́n ti sòfófó mi fún un mo rá wọ abẹ́ ìtàkùn náà mo fi ara pamọ́ bẹ́rẹ́bẹ́rẹ́.
Awọn alaṣẹ ile iwosan naa ni iru rẹ ko ṣẹlẹ ri lati igba ti wọn ti da ile iwosan naa silẹ.
Nigba ti o n ba akoroyin ile Akede soro ni Dapchi, Mallam Bukar so pe,  oko-akeru nla kan lo ko awon akekoo naa wa ni nnkan bi agogo mejo owuro oni ojo kokanlelogun osu keta odun 2018.
ori, olugbani-nimoran lori oro oselu abbl.
ng Àkọlé àwòrán, Wọ́n ni ọjọ́ nàá yó le fún àwọn aráàlú ní ànfàání láti ṣe àjọyọ̀ ọjọ́ ìṣèjọba àwaarawa.
Ninu oro ikinni Aare lo ti parowa fun gbogbo eniyan to n ba olojo ibi yo loni lati ko eko rere ninu iwa irele, ifarajin, ooto inu ati ife ilu to wa lowo Olusoagutan Adeboye.
Ọkunrin kan wà láàrin wọn tí ó wọ aṣọ funfun, ó sì ní àpótí ìkọ̀wé kan lẹ́gbẹ̀ẹ́.
Igbagbọ wa ni ìṣẹ́gun lórí ayé.
Awọn ènìyàn Naijiria kò lè tètè gbagbe Baṣọrun Kashimaawo Olawale Abiọla fún iṣẹ ribiribi to ṣe silẹ ki ọlọjọ to de.
Ara mi rẹwà ló jẹ́ kí n máa ṣí ara sílẹ̀- Victoria Kolawole Èyí ni àwọn aṣíwájú ìjọba tí ajé ìwà ìjẹkújẹ ti ṣí mọ́ lórí láàrin ọdún 1960 sí àsìkò yí Ṣé lóòtọ́ ni tírélà ti gba ààrín Ronke Odusanya àti bàbá ọmọ rẹ̀, Jago?
OLUWA ní ẹjọ́ tí yóo bá àwọn ọmọ Juda rò, yóo jẹ àwọn ọmọ Israẹli níyà gẹ́gẹ́ bí ìwà wọn, yóo sì san ẹ̀san iṣẹ́ ọwọ́ wọn fún wọn.
“Bo tilẹ ṣe pe nnkan ko tii maa dun bi ọpọ ṣe n reti, sibẹ awọn eniyan wa ni igbagbọ, wọn si n ṣatilẹyin ati adura fun wa.
Ninu ifọrọwanilẹnuwo pẹlu awọn akọrọyin, ọkan lara awọn agbẹjọro fun Sẹnetọ Kọla Balogun, Amofin Isiaka Abiọla Ọlagunju ṣe alaye wi pe ohun ti ko kan Ajimọbi lo n dasi.
Iran yoo maa koju Morocco ninu ifesewonse kinni won lojo karundinlogun osu kefa ni papa isere Nizhny Novgorod.
tí a bá padà sí àwọn àpẹẹrẹ ( 1,2 ) ti òkẹ ̀ , ẹni tí n sọ ̀ rọ ̀ lórí bí a ṣe lè mọ àwọn tí ó dá dúró yìí to jẹ ́ ọ ̀ rò orukọ tí o lè wà ní ipò tó ṣe kóko ; olùwà àti àbọ ̀ .
Wo àwọn Adelé-Ọba aládé méje tó jẹ́ obìnrin nílẹ̀ Yorùbá Mi ò le tòṣì láéláé!
O yẹ ki awa naa maa ronu, ka si maa gbe awọn igbesẹ lori ohun to lee mu alaafia, idagbasoke ati ominira ba awujọ wa, boya obinrin ni wa, abi ọkunrin, ọmọde ni wa, abi agba.
O rọ àwọn Dokita lati mu iṣẹ wọn ni ọkunkundun láì ba ayé àwọn alaisan jẹ́ nitori pe 'Bayii kọ ni wọ́n ṣe bi mi o!
O tun lọ si ile iwe akọṣẹmọṣẹ ti Yaba Poly to jẹ ti gbogboniṣe ni ipinlẹ Eko lati kọ nipa imọ ontẹwe ati awọn iṣẹ ọwọ miran.
adari nile igbimo asoju ninu omo egbe to kere julo ni:ogbeni  Ndudi Elumelu lati ipinle Delte, adari omo egbe
Ó tún gbé ọdún mẹtalenirinwo (403) sí i láyé lẹ́yìn tí ó bí Ṣela, ó sì bí àwọn ọmọ mìíràn lọkunrin ati lobinrin.
Nígbà tí Israẹli rí àwọn ọmọ Josẹfu, ó bèèrè pé, “Àwọn wo nìyí?
BBC ba diẹ lara awọn to n gbogun ti Ebola sọrọ, lori idi ti eyi fi n ṣẹlẹ si wọn.
Angela Merkel ti ilẹ Germany ni ọpọ se apejuwe gẹgẹ bi akinikanju ilẹ Yuroopu ninu didoju ija kọ ajakalẹ arun yi.
Ile iwosan kaakiri ni wọn ti n toju awọn ti otutu ati yinyin ti fa aisan si lara bayii.
Wọ́n bá tẹ̀dó sórí ilẹ̀ àwọn ọmọ Hori gẹ́gẹ́ bí àwọn ọmọ Israẹli náà ti tẹ̀dó sórí ilẹ̀ tí wọ́n gbà, tí OLUWA fún wọn.
3 7190 Orilẹede Sierra Leone 74 1.
 Gẹgẹ bi Dokita Nathalie MacDermott lati ile ẹkọ giga Kings College ni ilu London ṣe sọ."
Lówùúrọ̀ ọjọ́ kejì, lẹ́yìn tí mo fi mọ́ínmọ́ín mu ẹ̀kọ àgbàdo tútú tán, tí mo jókòó ní tèmi ni mo rí Àkàrà-òògùn tí ó yọ sí mi gbùlà bí ẹbọra.
Alaga ajo isokan ile Africa( AU) Moussa Faki Mahamat ti bu enu ate lu ikolu awon omo-ogun olote ni ilu Ouagadougou ti n se olu ilu orile-ede Burkina Faso.
Eyi ko sẹyin pe awọn agba ọjẹ yii wa lara awọn to kọkọ si oju awọn onkawe si iwe litiresọ akagbadun ni ede Yoruba.
Ṣaaju ni Gomina Wkie to jẹ eekan ninu ẹgbẹ oṣelu PDP sọ lori ẹrọ amohunmaworan wi pe ẹgbẹ oṣelu APC ti ṣeto lati yi ibo gomina to n bọ l'Ondo.
Oun naa gbadura ilera to peye ati ẹmi gigun fun Kabiyesi Alaafin.
Onimọ ẹṣin nikan kọ ni wọn n pe ni Uztas, onimọ ẹ̀rọ, onirori tabi awọn isẹ to nii ṣe pẹlu imọ ijinlẹ.
Oun ni oludasilẹ ile iṣẹ Home Advantage Africa to jẹ ile iṣẹ to n rani lọwọ ti kii ṣe tijọba.
Ọgbẹni Anwalu Taure Maude ni ẹgbẹrun mẹta-le-ni-ẹẹdẹgbẹrin ati
 orile ede Somali ,nibi ti awon agbejero ijoba ti fi esun Kan an , pe o kewi lati pe fun isokan Somali.
Sùn re o, ó digbà, o di gbóṣe.
Ọmọbìnrin ọdún 25 gún ọ̀rẹ́kùnrin rẹ̀ pa nítorí ó ní ko lọ ṣẹ́ oyún Èsì ìdánwò òhun tí a ṣé síwájú là n bá fínra báyìí ní Nàìjíríà- Yemi Shodimu Oríṣun àwòrán, Nigeria electricity Wo ọ̀nà tí o le è gbà láti má san àfikún owó iná ẹ̀lẹ́ńtíríìkì tuntun Awọn ileeṣẹ to n pese ina mọnamọna lorilẹ-ede Naijiria ti bẹrẹ si ni lo saa owo ina tuntun fun awọn to n lo ina ọba ni Naijiria bẹrẹ lati ọjọ Iṣẹgun, ọjọ kinni, oṣu kẹsan an, ọdun 2020.
Bẹẹ lotun ṣiṣẹ ni Fasiti ijọba apapọ ilu Eko, gẹgẹ bi olukọ, ni ọdun 1971 si ọdun 1978.
Yinka Ayefẹlẹ ni awọn ololufẹ ileeṣẹ igbohun s'afẹfẹ Fresh FM, to jẹ agbẹjọro ti gbe ijọba ipinlẹ Ọyọ lọ s'ile ẹjọ.
Iṣẹ ọna ilẹ Naijiria kan to ṣadede suyọ ni filati onile kẹjẹbu kan ni ariwa ilu London ti pa owo to le ni miliọnu pọun kan lọja gbanjo.
ó ti tú aṣọ lára Juda.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ohun tẹ́ẹ gbúdọ mọ nípa kókó orí ọyàn yín lásìkò fífọ́mọlọ́yàn WAEC 2020 timetable: Àlàkalẹ̀ fún ìdánwò ti ọdun 2020 rèé Ajọ to n ri si idanwo aṣekagba ileewe girama lẹkun Iwọ Oorun Afirika ti gbe atẹ alakalẹ bi idanwo WAEC yoo ṣe lọ fun ọdun 2020 jade.
Iye igba ti awọn darandaran ti se ikọlu si Adamawa, Benue, Taraba, Ondo ati Kaduna February 2013; Awọn Fulani pa ọgọọrọ eniyan ni Benue May 7, 2013: Awọn 47 ni wọn yinbọn pa nigbati wọn n sinku awọn ọlọpaa meji ti awọn Fulani darandaran sekupa Feb 20-21, 2014: Awọn Fulani darandaran pa eniyan 35, ọgọọrọ si di alainile gbe March 6, 2014: Awọn Fulani darandaran pa eniyan 30 ni agbeegbe Kwande, Katsina March 23, 2014: Eniyan 25 padanu ẹmi wọn nigba ti 50 si farapa nibi ikọlu awọn darandaran si agbeegbe Gbajimba,ni Benue March 15, 2015: Wọn se ikọlu si agbeegbe Egba ni Agatu LGA to si le ni eniyan 90 pẹlu obinrin ati ọmọde ti ẹmi wọn lọ si.
Eto Biggy 237 farajọ eto Big Brother Naija to n lọ lọwọ ni Naijiria.
Kò sí ẹni tí ó lè wà láàyè fún ara rẹ̀.
Àwọn Juu bẹ̀rẹ̀ sí sọ láàrin ara wọn pé, “Níbo ni ọkunrin yìí yóo lọ tí àwa kò fi ní rí i?
Ọrúkọ wo láà bá wá sọ Computer ní Yorùbá?
Pẹlu àṣẹ ni ó fi bá àwọn ẹ̀mí èṣù wí, wọ́n sì gbọ́ràn sí i lẹ́nu.
Jẹ́ kí á tẹ ìlú ńlá Sihoni dó,kí á sì fi ìdí rẹ̀ múlẹ̀.
Iyẹn fun ẹni to ba ṣ s'ọba.
Salawa tun ṣalaye pe aarẹ ara lo ṣe oun, kii ṣe ti aarun gogongo gẹgẹ bi ọpọ ti n ṣọ kaakiri.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Rashidi Ladoja: Ẹ jẹ́ kí Bùhárí gbá'pòtí ìbò, bóyá yóò borí Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Ọlọrun bá la ibi ọ̀gbun kan tí ó wà ní Lehi, omi sì bẹ̀rẹ̀ sí jáde láti inú ọ̀gbun náà.
Ipinnu ijọba Ghana ree Ileesẹ to n dari ọrọ ilẹ yoo fun ileesẹ ijọba Naijiria ni iwe ẹri to peye.
Okunrin ọun sọ̀rọ̀ nipa pe ijọba Naijiria n pín owó orí ẹ̀rọ ayélujára ti a mọ̀ sí Bitcoin.
Adekunle Peter Adeleye ni oludije gomina labẹ asia ẹgbẹ oṣelu African Action Congress, AAC to si jẹ ọmọ bibi ilu Itibukunmi ni Ilaje, Ondo.
ni ìbéèrè tí spọ̀ ń bèèrè O pari ọrọ rẹ pe ki ijọba san owo oṣu wọn, ko si tun ṣe eto bi owo oṣu wọn yoo fi maa lọ dede laisi idiwọ.
Ìwọ ni Ọlọrun mi,n óo máa dúpẹ́ lọ́wọ́ rẹ.
Lẹsẹkẹsẹ ọba rán ọmọ-ogun kan, ó pàṣẹ fún un kí ó gbé orí Johanu wá.
 Aare orile ede Naijiria  Muhammadu Buhari ti wa fi ikinni re ranse si
"Bakan naa ni mo tun ri awọn ọdọ, ti wọn n sare sọtun-sosi lasiko iwọde, ti ọpọ ẹmi si bọ sinu rẹ, bakan naa ni awọn dukia sofo pẹlu.
Nǹkan sì ń dára fún Daniẹli ní àkókò Dariusi ati Kirusi, àwọn ọba Pasia.
Gègé ni kí ẹ ṣẹ́, kí ẹ fi pín ilẹ̀ náà fún olukuluku ẹ̀yà gẹ́gẹ́ bí iye wọn.
Dá ire wa pada, OLUWA,bí ìṣàn omi ní ipadò aṣálẹ̀ Nẹgẹbu.
Àwọn kan ń sọ pé, “Òun ni!
Mayegun pari ifọrọwerọ naa pe, ki awọn ọmọ Yoruba kaakiri agbaye ṣe ara wọn ni oṣusu ọwọ, nitori ohun to ba n ṣe Abọyade, gbogbo Ọlọya lo n ṣe.
Akeugbagold, ẹni to sisọ loju ọrọ yii lasiko to n kopa lori eto BBC Yoruba kan, tun fikun pe, ọrọ ifẹ, iwa rere ati ibagbepọ alaafia ni oun maa n ṣe waasi le lori.
Igbẹjọ ṣi n lọ lori ẹsun ti wọn fikan awọn afurasi naa di bi a ṣe n sọrọ yi.
Ọrọ to wa nilẹ yii kii ṣe ti OPC nikan, a fẹ ri i daju pe gbogbo awọn ẹgbẹ to ni nkan ṣe pẹlu eto aabo lati jẹ ki wọn o wulo."
“Èmi OLUWA ni olùṣọ́ rẹ̀,lásìkò, lásìkò ni mò ń bomi rin ín;tọ̀sán-tòru ni mò ń ṣọ́ ọkí ẹnìkan má baà bà á jẹ́.
Bẹẹ si ni ọpọ ọmọ kootu oojiire nile ati loke okun to gbọ iroyin naa, lo n se yaginni yodo pe ọ̀rọ̀ eto aabo to mẹhẹ ọhun ko ni pẹ lojutu.
Níbo ni ó wá ti rí gbogbo nǹkan wọnyi?
Ò ń ṣe aájò, o sì ń dààmú nípa ohun pupọ.
Adadi bá ojurere Farao ọba pàdé, ọba bá fi arabinrin ayaba Tapenesi, iyawo rẹ̀, fún Adadi kí ó fi ṣe aya.
Fayemi - BBC News Yorùbá BBC News, YorùbáFò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ekiti APC Politics: Mo mọ̀ pé ọ̀rọ̀ ètè lásán lẹ̀ n sọ, ẹ ò lè yọ mí lẹ́gbẹ́ - Fayemi 24 Owewe 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 26 Owewe 2020 Oríṣun àwòrán, Google Bi aawọ ni ka pe e ni tabi ọrọ ija gidi, a o le sọ pato bo ṣe n lọ laarin ẹgbẹ oṣelu APC ni ipinlẹ Ekiti.
Nínú gbogbo àwọn ìròyìn tí à ń gbé síta a má ń fi ojú sùnùkùn wo ìròyìn tí a ba fẹ́ gbe síta láti rii dáju pe kìí ṣe èrò ara wa ní à ń gbe jáde.
O sisẹ gẹgẹ bi adari ẹka Le Centre Africain de Formation et de Recherche Administratives pour le Dèveloppement (CAFRAD) to wa fun idagbasoke ilẹ Afirika laaarin ọdun 2000 si ọdun 2004 ni ilẹ Morocco.
Ọrọ ti pọ bayii lori fidio to wa lori ọrọ ẹrọ ayaworan CCTV gẹgẹ bi iroyin ṣe n fo kiri pe wọn mọọmọ yọ ẹrọ ayaworan ọhun kuro ni Tollgate ṣaaju akoko ti wọn bẹrẹ si ni yinbọn ni.
O ni o seese ki obinrin to ba tete bere nkan osu, ki o tete dawọ nkan osu.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Kí ni Oluwo lọ ṣe ní Aso Rock lẹ́yìn lẹ́tà rẹ̀ sí ààrẹ Buhari?
Bákàn náà ni àwọran miran tun jáde tí ọ̀pọ ẹ̀mí si sòfò, sùgbọ́n àyẹ̀wò fihan pé àwọn ènìyàn náà kìí tilẹ ṣe ara Naijiria àti pé Dominican Republic ni fóto náà ti wá, ìṣẹ̀lẹ̀ ìjàmba ojú pópó ló fàá lọ́dun 2015.
ero ,wa ro gbogbo omo orile ede Naijiria lati maa lo ogbon atinuda won ni eyi
Ìròyìn fi yé wípé àwọn ọmọ ẹgbẹ́ òṣèlú tí ó wà lórí ipò ìyẹn Awami League gbé ẹ̀rọ tatapùpù wá sí ibẹ̀, wọ́n sì da ilé náà wó.
    “Láti ọjọ́ tí ọ̀fọ̀ ńlá yìí ti ṣẹ̀ mi, n kò yé lá àlá rí bàbá mi, àfi bí ẹni pé ó wà láyé ni, èyí tí ó sì wá jọ mí lójú jù pátápátá ni pé, nígbà tí mo bá rí i lójú àlá n kò níí rántí pé o ti kú mọ́, a sì dàbí ẹni pé ó wà láyé ni.
EFCC sọ pe ara fu oun pe owo ti olujẹjọ ko jọ lọna aitọ lo fi ra wọn.
Wọ́n pa àwọn tí wọ́n sọtẹ́lẹ̀ pé Ẹni olódodo yóo dé.
Iṣẹ́ bọ́ lọ́wọ́ ọlọpàá mẹ́rìn to pa afurasí, wọ́n tún dèrò ẹ̀wọ̀n Ajínigbé ń bèèrè fún epo, iṣu àti ọ̀tí Schinap gẹ́gẹ́ bí owó ìtanràn Wo ohun tó yẹ kí o mọ̀ nípa àwọn obìnrin méje ti Buhari fẹ́ yàn sípò minista Nǹkan kò ṣẹnuure fáwọn obìnrin nínú ìgbìmọ̀ ìṣèjọba Buhari Awọn miran to ti jẹ olori Yoruba sẹyin ni Oloogbe Obafemi Awolowo, oloogbe Adekunle ajasin ati Oloogbe Abraham Adesanya.
Ṣimei ń wí fún Dafidi bí ó ti ń ṣépè pé, “Kúrò lọ́dọ̀ mi!
ó sì pa àwọn ọba olókìkí,nítorí pé ìfẹ́ rẹ̀ tí kì í yẹ̀ wà títí lae;
Lọsẹ to kọja ni awọn Gomina kede ipinnu wọn lẹyin ti Gomina Nasir Elrufai jabọ ipade igbimọ ọrọ Aje lati ya ninu owo ifẹyinti oṣiṣẹ fun ipese awọn ohun amayedẹrun.
Yàtọ̀ sí ǹkan tí ó ṣẹlẹ̀ lọ́dún 2016, ó jọ bí ẹni pé, ìdẹnukọlẹ̀, ọ̀rọ̀ ajé tí àsìkò yìí yóò buru ju ti àsìkò 2016 lọ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, The New Pandemic: Kíni àwọn onímọ̀ sáyẹ́ńsì ń sọ nípa rẹ̀?
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù NIS ní àwọn kò ṣèṣẹ̀ máa fí ìwé irinnà ránṣẹ sí àwọn tó bá fẹ 25 Òkùdu 2019 Oríṣun àwòrán, Channels TV Àkọlé àwòrán, Fi adirési to wu ọ silẹ, ki a fi iwe irinna rẹ ranṣẹ si ẹ Ileeṣẹ to n ṣeto igbokegbodo awọn to n wọ orilẹ-ede Naijiria ti ṣe alaye nipa fifi iwe irinna ranṣẹ si adirẹsi ti ẹni tó ba fẹ gba iwe naa fi silẹ lọdọ awọn.
 ounjẹ ni ọpọlọpọ awọn ibi ni ayika agbaye ati pẹlu amẹrika .
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Kunle Afolayan: èmi kò fẹ́ fi ogún sílẹ̀ fún ọmọ mi Ọgbẹni Omondi sọ pe, oun ko da iya oun l'ẹbi pe ko sọ ootọ fun oun.
Àwọn agba bọ wọn ni a ko ri iru eyi rii, ẹru la fi n da bara ẹni; Aarẹ Buhari kọ ni aarẹ akọkọ ti yoo foju wina atako awọn eeyan rẹ ti wọn yoo gbe ka ori pepele itiju kaakiri agbaye.
” Ó bá sọ ọmọ náà ní Isakari.
Ní gbogbo ọjọ́ ayé rẹ̀, wọn kò yipada kúrò lẹ́yìn OLUWA Ọlọrun àwọn baba wọn.
ere idaraya lopolopo, eleyi ti abewo awon agbaboolu jankan-jankan naa yoo
Osu Kejila ọdun 2019 si ni wọn tun mu sahamọ pe o lọwọ ninu iwa ajẹbanu.
Awọn eeyan ọhun ni wọn ni iṣẹ aje ni awọn ba de orilẹ- ede Oman ki awọn to ṣeto bi wọn ṣe lọ o to yi idi ọrọ pada.
Ọ̀gbẹ́ni Ajúṣefínní: Òun ní ó ra kòkó lówó Àkàngbé.
Ile ise NIS, so oro ohun di mimo lori ero ayelujara won pe, awon ti fowo sikun mu asofin Melaye ti o je asoju-sofin eka ila oorun ipinle Kogi.
Owo ti ajọ iṣọkan agbaye gbe kalẹ naa yoo wa fun ipese omi to mọ gaara fun awọn eeyan to ju miliọnu kan ati ẹgbẹta lọ, ko si tun ṣeto ayika to peye fun awọn agbegbe ti ọrọ kan.
'Obìnrin tórí ẹ̀ pé lè tọ́ ọmọ láì nílò ọkọ rẹ̀' Fake News: BBC Kò ṣe ètò ìrànwọ́ ìwé kíkà lásìkò yìí Awọn kan gba pe o lewu lati gbe pẹlu awọn to ni aisan yii.
 éjì nínú orúkọ àmútọ ̀ run wá yorùbá tó gbajúmọ ̀ jù ni táíwò ( tàbí táyé ) àti kẹ ́ hìndé tí wọ ́ n fún àwọn ìbejì ní pàtàkì .
Bẹ́ẹ̀ ni wọ́n sì ń ṣe títí di òní olónìí.
Ẹgbegberun eeyan lo man se ayeye ọdun Ọsun ti wọn si man sure fun ọmọ bibi ati orire.
Pataki idajọ yii ni wi pe a o fi lee mọ boya lootọ ni ijọba to wa lode bayii nfẹ anfani araalu tabi oun pẹlu yoo pẹlu ọbọ jawura nipa kikuna lati fi ọna ofin wa egbo dẹkun si awọn ofin fa-mi-lete-n-tutọ ti awọn adari orilẹede yii kan nlo lati fi rẹ araalu jẹ.
”Sara fetí mọ́ ògiri lẹ́nu ọ̀nà àgọ́ lẹ́yìn ibi tí àwọn àlejò náà wà, ó ń gbọ́ gbogbo ohun tí wọ́n ń sọ.
''Olóde'' ni Yorùbá ń pe coronavirus, iléeṣẹ́ Yemkem ti rí òògùn rẹ̀ báyìí- Olùdásílẹ̀ Yemkem Ṣé YouTube ń jèrè nínú lílo ayédèrú fídíò ìwòsàn ààrùn jẹjẹrẹ?
Iṣẹ́ Kudirat Abiọla ṣì ń fọhùn síbẹ̀, lẹ́yìn ọdún 23 tó papòdà Ọ̀nà márún-ún láti mú àdínkù bá dátà (Data) lílò rẹ Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Ile ise mejeeji ni awon yoo fowosopo pelu awon oluse iwadii lori ijamba afara naa.
Ọjọru si ni gbogbo awuyewuye to n waye lori ẹni ti yoo jẹ alaga fun ẹgbẹ oselu APC da bi pe o ti dopin.
Ní ọjọ́ keje, àwọn mìíràn ninu àwọn eniyan náà jáde láti lọ kó oúnjẹ, ṣugbọn wọn kò rí ohunkohun.
 “ Nibayii ti ẹ ti ni ajọ ti yoo
Akanbi mi, má fọ̀ ọ́, mo wà pẹ̀lú ẹ; Ẹni tó ṣe ìgbéyàwó olórùka ló l'ọkọ- Lizzy Anjorin Iléeṣẹ́ ológun òfúrufú ti dárúkọ ẹni tó fi ọkọ̀ pa Tolulope Arotilẹ Ọmọ ipinlẹ Delta ni Dorathy, o si ti jẹ ko di mimọ fun olugbalejo eto agbelewo naa pe, oun wa lati jaye ori oun lori eto naa ni.
Pẹ̀lú ayọ̀ ni àwa fi ń lọ lónìí kí ayé ọmọ elòmíràn bà dára.
O ni ileeṣẹ eto ilera ti n ṣe iwadii lori awọn eeyan ti ẹni to ko aarun naa ba da nnkan pọ lati mọ awọn to ṣeeṣe ko ti ko aarun ọhun lọwọ yii nipasẹ rẹ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Coronavirus Updates: UCH ní èròjà Covid-19 tíjọba fún òun kò tó ₦1m 21 Ìgbé 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 25 Òkùdu 2020 Oríṣun àwòrán, Others O ti to ọjọ mẹta bayii ti awuyewuye ti n lọ laarin ijọba ipinlẹ Oyo ati ile iwosan UCH lori ibi ti miliọnu mejidinlọgọfa naira wa.
Ẹ wo bí àwọn ènìyàn ṣe dóòlà èmí erin tó kó sí kòtò Wo àwọn oúnjẹ márùn ún tó ń mú kí àtọ̀ ọkùnrin dára síi Kìí ṣe gbogbo ohun tí dókìtà ni kí n má jẹ torí àìsàn jẹjẹrẹ ni mo tẹ̀lé- Soyinka Àwọn jàǹdùkú dojú ìjà kọ ọlọ́pàá, DPO faragbọta, ọlọ́pàá mẹ́rin di àwátì O ni lati ọmọ ọdun mẹta ni oun ti maa n lu ike ati agolo kaakiri ni eyi ti awọn obi oun ro pe ariwo lasan ni oun fi n pa.
Fulani kò leè dúró, táa bá lo ohun ta jogún lọ́dọ̀ àwọn bàbá wa - Sunday Igboho Ọjà Àgbáláta ní Badagry rèé, níbití ẹran ejò ti dùn ju ẹran adìẹ lọ Soworẹ ń déte láti dìtẹ̀ gba ìjọba Nàíjíríà lá ṣe gbé e - DSS Ọlọ́pàá àti àwọn olùfẹ̀hónúhàn gbéná wojú ara wọn níbi ìwọ́de Revolution Now Ajafẹtọ ọmọ eniyan naa, ni awọn ko le e sọ pato igba ti ijọba yoo fi Sowore silẹ nitori o ti yẹ ki wọn fi silẹ tabi ki wọn gbe lọ si ile ẹjọ gẹgẹ bi ofin ti sọ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Adebola Ademilua: Àìrísẹ́ ṣè lẹ́yìn ìwé kíkà ló sọ mi dí ìyá onírú, mo dúpẹ́ tèmi Ẹwẹ, agbẹnusọ ile iṣẹ ọlọpaa ni ipinlẹ Rivers Nnamdi Omoni naa fidi iṣẹlẹ naa mulẹ, o si fi kun pe obinrin ti o ba arakunrin naa ni ajọṣe pọ ti wa ni ahamọ ọlọpaa bayii O fi kun pe wọn ti dari ẹjọ naa si ẹka iwadii iwa ọdaran ni ipinlẹ River fun iwadii to peye.
Irọlẹ ọjọ ni wọn fi ilẹ bo oku asofin Tunde Braimoh ni asiri nilu Eko ni deedee aago meji ọsan.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ibadan Murder: Shagbada pa ọ̀rẹ́bìnrin torí kò gbà kó bá a lò pọ̀ 24 Òkùdu 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 1 Agẹmo 2020 Oríṣun àwòrán, Others Ileeṣẹ ọlọpaa ipinlẹ Oyo ti fi oju ẹni ọdun mẹrinlelogun kan han, lẹyin ti wọn fẹsun kan an pe o pa ọrẹbinrin rẹ Happiness Winfred ni ij̣oba ibilẹ Akinyele ni ilu Ibadan.
"Gẹgẹ bi ohun ti Dokita Bharat Pankhania sọ ""kokoro aifojuri yi a ma da wahala silẹ pẹlu titobiju ẹya ara ti eleyi a si mu ki awọn ẹya ara pupọ juwọ isẹ silẹ"" Ti awọn ọmọ ogun inu ẹjẹ ko ba si ribi bori kokoro aifojuri yi,ko si nkan mi ju pe yoo tan kaakiri agọ ara ti yoo si se akoba si fara ẹni naa."
Ewee Ogbeni Samura Kamara ti o je omo egbe oselu ti o wa lori aleefa bayi benu atelu eto idibo naa wipe o kun fun magomago.
"Lai ṣalaye pe ""Idi pataki ti a fi ṣafikun iye owo naa ni pe, awọn eeyan n ru ofin ọhun nigba ti iye owo itanran rẹ wa ni ẹgbẹrun lọna ẹẹdeẹgbẹta naira nitori o rọrun fun wọn lati san."
’ Nítorí náà, kí Farao jọ̀wọ́, fún mi láàyè kí n lọ sin òkú baba mi, n óo sì tún pada wá.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Murphy Elégungun Rọba: Mo fẹ́ di ẹnití egungun rẹ rọ jùlọ ní àgbáyé Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 3 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 5 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Nígbà tí wọ́n rí ìgboyà Peteru ati ti Johanu, tí wọ́n wòye pé wọn kò mọ ìwé àtipé òpè eniyan ni wọ́n, ẹnu yà wọ́n.
Abdulfatai Ahmed to jẹ Gomina kẹyin nipinlẹ Kwara wa lati ẹkun idibo Guusu Kwara.
Bobrisky gbé N1m fún Erica torí ẹnu tó ń kùn-ún Oríṣun àwòrán, Others Lẹ́yìn awuwuye tó tẹ̀lé bí Erica ṣe hùwà sí Laycon nínú ilé ẹlégbọ́n àgbà lẹ́yìn páti alẹ́ ọjọ́ Satide.
Gbogbo àwọn eniyan ni ó ń wá a, kí wọ́n lè fi ọwọ́ kàn án nítorí agbára ń ti ara rẹ̀ jáde.
Èyìí ló dífá fún gbogbo èdè pátápátá kárí aiyé!
Ìdí rèé táwọn àkàndá ẹ̀dá fi dí iwájú iléeṣẹ́ ìjọba ìpínlẹ̀ Oyo pa l'Agodi n'Ibadan Ọlọ́pàá, sójà yabo Lekki Toll Plaza láti dènà ìfẹ̀hónúhàn míràn Kò sí ẹnikẹ́ni tó kú níbi rògbòdìyàn tó wáyé lánàá - Deji ilu Akure Wo ibi fún èsì ìdìbò láti yan aàrẹ tuntun ní orílẹ̀-èdè Ghana O ni ki ijọba apapọ má reti ki awọn olukọ fasiti naa pada sile iwe titi di igba to ba san owo to jẹ wọn.
Obinrin náà bá sọ fún Eliṣa pé, “Ǹjẹ́ mo tọrọ ọmọ lọ́wọ́ rẹ bí?
ninu daru- dapo to waye ni asiko ti idibo gomina ati ti ile igbimo asofin
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Lagos Tanker Explosion:Ọkọ̀ agbépo gbiná l'Eko Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Gbọ́, Oyinlọla kọ̀wé fipò rẹ̀ sílẹ̀ ni NIMC10 Èbibi 2018 NIN Registration:Àjọ NIMC sọ pé ọ̀fẹ́ ni gbígba nọ́mbà NIN31 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 NIMC: NIMC, NCC, NITDA àti GBB gbọ́dọ̀ ṣiṣẹ́ papọ̀ kí ètò aàbò Nàìjíríà lè dára síi31 Ògún 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 3 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 5 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Lọwọlọwọ, ọrọ yiyọ adajọ Onnoghen nipo ti n da awuyewuye silẹ laarin awọn amofin ati ẹka alaṣẹ ijọba ti a si gbọ pe awọn ọmọ ẹgbẹ agbẹjọro ati awọn ẹgbẹ ajafẹtọ ẹni kanna fẹ ṣe ipade pajawiri ati iwọde.
Odunlade fẹ́ j'ọba, Bolanle Ninalowo fun ìyàwó rẹ̀ ni ẹ̀bun kanka, Pá Kasumu rebi àgbà ree Eyi lo mu ki awọn ololufẹ wọn o maa beere pe, ṣe o ṣeeṣe ko jẹ pe wọn ti ṣe igbeyawo ni tootọ?
Wọn ni wọn ti gbe ọmọ naa lọ si ilẹ Ariwa pada'' Kini o ṣẹlẹ sẹyin?
 o gbajumo fun iwari elektronu ati awon agbaayekanna , ati fun ida osuwoninale akojo .
Ni apapọ, eniyan to ti ni arun Coronavirus ni ipinlẹ Ekiti bayii ti da mẹẹdọgbọn.
Bí mo bá sọ nǹkan ti ayé fun yín tí ẹ kò gbàgbọ́, ẹ óo ti ṣe gbàgbọ́ bí mo bá sọ nǹkan ti ọ̀run fun yín?
” OLUWA ba kọjá lọ, ẹ̀fúùfù líle kán fẹ́, ó la òkè náà, ó sì fọ́ àwọn òkúta rẹ̀ sí wẹ́wẹ́ níwájú OLUWA.
” Nítorí náà wọ́n jọ lọ sí Bẹtẹli.
Kọmíṣọ́nà ọlọ́pàá ó ṣeṣe kó jẹ́ pé ará ló sán pa ènìyàn mẹ́ta
Ko pẹ pupọ ni mo ri i pe awọn ọmọ 'yahoo-yahoo' kan n gbiyanju lati lu u ni jibiti, ni mo ba ya a fi ọrọ ranṣẹ si i pe ko ma ṣe da awọn Yahoo boys yẹn l'ohun o, iyẹn lo fa a l'oju mọra.
Ewe Salah ti gba ami-ayo mọ́kànlélógójì sinu agbon fun iko re Liverpool ni saa yii, saaju akegbe re ti o n kopa fun iko agbaboolu Manchester City Kevin de Bruyne.
OLUWA sọ fún mi pé, “Kí ó tó tó ọdún kan, ní ìwọ̀n ọdún alágbàṣe kan, gbogbo ògo Kedari yóo dópin; 
ti aisan iba bẹrẹ lati ọdọ mi”.
Lẹyin eyi, ijọba ipinlẹ Kwara naa ti ṣeleri lati ko awọn ti alafia wọn ba ku diẹ kaato lọ fun iwosan to peye.
Ti eto idibo, oṣelu ba kasẹ nilẹ, wọn a di 'alainiṣẹ lọwọ.
Fifi ẹhonu han yi di rangbọndọn kete ni osu ti owo ounjẹ wẹwẹwẹ goke sii ti wọn si fipa mu ki ijọba din i ku.
Àwọn ọmọ ogun Israẹli pa ọ̀kẹ́ marun-un (100,000) ọmọ ogun tí wọn ń fi ẹsẹ̀ rìn lára àwọn ti Siria ní ọjọ́ kan.
Odusile tun rawọ ẹbẹ sawọn ileesẹ iroyin to ba jẹ awọn akọroyin lowo osu lati tete san owo naa nitori oogun alaaru ko gbọdọ gbẹ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Seyi Makinde: Ọdún 2023 ni màá jíyìn iṣẹ́ ìríjú mi ní ẹ̀kúnrẹ́rẹ́ 30 Èbibi 2020 Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, May 29: Akala, Aleshinloye sọ̀rọ̀ lórí ọdún kan Seyi Makinde gẹ́gẹ́bíi gómìnà Arise ni arika, arika si ni baba iregun, eyi lo mu ki gomina ipinlẹ Oyo, Onimọ ẹrọ Seyi Makinde fi ṣe alaye aseyọri rẹ ni aarin ọdun kan.
Obinrin meji ni wọn fi ipa ba lopọ̀, ti wọn si tun pa, nilu Ibadan.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Sept 11 bomb: Wọ́n mú ọjọ́ ìgbẹ́jọ́ agbésúnmọ́mí 9/11 tó ṣẹlẹ̀ l'Amẹrika 31 Ògún 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Iyan ogun ọdun.
FIFAWWC: Ifẹsẹ̀wọnsẹ̀ Germany ati Naijiria ti parí pẹ̀lú àmi ayò ìbànújẹ́ mẹ́ta
Mummy calm down: Ìyá Ore sọ pé gbogbo ìgbà tí óun bá n bá a wí ló ma n ṣe àwàdà
Ṣugbọn àwọn ọmọ Israẹli kò sun èyíkéyìí ninu àwọn ìlú tí wọ́n kọ́ sórí òkítì níná, àfi Hasori nìkan ni Joṣua dáná sun.
 Àgùrá si ni ọba wọn .
Mo fi igi gba ọkan ninu wọn ati ikeji.
#BBCNigeria2019 Ṣugbọn, nitori pe ejo naa jẹ eyi ti ko ni oró lara, wọn kan ba a tọju iho ti ejo lu si lara ni.
Saraki: Kàkà kí Oshiomọlẹ sọ̀rọ̀ gidi, èpè ló ń sẹ́ Àkọlé àwòrán, Saraki ni oun kmo ni kọwe fipo silẹ Olori Ilé Ìgbìmọ̀ Aṣòfin Àgbà, Bukola Saraki bẹnu àtẹ lu bi alagba ẹgbẹ oṣelu APC, Adams Oshiomhole ṣe ni pe ko kọwe fipo silẹ latari bi o ṣe kuro ninu APC lọ PDP.
Gomina ohun, eni ti o so pe, oun w anile-ise Aare lati fi ipo ti ipinle naa wa to Aare leto, ni eyi ti o so pe, ijoba apapo ti safihan erongba re si awon asafogun naa.
Bakan náà ni o gbé oriyin fún ìjọba ìpínlẹ̀ Kwara ati Niger fun ìgbésẹ̀ weọ́n lati fokun so àjàkálẹ̀ ààrun COVID19.
Hesekaya, ọba fún àwọn eniyan náà ní ẹgbẹrun (1,000) akọ mààlúù ati ẹẹdẹgbaarin (7,000) aguntan láti fi rúbọ.
Ni ayé ọ̀làjú ti òde òni, àṣà ṣì ṣúpó ti din kù púpọ̀, nitori ẹ̀sìn àti àwọn obinrin ti ó kàwé ti ó si ni iṣẹ́ lọ́wọ́ kò ni gbà ki wọn ṣú ohun lópó fún ẹbi ọkọ ti kò ni ìfẹ́ si.
Ìtẹ́ OLUWA ni wọ́n óo máa pe Jerusalẹmu nígbà náà.
@femigbajaCopyright: @femigbaja Gbajabiamila di olórí ile aṣojú-ṣòfin kẹsàn-ánImage caption: Gbajabiamila di olórí ile aṣojú-ṣòfin kẹsàn-án Article share tools Facebook Twitter ṢàpínlòView more share options Share this post Copy this linkKà síwájú síi nípa àwọn ìtọ́kasí wọ̀nyí.
Lapapọ, a ri ká pé àwọn dúkìá tí ọba Olagbegi pàdánù sínú rukerudo náà lè ni ẹgbẹ̀rún lọ́nà ọgọ́rùn-ún pọn-un (£100,000) láyé ìgbà náà.
Àwọn ọmọ ogun Israẹli lé àwọn ọmọ ogun Siria pada, Dafidi ati àwọn eniyan rẹ̀ pa ẹẹdẹgbẹrin (700) ninu àwọn tí wọ́n gun kẹ̀kẹ́ ogun Siria, ati ọ̀kẹ́ meji (40,000) ninu àwọn ẹlẹ́ṣin wọn.
Trump ni oun yoo maa ṣe afẹẹri Robert ni laelae, ṣugbọn o ni oun mọ pe awọn yoo tun pade lẹsẹ Olugbala.
Nítorí pé n kò tíì gbé inú ilé kankan láti ìgbà tí mo ti kó àwọn ọmọ Israẹli kúrò lóko ẹrú títí di òní.
Olaniyi ṣalaye pe ninu oṣu Kejila ọdun 2020 ni Asofin Folarin fẹ ẹ pin awọn irin'ṣẹ naa fun awọn eeyan ti ko ri ọwọ rọri ni ẹkùn idibo rẹ, amọ awọn janduku ti ko gbogbo rẹ lọ.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Èmi àti Bọla Tinubu fẹ́ lo ‘German Mercenaries’ láti gbé MKO Abiọla kúrò lẹ́wọ̀n - Dele Momodu Àwọn alálẹ̀ kò ní forí jìn mí tí ń kò bá ṣe ọdún Ṣàngó - Alaafin Buhari, ṣí ìwé àkọsílẹ̀ orúkọ àwọn gómìnà tó jẹ̀bi ìkówójẹ, káráyé mọ̀ wọ́n - SERAP O dùn mí pé Buhari kò yàn mí sípò Mínísítà lẹ́ẹ̀kejì àmọ́ mò gbà kádàrá - Adebayo Shittu Makinde, jọ̀ọ́ kéde Aug 20 ọdọọdún bíi ọjọ́ ìsinmi fún ìṣẹ̀ṣe - Àwọn oníṣẹ̀ṣe Ọyọ Iroyin yiyọ ti wọn yọ Gedoni yii lo gbomi loju Khafi bi ẹni ọfọ ṣẹ, bo tilẹ jẹ pe o gbiyanju lati maṣe da omi loju.
Ni aarin gbungbun olu ilu naa, ni
Àjọ NCDC kéde ènìyàn 779 tó tún ṣẹ̀ṣẹ̀ ní Coronavirus ní Nàìjíríà Mí ò tíí ní ìpinnu lóri ìdíje ààrẹ ọdún 2023 Peter Okoye, ìyàwó àti ọmọ lùgbàdì ààrùn Coronavirus Ni nkan bii ago mẹwaa kọja iṣẹju marun owurọ yii ni wọn sin in.
Kane fikun-un oro re pe “Mo fi igbesi aye omo mi bura pe ese mi kan boolu naa wole, sugbon ko si n kan ti mo le se si, leyin ti won ko lati ka fun mi,”Ni ipari, Spurs yoo maa waako pelu iko agbaboolu Manchester City  ninu idije EPL lojo Aiku(Saturday), kii won o to koju iko Manchester United ninu ifesewonse ipele keji si asekagba idije FA Cup .
Ayafi fidio kan ti Toyin fi sita lati ṣafihan pe lootọ loun bimọ sile iwosan to ṣe pe awọn dokita oyinbo lo n gbẹbi nibẹ, kii ṣe ile alagbo ọmọ gẹgẹ bi Lizzy ṣe n pariwo rẹ.
Ṣugbọn olukuluku yóo jókòó lábẹ́ àjàrà rẹ̀,ati lábẹ́ igi ọ̀pọ̀tọ́ rẹ̀, kò sì ní sí ẹni tí yóo dẹ́rùbà wọ́n;nítorí pé OLUWA àwọn ọmọ ogun ni ó sọ bẹ́ẹ̀.
Ṣugbọn a dupẹ lọwọ Ọlọrun pe irinajo naa jẹ adun lati ibẹrẹ pẹpẹ.
Èyí ni yóo jẹ́ ìlànà fún ẹbọ sísun ìgbà gbogbo.
Ṣugbọn Jesu kò pé òun gbọ́ ohun tí wọn ń sọ, ó wí fún ọkunrin náà pé, “Má bẹ̀rù, ṣá ti gbàgbọ́.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, The Polytechnic Ibadan: Ẹ̀rọ abẹ́lé tó ń fọ ọwọ́ àti ‘Ventilator’ ló ṣẹ̀ṣẹ̀ gbé jáde Ki lo ti ṣẹlẹ sẹyin?
” Kò sì sí ẹnìkan tí ó ní ìgboyà láti tún bi í ní ìbéèrè kankan mọ́.
Mo fi inú pápá ṣe ilé rẹ̀,ilẹ̀ oníyọ̀ sì di ibùgbé rẹ̀.
Nítorí náà ẹ jáde kúrò láàrin wọn, ẹ ya ara yín sọ́tọ̀, ni Oluwa wí.
Ninu ọrọ ifaramọ ipo alaga naa, Agbẹnusọ Ile Igbimọ Aṣofin Ipinlẹ Eko, Aṣofin Ọbasa ṣapejuwe ipo tuntun naa gẹgẹ bi ọla nla ati anfani to ṣe pataki lati tubọ fi sin ilu“Ipo yii jẹ ipo ọwọ eleyii ti o nii ṣe pẹlu ojuṣe pataki lati fi sin awọn akẹgbẹ mi paapaa orilẹ-ede yii lapapọ siwaju”.
Eyi to kun fun ọpọlọpọ koto.
Agbẹnusọ fun Gomina ipinlẹ Kogi, Fanwo Kingsley sọ fun ileeṣẹ BBC wi pe ko si otitọ ninu ọrọ ti awọn oniroyin nsọ nipa ijọba ipinlẹ naa.
com/yoruba yii ki o le maa mọ bi wọn ṣe n mu esi naa wa.
Eyi mu ki Obaseki tara sasa lọ ba Aarẹ Buhari lọjọ Isẹgun pẹlu erongba pe yoo ba wọn pẹtu si ede-aiyede yi.
Nítorí bí kò bá sí ìwo àgbáǹréré àràmàǹdà, ẹ kò bá tí mọ̀ pé ara olùfẹ́ yín kò le, bí kò bá sí ẹní ìyanu, ẹ kò bá ti lè de ilé tí òun ìbá fi kú, bẹ́ẹ̀ ni bí kò bá sí èso igi ìgbàlà ẹ kò bá ti lè yọ Ewadapọ̀ nínú àìsàn rẹ́.
Nupeng àti Pengassan gùnlé ìyanṣẹ́lódì Ààrẹ Mali tẹ́lẹ̀, Amadou Toumani Toure jáde láyé Làásìgbò ọ̀tun súyọ nínú ẹgbẹ́ òṣèlú APC Báwo ni Joe Biden yóò ṣe mú ìyípadà bá òfin tí Trump fi de orílẹ̀èdè àgbáyé?
Goodluck Jonathan kí Ààrẹ Buhari kú ọjọ́ ìbí Ẹ wo àwòrán tó làmìlaaka níbi ọjọ́ ìbí Gomina ìpínlẹ̀ Ọyọ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Gbogbo ènìyàn ló wọ agbádá ikú, ẹni tó kàn lẹnìkan kò mọ̀ Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Gbogbo wọn ni wọ́n gbà fún un, ẹnu sì yà wọ́n fún ọ̀rọ̀ oore-ọ̀fẹ́ tí ó ń sọ jáde, wọ́n wá ń sọ pé, “Àbí ọmọ Josẹfu kọ́ nìyí ni?
Seyi Makinde ṣèlérí owó oṣù kẹtàlá fáwọn òṣìṣẹ́ Amotekun l' Oyo
Salawa Abeni: Ìpolówó ọjà ni àwòrán tí èmi àti Kolington ti dì mọ́ra, ìfẹ́ kọ́
Oríṣun àwòrán, AFP Orilẹede Iran kọ lati gbọ ọrọ si Trump lẹnu, eleyii to mu ki ọrọ aje wọn dẹnukọlẹ.
Arun yii maa n se atagba ati omode ni, o le ni aadorin milionu eniyan ti o n baja lagbaye ti awon milionu mewaa ti di afoju patapata.
Ó tú ibinu gbígbóná rẹ̀ lé wọn lórí:ìrúnú, ìkannú, ati ìpọ́njú,wọ́n dàbí ikọ̀ ìparun.
Ẹ sọ́ra fún ìwà olè àti jàgídíjàgan nílẹ̀ Yorùbá - Sunday Igboho Ọkan gboogi lara awọn ajafẹtọ ọdọ lorilẹede, Oloye Sunday Adeniyi Adeyemo ti ọpọ eniyan mọ si Sunday Igboho, ti pe fun alaafia laarin awọn ọdọ kaakiri orilẹede Naijiria.
Nígbà tí wọ́n parí, Dafidi pada sí ilé láti súre fún àwọn ará ilé rẹ̀.
Ọlọrun Olodumare yóo rọ òjò ibukun sórí rẹ láti òkè ọ̀run wá,yóo sì fún ọ ní ibukun omi tí ó wà ní ìsàlẹ̀ ilẹ̀,ati ọpọlọpọ ọmọ ati ọpọlọpọ ẹran ọ̀sìn.
Awọn mọlẹbi rẹ to fi iroyin naa lede sọ pe ati ẹbi ati ara lo wa lọ́dọ̀ akinkanju naa nigba to papoda.
ede  Jamaica, lojo Abameta , ojo karundinlogun
Ẹ óo máa rú ẹbọ wọnyi kún ẹbọ sísun ati ẹbọ ohun jíjẹ ati ẹbọ ohun mímu ojoojumọ.
Sìgá mímu ń di èèwọ̀ oògùn ìlera pípé lagbaye Rochas Okorocha, káàbọ̀ sí àwùjọ àwọn gómìnà tí EFCC ń wá - Fayose Èrè ńlá ńbẹ fáwọn obìnrin nínú okoòwò ọ̀fẹ́ ní Áfíríkà Ohun tó wù kí ileẹjọ́ kòtẹ́milọ́rùn sọ, Adeleke kò lè di gómínà Ọ́ṣun - APC Odu ni ẹgbẹ agbabọọlu Liverpool ninu idije UEFA Champions league.
N óo san ẹ̀jẹ́ mi fún OLUWA,lójú gbogbo àwọn eniyan rẹ̀.
Ọwọ́ tẹ Akeem tó fipá bá ọmọbǹrin ọdún 16 sùn létí odò l'Oṣun Ileeṣẹ ọlọpaa ni ipinlẹ Osun ni ọwọ awọn ti tẹ arakunrin kan ti orukọ rẹ n jẹ Akeem Adebayọ lori ẹsun pe o fi ipa ba ọmọbinrin ọdun mẹrindinlogun kan lo pọ leti odo kan ni ilu Ido Ọṣun.
Visa Free Wiwọ Naijiria lai ni 'visa' Aarẹ Muhammadu Buhari kede l'ọdun to kọja pe oun yoo jẹ ki awọn ọmọ ilẹ Africa o maa wọ Naijiria, ti wọn yoo si gba iwe irinna 'visa' ti wọn ba wọle.
Yóo tú àwọn ọmọ ogun ká níwájú rẹ̀, ati ọmọ aládé tí wọn bá dá majẹmu.
"Oríṣun àwòrán, O R Thambo Gẹgẹ bi o ti sọ, ""Ni papakọ O R Tambo ni Johannesburg nikan ṣoṣo ni South Africa, miliọnu mejilelogun arinrinajọ lo n lo papakọ lọdun."
OLUWA sì dáhùn pé, “Saulu ati ìdílé rẹ̀ jẹ̀bi ẹ̀ṣẹ̀ ìpànìyàn, nítorí pé ó pa àwọn ará Gibeoni.
Koda gbajugbaja olorin, Florence Ifeoluwa Otedola ti ọpọ mọ si DJ Cuppy ti banujẹ pe nigba ti oun fi Arsenal silẹ darapọ mọ Man United ni Arsenal bẹrẹ si ni ṣe daadaa.
 Òun ló fà á tí ikojá òdò oya ( river niger ) àwon omo ogun biyafira biafra se já sí pàbó .
Wọn tun jiroro lori ipa ti UK n ko ninu eto ẹkọṣẹ ati tita nakn ijagun fun ileeṣẹ alaabo Naijiria.
Bobrisky: Ìléeṣẹ́ ọlọ́pàá ṣàlàyé ohun tó gbé wọn dé ibi ìnáwó ọjọ́ ìbí
"Ni nkan bi aago mẹfa ku iṣẹju mẹẹdogun ni awọn ọlọpaa to n bojuto oju omi gba ipe ijaya pe ọkọ oju omi akero Mount Zion transport ti n ri somi oo, to si gbe ogun ero lati Badagry.
 Awọn ajoji yoo bẹrẹ si ni di onile lorilẹede Liberia."
Àwọn agbègbè náà ni wọ́n ń gbé, wọ́n sì ní àkọsílẹ̀ ìdílé wọn.
Wọn ni èyí yóò sì níra fún àwọn orílẹ̀-èdè Yuroopu láti sàyẹ̀wò wọn lásìkò ìrìnàjò si orilẹede awọn.
Ṣugbọn bi akọroyin BBC ṣebẹwo si ilu naa, ṣe lawọn araalu n ṣe owo tiwọn lọ ni rẹpẹtẹ lai naani lilo ibomu tabi ṣiṣe ijina sira ẹni.
" Ènìyàn lásán ní ọba ilẹ̀ Yoruba tí kò bá ṣe ètùtù, ẹ má tẹ ìṣẹ̀ṣe mọ́lẹ̀ - Elebuibon Háà, Coronavirus ba ọjọ́ ìbí mi jẹ́ tán, díẹ̀ ló kù, mo yára ṣàtúnṣe sí i - Obasanjo Ẹ wo ọpọ eré ìdárayá nílẹ̀ Yorùbá tó ti ń di ohun ìgbàgbé Coronavirus tún ti ṣe ọṣẹ́ lórí iṣẹ́ líla ojú ọ̀nà relùwe láti Eko sí Ibadan - Ìjọba àpapọ̀ Ẹ̀ṣẹ́ ju ẹ̀ṣẹ́ lọ!
A ti rí ìràwọ̀ rẹ̀ ní ìlà oòrùn, nítorí náà ni a ṣe wá láti júbà rẹ̀.
Lẹ́yìn náà, ó se àsè ńlá fún gbogbo àwọn òṣìṣẹ́ rẹ̀.
Ẹ wá sí ibi ẹbọ ńlá tí mo fẹ́ ṣe fun yín lórí àwọn òkè Israẹli.
Ṣugbọn o ṣeni laanu pe iwe ti Samuel mọ daada naa ni yoo fi opin si iwe kika a rẹ.
Àmọ́ àwọn tí ọ̀rọ̀ mí kàn lónìí ni àwọn oníṣòwò wa.
 Lojo Aiku to koja ni won fagbahan Cameroun pelu ami ayo merin si odo.
Oríṣun àwòrán, facebook/Amotekun Àkọlé àwòrán, Ọjọ kẹsan an Oṣu Kinni ọdun yii ni awọn gomina ipinlẹ mẹfa lati ilẹ Yoruba ṣe ifilọlẹ ikọ Amọtẹkun nilu Ibadan Akọwe ẹgbẹ YCE, Dokita Kunle Olajide ni ọrọ ti agbẹjọro agba fun ijọba apapọ sọ lori ikọ naa ko daa to.
18 Nítorínáà wọn kò lè bá ara mu, àwa yíò sì sọ pé òun ti pa irọ́ nínú awọn ọ̀rọ̀ rẹ̀, àti pè òun kò ní ẹ̀bùn, òun kò sì ní agbára.
Lóru náà ni mo gba àfonífojì Kidironi gòkè lọ, mo sì ṣe àyẹ̀wò odi náà yíká, lẹ́yìn náà, mo pẹ̀yìndà mo sì gba Ẹnubodè Àfonífojì wọlé pada.
Orúkọ wọn yóo máa jẹ́ ẹnubodè Josẹfu, ẹnubodè Bẹnjamini ati ẹnubodè Dani.
N kò bá wọn sọ̀rọ̀, sibẹsibẹ wọ́n ń sọ àsọtẹ́lẹ̀.
Gbigba ile gbigbe: A ti gba ile ni orilẹede Naijiria lera fun awọn obinrin ti ko ba ti i lọkọ tabi ni afẹsọna nitori awọn onile a kọ lati fun wọn ni ile gbe nitori wọn ko ni ọkọ.
Gbogbo àwọn ará Juda tí wọ́n wà ní Ijipti ni ogun ati ìyàn yóo pa láìku ẹnìkan.
Ibeere ti ọpọ ọmọ Naijiria n beere ni yii lẹyin ti aba eto iṣuna ọdun 2020 fihan pe ida aadọrun un le kan ni ileeṣẹ ọlọpaa atawọn ologun yoo na lori owo oṣu.
Òmìrán kan tí ń jẹ́ Iṣibibenobu, gbèrò láti pa Dafidi.
Ibudo idibo to wa ni ile-ẹkọ awon amofin Mohammed Goni( College of Legal
A sì fún un ní agbára láti jọba.
 Àwọn olórò ìlú kan lè mú orò wọn dé ìlú mìíràn láìsí ìjà láìsí ìta .
“Ṣugbọn Abrahamu dá a lóhùn pé, ‘Wọ́n ní ìwé Mose ati ìwé àwọn wolii.
Gbogbo ohun ìní yín, èmi lẹ fi tọ́jú, kò sì sí nǹkan tó kù lóde ayé yìí tí ẹ kò fi kẹ́ mi.
2 131264 Orilẹede El Salvador 1469 22.
Oríṣun àwòrán, Femi Ojudu/Kayode Fayemi Facebook Neo n fọ pátá Vee nílé ẹlẹ́gbọ́n àgbà BB Naija, wo ohun táwọn olólùfẹ́ ètò náà n sọ Ọgbọ́n àti kówójẹ n'ìgbèsẹ̀ ìjọba láti ná $1.
O ni: Ara Salah ti ya, a ni ireti pe yoo gba bọọlu pẹlu ara lile."
Michael Jordan: $560,000 ni wọn lu gbàǹjo bàtà ìlúmọ̀ọ́ká agbábọ́ọ́lùù àlápẹ̀rẹ̀ náà fún ẹ̀ṣọ́ ilé
    Nígbà tí a yí ilé náà po tán tí a padà dé ibi tí a ti kọ́ jókòó, a rí i pé ọba kò tíì wọlé.
Jeremy Hunt ni òun gbà pé Boris Johnson á ṣiṣẹ́ dáadáa Dalung, Audu Ogbe, Shittu Adebayo àti Isaac Adewole kò wọlé Ìbọn ọlọ́pàá ló pa èèyàn, ẹgbẹ́ wa kìí lo ìbọn - Shiite fárígá 5:30 p.
Nígbà tí a yà ní ilé rẹ̀, ìyàwó rẹ̀ ní ìrọ̀lẹ́ àná ni inú kan tí ń dà á láàmú, tí kò gbádùn.
Awọn owe yii la lee fi se akawe iwa aidaa ti afurasi ọkunrin kan, Ashimu Aliyu, ẹni ogoji ọdun hu, ẹni ti wọn fura si pe o kundun ko maa ba awọn ọmọ ọwọ lopọ.
Yóo wá kọlu ilẹ̀ Ijipti, yóo jẹ́ kí àjàkálẹ̀ àrùn pa àwọn tí yóo kú ikú àjàkálẹ̀ àrùn, yóo kó àwọn tí yóo lọ sí ìgbèkùn lọ sí ìgbèkùn, yóo sì fi idà pa àwọn tí yóo kú ikú idà.
Amọ, awọn eniyan ti bẹrẹ si ni fesi loju opo Twitter pe, ọna ati ọgbọn lati jẹ ki ẹya Hausa nikan ma a ṣe ijọba lorilẹede Naijiria ni wọn n wa.
Bẹtẹli wà ní ìhà ìwọ̀ oòrùn ibùdó rẹ̀, Ai sì wà ní ìhà ìlà oòrùn.
Eniyan rere ni Josẹfu ọkọ rẹ̀, kò fẹ́ dójú tì í, ó fẹ́ rọra kọ̀ ọ́ sílẹ̀ ní bòńkẹ́lẹ́.
Òun yóò se ọbẹ̀ tí ó jọjú kí njẹ-ẹ́ pẹ̀lú ẹran ìgalà àti iyán tí ó gbámúṣé; odidi ọ̀yà kan lòun yóò sì gbé fún mi relé lẹ́hìn tí mo bà gbádùn ara-à mi tán.
Akonimoogba agba iko agbaboolu Liverpool, Jurgen Klopp ti gbosuba kare lai fun iko re leyin ti won ja iko agbaboolu akegbe won Manchester City jade kuro ninu idije Uefa Champions League pelu ami-ayo meji sookan(2-1) , lati pegede sipele keji si asekagba idije ohun.
Ọkan lara awọn olupẹjọ naa, Aloys Onyango sọ fun ile ẹjọ pe ko paṣẹ fun awọn alaṣẹ ọgba ẹwọn lati sanwo oṣu oun fun ọdun mẹrindinlogun t'oun lo lẹwọn.
Keyamo: Cocaine tí ò ń fà ní o da orí rẹ rú
won ko o wa lati ilu okeere,awon igi ti won lo, lo jẹ pe o wa lati inu omi ti
Idi ni pe atamatase ti ẹ n wo yi ni agbabọọlu ti wọn n san owo julọ fun ni ilu rẹ.
Sanitáísa leé ba ìwé ìtẹ̀ka ìbò jẹ́ - Àjọ CDC kìlọ̀ Ibi ti ajakalẹ arun Coronavirus bá orilẹede Amẹrika de ti ni ipa nla lorii idibo wọn.
Ni tirẹ, oun naa kede loju opo Twitter pe oun ti ya ara oun sọtọ fun itọju bayii bo tilẹ jẹ pe ko fi ami kankan han lara rẹ pe o ni arun Covid-19.
Ẹnikẹ́ni tí ó bá ṣe àwọn nǹkan tí a dárúkọ wọnyi di ohun ìríra níwájú OLUWA, ati pé nítorí ohun ìríra wọnyi ni OLUWA Ọlọrun yín ṣe ń lé àwọn orílẹ̀-èdè jáde fun yín.
Ibẹ̀ ni mo wà tí mo rí àwọn ọmọ Ẹlẹ́gbára tí wọ́n ń kọjá lọ, mo rí wọn dáadáa.
Àkọlé àwòrán, Ọjọgbọn Wọle naa ti darapọ mọ awọn ọmọ Naijiria kan lati tọkasi aleebu isejọba aarẹ Muhammadu Buhari Ọpọ asise to kun inu ijọba Buhari lo jẹ afọwọfa Soyinka wa mẹnuba igbesẹ bi Buhari se pe akọwe apapọ fun ajọ to nse amojuto eto adojutofo nidi ilera (NHIS), Usman Yusuff pada sẹnu isẹ, lẹyin ti minisita feto ilera, Ọjọgbọn Isaac Adewọle ni ko lọ rọọkun nile na nitoripe o se owo ilu basubasu, gẹgẹ bii apẹrẹ kan to n safihan pe oniruuuru asise afọwọfa lo kun inu isejọba Buhari dẹnu.
Akon bale si papako-ofurufu olu ilu orile-ede ohun, Addis Ababa pelu iyawo re, Rozina Nigussie fun ajoyo ayeye nla naaBakan naa, yatosi wiwa lati sajoyo odun méjìlélọ́gọ́fà ijagbara ogun Adwa yii, Akon lo anfani ohun lati ro ajo A.
UK, Europe, US, Canada: Ọ̀pọ̀lọ̀pọ̀ ọkọ̀ ayókẹ́lẹ́ ló ti rì sàbẹ̀ yìnyín
Awọn agbabọọlu naa ko ti i gba ẹgbẹrun mẹwaa Dọla, to yẹ ko jẹ owo ajẹmọnu fun pe wọn dije, ti wọn ṣe ileri rẹ fun ẹnikọọkan wọn.
Ìyàwó Gbenga Adeboye àti àwọn ọmọ wọn David àti Elijah.
Láti inú ẹ̀yà Aṣeri, ọ̀kẹ́ meji (40,000) ni àwọn ọmọ ogun tí wọ́n ti dira ogun.
Paulu wá pe ọ̀kan ninu àwọn balogun ọ̀rún, ó ní, “Mú ọdọmọkunrin yìí lọ sọ́dọ̀ ọ̀gágun, nítorí ó ní ọ̀rọ̀ kan láti sọ fún un.
 Egbe oselu APC wa ro ajo to n mojuto eto idibo ati ile-ise alaabo lati se ise won bi ise, ki won maa se fayegba iwa ohun ni awon eka ibudo idibo gbogbo.
Gbogbo eniyan bá tẹ̀lé e pada, wọ́n ń fọn fèrè, wọ́n ń hó fún ayọ̀.
Awon eniyan woye wi pe ko le si ariyanjiyan.
O ti figba kan jẹ amofin to n mojuto ọrọ igbogunti iwa ipa si awọn ọmọde ati obinrin ni ẹkun Manhattan ni New York ni Amẹrika.
Alaṣe ijọba maa n waye nibi ti wọn yoo ti jọ ṣagbeyẹwo awọn ohun to yẹ
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Òwò ẹrú ọmọdé àti obìnrin lórí ayélujára Aàrẹ, igbákejì aàrẹ àti aàrẹ ilé ìgbìmọ̀ aṣòfin kọ̀wé fipò sílẹ̀ lọ́jọ́ kan náà Ẹ̀yin mùsùlùmí, ẹ yé jẹ́ káwọn alákatakítí ẹ̀sìn b'ọmọ yín láyé jẹ́ - Buhari Mo ní àwọn ẹ́rì pé Ààrẹ Buhari fẹ́ dupò fún sáà kẹta - Femi Falana Makinde vs Adelabu: Ilé ẹjọ́ tó ga jùlọ ní Nàìjíríà ní yóò yanjú ọ́rọ́ ìdìbò Gómìnà Oyo Ọmọ Ken Saro-Wiwa bu ẹnu atẹ lu igbesẹ ijọba lati bẹrẹ iwapo ni agbegbe naa, ti o si ni wi pe awọn eniyan gbodo dide lati ja fun ẹtọ agbegbe naa.
Amọ, onikaluku lọ lọna tirẹ lẹyin ti oun ri ihuwasi to yatọ ninu ihuwasi Saheed.
Àkọlé àwòrán, Awon alawo funfun ti won wa yẹ ayẹyẹ ọdún náà Àkọlé àwòrán, Aworan lati ibi ojubọ.
Agbẹ̀bí náà bá wí pé, “Ṣé bí o ti fẹ́ rìn nìyí, ó hàn lára rẹ.
Lọdun 2014 si ni ile ẹjọ to ga julọ nilẹ wa gbe idajọ kalẹ lati ẹnu adajọ agba tẹlẹ ni Naijiria, Walter Onnoghen pe ilana to gbe ọba Falabi de ipo bii Akire, ku díẹ̀ kaato.
14 Èbibi 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 17 Èbibi 2020 Ajakalẹ arun coronavirus lo ti gba ọpọlọpọ ẹbọ lọwọ gbogbo agbaye lati oṣu kejila, ọdun 2019 to ti bẹrẹ ni Wuhan lorilẹ-ede China.
Nígbà tí ó di ìrọ̀lẹ́, tí oòrùn wọ̀, àwọn eniyan bẹ̀rẹ̀ sí gbé gbogbo àwọn tí ara wọn kò dá ati àwọn tí wọ́n ní ẹ̀mí èṣù wá sí ọ̀dọ̀ rẹ̀.
Igbe aye awọn eeyan yoo si tubọ pegede sii , tileesẹ iroyin kan ba n pese iroyin fun wọn ni ede abinibi wọn.
Ni ọjọ Ẹti ni alaga ajọ Inec lorilẹede Naijiria gbe igbimọ kalẹ lati se agbeyẹwo ẹsun ti wọn fi kan ajọ naa laipẹ yii wipe o n gba awọn majesin laaye lati fi orukọ silẹ dibo ni ipinlẹ Kano.
Ó kó àwọn nǹkan tí Abija, baba rẹ̀, ti yà sí mímọ́ fún Ọlọrun lọ sinu tẹmpili pẹlu gbogbo nǹkan tí òun pàápàá ti yà sí mímọ́: fadaka, wúrà, ati àwọn ohun èlò.
Gbogbo ẹ̀yìn agbada yìí ni ó ya àwòrán mààlúù sí ní ìlà meji meji yíká ìsàlẹ̀ etí rẹ̀.
Ibẹrẹ aye Eji Gbadero: Jimoh Isola Adeyemi ni orukọ abisọ ọkunrin ta n sọrọ rẹ yii, ti awọn inagijẹ rẹ si n jẹ Eji Gbadero, Kiniun baba Moradewun ati Kiniun Mushin, ṣe orukọ to ba wu ọmọ nii jẹ lẹyin odi.
Oríṣun àwòrán, Saheed Balogun/Instagram Saheed Balogun gbẹyin iya rẹ Mama Arikẹ Jọlade.
Bí omi náà ti ń pọ̀ sí i ni ọkọ̀ náà ń lọ síhìn-ín sọ́hùn-ún lórí rẹ̀.
"Àwọn agbófinró ti mú Eji tó jẹ́ ìgbákejì Ebila, olórí ẹgbẹ́ òkùnkùn ""One Million Boys"" sí gbaga Ọwọ́ ọlọ́pàá tẹ afurasí ọkùnrin tó gé akẹ́kọ̀ọ́ ọ̀rẹ́bìnrin rẹ̀ wẹ́lẹ́ wẹ́lẹ́ fún òògùn owó ní Ikorodu Áṣẹyin kìlọ̀ fáwọn adarí olóṣèlú Nàìjíríà láti ṣe ohun tó yẹ nítorí ará ọ̀run ń wò wọ́n!"
"Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Saa kẹta tọ si Ajimọbi - Olubadan ‘Èmi kò leè gbà kí Ọba Ìbàdàn di 48 Ta ni Aminat Abiọdun, Ìyálóde ilẹ̀ Ìbàdàn tó d'olóògbé ""Bi Olubadan se ni ka si ade ori wa, to ni ‘ko bofin mu’, kii se ohun to dara."
OLUWA ní, “Àwọn olùṣọ́-aguntan tí wọn ń tú àwọn agbo aguntan mi ká, tí wọn ń run wọ́n gbé!
Ọjọ Aiku ni fidio kan gba ori ayelujara, eyi to ṣafihan Florence, nibi to ti n tahun si igbakeji gomina ipinlẹ Ọyọ, Rauf Olaniyan, pe wọn ko ba oun kẹ́dùn iku ọkọ oun.
Bo tilẹ jẹ pe Kabiesi ni wọn kọ ara wọn silẹ lataari awọn iyatọ to wa laarin wọn ti ko ṣee yanju.
Wọn fẹsun kan afurasi naa, ti awọn obi rẹ jẹ ọmọ bibi ipinlẹ Sokoto, pe o ti aburẹ rẹ ọkunrin sinu kanga.
Ẹgbẹ agbabọọlu Tottenham ti Jose Mourinho jẹ akọnimọọgba wọn lo si wa loke tente bayii lori tabili idije EPL.
Fifi okan si ati sise asaro naa tun jẹ ọna miran lati fopin si iru nkan wọnyii, Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Neha Sharma: obìnrin tó ń múra bíi ọkùnrin láti leè ṣiṣẹ́ gẹrígẹrí Imọran fun ọ ni pe ki o maa ro asaro lori rẹ ko si gbe ọkan rẹ kuro nibẹ ni kia.
Bi wọn ṣe n ba ọrọ naa lọ, kan lara awọn ọrẹ rẹ ni lae ko le ba Amaka mọ oloṣo dan an wo tori wọn ṣe apejuwe rẹ gẹgẹ bi ẹni ti wọn gba lọga ninu ibalopọ.
O ni ọpọ eeyan lo n rin kiri pẹlu aarun coronavirus lai mọ.
dibo wọn ni irọwọ ati irọsẹ, paapaa julọ ni agọ idibo Aliyu
Switzerland ati Colombia ti ko ẹrù wọn pada sile.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Seyi Makinde: Wo ìdí tí gómìnà Oyo fi pàṣẹ ìdádúró iṣẹ́ fún kọmíṣọ́nà rẹ̀ 10 Ògún 2020 Àkọlé àwòrán, Seyi Makinde: Wo ìdí tí gómìnà Oyo fi pàṣẹ ìdádúró iṣẹ́ fún kọmíṣọ́nà rẹ̀ Gomina ipinlẹ Oyo, amojuẹrọ Seyi Makinde ti paṣẹ idaduro lẹnu iṣẹ fun Kọmiṣọna iṣẹ ode, eto amayedẹrun ati irina, Ọjọgbọn Raphael Afonja.
Coronavirus cases: Àjọ WHO ní ọ̀rọ̀ àrùn coronavirus ti di èyí tí yóò máa bá ọmọnìyàn gbé láéláé
Abadofin kan lori lile eeyan kuro ni orilẹede naa lo tan ina wa ibinu araalu nibẹ.
Ìran tí Peteru rí yìí rú u lójú.
Aare orile-ede Amerika, Donald Trump ti fesun iberu egbe awon to ni ibon, iyen National Rifle Association, NRA, kan awon omo ile igbimo Asofin lati egbe oselu mejeeji nile Amerika.
Tí ẹ bá ń ṣe èyí, kò ní sí ìdènà ninu adura yín.
Ìkáwọ́ rẹ̀ ni mànàmáná wà,ó sì ń rán ààrá láti sán lu ohun tí ó bá fẹ́.
Nig vs Argentina: Óyá ẹ mú olóngbo àti ẹlẹ́dẹ̀ wọ̀nyẹn wá Kìnìún tí wọn ń sìn yarí, ó pa olówó ati ọmọ olówó rẹ̀ Kí ló yẹ ká se sí ẹkùn tó pa ènìyàn márùń?
G'ẹ́gẹ́bí olùdarí Arsenal, Wenger mú oríṣiríṣi àrínyànjiyàn wá láàrín àwọn olólùfẹ́ ẹgbẹ́ agbábọ́ọ̀lù náà.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Lara awọn awọn igbesẹ ọhun ni pe ẹlẹsẹ ayo Luis Suarez at'awọn mii yoo ni lati fi ẹgbẹ agbabọọlu naa silẹ.
 lára àwọn ìlú náà ni Ọ ̀ yọ ́ -ilé , ahoro Òkò , Ìkòyí , ilé igbọn , Ìrẹsà àti bẹ ́ ẹ ̀ bẹ ́ ẹ ̀ lọ .
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Mobile Wash: iṣẹ́ fífọ́ mọ́tò tà ni mó yàn láààyò- Slay Mama Lọdun 1837, ajakalẹ aarun mii bẹ silẹ niluu mimọ eyi to jẹ ki wọn wọgile eto Hajj titi di ọdun 1840.
Ní ọdún kẹta ìjọba rẹ̀, ó pe àwọn marun-un ninu àwọn ìjòyè rẹ̀: Benhaili, Ọbadaya, ati Sakaraya, Netaneli, ati Mikaya, ó rán wọn jáde láti máa kọ́ àwọn eniyan ní ilẹ̀ Juda.
nipa ikọlu awọn ọmọ orilẹ-ede Naijiria ti wọn n gbe ni orilẹ-ede South
O salaye pe Iya Rainbow maa n gba awọn ni imọran bii ẹni pe o mọ ohun to fẹ sẹlẹ lọjọ iwaju ni, ẹnikẹni to ba si tapa si imọran iya naa yoo ge ika abamọ jẹ nigbẹyin ni, idi si niyi ti oun se n pe Iya Rainbow ni Ajẹ pọnbele.
O ni awọn oṣiṣẹ wọn ati awọn ọlọpaa ni ẹtọ lati da abo bo ara wọn ni asiko ti wọn ba ri ikọlu lojukoroju.
Ní gbogbo ibi gíga, ati àwọn orí òkè ati abẹ́ gbogbo igi ni Ahasi tií máa rúbọ, tíí sìí sun turari.
”Ewe, aare Maria tun gbosuba kare lai fun
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù World TV Day: Èwo nínú àwọn amóhùnmáwòrán yìí lẹ rántí?
Awọn eeyan ma n mu ẹbẹ adura wa fun awọn ẹbi wọn.
Bi a ko ba gbagbe arun coronavirus yii naa ti ṣọṣẹ laarin awọn ilumọọka ati wọọ-ki-ilu-mọ kaakiri agbaye.
Awọn ni wọn bori ninu idije wọn pẹlu orilẹ-ede USA to dara julọ ni agbaye lọdun 2011.
O tilẹ maa n gba iṣẹ́ lọwọ minisita ti ko ti ẹ ri soju ri.
Ṣugbọn alukoro ileeṣẹ ọlọpa ipinlẹ Eko, Chike Oti, kọ̀ lati fi idi eyi mulẹ fun akọroyin BBC, tabi sọ bi iṣẹlẹ naa ṣewaye ati ibi ti nkan de duro.
O fikun pe, lẹyin to tẹ oun lori ati ẹnu tan, ni Wasiu to wa sẹsẹ tun n gbe oun lori dide, eyi ti ko bojumu rara.
ni lati gbaruku ti eto naa, ki o lee se aseyọri.
Ìtìjú ni yóo bò yín dípò ògo.
Ninu fidio naa, niṣe ni Paitọ n tahun si Kweku Perry ọmọ iya iyawo Pasitọ lọkunrin nitori pe Pasitọ naa n lu iyawo rẹ Lasiko ti awọn mọlẹbi rẹ tẹle lati wa ko ẹru kuro ninu ile Pasitọ Ofori ni iṣẹlẹ yi waye.
Maina dákú fún ọ̀pọ̀ ìṣẹ́jú, iléejọ́ sáré so ìjókòó rọ̀ Oríṣun àwòrán, @IamOhmai Iroyin to n tẹ wa lọwọ ni yajoyajo ti kede pe alaga tẹlẹ fun ajọ to n se akoso owo ifẹyinti, Abdulrasheed Maina ti dku nile ẹjọ.
Gege bi abajade eto idibo to waye lojo abameta(Saturday), “Luisa Damiao ni igbakeji aare orile-ede Angola bayii.
Jókòó ní ilẹ̀ẹ́lẹ̀, láìsí ìtẹ́-ọba,ìwọ ọmọbinrin Kalidea.
Kokoko ni aawọ APC Kaduna nle si ‘Aawọ abẹnu lee koba APC ni 2019’ Wọn fikun wipe, awọn ọlọpa to tete koju isẹlẹ naa, ni ko jẹ ki ọrọ naa di ti ija ẹsin.
Rakẹli wí fún baba rẹ̀ pé, “Jọ̀wọ́, oluwa mi, má bínú pé n kò dìde lójú kan tí mo jókòó sí, mò ń ṣe nǹkan oṣù mi lọ́wọ́ ni.
"Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé Ajafẹtọ ẹni naa fi kun pe ""kii ṣe pe mo n ja fun ominira Yoruba nitori mo n wa ipo tabi orukọ fun ara mi, ṣugbọn mo fẹ jẹ ọkan lara awọn to ja fun isọkan ati irẹpọ Yoruba."
Ọlọrun, jẹ́ kí àwọn eniyan rẹ máa bẹ̀rù rẹ láti ìran dé ìran,níwọ̀n ìgbà tí oòrùn bá ń ràn, tí òṣùpá sì ń yọ.
Muhammed Isah wi pe ko si ẹnikẹni ninu awọn minisita tuntun naa ti wọn yoo ṣebura wọle fun lai kọkọ kede dukia wọn.
Wọn kò wá mọ ìdáhùn tí wọn ì bá fi fún un mọ́.
Alaafin Ọyọ ni imulẹ nla lo n bẹ laarin oun ati Gomina Seyi Makinde, nitori naa ko si ohun to lee fa ikunsinu laarin oun ati gomina naa.
Ṣugbọn Pilatu dá wọn lóhùn pé, “Ohun tí mo ti kọ, mo ti kọ ọ́ ná.
Naijiria, lọjọ Isẹgun leyin ti won ba ti bura fun aare naa tan.
Inú àwọn eniyan náà dùn pé wọ́n fi tinútinú mú ọrẹ wá nítorí pé tọkàntọkàn ati tìfẹ́tìfẹ́ ni wọ́n fi mú ọrẹ wá fún OLUWA; inú Dafidi ọba náà sì dùn pupọ pẹlu.
 ní déédé ọmọ ọdún mẹ ́ rìnlá ( age 14 ) , johnson lọ sí < nowiki > oakland < / nowiki > , ìpínlẹ ̀ < nowiki > california < / nowiki > ó kàwé ní ilé-ìwé gíga ti oakland technical high school ó sì kẹ ́ kọ ̀ ọ ́ gboyè ní ọdún 1984.
Ọkùnrin mẹ́ta, Baba-onírùngbọ̀n-yẹ́úkẹ́, ẹni tí ń gbé ibi gegele òkúta.
”Ipinlẹ Eko gẹgé bii ibudo igbafẹ:Ogbẹni Akinwunmi Ambode fi ye wọn pe ipinlẹ Eko ti n ṣiṣẹ tipẹ lori amojuto awọn ibudo igbafẹ ati orisun aṣa gbogbo kakairi ipinlẹ naa.
Eyi jẹ ki ipinle Èkó mókè ju gbogbo ìpínlẹ̀ yókù lọ.
Abd-Ganiy Adekunle Salaueen Oloogunebi Ajinese 1 fikun un pe igba ati akoko gomina Seyi Makinde yoo rọ wọn lọrun.
Jubril Martins-Kuye: Mínísítà lẹ́ẹ̀méjí, Jubril Martins-Kuye ti jáde láyé
Won tun ro ajo naa lati ri i pe awon osise ti won fọwọsi
Ṣugbọn Dokita Brown sọ pe ọpọlọpọ obinrin to ni oyun iju kii ri ami kankan.
Ẹ kò ì tíì ní igbagbọ sibẹ?
Ìtura ẹnu ọ̀nà ilé ọmọ (Cervical Orgasm) Eyi jẹ ọkan lara àwọn ọ̀nà pataki ti obinrin fi maa n gba itura lasiko ibalopọ, paapa ti nkan ọmọkunrin ba wọ inu oju ara daada.
Wọ́n tún ti fipá bá akẹ́kọ̀ọ́bìnrin míì ọmọ pásítọ̀ lòpọ̀ l'Akinyele n'Ibadan wọ́n sì tún pa á Kollington, Bàbá Suwe, Ogun Majek wà lára àwọn gbajúmọ̀ òṣèré tí ayé ti parọ́ ikú mọ́ sẹ́yìn Coronavirus Updates: Àì gba ìwé àṣẹ ìjọba ṣàkóbá fún sinima orítá ọmọkùnrin yìí June 12: Sadik ní àwọn tó ṣiṣẹ́ pẹ̀lú Abacha ní kò kówó jẹ, ó fi pamọ́ fún ìdí kan ni Eeyan 5101 lo ti ri iwosan gba, nigba ti awọn 407 ti dero ọrun nitori arun ọhun.
Ó dá quincy herbals sílè pẹ ̀ lú ẹgbẹ ̀ dọ ́ gbọ ̀ n naira .
iko agbaboolu Rennes fun miliọnu meje owo ile okere pọunds,  eleyi ti o jẹ owo to pọju lọ ti wọn san fun
 bakanna mọ ́ rna àti dna iye nínlá àwọn a large number of artificial núkléì kíkan ajọra aláfọwọ ́ dá náà tún ti jẹ ́ dídá láti le ṣe àgbékà àwọn ohun ìní núkléì kíkan , tàbí fún lílò nínú ọ ̀ rọ ̀ oníṣẹ ́ ọ ̀ nàalàyè .
Ìtàn Mánigbàgbé: Ṣé òótọ́ ni pé èpè Alaafin Aole ń ja Yorùbá?
Mo dùbúlẹ̀ láìlè sùn,mo dàbí ẹyẹ tí ó dá wà lórí òrùlé.
ti jẹ anfaani gbigbogun ti iwa ibajẹ lawujọ bayii , ni eyi ti aare Muhammadu
Ní ti Ọlọrun, ọ̀nà rẹ̀ pé,pípé ni ọ̀rọ̀ OLUWA;òun sì ni ààbò fún gbogbo àwọn tí ó sá di í.
Niger Delta, ogbeni Festus Keyamo,ni  wọn ti gbe lọ lati jẹ minisita
4M) lọwọ rẹ lasiko to n lọ sile ifowopamọ ladugbo Dugbẹ.
Ọba tó ṣe fi yangàn láàrín ọba Nàìjíríà ni Ọlọ́fà ìlú Offa-Oluwo Kíni Gómìnà ìpínlẹ̀ Ekiti, Kayode Fayemi ṣe fun baba tó ni ọmọ òun ko gbọdọ tèlé oun déle?
''Lootọ lawọn onwoye ibo kan to jẹ ti abele maa n gbabọde fun awọn oloselu kọọkan ṣugbọn ni ti awọn to n bọ lati ilẹ okere wọn kii figba kan bọ ikan ninu'' Oríṣun àwòrán, SEYLLOU DIALLO/AFP/GETTY Àkọlé àwòrán, Awọn ọdọ wọnyi n fa wahala lẹyin esi idbo ọdun 2011 nilu Kano Moshood tẹsiwaju pe awọn oloseelu ni lati ṣọra fun ọrọ to le da 'rogbodiyan silẹ laarin awọn ara ilu paapa julọ bi eto idibo ti ṣe n kan lẹkun bayi ni Naijiria.
Nítorí èyí, nígbà tí ẹ bá péjọ sí ibìkan náà, kì í ṣe Oúnjẹ Alẹ́ Oluwa ni ẹ̀ ń jẹ.
Oríṣun àwòrán, Akereolu/Facebook Akeredolu tun dupe lọwọ aarẹ Muhammadu Buhari ati igbakeji rẹ, Yemi Osinbajo fun atilẹyin wọn saaju ati lasiko idibo naa.
Ó wá gbọ́ ohùn ẹnìkan tí ó bi í pé, “Saulu!
  Ṣùgbọ́n fún ẹni tí ó ní ìgboyà, àwòrẹ́rìín ni eléyìíjẹ́.
Dafidi sá kúrò ní ìlú Gati, lọ sinu ihò òkúta kan lẹ́bàá Adulamu.
Amẹ́rika dá akẹ́kọ̀ọ́ padá nítori Facebook Koda aarẹ Muhammadu Buhari funrarẹ ko ṣai mẹnu le ọrọ yii nibi ipade idagbasoke Afirika to lọ ṣe ni Japan.
re ohun yoo maa gbese fun saa merin tuntun miiran ti o wa ninu re yii .
 lágbayé ní 2012 , iye ìṣẹlẹ ̀ lílé ti ẹ ̀ tẹ ̀ jẹ ́ 189,000 àti iye ìṣẹlẹ ̀ titun jẹ ́ 230,000 .
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Àrìnfẹsẹ̀sí - Ìbéèrè ni a bèrè lọ́wọ́ àwọn èèyàn, ika òṣì ni wọ́n ń ta dànù OGUN: Ogun yii jẹ orukọ ti wọn fun aawọ ati iporogan to ba n waye laarin ilu meji tabi ju bẹẹ lọ.
Saunders gba okun igbadi ohun fun igba meta bayii, ti o si fagbahan David Lemieux ninu ifagabaga keyin ti o waye ni Canada.
O fi kun un pe, ki gomina MAkinde to ni arun Coronavirus lo ti maa n jẹ awọn nnkan wọnyii.
Wọn yóo dárò rẹ, wọn yóo máa wí pé, ‘Ó ṣe, oluwa mi,’ nítorí pé bẹ́ẹ̀ ni èmi OLUWA ṣe ìlérí; èmi ni mo sọ bẹ́ẹ̀.
Wo bí o ṣe leè lo èròjà agbohùnsílẹ̀ tuntun tí Twitter gbé dé Awọn eeyan ti n pariwo lori ayelujara atawọn opo ikansiraẹni gbogbo lẹyin ti ileeṣẹ Twitter kede pe awọn ti gbe eroja kan dide loju opo wọn eyi to lee mu ki awọn eeyan maa ka ohun wọn lati fi ranṣẹ pẹlu akọsilẹ wọn gbogbo lori Twitter.
Èmi kì í ṣe ẹni tí ẹ rò.
Àwọn aláṣẹ tí ó sì wà, Ọlọrun ni ó yàn wọ́n.
World TB Day: Funkẹ Dosumu ni ikọ́ ife kìí pani, ta bá lo òògùn rẹ̀ déédé
Amasaya bèèrè lọ́wọ́ wolii náà pé, “Kí ni kí á ṣe nípa ọgọrun-un talẹnti tí mo ti fún àwọn ọmọ ogun Israẹli?
Accra, Central ati Western ni gbogbo oju wa bayii.
Mẹ̀kúnnù 80,000 l'Ọṣun ti j'ànfàaní ètò ìlera láìsan kọ́bọ̀ - Oyetola Sanwo-Olu ń sanwó Eko!
Magun Ẹlẹyin: Bi ọkunrin ba lu Magun yii, yoo maa wa ẹyin kiri ni, to ba si ti rii ni yoo jade laye.
Aarẹ Ọna Kakanfo kilọ fun awọn darandaran fulani
Oríṣun àwòrán, Twitter/@HHShkMohd Àkọlé àwòrán, Ṣaaju ikede yii, awọn arinrinajo igbafẹ le duro ni ilẹ UAE fun aadọrun ọjọ pẹlu iwe irinna alaimọye igba to jẹ ọfẹ.
Wo àwọn òṣèré tíátà Yorùbá mẹ́fà tó bẹ̀rẹ̀ eré ṣíṣe láti kékéré Mo fi ilé yìí dúpẹ́ lọ́wọ́ ìyá mí fún àtìlẹyìn àti àdúrà rẹ̀ - Emmanuella Wo ọ̀pọ̀ àǹfààní tó wà lára ọkọ̀ tó ń lo bátìrì tó sẹ̀sẹ̀ dé Nàíjíríà Buhari, a rántí ìjọba rẹ̀ fún ìyà, ìṣẹ́ àti ebi tó peléke - Araàlú faraya Bàbá àádọ́rin ọdún fún ọmọ-ọmọ rẹ̀ ọdún mẹ́ẹ̀dógún lóyún, lọ̀rọ̀ bá pèsì jẹ Wo iye obìnrin tó bá Ginimbi ọ̀dọ́mọdé olówó kú àti obìnrin to ṣeéṣe kó jogún rẹ̀ ''Aláàfin kìí ṣe ọkùnrin tí wàá jẹ lásán, tó sì wá sálọ - Aráàlú fèsì fún Olorì Anu Wo ọ̀pọ̀ ìgbà tí Ginimbi ọ̀dọ́mọdé olówó ti ṣe àríyá aláṣọ funfun kó tó kú Gbogbo ìgbésẹ̀ Aláàfin láti jí mi gbé ló já sí pàbó, n kò le panumọ́ - Olori Anu Oba Lamidi Olayiwola Adeyemi ni o ṣeni laanu pe awọn kan lo ifẹhọnuhan naa lati da rogbodiyan silẹ, ati ija ẹlẹyamẹya.
Ohun tí a mọ̀ nìyí nípa ìròyìn Ajimobi kú, kò kú, táyé ń gbé kiri Ọ̀rọ̀ ńlá, àwọn adigunjalè ja àgọ́ ọ́lọ́pàá lólè Fatima Ganduje, ìyàwó ọmọ Ajimọbi ní iró ni pé Bàbá ọkọ òun kú!
ó sì gbadura báyìí pé “Ìwọ OLUWA Ọlọrun Abrahamu, oluwa mi, jọ̀wọ́, ṣe ọ̀nà mi ní rere lónìí, kí o sì fi ìfẹ́ ńlá rẹ tí kì í yẹ̀ hàn sí Abrahamu, oluwa mi.
Kọmiṣana ọlọpaa ipinlẹ Kwara, Ọgbẹni Kayode Egbetokun ni agbajọwọ ikọ to ṣawari ile yii pẹlu agbekalẹ iṣẹ ọpọlọ lo mu iṣẹ naa yọri si rere ati pe awọn yoo tubọ tẹra mọ iru igbesẹ yii lati tu aṣiri awọn ibudo mii bii ti eleyi kaakiri ipinlẹ naa.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ọ́lọ́jọ́2018: Aṣọ ń pe aṣọ ránṣẹ́ nílé Ifẹ̀ 29 Owewe 2018 Ìlú Ilé Ifẹ̀ sọkutu wọ̀wọ̀, tí ẹsẹ̀ kò sò gbèrò lásìkò ọdun Ọlọ́jọ́.
Orúkọ àwọn eniyan agbègbè náà, tí wọ́n pada ninu àwọn tí Nebukadinesari ọba Babiloni kó lọ sí ìgbèkùn, tí wọ́n pada sí Jerusalẹmu ati Juda, tí olukuluku wọn sì pada sí ìlú rẹ̀ nìwọ̀nyí.
New Delhi (India) lo wa ni ipo kẹjọ.
ọ̀nà sí ẹ̀gbẹ́ kan, kí ó má fi dí ọkọ̀ wọn lọ́ nà.
" O wa dupẹ pupọ lọwọ awọn ololufẹ rẹ ti wọn pe, tabi gbadura fun nigba ti wọn ri aworan hun, o ni awọn naa ko ni se aisan.
Bakan naa lọdun 2016, ile aṣofin agba kọ aba aarẹ Buhari lati ya owo to le ni biliọnu mọkanlelọgbọn Dọla ($29.
Ní àkókò náà, ìmọ̀ràn tí Ahitofeli bá dá, ni àwọn eniyan máa ń gbà, bí ẹni pé Ọlọrun gan-an ni ó ń sọ̀rọ̀; Dafidi ati Absalomu pàápàá a máa tẹ̀lé ìmọ̀ràn rẹ̀.
Nigba ti ao si fi duro, a ri i pe ina ti n jo ni abẹ ọkọ mi.
Eyi lo mu wọn forikori lati ṣe iwọde, eyi ti ẹgbẹ Iṣokan awọn obinrin Abẹokuta ṣaaju rẹ̀.
Lẹ́yìn náà OLUWA sọ fún mi pé, “Israẹli jẹ̀bi, aiṣootọ, ṣugbọn kò tíì tó ti Juda, ọ̀dàlẹ̀.
Lọ́wọ́ ẹni tí kò ní ni a óo sì ti gba ìwọ̀nba díẹ̀ tí ó ní.
ede Naijiria,  ogbeni  Rotimi  Amaechi lo so eleyii lasiko ti o
Ìjọba kò tú Dasuki àti Sowore sílẹ̀ látàri akitiyan ilẹ̀ Amẹrika- Dasuki Ọkọ̀ agbépo tó da epo nù fa súnkẹrẹ-fàkẹrẹ lòpópónà márosẹ̀ Eko sí Ibadan Ẹ ronúpìwàdà lásíkò ọdún, àti àwọn ìkíni mìrán tó jẹ yọ fún Kérésì Èyí ni 'àbẹ́tẹ̀' àgbo ìgbàlódé Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí 2 sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 2:23 Fídíò, Water Generator: Ó leè ṣiṣẹ fún wákàtí mẹfà, kó tó sinmi, Duration 2,2310 Òkùdu 2020 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
 O tesiwaju pe, apapo awon toro kan gbongbon ati awon omo egbe oselu APC ti yan aare kio ma ba ise re lo.
Ebi oloogbe naa lo fidiẹ mulẹ pe lẹyin aisan ranpẹ ni iku wọle mu Wolii naa to dije dupo aarẹ Naijiria labẹ ẹgbẹ oṣelu National Action Council (NAC).
Agbenuso fun ajo to n ri si iwa –ibaje lorile ede Serira Leone, so pe awon mu won lojo keji  ti aare  Julius Maada Bio se idasile ajo naa, lati gbokun ti iwa-ibaje to ti di gbaju-gbaja lasiko aare ana Ernest Koroma.
Ní kété tí Sioni bẹ̀rẹ̀ sí rọbí,ni ó bí àwọn ọmọ rẹ̀ ọkunrin.
Lẹ́yìn wọn ni Sakuri ọmọ Imiri bẹ̀rẹ̀ iṣẹ́, ó mọ abala tí ó tẹ̀lé e.
Ni ipari, aare Keita tun yan Kamissa Camara gege bi minisita ti yoo maa mojuto oro ile okere, leni ti o ti figba kan tele ri je olugbani-nimoran pataki sile ise aare nipa oro ile-okere.
Ọlọ́pàá àti àwọn olùfẹ̀hónúhàn gbéná wojú ara wọn níbi ìwọ́de Revolution Now Ìwọ́de #RevolutionNow forí ṣánpọ́n ní Ibadan, àgbófinró gbàkóso ojú pópó Sowore àti àwọn ọmọ ẹgbẹ Revolution Now kò ṣẹ̀ ṣófin lórí ìwọ́de, ẹ tú wọn sílẹ̀ - NLC Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, RevolutionNow: Ẹ̀rù ò bàwá, a ṣetan láti wà ní àtì mọ́lé- olùfẹ̀hónúhàn Gẹlẹ to ku ọjọ kan pere ki iye ọjọ ti ijọba ni ko fi wa latimọle o pe ni wọn na iwe ẹsun meje si i eyi to si fun ile isẹ ọtẹlẹ muyẹ laṣẹ lati sọ iye ọjọ atimọle rẹ di marunlelogoji.
Igbimọ to n ri si ọrọ idajọ ati ẹtọ ọmọniyan yoo kede ọjọ kan laarin ọsẹ to n bọ fun ijiroro itagbangba lori aba ọhun.
Òun náà sì tún fèsì, ó ní Olówó-ayé, èmi ni mo wí fún ọ, kò sí nǹkan, koko l’ara ọkùnrin le, ẹ kúu jíjẹ, ẹ kúu mímu, ẹ kú àjẹ-ìbéèrè-ẹni.
O fikun pe nigba miran, ọrọ Oluwa lee ma wa si imusẹ logun ọdun, to si seese ki eyi sokunfa bi awsn eeyan yoo se si irufẹ ojisẹ Ọlọrun naa gbọ.
Okere ní oloju jinjin ti n mẹkun sún Ẹni to ba da ile NGO silẹ nítori òṣèlú O ni Jibiti ni"" Ogunbanjọ Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!"
Nígbà tí Jesu jáde ninu ọkọ̀ ó rí ọpọlọpọ eniyan, àánú ṣe é nítorí wọ́n dàbí aguntan tí kò ní olùṣọ́.
Ilé Asòfin: Buhari kò fi asojú South-South, South-East sínú olùdarí EFCC
 Àwọn ará ilé Ọ ̀ rúntọ ́ gbà fún odùduwà láti jẹ ́ olórì wọn nítorì pé alágbára ni .
Yatọ si eyi, wọn tun kede apapọ iye ti olukopa kọọkan jẹ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Farms to You: Irú ajílẹ̀ wo ló yẹ fún lílò lásìkò yìí- Aisha Bí àwọn ọ̀rọ̀ náà àti ìtumọ wọ́n ṣe lọ rèé nínú Iwe ìtumọ Oxford English Dictionary Ọ̀gá ọlọ́pàá tó wà ní 'Check Point' kàgbákò ikú òjijì lọ́wọ́ awakọ̀ l'Eko Ara gbígbóná, èébì, ara ríro, àti àwọn àpẹẹrẹ mìrán tí ibà Lassa máá n fihàn Ààrùn ‘Coronavirus’: Ẹ yé rìnrìn àjò lọ sí ìlú Wuhan mọ́ Olanrewaju Bamidele fi 'Screw driver' gún ìyáwo rẹ̀ pa Ibà Lassa bàlẹ̀ sí ìpínlẹ̀ Enugu!
Buhari kàn ń kọwọ́ bọ̀wé nílẹ̀ òkèèrè kiri ni, a ò rí ipa ní Nàijíríà- Onímọ̀ ọrọ̀-ajé Ilẹ̀ Gẹ̀ẹ́sì yóò kúrò pátápátá lára àjọ EU ní Jan 31 ọdún 2020 Àwọn òńkọ̀wé ń dárò Okediji tí kò bá pé ẹni ọdún 90 lókè eèpẹ̀ lónìí Ọdun 2018 ni ọga ile isẹ irinna Naijiria sọ wi pe Osu Kejila, ọdun 2018 ni awọn eniyan yoo bẹrẹ si ni lo iwe irinna tuntun naa.
Oríṣun àwòrán, Dbanj Àkọlé àwòrán, Dbanj ni gbogbo ipenija yoowu ti o lee koju oun tabi ẹbi oun, iyawo oun ni iyawo oun yoo ma jẹ o Lati igbayi wa, DBanj yẹra fun ikanni ayelujara gbogbo titi di ibẹrẹ oṣu keje to gbe atẹjade kan jade ninu eyi to ti dupẹ fun atilẹyin gbogbo eeyan to ṣugbaa rẹ.
Ati pe ko ẹnikẹni ko ni le ri kaadi idibo gba titi di ẹyin idibo.
Lọ́jọ́rú ọjọ́ kẹ́wàá oṣù kẹ́wàá ni èyí wáyé lórí ẹ̀sùn pé wọ́n dá òṣìṣẹ́ ogún dúró lẹ́nu iṣẹ́.
Eyi ni esi ifesewonse idije Nigeria Professional Football League (NPFL), ti o waye lojo Aiku(Sunday):MFM FC 0-0 Lobi Stars FCEnyimba International 2-1 Sunshine Stars FCKwara United 0-1 Rivers UnitedWikki Tourists 1-1 Katsina UnitedRangers International 1-1 Kano PillarsYobe Desert Stars 2-0 El-Kanemi WarriorsNiger Tornadoes 2-0 Abia WarriorsFC IfeanyiUbah 1-0 Nasarawa United.
" Àbíkéjì yemọja tó jẹ ́ obìnrin tí orúkọ rẹ ̀ ń jẹ ́ "" gẹ ̀ lẹ ̀ dẹ ́ "" ni ó sanra gẹ ́ gẹẹ ́ bí ìyá wọn , tí ó dì fẹ ́ ràn ìyá wọn gidigidi , tí òun náà sì fẹ ́ ràn láti ma jó ."
Ní ọdún 2011 ni wọn ṣe òfin pé ẹgbẹ̀rún méjìdínlógún naira ni yóò máà jẹ́ owó oṣù to kéré jù ní Nàìjíríà.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Akomolede ati Aṣa: Mọ̀ síi nípa ìró afárànma àti agbárànmọ́ fáwẹ́ẹ̀lì Yorùbá Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Omah Lay àti Tems yóò tó darí padà sí Nàìjíríà15 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Tanko Muhammad: Ààrẹ Buhari fikún sàá Muhammad Tanko nípò adelé adájọ́ àgbà20 Ìgbé 2019 Walter Onnoghen: UNO bẹnu àtẹ́ lu ìdàdúró adájọ́ àgbà11 Èrèlè 2019 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Gẹgẹ bi o se sọ , ile-ise eto
Ẹ kúrò lọ́dọ̀ mi, gbogbo ẹ̀yin oníṣẹ́ ibi,nítorí OLUWA ti gbọ́ ìró ẹkún mi.
Gbogbo àwọn tí wọ́n pa jẹ́ jagunjagun tí wọn ń lo idà.
Kí Olódùmarè tọ́jú ilé yín fún yín kí Ó sì tọ́jú ọ̀nà yìn pẹ̀lú.
Àdàbà náà fò pada ní ìrọ̀lẹ́ ọjọ́ náà pẹlu ewé olifi tútù ní ẹnu rẹ̀, bẹ́ẹ̀ ni Noa ṣe mọ̀ pé omi ti fà lórí ilẹ̀.
“Awon osise ti won jo n sise po ni ipago iko ohun nilu Essentuki, pese akara oyinbo ati ododo lati fi sajoyo pelu re,”Happy birthday to @NGSuperEagles Coach Gernot Rohr.
Ajibola, to tun jẹ Kọmisana fun ajọ to n mojuto ẹtọ ọmọniyan, Human Rights Commission ni, ko si ẹmi ootọ lara awọn olori Naijiria lati ṣe amulo awọn aba fun irufẹ ipade bẹẹ.
Ẹẹmẹrin ọtọọtọ lo mu bọọlu ti ko ba di goolu mọ wọn lọwọ ni eyi ti wọn ko ba fi di apẹrẹ ajaṣẹ ninu idije ife ẹyẹ agbaye naa.
" Mo ké bòòsí tòò bí mo ṣe bí ìbejì, ti ọ̀kan jẹ́ àfín, ìkejì jẹ́ dúdú-Màmá Ọlátẹ́jú Iya Woli: Ẹ̀mí ìjókíjó, Wòó, Ṣọ̀kí, Wojú, Ṣàkùṣákù, One Corner.
O ni ọsẹ meji akọkọ lawọn eeyanfi ṣe boju boju amọ lẹyin rẹ, wọn ti rẹwẹsi.
Ó kílọ̀ fún mi kí ó tó lọ pé ki n sọra abàmì ẹ̀dá náà nítorí kí ó má ba à pa mi jẹ nítorí Ìbẹ̀ǹbẹ́-Olókùnrùn ni ó le jéun ju gbogbo ẹ̀dá tí ń bẹ ni orí ìlẹ̀ ayé, òun ni o sì lè mu omi ju gbogbo wọn lọ.
Amọ ṣa idaamu Huawei l'Amẹrika ko pin sibẹ.
Ọgbà ẹ̀wọ̀n ní Pásítọ̀ ìjọ Sotitobire yóò ti ṣe Kérésì Pásítọ̀ Kérúbù rẹ́wọ̀n he ní UK torí ó fi ‘ìwẹ̀ mímọ́’ bá ọmọdébìnrin mẹ́fà lòpọ̀, ṣẹ́yún fún wọn Gbogbo ọba alayé, tó fi mọ́ Ọọ̀ni àná, Sijuwade ló mọ̀ pé mo fẹ́ jẹ Mayegun - Wasiu Ayinde Èèyàn mẹ́sàn-án kú nínú ọkọ̀ akérò tó jóná lójú ọ̀nà Ore sí Ijebu Ode Ìtàn ìgbé ayé Bode Thomas rèé, ó kọ́ wa láti máa kó ẹnu wa ní ìjánu Obasanjo, Makinde ṣèpàdé bòńkẹ́lẹ́ lórí ìhà tí ìjọba àpapọ̀ kọ sí Amotekun Adajọ paṣẹ pe ki wọn ju pasitọ naa si gbaga fun ọjọ mọkanlelogun, bakan naa ladajọ sọ pe igbẹjọ yoo tẹsiwaju lọjọ kẹtadinlogun oṣu kinni ọdun 2020.
21 Òkùdu 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 11 Ògún 2020 Oríṣun àwòrán, Getty Images Ṣaaju ni ẹgbẹ oṣiṣẹ awọn dokita oniṣegun oyinbo ti kọkọ gun le iyanṣẹlodi lati fẹhonu han lori aini irinṣẹ to to ati lori owo ti wọn n gba, ṣugbọn awọn to n ṣiṣẹ lawọn ibudo iyasọtọ fun aarun coronavirus n ṣiṣẹ ni ti wọn.
Gomina Ekiti ni ijọba ti ṣetan lati rii wi pe eto daabo gbopọn sii nilẹ Yoruba.
Agbẹnusọ fún Ààrẹ Buhari, Garba Shehu tó fi ìkéde nàá síta lójú òpó ìkànsíraẹni Twitter rẹ̀, sọ pé, Ọ̀ba Morocco, Mohammed Kẹfa, ló ránṣẹ́ pe Buhari.
A ni a fẹ se iwọde alaafia lati beere ẹtọ wa lọwọ ijọba Naijiria, kii se pe a fẹ ja, kii se pe a fẹ da ilu ru tabi gba ijọba, wọn wa ko ọlọpaa bii miliọnu kan ati Sọja pẹlu ọtẹlẹmuyẹ si gbogbo ọna ile mi."
Èrò àwọn ènìyàn nípa ikú Khadijat Olubọyọ NYSC: Kí ni òfin sọ nípa ìwé ẹ̀rí fún àyẹwò iyansipo?
Lẹ́yìn náà Labani sọ fún un pé, “O wá gbọdọ̀ máa sìn mí lásán nítorí pé o jẹ́ ìbátan mi?
Ilé náà, tó jẹ́ àwọ̀ búlùù ti ojú sánmọ̀ àti ti ọtí wáìnì, ló ní gbàgede ìgbafẹ́ ní òkè àti ìsàlẹ̀, bẹ́ẹ̀ ló tún ní ilẹ̀ tó tẹ́jú nínú àgbàlá rẹ̀ láti yan fanda, Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Tunrayo Adeoye,òsèrè tíátà míì jáde láye Àkójọpọ̀ fọ́tò ìsìnku Aisha Abimbola Ìrántí Moji Ọlaìyá lẹ́yìn ọdún kan Mercy Aigbe, tó ti se eré tíàtà ní èdè Yorùbá àti òyìnbó, ló kéde pé òun ti di ìyá onílé tuntun, ní ojú òpó Twitter rẹ̀ ní ọjọ́ ìsẹ́gun.
Argentina lé Nàìjírìa lọ 'lé láti Russia #Russia2018: Super Eagles ti koju Argentina rí Won ní dandan, dandan olóngbo àti ẹlẹdẹ to sọ àsọtẹlẹ pé ìkọ Super Eagles yóò pegede nínú ìdíje náà gbódò wá salaye bi ọrọ se gba ọ̀nà míì yọ.
Omi tí wọn ń mu ni ìlú yìí burú gidigidi, nítorí etí odò tí wọ́n ti ń pọn ọ̀n ni wọn ń, ṣe ìgbọ̀n sẹ̀ sí bẹ́ẹ̀ ni odò náà kò ju kékeré lọ.
Kí ló dé tí ẹ sì fi ń dán OLUWA wò?
Ṣugbọn nígbà tí Sanbalati ati Tobaya ati àwọn ará Arabu, ati àwọn ará Amoni, ati àwọn ará Aṣidodu, gbọ́ pé a ti ń ṣe àtúnṣe àwọn odi Jerusalẹmu ati pé a ti ń dí àwọn ihò ibẹ̀, inú bí wọn gidigidi.
Erelu Elemure ni orukọ itage rẹEde Ekiti kan naa ti baba rẹ, Peter Ogunyemi elemure to ti di oloogbe bayii ma fi n kọ orin loun naa nlo, koda bii ọkunrin lo yan lati maa mura ninu ẹwu bii Agbada, Sokoto ati sọọrọ.
A perí olóṣèlú kilọ̀ fún jẹgúdújẹrá wọn
Ori ẹrọ ayelujara ni iburawọle naa ti waye ni Ọjọ Iṣẹgun.
Malabu Deal: Ìgbẹ́jọ́ bẹ̀rẹ̀ lóri rìbá tí Eni, Mobil san fún Nàíjíríà
“A ni iko ti o le fakoyo ni Russia, bee si ni a le de ipele ti o lapere ti a ba ni okun ati ilera ara ti o pe,.
Ẹni to bori: Burundi South Africa vs Senegal.
Minisita abẹle fun epo rọbi, Timipre Marlin Sylva ti kọkọ ṣalaye pe owo iranwọ ti ijọba ko fi si ori epo mọ lo jẹ ki ayipada maa ba iye tawọn ọmọ Naijiria n ra epo looreekooree.
Oba Adeniran Adeyemi II ní bàbá Lamidi kí wọn to lé kúrò lóri oye fún ibasepọ rẹ̀ pẹ̀lú NCNC.
O ni ipele kan náà ni àwọn méjèèjì wà.
Oríṣun àwòrán, BORNO STATE GOVERNMENT Àkọlé àwòrán, Gomina ipinlẹ Borno shettima tẹwọgba awon okoolerugba agbesunmọmi tẹlẹ Adari ikọ Boko Haram , Abubakar Shekau, ninu fọnran to ti soro lede Hausa, sọ wip,e digbi ni ara ohun wa, ti ko si si ohunkohun to se ohun.
 wọ ́ n yà pineda holidays tó wà ní telford .
Ọ̀wọ́ EFCC tẹ ayédèrú Babaláwo pẹ̀lú òògùn abẹnugọ̀ǹgọ̀ Sinimá oríta, àwòòtán.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Itan Ilu gangan Alaafin ni ọpọlọpọ awọn ọdọbinrin ni Olori, ti awọn eniyan si maa n wo o pe kini awọn obinrin naa n ri ti wọn fi n fẹ ẹ.
Lára àwọn tí yóò tún gba itusile ni àkòroyín kan Fakadu Mahtemework.
Ìfẹ́ owó ni ìpìlẹ̀ gbogbo nǹkan burúkú.
Barbados: Orilẹ ede yii wa ni Ila Oorun ilẹ Afrika ti o si jẹ bii ọgọrun kilomita si Iwọ Oorun Odo Caribbean ati Odo Windward.
"Awọn aseyọri Ajimọbi wu wa lori Nigba to nsọrọ, Olubadan ni, ""Mo dupẹ lọwọ gomina nitori pe anri isẹ to ti se, taa si ngbadura pe ko ni koju aiseese."
Wọn óo máa ṣe iṣẹ́ iranṣẹ wọn ninu Àgọ́ Àjọ pẹlu rẹ.
Àwọn tí ó gbé ọ̀rọ̀ nípa ìkọlà Titu jáde ni àwọn arakunrin èké tí wọ́n yọ́ wá wo òmìnira wa tí a ní ninu Kristi Jesu, kí wọ́n lè sọ wá di ẹrú òfin.
Awọn mejeeji jọ n gbe papọ,koda, Dupe tun bimọ kan fun.
Akoko mii ti ko ṣee gbagbe ninu ipa rẹ ni igba to dari awọn ọmoogun Naijiria lati koju awọn ọmọogun Chad to ya wọ ipinl Borno lọdun 1983.
'Ẹ dúró nílé bí ẹ kò bá ní ìdí láti jáde' Ọ̀jọ̀gbọ́n Erin Bromage to jẹ́ onímọ̀ nípa àwọn èròjà tó ń gbógun ti ààrùn lágọ̀ọ́ ara bá wa sọ̀rọ̀ lórí awon ọ̀nà tí a lè gbà láti mú àdínkù bá ewu kíkó ààrùn Coronavirus, o jẹ́ olùkọ́ ìmọ̀ àjàkálẹ̀ ààrùn ni Fásitì Massachusetts Dartmouth ní US, o sì ti bojú tó ààrùn Coronavirus yìí láti ìgbà to ti bẹ̀rẹ̀.
''Awọn sare yọ ọmọ naa kuro ninu ilẹ, amọ ẹpa ko boro mọ nigba ti wọn de ileewosan.
A dúpẹ́ lọ́wọ́ Ọlọrun, Baba Oluwa wa Jesu Kristi, Baba aláàánú ati Ọlọrun orísun ìtùnú, 
O mú kí àwọn ọ̀tá mi sá fún mi,mo sì pa àwọn tí wọ́n kórìíra mi run.
Tani yóò borí nínú Belgium àti France lónìí?
Oríṣun àwòrán, Reuters Àkọlé àwòrán, Ọjọ Iṣẹgun ni oludamọran fun Trump, Stephen Miller sọ pe oun ni coronavirus Bo tilẹ jẹ pe Aarẹ Trump ti pada sile ijọba, alatako rẹ to tun jẹ oludije fun ipo aarẹ ninu eto idibo to n bọ lati inu ẹgbẹ oṣelu Democrat, Joe Biden, ti sọ pe Trump ko gbọdọ ba oun ṣe itakusọrọ ti aarun naa ko ba tii fi silẹ.
ja lule lojo kini anaGege bi iroyin se salaye irin ajo re, oloogbe Adesanmi n lọ fun
Ọmọ naijiria kẹta ti yoo di ipo oṣelu mu l'Amẹrika bayii ni Oye Owolewa.
Ṣugbọn, oun padanu oyun naa ni ọjọ keji ti awọn bẹrẹ ibalopọ ọlọjọ meje.
" Lẹyin ọjọ diẹ ni iroyin naa wa lawọn opo ayelujara kan pe ojisẹ Ọlọrun naa ti gba china lọ amọ o wa nile iwosan nibẹ to n gba itọju lẹyin tọwọ arun arun Coronavirus gba mu.
Bakan naa, lodi si ero awọn eeyan kan pe, ọmọ ti wọn ba bi ni ilana IVF kii dape lara, Okiki ni imọ sayẹnsi ti lọ siwaju kọja ero yii.
 Ni bayii, awon omo orile-ede Uganda ti n fi ibinu so si oro Twinamasiko lori ero ayelujara Twitter, eyi ti won fi n pe fun ikowe fipo re sile ni kiakia.
Ọlọrun bi í pé, “Ta ló sọ fún ọ pé ìhòòhò ni o wà?
Ninu ọrọ to sọ ni olu ile ẹgbẹ awọn oṣiṣẹ ijọba ibilẹ to wa ni adugbo Challenge n'Ibadan, alaga ẹgbẹ oṣiṣẹ nipinlẹ naa, Bayọ Titilọla-Sodo sọ fun awọn akọroyin lọjọru pe ''ko tọ̀ si ijọba kankan lati maa lo awọn oṣiṣẹ ni ilo ẹrú.
Ó tún bi wọ́n pé, “Ǹjẹ́ ẹ mọ Labani ọmọ Nahori?
O salaye pe, ko si enikeni to padanu emi re tabi ti o farapa,
Oríṣìíríṣìí oyè ni wọ́n máa ń jẹ ní Iléṣà tí wọn sì n jẹ ní Ìjẹ̀bú Jẹ̀ṣà a rí Ògbóni ní Iléṣà bẹ́ẹ̀ náà ni ó wà ní Ìjẹ̀bú Jẹ̀ṣà.
Nitori Yoruba gbagbọ wi pe awọn akin nii lọ s'ogun, ẹmii wọn ni wọn si n fi si ori aala lati daabobo ilu.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Orlando Owoh: Èmí àti Oladipupo Owomoyela jọ lọ ẹ̀wọ̀n Alágbọn- Caroline Owoh, aya Orlando Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Coronavirus cases in Ngeria today: ₦50 bílíọ́nù ni a fún ìpínlẹ̀ kààkan ní Naijiria láti kojú àrùn Covid-19 - Ìjọba àpapọ̀4 Bélú 2020 Lekki Tollgate shooting: Fídíò táa ní lọ́wọ́ kò ṣàfihàn gbogbo ohun tó ṣẹlẹ̀ nírọ̀lẹ́ ọjọ́ náà - LCC3 Bélú 2020 A ó ò dasẹ́ sílẹ̀ fún ojọ́ gbọọrọ tí ìjọba bá kọ̀ láti san owó oṣù mẹ́rin tó jẹ wa- Àwọn dokita ìpínlẹ̀ Ondo4 Bélú 2020 Fídíò, Soyinka Cancer: Àṣe ara mi ni iso ti n run gbogbo bí mo ṣe n ṣèrànwọ́ lórí jẹjẹrẹ27 Bélú 2019 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 3 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 5 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù FIFA: A fi òfin de ẹ̀yin eléré ìdárayá mẹ́ta wọ̀nyí láti ilẹ̀ Adúláwọ̀ títí ayé 20 Ògún 2019 Oríṣun àwòrán, FIFA Àkọlé àwòrán, Fun idagbasoke ere idaraya ni ofin ayeraye naa wa fun Bi ko ba nidi, ẹ̀ṣẹ́ kìí déédé ṣẹ́ ni àwọn agba maa n wi nilẹ̀ Oodua.
Ìdí tí Gúúsù Akure, Owo àti ìwọ̀orun Ondo yóò fi sọ ẹni tí yóò jáwé olúborí nínú ìbò gómìnà Ondo Agbẹjọro agba lorilẹ-ede Naijiria, Wahab Shittu naa wa rọ awọn ọmọ Naijiria lati dẹwọ ifẹhọnu wọn, lati le fun ijọba laaye lati ṣe ohun to yẹ lori igbesẹ ti wọn kọkọ gbe lati tu ikọ SARS palẹ.
Opo eniyan ni won n se idaro leyin onkorin to ju awa sile lodun mokandinlaadorin odun yii.
O fikun ọrọ rẹ pe irufẹ oju buluu bayii ko ni ki wọn maa riran daadaa.
Fayoṣe figbe ta pé wọ́n fẹ́ gbẹ̀mí òun Ìdìbò Ekiti: àáyá bẹ́ sílẹ̀, ó bẹ́ áré Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ekiti Election: Ìjọba ìbílẹ̀ làwọn òsìsẹ́ Inec yóó sùn mọ́jú ọjọ́ ìbò Dokita Odumakin wa rọ awọn eeyan ipinlẹ Ekiti lati maṣe ko aya soke, ṣugbọn kiwọn jade lati ṣe ojuuṣe wọn ki wọn si dibo fun oludije ti o ba wu wọn.
Ṣugbọn èmi wá ń sọ fun yín pé, ẹ fẹ́ràn àwọn ọ̀tá yín.
0 17 Erekusu Solomon Islands 0 0.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Buhari fún Ẹ̀ka ìdájọ́, ilé àsòfin ìpínlẹ̀ l'òmìnira owóòná 8 Òkùdu 2018 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 9 Òkùdu 2018 Oríṣun àwòrán, Buhari/ Twitter Àkọlé àwòrán, Ààrẹ Muhammadu Buhari tí fún ilé-iṣẹ́ adájọ ìpinlẹ̀ àtí àwọn ilé ìgbìmọ aṣofin ìpínlẹ̀ mẹ́rìndínlọ́gbọ̀n ni òmìnira owóòná, Ààrẹ Buhari tí f'ofin de igbákejì gómìnà àti ti àarẹ láti lo sáà meji gẹ́gẹ́ bii olórí tuntun Aarẹ buwọ́lu abadofin mẹrin, ọ̀kan níbẹ̀ ní o ti fún ilé-iṣẹ́ adájọ ìpinlẹ̀ àtí àwọn ilé ìgbìmọ aṣofin ìpínlẹ̀ mẹ́rìndínlọ́gbọ̀n ni òmìnira owóòná.
Ní ọjọ́ keje ẹ óo máa ní àpèjọ mímọ́, ẹ kò sì gbọdọ̀ ṣe iṣẹ́ líle kankan.
Mo mọ̀ láti òrú lọpé ọ̀rọ̀ rere a máa yọ obi lápò; ọ̀rọ̀ burúkú a máa yọ ọfa lápá, nítorí náà bí mo bá sẹ baálé mi, tí ó di pé o ń bínú, n ó sọ̀rọ̀ tútù fún un.
Akori ipade naa, eyiti igbakeji aarẹ Yẹmi Ọsinbajo dari rẹ ni idokowo ninu agbega ọmọniyan lati se atilẹyin fun afojusun idagbasoke ọrọ aje awọn mẹkunnu"" Awọn iroyin ti ẹ lee nifẹẹ si: Koko iroyin: Awuyewuye Dapchi, alaboyun tan’gbaloju nibi irọbi Nigba wo ni isuna 2018 yoo dohun?"
– ìwọ rí mi, èmi rí ọ, èmi ń bọ̀, ìwọ náà ń bọ̀, ìwọ kò bá ẹsẹ̀ rẹ sọ̀rọ̀, ìwọ ń rìn bí aláìbíkítà níwájú mi.
ko si abamo ninu oro wa lorile ede yii, rara.
Ẹni tí ó bá ń wá ire, yóo rí ojurere,ṣugbọn ẹni tí ó bá ń wá ibi, ibi yóo bá a.
Ẹgbẹgbẹrun awọn Tutsis ni wọn n rọpọ si ẹgbẹ kan ni ijọ Aguda ẹka Nyamasheke, ti wọn si jijadu ẹmi wọn fun ọṣẹ kan gbako, bi afoju ri Stanislus Kayitera to ti pe ọdun mẹtaleláàdọta bayii jẹ ọkan lara awọn to ru iṣẹlẹ naa la pẹlu awọn oniruuru apa lara .
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù #Revolution March: Ìjọba Buhari ń wùwà bíi ìjọba Abacha lórí ọ̀rọ̀ Ṣoworẹ- Ṣoyinka 4 Ògún 2019 Oríṣun àwòrán, Twitter/Presidency Ọjọgbọn Wole Soyinka ti sọ pe ijọba aarẹ Muhammadu Buhari n wuwa bi ijọba ologun labẹ oloogbe aarẹ Sani Abacha.
Ọba Ewuare II ni iwa oṣo ṣiṣẹ, yatọ si pe o ṣajeji si aṣa ati iṣe ilẹ Benin, ko si ninu iwa ati aṣa itẹwọgba ni ilẹ kilẹ lorilẹ Afirika.
Akọsilẹ iwe iroyin kan ni Naijiria sọ pe Buhari lo ida kan ninu idamẹta ọdun mẹta to kọkọ lo lọfiisi ni lati igba to ti di aarẹ lọdun 2015.
Nígbà tí wọ́n bá fẹ́ lọ sọ́dọ̀ àwọn eniyan ní gbọ̀ngàn ìta, wọn yóo bọ́ aṣọ tí wọ́n wọ̀ nígbà tí wọn ń ṣiṣẹ́ iranṣẹ sí àwọn yàrá mímọ́.
Bí-ó-ti-lẹ̀-jẹ́-wípé àwọn òǹdíje sí ipò ààrẹ t'ó 73, eré Àpáta Agbára – ibùjókòó ààrẹ orílẹ̀-èdè Nàìjíríà – yóò wáyé ní àárín-in ẹgbẹ́ olóṣèlú méjì tí ó ti ń figagbága ní ọjọ́ tí ó ti pẹ́ àti àwọn òǹdíje tí a pè ní “agbára ìkẹta”, ìyẹn àwọn ẹgbẹ́ a ṣẹ̀ṣẹ̀ dé sínú ìṣèlú orílẹ̀-èdè Nàìjíríà.
Obinrin yìí tún wí fún ọba pé, “Kabiyesi, jọ̀wọ́, gbadura sí OLUWA Ọlọrun rẹ kí ẹni tí ó fẹ́ gbẹ̀san ikú ọmọ mi kinni má baà pa ọmọ mi keji.
Won koi so pato igba ti won yoo gbe oku ologbe naa wa sorile-ede Zimbabwe Ronke Osundiya.
Oríṣun àwòrán, EPA Àkọlé àwòrán, Arabinrin Svetlana Tikhanovskaya ni alatako gboogi to koju Aarẹ Lukashenko Ileesẹ ayelujara NetBlocks tí ẹ sọ pe ayelujara ko ja geere lọjọ Aiku, bí awọn eeyan ṣe n dibo.
Jacob Zuma: Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Afihan idẹyẹsi ati ikorira ni aṣa jiju bata lu eniyan ni aṣa awọn larubawa Lasiko ajọyọ iranti Nelson Mandela ti wọn ṣe ni ilu Johannesbourg ni awọn eeyan to wa nibẹ ti pariwo idẹyẹsi le Zuma lori lẹyin ti wọn ti kigbe ẹyẹ nigba ti wọn pe orukọ aarẹ amẹrika nigba naa, Barack Obama.
Awọn wo lon du ipo rẹ Labẹ asia ẹgbẹ APC ni Funke Adedoyin to di ipo naa mu tẹlẹ wa ki o to lọ si ẹgbẹ PDP.
Wọn a tun fun wọn ni ile meji, ọkan ni ilu Eko ati omiran nilu Abuja, bi Gomina naa ba ṣe saa kan, ile kan ṣoṣo ni wọn yoo fun wọn.
Ipo kẹta ni ikọ Tottenham wa lori tabili Premier League, ami ayo kan si ni wọn fi siwaju Manchester United to wa ni ipo kẹrin.
Ó rẹ àwọn alufaa sílẹ̀,ó sì gba agbára lọ́wọ́ àwọn alágbára.
Gbogbo àwọn agbowó-odè ati àwọn ẹlẹ́ṣẹ̀ ń súnmọ́ ọ̀dọ̀ rẹ̀ láti gbọ́ ọ̀rọ̀ rẹ̀.
Àwọn ọna ti ọjọgbọn Fatunde ro pe Naijiria fi le yọ ọwọ awọn baba isalẹ ninu oṣelu ree: 1.
Amọ ninu fidio kan ni Naira Mailey ti sọ pe oti to igba 124 ti wọn ti fi panpẹ mu oun ni Ilẹ Gẹẹsi.
Kò sí ǹkan tó ń ṣe Idris agbébọn ní Kano
Ṣugbọn nígbà tí Elihu rí i pé àwọn mẹtẹẹta kò lè fún Jobu lésì mọ́, inú bí i.
Àwọn olùgbé ìlúu Abidjan ló kò àrùn Coronavirus wọ Ọ̀ṣun-Gómìnà Oyètọ́lá Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Coronavirus in Nigeria: Gómìna Oyetola ní àwọn àbọ̀dé orílẹ̀èdè Côte d'Ivoire ló ń Gomina ipinlẹ Ọṣun, Alaaji Adegboyega Oyetọla ti ke gbajare sita pe awọn abọde lati orilẹede Côte d'Ivoire ni wọn jẹ ki ajakalẹ arun Coronavirus tubọ gogo sii ni ipinlẹ naa.
Nítorí náà, ẹ̀bi ikú àwọn eniyan rẹ wà lọ́rùn mi.
4 billion) owo ere ori epo laarin ọdun 1988 si 1994.
A rii pe, n ṣe ni ijọba kan n ṣe lilọ bibọ loju kan naa lori awọn ijiroro wa gbogbo.
Wọ́n hùwà bí ẹranko, wọn kò ní Ẹ̀mí Mímọ́.
Ẹni tí ó wà nínú ayé tí ó ń rìn pẹ̀lú ìbẹ̀rù kò sí nínú àwọn alààyè, ibá ṣe pé àwọn ènìyàn ńlá ń sọ ohun gbogbo tí wọ́n ti bá pàdé kí wọ́n tóó di ènìyàn ńlá ni, àwọn ẹlòmíràn ìbá máa gbàdúrà kí àwọn kú sí ipò ẹ̀hìn.
Democratic Party, PDP) pe o jawe olubori fun saa keji  gẹgẹ  bi gomina ni ipinlẹ Benue ,ninu eto idibo  gomina to waye  lọjọ  Abamẹta.
Ìgbà tí ó gbọ ìròyìn nípa ikú duchesne ni ó ṣẹ ̀ ṣẹ ̀ padà lọ fẹ ́ ọmọ rẹ ̀ .
ilẹ ̀ turkey náà dá sí ogun yìí ní osù kẹwàá ọdún 1914 .
Gomina Simon Lalong, so pe ijoba  yoo ri daju lati mu atunse ba papa isere ohun gege bi ilana ti ajo CAF fi sile lati tele saaju kii idije CAF miran o to bere.
Aare Buhari ni eni yoo je ikarunun ninu awon ti yoo maa soro nibi ipade apero ajo agbaye ohun , ni eyi ti yoo bere lojo Isegun.
Ido-Ani Robbery: Àhámọ́ làwọn afurasí náà yóò wà di ọjọ́ Kejì oṣù Karùn-ún
ati awon omo orile ede Niger Republic, kẹdun lori iku awon omo-ogun méjìdínlógún  rẹ ti won pa ni ojo kinni osu keje, lodun yii, ni ẹkun
Ibi mímọ́ ni kí ẹ ti jẹ ẹ́, nítorí pé òun ni ìpín yín ati ti àwọn ọmọ yín, ninu ẹbọ sísun OLUWA, nítorí pé bẹ́ẹ̀ ni OLUWA pa á láṣẹ fún mi.
Ṣe ni baba oyinbo naa gbe apa ijo gẹngẹ.
Ilẹ̀ yanu, ó gbé Datani mì,ó sì bo Abiramu ati àwọn tí ó tẹ̀lé e mọ́lẹ̀.
Duro Ladipọ, ìlúmọ̀ọ́ká òṣèré tíátà àti ọmọ àlúfà tí kò gbàgbé àṣà ìbílẹ̀ Ẹ̀yin Onínúfùfù ẹ wo ìdí tí ìbínú fi dára púpọ̀ Kachikwu fikun wi pe, o se ni laanu wi pe awọn ti wọn n se karakata epo bẹntirol ko i tii gba gbogbo owo iranwọ ti ijọba n jẹ wọn.
wiwọle ati jijade lorile ede Naijiria(Nigerian Immigration Service ) ti se gudu gudu meje
Mo mọ ọ̀rọ̀ ìbàjẹ́ tí àwọn tí wọn ń pe ara wọn ní Juu ń sọ, àwọn tí kì í sì í ṣe Juu; tí ó jẹ́ pé ilé ìpàdé Satani ni wọ́n.
 ní ilẹ ̀ yorùbá lóde òní , àwọn Ìgbómìnà wà ní ìpìnlẹ ̀ Ọṣun àti kwara .
Republic, Attahiru Haliru ati akowe agba fun ajo to n mojuto ile okeere,
'Sẹ́ríkí Fúlàní ní ìpínlẹ̀ Ọṣun ní kò sí ìdí fún àwọn darandaran láti kúrò l'Ọ́ṣun
Kunlere tun ṣalaye pe ọpa aṣẹ ni ami agbara ninu ile igbimọ aṣọfin.
Wa tẹ awọn nọmba atẹsanwo gba ina ọba naa si oju kaadi rẹ ni ṣiṣẹ n tẹle bi wọn ṣe fi ranṣẹ si o.
Wo àwọn ẹranko tí wọ́n máa figagbaga ni Egypt Wo ohun tuntun tó n ṣẹlẹ̀ lágboolé CAF Super Falcons gòkè odò bọ́ sípele ìkẹrìndínlógún ní France Bí eṣinṣin bá kọ́já, wíwọ́n ní, lásìkò ìṣíde AFCON 2019 Loni ni Naijiria yoo maa gbena woju awọn akẹgbẹ wọn lati Burundi.
 Àkọ ́ kọ ́ kọsílẹ ̀ nípa àtànkálẹ ̀ rẹ ̀ láàrin àwọn ènìyàn wáyé ní ọdún 2007 ní Ìjọba Ìpínlẹ ̀ micronesia .
Ọjọgbọn Omọtayọ fẹran aṣọ hihun, iwe kika, o jẹ iya to fẹran ọmọ, ati aya rere lọdẹ ọkọ rẹ, eyi ni, ajagunfẹhinti Olufemi Olutoye.
Ero awọn akẹkọ yapa lori iyansẹlodi ASUU Ariwisi awọn akẹkọ ṣe ọtọọtọ ninu ifọrọwanilẹnuwo ti ikọ BBC Yoruba ṣe pẹlu diẹ lara awọn wọn lori iyanṣẹlodi naa.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Niger-Delta: Ẹ maa reti ikọlu 22 Sẹ́rẹ́ 2018 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ẹgbẹ ajijagbara Niger Delta Avengers Ẹgbẹ ajijagbara Niger Delta Avengers, ninu atẹjade kan to fi sita lori itakun agbaye ẹgbẹ naa ti sọ wipe, laipẹ jọjọ, awọn yoo se ikọlu si awọn agbegbe to wa ni oriko nibiti awọn ọpa epo robi orilẹede Naijiria wa.
Lẹ́yìn náà ó mú aṣọ àwọ̀lékè Elija tí ó bọ́ sílẹ̀, ó sì pada lọ dúró ní etí odò Jọdani.
Ajọ naa, tó sisọ loju ọrọ naa loju opo Twitter rẹ fi kun pe, ọrọ dii bo o lọ, oya a mi, sugbọn awọn ri ọkọ ayọkẹlẹ mẹwa gba silẹ, ti awọn si fi panpẹ ọba mu awọn mejila miran ni bi ile igbafẹ naa.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Kwara: Ọti tita ati rira di eewọ nilu Ilọrin 13 Ẹrẹ̀nà 2018 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ọpọ ipinlẹ lo ti se ofin Sharia to tako ọti mimu ni Naijiria Ijọba ipinlẹ Kwara ti fọwọsi ofin kan eyi to tako asa ọti rira ati tita nipinlẹ naa.
Arakunrin ẹni ọdun mọkandinlogun naa ṣalaye pe babalawo kan ti o jẹ ẹni aadọta ọdun lo n ran oun ni iṣẹ ibi naa.
Gbogbo àwọn ìjòyè ati gbogbo eniyan fi tayọ̀tayọ̀ mú owó orí wọn wá, wọ́n ń sọ ọ́ sinu àpótí náà títí tí ó fi kún.
Nígbà tí Ehudu fi ìṣákọ́lẹ̀ náà jíṣẹ́ tán, ó ní kí àwọn tí wọ́n rù ú máa pada lọ.
Ṣugbọn obinrin tí ó bá ní ọkọ yóo máa páyà nípa àwọn nǹkan ayé, yóo máa wá ọ̀nà láti tẹ́ ọkọ rẹ̀ lọ́rùn.
Ohun tó já ju ni pé tá bá fẹ́ gbajumọ lọkọ àbí láyà, a gbọ́dọ̀ ṣe sùúrù gidigidi.
orile ede Naijiria ti bori ipenija to n doju ko won , o wa ro awon omo orile
Wọn fi ye BBC laipẹ pe awọn ti bẹrẹ iṣẹ iwadii ni kikun lori awọn afurasi mẹrin ti wọn n wadii lori iṣẹlẹ naa.
Lara awọn oye ti Oyinkan jẹ nigba aye rẹ ni Moroye tilu Eko ati iya Abiye tilẹ Ẹ̀gbá.
Saaju ninu oro ikini kaabo re ,oludari ati oludasile iwe
Eeyan le lo to ọgbọn oṣu lẹwọn to ba tasẹ agẹrẹ si ofin yi.
Ozekhome ni, kilode ti aarẹ ṣe maa n fi awọn irinajo ti tẹlẹ to awọn aṣofin leti ti yoo si gbe ijọba le Osinbajo lọwọ?
Ni ẹkun iwọ oorun Guusu orilẹ-ede yii ati ilẹ Kaarọ Oojiire lapapọ, ipinlẹ mẹta ni pere ni ẹgbẹ oselu APC ti gbe orukọ awọn oludije gomina to pegede sita.
Mo wá gbọ́ ohùn ẹnìkan tí ó sọ fún mi pé, ‘Peteru, dìde, pa àwọn ẹran tí o bá fẹ́, kí o sì jẹ.
E ma ṣe oun kankan si i, nkan ti ko buyi kun un ni.
ati ògòǹgò, ati òwìwí, ati ẹ̀lulùú, ati oríṣìíríṣìí àwòdì, 
nigba ti won  fẹ se se isẹ ibi won ni
A sì fi ìdílé Josẹfu han Farao.
Nítorí pé bí a kò bá jí àwọn òkú dìde, a jẹ́ pé a kò jí Kristi dìde.
Mo kórìíra ìbọ̀rìṣà; nítorí náà bí ẹ bá jáwọ́ ninu rẹ̀, tí ẹ kò bá ṣìnà kiri mọ́, 
Awọn igba wọnyi ni aye o ba ti parẹ: 1.
Josẹfu a sì máa sọ gbogbo àṣìṣe àwọn arakunrin rẹ̀ fún baba wọn.
Manchester City dáná sun Brighton, gba Premier League 12 Èbibi 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Bi eeyan ba n ṣe iyemeji tẹlẹ, ko si aniani mọ, Manchester City ti gba ife ẹyẹ Liigi Premiership ti ọdun yi.
Awọn nnkan to le fa oyun ìju ninu ikun obinrin: Ko si ẹni to mọ nkan to n fa a ni pato, ṣugbọn awọn onimọ sọ pe awọn nkankan wa to le fi obinrin sinu ewu rẹ Ẹya: Awọn obinrin to jẹ alawọ dudu lo wa ninu ewu ju lati ni oyun iju, ju awọn obinrin to jẹ alawọ mii Ajogunba: Obinrin ti iya tabi ẹgbọn tabi aburo rẹ obinrin ba ni oyun iju, wa ninu ewu lati ni i Awọn ọmọbinrin to tete bẹrẹ nkan oṣu: Awọn obinrin to ba bẹrẹ nkan oṣu ki wọn o to o pe ọmọ ọdun mọkanla, lo ṣe e ṣe ko ni oyun iju, ju awọn akẹẹgbẹ wọn to bẹrẹ nkan oṣu lẹyin ti wọn pe ọmọ ọdun mẹtala Oríṣun àwòrán, other Àkọlé àwòrán, Dokita n lo ẹrọ Ultrasound lati mọ boya obinrin ni oyun iju Sisanra ju bo ṣe yẹ lọ: Oyun iju ma n mu ki eroja ara 'estrogen' pọ si ninu ara, to si ma n mu ki ọra pọsi ninu ikun Obinrin ti ko loyun ri: Obinrin ti ko ba tete bimọ wa ninu ewu lati ni oyun iju Itọ ṣuga: Obinrin to ba ni aisan itọ ṣuga wa ninu ewu nla, lati ni oyun iju Àkọlé àwòrán, Dokita Brown sọ pe adinku le ba bi awọn obinrin ṣe n ni oyun iju, ti wọn ba le mojuto ilera wọn, nipa mimu adinku ba bi wọn ṣe n jẹ awọn ounjẹ to ni caffeine; tabi dena itọ ṣuga ati ẹjẹ riru, to fi mọ sisanra ju .
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Mr Macaroni sọ nípa eré tí Fraky freaky, Sugar Daddy, You are doing well, freaky spicy fẹ́ Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Fídíò, Akomolede: Bolaji Faleke ni Olùkọ́ tó ń kọ́ wa ní àṣà oge ṣiṣe lórí BBC Yorùbá1 Owewe 2020 6:18 Fídíò, Natalia Mufutau ìyá Yakub, Kamil àti Adam sọ̀rọ̀ lórí bí wọ́n ń sọ èdè mẹ́rin pàpọ, Duration 6,1831 Ògún 2020 Fídíò, Yoruba Language: Akomolede ati Asa Yoruba tọ̀sẹ̀ yí rèé lẹ́nu olùkọ́ wa30 Ògún 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Nítorí mo kà á sí ẹ̀tọ́ mi, níwọ̀n ìgbà tí mo wà ninu àgọ́ ara yìí, láti ji yín ninu oorun nípa rírán yín létí.
Oju opo wọnyii ti o jẹ ti ajọ aladani a maa fun awọn eeyan lanfaani lati wa ọkọ tabi iyawo.
"Iwa ti ko ṣe e gbọ seti, ati ọrọkọrọ to n jade lẹnu awọn kan, paapa awọn aṣofin to n fi ẹsun kan aarẹ pe ko ja ọrọ naa kunra nitori pe ko ti i ba awọn ọmọ Naijiria sọrọ lori amohunmaworan.
Gẹ́gẹ́ bí ìwé ìròyìn eré ìdáraya orílẹ̀èdè Russia se sọ ọ́, arákùnrin náà, Tolulọpẹ Akindi ẹni ọdún mẹ́rìndínlọ́gbọ̀n wá sí Russia láti wá wó ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ ife ẹ̀yẹ àgbáyé ni.
Ọ̀gá Bello: Àìgbọ́n ló ń da àwọn òsèré tíátà tó ń jà lórí ayélujára láàmú
Iyaafin Ambode soro naa di mimo lojo isegun(Tuesday) lati fi sajoyo ayeye ose odun ifomo loyan todun yii, Commemorate the 2018 World Breastfeeding Week, pe anfaani ti oyan n se lara omo ko se yesile.
Ori ibusun ni iyawo mi wa nigba ti omiyale naa bẹrẹ laago mọkanla alẹ'' ""Bi mo ti se n sapa lati di nnkan mu ni omi naa gbe lo."
Wọn ri ere idaraya awọn egungun gẹgẹ bi etutu, ti yoo ṣe pese ọna abayọ si awọn oniruuru iṣoro bi airọmọbi, ailaya, oṣi, aini ati awọn iṣoro mii to le ma a ba awọn eeyan ilu finra.
Awọn ijọba ibilẹ ti wọn kede naa ni Irele, Ile Oluji, Ondo East, Owo, Akoko North East, Akoko South West, Idanre, Akoko North West, Akure North, Akoko South East and Akure South.
Oníròyìn ọmọ Uganda Charles Onyango-Obbo, tí òun náà wà ní FIFA, mẹ́nu ba òwe Igbo tí gbajúgbajà òǹkọ̀wée nì Chinua Achebe mú di mímọ́ tí ó sọ wípé:
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Europa League Semi-final: Chelsea rọ́ Eintracht Frankfurt lágbo dà sí iná ni Stamford Bridge 10 Èbibi 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Europa League Semi-final: Chelsea rọ Eintracht Frankfurt lágbo dà si iná Chelsea gbo ewuro soju Eintracht Frankfurt pẹlu ami ayo mẹ́rin sí mẹ́ta nigba won jọ wako ni Stamford Bridge.
Aisi abo to peye ati ibanisọrọ to ye kooro n mu ko nira fun ijọba atawsn ajs aladani gbogbo lati ṣe ayẹwo to tọ.
 Ìkeke ni a fi maa nlù .
2019 Elections: Sowore ní pàṣán ni Buhari yóò fi bá Nàìjíríà ṣe ní sáà kejì
Gẹgẹ bi a ṣe gbọ, ni kete ti awọn araalu ti gbọ iroyin naa ti bọ sita lawọn eeyan ti ya wọ aafin ti wọn si ti bẹrẹ gbogbo ijo ati ilu; bẹẹ ni orin n lọ lakọlakọ.
Ẹni tí ó rí mi, rí ìyè,ó sì rí ojurere lọ́dọ̀ OLUWA,
Oríṣun àwòrán, Chris Ngige/Facebook, NLC Àkọlé àwòrán, Ngige àti àwọ́n òṣìṣẹ́ Wọ́n ní bí Mínísítà ṣe sọ pé ìjọba ṣí ń dúnàá dúrà ọ̀rọ̀ náà pẹ̀lú ẹgbẹ́ àwọn òṣìṣẹ́ kìí ṣe òtítọ́.
Ìdáhùn sí ìbéèrè yìí kọyọyọ ní Azerbaijan.
Èrò àwọn ọmọ Nàìjíríà ṣọ̀tọ̀ọ̀tọ̀ lórí ọ̀rọ̀ Obi àti Ọṣinbajo Ẹ̀kọ́ mẹ́fà tó jáde nínú ìdíje Premier League òpin ọ̀sẹ̀ Àwọn àwòrán mánigbàgbé nípa Ààrẹ Muhammadu Buhari Ìyanṣẹ́lódì òṣìṣẹ́ ilé aṣòfin bẹ̀rẹ̀ ní pẹrẹwu nílé aṣòfin Nàìjíríà Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Alápinni: Kò sí ẹni to fẹ́ kọ́kọ́ kọ́ iṣẹ́ òṣèré bíi ti àtẹ̀yìnwá Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, CJ Gold: ẹ̀rù kọ́ka ba ìyá mi nígbà ti mo fẹ́ bẹ̀rẹ̀ iṣẹ́ ìjà jíjà Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
"Àkọlé àwòrán, Rose Mishayi ni awọn ko mọ bi coronavirus ṣe ri ""Coronavirus yii, awa o mọ nkankan nipa rẹ o ati bo ṣe n ran awọn eeyan."
Àwọn eniyan yóo sì máa dáhùn pé, ‘Nítorí pé wọn kò mú majẹmu OLUWA Ọlọrun ṣẹ, tí ó bá àwọn baba wọn dá nígbà tí ó kó wọn jáde ní ilẹ̀ Ijipti.
Baba ọmọ tuntun yii ti jagun lọ nigba naa, ti ko si si nile, amọ wọn sọ ọmọ naa ni orukọ Adesọji Tadeniawo Aderẹmi Ni kete ti baba rẹ si ti oju ogun de lo tọ Ifa lọ lati mọ ẹsẹ n taye ọmọ tuntun naa tabi ayanmọ to gbe wa sile aye Ni kete ti wọn gbe ọpẹlẹ janlẹ, ni Ifa sọ fun Ọmọọba Gbadebọ pe, ko tete fori balẹ fun ọmọ tuntun naa.
Ami eye BET je eyi ti Black Entertainment Television gbekale lati fi mo riri asa ile Adulawo ati ti Amerika fawon onkorin nita ile Amerika.
Igikígi tí kò bá so èso rere, gígé ni a óo gé e lulẹ̀, tí a óo sì fi dáná.
Koda, awọn ileesẹ ẹrọ ibaraẹnisọrọ naa si ti n pariwo pe idakureku eto ibaraẹnisọrọ yoo wa lawọn agbegbe ọhun, ti ko ba si eroja epo ni arọwọto wsn lawọn agbegbe naa.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù 2019 Election: Ilé Asófin késí INEC láti fi N143bn sọwọ́ sí wọn lẹ́ẹ̀kan si 5 Ògún 2018 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 28 Ògún 2018 Oríṣun àwòrán, Senate Nigeria Àkọlé àwòrán, Ọjọ karundinlọgbọn Oṣu Kẹsan ni awọn aṣofin agba yoo pada si ẹnu iṣẹ Ariyanjiyan su yọ laarin ajọ eleto idibo lorilẹede Naijiria ati Igbimo to n bojuto ọrọ eto idibo ni Ile Igbimo Asofin.
Boasi bèèrè lọ́wọ́ ẹni tí ó jẹ́ alákòóso àwọn tí ń kórè, ó ní, “Ọmọ ta ni ọmọbinrin yìí?
Eyi ti o kẹyin yii ni ipenija rẹ pọju nitori wipe awọn eniyan kii fẹ fi ile wọn haya fun ohunkohun ti o ba niiṣe pẹlu awọn ọmọ t'ohun gbe lojupopo.
” ’ ”Àwọn ọkunrin náà sì lọ jíṣẹ́ fún Josaya ọba.
Pẹlu ikunsinu wọn yii, o ṣeeṣe ki wọn o lọ sile ẹjọ.
Oga agba yanyan fun ile-ise omo ogun, ogagun Tukur Buratai ti sabewo si iko omo ogun to n gbogunti awon omo ogun olote boko haram ni eka ila oorun orile-ede Naijiria.
Akọroyin BBC nibẹ jẹ ko di mimọ pe kọmiṣọna fun Eto Ẹkọ, imọ sayẹnsi ati imọ ẹrọ, Ọmọwe Ọlabimpe Aderiye ṣalaye pe igbesẹ naa di kanranngida lati daabo bo ẹmi awọn akẹkọọ, olukọ atawọn oṣiṣẹ miran kaakiri awọn ileewe.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Kí lo mọ̀ nípa Olùṣirò owó Àgbà àkọ́kọ́ ní Afrika?
Sẹnẹtọ Chimaroke Nnamani to jẹ gomina ipinlẹ Enugu tẹlẹ ri nikan lo tako kile sọ aba naa di ofin.
EndSARS protest in Nigeria: Mr Macaroni, Falz, Wizkid, Tiwa Savage àtàwọn míì ṣe ìwọde Owó oṣù tuntun fáwọn olùkọ́ tí Buhari kéde yóò dá aáwọ̀ sílẹ̀- Wike Àfikún owó epo, owó iná àti owó orí VAT ló jẹ́ ká fowó kún tàríìfù DSTV- Ọ̀gá MultiChoice Kò gbọdọ̀ sí ìfẹ̀họ́núhàn EndSARS ní ìpínlẹ̀ Rivers - Gomina Wike Ẹfunsetan Aniwura, ọmọ Ẹ̀gbá tó di akíkanjú obìnrin nílẹ̀ Ibadan Pasito Adeyemi ni: ''Ọdun mẹrindinlọgbọn si mẹtadinlọgbọn sẹyin ni awọn ti ṣe iru ifẹhọnuhan yii ri to si di ohun to jẹ ki eto oṣelu tiwantiwa jinlẹ de ibi to de loni ni Naijiria.
Oniru of Iru land: Onírù tuntun Oba Abdulwasiu Gbolahan Lawal gba ọ̀pá àṣẹ
Mo mọ̀ dájú pé ibukun ni fún ẹni tí o bá súre fún; ẹni tí o bá ṣépè fún, olúwarẹ̀ gbé!
O Chijioke n dari lo ṣedajọ naa lọjọ kẹtalelogun, oṣu kejọ ọdun yii.
 O tun wa gbosuba fun adari awon egbe osise lorile
Ìlú kò mọ ohunkóhun nípa iṣẹlẹ màálù tó kú nilu Ikarẹ- Oba Olukarẹ EFCC gbé ọ̀gá owó ìfẹ̀yìntì tẹ́lẹ̀ lọ sÍ ilé ẹjọ́ fún ìwà ìbàjẹ́!
Ni bayii apapọ eniyan to ti ni aarun naa ni Naijiria jẹ ẹgbẹẹdogun din aadọta.
Juda bá tọ̀ ọ́ lọ, ó ní, “Jọ̀wọ́, oluwa mi, jẹ́ kí n sọ gbolohun ọ̀rọ̀ kan, má jẹ́ kí inú bí ọ sí èmi, iranṣẹ rẹ, nítorí kò sí ìyàtọ̀, bíi Farao ni o rí.
Mo dupe lowo re fun ise ti o se lasiko ijoba yii ati
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Cerebral Palsy: àrùn tó n gba omijé lójú ẹni láìnídìí Yusuf ni igbesẹ yi yoo ṣina oko owo nipasẹ tita ọja tawọn ile iṣẹ Naijiria n ṣe lawọn orile-ede miran.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Jiti Ogunye: Ìjọba àkóbá lológun gbé kalẹ̀ ni 1999 Ọjọ Kẹrin, oṣu Kẹfa, ọdun 2019 ni Super Falcons yoo gbera kuro ni Austia lọ si orilẹ-ede France ti idije naa yoo ti waye.
Nítorí náà, nígbà tí ara wa kò gbà á mọ́, a pinnu pé kí ó kúkú ku àwa nìkan ní Atẹni; 
Kaini lọ tẹ ìlú kan dó, ó sọ ìlú náà ní Enọku, tí í ṣe orúkọ ọmọ rẹ̀.
Anbua so pe, fun idagbasoke, o ti ye ki awon agbe ti bere si ni gbaradi fun gbgbe awon ire oko won.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Neighbours clash: Ọkùnrin kan kú nítorí pé o fi ẹ̀sùn kan alájọgbélé rẹ̀ pé o n yan ìyàwó ẹnìkan lálè 1 Owewe 2020 Oríṣun àwòrán, others Ibẹrẹ ọrọ yii ni wọn sọ pe Stanley fi ẹsun kan Adekunle ti wọn jọ n gbele papọ pe, o n yan iyawo ayalegbe miran, Arinze Onuoha, ni ale.
Ohun ti aarẹ ẹgbẹ awọn agbaagba oṣiṣẹ fasiti lorilẹede Naijiria, SSANU, Kọmureedi Samson Ugwoke sọ ni peawọn owo ajẹmọnu kan ti ijsba jẹ wọn, pẹlu bi ijọba ṣe le awọn oṣiṣẹ ileewe alakọbẹrẹ ati girama to wa labẹ iṣakoso awọn fasiti to fi mọ awọn ẹhonu pẹ-pẹ-pẹ miran to nii ṣe pẹlu bi nnkan ṣe n lọ si ni ẹka ileewe giga fasiti lorilẹede Naijiria ni o n sun awọn kan ogiri ti wọn fẹ fi gun le iyanṣẹlodi yii.
Ẹgbẹ́ ọmọlẹ́yìn Kristi kéde àdúrà nítórí àrùn Coronavirus Àwọn ọmọ Nàìjíríà ń kérora àdánù tí àṣẹ ìjọba tó wọ́gilé ìrìnàjò láti òké òun mú bá wọn Ilé ẹjọ́ dá pásítọ̀ ìjọ Sotitobire padà sọ́gbà ẹ̀wọ̀n, ó sún ẹjọ́ síwájú Coronavirus:Ọmọ mi to ṣẹ̀sẹ̀ dé láti UK ko fi àmi Coronavirus han, sùgbọ́n.
" Aarẹ Buhari ti de si ọdọ Aarẹ Ramaphosa ni Pretoria ni South Africa Ẹ tètè pè fún àjọ tó ní irònú pìwàdà kó tó pẹjù- NLC/TUC Ilééṣẹ́ Aṣọ́bodè Naijiria n pa bílíọ̀nù N5.
Agbẹnusọ fun Aafin ile Oodua, Moses Ọlafare to fidi eyi mulẹ ni aṣalẹ ọjọ Aiku ṣalaye pe ẹni ọdun mẹtalelọgọrun ni iya naa ki ọlọjọ to de.
Eyi lo difa fun gbajugbaja oṣere tiata Yoruba, Nkechi Blessing to sọ fawọn akọroyin pe ikebe ti Eleduwa fi jinki oun tobi ju ohun ti oun le dọwọ bo lọ.
 wọ ́ n sọ wípé will rogers , aláwàdà ará amẹ ́ ríkà ni ó sọ ọ ̀ rọ ̀ tí ó wà níwájú àmì ìṣafihan .
    Lẹ́yìn náà ni iwin yìí bẹ̀rẹ̀ si ọ̀rọ̀ i sọ, ó ní;
Aare fokan awon omo egbe bale pe , nipa isokan ati emi ifokansin , o daju pe egbe APC ni yoo jawe olubori ninu eto idibo odun 2019, ni pinle Kwara.
Ibugbamu ado oloro  ti sele nibi ti awon oko n duro si ni Gusu Moyale to wa ni Huruka Godana lorile ede Ethiopia.
Ọpọ obinrin to ba jẹ asaraloge, to si maa n setọju awọ ara wọn loore koore ni kii fi eroja Cucumber sere rara.
Ekiti Election: Ẹ́gbẹ̀rún mẹ́rin nàirà ni ẹnikọ̀ọ̀kan ń gbà
ASUU jẹ́ pàtàkì igun ilé fún àjọ wa láti ṣe ètò ìdìbo tó ṣe mú yangan láwujọ àwọn orílẹ̀-èdè.
”Oba Enugu Aguleri, Igwe Chukwuemeka Eri ninu oro re ro ijoba lati ri si siso igi Aguve ti won n pe ni igi metalokan ati awon ibudo itan iran ile igbo bii Abu Gad ni Anambra di ajitannawo.
ẹ jẹ́ kí ó hàn sí gbogbo yín ati gbogbo eniyan Israẹli pé, ọkunrin yìí dúró níwájú yín pẹlu ara líle nítorí orúkọ Jesu Kristi ará Nasarẹti, ẹni tí ẹ kàn mọ́ agbelebu, tí Ọlọrun jí dìde kúrò ninu òkú.
Ìyanṣẹ́lódì òṣìṣẹ́ ilé aṣòfin bẹ̀rẹ̀ ní pẹrẹwu nílé aṣòfin Nàìjíríà Goodluck Jonathan kí Ààrẹ Buhari kú ọjọ́ ìbí Agbébọn pa ènìyàn 14, ọmọọ̀gun Naijiria sígun ni Kaduna Àwọn àwòrán mánigbàgbé nípa Ààrẹ Muhammadu Buhari Aarẹ Buhari ni afojusun abadofin naa ni lati tubọ fi ẹsẹ eto ọrọ aje Naijiria rinlẹ ni oju ọna ọrọ aje ti o ko akoyawọ lati mu awọn ọmọ orilẹede Naijiria kuro ni ọgbun oṣi ati iṣẹ.
Níbi tí kò bá sí mààlúù tí ń tu ilẹ̀, kò lè sí oúnjẹ,ṣugbọn agbára ọpọlọpọ mààlúù níí mú ọpọlọpọ ìkórè wá.
Dokita Iyabọ Ọbasanjọ naa gbena woju rẹ Igba keji ni ti akọbi rẹ, Iyabọ Ọbasanjọ to ti figba kan jẹ kọmisana fun eto ilere ni ipinlẹ Ogun.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Covid-19 second wave: ''Ìjọba kò tíì pàṣẹ ìlànà ìtakété-síra-ẹni padà nínú BRT la ò ṣe tíì ma tẹ̀le'' 15 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Oríṣun àwòrán, Facebook/LBLS Kaka ki ewe agbọn dẹ, niṣe lo n le koko sii.
Pẹlu abajade ifẹsẹwọnṣẹ yi, England yoo tẹsiwaju si abala tokangun si kelyi to kangun si aṣekagba idije naa.
Joaṣi wà pẹlu wọn níbi tí wọ́n gbé e pamọ́ sí ninu ilé OLUWA fún ọdún mẹfa tí Atalaya fi jọba ní ilẹ̀ náà.
PDP: Kẹmi Adeosun gbọ́dọ̀ fojú winá lórí ẹ̀sùn ayédèrú ìwé ẹ̀rí NYSC rẹ̀ Oríṣun àwòrán, @HMKemiAdeosun Àkọlé àwòrán, Kẹmi Adeọṣun kọwe fipo minisita feto iṣuna silẹ lori ẹsun ayederu iwe ẹri ti wọn fi kan an Lẹyin ti minisita feto iṣuna, Kẹmi Adeọṣun kọwe fipo silẹ lọjọ ẹti lori ẹsun ayederu iwe ẹri agunbanirọ rẹ, ẹgbẹ oṣelu PDP to jẹ aṣaaju ẹgbẹ oṣelu alatako lorilẹede Naijiria ti beere fun fifi minisita naa jofin lori ẹsun ko ṣe eto isinruulu NYSC rẹ ti o si tun lọ lo ayederu iwe ẹri fun.
 a lè yọ àràn náà kúrò díẹ ̀ díẹ ̀ láárin ọ ̀ sẹ ̀ díẹ ̀ nípa yíyí lóri igi .
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Etuhu: Ilé ẹjọ́ ni agbábọ́ọ̀lù Nàìjíríà, Dickson Etuhu jẹ́bi ẹ̀sùn títa ìdíje 14 Bélú 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Etuhu: Ilé ẹjọ́ ni agbábọ́ọ̀lù Nàìjíríà, Dickson Etuhu jẹ́bi ẹ̀sùn títa ìdíje Awọn ẹgbẹ agbabọọlu bii Manchester City, Sunderland, Preston, Blackburn ati Fulham ni agbabọọlu ọmọ Naijiria, Dickson Etuhu.
Nítorí bí ènìyàn bá mọ nǹkan títọ́ ní títọ́ àti nǹkan yíyẹ ní yíyẹ a kò ni í bá olúwaarẹ̀ ní ìdí nǹkan tí kò yẹ ọmọ ènìyàn.
Ṣaaju igbẹjọ yii, wọn fẹsun kan Mompha ti o ma n gbe igbe aye olowo pẹlu bii o se ma n fi aworan owo ilẹ okeere si ori ikanni Instagram rẹ, ati adura ni ọpọ igba.
Mu omi dáadáa, sún lásìkò, kí o sí ṣé wàhálà ni iwọnba ti agbára rẹ ba ká.
Asojú ẹgbẹ́ ajàfẹ́tọ́ ọmọnìyàn kan tó ńjẹ́ Pepper Dem, Maame Akua sọ wípé àgbára àìdọ́gba ọkùnrin s'óbìnrin wà ní orílẹ̀èdè Ghana tí wọ́n gbùdọ̀ wá ojútùú sí.
Aarẹ Putin salaye pe sise amugbooro okun ajọsepọ laarin awọn orilẹede Afirika jẹ ọkan lara awọn ilana ilẹ okeere to jẹ wọn logun.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Hubert Ogunde rèé, baba àwọn òsèré tíátà Samuel Ladoke Akintọla jẹ́ Agbẹjọ́rò àti Akọ̀ròyìn tí ọ̀rọ̀ dá lẹ́nu rẹ̀ Àràbarà pósí rèé, ibùgbé ìkẹyìn tó jẹ ojú ní gbèsè D.
Bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé wọ́n ti ta ara wọn fún àwọn orílẹ̀-èdè mìíràn, n óo kó wọn jọ láìpẹ́, láti jẹ wọ́n níyà, fún ìgbà díẹ̀, lọ́dọ̀ àwọn ọba alágbára tí yóo ni wọ́n lára.
Onírìn àjò ìgbafẹ́ tí ó ń lo ìwé-ìrìnnà Orílẹ̀-èdè Canada ni apànìyàn náà, ẹni tí ó gún òǹtajà ìsọ̀ náà nígbà tí òǹtajà bíi léèrè ìdí tí ó fi kó ọjà láì san owó.
Awọn ajinigbe mẹwa ni wọn ṣọsẹ loju ọna mọrosẹ Abuja si Kaduna lọjọ Aiku nibi ti wọn ṣeku pa ọmọ ologun kan ti wọn si ji ọpọ arinrinajo gbe.
Akọnimọọgba Supe Eagles Gernot Rohr ti sọ pe ẹgbẹ agbabọọlu Naijiria ti ṣetan lati jẹwọ ara wọn fun Brazil ninu ere bọọlu lorilẹede Singapore.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Premier League: Everton da yẹ̀pẹ̀ sí gaàrí Manchester United 21 Ìgbé 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 22 Ìgbé 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Idije Premier League Igbaju igbamu ni kẹrikẹri n ba rode ni Everton fi ṣe fun ẹgbẹ agbabọọlu Manchester United ninu idije Premier League.
Awọn oninu 're gbọdọ fọwọsowọpọ Ọjọgbọn ni ti ọdọ oloṣelu to fẹ yii ọrọ oṣelu Naijiria pada si rere ba fẹ de ipo lai fi ti awọn baba isalẹ ṣe, ẹni bẹẹ gbọdọ fọwọsowọpọ pẹlu awọn to ni ọkan bii tirẹ.
Gbogbo wọn pa àwọn ọmọ ogun wọn pọ̀ ní àfonífojì Sidimu (tí ó tún ń jẹ́ òkun iyọ̀).
 o je elebun nobel ninu fisiksi pelu william alfred fowler fun ise won lori opo elero ati iyojade awon irawo .
Wayii o, iwadii si n lo lowo
Dájúdájú Ọlọrun ti dá mi lágara,ó ti sọ gbogbo ilé mi di ahoro.
Ile ẹjọ kan ni orileede Faranse dajọ pe minisita ọrọ epo rọbi tẹlẹri Dan Etete jẹbi magomago ti o si fi owo eru ra ọkọ oju omi ati ile nla kan.
Ọmọogun Naijiria bẹrẹ Operation Cat Race Fulani darandaran lo iwa ipa ni guusu Akurẹ Ọlọrunwa ni ẹni ti ọlọpaa sọ wipe idaniloju wa pe o gbe iṣẹ ipaniyan fun Ade Lawyer"" lati pa alabadupo rẹ, ti wọn pe ni Azeez Lawal."
Umaru Musa Yar'adua Àkọlé àwòrán, Ààrẹ Umaru Musa Yar'adua Umaru Musa Yar'adua ni aarẹ ikẹtala to jẹ lorilẹede Naijiria.
Femi Falana: Ojú Elzakzaky kan ti fọ́ nítorí àìsí ìtójú tó
''Irọ ni pe mo ko lọ sile ọkunrin mii, ọdọ ọrẹ mi ni mo lọ nigba ti iṣẹ gbe ọkọ mi lọ si Borno,'' Nkem lo ṣalaye bẹẹ.
O si ti ṣe ọpọlọpọ ikọlu nibẹ lábẹ́ orúkọ ISIL to n jẹ bayii.
Ogo bá bẹ̀rẹ̀ si nii tán, o bẹ̀rẹ̀ si ni ṣeré orin lori itage fún iléese Nigeria Broadcasting Corporation, Amosa, pupọ owó tó bá wọlé nígbà náà lọhun, ọwọ oga orin lo máa ń lọ táwọn ọmọṣe elegbe kan máa ń rí taatata.
Oríṣun àwòrán, EPA Àkọlé àwòrán, Eeru lati ara oku ti wọn ti jo nina ni awọn ẹlẹsin Aghoris ma n fi para.
Dokita Olaolu Oyeniran to n ṣoju fun ẹkun idibo Odo-ọtin nipinlẹ Ọsun ti gbera sọ lọ si ẹgbẹ oṣelu ADC.
" "" ojú iná kọ ́ ni ewùrà ń hurun "" ."
Abẹ́rẹ́ kan kìí kọ ohùn aṣọ
Tunde Ednut: Ìdí mẹ́fà rèé tí Instagram, Facebook le fi wọ́gilé ojú òpó ìkànsíraẹni rẹ
Inú wá bí ọba náà, ó bá rán àwọn ọmọ-ogun rẹ̀ kí wọ́n pa àwọn apànìyàn wọ̀n-ọn-nì run, kí wọ́n sì dáná sun ìlú wọn.
Ọ̀rẹ́ ìmùlẹ̀ pátápátá ni àwọn ara ilé Òmùgọ́parapọ̀ àti Wọ̀bìáparapọ̀ jẹ́, ọ̀rẹ́ náà jinlẹ̀ gidigidi.
n óo rán ìjì líle kan sí Babiloni,ìjì náà yóo fẹ́ ẹ dànù bí ìyàngbò ọkàyóo sì sọ ilẹ̀ rẹ̀ di ahoro,nígbà tí wọ́n bá gbógun tì í yípo, ní ọjọ́ ìpọ́njú.
Ìdí rèé tí kò ṣe sí iná mọ̀nàmọ́ná láwọn agbègbè kan ní Nàìjíríà Naira Marley gba ipò mọ́ Atiku lọ́wọ́ gẹ́gẹ́ bí èèyàn tí wọ́n ń wá jùlọ ní Google lọ́dún 2019 Ìgbà Marún-un ti Aisha Buhari ti tako ìjọba Buhari Kìí ṣe ìwà ọ̀lẹ ni bàwọn obìnrin ayé òde òní kìí ṣe dàra pọ̀ mọ àwọn olobinrin ilé Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Akure Kidnap: Àwọn abiyamọ fẹ̀hónúhàn lórí ọmọ tí wan jígbé nílé ìjọsìn Akurẹ Bẹẹni pẹlu iroyin ti o jadi laipẹ yii, oun ni ọmọ orilẹede Naijiria ti awọn eeyan ṣe afẹri rẹ juls lori oju opo google lọdun 2019.
Orísirísi ni àwọn àbùdá tí èdè Yorùbá ní.
Bẹ́ẹ̀ gan-an ni kí ẹ máa ṣọ́nà nítorí ẹ kò mọ ìgbà tí baálé ilé náà yóo dé: bí ní ìrọ̀lẹ́ ni, tabi ní ọ̀gànjọ́, tabi ní àkùkọ ìdájí, tabi ní àfẹ̀mọ́jú.
Mo fọ́ wọn túútúú, wọ́n sì dàbí erùpẹ̀ ilẹ̀;mo tẹ̀ wọ́n mọ́lẹ̀, wọ́n sì dàbí ẹrọ̀fọ̀ lójú títì.
''Òsìsẹ́ Custom tó déédé sọ ara rẹ̀ di Ọ̀gá Àgbà CG ní ìdàmú ọpọlọ'' Ilééṣẹ́ Aṣọ́bodè Naijiria n pa bílíọ̀nù N5.
Awọn kan tiẹ sọ pe ko yẹ ki n maa sọ iru iṣẹlẹ buruku yii fawọn eeyan lawujọ, ṣugbọn n ko ni ọrọ lati ba iru awọn bẹẹ sọ.
Ayẹwo aworan lọna igbalode lori ayelujara fihan pe ni oṣu kẹta ọdun 2020 ni aworan iṣẹlẹ naa ti waye lasiko ti awọn Biṣọbu ijọ Aguda lorilẹede Naijiria ṣe ipade apapọ wọn, (CBCN) ni ilu Abuja ti wọn si wọde lati fi ẹhonu han lori iṣẹlẹ ipaniyan ati ijinigbe to wa di tọrọfọnkale nigba naa.
 Àtún lè lo oògùn yìí ní ìpele kẹta oyún .
ijoba apapo ati ipinle lati san ẹkun owoosu ọgbọ̀n ẹ̀gbẹ̀rún , ti ijoba apapo bọwọlu
Nibayii, iye awọn to ti ri iwosan gba ti le ni ẹgbẹjọ(1644), ti eniyan mọkanlelaadọwa si ti ri ku nitori arun naa.
Láti ìparí ọdún 2016, a ti fi ìtàn àwọn ènìyàn ṣe ìdánilẹ́kọ̀ọ́ àyíká fún àwọn èwe ní ìgbèríko Laos àti Thailand.
Eyii kii ṣe irufẹ ikọ ti eeyan n wu lẹẹkọọkan o, bikoṣe eyi ti yoo maa waye ni lemọlemọ laisi idi kan gbogbogi.
Alukoro awọn ọlọpaa ni Kaduna, PPRO wọn ni irọ funfun balau ni awọn ẹlẹsin Shiite n sọ.
Yàtọ̀ sí ife ẹ̀yẹ AFCON, orílẹ̀èdè wo ló tún leè mókè lẹ́ka míràn l‘Afirika Wo ìdí tí àwọn obìnrin kan fi n yọ ilé ọmọ wọn kúrò Èyí ni ọ̀nà tí àwọn obìnrin n gbà kó ara wọn sí wàhálà nítorí ara bíbó Wole Soyinka rèé láti kékeré Igba mẹjọ ọtọọtọ ni Naijiria ti fagba han Algeria ninu idije sẹyin nigba ti wọn ti jọ gba ọmi ni ẹẹmarun un.
O ni ijọba n dun kooko mọ oun ni ati pe wọn ti ṣaaju bere nipa iṣẹ ati mọlẹbi oun ki wọn to gbe oun.
Akosemose lori itoju ayika, Richard Inyamkume, ti gba awon eniyan nimoran lati dekun igbe sisun ati jijo ile nina nitori pe o maa n je ki ile padanu eroja ile.
Ipo ti Olódùmarè fi ọmọ ènìyàn sí, wọn kò mọ̀ ọ́, ẹ̀wù funfun tí Olódùmarè gbé bọ ọmọ ènìyàn lọ́rùn, wọ́n da epo pupa si i, Ẹlẹ́dàá fún wọn ni aṣọ iyì, ṣùgbọ́n wọ́n rìn ní ìhòòhò- ẹ̀yin aláìmoore, ẹ̀yin kò mọ̀ pé òkúta tí ó ga jù yin ni ìgbà ẹgbẹ̀rún, ẹ̀yin a maa fọ́ o, igi tí ó ga jù yín ní ìgbà àádọ́ta, èyin a máa bẹ́ ẹ lulẹ̀, omi òkun bí ó ti tóbi tó ni, ó wà níkàá wọ́ yín, ẹ̀ ń fi ọgbọ́n yín mu erin, ẹ̀ ń fi mú ẹkùn, ẹ sì fì ń mú kìnnìhún ọba ẹranko.
Ó bi Jehoṣafati pé, “Ṣé o óo bá mi lọ, kí á jọ lọ gbógun ti ìlú Ramoti Gileadi?
Abẹrẹ naa ti wọn pe orukọ rẹ ni RTS, S ma kọ awọn ọmọ ogun inu ẹjẹ bi wọn yoo ṣe doju ija kọ kokoro aarun iba ti awọn ẹfọn ma n gbe kaakiri.
7 Èbibi 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Idije Champions League Ayo mẹta sodo ni Liverpool jẹ lọwọ Barcelona ni papa iṣere Camp Nou ninu abala akọkọ ifẹsẹwọnsẹ to kangun si aṣkagba idije UEFA Champions League.
Eyi lo mu ki BBC kan si ọọfiisi gomina Sanwo Olu lati mọ erongba wọn lati fopin si iṣẹlẹ yii ko too maa gbẹbọ lọwọ ipinlẹ Eko.
Kí ní ń bà ọ́ lọ́kàn jẹ́?
Yoo se gẹgẹ bi ofin ṣe sọ ni.
Odumosu, lasiko to gbe Bimbo sita fun ifọrọwanilẹnuwo ni olu ile isẹ ọlọpaa ipinlẹ Eko to wa ni Ikeja, ni ogun eniyan lo wọkọ oju omi naa lati Kirikiri.
Nítorí bí ó bá jẹ́ pé ní Sodomu ni a ti ṣe àwọn iṣẹ́ ìyanu tí a ṣe ninu rẹ ni, ìbá wà títí di òní.
Iṣẹlẹ yii waye lasiko ti awọn agbebọn naa fi kọlu ileewe girama kan ni ipinlẹ Yobe.
” Nígbà tí wọ́n gbọ́ bẹ́ẹ̀, ẹ̀rù bà wọ́n gidigidi, wọ́n ń wo ara wọn lójú, wọ́n sì bẹ̀rẹ̀ sí gbọ̀n, wọ́n ní, “Irú kí ni Ọlọrun ṣe sí wa yìí?
Amọ sa, atẹjade naa ko salayeohun to fa sababi isẹlẹ naa.
lati maa ni imo ero igbalode.
Wọn óo wá mọ̀ pé èmi ni OLUWA nígbà tí mo bá ṣe ìdájọ́ fún àwọn tí ń gbé inú rẹ; tí mo sì fi ìwà mímọ́ mi hàn wọ́n.
Nítorí bí ọ̀run ti jìnnà sí ilẹ̀,bẹ́ẹ̀ ni ìfẹ́ rẹ̀ tí kì í yẹ̀ ṣe tóbi tósí àwọn tí ó bẹ̀rù rẹ̀.
Nínú ọgba ẹwọn lo ti ń ni ajọsẹpọ pẹ̀lú àwọn aráa rẹ̀ to kù nita pàápà jùlọ àwọn ti àjọ EFCC ń ṣewadiìí wọn fún kíkó owó ìlú pamọ lọ́nà àìtọ.
Àgbo tí mò ń lò láti jò kó bá mi, ìdí mi ti yọ́ tán - Nkechi Blessing figbe ta Iyatọ nla si lo wa nipa igbeyawo naa si eyi to ti n waye tẹlẹ, bẹrẹ lati ori ife imumi, akara oyinbo, ẹbun wi wọn ha, ounjẹ ti wọn se ati asọ iyawo funra rẹ.
Ikọlu yii lo ṣokunfa iwọde lodi si awọn Tamil ni eyi to gba pe ko ṣeyin wọn ni abule rẹ ni Vishwamadu ni ariwa Sri Lanka.
Arike Ogunbowale ran re iko agbaboolu afowogba Notre Dame lati gba ife-eye idije National Collegiate Athletic Association (NCAA) todun 2018 pelu ami-ayo mọ́kànlélọ́gọ́ta si mẹ́rìndínllọ́gọ́t(61-58) lati fagbahan Mississippi State.
Bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé ó ti rẹ̀ wọ́n, sibẹsibẹ wọ́n ń lé àwọn ará Midiani lọ.
Ati pe ki ijọba dakun gbe igbesẹ lati lee ko wọn pada wa si ile gẹgẹ bi wọn ṣe n ṣe fun awọn to wa lawọn orilẹ-ede miran.
Ó wí fún un pé kó fi àrẹ̀mọ rẹ̀ rúbọ sí Òun.
O kọ imọ ofin ni ilu London, ni Ilẹ Gẹẹsi, ti o si lọ ile iwe awọn agbejọrọ ni orilẹede Naijiria ni ọdun 1968.
Ìwádìí fi hàn pé, gbogbo ànfàni yìí kìí ṣe fun àwọn onílùú nìkan, bí kò ṣe àwọn míràn ti wọn wá tẹ̀dó si orílẹ̀-èdè wọn náà.
Kàkà bẹ́ẹ̀, wọ́n níláti sìn wọ́n tara-tara, nítorí àwọn tí wọn ń ṣiṣẹ́ fún jẹ́ arakunrin ninu igbagbọ ati ìfẹ́.
Ó pèsè oyin fún wọn láti inú àpáta,ó sì mú kí igi olifi hù fún wọn lórí ilẹ̀ olókùúta.
Gíga ọ̀kan ninu àwọn òpó náà jẹ́ igbọnwọ mejidinlogun, ọpọ́n idẹ tí ó wà lórí rẹ̀ jẹ́ igbọnwọ mẹta, wọ́n fi bàbà ṣe ẹ̀wọ̀n bí ẹ̀gbà ọrùn ati pomegiranate yí ọpọ́n náà ká, òpó keji sì dàbí ti àkọ́kọ́ pẹlu ẹ̀wọ̀n bàbà náà.
Kí ẹ rú ẹbọ sísun yín ati ẹran ati ẹ̀jẹ̀ rẹ̀ lórí pẹpẹ OLUWA Ọlọrun yín, ẹ da ẹ̀jẹ̀ ẹbọ yín sórí pẹpẹ OLUWA Ọlọrun yín, kí ẹ sì jẹ ara ẹran rẹ̀.
Àwọn ọmọ Lefi yóo ní ìpínlẹ̀ tiwọn lẹ́gbẹ̀ẹ́ ilẹ̀ tí a pín fún àwọn alufaa, òòró rẹ̀ yóo jẹ́ ọ̀kẹ́ kan ati ẹẹdẹgbaata (25,000) igbọnwọ (kilomita 12½), ìbú rẹ̀ yóo sì jẹ́ ẹgbaarun (10,000) igbọnwọ (kilomita 5).
"O ní ìjọba yóò ṣeto àwọn ibùdó ti àwọn ènìyàn yóò ti maa fọ ọwọ wọ́n nínú ọgbà, bẹ́ẹ̀ ni àwọn òṣìṣẹ́ kọ̀ọ̀kan yóò maa gba ""hand sanitizer"" àti ìbòjú-bomú."
Osise ijoba kan so pe”isedo omi Patel lo fa omiyale naa nipa ojo nla kan  to ro.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Àwọn òṣèré Nollywood tí wọn ò sí lóri amóhùmáwòrán mọ́ Àwọn fíìmù Nollywood ń mú kí òògùn owó àti ìjínigbé gbilẹ̀ síi - Fashola Díẹ̀ lára àwọn òṣèré Nollywood ti wọ́n ti ṣe ìgbéyàwó lẹ́ẹ̀kejì Kíni ẹ mọ̀ nípa àwọn gbajúgbaja Yollywood?
Wọ́n jẹ́ ọrẹ ẹbọ Naṣoni, ọmọ Aminadabu.
itoju oju fun tomode tagba lorilede Naijiria, eleyii ti Christobel Blinden
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Josh Posh: Inú mi máa ń dùn láti kọrin fún àbúrò mi ní kékeré Nígba ti Joshua pè ọmọ ọdun mẹ́ta o ti bẹ̀rẹ̀ si ni kàwé geerege tó si ń sọ èdè Japàní, bákan náà lo tí mọ ǹkan kọ sori kọmputa ko to bẹ̀reẹ̀ si ni kọ̀wé pẹ̀lu bírò.
    Nígbà tí ó yọ, , àbúrò rẹ̀ bẹ̀rẹ̀ síi kíi, ẹ máa wolẹ̀, ẹ máa rọra, ẹ máa wọlẹ̀, ẹ máa rọra, a bu ọla fún yín, a ba búrúbúrú, ẹ máa wolẹ̀ ẹ̀gbọ́n mi, ẹ máa rọra, ẹ máa rọra, ọmọ onílẹ̀ tẹ̀ ẹ́ jẹ́jẹ́, àjèjì tẹ̀ ẹ́ gìrìgìrì, ẹ̀yin lẹ ni mi, ẹ̀yin lẹ ni lẹ̀.
Wọ́n jù mí sinu ihò láàyè,wọ́n bẹ̀rẹ̀ sí sọ òkúta lù mí mọ́lẹ̀.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ètò ìsìnkú Abba Kyari tako ìlànà ìjìnàsíraẹni lórí ààrùn covid-19- Àwọn ọmọ Nàìjíríà yarí Lara awọn ti Kari sọ wi pe o le rọpo Kyari ni Asoju ilẹ Naijiria, Babagana Kingibe, Adari ileeṣẹ ẹṣọ ibode lorilẹede Naijiria, Hammed Ali ati Minisita fun eto ẹkọ, Adamu Adamu.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Iyalẹnu lo jẹ pe iṣẹju marun un ti wọn bẹrẹ ifẹsẹwọnsẹ naa ni Richarlison gbayo kan wọle Chelsea lairo tẹlẹ.
O ni eyi lo jẹ ki ẹgbẹ awọn onile iṣẹ akọroyin BON fẹnuko pe eto ọrọ aje Naijiria ko burẹkẹ to lasiko yii.
2m ọmọdé kò ṣe lọ sílé ẹ̀kọ́ - SERAP ké tọ iléẹjọ́ àgbáyé Ọrọ̀ ajé Nàíjíríà tún leè dagun tí Buhari bá fi ìyànsípò àwọn mínísítà falẹ̀ si - Onímọ̀ A óò wá àwọn ọmọ ilẹ̀ Turkey mẹ́rin tí wọ́n jígbé rí láàyè- Ọlọ́pàá Kwara Amọṣa lasiko idibo apapọ to kọja, ọpọ awọn ọmọ orilẹede yii paapaajulọ awọn to jẹ alatilẹyin Aarẹ Muhammadu Buhari ni wọn kọju ija sii lori ọpọ oju opo ayelujara wi pe o n tẹle oludije fun ẹgbẹ oṣelu PDP lasiko idibo naa, oloye Atiku Abubakar.
Ọladele ni ' O damiloju pupọ pe aburo mi ki i ni ibalopọ ọkunrin s'ọkunrin rara, o kan ṣirin ni.
Laipẹ yii ni iroyin kan kaakiri orilẹede Naijiria wipe awọn ọmọde ti ọjọ ori wọn ko to ọdun mejidinlogun fi orukọ silẹ lati dibo ni ipinlẹ Kano, eleyi ti ọpọlọpọ eniyan fi oju laifi wo.
Ọpọlọpọ awọn eeyan ni wọn ti n pariwo lori ọṣẹ ti awọn ọkọ ajagbe, yala eyi to n gbe epo ni tabi awọn ẹru miran, maa n ṣe lawọn oju popo; paapaa julọ ni ipinlẹ Eko.
" Soyinka sọ pe ọdun 2020 kii ṣe ọdun to dara rara fun oun, ni gbogbo ọna.
Ijọba Ogun ko danu duro lori ikinni nikan, wọn tun ni ko ma gbagbe lati san owo ori rẹ fun ọdun 2021 ninu owo to jẹ naa.
Aarẹ ile igbimọ aṣofin Sẹnetọ Ahmad Lawan ati adari ile igbimọ aṣoju-ṣofin, Femi Gbajabiamila wa nibi ipade naa lojukoroju.
Kò ní falẹ̀ mọ́, ṣugbọn níṣojú ẹ̀yin ìdílé ọlọ̀tẹ̀, ni n óo sọ̀rọ̀, tí n óo sì mú un ṣẹ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Arap Moi: Ilé ẹjọ́ ní kí aààrẹ Kenya àná san owó ìtanràn $10m fún opó nítorí ilẹ̀ 18 Èbibi 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Daniel arap Moi jẹ́ aarẹ Kenya fún ọdun mẹ́rinlelogun Bi irọ ba lọ logun ọdun, ọjọ kan lotitọ yoo ba ni ọrọ Aarẹ orilẹede Kenyan nigba kan ri Arap Moi ti ile ẹjọ kan ni orilẹede naa ni ko say miliọnu mẹwa ati aabọ dọla gẹgẹ bi owo itanran fun opo kan ti o gba ilẹ rẹ ni ọdun mẹrindinlogoji sẹyin.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, #EkitiDecides: Sẹgun Adewale ní ìpèsè ohun ìdẹ̀rùn yóò bá ìfẹ́ aráàlú mu Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, #EkitiDecides: Fayose sùn lórí ibùsùn aláìsàn Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ekiti Election: Idibo ti bẹrẹ ni pẹrẹwu!
O wa ro awon omo-ogun ohun lati tunbo tepa mo ise won, ki won si se e doju ami, bi o ti to at bi o se ye,Bakan naa ni o fi idunnu re han si agbedide ayeye olodoodun ile-ise ologun ohun ti won ti da duro lati bi odun meje seyin.
tabi kí ó máa sa òògùn sí ẹlòmíràn, tabi kí ó máa bá àwọn àǹjọ̀nú sọ̀rọ̀, tabi kí ó di abókùúsọ̀rọ̀.
Báwo sì ni àwa ará ìlú Ṣekemu ṣe jẹ́ sí i, tí a fi níláti máa sìn ín?
Labẹ ofin Vienna to de ibaṣepọ laarin awọn orileede, eeyan ko le fọwọ kan ilẹ orileẹde kan nibi to ba wa nilẹ mii.
dájúdájú hárúnà Ìṣọ ̀ lá ni olórin àpàlà tí ó gbajúmọ ̀ jùlọ nínú ìtàn nàìjíríà .
Lẹ́yìn náà, wọ́n kọ orin kan, wọ́n bá jáde lọ sórí Òkè Olifi.
Bẹ́ẹ̀ ni àwọn mejeeje ṣe, wọ́n kú láì ní ọmọ.
Nǹkankan ni èmi mọ̀: afọ́jú ni mí tẹ́lẹ̀, ṣugbọn nisinsinyii, mo ríran.
Ko pẹ lẹyin ti wọn ji awọn ọmọ yii gbe ni awọn obinrin kan ko ara wọn jọ pẹlu akọle ẹ da ọmọbinrin wa pada: Bring back our girls)."
Bakan naa lo fi kun un pe ọrinlelẹẹdẹgbẹrin o le mẹsan lawọn eeyan to ti jade laye nipasẹ arun yii lorilẹ-ede Naijiria.
Bill ati National Agricultural Seeds Council Bill).
Ọwọ́ tẹ èèyàn kan pẹ̀lú orí ọmọdé nílé aṣòfin àpapọ̀ Àlàyé rèé láti ẹ́nu mọ̀lẹ́bí ìyàwó Pásítọ̀ Sylvester Ofori ọmọ Ghana tó yìnbọn pá aya rẹ̀ l'Amẹrika Ilé aṣọ̀fin Nàìjíríà ń gbèrò ẹ̀wọ̀n f'áwọn olùkọ̀ tó bá dẹnu ìfẹ́ kọ akẹ́kọ̀bìnrin Pope Francis wọ́gilé òfin tó n dáàbò bo àlùfáà tó bá bá ọmọdé l'òpọ̀ Àjọ ọlọpàá Eko kédé pé ìbalòpọ̀ nítà kò bójúmu Àwọn ọ̀nà tí obìnrin fi le gbádùn ìbálòpọ̀ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Tóò bá fún ọkùnrinn lóúnjẹ́ tóo tẹ́ kiní yẹn sílẹ̀ fún un dáadáa.
Àwọn tó jí ìbejì mi gbé ti pè mí ṣùgbọ́n N50 mílíọ̀nù tí wọ́n ń béèrè pọ̀ ju agbára mi lọ-Akeugbagold Akeugbagold, bàbá ìbejì tí wọ́n jí gbé n'Íbàdàn ní òun ti ń tà dúkìá òun láti rówó àmọ́ ohun táwọn ajọmọgbe ń bèèrè kọjá agbára Oríṣun àwòrán, Akeugbagold Sheik Taofeeq Akeugbagold, tí àwọn gende agbebọn jí ìbejì rẹ gbé lọ, tí fìdí rẹ múlẹ̀ pé àwọn tó gbé ìbejì òun ti kan sì òun.
Iyawo oníjà dàbí omi òjò,tí ń kán tó!
Ọsẹ mẹfa sẹyin lo gba lati ja lẹyin ti ẹni to yẹ ki oun ati Joshua jọ ja, Jarrell Miller kuna ayẹwo oogun oloro ti wọn ṣe fun un.
Mummu ni lo sọ ọrọ naa lẹyin ti ẹgbẹ oṣelu APC ni awọn to ba nifẹ lati kopa ninu idibo abẹle gomina ipinlẹ Ondo ati Edo ni lati san miliọnu mejilelogun atabọ naira gẹgẹ bi owo fọọmu.
Ṣugbọn Labani dá a lóhùn pé, “Gbà mí láàyè kí n sọ ọ̀rọ̀ yìí, mo ti ṣe àyẹ̀wò, mo sì ti rí i pé nítorí tìrẹ ni OLUWA ṣe bukun mi, 
Oríṣun àwòrán, Insatagram/lizzyanjorin Awọn ololufẹ Lizzy Anjorin Tawakalitu Lawal to jẹ ololufẹ rẹ bu ẹnu atẹ lu bi Lizzy ṣe n sọrọ alufansa si ojugba rẹ ninu iṣe sinima.
Ninu idajọ to gbe kalẹ ni ọjọọbọ ni ileẹjọ naa ti faaye gba ajọ to n gbogunti ṣiṣe owo ilu baṣubaṣu, EFCC lati fi agadagodo le aṣuwọn naa.
'Nínúu kí a yọ oyún inú rẹ tórí iṣẹ́ abẹ tàbí kóo wà nínú ìrora' Irú ẹ̀dá wo ni Ọjọgbọn Folasade Ogunsola jẹ́?
Ìjọba ìpínlẹ̀ Kano tilẹ̀kùn ibodè rẹ̀ nítorí aàrùn coronavirus Olóòtú Ilẹ̀ Gẹ̀ẹ́sì, Boris Johnson ti kó àrùn Coronavirus!
Bi otile je pe, ko si egbe Kankan ti o so pe, awon ni won wa nidi ikolu ohun, amo ijoba gbagbo pe, awon omo ogun alakata-kiti elesin Islam  al-Shabab ni won wa nidi ikolu ohun.
Sunkẹrẹ Fakẹrẹ loju popo Awọn iwe iroyin oke okun kan tilẹ jabọ iroyin pe lọdun 2012, ninu gbogbo ilu ti sunkẹrẹ fakẹrẹ ọ̀kọ̀ wa lagbaye, ti ilu Eko lo gbegba oroke.
Angẹli OLUWA bá pàṣẹ fún Gadi pé kí ó lọ sọ fún Dafidi pé kí ó lọ tẹ́ pẹpẹ kan fún OLUWA ní ibi ìpakà Onani ará Jebusi.
Iyinbọn paniyan naa lo jẹ ẹlẹyi to buru ju l'Amerika lati ọdun 2012 o si ti n fa ariyanjiyan lori fif'ofin de ibọn rira.
Bótilẹ̀ jẹ́ pé ìjọba kọ́kọ́ sọ pé kìí ṣe àwọn sójà ló ṣe iṣẹ́ náà, wọ́n padà mú àwọn ọmọogun méje sùgbọ́n àwọn méjì ninú wọ́n ni wọ́n dásill pé wọ́n kò jẹ̀bi ẹ̀sùn kankan.
"O ni ""Lẹyin naa lo ko yanri sẹnu ọna ile ọhun lati le dina mọ awọn to ba fẹ wọle sibẹ."
“Ọ̀rọ̀ náà rí bí ó ti wà ní àkọsílẹ̀ ninu Ìwé Orin Dafidi pé, ‘Kí ibùgbé rẹ̀ di ahoro,kí ẹnikẹ́ni má gbé ibẹ̀.
Ṣugbọn o fi kun ọrọ rẹ pe ile iṣẹ ọlọpaa yoo ri daju pe ọwọ ofin ba awọn ajinigbe ọun.
 Eyi je afihan ipinnu wa lati ri orile-ede Naijiria ko se aseyori gege bi a se panupo pe ko si orile-ede ti o le ni ilosiwaju lai si isokan laarin won.
Agbẹnusọ fun ajọ JAMB, ọmọwe Fabian Benjamin sọ fun BBC pe ẹgbẹrun mẹta abọ Naira (N3500) ni iye owo fọọmu.
Ẹ níláti sọ fún baba mi nípa gbogbo ògo mi ní Ijipti, ati gbogbo ohun tí ẹ ti rí.
Ta ló ń ro ikú ro olórin Raggae, Majek Fashek?
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ojú mi ti rí lọ́pọ̀ lọpọ̀, àmọ́ mo dúpẹ́ pé mo ti pé ọdún márùn ún lórí oyé- Ooni Ìjọ 10,000 tuntun ni a dá sílẹ̀ láì gba owó ọrẹ lọ́wọ́ ọmọ ìjọ lásìkò àrùn Coronavirus- Oyedepo Oluṣọ agutan agba ijọ Living Faith, pasitọ David Oyedepo ti ṣi aṣọ loju eegun pe bo tilẹ jẹ arun Covid-19 ba gbogbo agbaye finra lọdun 2020, ẹka ẹgbẹrun mẹwaa tuntun ni ijọ naa ṣi lai gba kọbọ lọwọ ọmọ ijọ kankan.
 orílẹ ̀ èdè tí ó ní àjẹsára yìí púpọ ̀ kìí ń sábà rí ìṣẹ ̀ lẹ ̀ arun rubella tàbí ti congenital rubella syndrome .
Minisita naa sisọ loju ọrọ yii lasiko to n bawọn akọroyin ile ijọba sọrọ lopin ipade igbimọ alasẹ ijọba ilẹ yii.
egbe ohun yoo se ayajo ose akoroyin ninu eyi ti won yoo se ere idaraya olore-sore
Kò sí àrídájú bóyá ẹnikẹ́ni san owó ìtanràn kí wọ́n tó dá a sílẹ̀.
Gẹgẹ bi awọn nkan to gbe ṣe yanju ṣe wa lasiko iṣejọba rẹ, bẹẹ naa ni awọn ti ko ri yanju wa.
81tn) lo wọle si apo ijọba, eyi ti ko ju ida mejidinlaadọrin ninu ida ọgọrun un ti ijọba n reti lọ.
Aare tun wa dupe lọwọ Ọlọrun
Eeyan mẹta, akukọ meje ati awọn nkan ija mii to fi mọ owo ilẹ Phillipines to to dọla mọkanla lọlọpaa ri gba nigba ti wọn yabo ibi ti wọn ti n fi akukọ ja.
Fatai Rolling Dollar pẹlu ohun ti gbogbo eeyan fi mọ ọ jẹ gbajugbaja olorin to ma n ta jita pọ mọ orin kíkọ ó sì tun jẹ ó onímọ̀ nípa duuru ibilẹ Yoruba to ń jẹ Agidigbo.
Ẹ̀rù ba àwọn ẹlẹgbẹ́ mi aláwọ̀funfun náà.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Mo máa n forin mi kìlọ̀ ìwà ìbàjẹ́ láwùjọ ni -Hameen Buhari ni oun yoo maa tun ọrọ oun sọ lori gbigbogun ti iwa jẹgudu jẹra nitori eyi jẹ iṣe oun lati igba ti oun ti wa nijọba ologun Naijiria.
Arun itankalẹ igbẹ ọrin yii lo waye lataari inu didaru fawọn eeyan ni ipinlẹ Eko ni guusu Naijiria.
Kì í ṣe ẹni ti ẹ̀mí ni ó kọ́kọ́ wà bíkòṣe ẹni ti ara, lẹ́yìn náà ni ẹni ti ẹ̀mí.
Bi awọn kan ṣe ni Dino ko bọwọ fawọn to wa nipo, ti awọn kan n gbe lẹyin ọrọ rẹ, bẹ lawọn miiran n sọ pe Iru iwa bẹ ta abuku si i gẹgẹ bi aṣofin agba Naijiria.
Àwọn ọ̀gágun ajagun fẹ̀yìntì orílẹ̀-èdè Nàìjíríà wọ̀yáàjà láti nípa lórí ètò ìdìbò ọdún-un 2019
"Pasitọ to wa lara awọn eeyan to n ṣanwo waasi mi yii nifẹ awọn ọrọ ti mo maa n sọ eyi ti ko da lori ẹṣin.
John's Anglican nilu Agodo iyẹn ni ijọba ibilẹ Ogun waterside pẹlu ada lasiko isere wọn, to si ṣa awọn ọmọ meji, Mubarak Kalesowo pẹlu Sunday Obituyi pa.
Oríṣun àwòrán, @BBNaija Àkọlé àwòrán, Awon omo inu ile ni season 5 n gbaradi Agbofinro to dantọ ni Ebuka jẹ.
Àwọn ẹlòmíràn ń dẹ ẹ́, wọ́n ń bèèrè àmì ọ̀run láti ọ̀dọ̀ rẹ̀.
Koda o ṣiṣẹ agbofinro de bi oye Attorney niSan Francisco ati Attorney general ni California.
6bn padà Sìgá mímu ń di èèwọ̀ oògùn ìlera pípé lagbaye Amọṣa ni ọjọ Aje ni ileeṣẹ ọlọpaa nipinlẹ Ọyọ fi oju awọn ọmọ ẹgbẹ awakọ ero ipinlẹ Ọyọ mọkandinlọgbọn han fawọn oniroyin lẹyin ti wọn ni ọwọ tẹ wọn ni ibi ti wọn ti n gbero ati da wahala silẹ lawọn ibudokọ kan nipinlẹ naa.
Igba akọkọ kọ niyi ti iru iṣẹlẹ bẹẹ yoo waye ni South Africa.
Dìde, OLUWA; Ọlọrun, wá nǹkankan ṣe sí i;má sì gbàgbé àwọn tí a nilára.
Aare Buhari tun fi edun okan re han si ijoba ati awon eniyan ipinle Edo , pelu omo egbe oselu Peoples Democratic Party (PDP) lori iku oloogbe naa, ti o tun je okan lara igbimo alase fun egbe oselu PDP.
ṣugbọn tiyín kò gbọdọ̀ rí bẹ́ẹ̀.
Irọ funfun báláwú ni, Boko Haram kò dawa lọnà rárá -Ọmọ ogun Naijiria Ìdúnàdúrà ṣì n lọ láti dóòlà ọmọ Ọffa mẹ́fà lọ́wọ́ ajínigbé- ODU Ọlọ́pàá Nàìjíríà àti Ẹgbẹ́ IMN n ṣé fakinfa lórí ikú àwọn olùwọ́de ìdárò Ashura Agbejọ́rò Dakolo:Mílíọ́nù mẹ́wàá náírà tí a béèrè kì í ṣe owó gbà má-bínú Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Awon kan ni o se e
Jese bí ọmọ meje; orúkọ wọn nìyí bí wọ́n ṣe tẹ̀lé ara wọn: Eliabu ni àkọ́bí, lẹ́yìn náà Abinadabu ati Ṣimea; 
Àwọn ọmọ Israẹli gbéra láti òkè Hori, wọ́n gba ọ̀nà Òkun Pupa, láti yípo lọ lẹ́yìn ilẹ̀ Edomu.
Amọṣa, oludari ipolongo ati idanilẹkọ lajọ INEC, Oluwọle Osaze-Uzzi ṣalaye fun BBC News Yoruba pe ko si nnkan ti o kan Hajia Zakari pẹlu ibo kika ni ipo tuntun ti wọn ṣẹṣẹ yan an si naa.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ẹ wo ọpọ eré ìdárayá nílẹ̀ Yorùbá tó ti ń di ohun ìgbàgbé A n ṣé àyẹwò ẹni tá fúnra sí pé o ní Coronavirus l'Eko-Kọmísánà ìlera Wakati kan ni ijọba fún wa lati kúro ni ibi ti a ngbé Ìdá 90% nínú àwọn olówó Naijiria lo n lọ ilé babaláwo- Mr Latin Ọbasanjọ ni ọmọ òrùkàn tó di olóri orílẹ̀èdè lẹ́ẹ̀mẹ́ta ọ̀tọ̀ọ̀tọ̀ Minisita naa fikun pe, awọn oṣiṣẹ ile iṣẹ to n ṣe eto oju ọna irin, CCECC ko i tii pada wa si Naijiria, nitori ati koju arun coronavirus nilẹ wọn ati itankalẹ rẹ.
 Bakan naa, eyi ti a tun gbodo mu enu ba ni, balogun iko yii, Mikel ti oun fe omo ile Russia.
Coronavirus in Nigeria: Ẹ wo àǹfààní tó wà nínú àrùn Coronavirus
Ọdún mẹ́ta lẹ́yìn Adebayo Faleti, ìran Yorùbá ń ṣe ilédè rẹ!
Ìgbín, iṣu, epo, àádùn, obì, iyọ àti oyin wa lára ohun ti a fi sọ ọmọ tuntun Ọọni Ifẹ lórúkọ!
Awọn kan n sọ wipe awọn akẹkọbirin naa to adọta nigba ti awọn kan si wipe awọn ọmọ ile iwe naa to ọgorun.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ayinla Ọmọwura kò kàwé, àmọ́ ó kópa sí àgbéga orin àti èdè Yorùbá 19 Òkùdu 2019 Oríṣun àwòrán, Ayinla Omowura Ni ilẹ Yoruba, awọn ẹja nla ti lọ lomi, awọn ajanaku ti sun bi oke, awọn erin ti wo niju, ti wọn ko si lee dide.
Èmi ó fi orin yin orúkọ Ọlọrun;n óo fi ọpẹ́ gbé e ga.
À ń ru ikú Jesu káàkiri lára wa nígbà gbogbo, kí ìyè Jesu lè hàn lára wa.
A le pa òwe gẹ́gẹ́ bí àwọn elédè ti ń pa á tàbí bí gbogbo ènìyàn ti ń pá gan-an.
Lẹ́yìn náà, ó lọ sí ilé OLUWA, ó tẹ́ ìwé náà sílẹ̀ níwájú OLUWA.
Ni ipari, o gba won nimoran lati maa lo sile iwosan oju fun itoju lasiko nitori opolopo akosemose ni Eledaa fi bukun Naijiria.
23 Èbibi 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 7 Èbibi 2020 Ara mi rọ̀, kò si bí mi ò ṣe lè ká ẹsẹ̀ mi- Oyindamola.
Ojoojumọ, ọsọọsẹ koda, oṣooṣu lawọn ẹlẹwọn ni El Helicoide ma n foju ba ile ẹjọ.
Gbogbo ìwà ati ìṣe yín níláti jẹ́ èyí tí ó tọ́ níwájú OLUWA Ọlọrun yín.
kí ìtọrẹ àánú rẹ jẹ́ ohun ìkọ̀kọ̀.
Okunrin kan ni wọn ni o n wa mọto rẹ lọ lati agbegbe Midland si Odessa ni ipinlẹ Texas ni orilẹ-ede Amerika.
ó ní, “Amin, kí OLUWA ṣe bẹ́ẹ̀.
Wọn á máa wí pé, “Ní Jerusalẹmu ni wọ́n ti bí eléyìí.
Ni ọjọ kan, Aole ke si Afonja, tii ṣe Aarẹ Ọna Kakanfo rẹ pe ko gbe ogun lọ si awọn ilu kan, ninu eyi ti ilu Iwere ile wa, ti Afonja si yari pe ko ni ṣeeṣe nitori egun ti Alaafin Ajagbo ti fi lelẹ saaju.
Ìgbà tí a dé ọ̀hún, o mú wa tọ ìyá rẹ̀ lọ, o fi wa hàn án, ìyá rẹ̀ náà sì kí wa dáadáa, ìyá rẹ̀ náà sanra díẹ̀ gbogbo ara rẹ̀ si ń dán, ó mọ́ tónítóní ṣùgbọ́n ojú rẹ̀ kò dàbí ojú ènìyàn nítorí ṣe lo ri rubutu b’’i ojú igbá tàbí ojú ife ẹmu, ojú méjì ni ṣe ni àwọn ojú méjì náà sì ń yí sókè sódò lẹ́ẹ̀kọ̀ọ́kan, ó ba ni lẹ́rùn gidigidi.
ogbeni  Akeredolu gege bi alaga ti yoo
But Covington's fortunes changed when Usman broke his jaw at the end of the third round with a hard right.
O ti di eyi ti awọn olori orilẹ-edefi n ṣaisun lelori.
Mo kó òjíá ati àwọn turari olóòórùn dídùn mi jọ,mo jẹ afárá oyin mi, pẹlu oyin inú rẹ̀,mo mu waini mi ati wàrà mi.
Oyindamọla Kọlawọle Emmanuel ti o n lọ́ ẹran ara rẹ ati egungun rẹ fi da àrà to wù ú, eyi ti awọn oloyinbo n pe ni 'Contortionist' ṣalaye ohun to ṣokunfa eyi fun BBC Yorùbá.
Ṣaaju ni iru iṣẹlẹ yii waye ni ọjọ keji oṣu kinni ọdun 2018 nibi ti awọn ajinigbe ti ji awọn oṣiṣẹ ijọba ibilẹ Emure to wa nipinlẹ Ekiti gbe.
Ẹ má ṣe ohunkohun pẹlu ẹ̀mí àṣehàn tabi láti gba ìyìn eniyan, ṣugbọn pẹlu ọkàn ìrẹ̀lẹ̀, ẹ máa fi ẹnìkejì yín ṣiwaju ara yín.
O ṣalaye pe lootọ ko dẹrun lati rin irin ajo bẹẹ gẹgẹ bi obinrin alawọ dudu, ti o tun gẹrun ori rẹ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Èèyàn kan kú, ẹni mẹ́ta farapa nínú àkàsọ̀ ìgbàlódé(lift) tó já ní Cocoa House n'Ibadan 6 Sẹ́rẹ́ 2021 Oríṣun àwòrán, Facebook Ile isẹ Odu'a Investment Company Limited ni nkan bi aago mọkanla owurọ oni ni awọn osisẹ to n mojuto atunse akasọ igbalode fun igbokegbodo to yanranti lenu iṣẹ ni wahala dede ṣẹyọ ti akasọ naa si ja lọlẹ.
' Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Kaduna ni àjọ NYSC pín mi sí sùgbọ́n.
tí yóo ṣàánú rẹ̀, tí yóo sì wí pé,‘Ẹ gbà á sílẹ̀, ẹ má jẹ́ kí ó lọ sinu ibojì,mo ti rí ìràpadà kan dípò rẹ̀.
Àwọn ọkọ̀ àti kẹ̀kẹ́ akérò ní Ìlú Èkó
Ọjọ kẹta, oṣu kejila, ọdun 2003 ni wọn ṣe igbeyawo wọn, lẹnu iṣẹ tiata ni a gbọ pe awọn mejeeji ti pade o.
A bere re ni nkan bii odun mewaa seyin nipa sise atileyin to ye fun aseyori awon ayeye odun ibile wonyii fun isokan ati idagbasoke agbegeb kookan to n se won.
Willian ni agbabọọlu Chelsea to jẹ goolu mejeeji fun Chelsea ni abala kini ifẹsẹwọnsẹ naa.
 fúndìi èyí , ó jáwé olúborí nínú àwọn ìdíje ọlọ ́ kan ò jọ ̀ kan abẹle .
Papa isere ilu Wroclaw ni Naijiria ati Poland yoo ti maa waa ko gẹgẹbii ara igbaradi awọn ikọ agbabọọlu mejeeji fun idije ife ẹyẹ agbaye ti yoo waye ni osu kẹfa ọdun yii.
Amọ Ọba Oke ko ọkan lara wọn yọ nigba ti awọn ọmọ ikọ Amotekun tete gba ọkan silẹ ninu wọn amọ ti awọn ajinigbe naa wọ ekeji wọ inu igbo ni tipatipa.
Nítorí ìkọlù àjòjì ní South Africa, èèyàn 5000 ló padánù iṣẹ́ wọn ní Nàìjíríà Iye epo rọ̀bì tí wọ́n ń kó níbùdó ìpọnpo ti dínkù, ṣé ẹ fẹ́ mọ ìdí i rẹ̀?
Ipade ohun yoo waye bere lati ojo AIku(Sunday) si ojo Isegun(Tuesday).
OLUWA Ọlọrun yín wà lọ́dọ̀ yín,akọni tí ń fúnni ní ìṣẹ́gun ni;yóo láyọ̀ nítorí yín,yóo tún yín ṣe nítorí ìfẹ́ rẹ̀ si yín,yóo yọ̀, yóo sì kọrin ayọ̀ sókè
OLUWA ní, “Ṣé bí ọkọ bá kọ iyawo rẹ̀ sílẹ̀,tí iyawo náà sì kó jáde nílé ọkọ,tí ó lọ fẹ́ ẹlòmíràn,ṣé ọkọ rẹ̀ àkọ́kọ́ lè tún lọ gbà á pada?
 a bí barack obama ní ọjó ìkérin , oṣù èkéjọ , odún 1961 .
 ní 1915 , oluwosàn rodolfo robles ni ó kọ ́ kọ ́ so arùn ojú mọ ́ aràn .
Ni Paulu bá dìde, ó gbé ọwọ́ sókè, ó ní:“Ẹ̀yin ọmọ Israẹli ati ẹ̀yin tí ẹ̀ ń sin Ọlọrun wa, ẹ fetí sílẹ̀.
Oríṣun àwòrán, Hujjaj in Masjid al Namirah, Arafat BBC ṣe ifọrọwerọ pẹlú agba Alfa ẹsìn Islam kan ní Nàìjíríà, Ọmọwe Ibrahim Disina, lóríi àwọn nǹkan tó se pataki to yẹ kí àwọn èèyàn ṣe ni ọjọ Arafa.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Mother Language Day: Bàbá míì ní àìkọ́ ọmọ òun ní Yorùbá ló mú kò pàdánù iṣẹ́ olówó ńlá Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Awọn minisita naa ree pẹlu orukọ ileeṣẹ ti wọn yoo dimu: Ọmọwe Okechukwu Ogar- Minisita abẹle fun idagbasoke Irin tutu ati iwakusa Muhammadu Bello-Minisita fun Olu ilu Ilẹẹwa, FCT Sẹnetọ Godswill Akpabio- Minisita fun agbegbe Niger Delta Dokita Chris Ngige-Minisita fun ọrọ oṣiṣẹ ati igbanisiṣẹ Sharon Ikeazor- Minisita abẹle fun ọrọ ayika Mallam Adamu Adamu- Minisita fun eto ẹkọ Mariam Katagum- Minisita Abẹle fun ọrọ ileeṣẹ, idokoowo, ati karakata Timiprey Silva- Minisita kekere fun epo rọbi Sẹnetọ George Akume- Minisita fun akanṣe iṣẹ ati ọrọ ilẹ okeere Mustapha Baba Shehuri - Minisita kekere fun eto ọgbin ati idagbasoke igberiko Goddy Jedi Agba (Cross River)- Minisita kekere fun ipese ina manamana Festus Keyamo (Delta)- Minisita kekere fun ẹkun Niger Delta Ogbonaya Onu (Ebonyi)- Minisita fun imọ Sayẹnsi ati imọ ẹrọ Osagie Ehanire (Edo)- Minisita fun eto ilera.
Ninu awọn akẹkọọ 1,549,740 to ṣe idanwo naa, awọn 1,338, 348 lo pegede ninu iṣẹ marun un ninu mẹsan an ti wọn ṣe eyi to jẹ ida mẹrindinlaadọrun un ninu ida ọgọrun un to ṣe idanwo naa.
Láì wípé ọ̀kan ju ọ̀kan lọ, àwọn wọ̀nyí ni orin tí a rò wípé yóò figagbága nínú Ijó ìta-gbangba Ìwọ́de Ojúnà Trinidad àti Tobago ọdún-un 2019…
Oluwo bu èpè lu àwọn tó dá a lẹ̀bi pé ìgbéyàwó rẹ̀ túká Oral Sex: Bóo bá ń gba ẹnu ní ìbálòpọ̀, wo àìsàn tóo lè kó lójú ara rẹ Oríṣun àwòrán, @oluwo Oluwo ṣalaye idi to fi gbadura iru iyawo bi Chanel Chin fawọn to n bu ẹnu ẹtẹ lu lori ọrọ naa.
Bakan naa ni won ta dollars kan ni odunrun-o-le marun-un at N305.
Awọn ọlọpaa yoo pada ranṣẹ pe e ti o ba jẹ dandan.
Mose sì kà wọ́n gẹ́gẹ́ bí OLUWA ti pàṣẹ fún un.
Síńimá kòṣewòtán, Pásítọ̀ fo fẹ́ǹsì láti sá mọ́ agbófinró lọ́wọ́ ní Àkúrẹ́ Inú ìbèrù bojo ni àn gbé báyìí- Awọn ènìyàn àdúgbo, Ogba, Agbado Ijaye àti Agege Ìrìnàjò Toyin Abraham, láti orí gbèsè jíjẹ, ó di onílé, onimọto àti aya lọ́ọ̀dẹ̀ ọkọ 82% ọkùnrin ní kó mọ̀ pé òun ní àìsàn jẹjẹrẹ asẹtọ ní Naijiria Auxiliary ni ọkùnrin kan tí wọn ń pè ní Remi Soka lo kọlu àwọn ọmọlẹ́yìn òun ti ìjọba yàn láti máa gba owó lọwọ àwọn ọlọkada ni adugbo Soka, tó na wọn pé àdúgbò òun ni ibẹ, wọn kò sì ní ẹtọ láti máa gba owó.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Lagos Impeachment: Tinubu parí aáws Ambode àtàwọn aṣòfin ìpínlẹ̀ Eko 3 Èrèlè 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 4 Èrèlè 2019 Àkọlé àwòrán, Ó ti tó bí ọ̀sẹ̀ díẹ̀ báyìí tí awuyewuye láàárín gómìnà Ambọde àtàwọn aṣòfin ìpínlẹ̀ Eko ti ń jà rànyìnrànyìn ní ìgboro O ṣeeṣe ki gbun-gbun-gbun to wa laaarin gomina ipinlẹ Eko, Akinwunmi Ambọde atawọn aṣofin ipinlẹ Eko, eleyi to ti n mu ariwo iyọnipo gomina naa kari aye o pari bayii lẹyin ti aṣiwaju ẹgbẹ oṣelu APC lorilẹede Naijiria, Bọla Tinubu da sii.
Ṣugbọn àwọn tí kò gbàgbọ́ wà ninu yín.
Bi awọn miran ṣe n gboriyin fun ọrọ ti Kanu Nnamdi sọ yii, ni awọn miran n bu ẹnu ẹ̀tẹ́ lu ọrọ to fi lede lasiko to n ba awọn ọmọ ilẹ Biafra sọrọ lati ilu London, ni Ile Gẹẹsi.
Awọn ede ti Gal Pissetzky gbọ Hebrew Polish Spanish Awọn ibi ti Gal Pissetzky ti ṣiṣẹ ri Pissetzky & Berliner, LLC (2006 si asiko yii) Meczyk & Associates (2002 - 2006) Cook County State's Attorney's Office (2000 - 2002) Awọn ileewe ti Gal Pissetzky lọ J.
Oríṣun àwòrán, Tope Alabi Nigba to n sọrọ lori awọn ipenija to n koju rẹ, Tọpẹ Alabi ni ọrọ alufansa ti awọn eeyan kan maa n sọ nipa awọn olorin ni kii fun awọn ni iwuri, to si laa pe, oun si n kọ orin nipa ijọba ọrun, tori ko si ohunkohun to lee gba orin ijọba ọrun ni ọwọ oun.
’ Ẹ ti tàbùkù pẹpẹ mi, nípa rírò pé ẹ lè tàbùkù rẹ̀.
Ẹ̀rọ ayàwòrán ara ọlọ́pàá fihàn pé ìgbà ogún ni George Floyd pariwo, kó tó kú Iléesẹ́ rẹ́kọ́ọ̀dù tí mo ti bẹ̀bẹ̀ láti kọrin, padà di tèmi lónìí - Ebenezer Obey Ọ̀pá epo NNPC bú gbàmú ní Benin, òṣìṣẹ́ méje kàgbákò ikú òjijì Ọ̀fọ̀ ńlá ṣẹ̀ ní Ivory Coast, Olóòtú ìjọba, Amadou Gon Coulibaly jáde láye Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 3 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 5 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Ẹ jọ̀wọ́, ẹ gbà mí láyè kí n sọ̀rọ̀ díẹ̀ bí aṣiwèrè.
Kamilu, ẹni tó sàlàyé bo se de ìdí ere tíátà, sísọ lójú rẹ pé, ile ẹ̀kọ́ alakọbẹrẹ ni òun ti bẹ̀rẹ̀ si ní ìfẹ́ si eré tíátà, tí òun sì darapọ mọ ẹgbẹ́ osere Seyi Adeoye.
Oun pẹlu si ti dide lati gbeja ara rẹ pe, o ni idi ti ọrọ fi ri bẹẹ fun oun lẹyin oṣu mẹsan ti oun gun ori aleefa.
Gẹgẹ bi ohun ti a gbọ lati ẹnu alukoro ọlọpaa ni ipinlẹ Kogi, ikọ awọn oṣiṣẹ ọgba ẹwọn naa ati awọn ajọ ori lalakanfinsọri lo dijọ n wa awọn ẹlẹwọn to na papa bora yii.
Nigba naa ni Joshua padanu bẹniti rẹ mẹtẹẹta to ko kalẹ nibi ija naa.
Awọn dokita ni ẹsẹ naa ti bajẹ kọja ala, iṣẹ abẹ si lo gbudọ ṣe ṣugbọn oyun to wa ninu ko lee jẹ́ afi ko gbe oyun naa titi di oṣu mẹsan ninu irora ati titi di oṣu mẹfa akọkọ ọmọ naa.
Awọn agbofinro, awọn omuwẹ ṣi n gbiyanju lati wa Apidan naa pẹlu awọn onworan to rii nigba to bẹ sodo.
 Ise akanse keji ni titun onaBill Clinton Drive se lati iyana afara tuntun ti won sese ko soju ona papako ofurufu.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, AFCON 2019: Inú mi dùn pé mo jẹ́ ẹni àkọ́kọ́ tó ṣojú Nàíjíríà fún ìgbà 100 Awọn agbabọọlu Zimbabwe bii Ovidy Karuru naa gbiyanju ṣugbọn ẹ̀pa ko boro titi idije naa fi pari.
Oríṣun àwòrán, @CSS Iyawo re wa ninu oyun nigba to sere eegun lọ to si fa a le Dasofunjo ọrẹ rẹ ti wọn jọ jẹ Ojẹ eegun lọwọ nigba to n lọ.
Níbẹ̀ ni kí ẹ sin mí sí.
*Ọdún 2014: Minisita feto isunna, Ngozi Okonjo-Iweala tún padà kéde pé mílíọ̀nù lọ́nà ẹẹdẹgbẹta dọla ($500m), tí ìjọba Olusegun Obasanjo tún rí gbà lára owó tí Sani Abacha kò lọ sókè òkun, táwọn sì ti lo owó náà fún isẹ ìdàgbàsókè agbègbè.
epo robi lorile ede Naijria iyen NNPC nikan lo n gbe epo robi lati oke okun wa
Ọlọpaa ti wọn pin si agọ wọn to wa ni agbegbe Trade Fair l'Eko ri ọpa aṣẹ naa gba ni nkan bii ago mẹjọ abọ owurọ ọjọ Ẹti, ọjọ kọkanla, oṣu Kejila ọdun 2020, ni agbegbe Abule Ado""."
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Èyí ni bí àwọn agbébọn ṣe gbé òṣìṣẹ́ Shell méjì, wọ́n tún pa àwọ̀n aláàbò wọ̀n ní Rivers 27 Ìgbé 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ileeṣẹ elepo Shell jẹ ọ̀kan pataki lara awọn ileeṣẹ to n pese epo bẹtiro ni Naijiria Ọga gba meji nileeṣẹ elepo rọbi Shell ko ti i di riri lẹyin ti awọn ajinigbe gbe wọn, ti wọn si tun pa awọn ọlọpaa to n daabo bo wọn.
Ṣùgbọ́n nígbà tí ó ṣe ó bọ́ sí àtẹ̀gùn tí ó tẹ̀lé èyínì, nígbà tí ó tún ṣe ó tún bbọ́ sí ìsàlẹ̀ eléyìíni pẹ̀lú, nígbà ‘t ió tún ṣe ó tún bọ́ sí ìsàlẹ̀, bẹ́ẹ̀ bẹ́ẹ̀ kí á tóó kúrò nínú ilé náà orí ilẹ̀ ló jókòó lé.
Ẹgbẹ ikùn ni a gbọ pè ibọn ti ba Linda, ti wọn si gbe e digbadigba lọ ile iwosan.
Pàápàá jùlọ, àsìkò tí a ti súnmọ́ àjọ̀dún kérésìmesì gbọ̀ngbọ̀n, oríṣìíríṣìí iná aláràbarà ni àwọn ará ilẹ̀ yìí fi ń ṣe ìgboro wọn lọ́ṣọ̀ọ́.
 Ìgbéyàwó ẹ ̀ àkọ ́ kọ ́ pàrí pẹ ̀ lú ikú ìyàwó rẹ ̀ tí kò bímọ mary farley ní ọdún 1799 ; ó fẹ ́ ìyàwó míràn , ó bí ọmọ mẹ ́ fa pẹ ̀ lú ìyàwó rẹ ̀ maria carter , tí ó kú nígbà tí ó pé ọdún méjìdínlógójì ní ọdún 1823 .
Ẹnu yà wọ́n nítorí ẹnìkọ̀ọ̀kan wọn gbọ́ tí wọn ń sọ èdè tirẹ̀.
Atiku Abubakar to du ipo aarẹ ninu idibo aarẹ Naijiria lọdun 2019 naa tẹlẹ ti agbabọọlu nii Neymar ati alaga awọn awakọ ipinlẹ Eko, MC Oluomo naa ko gbẹyin.
Àbàwọ́n funfun ló sún Temilola di arìnrìnoge Vitiligo Leprosy Day: 'Kọ̀ńgílá ni mí kí ń tó di adẹ́tẹ̀ ni 1996' Ojú mi gún régé àmọ́ wọ́n ń sá fún mi - Arẹwà Àkàndá ‘Mo ké bòòsí tòò bí mo ṣe bí ìbejì, ti ọ̀kan jẹ́ àfín, ìkejì jẹ́ dúdú’ 'Mo lè fi ẹsẹ̀ mi jẹun, fọṣọ, mó tún lè fi gbá ẹni tó bá ṣẹ̀ mí létí' Dókítà tó ń ṣàbójútó àwọ̀ ara ní irú àisàn yìí kò wọ́pọ̀ kò sì gbóògùn.
Somorin fi kun pe ijọba ti ṣetan lati ṣi awọn ile iwe naa ni ibamu pẹlu ilana to rọmọ Covid-19.
Ẹ̀yin aya, ẹ máa bọ̀wọ̀ fún àwọn ọkọ yín, gẹ́gẹ́ bí ó ti yẹ kí onigbagbọ máa ṣe.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ọmọ Nàíjíríà: Ó yẹ kíjọba gbé ìgbẹ́sẹ̀ akin lásti dẹ́kun ìpànìyàn 29 Agẹmo 2018 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ọ̀pọ̀lọpọ̀ ènìyàn ló ti pàdánù ẹ̀mí wọn ní Zamfara l'ọ́dún 2018.
" Ẹsun naa ko ti i pari o.
Wabba,wa ni o ye ki atunse maa
Ọ̀nà ọ̀run àpáàdì gbòòrò, ẹnu ọ̀nà rẹ̀ sì fẹ̀.
Awọn olorin bii Bola Arẹ, King Sunny Ade, Obey Commander, Oloogbe Wasiu Ayinde, Baba lẹgba atawọn miran lo maa n mu inu awọn eeyan dun ti onikaluku a si fijo rasẹ paapaa nibi inawo Àkọlé àwòrán, Oriṣiriṣi owe, aṣamọ, akanlo ede ati akoonu to kun fun ero ọgbọn ati girama to pe ni Yoruba fi maa n ba ara wọn sọrọ.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Njẹ́ o mọ̀ pé bíi ọdún 700 sẹ́yìn ni wọ́n ti ń bọ Osun-Osogbo?
Àkọlé àwòrán, Ileeṣẹ BBC gba'lejo ife agbaye FIFA nipinlẹ Eko Gbajugbaja agbabọọlu orilẹede France ni, Chritian Karembeu pẹlu Ọgbẹni Peter Njonjo to jẹ aarẹ ileeṣẹ Coca cola lẹkun iwọ oorun ilẹ Afirika lo ṣi aṣọ loju eegun ife ẹyẹ yii lọwọ lorukọ ajọ to n ṣe amojuto ere bọọlu afẹsẹgba lagbaye, FIFA.
Nígbà náà ni OLUWA dá Jobu lóhùn láti inú ìjì líle.
wọ́n ń dínà ìdájọ́ òdodo fún àwọn aláìní,wọn kò sì jẹ́ kí àwọn talaka ààrin àwọn eniyan mi rí ẹ̀tọ́ wọn gbà,kí wọ́n lè sọ àwọn opó di ìkógun.
olubori ninu eto idibo aarẹ pe oun ni ibo milionu kan
Ọdún 1988 ni Samuel Okwaraji darapọ̀ mọ́ Green Eagles èyí to di Super Eagles lónìí, lásìkò African Nations Cup, o gbá bọ́ọ̀lù lásìkò yìí náà ní Morocco ti o sì gbá bọ́ọ̀lù sáwọ̀n láàrin isẹjú kan níbi ifsẹwọnsẹ pẹ̀lú Indomitable Lions ti Cameroon.
Ọjọbọ kẹrin ninu oṣu Kọkanla lọdọọdun ni wọn maa n ṣe e.
A ko si ni ṣe idiwọ fun ijiya to ba tọ si ẹnikẹni to ba hu iwqa ti ko tọ ọ.
Títàn káàkiri ìròyìn òfégè máá ń t'àbùkù bá ojúlówó ìròyìn.
abajade ipade apero yii , ni a o fi ranse si aare Muhammadu Buhari ,awon ipinle
Aṣiwaju yii ni yóò rọ́pò Abraham Adesanya tó ti n dari Yoruba to kú nínú oṣù kẹ́rin, ọdún 2008.
 Awọn osisẹ alaanu yii lo gbogbo oru lati gbe awọn eeyan sọkalẹ lati ori igi."
Bakan naa, wọn tun se ọrẹ debi pe ọdun 2018 ni Badirat ati Memunat dijọ bi ibeji, tawọn ibeji Memunat si jẹ obinrin, ti oun naa ti bi ọkunrin fun Alaafin saaju awọn ibeji.
Kí ó mú àwo turari àwọn ọkunrin tí wọ́n kú nítorí ẹ̀ṣẹ̀ wọn, kí ó fi wọ́n rọ àwo fẹ́lẹ́fẹ́lẹ́ fún ìbòrí pẹpẹ, nítorí níwọ̀n ìgbà tí wọ́n ti mú wọn wá siwaju OLUWA, wọ́n ti di mímọ́.
Joṣua bá sọ fún àwọn alufaa pé, “Ẹ gbé Àpótí Majẹmu náà kí ẹ sì máa lọ níwájú àwọn eniyan yìí.
Loni ọjọ kejila, oṣu karun un ni idije Premier League yoo wa s'ipari ti a o si mọ ikọ agbabọọlu ti yoo gba ife ẹyẹ naa laarin Manchester City ati Liverpool.
Oríṣun àwòrán, @Dorathy Àkọlé àwòrán, Ta ni Dorathy Bachor?
Bakan naa ni Ọga ọlọpaa, Mohammed Adamu naa sọ fun wọn wi pe bi awọn eniyan tilẹ bu wọn tabi sọrọ kubakugbe si wọn, iyẹn ko to lati jẹ ki awọn ọlọpaa ma ṣiṣẹ wọn bii iṣẹ lorilẹede Naijiria.
Ìjàmbá ọkọ̀ ojú'rin tó ṣubú wáyé ní Agége l'Eko
Coronavirus: Èyí ni àwọn irọ́ bàǹtà-banta tí a ń pa fún ara wa nítorí Coronavirus
Èmi ò mọn kíni fáàrí tí ń lọ lóde.
O ni Owa ti ilu Idanre joko sori itẹ rẹ to si n wo bi awọn janduku naa ṣe n na oun ni ilu bara.
Alufaa yóo ti ìka bọ inú ẹ̀jẹ̀ ẹran tí wọ́n fi rú ẹbọ ẹ̀ṣẹ̀ yìí yóo fi sí ara àwọn ìwo pẹpẹ ẹbọ sísun; yóo sì da ẹ̀jẹ̀ yòókù sílẹ̀ nídìí pẹpẹ.
Tọkàntọkàn ni mò ń wá ojurere rẹ,ṣe mí lóore gẹ́gẹ́ bí ìlérí rẹ.
N kò sì ní bá wọn lọ́wọ́ sí nǹkankan.
Amọ, awọn ẹgbẹ ọmọ Yoruba ati ẹgbẹ miran lapapọ ti n fesi si ọrọ gbọn mi si omi o to to n waye laarin awọn mejeeji.
Ní ìgbẹ̀yìn àwọn meji kan wá.
Technovation 2018: Àwọn akẹ́kọ̀ọ́-binrin Naijiria gba ipò kínní
Ó mọ mi denudenu, to sì fẹ́ràn mi tọkàntọkàn, tí ọkàn mi bá sì rẹ̀wẹ̀sì, ìyá mi lo máa ń tú mi nínú.
  Amo ko so pato awon ijiroro ti won nilati se naa.
Kódà, kò yọ àwọn tó n kọrin sílẹ̀, nítorí pé àwọn kan lára wọn ti kọrin tó mú kó dà bí ẹni pé, wọ́n n kan sáàrá sí àwọn tó n ṣe é.
1 Ní orí yín ẹ̀yin ìránṣẹ́ ẹlẹgbẹ́ mi, ní orúkọ Mèssíà mo fi oyè àlùfáà ti Aarónì fũn yín, èyí tí ó ní kọ́kọ́rọ́ ti ìṣẹ́ ìránṣẹ́ àwọn ángẹ́lì, àti ti ìhìnrere ironúpìwàdà, àti ti ìrìbọmi nípa rírì bọmi fún ìmúkúrò àwọn ẹ̀ṣẹ̀; àti pé a kì yíò mú èyí kúrò ní ilé ayé mọ́ láí, títí tí àwọn ọmọ Léfì yíò fi rúbọ lẹ́ẹ̀kan síi ẹbọ-ọrẹ kan sí Olúwa nínú òdodo.
Sẹ́gílọlá: Arúgbó awẹ́lẹ́wà tó ń ṣiṣẹ́ omidan
O seese kẹ le dawọ ijijagbara naa duro ni ibẹrẹ pẹpẹ amọ nigba to ba ya, wahala naa yoo fẹju sii, ti ko si ni dawọ duro mọ.
Mo mu igi mo wa so pe Iku lo tọ si Tutsis!
Ó yẹ kí á mò pé nítorí ìdàgbàsókè ni ẹ̀dá fi ń gbé papọ̀.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Oyenusi ló mú mi wọ ẹgbẹ́ adigunjalè kó tó di pé mo b'Ólúwa pàdé' Awọn afurasí Babaláwo pa ìyáwó Ìmáàmù àgbà ìlú Ayere ní Kogi, Alayere dá sọ́rọ̀ Ọ̀fíìsì ni mo wà tí mo rí Hẹlikọ́ptà tó ń yí bírí bírí lójú òfurufú, àfi tí a gbọ́ gbàà!
ayelujara ni awon igberiko to wa lorile ede Naijiria.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Tanker Accident: Awakọ̀ dèrò ilé ìwòsàn lẹ́yìn tí ọkọ̀ agbépo dànù L’eko 13 Ọ̀pẹ̀̀ 2019 Oríṣun àwòrán, LASEMA Àkọlé àwòrán, Ọga agba LASEMA Olufemi Damilola, sọ fun BBC pe, ọkọ ọhun ṣubu lẹyin ti ọkan lara taya rẹ fọ lojiji lori irin Ileeṣẹ to n mojuto iṣẹlẹ pajawiri nipinlẹ Eko, LASEMA, ti fidi rẹ mulẹ pe lootọ ni ọkọ agbepo kan ṣubu lulẹ ni agbegbe Victoria Island l'Eko, ti pupọ ninu epo to gbe, si danu.
Orisirisi  ayeye bi ere idaraya,ijo ati orin kiko latodo awon omo orile-ede China ati Nigeria ni o waye ati awon olokan-o-jokan ayeye miira.
Wọ́n jí ọmọ yìí gbé láti máa fi tọrọ bárà l'Eko Kí ló ṣe ikú pa Adewura Latifat Bello lẹ́yìn ọ̀sẹ̀ méjì tí wọ́n ń wá a?
Ṣugbọn tí ọkọ rẹ̀ bá ti kú, ó bọ́ lọ́wọ́ òfin igbeyawo, kì í ṣe àgbèrè mọ́, bí ó bá lọ fẹ́ ọkọ mìíràn.
Ìdí tí ìjóba ìpínlẹ̀ Eko fí ṣí àwọn ilé ìwé kan padà Ìwọ̀ Òòrùn Afrika (Boko Haram lo ranṣẹ pe awa Islamic State): Oṣu Kẹta, ọdun 2015, ni IS kede pe oun ti da ẹka silẹ ni Ìwọ̀ Òòrùn Afrika.
Ìtìjú agbami agbaye ni eleyii lati ọwọ aarẹ ti ko mọ̀ ju ki o maa di ẹbi gbogbo ijakulẹ rẹ̀ ru ẹlomiran lọ.
Ṣugbọn nígbà tí àwọn kan ninu àwọn ará Kipru ati Kirene dé Antioku, wọ́n bá àwọn ará Giriki sọ̀rọ̀, wọ́n ń waasu Oluwa Jesu fún wọn.
Talaka tí ń rìn pẹlu òtítọ́ inú,ó sàn ju òmùgọ̀ eniyan, tí ó ń sọ̀rọ̀ ẹ̀tàn lọ.
Ẹ wo tọkọtaya yii, Malaam Sulaiman Abdulquadri ati aya rẹ, Mujidat ni wọn ni ipenija oju, amọ ti wsn pinnu lati fẹ ara wọn.
Kódà wọn a tún máa ṣè’kan pẹlẹbẹ láti igbá-àyà adìẹ, wọ́n á tẹ́ ẹ pẹrẹsẹ sí ààrin búrẹ́dì pẹ̀lú ẹ̀fọ́ díẹ̀ àti àwọn midinmíìdìn ní ọlọ́kanòjọ̀kan.
O ni Buhari ṣetan lati ṣe nnkan iwuri fun gbogbo ọmọ Naijiria nibi apero to da lorim igbasoke ilẹ Afirika ẹlẹẹkeje iru rẹ TICAD7.
A ti gbáradì fún ìdájọ́ ilé ẹjọ́ lórí èsì ìdìbò Osun - Ọlọ́pàá Àwọn ará Ijegun fara ya lórí ọ̀pá epo tó ń gbaná ní gbogbo ìgbà Ààrẹ Buhari jámi lórí ètò RUGA ná Oríṣun àwòrán, @Dino Melaye Bakanna lo fọwọ sọya pe oun yoo gba awọn eeyan Kogi kuro lọwọ ijọba amunisin eleyi to ṣe apejuwe rẹ gẹgẹ bi Farao tabi Nebukadinesari to n fi iya jẹ awọn ọmọ Isrẹli ninu Bibeli.
La liga: Barcelona lè téńté orí tábìlì pẹlú àmì ayo mọ̀kànlá
Wọn ni idi ni pe awọn ko ri oṣu Muharram, ti o n tọka pe oṣu naa ti bẹrẹ.
Iru isele yii waye lọdun 2011 ati 2014 ti ijọba lasiko naa ko se nnkankan nipa re.
2 566440 Orilẹede Turkey 15751 19.
Nígbà tí ó yá, ìyàn mú ní gbogbo ilẹ̀ Ijipti ati ní ilẹ̀ Kenaani.
 nígbà tí àwọn olófìn-íntótó dé ilé orímóògùnjẹ ́ láti bẹ ̀ rẹ ̀ ìwádìí .
Wo òfín tuntun tí INEC ṣe fún ìdìbò 2019 Wo àwọn tó dipò ìlú mú tí wọ́n jẹ́jọ́ lórí dúkìa Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Oduduwa Alphabet: òmìnira èdè ti dé fún Port Novo báyìí Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Ilé ẹjọ́ dájọ́ ẹgba mẹ́ẹ̀dóògún fún ọ̀daràn tó jí Iphone ní Kaduna Wo dókítà ọmọ Nàìjíríà tí àgbáyé ń wárí fún nítorí abẹ́rẹ́ àjẹsára COVID-19 Wo ọkùnrin ẹni ọdún 55 tí wọ́n ká agbárí èèyàn mẹ́rin, àti àwọn ẹ̀yà ara mìí mọ́ lọ́wọ́ ní Ogun Ìyàwó wọ sòkòtò fún ayẹyẹ ìgbéyéwò rẹ̀, ní wáhálà bá bẹ́ sílẹ̀ 8.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Chelsea v Arsenal, Chelsea vs Arsenal, gbẹgẹdẹ yóò gbiná ní Europa League Final!
Àlàyé rèé lóríi ìdí tí wọ́n fi ń pe aya ní ìyàwó Mọ̀ síi nípa Shina Rambo tó pàdé Jesu lọ́gbà ẹ̀wọn lẹ́yìn tó ti jalè Afọnja, ẹni tó finú wénú ní Ilọrin, àmọ́ tó jẹ iwọ Ọ̀rọ̀ǹpọ̀tọ̀niyùn, Aláàfin obìnrin àkọ́kọ́ rèé, tó ní nǹkan ọkùnrin Ẹfunsetan Aniwura, ọmọ Ẹ̀gbá tó di akíkanjú obìnrin nílẹ̀ Ibadan Ìtàn Àrọ̀gìdìgbà jẹ́ kí ń rò pé bàbá mi yan Yemọ̀ja ní àlè - Ọmọ Fagunwa Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Cancer: Àṣe ara mi ni iso ti n run gbogbo bí mo ṣe n ṣèrànwọ́ lórí jẹjẹrẹ Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Adeyeye Ile Ife: Kílódé tí Ọọni Ife, Oba Ogunwusi kò fi gbọdọ̀ rí ọmọ rẹ̀ tuntun títí di ẹ̀yìn oṣù mẹ́fà?
Gẹgẹbi ileeṣẹ eto ilera ṣe sọ, eeyan mẹtadinlọgọrin ni ayẹwo ti fihan pe o ni arun naa ti wọn ko si tii ni ẹnikẹni ti ara rẹ tii yaa ninu wọn.
Dokita naa, Harold Bornstein sọ fun ile isẹ iroyin CNN, ni Ọjọ Isẹgun wipe, Trump funra rẹ lo sọ awọn ọrọ ti awọn kọ si inu iwe ilera rẹ naa.
Òní jẹ́ ọjọ́ kejìlá, oṣù kejìlá, ọdún kejìlálélẹ́gbàá.
Ẹ̀yin eniyan mi, ẹ dẹtí sí ẹ̀kọ́ mi;ẹ tẹ́tí si ọ̀rọ̀ ẹnu mi.
O wa gbé oríyín fún àwọn ọlọ́pàá lórí isẹ takuntakun tí wọn ṣe láti ìgbà tí ìṣẹ̀lẹ̀ náà tí wáyé, ṣùgbọ́n ó ni ọrọ òun àti ti àwọn tó gbé ọmọ òun yàtọ̀ sí ti àwọn ọlọ́pàá, yóò sì dára kí àwọn èèyàn náà kan sì oun.
pe , owo naa poora nile ise naa, sugbon ti o kọ lati sọrọ nipa isele naa.
Bakan naa ni awọn imọran awọn eleto ilera to sọ pe ọpọ to ni aarun Covid-19 yoo ru u là, tabi pé fifi omi ati ọsẹ fọ ọwọ rẹ yoo mu ọ mọ tonitoni, to fi mọ fifọ aṣọ rẹ bi i ti tẹlẹ yoo mu kokoro naa kuro lara rẹ, le fi ọ lọkan balẹ.
Àwọn eniyan ibẹ̀ yóo lò wọ́n bí ẹrú, wọn óo pọ́n wọn lójú fún irinwo (400) ọdún.
Wọn gbọdọ ṣe eto ati ilana to le mu ki ẹgbẹ wọn o bori.
Sugbọn ere itage alafi orin kọ ni obinrin yii n se ni orilẹede Tunisia Oríṣun àwòrán, AFP Àkọlé àwòrán, Ero ree lode lasiko ti akọrin adulawọ kan, Aya Nakamura bọ sori itage lati kọrin lasiko ajọdun orin lorilẹede South France.
Ràn mi lọ́wọ́, jọ̀wọ́, ọmọ ènìyàn, bá mi bọ ẹ̀wù ìgbéraga.
"Baba to bi mi ṣe aṣeyọri emi naa yoo si ṣe e""."
Wíwá tí ó tún wá síhìn-ín, ó wá pẹlu àṣẹ láti ọ̀dọ̀ àwọn olórí alufaa láti de gbogbo àwọn tí ó ń pe orúkọ rẹ ni.
Gbogbo ipá kò tíì pin lórí ọmọ ọdún méjì tó kó sí àǹga
''Nini anfaani si ipele eto ẹ̀kọ́ to ga ati owo oṣu ti ko dawọ duro jẹ pataki lara awọn nkan ti yoo mu ko ṣeeṣe fun awọn ẹbí lati le ni eto ọrọ̀ aje to f'ẹsẹ mulẹ ni South Africa.
- Oluwo Ẹlẹsẹ ayo, Asisat Oshoala lo fi ọba le fun Naijiria pẹlu goolu keji fun Super Falcons.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Newcastle vs Manchester United: Newcastle da iyọ̀ sójú egbò Manchester United 6 Ọ̀wàrà 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Aṣe tẹni to de laari, ko si ẹni to mọ tẹni to n bọ.
Ninu ọrọ ọga kan lati Ajọ Aṣamojuto Aabo Awujọ ni Ipinlẹ Eko’ (Lagos State Environmental Protection Agency (LASEPA), o ni ara idi ti ijamba omiyale fi n ṣẹlẹ ni ilu Eko ni awọn koto-idaminu ti awọn idọti onike yii ti di, eleyii gan-an lo si n fa ọpọ ẹfọn ti o n ṣokunfa  arun loriṣiriṣi.
Ohun tí àwọn olùdìbò fún ìgbà àkọ́kọ́ ńbèèrè lọ́wọ́ ìjọba tó ńbọ̀ APC, PDP, CUPP kọ etí ikún sí òfin INEC Dino fẹ́ fún èèyàn mẹwa ní ₦10m tí Atiku bá wọlé kẹ̀?
Àtẹ̀jáde náà, tí wọn fi síta ní ọjọ́ kẹwàá, osú karùn-ún ọdun 2018, èyí tí Olùsọ́ àgùtàn J F Ọdẹ́sọlá fọwọ́ síí, ní Alákóso ìjọ Redeem lágbàáyé, Olùsọ́ àgùtàn Adéjàre Adébóyè ló pàsẹ pé káwọn tó ń darí ìjọ máa se àyẹ̀wò náà fáwọn àfẹ́sọ́nà tó fẹ́ di tọkọ-taya nínú ìjọ náà Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: 'Ẹ̀mí èṣù gbénú àwọn tó pààyàn ní Benue' Kíni ilé iṣẹ́ Akọ̀wé ìjọ̀ba Naijiria fẹ fí ojú òpó 64,000000 ṣé?
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ndidi kopa ninu idije mẹrinlelọgbọn ni saa Premier League to n lọ lọwọ, to si gba bọọlu sinu awọn lẹẹmeji.
" Ẹlomiran ti ọmọ rẹ tun di awati sọ pe, obinrin kan lara awọn ti wọn ji ọmọ rẹ ladugbo ọhun ti ya were nitori iṣẹlẹ naa.
Àìsọ̀rọ̀ Buhari lórí ìṣẹ̀lẹ̀ Lekki, ìkọjú ìjà sí Yoruba ni - YWC Kò sọ́rọ̀ nínú ọ̀rọ̀ Buhari, àtúntò Nàíjíríà nìkan lọ̀nà àbáyọ - Àgbà Yorùbá Amọ nibayii, awọn ojisẹ Ọlọrun kan to gbajumọ bii isana ẹlẹẹta lorilẹede Naijiria, ti fọwọ gbaya pe awọn ti sọ asọtẹlẹ nipa rogbodiyan naa saaju.
Ọkunrin náà bá fi ọ̀nà tí wọn ń gbà wọ ìlú náà hàn wọ́n, wọ́n bá fi idà pa gbogbo àwọn ará ìlú náà, ṣugbọn wọ́n jẹ́ kí ọkunrin náà ati gbogbo ìdílé rẹ̀ jáde lọ.
ati ẹyẹ àkọ̀, ati oríṣìíríṣìí ẹyẹ òòdẹ̀, ati ẹyẹ atọ́ka, ati àdán.
) Àwọn ni àwọn ọmọ Ada, aya Esau.
Mo ranti igbagbọ rẹ tí kò lẹ́tàn, tí ó kọ́kọ́ wà ninu Loisi ìyá-ìyá rẹ, ati ninu Yunisi ìyá rẹ, tí ó sì dá mi lójú pé ó wà ninu ìwọ náà.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù EFCC gbé ọmọ ilẹ̀ Britain sẹ́wọ̀n lórí ẹ̀sùn ìkówójẹ 22 Ọ̀wàrà 2019 Oríṣun àwòrán, @officialEFCC Ajọ to n ri si iwa jẹgudujẹra lawujọ lorilẹede Naijiria, EFCC ti fẹsun mẹrindinlogun kan awọn ọmọ ilẹ Britain meji kan to ni ṣe pẹlu kikowo jẹ.
Àrà ọ̀tọ̀ inú orin tó jáde lọ́dún 2018 ní Nàìjíríà A kò tíì gbọ́ nípa ikú aṣòfin Ayeọla -INEC 'Logo Benz yóò lẹ́yìn fún àwọn ọ̀dọ́ tó bá ṣògùn owó' 'Shehu Shagari dáríji Buhari kó tó kú' Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Àwọn arìnrìàjò ní pápákọ̀ òfúrufú MMA2 Wọn ti fi ọrọ yi to Minisita fun ọrọ ofurufu leti o si damiloju wi pe ko ni fẹ ki iyanṣelodi yi waye nitori pe yoo mu inira ba ara ilu Chuks ni nnkan to n ṣelẹ labẹ NCAA ku diẹ kaato ati wi pe ifẹhonu han awọn oṣiṣẹ naa ko kọja ala.
Amad Diallo: Manchester United ra Ahmad Diallo lọ́wọ́ Atalanta fun ọ̀dun mẹ̀rin abọ̀
Olùkọ́ àgbà tó fipá bá ọmọ ọdún 13 lò yóò fojú ba ilé ẹjọ́ ni Benue Ẹṣẹ wo ni Ambode ṣẹ̀ tí ilé aṣòfin Eko fẹ́ fí ọlọ́pàá mú u?
Ọmọwe Abubakar Kari to jẹ onimọ nipa ẹkọ oselu to wa ni Fasiti Abuja sọ fun BBC pe Aarẹ Buhari ko lẹnu ninu ọrọ ẹgbẹ ni ipinlẹ rẹ ka to wa sọ pe lorileede Naijiria lapapọ.
Ti ara wọn ba ti balẹ, yoo rọrun fun nnkan ọkunrin lati jade kuro loju ara obinrin to ha si ni wọọrọwọ, laisi isoro kankan.
Diezani gan an ní Hushmummy tó ń bú àwọn Yahoo boys- Àwọn Ọmọ Naijiria lórí Twitter A ti bẹ̀rẹ̀ ìwádìí lórí ibì tí owó tí àwọn adigunjalẹ̀ gbé ní banki Okeho wọ̀lẹ̀ sí- Ọlọ́pàá Awuyewuye ń wáyé lórí bí ìjọba Ìpínlẹ̀ Kaduna ṣe kó àwọn oníbárà sí àhámọ́ Ìyàwó Bukola Saraki fún tìyá-tọmọ olójú búlúù ní N250, 000!
Tukikọsi, àyànfẹ́ ati arakunrin wa, yóo fun yín ní ìròyìn nípa mi.
Ni ipinlẹ Sokoto, laaarin Aminu Tambuwal ti ẹgbẹ oṣelu PDP ati Aliyyu Sokoto ni idije naa wa.
gbogbo ohun ti o ba dawo le, o di dandan ki eyan kan tabi keji mo boya o se
Ordega to jẹ ẹni ọdun marundinlọgbọn ti gba bọọlu lorilẹede Russia, Sweden, America, Australia, Spain ati China.
Ẹni tó bá ń bínú kàn ń bínú lásán ni- Oyedepo Wo àwọn ohun tí Amotekun kò ní le è ṣe mọ́ ní ìpínlẹ̀ Oyo.
Ṣugbọn, ọrẹkunrin rẹ gan n gan ni iroyin sọ pe o ti fi silẹ bayi nitori iṣẹlẹ naa.
 Sẹnatọ Bukọla Saraki, Aarẹ ile asofin agba orilẹede Naijiria."
Wúrà ati fadaka ni àwọn orílẹ̀-èdè yòókù fi ṣe oriṣa wọn,iṣẹ́ ọwọ́ eniyan ni wọ́n.
Ijọba Musa lọ ṣua bi ẹgbẹrun meji mailli lati eti okun to fi de ibi ti orilẹede Niger wa loni.
Nǹkan burúkú tí mo tún rí láyé ni, irú àṣìṣe tí àwọn aláṣẹ pàápàá ń ṣe: 
Ibok-Ete Ibas  wa salaye fun awon
“Gbogbo yín kọ́ ni ọ̀rọ̀ mi yìí kàn.
Magu ṣalaye ọrọ yii lọjọbọ ni ẹka ile iṣẹ naa ti o wa ni ilu Eko pe, awọn iya ọmọ wọnyii n gbiyanju lati da ẹgbẹ silẹ.
Agbenuso fun ile-ise ti o n ri oro awon arinrinajo lorile-ede Mozambique, Cira Fernandes so pe, awon omo orile-ede Ethiopia naa ko niwe irina tabi awon iwe idanimo miiran.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ladoja Lakotan ọrọ rẹ, Obasanjo sọ pe oun lọ si ọdọ Adedibu to si ni lootọ lọrọ ti Alayande sọ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Akomolede ati Asa: Mọ̀ si nípa àwọn ọ̀nà tí Yorùbá ń gbà ran ara wọn lọ́wọ́ Saaju ni BBC ti beere pe: Kí làwọn kókó ohun tí Ààrẹ Buhari yóò bá ọmọ Nàìjíríà sọ̀rọ̀ l''aago méje alẹ́ òní?
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Coronavirus in Nigeria: Èèyàn méje l'Eko, mẹ́ta l'Abuja kó àrùn Coronavirus 21 Ẹrẹ̀nà 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 23 Ẹrẹ̀nà 2020 Ìròyìn tó ń tẹ̀ wa lọ́wọ́lọ́wọ́ ní wí pé Eeyan mẹwaa miran ni wọn tun ti ṣawari bayii pe wọn ni aarun Coronavirus.
Àyájọ́ òṣíṣẹ́ àti ìpèníjá ọjọ́ ọ̀lá f'óṣìṣẹ́ Nàìjíríà lẹ́yìn COVID-19 Ìpínlẹ̀ Eko ń bá àwọn iléètura sọ̀rọ̀ fún ìpèsè ibùsùn fáwọn aláàrùn Coronavirus Mo gbé òkúta léná kí àwon ọmọ mi le rò pé oúnjẹ ni mo ń sè- Obìnrin Opó Òrìṣà ni ìyá mi, kìí ṣe ènìyàn, òun sì ni alátìlẹ́yìn mi - Wòlíì Àrólé Nígbà tó ń ṣàlàyé ìdí tí ìjọba Ìpínlẹ̀ Osun fi gbé ìgbésẹ náà, gomina Adegboyega Oyetola, nínú ọ̀rọ̀ tó bá àwọn èèyàn Ìpínlẹ̀ náà sọ ṣàlàyé pé, didẹ okun lọrun àṣẹ konile ó gbélé náà yóò mú kó rọrùn fáwọn aráàlú láti máa ṣíṣẹ oojọ wọn.
Ile-ejo so pe, o ye ki ijoba ti sun eto idibo naa siwaju leemeji  ki o to di ogbon ojo osu kerin.
olu ilu ipinle Cabo Delgado ti fara gba ekun omiyale ti o to mita meji(2m)
Èyí ẹ̀kẹrin jẹ́ obìnrin, ó sùn sí orí ẹní kan ó ń yí ní ilẹ̀ kiri bí ẹni pé ó ní ìrora ńlá kan, àkísà ní aṣọ tí ó fi bora, lára àkísà náà wọ́n sì kọ ìwé yìí sí i.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Samuel Ortom, ẹgbẹ́ òṣèlú PDP tó jáwe olúbori ní Benue Bakan náà ní ìpínlẹ̀ Benue, ẹgbẹ́ òṣèlú APC nínú àtẹjade kan to fí síta ní Markudi sàlàye pé, èsì àtúndi ìbò to wáye lọ́jọ́ satide kò ṣe àfihan ìfẹ́ àti ìpinnu ará ìlú.
Alaga igbimo egbe naa ,ogbeni John Oyegun lo soro yii nigba ti o ba awon oniroyin soro leyin ipade to se pelu awon gomina egbe APC ati  awon igbimo amuseya  ni olu-ilu, ile egbe won, to wa niluu AbujaTi a o ba gbagbe pe , egbe All Progressives Congress,( APC)ti yan igbimo amusese lati foju lameeto wo ofin to ro mo igbese egbe lati fi osu mejila kun odun to ye ki awon igbimo  apapo, ipinle ati ibile egbe won yoo lo lori ipo.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, N100,000 Nairà mà ni Dino gbé dání lójú agbo, kò náwó yàlà-yòlò - Ayefele Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Nípasẹ̀ẹ ìtàn, ìlú yóò wá ọ̀nà ìgbàmọ́ra àti/tàbí ìkọjú-ìjà sí ìyípadà tí ó ń ṣẹlẹ̀ ní odò Mekong.
Osere tiata ni ọkọ Madam sajẹ, wọn si jọ n sere tiata naa ni.
Gbogbo àwọn tí wọn ń dẹ́ṣẹ̀ láàrin àwọn eniyan mi ni ogun yóo pa, gbogbo àwọn tí wọ́n ń sọ pé, ‘Ibi kankan kò ní bá wa!
Àwọn tí wọ́n wà lábẹ́ àjàgà ẹrú níláti rí i pé wọ́n ń bu ọlá fún àwọn ọ̀gá wọn ní ọ̀nà gbogbo, kí àwọn eniyan má baà sọ̀rọ̀ ìṣáátá sí orúkọ Ọlọrun ati ẹ̀kọ́ onigbagbọ.
Awọn ọlọja naa ni awọn ko le e gbagbe iyalọja naa titi ayeraye, nitori o duro ti wọn nigba to le ati igba to dara.
N óo mú kí wọn máa pa ọmọ wọn ọkunrin ati obinrin jẹ.
Minisita feto iroyin ati asa naa wa rọ iyawo Nnamdi Kanu lati kede ibi ti ọkọ re wa sita, nitor iwipe iyawo rẹ nikan lo mọ ibi to wa.
Onímọ ìṣègùn tó ni ìmọ jù lọ ni ilẹ̀ gẹ̀ẹ́sì ní ọdun to koja ti kìlọ pé ọ̀pọ̀ awọn eniyan ni wọ́n ti tan jẹ pẹlú irọ lóri abẹ́rẹ́ ajẹsára pàpá jùlọ lori ẹ̀rọ ayhelujara, ti olùwádìí ọmọ ilẹ̀ Amrika kan naa si ti ri ìdí ọ̀rọ̀ pé àwọn Russia ni wọ́n n lò láti iròyìn náà ka fún araye.
”Gege bi Berhalter,“Iyansipo tuntun yii buyi fun mi lopolopo, mo mo ohun ti o je lati kopa fun iko yii gege bi agbaboolu.
Ko tii si ẹni lee sọ ohun to ṣẹlẹ ti wọn fi tuu silẹ bayii.
Ẹni tí a bá sì fi nǹkan pupọ ṣọ́, nǹkan pupọ ni a óo bèèrè lọ́wọ́ rẹ̀.
Dare ni ‘Sim Card’ awọn eniyan miran di ofutufẹtẹ nitori wọn ko tẹ ika wọn daradara soju ẹrọ ti wọn fi se iforukọsilẹ, ati wi pe wọn ko fi aworan wọn si ibẹ daradara.
Ọgbẹni Yinka ni awọn gba ipe kan nigba ti wọn de ọfiisi wọn ti ni naa si ni oun n bọ pẹlu olowo Kinihun yii lati wa ba wọn ni gbolohun.
Bakan naa ni wọn ja ọkọ afẹsọna oun laya titi ti o fi wa sọ fun oun wi pe ọkọ afẹsọna naa yoo ku ti o ba fẹ oun, nitori idile ẹru ni oun ti wa.
Nígbà wo ni a rí ọ tí o ṣàìsàn, tabi tí o wà lẹ́wọ̀n, tí a wá sọ́dọ̀ rẹ?
"O ni bo ba ṣe orile-ede Germany ni, ""Konid Abdurasheed Adewale Akanbi lo yẹ ki n maa jẹ"" Kabiyesi ba ni ko da ""Oriṣa ni gbogbo yin"" pẹ̀lu alaye lẹnu Oluwo."
Adebajo na owo, o na ara lati rii pe ẹgbẹ yi tàn bi oṣumare ti pupọ awọn alatilẹyin rẹ si kan sara si ọgbọn ati oye ti o fi ṣakoso ẹgbẹ naa.
Ninu ilẹ̀ ìdajì ẹ̀yà Manase ni wọ́n ti fún àwọn ọmọ Geriṣoni ninu ìdílé Lefi ní àwọn ìlú wọnyi: Golani ní ilẹ̀ Baṣani pẹlu àwọn pápá ìdaran tí ó wà ní àyíká rẹ̀.
Igbakeji gomina ni ipinle naa Alhaji Usman
    Ìgbà tí ó ṣe lẹ́yìn èyí, Kùmọ́dìran náà ń fẹ́ fi ara wé Ìrèké òun náà tún wí fún àwọn ẹranko pé oun ni kí gbogbo wọn nà ní kùmọ́ titi ilẹ̀ ọjọ́ kejì fi maa ṣu, òun ni òun fẹ́ kí àwọn ẹranko bá jà lọ́jọ́ náà.
Nígbà tí ẹsẹ̀ àwọn alufaa tí wọ́n gbé Àpótí Majẹmu OLUWA gbogbo ayé bá kan odò Jọdani, odò náà yóo dúró; kò ní ṣàn mọ́, gbogbo omi tí ń ṣàn bọ̀ láti òkè yóo sì wọ́jọ pọ̀ bí òkítì ńlá.
Nítorí náà, ẹni tí ó bá fojú di aláṣẹ ń tàpá sí àṣẹ Ọlọrun.
Ninu atẹjade ka ti agbẹnusọ rẹ, Olawale Rasheed fi sita, Adeleke ni gẹgẹ olufẹ ijọba awa ara wa to n pa ofin mọ, oun gba idajọ ile ẹjọ.
 Awọn lo n wọ aṣo iwọkuwọ, awọn lo n ṣe Yahoo, awọn naa lo n digunjale.
"Florence Ajimobi tahùn sí igbákeji gómìnà Oyo lórí ikú ọkọ rẹ̀, ""Gbogbo wa làó kú"" Oríṣun àwòrán, BBC Sport Ọrọ ti n ba ọrọ bọ lori iku to mu ẹmi gomina ana nipinlẹ Oyo lọ ati ipa ti ijọba ipinlẹ Oyo ko lasiko ti oloogbe naa wa ni idubulẹ aisan."
 Àkókò dálé ọ ̀ nàréré tí kòkòrò àkóràn gbọ ́ dọ ̀ rìn láti dé ẹ ̀ yà ara bí ọpọlọ àti egungun ẹ ̀ hìn .
'Báyìí la ṣe rìn ín láti pápákọ̀ òfurufú Abuja sí Eko bí ìrìnà òfurufú abẹ́lé ṣe bẹ̀rẹ̀' Ààrùn Coronavirus tún ti ran ènìyàn 664 l'órílẹ̀-èdè Nàìjíríà Ilé alájà mẹ́ta wó lúlẹ̀ l‘Eko, ènìyàn méjì rọ̀run ọ̀sán gangan Ilé alájà méjì wó lu ọmọ mẹ́rin ni Bariga Wọ́n ti dóòlá ẹ̀mí ẹni tó há sábẹ́ àwókù ilé l‘Eko Eyi fun awọn eeyan lanfani lati maa sọrọ bi wọn ṣe n ba ara wọn lo pọ tabi bo ṣe wu wọn lati ṣe e tabi bi bi wọn ṣe n ni imọlara rẹ lasiko ibalopọ.
Iṣẹlẹ naa waye ni ilu Akurẹ, ti i ṣe olu ilu ipinlẹ Ondo.
Bakan naa, awọn abani ṣeto ayẹyẹ naa ba BBC sọrọ nipa bo ṣe maa n ri bi iru iṣẹlẹ yii ba ṣẹlẹ.
Plastic Bags: Kíni ìdí tí wọn fi fẹ́ fòfin de lílo nylon ní Naijiria?
O ni ọmọ ẹgbẹ PDP Akin Ogunbiyi lo gbe ẹjọ na lọ si iwaju ile ẹjọ lakure atti pe ko ni ohun kankan ṣe pẹlu idajọ ti ile ẹjọ kotmilọrun ti wọn ko ti da nilu Abuja.
O ni amuyẹ mejeeji ni awọn ibẹta oun ni.
Nígbà tí àwọn ará Amoni rí i pé Dafidi ti kórìíra àwọn, Hanuni ati àwọn eniyan rẹ̀ fi ẹgbẹrun (1,000) talẹnti fadaka ranṣẹ sí Mesopotamia, ati sí Aramu-maaka ati sí Soba, láti yá kẹ̀kẹ́ ogun ati àwọn ẹlẹ́ṣin.
Oríṣun àwòrán, BBC, @YeleSowore Lorukọ adajọ agba orilẹede yii ati minisita fun eto idajọ, Abubalar Malami to jẹ amofin agba, ni agbẹjọro o wa ni ẹka ipẹjọ ile iṣẹ naa, Aminu Aliyu buwọlu iwe ẹsun ọhun.
Ile-ise omo oogun ofurufu orile ede Naijiria  ti se atileyin fun iko omo- oogun ori-ilẹ lati doju ija ko iko  olote Boko Haram ni Gashigar to wa ni ipinle Borno.
Ajo to n mojuto itankale arun ni Naijiria, NCDC ti kede isele arun iba Lassa marundinlogoji tuntun.
"Jacinta ni"" mo mọ̀ pé mi o lé ri ọmọ mi mọ nítori èmi gan ko ṣe tán láti wà láàye, ṣùgbọ́n àwọn ẹbi Arinze yóò fiya jẹ ọmọ mi nítori wọ́n korira mi."
Ile ijọba ti wa kede pe, Trump yoo wa nile iwosan fun ọjọ diẹ nitori lara apẹẹrẹ tawọn n ri lara rẹ ni pe o ni iba.
Ẹ̀ṣẹ̀ ni ohun tí ó ṣe yìí, ẹ̀ṣẹ̀ yìí ni ó sì run ìran rẹ̀ lórí oyè, tí wọ́n fi parun patapata lórílẹ̀ ayé.
Amọ mo n rọ awọn obinrin ti ọkọ ba n na wọn lati ko kuro nibẹ, ko ma baa pa a nitori ọmọ wọn ní ọkọ wọn.
Ti won ba pari etikun ohun tan ni odun 2020, yoo ni awon ohun igbalode eyi ti yoo se adinku ifugun-moni etikun Tincan ati Apapa, eyi ti yoo ni agbara lati le gbe awon oko oju omi nlanla.
A ko ti i le fi idi nkan to fa ibugbamu ina naa mulẹ, ṣugbọn lori ayelujara, bi awọn kan ṣe n sọ pe awọn to fẹ ẹ ji epo wa nibi ọpa epo naa, to wa nitosi ileepo kan lo fa ina naa, ni awọn kan n sọ pe ọkọ agbepo kan lo ṣubu lu ọpa epo.
Ti ẹ ba ranti, igbakeji balogun ikọ̀ Super Eagles Ahmed Musa sọ sẹyin ni Alexandriar orilẹede egypt nibi ti idje ife ẹyẹ AFCON ti n waye.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Àjẹ́ ké lánàá, ọmọ kú lónìí ni ọ̀rọ̀ Tinubu àti ìṣẹ̀lẹ̀ Lekki Tollgate - Bode George Ẹ̀wẹ̀, ilé iṣẹ́ ọmọogun Nàìjíríà nínú àtẹ̀jáde tó fi síta ló ti sàlàyé pé, ọmọogun orílẹ̀-èdè Nàìjíríà kò dédé jáde sítà, bíkòṣe pé, ìjọba ìpínlẹ̀ Eko ló bẹ òun lọ́wẹ̀ láti ràn ìlú lọ́wọ́ lẹ́yìn tí àwọn ọ̀daran kan tí n jó àgọ́ ọlọ́pàá tí wọ́n sì ń ba ǹkan jẹ́ ní nìlú Eko.
Kerioti, Bosira, ati gbogbo àwọn ìlú ilẹ̀ Moabu, ati àwọn tí wọ́n wà nítòsí, ati àwọn tí wọ́n wà lókèèrè.
”Adari orile-ede Japan, Shinzo Abe ki Osaka ku oriire aseyori idije naa lori ero ayelujara(Twitter), O ki pupo fun ipa ribiribi re pelu gbigbe orile-ede Japan laruge lagbaye”.
Opo ninu awọn eroja ibalopọ yii jẹ ounjẹ aṣaraloore ti wọn wulo fun ara.
'A sinmi ìwádìí lóri Kemi Adeosun' CBN gbé òfin tuntun jáde fún àwọn Báǹkì Hẹlo!
George Weah se ibura wọlẹ gẹgẹ bi aarẹ orilẹede Liberia
Solomoni ọba ní,“OLUWA, o ti sọ pé o óo máa gbé inú òkùnkùn biribiri.
Arun coronavirus naa to bẹrẹ ni Osu Kejila, ọdun 2019 ni orilẹede China ti pa eniyan to le ni ẹgbẹrun meji, ti o si ti ran ẹgbẹgbẹrun eniyan lorilẹede China ati awọn orilẹede mẹẹdọgbọn miran kaakiri agbaye.
Lọdun 2011 ni ẹgbẹ OIC yi orukọ rẹ pada Organisation of Islamic Conferencde ssi Organisation of Islamic Cooperation.
Ẹ óo di ẹni ìríra, ẹni àmúpòwe ati ẹni ẹ̀sín, láàrin gbogbo àwọn eniyan, níbi tí OLUWA yóo le yín lọ.
Ikú kò ní pa yín, àrùn kò ní gbé yín dè, ẹ óò gbó ẹ óò tọ́, ẹ ó ṣe baba wa pẹ́ títí.
Ko si olori orilẹẹde Amerika kankan to ṣe ipade ri pẹlu olori orilẹẹde North Korea.
Ìyà á jẹ ìyàwó àti ọmọ
Oko ofurufu Dana to ni nomba 9J0363 to n ko ero lo lati Abuja lo si Port Harcourt ti ya kuro lojuna re ni papako ofurufu nla ti Port Harcourt.
O salaye pe o seese ki wọn lo awọn ike ATM shun fun iwa lilu jibiti ati kiko owo tuulu rin, to si leri leka pe gbogbo ẹni to ba lọwọ ninu isẹlẹ yii ni yoo fi imu ko ata ofin.
O ni won yoo jo sise papo lori ofin sise aigbe awon ere olosoose yii sit alai koko gba ase lowo ajo NFVCB paapaa ere onise, orin, ijolorin, atawon idanilaraya miran ni eyi to maa fo idoti ati abawon kuro ninu awon ohun ti a n safihan ni Naijiria.
ẹ ṣàkíyèsí odi rẹ̀;ẹ wọ inú gbogbo ilé ìṣọ́ rẹ̀ lọ,kí ẹ lè ròyìn fún ìran tí ń bọ̀
Abajade eyii naa ni sunkẹrẹ fakẹrẹ ọkọ.
Bákan náà, ààrẹ tún gbóríyìn fún àwọn àwọn ará ìpínlẹ̀ Ekiti pé ìhùwàsí wọn àti àláfíà gẹ́gẹ́ bí wọ́n ṣe fi àgbara ìtẹ̀ka wọn láti yan ẹni tí wọ́n fẹ́.
"N jẹ ẹ mọ bi eyi se lagbara to bi nigba miran, to si tun maa n gba akoko ẹni.
Ewe, CR7 wa dupe lowo awon ololufe iko agbaboolu Juventus fun ife ati atewo ti won fihan si oun leyin boolu afosoke gbawole ti o oun se.
Bakan naa lo pa ààlà pẹlu ipinlẹ Jigawa ni ilu Kazaure.
O ni 'ohun to ṣe pataki ni ki oludibo ma jẹ ki ami ika rẹ re kuro laarin alafo ẹgbẹ to fẹ yan si ibo miran.
Àgbéyẹ̀wò àṣà: Ìdí tí Yorùbá kìí fí tufọ ikú òjìji fún èèyàn Ẹ jọ̀ọ́, òógùn ojú mi kò gbọdọ̀ já sásán lórí sinimá tí mo yà pẹ̀lú oyún oṣù mẹ́fà - Toyin Abraham Èmi kò sí nílé, ọkọ́ mi ló leè sọ bóyá lóòtọ́ọ́ ló fẹ́ gbéyàwó àbí bẹ́ẹ̀ kọ́ - Aisha fèsì Ìjọba Ondo kéde ìsimi ọ́sẹ̀ mẹ́ta fún àwọn ilé ìwé to lùgbàdì omíyalé!
Aṣofin Adefunmilayo Tẹjuoṣo ninu ọrọ tirẹ ṣalaye pe akori abadofin naa ti wọn yọ ọrọ ‘were’ kuro ninu rẹ dara, nitori ọrọ naa maa n tabuku ba awọn alarun ọpọlọ.
Kọkọrọ kan to le ba eyin aja jẹ: Ẹru to n ba wọn nisinyi ni ikọlu tuntun to ṣẹlẹ lọjọ Aiku, ọjọ ajinde to kọja.
Ẹ pade wọn ninu fidio yii.
Yinka Ayefele le è dúró kọrin pẹ̀lú kẹ̀kẹ́ tuntun Mílíọ́nù kan Naira ni wọ́n fún wa láti pa Uwaila sínú ṣọ́ọ́ṣì ní Benin - Afurasí Ọba Akanbi ni eeyan ko le maa ta epo si ojubọ ki o si maa reti awọn eeyan lati wa woran.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ko si aniani pe iṣoro igbọnsẹ pọ lorilẹede Naijiria, papaa julọ lawọn ẹsẹ pupu Bakan naa lo ni ida mọkandinlogoji ninu ọgọrun awọn ọmọ orilẹ-ede Naijiria ni wọn lanfani si ile igbọnsẹ to jẹ pe idile kan nikan lo n lo o.
Èèyàn 296 ló forí kó Covid -19 ní Nàìjíríà lọ́jọ́bọ Wo àṣẹ tuntun tí Buhari gbé síta nípa owó iná ọba Kìí ṣe torí ìbèérè ni mo ṣe bẹ́ Fani-Kayode, àwọn akẹẹgbẹ́ mi ló kó mi láyà jẹ - Eyo Charles Ni bayii, wọn ni yoo foju bale ẹjọ lori ẹsun ipaniyan.
Yóo ṣe ìdájọ́ láàrin àwọn orílẹ̀-èdè; yóo sì bá ọpọlọpọ eniyan wí.
Èmi kò wá mọ ìdí táwọn èèyàn fi ń ní iya ń jẹ àwọn èèyàn yìí.
'Black Friday' àyájọ́ ẹ̀dínwó ọjà tó gbá ayé kan Hisbah mú ọkùnrin mẹ́ta tó pín fídíò ìfipábánilòpọ̀ ọmọdébìnrin 16 tó fẹ́ ṣèyàwó lórí ayélujára Òbinrin kan fẹ́ ọkọ méjì torí ọkọ àkọ́kọ́ rìnrìnàjò fún ọdún méjì péré Olórin Kano tí wọ́n dájọ́ ikú fún pe ẹjọ́ kòtẹ́milọ́rùn Awakọ̀ Maruwa tó bá gbé okùnrin àti obìnrin papọ ní Kano yóò jẹ búlálà mẹ́wàá- Hisbah Bí mo bá leè rí ọmọ alágbe t'áyé fẹnu sí pé mo fi ẹlẹ́rìndòdò lá lójú, máa kúnlẹ bẹ ẹ - Motara Wọn sọ ninu lẹta naa pe Musulumi ni ọpọ awọn to n gbe nipinlẹ Kano, ti wọn si ka ọjọ Jimọ si ọjọ Mimọ."
US election 2020: Bi kò tilẹ̀ wọlé, ẹ wo ayípadà tí Ààrẹ Trump mú bá awọn orilẹede ní àgbáyé
" Oríṣun àwòrán, Toyin Abraham Bẹẹ bá gbàgbé, ọjọ́ kẹrin oṣù keje ọdún 2019 ni Toyin Abraham àti ọkọ̀ rẹ, Kolawole Ajeyemi ṣe ayẹyẹ ìdána n'ilu Ibadan, tí ọba òkè si fi ọmọkùnrin kan lanti lanti tá wọn lọrẹ, ti orúkọ rẹ ń jẹ Ire.
Ṣaaju ni ijọba apapọ ti sọ oun ti fi biliọnu mẹsan an din diẹ naira kun owo ajẹmọnu owo Covid-19 wọn, eyii to jẹ wọn fun oṣu kẹfa ọdun 2020.
 wọn tún jẹ ́ olùsìn adìẹ ati ewúrẹ ́ èyí sì kó ìpa tó jọjú nínú àtijẹ wọn lójojúmọ ́ .
Ní ọjọ́ kẹta, nígbà tí ará kan wọ́n, meji ninu àwọn ọmọ Jakọbu, Simeoni ati Lefi, arakunrin Dina, mú idà wọn, wọ́n jálu àwọn ará ìlú náà lójijì, wọ́n sì pa gbogbo ọkunrin wọn.
Ẹ kéde ààwẹ̀, kí ẹ sì pe àpèjọ.
Ìjọba Nàìjíríà kìlọ̀ ìṣọ́ra ní ìlú London Oríṣun àwòrán, @abikedabiri Àkọlé àwòrán, Abike Dabiri lon kede ikilo fun awọn ọmọ Naijiria ni ilu London Ijọba orilẹede Naijiria ti kilọ fun awọn ọmọ ilẹ naa to wa ni ilu London lati ma a sọ ara se nitori iṣekupani to n waye lagbeegbe naa.
Pọ̀pọ̀-ṣìnṣìn fún ìsìnkú ìyálódé Ibadan bẹ̀rẹ̀ O tun ni ki awọn ọmọ Naijiria ma bẹnu ẹ̀tẹ́ lu awọn gomina ati awọn olori ilu, ni ọpọ awọn to ka iroyin naa ba lọ ori Twitter lati tabuku arọwa alufaa naa.
Nisinsinyii, OLUWA, tí ó ṣẹ̀dá mi ninu oyún,kí n lè jẹ́ iranṣẹ rẹ̀, láti mú Jakọbu pada tọ̀ ọ́ wá,ati láti mú kí Israẹli kórajọ pọ̀ sọ́dọ̀ rẹ̀; nítorí mo níyì lójú OLUWA,Ọlọrun mi sì ti di agbára mi.
Wọ́n bá dáhùn pé, “Kọniliu ọ̀gágun ni ó rán wa wá; eniyan rere ni, ó sì bẹ̀rù Ọlọrun tóbẹ́ẹ̀ tí gbogbo àwọn ọmọ Juu fi lè jẹ́rìí sí i.
oludije sugbon to n gbe ni  Washington
ìjọba àpapọ̀ - BBC News Yorùbá BBC News, YorùbáFò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Custom: A ti gbẹ́sẹ̀ lé ọjà tí oye rẹ̀ lé ní bílíọ́nù kan náírà lẹ́yìn tí a ti ibodè - ìjọba àpapọ̀ 14 Ọ̀wàrà 2019 Oríṣun àwòrán, FACEBOOK/NIGERIA CUSTOMS SERVICE Àkọlé àwòrán, Lati igba ti a ti gbe kọkọrọ si ẹnu ibode, ọrọ aabo Naijiria ti ṣẹnu ire ju ti tẹlẹ lọ Ajọ aṣọbode Naijiria ni oun ti sẹ ẹdinku si bi wọn ṣe n ko ohun ija wọle sorilẹ-ede yii, lẹyin to gbe agadagodo sẹnu ibode to wọle si Naijiria.
Nibayii, awọn to n ta epo bẹntirol ni yoo ma sọ iye ti wọn ba fẹ ta epo bẹntirol naa loore-koore.
Ozo-Eson, naa  ni igbimo egbe awon osise
Kong Thong: Àwọn òbí máa ń súfèé kọrin tàbí hu láti pe ọmọ tó bá dàgbà
Kí ló dé tí ẹ fi sílẹ̀?
Aarẹ Biya kii ṣe ipade pẹlu awọn minisita rẹ Oríṣun àwòrán, ALEXIS HUGUET Àkọlé àwòrán, Orilẹede Isreal ni awọn oṣiṣẹ alaabo Biya ti n kẹ́ẹ̀kọ̀ọ́ Aarẹ Biya kii ṣe ipade pẹlu awọn ọmọ igbimọ iṣakoso ati minisita rẹ ni gbogbo igba, ayafi asiko to ba fẹ ẹ yan minisita sipo nikan.
Afikun owo ori Ọpọlọpọ ọmọ Naijiria lo n wo bi nkan yoo ṣe ri l'ọdun 2020 fun awọn nkan bi i ọja rira lori ayelujara, ati fifi owo ranṣẹ nilana igbalode, ti afikun de ba owo ori wọn.
Ọmọ agbole Are ni Oke Are ni Ibadan nii se, ọmọwe Lalekan si tun jẹ onimọ nipa ọgbin, ti o si jẹ onisowo pataki lawujọ.
Ẹ wo àwọn gbajúmọ̀ òṣèré tíátà tó jogún eré ṣíṣe lọ́dọ̀ òbí wọn Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Gbajugbaja oṣere tiata, Bolaji Amusan fi hann wa bo se láyà to lori ètò ṣé o láyà.
Iṣẹlẹ ijinigbe ko ṣẹṣẹ ma a waye ni apa Ariwa Naijiria, ati awọn ibomii.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìtàn Mánigbàgbé: D.
 Ó jé olórin jùjú , african pop òun ló nilé işé agbórinjáde ( i.
Yin ni, yin ni, k’ẹni leè ṣe òmíràn
Jẹ́ ẹ̀jẹ́ fún OLUWA Ọlọrun rẹ, kí o sì mú un ṣẹ,kí gbogbo àwọn tí ó yí i ká mú ẹ̀bùn wáfún ẹni tí ó yẹ kí á bẹ̀rù.
Ani sẹ, Ọọni ran alaabo rẹ simi - Oluwo Ija eerin meji: Oluwo ati Ọọni Bí a kò bá ní gbàgbé, láìpẹ́ yìí ni awuyewuye sọ nigba ti Olúwó ni Emir ni orùkọ oyè tí òun fẹ́ máa lo.
Gẹgẹ bi ajọ akoroyinjọ lorilẹede Naijiria se wi, awọn akọwe agba nileesẹ eto isuna ati ọrọ osisẹ lo peju sibi ipade naa, ti igun mejeeji si pinnu lati gba ki aarẹ da si ọrọ naa, ko lee tete ni ojutu.
Oríṣun àwòrán, Remo Stars/Police Oṣu Kini, ọdun 2019 Ọga Agba ọlọpaa lorilẹede Niajiria to jẹ adele nigba naa, Mohammed Adamu lo tu ikọ SARS ti ijọba apapọ ka patapata( ohun kan naa lo ṣe ni Oṣu Kẹwaa, ọdun 2020).
Ewe, iroyin so pe, Djokovic  ti bere igbaradi bayii lati kopa ninu idije Australian Open.
26 Owewe 2020 BBC News, Yorùbá Ìdí tí ẹ fi le è nígbàagbọ́ nínú ìròyìn BBC Ìlànà Lílò Nípa BBC Òfin Àṣírí Cookies Kàn sí.
Yatọ si awọn wọnyi, amugbalẹgbẹ iyawo Trump, Hope Hicks, ati awọn sẹnetọ ẹgbẹ oṣelu Republican, naa ti ni aarun ọhun.
Ko ni ipinnu lati pada si Ghana.
Mo rí ohun tí ó burú gan-an ní Israẹli; ìbọ̀rìṣà Efuraimu wà níbẹ̀, Israẹli sì ti ba ara wọn jẹ́.
Gbogbo àwọn ohun ẹlẹ́mìí, akọ kan, abo kan, ní oríṣìí kọ̀ọ̀kan wọlé gẹ́gẹ́ bí Ọlọrun ti pàṣẹ fún Noa.
#BBCNigeria2019 Day 25: Àwọn ọmọ Nàìjíríà sọ̀rọ̀ lórí níní adarí tó ju ọdún 70 ló lọ́jọ́ orí #BBCNigeria2019 Àwọn Ẹ̀gbá àti Òwu ń ṣàárò MKO Abiola Nàìjíríà á bí ọmọ 25, 685 lọjọ́ kínni, oṣù kinni, ọdún 2019.
Oríṣun àwòrán, Amotekun Lẹyin naa ni iwadii fihan pe ẹni to n ṣe aṣọ naa wa ni arakunrin Mathew Aderanijo ni agbegbe Challenge ni ilu Ibadan.
•Ẹnikẹni to ba lo aworan, fidio tabi akọsilẹ ẹlomiran lai gba aṣẹ lọwọ ẹni ti o nii le fa ki wọn gbegile oju opo rẹ, ti oni nkan ba fi ẹjọ rẹ sun wi pe o lo ọgbọn ati aroko oun lai gba aṣẹ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Mayowa Omoniyi: Kò sí orin Obey, Sunny Ade abí tàkasúfèé tí ń kò le ta gìtá sí Adajọ Erdoo Ter to n dajọ ni majisireei naa wa ni ki wọn gba iduro pẹlu oniduro kan ati ẹgbẹrun lọna ọgọrun naira.
Ikeazor  gba ami ẹyẹ  ti eni to yege julọ lorile ede Afirika ti
Ti eniyan ba ji dide lojiji, o le e ku iku ojiji.
Wọn ni o ti kọkọ fi ọkọ rẹ kọlu obinrin ẹlẹha kan lagbegbe Olowo-Bida nilu Ẹdẹ kan naa.
Okunrin naa ni wọn ni o n wa mọto rẹ lọ lati agbegbe Midland si Odessa ni ipinlẹ Texas nigba to ṣadeede yinbọn pa agbofinro to kọkọ da ọkọ rẹ duro ko too tun kọju ibọn sawọn ero atawọn awakọ nibẹ.
Ariyanjiyan Ijọba to wa ni iṣakoso n tẹnumọ pe oun ti pa ìṣẹ́ run, to si n di ẹbi ru awọn iṣakoso to kọja pe wọn ṣe aṣilo ileeṣẹ eporọbi ati ọrọ aje.
Nítorí náà, àwọn ati àwọn ọmọ wọn ni wọ́n ń ṣe alabojuto ẹnu ọ̀nà ilé OLUWA, àwọn ni wọ́n fi ṣe olùṣọ́ Àgọ́ Àjọ.
 Óunjẹ ati àwọn egbògi múràn .
AFCON 2019: Debola olólùfẹ́ Super Eagles mú BBC Yorùbá dé ibùdó Bọ́ọ̀lù wíwò
leyin ipade ti won jo se papo.
Abiola fi aya rẹ, Oloye Florence Ajimobi ati ọmọ marun-un silẹ saye lọ.
Eliṣa ranṣẹ sí ọba Israẹli pé kí ó má ṣe gba ibẹ̀ nítorí pé àwọn ará Siria ba sibẹ.
Saulu wà ninu àgọ́, àwọn ọmọ ogun rẹ̀ sì pàgọ́ yí i ká.
Awọn neiyan Zimbabwe n ṣelede lẹyin Mugabe.
52Fifun eleka-jekan lowo-na, alakoso ohun so pe, eka eto oro-aje yoo ko bilionu merilelogun N24.
Ó jẹ́ ọmọ ẹgbẹ́ tó ní áápọn ní ìlú àjọgbé àwọn Tibet tí ó wà ní Toronto àti pé ó ti kópa nínú ìjàfẹ́tọ̀ọ́ kan tí ó wáyé níta Akànkọ́ Ilé Ẹ̀kọ́ Confucius tí fáfitì ọ̀hún, ẹ̀ka ìbílẹ̀ àjọ ìsọdọ̀kan àṣà Ilẹ̀ China tí ìjọba China ń ṣe agbátẹrù fún lọ́nà tí ó fi ń mú kí China lágbára sí i ní ilẹ̀ òkèèrè.
Ẹ yìn ín, ẹ̀yin òkè ńláńlá ati òkè kéékèèké,ẹ̀yin igi eléso ati igi kedari;
Gẹgẹ bi wọn ti ṣe e ni alaye, awọn ero ọkọ yoo maa san Ẹẹdẹgbẹta naira dipo Ẹgbẹrun kan naira ti awọn ọkọ oju omi miiran n gba.
Wayii o, bi iko ohun se tun gbaradi fun idije boolu agbaye tawon obnrin , FIFA Women’s World Cup, ti yoo waye lorile-ede France, aare wa ro won lati ni afojusun, ki won si tun safihan iwa akinkanju ti o mu won gbe igba oroke ninu idije WAFU lorile-ede France.
Naira Marley: Adájọ́ ṣún ìgbẹ́jọ́ síwájú di oṣù kejì ọdún 2020
Ṣugbọn ẹrọ ayaworan kamẹra ko ṣafihan ohun to n lọ laarin awọn mejeeji.
Aare fikun un oro re pe, o ti di dandan ki ijoba mu lokun-kundun lati jawe olubori ninu kikoju iwa ibaje lorile-ede yii, bee si ni ki awon omo orile-ede yii naa ri ija ohun gege bi ija ara won.
ẹ̀rù ìrora mi á bẹ̀rẹ̀ sí bà mí,nítorí mo mọ̀ pé o kò ní gbà pé n kò dẹ́ṣẹ̀.
Ọpọ lo si n wadii pe ki lo le fa iru iṣẹlẹ naa.
33 Ẹ má ṣe bẹ̀rù láti ṣe rere, ẹ̀yin ọmọ mi, nítorí ohunkohun tí ẹ̀yin bá fúrúgbìn, èyìínì náà ni ẹ̀yin yíò kórè; nítorínáà, bí ẹ̀yin bá fúrúgbìn rere ẹ̀yin yíò kórè rere gẹ́gẹ́bí èrè yín.
Gẹgẹ bi alaye ti Omotara ṣe pe alumajiri ni ọmọ naa.
Ni deede ọdun mẹta sẹyin ni wooli kan nilu Eko, Olagorioye Faleyimu ti ijọ Mountain of Blessing and Miracle ni o lè ma ri ọmọ bi.
Jesu fẹ́ràn Mata ati arabinrin rẹ̀ ati Lasaru.
Oríṣun àwòrán, Lagos State Government Àkọlé àwòrán, Ambode ní kí ìjọba gbe fídíò àti ìgbóhùinsílẹ̀ ìgbẹ̀yìn ayé Abiola síta Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Oríṣun àwòrán, @VickyShegzy Yatọ si pe o jẹ olori oṣiṣẹ aarẹ Buhari, Abba Kyari tun jẹ ọrẹ timọ-timọ aarẹ Buhari nigba aye rẹ.
Oríṣun àwòrán, @SZakzakyOffice/Twitter Awọn ọmọ ẹgbẹ naa si ti n ja fun itusilẹ olori wọn to ti wa ni atimọle lati ọdun 2015 toun ti pe ile ẹjọ giga mi Abuja paṣẹ ki wọn tu silẹ.
Iṣẹ ti pọ lọwọ awa mejeeji, ko si aye.
MFM pegede lapapo ami-ayo ifesewonse ohun, leyin ti iko ohun gba ami-ayo kookan ninu ifigagbaga akoko ti o waye lorile-ede Mali, ki won o to wa gba ami-ayo kan sodo ni papa isere AgegeAkuneto Chijioke lo gba ami ayo kan soso ohun wole ni saa keji ifesewonse naa, eyi ti Lawal Abayomi omo odun merindinlogun si se iranwo ami-ayo ohun.
Oga àgbà kan láti àjọ UN ní orílẹ̀ èdè South Sudan, Alain Noudehou sọ pé ibi tí àwọn ènìyàn Òun wọlé sí ní àwọn kò mọ O ni botilejepe pé ilahilo wá láàárín ìjọba àti àwọn abajoba sọtẹ̀ lágbègbè tí wọn ti lọ ṣíṣe, ó rọ wọn láti jọ̀wọ́ wọn lálàafia.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ọ̀rọ̀ Nàíjíríà kúrò ní sinimá àwòrẹ́rìn-ìn, Buhari gbé ìgbésẹ̀ bíi òbí àti olórí - Obasanjo gbarata Ilẹ̀ Amẹ́ríkà wà lẹ́yìn àwọn olùwọ́de, Buhari dẹ́kun ìpànìyàn - Joe Biden Mọ̀ nípa DJ Switch, akíkanjú obìrin sàfihàn fídíò ìpànìyàn Lekki bó ṣe ń wáyé Buhari, máṣe gbá ìpànìyàn Lekki sórí ààtàn, kò yẹ́ kí ológun yin ọ̀dọ́ níbọn - Bode George Ọ̀kan lára olùwọ́de tó fara gbọgbẹ́ ní Lekki jáde láyé - Sanwo-Olu Kò sí olùwọ́de tó kú ní Lekki - Sanwo-Olu N kò lọ́wọ́ nínú ìpànìyàn, kò dáa bí wọn ṣe lo ọta ìbọn ní Lekki - Tinubu Ọjọ́ Ìsẹ́gun di ọjọ́ ìbànújẹ́ fún ọ̀pọ̀ ìdílé ní Nàíjíríà torí òkú tó ṣùn Ọ̀dọ́ 30 ń gba ìtọ́jú lọ́wọ́ nílé ìwòsàn torí ọ̀gbẹ́ ìbọn ní Lekki - Sanwo-Olu ṣàlàyé O nijọba apapọ gbọdọ rii daju pe awọn ọlogun to ṣọṣẹ naa foju winna ofin ati pe, awọn ọbalaye lorilẹede Naijiria ti n gbe igbesẹ lati jẹ alarinna laarin ijọba apapọ atawọn onigbọwọ iwọde naa.
Odumakin ni, Baba Fasanmi jẹ ọkan ninu awon to di opo ẹgbẹ afẹnifẹre mu, amọ wọn yapa diẹ kuro ninu ẹgbẹ afẹnifẹrẹ nigba to ku diẹ ki wọn ku.
Oríṣun àwòrán, @GbenroAdegbola Àkọlé àwòrán, Lateef Alabi ti gba oriyin lọdọ awọn eeyan kaakiri agbaye Aworan Lateef jẹ eleyi ti ọpọ eeyan ri pẹlu aṣọ rẹ ti o kun fun ẹjẹ.
Ìgbà náà ni Jin wí fún mi pé kí n má wùlẹ̀ wo ìwé-oúnjẹ́ tí wọn fún wa.
Oga Audu Kareem ni ọga agba ọlọpaa ti ọwọ rẹ̀ ko mọ rara, to si n huwa ibi nitori riba to n gab lọ́wa awọn ole ati ajinigbe.
ní ọjọ kọọkanlelọgọrin lẹyìn ìgbà náà.
O salaye pe “ojuse wa ni lati maa da emi awon eniyan legbodo”Alakoso eka igbonpo ti ilu Warii, ogbeni Reuven Okon wa ro ijoba apapo lati maa pese epo-robi fun awon ara ilu loore-koore.
Àkọlé àwòrán, Ẹgbẹ́ òṣèlú APC ló ń ṣe àkóso ìpínlẹ̀ Ọyọ Àkọlé àwòrán, Lori ijọba ibilẹ, gbogbo awọn oludije ni wọn ni awọn yoo da idaduro ijọba ibilẹ pada Àkọlé àwòrán, Gbogbo awọn oludije to yọju lo wu awọn eniyan lori pẹlu gbogbo alakalẹ aato wọn lọlọkan o jọkan ti wọn ni awọn yoo gbe ṣe bi awọn ba di gomina ipinlẹ Ọyọ.
Ẹwẹ, ki awọn ikọ aṣeranwọ gan to de ni iku Ajibola ti waye ati ti wọn si tun ti gbe awọn mẹrin to fara pa nibẹ lọ sile iwosan.
 Ọgba ẹwọn naa ni ẹlẹwọn mejidinlọgọwa, to si kere jọjọ."
 a jẹ ́ kó di mímọ ̀ pé a lè ṣe ìyísódì eyọ ọ ̀ rọ ̀ ; a lè ṣe ìyísódì fọ ́ nrán ìhun gbólóhùn , a sì lè ṣe ìyísódì odidi gbólóhùn .
Gbọ iroyin iṣẹju kan BBC Fidio wa fun toni Gómìnà ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́ tẹ́lẹ̀rí, Rashidi Ladoja wípé kí àwon ọmọ Nàìjíríà jẹ́ kí Ààre Bùhárí gbé àpótí ìbò wò, bóyá yóò borí.
Nigba ti BBC Yoruba béèrè ọrọ yìí lọwọ Omisore, ọgbọn tí Ọga ẹdà fi n sa fún ẹlẹwọn to ba buru lo fi yẹba fún ìbéèrè náà.
Biliọnu mẹta abọ dọla owo ilẹ Amẹrika, $3.
Jonadabu dáhùn, ó ní, “Lọ dùbúlẹ̀ lórí ibùsùn rẹ, kí o sì ṣe bí ẹni pé ara rẹ kò yá.
Àwọn ọmọ ọba wà lára àwọn obinrin inú àgbàlá rẹ,ayaba dúró ní ọwọ́ ọ̀tún rẹ,ó fi ojúlówó wúrà ṣe ọ̀ṣọ́ sára.
Awọn eleto ẹko ti kede awọn ilana kan kalẹ fawọn akẹkọọ eyi ti yoo mojuto idaabo wọn lọwọ ajakalẹ arun Covid-19.
Ida kọnkọ si ni wọn ti maa n ṣe awọn ayẹyẹ wọn.
Satani bá lọ kúrò níwájú OLUWA, ó sì da oówo bo Jobu lára, láti àtẹ́lẹsẹ̀ títí dé orí.
Ṣugbọn ọrọ bẹyin yọ lẹyin ti oludije ẹgbẹ oṣelu Democrat, Joe Biden fẹyin rẹ gbolẹ ninu eto idibo naa.
mojuto bi eto ohun se lo jake-jado ipinle kookan lorile-ede Naijriia.
Kò sí ẹni tí ó lè mọ orin náà àfi àwọn ọ̀kẹ́ meje ó lé ẹgbaaji (144,000) eniyan tí a ti rà pada ninu ayé.
 O fi kun ọrọ rẹ pe, “bi wọn ba sọ abadofin yii di ofin tan, yoo le fun awọn alarun ọpọlọ ni itọju to yẹ gẹgẹ bi a ṣe nii ni ipele ijọba apapọ naa”.
Oríṣun àwòrán, Karen Charmaine Chanakira Kia ni mo bẹrẹ si ni t'ọju tọte, mo si n tun ara ṣe ju ti tẹlẹ lọ.
Àwa pàápàá fi ojú wa rí i bí OLUWA ti ṣe àwọn iṣẹ́ ìyanu ńlá tí wọ́n bani lẹ́rù sí àwọn ará Ijipti ati sí Farao ọba wọn, ati gbogbo àwọn ará ilé rẹ̀.
Ẹnìkan kò ní gbé ibẹ̀ mọ́,bẹ́ẹ̀ ni ẹnikẹ́ni kò ní dé sibẹ mọ́.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Africa Eye: Olùkọ́ méjì ní fásitì Eko àti Ghana lùgbàdì ọ̀fíntótó BBC lórí ìwà ìbàjẹ́ Nibayii, ileeṣẹ ọlọpaa ti fi olukọ naa si ahamọ, lẹyin to jẹwọ pe lootọ ni oun jẹbi ẹsun naa.
Ṣugbọn olódodo ni OLUWA,ó ti gé okùn àwọn eniyan burúkú.
Chelsea jawe olubori lẹẹmẹwaa ninu ifẹsẹwọnsẹ mọkanla ti wọn kẹyin ninu idije EFL.
Ní ọjọ́ kinni oṣù, ní ọdún kọkanla tí a dé ìgbèkùn, OLUWA bá mi sọ̀rọ̀: ó ní, 
Oríṣun àwòrán, Wikipedia Àkọlé àwòrán, Minisita Feto ilera lo fi iroyin yii sita ṣalaye pe awọn eeyan naa ṣẹṣẹ de lati awọn orilẹede bii Canada, France ati ilẹ Gẹẹsi ni.
Ikú Caruana Daphne: Bí mo ṣe jà fún ìdájọ́ òdodo lórí ìyá mi tí wọ́n ṣekú pa
Ojijeogu ni awọn n ṣiṣẹ karakara lati ri wipe esi idanwo naa jade lasiko ti awọn fi to awọn eniyan leti wi pe yoo jade.
Eyi yoo mu ki o rọrun lati mọ orisun ibi ti ọja kankan to ba ni wahala ninu ti wa.
Bawo lo ṣe n ṣe e?
Ọgbẹni Oyeyemi ni ileeṣẹ ọlọpaa yoo gba ọkọ oju omi tawọn ajinigbe gbe lọ pada.
Wọn tun ni iṣẹ iwadii yoo bẹrẹ lori awọn to ti ṣowo ilu mọkumọku.
Ahasi ranṣẹ lọ bá Tigilati Pileseri, ọba Asiria, ó ní, “Iranṣẹ ati ọmọ rẹ ni mo jẹ́, nítorí náà, jọ̀wọ́ wá gbà mí lọ́wọ́ àwọn ọba Siria ati ti Israẹli tí wọ́n gbógun tì mí.
Ọkọ-ofurufu naa to jẹ irufẹ 777 ti kọkọ balẹ, to n si n gbiyanju ati gbalejo awọn ero ko to gbera lọ Dubai nigba ti iṣẹlẹ naa ṣẹlẹ.
Ó bá sọ fún Efuroni lójú gbogbo wọn, ó ní, “Ṣugbọn, bí ó bá ti ọkàn rẹ wá, fún mi ní ilẹ̀ náà, kí n sì san owó rẹ̀ fún ọ.
1 1441 Orilẹede Sao Tomẹ́ and Principe 17 8.
Ajọ Amnesty International ni mimu ti wọn muu ni ọwọ kan nipa iroyin to n kọ ninu ni eyi ti awọn agbẹjọrọ ijọba Morocco ti ni irọ ni.
O ni aare Buhari ti pese isẹ lọpọ janturu
N óo fi sùúrù dúró jẹ́ẹ́ de ọjọ́ tí ìṣòro yóo débá àwọn tí wọ́n kó wa lẹ́rù.
Mose bá pàṣẹ fún wọn pé, “Ní ìparí ọdún keje-keje, ní àkókò tí a yà sọ́tọ̀ fún ọdún ìdásílẹ̀, ní àkókò àjọ̀dún àgọ́, 
Ó wá bèèrè pé, kí ni mo tún ń fẹ́ nisinsinyii?
Nígbà tí wọ́n bá òkú agbẹjọ́rò tí ó jẹ́ ẹni ọdún 26, Carolina Joaquim de Sousa da Silva nínú ilée rẹ̀ ní ọjọ́ 3, oṣù Ọ̀pẹ ọdún 2018, ọkọ rẹ̀ jẹ́wọ́ ọ̀ràn náà, ó sì di èrò àhámọ̀ ẹ̀ka tí ó ń ṣe ìwádìí ìwà ọ̀daràn ti Angola tí a mọ̀ sí SIC.
 Òun náà ni ó lọ rọ kọ ́ kọ ́ rọ ́ lọ ́ dọ ̀ bàbá àgbẹ ̀ dẹ tí Àṣàkẹ ́ fi dán séèfù wò .
Lasiko to n sọsọ, Bọla Tinubu ni ọrọ yii kii kan n ṣe ọrọ ipolongo lasan, bikoṣe ilepa ti ẹgbẹ APC gbọdọ mojuto lati da igba ọtun pada fun awọn eeyan orilẹede Naijiria.
Gómina ko fi àmì kankan hàn báyìí, bákan náà losi ti wọ́gile gbogbo àwọn ìpáde to yẹ ki o ní.
Pupọ awọn ilu lofin konileogbele ti fẹsẹmulẹ,lilọ bibọ ọkọ ofurufu ni ijọba wọgile tawọn ajọdun ati ayẹyẹ miran naa si ti dẹnukọle.
 gbogbo ìgbà tí ẹ ̀ nìyàn bá wọsọ olúmẹ ̀ yẹ kọ ́ laráyé máa ń fẹ ́ kọ ́ yẹni .
Alukoro ile isẹ ọlọpaa naa wa rọ awọn ara ilu, lati ran awọn lọwọ lati fi iroyin lede ti wọn ba gbọ nkankan, nitori awọn ọlọpaa gbagbọ wi pe awọn ajinigbe yii n gbe laaarin awọn eniyan ninu ilu.
Baba Ọlọsun to ni ere ojulowo ere Ọsun si wa lọdọ oun, wa rọ Ataoja lati pe oun fun ifikunlukun, to ba fẹ ki oun da ojulowo ere Ọsun pada si ojubọ rẹ ni Osogbo.
13bn) siwaju Ile Asofin ipinlẹ naa.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Nigeria COVID-19 cases: Abẹ́rẹ́ àjẹsára kò tíì sí fún COVID-19, síbẹ́ àwọn òṣìṣẹ́ kólẹ̀-kódọ̀tí ń fi ẹ̀mí wọn wéwu 21 Agẹmo 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 11 Owewe 2020 Ọwọja arun coronavirus n fojojumọ peleke sii lorilẹ-ede Naijiria.
Nǹkan yan, àwọn aṣẹ́wó fẹ́ daṣẹ́ sílẹ̀ nítorí ẹ̀kúnwó epo ní Nàìjíríà Ìbúgbàmù gbogbo ìgbà nílù ú Èkó, kí ló ń ṣokùnfà rẹ̀?
Bi o ti le je pe, iko agbaboolu Eaglets padanu ifesewonse akoko ninu idije ohun sowo orile-ede Burkina Faso pelu ami-ayo meta si meji(3-2), sugbon won tara ji ninu ifesewonse keji lati fagbahan orile-ede Ivory Coast pelu ami-ayo marun sookan(5-1) lati bo si oke tente tabili ipele keji(Group B).
Ìbá ṣe pé mo ní ilé èrò kan ninu aṣálẹ̀,ǹ bá kó àwọn eniyan mi dà sílẹ̀ níbẹ̀,ǹ bá sì kúrò lọ́dọ̀ wọn;nítorí alágbèrè ni gbogbo wọn,ati àgbájọ àwọn alárèékérekè eniyan.
Àwọn ọjọ́ ọṣù tí ọjọ́ ndọ́gba báyìí a máa fi ọjọ́ kan sí méjì yàtọ̀ lọ́dọọdún.
Fasọla ni bakanaa l'ọmọ sori pẹlu isẹ kikọ afara Niger keji, to si n para poro pe awọn isẹ akanse mejeeji yi se pataki pupọ, ti a ko si gbọdọ fi akoko sofo nipa diduro de eto iduna-dura ọlọjọ pipẹ to maa n waye lasikoigbesẹ idokowo laarin ijọba ati ẹka aladani gẹgẹbi ọna min lati pese owona fun isẹ naa,pẹlu afikun pe ilana idokowo laarin ijọba ati ẹka aladan toun jogun lasiko toun gba ipo minisita ko ni oore kankan ti yoo se fun ilẹ wa.
O fi kun un pe iyawo Sanusi Lamido keji torukọ rẹ n jẹ (Goggo) Mamie lo bẹ Emir ana naa pe ko sọ ọmọ ọhun ni orukọ iyawo rẹ akọkọ, iyẹn Yaya (Giwa) ti wọn ni o tọju Saadatu`nigba to wa ninu oyun.
Nígbà tí wọn ń kó owó tí àwọn eniyan ti mú wá sinu ilé OLUWA jáde, Hilikaya, alufaa rí ìwé òfin OLUWA tí Ọlọrun fún Mose.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Fish skin: Kóòmù ni wọ́n fi ń họra fún Amida nítorí bí àwọ̀ rẹ̀ ṣe rí Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Fish skin: Kóòmù ni wọ́n fi ń họra fún Amida nítorí bí àwọ̀ rẹ̀ ṣe rí 4 Ògún 2019 Latifat Sulaiman tó jẹ́ ìyá Amida ṣalàyé wí pé ṣe ni inú òun ma ń gbóná nígbàtí òún lóyún rẹ̀.
Eyi ni igba keji ti Kayode Fayemi yoo jẹ gomina ipinlẹ Ekiti.
Ohun tí wọn n sọ nipe niṣe ni Olubadan kan gbe Ọgbẹni Abass le awọn lori.
Bí ó ti lẹ̀ jé pé ó ní àríyànjiyàn bóyá “Famalay” yóò kópa nínú Ìwọ́de Ojúnà tàbí kò ní í kópa, nítorí Skinny wá láti St.
Ṣugbọn ileeṣẹ ologun ti sẹ pe oun ko mọwọ mẹsẹ ninu bi wọn ṣe dana ibọn bo awọn oluwọde.
Àmóṣá, ìpínlẹ̀ náà ń dojú kọ abala ọ̀pọ̀lọpọ̀ ọ̀rọ̀ míì lẹ́yìn tí wọ́n ti dá gbogbo akọ̀wé ètò ẹ̀kọ́ ìpínlẹ̀ náà dúró.
"Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, ọ̀gá ọlọ́pàá sọ̀rọ̀ lórí SARS Chinenye ni, ""Ọlọpaa ni wọn gbọ ti aburo mi n paruwo 'ẹ gba mi, wọn ti ji mi gbe' ni awọn ṣe yinbọn si ọkọ naa."
 lọ Ìdí nìyí tí a fi ṣe ìwé yìí lórí èdè , tí a sì lo ìmọ ̀ ẹ ̀ dà-èdè láti fi ṣàlàyé àwọn orí-ọ ̀ rọ ̀ fonọ ́ lọ ́ jì àti gíràmà .
- Ìjọba Oyo Ọkọ mi kò fẹ́ràn oúnjẹ òyìnbó àfi ti ìbílẹ̀ - Lizzy Anjorin Iléẹjọ́ gíga Akure kọ̀ láti gba onídùróó olórí ìjọ Sotitobire Ọwọ́ ọlọ́pàá tẹ afurasí tó ní òun ló jí ọmọ gbé láti parọ́ mọ́ pásítọ̀ ìjọ Sotitobire Ó mà ṣe o!
Gbogbo ohun tí ó bá dáwọ́lé níí máa yọrí sí rere.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Europa League Final: Chelsea lu Arsenal ní àlùdákú ní Baku.
Ẹ múra kí ẹ kọ́ ilé ìsìn fún OLUWA Ọlọrun, kí ẹ baà lè gbé Àpótí Majẹmu OLUWA ati gbogbo ohun èlò mímọ́ fún ìsìn Ọlọrun lọ sinu ilé tí ẹ óo kọ́ fún OLUWA.
Ajọsẹ ni ẹgbẹrun marun-le-igba ati mẹsan-an (5,209).
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Wọ́n ta ère Ọ̀ṣun Osogbo sí Togo - Bàbá Ọṣun figbe ta Baṣọ̀run Gáà, tó yan ọba mẹ́rin, pa ọba mẹ́rin àmọ́ ọba karùn-ún ló pa á Ọbasanjọ sọ àsírí sàgbàdèwe rẹ̀ Jesu Oyingbo rèé, pásítọ̀ tó láṣẹ ìbálòpọ̀ lóri ọmọ ìjọ obìnrin Lẹta naa, ti Ọmọọba Ayọdeji Abass Alẹsinlọyẹ ati Ọlayinka Jestoye dijọ fọwọsi, lọjọ Karun osu Kẹfa ọdun 2019, lorukọ awọn alaga ijọba ibilẹ yoku naa fikun pe, Nigba to n ba BBC Yoruba sọrọ lati fidi ootọ mulẹ nipa lẹta naa, Ọmọọba Ayọdeji Abass Alẹsinlọyẹ salaye pe yoo dara ki aarẹ dasi ọrọ naa, tori asẹ ileeẹjọ ti wa nilẹ tẹlẹ, eyi to ni gomina Makinde ko gbọdọ yọ awọn lori oye.
Àkàndá ẹ̀dá Nàíjíríà mókè nínú irin gbígbé Sé Man City leè borí Liverpool?
Nítorí náà, ẹ fẹ́ràn àwọn àlejò; nítorí pé ẹ̀yin náà ti jẹ́ àlejò ní ilẹ̀ Ijipti rí.
Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kan 8 Èrèlè 2018 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 22 Agẹmo 2020 Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kan Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí 3 sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 2:23 Fídíò, Water Generator: Ó leè ṣiṣẹ fún wákàtí mẹfà, kó tó sinmi, Duration 2,2310 Òkùdu 2020 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
 Àwọn àyíká rẹ ̀ ni ilé ìjọsìn st jude àti ilé ìwé african salem school àti ilé ìjọsìn salvation army .
Bi o ba ri bẹẹ, bawo wa ni Zakari ati Buhari ṣe wa tan ?
Ó wá rí Abrahamu ní òkèèrè pẹlu Lasaru ní ọ̀dọ̀ rẹ̀.
Àṣé 'Fashola' ló fún Naira Marley láǹfàní àti gbé bàlúù lọ sí Abuja lọ kọrin Oríṣun àwòrán, Twitter/naira marley Bi wọn ba ni ka wẹni rere ba jorukọ aṣe nitori ọjọ afiyesi kan ni.
Wọn ni ninu igbo Sambisa ni awọn ti kọlu Shekau ti wọn si ti ṣee lọṣẹ to kọja bẹẹ.
Ìrẹ̀sì kò gbọdọ̀ wọlé níbáyìí ta ṣí ẹnu bodè padà - Ìjọba àpapọ̀ Minisita feto ẹnawo, eto isuna ati aato ilu, Zainab Ahmed ti kede pe ijọba apapọ si gbẹsẹ le awọn eroja kan pe ko ma wọle sorilẹede yii.
Democratic Party – PDP Ipinle Bauchi: ajo eleto idibo (Independent National Electoral
"Gẹ́gẹ́ bi ọ̀rọ̀ rẹ̀ ""Èmi kìí ṣe asoju àjọ NCDC, mí kò si nífẹ̀ẹ́ si irú àláye ti wọ́n ba mi fi síta yìí pé mó fi ẹrú gbà ìbùkùn lọ́wọ́ akẹgbẹ́ mí"" Bí ọ̀rs se ri ni pé, mó wà lára àwọn to ṣe ìpolongo lòdì sí Covid -19 mo si fara han nínú fọ́nran náà, sùgbọ́n ó ṣe pàtàkì ki a má fa ẹnìkàn wále nítori ire ti yín."
Champions League: Ẹ ò ní dúró!
O kọkọ kopa labẹ asia Togo nibi idije Winter Olympics lọdun 2014 ni ilu Sochi.
Ewe, aare tun gbosuba kare lai fun awon akonimoogba won gbogbo, ajo NFF ati awon ololufe jake-jado lagbaye ku ise ribi-ribi eleyi ti o fara han ninu bi won se kopa si.
"O jẹ ko di mimọ pe "" ko si itiju ninu sisọ iye awọn to ni i nipinlẹ yin."
Oshodi ati Dada ba eebo lọ soke okun lootọ amọ ilẹ Amẹrika ni wọn lọ, tí wọn si pada de lẹyin ọpọlọpọ ọdun, Lẹyin eyi ni awọn oyinbo si gba Oshodi Tapa si idi okoowo wọn nitori o ti mọ apade alude oko-owo naa loke okun.
Ìwé yìí fún un ní àṣẹ pé bí ó bá rí àwọn tí ń tẹ̀lé ọ̀nà ẹ̀sìn yìí, ìbáà ṣe ọkunrin ìbáà ṣe obinrin, kí ó dè wọ́n, kí ó sì fà wọ́n wá sí Jerusalẹmu.
Darandaran Fulani kìí lo ìbọn, 'pọ̀pá' la máa ń lò Iléeṣẹ́ ọlọ́pàá Èkó ní àwọn kò mọ ohunkohun nípa ìwadìí ẹjọ́ Dakolo àti pásítọ̀ COZA mọ́ Àgùnbánirọ̀ akọ̀ròyìn Channels náà ti dágbére fáyé látààrí ìkọlù Shiite l'Abuja Yinka Ayefele di bàbá ìbẹta Oru ana ni wọn fi orukọ ranṣẹ sile igbimọ aṣofin ki ile to kaa ni owurọ oni.
”Àwọn olórí alufaa dá a lóhùn pé, “A kò ní ọba lẹ́yìn Kesari.
Bí ó bá jẹ́ pé wọ́n tún ń ronú ti ibi tí wọ́n ti jáde wá, wọn ìbá ti wá ààyè láti pada sibẹ.
Ibi tí kinniun ń gbé oúnjẹ rẹ̀ lọ,tí àwọn ọmọ rẹ̀ wà,tí kò sí ẹni tí ó lè dà wọ́n láàmú?
O ni ọpọlọpọ awọn obi kan ti ba oun sọrọ pe, iru nkan bẹ ẹ ṣẹlẹ si ọmọ wọn, ṣugbọn ibẹru ni ko jẹ ki wọn o sọ sita.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Lekki Toll Gate: CNN vs Lai Mohamamed rèé o!
Mẹta ni wọn, awọn naa si ni, Anthony Joshua, Israel Adesanya ati Kamaru Usman.
Èèyàn méjì tó ń gbọ́n epo bá ìṣẹ̀lẹ̀ ọkọ̀ epo tó gbiná rìn n‘Ibadan Ṣugbọn nigba ti akọroyin BBC beere lọwọ rẹ pe eelo ni ẹkunwo kekere ti yoo gun ori owo oṣu, o kọ̀ lati sọrọ.
Bí ó ti gbójú sókè, bẹ́ẹ̀ ni ó rí àwọn ọkunrin mẹta kan, wọ́n dúró ní ọ̀kánkán níwájú rẹ̀.
Bí ẹlẹ́ṣẹ̀ bá kú ní ẹni ọgọrun-un ọdún,a óo sọ pé ó kú ikú ègún.
O gbajumọ ninu ere ''se bo o ti mọ'', paapa ninu ere rẹ ''Alakada''.
Abdulaziz Yari: 'Àwa gomina ṣì ń tiraka láti san N18,000, a ò lè san N24,000 NLC: Àwọn olósèlú ń la títì láì sanwó osù torí owó tí wọn yóò rí lórí àkànse isẹ́ Àkọlé àwòrán, Awa naa n fẹ ẹkunwo owo oṣu Ìwọdé naáà ń wáyé jákè-jádò àwọn ìpínlẹ̀ tó ń bẹ lórílẹ̀-èdè yìí láti kìlọ̀ fún ìjọba àpapọ̀ lórí ohun tí àwọn òṣìṣẹ́ ń bèèrè fún.
Ọna lati daabo bo iya Sara lo mu ki oun ati ọkọ rẹ dete pe Karoline n se aisan, to si nilo itọju gidi nilu ọba.
Kí ni OLUWA fẹ́ kí o ṣe, ju pé kí o jẹ́ olótìítọ́ lọ, kí o máa ṣàánú eniyan, kí o sì máa rìn ní ìrẹ̀lẹ̀ pẹlu Ọlọrun rẹ?
Báyìí ni mo dé ìlú àwọn ÈDìdàrẹ́ ní ibi tí wọn ti  ń pè ọba lẹ́jọ́ kọ́bọ̀ kan.
Adesina sọ pe aarẹ ko pinnu lati ba awọn ọmọ Naijiria sọrọ, ati pe ohun yowu to ba yẹ ki awọn eeyan mọ nipa ibi iṣẹ de duro lori arun Coronavirus ni igbimọ amuṣẹya ti aarẹ gbe kalẹ yoo fi to awọn eeyan leti.
Ayo Adesanya bẹ̀rẹ̀ eré àgbéléwò ní ọdún1996 lẹ́yìn tó párí àgùnbánirọ̀ rẹ̀ kò tò dara pọ̀ mọ́ àwọn òṣèré fíìmù Yorùbá.
Ó kọ àwọn àlàyé náà sinu ìwé kan, ó sì gbé e siwaju OLUWA.
  “Ohun to sele ti sele, bi o ti le je pe, a ri boolu agbesile gba, sugbon ti adari ayo ko lati fun wa.
Awọn akẹkọọ n fọ ọwọ wọn loorekoore, wọn ko jẹ ki wọn sunmọ ara wọn rara.
Ninu ijoko ilé ni wọn ti gbe ofin kan dide ti wọn fi ṣatunṣe yii.
O si jẹ ọkan lara awọn aisan jẹjẹrẹ to wọpọ julọ.
OLUWA ti gbọ́ ẹ̀bẹ̀ mi,OLUWA ti tẹ́wọ́gba adura mi.
awon janduku kan fẹ da ibo ru, ti awon agbofinro si tete ka apa wọn.
Àsìkò yìí jẹ́ èyí tí ó le.
Ẹ ṣe bí akọni, bí bẹ́ẹ̀ kọ́, a óo di ẹrú àwọn ará Heberu gẹ́gẹ́ bí wọ́n ti jẹ́ ẹrú wa, nítorí náà, ẹ ṣe bí akọni, kí ẹ sì jà.
Awọn yoku yoo pariwo pe ‘rara ma waa wo’, a wa ni ko tẹle oun ka lọ.
Bí ọwọ́ ọ̀tún rẹ bá mú ọ kọsẹ̀, gé e sọnù.
Jesse Lingard's reaction to Marcus Rashford's penalty…Absolutely brilliant 😂 pic.
Bẹ́ẹ̀ ni kò sí ní òdìkejì òkun tí ẹ óo fi wí pé, ‘Ta ni yóo la òkun kọjá fún wa, tí yóo lọ bá wa mú un wá kí á lè gbọ́ kí á sì pa á mọ́?
Oríṣun àwòrán, AFP Gẹgẹ bi igbakeji aarẹ Obama lọdun 2009, ori kan yan an ni lo fi jẹ eeyan alawọdudu akọkọ to jọ dije dupo gẹgẹ bi aarẹ ati igbakeji pẹlu Obama.
Oyetola sọrọ yii lasiko to gbalejo awọn agbaagba ẹgbẹ oṣelu SDP to wa ki i ni ile ijoba nilu Osogbo.
Àwọn ni baálé baálé ninu ìran Lefi, ní ìdílé ìdílé, gẹ́gẹ́ bí àkọsílẹ̀ àwọn tí wọ́n tó ogún ọdún ati jù bẹ́ẹ̀ lọ, tí wọ́n dàgbà tó láti ṣiṣẹ́ ninu ilé OLUWA.
 Oríṣun àwòrán, @LFCGoshen Wo oríṣìí àrùn márùn ún tí ìgbéyàwó láàrin ìbátan si ìbátan máa ń fà Sanwo-Olu, El-Rufai fara pamọ́ torí COVID-19 lẹ́ẹ̀kejì Iléeṣẹ́ epo rọ̀bì ná ₦116m lórí báírò, ìwé ìkọ̀wé, àwọn aṣòfin fìka hánu Agbébọn tún gbẹ̀mí àgbẹ̀ míì lọ́nà oko lágbègbè Ibarapa Àádọ́ta Náírà tí báńkì ń yọ nínú owó ìpamọ́ oníbàárà kò tọ̀nà - Iléejọ́ Ẹni to ba gbagbọ ninu Covid-19 ni arun naa yoo ran, ẹni ti ko ba gbagbọ ninu rẹ ko ni lugbadi arun naa.
Oríṣun àwòrán, Instagram/K1 the ultimate O rọ awọn eeyan wi pe ki wọn ye oju opo ayelujara ni ilokulo, Ọba Alaafin ni ilokuko oju opo ayelujara lo jẹ kawọn kan ṣi oun gbọ lori ọrọ oye Mayegun.
Igba to ba wuwa la n rin jade ti awọn oṣiṣẹ alaabo naa si wa ni ṣẹpẹ'' Mo le ni eto wọn nilu yi muna doko daada ti o si wu mi ki ijọba Naijiria naa wo awokọṣe lara wọn.
"O yẹ ka ro lootọ pe awọn eeyan to maa n lọ silẹ okeere lọ gba itọju maa fẹ lati joko sile bayii nitori awọn orilẹede ti wọn ti maa n lọ gba itọju lo ti lugbadi Coronavirus.
Atiku Abubakar ti seleri lati pese miliọnu mẹta iṣe lọdọọdun Oludije ipọ Aarẹ fun ẹgbẹ oselu PDP lorileede Naijiria Atiku Abubakar ti seleri lati pese miliọnu mẹta iṣe lọdọọdun, ti ohun ba jẹ Aarẹ Naijiria.
Kí Oluwa mú kí ìfẹ́ yín sí ara yín ati sí gbogbo eniyan kí ó pọ̀ sí i, kí ó sì túbọ̀ jinlẹ̀, gẹ́gẹ́ bí tiwa ti rí si yín.
Ẹ má lòdì sí OLUWA, ẹ má sì bẹ̀rù àwọn eniyan tí ń gbé ilẹ̀ náà.
Ilumọọka ọjọgbọn yi ni botilẹ jẹ pe oun ko gba ti Obasanjo nitori o pẹlu awọn adari to ba Naijiria de ibi to wa bayii, lori ọrọ to sọ, oun gbe lẹyin rẹ.
Àwọn ọmọ Ahimotu nìwọ̀nyí: Elikana ni baba Sofai, Sofai ni ó bí Nahati; 
 Gomina ana ni ipinle Ondo, Oluṣẹgun Mimiko ti dibo bayiiGomina Ajimọbi àti iyawo  re, Florence, naa dibo níluu IbadanGomina ipinle Oyo, Abiọla
Awọn oluwọde ni ilẹ Gẹẹsi wo ere oniṣowo ẹru kan lasiko iwọde wọn.
Ní àkókò ìkórè ọkà alikama, Reubẹni bá wọn lọ sí oko, ó sì já èso mandiraki bọ̀ fún Lea ìyá rẹ̀.
Nígbà náà ni àwọn Farisi ati àwọn amòfin wá sọ́dọ̀ Jesu láti Jerusalẹmu, wọ́n bi í pé, 
4 6349 Orilẹede Mayotte 51 19.
Alufaa yóo kó o lé orí ẹbọ náà, yóo sì fi iná sun ún lórí pẹpẹ fún OLUWA.
Oríṣun àwòrán, Others Àkọlé àwòrán, Ìpínlẹ̀ Ogun, Eko ti késí aráàlù láti pa òfin ìmọ́tótó mọ́!
Ọpọ ọmọ Naijiria lo faraya lori ayelujara ti wọn si sọ pe ki ijọba ilẹ Lebanon fi ọwọ ofin mu un.
Ṣugbọn agbẹnusọ rẹ, Jason Schechter ti sọ f'awọn akọroyin pe Bloomberg yoo kede erongba rẹ lọsẹ to n bọ.
Ọlọrun Abrahamu ati Ọlọrun Nahori, àní, Ọlọrun baba wọn ni onídàájọ́ láàrin wa.
Nígbà tí OLUWA rí i pé ìwà burúkú eniyan ti pọ̀ jù láyé, ati pé kìkì ibi ni èrò inú wọn nígbà gbogbo, 
omo egbe naa se pọ bayii ti fihan pe awon eniyan nifẹẹ si egbe naa.
9 146937 Orilẹede China 4796 0.
Alefọ yóò jáde làwọn agbegbe ara tó sún mọ́ ibi tí kòkòrò ọhun gba wọlé sí agọ ara, yóò kọ́kọ́ wú, kò tóo fọ, tí yóò sì di egbò.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Siga igbalode (e-cigarettes) ko ni ewu to taba Ajọ WHO ni taba ti di ohun to jọ ajakalẹ arun ati pe o wa lara ohun to jẹ ewu fun alaafia ju lagbaye.
Tola si ni alaga igbimọ alaṣẹ iwe iroyin Tribune titi ti o fi faye silẹ.
Wọ́n tọ Joṣua lọ ninu àgọ́ tí ó wà ní Giligali, wọ́n wí fún òun ati àwọn ọmọ Israẹli pé, “Ọ̀nà jíjìn ni a ti wá, nítorí náà, ẹ jẹ́ kí á dá majẹmu.
47 Àti pé mo wí fún wọn, pé a ó fi fún wọn gẹ́gẹ́bí ìgbàgbọ́ wọn nínú àwọn àdúrà wọn;
Super Eagles ti wọn jẹ agbabọọlu àgbà fun ilẹ wa ni wọn ti gunlẹ si ilu Dnipro sugbọn ti wọn ko ranti ko awọn ohun eelo igba bọolu wọn dani.
Àmọ́ kí ẹnikẹ́ni máà rò wípé iṣẹ́ ọpọlọ nìkan ni ìrìnàjò sí Ìwọ́de Ojúnà.
A gbọ pe pẹlu ọta ibọn, afẹfẹ tajutaju ati ẹrọ katakata ni wọn fi ni ki awọn olugbe agbegbe ọhun kuro ni ibugbe wọn naa.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Buhari: Obasanjo ló mú ìgbéga bá òṣèlú Nàìjíríà, ó yẹ ká yìn-ín 6 Ẹrẹ̀nà 2019 Oríṣun àwòrán, Obasanjo Official Àkọlé àwòrán, Muhammadu Buhari: Obasanjo ló mú ìdàgbàsókè bá ìjọba àwa-àra-wa Nàìjíríà Ààrẹ Muhammadu Buhari ti ṣe àfiwé ààrẹ àná, Olusegun Obasanjo gẹ́gẹ́ bíi olùfarajì tòótọ fún ìdàgbàsóke Nàìjíríà tó sì yẹ láti máà gbóríyìn fún.
Mo sì sọ gbogbo ohun tí OLUWA fihàn mí fún àwọn tí wọ́n wà ní ìgbèkùn.
dandan fun gbogbo awon to ba fẹ dipo ijoba mu lati salaye lẹkununrẹrẹ ninu iwe
Ṣugbọn Ọlọrun gba aláìníbaba kúrò lọ́wọ́ wọn,ó gba àwọn aláìní kúrò lọ́wọ́ àwọn alágbára.
Àkọlé àwòrán, Ìtàgé ti tò fún ọdún ọlọ́jọ́ 2018 Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ sí: Omiṣore sọ̀rọ̀ lórí èsì ìdìbò Ọṣun Adeleke fi ìdùnú rẹ̀ hàn ní Ọṣun Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Iriwisi àwọn ará ìlú ṣe ọtọtọ lórí èsì ìdìbò Osun Kó tó bẹ̀rẹ̀ ìsélé, Ọọ̀ni ti ṣe àbẹ̀wò sí ojúbọ 'Ilemọle' ní ìlú Moore láti ṣìpẹ̀ kò tó lọ ṣe 'ra rl mọ́lé níbi tí ojú òun àti ẹ̀dá alàyè kankan kò ní gáání ara wọn títí dí ọjọ́ ẹtì.
Awa fi ẹ̀rí yìí fún ayé, pẹ̀lú Olúwa bíi olùrànlọ́wọ́ wa; ó sì jẹ́ pé nípasẹ̀ ore ọ̀fẹ́ Ọlọ́run Bàbá, àti Ọmọ Rẹ̀, Jésù Krístì, ni a fún wa ní ààyè láti ní ànfàní ti jíjẹ́rìí yìí sí ayé, nínú èyítí awa yọ̀ lọ́pọ̀lọpọ̀, ní gbigbàdúrà sí Olúwa nígbà gbogbo pé kí àwọn ọmọ ènìyàn ó lè jẹ ànfàní nípa rẹ̀.
Fun awọn ile ounjẹ, gomina Sanwo-Olu sọ pe wọn le maa taja laarin aago mẹsan aarọ di aago meje alẹ nitori awẹ Ramadan to n lọ lọwọ.
Ọjọbọ ni ẹgbẹ Feminist Coalition kede pe oun ko ni ni ohunkohun se pẹlu iwọde kankan mọ.
ìlú Eko kọ́ ló léwu jùlọ láti gbé lágbàáyé- Ìjọba Eko Ǹkan mẹ́jọ tó máa kọ́kọ́ ṣẹlẹ̀ kí olólùfẹ́ méjì tó pa ara wọn Laipẹ́, ọmọ tí kò bá pé ọdún méjìdínlógún kò ní leè jáde girama l’Ọṣun Wọ́n ti pa ẹni to yìnbọn pa ará Texas márùn ún -ọlọ́pàá Lara awọn ẹya to wa nipinlẹ naa la ti ri ẹya Igala to saaba maa n dipo gomina mu ti awọn ẹya to ku a si maa di ipo igbakeji gomina tabi omiran to ba bọ si wọn lọwọ mu.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Funke Akindele, oníròyìn, agbẹjọrò àti òṣèré; ohun tí ẹ kò lérò nípa rẹ̀ 29 Owewe 2019 Oríṣun àwòrán, funkejenifaakindele Sulia kan, Ayetoro kan!
Tun wẹ, ileesẹ aladani nla to wa fun ohun amusagbara lati Russia, Lukoil, la tun gbọ pe o n se isẹ lorilẹede Cameroon, Ghana ati Naijiria, to si tun n lakaka lati tẹdo si orilẹede Congo.
1 Owewe 2020 Oríṣun àwòrán, Getty Images Gbajugbaja oṣere kritẹni, Mike Bamiloye to jẹ oludasilẹ ẹgbẹ oṣere Mount Zion ti ja gudugbẹ ọrọ lulẹ lori aṣọ wiwọ ni ṣọọṣi.
Àwọn tí ó ń lọ ní iwájú ati àwọn tí ó ń bọ̀ ní ẹ̀yìn ń kígbe pé, “Hosana!
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ sí: ‘Ko si ìdí fun 30, 000 ọlọpaa ni Ekiti’ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ekiti Election: Pọpọ sinsin idibo n lọ lori lawọn wọọdi Nínú ilé rẹ̀ níbi tí òun àti àwọn gómìnà ẹgbẹ́ òṣèlú APC ti jọ wo ìkéde náà lórí ẹ̀rọ asọ̀rọ̀mágbèsì, n'íṣe ni àyọ̀ wọn kún.
Sọ fún wọn pé kí wọ́n fọ aṣọ wọn, kí wọ́n wà ní ìmúrasílẹ̀ ní ọjọ́ kẹta, 
Èmi, OLUWA àwọn ọmọ ogun, n óo fi ọ̀pá mi nà wọ́n, bí ìgbà tí mo na àwọn ará Midiani ní ibi àpáta Orebu.
Ipo kẹwaa ni Naijiria wa nilẹ Afrika ninu awọn orilẹ-ede ti iwa ipara ẹni tí wọ pọ julọ.
Ìwọ ni mò ń ké pè, OLUWA,OLUWA, ìwọ ni mò ń bẹ̀.
Oríṣun àwòrán, @ajplus Àkọlé àwòrán, Lekki Ipinlẹ Ogun: Ni ipinlẹ Ogun, awọn olufẹhonuhan korajọ si opopona marosẹ Eko si Ibadan, iyẹ loju ọna to lọ si Mowe ni ipinlẹ Ogun, ti wọn si n kọrin pe Sọrọ soke"" ati pe ki ijọba apapọ ""End SARS."
Timi Frank: Àjọ UN, EU ẹ báwa kìlọ fún Ààrẹ Buhari
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Daddys Showkey sí Naira Marley: Mi ò gbè lẹ́yìn Naira Mailey fún ìwà ìbàjẹ́ 22 Èbibi 2019 Oríṣun àwòrán, Google Àkọlé àwòrán, Ọ̀pọ̀lọpọ̀ awuyewuye ló jẹyọ lórí ọ̀rọ̀ tí Daddyshowky sọ lórí bí àjọ EFCC se se naira mailey.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù World Water Day; Àwọn ara Ezeukwu ma ń rin ìrìn wakati méjì torí omi mímu Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ World Water Day; Àwọn ara Ezeukwu ma ń rin ìrìn wakati méjì torí omi mímu 28 Ẹrẹ̀nà 2020 Awọn ara agbeegbe Ezeukwu ni ipinlẹ Abia ti sọ iriri wọn nipa wiwa omi to mọ lati lo nigba ẹrun.
n óo ranṣẹ lọ kó gbogbo àwọn orílẹ̀-èdè àríwá wá.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Boko Haram: Buhari yoo gba itusilẹ gbogbo onde 26 Èrèlè 2018 Oríṣun àwòrán, BUHARI /TWITTER Àkọlé àwòrán, Awon oluko meta lati ile-iwe giga ti Maiduguri( Unimaid) ati awọn obinrin miran bọ lọwọ ikọ Boko Haram laipẹ yii Awọn olukọ mẹta lati fasiti Maiduguri, Unimaid ati ọkan lara awọn obinrin ti wọn jajabọ lọwọ ikọ Boko Haram ti wa lọdọ aarẹ Muhammadu Buhari lati sepade pẹlu rẹ.
Oṣu Kẹjọ, ọdun 2019 ni awọn ibode naa ti wa ni titi pa, nitori pe ijọba 'fẹ ẹ fi opin si kiko nkan ijagun wọle lọna aitọ, ki opin le ba ipenija to n koju eto aabo, ati lati mu idagbasoke ba ọrọ aje Naijiria.
Ẹ maa laagun jinna, ẹgbẹ awọn ọkunrin to lahun s'awọn ọrẹbinrin wọn ni ti wọn n pe ni Stingy Men Association of Nigeria.
O ni oun fẹ maa gbeja awọn eeyan ni nitori pe ọkunrin kan oloye kan ni abule ohun nigba naa.
Wò mí, ọ̀rẹ́ mi, ṣọ́ra ni ìgbésí-ayé rẹ, bí ìwọ bá sin ẹnìkejì rẹ lọ sí ilé ìyàwó àfẹ́sọ́nà rẹ̀, ronú ki o tó dá sí ọ̀rọ̀ ti wọ́n bá ń ṣo nítorí bí ìwọ kò bá ṣe bẹ́ẹ̀ ìwọ yòó da bi àbàwọ́n pẹ̀lú aṣọ funfun, bí wọ́n bá si ń fi ojú rẹ́rìn-ín si ọ wọn kò ní ṣàì máa wí ní ibi kọ́lọ́fín ọkàn wọn pé, ‘Alákọrí yìí kò jẹ́ kí a gbádùn eré wa.
O ni nipasẹ abala iwe ofin irinna Section 325, ko si eeyan titi dori awọn to di ipo oṣelu mu, to kọja ibawi, bi wọn ba tapa si ofin irinna lorilẹede Naijiria.
Bákan náà ni àwọn ọba alayé méjèèjì ilẹ̀ Yorùbá náà, Ọọ̀ni ilé ifẹ̀, Oba Adeyeye Ogunwusi Ọ̀jájá kejì àti Olúwó ti ìlú Iwò Oba Abdulrasheed Akanbi ní kò sí dúkùú kankan mọ́ làárín awọn.
Dípò irin, fadaka ni n óo mú wá.
" Ifedayo ni ki olùṣọ́ àguntan náà tọrọ àforijì lọ́wọ́ àwọn oníṣẹ́ ìròyìn to bẹ̀nu àtẹ́ lù, tó si fí iṣẹ́ wọ́n wọ́lẹ̀ tuurutu.
Awọn eniyan Ohu lo n fi awọn eniyan bi ti wọn ṣe owo ẹru, amọ awọn ara orun lo ni awọn ẹru ti wọn n pe ni Osu, ti wọn si ti fi wọn rubọ si awọn oriṣa.
Precious Adams - Onijo nilẹ Amẹrika Precious Adams, lati Ọmọ ọdun mẹjọ, lo ti n lo ọpọ akoko lati maa jo kiri yara igbalejo ti iya rẹ fi ọwọ si fun lati maa lo fun idanilẹkọ.
Boo ba ri i nibẹ, o ti gba fa fa fa fao"" Wo beba tabi ọra ti wọn lẹ mọ ọ lara."
awon kan farapa , awon kan si tun padanu ẹmi won.
Yóo kọ́ yọ bí òdòdó, lẹ́yìn náà yóo sì rẹ̀ dànù.
Ìdájí ìdájí lo l’ógùn ń kú, ọmọ Àgbókí l’ádífá
Osun Guber Poll: PDP ní ìdájọ́ ilé ẹjọ́ gíga lórí ọ̀rọ̀ Adeleke kò fẹsẹ̀ múlẹ̀
Kí Ọlọrun pa mí bí mo bá fi ẹnikẹ́ni sílẹ̀ láìpa ninu àwọn eniyan Nabali títí di òwúrọ̀ ọ̀la.
Ìpínlẹ̀ Oyo àti Eko kò nífẹ̀ẹ́ láti gba 'Ruga Settlement' láyè Ogedengbe Agbógun Gbórò, Akọni tó ń dẹ́rù ba ikú.
O si jẹ ẹni to maa n po orin pọ (DJ) to si jẹ olootu ẹto lorii redio.
Akọwe ìjọba wa rọ gbogbo ọmọ Naijiria lati tẹle àwọn ilana to yẹ lati dena aarun Coronavirus nitori pe aarun naa ko mọ olowo tabi talaka.
Shiloh 2020: Oyedepo ní òun kò le tòṣì láéláé!
ni o sokunfa idi pataki ti a fid a ise akanse ti a pe ni `Operation Puff Adder’
kí wọn lè ní àṣẹ láti máa lé àwọn ẹ̀mí èṣù jáde.
"O ni ""Wọn dana sun awọn mọto wa, wọn tun se awọn osisẹ kan lese sugbọn ko si ẹni to ku sinu isẹlẹ yii."
Loṣu kẹfa to kọja ni Monguno sọ pe ijọba apapọ n gbero lati fi opin si Almajiri ki iru awọn ọmọ le lanfaani lati lọ si ile iwe.
Ó mú ọ̀rá ọ̀dọ́ mààlúù náà, ati àwọn kíndìnrín rẹ̀ ati ẹ̀dọ̀ rẹ̀ kúrò ninu ẹbọ ìmúkúrò ẹ̀ṣẹ̀, ó sun wọ́n lórí pẹpẹ bí OLUWA ti pàṣẹ fún Mose.
Lóòótọ̀, bẹ́ẹ̀ ni àwọn ẹranko àti iwin ṣe, ṣùgbọ́n Kùmọ́dìran ti ṣe àṣejù, lóòótọ́ ni ìsẹ̀dá rẹ̀ jẹ́ èyí tí bí wọn kò bá nà an ní kùmọ̀ ara rẹ̀ kìí le, ṣùgbọ́n ẹnikẹ́ni kò nà án ni kùmọ̀ tó ogojì lẹ́ẹ̀kan ṣoṣo rí.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Boko Haram: obìnrin tórí kó yọ ní omi àti ewé ńi òun jẹ nínú igbó 24 Ẹrẹ̀nà 2019 Oríṣun àwòrán, @elharsh Obinrin kan ti ori ko yọ lọwọ ikọ agbesunmọmi Boko Haram, ti salaye fun pe inu tubu kan naa ni oun ati Leah Sharibu wa, ti o si wa ni alaafia.
Ṣugbọn kò pa àwọn pẹpẹ ìrúbọ run; àwọn eniyan kò tíì máa fi tọkàntọkàn sin Ọlọrun àwọn baba ńlá wọn.
Á dí orísun àwọn odò,tóbẹ́ẹ̀ tí wọn kò fi lè sun,á sì wá àwọn ohun tí ó pamọ́ jáde.
Sugbọn alaye miran to yọju sita lọjọ Aiku lo sisọ loju rẹ pe, ẹgbẹ awọn Emere onitẹsiwaju lo se ipade, kii se ẹgbẹ awọn Oṣo ati Ajẹ, gẹgẹ bi iroyin ti gbe sita.
- Joseph Yobo Oko òkú rèé, níbití òkú ti ń jẹrà mọ́lẹ̀ fún àyẹ̀wò Bí eṣinṣin bá kọ́já, wíwọ́n ní, lásìkò ìṣíde AFCON 2019 Ìgbà Marún-un ti Aisha Buhari ti tako ìjọba Buhari Iwadii fihan pé arun ebola tun n pada wa silẹ Adulawọ nitori pé awọn eeyan ilẹ Afrika kii ye jẹ ẹran igbẹ.
Kíni ìdí ti wọn fi ń lọ ọmú obinrin Àwọn arẹwà obinrin Yollywood, tá ló mọ iṣẹ́ rẹ̀ jù?
Àwọn tí wọn ń jókòó sí itẹ́ òkú,tí wọn ń dúró níbi ìkọ̀kọ̀ lóru;àwọn tí wọn ń jẹ ẹran ẹlẹ́dẹ̀,tí ìṣaasùn ọbẹ̀ wọn sì kún fún ẹran aláìmọ́.
 Bee si ni, minisita FCT, Alhaji Mohammed Musa Bello, yoo gba alejo iko naa loni.
Ẹlẹ́wọ̀n: Ẹ̀sùn ìbálòpọ̀ ọmọdé ló gbé dé mi dé ẹ̀wọ̀n
“Èwo lẹ tún rí o Alákọ̀wé?
Ninu ìyà ati ebi,wọ́n ń jẹ gbòǹgbò igi gbígbẹ káàkiri lálẹ́ ninu aṣálẹ̀.
Koda, awọn ololufẹ wọn maa n ṣe afiwe ẹni to lowo lọwọ julọ laarin wọn.
"Oríṣun àwòrán, Getty Images Ọ̀pọ̀ èèyàn sì lo ń wá fídíò kiri lórí ayélujára nípa bí wọn ṣe leè lo pineapple àti ọkà bàbà pẹlu sogomu fi ṣe ọtí líle ni abẹle, tí wọn ń pè ní ""Umqombothi""."
Gbogbo eniyan ilẹ̀ Judia ati ti ìlú Jerusalẹmu jáde tọ̀ ọ́ lọ, wọ́n ń jẹ́wọ́ ẹ̀ṣẹ̀ wọn, ó sì ń ṣe ìrìbọmi fún wọn ninu odò Jọdani.
Igbakeji aarẹ orilẹede Naijiria, Ọjọgbọn Yemi Osinabjo lo sọrọ yii ninu atẹjade kan to fi sita to si tun wa loju opo Twitter rẹ.
Nítorí ó tó àkókò tí ìdájọ́ yóo bẹ̀rẹ̀, láàrin ìdílé Ọlọrun ni yóo sì ti bẹ̀rẹ̀.
Gomina Ganduje si kọwe mabinu si Emir nigba naa.
ohun, Frank Mbah,ni komisona ilu Abuja, Bala Ciroma ti bẹrẹ iwadii lori isẹlẹ
Ijọba Ọ̀yọ́ ní igbesẹ naa tọna Ṣugbọn Gomina ipinlẹ Ọyọ Abiola Ajimobi lọ sile ẹjọ ko tẹmilọrun lori ọrọ naa.
Amọ, ko i ti di mimọ iru ẹsun ti wọn yoo fi kan Kajwang naa.
O fikun pe laye ode oni, ohun ti aye ko ka si nkankan ni awọn eeyan n tẹwọgba.
iroyin sọ pe lakoko yii, ṣe ni awọn ẹṣọ aṣọbode yii n lepa yara ikorẹsi pamọ si aitọ kan to wa lẹba ile epo naa.
Bakan naa , ogbeni Olayiwola ro ijoba ki won fi owo epo
N kò ní gba akọ mààlúù lọ́wọ́ yín,tabi òbúkọ láti agbo ẹran yín.
A tun ni ipinnu lati tun tesiwaju ninu igbiyanju wa lati mu awon
Bi èniyàn bá pàdé ẹni kan tàbi meji ni àkọ́kọ́, ti ó ti ẹ̀yà tàbi ilú kan jade, ti ó si hùwà rere, ni ọ̀pọ̀ igbà, ó wọ́pọ̀ lati rò wi pé gbogbo ará ilú bẹ́ ẹ̀ ló dára, ni ida keji, ti irú ẹni bẹ́ ẹ̀ ba hùwà burúkú, ó wọ́pọ̀ lati rò wi pé gbogbo ẹni ti ó ti irú ẹ̀yà yi jade ni ẹni burúkú.
 Adari Nir Barkat ni ijo yii je ilu naa ni ogosan milionu owo dola ile okeere gege bii owo ori ki won to tii pa tele”.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Toyin Ibietan: Àlòkù táyà ọkọ̀ ló mú mi rí nǹkan ṣe lásìkò ìgbélé COVID-19 Ọgagun Ndayishimiye, to bi ọmọ mẹfa, lo jẹ olujọsin gidi ninu ijọ Katoliki, gẹgẹ bii aarẹ to ṣe ijọba saaju rẹ, oun naa n tẹnumọ ojuse Ọlọrun ninu iselu.
Lẹyin atotonu agbẹjọro EFCC ati agbẹjọro fun Naira Marley ni ile ẹjọ sun igbẹjọ naa di ọjọ kẹtalelogun ọṣu yii, ti ṣe ọla ode yii.
Bẹẹni oríṣiríṣi góólù n tanna yinrin-yinrin lọ́wọ́ ìyàwó ọ̀sìngín.
A ti máa wọlé sùn pẹlu ọrọ̀ tẹ́lẹ̀, ṣugbọn kò ní rí bẹ́ẹ̀ fún un mọ́.
Bournemouth vs Tottenham: Báwo ni Tottenham se gba káàdì pupa méjì láàárín ìṣẹ́jú márùn ún?
"O ṣe pataki ki awọn eeyan mọ pe ""a o ki n ṣe ọmọ buruku."
Ní ọ̀sán, OLUWA fi ìfẹ́ rẹ̀ tí kì í yẹ̀ hàn,ní òru, orin rẹ̀ gba ẹnu mi,àní, adura sí Ọlọrun ìyè mi.
Díẹ̀ ninu àwọn ọlọ́gbọ́n yóo kú lójú ogun, a óo fi dán àwọn ọmọ Israẹli wò láti wẹ̀ wọ́n mọ́ ati láti mú gbogbo àbààwọ́n wọn kúrò títí di àkókò ìkẹyìn, ní àkókò tí Ọlọrun ti pinnu.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ọbẹ Ẹgusi sise ati jijẹ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, #Queen Dihya: Obinrin tó gbógun tàwọn agbésùnmọ̀mí ni Algeria Amọ, awọn mii fi aake kọri, wọn ni Ole kii ṣẹgbẹ Van Persie ni gbogbo ọna pẹlu ohun nla to gbe ṣe nigba to wa ni Man U.
 Òun ni irú rẹ ̀ àkọ ́ kọ ́ tí yóò kọ ́ kọ ́ bẹ ̀ ṛ ̀ ẹ ̀ ifúfẹ ́ iṣ ́ ẹ ́ ̣ àgbéyẹ ̀ wò yìí nípa nollywood .
Naira Marley, Burna Boy àti Rema ló kó àmì ẹ̀yẹ tó pọ̀jù ló ni MVP Ẹranko abìjàwàrà tí kò ṣe é gbeńa wo ojú rẹ̀ ni Àmọ̀tẹ́kùn - Onímọ̀ A ṣetán láti gba obìnrin tó wà lóko ẹrú ní Lebanon sílẹ̀ - Ìjọba Kwara Ọlọ́pàá Uganda rí ohun ìpara olóró nínú ‘baby’ tí ẹnìkan pọ́n sẹ́yìn bí ọmọ Bakan naa, wọn royin gẹgẹ bi Sheikh Isa Busuulwa to jẹ Imam Mọṣalaṣi ti Sheikh Mutumba ti n waasu pe wọn ti jawe lọ gbele ẹ fun un lati lee da abo bo ofin ẹsin Islam.
” Saulu dìde, òun ati Samuẹli bá jáde sí òpópónà.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Sextuplet: Àdúrà Ìbùkún ló kú lẹ́yìn ọmọ mẹ́fà yìí- Ifeoma Thelma àti Onyemaechi Chiaka Ilé iṣẹ́ tó ri si ètò ẹ̀kọ́ l'Abuja kò tí ì rànsẹ́ pé UNILAG ti ni Giwa tuntun Ó ti tó bi ọja mẹ́ta tí awuyewuye ti ń wáye lóri yíyọ giwa Fásitì Eko Tí ọ̀rọ̀ nááà sì ti dí gbọ́nmísi-omi ò tóo nípa oníruuru ìròyìn tó ń jáde láti ilé iwé ọhun.
Awon oluranlowo ti won fe gba awon eniyan to wa ninu ihamo ewu ijamba ina  naa sile, ni lati fo awon ogiri ile naa, ki won to raye wole.
Adeoye Ayoade to jẹ adari ajọ ọhun lo sọ ọrọ naa ninu ifọrọwerọ pelu BBC Yoruba.
Àwọn mejeeji yóo wá di ara kan?
< Muhammadu Buhari Ẹgbẹ oṣelu APC yoo mu gbogbo ilana ẹkọ to wa ninu eto Universal Basic Education Act wa si imusẹ lori eto igbaniwọole to dọgba laarin akọ ati abo ni ile iwe alakọbẹrẹ ati girama, pẹlu ipese eto ẹkọ to lamilaaka: awọn yoo lo ida marundinlogun owo isuna ọdọọdun si eto ẹkọ ki wọn ba le pese iranwọ ati idanilẹkọ to yanju fun awọn olukọ.
Ilé aṣofin Ondo fọwọ́ òsì júwe ilé fún aṣòfin mẹ́ta pé wọ́n tàpá sí òfin ilé Ìpínlẹ̀ Eko kéde ọ̀nà àbáyọ sí súnkẹrẹ-fàkẹrẹ ọkọ̀ lásìkò àtúnṣe afárá Third Mainland Wo ìgbẹ́sẹ̀ méjọ tí ilé aṣòfin ìpínlẹ̀ gbọdọ̀ tẹ̀lé láti yọ igbákejì gómìnà Àlàyé rèé lórí ìdí tí Magu àti awọn alága EFCC míràn ṣe bá ìtìjú kúrò nípò Ṣaaju ni alaga igbimọ amuṣẹya to n ri si ọrọ Covid-19 ni Naijiria, PTF, Boss Mustapha ti kọkọ sọ pe ipele awọn akẹkọọ kan yoo pada sẹnu ẹkọ wọn lọna ati gbaradi fun idanwo aṣekagba.
Tí wọn kò bá rí i tún ṣe, wọn á fi tuntun irú rẹ̀ ránṣẹ́ sí mi.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ilé ẹjọ́ dájọ́ ikú fún àwọn tó pa Tìmílẹ́hìn, akẹ́kọ̀ọ́ fásitì UNIOSUN l'Oṣogbo 4 Èrèlè 2019 Oríṣun àwòrán, Ope'biosu Àkọlé àwòrán, Oṣù kẹfà ọdún 2017 ni wọ́n ṣekúpa akẹ́kọ̀ọ́ fásitì UNIOSUN náà nílùú Òṣogbo Ile ẹjọ giga ipinlẹ Ọṣun kan to fikalẹ silu Oṣogbo ti dajọ iku fun awọn ọdaran mẹta kan ninu marun ti wọn fi ẹsun kan pe wọn lọwọ ninu pipa akẹkọ fasiti ipinlẹ Ọṣun kan ti orukọ rẹ n jẹ Ṣonibarẹ Timilẹhin.
“Tí kì í bá ṣe pé OLUWA tí ó wà lẹ́yìn wanígbà tí ọmọ aráyé gbógun tì wá,
Ọgbẹni Adikum ni APC ri ibo 36, 811 nigba Emmanuel Okewulonu ẹgbé oṣelu PDP ṣe ipo keji pẹli ibo 31, 903.
Loni to pe ọdun mẹtalelọgbọn ti ọmọ Giwa dagbere faye, ọpọ eeyan lo ṣi n daro rẹ ti wọn si n beere ẹni to wa nidi iku rẹ.
O dùn mí pé Buhari kò yàn mí sípò Mínísítà lẹ́ẹ̀kejì àmọ́ mò gbà kádàrá - Adebayo Shittu Dalung, Audu Ogbe, Shittu Adebayo àti Isaac Adewole kò wọlé Wọ́n gbé Akọ̀ròyìn ní Morocco lọ sílé ẹjọ́ lórí ẹ̀sùn àgbèrè àti oyún ṣíṣẹ́ PDP tá ko ìgbésẹ̀ Gómìnà Kwara lórí àwọn alága ìjọba ìbílẹ̀ Adebayo Shittu ni Ajimọbi da ilẹ̀ idasilẹ ẹgbẹ oṣelu APC ni nipinlẹ Oyo.
O ni eleyi ti ko le jẹ itẹwọgba ni bi oludije ba ṣe ayederu iwe ẹri lati dije fun ipo oṣelu.
Ẹ dúró ní ipò yín, pẹlu àṣíborí lórí yín.
Onimo ero Seyi Makinde ti gba iwe eri ‘mo di gomina’ lowo ajo INEC ni Ipinle
Won da awon marundogun yoku sile, ki won maa lo lalaafia.
04 si pari okoowo ni aago 14.
"Èèyàn mẹ́fà kú, 920 tuntun míràn tún lùgbàdì Coronavirus ní Naijiria Abẹ́rẹ́ àjẹsára Covid-19 yóò dé sí Nàìjíríà nínú oṣù kíní ọdún 2021 Irọ́ ni pé mò kò ""Palliatives"" pamọ́ sí ilé mí-Abike Dabiri-Erewa Loju opo rẹ ni Twitter lo kọ ọrọ yi si pẹlu bi ọwọja itankalẹ arun Covid-19 ṣe n peleke si ni Naijiria."
Ni South Africa, wọn ṣi n ṣe ayẹwo boya ọwọ tuntun ti Covid-19 yii n gbilẹ pẹlu arankan amọ wọn ṣaa mọ pe awọn eeyan ti ko dagba lo n ran ju.
Ere pari ni feere ti rẹfiri fọn fun aṣekagba idije ife ẹyẹ agbaye to waye ni papa iṣere Luzhniki ni Moscow, Russia.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ekiti 2018 Election:Irọ́ lásán ni ìgbẹ́jọ́ Fayemi tó jáwé olúborí 28 Sẹ́rẹ́ 2019 Oríṣun àwòrán, Google Àkọlé àwòrán, Ẹgbẹ́ òsèlú PDP lọ ilé ẹjọ́ láti tako ìdìbò tó gbé Kayode Fayemi wọlé gẹ́gẹ́ bí Gomina ìpínlẹ̀ Ekiti.
O ni nkan bii oṣu meji ni awọn ti n ṣọ ọ nitori pe o dabi ẹni pe oogun ti wọn n lo fun un ko ṣiṣẹ bi o ti yẹ.
Nínú ọ̀rọ̀ olupẹ̀jọ́ ijọ̀ba,ni ọjọru ọ̀sẹ̀ yii won fi arakunrin naa ti orukọ rẹ̀ njẹ́ Amaechi Fred O si atimole lodo awon olopaa ni ilu Bavaria.
Ìpàdé NLC àti ìjọ̀ba àpapọ̀ lórí owó osù tuntun forí ṣánpọ́n Díẹ̀ lára èrò àwọn eniyan Naijiria ni pé: Loju àwọn kan, wahala ni eleyii maa bi ninu ijọba to ba faaye gba awọn ologun lati maa ṣe ohun to wu wọn nigba to wu wọn.
Awọn asamọ ọrọ yii lo n se apejuwe itan igbe aye Olori Badrat Olaitan Aajoke Adeyemi, gẹgẹ bo se salaye loju opo Instagram rẹ, lasiko to n se ayẹyẹ ọjọ ibi rẹ.
Bàbá wọn náà kò ṣàì máa bá a wí.
O tun je ile-ise ti ijoba  apapo da sile  lati ro awon eniyan lagbara, ni eyi ti o wa lara ipinnu ati erongba  ijoba aare Muhammadu Buhari .
"Oríṣun àwòrán, Falz àti ileeṣẹ ọlọpaa Ninu ọrọ kan to kọ si ori ayelujara Twitter rẹ ati atẹjade to fi sita, Adeboye sọ pe ko si bi ""awọn ọmọbinrin wa yoo sẹ maa sọ asọtẹlẹ, tabi awọn ọmọkunrin yoo ṣe ma a riran, ti a ko ba jẹ ki wọn o wa laaye"" Háà, àṣé Pastor Adeboye kò léè dá èékánná ara rẹ̀ gé, àwọn ọmọ Nàìjíríà kan pariwo Wo bí àwọn jàndùkú ṣe yabò àwọn olùwọ́de #ENDSARS ní Alausa l'Eko àti Abuja Èèyàn 179 ló tún ṣẹ̀ṣẹ̀ ní àrùn Coronavirus ní Nàìjíríà Nàìjíríà bá RCCG, ìyá Folu Adeboye yọ ayọ̀ 70 RCCG: Pásítọ̀ Adeboye ṣáájú ìwọ́de àdúrà CAN lòdí sí ìpànìyàn ní Nàìjíríà Adeboye, ìmọ̀ràn rẹ láti dènà panṣágà tako àwọn obìnrin - Ọmọ Nàíjíríà Bakan naa ni atẹjade ti ọkan lara awọn oluranlọwọ pataki rẹ, Pasitọ Johnson Odesola, fi sita lorukọ ijọ naa."
Nítorí kí ni ẹ ṣe ń wá ọ̀nà láti pa mí?
Akọnimọọgba Emery fi kun ọrọ rẹ pe oun fẹ ki gbogbo agbabọọlu ikọ naa maa gbiyanju agbara wọn lati fakọyọ nigbakugba ti wọn ba lanfani lati ṣoju ẹgbẹ agbabọọlu Arsenal.
Oriṣiriṣi orilẹ-ede lo ti fi amọran lede fun awọn eeyan wọn lori awọn ohun ti wọn le ṣẹ ti wọn ba lugbadi arun naa tabi fara kan ẹni ti wọn funra si pe o ni arun ọhun.
Nítorí nígbà tí Dafidi ti sin ìran tirẹ̀ tán gẹ́gẹ́ bí ète Ọlọrun, ó sun oorun ikú, ó lọ bá àwọn baba rẹ̀, ara rẹ̀ rà nílẹ̀.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Sultan Sokoto kéde òpin àwẹ̀ Ramadan Ọ̀gá NIMASA tẹ́lẹ̀ fi ẹ̀wọ̀n ọdún 42 jura ìjọba Nàìjíríà ti kéde ìsinmi lọ́jọ́ Ìṣẹ́gun àti Ọjọ́rú Lẹyin-o-rẹyin ni o to han gbangba pe ọrọ naa ko ri bẹẹ rara.
Ẹni tí ó pè yín yóo ṣe bẹ́ẹ̀, nítorí pé olóòótọ́ ni.
Àwọn tí wọ́n lọ nìwọ̀nyí: Iṣimaeli, ọmọ Netanaya, Johanani, ọmọ Karea, Seraaya, ọmọ Tanhumeti, àwọn ọmọ Efai, ará Netofa, Jesanaya, ọmọ ará Maakati, àwọn àtàwọn eniyan wọn.
Láti ọjọ́ náà ni mo ti wà lójú kan báyìí ti n kò lè yí ara padà mọ́, n kò jẹun bẹ́ẹ̀ ni ebi kò pa mi bẹ́ẹ̀ ni n kò sì kú.
Bí Eliṣa ti rí ìṣẹ̀lẹ̀ yìí, ó kígbe pe Elija, ó ní, “Baba mi, baba mi, kẹ̀kẹ́-ogun Israẹli ati àwọn ẹlẹ́ṣin rẹ̀.
irin, oju- popo,ina mọna-mọna, ebute ọkọ oju  omi, ki a si tun wa ona miiran lati mu igbeeru
5bn Pẹlu bi ohun ati Garba Sheu ṣe tun tahun sirawọn yi, a ni ki a se akojọpọ iye igba ti Aisha Buhari ti tako ijọba ọkọ rẹ.
Nígbà tí àwọn ará Filistia dé ibi àfonífojì Refaimu, wọ́n dúró níbẹ̀.
Oòrùn bá yí pada nítòótọ́, òjìji sì pada sẹ́yìn ní àtẹ̀gùn mẹ́wàá tí ó ti sọ tẹ́lẹ̀.
“Nígbà tí OLUWA Ọlọrun yín bá mu yín wọ ilẹ̀ tí ó búra fún Abrahamu, ati Isaaki, ati Jakọbu, àwọn baba yín, pé òun yóo fun yín, ilẹ̀ tí ó kún fún àwọn ìlú ńláńlá tí wọ́n dára, tí kìí ṣe ẹ̀yin ni ẹ tẹ̀ wọ́n dó, 
Ó súre fun ẹ̀yà Dani pé:“Dani dàbí ẹgbọ̀rọ̀ kinniun, tí ó fò jáde láti Baṣani.
Oríṣun àwòrán, Mike Bamiloye Darasimi ni abigbẹyin, ọmọ kẹta fun idile oṣere Kristẹni Mike ati Gloria Bamiloye ti wọn jẹ gbajugbaja ninu awọn fiimu ẹsin Kristẹni ti awọn eeyan mọ si Mount Zion Films.
Ẹni to bori: Kenya Nigeria vs Ghana.
Tonile talejo lo peju sibi ibura-wọle fun gomina tuntun Ipinlẹ Ọṣun, Adegboyega Oyetọla ni papa iṣere ni Ilu Oshogbo.
Ijọba Ethiopian ti ni isẹ yoo bẹrẹ ni pẹrẹu lati si oju ọna to lọ lati Ethiopia lọ si ebute ọkọ oju omi  Eritrea to wa ni Assab.
Bẹẹ ni ọrọ ri lọjọru, ọjọkarun osu keji ọdun 2020 nigba ti tọkọ-taya tẹlẹ, Saheed Balogun ati aya rẹ tẹlẹ, Fathia Balogun dijọ se ọjọ ibi wọn.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Mo kàn máa ń lọ́ ayẹyẹ kiri torí ijó láì ṣe pé wọ́n pe mí ló sọ mí di DJ olórin Fuji nìkan' Mi ò to iṣẹ́ Regina Daniels rárá kí n tó fẹ́ ẹ láàrin ọ̀sẹ̀ mẹ́ta, mo sì tún le fẹ́ ìyàwó míì - Ned Nwoko Àyà mi já nígbà tí Ganduje rọ Sanusi lóyè Emir Kano tó fi Bayero síi, ṣùgbọ́n.
Samuẹli dáhùn pé, “Báwo ni n óo ṣe lọ?
Gbé ìgbésẹ̀ kí o kọ àjọ̀dún Òyìnbó.
Ọpọ awakọ ati awọn ero loju popo lo maa n huwa ti ko tọ laarin titi ati ni ẹgbẹẹgbẹ opopona.
Mohammed said that the feat could be easily achieved by bringing the nation’s TV advertisement market in line with global​ ​best practice.
Idije ile geesi(EPL, England) Manchester City 1-0 Tottenham
Oríṣun àwòrán, Reuters Ipinlẹ Eko ti isẹlẹ yi ti waye ko ni agbara tabi ipalẹmọ kankan ti wọn se kalẹ de aarun Ebola sugbọn igbiyanju Dokita Stella ko ipa ribiribi lati le dena aarun naa.
Akọroyin BBC to ṣe ibẹwo si ile rẹ fabọ jẹ ni pe wọn ti gbe aṣofin naa lọ si ọfiisi awọn ọlọpaa kogberegbe SARS fun ifọrọwanilẹnuwo.
20 Òkùdu 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Pẹlu bi awujọ agbaye ko ṣe ni ifọkantan to jọju ninu elo abẹrẹ ajẹsara, o daju pe ina igbogun ti awọn aisan kaisan lawujọ yoo jo ajorẹyin ni, gẹgẹ bii awọn onimọ ti ṣe kilọ.
Àkọlé àwòrán, Àwọn ará Ipinlẹ Osun ko ilu síta láti ṣe ajọyọ idajọ ile ẹjọ kotẹmilọrun tó gbade fun Gboyega Oyetola ti APC Àkọlé àwòrán, Dùndún, àkàrà tàbí ẹran díndín, ẹ mú tiyín níbẹ̀ BBC News, Yorùbá Ìdí tí ẹ fi le è nígbàagbọ́ nínú ìròyìn BBC Ìlànà Lílò Nípa BBC Òfin Àṣírí Cookies Kàn sí.
Ṣugbọn ẹ̀mí Ọlọrun kó sí mi ninu, ó sì gbé mi nàró; ó bá mi sọ̀rọ̀, ó sọ fún mi pé, “Lọ ti ara rẹ mọ́ ilé rẹ.
Nigba to n sọrọ lori ibasepọ rẹ pẹlu alawada miran lori ayelujara ti wọn n pe ni Cute Abiola, lizzy ni ọrẹ timọ-timọ oun ni ọmọkunrin naa, ti awọn si dijọ ma a n ṣe awada papọ lori ayelujara.
Macron da ẹgbẹ ti rẹ silẹ fun eto idibo to gbe e wọle ni ilẹ Faranse.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Akọ́mọlédè àti Àṣà lórí BBC Yorùbá: Kọ̀ síi nípa iṣẹ́ tí oúnjẹ ń ṣe lára níbí Idibo naa waye, nitori iwe ẹsun kan ti awọn ọmọ Naijiria to le ni ẹgbẹrun lọna igba (220,000) fi ọwọ si Awọn aṣofin naa n fẹ ki ijọba United Kingdom ṣe iwadii awọn ẹsun aṣilo agbara, ati awọn olori ijọba ni Naijiria to lọwọ si ipaniyan to waye ni Lekki nipinlẹ Eko.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: A kò ní fara mọ́ fífi àkókò ṣòfò lórí ẹjọ́ Sotitobire - Ìjọba Ondo Kò sí àníàní, Coronavirus ló mú ẹ̀mí Ajimobi lọ - Ìjọba Eko Wọ́n sún ìsìnkú Abiola Ajimobi di ọ̀la Satide Ìtàn ìgbésí àyé olóògbé Isiaka Abiola Ajimobi O ni Aarẹ Buhari to fi ṣe ọrẹ ti sọ di ọta, ti gbogbo ero rẹ lori ẹgbẹ oṣelu APC si ti jasi pabo.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Lilo ike rọb lẹẹkan n ṣakoba fun ayipada oju ọjọ ni agbaye ni Omíyalé gbẹ̀mí èèyàn méje, o tún ba dúkìá púpọ̀ jẹ́ Wo aláànú tó n wa ọkọ̀ tí wọ́n fi n gbé aláìsàn lọ́fẹ̀ẹ́ Kínni ife ẹ̀yẹ ti Tiger Woods gbà ní Augusta fi yàtọ́?
Koda, o tiẹ fi awo orin kan ki awọn obinrin to si sọọbu ọti tita, eyi ti awujọ tako.
Abrahamu gbé igi ẹbọ sísun náà lé Isaaki, ọmọ rẹ̀ lórí, ó mú ọ̀bẹ ati iná lọ́wọ́.
Naijiria gbojule owo epo rọbi fun ida marundinlaadọrin owo to n pa wọle, eyii to mu ki iye owo epo maa ṣakoso bi eto ọrọ aje rẹ yoo ṣe ri.
Amọṣa ninu iwe kan ti awọn iwe iroyin lorilẹede Naijiria gbe jade pe akọrin 'Orente' naa fi iroyin kan sita pe 'Ṣaaju ni ọdun 2018, mo ke si afẹsọna mi ọdun marun pe ko wa di iyawo mi.
Nítorí náà, Eli rò pé ó ti mu ọtí yó ni.
Ọrọ pọ ninu iwe kọbọ lori ayajọ ọjọ ọmọbinrin lagbaye lori ayelujara Twitter.
Àwọn ọmọ Harimu jẹ́ ẹgbẹrun ó lé mẹtadinlogun (1,017)
 O ni Ọba Akiolu ki i sẹ ẹlẹyamẹya tabi tabi korira ẹsin kan, pe gbogbo ẹya ati ẹsin ni wọn ko mọra gẹgẹ bi Ọba gidi.
"ko si iru igbinyanju kankan lati ibikibi ti yoo mu ki ijọba pahunda lori asẹ yi, bẹk si tun ni yoo di ẹsẹ fun ẹnikẹni lati maa fo opopona Ọja Ọba laibikita, ti a ko si tun ni faaye gba ikiri ọja lẹba oju popo ọja naa.
Baba Suwe: Gbajugbaja ati ilumọọka apanilẹ́rìn ín ni Babatunde Omidina, ti ọpọ eeyan mọ si 'baba suwe' lagbo adẹrinpoṣonu ninu sinima ni ilẹ Yoruba.
O ṣalaye pe inu oṣù kẹfa lawọn ṣẹṣẹ bẹ̀rẹ̀ sí ní lọ sí ìjọ́ tí iṣẹlẹ laabi yii ti waye.
’ Mo bá mu omi, ó sì fún àwọn ràkúnmí mi lómi mu pẹlu.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ifa Priest: ọdún mọ́kànlá ni mo fi ṣe iṣẹ́ agbejọ́rọ̀ kí n tó gbọ́ràn si Ifá lẹ́nu Bakan naa lo fikun pe ohunkohun to ba kan iran Yoruba lapapọ lo kan oun naa, ti eto to wa fun ipese aabo to peye naa yoo si mu ilọsiwaju ati idagbasoke ba awujọ ati gbogbo ọmọ ilẹ Kaarọ oojire lapapọ.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Afurasi kan fipá bá akẹ́kọ̀ọ́ UNILAG lò pọ̀, ó tún jí pátá rẹ̀ - Iléeṣẹ́ ọlọ́pàá Ekiti: Ìjọba gbé ìgbésẹ túntún láti fí ìyà jẹ ẹni tó bá bá ọmọdé lòpọ̀ Ìjì líle mú ẹ̀mí èèyàn 1000 lọ, odidi ìlú kan bàjẹ́ A gba ìwé ìpẹ̀jọ́ ₦200m lọdọ mọlẹbi Sugar - UCH Owó dé!
Meje ni awon ọdaran naa, ọkunrin mẹfa ati obinrin kan ti wọn gba lati tọju awọn ibeji ni gbogbo ọjọ mẹjọ ti wọn lo lakata awọn ajinigbe.
Nibayii, ijọba ti gbe igbesẹ lati ri wi pe arun naa ko tan kalẹ si ni ileewe naa.
Bakan naa si ni gbogbo igbiyanju lati ba awọn obi ati alakoso ile ẹkọ naa sọrọ ja si pabo lasiko ti a ṣe akojọpọ iroyin yii.
com Àkọlé àwòrán, Buhari ba ọkọ ati iyawo sajọyọ Yatọ si aarẹ Buhari ti iyawo rẹ naa ba kọwọ rin, nibi igbeyawo ọun ni a tun ti ri awọn jankanjankan bii Gomina Amosun ti ipinlẹ Ogun, Gomina Ajimọbi ti ipinlẹ Ọyọ, Gomina Rochas Okorocha ati bẹẹbẹẹ lọ.
Ilu Eko jẹ ibi ti sunkẹrẹ fa kẹrẹ ọkọ ti pọju ni Naijiria ti o si n ṣe akoba fun eto ọrọ aje ati idokowo.
 tí ogun bá sì wà , tí wọ ́ n bá ti ń lu ìlù náà , kí ó máa jà lọ láìwo ẹ ̀ nìyàn ni .
Ninu idije agbaye naa, eleyi ti iko agbaboolu Super Eagles je iko kinni ti o koko pegede fun idije ohun nile Afrika, ni won yoo maa waako pelu Argentina, Croatia ati Iceland.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Public Anger: Irú ọ̀rọ̀ wò láwọn olóṣèlú Nàìjíríà márùn ùn yí sọ tó mú ìbínú ará ìlú wa?
O difa fun bi wọn ṣe ṣe ikọlu sawọn oṣiṣẹ ajọ ẹsọ oju popo Naijiria, FRSC kan ti wọn rin irinajo lati ẹka ajọ naa ni Kebbi ati Sokoto wa si Udi.
tí OLUWA paláṣẹ fún Mose, ní orí òkè Sinai ní ọjọ́ tí ó pàṣẹ fún àwọn eniyan Israẹli láti mú ẹbọ wọn wá fún òun OLUWA ninu aṣálẹ̀ Sinai.
Lẹ́yìn náà, o gba aya rẹ̀.
Wọ́n lè sọ̀rọ̀ pẹlu ọpọlọpọ ìgboyà nípa igbagbọ tí ó wà ninu Kristi Jesu.
Ohun tí ẹ nílò ni ìfaradà, kí ẹ lè ṣe ìfẹ́ Ọlọrun, kí ẹ baà lè gba ìlérí tí ó ṣe.
O ni ko pẹ lẹyin eyi ni àwọn agbofinro fi ẹsẹ fẹẹ lẹyin ti awon alatilẹyin awọn oludije tutọ soke.
Aṣofin Ọbasa sọrọ yii nibi ipade apero
N kò gba ohun tí wọ́n sọ fún mi gbọ́ títí tí mo fi dé ìhín, tí èmi gan-an sì fi ojú ara mi rí i.
Láti ibẹ̀, ó tún bẹ̀rẹ̀ láti orí òkè títí dé odò Nefitoa, ó lọ sí apá ibi tí àwọn ìlú ńláńlá wà lẹ́bàá òkè Efuroni, ó wá pada sí apá Baala (tí a tún ń pè ní Kiriati Jearimu.
Dírẹ́bà ọkọ̀ yìí kò mọ ọkọ̀ wà dáadáa.
O ni Ojojumọ ni mo maa n sunkun nitori akọbi ati ọmọ kan ṣoṣo ti mo bi, ti wọn ji gbe."
Koda, awọn oniroyin ko sinmi lati maa kan sara si wọn fawọn igbesẹ ti wọn gbe lati koju arun yi.
awon omo orile ede won lati dibo lati ilu okeere, ko si eredi ti awon omo orile
Kì í ṣe àwọn nǹkan tí a lè fi ojú rí ni a tẹjúmọ́, bíkòṣe àwọn nǹkan tí a kò lè fi ojú rí.
Oga agba ohun so pe, laarin saa odun kan re, yoo sagbode-gba anfaani alekun itoju alaboyun ati sise ayewo eje won fun aarun HIV.
Ṣugbọn lati ọjọ ti wọn ti bi wọn, iya wọn ni ayọ nikan ni wọn n mu ba oun.
pelu aare orile-ede France, Emmanuel Macron, leni ti o ti figba kan tele benu
Imura rẹ yii lo ku ki gbogbo awọn alejo lasiko igbeyawo naa maa kọ Ha!
Tọkọtaya naa si ni wọn mọriri Emir fun bo se da si aawọ naa sugbọn aridaju ko tii wa pe Risikatu ti pada sile ọkọ rẹ.
Lasiko rẹ, ọpọ awuyewuye waye laarin awọn oloṣelu paapa awọn ti ile asofin agba to fi mọ awọn ajafẹtọmọniyan kan ti wọn jijọ wọya ija.
He played a key role in the actualization of the objectives of the Global Fund to fight AIDS, Tuberculosis and Malaria for which Nigeria enjoyed the support of Gates Foundation who made available funds that could be used to support its AIDS programme sometime in 2000.
Tunisia ni Super Eagles naijiria fi se ifajẹ ti wọn se ipo keta.
Nigeria COVID-19 cases: Abẹ́rẹ́ àjẹsára kò tíì sí fún COVID-19, síbẹ́ àwọn òṣìṣẹ́ kólẹ̀-kódọ̀tí ń fi ẹ̀mí wọn wéwu
Ní òdìkejì odò Jọdani, ní apá ìlà oòrùn Jẹriko, wọ́n ya Beseri tí ó wà ninu aṣálẹ̀ ní ilẹ̀ tí ó tẹ́jú sọ́tọ̀.
6m lórí ètò BBNaija torí pó sọ̀rọ̀ ìwúrí nípa Nàíjíríà Bí mo ṣe dúró ti Toyin nílé ìgbẹ̀bí jẹ́ kí ń mọ̀ pé ó yẹ kí ọkùnrin máa bọ aya wọn - ọkọ Toyin Abraham Ìjíròrò forí ṣánpọ́n lóri sísan owó oṣù tuntunÌdí rèé tí mi ò fi yọjú sí ìgbìmọ̀ àjọ PFN- Fatoyinbo SERAP ni iwe naa ni yoo ṣafihan orukọ awọn gomina ipinlẹ atawọn eekan ijọba miran, ti ile ẹjọ ti da lẹbi fun ẹsun ikowojẹ, bẹrẹ lati ọdun 1999.
Ọmọ ìbílẹ̀ Giriki ni obinrin yìí, a bí i ní Fonike ní Siria.
Nigba ti Okon n jabo oro ti komisona awon olopaa ni ipinle Borno  so , pe, awon olopaa ipinle naa ko ni kaaare lati daabobo dukia ati emi awon eniyan ipinle naa.
Ko si ani-ani pe iṣoro igbọnsẹ pọ lorilẹ-ede Naijiria, paapaa julọ lawọn ẹsẹ pupu.
O ní títí lae ni yóo di ahoro.
Earlier this year, a baby dugong in Thailand died after eating plastic.
Ọmọ ti lọ kí baba, Fayemi bẹ Aláàfin wo l‘Ọyọ, wọ́n jírórò lórí lẹ́tà Àwọn ọba Yorùbá kan rèé tí wọ́n rọ̀ lóyè, tí ọba míràn jẹ lójú ayé wọn Sááju ki wọ́n to ri ẹni kẹta yìí ni ìjọba apapọ ti sọ pe oun ko ni fofinde ẹnikẹni lati ilẹ̀ òkèrè to fi mọ àwọn ibi ti ààrun Coronavirus pọ sí Oloriegbe wá fi kún pẹ lẹ́yin ti wọ́n ba fòfin dè wọ́n, kí àwọn Naijiria náà ko gbọdọ rìnrin àjò lọ si àwọn orilẹ̀-èdè ti ààrùn náà ti n ṣọṣẹ.
OLUWA wí fún mi pé, “Ìlẹ̀kùn yìí yóo máa wà ní títì ni, wọn kò gbọdọ̀ ṣí i; ẹnikẹ́ni kò sì gbọdọ̀ gba ibẹ̀ wọlé, nítorí èmi OLUWA, Ọlọrun Israẹli, ti gba ibẹ̀ wọlé.
u kuro lati isale wa si oke , ti o si di eniyan pataki lawujo, ti o tun je ki
Ọlọ́pàá Sharia Kano mú èèyàn tó lé ní 80 tori oúnjẹ nínú ààwẹ̀ Àwọn àdúgbò Ibadan gborúkọ tuntun látẹnu Ajimobi Ni bayii, minisita yoo kuro lori alefa ni nkan bi ọsẹ meji.
Gẹ́gẹ́ bí àṣà Yorùbá, àti bí olùgbani nímọ̀ràn Ọba lórí ìròyìn ṣe sọ ọ́, gbogbo ètò tó yẹ sájájú mímú olórì tuntun wọ ààfin ni wọ́n ti ṣe.
Ìròyìn fi ìdí rẹ̀ múlẹ̀ pé, Nyantakyi n lo orúkọ Ààrẹ Akufo-Addo tó fi mọ́ ti igbákejì rẹ̀, àti àwọn òṣìṣẹ́ àgbà lẹ́nu iṣẹ́ ọba, láti fi fa ojú àwọn olùdókòwò mọ́ra, láti fi gba ọ̀pọ̀lọpọ̀ mílíọ́nù Dọ́là lọ́wọ́ wọn.
Èmi a máa fi ẹ̀ṣẹ̀ baba bi ọmọ, títí dé ìran kẹta ati ẹkẹrin lára àwọn tí wọ́n kórìíra mi.
Fun raa mi ni mo si bi wọn lai lo iṣẹ abẹ.
Bí wọ́n bá tẹ ẹran kan lọ́dàá, tabi bí kóró abẹ́ rẹ̀ bá fọ́, tabi tí abẹ́ rẹ̀ fàya, tabi tí wọ́n la abẹ́ rẹ̀, tabi tí wọ́n ṣá a lọ́gbẹ́ ní abẹ́, ẹ kò gbọdọ̀ mú un wá fún OLUWA, tabi kí ẹ fi rúbọ ninu gbogbo ilẹ̀ yín.
Oríṣun àwòrán, EPA Àkọlé àwòrán, Bianca nigba to lulẹ ninu idijeẹ lọdun to kója.
” Samuẹli sì ṣe ìdájọ́ àwọn eniyan Israẹli ní Misipa.
Ó dí ojú òṣùpá,ó sì fi ìkùukùu bò ó.
I am deeply honoured by this gesture and I appreciate everyone who made this testimonial match a reality; the organisers, the players, all the people who came to watch  and all Lagosians.
Hananaya bí ọmọ meji: Pelataya ati Jeṣaaya, àwọn ọmọ Refaaya, ati ti Arinoni, ati ti Ọbadaya, ati ti Ṣekanaya.
Ẹ sì mọ̀ pé Jesu wá láti kó ẹ̀ṣẹ̀ lọ, bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé òun alára kò dá ẹyọ ẹ̀ṣẹ̀ kan.
" O wa rọ ijọba lati mu ipese awọn ohun elo amayedẹrun fun araalu nibaada, ko si pese iṣẹ fun awọn ọdọ, eyi ti yoo mu ko rọrun fun wọn lati tete yanju isoro lasiko to ba de.
O ni o le ni ida ọgọta ninu ọgọrun un awọn akẹkọọ ti JAMB maa n fun ni ọna igbaniwọle kẹkọọ lọdọọdun.
 díẹ ̀ lára àwọn àdúgbò wọ ̀ nyí wà ní ifẹ ̀ , fún àpẹrẹ , oríyangí , mòọ ̀ rẹ ̀ , Òkè-Ẹ ̀ ṣọ ̀ , àti Òkèèsodà .
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù NURTW: Yasin ní àbẹ̀wò òun sí Makinde dá lórí ọ̀rọ̀ ẹgbẹ́ awakọ̀ èrò tó fòfin dè 14 Òkùdu 2019 Oríṣun àwòrán, Seyi Makinde Ààrẹ àpapọ̀ fún ẹgbẹ́ àwọn awakọ̀ lorílẹ̀-èdè Nàìjíríà (NURTW), Alhaji Nojeem Yasin tí fí ọkàn àwọn awakọ ìpínlẹ̀ Ọyọ́ balẹ̀.
Bóò ṣe lè yẹra fún ikú nígbà òjò - Onímọ̀ Ehi Iden Ààrẹ Muhammadu Buhari buwọ́lu owó ìṣúná ọdún 2019 Aisha Buhari ké gbàjare pé ètò ìjọba Buhari kò ṣànfàní f'óbìrin Kò sí àyè fún fíìmù eré ìfẹ ṣíṣe ni Kannywood mọ́ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Contortionist: Mo lè gbé ìfun mi pamọ́ ki n tún se èémí!
O tun ni ọpọ wọn lo fẹ wọ ileewe giga bii fasiti ṣugbọn ti ko si owo, iṣejọba mi yoo ran wọn lọwọ""."
Saaju, lasiko  abewo gomina ati oga agba ile-ise Paxherbal Fr.
DJ Switch lo sọ ọrọ naa ninu fidio to fi lede loju opo Instagram rẹ.
Solomoni jókòó lórí ìtẹ́ OLUWA gẹ́gẹ́ bí ọba, dípò Dafidi, baba rẹ̀.
Nìgbà bá bẹ̀rẹ̀ sí ní yípadà fún àwọn ènìyàn.
FCT àti Rivers ní mẹ́wàá, nígbà tí ìpínlẹ̀ Kwara ni èèyàn mẹ́sàn-án, ti Delta ati Kaduna ṣe ni márùn-ún, Sokoto ati Oyo ní mẹ́rin, bákan náà ni Kebbi, Nasarawa àti Osun ni mẹ́ta, Ondo si ni èèyàn mẹ́jì.
Lodun 1974 ti wọn fẹ kopa ni wọn tun yọwọ ninu idije.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ghana election: Ààrẹ Akufo-Addo la Mahama mọ́lẹ̀ wọlé ìbò ààrẹ Ghana fún sáà kejì 9 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Oríṣun àwòrán, Facebook/Nana Akufo-Ado Aarẹ orilẹde Ghana, Nana Akufo-Addo ti wọlẹ ibo aarẹ ilẹ fun saa keji.
Àwọn Olórí ìdílé wọn nìwọ̀nyí: Eferi, Iṣi, Elieli, ati Asirieli; Jeremaya, Hodafaya ati Jahidieli, akikanju jagunjagun ni wọ́n, wọ́n sì jẹ́ olókìkí ati olórí ní ilé baba wọn.
Ohun to yẹ ko mọ nipa D.
Fetí sí ọ̀rọ̀ mi, OLUWA;kíyèsí ìmí ẹ̀dùn mi.
Ọmọkùnrin tó ya 'Blue film' nínú igbó Osun Osogbo ti bayé ara rẹ̀ jẹ́ - Yemi Elebuibon Ọwọ́ tẹ èèyàn kan pẹ̀lú orí ọmọdé nílé aṣòfin àpapọ̀ Afurasí kan yin Oloruntoba níbọn nítorí èdèàìyedè nílé oní Sharwama Ọga patapata ajọ naa Boboye Oyeyemi sọ pe awọn ti fi ọrọ yi to awọn agbofinro leti ki wọn baa le tete doola ẹmi awọn oṣiṣẹ wọn ti wọn jigbe.
Àwọn olùgbé ìlú náà àtàwọn ọlọ́pàá fí àrídájú hàn wípé wọn kò tíì mọ iye ènìyàn tó bá ìsẹ̀lẹ̀ náà rìn.
Bi o tilẹ jẹ pe awọn ijọba ipinlẹ ti kede pe eto ti to ni sẹpẹ nipa idena arun Coronavirus lawọn ibudo ti idanwo yoo ti waye, sibẹ ọkan awsn eeyan kan ko balẹ.
Bẹẹ, eewọ ni ki wọn na ọpa si ọba.
Bẹ́ẹ̀ni, wá sí ọ̀dọ̀ èmi Olùgbàlà rẹ.
Kí gbogbo rẹ̀ lè dọ́gba, ọjọ́ kẹjọ ni à ń sọ ọmọ lórúkọ ní ibi púpọ̀ ilẹ̀ Yorùbá.
Ninu ọrọ rẹ, o ni o san ki awọn ijọba fun awọn ọmọ yi ni ẹkọ iwe igbalode ju ki wọn ma rin kaakiri titi.
Jesu dáhùn pé, “Mo fẹ́ kí ẹ mọ̀ dájúdájú pé, kò sí ẹnìkan tí ó fi ilé tabi arakunrin tabi arabinrin, tabi ìyá, tabi baba, tabi ọmọ, tabi ilẹ̀, sílẹ̀ nítorí mi ati nítorí ìyìn rere, 
Ọmọ Nàìjíríà mẹ́jọ gba ìdájọ́ ikú ní UAE Kelechi Iheanacho, Wilfred Ndidi yóò jọ du àmì ẹ̀yẹ Leicester City O ni kia ni awọn oṣiṣẹ oun kan sagbami iṣẹ ti wọn ti pese gbogbo iranwo ilera fun ẹlẹwọn naa.
” Àwọn ọkunrin náà lọ ṣe amí ìlú Ai.
Ṣebí tibi tirẹ la dálé ayé .
Gbogbo igbesẹ ati wa nkan ṣe sii kan tun bi afikun ọkọ ti awn eniyan ra ti wọn forukọ rẹ silẹ.
Orilẹ-ede naa si ni ẹgbẹ ajijangbara naa ti ṣe ikọlu julọ.
 alaga ayẹyẹ naa ni amòfin àgbà tí a n pè ní wole olanipekun .
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ekiti Election: Àkójọpọ̀ àwòrán bi idibo se n lọ ni Ward ati Unit 12 Agẹmo 2018 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 14 Agẹmo 2018 Ètó gbogbo ti n lọ ní ìdìbò gómìnà tí oun lọ lọwọ ni ìpínlẹ̀ Ekiti lọ́jọ́ Satide, Ọjọ Kẹrinla, ọdun 2018.
Ironu ati oti amupara lo ba finra saaju iku re ki o to di ero ile iwosan nibere osu yii ni Los Angeles.
ati pẹpẹ idẹ ati ààrò idẹ rẹ̀, àwọn ọ̀pá rẹ̀ ati gbogbo ohun èlò rẹ̀, agbada idẹ ati ìtẹ́lẹ̀ rẹ̀.
Ìwé Mímọ́ sọ pé, “Kò sí ẹnikẹ́ni tí ó bá gbà á gbọ́ tí ojú yóo tì.
Ẹ má bọwọ́ kí ara yín mọ́, ìkúùkù ni kẹ fi lu àyà torí Coronavirus kọjá bẹ́ẹ̀ - Aregbesola Oríṣun àwòrán, Bayo Omoboriowo Minisita fọrọ abẹle lorilẹede naijiria, Rauf Arẹgbẹsọla ti n laago ikilọ tan tan tan fawọn ọmọ Naijiria pe ki wọn mase bọ ara wọn lọwọ lasiko yii nitori arun Coronavirus.
Ni idakeji, arabinrin Ọlawale Ọnabajo lòdì sí koko ọrọ arabinrin Adepeju pe ọkunrin ni ko maa san owo ile iwe awọn ọmọ wọn.
Lori ajakale arun Coronavirus ati ọrọ aje agbaye to dagun eyi ti ko yọ South Africa to wa silẹ, agba Inaki ni ijọba ilẹ naa ti ṣeto owo iranwọ fun awọn olokoowo alabọde lati se gbera sọ, bẹẹ lo ni ko fẹẹ si alaini ti kó ri ọwọ ijọba nibẹ.
di dandan ki ọkan tẹ , iko agbabọọlu Super Eagles ti orile ede Naijiria ti
"Oríṣun àwòrán, Screenshot/ronkeodusanya/instagram O ni ""mo le gbeja ara mi, ṣugbọn mi o fẹ ki ọmọ mi dagba tan, ko ma a ka iru iroyin radarada, ti ko ni ootọ kankan ninu."
Oyedepo àti ìjọba ń tahùn síra lórí bí ìjọba ṣe ń gba àkóso àwọn ilé ìjọsìn Ìjọba àpapọ̀ ní kó lọ dá orilẹ̀èdè tiẹ̀ sílẹ̀, bí kò bá ní tẹ̀ lé òfin Oríṣun àwòrán, @DavidOyedepoMin Ọkan lara awọn amugbalẹgbẹ aarẹ Muhammadu Buhari Lauretta Onchie ti bẹnu atẹ lu ọrọ kan ti oludasilẹ ati adari ijọ Winners Chapel, Bisọọbu David Oyedepo sọ, lori ofin tuntun ti ijọba gbe kalẹ fun awọn ijọ.
ofurufu  ni awon ekun ile Afirika ko kere.
Kini nkan ti obìnrin tó bá fẹ́ lọ bímọ nílé ìwòsàn yẹ kí o gbé dání?
"Àjẹsára meningococcal jẹ ́ èyíkèyí àjẹsára tí a fi ń dáàbò bo ara ẹni lọ ́ wọ ́ àkóràn kòkòrò àìlèfojúrí afàìsàn kan tí à ń pè ní "" neisseria meningitidis "" ."
Oríṣun àwòrán, @Bashir Kí làwọn nǹkan tó lè rán ọkùnrin sí ọ̀run alákeji lásìkò ìbálòpọ̀ pẹ̀lú obìnrin?
Igba wo ni Seyi ri Tacha gbẹyin?
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Lẹ́yìn ọdún mẹ́tàlélọ́gbọ̀n; àwọn èèyàn sí n bèèrè pé: Ta ló pa Dele Giwa?
Awọn eniyan ti isẹlẹ naa soju rẹ wipe ija naa bẹ s'ilẹ laarin awọn ẹgbẹ OPC ti wọn pe ara wọn ni New Era Faction ti OPC ati awọn ẹya miran ti wọn durosinsin lẹyin Aarẹ Ọnọ Kakanfo tuntun, oloye Gani Adams.
Oríṣun àwòrán, AFP Ile ijọsin Fountain of Praise yii ni wọn gbe oku Floyd si nibi ti awọn abanikẹdun jorajọ si.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Akure Church Kidnap: Òbí ọmọ tí wọ́n jígbé àti asọ́nà ṣọ́ọ̀ṣì 14, lọ́ búra nì'dí imọlẹ̀ l'Akure 28 Bélú 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 29 Bélú 2019 Idi imọlẹ abalaye ni aafin Ọba Deji ti Akure ni iya ọmọ, baba ọmọ ọdun kan ti wọn jigbe ni ilu Akure ni ipinlẹ Ondo pẹlu awọn aṣona ṣọọṣi mẹrinla ile ijọsin ti wọn ti ji ọmọ gbe.
O ti le ni ọdun mẹwa, ti awọn ọmọ ikọ Boko Haram ti n ṣiṣẹ ni Ila oorun Ariwa Naijiria, paapaa ni ipinlẹ Borno ati awọn to yi i ka.
Àkọlé àwòrán, Ibeji ati Idowu wọn di ero ilé iwosan ni Bariga Ogbẹni Kabiru ni oun ti fẹ ko kuro ninu ile naa tẹlẹ nitori pe ojoojumọ ni ibi kọọkan n ya ti iho n han nibẹ ti ile naa si n sọ òkò ifura.
Ayo Ọpadokun ni, ó ti pẹ́ ti àwọ́n ti ń bèèrè fun JUne 12 gẹ́gẹ́ bi àyájọ ọjọ́ ìjọba awa ara wa, nítori pe ọjọ náà ni gbogbo Nàìjíríà gbà pé ìdìbò àwọn ló gbé Abiola wọle.
Onimọ nipa ihuwasi eniyan, Racheal Olaniyan lasiko to n ba BBC Yoruba sọrọ sọ nipa awọn ohun ti o ma n mu ki awọn eniyan ṣe aṣemaṣe lasiko idanwo.
Lara awọn oun to gbọdọ wa ninu lẹta naa ni ibi ti oloogbe naa gbe titi ọlsjọ fi de, ohun to ṣokunfa iku rẹ, ati ẹjẹ lati ọdọ awọn mọlẹbi lati tẹle gbogbo ofin ti ijọba gbe kalẹ lori ilana oku sinsin lati dena ajakalẹ arun coronavirus ni ipinlẹ naa.
Angẹli Oluwa kan bá yọ sí i, ó dúró ní ẹ̀gbẹ́ ọ̀tún pẹpẹ turari.
Ọ̀gá rẹ̀ yóo wá nà án, yóo fi í sí ààrin àwọn alaiṣootọ.
3 Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold 4 Ọjọ́ orí wo ló yẹ kí ikùn ẹ̀dá bẹ̀rẹ̀ sí tóbi?
Sunday Shodipe: Ilé ẹjọ́ fi Sunday Shodipe, afurasí ìṣekúpani l'Akinyele pamọ́ sí ọgbà ẹ̀wọ̀n
Ṣebi aileja lojude ile baba mi ko de bi.
O ni isu mẹrin pere ni oun lee se ni ere alaworan ninu itan naa, to si n kesi awọn onileesẹ nlanla atawọn eeyan to nifẹ agbega asa ati ede Yoruba lati dide, se iranwọ owo fun oun, ki isẹ naa lee pari.
Ijoba ti ajo isokan orile-ede agbaye n se atileyin fun lorile-ede naa ti o wa ni ilu Tripoli ti so pe, eto idibo yoo waye ninu odun ti a wa yii, igbese ohun ni atileyin ni kikun ajo-isoka UN, orile-ede America ati awon egbe miiran.
Ìkéde ìjọba àpapọ̀ pé àkẹ́kọ̀ọ́ kò ní ṣe ìdánwò WAEC yàtọ̀ sí àdéhùn wa - ANCOPSS Ǹjẹ́ o mọ̀ pé irú àwọn ìnàkí yìí wà ní Nàíjíríà?
Mercy Aigbe Awọn oṣiṣẹ eleto ilera ni Mercy Aigbe gboṣuba rabandẹ fun ni tiẹ.
Iṣẹ ti iya-iya-iya rẹ kọ ọ ni ti wọn si fi le e lọwọ ni ti oun naa ko si jẹ ko parun.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Coronavirus lockdown Kayeefi: Àkójọpọ̀ ìṣẹ̀lẹ̀ tó yanilẹ́nu lásìkò àjàkálẹ̀ ààrùn Covid-19 Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Coronavirus lockdown Kayeefi: Àkójọpọ̀ ìṣẹ̀lẹ̀ tó yanilẹ́nu lásìkò àjàkálẹ̀ ààrùn Covid-19 24 Ìgbé 2020 Ara ọtọ ni eto Kayeefi BBC ba de l'oṣu yii, nitori pe oriṣiriṣi iṣẹlẹ agbọ damiẹnu la mu wa fun yin.
Amọ ohun to da wa loju ni pe adirẹsi ilu Eko ni awọn ileesẹ aje ayaba naa wa, to si daju pe ilu Eko ni olori naa ti n ri taje se.
Wọn ni ilẹ naa wa lara awọn ilẹ to wa labẹ akoso idile ọmọọba Osu ni agbegbe naa.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Aare Buhari n fẹ ojutu si aawọ abẹle ninu APC O ṣalaye pe 'ẹni ti yoo ba pari aawọ gẹgẹ bi iṣẹ ti wọn gbe fun Tinubu, oun gaan ko gbọdọ maa ni ija pẹlu awọn ọmọ ẹgbẹ.
Nàìjíríà àti Ghana léwájú nínú wíwá òògun ìsẹ́yún Kíni ìdí ti wọn fi ń lọ ọmú obinrin Àwọn arẹwà obinrin Yollywood, tá ló mọ iṣẹ́ rẹ̀ jù?
Awọn ọmọ ikọ Boko Haram maa n jo ile, pa eeyan bo se wu wọn, wọn n ji eeyan gbe gba owo, ti wọn ko si mọ ọmọde tabi agba, koda, eremọde ni ado oloro jiju jẹ fun wọn.
Olùbádàmọ̀ràn pàtàkì fún ààrẹ tún fi kún pé ìjọba àpapọ̀ ń mójú to àwọn ìpèníjà míràn tó ń jẹyọ láti ẹ̀yìn odi orílẹ̀-èdè yìí.
Wọ́n ní kí a lọ sí ẹ̀hìnkùlé, ó rẹ àwọn púpọ̀, àwọn sì fẹ́ lọ sinmi.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Awọn ọmọde n jo, wọn fo fáyọ̀.
Àgàgà lọ́dọ̀ àwọn ará Pakistan àti India.
“Bí mààlúù bá kan eniyan pa, kí wọ́n sọ mààlúù náà ní òkúta pa.
nigba ti mo wo oju rẹ, mo ro o wi pe ki a gba owo naa.
Ìwadìí ti bẹ̀rẹ̀ lórí àrá tó sán pa òṣìṣẹ́ FRSC mẹ́ta nípínlẹ̀ Ogun- Ọ̀gá àjọ FRSC Ohun tí a mọ̀ nìyí nípa ìròyìn Ajimobi kú, kò kú, táyé ń gbé kiri Invictus Obi, Hushpuppi, àwọn ọ̀dọ́ Nàìjíríà méjì tí ẹ̀sùn gbájúẹ̀ wà lọ́rùn wọn Ọ̀rọ̀ ńlá, àwọn adigunjalè ja àgọ́ ọ́lọ́pàá lólè Ni ipinlẹ Eko, Gomina Akinwumi Ambode ati agbaọjẹ oloselu ipinlẹ naa Ahmed Bola Tinubu to faa kalẹ gẹgẹ bi Gomina, pada gbena woju ara wọn.
àwọn tí o parun ní Endori,tí wọ́n di ààtàn lórí ilẹ̀.
Iforukọsilẹ fun iwe irinna: Ajọ to n risi iwọle-wọde ni Naijiria ti sọ ọ di dandan fun ẹnikẹni to ba fẹ ẹ gba iwe irinna pasipọọti tuntun, tabi tun ti akọkọ ṣe, gbọdọ ṣe afihan NIN rẹ ko to o di ṣisẹ.
Rabi, to jẹ iyawo ile sọrọ yii nigba ti ileeṣẹ ọlọpaa ipinlẹ Katsina ṣe afihan rẹ lọjọ Iṣẹgun, pẹlu afikun pe oun ko mọ pe ọkọ oun le gba idi aawọ naa dero ọrun.
Pẹlu ipá ni Solomoni ọba fi kó àwọn eniyan ṣiṣẹ́, tí ó fi kọ́ ilé OLUWA ati ààfin rẹ̀, ó sì kọ́ Milo, ati odi Jerusalẹmu, ati ìlú Hasori, ìlú Megido ati ìlú Geseri.
Iyabo Ojo: Ìjà òṣèré tíàtà nìkan kọ́ nìkọlù South Africa, ti gbogbo wa ni
Ohun ni wọn yoo maa fi ṣe ayẹwo kiri.
Botilẹjẹ pe iṣẹlẹ yii ti da ibẹru silẹ, ijọba sọ pe oun ko ni i titori eyi da awọn baalu to n wọle lati okeere duro.
Àgbò tí ẹ fi ń rú ẹbọ sísun sí mi ti tó gẹ́ẹ́;bẹ́ẹ̀ náà sì ni ọ̀rá ẹran àbọ́pa.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Bakan naa ni ipinlẹ Plateau, gomina Simon Lalong ti kede pe gbagbagba ni oun n se atilẹyin fun agbekalẹ abule Ruga nitori igbesẹ naa yoo mu opin de ba aawọ to maa n fi ojoojumọ waye laarin awọn agbẹ ati darandaran yika orilẹede yii.
Wọn bẹrẹ igbese bi o ṣe kọ ọkọ rẹ silẹ ile ẹjọ si fun wọn lasẹ lati lọ se igbeyawo wọn Saaju ni Osadebe ri ta gbogbo nkan ini wọn ni Eko.
 Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Oyenusi ló mú mi wọ ẹgbẹ́ adigunjalè kó tó di pé mo b'Ólúwa pàdé' Pipada to pada sinu ile, ni ọkan lara awọn ti wọn jọ n gbele, fi ẹsun kan an pe Iya Muiz, ṣe ẹyin kọ lẹ gbe ọmọ ju si akitan ni?
Àwa tí a wà ninu àgọ́ ara yìí ń kérora nítorí pé ara ń ni wá, kò jẹ́ pé a fẹ́ bọ́ àgọ́ ara yìí sílẹ̀, ṣugbọn àgọ́ ara yìí ni a fẹ́ gbé ara titun wọ̀ lé, kí ara ìyè lè gbé ara ikú mì.
Ọlọrun ní, “Mú Isaaki ọmọ rẹ kan ṣoṣo tí o fẹ́ràn, kí o lọ sí ilẹ̀ Moraya, kí o sì fi ọmọ náà rú ẹbọ sísun lórí ọ̀kan ninu àwọn òkè tí n óo júwe fún ọ.
Badagry ní ogún àjogúnbá tó pọ̀ yàtọ̀ sí òwò ẹrú
O tèsíwájú nínú atẹjade náà :''o ti fojú hàn pé ìgbésẹ tí a gbé láti kéde ìyípadà àṣìṣe ti awọn kan ṣé ló n biwon nínú nipasẹ ètò ìdìbò ti ará ìlú gba pé òhun lo yanranti julọ.
 “Bo tile je pe ,won n gbe  ekunwo owo osu yii n lọ si ile igbimo
Ile ẹjọ ni agbofinro Austine huwa buruku yii lasiko to n ṣayẹwo ohun ini awọn eeyan lọna aitọ ni agbegbe Durban ti Okoli n gbe.
Ó sì jẹ́ ìṣòro tí ó ń ro ti ìbáṣe láàárín tọkọtaya – ìṣòro àtilẹ̀wá ni.
Ko si eni ti yoo dun ikooko mo enikankan, eleyii ki i se isẹ wa.
Ìràwọ̀ òṣèrée soca Machel Montano, ẹni tí ó ṣe ojúkòkòrò jáwé olúborí nínú Ìwọ́de Ojúnà ní ẹ̀rìnmẹ́sàn-án, ṣe àpèjúwe rẹ̀ gẹ́gẹ́ bí “orin tí ó máa ń mú àwọn ènìyàn ní ìdùnnú  àti tí máa ń mú àwọn ènìyàn jáde nínú ara wọn”  akọrin wo ni kò ní fẹ́ gba irú oyè bẹ́ẹ̀?
Ibo ẹgbẹrun mẹta ati ọdunrin o le mọkandinlaadọrin ni Yahaya fi bori awọn oludije mẹsan miran ti wọn jọ sa ere ije naa eyi to waye nilu Lọkọja.
Wo ìdí tí ètò ìdìbò gómìnà ìpínlẹ̀ Edo ṣe lọ ní ìrọwọ́-rọsẹ̀ Asiwaju BolaTinubu sọ̀rọ̀ lóríi ìròyìn ẹlẹ́jẹ̀ pé òun gbà pé APC fìdí rẹmi ní Edo Wo bí Sunday Shodipe ṣe pa Funmilayo tó pa kẹ́yìn l' Akinyele Ọlọ́jọ́ Festival 2020:Ọ̀ọ̀ni ti Ilé Ifẹ̀ tí wọ ìléèdí ọlọjọ méje tí kò ní rí ẹnikẹ́ni sójú Oríṣun àwòrán, SMES SURVIVALFUNDNG Bakan naa, wọn ni isọri awọn ti yoo kọkọ jẹ anfani rẹ ni awọn ileewe.
Victor Taiwo to sọrọ nibi ifilọlẹ to waye ni ilu Ibadan naa ni ilẹ Yoruba nilo idagbasoke.
Aiyé daiyé òyìnbó 🙂  Nítorí ìgbésí aiyé alákọ̀wé yàtọ̀ sí ti àtijọ́, àti pé jíjí tí wọ́n njí lọ ibiṣẹ́ lójoojúmọ́ ò fààyè sílẹ̀ fún ilẹ̀ gbígbá.
2 mílíọ́nù owó ìtanràn Àjẹ́ àti Aṣẹ́wó ní ìyá Rainbow - Òjòpagogo Cardi B ṣàlàyé ohun tó gbé fọ́tò ìhòhò rẹ̀ d'órí ayélujára Instagram Dokita Tokunbọ Dosunmu ṣalaye fun BBC pé Arabinrin Tola Oyediran Awolowo ko ṣaarẹ rara ki ọlọjọ to de.
Àkókò pípa wà, àkókò wíwòsàn sì wà,àkókò wíwó lulẹ̀ wà, àkókò kíkọ́ sì wà.
"Àkọlé àwòrán, Owo ori epo to gbẹnu soke ti se akoba fun owo ori ọja pẹlu Lara awọn ohun ti wọn kọ si ara patako ti wọn gbe dani ni awọn ọrọ bii, 'Aarẹ tẹti si awọn awakọ', "" Kii se ileri too se fun wa niyi', ati 'Aarẹ, ẹ din owo yi ku."
Ìtànṣán ògo OLUWA wọ inú Tẹmpili láti ẹnu ọ̀nà tí ó kọjú sí ìlà oòrùn.
Oríṣun àwòrán, @ife Àkọlé àwòrán, Awọn Olobatala naa n ṣọdun wọn lasiko wọn.
Jesu wí fún un pé, “Mo fẹ́ kí o mọ̀ dájúdájú pé, ní alẹ́ yìí kí àkùkọ tó kọ ní ẹẹmeji, ìwọ náà yóo sẹ́ mi ní ẹẹmẹta.
Ẹ̀yin ọmọ Israẹli, ẹ ní ìrètí ninu OLUWA!
Awọn miran tilẹ gboriyin fun Mamman Daura wipe, otitọ ọrọ lo sọ nitori sise ipo aarẹ ni ẹlẹkunjẹkun ti sakoba fun wọn, ti ko si mu idagbasoke dani.
- Amina Zakari Kíni ìwọ mọ̀ nípa Funmilayọ Ransome-Kuti?
“Èyí ni òfin tí ó jẹmọ́ ẹbọ ohun jíjẹ.
Nitori naa, ipo ọwọ ni wọn wa, wọn ko le e ṣa deede kan huwa ohun to wu wọn ni ṣiṣe, paapaa bi ifa ko ba fọwọ sii.
Mahmood ni ibo aarẹ yoo waye ni ọjọ Kejidinlogun, oṣù Keji, ọdun 2023.
Ó ṣe, nígbà kan ni, ọba kán rán ìyàwó rẹ̀ kí ó lọ se ọbẹ fún òun.
Alapinni Oosa wúre ọdún 2019 fún gbogbo ìran Yorùbá 'Akẹ́kọ̀ọ́gboyè ní mí ṣùgbọ́n aṣọ òké ló ń pawó wọlé' Pé ó gbà kí ọkọ àfẹ́sọ́nà rẹ bá ọ ní àjọṣepọ̀ kò ní kó fẹ́ ọ - Ṣọla Allyson Ẹgbọn wọn agba lo maa n ba wọn dari fidio ti wọn n ya fi sin awọn agbajugbaja oloṣere jẹ lori ayelujara.
Kódà lásikò àwọn ìjọba òyìnbó amúnisìn, wọn ó fọ́wọ́ kan ìtàn Kano gẹ́gẹ́ bí èyí ti gómìnà wọn ń ṣe yìí ọjọgban Tijani Naniya ti ẹka ìmọ̀ Itan Fasíti Bayero ni Kano lo sàlàye èyí.
Ori lo ko Tottenham pẹlu yọ lọwọ ogun atẹyinja ṣugbọn ṣa wọn sun iya ta lagba niluu London di ọjọ mii, ọjọọ re.
Kogi alleged rape: Agbẹjọ́rò fún arábìnrin tó fẹ̀sùn ìfipábánilòpọ̀ kan kọmíṣọ́nà Kogi ní ó ṣeéṣe kí ìyípadà rẹ̀ lórí ẹ̀sùn náà ó lọ́wọ́ àwọn alágbára nínú
 Nigba ti Aare n soro ni Aafin
Joshua Kimmich lo gba ami ayo kinni wole fun Bayern, kii Marcelo o to da ami ayo ohun pada kii saa akoko ifesewonse naa o to wa si ipari.
Gómìnà Godwin Obaseki yóò d'ọmọ ẹgbẹ́ òṣèlú PDP lọ́sẹ̀ yìí O daju pe ẹgbẹ oṣelu Peoples Democratic Party, PDP ni Gomina Godwin Obaseki nlọ, yoo si darapọ mọ ẹgbẹ naa ki eto idibo abẹle lati yan oludije ipo gomina ipinlẹ Edo lọjọ kọkandinlogun ati ogunjọ oṣu yii.
orile ede Naijiria ni lati tun tesiwaju lori ipinnu won lati pese eto
Mo tún gbọ́ ohùn kan láti ọ̀run tí ó sọ fún mi pé, “Lọ gba ìwé tí ó wà ni ṣíṣí tí ó wà lọ́wọ́ angẹli tí ó dúró lórí òkun ati lórí ilẹ̀.
Ní ọjọ́ kinni oṣù kinni ọdún tí Noa di ẹni ọdún mọkanlelẹgbẹta (601), omi gbẹ tán lórí ilẹ̀.
Kí ooru oòrùn ti máa yòòrò gbogbo omi-dídì káàkiri àgbàyé.
Kí ló dé tí èmi iranṣẹ rẹ yóo máa gbé inú ìlú kan náà pẹlu rẹ?
Ọmọ Nàíjíríà: Ó yẹ kíjọba gbé ìgbẹ́sẹ̀ akin lásti dẹ́kun ìpànìyàn
Ẹ máa ṣoore fún ara yín, ẹ ní ojú àánú; kí ẹ sì máa dáríjì ara yín, gẹ́gẹ́ bí Ọlọrun ti dáríjì yín nípasẹ̀ Kristi.
Nígbà náà ni gbogbo igi igbó yóo fi ayọ̀ kọrin,
Ará, mo fi Oluwa wa Jesu Kristi ati ìfẹ́ ti Ẹ̀mí Mímọ́ bẹ̀ yín pé, kí ẹ máa fi ìtara bá mi gbadura sí Ọlọrun pé 
Kò yẹ ki ìjọba àpàpọ lágbára lóri ìjọbá ìpínlẹ̀ nígbà ti wọn dé, èyí si ni ó gba àgbà lọ́wọ́ àwọn gómìnà ìpínlẹ̀, àti pé ìjọba kò ti ṣe òun ti ó tọ, ti wọ̀n ò bá pàdà sí ìgbà ti àwọn gómìnà ìpínlẹ̀ ba ní akoso ohun to tọ si wọn, láti fí mú ìdàgbàsóke bá ìpínlẹ̀ wọ́n láì kọ́kọ́ lọ si Abuja.
9 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 EndSars in Portharcourt: Ọjọ́ méjì sẹ́yìn ni aya awakọ̀ Márúwá tí ọlọ́pàá pa bímọ tuntun10 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Ọpọ lo ti lẹ n sọ pe kini ijọba fi obitibiti biliọnu Naira ti wọn n fi sinu owo iṣuna lati fi gbọ bukaata ileewosan to wa nile ijọba l'Abuja.
com/iamcertified_eyinjueledu Ọrọ naa wa kadi nilẹ pe ọjọ kan yoo jọkan, laarin isẹju kan, ti gbogbo rẹ yoo tan, ti yoo si ku wa ati iwa wa ninu saare.
com/officialapcng/ YouTube: Official APC Nigeria Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Ohun kansoso ti ajọ eleto ilera lagbaye kede pe o lee wo Coronavirus san ni ka maa fọ ọwọ wa deede, nitori eyi se pataki lati dena kokoro arun naa.
" Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Papa ọkọ ofurufu to wa l'Eko Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Bí àwọn eniyan ṣe ń ṣí káàkiri ní ìhà ìlà oòrùn, wọ́n rí ilẹ̀ tí ó tẹ́jú ní agbègbè Babiloni, wọ́n sì tẹ̀dó sibẹ.
Obìnrin kan bí ibejì lẹ́yìn ọjọ́ 26 tó bí ọmọkùnrin Tinubu kìlọ̀ fún Buhari lórí ohun tó leè ṣàkóbá fún sáà kejì rẹ̀ Sẹ́nétọ̀ Omo-Agege, tó gbẹ́ ọ̀pá àṣẹ ile lọ́jọ́sí, 'jẹ gbèsè' nítorí àti di Sẹ́nétọ̀ lẹ́ẹ̀kejì Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Jeremiah Addo: Ọmọ ọdún méjì tó ṣeeṣe kò mọ̀wé jù l'ágbàáyé Elkanaa ni olukọ ti wọn fẹsun naa ni wi pe oun ko jẹbi ẹsun naa, amọ iwadii n tẹsiwaju lori isẹlẹ naa, ti awọn yoo si gbe lọ si ile ẹjo ti awọn ba ti pari iwadii naa.
Má fara kàn mí,nítorí mo jẹ́ ẹni mímọ́ jù ọ́ lọ.
Ẹni tí ó jókòó lórí ìtẹ́ náà yóo máa bá wọn gbé.
Ọmọ ọdún mẹ́wàá ń fọn fèrè lágbo àríyá Baṣọ̀run Gáà, tó yan ọba mẹ́rin, pa ọba mẹ́rin àmọ́ ọba karùn-ún ló pa á Ìyá àgbà Ọlayinka, arúgbó tó ń ṣoge bí omidan Oshisko twins, àwọn 'ìbejì' tó ń dẹ́rìn ín p'òṣónú Wọ́n ta ère Ọ̀ṣun Osogbo sí Togo - Bàbá Ọṣun figbe ta Ọbasanjọ ni riro ni ti eniyan lọrọ naa jẹ, tori sise ni ti Ọlọrun ọba, sùgbọ́n nípa ore ọfẹ́ Ọlọ́run, oun nìkan ni oun jáde laaye lọgba ẹwọn.
Bẹ́ẹ̀ ni àwọn ọmọ ilẹ̀ Juda ṣe tẹ orí àwọn ọmọ Israẹli ba tí wọ́n sì ṣẹgun wọn, nítorí pé àwọn ọmọ Juda gbẹ́kẹ̀lé OLUWA Ọlọrun àwọn baba wọn.
” (Ìtumọ̀ Siloamu ni “rán níṣẹ́.
Gbogbo ohun èèlò wúrà tí wọ́n wà ninu ilé OLUWA, tí Solomoni ọba Israẹli ṣe, ni ó gé sí wẹ́wẹ́, gẹ́gẹ́ bí Ọlọrun ti sọ tẹ́lẹ̀.
Ó tún bi wọ́n pé, “Nígbà tí mo fi burẹdi meje bọ́ àwọn ẹgbaaji (4,000) eniyan, agbọ̀n ńlá mélòó ni àjẹkù tí ẹ kó jọ?
Gomina ipinlẹ naa, Ahmadu Umaru Fintiri sọ pe wọn ti pin awọn ounjẹ ọhun ṣugbọn awọn to ku ni wọn n gbe igbesẹ lati pin lọjọ Aje, ọjọ kẹrindinlọgbọn, oṣu Kẹwaa, ọdun 2020, ki wahala to bẹ silẹ.
Nígbà tí ó dé ṣóńṣó ìgbéga rẹ̀ tán, Olódùmarè rẹ̀ ẹ̀ sílẹ̀, ó ṣubú, ó di èrò ẹ̀hìn, ìbànújẹ́ dé bá a, ọkàn rẹ̀ kún fún ìrẹ̀wẹ̀sì, orúkọ rẹ̀ sì burú tóbẹ́ẹ̀ nínú ayé tí àwọn ènìyàn kò jẹ́ fi orúkọ náà sọ ọmọ wọn.
O maa n sọrọ lori awọn iṣoro to n koju awọn eniyan Naijiria, awọn wahala to de ba eto ọrọ aje ati igbe aye alaafia Naijiria nigba aye rẹ pupọ.
Orilẹede Naijiria ti ke si ajọ agbaye lati pese iranwo awọn ohun elo idaabobo fun awọn ọmọ Naijiria lati koju arun Coronavirus.
2bn Naira tó fẹ́ ẹ yá lọ́wọ́ Brazil Ẹ wo ẹyẹ ayékòótọ́ tó kó olówó rẹ̀ yọ lọ́wọ́ ikú gbígbóná Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Fídíò, Akomolede àti Asa lórí BBC Yorùbá: Mọ̀ síi nípa ẹ̀kún ìyàwó níbí3 Bélú 2020 Fídíò, Soyinka Cancer: Àṣe ara mi ni iso ti n run gbogbo bí mo ṣe n ṣèrànwọ́ lórí jẹjẹrẹ27 Bélú 2019 Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Nigbati Olóri-ogun Badamasi Babangida gba Ìjọba, inú ilú dùn nitori àyè gba ará ilú lati ṣe bi wọn ti fẹ lati ri owó.
 Awọn iroyin ti ẹ lee nifẹẹ si: Arisekọla Alao: Ka ni Baba n bẹ laye."
Orí kò òṣìṣẹ́ EFCC méjì yọ lọ́wọ́ ìjàmbá iná N24bn pọ̀ jù láti kọ́ ọ́fíìsì EFCC - Onímọ̀ Fayose ke s'ijọba lati kede dukia ti EFCC gba Ajọ naa to ti n ṣe iwadi gomina naa tẹlẹ fun ẹsun kiko biliọnu mẹtadinlogun Naira pamọ lọna aitọ, ti 'iṣẹ iwadi wọn si fihan pe, Orji ko diẹ lara owo naa pamọ nipasẹ awọn ọmọ rẹ ọkunrin.
"Bí o bá ṣe ìdánwò àṣewọ'léeṣẹ́ ọmọogun òfúrufú, wo bí o ṣe le rí èsì rẹ̀ níbí Wo ọ̀rọ̀ Fani-Kayode sí akọ̀ròyìn ""blog"" tó ní lílù ìyàwó rẹ̀ bíi bàrà ló mú wọn túká Wo ohun to yẹ kóo mọ̀ nípa fọ́ọ̀mù 'self-certification' tí ìjọba àpapọ̀ ṣẹ̀ṣẹ̀ gbé kalẹ̀ àtàwọn tó kàn Wo ọjọ́ tí wòlíì Sotitobire yóò gba ìdájọ́ Inú mi dùn lórí òfin títẹ àwọn àfipábánilòpọ̀ ní ọ̀dá - Foluke Daramola Ọdún mọ́kànlá rèé témi àti ọkọ mi bẹ̀rẹ̀ ìfẹ́ láti ilé ẹ̀kọ́ girama - Bukunmi Oluwasina Ọ̀pọ̀lọpọ̀ Ọbalayé ní kò yàtọ̀ sí èèyàn lásán - Elebuibon Amọ, wọn ni awọn doola ẹmi ati dukia awọn eniyan nigba ti wọn de ibẹ."
Wọ́n fi ẹ̀sùn kan Kasali wípé ó lù ìyàwó rẹ̀ títí tó fi dákú.
O ni lẹyin ipade rẹ pẹlawọn ọmọ igbimọ abo ni Naijiria aarẹ yoo sọrs lori hilahilo to n waye lati igba ti iwọde #EndSARS ti dẹsẹru bi ẹsẹ telọ.
Ṣùgbọ́n kí wọn tóó bẹ̀rẹ̀ ìjà ní ẹ̀ẹ̀keejì ni àwọn nǹkan Igbó Olódùmarè ti pejọ́ bámúbámú.
Ni bayii, o se e se ki West Bromwich Albion  maa lanfaani lati kopa ninu idije ohun ni saa to n bo latari ipo ti iko ohun wa.
Iléẹjọ́ ní Elijah Abbo kò lẹ́jọ́ jẹ́ Ẹ̀sín wa kò ní bọ́ sọ́wọ́ ọ̀tá, Arsenal gbọdọ̀ na Chelsea lónìí - Lacazette Ọmọ Nàíjíríà mọ̀ pé ìjọba mi gbìyànjú, mo ṣapá mi lórí ètò ààbò - Buhari Bakan naa lo fi kun un pe, awọn agbofinro pẹlu ti n gbaradi lati bẹrẹ sifi panpẹ ọba gbe awọn ọmọ ẹgbẹ naa.
Agbẹnusọ ileeṣẹ ọlọpaa, Abdullahi Haruna ni awọn fi iwe pe Ahmed , ti wọn si ba sọrọ iyanju lori ẹrọ ayeluyara ko to di wi pe o jawo ninu ero lati pa ara rẹ.
Ninu ẹgbẹ aaro ti Laṣabi ati awọn ẹgbẹ rẹ n se, Lisabi maa n sisẹ takuntakun lati ro oko awọn ọmọ ẹgbẹ rẹ to ba kan lati gba aaro, ti oun funra ara rẹ ko si gba aaro kankan lọwọ awọn ọrẹ rẹ fun ọjọ pipẹ.
Ajọ isọkan agbaye, UN fi sita lọjọ Aiku pe lodi si mẹtalelogoji ti awọn oniroyin Naijiria n gbe jade pe o ku, awọn ti ko din ni aadọfa gangan lo ku.
Aaro rẹ maa n sọ mi gidigidi nitori ọdun 2018 ni a ti foju kan gbẹyin, inu mi si dun lati gbaa ni alejo lẹẹkan si lorilẹede Amẹrika.
Ajọ FCCPc sọ pe ninu iwadii oun lo ti han pe ọna ti ko tọ ọ ni ileeṣẹ naa n gba ṣe ororo naa, to fi mọ bo ṣe n rọ oro naa sinu ọra, ni ẹka ileeṣẹ rẹ ni Abuja.
Ọlọ́pàá mú afẹ̀sùnkàn Boko Haram tó ti pa ju ènìyàn 200 Àwa kìí bá ikọ̀ adúnkookò mọ́ni sọ̀rọ̀ - Red Cross 'EFCC mo dé' àti àwọn àṣà míì táwọn olóṣèlú fi dagbo rú ní 2018 Àrà ọ̀tọ̀ inú orin tó jáde lọ́dún 2018 ní Nàìjíríà Ọpọ eeyan lo ti ṣe alabapin fidio naa to fi mọ oluranlọwọ fun Aarẹ ana Goodluck Jonathan Reno Omokri Lati ọdun 2009 ni Boko Haram ti n da wahala silẹ́ lorileede Naijiria ati awọn orileede to yii ka bi Niger, Chad ati Cameroon.
89 biliọnu silẹ gẹgẹ ara ohun ti awọn olukọ fasiti naa n ja fun, idunnu nla lo gba ọkan ọpọ.
” Wọ́n bá jáde kúrò ninu iná lẹsẹkẹsẹ.
Arsenal: Emery ní òun fẹ́ kí agbábọ́ọ̀lù tí kò fakọyọ bínú
13 Ṣe ohun yìí èyí tí èmi ti paláṣẹ fún ọ, ìwọ yíò sì ṣe rere.
Ẹlẹri kan ti salaye fadajọ to n gbọ ẹsun ajẹbanu ti wọn fi kan Minisita eto aabo tẹlẹri ni Naijiria,Musiliu Obanikoro, bi oun ti ṣe gbe owo to le ni biliọnu naira fun un.
Àdùnní ti di olóògbé, ìyẹn nip é ó ti kú.
Mo fi ibinu tẹ àwọn orílẹ̀-èdè mọ́lẹ̀, mo fi ìrúnú rọ wọ́n yó,mo sì tú ẹ̀jẹ̀ wọn dà sílẹ̀.
Mohammed so oro yii lojoRu nigba ti o n ba awon akoroyin ile-ise aare soro leyin ipade igbimo ijoba to waye lose yii.
Ẹ̀rù ló n bà NEDG ni kò jẹ́ kí wọ́n pè mí sí ìfọ̀rọ̀wérọ̀ f'áwọn olùdíje
Ìpínlẹ̀ mẹ́tàdílógún ni àwọn ènìyàn to ṣẹ̀ṣẹ̀ lùgbàdì ààrùn náà ti jẹyọ ni àná Plateau-85 Enugu-46 Oyo-31 Lagos-21 Rivers-20 FCT-15 Kaduna-13 Bauchi-12 Delta-11 Ekiti-11 Akwa Ibom-7 Ebonyi-6 Kwara-5 Ogun-4 Osun-4 Gombe-3 Niger-2 Ibi ti ìpińlẹ̀ kọ̀ọ̀kan de dúró ni Naijiria rèé NCDC ní ènìyàn 296 míràn ló tún fara kásá Covid-19 ní Nàìjíríà Ikéde àbájáde àyẹ̀wò àwọn tó ṣẹ̀ṣẹ̀ lùgbàdì ààrùn Covid-19 ni Nìàjíríà kò ju igba àti mọ́kànlélógún lọ lọ́jọ́rú.
Nigba to n dahun awọn ibeere lori eto ileeṣẹ redio kan ni ilu Ibadan, Ajagunfẹyinti Olayinka Olayanju sisọ loju ọrọ naa.
Xenophobic Attack: 'Nàìjíríà ló máa forí kó kíkọlu iléeṣẹ́ South Africa jùlọ' Xenophobic Attack: Àwọn ọmọ Nàìjírìá bínú kọlu Shoprite l'Eko Àjọ Commomwealth gbọ̀dọ pé ìpáde pàjáwìrì lori ọ̀rọ̀ Brexit- Wole Soyinka Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Òun tọjú àwọn ọmọ Nàìjíríà n rí ní South Áfríkà kọjá afẹnusọ Bẹẹ lo wa kesi ijọba orilẹede naa lati dide ati lati wa wọrọkọ fi sada lori ipaniyan naa ki oun gbogbo le pada si ipo.
Wọ́n á sì wọ ìbòjú padà.
 Èyí ni láti sọ pe ẹlẹ ́ sẹ ̀ ni gbogbo ọmọ adárí hurun .
Minisita to n ri si sise eto ile-iwe, ogbeni Adamu Adamu, lo kede oro naa lasiko to n yanana abajade oro ohun fun ile igbimo asoju sofin.
Igbesẹ yii lo waye lẹyin ti pastitọ naa atawọn mẹfa miran ti wọn fẹsun kan pari awijare wọn niwaju ile ẹjọ ọhun.
kaarẹ ninu ojuse won lati ri i pe won pa ohun to n jẹ Boko Haram run lorile ede
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Naijiria: Asiri awọn ibudo igbafẹ ẹranko 23 Èrèlè 2018 Oríṣun àwòrán, CHESTER ZOO Àkọlé àwòrán, Inu igbó kìjikìji lawọn ìnàki orilẹede Naijiria n gbe Awọn inaki ti wọn jẹ ti orilẹede Naijiria ati ilẹ Cameroon ti wọn ti ri ni awọn igbo Gashaka Gumti, ti eyi si jẹ́ ireti pe awọn inaki ọhun ni ọjọ́ ọla.
 Bi iko agbaboolu mejeeji yoo se to re:Liverpool XI: Adrian; Alexander-Arnold, Gomez, Van Dijk, Robertson; Wijnaldum, Fabinho, Henderson; Salah, Firmino, ManeArsenal XI: Leno; Maitland-Niles, David Luiz, Sokratis, Monreal; Guendouzi, Xhaka, Ceballos; Pepe, Lacazette, Aubameyang.
Balogun Golden Eaglets, Tijani lo gba goolu ẹlẹẹkẹrin sawọn Hungary eleyi to jẹ ki Naijiria gbegba oroke pẹlu ami ayo mẹrin si meji.
 Awon mejeeji naa seleri lati fowosopo pelu Naijiria fun idagbasoke to ye.
Nígbà tí wọ́n gbára le yín, ẹ dá ẹ sì jẹ́ kí wọ́n dá lẹ́yìn.
Amosun ni ohun kìí ṣe ẹni ti yóò máà farapamọ sábẹ́ ìka kan, Ó sàlayé lónìí ọjọ́ ajé níbi ìpadé àwọn ọmọ lẹ́yìn rẹ̀, tó wáyé nío ilé igbé ààrẹ tó wà ní Ibara Housing Estate Abeokuta.
Kò burú tí o bá ṣiyèméjì bóyá ìléèṣẹ́ ìròyìn tí o kò gbọ́ nípa rẹ̀ rí lógbé ìròyìn nàá jáde.
Ṣé kí n máa yìn yín ni?
"Majek jẹ ẹni ti ko si nkan ti ko ba lara mu, to si tutu ni iwa.
O ni Sé a kò le bèèrè ìbéèrè ni?"
Onkọwe, olukọ ewi ati olukọ arosọ.
Orile-ede Mauritius ti o wa apa ila-orun ile Africa sami ayeye ayajo adota odun ti orile-ede ohun ti olominira, bakan naa ni orile-ede ohun tun sami ayeye odun merindinlogbo ijoba tiwa-n-tiwa.
Iwe arosọ meji to kọkọ kọ ni Aja lo lru (1969) ati Agbalagba Akin (1971).
 ìwé fonọ ́ lọ ́ jì àti gírámà yorùbá yìí jẹ ́ ìgbésẹ ̀ kejì lórí lílo èdè-ìperí yorùbá nítorí pé a ṣe àlàyé àwọn èdè-ìperí tí ó bá ẹ ̀ dá-èdè lọ dáadáa ; a sì lo àpẹẹrẹ oríṣiríṣi láti fi ìtumọ ̀ wọn hàn kedere .
Ẹgbẹ́ alátakò PDP ni, kìí ṣe ohun tó tọ́ ni ki ààrẹ maa bu ẹnu àtẹ́ lu àwọn olùgbé ìlú Abuja nítori pé wọn kò láti dibò fún nínú ìdìbò aààrẹ tó wáye nínú oṣù kejì ọdún 2019.
awon omo orile-ede Naijiria lati gba awon osise alaabo laaye ki won sise won.
"Oríṣun àwòrán, Joel Kouam ""Mo máa ṣe afẹri imoran ti Rema maa n gba mi pe ki n yago fun ọti mimu ki n si maa lọ si ile ijọsin deede."
Spiny Babbler máa ń bà lé ẹ̀ka koríko àti igi kéékèèké láti kọrin, àgógó ẹnu ẹyẹ yóò wà ní òkè irú ní ìsàlẹ̀.
Ṣugbọn Ọlọrun ni ó ṣe ohun gbogbo.
O fi wahala abele to n sele lowo nipinle Kano se apere laarin gomina to wa lori aleefa bayii, iyen, Abdullahi Ganduje ati gomina to kogba wole, iyen, asojusofin Rabiu Kwankwanso ni eyit i opolopo ri pe ko ni bi eso rere fun eto idibo odun 2019 to m bo lona.
”Josẹfu dá wọn lóhùn, ó ní, “Ṣebí Ọlọrun ni ó ni ìtumọ̀ àlá?
- Ilé ẹjọ́ ìpínlẹ̀ Ondo Ilé ìwòsàn kan rèé tó ń fi àtùpà gbẹ̀bí aláboyún Ní báyìí, ènìyàn tó lé ni ẹgbẹ̀rún mẹ́rìnlélógún ló ti lùgbàdì Covid-19 ni Nàìjíríà, ti Ghana si ni ènìyàn ẹgbẹ̀rún mẹ́tàdinlógún.
Awọn yooku tun ni: Ali Ndume, Abubakar Kyari, Baba Kaka Garbai, Aliyu Abdullahi, David Umaru, , Abdullahi Adamu, George Akume, Francis Alimekhina, Andrew Uchendu, Magnus Abe, Ovie Omo-Agege, John Enoh,  Nelson Effiong, Andy Uba, Sunny Ugboji, Hope Uzodinma, Ben Uwajimogu,  Yusuf Yusuf, Oluremi Tinubu, Gbenga Ashafa, Solomon Adeola, Tayo Alasoadura, , Soji Akanbi, Ajayi Boroface, Yele Omogunwa, Fatima Rasaki, Olanrewaju Tejuoso ati Yahaya Abdullahi.
Mose kó egungun Josẹfu lọ́wọ́ nígbà tí wọ́n ń lọ, nítorí pé Josẹfu ti mú kí àwọn ọmọ Israẹli jẹ́jẹ̀ẹ́, ó ní, “Ọlọrun yóo gbà yín là, nígbà tí ó bá yá tí ẹ̀ bá ń lọ, ẹ kó egungun mi lọ́wọ́ lọ.
Ìtàn kejì ni pé láti ìlú mẹ ́ kà ni lámurúdu tí ó jẹ ́ baba odùduwà ti wá sí ifẹ ̀ .
N óo pa á run láàrin àwọn eniyan mi; ẹ óo wá mọ̀ pé èmi ni OLUWA.
 “Ni bayii ajo ijọba ati ajo agbaye to
Igbimọ naa to ṣapejuwe lile Emir Sanusi kuro niluu Kano lẹyin ti wọn rọ ọ l'oye, gẹgẹ bi nkan ti ko ba ode oni mu sọ pe ko si ninu ofin Naijiria.
Coronavirus: Àwọn ohun tí a kò tíì mọ̀ nípa àrùn Covid-19 Inira ti ba nipa mimi toun ti pe wọn si gbe si abẹ fẹntilatọ lati ran mimi rẹ lọwọ, ẹdọ foro rẹ pada kọsẹ silẹ ni ti o si pada papoda.
Orúkọ ọmọ keji ni Elieseri, (ìtumọ̀ rẹ̀ ni pé, “Ọlọrun baba mi ni olùrànlọ́wọ́ mi, òun ni ó sì gbà mí kúrò lọ́wọ́ idà Farao.
Ko to di atunbi, ogbontarigi ọdaran ni Kayode Williams ti orukọ rẹ ti yipada si Biṣọọbu Kayode Williams bayii.
Helesi, ará Paliti, Ira, ọmọ Ikeṣi, ará Tekoa; 
Abdullahi Sani to tun jẹ aráìlú Kano míràn sọ pe ọmọ ogoji ọdun ní oun, Emirati Kano si ni òun mọ ti òun si fẹ́ràn Ẹlòmiràn to tún ni ìpèníja ojú to si jẹ olùgbé Kano, Saifullah Mukhtar sọ pé oun ri ìgbẹ́sẹ̀ náà gẹ́gẹ́ bii ǹkan to dára ti yóò si ní ipa lára àwọn ara ìlú ti yóo si mu ki ọbá súnmọ ara ìlú, àti pe àdíkù yóò ba diduro fún ìgbà pípẹ́ láti gbọ abọ láti Emir Kano Bótilẹ̀ jẹ́ pe àwọn ìwé ìròyín ìbílẹ̀ sàlàye pe ilé ẹjọ gíga ní ìpínlẹ̀ Kano ni ọjọ jímọ to kọja ti fi iwé síta pé gómìnà ò ní àṣẹ láti fi àwọn Emir túntun náà lọ́lẹ̀, síbẹ̀ ìjọba ti fi ọ̀pá àṣẹ́ le àwọn Emir tuntun náà lọ́wọ́ lọ́jọ́ ajé Láàrin gbogbo ìṣẹ́lẹ̀ yìí, ó ṣe pàtaki láti mọ̀ pé ìpínlẹ̀ Kano nìkan kọ ni ìrú èyí kọ́kọ́ ṣẹlẹ̀ si ní ǹkan to jọ bi ẹni pe o ní ọ̀rọ̀ òṣèlú nínú ní lọ́lọ́ yìí.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Wo ọ̀nà tí àwọn ‘ẹ̀lẹ̀ Daddy’ gbà dé ààfin Ọyọ Ìjọba tó wà lóde yìí kò ní ìfẹ́ aráàlú la ṣe dá ẹgbẹ́ NCF sílẹ̀ - Femi Falana Àlàyé rèé lórí ikú tó pa Adegbenro, Kọmísánà l‘Ondo Bí òṣìṣẹ́ tó ń ta epo nílé epo ṣe di onímọ̀ ìṣẹ́gun òyìnbó, kàyéèfì ńlá!
Iṣẹ́ wo ni o óo ṣe?
Mànàmáná ati ìró ààrá ń jáde láti ara ìtẹ́ tí ó wà láàrin.
 Ó ṣiṣẹ ́ gẹ ́ gẹ ́ bí atẹ ̀ wé fún ilé-iṣẹ ́ tí ó pọn ọtí nigerian breweries , lẹ ́ yìn náà ni wọ ́ n gbà gẹ ́ gẹ ́ bí òǹtẹ ̀ wé ránṣẹ ́ ní ilé-iṣẹ ́ ológun ilè nàìjíríà nigerian armylát ̀ arí akitiyan rẹ ̀ ́ , lásìkò ogun abẹ ́ lé .
Igbagbọ Yoruba niyi ṣugbọn pups lo n woye pe ṣe lootọ lo wa tabi ara awọn itan atẹnudẹnu leyi.
Amaechi ni ko ni rọrun lati lè móju to àwọn èrò to ba n ninu ọkọ ojú irin pàápàá jùlọ lásiko ti wọn ba ń rin irin ajo Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Iléeṣé MTN ti san bíliọnù N55 owó ìtanràn wọn tó kù -MTN Wọ́n ti ni kí àwọn alága ìjọba ìbílẹ̀ Ogun lọ rọọ́kún nílé SEC: Tinubu kò gbọdọ̀ ṣe olúdarí iléeṣẹ kankan fódùn márùn ún Sìgá mímu ń di èèwọ̀ oògùn ìlera pípé lagbaye Ẹwẹ, ajọ to n ri si ere bọọlu ni Naijiria ti sọrọ pẹlu igboya pe Flying Eagles yoo jawe olubori ninu ifẹsẹwọnsẹ wọn pẹlu Senegal.
Wọ́n bá lọ sọ fún Saulu pé, “Àwọn eniyan ń dẹ́ṣẹ̀ sí OLUWA nítorí wọ́n ń jẹ ẹran tẹ̀jẹ̀tẹ̀jẹ̀.
OLUWA sọ fún àwọn eniyan rẹ̀ pé, “Ẹ sá àsálà kúrò ní ilẹ̀ àríwá.
Àjọ elétò ìdìbò lórílẹ̀èdè Nàíjíríà, INEC, ní igbésẹ̀ àti yọ Sẹ́nétọ̀ Dino Melaye ni ilé ìgbìmọ aṣòfin àgbà ti fìdí rẹmi nítorí pe idá márùń nínú ọgọ́rùń àwọn ìdìbò tó f'orúkọ sílẹ̀ ní agbègbè ìwọ̀ oòrùn Kogi nikan ló jáde láti wá ṣe àyẹwò orúkọ wọn ní ọjọ́ Àbámẹ́ta.
"Mo fẹ́ fi dá a yín lójú pé gbogbo ohun tí a mọ̀ ìpínlẹ̀ Ekiti fún gẹ́gẹ́ bíi ìwà ìrẹ̀lẹ̀ àti àláfáà ni a ṣe tán láti mú padà wá.
 ninu idiboyan 2008 , clinton je eniagbewo fun idaloruko ipo aare egbe oloselu democratiki .
Lẹyin eyi lo dara pọ awọn oṣere tiata lẹkunrẹrẹ lọdun 2006.
Ọmọ to n ri ẹ̀bí, ará, ọ̀rẹ́ yin tabi iyekan yin kan to n sá tabi to n farapamọ.
Ìtàn yìí kó wa wípé kò yẹ kí á máa f'ojú tẹ́ńbẹ́lú ẹnikẹ́ni nítorí ẹ̀dá kò láròpin.
Jiti Ogunye: Ẹgbẹ Musulumi Sunni ni ijọba Naijiria lọwọlọwọ!
Tí ẹ bá jẹ́ ti Kristi, a jẹ́ pé ẹ jẹ́ irú-ọmọ Abrahamu, ẹ sì di ajogún ìlérí.
’Awọn sọja Cameroun tu mi sihoho' Ẹgbẹ́ òṣìṣẹ́ ìpínlẹ̀ Ọyọ bẹ̀rẹ̀ ìyanṣẹ́lódì aláìní gbèdéke 82% ọkùnrin ní kó mọ̀ pé òun ní àìsàn jẹjẹrẹ asẹtọ ní Naijiria Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Jiti Ogunye: Ìjọba àkóbá lológun gbé kalẹ̀ ni 1999 Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Obinrin Akansẹ: Ẹsẹ kiku bi ojo kọ mi lati di alagbara Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
maa sajọyọ ayẹyẹ ogun odun eto ijoba tiwa-n-tiwa lorile ede Naijiria,won tunn
Awọn obi kan naa ni iwọle pada awọn akẹkọọ yoo dara, ti wọn ba tẹle ofin ti ijọba lakalẹ lati dẹkun itankalẹ arun Coronavirus.
Ìjọba ìpínlẹ Eko yóò lu ọkọ̀ 44 ní gbàǹjo lẹ́yìn tí àwọn awakọ̀ tàpá sófin ìrìnnà ojú pópó Makinde ya ₦56.
Pẹ̀lú àwọn ìdojúkọ wọ̀nyí, “ipò náà” le sí i.
Kete ti Sophie ti ile iwosan de ni gbogbo ara rẹ ko ti gbadun.
Koda, o ti figba kan gbe ilu Eko ri nigba to n dagba.
Oríṣun àwòrán, @queenomohone/Instgram Njẹ ki wa ni asiri agbara Alaafin, ẹni to ti le ni ọgọrin ọdun, to fi nbi ibeji ati ibẹta ni ọpọ igba?
Yàtọ̀ sí Ọ̀ṣun Òṣogbo, Ṣàǹgó pẹ̀lú a máa ní arugbá lóde Ọ̀yọ̀ Ọlọ́pàá Ogun gb'ọmọ Ìmáàmù lọ́wọ́ ajínigbé, ṣùgbọ́n wọ́n gbé ọkọ̀ ojú omi ọlọ́pàá lọ Ọ̀pọ̀ èèyàn bẹnu ẹ̀tẹ́ lu Mercy Aigbe lórí bó ṣe ki Adeniyi Johnson Buhari gbóṣùbà fún D'Tigress lẹ́yìn tí wọ́n lu Senegal gba ife AfroBasketWomen Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Iyatọ nla wa laarin ẹsin ati asa, ẹ mase jẹ ki oju ti yin lati maa wọ awọn asọ ajogunba Yoruba, koda asa wa gan gbọdọ fara han ninu awọn ounjẹ ta n jẹ"" Khafi jẹ̀bùn ọkọ̀ ₦7."
Ọ̀gá ọlọ̀pàá: Saraki gbọdọ̀ wá sọ àsọyé lórí lẹ́tà tó kọ
Gómìnà tẹnu mọ́ọ pé ifarajì rẹ̀ láti ríi dájú pé Akinlade yóò górí àléfà lẹ́yìn ohun nínú oṣù kárún ọdún 2019 àti pé kò sí ọ̀nà abáyọ fún Dapọ Abiodun nítori pé ó jí nkan tó tọ́ sí Akinlade ninú ẹgbẹ́ APC ní.
"Ẹ bá mi wá nọ́ńbà ìpè òbí ọmọ Mummy Calm Down jáde - Yinka Ayefele Aláwàdà ni ọmọ mi láti kékeré, kò ṣẹ̀ṣẹ̀ máa gbé mi mọ́ra- ìyá ‘Mummy calm down’ Oreoluwa ninu fidio Mummy Calm Down fẹ́ di 'Ambassador' N kò ri ipa ẹ̀jẹ̀ lára ọmọ mi tó kú sí iléeṣẹ́ ọṣẹ, èjò lọ́wọ́ nínú - Òbí àkẹ́kọ̀ọ́ UI Ìyá àwọn ọmọ oní ""Blue Eyes"" n'Ilorin t'ọ́kọ dà síta bá BBC Yoruba sọ̀rọ̀ 'Ẹ̀yin obìnrin ẹ wá kẹ́kọ̀ọ́ ìbálòpọ̀ láti tẹ ọkọ yín lọ́rùn' O ni niṣe ni inu oun dun pe ọmọ naa ko oun jade si ire, paapa nigba ti gomina tun pe wọn lori ẹrọ ibanisọrọ."
Minisita ipinle to n ri si  ọrọ to jẹ mọ 
Ọ̀gbẹ́ni Barbier ló dáhùn ìpèníjà yìí nígbà náà.
Buhari: Àwọn ọmọ Nàìjíríà faraya lórí Ìrìn-àjò ààrẹ lọ sí Jordan
Idi miran ti awọn onwoye tun fi sọ pe o ṣeṣe ki Trumnp bori lọna ti yoo jọ awọn eeyan kan loju ni igbagbọ pe o mọ bi wọn ṣe n polongo ibo ju Biden lọ.
Láti ìrọ̀lẹ́ ọjọ́ kẹrinla oṣù kinni yìí títí di ìrọ̀lẹ́ ọjọ́ kọkanlelogun oṣù náà, burẹdi tí kò ní ìwúkàrà ni ẹ gbọdọ̀ máa jẹ.
musulumi lokunrin ati lobinrin jake jado Ipinle Oyo ti pejo si yidi  (ibudo adura) lati lo dupe lowo Allah to mu
Bakan naa, lọjọ kejidinlọgbọn, oṣu ati ọdun kan naa, ile ẹjọ tun fi ẹsun yii kan naa kan an.
ati ìlú Baalati, ati Tamari tí ó wà ní aṣálẹ̀ Juda, 
Eyi ko si sẹyin bi igbakeji rẹ se kuro ni ẹgbẹ oṣelu APC lọ si PDP, lati dije du ipo Gomina ninu eto idibo ti yoo waye ni Oṣu Kẹwa, ọdun yii.
Ewe, minisita fun eto iroyin Alhaji Lai Mohammed ti fi alekun iye awon akekoo binrin ti won da sile loni ojo-Ru mule pe, won je mokanlelogorun bayii.
Ṣé irú ohun tí ó yẹ kí ẹ fi san án fún OLUWA nìyí,ẹ̀yin ìran òmùgọ̀ ati aláìnírònú ẹ̀dá wọnyi?
Mo ríbà ‘i’ ríbá, mo ríbà ìyá mi oo
 ti so pe,o kere tan eniyan marun un ni o
UNO bẹnu àtẹ́ lu ìdàdúró Onnoghen Ààrẹ Buhari ṣí ibùdó ìtọ́jú àìsàn jẹjẹrẹ l'Eko Lẹyìn tí mo figbe ta, INEC mú PVC mi wá bá mi nílé - Gani Adams Ibà Lassa ti kan Ipinlẹ 19 ní Nàìjíríà Ààrẹ Muhammadu Buhari gbé ìpolongo ìbò dé ìlú Eko Nṣe ni wọn fara gbọgbẹ loriṣiriṣi lasiko ti wọn fi n gbiyanju lati sa asala fun ẹmi wọn.
Ibanujẹ lo jẹ fun agbo ile tiata Yoruba, Lẹyin ti iroyin iku rẹ jade sori ayelujara.
Oun naa si ti sọ laimọye igba pe, oun ko dije.
Amọ ijọba fikun wi pe, ọrọ naa ko nii se pẹlu awọn ile ẹkọ aladani ni ipinlẹ naa.
Iwadii BBC ṣafihan pe ileeṣẹ ijọba to n ṣakoso N-Power ti bẹrẹ si ni ṣe agbeyẹwo awọn to fiiwe ranṣẹ bẹẹ naa ni wọn ni gbiyanju lati yanju ajẹsilẹ owo awọn to kopa ninu abala ikini ati ikeji eto naa to wa nilẹ.
Nígbà tí ó máa fi tó ọdún mẹ́fà wọ́n ti bẹ̀rẹ̀ sí ṣe ètùtù, wọ́n ń rúbọ sí Ọlọ́run Ọba wí pé kí Ó jẹ́ kí aṣojú-Olódùmarè tètè padà kí ó wáá fi àwọn sí ipò tí àwọn ti wà ri.
Àìsọ̀rọ̀ Buhari lórí ìṣẹ̀lẹ̀ Lekki, ìkọjú ìjà sí Yoruba ni - YWC Kò sọ́rọ̀ nínú ọ̀rọ̀ Buhari, àtúntò Nàíjíríà nìkan lọ̀nà àbáyọ - Àgbà Yorùbá Amọ nibayi, idile Akinsemoyin, ti ọba Akiolu ti jade wa, ti wa ke fewe ọmọ mọ awọn janduku ti ọpa asẹ naa wa lọwọ wọn lati da pada lẹyẹ o sọka.
Oríṣun àwòrán, Others Ifẹ rẹ fun iroyin lo jẹ ko lọ si ileesẹ agbohunsafẹfẹ BBC lati lọ gba imọ kun imọ nipa isẹ igbohunsafẹfẹ lọdun 1962.
Àláfíà àti ìfọ̀kànbalẹ̀ ṣe pàtàkìfún ìlera wa.
Ikọ alaabo yii lo n ri si biboju to alaafia ni ipinlẹ Plateau atawọn apa ibi kọọkan ni Bauchi ati iha Guusu Kaduna.
’N óo sọ fún ìhà gúsù pé,‘O kò gbọdọ̀ dá wọn dúró.
" Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Akomolede ati Aṣa: Mọ̀ síi nípa ìró afárànma àti agbárànmọ́ fáwẹ́ẹ̀lì Yorùbá Bẹẹ lo sàlàyé fún àwọn aṣofin ile ilẹ naa pe nise lawọn ṣakiyesi alekun iye àwọn to ni arun naa kaakiri London, Kent, apa kan agbegbe Essex ati Hertfordshire.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Bolaji Faleke ni Olùkọ́ tó ń kọ́ wa ní àṣà oge ṣiṣe lórí BBC Yorùbá Bawo lọrọ ṣe bẹrẹ?
Ninu ọrọ ni Bauchi, Buhari ki awọn to ṣẹṣẹ wọ ẹgbẹ oṣelu rẹ naa kaabọ, to si rọ wọn ki wọn ṣiṣẹ takuntakun fun aṣeyọri APC ninu ibo gbogbogbo to nbọ.
“O jẹ ohun itiju pe won n fi iyatọ han laarin osise ipinle ati osise
” Nítorí náà, ó fi wọ́n sílẹ̀ kò sì pa wọ́n bí ó ti pa àwọn yòókù wọn.
Nítorí náà, ìyàn ńlá mú ní ìlú náà tóbẹ́ẹ̀ tí wọ́n fi ń ta orí kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ ní ọgọrin ìwọ̀n ṣekeli fadaka ati idamẹrin òṣùnwọ̀n kabu ìgbẹ́ ẹyẹlé ní ìwọ̀n ṣekeli fadaka marun-un.
Ẹnikẹni ti yoo ba kopa ninu idije naa gbọdọ kọ arokọ ti ko le ni ẹgbẹrin ọrọ (800 words) lori koko to da le, Is Africa ready for female political leadership?"
Oríṣun àwòrán, @Chikelinks Wọn fẹsun kan ọgagun naa pe o ko owo awọn ọmọ marun un to salọ sapo ara rẹ lọdun 2019.
 Ẹ ̀ wẹ ̀ , ilé-ẹ ̀ kọ ́ náà ń fún ninní ìwé ẹ ̀ rí diploma oní gbèdéke fún àwọn ọmọ orílẹ ̀ -èdè nàìjíríà tí ó bá tún fẹẹ ́ tẹ ̀ síwájú si , yà ní ilẹ ̀ baba wọn tàbí ilẹ ̀ òkèrè , níoasẹ ̀ ìlànà jókòó-sílé kàwé lókè òkun , tàbí nílànà jókòó nílé jàwé gboyè.
Saaju, alaga egbe naa, ogbemi Sunday Nwosu so idi pata ki, ti won fi se agbekale ayeye ami idanilola naa ni pe, lati ta awon ile-ise miiran ji giri nipa  sisan owo-ipin idokowo fun awon onibara won.
 Lootọ, wọn n fi aworan rẹ han mi, amọ ko tẹmilọrun.
Amọ o ni ẹkọ ile ti wọn ba ni, ni yoo sọ bi wọn yoo se gba imọran oun si.
Ẹ ti sọ mí di ẹni ìríra lójú àwọn eniyan mi nítorí ẹ̀kún ọwọ́ ọkà baali mélòó kan ati èérún burẹdi.
Ọba náà ná owó púpọ̀ nítorí ìgbéwàyó mi yìí, ó ná owó, ó ná ara, ó ṣe ìtọ́jú mi bi ó ti yẹ kí ẹni tí ó bá fẹ́ràn ẹni ṣe nítorí náà mo sì rò pé ó yẹ kí n bẹ̀rẹ̀ sí máa kọ ìtàn ìgbésí-ayé mi yìí sílẹ̀ nítorí ojú mi ti rí nǹkan sí ẹ̀hìn, ìwà tí ọba yìí hù sì ti fi hàn mí pé nǹkan tí ojú ń rí nínú ayé yẹ ní kíkọ sílẹ̀ fún àwọn tí ń bọ̀ lẹ́hìn, nítorí ayé kún fún kòtò, pẹ̀tẹ́lẹ̀, àti àwọn òkè gbogbo.
Igbakeji aare so pe  “A o fun un yin ni egberun mewaa; ti e ba san an pada laarin osu mefa;waa tun gba egberun meedogun, ti e baa san an pada ;wa a gba ogun egberun.
Ọjọ Aiku si ni wọn ri oku rẹ nibi ti ko jina si ile rẹ.
Onnoghen fun ise ribi-ribi ti o ti gbe se 
Àwọn ìròyìn mìíràn tí ẹ lè nífẹ̀ẹ́ sí: Wo ohun tuntun tó n ṣẹlẹ̀ lágboolé CAF Ìgbésẹ̀ tó tọ́ ni ìjọba Eko gbé lẹ́yìn ìjàmbá ilé tó wó - Aisha Buhari 'Ìwadìí yòó yàtọ̀ lórí ilé tó wó nítorí ààrẹ ti gbọ́ síi' Ẹyẹ ju ẹyẹ lọ, Super Eagles fi àmì ayò kan gbé ẹyẹ Swallow ti Burundi mì Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ebola Virus: ìdí tí Ebola fi ń tàn kálẹ̀ Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
to n mojuto eto ilera fun awon ọmọde ati alaboyun ( Institute of Maternal and
EndSARS Ogbomosho: Gómìnà Makinde f'òkò kan pẹyẹ méjì nílé àwọn tó kàgbákò ìwọ́de EndSARS àti ààfin Soun
“N óo ṣẹ́wọ́ sí wọn,n óo sì kó wọn jọ sinu ilé.
Wọ́n ya Kedeṣi sọ́tọ̀ ní Galili ní agbègbè olókè ti Nafutali, ati Ṣekemu ní agbègbè olókè ti Efuraimu, ati Kiriati Ariba (tí wọ́n ń pè ní Heburoni), ní agbègbè olókè ti Juda.
Abineri bá ranṣẹ sí Dafidi ní Heburoni pé, “Ṣebí ìwọ ni o ni ilẹ̀ yìí?
"Àkọlé àwòrán, Kofi Wilson fara gbọta nigbati o lọ ge irun ori rẹ ""Kii ṣe ipinnu mi lati jẹ dudu [eniyan],"" o tẹsiwaju."
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ohun ti ko dara ni láti maa lọ ọmú obinrin 26 Ẹrẹ̀nà 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 30 Èbibi 2020 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Apere eni ti wọn lọ ọmu fún lasiko ti ẹgbo ba a n jina O ti wá ṣe pataki báyìí láti fi ẹkọ lílọ ọmu sinu ìwé ìlàna ẹkọ ilé ẹkọ alakọbẹ̀rẹ̀ fun ilanilọyẹ àti láti dènà ìpalára fún awọn ọmọ obinrin.
Yóo bá máa yọ ìfòòfó lẹ́nu, ni ẹ̀mí yìí yóo bá gbé e ṣánlẹ̀; kò sì ní tètè fi í sílẹ̀.
Kò tún sí irú turari tí ọbabinrin yìí mú wá fún Solomoni ọba mọ́.
to ni fun orile ede Naijriia wa si imusẹ.
Uzor Kalu: Oríṣun àwòrán, orjikalu,com Sẹnetọ Uzor Kalu lo n ṣoju ẹkun ariwa ipinlẹ Abia ni ile igbimọ Asofin agba lorilẹede Naijiria, to si tun ti jẹ gomina tẹlẹ nipinlẹ Abia.
O rọ awọn olori ilu lati tubọ ma pawọpọ pẹlu awọn ọmọ ogun nipa titawọn lolobo iroyin nipa awọn agbesunmọmi.
Wọ́n la ilẹ̀ náà kọjá láti Pega títí wọ́n fi dé ìlú Antioku lẹ́bàá ilẹ̀ Pisidia.
Irinajo si orilẹ-ede Russia Aarẹ Buhari ṣẹṣẹ de lati orilẹ-ede Russia nibi to ti lo ọjọ mẹta.
Amọsa o, ipa ayipda ati idagbasoke ọrọ aje yii ko tii maa fi ara han ninu igbe aye awọn ọmọ orilẹede Ghana.
Anderson Bankole, to je okan lara awon omo igbimo isakoso NTTF ni isele naa dun ajo ohun pe: “Iroyin iku re ya mi lenu gidi, Naijiria ti padanu eekan nla to wa ni odo to mo ise re se lasiko fun ogo ile baba re.
Aare Muhammadu Buhari ti ki ogbontarigi olutaja epo robi
Iko ohun ti o kun fun olukopa obinrin kan soso ati okunrin meta filuu Eko sile lo sorile-ede China pelu oko baalu Ethiopia.
Wọ́n bá wá sọ́dọ̀ Mose, wọ́n ní, “A ti ṣẹ̀ nítorí tí a ti sọ̀rọ̀ òdì sí OLUWA ati sí ọ.
Amọ bi awọn ti ko gba ti ọrọ rẹ ṣe n sọ tiwọn, lawọn miran n kan sara si.
O ni eyi ribẹ nitori pe awọn ololufẹ oun ma n fẹ ẹ ya fọto pẹlu oun, ti oun ko si le sọ pe rara, koda ti kop ba wu oun.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Owó ounjẹ El-Zakzaky lósù kan nijọba lè fi bọ́ ẹlẹ́wọ̀n 208 28 Ọ̀wàrà 2018 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 9 Bélú 2018 Oríṣun àwòrán, Islamic movement Àkọlé àwòrán, Agbẹnusọ fun ijọ ẹsin Shiite ni El-Zakzaky n kerora lori ohun ti oju rẹ n ri nipa ounjẹ Miliọnu mẹta ati aabọ ti ijọba apapọ ni awọn fi n bọ olori ijọ Shiite Ibrahim El-Zakzaky to wa ni atimọle ni oṣooṣu ni iye ti ijọba apapọ fi n bọ ẹlẹwọn mẹjọlenigba ni Naijiria.
Adajọ Muhammad lo dari igbimọ igbẹjọ ẹlẹni meje to jẹ asan adajọ lati gbọ ẹsun awuyewuye to jẹyọ nibi ibo gomina ipinlẹ Bauchi, Kano, Sokoto, Plateau, Benue ati ipinlẹ Imo.
'Tattoo’ ara mi kò tí ì pọ̀ tó, mà á sì se si’ Bakan naa ni Sẹnetọ Ọpẹyẹmi Bamidele toun naa da si ijiroro ọhun ni iwa ti Sẹnetọ Abbo hu tapa si abala iwe ofin orilẹede Naijiria.
"Iléeṣẹ́ ọlọ́pàá sọ afurasí ọlọ́pàá tó yìnbọn fún ọ̀dọ́kùnrin tó fún èèyàn lóyún s'átìmọ́lé Àwọn agbófinró ti mú Eji tó jẹ́ igbákejì Ebila, olórí ẹgbẹ́ òkùnkùn ""One Million Boys"" sí gbaga Wo bí odò Nile tó gùn jù l'Áfíríkà, ṣe ń fójúu ilẹ̀ Egypt, Ethiopia àti Sudan han màbo Bí ẹgbẹ́ One Million Boys ṣe bẹ̀rẹ̀ rèé àti ọṣẹ́ tó ṣe n'Ibadan Èèyàn kan kú, ọmọ méjì sọnù nínú òjò tó rọ̀ nílùú Ilorin Lara awọn olugbe ilu Abuja sọ wi pe, iyalẹnu lo jẹ fun awọn nigba ti wọn ko ri burẹdi ra jẹ."
“Ọ̀rọ̀ tí mo tún fẹ́ ba yín sọ pọ̀, ṣugbọn ọkàn yin kò lè gbà á ní àkókò yìí.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Lionel Messi: Thiago Silva ìwà agọ̀ ló mú Messi sọ fun akọ́nimọ̀ọ́gbá Brazil pé kó gbẹ́nu dákẹ́ 16 Bélú 2019 Oríṣun àwòrán, Other Bo tilẹ jẹ pe Messi naa lo gba goolu kan ti ẹgbẹ agbabọọlu Argentina fi bori sawọn.
Eyí tó mú kí BBC Yoruba ṣe àkójọ ìtàn nípa akọni ọmọwe náà, wọn sá ní arise ni arika, arika si ni baba ìtàn.
Berhan Taye, atọ́kùn ìtàkùrọ̀sọ, bi ẹgbẹ́ yìí ní ìbéèrè ìrírí wọn ní inú túbú.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù #EndSARS: Oṣinbajo ní Ìjọba àpapọ̀ ti ń wáàdí àṣemáṣe ikọ̀ SARS 28 Agẹmo 2018 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Oṣinbajo ni ohun to kan awọn ikọ ọlọpaa kogberegbe SARS ni gbigbogun ti iwa idigunjale ati ijinigbe pẹlu awọn iwa ipa gbogbo miran Ijọba apapọ ti n boju wo gulegule wahala awọn ọlọpaa kogberegbe SARS lori oniruru ẹsun aṣemaṣe ti wọn n fi kan awọn ọlọpaa ikọ naa.
AMAA 2018 Ami eye orin abele to dara julo
 ifá ní kí Ẹ ̀ fẹ ̀ òun gẹ ̀ lẹ ̀ dẹ ́ ó rúbọ tí ìyá wọ rú kí àwọn náà ó lè dọlọ ́ mọ láyé .
"Lizzy jẹwọ pe oniṣowo aṣọ loun gẹgẹ bo ṣe ri i pe latori aṣọ oke to fi ṣe imana, aṣọ iyawo funfun ti awọn oloyinbo n pe ni Wedding Gown"", Ẹgba ọrun ati tọwọ, gbogbo wiwọ to fi ṣara rindin, oun funrarẹ lo ṣe e si ara rẹ lọrun."
Kí ni eniyan lè fi mí ṣe?
" Oríṣun àwòrán, Rauf Aregbesola/facebook O ni oun ko ju ẹni ọdun mẹrinlelọgbọn lọ nigba ti oun ati ọkọ oun (Bola Tinubu) pinya, fun igba akọkọ.
Lasiko ti wọn de lade, o si jẹ akẹkọọ ni fasiti ijọba ipinlẹ Ondo, iyẹn fasiti Adekunle Ajasin to wa ni Akungba-Akoko nibi to ti n kẹkọọ nipa iṣeto ilu.
O fi kun ọrọ rẹ pe, o ṣe ni laanu pe iru iṣẹlẹ naa waye, paapa nilẹ Yoruba.
Oríṣun àwòrán, Reuters Pẹlu bi nkan ti ṣe duro bayi, Arsenal wa ni ipo Kẹrinla lori afara liigi.
Ta ló lè sọ iṣẹ́ agbára OLUWA tán?
Nígbà tí ọpọlọpọ ibi ati wahala bá dé bá wọn, orin yìí ni yóo jẹ́ ẹ̀rí fún wọn (nítorí pé arọmọdọmọ wọn yóo máa kọ ọ́, wọn kò sì ní gbàgbé rẹ̀); nítorí pé mo mọ ète tí wọn ń pa, kí ó tilẹ̀ tó di pé mo mú wọn wọ ilẹ̀ tí mo búra láti fún wọn.
Ile ẹjọ ko ṣe iye meji ki o to dajọ pe o jẹbi ẹsun ipaniyan ti ijọba ipinlẹ Eko fi kan.
'Ọrọ naa le debi pe, mo bẹrẹ si ni lo oogun oloro ati siga.
Oriṣiriṣi awọn eniyan ni wọn n polowo lori ẹrọ ayelujara rẹ ati irufẹ awọn Dokita to le ṣe fifi idi tobi to fi mọ ti ilẹ Brazil.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù ENDSARS, End SWAT: Ààrẹ Buhari ló pa àṣẹ tó mú kí iléeṣẹ́ ọlọ́pàá ó dá ikọ̀ SARS sílẹ̀, Fulani Kwajafa tó dá SARS sílẹ̀ ṣàlàyé 15 Ọ̀wàrà 2020 Oríṣun àwòrán, Aisha yesufu Kaakiri agbaye, ọrọ ikọ kogberegbe ọlọpaa ti ọpọ mọ si SARS lo gbaye kan bayii.
Nítorí ìdí èyí ọba yára ránńṣẹ́ sí ọkùnrin apẹja náà wí pé kí ó lọ pa irú ẹja mẹ́ta bẹ́ẹ̀ wá fún òun.
Ǹ báà kò gbogbo ohun tí mo ní, kí n fi tọrẹ, kódà kí n fi ara mi rú ẹbọ sísun, bí n kò bá ní ìfẹ́, kò ṣe anfaani kankan fún mi.
Bí aṣọ ìlọ́dìí tií lẹ̀ mọ́ ọkunrin lára, bẹ́ẹ̀ ni mo mú kí gbogbo ilé Israẹli ati gbogbo ilé Juda súnmọ́ mi, kí wọ́n lè jẹ́ eniyan mi, ati orúkọ mi, ìyìn mi, ati ògo mi.
Ẹni to ba jawe olubori lati gba alejo idije yiI lọdun 2019 yoo mura gidi ni nitori oṣu mẹfa pere ni wọn yoo ni lati palẹmọ fun idije naa ti orileede merinlelogun fẹ kopa ninu rẹ laarin ọjọ kẹẹdogun oṣu kẹfa Si ọjọ kẹtala oṣu keje.
Àkọlé àwòrán, Oluwo fẹ fi ọgbọn rẹ kun ohun to yẹ ni ilẹ̀ Yoruba Ọba Oluwo, Oba Olugbo, Ọba Eleruwa, ati gbogbo alade lo n forikori pé kini ọna abayọ?
Akẹ̀ nínú àwọn ènìyàn wa tilẹ̀ dá àbá pé kí a lọ kí Aláṣetẹ́ ọba wọn, ṣùgbọ́n nígbà tí a rántí Òmùgọ̀dìmejì àti Òmùgọ́dimẹ́ta àwọn ọba Èdìdàrẹ́ àti ohun tí ojú wa rí ílú wọn, a pínnu, pé a kò ni lọ.
“Lẹyin eto iforukọsilẹ awọn ondibo to kọja yii, a ti ni akọsilẹ awọn to ṣẹṣẹ forukọ silẹ ẹgbẹrun lọna ẹẹdẹgbẹta (700,000) ni Ipinlẹ Eko, ati pe, ohun ti eyi tumọ si ni pe a o nilo alekun awọn ibudo idibo kekere.
Àwọn ọmọ Esau ni Elifasi, Reueli, ati Jeuṣi; Jalamu ati Kora.
Atiku ni INEC gbọdọ yanju ọrọ ohun elo idibo ko to di Satide Atiku ti wa ke pe ajọ INEC pe, wọn ko gbọdọ ṣegbe lẹyin ẹgbẹ oṣelu kankan.
Àwọn nǹkankan wà tí ń jọ mí lójú,àwọn nǹkan mẹrin kò yé mi:
Ojo Aje ọsẹ yii ni wọn gbe arakunrin naa lọ si ile iwosan, ti wọn ko si sọ ohun to ṣe e, lẹyin naa ni wọn gbe e lọ si ile igbokusi.
Wọ́n wá ìrànlọ́wọ́ káàkiri,ṣugbọn kò sí ẹni tí ó lè gbà wọ́n;wọ́n pe OLUWA,ṣugbọn kò dá wọn lóhùn.
Lẹ́yìn ìgbà tí Jobu gbadura fún àwọn ọ̀rẹ́ rẹ̀ mẹtẹẹta tán, OLUWA dá ọrọ̀ Jobu pada, ó sì jẹ́ kí ó ní ìlọ́po meji àwọn ohun tí ó ti ní tẹ́lẹ̀.
Ẹ jẹ́ ká dé Ìpínlẹ̀ Èkó, ká wòran díẹ̀.
O seleri lati mase gbe igba ibo mọ amọ ti ko mu ileri naa sẹ: Oríṣun àwòrán, Abiola Ajimobi Igba miran ti ẹnu tun kun Abiola Ajimobi ni akoko to ṣeleri pe oun ko ni gbe igba ibo mọ lati bẹbẹ fun ipo oṣelu lọdọ araalu.
Bẹẹni awa na ti ṣe ro amọ ifẹsẹwọnse ti yoo waye lale oni lo mu ki orẹ di ọta ki ọta si di ọrẹ.
Kì í sì í ṣe ìmẹ́lẹ́ nìkan, wọn a máa di olófòófó ati alátojúbọ̀ ọ̀ràn-ọlọ́ràn, wọn a sì máa sọ ohun tí kò yẹ.
Wọ́n ń gbọ́ ohun tí ò ń wí, ṣugbọn wọn kò ní ṣe é.
kefa , lara awon to tẹle aare Buhari ni gomina 
Wo bi o ṣe le mu ara rẹ ji pepe sii fun ibalopọ: Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Fi ọkan rẹ sinu adun ti o fẹ gbadun pẹlu ololufẹ re.
Ṣugbọn àwọn ojo, àwọn alaigbagbọ, àwọn ẹlẹ́gbin, àwọn apànìyàn, àwọn àgbèrè, àwọn oṣó, àwọn abọ̀rìṣà, ati gbogbo àwọn èké ni yóo ní ìpín wọn ninu adágún iná tí ń jó, tí a fi imí-ọjọ́ dá.
Mose sọ fún àwọn eniyan náà pé, “Nisinsinyii ni ẹ óo mọ̀ pé èmi kọ́ ni mo yan ara mi ṣugbọn OLUWA ni ó rán mi láti ṣe gbogbo ohun tí mò ń ṣe.
Wọ́n pa àwọn ọmọ ogun Filistini ní ọjọ́ náà, láti Mikimaṣi títí dé Aijaloni; ó sì rẹ àwọn eniyan náà gidigidi.
Lasiko ti awọn ọlọpaa mu Hushpuppi, ọwọ wọn tẹ awọn iwe akọsilẹ nipa jibiti kan, ti owo rẹ to ojilenirinwo din maarun miliọnu Dọla, t'oun n murasilẹ fun.
Jemimah: Wàhálà àwọn òbí mi pọ̀ ló jẹ́ kí n gbé ara mi níyàwó
”Ninu ipade ohun lati ri: oga agba yanyan fun ile-ise olopaa, ogagun Ibrahim Idris ati awon oga agba ile-ise alaabo miiran,  lati ba awon oludije ati awon eniyan won lapapo soro lati ri daju pe, eto idibo ohun lo nirowo-rose.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Iná Ibadan: Gbogbo dúkìá tó wà lókè ilé alájà kan náà ló jóná tán Oṣe meji ni ijọba apapọ buwọlu lẹyin ti igbimọ naa tọrọ aye si lọdọ ijọba.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Irọ́ ńlá ni pé ewé dongoyaro le wo ààrùn coronovirus Atẹjade kan tí àjọ eleto ìlera náà fisita ni ẹ̀jẹ̀ náà ni àwọn yóò lo ni ìbẹ̀rẹ̀ láti dán-án wo, bóyá yóò lè wo àrùn Covid-19 san""."
Oríṣun àwòrán, Genesis global Awọn aṣọna Awọn wọnyii lo ma n duro ni awọn ẹnu ọna to wọ inu ṣọọṣi naa.
Nibi ipade naa ni wọn ti fi ẹnu ko pe ki wọn da ikọ pataki kan silẹ ti yoo maa gbena woju awọn adigunjale naa nigba naa.
Bẹ́ẹ̀ gan-an ni ẹ̀yin náà rí lóde, lójú àwọn eniyan ẹ dàbí ẹni rere, ṣugbọn ẹ kún fún àṣehàn ati ìwà burúkú.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Wọ́n ké sí ààrẹ láti wá dáhùn ìbéèrè lórí àwọn ẹ̀mí tó nù 26 Ìgbé 2018 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ilé asòfin ní kí Buhari wá sọ tẹnu ẹ Wọ́n ti ké sí ààrẹ orílẹ̀èdè Nàìjíríà, Mohammadu Buhari kó wá farahàn níwájú ilé ìgbìmọ̀ asojú-sòfin láti dáhùn àwọn ìbéèrè nípa ìsẹ̀lẹ̀ ibi tó wáyé ní ààrin gbùngbùn Nàìjíríà èyí tó ti fa ikú ọ̀pọ̀lọpọ̀ lọ́dún yìí.
Lẹ́yìn rẹ̀ ni Pedaaya, ọmọ Paroṣi, 
 ipele àkọ ́ kọ ́ àkóràn àrùn náà ni a lè dámọ ̀ nípasẹ ̀ kókó tàbí ibití ó wú lára ẹni .
Josẹfu bá dìde ní òru, ó gbé ọmọ náà ati ìyá rẹ̀, ó lọ sí Ijipti.
Oríṣun àwòrán, Eric Lafforgue/Art in All of Us Àkọlé àwòrán, Sufi whirling dervish at Omdurman sheikh Hamad el Nil tomb, Khartoum State, Omdurman, Sudan on January 4, 2019 in Omdurman, Sudan.
 Eyi sele leyin ojo kejo ti awon omo ile igbimo gba isuna owo naa wole tan.
Igbakeji aare pelu iyawo re, Dolapo
Oríṣun àwòrán, @ProfOsinbajo Àkọlé àwòrán, Àwọn obìrin náà a máa du igbákejì Ààrẹ Osinbajo ṣùgbọ́n.
Ki lo wa ninu ofin tuntun naa?
Iná ẹ̀lẹ́ńtíríkì pa ọlọ́kadà, obìnrin kan ní Ibadan, àjọ IBEDC ní àwọn ti bẹ̀rẹ̀ ìwadìí Oríṣun àwòrán, undark magazine Saaju la ti mu iroyin wa fun yin pe opo ina mọnamọna ti wo pa ọlọkada kan ati obinrin kan lagbegbe Iwo road ni ilu Ibadan.
Wọ́n ṣọ̀fọ̀, wọ́n sọkún, wọ́n sì gbààwẹ̀ títí di ìrọ̀lẹ́; nítorí Saulu ati Jonatani, ọmọ rẹ̀, ati àwọn ọmọ Israẹli, eniyan OLUWA nítorí pé ọpọlọpọ wọn ni wọ́n ti pa lójú ogun.
’ Àwọn ìbéèrè tí ó ń bèèrè ni ó mú kí á sọ ohun tí a sọ fún un.
"Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: ""Ojú wa rí tó ní Egypt, bí wọ́n ṣe ń tẹ̀ wá lọ́mú, ni wọ́n ń gbá wa ní ìdí"" Wo orílẹ́èdè tí wọ́n tí ń dáwó ìsìnkú ara wọn pámọ́ Àtúntò alágbára yóò bá ètò ìgbóhùnsáfẹ́fẹ́ - Lai Mohammed A kò fẹ́ 23% tẹ fẹ́ yà sọ́tọ̀ bíí owónàá fáwọn ìjọba ìbílẹ̀ - ALGON Ọlọ́wọ̀ tìlú Ọ̀wọ̀ tuntun gorí ìtẹ́, idà àlááfìà ló mú ní Ìpèbí Á máa ṣíjú àánú wo ẹlẹ́wọ̀n láti mú àdínkù bá ọgbà ẹ̀wọ̀n - Ìjọba Ọyọ Toyin Abraham kìí bá èmi náà yọ̀, ni kò jẹ́ kí ń gbé e lárugẹ fún ayọ̀ ọmọ - Lizzy Anjorin Wọn ni eyi ni yoo jẹ ki aarẹ orilẹede yii, Muhammadu Buhari bawọn da si ọrọ naa ti ko fẹẹ ni ojutu rara bayii, ti wọn yoo si ni anfaani lati se atunse si owo osu tuntun naa."
Wọn kò ní pada, àfi àwọn bíi mélòó kan ni wọ́n óo sá àsálà.
Mose bá dá wọn lóhùn, ó ní, “Bí nǹkan tí ẹ sọ yìí bá ti ọkàn yín wá, tí ẹ bá di ihamọra ogun yín níwájú OLUWA, 
Ẹ má kó ìbànújẹ́ bá Ẹ̀mí Mímọ́ Ọlọrun, tí Ọlọrun fi ṣèdìdì yín títí di ọjọ́ ìràpadà.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Sibahle Zwanen fi ìmọ̀ ìṣìro da orí ayélujára rú Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ọpọlọpọ awọn ẹya Hindu tako igbe aye awọn ẹlẹsin Agoris.
Ajo  INEC , yoo se ipade pẹlu awon ajo eleto aabo
Ìdí abájọ ni pé àwọn ihò ojú-ewé náà, álúfábẹ́ẹ̀tì àti ònkà afọ́jú tí wọ́n npè ní Braille ni wọ́n jẹ́.
Wọ́n bá wí fún Samuẹli pé, “Má dákẹ́, gbadura sí OLUWA Ọlọrun wa, kí ó gbà wá lọ́wọ́ àwọn ará Filistia.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Erin meji ni Masai Mara ni Kenya Idanre jẹ ilu ti o lewaju ninu awọn ilu ti o n ṣe iṣẹ ọgbin cocoa ni orilẹede Naijiria, ṣugbọn awọn olugbe kan ni idanre sọ wipe awọn erin ti n pa awọn ere oko wọn lati ọjọ pipẹ.
Afeez sọrọ lori àwọn idojukọ ti oju rẹ n ri lori gigun to gun yii bii ki o ṣalai ri aṣọ to maa gbaa lọja tabi ki o di àpéwò fun awọn eniyan nigba ti wọn ba kọkọ foju kan an.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Fatai Rolling Dollar: Baba 70 jayé kọjá 70 kó tó dágbére fáyé pé ó dìgbóṣe!
Nítorí àgbájọpọ̀ àwọn ìràwọ̀ ojú ọ̀run yóo kọ̀, wọn kò ní tan ìmọ́lẹ̀.
 níhìín ni wọn yíò tí máa sun rárà kí gbogbo àwọn àlejò tí ó bá ń lọ kí aláàfin .
Nígbà tí òun náà dé ibẹ̀, tí ó rí i, ó gba òdìkejì kọjá lọ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ijinigbe: BBC ṣe ìwádìí bí ikọ̀ IRT ṣe ń gbéjà ko awọn ajinigbe lójú Kehinde to n sọrọ lorukọ ọga agba LASEMA, Oluwafẹmi Oke-Osanyintolu sọrọ lori pataki ki awọn ara ilu tẹle awọn ofin to de irinna oju omi.
Bẹẹ ni yoo ma kọrin titi yoo fi ri awọn ẹni keji rẹ.
Bí arákùnrin àgbẹ̀ náa ti rí mi ló súré tete tọ̀ mí wá, a wá jọ pasẹ̀pọ̀ dé ibi abà rẹ̀.
Èèyàn mẹ́rin míràn ti lùgbàdì àrùn Coronavirus ní Naijiria Máfọ́, mo wà pẹ̀lú ẹ, Ajimọbi kàn sí Makinde lóri Coronavirus to ni Ǹjẹ́ fífi omi àti iyọ̀ yọnu leè dènà àrùn Coronavirus?
Ilé Ìsìn Ti Ayé ati Ti Ọ̀run.
Ó gbé e kalẹ̀ ní pẹ̀tẹ́lẹ̀ Dura ní agbègbè Babiloni.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ademọla Adeleke: Àwọn akẹẹgbẹ́ mi ní iléẹ̀kọ́ girama mọ̀ mi bíi ìsáná ẹlẹ́ẹ́ta 8 Ògún 2018 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 10 Ògún 2018 Oríṣun àwòrán, @IsiakaAdeleke Àkọlé àwòrán, Adeleke ni oun lọ si fasiti kan ni ilẹ Amẹrika lai lo iwe ẹri oniwe mẹwa Waec ti oun ni Ademọla Adeleke, tii se oludije fun ipo gomina labẹ́ẹ ẹgbẹ oselu PDP ni ipinlẹ Ọsun sọrọ lẹyin idajọ ile ẹjọ nipa iwe ẹri rẹ.
Awọn aladugbo naa ni wọn fi ipa mu u lati fi saare to sin baba rẹ naa si han ti wọn si tun ni ko hu oku rẹ jade pada.
Ọ̀pọ̀ eniyan a máa ka ara wọn kún olóòótọ́,ṣugbọn níbo la ti lè rí ẹyọ ẹnìkan tó jẹ́ olódodo?
Ninu oṣu kẹta ajọ FIFA buwọlu aatọ Infantino fun ikọ agbabọọlu ẹlẹni mẹrinlelogun ti yoo bẹrẹ lọdun 2021 bi o tilẹ jẹ pe awọn ikọ agbabọọlu ilẹ Yuroopu to lokiki ni awọn ko ni yẹ idije naa.
Ṣugbọn inú àpò awọ titun ni à ń fi ọtí titun sí.
Bẹẹ naa ni ijọ Foursquare Gospel Church sọ pe ki Igbeneghufi ipo rẹ silẹ gẹgẹ bi pasitọ ijọm ọhun.
Ti ènìà bá rin ọ̀nà yìí díẹ̀ , yó máa wo òkúta nlá kan lókèrè.
Èyí ni iye ọdún tí wọ́n fi dẹ́ṣẹ̀.
Ta bá yá owó lókèèrè kò láìfí, ìpèsè ohun amáyédẹrùn là ń ṣe – Lai Mohammed Ìtàn ayé Alájọ Ṣómólú rèé, tó ta mọ́tò ra kẹ̀kẹ́?
" Oríṣun àwòrán, Akeugbagold/Facebook Nigba to n salaye pe oun kii fi owo jẹ awọn oṣiṣẹ oun niya, agba Alfa naa tun sísọ loju rẹ pe, ẹgbẹrun lọna ọgọrun naira ni oun maa n ṣan fun awọn mejeeji to n ṣe akoso oju opo itakun agbaye oun lẹyin aawẹ Ramadan.
Bisobu Oyedepo wa ro awon onigbagbo lati maa se kaare ninu adura gbigba fun amupada alaafia ni ipinle Plateau ati awon agbegbe miiran ti emi okunkun ti joba kaakiri orile-ede Naijiria.
Ẹgbẹgbẹ̀rún ọmọ Nàìjíríà ní yóò má a kú lójoojúmọ́ tí wọn bá gbà wọ́n láàyè láti gbébọn dání- Amofin Ooni Ifẹ bu ẹnu ẹ̀tẹ́ lú ètò BBNaija nítorí ó tàbùkù àsà Yoruba Immaculate Okochu ń múra ìyàwó lọ́wọ́ ló k'àgbákò ikú Ìjọba ìpínlẹ̀ Osun tí búwọlù ìlànà àyẹyẹ Osu-Osogbo ọdún 2020 O dara fun wa gẹgẹ bii Musulumi ati tori bi ilu ṣe n lọ bayii tori bi wọn ba sọ pe nile aye yii, nkan bii ifipabanilopọ lee gbilẹ to bayii, iyẹn nipe eniyan ko wulo."
Ọdún Ọlọ́jọ́ dùn ní Ilé Ifẹ̀, ó lárinrin Taa ni Jọkẹ Silva, òsèré tíátà tó ń se ọjọ́ ìbí ?
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Alaafin: Lẹ́yìn rògbòdìyàn ààfin Ọyọ, ẹ wo bẹbẹ tí Olorì Badra ń ṣe 27 Owewe 2020 Yoruba ni laala to roke, ilẹ lo n bọ, bẹẹ ni aaro kii gbona di alẹ.
 o gbajumo fun ajotunmo hegemoni asa gege bi ona ti orileijoba ninu awujo kapitalisti , be na sini won gba bi akopa koko ninu imoye .
Nígbà tí wọ́n kà á, inú wọn dùn sí ọ̀rọ̀ ìyànjú tí ó wà ninu rẹ̀.
Orúkọ arakunrin rẹ̀ ni Jubali, òun ni baba ńlá gbogbo àwọn tí wọn ń lu hapu ati àwọn tí wọn ń fọn fèrè.
 wọ ́ n sì le kọrin ki ifá .
 “Bi o se je pe, isejoba
"Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Àwọn kànga ìṣẹ̀ǹbáyé rèé ní Badagry tó ń pa ẹrú níyè Ìyàwò lárìnlọọ̀dù mi pè mí ní akálòlò ni mo ṣe paa - Afurasí ""Ambode, wá jẹ́jọ́ lórí ọkọ̀ BRT 5000 to ló fi ₦45b rà, àmọ́ 820 péré ló kó wá"" Buhari, pe ìpàdé àpérò ọmọ Nàíjíríà fún àgbékalẹ̀ òfin tuntun - Afe Babalola ‘Kò sí ohun tó lè yẹ ìfèhọnú ọjọ karun un Oṣu Kẹsan lórí àtìmọ́lé Omoyele Sowore’ Buhari, pe ìpàdé àpérò ọmọ Nàíjíríà fún àgbékalẹ̀ òfin tuntun - Afe Babalola Awọn ti yoo wa ninu igbimọ alaabo alajumọse naa ni awọn osisẹ ologun, ọlọpaa, aabo ara ẹni laabo ilu, asọgbo, ọdẹ ibilẹ, ọmọ ẹgbẹ Oodua (OPC) ati awọn osisẹ alaafia."
Gẹgẹ bo ṣe sọ, o ni ijọba ti bẹrẹ eto ayẹwo ti ileeṣẹ naa gbe kalẹ fun oṣiṣẹ rẹ, yoo si fi iya to tọ jẹ ileeṣẹ ọhun lẹyin iwadii rẹ.
International School, Jalingo, to wa ni ipinle Taraba , ni Ariwa orile ede
Ṣé mo ti sọ tẹ́lẹ̀ nípa ìyànjẹ owó ọkọ̀ ofurufú nígbàkan?
Buhari: Mo tara lori ijinigbe ju ijọba ana lọ
Oun lo ṣaaju ìwọ́de ti wọn ṣe lati fẹhonu han lori owo orí gọbọi àti ìyà ti wọn n jẹ lọwọ awọn Oyinbo Ajẹ́lẹ̀.
Bí wọ́n bá bi ọ́ pé níbo ni kí àwọn ó lọ, sọ fún wọn pé èmi OLUWA ní, ‘Àwọn tí wọn yóo kú ikú àjàkálẹ̀ àrùn,kì àjàkálẹ̀ àrùn pa wọ́n;àwọn tí wọn yóo kú ikú ogun,kí ogun pa wọ́n.
Mose dáhùn pé, “Wọn kò ní gbà mí gbọ́, wọn kò tilẹ̀ ní fetí sí ọ̀rọ̀ mi, wọn yóo wí pé, OLUWA kò farahàn mí.
Bakan naa, oluranlọwọ agba fun aarẹ sọ pe aarẹ Buhari ti kọwe si adele adajọ agba Tanko Muhammed lati yan adajọ marun un mii si ile ẹjọ giga ju lọ ti orilẹede Naijiria.
“Àwọn àjọ̀dún wọnyi ni OLUWA ti yà sọ́tọ̀; ẹ óo máa kéde wọn gẹ́gẹ́ bí àkókò ìpéjọpọ̀ mímọ́, láti máa rú ẹbọ tí a fi iná sun sí OLUWA, ẹbọ sísun, ati ẹbọ ohun jíjẹ; ati ẹbọ ohun mímu, olukuluku ní ọjọ́ tí a ti yàn fún wọn.
”Adari orile ede wa seleri pe , ijoba oun yoo wo ona lati mu ilana eto isuna rọrun lona ti orile ede yii yoo se padasi igba aey atijo  nipa gbigbe iwe eto isuna lo sile igbimo asofin ni kiakia,ni osu kejila si osu kinni odun.
Wọ́n ń sọ pé:“Ṣé ìlú yìí ni à ń pè níìlú tí ó lẹ́wà jùlọ,tí ó jẹ́ ayọ̀ gbogbo ayé?
gomina ana ni ipinlẹ Oyo to ti di oloogbe bayii, Abiola Ajimobi lo gbe ọpa aṣẹ le ọba Saliu lọwọ to si sọ ọrọ iyanju lọjọ naa pe ki awn oloye alabaṣiṣẹpọ rẹ takete si gbogbo ọrọ oṣelu.
Bi onirese Duro Ladipọ ko si fingba mọ, eyi to ti fin silẹ ko to jade laye ko lee parun, tori pe o dabira lagbo tiata ko to jade laye.
Kii ṣe ilu Abuja nikan ni coronavirus ṣọṣẹ lọjọ Abamẹta, eeyan meji lo gbẹmi mi ni ipinlẹ Kebbi nigba ti eeyan kọọkan ki nipinlẹ Bornu, Katsina, Kaduna, Kwara ati Nasarawa.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù World Food Day 2020, Yollywood; Dayọ̀ Amúsà jẹ́wọ́ ara rẹ̀ lórí ètò Àjẹpọ́nulá Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ World Food Day 2020, Yollywood; Dayọ̀ Amúsà jẹ́wọ́ ara rẹ̀ lórí ètò Àjẹpọ́nulá 4 Èbibi 2018 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 16 Ọ̀wàrà 2020 Gbajúgbajà òsèré tíátà Yoruba, Dayọ̀ Amúsà kò kàn jẹ́ obìnrin òsèré lásán, ó tún jẹ́ obìnrin nínú ilé.
Ní ọdún kẹsan-an tí Hoṣea jọba, ọba Asiria ṣẹgun Samaria, ó sì kó àwọn ọmọ Israẹli ní ìgbèkùn lọ sí Asiria.
Oṣu Kẹrin, ọdun 2019, ni IS kede idasilẹ rẹ nibẹ.
3 trillion ni CBN gbé jáde fún ọdun 2020 Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ọmọ Yahoo tú àṣírí ara rẹ̀ fún, bí wọ́n ṣe ń ṣe é BBC Yorùbá Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Gomina Ortom ni fifun awọn ọmọ Naijiria ni anfaani naa yoo dẹkun eto aabo to dẹnukọlẹ ni Naijiria.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ankara Design: Ai ri oníbara ló jẹ́ kí n wá ọ̀gbọ́n àtinúdá tèmi.
George padanu iṣẹ iṣẹ rẹ tori ajakalẹ aarun coronavirus l'Amẹrika Iṣẹ eṣọ ni George Floyd n ṣe pẹlu ileeṣẹ kan, Salvation Army charity ni Minneapolis.
Ojó keta òrò yìí ni oba wàjà.
"Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Coronavirus: 'Ewu ni tí Covid-19 bá wọ àdúgbò wa bí a ṣe fún pọ̀ yìí' Rev Juliet, Alufaa kan ni ilu Eko ni ""Ọlọrun lo yan Trump pe o ni ."
Díẹ̀ lára àwọn àṣọ to dá ẹrọ ayélujara rú rèé níbi ayẹyẹ náà.
Eyi ko ṣẹyin bi awọn ajinigbe tun ṣe ṣe ikọlu si ọkọ Toyota Sienna to gbe awọn eniyan mẹjọ to n lọ lati ilu Abuja si Eko ni Ọjọru.
Ẹwẹ, ile aṣofin agba naa fidi rẹ mulẹ pe awọn ṣetan lati ṣe agbeyẹwo ero awọn ọmọ Naijiria lori abadofin ọhun.
Amọ ọjọ Aje ni iroyin gbalẹ pe, ile ẹjọ giga ilu Abuja ti ni ki Sẹnatọ Abbo yii lọ san miliọnu lọna aadọta naira fun obinrin naa, ti Abbo fiya jẹ.
“Àwọn àjèjì tí ó bá darapọ̀ mọ́ OLUWA, tí wọn ń sìn ín,tí wọn fẹ́ràn rẹ̀, tí wọn sì ń ṣe iranṣẹ rẹ̀,gbogbo àwọn tí ó bá pa ọjọ́ ìsinmi mọ́, tí kò sọ ọ́ di ohun ìríra,tí ó sì di majẹmu mi mú gbọningbọnin,
Awakọ naa sọ ọ di mimọ wipe kete ti iṣẹlẹ naa ṣẹlẹ ni oun ti pe awọn ọlọpa ni ẹka ti Yaba ni Ondo.
Amọṣa, o ni bi o ti wu ko ri, oun ti gba ohun ti awọn ọmọ ẹgbẹ sọ ati ẹni ti wọn yan.
Roy soro yii nilu Abuja pe ise ona awon omo Naijiria maa n ya oun lenu nigba gbogbo ni.
Nigba tohunkohun ko waye ninu oṣu karun un, ni Camping sọ pe idajọ inu ẹmi lo ti ṣẹlẹ lọjọ naa ati pe igbasoke ati idajọ gangan yoo waye papọ ninu oṣu kẹwaa.
Ó ní gbogbo ọmọ ẹgbẹ́ ló ń tẹ̀lé àṣẹ́ ijọba nípa títà á ni ìye ti ijọba sọ, tí àwọn míràn tilẹ̀ ń tà á ni ìye tó tún kéré jù bẹ́ẹ̀ lọ.
Ní gbígbọ́ nípa ìparun ilé iṣẹ́ ìtẹ̀wé ti Missouri, Joseph Smith àti àwọn olùdarí Ìjọ mìíràn bẹ̀rẹ̀ àwọn ìpalẹ̀mọ́ láti tẹ àwọn ìfihàn náà ní Kirtland, Ohio.
"Lọsẹ yii a ti padanu arabinrin wa, ẹni daradara ati arẹwa obinrin, Ibidunni.
Ní gbogbo àsìkò tí Asa ọba Juda ati Baaṣa ọba Israẹli wà lórí oyè, ogun ni wọ́n ń bá ara wọn jà.
Fiimu yii naa yombo akọni ẹda itan.
Google bẹ̀rẹ̀ sí lo ohùn Nàìjíríà lórí ẹ̀rọ̀ ajúwe ọ̀nà Agbébọ́n tún ṣoro ní márosẹ̀ Ibadan sí Eko, wọ́n jí èèyàn mẹ́ta gbé Ta ló ni $1.
O ko gbọdọ kuru ju iwọn 1.
17 Bélú 2020 Fídíò, Oba Adedokun Abolarin ti Oke Ila: Ó ya ọ̀pọ̀ tó súnmọ́ mi lẹ́nu bí mo ṣe ń kọ́ àwọn akẹ́kọ̀ọ́ pẹ̀lú ipò Ọba23 Bélú 2020 Fídíò, The New Pandemic: Kíni àwọn onímọ̀ sáyẹ́ńsì ń sọ nípa rẹ̀?
Bakan naa nitori pe ọna irinajo lati ibi kan si ibi keji ni ọpọ agbegbe ilẹ Adulawọ ko rọr\\uin, eyi ko jẹ ki awọn eeyan tun tan arun naa kalẹ pupó bii ti awọn orilẹ-ede ti idagbasoke wọn ti pọ.
”Adonija dá a lóhùn pé, “Alaafia ni, 
Amọ́, lẹ́yìn ìwádìí náà ni Ọgagun Adebayo bá kéde pé òun tún rọ ọba Olateru-Olagbegi Kejì lóye, tó sì le lọ silu Òkìtìpupa.
    Ṣùgbọ́n mo sàkíyèsí pé bí wọn tí ń bọ̀ tí wọn n wọ aṣọ dídára to nì, ẹkún ni àwọn méjéèjì ń sun.
A óo dójúti àwọn aríran, ojú yóo sì ti àwọn woṣẹ́woṣẹ́; gbogbo wọn yóo fi ọwọ́ bo ẹnu wọn, nítorí pé, Ọlọrun kò ní dá wọn lóhùn.
Wọn tun rọ àwọn ọmọ Nàìjíríà láti máse káárẹ̀ nípa orilẹ̀-èdè yìí nitori ìgba ọtun ti dé , wọn wa rọ gbogbo ènìyàn láti túbọ máà gbádúra fún ìtẹsíwájú àti àláfíà Nàìjíríà.
Irufẹ oko oku bayi si to mẹfa ọtọtọ to wa nilẹ Amẹrika, tawọn orilẹede bii Australia, Canada ati UK naa si n gbero lati ni oko oku ti wọn naa.
Ọwọ wọn si tẹ afurasi meji.
Wọn kò mú aṣọ náà kúrò, nítorí nípasẹ̀ Kristi ni majẹmu àtijọ́ fi di asán.
 iṣẹ ́ ribiribi ni ó ṣe láàrin ọdún mẹ ́ wàá tí ó fi ṣe olóòtú ìjọba .
Nítorí mo fẹ́ kí o rántí pé bàbá mi ti lọ sí ilé-ìwé kí ó tóó di pá ó bẹ̀rẹ̀ ọdẹ-ṣíṣe, ọgbọ́n tí ó sì kọ́ ní ilé-ìwé ń ràn án lọ́wọ́ àti kó owó jọ.
Lekki Toll gate: Àwọn ọlọtẹ̀ ló ń gbìyànjú láti dá ọ̀tá sílẹ̀ láàrin èmi àti ẹ̀yin ènìyàn mi
Ẹ máṣe gba ààwẹ̀ dójú ikú, ẹ gba iye tí agbára yín gbé - Dókítà O ni eyii nii ṣe pẹlu bi awọn ajọ alaabo ṣe ti awọn aala orilẹ-ede Naijiria pẹlu awọn orilẹ-ede gbogbo to yii ka lọna ati lee dẹkun fayawọ lorilẹ-ede Naijiria.
Yusuf sọ pe babalawo nikan lo mọ ibi ti oku Kembi wa.
Oòrùn bẹ̀rẹ̀ sí jó àwọn eniyan bí iná ńlá, wọ́n bá bẹ̀rẹ̀ sí sọ ọ̀rọ̀ àfojúdi sí orúkọ Ọlọrun tí ó ní àṣẹ lórí àwọn àjàkálẹ̀ àrùn wọnyi, dípò kí wọ́n ronupiwada, kí wọ́n fi ògo fún un.
Ó wọn òòró yàrá náà, ó jẹ́ ogún igbọnwọ, (mita 10), ìbú rẹ̀ sì jẹ́ ogún igbọnwọ (mita 10), níwájú ibi mímọ́ náà.
” Obedi yìí ni baba Jese tíí ṣe baba Dafidi.
Nítorí náà nípa oúnjẹ tí a fi rúbọ fún oriṣa, a mọ̀ pé oriṣa kò jẹ́ nǹkankan ninu ayé.
Eto igbalejo ounjẹ ọsan yii kò wa fun gbogboogbo ni ilu Ọba.
Okunnu ṣàlàyé pé, ara ìyá òun ni òun ti mú ẹ̀bùn awada sise.
Iṣẹlẹ miran to jọọ ti waye lorilẹede Burundi sugbọn oogun abẹnu gọngọ ni wọn di ẹbi iṣẹlẹ yii ru o.
Ẹ̀kọ́ kẹrin ni pé kí àwọn ọrẹ méjì má ṣe torí ọ̀rọ̀ òṣèlú sọ ara wọn di ọ̀tá ayérayé.
Ohun tí ó bá ti wọ́, ẹnìkan kò lè tọ́ ọ, bẹ́ẹ̀ ni ẹnìkan kò lè ka ohun tí kò bá sí.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Akomolede ati Aṣa lori BBC: Mọ̀ si nípa oríṣìí ẹ̀ka ìsọ̀rí ọ̀rọ̀ àti ìwúlò wọn Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Akomolede ati Aṣa lori BBC: Mọ̀ si nípa oríṣìí ẹ̀ka ìsọ̀rí ọ̀rọ̀ àti ìwúlò wọn 8 Owewe 2020 BBC Yoruba tun ti de laarọ yii lati la wa lọyẹ nipa ẹkọ ede Yoruba lori eto wa Akọmọlede ati Aṣa.
Gomina Sanwo-Olu ranṣẹ ibanikẹdun si awọn ti ẹbi ati ara ba iṣẹlẹ naa atawọn ti ile wọn ati ọpọ dukia wọn ṣofo ninu iṣẹlẹ naa.
Kìnìhún nìkan kọ́ ló burú, àwọn ajá mẹ́wàá yìí náà kò fararọ!
Iléeṣẹ́ ọmọ ogun dá Bashir tó ri owó he lọ́lá Ẹ ṣọ́ra fún ìròyìn ẹlẹ́jẹ̀ lórí ètò ààbò - Ọlọ́pàá Etí ìjọba Buhari di sí ìmọ̀ràn àwọn ará ìlú -Jiti Ogunye Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Kayeefi: Facebook ni Wolii Arole Jesu fi tàn an wọ agbo, orí rẹ̀ ni wọ́n fi s'owó Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Mo mọ̀ dájú pé Ọlọrun ń bẹ fún mi.
Ìdí mi di omi, okùn ṣòkòtò mi sì tú.
Àwọn náà ni wọ́n wà fún ati máa ṣe iṣẹ́ ìsìn lẹ́nu ọ̀nà àgọ́ OLUWA, ati láti máa kọrin ọpẹ́ ati ìyìn sí OLUWA.
Lẹyin naa ni wọn pa aṣọ eṣi rẹ da ni Naijiria si 9mobile.
Oríṣun àwòrán, OTHER Ọṣẹ ti one million boys ṣe ni Ibadan: Ni alẹ Ọjọbọ, ọjọ kọkandinlogun oṣu Kejila ọdun 2019, awọn ọmọ ẹgbẹ one million boys ya bo mọsalasi kan ladugbo Kudeti, pẹlu ọkọ Micra kan, kẹkẹ ẹlẹṣẹ mẹta ati ọkada pupọ.
Mustapha wa kilọ fun awọn to wa nipo aṣẹ lati sọra nitori gbogbo awọn to ti lugbadi arun laipẹ ba ṣe aisan, eyi yoo di isejọba lọwọ lati seto ilu ati lati daabo bo wọn.
Ẹ ṣọ́ra, kí ẹ̀tàn má baà wọ inú ọkàn yín, kí ẹ má baà yipada sí àwọn oriṣa, kí ẹ sì máa bọ wọ́n.
Building Collapsed: O kéré tán, ènìyàn 10 ló ti jáláìsí níbi ìṣẹ̀lẹ̀ ilé tó wó ọ̀hún
Akeredolu nijoba yoo bere idanilekoo lori ogbin koko lona igbalode ati igbelaruge lilo koko labele fun ipese ohun mimu gege bi o se wa ninu erongba aare Buhari.
òun ni mò ń rò nígbà gbogbo, sibẹ, ó ṣì ń rú mi lójú: Láàrin ẹgbẹrun ọkunrin a lè rí ẹnìkan ṣoṣo tí ó jẹ́ eniyan rere, ṣugbọn ninu gbogbo àwọn obinrin, kò sí ẹnìkan.
Má ṣe ìlara ẹni ibimá sì ṣe tẹ̀ sí èyíkéyìí ninu àwọn ọ̀nà rẹ̀.
Ìbànújẹ́ ńlá ló sì jẹ́ fún àwọn ara ilé Òmùgọ́parapọ̀ pé bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé gbogbo wọn ni ó ní ìyàwó, síbẹ̀síbẹ̀ ìyàwó wọn kan ṣosọ kò bímọ.
Ọjọ Iṣẹgun, ọjọ kọkanla, oṣu kẹfa ni ibo naa yoo waye niluu Abuja.
Èyí gbé ògo rẹ̀ yọ, àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ sì gbà á gbọ́.
Baba Ijesha ni: Ọlọrun wa kọ si mi nibi ti mo dede jokoo si mo ni (léde Ijesha) Anti mi."
ni jibiti tabi awon iwa ibaje miiran ti ko se feti gbo.
ijoba se ifilole ipolongo kan, leyin ti Aare orile-ede Egypt Abdel Fattah al-Sisi, eni ti o fe dije ninu eto idibo fun saa keji ninu osu ti a wa yii, fun awon omo-ogun naa ni osu meta pere lati pa awon alakata-kiti naa ru pata-pata.
Amugbalegbe aare Buhar lori eto iroyin, Bashir Ahmad, soro yii di mimo lori ero ayelujara(tweeter), niluu Abuja.
Àkọlé àwòrán, Ìtàn Manigbagbe: Ẹ fokan balẹ, àwọn ajakale àrùn kan rèé to burú ju Coronavirus lọ Ìtàn fi yẹ wá pé ó tó mílíọ̀nù lọ́nà àádọ́ta èèyàn ló bá ajakale àrùn Maáwú-maáwú ìí lọ, èyí tó bẹ silẹ laarin ọdún 482 sí 565 CE, to sì gba to ọdún metalelọgọrin kò to kaṣẹ nilẹ.
ninu awon agbofinro ati eso eleto aabo ,nipa fifun won ni iroyin nipa awon
Ẹsun ti igbimọ tẹẹkoto to n risi iwa ibajẹ fun ajọ FIFA fi kan Siasia ni ẹsun riba.
Àwọn ará Marotu ń retí ire pẹlu gbogbo ọkàn wọn, nítorí pé ibi ti dé sí bodè Jerusalẹmu láti ọ̀dọ̀ OLUWA.
Ohun tí ó bá ti sọ ni yóo ṣe,bí ó bá sì sọ̀rọ̀ yóo rí bẹ́ẹ̀.
Àgbálùmọ̀, ohun mẹ́fà tó ń ṣe lára tí o kò mọ̀
 leyin atigba yi oye-ona yi gbale lati kan gbogbo ibase to ni okun-inu itanyindinyindin gegebi itori ibu ilaruru tabi frikuensi .
O ni oun yoo tun ri daju pe oun se amusẹ awọn ipinnu ti wọn ba gbe kalẹ ni kete ti wọn ba se ibura tan fun oun ni osu kinni ọdun to n bọ.
Oluwa iranṣẹ náà sọ fún un pé, ‘Lọ sí ọ̀nà oko, kí o bẹ àwọn ẹni tí o bá rí, kí wọ́n wọlé wá, kí inú ilé mi baà kún.
Ni ọjọ isinmi ni oluranlọwọ pataki fun aarẹ lori eto iroyin ati ibaraalu sọrọ Femi Adesina foju ọrọ oun lede ninu atẹjade kan.
'Fífún ọkọ àti ọmọ l'ọ́yàn ń dènà jẹjẹrẹ ọyàn' O ti pẹ ti ariyanjiyan ti wa lori ẹni to ni ọyan aya obinrin laarin ọkọ rẹ ati ọmọ wọn.
Timi Agbale ko fura pe isẹ iku ni Ọba ran oun, to si lọ lai se awawi kankan pẹlu awọn ọmọ ogun rẹ, to si lọ tẹdo si abẹ igi kan ti wọn n pe ni Ẹdẹ, eyi to wa laarin ilu Arà ati Awó.
Ẹgbẹ Akọmọlede wa dupẹ lọwọ ijọba ipinlẹ Kogi fun bo se gba ẹgbẹ naa lalejo, fun ayẹyẹ aadọta ọdun wọn, ti wọn si gbadura pe iwaju ni ọpa ẹbiti ipinlẹ naa yoo maa re si.
Ṣugbọn wọn kò ṣe anfaani rárá láti jẹ́ kí eniyan borí ìfẹ́kúfẹ̀ẹ́ ti ara.
O kẹkọ gboye ninu imọ ofin ni fasiti ilu Ibadan lọdun 2013 to si tẹsiwaju ninu ẹkọ rẹ nileewe imọ ofin, Yola.
Kila, niluu Ibadan lasiko to n se iwode lati mo bise naa se n lo si.
ipo aare naa yoo maa waye lojo toni.
Dafidi ati àwọn eniyan rẹ̀ ń múra láti sá fún Saulu ati àwọn eniyan rẹ̀ nítorí pé wọ́n ń rọ̀gbà yí wọn ká láti mú wọn.
“Òtítọ́ ni mo sọ fun yín pé opó pọ̀ ní Israẹli ní àkókò Elija, nígbà tí kò fi sí òjò fún ọdún mẹta ati oṣù mẹfa, tí ìyàn fi mú níbi gbogbo.
Kò tún sí ọ̀kan ninu àwọn aposteli yòókù tí mo rí àfi Jakọbu arakunrin Oluwa.
Àkọlé àwòrán, Awọn oluranlọwọ alejo nibi ipade ifọrọwerọ BBC Yoruba nipinlẹ Eko BBC News, Yorùbá Ìdí tí ẹ fi le è nígbàagbọ́ nínú ìròyìn BBC Ìlànà Lílò Nípa BBC Òfin Àṣírí Cookies Kàn sí.
’ fun saa keji gege bi aare orile-ede Naijiria niluu Abuja.
naa, ni a  n se itọpinpin lori ohun ti o
Wahala ọrọ aabo to gbode ni irinajo aarẹ da le lori Iroyin sọ wi pe, ọgọọrọ awọn olugbe ipinlẹ naa ni wọn tu sita lati ki Aarẹ buhari kaabọ sibẹ.
Ṣugbọn iwadii ọhun dojuru lẹyin ti awọn ti wọn fiwe pe lati NDDC jade kuro niwaju igbimọ naa pẹlu ibinu.
Mohammad Sajadi to jẹ aṣaaju ikọ iwadii naa ni abajade naa fihan pe ibi tutu lo ti n tankale ju ibi to mu ooru lọ.
Ọ̀pọ̀ àwọn mííràn ò kéde síta nígbà ti àwọn mííràn ni àwọn ń ba àwọn akẹgbẹ́ àwọn sọ̀rọ̀ lábẹ́lẹ̀.
Àwọn ọmọ Jafẹti nìwọ̀nyí ní ìdílé ìdílé wọn, olukuluku ní agbègbè tirẹ̀.
Pupọ awọn alatilẹyin oloṣelu ni ija wọn kii saba pari ayafi ti awọn ti wọn n gbe lẹyin wọn ba ni o to gẹ.
 murtala mú gbogbo yunifasiti tó wà lábé ìjoba ìpínlè sí abé àkoso ìjoba àpapò .
Àwọn obinrin wọn ń bá ara wọn ṣe ohun tí kò bójú mu.
Bẹ́ẹ̀ ni Saulu ṣe kú nítorí aiṣododo rẹ̀; ó ṣàìgbọràn sí àṣẹ OLUWA, ó sì lọ ṣe àyẹ̀wò lọ́dọ̀ abókùúsọ̀rọ̀, ó lọ bèèrè ìtọ́sọ́nà níbẹ̀, 
”Asofin Desmond Eliot to je alaga igbimo ile lori asa, ise ona ati irin ajo afe ninu oro re pe akiyesi won si awon ona igbalode ti idagbasoke fi le kari ni ipinle Eko.
“Èmi OLUWA, àwọn ọmọ ogun, Ọlọrun Israẹli ní kí o lọ sọ fún àwọn ará Juda ati àwọn tí ń gbé Jerusalẹmu pé, ṣé wọn kò ní gba ẹ̀kọ́ kí wọn sì fetí sí ọ̀rọ̀ mi ni?
Oṣù kẹwàá ọdún 2020 ní INEC à ṣetò ìdìbò míì ní ìpínlẹ̀ Ondo Ni ìgbẹyin ohun gbogbo ninu ẹgbẹ oṣelu PDP ni ipinlẹ Ondo.
    Ìgbà tí ó wí báyìí tán, iwin náà kò pa á, ó ni kí ó maa fi ibi tí a sá pamọ́ sí han òun, wéré Ayédèrú-ẹ̀dá tọ́ka sí mi ní ibi tí mo lóṣòó sí tí mo fi àwọn ewé bojú lórí àpáta.
dibo ni kọrọ, sugbọn ti wọn yoo wa fi iwe idibo wọn sinu apo idibo ni gbangba.
" Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Toyin Atoyebi mechanic: Ẹ wo Toyin, ọmọbinrin ọdún 16 tó ń tún skadà àti gẹnẹrátọ̀ ṣe ní O ṣalaye pe kii ṣe igba akọkọ niyi ti ẹni naa ti n tabuku Oba Akanbi, sugbọn to n ja si ofo.
Nigba to di ọdun 1979, eyiun ọdun mẹrin lẹyin ti Gbadero pa Raji Oba, ijoba yẹ igi fun oun naa, ti Kiniun baba Moradewun si dagbere fun aye pe o digbose.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Akeredolu ati Abraham ni wọn jọ figagbaga fun asia ẹgbẹ oselu APC fun ipo gomina ipinlẹ Ondo lọdun 2016 Ọgbẹni Abraham npẹ ẹjọ lori idibo abẹle ninu ẹgbẹ oselu APC, eleyi to fa Rotimi Akeredolu kalẹ gẹgẹbii oludije fun ipo gomina, lasiko idibo gomina nipinlẹ naa to waye kẹyin.
“Ṣugbọn, ìdájọ́ eniyan burúkú dé bá ọ,ọwọ́ ìdájọ́ ati òdodo sì ti tẹ̀ ọ́.
Koda iṣẹlẹ ijinigbe kan tun ṣẹlẹ l'Ọjọbọ nibi ti wọn ti ji ọga ileewe kan lọ.
 Iroyin fi mule pe, lataari sise agbateru idije agbaye naa, eleyi ti yoo waye nilu mokanla otooto lorile-ede ohun, orisirisi atunse  ati ise akanse ni Russia ti gbese ni awon papa isere won gbogbo, ki papa isere won ohun le wa ni ibamu pelu ofin ati ilana ti ajo FIFA la sile Gege bi Putin se so,“ Ti idije agbaye naa ba pari, Orun awon adari eka kookan orile-ede yii, ni ise ohun maa wa.
Ọkan lara awọn oniwadii fun Ajọ EFCC ni lẹyin ọdun 2012 ti arabinrin naa di minisita, lo bẹrẹ si ni ko ọrọ ẹṣọ ara naa jọ.
Jiti Ogunye fikun wi pe ilakaka awọn oloselu lati de ipo ti ma n pọju, eleyii ti ohun mu ifasẹyin ba orilẹede lapaapọ.
Ni ilu Igboora, ijọ kan n bẹ nibẹ.
Àwọn ọmọ Israẹli bá tún ké pe OLUWA pé kí ó ran àwọn lọ́wọ́, nítorí pé ẹẹdẹgbẹrun (900) ni kẹ̀kẹ́ ogun Jabini tí wọ́n fi irin ṣe; ó sì ni wọ́n lára fún ogún ọdún.
Bi ẹ ko ba gbagbe, ikọ Boko Haram latẹnu adari wọn tun ṣẹṣẹ ṣe fidio kan jade ni ninu eyi to ti ṣalaye bi awọn ṣe pa awọn agbẹ naa.
Gbogbo paanu ti atẹgun ojo ṣi danu ni awọn to n gbe awọn ile naa ti n gbiyanju lati kojọpọ si ẹgbẹ kan lasiko ti ikọ iroyin BBC Yoruba ṣe abẹwo si agbegbe kan.
Agẹsin Adimula ni Ifa eyi naa lo si ka ọpọlọpọ eewọ fun wọn gẹgẹ bi iṣẹṣe eyi ti wọn ko gbọdọ tapa si bi o ti wu ki aye di aye ọlaju to.
Amọsa ọrọ bẹyin yọ nigba ri oorun ijẹkujẹ bẹrẹ si ni run sita labẹ eto naa.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Christmas & Border Closure: ìrẹsì dí góòlù fún Kérésì 2019 Ni bayii, ikọ Chelsea ti wa ni ipo kẹrin lori tabili lẹyin to n tẹle Manchester City lẹyin.
Bẹ́ẹ̀ ni mò ń fi kọ́ gbogbo àwọn ìjọ.
dollar (400US Dollars), ero ibanisoro Samsung kan ati
Ṣugbọn OLUWA ti di ibi ìsádi mi,Ọlọrun mi sì ti di àpáta ààbò mi.
N óo dúró ní ibi tí wọ́n ń gbà la odò kọjá ní ijù níhìn-ín, títí tí n óo fi rí oníṣẹ́ rẹ.
O ti sọ wọ́n di ìjọba ti alufaa láti máa sin Ọlọrun wa.
awon to peju sibi ipade apero ohun leti pe ipade ohun je eleekeji iru re.
Ṣugbọn ẹ má fọwọ́ kan ẹnikẹ́ni tí àmì bá wà níwájú rẹ̀.
Elikana ati Ìdílé Rẹ̀ ní Ìlú Ṣilo.
ko ba si ẹni to jawe olubori lọna to lamilaaka si ipo gomina tabi aarẹ
Ṣugbọn àwọn ọmọ wa yóo máa gbé ninu ìlú olódi níhìn-ín kí àwọn eniyan ilẹ̀ náà má baà yọ wọ́n lẹ́nu.
Àwọn tí ń dẹ́rù bani nígbà tí wọ́n wà láyé, gbogbo wọn ni wọ́n ti kú ikú ogun.
Láti Matana, wọ́n ṣí lọ sí Nahalieli, láti Nahalieli wọ́n ṣí lọ sí Bamotu, 
Sáré lọ pàdé rẹ̀ kí o sì bèèrè alaafia rẹ̀ ati ti ọkọ rẹ̀ ati ti ọmọ rẹ̀ pẹlu.
Akinwumi Adesina bọ́ lọ́wọ́ ẹ̀ṣùn jẹgúdújẹrá tí wọ́n fi kan - AFDB Ìjọba Nàìjíríà kéde ìsinmi ọlọ́jọ́ méjì f'ọdún Iléyá Ìyá Barakat fi ẹ̀mí ìmoore hàn sí gbogbo àwọn tó nawọ́ síi lẹ́yìn ikú ọmọ rẹ̀ A kọ òfin gígé nǹkan ọkùnrin tó bá fipá bá obìnrin lòpọ̀ - Àwọn Alfa yarí Ẹgbẹ ọmọlẹyin Kristi lorilẹede Naijiria naa ni ohun to buruju ni pe ijọba aarẹ Buhari ni ọrọ oṣelu lo n fa iṣekupani to n waye ni Guusu Kaduna naa.
Adajọ naa wa paṣẹ fun ajọ INEC lati tun ibo naa di laarin aadọrun un ọjọ.
Naijiria fi ìgbájú mẹ́ta lé Cameroon kúrò ní AFCON Wo àwọn ẹ̀ṣọ́ ara tó tó $40m Diezani Madueke tí ilé ẹjọ́ gbẹ́sẹ̀ lé Kí ló mú kí àwọn èèyàn máa jẹ ọ̀rọ̀ Adeboye lẹ́nu lórí Twitter Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, CAN: Samson ni ọrọ awọn ajinigbe ti gba àpérò ní Naijiria Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Kí ó sì máa ṣe àkíyèsí gbogbo nkan tí ń lọ ní’tòsí.
Ẹ fi ọpẹ́ fún OLUWA, ẹ képe orúkọ rẹ̀,ẹ kéde ohun tí ó ti ṣe fún àwọn orílẹ̀-èdè.
O ni lọjọ Isẹgun nikan, eeyan mejidinlogoji lapapọ lo jade laye lasiko iwọde ọhun yika orilẹede wa.
Nínú àtẹ̀jáde náà, wọ́n ni ọkọ̀ òfurufú kankan ko le kó ju igba ènìyàn lọ, wọ́n fi ku pé àwọn fọ́wọ́si iye yìí nitori pe ó le ni ènìyàn ẹgbẹ̀run kan to maa n wa si papakọ òfurufú lọ́ọ̀jọ́.
Wọ́n wá na ìtì igi kedari lé àwọn òpó náà lórí.
Tá a bá ń lọ se ìkọlù wa, wọn yóò fún wa ní òògùn náà láti lò, bí bẹ́ẹ̀ kọ́, tó o bá mu ú, wọ́n leè pa ọ́."
"Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: WAEC: Ìwé àfihàn pé Ààrẹ Buhari ṣèdánwò la fún un Ọmọ ìyá mẹ́ta fi oyún ṣe àńkò NAFDAC: Ẹ ṣọ́ra fún ẹja aṣekúpani Puffer Fish ""Ti o ba gba awọn aṣofin apapọ ni oṣu meje lati buwọlu abadofin iṣuna, o yẹ ki aye ko yin wa fun awọn ohun ribiribi ti a ti gbe ṣe."
Itankalẹ aarun coronavirus ṣe idiwọ fun awọn mọṣalaaṣi pupọ, nitori pe ọpọ wọn ni ko lanfaani lati kirun apapọ lọjọ Jimọ.
Ààlà ilẹ̀ náà lọ kan Tabori, Ṣahasuma ati Beti Ṣemeṣi, kí ó tó lọ pin sí odò Jọdani.
àwọn kíndìnrín rẹ̀ ati ọ̀rá tí ó wà lára wọn níbi ìbàdí ati àwọn tí ó bo ẹ̀dọ̀ ni wọn óo mú pẹlu àwọn kíndìnrín náà.
Obinrin naa, Josephine Majani, nigba to n s'ọrọ nile ẹjọ naa ni wipe awọn nọọsi alabẹrẹ gba oun loju niwaju gbogbo awọn eniyan, ti wọn ko si ṣe iranwọ kankan fun oun nigba to n rọbi ni ilẹ nlẹ ile-iwosan naa.
Imam ọhun ti wa bẹbẹ lọdọ mi lọpọ igba nitori naa igba to ṣe e de ibi gẹgẹ, o ti fẹ tẹ nu un.
Nígbà tí ó dé etí kànga jíjìn tí ó wà ní Seku, ó bèèrè ibi tí Samuẹli ati Dafidi wà.
Ni ọ̀pọ̀lọpọ̀ itàn Yorùbá, Ìjàpá jẹ ọ̀lẹ, òbùrẹ́wà, kò tóbi tó àwọn ẹranko yoku, ṣùgbọ́n ó ni ọgbọ́n àrékérekè ti ó fi ngbé ilé ayé.
O salaye pe, awon ohun elo yii yoo mu alekun ba ayipada igbe-aye awon omo ipinle naa.
Awon miiran tun ni : Most Rev.
Ìmọ́lẹ̀ tí ó yí i ká dàbí òṣùmàrè tí ó yọ ninu ìkùukùu lákòókò òjò.
Ìwà ìrẹ ̀ lẹ ̀ jẹ ́ ara ìṣe wa ní wikipedia , ó sì wà lára òpó marún tí ó gbé wikipedia ró .
Ẹ̀yin tí ẹ wà lókè réré,ẹ gbọ́ ohun tí mo ṣe;ẹ̀yin tí ẹ wà nítòsí,ẹ kíyèsí agbára mi.
Jesu dá wọn lóhùn pé, “Mo ṣebí àkọsílẹ̀ kan wà ninu Òfin yín pé, ‘Ọlọrun sọ pé ọlọrun ni yín.
‘Àwọn jàǹdùkú pa fadá ní Taraba’ Àlejò àpàndodo ni Fayoṣe, a kò fìwé pèé - Afuye Ọkọ̀ òfúrufú ọlọ́pàá yóò bẹ̀rẹ̀ sí ní káàkiri Naijiria - Ọgá Ọlọ́pàá Kìí ṣe gbájúẹ̀ nìkan lọmọ Nàìjá ń ṣe lókè òkun!
Nígbà tí ó di ọ̀gànjọ́ òru, OLUWA lu gbogbo àwọn àkọ́bí ilẹ̀ Ijipti pa, ó bẹ̀rẹ̀ láti orí àrẹ̀mọ ọba Farao tí ó wà lórí ìtẹ́, títí kan àkọ́bí ẹrú tí ó wà ninu ọgbà ẹ̀wọ̀n, ati àkọ́bí gbogbo ẹran ọ̀sìn.
Fun ẹkunrẹrẹ fidio yii, kàn si ojú òpó yii ti o ba fẹ mọ ohun to le jẹ ki IJỌBA TO WA LORI ALEEFA BAYII WỌ INÁ.
Awọn kan tun fi oju mii wo ikọ Manchester City bi ẹgbẹ agbabọọlu ti yoo gba ife ẹye naa fun igba akọkọ lẹyin ti Joao Cancelo ti dara pọ mọ ikọ ọhun, ti Kevin de Bruyne si ti gbaradi fun ere ori papa lẹyin ti ara ti mokun sii.
Èmi kò forí ṣọta ìjàmbá ọkọ̀ òfúrufú kankan - Obasanjo BBC Yoruba ṣagbeyẹwo diẹ lara awọn ileri ti wọn ti n fọn rere ẹ koda ṣaaju eto ibura wọn Gomina Abdulrazaq Abdulrahman ti ẹgbẹ́ oṣelu APC ti wọn bura fun lati tukọ ipinlẹ Kwara titi di 2023 ṣeleri lati ṣatunṣe si eto ọgbin atawọn ohun amayedẹrun.
O wa fi kun pe igba mẹrin ni osiṣẹ ni ore ọfẹ lati gbaaye ibimọ yii lẹnu iṣẹ ijọba ipinlẹ Oyo.
Àwọn olùdibo jákejádò ilẹ Amerika ń gbìyànju láti kopa nínú ètò ìdìbò ọdun 2020 ti yoo wáye ni orílẹ̀-ede Amẹrika.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Alaafin: Olori Aanu Adeyemi ṣàlàyé ìdí tó ṣe gẹ́ Oba Lamidi Adeyemi ti ìlú Oyo Ni ti Olori Dami, a ko ṣakiyesi ayipada kankan loju opo Instagram rẹ.
Trump, ọwọ́ ara ààrẹ ló fi pe Coronavirus fún ara rẹ̀ - Aráàlú Lowurọ ọjọ Ẹti ni iroyin tan ka gbogbo agbaye pe aarẹ ilẹ Amẹrika, Donald Trump ti lugbadi aarun Coronavirus.
Femi Adebayo ni oun tiẹ ti fun awọn ẹran agbo oun lorukọ tittun Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Salawa abeni Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Awọn agba amofin lorilẹ-ede Naijiria pẹlu ko dakẹ lori ọrọ ọhun o.
com/7wqOwveCfz— Arsenal FC (@Arsenal) 20 April 2018“Mo dupe lopolopo fun anfani lati sin iko yii fun opolopo odun.
Gẹgẹ bi abọ iwadii ti ileeṣẹ to n ṣakoso awọn ẹnu ibode naa, Lekki Concession Company, LLC, gbe jade, amọ ijọba Eko ṣi n pa owo lori awọn ipolowo ọja to wa lori awọn iloro ọhun.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Mò ń gbé Busola Dakolo lọ ilé ẹjọ́ - Fatoyinbo Seyi Makinde yan obìnrin míràn sípò akọ̀wé ìjọba SSG Àwòrán apanilẹ́rìn-ín fún ọ̀sẹ̀ yìí, ìtọ́wò rèé Ọlọ́pàá Ondo: Ètò ààbò kò mẹ́hẹ ní ọ̀nà Akure sí Ikere Lara awọn to ti sọrọ ni Funmi Iyanda, gbajugbaja agbohunsafẹfẹ to ni oun gba gbogbo ọrọ ti Busọla sọ lai ku ẹyọkan gbọ ati pe ireti oun ni pe ẹwọn lo yẹ ki atubọtan iranṣẹ Ọlọrun naa jẹ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Kong Thong: Àwọn òbí máa ń súfèé kọrin tàbí hu láti pe ọmọ tó bá dàgbà Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Kong Thong: Àwọn òbí máa ń súfèé kọrin tàbí hu láti pe ọmọ tó bá dàgbà 21 Agẹmo 2019 Ara meeriri ree o, a ri ori ologbo lori atẹ, airin jinna si ni airi abule ọkẹrẹ, bi eeyan ba rin jinna, yoo ri ibi ti wọn ti n fi odo ibulẹ jẹun.
Ọkùnrin kan tó yasó nínú ọkọ̀ Uber rí ẹ̀wọn he Kí ló ń ṣẹlẹ̀ láàfin Oyo táwọn èèyàn fi ń ki Alaafin ní mẹ́sàn án mẹ́wàá?
49 Nísisìyí, èyí nìkan kọ́—ìgbàgbọ́ wọn nínú àwọn àdúrà wọn ni pé kí ìhìnrere yìí lè di mímọ̀ bákannáà, bí ó bá jẹ́ pé ó ṣeéṣe pé kí àwọn orílẹ̀ èdè míràn ó ní ilẹ̀ yìí ní ìní;
Ẹnu ti ya ọpọlọpọ eniyan nítorí rẹ̀.
Kolawole sọ pe eyi ti aarẹ Buhari ṣe pẹlu mimu adinku ba iye owo ati ọjọ tawọn oṣise ijọba yoo maa na ni irinajo ko buru, ṣugbọn ko tan iṣoro to n dojukọ Naijiria lasiko yii.
Bẹ́ẹ̀ ni ó máa ń wádìí ọ̀rọ̀ lọ́wọ́ àwọn alásọtẹ́lẹ̀ ati àwọn abókùúsọ̀rọ̀.
Amọ ati ri wi pe lọpọ igba awọn eniyan fẹran iroyin ofofo tabi ti awọn oṣere ni ilẹ Yoruba.
Wo àwọn ẹ̀ṣọ́ ara tó tó $40m Diezani Madueke tí ilé ẹjọ́ gbẹ́sẹ̀ lé Kí ló mú kí àwọn èèyàn máa jẹ ọ̀rọ̀ Adeboye lẹ́nu lórí Twitter 'Èèyàn mi mẹ́ta ló wà nínú ọkọ̀ ojú omi tó dà nù l'Eko!
“Nígbà tí mo ti pada sí Jerusalẹmu, bí mo ti ń gbadura ninu Tẹmpili, mo rí ìran kan.
igbimo naa n se isẹ won.
Eyi si ma n ran awọn olookowo Bitcoin kan lọwọ lati fi ara pamọ.
Obinrin naa, Madiha Siddiqi ko si fi akoko ṣere rara to fi dahun pe ọkọ mi niyẹn.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ondo Land Death: Opó àti àbúrò olóògbé ní aáwọ̀ ilẹ̀ ló fá ikú òjijì fún Olayinka Olabode Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Lady Peller: Ọjọ́ ni ọjọ́ tí idán yíwọ́ fún ọkọ mi lẹ́yìn tó gé mi sí méjì, mo kú tán Lady Peller ni bó tilẹ̀ jẹ́ pé, Professor Peller ku', idán kò kú o torí ó ni ọmọ kan tó ń jẹ́ Zeeto Peller, agbẹjọrò ni, sùgbọ́n òun náà gbówọ́ nínú idán pípa.
Ṣugbọn Lea dá a lóhùn pé, “O gba ọkọ mọ́ mi lọ́wọ́, kò tó ọ, o tún fẹ́ gba èso mandiraki ọmọ mi lọ́wọ́ mi?
Èyí jẹ́ ìyanu fún àwọn ará Samaria, wọ́n ní ẹni ńlá ni ọkunrin náà.
Ogún tí a fi ìkánjú kójọ níbẹ̀rẹ̀,kì í ní ibukun nígbẹ̀yìn.
Ó máa ń ti Gbọ̀ngán wá sí Ifẹ̀.
Bẹẹ naa ni igbakeji aarẹ ana, Atiku Abubakar sọ pe ọfọ nla ni iku Funtua jẹ, lẹyin naa lo ba awọn ẹbi rẹ kẹdun.
OLUWA Ọlọrun ní:“ọpọlọpọ ìyà tí mo fi jẹ ẹ̀gbọ́n rẹ ni n óo fi jẹ ọ́,wọn óo fi ọ́ rẹ́rìn-ín,wọn óo sì fi ọ́ ṣẹ̀sín,nítorí ìyà náà óo pọ̀.
Iwe ẹri naa ni ajọ WAEC fun aarẹ lọjọ ẹti.
Kàyééfì, oyún inú nínú ilé ìgbọ̀nsẹ ọkọ̀ òfurufú Ẹyẹ ju ẹyẹ lọ, Super Eagles fi àmì ayò kan gbé ẹyẹ Swallow ti Burundi mì Oko òkú rèé, níbití òkú ti ń jẹrà mọ́lẹ̀ fún àyẹ̀wò Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Oríṣun àwòrán, Getty Images Ọlọpaa Minnisota sọ pe ọgbẹni Floyd ẹni ọdun mẹrindinlaadọta jẹ aṣọna ni ile ounjẹ kan, o sì ku lẹyin ti ọlọpaa ṣee bi ko se yẹ.
Irú òkúta tí wọ́n fi kọ́ gbogbo àwọn ilé abúlé náà ni wọ́n tò lé arawọn tí odi fi ga díè tí ó jẹ́ pé àgùntàn àbí màlúù kankan ò lè fòó kọjá sí òdì kejì.
N kò ní alaafia,bẹ́ẹ̀ ni ara kò rọ̀ mí,n kò sì ní ìsinmi, àfi ìyọnu.
Ẹ wí láàrin àwọn orílẹ̀-èdè pé, “OLUWA jọba!
Ẹ sọ fún un pé mo sọ pé kí ó wá máa gbé ní ilẹ̀ Goṣeni nítòsí mi, òun ati àwọn ọmọ rẹ̀, ati àwọn ọmọ ọmọ rẹ̀, ati agbo mààlúù rẹ̀, ati ohun gbogbo tí ó ní.
Ìyakọ yóo lòdì sí iyawo ilé, iyawo ilé yóo lòdì sì ìyakọ rẹ̀.
Oríṣun àwòrán, others O le lẹgbẹrun mẹta awọn ọmọ oṣelu APC lati ẹkun idibo mẹtalenigba kaakiri ipinlẹ Ondo ti yoo kopa ninu idibo naa lati yan ẹni ti yoo gbe apoti ibo sipo gomina ni ipinlẹ Ondo.
Iranṣẹ tí ọba rán lọ pe Mikaaya wí fún un pé, “Gbogbo àwọn wolii yòókù ni wọ́n ti fi ohùn ṣọ̀kan tí wọ́n sì sọ àsọtẹ́lẹ̀ rere fún ọba, ìwọ náà jẹ́ kí ọ̀rọ̀ rẹ ó bá tiwọn mu, kí o sọ àsọtẹ́lẹ̀ rere.
Funmilayọ ni obìnrin akọkọ to wa ọkọ̀ ayọkẹlẹ ni Naijiria Oun naa ni akikanju obinrin ti o di ìyá agba fun awọn èèkàn nla lasiko yii.
Russia Covid 19 Vaccine: Nàìjíríà ṣetán àjọṣepọ̀ pẹ̀lú Russia lórí ìpèsè abẹ́rẹ́ àjẹsára
Èmi OLUWA ni yóo jẹ́ ìpín ati ìní rẹ láàrin àwọn ọmọ Israẹli.
Senetọ Basiru Ajibọla to n ṣoju aarin gbungbun Oṣun naa bu ẹnu ẹ̀tẹ́ lu iwa biba nkan ẹlomiran jẹ to ṣẹlẹ ni orilẹ-ede South Africa.
Gígùn rẹ̀ yóo jẹ́ ọ̀kẹ́ kan ati ẹẹdẹgbaata (25,000) igbọnwọ, ìbú rẹ̀ yóo sì jẹ́ ọ̀kẹ́ kan (20,000) igbọnwọ.
Òhun ni wí pé láti ìgbà tí a ti kúrò ní ibi ti Ẹlẹ́gbára ti lé wa, ọkàn mi kò kúrò lára obìnrin tí ó ṣe ìtọ́jú mi nígbà tí Ẹlẹ́gbára fi le mi kọjá òkè odò.
Iru ailera MRKH ti mo ni tumọ si pe mi ko ni oju ara obinrin, ile ọmọ, ati pe kindinrin kan ṣoṣo ni mo ni.
Lati kekere ni Laycon ti n kọrin.
Nínú ìfọ̀rọ̀wanilẹnuwò pẹ̀lú oníròyìn ni ọ̀gbẹ́ni Simeon ti fìdí rẹ̀ múlẹ̀ pé, àgọ́ ọlọ́pàá Iyaganku àti Mọkola ni wọ́n kó àwọn ọdaran náà lọ, ti wọn sì kọ̀ láti gbà wọ́n si atimole.
shaikh hassan ahmad zaruq kẹ ́ kọ ̀ ọ ́ nípa súfí lójú ọ ̀ nà tijaniyyah , láti ọ ̀ dọ ̀ ọ ̀ pọ ̀ lọpọ ̀ àwọn ẹni oríṣà tí wọ ́ n lààmì laaka láàrín àwọn Àfáà mùsùlùmí .
Child marriage: Wo ọmọbìnrin ọdún méjìlá tó ṣè'gbéyàwó pẹ̀lú ọkùnrin méjì láàrin oṣù kan
kí ọkàn rẹ̀ sì yipada kúrò ní ọkàn eniyan sí ti ẹranko fún ọdún meje.
Abiola Ajimobi: Kíni ó ń ṣẹlè sí Senetọ Abiola Ajimobi?
Eyi to ṣe kẹyin ni ti oniṣowo epo ti wọn jigbe, ti wọn si gba ọgọrun miliọnu Naira, ki wọn to tu u silẹ.
Ìdágìrì yóo bá wọn ní ìrọ̀lẹ́,kí ilẹ̀ tó mọ́ wọn kò ní sí mọ́;bẹ́ẹ̀ ni yóo rí fún àwọn tí wọ́n fogun kó wa,bẹ́ẹ̀ ni yóo rí fún àwọn tí wọ́n kó wa lẹ́rù lọ.
Oṣù kẹjọ ọdọọdun ni iran Yoruba maa n bọ odò Ọṣun ni ilu Oṣogbo ni ipinlẹ Ọṣun ni ẹkun iwọ oorun Naijiria.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Manchester United vs Barcelona: Gbajúgbajà apanilẹ́rín, Wòlíì Àrólé ní ìrètí ṣì wà fún Man United ní Camp Nou 11 Ìgbé 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 13 Ìgbé 2019 Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Wolii Arole Kii ṣe iroyin mọ pe ikọ manchester United fi idirẹmi ninu ifẹsẹwọnsẹ wọn pẹlu Barcelona ninu idije Champions league, amọṣa bi ọkọọkan awọn ololufẹ ẹgbẹ agbabọọlu naa ṣe n gba iroyin yii sara lo ṣe ọtọọtọ.
Ọgọrọ awọn olugbe adugbo naa lo n sa asala fun ẹmi wọn bayii.
Biodun Fatoyinbo fi ipò sílẹ̀ lorí ẹ̀sùn ìfipábánilòpọ̀ COZA: Mi ò fípá bá obìrin lò pọ̀ rí láyé mi - Pásítọ̀ Fatoyinbo Ọjọ Aiku ni fidio kan gba ori ayelujara, to si ṣafihan awọn pasitọ kan ti wọn ni awọn jẹ aṣoju ẹgbẹ CAN ẹka ilu Abuja, lẹnu abẹwo lọ si olu ijọ COZA, to wa nilu Abuja.
Dokita Fredrick Fasheun to jẹ oludasilẹ ẹgbẹ OPC nilẹ Oodua to tun ṣiṣẹ takuntakun ni NADECO naa dagbere faye nibẹrẹ oṣu yii.
Aimoye igba ni wọn ti tan wa jẹ.
Ati pé, kí àwọn alufaa tí yóo súnmọ́ ibi tí OLUWA wà, ya ara wọn sí mímọ́, kí n má baà jẹ wọ́n níyà.
Ẹ gbọdọ̀ bẹ̀rù OLUWA Ọlọrun yín, kí ẹ sì máa sìn ín.
Lọwọlọwọ apapọ iye eeyan to ti ba arun naa lọ ti pe 1201 ti apapọ awọn to lugbadi r ni Naijiria si jẹ 76207 ti ara awọn 67110 si ti ya.
Akọwe ẹgbẹ agbabọọlu naa, Kabiru Adekunle ati adele adari igbimọ alabojuto ere idaraya ni Osun, Rotimi Oludunmoye naa peju si bẹ pẹlu.
Abikẹ Dabiri: irọ́ ni wọ́n ń pa f'awọn ọ̀dọ́ pé wọn a ríṣẹ́ ṣe Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Abikẹ Dabiri: Iṣẹ́ pọ̀ lọ́wọ́ Naptin àti àwọn aṣọ́bodè Nàìjíríà Ọmọ Nàìjíríà mẹrindínlógún ni wọn ti fẹ̀sùn kàn ni Paris pé wọn ń f'awọn ènìyàn ṣiṣẹ́ aṣẹwo ni France, Italy ati Spain.
Wọ́n gba ẹgbẹrun (1,000) lọ́dọ̀ ọba Maaka ati ẹgbaafa (12,000) ninu àwọn ará Tobu.
" Oríṣun àwòrán, Instagram Nigba to n sọrọ lori bi wọn se ni o yaju si Alaafin ati Ọọni, Oluwo ni oun ko gba ade ni Ọyọ, oun si ni oun lasẹ lati fi ọba miran jẹ nilẹ Iwo, kii se Alaafin, gẹgẹ bo se waye ni Ikoyi.
Ninu irinajo iranṣẹ olodumare, àpèrè ayọrunbọ ni yoo gun wa si aye, eyi to dabi ẹlikọpita laye ode oni.
Dokita Adanze Anunobi to je onisegun oyinbo fun itoju awon omo wewe paapaa ohun to nii se pelu itoju kindinrin lo so eyi di mimo nilu Ibadan pe UCH sayewo ito suga, ifunpa giga, eje riru ati atogbe.
Ajimobi wa gbe osuba kare fun  isejoba Aare
African in Greenland: Kí ló sún ilẹ̀ Afirika dénú gbígbé inú yìnyín?
Igbesẹ ijọba yoo tubọ mu ki owo pọ ni apo awakọ ero kọọkan ni, ti yoo si mu si gba owo kuro lọwọ awọn asaaju ẹgbẹ."
Láti ọ̀nà jíjìn, níkọjá àwọn odò Etiopia, àwọn ọmọbinrin àwọn eniyan mi tí a fọ́n káàkiri yóo mú ọrẹ ẹbọ wá fún mi.
Ọmọ naa to papoda, ti orukọ rẹ n jẹ Mattew, wa ni ile -iwe girama onipele ikẹta.
”inu mi baje pe baba Akanbi ti fi wa sile .
Gẹgẹ bi ọga ọlọpaa naa ti ṣe wi, olorin naa ti wa ninu irufẹ ẹsun yii ri ti wọn ni o yin ibọn eyi to ṣe awọn eeyan mẹrin lẹṣe ti wọn si di ero ileewosan.
Dokítà Kadiri sọ pé kò sí ẹni tí kò lè gbìyànjú láti gba ẹmi ara rẹ̀, ọ̀rẹ́, ẹbi, tó fi jẹ́ alájùmọ̀ ṣiṣẹ́ pọ̀ àti ìwọ fúnra rẹ gan.
Ṣugbọn o ṣeni lanu pe, gẹgẹ bi ọrọ ti ajọ to n risi eto ilera lagbaye WHO ṣe sọ, ko tii si abẹrẹ ajẹsara arun ọhun.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìgbeyàwó Fayose: Ìjó Shaku-shaku ni gómìnà fi dárayá 21 Ògún 2018 Igbeyawo alarinrin naa waye laarin Tomilọla Fayose ati Arẹwa Ọdunlade lọjọ Satide, ọjọ kejidinlogun, osu kẹjọ ọdun 2018.
Ẹ dá majẹmu níwájú mi ninu ilé tí à ń fi orúkọ mi pè.
“Bí ẹ bá tẹ́wọ́ adura,n óo gbé ojú mi kúrò lọ́dọ̀ yín.
Iyawo rẹ ni Remi Blaq ti oun naa jẹ akọtan ere ati òṣere to maa n fara han fun ipa pataki ninu ere.
Àwọn ọlọ́lá Jerusalẹmu yóo já sinu rẹ́,ati ọ̀pọ̀ ninu àwọn ará ìlú,ati àwọn tí ń fi ìlú Jerusalẹmu yangàn.
 ) ( he our team got three goals .
Lati ipasẹ fifi ara ẹni pe ẹlomiran yii, lo ti lu oyinbo Koraa kan ni jibiti owo to to Ọgbọn miliọnu naira niye.
Kiiling of Nigerians: Ijọba Nàìjíría fá orílẹ̀-èdè South Africa létí
nígba tí ìyàwó onikoromebi náà yan babalawo ti wọn ni ko ba wọn wo aiṣan agbere lara rẹ .
Boo ba ni i, ijọba tun ti ṣeleri lati ran eeyan 250,000 lọwọ fun sabuke CAC.
O fikun un wi pe ọsẹ to kọja naa ni wọn mu afurasi miran ti awọn mejeeji jẹ ọrẹ, ti oun naa sọ wi pe ọmọ naa wa ni ọwọ oun ki ọlọpaa to gba a mu ni ilu Port Harcourt.
“Nígbà tí àwọn ọ̀tá bá ṣẹgun àwọn eniyan rẹ lójú ogun nítorí pé wọ́n ti ṣẹ̀ ọ́, ṣugbọn bí wọ́n bá ronupiwada, tí wọ́n ranti orúkọ rẹ, tí wọ́n bá gbadura, tí wọ́n sì bẹ̀ ọ́ ninu ilé yìí, 
Awon omo orile-ede Sierra Leone yoo dibo yan aare tuntun ati awon asofin, aare Ernest Bai Koroma to wa lori alefa ko ni dije ninu eto idibo naa, leyin ti o ti dari orile-ede ohun fun bi odun mewaa.
Fun idi eyi ki wọn ya sewe agbejẹ mọwọ” O wa rọ awọn ọmọ orilẹ-ede
Ẹ̀ka alafọgbọn wadii ti ile iṣẹ ọlọpaa Eko ti wa lẹnu iṣẹẹ ṣiṣe awari awọn ti wọn ji gbe atawọn ajinigbe ọhun, yoo si di ṣiṣe lai fi ohunkohun silẹ lai ṣe.
Ojú ọ̀nà tààrà ni n óo máa gbà lọ.
"Yorùbá rẹwà, kọ́ nípa àwọn ọ̀rọ̀ tí ìró ẹnu wọn jọra àmọ́ tí ìtumọ̀ wọn yàtọ̀ Àríwá Nàíjíríà, ẹ sọ ẹran jọ̀bọ̀-jọbọ nù pẹ̀lú Sanusi tẹ yọ lóyè - Soyinka gbarata Coronavirus tún ti bẹ́ gìjà sí Ghana àti Gabon Coronavirus ti di àjàkálẹ̀ àrùn káàkiri àgbáyé- WHO Nigba ti esi ayẹwo rẹ fihan pe o ti Lugbadi arun ọhun, ẹni ọdunn ọdun mẹtadinlọgbọn naa ni ""O ṣeni laanu."
Ọmọ Yorùbá mẹ́wàá tó jẹ́ àmúlùúdùn ní Amẹ́ríkà àti Yúróòpù Èèyàn 38,344 ló ti ní COVID-19 ní Nàìjíríà lẹ́yìn tí 543 kún un lọ́jọ̀rú Eyitayọ Jegede (PDP) ló máa gbéná wojú Rotimi Akeredolu (APC) nínú ètò ìdìbò Ondo tó ń bọ̀!
Sibẹsibẹ mo bí ọmọ fún un nígbà tí ó ti di arúgbó.
Ẹ tètè máa lépa wọn lọ, ẹ óo bá wọn lọ́nà.
 Ènìyàn nìkan ni o ńkó àrùn yíì , àwọn pírámétì míìràn , àti ọ ̀ pọ ̀ ẹ ̀ ya ẹ ̀ fọn míìràn .
Iye kan náà ni wọ́n fún un ní ọdún keji ati ọdún kẹta.
Gomina ipinlẹ Rivers, Nyeson Wike ti ṣalaye wi pe oun ko wo Mọṣalasi rara tako awuyewuye ọrọ to n lọ lori ayelujara pe oun ṣe bẹẹ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù #MeToo movement: Harvey Weinstein tó fi ipá bá àwọn ènìyàn lòpò ti rí ẹ̀wọ̀n ọdún 23 he!
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Eku sé oko ìrẹ́si lọsẹ́ ni Kebbi 16 Èrèlè 2018 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Awọn eku naa n ya wọ awọn oko irẹsi ni ipinlẹ Kebbi Awọn alasẹ ni ipinlẹ Kebbi to wa ni iwo-orun ariwa Naijiria sọ wipe awọn ofan ati kokoro ya wọ inu awọn oko irẹsi ti wọn si ba awọn nkan ọgbin jẹ Iroyin fi han wipe ajalu yii ti bẹrẹ si s'okunfa ifi ise agbe silẹ laarin awọn ti ajalu naa ba.
 O ni ifowosopo lo se Pataki laarin ile ise ijoba apapo atawon aladani.
73 Super Eagles, ẹ máṣe gbá bọ́ọ̀lù fún Nàìjíríà mọ́ nítorí ìhà tí ìjọba kọ sí ìwọ́de EndSARS - John Ogu Oríṣun àwòrán, @VillaUpdates1 Atamatase ẹgbẹ agbabọọlu Super Eagles, John Ogu ti ke si awọn akẹgbẹ rẹ, lati maṣe kopa ninu ifẹsẹwọnsẹ Naijiria to n bọ lọjọ iwaju.
Alex Badeh kú ní alẹ́ ọjọ́ kejìdínlógún ọdún yìí lásìkò tó ń bọ̀ lati oko rẹ̀.
Aarẹ Trump ni ki wọn tunbọ mu itẹsiwaju ba ayẹwo finifini ki wọn to o ta ibọn, ki wọn si sun ọjọ ori ti eeyan le ra ibon lati ọdun mejidinlogun si ọdun mọkanlelogun.
Ajọ isọkan orilẹede agbaye, United Nations UN, tun ti sisọ loju rẹ pe, arun Coronavirus ọhun lo ti n mu irẹwẹsi ọkan ati arun ọpọlọ ba awọn eeyan lagbaye, paapaa ni awọn orilẹ ede ti wọn kii ti ja itọju arun ọpọlọ kunra, to si rọ awọn adari ijọba lati ri itọju arun ọpọlọ bii ojuṣe koowa wọn.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Senator Elisha Abbo: Adájọ́ ní ọlọ́pàá kò fi ẹ̀rí tó dájú múlẹ̀ lórí ẹ̀ṣùn ìfìyàjẹni 22 Agẹmo 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 1 Ògún 2020 Oríṣun àwòrán, @ElishaCliff Ileẹjọ majisireti kan to kalk silu Abuja ti wọgile ẹsun ifiyajẹni ti wọn fi kan Sẹnatọ Elisha Sanbo lati ipinlk Adamawa.
Eyi to mu ki Ọba gbe onisẹ kan dide, Tọbalagbọ, lati lọ wadii ohun to mu ki Timi dawọ sisan isakọlẹ duro.
Lẹyin ti ile iṣẹ BBC gbe iwadii wọn sita lori awọn olukọ kan nile iwe giga iwọ oorun ilẹ Adulawọ ti wọn n beere fun ibalopọ ṣaaju maaki ni oriṣiiriṣii nkan ti n ṣẹlẹ.
Kó bá mi béèrè lọ́wọ́ ikú oun mo ṣe fún - un
Ní ọjọ́ kan, Peteru dìde láàrin àwọn arakunrin tí wọ́n tó ọgọfa eniyan, ó ní, 
Ṣugbọn ileeṣẹ ọlọpaa sọ pe, awọn ọmọ ogun naa tu ogbontagi balogun ajinigbe kan, Alhaji Hamisu silẹ ni ipinlẹ Taraba, to si salọ lẹyin ti wọn yinbọn pa mẹta lara awọn ọlọpaa to n gbe e lọ si olu ileeṣẹ ọlọpaa, ati araalu kan.
Ninu ìdílé Nebo: Jeieli, Matitaya, Sabadi, Sebina, Jadai, Joẹli, ati Benaaya.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Video from the scene shows the aftermath of the crash Minisita orilẹ-ede Ukraine fun ọrọ to nii ṣe pẹlu ilẹ okeere, Vadym Prystaiko lọ sọ bee.
Ó rán àwọn ẹrú rẹ̀ lọ pe àwọn tí ó dájọ́ igbeyawo náà fún, ṣugbọn wọn kò fẹ́ wá.
Wike sọ pe o rọrun fun wọn lati fi Oyigbo boju ṣe ikọlu, nitori pe o sunmọ ipinlẹ Abia.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Human Rights day: Aṣíwájú ajàfẹ́tọ̀ọ́ ní Àìbọ̀wọ̀ fẹ́tọ̀ọ́ ọmọnìyàn ló ń fa wàhálà ètò àbò Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Human Rights day: Aṣíwájú ajàfẹ́tọ̀ọ́ ní Àìbọ̀wọ̀ fẹ́tọ̀ọ́ ọmọnìyàn ló ń fa wàhálà ètò àbò 10 Ọ̀pẹ̀̀ 2018 Ọjọ ẹti ọjọ kẹwa oṣu kejila ni ayajọ ibọwọ un ẹtọ ọmọniyan lagbaye, BBC News Yoruba ba aṣiwaju amofin lori ẹtọ ọmọniyan lagbaye, Amofin Adeola Oyinlade Sọrọ lori pataki ọjọ yii lorilẹede agbaye, paapaajulọ lorilẹede Naijiria.
Ó mú dòjé tí ó mú lọ́wọ́.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Àwọn olùgbọ́ BBC Yoruba fi èrò han lẹ́yìn #BBCGovDebate Eko Nibi ijoko ile to waye ni iroyin ti tan kalẹ pe wọn n gbimọ lati yọ gomina naa kuro ni ipo.
 Ọgbẹ ́ -inú náà lè tóbi nínú ju lórí awọ ara lọ , àyíká rẹ ̀ sí lè wú .
O ṣalaye pe nigba tijọba gbọ nipa bi wọn ṣe fi ọmọbinrin naa sẹwọn, ni ijọba bẹẹrẹ iwadii to tu aṣiri pe awọn ikọ oloogun oloro kan lo maa n fi ọgbọn gbe oogun oloro sinu ẹrù awọn eniyan to n lọ si Saudi Arabia.
Bo tilẹ jẹ pe o wu lati wa lori eto naa sibẹ, Lilo ni inu oun dun lati fi ori ọhun silẹ ni kiakia, nitori oun ko mọ oun ti oun n ṣemọ latari ibadọrẹ oun ati arakunrin Eric naa, ọrọ si ti n kọja oju ẹ.
28 Àti pé bí wọ́n bá ní ìfẹ́ láti gba orúkọ mi sí orí wọn pẹ̀lú ẹ̀kúnrẹ́rẹ́ èrò ọkàn, a pè wọ́n láti lọ sí gbogbo ayé láti wàásù ìhìnrere mi sí gbogbo ẹ̀dá.
A FI OJÚ WA RÍ Ọ̀RUN ÀPÁÀDÌ
Buhari salaye ọrọ yii lasiko to fi n gba alejo asoju ijọba orilẹede South Africa si Naijiria, Lulu Loius Mnguni to wa dagbere fun-un lati pada si orilẹede rẹ lẹyin ti saa isẹ rẹ pari.
Aisan kidinrin lo n yọọ lẹnu, aisan naa lo si ṣokunfa iku rẹ lọsan oni.
Funke Akindele fún mi lówó tí mo fi gba ilé, kò ra ilé fún mi o - Ajirebi Funke Akindele, oníròyìn, agbẹjọrò àti òṣèré; ohun tí ẹ kò lérò nípa rẹ̀ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Funke Akindele jẹ àkàndá ẹ̀dá - Adaku Oríṣun àwòrán, Funke Akindele Kaakiri agbaye ni wọn ti mọ Funke gẹgẹ bii gbajugbaja apanilẹrin laarin awọn oṣere fiimu Yoruba ati ti ede oyinbo koda to fi mọ awọn toke okun kọọkan.
09 Ilegbe ati itọju auwjọ - 40,280,489,878.
 A n pin abere ajesara loorekoore laarin awon eniyan ti won n bo nigbekun awon boko haram.
Ara gbigbona to tẹle ati ara wiwuwo ko sẹyin pe awọn ọmọ ogun inu ara eeyan to n ba arun naa koju Ohun to sẹlẹ ni pe wọn ti ri kokoro aifoju ri yi gẹgẹ bi ẹni gbogun ti ara ti wọ́n a si ma ransẹ si awọn eya ara pe nkankan ti n sẹlẹ.
Channel One ò sọ bí ìyàtọ̀ ṣe wà láàárín bí ọkùnrin àti obìnrin ṣe ń ronú sí ìfowópamọ́.
Bóyá ó ronú lọ ni, bóyá ó sì wọ ilé ìgbọ̀nsẹ̀ lọ ni; tabi ó lè jẹ́ pé ó lọ sí ìrìn àjò ni.
Nigba ti awọn akọroyin beere iye ọdun ti eeyan fi le kọ iṣẹ Ifa, o ni o kere tan kikọ iṣẹ Ifa yoo gba ọdun mẹwaa ati abọ.
Ṣugbọn ní ọdún kinni ìjọba Kirusi, ọba Babiloni, ó fi àṣẹ sí i pé kí wọ́n lọ tún tẹmpili náà kọ́.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsèjẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọ Ọga agba ajọ ẹṣọ oju popo loju ọna naa wa ke sawọn ọlọkọ lati maṣe jaya nitori pe wọn ti kan san akọṣẹmọṣẹ to mọ nipa rẹ lati gbe igbesẹ ti ko ni fi jasi ijamba nla miran ti yoo la ẹmi lọ.
”Àwọn aadọrin ọmọ Ahabu náà wà ní abẹ́ ìtọ́jú àwọn àgbààgbà ìlú Samaria.
O ni igun kan ninu ikọ Boko Haram, Barnawi ti kan si oun lọjọbọ pe ọdọ awọn lawọn ọmọ Dapchi ti wọn ji gbe wa.
Nàìjíríà ló wà nípò kẹfà nínú ewu ikú àìtọ́jọ́ l'ágbàáyé nítorí nkan mímú tó ní ṣúgà Ìdíje bọ́ọ̀lù fa ìtàjẹ̀ sílẹ̀ ní Poly Ibadan Oyè Mọ́gàjí àti Báálẹ̀ ti di owó rèé, ọjà rèé ní Ibadan - Lekan Balogun Ọkọ̀ ojú omi ''fẹri'' kọlu afárá, ọkọ̀ méjì já sódò 2.
Asofin naa tun tẹsiwaju pe awon
 mọ pe gbogbo iran lo ni awon irinse ti o
Mercy ló gbadé BBNaija ọdún 2019 Ijọba fi kun wi pe, oun to lewu pupo ni fun obinrin lati ma a ba Bobrisky lo ile igbọnsẹ pọ, wọn ni o buru ju aisan Ebola lọ.
Iru ipade yii ni Firdausi lọ ni ọdun 2000.
Iroyin kan to sọ pe Aarẹ orilẹede Tanzania John Magufuli sọ fun awọn ọkunrin lati fẹ ju iyawo kan lọ lati dena iwa agbere lu ayelujara pa.
Àwọn èèyàn kò fi bẹ́ ẹ̀ ní ìbálòpọ̀ lásìkò ìgbélé yìí - Iléèṣẹ́ kọ́ńdọ́ọ́mù Durex Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Coronavirus: 'Ewu ni tí Covid-19 bá wọ àdúgbò wa bí a ṣe fún pọ̀ yìí' Okun rẹ ni ki o fi yọ ọ kuro ni oju rẹ.
“Tìjàtìjà ni gbogbo wọn máa ń rìn, ìpayà á bá gbogbo eniyan bí wọ́n bá ti ń súnmọ́ tòsí.
Bakan naa ni ko ni adehun ninu tun tumọ si pe, lọgan ti ilẹ Gẹẹsi ba fi ajọ isọkan ilẹ Yuroopu silẹ, naa ni yoo kuro ninu awọn ajọ to wa labẹ rẹ bii ileẹjọ apapọ fun ilẹ Yuroopu ati ileesẹ agbofinro apapọ wọn taa mọ si Europol.
Muhammad Buhari fun ise ribi-ribi to n se lati mu orilede Naijiria dara ju bo se
idanwo naa lati maa jẹ ki awon kan tan won jẹ , nipa fifun won ni iroyin ti ko
Ẹni bá láyà kó wá wọ̀ọ́, ṣé ìwọ lè fàmì sí ọ̀rọ̀ yìí?
ẹ jẹ́ kí òróró tí Jesu ta si yín lórí máa gbé inú yín, ẹ kò sì nílò ẹnikẹ́ni láti máa kọ yín lẹ́kọ̀ọ́.
Amọ ọpọ igba ni awọn eniyan kii fẹ sọrọ nipa ori pipa.
Lẹ́yìn náà, Samuẹli pada lọ sí Rama, Saulu ọba sì pada lọ sí ilé rẹ̀ ní Gibea ti Saulu.
"Arsenal rántí ""Invincibles,"" ó pé ọdún mẹ́rìndínlógún tí Arsenal gba ife Premier League"
Ìwọ ati gbogbo àwọn ọmọ ogun rẹ yóo rìn yípo ìlú náà lẹ́ẹ̀kan lojumọ fún ọjọ́ mẹfa.
Ọkunrin náà dáhùn pé, “Alàgbà, ta ni ẹni náà, kí n lè gbà á gbọ́?
Lizzy Anjorin: Ẹ̀yin tẹ bímọ fún ọkọ mi, ẹ kó ọmọ wa ká ṣe àyẹ̀wò DNA fún wọn
Òkèèrè ni èyí yóo ti wá,láti àríwá ati láti ìwọ̀ oòrùn, àní láti ilẹ̀ Sinimu.
Bakanna ni afurasi yi ti o jẹ olukọ ni ile-ẹkọ giga aladani Methodist ti o wa ni Arigbajo, sọ pe wọn fi ipa mu oun darapọ mọ ẹgbẹ okunkun ni.
Ǹjẹ́ bí Ọlọrun bá wọ koríko ìgbẹ́ láṣọ báyìí, koríko tí yóo wà lónìí, tí a óo fi dáná lọ́la, mélòó-mélòó ni yóo wọ̀ yín láṣọ, ẹ̀yin onigbagbọ kékeré?
" Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Moses Melaye: Dino Melaye sùn ìta gbangba mọ́jú níléesẹ́ DSS O ni n ṣe ni ijọba n jẹ ko han sawọn ọmọ Naijiria pe nnkan miran wa lẹyin ọrọ ọhun ju eyi to han faraye.
N kò mọ bí wọ́n ṣe n bá obìnrin sọ̀rọ̀ ìfẹ́ - Aláàfin Mo le búra pé kò sí ìbáṣepọ̀ láárin Olorì Badrat àti Wasiu Ayinde - Olori Folashade Alaafin bi ibeji l‘ẹẹmeji lọsẹ kansoso Wò ó bí Alaafin àti aya àkọ́fẹ́ rẹ̀, Olorì Abibat ṣe pàdé ní èwe Àṣírí ńlá tó ń bẹ láàrín Alaafin àtàwọn onílù rẹ̀ rèé Ọdun 2008 ni iroyin kọkọ gbale-gboko nipa apọnbeporẹ olori naa, lasiko to bi ibẹta lanti-lanti ni ọọdẹ Alaafin.
 ní oṣù kọkànlá ọdún 2014 , wọ ́ n kéde rẹ ̀ wípé Ó tún fọwọ ́ bọ ̀ wé àdéhùn míìràn pẹ ̀ lú ikọ ́ ̀ rè yíi connacht láti wà pẹ ̀ lú ikọ ̀ náà títí di òpin ọdún 2016-17 .
Wọn lọ ṣe atipo ni orilẹ-ede Canada nibẹre ọdun 1990.
O le ṣe e fun iṣẹju diẹ, sinmi, ki o si tun tẹsiwaju.
Olofa ina: ẹ parí òwe yìí pé ìgbà tí ara bá tu ìgbẹ́ láà ri eṣú.
Ninu atẹjade naa, ẹgbẹ oṣiṣẹ ni o jẹ nkan to ṣeni laanu pe ijọba ipinlẹ Ọyọ kọwe si ẹgbẹ naa lai wa ojutuu si 'iya to n jẹ awọn oṣiṣẹ ijọba ni ipinlẹ naa.
Sé lóòtọ́ ni agbára Adárí Òsìsẹ̀, Abba Kyari ju ti igbákejì Ààrẹ Nàìjíríà lọ?
Lacazette sọ pe ''A padanu awọn anfaani kan to yẹ ki a fi gbegba oroke'' Oríṣun àwòrán, Reuters ''Saa bọọlu yii ko rọgbọ, a ti paarọ akọni-mọọgba wa, a ni isinmi ọlọjọ-gbọọrọ, a tun parọ awọn agbabọọlu wa kan'' O ni toun ti pe saa bọọlu yii jẹ ọkan lara awọn to gbomi mu fun oun, oun wa gbegba oroke ni Arsenal n,i nitori naa, ''ife FA Cup ṣe pataki gan ni gbigba'' Oríṣun àwòrán, Getty Images Akọnimọọgba ikọ Chelsea Frank Lampard ati akẹgbẹ rẹ Mikel Arteta jijọ n gbiyanju lati gba ife yii ni igba akọkọ wọn, bi akọnimọọgba.
Lẹ́yìn tó ṣá Monisola aya rẹ̀ ládá, Oniya ní iṣẹ́ èṣù ni Wèrè tí mò ń ṣe ní Facebook ló pawó fún mi-Esabod Èèyàn 104 kó covid-19 ní iléeṣẹ́ kan ṣoṣo ní Sagamu- Ìjọba Ogun Bí Gómìnà Makinde bá ṣẹ̀ mí, lẹ́tà lásán ló jẹ mí- Aláàfin Ọ̀yọ́ Kónílé-ó-gbélé Covid 19 ló tú àṣírí àwọn àfipábánilòpọ̀ láwùjọ- Mínísítà ọ̀rọ̀ àwọn obìnrin Alukoro ọlọpaa nilu Kano sọ fun BBC pe ọwọ awọn ti pada tẹ Muhammad Zulfara'u Alfa to jẹwọ pe oun fipa ba awọn obinrin yi lopọ ni ilu Kwanar Dangora ni Kano.
Ile, Ọgbẹni Azeez Sanni ka a ni igba kẹta.
ipinle ,Borno, Katsina ati Kebbi .
fun awon ile-ise to n mojuto sisan owo osu awon osise, lati mase fi owo osu
O fesi yi ni idahun si ibeere BBC nipa esi ile ẹjọ kotẹmilọrun ni orukọ ọga rẹ,Olusola Ẹlẹka.
'Ohun ti mo kọkọ ṣe ni lati gbe ibusun iyawo mi sita, ti mo si bẹrẹ si ni ran awọn dokita ati nọọsi lọwọ.
Wọn ko si fi aaye silẹ fun ẹnikẹni lati ṣe abẹwo si ibẹ.
Hasaeli dáhùn pé, “Ta ni mí, tí n óo fi ṣe nǹkan tí ó lágbára tóbẹ́ẹ̀?
BBC Yorùbá bá ọmọdébìnrin náà tó fẹ́ dà bí Anthony Joshua, lálejò, ó kọjá àfẹnusọ.
Ramu bí Aminadabu, Aminadabu bí Naṣoni, Naṣoni bí Salimoni.
O ni ni igbimọ yoo sọ ipinu wọn, ṣugbọn nkan eyọkan to daku ju ni pe, ọmọ ilẹ Gẹẹsi kọọkan gbọdọ se ayẹwo ki o si ma ni aarun.
Judasi, ọ̀kan ninu àwọn ọmọ-ẹ̀yìn, ni ó ṣiwaju wọn.
Mi ò fẹ́ di ọlọ́lá jùlọ tí mo bá di gómìnà Ondo, màá tẹ̀lé ìfẹ́ aráàlù póńbélé - Ojon YPP Ojú àwọn èèyàn Ondo ti là pé ìnira ni ẹgbẹ́ APC mú wá - Jegede PDP Àwọn kan ṣónú bí wọ́n bá di gómìnà, ẹ fún wa láyè láti wá parí iṣẹ́ táa bẹ̀rẹ̀ - Akeredolu 'N500 dé fún gbogbo ọmọ tuntun lóṣooṣù bí mo bá di gómìnà Ondo - Adeleye AAC Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí 2 sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
Wọ́n kó wọn jọ ní òkítì òkítì, gbogbo ìlú sì bẹ̀rẹ̀ sí rùn.
Wọn tẹsiwaju ninu ọrọ wọn pe niṣe ni awọn ọlọdun oro yii nawọ ayẹyẹ wọn de aarin gbungbun awọn ilu yii, ti wọn si n ti itori bẹ paṣẹ konileogbele lọsan gangan fun awọn ara ilu.
Ninu fidio yii, gbajugbaja osere naa salaye ipo ti igbeyawo rẹ̀ wà ati igbẹsẹ ti o gbe lati koju awọn ipenija ti o koju.
Oṣu mẹta naa ni anfani iwe igbelu na.
Iṣẹ́ ọnà awọ tí wọ́n fi ń ṣe àgọ́ ni wọ́n ń ṣe.
Mà á fún àwọn ọba alayé ní ojúṣe nínú ìjọba mi - Seyi Makinde Lẹ́yìn ọlọ́pàá, VIO nìkan ló láṣẹ láti dá ọkọ dúró láìṣẹ̀ - Ọ̀gá VIO Eko Àwọn àṣà àti ìse tó yọ obìnrin sílẹ̀ nílẹ̀ Yorùbá Sanwo-Olu kò lè tori ìjà Ọjọta fòfin de NURTW ní Eko - Agbẹnusọ gómínà Lọdun 1998 ati 2002 ni Burundi yẹba ninu idije lẹyin ti wọn gbiyanju lati kopa ninu idije ife ẹyẹ agbaye.
Raqiya Mahamed Ali, ti oun naa wa ninu ọgba naa nigba isẹlẹ oun ni ''ẹnu isẹ wa la wa ki a to saa dede gbọ ibugbamu naa'' O sọ fun ile isẹ iroyin Reuters pe ''Mo sa asala fun ẹmi mi si abẹ tabili.
Ọlọ́pàá Eko ní kí olùkọ́ UNILAG Boniface wá sọ tẹnu rẹ̀ lórí ẹ̀sùn ìfipábánilòpọ̀ A ti mọ òbí 40 nínú 108 t'ọ́mọ wọn bọ́ ní ayédèrú ibùdó atúnwàṣe Ilorin - Ọlọ́pàá Kwara Ìlú kò mọ ohunkóhun nípa iṣẹlẹ màálù tó kú nilu Ikarẹ- Oba Olukarẹ Tọpẹ ni ọjọ mẹrin pere ni oun ti lo nibudo naa, ki ori to ba oun se ti awọn ọlọpa fi wa fọ ibudo ọhun.
N óo sì fún àwọn ìjọba gbogbo ilẹ̀ ayé mu pẹlu.
RCCG: Àwọn Pásítọ́ ijọ Redeem márùn ún bọ́ sọ́wọ́ ajínigbé ní Ijebu Ode
Ẹgbẹ naa wa rọ awọn eeyan to lami laaka lorilẹede Naijiria lati maa sọrase, ki wọn si maa huwa ọlọgbọn lasiko ti wọn ba n dasi ọrọ ilu lọna ati mase bu epo eebo si rogbodiyan to wa nilẹ.
Ile iṣẹ ọlọpaa ti kede pe ọwọ awọn ti tẹ afurasi mẹta ti wọn jẹ agbatẹru ipaniyan to waye ni ipinlẹ Zamfara.
Nígbà tí ilẹ̀ ọjọ́ keji mọ́, mo ṣe bí OLUWA ti pàṣẹ pé kí n ṣe.
Chelsea vs Manchester City: Man City gba fújà lọ́wọ́ Chelsea n'íbẹ̀rẹ̀ ọdún tuntun
Chris Ngige naa wa ni ẹ̀gbẹ̀rún
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Working religious women: Ẹ̀lẹ́hàá kìí ṣe ọ̀lẹ- Aminat Adegoke Amọ, awọn eniyan kan gboriyin fun Diezani Alison-Madueke fun ọrọ to sọ tako iwa jibiti lawujọ.
A gbé wọn ga fún ìgbà díẹ̀,lẹ́yìn náà, a rẹ̀ wọ́n sílẹ̀,wọn á rọ, wọn á sì rẹ̀ dànù bí ewé,a ké wọn kúrò bí orí ọkà bàbà.
Ó sọ òkun di ìyàngbẹ ilẹ̀,àwọn eniyan fi ẹsẹ̀ rìn kọjá láàrin odò.
Ams nigba to ya, o bẹrẹ si gba owo fun isẹ orin kikọ, eyi to fi n bọ ẹbi rẹ, to si tun n ran ara rẹ ni ile ẹkọ girama ni Baptist Boys High school, Abẹokuta Nigba ti wọn wa nile ẹkọ girama yii, ọpọ awọn eeyan jankan jankan lawujọ loni ni o jẹ ọmọ ileẹkọ MKO Abiọla nigba naa, ninu wọn la ti ri Oloye Olusẹgun Ọbasanjọ, to jẹ aarẹ tẹlẹ ni Naijiria.
Raheem Sterling lo kọkọ gbayo wọ le fu Man City ṣugbọn Joel Matip sayo naa pada, lo ba di ọmi alayo kọọkan.
leyin opo odun ti won ti n reti owo yii.
Ṣugbọn gẹ́gẹ́ bí Ọlọrun ti kà wá yẹ, tí ó fi iṣẹ́ ìyìn rere lé wa lọ́wọ́, bẹ́ẹ̀ ni à ń sọ̀rọ̀, kì í ṣe láti tẹ́ eniyan lọ́rùn, bíkòṣe pé láti tẹ́ Ọlọrun tí ó mọ ọkàn wa lọ́rùn.
Ọkọ Jiibu Hilux ni Auxiliary gbé wa sadugbo Soka láti yaju sí àwọn ọlọkada nítorí bí wọn ṣe kùnà láti san owó ojúmọ́ tó yẹ, bẹ́ẹ̀ sì ni kò yẹ kí wọn máa yọ àwọn ọlọkada náà lẹ́nu nítorí ìjọba Ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́ tí ní kí wọn má ṣe san owó náà mọ."
Nígbàkúùgbà tí ó bá sì dúró, yóo wí pé “OLUWA, pada sọ́dọ̀ ẹgbẹẹgbẹrun àwọn eniyan Israẹli.
A bá wọ ilé ọkunrin náà.
ilera oju, eleyii to waye ni ile igbafe His Grace Hotel and Suites ni agbegbe
Iroyin ti a gbọ ni pe, ọja to to ẹgbẹlẹgbẹ miliọnu owo naira lawọn janduku ọhun jigbe lọ.
Ojú rẹ ni gbogbo àwọn ọmọ Israẹli ń wò báyìí, pé kí o fa ẹni tí o bá fẹ́ kí ó jọba lẹ́yìn rẹ kalẹ̀ fún wọn.
" Ó wá di dandan fún Àjàpadá láti kúrò ní ìlú "" Òyè ' fún ààbò ."
Mò ń kìlọ̀ fun yín, ẹ̀yin ọmọbinrin Jerusalẹmu,mo fi egbin ati àgbọ̀nrín inú igbó búra,pé, ẹ kò gbọdọ̀ jí olùfẹ́ mi, títí yóo fi wù ú láti jí.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Mo ni baba isalẹ' Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Aláàbọ̀ ara tó ń dari ọkọ̀ ojú pópó ní àìlera kìí ṣàrùn' Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
5 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Oríṣun àwòrán, @EagleFMNam Bi ẹ ba gbọ orukọ yi kini iru ero to maa n wa si ọkan yin?
Gbogbo ẹranko inú igbó yóo tẹ àwọn ẹ̀ka rẹ̀ mọ́lẹ̀.
Oríṣun àwòrán, OTHERS Àkọlé àwòrán, Ìjọba ní Naijiria yóò padà sí ní san owó ‘tollgate’ O tun mẹnuba idagbasoke ti sisan owo yii yoo mu wa fun gbogbo olugbe Naijiria.
Ní ọdún kejidinlogoji tí Asa, ọba Juda gorí oyè ni Ahabu, ọmọ Omiri gorí oyè ní Israẹli, Ahabu sì jọba lórí Israẹli ní Samaria fún ọdún mejilelogun.
 Besini O je okan lara awon agbaboolu Naijiria ti o ti saseyori ninu ere boolu lagbaye.
Bí ó ti wí báyìí ni ẹsẹ̀ tí ó ti jẹ́ òkúta yíi padà sí ara ènìyàn tí ọkùnrin yìí sì dìde.
Pé kó yáa sáré lọ wá nkan jẹ, kí òyì má kọ́ọ kó má dàákú síwa lọ́rùn o.
Joabu ati àwọn ogun Israẹli súnmọ́ àwọn ọmọ ogun Siria láti bá wọn jà, ṣugbọn àwọn ọmọ ogun Siria sá fún wọn.
Seun Kuti: Seun, ọmọ Fela, lóòtọ́ lóun yìnbọn níbi yánpọnyánrin pẹ̀láwọn tó wa ọkọ̀ dí ilé òun, àtipé bó jẹ́ ìjọba àpapọ̀ ló ṣ'àìtọ́ nílé òun ìbọn á sọ
Ẹlẹ́wọ̀n, ẹni ọgọ́rùn ọdún n bẹ̀bẹ̀ fún òmìnira Taa ni Jọkẹ Silva, òsèré tíátà tó ń se ọjọ́ ìbí ?
Àwọn ọmọ ogun rẹ̀ tí a kà jẹ́ ẹgbaa mẹtadinlogun ó lé egbeje (35,400).
Liverpool vs Chelsea: Lampard wọ gàu!
8 ninu ida ogorun ba eto oro aje orile-ede naa ni oun 2018, latari bi ogbele ati laasigbo oloselu se sakoba fun   eto oro aje orile-ede naa.
Isẹlẹ ina naa, ti wọn ko tii sọ ohun to fa a, lo waye lẹyin ina alagbara to sẹlẹ nibẹ lọjọ kẹrin osu Kẹjọ ọdun 2020.
Ibinu ọba dàbí bíbú kinniun,ṣugbọn ojurere rẹ̀ dàbí ìrì lára koríko tútù.
Alaafin Adeyẹmi III, fi idi rẹ mulẹ pe lootọ iṣọkan ṣọwọn laarin awọn oriade atipe ko sohun meji to fa eyi ju wi pe awọn wọn ti ti oṣelu bọ gbigbe awọn ọba si akasọ to yẹ koowa wọn.
Ninu àwọn ọmọ Bebai, Sakaraya, ọmọ Bebai, ni olórí;orúkọ eniyan mejidinlọgbọn ni wọ́n kọ sílẹ̀ pẹlu rẹ̀.
7 1463110 Orilẹede Colombia 37808 76.
Bakan naa ni ọrọ ikini n jẹyọ lọtun losi latọdọ awọn ọmọ Naijiria lati dupẹ lọwọ ikọ Super Eagles ati lati fi anfani naa sọ ireti wọn.
Israẹli ti kọ ohun rere sílẹ̀; nítorí náà, àwọn ọ̀tá yóo máa lépa wọn.
"Oríṣun àwòrán, Alamy ""kato wi ka to fọ, wọn a maa wi pe o jọ Bobrisky, ṣe Bobrisky kii ṣe eeyan ni."
Ó kúrò níbẹ̀ lọ si Ẹẹ̀sún.
Lẹ́yìn náà ni àwọn ẹgbẹ́ àwọn òṣìṣẹ́ sọ̀ fún ìjọba pé kí owó òṣù tuntun tí ìjọba ṣe ìlẹ́rí má yẹ̀.
n óo fi ibinu kẹ̀yìn sí yín, n óo sì jẹ yín níyà fúnra mi, nítorí àwọn ẹ̀ṣẹ̀ yín.
Ó bá bèèrè pé, “Kí ni ìṣòro rẹ?
Nígbà tí wọ́n fojú kàn án, ẹnu yà wọ́n,ìpayà mú wọn, wọ́n sì sá;
Bí ó bá tètè dé, èmi ati òun ni a óo jọ ri yín.
Oríṣun àwòrán, Akeredolu Twitter Ọjọ́bọ̀ la ó mọ̀ bóyá a ní Coronavirus - Aṣòfin Ondo Agbẹnusọ awọn asofin nipinlẹ Ondo, Gbenga Omole lo fi idi ọrọ naa mulẹ fun BBC Yoruba.
Akọni to dije dupo aarẹ Naijiria labẹ ẹgbẹ oṣelu SDP eyi ti ijọba ologun Naijiria wọgile lọdun 1993 ni wọn n ṣe iranti rẹ lasiko yii ni Naijiria.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù RRS gbé ẹlẹ́wọ̀n lẹ́yìn ọjọ́ 5 tí wọn tú sílẹ̀ ní ọgbà ẹwọ̀n Ikòyí 14 Ọ̀wàrà 2018 Oríṣun àwòrán, RRS Àkọlé àwòrán, Ọlọ́pàá tún ọ̀daràn mú lẹ́yìn ọjọ́ karún tó kurò lẹ́wọ̀n Àwọn ẹka ọlọ́pàá RRS (Rapid Response Squad) tí ìpínlẹ̀ Eko tí tún ọdaran kan mú lẹ́yìn ọjọ́ marún-ùn tí tí ó gbà òmìnira kúrò ní ẹwọ̀n Ikoyi.
Bí àwọn ìlú wọn tí ń dára sí i ni àwọn ọ̀wọ̀n oriṣa wọn náà ń dára sí i.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Sogidi Lake: Kòṣẹja-kòṣèèyàn lá bá nínú adágún odò náà -Ojedele O ni ètò ààbo mẹ́hẹ lasiko naa, ni òun ṣe dá ìgbàkegbodo wọn dúro.
Ọjọ́ kan dé tí Olódùmarè dán Ibrahim wò.
Iṣẹlẹ yìí lo mu ki ijọba ipinlẹ Kaduna kede aṣẹ ko nile o gbele fun wakati mẹrinlelogun.
NBC fọwọ́ sí ìdásílẹ̀ ilé iṣẹ́ Fulani Radio Àwọn bàbá ìsàlẹ̀ òṣèlú tó bá ìtìjú bọ̀ nínú ìbò Gómìnà rèé Afurasi tó fa ìpayà nílé ìwé Port Harcourt ti wọ gàù Ọ̀rọ̀ Aisha Buhari sí Ramaphosa wú ọ̀rọ̀ síta lẹ́nu àwọn ọmọ Nàìjíríà @Chima_Saboyo ni tirẹ woye pe Naijiria ti fi ori inu ba tode jẹ lori ọrọ owo yii.
Ọkan-o-jọkan isẹlẹ idigunjale, ifipa se'wọde ati ipaniyan to lọwọ awọn darandaran lọwọ lo ti n ranju mọọ mọeto abo lorilẹede Ghana.
Oríṣun àwòrán, Facebook/Muhammadu Buhari Ṣugbọn ijọba apapọ ti sọ pe ohun yoo sa gbogbo ipa oun lati ri pe nnkan pada bọ sipo, ati pe igbe aye dẹrun fun awọn ara ilu.
Bi awọn kan ṣe n faraya pe nitori pe Joshua lorukọ, o tete ri tirẹ gba, ṣugbọn ọpọ ni o ti wa lẹnu igbesẹ ati gba iwe idanimọ ati nọmba naa ṣugbọn ti ko si ohun to jade nibẹ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Kini Yoru[bá ń pe Necklace?
Ìlà oòrùn iléṣà jẹ ́ agbègbè Ìjọba Ìbílẹ ̀ ní Ìpínlẹ ̀ Ọ ̀ ṣun ní naijiria .
"Mi o gbọ pe ọlọpaa pa ẹnikẹni nibi iṣẹlẹ naa, ṣugbọn nkan ti mo le sọ ni pe iwa ọdaran ni didana sun ile onile.
Agbára kákáni ó fi kí wa pé a kú ile.
Boo ba si se tete jade kuro ninu ẹmi si, ni yoo fi dara si.
Ṣugbọn orílẹ̀-èdè tí ó bá ti ọrùn ara rẹ̀ bọ àjàgà ọba Babiloni, tí ó sì ń sìn ín, n óo fi sílẹ̀ lórí ilẹ̀ rẹ̀, kí ó lè máa ro ó, kí ó sì máa gbé ibẹ̀.
Sùgbọ́n nígbà míràn èròjà tó n gbógun tí ààrùn lára yóo ti gbé ẹrù tó jùúlọ, àsìkò yìí ni ààrẹ yóò de si àgọ́ ara, nítorí àsìkò tó yẹ ki ó gbógun ti ààrùn lára, yóò kòjú si ara fún rarẹ láti jà.
Àwòrán bí ẹ̀kún omi ti ṣọṣé l'Eko àtàwọn ìlú míì nílẹ̀ Yorùbá rèé Tunbọsun mẹnuba iwa ibajẹ ki awọn eniyan maa ya igbẹ tabi ṣe igbọnsẹ sinu odo ati inu agbara ni eyi to n ran itankalẹ arun lọwọ bayii.
Modric gba adé Ballon D'or fún 2018 AFCON bọ́ mọ́ Cameroun lọ́wọ́ nítorí ìdí méjí-CAF Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, BBC African Footballer: Salah gba àmì ẹ̀yẹ̀ lẹ́ẹ̀kan síi Orilẹede Egypt ati South Africa ni wọn jọ n du ati gba alejo idije naa.
Awọn ẹlẹri-osojumi salaye fun BBC wi pe awọn apaniyan kan dẹnu ibọn kọ ọkọ ayọkẹlẹ Alaga ẹgbẹ, Kunle Poly,ti wọn si yin in nibọn loru ọjọ isẹgun laimọ wi pe Alaga (Kunle Poly) ko si ninu ọkọ ayọkẹlẹ rẹ sugbọn ọmọlẹhin rẹ kan, Swagger ko agbako yi ti o ku lẹsẹkẹsẹ ti awọn meji miran si fara gbọta ninu ijamba naa.
” Amosa, ki won to yọ  ayederu abajade esi ibo naa kuro ninu ẹrọ
Eyi mu ki ilẹ Afrika ma padanu owo to to biliọnu mẹrinla dọla owo ori to yẹ ki wọn ma gba lọdọọdun.
9 biliọnu baṣubaṣu lasiko ti o fi jẹ ọgagun agba ileeṣẹ ọmọogun ofurufu.
Iṣu ló wà nínú mọ́tò mi, kìí ṣe èèyàn ni mo sọ di iṣu - Afurasí Ajínigbé figbe ta Dúkìá àti ọkọ̀ jóná, ọlọ́pàá mẹ́sàn-án fara gbọta lásìkò ìwọ́de Shiite Ìjọba ló ń ṣe kóríyá fún àlàfo ńlá láàrin ọlọ́rọ̀ àti mẹ̀kúnnù - Oxfam Àgùnbánirọ̀ gbẹ́mìí mì látàrí 'Snipper' tó fi fọ irun rẹ̀ Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Eyi fihan pe Mohammadu Buhari ni gbogbo wọn ninu ẹgbẹ oṣelu APC ti faramọ pe ko tun dije lorukọ ẹgbẹ sipo aarẹ ninu idibo Naijiria to m bọ lọdun 2019.
Ohun ìtìjú ni wọ́n fi ń ṣe ìgbéraga.
Lẹ́ẹ̀kansíi láti ṣe àtúnṣe àwọn àṣìṣe, ṣe àfọ̀mọ́ àwọn ọ̀rọ̀, àti ṣe ìdámọ̀ àwọn ìdàgbàsókè nínú ẹ̀kọ́ àti ìgbékalẹ̀ Ìjọ, Joseph Smith mójútó yíyẹ̀wò ọ̀rọ̀ inú àwọn ìfihàn kan láti palẹ̀ wọn mọ́ fún títẹ̀jáde ní 1835 bíi Doctrine and Covenants of the Church of the Latter Day Saints.
Ní kúkúrú, kí ó jẹ́ ẹni tí ń ṣe iṣẹ́ rere nígbà gbogbo.
Eyi ko ṣẹlẹ ri lati bi igba ọdun ti adura Eid ti n waye nilu Kano.
Olùkọ́ fásitì méjì ń bèèrè ìbálòpọ̀ lọ́wọ́ akẹ́kọ̀ọ́ fún máákì Fídíò rèé nípa bí Aláké tuntun ṣe ń gba ìwúre lábẹ́ Olúmọ kó tó gba adé Ọdún ìbejì sọkutu-wọ̀wọ̀ ní Igboọrà, àṣírí bí wọn ṣe ń bí ìbejì tú Sanusi Adebisi Idikan rèé, olówó tó ń san owó orí fún gbogbo ọkunrin ilẹ̀ Ibadan Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
#67yearoldmother: Ọ̀pọ̀ gbà pé àdúrà ló gbà lóri tọkọtaya Otubusin Ṣe ẹ ranti iroyin iya ọmọ ọdun mẹtadinlọgọrin to bi akọbi rẹ ni ilu Abẹokuta?
’Ó ń gbóòórùn ogun lókèèrè,ó ń gbọ́ igbe ọ̀gágun tí ń pàṣẹ.
Àwọn arabinrin wọn ni Seruaya ati Abigaili.
Nibẹrẹ oṣu yii, obinrin kan to jẹ ọmọ orilẹede Britain jẹ ọ̀kan lara eniyan meji ti awọn agbebọn pa lasiko ti wọn kọlu ibudo igbafẹ kan niluu Kaduna.
Wo àwọn olóríire tó borí nílé BB Naija sẹ́yìn àti iye òjò owó tó rọ̀ fún wọn Àwọn afọbajẹ wọ́ Oluwo relé ẹjọ́, ìjọba Osun kò tíì fọùn Ẹ gbà mí, Nàíjíríà gbá mi lórí àyẹ̀wò Covid-19 - Iyabo Ojo figbe ta A ti ja aráàlú kulẹ̀, ta bá pè wọ́n fún ìwọ́de, wọn kò ní jẹ́ wa mọ́ - NLC Eko Fìdíhẹẹ́ ní Banji Akintoye nínú YWC, lílọ ni yóò lọ - Tola Adeniyi Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Fìdíhẹẹ́ ní Banji Akintoye nínú YWC, lílọ ni yóò lọ - Tola Adeniyi Ó ti lé ni ọ̀ṣẹ̀ kan báyìí ti awuyewuye ti ń ṣẹ̀lẹ̀ láàrin àwọn ọmọ ẹgbẹ́ Yoruba World Congress (YWC), ti àwọn kan si ti kéde pé ọ̀jọ̀gbọ́n Akintoye kìí ṣe olórí ẹgbẹ́ náà.
Ṣe to ba jẹ tootọ ni pe wọn ji aburo mi gbe, ṣe nkan to kan ni pe ki wọn yinbọn pa?"
Àárẹ̀ mú èmi Daniẹli, mo sì ṣàìsàn fún ọpọlọpọ ọjọ́.
Ẹni tí a ṣe lóore tí kò mọ̀ ọ́n dàbí ẹni tí a gbà kúrò lọ́wọ́ ìjàǹbá tí ó rí àrẹ̀mọkùnrin ẹni tí ó tún yin ìbọn sí i, ìdájọ́ eléyìínì kò sí lọ́wọ́ ènìyàn, ó wà lọ́wọ́ Ọlọ́run Ọba.
 Ìyí ọ ̀ rọ ̀ adúróṣinṣin jẹ ́ 0 .
” Samuẹli bá pada lọ sùn.
Minisita naa wa ni ọna abayọ si ọrọ epo bẹntirol ni ki ile isẹ aladani gba isakoso karakata epo bẹntirol, ki ijọba si wa ọna abayọ kiakia lati tun gbogbo ile isẹ ibudo ifọpo to wa lorilẹede Naijiria se, ki wọn ye e dara le epo ti wọn n gbe wa lati ile okeere.
Ẹ ṣọ́ra o, ayédèrú abẹ́rẹ́ àjẹsára COVID-19 gbòde ní Nàìjíríà, NAFDAC pariwo síta Wo àwọn ààrẹ Amẹ́ríkà mẹ́rin tí wọn rọ̀ lóyè àti ẹ̀ṣẹ̀ wọn Wo ẹ̀kọ́ mẹ́rin tí Naijiria kùnà láti kọ́ lára ogun abẹ́lé Pasipaarọ ọmọ nile iwosan: Iwadii naa ti fihan pe o see se ki wọn paarọ ọmọ mọ iyawo ile lọwọ nile iwosan lai jẹ pe o mọ nipa rẹ.
awọn amoye ṣe akiyesi pe gdp ko ni iwọn deede ti ipinle ti awujọ ati pe a gbọdọ ṣe afihan itọnisọna miiran .
Ọ̀rẹ́ mi ni yín bí ẹ bá ń ṣe gbogbo nǹkan tí mo pa láṣẹ fun yín.
Àwọn tí wọ́n yí ọ ká yóo gbógun tì ọ́, wọn óo sì fi idà pa ọpọlọpọ eniyan ninu rẹ,’ nígbà náà o óo wá mọ̀ pé èmi ni OLUWA.
Ipinlẹ Eko lo ṣiwaju pẹlu 250, Oyo si tẹle pẹlu 100.
Fidio orin naa lo ṣe afihan aarẹ orilẹede Naijiria, Muhammed Buhari, nibi ti o ti n ṣe ipade pẹlu awọn adari eto aabo lorilẹede Naijiria.
Oríṣun àwòrán, LASEMA Lasema ni ni kete ti wọn ba ti doola ẹmi ẹni to ha sinu ile naa ni awọn yoo wo awoku ile naa kanlẹ, ko maa baa jẹ ewu fun awọn ara adugbo naa.
Ọmọ Àṣàkẹ́ ni Jayéjayé kan ni Àṣàkẹ́ máa ń wọ àdìrẹ tàbí borokéèdì ó sì máa ń wọ súwẹ́ta nígbà òtútù.
ede Naijiria ,Umar Ganduje , ti o dije fun ipo
Àti ìyá àti bàbá wa kò fi ẹnu kan óńjẹ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Coronavirus Nigeria : Àwọn gómìnà Naijiria mẹ́rin tó tí ní àrùn Coronavirus 8 Òkùdu 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 22 Agẹmo 2020 Oríṣun àwòrán, others Lati igba ti arun Coronavirus ti rapala wọ orilẹ-ede Naijiria loṣu keji ọdun 2020, ọpọlọpọ eeyan ni o ti ran.
Akowe agba fun ajo to n ri si  eto isẹ ati igbanisisẹ lorile ede Naijiria (Federal
Ọga ọlọ́pàá tí oun dari ẹ̀ka asèwádìí ile iṣẹ́ ọlọ́paa tí a mọ si IRT Abba Kyari sọ wipe 'Rambo' ni wọ́n ń pe Barau ni awọn agbegbe ti o ti n ṣọṣẹ́ látàri bo ṣe máa ń lo ibọn AK47 meji lẹ́ẹ̀kan náà.
“Ní ìhà ìwọ̀ oòrùn Òkun ni yóo jẹ́ ààlà yín.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Dolapo Badmus: Abayomi Shogunle, Dolapo Badmus ṣì wà lẹ́nu iṣẹ́ ọlọ́pàá-PSC 17 Ọ̀wàrà 2020 Oríṣun àwòrán, Pulse.
Ìbẹ̀rùbojo gba ọkàn àwọn olùgbé Eko àti Ogun nítorí adágún omi Ọ̀yan tí yóò di ṣíṣí láìpẹ́ Oríṣun àwòrán, @followlasema Àkọlé àwòrán, Ọpọ dukia lo ba omi lọ lawọn agbegbe bii Isheri, Warewa, Arepo, Magboro ati Ibafo ni ipinlẹ Ogun Inu ibẹrubojo ọkan lawọn olugbe agbegbe eti omi ni ipinlẹ Eko atawọn agbegbe miran ni ipinlẹ Ogun wa bayii ni ireti pe adagun omi Oyan yoo di ṣiṣi laipẹ.
Lọjọ ti wọn fagile ibo, a wọ ọkọ lọ si ilu Oṣogbo ṣugbọn ẹsẹ ni a rin pada lọ si ilu Ire tori rogbodiyan ti bẹrẹ nigba naa.
Ọjọbọ ni Adeleke yoo mọ ibi ti ọrọ yoo fi si, ti awọn ara Ipinlẹ Osun yoo si mọ ẹni ti yoo jẹ ojulowo gomina wọn.
" Iya rẹ naa fi ara rk jin pẹlu bi o ṣe maa n kọ awọn ọmọ naa ni ede gẹẹsi.
Ijọ Trinity House sọ pe eto isinku ọhun yoo waye lori ẹrọ ileeṣẹ Arise TV lori itakun DSTV channel 416 ni aago mẹrin irọlẹ.
Lẹ́yìn ọdún mẹrinla ni mo tó tún gòkè lọ sí Jerusalẹmu pẹlu Banaba.
Àìsàn tí ó ṣe é tí ó fi kú kò ju ọjọ́ mẹ́wàá lọ.
Tchelete - (Davido ati Mafikizolo) (2014) Oríṣun àwòrán, @TheReUpShow Orin Tchelete jẹ orin ayẹyẹ to si kun fun agbara.
Òǹwòye ìdìbò YIAGA - BBC News Yorùbá BBC News, YorùbáFò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Nigeria Election 2019:El-Rufai, lọ tọwọ́ ọmọ rẹ bọ aṣọ!
Ó bá pe Jeteri àkọ́bí rẹ̀, ó ní, “Dìde, kí o sì pa wọ́n,” ṣugbọn ọmọ náà kò fa idà rẹ̀ yọ nítorí pé ẹ̀rù ń bà á, nítorí ọmọde ni.
Ohun tí ó tọ́ ni mò ń kéde.
OLUWA dá Samuẹli lóhùn, ó ní, “Gbọ́ gbogbo ohun tí àwọn eniyan náà wí fún ọ, nítorí pé kì í ṣe ìwọ ni wọ́n kọ̀, èmi ni wọ́n kọ̀ lọ́ba.
Dafidi sáré sí Goliati, ó yọ idà Goliati kúrò ninu àkọ̀, ó sì fi gé orí rẹ̀.
Asofin Sugar je okan lara omo ile-igbimo
Oríṣun àwòrán, @abdulakeemibra8 Kudirat Abiola tun ṣaaju igbesẹ kan lọdun 1994 eyi to bi iyanṣẹlodi ọlọsẹ mejila ti awọn oṣiṣẹ ileepo.
 ""Ipenija owo ni mo le sọ pe mo ni lẹnu iṣẹ."
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ìtàn Mánigbàgbé: Ìtàn Adegbọrọ kọ́ wa láti ṣiṣẹ́ kára pẹ̀lú ìforítì Nigba to ya, pẹlu aforiti ati iṣẹ aṣekara, to si mọ baa ṣe n pọn omi silẹ de oungbẹ, Adegbọrọ fi owo pamọ, to si ra ọmọlanke lati maa fi ṣe aaru dipo ori to fi n ru ẹru.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Buns ni ọmọ mi jẹ tán ní ṣọ́ọ̀ṣì, ló bá di àwátì' Gbogbo igbiyanju awọn obi rẹ lati ri lo ja si pabo, koda ọrọ ti di tileeṣẹ ọlọpaa.
Trump Ààrẹ - BBC News Yorùbá BBC News, YorùbáFò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ààrẹ Donald Trump: Qasem Soleimani ń gbìmọ̀ràn láti kọ lù wá l'Amerika la ṣe kọ́kọ́ yára pa á - Trump Ààrẹ 4 Sẹ́rẹ́ 2020 Oríṣun àwòrán, Getty Images Aarẹ ilẹ Amẹrika, Donald Trump ti ni kii ṣe lati bẹ̀rẹ̀ ogun lawọn ṣe pa olori ọmọ ogun alagbara nni lorilẹede Iran bi ko ṣe lati pa ina ogun ko to bẹrẹ.
Ibadan Kings: 2,000 si 5,000 ni Oyè Ibadan, àmọ̀ Olubadan ń gba N30m
Ìran kì í sú ojú, bẹ́ẹ̀ ni ọ̀rọ̀ kì í kún etí.
Bí ìgbéraga bá wọlé, àbùkù a tẹ̀lé e,ṣugbọn ọgbọ́n wà pẹlu àwọn onírẹ̀lẹ̀.
Adajọ ni, wọn yoo pa wọn pẹlu okun lọrun wọn ni.
Ikú ni ìpín wọn bí àgùntàn lásánlàsàn,ikú ni yóo máa ṣe olùṣọ́ wọn;ibojì ni wọ́n sì ń lọ tààrà.
“Oṣù yìí ni yóo jẹ́ oṣù kinni ọdún fún yín.
Nítorí náà àwọn eniyan mi óo lọ sí oko ẹrú nítorí àìmòye wọn,ebi ni yóo pa àwọn ọlọ́lá wọn ní àpakú,òùngbẹ óo sì gbẹ ọpọlọpọ wọn.
Dalung fikun ọrọ rẹ pe owo yii wa fun agbekalẹ ere ije kan ni, eleyi ti o si ti waye.
Ọrunmila lo ọjọ meje ni ilu Iwo amọ Wuraọla ko fi lọrun silẹ pẹlu ọrọ abuku, to si mu kile aye le fun amọ Ọrunmila ko fesi pada, koda o tun lo ọpọn Ifa Ọrunmila lati dana.
Iku rẹ ko sẹhin awuyewuye lori ija ti o wa laaarin awọn ọmọ ẹgbẹ awakọ ti ẹka Lagos Island.
 Mo ni obinrin kan ti mo nifẹ si sugbọn n ko setan lati kede rẹ tabi igba ta se igbeyawo.
Iwadi naa fihan pe, bi wọn ba fa eefin siga simu ju wakati mẹwa lọ lọsọọsẹ, o ṣeeṣe ki wọn ni aisan ọkan, rọpa-rọsẹ, to fi mọ aisan ọna ọfun.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Bola Tinubu Colloquium: Tinubu kìlọ̀ fún Buhari lórí ohun tó leè ṣàkóbá fún sáà kejì rẹ̀ 29 Ẹrẹ̀nà 2019 Oríṣun àwòrán, @batcolloquium Àkọlé àwòrán, Tinubu ni agbekalẹ iṣejọba ti yoo mu ilu dẹrun fun araalu ni ki Buhari ati igbimọ iṣejọba rẹ o mojuto Eto ipade apero eyi ti awọn ọrọ ṣe fun agba oṣelu to tun jẹ aṣiwaju ẹgbẹ oṣelu APC lorilẹede Naijiria, Bọla Tinubu waye nilu Abuja, ọpọ lo si ti n sọrọ lori awọn koko ọrọ ti agba oṣelu naa ba ijọba atawọn oloṣelu sọ.
Kí ó lè máa fi òdodo ṣe ìdájọ́ àwọn eniyan rẹ,kí ó sì máa dá ẹjọ́ àwọn tí ìyà ń jẹ ní ọ̀nà ẹ̀tọ́;
Nígbà tí ó padà dé ní alẹ́ ó tún béèrè bí olóko ti wí.
" Oríṣun àwòrán, Pastor Adeboye/twitter Gbajugbaja pasitọ naa tun woye pe, iye awọn alarun Coronavirus ti ara wọn n da n ya ni lẹni pupọ, ti iye awọn eeyan ti arun naa n pa si kere si iye awọn ti ara wọn n ya.
Awọn akẹkọ ko lee joko se idanwo mọ lọsẹ to n bọ.
Àwọn òṣèré Nollywood tí wọn ò sí lóri amóhùmáwòrán mọ́ Díẹ̀ lára àwọn òṣèré Nollywood ti wọ́n ti ṣe ìgbéyàwó lẹ́ẹ̀kejì Kíni ẹ mọ̀ nípa àwọn gbajúgbaja Yollywood?
Nígbà tí obinrin náà rí i pé ó wà ninu ọpọlọpọ ìbànújẹ́, ó sọ fún un pé, “Oluwa mi, mo fi ẹ̀mí mi wéwu láti ṣe ohun tí o bèèrè.
Má ṣe làálàá àṣejù láti kó ọrọ̀ jọ,fi ọgbọ́n sẹ́ ara rẹ.
Àwọn ìmọ̀ràn rẹ̀ rèé láti wà ní àlàáfíà bí a ṣe ń padà sí bí a ṣe ń ṣe tẹ́lẹ̀.
Ẹ má jẹ́ kí ọkàn yín dàrú, ẹ má sì jẹ́ kí ẹ̀rù bà yín.
 Àpẹẹrẹ nínú èdè nama , ogún ni kílíìkì tí wọ ́ n ń lò nígbà tí wọ ́ n n lo mẹ ́ tàlélógọ ́ rin nínú ède kxoe tí ó jẹ ́ ọ ̀ kan lára èdè khoisan .
Bakan naa, Woods ti gba ife eye merinla otooto, bee si ni, O tun kopa ninu ifigagbaga meje otooto lodun yii, leyin aseyori ise abe opa eyin eyi ti o lakoja ninu osu kerin odun ti o koja.
Nítorí náà Ọlọrun fi wọ́n sílẹ̀ láti máa ṣe ìfẹ́kúfẹ̀ẹ́ ọkàn wọn.
Amọ kii ṣe nitori Baba Obafemi Awolowo ti gbogbo wa mọ bi ẹni mọ owo, ọmọ ọmọ rẹ kan Seyi Awolowo laye n sọrọ nipa rẹ.
Ko si ẹni to ku nipasẹ coronavirus l'Ọjọbọ ni Naijiria, eeyan 1,155 to ti ku naa si ni o wa loju Twitter ajọ NCDC.
Nítòótọ́ ibi tí ń yọ̀ ni ó gbé wọn lé,ó sì mú kí wọn ṣubú sinu ìparun.
Oríṣun àwòrán, others Ninu atejade naa ni wọn ti wa salaye awọn ohun to ṣokunkun si awọn eniyan; Ọjọgbọn Pondei di Adele Adari Ajọ NDDC ni Ogunjọ, Oṣu Keji, ọdun 2020, amọ Ọjọ Karun un, Oṣu Karun un ni Ile Igbimọ Aṣofin paṣẹ ki wọn ṣe iwadii adari naa.
Bi eto ibura fun awon asofin nile igbimo asofin to wa niluu Abuja yoo se maa waye ni lojo  Isegun , ti awon igbmo aosfin yoo si dibo  yan abenugan , ti yoo maa dari igbimo naa ti yoo jẹ ikẹ́sán án iru re ti yoo waye lorile ede yii, awon asofin ti o je omo egbe oselu ,People’s Democratic Party, (PDP) ti fẹnuko lati yan asofin Ahmad Lawan gege bi abenugan ti yoo maa dari won.
SWAN so ninu oro re, eyi ti igbakeji akowe egbe ohun, Abdulrosheed Okiki gbe jade nilu Ilorin pe, iyansipo dokita naa ni n se pelu ise takuntakun ti o n gbese ati aseyori re ninu ojuse torile-ede yan fun.
Ṣugbọn kí ẹwà yín jẹ́ ti ọkàn tí kò hàn sóde, ọkàn ìrẹ̀lẹ̀ ati ìwà pẹ̀lẹ́.
N kò ní í gbàgbé ìmọ̀ràn tí ó fún mi, ọ̀nà tí ìwọ àti bàbá mi fi lé ilẹ̀ ni n ó máa tọ̀, ìfẹ́ yín sí ara yín yóò jẹ́ àpẹẹrẹ rere fún mi, mo sì fẹ́ kí ẹ mọ̀ dájú pé ó rọrùn kí ẹnu mi gbàgbéoúnjẹ kí ọwọ́ mi kí ó sí gbàgbé òkèlè ju pé kí n gbàgbé ohun tí ẹ ṣe fún mi.
O tẹsiwaju pe awọn nsọ ibi ti awọn patako naa wa sugbọn ko tii si apẹrẹ pe ijọba yoo gbe igbesẹ lati wo patako ipolongo ti awọn gbe kalẹ.
Awọn gomina nigba kan ri ni ipinlẹ Rivers, Akwa Ibom, Eko, Plateau to fi mọ Ebonyi wa lara awọn to parọ ipo.
Ojú gbogbo wọn óo pọ́n kankan, wọn kò ní ṣàánú ọmọde, bẹ́ẹ̀ ni wọn kò ní bọ̀wọ̀ fún àgbà.
Oríṣun àwòrán, Facebook/Policeng Ọkunrin mẹta, obinrin meji.
Obinrin tí àwọ̀ rẹ̀ tutù jùlọ, tí ó sì jẹ́ afínjú jùlọ ninu àwọn obinrin yín, tí kò jẹ́ fi ẹsẹ̀ lásán tẹ ilẹ̀ nítorí àwọ̀ rẹ̀ tí ó tutù ati ìwà afínjú rẹ̀, yóo di ahun sí ọkọ tí ó jẹ́ olùfẹ́ rẹ̀, ati ọmọ rẹ̀ lọkunrin ati lobinrin.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù World Hepatitis Day: A kò leè kó o nípa dídìmọ́ ara ẹni Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ World Hepatitis Day: A kò leè kó o nípa dídìmọ́ ara ẹni 20 Sẹ́rẹ́ 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 28 Agẹmo 2020 Awọn ti wọn ni arun 'Hepatitis C' ni Naijiria to miliọnu mẹrin lọdun 2019.
Agboole nibi ti awọn obinrin bii meje si mẹjọ ti jọ n loyun lasiko kan naa ni Florence n gbe.
tí wọ́n jẹ́ ọmọ Kohati, tíí ṣe ìran Aaroni, nítorí pé àwọn ni gègé kọ́kọ́ mú.
Àti pé kò fẹ́ẹ másìí iṣẹ́ tí kò lè ṣe.
Wumi Toriọla ṣè ìgbéyàwó alárédè ní ọjọ́ kẹ́tàlá oṣù kárùn-ún ọdún 2018.
Awọn ọmọ igbimọ oluṣakoso ẹgbẹ tẹlẹ sọ pe nkan ti aarẹ ṣe ko ba ofin mu.
Jona rin ìlú náà fún odidi ọjọ́ kan, ó sì ń kéde pé: “Níwọ̀n ogoji ọjọ́ sí i, Ninefe óo parun.
A tún gbọ́ pé orógbó  tàbí obì ni àjẹsára tọ́n lè báni yẹra fún ààrùn Ebola.
Jonathan ṣalaye pe iṣejọba oun ko figba kankan ṣe ohun to jọ bẹẹ ati pe eto ẹyawo da ibujẹko maaluu silẹ RANCHES ni oun gba lero.
Awọn ara ilu ni ẹkun idibo Alimọṣọ kinni ni Ipinlẹ Eko ti rọ Gomina Akinwunmi Ambọde ti Ipinlẹ Eko lati tubọ moju to kiko awọn idọti kuro loju awọn opopona ni lati le gegi dina ajakalẹ arun to le tara eyi jẹyọ.
Falz f'ohùn lẹ̀ fún PDP, APC, MURIC, àwọn ọmọ Yahoo Zanku tó gbòde kan, wo ìtumọ̀ àti bó ṣe bá orin tuntun Zlatan mu Nigba ti o n ba awọn akọroyin sọrọ, o wi pe, pupọ awọn iya wọnyii lo n sọ wi pe, awọn fi ara mọ iṣẹ ti ọmọ wọn n ṣe nigba ti ko si ọkọ tabi ti ọkọ ti sa lọ fun wọn.
Báyìí ni ohun tí wolii Jeremaya, wí ṣẹ, nígbà tí ó sọ pé, “Wọ́n mú ọgbọ̀n owó fadaka náà, iye tí a dá lé orí ẹ̀mí náà, nítorí iye tí àwọn ọmọ Israẹli ń dá lé eniyan lórí nìyí, 
Ó mú wàràǹkàṣì, ati omi wàrà, ati ẹran ọ̀dọ́ mààlúù tí wọ́n sè, ó gbé wọn kalẹ̀ fún àwọn àlejò náà, ó sì dúró tì wọ́n bí wọ́n ti ń jẹun lábẹ́ igi.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù EKSU: Fásitì ìpínlẹ̀ Ekiti dá òṣìṣẹ́ 355 padà sẹ́nu iṣẹ́ 8 Sẹ́rẹ́ 2020 Oríṣun àwòrán, @Titiloye_Blog1 Àkọlé àwòrán, Awọn eeyan ọhun ni wọn da pada sẹnu iṣẹ ninu awọn eeyan ẹgberun o le diẹ Fasiti ijọba ipinlẹ Ekiti to wa ni Ado Ekiti ti da awọn oṣiṣẹ marundinlọgọtalelọọdunrun pada sẹnu iṣẹ lara awọn to da duro loṣu Kẹwaa, ọdun 2019.
Ni Ọjọru ni iṣẹlẹ yii waye ni nnkan bii agogo mẹrin irọlẹ lasiko ti gomina naa fẹ wọ ilu Baga l'awọn agbọn naa ba ṣina ibọn bolẹ.
Bakan naa,ọrọ bii PortHarcourt-Lagos, Abia-Lagos, Kaduna-Lagos, lẹ o maa gbọ bẹẹ ba lọ si ibudokọ tẹẹ tun fẹ rinrinajo lọ si ipinlẹ miiran lorilẹede Naijiria, gbogbo awọn baalu lo ti maa n kun fọfọ tori awọn ọmọ ijọ Reedemu ti n tẹ gbogbo ọkọ leti wa si Eko.
Wọ́n bá sọ fún mi pé, bí o bá gbọ́ àlá, o óo lè túmọ̀ rẹ̀.
Abrahamu bá dìde ní òwúrọ̀ kutukutu ọjọ́ keji, ó di kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ rẹ̀ ní gàárì, ó mú meji ninu àwọn ọdọmọkunrin ilé rẹ̀, ati Isaaki ọmọ rẹ̀ lọ́wọ́.
Gómìnà àná ní ìpínlẹ̀ Rivers Chibuike Amaechi tí wó àwọn ilé o wà ni àgbègbè Rainbow ni Trans-Amadi níbi ti ilẹ̀ náà wà.
Ipinlẹ Eko, Adari-ogun Abdllahi Hassan Inuwa sọ pe mọṣalaṣi jẹ ibi ijọsin si Ọlọrun Allah, ati pe Anọbi Mohammed bẹrẹ irin-ajo
O fi idi rẹ mulẹ pe ilu Ugbe Akoko ni awọn ti doola wọn.
Ṣugbọn ní ọjọ́ kẹta a óo jí i dìde.
Ọpọ awọn ololufẹ rẹ lo si n ki ni mẹsan an mẹwaa.
Bí wọ́n ti fẹ́ mú Paulu wọ inú àgọ́ ọmọ-ogun, ó sọ fún ọ̀gágun pé, “Ṣé kò léèwọ̀ bí mo bá bá ọ sọ nǹkankan?
Ọwọ́ ati ẹsẹ̀ rẹ̀ dàbí idẹ dídán, ohùn rẹ̀ sì dàbí ohùn ọpọlọpọ eniyan.
Ni bayi, Manchester City ti n fi ami ayo kan sagba Liverpool ti o ni ami ayo méjídínláàdọ́rùn ún ti Manchester City si ni mọ́kàndínláàdọ́rùn ún.
Irú òye wo ni ẹ fihàn wọ́n?
Oríṣun àwòrán, Osinbajo/instagram Àkọlé àwòrán, Osinbajo kò gbàdúrà ikú fún Buhari -Laolu Akande Ta ni ọrẹ tímọ-timọ Buhari to wà níbẹ̀, to dédé sàbẹ̀wò sí ààrin wọn, to si mú ẹri wá fún ààrẹ?
Wo àwọn nkan tí o le ṣe gẹ́gẹ́ bi aláboyún lásìkò àjàkálẹ̀ ààrùn Covid-19 Ohun rere tí Umar Yar'adua ṣe lórí aleefa: Ìkéde dúkìá faraye: Ohun àkọ́kọ́ tí Ààrẹ tó ti di olóògbé náà ṣe lórí àga àkọ́so, tí a kò leè gbàgbé ni pé òun ni aarẹ àkọ́kọ́ tó kéde dúkìá rẹ fún gbogbo ayé, lai ju ọgbọn ọjọ́ lọ tó di Aare, èyí tó sì dun mọ àwọn ọmọ Nàìjíríà nínú pupọ.
Ṣugbọn bí ẹni náà bá fẹ́ ra ẹran náà pada, yóo fi ìdámárùn-ún kún iye owó rẹ̀.
Àtunbọ̀tán òjò òwúrọ̀ ọjọ́ ajé nílùú Eko Àkójọpọ̀ àwòrán Òjò òwúrọ̀ Ọjọ Àjé l'Eko Oró ò!
Aaroni ati Huri wà pẹlu yín, bí ẹnikẹ́ni bá ní àríyànjiyàn kan, kí ó kó o tọ̀ wọ́n lọ.
com Àkọlé àwòrán, Kò tíì dájú bóyá ọwọ́ àwọn agbófinró tíì tẹ ẹnikẹ́ni lórí ìṣẹ̀lẹ̀ náà Gẹgẹ bii ọrọ ti Abiọdun Ọlarewaju, alukoro fasiti naa sọ, ilẹ ti ijọba ti fun fasiti naa lati aye Ọọni Adesọji Aderẹmi lawọn eeyan kan fẹ gba pada.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ojú òpó ayélujára ń gbóná girigiri lórí ọ̀rọ̀ Omotola sí ìjọba Buhari Duro Ladipọ, ìlúmọ̀ọ́ká òṣèré tíátà àti ọmọ àlúfà tí kò gbàgbé àṣà ìbílẹ̀ Ó di gbéré!
'Ẹwọn ọdun mẹẹdọgbọn ko pọ ju fun afipabanilopọ' Ẹ̀sùn ìfipábánilòpọ̀: Orí Twitter ló ti bẹ̀rẹ̀, ikú ló já sí Eyi tumọ si pe ọkunrin naa yoo le yọ ara rẹ ninu ẹsun ifipabanilopọ to ba le fidirẹmulẹ pe oun ni lọkan lati fẹ ọmọbinrin naa, sugbọn oun pada yi ero ọkan oun pada.
 meta ni ooni pa, ti erinmilokun  si pa  enikan lodun yii.
Bákan náà lo fi kun un pé, òun yóò pèsè ẹ̀rọ amúná wá 150kva fún àwọn ọlọpàá àti pé ìjọba yóò sowọ́n pọ mọ́ ilé iṣẹ́ mọ̀nàmọ́nà aládani, tí wọn yóò fi máa ní iná ni gbogbo ìgbà ìgbà.
Buhari fọwọ idaniloju yii sọya nibi ipade ilu kan to se pẹlu awọn ọba alaye atawọn olori agbegbe pẹlu awọn eeyan mii ti ọrọ Ilu Damaturu nipinlẹ Yobe gberu eyi to jẹ ara eto ti wọn la kalẹ fun abẹwo rẹ.
Ni orilẹede bii Naijiria nibi ti o jẹ iṣoro fun obinrin lati sọrọ bi wọn ba fi ipa baa lo pọ, Seun ba BBC News Yoruba sọrọ lori ipenija rẹ atawọn obinrin miran lori iwa buruku yii.
O tẹsiwaju wipe ajọdun ibeji tọdun yii jẹ ọkan lara awọn alakalẹ eto fun ayajọ ọjọ irinajo igbafẹ ni agbaye fun ọdun 2018, lati ọwọ ijọba ipinlẹ Ọyọ, pẹlu alaye wipe gbogbo ọna ni ijọba ipinlẹ naa n gbaa lati rii daju wi pe idagbasoke de ba eto ọrọ aje, aṣa ati ẹka irinajo igbafẹ.
Bakan naa lo fi idi rẹ mulẹ pe ọjọ Iṣẹgun, ọjọ karun un oṣu kini ọdun 2021 ni Oriṣabunmi jade laye.
Nítorí OLUWA kò ní ta wá nù títí lae.
Kíni igbimọ NJC fẹ́ jíròrò lè nípa Onnoghen Ìjíròrò láàrin àwọn olùdíje ipò gómìnà Èkó Sanwo-Olu, Jimi Agbaje yọ kúrò nínú ìfọ̀rọ̀wérọ̀ ìtagbangba BBC ní Eko Àwọn àwòrán ẹ̀yìn ìtàgé níbi ìpàdé ìfọ̀rọ̀wérọ̀ BBC Yorùbá l'Eko Oluwatimilẹhin ni ṣalaye ìgbé ayé gbogbo àwọn mẹtadinlogoje ti wọn n gbe ni 'Lepers Colony' nipinlẹ Ondo ni Naijiria.
Èmi OLUWA ni, ẹni àkọ́kọ́ ati ẹni ìkẹyìn.
O ni koko ti oun ri ni pe irinajo oṣelu ti yatọ si ti atẹyinwa ati pe ko sẹni to le dipo mu lai nii ṣe pẹlu ẹgbẹ oṣelu.
Láti ìgbà náà ni Edomu ti ń bá Juda ṣọ̀tẹ̀ títí di òní olónìí.
”Ogagun Dambazau tun pe awon omo orile-ede yii ti won fi oke okun se ibugbe lati fowosowopo, bee si ni lati se atileyin fun isakoso ijọba aare Muhammadu Buhari ninu erongba re lati mu igbe aye irorun ati isokan joba lorile-ede yii.
Ipinlẹ Adamawa, Benue, Taraba, Ondo ati Kaduna ti foju ri ọpọlọpọ idamu ni osu diẹ sẹyin pẹlu wahala awọn agbẹ atawọn Fulani daran daran to nru soke di gbọnmi sii omi o to o ni gbogbo igba.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, coronavirus prevention badge update: Wo òótọ́ àti irọ́ tó wà nínú báàjì àyà náà Amọ, alukoro ileeṣẹ ọlọpaa ni awọn yoo ṣa gbogbo ipa lati mu ọlọpaa naa.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ṣé ẹ ti rí kí èèyàn ní àwọ̀ ara tó ń ṣí bíi ìpẹ́pẹ́ ẹja rí?
Nítorí náà, òun ni mo lérò pé n óo rán nígbà tí mo bá mọ bí ọ̀rọ̀ mi yóo ti já sí.
Awọn ẹsun ti wọn fi kan Ribadu nigba naa ni pe, o lọwọ si fifi iya jẹ awọn afurasi ti ọwọ ajọ naa ba tẹ lọna to tako ẹtọ ọmọniyan.
O fikun ọrọ rẹ wipe, lati inu osu kẹfa ọdun 2017 niwọn ti kọwe si Ayefele lati wa se atunṣe, sugbọn o kọ eti ọgboin sijọba.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Akomolede ati Aṣa lori BBC: Mọ̀ si nípa oríṣìí ẹ̀ka ìsọ̀rí ọ̀rọ̀ àti ìwúlò wọn Àrà mánigbàgbé tí Baba Legba dá lágbo tíátà rèé Ikudoro, iku ti sika, iku ti mu gbajumọ agba ọjẹ ninu isẹ tiata miran lọ.
n óo bukun ọ lọpọlọpọ, n óo sọ àwọn ọmọ ọmọ rẹ di pupọ bí ìràwọ̀ ojú ọ̀run, ati bíi yanrìn etí òkun.
 ní àwọn 18 àti 19 century , ìbà pọ ́ njú-pọ ́ ntọ ̀ ni wọ ́ n rí bíi èyí tí ó léwu jùlọ àrùn àkóràn .
A ó kàn sí mọ̀lẹ́bí àwọn ẹlẹ́wọ̀n tó kú létí ná kí a tó kéde orúkọ wọn-Iléeṣẹ́ Ọgbà ẹ̀wọ̀n Òṣìṣẹ́fẹ̀yìntì, ọmọ ọdún 71 wọ gbaga ọlọ́pàá fún pípe iléeṣẹ́ kan fún ìgbà 24, 000 Buhari já ọ̀ra lára ọkọ̀ ìjagun ológun tiwantiwa ní Kaduna Ọwọ́ tẹ àwọn pásítọ̀ oniíṣẹ́ ìyanu èké méji nílùú Eko Papa iṣere Mobọlaji Johnson (Mobolaji Johnson Stadium) Ilu Eko Oríṣun àwòrán, others Papa iṣere ti wọn kọkọ kọ sibẹ wa saye ni ọdun 1930 nitosi gbagede Tafawa balewa Square.
Ẹni ọdun mọkandinlọgbọn ni lasiko naa.
Pataki erin ninu ọrọ gbogbo Orilẹede Botswana ni yoo fẹẹ jẹ orilẹede kan ṣoṣo lagbaye ti ọrọ erin yoo lagbara lori eto idibo.
Ẹ ti lé àwọn alufaa OLUWA kúrò lọ́dọ̀ yín: àwọn ọmọ Aaroni, ati àwọn ọmọ Lefi.
Arun Coronavirus maa n tan kan nigba ti ẹni to ba ti lugbadi arun naa ba hukọ, ti afẹfẹ si gbe.
 Ìlù yi dabi ìbẹ ̀ mbẹ ́ .
Loju opo Twitter rẹ, Biden gboriyin fun igbes tuntun yii to ṣapejuwe gẹgẹ bii ipese irọrun""."
Nígbà tí ó bá yá, àwa náà yóo ba yín lọ síbi ilẹ̀ tí wọ́n pín fun yín.
Idà mi yóo sì bẹ́ gbogbo àwọn tí wọ́n lòdì sí mi.
Ọpọ eeyan lo ti padanu ọwọ ati ẹsẹ wọn sọwọ awọn janduku naa, ti wọn sapamọ sabẹ awọn oluwọde yii, ti wọn si n da omi alaafia ipinlẹ naa ru.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fọ́nrán ohùn, Aabo to peye gbọdọ wa fawọn olutọju alaisan Onimọ naa ni yatọ si eyi, idagbasoke ko ti i de ba ọrọ oṣelu ni Naijiria de ibi ti wọn fi le gbe iṣakoso ileeṣẹ ọlọpaa le awọn gomina lọwọ.
Oríṣun àwòrán, Lizzy Anjorin Awọn eyin funjowo ati ẹlẹyinju ẹgẹ ree nibi ayẹyẹ Lizzy Anjọrin Oríṣun àwòrán, Lizzy Anjorin Iyabọ Ojo ree, ọkan lara awọn gbajugbaja elere ori itage lobinrin, ti wọn wa yẹ Lizzy Anjọrin si lọjọ iwuye rẹ.
Olootu ijọba New Zealand, Jacinda Arden dara pọ mọ ẹgbẹgbẹrun awọn oludaro to peju pesẹ lẹgbẹ Mọsalaṣi Al Noor, ọkan lara awọn aye ijọsin ti agbebọn naa ti yinbọn pa awọn olujọsin.
Oluwa kò jáfara nípa ìlérí rẹ̀, gẹ́gẹ́ bí àwọn kan ti rò, ṣugbọn ó ń mú sùúrù fun yín ni.
sugbon ti ajo eleto idibo orile ede Naijiria INEC sun un siwaju nitori idi kan
ipenija lọdun 2018, ijoba yoo sa ipa re lati yanju awon ipenija naa.
Ìgbéraga eniyan a máa rẹ̀ ẹ́ sílẹ̀,ṣugbọn onírẹ̀lẹ̀ ọkàn yóo gba iyì.
Osun Election Results 2018: Ademola Adeleke ní wọ́n jà òun lólè Ṣe ẹ ranti Sẹneto onijo, iyẹn Sẹnetọ Ademọla Adeleke?
Díẹ̀ nínú àwọn ọ̀nà àrà náà nìwọ̀nyí;
Ko si ẹni to le sọ pato ipa ti aarẹ Trump kọ si ayipada oju ọjọ.
N óo wó ilé tí ẹ kọ́ fún ìgbà òtútù ati èyí tí ẹ kọ́ fún ìgbà ooru; bẹ́ẹ̀ ni àwọn ilé tí ẹ fi eyín erin kọ́ ati àwọn ilé ńláńlá yín yóo parẹ́.
Ìfihàn náà ní pípé, tí a mọ̀ ní àkókò náà bíi Àwọn Nkan ati Àwọn Májẹ̀mú, ni ó ṣeéṣe kí a ṣe àkọsílẹ̀ rẹ̀ ní kété lẹ́hìn ọjọ́ kẹfà Oṣù Kẹrin 1830 (ọjọ tí a ṣe ìgbékalẹ̀ Ìjọ).
Ìtàn ọ̀rẹ́ tó fi òògùn gba ọkọ ọ̀rẹ́ rẹ̀ ni Akomolede BBC Yorùbá fẹ́ kọ́ wa lònìí Wá kẹ́kọ̀ọ́ nípa ègé ọ̀rọ̀ ohùn Yorùbá tí a mọ̀ sí Sílébù Àṣà Oge Ṣíṣe ní Akọ́mọlédè BBC Yorùbá ń gbé yẹ̀wò lónìí, Ó yá, iṣẹ́ ti bẹ̀rẹ̀.
Eyi ko sẹyin esi ayẹwo ti ajọ to n mojuto itankalẹ ajakalẹ aarun ni Naijiria, NCDC, fi sita lọjọ Aiku, to safihan pe eeyan mọkandinlọgọrin pere lo ṣẹṣẹ ni.
Ẹ̀yin ará Samaria kò mọ ẹni tí ẹ̀ ń sìn.
Àwọn Ọmọ Israẹli Bèèrè fún Ọba.
Yóo máa ṣọ́ wọn títí lae,ṣugbọn a óo pa àwọn ọmọ eniyan burúkú run.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù ENDSARS Tribunal: ọlọ́pàá àti olùjẹ́rìí tó gbá létí lẹ́ẹ̀mẹrin pàdé níwájú ìgbìmọ̀, ariwo sọ!
Igbakeji minisita to n mojuto oro iforotonileti lorile-ede Liberia, Eugene Fahngon ni won fi satimole latari ede ti o lo lati tabuku ba omo ile igbimo asofin meji naa.
Ogbeni Garba Datti-Muhammad ti o n soju fun ekun kan nipinle Kaduna so pe awon opolopo ketekete ni o n la orisirisi idojuko koja, eleyi ti ko si bojumu.
Nítorí aṣẹ́wó dàbí ọ̀fìn jíjìn,obinrin onírìnkurìn sì dàbí kànga tí ó jìn.
Nitori pe agbẹjọro agba naa lo yẹ ko tọ ọ sọna lori ọrọ naa.
 A si gbọ pe awọn kan ni wọn ko ni i fi ẹsun ibalopọ ọkunrin s'ọkunrin kan wọn mọ, pe ki wọn ko wọn pada lọ si ẹka ileeṣẹ ọlọpa to n gbogun ti ẹgbẹ okunkun ṣiṣe.
Oyelowo jẹ ilumọka oṣere sinima to kopa ninu awọn sinima bi Selma (2014), The Butler (2013), The Last King of Scotland (2006) ati Queen of Katwe (2016).
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Àìle è ka kéú ló sọ mí di Krìstíẹ̀nì - Adewale Ayuba Háà!
Ọjọgbọn Oyebọde sọ eyi nigbati oun ba BBC Yoruba sọ ọrọ lori abẹwo adari Ilẹ Germany, Angela Merkel si olu-ilu Naijiria ni Abuja.
ile-ise to n mojuto eto ise lati orile ede Amerika , ni eyi ti  Kurt
Ti eniyan ko ba mu omi to, itọ eniyan le ni awọ ti ko ba oju mu to, ki o maa pọn tabi ki o ni oorun to lagbara ju bi o ṣe yẹ lọ.
Gbajugbaja ile itura Palau ti di titi pa lati oṣu kẹta, koda gbogbo ile ounjẹ naa ṣofo Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Bolaji Faleke ni Olùkọ́ tó ń kọ́ wa ní àṣà oge ṣiṣe lórí BBC Yorùbá Awọn orilẹede ti ko ni akọsilẹ coronavirus ree Palau Micronesia Marshall Islands Nauru Kiribati Solomon Islands Tuvalu Samoa Vanuatu Tonga Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Natalia Mufuta ìyá Yakub, Kamil àti Adam sọ̀rọ̀ lórí bí wọ́n ń sọ èdè mẹ́rin pàpọ Palau Okun to wa ni Palau ko ni afiwe kaakiri agbaye, oludari ile itura Palau, Brian Lee lo sọ bẹẹ.
Igbó nlá ni igbó náà jẹ́ .
Mo kó fadaka ati wúrà jọ fún ara mi; mo gba ìṣúra àwọn ọba ati ti àwọn agbègbè ìjọba mi.
Èyí ló mú kí adájọ rànṣẹ́ pe ki ọgá àgbà ilé iṣẹ́ ọmọogun jọ̀wọ́ àwọn ọmọogun mẹ́wàá tí ọ̀rọ̀ náà kàn fún àjọ ọlọ́pàá.
Ṣugbọn kò ní dára fún ẹni ibi, bẹ́ẹ̀ sì ni ọjọ́ rẹ̀ kò ní gùn bí òjìji, nítorí kò bẹ̀rù Ọlọrun.
Ajo to n mojuto isẹlẹ pajawiri
 o je mimo fun ipa re niu igbedagba iseaworan .
ó rí i tí ọba náà dúró lẹ́bàá òpó lẹ́nu ọ̀nà, àwọn ọ̀gágun ati àwọn tí wọn ń fọn fèrè dúró lẹ́gbẹ̀ẹ́ rẹ̀.
Lara awọn to peju sibi ayẹyẹ isninku naa ni Dayo Amusa, Toyin Abraham atawọn gbajugbaja oṣere tiata Yoruba miran.
O fi kun ọrọ rẹ pe inu rirun, eebi, igbẹ gbuuru, pipọ ẹjẹ, aisan jẹjẹrẹ, tabi iku ni lilo nkan bẹ ṣaba ma n yọri si.
Yóo jẹ́ ìpín tiwọn lára ilẹ̀ tí a yà sọ́tọ̀ fún OLUWA, ilẹ̀ mímọ́ jùlọ; yóo wà lẹ́gbẹ̀ẹ́ ilẹ̀ ti àwọn ọmọ Lefi.
Eyi fihan bi awon fayawo se n fipa wa owo.
Wọ́n kí irún Jimọ àkọ́kọ́ ní Hagai Sophia lẹ́yìn ọdún 85 ní Turkey 'Kìí ṣe pé ìjánu Ọkọ̀ tó pa Tolulope Arotile já tàbí kò já, ìwádìí wà lọ́wọ́ ọlọ́pàá' Ilé iṣẹ́ ọmọogun òfurufú ni ẹka ọmọgun to ń lo bàlùú, ẹlikọpta àti àwọn irinṣẹ́ miran ti wọ́n fi ń fò láti dáàbò bo orílẹ̀-èdè Nàìjíríà lókè Ìgbaniṣíṣẹ́ ti ọdún 2020 jẹ́ ti ẹ̀kọ́ Basic Military Training (BMTC) tí sílẹ̀ fun gbogbo éni to ba ti jẹ́ ọmọ bíbí Nàìjíríà, tí sì yóò si pari ni ọjọ́kọkanlélógún oṣù kẹjọ ọdún 2020.
Ẹwẹ, alaga igbimọ ile aṣofin to n ri si ọrọ idajọ ati ẹtọ ọmọniyan, Opeyemi Bamidele ṣalaye pe igbimọ yii yoo kọkọ ṣepade pẹlu Sẹnẹtọ to ṣagbatẹru aba naa kawọn eeyan to lanfaani lati da si i ninu ijiroro itagbangba ọsẹ to n bọ.
Solomoni ní ìlọsíwájú, gbogbo àwọn eniyan Israẹli sì ń gbọ́ tirẹ̀.
 Besini, Mo tun dupe lowo awon akegbe mi gbogbo ati awon osise iko yii ti o je ki irinajo yii seese.
Fun igba keji laarin osu kan, Aarẹ Ọna Kakanfo nilẹ Yoruba, Iba Gani Adams tun ti n ke tantan pe awọn agbébọn ti farasin siluu Kishi, lagbegbe Oke Ogun.
Kíní ǹkan ti Khafi le pàdánù: Gẹ́gẹ́ bí ọlọpàá MET ní ilẹ̀ Gẹ̀ẹ́sì, tó sì wà ni ipò ti Khapilat Kareem wa lẹ́nú iṣẹ́, ó ni ẹ̀tọ́ sí owó osù bíí ẹgbẹ̀rún mọ́kàndílógójì poun (£39,000) lọ́dun.
Adegbọrọ wa da wọn lohun pe ti wọn ba fẹ lowo, ki awọn naa kalọ si ọja Oyingbo.
"Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, ẹ̀fọ́ rírò jẹ́ alábárìn iyán, fùfú, ẹ̀bà, àmàlà àti ìrẹsi funfun ""O si yẹ k'oju ko ti ijọba pe iru eniyan bi Lai Mohammed n parọ."
Coronavirus treatments: Ọ̀gá àgbà ọlọ́pàá pàṣẹ pé kò gbọdọ̀ sí ìdádúró fún àwọn tí iṣẹ́ wọn ṣe kókó lásíkò ìséde
N óo kó ìpayà bá ọ,láti ọ̀dọ̀ gbogbo àwọn tí wọ́n yí ọ ká;èmi OLUWA Ọlọrun àwọn ọmọ ogun ni mo sọ bẹ́ẹ̀.
Ọna ti wọn o gbegba ni pe, adinku yoo ba owo ori, ti wọn o si fi kun bi ijọba ṣe n nawo.
7 28669 Orilẹede Syria 809 4.
Ìgbà tí mo ka èso rẹ̀ kan, fàdákà ni gbogbo ara rẹ̀ jẹ́, ọ̀kan ṣoṣo yìí náà ni mo lè ká nítorí àwọn èerà olóró gbogbo ni wọ́n ń rìn mi ní ẹ̀gbẹ́ ti wọ́n ń já mi jẹ.
Awọn panapana mẹtadinlọgbọn lo gbẹmi mi ni ile ẹkọ Kurani.
Bàbá àgbàlagbà ọ̀hún kò le sọ̀rọ̀ mọ́, ó sì n ṣe bi ẹni tó ní àìsàn, débi pé ọmọ rẹ̀ ló n gba ẹnu rẹ̀ sọ̀rọ̀.
Ìwọ ọkùnrin onírẹ̀lẹ̀, ìwà ìrẹ̀lẹ̀ lo mú ọ sọ irú èyí.
Fọnran yii si lo n se afihan awọn olukọ fasiti meji lawọn ileẹkọ mejeeji yii ti wọn n beere ibalopọ lọwọ awọn akẹkọ to fẹ wọle sọgba ile ẹkọ wọn.
Ọmọ bibi ipinlẹ Enugu ni Regina sugbọn ilu Eko lo gbe dagba, to si n fi ede Yoruba dabira ninu sinima.
N óo di ẹni ìdọ̀tí lójú àwọn orílẹ̀-èdè mìíràn nítorí rẹ, o óo sì mọ̀ pé èmi ni OLUWA.
Ninu fidio yii ni afihan Aisha Buhari to jẹ aya Aarẹ Buhari lasiko to n binu to n sọ pe wọn ko jẹ ki oun wọ aaye naa ninu ile ati pe ko si nkan ti awọn agbofinro to le ni igba to wa nibẹ ri ṣe si ohun to n ṣẹlẹ.
Ṣugbọn Jesu wí fún gbogbo wọn pé, “Ìyá mi ati àwọn arakunrin mi ni àwọn tí ó gbọ́ ọ̀rọ̀ Ọlọrun, tí wọ́n sì ń ṣe é.
Omotara kan ìdin nínú iyọ̀, àwọn ọmọ ilẹ̀ Faranse náà bínú síi nítorí alágbe tó fi ṣe yẹ̀yẹ́.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ondo disability day: Ijọba ẹ gbà wá ní ariwo tí àkàndá ẹ̀dá ń pa Agbẹjọro fun ijọba, Akin George ni lẹyin oṣu meji ni wọn to ri oku obinrin naa nibi ti wọn sọ ọ si ninu kanga ọhun.
Nibayii, Tikhanovskaya ti sa kuro lorilẹede Belarus lọ si Lithuania, ti minisita fun ọrọ ilẹ okeere ni Lithuania si sọ wi pe alaafia ni arabinrin naa wa.
Ọlọrun, tí mo yin ọ̀rọ̀ rẹ̀,OLUWA, tí mo yin ọ̀rọ̀ rẹ̀;
Lẹ́yìn ò rẹyìn, Amotekun dòhun, gbogbo ilé aṣòfin nílẹ̀ Yorùbá fòǹtẹ̀ lu Ilé aṣòfin Oyo àti Ogun buwọ́lu àbádòfin ikọ̀ aláàbò Amotekun Oshiomole: irọ́ ni wọ́n ń pa,èmi ṣí ní Alága APC!
Ó ní, “Fún ọdún mẹtalelogun, láti ọdún kẹtala tí Josaya ọmọ Amoni ti jọba Juda, títí di ọjọ́ òní, ni OLUWA ti ń bá mi sọ̀rọ̀, tí mo sì ti ń sọ ọ́ fun yín lemọ́lemọ́, ṣugbọn tí ẹ kò sì gbọ́.
Ìdije yii ko ba jẹ́ anfaani fun Mauricio Pochettino lati yi ìtàn ọdún mẹ́rin rẹ̀ pada ninu ẹgbẹ́ agbabọọlu Tottenham Hotspur, sùgbọ́n ti Man United kò jẹ́ ki àlá dòun fun akọ́nimọ̀ọ́gbá ọ̀ún lati gba ife àkọ́kọ́ fun Tottenham.
lami-laaka ,ni orile ede to wa ni isọkan.
Iṣẹ́ wo ni ẹ̀ ń ṣe?
Mama Arsenal ṣeé débi èrè, ẹgbẹ́ kan ti fún màmá l'ẹ̀bùn owó 'Ní ìjọ wa, ọtí mímú la fi ń pe ẹ̀mí Ọlọ́run sọ̀kalẹ̀' Oyenusi ló mú mi wọ ẹgbẹ́ adigunjalè kó tó di pé mo b'Ólúwa pàdé - Kayode Williams Oral Sex: Bóo bá ń gba ẹnu ní ìbálòpọ̀, wo àìsàn tóo lè kó lójú ara rẹ Tunde Idiagbon, ọ̀gágun kògbagbẹ̀rẹ́ tó ní ẹ̀ẹ̀kan lóṣù ló yẹ kí ológun máa rẹ́rìín Ọmi alayo kọọkan ní ifẹsẹwọnsẹ naa pari si ki wọn to fi pẹnariti yanju ẹ.
Dipò ki wọn ronú bi nkan yio ti rọrùn fún ilú nipa ipèsè ohun amáyédẹrùn bi iná mọ̀nàmọ́ná, ilé-iwé, ilé-ìwòsàn, ojú ọ̀nà ti ó dára, òfin lati jẹ ki ilú tòrò, ṣe ni wọn bẹ̀rẹ̀ si ji owó ilú.
Gbogbo eniyan ni gbogbo ibi gbudọ dara pọ mọ wa.
Ẹ wo ìkìlọ̀ tí ìjọba America fi léde lórí ìdìbò gómínà Ondo, Edo Ipa tí Fathia Balogun kó nínú bí mo ṣe dèèyàn lágbo òṣèré fíìmù Yorùba rèé - Baba Ijesha Ìwà Bashorun Gaa ni Obaseki hù ní ipínlẹ̀ Edo -Tinubu Aya gómìnà Kwara fẹ́ ran tìyá- tọmọ olójú búlúù lọ́wọ́ Ìdí tí a fi ṣàfikún owó ìtanràn ọ̀rọ̀ kòbákùngbé ní Nàìjíríà sí 5 Mílíọ̀nù rèé - Lai Mahammed Nigba to n fi da ẹbi naa loju pe ijọba yoo fun ẹbi oloogbe naa lowo gba mabinu, o ni ijọba labẹ iṣakoso Seyi Makinde ko ni la oju rẹ silẹ ki iya maa jẹ awọn ara ilu.
Àwọn àgbààgbà Gileadi dá a lóhùn pé, “Ìyọnu tí ó dé bá wa náà ni ó mú kí á wá sọ́dọ̀ rẹ; kí o lè bá wa lọ, láti lọ gbógun ti àwọn ará Amoni.
Bẹẹ lo fi kun ọrọ rẹ pe, o yẹ ki awọn ti wọn ṣagbatẹru eto pe Ọmọyẹle Ṣoworẹ, to jẹ oludije fun ipo aarẹ fun ẹgbẹ oṣelu African Action Congress(AAC) pẹlu.
Ó dùbúlẹ̀ lábẹ́ igi náà, ó sì sùn.
Lẹyin ti alamojuto ifẹsẹwọnsẹ naa fun feere pe ere gbogbo pari, ami ayo meji si odo ni Arsenal fi gbẹyẹ mọ Manchester City lọwọ ninu ifẹsẹwọnsẹ ipele to kangun si a'sekagba idije FA Cup ti ọdun yii ni orilẹ-ede Gẹẹsi.
Sibekai, ará Huṣati, pa ìran òmìrán kan, ará Filistia, tí orúkọ rẹ̀ ń jẹ́ Sipai, àwọn ará Israẹli bá ṣẹgun àwọn ará Filistia.
Christmans celebrations: Alaafin Oyo gba àdúrà ọdún fún àwọn ọmọ Nàìjíríà, pẹ̀lú ìmọ̀ràn lórí ààrùn COVID-19
Agba kii wa lọja, ki ori ọmọ tuntun wọ, idi ree ti awọn agba meji nilẹ Yoruba fi fori kori lori iwọde EndSARS to n lọ lọwọ yika Naijiria.
Kọjú sí mi kí o ṣe mí lóorebí o ti máa ń ṣesí àwọn tí ó fẹ́ràn rẹ.
O wa gbosuba fun awon omo egbe bi eto idibo egbe naa to waye lojo Abameta ni irowo-irose ni  ijoba ibile mokanlelogun to wa ni ipinle naa.
02  ninu ida ogorun, ti o si pajude si 42,579.
Nítorí kò sí ilé kan tí kò jẹ́ pé eniyan ni ó kọ́ ọ.
Lọpọ igba ni yoo maa yọ aleebu ara awọn ọkunrin to ba dẹnu ifẹ kọọ ni ọkọọkan lọna ati le wọn kuro ni sakani rẹ.
Kì í ṣe ìlú yìí ni mo fẹ́ parun.
Bakan naa, ni  igbakeji aare tun dupe lowo awon igbimo alakoso fun egbe awon musulumi lorile ede yii(Nigerian Supreme Council for Islamic Affairs, ati olori egbe awon obinrin musulumim (Federation of Muslim Womens Association of Nigeria ,FOMWAN),  ati  alakoso egbe awon akekoo musulumi lorile ede Naijria (Muslim Students Society of Nigeria) lati wa sibi ipade naa.
O ni iwa ipá ni awọn APC atawọn oṣiṣẹ eleto aabo lo fawọn eniyan PDP atawọn ara Ekiti.
Èmi ṣì ni Jagaban, aṣíwájú Eko gangan, èmi ò lè sá kúrò l'Eko- Ahmed Tinubu Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ọpọ ipinlẹ lo n koju aawọ abẹnu ninu ẹgbẹ APC lorilẹede Naijiria Agba ọjẹ oloṣelu ninu ẹgbẹ All Progressives' Congress, APC, Asiwaju Bola Ahmed Tinubu ti ṣe abẹwo si gomina ipinlẹ Eko, Babajide Sanwo-Olu lati ba a kẹdun lori awọn iṣẹlẹ to waye nipinlẹ Eko l'ọsẹ yii.
Gomina Ifeanyi Okowa sọ pe ọna lati dẹ́kun itankalẹ aarun naa ni ijọba ṣe pasẹ naa.
Òdodo ní ń gbé orílẹ̀-èdè lékè,ṣugbọn ẹ̀ṣẹ̀ jẹ́ ẹ̀gàn fún orílẹ̀-èdè.
Ó súre fún ẹ̀yà Lefi pé: “OLUWA, fún Lefi, ẹni tíí ṣe olódodo, ní Tumimu ati Urimu rẹ;Lefi, tí o dánwò ní Masa,tí o sì bá jà níbi odò tí ó wà ní Meriba;
O lé mi kúrò lórí ilẹ̀, ati kúrò níwájú rẹ, n óo sì di ìsáǹsá ati alárìnká lórí ilẹ̀ ayé, nígbà tí ó bá yá, ẹnikẹ́ni tí ó bá rí mi ni yóo pa mí.
Igba akọkọ kọ niyii ti Pogba fi ayẹyẹ ọjọ ibi rẹ sọ ori iranlọwọ ṣiṣe.
Oríṣun àwòrán, LAYCON/INSTAGRAM Katung Aduwak: Olubori akọkọ lọdun 2006 Isọri kinni BB Naija ti wọn kọkọ se ni Naijiria waye ni ọjọ karun un, oṣu kẹta titi wọ ọjọ kẹrin, oṣu keje, ọdun 2006.
O fikun oro re pe, ijoba ti
Yoruba Language: Ìran Yorùbá gbayì ní Austria
“Ta ló dàbí Jobu,tí ń kẹ́gàn Ọlọrun nígbà gbogbo,
Ó bá gbé ọwọ́ lé ọ̀kọ̀ọ̀kan wọn, ó wò wọ́n sàn.
bí wọn bá sọ fun yín tabi ẹ gbọ́ nípa rẹ̀, ẹ fi pẹ̀lẹ́pẹ̀lẹ́ wádìí.
Olukuluku wọn ní ọjọ́ àsè tirẹ̀, wọn a sì máa pe àwọn arabinrin wọn wá sí ilé láti bá wọn jẹ àsè.
Múra, kí o sì ṣe ọkàn gírí, nítorí ìwọ ni o óo jẹ́ kí àwọn eniyan wọnyi gba ilẹ̀ tí mo ti búra fún àwọn baba wọn, pé n óo fún wọn.
 ní ọdún 1916 pinnock ṣe àwárí ibùdó , oke egunya , tí ó sì ra ilẹ ̀ náà .
Pataki ọjọ naa ni Gomina Akinwunmi Ambode ti Ipinlẹ Eko, ẹni ti Alakoso
Iroyin kan tiẹ tun sọ pe awọn ọlọpaa yin tajutaju lati dari awọn ero nibi eto isinku naa.
Obinrin náà sọ fún un pé, “Alàgbà, mo wòye pé wolii ni ọ́.
’ Nítorí náà kì í ṣe àwọn olódodo ni mo wá pè, bíkòṣe àwọn ẹlẹ́ṣẹ̀.
Kò sí ọ̀kan ninu wọn tí a wòsàn, àfi Naamani ará Siria.
Ṣugbọn nítorí tí wọn kò ní gbòǹgbò ninu ara wọn, àkókò díẹ̀ ni ọ̀rọ̀ náà gbé ninu wọn.
06% ni saa keta odun 2017.
Ila Ariwa Gusu lo soro ninu atejade fun ikini ku odun, ti akowe agba re Emmanuel Uzor, gbe jade lojo Aje niluu
Ninu ìdílé Bani: Meṣulamu, Maluki, ati Adaaya, Jaṣubu, Ṣeali, ati Jeremotu.
" Mo ti fi ṣe afisẹyin, ti eegun n fi aṣọ, mo si ti tẹsiwaju.
O kọ ọ pe ofifo ni igbeaye oun wa, ki Okochu, to fi ayọ ati idunnu kún.
Ọpọ awọn ololufẹ BBNaija lo ti fẹran Vee papaa julọ nitori ibaṣepọ rẹ pẹlu Laycon ninu ile.
Wọ́n ń ṣe inúnibíni wa, ṣugbọn à ń fara dà á.
Losu Karun ọdun 2020 yii, Naijiria gba ọọdunrun miliọnu dọla owo Abacha lati ọwọ ijọba ilẹ Amẹrika ati ẹkun Jersey.
lori iwa ifiyajẹni lọna aitọ  ti asofin Abbo Eliṣa hu si arabinrin kan, niluu Abuja.
Ṣé ẹ máa ń sọ pé, ‘Ìkórè ku oṣù mẹrin.
 Ajayi Shuaib ni oun ko mọ ohunkohun mọ lẹyin eyi ."
A tun ti pese anfaani  fun awọn ile-isẹ ijọba lati le satunse si oju ọna ọkọ nipa lilo owo-ori, ni eyi ti igberu yoo fi de ba eto ọrọ aje.
Nigba ti Southampton na Arsenal pẹlu ami ayo mẹta si meji lati fidi Arsenal gbolẹ lọjọ Aiku.
Ìgbòwó ló n mọ́lẹ̀, ọmọ Kòsọ́kọ́
Lẹ́yìn náà, ó yipada, ó wọn ìhà gúsù, ó jẹ́ ẹẹdẹgbẹta (500) igbọnwọ (mita 250), gẹ́gẹ́ bí ọ̀pá rẹ̀.
Nígbà tí ìwà burúkú bá dé, ẹ̀gàn yóo dé,bí àbùkù bá wọlé ìtìjú yóo tẹ̀lé e.
O wa gbe oriyin fawọn ẹgbẹ ibilẹ to ti tako igbesẹ naa, eyi to se apejuwe bii ọna lati baana owo miran.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ekiti: Fayemi gbẹ́sẹ̀ lé èdè òyìnbó sísọ fáwọn òṣìṣẹ́ nípinlẹ̀ Ekiti 19 Ògún 2019 Oríṣun àwòrán, Ekiti state government Oyinbo sisọ ti di eewọọ fun awọn oṣiṣẹ ijọba ni ipinlẹ Ekiti bayii.
Ènìyàn 339 ló ní àrùn Coronavirus ní Ọjọ́ọ́bọ̀ ní Nàíjíríà Eniyan ọọdunrunlemọkandinlogoji lo tun ṣẹṣẹ ni arun Coronavirus ni Naijiria ni Ọjọọbọ.
Ami ayo meji ni ẹgbẹ agbabọọlu orilẹ-ede Chile fi na Thailand ninu idije ifẹ ẹyẹ agbaye tawọn obinrin to n lọ lọwọ ni France.
Oríṣun àwòrán, PAstor Adeboye Fun ọpọlọpọ, ṣe ni awọn ọrọ naa wu awọn eeyan lori bi ifẹ to jinlẹ to eyi ṣi ṣe wa laarin awọn lọkọ laya iranṣẹ Ọlọrun yii pẹlu bi wọn ṣe dagba to - afi bii ifẹ ti kii ti tabi d'ogbo.
Wo ohun tó yẹ kí o mọ̀ nípa Laycon, akẹ́kọ̀ọ́jáde UNILAG tó ń kópa nínú BBNaija 2020 Gbogbo ohun tí Godswill Akpabio sọ níbi ẹ̀sùn ìnákùnàá tí wọ́n fi kàn án rèé Òògùn ìtura dé fún Coronavirus!
Rí i dájú pé o mọ̀ bí agbo ẹran rẹ ti rí,sì máa tọ́jú ọ̀wọ́ ẹran rẹ dáradára;
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, OsunDecides: Omisore ní ẹni tó bá fẹ́ ra ìbò, àwọn yóò lọ lásọ mú ni Atẹjade naa tun salaye pe, bi o tilẹ jẹ pe awọ̀n afurasi gbajuẹ naa ti wa ni ahamọ ọlọpaa, sibẹ awọn si tun n wa awọn eeyan kan to tun lẹbọ lẹru lori isẹlẹ yii.
"Oríṣun àwòrán, others Iroyin ni: ""Bo si ṣe rí oku agbẹ meji nilẹ ni Tafa Adeoye tarapooro pe, ṣe awọn eeyan yii wa ba wa ja ni?"
"Wọn bi mi pẹlu ipenija ilera kan ti wọn n pe ni Mayer-Rokitansky-Kusher-Hauser syndrome (MRKH).
Aldrin ati Collins si wa laye, amọ Armstrong ku ni ọdun 2012 ni ẹni ọdun mejilelọgọrin.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ǹjẹ́ o leè fẹ́ ẹni tó bá ń jẹ ẹran Ajá?
Ọjọ́ meje gbáko ni ẹ gbọdọ̀ fi máa jẹ burẹdi tí kò ní ìwúkàrà.
Ẹni ìyìn ni OLUWA, nítorí pé, lọ́nà ìyanu,ó fi ìfẹ́ rẹ̀ tí kì í yẹ̀ hàn mí,nígbà tí ilẹ̀ ká mi mọ́.
Àkọlé àwòrán, Aṣọ ń pe aṣọ ránṣẹ́ ni lásìkò ìbúra gómìnà àti ààrẹ Akojọpọ awọn aworan yii wa lati ile isẹ BBC ati Twitter Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Ẹ ma ṣe bínú pé a kò mọ yín nígbà tí a dé, kì í ṣe gbogbo wa ni kò mọ̀ yín, nítorí èmi ti mo dúro yìí, rírí tí mo ti rí yin ni mo ti mọ̀ pé ọba pàtàkì ni ẹ jẹ́.
Ati pe ko si nkan naa to munilọkan ti oun ko le ya pẹlu kalamu oun.
Àṣìta ìbọn pa èèyàn kan lásìkò tí SARS ń kojú adigunjalè l'Eko Ọlọ́pàá Bayelsa ní àwọn ti kán lugbó láti wá ìyá Siasia 'Kò sí ǹkan tó jọ tòmátò tó ní májèlé ní Nàìjíríà' Lẹ́tà Obasanjo: Àjálù ń bọ̀ bíi ti Rwanda, tí Buhari kò bá ṣàtúnṣe ètò ààbò Awọn obinrin mẹrẹẹrin ti fesi pe àwọn yoo gbajumọ ọrọ oṣelu to ṣe koko ju ọrọ ti ko ba ara ẹran ti Trump n sọ lọ.
Odò kan ṣàn jáde láti inú ọgbà Edẹni tí omi rẹ̀ máa ń mú kí ọgbà náà rin.
Nígbà tí a dé Jerusalẹmu a wà níbẹ̀ fún ọjọ́ mẹta.
Mo tún ń sọ fun yín pé, ọpọlọpọ eniyan yóo wá láti ìlà oòrùn ati láti ìwọ̀ oòrùn, wọn yóo bá Abrahamu ati Isaaki ati Jakọbu jẹun ní ìjọba ọ̀run.
Wọ́n pe Banaba ní Seusi, wọ́n pe Paulu ní Herime nítorí òun ni ó ń ṣe ògbifọ̀.
 Ìgbà tí ó yá ó ṣiṣẹ ́ pọ ̀ pẹ ̀ lú àwọn ẹgbẹ ́ eléré orí ìtàgé àti àrìnjó ní ìlú Ìbàdàn àti Èkó .
Wúrà ni wọ́n yọ́ sí títì ìlú náà.
Sextuplet: Àdúrà Ìbùkún ló kú lẹ́yìn ọmọ mẹ́fà yìí- Ifeoma Thelma àti Onyemaechi Chiaka
Jacob Adekomi ni alẹ ọjọ aje ni awọn aṣoju ẹgbẹ oṣiṣẹ ati ijọba ṣepade nibi ti wọn ti fẹnu ọrọ jona lori rẹ.
S\\ugbọn bayii, o ni awọn agbofinro ti pẹtu si aawọ naa ni eyi ti awọn to ni kaadi idibo si ti lọ gbaojulowo bébà idibo bi o ti yẹ.
”Satani dá OLUWA lóhùn pé, “Mò ń lọ sókè sódò káàkiri gbogbo ayé.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Sotitobire: Ọkọ mi kò mọ̀ Jegede PDP rí, kódà kò fa ẹnikẹ́ni kalẹ̀ dípò Akeredolu- Bisola Kanye West, Ozil, Boyega, àti àwọn gbajúmọ̀ ilẹ̀ okèèrè tó ṣàtìlẹyìn fún ìpolongo #ENDSARS Lati bi ọjọ mẹjọ ti iwọde ati ipolongo ti n lọ ni Naijiria, ọgọọrọ awọn ilumọọka ati gbajumọ kaakiri agbaye lo ti n fi ọrọ kan tabi ikeji ṣe atilẹyin fun ipolongo #ENDSARS.
Ami ayo meji si ẹyọkan ni Manchester City fi se agba fun ikọ Chelsea ninu Idije Premier League to n lọ lọwọ.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Harry ni ṣaka lara iya ati ọmọ le Bakan naa, olori ilu Toronto, John Tory ti ki awọn baba ati iya tuntun naa ki oriire.
Ẹ óo sì máa bọ oriṣa tí a fi igi ati òkúta gbẹ́ níbẹ̀.
Àwọn ará Ijegun fara ya lórí ọ̀pá epo tó ń gbaná ní gbogbo ìgbà Grandpa àti Uncle mi, ń fipá bá mi lòpọ̀ láti ọmọ ọdún mẹ́rin"" Ààrẹ fi nǹkan ọkùnrin rẹ̀ pa mí lójú, kó tó fipá bámi lòpọ̀ - Ọmọge Arẹwà O wa kii nilọ fawọn ileeṣẹ to n ta epo, lati maṣe yi owo kuro ni naira marundinlaadọjọ lori lita epo pẹtiro kan."
Ó ní bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé òun jàre, Ọlọrun ka òun kún òpùrọ́,bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé òun kò dẹ́ṣẹ̀, ọgbẹ́ òun kò ṣe é wòsàn.
 Mo dupe pupo fun iko naa, awon ololufe, awon akegbe mi, awon akonimoogba gbogbo ati awon osise patapata fun aseyori mi ninu iko yii.
Eyi kọ ni igba akọkọ ti Biṣọbu oyedepo yoo ma sọko ọrọ ranṣẹ si aarẹ Muhammadu Buhari ati ijọba rẹ.
Awọn mọlẹbi obi ọmọdekunrin naa tun ba BBC sọrọ lori ipinlẹ bi wọn ko ṣe le sọrọ.
Oríṣun àwòrán, others Àkọlé àwòrán, Àwọn ọlọ́pàá kò kọbiara si ọ̀rọ̀ ìwà ipá lásìkò ìgbéle Covid -19 ni ìwà ipá ṣe pọ̀ - Ajàfẹ́tọ obìnrin Kò tán síbẹ̀, Nípìnlẹ̀ Ondo, ọkùnrin kan ti wọ́n ń pè ni Oniya lo sá ìyàwó rẹ̀ yánayàna nítori pe ìyàwó rẹ̀ kọ ìbálòpọ̀.
Ohun tí o wí ṣẹ, o sì ti rí i.
”Wọ́n dáhùn pé kí wọ́n gbé e lọ sí Gati; wọ́n bá gbé e lọ sibẹ.
Tí a fiṣọwọ́ ní 17:05 10 Ọ̀pẹ̀ 202017:05 10 Ọ̀pẹ̀ 2020 Wo ìròyìn tó pọ̀ jùlọ táwọn èèyàn ń wá ní Google lọ́dún 2020 Oju opo Google ti ṣagbejade akọsilẹ ohun tawọn eeyan n beere ibeere nipa rẹ julọ lagbaye lọdun 2020.
Ṣugbọn wọn fakọyọ ni ipele ẹlẹni mẹjọ lẹyin ti wọn fiya jẹ Madagascar pẹlu ami ayo mẹta sodo.
" Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, O dabi wi pe Trump setan lati koju ẹgbẹ to'n ja fun lilo ibọn lamerika Nigba ti o'n du ipo aarẹ lodun 2016, ẹgbẹ NRA fi o'ntẹ lu iyansipo Trump.
Ìyen ni òpin ọ̀sẹ̀ tí kò l’á nsáré jẹun kí a le tètè jáde nílé lọ ibiṣẹ́ l’áàrọ̀ kùtùkùtù.
5 2092 Isle of Man 25 29.
''Iyalẹnu lo jẹ si mi'' ati pe ''eeyan pupọ lo ti n ta awọn alaini lọrẹ, awọn eeyan n sọrọ daada nipa igbiyanju wa'' Oríṣun àwòrán, Getty Images Mohammad sọ pe oun n foju sọna di igba ti oun yoo ba awọn akẹgbẹ rẹ sọju Musulumi to si ni o ṣeese ki oun wa baba keresi ti yoo fun wọn lẹbun ni igba naa.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Wo ohun tí wọ́n sọ nípa Owa Ale ìlú Ikare, Ọba Samule Kolapo Adegbite Adedoyin tó wàjà Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
O ni ki lo kan Ajimọbi nipasẹ ẹsun ti o fi kan pe Sẹnetọ Balogun ko kopa ninu eto idibo abẹnu ki o to dije ninu ẹgbẹ oṣẹlu PDP.
Bí ó bá jẹ́ pé bí o óo ti ṣe mí nìyí, mo bẹ̀ ọ́, kúkú pa mí bí inú rẹ bá yọ́ sí mi, kí n má baà kan àbùkù.
ti o to,lati fi dupe lọwọ wọn.
Bi o ṣe maa nipese eroja melanin ku ninu ara, naa lo le ba àwọ ara jẹ.
Ò báà lóṣó, kí o lájẹ̀ẹ́,kí àfọ̀ṣẹ rẹ sì múná jù bẹ́ẹ̀ lọ.
Ninu ọrọ tirẹ, adari ikọ Amọtẹkun nipinlẹ Osun, Comrade Amitolu Shittu ni inu oun ko dun si bi awọn janduku ṣe yabo ileeṣẹ ijọba, ti wọn si ba awọn ohun ini awọn eniyan jẹ kaakiri.
ko ti di pe ijoba alase orile ede naa gbesẹ le nina owo ile okeere
Ọjọ mẹfa ni aarẹ lo niluu Tokyo fun apero naa to jẹ ẹlẹẹkeje iru rẹ.
O tun beere wi pe kilode ti ijọba ṣe n fi eto ilera awọn araalu wewu lori bi wọn ti n gbe oku Abba Kyari ni gbangba.
O tun maa n je ki ifaseyin de ba ohun amayedurn ati igbaye –gbadun awon eniyan.
Ẹ máa pa wọ́n mọ́, kí ẹ sì máa tẹ̀lé wọn, wọn yóo sì sọ yín di ọlọ́gbọ́n ati olóye lójú àwọn orílẹ̀-èdè mìíràn.
OLUWA sọ̀rọ̀ níwájú àwọn ọmọ ogun rẹ̀,nítorí àwọn ọmọ ogun rẹ̀ pọ̀ lọpọlọpọ,alágbára ni ẹni tí ń mú ọ̀rọ̀ rẹ̀ ṣẹ.
Fun igba akọkọ wọn ṣe ifilọlẹ sinima lọse to lọ ni eyi to ṣi ona fun ayẹwo sinima bii ọgọta sii.
Ní òde, wọ́n dàbí aguntan, ṣugbọn ninu, ìkookò tí ó ya ẹhànnà ni wọ́n.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Sovereign Conference: Àwọn òǹwòye ní ìpàdé àpérò dára ṣùgbọ́n kò lè tàn ìṣòro Nàìjíríà 28 Ògún 2019 Oríṣun àwòrán, Others Aisi ẹmi ootọ lọdọ awọn olori wa lo mu ki Naijiria ma lee tẹle abajade awọn ipade apero taa ba ṣe bayii, tabi eleyi ta ti ṣe kọja.
Oríṣun àwòrán, @Pearl video Àkọlé àwòrán, Lisa trọ aforijin lọwọ iya Onile rẹ lẹyin ti fidio lu jade tan Ṣugbọn lati igba ti akara rẹ ti tu sepo lo ti yipada ti o si ti fihan gbogbo eniyan ni ojule ti o wa ni ariwa Xi'an ti o si ti di ilumọọka.
Ọkan lara awọn eeyan naa, Allen Olusegun ni mo maa gbe owo mi kuro nile ifowopamọ Access, mo si maa gbe lọ sile ifowopamọ olokowo kekeke."
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Rex Tillerson: Amẹrika yoo ṣe'ranwọ owo tuntun fun Afirika Ọgbẹni David Amanor to ba John Stremalu, ẹni to jẹ ọjọgbọn ninu imọ niba ibasepọ ilẹ okeere lo sọ eyii.
Ayọ̀ ń bẹ fún ẹni tí ó bá forítì í ní gbogbo eedegbeje ọjọ́ ó lé ọjọ́ marundinlogoji (1,335) náà.
Aare tun ni “Bi a se n lọ dibo
Jose Mourinho: Iṣẹ́ bọ́ lọ́wọ́ akọ́nimọ̀ọ́gbá Man United
Wọ́n fún un ní ilẹ̀ tí ó bèèrè fún gẹ́gẹ́ bí àṣẹ OLUWA.
" Awọn dokita iṣegun oyinbo ni ileewosan nla fasiti LUTH nilu Eko ni kudiẹkudiẹ ti o waye lori owo iṣuna ileewosan naa ninu eto iṣuna ti awọn alaṣẹ ileewosan naa fi ranṣẹ si ileeṣẹ eto iṣuna ijọba apapọ lo ṣokunfa aisan owo oṣu wọn.
Ọ̀pọ̀ eniyan ni yóo wí fún mi ní ọjọ́ ìdájọ́ pé, ‘Oluwa, Oluwa, a kéde ọ̀rọ̀ Ọlọrun ní orúkọ rẹ; a lé àwọn ẹ̀mí èṣù jáde ní orúkọ rẹ; a sì ṣe ọ̀pọ̀ iṣẹ́ ìyanu ní orúkọ rẹ.
Bẹẹ lọrọ ri pẹlu ọdun Ọṣun Ọṣogbo fun tọdun 2019, eyi to ti ko bayii, ti yoo si waye lọjọ́ Ẹti.
Ikú Williams Aanuoluwa lágbo òṣèré hú ọ̀pọ̀ ọ̀rọ̀ síta Àlàyé rèé lórí bo ṣe le è dá Emèrè mọ̀ tàbí dara pọ̀ mọ́ ẹgbẹ́ wọn Àṣírí ńlá tó ń bẹ láàrín Alaafin àtàwọn onílù rẹ̀ rèé Àwọn ọba Yorùbá kan rèé tí wọ́n rọ̀ lóyè, tí ọba míràn jẹ lójú ayé wọn Ìtàn Gbọnka àti Timi, akọni méjì tó borí Aláàfin Ṣango Wo ibùdó arẹwà tí ọ̀pọ̀ èrò ń ya lọ ní Abuja Ajọ iṣọkan agbaye ati ajọ to n ri si ṣiṣikiri awọn eeyan to n rinrin ajo lori omi okun ti sọ pe awọn to n doola ẹmi awọn arinrin-ajo lori omi gbodọ pọ si.
Abule mekaniki to wa lẹba ibudo idalẹsi Olusosun ladugbo Ọjọta nibiti eefin nla pẹlu afẹfẹ oloorun buruku ti gba ile kan ni isele naa ti waye.
Igbimo amusese ijoba apapo ti fenuko pe, ki orile-ede Naijiria fowo siwe adehun sise idasile eto kara-kata laarin awon orile-ede ile Africa laisi idiwo tabi owo-ori ninu, ti a mo si Continental Tree Trade Area (CFTA).
Ọpọ awakọ lo ti tete rinrinajo kuro ni erekuṣu to jẹ Island lọ si Mainland ki aago mejila ti ijọba kede to lu lalẹ ọjọ Eti nigba ti awọn to ni nkan ṣe lopin ọsẹ yii naa ti de lati Mainland nitori ibẹru sunkéré-fakẹrẹ ọkọ.
Ẹ̀yin ẹ yipada sí mi, èmi náà óo sì yipada si yín.
N kò sọ ọ́ níkọ̀kọ̀, ninu òkùnkùn.
Soleimani lo dari awọn ikọlu to waye ni aarin gbungbun orilẹede Iran gẹgẹ bi adari ẹgbẹ ọmọ ogun kan to n jẹ Quds Force.
Oríṣun àwòrán, Channel Iroyin naa ni iwọde naa ti n gbọna miran yọ, to si seese ko jẹ pe awọn janduku ti gba akoso iwọde ọhun.
 Awon ile igbimo safikun si eto isuna naa kuro lati N7.
O gbiyanju ti ti ti kò gbọ́ wẹ̀ẹ́nn wẹ̀ẹ́n ọmọ ìkókó àfìgbà tí ẹlomiran ba a gbe oyun Ṣe ẹ mọ̀ pe awọn dokita o kuku ni ijaya ọrọ to tobi lati sọ, tori ọrọ kii tobi titi loju tiwọn, wọn a f'ọbẹ bu u ni.
Wọ́n bá kó gbogbo àwọn àjèjì oriṣa tí ó wà lọ́wọ́ wọn dànù, wọ́n sì ń sin OLUWA.
Iroyin kan tiẹ sọ pe o le ni ẹgbẹrun lọna ogun awọn ọlọsin ẹyẹle lo wa Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Àṣírí tú!
Fásítì Babcock lé akẹ́kọ̀ọ́bìnrin tó hàn nínú fídíò ìbálòpọ̀ lọ sílé Àráàlú yarí fún fásitì Babcock fún bo ṣe lé akẹ́kọ̀ọ́ tí wọn bá lòpọ̀ nínú fídíò Davido, Fani Kayode, Kemi Olunloyo, sọ̀rọ̀ lórí ẹ̀sùn jìbìtì Allen Onyeama Pasuma kìí ṣe ọkọ mi o!
Ọdún meje kan ń bọ̀ tí oúnjẹ yóo pọ̀ yanturu ní gbogbo ilẹ̀ Ijipti, 
Oun tó sọ sọrí ayélujára rèé: Torí bá kó ọ yọ lọ́wọ́ àwọn ajínigbé, àmọ́ tí pátá rẹ̀ bọ́ sọ́wọ́ àwọn ẹni ibi, o ò jájábọ́ o."
Boya eyi lo mu ki ọmọbinrin kan, Victory Omogiate fi n leri leka pe oun le gba ẹmi ara oun nitori ijakulẹ ifẹ to ba pade lati ọdọ gbajumọ adẹrinposonu kan lori ayelujara, Cute Abiola.
Lasiko to n ba BBC Yoruba sọrọ, Oluwaseun ni o le lootọ lati jẹ ẹni ti wọn fi tipa ba lopọ, nitori ipa to n ni lara onitọun, ninu ọkan ati ọpọlọ rẹ.
" O tẹsiwaju lati maa bẹ awọn ọmọde t'oun gbe lawọn oju opopona lawọn agbegbe mi i to wa ni ilu Calabar, ko si pẹ ti o fi di gbaju-gbaja laarin wọn, debi wipe, niṣe ni wọn maa n sare pẹlu idunnu lọ ọ pade bọọsi tabi takisi ti wọn ba ri i ninu rẹ.
Èèyàn 627 ló lùgbàdì àrùn Coronavirus ní Naijiria ní Ọjọ́ Ẹtì Irọ́ ni pé Gómìnà Edo Obaseki ti darapọ̀ mọ́ ẹgbẹ́ PDP Alhaja Kudirat Abiola: Odindi géńdé ọkunrin mẹ́fà ni wọ́n gbé iṣẹ́ ikú rẹ̀ fún Ìwọ́de gbòde kán lórílẹ̀èdè Amẹ́ríkà nítorí ikú George Floyd 4.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù End SARS, End SWAT: MC Oluomo ní òun kọ́ ló rán àwọn jàǹdùkú sáwọn olùwọ́de l'Eko 4 Ọ̀wàrà 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 15 Ọ̀wàrà 2020 Oríṣun àwòrán, Twitter/mcoluomo Alaga ẹgbẹ awakọ ero NURTW ni ipinlẹ Eko, Alaaji Musiliu Akinsanya ti ọpọ mọ si MC Oluọmọ ti ṣapejuwe ẹsun ti awọn kan n fi kan an pe oun lo ran awọn janduku lati ls da iwọde #ENDSARS ru l'Eko gẹgẹ bi irọ lasan.
Nigba ti BBC Yoruba ba onimọ nipa eto isuna sọ̀rọ̀ lori isuna yii, Ọgbẹni Tunde Bello jẹ ko di mimọ pe igba ti gomina kan ba gbe iru eto isuna yii jade, kii ṣe ẹbi rẹ nitori wi pe ọpọlọpọ eniyan ni yoo lọwọ si eto isuna ko to di gbigbe sita.
Sibẹsibẹ, nígbà tí wọ́n ronupiwada tí wọ́n sì gbadura sí ọ, o gbọ́ lọ́run, lọpọlọpọ ìgbà ni o sì gbà wọ́n gẹ́gẹ́ bí ọ̀pọ̀ àánú rẹ.
Àkọlé àwòrán, A ju ara wa lọ, ijakadi kọ ni ọrọ awọn to n yan bi ologun ni papa iṣere Adamasingba ni Naijiria ti wọn yọ ayajọ ọjọ ominira Naijiria.
Àkọlé àwòrán, Ijọba ipinlẹ eko se afikun owo irinnọ ẹnu ibode ni agbegbe lekki lati ọjọ kni osu keji ọdun yi Adari awọn afẹhonuhan, Dotun Hassan salaye wipe o jẹ ohun ibanujẹ fun awọn olugbe lori ijọba awarawa nipinlẹ eko fun ijọba ati igbimọ ti o n risi eto irinna jadejado ipinlẹ yii lati fi kun owo irinna.
Farao sọ fún Josẹfu pé kí ó sọ fún àwọn arakunrin rẹ̀ kí wọ́n múra, kí wọ́n di ẹrù ru àwọn kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ wọn, kí wọ́n tètè pada lọ sí Kenaani, 
O fi da Oluwo loju pe oun yoo gbe igbesẹ lori ọrọ naa bi o ti tọ ati bi o ti yẹ.
Àkọlé àwòrán, Jamilu Shehe Kii ṣe wi pe mo ṣarifin si Sultanamọ lati kekere ,bi mi o ba foju ri oṣu emi kii gba awe."
Ninu ọrọ to sọ nibi ayẹyẹ naa, ko pamọ pe ọba alayeluwa naa n kọminu lori bi awọn ọdọ ṣe n lọwọ ninu ogun owo ṣiṣe bayii.
awon tọrọ kan nitori pe ajo naa setan 
Amọ ṣaa, ọpọlọpọ ọmọ Naijiria lo tako alaye ti ileeṣẹ America sẹ naa.
Alaafin sọ siwaju pe agba ti ko ba kẹhun sọrọ, afaimọ ko ma kẹtan sare, idi si ree ti oun fi n fa Fayemi leti pe ko gbọdọ yi asa ati ise wa pada nipinlẹ Ekiti lọna ti ko bojumu.
Torí orúkọ orílẹ̀ èdè Nàìjíríà tí ọmọ Alfred Adésànmí ti tàn ká
Ṣugbọn báyìí ni Ìwé Mímọ́ wí nípa ìdáláre tí à ń gbà nípa igbagbọ, pé, “Má ṣe wí ní ọkàn rẹ pé, ‘Ta ni yóo gòkè lọ sọ́run?
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Lagos gas explosion: Ènìyàn 5, ilé 25 ilé ìtajà 16 àti àwọn ǹkan mírà lo bá ìṣẹ̀lẹ̀ iná naa rìn.
Lẹ́hìn náà ó fi fèèrè yìí lé Olóhùn-ún-dùùrù lọ́wọ́ ó sì wì fúnun pé bí a bá ti ń súnmọ́ ìlú àwọn ejò kí ó bẹ̀rẹ̀ sí fun ún àti pé nígbà tí àwọn ọlọ́pàá tí ń ṣọ́ ojú ọ̀nà ìlú wọn bá ti gbọ́ fèèrè náà gbogbo wọn ó sùnlọ.
Bẹẹ, ọpọ igbesẹ lo maa n bẹrẹ pẹlu erongba rere ṣugbọn ti igbẹyin rẹ le ma dara bii ti Boko Haram to ti di igi ose ti ipa ko fẹ ka mọ.
Ẹ má ṣe jẹ́ kí ohunkohun dààmú yín, ṣugbọn ninu gbogbo adura ati ẹ̀bẹ̀ yín, ẹ máa fi àwọn ìbéèrè yín siwaju Ọlọrun pẹlu ọpẹ́.
Ṣugbọn kò sí ẹnìkan tí ó kápá ahọ́n.
" Shittu ni nigba ti ilẹ ọjọ Aiku yoo ba fi su, ẹgbẹ oselu PDP yoo kede erongba rẹ fun araye gbọ nipa esi ibo naa.
Mo tún gbé ojú sókè, mo rí kẹ̀kẹ́ ogun mẹrin tí ń bọ̀ láàrin òkè meji; òkè idẹ ni àwọn òkè náà.
Èyí ni iye àwọn tí Mose ati Aaroni kà ninu àwọn ọmọ Merari gẹ́gẹ́ bí OLUWA ti pàṣẹ fún wọn.
Hanan Buhari: Ìjọba ní Ọmọ Buhari lásẹ láti wọ bàálú Nigeria Air force
Ìjọba Èkó fí ìgbé ìkìlọ̀ ta Ajọ JAMB naa wa parọwa si awọn lati ri wi pe wọn tọju awọn ohun to se pataki si esi idanwo wọn bii nọmba ti wọn fi se iforukọsilẹ.
Ni bayii , ni a wa n ri awon to n paro pe daran-daran  ni won ,ti won n lo  ibọn AK47.
wọ́n sanra, ara wọn sì ń dán.
 a sì sọ ọ ́ di ilẹ ̀ ifẹ ̀ .
Itẹ oku si ni wọn ti fun ni obìnrin kan bíi aya to maa n tẹle lọ digunjale ti gbogbo aye mọ si Alhaja, awọn eeyan ro pe eeyan ni amọ alujannu ni.
Ẹni rere a máa sọ ọ̀rọ̀ rere jáde láti inú ìṣúra rere; eniyan burúkú a sì máa sọ ọ̀rọ̀ burúkú jáde láti inú ìṣúra burúkú.
I fé̩ àwo̩n ènìyàn ìlú ni yóò jé̩ òkúta ìpìlè̩ fún à s̩e̩ ìjo̩ba; a ó máa fi ìfé̩ yìí hàn nípasè̩ ìbò tòótó̩ tí a ó máa dì láti ìgbà dé ìgbà, nínú èyí tí e̩nì kò̩ò̩kan yóò ní è̩tó̩ sí ìbò kan s̩os̩o tí a dì ní ìkò̩kò̩ tàbí nípasè̩ irú o̩ nà ìdìbò mìíràn tí ó bá irú ìdìbò bé̩è̩ mu.
Oríṣun àwòrán, Facebook/From-The-Palace-of-Ooni-of-Ife Bẹẹ si ni Ọọni Ile Ifẹ, Ọba Adeyẹye Ẹnitan Ogunwusi ti sọ pe, ko si ootọ kankan ninu iroyin to gbode naa pe iyawo oun bimọ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù INEC:Ìròyìn òfégè ní pé ilé ẹjọ pàṣẹ fún wa láti dáwọ àkójọ èsì ìbò Gómìnà Rivers dúró 20 Ẹrẹ̀nà 2019 Oríṣun àwòrán, INEC Situation room Àkọlé àwòrán, Alaga ajọ eleto idibo Mahmud Yakubu Ajọ eleto idibo Naijiria ti ni ko si ootọ ninu iroyin to n ja rain-rain pe ile ẹjọ ni ki awọn da akojọ esi idibo Gomina ipinlẹ Rivers duro.
Aare  Buhari ni inu oun dun pe orile ede Najiria mọ
Oludari eka ibara- eni -sepapọ nile-ise to n mojuto irinna oko oju
Sowore Revolution Now: Nǹkan tó yẹ kí o mọ̀ nípà Omoyele Sowore tó ń ṣe agbátẹrù ìfẹ̀hónú hàn jákèjádo Nàìjíríà
Ileeṣẹ aarẹ orilẹede Tunisia lo kede rẹ.
Atẹjade ti ileesẹ ọlọpaa ipinlẹ Eko fisita fun awọn akọroyin salaye pe, lẹyin ti Chris gun Olamide to jẹ afẹsọna rẹ pa tan, ẹti tii se ẹni ọdun mẹẹdọgbọn, lo ba gbe ogun oloro jẹ.
 Ọ ̀ rọ ̀ náà tilẹ ̀ ti sú àwọn ará ile jìjì pàápàá ' .
Lẹ́yìn èyí, mo rí àwọn angẹli mẹrin tí wọ́n dúró ní igun mẹrẹẹrin ayé, tí wọ́n di afẹ́fẹ́ mẹrẹẹrin ayé mú kí afẹ́fẹ́ má baà fẹ́ lórí ilẹ̀ ayé ati lórí òkun ati lára gbogbo igi.
Ṣugbọn iwadii BBC Yoruba ti fihan pe ahesọ ọrọ ati irọ nla to jinna si ootọ ni ikede naa, nitori Olu Jacobs si wa laaye, to n mi loke eepẹ.
O fidi eyi mulẹ lẹyin ti ajọ naa sọ fun awọn aṣofin ti ko pada sile lati da nọmba mọtọ ti wọn lo pada.
Bí wọn bá fẹ́ kí wọn gbọ́, bí wọn sì fẹ́, kí wọn má gbọ́.
Ẹbi ta ni ti ile bá dà wó?
Oríṣun àwòrán, TWITTER Amọ adari ajọ eleto idibo niipinlẹ naa, Ọjọgbọn James Apam sọ wi pe awọn ti bẹrẹ pinpin awọn ohun eelo idibo, ti wọn si ni awọn wa ni sẹpẹ fun idibo naa.
latari ija ajakuakata ti eleyameya to n waye lorile-ede naa lati osu mefa sehin.
Bí wọn bá dúró, àwọn náà á dúró.
Ni Mata bá wá, ó ní, “Alàgbà, arabinrin mi fi èmi nìkan sílẹ̀ láti máa tọ́jú oúnjẹ, o sì dákẹ́ ò ń wò ó níran!
Ọpọ obi n fi ẹrọ ibanisọrọ beere irin ọmọ wọn ati ohunkohun to n ṣẹlẹ si wọn laisko ti wọn wa nile iwe ni eyi to n fi wọn lọkan balẹ.
Nítorí bí o bá dákẹ́ sí min óo dàbí àwọn òkú, tí wọ́n ti lọ sinu kòtò.
    Bí a ti ń lọ, afi ìgbà tí a déedée ń gbọ́ ìlù bàtá láàrin igbó yìí, wọ́n ń lúù tẹ̀lé Ìnàkí-ìbẹ̀rù, mo sì bẹ̀rẹ̀ sí í gbọ́ tí bàtá ń wí báyìí, ‘Ìnàkí-ìbẹ̀rù, Ìnàkí-ìbẹ̀rù, òní ni, ọla kọ́, òní ni, ọla kọ́, òní ni ìjàkadì, òní ni ìjàkadì, Ìnàkí-ìbẹ̀rù, Ìnàkí-ìbẹ̀rù yí ọmọ ènìyàn bíríbírí, yí ọmọ ènìyàn kọ́rọ́kọ́rọ́, yí ọmọ kítíkítí, gbé wọn na lẹ̀ bámúbámú, kí wọ́n máa rá pálápálá, fòkúta gùn wọn ṣókíṣókí, kí wọ́n họra pátípátí.
Èèyàn 373 ni ààrùn coronavirus tún ṣẹ̀ṣẹ̀ ràn ní Nàìjíríà - NCDC Ìjọba ìpínlẹ̀ Osun tí búwọlù ìlànà àyẹyẹ Ọṣun-Oṣogboo ọdún 2020 Wo díẹ̀ nípa ohun tí Walter Carrington gbé ṣe nígbà ayé rẹ̀ ‘Àwọn òlóṣèlú kò ní ìwà ọmọlúwàbí ló jẹ́ kí wọ́n má a lọ láti ẹgbẹ́ òṣèlú kan lọ sí òmìràn’ Ogun Àgbẹ́kọ̀yà, ẹ̀kọ́ wo ló yẹ́ kí àwá ọ̀dọ́ kọ́ níbẹ̀?
Yorùbá dùn lédè, sáré pé gbólóhùn yìí wò tóo bá dá ara rẹ lójú
Nítorí náà, kì í ṣe gẹ́gẹ́ bí eniyan ti fẹ́ tabi bí ó ti gbìyànjú tó ni Ọlọrun fi ń yàn án, bí ó bá ti wu Ọlọrun ninu àánú rẹ̀ ni.
Akonimoogba agba iko Poland, Adam Nawalka, se gudugudu meje ohun yaya mefa lati ran iko agbaboolu Poland, lowo lati pegede fun idije boolu agbaye todun yii lati odun 2006 ti iko naa ti kopa keyin.
Ẹ yan alufaa mìíràn dípò wọn bí àwọn ọmọ orílẹ̀-èdè mìíràn ti ṣe.
Ko sẹni to maa ri awọn ololufẹ meji yii ti wọn n dọwẹkẹ ti ko ni ya lẹnu.
Awon igbese yii tun ti je ki  idagbasoke ba oruko orile ede yii nile okeere.
Ǹjẹ́ ohun kankan wà tí a lè tọ́ka sí pé: “Wò ó!
O wa ro gbogbo omo orile ede lati fowosowopo pelu ijoba  ni ona ti won yoo fi lee mu idagbasoke ba orile ede yii.
Èyí rí bẹ́ẹ̀ kí ọ̀rọ̀ tí wolii Aisaya sọ lè ṣẹ pé:
Lasigbo to waye l'ọjọ aje bẹrẹ nigba ti awọn ẹgbẹ Oodua Peoples Congress, OPC ti wọn s'orogun ara wọn fija pẹẹta, ti ọpọlọpọ eniyan si farapa ninu isẹlẹ naa.
Pípa tí ó pa àwọn aláìṣẹ̀ wọnyi, ọrùn mi ni ó pa wọ́n sí, ẹrù ẹ̀bi wọn sì wà lórí mi.
Ipade ohun ni iroyin fi mule pe o da lori eto idibo gomina ipinle Osun to n bo lona lojo kejilelogun osu kesan odun ti a wayii.
Adari ẹgbẹ osisẹ tẹlẹri ọhun fi kun ọrọ rẹ wipe ''ipinlẹ Ọṣun nilo ẹni to ni oye kikun ati ọgbọn atinuda nipa eto iṣejọba, yatọ si ẹni ti wọn ṣẹṣẹ n kọ.
Gẹgẹ bi ọrọ rẹ ọmọ iya loun ati Ọọni jẹ.
Nítorí náà, àwọn ẹ̀yà Lefi kò ní máa ru Àgọ́ Àjọ ati àwọn ohun èlò tí wọn ń lò ninu rẹ̀ káàkiri mọ́.
”Aare tun kẹdun pelu ijoba orile-ede Sudan ati awon eniyan re lataari isele ala-ile eleyi ti o gba emi eniyan mewa lorile-ede naa.
Awokose saa ni awọn jẹ lawujọ, bẹẹ si ni ohun ti eeyan ba ni lọpọlọ lo ja ju, kii se afihan ọyan, idi abi ara bibo.
Ẹ̀jẹ̀ wọn yóo ṣàn dànù bí omi, a óo sì sọ ẹran ara wọn nù bí ìgbẹ́.
 Àyẹ ̀ wò yìí fihàn pé bíi méjìdínlọ ́ gbọ ̀ n olé diẹ ̀ nínú ọgọ ́ rún àwọn obìrin tí ó ń gbé ní ìgboro ní wọ ́ n ti dábẹ ́ fún tí ó sì jẹ ́ wípé mẹ ́ rìnlá nínú ọgọ ́ rún àwọn obìrin tí ó ń gbé níabúlé ni wọ ́ n ti dábé fún .
Nínú ọ̀rọ̀ rẹ̀, Lizzy Anjonrin to ti di Abilekọ Lawal ni kí gbogbo àwọn agbọ́yì sọ̀yí lọ gbọ dáada pé ọkọ oun ko fẹ́ ìyàwó mẹrin ko to fi oun ṣaya.
Obinrin ni ó bí i, ó bí i lábẹ́ òfin àwọn Juu, 
1 843898 Orilẹede Ecuador 13778 80.
Gómìnà ìpínlẹ̀ Ekiti tẹ́lẹ̀, Ayọdele Fayoṣe, ti gba ìtúsílẹ̀ l'ọ́gbà ẹ̀wọ̀n.
Ajọ iṣọkan agbaye ni ilu yii le jẹ ọna abayọ si ẹkun omi to n de ba okun.
Yatọ si pe awọn janduku naa ba nkan jẹ ninu aafin naa, ni ṣe ni wọn tun ji ọ̀pá àṣẹ ọba gbe lọ.
00) péré ni wọ́n bá ní abẹ́ ìrọ̀rí Àkàngbé nígbà tí ó kú.
Awon igbimo wonyi ni gomina Ajimobi yan lati ri daju pe
pelu awon obinrin ile ise ologun ohun.
wa ni igbimo ise akanse fun egbe oselu APCGbogbo awon
’ Kò sí ẹnikẹ́ni nítòsí tí ó lè gbà á sílẹ̀.
” Òun ni òǹdíje ní abẹ́ àsíá Ẹgbẹ́ Olóṣèlú Ìtẹ̀síwájú Ọ̀dọ́ – YPP.
Ekironi pẹlu àwọn ìlú ati ìletò rẹ̀; 
Baluwẹ atijọ ti wọn pa oloogbe Barakat si naa ti di wiwo, bẹẹ si ni iṣẹ ti n lọ lọwọ lorii ile iwẹ ati ile igbọnsẹ igbalode ti wọn kọ mọ ile naa.
” Ìjọ eniyan sì mú ọrẹ ati ẹbọ ọpẹ́ wá, àwọn tí wọ́n fẹ́ sì mú ẹbọ sísun wá.
Ighalo Transfer Fee: Ilé aṣòfin Osun ní òun kẹ́ẹ́fín pé àpò àdáni ní owó náà wà
Wọ́n tún ń lépaà mi o!
O ni o dẹ ṣeeṣe fun ẹnikẹni lati yi awọ oju rẹ pada nipa wiwọ awọn nkan to le yi awọ oju pada boya fun oge tabi fun iṣẹ bii ti awọn oṣere ni gbedeke asiko kan.
 Ni eekan si, a tun ti jawe olubori,”Ireti wa tele pe, Ta Lou yoo lo dije pelu ayara bi asa omo ile Naijiria, Blessing Okagbare, ninu ere ije ogorun mita, sugbon ko ni waye mo bayii.
Aráàlú tó bá ṣíwọ́ lu ọlọ́pàá yóò jẹ'yán rẹ̀ níṣu lábẹ́ òfin Ẹ bá mi dúpẹ́ lọ́wọ́ Sunday Igboho, Ajimobi, Seyi Makinde àti àwọn ọlọ́pàá fún iranwọ wọn láti rí ìbejì gbà padà Àwọn èèyàn kò fi bẹ́ ẹ̀ ní ìbálòpọ̀ lásìkò ìgbélé yìí - Iléèṣẹ́ kọ́ńdọ́ọ́mù Durex Obìnrin pa olólùfẹ́ rẹ̀, ó fi se ìrẹsì Bakan naa lọwọ awọn agbofin ikọ naa tun tẹ awọn mẹwaa miran pẹluu wọn ti wọn jẹ ọmọ agbegbe naa.
OLUWA ní ń tọ́ ìṣísẹ̀ ẹni,eniyan kò lè ní òye ọ̀nà ara rẹ̀.
Ọmọ ilẹ̀ Italy tó kó Coronavirus wọ Naijiria kò ní àrùn náà mọ́ Gomina ọhun tẹsiwaju pe imọtoto ara ẹni ṣe pataki lasiko yii.
- Tan imọlẹ si i - Lotitọ, ọtọọtọ ni iwa ẹda ṣugbọn onimọ nipa ọpọlọ, Dokita TBS Balamurali ni itansan oorun tohun ti afẹfẹ oloore lati ita ati nini imọlara ohun ti Ọlọrun da dara pupọ fun ilera ọpọlọ rẹ.
 jíjáde rẹ ̀ yìí bà mi lẹ ́ ru gan-an ni .
Eré náà ló wà ní ọgbà ìgbafẹ́ MKO Abiola ní Alápẹ̀rẹ̀, Ketu.
Osanyintolu ni pe ninu awọn to ku ninu iṣẹlẹ naa ni ọmọdekunrin kan ati agbalagba ọkunrin kan.
Iroyin ohun tun fihan pe, awon omo-ogun eleto ijoba, ile-ise ologun, ati ile-ise olopaa lorile-ede South Sudan ni won nidii isele fifi eto omo eniyan gbole naa.
 Lati igba ti arun naa ti ṣẹyọ ni ilu Wuhan lorilẹ-ede China lopin ọdun 2019, miliọnu mejilelogun eeyan lo ti fara kasa arun ọhun kaakiri agbaye, ti eeyan ẹgbẹrun lona ẹgbẹrin si ti ku."
Díẹ̀ lára àwọn abódiakọ-akọ́diabo ènìyàn du ipò ìjọba nínú Ìbò ọdún 2018 fún ìgbà àkọ́kọ́.
"Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Pásítọ̀ ló sọ fún mi pé Ọlọ́run pè mí láti di Olokun tó ń bọ omi' ""Mi o tii fi iru atẹjade bayii sita ri ṣugbọn nitori ọpọlọpọ iṣẹ nla ati ifarajin to wa niwaju mi pọ""."
Alẹ ni iṣẹlẹ naa ṣẹlẹ lọjọ naa lọhun.
" Aarẹ ileẹjọ ibilẹ naa, Arabinrin Funmi Adeọla, wa kede pe tọkọ-taya naa ko lee maa gbepọ ni alaafia mọ, nitoripe iwadi ti fihan pe lootọ ni ẹbọ nbẹ lẹru iyawo, to si jẹbi ẹsun ti ọkọ rẹ fi kan-an.
Idi ni pe oore ọtun miran tun sẹsẹ wọle tọ idile naa ati awọn ọmọ wọn wa ni.
Iwadi naa fihan pe, ijamba ti awọn ọmọde ti obi wọn n fa siga ba fi ori ko, lati igba ti wọn wa ni kekere yoo ba wọn dagba, ti yoo si fa aisan ninu ọpa to n gbe eemi jade.
Òun ló pa àwọn àkọ́bí ní ilẹ̀ Ijipti,ati teniyan ati tẹran ọ̀sìn.
Ó ti wá jókòó ní ọwọ́ ọ̀tún ìtẹ́ Ọlọrun.
DJ Switch jẹ ọkan gboogi lara awọn to n lọgun iwọde End SARS lori ayelujara.
Ṣugbọn ó yọ aláìní kúrò ninu ìpọ́njú,ó sì mú kí ìdílé wọn pọ̀ sí i bí agbo ẹran.
Oluwa fúnrarẹ̀ ni ó kọ́kọ́ kéde ìgbàlà yìí ní ìbẹ̀rẹ̀.
fun ajo NCC ki I se lati fi yọ awon onibara won kuro nipa lilo ero ibanisọrọ
Adajọ ni awọn nnkan ini rẹ ajọ EFCC gba ko ni ohun kankan ṣe pẹlu ẹsun ikowo tuulu lọ si oke okun ti wọn kan an.
O ni Awọn eleto ilera ti fi han pe fifọ ọwọ ẹni pẹlu ọṣẹ ati omi fun ogun aaya ati lilo ipawọ apa kokoro lee jẹ ki arun naa jina si eeyan."
Lẹhin ọsẹ̀ mẹ́fà tàbi ogoji ọjọ́ tàbi ó lé kan ti wọn ti bi ọmọ, ìyá àti ọmọ lè lọ òde, ìyá á pọn ọmọ lati jáde.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Great Danes Wolf Hybrid: Gẹgẹ bi a se mọ wi pe awọn aja wa lati ara ikooko, amọ awọn eniyan kan si n gbe aja gun ẹya ikooko, eleyii ti o mu won buru si.
The New Pandemic: Kíni àwọn onímọ̀ sáyẹ́ńsì ń sọ nípa rẹ̀?
N kò ní fún OLUWA ní nǹkan tí ó jẹ́ tìrẹ, tabi kí n rú ẹbọ tí kò ná mi ní ohunkohun sí OLUWA.
Kò sí iléẹjọ́ tó le dá wa dúró, ìyanṣẹ́lódì yóò bẹ̀rẹ̀ ní Ọjọ́ Ajé - NLC Wo iye ìgbà tí ẹgbẹ́ òṣìṣẹ́ àtàwọn ọmọ Nàìjíríà ti ṣèwọ́de lórí àfikún owó epo bẹntírò Èkúté tó sàwárí bọ́mbù ilẹ̀ gbàmi ẹ̀ye wúrà fún iṣẹ́ takuntakun Ẹ gbọ́ òhun tí àwọn olùdíjé sípò gómìnà nípínlẹ̀ Ondo sọ nípa Bàbá ìsàlẹ̀.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ẹ wo bí ìsìnkú Fẹ́lẹ́ se lọ Saraki, yára kọ̀wé fipò sílẹ̀ tàbí ká lé o - Miyetti Allah Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Àwọn èèyàn àti awakọ̀ ké igbe ìrora bí àwọn ọkọ̀ ńlá ṣe dí ọ̀nà mọ́rosẹ̀ Apapa-Oshodi pa MC Oluọmọ ni obitibiti ero to peju kii ṣe iyalẹnu nitori irufẹ eeyan ti oloogbe Fẹlẹ jẹ nigba aye rẹ.
Cardiff fọ́wọ́ òsí júwe Europa fún Manchester United
Ohun rere mà pọ̀ lọ́wọ́ rẹ otí o ti sọ lọ́jọ̀ fún àwọn tí ó bẹ̀rù rẹ,tí o sì ti pèsè ní ìṣojú àwọn ọmọ eniyan,fún àwọn tí ó sá di ọ́.
“Mú àwọn igi tí o kọ nǹkan sí lára lọ́wọ́, lójú wọn, 
Yollywood: Saheed Balogun sìnkú ìyá rẹ̀, Ìròyìn ohun tó ṣẹlẹ̀ lágbo òṣèré lọ́sẹ̀ yìí nìwọ̀nyí
Adarí àjọ NDDC, Pondei ṣetán láti sọ ohun tó mọ̀ nípa ìwàdíì tó bá ti gbádùn- NDDC Wo bí ètò ìsìnkú Isa Funtua ṣe wáyé ní ìlú Abuja Kí ló dé tí ìjọba ìpínlẹ̀ Oyo kéde fífagilé Sáà ètò ẹ̀kọ́ kẹta fún àwọn akẹ́kọ̀ọ́?
Oríṣun àwòrán, Getty Images Ọpọ lo ti kọkọ ro pe Arsenal yoo jẹri ara wọn lọjọ Abamẹta nigba ti wọn ba koju Brighton, ṣugbọn ọrọ bẹyin yọ ninu ere bọọlu ọhun.
Pẹ̀lú ayọ̀ ni ọkùnrin yìí fi ń lọ nítorí ìgbà-kígbà tí ó bá ti mú ẹja wọ̀nyí wá, owó geregere ni ọba ń san fún un.
Lẹ́yìn èyí, ó tó àkókò fún ọ̀kan ninu àjọ̀dún àwọn Juu: Jesu bá lọ sí Jerusalẹmu.
Gbogbo awọn awakọ ero ni wọn gbọdọ maa lo ibomu wọn, ti wọn si gbọdọ ma lo eroja ifọwọ Hand sanitizer.
-Big Brother sọ fún Dorathy Dorathy fẹ́ da orí Big Brother rú pẹ̀lú ẹrù àyà rẹ̀, ló bá yáa ní kó lọ pàrọ̀ aṣọ Okun ọrun ko yẹ adiẹ, ohun ti a ba si gbe pamọ lo n niyi.
Konanaya, ọmọ Lefi, ni olórí àwọn tí wọn ń bojútó wọn, Ṣimei, arakunrin rẹ̀ ni igbákejì rẹ̀.
Àwọn ọmọ Naijiria fèsì sí Osinbajo tó ṣetán láti wàákò pẹ̀lú Timi Frank Ọpọlọpọ awọn ọmọ Naijiria lo ti fesi si igbesẹ Igbakeji aarẹ orilẹede Naijiria, Yemi Osinbajo to ni awọn eniyan kan n ba oun lorukọ jẹ, nitori naa oun gbe wọn losi ile ejọ.
Sibẹsibẹ nígbà gbogbo ni mo wà lọ́dọ̀ rẹ;o sì di ọwọ́ ọ̀tún mi mú.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ojú Shagbada Erigga rèé lẹ́yìn tó pa ọ̀rẹ́bìnrin rẹ̀ l'Akinyele ní Ibadan Ìdí tí lílọ Yúrópùù fi di èèwọ̀ fún Nàìjíríà àti àwọn orílẹ̀-èdè adúláwọ̀ míì Arúfin ni Seyi Makinde pẹ̀lú bó ṣe gbà kí wọ́n sin Ajimobi sí GRA - Amòfin Ṣé ó leè jẹ́ ilẹ̀ tí Makinde kò jẹ́ kí Florence Ajimobi gbà ló ń bi nínú?
OLUWA dáhùn pé, “Ó dára, mo gbọ́ ẹ̀bẹ̀ rẹ, n kò ní pa ìlú náà run.
INEC yóò ṣàmúlò ẹ̀rọ ayélujára láti fi gba fọ́ọ̀mù àwọn olùdíje fún ìbò gómìnà Ondo àti Edo Ṣé lóòtọ́ ni Kayode Fayemi, gómìnà ìpínlẹ̀ Ekiti fẹ́ du ipò ààrẹ orílẹ̀èdè Nàìjíríà?
Láti ìgbà tí Amasaya ti pada lẹ́yìn OLUWA ni àwọn eniyan ti dìtẹ̀ mọ́ ọn ní Jerusalẹmu, nítorí náà, ó sá lọ sí Lakiṣi.
Kí ní kan ṣa ni, a kò gbọ̀dọ̀ màa ṣoore bí òmùgọ̀, kí a máa so ẹ̀wọ̀n góòlù mọ́ ẹlẹ́dẹ̀ lọ́rùn, ẹni tí ó bá mọ iyì wúrà ni kí a ta wúrà wa fún.
Lara awon to wa nibi ipade naa
Bákan náà ni ẹ̀yà Fulani tí Kurunmi tí ìjàyè lẹ́yìn, láti fi iya jẹ ibadan torí bo se di wọn lọwọ láti tán ẹṣin Islam yíká ilẹ Yoruba.
Ṣugbọn ibeere ti ọpọ eeyan n beere ni pe, ṣe opin patapata ti de ba ẹgbẹ aseku pani one million boys ni bayii ti olori wọn ti silẹ bora?
Àwọn ẹrú tí wọ́n ní ọ̀gá onigbagbọ kò gbọdọ̀ sọ ara wọn di ẹgbẹ́ ọ̀gá wọn, wọn ìbáà jẹ́ ará ninu Kristi.
Gomina fi èrò ìgbàgba han pé, àrun buruku ko ni ya ilé ẹnikẹni.
Lẹsẹkẹsẹ ó wọ inú ọkọ̀ ojú omi pẹlu àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀, ó bá lọ sí agbègbè Dalimanuta.
Nítorí náà, èmi ń tẹ̀lé gbogbo ẹ̀kọ́ rẹ,mo sì kórìíra gbogbo ọ̀nà èké.
Nítorí kì í ṣe nípa ara wa ni à ń waasu.
Obinrin gbo‘rinyin l'ayajọ awọn obinrin Chibok Girls: ilé ejọ́ ju ajínigbe sẹ́wọ̀n Oríṣun àwòrán, Osinbajo/twitter Àkọlé àwòrán, O ni àwọn ise ìrànwọ ti ó ń wọn se fawọn ọ̀dọ́ àti àwọn alaini kò lẹ́gbẹ́.
Lara awọn obrinrin to n dojukọ iru nnkan bayii ni Zarka, ti ọkọ rẹ fi ọbẹ ge ni imu sọnu.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ondo disability: Kò sí ẹni tí àkàndá kò lè ya ilé rẹ̀- Ayọdele Oyedele jẹ ayaworan to n fi kalamu da ara to ba wuu ti awọn eniyan si n kọ Haa le lori nigbakigba ti o ba gbe aworan naa kalẹ bii ti Donald Trump yii.
Davido ni wọn fun ni ami ẹyẹ akọrin to gbayi julẹ pẹlu awo orin rẹ FIA.
Nítorí mo mọ ibi tí mo ti ṣẹ̀,nígbà gbogbo ni ẹ̀ṣẹ̀ mi sì wà níwájú mi.
#NigeriaDecides: Buhari Sudan ló n díje dupò aàrẹ -Nnamdi Kanu (IPOB) Àwọn ológun dojú ìjà kọ ara wọn ní Khartoum Oun tí ẹ lè má mọ̀ nípa Omar al-Bashir, olórí Sudan ti wọ́n yọ nípò Kí ni àwọn ẹ̀ṣẹ̀ àti ẹ̀sùn tó ń da Oshiomole láàmú?
Nigba to si jẹ pe aisan lo ṣe e wo, a ri ti ọlọjọ ṣe, Isiaka Abiola Akanji Ajimobi mi kanlẹ nile iwosan kan nilu Eko ni Ọjọbọ, ọjọ Kẹẹdọgbọn, oṣu kẹfa, ọdun 2020, to si ki aye pe o digbose.
Sima ṣalaye nipa ọmọ rẹ pe akanda ẹda ti kò le sọrọ, to oun nilo lati maa ṣe gbogbo nkan fun ni Hridoy.
Isiaka ni eto ilera ko si ni ipo to joju.
 Owo to din die ni bilionu meje owo dola ile okeere fun awon ile ise awon ara China CCECC”.
Yatọ̀ fún orí ìtàgé, wo ohun tí o kò mọ̀ nípà Mr Latin 'Ọwọ́ wa tún tẹ ojúkòó tí wọ́n tí ń bá àwọn ọmọdékùnrin lò pọ̀ ní Daura' Díẹ̀ lára àwọn òṣèré Nollywood ti wọ́n ti ṣe ìgbéyàwó lẹ́ẹ̀kejì Buhari ba osinbajo sayẹyẹ igbeyawo ọmọ rẹ Khadijah, obìnrin àkọ́kọ́ tó dẹnu ìfẹ́ kọ àyànfẹ́ rẹ̀ Aisha Buhari ké gbàjare pé ètò ìjọba Buhari kò ṣànfàní f'óbìrin Àṣà ìbálé lálẹ́ ìgbeyàwó ń dọdẹ àwọn obìnrin òde òní Arabinrin Fatima salaye wi pe, baba oun ati Aarẹ dabi tẹgbọn taburo ni, ti awọn si n gbe ni Ile Aarẹ lati bi ọdun melo ṣẹyin.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù EFCC: Ìwádìí iléeṣẹ́ Alpha Beta Consulting Ltd ṣì ń tẹ̀síwáju lórí ẹ̀sùn N100b 14 Agẹmo 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Eeyan kan kọwe ifisun tako Alpha Beta Consulting Limited niwaju ajọ̀ EFCC ṣugbọn ajọ naa ni iwadii ṣi n lọ Ajọ to n gbogun ti iwa ijẹkujẹ lorilẹ-ede Naijiria, EFCC ni awọn ṣi n wadii ileeṣẹ Alpha Beta Consulting Limited.
“Nígbà tí ẹnìkan bá pè ọ́ sí ibi iyawo, má ṣe lọ jókòó ní ipò ọlá.
Koda ọpọ ninu awọn eeyan yii lo tun n beere pe, abi tootọ ni iroyin to ja rain-rain nijooni pe, Alaafin ti le Olori Badrat jade kuro ninu aafin rẹ lori ẹsun asemase?
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Àgungùnlá!
Ẹni aadọrin ọdun si ni ko to o kú.
si ọrọ to jẹ mọ abẹle, Georgina Ehuriah, naa so pe , “ile-ise to n ri si
Ilumọọka agbabọọlu ẹlẹyin, Serena Williams, ti fi lede pe oun ko ni kopa ninu Idije Ife Ẹyẹ Rogers Cup ti yoo waye ni Canada ni ọsẹ to n bọ.
 Òpin ìfé láàrin òun àti heliose kò dára.
Alaafin ni àwọn òògùn ìbílẹ̀ wà dáadáa láyé àtijọ́, tó ń wo àwọn àrùn bíi ìgbóná tàbí Sanponna àti atọgbẹ, tí àwọn oníṣègùn ìbílẹ̀ náà sì ní agbára láti fi ohùn lásán ransẹ sì ẹni tó wà nílẹ òkèèrè, tí ohun tí wọn ba sọ, yóò sì máa ṣẹ lójú ẹsẹ.
“Ẹ gbọ́, ẹ̀yin eniyan Israẹli, kò sí ohun tí OLUWA Ọlọrun yín fẹ́ kí ẹ ṣe, àfi pé kí ẹ bẹ̀rù rẹ̀, kí ẹ máa rìn ní ọ̀nà rẹ̀, kí ẹ fẹ́ràn rẹ̀ pẹlu gbogbo ọkàn yín ati ẹ̀mí yín, 
Àwọn nǹkan àtijọ́ ti kọjá,àwọn nǹkan tuntun ni mò ń kéde nisinsinyii.
Àmọ́ ní'lùú ńlá bí Ìbàdàn, ewú ńlá ń bẹ lójú títì fún oníkẹ̀kẹ́.
Bó tilẹ jẹ Ayobami ní ootọ ni pé wọn ní ajọsọ lori ọrọ iṣẹ, òun ko ṣèlérí fún pe òun yóò lo ipò mama oun ninu ìjọba láti sọ di oṣiṣẹ to ń gba owo oṣù lai yọjú sí ileeṣeẹ ìjọba kankan.
Ọbasanjọ gbe imọran yii kalẹ ninu atẹjade kan ti amugbalẹgbẹ rẹ feto iroyin, Kẹhinde Akinyẹmi fisita, eyi to ni o waye lasiko ti Ọbasanjọ n gbalejo awọn ọmọ igbimọ oludari feto iroyin ori ayelujara nibudo iyawe kawe rẹ.
Bakan naa ni aarẹ Trump kọ ibode ti ko ni faaye gba awọn ara orilẹede Mexico lati ma a wọ ilẹ Amerika lati ibode to so awọn mejeeji pọ.
Ọgọọrọ awọn to n gbe igberiko lorilẹede Amẹrika ni ko gba ti Trump mọ rara.
Oun ati Philippe ti n fẹra wọn fun bi i ọdun kan ataabọ.
“Má ṣe fi èyíkéyìí ninu àwọn nǹkan tí a dárúkọ wọnyi ba ara rẹ jẹ́, nítorí pé, nǹkan wọnyi ni àwọn orílẹ̀-èdè tí mò ń lé jáde kúrò níwájú yín fi ba ara wọn jẹ́.
Ọdun mẹfa ni orilẹ-ede Ethiopia fẹ fi ṣe iṣẹ naa.
Erica gungi rékọjá ewé pẹ̀lú ìwà tó hù lálẹ́ ọjọ Satide - Ọmọ Nàíjíríà faraya Mo gbọ́dọ̀ fún ọ lóyún ká tó kúrò nílé BB Naija - Neo sọ fún Vee Tinubu, yé é sọ̀rọ̀ abẹ́lẹ̀, bọ́ sí gbangba láti bèèrè àtúntò Nàíjíríà lọ́dọ̀ Buhari - Afẹnifẹrẹ Wo àànfàní ‘Masturbation’, fífún ara rẹ̀ ní adùn ìbálòpọ̀ Wo àwọn ìlànà tuntun ti o gbọdọ tẹlèé rèé ki ó to le wọkọ̀ òfurufú lọ sókè òkun Ìdí ti mo fi da sọ́ọ̀sì rú lásìkò ìgbéyàwó ìyáwó mi tó ló fẹ́ ọkọ míran- Osadebe Ẹ fura o, Boko Haram ti pàgọ́ sí Abuja, yóò ṣe ìkọlù láìpẹ́ - Iléèṣẹ́ Aṣọ́bodè lọgun Ṣugbọn oloye Taye Ayorinde to jẹ Baalẹ Ekotedo sọ pe, Akintoye ṣi ni aṣaaju awọn ọmọ kaarọ oojiire gẹgẹ bi awọn ẹgbẹ ọmọ Yoruba to le ni aadọrin ṣe yan an sipo.
Nígbà náà ni inú rẹ yóo dùn sí ẹbọ tí ó tọ́,ẹbọ sísun, ati ẹbọ tí a sun lódidi;nígbà náà ni a óo fi akọ mààlúù rúbọ lórí pẹpẹ rẹ.
"Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Wo Bullet, ọmọ ọdun mẹjọ tó fẹ́ lùwẹ̀ wọ Olympics ""Ọkọ̀ aképo náà forí sọ òpó iná ló fi laná ní Gowon Estate l'Èkó"" Àgbẹdọ̀!"
Ni bayi, Super-Eagles yoo lo koju Poland lojo ketalelogun osu keta odun ti a wayi, besini won yoo tun koju Serbia lojo ketadinlogbon osu keta nilu London.
Kumuyi sọ ni iwaasu rẹ ni ijọ olu ijọ Deeper Life to wa ni Gbagada nilu Eko pe ko tọ si ọmọ Naijiria lati maa bẹnu ẹ̀tẹ́ lu awọn adari wọn.
hun tunbo fese mule”Igbimo kan ni eyi ti awon minisita fun oro ile okere ati awon olori eleto aabo ni orile-ede mejeeji se ipade nilu Cairo lorile-ede Egypt losu to koja, ni iyanju ati wa woroko fi sada.
Nigba to n sọ ero rẹ lori ohun to fa bi ọpọ igbeyawo awọn oṣere tiata ṣe n daru, Opeyemi ni ki awọn eeyan dẹkun didi ẹbi igbeyawo to daru ru oṣere tiata nikan.
Jesu mọ̀ pé Baba ti fi ohun gbogbo lé òun lọ́wọ́, ati pé ọ̀dọ̀ Ọlọrun ni òun ti wá, ọ̀dọ̀ Ọlọrun ni òun sì ń lọ.
Lẹ́yìn náà, Joṣua ati gbogbo àwọn ọmọ Israẹli pada sí àgọ́ wọn, ní Giligali.
Sise Atileyin Fun Aare Ogbeni Okechukwu tun sapejuwe aseyori ijoba aare Buhari gege bi ohun ti o lonka, paapaa julo sise agbekale apo ifowopamo kan soso, eleyi ti o dena sise owo ilu kumo-kumo.
He said the Holy Prophet Muhammad used to spend very generously on the poor and the needy during this period, and urged Muslims in the country and all over the world to copy the good example.
Ni ọjọ Aiku lawọn obi ati alagbatọ ni ipinlẹ Ogun fọn si igboro ilu Abẹokuta lati fi ẹhonu wọn han lori ẹgbẹrun marundinlọgbọn naira ti ijọba ipinlẹ naa kede pe ki awọn akẹkọọ ileewe aladani o san fun ayẹwo kokoro arun COVID-19 ki wọn to lee wọle pada si ileewe.
Igbesẹ adele ọga ọlọpaa tuntun yi yoo ma ṣe afihan boya nnkan ti yi pada tabi oun naa n ṣe bi ẹni gbe lẹyin ẹgbẹ oṣelu kan.
Mo tilẹ mọ ọkan lara wọn.
Action Against Hunger: Àwọn òṣìṣẹ́ olùrànlọ́wọ́ képe ìjọba kó gbàwọn lọ́wọ́ ajínigbé
 “Mo wa  ki aare lori aseyọri rẹ fun eto idibo aare to
“Nígbà tí ẹ bá dé ilẹ̀ Kenaani tí n óo fun yín, tí yóo jẹ́ ohun ìní yín, bí mo bá fi àrùn ẹ̀tẹ̀ sí ilé kan ninu ilẹ̀ yín.
Ọjọ Satide nileesẹ ologun kede pe oun fẹ bẹrẹ akanse eto igbogun tawọn agbesunmọmi ati ọdaran lawujọ ni ori ayelujara.
Fún àpẹrẹ, àwọn abúlé ti àwọn óṣìṣẹ́ elétò ìlera àti àwọn òṣìṣẹ́ ilera míràn ṣe n ṣe àkọsílẹ̀ ikú Covid-19, bii ti orílẹ̀-èdè Chad, ó ṣeeṣe kí a ri ikú to pọ̀ ju bóṣe yẹ lọ.
Ọga Agba Ọlọpaa, DSP Nafiu Abubakar, to fidi iṣẹlẹ naa mulẹ sọ pe awọn ṣi n wadii nkan to mu ki awọn òbí ọmọ naa fi ìyà jẹ ẹ to bẹ ẹ, debi pe wọn ni ko ma a sun pẹlu awọn ewurẹ wọn.
Ọmọ naa wa ninu gareeji ọkọ fun ọdun meje lai si ounjẹ kan saan tabi itọju fun ilera.
Kanya ti iya rẹ kọ silẹ lati kekere jẹ akinkanju obinrin to n sọrọ iwuri fun awọn eniyan kaakiri.
Gbogbo àwọn ọmọ ogun rẹ ati àwọn èrò tí ó wà ninu rẹ,ni yóo rì sí ààrin gbùngbùn òkun, ní ọjọ́ ìparun rẹ.
Atiku pe Buhari ni ‘Ọgagun’ ninu gbogbo ọrọ rẹ Ninu ọrọ rẹ, 'ọgagun' ni Atiku pe Buhari dipo ti yoo fi pe e ni 'aarẹ'.
Agbẹnusọ fun ajọ alakoso isẹlẹ pajawiri (sema) ti ipinlẹ Borno, Bello Dambatta fi idi ikọlu yi mulẹ pẹlu alaye wipe ogunlọgọ awọn eniyan miran ni wọn fi ara pa nigbati awọn agbesunmọmi Boko Haram ju inọ si awọn ile lorisirisi ninu abule naa.
O ni nkan meji lo wa nidi iṣẹlẹ yi.
 fún àwọn tó bá jẹ onígbàgbó nìkan ló lè ní òye ìtumọ ̀ àwọn òpó igbagbo tí ẹ ̀ sìn yí dìró mọ ́ dáradára .
 Bakan naa, eto yii tun si anfaani sile fun
Badfield Ndiaye, ọmọ ọdun mẹẹdọgbọn jẹ ọmọ ẹgbẹ agbabọọlu fun orilẹ-ede Senegal.
Òmíràn tún ni ìròyìn kan tí gbajúgbajà akọ̀ròyìn, Dele Mọmọdu gbé jáde pé àjọ EFCC gbẹ́sẹ̀ lé àsùnwọ̀n gbajúgbajà olórin, David Adeleke (Davido) àti gbogbo ẹbí Adeleke nítórí pé ọ̀kan lára wọn, Ademọla Adeleke n dupò gómìnà l'Ọṣun.
Wọ́n sọ ìwọ̀n sinu òkun, wọ́n rí i pé ó jìn tó ogoji mita.
ti le je pe, iko agbaboolu Swansea City lo kọkọ gbayo meji wọ le ninu
World Sàngó Festival 2019: Ìyàtọ̀ tó wà láàrín arugbá Ọ̀ṣun Òṣogbo arugbá Ṣàǹgó lóde Ọ̀yọ̀
#SacktheServiceChiefs làwọn èèyàn ń pariwo sí ààrẹ Buhari ti sú àwọn ọmọ Nàìjíríà lórí àìsí àbò.
”Asofin Ben Murray Bruce so pe:“Ise ribiribi ni e se.
Eyi lo faa ti iye owo ori epo robi agba kan se lo soke si 73.
Ẹ wo ìrírí aláboyún tó ń rọbí lọ́wọ́ lásìkò ìbúgbàmù tó wáyé ní Lebanon Arabinrin Emmanuelle n gbaradi lati bi ọmọ tuntun ni ile iwosan St George's ni ilu Beirut nigba ti ibugbamu naa ṣẹlẹ.
Oríṣun àwòrán, CHADWICK BOSEMAN Àkọlé àwòrán, Ẹni ọdun mẹtalelogoji ni Chdwick Boseman ki aisan 'colon cancer' to pa Yatọ si awọn nkan wọnyii, awọn to ba ni aisan bi ulcerative colitis fun bii ọdun mẹwa, naa le ni jẹjẹrẹ yii.
Iṣẹ́ abẹ oyún ìju (Fibroid) ni Christianah Ohunya ba lọ sile iwosan ijọba ni Orile Agege nipinlẹ Eko.
“Egbò yín kò lè san mọ́,ọgbẹ́ yín sì jinlẹ̀.
" o máa ń pèé ní "" Òkúta iyebíye tí kò lẹ ́ gbẹ ́ "" ."
Ladipo sọ fun awọn oniroyin wi pe iwe kika ti wa di oun amuyangan laarin awọn ẹlẹwọn ipinlẹ naa.
Bakannaa lo ni lara awọn iwa titapa sofin ati aṣẹ naa ni bi o ṣe kọ lati farahan lawọn ipade ati eto ti ijọba ipinlẹ naa ba gbe kalẹ laisi awijare to yanranti.
Oríṣun àwòrán, Manohar Shewale Àkọlé àwòrán, Ọjọ ti Nuha pe ọmọ ọdun mejidinlogun lawọn mọlẹbi rẹ pa Neha Sharad Chaudury, ọmọ ọdun mejidinlogun lati orileede India Neha Sharad Chaudury ṣe alabapade iku lọwọ awọn mọlẹbi rẹ lọjọ ti o pe ọmọ ọdun mejidinlogun.
Ẹgbẹrun mẹtalelọgọta ati ojilelẹgbrin o din ẹykan (63, 839) lawọn ti ara wọn ti ya nigbati aarun naa si ti gbẹmi awọn ẹgbẹrun kan ati mejilelaadọjọ (1173) eeyan.
 ayò ọlọ́pọ́n, ǹjẹ́ ìwọ mọ bí wón ti ṣe ń ta ayò yìí
Bo gbogbo wọn mọ́lẹ̀ papọ̀,dì wọ́n ní ìgbèkùn sí ipò òkú.
Àwọn Filistini tí wọ́n fara gbọgbẹ́ sì ṣubú láti Ṣaaraimu títí dé Gati ati Ekironi.
Ní ọjọ́ kẹjọ, yóo mú àdàbà meji tabi ọmọ ẹyẹlé meji tọ alufaa wá ní ẹnu ọ̀nà Àgọ́ Àjọ.
24 Òkùdu 2020 Àwọn òmùwẹ̀ ń wá èèyàn kan tó pòórá lẹ́yìn ìjàmbá ọkọ̀ ojú omi to dójúdé l'Eko24 Òkùdu 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Inú mí dùn bí ìpínlẹ̀ Ọyọ se setán láti bẹ̀rẹ̀ ilé-ìwé tí àwọn akẹkọ̀ọ́ ń gbé- Òbí Èmi kò jẹ̀bi pẹ̀lú àlàyé -Omoyele soworẹ Àwọn mẹ́rin t'íjọba Buhari k'etí ikún s'àṣẹ òmìnira iléẹjọ́ lórí wọn rèé Ìjà arọ méjì lálẹ́ òní ní pápá ìṣeré Old Trafford Ṣaaju ni ijọba apapọ ti fi ẹsun to ni ṣe pẹlu fifi ipa gba ijọba kan oun ati ẹnikeji rẹ, Olawale Bakare, ti awọn memeji si ni awọn ko jẹbi ẹsun naa.
Itse Sagay fikun pe irọ to jinna si ootọ ni ọrọ kan ti Lawan sọ pe ẹgbẹrun lọna ọtalelẹẹdẹgbẹrin o din mẹwa naira, (₦750,000) ni asofin kọọkan n mu ls sile losu.
Nígbà tí ó bá dàgbà, ó di igi, àwọn ẹyẹ ojú ọ̀run wá ń ṣe ìtẹ́ wọn sí orí ẹ̀ka rẹ̀.
Ó ní, “Ẹ lọ, kí ẹ fẹ̀sọ̀ wádìí nípa ọmọ náà.
Ṣugbọn bí ó bá ti tọ́jú oko rẹ̀ tán,ṣé kò ní fọ́n èso dili ati èso Kumini sinu rẹ̀,kí ó gbin alikama lẹ́sẹẹsẹ;kí ó gbin ọkà baali sí ibi tí ó yẹ,kí ó sì gbin oríṣìí ọkà mìíràn sí ààlà oko rẹ̀?
O pada lọ darapo mọ ẹgbẹ oṣelu APC lọdun 2015 ni eyi ti awọn neiyan gba pe o ṣiṣẹ lodi si ẹgbọn rẹ ninu idibo to kọja lọ to fi to gẹ ni Kwara.
awon igbimo asoju pe eni to ba fẹ da si eto isuna odun 2019, ni lati fi oruko
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Buhari: Maa ran Ghana lọwọ lati jagun iwa ijẹkujẹ 6 Ẹrẹ̀nà 2018 Oríṣun àwòrán, AFP Àkọlé àwòrán, Ọpọ ogun ni Buhari gbe dide lati wa ọwọ iwa ijẹkujẹ bọlẹ ni Naijiria Aarẹ orilẹede Naijiria, Muhammadu Buhari ti safihan ifẹ rẹ lati fọwọsowọpọ pẹlu orilẹede Ghana lati gbogun ti iwa ijẹkujẹ lorilẹede mejeeji.
Ẹni tí yóo pa ilẹ̀ Moabu ati àwọn ìlú rẹ̀ run ti dé,àwọn àṣàyàn ọmọkunrin rẹ̀ sì ti lọ sí ibi tí wọn ó ti pa wọ́n.
Won fenuko lori adehun yii lasiko ti aare  Akufo-Addo lo fun irinajo olojo meji ni orile
" Ibudo ọgba ẹranko Chester ti n se iranlọwọ fun igbo ẹran Gashaka Gumti, ti wọn si n gbiyanju lati ri pe, aabo to péye wà fawọn ẹranko to wa ninu igbo ọhun.
Bi o ti le je pe orisirisi ipenija
EFCC kii ṣiṣẹ lori ahesọ ọrọ bikoṣe arigbamu ẹri."
Aarẹ Mohammadu Buhari kẹdun iku oloogbe naa, o kede pe ki gbogbo asia Naijiria wa ni idaji fun ọjọ meta lati fi bu ọla fun Shagari.
Orukọ ti wọn yoo maa pe ni Special Weapons and Tactics (SWAT).
Minisita fun oro abele , Abdulrahman Danbazzau so wipe eto-abo  to daju ti wa nile lati dabobo emi ati dukia awon eniyan ni ilu Abuja.
Nibayii, wọn ti sun igbẹjọ rẹ siwaju di Ọjọ Kẹrindinlogun, Osu Kini, ọdun 2021.
Ẹni to bori: Morocco South Africa vs Senegal.
O wa fi da awọn obi ati alagbatọ to fi mọ akẹkọ leti pe wọn ti wojutu si majele naa, ayẹwo imọ ijinlẹ ti waye eleyi to ti fidi rẹ mulẹ pe o ti daa fun mimu bayii.
Bo tilẹ jẹ pe idile, awọn ọrẹ atawọn ololufẹ rẹ ti n ṣeto bi ayẹyẹ ọjọ ibi ọdun ogoji rẹ yoo ṣe ri ṣugbọn ọlọjọ de ko to di ọjọ kọkandinlogun oṣu keje ọdun 2020.
Nígbà tí ara wọn bá gbóná,n óo se àsè kan fún wọn.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Nigeria Army Recruitment 2020: Wo bí o ṣe le fi orúkọ sílẹ̀ fún iṣẹ́ ológun Nàìjíríà 18 Èrèlè 2018 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 20 Ògún 2020 Oríṣun àwòrán, @HQNigerian Army Àkọlé àwòrán, Ileesẹ ologun yoo kọ oniruuru ibudo sigbo Sambisa lati gbakoso ibẹ patapata Ileesẹ ológun Naijiria ti ṣi oju opo itakun agbaye rẹ fun eto igbani sisẹ fun ọdun 2020.
Symington wa gbosuba fun awon  ajo eleto ilera orile ede yii fun akitiyan won
D) ni fasiti kan ni Amẹrika.
4 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Oríṣun àwòrán, Iyabo Ojo/Nkechi/Toyin/Omotola Oriṣiriṣi awọn nnkan lo ṣẹlẹ laarin ọsẹ yii lagbo oṣere tiata Yoruba.
Àwọn ọmọ Yorùbá àtàtà: Báwo lẹ se gbọ́ òwe sí ?
Ahabu ọba Israẹli bá pe àwọn wolii bí irinwo (400) jọ, ó bi wọ́n pé ṣé kí òun lọ gbógun ti ìlú Ramoti Gileadi àbí kí òun má lọ?
Naira Marley ti tèṣù mọ́lẹ̀ nílé ẹjọ́ májísíréètì lórí ẹ̀sùn ìjọ́kọ̀gbé Aláàfin Ọyọ: Ọba tó bá n mú ọtí ní ìta kò yẹ ní ẹni tàá bọ̀wọ̀ fún Idásilẹ̀ Amotekun ko ba òfin ọdún 1999 mu- Malami Ọ̀gá mi fẹ́ fi tipá bámi lòpọ̀ ní Lebanon àmọ́ ìjọba yọ mí l'óko ẹrú - Ọmọ Nàíjíríà míì Bo tilẹ jẹ wi pe ijọba Naijiria pada gba ilu Benin pada ni ogunjọ, oṣu Kẹsan an, awọn eniyan Biafra mu ipinnu wọn ṣẹ nipa kikapa awọn ọmọ ogun Naijiria kan.
Lati ọdun 2011 ti olori orilẹede Libya tẹlẹ, Muammar Gaddafi ti ku ni awọn aṣatipo ti n gba ibẹ lọ sọda si Yuropu.
Oun si ni oludasilẹ ileeṣẹ kan to wa fun ipese ohun amuṣagbara.
"Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Mo fura pé ẹ fẹ́ da Nàíjíríà rú, ń kò ṣe ìwọ́de mọ́ - Segalink, agbátẹrù ìwọ́de yọwọ́ Ìwọ́de EndSARS gboró n‘Ibadan, kò sẹ́ni tó le wọlé tàbí jáde ""Buhari, ìwọ́de yóò yíwọ́, tó gbá jẹ́ káwọn ológun bá bẹ̀rẹ̀ ‘Operation Crocodile Smile’ "" Ìjọba Eko pàdánù ₦234m láàrín ọ̀sẹ̀ kan torí ìwọ́de End SARS Bí o bá fẹ́ darapọ̀ mọ́ ikọ̀ ọlọ́pàá SWAT tí yóò rọ́pò SARS, wo àmúyẹ tí o gbọ́dọ̀ ní Aisha Buhari polongo àwo orin tó ní Nàíjíríà ń ṣun ẹ̀jẹ̀ lásìkò ìwọ́de Lizzy Anjorin ń kiri àgọ́ ọlọ́pàá láti gba ọ̀dọ́ afẹ̀hónúhàn, tó wà láhàámọ́ sílẹ̀ 2015 ni mo ti ń kígbe pé gudugbẹ̀ máa já ní Nàíjíríà - Oyedepo Iroyin kan tiẹ ni wọn gun ọkan lara awọn oluwọde ni ọbẹ, to si ku sile iwosan."
N óo sọ ìmọ̀ àwọn ará Juda ati ti àwọn ará ìlú Jerusalẹmu di òfo, n óo jẹ́ kí àwọn ọ̀tá wọn ati àwọn tí wọn ń wá ẹ̀mí wọn fi idà pa wọ́n.
Bí ó bá gbọ́ ìkìlọ̀ ni, kì bá gba ẹ̀mí ara rẹ̀ là.
Olori ileto Bordo, Alhassan Haruna fi to BBC leti pe, pẹlu bi ọkọ naa ṣe wa fun ríran awọn alaboyun lọwọ, sibẹ opopona ko dara.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Amina Zakari: INEC ní Amina Zakari kọ́ ni yóò wà ní ìdí ìbò kíkà lásìkò ìdìbò 2019 4 Sẹ́rẹ́ 2019 Oríṣun àwòrán, INEC Àkọlé àwòrán, Ìgbàkejì nìyí tí ìyànsípò Amina Zakari yóò máa fa awuyewuye lórílẹ̀èdè Nàìjíríà nítorí àhesọ ọ̀rọ̀ pé ó tan mọ́ Ààrẹ Buhari Ajọ INEC ti sọrọ lori awuyewuye to n ja ranyinranyin lori iyansipo Amina Zakari gẹgẹ bi olori igbimọ ibudo ikabo aarẹ ti yoo waye loṣu keji ọdun 2019.
Bi awọn kan se n sọ pe o dara bo se jẹ Hausa to jade sita niru eto bẹẹ ni awọn mii ni ko si ninu asa ọmọbinrin Hausa lati kopa ninu iru eto bii BB Naija yii.
"Àhesọ ni pé Ìjọba àpapọ̀ ní kí wọ́n yọ Onnoghen - Femi Adeshina Kò tọ̀nà láti gbé adájọ́ Onnoghen lọ síwájú CCT - Adájọ́ fẹ̀yìntì Pe Buhari wa yọ adajọ agba, leyi ti ko si ninu ofin, emi o mọ iru wahala to le fa o,"" bẹẹ ni Olisa wi."
Bakan naa ni ireti wa pe,  yoo jiroro lori ona ti igberu fi le ba eto abo ati alaafia, isakoso ijoba rere, ati ajosepo to dan moran lori eto idokowo pelu Aare Buhari.
Ṣe ẹ mọ pe ẹnu awọn olukọ Yoruba maa n dun fun itan sisọ, bẹẹ gẹlẹ ni olukọ wa Zainab Olaitan ko ṣe ja wa kulẹ rara lonii pẹlu awọn ọrọ afiwe, ọrọ apọnle to n jẹyọ.
Dokita ọhun tun ni, aisan itọ ṣuga ma n jina rere si ẹni to ba n ṣe ere idaraya.
Ninu atẹjade ti ẹgbẹ naa fi sita lọjọ Aje, wọn wipe inu awọn ko dun si bi nkan ṣe ri ni Naijiria.
Ìjọba àti àwọn àjọ rẹ̀ máa ń sábà fi èyí ṣe bójúbójú fún ìtẹríbọlẹ̀ òmìnira ọ̀rọ̀ sísọ.
Ní bayíì, ènìyàn marunlélọ́gọ́rin ló ti ri ìwòsàn ti wọ́n si ti lọ ilé wọ́n nígbà ti iye ènìyàn to kú kò tíle ni mẹ́wàá Ẹ̀wẹ̀, ìpínlẹ̀ makandinlogun lo ti kéde ààrun Coronavirus bayii lórilẹ̀-èèdè Naijiria.
 lásìkò tó wà ní Ìbàdàn , ó jẹ ́ ọ ̀ kan lára àwọn ìgbìmọ ̀ tó dá ẹgbẹ ́ òṣèré m ̀ bárí m ̀ báyọ ̀ kalẹ ̀ , ní èyí tí ó sì tún ṣe ìfilọ ́ ọ ́ lẹ ̀ ẹgbẹ ́ náà ní Òṣogbo tí ẹgbẹ ́ náà sì digi àlọ ́ yè fún ìdàgbàsókè àti ìgbélárugẹ iṣẹ ́ ọpọpọlọ àti ọpọ òṣèré ní ìlú lẹ ́ yìn tí ó ti rí ọ ̀ pọ ̀ lọpọ ̀ ìwúrí láti ọ ̀ dọ ̀ beier , Òṣogbo .
wọ́n sọ fún un pé, “Ohun tí àwọn eniyan náà mú wá ti pọ̀ ju ohun tí a nílò láti fi ṣe iṣẹ́ tí OLUWA pa láṣẹ fún wa.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Yollywood: Yomi Fabiyi ní ìwà aṣiwèrè ni bí ọlọ́pàá ṣe ń tẹ ẹ̀tọ́ ọmọnìyàn lójú, táwọn òṣèré tíátà náà ń lò nínú fíímù 6 Ọ̀wàrà 2019 Oríṣun àwòrán, Others Ilumọọka osere tiata kan, Yomi Fabiyi ti gbarata loju opo Instagram rẹ pe, ohun ti ko dara ni bi awọn agbofinro se n tẹ ẹtọ ọmọniyan loju, eyi ti awọn osere tiata naa n gbe jade ninu ere.
A rò pé ó dára kí á gbọ́ ohun tí o ní lọ́kàn, nítorí pé ó ti dé etígbọ̀ọ́ wa pé níbi gbogbo ni àwọn eniyan lòdì sí ẹgbẹ́ tí ó yàtọ̀ yìí.
Lẹ́ẹ̀kan sí i, mo dúpẹ́ lọ́wọ́ gbogbo yín o, bí ẹ sì ti ń ti àwọn ìwé mi wọ̀nyí lẹ́yìn yìí, Olódùmarè ti gbé akeǹgbè ìbùkún, ti yóò tú lé orí gbogbo yín káríkárí.
Lẹ́tà Obasanjo: Àjálù ń bọ̀ bíi ti Rwanda, tí Buhari kò bá ṣàtúnṣe ètò ààbò Obasanjo, Makinde ṣèpàdé bòńkẹ́lẹ́ lórí ìhà tí ìjọba àpapọ̀ kọ sí Amotekun Kí ló fà á tí àwọn ọmọ Obasanjo ń ta kò ó ní gbangba?
Ẹ wo òkun bí ó ti tóbi tí ó sì fẹ̀,ó kún fún ọ̀kẹ́ àìmọye ẹ̀dá,nǹkan abẹ̀mí kéékèèké ati ńláńlá.
 Àwọn ààlà ibí pípọ ́ n yìí kìí mú tí ó sì maa ń fa kí awọ ara wú .
Gẹ́gẹ́ bí òtítọ́ Kristi ti wà ninu mi, kò sí ohun tí yóo mú mi yipada ninu ohun tí mo fi ń ṣe ìgbéraga ní gbogbo agbègbè Akaya.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ogun Accident: FRSC ní Sokoto làwọn èrò náà ti ń bọ̀ wá sí Ijẹbú Ode 29 Sẹ́rẹ́ 2020 Oríṣun àwòrán, Abiodun Iroyin to n tẹ wa lọwọ fi ye ni pe ọpọ oku lo ti sun, ti ọkẹ aimọye si farapa lasiko ti ọks akẹru kan rebọ sinu odo Ogun lopopona Ibadan silu Ijẹbu Ode lọjọ Isẹgun.
Nígbà tí ó yá, Nahaṣi, ọba àwọn ará Amoni kú, Hanuni ọmọ rẹ̀ sì jọba lẹ́yìn rẹ̀.
Peteru bá jáde lọ, ó bú sẹ́kún, ó bẹ̀rẹ̀ sí hu gan-an.
Igba melo ni ẹgbẹ osisẹ ti gunle iyansẹlodi labẹ isakoso Ayuba Wabba?
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Coronavirus in Nigeria: Ẹ wo àǹfààní tó wà nínú àrùn Coronavirus Odun 2018 ní Didier Drogba feyinti nìdí eré bọọlu.
Ajọ to n gbogun ti ajakalẹ aarun ni Naijiria, NCDC, ti kede pe esi ayẹwo Covid-19 ti fihan pe igba din maarun eeyan lo tun ti ni aarun naa l'orilẹ-ede Naijiria.
Nígbà tí olódodo bá borí, àwọn eniyan á yọ̀ ṣẹ̀ṣẹ̀,ṣugbọn nígbà tí ìkà bá dìde, àwọn eniyan á sá pamọ́.
Ninu esi ọrọ yi, Gbajabiamila ni oun ṣẹ labẹ ofin awọn to n ṣe akoso eto amofin ni, ti oun si ti gba ijiya to tọ.
Wọn ti fi ẹsun kan to dalori ipaniyan kan ọmọ orileede Australia, Brenton Tarrant ti o pa awọn eeyan naa ti ireti si wa pe wọn yoo fi awọn ẹsun miran kan an.
A ko i ti i ri lati igba ti a ti pe ẹjọ.
Mo tún ṣakọ pé irúfẹ́ ata tí èmi Alákọ̀wé ò lè jẹ – wọn kò tí ì ṣẹ̀dá ẹ̀ nílẹ̀ yìí.
Ni bi a ṣe n sọrọ yii, ọwọ ọlọpaa ti tẹ Sani Garba ni ipinlẹ Niger.
 Un grand merci du fond du cœur à toute ma famille, mon « équipe personnelle » de m’avoir soutenu durant toute ma carrière, dans les bons comme dans les mauvais moments.
Nígbà tí àwọn afọnfèrè bá fọn fèrè mejeeji, gbogbo àwọn ọmọ Israẹli yóo wá sọ́dọ̀ rẹ ní ẹnu ọ̀nà Àgọ́ Àjọ.
Ọlọrun tún fi lé ọba Israẹli lọ́wọ́, ó ṣẹgun rẹ̀, ó sì pa àwọn ọmọ ogun rẹ̀ ní ìpakúpa.
Bee si ni awọn ohun alumooni orile ede yii paapaa julom omi ati ilẹ ko pọ si i.
Oríṣun àwòrán, Bashir Ahmad Àkọlé àwòrán, Buhari ni ko yẹ ki ọrọ ẹkunwo oṣu o di gbese si ọrun ijọba Wahala lori ilana owo oṣu tuntun yii ti gbode kan ninu ọdun 2018 pẹlu oniruru igbesẹ ati ijiroro laarin ijọba apapọ atawọn adari ẹgbẹ oṣiṣẹ ki wọn to fẹnu ko si ẹgbẹrun lọna ọgbọn naira gẹgẹ bii owo oṣu oṣiẹ to kere julọ lorilẹede Naijiria.
Oríṣun àwòrán, Others Yatọ si aworan to fi sita nipa ọmọ iya rẹ obinrin to bimọ lọdun 2019, awọn eeyan ko le tọ ka si pe lagbaja tabi tamẹdun ni ọmọ iya Hushpuppi.
Ní ọjọ́ ìpọ́njú ati ìbànújẹ́,Jerusalẹmu ranti àwọn nǹkan iyebíye tí ó ní ní ìgbà àtijọ́.
’ rèé Afọnja, ẹni tó finú wénú ní Ilọrin, àmọ́ tó jẹ iwọ Ẹfunsetan Aniwura, obìnrin tó ju ọkùnrin lọ Ọ̀rọ̀ǹpọ̀tọ̀niyùn, Aláàfin obìnrin àkọ́kọ́ rèé, tó ní nǹkan ọkùnrin Iwadii rẹ fihan pe: Oju maa n ti awọn ọkunrin lati ro iru ẹjọ bẹ ẹ sita - wọn le fi ẹjọ iwa buruku iyawo wọn sun o, ṣugbọn wọn ko ni i sọ pe o n fi tabi fẹ ẹ fi ipa ba wọn lo pọ.
Ẹ gbọ́ bí ẹṣin wọn tí ń fọn imú, ní ilẹ̀ Dani;gbogbo ilẹ̀ ń mì tìtì nítorí ìró yíyan ẹṣin wọn.
O ni èyí sì le túmọ sí pé ayẹwò ti wọ́n ń ṣe kò pọ̀ tó.
Ó fún wa ni ogún ainipẹkun, ogún tí kò lè díbàjẹ́, tí kò lè ṣá, tí a ti fi pamọ́ fun yín ní ọ̀run.
Bakan naa ni ipinlẹ Edo, Eko, Plateau , Ondo ati Ekiti.
Kaakiri agbaye si ni wọn ti fi awọn fidio naa ranṣẹ si wa.
Wó̩n sì ní è̩tó̩ sí àà bò lábé̩ òfin láìsí ìyàsó̩tò̩ kankan.
Wọ́n ṣebí àwọn lè fi àlá tí olukuluku wọn ń rọ́ fún ẹnìkejì rẹ̀ mú àwọn eniyan mi gbàgbé orúkọ mi, bí àwọn baba wọn ṣe gbàgbé mi, tí wọn ń tẹ̀lé oriṣa Baali.
won ti yọ eniyan bii àádọ́ta
Lẹ́yìn náà, ó mú mi lọ sí ibi ẹnu ọ̀nà tí ó wà ní ìhà àríwá, ó sì wọ̀n ọ́n, bákan náà ni òun náà rí pẹlu àwọn yòókù.
World Food Day: Wo àwọn oúnjẹ ìṣẹ̀mbáyé Yorùbá tó ti ń di àpatì ‘Ọọni pè fún ìfè òtító láàárín àwọn olósèlú’ Akẹ́kọ̀ọ́ Ilaro Poly tó pegedé jù jẹ ẹ̀bùn iṣẹ́ ọ̀fẹ́ lọ́wọ́ Gómìnà Abiodun 'Lẹ́yin wákàtì mẹ́ta tí iná Onitsha bẹ̀rẹ̀ ni ọkọ̀ panápaná tó yọjú' Àwọn ojú oge Yollywood t'ọ́jà wọ́n ṣì ń tà wàràwàrà Àgbo ló ṣiṣẹ́ fún mi l''asìkò tí mò ń wojú Olúwa fún ọmọ - Toyin Abraham Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Painter: Samuel ni ìdàgbàsókè Nàìjíríà ló jẹ òun lógún!
 tí kò bá sí ní protein , ó maa ń ṣe àwọn iṣẹ ́ pàtàkì bíi nuerotransmitter àti ìṣẹ ̀ dá ní ara .
Awọn  komisona naa ni Ali Janga, J.
 Àwọn awọ tẹ ́ rẹ ́ wọ ̀ nyí ni omílù yóò fọwọ ́ kọ ́ tí yóò sì ma fi apá fun mọ ́ ra áti lè fun ní irúfẹ ́ ìwọ ́ hùn tí ó bá fẹ .
Ọkùnrin kan rí ẹ̀wọ̀n ọdún mẹ́rin he lẹ́yìn tó jí ẹ̀rọ ìléwọ́ iPhone ní ìpínlẹ̀ Ogun Ẹ fún wa lówó oṣù wa tàbí kí a gùnlé ìyanṣẹ́lódì ọlọ́jọ́ gbọọrọ- Àwọn dokita ìpínlẹ̀ Ondo Coronavirus gbẹ̀mí èèyàn mẹ́rin lánàá Ọjọ́rú ní Nàìjíríà, èèyàn márùndínlọ́gọ́jọ 155 míì tún kóo Wo àfipábánilòpọ̀ ẹni ọdún 51 tí ìjọba ìpínlẹ̀ Ekiti tú làṣirí ní gbangba Oríṣun àwòrán, Instagram/oye4dc Owolewa jáwé olúborí gẹ́gẹ́ bìi ọmọ Naijiria àkọ́kọ́ nílé ìgbìmọ̀ aṣòfin Amẹrika Ọmọ Naijiria to n dije lati ṣoju ẹkun Colombia nilẹ Amẹrika, Oye Owolewa, ti jawe olubori ninu idibo to n lọ lọwọ.
Òmíràn ní ojú kan, òmíràn ní ẹnu sí igbá àyà, òmíràn kò ní imú rarta, ojú òmíràn gùn ó dàbí ojú ìṣaasùn, ọrùn òmíràn gùn tó bẹ́ẹ̀ gẹ́ẹ́ tí ó dàbí igi gíga lẹ́gbẹ̀ẹ́ tábìlí, bẹ́ẹ̀ ni gbogbo wọn ni wọ́n ń fẹ́ bá àwọn ọdẹ sọ̀rọ̀ kí wọ́n bá wọn ṣe àwàdà.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Godfatherism: Ṣé ọ̀rọ̀ bàbá ìsàlẹ̀ nínú òṣèlú lè dópìn bí El-Rufai ṣe sọ?
Lára àmin àròkàn ni: à i lè sùn, à i lè jẹun, ìbẹ̀rù, ẹkún igbà gbogbo, ibànújẹ́ tàbi ọgbẹ́ ọkàn.
Ọgbọ́n dára ju ohun ìjà ogun lọ, ṣugbọn ẹlẹ́ṣẹ̀ kanṣoṣo a máa ba nǹkan ribiribi jẹ́.
Ijọ naa dahun pe awọn to n pe ara wọn ni 'eniyan Ọlọrun' nikan ni o maa n ṣe iṣẹ ibi ti ijọ wọn si maa n da aṣọ bo wọn lara.
Èyí ló fa máalọ-máabọ̀ ojoojúmọ́ gbogbo ẹ̀dá.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ilé aṣòfin àgbà Nàìjíríà dàbí ọjà bí Saraki ṣe pa Akpabio lẹ́nu mọ́ 17 Ọ̀wàrà 2018 Niṣe ni ile aṣofin agba Naijiria ri bi ọja Oyingbo l'Ọjọru lẹyin ti Aarẹ ile aṣofin naa, Sẹnetọ Bukọla Saraki, ko gba ki Sẹnetọ Godswill Akpabio o joko si aaye to tọ si i.
Laipẹ yii ni iroyin kan gbe e pe awọn ajinigbe naa ti bere fun miliọnu marun un lati fi gba dẹrẹba naa ti wọn jigbe.
0 391529 Orilẹede Saudi Arabia 6012 17.
Loṣu kẹrin ni Adeyẹmi Smart pe ẹjọ naa pe oun lo bori ninu idibo fun ipo aṣojuṣofin ẹkun yii.
Ko pẹ lẹyin ikede oku rẹ yii lo tun sọrọ jade ninu fidio kan lori ayelujara to fi tun kede ara rẹ gẹgẹ bii ọga agba pata fun awọn Boko Haram.
Onidajọ Olukunle Idowu, ti ile ẹjọ Majistreti naa gẹgẹ bi iwe iroyin Vanguard ṣe sọ, dajọ pe ki wọn o fi wọn pamọ si ọgba ẹwọn Ileṣa titi di ọjọ kẹẹdọgbọn, oṣu Kẹta, ọdun 2020, ti igbẹjọ yoo waye nile ẹjọ giga lori ẹsun ti wọn fi kan wọn.
Lori Facebook, Abu Mutalubi Omobolaji ni awọn ololufẹ Barrister n ṣeranti ẹni re to lọ.
"Oríṣun àwòrán, Getty Images ""Aarẹ gbagbọ pe isejọba orilẹ-ede jẹ nkan ti Ọlọrun lọwọ si, lati le mu ilọsiwaju ba awujọ, ati ọmọniyan."
Oríṣun àwòrán, Oba Adeyeye Ogunwusi Amọ sa, Ọọni wa fọrọ ransẹ si awọn eeyan to n lu ilu ogun jija, to fi mọ awọn oloselu ti wọn di esu to n ta epo si ọrọ naa pe, ki wọn ti ọwọ ọmọ wọn bọ asọ lori awọn iwa naa.
Ìrìbọmi ní orúkọ Oluwa Jesu nìkan ni wọ́n ṣe.
Sìgá mímu ń di èèwọ̀ oògùn ìlera pípé lagbaye Òfin má wàásù láì gbàṣẹ nìpínlẹ̀ Kaduna ti ń gba àpérò Ìpínlẹ̀ Oyo gba ipò ìkíní mọ́ Edo lọ́wọ́ nínú fífí ọmọdé ṣ'ẹrú Ẹ̀mí 18 ṣòfò ní Òpópónà Akure sí Ọwọ Sibẹ, Fairstein ṣi sọ pe ọwọ awọn ọdọmọkunrin ti wọn sẹ aṣiṣẹ fẹsun ifipabanilopọ naa kan ko mọ.
Lati ọjọ kẹtadinlogun oṣu kẹjọ ọdun 2020 yii ni ileẹjọ so pe ki Balogun bẹrẹ si ni dari igboke-gbodo ọkọ lẹyin ileeṣẹ ijọba to n ri kikọ ile si ilu.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Èrò ọmọ Nàíjíríà yapa lóríi mímú Mélayé Sẹ́nẹ́tọ̀ pe ọ̀gá ọlọ́pàá lórí ọ̀rọ̀ Dino Ìdààmú Sẹ́nétọ̀ Dino Melaye Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Èdè Akurẹ àti Ibadan ni wọ́n fi fà mí léti pé ẹni re kìí 'se òṣèlú - Seyi Makinde Ẹ yọjú sí FBI bí ẹ kìí bá ṣe ''yahoo boys'' - Abike Dabiri-Erewa Mo nífẹ̀ẹ́ Khafi torí kìí díbọ́n tàbí hùwà oníwà - Gedoni sọ̀rọ̀ ìdágbére Kíni ẹ mọ̀ nípa Tolani Alli, ayàwòrán tí igbákejì ààre Osinbajọ ṣẹ́ṣẹ́ yàn?
" Nítorí ìdí èyí, ìjọba ti wọ́gilé gbogbo àyéyé to niṣe pẹ̀lú ètò náà, ó sì gbàdúrà, àwọn ètò mírà ti yóò maa wáye lọ́jọ́ ìwáju yóò lọ bí ó ṣe tọ́ àti bí ó ṣe yẹ.
Bẹ́ẹ̀ gan-an ni a níláti dán igbagbọ yín tí ó ní iye lórí ju wúrà lọ wò.
Ìfọwọ́sowọ́pọ̀ nìkan ni ọ̀nà abáyọ sí ìṣòro Nàìjíríà- Olusegun Obasanjo Buhari, o ṣẹ ilẹ̀ Yorùbá púpọ̀, ló àyájọ́ ìbí rẹ̀ láti tọrọ àforíjìn - PDP Ìtura ìgbà díẹ̀ ni bọ́dà tí ìjọba ṣí padà, kò lóòre nínú - Onímọ̀ ọrọ̀ ajé Wo ìdí tí ààrẹ Buhari kìí fi ṣe ẹ̀dà Jubril láti Sudan Àwọn ohun kàyéèfì tó le mú kí ọmọbìnrin ní oyún ìju Nigba ta n wi yii, mo lọ ba Alagba Emmanuel Alayande to si sọ fun mi pe, ẹni to n du ipo Gomina ko kunju oṣunwọn'' Bo ti lẹ jẹ wipe Obasanjo ko darukọ ẹni naa, Gomina tẹlẹ ri, Rasidi Ladoja lo jẹ oludije ẹgbẹ PDP nigba naa, to si pada wọle si ipo Gomina.
Neko rán ikọ̀ sí Josaya pé, “Kí ló lè fa ìjà láàrin wa, ìwọ ọba Juda?
Coronavirus: Ọ̀rá ni àwọn dókítà fi ń dáàbò bo ara wọn nílẹ̀ẹ Gẹ̀ẹ́sì
Covid19 Benefit: Àsìkò Coronavirus yìí jẹ́ kí n di télọ̀ tó mọṣẹ́ gidi
Wo ìdí tí àwọn obìnrin kan fi n yọ ilé ọmọ wọn kúrò Egypt dá akọ́nimọ̀ọ́gbá Aguirre dúró lẹ̀yìn ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ Òsìsẹ́ Custom tó dédé sọ ara rẹ̀ di Ọ̀gá Àgbà CG ní àrùn ọpọlọ - Attah Amuneke fipò sílẹ̀ gẹ́gẹ́ bí akọ́nimọ̀ọ́gbá Tanzania O ni asiko ti to ki gbogbo ori ade ati eekan ninu iran Yoruba dide si iwa ipa yii.
Mo fi owo ọhun san owo itju ọmọ mi ọkunrin.
Jìnádù bínú nítorí pé ó sọ pé Ògúndélé sin òun ní owó ní àárí àwùjọ.
Ó gbé egungun ìhà mẹta há ẹnu, ó wa eyín mọ́ ọn.
Aare pe ipe yii nilu Abuja lasiko to n se ipade pelu awon olori egbe oselu All Progressives Congress, APC, ti won n tuko Naijiria lowolowo.
'Àwa ọmọ Nàìjíríà tó farapa fẹ́ wálé láti Lebanon, ìjọba kó wa pamọ́' Ọlọ́run nìkan ló mọ bí ìrìnàjò ìfẹ́ ẹ̀dá á ṣe rí láyé, ọ̀dọ́ Aláàfin ní orí gbémí yà sí, ó sì tẹ́milọ́rùn- Olorì Aanu Èèyàn 334 ló gbàwòsàn lọ́wọ́ Covid-19 l'Ọjọru, 453 míì tún lùgbàdì rẹ̀- NCDC Wọ́n dájọ́ ikú nípa sísọ̀kò pa ẹni ọdún 61 ní Kano Ooni ni eleyii fihan pe awọn ọdọ lorilẹede Naijiria fẹran afẹfẹyẹyẹ ati ohun ti ko ni bun iyi kun iṣẹ ọwọ wọn.
Tẹ awọn numba ti wọn ti kọkọ fi ranṣẹ si ọ.
Oladapo Adu: Nàíjíríà já mi kulẹ̀ torí wọn kò wá gbé mi
Ní àkókò tí a bá ń sọ fún eniyan pé: má ṣe èyí, má ṣe tọ̀hún, kì í dùn mọ́ ẹni tí à ń tọ́.
Gomina Zulum ṣalaye yii lasiko ti aarẹ ile aṣofin agba lorilẹede Naijiria, Sẹnetọ Ahmed Lawal ko iks ti aarẹ ran si ilu Maiduguri sodi wa si ọfiisi rẹ lati daro lori iku awọn eeyan ti wọn pa naa.
Oríṣun àwòrán, Jaiye Kuti Wo àwọn akọrin Nàìjíríà tó fakọyọ ní àmì ẹ̀yẹ AFRIMA Davido, Fani Kayode, Kemi Olunloyo, sọ̀rọ̀ lórí ẹ̀sùn jìbìtì Allen Onyema Fún ìgbà kẹ́ta láàrín oṣù mẹ́ta, àrá tún sán pa àwọn màlúù Fúlàní.
Olè gbé òrùka ìgbéyàwó mì ní Eko Ọlọ́wọ́ idán Houdini kò yè é o, ó bómi lọ!
wahala to waye lopin eto naa wa laaarin awọn igun ẹgbẹ meji kan ti wọn wa nibi eto naa."
Judasi, ẹni tí ó fi í fún àwọn ọ̀tá, mọ ibẹ̀, nítorí ìgbà pupọ ni Jesu ti máa ń lọ sibẹ pẹlu àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀.
UEFA Champions League: Ó di gbéré!
Aare wa tun gbosuba fun Oshimole  fun  eto  idagbasoke lori eto ijọba tiwa-n-tiwa lorile
pẹlu ìdámẹ́wàá ìyẹ̀fun òṣùnwọ̀n efa tí a fi idamẹrin òṣùnwọ̀n hini òróró tí a gún pọ̀.
Ipo Karun: Owona lori awọn osisẹ Owona lori awọn osisẹ ijọba ipinlẹ Ọyọ lo ko ipo karun ninu eto isuna 2020, ti adinku ida ọgọrun si ti wọ iye owo ti awọn osisẹ n gbe lọ nipinlẹ Ọyọ Makinde ni ọjọ kẹẹdọgbọn osoosu ni awọn osisẹ n gba owo osu bayii bẹrẹ lati osu kẹfa ọdun 2019, ti wọn si tun ti san lara obitibiti owo ajẹmọnu awọn osisẹfẹinti to wa nilẹ Owoya fun ilegbe ti wọn maa n fun awọn osisẹ ijọba, to jẹ miliọnu meji naira tẹlẹ lo ti di miliọnu mẹta naira bayii Owoya fun ọkọ ayọkẹlẹ, to jẹ ẹgbẹrun lọna ẹẹdẹgbẹta naira tẹlẹ, lo ti di ẹgbẹrun lọna ẹẹdẹgbẹrin naira Ijọba ti gunle ayẹwo orukọ awọn osisẹ ipinlẹ Ọyọ, ti yoo si gbe wọn sori ẹrọ ayarabiasa fun akọsilẹ titi laelae.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Awọn eniyan n ho fun ayọ nigba ti wọn ba kede poopu tuntun Lẹyin eto idibo, wọn yoo kọ awọn esi ibo sinu iwe kan, wọn yoo si gbe e le poopu tuntun lọwọ.
Yellow Fever in Nigeria: Àrún ibà pónjú ti pa ènìyàn 172 ni Nàìjíríà
Lẹ́yìn ìpàdé òní l‘Abuja, ṣé ASUU yóò yanṣẹ́ lódì àbí bẹ́ẹ̀kọ́?
Ọrọ naa bi ọpọ eeyan ninu to fi mo ajọ to nse akoso ẹka idajọ to ni ki adajọ to da ẹjo naa lo rọọkun nile fun ọdun kan lori idajọ to da.
"Ilé aṣọ̀fin Nàìjíríà ń gbèrò ẹ̀wọ̀n f'áwọn olùkọ̀ tó bá dẹnu ìfẹ́ kọ akẹ́kọ̀bìnrin Ìṣòro Nàíjíríà kọjá kí Bobrisky àtàwọn ẹlẹgbẹ́ rẹ̀ dá ní ilé ìgbọ̀nsẹ̀ lọ́tọ̀"" Fayẹmi fi ipinlẹ Ekiti rẹ ṣe apẹrẹ pe kini sẹnetọ mẹta n ṣe lati Ekiti kekere yẹn ki ato sọ awọn ipinlẹ ti ko tun tobi to Ekiti."
Iwọde naa ti ẹgbẹ Osun Concerned Citizens ṣe agbatẹru rẹ waye ni ilu Oṣogbo.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ìtàn ayé Ọba Seriki Abass ti Badagry, tó ní aya 128, ọmọ 144 Ilé ẹjọ́ yá lórí òfin CAMA tó fẹ́ gba àkóso ilé ìjọsìn, tẹ ẹ̀tọ́ aráàlú mọ́lẹ̀ - SERAP Wo bí o ṣe le fi orúkọ sílẹ̀ fún ìgbani ṣíṣẹ́ ológun Nàìjíríà tó bẹ̀rẹ̀ Ọmọdé 5 àti àgbà 40 bómi òkun lọ, 37 mórí bọ́ lásìkò tí ẹ́ńgínì ọkọ̀ ojú omi gbiná Kò sí ọ̀nà láti jáde tàbí wọlé sí Mali, ikọ̀ ológun ọlọ́tẹ̀ kéde ìṣédeWo ibùdó arẹwà tí ọ̀pọ̀ èrò ń ya lọ ní Abuja Obìnrin kan dèrò ilé ẹjọ́ lórí ẹ̀sùn pé ó fi ọ̀bẹ rẹ́ ọmọ rẹ̀ lọ́rùn Makinde ti sọ̀rọ̀ lẹ́yìn tí asekúpani Akinyele sálo mọ́ àwọn ọlọ́pàá lọ́wọ́ ní àhámọ́ Olólùfẹ́ mi ṣèèsì fi ọkọ́ gbá mi sí gọ́tà, mo rò pé ọlọ́jọ́ dé ni - Iya Osogbo Awọn eeyan kan to ba BBC sọrọ nileesẹ aarẹ amọ ti wọn ko fẹ darukọ wọn ni ibatan aarẹ naa rinrinajo lọ silu oyinbo lootọ, amọ kii se oun nikan lo lọ.
Ṣaaju ni Shodipe ti kọkọ sa mọ awọn ọlọpaa naa lọwọ lẹyin ti ọwọ tẹ ẹ́ lori ẹsun pe o lọwọ ninu ọpọ ẹmi to sọnu lagbegbe Akinyele, ni ilu Ibadan.
NCP, FRESH, PDP, APC ,SDP ati bbl.
Nígbà tí ó bá sọ̀rọ̀,ojú ọ̀run yóo kún fún alagbalúgbú omi,ó sì ń mú ìkùukùu gòkè láti òpin ilẹ̀ ayé.
"'Coro' wà 'Coro' ò sí o, èmi á lọ́ sókè òkún bí mo bá ríṣẹ́ - dókítà Ègún ọ̀dá owó yóò jà yín, tẹ́ ẹ̀ bá san ìdá mẹ́wàá - Oyedepo Ohun tí o kò mọ̀ nípa Ebila ""One Million Boys"" àti Ekugbemi, olórí ẹgbẹ́ òkùnkùn méjì tó da ìlú Ibadan rú Wo àwọn olorì àgbà mẹ́rin tí Aláàfin ń wárí fún Jonathan: Buhari ní ìwúrí ńlá nìwà ìrẹ̀lẹ̀ Goodluck Jonathan jẹ́ fún ọ̀pọ̀ èèyàn ní Nàìjíríà Oríṣun àwòrán, Facebook/Femi Adesina Aarẹ Muhammadu Buhari ti ṣapejuwe aarẹ ana, Goodluck Jonathan gẹgẹ bi olori to jẹ olufọkansin bi Ọgbẹni Jonathan ṣe pe ẹni ọdun mejilelọgọta l'Ọjọru."
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Baby abandoned on dunmpsite: Mo ti bímọ mẹ́rin tẹ́lẹ̀ fún bàbá méjì nínú òṣí- Dupe Ogbomos Akinsemola ni titi di asiko yii, ko si ẹni to le e sọ pato ohun to ṣẹlẹ laarin awọn ajinigbe naa ati awọn ti wọn lọ san owo naa.
Ìjàpá ni ọ̀rẹ òhun kò fẹ́ ki ẹni kan mọ àṣiri yi.
Kí olukuluku pa ọ̀nà burúkú ati ìwà ipá tí ó wà lọ́wọ́ rẹ̀ tì.
remain a source of strength for the development of the country.
Lati fi ero awọn eniyan han nigba kan, onimọ ilera ara Netherlands, Giles Everard ni igbagbọ pe taba lilo lagbara de ibi pé ko ni jẹ ki awọn dokita ri iṣẹ ṣe.
Ó kéré tan èniyàn tó lé ni ọgọ́fa ló wà nínu igbìmọ̀ ìpolongo náà, tí mẹ́rìndínígbà si jẹ́ àwọn oṣere tíátà.
Pupọ ninu awọn ojugba rẹ ninu iṣẹ tiata Yoruba lo n kii ni mẹsan an mẹwaa lọjọ to n ṣe ayẹyẹ ọjọ ibi ọhun, koda ọgbẹni kan fi orin aladun kan sọri rẹ.
Lẹ́yìn náà OLUWA dáhùn pé, “Mo ti rí ìpọ́njú àwọn eniyan mi tí wọ́n wà ní Ijipti, mo sì ti gbọ́ igbe wọn, nítorí ìnilára àwọn tí ń kó wọn ṣiṣẹ́, mo mọ irú ìyà tí wọn ń jẹ, 
Wọn gbagbọ pe ọmọ ijọ to ba tako ofin to de oogun oloro ni orilẹ-ede rẹ, ṣe e si iparun ara rẹ.
Àkọlé àwòrán, Papa iṣere Akwa Ibom wa lara awọn eleyi to gbaaye julọ ni Naijiria Bakan naa ni ijọba sọ pe ileeṣẹ Julius Berger to n mojuto papa iṣere naa ti lọ fun isinmi opin ọdun, ti wọn ko si nile ṣi i titi di ọjọ keje, oṣu Kinni, ti wọn ba pada bẹrẹ iṣẹ.
Ó lẹ́tù lójú lọpọlọpọ; èso inú rẹ̀ nìwọ̀nyí.
Nítorí pé ẹnikẹ́ni tí kò bá ní Ẹ̀mí Kristi ninu rẹ̀, kì í ṣe ti Kristi.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Boxer Great Danes: O jẹ aja to tobi to si ma n jẹ ibẹru fun awọn eniyan, ti wọn ko ba kọ aja naa daadaa, o le se ipalara fun wọn.
Awọn asofin naa ni bi awọn ṣe yara si abadofin naa fihan gbangba wi pe awọn ṣetan lati rẹyin iwa ọdaran ati iṣekupani to n waye ni agbeegbe naa.
“Igbimo yii ti setan lati bowolu iwe isuna eto idibo odun 2019, ti iye re je bilionu mẹ́tàlélógóje le bilionu meta owo Naira, ti owo isuna naa yoo si jeyo kara eto isuna odun 2018 gege bi aare se so fun ile-ogbimo asofin.
O ni aare Muhammadu Buhari ti n
Ó bi mí pé kí ni mo rí.
Mo gbe iwọ Rachel niyawo Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ọgbẹni Thomas to jẹ baba Meghan Markle ko lee farahan nibi igbeyawo naa nitori ailera ara rẹ Nigba ti asiko ati fi aya fun ọkọ ba to, ma ṣe foya nigba ti o ba gbọ, 'mo gbe iwọ Rachel niyawo' nitori Meghan ni ọpọ mọ orukọ iyawo si.
“Ajíṣe bí Ọ̀yọ́ làá rí o….
Ṣugbọn iya Risikat naa sọ pe niṣe ni ọkọ pa a ti pẹlu awọn ọmọ ti ko si bikita nipa wọn mọ.
Ní ọdún yìí gan-an ni o óo sì kú, nítorí pé o ti sọ ọ̀rọ̀ ọ̀tẹ̀ sí OLUWA.
Gbogbo àwọn ọmọ Israẹli: àwọn alufaa, àwọn ẹ̀yà Lefi ati àwọn tí wọ́n ti oko ẹrú pada dé bá fi tayọ̀tayọ̀ ṣe ayẹyẹ ìyàsímímọ́ tẹmpili náà.
Àti pé níṣe lòún fi ìgbésẹ̀ nàá pawó wọlé fún orílẹ̀èdè Nàìjíríà.
Nípa ṣíṣe bẹ́ẹ̀, ó ṣìnà sínú igbó, nítorí orò ti ń ké kì í ṣe ojú lásán, àwọn iwin ni wọn mú orò jáde kí a má sa fà á gùn lọ títí ilẹ̀ ṣú u sínú igbó.
Ijọba ipinlẹ naa sọ lẹyin iṣẹlẹ naa pe, lara ibi ti wọn kọlu jẹ ti ajọ NAFDAC, nibi ti wọn n ko awọn oogun to ti bajẹ pamọ si.
Man City fìbínú gbèsan lára Tottenham 20 Ìgbé 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images B'adiẹ dami mloogun nu, maa fọ lẹyin ni Manchester City fi ṣe fun ẹgbẹ agbabọọlu Tottenham nigba ti gbẹsan bi wọn ṣe na wọn kuro ninu idije UEFA Champions League.
, o si tun lee se akoba fun ala ati oorun rẹ.
Wọn a maa fi ẹ̀pa lílọ àti ata dindin, díẹ̀díẹ̀ yóò maa yọ yoo si di omí si inú abọ.
Ẹsun tijọba fi kan wọn da lori gbigbe alaga ile ẹjọ ton se'dajọ iwa ibajẹ laarin awọn osisẹ ati awọn oselu (CCT), Danladi Umar, lori ẹsun iwa ibajẹ ni orukọ ijọba.
Nítorí àwọn kan ti yọ́ wọ inú ìjọ, àwọn tí Ìwé Mímọ́ ti sọ nípa wọn lọ́jọ́ tó ti pẹ́ pé ìdájọ́ ń bọ̀ sórí wọn.
Oríṣun àwòrán, @MBuhari/Twitter Àkọlé àwòrán, Buhari sọ pe ko si aaye fun iwadii arumọjẹ latọdọ awọn ọlọpaa lori ija ẹsin Kaduna Buhari sọ pe ipaniyan ko bojumu rara ni Naijiria, ati pe ko si aaye fun iwadii arumọjẹ latọdọ awọn ọlọpaa lori wahala naa.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Baruwa Gas Explosion: Àwọn tó forí sọta ìjàmbá iná ń bẹ ìjọba láti dìde ìrànwọ́ Sonko ni awọn eeyan to kundun kiko owo ilu jẹ nilu Nairobi ti oun da lọwọ kọ nidi iwa ajẹbanu lo n ba oun ja lati ri ẹyin oun.
Oríṣun àwòrán, PA Àkọlé àwòrán, Aàrẹ Donald Trump àti Melania aya rẹ̀ jẹ oúnjẹ ọ̀sán pẹ̀lù Obabìnrin Elizabeth ni Buckingham Palace lọjọ kinni abẹwo naa.
Oríṣun àwòrán, Alaafin Oba Lamidi Adeyemi III Ẹni to ba si se akiyesi aworan naa finni-finni lati mọ ewo ninu awọn olori ni ko si ninu aworan naa, a ri pe Olori Badrat Olaitan Ajoke Adeyemi ni ko bawọn peju ya fọto lọjọ Ileya.
Kò sí ewé náà nínú igbó tí ọkùnrin yìí kò mọ̀ bẹ́ẹ̀ ni kò sí egbòogi tí ó ṣe ìpamọ́ fún un.
" Nigba ti awọn meji naa subu lulẹ.
EndSars in Portharcourt: Ọjọ́ méjì sẹ́yìn ni aya awakọ̀ Márúwá tí ọlọ́pàá pa bímọ tuntun
O ṣalaye wi pe aburu ti eleyi le fa ni wipe anfaani to yẹ ji ara ilu jẹ lọdọ ẹgbẹ to wa ni ijọba yoo di oun igbagbe.
Pẹlu bi eto idibo gbogboogbo ọdun 2019 ṣe n bọ lọna ni Naijiria, ṣe kii ṣe pe asiko tun ti to fun awọn janduku oloṣelu lati tun ri iṣẹ sẹ?
Tamari bá ku eérú sí orí, ó fa aṣọ rẹ̀ ya, ó káwọ́ lórí, ó sì bẹ̀rẹ̀ sí sọkún bí ó ti ń lọ.
Ṣugbọn àwọn irúgbìn mìíràn bọ́ sórí ilẹ̀ rere, wọ́n sì ń so èso, àwọn mìíràn ń so ọgọọgọrun-un, àwọn mìíràn ọgọọgọta, àwọn mìíràn, ọgbọọgbọn.
Ní ọjọ́ kejila ni Ahira ọmọ Enani, olórí àwọn ẹ̀yà Nafutali, mú ọrẹ tirẹ̀ wá.
Ko to jade laye, Sheik Orunsolu ni aarẹ fun gbogbo awọn imaamu ati aafa ni ipinlẹ Ogun.
Wọn ti ni ayẹyẹ ibura fun ni naa ko pọ pupọ lọtẹ yii ni Abuja.
 wọ ́ n máa ń ṣe ọdún egúngún , Ṣàngó , Ògún , Ọrẹ ̀ àti bẹ ́ ẹ ̀ bẹ ́ ẹ ̀ lọ .
Ó ṣe ohun tí ó dára lójú OLUWA, nítorí pé ó tẹ̀lé àpẹẹrẹ Dafidi, baba ńlá rẹ̀.
Ebedimeleki jáde ní ààfin, ó lọ bá ọba ó sì wí fún un pé, 
Kò sí ẹni rere kan àfi Ọlọrun nìkan ṣoṣo.
Eyí lo fàá ti BBC Yorùbá ṣe n ṣe àkójọ pọ̀ àwọn ọmọ ilé ìgbìmọ̀ Aṣòfin tó ti ń sùn lásìkò ìjòkó ilé.
Nígbà tí ó di ọjọ́ Àjọ̀dún Àìwúkàrà, ní ọjọ́ tí wọ́n níláti pa ẹran àsè Ìrékọjá, 
bi o se ran oun lọwọ ninu eto iselu ati ipa ribi-ribi ti o ko ninu igbesi aye rẹ.
Ogundoyin, eni odun mokanlelogbon lo n soju ekun idibo
O ni eyi lo fa agbekale.
Èyí tí a wò jùlọ 5:03 Fídíò, Omolola Arohunmolase Welder: Mo ti fí iṣẹ́ 'Welder' gbayì láwùjọ, tó mo fi tọ́ ọmọ yanjú, Duration 5,039 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 5:39 Fídíò, Akomolede ati Asa lori BBC: Olùkọ́ Kikelomo Ogunboye tan ìmọ́lẹ̀ sí ìwà olè ọ̀gá ọlọ́pàá Audu gẹ́gẹ́ bí àwòkọ́ṣe àsìkò yìí, Duration 5,398 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 4:11 Fídíò, Oba Adeyeye Ogunwusi: Ojú mi ti rí lọ́pọ̀ lọpọ̀, ọ̀pọ̀ èèyàn ni kò tilẹ̀ gbàgbọ́ pé mo lè jọba- Ooni, Duration 4,117 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 4:43 Fídíò, Promise Akinlade: ọmọ ọdún mọ́kànlá tó ń fi ìlù dárà bíi àgbàlagbà sọ̀rọ̀ nípa tálẹ́ǹtì rẹ̀, Duration 4,437 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 0:59 Gbọ́, Ìsẹ̀lẹ̀ jákèjádò orílẹ̀èdè àgbáyé láàárín ìṣẹ́jú kan, Duration 0,59wákàtí 5 sẹ́yìn 7:03 Fídíò, Olumuyiwa Bolade Adedeji Military Bruitality: Bí arákùnrin onípèníjà ara tí sọ́jà lù ṣe dé, Duration 7,035 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 4:45 Fídíò, Yoruba Films: Ẹ̀ẹ́ bẹ̀ mi kúrò láyé ni, mi ò lè kú - Fadeyi Oloro, Duration 4,4526 Èrèlè 2020 2:48 Fídíò, Esther Ajayi: Èmi náà ti borí ìṣòro rí ló ń mu mi ṣojú àánú, Duration 2,481 Ògún 2019 6:08 Fídíò, Adebola Ademilua: Àìrísẹ́ ṣè lẹ́yìn ìwé kíkà ló sọ mi dí ìyá onírú, mo dúpẹ́ tèmi, Duration 6,0827 Bélú 2020 2:36 Fídíò, Sotitobire: Ìdájọ́ òdòdò ló fẹsẹ̀ múlẹ̀ lórí ọ̀rọ̀ Pásítọ̀ Sotitobire - Agbẹjọ́rò fún ìjọba, Duration 2,367 Ọ̀wàrà 2020 BBC News, Yorùbá Ìdí tí ẹ fi le è nígbàagbọ́ nínú ìròyìn BBC Ìlànà Lílò Nípa BBC Òfin Àṣírí Cookies Kàn sí.
Alẹ́ ọjọ́ náà ni kí wọ́n sun ẹran náà, kí wọ́n sì jẹ ẹ́ pẹlu burẹdi tí kò ní ìwúkàrà ninu, ati ewébẹ̀ tí ó korò bí ewúro.
Awọn orilẹede ti ọrọ kan ni China, Iran, South Korea, Germany, Italy, Amẹrika, Ilẹ Gẹẹsi, Switzerland, Norway, Netherlands, Spain, France ati Japan.
Ẹwẹ, Samuel Aluko to jẹ aarẹ ẹgbẹ awọn dokita ọhun ni ẹka ile iwosan ijọba apapọ, FMC to wa ni Owo, ni ipinlẹ Ondo ni tirẹ ṣalaye fun BBC pe ijọba ti sun awọn dokita kan ogiri lo jẹ ki iyanṣẹlodi naa waye.
ni esun ti won fi kan oun, ni ọwọ oselu ninu.
Idi iṣẹ ẹni ni a ti n mọni lọlẹ ni awọn agba maa n wi nilẹ Yoruba.
Oun kan naa lo pari ileeṣẹ to n ṣe irin, Delta Steel Complex lọdun 1982.
Ọba bá pe Abiṣai, ó ní, “Ìyọnu tí Ṣeba yóo kó bá wa yóo ju ti Absalomu lọ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Promise Akinlade: ọmọ ọdún mọ́kànlá tó ń fi ìlù dárà bíi àgbàlagbà sọ̀rọ̀ nípa tálẹ́ǹtì rẹ O tun fi kun pe isọwọ bi ẹjẹ ṣe n tu gba inu kaṣan lasiko ibalopọ ti wọn n pe ni ''adrenaline rush'' le mu inira wa lasiko ibalopọ.
O ni eyi ri bẹẹ tori igba ikẹyin la wa yii, tii se igba ewu ti ole, ipaniyan, ogun, ọtẹ ati iwa ika too gbilẹ pupọ gẹgẹ bi asọtẹlẹ ti wa nipa wọn ninu iwe mimọ.
Òṣèré tíátà, Kemi Afolabi fi ohùn ìdúpẹ́ ránṣẹ́ láti Meccah fún àdúrà ọmọ Nàíjíríà Àwọn arẹwà obinrin Yollywood, tá ló mọ iṣẹ́ rẹ̀ jù?
funra wọn ni wọn n ṣaanu fawọn ara ilu.
Iwa nabi tu igbeyawo ọgbọn ọdun ka Ikọ̀ ẹlẹ́sìn Hàkíkà rèé, níbití wọn ti ń pààrọ̀ ìyàwó láàrín ara wọn Ọ̀rẹ́kùnrin mi fún mi ní àárùn HIV, mo sì gbẹ̀san Ìpínlẹ̀ Ọ̀ṣun ń sàìsàn, òṣìṣẹ́ ọba ti pọ̀ jù - Oluwo Ìbéèrè àti ìdáhùn pẹ̀lú Seyi Awolowo ti BBNaija lórí BBC Yorùbá Wo diẹ lara akọle ati awọn aworan apanilẹrin to wa lori ayelujara: Lóòni ni ayẹyẹ ìgbéyàwó ààrẹ Buhari ni'lù Abuja ni eyi ti ero ti n de si Abuja: Oríṣun àwòrán, Ogundamisi Àkọlé àwòrán, Awọ asọ oni ni Pepper-Dem Green àti Wailers white Ní bayìí àwọn èèkan ilú, àwọn olóṣèlú àwọn ọmọ Naijiria jákejádo lo ti si nń gúnlẹ̀ sí ìlú Abuja.
Kò fi ohunkohun sílẹ̀ láìṣe, ninu gbogbo nǹkan tí OLUWA pa láṣẹ fún Mose.
O Fagunwa, Adebayo Faleti, Akinwumi Iṣọla, Lawuyi Ogunniran àti Oladejo Okediji ṣiṣẹ silẹ ki wọn to lọ3 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Assistant Commissioner of Police: Àwọn afurasí ṣá ìgbákejì kọmísọ́nà ọ̀gá ọlọ́pàá láàké dójú ikú2 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
85 millionu ni oun naa gba pe o se ipo keji.
Oríṣun àwòrán, Others Oludari agba fun ajọ NNPC wa n rọ awọn ọmọ Naijiria lati gbaradi fun inira osu mẹta, o kere tan, ki ọja agbaye to bọ lọwọ wahala yii, eyi ti yoo ni ipa ti kii se kekere lori ọrọ aje Naijiria.
Àkójọpọ ̀ èdè tí ó tó ọgọ ́ ta tí nǹkan bíi mílíọ ̀ nù márùn-dínlọ ́ gọ ́ fà ènìyàn ń sọ ni a ń pè ní  altaic ' ."
Nítorí náà ni wọ́n ṣe bẹ̀rẹ̀ sí pe ibẹ̀ ní Beraka títí di òní olónìí.
A fún un ní adé kan, ó bá jáde lọ bí aṣẹ́gun, ó ń ṣẹgun bí ó ti ń lọ.
Bẹni wọn lo òfin burúkú yi naa lati pa Aláwọ̀dúdú lẹhin isin ni aarin igboro lai ya Aláwọ̀dúdú ti wọn kó lẹ́rú lati ilẹ Yorùbá sọtọ.
Ṣugbọn, pupọ lara wọn ti kuro nileewosan bayii.
Kọmisọnna naa ni awọn ṣẹ awari awọn eniyan tuntun to lugbadi arun naa lẹyin ti wọn bẹrẹ si ni wa awọn to ti farakan obinrin kan ti ayẹwo fihan pe o ni aarun Coronavirus ni ileewosan.
Nígbà ti BBC Yoruba beere lórí ìdí tí àwọn alagbata míràn fí n ta jálá epo kan ní náírà márùndínláàdójé, nígbà tí ìjọba ni kí wọ́n máa tà á ni náírà mọ́kànlélọ́gọ́fà àbọ̀, Okonkwo sọ pé àsìkò péréte náà ló kù tí irú wọ́n kò fì ni lé ṣe bẹ́ẹ̀ mọ nítorí tí ará ìlú bá rí ibi ti epó ti dínwó, wọ́n kò ni lọ sí ibi ti ó ti wọ́n.
Ṣugbọn agbára irin yóo hàn lára rẹ̀, gẹ́gẹ́ bí o ti rí i tí irin dàpọ̀ mọ́ amọ̀.
Mwalimu sọ pe ọmọ ilẹ Tanzania kan to de lati orilẹede Belgium lọjọ karundinlogun Oṣu Kẹta ọdun yii lo ko arun naa wọle.
ati nipa eto idibo to n bo lona.
Ìkíní ni ààrẹ òní Barak Obama.
Ilé Aṣòfin Àgbà fòǹtẹ̀ lu N30,000 owó oṣù òṣìṣẹ́ni oṣu meji ṣẹyin.
INEC kede Fayemi Sáájú, ajọ eleto idibo ti kede Kayode Fayẹmi to jẹ oludije fun ipo gomina ni ẹgbẹ oṣelu APC gẹgẹ bi oludije to jawe olubori ninu idibo gomina ipinlẹ Ekiti.
Apo alubosa ti won ta ni egberun metala N13,000  tele, ti di egberun merinla N14, 000 bayii, nigba ti apo ewa ti egberun lona ogbon atabo N30,500 bakan naa ni apo iresi di egberun mejidinlogun atabo N18,500 lati egberun metala N13,000 tele riKilo Turkey kan ti di egberun kan o-le N1,350.
 O ni ọmọ Naijiria ni gbogbo wa, ti Naijiria ba si dara ju bo ṣe wa yii lọ, gbogbo wa la o ni ibi ti a le pe nile, ti a si ma a gbe ninu irọrun.
Lójú kan náà ó ṣubú lulẹ̀ ọkàn rẹ̀ sì rẹ̀wẹ̀sì tó bẹ́ẹ̀ tí ó kú gbée.
ati pé ẹnikẹ́ni tí kò bá sin OLUWA Ọlọrun Israẹli, ìbáà ṣe àgbà tabi ọmọde, ọkunrin tabi obinrin, pípa ni àwọn yóo pa á.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Wo ohun márùn-ún tó ń fa ìjàmbá iná nínú ilé Iléẹjọ́ òṣìṣẹ́ tún dáwọ́ ìgbẹ́jọ́ Onnoghen dúró lọ́dọ̀ CCT Iléẹjọ́ òṣìṣẹ́ tún dáwọ́ ìgbẹ́jọ́ Onnoghen dúró lọ́dọ̀ CCT Ọbasanjọ: Ó yẹ kí Amina Zakari kọ̀wé fipò sílẹ̀ Gbàjarè!
Amọ sa, igbesẹ titi ibudo itaja Palm Mall ti n se akoba nla fun awọn ọmọ Naijiria to ni sọọbu sinu ibudo itaja naa nitori kii se Shoprite nikan lo n ta ọja nibẹ.
Super touch: Roller Blader ni mí láti ọdún mẹ́jọ sẹ́yìn
O óo sọ ní ọjọ́ náà pé,“N óo fi ọpẹ́ fún OLUWA,nítorí pé bí ó tilẹ̀ bínú sí mi,inú rẹ̀ ti rọ̀, ó sì tù mí ninu.
O tun fi da wọn loju pe didun lọsan a so fun awọn onile ise Aladani nipinlẹ Eko laipẹ Ọmọ Nàìjíríà di agbábọ́ọ̀lù Áfíríkà tí iye owó tí wọ́n rà à ga jù nínú ìtàn!
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Minimum Wage: Buhari gbọdọ̀ fi àbá owó osù tuntun sọwọ́ sáwọn asòfin 6 Bélú 2018 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 7 Bélú 2018 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Awọn gomina lawọn o le san ọgbọn ẹgbẹrun Naira f'oṣiṣẹ Sẹnetọ Rafiu Ibrahim, to n ṣoju ẹkun idibo Guusu ipinlẹ Kwara salaye pe, ileeṣẹ aarẹ gbọdọ kọkọ fi aba ofin ranṣẹ sile aṣofin fun ayẹwo.
” Olùṣọ́ náà wí pé, “Oníṣẹ́ náà dé ọ̀dọ̀ wọn ṣugbọn kò pada wá.
Wolii ijọ Sinagọgu naa si ti sọ asọtẹlẹ to fara pẹ laasigbo to tidi iwọde EndSARS yọ, amọ o kan jẹ pe ọjọ ti pẹ, to ti sọ asọtẹlẹ naa.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Lagos Beggars: Bí wọ́n ṣe jí ọmọ yìí gbé láti máa fi ṣiṣẹ́ bárà l'Eko 22 Èbibi 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 23 Èbibi 2019 Àkọlé àwòrán, Ohun kan ti ẹbi rẹ mọ ni pe wọn lo gun kẹkẹ lọ sita.
Coronavirus: Kínni ìtàkùn ayélujára 5G nííṣe gan na pẹ̀lú ààrùn coronavirus?
" Amọsa, ileesẹ aarẹ orilẹede Naijiria ni ariwo ati atako lati ọdọ awọn ẹgbẹ osisẹ, ẹka idokoowo lo sokunfa bii aarẹ se jawọ ninu rẹ.
Okoye ṣalaye awọn igbesẹ ti ajọ INEC ti la kalẹ nipa eto idibo naa.
Àgùnbánirọ̀ akọ̀ròyìn Channels náà ti dágbére fáyé látààrí ìkọlù Shiite l'Abuja Mo mọ̀ọ́mọ̀ dá €37,000 ti mo rí he padà ni -Ọmọ ogun Bashir Àwọn kan fẹ́ da Naijiria rú torí ààbò tó mẹ́hẹ - Osinbajo gbarata Iléeṣẹ́ ọlọ́pàá Èkó ní àwọn kò mọ ohunkohun nípa ìwadìí ẹjọ́ Dakolo àti pásítọ̀ COZA mọ́ Agbẹnusọ fun aarẹ Buhari gboriyin fawọn agbofinro Naijiria pe wọn gbiyanju lasiko iwọde awọn ijọ Shiite to wyae ni Abuja.
JÀGÙDÀ; Èyí ni eni tí o máa n gbé ohun tí ó bá rí tán làìnáání bí yóò ti dún olóhun sí.
Ìyá dú ọmọ rẹ̀, o yíi láta, ó sì tún jòkó jẹ ẹ́ Egboogi yii si lo ti se nilana ti oloyinbo sinu apo kan, to fi sọ orukọ ara rẹ.
Èyí ẹ̀karùn-ún ni ó fi àìka nǹkan sí bá ayé ara rrẹ̀ jẹ́.
 Ṣe wọn wa ni ọgba ẹwọn to le gba gbogbo wa bi wn ba fẹ maa ko wa?"
Ọ̀jọ̀gbọ́n náà, nígba tó ń fèsì sí fọ́rán ìdínilẹ́kọ̀ọ́ kan tó ń sọ àwọn àǹfàní tó wà lára òróró àgbọn lórí Youtube.
awon ipinle mẹ́fà ti eto idibo yoo tun waye
BBC ṣe akíyèsí nínú ọ̀rọ̀ àwọn tí ó ń lo ojú òpó ìkànsíraẹni ní Naijiria àti Keyan pé ọ̀pọ̀lọ́pọ̀ ni kò mọ̀ bí wọ́n ṣe máa ń dá ìròyìn òfégè mọ̀.
Basket mouth to ṣapejuwe oloogbe naa gẹgẹ bii 'ẹjẹ'rẹ ati 'ọrẹ'rẹ sọrọ nipa awọn asiko manigbagbe ti wọn jumọ ni.
Ẹ ní ìfẹ́ láàrin ara yín bíi mọ̀lẹ́bí.
Bí ẹnikẹ́ni bá fìyà jẹ wọ́n, tí wọ́n bá ké pè mí, dájúdájú n óo gbọ́ igbe wọn; 
 Isakoso yi ti bere ise akanse ti o to metalelaadota ti o n lo lowo, eyi si ti pese ise fun awon odo ati awon ti ko ni ise lowo.
Àwọn òfin mẹ́wàá yìí ni OLUWA sọ fun yín lórí òkè láti ààrin iná ní ọjọ́ tí ẹ péjọ sí ẹsẹ̀ òkè náà.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Igbẹjọ to kọkọ waye saaju si ti kede pe igbeyawo nilana ẹsin Islam wa laarin awọn mejeeji, to si ba ofin igbeyawo ilẹ Gẹẹsi mu.
Ẹkẹwaa mú Ṣimei, òun ati àwọn ọmọ rẹ̀ ọkunrin, ati àwọn arakunrin rẹ̀ jẹ́ mejila.
Seti bí ọmọkunrin kan, ó sọ ọ́ ní Enọṣi.
Koda o kede pe oun yoo fun awọn eeyan lẹbun owo ni iranti rẹ.
Ǹjẹ́ ẹ mọ ohun tí igbákejì ààrẹ Yemi Osinbajo sọ nílé bàbá Fasoranti EFCC ń wádìí iléeṣẹ́ 'Bola Tinubu,' Alpha Beta Consulting Ltd' Aago Nàìjíríà ti kún àkúnwọ́sílẹ̀ - Tunde Bakare Àṣìta ìbọn pa èèyàn kan lásìkò tí SARS ń kojú adigunjalè l'Eko A ó gbé'gbésẹ̀ lẹ́yìn ìwádìí fídíò tí Dino ti ń náwó lójú agbo- Ọlọ́pàá Aarẹ ana orilẹ-ede Naijiria naa ni ọjọ ti pẹ to ti yẹ ki aarẹ yi ọwọ pada lori eto igbogun ti iwa ọdaran niwọn igba ti o jẹ wi pe ajagun fẹyinti ni ko to darapọ mo oṣelu.
INEC fidi rẹ mulẹ pe awọn ti fi iṣẹlẹ naa awọn agbofinro leti, bẹẹ iwadii si n lọ lori rẹ Ṣaaju akoko yii, ọga INEC nipinlẹ Benue, Ọmọwe Nentawe Yilwatda jẹri si ikọlu naa to ṣẹlẹ loju ọna ilu Gboko si Makurdi.
"O ni ""owo ni awọn eeyan maa n na lati lọ dibo - bii awọn ti yoo rinrin ajo tẹbi tara wọn lọ si ilu mi i lati dibo, to fi mọ awọn to ti ile iṣẹ ati ile itaja wọn pa, eyi to tumọ si pe o yẹ ki ijọba tun sọ pe gba, ẹ ma binu""."
Adio Atawẹwẹ: Orin Fuji ló gba iwé kíkà lọ́wọ́ mi
Oshiomole: irọ́ ni wọ́n ń pa,èmi ṣí ní Alága APC!
Loni ọjọ ẹti, ọjọ kejilelogun oṣu kẹta ọdun 2019 ni ile ẹjọ to n gbọ ẹjọ kotẹmilọrun to suyọ lori idibo sipo gomina ni ipinlẹ Ọṣun yoo gbe idajọ rẹ kalẹ lori ẹni gan an to bori idibo naa.
Ere bọọlu naa ko ri bi ọpọ ti ro pe yoo rii, ko da Roberto Firmino ni lati jade fun Divock Origi.
lee lo lati yanju ipenija rẹ.
Fídíò àkàndá ẹ̀dá tó di amòfin
Ẹ̀rẹ̀kẹ́ rẹ̀ dàbí ebè òdòdó olóòórùn dídùn,tí ń tú òórùn dídùn jáde.
Bẹẹ ni ọrọ ri bayii fun ọmọdekunrin, ọmọ ọdun mẹrin Oreoluwa Lawal-Babalola, to n sọ fun iya rẹ pe, ko 'calm down' lasiko to fẹ na a.
Àwọn èèkàn òṣèré Nollywood nìyí pẹ̀lú àmì ohùn èdè Yorùbá Ojú Shagbada Erigga rèé lẹ́yìn tó pa ọ̀rẹ́bìnrin rẹ̀ l'Akinyele ní Ibadan Ìjọba àpapọ̀ fẹ́ f'òfin dé irina ọkọ̀ akero jakejado Nàìjíríà Oluwo bẹ Ìjọba àpapọ̀ láti ṣe òfin tí yóò mú àdínkù ba ìwà ìfipá báni lòpọ Bakan naa ni awọn eeyan ati ajafẹtọ ọmọniyan sọ iriri wọn lori ifipabanilopọ ni eyi ti o yẹ ki gbogbo awujọ fọwọsowọpọ gbogun ti lasiko yii.
Nígbà tí ó yá, ó tún wọn ẹgbẹrun igbọnwọ (mita 450), mìíràn sí ìsàlẹ̀, odò náà jìn ju ohun tí mo lè là kọjá lọ, nítorí pé ó ti kún sí i, ó jìn tó ohun tí eniyan lè lúwẹ̀ẹ́ ninu rẹ̀.
Ó ti kẹ́kọ̀ọ́ rẹ̀ gboye bayii ninu imọ Medical Laboratory Science (Heamatology) ṣùgbọ́n ipele ikarun lo ṣi wa ti ifa yan an lati wa jẹ adele Ọba ilu rẹ.
Nígbà tí ó yá, Jehoṣafati kú, wọ́n sì sin ín sí ibojì àwọn ọba, ní ìlú Dafidi, baba ńlá rẹ̀.
“Mo fẹ́ kí ẹ mọ̀ dájúdájú pé ẹni tí ó bá gbọ́ ọ̀rọ̀ mi, tí ó bá gba ẹni tí ó rán mi níṣẹ́ gbọ́, olúwarẹ̀ ní ìyè ainipẹkun, kò ní wá sí ìdájọ́, ṣugbọn ó ti ré ikú kọjá, ó sì ti bọ́ sinu ìyè.
'Ọmọ tó bá lanu gbàgà sọ̀rọ̀ sí àgbà, bàbá àti ìyá rẹ̀ ló ń bá wí' Mà á ṣiṣẹ́ bí i gómìnà tó ní èrò aráàlú lọ́kàn - Seyi Makinde Dapọ Abiọdun ree, ẹni tó dépò gómìnà ní àyájọ́ ọjọ́ ìbí rẹ̀ Oṣupa sọrọ lori ọna abayọ si ọjọ iwaju fuji ni Naijiria.
Ifẹsẹwọnsẹ naa koko bi oju ẹja bi awọn ikọ Naijiria ati Argentina ti n yi ara wọn sọtun sosi.
Eeyan 126 ló ní Covid-19 ní Nàìjíríà lọ́jọ́rú Ajọ to n gbogun ti ajakalẹ aarun lorilẹ-ede Naijiria, NCDC ti kede pe eeyan 126 miran ti kun iye awọn to ti ni aarun COVID-19 ni Naijiria.
Angẹli náà tún sọ fún mi pé, “Lọ kéde pé OLUWA àwọn ọmọ ogun ní, àwọn ìlú òun yóo tún kún fún ọrọ̀ lẹ́ẹ̀kan sí i, òun OLUWA yóo tu Sioni ninu, òun óo sì tún yan Jerusalẹmu ní àyànfẹ́ òun.
Agbẹjọro kọkọ pe fun ki wọn sun ẹjọ naa siwaju lonii lori oun to pe ni aridaju mẹrindinlogun ṣugbọn adajọ faake kọri to si fagile ipẹjọ rẹ.
Ẹru n ba ọpọ eeyan nipinlẹ Eko pe o ṣeeṣe ki iyanṣẹlodi awọn dokita ko pẹ eyi ti yoo ṣakoba fun akitiyan ijọba lati dẹkun itankalẹ coronavirus l'Eko.
Nígbà tí wọ́n gbọ́ ìró yìí, àwọn eniyan rọ́ wá.
Banki apapọ lorilẹede Naijiria, CBN ti sọ wi pe ko si owo to sọnu ni banki apapọ, lẹyin ti fọnran kan gbe e jade wi pe wọn ji ẹẹdẹgbẹta bilioọu Naira ni apo ijọba.
Ó ń tẹ́ ìfẹ́ àwọn tí ó bẹ̀rù rẹ̀ lọ́rùn;ó ń gbọ́ igbe wọn, ó sì ń gbà wọ́n.
Iyanrìn làwọn ẹbí olóògbé bàálù Ethiopia rí gbà dípò òkú Kàyééfì, oyún inú nínú ilé ìgbọ̀nsẹ ọkọ̀ òfurufú Ọdun to kọja ni wọn dibo yan Ọgbẹni AhmedAbiy Ahmed di olóòtú ìjọba Ethiopia, to si ti gbe igbesẹ lati fi opin si ija oṣelu.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Ohun ti agbọ ni pe awọn ẹgbẹ agbabọọẹu naa ni asiko kọ niyi lati jiroro boya ọgbọọjọ oṣu kẹfa ni ki wọn bẹrẹ tabi rara.
Odò Kiṣoni kó wọn lọ,odò Kiṣoni, tí ó kún àkúnya.
A bí Babatunde Omidina ( Baba Suwe)ni inú oṣù kẹjọ ọdun 1958 ni opopona Inabere to w ni Lagos Island sùgban ọmọ Ikorodu ni ìpíinlẹ̀ Eko ni.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ìgbín ní èmi àti ìyá mi máa ń he kiri, ká tó lee jẹun - Lizzy Anjọrin Ọkùnrin mẹrin wọ gàù 'torí ìgbéyàwó orí Facebook Adeleke ló ní ọmọ ẹgbẹ́ tó pọ̀jù l‘Ọṣun, nipò gómìnà ṣe tọ́ si ní 2022 - PDP Ọṣun ''Wàhálà Ikẹja ló sọ mí di oníṣẹ́ ọwọ́ àgbọn ní Badagry'' Abdusalam, nigba to n fesi, gboriyin fun gomina Makinde, to si ni ọgbọn ati imọ to n lo nigba to n sisẹ aladani yoo ran an lọwọ lati tukọ ipinlẹ naa de ibi aseye.
Àkọlé àwòrán, Financial magazine Forbes says Mohammed Dewji is worth $1.
Wọ́n tẹ̀lé ọ̀nà Balaamu ọmọ Beori, tí ó fẹ́ràn èrè aiṣododo.
Nibayii, ko tii si ẹni lee sọ ohun ti yoo ṣẹlẹ sawọn alaisan ti wọn wa labẹ itọju ni ileewosan naa ṣaaju iyanṣẹlodi ọhun.
Gẹgẹ bi a ti se akojọpọ itan igbe aye Samuel Ajayi Crowther lori itakun agbaye, ololufẹ oniruuru ede ni, to si kọ ẹkọ nipa ede to to mẹrin.
"Àwọn ọmọ FIBAN kò gbọdọ̀ lo orin Wasiu Ayinde mọ́ lẹ́yìn ìfìyàjẹní Murphy- FIBAN Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fọ́nrán ohùn, ""Wasiu Ayinde fi bàtà tẹ̀ mí lórí àti imú mọ́lẹ̀, ọmọ ẹ̀yìn rẹ̀ gbá mi létí"" Ẹgbẹ awọn oniroyin aladani, FIBAN ti kede pe ọmọ ẹgbẹ wọn kankan ko gbọdọ lo orin Wasiu Ayinde kankan mọ lori eto wọn."
Àjọ ọlọpàá ìpínlẹ̀ Ondo kò gbọ́ ǹkankan nípa ọ̀daràn tó ní ààrun Corornavirus Corornavirus: Àjọ ọlọpàá ìpínlẹ̀ Ondo kò gbọ́ ǹkankan nípa ọ̀daràn tó ní ààrun Corornavirus Oríṣun àwòrán, others Àkọlé àwòrán, Àjọ ọlọpàá ìpínlẹ̀ Ondo kò gbọ́ ǹkankan nípa ọ̀daràn tó ní ààrun Corornavirus Lẹ́yìn tí kọmísọ́nà ìlera ìpínlẹ̀ Ondo sọ fún BBC Yorùbaá pé awọn ẹlẹwọn atawọn oṣiṣẹ ọlọpaa ikọ kogberegbe SARS to muu ni wọn ti bẹrẹ si ni mojuto lati mọ boya wọn ti ti ara rẹ ko arun naa.
Àwọn mejeeji jọ tẹríba, wọ́n jọ doríkodò,wọn ò lè gba àwọn ẹrù wọn kalẹ̀.
Bi nnkan ti ṣe n lọ re e : Odion Ighalo lo gba goolu akọkọ wọle ni iṣẹju kọkandinlogun ifẹsẹwọnsẹ naa Bahoken da goolu kan pada fun Cameroon ni iṣẹju kọkanlelogoji idije naa.
Ṣugbọn to wa nibe ni pe awọn oludari ile ijọsin yi gbọdọ ri pe awọn eeyan tẹle ilana ijinasiraẹni ati ìmọtótó lasiko ijọsin ti won ko si gbọdọ jẹ kí ọrọ iwaasu wọn pẹ pupọ.
Ayẹyẹ iwuye naa to wa ni aafin Olubadan lọjọ Ẹti lo waye lẹyin ti gomina ipinlẹ Ọyọ, Onimọ ẹrọ Seyi Makinde fọwọsi igbega iyalode tuntun fun ilẹ Ibadan naa.
Tí a fiṣọwọ́ ní 12:51 9 Ọ̀pẹ̀ 202012:51 9 Ọ̀pẹ̀ 2020 Níbi tí ọ̀rọ̀ èsì ìbò ààrẹ orílẹ́èdè Ghana dé dúró nìyìí Ghana election update: Níbi tí ọ̀rọ̀ èsì ìbò ààrẹ ilẹ̀ Ghana dé dúró nìyìí Ghana ECCopyright: Ghana EC Esi ibo aarẹ ẹsun mẹsan an lawọn ọmọ orilẹede Ghana n reti bayii bayii lati mọ ẹni ti yoo jawe olubori ninu ibo ọjọ Aje.
won lo naa lati fi gbe  ẹri won lẹsẹ.
Èrò ọkàn ni ti eniyanṣugbọn OLUWA ló ni ìdáhùn.
Wo bó se ń lọ nínú ìdíje Russia 2018 Russia 2018: Àwọn wo ló ti gbá bọ́ọ̀lù sáwọ̀n?
Ọwọ́ ọlọ́pàá tẹ ẹ̀gbọ́n tó dáná sun àbúrò rẹ̀ toyúntoyún nílùú Eko ₦22.
Awon iko yii yoo lo si Washington ni orile-ede America lati lo fun awon olori ijoba labo ijiroro won pelu North Korea.
OLUWA, gbogbo ọba ayé ni yóo máa yìn ọ́,nítorí pé wọ́n ti gbọ́ ọ̀rọ̀ ẹnu rẹ.
Wọn yóo máa sá sókè sódò láti wá ọ̀rọ̀ Ọlọrun, ṣugbọn wọn kò ní rí i.
Ọjọ́ kẹfà ni ti àwọn ìbejì tí ọ̀kan jẹ́ ọkùnrin tí èkejì jẹ́ obìnrin.
Ìgbájú ìgbámú ni Senegal fi lé Nàìjíríà kùrò ní ìdíje ife àgbáyé FIFA U-20 Ibanuje d'orí agbà k'odò, Ruiz fi ẹ̀ṣẹ́ sọ Anthony Joshua di ọmọ ológo àná Liverpool da ata gúngún sójú Tottenham gba ife ẹ̀yẹ Champions League Beckham, àgbábọ́ọ́lù tẹ́lẹ̀ rèé tó ń sọ èdè Yorùbá Ọjọ Iṣẹgun ni Ọgbẹni Hearn ṣalaye loju opo Twitter rẹ awọn yoo kede ibi ti ija naa yoo ti waye laipẹ.
Ní ọjọ́ náà,àwọn eniyan óo kó àwọn ère fadaka wọn dànù,ati àwọn ère wúrà tí wọ́n fi ọwọ́ ara wọn ṣe, tí wọn tún ń bọ.
Fury ni ẹni ti ọwọ rẹ moke ju ninu ija naa, igba keji si ree ti wọn yoo pade lori papa, ṣugbọn ninu abala keje ija ọhun lo ti fọ Wilder lẹnu tan patapata, ti onitọun ko si lee ta putu.
Aare Muhammadu Buhari ti bu enu
Fi pákó ṣe pẹpẹ náà, kí o sì jẹ́ kí ó jin kòtò, bí mo ti fi hàn ọ́ ní orí òkè, bẹ́ẹ̀ gan-an ni kí o ṣe é.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Adájọ́ rán agbẹjọ́rò àgbà lọ sẹ́wọ̀n oṣù kan 30 Ìgbé 2018 Oríṣun àwòrán, JNCLAWFIRM Àkọlé àwòrán, Nwobike ní òótọ́ ni òun fi ìfìwéránṣẹ́ sí àwọn òṣìṣẹ́ náà Ilé ẹjọ́ kan ní Ìpínlẹ̀ Èkó ti rán agbẹjọ́rò àgbà kan Joseph Nwobike lọ s'ẹ́wọ̀n oṣù kan lorí ẹ̀sùn pé ó fẹ́ yí da ojú òfin bolẹ̀.
Mo ti ṣìnà bí aguntan tó sọnù;wá èmi, iranṣẹ rẹ, rí,nítorí pé n kò gbàgbé òfin rẹ.
Kí á fi kálàmú irin ati òjékọ ọ́ sórí àpáta, kí ó wà níbẹ̀ títí lae.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Amitabh Bachchan: Òṣèré India, Amitabh Bachchan tó lùgbàdì ààrùn Coronavirus ti móríbọ́ 12 Agẹmo 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 2 Ògún 2020 Oríṣun àwòrán, facebook/Amitabh Bachchan Gbajugbaja oṣere fiimu India, Amitabh Bachchan ni oun ti bọ lọwọ arun COVID-19 to da oun wolẹ.
Ẹranko à máa ṣe àìsàn wọn si ń gba ìtọjú láàrìn ara wọn pẹ̀lú.
Owó wọ̀nyí ń jáde láéláé ni kò sì tán; òun náà ni mo bá sì fi di olówo, bí ó tilẹ̀ jẹ́ pá níkẹhìn olè jí àdó náà lọ.
Ṣugbọn nígbà tí Galio di gomina Akaya, àwọn Juu fi ohùn ṣọ̀kan láti dìde sí Paulu.
Oladejo Okediji àti ìgbé ayé ìtàn kíkọ rẹ̀ Wo bí o ṣe lè kọ́ ọmọ rẹ lẹ́kọ̀ọ́ ìbálòpọ̀ Ìfipá-bọmọdélòpọ̀ jẹ́ ohun tí òbí gbudọ̀ sàkíyèsí Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí kan sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
Lati ọdun 2017 lorilẹede Amẹrika ti n kede pe awọn yoo gbe ote le fifun awọn ara Eritre ni irufẹ iwe aṣ irina kan pato.
 Ẹ ̀ ka Èdè bíi : anhaki , kagbaaga , kajoko , kamọna àti orango wọ ́ pọ ̀ nínú èdè bidgogo .
Ninu 479 ni ipinlẹ Katsina ti ni eniyan mọkanlelaadọta, 51, eyi to ju ida mẹwa gbogbo awọn ti wọn gba siṣẹ jake-jado Naijiria lọ.
”Gege bi Asofin Olujimi, “Mo gboriyin fun aare Muhammadu Buhari fun eleyi ti o se yii, ni papaajulo fun awo ti a wa lati apa gusuu iwo oorun orile-ede Naijiria.
Ṣugbọn o fikun pe, imọ ijinlẹ ti gbinlẹ ju ti ọdun 1918 lọ, nitori naa, o ṣeeṣe ki Coronavirus kogba wọle ki ọdun meji to pe.
Ẹgbẹ ajafẹtọ ẹni naa ti orukọ wọn n jẹ, 'The Alliance on Surviving Covid-19 and Beyond' ti agbẹjọro agba, Femi Falana ṣe adari fun lo kede bẹẹ.
Ṣugbọn Ọlọrun ni olùrànlọ́wọ́ mi,OLUWA ni ó gbé ẹ̀mí mi ró.
Tilu tifọn pẹlu awọn orin onigbagbọ nibi eto isinku ọmọ lẹyin Kristi ati tologun ni wọn kọ nibi eto isinku akọni obinrin naa.
Nitori naa ti Naijiria ba fẹ si ibode wọn, wọn gbọdọ ri pe gbogbo eto wa nilẹ lati dẹkun itankalẹ arun Coronavirus.
Nígbà tí wọ́n rí i ní òdìkejì òkun, wọ́n bi í pé, “Olùkọ́ni, nígbà wo ni o ti dé ìhín?
Àgádágodo aláwọ̀ ìyeyè ni nkan náà.
Ranti Abrahamu ati Isaaki ati Jakọbu, àwọn iranṣẹ rẹ.
”o je ohun ibanuje fun mi pe, ifarapa yii waye lakoko ti idije bere,”Ewe, Pearson, ti o gba ami-eye goolu ninu idije Olympics ti o waye nilu London so pe, oun ti mo tele pe oun ko ni le tesiwaju ninu idije ohun, sugbon ti o oun monmon lati da ikede ohun duro lati kopa ninu ayeye ibere idije naa ti o waye ni papa isere Carrara lojoRu(Wednesday).
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Oluwatoyin Olanipekun: Wo àwọn òyìnbó tó ń kẹ́kọ̀ọ́ èdè Yorùbá ní Michigan, America Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Oluwatoyin Olanipekun: Wo àwọn òyìnbó tó ń kẹ́kọ̀ọ́ èdè Yorùbá ní Michigan, America 9 Ògún 2020 Iṣesi ati iwa àwon ọdọ Naijiria to wa ni America fihan pe iṣẹ m bẹ lọwọ awọn Olukọ- Oluwatoyin Olanipekun.
Wọn ni nitori pe iwadii DSS nigba naa fi han pe, ko yẹ lẹni to le di ipo naa mu.
Gege bi Malami se sọ, o ni ise akanse yii je okan lara ise akanse mẹ́rìndínlọ́gbọ̀n to waye lati fi dena omiyale, agbara ya sọbu ni awon abule ti o wa ni ipinle naa.
Nítorí pé ati àwọn Giriki tí wọ́n jẹ́ ọ̀jọ̀gbọ́n, ati àwọn kògbédè tí kò mọ nǹkan, gbogbo wọn ni mo jẹ ní gbèsè.
Ẹka Ile iṣe iwe iroyin Daily Trust to wa ni ilu Maiduguri la kọkọ gbo pe wọn yabo ti wọn gbe Uthman Abubakar to jẹ olootu iwe iroyin naa lagbegbe ohun pẹlu akoroyin rẹ kan Ibrahim Sawab lọ.
Amugbalegbe pataki si aare lori oro ifitonileti, Garba Shehu, ti fito awon akoroyin leti tele lojoBo(Thursday) pe won yoo se atunse ranpe si baluu oko ofurufu aare ohun, leyi ti o sokunfa idaduro silu London,”Bakan naa, ni ireti wa pe aare yoo lo silu Daura, nipinle Katsina ti n se ilu re lojo Eti(Friday) fun isinmi.
 Ó máa ń dúró gẹ ́ gẹ ́ bíi ìdáhùn gbólóhùn ìbéère.
"Ẹ má dá NEF lóhùn, kò síbi t'ọ́mọ Nàìjíríà kò lè gbé nílẹ̀ yìí - Buhari Ìtàn tó rọ̀ mọ́ òwe ""Ẹni tí kò ṣe bíi aláàárù l‘Oyingbo."
Ilé ẹjọ́ sún ìgbẹ́jọ́ Sẹ́nétọ̀ Elisha Abbo tó lu obìrin Dúkìá àti ọkọ̀ jóná, ọlọ́pàá mẹ́sàn-án fara gbọta lásìkò ìwọ́de Shiite Ọlọ́pàá ló ń fa rúkèrúdò lásìkò ìwọ́de wa-ẹgbẹ́ Shi'ite ICC pari iwadi lori pipa Shiites, IPOB Awọn alaṣẹ ati oṣiṣẹ ileeṣẹ iroyin gbogbo lo ba Channels kẹdun ọfọ ọdọmoọkunrin Precious Owolabi yii.
"Irọ́ ni pé mò kò ""Palliatives"" pamọ́ sí ilé mí-Abike Dabiri-Erewa Gbọ́yì-sọ̀yí àti ìròyìn èké láti ọ̀dọ̀ àwọn olólùfẹ́ wa ló ṣáábà ma ń da ìgbéyàwó àwọn òṣèré rú- Ọpẹ Ayeola Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Promise Akinlade: ọmọ ọdún mọ́kànlá tó ń fi ìlù dárà bíi àgbàlagbà sọ̀rọ̀ nípa tálẹ́ǹtì rẹ Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 3 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 5 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!"
Kamilu Compo, lásìkò to ń kópa lórí ètò BBC Yoruba ṣàlàyé pé, àrùn Covid-19 kii se ohun ti a n fi ọwọ yẹpẹrẹ mú nítorí kò tíì sí òògùn fún ìwòsàn rẹ.
"Ǹkan tí ara mi ma ń ṣe fúnra rẹ̀ láì nílò kí n rò ó tàbí mú u ṣiṣẹ́""."
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Aisha Buhari, Dubai trip: Ṣé lóòtọ́ ni pé Aisha Buhari ti kó lọ sí Dubai?
Mose bá pe Aaroni, ó wí fún un pé, “Ohun tí OLUWA wí nìyí, ‘N óo fi ara mi hàn gẹ́gẹ́ bí ẹni mímọ́ láàrin àwọn tí wọ́n jẹ́ òjíṣẹ́ mi, n óo sì gba ògo níwájú gbogbo àwọn eniyan’ ” Aaroni dákẹ́, kò sọ̀rọ̀.
52 Àti nísisìyí, kíyèsíi, gẹ́gẹ́bí ìgbàgbọ́ wọn nínú àdúrà wọn ni èmi yíò mú abala yìí ti ìhìnrere mi wá sí ìmọ̀ àwọn ènìyàn mi.
"Nkan ti wọn fi ara balẹ ṣeto ni, pẹlu iranlọwọ Boko Haram ati imọ adari rẹ, Abubakar Shekau.
Bẹẹ ni ọkan o jọkan akitiyan lawọn ijọba gbogbo ti gbe lori rẹ, ṣugbọn kaka ko san lara iya ajẹ, n ṣe lo tun n fi gbogbo ọmọ rẹ bi obinrin, ni ọrọ naa n jẹ.
Ó gbé ọ̀kan kalẹ̀ ní ìlú Bẹtẹli ó sì gbé ekeji sí ìlú Dani.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù #Russia 2018: Belgium kojú France n'ìpele ''semi finals'' 10 Agẹmo 2018 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Pẹ́pẹ́pẹ yóò pọmọ bí France ti kojú Belgium nínu ìdíje ife ẹ̀yẹ àgbáyé ní Russia Ikọ agbabọọlu Belgium yoo waako pẹlu ikọ Faranse lọjọ ìṣẹgun ninu ifẹsẹwọnsẹ to kangun si aṣekagba ninu idije ife ẹyẹ agbaye to n lọ lọwọ l'orilẹede Russia.
O ni IFAD ti gba awon egbe agbe to le nigba ni ekun yii yato si ti eto akanse idanilekoo lori ayipada oju ojo ati ewu awujo kookan to n fa isele pajawiri ati ona to fi kan ise agbe.
Lai pari ọrọ rẹ pe ki awọn to n bu ẹnu atẹ lu akitiyan ijọba to wa lode yii ronupiwada, ki wọn si dojukọ aṣeyọri ti ijọba n ṣe lati pana iwa jẹgudujẹra lorilẹ-ede yii.
fi le e gbowo mo, ti o si sun gbalaja silẹ bi eja to n pongbe omi.
Ọba dúró sí ààyè rẹ̀, lẹ́bàá òpó, ó bá OLUWA dá majẹmu pé òun óo máa rìn ní ọ̀nà OLUWA ati láti pa àwọn òfin rẹ̀ mọ́ ati láti mú gbogbo ohun tí ó wà ninu Ìwé náà ṣẹ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Tony Elumelu 2018: Mahassin Quadri ló gbà ìrànwọ owó 25 Ọ̀wàrà 2018 Ọdọọdun ní Tony Elumelu Foundation máa ń fún àwọn ọdọ tí wọn ni ìmọ̀ lóri ètò ọrọ̀ ajé láti wa sọ tẹnu wọn lọ́rí owò túntun.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Gift Sotonye-Frank: Bó ṣe gba oyè ọ̀mọ̀wé nípa òfin, náà ló gba àmì ẹ̀yẹ 4 Agẹmo 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 5 Agẹmo 2019 Oríṣun àwòrán, @QUBelfast Ọmọ Naijiria kan, arabinrin Gift Sotonye-Frank, to n kẹkọ gboye ọmọwe lẹka imọ ofin ni Queen's University to wa nilu Belfast ti gba ami ẹyẹ akẹkọ to dantọ julọ nileẹkọ naa.
Amọ, o ni awọn yoo ṣe agbeyẹwo agbegbe 'West Bank' to n fa ija laarin oriḷede Palestine ati Isrẹli fun ọpọlọpọ ọdun bayii.
Kí n lè rí ire àwọn àyànfẹ́ rẹkí n lè ní ìpín ninu ayọ̀ àwọn eniyan rẹ,kí n sì lè máa ṣògo pẹlu àwọn tí ó jẹ́ eniyan ìní rẹ.
ìjọba Tanzania ko 30 Mílíọ̀nù rẹ̀ wọ̀lú Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Ògbólógbòó Ìjàpá tó máa ń sọ̀rọ̀ bí ènìyàn
Juventus: Ronaldo gbáyò sáwọ̀n fún ìgbà àkọ́kọ́
Iwọde naa yóò gberasọ lati Area 1.
Bi olori arojọtakoni ile ẹjọ ICC ba fi buwọlu pe ki wọn o f'oju wọn wina ẹjọ, yoo jẹ igba akọkọ ti ọmọ Naijiria yoo jẹjọ lori hihu iwa ọdaran si ọmọniyan niwaju ile ẹjọ naa.
Nígbà tí wọ́n bá dé, wọ́n óo rí ògo mi.
Awọn to n ṣewọde ọun mu orisiiriṣii beba dani ti wọn fi n beere lọwọ ijọba ilẹ Gẹẹsi pe ki wọn wa nnkan ṣe lori ọrọ naa.
Baba rẹ lo kọ ni Tennis gbaa Igbese Baba Serena Wiliams nipa bi o ti se kọ awọn omobirin rẹ ni Tennis lo jẹ iwuri fun Baba Naomi,Leonard Francois lati ko Naomi ati ẹgbọn rẹ Mari nipa Tennis.
Iwadii fihan wi pe ni ṣe ni awọn adigunjale naa digun lu ile ifowopamọsi First Bank to wa ni agbegbe naa, ti wọn si kọkọ lọ sigun bọ agọ ọlọpaa to wa ni ibẹ.
Àwọn òmìrán wà láyé ní ayé ìgbà náà, wọ́n tilẹ̀ tún wà láyé fún àkókò kan lẹ́yìn rẹ̀.
tí àwọn ènìyàn mọ ̀ sí hid , jẹ ́ ọmọ bíbí ìlú kékeré kan tí wọ ́ n ń pè ní ikenne ní ìpínlẹ ̀ Ògùn ní orílẹ ̀ èdè nàìjíríà .
gbagede kan lati yẹ wo; lati le wo ibi kan ati lati le fọwọ ṣinkun ofin mu
Baba rẹ da ọpọlọpọ sọọsi silẹ.
 O ni ọpọ ninu awọn ọrẹ ni ọkọ wọn ni ki wọn yẹra fun mi bẹẹ ko si ẹni to wù láti dalemoṣu laye."
Eto aabo to le dahin-dahin lo wa ni Ado Ekiti ,nipa bi aare orile ede Naijiria Muhammadu Buhari se dari awon agba egbe oselu APC lo si ipinle Ekiti fun ipolongo gomina  ti yoo pari lonii yii.
Ẹni tí ó ń waasu ju ẹni tí ó ń fi èdè àjèjì sọ̀rọ̀ lọ, àfi bí ó bá túmọ̀ ohun tí ó fi èdè àjèjì sọ, kí ìjọ lè rí ẹ̀kọ́ kọ́ fún ìdàgbà ẹ̀mí.
"Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: ""Mo fẹ́ pa ara mi torí ojú àbùkù tí wọn ń fi wò mí pé mo fi iṣẹ́ abẹ bímọ"" Fulani kò leè dúró, táa bá lo ohun ta jogún lọ́dọ̀ àwọn bàbá wa - Sunday Igboho Ọjà Àgbáláta ní Badagry rèé, níbití ẹran ejò ti dùn ju ẹran adìẹ lọ Ọlọ́run yóò ṣe ìdájọ́ nkan tó wà láàrin èmi àti Ireti Ajanaku - Tope Alabi A kò jáde ṣe ìwọ́de ìtagbangba mọ́, inú ọkàn wa lá ti máa ṣe ìfẹ̀hónú hàn - Revolution Now Ninu ifọrọwerọ rẹ pẹlu BBC Yoruba, Fathia Balogun ni sinima Aje Ọja ti oun sẹsẹ se yii, ni yoo fi da awọn eeyan loju pe ija ti dopin, ti ogun si ti tan laarin oun ati Saheed Balogun."
Wọn tun ni ọra awọn ile iwe ijọba apapọ ti ICPC n sọ yatọ si ti awọn akẹkọọ ti awẹn fun ni ounjẹ lasiko Coronavirus.
Nítorí dandan ni ó jẹ́ fún mi.
Àwọn Eniyan náà Jẹ́wọ́ Ẹ̀ṣẹ̀ Wọn.
yii, lati din wahala ti awon ero n koju lasiko irinajo  lati  ilu Abuja lo si Kaduna .
Erongba fifun awọn eeyan ni iroyin ti wọn lee lo (ni ede abinibi wọn), lo n mu ki iroyin naa sun mọ wọn pẹkipẹki, to si tun n jẹ ki wọn jẹ olotitọ si oju opo to n fun wọn ni iroyin naa kọja ero ẹnikẹni.
Naijiria, ti a mọ si Super Eagles ati iko agbabọọlu orile ede South  Africa Bafana Bafana yoo maa wako ninu idije
Rabiu Yusuf, ìgbákejì ọ̀gá àgbà ọlọ́pàá Nàìjíríà (AIG) lẹ́kùn Katsina jáde láyé Lori pe ijọba Ghana ti awọn ile itaja to jẹ ti awọn ọmọ Naijiria, Nkrumah sọ pe awọn onitọhun ko tẹle ilana ti ijọba fun wọn, ni ọrọ ṣe ri bẹ ẹ.
Nínú ọ̀rọ̀ Tinubu, ó bẹnu àtẹ lu bi àwọn Gomina àti agbẹjọrò àgbà ṣe jẹ ki ọ̀rọ̀ náà dà.
Ni ọdun yii bakan naa ni ijọba pinnu lati na N418bn lapapọ, eleyii to fẹrẹ dọgba pẹlu owo oṣu fun awọn to wa ni ẹka eto ẹkọ.
Mo ti dé òpin iré ìje náà.
A kò sí lára àwọn tó ń ṣèwọ́de tako èlé owó epo àti iná ọba - NLC Jàńdùkú olóṣèlú gbàkóso ilé aṣòfin l‘Ondo Temitope Akinnusi: Ọ̀pọ̀ iléeṣẹ́ ló takú láti gbà mí síṣẹ́ torí mo ní ojú kan Eruku ìjà sọ lálá lórí ayelujára láàrin Oyedepo àti Daddy Freeze Ọmọ Nàíjíríà kó N6m jọ lórí ayélujára fún Erica tí wọn lé ní BB Naija Mo fòpin sí àjẹbánu lórí owó ìrànwọ́ epo àti iná ọba, ní èlé ṣe wáyé - Buhari A wa n ki Risikat ati ọkọ rẹ pe wọn ku oriire ayọ igbeyawo, Ọlọrun yoo se wọn ni ọrẹ ara wọn.
Èmi kò wá láti pe àwọn olódodo.
Ilé iṣẹ́ amuṣagbara tí wà lára ilé iṣẹ́ tó ń ri si ọ̀rọ̀ iṣẹ́ àti ilé igbé tí Babatunde Fashola jẹ mínísita rẹ̀ tẹ́lẹ̀.
Ó kọ ọ́ sínú ìwé náà wípé:
Ilu Swansea - Andre Ayew: Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Andre Ayew jẹ ogbontarigi agbabọọlu fun orilẹede Ghana Swansea City ni ireti wipe awọn yoo se adehun pẹlu Andre Ayew lati ẹgbẹ agbabọọlu West Ham.
ASUU strike : Ìdí tí àwọn olùkọ́ kò ṣe tíì f'òpin sí ìyanṣẹ́lódì
" Àpẹẹrẹ ní fíìmù kan tí wọ ́ n pè ní "" not without my daughter "" ( láìsí ọmọbìnrin mi ) tí ó ń sọ ìtàn nípa okùnrin mùsùlùmí kan àti obìnrin kìrìsìtẹ ́ nì kan tí wọ ́ n fẹ ́ ṣe ìgbéyàwó tí wọ ́ n sì tún rí oríṣi ìṣòro nígbà tí wọ ́ n ń gbáradì fún ìgbéyàwó wọn ."
Oun tó bá léni léni tí kò ríni mú, ṣèbí òun ni Ìmúnitì.
Ipò wo wá ni òfin wà?
Kí ló dé, Jakọbu, tí o fi ń rojọ́?
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Coronavirus: Kínni ìtàkùn ayélujára 5G nííṣe gan na pẹ̀lú ààrùn coronavirus?
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Oriọla: ó yẹ kí a jẹ́ káwọn ọmọ ìsinyi mọ pàtàkì ṣíṣe eré ìdárayá papọ̀ Minisita naa sọ pe igbese to dara ni pe Theresa May n bọ ni Naijiria lati wa se ipade bọ pẹlu Aarẹ Muhammadu Buhari.
Gomina salaye pe isejoba oun yoo se ifilole ajo to n ri
Ọkúnrin náà to fẹ ki BBC fi orúkọ bo oun lásírí sàlàyé pé nínú ibẹrun bojo ni àwọn n gbe ni àdúgbò báyìí nítori ẹru n ba olúkúlu láti jáde.
Ìgbé ayé Abiola Ajimobi nínú àwòràn pẹ̀lú àwọn ǹkan tó ṣẹlẹ̀ Àwọn àdúgbò Ibadan gborúkọ tuntun látẹnu Ajimobi Ẹ wo àwòrán bí ìsìnkú Abiola Ajimobi ṣe lọ!
Ojọ Kẹrin, oṣu Keje, ọdun 1983 lo darapọ mọ iṣẹ ologun, to si gba igbega titi to fi di ọgagun agba Major General lọjọ Kẹrin, oṣu Keje, ọdun 2014.
"Iṣẹ́ fẹ́ bọ́ lọ́wọ́ ọlọ́pàá tó gba N100k lọ́wọ́ awakọ̀ tó gba""One way"" l'Eko Mílíọ́nù mẹ́wàá Náírà ni ilé ẹjọ́ ni kí Kábíyèsí san gẹ́gẹ́ bí owó ìtaran ilẹ̀ tí ó gbà lọ́nà àìtọ́ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Oba Adedokun Abolarin ti Oke Ila: Ó ya ọ̀pọ̀ tó súnmọ́ mi lẹ́nu bí mo ṣe ń kọ́ Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí #EndSars Lagos Judicial Panel: Iléeṣẹ́ ológun ní òtítọ́ làwọn sọ́jà gbé ìbọn tó lọ́ta gidi nínú lọ sí Lekki Toll Gate22 Bélú 2020 Shark Attack Australia: Arákùnrin òmùwẹ̀ kó s'ọ́wọ́ ẹja Sháàki, ikú ló padà já sí23 Bélú 2020 Femi Gbajabiamila: DSS ti fi ẹ̀sọ́ àbò Gbajabiamila tó pa fẹ́ndọ̀ l'Abuja sátìmọ́lé23 Bélú 2020 Nigeria government - Lekki Toll Gate - Kí ló wà ninú lẹ́tà tí ìjọba Naijiria kọ sí CNN24 Bélú 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?"
ENDSARS: Ẹ̀yin ọmọ Nàìjíríà, ẹ ṣè ìrànwọ́ irinṣẹ́ fáwọn ọlọ́pàá- Naira Marley bẹ̀bẹ̀ Ẹ̀wọ̀n ni wàá gbẹ̀yìn sí, kò sí bóo ṣe dọ́gbọ́n tó - Seyi Makinde wa ègúná ọ̀rọ̀ lé Fayose INEC kéde agbègbè ẹsẹ̀ odò 270 ti èrú ìbò ti le wáyé ní ìpínlẹ̀ Ondo Wòlìí náà àti àwọn ọlùkọ́ ilé ìjọsìn ọmọde àti àwọn asọ́nà mẹ́fà ni ọ̀rọ̀ náà kan ti wọ́n si ṣe ìdájọ ẹwọn gbéré fún gbogbo wọ́n.
Ìyàwó Ọ̀ọ̀ni Ogunwusi kò bímọ tuntun A kò ṣetán láti fa olùdíje kanṣoṣo kalẹ̀ fún ìbò gómìnà l‘Ondo - Àgbáríjọ ẹgbẹ́ òṣèlú INEC ní o tó àwọn ilé orí omi bíi méjìlélọ́gọ́ta àti ibudó ìdìbò ọ̀rinlérúgbà ó din mẹ́wàá to wa ni agbègbè ẹsẹ̀ odò, tawọn oju omi tó tó ẹgbẹ̀rún mẹ́ta àti mẹ́sàn sì wà ni ìpinlẹ̀ náà.
Rabuṣake ní, “Mo fẹ́ kí Hesekaya bá oluwa mi, ọba Asiria, ṣe pàṣípààrọ̀ kan, n óo fún un ní ẹgbaa ẹṣin bí ó bá lè rí eniyan tó tí ó lè gùn wọ́n.
"Idi eyi ni pe awọn iwe itẹka to n jẹ ""ballot"" ti ogun apakokoro sanitaisa ba jẹ ko tutu lee lẹpọ o si lee ha sẹnu ẹrọ idibo."
Bí ó bá jẹ́ aláìní ni olúwarẹ̀, aṣọ tí ó bá fi dógò kò gbọdọ̀ sùn lọ́dọ̀ yín.
Adajọ agba tele ri lorile-ede Naijiria ti o di oloogbe, adajọ Idris Legbo Kutigi ni won ti te si afefe rere lojoRU(Wednesday), leyin adura ikeyin  ti o waye ni mosalasi, niluu Abuja.
Wọ́n gbé wa ṣubú, ṣugbọn wọn kò lè pa wá.
Bakan naa, leyin ipade apero ohun, aare yoo tun se ipade po pelu aare orile-ede Poland, Andrzej Duda ati oludari orile-ede naa, Mateusz Morawiecki.
ri wi pe won se ojuse won bi o se to ati bo se ye lojuna ati ri daju pe eto
Àwọn òṣèré Yollywood tó ń pàrònú rẹ́ EFCC: Ẹ yàgò fún MMM, àwa ké fún un yín tó o!
Kohati ni baba ńlá àwọn ọmọ Amramu ati àwọn ọmọ Iṣari, àwọn ọmọ Heburoni ati àwọn ọmọ Usieli.
O Salawu paṣẹ ki wọn fi si ahamọ titi diigba ti Oludari eka olupejo labe ijoba nipinle naa yoo fi lawọn lọyẹ lori ẹjọ naa.
Nígbà tí ilẹ̀ fẹ́rẹ̀ mọ́, Paulu gbà wọ́n níyànjú pé kí gbogbo wọn jẹun.
Akọ̀royin BBC ni, kò pẹ́ tí iwọde naa bẹrẹ ti awọn kan de ninu ọ̀kọ̀ nla mérin ti wón si da aarìn wón ru.
Seyi: Mi o sá fun oṣelu ṣugbọn o di tasiko Ọlọrun ba to.
Eyi mu ki EFCC tẹle awọn ọmọkunrin mejeeji lọ sile ti wọn n gbe, ti ayẹwo wọn si fihan pe, ọgọrun miliọnu Naira ni ọmọkunrin Orji ra ọkọ ayọkẹlẹ to n lo, ti ti ọrẹ rẹ, Kelvin Ilonah si jẹ miliọnu marundinlogoji Naira.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Kí ló mú bàbá àti ọmọ rẹ̀ méjì rẹ́wọ̀n oṣù mẹ́fà he ?
Ahọ́n ọmọ ọmú lẹ̀ mọ́ òkè ẹnu rẹ̀ nítorí òùngbẹ.
Bó bá jẹ́ pé o ṣe rere ni, ara rẹ ìbá yá gágá, ẹbọ rẹ yóo sì jẹ́ ìtẹ́wọ́gbà.
1 369823 Orilẹede Slovakia 3362 61.
Ṣé eniyan ni mò ń bá rojọ́ ni?
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ido-Ani Robbery: Àwọn adigunjalè pa ènìyàn mẹ́fà ní báńkì kan nìpínlẹ̀ Ondo 8 Ìgbé 2019 Oríṣun àwòrán, Thenationonline Àkọlé àwòrán, Wọn fi agidi mu awọn oṣiṣẹ ileefowopamọ lati ṣi ilẹkun rẹ, ṣugbọn owo ti wọn ba nibẹ ko jọ wọn loju rara.
Aaroni yóo fa ẹran tí gègé OLUWA bá mú kalẹ̀ níwájú OLUWA, yóo sì fi rú ẹbọ ìmúkúrò ẹ̀ṣẹ̀.
Ọgbẹni Tope ni titi ago mejila oru ọjọ Satide lawọn wa lori ọrọ yii pẹlu awọn ọlọpaa.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Kèǹgbè lílù ní Ilọrin rèé, orin ìgbéyàwó, àwàdà àti ẹ̀ẹ̀kẹ́ èébú Ọba Lamidi Adeyẹmi, òṣìṣẹ́ adójútòfò àti Abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò kó tó jọba Kíni ìwọ mọ̀ nípa Funmilayọ Ransome-Kuti?
Ọlọ́pàá kọlu àwọn ọmọ onílẹ̀, ní ìbọn àṣìyìn pa ènìyàn méjì Ẹ wá ná, kí ló ń ṣẹlẹ̀ pẹ̀lú APC àti Kayode Fayemi ní Ekiti gan an?
Ọ̀rọ̀ náà dùn mi púpọ̀, nítorí nígbà tí a pàdé wọn, minimini ni àwọn ti a jọ ń lọ dákẹ́, ẹ̀rù ń bà wọ́n, èmi tí mo sì tilẹ̀ ṣe ọkùnrin díẹ̀ tí mo sọ̀rọ̀, dípò kí wọn yìn mí, búbú ni wọ́n ń bú mi mo ni, ‘Njẹ́ ìwọ, ìwọ Gọ̀ǹgọ̀ṣú t[kìtí, ìgbà tí a pàdé wọn, ìwọ tó ọ̀rọ̀ i sọ?
Nítorí òfin ni ó ń mú ibinu Ọlọrun wá.
Ilu San Francisco ni California ni orilẹ-ede Amẹrika ni ijọ Satani kalẹ si.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, The Polytechnic Ibadan: Ẹ̀rọ abẹ́lé tó ń fọ ọwọ́ àti ‘Ventilator’ ló ṣẹ̀ṣẹ̀ gbé jáde Bakan naa ni owo ori ti wọn n san ko ṣe ọgbọọgba lati ọdọ agbẹ kan si ekeji, ti katakara oko-owo koko si n ṣe sege sege.
Nígbà tí Ọlọrun bá Abrahamu sọ̀rọ̀ tán, ó gòkè lọ kúrò lọ́dọ̀ rẹ̀.
ti won n se isẹ losan ati loru , ti won si n ba awon omo egbe sọrọ lati
Bakan naa lawọn ẹgbẹ ''Black Lives Matter'' naa ti ṣewọde kaakiri UK to fi mọ ilu London.
O so pe “A ti soro nipa imo ero, ohun amaye derun ati idasile ile-ise.
5 107814 Orilẹede Greece 3370 32.
BBCCopyright: BBC Ìdìbò ń lọ lọ́wọ́ láti yan olórí ilé aṣojú-ṣòfinImage caption: Ìdìbò ń lọ lọ́wọ́ láti yan olórí ilé aṣojú-ṣòfin Article share tools Facebook Twitter ṢàpínlòView more share options Share this post Copy this linkKà síwájú síi nípa àwọn ìtọ́kasí wọ̀nyí.
Nígbà tí à ń dìbò ìgbìmọ̀ akẹ́kọ̀ọ́, mo máa ń tẹnu mọ ọn pé ó yẹ kí àwọn tí wọ́n ayàsọ́tọ̀ ní aṣojú nígbà ìdìbò.
 Ó sàfihàn ọlọ ́ dẹ adonis tí ó sùn sí orí itan venus .
Àwọn ará Romu ni wọ́n tẹ ìlú yìí dó.
Bamgboṣe rọ àwọn ilé ẹ̀kọ́ àti Yorùbá láti jẹ́ kí èdè Yorùbá mú igbà orókè láwùjọ wa.
" Mo fẹ́ fi àkàrà òyìnbó ọjọ ìbímí tọrẹ- Bobrisky Lẹ́yìn ti àwọn ọlọpàá yabo ìbí àyẹyẹ ọjọ́ ìbí Okuneye Idris Olarewaju ti gbogbo ènìyàn mọ si Bobrisky lọ́ja sátide tí ayẹyẹ naà ko si lé wáye mọ.
Afe Babalola: Adarí Nàíjíríà kankan kò leè ṣàṣeyọrí pẹ̀lú òfin ọdún 1999
Ẹnìkan tí ó jẹ lówó kí ó tó kú fẹ́ kó àwọn ọmọkunrin mi mejeeji lẹ́rú, nítorí gbèsè baba wọn.
Ko si oju opo itakun agbaye Iwadi agbaye naa fihan pe, ọpọ awọn eeyan lo ṣalaye pe igbẹkẹle diẹ lawọn ni ninu abẹrẹ ajẹsara.
Ilẹ̀ kò ì tí ì ṣú nígbà tí mo ń sọ̀rọ̀ rẹ̀ yìí, nígbà tí ọ̀rẹ́ mi náà sì ronú ohun tí à bá fi dáráyá títí, ò dàmọ̀ràn wí pé kí a lọ dé ilé Àrùn tí í ṣe ìyàwó Ikú ṣùgbọ́n mo kọ̀ fún un: nítorí nígbà tí mo dé ilé ọkọ rẹ̀ ṣáájú eléyìínì ilé náà kò fà mí mọ́ra, kí olúwaarẹ̀ rí Ikú kí ó tún lọ rí Àrùn kì í nǹkan rere.
Nítorí pé n óo na ọwọ́ ibinu mi sí àwọn tí ń gbé ilẹ̀ náà.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Kengbe Ilorin: Àṣà ẹ̀yà Fulani, Bariba àti Gambari tó dàpọ̀ mọ́ ti Yoruba Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Shittu ni, gbogbo ohun ti ko yẹ ko sẹlẹ lo waye lasiko idibo naa, ati wi pe, awọn ọlọpaa fi panpẹ ọba mu awọn ẹgbẹ oselu PDP ki idibo to bẹrẹ rara, tawọn ọlọpaa si n sa wọn kaakiri.
Wọn ti fi aye gba wa lati beere ibeere, ṣugbọn ẹ ma ja tabi ba ohunkohun jẹ.
ẹ má lọ sí Bẹtẹli, ẹ má sì wọ Giligali, tabi kí ẹ kọjá lọ sí Beeriṣeba; nítorí a óo kó Giligali lọ sí oko ẹrú, Bẹtẹli yóo sì di asán.
ara ilu, ni eyi ti o tun lee  maa ran  iko olote lowo .
Ẹ fọ́ ara yín lójúkí ẹ sì di afọ́jú.
‘Wọn ti ji Dino Melaye gbe’ Ìpinu Gómìnà Ortom ya ni lẹ́nu - APC Àwọn òṣìṣẹ́ NAN ya bo Abuja fún ẹ̀tọ́ wọn Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ṣé ẹ rántí orin - Má ṣe jẹ́jẹ́ ma wà mi lọ?
Lati nkan bi ọdun maarun, apá mi ti ka ipaya ti OCD maa n fun mi:mo ti mọ ẹ̀rù to tọ́ ati eyi ti ko yẹ ki n gba laaye.
Gbogbo òkúta ilẹ̀ ibẹ̀ funfun gbòò bí iyọ̀.
Láti ìgbà degba sì ni àwọn ọlọ́pàá ara yìí máa ń dàgbà, tí wọn yóò sì farahàn nínú èròjà Plasma, tíì ṣe ẹ̀jẹ̀ tó ń ṣàn nínú agọ ara Àjọ eleto ìlera tí wá ń tọ àwọn èèyàn tó jajabọ lọ́wọ́ àrùn Coronavirus lọ, láti mọ bóyá èròjà Plasma tó wà nínú ẹ̀jẹ̀ wọn ṣe é fún àwọn aláìsàn miran tó lugbadi àrùn Covid-19.
Wò ó, Ọlọrun kò fọkàn tán àwọn angẹli,àwọn ọ̀run kò sì mọ́ níwájú rẹ̀.
egbe oselu APC nipinle Zamfara ko lati se idibo abele, eleyi ti o si lodi si ofin
 Nigerians Evacuated from UK: Ọgọ́jọ ọmọ Nàìjíríà tí coronavirus ṣé mọ́ Amẹrika ti gúnlẹ̀ s'Abuja Oríṣun àwòrán, Twitter/Nigerians in diaspora Ọgọjọ ọmọ Naijiria ti coronavirus ṣe mọ ilẹ Amẹrika ti gunlẹ silu Abuja lọjọ Aiku, ọjọ kẹwaa oṣu karun un, ọdun 2020."
Ìtàn Yorùbá bi Àdán ti di “Ko ṣeku, kò ṣẹyẹ”
tenerife , to je erekusu ti spain , ni o tobijulo ninu awon erekusu kanari mejeje ni okun atlantiki leba eti odo afrika .
Jakọbu pada sọ́dọ̀ Isaaki, baba rẹ̀, ní Mamure, ìlú yìí kan náà ni wọ́n ń pè ní Kiriati Ariba tabi Heburoni, níbi tí Abrahamu ati Isaaki gbé.
Ní àkókò yìí ni wọ́n gbé àwọn ọmọde wá sọ́dọ̀ Jesu, kí ó lè gbé ọwọ́ lé wọn, kí ó sì súre fún wọn.
Iwe naa n fẹ ki Magu s'alaye nkan to faa, ti wọn fi f'ẹsun iwa'bajẹ kan alaga ile-ẹjọ CCT naa lẹyin ti EFCC ti safọmọ rẹ ninu ẹsun iwa ibajẹ lẹẹmeji.
Ortagus ṣalaye pe lati ọjọ kẹrinlelogun, oṣu kinni ọdun ni Amerika ti n gbiyannju lati gbe igbesẹ yii paapaa lori awọn oloṣelu ti ko fẹ ilọsiwaju eto oṣelu.
''Alami ẹyẹ Scrabble ni Naijiria naa wa gbera pẹlu ọrẹ rẹ, lati lọ san owo ẹmi ti awọn ajinigbe naa beere fun ni agbegbe ti wọn ti ji gbe.
”Aare  Buhari tun sọ pe inu ohun dun si gbogbo odun mẹ́sán án  ti asoju naa fi wa lorile ede Naijiria ,“O duro, o si tun mọ  nipa awon eniyan ati asa wọn.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, '500 level'' ni mo wà nígbà tí mo di adélé Ọba' Benjamin tun kilọ fun awọn to se idanwo JAMB lati ri wi pe wọn sọ nọmba ti wọn fi se iforukọsilẹ, ki awọn onijibiti ma ba a lu wọn ni jibiti.
Oríṣun àwòrán, joke silva Àkọlé àwòrán, Igbeyawo Olu Jacobs ati Joke Silva ti pe ọdun mẹtalelọgbọn Laipẹ yii ni wọn ṣe ajọdun ọdun kẹtalelọgbọn ti wọn ṣegbeyawo.
ni egbe  APC  ni iye ibo 289,903 lati feyin egbe oselu  People’s Democratic Party (PDP), janlẹ nigba
Tí a fiṣọwọ́ ní 16:53 3 Ọ̀pẹ̀ 202016:53 3 Ọ̀pẹ̀ 2020 Báwo ní gbogbo àgbáyé ṣe lè gba abẹ́rẹ́ ajẹ́sara àrún Coronavirus?
Pasuma sọ ninu ifọrọwerọ rẹ pẹlu iwe iroyin The Punch pe, diẹ lo ku ki apo asunwọn oun gbẹ fun owo, nitori awọn toun se iranlọwọ fun lasiko ti arun naa gbilẹ ni Naijiria.
Ìsekúpani ní àgbáyé Orilẹede mẹrin bii Saudi Arabia, Iraq, Pakistan ati Iran lo ti kopa ninu idajọ iku ni ọdun 2017, pẹ̀lú orilẹede China ti wọn ko yẹ ki iye rẹ han si ita.
Ere ki laja n ba ẹkun se?
Wéré wọ́n lọ sí iyààrá Ẹwadapọ.
Ọjọ naa si ni awọn ikọ ọlọpaa ọtẹlẹmuyẹ mẹrin, ti orukọ wọn n jẹ Insipẹkitọ Aruah, Sajẹnti Olawaiye ati Sule Agbabiaka pẹlu Kọburu Ariyo ya bo ilu Efon Alaaye lati finmu-finlẹ nipa ibi ti Adediwura wọlẹ si.
Igbimo to n mojuto eto ifowopamo ati ona adojutofo ni ile igbimo asoju-sofin lÁbuja ti bere iwadii lori ohun to sokunfa owongogo awon owo naira wewe bii naira marun un, naira mewaa, ogun naira ati aadota naira pelu ogorun un naira lasiko yii.
Jesu wo Arọ kan Sàn ní Jerusalẹmu.
Gbogbo àwọn ọmọ ati àwọn ọmọ ọmọ Jakọbu jẹ́ aadọrin, Josẹfu ti wà ní Ijipti ní tirẹ̀.
Nígbà tí Ọlọrun ṣe ìlérí fún Abrahamu ati irú-ọmọ rẹ̀, kì í ṣe ọ̀rọ̀ gbogbo irú-ọmọ rẹ̀ ni Ọlọrun ń sọ, ṣugbọn ọmọ kanṣoṣo ni ó tọ́ka sí.
Ìwà ipá àwọn ẹni ibi ni yóo gbá wọn dànù,nítorí pé wọ́n kọ̀ láti ṣe òtítọ́.
1) Moyinoluwa Olubunmi Falowo: Falowo ni adele ọba ilu Ibulẹ, ni ijọba ibilẹ Ifedore, ni ipinlẹ Ondo.
Yoruba wo ló fẹ́ gbé Oduduwa Republic tẹ́ n pariwo - Lizzy Anjorin Pásítọ̀ CAC àti afurasí 'Yahoo boy' Olawale tó lu Hayatou ní jìbìtì N12.
Oríṣun àwòrán, @JAMB Ọjọ Aje ni ajọ JAMB fi ẹnu ko si igbesẹ tuntun yii.
Bawo ni o ṣe mọ ede rẹ si?
Àwọn òṣìṣẹ́ aláàbò kọlu àwọn tó n ṣe ìwọ́de ní Sudan Ibanuje d'orí agbà k'odò, Ruiz fi ẹ̀ṣẹ́ sọ Anthony Joshua di ọmọ ológo àná Sultan pàṣẹ fún àwọn mùsùlùmí láti ṣ'ọdẹ òṣùpá lónìí 'Ọmọ SS 1 mu èso olómi, ṣùgbọ́n ilé ìwé wa kọ́ ló kú sí' Lara awọn eekan to fi ẹgbẹ oṣelu naa silẹ ni aarẹ ile aṣofin agba, Sẹnetọ Bukọla Saraki, ati olori ile aṣoju-ṣofin, Dogara, gomina Aminu Tambuwal atawọn eekan miran.
Aare Vaz ,ni oun wa ni ilu Abuja lati gba imoran lati odo aare Buhari, oun si ti setan lati tele awon imoran ti o fun oun.
Ìjàpá ṣe àkàrà ti ó fi oyin din, o di sinú ewé, ó gbe tọ Ẹkùn lọ.
gbagede Lateef Jakande ni gbagede Ile Igbimọ Aṣofin naa lori ọrọ yii lẹyin
Funke Akindele: Bukunmi Oluwasina ní ọ̀kan lára àlá òun ló wá sí ìmúṣẹ
Ṣùgbọ́n kí Àǹjànnú-ìbẹ̀rù tóó yí padà kúrò nínú èyìínì, Olówó-ayé yí padà ó di erin, nígbà tí erin sì fi ọwọ́-ìjà rẹ̀ mú ọká ni àtàrí, ó fọ́ ọ yánmúyánmú.
7 Ẹ béèrè, ẹ̀yin yíò sì rí gbà; ẹ kan ilẹ̀kùn, a ó sì ṣí i sílẹ̀ fún yín.
Aare ajo CAF, Ahmad naa fikun un pe, Nyantakyi tun kowe fipo re sile gege bi igbakeji aare ajo ohun.
N118 miliọnu ni wọn na lori iranwọ ileewosan ijọba to wa ni kọlẹẹji fasiti Ibadan fun ṣiṣe awọn ayẹwo arun COVID-19.
lasiko ti o n ba awon akoroyin soro leyin ipade igbimo ti igbakeji aare  Yemi Osinbajo dari rẹ.
SERAP and Pension: Àjọ SERAP ké sí Buhari lórí èròngbà àwọn Gómìnà láti ná N17trillion nínú owó ìfẹ̀yìntì òṣìṣẹ́
Pa òfin ọba mọ́, má sì fi ìwàǹwára jẹ́jẹ̀ẹ́ níwájú Ọlọrun.
Bẹ́ẹ̀ ni Abramu ṣe jáde lọ, gẹ́gẹ́ bí OLUWA ti sọ fún un, Lọti sì bá a lọ.
Àwọn iranṣẹ rẹ̀ dáhùn pé, “Kabiyesi, ohunkohun tí o bá wí ni a óo ṣe.
Ẹrú náà bá dọ̀bálẹ̀, ó bẹ olówó rẹ̀ pé, ‘Ṣe sùúrù fún mi, n óo san gbogbo gbèsè mi fún ọ.
    Ki n má fa ọ̀rọ̀ náà gùn lọ títí, kò pẹ́ púpọ̀ tí mo ti ń lọ sí ile rẹ̀ tí a dá ọjọ́ ìgbéyàwó wa.
Yeye Olokun of Lagos Omolara Fasola Fanimokun: Pásítọ̀ ṣọ́ọ̀ṣì ló sọ ìran pé kí n di Olókun
Mo fẹ́ fi àkàrà òyìnbó ọjọ ìbímí tọrẹ- Bobrisky Child Engineer: Olamide Odusanya nílò ìrànlọ́wọ́ láti lọ síléẹ̀kọ́ ìmọ̀ ẹ̀rọ Àwọn òṣèré tíátà kan rèé, tí wọn fẹ́ ara wọn, tí ìgbeyàwó wọn sì pẹ́ N kò lóyún, bẹ́ẹ̀ ni ń kò ní ọkọ, ẹ fi mí lọ́rùn sílẹ̀ - Dayo Amusa Ike Ekeremadu naa parọwa si Ajọ isọkan Ilẹ Afirika, Africa Union lati da si ọrọ naa, ki o to di gbọnmi si, omi o to laarin orilẹede mejeeji.
    Nígbà tí ó di ọjọ́ kan, lẹ́yìn òkú bàbá mi, bí mo ti múra tí mo ń fẹ́ lọ sí òde kan báyìí ni mo déédée’rí ìránṣẹ́ ọba tí ó wọlé wá bá mi.
Gege bi ero ayelujara own goal Nigeria se so,” Rohr ti se atunse si iko ti o fagbahan iko agbaboolu Poland lojoEti(Friday).
Eleyi jẹ ki ọ̀pọ̀lọpọ̀ olówó ojiji pọ̀ si lati igbà na a titi di oni.
Jide Kosoko forin sẹ́nu pé òun ni igi lẹ́yìn ọgbà Mr Latin lórí ipò ààrẹ TAMPAN tó wà Ó pé ọdún mẹ́wàá tí Barrister kú; wo ǹkan tó yẹ láti mọ̀ nípa rẹ̀ gẹ́gẹ́ bíi olórin, tẹ̀wé-tẹ̀wé, akọ̀wé àti sọ́jà Ìdí tí àwọn ìpińlẹ̀ se ń ti ilé ẹ̀kọ́ ní ìhà ìwọ̀ Oòrun-Àríwá Nàìjíríà rèé Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsèjẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọ O ṣalaye pe idi ti wọn fi gbe awọn ibode naa tipa wa lara akitiyan ijọba lati dẹkun kiko awọn nkan ija oloro ati oogun oloro wọ orilẹede Naijiria lọna aitọ.
N óo run ọ̀tá rẹ̀ níwájú rẹ̀;n óo sì bá àwọn tí ó kórìíra rẹ̀ kanlẹ̀.
Awon miiran ti o tun wa nibi
Iwo road crisis: Ẹgbẹ́ awakọ̀ ní wahálà wà, 'Auxilliary'ló sì ń fàá; ọlọ́pàá ní kò sí ìjà, pẹ̀sẹ̀ bí omi òwúrọ̀ ni Iwo road wà ní Ìbàdàn Oríṣun àwòrán, others Ọ̀rọ̀ di boo lọ, ko yàgò fún mi ní àárọ̀ ọjọ́ Aje nígbà ti rògbòdìyàn miran tun bẹ silẹ ni agbegbe Iwo Road nilu Ibadan.
Lẹyin naa ni atọkun bere ọrọ N30,000 yii lọwọ awọn to ku ti gbogbo wọn si ni awọn yoo san awọn.
Oloye Ọlajide woye ọrọ yi lasiko to n bawọn akọroyin sọrọ pẹlu afikun pe awọn agbaagba ilẹ Yoruba ti sin Aarẹ tuntun ni gbẹrẹ ipakọ pe asiko to se pataki pupọ ninu itan ilẹ Yoruba ati Naijiria lo gba ipo naa.
O gbé ibukun dáradára pàdé rẹ̀;o fi adé ojúlówó wúrà dé e lórí.
Awọn ibudo ti ijọba fọwọ si fun iforukọ silẹ NIN niyii: Oríṣun àwòrán, Nimc Awọn ibudo naa jẹ akojọpọ awọn ileeṣẹ aladani, ti ijọba, ileeṣẹ ibaraẹnisọrọ, ati awọn ajọ ti kii ṣe ti ijọba.
ati oro Ile gbigbe, pelu Alakoso gbogboogbo fun igbimo to n samojuto ipese
“OLUWA, ìwọ ni o gbé mi ga ju àwọn ọ̀tá mi lọ,o sì dáàbò bò mí, lọ́wọ́ àwọn oníwà ipá.
Nígbà tí ọwọ́ àwọn tí yóo dá wọn lẹ́bi bá tẹ̀ wọ́n,wọn óo gbà pé, òtítọ́ ni ọ̀rọ̀ OLUWA.
Amọ, bi o tilẹ jẹ pe ẹjọ ọba yiyan ni Ọyọ ṣi wa ni ilẹ ẹjọ, Emir Sanusi ko i ti i fesi lori igbesẹ gomina ipinlẹ Kano yii.
Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí 1:47 Fídíò, Ayàwòrán Obama: Ọ̀pọ̀ ìgbà ni èmi àti ìyá mi pa èbi mọ́nú kí n tó jẹ́ èèyàn, Duration 1,4717 Bélú 2018 Adewale Adeyemo: Wally ọmọ Yoruba tí yóò jẹ igbákejì akọ̀wé akápò ní ilẹ̀ Amẹrika30 Bélú 2020 Emmanuella: Ohun mẹ́wàá tó yẹ kóo mọ̀ nípá Emmanuella tó kọ́ ilé ńlá fún ìyá rẹ̀15 Bélú 2020 Agba Inaki sọ pé làásìgbò to ń wáyé ní South Africa pẹ̀lú àwọn ẹ̀yà mìí kò tó bí wọ́n ṣe ń pariwo rẹ̀24 Èbibi 2020 Technovation 2018: Àwọn akẹ́kọ̀ọ́-binrin Naijiria gba ipò kínní11 Ògún 2018 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí kan sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
A bi Yusuf Ojewale Satia lọjọ kẹsan, an, oṣu kẹta lọdun naa lọhun.
Gẹgẹ bi PDP awọn naa a ma saaba na ika abuku si gbẹ alatako pe awọn ni wọn wa nidi magomago tabi iwa to le mu ifasẹyin ba eto oṣelu ni Naijiria.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Xenophobia: Kò sí wàhálà fún àwọn okòwò South Africa ni Eko 8 Owewe 2019 Oríṣun àwòrán, @sanwo olu Àkọlé àwòrán, Awọn ara South Africa ko ni bẹru Gomina Sanwo Olu fi ọkan awọn eeyan South Africa balẹ lori awọn okowo wọn.
"Aisha ni: ""Alabosi ni gbogbo wọn, ẹgbọn agba, lonii awọn kan o ṣe daadaa si ọ, to ba di ọla eni naa a tun maa huwa baami."
Àwọn ọmọ ogun tí a kà ninu wọn jẹ́ ẹgbaa mẹtadinlọgbọn ó lé irinwo (54,400).
BBC Yoruba kan si obi Richard Gbadebo ti wọn kede iku rẹ lọjọ Isẹgun pe o ku sẹnu ẹrọ kan to n se ọsẹ nileesẹ kan nilu Ibadan.
fun egbe APC ti safihan oruko igbimo fun  ise akanse ti yoo maa sakoso eto ipolongo eto
Bi aisan ibà ṣe n wọ inu ara Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Awọn ẹ̀fọn ti eyikeyi ninu oriṣi kokoro aifojuri Plasmodium ba wa lara arẹ lo maa n pin aisan naa Ni ọpọ igba, aisan iba maa n wọ ara ti abo ẹ̀fọn (Female Anopheles) ba jẹ eniyan - oriṣi abo ẹ̀fọ̀n to wa le ni irinwo, ninu eyi ti bi ọgbọ̀n jẹ 'olokoowo iba' to jẹ pataki.
Yusuff, Yinka Ogundimu, Mojisola Meranda, M.
Ogunjọ oṣù kẹta ọdun 1984 ni wọn ṣe ifilọlẹ ofin naa.
Ọkunrin kan wà níbẹ̀ tí ọwọ́ ọ̀tún rẹ̀ rọ.
kambodia je ifobaje onilana-ibagbepo pelu norodom sihamoni gege bi oba .
Olówo rẹ̀ ni arábinrin kan ti orúkọ rẹ̀ ńjẹ́ Juliette Stevens.
Ẹ kò gbọdọ̀ ru ẹrù jáde ní ilé yín ní ọjọ́ ìsinmi.
OLUWA ní: “Àwọn ará Amoni ń dẹ́ṣẹ̀ kún ẹ̀ṣẹ̀, dájúdájú, n óo jẹ wọ́n níyà; wọ́n fi ìwà wọ̀bìà bẹ́ inú àwọn aboyún ilẹ̀ Gileadi, láti gba ilẹ̀ kún ilẹ̀ wọn.
Ọga agba ọlọpaa naa tun gba awọn ọlọpaa nimọran pe ki wọn ma dara pọ mọ oṣelu kankan ki wọn le da yatọ lẹnu iṣẹ wọn.
ile alawo funfun (UK ) to n soju fun ile  Africa, Harriet Baldwin.
Ìyá àgbà Ọlayinka, arúgbó tó ń ṣoge bí omidan Oshisko twins, àwọn 'ìbejì' tó ń dẹ́rìn ín p'òṣónú Wọ́n ta ère Ọ̀ṣun Osogbo sí Togo - Bàbá Ọṣun figbe ta Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Mí ò ya wèrè, mí ò burú, ọ̀nà àtijẹ là ń wá' Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Oun si lo n salaye nipa ohun to ṣẹlẹ ni ọjọ ti ọmọ kekere, ọmọ ọdun kan, Kolawole Gold sọnu.
Ìdí rèé tí ìjọba fi ń gbèrò pé kí àwọn tó ń gba 'minimum wage' má san owó orí mọ́ Ilé aṣòfin orílẹ̀-èdè UK n gbèrò fífí ìyà jẹ àwọn adarí Naijiria tó lọ́wọ́ nínú rògbòdìyàn ENDSARS Ọmọ ilé asofin lábẹ́ ẹgbẹ́ òṣèlú Labour Monica Lennon to ti jàjàjà lóri òṣì lásìkò ǹkan oṣù yìí lati ọdun 2016 sàlàyé pé àjàkálẹ̀ ààrùn Corornavirus ti sọ ọ dí dandan báyìí.
A óo kọ obinrin náà sílẹ̀, òun ati àwọn iranṣẹ rẹ̀, ati ọmọ rẹ̀, ati alátìlẹ́yìn rẹ̀.
” Peteru dá a lóhùn pé, “Ìwọ ni Kristi náà.
Ṣugbọn nisinsinyii, mo yan Jerusalẹmu fún ibi ìjọ́sìn ní orúkọ mi, mo sì ti yan Dafidi láti jẹ́ olórí Israẹli, eniyan mi.
Lọdun 2019 ni wọn di iya ati baba Ibẹfa lẹyin gbogbo igbiyanju wọn lori ati di ọlọmọ laye.
O ni koda iyekiye ti ẹnikẹni ba ni to dọti ni ki wọn ko lọ fun paṣipaarọ ni banki ki wọn le maa na owo naira tuntun.
Lẹ́yìn náà, ará Kuṣi náà dé, ó sì wí fún ọba pé, “Ìròyìn ayọ̀ ni mo mú wá fún oluwa mi, ọba!
Agiripa bá wí fún Fẹstu pé, “Èmi fúnra mi fẹ́ gbọ́ ọ̀rọ̀ lẹ́nu ọkunrin náà.
Nígbà tí a bá gbé e lọ sí itẹ́,àwọn olùṣọ́ a máa ṣọ́ ibojì rẹ̀.
Ogbooji lati tesiwaju ninu ise rere ti a ni fun awon omo orile-ede Naijiria.
Lara wọn la ti ri Fọlasade ati Taibat ti wọn ti jẹ Kọmisọnna nipinlẹ Ọyọ nigba kan ri ati Akeem Adeniyi, to ti jẹ alaga ijọba ibilẹ ri, to tun lọ sile asofin apapọ ilẹ wa.
Ẹ̀mí OLUWA sì wà lára mi, ó sọ fún mi pé, “Dìde, lọ sí àfonífojì, níbẹ̀ ni n óo ti bá ọ sọ̀rọ̀.
Atẹjade kan ti olu ile ẹgbẹ akọroyin nilu Abuja fisita, ti akọwe apapọ ẹgbẹ, Shuaib Usma Leman fọwọsi, ni ọrọ yii ti jẹyọ.
Nibi igbẹjọ losu to kọja, ni adajọ ile ẹjọ giga, to gba ẹjọ naa lọwọ ileẹjọ majisireti ti sun igbẹjọ siwaju di ọjọ Aje, ọjọ Kẹrindinlogun, ikẹtadinlogun ati ikejidinlogun osu kẹta ọdun yii.
niluu Abujua lọjọ Ẹti, lasiko ti o n ba awon akoroyin soro lẹyin ti o wa ki aarẹ
Ọ̀daràn tó wà lẹ́wọ̀n tún wọ́'ke $100miílíọnu - EFCC Wada: Alága àjọ ìdìbò INEC àti ọgá ọlọ́pàá, mò fà yín lè Ọlọrun lọ̀wọ́ Minisita abẹle fun ọrọ to jẹmọ epo bẹntiroolu, Oloye Timipre Sylva ati Gomina ti wọn dibo yan ni ipinlẹ Bayelsa, David Lyon pẹlu awọn to lo ṣe abẹwo naa.
Àwọn ọ̀tá wọn ni wọ́n lára,wọ́n sì fi agbára mú wọn sìn.
Mọ̀ sí i nípa àwọn ọmọ Nàìjíríà mẹ́sàn-án tó ń díje nínú ìdìbò ilẹ America lọ́jọ́ Ìṣẹ́gun Ta ni Wolii Olapade Agoro tó re ibi àgbà ń rè tí ayé ń pariwo rẹ̀ yìí?
Lẹ́yìn náà, yóo wẹ̀, yóo sì di mímọ́.
orile ede to wa nile Afirika fi n wo orile ede Naijiria,lasiko ti oun jẹ
Èmi ni mo fa ẹrubinrin mi lé ọ lọ́wọ́, nígbà tí ó rí i pé òun lóyún tán, mo wá di ẹni yẹ̀yẹ́ lójú rẹ̀.
Ti asiko ba to, a o gba ọmọ tọ.
Ṣugbọn bí àwọn wolii èké ti dìde láàrin àwọn eniyan Israẹli, bẹ́ẹ̀ ni àwọn olùkọ́ni èké yóo wà láàrin yín.
Ìwọ ni wọ́n bí mi lé lọ́wọ́;ìwọ ni Ọlọrun miláti ìgbà tí ìyá mi ti bí mi.
 “Mo wa sibi lati koko dupe pupo lowo Aare fun abewo ibani-kedun si ipinle naa leyin iseku-pa-ni to waye ni ipinle ohun, ati lati fi to leti ipo ti awon eniyan ti iye won n bi egberun lona edegbejo (175,000 )wa bayii ni awon ipago mejo.
6m ni mo fi borí Buhari, ojú òpó INEC gan leè jẹ́rì si - Atiku Atiku: Ó dá mi lójú pé mi ò le fìdí rẹmi nínú ètò ìdìbò ààrẹ Àwọn ìdí márún ti Atiku kò fi wọlé ààrẹ O salaye pe ninu gbogbo awọn awawi ti Atiku kojo ninu iwe ipẹjọ rẹ lori esi ibo aarẹ to ti fidirẹmi,eleyi to sọ pe oju opo Inec le jẹri wsi pe ohun fi ibo1.
pe akiyesi awọn ọmọ ẹgbẹ Ile Igbimọ Aṣofin naa si iwa ikọlu awọn ajoji
Ó dájú pé ìfẹ́ Ọlọrun ti di pípé ninu ẹnikẹ́ni tí ó bá ń pa ọ̀rọ̀ rẹ̀ mọ́.
Ó tún bi wọ́n pé, “Kò ì tíì ye yín sibẹ?
Lati ọjọ kẹtala oṣu kẹta ni wọn ti gbe idije liigi ilẹ Gẹẹsi ti si ẹgbẹ kan nitori ajakalẹ arun Coronavirus.
Òun náà ṣe ohun tí ó burú lójú OLUWA gẹ́gẹ́ bíi baba rẹ̀.
Baba ikoko naa sọ bi iku se ku, ati bi ọbẹ se bẹ nipa isẹlẹ naa, lori eto wa Kayeefi ta mu wa fun yin lọjọ Ẹ́ti, amọ, itọwo rẹ ree, ẹ gba.
Tope Ogunleye to n soju ẹkun idibo Ilejemeje ni ''inu mi ko dun si gbogbo ohun to n sẹlẹ yi.
Ogún ọdún ni ó fi ṣe aṣiwaju ní Israẹli.
Àṣẹ ayérayé tí kò lè yẹ̀ ni àṣẹ rẹ̀, ìjọba rẹ̀ kò sì lè parun.
Meji ninu àwọn olórí náà: Elidadi ati Medadi, kò bá wọn lọ, wọ́n dúró sinu àgọ́ wọn.
Nítorí bí ọ̀rọ̀ bá rí báyìí fún igi tútù, báwo ni yóo ti rí fún igi gbígbẹ?
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Zlatan: Ọ̀rẹ́ ni mo sìn lọ ‘studio’ tí mo fi bẹ̀rẹ̀ orin lẹ́yìn tí mo kùnà ìdánwò WAEC Lẹyin naa lo ki awọn ẹbi Barrister ku oriire pe wọn gbẹyin ologbe ọhun, paapaa lori ipa to fi silẹ ko to fi aye silẹ.
Igbakeji adari ajọ to n ri si ọrọ iṣẹlẹ pajawiri, Seji Saji to ba BBC sọrọ, fidi rẹ mulẹ pe awọn ri oku eeyan mẹrin to ku ninu ọkọ awọn ologun lagbegbe Adjei-Kojo.
Lẹ́yìn náà ló sọ pé, wọ́n padà sí inú igbó níbi tí wọ́n ti ń rán wọ́n níṣẹ́ láti lọ ṣe alamí àti kíkó àlàyé jọ nípa ibi tí wọ́n fẹ́ kọlù.
Eyi lo mu ki a ṣe agbeyẹwo ipa to ti ni l'ara awọn eniyan, ati ayika wọn.
Communications Commission ,NCC) ti fokan awon onibara won bale lorile ede
SERAP ni owo tabua-tabua ti awọn aṣofin bu fun ara wọn naa lodi sofin.
Nítorí OLUWA Ọlọrun, Ẹni Mímọ́ Israẹli ní:“Bí ẹ bá yipada, tí ẹ sì farabalẹ̀,ẹ óo rí ìgbàlà;bí ẹ bá dákẹ́ jẹ́ẹ́ tí ẹ sì gbẹ́kẹ̀lé Ọlọrun,ẹ óo lágbára.
N óo lé àwọn tí wọ́n wà níwájú lọ sí inú òkun, ní apá ìlà oòrùn,n óo sì lé àwọn tí wọ́n wà lẹ́yìn lọ sí inú òkun, ní apá ìwọ̀ oòrùn.
Kin lo de ti ọ̀rọ̀ ajínigbé ni Kaduna ń peléke síi?
Àríyànjiyàn Osinbajo àti PDP Mi ò kọ̀wé fipò sílẹ́ - Osinbajo Yemi Osinbajo: Ìgbákejì Ààrẹ tó gbọ́ nípa ẹ̀!
paapaa julo lori ironilagbara Orile ede India gba ominira  lowo
Leah Sharibu wa lara awọn ọmọbinrin ile iwe Dapchi ti ikọ agbesunmọmi Boko Haram jigbe ni Osu Keji, ọdun 2018, amọ ti wọn ko lati fi silẹ nitori o kọ lati kọ ẹsin kristẹni silẹ.
Oríṣun àwòrán, Tommyvicceti/twitter Títí di àsìkò yìí kò sí ẹni tó yé ìdí ti àwọn okùnrin fi fáríga lórí pé àwọn kò ni fún obìnrin lówó mọ.
Maṣe ka àwọn ohun mímọ́ sí yẹpẹrẹ.
’’O wa ro awon oludari ajo EFCC lati maa se kaare ninu igbiyanju won nipa gbigbogun ti iwa ibajẹ lonakona lawujo wa.
Bí wọ́n ti jókòó tí wọ́n fẹ́ máa jẹun, ojú tí wọ́n gbé sókè, wọ́n rí ọ̀wọ́ àwọn ará Iṣimaeli kan, wọ́n ń bọ̀ láti Gileadi, wọ́n ń lọ sí Ijipti, àwọn ràkúnmí wọn ru turari, ìkunra olóòórùn dídùn ati òjíá.
Odo Alhaji Bako, Luga, Wayam ati Nafsira ni odo mẹrin ti wọn n gba kọja lọs i ile iwosan ni eyi ti ko si afara lori ikọkan ninu wọn.
Ṣé òtítọ́ ni pé nǹkan oṣù obìnrin le ba òògùn ìbílẹ̀ jẹ́?
Ọpọ́n idẹ orí rẹ̀ ga ní igbọnwọ marun-un, wọ́n ṣe ẹ̀wọ̀n bí ẹ̀gbà ọrùn ati èso Pomegiranate yí ọpọ́n náà ká.
Ọna lati wa idahun sawọn ibeere yii lo mu ki BBC Yoruba fi imu finlẹ, lati mọ bi ọpọ awọn ayaba naa se di olori laafin.
Odun 2006 ni ebuka funra rẹ kopa ninu eto BB Naijia.
Efuraimu kò gbọdọ̀ jowú Juda mọ́,bẹ́ẹ̀ ni Juda kò gbọdọ̀ ni Efuraimu lára mọ.
Olamide ati Lil Kesh dá wàhálà sílẹ pẹ̀lú 'Logo Benz' Oni lo pe pe ọdun mẹsan an geerege ti ilumọọka olorin Rap nii, Olaitan Oladapo Olaonipekun 'Dagrin', ti wọn tun mọ si ‘Chief Executive Omo-Ita’ jade laye.
Lẹ́yìn ọlọ́pàá, VIO nìkan ló láṣẹ láti dá ọkọ dúró láìṣẹ̀ - Ọ̀gá VIO Eko Honorebu Favour ni iṣẹ ọwọ oun ni baba isalẹ oun ṣugbọn o sọ ipa pataki ti Arabinrin Betty Anyanwu Akeredolu ko ninu irinajo oṣelu oun.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ekiti Ghost Workers: Gómìnà Fayemi ní N400m ló ń sọnù ní ọdọọdún nítorí àwọn tó ń gba owó òṣù láì ṣiṣẹ́ 4 Bélú 2020 Oríṣun àwòrán, Google Gomina ipinlẹ Ekiti, Kayode Fayemi ti sọ wi pe iye owo ti ipinlẹ Ekiti n sọnu ni ọdọọdun to irinwo miliọnu Naira nitori awọn to n ṣiṣẹ lai gba owo ni awọn ijọba ibilẹ.
Bẹ́ẹ̀ ni kí o ṣe yan iṣẹ́ ìsìn àwọn ọmọ Lefi fún wọn.
 N kò mọ bí mo ṣe fẹ́ rí àwọn nkan ti wọn n bèèrè yìí, tí ń kó bá sọ síta.
 iye owó rẹ ̀ lójú pálí jẹ ́ bíi 5.
Wabara tun ni ,ohun to  n mu ki eto naa fa sẹyin ni  lati je ki gbogbo awon osise jegbadun ekunwo
Àwọn tí ń dẹ́rù bani nígbà tí wọ́n wà láàyè, wọ́n fi ìtìjú wọlẹ̀ lọ sí ìsàlẹ̀ ilẹ̀, wọn lọ bá àwọn tí wọ́n wà ní ipò òkú.
O ni ko si orilẹ-ede ti o le e de ibi giga lai jẹ pe o fi awọn to tọ si ipo to tọ dipo ọmọ wa ni ẹ jẹ ko ṣe.
Gẹgẹ bẹẹ lọrọ ri pẹlu ọkan lara ọmọ igbakeji Aarẹ orilẹeede Naijiria, Kiki Osinbajo pẹlu ọrọ to sọ nipa eto agbelewo BBNaija.
OLUWA wí fún Joṣua pé, “Lónìí yìí ni mo mú ẹ̀gàn àwọn ará Ijipti kúrò lára yín.
Gbogbo igbiyanju BBC lati ba awọn alaṣẹ ajọ TRACE sọrọ lo jasi pabo, nitori pe agbẹnusọ ajọ naa, Babatunde Akinbiyi, ko gbe ipe sori ẹrọ ibanisọrọ rẹ.
Ọmọkunrin naa ni iya rẹ to jẹ ọmọ ọdun mẹẹdogun, bo mọlẹ ki awọn obi rẹ maa ba a mọ pe o loyun.
Oríṣun àwòrán, Instagram/Lizzy Anjorin Ipolowo ọja asọ yii ni Lizzy kii fi sere rara lori ayelujara, bo si se n jo lati polowo fun awọn onibara, naa lo n kọrin lati fa oju wọn mọra.
Ileeṣẹ ọlọpaa bu ẹnu atẹ lu bi awọn eeyan ṣe n fi idajọ si ọwọ ara wọn bayii eyi ti wọn ni o ti wa n di lemọlemọ bayii ni ilu Ibadan ati ipinlẹ Ọyọ.
Dárúkọ àwọn tọ ń gbaṣẹ́ lọ́wọ́ NDDC tàbí kí o fojú winá òfin- Gbajabiamila sọ̀kò ọ̀rọ̀ sí Akpabio Agbofiro Odame ṣalaye pe nitori naa ni awọn ṣe ran ikọ ọlọpaa lọ si agbegbe naa, ti awọn ọlọpaa si tiraka lati ba a sọrọ, amọ niṣe lo bẹrẹ si ni fi ada le wọn, ti awọn ọlọpaa si salọ fun un.
“Alufaa kò gbọdọ̀ ṣọ̀fọ̀ débi pé kí ó fá irun rẹ̀, tabi kí ó gé ẹsẹ̀ irùngbọ̀n rẹ̀ tabi kí ó fi abẹ ya ara rẹ̀.
Atẹjade ọhun tun sọ pe iyawo El-Zakzaky fẹsun kan awọn oṣiṣẹ eleto aabo pe awọn ni wọn pa awọn ọmọ oun.
Ó ta díẹ̀ ninu òróró náà sí Aaroni lórí láti yà á sí mímọ́.
Ilé olódodo kún fún ọpọlọpọ ìṣúra,ṣugbọn kìkì ìdààmú ni àkójọ èrè eniyan burúkú.
Khadijah, obìnrin àkọ́kọ́ tó dẹnu ìfẹ́ kọ àyànfẹ́ rẹ̀ Ọwọ ṣìkún òfin ti tẹ Maina, alága àná fún ọrọ owó ìfèyìntì - DSS Ilé ẹjọ́ rán àwọn mérìndínlógún lẹ́wọ̀n gbére fún dídáná-sun Nusrat Ọgbẹni Adeniyi ni ọdun mẹsan an sẹyin ni wọn taare oun lọ sọgba ẹwọn ni ilu Ẹnugu pe ki oun wa nibẹ titi di igba ti wọn yoo fi yanju ẹjọ lori ẹsun ti wọn fi kan oun nipa wahala ija laarin ileto si ileto kan to waye nigba naa.
“Mú ojúlówó àwọn nǹkan olóòórùn dídùn wọnyi kí o kó wọn jọ: ẹẹdẹgbẹta (500) ìwọ̀n ṣekeli òjíá olómi, ati aadọtaleerugba (250) ìwọ̀n ṣekeli sinamoni, ati aadọtaleerugba (250) ìwọ̀n ṣekeli igi olóòórùn dídùn kan tí ó dàbí èèsún, 
Osatuyi ni lóòyọ́ ni wọ́n kéde, sùgbọ́n lẹ́yìn ìkéde wọ́n ó yẹ ki àjọ PPMC náà fi ikéde tirẹ̀ sita láti mọ iyé ti o tọ́ fún ará ilú láti maa ràá.
Àwọn ọmọ Peresi nìwọ̀nyí: ìdílé Hesironi ati ìdílé Hamuli.
Bì ohunkóhun bá ṣe Dino, àwọn agbófínró ni yóò forí fá a.
Iṣẹ́ ọnà ìtànná lílì ni wọ́n ṣe sára àwọn òpó náà.
Ìfinijoyè náà ni a ṣe lati ọwọ́ angẹ́lì kan tí ó kéde ara rẹ̀ bíi Jòhánnù, ẹ̀ni kannáà tí a pè ní Jòhánnù Onítẹ̀bọmi nínú Májẹ̀mu Titun.
Àwọn òṣìṣẹ́ pápákọ̀ òfúrufú MMA2 ṣẹ́welé ìyansẹ́lódì Òṣìṣẹ́ ẹka arinrinajo ọkọ̀ òfúrufú Nàìjíríà fagilé ìyanṣẹ́lódì Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Àwọn òṣìṣẹ́ pápápọ̀ òfurufú ní Ìpínlẹ̀ Eko fi ẹ̀honú wọn hàn Awọn oṣiṣẹ ń bere fun ki ijọba ṣe agbekalẹ igbimọ awọn oṣiṣẹ ijọba ti ile iṣẹ irina ofurufu atawọn nkan mii ti wọn n bere.
Nkan bii ẹgbẹrun mẹwa awọn ọmọ orilẹede Naijiria ni iwadi si sọ wipe o ti padanu ẹmi wọn ninu irinajo ẹni-ori-yọ-o dile yii laarin osu marun pere ninu ọdun to kọja.
Fulani ni Ojukokoro ati ainitẹlọrun awọn ọga SARS ati awọn agbofinro SARS lo ba SARS de ibi to wa yii.
A tún ní alufaa àgbà tí ó wà lórí ìdílé Ọlọrun.
Baba kebe n kwara dahun ibeere nla to n fa ariyanjiyan lagboole Fuji lori eni to da ere Fuji sile.
Saulu bá pàṣẹ fún àwọn tí wọ́n wà lọ́dọ̀ rẹ̀ pé kí wọ́n ka gbogbo àwọn ọmọ ogun, láti mọ àwọn tí wọ́n jáde kúrò láàrin wọn.
Sùgbọ́n ìjọba ní awọn ṣe òfin náà láti mú kíí ààbò tó péye wà lóri ìlú, bótilẹ̀ jẹ́ pé àwọn ọmọ ẹgbẹ́ alátakò ríí gẹ́gẹ́ ọ̀nà láti mú adíkù bá ọ̀rọ̀ ti ará ìlú ń jà sí pé ìdílé kan ṣoṣo ló ti ń ṣe ìjọba láti ọdun 1967.
Mo rán oníṣẹ́ mi ṣiwaju rẹ òun ni yóo palẹ̀ mọ́ dè ọ́.
Nítorí náà ni mo ṣe pè é ní,‘Rahabu tí ń jókòó lásán.
A ò ní gbà kẹ́ẹ buwọ́lu ofin tí yó máa dí wa lẹ́nu lórí ayélujára Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Buns ni ọmọ mi jẹ tán ní ṣọ́ọ̀ṣì, ló bá di àwátì' Orileede Ghana n ta to ọgọrun Megawatts ina ọba ninu ina ti wọn n pese lati ibudo amunawa wọn fun orileede Côte d'Ivoire.
Ọrọ Ẹyan ni koko girama ti an gbe yẹwo loni.
Nígbà tí àwọn ará Siria rí i pé àwọn ará Israẹli ṣẹgun àwọn, wọ́n ranṣẹ lọ pe àwọn ọmọ ogun Siria tí wọ́n wà ni ìkọjá odò Yufurate, wọ́n sì fi wọ́n sí abẹ́ Ṣobaki, balogun Hadadeseri.
kí ẹnikẹ́ni tí ó bá paniyan lè máa sálọ sibẹ; kí ẹnikẹ́ni tí ó bá ṣèèṣì pa aládùúgbò rẹ̀, láìjẹ́ pé wọ́n ní ìkùnsínú sí ara wọn tẹ́lẹ̀, lè sálọ sí ọ̀kan ninu àwọn ìlú wọnyi, kí ó lè gba ẹ̀mí ara rẹ̀ là.
Koda, ni ilu to gbe dagba, Crowhurst, oju awọn alarinkiri ati ẹni ti ko pe ni wọn fi n wo alawọ dudu, ti ileewe rẹ kan si maa n ko ounjẹ jọ fun awọn ọmọ ti ebi n pa lorilẹede Ethiopia.
Láti ọja ajé, ọjọ́ kejila, oṣù kẹwàá, ọdún 2020, Fayose kò ni láànfàni láti kópa nínú ètò kankan nínú ẹgbẹ́ PDP, àyàfi tó bá wá túbá lórí gbogbo àwọn ọ̀rọ̀ tó sọ.
Wọn ni ijamba ina naa bẹrẹ lọjọru nigba ti awọn ẹlẹwọn kan sọ ina si ibusun wọn, ki wọn ba le ri ọna sa jade.
Gege bi minisita to n mojuto eto ifitonileti, asa ati igbodegba lorile-ede Naijiria, Alhaji Lai Mohammed, isakoso ijoba yii ko ni dekun lati ma salai se ojuse re lojuna lati pana ogun patapata lorile-ede yii.
Ìgbà tí iwin náà ń bọ̀ gbogbo ìsàlẹ̀ ilẹ̀ bẹ̀rẹ̀ sii lù kìkì bí ẹwìrì àggbẹ̀dẹ, gbogbo agbegbe ń pariwo bí ìgbà tí omi ńlá bá ń sọ̀kalẹ̀ lórí àpáta, ogunlọ́gọ̀ àwọn iwin ti wọn ti ń ṣe ìránṣẹ́ fún tọkọtaya yìí ni wọ́n dákẹ́ pátápátá tí wọ́n sá lọ bámúbámú, ẹ̀rù ba ènìyàn, ẹ̀rù ba ẹbọra.
Hana ń gbadura ninu ọkàn rẹ̀, kìkì ètè rẹ̀ nìkan ní ń mì, ẹnikẹ́ni kò gbọ́ ohun tí ó ń sọ.
Ninu ọrọ rẹ, Gomina Rotimi Akeredolu ni ipinlẹ Ondo n ri owo to to N600m si N700m pa wọle si ipinlẹ naa ni oṣooṣu.
ro o daa da a Onimọ nipa ihuwasi naa wa rọ awọn eniyan lati ri wi pe wọn lo agbara wọn lori ibinu fufu, nitori ohun ti eniyan lagbara le lori ni, ti ko si yẹ ko lagbara lori eniyan, ki o ma ba a fa wahala tabi laasigbo lawujọ.
O fikun ọrọ rẹ pe Tolu ko banu jẹ nigba to fẹ ku, o ni ẹrin wa loju Tolu nigba ti o dakẹ.
Tanzania ati Uganda ti darapọ mọ orilẹede Egypt to n gbalejo idije naa, Nigeria,Burundi, Mali, Cameroon, Morocco, Angola, Mauritania, Senegal, Madagascar, Algeria, Benin, Ghana, Kenya, Zimbabwe, Congo, Guinea, Ivory Coast, Tunisia, Guinea-Bissau ati Namibia gẹgẹ bi awọn ikọ ti yoo kopa ninu idije AFCON 2019.
Aarẹ ile aṣofin agba, Sẹnetọ Ahmad Lawan pẹlu olori ile aṣofin-ṣoju, Fẹmi Gbajabiamila si lo n ba aarẹ se ipade naa.
 o dìgbà tọmọ èkọ ́ sẹ ́ ifa ba to fojú ba odù ko to dẹni ara rẹ .
Ọgbẹ́ni Adegbola tó jẹ́ Eleruwa ti ilú Eruwa dórí oyè lọ́dún 1998, lẹ́yìn ti Oba Bolanle Olaniyan kú lọ́dun 1994.
Iroyin sọ wi pe, Ogundipe ti kọkọ sọ fun awọn ọlọpàá naa pe oun ni lati ba agbẹjọro sọrọ ki oun to le lọ ile ẹjọ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù PDP: Lọgan ní a máa fún Ambode ni tíkẹ̀ẹ̀tì Gómìnà to ba dárapọmọ́ wà 30 Ọ̀wàrà 2018 Oríṣun àwòrán, Idowu-Sowunmi Àkọlé àwòrán, O jọ bi igba pe aawọ laarin Gomina Ambode ati Asiwaju Tinubu ti pari 'Iwọ sáà tí sọ pé o fẹ tikẹẹti gómìnà labẹ ẹgbẹ́ òṣèlú wà, kíá làá fí fún ọ.
Ẹ̀yin alára mọ̀ dájú pé kò sí ẹnikẹ́ni tí ó ń ṣe àgbèrè, tabi tí ó ń ṣe ìṣekúṣe, tabi tí ó ní ojúkòkòrò, tabi tí ó ń bọ̀rìṣà, tí yóo ní ìpín ninu ìjọba Kristi, tíí ṣe ìjọba Ọlọrun.
Mo ti rí ọ̀pọ̀ wahala ati ìṣòro.
Ilu naa lo si sun mọju.
Ẹwẹ, ni iha ti awọn araalu to n sọ bẹẹ, Ọmọwe ni o ku diẹ kaato tori gomina gan ko tilẹ tii lo ju oṣu mẹfa lọ ti wọn si ti wa n sare da orin ko wa ṣe dun mẹrin mii.
 “Aare Muhammadu Buhari  GCFR gbagbo ninu sise iranlowo fun awon obirin ati awon odo  kiise fun gbi gbogun ti ise ati osi lawujo wa nikansoso sugbon lati so won di onise ara won ,ki won si gbogun ti iwa ibaje nipase awon eto idanileko lori ise owo fun awon omo orile-ede yi .
Ẹni tí ń wa kẹ̀kẹ́ lójoojúmọ́ tó tún sanra ṣọ̀wọ́n.
Ọmọ ọdun marun kan wa lara awọn eyan meji to ku lasiko ikọlu naa to waye lọjọ Satide, eyi ti wọn lo jẹ isẹ ọwọ awọn adunkookomọni.
Ó ka gbogbo àwọn Lefi tí wọ́n jẹ́ ọkunrin tí wọ́n dàgbà tó ọmọ ọgbọ̀n ọdún sókè, gbogbo wọn jẹ́ ẹgbaa mọkandinlogun (38,000).
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ẹgbọn-taburo ṣegbeyawo nipinlẹ Anambra 23 Èrèlè 2018 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Awọn araalu Agba ni eewọ ni igbeywao naa Awọn ara abule kan nipinlẹ Anambra lẹkun iwọ oorun guusu Naijiria, dana sun ile ijọsin awọn ọmọlẹyin kristi kan lẹyin ti alufa ijọ naa so ọkunrin kan ati aburo rẹ obinrin pọ gẹgẹ bi ọkọ ati aya.
Itán sọ fún wa pé ibẹ̀ náà ló ti mú un bọ̀.
Samuẹli dáhùn pé, “Kí ló dé tí o fi ń bi mí, nígbà tí OLUWA ti kọ̀ ọ́ sílẹ̀, tí ó sì ti di ọ̀tá rẹ?
O Fagunwa, Adebayo Faleti, Akinwumi Iṣọla, Lawuyi Ogunniran àti Oladejo Okediji ṣiṣẹ silẹ ki wọn to lọ3 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Assistant Commissioner of Police: Àwọn afurasí ṣá ìgbákejì kọmísọ́nà ọ̀gá ọlọ́pàá láàké dójú ikú2 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Ọlọ́pàá ìpínlẹ̀ kọ́ ní ojútùú ìṣòro ìjínigbé ilẹ̀ Yoruba - Onímọ̀ ọ̀rọ̀ ààbò Àwọn orílẹ̀èdè àjọ ECOWAS yóò máa ná owó kan nàá l'ọ́dún 2020 Seyi Awolowo, ọmọ-ọmọ Awolowo, kí ló ń wà lórí ètò BB Naija?
Ọdẹ aperin ṣìnà sínú Igbó Olódùmarè: gọngọ sọ
Ọba Lamidi Adeyẹmi, òṣìṣẹ́ adójútòfò àti Abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò kó tó jọba Dangote, jọ̀ọ́ nawọ́ ìrànwọ́ láti dá iléeṣé sílẹ̀ fún wa ní Ọyọ - Aláàfin rawọ́ ẹ̀bẹ̀ Aláàfin Ọyọ pé ọdún 48 lórí àpèrè Lord Lucifer ni ó kọkọ ni ènìyàn mílíọnù kan to wòó lóri Youtube- Yekini Bakare Ninu alaye ọrọ rẹ paapaa lori pe oun ko ni ki ẹnikankan ri awọn Ọba fin, Kabiesi ni ''eyikeyi Ọba ti koba bọwọ fun ipo rẹ ti o si n mu ọti tabi to n jo nile igbafẹ ko yẹ lẹni apọnle'' Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Bakare Mubarak: ọ̀pọ̀ èèyàn ló máa ń fẹ́ dúró sí ẹgbẹ́ mí tójú si máa n tì mí Lori ọrọ tawọn kan n sọ pe Alaafin ni ki Wasiu Ayinde ma dọbalẹ ki awọn Ọba kan, Alaafin ṣalaye pe ''Emi o ni ki Wasiu ma bọwọ faṣa Yoruba, yoo ṣe apọnle awọn Ọba ṣugbọn kii ṣe awọn ti ko fi ara wọn si ipo ọba'' Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ifa Priest: ọdún mọ́kànlá ni mo fi ṣe iṣẹ́ agbejọ́rọ̀ kí n tó gbọ́ràn si Ifá lẹ́nu Awọn Ọba wo gan an ni Wasiu ko le dọbalẹ fun?
Miss Africa 2018: Àwọn nkan tó ṣẹlẹ̀ ní Miss Africa 2018, Calabar
Ẹ̀mí kan bá jáde siwaju OLUWA, ó ní, ‘N óo lọ tàn án jẹ.
oju to wa ni Eleta nilu Ibadan, (Eleta Eye Institute) ati Standard Chattered
Àwọn ni ìjòyè ní Edomu, gẹ́gẹ́ bí ìlú wọn ní ilẹ̀ ìní wọn, Esau tí àdàpè rẹ̀ ń jẹ́ Edomu sì ni baba àwọn ará Edomu.
OLUWA sì ti ṣèlérí fún ọ pé, ìwọ ni o óo jẹ́ aṣiwaju àwọn eniyan rẹ̀, ati ọba wọn.
Ohun ti awọn ọmọdebinrin naa n lepa ni lati ri daju pe, awọn gbe ẹsẹ bakan naa, amọ ti ẹsẹ wọn ko ba dọgba, ẹni to ṣi ẹsẹ gbe lo kuna ninu ere naa.
A ti fi gbogbo àwọn tí ó gbẹ́kẹ̀lé iṣẹ́ òfin gégùn-ún.
Ọkan nínú àwọn ti ọ̀rọ̀ yìí kan bákan náà Samuel Anyanwu, sọ fun BBC pe ẹkun ibi ti òun ṣoju fun ni òun ni ki wọ́n dari ṣẹ́ o tọ́ si wọ́n lọ, ati pé oun ko gba iṣẹ́ kankan.
Nígbà tí wọn rí i pé wọ́n ti fi kọ́kọ́rọ́ ti gbogbo ìlẹ̀kùn yàrá orí òrùlé náà, wọ́n rò ninu ara wọn pé, bóyá ọba wà ninu ilé ìgbọ̀nsẹ̀ tí ó wà ninu yàrá orí òrùlé náà ni.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ìdílé tí ọkọ da ọmọ síta tóríi ojú Búlùú tí wọ́n ní bá BBC sọ̀rọ̀ Nigba to n gbe idajọ kalẹ lori rẹ, Onidajọ Oduṣọla ṣalaye wi pe oun ko ni fọwọ si gbigba beeli wolii Sọtitobirẹ atawọn ọmọ ijọ rẹ mẹfa ti wọn n jẹjọ pẹluu rẹ.
Koda, inu mi si n dun dẹyin.
Àkọlé àwòrán, Wọn ko ṣi ilẹkun Mọṣalaaṣi An-nur rara, debi ti awọn eniyan o wa a kirun.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Iléẹjọ́ fún Seyi Makinde láṣẹ láti yan adelé alága ìbílẹ̀ ní ìpínlẹ̀ Oyo Olóòtú ìjọba Gẹ̀ẹ́sì yan ọmọ Yorùbá ní Mínísítà Òṣèré tíátà, Kemi Afolabi dùbúlẹ̀ àìsàn ní ìlú Mecca Àṣírí mẹ́wàá tí mo mọ̀ nípa Boko Haram-Naomi Adamu Amọ, awọn aworan to lu ayelujara pa ọhun wa lati ibi ayẹyẹ kan niluu Kiserian, lagbegbe Nairobi lorilẹede Kenya.
Mò ǹ wá ọ̀dọ́ Lekki tó farapa láti fún wọn ní ìrànwọ́ - Anthony Joshua Oríṣun àwòrán, @jidesanwoolu Ilumọọka abẹsẹkubiojo ọmọ Naijiria nii, Anthony Joshua ti dara pọ mọ awọn gbajumọ ati eekanlu jakejado agbaye, to n bẹnu atẹ lu bi awọn ologun ṣe yinbon pa awọn oluwọde ENDSARS ni ilu Eko.
Ojuse wa tun ni lati seto itaniji fun awon ara-ilu , lati yera fun iru nnkan bee toripe, didi ati kiko iru awon  ounje bee mo ounje miiran yoo ba won je, o dara ki aa sora nipa kiko awon ounje ile-okere wole, ki a maa je eyi ti a ni lorile-ede wa, toripe, pupo awon ounje ohun ko sara loore”.
Ilú Èkó n fẹ̀ si, ṣùgbọ́n ọ̀nà kò fẹ̀ tó bi èrò àti ọkọ̀ ti pọ̀ tó, nitori eyi, sún-kẹrẹ fà-kẹrẹ ọkọ̀ kò jẹ́ ki ará ilú gbádùn.
Kò sí ẹni tí ó ń pe ẹjọ́ àre,kò sì sí ẹni tí ó ń rojọ́ òdodo.
Àwọn kan tẹ̀lée padà sílé, wọ́n sì ya àwòrán nínú ilée wọn.
Akure Kidnap: Ilé ẹjọ́ fi Wòlíì Alfa sí ẹ̀wọn ọjọ́ mọ́kànlelógún
Dáàbò bò wọ́n,kí àwọn tí ó fẹ́ràn orúkọ rẹ sì máa yọ̀ ninu rẹ.
O si tun paṣẹ fun pe ki ẹlẹwọn naa ko san owo itanran to le ni ẹgbẹrun lọna mejidinlọgọsan dọla fun ẹsun jibiti rẹ.
Wọ́n tẹ́ ẹ sí ibojì, pẹlu àwọn eniyan burúkú, wọ́n sì sin ín pẹlu ọlọ́rọ̀,bẹ́ẹ̀ ni kò ṣe ẹnikẹ́ni níbi,kò sì sọ̀rọ̀ ẹ̀tàn.
Joṣua bá to àwọn òkúta mejila tí wọ́n kó jáde láti inú odò Jọdani kalẹ̀ ní Giligali.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Àwọn ọ̀dọ̀ ti ń gbógun ti ara bíbó, ṣùgbọ́n ó ṣì wọ́pọ̀ Orilẹ-ede South Africa ní awọn ofin alagbara to gbogun ti ara bibo.
tun so pe “Sugbon a ko ni fun Sudan lowo laijẹ pe won yanju gbese to wa
Ẹni tí ó bá sì fẹ́ obinrin tí a kọ̀ sílẹ̀, òun náà ṣe àgbèrè.
“Ẹ dákẹ́ jẹ́ẹ́, kí ẹ sì gbọ́ ọ̀rọ̀ mi, ẹ̀yin erékùṣù,kí àwọn eniyan gba agbára kún agbára wọn,kí wọ́n súnmọ́ ìtòsí, kí wọ́n sọ tẹnu wọn,ẹ jẹ́ kí á pàdé ní ilé ẹjọ́.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Katsina Child sale: Obìnrin olówònààbì ta ọmọ rẹ̀ tuntun jòjòlò ní N300,000 2 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Oríṣun àwòrán, KATSINA POLICE COMMAND Ọwọ sinku ọlọpaa ti tẹ obinrin olowo naabi to ta ọmọ oṣu mẹrin fun iye owo to to ẹgbẹrun lọna ọọdunrun.
Ní ìgbà ayé àwọn tí ó ti kọjá, ó jẹ́ kí gbogbo àwọn orílẹ̀-èdè máa ṣe ohun tí ó wù wọ́n.
Nígbà tí o bá ṣe nǹkan tí ó bani lẹ́rù,tí ẹnikẹ́ni kò retí,o sọ̀kalẹ̀, àwọn òkè ńlá sì mì tìtì níwájú rẹ.
“Mú ọkunrin tí ó ṣépè náà jáde kúrò láàrin ibùdó, kí gbogbo àwọn tí wọ́n gbọ́ nígbà tí ó ṣépè gbé ọwọ́ lé e lórí, kí gbogbo ìjọ eniyan sì sọ ọ́ ní òkúta pa.
'Mo lè fọwọ̀ sọ̀yà fún yín pé Sunday Shodipe ti wà láhàmọ́ wa - Alukoro Ọlọ́pàá Oyo Nigeria Police Recruitment 2020: Àwọn ohun tí ẹ nílò fún àyẹ̀wò ìgbanisíṣẹ́ ọlọ́pàá tí yóò bẹ̀rẹ̀ ní Mon, Aug 24 Orí àkìtàn ni wọ́n ti rí ọkùnrin tó ń fi ìgbẹ́ jẹ Búrẹ́dì -Iléeṣẹ́ ọlọ́pàá Oyo Ọkùnrin tó dàgbà jù lágbàyé jáde láyé lẹ́ni ọdún 116 Nigba ti wọn gbe e de ile iwosan Solad Hospital.
8 Nítorí-èyí, èmi yíò ṣe àlàyé ohun ìjìnlẹ̀ yìí fún ọ, nítorí ó yẹ kí ìwọ mọ̀ àní gẹ́gẹ́bí àwọn àpostélì mi.
Nigba ta kan sileesẹ ọlọpaa ipinlẹ Eko lori isẹlẹ yii, alukoro fun ileesẹ ọlọpaa naa, Muyiwa Adejobi salaye pe, ileesẹ ọlọpa yoo fi ikede sita laipẹ.
Dokita naa pari ọrọ rẹ pe ni ṣe lo yẹ ki awọn eeyan gbe ẹnikẹni to ba ṣeṣe ninu ijamba ọkọ lọ sile iwosan, ki wọn si tun fi ọrọ naa to ileeṣẹ ọlọpaa leti kaka ki wọn ṣedajọ funra wọn.
O ni awọn ọmọ ilẹ naa gbọdọ ja fitafita lati maa tẹ siwaju lori rẹ nipa riri daju pe wọn ko fi aye silẹ fun awọn kan lati fi owo ra ipo Ọbalaye ilẹ naa.
"Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Buhari ṣètò N10 bílíọ́nù fún àtúnṣe ìletò tí wàhálà bàjẹ́ Day 13: Àwọn ńkan méje tí ẹ lè má mọ̀ nípa Igbákejì Ààrẹ Osinbajo #BBCNigeria2019 Ọsinbajo pe fun ọlọpa agbegbe Osinbajo: Ẹ dìbò fún Buhari, kí ẹ̀yà Yorùbá lé gbàjọba ní 2023 O ni ""Mi o ti i kọwe fipo silẹ o."
Sugbọn sa, Keyamo sọ lọjọ Iṣẹgun pe awọn oloṣelu kan ti fẹ ẹ gba isakoso eto naa.
Bakan naa ni igbakeji Aarẹ kẹdun pẹlu idile Jimoh Isiaq ti ibọn ọlọpaa pa niluu Ogbomoso atawọn mii naa to ti ba iwọde #EndSARS lọ.
Akala, to ni oun yoo jaa nija ni, tun salaye pe, ẹgbẹ oselu APC ko tẹle ofin pẹlu bi wọn se kede pe awọn ti yọ ọmọ oun nipo alaga ijọba ibilẹ.
Won mu omidan Qorane ni osu kinni, leyin ti o pada lati Mogadishu to je olu –ilu.
Ti ẹ ko ba gbagbe, Ọjọ Kẹtalelogun, Oṣu Kẹsan an, ọdun 2020, ni ijọba ipinlẹ Kwara pẹlu iranwọ Ajọ CACOVID ṣe ifilọlẹ awọn ohun iranwọ naa, ati bi wọn yoo ṣe pin ti yoo kari gbogbo eniyan.
Ṣugbọn Jesu yipada, ó bá wọn wí.
Alaga igbimọ to n ri si iroyin nile aṣofin naa, Ọmọwe Samuel Ọmọtọṣọ, ni ile gbe igbesẹ naa lẹyin ọpọlọpọ ifisun lati ọwọ olori ọrọ iṣẹ gbogbo nile aṣofin ọhun, Aṣofin Tunji Akinlẹyẹ ati abajade iwadii kan ti igbimọ ile naa ṣe.
Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí 2 sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
Ẹ sá fún ibinu OLUWAati ògo ọlá ńlá rẹ̀.
nítorí pé nígbà tí ó gbọ́ nípa ìyà tí n óo fi jẹ Jerusalẹmu ati àwọn tí ń gbé ibẹ̀, ó ronupiwada, ó rẹ ara rẹ̀ sílẹ̀ níwájú mi, ó fa aṣọ rẹ̀ ya, ó sì sọkún níwájú mi, mo sì ti gbọ́ adura rẹ̀.
Rodrigo, ọmọ Valencia lo da okuta si gaari Lampard ninu ifẹsẹwọnsẹ rẹ akọkọ ni idije Champions league gẹgẹ bii olukọni Chelsea.
O tesiwaju pe awon ohun ti won
Lapapọ bayii, eeyan 61,194 lo tu laarun naa ni Naijiria, nigba ti 52,304 ti ri iwosan, eeyan 1,119 lo si ti ba aarun naa lọ.
Ati pé kí n lè fi ìgboyà sọ̀rọ̀ tí àwọn eniyan yóo fi mọ àṣírí ìyìn rere 
Nígbàkúùgbà tí wọ́n bá jáde lọ láti jagun, OLUWA á kẹ̀yìn sí wọn gẹ́gẹ́ bí ó ti kìlọ̀ fún wọn tí ó sì búra fún wọn, ìdààmú a sì dé bá wọn.
Àkọlé àwòrán, Peter Tabichi ni alaanu to ba ami ẹyẹ Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Ninu awọn eniyan 382, 000 to ti lugbadi aarun yii, awọn eniyan 102, 000 ni akọsilẹ fasiti yii fidiẹ mulẹ pe wọn ti gbadun tan patpata bayii.
Kawu ni o di dandan ki igbimọ fidiẹ naa ri si eto iforukọsilẹ awọn ọmọ ẹgbẹ, eyi to maa n waye ni ọdun mẹfa mẹfa lati mọ bi ẹgbẹ naa se ni eeyan si.
 nitoripe o siwaju gbogbo awon omo afrika amerika ni ile asoju , ohun ni omo afrika amerika akoko ni kongresi u.
Mò ń dá ìdámẹ́wàá gbogbo nǹkan tí mo bá gbà.
Wọ́n mú àwọn eniyan mi lọ lọ́fẹ̀ẹ́, àwọn alákòóso wọn ń pẹ̀gàn, orúkọ mi wá di nǹkan yẹ̀yẹ́?
Sinmi ìwọ ọkàn mi, bíi ti àtẹ̀yìnwá,nítorí pé OLUWA ṣeun fún ọ lọpọlọpọ.
OLUWA ní,“Níṣojú yín ni n óo fi san ẹ̀san fún Babiloni,ati gbogbo àwọn tí wọn ń gbé Kalidea,fún gbogbo ibi tí wọ́n ṣe sí Sioni;èmi OLUWA ni mo sọ bẹ́ẹ̀.
O ni awọn gbiyanju lati ba awọn ileeṣẹ ologun sọrọ ṣugbọn awọn ko laanfaani lati ri wọn ba sọrọ.
Ile ẹjọ ti wọgile ẹsun pé Buhari parọ lori ẹkọ ọfẹ rẹ Gbàgbé ẹ̀sọ́ ara $40m rẹ pátápátá - Ilé ẹjọ́ sí Dienzani Kí a tó sanwó ajínigbé ní àwọn agbófinró dóòlà ọmọ Ọffa mẹ́fà -ODU Ẹ wo márùn ún lára àwọn tí ilé ẹjọ́ ti yọ kúrò nípò lẹ́yìn ìdìbò ọdún 2019 Abikẹ Dabiri jiṣẹ erongba ijọba Naijiria fawọn ti wọn n bọ lati South Africa: Ìjọba ti ṣetán láti tọ́jú àwọn ọmọ Naijiria tó ń bọ padà láti South Africa A ṣi n reti wọn ki wọn de layọ ni adura -Abike Dabiri.
Ọ̀pọ̀ ọ̀rọ̀ ìwúrí ni wọ́n fi bẹ̀ wá pé kí á jẹ́ kí àwọn náà lọ́wọ́ ninu iṣẹ́ oore-ọ̀fẹ́ yìí fún àwọn onigbagbọ.
Ta ló tó bó awọ rẹ̀,tabi kí ó fi nǹkan gún igbá ẹ̀yìn rẹ̀?
Ọjọgbọn Ramon Hermida jẹ olori iṣẹ iwadii naa sọ pe awọn dokita le maa sọ fawọn to ba laarun ẹjẹ riru lati maa loogun wọn lalẹ ki wọn to sun bayii lẹyin ti iwadii ti fidi rẹ mulẹ.
O kéré tán, ènìyàn 5 ló ti jáláìsí níbi ìṣẹ̀lẹ̀ ilé tó wó ọ̀hún Ọlọ́pàá Bayelsa ní àwọn ti kán lugbó láti wá ìyá Siasia 'Kò sí ǹkan tó jọ tòmátò tó ní májèlé ní Nàìjíríà' Sanwo Olu yan kọ̀míṣọ́nnà 25 àtàwọn olùbádámọ́ràn Amọ, oun ati iyawo rẹ ni wọn jọ ni ọkan ninu awọn dukia rẹ to wa l'Amẹrika.
Nígbà tí ọ̀gágun náà rí ohun tí ó ṣẹlẹ̀, ó yin Ọlọrun lógo, ó ní, “Lóòótọ́, olódodo ni ọkunrin yìí.
Èṣi àyẹ̀wò jáde, Gómìnà Bauchi ti ní aàrùn coronavirus báyìí Coronavirus wọ ìpínlẹ̀ Osun, èèyàn míì tún tí ni l'Eko, ó di èèyàn 46 tó níi ní Nàìjíríà Ṣugbọn Ajimobi ni bakan naa ni gbogbo ọmọ tun kopa ninu ijakulẹ ẹgbẹ APC ninu idibo gbogbogbo ọdun 2019 lọna kan, tabi omiiran.
Bí a ti ń lọ si Igbó Olódùmarè yí ẹ̀rù kò le bà mi ju bẹ́ẹ̀ lọ, bí iwọ bá ń ṣe ojúṣe rẹ gẹ́gẹ́ bí ẹ̀gbọ́n ti inú Ẹlẹ́dàá bá si dùn si ọkọ mi àfẹ́sọ́nà, òun kò ní ṣàìpadà dé ilé dandan.
Ori ẹrọ ayelujara la ti pade.
Àwọn tí wọ́n kọ òfin sílẹ̀ni wọ́n máa ń yin àwọn eniyan burúkú,ṣugbọn àwọn tí wọn ń pa òfin mọ́ máa ń dojú ìjà kọ wọ́n.
"O tẹsiwaju pe ''pẹlu iwe ipe nikan si ni awọn eeyan yoo fi wọle"", Ohun to o ni lati mọ nipa Darasimi Bamiloye Oríṣun àwòrán, Darasimi/Lawrence Oyor Instagram Oluwadarasimi Mike-Bamiliye (gẹgẹ bi apeja orukọ rẹ) kẹkọ gboye ninu imọ ede Gẹẹsi ni fasiti Babcock, Naijiria."
Bí a bá gba gbogbo ohun tí wọ́n fẹ̀mí tẹ̀,ṣé wọn kò ní kú bí aláìgbọ́n?
Mo lè sọ arúgbó dí ọmọge nígbàkúgbà - Hakeem Effect Kí ni àwọn olùdíje ìpínlẹ̀ Eko fẹ́ ṣe nípa ètò ìlera?
Electricity new tariff: ''Àjọ NERC ti fún Disco láṣẹ láti padà sí owó tàríìfù tuntun iná mọ̀nàmọ́ná''
” Wọ́n lérò pé Dafidi kò le ṣẹgun ìlú náà.
Mo ti sọ̀rọ̀ ju bí ó ti yẹ lọ,n kò sì ní sọ̀rọ̀ mọ́.
Nígbà tí a ké pe OLUWA fún ìrànlọ́wọ́, ó gbọ́ adura wa, ó sì rán angẹli rẹ̀ láti mú wa jáde kúrò ní Ijipti.
Aare ni:“Awon omo orile ede Naijiria gbodo
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìfipábánilòpọ̀: Ọlọ́pàá ní ọkùnrin tó fipá bá ọmọ ilé ìwé UNILAG lò, tún jí pátá rẹ̀ 20 Ẹrẹ̀nà 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Se ni awọn eeyan yanu sile, lai lee pa de nile ẹjọ to n gbọ awọn akanse ẹsun, nigba ti ẹjọ kan afurasi kan ti wọn lo fipa ba ọmọ ile iwe fasiti UNILAG meji lo pọ.
(Sibẹsibẹ kò lè ran àwọn Filistia lọ́wọ́, nítorí pé lẹ́yìn tí àwọn ọba àwọn Filistini jíròrò láàrin ara wọn, wọ́n ní “Ewu ń bẹ nítorí pé yóo darapọ̀ pẹlu Saulu, ọ̀gá rẹ̀.
Ibi tí ó tilẹ̀ ti ń kánjú díẹ̀ ló kù kí ó gbàgbé egbòogi pàtàkì kan báyìí tí ń bẹ nínú àdó, bẹ́ẹ̀ ni bí kò bá mú eléyìínì lọ́wọ́ àtimọ ọ̀nà igbó náà yóò jẹ́ ìṣòro.
Àfàìmọ̀ ká máa dá ìforúkọsílẹ NIN dúró tórí ewu coronavirus- Mamora Pásítọ̀ Adeboye kéde ààwẹ̀ ọjọ́ 63 fọ́mọ ìjọ rẹ̀, ariwo sọ lórí ayélujára Losu Kejila ọdun to lọ, ikọ Amọtẹkun tun ni wọn lo pa akẹkọọ kan ti wọn ni adigunjale ni.
 lilanu silẹ ọpa ti o ngbe ẹjẹ ni ayika ọpọlọ le fa [ [ ẹfọri ] ] .
Ìwọ ni àwọn baba wa gbẹ́kẹ̀lé;wọ́n gbẹ́kẹ̀lé ọ, o sì gbà wọ́n.
Ọkùnrin kan dèrò àtìmọ́lé lórí ẹ̀sùn fífi ipá bá ọmọ bíbí inú rẹ̀ méjì lòpọ̀ Ọwọ́ ọlọ́pàá tẹ ọkùnrin mẹ́rin pẹ̀lú orí èèyàn ní ìlú Akure Amọ lati igba ti iṣẹlẹ ọhun ti waye ni awọn eeyan ti n lakaka boya lootọ ni olori Badirat Ola si wa ninu aafin Oyo abi bẹẹ kọ.
Nígbà tí Jakọbu rí wọn, ó ní, “Àwọn ọmọ ogun Ọlọrun nìyí.
Nítorí náà ìfẹ́ ni àkójá òfin.
Isele yii ni elekefa iru re nile iwe lodun 2018.
Alukoro ileeṣẹ ọlọpaa, Ọgbẹni Femi Joseph sọ fun BBC Yoruba pe awọn to dana sun ile ijọsin naa pa ọkan lara awọn ọlọpaa to lọ dena wahala.
Ewe, ni kete tis aa keji bere Oparanozie gba ami ayo miiran sagbon, ki Amarachi Okoronkwo o to fi oba le lori lati so apapo ami ayo ohun di merin.
Ijamba ọkọ naa ṣẹlẹ ni opopona Shagamu si Abẹokuta nínú eyi ti ẹ̀mí ọrẹ gomina ba a lọ ṣaaju idibo aarẹ to n lọwọ kaakiri Naijiria bayii.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ààrẹ Gani Adams sọ ẹni tí Yorùbá yóò dìbò fún ní ọdun 2019 #BBCNigeria2019 Kí ló jó Káàdì ìdìbò 15,000 ní iléeṣẹ́ INEC ní Abia?
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Akomolede ati Aṣa lori BBC:Wo ìrúfẹ́ ìgbeyàwó méje tó wà nílẹ̀ Yorùbá àti ojúṣe Alárinà Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Fídíò, EndSars Protest;Oluwapọ̀nmile sọ ìrírí rẹ̀ lọ́wọ́ àwọn sójà tó fìyàjẹ́ ní Ibadan3 Bélú 2020 Lekki Toll Gate: CNN vs Lai Mohamamed rèé o!
Ẹ yà wọ́n sọ́tọ̀ fún ẹbọ ohun jíjẹ, ati ẹbọ sísun ati ẹbọ alaafia, kí wọ́n lè ṣe ètùtù fún àwọn ọmọ Israẹli.
‘Alẹ́ làwọn ọkùnrin fẹ́ bá mi jáde, torí mo kọ ilà’ Oluwo gba Aláàfin nímọ̀ràn pé kí olorì máa dé adé Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ọpẹmipọ Bamgbọpa: Obìnrin gbọdọ̀ kó ara rẹ̀ níjànu lórí ọ̀rọ̀ ìfẹ́ nínú tíátà Sise afihan ounjẹ yii yoo fi agbara fun ero awọn eniyan wi pe, ohun to kọju si ẹnikan, ẹyin lo kọ si ẹlomiran.
ó sì rí i bí àwọn ọmọ Israẹli ti pa àgọ́ wọn, olukuluku ẹ̀yà ni ààyè tirẹ̀.
“a o se ojuse wa pelu iberu Olorun , a o si gbiyanju lati ri I pe awon to kun oju osuwon ni won fun ni anfaani yii”.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Àrà méèrírí lórí òkè táwọn ará ìlú Idanre l'Ondo ń gbé láyé gbọ́ngan sẹ́yìn O ni ko din ni ọọdunrun ọkọ akẹru latori orilẹ-ede Ghana to fara ko ọwọja ẹnubode ti Naijiria ti naa.
Èèyàn 239 míràn ṣẹ̀ṣẹ̀ kó COVID-19 ní Nàìjíríà Ajọ to n gbogun ti ajakalẹ aarun lorilẹ-ede Naijiria, NCDC ti kede pe eeyan ojilelugba o din ẹyọ kan miran ti kun iye awọn to ti ni aarun COVID-19 lorilẹ-ede Naijiria.
E wo awon to wa ni Rann ti won to ogorin egberun ti won wa ni ewu ebi ati aisan lorisiirisii lataari aisi ounje ati oogun ni ibudo yii.
Aṣiri to tu yii lo yi ọrọ ijọba Cameroon pada lori awọn oniṣẹ ibi wọnyii.
Diẹ ree lara awọn ohun ti ẹka kọọkan yoo janfaani rẹ ninu eto isuna ọdun 2020 nipinlẹ Eko.
Mo rí i pé, nǹkankan wà tí ó burú ju ikú lọ: òun ni obinrin oníṣekúṣe.
Àwọn aṣekúpani tún ti pa ọmọ ọdún 16 ní Akinyele nípìnlẹ̀ Oyo Ileeṣẹ to n ri si ọrọ iṣẹ agbegbe ni ipinle Eko ni opopona to lọ si Oworonsoki ni yoo kọkọ di titi pa fun oṣu mẹta, lẹyin ti iṣẹ abala naa ba pari ni wọn yoo sun si iha Island.
Wo àwòràn ohun tó ṣẹlẹ̀ nílé ìjọsìn Sotitobire tí wọ́n sun ní àná Mí o mọ ǹkan kan nípa fọ́nran ìpolongo COZA- Davido Ọlọ́pàá bẹ̀rẹ̀ ìwadìí lórí ikú olùṣirò owo táwọn agbénipa pa ní Ikorodu Gbajue ń lọ orúkọ mi láti gba owó- Mama Rainbow Igba o le ọgbọn, 230 awọn aṣofin lo dibo ki wọn yọ ọ lori ẹsun aṣilo ipo ti awọn mẹtadin ni igba, 197 si ta ko o.
Alaboyun ko gbọdọ rin ninu oorun, bibẹẹkọ, aafin ni yoo fi ọmọ inu rẹ bi.
Bi ẹ ba lọ si ẹka karakata, awọn ọmọ ilẹ Aṣia lo n jaye ọba nibẹ.
Àwọn ẹlòmíràn á fi owó fẹ́ ikú wá ilé wọ́n á wí pé àwọn fẹ́ obìnrin, àwọn ẹlòmíràn a fi owó fẹ́ gbèsè wọ́n á wí pé àwọn fẹ́ ìyàwó, àwọn ẹlòmíràn á ti ìtirí wọ̀bìà wọn a sọ ìfẹ ìyàwó pàtàkì nù.
'À ń lọ ilé-ẹjọ́ kòtẹ́milọ́rùn fún ẹ̀kúnwó owó oṣù ẹlẹ́wọ̀n' Ẹ̀yin ẹ̀ṣọ́, ẹ kò gbọdọ̀ fààyè gba jíjí àpótí ìdìbò ní Kogi àti Bayelsa- Buhari Kin lo fa iyatọ ọjọ idibo ipinlẹ Kogi si tawọn to ku?
Oba Lekan Balogun tun salaye siwaju sii pe gbogbo igbese
ó sì kó àwọn ọmọ Israẹli jáde kúrò láàrin wọn,nítorí pé ìfẹ́ rẹ̀ tí kì í yẹ̀ wà títí lae.
Oluwo kọ̀ láti sọ̀rọ̀ lórí àwọn afọbajẹ tó fẹ́ yọ ọ́ nípò, aráàlú fọ́n síta láti fẹ̀hónú hàn Ìdùnnú subú layọ̀ nípìnlẹ̀ Ọyọ́, àwọn tó dé láti Lebanon sọ ọmọ wọn ní Seyi Mo ṣetán láti ṣe Paulo Costa bí ọṣẹ sẹ ń ṣojú lọ́la- Israel Adesanya Èèmọ̀!
Ní ìlú Paris ni ayẹyẹ ọhun ti waye lọsan ọjọ́ Aje.
Ó wà ní àkọsílẹ̀ bẹ́ẹ̀ pé, “Kò sí ẹnìkan tí ó jẹ́ olódodo; kò sí ẹnìkankan.
Wọn yóo mu ún, wọn yóo sì máa ta gbọ̀n-ọ́n-gbọ̀n-ọ́n, wọn yóo máa ṣe bí aṣiwèrè nítorí ogun tí n óo rán sí ààrin wọn.
Bi awọn ipinlẹ to ni Coronavirus ni Ọjọ Abamẹta ṣe lọ ree: Eko-53 Gombe-21 Oyo-19 Delta-12 Ondo-11 Plateau-10 Ebonyi-9 FCT-6 Kwara-6 Kaduna-5 Rivers-3 Ogun-2 Anambra-2 Imo-2 Ekiti-1 Ènìyàn 156 míràn ló tún kó Coronavirus ní Nàìjíríà ní ọjọ́ Ẹtì Ajọ to n gbogun ti ajakalẹ arun lorilẹede Naijiria, NCDC ti kede pe eeyan 156 miran ti lugbadi arun Covid-19 ni Naijiria.
Ṣugbọn OLUWA sọ fún Mose pé, “O óo rí ohun tí n óo ṣe sí ọba Farao; ó fẹ́, ó kọ̀, yóo jẹ́ kí àwọn eniyan mi lọ, fúnra rẹ̀ ni yóo sì fi ipá tì wọ́n jáde.
 wọ ́ n máa ń sọ èyí fún ẹni tí ó bá ń kọjá ààyè rẹ ̀ ni .
O ni: Ä se idanilekoo yii pelu ifowosowopo Banki Naijiria lati fi je ki igbe aye awon abiyamo ipinle Benue tubo rorun sii ki ebi ma pa ilu.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù George Weah: Nàìjírìa fìyà jẹ Ààrẹ Liberia pẹ́lú ikọ̀ rẹ̀ 12 Owewe 2018 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, George Weah kópa nínú ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ ọlọ́rẹ̀ẹ́sọ́rẹ̀ẹ́ pẹ̀lú Nàìjírìa Aarẹ orilẹede Liberia George Weah pada sori papa ni ọmọ ọdun mọkanlelaadọta nibi to ti kopa ninu ifẹsẹwọnsẹ ọlọrẹsọrẹ pẹlu orilẹede Naijiria lọjọ Iṣẹgun nilu Monrovia.
Awọn to maa n ṣẹ owo ilẹ okere, Bureau De Change, sọ pe idi ti owo naira ṣe n lọ soke silẹ ko ṣẹyin awọn eeyan kan.
Ẹ wó o títí dé ìpìlẹ̀ rẹ̀.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ekiti Election: Èyí ń rán wa létí pé iná èèsì kò gbọdọ̀ jó wa ní ẹ̀ẹ̀kejì 13 Agẹmo 2018 Awọn aworan yii lo n sọ nipa awọn isẹlẹ̀ to waye lọdun 2014 lasiko eto idibo gomina ni ipinlẹ Ekiti.
Ènìyàn 653 míràn tún kún iye àwọn tó ní COVID-19 ní Nàìjíríà Ẹgbẹ́ Boko Haram pa àwọn òṣìṣẹ́ UN márùn ún tó wá ṣiṣẹ́ ìrànwọ́ ní Nàìjíríà Bí o bá ń se N-Power tóo sì ti ríṣẹ́ sí ibòmíràn, olè ni ọ́!
Awọn to n ṣa ike rọba Gbogbo ike omi ati ọti ẹlẹrindodo ti awọn eeyan ba mu kii ṣofo bẹẹ si ni kii dọti ilẹẹlẹ inu ipagọ.
"Ẹ̀yin òṣèrè tíátà, ẹ ní ṣùúrù de àsìkò Ọlọ́run, ẹ máṣe kánjú kọjá kádàrá - Madam Ṣajẹ Ọdọọdún làwọn ọmọ ònilẹ̀ ń dà wá láàmú ní Soka, kí Sunday Igboho tó gbà wá sílẹ̀ - Àwọn olùgbé Soka ""Se ẹ mọ pe oniruuru àhesọ lo ti wáye lati igba ti ọ̀rọ̀ coronavirus ti de, awọn kan ni inú ẹrànkò kan ti wan n pe ni Pangolin, sùgbọ́n ọ̀rọ̀ ti oni broiler yii tu ya mi lẹ́nu."
Ninu wọn la ti ri Gomina ipinlẹ Oyo tẹlẹ ri Senatọ Abiola Ajimobi ti wọn yan si ipo igbakeji alaga ẹgbẹ fun Iwọ oorun Guusu.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Ìyá Tíṣà lòdì sí kí n mutí, fagbó tàbí sìgá' Avengers: Infinity War Sinima yii mi igboro tìtì lagbaye debi pé wọn gbee de ipinlẹ̀ Eko ni Naijiria.
Àwọn ìbátan wọn gẹ́gẹ́ bí wọ́n ti tò wọ́n sinu ìwé jẹ́ ẹẹdẹgbẹrun ó lé mẹrindinlọgọta (956).
Láàrin ọdún meje tí ọ̀pọ̀ oúnjẹ wà, ilẹ̀ so èso lọpọlọpọ.
Lara ohun to rọ mọ owo iya yi ni ki ijọba mu adinku ba iye ile ẹko fasiti to wa ni Naijiria lati mejidinlọgbọ si maarun.
Obaseki la Ize-Iyamu mọ́lẹ̀ wọlé ìbò gómìnà lẹ́ẹ̀kejì ní ìpínlẹ̀ Edo Kí ló le è mú kí agbábọ́ọ̀lù subú, kó sì kú lásìkò ìfẹsẹ̀wọ̀nsẹ̀?
Lara awon osise ijoba ti bu enu ate lu ijoba Aare Uhuru Kenyatta pe, ko bobi ara si oro awon osise, bakan naa ni ko tun gbogun ti iwa ibaje to gbinle bi olu oran, ni eyi ti won n sowo ti o ye ki won fi san ekunwo fun awon osise kumo-kumo.
 Àgbàrà òjò ò lòun kò ní iléé wo, sùgbọ́n onílé ni kòní gba fún un” Sẹ́ láyà lètò, ètò ni sẹ́ láyà
Mose, Aaroni ati àwọn olórí àwọn ọmọ Israẹli ka àwọn ọmọ Kohati ní ìdílé-ìdílé gẹ́gẹ́ bí ilé baba wọn.
Ọjọ Ẹti, ọjọ kẹjọ, oṣu kẹsan an ọdun 2017 ni wọn sin Baba Faleti ni First Baptist Church, Isokun ni ilu oyo ni ipinlẹ Oyo ni guusu Iwọ oorun Naijiria.
O ni kọmiṣọna ọlọpaa ti gbẹṣẹ kuro lori ofin naa pẹlu ọrọ pé a kò le sọrọ lori awọn iye eniyan to ku sinu ija naa ati awọn to farapa mọ pẹlu awọn oniroyin.
ni wọ́n ń ṣàkóso àwọn tí wọn ń ru ẹrù, ati àwọn tí wọn ń ṣe oríṣìíríṣìí iṣẹ́ mìíràn.
Ìwà ìbàjẹ́, àbẹ̀tẹ́lẹ̀ gbi gbà fún ọ̀pọ̀lọpọ̀ ọdún ló da ọbẹ̀ ohun amáyédẹrùn danu.
Láti ìsinsìnyìí lọ, ẹnikẹ́ni tí ó bá jalè ati ẹnikẹ́ni tí ó bá búra èké, a óo yọ orúkọ rẹ̀ kúrò ní ilẹ̀ náà.
"Oríṣun àwòrán, @HQNigerianArmy ""Ere ti wọn ri nidi tita ẹja gbigbẹ ti wọn n ko wọle ni wsn n lo lati fi ra eroja ounjẹ, eso, oogun ti wọn n lo, awọn ohun eelo ojoojumọ ninu ile, ẹya ara ọkọ ati awọn ohun eelo miran to wulo fun isẹ apaniyan ti wọn rawọ le."
” Mose sì ti ọwọ́ bọ abíyá rẹ̀ pada; nígbà tí ó yọ ọ́ jáde, ọwọ́ rẹ̀ pada sí bí ó ti wà tẹ́lẹ̀.
Samuẹli bá wí fún un pé, “Ìwà òmùgọ̀ patapata gbáà ni èyí.
Oladimeji Solomon, ọmọ Naijiria to fi London ṣe ibujoko ni United Kingdom ba BBC sọrọ lori ipa ti ofin konile-o-gbele to ṣẹlẹ ni UK ni bayi.
Ni ọdun 1980, o gba oye imọ ijinlẹ akọkọ ninu imọ nipa ibagbepọ ẹda, Sociology, ni fasiti Warwick.
Àarẹ Trump sọ̀rọ̀ náà, nígbà tí ó ń gbàlejò akẹgbẹ́ẹ rẹ̀ láti Nàíjíríà, Àarẹ Muhammadu Buhari nílé ìjọba Amẹrika, White House.
Awon agbe obinrin nipinle Nasarawa ti pe ijoba apapo ati ijoba ipinle lati seranlowo lori eyawo ti ko lere lori, latari ati mu igberu ba eto ogbin won.
Dájúdájú bí obinrin alaiṣootọ tíí fi ọkọ rẹ̀ sílẹ̀,bẹ́ẹ̀ ni o ti ṣe alaiṣootọ sí mi, ìwọ Israẹli.
Àwọn mààlúù igbó yóo kú pẹlu wọn,bẹ́ẹ̀ sì ni àwọn ẹgbọ̀rọ̀ mààlúù ati àwọn akọ mààlúù ńlá.
Mobolaji Johnson: Kíkọ́ Eko Bridge, wíwó ibojì òkú Ajẹlẹ àti àwọn mánigbàgbé míì tó ṣe l'Eko Yinka Quadri: Mo dúpẹ́ pé Ogogo jẹ́ ọ̀rẹ́ mi!
O ni iyawo baba oun naa maa n fi iya jẹ oun leyin ti ija bẹ silẹ laarin baba ati iya oun, ti baba oun si gbe obinrin naa niyawo.
 Ọ ̀ rúnmìlà tí gbàgbé pe bí ojo oore ba pé asiwèrè a gbàgbé àti pé ìwọ ̀ n ní oore .
Risikat gan an fun ra rẹ ko le sọ pato bo ya oun ati ọkọ rẹ le pada jọ maa gbe pọ.
 a ) nínu ìmọ tíátà ní yunifásitì kan náà ní ọduń 1995 .
Ọmọ Risikat olójú búlúù méjèéjì jẹ̀bùn oríire àti ìfà ńlá Ẹ má bínú pé mo kọ́kọ́ ní akẹ́kọ̀ọ́ mẹ́wàá péré ni wọn kó nílé ìwé Kankara - Garba Shehu Àìmọ̀kan ló mú mi hu ìwà tí mo hù kọjá sẹ́yìn, Jonathan dárí jì mí - Dino Melaye Ẹ́ tú èékánná lọ́rùn Sowore, ẹ kò ní ẹ̀rí láti ba ṣẹjọ́ - Ẹgbẹ́ Amòfin Amẹ́ríkà Irú iṣẹ́ wo ní Funke Akindele rán sí Bukunmi Oluwasina, tó fa ariwo lórí ayélujára?
 Aare orile-ede Kenya ati orile-ede Senegal ti jiroro saaju lori oro ina mona-mona.
Aregbesola, ẹni to n lọgun pe igbọran san ju ẹbọ ruru lọ lasiko ifilọlẹ ibudo kan nilu Abuja, tun gba awọn araalu nimọran pe ki wọn mase so mọ ara wọn tabi bu ara wọn so lasiko yii, nitori ede ara kii sa fun ara, ti di ọrọ itan.
Ko pe ti awọn ọmọ iya mejeeji naa bẹrẹ iṣẹ ti ọkọ rẹ ka wọn mọ oko ti o si pa Judith.
Ọpọ lo n sọ pe ko yẹ ko ribẹ, wọn sọ pe ibikibi ti ẹni to ni aarun naa ba n gbe loyẹ ki wọn o ti tọju rẹ.
Àwọn àjèjì sì ti jẹ ilẹ̀ yín run níṣojú yín.
African Games: Àwọn akọni Nàìjíríà padà sílé pẹ̀lú àmì ẹ̀yẹ 121 láti Morocco
Lẹ́yìn wọn ni Bẹnjamini ati Haṣubu ṣe àtúnṣe apá ibi tí ó kọjú sí ilé wọn.
"Ọrọ naa dabi ayo tita ni, asiko ọtọọtọ ni awọn to n ta ayo ma n mu olori ayo wọn jade.
Ireti ni pe aarẹ aarẹ yoo pada de si orilẹede Naijiria ni ọjọ kọkanlelogun oṣu karun yii kan naa.
Ó fi ààyò ọmọ rẹ̀ rúbọ, bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé Ọlọrun ti ṣe ìlérí fún un nípa rẹ̀, 
Eto abo ti dẹnukọlẹ gidigidi, ijinigbe si wa kaakiri"" ni ọrọ ti Ọbasanjọ sọ ni oṣu kinni."
Bi o tilẹ jẹ pe gẹgẹ bi oniroyin aṣewadii, mo ti kọ ọpọlọpọ iroyin nipa Senegal atawọn ileeṣẹ epo.
O fi kun pé, àwọn ń retí ǹkan ti wọ́n yóò ṣe , sùgbọ́n ó ṣe pàtàkì kí ki gbogbo ọ̀dọ́ ṣe ara wọn lọ́kan látu yanjú ìṣòro tó wà nílẹ̀.
Òtútù o dára fún eegun àgbà.
alatako rẹ, egbe People’s Democratic Party (PDP), nigba ti o ni iye ibo  218,207.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: DSS tu akọroyin ti wọn mu silẹ Akọ̀ròyìn Reuters méjì rẹ́wọ̀n he ní Myanmar Ẹ̀sun olè ají-ìwé-àkọsílẹ̀ ní a fi kan Akoroyin Samuel Afara tuntun já, Gómìnà rè sodò Nitori naa, ọlọpaa naa wa sile wa ni ọganjọ oru lati wa gbe iya mi ti mọle fun ẹsun kan ti wọn pe ni fifi ero ti ti ofin ko gba laaye han.
Ṣugbọn irú àwọn bẹ́ẹ̀ yóo ní ìpọ́njú ní ti ara.
”Ọ̀kan ninu àwọn iranṣẹ Joramu bá dáhùn pé, “Eliṣa ọmọ Ṣafati, tí ó jẹ́ iranṣẹ Elija, wà níhìn-ín.
Oró agbọ́n leè wo àìsàn jẹjẹrẹ ọmú sàn, wo ohun tí wàá lò pọ̀ mọ́ra wọn Sinimá àwòdamiẹnu, Ẹ̀fáńjẹ́líìsì jìyà àjẹmumi nílé aṣẹ́wó l'Ejigbo ní ìlú Eko Wo ìtàn ayé gbajúmọ̀ adigunjalè méje nílẹ̀ Yorùbá Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí 6:30 Fídíò, Akomolede ati Aṣa lori BBC: Mọ̀ si nípa oríṣìí ẹ̀ka ìsọ̀rí ọ̀rọ̀ àti ìwúlò wọn, Duration 6,308 Owewe 2020 Ọba Mohammed bin-Salman ti Saudi yọ ọmọ rẹ̀, Fahad, Abdulaaziz àti àbúrò rẹ̀, Ahmed kúrò nípò nítorí ìwà àjẹbánu3 Owewe 2020 Fídíò, Akomolede: Bolaji Faleke ni Olùkọ́ tó ń kọ́ wa ní àṣà oge ṣiṣe lórí BBC Yorùbá1 Owewe 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
ile-itura naa , ko daa si ọrọ rẹ, ti o si faake kọri pe, ki o maa tan oran rẹ.
Nigba to n sọrọ ninu atẹjade kan, Soyinka ni iyọnipo Sanusi tumọ si pe, awọn ara Ariwa Naijiria ko tii ṣetan, lati gba otitọ ati asa igbalode laaye.
Ṣugbọn nnkan ko ṣẹnu 're mọ lati igba ti wọn ti ti ibode pa.
Iko omo ogun sawari ipago naa lojo Aiku(Sunday), lagogo mesan an owuro.
Ondo Kidnap: Ìyá ọmọ tí wọn jí gbé wà nílé iwòsàn tí wọn ń fa omi sí lára
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Tóo bá pá lórí, Mílíìkì sóyà àtàwọn ǹkan mẹ́ta yìí leè mú irun rẹ hù padà!
 kòkòrò-àrùn jẹ ̀ dọ ̀ jẹ ̀ dọ ̀ c ni ó máa n fa àrùn náà .
Ó fún àwọn ọmọ Geriṣoni ní ọkọ̀ ẹrù meji ati akọ mààlúù mẹrin, gẹ́gẹ́ bí iṣẹ́ ìsìn wọn.
Bakan naa, ajo NFF tun ki agbaboolu owo eyin iko Super Eagles, Leon Balogun ti o pe ogbon odun lojobo(Thursday).
Wọn wa n fapa janu pe ọlaju ti ba pataki ibeji jẹ ni awujọ wa, ti wọn si tun fi idi rẹ mulẹ pe, ti ibeji to ba n saisan, ba jẹ ẹwa, ara rẹ yoo da.
Orilẹ-ede Russia ri eyi gẹgẹ bi aṣeyori nitori awọn ni wọn kọkọ pese oogun to n se iwosan fun aarun Coronavirus ni agbaye.
Lere ni gbese tiijọba ipinlẹ Ekiti jẹ kalẹ jẹ N59.
Ti ẹ ba wo awon ohun ti o n sele lori
Àwọn tí wọn ń kó àwọn ọmọ Israẹli ṣiṣẹ́ bá jáde tọ̀ wọ́n lọ, wọ́n sọ fún wọn pé, “Ẹ gbọ́ bí Farao ti wí; ó ní òun kò ní fún yín ní koríko mọ́.
Ẹni to bori: Benin Egypt vs Algeria.
”Jehoṣafati dáhùn pé, “Tìrẹ ni èmi ati àwọn eniyan mi, a óo bá ọ lọ jagun náà.
Ẹ jẹ́ kí n máa lọ́, ẹ kí ará ilé gbogbo, ẹ tún ẹ̀yìn mi ṣe, ọkùnrin ń lọ, ẹ bá mi kéde fún gbogbo àwọn ènìyàn pé alágbára lọ bí alágbára sí ibi tí àwọn alágbára ń lọ, ènìyàn pàtàkì lọ bí ènìyàn pàtàkì sí ibi tí àwọn ènìyàn pàtàkì ń rè, kí tọmọdé-tàgbà bọ̀ọ̀kìnní máṣe wí pé èrò igbó Olódùmarè kò ni í bọ̀ mọ́, kí gbogbo àwọn ọmọlúwàbí inu ayé si máa ṣe ìrètí eégúnlẹ́gi.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Arakunrin kan n ju asia orilẹede Sudan lati oju ferese ọkọ rẹ bi awọn mii naa ṣe tu sigboro lati ba awọn ara wọn to ku ṣe ajọyọ.
Lagos Explosion: Àwọn akẹ́kọ̀ọ́ iléẹ̀kọ́ Bethlehem ń gbàdúrà òwúrọ̀ lọ́wọ́ ní ìbúgbàmù wáyé
Ọgbẹni Trump, ti ko figba kan maa sọ pe oun ko jẹbi ẹsun naa, yoo kopa ninu idibo fun saa ọlọdun mẹrin miran ni oṣu Kọkanla ọdun 2020.
Aya aare, Aisha Buhari atawon èèkàn kaakiri Naijiria ti bẹ̀rẹ̀ ifowosopọ̀ lori gbigbogun ti iwa ibaje yii.
EFCC sọ pé wọ́n ti fi pańpẹ́ ọba mú ọmọ ọdún mẹ́rìndínlógójì afurasi oní jìbìtì kan ní ìlú Ilọrin.
Sirika lo soro yii nibi idanilẹkọọ ọlọjọ meji lori ipenija to n de ba idagbasoke
Mose bá tún kígbe pe OLUWA, ó ní, “Kí ni n óo ṣe sí àwọn eniyan wọnyi, wọ́n ti múra láti sọ mí lókùúta.
ifesewonse olorejore ohun yoo waye ni ose meji si idije boolu agbaye ohun.
 Ẹnì tí ogun bá jà lójú rẹ ̀ rí , kò ní bẹ ọlọ ́ run kí ogun tún wáyé ní ojú òun .
Wọ́n tún wí lẹẹkeji pé, “Haleluya!
Noa tẹ́ pẹpẹ kan fún OLUWA, ó mú ọ̀kọ̀ọ̀kan ninu àwọn ẹran ati àwọn ẹyẹ tí wọ́n mọ́, ó fi wọ́n rúbọ lórí pẹpẹ náà.
Ti mo ba ku bayii, awọn eeyan yoo ri nnkan rere tọka si nipa mi.
Eku gba ìjọba ní Estonia, ìjọba pàdánù owó gọbọi Ilé ìwòsàn New Jersey ṣ'àṣìṣe ṣiṣẹ́ abẹ kìndìrín fún aláìṣàn l'Amẹrika Ilé ẹjọ lé Ọba Èrúwà kúrò lórí Àpèrè lẹ́yìn ọdun 21 Àwọtẹ́lẹ̀ ọkùnrin àti Ìdọ̀tí Kilo méje ṣekú pa Ìgalà Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Cancer: Àṣe ara mi ni iso ti n run gbogbo bí mo ṣe n ṣèrànwọ́ lórí jẹjẹrẹ Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Benin: UK get plans return Nigeria 'Okukor' wey dem tiff for 19 century Di bronze cock bin dey for Cambridge University Jesus Hall until dem start to dey tok about how di artwork enta da and im link to slavery.
igbimo asofin, asofin Ita Enang soro ohun di mimo fun awon akoroyin niluu Uyo.
Wọ́n yan àwọn ọmọ Lefi, arakunrin wọn yòókù láti máa ṣe àwọn iṣẹ́ mìíràn tí ó kù ninu ilé Ọlọrun.
Sugbọn bi awọn mejeeji se n gbiyanju pe ki oju opo naa pese ọpọ idahun fun awọn to n wa imọ, sibẹ, o dabi ẹni pe awọn ibeere kan si wa to nira lati wa idahun si loju opo naa.
Asafu ni olórí, àwọn tí ipò wọn tún tẹ̀lé tirẹ̀ ni: Sakaraya, Jeieli, Ṣemiramotu, Jehieli, Matitaya, Eliabu, Bẹnaya, Obedi Edomu ati Jeieli àwọn tí wọ́n ń ta hapu, tí wọ́n sì ń tẹ dùùrù.
Ilé iṣẹ́ ọlọ́pàá ń ṣe ìpàdé pẹ̀lú Naira Marley lọ́wọ́lọ́wọ́ Ọ̀gá àgbà àjọ ọlọ́pàá Nàìjíríà ní àwọn ń fí àsìkò yìí pé àwọn ọdọ́ Nàìjíríà pé, gbogbo àriwo wọn ni àwọn ti gbọ́ lórí àwọn ìwà ìbàjẹ́ tí àwọn kan ń hù nínú iṣẹ́ ọlọ́pàá pàápàá jùlọ àwọn ikọ SARS.
Wọ́n ń kígbe pé, “Oriṣa ńlá ni Atẹmisi, oriṣa àwọn ará Efesu!
•Bakanaa, o seese ko nira diẹ lati gbe iwe irinna jade, o si to ẹgbẹrun lọna igba awọn eeyan to n beere fun iwe asẹ irinna, ti wọn ko tii gbe iwe wọn jade, ti wọn yoo si gbe ẹnu ọna awọn ileesẹ yi ti lasiko ti idakureku fi ba eto isejọba yi.
A o maa mu wa fun yin ohun to ba selẹ nibẹ.
Oríṣun àwòrán, Fellipe Abreu Àkọlé àwòrán, Orilẹede Ghana lo n pese eso koko julọ lagbaye, idi ree ti awọn mọlẹbi kan nigberiko se maa n fi owo pamọlati sin agbẹ onikoko sinu posi.
Food Measurement: Wo oríṣiríṣi ọ̀nà tí ò lè fi wọn oùnjẹ́ bó bá rú ọ lójú
Ó bá dá Ṣimei lóhùn, ó ní, “Mo búra fún ọ pé ẹnikẹ́ni kò ní pa ọ́.
Ó kọjú sí ìta gbangba tí ó wà lẹ́bàá Ẹnubode Omi láti àárọ̀ kutukutu títí di ọ̀sán, níwájú tọkunrin tobinrin ati àwọn tí ọ̀rọ̀ òfin náà yé, gbogbo wọn ni wọ́n sì tẹ́tí sí ìwé òfin náà.
Jakọbu, ranti àwọn nǹkan wọnyi,nítorí pé iranṣẹ mi ni ọ́, ìwọ Israẹli.
lati ọwọ Denise Mitchell ni Bicester Eyi ti wọn n beere ju Iroyin BBC Ikọ eleto ilera Nigba ti ara awọn eeyan ba ti ya tán, awọn ohun eelo ija kan a ṣi ṣẹku ni agọ ara wọn lati gbogun ti irufẹ ikọlu naa sii Awọn eroja igbogun ti ni agọ ara kii ṣe titi aye nitori pe o le dinku ni agbara ti ọjọ ba ṣe n pẹ sii Ti o ba ti ni coronavirus, ara rẹ yoo maa ja fun ẹ nitootọ ṣugbọn a ko tii mọ odiwọn igba ti agọ ara ẹ le ja fun mọ lẹyin igba akọkọ too ni coronavirus Kini odiwọn akoko ti coronavirus le ṣe lara eeyan?
láti fi ìmọ̀ ìgbàlà fún àwọn eniyan rẹ̀,nípa ìdáríjì ẹ̀ṣẹ̀ wọn,
" Oríṣun àwòrán, Adetomi Akin Ẹlẹ̀wọ̀n 1,993 la ri ẹ̀rí pé wọ́n sá lọ́gbà ẹ̀wọ̀n méjì ní Ìpínlẹ̀ Edo- Ìjọba Nàìjíríà Oríṣun àwòrán, @kizento_ Oludari eto iroyin nileeṣẹ to n ri si ọrọ abẹle ni Naijiria, Mohammed Manga lo fi ọrọ yi to awọn akoroyin leti.
Àìpẹ́ yìí ni ìjọba ìpínlẹ̀ náà fún wọn ní ìwé iṣẹ́, ṣùgbọ́n Kọmíṣọ́nà fún ètò Ẹ̀kọ́ ní Ìpínlẹ̀ Kaduna, Ja'afaru Sani, sọ wípé wọ́n pinu láti lé wọn lọ nítorí wípe ọ́gbọ́n àlùmọ̀kọ́rọ́yí ni wọ́n gbà wọlé.
Má ṣe dá òmùgọ̀ lóhùn gẹ́gẹ́ bí ìwà òmùgọ̀ rẹ̀,kí ìwọ pàápàá má baà dàbí rẹ̀.
Ẹ woo ọrọ ree lẹnu ọlọrọ.
Ninu ọrọ tirẹ, alaga ẹgbẹ PDP ni ipinlẹ Ekiti ti a ri pe o buwọlu iwe ti Lere Olayinka fi sọwọ si wa sọ pe ayederu iwe ni Fayose n gbe ka ati pe ohun ko buwọlu iwe kankan.
Owurọ kutu ọjọ Aiku ni operation Burst ri wọn mu lẹ́gbẹ odo Ofiki loju ọna Tapa /Igangan ni ijọba ibilẹ ariwa Ibarapa nipinlẹ Oyo.
Ibrahim jẹ́ ẹnìkan tó ní ìfẹ́ àti ìbẹ̀rù Ọlọ́run gidi gaan ni.
Seal ti ta awo rẹkọọdu to le ni ogun miliọnu sita jakejado agbaye, to si ti gba ami ẹyẹ Grammy nigba mẹrin ọtọọtọ.
Ogun eeyan lo di oloogbe latipasẹ akọtun ikọlu miran to waye lọsan ọjọ isẹgun.
Gẹgẹ bi baba Ọsun, Oloye Adigun Iyanda, to n setọju ere Ọsun ti figbe ta fun araye, ti iya Ọsun, Oloye Ọṣunkẹmi Ọṣunwẹdẹ, to n bọ Ọsun naa si kin lẹyin, wọn ni Ọba ti ta ere Ọsun silẹ okeere, ki Ọsun to taku si papakọ ofurufu, ti baba Ọsun si lọ gbe nibẹ.
Timi Frank lo fi ẹgbẹ oselu APC silẹ ni Osu Kẹjọ, ọdun 2018 peẹu ileri wi pe oun ko ni dakẹ lati ma sọrọ tako iwa ibajẹ lawujọ.
Àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ wá sọ́dọ̀ rẹ̀, wọ́n bi í pé, “Kí ló dé tí o fi ń fi òwe bá àwọn eniyan sọ̀rọ̀?
Ìlọ́po meji owó ọjà tí ẹ óo rà ni kí ẹ mú lọ́wọ́, ẹ mú owó tí ó wà lẹ́nu àpò yín níjelòó lọ́wọ́ pẹlu, bóyá wọ́n gbàgbé ni.
Ile iṣẹ rẹ METL pẹka ni orileede Afrika mẹfa ti wọn si n ṣe aṣọ,ounjẹ ati ororo.
Iwadii ti fi mulẹ pe wọn le fun ẹnikẹni lẹjẹ ti wọn ba ti n jẹun ti eroja aṣaraloore pe sinu ẹ lasiko.
Ayọ̀ ati ìdùnnú ni yóo máa wà ninu rẹ̀,pẹlu orin ọpẹ́ ati orin ayọ̀.
 kò sí ìlú kan tí kò ní ọjà tirẹ ̀ , sùgbọ ́ n àwọn ọjà ń lá kan wà tó ti di ti gbogbo gbo .
Láyé òde òni o, Braille yìí tí wọ́pọ̀ lóríṣìíríṣìí èdè káàkiri àgbáyé.
Ó tún wí pé, “Bí ìjọba Ọlọrun ti rí nìyí: ó dàbí ọkunrin kan tí ó gbin irúgbìn sí oko; 
Sleeping naked: Ìdí mẹ́ẹ́rin tí sísùn ní ìhòhò lé gbà ṣe ara a rẹ l'óore
Ọjọ Arafa jẹ ọjọ ti awọn musulumi ya sọtọ patapata lati gba adura fun idariji ẹsẹ ti ọdun to kọja ati eleyii ti n bọ.
Iye wọ́n jẹ́ ẹgbẹrinla ó dín aadọta (2,750).
se pupọ ti ẹ wa lati ilu okeere lati wa darapọ mọ eto ibura aare Buhari.
Lẹyin naa ni wọn mu awọn ọlọpaa lọ si Ikenne ti babalawo to jẹ ẹni kẹrin, ti wọn si ni oun lo ni ki awọn lọ ge ori oku naa fun irubọ.
Ajọ eto ilera l'agbaye, WHO, ti gba awọn eeyan nimọran pe ki wọn o ma ṣe lo oogun tabi agbo ti ko ti wọn ko se ayẹwo rẹ fun itọju Covid-19.
Arúfin ni ọkùnrin náà jẹ́ a sì máa jalè lọ́wọ́ àwọn olówó àti ọlọ́ á.
Àwọn olórí alufaa ati àwọn aṣiwaju àwọn Juu bá gbé ọ̀rọ̀ Paulu siwaju rẹ̀.
Gboyega Adeoye to je alukoro fun ẹgbẹ atunbi ilẹ Ekiti, Ekiti Rebirth Organisation (ERO ) nigba ti o'n ba BBC Yoruba sọrọ ni lootọ ni wọn mu iwe wa fun awọn pe ki awọn san owo ki wọn to le ri patako ipolongo, sugbọn ''wọn o jẹ ki gbedeke ọjọ mẹrinla pe ki wọn to sofin lati maa wo patako wa'' Ọgbẹni Adeoye ni awọn setan lati tẹle ofin ipinlẹ naa sugbọn ko yẹ ki ijọba to wa nigboro ma dun kukulaja mọ araalu.
O ni nigba to ya ni Zaharadeen n beere owo rẹ ti Farawa si ni oun ko tii ni owo naa ni eyi to dija laarin awọn mejeeji.
Gbogbo awon dukia ti awon eniyan fi owo ilu ra ni a o ta, ti a o si da owo naa pada si apo ilu , fun anfaani  awon omo orile ede Naijiria.
ti o yẹ ki won maa gbosuba ati iyin  fun,
Trump impeachment: Trump kò fìdí janlẹ̀ tán, àmọ́ níbo ni yóò jásì?
Kii ṣe igba akọkọ ti iru nkan bayii maa ṣẹlẹ ni orilẹ-ede China ni yii.
O tún ṣàlàyé pé àkókò tí òkìkí òun kàn jùlọ nínú iṣẹ́ tíátà ni òun ṣe ìgbéyàwó.
Bẹ́ẹ̀ ni ẹ óo ṣe jẹ́ ọmọ-ẹ̀yìn mi.
agbesunmomi sekupa nijoba ibile Goronyo nipinle Sokoto.
”  Ojogbon Osinbajo sapejuwe ojuse ajo to n ri si oro ile-okere gege bi eti ilu sagbaye, ti o si se koko lati se ojuse won bi o se to ati bi o se ye, lati fi apere ohun le le nile, ati lati ro ijoba ni gbogbo igba lati se awon ohun ti o to lasiko.
Kò sọ̀rọ̀ nípa àwọn ohun tí ó yẹ kí wọ́n ṣe sí ìyàsọ́tọ̀ àwọn ọmọ Roma ní Serbia…
Ṣé ẹ wá rí i bí ìbànújẹ́ tí ẹ faradà gẹ́gẹ́ bí Ọlọrun ti fẹ́, ti yọrí sí fun yín?
Ahmed Musa ati akegbe re Moses Simon ti darapo mo igbimo to n sakoso DW sports.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Bakan naa ni itan igbe aye Basọrun Gaa yii kọ wa lati mase se ika nitori ati oore, ati ika, ọkan kii gbe, ati ile aye yii si la ti n jere gbogbo iwa ta a ba hu, ta a si gba ẹsan rẹ lọrun pẹlu.
” Dafidi ní kí ó máa lọ, ó sì lọ ní alaafia.
tun gba awọn nimọran loju opo Twitter rẹ pe ki wọn ma ṣe fẹ iyawo lawin.
Weah je omobibi inu agbaboolu teleri fun orile-ede Liberia, iko
Igbele naa yoo maa waye laarin agogo meje irọlẹ si meje aarọ.
Kí ni àwọn olùdíje ìpínlẹ̀ Eko fẹ́ ṣe nípa ètò ìlera?
Ó wí fún wọn pé, “Mo ṣàkíyèsí pé baba yín kò fi ojurere wò mí bíi ti àtẹ̀yìnwá mọ́, ṣugbọn Ọlọrun baba mi wà pẹlu mi.
Nígbà tí ìparun ń bọ̀ wá bá gbogbo nǹkan báyìí, irú ìgbé-ayé wo ni ó yẹ kí ẹ máa gbé?
O ṣeeṣe ko jẹ awọn oṣiṣẹ ni ileewosan ati awọn oṣiṣẹ eto ilera ni yoo kọkọ ni anfaani abẹrẹ ajẹsara yii.
Oloye Obasanjo, lasiko to lọ se kara o le si ọọni salaye pe iwọde to n lọ yika Naijiria yii ti fun ijọba lanfaani lati sọ fun araalu pe oun naani wọn.
Mikaaya sọ gbogbo ohun tí ó gbọ́, nígbà tí Baruku ka ohun tí ó kọ sinu ìwé fún wọn.
Obinrin náà bá lọ sọ ìtumọ̀ àlọ́ náà fún àwọn ará ìlú rẹ̀.
O ni irufẹ alaisan bẹẹ yoo ni lati san afikun owo tabi ki mọlẹbi rẹ sun ni ita gbangba.
Ọmọ ọdún márùn-ún àti àgbà mẹ́rin ló bá ìṣẹ̀lẹ̀ ọ̀pá epo bẹntiróò tó gbiná ní Abule Egba lọ láìpẹ́ yìí.
Ninu atẹjade kan ti agbẹnusọ fun ileeṣẹ ọlọpaa Ekiti, Ọgbẹni Sunday Abutu fi sita ṣalaye pe ado oloro IED, igbo, ọti ati foonu meji lawọn ri ninu awọn ọkọ naa.
Mi ò fẹ́ ìrànwọ́ ẹgbẹ́ òṣèré, àwọn kọ́ ló kóbá mi- Chief Kanran Wo ọ̀nà tí o le è gbà láti má san àfikún owó iná ẹ̀lẹ́ńtíríìkì tuntun Mi o tíì rí olórí tó fẹ́ràn Naijiria tó Baba Obasanjo- Yoruba Council of Elders Buruji Kashamu jẹ́ ènìyàn tó nífẹ̀ aráàlú- Gómínà Dapo Abiodun Ọlọpaa naa fi kun un pe eyi tako ofin Criminal Code ipinlẹ Ogun, ọdun 2006 Adajọ Majisirati oun B.
Ní ọjọ́ náà, n óo jẹ àwọn tí ń fo ẹnu ọ̀nà kọjá bí àwọn abọ̀rìṣà níyà, ati àwọn tí ń fi ìwà ipá, ati olè jíjà kó nǹkan kún ilé oriṣa wọn.
Jọ̀wọ́ jókòó tì mí, máa bá mi ṣiré, nítorí mo wà ní èmi nìkan, alábàáṣiré sì ń wù mi.
Atiku Samuel lasiko to n ba BBC Yoruba sọrọ ni eto ọrọ aje Naijiria naa yoo gbooro sii, amọ awọn ipenija kọọkan yoo wa ni ọdun akọkọ ti wọn ba bẹrẹ si ni san owo osu osisẹ tuntun naa.
Ni deede aago mẹ́wàá oni,  gbogbo
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Wo ìròyìn, àwòrán àti fídíò èké nípa ìwọ́de EndSARS Super Eagles, ẹ máṣe gbá bọ́ọ̀lù fún Nàìjíríà mọ́ nítorí ìhà tí ìjọba kọ sí ìwọ́de EndSARS - John Ogu Ará Eko, ẹ pariwo ó tó gẹ́ẹ́ lórí làásìgbò tó gbòde torí ìwọ́de EndSARS - Sanwo-Olu Ọ̀tá Yorùbá ló lo ìwọ́de láti dojú ogun kọ wá - OPC Àwọn ọ̀tá Nàíjíríà tó fẹ́ dojú ìjọba bolẹ̀ ló wà lẹ́yìn ìwọ́de EndSARS"" Ó parí ni ohùn tó gbẹnu ọ̀pọ̀ ọmọ Nàíjíríà lẹ́yìn ọ̀rọ̀ Buhari Ìwọ́de EndSARS kìí ṣe ọ̀rọ̀ ẹlẹ́yàmẹ̀yà, ara ti kan àwọn èèyàn ni - Afenifere Buhari kọ́ ni ìṣòro wa, bó ṣe wà láti láéláé rèé - Fr Mbaka O wa rọ awọn alatilẹyin ẹgbẹ naa nilẹ yii ati loke okun, lati dẹkun fifi owo sọwọ sinu apo asunwọn ẹgbẹ naa ti wọn fi n ko owo jọ, eyi towo inu rẹ bayii jẹ miliọnu lọna mẹtadinlaadọjọ naira."
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ẹ wo adúrú ẹnu tí mó n bọ́ - Jaiye Kuti Wo orílẹ́èdè tí wọ́n tí ń dáwó ìsìnkú ara wọn pámọ́ Ayédèrú Ọ̀ṣun ni wọ́n ń bọ lónìí, kìí ṣe ojúlówó - Bàbá Ọlọ́ṣun tún figbe ta ''Àwọn ọmọ wa ma ń wọ ọkọ̀ ojú omi láìsí ẹ̀wù ìdàábòbò nítorí àti kàwé'' Tinubu ní kò jẹ́ kí àwọn ọmọ bíbí Eko gbérí nínú òṣèlú Koda, wọn sọ ọpọ aayan ti wọn n se lati ri daju pe awọn ko gbagbe asa ati ise wa, ti wọn si n fi kọ awọn ọmọ wọn ti wọn bi si ajo pẹlu.
O ni iko olote naa fe pa awon eniyan to n gbe ni agbegbe Kaleri.
Dandan ni kí n fi ìyà jẹ ìlú náà,nítorí kìkì ìwà ìninilára ló kún inú rẹ̀.
Ẹ̀mí àgbèrè ẹ̀sìn ti mú wọn ṣáko, wọ́n ti kọ Ọlọrun wọn sílẹ̀ láti máa bọ ìbọkúbọ.
" Onwoye awujọ kan ni amulo ọmọogun kọ lọrọ naa kan Sugbọn ninu ọrọ ti onimọ nipa eto aabo, ajagunfẹyinti Ayo Olaniyan, o ni alaafia lo se pataki julọ ni awujọ ọmọniyan.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù ISIS: Orílẹ̀-èdè mẹ́wàá tí ẹgbẹ́ alákatakiti Islamic State n fínna mọ́ ní àgbáyé 9 Agẹmo 2020 Oríṣun àwòrán, Others Àkọlé àwòrán, Awọn orilẹ-ede ti IS ti ni ipa l'agbaye Awọn alakatakiti ẹsin Islam ti wọn n jẹ Islamic State lo kéde pe ki gbogbo musulumi agbaye darapọ mọ awọn lọdun 2014.
Ajọ WHO sọ pe egboogi to n dena iba ṣe koko fun amojuto ati iparun aisan naa - o si n polongo ṣiṣe titọ pinpin ni awọn orilẹede ti ibà ti wọpọ ju.
Gomina ọhun lo fi ọrọ naa lede nibi ayẹyẹ ikẹyin to ṣe fun iya rẹ.
Àjẹsára ibà jẹ ̀ dọ ̀ jẹ ̀ dọ ̀ a jẹ ́ àjẹsára tó má a n dènà ibà jẹ ̀ dọ ̀ jẹ ̀ dọ ̀ a.
Gbogbo ọ̀rọ̀ yìí ni Natani sọ fún Dafidi, gẹ́gẹ́ bí ó ti rí i lójú ìran.
Ọjọ diẹ lẹyin ipade ọhun ni igbimọ awọn gomina lorilẹede Naijiria ba gba gbogbo awọn gomina to wa nibi ipade naa nimọran pe ki wọn lọ ṣe ayẹwo ara wọn nitori iroyin to n jade pe lara awọn to wa nibi ipade naa ti ko arun ọhun.
Ile-ise aare bu enu ate lu iroyin eleyi ti won ka si aheso oro lasan-lasan ti ko si ododo oro ninu re, eyi ti ogbeni Akin Oshuntokun ti o je agbodegba egbe CNM te jade lojo meji seyin pe, ibugbamu ado oloro sekupa eniyan méjídínláàdọ́rùn ún  nipinle Borno, ti n se ipinle ti o kogun si eka ila oorun orile-ede Naijiria.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Mr Macaroni sọ nípa eré tí Fraky freaky, Sugar Daddy, You are doing well, freaky spicy fẹ́ Baba rẹ wọle ba nibẹ pẹlu ìbọn to ṣẹṣẹ to tan, o ni inu baba oun bajẹ, to si fẹ pa oun, o yin ìbọn mọ oun nitootọ amọ ori ko oun yọ, ti oun si sa jade.
Aare Muhammadu Buhari ba ijoba ati gbogbo eniyan ipinle Ogun atawon omo bibi ile Egba lai yo ebi ara ati ololufe Oba naa ku oriire.
Ṣé ẹ̀yin gbọ́rọ̀-gbọ́rọ̀ ni ọ̀gá àwa sọ̀rọ̀-sọ̀rọ̀.
Àwọn ọba Yorùbá kan rèé tí wọ́n rọ̀ lóyè, tí ọba míràn jẹ lójú ayé wọn Lóòótọ́ lòògùn owo wà ṣùgbọ́n ayédèrú aláwo ló ń lo ẹ̀yà ara -Ẹlẹ́búìbọn Bí Fayemi bá tasẹ̀ àgẹ̀rẹ̀, àwọn oníbáwí rẹ̀ wà l'Ekiti-Peter Fatomilọla Ogun ebi ni Nàìjíríà ń bá fínra lọ́wọ́, ogun coronavirus kò gbọdọ̀ kún un-Oluwo Ǹjẹ́ ẹ mọ̀ pé Peter Fatomilola ni 'Papa Ajasco' àkọ́kọ́?
Agbẹnusọ fun ile ise ọlọpaa ni ipinlẹ Eko, Chike Otti, sọ pe isẹlẹ naa to waye laago meje abo, owuro Ọjọbọ ni wọn ni o buru ju nkan ti eniyan le mẹnu ba lọ.
 Àwọn ohun èèlò tí Olóògbé Olóyè Obafemi Awọ́lọ́wọ̀ lò gbẹ́yìn Gomina Makinde gbàlejò àwọn Imam lásìkò àjàkálẹ̀ àrùn Coronavirus Dòkítà tó ṣe iṣẹ́ abẹ fún oyún inú l‘Amẹrika ló ń sọ Yorùbá yìí, bíi ẹní la oyin Ìgunnukó nìyí, òrìsà Tápà, òrìsà olówó àti tọlọ́mọ""Nibi ti awọn eniyan ko ba tiẹ ti to ogun to n ṣe sinima kan, ọpọ ero ti yoo ṣu jọ sibi ti wọn ti n ya sinima lati woran lee tako ofin ijọba, abi bawo ni a ṣe fẹ bọwọ fun ofin tita kete sira ẹni?"
Ki Olorun si tu awon ebi ati ore oloogbe naa ninu.
Ó wà ní àkọsílẹ̀ pé, “Orúkọ Ọlọrun di ohun ìṣáátá láàrin àwọn tí kì í ṣe Juu nítorí yín.
Àràfá 2018: 100,000 òsìsẹ́ aláàbó ni Saudi lò fún ààbò tó péye
Delila mú kí Samsoni sùn lórí ẹsẹ̀ rẹ̀, ó bá pe ọkunrin kan pé kí ó fá ìdì irun mejeeje tí ó wà ní orí Samsoni.
Ṣáájú kí àrùn Coronavirus tó wọlé sí ilẹ̀ South Africa, ó to àwọn èèyàn bíi ẹgbẹ̀rún lọ́nà mẹrinlelọgbọn, tí wọn máa ń gbé wa sáwọn ílè ìwòsàn ni orílẹ̀ èdè náà ni ọṣẹ kan ṣoṣo, ẹyọ tó lọ́wọ́ ọtí líle ninu.
Èmi OLUWA yóo dojú ìjà kọ ìhà àríwá, n óo pa ilẹ̀ Asiria run; n óo sọ ìlú Ninefe di ahoro, ilẹ̀ ibẹ̀ yóo sì gbẹ bí aṣálẹ̀.
5 million) lo wa lọrun ajọ naa lẹyin ti wọn ni ọpọ owooya lawọn ileeṣẹ ijọba kan gba ti wọn ko san pada.
"Ọjọ 2, Osu Kẹta Ajafẹtọ ọmọeniyan kan lorilẹede Naijiria ti orukọ rẹ njẹ, Aisha Wakil, ti awọn eniyan mọ si ""Mama Boko Haram"" nitoripe o mọ lara awọn ikọ Boko Haram naa nigba ti wọn wa ni kekere, sọ fun awọn oniroyin wipe igun Barnawi sọ fun oun wipe awọn lawọn ji awọn akẹẹkọ naa gbe."
Oludije ninu ifiga-gbaga (WBO) Billy Saunders, ti o tun je eni ti o gba ife eye okun igbadi (Belt) ohun keyin, ti sun ifigagbaga ti yoo waye laarin re ati Martin Murray sinu osu to n bo latari ifarapa owo ti o ni lasiko igbaradi.
Ni ipari, o rọ awọn ọmọ Naijiria tootọ lati ṣe itọju owo naira bi o ti yẹ.
Koda, loṣu meji ṣeyin ni ọkọ kan fi ọmọ odo lu iyawo rẹ pa nitori pe ko tete jẹ iṣẹ ti oun ran an.
 Àwọn méjì nínú àwọn olórí ogun wọn ni eésinkin ajagun-má-rùkú àti eníkọ ̀ tún tí wọ ́ n pe àpèjà rẹ ̀ ní lámọdi .
Wọ́n ní ara Saraki nìkan ló ń fi ipò náà tọ́jú, tí ìlú kò sì mọ ipa rẹ̀ lára.
"com/bbcnewsyoruba/videos/511269552612226/ ti fidio naa wa, ọpọlọpọ awọn to wo eto naa lo da si koko ọrọ yii pe ""ṣe o yẹ ki obinrin maa san owo ile iwe ọmọ?"
O wa sọ siwaju sii pe, aṣẹ ti jade tọ awọn agbofinro lọ lati wa ni igbaradi lati rii pe, ko si idarudapọ laaarin igboro ati pe ẹnikẹni to ba gbimọran ati da omi alaaafia ilu ru, yoo jẹ iyan rẹ niṣu.
Bakan naa ni wọn ma n ṣe ifẹhọnuhan tako ofin ''Jim Crow'' ni Guusu ilẹ Amẹrika.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Mò ń fi lẹ̀kẹ̀ ya àwọnran láti jèrè ǹkan méjì - Olaniyi Olaniyan Ó kìlọ̀ pe, gbogbo àwọn oṣìṣẹ ti ọwọ́ pálábá ba ṣegi nínú tita tíkẹ̀ti ní owó rẹ jú iye to yẹ ko jẹ lọ, yóò fi oju wina ofin.
Ẹ̀rù ń bà mí pé nígbà tí mo bá tún dé, kí Ọlọrun mi má dójú tì mí níwájú yín, kí n má ní ìbànújẹ́ nítorí ọpọlọpọ tí wọ́n ti ṣẹ̀ tẹ́lẹ̀ tí wọn kò ronupiwada kúrò ninu ìṣekúṣe, àgbèrè ati ìwà wọ̀bìà tí wọ́n ti ń hù.
Dafidi dá a lóhùn pé, “Nígbà tí mo ti rí Doegi níbẹ̀ ní ọjọ́ náà ni mo ti fura pé yóo sọ fún Saulu.
Ó tún lá àlá mìíràn, ó sì tún rọ́ ọ fún àwọn arakunrin rẹ̀, ó ní, “Ẹ gbọ́, mo mà tún lá àlá mìíràn!
Ọ̀pọ̀ olólùfẹ́ Iya Jogbo banújẹ́ lórí ìròyìn ikú rẹ̀ Ọdún mẹ́ta lẹ́yìn Adebayo Faleti, ìran Yorùbá ń ṣe ilédè rẹ!
 Inu mi dun pupo fun eto alaafia ti ẹ gba laaye lasiko idibo aare ati ile igbimo asofin yii, nitori naa, mo setan lati tun sin orile ede yii fun odun merin miiran.
Oríṣun àwòrán, @Nazir Ni ọjọbọ ni ile ẹjọ kan ni Kano dajọ pe ki wọn gbe olorin naa lọ si ẹwọn titi yoo fi le ṣe ohun ti wọn bere fun gẹgẹ bii beeli rẹ.
Ẹni to bori: Morocco Senegal vs Congo DR.
Ṣugbọn kí ọ̀ṣọ́ wọn jẹ́ ọpọlọpọ iṣẹ́ rere, bí ó ti yẹ fún àwọn obinrin olùfọkànsìn.
“Ṣugbọn Sihoni, ọba Heṣiboni kọ̀ fún wa, kò jẹ́ kí á kọjá lọ́dọ̀ rẹ̀; nítorí OLUWA Ọlọrun yín mú kí ọkàn rẹ̀ le, ó sì mú kí ó ṣe oríkunkun, kí ó lè fi le yín lọ́wọ́, bí ó ti ṣe lónìí.
Awọn ọdọ adugbo naa lo wa gba ọdọ meji, afurasi ti wọn ni gbe ohun abugbamu naa kalẹ ki awọn ọlọpaa to de.
Lati jẹ ki awọn ilu to parapọ lati jẹ ọwọ ogun kan naa wọ ara wọn daadaa, Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, COZA: Ọpọ èrò ló jáde ṣe lòdì sí ẹ̀sùn ìfipábánilòpọ̀ Fatoyinbo Ogedengbe fẹ iyawo kaakiri gbogbo ibi to ti lọ jagun.
oun yoo mojuto eto idagbasoke ati igbaye –gbadun gbogbo omo orile ede Naijiria.
UN: Nàíjíríà, ẹ sọ ìlò igbó fún ìwòsàn di òfin
Nigba ti wọn fẹ ki ọpa bọ mi loju, ṣe ki n maa wo wọn niran ni?
ẹni tí ó fi ẹ̀mí rẹ̀ lélẹ̀ nítorí ẹ̀ṣẹ̀ wa, kí ó lè gbà wá kúrò lọ́wọ́ ayé wa burúkú yìí, gẹ́gẹ́ bí ìfẹ́ Ọlọrun Baba wa, 
“Àwọn ọmọ rẹ tí ń pada bọ̀ kíákíá,àwọn olùparun rẹ yóo jáde kúrò ninu rẹ.
Minisita fún ìdẹ̀rùn aráàlú náà fikùn pé, ileesẹ òun ti fi ọkọ akeru ọrinlerugba ó dín kan (279) ransẹ sáwọn ìjọba Ìpínlẹ̀ nínú ẹgbẹ̀rún lọ́nà àádọ́rin tọọnu èròjà onihoro tí ìjọba àpapọ̀ fọwọ́ sì, gẹgẹ bii eroja oúnjẹ feto ìdẹ̀rùn aráàlú.
It is meant to inculcate righteousness and discipline, he said.
" Auxiliary ń ní wá lára pẹ̀lú gbígba owó aitọ, a ń ko ọkọ̀ wa kúrò lójú pópó - Awakọ èrò Ayẹwò kò dáwọ́ dúro botílẹ̀ jẹ́ pé èròjà ayẹwò (Reagents) kò si mọ́ Ayinla Ọmọwura, orin èébú àti oríyìn lo fi di ọ̀rẹ́ àwọ̀n obìnrin Aláboyún ọmọ Naijiria bímọ nínú bàálù tó ń gbé wọn bọ̀ láti Dubai Oyedepo ni ohùn òkùnkùn lo fẹ́ ń darí àwọn èèyàn ní gbogbo ẹ̀ka yìí, tó sì dojú kọ ìjọ Ọlọ́run nítorí bí àwọn sọọsi ṣe ń gbòòrò lo ń fọ èṣù lórí, àmọ́ ẹnu ọ̀nà ọrùn àpáàdì kò ní borí, Èṣù àti àwọn ọmọ ogun rẹ yóò jìyà rẹ.
Ẹ̀ṣọ́ Amotekun ní láti ṣiṣẹ́ pọ̀ pẹ̀lú ọlọ́pàá agbègbè- Ọ̀gá ọlọ́pàá Naijiria Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Inter-family marriage: Wo oríṣìí àrùn márùn ún tí ìgbéyàwó láàrin ìbátan máa ń fà17 Sẹ́rẹ́ 2021 DNA: Wo àkójọpọ̀ ọ̀nà méje tí ọmọ àlè fi le wọnú ilé láì jẹ́ pé ìyàwó ṣe aṣemáṣe17 Sẹ́rẹ́ 2021 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú15 Sẹ́rẹ́ 2021 Habits that damage brain: Wo àwọn ìṣesí ojoojúmọ́ mẹ́wàá tó le ṣàkóbá fún ọpọlọ rẹ16 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Eyi lo jẹ ki man U lọ fun ẹleṣẹ ayo ẹgbẹ agbabọọlu PSG tẹlẹ, Edinson Cavani, ẹni ọdun mẹtalelọgbọn.
Ọlọrun nìkan ṣoṣo, Olùgbàlà wa nípasẹ̀ Jesu Kristi Oluwa wa ni ògo, ọlá, agbára ati àṣẹ wà fún, kí á tó dá ayé, ati nisinsinyii ati títí ayé ainipẹkun.
Ọgọta ọdun, ikuna isejọba ati ajẹbanu.
Oríṣun àwòrán, TWITTER Ajọ EFCC ni awọn yoo gbe Mompha lọ si ile ẹjọ, lẹyin ti wọn ba pari iwadii wọn.
Ó wọn apá ìlà oòrùn pẹlu ọ̀pá rẹ̀, ó jẹ́ ẹẹdẹgbẹta (500) igbọnwọ (mita 250), gẹ́gẹ́ bí ọ̀pá rẹ̀.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ọọ̀ni: Àwọn ọ̀daràn Fulani fẹ́ ba orúkọ rere Nàíjíríà jẹ́ ni 20 Òkùdu 2019 Oríṣun àwòrán, Oba Adeyeye Ogunwusi Awọn ọba alaye lorilẹede Naijiria ti n wa ọna ti wọn yoo fi le eyikeyi ọdaran laarin awọn Fulani to wa nidi ọpọ iwa aifararọ eto aabo nilẹ Yoruba atawọn apa ibomiran lorilẹede yii tefetefe si ayika wa.
Ajọ to n polongo tako aisan jẹjẹrẹ nilẹ Amẹrika lo ṣe agbatẹrun iwadi naa, laarin ọkunrin ati obinrin ti ki i fa siga, ti wọn to ẹgbẹrun lọna okoolelẹẹdẹgbẹrin o din mẹwaa.
 Alaga igbimọ to n ri si irinajo afẹ ni Uganda, Stephen Asiimwe sọ fun akọroyin BBC pe awọn fẹ ṣe akọsilẹ gbogbo iṣẹlẹ naa bi o ti yẹ ni.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ọjọ́ Kẹjìlélógún, Osú Kẹ̀sán an, Ọdún 2018 ni ìdìbò sí ipò gómínà yóò wáyé ní ìpínlẹ̀ Osun.
Awọn iroyin miran ti ẹ le nifẹ si: Ibeere mẹfa lori ijinigbe Dapchi Ọwọ ologun tẹ darandaran mẹwa ni Benue Wahala Kaduna: Ọwọ ọlọpaa tẹ eeyan mẹwa Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Afẹnifẹre: Buhari kò tara nípa ikú ọ̀pọ̀ Sojà tí Boko Haram pa28 Bélú 2018 'Oriṣiriṣi ọkunrin ni mo ba sun lọna ati jẹ ni Russia'26 Èrèlè 2018 Gomina Ambode buwọlu aba isuna ti o le ni trillionu kan naira27 Èrèlè 2018 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Nigba ti Funmilayọ pada sile ni Naijiria, o rii pe, awọn oyinbo Ajẹlẹ ti n ṣiṣe ibi nipa gbigbe owó orí gọbọi le awọn eniyan lori.
Lẹyin o rẹyin, ile asofin Oyo fontẹ lu aba isuna ọdun 2021 naa, eyi ti apapọ owo rẹ jẹ biliọnu lọna ọtalerugba naira o le mẹjọ (N268bn).
Ẹnìkan ninu ìdílé rẹ tí n kò ní mú kúrò ní ibi pẹpẹ mi, yóo sọkún títí tí ojú rẹ̀ yóo fi di bàìbàì, ọkàn rẹ̀ yóo sì kún fún ìbànújẹ́.
Àsìkò tó láti fi ìwọ́de gba ara wa sílẹ̀ lọ́wọ́ ebi àti oko ẹrú - Sowore Ọ̀gá àgbá ọlọ́pàá pàṣẹ pé kí wọn ṣàwárí àwọn pásítọ̀ tí wọn jí gbé Èmi kò gbé pọ̀ pẹ̀lú Kollington Ayinla àmọ́ ọjà t'ọ́mọ ti wọ̀ lọ̀rọ̀ àwa méjééjì - Salawa Abẹni Òṣèré tíátà, Kemi Afolabi fi ohùn ìdúpẹ́ ránṣẹ́ láti Meccah fún àdúrà ọmọ Nàíjíríà Pásítọ̀ ọmọ Nàìjíríà, Omotoso, tí wọ́n fi ẹ̀sùn ìfipábánilòpọ̀ kàn pàdánù ìwé ìgbélùú ní South Africa Ile iṣẹ ọlọpaa ni gẹgẹ bi orilẹede olominira, eto idibo lọna kan gbogi tawọn ọmọ Naijiria le lo lati yi ijọba pada.
Lọjọ Aje ni wọn gbe Maradona lọ si ile iwosan Ipensa to wa niluu Buenos Aires.
Ijiya wo lo tosi ẹni to ba ru ofin to lodi si sinsin oku si ilẹ ijọba GRA?
Bakan naa, Omoleye, ti o je oludari agba fun awon osise tuntun, ti figba kan sise nile iwe giga fafiti.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Akomolede ati Asa lori BBC: Olùkọ́ Kikelomo Ogunboye tan ìmalẹ̀ sí ìwà olè ọ̀gá ọlọ́pàá O fikun ọrọ rẹ pe awọn ko gba kawọn ero maa duro ninu awọn ọkọ naa mọ, wọn kan n joko lasan an ni.
  Aare so pe orile-ede Naijriia ati Israel ni ibasepo to gboro,
ipinlẹ Eko lọjọRU lati sefilọlẹ awon ise akanse  ti ijọba ipinle Eko ti se.
Oríṣun àwòrán, African Drum Ferstival/Facebook Ọdun 2016 ni gomina ipinlẹ naa, Ibikunle Amosun fi ajọdun naa le lẹ.
Ìwọ̀nyí ni yóo jẹ́ ẹnubodè àbájáde ìlú náà.
Elija tún sọ fún Eliṣa pé, “Dúró níhìn-ín nítorí pé OLUWA rán mi sí odò Jọdani.
1 Èbibi 2018 Oríṣun àwòrán, Huw Evans picture agency Àkọlé àwòrán, Ó yẹ ki ìjọba àpapọ̀ ti kede àwọn darandaran gẹ́gẹ́ bíi ẹgbẹ́ adúnkookò-mọ́ni Pẹ̀lú awuyewuye tó gbòde kan pé kí ìjọba àpapọ̀ kéde àwọn darandaran bí ẹgbẹ́ adúnkookò-mọ́ni Àwọn ọmọ orile-ede Nàìjíríà tí ń bèèrè pé kinni ìdí tí ìjọba kò ṣe tii ṣe bẹ́ẹ̀ disinyii.
Ọjọ Karun osu Kẹwa ọdun 2020 yii tii ṣe ayajọ ọjọ awọn olukọ lagbaaye ni ijọba apapọ kede akanṣe owo oṣu tuntun fawọn olukọ ni Naijiria.
Ọ̀kan ninu àwọn ọmọ-ẹ̀yìn Jesu, ẹni tí ó fẹ́ràn, jókòó níbi oúnjẹ, ó súnmọ́ Jesu pẹ́kípẹ́kí.
pelu iko agbaboolu Leicester, eleyi ti o pari si ami ayo kookan(1-1).
“Nígbà tí àrùn ẹ̀tẹ̀ bá mú ẹnìkan, kí wọ́n mú olúwarẹ̀ tọ alufaa lọ.
Ẹkọ ti itan igbe aye Oshodi Tapa kọ wa: Ẹkọ akọkọ ni pe ki ọmọde tete mọ ohun to fẹ fi ile aye rẹ ṣe lai naani ọjọ ori rẹ abi ipo to wa.
OLUWA wí fún Solomoni ọba pé, 
Àmọ́ ẹ ríi pé ẹ dáàbò bo ẹ̀mí yín - Ọ̀gá àgbà ọlọ́pàá Ojúmọ́ kan, ìdàmú kan ni mo fi lo ogún ọdún àkọ́kọ́ lórí oyè - Alaafin Tí iye iná tí ẹ rí gbà bá kéré ju owó tí ẹ rà á lọ, ẹ ti jẹ gbèsè tẹ́lẹ̀ ni - Iléeṣẹ́ apínnáká Gomina Sanwo-Olu lo ran w anise lati lo doju ko awon afehonuhan Lekki Tollgate - Iko Omoogun Naijiria Awuyewuye bẹ silẹ lọsẹ yii lẹyin ti ikọ ọmọogun Naijiria ke sita wi pe gomina ipinlẹ Eko, Babajide Sanwo-Olu gan an lo wa nidi iṣekupani to waye ni Lekki.
Wọ́n jẹ́ orílẹ̀-èdè tí ń dá gbé;wọn kò da ara wọn pọ̀ mọ́ àwọn orílẹ̀-èdè yòókù.
gbogbo àlà orile ede Naijiria pa lati aago mejila osan , ojo kàrúndínlógún, Ẹti titi di ojo kẹ́tàdínlógún  ojo Aiku.
 "" Ẹkẹ ́ rìí ìpín "" "" ( witness of fate ) ."
Dipo ki wọn si maa taporogan pẹlu ijọba, wọn gba ileejọ lọ Alaafin ni niwọn igba ti ẹjọ ọhun ti wa nile ẹjọ, ohun ko ni sọrọ lori rẹ pupọ, oun si ro pe o yẹ ki Fayemi naa ro eyi, ko to di pe o tun lọ gbe igbesẹ miran lori isẹlẹ ọhun.
fi se ayederu ibo , ni eyi ti o fi je pe won ko ni ka ibo ti awon eniyan ba di,
Ọ̀dọ́ Aguntan náà bá wá, ó sì gba ìwé náà ní ọwọ́ ọ̀tún ẹni tí ó jókòó lórí ìtẹ́.
Aṣofin Tunde Braimoh, sọrọ yii di mimọ ninu ipade apero ẹlẹẹkẹrin rẹ ti ẹkun idibo Kosọfẹ keji, to waye ni gbọngan  ile-iwosan abọde, iyẹn Health Centre ni Ketu lagbegbe Idagbasoke ijoba Ibile Agboyi-Ketu, Ipinlẹ Eko.
Agbébọn yabo àgọ́ ọ́lọ́pàá, wọ́n pa DPO àti ọlọ́pàá mẹ́ta míràn Àwọn aṣòfin àpapọ̀ ń dí mi lọ́wọ́ iṣẹ́-Buhari D.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: N kò le è dìbò yan Buhari tàbí Atiku ní olórí mi láéláé - Soyinka ‘Nàìjírìà kò nílò àtúntò, ìjìjàgbara la nílò’ Pẹ̀lú abẹ̀rẹ̀ àjẹsára yìí, ẹ̀fọn kankan kò lè mú àìsàn ibà wá O ni lara ijamba ti iforukọsilẹ ni wi pe eniyan to ba jẹbi ẹsun naa le fi ẹwọn ọdun mẹẹdọgbọn jura lori ẹsun pe o pa irọ orukọ rẹ labẹ ofin.
Oríṣun àwòrán, @davidoofficial Àkọlé àwòrán, ọ̀rọ̀ ìfẹ́ lágbára Davido fun un ni ọkọ̀ Porsche oní milionu marundinlaadọta naira pẹlu nọ́mbà Assurance niwaju ati leyin ọkọ̀ ọ̀hún fún ìsàmì ayẹyẹ ọjọ́ ìbí Chioma.
  Awon olutaja ti o n sakoso ayeye naa, ni erongba won ni lati ta iwe pelebe iworan ohun fun awon tokotaya ti ko ju ogun loEwe, okiki igbeyawo naa ti gbode kan jakejado lati inu osu kokanla ti won ti kede re.
Adeogun 36PPAAdedokun Musbau Olalekan - Ibrahim Bukola 37PPCIfeolu Kehinde Adewumi - Sunday Makinde Babawale 38PPNAkintunde Adesoji - Akanmu Saheed Abiodun 39PRPBadmus Tajudeen Adefola - Olajire Gbolahan 40PTAdegboyega Aderemi - Usman Omobolaji Taofeek 41RPAyodele Mercy Tosin - Adejumo Mukaila 42SDPIyiola Omisore - Lawal Azeez Olayemi 43SNPAyoade Ezekiel Adegboyega - Omolade Anike Adebayo 44SPNAlfred Adegoke - Lameed Gafar 45SPNAdediji Olanrewaju Adewuyi - Alabi Ola-Olu Adeniyi 46UPPOdutade Olagunju Adesanya - Karonwi Festus Olamilekan 47YDPAdebayo Adeolu Elisha - Aleem Atinuke 48YPPAdetunji Olubunmi Omotayo - Salawu Kareem Adeniyi Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ọ̀rọ̀ Imam yìí ṣe kòńgẹ́ bó ti ń rí láàrin lọ́kọ láya Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Oṣere ni, oniṣẹ ọwọ si ni pẹlu to ti gbajugbaja laarin awọn oṣere Yoruba to bẹrẹ si ni kopa ninu ere lọdun 2013.
Bí a ṣe lè ri lára ìtú ìmọ̀ ìfọ̀rọ̀wọ́rọ̀ agbóhùnsáfẹ́fẹ́ REAL TV l'órèfé, Aliyev sọ àsọdùn ọ̀rọ̀ nínú ìgbóríyìn fún arúgbó ọ̀hún, bí ò tí ṣe perí rẹ ní sísẹ̀ntẹ̀lé:
Ijoba orile ede Naijiria ti kede ojo kàrúndínlógún , Eti ati ojo kéjìdínlógún Aje, osu kefa, odun 2018 fun isinmi lati sajoyo odun Id-el fitr.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Internet fraud: Ọwọ́ EFCC tẹ afurasú 'Yahoo boy' Olawale àti pásítọ̀ CAC tó lu Hayatou ní jìbìtì N12.
ẹ̀kọ́ nípa ìrìbọmi, ìgbé-ọwọ́-lé eniyan lórí, ajinde kúrò ninu òkú, ati ìdájọ́ ìkẹyìn.
siluu Abuja leyin irin-ajo re siluu Makkah lorile ede Saudi Arabia fun ipade
Bakan naa ni wọn rọ awọn eniyan lati maṣe daba lati ma a ko epo bẹntirolu to danu naa, ki ijamba miran ma ba a waye.
Ko pọn dandan ki awọn cardinal naa o yan ọkan lara wọn - ninu akọsilẹ, ọkunrin ijọ Aguda yoo wu to ba ti ṣe iribọmi ni wọn le yan ni poopu - ṣugbọn àṣà sọ pe cardinal ni wọn yoo fẹ ẹ gbe e fun.
O ni: “Pataki abewo mi ni lati mo ohun to ye ni sise lati fi se ayesi Alufaa Tansi ki a de tun ki awon eniyan Aguleri fun idagbasoke ti won n se si asa.
Nígbà tí wọ́n gbọ́ ariwo àwọn ẹlẹ́ṣin ati ti àwọn tafàtafà,gbogbo ìlú sá jáde fún ààbò.
Alhaji Lai Mohammed salaye iku gbajugbaja osere ohun gege bi isele ti o bani lojiji ti o si dun ni lopolopo.
Kí Olódùmarè dá wa sí o.
Ọdọọdun si ni wọn maa n ṣe ajọyọ fawọn ibeji nibẹ.
Wo ẹsẹ̀ àwọn tí wọ́n lọ sin ọkọ rẹ lẹ́nu ọ̀nà, wọn yóo gbé ìwọ náà jáde.
Oríṣun àwòrán, Instagram/regina chukwu Ọjọ kẹtalelogun, oṣu Kẹta ni ọjọ ibi rẹ.
Wọn maa n lo lati fi sọrọ ati lati fi sin ẹlomiran jẹ.
bí wọn tí ń ṣe láyé náà ni wọn ń ṣe lọ ́ run .
ti won kọkọ dibo ni wodu Sarkin Yara.
Àṣẹ tí a rí gbà láti ọ̀dọ̀ Jesu Kristi ni pé ẹni tí ó bá fẹ́ràn Ọlọrun, kí ó fẹ́ràn arakunrin rẹ̀ pẹlu.
Gẹ́gẹ́ bi àwọn ti ọ̀rọ̀ náà sojú wọn ṣe sọ, ìjànú ọkọ̀ àjàgbé tó kó ìrẹsì ló já èyi si lo mú ki ọkọ̀ náà yawọ si inú ọjà tí o sì pà ọ̀pọ̀ ènìyàn.
Bí mo ti sin baba rẹ, bẹ́ẹ̀ gan-an ni n óo sin ìwọ náà.
Kekere kọ nike Ramọ ni oun ti oju awọn eeyan n ri nile yii.
Oríṣun àwòrán, Leadership Newspaper Bakan naa, wọn fi ẹsun kan Metuh lori iye owo miliọnu meji dollar kan ti ko gba banki kankan kọja rara eyi si ni ajọ EFCC ni o lodi si ofin.
Aare orile ede Egypt tẹlẹri, Morsi subu lulẹ ti o
Liverpool fí ògùn ẹ̀yìn ja Barcelona Ààrẹ ẹgbẹ́ agbábọ́ọ̀lù Nàìjíríà, Pinnick yóò fojú ba ilé ẹjọ́ Ninu idibo yii, awọn oludibo yoo ma dibo yan awọn aṣojusofin lati ẹgbẹ oṣelu to wu wọn, nigbati awọn aṣojusofin yii yoo wa lọ dibo yan aarẹ.
Awon eniyan Cuba dibo lojo Aiku ninu eto idibo elegbe oselu kan soso nibi ti won yoo ti le yan Aare tuntun losu to m bo.
Iṣẹ́ ọkùnrin náà kò hàn sí òde jù bẹ́ẹ̀ lọ, nígbà tí wọ́n bá sì ń gbé àwọn ẹlẹgbọ́ rẹ̀ sí ìwájú wọn kò ní í gbé òun nítorí lẹ́ẹ̀kọ̀ọ̀kan tí àwọn olórí bá lọ bẹ ọkùnrin náà wò a máa gbéraga sí wọn nítorí tí kò mọ̀ pé iṣẹ́ òun kò dára tó ti àwọn ará ibòmíràn, ó jókòó sí ìlú kan, kò jẹ́ jáde sí gbángba, òun kò mọ̀ wí pé ẹni tí ó fi inú iyàrá ṣe ibùgbé ọgbọ́n iyàrá nìkan ni yóò ní mọo.
''Mi o ṣe idiwọ fun ọdọ to ba fẹ du ipo.
Ewe, Shehu Dikko darapo mo igbimo ajo FIFA ninu osu kokanla odun 2017.
Ahasaya jọba ní ilẹ̀ Juda ní ọdún kọkanla tí Joramu ọmọ Ahabu ti jọba ní Israẹli.
Eyitayo Jegede gbé Akeredolu lọ síwájú ìgbìmọ̀ tó n gbọ́ ẹ̀sùn ìdìbò Ẹ gbọ́ Ohun tí Desmond Elliot àti Mojisola Alli-Macaulay sọ lórí ayélujára táwọn ọmọ Nàìjíríà fi ìbínú Àwọn olóṣèlú Nàìjíríà márùn ùn tó sọ̀rọ̀ tí ará ìlú fà ìbínú yọ Remilekun Fatolu bú sẹ́kún fún ohun tó ti pàdánù láyé torí ọyàn ńla rẹ̀.
Olamide Wonma nurse video: Nọ́ọ̀sì kan ní lóòótọ́ làwọn aláìsàn ń dẹnu ìfẹ́ kọ àwọn
Nítorí náà o kò ní sàn ninu àìsàn yìí, o óo kú ni.
Ni kete ti ESAT rii pe ayederu ni fidio naa ni wọn ti yọọ kuro lori afẹfẹ wọn ti wọn si tọrọ aforiji ni ori ikanni Youtube wọn.
Day 28: Ezekwisili, akíkanjú obìnrin tó ń dupò ààrẹ #BBCNigeria2019 Arabinrin Yetunde Olawale jẹ onimọ ofin ati aṣoju loge, o jẹ ko di mimọ pe ọpọ ọkunrin lo maa n diju si ojuṣe wọn gẹgẹ bi ọkọ.
pẹlu egbe oselu alatako ninu  igbimo ti
O ni ki wọn maa ṣọ ọ fun oṣu Shawwal 1440AH ni kete ti oorun ba wọ lọjọ Aje, ọjọ kẹta, oṣu Kẹfa, ọdun 2019.
Asofin Sagius Ogun lo saaju gbigbe abadofin naa siwaju awon omo ile pelu ireti pe yoo din owo ile okeere ti Naijiria n padanu lodoodun ku nitori pe o le ni egberun marun un eniyan Naijiria to n lo sile okeere losoosu fun ayewo ati itoju ni India atawon orile ede miran.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Abdulfatah Ahmed: Àwọn Kwara fẹ́ dán ilé ọkọ kejì wo ni lásìkò yí Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Abdulfatah Ahmed: Àwọn Kwara fẹ́ dán ilé ọkọ kejì wo ni lásìkò yí 24 Èbibi 2019 Màá lọ mojuto àwọn ilé iṣẹ́ aládani mi ni bayii- Abdulfatah Ahmed.
Lẹyin bi ọjọ mejila, gbajugbaja iwe iroyin meji The Nation ati Vanguard naa fi iroyin ti akori rẹ jọ iroyin yii sita.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Akomolede ati asa Yoruba: Ẹ wá kọ́ nípa àpòtí ìṣura èdè wa lórí BBC Yorùbá Ileeṣẹ ọmọ ogun Naijiria naa ti fi atẹjade sita ni eyi ti wọn ti ni tootọ ni awọn alakatakiti Islamic West Africa Province ṣe ikọlu sibudo ọmọ ogun ilẹ ni Kukawa.
Diẹ lara awọn asiko mọlegbagbe ọhn nigba ti idije naa n lọ lọwọ niyii.
"Ẹ̀sín wa kò ní bọ́ sọ́wọ́ ọ̀tá, Arsenal gbọdọ̀ na Chelsea lónìí - Lacazette Àwọn akópa tó ti jáwé olúborí ní BBNaija sẹ́yìn àti ibi tí wọ́n wà báyìí Kí ìjọ mi ní Sagamu le gbòòrò ni mo fi ń ṣiṣẹ́ ajínigbé pawó - Pásítọ̀ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Owu Water Fall: Ọba Oyewole ni ibùdó ìrìn àjò afẹ́ gidi ni àmọ́ ọ̀nà ibẹ̀ burú jáì ""Mo ti lọmọ, ọmọ-ọmọ ati ọmọ-ọmọ-ọmọ, Ọlọrun ti bukun mi"" O ṣalaye pe ""oponu agbalagba ni yoo ma a gbeero lati fẹ ọdọmọbinrin, nibi ti ọjọ ori mi de bayii""."
Ẹni tó jí ọ̀pá aṣẹ ń bọ̀ wá túbá fúnrarẹ̀, mo fi dáa yín lójú gẹ́gẹ́ bí ìyá - Erelu Kuti Ilẹ̀ Yorùbá pátá ló ni oúnjẹ ìdẹ̀rùn Covid-19 tẹ kó l'Eko - Ìjọba Eko figbeta Ijọba ipinlẹ Eko ti sọrọ lori awọn erojẹ ounjẹ fun eto idẹrun Coronavirus, tawọn araalu kan ji ko nibudo ẹru ti wsn ko pamọ si, lọjọ bọ.
Tààrà ni kí olukuluku máa lọ títí yóo fi jáde.
'Ò ń f'ẹ̀mí ara rẹ wéwu tó bá fẹ́ kọ́kọ́ yẹ ọlọ́pàá wò' Má jẹ́ kí Whatsapp rẹ gbàbòdè, tètè ‘Update’ Akeredolu, Ọgá NDLEA lọ kọ nípa gbíngbin igbó ní Thailand Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Bí ìrẹsì tèmi Ayinde bá ń pàkùta, kò tọ́ sẹ́nu aláàrù Barrymaade' Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
43 Àti nísisìyí, lẹ́hìn tí ẹ bá ti gba èyí, ẹ̀yin gbọ́dọ̀ pa àwọn òfin mi mọ́ nínú ohun gbogbo.
Adari ẹgbẹ naa, Olarotimi Smith sọ pe o yẹ ki ijọba ṣe ofin ti yoo fi iya jẹ gbogbo awọn afipa bani lopọ.
Mose bá sọ fún Aaroni ati àwọn ọmọ rẹ̀ ọkunrin pé, “Ẹ lọ bọ ẹran àgbò náà lẹ́nu ọ̀nà Àgọ́ Àjọ kí ẹ sì jẹ ẹ́ níbẹ̀, pẹlu burẹdi tí ó wà ninu agbọ̀n ọrẹ ẹbọ ìyàsímímọ́, gẹ́gẹ́ bí mo ti pa á láṣẹ pé: ‘Aaroni ati ọmọ rẹ̀ ni kí wọ́n máa jẹ ẹ́’.
 Ọkùnrin arẹwà ti mo ri lójú mọ ́ lúbi yìí rẹwà ; ẹ ̀ gàn ni hẹ ̀ ẹ ̀ ẹ ̀ .
Ninu ilẹ̀ náà ni àwọn ìlú wọnyi wà: Sora, Ẹṣitaolu, Iriṣemeṣi; 
Amẹrika ń gbẹ̀san lára Nàíjíríà, owó ‘Visa’ di ọ̀nà méjì láti wọ Amẹrika A kó dúkòkò mọ́ Ambode, isẹ́ wa là ń ṣe - Ilé Aṣòfin Eko A ṣetán láti ran àjọ aláàbò alájùmọ̀ṣe lọwọ fún ààbò tó péye nílẹ Yorùbá - Ọlọ́pàá Ogun Ìpàdé àpérò kọ́ ló kàn, àdánìkànjẹ ẹ̀yà kan ni ká dẹ́kun ní Nàíjíríà - Òǹwòye Minisita fun ọrọ abẹle lorilẹ-ede Naijiria, Ogbeni Rauf Aregbesola sọ wi pe lẹyin ajoyepo pẹlu igbimọ ni awọn gbe igbesẹ lati mu ẹdinku ba iye owo iwe irinna naa.
Ẹbi, ara, ọrẹ, ojulumọ ati awọn alajọ ṣiṣẹ pọ Bashir Umar ni wọn wa nibi idanilọla naa.
Oloye Ifayẹmi Ẹlẹbuibọn, lasiko to n ba BBC Yoruba sọrọ ninu ifọrọwanilẹnu kan woye pe, o ṣe e ṣe ko jẹ akufa ni iṣẹlẹ iku tẹle n tẹle to waye ninu ẹbi gbajugbaja oṣere-binrin naa.
Ọmọ ki i sùn ni ọ̀tọ̀, ẹ̀gbẹ́ ìyá ọmọ ni wọn ntẹ́ ọmọ si.
Nígbà tí bàbá mi yọ ní ìsàlẹ̀, iwin náà gbé ìwé rẹ̀ nì lọ́wọ́, ó ń kà á, nígbà tí ó sì rí bàbá mi, ó gbé ìwé náà sílẹ̀ ní apá kan, ó yẹ kùmọ́ rẹ̀ wò, ó fi ọwọ́ ba àwọn ẹrù pàṣán, nígbà tí ó sì wo àwọn ohun ìjà wọn-ọnnì tán, ó bú sí ẹ̀rin, ó fi ọwọ́ tẹ ìbàdí, ó rìn díẹ̀ síwájú, ó ń wo Olówó-ayé bí ó ti ń bọ̀ bí aláìbàkítà ènìyàn, tí ó ń rìn bí jagunjagun.
Nigba ti PDP ni 5, 363 ninu atundi ibo mọ eyi to wa nilẹ to fi jẹ 204, 877 ibo lapapọ.
 bákan nàá ni àdúgbò yí tún ní ọjà ńlá kan tí tẹrú tọmọ ń ná ìyẹn : Ọjà bódìjà èyí tí ó jẹ ́ ọ ̀ kan pàtàkì lára ọjà tí ó tóbi jùlọ ní ìgboro Ìbàdàn .
Ní bayíì, ènìyàn ààdọrin ló ti ri ìwòsàn ti wọ́n si ti lọ ilé wọ́n nígbà ti àwọn mẹ́wàá ti baa ààrun náà lọ Okòólélọ́dúnrun àti mẹta ènìyàn lo ti ni àrun náà ni Naijiria gẹ́gẹ́ bi NCDC se sọ Ẹ̀wẹ̀, ìpínlẹ̀ mọ́kandinlogun àti Abuja lo ti kéde ààrun Coronavirus náà bayii lórilẹ̀-èdè Naijiria.
 a sàwarí ìwádìí àìsàn yíì nípa wíwá acid-fast bacilli ní àyẹ ̀ wò ìsú-ara ti awọ ̀ ara tàbí nípa ṣísàwarí dna nípa polymerase àbájáde ìṣẹ ̀ lẹ ̀ tẹ ̀ létẹ ̀ lé .
Coronavirus: Afurasí aláàrùn coronavirus ní ìpínlẹ̀ Enugu ti wà ní ìyàsọ́tọ̀
Atúniká ti gbógun tì ọ́, ìwọ Ninefe.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Ki lo n fa ina igbẹkẹle ninu abẹrẹ ajẹsara to n jo ajorẹyin?
Amọ niwọn igba to jẹ pe BBC Yoruba kii bawọn he eera ti ko ni ọmọ ninu, idi ree ta fi kan si aafin Ọọni lati wadi iroyin naa, ka si fi idi otitọ mulẹ nipa isẹlẹ yii.
"Amofin naa ni, ""Bo ti wa di pe aarẹ lọ irinajo laisọ oun ti o fẹ lọ ṣe nibẹ, ko ṣeeṣe fun un lati ṣe alaga igbimọ to n dari ilu."
“Lẹ́yìn náà, a gbéra, a doríkọ ọ̀nà Baṣani.
Agbẹnusọ naa ti igbakeji rẹ, Aṣofin Wasiu Ẹshinlokun-Sanni ṣoju fun ṣalaye pe  bi abadofin naa ba di ofin yoo wulo pupọ ati pe o ṣe pataki ki awọn alẹnulọrọ fi kun awon koko inu abadofin ọun, ki o le kun.
Nítorí ẹ̀rù ìpọ́njú láti ọ̀dọ̀ Ọlọrun ń bà mí,nítorí ògo rẹ̀, n kò lè dán irú rẹ̀ wò.
Liverpool ṣé Barcelona ríṣarìṣa pẹ̀lú àtòrì ẹlẹ́nu mẹ́rin
Wo ìròyìn tó pọ̀ jùlọ táwọn èèyàn ń wá ní Google lọ́dún 2020 Obasanjo àti Gani Adams tẹ́ mi pẹ̀lú bí wọn ṣe tahùn síra wọn - Adebanjo Ọkùnrin kan rí ẹ̀wọn he lẹ́yìn tó lu obìnrin ní jìbitì ìfẹ́ tí iye rẹ̀ tó $15,000 lórí ayélujára Ọmọ ẹgbẹ́ òkùnkùn ṣoro ní Ijebu Ode, ọ̀pọ̀ ẹ̀mí sọnù Iwuri ni Joshua Ọpọ ọdọ ni ẹkun Guusu-Ila Oorun lo ti n fi Joshua ṣe awokọṣe pẹlu bi wọn ṣe n wo o ti wọn si n farabalẹ kọ bo ṣe n goke.
 latigba na lo lo ti unse idiboyan oselu to gbomitoro .
ẹni to tako ọpọ ọrọ ti Kọla Abiọla sọ ninu ifọrọwerọ kan lati tako Oloye Bọla Tinubu pe o dalẹ MKO Abiọla, wa sisọ loju rẹ pe oun ati Tinubu jọ sisẹ pọ bii ọmọ ẹgbẹ Nadeco nigba naa, ti awọn si ja fitafita lati gbe Abiọla jade ni ahamọ to wa.
"Bakanaa, Aarẹ Weah sapejuwe abala ofin to ni ""awọn alawọ dudu nikan"" lo lee ni ilẹ lorilẹede Liberia gẹgẹbi eyi ti ko tọ, iwa ẹlẹyamẹya ati ofin ti ko nitumọ."
Fadeyi ni iru rẹ ko le ṣẹlẹ pe ki awọn agbofinro tẹlẹ awọn ọmọ onilẹ lọ maa ja lẹyin idajọ ile ẹjọ.
Jesu wá sọ fún wọn pé, “Mo bi yín, èwo ni ó bá òfin mu, láti ṣe nǹkan rere tabi nǹkan burúkú ní Ọjọ́ Ìsinmi?
Ni sisẹ n tẹle, akọwe pe orukọ wọn, wọn si jẹ ẹ ni mo wa tabi ko wa.
Bí mo ti sọ, a ní ìgboyà.
Bẹẹ si ni gbogbo ẹbẹ ti banki CBN se lati mu ki ile ẹjọ wọgile igbẹjọ naa lo ja si pabo, ti adajọ si tun koro oju si ọwọ tawọn ileesẹ ijọba fi maa n mu idajọ ileẹjọ.
Ewe, asoju ajo NEMA, Benjamin Ogehena lasiko ipade pajawiri ohun yanana awon ohun ti o sokunfa ikolu omiyale lodun 2012.
Ẹ̀yin ará, mo fẹ́ kí ẹ mọ̀ pé gbogbo ohun tí ó ṣẹlẹ̀ sí mi mú kí iṣẹ́ ìyìn rere túbọ̀ tàn kalẹ̀ ni.
Abeli náà mú àkọ́bí ọ̀kan ninu àwọn aguntan rẹ̀, ó pa á, ó sì fi ibi tí ó lọ́ràá, tí ó dára jùlọ lára rẹ̀ rúbọ sí OLUWA.
UNICEF: ọmọ tuntun 395, 072 máa wá sáyé lagbaye lónìí
Ẹni ogún ọdún ni Ahasi nígbà tí ó jọba, ó sì wà lórí oyè fún ọdún mẹrindinlogun.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ibadan: Olóòlù kò ni kọ́ja agboolé rẹ̀ fún ọdún eégún ìlú Ibadan tọdún yìí Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Ibadan: Olóòlù kò ni kọ́ja agboolé rẹ̀ fún ọdún eégún ìlú Ibadan tọdún yìí 29 Òkùdu 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 30 Òkùdu 2020 Ọdọọdún ni ayẹyẹ ọdún eégún máa n wáye nílu Ibadan tí ọ̀pọ̀lọpọ̀ elégún oníruurú si má n yọjú lásìkò ayẹyẹ yìí.
Ti awọn obi wọn ba de, a o tu wọn silẹ'' Ọkan lara awọn ti wọn mu ṣugbọn ti ko fẹ sọ orukọ rẹ fakọroyin sọ pe ọrẹ oun lo pe oun wa si ibi apejẹ naa ki ọwọ palaba awọn to ṣegi.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Oniṣegun iwosan: Eefin oluṣosun lewu pupọ fun ilera awọn olugbe 21 Ẹrẹ̀nà 2018 Àkọlé àwòrán, Awon olugbe yari lati kuro ni adugbo won Awọn oniṣegun iwosan oyinbo ti n ṣe ikilọ fun awọn olugbe ni ayika Olusosun lati yẹra fun eefin ina ti o le fa ipalara ni agbegbe naa lẹyin ti ile idalẹsi yi gba'na jẹ lọsẹ to kọja.
Èéṣe tí o tàn mí jẹ?
Nigba to n ba ipejọpọ naa sọrọ lọjọbọ, eyi to jẹ akọkọ iru ayẹyẹ bẹẹ ti ẹgbẹ itẹsiwaju awọn ajẹ ati oṣo ipinlẹ Oṣun yoo se, Elebuibọn rọ ijọba apapọ lati tete wa wọrọkọ fi ṣada, lori ipaniyan to n waye lorilẹede Naijiria.
Eyi si sọ iye awọn to ti lugbadi aarun naa bayii di ẹgbẹrun marundinlọgọrun ati ẹẹdẹgbẹrun o le mẹrinlelọgbọn, (95, 934).
Bí o ti wí báyìí ṣe ni mo déédéé rí ètè mi tí o ń sọ̀rọ̀ láìjẹ́ pé mo rán an, tí o sì sọ gbogbo ẹ̀sẹ̀ tí mo ti sẹ̀ láti ọjọ́ tí mo ti dé inú ayé, ọjọ́ tí mo bu ẹnìkan, lọ́jọ́ tí mo sẹ èpò, lọ́jọ́ ti mo bínú, lọ́jọ́ ti mo purọ́, gbogbo rẹ̀ ni ètè mi ń sọ, ìgbà tí o sì dákẹ́ ọ̀rọ̀ i sọ, ẹni tí o gbé àáké yìí ní ki ń bọ́ sí èyìn òun.
Ṣugbọn àwọn eniyan kò gbọ́, wọ́n ṣe oríkunkun, wọ́n kọ̀ wọn kò gbọ́ tèmi.
O ni ''Bi a ba ṣe iṣẹ ku, a ki fẹ pari rẹ nitori pe ijọba miran lo ṣe e.
Ki lo de ti eyi fi ri bẹẹ, paapa nigba tẹ ti jẹjẹ saaju pe ẹ maa se atilẹyin fun awọn ọdọ.
Ọjọgbọn Ogundipe ni oun ni atilẹyin awọn oṣiṣẹ ati olukọ fasiti naa, nitori wi pe ọna ti wọn gba fi yọ oun tako ofin to de fasiti lorilẹ-ede Naijiria.
" Popoọla ni iye owo ti yoo ṣe atunṣe ile ẹkọ naa ko di ni milliọnu meji naira, bẹẹ sini awọn to ya ile igbe lo jẹ gbese nitori baba to ni ile ti darugbo.
Láti àkókò yìí ni Jesu ti bẹ̀rẹ̀ sí waasu pé, “Ẹ ronupiwada, nítorí ìjọba ọ̀run súnmọ́ ìtòsí.
 Ìlo rẹ ̀ nínu gbólóhùn ni :.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù AFCON 2019: Rohr já Iheanacho àti Semi jùú lẹ̀ lọ Egypt 9 Òkùdu 2019 Oríṣun àwòrán, Twitter/NFF Àkọlé àwòrán, Igbaradi Super Eagles for idije AFCON 2019 Ikọ agbabọọlu Naijiria, Super Eagles ti mori le ilu Ismaila lorilẹ-ede Egypt fun aṣekagba igbaradi wọn for idije ere bọọlu awọn ọkunrin l'Afirika.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ninu ìsèjọba aarẹ Jonathan ni wọn ti ji awọn ọmọ ọ̀ún ko lọdun 2014 O ni oun wá gbìyànjú lati lati sètò síse pàsípààrọ̀ awọn ọmọ ọ̀ún pẹlu awọn afurasí ọmọ ikọ̀ Boko Haram ti ìjọba mú nigba naa, sùgbọ́n tó jẹ́ pe, èèemarùún ọ̀tọ̀ọ̀tọ̀ ni eléyìí já si pàbó latari bí ìjọba Goodluck Jonathan se fi ọ̀rọ̀ naa falẹ̀.
Aare Muhammadu Buhari ni irinajo aarẹ orile ede China Xi Jinping ti salaye ni pataki ibasepo re pelu awon orile ede Afirika.
Ọjọ kẹtalelogun, oṣu Kẹta nijọba ti awọn papakọ ọkọ ofurufu ni Naijiria, nitori itankalẹ aarun Covid-19.
Bakan naa lo sọ pe awọn ileewe le ma a mura silẹ fun wiwọle pada.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù AfCFTA:Ohun tí Nàìjíríà gbọ́dọ̀ ṣé láti jẹ adùn àdéhùn okòwò kan nàà ní Afrika 7 Agẹmo 2019 Oríṣun àwòrán, Babangida Yaya Jarmari Àkọlé àwòrán, Aarẹ Buhari ti kọkọ sọ pe nilo akoko lati fi ikun lu ikun, gba imọran ni orilẹede oun.
Ènìyàn 675 ni èsì àyẹ̀wò sọ pé ó ní Covid-19 ní Nàìjíríà ní 22/06/2020 Ajọ NCDC kede pe eniyan 675 ni esi ayẹwo tun fihan pe o ti ni coronavirus ni Naijiria.
Láti ìgbà tí ìjọba àpapọ̀ si ti tẹ pẹpẹ owoya náà síwájú àwọn asofin àgbà, làwọn ọmọ orílẹ̀ èdè yìí tí ń béèrè pé ṣe ilẹ̀ wá tún nílò owoya kankan lásìkò tí ọrọ aje agbaye ti dagun yìí?
Tiofilu mi ọ̀wọ́n: Ninu ìwé mi àkọ́kọ́, mo ti sọ nípa gbogbo ohun tí Jesu ṣe ati ẹ̀kọ́ tí ó ń kọ́ àwọn eniyan, 
 Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ìjà àgbà méjì!"
"Ọlọ́páà Eko kìlọ̀ fún àwọn ọlọ́kadà Àwòrán nọ́mbà jẹẹsí Super eagles rèé Agbenusọ fun MOSOP, Fegalo Nsuke tọka si ọrọ ti aarẹ Buhari sọ ninu ọrọ ayajọ ijọba tiwantiwa to ka fawọn ọmọ orilẹede yii ninu eyi to ti sọ pe eto afọmọ agbegbe Ogoni n lọ ""bi o ti tọ ati bi o ti yẹ."
Wike, má gbé jàgídíjàgan wá sí Ondo, APC kò ní ṣ'èèrú nínú ìdìbò gómìnà tó ń bọ̀- Kalejaye Ninu ọrọ rẹ Adeboye gbadura, o si tun dupẹ pe aarun Coronavirus ti rọlẹ ni Niajiria, to si gbagbọ wi pe laipẹ laijina ni arun Coronavirus yoo di ohun igbagbe ni Niajiria.
Bí ẹgbẹ́ One Million Boys ṣe bẹ̀rẹ̀ rèé àti ọṣẹ́ tó ṣe n'Ibadan Ile iwosan di ile ekute Oríṣun àwòrán, The Daily Maverick Awọn dokita ati nọọsi to n ṣiṣẹ nile iwosan Port Elizbeth sọ pe ile iwosan naa dabi eyi to wa loju ogun ni, nitori ẹjẹ ma n wa nilẹ kaakiri, bẹẹ lawọn eku maa n sare kiri nile iwosan naa.
Lẹ́yìn tí Dafidi ọba ti bẹ̀rẹ̀ sí gbé inú ààfin rẹ̀, tí OLUWA ti fi ọkàn rẹ̀ balẹ̀, tí ó sì dáàbò bò ó lọ́wọ́ gbogbo àwọn ọ̀tá rẹ̀, 
Wọ́n fi idà pa ọba wọn ati gbogbo àwọn ará ìlú náà.
 awon musulumi na un pe ni maria mimo tabi syeda mariam , to tumosi màríà Ìyá wa .
6 13233 Orilẹede Sierra Leone 74 1.
Oun ni igbakeji oludari nileeṣẹ ijọba to n mojuto eto ẹkọ ko to lọ gba iṣẹ akọwe agba ni UNESCO lọdun 2001.
Lẹ́yìn náà, Jẹfuta ranṣẹ sí ọba àwọn ará Amoni pé, “Kí ni mo ṣe tí o fi gbógun ti ilẹ̀ mi.
Egbe-oselu to wa lori alefa lorile-ede Sierra leone All Peoples Congress ti ko ijokoo metalelogota 63 ninu ijokoo adoje o-le-meji 132 omo ile-igbimo asofin orile-ede naa, nigba ti egbe oselu alatako Sierra Leone Peoples Party ko ijokoo merindinladota 46, eyi ti o fi je pe, egbe oselu to n sejoba ni ijokoo to po ju ninu ile-igbimo asofin naa.
Nitori naa, sisin tabi hihu ikọ si inu tiṣu, ki o ma fi ọwọ rẹ kan oju lai fọ, ati yiyago fun ẹni to ba ni aarun naa ṣe pataki.
Kíni àwọn ojúṣe olórí àwọn òṣìṣẹ́ ààrẹ̀ Nàìjíríà?
"Bakada ni ""ọjọ meji ni mo fi daku, ki n to ji, ti mo si ri pe ẹsẹ mi ti da, tawọn oniruuru ọgbẹ si wa lara mi."
"O ni ""ti wọn ba bere lọwọ mi nipa Covid-19, esi mi ko ju pe, Covid-19 wa, bẹẹ ni ko si."
Ọmọ ọdun mẹẹdogun ni Maradona wa nigba to bẹrẹ si ni maa gbabọọlu lẹyin to darapọ mọ ẹgbẹ agbabọọlu Boca Juniors logunjọ oṣu kẹwaa ọdun 1979.
Bi ọwọ awọn ọlọpaa ṣe tẹ awọn afurasi naa ti orukọ wọn njẹ Pauline Moraa, Elizabeth Atieno, Nancy Auma ati Mercy Achieng nitosi ileto kan ti orukọ rẹ n jẹ Banga lagbegbe Mbunguni ni wọn ti fọwọ ofin mu wọn Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ṣé ẹ̀yin lè ṣe jú àwọn tó f'àmì sí Awọlumatẹ?
Àkọlé àwòrán, Awọn alaṣẹ Taliban ni tootọ ni ijiroro n waye.
O ni idariji ẹṣẹ ni koko pataki ẹsin Christiẹni.
Sun daradara ni alẹ ọjọ idanwo rẹ nitori aisun ma n fa ipaya fun awọn ẹlomiran Iroyin ṣe koko lasiko idanwo, ri daju wi pe o mọ gbogbo ohun to yẹ ko o mọ nipa ibi ti idanwo naa yoo ti waye ati akoko ti yoo waye, eyi le fa ipaya ti o ba di ọjọ idanwo ki eniyan to mọ, oṣeeṣe ki gbogbo iwe ti eniyan ka fo lọ ti ko ba ni imọ nipa ibi ati akoko ti idanwo naa yoo waye.
Ẹgbẹ́ òṣèlú-ìpínlẹ̀ ti kọ ẹ̀yìn sí àjọ̀dún Òyìnbó.
Fọlarin tẹsiwaju wi pe yoo nira lati di alafo ni iku Ajimọbi ṣi silẹ ninu ẹgbẹ oṣelu APC l'apapọ.
Wọ́n kéde ká gbogbo ìjọba pé Daniẹli ni igbá kẹta ní ìjọba.
Àwọn oníkẹ̀kẹ̀ 'Napep' tí wọ ilẹ Gẹ̀ẹ́sì Amọṣa, Theresa May ṣeleri pe ni kete ti oun ba ti lee jajabọ lori aba ajọmọ lori adehun ati yẹra ilẹ Gẹẹsi kuro ni awujọ awọn orilẹede Yuroopu, EU, iyẹn BREXIT ti o n lepa rẹ lọwọ, ni onikoyi oun yoo lọ simi ogun.
Naira Marley pẹlu Simi Oríṣun àwòrán, NAira marley/instagram Ni oṣu karun ọdun 2019 ni akọrin ara, Simi pariwo sita lori ikanni ayelujara lati koro oju si bi awọn ọdọ ṣe n kan si agbami iwa jibiti ori ayelujara.
“ ‘N óo da oríṣìíríṣìí ibi sórí wọn,n óo sì rọ òjò ọfà mi sára wọn.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Iléèṣẹ́ ọlọ́pàá: ìwádìí bẹ́rẹ́ lórí ikú ọdaran tó tojú orun dójú ikú' 7 Ògún 2018 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 15 Ògún 2018 Oríṣun àwòrán, @sahara Àkọlé àwòrán, Àsùnjí o fún olóorun ajínigbé oní Tramadol Láti ojú oorun de ojú ikú, ṣe àwọn ọlọpaa ṣe ohun to yẹ?
399Iye ibo to yege jẹ- 580, 778iye ibo ti won fagile jẹ-
Bẹ́ẹ̀ ni kò sẹ́ni tó le-è mú mi bí mo bá fi lu ìlù ògìdìgbó, tí ọlọ́gbọ́n bá bá mi jό-o tí ọ̀mọ̀ran sì bá mi mọ̀n-ọ́n.
'Nkan to ba wu ẹlẹnu ni ko fẹnu rẹ sọ, fila ma wo ibẹ ni mo de' Ẹnikan tilẹ sọ fun mi pe ki n lọ si ibi ti wọn yoo ti gbadura fun mi.
Nígbà tí mo bá sọ ilẹ̀ Ijipti di ahoro, tí mo bá pa gbogbo ohun tí ó wà ninu rẹ̀ run; tí mo bá pa gbogbo àwọn tí ń gbé inú rẹ̀ run, wọn yóo mọ̀ nígbà náà pé èmi ni OLUWA.
Ẹwẹ, Kabiyesi wa pe akiyesi Ile naa si bi wọn ko ṣe jẹ ki awọn ọba ni ipa ninu iṣakoso ati oṣelu lorilẹ-ede Naijiria, eleyii ti o n yọ silẹ bayii ninu ilana iṣakoso ilu gbogbo.
Àmọ́ ìfẹ́ tí mo ní sì iṣẹ́ tíátà lo mú kí n padà sì ìdí ise naa.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù US Embassy: Ìdùnnù wa kọ́ ni kí á má fún ọmọ Nàìjíríà ní 'Visa 16 Ìgbé 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Awọn kan gbagbọ pe orilẹ-ede America mọọmọ n fi iwe irinna dun awọn ọmọ Naijiria laini idi pataki kankan.
Ohùn àkásílẹ̀ nípa àjọsọ ọ̀rọ̀ láàárín akẹ́kọ́bìnrin ọ̀hún àti ọ̀jọ̀gbọ́n Richard Akindele lórí ẹ̀rọ ìbánisọ̀rọ̀ ti wọ́n ká sílẹ̀ sórí ìkànnì ayélujára, ló tí ń jà ràìn-ràìn káàkiri báyìí.
"Adeola jẹwọ pe Ọgbẹni Ọlọhunwa ti n pe oun lati iṣọra daradara nibi ti o farapamọ si ati pe ọwọ ọlọpaa ti tẹ awọn ọmọ ẹyin oun.
Olódodo a máa ka ẹ̀mí ẹran ọ̀sìn rẹ̀ sí,ṣugbọn eniyan burúkú rorò sí tirẹ̀.
Àkọsílẹ̀ NBS fi han pé ìdàgbàsókè owó epo rọ̀ọ̀bì (Oil GDP) wa lára àwọn owó wa já wálẹ̀ jùlọ lásìkò yìí, ó si ti fí ìdá mẹ́tàlá ati díẹ̀ súnkì nínú ìdá ọgọ́rùn.
Bẹ́ẹ̀ ni Ọlọrun dá eniyan ní àwòrán ara rẹ̀.
“Sọ fún àwọn ọmọ Israẹli pé, nígbà tí ẹ bá dé ilẹ̀ tí n óo fun yín, àkókò ìyàsọ́tọ̀ kan gbọdọ̀ wà fún ilẹ̀ náà tí yóo jẹ́ àkókò ìsinmi fún OLUWA.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù River Nile: Ọmọ ilé-ìwé Kenba 24 ló kú s'ómi ní Sudan 15 Ògún 2018 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 17 Ògún 2018 Àkọlé àwòrán, Afi ki ọlọrun ma jẹ ki abiyamọ fojú sunkun ọmọ.
kí á lè gbà mí lọ́wọ́ àwọn alaigbagbọ ní Judia, ati pé kí iṣẹ́ tí mò ń lọ ṣe ní Jerusalẹmu lè jẹ́ ìtẹ́wọ́gbà níwájú àwọn onigbagbọ ibẹ̀.
Ṣé àwọn nǹkan wọnyi ni yóo mú kí inú mi yọ́?
O dije fun ipo yii kan naa lọdun 2018, sugbọn ẹni to wa nipo naa, Lyndon Yearick, ti ẹgbẹ oṣelu Republican, fi ẹyin rẹ janlẹ .
A óo rẹ ọlọ́kàn gíga eniyan sílẹ̀,a óo sì rẹ àwọn onigbeeraga sílẹ̀;OLUWA nìkan ni a óo gbéga ní ọjọ́ náà.
Tí òṣèré tíátà yóò fi kú, eré ni wọn yóò ló ń ṣe - Ibrahim Chatta Aṣòfin méje yarí mọ́ Akeredolu lọ́wọ́ torí ọkọ̀ ayọ́kẹ́lẹ́ tí kò pín fún wọn Aya gómìnà Kwara gba ilé fún Risikat olójú búlúù àti ọkọ rẹ̀ Iná míràn tún fẹ́ ràn lẹ́ka ilera Nàìjíríà Ṣaaju iwọde naa ti ẹgbẹ awọn ọmọ ile iwe ni Naijiria, NANS.
O ni sise odun LAAFEST nipinle Eko to kun fun milionu metalelogun eniyan yoo je ki oro aje re bureke sii lagbaye ki awon eniyan lati ile okeere tun was ii fun irin ajo afe ati okowo sise lorisiirisii.
Mo lè sọ arúgbó dí ọmọge nígbàkúgbà - Hakeem Effect Kí làwọn ìdàmú tí Coronavirus n mú bá àgọ́ ara?
Dafidi sì pàṣẹ fún àwọn eniyan rẹ̀ pé, “Ẹ sán idà yín mọ́ ìdí.
Paulu dáhùn ó ní, “Fẹstu ọlọ́lá, orí mi kò dàrú.
'Báyìí la ṣe rìn ín láti pápákọ̀ òfurufú Abuja sí Eko bí ìrìnà òfurufú abẹ́lé ṣe bẹ̀rẹ̀' Rwanda Sex: Ìṣòro mi ni pé mo tètè ṣe tàn, ṣùgbọ́n ó wù mí kí n ní ìbálòpọ̀ síi August Alsina ti fèsì sí ọ̀rọ̀ ìyàwó oníyàwó tó ń bálòpọ̀ Ọmọ Ibadan, Peace Busari tí wọ́n fẹ́ tà lórí Facebook ti dé sí Naijiria láti Lebanon Ààrùn Coronavirus tún ti ran ènìyàn 664 l'órílẹ̀-èdè Nàìjíríà Amọ, Ikọ ọmọogun orilẹede Naijiria fi si oju opo Twitter wọn wi pe ko si otitọ ninu iroyin to sọ wi pe awọn ọmọogun naa ti fi ipo silẹ.
Eyi lo si mu ki ọpọlọpọ máa sọ lori ayelujara pe o ṣee ṣe ko jẹ nkan to n bi iyawo Ajimobi ninu gan-an ni pe Gomina Makinde ko jẹ ko gba ilẹ naa to wa ni Agodi GRA ko di tara rẹ.
Bakannaa , o kede fun ijoko naa wi pe igbimo ijoba apaapo ti fowo si ise akanse rira oko fun ile-ise panapana, ti iye re to million ojilerugba owo Naira.
Ẹni tí kò bá ní ìfẹ́ wà ninu ikú.
“N óo wá àwọn tí ó sọnù, n óo sì mú àwọn tí wọ́n ṣáko lọ pada, n óo tọ́jú ọgbẹ́ àwọn tí wọ́n farapa, n óo fún àwọn tí kò lókun lágbára, ṣugbọn àwọn tí wọ́n sanra ati àwọn tí wọ́n lágbára ni n óo parun, nítorí òtítọ́ inú ni n óo fi ṣọ́ àwọn aguntan mi.
Òdodo ni yóo fi ṣe àmùrè ìgbàdí rẹ̀, yóo sì fi òtítọ́ ṣe àmùrè ìgbànú rẹ̀.
Wolii àgbàlagbà, ará Bẹtẹli náà bá purọ́ fún un pé, “Wolii bíi rẹ ni èmi náà.
Ile gbe igbesẹ yii lẹyin ti igbimọ ile to wa f'eto idaleesẹ silẹ ati ọrọ osisẹ ọba gbe abọ rẹ kalẹ nibi ijoko ile asofin naa to waye nilu Ilọrin.
Wọ́n ń sáré bí akọni,wọ́n ń fo ògiri bí ọmọ ogun.
 Ọgbẹ ́ ti àràn tí o ń jáde yi ńfa ni o lè ní kòkòrò àkóràn .
Aare ile-ise CCCN lorile-ede Nigeria, .
Àbí ìwà ìrẹ ̀ lẹ ̀ , ìwà tútù , ìwà ọmọlúàbí tó yẹ kí olorì Ọba ní ?
T’ọ̀wọ̀ t’ọ̀wọ̀ ni mo fi sọ̀rọ̀ yí o, ṣùgbọ́n èro mi ni pé àwọn tí wọ́n sọ computer ní ayárabíàṣá, ìtumọ̀ Computer"" àti iṣẹ́ tí ó nṣe kò yé wọn dáadáa ni."
Amọ ṣa lọdun yi,ko yi daju ibi ti ọpa ẹbiti yoo re si nitori ajakalẹ Covid-19 to n da ọpọ eto ru.
Lẹyin ipade pajawiri ti wọn ṣe lọjọ Aje, ẹgbẹ oṣelu APC fi abajade ipade ti wọn naa sita lorukọ alaga ẹgbẹ Adams Oshiomole.
Ó fún olukuluku wọn ní ìpààrọ̀ aṣọ kọ̀ọ̀kan, ṣugbọn ó fún Bẹnjamini ní ọọdunrun (300) ṣekeli fadaka ati ìpààrọ̀ aṣọ marun-un.
A máa jó bí iná,bí ọwọ́ iná tí ó lágbára.
Ẹ̀yin ọmọ oṣó wọnyi,ẹ súnmọ́bí fún ìdájọ́,ẹ̀yin ọmọ alágbèrè ati panṣaga.
Charlie boy sọrọ yii nigba to darapọ mọ awọn ajafẹtọ ẹni miiran nibi apero kan ni ilu Osogbo.
''Owo osu N30,000 ti da N9 nitori owongogo ti ba ounjẹ ti ko si ṣe e ra mọ.
Bakan naa ni awọn alaṣẹ ijọ Olorun Four Square ti ọmọwe Boniface ti n jọsin naa kede pe ko dẹkun gigun pẹpẹ iwaasu titi iwadii wọn yoo fi pari.
Lọ́jọ́rú ni Tinubu fi ọ̀rọ̀ náà léde lójú òpó twitter rẹ̀ ló ti kí gómìnà ìpińlẹ̀ Eko ku oríre fún abájá bi ó ṣe ka ìsúnà owó ọdún 2021 ti o pé akọlé rẹ̀ ni títa ìrètí jí.
Aare ajo FIFA, Gianni Infantino so pe, oun ko i ti ni iye meji nipa sisamulo ero igbalode fonran, video assistant referee (VAR) ninu idije boolu agbaye to n bo lona, pelu gbogbo ariyanjiyan lilo ero ohun to n lo labele.
Ọdún 38 ni ìyá mí fi ṣiṣẹ́ ní UCH, màá kọ́ ibùdó ìtọ́jú àrùn jẹjẹrẹ ní ìrántí rẹ - Ọọ̀ni Mo bí ìyá mi padà lẹ́yìn tó yọ sí mi lójú oorun- Iya Yetunde Gómìnà Ondo Akeredolu ṣí ilẹ̀kùn ṣọ́ọ̀ṣì àti mọ́ṣáláṣí sílẹ̀ fún ìjọ́sìn Ǹjẹ́ ewé dongoyaro lè wo aàrùn coronavirus?
"Mo Salah tó jẹ ìlú mọ̀ọ́ka agbábọọlu ni Liverpool, èyi ti wọn ti yí pada si ""Liver fuul""Egyptian footballer Mo Salah is the star player of winning side Liverpool, which has been changed here to ""Liver Fuul"" nínu ere kan ni Sudan ti wọn pe ni ounje ẹwa ""Fuul""."
Ọlọ́pàá ké sí bàbá tó na ọmọ rẹ̀ tó kùnà nínú ìdánwò Ó ti pé ènìyàn 873 tó ní Coronavirus ní Nàìjíríà báyìí Ìséde ń bọ̀ káàkiri Nàìjíríà, àwọn gómìnà ìpínlẹ̀ fẹ́nukò Ìyàn ń bọ̀ ní Nàìjíríà lẹ́yìn coronavirus àyàfi.
"Bi eeyan ba ni ọgbọn ti o si kawe, iru eeyan bẹẹ yoo ms bi a ti n ba awọn to ba wa nipo alaṣẹ ṣe pọ"" Iku Baba yeye, Ọba Lamidi Adeyẹmi kẹta ṣalaye lori ohun to ṣẹlẹ nipa ti ọrọ idasilẹ ọwọ ileeṣẹ ọlọpaa kogberegbe naa."
Àwọn agbébọn tún pa Alùfáà ìjọ Baptist kan ní Ekiti Ààrẹ Buhari: Ìwa wèrè ni àwọn Boko Haram tó dúmbú àgbẹ̀ 40 hù Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ọkùnrin tó fẹ́ fipábámilòpọ̀ fín ǹkan sí mi lójú ló ṣe rọ́nà wọlé sí mi lára Gẹg bi iroyin to tẹ wa lọwọ, iṣẹlẹ naa waye lalẹ ọjọ Abamẹta, ṣe ni awọn ọmọ ijọ sa asala fun ẹmi wọn ti ẹnikẹni ko si farapa.
OLUWA, gbà mí lọ́wọ́ àwọn ọ̀tá mi;ìwọ ni mo sá di.
Ọpọlọpọ eniyan ni yóo wá, tí wọn yóo máa wí pé:“Ẹ wá!
"Mo n fi da yin loju pe awọn dibo fun mi pupọ, ọpọ̀ awọn asoju to dibo lo n se temi, lagbara Ọlọrun, maa gba ipo mi pada bii oludije fun ipo gomina fẹgbẹ oselu PDP nipinlẹ Ọsun.
Baba wọn sì fún wọn ní ogún láàrin àwọn arakunrin wọn.
Angẹli náà sọ fún un pé, “Di ìgbànú rẹ, sì wọ sálúbàtà rẹ.
”Eliṣa sì dáhùn pé, “Mo bẹ̀ ọ́, jẹ́ kí ìlọ́po meji agbára rẹ bà lé mi.
Bo tile je pe ijoba Ologun koti ikun leyin gbogbo ijiroro, eyi sokunfa igbese ijoba apapo lati so gbogbo ojo kejila osu kefaa ti ajodun eto ijoba tiwa-n-tiwa yoo maa waye lorile ede Naijiria.
Gege bi aare Mohamed Abdullahi Mohamed se so, lasiko to n kedun iku awon oloogbe naa,“omo ogun olote islam Al Shabaab lo wa ni idi ibugbamu ado oloro naa.
Bí àwa kò bá tilẹ̀ ṣe é gbẹ́kẹ̀lé,òun ṣe é gbẹ́kẹ̀lé nígbà gbogbo,nítorí òun kò lè tan ara rẹ̀ jẹ.
Israel Adesanya fẹ́ gbéná wojú Romero Isreal Adesanya fàgbàhàn Kelvin Gastelum ni Atlanta Israel Adesanya ti fi ẹ̀ṣẹ́ yanjú Romero Israel Adesanya fi ẹ̀ṣẹ́ mú ẹ̀jẹ̀ jáde nímú Whittaker láti gba àmì ẹ̀yẹ UFC Loju opo Twitter awọn ọmọ Naijiria to fi mọ Minisita feto ọdọ ati idaraya Sunday Dare ti n ki ku orire ija naa Oríṣun àwòrán, Getty Images Mo ṣetán láti ṣe Paulo Costa bí ọṣẹ sẹ ń ṣojú lọ́la- Israel Adesanya Ọjọ nii pẹ, ipade kii jian.
Mo wá rò ó pé, àwọn òkú, tí wọ́n ti kú,ṣe oríire ju àwọn alààyè tí wọ́n ṣì wà láàyè lọ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Inu mi bàjẹ́ nígbà tí mo bí i, odidi oṣù mẹ́ta, mi ò lè gbàdúrà s'Ọ́lọ́run' 7.
Nígbà tí wọ́n gbé e fún ẹni tí kò mọ̀wétí wọ́n ní, “Jọ̀wọ́ bá wa kà á.
O ni ''A n tẹsiwaju pẹlu iwadii wa bo tilẹ jẹ pe awọn agbegbọn naa ni awọn n tọ pinpin awọn ajinigbe kan to fẹ gba owo lọwọ mọlẹbi eeyan ti wọn ji gbe ni'' Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé Amọ sa, oludari awọn ọmọ ẹgbẹ OPC ni ipinlẹ Oyo, Rotimi Oluomo sọ fun ileesẹ Punch pe awọn afurasi yi gan lo ji eeyan gbe, ti awọn OPC to pẹlu Operation Burst si jẹri si ọrọ yi.
Awọn ti ọrọ naa soju wọn sọ fun AFP pe, gbogbo ile to wa ni abule naa ni wọn fẹ jo nina tan.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ogun Cholera: Ọdọọdún ni àrùn onígbá-méjì máa n ṣọṣẹ́ ní Nàìjíríà -NCDC Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Ogun Cholera: Ọdọọdún ni àrùn onígbá-méjì máa n ṣọṣẹ́ ní Nàìjíríà -NCDC 30 Bélú 2019 Arun onigba-meji ni awọn miran n pe ni arun maa ya igbẹ ọọrin- ko-tun-maa-bi.
 ""Mo le sọ pe orisunmibare ni aisan rọpa-rọsẹ jẹ fun mi."
Ewe, abajade  ipo ate tuntun ohun ni yoo di eekeji ti Quadri yoo lanfaani lati wa lara ogun eniyan lagbaye ti o danto julo, leni ti o tun dipo naa mu ninu osu kinni odun ti a wayii.
Koda, awọn eeyan to jẹ agbọti, agbounjẹ, osisẹ eleto aabo, awọn gbogbo elere to n lu awo orin, awọn atọkun eto to fi mọ awọn asọna lo jẹ obinrin, laisi ọkunrin ninu wọn.
Alukoro ileeṣẹ ọlọpaa ipinlẹ Eko, Bala Elkana sọ fun BBC pe, awọn ọlọpaa bẹrẹ iwadii lẹyin ti fidio naa fa awuyewuye lori ayelujara.
Nigeria Immigration Service: kò sí àjòjì darandaran kankan ní Nàìjíríà
Ibeere nla lori ọrọ yii wa ni pe, Ki gan lo wa faa ti awọn eeyan kan fi n fi ipapanu Pizza to wa larọwọto wọn lorilẹede Naijiria silẹ lọ maa wa ti ilu ọba kiri?
To n tumọ si pe lati nnkan bi ọdun marun un ṣeyin labẹ iṣejọba Aarẹ Muhammadu Buhari, gbese tun Naijiria tun pele si ni pẹlu nnkan bii tiriliọnu mejidinlogun naira.
Lẹ́yìn rẹ̀, Nehemaya ọmọ Asibuki, aláṣẹ ìdajì agbègbè Betisuri ṣe àtúnṣe dé itẹ́ Dafidi, títí dé ibi adágún àtọwọ́dá ati títí dé ilé àwọn akọni.
Ranti majẹmu rẹ;nítorí pé gbogbo kọ̀rọ̀ ilẹ̀ wa kún fún ìwà ipá.
Oríṣun àwòrán, @slay_jimmy Ẹlomiran to ti fopin si ibaṣepọ rẹ pẹlu banki Access ṣugbọn ti ko fẹ darukọ ara rẹ sọ fun BBC pe, oun ko owo oun kuro ni banki naa nitori o gbẹsẹle owo awọn oluwọde EndSARS.
Yoruba yọ lẹnu gbajumọ oṣere tiata lọkunrin naa debi pe ko si owe ti ko lee pa ninu sinima, to si tun maa n ṣe tiata lede oyinbo pẹlu.
Omowe Jummai Ahmadu to je oludasile The Founder of Helpline Foundation ro egeb akoroyin lobinrin lati tubo kede ati lati tubo se idanilekoo sii fawon eniyan lori arun jejere.
Nígbà tí mo wà ní kékeré, èmi àti ẹ̀gbọ́n ọ̀n mi àti àwọn ọ̀rẹ́ wa máa ń fẹ́nu fa oje òdòdó mun.
Ṣugbọn awọn ẹlẹrii Eji Gbadero naa tako wọn pe inu ile ni olujẹjọ naa wa, to n tọju awọn alejo rẹ níbi ayẹyẹ ikomọ jade rẹ.
 If anyone tells you your dreams are too big, just say thank you and work harder and smarter to turn them into reality.
O si bu ẹnu ẹtẹ lu iwa ifẹmiṣofo ti o ti di tọrọ-kọbọ lorilẹ-ede yi.
Ní àkókò yìí lọ́la tabi ní ọ̀tunla n óo wádìí nípa rẹ̀ lọ́wọ́ baba mi.
Action Against Hunger: Ẹgbẹ́ agbésùmọ̀mí ISWAP ṣekú pa àláànú kan
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Akomolede ati Aṣa lori BBC: Kí ní ìtúmọ̀ Sílébù àti àmi ohun tó ń fún ni?
Oríṣun àwòrán, Getty Images BBC ri awọn obinrin laafin Emir kano ti wọn n ju oko lati fi ẹhonu han Aminu Ado Bayero rọ́pọ̀ Lamido Sanusi gẹ́gẹ́ bí Emir ìlú kano Ọba mẹwaa igba mẹwaa, Aminu Ado Bayero rọ́pọ̀ Lamido Sanusi gẹ́gẹ́ bí Emir tuntun ìlú kano.
" Eyi ni ọrọ ikilọ ti Ọba ilu Benin, Ọba Ewuare II gbe kalẹ nibi aṣekagba ọdun Igue to waye nilu Benin.
” Wọ́n bá bẹ̀rẹ̀ sí sọ̀rọ̀ sí i pẹlu ibinu.
O fi ireti re mule pe, awon yoku ti won si wa ninu igbeku, ni eyi ti awon akekoo Chibok si wa lara won, ni won yoo darapo mo awon ebi won laafia.
Ẹgbẹ afẹnifẹre naa wa lara awọn to bu ẹnu atẹ lu ọrọ ti Mamman Daura sọ, wọn ni bi wọn ṣe n pin ka laarin Ariwa ati Guusu naa ni ko se ma a lọ.
Wo ohun tó ti ṣẹlẹ̀ sẹ́yìn.
Imo: Aléjò mẹ́wàá ṣòfò ẹmí níbi ayẹyẹ ìgbéyawó
Lọwọlọwọ, wọn ṣi n wa awọn kan lara awọn agbẹ onirẹsi ti awọn agbebọn kọlu ni Borno yala wọn ku ni tabi wọn ye.
Bi baale ile ko ba si si nile,ni kete to ba tajo de, awọn ara ile a ma jabọ oun to sẹlẹ nigba to wa lajo fun.
Ṣugbọn o pada tọrọ aforiji fun aṣiṣe naa.
Nọmba 19, Olowora ni awọn ara adugbo Mafoluku ti ri oku ọkunrin kan, ati iyawo rẹ pẹlu awọn ọmọ mẹrin ati alejo wọn ti oyun wa ninu rẹ.
Olatunji ni awọn ko le e sọ pe awọn fọwọ si igbesẹ naa tabi awọn ko fọwọ si i, ṣugbọn awọn yoo wo igbesẹ naa finifini ti awọn ba de ipo, lati wo boya ọna to gba de ipo ba ofin mu gẹgẹ bi akowe agba tabi bẹẹ kọ.
Ọrọ pọ ninu iwe kọbọ ti gbajugbaja olorin yii tu sita fun BBC Yoruba.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ó kéré tán ọkùnrin 15 ló ń bámi lòpọ̀ lójúmọ́, mo sì ti ní egbò lójú ara - Adeola tí wọn fi sòwò ẹrú Òfò lásán, tí kò ní ẹ̀rí ní àbọ̀ ìwádìí àjọ Transparency lórí ìwà ìbàjẹ́ - Ìjọba àpapọ̀ Ìbọn kọ́ ni wọn fi pa èèkàn ẹgbẹ́ APC n‘Ibadan, ọ̀bẹ ni wọ́n fi gé iṣan ọrùn, ọrùn ọwọ́ àti ẹsẹ̀ rẹ̀ - Ọlọ́pàá Mo dúpẹ́ pé Ọlọ́run dá mi láre lórí ikú Sugar, tí adájọ́ sì tú mi silẹ̀ - Akinmoyede Ìṣọ̀rí Amotekun ta pè ní ‘Irúnmọlẹ̀’ ní yóò máa gun ọ̀kadà kiri láti pèsè ààbò - Àjọ Dawn Ohun ta ri gbọ ree lati ẹnu agbẹnusọ fun igbakeji aarẹ Naijiria, Laolu Akande to fi ọrọ yi soju opo Twitter rẹ.
Awọn asoju lati Ajọ Isọkan ilẹ Yuroopu EU, China, Russia, Egypt, Jordan ati Ilẹ Gẹẹsi, UK ni yoo darapọ mọ ipade naa.
Mo wá rí àmì ńlá kan ní ọ̀run.
Èdè-àìyedè kan bẹ́ sílẹ̀ láàrin àwọn mejeeji, obinrin yìí bá kúrò lọ́dọ̀ ọkunrin náà, ó lọ sí ilé baba rẹ̀ ní Bẹtilẹhẹmu, ó sì ń gbé ibẹ̀ fún nǹkan bí oṣù mẹrin.
Ohun ti ko dara ni láti maa lọ ọmú obinrin
 ₦35,000 ni mò ń gbà bíi Adelé ọba, kò sí ọkọ̀ ayọ́kẹ́lẹ́ - Adelé Olúbọ̀rọ̀pa Ìrántí Sani Abacha, apàṣẹ wàá tó tún kó owó Nàìjíríà mì Àwọn 'ẹ̀bùn' tí ikú George Floyd fún àgbáyé Hubert Ogunde rèé, baba àwọn òsèré tíátà Irú ẹ̀dá wo ni olówó yalumọ àkọ́kọ́ nílẹ̀ Yorùbá, Candido Da Rocha?"
Àrà mánigbàgbé tí Baba Legba dá lágbo tíátà rèé Àwọn ọ̀daràn tó jí ìbejì ọmọ Akeugbagold kó ti fojú ba ilé ẹjọ́ lòníì Fìdíhẹẹ́ ní Banji Akintoye nínú YWC, lílọ ni yóò lọ - Tola Adeniyi A kò sí lára àwọn tó ń ṣèwọ́de tako èlé owó epo àti iná ọba - NLC Aarẹ Ghana lo n gba a lọwọ aarẹ Muhammadou Issoufou tó jẹ aarẹ ilẹ Niger.
Ṣugbọn ó mú àwọn igẹ̀ ẹran náà ati itan ọ̀tún wọn, ó fì wọ́n gẹ́gẹ́ bí ẹbọ fífì níwájú OLUWA, bí Mose ti pa á láṣẹ.
Jesu Oyingbo rèé, pásítọ̀ tó láṣẹ ìbálòpọ̀ lóri ọmọ ìjọ obìnrin Igbó mímu lè ṣe kóríyá, kò lé fi kún orín ẹnu òṣèré - 9ice Ìtàn tó wà nídi òwe ‘Sebótimọ Ẹlẹ́wà Sàpọ́n’ Ọba Oyewọle fikun pe oju ọna to wọ ibudo naa buru jai lai naani ọpọ ohun alumọni to sodo si agbegbe omi Ówù ọhun.
Rape: Ó kéré tán wọ́n ń fipá bá obìnrin kan lòpò láàrín wákàtí márùn ún ní Naijiria
Já a sí wẹ́wẹ́, kí o sì da òróró lé e lórí, ẹbọ ohun jíjẹ ni.
Irinwo ninu àwọn ọdọmọkunrin rẹ̀ bá a lọ; igba (200) sì dúró ti ẹrù wọn.
Jiti Ogunye: Ọjà òkùnkùn ni àyẹ̀wò Minisita ní Ilé Asòfin
Kí àwọn ọmọdé, má ba tètè mọ iyì yín
Ọlọrun sì dá a lóhùn pé, “Má ṣe bá wọn jà níhìn-ín, ṣugbọn yípo lọ sẹ́yìn wọn kí o kọlù wọ́n ní òdìkejì àwọn igi balisamu.
‘ Oluwo kò gbọdọ̀ darí ìrun ní ọdún Iléyá!
 sọ ́ sọ ́ sọ ́ ni ìrinlẹ ̀ àti ìmúnilọ ́ kàn wọn máa ń wọ gbogbo ìgbésí ayé àwọn ènìyàn gẹ ́ gẹ ́ bí ẹnì kọ ̀ ọ ̀ kan , ní ẹlẹ ́ gbẹ ́ jẹgbẹ ́ àti ní àwùjọ .
A o maa mu alaye kikun si wa ni kete ti a ba ti mọ bo ṣe gba itusilẹ.
Ó fún Nàìjíríà l'èsì àwọn ẹ̀sùn tó fi kàn-án Ìdí tí mo fi ń ṣe ayẹyẹ ọjọ́ ìbí 35 lọ́dọọdún rèé- Allwell Ademola Wo ojú Akeem t'Ọlọ́pàá mú pé ó fipá bá ọ̀dọ́mọbìnrin kan sùn létí odò l'Oṣun Yàtọ̀ sí Eko, wo ohun t'áwọn ìpínlẹ̀ meje míràn ń sọ nípa ìwọlé àwọn akẹ́kọ̀ọ́ Ogun oṣiṣẹ lo n ṣiṣẹ nilu itura Palau, ko si ẹni ti wọn da duro ninu wọn.
Ijọba aarẹ ana to ti di oloogbe, Umar Yar'Adua lo pada ṣe adinku owo epo naa, to si gbe lọ si N65.
”Anthony Martial darapo mo Manchester United lodun 2015 lati inu iko agbaboolu Monaco fun iye owo ti o to milionu mẹ́rìndínlógójì euro owo ile okere £36 million ($47m), lati igba naa ni o ti n ri ara re gege bi okan lara agbaboolu odo ti o darajulo.
Àwọn ọmọ Israẹli tún ṣe ohun tí ó burú lójú OLUWA, wọ́n ń bọ àwọn oriṣa Baali, ati Aṣitarotu, oriṣa àwọn ará Siria ati àwọn ará Sidoni, ti àwọn ará Moabu ati àwọn ará Amoni, ati ti àwọn ará Filistia.
“Nígbà tí ẹ bá ń kọjá lọ ní ibi ọgbà àjàrà ẹlòmíràn, ẹ lè jẹ ìwọ̀nba èso àjàrà tí ó bá tẹ́ yín lọ́rùn, ṣugbọn ẹ kò gbọdọ̀ mú ẹyọkan lọ́wọ́ lọ.
Lẹ́yìn àyẹ̀wò, kò sí alárùn Coronavirus ní Nàíjíríà, sáká lara wa dá - Mínísítà Obìnrin tó ń ṣiṣẹ́ ẹrú ní Oman tó bá fẹ́ òmìnira, yóò bá ọ̀gá rẹ̀ ṣùn - obìnrin méjì tó ti oko ẹrú dé Kaduna tún gbàlejò ìkọlù àwọn agbébọn, àádọ́ta èèyàn míì rọ̀run ọ̀sán gangan Ti ẹ o bá gbàgbé ìgbìmọ ìwádiìí ti Gomina Gboyega Oyetola gbe kalẹ̀ ni ọjọgbọ́n Olu Aina jábọ rẹ̀ fun Gomina ni ọ̀ṣẹ̀ to kọja ti wọ́n si gba ìjọba ni ìmọ̀ràn láti dá ìwọ̀sọ àwọn akẹkọọ pada si bi wọ́n se wà tẹ́lẹ̀.
Kí olúwarẹ̀ sọ̀rọ̀kí ó kéde rẹ̀ níwájú mi.
Wolii ni, iṣẹ́ rẹ̀ ati ọ̀rọ̀ rẹ̀ sì fi agbára hàn níwájú Ọlọrun ati gbogbo eniyan.
O tunbọ daro iku oluwọde to padanu ẹmi rẹ ni Ogbomosho nipinlẹ Oyo iyẹn Isiaq Jimoh.
Orúkọ wọn ni: Otini, Refaeli, Obedi, ati Elisabadi, ati àwọn arakunrin wọn, Elihu ati Semakaya, tí wọ́n jẹ́ alágbára eniyan.
Ìbátan rẹ̀ yìí ni yóo jogún rẹ̀.
O tun le jẹ igbadun ririn ajo ori omi tabi ibi itaja ti o wa ni Treichville tabi Cocody.
Ijiroro ṣi n lọ lọwọ lori boya ajọ WTO faramọ ẹni to ni ibo to pọju lọ.
Dájúdájú, OLUWA yóo fúnni ní ohun tí ó dára;ilẹ̀ wa yóo sì mú èso jáde lọpọlọpọ.
Gbogbo igba ti wọn ba si ti waako ni awọn ololufẹ ere bọọlu maa n ri awọn ohun manigbagbe di mu.
Akẹkọ naa la gbọ pe o gba maaki okoolerugba o din mẹsan ninu idanwo asewọle sile ẹkọ naa , to si fẹ kọ nipa isẹ ibaraẹnisọrọ, Mass Communication.
Fun apẹrẹ, lori ipa ọrẹkunrin si ọrẹbinrin, ọkunrin ko le gbe obinrin le itan o, bẹẹ si ni mi o le fẹnu ko iyawo oniyawo lẹnu ninu ere toripe a fẹ ko ye awọn eeyan.
Ẹ má fi Jerusalẹmu búra, nítorí ìlú ọba tí ó tóbi ni; 
Ogbeni Sunday Dare to je komisona fun eto   ise akanse  ni ajo naa ,NCC lo so eleyii niluu Abuja.
“Orile ede China lo  ni  eto oro aje to ga julo ni ekun ile Afirika yala ni  ile-ise aladaani ati ile-ise ijoba , ti won si lowo ninu ;ohun amayederun, ina mona-mona, eto agbe, ohun alumooni -ilẹ, iyipada ọjọ ati eto ilera.
Simoni Peteru wà níbi tí ó dúró, tí ó ń yáná.
Ṣugbọn nígbà tí Peteru wà ní Antioku, mo takò ó lojukooju nítorí ó ṣe ohun ìbáwí.
Wo àfipábánilòpọ̀ ẹni ọdún 51 tí ìjọba ìpínlẹ̀ Ekiti tú làṣirí ní gbangba Oyinkan Abayomi, akọni obìnrin tó fi ìfẹ́ pa orúkọ ọkọ kejì dà sí ti ọkọ àárọ̀ Banki Nàìjíríà, CBN ṣàlàyé nípa àwọn tó máa rí gbà nínú owó ìrànwọ́ N75b tíjọba gbé kalẹ̀ Oṣú mẹ́fà ni òṣìṣẹ́ ìjọba tó bá bímọ yóò máa lò nílé kó tó wọṣẹ́ padà- Seyi Makinde Agọ ọlọpaa meje ati ọpọ ọkọ tawọn ọlọpaa fi n ṣiṣẹ ni wọn dana sun lasiko rogbodiyan to bẹ silẹ lẹyin ifẹhonuhan EndSARS.
Oríṣun àwòrán, Facebook/ajikecentre Nigba ti BBC beere lọwọ Risqot nipa yiyanju gbọnmi si omi ooto to wa laarin oun ati ọkọ rẹ o ni ''wọn yanju fun wa'' Ọpọ eeyan lo ti ṣe ileri iranwọ yala nipa owo tabi riran awọn ọmọ rẹ lọ si ileẹkọ fun Risikat.
Iṣọla Oyenusi rèé, ẹnití ìfẹ́ obìnrin ṣun dé ìwà ìdigunjalè Ẹfunroye Tinubu - Ògbóǹtagí oníṣòwò, olówò ẹrú àti afọbajẹ Samuel Ajayi Crowther, òjíṣẹ́ Ọlọ́run tó gbé èdè Yoruba lárugẹ BBC gbiyanju lati ba Ọgbẹni Jammeh, to n gbe ni orilẹede Equatorial Guinea lọwọlọwọ sọrọ, lati gbọ tẹnu rẹ lori ẹsun naa.
#BBCNigeria2019 Atiku wọ orílẹ̀èdè Amẹ́ríkà lẹ́yìn-ò-rẹyìn Minisita fun ibaraẹni sọrọ, Adebayo Shittu kede eleyii lọjọbọ nibi eto ajọṣepọ awọn amoju ẹrọ eyi to waye nilu Abuja.
Jesu yìí ni Ọlọrun fi ṣe ètùtù ẹ̀ṣẹ̀ fún ẹni tí ó bá gbàgbọ́, nípa ikú rẹ̀.
"Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Kara bridge fire: Ìséde ká mi mọ́ ọ̀nà ni mo ní kí n sùn, ki ọkọ̀ mi tó jóná Tiamiyu sọ pe ""mo n mura lati sun ninu ọkọ katakata (tractor) ti mo maa n sun si, ni ọkọ bẹtiro kan ti bureeki rẹ da kọ lati ṣiṣẹ kọlu ọkọ mi, ati ọkọ bẹtiro."
OLUWA bá bi mí léèrè, ó ní, “Ìwọ ọmọ eniyan, ǹjẹ́ àwọn egungun wọnyi lè tún jí?
Kàkà bẹ́ẹ̀ ńṣe ni ẹ̀ ń fi ìwọ̀sí kan ara yín tí ẹ̀ ń rẹ́ ara yín jẹ, ẹ̀yin tí ẹ jẹ́ onigbagbọ!
Alukoro ajọ ọlọpa ipinlẹ Ondo, Fẹmi Joseph to ti fidi isẹlẹ naa mulẹ, sọ pe awọn ọlọpa ti bẹrẹ iwadi lori ọrọ naa.
Ajọ naa gbe awọn ọkunrin naa lọ si olu ileeṣẹ wọn l'Oshodi fun ifọrọwanilẹnuwo lẹyin ti wọn mu ọkọ ti wa ninu rẹ.
AMAA 2018 Ami eye fiimu to dara julo
Adesina ni sps ìgbà ni Nàìjíríà tí sùgban sùgbọ́n tó tún dìde, nítori náà ó ṣe pàtàkì láti máá wá ìwájú fún ọ̀nà àbáyọ.
Amọṣa to ba jẹ pe o n ba awọn eeyan miran gbe, gbogbo wọn gbọdọ wa ni igbele fun ọjọ mẹrinla Bi o ba wa di wi pe aisan naa n tubọ burẹkẹ sii lara rẹ, tabi ko tete lọ bọrọ, a dara ki o kan si awọn ileewosan to ba wa nitosi rẹ ki o si ṣalaye fun wọn ni kikun.
A ti nílé, dúkìá àti ẹbí ní South Africa, àwa kò ṣetán láti padà sílé Ta ló leè rò pé ọmọ mẹ̀kúnnù bí èmi leè dé ipò alága NURTW?
    Nígbà tí ó di òwúrọ̀ ọjọ́ kejì, wọ́n gbé àpótí kan jáde, àpóti ti mo sọ pé mo rí pẹ̀lú wọn lójú ọ̀nà ni.
Ẹ̀mí Mímọ́ ati àwa náà pinnu pé kí á má tún di ẹrù tí ó wúwo jù le yín lórí mọ́, yàtọ̀ sí àwọn nǹkan pataki wọnyi: 
afurasi odaran ohun ni oko ayokele, oniruuru ero ilewo ibaranisoro, ati ero
Wo ilana yii ni ṣiṣẹ n tẹle lati mọ bi o ṣe maa lo o: Kọkọ fi omi ati ọṣẹ fọ ọwọ rẹ ki o si fi tiṣu nu u, tabi lo sanitaisa ki o to lo ibomu-bẹnu.
Gomina ipinlẹ Jigawa, Mohammed Badaru Abubakar, ti o jẹ
Nítorí náà, ẹ fa ara yín mọ́ra gẹ́gẹ́ bí Kristi ti gbà yín, kí á lè fi ògo fún Ọlọrun.
Lagos-Ibadan road: Ọkọ̀ agbépo tó gbiná ní Ibafo dá súnkẹrẹ fàkẹrẹ sílẹ̀ Ọlọ́pàá fi afẹ́fẹ́ tajú-tajú àti omi tú àwọn tó fẹ́ ṣun ilé ìtajà ShopRite l‘Abuja ká Àwọn òṣèré tíátà takò ìkọlù South Africa àti ìgbẹ̀san ọmọ Nàíjíríà ShopRite Ibadan gbé ìlẹ̀kùn tìpa torí ìkọlù àwọn tó ń fẹ̀hónú hàn Ninu ọrọ ti wọn, ajọ EFCC naa wa rọ Oba Adeyeye Ogunwusi lati kesi awọn ọba ni ile Yoruba, ki awọn naa tiraka lati gbogun ti iwa ibajẹ ni agbeegbe wọn.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Àgbà ni Obasanjo, oun tó ń sọ yé e, ìjọba ni kó tají - Wale oke Lara awọn osere tiata to ti ki Bidemi ku ayọ abara tintin la ti ri Antar Laniyan, Madam Sajẹ, Wumi Toriọla, Ronkẹ Oshodi Oke, Ọdunlade Adekọla ati bẹẹ bẹẹ lọ.
Forúkọ sílẹ̀ nínú ìròyìn yìí Ọba Ilorin ló pàṣẹ pé kí ń padà sọ́dọ̀ ọkọ mi - Risikat olójú búlúù Access Bank, dá ₦206,000 ìyá mi pádà lónìí, bí bẹ́ẹ̀ kọ́.
Gbogbo wọn lọ sinu ilé ìsìn Baali, wọ́n sì kún inú rẹ̀ títí dé ẹnu ọ̀nà kan sí ekeji.
Minisita tun so pe isẹlẹ  to fa iku aitọjọ  arabinrin Faye Mooney, omo orile ede Britain
FC, England); John Ogu (Hapoel Be’er Sheva, Israel)Awon agbaboolu
Bí wón ti ń kó ọmọ, bẹẹni wón ńkọ́ aya.
Lara awọn ọkọ ayọkẹlẹ naa si ni ọmọ ẹgbẹ oselu PDP mejidinlogun naa wa, ti wọn n lọ ki gomina wọn kaabọ pada waye.
Ọpọlọpọ eniyan ni wọ́n pa, nítorí pé Ọlọrun ni ó jà fún wọn; wọ́n sì ń gbé ilẹ̀ àwọn ọ̀tá wọn títí tí àwọn ará Asiria fi kó wọn lẹ́rú.
ó ní, “Mo fi ara mi búra pé nítorí ohun tí o ṣe yìí, tí o kò kọ̀ láti fún mi ní ọmọ rẹ kan ṣoṣo, 
"Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ìdẹ̀ra dé, Gẹnẹrátọ̀ tó ń lo omi dé, a bọ́ lọ́wọ́ òkùnkùn Ẹ̀rù àti oríkunkun ló mú kíjọba máa fi ọlọ́pàá, ológun halẹ̀ mọ́ aráàlú - Ṣoyinka ""Ojú wa rí tó ní Egypt, bí wọ́n ṣe ń tẹ̀ wá lọ́mú, ni wọ́n ń gbá wa ní ìdí"" Ọlọ́wọ̀ tìlú Ọ̀wọ̀ tuntun gorí ìtẹ́, idà àlááfìà ló mú ní Ìpèbí Nigba ti ọwọ wa tẹ Wadume, lo ba figbe ta pe oun kii se apaayan abi ajinigbe rara, oloselu ni oun, ti ẹgbẹ oselu APC si mọ oun bii ẹni mọ owo, koda wọn fun oun ni miliọnu mẹtala naira lasiko ibo to kọja fun ipolongo ibo, amọ ti oun na miliọnu meje naira nibẹ."
Lọdọọdun ni a n gba awon eniyan sibi ise
Awọn ọmọ ẹgbẹ ajijagbara Taliban naa si n doju ogun kọ wọn ni Pakistan.
Àyà mi kọ́ já ṣùgbọ́n ó ni ki n dì mọ́ òun lẹ́yìnn dáadáa kì n má ba à já lulẹ̀ mo rọra dọ̀bálẹ̀ lé e lẹ́yìn mo di iké ẹ̀yìn rẹ̀ mú dáadáa.
Kí ló wá yà mí lẹ́nu?
Ìdí rèé táwọn àkàndá ẹ̀dá fi dí iwájú iléeṣẹ́ ìjọba ìpínlẹ̀ Oyo pa l'Agodi n'Ibadan Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Cancer: Àṣe ara mi ni iso ti n run gbogbo bí mo ṣe n ṣèrànwọ́ lórí jẹjẹrẹ Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Andrew Haruna: So-bàtà tó di ọ̀jọ̀gbọ́n fásitì tó di ọ̀gá àgbà9 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 America blacklisted Nigeria: Amẹ́ríkà fi orukọ Nàìjíríà sínú ìwé 'mágùn' nítorí òmìnira ẹ̀sìn.
Ninu ọrọ to ba BBC News Yoruba sọ, Kọmiṣọna fun eto iroyin ati itaniji, Ọgbẹni Wasiu Ọlatubọsun ṣalaye pe aay bẹ silẹ o bẹ are ni gomina Makinde fẹ fi ọrọ ipadabọ rẹ ṣe bayii pẹlu pipada si ẹnu iṣẹ lẹyẹ o ṣọka lati tẹsiwaju pẹlu eto gbogbo lati le arun Coronavirus wọgbẹ ni ipinlẹ Ọyọ.
N ò rí ohun tí kòlè fi tọrọ
Olori Memunat wa ṣe apejuwe Alaafin bii ẹni to jẹ awokọṣe rere, olutọnisọna, ọmọwe ati ọlọrọ apọnle.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Teach your children Yoruba: Wo àwọn òyìnbó tó ń kẹ́kọ̀ọ́ èdè Yorùbá ní Michigan, America Bó tilẹ̀ jẹ́ pé lẹ́yìn ti orin náà jáde ni wọ́n ti mu ọmọkunrin olórín ọhun.
- Trump Ẹyin ni wọ́n fi n gba ìbále ẹlòmiran lára wa ki a to lọ pàde àwọn oníbara Ìbọn kọ́ ni wọn fi pa èèkàn ẹgbẹ́ APC n‘Ibadan, ọ̀bẹ ni wọ́n fi gé iṣan ọrùn, ọrùn ọwọ́ àti ẹsẹ̀ rẹ̀ - Ọlọ́pàá Yaba Left: Àṣírí tú!
Ó jẹ́ ọ̀wọ̀ ẹyẹ tí kò ka àwọn onímọ̀ ìjìnlẹ̀ sáyẹ́ǹsì sí fún ọdún gbọgbọrọ, láti ọdún 1843 tàbí 1844.
Mí ò mọ̀ pé ọ̀rọ̀ ọlọ́pàá ni ìwọ́de #EndSars níṣe pẹ̀lú - Anthony Joshua Allwell Ademola sọ̀rọ̀ lórí ìdí tó fi ń ṣe ọjọ́ ìbí 35 lọ́dọọdún Awọn ti iṣẹlẹ naa ṣe oju wọn ṣalaye pe olounjẹ ni arabinrin naa, o si wa si agbegbe naa ni lati wa gba ẹgbẹrun kan naira ti ọkan lara awọn ọlọkọ ero lagbegbe naa jẹ ni ki iṣẹlẹ buruku naa to ṣẹlẹ.
Lẹ́yìn náà ni Ọlọrun ranti Rakẹli, ó gbọ́ ẹ̀bẹ̀ rẹ̀, ó sì ṣí inú rẹ̀.
Akeugbagold ni oun ti darijin awọn afurasi ajọmọgbe naa, ti oun si setan lati ran lọwọ to ba jade ni ahamọ, oun si n gbadura fun pe ko yi iwa rẹ pada, ko le di aafa nla.
“Mú ìwé mìíràn kí o tún kọ gbogbo ohun tí ó wà ninu ìwé ti àkọ́kọ́, tí Jehoiakimu, ọba Juda fi jóná sinu rẹ̀.
Ọba Babiloni kọ ìwé kí Hesekaya.
Àwọn tí wọ́n jẹ́ olórí ninu àwọn akọni ọmọ ogun Dafidi nìwọ̀nyí; àwọn ni wọ́n fọwọsowọpọ pẹlu àwọn ọmọ Israẹli, láti fi Dafidi jọba, tí wọ́n sì fi ìdí ìjọba rẹ̀ múlẹ̀, gẹ́gẹ́ bí ìlérí tí OLUWA ti ṣe fún Israẹli.
Kàkà bẹ́ẹ̀ ṣe ni igbagbọ rẹ̀ túbọ̀ lágbára sí i, ó fi ògo fún Ọlọrun 
Amọ o ni oun si wa digbi ninu ẹgbẹ oselu APC nitori ẹgbẹ gbogbo awọn ni, ẹgbẹ ti oun nifẹ si ni, kii si se ẹgbẹ Akeredolu nikan.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Boko Haram 113 dèrò ẹ̀wọ̀n nípínlẹ̀ Niger Ibeere mẹfa lori ijinigbe Dapchi DSS tu akọroyin ti wọn mu silẹ Awọn agbesunmọmi Boko Haram tẹlẹ gba idande Òun ní ẹnìkejì tí wọn ti se idajọ fún lẹ́yìn Haruna Yahaya ti wọn dájọ́ ẹwọn ọdún mẹ́ẹ̀dógún fún nínú oṣù kejì ọdún yìí ní ìpínlẹ̀ Niger lẹ́yìn ti wọn jẹ́wọ pe àwọn lọ́wọ́ nínú ìjínigbe náà.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù 9th Assembly: Dogara kìlọ̀ fáwọn ẹgbẹ́ òṣèlú láti má dásí yìyan olórí ilé 9 Ìgbé 2019 Oríṣun àwòrán, @YakubuDogara Adari ile aṣoju aṣofin l'Abuja, Yakubu Dogara ti rọ awọn alaṣẹ ẹgbẹ oṣelu lati jẹ ki awọn ọmọ ile aṣofin mejeeji yan awọn olori wọn fun ra wọn.
 Emi kii se iru eeyan tẹ ro pe mo jẹ.
a ṣe àfiikún àwọn àpólà tí a kó tí olùsọ èka-èdè lè lò pé kò ní ẹ ̀ kun ó sì peléke .
Oríṣìíríṣìí ẹyẹ yóo pa ìtẹ́ sí abẹ́ òjìji ẹ̀ka rẹ̀.
Ṣaaju eyi, Agbenusọ Ile Igbimọ Aṣofin Ipinlẹ Eko, Aṣofin Mudasiru Ọbasa ninu ọrọ ti o fi ṣi ipade sọ pe eredii ipade naa ni lati fi orikori pẹlu awọn alẹnulọrọ gbogbo lori ọrọ owo yii ati bi Ipinlẹ Eko yoo ṣe tẹ siwaju.
Yiyan ọba mọkalelogun ni ọjọ kan: Oríṣun àwòrán, Others Eruku sọ lala lori Abiola Ajimobi lasiko to se atunto ofin ati ilana oye ọba jijẹ nilẹ Ibadan.
Ilu Caracas lorilẹede Venezuela lo gba ipo kini, ti ilu Damascus lorilẹede Syria si tẹlee, ilu Tashkent ni orilẹede Uzbekistan, Almaty ni Kazakhstan ati Bangalore lorilẹede India lo tẹlee ni ipo kẹta, kẹrin ati ikarun ni ṣisẹ n tẹlee.
Agbẹnusọ fun gomina naa, Taiwo Adisa fi kun un wi pe gomina Makinde ṣe tan lati jẹjọ ti ajọ naa ba ri i wi pe oun ru ofin iwa ibajẹ.
 Àwọn ọmọ yìí ti di tèmi, mo si ti pé agbẹjọ́rò mi láti ṣi àpò owó fún wọ́n títí ti wọ́n yóò fi tójuubọ́ ọ̀rọ̀ Femi Gbajabiamila rèé Ẹ̀sọ́ abẹnugan ilé, to jẹ́ ọkan lára àwọn òṣìṣẹ́ ọ̀tẹlẹ̀múyẹ (DSS) Nàìjíríà, Abdullahi M.
00) ni wọ́n bá ní ilé Àṣàkẹ́, ìyẹn ìyá Bándélé nígbà tí àwọn Akin Ọlọ́fìn-íntótó yẹ ilé rẹ̀ wò.
Bukola Saraki kò kọjá òfin - EFCC Ilé ẹjọ́ gba onídúró Naira Marley pẹ̀lú mílíọ́nù méjì náírà Onnoghen gba ìwé ìfisùn míràn látọ̀dọ̀ ìgbìmọ̀ NJC Magu ati Keyamo ri‘binu ijọba Ninu idajọ rẹ, Onidajọ Oweibo paṣẹ pe ki EFCC kede gbigbẹsẹ le awọn dukia naa ninu gbaju-gbaja iwe iroyin kan laarin ọjọ mẹrinla, lati fun olujẹjọ tabi ẹlomii to ba nifẹ ninu wọn ni anfaani lati sọ idi ti ijọba ko fi gbọdọ gbẹsẹ le wọn titi lai.
nítorí pé Ọlọrun ti sé gbogbo àwọn obinrin ilé Abimeleki ninu nítorí Sara, aya Abrahamu.
Idibo naa ti wọn sun siwaju lati ọjọ kọkanla, oṣu kejila, ọdun 2018 lo n ka wakati igba ti orilẹ-ede naa yoo dagbere fun EU ni ọjọ kọkandinlọgbọn, ọsu kẹta.
Wọ́n kó ọrun ati ọ̀kọ̀ lọ́wọ́,ìkà ni wọ́n, wọn kò ní ojú àánú.
OLUWA ni yóo ṣe ìdájọ́ láàrin èmi pẹlu rẹ.
 bakanna awon omo mejeji awon joliot-curies , hélène ati pierre na je onimo sayensi pataki .
 Ẹ ̀ gbá gbágùrá lo n fi òsì àti Òdọ ̀ fin sílẹ ̀ .
Ninu ọrọ rẹ si ni Gomina Makinde ti rawọ ẹbẹ si Alaafin pe ko jẹ eburẹ lori bi oun ṣe gbe ibudo Ọlọpa kan lọ si agbegbe Oke Ogun dipo ko wa nilu Oyo gẹgẹ bi Alaafin ti n fẹ.
Atâyi Babs to jẹ adari Ajọ 'Climate and Sustainable Development Network' ti ni ida aadọrun eniyan lo n lo ike rọba lai si pe wọn maa tun un lo nigba miran lati dawọ ẹkun omi duro lagbaye.
Àwọn ọmọ orileede Ethiopia tí kò bá lè san owó náà, ijoba ni àwọn yóò sanwó wọn.
O ni obinrin ẹni ọdun mẹtalelọgbọn naa ra irẹsi ati omi tutu ni ọja Kutọ to ti n ta ọja ṣugbọn Abule Ọtun ni Lafẹnwa to n gbe ni wọn ti sare gbee lọ sile iwosan Oríṣun àwòrán, Others Àkọlé àwòrán, Ọdọọdún ni àrùn onígbá-méjì máa n ṣọṣẹ́ ní Nàìjíríà -NCDC Wọn ni iṣẹlẹ arun onigba-meji yii ti ba eniyan mejila ni ipinlẹ Ogun ni eyi to ti mu ẹmi ẹni marun un lọ ti awọn to ku n gba itọju nile iwosan.
Bukola Saraki figbe ta pé iléẹjọ́ ń fá orí òun lẹ́yìn òun Ọwọ́ EFCC tẹ ọ̀kan lára àwọn ti FBI fi èsún jìbìtì kàn!
Judasi bá da owó náà sílẹ̀ ninu Tẹmpili, ó jáde, ó bá lọ pokùnso.
“Bakan naa, mo ni lati sise takunutakun lati ri pe, iko yii pegede fun idije AFCON lodun to n bo.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Lagos Tanker Accident: Ìjàmbá ọkọ̀ agbépo mú ẹ̀mí èèyàn kàn lọ ní Èkó, awakọ̀ tírélà f'ẹsẹ fẹ́ẹ 21 Èbibi 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 7 Ògún 2020 Oríṣun àwòrán, LASEMA Ijamba ọkọ tirela agbepo kan to ṣubu lulẹ nilu Eko ti mu ẹmi eeyan kan lọ ti dirẹba ọkọ naa si ti na papa bora.
Oríṣun àwòrán, Twitter O fikun pe oun yoo ṣiṣẹ pọ pẹlu awọn lọbalọba ni ipinlẹ naa fun ijiroro lori ọna ati mu nkan lọ deede fun awọn to wa ni awọn ilu kereje-kereje.
ko nipa ojo iwaju orile ede yii, ti won wa lati fẹ gbọ nipa bi ijoba yii se fe
Ní ọjọ́ tí wọ́n fi ẹ̀yìn Bádérù ti àgbá, ńṣe ni ìlú ń rọ́ kẹ̀kẹ̀.
Ni irọlẹ ọjọ Aiku, ọjọ Kejila oṣu Keje ọdun 2020 ni ariwo gba ilu kan pe ọwọ ti tẹ olori ọmọ ẹgbẹ one million boys, Abiola Ebila, to si ti jẹ Ọlọrun nipe.
Makinde fi kun ọrọ rẹ wi pe iya oun fi ọwọ rọri ku ni.
 Ogbeni Nyagali je omo egbe oselu
 Àrùn náà wọ ́ pọ ̀ jùlọ ní àwọn agbègbè ipa ọ ̀ nà òòrùn ní àgbáyé ṣùgbọ ́ n ó lè wáyé níbikíbi .
 nigbà ti ó dáfá , won ni ki ó fe síwáju bì ó bà ń fé kì àbìkú dúró .
“Má bẹ̀rù mọ́, ọdọmọbinrin Sioni,Wò ó, ọba rẹ ń bọ̀ wá,ó gun ọmọ kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́.
Akọ̀ròyìn Morocco, Hajar gbà ìdájọ́ ẹ̀wọ̀n lórí ẹ̀sùn àgbèrè àti pé o ṣẹ́yún Nǹkan kò tíì ṣẹnu ire fún àwọn ọmọ orílẹ̀-èdè yìí - Atiku Bi o tilẹ jẹ pe ọpọlọpọ awọn ololufe ere ori papa ni ko yọju lati wo Shelly-Ann ni igba to n sa ere naa, o ni oun ko bikita rara.
Àwọn ohun tó bá lè fa ìwà ọ̀daràn bíi aṣọ ìwọ̀kuwọ̀ ló yẹ ká ti ọwọ́ rẹẹ̀ baṣọ - Amotekun Osun Ọga agba ikọ Amotekun ni ipinlẹ Osun, Amitolu Shittu ti sọ pe o yẹ ki awọn ẹṣọ alabo dẹkun bi awọn ọdọbinrinṣe ṣe maa n wọ aṣọ to ṣi ara silẹ lawujọ.
”Bakan naa, iroyin tun fi mule pe, won tun sekupa awon omo ogun marundinlogun ni awon agbegbe miiran ti o tun sun mo ilu ohun.
River Nile: Ọmọ ilé-ìwé Kenba 24 ló kú s'ómi ní Sudan
Eyi ati awọn ibeere miran ni ọpọ ọmọ Naijiria n beere bayii lọwọ awọn gomina ipinlẹ Ariwa ti wọn ti kọkọ n ṣatilẹyin fun aṣa Almajiri tẹlẹ.
Ekiti Bank Robbery: Iléeṣẹ́ ọlọ́pàá rí ọkọ̀ mẹ́ta gbà lọ́wọ́ adigunjalè báńkì Iyin-Ekiti
Gbogbo yara mẹrinlelaadọta to wa nile itura rẹ lawọn alejo maa fẹ n gba tan.
Peresi bí Hesironi, Hesironi bí Ramu.
O menuba edinku to ti de ba iye nomba awon abiyamo ti won n fun awon omo ni arun kogboogun naa ni Abuja ati agbegbe re ni eyi tile ise re n sise sii lati mu Ilosiwaju bae to ilera awon eniyan ekun yii, paapaa ninu itoju awon alaisan arun kogboogun.
Johnson-Sirleaf fi alefa sile ninu odun to koja, eyi ti Aare George Weah ti o je agbaboolu teleri  gbakoso orile-ede naa bayii.
”Ewe, Igbalo wa loju opon lowo bayii, pelu ipa re ti o se yesile ninu idije orile-ede China Changchun Yatai.
Lọdun to lọ ni Bianca ja nibẹrẹ idije ti ko si si lara awọn igba akọkọ to ṣaaju ninu gbigba bọọlu ọhun.
Samuel Okwaraji: Ó pé ọdún mọ́kànlélọ́gbọ̀n tí Samuel Okwaraji ṣubú lójú ìjà
Oríṣun àwòrán, Pastor Adeboye Haa, aṣe Baba Adeboye ko lee da ounjẹ jẹ, ko si lee da eekanna ara rẹ ge laisi iyawo rẹ lariwo ti awọn eeyan kan n pa bayii lori ayelujara ni kete ti iranṣẹ Ọlọrun Adejare Enoch Adeboye ki aya rẹ ku ọjọ ibi rẹ to waye ni ọjọ kẹtala oṣu keje.
Ọrọ kan ṣoṣo le ni itumọ mẹfa ṣugbọn ami ohun ori rẹ lo maa ṣafihan irufẹ itumọ to yẹ ki ọrọ naa ni.
Bakan naa ni ile ẹjọ ni ki wọn dawọ duro na lori sise isẹ abẹ fun ọmọ ọdun marun naa titi ti ọmọ naa yoo fi lee sọ boya nkan ọkunrin ni oun fẹ ni ni, abi ti obinrin.
Egiloni yìí kó àwọn ará Amoni ati àwọn ará Amaleki sòdí, wọ́n lọ ṣẹgun àwọn ọmọ Israẹli, wọ́n sì gba Jẹriko, ìlú ọlọ́pẹ, lọ́wọ́ wọn.
" Oríṣun àwòrán, facebook Joseph salaye pe, iwadi ileesẹ ọlọpa fihan pe ọkunrin Chibusor naa ti lọ sẹwọn ri nitori iwa lilu jibiti, eyi kii si se igba akọkọ rẹ ti yoo ko si gbaga ofin.
Oríṣun àwòrán, Empics Àkọlé àwòrán, Ìbúgbàmù Beruit wáye lásìkò ìgbéyàwó àwọn lọ́kọláya yìí.
Nígbà tó bá yá, eniyan mẹ́wàá láti oríṣìíríṣìí orílẹ̀-èdè yóo rọ̀ mọ́ aṣọ Juu kanṣoṣo, wọn yóo sì wí fún un pé, ‘Jẹ́ kí á máa bá ọ lọ, nítorí a gbọ́ pé Ọlọrun wà pẹlu yín.
Nígbà náà ni Elifasi, ará Temani, dá Jobu lóhùn, ó ní:
Àánú ọkùnrin yìí ṣe àwọn ẹranko wọn-ọnnì, nígbà tí wọ́n sí ronú ohun ti wọn ìbá ṣe fún un títí tí wọ́n kò mọ̀ ọ́n, wọ́n fún un ní agbára àti gbọ́ ohhùn àwọn ẹyẹ àti àwọn ẹranko bí wọ́n bá ń sọ̀rọ̀ sí ara wọn.
Transfer deadline day: Man United ra arúgbó ọjọ́ Cavani, Arsenal bínú ra Partey, Walcott padà sí ẹsẹ àárọ̀
Apapọ gbọdọ gbe igbesẹ bayii lati ri i daju pe awọn ọmọ orilẹ-ede
Bloomberg jina si aarẹ Trump ninu ọrọ nini, nitori biliọnu mẹta ni gbogbo ohun in Trump jẹ.
O ṣalaye pe to ba kan ge laarin ni, atunṣe ṣi wa.
Àwọn agbébọn tún gbìyànjú láti gbé akẹ́kọ̀ọ́ ilé Keu 80 ní Katsina Njẹ́ ó wù ọ́ láti jànfàání ẹ̀kọ́ ọ̀fẹ́ àjọ Commowealth 2020/2021?
Ninu atẹjade ti Igbakeji Gomina naa fi lede gba ọwọ oluranlọwọ rẹ, Allen Sowore ni idi ti awọn fi n pe fun ki wọn yọ Abẹnugan naa ni wi pe iṣẹ rẹ ko kujuwọn to.
Òṣèré méjì yìí ń fi ẹ̀wọ̀n runmú tóríi fíìmù Ife"" táwọn obìnrin ń bá ara wọn lòpọ̀ Njẹ́ o mọ̀ pé bíi ọdún 700 sẹ́yìn ni wọ́n ti ń bọ Osun-Osogbo?"
" wón máa ńki àwon ará àdúgbò yìí pé "" omo olá tó pò títí , olá tí ò ní pèkun ."
41 Nítorínáà, ìwọ yíò tumọ̀ àwọn ìfín tí wọn wà ní orí àwọn àwo ti Néfì, sí ìsàlẹ̀ àní títí tí ìwọ yíò fi dé àkókò ìjọba ọba Bẹ́njámẹ́nì, tàbí títí ìwọ yíò fi dé ibi tí ìwọ túmọ̀ dé, àwọn èyí tí ìwọ ti dá dúró sí ọwọ́;
Buhari, dakun mu adinku ba owo epo bẹtiro Awọn kan n fẹ ki Aarẹ Buhari din iye ti wọ̀n n ta jaala epo bẹtiro ku.
Eto ilera ara rẹ gbọdọ peye.
Esi ti a ri gba ya wa lẹnu.
Àwọn Olúkọ ìpínlẹ̀ Oyo fakọyọ lórí ètò Akọ́mọlédè àti Àṣà púpọ̀ Wo bí ilé ìwòsàn LUTH ṣe ń gba owó ibùsùn lọ́wọ́ àwọn aláìsàn, tí àwọn míràn sì ń sun ìta Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Adebola Ademilua: Àìrísẹ́ ṣè lẹ́yìn ìwé kíkà ló sọ mi dí ìyá onírú, mo dúpẹ́ tèmi Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí D.
Agbenuso kan salaye pe, arabinrin kan ti won koi ti mo orile-ede re, ni won gbe digba-digba lo sile-iwosan  Kisubi, ti o wa nitosi, amo o papoda ni kete ti o de ile-iwosan naa.
Oríṣun àwòrán, Others Foluke Daramọla ni ohun manigbagbe ti oloogbe naa ṣe fun oun ni adura to maa n gba fun oun ni araarọ, to ba ti pe oun lori aago.
Bakan naa si ni ajọ EKEDC ti fi iroyin sita pe ebu lasan ni iroyin naa.
Diẹ lara orukọ to ni awọn eeyan maa n pe oun ni: Baba Marlians, Prof.
Kò ní sí ikú mọ́, tabi ọ̀fọ̀ tabi ẹkún tabi ìrora.
Ẹ gbọdọ̀ ka alufaa sí ẹni mímọ́, nítorí òun ni ó ń rú ẹbọ ohun jíjẹ sí Ọlọrun yín.
Bí apànìyàn kan bá sá lọ sí ìlú ààbò, ẹ kò gbọdọ̀ gba owó ìtanràn lọ́wọ́ rẹ̀, kí ó baà lè pada sí ilẹ̀ ìní rẹ̀ ṣáájú ikú olórí alufaa.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Lazarus Chakwera: Ààrẹ orílẹ̀-èdè Malawi 'tó bá Ọlọ́run jiyàn' 1 Agẹmo 2020 Oríṣun àwòrán, Reuters Yoruba bọ, wọn ni iwa kii fi oniwa silẹ, bẹẹ gan-an ni ọrọ ri fun aarẹ ti wọn ṣẹṣẹ dibo yan lorilẹ-ede Malawi, Lazarus Chakwera lasiko to ba awọn eeyan orilẹ-ede naa sọrọ nípa isọkan lẹyin ti wọn búra fun tan.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Eid-el Kabir: Saudi ṣàtúnṣe lílẹ òkò mọ́ Asitani láti dẹ́kun títẹra-ẹni-pa 5 Ògún 2019 Oríṣun àwòrán, Twitter/Nigeria Hajj Comm Àkọlé àwòrán, Iṣẹ haji Awọn alaṣẹ orilẹede Saudi Arabia ti ṣe atunṣe lilẹ oko mọ Asitani mẹta ni Muna lọkọ keji tawọn oniṣẹ Haji ba goke Arafat.
Nítorí náà bí o bá kà mí sí ẹni tí a jọ gba nǹkankan náà gbọ́, kí o gbà á pada tọwọ́-tẹsẹ̀ bí ẹni pé èmi alára ni o gbà.
Ẹsita bá pe Hataki, ọ̀kan ninu àwọn ìwẹ̀fà ọba, tí ọba ti yàn láti máa ṣe iranṣẹ fún un.
tesiwaju lo sile-iwe girama Ikolaba Grammar School, St Luke’s College, Molete
nígbà tí àwọn eniyan bá bèèrè pé, ‘Kí ló dé tí OLUWA Ọlọrun wa fi ṣe gbogbo nǹkan wọnyi sí wa?
Jẹ́ àpáta ààbò fún mi;àní ilé ààbò tó lágbára láti gbà mí là.
Márosẹ̀ Eko sí Ibadan àti Ibadan sí Eko dí pa fún ṣúnkẹrẹ́-fàkẹrẹ ọkọ̀ 'Ẹ bá wa sọ fún Sanwoolu kó dárí jì wá o, ìpinú tí wọ́n ṣe l'Eko kò m'ọ́gbọ́n wá rárá' Èèyàn mẹ́sàn-án kú nínú ọkọ̀ akérò tó jóná lójú ọ̀nà Ore sí Ijebu Ode Oríṣun àwòrán, Goldmyne Àkọlé àwòrán, Lagos -Ibadan Express: Súnkẹ́rẹ fakẹrẹ ọkọ òpópónà marosẹ̀ tòní tún kọ sísọ Kíní àwọn ènìyàn ń sọ lórí ìṣẹ̀lẹ̀ náà Ọ̀pọ̀ lo n da èbi ìṣẹ̀lẹ̀ yiì ru ìjọba ààrẹ aná Olusegun Obasabjo, Yara'Adua àti Jonathan.
"O ni wọn ti ""wagbo dẹkun"" si wọn lati ọdun 2015 ni ipinlẹ Borno."
Oríṣun àwòrán, others Ni ọjọ Aiku ni ọkan lara awọn oṣere sinima lorilẹede Naijiria, Gbajúmò òṣèré tíátà, Ogun Majek ń ṣàìsàn líle, ó sì nílò ìrànwọ́ owó yín- Foluke Daramola Oríṣun àwòrán, Instagram/Foluke Daramola Ọkan lára àwọn gbajumọ osere tiata lọkunrin lédè Yoruba, Gbolagadé Akinpelu, tí gbogbo èèyàn mọ sì Ogun Majek, n ṣàìsàn báyìí, to sì lè pupọ.
Oríṣun àwòrán, @ShehuSani Àkọlé àwòrán, Shehu Sani tu kẹkẹ ọrọ silẹ lori iye owo ti awọn asofin Naijiria n gba Laipe yi ni Sẹnatọ kan, Shehu Sani tu asiri awọn asofin nipa miliọnu mẹtala ati aabọ naira ti wọn gba lososu.
Bí Peteru ti ń bá àwọn eniyan sọ̀rọ̀ lọ́wọ́, Johanu wà lọ́dọ̀ rẹ̀, àwọn alufaa ati olórí àwọn ẹ̀ṣọ́ Tẹmpili ati àwọn Sadusi bá dé.
Èdè wúlò fún fífi sọ èrò ọkàn wa àti fífi ìtara hàn sí ohun tí a gbọ́ rí tàbí tí ó ṣelẹ̀ sí wa.
Ninu osu kesan an odun to koja ni opolopo awon eniyan fi ilu naa sile nitori ija to waye laarin awon iko mejeeji yii, ni eyi ti opo emi sofo .
Awọn alaṣẹ ajọ naa ṣe ipade pẹlu awọn aṣoju ajọ Confederation of African Football (CaF), to n mojuto bọọlu gbigba ni Africa l'Ọjọru nilu Yaounde.
Ìjọba ní ọmọ Naijiria yóò padà sí ní san owó ‘tollgate' Ìpínlẹ̀ Ekiti ló bàjẹ́ jùlọ ní Naijiria- Afe Babalola Orìlẹ-èdè mẹrindínlọgbọn tí ọmọ Nàìjíríá lè wọ̀ láì ní àṣe ìwé ìgbélùú Awọn agbofinro Mozambique ni awọn ṣi n wa oniṣegun to sọ fun mọlẹbi yii pe ọwọ baba agba naa ko mọ́ si awọn mọlẹbi rẹ.
Kò sí ẹni tí ó ranti àwọn nǹkan àtijọ́ mọ́, bẹ́ẹ̀ sì ni, kò sì ní sí ẹni tí yóo ranti àwọn ohun tí yóo ṣẹlẹ̀ lẹ́yìn ọ̀la.
Àwọn tí wọ́n gbọ́n ni à ń pè ní amòye,ọ̀rọ̀ tí ó tuni lára a máa yíni lọ́kàn pada.
Elephants Death: Erin mẹ́fa d'olóògbé níbi tí wọ́n ti fẹ́ dóòlà ẹ̀mí ara wọn
ninu eto idibo to waye ni ibẹrẹ ọdun yii ”.
 ede mambila , ẹ ̀ yà bantu ni wọ ́ n sì ń sọ .
Kollington Ayinla ti sọ ẹni tó dá orin Fuji sílẹ̀ gan an ní Nàiìjíríà Ìjọba gbé ilé ijó oníhòhò tì pa lórí ẹ̀sùn títàpá sí ìlànà àti dẹ́kun coronavirus Wo àwọn Adelé-Ọba aládé méje tó jẹ́ obìnrin nílẹ̀ Yorùbá Mi ò le tòṣì láéláé!
Ọjọ kẹrindinlogun, oṣu Kẹwaa, ọdun 1942 ni wọn bi Iya Rainbow.
Gbogbo àwọn eniyan rí i tí ó ń rìn, tí ó ń yin Ọlọrun.
Àwọn tí wọn kò bá ní ìmọ̀ yóo sì parun.
Kwesi gbòmìnira lọ́wọ́ ọlọ́pàá lẹ́yìn ìfọ̀rọ̀wánilẹ́nùwò
Falana, lasiko to n sọrọ lori ifidimulẹ ikọ alaabo ọhun nilẹ Yoruba kede pe, gbogbo awuyewuye to n waye lori agbekalẹ ikọ Amotekun ko ba ti ri bẹẹ, to ba jẹ pe awọn gomina ti kọkọ se ohun to yẹ ki wọn se ni, nipa sise ofin ti yoo ti ikọ naa lẹyin nipinlẹ koowa wọn.
Oshiomole ni ohun to kan fun Saraki lẹyin to fi ẹgbẹ awọn silẹ ni lati fi ipo rẹ silẹ gẹgẹ bi Aarẹ ile aṣofin.
Níbo ni Messi fẹ́ mórí lé báyìí lẹ́yìn tó jáwée ó tó gẹ́ fún Barcelona?
Lati sisẹ lori fọọmu naa, o nilo foto pelebe, awọn iwe ẹri ileewe ti o lọ, ẹri idanimọ gẹgẹ bi ọmọ ẹgbẹ akọṣẹmọṣẹ kankan ti o ba ni, iwe ẹri lati ipinlẹ ti o ti wa, iwe ẹri ọjọ ori tabi iwe ibura ọjọ ori rẹ.
Ọlọrun gbọ́ ìkérora wọn, ó sì ranti majẹmu tí ó bá Abrahamu, ati Isaaki, ati Jakọbu dá.
Ona abayọ lo ku bayi, ko si tii daju ẹni ti yoo wa abayọ si ipenija to wa nilẹ yi.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Oluwo: Èmi ni adarí àti aláṣẹ lórí gbogbo òrìṣà ilẹ̀ Yoruba àti káàkiri àgbàyé 16 Bélú 2020 Oríṣun àwòrán, Oluwo of Iwo Oluwo ti ilu Iwo, Ọba Abdulrasheed Adewale Akanbi ti sọ pe oun gangan lo n ṣoju Ọlọrun Eledumare, nitorinaa ni oun ṣe n joko lori itẹ rẹ nile aye.
Nígbà kan, Jesu wà níbìkan, ó ń gbadura.
Ibrahim Magu, Alága àjọ EFCC yóò gbé ìwé àwíjàre rẹ̀ tọ ìgbìmọ̀ olùwádìí Aàrẹ wò lónìí
“OLUWA sọ fún mi pé, ‘Solomoni, ọmọ rẹ ni yóo kọ́ ilé mi ati àgbàlá mi, nítorí mo ti yàn án láti jẹ́ ọmọ mi, èmi yóo sì jẹ́ baba fún un.
Ẹ wò wọ́n, bí wọ́n ṣe wà ninu ẹ̀rù ńlá,ẹ̀rù tí kò tíì sí irú rẹ̀ rí!
O ti pa ààlà tí wọn kò gbọdọ̀ kọjá,kí wọn má baà tún bo ayé mọ́lẹ̀ mọ́.
Solomoni bí Rehoboamu, Rehoboamu bí Abija, Abija bí Asa.
Allen ni, nigba miiran, ijọba yoo ba awọn oniroyin sọrọ laiba awọn obi gan ti ọrọ kan sọ nkankan.
Nítorí náà àwọn tí yóo máa le yín,wọn óo lè sáré gan-an ni.
Samsoni bá bẹ ọdọmọkunrin tí ó mú un lọ́wọ́, ó ní, “Jẹ́ kí n fi ọwọ́ kan àwọn òpó tí gbogbo ilé yìí gbé ara lé kí n lè fara tì wọ́n.
Àdó okoró búrẹ́kẹ' Iroyin tun sọ pe nigba to ka a lara wipe gomina o naani ọrọ ohun amayerọrun yii lẹyin ọdun kan, ṣe lo tun yi ohun rẹ soke to tẹnu mọ ọ pe bi nkan amayerọrun nile aṣofin ṣe n di akurẹtẹ nilo amojuto gidi.
O kàn ní orúkọ pé o wà láàyè ni, òkú ni ọ́!
"Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Akomolede ati Asa: Mọ̀ si nípa àwọn ọ̀nà tí Yorùbá ń gbà ran ara wọn lọ́wọ́ O ni ""A rọ gbogbo awọn to ti kopa ninu ipejọpọ elero pupọ tabi ti wọn ba n ṣafihan apẹrẹ Covid-19 lati lọ ṣayẹwo."
Lara awon ti yoo maa tẹle aare
Awọn ololufẹ Lisa mii ni ko ni ootọ ati pe o ti ṣi awọn ọdọ miran lẹsẹ pe igbe aye ori ayelujara lo dara.
Minisita feto ilera lorilẹede Naijiria ni ko dara bi pupọ awọn ipinlẹ ko se ni ibi ayẹwo to yẹ fun ayẹwo arun lassa ki wọn lee maa pẹka iroko rẹ ki o to maa gba ẹbọ.
Níhìn-ín ni kí wọ́n ti pa wọ́n, kí wọ́n sì jẹ wọ́n.
Ó bá lọ dúró lẹ́bàá ibùsùn ìyá náà, ó bá ibà náà wí, ibà sì fi ìyá náà sílẹ̀.
Mo pe awọn rẹ mi ni Yobe ati Maiduguri wọn si pe an ko tifoju ri oṣu'' ''Emi o ṣarifin Sultan amọ ilana ti mo n lo lati gbawe leleyi ti awọn obi mi ati olukọ mi fi mọ mi'' Àkọlé àwòrán, Sani Musa Sani Musa naa wa lara awọn ti kii bẹrẹ awẹ lai foju r'oṣu.
Ṣugbọn ẹnìkan lè bèèrè pé, “Báwo ni a óo ti ṣe jí àwọn òkú dìde?
O tesiwaju pe banki agbaye wa si orile ede Naijiria “lati mo nipa eto ilana ti ijoba ti la sile , ki banki agbaye le mo ojuse ti won fe gbe lati ran orile ede Naijiria lowo lona ti idagbasoke yoo fi le ba eto oro aje won” ati “lori igbese ti ijoba orile ede yii n gbe lati mu osi kuro ati lati ri i pe ekunwo ba iye owo ti awon mukunnu n gba.
Oke Obi-Enadhuze:, Lekkitollgate, EndSars: Mọ̀ síí nípa Oke Obi
Steven Spielberg ati Tom Hanks wa laaarin awọn alejo nibi ifilọlẹ naa.
Agbẹjọ́rò fún ìjọba - BBC News Yorùbá BBC News, YorùbáFò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Sotitobire: Ìdájọ́ òdòdò ló fẹsẹ̀ múlẹ̀ lórí ọ̀rọ̀ Pásítọ̀ Sotitobire - Agbẹjọ́rò fún ìjọba Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Sotitobire: Ìdájọ́ òdòdò ló fẹsẹ̀ múlẹ̀ lórí ọ̀rọ̀ Pásítọ̀ Sotitobire - Agbẹjọ́rò fún ìjọba 7 Ọ̀wàrà 2020 Ọjọ Iṣẹgun, ọjọ kẹfa, oṣu Kẹwaa, ọdun 2020 ni ile ẹjọ giga ti ijọba ipinlẹ Ondo dajọ ẹwọn gbere fun Alfa Babatunde, to jẹ oludasilẹ ijọ Sotitobire Praising Chapel, ati awọn ọmọ ijọ rẹ marun, ti wọn fi ẹsun kan pe wọn lọwọ si bi ọmọ ọdun kan, Gold Kolawole ṣe di awati ninu ijọ naa ni ọdun 2019.
‘OLUWA Ọlọrun, o ṣẹ̀ṣẹ̀ bẹ̀rẹ̀ sí fi títóbi ati agbára rẹ han èmi iranṣẹ rẹ ni; nítorí pé, oriṣa wo ló wà, lọ́run tabi láyé yìí tí ó lè ṣe àwọn iṣẹ́ ìyanu bíi tìrẹ?
Ó ń lo àfọ̀ṣẹ, ó ń woṣẹ́, a sì máa lọ sọ́dọ̀ àwọn abókùúsọ̀rọ̀.
Irú ìyà ńlá wo ni ẹ rò pé Ọlọrun yóo fi jẹ ẹni tí ó kẹ́gàn Ọmọ rẹ̀, tí ó rò pé nǹkan lásán ni ẹ̀jẹ̀ majẹmu tí a fi yà á sọ́tọ̀, tí ó sì ṣe àfojúdi sí Ẹ̀mí tí a fi gba oore-ọ̀fẹ́?
Bi o tilẹ jẹ pe ami ẹyẹ to gba jẹ ti ẹka fiimu oloyinbo, sibẹ eyi kii se igba akọkọ ti yoo gba ami ẹyẹ naa.
Dokita Moeti ni o ṣeeṣe ki arun naa tun gbẹnu soke sii ni ile Adulawọ ti wọn ko ba gbe awọn igbesẹ to yẹ.
 Ó wá láti Ìjẹ ̀ bú etí-Òsà nị ́ ìpínlẹ ̀ Ògùn .
Chidozie Awaziem (Caykur Rizespor, Turkey); William Ekong (Udinese FC, Italy)Leon Balogun (Brighton &
Lara awon eniyan jankan-jankan ti o lo pade aare ni papako ofurufu ni gomina ipinle Anambra, Willy Obiamo,  gomina ipinle Katsina, Aminu Masari ati gomina ipinle Ekiti, dokita Kayode Fayemi.
Douye Diri di gómìnà Bayelsa lẹ́yìn ìbúrawọlé, iléeṣẹ́ ọlọ́pàá kéde kóńlé ó gbélé Yàjóyàjó: Èsì ìdìbò Kogi tó gbé Yahaya Bello wọlé rèé Gbọingbọin lọmọ Nàìjíríà wà lẹ́yìn iléẹjọ́ gíga jùlọ lórí ìdájọ́ ìbò Bayelsa- Atiku Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Kogi vs Bayelsa: Primate Ayodele sọ àsọtẹ́lẹ̀ Idajọ to waye lọjọ kẹtala oṣu keji ọdun yii ba ọjọ ifilọl David Lyon jẹ to si gbe ade fun Sẹnetọ Duoye Diri ti gbẹ oṣelu PDP gẹgẹ bii gomina ipinlẹ Bayelsa.
Gomina tẹlẹri ni ipinlẹ Ekiti, Ayodele Fayose ti bu ẹnu atẹ lu idajọ ajọ to n gbọ ẹjọ eto idibo sipo gomina to waye ni ipinlẹ Ekiti.
Gbá asà ati apata mú,dìde, kí o sì ràn mí lọ́wọ́!
Super Eagles kò ní já àwọn ọmọ Nàìjíríà kulẹ̀- Musa Asamoah Gyan: O ṣeéṣe kí èyí jẹ́ ìdíje AFCON ìkẹyìn mi Bí ìdíje láàrin Nàíjíríà àti South Afrika ṣe lọ sí Oríṣun àwòrán, Ahmad Bashir Àkọlé àwòrán, Aworan Aarẹ Buhari ati ikọ Super Eagles ki wọn to gbera lọ ife ẹyẹ agbaye Russia 2018 Aarẹ Buhari ninu ọrọ to fi sita loju opo Twitter sọ pe ohun iwuri lo jẹ ti ikọ naa si ṣe afihan ifarajin ati ọkan akin eleyi ti a mọ Naijiria si.
Kọmísọnà fún ìgbóhùn sáfẹ́fẹ́ Dayo Adeneyhe àti Modupe Mujota kọmisọnà fún ètò ẹkọ wà lárá àwọn tó kọ́wọ̀ọ̀ rí lọsí inú ẹgbẹ́ APM Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
O ni to ba si jẹ pe awọn fẹ gba eyi kanri ni, ọrọ naa ko ba ti bọwọ sori fun Oluwo amọ awọn kii se ọmọde nitori naa lawọn se fi ọwọ ẹrọ mu ọrọ ọhun nigba naa.
Ọkunrin náà tẹjú mọ́ àwọn nǹkan tí ó wà ní àyíká rẹ̀, ojú rẹ̀ sì bọ̀ sípò, ó wá rí gbogbo nǹkan kedere, títí kan ohun tí ó jìnnà.
Ọpọ Itan Fagunwa lo kọ wa lati maa se aye rere: Ọlọrunfẹmi Fagunwa maa n kọ itan bii ẹni pe o n waasu ni, awọn iwe rẹ lo kun fun ọgbọn, oye ati ẹkọ nipa bi a ti lee se aye rere.
Àwọn ohun tí ó yẹ kí a ṣe àkíyèsí ní orí yìí ni ìwọ̀nyí: Láti lè mọ iye tí Ọ̀sanyìnnínbí gbà fún kòkó tí ó tà fún Ajéwọlé, ọgbọ́n ni wọ́n fi tan Ọ̀sanyìnnínbí.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Òbìnrin mánigbàgbé mẹ́ta nínú ìjọba tiwantiwa láti 1999 3 Bélú 2018 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Lati igba ti orilẹede Naijiria ti pada si iṣejọba tiwantiwa, oniruru awọn obinrin lo ti sa ipa ti wọn Lati ọdun 1999 ti orilẹede Naijiria ti pada si iṣejọba tiwantiwa, oniruru awọn obinrin lo ti ṣa ipa ti wọn ninu idagbasoke iṣejọba tiwantiwa ti gbogbo agbaye si mọ kale-kako.
5 11531 Orilẹede Singapore 29 0.
Bakan naa lo n ṣe aṣoju awọn ipolowo ọja gidigidi.
 Èyí mú kí ó di olówó , alágbára àti olókìkí láàrin àwọn ẹ ̀ gbọ ́ n rẹ ̀ .
atejade kan ti oluranlowo ijoba lori iroyin ati ikede , Femi Adesina sọ pe :“
À bá pè é ní Gbajúmọ̀, bí kìí ṣe bí ẹní dá a kéré  ni.
Alaga ajọ LASEMA, Ọmọwe Olufẹmi Damilsla Oke-Ọsanyintolu ti rọ awọn olugbe agbegbe naa lati ṣe pẹlẹ titi digba ti wọn yoo fi gbe e kuro nibẹ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, No reception wedding: Adewale ni àpèjẹ kò ṣe pàtàkì sí òun Fatima to jẹ ibatan Aarẹ Muhammadu Buhari ti ni Iyawo Aarẹ, Aisha Buhari n hu iwa ipa ni Ile Aarẹ ni Ilu Abuja.
Aare Muhammadu Buhari ti fi idunnu re han si ijoba orile-ede China fun akitiyan ati ibasepo won lojuna ati mu igberu ba eto oro aje orile-ede Naijiria.
Osinbajo gbagbọ pe iwọde #EndSARS to n lọwọ kaakiri orilẹede Naijiria ju ọrọ awọn ọlọpaa to n dunkoko mawọn ọdọ lọ nikan.
Yatọ si eyi, Ronke tun maa n gba isẹ alaga iduro nibi ayẹyẹ igbeyawo, gbogbo awọn okoowo naa si lo n mu ki Oshodi Oke ri taje se.
Àkọlé àwòrán, Supporters of Rabiu Kwankwaso wear red hats Ganduje ati Kwankwaso Gomina ipinlẹ Kano, Abdullahi Ganduje naa ti pin gaari pẹlu baba isalẹ rẹ, Rabiu Kwankwaso to ṣe agbatẹru fun un lasiko idibo sipo gomina ni ọdun 2016.
"O le debi i pe mo ni aisan to n mu ni gbagbe nkan 'Amnesia', nigba ti mo pada de, nitori pe iṣoro naa ti pọju.
Gbajugbaja ni ọrọ yii, Awọlumatẹ ninu awẹ owe Yoruba kan.
Chioma, iyawo Davido ko arun Coronavirus eleyi ti ọkọ rẹ, Davido kede faye ni ọsẹ to kọja.
Ó ti di bárakú tàbí àṣà fún wa pé a gbọ́dọ̀ kọ́ ọmọ tí a bá ṣẹ̀ṣẹ̀ bí ni èdè.
Iroyin kan latodo ajo isokan orile-ede agbaye UN ti bu ate lu bi orile-ede South Sudan se n fi oju eto omo eniyan gbole, “ eyi ti o n dena ipade ijiroro alaafia lorile-ede ti ogun abele ti n waye naa”.
Bawọ ni ifipagbajọba ti pọ to nilẹ Afirika?
eji Ebuka Obi Uchendu to ti n gbalejo eto agbelewo yii fun ọdun diẹ sẹyin naa ni yoo tun gbalejo rẹ lọdun yii.
  Nṣe ni wọ́n fi àwọn ẹranko wọ̀nyí sílẹ̀ kí wọ́n máa báíyé wọn lọ.
Kí ó rẹ ara rẹ̀ sílẹ̀ tọ̀wọ̀tọ̀wọ̀,bóyá ìrètí lè tún wà fún un.
Ọmọ náà yóò ké nítorí omi náà ṣàjejì lára rẹ̀.
Mike Bamiloye ti Mount Zion fi ọmọbìnrin rẹ̀ kan ṣoṣo, Darasimi fún ọkọ nílùú Ibadan
Kí ló dé tí ẹ fi tún fẹ́ gbọ́?
Ó pé ọdún kẹrin tí àwọn ọmọbìnrìn Chibok nù Kí la tún gbọ́ nípa ìdámẹ́wàá?
Ó yọ ojú Sedekaya mejeeji, ó fi ẹ̀wọ̀n dè é, ó mú un lọ sí Babiloni, ó sì jù ú sí ọgbà ẹ̀wọ̀n, títí tí ó fi kú.
New Covid 19 update: Ẹ̀yà kòkòrò Covid-19 míràn jáde ní ọgọ́ta agbègbè nílẹ̀ Gẹẹsi, àjọ elétò ìlera fọkàn ará ìlú balẹ̀
Ọ̀jọ̀gbọ́n Ukertor Moti, tó ka èsì náà, sọ nínú fídíò tí àjọ náà gbé jáde lórí Twitter wípé, bí ó ti lẹ̀ jẹ́ pé àwọn olùdìbò agbègbè náà ju ẹgbẹ̀rún lọ́nà ọ̀tàlélọ́ọ̀dúnrún ó dín mẹ́sàn án lọ (351,146), àwọn tó jáde láti wá ṣe àyẹwò orúkọ náà, kò ju ẹgbẹ̀rún lọ́nà ogún lọ (20,868).
Oríṣun àwòrán, Getty Images Awọn ọja ati ṣọọbu ti kii ṣe ti ounjẹ yoo maa ṣi ilẹkun wọn laarin aago mẹsan owurọ si mẹta ọsan ni ọjọ Aje, Ọjọru ati ọjọ Ẹti.
Amọṣa ninu ọrọ to ba BBC Yoruba sọ, agbẹnusọ fun ikọ ipolongo Moshood Adeoti ti ẹgbẹ oṣelu ADP, salaye pe, ohun to fa ìpàdé naa ko ṣeyin bi wọn yoo ṣe fopin si iwa janduku ati madaru lasiko idibo naa.
Bi ori ba n fọ eeyan lasan, wọn a ní ko lọ lo oogun ori fifọ tabi ko lo oogun ara riro ti ara eeyan ba n ṣe bakanbakan.
Ó wọlé wá bá mi láti bá mi lòpọ̀, ni mo bá pariwo.
O ṣe ìpinnu lati koju wọn ṣugbọn igbesẹ yi léwu fún un.
Ó nira láti lè sọ iye obìnrin nílẹ̀ Gẹ̀ẹ́sì tó ń jìyà vaginismus bí ó tilẹ̀ jẹ́ wí pé ìwádìí kan fihàn wí pé ọ̀kan nínú mẹ́wàá obìnrin wọn ni kìí gbádùn ìbálòpọ̀.
 Ile iwosan Garki nilu Abuja je okan lara awon ile iwosan ti won ti n toju kidinrin ti won ti n se pasipaaro okan ati awon eya ara miran ni Naijiria.
Lásìkò ti ilé iṣẹ́ ìròyìn BBC bá ti gbarale orisun kan fun ìròyìn rẹ̀, à ó kọ orúkọ ẹní náà sii tí ààyè rẹ̀ bá yọ.
nígbà tí ó pàṣẹ fún òjò,tí ó sì lànà fún mànàmáná.
Buhari: Sáà kan ṣoṣo loó máa lò látìsinyìí lọ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Ọpọ̀ ẹ̀mí èèyàn ló bọ́ lọ́wọ́ Abacha láàrín 1993 sí 1998' Ẹ̀wẹ̀, ìkéde nàá tún sọ pé wọn yòó sọ̀rọ̀ lórí ètò ẹ̀kọ́, àti iṣẹ́ àkànṣe afẹ́fẹ́ gáàsì tó pa orílẹ̀-èdè méjéèjì pọ̀.
Bakan naa ni ijọba ti si papakọ ofurufu ni abẹle ati ni ilẹ okeere, eleyii ti o mu u rọrun fun awọn eniyan lati rin irinajo lati ibi kan si omiran.
Kí wọ́n sun ìyókù mààlúù náà: awọ rẹ̀ ati ẹran ara rẹ̀, ẹ̀jẹ̀ rẹ̀ ati ìgbẹ́ rẹ̀; kí wọ́n sun gbogbo rẹ̀ níwájú alufaa.
Lẹyin ti wọn ni ki Onnoghen lọ rọọkun nile ni o ba kuku kọwe ifẹyinti funra rẹ lọjọ kejidinlọgbọn, oṣu karun un, ọdun yii.
O ṣalaye pe ẹsẹ ti ọgagun Ibrahim Babangida fi pa lasiko ogun abẹle Naijiria nikan lo ṣi n dun un ṣugbọn eyi kan kun ọjọ ogbo lasan ni."
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Aimọye ọmọ Naijiria ni wọn fi ẹtan mu lọsowo nabi nilẹ okeere.
Ọ̀rọ̀ LAUTECH gba àpérò f'áwọn Olúdíje Ọṣun Àwọn olùdíje Ọṣun jẹ́wọ́ ara wọ́n Ìpínlẹ̀ méjìlá nínú ewu àgbárá òjò ní Nàìjíríà Aago méjìlá ọjọ́ Ẹti ni ìséde yóò bẹ̀rẹ̀ ṣáájú ìdìbò náà A kú ewu ọmọ Linda Ikeji oo Hẹlo!
 Àwọn ìjọba àpapọ ̀ , ìpínlẹ ̀ àti ìbílẹ ̀ , àwọn ilé ìṣòwò , àti àwùjọ jẹ ́ pípọndandan láti kojú àwọn ìwọ ́ de wọ ̀ nyí tí wọ ́ n tọ ́ kasí àwọn àìbánidọ ́ gba tó únkojú àwọn ọmọ Áfríkà amẹ ́ ríkà .
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ifeanyichukwu Chiejine: Agbábọ́ọ̀lù Chiejine jáde láyé lẹ́yìn ààsàn ráńpẹ́ 22 Ògún 2019 Oríṣun àwòrán, Twitter/NFF Àkọlé àwòrán, Agbabọọlu Super Falcons tẹlẹ jade laye Iku doro, iku ṣeka, agbabọọlu Super Falcons Naijiria tẹlẹ ri, Ifeanyichukwu Chiejine ti jade laye lẹni ọdun mẹrindinlogoji.
Kọjú sí mi kí o sì ṣàánú mi;nítorí n kò lẹ́nìkan, ojú sì ń pọ́n mi.
Iroyin ni, lati afin Ataoja ilu Osogbo nibi ti Arugba ti gbe igba lọ si odo Osun lati ṣetutu atawọn nnkan miran to rọ mọ ọdun naa, ni ko ti si ẹnikẹni to tẹlẹ ofin ijinasiraẹni.
Koda, a gbọ pe awọn araalu ti inu wọn dun si bi awọn ọdẹ naa se mu mẹrin balẹ ninu awọn adigunjale ọhun, tun dana sun oku wọn.
Sex for Grades: Àjọ ọlọ́pàá ìpínlẹ̀ Eko fìwé pe olùkọ́ UNILAG Boniface Igbeneghu
Ninu ilẹ̀ wọn ni ìdajì Gileadi wà ati Aṣitarotu ati Edirei, àwọn ìlú ńláńlá ilẹ̀ ìjọba Ogu, ọba Baṣani; Mose pín wọn fún àwọn ìdajì ìdílé Makiri, ọmọ Manase, gẹ́gẹ́ bí iye ìdílé wọn.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àwọn ìròyìn mìíràn tí ẹ lè nífẹ̀ẹ́ sí: Àwọn oníkẹ̀kẹ̀ NAPEP fárígá ní Maiduguri Ọ̀pọ̀ òṣèré tíátà tó ń sàìsàn ni kò ṣe dáadáa fẹ́gbẹ́ - Jide Kosọkọ Kíni ìdí ti wọn fi ń lọ ọmú obinrin Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Pẹlu esi yii Arsenal yoo maa fi ami meji la Manchester United lori atẹ liigi ilẹ Gẹẹsi pẹlu bi ere ije tani yoo wa laaarin ipo mẹrin akọkọ ninu liigi naa ṣe n gbona sii.
” Gideoni bá dìde, ó pa Seba ati Salimuna, ó sì bọ́ ohun ọ̀ṣọ́ tí ó wà ní ọrùn ràkúnmí wọn.
Pupo awon obi ni won so pe, awon omo won yoo lo sile-iwe,, laifi isele ti o waye naa se, amo  won ro ijoba lati pese abo to nipon ni awon ile-eko gbogbo Ronke Osundiya.
”O tun so pe : “Aare Buhari je bi egbon fun mi, idi niyi ti mo se fe lati wa ri I fun imoran.
" Akeredolu sọ pe ọjọ diẹ ti oun lo ni igbele fun oun laye lati ro arojinlẹ lori awọn ipenija ti Covid-19 mu ba ipinlẹ Ondo.
Àkúntúnkú, ìgbà márùn ún rè é tí Shekau kú tí wọ́n ní kò kú mọ Mo rò pé mò ń jà fún Islam ni, ó pẹ́ kó tó yé mi – Boko Haram tẹ́lẹ̀ Òwò ẹrú pé irinwó ọdún tó bẹ̀rẹ̀, àwọn Amẹrika tó jẹ́ dúdú wá sí Afirika láti bẹ ilé wò Fidio bi wọn se yọ eyin naa ree: Awọn dokita onisẹ abẹ marun ati awọn onimọ nipa ẹjẹ meje lo sisẹ lasiko isẹ abẹ naa, ki wọn to ri awọn ọpọ eyin naa yọ, bẹẹ si ni ijọba lo sanwo isegun ọmọdekunrin ọhun.
Say no to rape: Ìdájọ́ ikú ni a fẹ́ fún àwọn afipábánilòpọ̀
Lakotan, itan Shina Rambo kọ wa pe ko si ẹda ti Ọlọrun ko le lo fun itankalẹ isẹ rẹ, lai naani bi igbe aye onitọun ti buru to ni ìbẹ̀rẹ̀ pẹpẹ.
Awọn ajọ mejeeji yii tọka si awọn ipinlẹ ti ọrọ shun yoo kan gẹgẹ bii ipinlẹ Kogi, Kebbi, Niger, Kwara, Edo, Anambra, Rivers, Bayelsa ati Delta.
Àwọn aṣọ́nà bá sọ fún àwọn tí wọ́n wà ní ààfin ọba.
Dapọ Lam Adesina ni, o yẹ ki ijọba ipinlẹ Ọyọ duro de idajọ ileẹjọ ko to lọ̀ da ileesẹ redio naa wo niwọn igba ti ọrọ naa ti wa niwaju ileẹjọ.
Ṣebí OLUWA tí a ti ṣẹ̀ ni,ẹni tí wọ́n kọ̀, tí wọn kò rìn ní ọ̀nà rẹ̀;tí wọn kò sì pa òfin rẹ̀ mọ́.
Oun si lo siwaju iwọde kan to waye yika orilẹede naa, to ko ẹgbẹlẹgbẹ awọn obinrin kaakiri igboro ilu Cape Town, to si n pe ijọba orilẹede naa nija lati se amusẹ ofin to jẹ isẹlẹ yii.
Ọrọ naa di tile ẹjọ, ti Baba Suwe si jare bo tile ẹjọ si ni ki Ileesẹ aṣọbode san ẹgbẹrun lọna ọgọrun un pọun fun un, gẹgẹ bii owo 'gba ma binu'.
Àwọn dókítà yóò bẹ̀rẹ̀ ìyanṣẹ́lódí lọ́jọ́ Ajé Wo ọ̀nà ìsanwó tuntun fún àwọn oníbárà iná mọ̀nàmọ́ná ní Eko (EKDC) Nàìjíríà làwọn ní ìfẹ́ sí ìpèsè abẹ́rẹ́ àjẹsára Covid-19 tí Russia ṣe Níbo lọ̀rọ̀ dé dúró nípa iṣẹ́ àwọn tó n wa iṣẹ́ N-Power?
 Èyìí fẹ ́ jọ ohùn arò .
Gbogbo rẹ ni àwọn yóò fọ́nká sí ibikíbi nílé ayé
Oríṣun àwòrán, @Oyinkan Ibẹrẹ igbe aye Oyinkan Abayomi: Ọjọ Kẹfa, osu Kẹta ọdun 1897 ni wọn bi Oyinkansola de si idile Ọlọla Kitoye Ajasa, to si ni aburo ọkùnrin kan ṣoṣo.
Level, abbl, ti won si tun fun awon eniyan ni oogun ofe.
Sugbon, omo ogbon odun naa ti yege ifigagbaga marun-un lodun yii, ti o si padanu ifigagbaga akoko ninu idije Indian Wells ninu ose yii.
Àwọn òsìsẹ́ aláàbò tí se se se lórí kíkojú ìkọlù gbogbo ìgbà láàrin àwọn àgbẹ̀ àti fúlání darandaran.
saba maa n ba ara wọn se papọ , “A
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fọ́nrán ohùn, Ọlọ́fà tí Ọffà:Mo kí Ọ̀ọ̀ni kú iṣẹ́ ribiribi fún ìdàgbàsókè ilẹ̀ Yorùbá Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Oluwo gba Aláàfin nímọ̀ràn pé kí olorì máa dé adé Ọọni kọ́lé fàwọn ọmọ òrukàn ní Ibadan Ǹkan márùn-ún tó yẹ ko mọ̀ nípa Ọba Adeyeye Ogunwusi Ó ṣe pàtàkì kí à sọ àwọn ǹkan tí ọ̀pọ̀ ènìyàn kò mọ nípa rẹ̀ gẹ́gẹ́ bí ọba yìí ṣe jẹ́ ọkan gbòógì nínú àwọn ọba aláde nílẹ̀ káàrọ̀-òòjíre.
(Herimoni Sirioni ni àwọn ará Sidoni ń pe òkè náà, ṣugbọn àwọn ará Amori ń pè é ní Seniri.
Wọ́n dàbí akọ ẹṣin tí a kò tẹ̀ lọ́dàá, tí ó yó,olukuluku wọn ń lé aya aládùúgbò rẹ̀ kiri.
Àwọn Iyagba ńkọ mẹ́ta-mẹ́ta tí ó fẹẹ papọ̀ l’eba ẹnu wọn.
Awọn alaṣẹ ni ọpọ eeyan farapa ninu iṣẹlẹ ohun.
idibo bẹrẹ ni pẹrẹu lorile ede South Africa lonii yii to jẹ ọjọ  kẹjọ, osu karun un , ni eyi ti  awon oludibo yoo lọ maa dibo yan oludije ti
Mo mọ pe ohun ti awọn eeyan ipinlẹ Ọyọ n beere fun ko pọ ju.
Nítorí náà ni a kò fi sọ ìrètí nù.
iru ile naa lasiko ti a wayii.
“Ní ọjọ́ náà, OLUWA yóo mú ọba Asiria wá láti òdìkejì odò.
Jesu wí fún un pé, “Kí ni tèmi ati tìrẹ ti jẹ́, obinrin yìí?
Ẹni naa ti wọn pe orukọ rẹ ni Bamidele Emmanuel salaye pe, iṣẹ agbaṣe ọkọ fifọ ati agbaru lo maa n ṣe fawọn eeyan lagbegbe naa.
Adójú ti ni àti orílẹ̀-èdè ni Bobrisky""."
”Bakan naa, ogbeni Awwal Sani, igbakeji oludari ile ise ajo to n mojuto oro ayika ohun, wa ro awon ara agbegbe naa lati ri daju pe, won n se itoju damu omi naa lore-koore.
Ilé ẹjọ́ gíga ní kí òsìsẹ́ First Bank tẹ́lẹ̀ lọ sí ẹ̀wọ̀n ọdún 98 lórí ẹ̀sùn pé o jí mílíọnù 49 àti $368, 000 níbẹ̀ Laycon, kú oríire àmọ́ bá ń kó owó orí nínú ẹ̀bùn rẹ nílé BB Naija - Ìjọba Eko Wike, má gbé jàgídíjàgan wá sí Ondo, APC kò ní ṣ'èèrú nínú ìdìbò gómìnà tó ń bọ̀- Kalejaye Ayuba Sarafa, Olọ́kadà kan tó jẹ́ eni ọdún 22 pokùnso ní Ibadan Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí BB Naija: Kí ló pa Elisha Abbo, Leycon àti Naira Marley pọ̀, tí àríyá yóò fi wáyé?
Wọ́n bẹ̀rẹ̀ sí sọ láàrin ara wọn pé, “Nítorí a kò ní burẹdi ni.
Oríṣun àwòrán, Nysc Edo State/facebook Atẹjade to fi igbesẹ naa han sita jẹyọ loju opo facebook lowurọ Ọjọru.
Lórí òkè mímọ́ mi, lórí òkè gíga Israẹli, ni gbogbo ẹ̀yin ọmọ ilé Israẹli yóo ti máa sìn mí.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Bí nǹkan ọkùnrin bá há sójú ara obìnrin, kìí ṣe Mágùn, ẹ má páyà Owó tí Kiddwaya bá rí ní BB Naija, ìdá kan fún Erica, ìkejì fọ́mọ aláìníyàá - Baba Kiddwaya Kí ló le è mú kí agbábọ́ọ̀lù subú, kó sì kú lásìkò ìfẹsẹ̀wọ̀nsẹ̀?
Tabi iyawo àṣẹ̀ṣẹ̀gbé lè gbàgbé àwọn aṣọ rẹ̀?
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ipenija oju kii ṣe idena si atijẹ Fídíò bí Salisu Yusuff se gba àbẹ̀tẹ́lẹ̀ ‘Àwọn olè níkan ló leè jẹ ààrẹ Nàíjíríà Ohun méje pàtàkì nípa Commonwealth Mo sọ̀rọ̀ tako ọkọ mi torí òtítọ́ - aya Bùhárí Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí 2 sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
Èṣù dáhùn Èṣù wí pé: Àwa tí ó jẹ́ pé iṣẹ ibi ni iṣẹ́ wa mọ̀ pé ẹ̀san ń bọ̀ lọ́jọ́ kan, ṣùgbọ́n a kò mọ wákàtí náà tí ẹ̀san ó dé.
Ojú ati ọkàn mi yóo wà níbẹ̀ nígbà gbogbo.
Saaju ninu ọdun yii, ni iwe iroyin Wall Street ni, wọn fi panpẹ ọba mu awọn ọmọ ile ọba mẹta, to fi mọ aburo ọba, ọmọ ọba Ahmed bin Abdulaziz ati ati ọmọ oye nigba kan ri, Mohammed bin Nayef.
Ibeere: Ọna wo ni abadofin yii ti ṣe anfani fawọn akẹkọọ ni ẹkun ti wọn ti n bere fun igbesẹ?
Wọ́n bá kó ẹ̀rúnrún àjẹkù jọ, ó kún apẹ̀rẹ̀ ńlá meje.
Òórùn òróró náà bá gba gbogbo ilé.
Nítorí pé aládùúgbò tí ó súnmọ́ ni sàn ju arakunrin tí ó jìnnà sí ni lọ.
orile-ede Naijiria setan lati sagbateru idije yii”“Inu
Oniroyin BBC, Is'haq Khalid jabọ iroyin lati Abuja pe: Ogun eeyan ni wọn fidirẹmulẹ pe o jẹbi awọn ẹsun to niiṣe pẹlu ẹsun igbesunmọmi, ipaniyan ati ijinigbe.
Awọn akọroyin naa, Chioma Obianinwa ati Nnamdi Agbanelo pẹlu awakọ wọn, Ndubuisi Nwafor ni awọn fada meji mii tẹle lọ sibi ifọrọwanilẹnuwo sọdọ Mbaka.
O fikun pe ọpọ ija ti oun ati Barrister maa n ja kii se pe awọn n se ọta, amọ ija orogun owo lasan ni, ti awọn si maa n lọ sile ara awọn lati jẹun eyi ti ko han si ọpọ ololufẹ awọn to n tori awọn mejeeji ja lainidi.
Malala Yousafzai to jẹ ajafẹtọ ọmọbinrin, to si ti gba ami ẹyẹ Nobel Peace, sọrọ loju opo rẹ pe o ṣe pataki lati mu ra ọmọbinrin silẹ loni fun iṣẹ lọjọ ọla.
Ibadan Rape: Àjọ ọlọ́pàá, Ìjọba ìpínlẹ̀ Ọyọ jẹ́jẹ̀ẹ́ láti ṣàwárí òòsà tó ń mu ẹ̀jẹ̀ nílùú Ìbàdàn
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Orúkọ ọmọ ni Yorùbá gbà pé ó máa ń ro ọmọ nílẹ̀ Oodua Ajọ naa ko ti i ṣalaye igbesẹ ti yoo gbe lori awọn to n lo ayederu iwe naa lẹyin ti agbeyẹwo iwe ẹri naa ba pari.
Amọ ṣa iyipada to de ba owo Dangote yii ti mu iriwisi wa lati ọdọ awọn ọmọ Naijiria ti awọn kan si n naka abuku si ijọba Aarẹ Buhari gẹgẹ bi igi wọrọkọ to mu adinku ba owo Dangote.
baba Buki, baba Usi, baba Serahaya; 
Boko Haram: Ikọ̀ afẹ̀jẹ̀wẹ̀ kọlu Gómìnà Borno lẹ́ẹ̀kejì pẹ̀lu kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ aládòó olóró
àwọn ìlú Berota, Sibiraimu (tí ó wà ní ààlà Damasku ati Hamati), títí dé Haseri Hatikoni, tí ó wà ní ààlà Haurani.
Ẹ jẹ́ kí á kọlu Gibeoni, nítorí pé ó ti bá Joṣua ati àwọn ọmọ Israẹli dá majẹmu alaafia.
Kàkà bẹ́ẹ̀, ẹ tọ àwọn aguntan ilé Israẹli tí ó sọnù lọ.
Ọga ọlọpaa Mike Bush lorileede naa ti saaju fidi ọrọ mulẹ pe eeyan mẹrin ti wa ni ahamọ ṣugbọn awọn ko le sọ pato boya ẹlomiran wa to kopa ninu iṣẹlẹ ibi yi.
"Àwọn sẹ́nétọ̀ Nàìjíríà fa ìbínú yọ 'torí N2Miliọ̀nù owó àjẹmọ́nú Kérésì tí wọ́n fún wọn Àwọn ọjọ́ ìsìnmi tó máa wà nínú ọdún 2020 ní Nàìjíríà Ilé ẹjọ́ tú ìgbéyàwó ọdún mẹ́sàn ká lẹ́yìn tí ọkọ fi ẹ̀sùn olè kan ìyàwó Ọbabinrin Ilẹ̀ Gẹ̀ẹ́sì àti Ọmọọba Harry yóò sèpàdé ní Ọjọ́ Ajé Ọbabìnrin Elizabeth ti fara mọ́ ìpinnu ọmọ ọba Harry àti Meghan láti lọ ṣiṣẹ́ ajé Ọbabinrin ilẹ Gẹẹsi, ti faramọ 'asiko iṣipopada"" ti Duke ati Duchess ti Sussex yoo maa lo ni Canada ati United Kingdom."
Nítorí ohun kinni tí ó ṣe pataki jùlọ tí èmi fúnra mi kọ́, tí mo sì fi kọ́ yín ni pé Kristi kú nítorí ẹ̀ṣẹ̀ wa, gẹ́gẹ́ bí Ìwé Mímọ́ ti wí.
Ijiya lilo si ewon ko to lati je ki awon oniwa ibajẹ yii ronu piwada.
Amọ sa, o wa sekilọ fun awọn ọmọ ologun to gba ijọba pe ki wọn mase lero pe awọn yoo pẹ lori aga akoso rara.
Oríṣun àwòrán, María Conejo/BBC Nitori awọn idiwọ yii lo wa mu ki Zoe ati Maria sefilọlẹ oju opo kan lori itakun agbaye losu keje ọdun 2019, eyi ti wọn pe ni 'Pussypedia', awọn eeyan to to ẹgbẹrun lọna aadoje si lo ti n bẹ oju opo naa wo lati wa imọ kun imọ wọn nipa ẹya ara obinrin.
Ọkunrin náà bá wọlé, Labani sì tú gàárì àwọn ràkúnmí rẹ̀, ó fi koríko ati oúnjẹ fún wọn.
Awọn alaṣẹ ilẹ naa bẹru pe awọn janduku le lọ ji awọn ohun mere mere to wa ni iboji naa ti ko ba si eto abo to mọyan lori níbẹ.
Israẹli, baba wọn bá sọ fún wọn pé, “Bí ó bá jẹ́ bẹ́ẹ̀, ó dára, báyìí ni kí ẹ ṣe, ẹ dì ninu àwọn èso tí ó dára jùlọ ní ilẹ̀ yìí sinu àpò yín, kí ẹ gbé e lọ fún ọkunrin náà.
"Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù ""Àlùfàá méjì wà lára àwọn mẹ́rin tó fi ipá bámilòpọ̀"" 25 Èbibi 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 26 Èbibi 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Olukọ kan tun bamilopọ pẹlu ipá."
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Wọn ti ti ọja oba ilu naa, ti wọn si ti si ọja lọ si ibo miran.
Ní Antioku ni a ti kọ́ pe àwọn ọmọ-ẹ̀yìn Kristi ní “Kristẹni.
Ní ọjọ́ kẹrinlelogun oṣù kinni ọdún tí à ń wí yìí, mo dúró létí odò Tigirisi.
Ó fa aṣọ rẹ̀ ya, ó sì ku erùpẹ̀ sórí láti fi ìbànújẹ́ rẹ̀ hàn.
Eeyan mẹtala lo ribi sa asala fun ẹmi wọn gẹgẹ bi ọrọ̀ ti gomina sọ pe awọn adukokomọni ọhun n dumbu awọn eeyan bii ẹran maalu.
Mo rìn títí n kò rí nǹkan kan.
Oríṣun àwòrán, Others Atẹjade naa fi jẹ ko di mimọ pe, Sunday Shodipẹ ni afurasi ti wọn mu fun ipaniyan ṣisẹ-n-tẹle to waye lagbegbe Akiyẹle ti wọn ṣe afihan rẹ pẹlu awọn meji miran lọjọ kẹtadinlogun, oṣu keje ọdun 2020, ti wọn si gbe lọ si ileẹjọ, ki wọn to da a pada si ahamọ ọlọpaa.
Tó bá di ìgbà náà, ọ̀nà tí ó tóbi kan yóo wà láti Ijipti dé Asiria–àwọn ará Asiria yóo máa lọ sí Ijipti, àwọn ará Ijipti yóo sì máa lọ sí Asiria; àwọn ará Ijipti yóo máa jọ́sìn pẹlu àwọn ará Asiria.
"Ijọba sọ ninu atẹjade ti wọn fi sita lori iṣẹlẹ naa pe ""o ba ni lọkan jẹ pe lati ọdun meji sẹyin ti ìyá ọmọ naa ti kú, ni igbeaye rẹ ti yi pada."
"Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Holy Thursday: Àlúfáà àgbà ìjọ́ Anglican sọ oun tó tọ́ láti máà ṣe 18 Ìgbé 2019 Oríṣun àwòrán, Olukayode Akinyemi/Facebook Getty Images Àkọlé àwòrán, Alufa agba ijọ Anglican Ọjọ ọjọbọ mimọ, ""kii ṣe ki a kan maa wẹ ẹsẹ lasan, o gbudọ ni itumọ ninu irinajo igbagbọ gẹgẹ bi ọmọlẹyin Kristi"" BBC Yoruba fọrọ wa Olukayode Akinyemi to jẹ ọkan lara awọn alufa agba ni ijọ Anglican ti orilẹede Naijiria lati fi oye ye awọn eniyan itumọ ọjọ ọjọbọ mimọ ti wọn n pe ni Holy Thursday tabi Maundy Thursday."
Ọkàn mi wí pé, “OLUWA ni ìpín mi,nítorí náà lọ́dọ̀ rẹ̀ ni ìrètí mi wà.
Awọn ileewe ti akẹkọọ n gbe nibẹ ni G.
Gbajugbaja omidan to n safihan aso nile Amerika, Naomi Campbell ti ni ki won se ifilole iwe iroyin atigbadegba Vogue ti yoo da lori isele ile Adulawo lati fi mo riri ipa nla ti awon eniyan ile Afirika n ko ninu idagbasoke oge sise lagbaye.
Agbẹnusọ fún ikọ̀ Operation Lafiya Dole, Ọ̀gágun Onyeama Nwachukwu ní lóòtọ́ ní àwọn ọmọ ogun àti ikọ̀ Boko Haram d'ojú ìjà kọ ara wọn, tí àwọn ọmọ ogun Nàìjíríà sì pa ọ̀pọ̀lọpọ̀ nínú àwọn ọmọ ogun Boko Haram, tí wọ́n sì tún rí àwọn nkan ìjagun wọn kó.
Àkọlé àwòrán, Ikọlu aarin gbungbun Dambulla lo jẹ ki Roshan darapọ mọ awọn ọmọ ogun Gauri ni oun gbagbọ pe aaro ile n figba gbogbo sọ Roshan paapaa nitori aigbọ ede wọn yii.
Láti òpin ayé ni a ti ń gbọ́ ọpọlọpọ orin ìyìn,wọ́n ń fi ògo fún Olódodo.
Mohammed Bago ti dide pe àṣìṣe ńlá ni ẹgbẹ́ APC ṣe láti pín ipò agbẹnusọ sí ìhà iwọ oorun Guusu nítori náà oun kò fara mọ ọ àti pé ìhà gbungbu Arewa kò ti de ipò agbẹnusọ ilé ìgbìmọ aṣoju sofin ri, nítori náà òun náà yóò dije fún ipò Agbẹnusọ Muhammed nínú àtẹjade kan sàlàyé pé iha Ila-òòrun-Gusu àti Gbungbun -Arewa ní ẹgbẹ ń fiya pínpín wọn jẹ jùlọ Ní báyìí, ìdìbò tí yóò wáye ní òní ọjọ kọkanlá oṣù kẹfà ódún 2019 ń pè kí Gbajabiamila kò ni ẹtọ láti lọ nítori ó yẹ ki àwọn àṣojú ẹgbẹ́ ó tún ètò náà ṣe.
Gbogbo wa kọ́ ni a óo kú, ṣugbọn nígbà tí fèrè ìkẹyìn bá dún, gbogbo wa ni a óo pa lára dà, kíá, bí ìgbà tí eniyan bá ṣẹ́jú.
Wuraola ni kii ṣe aisan kan to le koko ṣugbọn awọn mọ pe ko ni sinmi to ba de ile tori gbogbo igba lo maa n wa lorii foonu rẹ to n ṣiṣẹ.
ng/ Loju opo yii ni wọn yoo ti fi abajade esi ayẹwo Covid 19 si Lẹyin ọjọ meje lẹyin ti wọn ba wọ Naijiria ni wọn yoo tun ṣe ayẹwo covid 19 miran ni Naijiria nile ayẹwo ti ijọba fi ọwọ si.
Awọn bii Lade, àti Ijai gbà pe eyi n fihan pe nkan ko fararọ ninu ijọba ni bayii Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Kwara yóò gbàlejò BBC Yoruba Opọlọpọ lo gba pe ominira ọrọ yẹ ko jẹ ẹ̀tọ́ àwọn eniyan ati pe ko si ijọba to yẹ ko kọja ariwisi ki wọn le tubọ huwa akin sii.
"Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Blind DJ: Etu Omotayo kò ríran àmọ́ ó le to irinṣẹ́ eléré pọ̀ láti kọrin láì sí ìrànwọ́ O ni "" Awa Emere kii se Ajẹ abi Oṣo amọ ẹlẹgbẹ ọrun ni wa."
 ajíbógun ló lọ bomi òkun wá fún bàbá wọn - ọlọ ́ fin tí ó fọ ́ jú láti fi ṣe egbogi fún un kí ó lè ríran padà ó lọ , Ó si bọ ̀ .
Bí àwọn Òyìnbó bá ń ṣe àjọyọ̀ Ọdún Òṣùpá Tuntun, àwọn aráa China á gbéraga wọ́n á sì rí èyí gẹ́gẹ́ bí ìdàgbà ìsọjí àṣà ìbílẹ̀ China … Bí àwọn aráa China bá ṣe àjọyọ̀ àjọ̀dún Òyìnbó, kí ni ìdí tí a fi kà wọ́n sí ìgbógunti àṣà?
Eyi lo mu ki gomina ipinlẹ Eko, Babajide Sanwo-Olu pakiti mọlẹ lati ka ọwọja itankalẹ arun Coronavirus to n pelesi nipinlẹ naa ko nipa awọn igbesẹ kan.
idibo aare  fihan pe Atiku Abubakar ni
Alaga igbimọ amuṣẹya ti ijọba apapọ gbe kalẹ lori pipalẹmọ arun Coronavirus kuro lorilẹede Naijiria (Presidential Task Force on COVlD-19) ṣalaye fawọn oniroyin ninu Abuja pe ayẹwo to munadoko yoo maa waye fun gbogbo awọn eeyan to ba wọ orilẹede Naijiria lẹyin abẹwo sawọn orilẹede wọnyii; ti wọn yoo si fi wọn sinu ahamọ iyasọtọ ati ayẹwo fun ọjọ mẹrinla.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ṣé obìnrin leè ní àǹfààní ọ̀gbọọgba pẹ̀lú ọkùnrin lágbo òṣèlú Nàíjíríà?
Bí ẹ bá ti mọ̀ mí, ẹ óo mọ Baba mi.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù June 12: Buhari yóò la ọ̀na 2,000 kìlómítà, èèyàn 100 yóò yọ nínú òṣì 13 Òkùdu 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Mo fe gbajumo oro eto aabo lasiko yii Lasiko ayajọ June 12, ti i se ayajọ ijọba Tiwantiwa, aarẹ Muhammadu Buhari fi akoko naa sọ ọrọ apilkọ rẹ fun saa keji eyi to kun fun ọpọ ileri itunu fawọn ọmọ orilẹede yii.
Bí ó ti rí wọn, ó sáré lọ pàdé wọn, ó wólẹ̀, ó sì dojúbolẹ̀ láti kí wọn.
Ija eerin meji: Oluwo ati Ọọni Oluwo Ìwo ṣ'àlàye lori oyé Emir Imam Fuad tako Oluwo lori wiwe lawani Telu 1 ti ọpọlọpọ mọ si Oluwo ti ilu Iwo ṣalaye fun BBC Yoruba pe ilu Ile Ife ni idile Ọba ilu Iwo ti ṣẹ wa.
” Mose bá yipada kúrò níwájú Farao.
Ẹgbẹ JOHESU sọ ninu atẹjade naa pe iyanṣẹlodi ọhun yoo tẹsiwaju nitori ijọba ko ṣetan lati ṣe ohun tawọn n fẹ fawọn oṣiṣẹ eleto ilera.
Ijó ni a fi kúrò ní ìlú yìí, Ìjàǹbáforítì ni ó sì ń dá orín náà, orúkọ ara rẹ̀ ni ó sì fi ń kọrin náà.
Kí ó di ọ̀rọ̀ tòótọ́ tí a ti fi kọ́ ọ mú ṣinṣin, kí ó baà lè ní ọ̀rọ̀ ìwúrí nípa ẹ̀kọ́ tí ó yè, kí ó sì lè bá àwọn alátakò wí.
Ìwọ ni o fún mi lágbára láti jagun,o jẹ́ kí àwọn ọ̀tá mi rì lábẹ́ mi.
Agbabọọlu ọmọ Argentina naa ati arakunrin to tu'kọ naa, David Ibbotson nikan lo wa ninu rẹ.
funding for logistics and wages Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
 “Anfaani ise-akanse yii po, erongba ise-akanse ohun ni lati fi dode awon eru nlanla, ti o le n lo bi  miloinu meta si milionu marun lodoodun.
" hoffmann , won gba abo kan ebun nobel 2011 fun iwosan , fun "" iwari won nipa imusise ajesara inu ara "" ( abo keji lo si ralph m."
Agbẹjọro EFCC Mohammed Abubakar sọ lọjọ Iṣẹgun pe ati baba ati ọmọ ni ko ti yọju sile ẹjọ lati ọjọ kẹrinlelogun oṣu Kẹfa ọdun 2020.
Nígbà tí Jesu rí ọ̀pọ̀ eniyan, ó gun orí òkè lọ.
Asofin naa wa rọ awon akẹgbẹ
Bẹ́ẹ̀ ni, a ti ní Alexey Lazorenko gẹ́gẹ́ bí Adarí,  Irina Reyder ni nísẹ̀yín.
O mú ninu àwọn ohun ọ̀ṣọ́ wúrà ati ti fadaka rẹ, tí mo fún ọ, o fi wọ́n ṣe ère ọkunrin, o sì ń bá wọn ṣe àgbèrè.
Gbogbo àwọn ohun tí ń rìn káàkiri lórí ilẹ̀ patapata ni wọ́n bá Noa jáde kúrò ninu ọkọ̀.
Ibi mẹta gboogi ni yoo sọ ẹni to maa wọle ninu awọn oludije mejila naa.
Igbakeji  oga-agba ile-ise ile-kiko lorile-ede Egypt, Khaled Abbas so lasiko iforo-wanilenu wo kan pe,won fun orile-ede Egypt ni anfaani osu merindinlogbon si osu mejilelogoji, ti won ba pari kiko ile naa tan, ki won to bere si n san owo naa pada.
Ǹjẹ́ nítorí náà, ẹ̀yin ará, mo fỌlọrun aláàánú bẹ̀ yín pé kí ẹ ya ara yín sọ́tọ̀ bí ẹbọ mímọ́ tí ó yẹ láti fi sin Ọlọrun.
Elomiran ti ọrọ naa tun soju rẹ ni awon eniyan to wa ninu mọto to jona nigba ti ina bu gbamu ni awọn to ku ati awọn to farapa.
“Sọ fún àwọn ọmọ Israẹli pé, nígbà tí wọ́n bá ré Jọdani kọjá sí ilẹ̀ Kenaani, 
 nítorí àṣà yorùbá jẹ ́ àṣà tí ó gbajúmọ ̀ láàrín àwùjọ , àṣà àti ìṣe wa ṣeé mú yangàn nílé àti ní ọkọ .
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Collapsed Building: Ayálégbé ló dára bí ìjọba ṣe wólé àmọ́ wọ́n fẹ́ ìrànwọ́ ilé míràn Ni ọjọ ẹti ni ijọba ipinlẹ Eko bẹrẹ si ni wo awọn ile ti o ti di ẹbiti, kaakiri awọn agbegbe kan nipinilẹ Eko nitori iṣẹlẹ to ṣẹ naa.
Wọn óo kọ́ ilé Jakọbu ní ìlànà rẹ,wọn óo sì kọ́ àwọn ọmọ Israẹli ní òfin rẹ.
 cfa franc ni owonina ile benin .
Ẹ̀bẹ̀ nìkan ni mo lè bẹ̀ fún àánú,lọ́wọ́ ẹni tí ń fi ẹ̀sùn kàn mí.
Eyi lo mu ki ẹgbẹ Akọmọlede ati asa Yoruba, ẹka tipinlẹ Eko fi n fẹmi imoore wọn han si ileesẹ akọroyin BBC Yoruba fun isẹ takuntakun ti wọn n se lati se agbega asa, ede isesi ati awọn ohun ajogunba iran Yoruba.
Ẹ dúró bẹ́ẹ̀, nítorí n kò lẹ́bi.
Ìjọba àpapọ̀ fi Austria, Sweden kún àwọn orílẹ̀èdè tí kò lè wọ Nàìjíríà Ogun ebi ni Nàìjíríà ń bá fínra lọ́wọ́, ogun coronavirus kò gbọdọ̀ kún un-Oluwo Èyí làwọn ayẹyẹ nlá tí kò ní wáyé nítorí coronavirus Ajọ NACAA ni igbesẹ yii jẹ ọkan lara ọna lati dekun itankalẹ arun coronavirus lorilẹede Naijiria.
Ta ló lè fi ọgbọ́n ká ìkùukùu,tabi tí ó lè tú omi inú ìkùukùu dà sílẹ̀,
Toyin ni ohunkohun ti Ọlọrun ba seto rẹ pe yoo jẹ ti oun, yoo wa sọdọ oun lọjọ-kọjọ, Ọlọrun nìkan si lo ni akoso ohun gbogbo.
1 Mílíọ̀nù ni Ọlọ́pàá ti gbà lọ́wọ́ àwọn ọmọ Nàìjíríà EFCC, mò ń bọ̀ wá yọjú síi yín - Fayoṣe ‘PDP kò mọ̀ nìpa Femi Otedola tó ń dupò gomina’ Ọjọru ni Ambọde mu fọọmu to fifi erongba rẹ lati jẹ oludije ẹgbẹ naa ninu idibo sipo gomina l'ọdun 2019 han, lọ si olu ile ẹgbẹ All Progressives Congress to wa ni Abuja.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Èmi ò kí ń lu ìyàwó mi' Ọpọ igba ni Gauri ni awọn ko ri aaye wẹ debi jẹun ni asiko yii.
Gbogbo àwọn tí wọ́n jẹ́ baálé, tí wọ́n sì jẹ́ akọni ọkunrin jẹ́ ẹgbẹtala (2,600).
Àkọlé àwòrán, Títì pa ni pápá ìṣeré gbogboogbò ní Surulere nílùú Eko wà ní òwúrọ̀ ọjọ́ Ajé Àkọlé àwòrán, Àwọn òṣìṣẹ́ aláàbò kò jẹ́ kí àwọn tó fẹ́ ẹ̀ ṣe eré ìdárayá ní pápá ìṣeré gbogboogbò ní surulere rááyè wọlé.
Paitọ naa to jẹ oludasilẹ ijọ New Life Ministry, Lukosi ni Shagamu sọ fawọn ọtẹlẹmuyẹ ọlọpaa pe niṣe ni oun n ji awọn eeyan gbe nitori ki ijọ oun ba le gbooro si.
"Bo ṣe bẹ̀rẹ̀ gẹgẹ bii alu ohun eelo orin ninu gbajugbaja ẹgbẹ́ olorin ""Kokomba bands"" ni 1940s niyii."
Kókó mẹ́wàá tó sì jẹyọ rèé nínú ọ̀rọ̀ tó bá àwọn èèyàn Ìpínlẹ̀ ọ̀hún sọ.
Ọjọ nla ni ọjọ ti a n wí yi ti orile-ede Ivory Coast si borí Madagascar pẹlu ami ayo márún ún sí odo.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Oba Adedokun Abolarin ti Oke Ila: Ó ya ọ̀pọ̀ tó súnmọ́ mi lẹ́nu bí mo ṣe ń kọ́ Kini o gbọdọ mọ ki o to ṣe oniduro ẹnikẹni?
Obìnrin kan dèrò ilé ìwòsàn lẹ́yìn tí ilé ẹru jálé e lórí nílu Eko O ni ẹtanu ati ibanilorukọjẹ ni ajọ naa n ba kaakiri, ti ko si si otitọ kankan ninu gbogbo ẹsun ti wọn fi kan Aarẹ Muhammadu Buhari lori iṣejọba rẹ.
EFCC tun gbe Akala yọju sile ẹjọ Ọmọbinrin kan ku si sọọsi lasiko ijẹri Yatọ si awọn ti wọn n sisẹ ni ẹka ọgbin ati iwakusa, ọpọ awọn ile isẹ ti awọn ọmọ ilẹ China da silẹ ni wọn fẹsun kan wi pe wọn tapa s'ofin to de isuna lorilẹẹde Zimbabwe.
Oríṣun àwòrán, @BoringMe2Death Àkọlé àwòrán, Iṣẹlẹ yii waye lẹyin oṣu diẹ ti awọn ọlọpaa tẹ George Floyd to jẹ alawọ dudu Awọn eeyan orilẹ-ede Amẹrika ti gunle iwọde #BlackLivesMatter lọtun lẹyin ti awọn ọlọpaa alawọ funfu yinbọn lu ọkunrin alawọ dudu kan nigba meje.
Nítorí gẹ́gẹ́ bí ó ti wà ní àkọsílẹ̀, bí a bá mú Òfin tí a fi díwọ̀n iṣẹ́ ọmọ eniyan, kò sí ẹ̀dá kan tí a óo dá láre níwájú Ọlọrun.
Oríṣun àwòrán, ccc genesis global/instagram Ile ijọsin awọn ọmọde Ibi yii ni awọn ọmọ wẹwẹ ati ọdọ ti ọjọ ori wọn wa labẹ ọdun kan si ọdun mẹtadinlogun ti ma n jọsin.
Ìwọ a máa gbá ọmọ eniyan dànù; wọ́n dàbí àlá,bíi koríko tí ó tutù ní òwúrọ̀;
Ẹwẹ, Gomina ipinlẹ Eko tẹlẹ to jẹ minisita akanṣe iṣẹ ati ilegbe bayii, Babatunde Fashola naa sọ laipẹ yii pe o ṣe pataki ki APC ranti adehun ọdun 2014.
” Ṣugbọn Jonatani kò sọ fún Saulu, baba rẹ̀.
ati àwọn yàrá ẹ̀gbẹ́ gbọ̀ngàn fẹ̀ ní ogún igbọnwọ (mita 10), yíká gbogbo ẹ̀gbẹ́ tẹmpili.
Mose fún ìdajì ẹ̀yà Manase ní ìpín tiwọn gẹ́gẹ́ bí iye ìdílé wọn.
O ni ko si idi meji ju wi pe ijọba ipinlẹ Ondo ko fẹ ohun ti yoo fa hilahilo tabi wahala ba aabo awọn alaisan yooku atawọn oṣiṣẹ to n mojuto wọn.
Bakan la gba ni adura pe, irufẹ orilẹede ti Tunde Idiagbon nla ala pe ki Naijiria jẹ, to si ja fitafita fun, Ọlọrun yoo jẹ ko wa si imusẹ.
Amọṣa, irufẹ iba wo; tabi bawo ni iba rẹ ṣe lee lagbara to ti a fi lee funra pe boya coronavrus ti rapala wọle; Atipe, ki gan an ni a lee mu gẹgẹ bii ikọ ahugbẹ ni lemọlemọ?
 Àmó , Ààre kúrunmí mú àrokò ogun .
Davido: Gbajugbaja akọrin Naijiria, David Adeleke da bi ẹni pe ibaṣepọ wa laarin oun ati Hushpuppi.
Iku ọmọ Alagba Rueben Fasoranti ti da ọpọlọpọ awuyewuye Kí ló mú àwọn adarí Nàìjíríà tako ra wọn lórí ikú ọmọ alága ẹgbẹ́ Afenifere?
Wo àwọn Adelé-Ọba aládé méje tó jẹ́ obìnrin nílẹ̀ Yorùbá Wo àwọn ohun tí Amotekun kò ní le è ṣe mọ́ ní ìpínlẹ̀ Oyo.
Àkókò yìí ni mo wáá bẹrẹ̀ sí ṣe iyèméjì bóyá mo tún lè ṣe nǹkan kan lórí ilẹ̀ ayé yìí mọ́; ọkàn mi rẹ̀wẹ̀sì púpọ̀, èrò burúkú burúkú gbogbo ló sì ń bọ́ sí inú mi, ó sì dà bí ẹni pé kí n tìkara mi pa ara mi.
Ọkan lara awọn manigbagbe akọni obìnrin naa ni Oyinkansola Ajasa aya Abayomi, ti ọpọ eeyan mọ si Lady Oyinkan Abayomi.
Ohun to fa irinajo aare lo si ilu Jos ni  ipade ti Ojogbon Yemi Osibanjo  se pelu awon ti oro naa kan niluu  Jos  lojo Aje to koja yii.
N kò tún ranti ẹlòmíràn tí mo ṣe ìrìbọmi fún mọ́.
Láìsí àní-àní, oríṣìíríṣìí èdè ni ó wà láyé, ṣugbọn kò sí èyí tí kò ní ìtumọ̀ ninu wọn.
Ipolongo ibo ti ko mu ariwo dani Lati igba ti Biden ti n ṣe oṣelu, ni ọrọ ẹnu rẹ ti ma n ko si iyọnu, koda o ṣe akoba fun nigba to kọkọ gbegba ibo aarẹ lọdun 1987, ati ọdun 2007.
Bẹ́ẹ̀ ni ó mú kí wọn gbé Àpótí Majẹmu OLUWA yí ìlú náà po lẹ́ẹ̀kan, nígbà tí ó di alẹ́, wọ́n pada sinu àgọ́ wọn, wọ́n sì sùn sibẹ.
Ile ẹjọ ni pe oun ko le gbọ ẹjọ naa nitori pe o ti le ni ọjọ mẹrinla ti ofin la kalẹ lẹyin ti Buhari gbe igbesẹ naa ki wọn o to o gbe ẹjọ wa sile ẹjọ.
"Kii ṣe Ibadan nikan, o tun ba iṣẹ ogun jija rẹ de Ekiti, Akoko nibi to ti ta ọpọ wọn lẹru leyii fi jade ninu oriki rẹ pe ""O ṣọkọ Ekiti ṣọkọ Akoko""."
Ilu Abuja rosomu Ilu Abuja rosomu fun ayajọ ijọba awa ara wa eyi ti Aarẹ Muhammadu Buhari ṣẹṣẹ buwọlu pe ko maa waye ni gbogbo jọkejila oṣu kẹfa dun latoni lọ.
Awon osise apetusaawo medogun ni won seku pa ninu osu kejila odun to koja.
Iroyin so pe, eto oro-aje orile-ede Nigeria ti kuro ni bi o se denu-kole tele, pelu amugberu iko bi meji ninu ida ogorun ni saa kerin 1.
Ibú omi gbé ohùn wọn sókè, OLUWA,ibú omi gbé ohùn wọn sókè,ó sì ń sán bí ààrá.
Awọn ara adugbo ni o ti to igba diẹ ti awọn ololufẹ yii ti n fẹ ara wọn, amọ ija bẹrẹ nigba ti ọrẹbinrin naa kọ lati fẹ ẹ bi ọkọ nitori o ni o dagba ju oun lọ.
Ọ̀pọ̀ àwọn eniyan láti inú ìlú wá pẹlu obinrin náà.
 O ni ipade ifikunlukun Igbimọ Aṣofin ati Igbimọ
Kí ló mú kí àyájọ́ June 12 ṣe pàtàkì ní Nàìjíríà #NASS: Femi Gbajabiamila di olórí ilé aṣojú-ṣòfin Aarẹ ọna kakanfo Yoruba Kíni ìwọ mọ̀ nípa Funmilayọ Ransome-Kuti?
Eyi jẹ owo to pọ ju ti iṣẹ ọna igbalode lati ọwọ omo orilẹẹde yi yoo pa.
Wò ó, èmi ati ìdílé baba mi ti dẹ́ṣẹ̀.
talẹnti wúrà kan ni kí o fi ṣe ọ̀pá fìtílà náà ati gbogbo ohun èlò rẹ̀.
Amọṣa, ọkan lara awọn eto ti aarẹ Gani Adams gbe kalẹ lasiko ayẹyẹ naa ti n fa ọpọ awuyewuye.
Ó bá fi wọ́n sílẹ̀, ó sì jáde kúrò lọ sí Bẹtani.
“Ṣugbọn bí ẹnìkan bá fi ohun èlò irin lu arakunrin rẹ̀ tí ẹni náà sì kú, apànìyàn ni ẹni tí ó fi ohun èlò irin lu arakunrin rẹ̀, pípa ni wọn yóo pa òun náà.
Ni bayii, eniyan mẹrin lo ti ku, ti o si ti ran oṣiṣẹ eleto ilera mẹẹdogun ni orilẹede naa.
Àwọn ìdí márún ti Atiku kò fi wọlé ààrẹ Supplementary election: Ọlọpàá gbé ikọ míràn díde lọ si Gama wọọdu Ilé ẹjọ́ kéde Ademọla Adeleke gẹ́gẹ́ bíi gómìnà ìpínlẹ̀ Ọṣun Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Oshisko twins: Ojú wa rí, ṣùgbọ́nÌgbọ́raẹniyé ló ń ràn wá lọ́wọ́ Ọ̀pọ̀ àwọn olóṣelu àti ọ̀tọ̀kùlú ló ti ba sọ̀rọ̀ láti fija fọ́lọ́run jà sùgbọ́n ó ni òun yóò gbé ọ̀rọ̀ naa lọ ile ẹjọ.
Boris Johnson: Olukemi Olufunto Badenosh di mínísítà ní London
Ẹfunsetan Aniwura, obìnrin tó ju ọkùnrin lọ Hubert Ogunde rèé, baba àwọn òsèré tíátà Bi o tilẹ jẹ pe Ọlabisi Ajala ti fi ilẹ bora bii asọ, sibẹ o yẹ ki iran iwoyi mọ ohun kan tabi meji nipa rẹ nitori bi ọmọ ko ba ba itan, yoo ba arọba.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Coptic Christian: January 7 ni ọjọ́ àjọ̀dún kérésìmésì fún ẹ̀yà Krìstẹ́ní lágbègbè Lárúbáwá 7 Sẹ́rẹ́ 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 8 Sẹ́rẹ́ 2019 Oríṣun àwòrán, Analodu agency Àkọlé àwòrán, Ṣaaju ajọdun keresimesi yii, ọjọ mẹtalelogoji ni wọn fi n gba awẹ Ọjọ karundinlọgbọn oṣu kejila ọdun ni gbogbo onigbagbọ maa n ṣe ajọyọ keresimesi.
Lọtẹ yii, ohun ti ọpọ eeyan n sọ lori Twitter ni pe Fatoyinbo ti wọn fi ẹsun ifipabanilopọ, ko yẹ ni ẹni to yẹ ki wọn o pe si iru isin bi i Shiloh.
Gba ẹ̀kọ́ mi dípò fadaka,ati ìmọ̀ dípò ojúlówó wúrà,
Ni bayi Arsenal yóò kojú ọkan nínú Athletico Madrid, Marseille tàbí Salzburg ti awọn náà tẹsiwaju sí abala to kangun sí asekagba idije Europa.
Ọ̀pọ̀ ẹ̀mí àti ọkọ̀ jóná ní márosẹ̀ Ìbàdàn sí Èkó Ina jo ọja binukonu lọjọta nipinlẹ Eko Ibugbamu ibudo epo ni Ijegun Àwọn kàn ní ìjọba kò gbọdọ̀ fí ọwọ yẹpẹrẹ mú ọrọ̀ yí nítorí ìpalára tí àwọn ọkọ èpo àti àjàgbé n ṣé fún ará ìlú kọjá afẹnuso.
Ọjọ iṣẹgun ni orilẹ-ede Naijiria gba ifẹsẹwọnsẹ to gbẹyin ninu ipin wọn fun ipele akọkọ idije ife ẹyẹ agbaye FIFA naa, ṣugbọn ipo kẹta ni Falcons ṣe lẹyin France ati Norway.
Coronavirus: Ẹ̀yin tí ẹ lọ ra aṣọ Okirika l'Ọjà Ọba Akure, ẹ lọ ṣàyẹ̀wò àrùn Coronavirus
Ọlọrun tún sọ fún Mose pé kí ó wọlé tọ Farao lọ, kí ó sì sọ fún un pé kí ó gbọ́ ohun tí òun OLUWA Ọlọrun àwọn Heberu wí, kí ó jẹ́ kí àwọn eniyan òun lọ sìn òun.
Fun apẹrẹ, lọdun 1993 nigba ti FDD rebels pin agbara pẹlu ijọba Ọgbẹni Ndayishimiye ṣe igbakeji ọga awọn ọmọ ogun Burundi nigba naa, akẹgbẹ rẹ, Nkurunziza to jẹ minisita ọrọ abẹle.
Ṣugbọn adajọ Peter Afen sun igbẹjọ naa siwaju di ọjọ kẹta, oṣu kẹfa, bakan naa lo paṣẹ pe ki wọn si wa ni kolo ajọ EFCC titi di ọjọ naa.
"Ifẹ mi, mi o ni gbogbo aye yii lati gbe le ẹ lọwọ bayii!
Nígbà tí ọba ń pada bọ̀, àwọn eniyan Juda wá sí Giligali láti pàdé rẹ̀ ati láti mú un kọjá odò Jọdani.
Lẹ́yìn rẹ̀ ni àwọn ọmọ Lefi wọnyi ṣe àtúnṣe ọ̀dọ̀ tiwọn ní ìsọ̀rí-ìsọ̀rí: Rehumu ọmọ Bani ṣe àtúnṣe apá ọ̀dọ̀ tirẹ̀, lẹ́yìn rẹ̀ ni Haṣabaya, aláṣẹ ìdajì agbègbè Keila ṣe àtúnṣe agbègbè tirẹ̀.
Ile igbimo asoju sofin lorile ede Naijiria ti ro ile-ise olopaa orile ede yii Ibrahim Idris lati gbe igbese lati gba  awon adari olori elesin to wa nikawo awon agbesunmomi sile lorile ede Naijiria.
Awọn iroyin ti ẹ lee nifẹẹ si: Rasheed Tijani ko riran sugbọn o n lọ ata Kinni ohun to nmu idunnu ba ọkan re ?
Pasitọ naa ati awọn meje miiran ni ijọba lo foju bale ẹjọ lonii.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Promise Akinlade: ọmọ ọdún mọ́kànlá tó ń fi ìlù dárà bíi àgbàlagbà sọ̀rọ̀ nípa tálẹ́ǹtì rẹ Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí EndSars in Portharcourt: Ọjọ́ méjì sẹ́yìn ni aya awakọ̀ Márúwá tí ọlọ́pàá pa bímọ tuntun10 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Fídíò, Oba Adeyeye Ogunwusi: Ojú mi ti rí lọ́pọ̀ lọpọ̀, ọ̀pọ̀ èèyàn ni kò tilẹ̀ gbàgbọ́ pé mo lè jọba- Ooni7 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Oyo physically challenged protest: Ìdí rèé táwọn àkàndá ẹ̀dá fi dí iwájú iléeṣẹ́ ìjọba ìpínlẹ̀ Oyo pa l'Agodi n'Ibadan7 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 ASUU strike: Mi ò tíì lè sọ ní pàtó ìgbà tí a ó fòpin sí ìyanṣẹ́lódì wa - Aarẹ ASUU7 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Ó dá wa lójú pé ọkàn wa mọ́.
Ohun ti eyi tumọ si ni pe ko si awọn arinrinajo lati awọn orilẹede mẹtala naa to gbọdọ wọ orilẹede Naijiria.
Yíyí tí Saulu yipada kúrò lọ́dọ̀ Samuẹli, Ọlọrun sọ ọ́ di ẹ̀dá titun.
A kò ní máa pe aláìgbọ́n ní ọlọ́lá mọ́,bẹ́ẹ̀ ni a kò ní máa pe abàlújẹ́ ní eniyan pataki.
Lati bi ọsẹ diẹ sẹyin ni oniruuru ti n jade si oju opo ayelujara gbogbo nipa ipo ilera gomina ana nipinlẹ Ọyọ naa, Oloye Abiọla Ajimọbi.
Ti eto ẹkọ ko ba yanranti, ọrọ baba isalẹ ko le tan ninu oṣelu.
Ṣaaju ni Aarẹ orilẹ-ede Ghana, Nana Akufo-Addo tọrọ aforiji lọwọ orilẹ-ede Naijiriai lori bi wọn ṣe wo ile naa.
Sowore ti wa ni ahamọ lati ọjọ kẹta oṣu kẹjọ ọdun yii, lẹyin ti ajọ ọtẹlẹmuyẹ fi panpẹ ọba mu ni ilu Eko.
Bakan naa, o ṣiṣẹ gẹgẹ bi alabojuto iroyin ibudo fun iroyin ti ile iṣẹ Naijiria to wa ni orilede Abidjan, Cote d'Ivoire laarin ọdun 1992 si 1995.
 Àwọn ènìyàn yóò sì máa yọ ̀ pé baba àwọn dáhùn , pé kò tilẹ ̀ kú rárá .
Amọṣa ko si ẹni to lee fi idi rẹ mulẹ boya ẹmi lọ sii tabi bẹẹkọ.
Gbogbo wúrà, fadaka, idẹ, irin ati tánńganran ati òjé, 
Ẹ̀dá ọmọ ènìyàn ní “Kò tán bí!
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ẹ̀mí mẹ́ẹ̀dógún sọnù nínú ìjàmbá ọkọ̀ nípìnlẹ̀ Ògùn Wo àwòrán pápá ìṣeré MKO Abiola National Stadium Ghana ti mu àwọn afurasí ajínigbé ọmọ Naijiria mẹ́ta À ń wo àtubọ̀tán APC níbáyìí tó gba àkóso ilé aṣòfin - PDP Ninu ọrọ rẹ fun ayajọ June 12, Buhari ṣeleri lati tubọ ri si eto aabo fun ẹ̀mí àti dukia.
gbogbo ibon ati awon ohun elo ija miiran to wa kaakiri mọ, nitori laisi eyi ,yoo
“Sọ fún Rehoboamu ọmọ Solomoni, ọba Juda, ati gbogbo àwọn ọmọ Israẹli tí wọn ń gbé Juda ati Bẹnjamini pé, 
” Wọ́n bá ka ọgbọ̀n owó fadaka fún un.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù NUJ: A fẹ mọ ẹsẹ awọn akọroyin tẹ da duro 2 Ẹrẹ̀nà 2018 Oríṣun àwòrán, @AIT_Online Àkọlé àwòrán, Ọjọ pẹ ti ẹnu ti nkun ileesẹ AIT pe o jẹ owo osu osisẹ Ileesẹ BBC ti fidi rẹ mulẹ pe ileesẹ agbohunsafẹfẹ AIT ati ileesẹ itẹwe iroyin The Sun ti juwe ọna ile fawọn osisẹ rẹ to le ni ọọdunrun niye.
Mo sì gbọ́ tí ẹnìkan sọ fún un pé, ‘Dìde, kí o sì máa jẹ ẹran sí i.
Ní àkókò kan, láti ìlú Heṣiboni,àwọn ọmọ ogun Sihoni jáde lọ bí iná;wọ́n run ìlú Ari ní Moabu,ati àwọn oluwa ibi gíga Arinoni.
Bakan naa ni minisita sọ fawọn agbaṣẹṣe nibẹ lati kọ ileewe alakọbẹrẹ ati girama si fasiti ọhun.
Dájúdájú àwọn ẹlẹ́yà yí mi káàkiri,wọ́n ń fi mí ṣe yẹ̀yẹ́ lojukooju.
Aare  Muhammadu Buhari ti fi ilu Abuja silẹ lọ si
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Covid-19 Vaccine: Joe Biden náà ti gba abẹ́rẹ́ àjẹsara 22 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Oríṣun àwòrán, @Joe Biden Aarẹ orilẹede Amẹrika tunuti wọn ṣẹṣẹ dibo yan, Joe Biden naa ti gba abẹrẹ ajẹsara fun aarun Covid-19.
O ni Ọjọbọ ni wọn yoo pari eto idoola ẹmi to n waye ni ibudo iṣẹlẹ naa.
Sùgbọ́ǹ gẹ́gẹ́ bi músùlùmí, a mọ̀ pé àmúwa Ọlọrun ni gbogbo ǹkan ti o bá ṣẹlẹ̀ si ẹdá, sùgbọ́n, ẹnìkan tàbi èsù ni yóò lò.
Winter Olympics 2018 bẹrẹ ni South Korea 'Ijọba ti fún ọ̀pọ̀ eléré ìdárayá l'ẹbùn wọn' Ìbẹ̀rù nípa Amotekun ló ń mú káwọn èèyàn kan máa wí ìwíkùwí - Soyinka Ọọ̀ni obìnrin, Lúwòó Gbàgídà rèé, akọni tó ń gun ọkùnrin ní ẹṣin rìn Awọn ọmọ ikọ Agbabọọlu Cricket Naijiria ni awọn sa ipa awọn ki awọn le jẹ iwuri fun ikọ ojẹwẹwẹ to n bọ lọna.
Oṣu Karun un, ọdun 2017 ni wọn yan ọgagun Irabor Lucky lati rọpo Adeọṣun ni MNJTF, to si pada sile.
Lasiko igbẹjọ to waye kẹyin niwaju adajọ Nnamdi Dimgba ti ile ẹjọ giga ni ilu Abuja lo ti tu pẹpẹ ọrọ yi.
Ogbeni Osita soro yii nibi eto ifilole awon omo igbimo alamojuto nipinle Eko ti won gbe kale lati fi jiroro lori awon ohun eelo eto ogbin.
Ilé iṣẹ́ márùn ún tí wọ́n dárukọ kìí ṣe túntun- Garba Shehu Iṣẹ́ bọ́ lọ́wọ́ ọlọpàá mẹ́rìn to pa afurasí, wọ́n tún dèrò ẹ̀wọ̀n Ẹgbẹ́ Ilẹ̀ Yorubà gba Aṣíwájú tuntun!
Àwọn eniyan náà bi wọ́n pé, “Kí ni kí á fi ranṣẹ gẹ́gẹ́ bí nǹkan ètùtù?
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ninalowo: Mo ṣiṣẹ́ agbèrò rí lati ṣe aṣeyege Ìfipábánilòpọ̀ kìí se àwàdà - Ireti Yusuf Kíni àwọn ọmọ Nàìjíríà sọ lórí ìyanṣẹ́lódì tó ń rọ̀ dẹ̀dẹ̀?
Gbogbo awon alaga egbe mẹ́rìndínlógójì awon osise ni gbogbo  ipinle orile ede Naijiria lo wa nibi ipade naa.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Afenifere: Àsìkò tó tá tako ìkọlù darandaran nílẹ̀ Yorùbá 12 Agẹmo 2019 Oríṣun àwòrán, @chimbiko_jerome Iroyin to n tẹ wa lọwọ ni yajoyajo ti fiyeni pe awọn afurasi Fulani darandaran kan ti yinbọn pa ọmọbinrin alaga ẹgbẹ Afẹnifẹre, alagba Reuben Fasoranti.
Iroyin taa gbs ṣalaye pe iṣẹlẹ buruku yii ṣẹlẹ lagbegbe Oke Iyara ni Ijọka.
Bí ó bá ti dé kí ẹ bá mi kí i dáadáa.
ti o fun iko mejeeji ni ami kookan lori tabili.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: OAU: Ohùn ọ̀jọ̀gbọ́n Richard Akindele ni wọ́n ká sílẹ̀ OAU lé ọ̀jọ̀gbọ́n tó bèèrè ìbálòpọ̀ fún máàkì ‘Lóòótọ́ ni ọ̀jọ̀gbọ́n fẹ́ bá mi lòpọ̀’ Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Àwọn ọdaràn méjèèjì yìí wà lára ẹgbẹ́rún kan le ọkandínláàdọ́rinlélẹgbẹta àwọn ọmọ ikọ Boko Haram.
 nídà kejì , bí ọ ̀ rọ ̀ àwùjọ-ẹ ̀ dá ba jẹ ́ kónkó-jabele , ẹ ̀ tẹ ́ àti wàhálà ni ojú ọmọ ènìyàn yóó máa rí .
Àwọn alufaa ni wọ́n ni gbogbo àwọn ohun ìrúbọ, ati gbogbo ohun mímọ́ tí àwọn ọmọ Israẹli bá mú wá sọ́dọ̀ wọn.
O ni oun mọọmọ yọ wọn ninu idije toni ni ki wọn le sinmi ati pe Naijiria ni awọn agbabọọlu to pé to lati koju Madagascar.
Nígbà tí Jesu gbọ́, ó ní, “Àìsàn yìí kì í ṣe ti ikú, fún ògo Ọlọrun ni, kí á lè ṣe Ọmọ Ọlọrun lógo nípa rẹ̀ ni.
Iṣẹlẹ bí àwọn Fulani daran daran ṣe n paniyan, jiji akẹkọọ to le lọgọrun un gbe nile iwe ijọba Dapchi, ipinlẹ Yobe wa lara ipenija ti ijọba Aarẹ Buhari n doju kọ lagbegbe naa.
Aya sì níláti bọ̀wọ̀ fún ọkọ rẹ̀.
Wo àwọn míniístà mẹ́fà tí ẹnu ń kùn jùlọ Ẹ̀mí ológun kan bọ́, ọ̀pọ̀ arìnrìn àjò bọ́ sọ́wọ́ ajínigbé Ǹkan mẹ́jọ tó máa kọ́kọ́ ṣẹlẹ̀ kí olólùfẹ́ méjì tó pa ara wọn EFCC ti ri mílíọ̀nù 65.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, India: Ẹ wo bí àwọn ènìyàn ṣe dóòlà èmí erin tó jálulẹ̀ Ìjọba Nàìjíríà wá kéde ní ọjọ́ kejì pé àwọn ti mú àdínkù bá owó físà, sùgbọ́n Amẹrika ni àwọn ko ni àdínkù bá owó físà àfi ti wọ́n ba ṣe ni ìlana tó yẹ.
 Ó sì tún kópa nínú kíkọ Àsàyàn Ìtàn .
Iranṣẹ náà bá ti Tamari jáde, ó sì ti ìlẹ̀kùn mọ́ ọn.
Bakan naa ni awọn yoo bẹrẹ lọwọ Alaafin lati rọ ọ loye Mayegun ti Ilẹ Yoruba nitori ihuwasi rẹ ti ko ba ọna asa ati iṣe Yoruba mu.
EndSars Protest Update: Àwọn òṣìṣẹ́ ọgbà ẹ̀wọ̀n ń bẹ jàńdùkú àmọ́ wọ̀n kò gbọ́
Ni ajọ IAAF ba yari pe ohun kohun bii owo to ba tọ si AFN lati ọdọ IAAF, wọn ko ni le gba a mọ.
Finehasi, ọmọ Eleasari ni olórí wọn tẹ́lẹ̀ rí, OLUWA sì wà pẹlu rẹ̀.
 SERAP wa pe fun ki ile ẹjọ kan nipa fun ijọna Naijiria lati fi oju awọn aṣebi lede, ki wọn si fi wọn jofin."
Bakan naa ni awọn ololufẹ erebọọlu ni Naijiria fikun wi pe ipa takuntakun ti Babalade ko ninu ẹgbẹ agbọọla Enyinba lo jẹ ki wọn gba ami ẹyẹ CAF Champions League nigba rẹ.
“Lẹ́yìn èyí ó fún wọn ní àwọn onídàájọ́ títí di àkókò wolii Samuẹli.
Oríṣun àwòrán, OTHERS Àkọlé àwòrán, Ọ̀pọ̀ ènìyàn lo ti sọ ẹmi nù nítorí àìsàn Iba Lassa Ìbẹ̀rù nípa Amotekun ló ń mú káwọn èèyàn kan máa wí ìwíkùwí - Soyinka Ọọ̀ni obìnrin, Lúwòó Gbàgídà rèé, akọni tó ń gun ọkùnrin ní ẹṣin rìn Àkíyèsí nípa àìsàn ‘Coronavirus’ tó ń ṣàkóbá fún bí a ṣe ń mí Àwọn olùgbé Tarkwa Bay ń fọ́ ọ̀pá epo, jí epo ta, la ṣe lé wọn - Iléeṣẹ́ Ológun Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Nigeria's Under-19:Ẹ wo bí Ikọ̀ Cricket Naijiria ṣe mi àgbáyé titi Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Èyìí ni báwọn ọ̀dọ́ orílẹ̀èdè Ghana ṣe ń wa kùsà góòlù lọ́nà kòtọ́ láti rówó Iye ibo to ba wa lati ẹkun Ashante naa yoo ṣe daadaa fun NPP nigba ti ibo to ba wa lati ekun Volta yoo ran NDC lọwọ.
Koda oju ọta ni awa mejeeji fi n wo ara wọn ki ọrọ ifẹ to wọnu ọrọ wọn.
Ilu ti yoo wa lori omi yii ni yoo maa ṣe ipese ounjẹ ati ina ati omi pẹlu dida idọti rẹ nu lọna igbalode fun ara rẹ.
'Ayederu' fifọ ile itaja nla, ṣugbọn ti kii ṣe ayederu Fidio kan jade nipa wahala to waye ni ile itaja nla kan ni ipinlẹ Ọṣun nibi ti awọn eeyan kan ti lọ fọ ileetaja nla naa ti wọn si ko ẹru olowo iyebiye lọ.
Arabinrin Temitope (kii ṣe orukọ abisọ rẹ) sọ ohun gbogbo ti oju rẹ ri lasiko to ti ipasẹ awọn eniyan kan lọ ṣiṣẹ nilẹ okeere.
Àkókò fífa nǹkan ya wà, àkókò rírán nǹkan pọ̀ sì wà;àkókò dídákẹ́ wà, àkókò ọ̀rọ̀ sísọ sì wà.
Bi a ba gbe eyi sẹgbẹ ojilelẹgbẹrin ati meje alawọ funfun, ọrinlenirinwo o din meji ẹya Hispanic ati mẹrindinlaadọfa ẹya Aṣia to n gbe ni Chicago to ni arun naa Eeyan mejidinlọgọrun larun coronavirus ti ran lọ si ọrun alakeji ni ilu Chicago, ida mejilelaadọrin wọn lo si jẹ alawọ dudu nibẹ.
Gbogbo ìlú ati ìletò wọn jẹ́ mẹrindinlogun.
“Wò ó, Ọlọrun a máa ṣe nǹkan wọnyi léraléra fún eniyan,lẹẹmeji tabi lẹẹmẹta,
”O ni awon kan tile ti n gba
Ọgbẹni Pinnick sọ pe Dennerby yoo dari ikọ ọmọ ẹgbẹ Super Falcons di ọdun 2020 pẹlu asọtẹlẹ lori boya yoo gbawe isẹ tan tabi ki o tẹsiwaju gẹgẹbi akọni-mọọgba.
Obasanjo - BBC News Yorùbá BBC News, YorùbáFò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Obasanjo: Mo lòdì sí ìgbé ayé tí Gani Adams ń gbé látẹ̀yìnwá, ṣùgbọ́n n kò bá a jà - Obasanjo 3 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Oríṣun àwòrán, Eagleonline Aarẹ ana lorilẹede Naijiria, Oloye Oluṣẹgun Ọbasanjọ ti ni ko si idi fun oun lati pari ija pẹlu Aarẹ ọna Kakanfo ilẹ Yoruba, Iba Gani Adams.
Oríṣun àwòrán, osun state government O ni yat s si pe wọn yoo foju wina ofin, awọn ti wọn mu naa yoo tun san owo gba maa binu fun ijọba.
"Roland sọ fun BBC pe ""Bi o ba fi le wọ ibẹ ti o si jade, o ti di ẹlomiran ni yen,"" Awọn ẹgbẹ okunkun yi ni orisirisi orukọ bi Vikings, Black Axe, Eiye ati Buccaneers."
O ni awọn aisedeede to le mu dani losu kọkanla yii le pada fa idojuti fun America ko si ba itan idibo to dara jẹ́ ni America O ni awọn ẹgbẹ oselu Democratic le lo awọn irinsẹ idibo ti ko tọna nipasẹ eto idibo fifi ran sẹ nitori pe eto idibo yii ti kuna ni awọn agbegbe ti wọn ti loo sẹyin.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ọmọ onílẹ̀ wọ gàù, ó kó sí gbaga ọlọ́pàá Ayinla Ọmọwura, orin èébú àti oríyìn lo fi di ọ̀rẹ́ àwọ̀n obìnrin Wo àwòrán ńkan tó ń ṣẹlẹ̀ ní ìpádé ìran Yorùbá ní Ibadan báyìí Olúbàdàn, ẹ bá wa bẹ́ Seyi Makinde kó tú wa sílẹ̀ - Oyo NURTW Olùdíje ààrẹ bíi ọgọ́ta tako Atiku lórí ọ̀rọ̀ INEC Ifojusun wọn si ni lati fi agbajọwọ wa ojutu si gbogbo awọn ipenja to nii ṣe pẹlu eto aabo ni ẹkun iwọ-oorun guuṣu orilẹede yii.
Tafa ati Lapade ni awọn ẹda itan to ṣe gboogi nibẹ pẹlu iwa ifarada, iforiti ati fifọ awujọ́ mọ́.
si ko sinu panpa  ajo to n gbogun ti iwa
“Ṣugbọn níti ẹ̀yin tí ẹ kọ mí sílẹ̀,tí ẹ gbàgbé Òkè Mímọ́ mi,tí ẹ tẹ́ tabili sílẹ̀ fún Gadi, oriṣa Oríire,tí ẹ̀ ń po àdàlú ọtí fún Mẹni, oriṣa Àyànmọ́.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù AFCON 2019: Inú mi dùn pé mo jẹ́ ẹni àkọ́kọ́ tó ṣojú Nàíjíríà fún ìgbà 100 Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ AFCON 2019: Inú mi dùn pé mo jẹ́ ẹni àkọ́kọ́ tó ṣojú Nàíjíríà fún ìgbà 100 21 Òkùdu 2019 Iriri lo n jẹ́ agba, ko si se fi owo ra.
Bo tilẹ jẹ pe ijiroro si n waye lori pe boya ki ijọba fi aaye gba awọn akanda ẹ̀dá lati ma a tọrọ bara, awọn onímọ̀ sọ pe iyatọ wa laarin awọn to n tọrọ bara jẹun ati awọn ọmọ almajiri.
Nigba to'n ba awọn akọroyin sọrọ, o ni ''A fẹ fi asiko yi kan saara si ẹka idajọ ilẹ wa fun bi wọn ti se'n se daabo bo eto oselu tiwantiwa ati mimu agbega ba eto oselu ilẹ wa.
Ẹ̀mí fẹ́rẹ̀ bọ́ lẹ́nu mi ní ọpọlọpọ ìgbà.
Oríṣun àwòrán, @PoliceNG Adamu wa kẹdun pẹlu awọn mọlẹbi awọn agbofinro to jalaisi lọsan gangan ọhun, to si bu ọwọ nla fun wọn.
Nigba ti o n sọrọ lori awọn ọna ti wọn le gba lati fi dẹkun eto abo to n mẹhẹ ni ẹkun naa, Aṣofin  Oleyelogun sọ pe agbẹnusọ kọọkan ni lati ṣe ipade pẹlu awọn gomina wọn pẹlu awọn eniyan ti ọrọ kan lati wa ojutu si iṣoro yii.
Eyikeyi oṣiṣẹ to ba ni i yoo si gba itọju.
Kò sí ẹni tí ó láyà ninu àwọn ìyókù láti darapọ̀ mọ́ wọn.
Lórí ajakalẹ àrùn Coronavirus, Akeredolu ni àjálù ńlá ni àrùn náà, ìpínlẹ̀ Ondo sì ti dangajia nítorí àwọn tí ni oriri tẹ́lẹ̀ nípa itọju ibà lassa, tó ti kọkọ bá wọn fínra.
Gbé ara rẹ ga, Ọlọrun,gbé ara rẹ ga ju ọ̀run lọ,kí ògo rẹ sì tàn ká gbogbo ayé.
'Ìṣòro àìrílégbé ló burú jùlọ nínú ìṣòro ẹ̀dá láyé' Wo ìdí to fi gbọdọ̀ yàgò fún Bobrisky, akọ tó ń ṣe bíi abo Kí ló dé táwọn ọ̀dọ́ dìbò 140m fún BBNaija àmọ́ tí ìbò ààrẹ Nàíjíríà jẹ́ 28m?
Ní Amẹ́ríkà, ònkà oṣù ni wọ́n máa nkọ ṣáájú ònkà ọjọ́.
Igbe àwọn eniyan Israẹli ti gòkè tọ̀ mí wá, mo sì ti rí bí àwọn ará Ijipti ṣe ń ni wọ́n lára.
" Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ìtàn ọ̀rẹ́ tó fi ògùn gba ọkọ ọ̀rẹ́ rẹ̀ ni Akomolede BBC Yorùbá fẹ́ kọ́ wa lònìí Agbẹnusọ ile iṣẹ ọlọpaa nipinle Eko Olumuyiwa Adejobi ni awọn adurasi mẹfa to fi mọ Okikiola ni awọn n fi ọrọ wa lẹnu wo lọwọlọwọ lori iṣẹlẹ naa Agbẹnusọ Ọlọpaa ni Okikiola to jẹ ọrẹ rẹ to lọ pe e nile ko wa fi ẹjọ sun ni agọ ọlọpaa nigba ti iṣẹlẹ naa ṣẹlẹ kaka bẹẹ, o gbe lọ si ile Baba alawo lati lọ yọ ọta ibọn lara rẹ.
Nkechi Blessing: Blessing ní ìkébé òun tóbí ju ohun tí òun lè dọwọ́ bò lọ, gbogbo èèyàn ló mọ̀
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Akomolede ati asa Yoruba: Ẹ wá kọ́ nípa àpòtí ìṣura èdè wa lórí BBC Yorùbá Ki wọn ṣe agbekalẹ igbimọ kan ti yoo maa mojuto ilana aatẹlẹ wọnyii fun ile iwe wọn.
Se bo se gbe isẹ tiata lọ soke okun ni ka sọ ni abi aimọye ere itage akọnilọgbọn to ti gbe se nigba to wa loke eepẹ.
 O sọ wipe: ""Awọn kan ninu wa lo to ọjọ mejọ ninu igbo."
Èmi ni Ọlọrun Bẹtẹli, níbi tí o ti ta òróró sórí òkúta tí o sì jẹ́ ẹ̀jẹ́ fún mi.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Coronavirus update: Àwọn ẹgbẹ́ agbábọ́ọ̀lù ìlẹ̀ Gẹ̀ẹ́sì fẹnukò láti parí líìgì ọdún yìí 17 Ìgbé 2020 Oríṣun àwòrán, Getty Images Awọn ẹgbẹ agbabọọlu nilẹ Gẹẹsi ti fohun ṣọkan pe awọn yoo gba awọn ifẹsẹwọnsẹ to ku ninu idije liigi tọdun yii ti arun Coronavirus da duro.
Nígbà tí àkókò òtútù kọjá, ní àkókò tí àwọn ọba máa ń lọ jagun, Joabu gbógun ti ilẹ̀ Amoni; wọ́n dó ti ìlú Raba.
Ijamba naa lo waye ni oju ọna irin ni agbegbe Mangoro Ashade, lagbọ wipe ẹsẹ ọkọ oju'rin naa yẹ kuro loju ọna rẹ, to si fi ẹgbẹ lelẹ lasiko to wa lori ìrìn.
Wo àwọn ọmọ Naijiria mẹ́ta tó jáwé olúborí nínú ìdìbò sílé aṣòfin ilẹ̀ Amẹrika Bí ọwọ́jà ìjọba mi kò bá tíì dọ́dọ̀ yín, ẹ ṣe sùúrù pẹ̀lú wa- Ààré Buhari bẹ̀bẹ̀ Díẹ̀ ló kú kí owó tán l‘ápò mi torí ìrànwọ́ Coronavirus - Pasuma Trump ni ibo to le ni aadọrin miliọnu eyi to jẹ eleyi to pọ julọ sikeji ninu itan oṣelu orilẹede Amẹrika.
eniyan yoo se lee dibo fun wọn, ki won maa ro pe aare Buhari yoo se mogo-mogo
Lọwọlọwọ bayii, iwọde naa n lọ lọwọ ni ilu Eko, Abeokuta, Ibadan, Osogbo, Akure ati Ado-Ekiti.
"Sugbọn, ẹgbẹ agbabọọlu Watford naa tara mọ idije yii lati bori nitoripe ẹgbẹ agbabọọlu Chelsea jẹ ọkan ninu awọn ti o dara julọ nilẹ gẹẹsi""."
Ìgbà tí ó ṣe bẹ́ẹ̀, kò ríi, ṣùgbọ́n ó wí fún ni pe òun ri Ẹlẹ́gbára pàápàá, o ń jẹ òkú ènìyàn kan lọ́wọ́ àti pé òkú ènìyàn náà jọ òku Ìgnín-ènìyàn, nígbà tí àwa náà wò ó, òun ni.
Títí òṣèlú bọ ètò ẹ̀kọ́ lásìkò ìgbanisíṣẹ́ àti ìyànṣípò nàá n ṣe àkóbá fún ètò ẹ̀kọ́.
Iru awọn iroyin ti ẹ le nifẹ si: ‘Lootọ ni nkan pa emi ati Baba Suwe pọ’ Fela ni awokọṣe mi -Ọga akọrin RCCG 'Akonimu BBC' Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí 2 sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
” Abramu bá tẹ́ pẹpẹ kan níbẹ̀ fún OLUWA tí ó fara hàn án.
Onínúure bíi tíșà ò sí láyé.
Tabi kò dájú pé nítorí tiwa ni ó ṣe sọ ọ́?
"O te siwaju ninu ọrọ pe ""iwadii ti ẹgbẹ PFN ṣe ko nii ṣe pelu iwadii ti awọn ọlọpaa."
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Shiite: Ẹ̀mí àti ara wa kọ ohun tí ìjọba ń ṣe sìwa láti 2015 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Oríṣun àwòrán, Abike/ Dabiri Èyí ti mú kí ọ̀pọ ọmọ Nàìjíríà máá pé alága NICOM síta pe opurọ ni.
gẹ́gẹ́ bí ó ti sọ láti ẹnu àwọn wolii rẹ̀ mímọ́,láti ọjọ́ pípẹ́;
wọn ,pe ki ijoba da  olopaa ipinle ati ijoba
Laipẹ yii ni wọn pa awọn oṣiṣẹ aṣeranwọ mẹrin ni ipinlẹ naa.
Ẹkọ kẹrin ni pe, ki awọn oṣiṣẹ ijọba dẹkun riba gbigba, ki wọn si ṣe iṣẹ wọn lai fi ele ti yoo lọ sapo wọn kun un owo ti wọn n gba lọwọ araalu nitori eyi lee tun bi idarudapọ lọwọ iwaju.
Inu ọpọlọpọ araalu lo dun si aṣẹ tuntun yii nigba ti ijọba kede lati si ẹnu bode mẹrin pada ni Naijiria.
Oríṣun àwòrán, Muyiwa Ademola/Facebook Àkọlé àwòrán, Òsèré Tíátà Muyiwa Ademola Muyiwa Ademola A bí i ní ọjọ́ kẹrìndínlọ́gbọ̀n osù kínní ọdún 1971 ní Abẹokuta ìpínlẹ̀ Ogun.
Ogunleye sọ èyí nínú ìpàdé orí ayélujára nílùú Eko pé ètò náà wáyá láti pe àkíyèsí àwọn ènìyàn si pàtàkì ìwọ́ ọmọ fún ètò ìwòsàn láwùjọ.
lati ojo kọ́kàndínlógún , osu kejila odun to koja ni awon to n fehonuhan lori ọwọn gogo ounjẹ
NURTW Oyo: Ìfikùnlukùn yóò wàyé pẹ̀lú Gómìnà Makinde láìpẹ́
Josakari, ọmọ Ṣimeati ati Jehosabadi, ọmọ Ṣomeri, àwọn olórí ogun, ni wọ́n pa á.
Baṣọ̀run Gáà, tó yan ọba mẹ́rin, pa ọba mẹ́rin àmọ́ ọba karùn-ún ló pa á Ìyá àgbà Ọlayinka, arúgbó tó ń ṣoge bí omidan Oshisko twins, àwọn 'ìbejì' tó ń dẹ́rìn ín p'òṣónú Wọ́n ta ère Ọ̀ṣun Osogbo sí Togo - Bàbá Ọṣun figbe ta Titi ti baba yii fi ka a dori gbigbaa oye Masters bayii lẹni ọgọrin ọ̀dun, ohun funra rẹ ni iwuri ara rẹ nipa titọ ara ẹni.
Lẹ́yìn náà, wọ́n lọ sí apá gúsù.
’’Marafa, wa gbosuba fun adajọ Ijeoma Ojukwu fun idajo otito re, o wa ni egbe APC  si lee foruko oludije won sile ni ipinle Zamfara ti idajo ile-ejo kotẹmilọrun to wa ni ipinle Sokoto  ba gbe won.
 Àsìkò yìí gan-an tí gbọ ́ nmi-síi , omi-ò-tóo ń wáyé ní ìlú rẹ ̀ , bahia lórí ọ ̀ rọ ̀ òwò ẹrú yìí ní pàtàkì .
Ofin orilẹede Burundi ko faaye gba ifiyajẹni tabi fifi ẹgba lu'yan.
Kò ní ranti iye ọjọ́ ayé rẹ̀ nítorí pé, Ọlọrun ti fi ayọ̀ kún ọkàn rẹ̀.
#BBCNigeria2019 Ààrẹ Gani Adams sọ ẹni tí Yorùbá yóò dìbò fún ní ọdun 2019 #BBCNigeria2019 Bí Hazard bá fẹ́ lọ kó máa lọ - Sarri Ta ló jáwé olúborí nínú eré ìdíje ní Eko?
“Lọ bá Ahabu, ọba Israẹli, tí ń gbé Samaria; o óo bá a ninu ọgbà àjàrà Naboti, tí ó lọ gbà.
Wike wa fi idunnu rẹ si ipa pataki ti Fayẹmi ko lojuna ati pana ahesọ ọrọ naa ni pataki laarin awọn Musulumi ipinlẹ naa.
O ni atunse naa ti yo Shuaibu Salisu to je eni keji ti won fesun kan , kuro nibe, o wa ro ile-ejo lati gba atunse naa wole , ki won si tun  sun esun naa siwaju.
Ó ní òun óo rán ogun, ìyàn ati àjàkálẹ̀ àrùn sí wọn, títí wọn yóo fi kú tán, tí kò ní ku ẹyọ ẹnìkan lórí ilẹ̀ tí òun fún àwọn ati àwọn baba ńlá wọn.
ṣagbatẹru rẹ lọdọọdun ati ṣiṣi moṣalasi tuntun ti Ile Igbimọ Aṣofin
Wọn ni eyi ko ṣẹyin bi awọn eeyan ko ṣe tẹle ilana eto idaabobo mọ, ti onikaluluku si n ṣe nkan to wu u jakejado orilẹ-ede Naijiria.
wọ́n ní, “Ọlọrun ti kọ̀ ọ́ sílẹ̀;ẹ lé e, ẹ mú un;nítorí kò sí ẹni tí yóo gbà á sílẹ̀ mọ́.
Ó dúró lórí iyanrìn etí òkun.
awon omo orile ede Naijiria lati maa se ta ibo won , tabi dibo fun awon ti yoo
" Baba Adeboye ni koda lasiko kan, iyawo oun ti gẹ irun fun oun nitori ilu ti iṣẹ iranṣẹ gbe wọn lọ lasiko naa.
O tun gbaju gbaja gẹgẹ bi ọdọ oṣere to ti di mọlumọọka.
Ni bayii, ọga agba ọlọpaa lorilẹede Ghana, James Oppong-Boanuh ti ran awọn agbofinro lọ si ẹkun naa lati lọ ṣawari iya olooṣa ọhun, atawọn araalu to pa obinrin naa.
Naijiria ni  milionu márùndínlọ́gọ́rin dọlalati fi pese ina mona-mona , ki ibasepo to monyan lee  wa laarin orile ede Naijiria ati orile ede
Ògiri ṣọ́ọ̀ṣì wó pa àwọn olùjọ́sìn mẹ́tàlá Napoli Vs Arsenal: Àwọn olólùfẹ́ Arsenal ń gara pẹ̀lú àṣeyọrí Europa Kọmisana ọlọpaa ni gbogbo ẹ ṣẹlẹ nigba ti awọn ọlọpaa to n ṣewadii iṣẹlẹ ijinigbe san ọna lọ si ilu Atali.
John Mikel obi ní iṣẹ́ to pọ̀ láti ṣe nínú ìdíje tó lọ lọ́wọ́ yìí, ó ṣe wáhala púpọ̀ láàná nítori ó ba àwọn ìjọba sọ̀rọ̀ sùgbọ́n àwọn ọmọ ikọ rẹ̀ ló ṣe fún.
Ó gbé e ka téńté òrùlé Tẹmpili.
‘Kò sí ohun tó lè yẹ ìfèhọnú ọjọ karun un Oṣu Kẹsan lórí àtìmọ́lé Omoyele Sowore’ Amẹrika ń gbẹ̀san lára Nàíjíríà, owó ‘Visa’ di ọ̀nà méjì láti wọ Amẹrika O ni yoo nira pupọ, ti yoo si jẹ isoro nla fun eyikeyi adari orilẹede Naijiria lati se aseye ti alakan n se epo lori aleefa, ta ba si n lo ofin naa, pẹlu afikun pe ofin ọdun 199 kogbewọn to fun irufẹ akanda orilẹede ti Naijiria jẹ.
ki awon omo orile ede Afirika lee maa  rin lati orile ede kan si ekeji laini wahala
Yatọ si Olivier Giroud,Alonso ati Callum Hudson-Odoi wa lara awọn ti wọn jẹ goolu ninu ifẹsẹwọnsẹ naa.
Ẹ máa dúpẹ́ lọ́wọ́ Ọlọrun Baba nípasẹ̀ rẹ̀.
Dafidi ń gbé aṣálẹ̀ Sifi ni Horeṣi.
Orile ede mejeeji naa jọ tọwọbọ iwe adehun leyin ipade ti minista to n ri si ọrọ to jẹ mọ ilẹ okeere, Geoffrey Onyeama ati minisita fun Orile
Olóòtú ìjọba náà ti kéde bílíọnu mẹ́rin Pọun láti ran ọrọ̀ àjé ilẹ̀ Afíríka lọ́wọ́ Sùgbọn, bí Nàìjíríà ṣe ń múra sílẹ láti gba Theresa May lálejò ní àwọn ọmọ Nàìjíríà ti ké pe ààrẹ Muhammadu Buhari lati ríi dáju pé ó sọ ohun tó tọ àti ọ̀nà ti ìbaṣepọ̀ ilẹ̀ Gẹ̀ẹ̀sí yóò fí ṣe Nàìjíríà láànfàní.
Ikọlu ikọ adunkookomọni Boko Haram: Oríṣun àwòrán, Sabah Isẹlẹ miran to tun n dunkooko mọ isọkan ati irẹpọ orilẹede Naijiria, to si tun wa nibẹ lọwọlọwọ bayii ni idasilẹ ati ọsẹ ikọ adunkooko msni Boko Haram.
Ènìyàn 229 ló tún ṣẹ̀ṣẹ̀ ní ààrùn Covid-19 ní Nàìjíríà Èrò ọmọ Nàìjíríà sọ̀tọ̀tọ̀ lórí fàákájáa láàrin Abike Dabiri-Erewa àti mínísítà ètò ìbárẹ̀nisọrọ̀, Ọwọ́ ọlọ́pàá tẹ ẹ̀gbọ́n tó dáná sun àbúrò rẹ̀ toyúntoyún nílùú Eko ₦22.
Àwọn ọmọ Nafutali ní ìdílé-ìdílé nìwọ̀nyí: ìdílé Jahiseeli, ìdílé Guni, 
Ǹjẹ́ inú OLUWA yóo dùn bí mo bá mú ẹgbẹẹgbẹrun aguntan wá, pẹlu ẹgbẹgbaarun-un garawa òróró olifi?
 Inu mi dun pe mo fe lo ba omo mi bayii pelu idunnu pe mo jawe olubori.
Oríṣun àwòrán, TOBI JAMES Gomina ipinlẹ Ọyọ tẹlẹri naa wa rọ awọn ọdọ lati fi ọkan si oun gbogbo ti wọn ba n se, ki itẹsiwaju le ba ọrọ aje wọn.
Wò ó, OLUWA yóo fi àjàkálẹ̀ àrùn ṣe àwọn eniyan rẹ, ati àwọn ọmọ rẹ, ati àwọn aya rẹ ati gbogbo ohun tí o ní.
Sugbọn ni ọdun 2003 ni orilẹ-ede ọhun gba awọn obinrin laaye lati ni ida ọgbọn ijoko ni ile igbimọ aṣofin orilẹ-ede naa.
Ní ọjọ́ kẹtala oṣù Adari ni èyí ṣẹlẹ̀.
Chutni Mahato ti Saraikela ní Jharkhand jẹ́ ọ̀kan lára wọn.
Aare Buhari soro re di mimo
A Ọdẹkomaya, Ọgbẹni Abiodun Aigbe ti wọn jẹ agba oloṣelu lẹgbẹ APC ni agbegbe naa ati awọn eniyan pataki miiran.
Robert Mugabe ti Zimbabwe Oríṣun àwòrán, others Nitori ọrọ to sọ tako ijsba, wọn ran Mugabe lọ si ẹwọn laarin ọdun 1964 si 1974.
Amo, Aare Ernest Bai Koroma ti o n kogba wole, yoo fe gbe ipo naa fun oludije egbe oselu re, nigba ti egbe oselu alatako gboogi yoo fe gba ipo naa pada, leyin odun pipe ti won ti gba isakoso ijoba lowo egbe oselu alatako naa.
Nígbà tí Olódùmarè ṣẹ̀ṣẹ̀ dá àwọn ọmọ ènìyàn sí òda ayé ti ẹ̀sẹ̀ kò ì tíi sí àwọn ará òde ọ̀run a máa wá ba àwọn ará odee ayé ṣiré wọn a jọ máa ṣe àríyá pọ̀ ni.
Nígbà tí wọ́n dé Ikoniomu, wọ́n lọ sí ilé ìpàdé àwọn Juu gẹ́gẹ́ bí ìṣe wọn.
Abineri ati àwọn ọmọ ogun rẹ̀ sì sùn yí i ká.
Aisan Aisan mii kii jẹ ki ounjẹ walẹ bii awọn aisan to ma n koba inu kikun.
Bí-ó-ti-lẹ-jẹ́-pé ẹ̀yà ẹyẹ orílẹ̀ èdè Nepal ju 800 lọ, ẹyẹ Spiny Babbler (Turdoides nipalensis) jẹ́ ẹ̀dá tí kò sí ní ibòmíràn àyàfi orílẹ̀ èdè náà.
Nínú Oṣù keje, ilẹ Amẹrika ti ní gbogbo ẹni tó ba ń fẹ́ láti gba iwé ìrìnà ilẹ̀ Amẹrika gbọ̀dọ̀ sàfihan àwọn ojú opó ayélujara wọn, èyí jẹ́ ọkan pàtàkì lárá òfin tuntun ti wọ́n yàn Wọn fi kún pé arinrin ajo yóò mú orukọ to n lọ loju opo ayelujara rẹ̀ kalẹ̀, pelu gbogb atẹjisẹ tó ti gbà láti ọdún márun ṣẹyin àti nọmba foonu wọ́n Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí FBI List: EFCC join recover $314,000 and N373m from yahoo yahoo pipo27 Ògún 2019 US visa: America sama Nigeria do-me-I-do-you issuance fee for application dem approve27 Ògún 2019 Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Aare Buhari wa gbadura fun Ikpea to je omo bibi ilu
Ọgbẹni Zulum sọ eyi fun ileeṣẹ iroyin BBC lọjọ Aje lẹyin ipaniyan to waye si o kere tan, awọn agbẹ mẹtalelogoji ni ipinlẹ Borno lọjọ Abamẹta, ọjọ kejidinlọgbọn oṣu kọkanla.
Àwọn ará Juda bẹ̀rẹ̀ sí kọrin pé,“Agbára àwa tí à ń ṣe iṣẹ́ ń dín kù,iṣẹ́ sì tún pọ̀ nílẹ̀;ǹjẹ́ a ó lè mọ odi náà mọ́ báyìí?
Ileeṣẹ ologun ninu atẹjade kan lati ọdọ ọgagun Sani Usman to jẹ agbẹnusọ wọn ni niṣe ni ajọ naa n gbero lati tu Naijiria ka.
Agbabọọlu orilẹede Chile naa to jẹ ẹni ọdun 29, darapọ mọ Man Utd ninu osu kinni lori adehun ọdun mẹrin abọ lẹyin igba ti wọn ṣe pasiparọ rẹ pẹlu Henrikh Mkhitaryan.
Eeyan mọkanlelogun lo wa ninu ọkọ naa lasiko to fi ri sinu agbami 'Èèyàn mi mẹ́ta ló wà nínú ọkọ̀ ojú omi tó dà nù l'Eko!
OLUWA ti yà á sọ́tọ̀ fún ìparun, ati gbogbo ohun tí ó wà ninu rẹ̀, àfi Rahabu, aṣẹ́wó, ati àwọn tí wọ́n wà ninu ilé pẹlu rẹ̀, ni yóo wà láàyè; nítorí òun ni ó gbé àwọn amí tí a rán pamọ́.
0 694 Saint Barthélemy 1 10.
World No Tobacco Day: Bí sìgá mímu ṣe kúrò ní òògun ìlera di ewu ńlá
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: 'Tattoo’ ara mi kò tí ì pọ̀ tó, mà á sì se si’ Èéfín gẹnẹratọ gbé ayálégbé délé ẹjọ́ Ìyansẹ́lódì ASUU mú káwọn akẹ́kọ̀ọ́ kan dunnú Ìgbà méèló ni ẹgbẹ́ òsìsẹ́ ti yansẹ́lódì lábé Ayuba Wabba?
Revolution Now: Ẹgbẹ́ òṣèlú AAC lé Ṣowore àti àwọn 28 mííràn
Làálàá mú kí agara dá ọkàn wọn,wọ́n ṣubú lulẹ̀ láìsí olùrànlọ́wọ́.
Ẹ wo àwọn ààrẹ tí ikọ̀ ọmọ ogun ti gba ìjọba lọ̀wọ̀ wọn Òfin ọ̀dájú ni àṣọ́bodè ṣe pé epo kò gbọdọ̀ dé ẹnu bodè Nàíjíríà - Ilé aṣojú-ṣòfin Ìjọba Ọyọ yàtọ̀ sí ti Ọṣun àbí Ekiti tí APC leè fi àṣẹ iléẹjọ́ lé dànù - Seyi Makinde Kọmisana naa fi kun pe, laipẹ laijinna ohun gbogbo yoo yipada lorii imọtoto ilu Ibadan ati ipinlẹ Ọyọ lapapọ, lọgan ti adari tuntun lẹka ileeṣẹ to n ṣe imọtoto ilu, ba wọle s'ẹnu iṣẹ.
Ṣaaju, bi ẹ ko ba gbagbe, loṣu kẹta ọdun yii ni wolii TB Joshua ti kọkọ sọ pe arun naa yoo parii Iyẹn lasiko ọkan lara awọn isin ijọ rẹ amọṣa ti arun yii faake kọri ti ko lọ.
Mo ni ọwọ nla fun Afrika-Trump PDP: Ẹní ṣe nǹkan ètùfù ní kíyèsí ẹ̀hìnkùlé, ọmọ ẹgbẹ́ wà kò hùwà àìtọ́ lásìkò ìdìbò Donald Trump kéde pé ìpàdé òun pẹ̀lú Kim já si rere Nàìjíríà ń wá ẹlẹ́dẹ̀ aríran Ẹsun agbesunmọmi, iwa ibajẹ lasiko ogun, ati iku awọn eniyan to to ẹgbẹrun mẹta ni wọn fi kan wọn.
Ejo bu arabinrin kan ni ìdí jẹ́ lasiko to fẹ ẹ lo ile igbọnṣẹ kan nile rẹ l'orilẹ-ede Australia.
7 miliọnu ni wọn na lori ayẹwo, ohun eelo fun ayẹwo atawọn nkan jijẹ fun ilera Nigba ti wọn na N321.
Oríṣun àwòrán, others Aseyin wa aseyinbọ, Ivory Coast lo tẹsiwaju lọ ìdíje agbaye.
Ìgbàgbọ́ọ wa ni wípé bí ikú bá kanlẹ̀kùn, ẹ̀míi wọn yóò máa ráre kiri ní àárín-in àdúgbò àti ní òpópónà, láti máa rán àwọn ènìyàn létí nípa ìtúmọ̀ ìwà láyé.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Bàálù Ọsinbajo: Kété tó gbéra tán ló ń yọ̀ èèfín 7 Òkùdu 2018 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 8 Òkùdu 2018 Àkọlé àwòrán, Baalu kekere naa lo ni isoro ranpẹ laarin isẹju perete to gbera nilẹ.
Roberts fẹsun kan ijọba pe ko pese ohun to yẹ fun awọn oṣiṣẹ ile iwosan rẹ, idi ree ti wọn ṣe n lo ọra lati fi dabo ara wọn, eyi ti ko bojumu.
Wo àwọn nkan tó yẹ́ kí o mọ̀ nípa 'Awawa Boys', ọ̀kan lára ẹgbẹ́ òkùnkùn tó n dá Eko rú Ki lo fa ija gangan?
to kọja ni iwe ẹri mo yege, ki o to di ọjọ kọ́kàndínlógún ,
O to gẹẹ, gbogbo igba lawọn ọlọpaa fi n gba owo lọwọ wa lai ni idi kan pato."
Joy ti n se isẹ pelu ile itura naa lati bi odun meji,ki o to di pe isẹlẹ ina
Ní ọjọ́ tí Dáúdà ta rọ́bà fọ́ agbè ẹmu bàbá Sídí ní ọ̀nà oko wọn, bàbá rẹ̀ nà án funfun gbẹ́ru gbẹ́ru.
Ìròyìn fi hàn pé ibùdó ìgbáfẹ́ẹ 84 Parks and Gardens ni àwọn ènìyàn náà péjú sí ní àdúgbo Abule Egba fún ayẹyẹ ọjọ́ ìbí náà.
Ó ṣe àgbàlá kan, aṣọ funfun, onílà tẹ́ẹ́rẹ́tẹ́ẹ́rẹ́, ni ó fi ṣe aṣọ títa ìhà gúsù àgbàlá náà, gígùn rẹ̀ jẹ́ ọgọrun-un igbọnwọ.
Wọn óo borí àwọn ọ̀tá wọn,wọn óo fi idà pa àwọn ọ̀tá wọn,ẹ̀jẹ̀ wọn yóo sì máa ṣàn bíi ti ẹran ìrúbọ,tí a dà sórí pẹpẹ,láti inú àwo tí wọ́n fi ń gbe ẹ̀jẹ̀ ẹran.
Ajo NFF tun fi anfaani ohun ki pe,“O ku ayeye ojo ibi ‪Leon Balogun,”Happy birthday @NGSuperEagles defender @LeonBalogun 🎂🎂🎆🎆🎂 pic.
Gẹgẹ bi ohun ti o sọ, O ni awọn alafojuri nibi iṣẹlẹ naa bi ọkọ naa ṣe ya lojiji lo mu ki awọn miran to n bọ lẹyin rẹ fori sọ ara wọn.
Segalink: ìkùnsínú pọ̀ láàrin àwọn agbófinró; bẹ́ẹ̀, wọn kò ni agbẹnusọ
Bakan naa ni ajọ to ṣewadii naa fikun un pe awọn eniyan n bere fun etọ ti awọn ọlọpaa yii ni labẹ ofin lati ṣe iru ofintoto bẹẹ, ati wi pe ki atunse ba eto ofintoto awọn ọlọpaa lorilẹ-ede naa.
Eyín akọ̀ròyìn fò yọ lásìkò tó n ka ìròyìn lọ́wọ́ lórí tẹlifísàn Wo àwọn olorì àgbà mẹ́rin tí Aláàfin ń wárí fún Awọn obinrin naa ṣalaye pe awọn fẹ ki ijọba apapọ o boju wo awọn ọmọ orilẹ-ede Naijiria to wa ni Oman atawọn orilẹ-ede Larubawa miran.
Yóo gbá ilẹ̀ ìpakà rẹ̀ mọ́ tótó.
O ṣe pàtàkì láti tọ́ka si pé àwọn orilẹ̀ èdè Afíríkà kan, ó nira láti mọ ǹkan tó ń ṣelẹ̀ nítori kò tilẹ̀ sí àkọsilẹ̀ kankan, tàbi kí wọ́n ma pari àkọ́silẹ̀ náà.
ṣugbọn OLUWA sọ fún mi pé mo ti ta ọpọlọpọ ẹ̀jẹ̀ sílẹ̀, mo sì ti ja ọpọlọpọ ogun; nítorí ọpọlọpọ ìtàjẹ̀sílẹ̀ náà, òun kò ní gbà pé kí n kọ́ tẹmpili òun.
"Ni ti Adams Oshiomole, o ni ""INEC ko le ṣe lodi si ofin."
Aden Marwa omo ile Kenyan ohun, ni won fi ero fonron igbalode ganni re pe O gba ẹgbẹ̀ta dola owo ile okere lasiko idije Confederation of African Football (CAF) ti o waye lorile-ede Ghana.
Wọn lo kopa ninu ikolu ile iwe ati ijinigbe O jewo wipẹ ọun kopa ninu ikolu mẹrin laarin ọdun kan to fi jẹ ọmọ ẹgbẹ naa.
Eyi mu ki o danikan wa, nitori pe ko si ọmọde miran nile wọn.
"O ni ""A ko yá owo lati na a lori awọn nnkan miran, ṣugbọn awọn owo ti a n ya, awọn nnkan amayedẹrun bii ọna oju irin, opopona to ja gaara, afara igbalode, ina mọnamọna, atawọn nnkan miran ni a fi n ṣe."
À ń pa wá dà sí ògo mìíràn tí ó tayọ ti àkọ́kọ́.
Oríṣun àwòrán, Instagram/ts_esther Oun ni agbẹjọro akọkọ ti yoo kopa lori eto naa.
Tí a fiṣọwọ́ ní 12:03 11 Òkùdu 201912:03 11 Òkùdu 2019 Ta wa ni yóò jẹ igbákejì ààrẹ ilé ìgbìmọ̀ aṣòfin àgbà?
U Adikwu lo kede abajade esi idibo naa pe iye ibo ti  egbe APC ni  jẹ 285,894 .
Ohun tí ó bani lẹ́rù gidigidi ni pé kí ọwọ́ Ọlọrun alààyè tẹ eniyan.
7 Ìgbé 2020 Iroyin ti lu ori ayelujara pe wi pe lilo oogun vitamin C la pa aarun coronavirus to n ba gbogbo agbaye finra lọwọ yii.
ibi tí OLUWA Ọlọrun yín bá yàn láti fi ibùgbé rẹ̀ sí nígbà náà, ni kí ẹ kó gbogbo àwọn nǹkan tí mo pa láṣẹ fun yín wa, ẹbọ sísun yín ati àwọn ẹbọ mìíràn, ìdámẹ́wàá yín, ati ọrẹ, ati gbogbo ẹ̀jẹ́ yín tí ẹ bá jẹ́ fún OLUWA.
Ọlọrun mọ irú ẹni tí a jẹ́, mo sì rò pé ẹ̀rí-ọkàn yín jẹ́rìí sí mi pẹlu.
Ọmọ ọgbọn ọdun ni ọmọ Naijiria naa, ipinlẹ Oyo ni o ti wa.
Awon orile-ede miran ti o tun gbero lati sagbateru idije yii papo lorile-ede U.
Toyin Abraham kọ ni gbajugbaja oṣere akọkọ ti yoo ke sawọn ololufẹ wọn ati gbogbo ọmọ orilẹede Naijiria pe ki wọn tọju imọtoto wọn lasiko ajakalẹ arun yii.
Ọlọ́fìn-íntótó gbádùn láti máà fi ọwọ́ pa túbọ̀mu rẹ̀.
O ni ẹni to lowo lo n san owo eto adojutofo ṣugbọn ni ijọba toun, ilera ọfẹ ni.
O ni o ṣe pataki ki ayẹyẹ ọdun ọhun ma waye nitori ajakalẹ arun Coronavirus to n ba gbogbo agbaye finra, ti ko si yọ Naijiria sẹyin.
Nígbà tí yóo fi di òwúrọ̀ ọjọ́ keji, afẹ́fẹ́ ti kó eṣú dé.
27 Owewe 2020 Oríṣun àwòrán, KEMDI Yoruba bọ wọn ni airin jinna, ni airi abuke ọkẹrẹ, bi eeyan ba rin jinna, yoo ri ibi ti wn ti n fi odo ibulẹ jẹun.
Mẹrindinlọgọrun-un ni àwọn èso Pomegiranate tí ó wà lẹ́gbẹ̀ẹ́ kọ̀ọ̀kan; ọgọrun-un ni gbogbo èso Pomegiranate tí ó wà ní àyíká ẹ̀wọ̀n náà.
Sugbọn awọn ọmọ Naijiria kan koro oju si bi Aarẹ Muhammadu Buhari ti lọ sibi igbeyawo naa ti ko si lọ si ilu Dapbchi ti wọn ti ji awọn akẹkọbirin gbe.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìgbéyàwó Harry àti Markle: Ẹni ńlá ní ń ṣe ohun ńlá 19 Èbibi 2018 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ẹgbẹfa awọn araalu ni yoo kopa nibi eto igbeyawo naa Kaakiri agbaye ni okiki yoo ti kan ni ọjọ abamẹta ti Ọmọọba Harry ati Omidan Meghan Markle ba ṣe'gbeyawo wọn ni ilu Windsor nilẹ Gẹẹsi.
Bí o ti ṣe ni wọ́n óo ṣe wọ́n, wọn óo lọ sí ìgbèkùn.
“Nígbà náà ni ẹ óo rí ohun ẹ̀gbin tí wolii Daniẹli ti sọ tẹ́lẹ̀, tí ó dúró ní ibi mímọ́ (ìwọ olùkàwé yìí, jẹ́ kí ohun tí ò ń kà yé ọ).
Lati bẹ ni o ti de ori gbajugbaja opo ayelujara JamiiForums nibi ti o ti wa gbona fẹlifẹli ti o si tan ka de Kenya, South Africa, ati Ghana.
University of Transportation Daura: Nǹkan mẹ́wàá tó yẹ ní mímọ̀ nípa fásitì ẹ̀kọ́ ìrìnnà
Awọn ọmọde to ni arun to lagbara bi itọ ṣuga ati aisan ọkan ko ni le kopa ninu Hajj Wọn yoo maa tọpinpin ilera alalaji to ba kopa ninu Hajj naa loore koore Diẹ ninu awọn eto Hajj ni wọn yoo ṣe lati mojuto ilana ijina sira ẹni Awọn alalaji ti yoo kopa ko ni ju ẹgbẹrun mẹwaa lọ Ko ni si eeyan kankan ti yoo ti a ti ilẹ miran wa si Saudi lati wa ṣe Hajj Wọn yoo si ile iwosan pataki nitori titọju awọn to ba ni ipenija ilera pajawiri Lọdun 2019 eeyan miliọnu meji ati abọ kaakiri awọn orileede agbaye lo kopa ninu Hajj.
Fela ni awokọṣe mi -Ọga akọrin RCCG 'Làákàyè ẹni tó ń darí eré ju t'awọn òsèrè lọ' Ìsọ̀ oníwe ìròyìn àtàwọn tó ń kà a lọ́fẹ̀ẹ́ Ọlọ́pàá ti mú ẹni márùn ún lórí ìjà láàrin Hausa àti Yorùbá l'Eko Thomas Odia to jẹ oludari fiimu Eru Ajọ tuntun ti wọn n ya lọwọ ni Ibadan naa sọrọ lori ohun oju ri.
Super Eagles kò ní já àwọn ọmọ Nàìjíríà kulẹ̀- Musa Ìlú tí ọ̀daràn bá tí dẹ́ṣẹ̀ ló yẹ kí wọn tí gbẹjọ́ rẹ̀ -Agbẹjọ́rò Adele alukoro fun ileeṣẹ ologun Naijiria, Ogagun Sagir Musa ṣalaye pe kii ṣe ọgagun Lamidi nikan ni aarẹ Buhari gbega lẹnu iṣẹ ologun nitori iṣẹ takuntakun ti wọn n ṣe paapa ni ariwa Naijiria.
Èmi ni mo gbé Kirusi dìde ninu òdodo mi,n óo mú kí ó ṣe nǹkan bí ó ti tọ́;òun ni yóo tún ìlú mi kọ́,yóo sì dá àwọn eniyan mi tí wọ́n wà ní ìgbèkùn sílẹ̀,láìgba owó ati láìwá èrè kan.
Bẹ́ẹ̀ tún ni ìlú Sodomu ati Gomora tí ó dá lẹ́bi, tí ó sì dáná sun.
" Ìdí rèé táa fi fọwọ́ òsì júwe ilé fún òṣìṣẹ́ àádọta ọkọ̀ bààlú - Air Peace Ọkọ lé aya rẹ jáde nílé nítorí ìrísí ojú àwọn ọmọ rẹ méjì ní Ilorin Afẹ́fẹ́ Gáàsì tó ń yọ́ọ́ jò pa Ajibola lẹ́nu iṣẹ́ jórin-jórin Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ìdílé tí ọkọ da ọmọ síta tóríi ojú Búlùú tí wọ́n ní bá BBC sọ̀rọ̀ Oríṣun àwòrán, BBNaija O ni oun tete yofẹẹ Eric lori eto, ati pe oun lo kọkọ fi ẹnu ko o lẹnu nigba ti ere ifẹ wọn bẹrẹ.
Lẹsẹkẹsẹ, Saulu mú ẹgbẹẹdogun (3,000) akọni ninu àwọn ọmọ ogun rẹ̀, wọ́n lọ wá Dafidi ninu aṣálẹ̀ Sifi.
Tẹ ẹ ba gbagbe, oṣu Kẹta ọdun 2019 ni ile aṣofin agba buwọlu owo naa ti ijọba apapọ ati ti ipinlẹ gbọdọ maa san fun awọn oṣiṣẹ wọn.
Baba rẹ̀ ti jáde láyé, ṣugbọn nígbà ayé rẹ̀, òun náà mọ iṣẹ́ àgbẹ̀dẹ bàbà dáradára.
Aarẹ ẹgbẹ NLC, Ayuba Wabba sọ nibi ipade naa pe ''ti awọn gomina ba fi kọ̀ lati san iye ti awọn n beere fun, ohunkohun ko ni i di iwọde ti awọn fẹ ẹ ṣe jakejado orilẹede Naijiria l'ọjọ kẹfa, oṣu Kọkanla, ọdun 2018.
Nítorí náà ẹ kan kẹ̀kẹ́ ẹrù tuntun kan, kí ẹ sì tọ́jú abo mààlúù meji tí ń fún ọmọ lọ́mú tí ẹnikẹ́ni kò sì so àjàgà mọ́ lọ́rùn rí, ẹ so kẹ̀kẹ́ ẹrù náà mọ́ wọn lọ́rùn, kí ẹ sì lé àwọn ọmọ wọn pada sílé.
Winne Madikizela aya Nelson Mandela, sùn ùn re o.
Fídíò BBC ń fa gbùrù, gbùrù ń fa igbó ilé iṣẹ́ apoògùn
Ọ̀rọ̀ rẹ̀ pọ̀, ṣugbọn kò mú ọgbọ́n lọ́wọ́.
Ajo ti o n ri si idanwo abawo ile-eko giga lorile-ede Naijiria ti a mo si The Joint Admissions and Matriculation Board,JAMB ti gbe esi idanwo awon asedanwo ti iye won n lo bi milionu meji, 1,502,978, (One Million, Five Hundred and Two thousand, Nine Hundred and Seventy-Eight, ti won sedanwo abawole  sile-eko giga naa fun ti odun 2018 jade bayii.
Ṣugbọn, ìwọ OLUWA Ọlọrun mi, gbèjà minítorí orúkọ rẹ, gbà mí!
Oríṣun àwòrán, Getty Images Ninu ifọrọwanilẹnuwo BBC Yoruba pẹlu agbẹnusọ ileeṣẹ amunawa IKEDC, Felix Ofulue, o ṣalaye pe akanṣe eto adehun tawọn ni pẹlu awọn ara adugbo Magodo, lo mu igbadun ina ọba yi bawọn.
Lasiko idanwo naa, sinmi bi isẹju aaya lati le ronu si ohun ti o fẹ kọ.
Ni ipinlẹ Eko, ikọ amọtẹkun ko le e ṣiṣẹ fun awọn oloṣẹlu, bẹẹ ni wọn ko le ṣiṣẹ gẹgẹ bi ọlọpaa ni ipinlẹ ọhun.
Nígbà tí Maria gbọ́ ọ̀rọ̀ yìí, ara rẹ̀ kò balẹ̀, ó ń rò lọ́kàn rẹ̀ pé, irú kíkí wo nìyí?
Ìpínlẹ̀ Bauchi àti Kaduna láti máà tẹ àwọn afipábánilopọ̀ lọ́dàá Ó ti di ẹ̀ṣẹ̀ láti bẹ̀bẹ̀ fún afipábánilòpọ̀ nípìnlẹ̀ Ekiti- Ìjọba ìpínlẹ̀ Ekiti Olùkọ́ mi ń bá mi lòpọ̀ kí ń le yege ìdánwò WAEC - Akẹ́kọ̀ọ́ l‘Ogun Àlùfàá méjì wà lára àwọn mẹ́rin tó fi ipá bámilòpọ̀"" ""Ẹnikẹni to ba jẹbi ninu ọrọ naa, yala akẹkọọ tabi oṣiṣẹ ileewe, ko ni lọ laijiya."
Oludije ti ẹgbẹ PDP fa kalẹ, Razak Atunwa ni oludije ẹgbẹ APC, AbdulRazak Abdulrahman fidi ẹ janlẹ ninu eto idibo Naijiria to kọja.
Àkọlé àwòrán, Ori lo mọ ọlọrọ, ori lo mọ ọba.
 lẹ ́ yìn tí ilé ẹjọ ́ faransé kọ ìpẹ ̀ jọ ́ ẹ ̀ bẹ ̀ , gẹ ̀ ẹ ́ sì kàá sí ìjàmbá ikú ojijì ní oṣu kẹsan ọdún 2006 .
Kò sí ẹni tí ó mọ ẹni tí Baba jẹ́, àfi Ọmọ; àtúnfi àwọn tí Ọmọ bá fẹ́ fi Baba hàn fún.
apapọ gbogbo r jẹ́ 769, 495.
Àwọn tí ó bọ́ sẹ́bàá ọ̀nà ni àwọn tí wọ́n gbọ́, lẹ́yìn náà èṣù wá, ó mú ọ̀rọ̀ náà kúrò ní ọkàn wọn, kí wọn má baà gbàgbọ́, kí a sì gbà wọ́n là.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fọ́nrán ohùn, Ilé ẹjọ́ kòmítẹlọ́rùn yá lórí ìbò gómìnà Oṣun- PDP Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Àwòrán bí ìjàmbá iná ṣe lọ ní Ìjẹgun Ọmọ Nàíjíríà gba àmì ẹ̀yẹ akẹ́kọ̀ọ́ tó pegedé jùlọ ní fásitì òkè òkun Àkàndá ẹ̀dá fipá lòpọ̀ pẹ̀lú ọmọ ọdún mẹ́rìnlá, tó sì di óyún 'Ìyá mi kó HIV ràn mí, tó sì kú láì sọ fún mi pé mo ni i' Ẹjọ naa lọ ile ẹjọ kotẹmilọrun lẹyin ti oludije ẹgbẹ oṣelu APC Gboyega Oyetola bori oludije PDP, Ademola Adeleke, nigba ti wọn kọkọ gbe ẹjọ naa lọ iwaju ile ẹjọ kotẹmilọrun ni oṣu karun un.
Nítorí náà, níwọ̀n ìgbà tí Kristi ti jìyà ninu ara, kí ẹ̀yin náà di ọkàn yín ní àmùrè láti ṣe bẹ́ẹ̀.
Gbà mí lọ́wọ́ àwọn ọ̀tá mi, Ọlọrun mi;dáàbò bò mí lọ́wọ́ àwọn tí ó gbógun tì mí.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ondo: Dejí sun ọmọ méje àtagbalagba meji mọ́lé nítorí pé ó ń bínú Oríṣun àwòrán, @irdafrika Àkọlé àwòrán, Agbada ikoko nla kan lo maa fi n se ẹwa fun tita, to si n jẹ ere rẹpẹtẹ nibẹ lojoojumọ.
Nígbà tí ó di ìrọ̀lẹ́, ọkunrin ọlọ́rọ̀ kan, ará Arimatia tí ó ń jẹ́ Josẹfu wá.
Ni bayi, Koeman yoo waako pelu iko agbaboolu England ninu ifesewonse olorejore ni papa isere Amsterdam Arena lojo ketalelogun osu keta odun ti a wayi, bakan naa, yoo tun maa waako pelu iko agbaboolu Portugal ninu ifesewonse olorejore lojo keta si ifigagbaga pelu orile-ede England.
Àwọn tẹ̀gbọ́n-tàbúrò meje kan wà, èyí ekinni fẹ́ aya, ó kú láì ní ọmọ, 
Ẹ ranti àwọn nǹkan ńláńlá tí ó ti ṣe fun yín.
Gomeri lóyún, ó sì bí ọmọkunrin kan fún un.
Nítorí OLUWA àwọn ọmọ ogun ti ya ọjọ́ kan sọ́tọ̀,tí yóo dojú ìjà kọ àwọn agbéraga,ati àwọn ọlọ́kàn gíga,ati gbogbo nǹkan tí à ń gbéga.
Aminadabu bí Naṣoni; Naṣoni bí Salimoni; 
Ijoba ti seto igbaninimoran fawon akekoo to wole pada lojo Aje nitori won tile iwe naa pa lati gba ti ijamba oko naa ti sele.
O ni ọmọ Naijiria rere ni oun, ti kii se magomago ninu gbogbo ohun ti oun ba n se.
ti orile ede India, ni eyi ti won se niluu Abuja.
Aworan arabinrin  Gedi nibi ti o ti n sunkun pelu ẹjẹ lenu re,
Gege bi atejade kan ni odun 2017 pe, ajo FAO n tesiwaju lati wa ona abayo miiran si awon ijamba ti o n sele ni eka eto-ogbin.
19 Èbibi 2020 Oríṣun àwòrán, Getty Images Ọrọ lori awọn ọmọ ile Kewu ni ariwa Naijiria ti ọpọ n pe ni almajiri ti pe fun apero ọmọ eriwo paapaa lasiko coronavirus to n tankalẹ bayii.
Eeyan ko si lee pe ori akọni, ko ma fi ida lalẹ gaaraga ni ọrọ Ọba Aderẹmi, tI a ba wo bi ori ade naa se lami-laaka si nigba to wa loke eepẹ.
Bakan naa, ọrẹ timọ-timọ ni awọn eeyan tun mọ awọn osere mejeeji si, nitori bi wọn ṣe maa n ṣe wọle wọde, ti wọn si maa n jọ ya fọto pọ ni ori ayelujara.
Eyi kò yọ oludije dupo aarẹ lẹgbẹ oṣelu PDP, Atiku Abubakar silẹ Bẹẹ naa ni awọn kan n ṣakawe ohun ini ti Seyi kede pẹlu eyi ti aarẹ Buhari kede pe o jẹ dukia oun.
Ọkan lara awọn to n fẹhọnu han naa sọ bi ọrọ naa se bẹre pẹlu bi ajọ ileesẹ ọlọpaa ṣe bẹrẹ, bakan naa ni awọn miran si bẹrẹ si ni fi fidio bi awọn ọlọpaa se fi iya jẹ wọn lede.
 ní kúkúrú , àwọn ẹ ̀ pọ ́ n pp ti ọba àti ọba àti ọba jẹ wúnrẹ ̀ n tí a ní lò .
5 874605 Orilẹede Iran 12932 33.
” Siwaju si,“Ka mase gbagbe pe, ojuse ti o se pataki julo fun ile-ise alaabo lorile-ede yii, ni lati daabobo ara ilu ati ohun ini won gbogbo.
Òòró rẹ̀ jẹ́ aadọta igbọnwọ (mita 25), ìbú rẹ̀ sì jẹ́ igbọnwọ mẹẹdọgbọn (mita 12½).
 Èyí sì kan àwọn tó ní àrùn kògbóògùn hiv / aids pàápàá .
Awon olopaa ati awon alase n gbiyanju ati se adinku  awon eniyan, ki ofin si fese mule ni ilu naa, lagbami bi awon ara-ilu se fariga.
Ẹtọ ilu ni mo n ṣe, ija ilu ni mo n ja awọn araalu si lo n fun mi ni ẹri ti mo n lo, ti mo ba si sọrọ Ọba, mo ní ẹri to daju lọwọ.
Gbajúmọ̀ gbọdọ̀ jẹ́ àwòkọ́ṣé rere torí bí ìràwọ̀ ṣe ń kú, ni òmíràn ń tàn - Foluke Daramola Ann Grace Aguti, Obìnrin kan to fẹ́ ọkọ mẹ́ta lẹ́ẹkàn ṣoṣo A kò tíì rí ọmọ ọdún méjì tó kó sí kànga- Olootu India Fọ́tò ló ṣàfihàn ibi tí ọmọ ti Nọọsi jígbé lódún 1997 wà Somayya ni lootọ ni inu ọkọ oun dun lati gbọ eyi amọ ohun to dara ti bajẹ, ẹpa ko si boro mọ nitori o ti sọ ọpọ ọrọ kobakungbe si oun, to si ti hu ọpọ iwa abuku, ki asiri ohun adiitu naa to tu.
Ibinu Ọlọrun gba àwọn ohun ìní rẹ̀ lọ,àgbàrá ibinu yóo gbá wọn dànù.
Akoko eto idibo ti bẹrẹ kaakiri awọn ipinlẹ to kan Eto idibo ti bẹrẹ ni ipinlẹ Kano lawọn agbegbe kan ti ajọ INEC ti ni atundi eto idibo yoo ti waye.
Igba ti mo pada de ni mo yi ayederu oyinbo mọ awada Yoruba nikan ti mo n ṣe tẹlẹ, ti nnkan si tun lọ soke si fun mi.
Ọlọrun yóo pa òun náà run.
Iwosan: Nilẹ Naijiria, oniwaasu kan fi fidio ati iwe ikede kan sita, eyi ti wọn n pin loju opo Whatsapp pe, omi ọbẹ alata, taa mọ si Pepper Soup, lee wo arun Coronaviruas san.
Lẹ́yìn tí mo gbé ayé mi yẹ̀wò, mo ríi pé asán layé - Toyin Abraham Ó di gbéré!
Ìkórìíra a máa rú ìjà sókè, ṣugbọn ìfẹ́ a máa fojú fo gbogbo ẹ̀ṣẹ̀ dá.
Koke gba ami-ayo kinni wole niseju perete ti ifesewonse ohun bere, kii Antoine Griezmann ko to fobale ki saa akoko o to wa si ipari.
Aranṣọ, olórin àti àwọn mì í ti ko fẹ́ kí ìdìbò kásẹ̀ nílẹ̀ ní Nàìjíríà Kanu sọrọ lori ọna ti oun fi dawati lọwọ awọn ologun ti wọn ni ko wa gbe e tẹlẹ nigba ti o n ba akọroyin BBC sọrọ.
Ìbẹ̀rù OLUWA a máa mú ìyè wá,ẹni tí ó ní i yóo ní ìfọ̀kànbalẹ̀,ìṣẹ̀lẹ̀ burúkú kan kò ní ṣẹlẹ̀ sí i.
Abdulrahaman, Ọmọ ọdún 17 kó sí páńpẹ́ EFCC lórí ẹ̀sùn yahoo-yahoo ní Ibadan Ìjàmbà ọkọ̀ akẹ́rù ní Ikòròdú fa súnkẹrẹ-fàkẹrẹ ọkọ̀ ní Márosẹ̀ Irọ̀ ni ìjọba ń pa, Ikọ Amọtẹkun ba ofin Naijiria mu- Ìgbìmọ̀ Yoruba Wo ohun tó yẹ kó mọ̀ nípa Gomina Imo ti ilé ẹjọ́ giga ye àga mọ́ nídí O ni ki awọn gomina ipinlẹ Yoruba ma ka ọrọ ti adajọ agba naa sọ nipa ifilọlẹ ikọ Amotekun si.
"Adekunle koju Stanley, nigba ti awọn mejeeji de lati ibi isẹ wọn.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Obìnrin kan bí ibejì lẹ́yìn ọjọ́ 26 tó bí ọmọkùnrin Àwọn onímọ̀ ṣàwárí 'ihò ìyọ̀ tó gùn jù láyé' nítòsí ìbì tí ìyàwó Lọti inú Bíbélì ti di iyọ̀ Pím pim pim!
Bawọ wa ni kokoro yi se n ba ara ja,ki lo de tawọn kan fi n tọwọ rẹ ku,bawọ ni wọn se n tọju rẹ?
Nígbà tí wọn ti fi ṣe ẹlẹ́yà tẹ́rùn, wọ́n bọ́ aṣọ àlàárì náà kúrò lára rẹ̀, wọ́n fi tirẹ̀ wọ̀ ọ́.
Agbẹnusọ kan fún ibùdó ìwakùsà ọun sọ pe iná ẹ̀lẹ́tiríikì ti pada sinu akasọ̀ èèbo tí yóò gbé àwọn awakùsà ọ̀ún padà sóké.
PERESINI, a ti pín ìjọba rẹ, a sì ti fún àwọn ará Mede ati àwọn ará Pasia.
Aare tun  so pe  aseyori ti wa ni awon  oju –popo,oju irin, papa ofurufu ati  ina mona-mona lorile ede yii.
Lẹ́yìn wọn ni Refaaya ọmọ Huri, aláṣẹ ìdajì agbègbè Jerusalẹmu ṣe àtúnṣe abala tí ó kàn.
owo gba-mabinu fun awọn ẹbi awọn ọmọ orilẹ-ede Naijiria ti wọn fara gba
Bi eto idibo ti ku wakati méjídínláàdọ́ta,
Ìpínlẹ̀ méjì péré (Maine àti Nebraska) ló máà n pín ìbò àwọn kọ́lẹ̀jì ìdìbò, nítori bi iye àwọn olùdìbò tí wọ́n ni.
Ó sì sọ fún àwọn eniyan pé, “Ẹ kúrò ní agbègbè àgọ́ àwọn ọkunrin burúkú wọnyi, kí ẹ má sì fọwọ́ kan nǹkankan tí ó jẹ́ tiwọn, kí ẹ má baà pín ninu ẹ̀ṣẹ̀ wọn.
Tijjani, to jẹ aṣoju ajọ alaafia sọ pe, Keresimesi ma n fun awọn Musulumi ni anfaani lati fihan awọn aladugbo wọn to jẹ Kristiẹni pe, ẹsin alaafia, ifẹ ati ipamọra ni Islam.
Ẹ ó rántí pé àríyànjiyàn bẹ́ sílẹ̀ ní ọdún tó kọjá nígbà tí Gómínà Nasir El-Rufai dá ogunlọ́gọ́ àwọn olùkọ́ ìpínlẹ̀ náà dúro látàri wípé wọn kò mọ iṣẹ́ to, tí wọ́n sì fìdí rẹmi nínú ìdánwò tí ó yẹ kí ọmọ ilé ẹ̀kọ́ apá kẹrin lè mọ̀.
Ẹni to bori: Algeria Algeria Orilẹede Algeria lo ni ilẹ to fẹ julọ ni Afirika, to si wa ni ipo karun lagbaye.
Wọn kò mọ ohun tí ó ṣẹlẹ̀ sí Peteru.
Asisat Oshola, Desire Oparanozie ati Onome Ebi jẹ pataki lara ikọ ẹlẹnimẹtalelogun ti yoo ṣoju ẹgbẹ agbabọọlu obinrin ti Naijiria, Super Falcons ni France.
Ilé isẹ́ Àjọ INEC gbaná ní ìpínlẹ̀ Plateau INEC sùn ọjọ́ gbígba káàdì ìdìbò síwájú Ẹ̀yin ọ̀dọ́ ẹ má jẹ́ kí wọ́n lò yín láti dàbò rú- Buhari Rẹ́díò Fayose di títìpa l'Ekiti Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ọkọ àti ìyàwó sọ àsọtẹ́lẹ̀ tani yóò wọlé nínú PDP tàbí APC Bi idibo naa ti ṣe ku ọjọ diẹ, ọrọ ika ti awọn oludibo le lo lati fi dibo ti ko si nii ṣe akoba fun ibo wọn lawọn eeyan n ran lẹnu.
O pe àwọn ọ̀tá mi jọ sí mibí ẹni peniyan síbi àjọ̀dún;kò sì sí ẹni tí ó yèní ọjọ́ ibinu rẹ, OLUWA.
Gbogbo ìjọ eniyan Israẹli bá bẹ̀rẹ̀ sí kùn sí Mose ati Aaroni ninu aṣálẹ̀, 
O wọ agbo oṣere lọdun 1953 ni ile ijọsin kan nilu Eko, sugbọn ọmọ Abeokuta ni ipinlẹ Ogun ni Ni ọdun 2019, Agbako salaye pé aisan to jọ mọ ọkan lo se oun sugbọn oun ti se iṣẹ abẹ.
Oríṣun àwòrán, Google Adugbo Ajegunle ni ojule kọkandinlọgọta, Opona Ojora ni iṣẹlẹ naa ti waye ni ọjọ kejilelogun oṣu Kẹfa ọdun 2013.
“Nígbà tí àkókò bá tó, àwọn ọmọ Israẹli ati àwọn ọmọ Juda, yóo jọ wá pẹlu ẹkún, wọn yóo máa wá OLUWA Ọlọrun wọn.
Ninu àwọn ọmọ Paroṣi, Sakaraya ni olórí;orúkọ aadọjọ (150) eniyan ni wọ́n kọ sílẹ̀ pẹlu rẹ̀.
O ni yatọ si iya arugbo ẹni ọgọrin ọdun ti oun fipabalopọ, oun tun ba ọmọde ti ko to ọdun mẹwaa lajọsepọ nipa.
Naijiria wa lara awọn ilẹ ti ọrọ yi kan ti eyi si mu ki ijọba Naijiria tutọ soke foju gba a pe awọn naa ko ni gba ki baalu lati awọn ilẹ Yuroopu yi wọ oju ofurufu Naijiria.
Kódà lọ́dún 1998, ètò àgbéléwò 'Sex and the City' ya abala kan sọ́tọ̀ fún un láti kéde pé ó ti kúrò ní ǹkan ìṣeré lásán.
 josiah akinyele jèrè ọkàn abigail lápènọ ̀ sí inú ẹ ̀ sìn kìrìsìtẹ ́ nì tí ó jẹ ́ ọmọbìrin kukomi , tí ó jẹ ́ alágbára mìíràn ní ìlú Ìbàdàn lásìkò yí nípasẹ ̀ ọ ̀ gbẹ ́ ni hinderer gẹ ́ gẹ ́ bí ìyàwó kejì ní ọdún 1870 .
Irú rẹ̀ kì í ṣe nǹkan ìjọjú, nítorí Satani pàápàá a máa farahàn bí angẹli ìmọ́lẹ̀.
Inú àmì irin yìí ni wọ́n fi orísìírísìí nkan pamọ́n sí.
Ọpọ ọkọ akero Bus Rapid Transit, BRT ni Oyingbo Olùwọ́de 12 kú ni Lekki, 38 lapapọ kú lọ́jọ́ Isẹ́gun, 56 ni àròpọ̀ àwọn tó bá ìwọ́de lọ - Amnesty International Saaju la ti sọ fun yin pe gudugbẹ ọrọ ti jabọ lati ẹnu ẹgbẹ ajafẹtọ ẹni lagbaye, Amnesty International, ẹka ti orilẹede Naijiria lori iwa ipaniyan to waye ni Lekki lọjọ Isẹgun.
24 Ẹrẹ̀nà 2019 Oríṣun àwòrán, Twitter/Ganduje Àkọlé àwòrán, Atundi ibo gomina ni ipinlẹ Kano Gómìnà Abdullahi Ganduje, olùdíje ẹgbẹ́ òṣèlú APC, wọlé fún sáà kejì ní ìpínlẹ̀ Kano lẹ́yìn àtúndì ìbò Ajọ INEC ti kede Gomina Ganduje nirọlẹ ọjọ Aiku gẹgẹ ẹni to jawe olubori pẹlu ibo 1 Alatako Ganduje to nibo to sun mọ julọ, Abba Yusuf oludije fẹgbẹ oṣelu PDP ni ibo 10,239.
Wabba tun ni, “Awa egbe osise lorile ede Naijiria ko ti i ri ami idaniloju pe ijoba yii setan lati fi iwa otito ba awon osise ati ara ilu lo lorile ede yii.
Ahesọ yii ko ṣẹyin bi wọn ṣe kọkọ n sọọ kiri pe Ajimọbi ti lugbadi Covid 19 to si n gba itọju nile iwosan aladani kan ni ipinlẹ Eko.
Leah Morse, to ya aworan fidio bi oko ofurufu naa se n bale ni oun sakiyesi pe nkan kan n se oko naa loju ofurufu ko to wa blae nitosi ile oun pelu ariwo nla.
Ajọ NIMC sọ pe nkan ti wọn ba beere ninu iwe akọsilẹ naa nikan ni ki o kọ sibẹ.
wo àwọn nọ́mba ọlọ́pàá tí o lé pé láti mọ ọ̀nà àbáyọ25 Agẹmo 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
”Ṣugbọn kò sí ẹni tí ó yíjú pada.
 ruth nidesand jé ìyàwó rè ẹ ̀ kẹ ́ ta , wón sì ní ọmọ méjì .
Ṣùgbọ́n wọ́n pa á láṣẹ wí pé ọkùnrin náà kò gbọdọ̀ sọ fún ẹnikẹ́ni pé òun gbọ́ èdè ẹyẹ àti ti ẹranko àti pé ní ọjọ́ tí ó bá fi ìdí àṣírí náà han ọmọ ènìyàn ni yóò kú.
Àìsàn kíndìnrín tó dasẹ́ sílẹ̀ ló pa Fẹ́lẹ́ - Ààrẹ NURTW Loni, Ọjọru ni wọn yoo fi iyoku ara alaga ẹgbẹ ọlọkọ ero (NURTW) nipinlẹ Ọyọ, Alhaji Taofeek Oyerinde, ti gbogbo eeyan mọ si Fẹlẹ, fun ilẹ.
Oríṣun àwòrán, @pitharoy Gbogbo ohun tí ènìyàn nílò láti dári ni Tinubu ní - APC Ìpínlẹ̀ Osun yóò mú àyípadà bá àwọn ilànà ìṣèjọba Rauf Aregbesola Ó kéré tán, ẹ̀mí méjì míì ti lọ lórí ìfẹ̀hónú han Sagamu láàrin Ọlọ́pàá àti aráàlú Ìdí ti mo fi ṣe iṣẹ́ àmúrelé mi lábẹ́ ATM rèé - Dele Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Mose bi Aaroni pé, “Kí ni àwọn eniyan wọnyi fi ṣe ọ́, tí o fi mú ẹ̀ṣẹ̀ ńláńlá yìí wá sórí wọn?
Iwọde yii ni ipinlẹ Eko naa ti gberasọ.
N óo gba ìmọ̀ mi láti ọ̀nà jíjìn,n óo sì fi júbà Ẹlẹ́dàá mi, tí ó ní ìmọ̀ òdodo.
wa ni ibamu ofin abala 87 ti ilana eto idibo odun 2010 ( ni eyi ti won se
Idije naa to n lọ lọwọ ni orile-ede Poland jẹ ọkan ti ireti wa wi pe ikọ Naijiria yoo ti se daada.
Èyí yòó wáyé lẹ́yìn ìpàdé tí wọ́n ti kọ́kọ́ ṣe l'óṣù Kejìlá, ọdún 2016, lásìkò tí Ọba nàá ṣàbẹ̀wò sí Nàìjíríà.
Ẹ̀jẹ̀ wọn nìkan ni ẹ kò gbọdọ̀ jẹ, dídà ni kí ẹ dà á sílẹ̀ bí ẹni da omi.
Àsìkò tó láti fi ìwọ́de gba ara wa sílẹ̀ lọ́wọ́ ebi àti oko ẹrú - Sowore Ọ̀gá àgbá ọlọ́pàá pàṣẹ pé kí wọn ṣàwárí àwọn pásítọ̀ tí wọn jí gbé Alaga CCB, Prof.
Wọ́n kẹ̀yìn sí tẹmpili OLUWA, wọ́n sì kọjú sí ìlà oòrùn.
Onochie jẹ oluranlọwọ aarẹ Buhari lọri ọrọ itakun ayelujara.
Wọ́n kó òkítì òkúta jọ sórí rẹ̀.
Lọjọ aje ni ajọ to n gbogun ti iwa ibajẹ ni Naijiria, EFCC ti gbe gbajugbaja olowo ori Instagram ọhun, Ismaila Mustapha ti wọn n pe ni Mompha lọ ile ẹjọ lonii.
Loju opo Twitter wọn ti ikede yi wa, wọn ni kawọn obi ri wi pe wọn tẹle ilana idaabo Covid-19 ṣaaju ki awọn akẹkọọ to pada sile ẹkọ lọjọ Kẹrin oṣu Kini 2021.
Ẹnu yà mí pé ẹ ti kúrò lọ́dọ̀ ẹni tí ó pè yín nípa oore-ọ̀fẹ́ Kristi, ẹ ti yára yipada sí ìyìn rere mìíràn.
Nígbà tí BBC Yoruba ṣe àbẹwò sí àwọn agbègbè tí ìṣẹlẹ náà kàn ni ipinle Ogun ati Katsina n'isẹ ní àwọn ará àdúgbò n bá ará wọn kẹdun.
Kìí wá ṣe Wathoni àti Kiddwaya nikan lo fẹnukẹnu, Tolanibaj àti Kiddwaya náà tun ṣe bẹ́ẹ̀ lálẹ́ ọjọ́ kan náà.
Antony Sani ni ohun to ja ju lakoko yii ni akoso to peye nipa awọn ohun alumọni orilẹede yii, to si fi ohun to n waye nipinlẹ Eko se apẹẹrẹ.
Coronavirus tún ti ṣe ọṣẹ́ lórí iṣẹ́ líla ojú ọ̀nà relùwe láti Eko sí Ibadan - Ìjọba àpapọ̀ Àrùn Coronavirus fa'lẹ̀ya láwọn ìletò aláwọ̀dúdú ní Amẹ́ríkà Corornavirus: Òfin kónílé-ógbélé yoo dínku láti ọjọ kẹrin ọsù tó n bọ̀ Oríṣun àwòrán, others Àkọlé àwòrán, Ààrẹ Buhari ti fawọ kónile -ogbéle wálẹ díẹ̀ ní Eko, Ogun ati Abuja Aarẹ Muhammadu Buhari ti kede pé láti ọjọ keji oṣu kaarun ọdun yii adinku yoo ba ofin konileogbele diẹ ni ipinlẹ Eko, Ogun àti Abuja.
awon molebi ati ọrẹ awon oloogbe naa kẹdun .
Ofin naa ṣalaye wipe ẹnikẹni to ba pa irọ mọ ẹlomiran tabi to sọ oun ẹgbin ti ko ni ẹri kankan nipa ẹlomiran lori ayelujara yoo foju wina ofin, to si lọ lọ ẹwọn nitori bẹẹ.
Jobu tún ń bá ọ̀rọ̀ rẹ̀ lọ báyìí pé,
Bíi Tofeti ni n óo ṣe ìlú náà; Èmi OLUWA ni mo sọ bẹ́ẹ̀.
Mose pa mààlúù náà, ó gbé ẹ̀jẹ̀ rẹ̀, ó ti ìka bọ̀ ọ́, ó sì fi sí ara àwọn ìwo pẹpẹ yípo, ó fi yà wọ́n sí mímọ́.
Ijọba fikun pe awọn ti yoo jẹ anfaani naa ni awọn to wa ni igberiko abi awọn ilu nla ti ko jẹ anfaani ina ọba ni agbegbe wọn.
Mo ti gba àṣẹ lọ́wọ́ Olódùmarè kí n ‘t’t kúrò ni òde ọ̀run.
 Bakan naa ni o tun je omo egbe igbimo ajo CAF.
ile-itaja ni aarin gbungbun Afirika ati Asia.
Àgbèrè tìrẹ yàtọ̀ sí ti àwọn aṣẹ́wó yòókù, kò sí ẹni tí ń wá ọ láti bá ọ ṣe àgbèrè; ìwọ ni ò ń fún ọkunrin ní ẹ̀bùn dípò kí wọ́n fún ọ!
Wo àwọn Ṣọ́ọ̀ṣì Nàìjíríà àti l'Áfíríkà tó ń wólẹ̀ àdúrà kí Trump lè wọlé ìbò ààrẹ America Wo àfiwé owó oṣù Ọlọ́pàá Nàìjíríà pẹ̀lú akẹgbẹ́ wọn lókè òkun Orúkọ àwọn tó yege láti darapọ̀ mọ́ ikọ̀ Amotekun ní ìpínlẹ̀ Oyo ti jáde Gbajúgbajà òṣèré tó ṣe fíìmù James Bond tí jáde láyé lẹ́ní ọdún 90 Wo ojú àwọn òṣèré yìí láì lo Make-up"" orí ìtàgé bó ṣe rí gẹ́lẹ́ Oríṣun àwòrán, @Alhaja Adeola Agoro Owatapa ti Itapa Ijesha, Wolii Olapade Agoro jáde láyé Gbajugbaja oloṣelu to tun jẹ Wolii ni, Omowe Olapade Agoro ti dagbere faye pe o digboṣe."
Dafidi tún pe gbogbo àwọn akikanju ninu àwọn ọmọ ogun Israẹli jọ; wọ́n jẹ́ ọ̀kẹ́ kan ati ẹgbaarun (30,000).
Adari ajọ irinna ofurufu ni Naijiria, Sam Adurogboye fikun pe, awọn orilẹede miran to si papakọ wọn, lai tẹle ofin to n dẹkun itankalẹ arun Coronavirus, sakiyesi pe arun naa n peleke si.
“Ẹ kò gbọdọ̀ yá ère fún ara yín.
Oríṣun àwòrán, AFP Àkọlé àwòrán, L'orilẹede Mali, awọn Fulani yii n ṣe iwọde ni olu ilu orilẹede naa, Bamako, l'Ọjọbọ (Thursday) lori ikọlu laarin awọn daran-daran Fulani ati awọn agbẹ oloko ni aringungun Naijiria.
Ẹ fi owó náà ra ohunkohun tí ọkàn yín bá fẹ́, ìbáà ṣe akọ mààlúù, tabi aguntan, tabi ọtí waini, tabi ọtí líle, tabi ohunkohun tí ọkàn yín bá ṣá fẹ́.
Ó ran Israẹli ọmọ-ọ̀dọ̀ rẹ̀ lọ́wọ́nígbà tí ó ranti àánú rẹ̀,
Lọpọ igba ti awọn alaṣẹ pataki bi Aarẹ ba ṣe abẹwo si ipinlẹ Eko ni inira ma a n ba ara ilu nipasẹ sunkere fakere ọkọ ti o ma n tele iru abẹwo bẹẹ.
wọ́n ń gbé Gileadi, Baṣani ati àwọn ìlú tí wọ́n yí Baṣani ká, ati ní gbogbo ilẹ̀ pápá Ṣaroni.
Báyìí ni ọba náà sọ fún bàbá mi, bàbá mi náà sì dúpẹ́ bí ó ti yẹ kí ó ṣe, ó tún ṣe ìlérí pẹ̀lú pé òun yóó lọ si ilé kí òun fi ìmọ̀ràn náà síwájú ìyàwó òun, ìgbà tí àwọn bá jọ rò ó tán òun yóò wáá mú èsì fún ọba, lẹ́hìn èyí, wọ́n kí ara wọn ọba wọ inú iyẹ̀wù, bàbá mi náà sì bọ́ sí ẹ̀hìn òde.
 Ki ipade igbimo amusese ijoba apapo to se yii o to bere.
kẹ́sán án ti yan awọn adari gege bi awon igbimo
Ile ẹjọ ilẹ Amẹrika ti da ẹjọ ti wọn pe lodi si ọmọ Naijiria naa, Olalekan Ponle ti gbogbo eniyan mọ si Woodberry ti awọn ọlọpaa Dubai mu fun iwa gbajuẹ ori ayélujára nu.
si ni o ni awon osise ti o to egberun lona méjìdínlógún lorile-ede
Oríṣun àwòrán, LASEMA O ṣalaye pe awọn meji to mori bọ ninu iṣẹlẹ naa gba itọju lẹsẹkẹsẹ, nigba ti ẹni to farapa ju ti lọ si ile iwosan fun itọju to peye.
”Wọ́n dá a lóhùn pé, “Bẹ́ẹ̀ ni, Oluwa.
N óo máa fi ojurere wo àwọn olóòótọ́ ní ilẹ̀ náà,kí wọ́n lè máa bá mi gbé;ẹni tí ó bá sì ń hu ìwà pípé ni yóo máa sìn mí.
Bí kò bá sí ajinde òkú, a jẹ́ pé a kò jí Kristi dìde.
Ẹ ma dana sun idọti lọna aitọ Oríṣun àwòrán, Getty Images Onimọ naa kilọ pe ki ọmọ Naijiria dẹkun lati maa sun idọti bo ṣe wu wọn nitori eefin rẹ jẹ ọ̀kan lara awọn nkan to n fa ayipada oju ọjọ.
Aare bale si papako ofurufu Nnnamdi
Awọn ololufẹ Cardi B si ti bẹrẹ si ni i ṣe atilẹyin fun un lẹyin iṣẹlẹ naa.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù King Millie: Mo mọ ọsàn hó ní ìyàwó mí ṣe bá mi ṣọrẹ ní kékeré, a sì padà fẹra 11 Owewe 2020 Oríṣun àwòrán, @iKingMillie Yoruba ni ọrọ ifẹ, bii adanwo ni, bẹẹ si ni ifẹ ko mọ olowo abi talaka, bẹẹ ni ko mọ abuda ara.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Obateru Akinruntan: Wíwá ohun tá jẹ títí láé ló gbé wa kúrò nílé Ife Bi awọn kan ṣe n sọ pe agidi lo n fi n lo 'hashtag' naa, ni awọn kan n sọ pe, ko ti ọkan rẹ wa, pe ṣe karimi ni gbogbo rẹ.
Awọn gomina naa lo gbe atẹjade kan sita lẹyin ipade pajawiri ti wọn se lọjọbọ nilu Kaduna, eyi ti gomina Simon Lalong ti Plateau fọwọ si.
Wọ́n ṣèlérí òmìnira fún àwọn eniyan, bẹ́ẹ̀ sì ni ẹrú ohun ìbàjẹ́ wọn ni àwọn fúnra wọn jẹ́, nítorí tí ohunkohun bá ti borí eniyan, olúwarẹ̀ di ẹrú nǹkan náà.
Ẹ wo fidio naa nibi: Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Fídíò òògùn ikọ́ Codeine: Àpọ̀jù rẹ̀ ń ya ọ̀dọ́ ní wèrè Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ọ̀rọ̀ ń bọ́ lóríi fídíò Codeine Òǹyẹ̀ kò leè yẹ èlé owó osù - Ẹgbẹ́ òsìsẹ́ Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Oríṣun àwòrán, Others Dudu Emeka ni awọn ọjọgbọn ni abẹle ti ṣe awọn ogun to le e koju arun naa, amọ ijọba apapọ ko tilẹ fun wọn ni anfaani lati ṣe ayẹwọ rẹ boya ohun ti wọn le lo ni abi bẹẹ kọ.
24 Èbibi 2018 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, T'obìnrin àti t'ọmọde ni wọn ń jigbe kaakiri bayii Ọrọ ti di ojú ni alákàn fi ń ṣọ́rí nipinlẹ Kaduna báyìí lọ́wọ́ àwọn ajínigbé Ọpọ̀ ìgbà ni àwọn oníṣẹ́ ibi ti foju àwọn ènìyàn Brinin Gwari nipinlẹ Kaduna ri èèmọ̀ láti ìgbà díẹ̀ sẹyin.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Kogi Commissioner: Àlàyé rèé bí Kọmíṣọ́nnà ìlera Kogi ṣe bù sẹkùn lórí amóhùnmáwòrán 30 Ọ̀wàrà 2020 Oríṣun àwòrán, channelstv Awọn ọmọ Naijiria ti gba oju opo ayelujara lati tun da si ọrọ kan to n ja wititi lọkan awọn eeyan.
"Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: ""Mo fẹ́ pa ara mi torí ojú àbùkù tí wọn ń fi wò mí pé mo fi iṣẹ́ abẹ bímọ"" Fulani kò leè dúró, táa bá lo ohun ta jogún lọ́dọ̀ àwọn bàbá wa - Sunday Igboho Ọjà Àgbáláta ní Badagry rèé, níbití ẹran ejò ti dùn ju ẹran adìẹ lọ Ọlọ́run yóò ṣe ìdájọ́ nkan tó wà láàrin èmi àti Ireti Ajanaku - Tope Alabi A kò jáde ṣe ìwọ́de ìtagbangba mọ́, inú ọkàn wa lá ti máa ṣe ìfẹ̀hónú hàn - Revolution Now Tekno ti sọ pe fidio naa kii ṣe ipolowo fun ile faaji onihoho kankan."
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Pasuma: Ọ̀gáńlá Fújì ní ominú ń kọ òun lórí ọ̀dá àwọn ìràwọ̀ tuntun lágbo orin Fújì 7 Ẹrẹ̀nà 2020 Oríṣun àwòrán, Wasiu alabi pasuma/instagram Gbajugbaja akọrin Fuji ni, Alhaji Wasiu Alabi ti ọpọ eeyan mọ si Pasuma Wonder, iba wasi baba baraka ti ṣalaye pe ọrọ iyawo nini fun oun kii ṣe afi waduwadu ṣe o.
Ògo ni fún Ọlọrun lókè ọ̀run.
Ti kọmisana ọlọpa Olugbenga Adeyanju si ti ṣe ọpọlọpọ ipade pẹlu awọn ọba, ọdẹ ati awakọ nibi ti iṣẹlẹ yii ti maa n ṣẹlẹ lati ran iwadi lọwọ.
Aisan to le koko ni wọn n gbe lọ ile iwosan ijọba tabi ti akọṣẹmọṣẹ.
Kò lọ́mọ, kò lọ́mọ ọmọ,kò sì sí ẹni tí yóo rọ́pò rẹ̀ ní ibùgbé rẹ̀,láàrin àwọn eniyan rẹ̀.
Àwọn ọmọ Reubẹni ní ìdílé-ìdílé nìwọ̀nyí: ìdílé Hanoku, ìdílé Palu, 
"Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Fulani Heardsmen: Afenifere ní àṣẹ tó bá wu àwọn àgbàgbà agbègbè àríwá Nàìjíríà ni O ni ni tootọ ko si eyikeyi ninu wọn to dide ogun tabi wahala si oun ṣugbọn wọn duro si 'oju opopona marosẹ pẹlu ibọn lọwọ' A yoo ṣe àyẹ̀wò ọpọlọ fàwọn òṣìṣẹ́ FSARS - Iléesẹ́ ọlọ́pàá Bi wọn se pa ọga SARS Àgùnbánirọ̀ akọ̀ròyìn Channels náà ti dágbére fáyé látààrí ìkọlù Shiite l'Abuja Ilé ẹjọ́ sún ìgbẹ́jọ́ Sẹ́nétọ̀ Elisha Abbo tó lu obìrin Gẹgẹ bi alaye rẹ, ""awọn ẹṣọ alaabo to ba mi rin bi awọn eeyan ọhun pe kini iṣẹ wọn loju popo pẹlu ibọn lọwọ?"
Gbajumọ osere tiata naa ni oun ti gbe ninu ile alapa ri, ti iya oun si tun lo akisa lati fi wo oun, ọpọ eeyan si ni ko lee ye igbe aye ti oun ti la kọja sẹyin.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Tinubu, yé é sọ̀rọ̀ abẹ́lẹ̀, bọ́ sí gbangba láti bèèrè àtúntò Nàíjíríà lọ́dọ̀ Buhari - Afẹnifẹrẹ Wo àànfàní ‘Masturbation’, fífún ara rẹ̀ ní adùn ìbálòpọ̀ Wo àwọn ìlànà tuntun ti o gbọdọ tẹlèé rèé ki ó to le wọkọ̀ òfurufú lọ sókè òkun Ìdí ti mo fi da sọ́ọ̀sì rú lásìkò ìgbéyàwó ìyáwó mi tó ló fẹ́ ọkọ míran- Osadebe Àwòráń ọdún Ashura àwọn ẹlẹ́sìn Shiite tí ọ̀pọ̀ ń sọ̀rọ̀ nípa rẹ̀ lórí ayélujára Risikat olójú búlù dí aya Wasiu ní ìlànà Islam, tẹbí tará péjú síbẹ̀ Ó ń bọ̀ lọ́nà!
Lori sisan owo ori, iwadi naa ni ijọba kii gba owo ori pupọ lọwọ awọn eeyan to lowo lọwọ atawọn ileesẹ nla nla, bakan naa lo ni wọn kii jẹ awọn eeyan ati ileesẹ to n sa fun owo ori niya bo se yẹ, ka ma sẹsẹ sọ tawọn eeyan to ko owo ilu jẹ.
Arabinrin  Chege ni awon okunrin n so pe  “Awon obinrin gbodo mo bi won se  maa n  hu
Kii ṣe iroyin tuntun mọ pe aarin Gomina Ipinlẹ Ondo, Oluwarotimi Akeredolu ati Igbakeji rẹ, ko dan mọran mọ.
Bí òun pàápàá bá sì di ọlọ́rọ̀, ó lè ra ara rẹ̀ pada.
Kò ju ìṣẹ́jú mẹ́wàá tí bàbá mi kúrò ní ibi odò náà nígbà tí ó fi aginjù Ìdákẹ́rọ́rọ́ sílẹ̀ tí ó si ja sí ibi kan tí ó tobi tí ó sì tẹ́jú pẹrẹsẹ.
4 Má ṣe sáré púpọ̀ jù tàbí kí o ṣe iṣẹ́ ju bí o ti ní okun lọ àti àwọn ohun èlò tí a pèsè fún ọ láti ṣe ìtúmọ̀; ṣugbọ́n jẹ́ aláìṣemẹ́lẹ́ títí dé òpin.
Opeyemi, lasiko to n dahun ibeere lori eto kan ni ikanni BBC Yoruba salaye pe, ko si ẹni to kọ oun ni iṣẹ tiata rara, akọsẹ ba ni.
N óo máa yọ̀, inú mi óo sì máa dùn,nítorí ìfẹ́ rẹ tí kì í yẹ̀;nítorí pé o ti rí ìpọ́njú mi,o sì mọ ìṣòro mi.
Mò ń sọ nípa àwọn tí wọn ń dẹ́ṣẹ̀ tí kò jẹ mọ́ ti ikú.
  Kódà ibẹ̀ ni wọ́n ti nfọ́ gbogbo òkúta ti wọ́n nlò ní ìpínlẹ̀ Derbyshire káàkiri.
"Iran ti jáwọ nínú ìlù ogun tó n lù -Trump Ijamba baalu pa eeyan 66 ni Iran Àwọn ọmọ Iran yarí mọ́ ìjọba lọ́wọ́ lẹ́yìn tó jẹ́wọ́ọ jíjá bàálù Ukrain lulẹ̀ Ileeṣẹ iroyin Mehr sọ pe ọgbẹni Alqasimehr ni ""Awọn eeyan mẹrindinlogoji lawọn ti ri wi pe wọn lọwọ ninu iṣekupani ọgagun Soleimani."
"Bi igba ti eniyan lọ sile onile ni.
 Ìtọjú fún ẹ ̀ tẹ ̀ paucibacillary ní àwọn egbògi dapsone àti rifampicin fún osù 6 .
Ó tún dúró fún ọjọ́ meje sí i, lẹ́yìn náà, ó tún rán àdàbà náà jáde, ṣugbọn àdàbà náà kò pada sọ́dọ̀ Noa mọ́.
O ni 'mo si wa ninu ẹgbẹ PDP, gbogbo awọn to ba n so mi pọ mọ APC le tẹsiwaju lati maa ṣe ajọyọ titan ara wọn jẹ ninu oṣelu.
Nítorí náà n kò ní gbà yín là mọ́.
Eleyi ti wọn gbagbọ wipe yoo sokunfa ifipo silẹ aarẹ Jacob Zuma.
4m Ọjọ manigbagbe si ni ọjọ Satide, ọjọ Karun osu Kejila ọdun 2020 naa ti eto igbeyawo ọhun, ti wọn pe ni igbeyawo ọmọ ọba waye.
 Ẹ ̀ bùn kọ ̀ ọ ̀ kan jẹ ́ dídámọ ̀ ní pàápàá fún iṣé wọn .
Oríṣun àwòrán, @LASEMA Ọkọ akẹru yii lo wa lọ kọlu ọkọ agbepo bẹntiroo oni lita ẹlẹgbẹrun metalelọgbọn.
 ẹ pa òwe kan tí “ÌFẸ́” jẹ́ jáde nínú rẹ̀.
 Ìtọ ́ jú a má a wáyé nípasẹ ̀ lílo àwọn egbògi bíi rifampicin àti streptomycin .
Oríṣun àwòrán, @pear video Àkọlé àwòrán, Lisa bẹrẹ atunṣe si iyara rẹ lẹyin o rẹyin Ni kete ti Lisa pada sile lẹyin ti ọpọlọpọ miliọnu eeyan ti sọrọ lori ayelujara ni Lisa Li ti bẹrẹ si ni tun iyara rẹ ṣe.
atejade kan ti o fi ranse si awon akoroyin.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Coronavirus Updates: Báwo ló ṣe n tànkálẹ̀ l'Afrika?
Ojogbon Isaac Ajewole, to je minista fun ile ise to n mojuto eto ilera lorile-ede Naijira soro lori igbese akoni ti Naijiria gbe ni kete ti polio be sile ni awon ekun to ba ogun boko haram finra lodun to koja.
Odumosu se amugbooro ijọ rẹ siwaju, to si n fi gbohun-gbohun amohunbugbamu se iwaasu rẹ lẹba ọja Oyingbo, idi si niyi ti wọn se n pe ni Jesu Oyingbo Lọna ati gba awọn ọmọ ijọ tuntun mọra, Jesu Oyingbo maa n waasu iwa irẹlẹ ati igbọran, to si tun maa n na awọn ọmọ ijọ tuntun, ti wọn jẹ ọkunrin ni ina ẹgba mẹsan, lati gba wọn wọ agbo ijọ rẹ, ti ọpọ eeyan miran si gbagbọ pe asiri agbara rẹ ni pasan to jogun lati ọwọ baba rẹ naa, eyi to maa fi n na ọmọ ijọ tuntun, ki wọn ma baa sa lọ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ikogosi-Ekiti: Ilu ti omi tutu ti dapọ mọ gbigbona Iroyin miran ni Jesu Oyingbo lo jogun awọn iwe oogun ibilẹ ti baba baba rẹ kọ ko to ku, awọn iwe oogun ibilẹ bii Iwe iwosan, Iwe Egbogi, iwe isọji ati Ewe nla, ti wọn si ni inu awọn iwe naa ni asiri agbara rẹ wa A tilẹ gbọ pe ọpọ ọmọ ijọ rẹ lo gba pe lẹyin Jesu Oyingbo, ko tun si Ọlọrun miran mọ, ti iwalaye rẹ nigba naa si jẹ ipadabọ Jesu ni ẹẹkeji.
Nígbà náà ni n óo máa yọ̀ ninu OLUWA,n óo sì yọ ayọ̀ ńlá nítorí ìgbàlà rẹ̀.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ọmọ Bàbá Sala: Àwọn ènìyàn fẹ́ran Baba nìtorí apanilẹ́ẹ̀rín ni wọ́n 8 Ọ̀wàrà 2018 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 10 Ọ̀wàrà 2018 Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Fídíò mánigbàgbé nípa ìgbà ayé Bàbá Sala Ọpọ̀lọpọ̀ àgbà ọmọ yorùbá àti àwọn ọ̀dọ̀ yóò ránti gbajúgbajà òṣèré aláwàdà nnì, Moses Olaiya tí gbogbo ènìyàn mọ̀ sí Baba Sala.
Àṣé ọ̀rọ̀ pàtàkì ni orin òwe yìí ńbáwa sọ nígbà kékeré.
Wasiu Alabi Pasuma: Àjàkálẹ̀ àrùn Covid-19 kọ́ mi láti má a ṣọ́wó ná
Ero awọn eeyan lori ẹka BBC Yoruba
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Jude Chukwuka: Wọ́n yóò fi ojú ọlọgbọ́n wo akúrí tó bá sọ ojúlówó èdè Yorùbá Edo àti Kano ni méjìlá, Kwara ni mọ́kànlá, Ebonyi ní ènìyàn tuntun mẹ́wàá, Nasarawa, ni méje, Ogun ènìyàn mẹ́fà, Osun, Delta àti Niger ni èǹìyàn márùn.
Lori ẹsun mẹjọ ọtọọtọ ni adari ẹgbẹ Shiite El-Zakzaky ati iyawo rẹ, Zeenat fi n koju ile ẹjọ eyi ti ijọba ipinlẹ Kaduna fi kan wọn.
Oríṣun àwòrán, @SaifRikiji Iroyin ni ṣe ni awọn eniyan bẹrẹ si ni fariga, ti wọn si n rọ awọn ọlọpaa lati fun awọn ni adigunjale meji to wa ni panpẹ wọn, ki awọn ba le dana sun wọn.
Àwọn ẹṣin wọn jẹ́ ẹẹdẹgbẹrin ó lé mẹrindinlogoji (736), 
London Eye tí wọ́n kọ́ gẹ́gẹ́ bí àmì ẹ̀yẹ ọdún kẹgbẹ̀rúnkejì – ìyẹn ọdún márùndínlógún sẹ́yìn báyìí.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Action Against Hunger: Àwọn òṣìṣẹ́ olùrànlọ́wọ́ képe ìjọba kó gbàwọn lọ́wọ́ ajínigbé 25 Agẹmo 2019 Oríṣun àwòrán, AFP Ijọba orilẹede Naijiria ti bẹrẹ ijiroro pẹlu awọn to ji awọn oṣiṣẹ mẹfa to jẹ ti ajọ alaanu kan gbe lapa ila oorun ariwa orilẹede Naijiria.
O si ti to ọjọ mẹta bayii ti ẹnu ti n kun gomina Ambode pe, oun lo n dọgbọn se agbatẹru eto ipolongo oludije gomina labẹ asia ẹgbẹ oselu PDP, Jimi Agbaje, to si n gbe owo kalẹ fun.
Mo rọ àwọn olólùfẹ́ mi láti ṣe sùúrù lasiko yìí, ẹ jẹ ká bá ara wa sọ̀rọ̀ nínú ìdílé, ká sì ṣe àtúnṣe sì àwọn ohun tó jẹ́ kudiẹ-kudiẹ láàrin wá lákòókò igbele yìí"" Nígbà tó ń ṣàlàyé bo ṣe bẹ̀rẹ̀ ère tíátà, Okunnu ni Ọlọ́run ló kọọ pé òun yóò ṣe ere tíátà."
Olootu ijọba Germany bura fun saa kẹrin
Atanga je okan lara awon elede geesi meji ti won wa ninu isakoso ijoba orile-ede naa, leyin ti Aare Paul Biya ti o ti wa lori alefa fun odun pipe mu atunto ba igbimo amusese re.
O ni wọn n duro de awọn akọṣẹmọṣẹ to n ṣe akọsilẹ bo ṣe maa ri ki a to jọ woo kunakuna.
Oyema gbe ikun irin ti o le mọ́kànlélógóje Kilo(141.
Ẹgbẹ agbesunmọmi Islamic State ti yọ Abu Musab Al-Barnawi, to jẹ adari ẹka IS to wa ni iwọ oorun Afrika, ISWAP kuro nipo.
 isokan afrika je didasile ni 9 july 2002 , lati ropo agbajo okan afrika ( oau ) .
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Bola Tinubu 2023: Babachir Lawal sọ pé APC gbọdọ̀ fààye gba Tinubu láti díje fún ipò ààrẹ 8 Èrèlè 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 24 Ògún 2020 Oríṣun àwòrán, Getty Images Akọwe ijọba Naijiria nigba kan, Babachir Lawal, ti sọ pe dandan ni fun ẹgbẹ oṣelu All Progressives Congress (APC) lati fi aye gba ẹnikẹni to ba fẹ dije fun ipo aarẹ l'ọdun 2023.
Ẹ óo wá mọ̀ nígbà náà pé èmi OLUWA, ni mò ń jẹ yín níyà.
Nítorí pé o kò ranti ìgbà èwe rẹ, ṣugbọn o mú mi bínú nítorí nǹkan wọnyi.
O ṣalaye pe awọn ẹbi yoo maa kede ọjọ ti eto isinku naa yoo waye laipẹ.
 Lasiko re ni awon awuyewuye kan jeyo pe,  ikobi-ara ajo eleto ilera lagbaaye lori aarun Ebola ko ja fafa.
Àkọlé àwòrán, Akọroyin nigba kan ri ni yoo ṣoju APC dupò gomina Kwara Fun idi eyi o ni ,awọn oludije ti igbimọ amuseya ṣe idibo abẹnu fun ti wọn si jaweolubori ni ojulowo oludije ẹgbẹ APC ninu ibo 2019.
Kaduna: Ẹ̀mí tó sọ nú nínú àkọlù àwọn agbébọn pọ̀
"Bi wọn ba fun emi niṣẹ ni UK, maa lọ o.
Kini Aarẹ Buhari wa ri sọ leni lori ọrọ Naijiria?
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Tani otutu ma n mu ju laarin Ọkunrin ati Obinrin?
Ko tan sibẹ o, ajọ naa tun ti gba lati maa lo ọrọ 'Calm Down' gẹgẹ bii ọrọ akọmọna lati maa pẹtu si aawọ.
N ó tọ́jú ilé wa, n o tọ́jú owó ilé wa, n kò ní ná ìnákùná, ki n di ẹni ti ń tú owó baálé mi ká.
85, ti o je iko mokanlelogoji ninu ida ogorun, kere ju ti odun 2017, eyi ti iye re le ogota bilionu Naira N50.
Adaraloye sọ pe Ifeanyi atawọn ẹmẹwaa rẹ fọ ile ọkunrin kan ti orukọ rẹ n jẹ Olayinka Odunniyi, ti wọn si ji ẹrọ ilewo iPhone atawọn ẹrọ ilewọ olowo gọbọi miran.
Aare Buhari  tun so pe ipenija to n dojuko idagbasoke ile  Afirika ko ni dinku niwon igba ti awon eniyan ba si n gbe ni iberu okan ati ifooro emi won.
Ida mẹrin pere owo eto iṣuna lọdun ni ijọba maa n ya sọtọ fun ẹka ilera ni Naijiria.
Wọn pada de si papakọ ofuurufu ti Murtala Muhammed nilu Eko lalẹ ọjọbọ pẹlu ọkọ ofuurufu Buraq Airline ti nọmba jẹ 5A-DMG.
Ẹ̀ ń fọ òde ife ati òde àwo oúnjẹ nígbà tí inú wọn kún fún àwọn ohun tí ẹ fi ìwà olè ati ìwà ìmọ-tara-ẹni-nìkan já gbà.
Awọn eeyan naa ni wọn ko ri ounjẹ ati owo ti ijọba fi ranṣẹ.
Bí ayé bá fẹ́ fún ni l’óúnjẹ
Niṣe ni wọn wa si iyara wọn ti wọn si bẹrẹ si ni tu ẹru rẹ pe awọn ri ogun oloro ninu baagi rẹ tori naa o di dandan ko tẹle wọn.
Rẹgi ni ọrọ yii ni ipinlẹ Ekiti nibi ti ijọ́ba to wa lori oye kede pe awọn yoo da awọn kan ti ijọba ana yọ lẹnu iṣẹ pada ti awọn yoo si mu atunṣe ba eto igbanisiṣẹ ti ijọba ana ṣe.
fi ojo pe Aina, ile-ise Ologun ofurufu lorile ede Naijria ti se gudu gudu meje ,
Èmi Ọba tí wọ́n ń kó jẹ nígboro- Oluwo ti ilú Iwo Ki lo ti ṣẹlẹ sẹyin?
Oun ni ikẹtalelogun ninu ọmọ baba rẹ.
 tohùn-tẹnuè ni bàbá olówó ẹrú wọ inú Ọọ ́ fíìsì agbẹjọ ́ rò ọ ̀ rẹ ́ ẹ rẹ ̀ yìí tí ó sì bẹ ̀ rẹ ̀ sí í bèèrè lọ ́ wọ ́ ẹrú yìí , ìdí tí ó fi fẹ ́ fi òun sílẹ ̀ .
tí mo jẹ́ ikọ̀ fún, bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé wọ́n fi ẹ̀wọ̀n dè mí.
Pe ki Olorun tẹẹ si afẹfẹ rere ni adura gbogbo awọn eeyan ni ileeṣẹ Channels.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ọpọ O gbọdọ ṣiṣẹ lati ile Ijọba maa n sọ fawọn oṣiṣẹ ijọba ati ti adani pe ki wọn maa ṣiṣẹ lati ile wọn lasiko ti iṣede ba wa nilẹ.
Ọdun Ọlọ́jọ́ ṣe pataki si gbogbo ọmọ Yorùbá paapaa àwọn to wa lati Ile Ifẹ to jẹ orisun.
O sọ pe ipinu awọn ọlọpaa naa ni lati ri wipe ẹgbẹ oṣelu PDP koni le ṣe iwọde ti wọn fẹ ṣe loni.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Alao Akala:Èmi àti Ajimọbi kò ṣe ìlérí kankan fún ara wa Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
adari ile-ise olu-ilu Abuja wa kii fun  ayajọ
1) Lọjọ karun un, oṣu kẹwaa, ọdun 2015 ni wọn daa silẹ pe ko jẹbi ẹsun ti wọn fi kan an lẹyin to lo ọdun marun un ati oṣu mẹfa lọgba ẹwọn to n reti idajọ ile ẹjọ.
Erin wo, Ajanaku sun bi oke, eran nla ti lo lomi awon eekan, awon ojogbon atawon agba oje ti ko je ki ede Yoruba ku ti won ko lati je ki asa Yoruba wo ookun niran yii.
OLUWA ní, “Ẹ gbọ́, ẹ̀yin alufaa, ẹ̀yin ni àṣẹ yìí wà fún.
Sugbọn kii ṣe igba akọkọ niyẹn ti ẹgbẹ naa ṣe ikọlu nibẹ.
N óo da ọrọ̀ àwọn orílẹ̀-èdè lé e lọ́wọ́,bí odò tí ò ṣàn kọjá bèbè.
Aba Adeyẹye, ẹni to parọwa yii ni aafin rẹ lasiko ayẹyẹ ọdun isu tuntun tun sọ pe, ti ọwọn gogo ounjẹ ba fi wa nitori ija awọn agbẹ ati darandaran, a jẹ pe a n kọ lẹta ipe fun aisan ni.
 Tunisia – pelu ami ẹ̀gbẹ̀rún le mejila lori tabiliSenegal – ẹgbẹ̀rin le marundinlogbonCongo DR – ẹ̀ẹ́dẹ̀gbẹ̀rin le mokanlaMorocco – ẹ̀ẹ́dẹ̀gbẹ̀rin din mokandinlogunEgypt – ẹgbẹ̀ta le mẹ́rìndínlógójìNigeria – ẹgbẹ̀ta le márùndínlógójìCameroon – ẹgbẹ̀ta le metaGhana – ẹgbẹ̀ta le metaBurkina Faso – ẹgbẹ̀ta din mesanCape Verde Islands – ẹ̀ẹ́dẹ́gbẹ̀ta le márùndínláàdọ́taNi bayii, Ipo ate ajo FIFA miran yoo tun jade lojo ketadinlogun osu karun un odun ti a wa yii.
Ọga agba ọlọpaa kan, Abayọmi Shogunlẹ lo fi ikede naa sita, l'oju opo ikansiraẹni Twitter rẹ.
Agbabọọlu ilẹ Afirika, George Weah to ti di aarẹ orilẹede Liberia bayii nikan ni agbabọọlu ti osi gba ami ẹyẹ yii lasiko to fi n gba bọọlu jẹun fun Monaco lorilẹede France.
O tun wa ro won lati nifee orile ede Naijiria ati awon akekoo ju ife ti ara won lọ.
O sọ pe awọn kan riran si iya oun nigba to loyun pe ọmọ inu rẹ yoo ṣiṣẹ fun Ọlọrun, amọ iṣẹ alfa tabi imaamu ni awọn obi rẹ n fọkan si nitori ẹlẹsin Musulumi ti wọn jẹ lasiko naa.
Posi ree to joko rekete yii, to si yaayi Oríṣun àwòrán, Fellipe Abreu Àkọlé àwòrán, Isẹ aselaagun ni posi kikan jẹ, kii se ẹrọ lo n se awọn posi to jẹ oju ni gbese naa.
Adedimeji ní àdìtú layé, Toyin Abraham sọ pé kò sẹ́ni tó lè táyé lọ́rùn Ṣé ẹ mọ̀ pé Ẹ̀wà Sóyà, Ẹja Puffer, àti ewébẹ̀ yìí lè ṣekú pa'ni kíákíá?
si lo soju agbenusoro ile igbimo asoju-sofin, ogbeni Yakubu Dogara.
metalelogun ni o ti bale sipago iko naa ni papa isere Stephen Keshi Stadium, niluu
N óo máa sọ̀rọ̀ òfin rẹ níwájú àwọn ọba,ojú kò sì ní tì mí.
Ni bayii, orin ti yipada, awon obinrin ti n figa-gbaga pelu awon okunrin, nipa wiwa ise yala ni eka aladani tabi ti ijoba ati awon anfaani miiran gbogbo.
Ọdún kan ni ó kù kí ó jáde.
Inú bí Balaamu gidigidi, ó sì fi ọ̀pá rẹ̀ na kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ náà.
Aláàfin Ọ̀rọ̀ǹpọ̀tọ̀niyùn gbowọ ninu lilo ohun ijagun, o jẹ jagunjagun to da musemuse, oun si ni ọbabinrin to sẹgun ogun awọn ẹya Nupe to maa n da Ọyọ laamu laarin ọdun 1555.
Ni kete ti wọn kẹfin pe abuku wa lara awọn rọba idaabobo wọnyii ni wọn ti n ni kawọn ti wọn ti pin in fun da a pada.
'Nigba ti iya mi ku, lẹyin oṣu meji, dokita ni ẹgbọn mi obinrin, o si pe mi ki n da wa si ileewosan lati ri oun.
Wọn yóo di ẹni ègún, àríbẹ̀rù, àrípòṣé ati ẹni ẹ̀sín láàrin àwọn orílẹ̀-èdè tí mo lé wọn lọ.
Ọpọlọ eniyan a ma a sisẹ bi ago ti o ba n binu nitori wi pe, yoo fi ọkan soju kan lati ri wi pe oun jare gbogbo ọrọ ti oun sọ, eleyi yoo si mu ki o fi gbogbo agbara rẹ sọna kan.
O ma n jẹ awọn nkan bii irẹsi, ẹwa, dodo, o si ma n mumi nigba kan laarin ọsẹ meji.
Ẹ tẹra mọ́ iṣẹ́ Oluwa nígbà gbogbo.
Ahimaasi bá kígbe sókè pé, “Alaafia ni!
Mànàmáná wá bẹ̀rẹ̀ sí kọ, ààrá ń sán, ilẹ̀ ń mì tìtì; yìnyín sì bẹ̀rẹ̀ sí bọ́ sílẹ̀.
Awọn ileeṣẹ baalu si ni yoo san owo ayẹwo naa fun awọn oṣiṣẹ rẹ.
OLUWA yóo ṣíjú àánú wo Jakọbu yóo tún yan Israẹli, yóo sì fi wọ́n sórí ilẹ̀ wọn.
Ẹ wo iye t'óúnjẹ dà báyìí lọ́jà lẹ́yìn tí ìjọba ti ibodè Eku gba ìjọba ní Estonia, ìjọba pàdánù owó gọbọi Ibodè tí a tì ló fa ọ̀wọ́ngógó owó ọjà- Ìjọba Naijiria Àṣírí tú!
Nítori àwọn àtúgbẹ́yẹ̀wò, o níra láti ṣe àkójọpọ fún àwọn ọkọ́ naa Orisun: Johns Hopkins University atawọn ajọ eto ilera ilu Iye akọsilẹ to waye gbẹyin 15 Oṣù Ṣẹ́rẹ́ 2021 20:44 WAT+3 Murder: Alága ẹgbẹ́ NURTW tó gún ọlọ́pàá pá, gba ìdájọ́ ikú Oríṣun àwòrán, Other Ilé ẹjọ́ gíga ti Ikeja n'ilu Èkó tí dá ẹjọ́ ikú fún alaga ẹgbẹ́ awakọ èrò NURTW, ẹ̀ka ti Boundary/Ayetoro nipinlẹ Eko, Saheed Arogundade lórí ẹ̀sùn pé ó pa ọlọ́pàá kan.
Ninu ọrọ tirẹ, Ọba Ewuare pe fun adura lọwọ awọn alalẹ lati gba fun wọn, ki idibo naa lọ ni irọwọrọsẹ.
Oniruuru ọna ni Soyinka maa n gba bu nu atẹ lu iṣejọba Naijiria paapaa awọn to n ṣe ijọba apaṣẹ waa atawọn oloṣelu jagidijagan mii, ọna ọlọgbọn si lo maa n lo eyi to tun lee jẹyọ ninu awọn iwe rẹ nigba mii.
Iléeṣẹ́ BBC fi ètò Aim HIgh"" lọ́lẹ̀ fún àwọn àkàndá ẹ̀dá Ayọ̀ tó ń bẹ nínú orin Jazz- Olakunle Tejuoso Ọmọkùnrin kan sin Baba rẹ̀ láàyè torì pé ó gbàgbọ́ pé oṣó ni!"
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Àìsan ọkàn pa olùdásílẹ̀ sogúndogójì MMM MMM ti kógbá wọlé Arabinrin Oyindamọla sọ pe ''ohun to mu eto yii yatọ si MMM ni pe o ko ni i da owo mi i titi ti o fi gba owo rẹ lọwọ eniyan mẹjọ ti o ba mu wa.
Nígbà tí ọbabinrin Ṣeba rí i bí Solomoni ti gbọ́n tó, ati irú ààfin tí ó kọ́, 
Àpapò̩ ìgbìmò̩ Àjo̩‐ìsò̩kan orílè̩‐èdè àgbáyé s̩e ìkéde káríayé ti è̩tó̩ o̩mo̩nìyàn, gé̩gé̩ bí ohun àfojúsùn tí gbogbo è̩dá àti orílè̩‐èdè jo̩ ń lépa ló̩nà tó jé̩ pé e̩nì kò̩ò̩kan àti è̩ka kò̩ò̩kan láwùjo̩ yóò fi ìkéde yìí só̩kàn, tí wo̩n yóò sì rí i pé àwo̩n lo ètò‐ìkó̩ni àti ètò‐è̩kó̩ láti s̩e ìgbéláruge̩ ìbò̩wò̩ fún è̩tó̩ àti òmìnira wò̩nyí.
Orúkọ ekinni ń jẹ́ Bosesi, ekeji sì ń jẹ́ Sene.
Rẹ́rẹ́ rún nínú ìjàmbá iná Okobaba l‘Eko, ọ̀pọ̀ àwòrán rèé láti mọ̀ bó ti burú tó Ìjàmbá iná míràn tún ṣẹlẹ̀ ní Okobaba l‘Eko àmọ́ kò mú ẹ̀mí lọ Àwọn òǹtàjà kọjú ìjà sáwọn òṣìṣẹ́ tó ń wó ìsọ̀ wọn ní Ketu, ọta ìbọn ba éèyàn kan A ó pe àjọ DSS lẹjọ́ tí wọ́n bá kọ̀ láti tú Sowore sílẹ̀ - Falana Lọjọ Ẹti ni ileeṣẹ aarẹ fidi rẹ mulẹ pe Aarẹ Muhammadu Buhari lo paṣẹ idaduro lẹnu iṣẹ fawọn oluranlọwọ marundinlogoji igbakeji aarẹ Osinbajo.
Matanaya, Bakibukaya ati Ọbadaya, ati Meṣulamu, Talimoni, ati Akubu ni wọ́n jẹ́ olùṣọ́ ẹnu ọ̀nà bodè tí wọn ń ṣọ́ àwọn ilé ìṣúra tí ó wà ní ẹnubodè.
Ta ni ninu wa ló lè gbé inú iná ajónirun?
ni a bá pa ọmọ tèmi jẹ.
Fati Nayo - Dadin Kowa 129.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Premier league: Góòlù Sterling tún gbé Manchester city borí Arsenal lẹ́ẹ̀kansi 17 Ọ̀wàrà 2020 Oríṣun àwòrán, Premierleague.
1 x flag and a Grinding Machine.
Iṣẹ́ ọwọ́ Ọlọrun ni àwọn wàláà òkúta náà, Ọlọrun tìkararẹ̀ ni ó sì fi ọwọ́ ara rẹ̀ kọ ohun tí ó wà lára wọn.
awon eniyan ti o fara kaasa ikolu iko olote agbebon yii, eleyi ti o gbemi,  ti o si tun ba dukia awon alaise je nipinle
Mi ò kọ̀wé fipò sílẹ́ - Osinbajo Oríṣun àwòrán, Profosinbajo/Instagram Igbakeji Ààrẹ Yemi Osinbajo ti fesi si ahesọ ọrọ kan n to tan kalẹ lori ayelujara wipe, o ti binu kọwe fipo sile.
Wọ́n bá lọ, wọ́n sé ẹnu ibojì náà, wọ́n fi èdìdì sí ara òkúta tí wọ́n gbé dí i.
Tabi kí n rí bí ọmọtí a bí ní ọjọ́ àìpé,tí a bò mọ́lẹ̀ láì tíì lajú sáyé.
Ibeere ni Ikemba 1 fọrọ naa beere ni tiẹ.
Nítorí pé ó ti gbọ́ ohùn ẹ̀bẹ̀ mi.
Ẹ̀yin rí àkùkọ kí ó wí pé òun kò ní í kọ?
Baba Ijesha: Afi ki e fọọlu o, bẹẹ ba i le fọọlu, iya laa jẹ yin.
Obinrin ọlọti yi si lo fẹjọ sun Adamu pe Sajẹnti Timothy ko sanwo ọti to mu eyi tii se ọgarun naira.
" Àkọlé àwòrán, Àwọn òsìsẹ́ tó ń gbógun ti òògùn olóró ní Nàíjíríà fi idà yìí han Ruona Meyer, èyítí wọn gbà lọ́wọ́ àwọn amu òògun olóró Iléesẹ́ Emzor pharmaceuticals sọ fún wa pé, òun ti bẹ́rẹ́ ìwádìí lórí Ogbeni Madubuike ati ọ̀nà ti wọn fi ń pín òògùn ikọ́ olómi tó ní èròjà codeine síta.
Sibẹ wọn kò ní gbọ́ràn sí mi lẹ́nu.
Lẹ́hìn náà ni ọba yìí kígbe sókè ní ohùn rara, ó ní, ìwọ alágbára ọkùnrin, ìwọ ọmọ ènìyàn, níhìn-ín ni n ó ti ṣe ìgbéyàwó fún ọ, ọgbọ́n ń bẹ ní àtàrí rẹ, n óò gbé ìyàwó fún ọ nígbà tí ó bá tó oṣù méjì tàbí mẹ́ta lónìí, n óò rànṣẹ́ sí àwọn ọ̀rẹ́ mi jákèjádò inú igbó, n ó sì ránńṣẹ́ sí àjùlé ọ̀run kí wọ́n wáá ṣe àríyá nítorí ọ̀ràn rẹ.
Lati mọ bi ó ṣe ń lọ ẹ maa tẹ̀lé wa níbi Ní bayìí àwọn olùdíje Demola Ogunbanjo ti ẹgbẹ́ òṣèlú ANN àti Adekunle Akinlade ti ẹgbẹ́ APM Gboyega Nasiru Isiaka ti ADC ti wa níkàlẹ̀ bayìí láti gbọ ǹbkan ti àwọn ará ìlú fẹ́ bi wọn.
Eyi waye tori bo ṣe ni iwa ko ṣaa maa ko owo shile meji ti baba rẹ maa n fun gẹgẹ bii owo ti yoo fi ra nkan awọn aburo rẹ meji nigba ti baba wọn ba ti ṣe iṣẹ lọ si Ghana gẹgẹ bii awakọ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù 'God support stealing' fídíò ọlọ́pàá tó n da orí ayélujára rú'?
Bí Satani bá gbé ogun ti ara rẹ̀, báwo ni ìjọba rẹ̀ ṣe lè dúró?
N óo gòkè kọjá ìkùukùu ojú ọ̀run,n óo wá dàbí Olodumare.
Ohunkohun tí ó bá jẹ́ jíjẹ tí ó bá wà ninu ìkòkò amọ̀ yìí, tabi tí omi inú rẹ̀ bá ta sí lára, di aláìmọ́, ohunkohun tí ó bá jẹ́ mímu, tí ó wà ninu rẹ̀ náà di aláìmọ́.
Aare soro yii lasiko eto ayẹyẹ
Ni egbò rírà tí ń rùn bá dà bo àwọn tí wọ́n ní àmì ẹranko náà ní ara, tí wọ́n sì ń júbà ère rẹ̀.
Ọ̀rọ̀ èmi àti Olorì Chanel Chin kò yé ara wa mọ́ nínú ilé- Oluwo IBB tẹ ń pariwo pé ó kú, kò kú o, Ko ko lara ọta ń le- Agbẹnusọ Kassim Ọlọpàá mú ọ̀rẹ́kùnrin Matilda akékọ̀ọ́ fasiti Rivers ti wọ́n gún pa Bakare ni láye òdé oni iyáwo ti a ṣe ni ilé ẹjọ, ni ilé ijosin musulumi àti Kristeni ko ni ìgbàgbọ nínú ko si ǹkan ti yóò tẹyin rẹ̀ jáde ti tọkọtaya ba yẹ adehun ti wọ́n ṣe lọ́jọ́ ìgbéyawó.
Ojú tì wọ́n pupọ wọn kò lè pada sílé.
iroyin ati ikede Garba Shehu niluu Abuja.
Ronaldo ní Tottenham yóò jẹ moyó ìyà lọ́wọ́ Liverpool Ó ṣe f'ọ́mọ tó ń jeérú!
Nítorí náà, ẹ gbọ́ ohun tí OLUWA wí; ó ní, “Wò ó, mò ń gbèrò ibi kan sí ìdílé yìí; tí ẹ kò ní lè bọ́rí ninu rẹ̀; ẹ kò ní rìn pẹlu ìgbéraga, nítorí pé àkókò burúkú ni yóo jẹ́.
 sùgbon léyìn odún díè omo ti ó bà tún kú nì o bá bérè ariwo pé ikú tun to òun léyìn dé ibí yìí .
Àwọn ọmọ-ẹ̀yìn mejila ń bá a kiri.
 o se e se pe, onitọhun lero pe oun ni
Koda bi oludije kan ba ni ibo to pọ julọ nipasẹ araalu, bi awọn igbimọ agba ọjẹ oludibo alaṣẹ yii ba dibo fun alatako rẹ, alatako yẹn ni yoo di aarẹ Oríṣun àwòrán, Getty Images Ẹ maa jẹ ko ru u yin loju, alaye re e.
5 Nítorínáà, bí ìwọ bá béèrè ní ọwọ́ mi ìwọ yíò rí gbà; bí ìwọ bá kan ìlẹ̀kùn a ó ṣí i fún ọ.
Kò sí ìwé ìrìnnà 'VISA' fáwọn ọmọ Naijiria tó hùwà àìtọ́ nígbà ìdìbò Ìtàn tó rọ̀ mọ́ òwe Ẹni tí kò ṣe bíi aláàárù l‘Oyingbo."
Ohunkohun tí ẹ bá bèèrè lọ́wọ́ mi ní orúkọ mi, èmi yóo ṣe é.
Nígbà tí Solomoni rí i bí ó ti ń ṣiṣẹ́ kára kára, ó fi ṣe olórí àwọn tí wọn ń kóni ṣiṣẹ́ tipátipá ní gbogbo agbègbè ẹ̀yà Manase ati Efuraimu.
Ní báyìí, àwọn aláṣẹ fásitì náà ti gbé ìgbìmọ̀ ẹlẹni-márùn ún kalẹ̀ láti ṣèwaàdí sí ọ̀rọ̀ náà.
 Ẹ fojú sọ́nà fún oríkì ọmọbìnrin tí ó fi àpò rẹ̀ bo orí gẹ́gẹ́ bí eégún
Oríṣun àwòrán, @paj1official Àkọlé àwòrán, Lara awọn ti Ọlọrun gba fun ninu iṣe taiata ni Ibrahim Chatta Ọpọ ninu akẹgbẹ rẹ ninu iṣe tiata ni wọn si ba Chatta ṣe ajọyọ ọjọ ibi ọhun.
Lọwọ lọwọ, ofo ni South Africa n mu ninu ṣiṣe ayẹwo o si ti pọwọ lera wọn gan an ni gẹgẹ bi awọn akoroyin ṣe sọ Won ni eyi si ti ba iwulo gbogbo ilana ti wọn n gba ṣe ayẹwo jẹ tori igbe aisowo ti ijọba n pa.
Yahaya Bello lẹ́ẹ̀kan síi ni APC ṣe ní ìdìbò abẹ́lé ní Kogi Ọwọ́ mi mọ́ lórí ọ̀rọ̀ owó Káńsù l'Ekiti - Ayodele Fayose Wọ́n mú ọjọ́ ìgbẹ́jọ́ agbésúnmọ́mí 9/11 tó ṣẹlẹ̀ l'Amẹrika O ṣalaye awọn to n ṣe oogun ibilẹ le tọ awọn olukọ imọ sayẹnsi ni ileewe sọna nitori ''iwe kọ ni gbogbo nnkaa, ọgbọn ori lo ṣe koko.
Awọn aṣoju ijọba tẹlẹri, alabaṣiṣẹpọ ati aladugbo ko gbẹyin lara awọn to karibọnu nile Ajimọbi bayii.
Ohunkohun tí ó bá ti ṣe sí ọ láìdára, tabi ohun tí ó bá jẹ ọ́, èmi ni kí o kà á sí lọ́rùn.
Ṣugbọn nisinsinyii ẹ ti yipada sí olùṣọ́ yín ati alabojuto ọkàn yín.
Ki le fe je sir ?
Jí pátá obìnrin ko jẹ́jọ́ ìpànìyàn - Dolapo Badmos Mi ò tan mọ́ ààrẹ Buhari rárá o!
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: A kò ní fi adé wa sílẹ̀ nítorí Olubadan - Àwọn Ọba 27 Ọpọ̀ èèyàn ní kó mọ pẹ pápákọ̀ ofurufú ń bẹ nílùú Ibadan- Òṣìṣẹ́ Mo rò pé mò ń jà fún Islam ni, ó pẹ́ kó tó yé mi – Boko Haram tẹ́lẹ̀ Èèmọ̀ rèé o, Dókítà yọ eyín 526 lẹ́nu ọmọ ọdún méje Oshiomole, lasiko to n sọrọ nibi ayẹyẹ naa, wa gbarata lori iha ti awọn asaaju oloselu n hu loju ọna mimu agbega ba awọn osisẹ Nigeria, pẹlu afikun pe, awọn ẹgbẹ osisẹ yii gbọdọ mu ọwọ to le lati mu ayipada ba ipo ti wọn wa.
Ǹjẹ́ àwọn alàgbà Keila yóo fà mí lé Saulu lọ́wọ́?
Ó fi kun pé, àwọn ọmọ náà yóò de ìpínlẹ̀ Katsina ni alẹ́ òní pẹ̀lú ìrànlọ́wọ́ àwọn ẹlétò ààbò tí wọ́n yóò wọ́n yóò sì fójú kan ààrẹ.
Ìdí rẹ̀ nìyí tí èmi Paulu fi di ẹlẹ́wọ̀n fún Kristi Jesu nítorí ti ẹ̀yin tí ẹ kì í ṣe Juu.
Ẹ wó gbogbo pẹpẹ wọn lulẹ̀, ẹ fọ́ gbogbo òpó wọn, ẹ dáná sun àwọn ère oriṣa Aṣera wọn, ẹ gé gbogbo àwọn ère oriṣa wọn lulẹ̀, kí ẹ sì pa orúkọ wọn rẹ́ kúrò níbẹ̀.
'A máa ń bẹ́ orí ẹni tó bá gbé imọlẹ̀ ọdún ìjẹṣu tó bá ṣubú ni'
Oríṣun àwòrán, Getty Images O ni otitọ ni pe ijamba ṣe Barca lọwọ Bayern, ṣugbọn ọrọ naa gba ki onikaluluku ronu ọna lati tẹ agbabọọlu Barca siwaju.
O ni awọn ọlọkada ko ni lanfani ati ma gbe eeyan meji papọ mọ, bẹẹ ni awọn ọkọ korope ko ni ma gbe ju eeyan mẹrin lọ; ẹnikan niwaju, ẹnikan laarin ati meji pere lẹyin.
1 265 Orilẹede Fiji 2 0.
Buhari, tọwọ́ ọmọ rẹ basọ- Timi Frank Ọ̀nà wo lowó osù tuntun yóò tọ̀, kó tó dé àpò òsìsẹ́?
Solomoni dáhùn pé, “Bí ó bá jẹ́ olóòótọ́, ẹnikẹ́ni kò ní fi ọwọ́ kan ẹyọ kan ninu irun orí rẹ̀, ṣugbọn bí ó bá hùwà ọ̀tẹ̀, yóo kú.
lati mu idagbasoke ba orile ede Naijiria.
2,242396, ti eyi ti ko yege si jẹ 50,861.
Oríṣun àwòrán, Instagram/Okunnu_1 Nigba to n sọrọ lori ija to maa n waye laarin awọn oṣere tiata to jẹ obinrin, Okunnu ni abuda awọn awọn obinrin ni lati maa ba ara wọn ja, o ni ko si iru rẹ laarin awọn ọkunrin oṣere.
Wéré ló ti tí o sì bọ̀.
Báyìí ni wọ́n sì fi agogo náà sílẹ̀ sí agogo mẹ́rin ọ̀sán fún ọ̀sẹ̀ kan gbáko, kí àwọn ènìyàn baà mọ àsìkò tí Bàbá Eréko fi ayé sílẹ̀ gan an.
NHIS: Ìjọba àpapọ̀ gbé ìgbìmọ̀ ẹlẹ́ni méje kalẹ̀ lórí wàhálà iléeṣẹ́ adójútòfò ìlera
Odumakin wa gba ijọba ni imọran pe o yẹ ko dahun ohun ti awọn eeyan n beere.
s nínú ìmọ ̀ molecular biochemistry àti biophysics lati yale university , ó sí gba oyè ph.
Ọkàn rẹ yóo kún fún ayọ̀,nítorí pé a óo gbé ẹ̀kúnrẹ́rẹ́ ọrọ̀ inú òkun wá sọ́dọ̀ rẹ.
Ko ye ki awon eniyan  to wa ninu ahamo awon olopaa, lo ju wakati mejidinlaadota lo.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù #U20WC-Nàìjíríà,Senegal àti S/Africa ti pegedé fún Poland 2019 9 Èrèlè 2019 Oríṣun àwòrán, @NFF Àkọlé àwòrán, Naijiria ko ti gba ife eye yi ri ṣugbọn wọn ti kopa ninuidije naa nigba mejila.
Ohun ti wọn sọ ni pe ẹri wa wi pe awọn ọmọde kii ko tabi tan arun naa kaakiri.
    Ẹni tí ó dúró sí ipò keje ni ọkùnrin kan ti orúkọ ẹ̀ ń jẹ́ Fìlásayépọ̀ tí o ń gbé filà àràmàdà kiri.
Awọn maalu sediwọ fun ọkọ ofurufu nilu Akurẹ
 Ipinle Kaduna wa lara ipinle to n gbin iresi julo ni Naijiria paapaa awon ti Zazzau.
Àwọn aṣèwádìí ni Imperial College ni London tí wá isopo to wá láàrín bí ó bá ṣe dàgbà sì àti ìdí ti oo fi dé ilé ìwòsàn tí ó bá ní aarun Coronavirus.
Ijoba orile-ede Naijiria ti so pe, ohun yoo salekun owo lati gbogun  aarun kogbogun HIV/AIDS lorile-ede Naijiria, ni iyanju ati mu igberu ba eto-ilera awon ara-ilu.
Iwé ìròyìn Washington Post sàlàyé pé Ismail sọ̀rọ̀ lóri àtẹjáde kan.
Alaga ẹgbẹ́ òṣìṣẹ́ tún sàlàyé pé, atunyàn Chris Ngige sípò mínísítà fún ọ̀rọ̀ òṣìṣẹ́, jẹ́ kó mú ọ̀rọ̀ owó òṣìṣẹ́ ni òkúnkúndùn láti rii pe ó di sísàn.
Bí ó bá wá, n óo dákẹ́, n óo sì kú.
Oríṣun àwòrán, @NGRSenate Àkọlé àwòrán, Saraki ni ọranyan ni iforikori, ifikuluku lori ọna abayọ kuro ninu ikọlu ati ipaniyan lorilẹede Naijiria Ninu ọrọ rẹ, Igbakeji aarẹ Yẹmi Osinbajọ ni Ọkọọkan ọmọ orilẹede Naijiria lo lẹtọ si aabo to peye fun ẹmi ati duki wọn.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Dora Akunyili lo gbe eto Nigeria.
Nítorí náà, fún mi ní òkè yìí, tí OLUWA sọ̀rọ̀ nípa rẹ̀ ní ọjọ́ náà, nítorí pé ìwọ náà gbọ́ ní ọjọ́ náà pé, àwọn ọmọ Anakimu wà níbẹ̀.
Ọdún méjì ní máa fí ṣé àtúnto Nàìjíríà-David Mark Ọmọ MKO Abiọla fi APC sílẹ̀ Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
A kọ wọ́n sílẹ̀ kí ó lè jẹ́ ìkìlọ̀ fún wa, àwa tí a wà ní ìgbà ìkẹyìn.
Bẹ́ẹ̀ ni alufaa yóo ṣe ṣe ètùtù fún ẹ̀ṣẹ̀, OLUWA yóo sì dáríjì í.
Àwọn ọmọ Jedutuni ni wọ́n yàn láti máa ṣọ́ àwọn ẹnu ọ̀nà.
Johanu náà ń ṣe ìrìbọmi fún àwọn eniyan ní Anoni lẹ́bàá Salẹmu, nítorí omi pọ̀ níbẹ̀.
le fi yangan, orile ede to lee fọwọ sọya nipa rẹ.
Àkọlé àwòrán, Titi di asiko yii lati bi ọdun kan o le, àwọ ara Pereira ko ti i bọ sipo.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Adájọ́ fi amòfin tó pá ọkọ rẹ̀ satìmọ́lé títí yoo fi gbàmọ̀ràn 10 Èbibi 2018 Oríṣun àwòrán, Facebook Àkọlé àwòrán, Adájọ fi aya olóògbé Otike sátìmọ́lé lẹ́yìn tó gbádùn nilé ìwòsàn Udeme Odibi yóò wà látìmọ́lé tìtì Adájọ́ Kikẹlọmọ Ayeye yóò fi gba ìmọ́ran tó yẹ fún ìdájọ́ rẹ̀.
Ọbabinrin Ilẹ̀ Gẹ̀ẹ́sì àti Ọmọọba Harry yóò sèpàdé ní Ọjọ́ Ajé Ṣé àsọtẹ́lẹ̀ ìjàmbá iná kò tíì máa ṣe báyìí?
Amọ ṣa, Kunle Afọlayan ti ranṣẹ pada loju opo Instagram pe, oun ko mọọmọ kọ ọrọ naa ati pe, kii ṣe bi oun ṣe lero lo ṣe gbaa.
Ọ̀kan ninu àwọn ọmọ Israẹli mú ọmọbinrin Midiani wọlé lójú Mose ati gbogbo àwọn eniyan, níbi tí wọ́n ti ń sọkún lẹ́nu ọ̀nà Àgọ́ Àjọ níwájú OLUWA.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ronkẹ Oṣodi: Mo kórira ki aya má ni ìtẹríba fún ọkọ nínú ilé Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Ronkẹ Oṣodi: Mo kórira ki aya má ni ìtẹríba fún ọkọ nínú ilé 16 Ògún 2018 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 6 Sẹ́rẹ́ 2019 'òótọ́ ọ̀rọ̀ máa ń korò gan ni f'áwa èèyàn' Gbajugbaja oṣere Yollywood, Ronke Oṣodi Oke ba BBC sọrọ lori pataki ki lọkọ laya bọwọ fun ara wọn.
Ninu gbogbo ọ̀rọ̀ ọgbọ́n ati ìmọ̀ tí ọba bi wọ́n, ó rí i pé wọ́n sàn ní ìlọ́po mẹ́wàá ju gbogbo àwọn pidánpidán ati àwọn aláfọ̀ṣẹ tí ó wà ní ìjọba rẹ̀ lọ.
Àfi ilẹ̀ Goṣeni, níbi tí àwọn ọmọ Israẹli ń gbé nìkan ni yìnyín yìí kò dé.
Lara awọn eekan to kii ku ayẹyẹ ọjọ ibi rẹ ni Mercy Aigbe, Sunkanmi Ọmọbọlanle Làásìgbò òṣèlú wáyé nílùú Ondo, ọ̀pọ̀ èèyàn fara pa Kí ni ọkùnrin yìí ṣe tí bàbá rẹ̀ fi só mọ́lẹ̀ fún ọgbọ̀n ọdún?
Ipinlẹ Eko ni 288, Oyo si tẹle pẹlu 76.
Ó ti bàjẹ́; kò sì wúlò fún ohunkohun mọ́.
Àwọn ará Kalidea jó ààfin ọba ati ilé àwọn ará ìlú, wọ́n sì wó odi Jerusalẹmu lulẹ̀.
Nǹkankan wà láàrin àwọn ẹ̀dá alààyè náà tí ó dàbí ẹ̀yinná tí ń jó.
O ni lái ṣe pe ènikẹni ké si gbogbo àwọn ará ìpínlẹ Ọṣun, gbogbo wọn ló tu síta láti ṣe ajọyọ aṣeyori náà.
Awon Gomina s'agbatẹru fun ọlọpa ipinlẹ
Àṣé àṣírí wà nínú Hijabu tí Aisha Yesufu ń wọ̀ lọ ìwọ́de Ẹ wo èrò bìbà níbi ìwọ́de #EndSARS ní ìlú Ibadan Itan igbe aye Ọba Lamidi Ọlayiwọla Adeyẹmi Kẹta: Ọmọ-Ọba ni Lamidi Ọlayiwọla, nitori inu idile Ọba Alowolodu nilu Ọyọ ni wọn ti bii, baba ati baba-baba rẹ si jẹ Alaafin pẹlu Orukọ baba rẹ ni Ọba Adeniran Adeyẹmi keji, ẹni to wa lori itẹ, ki ijọba to rọ ọ loye nitori pe o n lọwọ ninu oselu sise Ọjọ Kẹẹdogun, osu Kẹwaa, ọdun 1938 ni wọn bi Lamidi Ọlayiwọla, eyi tii se ọdun mejilelọgọrin sẹyin Bi o tilẹ jẹ pe ọmọ ọba ni, sibẹ, wọn ko wo Lamidi kekere ninu aafin Ọyọ gẹgẹ bii ọmọ ọla, ilu Isẹyin lẹba Ọyọ ni wọn ti wo dagba, to si tun lọ sile keu nibẹ.
pọ ́ nna jẹ ́ ọ ̀ rọ ̀ tàbí gbólóhùn kan ṣoṣo tí ó ní ìtumọ ̀ tó ju ẹyọ kan lọ .
Epafirasi, ẹlẹ́wọ̀n ẹlẹgbẹ́ mi nítorí ti Kristi Jesu, kí ọ.
Olootu Ijọba ilẹ Canada, Justin Trudeau lo sọ ọrọ yii pe ijiroro gbọdọ waye lori ọna ti wọn yoo gbe gba ati iye owo ti yoo na wọn fun aṣeyọri igbeṣẹ wọn.
Ṣugbọn ajọ naa ni bibi akanda ọmọ ṣa baa wọ pọ laarin igbeyawo ibatan si ibatan.
Àwọn olówó Naijiria 5 tí owó wọn ju owó ìsúnná Naijiria lọ!
Ta ni mo tà yín fún,tí mo jẹ lówó?
“ ‘Sibẹsibẹ n óo dá díẹ̀ sí ninu yín; kí ẹ lè ní àwọn tí yóo bọ́ lọ́wọ́ ogun láàrin àwọn orílẹ̀-èdè mìíràn, nígbà tí ẹ bá fọ́n káàkiri ilé ayé.
Awọn agbaboolu yii kogoja lati gba ẹbun wura ti ilẹ Afrika lẹyin ọdun mejila ti wọn ti gba a gbẹyin.
Bakan naa , ni iru adura bayii yoo tun maa waye ni ile ijosin awon onigbagbo to wa niluu Abuja lojo Aiku(Sunday), ti n se ojo kẹ́tàdínlọ́gbọ̀n, osu kárùn ún.
Ìjọba àpapọ̀ Nàìjíríà fèsì sí ilẹ̀ gẹ̀ẹ́sì,EU àti Amẹ́ríkà
Sibẹ ofin ara bíbò ṣi wa fun obinrin ni eyi ti obinrin to dimọ Mohammed bin Salman tẹlẹ nitori pe oju rẹ nikan lo han sita ninu ibori to lo.
Gẹ́gẹ́ bí NIPOST ṣe sọ, àwọn ilé iṣẹ́ bi DHL, UPS àti FEDEX tí wọ́n máa ń báni fẹ̀rù ránṣẹ́ sí òkè òkun tàbi gba ẹrù wá láti òkè òkún, yóò maa san ogún mílíọnù náírà, tí wọ́n bá fẹ́ gba ìwé àṣẹ láti bẹ̀rẹ̀ irú ilé iṣẹ́ bẹ́ẹ̀.
Ó gbàgbọ́ pé gbogbo ìgbà lòun ń jẹ́ ọ̀dọ̀ tóun sì ń rẹwà sí i.
Mò ń dàníyàn láti ri yín, kí n lè fun yín ní ẹ̀bùn ẹ̀mí tí yóo túbọ̀ fun yín lágbára.
Ṣe wọ́n bí o ti ṣe àwọn ará Midiani,bí o ti ṣe Sisera ati Jabini ni odò Kiṣoni,
Khafi jẹ ẹbun ọkọ ti ileeṣẹ to n ṣe mọto, Innoson Motors gbe kalẹ fun ẹni to ba gba ipo kinni, ninu idije sisọ ọrọ lori bi orilẹede Naijiria ṣe n wu wọn lori to.
Alaga Ajo eleto idibo lorile ede Naijiria, Mahmood
Ìtumọ̀ eléyìí ni pé wákàtí meji péré ni yóò fi ṣínú, kí irun Maghrib ati Ishai ti yóò sì tún jẹ saari nínú rè!
OLUWA sọ fún Mose ati Aaroni pé, “Òfin àjọ ìrékọjá nìwọ̀nyí: àlejò kankan kò gbọdọ̀ ba yín jẹ oúnjẹ àjọ ìrékọjá.
"O jẹwọ, o ni, ""Mo n darapọ mọ ẹgbẹ buburu."
"Oríṣun àwòrán, Screenshot ""Wọn si tun le ṣe etutu lati mu ki ẹni to ji ọ̀pá da a pada tabi ki ọ̀pá àṣẹ fi ẹsẹ ara rẹ rin wa."
asofin ti won di ni ijoba ibile Oriade,A ti ko awon esi ibo yii lọ si ibi ti
Irú èpè wo ni Aláàfin Aolẹ ṣẹ́ fún ìran Yorùbá?
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Treatment for vaginismus includes psychosexual therapy and relaxation techniques Onímọ̀ nípa ara míìràn ló bi mí wí pé kí ni mo fẹ́ gaan láti dá lára.
Lẹnu ọjọ mẹta yii ni fa ki n fa ti n waye laarin Gomina ipinlẹ Edo, Godwin Obaseki ati Adams Oshiomole.
Lukuluku, ẹni to jẹ irọ̀ awọn alawada bii Baba Suwe lagbo tiata, lo kopa ninu ọpọ ere bii Legal Wife, Ami ọrun, Itunu ati bẹẹ bẹẹ lọ.
Alágbàṣe ni oko Kòkó ti wọn jogún
Awọn adajọ naa sọ pe ẹni ti wọn fi ẹsun kan ti mọ tẹlẹ pe oun ko ni i fẹ ọmọbinrin naa, pẹlu afikun pe ibalopọ to ba waye lasiko ti obinrin ṣi ọkunrin tumọ kii ṣe afinu-findọ ṣe.
Wọ́n kọ ìwé sí gbogbo àwọn Juu ní gbogbo agbègbè mẹtẹẹtadinlaadoje (127) tí ó wà ninu ìjọba Ahasu-erusi.
Ẹ̀kọ́ Nípa Ipò Ọkọ ati Aya sí Ara Wọn.
Ki Èdùmàrè gba olóògbé Ọba Sijúwadé si afẹ́fẹ́ rere.
Akure South Ìjọba ìbílẹ̀ Akure South ló tóbi jùlọ ní ìbílẹ̀ Ondo tí wọ́n sì ní ènìyàn tó dín díẹ̀ ní ẹgbẹ̀rùn okòó-lé-lẹẹ́dẹ̀gbẹ̀ta ti eniyàn oòkó-dín-lọ́ọ̀dúnrún si fọ́rúkọ sílẹ̀ fún ìdìbò.
Aburo rẹ toun funrarẹ jẹ olootu to n gbe ere sinima sita ba BBC sọrọ pe ohun to wa nidi ọrọ yii gangan ni pe ijọba kanlẹ ni nkan lodi si Sarkin Waka ni biko ṣe bẹẹ, ko yẹ ki eyi ṣẹlẹ.
A mu awon afurasi yii nipa ifitonileti lati odo awon eniyan kan.
Oríṣun àwòrán, @NGRPresident Àkọlé àwòrán, Awọn aarẹ igbakanri, adajọ agba igbakanri ati awọn gomina ipinlẹ wa lara Igbimọ olubadamọran to ga julọ lorilẹede Naijiria Ireti wa wipe awọn wahala ipaniyan awọn darandaran fulani yoo kun ara awọn ohun ti ireti wa wipe yoo wa fun ijiroro nibi ipade naa.
7 212812 Orilẹede Algeria 2822 6.
gbogbo àwọn ará Juda pada láti gbogbo ibi tí wọn sá lọ, wọ́n wá sí ilẹ̀ Juda, wọ́n lọ sí ọ̀dọ̀ Gedalaya ní Misipa, wọ́n sì kó ọtí ati èso jọ lọpọlọpọ.
    Èmi ni mo dúró sí ipò kín-ín-ní
Eka ti o n ri si oro-ise lorile-ede America so lojo-Eti pe, eto oro-aje orile-ede America se afikun ipese ise ti o po laarin odun kan abo ninu osu keji odun, laisi akosile awon agbe ti o pese ise ti o le ni odunrun ninu osu to koja.
Àwọn Tíṣà Oyo kó owó tó wà fún àkóso iléèwé jẹ, ni wọ́n fi ń fọwọ́ kọ ìdánwò pẹ̀lú ṣọ́ọ̀kì - Seyi Makinde Ẹ̀yin ṣọ́ọ̀ṣì àti Mọ́ṣáláṣí, mo wọ́gilé ìsìn àṣálẹ́ àìsùn ọdún àti ìṣọ́ òòru - Sanwo-Olu Ohun márùn ún tóo gbudọ̀ mọ̀ nípa ìtàn àti ayẹyẹ ọdún Kérésì Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Mo kàn máa ń lọ́ ayẹyẹ kiri torí ijó láì ṣe pé wọ́n pe mí ló sọ mí di DJ olórin Fuji nìkan' Muyiwa ni oun ṣeleri pe oun yoo to gbera kuro lori akete aisan ti awọn yoo si jọ ṣe igbadun ọdun 2021 papọ.
Sisunmọ ibi ti alaisan Covid 19 wa ko tumọ si ohun tawọn eeyan n ro nigba mii.
Àṣìlò òògùn ikọ́ olómi tó ní èròjà codeine nínú máa ń fa ki kíndìrín bàjẹ́, gìri, ọpọlọ dídàrú àti orí yíyí.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ilu gangan: O jẹ́ atọ́nà fún Alaafin àti àwọn ara ilu- Rahman Wahab Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Ilu gangan: O jẹ́ atọ́nà fún Alaafin àti àwọn ara ilu- Rahman Wahab 26 Èrèlè 2018 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 24 Agẹmo 2020 Ọtun onilu Alaafin Ọyọ ti salaye awọn ohun to rọ mọ ilu gangan Bakan naa lo tun sọ isẹ ti ilu ọhun n se ati awọn iwulo rẹ fun Alaafin ati awọn ara ìlú paapaa ni kikun.
Wọn óo rí ògo OLUWA,wọn óo rí ọlá ńlá Ọlọrun wa.
Ojogbon Yemi Osinbajo  tun wa tesiwaju pe ,ijoba orile ede Naijiria
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Obasanjo: Eré ìtàn nípa ìbí, àti jéèyàn pẹ̀lú ìpèníjà Olusegun Aremu Obasanjo Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Obasanjo: Eré ìtàn nípa ìbí, àti jéèyàn pẹ̀lú ìpèníjà Olusegun Aremu Obasanjo 5 Ẹrẹ̀nà 2020 Bi a ba pori akọni nṣe laa fi ida lalẹ gaaraga.
#7000 sí #10000 ni owó àbẹ̀tẹ́lẹ̀ fún bẹẹdi ní ilé àwọn aláìsàn ọpọlọ Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí 3 sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 2:23 Fídíò, Water Generator: Ó leè ṣiṣẹ fún wákàtí mẹfà, kó tó sinmi, Duration 2,2310 Òkùdu 2020 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
Tabili mẹrin kan tún wà tí wọ́n fi òkúta gbẹ́, tí wọn ń lò fún ẹbọ sísun.
Nitori ki BBC Yoruba ma baa jẹ agbẹjọ ẹni kan da to jẹ agba oṣika ni wọn ṣe kan si aya Wolii naa ko sọ iha ti ẹbi wọn lori idajọ naa.
Mo fẹ́rẹ̀ má tíì kúrò lọ́dọ̀ wọn,ni mo bá rí ẹni tí ọkàn mi fẹ́.
Ọba fi Bẹnaya jẹ balogun rẹ̀ dípò Joabu, ó sì fi Sadoku jẹ alufaa dípò Abiatari.
Wọ́n dá a lóhùn pé, “Rárá o, oluwa mi, oúnjẹ ni àwa iranṣẹ rẹ wá rà.
Àwọn aṣofin Nàìjíríà fẹ̀sùn kan Ọṣinbajo lórí ọ̀rọ̀ NEMA
Falz f'ohùn lẹ̀ fún PDP, APC, MURIC, àwọn ọmọ Yahoo
Eyi ko sẹyin bi ọwọ àwọn olopaa ti tẹ afurasii yii tí wọn sì ti gbé lọ sí ilé ẹjọ́ lónìí.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Somalia: 'Wọ́n pàṣẹ fún mi láti dá Ramla dúró ká tò lè ṣe igbeyàwó' Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Somalia: 'Wọ́n pàṣẹ fún mi láti dá Ramla dúró ká tò lè ṣe igbeyàwó' 11 Bélú 2018 Ọpọlọpọ ọdun ni Ramla Ali fi n kan ẹ̀ṣẹ́ ni kọ̀ọ̀rọ̀ ki ọgbọ́n ọkọ rẹ to fún un ni ominira si gbangba.
Lakotan ofin naa yoo ṣeranwọ fun abo orilẹede yoo si ri si igbesẹ ọdaran kankan to ba su yọ latari ẹka to n gba awọn eeyan laye lati lọ bimọ ni Amẹrika.
'Sẹ́nétọ̀ Abiola Ajimobi wà lọ́run rere' A ṣ sùúrù tó, ọmọ wa ló gbọ́dọ̀ jẹ́ ọ̀gá fásitì Ibadan lọ́tẹ̀ yìí - akóríjọ́ ẹgbẹ́ ọmọ Ibadan Kí ló dé tí Shoprite fẹ́ kógbá kúrò ní Nàìjíríà?
OLUWA, o óo gbọ́ igbe àwọn tí a nilára;o óo mú wọn lọ́kàn le,o óo sì dẹ etí sílẹ̀ sí igbe wọn
Orúkọ odò kẹta ni Tigirisi, òun ni ó ṣàn lọ sí apá ìlà oòrùn Asiria.
Fi ẹnu wọn ko ara wọn, kí wọ́n di igi kan lọ́wọ́ rẹ.
Aare Muhammadu Buhari to n tuko orile-ede Naijiria ti parowa fawon eniyan Naijiria lati tubo ni ifarajin fun ile baba won lasiko yii.
Oun ni won gba pe o je iya fun okan Eritrea to je asaaju fawon obinrin onkorin nile Adulawo lati opolopo odun seyin.
Ṣugbọn awọn sẹnẹtọ lati apa ariwa orileẹde Naijiria, ti wọn tun jẹ ọmọ ẹgbẹ oṣelu APC ni ki ile tẹsiwaju lati buwọlu orukọ awọn ti Aarẹ Buhari fi ranṣẹ sile.
Bakan naa ni Victor Boyle naa gbe imọ ẹrọ jade ti yoo ma se atunlo awọn nkan ti awọn eniyan ko lo mọ lati gbe ohun ara ọtọ jade.
“Egbe oselu PDP ko le nkankan miiran ju ki won o maa wa agbara lo ni gbogbo ona.
Nigba ti BBC bi Deji leere o ni oun ṣeeṣi gún ìyàwó oun àkọ́kọ́ pa nítorí #450,000 ni.
] Àmọ́ ṣá, ó ní àṣẹ ìjọba tí ó fi ààbò bo àwọn ilé àjogúnbá, àwọn agbèfúnjọba ti agbègbèe Rajdhani Unnayan Kartripakkha àti Àjọ Ìlúu Dhaka kò ṣe ohun tí ó yẹ kí wọn ó ṣe.
" Nigba to n sọrọ lori ẹgbẹ awọn osere ori itage TANPAN ati eto iranwọ to n fun awọn agba ọjẹ ninu ẹgbẹ, Fabiyi ni o ṣe ni laanu pe ko si ọmọ ẹgbẹ naa to n san owo sinu ẹgbẹ, ti wọn ko si pọn omi silẹ de ongbẹ.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Àwọn arẹwà obinrin Yollywood, tá ló mọ iṣẹ́ rẹ̀ jù?
won wa woroko fi sadaa lori eto aabo, ni eyi ti gbogbo omo orile ede Naijiria
Ohun tó yẹ kóo mọ̀ nípa Fásitì Babcock rèé Oúnjẹ márùn-ún tó lè ṣekú pa'ni kíákíá Uganda kó rọ́bà ìdáàbòbò mílíọ̀nù kan kúrò ní ìlú Lisabi Agbongbo Akala rèé, ẹni tó fi ìfẹ́, ìṣọ̀kan àti ìrẹ́pọ̀ gba ilẹ̀ Ẹ̀gbá lọ́wọ́ ìmúnisìn Ọkọ̀ òfurufú kékeré òun lo dédé já lulẹ ni kété to gbéra ni pápákọ̀ òfurufú ni owúrọ ọjọ aikú, ìdí ti ọkọ náà fi já lulẹ̀ kò ti yẹ ẹnikẹni titi di àsìkò yìí.
 Emi fun ra mi ti sabewo si papako ofurufu ti Nnamdi Azikiwe nilu Abuja lati wo bise ayewo naa se n lo si”.
Ajọ to n risi wiwo oju ọjọ, NIMET sọ pe ojo arọọrọda ọdọọdun maa n fa omiyale, agbara ya sọọbu.
O ni ohun to ṣẹlẹ ni pe awọn oṣiṣẹ awọn ni ko tan ina naa silẹ ki wọn to lọ sile nitori konileogbele to wa lode nipinlẹ Eko eyi ti ijọba Eko kede lọjọ iṣẹlẹ yii gangan.
Umar gbe igbesẹ naa lẹyin ti agbẹjọro fun ijọba, Aliyu Umar fi ọwọ si wi pe ọna ti wọn gba fun agbẹjọro agba Walter Onnoghen ni iwe igbejọ ko tọna rara.
Ó dájú pé ọkunrin yìí kò ṣe nǹkankan tí ó fi yẹ kí á dá a lẹ́bi ikú.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Apocalypse: Ìgbà mọ́kànlá tí ayé ò bá ti parẹ́ 21 Òkùdu 2020 Oríṣun àwòrán, EMMANUEL DUNAND Àkọlé àwòrán, Awọn to n ṣewọde mlẹyin ti Harold Camping ni aye yoo parẹ lọdun 2011 Ọjọ ti pada kọja bayii ti onkọwe kan, David Meade sọ asọtẹlẹ pe aye yoo parẹ ni ọjọ kẹtalelogun oṣu kẹsan ọdun 2017.
Aworan fidio to n ja ranyin kaakiri ṣe afihan awọn onijanduku ti wọn gbe ọpa aṣẹ ọba naa, ti wọn si n salọ.
Bẹ́ẹ̀ ni ọba ati gbogbo àwọn ọmọ Israẹli ṣe gbé àpótí ẹ̀rí OLUWA wọ Jerusalẹmu, pẹlu ìhó ayọ̀ ati ìró fèrè.
Opolopo oju popo la se lati Abuja lo si Port Harcourt, Benin si Onitsha ati bee bee lo.
Ààrẹ Buhari tẹ́wọ́gba àbá lórí ẹ̀kúnwó owó oṣù òṣìṣẹ́ Ìròyìn tó ń tẹ̀ wa lọ́wọ́ sọ pé Ààrẹ orileede Naijiria Muhammadu Buhari ti tẹwọgba àbá ẹkunwo owó oṣù òṣìṣẹ́ ti igbimọ to ṣiṣe lori rẹ jabọ fun un l'Abuja.
O lè tọ àwọn onímọ lọ, o lé ba dokita sọrọ tàbi ki o darapọ mọ àwọn ẹgbẹ́ fun ìrànwọ́ lọ́wọ́ àwọn ti wọ́n ti koju isoro kan náà láti ràn ọ lọ́wọ́ Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?"
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù School reopening: Ìjọba ìpínlẹ̀ Rivers kéde ọjọ́ tí àwọn iléèwé yóò wọlé padà 31 Ògún 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 26 Owewe 2020 Oríṣun àwòrán, Google Ìjọba Katsina ní kí àwọn iléèwé ṣì wà ní títìpa nítorí àrùn Coronavirus Ijọba ipinlẹ Katsina ti sọ wi pe ileekọ alakọbẹrẹ ati girama ko tii le wọle pada ni asiko yii ni ipinlẹ naa.
Idahun: Isọri owo oṣu N-power ree loṣu: N-Power Teach: ₦28,000 - si ₦30,000 loṣu.
Dafidi kó gbogbo ọmọ ogun rẹ̀ jọ, ó pín wọn ní ọgọọgọrun-un (100) ati ẹgbẹẹgbẹrun (1,000), ó fi balogun kọ̀ọ̀kan ṣe olórí ìsọ̀rí kọ̀ọ̀kan.
Ẹnìkan kò rí mi kí n máa bá ẹnikẹ́ni jiyàn ninu Tẹmpili.
Oṣu Keje, ọdun 2019 ni awọn agbebọn ṣekupa Funke Olakunrin nipinlẹ Ondo.
N'jie de lade ni isẹju kẹrinlelogoji fun Cameroon Ni abala Keji,Odion Ighalo da goolu kan pada ti o fi di 2-2.
Bẹ́ẹ̀ ni Jehu ṣe pa ìsìn Baali run ní Israẹli.
Ògo OLUWA Kúrò Ninu Tẹmpili Náà.
Ẹgbé agbábóólù orílẹ-èdè Naìjíríà gba ẹbuǹ wúrà ilẹ Afrika Kìí ṣe gbájúẹ̀ nìkan lọmọ Nàìjá ń ṣe lókè òkun!
gege bi awon akoroyin kan se n sọọ kaakiri.
Awọn ajinigbe ti ji olukọ agba fasiti Ọbafẹmi Awolọwọ to wa nilu ile Ifẹ kan, Ọjọgbọn Yinka Adegbehingbe gbe.
Eyi ni igbesẹ ti ile igbimọ aṣofin agba gbe bayii gẹgẹ bi ọna ati mu awọn to ba ru ofin to ni ṣe pẹlu ibalopọ lawọn fasiti orilẹ-ede Naijiria.
O ni ẹmi gigun, o ni alaafin, Ọ́ba Adeyemi tun lowo, o lọla, o ni gbajumọ, bakan naa lo n sọla ni agbala rẹ pẹlu awọn orekelẹwa obinrin, to si tun jẹ alayelugba ti awọn ọba ẹgbẹ rẹ n wari fun.
Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Vaccine rumours debunked: Àwọn ìròyìn òfegè nípa abẹ́rẹ́ àjẹsára Covid-194 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 11:29 Fídíò, EndSARS: Olatunde Abolarinwa London Tailor ní òun á ṣe baba fún mi, kò tilẹ̀ dúró ṣe bàbá àwọn ọmọ tirẹ̀ tóríi ìwà Ọlọ́pàá Mopol, Duration 11,295 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Obìnrin gbọdọ̀ ṣe ara wọn lọ́kan láti gba ara wọn sílẹ̀ lọ́wọ́ ìfìyàjẹni - Olùdásìlẹ̀ ẹgbẹ́ FIN Ṣọ́ra fún ìgbín inú omi, àrùn ‘Schistosomiasis’ ti ń bá ìjọba ìbílẹ̀ mẹ́fà l‘Eko jà Sinimá oríta, àwòòtán.
Ọba sọ fún un pé kí ó máa lọ sí ilé rẹ̀.
Iye awọn eeyan to ṣẹṣẹ ko arun naa ni ipinlẹ kọọkan ree: Gombe-73 Eko-68 Kano-46 Edo-36 FCT-35 Nasarawa-31 Kaduna-17 Oyo-16 Abia-15 Delta-13 Borno-13 Plateau-8 Niger-7 Rivers-7 Enugu-6 Ogun-6 Kebbi-3 Ondo-1 Anambra-1 Imo-1 Èèyàn 501 ló lùgbàdì àrùn Coronavirus ní Naijiria ní Ọjọ́ Abámẹ́ta Eeyan 501 tuntun mii lo ṣẹṣẹ lugbadi arun Coronavirus ni Naijiria.
Bakan naa lawọn dokita n ja fun aabo to peye lẹnu iṣẹ ati eto adojutofo fun wọn.
Ó ń tu àwọn tí ọkàn wọn bàjẹ́ ninu,ó sì ń dí ọgbẹ́ wọn.
Bí àwọn meji yìí ti ń kúrò lọ́dọ̀ Jesu, Peteru sọ fún un pé, “Ọ̀gá, ìbá dára tí a bá lè máa wà níhìn-ín.
Eliṣama ọmọ Amihudu ni olórí wọn.
Ida meta ninu ogorun un awon omo orile ede naa ti iye won le ni milionu kan lo n gbe ninu osi.
"A jọ n ṣe awada, a jọ n jo nibẹ ni"" O ni Oriṣabunmi n wu ikọ, ko lee mi daadaa."
Arsenal fa Chelsea ya pẹ́rẹpẹ̀rẹ gba ife FA Cup
Awọn iya isalẹ wọnyi a si maa dunkooko mọ wọn lori foonu pe wọn ko gbọdọ ṣalai sika adehun ti wọn sẹ.
Bí Jesu ti ń dàgbà, bẹ́ẹ̀ ni ọgbọ́n rẹ̀ ń pọ̀ sí i, ó sì ń bá ojurere Ọlọrun ati ti àwọn eniyan pàdé.
Gbà ninu ẹ̀jẹ̀ akọ mààlúù náà, kí o fi ìka rẹ tọ́ ọ sí ara ìwo pẹpẹ, kí o sì da ìyókù rẹ̀ sí ìsàlẹ̀ pẹpẹ.
yii to pari, nitori naa, mo fẹ rọ gbogbo eyin asofin ki ẹ gbaradi lati se ayẹwo
Nisinsinyii, ẹ lọ sí ilé mi ní Ṣilo, níbi ìjọ́sìn mi àkọ́kọ́, kí ẹ sì wo ohun tí mo ṣe sí i, nítorí ìwà burúkú Israẹli, àwọn eniyan mi.
Wo bí àwọn ọmọ yìí ti ń ṣe é Nitori pe BBC Yoruba ko fẹ ki ede Yoruba parun ni aṣe jade lọ beere ami ori ọrọ Konko-jabele lọwọ awọn eniyan.
 Aare so pe : ‘‘ A nilo atileyin yin, paapaa julo
Ẹni to jawe olubori lọdun to kọja, Joshuna Kipkorir lo se ipo keji ni ipele awọn ọkunrin lati ilẹ Ethiopia.
"Wo ọ̀rọ̀ Fani-Kayode sí akọ̀ròyìn ""blog"" tó ní lílù ìyàwó rẹ̀ bíi bàrà ló mú wọn túká Wo nkan tó yẹ́ kí o mọ̀ nípa òfin tuntun tí ìjọba Nàìjírià gbé síta nípa akáǹtì rẹ̀ ní báńkì Ohun méje tí Jimoh Aliu fi yàtọ̀ lágbo tíátà Inú mi dùn lórí òfin títẹ àwọn àfipábánilòpọ̀ ní ọ̀dá - Foluke Daramola Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Búrẹ́dì tí wọn ó fi jẹ ẹ̀wà ni wọ́n lọ rà ni wọ́n pàdé ikú gbígbóná' Ni oṣu keji ọdun yii ni igbẹjọ bẹrẹ lori ẹsun ijọmọgbe ati igbimọpọ hu iwa ijọmọgbe ti wọn fi kan awọn meje naa."
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ẹgbẹ́ agbábọ́ọ̀lù ilẹ̀ Gẹ̀ẹ́sí dé ìpele tó kángun sí àṣekágbá nínú ìdíje ife ẹ̀yẹ àgbáyé fún ìgbà àkọ́kọ́ ní ọdún méjìdínlọ́gbọ̀n Agbaọjẹ agbabọọlu Cristiano Ronaldo to jẹ ọmọbibi orilẹede Portugal gba ayo mẹrin sawọn ki orilẹede naa to lọ'le lati Russia.
Kò ní le kúrò níbẹ̀ lọ sí ibìkankan.
Aare tun salaye ninu ate twitter re  lojo Aiku peAare  @M.
Congress (APC) ti tun jawe olubori ninu eto idibo to waye ni ọjọ Abamẹta yii,
Ogundare ni awọn janduku naa pọ biba, ti wọn si to ẹgbẹrun meje, eyi to mu ki apa awọn osisẹ ọgba ẹwọn naa ma ka wọn.
Jakọbu bá bẹ̀ ẹ́, ó ní, “Jọ̀wọ́, sọ orúkọ rẹ fún mi.
"Oríṣun àwòrán, @___FAREED ""A ti ran awọn osisẹ wa to mọ nipa ado oloro lọ sagbegbe naa lati se tọpinpin isẹlẹ naa."
"Wọn sọ pe ""ọrọ omugọ lasan ni sisọ pe ayelujara 5G ni nkan ṣe pẹlu COVID-19."
Gbajugbaja oṣere to tun jẹ ọkan gboogi ọga lọga lagboTiata nile ati lẹyin odi, Ọjọgbọn Ayo Akinwale ti bẹrẹ irinajo rẹ lọ sọrun.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Aretha Franklin kọrin fun bi aadọrin ọdun Tẹru-tọmọ lo fẹran olorin naa ni orilẹede Amerika ati gbogbo agbaye.
Ó fi àwọn alufaa kan sibẹ, láti máa ṣe iṣẹ́ alufaa ninu àwọn ilé ìsìn tí ó kọ́ sibẹ.
O tun so pe ”Iko omo oogun olote tun fe ko ara won jo si eyin odi ilu naa, sugbon nigba ti omo- oogun ofurufu orile ede yii tun bere si n yin ibọn lu won lati inu oko ija oogun ofurufu naa ,ti opolopo won ku, ti awon miiran si farapa yanna-yanna, ni awon yooku ba salo.
Ileesẹ ọlọpaa ti wa kesi awọn olugbe ipinlẹ Eko lati dide tako iwakiwa to nii se pẹlu iwa ọdaran nitori iwa gbigba kamu si ohun to lewu kọ ni ọna abayọ sawọn iwa ọdaran bii iru eyi.
CBN: Kò sí owó tó sọnù ní banki àpapọ̀ Naijiria
Bi awọn kan ṣe n gboriyin fun igbesẹ yii ni awọn kan gbagbọ pe yoo da iwa ifiyajẹni ati inilara to googo laarin awọn oṣiṣẹ SARS pada saarin ilu.
Ó gbà wọ́n níyànjú, ó sì dágbére fún wọn, ó bá lọ sí Masedonia.
Ìṣẹ̀lẹ̀ Èkó: Aáwọ̀ Ọbàkan sọ ilé di áláwọ̀ méjì
N óo fọ́nnu nípa irú ọkunrin bẹ́ẹ̀.
O maa n lefo lori omi ninu awo igbọnsẹ o si le jẹ ki idi maa dun eeyan bi eeyan ba n ya iru rẹ ni gbogbo igba.
Mo gbadura sí OLUWA Ọlọrun mi, mo jẹ́wọ́ ẹ̀ṣẹ̀ àwọn eniyan mi.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Coronavirus Vaccine: Ṣé abẹrẹ àjẹsára ti wà fún àrùn COVID-19?
Wọ́n tẹra mọ́ ọ̀nà ẹ̀tàn Balaamu nítorí ohun tí wọn yóo rí gbà.
Ile-ise ologun ile Naijiria ti sọ wipe ko si otitọ kankan ninu iroyin naa.
O sọ fun akọroyin BBC, Mobeeb Azar, lasiko ifọrọwerọ kan pe, awọn anfaani bayii lo n fun ni: O ma n din aarẹ ara ku lati fun ara ni isinmi O ma n din ibẹru tabi aya jija ku O ma n ran awọn obinrin lọwọ lati ni imọ nipa ẹya ara wọn, ati nkan to le fun wọn ni adun ibalopọ O tun jẹ ọna lati ṣamulo ominira, nitori pe kii ṣe atọwọda Bakan naa ni Dokita kan ni Naijiria,Chidinma Njoku, sọ pe: 'Masturbation' jẹ ọna ti eeyan le gba kọ ẹkọ nipa bi agọ ara rẹ ṣe ri Ko si ibẹru oyun nibẹ Ko fi bẹ ẹ si ewu lati ko arun ibalopọ O ma n jẹ ki awọn to n ṣe e sun daadaa Fun awọn obinrin kan, o ma n din irora ku fun wọn lasiko ti wọn ba n ṣe nkan oṣu Amọ Njoku fikun pe gbogbo nnkan to n dan kọ ni wura, ninu ọrọ titẹ ara ẹni lọrun fun ibalopọ.
Nítorí náà, ẹ̀yin ọmọ ènìyàn, ẹ kíyè sí ọ̀nà yín.
BBC News Yoruba kan si agba oṣere naa to si fi ye wa pe igbagbọ oun ni pe ẹgbẹ awọn oṣere n gbe igbesẹ lori ọrọ oun.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Footballers: ìkà láwọn aṣojú agbábọ̀ọ̀lù míì lágbàyé Pẹlu omi ẹkun loju ni Theresa May fi ṣe ikede yii ni eyi to fidi aṣayan ọrọ Yoruba mulẹ pe ko si agbara ti ẹnikẹni le sà ju ti ẹni to juni lọ.
"Eyi si ni yoo kọkọ yọwọ atilẹyin wọn kuro lara awọn foonu ti oloyinbo n pe ni ""Windows Phone"" to n lo ilana iṣiṣẹ atijọ iyẹn operating system (OS)."
Amọ saa, aba ofin tuntun yi ko kan awọn ti wọn ba di ipo oselu tabi ti ijọba mu ti wọn ko si gba owo kankan fun ipo ti wọn di mu.
Ìfẹ́ ọkàn wa ni pé kí olukuluku yín fi ìtara kan náà hàn, tí ẹ fi lè ní ẹ̀kún ìrètí yín títí dé òpin; 
Yatọ si Dino Melaye, oludije miiran labẹ asia ẹgbẹ oṣelu PDP,Abubakar Suleiman naa gba fọọmu lati dije dupo ninu idibo Gomina ti yoo waye lọjọ Kẹrindinlogun oṣu Kọkanla.
Tí ẹ bá níláti jìyà, kí ó má jẹ́ gẹ́gẹ́ bí apànìyàn, tabi olè, tabi eniyan burúkú, tabi ẹni tí ń tojú bọ nǹkan-oní-nǹkan.
ri si wiwọle ati jijade lorile ede Naijiria,(Nigeria Immigration Service)ile-ise
Abileko Hauwa Musa to je oludari  egbe alajeseku naa lo so eyi di mimo nilu Abuja.
"Tinubu fọrọ naa lede nigba to kẹyin si awọn ẹgbẹ kan t'orukọ wọn n jẹ ""Asiwaju Reloaded Ambassadors."
O ni eyi atawọn iṣẹlẹ miran lo faa ti oun fi woo pe ko yẹ ko ri bẹ ti oun fi ni asiko to lati kọrin O to gẹẹ.
ọrọ aje orilẹede naijiria ko tii duro to lati gbe ojuse ti orilẹede Naijiria fẹ gbe lori adehun naa.
Iroyin ti a gbọ ni pe awọn ọlọpaa ẹkun naa ti kọkọ faake kọri pe awọn ko ni ayẹwo kankan lati ṣe.
Ọjọ Kerinla oṣù Karun ọdun 1985 si ni wọn ṣe ifilọlẹ rẹ.
Amọ pẹlu akitiyan rẹ, awọn kan lara wọn di ọba to n de ade ilẹkẹ, ti wọn si gba igbega lori igbelewọn awọn ọba nipinlẹ Ọyọ, ati ni awọn ipinlẹ bi Ọṣun ati Ondo.
"O ni ""agbẹjọro abi agbohunsafẹfẹ ni n ko ba jẹ, ka ni n ko ba baba mi ṣe iṣẹ tiata, nitori lẹyin ile ẹkọ girama ni wọn ti ṣe iwuri fun mi lati maa kopa ninu ere ."
Ìrìbọmi ni èmi ń ṣe fun yín ṣugbọn òun yóo fi Ẹ̀mí Mímọ́ wẹ̀ yín mọ́.
Àwọn ọmọ rẹ̀ sì wí fún un pé olóko pàápàá ti pinnu láti wá ṣíṣẹ́ rẹ̀ ni ọjọ́ kejì.
Koda ọga ọlọpaa DPO ṣalaye fawọn akọroyin pe akẹkọọ igba lo ti pada si ileewe naa lẹyin ti wọn ti sa sinu igbo lati alẹ ọjọ Ẹti.
Ó wí fún un pé, “Lọ bọ́jú ninu adágún tí ó ń jẹ́ Siloamu.
Aare Alassane Ouattara yoo yan awon asofin metalelogbon yoku.
Ó bá gbé ọwọ́ ọ̀tún rẹ̀ lé mi.
Igboho gbọnmu lori iwa aidaa ti awọn eeyan naa n hu si loju opo Instagram rẹ ninu fidio kan to ju sibẹ lọjọ Aiku.
" Bí ètò ọ̀rọ̀ ajé ìlú ṣe ń padà bọ̀ sípò, ètò ọ̀rọ̀ ajé ilẹ̀ Amẹrika ńilò ọ̀rọ̀ ìwúnilórí láti ṣe alábapade nǹkan ti àwọn òṣìṣẹ́ wọ́n ń fẹ́, èyí ni ọ̀rọ̀ ẹgbẹ́ àwọn oníṣòwò nínú àtẹ̀jáde kan lósù yìí, ti wọ́n sì ń kìlọ pé kí ìjọba máá gbé awọn òfin tuntun jáde mọ́ lórí àwọn arìnrin àjò.
Link Àwọn àwòrán ẹ̀yìn ìtàgé níbi ìpàdé ìfọ̀rọ̀wérọ̀ BBC Yorùbá l'Eko Day 19: Wo ohun àràmàndà tí àwọn olósèlú máa ń ṣe lásìkò ìbò #BBCNigeria2019 Sowore: olùdíje Ààrẹ tó fẹ gbà Nàìjíríà padà fún àwọn ọdọ Ọmọbọlanle Sarumi-Aliyu ko kẹrẹ rara pẹlu awọn ọrọ rẹ lati ibẹrẹ titi de opin to bẹẹ to fi jẹ wi pe bi awn kan ṣe n kan sara sii ni awn mii ni idakeji n bu ẹnu atẹ lu bi o ṣe sọrọ.
Eni mẹwaa lo ko covid-19 nipinlẹ Plateau lọjọ Aiku nigba ti eeyan mọkanla laarun naa lati ipinlẹ Rivers.
Bí eniyan ṣe ń kó fadaka, idẹ, irin, òjé ati páànù pọ̀ sinu ìkòkò lórí iná alágbẹ̀dẹ, kí wọ́n lè yọ́, bẹ́ẹ̀ ni n óo fi ibinu ati ìrúnú ko yín jọ n óo sì yọ yín.
#BBCNigeria2019 Owo ifẹyinti tan fawọn gomina ana ni Kwara Gomina Ahmed sọrọ kikun lori idi ti awọn eniyan Kwara fi yan ẹgbẹ oṣelu miran ninu idibo to kọja fun BBC Yoruba.
Jẹ́ kí o di ẹni n rágó, kí o ri bí ayé ti n yínmú sí ọ
Adeyeye sọ pe igbesẹ naa waye lẹyin ayẹwo ti awọn onimọ iṣegun oyinbo ṣe lawọn ileewosan kan ni China, ti esi ayẹwo wọn si fihan pe Chloroquine le kapa otutu aya ti aarun Coronavirus ba fa, ti eyi si le ke ẹmi aarun naa kuru.
Àwọn tí ó kú jẹ́ ẹgbaa meje ó lé ẹẹdẹgbẹrin (14,700) láìka àwọn tí ó kú pẹlu Kora.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Musa jẹ musulumi gidi Musa sọ ilu Tumbuktu lorilẹede Mali di gbajugbaja lagbaye, lẹyin ti okiki aworan ijoko ọba ti wọn fi goolu ṣe lori maapu Catalan lọdun 1375, se gba awujọ agbaye kan.
Ọkùnrin kan, Kabiru dèrò ẹ̀wọ̀n lẹ́yìn tó jí súùtì àti àwọ̀tẹ́lẹ̀ ọkùnrin nílé ìtàjà ní Abuja Sójà obìnrin lù mí lálù bami nílùú Ibadan Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Ọkọ mi wa ọkọ̀ tẹ Poly Bag"" lásán, àfi gbùùàà!"
 Ó lè fa ìrora díẹ ̀ pẹ ̀ lú wíwú ojú ibi abẹ ́ rẹ ́ , àti ibà díẹ ̀ .
OLUWA wí pé, “Mo ti fún àwọn ọmọ Lefi ní gbogbo ìdámẹ́wàá tí àwọn ọmọ Israẹli bá mú wá fún mi gẹ́gẹ́ bí ìní wọn fún iṣẹ́ ìsìn wọn ninu Àgọ́ Àjọ.
Dafidi dìde ní òwúrọ̀ kutukutu ọjọ́ keji, ó fi ẹnìkan ṣọ́ agbo ẹran rẹ̀, ó mú oúnjẹ náà, ó sì lọ gẹ́gẹ́ bí Jese ti pàṣẹ fún un.
Samuẹli sọ fún Saulu pé, “Dúró díẹ̀ níhìn-ín kí n sọ ohun tí Ọlọrun wí fún ọ.
Ọdun 2011 si 2012 ni wọn gba Intercontinental Bank Plc, ti wọn si fi ọwọ osi juwe ile fun ọpọlọpọ awọn osisẹ banki Intercontinental naa ki wọn to darapọ mọ ile ifowopamọsi Access Bank.
Àwọn ọmọ ìbílẹ̀ ẹkun gbùngùn kan ní Hawaii Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, N ó sọ orúkọ mí fún o tí ìwọ náà bá sọ tirẹ fún mi Nínú àṣà, àwọn Hawaii wọn máa ń sin ojú ara, wọn a tún fún un ní orúkọ tìfẹ́tìfẹ́.
Àwọn eniyan mi yóo pẹ́ láyé bí igi ìrókò,àwọn àyànfẹ́ mi yóo sì jèrè iṣẹ́ ọwọ́ wọn.
Ẹ wo àwọn ọ̀dọ́mọdé Naijiria tó ń ṣe bẹbẹ nínú isẹ́ aládaní nílé Àwọn agbébọn kọlu Kọmísánà fọ́rọ̀ ilẹ̀ àti ilégbèé ní Ọyọ, awakọ̀ dèrò ọ̀run Ǹjẹ o yẹ kí èèyàn máa sùn lẹ́nu iṣẹ́?
Àwọn ti kò wá lo fóònù ti Apple ṣe sùgbọ́n ti àwọn fóònù wọ́n ti gòkè àgbà tàbi tó jẹ́ pé Android 4.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, FIFA 2019: Ọdún 1991 làkọ́kọ́ irú rẹ̀ ní àgbáyé Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Ẹ kò gbọdọ̀ ṣe bí wọ́n ti ń ṣe ní ilẹ̀ Ijipti, níbi tí ẹ ti gbé rí, bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò gbọdọ̀ ṣe bí wọ́n ti ń ṣe ní ilẹ̀ Kenaani níbi tí mò ń ko yín lọ.
Oríṣun àwòrán, BIG BROTHER NAIJA Àkọlé àwòrán, Awọn olukopa marun-un to kẹhin sori eto BBNaija season 5, Laycon, Nengi, Dorathy, Neo àti Vee Awọn kan lara wọn ti jẹ ẹbun irinajo igbafẹ ati jijẹ aṣoju fun awọn ileeṣẹ to ṣe onigbọwọ eto naa.
Ọwọ́ tẹ àwọn pásítọ̀ oniíṣẹ́ ìyanu èké méji nílùú Eko Koda ipo Tottenham ti gberu si lori tabili idije Premier League, ipo kẹfa ni wọn wa bayii lẹyin ti wọn fakọyọ ninu ifẹsẹwọnsẹ mẹta ti wọn gba sẹyin.
Ni Ọjọbọ ni awọn ẹṣọ alaabo to wa pẹlu Họnọrebu Gbajabiamila 'yinbọn soke'lati tu awọn eeyan kan ti wọn ni wọn dabu ọkọ olori ile aṣojuṣofin naa ka.
O ni eyi jẹ ami pe ọmọ oun lee di gomina lọla bii Ọmọwe Kayode Fayemi.
O tun jẹ akọ ewi to n gbe nilẹ Amẹrika.
Àkọlé àwòrán, Lati ọdun 2009 ni ọrọ iwadi owo agbaṣe lẹka yi ti n mẹhẹ.
"Àkọlé àwòrán, Adugbo Olushosun ni Ojota ""Wọn le lọ si agbegbe miran fun igba diẹ, ki wọn si pada wa ti eefin naa ba ti walẹ"", o sọ."
Sugbọn, lọsan ọjọ Iṣẹgun, ileesẹ ologun nibi ipade oniroyin to ṣe, tun fi awọn eniyan kan han, pẹlu ẹsun pe wọn se mago-mago ibo.
Aare  Buhari so pe, “A n sa gbogbo akitiyan wa lati pese ise fun awon odo wa, a n igbese to nipon ni eka eto ogbin, latari sege-sege oja epo-robi ati airise se awon eniyan lorile-ede Naijiria, a setan lati fi igbagbo wa sori eto ogbin, inu mi dun pe awon odo langba wa n sise agbe bayii dipo ki won maa duro de ise alakowe, won n laagun ninu oorun lowolowo, eyi ti won yoo kere re laipe, tori pe eto ogbin ni ona abayo lowo ti a wa yii”.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, O ni ijọba ti fun gbogbo awọn alejo lati ilẹ okeere ni oṣu mẹta lati fi ṣeto iwe igbeluu wọn ni Naijiria.
O ku ọjọ kan ki ẹgbẹ agbabọọlu Mikel, Trabzonspor o koju Istanbul Basaksehir ni Obi fi ọrọ naa sita.
El-Zakzaky: Aago méjìlá ọ̀sán ku ogún ìṣẹ́jú lọ́jọ́ Ẹtì ni bàálù rẹ̀ gúnlẹ̀
OLUWA ló pè mí níbi iṣẹ́ mi, òun ló ní kí n lọ máa sọ àsọtẹ́lẹ̀ fún Israẹli, eniyan òun.
Wo àwọn tó ti dákú bíi Maina níwájú ìjẹ́jọ́ Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 3 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 5 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Otútù ń bẹ níta n kò sì re’bìkan 🙂
"Tí mo bá jí ní òwúrọ̀, màá gbé omi kaná láti fi wẹ̀ fun un.
láti inú ìdajì ẹ̀yà Manase tí ó wà ní Gileadi: Ido, ọmọ Sakaraya; láti inú ẹ̀yà Bẹnjamini: Jaasieli, ọmọ Abineri; 
Eyí ni àwọn arẹwà 'ẹ̀lẹ̀ Daddy', àfẹ́fẹ́ tí Aláàfin fi ń mí Ṣé lóòtọ́ ni olorì méjì míì tún ti kúrò láàfin Oyo?
Awọn ile iṣẹ igbohun safẹfẹ ti o jẹ ti ijọba ni wọn le paṣẹ fun.
 Àpèjá orúkọ yìí ni ó di Ìjẹ ̀ bú-Òde lónìí yìí .
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ọ̀pọ̀lọpọ̀ ìnira lojú àwọn ọ̀dọ́ ilẹ̀ Áfíríkà t''o ń wá ìgbé ayé rere lọ sí Yúróòpù ń rí Obinrin le loyun to ba ni ibalopọ lasiko to n ṣe nnkan oṣu Igbagbọ keje nipa nnkan oṣu obinrin ti ko fi idi mulẹ ni pe obinrin to ba ni ibalopọ lasiko to n ṣe nnkan oṣu le loyun.
Ipinlẹ Borno ni obinrin ti ọrọ kan n gbe, wọn si ti ba oun naa wi.
Ó ní bàbá òun tí orúkọ rẹ̀ ń jẹ́ Ayédùbúlẹ̀ ni ẹni t;i wọ́n bí bàbá Fìláswayépọ̀ ń gbé kiri.
Lẹyin ti awọn ọlọpaa ti kọkọ gbe e lọ si ile ẹjọ fun ẹsun yii ni ilu Abuja laipẹ yii, ẹjọ miran tun dide lori ẹsun yii kan naa ni ọjọ kẹtala oṣu karun ni ile ẹjọ giga apapọ to wa ni ilu Oṣogbo.
)Imọ ijinlẹ keji: Iwe ẹri imọ ijinlẹ akọkọ, iwe ẹri ọjọ ori, WAEC/WASSCE, iwe ẹri ilu abinibi, ati iwe ẹri NYSC.
Ní ọjọ́ yìí gan-an ni OLUWA mú àwọn ẹ̀yà Israẹli jáde kúrò ní ilẹ̀ Ijipti.
Aṣofin Yusuf tun rọ awọn olori ẹlẹsin ati awọn obi lati sapa wọn fun aṣeyori eto idibo yii, paapaa nipa ṣiṣe kilokilọ lori iwa ipanle ni ṣaaju idibo, lasiko idibo ati lẹyin idibo yii.
 Eyi nikan ti Oloye Oyelola Elebubon sọ fun BBC Yoruba lori ajọdun ẹgbẹ naa to waye laipẹ yii."
Bí ẹ bá tún ní ọ̀rọ̀ mìíràn tí ó jù yìí lọ, a óo máa yanjú rẹ̀ ní ìgbà tí a bá ń ṣe ìpàdé.
Mo n bẹru n fun ẹmi awọn ọrẹ mi'' Ọlọpaa kede pe awọn ti mu eeyan mẹrin Ko ti daju iye agbebọn to kopa ninu iṣẹlẹ naa ṣugbọn ọga ọlọpaa ti sọ fun awọn akọroyin pe awọn ti mu eeyan mẹrin bayi; ọkunrin mẹta obinrin kan.
“Ṣugbọn nisinsinyii, ará, mo mọ̀ pé ẹ kò mọ̀ọ́nmọ̀ ṣe é, bẹ́ẹ̀ ni àwọn ìjòyè yín náà kò mọ̀ọ́nmọ̀ ṣe é.
Laarin ọdun meji si asiko naa, Adeeko ti tun igbe aye awọn opo bii gba ati aadọta ti ọkọ wọn ku soju ogun ṣe, to pa wọ́n lẹ́rin ayọ̀ pẹlu iranlọwọ.
Dafidi ní, “OLUWA Ọlọrun Israẹli ti fún àwọn eniyan rẹ̀ ní ìsinmi, yóo sì máa gbé Jerusalẹmu títí lae.
Yóo mú kí àwọn baba wà ní ìrẹ́pọ̀ pẹlu àwọn ọmọ wọn.
Olukopa kan to ba BBC sọrọ, Arabinrin Oyindamọla, sọ pe oun ti fi ẹgblrun meji Naira t'oun fi bẹrẹ idokoowo pa ẹgbẹrun mẹrindinlogun Naira.
Buhari gbóṣùbà fún D'Tigress lẹ́yìn tí wọ́n lu Senegal gba ife AfroBasketWomen Manchester United dáná sun Chelsea bi ẹràn àgbò iléyá PFN: Fatoyinbo kọ̀ láti yọjú ni ìwádìí wa kò ṣe parí Àjẹ́ àti Aṣẹ́wó ní ìyá Rainbow - Òjòpagogo Ọlọ́pàá Germany ń wádìí àfurasí mẹ́rin nínú àwọn tó kọlu Ekweremadu ni Germany Chiejine ṣoju Naijiria nigba mọkanlelọgọta, bẹẹ lo si gba goolu mẹẹdogun sawọn nigba aye rẹ.
Nigba ti awọn awakọ yoo si maa gba abala to wa lati Lagos Island si Oworonsoki ni ọna to kọju si Oworonsoki, lati aago kan ọsan si mejila oru.
Nítorí ẹ̀dá alààyè wo ni ó mọ ohun tí ó wà ninu eniyan kan bíkòṣe ẹ̀mí olúwarẹ̀ tí ó wà ninu rẹ̀?
Ọpọ olukopa ni ẹni da owo fun wọn titi ti eto naa fi 'jona.
Ẹfunsetan Aniwura, obìnrin tó ju ọkùnrin lọ Ọ̀rọ̀ǹpọ̀tọ̀niyùn, Aláàfin obìnrin àkọ́kọ́ rèé, tó ní nǹkan ọkùnrin Awọn miiran ni awọn maa n gbagbe iṣoro wọn ni gbogbo igba ti wọn ba ti wo fọnran rẹ.
Bobrisky fi kun pé àwọn igbésẹ̀ iṣẹ́ abẹ náà ko tii tan, sùgbọn nígba ti yóò ba fi di ìwòyí amọdun, oun fẹ́ díje fun ètò obinrin to rẹ̀wa júlọ lágbàyé (Miss World 2020) Mo fẹ́ fi àkàrà òyìnbó ọjọ ìbímí tọrẹ- Bobrisky Kí ni ó gbé ọlọ́pàá dé ibi àjọ̀dún ọjọ́ ìbí i Bobrisky?
Ise akanse Iko omo-ogun ohun ti won pe ni Operation Diran Mikiya sekupa ogunlogo awon agbesunmomi ni agbegbe igbo aginju Sububu, Birnin Magaji ati igbo-aginju Rugu nipinle Zamfara ninu ikolu ti o sese waye ohun.
Shittu sọ eyi lasiko to n sọrọ lori iyatọ to wa laarin ki ijọba kan kede pe awọn ti tu SARS ka, ati wi pe ki o di ofin lorilẹede Naijiria fun BBC.
Ẹ wo oúnjẹ àràmàndà 11 tí wọ́n ń jẹ lágbààyé Yoruba bọ wọn ni bayii lati n se ni ilẹ wa, eewọ ibomiran ni.
Èémí kan náà ni wọ́n ń mí; eniyan kò ní anfaani kankan ju ẹranko lọ; nítorí pé asán ni ohun gbogbo.
Ilu Nairobi lorilẹede Kenya lo ma ti ṣẹlẹ, baba ọmọ naa to n gbe ni ẹkun Narok lapa iwọ oorun olu ilu Kenya lo kọkọ fi ọmọ naa fun ọkunrin kan ẹni ọdun mọkanlelaadọta.
N óo dúró fún ọmọ náà, ọwọ́ mi ni kí o ti bèèrè rẹ̀.
Hesekaya ranṣẹ sí Senakeribu, ọba Asiria, tí ó wà ní Lakiṣi nígbà náà, ó ní: “Mo ti ṣẹ̀, jọ̀wọ́ dá ọwọ́ ogun rẹ dúró; n óo sì san ohunkohun tí o bá bèèrè.
Ọpọ igba ni awuyewuye maa n waye lori owo awọn agbabọọlu Naijiria.
Ẹrọ akọkọ ni ẹrọ ifọwọ mẹtadọkan, eyi to n tẹ omi ati ọṣẹ sọwọ eeyan fun ra rẹ, ti yoo si tun tẹ afẹfẹ si ọwọ eeyan lẹyin taa ba fọ ọwọ wa tan.
”Judasi, ẹni tí ó fi lé àwọn ọ̀tá lọ́wọ́, dúró pẹlu wọn.
Kemi Remi Dairo: Iṣẹ́ abẹ nínú ọpọlọ àti ẹ̀rọ ni mo fi ń gbọ́ ọ̀rọ̀ báyìí
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ẹ̀mí mẹ́ta ṣòfò nínú ìjàǹbá ọkọ̀ nípinlẹ́ Èkó Ẹgbẹ́ òṣèlú APC yóò ṣèpàdé gbogboogbò Pásítọ̀ bẹ́'rí ọmọ ìjọ ní ìpínlẹ̀ Ògùn Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Òórùn burúkú yóo wà dípò òórùn dídùn ìpara,okùn yóo wà dípò ọ̀já;orí pípá yóo dípò irun tí wọ́n ṣe lọ́ṣọ̀ọ́,aṣọ ọ̀fọ̀ yóo dípò aṣọ olówó iyebíye.
eye naa si ,ise iwadii, imo eko , imo ise ọwọ, onimọ ẹrọ, awon onimo erọ  ati imọ sayensi , gbogbo awon ipele wọnyi ni
Pilatu sọ fún wọn pé, “Ẹ̀yin fúnra yín ẹ mú un lọ, kí ẹ ṣe ìdájọ́ fún un bí òfin yín.
Ìráhùn Ẹni tí Ìyà ń Jẹ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Làáhànmí: Ìwádìí ní èèyàn 219 ni ibà Lassa pa lọ́dún tó lọ́, 29 lọ́dún yìí, tètè dènà rẹ̀ Ọpọ ọmọ Naijiria lo n gbe orilẹede Amẹrika, ti Naijiria ati Amẹerika si jọ ni ajọṣepọ lati doju ija kọ awọn agbesunmọmi.
Gbogbo ọdún tí Enọṣi gbé láyé jẹ́ ẹẹdẹgbẹrun ọdún ó lé marun-un (905) kí ó tó kú.
Kò dá ẹnikẹ́ni sí, gbogbo wọn patapata ni ó parun gẹ́gẹ́ bí àṣẹ tí OLUWA Ọlọrun Israẹli pa fún un.
Àwọn agbéraga ti dẹ tàkúté sílẹ̀ dè mí,wọ́n dẹ àwọ̀n sílẹ̀ fún mi;wọ́n sì dẹ okùn sílẹ̀ fún mi lẹ́bàá ọ̀nà.
Ṣugbọn ohun tí ìbá dùn mọ́ mi ninu jùlọ ni pé kí ẹ lè máa waasu.
Ilé ẹjọ́ wọ́gilé ìgbẹ́jọ́ Olalekan 'Woodberry' Pọnle Òru òní ní ìjọba á ti afárá 'Third Mainland' ní Eko; Wo àwọn ọ̀nà míràn tí o leè gbà lẹ́yìn tí wọ́n bá tìí Ọlọ́lá jù lọ Terry Waya ni Bàbá Terseer Kiddwaya tó ń kópa nínú BBNaija 2020 Amọṣa ilumọọka wolii kan, Primate Elijah Ayọdele ni oun ti gba asọtẹlẹ idajọ Ọlọrun fun ẹnikẹni to ba gbiyanju ati ṣe eru lasiko idibo to n bọ ni ipinlẹ Edo.
wọ́n wí fún un pé, “Wò ó, àgbà ti dé sí ọ, àwọn ọmọ rẹ kò sì tẹ̀lé àpẹẹrẹ rere rẹ.
 orílẹ ̀ -èdè kejì wá ń dún kòkò lajà láti gba ìtú yìí padà .
"Onome ni ""Inu ile igbọnsẹ ni ọmọdebirin naa wa ki afurasi ọhun to wọle tọ ọ lọ, ṣugbọn o sẹ pe ohun ko fọwọ kan an."
Báyìí ni iṣẹ́ kíkọ́ ilé Ọlọrun ṣe dúró ní Jerusalẹmu títí di ọdún keji ìjọba Dariusi, ọba Pasia.
Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Iléèṣẹ́ ọlọ́pàá mú ọkùnrin ẹni ọdún 55 tó gé ẹ̀yà ara èèyàn nílẹ̀ ìsìnkú ṣọ́ọ̀ṣì l'Ogun25 Bélú 2020 Nigeria Tax Exemption: Ìjọba àpapọ̀ kéde pé òun ń fẹ́ fi òpin sí bí àwọn tó ń gba owó oṣù tó kéré jùlọ ṣe ń san owó orí25 Bélú 2020 India Wedding: Ìyàwó kan ní India wọ sòkòtò fún ayẹyẹ ìgbéyàwó rẹ̀- Wo ìdí tó fi ṣe bẹ́ẹ̀25 Bélú 2020 Adeyeye Ile Ife: Kílódé tí Ọọni Ife, Oba Ogunwusi kò fi gbọdọ̀ rí ọmọ rẹ̀ tuntun títí di ẹ̀yìn oṣù mẹ́fà?
“N óo bukun àwọn, ati gbogbo agbègbè òkè mi.
" ní ọdún 2004 , wọ ́ n yí orúkọ "" alva maersk "" , s "" í maersk alabama "" wọ ́ n wàá lọ sí united states , ilé iṣẹ ́ tó fi ń ṣisẹ ́ , maersk line , limited , tí ó wà ní norfolk , virginia ."
Kògbérèégbè mẹ́ta nínú òṣèré Yorùbá Àṣìta ìbọn pa èèyàn kan lásìkò tí SARS ń kojú adigunjalè l'Eko Lẹ́tà Obasanjo: Àjálù ń bọ̀ bíi ti Rwanda, tí Buhari kò bá ṣàtúnṣe ètò ààbò O ti lé ni òkú ẹni mẹ́wàá ti wọ́n ti ri yọ nínú ilé to dà wó ni Jos Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Olórí Ọ̀dọ́ l'Ondo ní oníkálùkù yóò bẹ̀rẹ̀ sí ní jà fúnra wọn Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Wo àwọn olóríire tó borí nílé BB Naija sẹ́yìn àti iye òjò owó tó rọ̀ fún wọn Àwọn afọbajẹ wọ́ Oluwo relé ẹjọ́, ìjọba Osun kò tíì fọùn Ẹ gbà mí, Nàíjíríà gbá mi lórí àyẹ̀wò Covid-19 - Iyabo Ojo figbe ta A ti ja aráàlú kulẹ̀, ta bá pè wọ́n fún ìwọ́de, wọn kò ní jẹ́ wa mọ́ - NLC Eko Àlàyé rèé lórí ìdí tí ẹgbẹ́ òṣìṣẹ́ kò fi ní bẹ̀rẹ̀ ìyanṣẹ́lódì mọ́ lónìí Ẹgbẹ́ òkùnkùn yìnbọn lu ọmọ kan ní ikùn lásìkò ìdárò akẹẹgbẹ́ wọn Laycon ni ọmọ ológo tó jáwé olúborí ní ètò BBNaija season 5 'Lockdown' Kí ló wà láàrin Olorì Badra àti Bobrisky, tí ọ̀rọ̀ wọn fi wọ̀?
Grandpa àti Uncle mi, ń fipá bá mi lòpọ̀ láti ọmọ ọdún mẹ́rin Ẹ má bínú, mo kábàmọ́ pé mo na obìnrin -Elisha Abbo Ààrẹ Buhari jámi lórí ètò RUGA ná Ajọ to n ri si iṣẹlẹ pajawiri ni ipinlẹ Eko LASEMA ni bi awọn ṣe de ibi iṣẹlẹ naa, wọn ri i pe awọn kan to maa n bẹ ọpa epo lati jale lo fa iṣẹlẹ naa to waye ni Fire Junction Ijegun.
O ni iranlọwọ dide loriṣiriṣi nitori bi awọn kan ṣee n gbe owo silẹ, ni awọn ẹlomii tun un pese awọn ohun elo ti yoo mu ayipada ba ile naa.
Àwọn adarí ìjọ olókìkí tó ti f'ara ko imí ẹ̀sùn àgbèrè ní Naijiria
" ni afikun si awọn aworan , awọn idaraya , awọn ijomitoro , ati idanileko ere idaraya kan ni ẹtọ ni "" awọn ọna ilẹ ti queer "" ."
Ajọ igbẹjọ oni eniyan mẹta ti Adajọ Agba, Danladi Adeck se adari fun naa kede oludije PDP.
Mò ń sọ ọ̀rọ̀ wọnyi ninu ayé, kí wọ́n lè ní ayọ̀ mi lẹ́kùn-únrẹ́rẹ́ ninu ọkàn wọn.
Fun ọpọlọpọ eeyan, ko si ohun meji to kọkọ n wa sọkan awọn eeyan bi wọn ba gbọ orukọ ilu Eko ju sunkẹrẹ fakẹrẹ ọkọ lọ.
Wọ́n ké sí ààrẹ láti wá dáhùn ìbéèrè lórí àwọn ẹ̀mí tó nù
Ninu títóbi ọláńlá rẹ, o dojú àwọn ọ̀tá rẹ bolẹ̀,o fa ibinu yọ, ó sì jó wọn bí àgékù koríko.
Ẹ wá wo iṣẹ́ OLUWA,irú iṣẹ́ ribiribi tí ó ṣe láyé.
Nítorí pé bí ọgbọ́n ṣe jẹ́ ààbò, bẹ́ẹ̀ ni owó náà jẹ́ ààbò; anfaani ìmọ̀ ni pé, ọgbọ́n a máa dáàbò bo ọlọ́gbọ́n.
Ikọ Liverpool to de ipele aṣekagba idije UEFA Champions League ni saa to lọ yoo maa ta kangbọn pẹlu ikọ FC Porto.
Oríṣun àwòrán, @danaf Àkọlé àwòrán, Ajurawalọ.
Ó ṣe fún ìlú ńlá náà!
"O ni ""Ni aye ọlaju ati ijọba tiwa-n-tiwa ta n se yii, iru igbesẹ wiwo ile bayii ko bojumu rara."
Oríṣun àwòrán, @Bellomatawalle1 Ko tan sibẹ, ọpọ awọn eeyan to forei sọta ijamba yii lo tun fara gba ọgbẹ lorisirisi.
Lati ọdun 2017 ti Serena Williams ti bi ọmọbinrin rẹ Alexis Olympia ni o ṣẹṣẹ gba ife ẹyẹ rẹ akọkọ.
nítorí pé Daniẹli, tí ọba sọ ní Beteṣasari, ní ìmọ̀ ati òye láti túmọ̀ àlá, ati láti ṣe àlàyé ohun ìjìnlẹ̀, ati láti yanjú ọ̀rọ̀ tí ó bá díjú.
5m, N8bn tí wọ́n kó pamọ́’ Ọ̀wọ́ngógó epo bẹntirò: NNPC ni 'ìròyìn ẹlẹ́jẹ̀' ni Ajọ NNPC ni aṣoju ẹka miran meje ni aarẹ Buhari tun yan sipo yatọ si Kyari.
“Àwọn baba-ńlá wa jowú Josẹfu, wọ́n tà á lẹ́rú sí ilẹ̀ Ijipti.
Àwọn ará Ninefe gba ọ̀rọ̀ Ọlọrun gbọ́, wọ́n bá kéde pé kí gbogbo eniyan gbààwẹ̀, àtọmọdé, àtàgbà, wọ́n sì da aṣọ ọ̀fọ̀ bora.
O ni awọn ọlọkọ gbọdọ rii daju pe ileeṣẹ VIO ni wọn ti n gba iwe wọn funrawọn.
Ẹ gbọ ohun ti wọn ni ki ara ilu ṣe nipa fifi orukọ silẹ lọna to tọ ati to yẹ.
Lataari arọọrọda ojo to n rọ lati ọjọ mẹjọ sẹyin lo ti fa omiyale ati agbara ya ṣọọbu ni ariwa ila oorun Ghana.
àkójọpọ iye ti US ko ni ti PuertoRico, ti Guam tabi Us Virgin Islands ninu.
Paulu kàn gbọn ejò náà sinu iná ni, ohun burúkú kan kò sì ṣẹlẹ̀ sí i.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù NANS: Ọ̀wọ́ngógó owó ilé ìwé ló jẹ́ kí àwọn akẹ́ẹ̀kọ́ máa fi fásitì sílẹ̀ 13 Èbibi 2019 Oríṣun àwòrán, Google Àkọlé àwòrán, Amọ ijọba ipinlẹ Ondo ni irọ ni adari awọn akẹẹkọ n pa nitori owó ilé ìwé kò nira láti san.
 Àwòrán ( 57 ) ní ó fi àwon èka wònyí hàn wá dáradára .
Manchester United, ti iko Crystal Palace si gbo ewuro ibanuje soju iko
ọlọja  beere lowo awon aadota leni ọ́ọ̀dúnrún
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Awọn mi i to tun ti wa ni Penny Wise, Swiss Golden, Twinkas, Plan well, Nopecsto ati bẹẹbẹ lọ.
Ó wá wo gbogbo wọn yíká, ó sọ fún ọkunrin náà pé, “Na ọwọ́ rẹ.
Dafidi ṣe akiyesi pé Ọlọrun ti fi ìdí ìjọba òun múlẹ̀ lórí Israẹli, ati pé Ọlọrun ti gbé ìjọba òun ga nítorí àwọn ọmọ Israẹli eniyan rẹ̀.
" Dogara fikun pe, ọkan lara isoro ti oun ri pẹlu awọn asaaju ẹgbẹ oselu PDP ati ijọba ipinlẹ Bauchi ni bi gomina ko se bọwọ fun agba atawọn ọba alaye, lodi si ileri rẹ.
Ogbeni Santander tun  so pe loooto ni won yin ibon lu olopaa kan.
Agbebọn pa ọmọ ogun mejila Afunrasi afipajinigbe k'agbako ni Ogun Alápatà lu ìyàwó rẹ̀ pa ní Ogun 'Gbogbo olùdíje Ogun fi dá àwọn ènìyàn lójú pé.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ajikanle ní òun ti ta ọ̀pọ̀ dúkìá lórí apá àti ẹsẹ̀ tó rọ láti ọdún kẹta náà 7 Òkùdu 2020 Oríṣun àwòrán, Instagram/murphyafolabi20 Yoruba ni ẹni ti ija ko ba, nii pe ara rẹ ni ọkunrin, bi ere ba si ba ẹdun nilẹ, yoo di ọlẹ ni.
Jonathan wa n beere pe, eelo ni wọn ta apo irẹsi kan nigba ti PDP gba akoso orilẹede yii ati iye ti wọn n ta bayii?
Lẹyin ti eyi sẹlẹ ni awọn oṣiṣẹ ti o wa ni ayika yin ibọn lu mẹta ninu awọn kiniun naa, ti wọn si ku.
O ni ẹ jọwọ mi o ṣọ pe eeyan 78 lo ku o, nigba ti mo n ṣe fidio lọwọ, awọn meje ti ku silẹ, ṣugbọn lẹyin ti ẹrọ ibanisọrọ mi ku, awọn 15 miran tun dagbere faye."
Bákan náà, àwọn kan ninu àwọn ọmọ Kohati, ni wọ́n máa ń ṣe ìtọ́jú àkàrà ìfihàn ní ọjọọjọ́ ìsinmi.
Wà pẹlu mi, pa mí mọ́ kúrò ninu ewu, má jẹ́ kí jamba ṣe mí!
Joṣua ati gbogbo ọmọ Israẹli tí wọ́n wà pẹlu rẹ̀ bá ṣe bí ẹni pé àwọn ará Ai ti ṣẹgun àwọn, wọ́n sì sá gba ọ̀nà aṣálẹ̀ lọ.
Ẹfọn ja baalu lulẹ ni Wembley lẹyin ti Arsenal fi iya bẹrẹ saa bọọlu tuntun fun Liverpool.
Olukuluku wa níláti máa ṣe ohun tí yóo tẹ́ ẹnìkejì rẹ̀ lọ́rùn fún ire rẹ̀ ati fún ìdàgbàsókè rẹ̀.
Nigeria 2019 Elections: Ẹnikẹ́ni tó bá ṣáájú láti jì àpótí ìbò ẹ̀mí rẹ̀ ló fi ń ṣeré- Buhari
Oríṣun àwòrán, Reuters Àkọlé àwòrán, Aubameyang gba bọọlu sinu awọn Watford lẹyin isẹju mọkandinlọgọta sigba ti wọn bẹrẹ ere Ikọ agbabọọlu Watford ri anfani ati gbesan lẹyin ti wọn fun wọn ni ayo gbelẹ-ko-gba-sile (Penalty) gẹgẹ bi itaran fun ẹṣẹ ti agbabọọlu Arsenal kan ṣẹ.
Àwọn ọba kan kò lè gbàdọ̀bálẹ̀ Wasiu mọ́ lẹ́yìn tó joyè Mayegun - Alaafin Imam tó fẹ́ ọkùnrin míì níyàwó forí kó ìjìyà òfin Amotekun: Kí ni iṣẹ́ tí Amotekun yóò máa ṣe gangan?
wa sedasilẹ igbimo alabẹ-sekele ti yoo sagbekalẹ  iwe aṣẹ fun isẹ akanse ti awọn gomina naa yoo maa lo.
Atẹjade kan to wa lati ọọfisi olootu ijọba ilẹ Canada ọhun, Justin Trudeau sọ pe obinrin naa yoo si wa labẹ aabo fun akoko kan na, bi o tilẹ jẹ pe saka ni ara rẹ da, to si n gba itọju to yẹ lọwọ, ti ami kokoro naa ko si tii foju han.
Shittu tó n gbèrò láti di olùdíje ẹgbẹ́ nàá sípò gómínà ìpínlẹ̀ Ọyọ l'ọ́dún 2019 ní wọ́n yọ ọwọ́ rẹ̀ kúrò ní àwo ìdìbò abẹ́lé nàá nítorí pé kò ní ìwé ẹ̀rí ìsìnrú ìlú, NYSC.
Ìwọ tí o ti rí ẹ̀kúnrẹ́rẹ́ ibinu OLUWA,ìwọ tí OLUWA ti fi ibinu jẹ níyà,tí ojú rẹ wá ń pòòyì.
ABUDA ÈDÈ YORÙBÁ Àbùdá èdè Yorùbá ni ó máa jẹ́ kí á mọ ohun tí èdè jẹ́ gan-an.
O tun fi kun wipe ni ọgba ile iwosan ọpọlọ to wa ni Yaba, ọpọlọpọ alaisan to wa nibẹ, igbo mimu lo da ori wọn ru.
Gẹgẹ bii alukoro ileeṣẹ ọlọpaa nipinlẹ Eko, Ọgbẹni Bala Elkana ṣe sọ fun BBC News Yoruba, wọn ti ko iwe ẹjọ naa lọ si olu ileeṣẹ ọlọpaa lorilẹ-ede Naijiria, nilu Abuja nibi ti iwadii naa ti n tẹ siwaju.
Goolu meji ni Lacazette gba wọle lẹyin ti agbabọọẹu Valencia, Mouctar Diakhaby ti kọkọ ṣide ajọdun goolu ni ifẹsẹwọnsẹ naa ni iṣẹju kọkanla.
Ó ń tọ́ wọn sí ìdájọ́ òtítọ́,ó sì ń pa ọ̀nà àwọn ẹni mímọ́ rẹ̀ mọ́.
Yóo kún fún Ẹ̀mí Mímọ́ láti ìgbà tí ó bá tí wà ninu ìyá rẹ̀; 
nígbà tí ó ti jẹ́ pé ẹ̀rí ni ẹ̀ ń wá pé Kristi ń lò mí láti sọ̀rọ̀.
Àràmọ̀ǹdà àwòràn láti ilẹ̀ àdúláwọ̀ lọ́sẹ̀ yìí Kéré o!
Iroyin fidirẹmulẹ p,e gbajugbaja oloye naa jade laye ni orilẹede Ghana lọjọ aiku, ọjọ Kẹrinlelogun oṣu Kẹta, lẹni ọdun mọkandinlọgọta.
Wọ́n bẹ̀rẹ̀ sí wá, atọkunrin atobinrin, gbogbo àwọn tí ó tinú ọkàn wọn wá, wọ́n mú yẹtí wúrà wá, ati òrùka wúrà, ati ẹ̀gbà wúrà, ati oríṣìíríṣìí ohun èlò mìíràn tí wọ́n fi wúrà ṣe; olukuluku wọn mú ẹ̀bùn wúrà wá fún OLUWA.
Kọmisọnna fun eto idajọ ati agbẹjọro agba ni ipinlẹ naa sọ wi pe gomina ipinlẹ ogun sa ipa rẹ lati mu ki eto naa gberu si.
O salaye pe, “pelu ise-akanse igbedo yii, ijoba  yoo fun wa letikun, pelu igbagbo pe, laipe ojo ayipada yoo ba ipinle Benue”.
O ti pa to igba miliọnu naira laarin ọsẹ meje pere ti fiimu naa jade.
Bíótiwùkíórí, ó ní láti bá agbára ìwàlóríoyè afigagbága rẹ̀ takọ̀ngbọ̀n.
Lara Funmilayọ ni àwọn ọmọ ti talẹnti wọn kuro ni kèrémi ti jáde Nínú wọn ni Olikoye Ransome-Kuti, to di minista fun eto ilera ni Naijiria, Fẹla Ransome-Kuti to jẹ ogbontarigi onkọrin Afrobeat ati Bẹkọ Ransome-Kuti to jẹ ajijangbara.
ọmọ Jakọbu, ọmọ Isaaki, ọmọ Abrahamu, ọmọ Tẹra, ọmọ Nahori, 
Diabetes - Ọmọ ọdún mẹ́ta péré leè kò àìsàn ìtọ̀ súgà Àsìlò oògùn Codeine: Ọwọ́ ba òsìṣẹ́ Emzor Ohun ìwòsàn pàjáwìrì ti di dandan Bakan naa ni wọn ba awọn ẹrọ agbelẹrọ ati ayederu iwe ẹri apoogun oyinbo ninu ile ti wọn n lo fun ṣiṣe awọn oogun naa.
Oríṣun àwòrán, Twitter Amọ awọn eniyan to fesi lori Twitter si lẹta naa sọ wi pe, ohun ti Alaafin n sọ yii lo n kilọ fun Fayemi wi pe, ilẹ Yoruba kii ṣẹ̀ ipinlẹ Kano ti gomina ti n yọ Emir, ti yoo si le kuro ni ilu nigba to ba wu u.
Ó ń lé àwọn ẹ̀mí èṣù jáde.
Ninu atẹjade kan ti ẹgbẹ naa fi sita lẹyin ipade igbimọ iṣakoso rẹ lo ti kede yii.
O lọ si ile ẹkọ Girama Adventist Secondary ni Ede ati Muslim Grammar school feto ẹkọ Girama.
Banki agbaye ti seleri lati ran orile ede Naijiria lowo lori idagbasoke eto oro aje.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ sí: BBC gbalejo Ife Ẹyẹ Agbaye ti Russia 2018 France wọ ìpele àṣekágbá Russia 2018 Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ẹtàn ni àwọn ọ̀rẹ́ fi ń tan èèyàn lọ si Libya pé iṣẹ́ gidi wà níbẹ̀ Ọ́ sàlàyé pé nígbà ti àwọn kọ́kọ́ dé bẹ̀, odidi ọja máàrun ni kò fi sí ounjẹ́ tàbí ibùsùn kí aṣójú Naijíríà lórílẹ̀-èdè Russia tó yojú.
Ninu atẹjade kan to fi sita lọjọru, Soyinka sọ pe isede kọ ni ọna abayọ, bi ko ṣe pe ki wọn o sọ fún ijọba apapọ lati ko awọn sọja to ko sita nitori iwọde naa, kuro.
Àkọlé àwòrán, Adebayo Adelabu sọ pe oun yoo gbe iṣe agbe larugẹ.
O ni ida marundinlọgọrun ninu ọgọrun awọn eeyan orilẹede naa ni ko fi oju wọn ri okuta dayamọndi ri.
Ranti pé ní àkókò tí kò sí ogun ni ó pa wọ́n; tí ó fi gbẹ̀san ikú ẹni tí wọ́n pa ní àkókò ogun.
Fayẹmi ni wọn lo sọ pe awọn ọba naa kọ lati wa si ipade awọn lọbalọba ati ijọba lati Osu Kẹjọ, ọdun 2019 nitori naa, ki wọn sọ idi ti wọn fi gbe iru igbesẹ bẹẹ.
 àwò-àìṣẹ ́ jú ; Àwòyanusílẹ ̀ ; awòsílẹ ̀ kùn èrò .
Ẹ máa gbé iyawo kí ẹ bímọ lọkunrin ati lobinrin.
Ohun tó ṣẹlẹ̀ ní Ghana yíì tí koba ẹgbẹ́ àgbábọ́ọ̀lù ibẹ̀ láti rí onígbọ̀wọ̀ fún eré bọ́ọ̀lú ní orílẹ̀-èdè náà.
Wọ́n bá sìn ín lọ sí ìdíkọ̀.
OLUWA ni agbára àwọn eniyan rẹ̀;òun ni ààbò ìgbàlà fún ẹni àmì òróró rẹ̀.
‘Erùpẹ̀ tí ó lẹ̀ mọ́ wa lẹ́sẹ̀ ninu ìlú yín, a gbọ̀n ọ́n kúrò kí ojú lè tì yín.
Ẹ jẹ ki a ranyin leti.
Àwọn olórí ìdílé náà ṣẹ́ gègé gẹ́gẹ́ bí àwọn ọmọ Aaroni, àwọn arakunrin wọn ti ṣe, níwájú ọba Dafidi, ati Sadoku, ati Ahimeleki, pẹlu àwọn olórí ninu ìdílé alufaa ati ti àwọn ọmọ Lefi.
Paul Primary School, ko to re si ile iwe alakọbẹrẹ St.
'Ìbànújẹ́ ni ohùn ọmọ wa tí a gbọ́ jẹ́ fún wa' - BBC News Yorùbá BBC News, YorùbáFò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Leah Sharibu - 'Ìbànújẹ́ ni ohùn ọmọ wa tí a gbọ́ jẹ́ fún wa' 21 Ẹrẹ̀nà 2018 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 28 Ògún 2018 Oríṣun àwòrán, ISAAC LINUS ABRAK Àkọlé àwòrán, Baba Leah Sharibu rọ ìjọba lati gba ọmọ oun Ileeṣẹ Aarẹ Naijiria ni awọn oṣiṣẹ ọtẹlẹmuyẹ ti n ṣe ayẹwo 'oohun Leah Sharibu' to gba igboro kan.
Kò si ohun irinna bi ayé òde òni, nitorina ẹsẹ̀ ni wọn fi nlọ lati ilú kan si ekeji.
Ọrọ pọ ti Sunday Igboho sọ ninu fidio yii pẹlu BBC Yoruba, ẹ sa wa nkan fidile lati woo.
 O ni, idi ti ile-iṣẹ Rite Food fi ṣatileyin fun Idije ere-Idaraya ori papa ilu Asaba ọdun 2018 naa ni wọn pe ni “Pipese Nnkan Ipanu fun Awọn Olubori (Refreshment for the Champion”.
''Mo bẹrẹ si ni tọju awọn ọmọ wa nitori iyawo mi ko tọju wọn mọ,'' Imana lo sọ bẹẹ.
to kangun si aṣekagba idije naa.
Ọ ̀ pọ ̀ lọpọ ̀ nínú àwọn fíìmù tí ó ń jáde ní orílẹ ̀ èdè nàìjíríà ló ní àkóónú tí ó níí ṣe pẹ ̀ lú ìṣòró tí ó ń kójú àwọn mùtúmùwà ilẹ ̀ Áfíríkà .
Inú iná ni ẹ ti níláti yọ àwọn mìíràn kí ẹ tó lè gbà wọ́n là.
Lati ọdun 2015 to si ni awuyewuye naa ti di gbajugbaja, nitori pe Buhari ko fun ajọ eleto idibo Naijiria, INEC, ni iwe ẹri rẹ gẹgẹ bi ara ohun ti wọn n gba lọwọ ẹnikẹni to ba fẹ ẹ dupo oṣelu ni Naijiria.
Ó bá bẹ̀rẹ̀ sí bẹ Jesu títí pé kí ó má ṣe lé wọn jáde kúrò ní agbègbè ibẹ̀.
Nígbà tí Paulu dé, àwọn Juu tí wọ́n wá láti Jerusalẹmu tò yí i ká, wọ́n ń ro ẹjọ́ ńláńlá mọ́ ọn lẹ́sẹ̀ lọ́tùn-ún lósì, bẹ́ẹ̀ ni kò sí èyí tí ó lẹ́sẹ̀ nílẹ̀ ninu gbogbo ẹjọ́ tí wọ́n rò.
"Ọkọ Funke Akindele kó eléré àti òṣìṣẹ́ jọ fi ṣe ""Surprise Pato"" fún un lọ́jọ́ ìbí rẹ̀ Ọlọ́pàá Amẹrika tún yìnbọn lu aláwọ̀ dúdú míì nígbà méje, ìwọ́de #BlackLivesMatter bẹ̀rẹ̀!"
Jọ̀ọ́, má wé orúkọ mi mọ́ ìjákulẹ̀ tó bá ọ - Seyi Makinde kìlọ̀ fún Lanlẹ́yin Iṣẹ́ ìlú ni ọkọ mi ṣe lọ ti wọ́n fi paá -Aya Ilori Òkú èèyàn mẹ́jọ ni wọ́n yọ níbi ìṣẹ̀lẹ̀ ìjàmbá ọkọ̀ nílùú Eko lọ́jọ́ Aje Ẹ̀mí ogójì ṣòfò, ọgọ́ta míràn farapa nínú ìjàmbá ọkọ̀ epo tó jóná Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí kan sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
Dokita Mike Ryan, tii se oludari iṣẹlẹ pajawiri labẹ ajọ WHO lo ṣe ikilọ naa pẹlu afikun pe, ki awọn eeyan dẹkun sisọ asọtẹlẹ nipa akoko ti ajakalẹ arun Coronavirus yoo kasẹ nilẹ.
" Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Sotitotbire: Ilé ẹjọ́ dá Alfa Babatunde padà sí áhàmọ́ọ́ bẹ́ẹ̀ni ó tún sún ìgbẹ́jọ́ si Ọjọ́-Bo̩16 Ẹrẹ̀nà 2020 Fídíò, Sotitobire: Mọ̀lẹ́bí ọmọ ọdún kan tó pòórá ní ṣọ́ọ̀ṣì figbe ta30 Òkùdu 2020 Fídíò, Sotitobire: Ìdájọ́ òdòdò ló fẹsẹ̀ múlẹ̀ lórí ọ̀rọ̀ Pásítọ̀ Sotitobire - Agbẹjọ́rò fún ìjọba7 Ọ̀wàrà 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Ọjọ kẹẹdogun osu kẹsan ọdun 2010, Jonathan kede loju opo facebook pe oun ti pinu lati du ipo aarẹ fun igba akọkọ.
Àgbọ̀nrín inú igbó pàápàá já ọmọ tí ó ṣẹ̀ṣẹ̀ bí sílẹ̀,nítorí kò sí koríko.
Unai Emery to jẹ akọnimọọgba Arsenal lọwọ bayii ni o ta Moura fun Tottenham.
“Ẹ ka iye àwọn ọmọ Israẹli, ní agbo-ilé agbo-ilé, ati ìdílé-ìdílé; kí ẹ sì kọ orúkọ gbogbo àwọn ọkunrin sílẹ̀ ní ọ̀kọ̀ọ̀kan.
Ohunkohun tí ó ń gbé inú omi, tí kò bá ti ní lẹbẹ ati ìpẹ́, ohun ìríra ni fun yín.
Ki lawọn onimọ ẹsin atawọn obi ọmọ Almajiri sọ?
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìwádìí kan ní Ilééṣẹ́ Facebook leè mọ ìgbà tí àwọn tó wà lójú òpó wọn bá ní ìbálòpọ̀ 12 Owewe 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ilééṣẹ́ Facebook mọ ìgbà tí àwọn tó wà lójú wọn ń nií ìbálòpọ̀ Awọn alaye ikọkọ kan, lara eyii ti igba ti eeyan ba n ni ibalopọ, ni ileeṣẹ Facebook lee mọ.
Òfin nípa Ìbálòpọ̀ Ọkunrin ati Obinrin.
Wọ́n mú etí kinni keji ẹ̀wọ̀n wúrà mejeeji, wọ́n so wọ́n mọ́ ojú ìdè wúrà ara ìgbàyà náà, wọ́n sì so wọ́n mọ́ èjìká efodu náà.
El-Rufai sọ ninu ikede ọhun pe oun yoo wa ni idanikanwa gẹgẹ bi ilana ajọ to n ri si idena ajakalẹ arun ni Naijiria, NCDC ṣe gbe kalẹ.
Àwọn olórí ogun rẹ̀ gbé òkú rẹ̀ sinu kẹ̀kẹ́ ogun kan láti Megido wọn gbé e wá sí Jerusalẹmu, wọ́n sì sin ín sinu ibojì rẹ̀.
Ija saba maa n waye laarin awon iko mejeeji yii , amosa, ko ti I si awijare Kankan lori ohun to fa isele naa.
Pilatu tún jáde lọ sóde, ó sọ fún àwọn Juu pé, “Mò ń mú un tọ̀ yín bọ̀ wá sóde, kí ẹ lè mọ̀ pé èmi kò rí i pé ó jẹ̀bi ohunkohun.
Agbabọọlu Man U, Anthony Martial lo kọkọ fi goolu sina iya fun Man City nigba ti idije naa wọ iṣẹju mọkandinlọgbọn.
Nigba ti awọn olujẹjo yooku, to fi mọ Ọgbẹni Moro, yọnda ara wọn fun iwadii, ti wọn si ti n jẹ jọ bayii, ajọ EFCC sọ pe Ọgbẹni Ahmadu ko yọju lati sọrọ l'ori ipa to ko ninu eto igbani sisẹ naa.
O gba ami ẹyẹ Grammy mejidinlogun nigba aye rẹ.
o pa àwọn eniyan rẹ ninu aṣálẹ̀ nítorí pé o kò lè kó wọn dé ilẹ̀ tí o ti ṣèlérí fún wọn.
Oluwatoyin Salau: Òkú Toyin làwọn ọlọ́pàáTallahassee ni àwọn rí lẹ́yìn ìpè rẹ̀ lórí twitter
Lionel Messi: Thiago Silva ìwà agọ̀ ló mú Messi sọ fun akọ́nimọ̀ọ́gbá Brazil pé kó gbẹ́nu dákẹ́
Bẹẹ lo ni asiko idakẹ jẹẹ fún àwọn ọmọ orilẹede Naijiria ti to gẹẹ, yoo si dara kí wọn dìde láti tako eru lasiko idibo.
Àkàrà olóyin dùn mọ́ Ẹkùn, ó ṣe iwadi bi òhun ti lè tún ri irú rẹ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Taraba: Àwọn Ọlọpàá ní ìwádìí ṣì ń lọ lówọ lórí ikú Fadá 30 Ògún 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 31 Ògún 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ilé isẹ́ olọ́pàá ìpínlẹ̀ náà ní àwọn jàgùdà Pipo lo se iṣẹ ibi naa ti wọn si dana sun un ninu ọkọ re.
Fasiti rẹ ba bẹrẹ si ni san 200 birr ($10) loṣu.
Ṣugbọn ajọ agbaye sọ pe ile ẹjọ mẹrin ọtọtọ lo ti dajọ pe ki wọn da igbẹjọ Onnoghen duro.
Nígbà tí Metusela di ẹni ọgọsan-an ọdún ó lé meje (187) ó bí Lamẹki.
Gege bi aare ohun se so, “ile-ejo ajo ECOWAS setan nigbakuugba lati ni ibasepo pelu ajo lorisirisi ni ona lati mu idagbsoke de ba ile Afrika, papaajulo lati tun le jo sowopo gbogun ti iwa-ibaje ti o gbode kan nile Adulawo.
A bi Olufunmilayọ Frances Abigail Thomas ni ilu Abeokuta, ni ipinlẹ Ogun, Naijiria ni ọjọ Kẹẹdọgbọn, oṣu kẹwaa, ọdun 1900.
Osu naa lo fẹra ku, ti ko si lee sọ ẹni to ni oyun, boya alawọ dudu ni abi alawọ funfun to jẹ afẹsọna rẹ.
Mo rò pé kò mọ́gbọ́n dání láti sọ tàbí kọ nǹkan kan l’ ésì si ohun tí Ààrẹ sọ.
Bí wọn se pọ to, awọn koko iroyin kan wa to jẹ manigbagbe.
Eyi lohun ti Said sọ fun akọroyin BBC.
Àwọn ọmọ tí Oholibama, ọmọ Ana, ọmọ Sibeoni, aya Esau, bí fún un ni Jeuṣi, Jalamu ati Kora.
Gán-na-gàn-na l'ó kù tí n ò ṣe
Lẹnu lọwọ lọwọ yii, ni iroyin gbode pe awọn eekan ẹgbẹ oṣelu APC ni ipinlẹ naa atawọn ọmọ ẹgbẹ naa kan, ti n gbe ina woju ara wọn lori fifi orukọ awọn ti yoo jẹ kọmiṣọna ranṣẹ si gomina naa.
”Ó ní,“Bí kò bá jẹ́ pé mààlúù mi ni ẹ fi tulẹ̀,ẹ kì bá tí lè túmọ̀ àlọ́ mi.
Nigba ti eeyan kan s pe ki wọn da ina ounjẹ orisi mejila ni arakunrin Husdsain ni ko sa'buru nibẹ.
eto idibo ti ajo INEC sun siwaju ku fun awon ara ilu.
” Aisaya bá ṣe bí OLUWA ti wí: ó bọ́ aṣọ ọ̀fọ̀ lára, ó sì bọ́ bàtà kúrò lẹ́sẹ̀.
 Nkan kan ni pe, baba mi sọ fun ọkọ mi pe ""mo nireti pe o ko ni di ọmọ mi lọwọ lati ma a lọ si ṣọọṣi."
Nigba ti mo wa ni ọdọ langba, wọn sọ pe mo ni ipenija Obsessive Compulsive Disorder (OCD).
Awọn Ọlọpaa sọ pe níṣe ni awọn ajinigbe naa yabo ile iwe naa pẹlu ibọn .
"Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ìdẹ̀ra dé, Gẹnẹrátọ̀ tó ń lo omi dé, a bọ́ lọ́wọ́ òkùnkùn Ẹ̀rù àti oríkunkun ló mú kíjọba máa fi ọlọ́pàá, ológun halẹ̀ mọ́ aráàlú - Ṣoyinka Irọ́ ló pa, a kò mọ̀ ọ́ rí tàbí fún ọ ní ₦13m - APC tako afurasí ajínigbé ""Ojú wa rí tó ní Egypt, bí wọ́n ṣe ń tẹ̀ wá lọ́mú, ni wọ́n ń gbá wa ní ìdí"" Ọlọ́wọ̀ tìlú Ọ̀wọ̀ tuntun gorí ìtẹ́, idà àlááfìà ló mú ní Ìpèbí Binta, ẹni to sọ pe o ku diẹ ko pe ogoji ọdun ti oun ti n sere tiata, tun fikun un pe oun korira ki obinrin maa si ara silẹ lasiko to ba n sere itage, O ni lati igba ti oun si ti bẹrẹ ere tiata, aye ko ri ihooho oun ju ejika oun lọ ri."
Kí ẹni ibi má baà lè ṣe àkóso,kí ó má baà kó àwọn eniyan sinu ìgbèkùn.
Ọjọgbọn Ogundipe fikun ọrọ rẹ pe alakalẹ wa lati yọ giwa fasiti nipo eleyi ti igbimọ alaṣẹ UNILAG ko tẹle to ba tiẹ jẹ pe lootọ ni wọn ti yọ ọ nipo.
Jẹ́ kí ẹ̀yìn wọn tẹ̀,kí wọn má lè nàró mọ́.
Maria bá dáhùn pé, “Iranṣẹ Oluwa ni mí.
Ọ̀nà igbó tí mo gbà tẹ́lẹ̀ kọ́ ni mo gbà padà o.
Oríṣun àwòrán, Others Tẹmitopẹ ni awọn ẹlomiran tilẹ ma n lọ ọna yii lati fi ra owo ile okeere, ti wọn a si ta a ni iye owo gọbọi fun awọn ẹlomiran.
Ìhà gúsù ilé náà ni àwọn Kerubu dúró sí nígbà tí ọkunrin náà wọlé, ìkùukùu sì bo àgbàlá ààrin ilé náà.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Silas Adekunle: Ó tún sẹ̀sẹ̀ fọwọ́sí àdéhùn alàìmọye mílíọ́nù dọ́là 7 Èrèlè 2018 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 19 Owewe 2018 Oríṣun àwòrán, Forbes Àkọlé àwòrán, Lẹyin ti Adekunle pari eto ẹkọ girama rẹ nilu Eko, lo tẹ ọ̀kọ leti lọ soke okun fun eto ẹkọ fasiti rẹ Silas Adekunle, tii se ọmọ Yoruba lati ipinlẹ Eko, ni onimọ ẹrọ to n se ‘Ẹrọ-deniyan’, taa mọ si ‘Rọbọti’, to n gba owo to pọ julọ ni ilu ọba.
Ọ́pọ awọn eeyan to ba BBC Yoruba sọrọ lo ni awọn n fẹ kawọn asaaju yii sisẹ, fun ipese awọn ohun eelo amayedẹrun lorisirisi si tibu tooro orilẹede yii.
Àbí ẹ̀yin fúnra yín kò mọ̀ pé Kristi Jesu wà ninu yín?
Lọwọ lọwọ bayii, ajọ kan ti kii se tijọba, to n gbogun ti iwa ipa ati ifiyajẹni ninu idile, ti fẹ yan ọmọ naa ni asoju ajọ naa, ti wọn n pe ni Ambassador.
"mv "" maersk andaman ( tẹ ́ lẹ ̀ tẹ ́ lè maersk alabama "" ) jẹ ́ ọkọ ̀ ojú omi ẹlẹ ́ rù ti maersk line limited tí ó wà ní ìmú ṣiṣẹ ́ waterman steamship corporation ."
Ninu ikede kan to fi sita l'oju opo ayelujara Twitter, gomina ipinlẹ Eko, Babajide Sanwo-Olu sọ pe lẹyin ti wọn pada ṣe ayẹwo fun ọkunrin naa ni wọn ri i pe ko ni arun naa lara mọ, lẹyin naa ni wọn si yọnda rẹ nileewosan.
O fidi rẹ mulẹ nigba to ba BBC Yoruba sọrọ pe ijọba ko lẹbi kankan ninu iṣẹlẹ to ṣẹlẹ.
Iroyin kan sọ pe Sala fi atẹjiṣẹ ranṣẹ si ore re kan ati awọn
"Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Nollywood: Ìdá 90% nínú àwọn olówó Naijiria lo n lọ ilé babaláwo 5 Ẹrẹ̀nà 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 6 Ẹrẹ̀nà 2020 Oríṣun àwòrán, Bolaji Amusan Àkọlé àwòrán, Ìdá 90% nínú àwọn olówó Naijiria lo n lọ ilé babaláwo- Mr Latin Àgbà òṣèré to tún jẹ́ gbájúgba nínú eré tíátà àti alaga ẹgbẹ́ òṣèré ẹ̀ka ti Tanpan ní Nàìjíría, ọ̀gbẹ́ni Bolaji Amusan, ti gbogbo ènìyàn mọ sí ""Mr Latin"" sọ ìhà tirẹ̀ lórí ẹsùn ti mínísita Raji Fasola fi kan Nollywood Mr Latin to jẹ́ alejo pataki lóri ètò àkànṣẹ́ ìfọ̀rọ̀wérọ ti ilé iṣẹ́ BBC lọ́sàn òni ọjọbọ to si fẹsì sí ọ̀rọ̀ kan ti o tẹnu mínísita orilẹ̀-èdè Naijira jáde wípe, àwọn òṣèré tíata ló kọ ara ilú bi wọ́n ṣe n ṣe òògùn owó kiri."
Ọjọ Aje, ọsẹ yii ni Aarẹ orilẹ-ede Naijiria, Muhammadu Buhari kede pe wọn yoo fi ọsẹ meji kun ofin konile-o-gbele lati koju arun Coronavirus to n tan kalẹ lorilẹ-ede Naijiria.
Àti àwọn ìbéèrè míràn 7 Èbibi 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 10 Èbibi 2020 Àkọlé àwòrán, Ìbéèrè àti ìdáhùn wọn O ti lé ni mílíọ̀nù mẹ́ta àti ọgọ́rùn ún mẹ́fà (3,600,000) ènìyàn to ni Corornavirus ni gbogbo àgbáyé tí ẹgbẹ̀rún lọ́nà ọtalenigba (251,000) ènìyàn ti kú- ẹgbẹ̀rún lọ́nà mokandinlogbonẹgbẹ̀run (29,000) nínú rẹ̀ ló wá láti UK nìkan.
Èmi nìkan ni gbogbo èyí ṣẹlẹ̀ sí tán!
Ogbeni Lai Mohammed, to je minista fun eto iroyin ati irinajo afe, ti kede pe sise akosile bi o ti ye nikan lo le mu idagbasoke ba irinajo afe ni Naijiria.
Ó sì ní ọpọlọpọ ọmọ sí i, lọkunrin ati lobinrin.
Awọn ibeere yii ati omilẹgbẹ miran lawọn ọmọ orilẹede Naijiria n beere bayii lori ikanni ayelujara gbogbo lati igba ti aarẹ ti gbe ọrs apilẹkọ rẹ jade.
Mí o ti lẹ̀ mọ pé lóju ayé mi mo lé rii asoju ijóba ti yóò gbèsẹ̀ lé a[wọn ilé ìgbìmọ aṣofin láti maa pé nílẹ̀ ìgbìmọ láti ṣe iṣẹ́ tí wọ́n yàn wọ́n láti ṣe, kí ni ìtumọ èyí ṣe Oliver Cromwell ti pada dé ní?
Ẹwẹ, titi di igba to gbe orin mii tuntun sita, ẹgbẹ MURIC ko tii gbe e lọ ile ẹjọ.
Oríṣun àwòrán, Femi Gbajabiamila/Facebook Ọrọ yii to tun jẹyọ lasiko to n du ipo olori ile, eleyi ti awọn alatako rẹ fi n sọ pe ko tọ ni ẹni to n di ipo olori ile asofin mu.
O ni oun dẹ sọ fun wọn pe maalu to ba wa lẹyin eleyii, ko fara mọ ohun toju ẹ ba ri.
Mùsùlùmí tó ń gbèrò láti lọ hajj ni Alhaji, Alhaja - Onímọ̀ Obìnrin Nàìjíríà tí wọ́n lù aago gbà njo lé lórí ní Lebanon sọ pé òun kò wá sílé mọ́ Agbẹnusọ ọlọpaa naa ni bo tilẹ jẹ pe wọn tete sin oku ọmọbinrin naa ki iwadii to bẹrẹ lẹkunrẹrẹ, awọn agbofinro yoo tu iṣu de isalẹ ikoko bi ọrọ ọhun ṣe jẹ.
CCT: Adájọ́ fẹ̀yìntì ní àwọn asòfin àpapọ̀ yẹ kó fòǹtẹ̀ lu ìgbẹ́jọ́ adájọ́ àgbà
Gẹgẹ bi ọlọpaa ṣe sọ, wọn n wa iya Hajia Filina to jẹ iya olooṣa naa, eeyan kan torukọ rẹ n jẹ Aliu to jẹ olukọ, Bumaye, Ashley ati Manafo, ti iroyin sọ pe wọn ti juba ehoro.
Bakan naa ni Aarẹ Buhari ya biliọnu mẹwaa dola, eleyii to ni o fi jẹ ogun biliọnu nigba naa.
Awọn mejeeji ti pin ya fun oṣu maarun ki ọkọ rẹ to pa.
Onimọ Ojikutu ni iba diẹ laaarin awọn ara Ekiti lo ni owo lati le rinrin ajo ofurufu, eyi to tumọ si wipe, owo ti wọn ba na si iru ọkọ ofurufu bẹẹ, ofo ṣaa ni.
Akosile iwadii ohun tun so pe, awon omode kekeke ti wn ko ni aye si omi ti dara mu, ni o seese ki won ku ni kekere, latari awon omi ti won mu, ryi ti o sokunfa aarun onigba meji, tabi igbe gbuuru, eyi ti o n sokunfa iku aitojo laarin awon omode ti ojo ori won koi ti to odun marun-un lorile-ede Naijiria.
aduroti rẹ  lasiko ti ipolongo eto idibo n lọ lọwọl,
Nigba ti asofin  Chukwuka Utazi,n soro lori iwe abadofin to pe ni  : “Lati mu ala to wa laarin awon ti won ni ati awon ti ko ni lorile ede Naijiria  kuro, ni eyi ti yoo fi din wahala to n sele lawujo ku”.
Ipinlẹ Ọyọ yoo da papa ijẹko silẹ fawọn darandaran
 Bakan naa ni o tun ki gbogbo ọmọ ẹgbẹ ati awọn oṣiṣẹ Ile Igbimọ Aṣofin Ipinlẹ Eko ku ayajọ awọn oṣiṣẹ tọdun 2018 yii.
Bí ẹgbẹ́ One Million Boys ṣe bẹ̀rẹ̀ rèé àti ọṣẹ́ tó ṣe n'Ibadan Wọn gbe Tolu digbadigba lọ si ile iwosan ṣugbọn ọwọ ti bọ sori, ẹlẹmi ti gba a.
Àwọn iranṣẹ tí àwọn adájọ́ rán wá lọ ròyìn ọ̀rọ̀ wọnyi fún wọn.
Iroyin kan sọ pe ọmọ orilẹ-ede Canada mẹjọ lo wa ninu ijamba baalu ọhun.
Laaarin ẹgbẹ oṣelu APC ati PDP ni awọn atundi ibo yii yoo ti waye.
Inú wá bí Jakọbu, ó bá bẹ̀rẹ̀ sí sọ̀rọ̀ sí Labani, ó ní, “Kí ni mo ṣe?
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Aṣọ ń pe aṣọ ránṣẹ́ ni lásìkò ìbúra gómìnà àti ààrẹ Ìtàn ìgbé ayé Abdulrahman Abdulrazak, gómìnà Kwara Èèyàn 5 farapa, ọ̀pọ̀ ọkọ̀ jóná nínú ìjàmbá iná márosẹ̀ Ibadan sí Eko Lọna ati fi idi okodoro ọrọ yii mulẹ, Akinyẹmi tun yii ẹrọ ibaraẹnisọrọ naa soke, ki akọroyin BBC le gbọ ohun Obasanjọ, ti oun funra rẹ naa tun sọ pe, ko si oun to ṣe oun ati wipe oun ko lọ ibi kankan, tabi wọ ọkọ ofurufu kankan.
Ohun ti awọn ileeṣẹ iroyin abẹle lorilẹede Naijiria kan n gbe kaakiri bayii ni pe, minisita Adeọṣun kọwe fi ipo silẹ ki ọrọ ẹsun ayederu iwe ẹri isinruulu NYSC ti wọn fi kan an ma baa pagi dina erongba ati pada sipo aarẹ lẹẹkeji eleyi ti aarẹ Buhari n gba fun ọdun 2019.
" Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Corornavirus: Ṣe lilo ìbọ̀wọ́ le dènà ààrùn Coronavirus Erongba awọn ọmọ Naijiria si abadofin ọhun Ọpọlọpọ awọn ọmọ Naijiria atawọn ẹgbe ajafẹtọẹni lo ti n sọ ohun ti wọn ro nipa abadofin naa loju opo Twitter pẹlu #stopncdcbill.
Oríṣun àwòrán, Others Oku Emmanuel si ni awọn ọlọpaa ba nilẹ pẹlu ọbẹ naa nigba ti wọn pe wọn sibi isẹlẹ ọhun.
Ṣugbọn OLUWA wà pẹlu mi bíi jagunjagun tí ó bani lẹ́rù.
si orile ede kan, to lee ni idagbasoke to mọnyan lori ,laijẹ pe o ni awon akinkanju
Kíni ẹ mọ̀ nípa Ọmọ́táyọ̀ Olútóyè, Ọ̀jọ̀gbọ́n obìnrin àkọ́kọ́ nínú ẹkọ́ èdè Yorùbá lágbàyé À ti fi àwọ̀n ọlọ́kadà 123 láti Jigawa sílẹ̀ -Ọlọpaa Ọwọ́ EFCC tẹ ọ̀kan lára àwọn ti FBI fi èsún jìbìtì kàn!
Oríṣun àwòrán, funkejennifaakindele Chief Daddy, Industreet, Isoken, Moms at War, A Trip to Jamaica, Pretty Liars, The Hero, Sheri Koko, Married But Living Single.
Ẹwẹ, onimọ eto ilera kan, dokita Wilson Ikubese sọ pe ko yẹ ko ri bẹ.
Bo tilẹ jẹ pe ko darukọ awọn orileede kankan ni pato, awọn to mọ nipa igbesẹ yii sọ pe, lara awọn orileede ti ọrọ yii le kan la ti ri Naijiria, Belarus, Eritrea, Kyrgyzstan, Myanmar, Sudan ati Tanzania.
 Ali Isa Pantami – Gombe, Minisita fun eto ibaranisọrọ (Communication) mọ́kàndínlógún) Emeka Nwajuba – Imo, Minisita abẹle fun eto Ẹkọ (Education), State ogún) Suleiman Adamu – Jigawa, Minisita fun ohun alumọni inu omi (Water Resources) mọ́kànlélógún) Zainab Shamsuna Ahmed – Kaduna, Minisita fun eto iṣuna ati aato ilẹ wa  (Finance, Budget and National Planning) méjìlélógún) Dr.
Jesu dáhùn pé, “Mo fẹ́ kí o mọ̀ dájúdájú pé, ẹnikẹ́ni tí a kò bá fi omi ati Ẹ̀mí bí, kò lè wọ ìjọba Ọlọrun.
Sibẹsibẹ, àṣẹ OLUWA ni àwọn ọmọ Israẹli ń tẹ̀lé kì báà ṣe pé ó jẹ mọ́ pé kí wọn tú àgọ́ wọn palẹ̀ ni tabi pé kí wọ́n tún un pa.
“Ẹ̀rù yóo bà á, yóo sì sá pada, yóo fi ibinu ńlá gbógun ti majẹmu mímọ́ Ọlọrun ati Israẹli, yóo sì máa tẹ̀lé ìmọ̀ràn àwọn tí wọ́n ti kọ majẹmu náà sílẹ̀.
Ohun gbogbo tí ẹ bá ń ṣe, ìbáà jẹ́ pé ẹ̀ ń sọ̀rọ̀ ni tabi pé ẹ̀ ń ṣe nǹkankan ni, ẹ máa ṣe é ní orúkọ Oluwa Jesu.
Nitori naa, ni mi o ṣe ra nkan ọmọ kankan.
O le ni ẹgbẹrun mẹrin le ni eeyan to ti tọwọ arun naa ku ni Germany to ni eeyan miliọnu mẹtalelọgọrin.
Bẹ́ẹ̀ náà ni ó pín ẹja meji náà fún gbogbo wọn.
Ìṣẹ́jú mẹ́ta sí ìgbà tí wọ́n padà láti ìsimi ní Ugochi Desire Oparanozie da kún un iṣoro Equatorial Guinea tí àmì ayò sì di 5-0.
Ọkan lara awọn afọbajẹ ilu Eko Oloye Fatai Abiodun Olumegbon, ti jade laye.
”Oluchukwu fikun pe, erongba awon odo naa ni lati sagbateru eto alafia jakejado orile-ede yii, besini a ro ijoba ipinle Benue lati jo sowopo gbe erongba ohun laruge.
” Ó bá na ọwọ́ sí Jehu, Jehu sì fà á sinu kẹ̀kẹ́ ogun rẹ̀.
O ti gbọdọ pari eto isinru ilu agunbanirọ pẹlu ojulowo iwe ẹri lọwọ.
Awọn to ti doloogbe si jẹ 628 Ìdí tí ìjóba ìpínlẹ̀ Eko fí ṣí àwọn ilé ìwé kan padà Ṣé lóòótọ́ ni pé Ambode ni APC fún ní tíkẹ́étì sẹ́nétọ́ fi dípò Osinọwo?
    “Kí ni èmi ha tíì ṣe fún yín, ẹ jọ̀wọ̀ ẹ máṣe ronú ikú, bàbá mi: ẹ jẹ́ kí ń ṣísṣẹ́ kí n di ẹni ti ń lówó lọ́wọ́ ki n ra agbádá ńlá ki n gbé e fún yín, ki n fi dàńdógó pàtàkì bọ̀ yín lọ́rùn, ki n ṣe fún yín bí ọmọ tí í ṣe fún bàbá.
Egbe awon olopaa obinrin ti won sese  se idasile re ni orile-ede Uganda laipe yii, ni  won pin aworan awon olopaa obinrin naa, ti won n dari oko loju-popo ni ilu naa kaakiri.
Ṣálángá oníhò tabi ile igbọnsẹ oniho jẹ irufẹ ile igbọnsẹ ti o n gba igbọnsẹ eniyan sinu iho ilẹ .
Ìpínlẹ̀ Katsina Gómìnà Aminu Bello Masari ti kéde pé ki wọ́n ti ilé ẹẹ̀ka lọ́jọ́ Àìkú, ọja kan lẹ́yìn ti àwọn awọ́n agbébọ̀n kọlu ilé ẹ̀kọ́ Govenment Science school ni ìlú Kankara.
jẹ ki ibasepọ to gboujẹ  fẹgbẹ- gbawo bọ,
ikoni-nija iko omo ogun ti n tesiwaju lati maa gbaradi fun awon olopaa, eleyi
Ati pe, o ṣe pataki fun ijọba lati ri i daju pe alaafia ati irẹpọ wa laarin awọn ọmọ ẹgbẹ awakọ nipinlẹ Oyo, nitori bi iṣẹ wọn ṣe ni ipa lara ọrọ aje.
Charly Boy ṣalaye pe irọ ni iroyin to n tan kalẹ lori ayelujara pe oun gba riba gẹgẹ bi ajafẹtọ ọmọniyan.
Bakan naa, ni aare tun se ipade po pelu awon omo egbe igbimo FEC, Federal Executive Council, adari awon ile-ise alaabo lorile-ede yii, nile aare ohun lojo isegun(Tuesday), niluu Abuja.
Ní kété tí Jehu parí rírú ẹbọ sísun rẹ̀, ó pàṣẹ fún àwọn olùṣọ́ ati àwọn olórí ogun pé kí wọ́n wọlé, kí wọ́n sì pa gbogbo wọn; ẹnikẹ́ni kò si gbọdọ̀ jáde.
Kí ló fà á t'Adeọsun tún fi wà lórí òpó ayélujára ìjọba?
Nitori naa, Helen ni oun ko kabamọ itan pe latara iṣẹlẹ ifipabanilopọ ni wọn ti bi oun.
Òróró ìpara rẹ ní òórùn dídùn,orúkọ rẹ dàbí òróró ìkunra tí a tú jáde;nítorí náà ni àwọn ọmọbinrin ṣe fẹ́ràn rẹ.
Alaga igbimọ naa, Onimọ ẹrọ Wasiu Olokunola ninu ọrọ rẹ, sọ pe igbimọ naa yoo ṣe iṣẹ to ni itumọ , nitori pe 'awọn ọmọ igbimọ naa ni iriri to yẹ ninu ile kikọ.
Ẹ óo sì mọ̀ pé èmi ni OLUWA Ọlọrun.
Oríṣun àwòrán, Iconnews Ìdí tí a fi pa àwọn àgbẹ̀ onírẹ̀sì ní Borno, Boko Haram ṣàlàyé nínú fídíò tuntun Ikọ agbebọn Boko Haram ti gbe fidio kan jade bayii ninu eyi ti wọn ti n fi ọwọ sọya pe awọn lawọn pa awọn agbẹ to le logoji ni ilu Koshebe nitosi Maiduguri nipinlẹ Borno.
owo Naira, ni wọn n gba lọdun; iṣẹ wọn kii sii ju ogoji wakati lọlọsẹ.
'A sinmi ìwádìí lóri Kemi Adeosun' Ọrọ aini ojulowo iwe ẹri NYSC ní Adeosun kòwé ransẹ́ láti gbààyè pe o sin ilẹ̀ baba rẹ nipa agunbanirọ lo jẹ ki o kọwe fipo silẹ.
Ajo to n gbogun ti iwa ibajẹ lorilẹede Naijiria, EFCC ti fi lede wi pe lootọ ni awọn fi panpẹ ofin mu olorin takasufe, Afeez Fashola, ti awọn eniyan m si Naira Mailey ati ikọ rẹ.
Ẹjẹ́ kí á kọ́ àwọn ọmọ wa ní ìgbélárugẹ Ásà, Èdè àti Ìṣe ilẹ̀ Yorùbá
Wò ó, bí kinniun tií yọ ní aginjù odò Jọdani láti kọlu agbo aguntan, bẹ́ẹ̀ ni n óo yọ sí Edomu n óo sì mú kí ó sá kúrò lórí ilẹ̀ rẹ̀ lójijì.
Lẹyin naa ni Sanwo-Olu parọwa si awọn eeyan ọhun lati Calm down"" paapaa lasiko ọdun Ileya to wole de wẹrẹ."
kẹ́rin  lasiko ti won fẹ lọ sin awon to
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ajọ Commonwealth jẹ́ ibaṣepọ awọn orilẹede to ti figba kan wa l'abẹ iṣakoso ilẹ Gẹẹsi Ṣaaju asiko yii, ohun ti ofin ilẹ Gẹẹsi faaye gba ni pe, ẹni ti i ki ṣe ọmọ orilẹede naa, ṣugbọn to fẹ ẹ darapọ mọ ileeṣẹ ologun wọn, gbọdọ ti gbe ni orilẹede naa fun ọdun maarun.
Gbogbo ẹyin onimọ Sayẹnsi ati ẹyin aṣewadii tẹ ṣe iṣẹ yii, a jẹ yin ni ọpẹ gidi gan o.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù 2019 Nigeria Budget: Wo pàsán ojú Buhari tó dá awuyewuye sílẹ 20 Ọ̀pẹ̀̀ 2018 Oríṣun àwòrán, Channels TV Àkọlé àwòrán, Aarẹ Buhari nibi ti o ti n ṣe agbekalẹ abadofin 2019 niwaju ile asofin Lọjọru ni Aarẹ orileede Naijiria Buhari lewaju awọn ọmọ igbimọ rẹ lo ṣe agbekalẹ abadofin isuna ọdun 2019 ṣugbọn oun ti awọn asofin ṣe fun lawọn eeyan n sọrọ nipa rẹ.
Mo ti ń wò ọ́ ninu ilé mímọ́ rẹ,mo ti rí agbára ati ògo rẹ.
Ni nkan bi ọdun diẹ sẹyin ni won bẹrẹ sii ni gberi ti wọn si mọ wọn si Neo Black Movement ni ibẹrẹ.
OLUWA tí ẹ sì ń retí yóo yọ lójijì sinu tẹmpili rẹ̀; iranṣẹ mi, tí ẹ sì tí ń retí pé kí ó wá kéde majẹmu mi, yóo wá.
Nítorí mo ti rẹkẹ idà mi lókè ọ̀run,yóo sọ̀kalẹ̀ láti ṣe ìdájọ́ àwọn ará Edomu;yóo sọ̀kalẹ̀ sórí àwọn tí mo fẹ́ parun.
- Ìjọba àpapọ̀ Ẹgbẹ́ Boko Haram pa àwọn òṣìṣẹ́ UN márùn ún tó wá ṣiṣẹ́ ìrànwọ́ ní Nàìjíríà Ṣe abẹwo si awọn ọrẹ ati ẹbi rẹ Nkan to yẹ Musulumi ni lati maa ṣe abẹwo si ẹbi ati ọrẹ ninu oṣu yii Kikọ itẹ oku O ṣe pataki lati ṣe afikun iye awon itẹ oku ni asiko oṣu ibukun yii.
Orísun ìyè ni ọgbọ́n jẹ́ fún àwọn tí wọn ní i,agọ̀ sì jẹ́ ìjìyà fún àwọn òmùgọ̀.
Ọgọrun ẹgbẹrun Naira owo oṣu oṣiṣẹ to kere ju - Awọn gomina ipinlẹ ati ẹgbẹ oṣiṣẹ ṣi n jiyan lori ọgbọn ẹgbẹrun Naira ti awọn oṣiṣẹ n fẹ gẹgẹ bi owo oṣu to kere ju.
akin ati ẹmi ifọkansin won lati mu idagbasoke ba awujọ ati eto ọrọ aje lorile
Ipinlẹ Kano lo ni eniyan to pọ ju ni orilẹede Naijiria gẹgẹ bi akọsilẹ eto ikaniyan ọdun 2006 ṣe sọ.
- Ooni Ile Ife Ohun tó yẹ kẹ́ẹ mọ nípà olùdíje mèjì tó lágbára nínú ìdìbò Ghana rèé O ṣalaye pe ọkan lara wọn ti orukọ rẹ n jẹ Alhaji Musa Hudu ti inagijẹ rẹ n jẹ Mai Cellular ko sí lára àwon yoku nigba ti wọn ya fọto papọ.
O ni wi pe ajọ oludiyele owo epo lorilẹ-ede Naijiria yoo maa boju wo bi nnkan ṣe n lọ si lọja epo rọbi lagbaye lati lee ma fun ajọ elepo rọbi lorilẹede Naijiria, NNPC atawọn ontaja epo ni amọran loṣooṣu lori ibi ti owo ori epo de duro Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Baby abandoned on dunmpsite: Mo ti bímọ mẹ́rin tẹ́lẹ̀ fún bàbá méjì nínú òṣí- Dupe Ogbomos Ki ni eyi tumọ si?
Lẹsẹkẹsẹ ni ọ̀rọ̀ náà ṣẹ mọ́ Nebukadinesari lára.
to n dije fun ipo abenugan kẹ́sán án, nile igibimo
Ile-igbim asoju sofin lorile-ede Nigeria tenumo erongba re lati fopin si jiji awon akekoo omodebinrin gbe, ati awon omo-ogun olote Boko Haram ti o n ja ran-in rain-in ni apa ariwa ila-orun orile-ede Naijiria.
Mo máa n forin mi kìlọ̀ ìwà ìbàjẹ́ láwùjọ ni -Hameen
Akọroyin BBC nilu Libreville, to jẹ olu-ilu Gabon, Charles Stephan Mavoungou jabọ iroyin pe, wọn fi panpẹ ofin mu oludari ileewosan naa l'ọjọ aje, wọn si fi ẹsun jiji ọmọ ikoko naa gbe kan an, bi o tilẹ jẹ wipe wọn pada fi oju fo ẹsun naa.
Nígbàkúùgbà tí ẹ bá ń mu ún, ẹ máa ṣe èyí ní ìrántí mi.
Wọn óo bẹ̀rù orúkọ OLUWA láti ìwọ̀ oòrùn,wọn óo bẹ̀rù ògo rẹ̀ láti ìlà oòrùn;nítorí yóo wá bí ìkún omi, tí ẹ̀fúùfù láti ọ̀dọ̀ OLUWA ń taari.
Alukoro ileesẹ ọlọpa ni asiko ti akọwe ileẹjọ ati awọn ọmọ onilẹ fẹ se amusẹ idajọ ileẹjọ to da wọn lare, lawọn eeyan kan to pe ni 'Janduku' jade sita si wọn, ti wọn si kọlu wọn, eyi to mu ki laasigbo waye nibẹ.
Wọ́n sì fa àwọn ọkunrin ìdílé Sabidi kalẹ̀ ní ọ̀kọ̀ọ̀kan, wọ́n bá mú Akani ọmọ Karimi, ọmọ Sabidi, ọmọ Sera, ti ẹ̀yà Juda.
Àwọn ọmọ ẹ́gbẹ́ NURTW kọjú ìjà síra wọn nítorí ipò l'Ekiti Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, #Queen Dihya: Obinrin tó gbógun tàwọn agbésùnmọ̀mí ni Algeria Aarẹ Buhari wa kesi Ajọ Ọlọpa lati fi gbogbo eto aabo sipo, ki alaafia le jọba ni agbeegbe naa lai doju ofin bolẹ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, The seed: Àwa sì wá láti mú ẹ̀bùn fún Ọba tí a bí lónìí Moms at War Funke Akindele, iya ibeji tuntun Funke Akindele ti di ìyábejì àti Omoni Oboli ni wọn jọ jẹ olu ẹda itan inu fiimu yii.
Ẹ yin Ọlọrun ninu ibi mímọ́ rẹ̀;ẹ yìn ín ninu òfuurufú rẹ̀ tí ó lágbára.
Nígbà tí ó yá ìyá rẹ̀ ati àwọn arakunrin rẹ̀ wá, wọ́n dúró lóde, wọ́n bá ranṣẹ pè é.
Nígbà tí Jesu jí dìde ní òwúrọ̀ ọjọ́ kinni ọ̀sẹ̀, ó kọ́ fara han Maria Magidaleni, tí Jesu lé ẹ̀mí èṣù meje kúrò ninu rẹ̀ nígbà kan.
Gbà mí lọ́wọ́ ẹ̀bi ìpànìyàn, Ọlọrun,ìwọ Ọlọrun, Olùgbàlà mi,n óo sì máa fi orin kéde iṣẹ́ rere rẹ.
Ija to waye laarin Femi Fani-Kayode ati ileeṣẹ iroyin Daily Trust ko ṣẹyin bi Fani-Kayode ṣe sọ ọrọ odi si akọroyin wọn lasiko ti Fani-Kayode n ba awọn akọroyin sọrọ ni Calabar, ni ipinlẹ Cross River.
Igbimo egbe awon osise lorile ede Naijiria (Nigeria Labour Congress, NLC) ti ni aheso oro lasan ni pe awon ko ti i fenuko lori ekunwo owo osu awon osise , ni eyi ti o ti ye ki ijoba apapo ti bere si ni maa san.
Ní ìbẹ̀rẹ̀ oṣù yìí, Ààrẹ Ilham Aliyev, tí ó di olórí ilẹ̀ Azerbaijan ní Oṣù Ọ̀wàrà ọdún 2003, ṣe ìtakùrọ̀sọ alákọ̀ọ́kọ́ọ rẹ̀ pẹ̀lú ilé ìṣẹ́ amóhùn-máwòrán ti ìlúu rẹ̀.
Lẹnnox Lewis: ni ọjọ kejilelogun ọdun 2001, Hasim Rahman ya agbaye lẹnu nigba to na Lennox Lewis to jẹ odu akanṣẹ nigba naa.
Orílẹ̀ èdè Gẹ̀ẹ́sì ni ìlú náà wà.
- Ọ̀gá àgbà ọlọ́páà Ọlọ́pàá hú òkú akẹ́kọ̀ọ́ fásítì LASU tí ọ̀rẹ́kùnrin rẹ̀ àti pásítọ̀ ṣekúpa Èèmọ̀!
Bẹ́ẹ̀ ni ẹ ó ṣe yọ ibi kúrò láàrin yín; gbogbo Israẹli yóo gbọ́, wọn yóo sì bẹ̀rù.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Yomi Lanso wipe ka jọ gbadun laye Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Yomi Lanso wipe ka jọ gbadun laye 5 Ẹrẹ̀nà 2018 Yomi Fash Lanso wipe oun tako ki awọn ojisẹ Olorun maa fẹla laye sugbọn ki wọn ma sọ fun ọmọ ijo pe igbadun tiwọn wa lọrun.
COZA: Ṣe Ilé ejọ́ Abuja ti ké si Fatoyinbo ati Busola Dakolo pé kí wọ́n yọjú?
Dídún ohun èlò orin Xylophone yii ni Nurudeen ti ṣalaye ọpọlọpọ idan ti o le pa.
 eléyìí lè jẹ ́ gẹ ́ gẹ ́ bí ẹ ̀ sìn ìdílé tàbí àwọn àwòrò òrìṣà tó jẹ ́ dandan fún wọn láti jẹ oyè àwòrò bí ó tilẹ ̀ jẹ ́ pé ẹlẹ ́ sìn mìíràn ni wọ ́ n nítorí ìdílé wọn ló ń jẹ oyè náà .
“Nisinsinyii, mo ti pinnu láti bá OLUWA Ọlọrun Israẹli dá majẹmu, kí ibinu gbígbóná rẹ̀ lè kúrò lórí wa.
Ijọba Naijiria sọwipe awọn ti bori ikọ Boko Haram- njẹ otito ni?
Ọpọ musulumi ni wọn ti ra ẹran agbo fun ayẹyẹ ọdun Ileya, ṣugbọn oniṣowo ẹran agbo ni Ojurin lagbagbe Alẹṣinlọyẹ niluu Ibadan, Ọgbẹni Fatai Ibrahim sọ fun BBC Yoruba pe awọn ẹran agbo t'oun ta ni ẹgbẹrun mẹẹdọgbọn nairia lọdun to lọ ti di ẹgbẹrun un mejilelogub bayii.
Amọṣa orukọ Ajayi Shuaib ni wọn ṣalaye pe o han ninu iwe ipẹjọ ti nọmba idanimọ rẹ jẹ FHC/OS/16/19 niwaju ile ẹjọ giga apapọ to wa nilu Oṣogbo pe o pe ẹjọ lorukọ ara rẹ atawọn ọmọ ẹgbẹ oṣelu naa kan lati fi ẹhonu han lori ẹsun ayederu iwe ẹri ti wọn fi kan Sẹnetọ Ademọla Adeleke.
Afẹ́fẹ́ gáàsì tí gbiná ní Ijora ìpínlẹ̀ Eko, bó ṣe n ṣẹlẹ̀ rèé Ẹkún àti ìbànújẹ́ láwọn mọ̀lẹ́bí fi sìnkú ọmọ méje ní Kumba, Cameroon lónìí Ìdájọ́ ikú ló bá dé fáwọn méjì tó fipá bá ọmọ ọdún mẹ́rìnlá lò pọ̀ Atẹjade naa ti olori awọn obinrin ẹgbẹ APC ipinlẹ Oyo, Mabel Williams ati igbakeji rẹ, Toyin Ajibade buwọlu ki Florence Ajimobiu ku irọju.
Bakan naa ni Bashir Ahmad to jẹ oluranlọwọ fun aarẹ Buhari lori eto iroyin igblode naa fi sita pe ẹbi awọn ti ọrọ kan ti fidiẹ mulẹ pe wọn san owo itanran ni.
Gbogbo ẹni to ba n lo opo MTN, Airtel, 9mobile ati Glo lo le lo nọmba yiNCC salaye pe o di dandan ki gbogbo ẹni to ba ni siimu lati je ki iroyin wọn pe perepere.
Ile-ise ohun so eyi di mimo ninu iroyin ori eto irina oko re  ti won gbe si ori ero ayelujara ninu osu kinni odun 2018.
Ṣugbọn ẹ dá ìkógun ati àwọn ẹran ọ̀sìn tí ó wà níbẹ̀ sí, kí ẹ sì kó o gẹ́gẹ́ bí ìkógun fún ara yín; ẹ ba ní ibùba lẹ́yìn odi ìlú náà.
Ní gbogbo Ọjọ́ Ìsinmi, a máa bá àwọn eniyan sọ̀rọ̀; ó fẹ́ yí àwọn Juu ati Giriki lọ́kàn pada.
Eto ipese ounjẹ naa gbajumọ debi wi pe, ijọba apapọ Naijiria ya lo, to si di eto ti ijọba apapọ naa n ṣe lati pese ounjẹ fun awọn akẹkọ lawọn ipinlẹ jakejado Naijiria.
Nítorí pé ninu ìròyìn tí àwọn ará Kiloe mú wá, ó hàn sí mi gbangba pé ìjà wà láàrin yín.
"Laolu Akande lo ń fèsì sí àpilẹkọ kan ti Festus Adedayo kọ apilẹkọ kan to kọ jade nínú ọ̀pọ̀ iwé ìròyìn lórí ayelujára lọ́jọ́ ajé to pe akọle rẹ ni ""The Trials of Brother Osinbajo""."
Eyi ko ṣẹyin igbesẹ Ile Igbimo Aṣofin naa lati yọ ọ ni ipo.
Uganda: Ila Oorun Aduilawọ ni ilu yii ti o si ni ibi itan bii obo Victoria ati awọn miiran ti o si fi aaye gba gbigba iwe ni ẹnu ọna iwọle.
Àìsí iṣẹ́ nígboro lọ̀pọ̀ ọ̀dọ́ fi fẹ́ gba iṣẹ́ Amotekun - Toogun A ti gba àwọn òṣìṣẹ́ 15,000 làti ṣètò ìdìbò gómìnà ní ìpínlẹ Ondo lóṣù kẹwàá - INEC Wo iye àwọn tó ti gbẹ̀mí ara wọn ní Nàìjíríà láàrin ọdún mẹ́rin ìjọba Buhari Gbèsè Nàìjíríà ti lé ní 18 tírílíọ́ọ́nù lábẹ́ ìṣèjọba Ààrẹ Buhari- DMO Wo ìyá ọlọ́mọ mẹ́ta tó ti pé ọdún 48 tó ń ṣe ìdánwò WAEC, kó le di nọ́ọ́sí Ileeṣẹ ọlọpaa sọ pe ọkunrin kan Samuel Joseph lo mu ẹjọ Danladi wa lọjọ kinni, oṣu kẹsan an, ọdun 2020 yii.
Ẹgbẹ oṣelu Republican si ni ibo miliọnu mẹrinlelaadọrin ati ẹgbẹrun lọna igba, (74.
Babiloni, ìwọ tí o lógo jù láàrin gbogbo ìjọba ayé, ìwọ tí o jẹ́ ẹwà ati ògo àwọn ará Kalidea,yóo dàbí Sodomu ati Gomora,nígbà tí Ọlọrun pa wọ́n run.
Revolution Now: Sowore, Bakare gbé ọga DSS lọ sílé ẹjọ́, wọn ń bèèrè fún bílíọ̀nù kan náírà
Orile ede Naijiria yoo tun tubo tesiwaju lati maa fowosowopo pelu ijọba ati awon omo orile ede Vanuatu, nipa eto oro aje ati ibasepo.
Àwọn ọmọ Israẹli pa Ogu ati àwọn ọmọ rẹ̀ ati gbogbo eniyan rẹ̀.
Nítorí mò ń gbọ́ tí ọpọlọpọ ń sọ̀rọ̀ kẹ́lẹ́kẹ́lẹ́ pé,“Ìpayà wà lọ́tùn-ún lósì,ẹ lọ fẹjọ́ rẹ̀ sùn.
jẹ́ ẹgbaa mejidinlọgbọn ó lé egbeje (57,400).
OLUWA ní kí n sọkún tẹ̀dùntẹ̀dùn nítorí àwọn olórí Israẹli, 
Amòfin náà wí fún un pé, “Bẹ́ẹ̀ gan-an ni, Olùkọ́ni.
Ó bá pada lọ sí ilé rẹ̀.
Lana ode oni ni ẹgbẹ awọn gomina ni iwo-oorun Naijiria sọ pe awọn Fulani darandaran ni anfaani lati duro nile Yoruba.
Nítorí náà, ẹ rẹ ara yín sílẹ̀ lábẹ́ ọwọ́ Ọlọrun tí ó lágbára, yóo gbe yín ga ní àkókò tí ó bá wọ̀.
Minisita naa sọ pe ileeṣẹ eto ẹkọ yoo pese atẹjade awọn akoko ti idanwo ọhun yoo waye lẹyin ipade pẹlu ajọ NCDC, ẹgbẹ awọn olukọ, NUT, atawọn ajọ miran ti ọrọ kan.
Hubert Ogunde rèé, baba àwọn òsèré tíátà Iyabọ Ojo wa kadi ọrọ rẹ nilẹ pe gbigbe ija ara wa kii se isẹ awọn gbajumọ nikan, gbogbo wa lo kan,to ba si jẹ pe ikọlu to n waye lorilẹ ede South Africa ka onitọun lara, yoo dara ko kuku maa bọ pada wa sile, ki gbogbo wa dijọ pawọpọ mu ayipada rere ba orilẹede yii.
O ni awọn oṣiṣẹ ajọ naa lo ṣe iṣẹ naa ṣugbọn ko tii le fi idi rẹ mulẹ iye awọn ti wọn mu nibẹ.
Iroyin kan ti ko fidi mulẹ, to n ja rainrain lori ayelujara salaye pe, ọmọde kan to n se ounjẹ lasiko ti iya rẹ n wo ere lori mohunmaworan lọwọ, lo se okunfa ijamba ina naa.
Amọ ko sai fikun pe oun si n tẹsiwaju lori iwadi oun lori isẹlẹ naa.
Oríṣun àwòrán, Instagram/Anthony Joshua Ẹ o ranti pe Ruiz Jr ya agbado ha si ọpọlọpọ lẹnu nigba to lu Joshua bi ẹni n lu bara nigba ti wọn kọkọ koju ara wọn niluu New York, lorilẹede Amẹrika.
Adamu Shehu to je alukoro fun ajọ ẹlẹto abo ara ẹni labọọlu (Nigeria Security and Civil Defence Corps) lo kẹdẹ ọrọ naa.
Àwọn òkú wa yóo jí,wọn óo dìde kúrò ninu ibojì.
OLUWA yóo mú ìpọ́njú ńlá bá ẹ̀yin ati arọmọdọmọ yín, ìpọ́njú ńlá ati àìsàn burúkú, tí yóo wà lára yín fún ìgbà pípẹ́.
Lasiko naa, gomina Ọgagun Robert Adeyinka Adebayo lo wa nipo, nigba naa lo gori oye ti wọn si gbe ọpa aṣẹ le e lọwọ.
    Àkíyèsí kan tí a bẹ̀rẹ̀ sii ṣe ni pé ìgbà tí a ba ń wo iwájú tí a ri tí ẹnìkan ń bọ̀ lọ́dọ̀ wa, ìgbà tí ó bá ṣe, a kò tún ní rí olúwarẹ̀ mọ́, ìgbà tí a bá sì maa wo ẹ̀yìn, a o ri i pé olúwarẹ̀ ti kọjá sẹ̀yìn wa.
Nibayii ọpọ aworan eyi lo si ti lu ori ayelujara pa.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Bakan naa, ni awọn miran to tun wa nibi ipade ti alaga igbimọ ile lori ọrọ ere idaraya, Abdullahi Adegbile pe ni awọn Alakoso ẹgbẹ agbabọọlu Osun United.
lo sibe lati lo pese aabo to peye.
Kò ní ṣàròyé, bẹ́ẹ̀ ni kò ní pariwo,bẹ́ẹ̀ ni ẹnìkan kò ní gbọ́ ohùn rẹ̀ ní títì.
Nítorí bí ó bá jẹ́ pé èmi fúnra mi ni mo yàn láti máa ṣe iṣẹ́ yìí, mo ní ẹ̀tọ́ láti retí èrè níbẹ̀.
Iná èèsì kìí jóni lẹ́ẹ̀mejì - Ọbásanjọ́ Lai Mohammed so pé àwọn kò ní jẹ kí ''ọrọ ti kò fidimule kánkan yí ìpinnu awọn pada, pàápàá jùlọ lẹyìn ìgbà tí àwọn ṣẹṣẹ kéde ìyípadà ti gbogbo ara ìlú tẹwọgbà.
Bakan naa ni ijoba tun gbodo pese eto ilera ofe ati awon ohun elo itoju ni awon ile-iwosan ni igberiko gbogbo lati se adinku iku alaboyun ati awon omo-wewe”.
Lori boya awọn agbaagba ẹgbẹ naa ṣe atilẹyin fun ọkan ninu awọn oludije naa, amofin Oke sọrọ ni kikun.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Kin lo de ti ọ̀rọ̀ ajínigbé ni Kaduna ń peléke síi?
"Àràn àfòmọ ́ ń tàn káàkíri nípa àwọn ìgéjẹ ti eṣinṣin dúdú ti irúfẹ ́ "" simuliumu "" ."
Ki ṣe iṣẹ́ akànṣẹ́ nikan ni Muhammad Ali dúró fún, ó dúró fún ohun ti ó gbàgbọ́ lai bẹ̀rù.
Ọlọrun si n ra baba lori omi.
Owo yii si re, owo ilu ni, eyi to yẹ ki a na si mimu igbe aye idẹrun ba ara ilu.
Hardy, ti dopin, sugbọn ti Naijiria ko ṣe i mi.
 Àwọn òbí rẹ ̀ ni michel akínlàdé àti elizabeth akínlàdé .
Ẹ óo máa rú ẹbọ yìí pẹlu ẹbọ ohun jíjẹ ati ẹbọ ohun mímu rẹ̀, gẹ́gẹ́ bíi ìlànà ti ọjọ́ kinni, 
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Amotekun: Àwọn aṣòfin Yorùbá ní ikọ̀ aláàbò náà yóò bẹ̀rẹ̀ iṣẹ́ lọ́sẹ̀ díẹ̀ s‘ásìkò yìí 4 Ẹrẹ̀nà 2020 Ọjọ Iṣẹgun ni abadofin ikọ Amọtẹkun kẹsẹjari kaakiri gbogbo ipinlẹ to wa ni ẹkun iwo oorun Naijiria lẹyin ti awọn ile asofin ni awọn ipinlẹ mẹfẹẹfa buwọlu.
Nigba to n sọ bi nọmba naa yoo ṣe maa ṣiṣẹ, Gomina Seyi Makinde ni awọn olugbe ipinlẹ Ọyọ to ba n dojukọ ipenija aabo bi idigunjale, rogbodiyan, ijamba ina jijo, tabi awọn ijamba miran lee pe fun iranwọ ajọ gbogbo to ba yẹ ni kiakia.
Asán ni èyí pẹlu, nǹkan burúkú sì ni.
Mo lọ lọjọ Aje, ọjọ Iṣẹgun.
Díẹ̀ nínú àwọn èròjà ọ̀hún rèé:
Abrahamu kò hu irú ìwà bẹ́ẹ̀.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Ó ṣojú mi kòró, ẹ wọ bí ìgbà ayé Bàbá Fagunwa ṣe rí' Nitori naa ni Ọbabinrin Daurama ṣe fẹ ẹ.
‘Aláìsàn la fi ẹlikọ́pútà gbé lópòpónà Benin sí Ọ̀rẹ̀’ Lónìí, ìdíjé náà ń tẹ̀síwájú láti tún mọ orílẹ̀-èdè mẹ́jì tí yóò kú.
Bákan náà ni bí wọ́n ṣe n kéde ikú ọ̀hún le nípa lóri iyé ènìyàn tó kú.
Ikú òjijì kò jìnnà àmọ́ ọ̀nà méje rèé láti dènà rẹ̀ Kenyon ni lẹyin tawọn agbebọn kọlu ọkọ tawọn ẹgbẹ agbabọọlu Togo wa ninu rẹ, loun ṣe ifọrọwanilẹnuwo pẹlu agbẹnusọ ikọ naa, tii ṣe Emmanuel Adebayor, to n ṣoju ikọ agbabọọlu Manchester City nigba naa.
Nana Akufo-Ado New Patriotic Party Ọjọ kọkandinlọgbọn oṣu kẹta ọdun 1944 ni wọn bi William Dankwa Akufo-Addo.
Ìgbìmọ̀ lọ́balọ́ba l'Ọ́sun ní kí Oluwo lọ rọ́ọ́kún nílé fún oṣù mẹ́fà Iroyin to n tẹ wa lọwọ ti kede pe igbimọ lọbalọba nipinlẹ Ọsun ti ni ki Oluwo tilu Iwo, Aba Abdulrasheed Akanbi lọ rọọkun nile fun osu mẹfa gbako.
oúnjẹ tí ó wà lórí tabili rẹ̀ ati bí àwọn ìjòyè rẹ̀ ti jókòó, àwọn iranṣẹ rẹ̀, ìwọṣọ ati ìṣesí wọn, àwọn agbọ́tí rẹ̀ ati ìwọṣọ wọn, ati ẹbọ sísun tí ó ń rú ní ilé OLUWA, ẹnu yà á lọpọlọpọ.
 Àrùn yíì lèràn láti ìyá sí ọmọ-inú oyún àti okùnfà microcephaly .
Ní àkókò yìí, baba rẹ̀ pàgọ́ ogun rẹ̀ sí abẹ́ igi pomegiranate kan ní Migironi, nítòsí Gibea.
Ó bá súnmọ́ Jesu, ó fi ẹnu kò ó ní ẹ̀rẹ̀kẹ́.
Bakan naa ni ẹgbẹ naa tun kọminu lori ẹgbẹ kan ti wọn ni o dide lapa oke Ọya to n fun ijọba apapọ ni gbedeke ọgbọn ọjọ lati bẹrẹ eto RUGA ni gbogbo ipinlẹ Naijiria bi wọn ko ba fẹ ki awọn dana wahala silẹ.
Aare fi ibanuje re han lori iku ogbontarigi akosemose lori isiro owo ati oloselu yii.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Osinbajo: Nasir El-Rufai ní igbákejì ààrẹ, Yemi Osinbajo ni alága àwọn 'kògajùgò' lórílẹ̀èdè Nàìjíríà 6 Èbibi 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 12 Èbibi 2020 Oríṣun àwòrán, Governor kaduna Ṣe ẹ mọ pe ai pepade awọn otoṣi ni ko jẹ ka mọ alaga iṣẹ?
Mose pẹlu Aaroni ati àwọn ọmọ wọn yóo pa àgọ́ tiwọn sí ìhà ìlà oòrùn, níwájú Àgọ́ Àjọ.
Tesiwaju si, Agara ati awon alabarin re wa lo sabewo si awon eniyan mẹ́tàdínlógójì ti o farapa nile iwosan Dalhatu Araf, niluu Lafia.
Èrò ọkàn mi ati ìran tí mo rí lórí ibùsùn mi kó ìdààmú bá mi.
 Igbese  yii tun wa lara ipinnu ijoba lati tan isoro to maa n dojuko awon onisowo keekeeke, awon onise owo, paapaa julo awon to n wa ekusa lorile ede Naijiria.
 láìsí óunjẹ yoo ṣòro fún ènìyàn lati máa gbé ní àlàáfíà , nítorí pé okun tinú la fi ń gbé tìta .
Eléyìí náà ni yóò sì fi hàn gbogbo ènìyàn irú ọmọ tí ìwọ yóò jẹ́, yálà bí ó bá ni lè tó ẹrù bàbá rẹ ẹ gbé, tàbí bẹ́ẹ̀ kọ́, bẹ́ẹ̀ ni Oyińdeyépọ̀ bàbá rẹ kìí ṣe kékeré ọkùnrin.
Oríṣun àwòrán, @NGRSenate Àkọlé àwòrán, aisi ifọkansin to loorin lati ọdọ ijọba gbogbo kun ara isoro ọgba ẹwọn lorilẹede Naijiria Ọga agba ileesẹ ọgba ẹwọn naa ni pẹlu bi ọda owo awo olokun se n ba ileesẹ ọgba ẹwọn orilẹede Naijiria finra to, ileesẹ naa n gbe igbesẹ lati mu igba ọtun ba awọn ẹlẹwọn rẹ gbogbo.
Gomina ipinle Kwara Alhaji Abdul Fatah Ahmed lo parowa yii leyin ipade
Ile alaja mẹta naa to wa ni Ita Faaji ni agbegbe Lagos Island lo wo lọjọ kẹtala oṣu Kẹta, to si fa ifarapa ati iku fun diẹ lara awọn to n gbe ninu ile naa.
Yorùbá dùn lédè, ẹ máa sọọ́ Ẹfunroye Tinubu - Ògbóǹtagí oníṣòwò, olówò ẹrú àti afọbajẹ Samuel Ajayi Crowther, òjíṣẹ́ Ọlọ́run tó gbé èdè Yoruba lárugẹ Mọrèmi Àjàṣorò, akọni obìnrin tó gba Ilé Ifẹ̀ sílẹ̀ lóko ẹrú Ọ̀rọ̀ǹpọ̀tọ̀niyùn, Aláàfin obìnrin àkọ́kọ́ rèé, tó ní nǹkan ọkùnrin Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, BBC Yorùbá: Temidayọ Ọlọfinsawo ní kò rọrùn láti darí òṣìṣẹ́ ọlọ́pọlọ pípé Yomi Fabiyi gboriyin fun Baba Suwe fun ipa ribiribi to ko ninu igbesi aye rẹ ati bi o se da olokiki eniyan ninu isẹ osere.
Kí wọ́n kó o sórí igi, ṣugbọn kí wọ́n má fi iná sí i.
Ninu atẹjade ti Ajọ SERAP gbe lede, Kolawole Oluwadare ni Fashola fi sọwọ si wọn gẹgẹ bi ilana ofin to rọ mọ ‘Information Act’ ti orilẹede Naijiria to fọwọ si wi pe ti ọmọ Naijiria ba bere iwadii kikun lori isẹlẹ, wọn gbọdọ fi lede.
O tenumo pe, aworan ti awon olopaa pese.
MKO Abiola: Ọmọ 23 ni bàbá MKO Abiọla bí saájú rẹ̀, àmọ́ òun ni àkọ́bí
Ṣé ọmọbinrin lè gbàgbé ohun ọ̀ṣọ́ rẹ̀?
Ó bá bi wọ́n báyìí pé, “Ta ni ninu yín tí yóo ní aguntan kan, bí ọ̀kan náà bá jìn sí kòtò ní Ọjọ́ Ìsinmi, tí kò ní fà á jáde?
Ìwọ ni o fọ́ àpáta tí omi tú jáde, tí odò sì ń ṣàn,ìwọ ni o sọ odò tí ń ṣàn di ilẹ̀ gbígbẹ.
Ẹ má tan ara yín jẹ, kò sí àwọn oníṣekúṣe, tabi àwọn abọ̀rìṣà, àwọn àgbèrè tabi àwọn oníbàjẹ́, tabi àwọn tí ó ń bá ọkunrin lòpọ̀ bí obinrin; 
Oríṣun àwòrán, @akhirebhulu Ṣọyinka wa rọ ijọba atawọn oṣiṣẹ eleto aabo lati jawọ ninu apọn ti o yọ, ki wọn da omi ila kana.
Nítorí pẹlu ọkàn ni a fi ń gbàgbọ́ láti rí ìdáláre gbà.
Bẹ́ẹ̀ ni Saulu ati àwọn ọmọ rẹ̀ mẹta, ati ọmọkunrin tí ń ru ihamọra rẹ̀ ati àwọn ọmọ ogun rẹ̀ ṣe kú ní ọjọ́ kan náà.
Ile iṣe ọlọpaa Naijiria lawọn kaju osunwọn lati koju ipenija ijingbe yi amọ ko jọ bi pe ipa wọn ka awọn ajinigbe naa ti iroko wọn ṣebi ẹni n pẹka si.
 Ọ ̀ sà yìí tòrò níwọ ̀ nba , tí àwọn ọkọ ̀ ojú omi nla tó ń gba ojú òkun kìí dàárú .
Yóo sì yọ àwọn nǹkan wọnyi ninu rẹ̀ láti fi rú ẹbọ tí a fi iná sun sí OLUWA: gbogbo ọ̀rá tí ó bo àwọn nǹkan inú rẹ̀, ati ọ̀rá tí ó bo ìfun rẹ̀, 
BBC gba'lejo ife agbaye FIFA Nàìjíríà bọ́ lọ́wọ́ àáké FIFA FIFA yan Infantino gẹ́gẹ́ bí ààrẹ fún sáà kejì Fifa yóò sọ olùgbàlejò Ife Àgbáyé 2026 Awọn orilẹ-ede mẹrinlelogun ni yoo kopa ninu ti ọdun 2019 FIFA f'òfin de Chelsea lórí ríra agbábọ́ọ̀lù Gbẹgẹdẹ gbiná ni Ghana, GFA gba rìbá!
Sibẹsibẹ awọn ọlọpaa ni awọn mu awọn afurasi to le ni igba t'awọn fura sì pe wọn kopa ninu ija to waye laarin awọn ẹgbẹ okunkun meji kan lẹyin iku ọkan ninu awọn olori wọn.
Ẹ wá tún di ẹ̀bi ẹ̀jẹ̀ ọkunrin yìí lé wa lórí?
Amọ lara awọn ayaba naa la ti ri awọn olo, ẹlẹjẹ tutu, apọnbeporẹ, orekelẹwa, ẹlẹyinju ẹgẹ, eyinfunjowo ati Ibadi aran, ti wọn jẹ mẹjọ, ti wọn maa n se idije lawọn oju opo ayelujara wọn, lati jẹ ki araye mọ pe ọla Alaafin ni awọn fi n yan.
Ìlànà ni èyí yóo jẹ́ fún arọmọdọmọ yín ní gbogbo ilẹ̀ yín títí lae.
Atiku sí America: Ẹ má fìyà ìjọba tó ń kùnà jẹ àwọn ọmọ Nàijíríà
Ó ṣe àgbàlá kan yí àgọ́ ati pẹpẹ náà ká, ó ta aṣọ sí ẹnu ọ̀nà àgbàlá náà.
Ní gbogbo àkókò yìí, Samuẹli ń ṣe iṣẹ́ iranṣẹ sin OLUWA, ó sì jẹ́ ọmọde nígbà náà, a máa wọ ẹ̀wù efodu funfun.
 Èdùmàrè báwa fún Babasuwe ní àlàáfíà tó péye
Oríṣun àwòrán, Genesis global/facebook O kiri ọja bi mọin-mọin ati burẹdi, bakan naa lo sẹ awọn iṣẹ pẹẹpẹẹpẹ lati ran awọn obi rẹ lọwọ gẹgẹ bi akọbi.
Iko agbaboolu Manchester City gbe igba oroke pelu ami méjídínlọ́gọ́rùn ún(98points) lori
" O ni ọlẹ ati ole lo n da awọn ọdọ iwoyii laamu ni wọn ko ṣe fẹ ṣíṣẹ ni Naijiria, bẹẹ si ni oke okun ko dabi ti tẹlẹ mọ, wọn kan n wa fi ara wọn jiya ni.
Eyi lo wa mu ki ọga agba ajọ NAFDAC, Ọjọgbọn Christiana Mojisọla Adeyẹye, gba awọn ọmọ Naijiria ni imọran pe ki wọn ma ṣe ra tabi jẹ ounjẹ ti wọn fi 'sniper' tabi kẹmika oloro mi i pa.
Eyi ni ọkan lara awọn koko to jẹyọ ninu iwadii ijinlẹ kan, ti ajọ to n gbogun ti itankalẹ kokoro arun HIV/AIDS lorilẹede Naijiria, NACA, ṣẹṣẹ gbe jade.
Àjẹ́ àti Aṣẹ́wó ní ìyá Rainbow - Òjòpagogo Ọkọ̀ òfúrufú ọlọ́pàá yóò bẹ̀rẹ̀ sí ní káàkiri Naijiria - Ọgá Ọlọ́pàá N650,000 péré ni mò ń gbà gẹ́gẹ́ bíi owó oṣù -Gomina Ọyọ A kò fòfin de owó naira tó ti pẹ́ ní Naijiria -CBN O fidi ọrọ rẹ mu lẹ ninu iwe Galatia ori kẹta ati ẹsẹ kejinlọgbọn.
Ohun gan an ni o n ṣaaju ọdun Ọṣun osogbo.
Pius Adesanmi: Awọn ọmọ Nàìjíríà ń ṣelédè lẹ́yìn akọni tó lọ
Mikali, ọmọbinrin Saulu, kò sì bímọ títí ó fi kú.
 Ṣùgbọn ó yẹ kí á rántí pé ki àgbàdo tóó dáyé ohun kan ni adìyẹ ń jẹ .
0 109 Orilẹede Timor-Laste 0 0.
One Million Boys: Ìforígbárí ẹgbẹ́ òkùnkùn Ebila àti Ekugbemi n'Ibadan
Oyún oṣù méje ló wà nínú Azeezat, kí wọ́n tó f'òkúta fọ́ ọ lórí pa Ẹ yé fipá bá obìnrin lòpọ̀ mọ́, ìbálòpọ̀ kìí ṣe dandan - Afẹ̀hónúhàn Ẹ̀wọ̀n gbére leè jẹ́ ìjìyà fún afipábánilòpọ̀ bí àwọn gómìnà ṣe dìde si"" Ọwọ́ ọlọ́pàá tún tẹ afurasí tó fipá bá odi àti adití lòpọ̀ nílùú Ibadan Ni ile oniwaasu ijọ CAC kan to wa ni Ori Sasa Ojoo agbegbe Akinyele ni iṣẹlẹ naa ti waye."
Egbe All Progressives Congress,  APC lorile ede Naijiria, ti gba iwe esun mẹ́rìnlélógún lati odo awon omo egbe, nipa ipade egbe ti won se niluu Abuja lati fi yan awon oloye egbe  tuntun won.
Ní tèmi o, mo mọ̀n dájú pé kòs'ẹ́ni mọ̀la.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ramadan: Kí ni Buhari, Saraki, àtàwọn gómìnà kan sọ?
O tesiwaju pe awon ijoba ni gbogbo eka lorile ede Naijiria n sa gbogbo ipa ni agbegbe won lati gbe asa laruge, bakan naa ni ijoba papo naa si n seto iranwo lati fun won ni  agbegbe to se e gbe, ni eyi ti yoo mu itesiwaju ba asa lorile ede yii.
Koda, ijọba ibilẹ naa ti sọ pe ko tun gbọdọ ko ijọ rẹ jọ mọ ni ilu naa, nitori pe o n ta epo si aṣọ àlà ilu naa.
Ṣugbọn wọ́n ṣọ̀tẹ̀ sí mi, wọn kò sì gbọ́ tèmi, ẹnìkankan ninu wọn kò mójú kúrò lára àwọn ère tí wọ́n ń bọ tẹ́lẹ̀, bẹ́ẹ̀ ni wọn kò kọ àwọn oriṣa Ijipti sílẹ̀.
Ní àkókò kan ní Ọjọ́ Ìsinmi, bí Jesu ti ń la ààrin oko ọkà kọjá, àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ bẹ̀rẹ̀ sí já ọkà jẹ bí wọn tí ń lọ lọ́nà.
Àwọn ọmọ ogun tí a kà ninu wọ́n jẹ́ ẹgbaa mọkandinlọgbọn ó lé eedegbeje (59,300).
Amọ awọn miran tiẹ fikun pe, o lee jẹ iṣẹ kan pere ni awọn n ri se ni odidi ọṣẹ kan.
Nigba ti a fi ọrọ wa ọmọdekunrin naa, to pe orukọ ara rẹ ni Ahmed Saka lẹnu wo, o ni oun lo n lọ si ẹba opopona marosẹ Ibadan si Eko, ladugbo Guru Maharaji ti mama oun ti n ta ẹran igbẹ ni.
Awọn olori ẹsin sọ pe yiyẹpẹrẹ eto igbeyawo ni ihuwasi wọn.
Igba keji niyi ti ikọ Arsenal ati Manchester city yoo maa waako lori papa lati igba ti Arteta ti fi Manchester city silẹ wa di ipo akọnimọọgba mu ni ẹgbẹ agbabọọẹu Arsenal.
Ẹsira bá dìde nílẹ̀, ó wí fún gbogbo àwọn olórí alufaa, ati àwọn ọmọ Lefi, ati gbogbo àwọn ọmọ Israẹli pé kí wọ́n búra pé wọn yóo ṣe gẹ́gẹ́ bí Ṣekanaya ti sọ, wọ́n sì búra.
Ṣugbọn, olori fun ileeṣẹ adoola ẹmi, Gerrit Branick, ni ko si ẹri kankan to fi idi rẹ mulẹ pe ẹ̀bi awọn oṣiṣẹ awọn ni, nitori gbogbo wọn lo mọṣẹ.
"Nínú àtẹ̀jáde kan tí oludari eto iroyin fun Gómìnà ìpínlẹ̀ Èkìtì náà, ọ̀gbẹ́ni Lere Olayinka fi síta, Fáyóṣé ní "" ìtìjú ń lá ló jẹ́ pé ààrẹ tún gbé àṣà kó máa di ẹ̀bi ru gbogbo èèyàn dé àwùjọ àgbáyé dé ibi pé ó tún ń di ẹ̀bi ru ẹni tó ti jáde láyé."
Minisita ohun ro awon ile-ise olupese ero igbalode oniruuru lorile-ede yii, lati dowopo pelu ero tuntun DSO ohun lati mu igberu ba ero naa.
"Oorun gaasi lo kọkọ ru bo wa ninu ile, ti mo si n sọ fawọn ọmọ pe ki wọn jẹ ka jade sita lati wọna abayọ, ibi ta ti n gbero lati jade, ni mo gbọ gbola lojiji, ti ohun gbogbo si pakasọ.
 ""Gbogbo wa gbọdọ jí kuro loju orun, nitori pe asiko niyii lati mu ki àlá wa sẹ."
Eyi ko ṣẹyin bo ṣe jẹ pe ọkan pataki ni igbogun ti iwa ibajẹ, ninu ilana iṣejọba Buhari.
Eyi jẹ ohun ti arabinrin Priscilla sọ.
Àwọn olórí wọn ni: Serubabeli, Jeṣua, Nehemaya, Seraaya, Reelaya, Modekai, Biliṣani, Misipa, Bigifai, Rehumu ati Baana.
"Ẹsun lilo owo baṣubaṣu naa kun ohun ti wọn fi kan Sowore pe o lodi si abala 15 (1) ninu ofin Naijiria nipa pe wọn ni o fi owo ranṣẹ lọpọlọpọ igba nipasẹ ikani ti wọn n pe ni ""swift transfer"" lori ẹrọ ayelujara."
’’Gomina ile ifowopamo ti ijoba apapo naa soro lori opo ise
Eleyi jẹ iyalẹnu fun ọpọlọpọ ololufẹ ere bọọlu papaajulọ idije Premier League nitori Mourinho sọrọ alufansa si Arsenal fun ọpọlọpọ ọdun.
Obìnrin ọ̀hún ti orúkọ rẹ̀ ń jẹ́ Monisola Adeola ní ọkọ òun kò ṣẹ̀ṣẹ̀ má a lu òun lóri àwọn ǹkan ti kò nílárí, sùgbọ́n orí kó Monisola yọ nítóri kò bá ìṣẹ̀lẹ̀ náà rìn kí wọn tó gbà á sílẹ̀ Ọ̀kan nínú àwọn ajàfẹ́tọ̀ọ́ obìnrin tó tún jẹ́ agbẹjọ́rọ̀ Toyin Taiwo Ojo tó bá BBC News Yoruba sọ̀rọ̀ jẹ́rìí sí pé ọ̀rọ̀ ìwà ipá ni àwujọ Nàìjíríà ń peléke síi lásìkò ìgbélé Coronavirus.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ladoja Ni ipari, Sunday James rọ ẹnikẹni to ba kẹfin darnadaran kankan to wọ Naijiria lọn aitọ lati jẹ ki ileeṣẹ NIS gbọ sii.
Nítorí náà, OLUWA Ọlọrun ní, mo fi ara mi búra pé, n óo fi ọ́ fún ikú pa, ikú yóo máa lépa rẹ, nítorí pé apànìyàn ni ọ́; ikú yóo máa lépa ìwọ náà.
Amọsa o, ileesẹ ọmọ lorilẹede Naijiria ti salaye ninu atẹjade kan wipe awọn ko ko ọmọogun kuro lagbegbe naa.
Wọ́n wí fún Jeremaya pé, “Kí OLUWA ṣe ẹlẹ́rìí òtítọ́ ati òdodo bí a kò bá ṣe gbogbo nǹkan tí OLUWA Ọlọrun bá ní kí o sọ fún wa.
Mo jija gbara, ti mo si ja fita-fita ni ki n to lee ni ominira funra ara mi.
Ọlọ́gbọ́n ọmọ a máa mú inú baba rẹ̀ dùn,ṣugbọn ẹni tí ń tẹ̀lé aṣẹ́wó kiri, ń fi ọrọ̀ ara rẹ̀ ṣòfò.
Ibeere ti Thomas Ibu ni tirẹ ni pe, ajọyọ kini Naijiria n ṣe gan-an?
ti awon eniyan to le ni igba Milionu si ni aarun oju kan tabi omiran gege bi
Nínú ọgbà wọ̀nyí mo fi ojú mi gbangba rí ọ̀pọ̀lọ́ tí ó tóbi tó àkúkọ adìẹ̀.
Amọ Lọwọlọwọ bayii, o ti le ni ọgọrun un eniyan to ti ni arun Coronavirus naa lorilẹede Naijiria.
Bo tilẹ jẹ pe ohun to ṣẹlẹ si awọn akẹgbẹ wọn mejilelogun to tẹri si iku ni ọsẹ diẹ sẹyin lo mu wọn kuro loju popo ṣugbọn bayii wọn ti ni eyi kii ṣe awawi lati sa kuro, ki wọn pada bi bẹẹ kọ, iṣẹ a bọ lọwọ ẹni bẹẹ.
Offa Bank Robbery: Àwọn afunrasi ní àwọn kò fí t'inu fẹdo jẹwo fún ọlọ́pàá
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Iboji ni awọn ẹlẹsin Agoris ma n lọ si julọ.
Ó ní láàrin ọdún márùn-ún sí mẹ́wàá, a ti di oníbarà tó ń fẹ́ ọjà ní mẹ́sàn-án mẹ́wàá.
Oyo government: Kí ló dé tí ọ̀rọ̀ Ìyálọ́jà àti Babalọja ń fà awuyewuye?
Oríṣun àwòrán, Abike dabiri Wayi o, ko sẹni to ti le fi okodoro ọrọ mulẹ boya lootọ ni awọn akẹkọkunrin to le ni ọọdunrun naa ti ri idande gba abi bẹẹ kọ.
Minisita naa mọ pe awọn ọmọ Naijira paapa awọn ọdọ ko gba toun.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Christchurch shootings: New Zealand pá lọlọ ni ìrántí awọ́n ti agbebọ́n pa ní Mọ́ṣáláṣí Christchurch 22 Ẹrẹ̀nà 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Awọn olujọsin Orileede New Zealand ti gbe irun pipe Musulumi sori afẹfẹ Rẹdio ati amohunmaworan gẹgẹ bii ara akanṣe eto irun Jimọ lati ṣe iranti awọn to ba iṣẹlẹ Christchurch lọ.
O ti mú kí ọjọ́ ìjìyà rẹ súnmọ́ tòsí, ọdún tí a dá fún ọ sì pé tán.
O kò gbọdọ̀ foríbalẹ̀ fún wọn, bẹ́ẹ̀ ni o kò gbọdọ̀ bọ wọ́n; nítorí Ọlọrun tí í máa ń jowú ni èmi OLUWA Ọlọrun rẹ.
Àwọn ará Bẹnjamini bá ṣe bí wọ́n ti sọ fún wọn.
Ẹni tí kò bá gbàgbọ́ yóo gba ìdálẹ́bi.
 fún isé ribiribi won fún ìlú ni a se so ibùdó náà lórúko won - ajèbú-olóde .
Olóòtú ìjọba Gẹ̀ẹ́sì yan ọmọ Yorùbá ní Mínísítà Lórí òpò twitter ilé iṣẹ olopaa ní ìròyín náà ti jáde.
Oríṣun àwòrán, Instagram/Mr Latin Mr Latin ni loootọ ni oun mọ pe ajakalẹ arun Coronavirus ti ṣe akoba nla fun ọrọ aje awọn osere tiata, sugbọn o san ki eeyan wa laye ninu ilera pipe, ju ko maa jẹ irora aisan lọ.
Ẹni to bori: Tanzania Madagascar vs Cameroon.
Wọn ni oun lo fa iku eniyan mejila lasiko to n gbe wọn lọ si ibudo wọn losu to kọja.
Nigba ti ipa wọn ko ka itọju awọn ọmọ yi ti awọn obi wọn ko si ni owo ti wọn yoo fun wọn, igba bara lọpọ maa n gbe lati le fi ri ounjẹ jẹ.
Ati pe oun ko fara mọ ofin aṣẹ gbigba koo too lee waasu naa rara.
Níbi tí orísirísi ọgbọ́n bá ti parapọ̀, ìlọsíwájú kò ní jìnnà si irú agbègbè bẹ́ẹ̀.
Ọkunrin náà wí fún un pé, “Ojú ogun ni mo ti sá wá lónìí.
Bakan naa, ọpọ ero inu baalu IX-1344 naa lo farapa, ti awọn ọmọde inu rẹ jẹ mẹwa, oṣiṣẹ baalu meji ati awakọ ofurufu meji.
Gbogbo àwọn tí wọn bá gba ibẹ̀ kọjá ni ẹ̀rù yóo máa bà,tí wọn yóo sì máa mi orí.
Jẹ́ kí ẹwù rẹ̀ máa mú inú rẹ dùn nígbà gbogbo,kí ìfẹ́ rẹ̀ máa mú orí rẹ yá nígbàkúùgbà.
Fagunwa ko ipa tiẹ si idagbasoke ọmọniyan lai le dukia aye lasan.
O wa daba pe ki ijọba kesi awọn onimọ ijinlẹ lati tete wa ọna abayọ si arun Coronavirus yii, nitori itọju la nilo, kii ṣe ka gbe ilẹkun ile ijọsin ti pa.
 O seni laanu pe awon mejeeji ko le se ise naa yanju lasiko yii.
Àwọn Ọba alayé ní Naijiria ṣàbẹ̀wò sí Ọba Eko, Gómìnà Eko àti Bola Tinubu lẹyin ìwọ́de EndSARS Àwòrán àwọn afurasí tí a fi léde kìí ṣe òfegè, ṣùgbọn a dọ́gbọ́n síi - Iléeṣẹ́ ọlọ́pàá Nigba to n sọrọ lori iṣekupani to waye ni Zabarmari, Baba-Ahmed sọ pe Buhari ti kuna lati tẹti si igbe awọn ọmọ Naijiria lati pese abo to peye fun wọn.
Wọ́n sanwó fún àwọn gbẹ́nàgbẹ́nà ati àwọn tí wọn ń mọlé, láti ra òkúta gbígbẹ́ ati pákó ati igi, kí wọ́n fi tún àwọn ilé tí àwọn ọba Juda ti sọ di àlàpà kọ́.
Nigba ti wọn bi i pe ki lo de ti wọn o jẹ ki Aisha wọ inu ile, o fesi o ni nigba ti aarẹ Buhari wọle ibo to de Aso Rock lo fun baba oun Mamman Buhari ni ile ti wọn n pe ni Glass House idi si niyii ti awọn ko fi jẹ ki Aisha wọle.
Se o seese ki aawọ inu ẹgbẹ oselu APC de ile ẹjọ bi?
Presidential Candidates: Ọ̀rọ̀kọ́rọ̀ ni àbọ̀ EU lóri ìbò 2019
Nigba t'oun naa fidi iṣẹlẹ naa mulẹ fun BBC, Akọwe agba fun ẹgbẹ Ondo Development Committee, Alufa Damilọla Akinwale, sọ pe awakọ Oloye Bademọsi lo pe ọọfisi ileeṣẹ naa ni owurọ Ọjọru pe ọga oun ti ku.
O ni bi ijọba ipinlẹ Oyo l'abẹ iṣakoso Abiola Ajimobi ṣe da Yewande Oyediran to pa ọkọ rẹ silẹ ko buru nitori bi ọrọ naa ṣe jẹ.
  Mo rí afárá ńlá alájà méfà.
Àbí o sì tún ń bínú sí wa, inú rẹ kò tíì rọ̀?
A nilo agọ ọlọpaa ni Orin Ekiti fún aabo wa -Falua
Koda, mawọtana ni awọn aworan rẹ to n gbe sori ayelujara lojoojumọ, to si dabi ẹnipe o ni ẹnikeji ti wọn jọ da okoowo naa pọ.
Ní ọjọ́ Eti ni àwọn ìkọ ìjọba ìpínlẹ̀ Eko ti sàbẹ̀wò sí pápákọ̀ òfururfú NMIA láti mọ̀ bi wọ́n ṣe múra silẹ̀ fún iṣẹ́ ìgbokègbodò to bẹ̀rl lónìí.
Jesu bi wọ́n pé, “Ǹjẹ́ ẹ gbàgbọ́ pé mo lè wò yín sàn?
Boxing Day: Kíni ìdí tí wọ́n fi ń pe ọjọ́ kejì ọdún Kérésì ní Boxing Day?
Awọn ile iwe gbọdọ ṣeto iwe kika lọna to rọrun fun awọn akẹkọọ ti wọn ko si ni korajọ pọ soju kan.
Sarai bá sọ fún Abramu pé, “Ibi tí Hagari ń ṣe sí mi yìí yóo dà lé ọ lórí.
Olori naa sọ pe, lẹyin ọdun kẹta ti oun di iyawo alaafin, l'oun to ri ọmọ bi, to si jẹ ibẹta.
" tí àkójọpọ ̀ náà bá jẹ ́ àkójọpọ ̀ àwọn nọ ́ mbà gidi , á so wí pé "" àwọn onírúiyepúpọ ̀ tó wà lórí àwọn nọ ́ mbà gidi "" ."
Olongbodiyan ni ki aarẹ Buhari lọ mọ wi pe ''ko si iru ihalẹ to le ha mọ awọn ọmọ Naijiria ti wọn ko fi ni tu jade lati wa dibo yọ kuro loye lọjọ kẹtalelogun Oṣu keji.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Sunday Ayẹni: Damilọla, aya ọmọ mi fìgbónára sọ mi sókùnkùn alẹ́ Ṣaaju ọjọ naa ni Yewande ti fi sisọọsi gun ọkọ rẹ nitori ẹsun kan naa.
Mo ṣetán láti ta ilé tí mo ń gbé, kí n le rí àwọn ìbejì mi padà - Akeugbagold Gbogbo ìgbésẹ́ to yẹ ni a gbé nígbà ti àwọn ọ̀daràn dé ọgbà wa- Agbẹnusọ ọgbà ẹ̀wọ̀n Kílóde tí àwọn èèyàn ṣe fẹ́ràn òfófó ju ojúlówó ìròyìn lọ?
Èmi ni n óo máa ṣe àkóso àwọn eniyan,àwọn erékùṣù yóo gbẹ́kẹ̀lé mi,ìrànlọ́wọ́ mi ni wọn yóo sì máa retí.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: BBC Yorùbá gba àmì ẹ̀yẹ akọni nídìí àgbéga àṣà àti èdè abínibí Ẹ má sọ Amotekun di ẹgbẹ́ OPC, ẹ fi wá sínú ẹ̀ṣọ́ aláàbò - Miyetti Allah Buhari, kí ló dé tó fẹ́ dá $100m owó Abacha padà fún gómìnà Kebbi?
Ṣugbọn Ọlọrun tó gbẹ́kẹ̀lé, kò ní jẹ́ kí ẹ rí ìdánwò tí ó ju èyí tí ẹ lè fara dà lọ.
Adonibeseki sá, ṣugbọn wọ́n lé e mú.
    Báyìí ni a rí bí ọ̀run Àpáàdì ti rí.
Omiṣore fi kun ọrọ rẹ wipe ẹgbẹ ti o ba ni ifojusun iṣejọba rere gẹgẹ bii ti ẹgbẹ oun(SDP) ni yoo ri atilẹhin gba ninu atundi ibo si ipo gomina ti yoo waye lọjọbọ.
Ó bèèrè ẹ̀mí gígùn lọ́wọ́ rẹ; o fi fún un,àní, ọjọ́ gbọọrọ títí ayé.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Oṣù Kínní ọdún 2020 ti pẹ́ jù, ẹ ṣe ìgbẹ́jọ́ mi kíákíaá - Donald Trump Ẹ̀jẹ̀ yóò sàn pẹ̀lú bí Amerika se pa Ọ̀gáagún wa - Iran Ọ̀pọ̀ ẹ̀mí ti lọ sí ìsìnkú Ọ̀gàgún Soleimani Ilẹ̀ Iran tí Amerika pa!
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Mo fi iṣẹ́ Banki silẹ̀ lọ bẹ̀rẹ̀ alápatà - Derin Ninu ikede dukia rẹ, Gomina Makinde nile mẹsan an ni Naijiria, meji l'Amẹrika pẹlu ẹyọ kan lorilẹ-ede South Africa.
"Awọn mọlẹbi rẹ sọ pe ọmọ nìkan ni àwọn yóò gbà"" Igboke ni bótilẹ jẹ́ pé lẹ́yìn ọ̀rọ̀ náà ti orisiri ija ti n ṣẹlẹ̀, àwọn ọlọpàá ni ki Arinze maa san ẹgbẹ̀run mẹ́wàá, pali Indomie kan ati irẹsi fun òun lóṣooṣu, sùgbọ́n Arinze ko ṣe bẹẹ yala óún pinu lati ṣe Igbeyawo, sibẹ̀ yoo maa sọ pé ko si owo."
Ninu ilé alágbèékà mẹta tí wọ́n kọ́ mọ́ ara ilé ìsìn náà, ẹnu ọ̀nà ilé tí ó wà ní ìsàlẹ̀ patapata wà ní apá gúsù ilé ìsìn náà, ó ní àtẹ̀gùn tí ó lọ sí àgbékà keji, àgbékà keji sì ní àtẹ̀gùn tí ó lọ sí àgbékà kẹta.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Imam tó fẹ́ ọkùnrin míì níyàwó forí kó ìjìyà òfin 13 Sẹ́rẹ́ 2020 Oríṣun àwòrán, Daily Monitor Àkọlé àwòrán, A ṣe ọkunrin to n fi Hijab bori ni Imam gbe ni iyawo sile Imam kan to ti n ro wi pe obinrin loun gbe niyawo ni wọn ti yọ kuro lori oye rẹ gẹgẹ bi iwe iroyin Daily Monitor ṣe jabọ.
Obinrin kò pọ̀ ni ipò agbára.
orile-ede Naijiria, ojogbon Yemi Osinbajo ati iyawo re, Dolapo, yoo dibo
si  ibudo oko oju omi to wa ni ipinle Rivers
Iroyin sọ wipe, awọn to tun to ẹgbẹrun lọna ọọdurun miran lo ti di alainile lori bayii lẹyin ojo arọọrọda ni orilẹede naa.
"Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ọkùnrin tó fẹ́ fipábámilòpọ̀ fín ǹkan sí mi lójú ló ṣe rọ́nà wọlé sí mi lára Oríṣun àwòrán, @EKEDP Igbe tawọn mii fi bọ ẹnu ni wipe laipẹ yii ni wọn ṣẹṣẹ fi kun iye owo ina ti awọn eeyan yoo ma san pẹlu ireti pe eleyii yoo mu ọrọ ṣegeṣege kuro ninu ina ọba paapaa pẹlu bo ṣe jẹ pe iye too ba fi kaadi ""prepaid"" rẹ ra naa ni waa ba nibẹ amọ wọn ni ọgbọn ki ijọba apapọ le ri owo ya lọwọ Banki agbaye eyi to pọn dandan ni wọn ṣe ṣe eyi."
Ile ẹjọ naa ni Onnoghen ko ni awijare to le mu ki ile ẹjọ naa sọ wi pe ko ma se jẹjọ, nitori wi pe ko si ẹni to kọja ofin.
Ọba ni mí, mi ò le b'ọ̀rìṣà, Olorì tuntun tó ń bọ̀ já gbogbo ''scale''- Oluwo ti Iwo Ta ni ìyàwó Chadwick Boseman, tó jẹ́ àwòkọ́ṣe rere f'áwọn ọ̀dọ́ Adúláwọ̀?
Àwọ́n ọmọ ogun faramọ pé ènìyàn mẹ́ta kú, sùgọ́n àwọn IMN sọ pé ọ̀pọ̀ ènìyaǹ ní wọ́n pa November 17, 2018 Ilé ẹjọ kọ ipẹ̀jọ́ náà láti dá a sílẹ̀ àti pé kò sí ẹ̀rí àr'\\idájú pé wọ́n ń ṣe àìsàn gẹ́gẹ́ bi àyẹ̀wò tí àwọ akọṣẹ́ mọ́ṣẹ́ onísègùn òyìnbó ṣe, láti gbe ìpèjọ́ wọ́n lẹ́sẹ̀.
"Ẹ wo ìṣẹ̀lẹ̀ nípa ẹ̀sùn ìfipábánilòpọ̀ tí wọ́n fi kan D'banj ní sísẹ̀-n-tẹ̀lé Ìdí tí Nàìjíríà ṣì fi múra sílẹ̀ fún Hajj 2020 láì fi ti Covid-19 ṣe Àlàyé rèé lórí ikú tó pa Ogun Majek Eji Gbadero, ọmọ Ibadan àti jayé-jayé ọmọ ónílẹ̀ ti wọn yẹgi fun l'Eko Ọkan lara awọn aladugbo ti o ba wa sọrọ, Ọgbẹni Lateef Nurudeen ṣe alaye wi pe ni nnkan bii aago marun un idaji ti wọn maa n lọ kirun n wọn deede gbọ ti ọkọ oloogbe n pariwo ""ẹ gba mi o""."
Eyí sì ló sokùnfa ìdí ti gbogbo àwọn orilẹ̀-èdè fi ni ki wọ́n maa wọ orílẹ̀-èdè àwọn mọ, pàápàá jùlọ ni àwọn ilẹ òkere alawọ funfun.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Mobile Wash: iṣẹ́ fífọ́ mọ́tò tà ni mó yàn láààyò- Slay Mama Bakan náà ní ìròyìn ti kan ni ọjọ Ajé tẹ́lẹ̀ pé ènìyàn mẹẹdógun ti jẹ́ ọlọrun nípe nípìnlẹ̀ Ondo nítori àìsàn náà ti o si di mẹ́rìnlélógun ni ọjọ Iṣẹ́gun.
Ẹwẹ, alatako rẹ, John Mahama ti ẹgbẹ oṣelu NDC naa ni ireti pe awọn oludibo yoo tun oun yan lẹyin saa kan ṣoṣo to lo gẹgẹ bi aarẹ Ghana ti ẹlomii fi gbajọba mọ ọ lọwọ.
 lẹ ́ hìn àkóràn àkọkọ ́ ènìyàn kòle ní àkóràn mọ ́ ní gbogbo ọjọ ́ ayé rẹ ̀ .
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Recruitment Nigeria Army form: Wo àmúyẹ kí o tó lè di ọmọ ogun ilẹ̀ Nàìjíríà pẹ̀lú fọ́ọ́mù tó jáde yìí 20 Ògún 2020 Oríṣun àwòrán, Nigeria army Fọọmu atigba ni si iṣẹ ologun ọmọ ogun ilẹ ni Naijiria ti jade.
Awon eniyan mẹ́tàdínlọ́gbọ̀n lo padanu emi won , ti oke aimoye si fara pa.
Mika bá sọ fún un pè, “Máa gbé ọ̀dọ̀ mi, kí o sì jẹ́ baba ati alufaa fún mi, n óo máa san owó fadaka mẹ́wàá fún ọ lọ́dún.
Ó pa Abineri, ọmọ Neri, ọ̀gágun àwọn ọmọ ogun Israẹli ati Amasa, ọmọ Jeteri, ọ̀gágun àwọn ọmọ ogun Juda.
Bakan naa lo tun kọ ẹkọ nipa ilera lọdun 2008 si 2012 ni Michigan Flint O tun kọ ẹkọ nipa fọto yiya ati iroyin ṣiṣe ni danish School of Media and Journalism Documentary Photography Course.
Ogunranti Abiodun, @Wonder_11 sọ loju opo Twitter rẹ pe, ọkan aarẹ ẹgbẹ NANs ti daru, to si n mu idarudapọ wa gẹgẹ bi orukọ rẹ ti fihan, o ni ko yara tete yọ orukọ toun kuro ninu ogun miliọnu akẹkọ ti yoo dibo fun Buhari.
Ó ní lẹ́yìn gbogbo ìwádìí, ó fi han pé àwọn ọlọ́pàá náà jẹ̀bi àwọn ẹ̀sùn yi wọ́n fi kan wọ́n, o sì di dandan ki i'sk bọ́ lọ́wọ́ wọ́n.
Wọn  yoo fowosi iwe adehun, ti wọn  ko gbodo tapa si, eni to ba tapa si iwe adehun yii , yoo foju wana ofin.
Joabu, ọmọ Seruaya, ni Balogun rẹ̀, Jehoṣafati, ọmọ Ahiludi ni olùtọ́jú àwọn àkọsílẹ̀.
Nígbà ayé wọn, wọn a ti máa ṣe wọlé-wọ̀de ní ibi mímọ́, àwọn eniyan a sì máa yìn wọ́n, ní ìlú tí wọn tí ń ṣe ibi.
Nígbà míràn gan-an ńṣe la máa kúkú sọ odidi òdòdó sẹ́nu kàló, tí a ó rún un lẹ́nu wọ̀mù-wọ̀mù, tí a ó sì gbé e mìn gbùn-ún, tí nkankan ò sì ní ṣe wá.
NYSC: Àwọn àgùnbánirọ̀ gbọ́dọ̀ gba àṣẹ kí wọ́n tó ṣètò ìgbafẹ́
BBC Yoruba ba baba oloogbe Kolade Johnson sọrọ lori ọ̀fọ̀ tó ṣẹ̀ wọn.
O si wa lara awọn oṣere ti Eleduwa fun lẹbun ere ṣiṣe lagbo awọn oṣere.
Nǹkan tí Faṣiti ṣe yìí yóo di mímọ̀ fún àwọn obinrin, àwọn náà yóo sì máa fi ojú tẹmbẹlu àwọn ọkọ wọn.
Kí iye òkúta tí ẹ óo gbé jẹ́ iye ẹ̀yà tí ó wà ninu àwọn ọmọ Israẹli.
Bí mo bá gba ẹ̀ṣẹ̀ láyè ní ọkàn mi,OLUWA ìbá tí gbọ́ tèmi.
Bi mo ṣe de họsibitu, mo ri i.
Ní ti pé ó jí i dìde kúrò ninu òkú, tí kò pada sí ipò ìdíbàjẹ́ mọ́, ohun tí ó sọ ni pé, ‘Èmi yóo fun yín ní ohun tí mo bá Dafidi pinnu.
Ajọ naa kori esi fọ si ibeere yi ti awọn eeyan n bere botilẹjẹwipe wọn ni awọn ko lowo lati tẹ kaadi fun awọn ọmọ Naijiria.
Andrews ni ọdún 1961, nígbà tó pé ọdún mejidinlọgbọn péré.
Agbẹnusọ ọlọ́paàá ìpińlẹ̀ Kwara, Ajayi Okasanmi tó fi ìdí ọ̀rọ̀ múlẹ̀ sàlàyé pé, ilé iṣẹ́ ọlọ́pàá Kwara ti bẹ̀rl ìwádìí.
Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Lion Mama: Di woman wey fight rapist wey attack her daughter31 Ẹrẹ̀nà 2019 Fídíò, Meet man wey dey save snakes, oda animals for Lagos24 Òkùdu 2019 Facebook marriage for Kano provoke Islamic police to declare couple wanted4 Agẹmo 2019 DSS arrest man wey create and share Buhari 'marriage' video3 Sẹ́rẹ́ 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Oríṣun àwòrán, Getty Images, Google Àkọlé àwòrán, Aworan Amina Zakari ati Aarẹ Buhari Iyansipo Amina Zakari gẹgẹ bi olori igbimọ ibudo ikabo aarẹ ti yoo waye loṣu keji ọdun 2019 ni ọpọ paapaa ẹgbẹ oṣelu PDP bẹrẹ si ni sọ pe ko tọ pẹlu oniruuru idi.
Nígbà tí wọ́n fọ́ gbogbo wọn túútúú tán, wọ́n pada lọ sí ìlú wọn, olukuluku sì lọ sí orí ilẹ̀ rẹ̀.
Ìwádìí náà wà láàrín ọmọogun ojú òfurufu, ọgá àgbà ọlọpàá àti ajọ ọlọ́páà ìpínlẹ̀ Nasarawa.
Orile-ede mejeeji jo ni adehun pe won yoo jo fowosopo mu atunse ba ile Syria, ti won ko si ni faye gba orile-ede miiran lati lowo si atunse ohun.
Ogbeni Chidia Maduekwe lo so eyi di mimo nibi iside eto naa nipinle Eko.
Ẹnìkọ̀ọ̀kan wa yóo sì fún ọ ní ẹẹdẹgbẹfa (1,100) owó fadaka.
Ọjọ kẹsan an, oṣu kẹfa ọdun 2019 lo yẹ ki saa wọ́n wà sópin
Gbogbo ògo Jerusalẹmu ti fò lọ kúrò lára rẹ̀,àwọn olórí rẹ̀ dàbí àgbọ̀nríntí kò rí koríko tútù jẹ;agbára kò sí fún wọn mọ́,wọ́n ń sálọ níwájú àwọn tí ń lé wọn.
95bn sórí reluwé làti Kano sí Niger Republic- PDP O ni wamuwamu lawọn ọlọpaa n duro de awọn oṣiṣẹ to ba fẹ ṣe iwọde, awọn yoo si se ohun to tọ labẹ ofin.
Ọmọ ipinlẹ Eko ni, o si n ṣiṣẹ agbohunsafẹfẹ.
Bákan náà láàrín oṣù kérin sí oṣù kẹfà ọdún 2016, ọ̀rọ̀ ajé Naijiria dẹnukọlẹ̀f;ún ìdá 2.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ìwọ́de EndSARS ló ń sọ pé inú ń bí àwọn ọ̀dọ́, ìjọba, ẹ náání wọn - Obasanjo Ẹ̀yin ọ̀dọ́ ti rí èrè ìwọ̀de yín lórí EndSARS àmọ́ ẹ ṣọ́ra, kẹ má baà sọ èrè náá nù - Tinubu Owó ìrànwọ́ Covid-19 dé, ìjọba fẹ́ san ₦75bn fún 54,000 olókoòwò Ìjọba ìpínlẹ̀ Eko ti iléèwé pa nítorí ìwọ́de #EndSARS Ìrẹ̀wẹ̀sì ń bá wa torí ìdánwò NECO tẹ ń ṣún síwájú lọ́pọ̀ ìgbà - Akẹ́kọ̀ọ́, ọ̀gá iléèwé Agbára ìgbìmọ̀ ìdájọ tí mo gbé kàlẹ̀ yóò dé ọ̀dọ̀ àwón ólọ́pàá tó ti kúrò lẹ́nu iṣẹ́ tẹ́lẹ̀- Sanwo Olu Wo àwọn orílẹ̀èdè míràn tó ń fojú winá ìwọ́de bíi ti ENDSARS Mo fura pé ẹ fẹ́ da Nàíjíríà rú, ń kò ṣe ìwọ́de mọ́ - Segalink, agbátẹrù ìwọ́de yọwọ́ ''Ti o ba ri ọmọ ilu Akure, ohun ti wa ri ni awọn eniyan to jẹ akinkanju, ti ọrọ wọn si ṣee gbẹkẹle.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Zainab Habib:Zainab Habib tí ilẹ̀ Saudi Arabia pa irọ́ mọ́ pé o gbé cocaine tí gba sabuké NYSC!
Akọwe ijọba ilẹ Naijiria nigbakanri, ọgbẹni Babachir Lawal ti gba ominira lati lọ sile lọwọ ajọ EFCC.
Oluwo ni òun kò fẹ́ kí àwọn èèyàn kú tàbí máa sunkún, òun sì ń fẹ́ kí Ọlọ́run mú ẹ̀mí oun lati kò Coronavirus kúrò nílẹ nítorí òun kò fẹ́ káwọn aráàlú máa kú báyìí.
Igbakeji gomina  wa bu enu ate lu bi awon eniyan ko se ni ife si eko isiro mo, o wa ro awon obi  lati  fowosopo pelu awon egbe to ni I se pelu eko isiro lati tubo ko ipa pataki lona ti awon akekoo yoo se nifee si kiko ati mimo eko isiro jake-jado orile ede NaijiriaO tun wa ro awon igbimo egbe onisiro lorile ede Naijiria lati fowosowopo pelu awon egbe to ni I se pelu eto yii, lati lati ko ipa pataki lona ti won yoo se ni awon oluko isisro to gbohunje-fegbe-gbawo- bo  ki idagbgasoke le e de ba orile ede Naijiria.
Bí ẹ bá fọn fèrè ìdágìrì lẹẹkeji, àwọn tí wọ́n pàgọ́ sí ìhà gúsù yóo ṣí, wọn yóo sì tẹ̀síwájú.
Esi yi jẹ idahun si atẹjade kan ti awọn orileede mejeeji fi sita lọjọ ẹti nibi ti wọn ti ni ko tọ bi ẹka alaṣẹ ijọba Naijiria ti ṣe yọ adajọ agba naa ni ogunjọ si idibo apapọ Ninu atejade kan ti agbẹnusọ ijọba Garba Shehu fi sita ti a ri ka loju opo ile iṣẹ iroyin Naijiria NAN, ijọba ni ''awọn lodi si ayọnusọ kankan to n gbero lati da ifoya silẹ́ laarin ara ilu tabi to fẹ ṣe idiwọ fun eto idibo to n bọ lọna.
Àbí Saulu náà ti di wolii ni?
 Ti enikeni ba fe nu eti, aso ilewo mimo kekere ni ki eni naa rora fi suuru ki bo iho eti nita ki o rora maa nu ;ai fi tipa tipa kii bo inu iho eti fi ko idoti eti bo sita”.
Láti ìpilẹ̀ṣẹ̀ ayé ni a kò ti kọ orúkọ wọn sinu ìwé Ọ̀dọ́ Aguntan tí a pa.
Ni Joabu ati àwọn ọ̀gágun rẹ̀ bá jáde kúrò níwájú ọba, wọ́n bá lọ ka àwọn ọmọ Israẹli.
Ajo to ń se amojuto iwa ibajẹ naa ti bẹẹrẹ iwadi lori ọro ọgbeni Siasia láti ọjọ kankanla osu keji ọdun yi.
Gbogbo àwọn eniyan rẹ yóo jẹ́ olódodo,àwọn ni yóo jogún ilẹ̀ náà títí lae.
    Ibi ti mo ti ń sími yìí ni mo ti déédéé rí obìnrin arẹwà kan tí ó yọ sí mi.
Ìbẹ̀rù-bojo gbalẹ̀ ní Oyigbo lẹ́yìn tí ọlọ́páà mẹ́ta àti sọ́jà kú nínú rògbòdìyàn EndSARS Banki Nàìjíríà, CBN ṣàlàyé nípa àwọn tó máa rí gbà nínú owó ìrànwọ́ N75b tíjọba gbé kalẹ̀ Gẹgẹ bo ṣe sọ, o ni to ba ti to akoko kan ti awọn eeyan n fi awọn oogun yii ṣetọju ounjẹ o lee yọri si awọn aisan bii ara rirẹ, ori fifọ, igbẹburu, eébì, ati bẹẹ lọ.
O le nigb aodun ti won ti n sayey odun ojude Oba ni Ijebu nibi ti o ti n mu emi isokan won gun sii kaakiri agbaye.
cs je fun opo odun amioro orile-ede top-level domain ( cctld ) fun czechoslovakia .
Awọ̀n oludije meje ni yoo maa kopa nibi ipade ifọ̀rọ̀wérọ̀ naa gẹ́gẹ́ bi ipe to jade sita si awọn oludije ti awọn eniyan yan pe awọn fẹ ri nibi ifọrọwerọ naa.
Nítorí èmi OLUWA Ọlọrun rẹ,ti di ọwọ́ ọ̀tún rẹ mú,èmi ni mo sọ fún ọ pékí o má bẹ̀rù, n óo ràn ọ́ lọ́wọ́.
Ó fi ọgbà náà fún àwọn tí wọn yá a,ó ní kí ẹnìkọ̀ọ̀kan wọn mú ẹgbẹrun (1,000) ìwọ̀n owó fadaka wá,fún èso ọgbà rẹ̀.
Fun ọpọlọpọ ọdun ni o fi wa pẹlu aarẹ Buhari gẹgẹ bi ọmọ ogun Naijiria.
NAFDAC: Ojú wa wà lára ìpara Blac Chyna náà Boko Haram pa ọmọ ogun Nàìjíríà 53 Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ọba Olutayọ: ìgbésẹ̀ Ọọni àti Alaafin ti ń mú ìṣọ̀kàn dé sáàrin àwọn Ọba Yorùbá Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, ASUU Strike: Bí àwọn kan se dunnú, làwọn kan fajúro Ìjọba àpapọ̀ ti ṣèpàdé pẹ̀lú àwọn adarí ẹgbẹ́ àwọn oṣìṣẹ́ fásitì Nàìjíríà lórí ìyanṣẹ́lódì àwọn ilé ìwé giga ti ìjọba tó bẹ̀rl lọ́jọ́ kẹrin, oṣù kọ́kànlá.
Oríṣun àwòrán, EPA Àkọlé àwòrán, Ile wiwo ni Kenya 3.
Omo Ibadan: Ó wù mí láti kàwé di dókítà oníṣègùn òyìnbó tàbí ọ̀mọ̀wé ni Fáṣítì
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, A nilo agọ ọlọpa ni Orin Ekiti fún aabo wa -Falua Ni Asia, awọn obinrin ìdá mọkanlelọgọta lo n bora ni India, ti ìdá ogoji si n lo wọn ni China.
Bakan naa, awọn ẹgbẹ naa n bu ẹnu atẹ lu u.
 Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Mayowa Omoniyi: Kò sí orin Obey, Sunny Ade abí tàkasúfèé tí ń kò le ta gìtá sí Fayose fikun pe tori Makinde wa nipo gomina loniii ko fun ni asẹ lati maa lọ sipinlẹ miran, to ba sipinlẹ temi, maa koju rẹ, maa bọwọ fun tori arakunrin mi ni, mo nifẹ rẹ pupọ, mo si mọ si bo se di gomina.
Awọn eeyan ni lati ṣora fun irin alẹ nitori awọn oniwa ijamba ti wọn maa n fẹran lati fi okunkun bora.
Dá òmùgọ̀ lóhùn gẹ́gẹ́ bí ìwà agọ̀ rẹ̀,kí ó má baà rò pé òun gbọ́n lójú ara òun.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Obasanjo: Ilé ni bàbá wà, kò wọkọ̀ òfurufu kankan 29 Èbibi 2019 Ko si ootọ kankan ninu iroyin kan to n ja rain-rain nilẹ pe, Aarẹ ana ni Naijiria, Oloye Olusegun Obasanjo, ni ori ko yọ ninu iṣẹlẹ ijamba ọkọ ofurufu kan.
Lọjọ Abamẹta, ọjọ kẹẹdogun oṣu kẹjọ ọdun 2020 ni Robert papoda nile iwosan kan niluu New York.
Èmi Peteru, aposteli Jesu Kristi ni mò ń kọ ìwé yìí sí ẹ̀yin tí ẹ fọ́n káàkiri àwọn ìlú àjèjì bíi Pọntu, Galatia, Kapadokia, Esia ati Bitinia.
Nítorí pé kìí ṣe nǹkan yẹpẹrẹ ni, òun ni ẹ̀mí yín.
Lataari ise takun-takun iko omo ogun Nigeria, eyi tun se iranwo nla bayii fun awon ebi kookan ti won ti padanu awon omo won sowo awon omo ogun olote boko Haram lati bi odun meji seyin ni agbegbe Ngafure ni ijoba ibile Dikwa Local Government nipinle Borno.
’ Ẹ̀yin ọmọ Israẹli, ìwà olukuluku yín ni n óo fi dá a lẹ́jọ́.
21 Ọ̀wàrà 2018 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 4 Bélú 2018 Oríṣun àwòrán, @NGRPresident Àkọlé àwòrán, Ajọ to n ri si idanwo aṣekagba ile iwe girama, WAEC ti ṣalaye wi pe kii ṣe pe awọn ṣẹṣẹ fun Aarẹ Buhari ni iwe ẹri tuntun lọjọ ẹti Ko si eeyan ti ko fẹrẹ mọ pe okun ifẹ laarin Aarẹ Muhammadu Buhari ati gomina ana nipinlẹ Ekiti, Peter Ayọdele Fayoṣe ko fi da bi ẹni gun rara nitori naa nigba ti wahala lori iwe ẹri aarẹ Buhari bẹrẹ, ọpọ lo reti ohun ti Fayoṣe yoo sọ lasiko naa.
 abẹ ́ nà ìmọ ̀ itan kejì yìí tilẹ ̀ fi kún ọ ̀ rọ ̀ rẹ ̀ pé lámurúdu àti odùduwà bá àwọn kan ni ilé-ifẹ ̀ nígbà ti wọ ́ n dé ifẹ ̀ .
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìbálópọ̀ nínú ọkọ̀: Ọlọ́pàá ìpínlẹ̀ Eko tako ìsesí yìí 12 Ọ̀pẹ̀̀ 2018 Oríṣun àwòrán, Getty Images Ijọba ipinlẹ Eko ti tako ọrọ ile isẹ ọlọpa apapọ wi pe kii se ẹsẹ lati ni ibalopo ninu ọkọ ayọkẹlẹ ni ita gbangba.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ondo: Dejí sun ọmọ méje àtagbalagba meji mọ́lé nítorí pé ó ń bínú Bayii ileeṣẹ MTN ti san owo itanran naa tán fún ajọ NCC Naijiria.
Bi emi naa ṣe tẹle niyẹn.
Ni àwọn kan ninu wa bá lọ sí ibojì.
Lẹyin naa lo ni ileeṣẹ ologun ba gbogbo ẹbi oloogbe naa kẹdun, o si gbadura pe ki Ọlọrun tẹ ẹ si afẹfẹ rere.
32 Kíyèsíi, èyí jẹ́ títóbi ati tí ìkẹhìn nínú òfin tí èmi yíò fi fún ọ nípa ohun yìí; nítorí èyí yíò tó fún irìn òòjọ́ rẹ, àní títí dé òpin ọjọ́ ayé rẹ.
Iye awọn eeyan to ṣẹṣẹ ko arun naa ni ipinlẹ kọọkan ree: Eko-142 FCT-60 Bayelsa-54 Rivers-39 Delta-37 Oyo-30 Kaduna-26 Imo-23 Enugu-19 Kwara-17 Gombe-11 Ondo-10 Bauchi-8 Ogun-7 Borno-6 Benue-1 Èèyàn 573 ló lùgbàdì àrùn Coronavirus ní Naijiria ní Ọjọ́ Aje Eeyan 573 tuntun mii lo ṣẹṣẹ lugbadi arun Coronavirus ni Naijiria.
"Ẹ wo fídíò òfò àti àdánù tó wáyé níbi ìkọlù sáwọn àjèjì ní South Africa ""A ti nílé, dúkìá àti ẹbí ní South Africa, àwa kò ṣetán láti padà sílé"" Bẹẹ ba gbagbe gomina Seyi Makinde lasiko to n bawọn akọroyin sọrọ lasiko ayẹyẹ ọgọrun ọjọ to gori oye, lo fẹsun kan ijọba ipinlẹ Ọsun pe o kuna lati san owo osu awọn osisẹ fasiti Lautech bẹrẹ lati idaji ọdun yii, gẹgẹ bo se wa ninu adehun."
Ẹni tí ó bá ń gbé inú ìfẹ́ ń gbé inú Ọlọrun, Ọlọrun náà sì ń gbé inú rẹ̀.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù ‘ASUU da ìyanṣẹ́lódì dúró' 7 Èrèlè 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 8 Èrèlè 2019 Oríṣun àwòrán, @ui Àkọlé àwòrán, Oṣu mẹfa ni iyanṣẹlodi naa fi waye Ìròyìn tó ń tẹ̀ wa lọ́wọ́lọ́wọ́ ní wí pé ẹgbẹ́ olùkọ́ àgbà ilé ẹ̀kọ́ gíga fásítì ASUU ti fagile iyanṣẹ́lódi oloṣumẹfa ti wọn gun lé.
Balogun ni idajọ naa jẹ aṣeyọri fun iṣejọba awa-ara-wa ni Naijiria ati fawọn eeyan ẹkun idibo guusu ipinlẹ Oyo.
Wọ́n fi sí àhámọ́ nítorí wọn kò tíì mọ ohun tí wọn yóo ṣe sí i.
Nígbà tí a ronú ọ̀nà tí a ó gbà tí a kò rí, Ènìyàn-ṣe-pẹ̀lẹ́ fún wa ní ìmọ̀ràn kan.
 O si tun wa ki won ku ori-ire  ẹkunwo osu 
Atẹjade kan ti ajọ to n ri si igbogun ti ajakalẹ arun lorilẹede Naijiria, NCDC fi sita loju opo Twitter rẹ ṣalaye pe, mẹtalelọgbọn ninu awọn eeyan naa wa ni ipinlẹ Eko, mejidinlogun wa lati ilu Borno, mejila ni ilu Osun, mẹsan ni ilu Katsina, mẹrin ni ilu Kano, mẹrin ni ilu Ekiti, mẹta ni ilu Edo, mẹta ni Bauchi, ẹyọkan ni Imo.
Bakan naa ni iwadii fihan pe aadọjọ ọmọ ikoko ninu ọọdunrun tawọn eeyan n bi lagbayee lọdọọdun lo wa lati Naijiria.
inú rẹ̀ bàjẹ́ gidigidi pé ó dá eniyan sí ayé, ó sì dùn ún, 
Boolọ o yago ni ọrọ di nigba ti ọta ibọn ati tajutaju n dun lakọ labo.
Chibok girls: 'Ìjọba ń ṣe bí ẹni pé ọ ń ṣe àwọn òbí tí Boko Haram kọ lọ́mọ́ ló lóore ni'
Ó sì sọ àwọn kànga náà ní orúkọ tí baba rẹ̀ sọ wọ́n.
"Toyin ni: ""A n gbero nipa ohun ti yoo sẹlẹ ni oṣu mẹfa si akoko yii bii ẹni pe ọla gan an daju fun wa, Eyin ololufẹ mi, aye ni Adiitu ti Olodumare fi ju ẹda lọ, a n ṣe eto ohun gbogbo amọ, Ọlọrun nikan lo le jẹ ko wa si imusẹ."
Ògo ati agbára yí i ká,ayọ̀ ati ìyìn sì kún Tẹmpili rẹ̀.
Gbogbo igbiyanju BBC lati beere sii nipa awọn ti iroyin ni ọwọ awọn agbofinro ti tẹ ko tii bi eso ti a n fẹ lọwọ.
" leprae "" , lọ ́ kọ ̀ ọ ̀ kan ) ."
Oríṣun àwòrán, Getty Images Diẹ lara awọn ọkunrin to ba BBC Yoruba sọrọ ninu fidio isalẹ yii ni ọkọ lo ni ọyan aya obinrin, pe ọmọ ti wọn bi kan ya a lo fun igba diẹ ni.
Ileeṣẹ ologun tun ki Ogagun Buluma Biu to n dari ikọ ọmọ ogun Division & ati Lafiya Dole ni Maiduguri àti Ogagun AJ Danjibun ti ikọ ọmọ ogun 211 Demonstration Batallion ni Bauchi.
Bi awọn ti wọn ko nigbekun ṣe ni ko sẹni to wa wo wọn wo ni baba ni awọn obi n wa.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Gbogbo ènìyàn ló wọ agbádá ikú, ẹni tó kàn lẹnìkan kò mọ̀ Igba akọkọ kọ ni yii ti ile isẹ ifowopamọsi Access yoo ma gba banki miran mọra.
Oludije fun ipo aare labe egbe oselu Peoples Democratic Party, PDP Atiku Abubakar ti so pe ijoba oun yoo tepele mo ibasepo laarin awon ara ilu ati ijoba, ti oun ba jawe olubori ninu eto  idibo  odun 2019.
25 Àti pé nígbànáà ni òun yíò sọ fún àwọn ènìyàn ìran yìí: Kíyèsíi, mo ti rí àwọn ohun tí Olúwa fi han Joseph Smith, Kekere, mo sì mọ̀ pẹ̀lú ìdánilójú pé wọ́n jẹ́ òtítọ́, nítorí mo ti rí wọn, nítorí a ti fi wọ́n hàn sí mi nípa agbára Ọlọ́run àti tí kìí ṣe ti ènìyàn.
Kí alágbàro ní oko má ṣe dúró mú ẹ̀wù rẹ̀ tí ó bọ́ sílẹ̀.
O ni nigba ti wọn jọ wọya ija ti wọn si n du ada mọ ara wọn lọwọ ni ada naa fa oloogbe naa nikun ya.
Bi ọrọ se ri ree lori bi awọn ajeji darandaran se n ya wọ ilẹ Yoruba eyi to n se akoba fun eto aabo wa.
Lọ́dọọdún, àwọn aláṣẹ China fi ọwọ́ agbára mú ìrántí ìṣẹ̀lẹ̀ náà, tí wọ́n sì fi àwọn agbọ̀rọ̀dùn sí àtìmọ́lé.
nipa fifun awon ayalegbe ni iwe ase lati jade kuro nile.
"O ni ""Gẹgẹ bi aṣa ati ilana eto iṣofin, o jẹ ohun ti wọn gba gẹgẹ bii ami aṣẹ ninu ile naa, o si ni bi wọn ṣe n lo."
Alaafin Oyo: Níbo ni Olorí Anu àti Dami wà?
Ninu ọrọ tirẹ, Ọgbẹni Francis Ogunrẹmi, Alaga ẹgbẹ oṣiṣẹ Trade Union Congress (TUC) sọ pe ọpọ awọn oṣiṣẹ ni awọn ile iṣẹ ni wọn ti ni eto yi.
OLUWA ní, “Kí ọlọ́gbọ́n má fọ́nnu nítorí ọgbọ́n rẹ̀,kí alágbára má fọ́nnu nítorí agbára rẹ̀;kí ọlọ́rọ̀ má sì fọ́nnu nítorí ọrọ̀ rẹ̀.
2 káàkiri àgbáyé ni ó ní àrùn ascariasis , tí àwọn àwùjọ tó sì ní àrùn náà púpọ ̀ jùlọ sì jẹ ́ àwọn ará gúsù sahara afirika , amẹrika latini , àti eṣia .
Iṣẹlẹ yii waye ni nkan bii aago mọkanla kọja iṣẹju mẹẹdogun alẹ ọjọ Eti gẹgẹ bi ohun ti igbimọ iwadii ilẹ Russia sọ.
Gẹgẹ bi ohun ti ajọ naa fi sita loju opo ẹyẹnkọrin Twitter rẹ, ipinlẹ Eko lo lewaju pẹlu eeyan mọkanlelogoji ti olu ilu ilẹẹwa naa si gba tẹlẹ pẹlu eeyan mẹtalelaadọrin.
Ó dá òṣùpá ati ìràwọ̀ láti máa ṣe àkóso òru,nítorí pé ìfẹ́ rẹ̀ tí kì í yẹ̀ wà títí lae.
"O ni o jẹ nkan itiju fun oun nigba ti oun kuna gẹgẹ bi agbẹjọro, o si tabuku ba isẹ nigba ti oun gbara le itumọ ọrọ inu ""Oxford Dictionary "" lati gba alabaṣiṣẹpọ oun ni imoran ni ilana isẹ wọn ti o si ja si pe awọn itumọ naa ko tọna to."
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù US Equality Day: Obìnrin 140,000 kọ̀wé bèèrè àtìlẹyìn àwọn olórí orílẹ̀èdè àgbáyé 27 Ògún 2019 Ti a ba n sọrọ bi awọn obinrin lorilẹede Naijiria se n kopa si ninu eto oselu, a lee ni wọn n ja fitafita, ti wọn si n kuro ni ipo oludibo lasan bọ si ipo oloselu, ẹni to n gbegba ibo ati ẹni to n se akoso ilu.
Akọwe agba wa fi kun un lorukọ gomina pe awọn dupẹ fun gbogbo ipa to ko lasiko rẹ lẹnu iṣẹ awọn si gboriyin fun un, wọn ṣadura oriire fun un ninu ohun gbogbo to ba dawọle lọjọ iwaju.
O sọ pe okunrin ti wọn ba tẹ lọdaa si le ta kebe bi okunrin, sugbọn iru okunrin bẹ ko ni le fun obinrin loyun.
Àwòrán nǹkan aláràmbarà oríṣiríṣi táwọn jàǹdùkú jí gbé lẹ̀yìn ìwọ́de EndSARS Mo ti tọrọ aṣọ àti yẹtí etí rí, kí n tó leè ṣe àwo orin - Tope Alabi Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Àjẹ́ ké lánàá, ọmọ kú lónìí ni ọ̀rọ̀ Tinubu àti ìṣẹ̀lẹ̀ Lekki Tollgate - Bode George Wo àwọn ìpínlẹ̀ tí ọlọ́pàá ti bẹ̀rẹ̀ àyẹ̀wò ojúlé sí ojúlé káàkiri Nàìjíríà torí ohun tí wọ́n jí kó Iroyin kan n fo kaakiri pe Ileeṣẹ ọlọpaa ipinlẹ Ondo ni awọn yoo bẹrẹ ayẹwo onile si ile lati lọ gba awọn ohun ini ti janduku ti jigbe lọ kaakiri ipinlẹ naa.
ẹwà rẹ yóo sì mú ọ wu ọba;òun ni oluwa rẹ, nítorí náà bu ọlá fún un.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ondo election 2020: Àwọn ara ìpínlẹ̀ Ondo ránṣẹ́ sí Akeredolu ohun ti wọ́n ń retí ní báyìí Akeredolu lo gba ibo ju bẹrẹ lati ijọba ibilẹ Akoko North West, Akoko North East, Akoko South East ati Akoko South West.
Àwọn tí wọ́n jẹ́ ìjòyè ninu àwọn ọmọ Esau nìwọ̀nyí, Lára àwọn ọmọ Elifasi, àkọ́bí Esau, tí Ada bí fún un: Temani, Omari, Sefo, Kenasi.
Ninu ọdún náà, ẹ kò gbọdọ̀ gbin ohunkohun, bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò gbọdọ̀ kórè ohun tí ó bá dá hù fúnra rẹ̀; bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò gbọdọ̀ ká àjàrà tí ó bá so ninu ọgbà àjàrà tí ẹ kò tọ́jú.
Ta ló tó ṣe oríkunkun sí i kí ó mú un jẹ?
Ó ní bí a bá tún mú eléyìí kúrò lọ́dọ̀ òun, bí ohun burúkú kan bá ṣẹlẹ̀ sí i, pẹlu arúgbó ara òun yìí, ìbànújẹ́ rẹ̀ ni yóo pa òun.
Ó gbà wọ́n pẹlu ayọ̀, ó bá bẹ̀rẹ̀ sí bá wọn sọ̀rọ̀ nípa ìjọba Ọlọrun, ó tún ń wo àwọn aláìsàn sàn.
Ṣugbọn ko sọ ohun ti wọn ti ṣe fun ọlọpàá to yinbon naa.
’ rèé Afọnja, ẹni tó finú wénú ní Ilọrin, àmọ́ tó jẹ iwọ Ẹfunsetan Aniwura, obìnrin tó ju ọkùnrin lọ Ọ̀rọ̀ǹpọ̀tọ̀niyùn, Aláàfin obìnrin àkọ́kọ́ rèé, tó ní nǹkan ọkùnrin Àwọn ìròyìn BBC tó tayọ lọ́sẹ̀ yìí Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
A kó dúnkoòkò mọ́ Ambode, isẹ́ wa là ń ṣe - Ilé Aṣòfin Eko Ijọba tí júwọlẹ̀ fún Amẹrika lóri iwé ìrìna!
Aya Adarí ilé ìgbìmọ̀ aṣòfin àgbà àná ní Nàìjíríà, Toyin Saraki náà ti fi ẹ̀bùn owó ránṣẹ́ sí obìnrin Risikat.
"Loju opo Twitter ajọ naa ni wọn ti kede eyii lalẹ ọjọ Iṣẹgun pe ""Ni ọjọ kinni."
Awọn ẹgbẹ to gbimọ pọ fẹ gun le iyanṣẹlodi yii ni ẹgbẹ awọn oṣiṣẹ ile iṣẹ irina ofurufu(NUATE), ẹgbẹ awọn ọga lẹnu iṣẹ irina ofurufu (ATSSSAN), ẹgbẹ awọn akọṣẹmọṣẹ ninu iṣ irina ofurufu (ANAP) to fi mọ ẹgbẹ awọn oṣiṣẹ atawọn awakọ ofurufu (NAAPE).
Oríṣun àwòrán, Femi Gbajabiamila/Facebook Àkọlé àwòrán, Femi Gbajabiamila Laarin igba naa titi di ọdun 2003 ti o kọkọ di aṣoju fun ẹkun Surulere nilu Eko nile aṣoju-ṣofin Naijiria, Femi Gbajabiamila da ile iṣẹ agbẹjọro tirẹ silẹ, ti o si tun bẹrẹ si ni kopa diẹ diẹ ninu oṣelu.
Lonii, ile ẹjọ giga ipinlẹ Ondo tun ti pe Wolii Sotitobire atawọn to pe ni ẹlẹri rẹ ki wọn wa wi tẹnu wẹnu wọn.
Gomina Sanwo-Olu pari ọrọ rẹ pe oun yoo nifẹ lati foju ganni ọmọdekunrin naa laipẹ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Oronpoto Animation: Akin Alabi ní kò dára bí eré aláwòrán fáwọn ọmọdé ṣe jẹ́ aláwọ̀ funfun Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Èmi Paulu, aposteli Kristi Jesu nípasẹ̀ ìfẹ́ Ọlọrun, ati Timoti, arakunrin wa, ni à ń kọ ìwé yìí sí Ìjọ Ọlọrun tí ó wà ní Kọrinti ati sí gbogbo àwọn eniyan Ọlọrun tí ó wà ní Akaya.
Ounje to kun fun gbogbo eroja aṣaraloore, igbe aye alaafia ati ọpọlọ to ji pipe a maa mu eniyan gbadun ibalopọ daadaa.
Ajọ to n risi ọrọ eto ẹkọ lorilẹede Naijiria (NANS) ti ni ọpọlọpọ akẹẹkọ lo ti kuro ni awọn ile iwe fasiti to wa ni ipinlẹ Ondo nitori Ọwọngogo owo ile iwe awọn akẹẹkọ.
Ẹni tí ó bá pa àwọn ọ̀rọ̀ àsọtẹ́lẹ̀ inú ìwé yìí mọ́ ṣe oríire.
Wo àwọn nkan tó yẹ́ kí o mọ̀ nípa 'Awawa Boys', ọ̀kan lára ẹgbẹ́ òkùnkùn tó n dá Eko rú Kanye West ti bẹ̀rẹ̀ ìpolongo àti díje dupò aàrẹ ilẹ̀ Amẹrika Lẹ́yìn gbogbo sinimá oríta ní Ondo, Akẹti jáwé olúborí ní APC Èèyàn 562 tuntun ló tún ti lùgbàdì COVID-19 ní Nàìjíríà ní àná Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Lockdown updates: Naira Marley gbóríyìn fún Jude Chukwuka pẹ̀lú #1 míliọnù Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Fídíò, Akomolede ati Aṣa lori BBC: Mọ̀ si nípa oríṣìí ẹ̀ka ìsọ̀rí ọ̀rọ̀ àti ìwúlò wọn8 Owewe 2020 Fídíò, Akomolede: Bolaji Faleke ni Olùkọ́ tó ń kọ́ wa ní àṣà oge ṣiṣe lórí BBC Yorùbá1 Owewe 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Ọ̀rọ̀ǹpọ̀tọ̀niyùn, Aláàfin obìnrin àkọ́kọ́ rèé, tó ní nǹkan ọkùnrin A ti mọ òbí 40 nínú 108 t'ọ́mọ wọn bọ́ ní ayédèrú ibùdó atúnwàṣe Ilorin - Ọlọ́pàá Kwara Ọlọ́pàá Eko ní kí olùkọ́ UNILAG Boniface wá sọ tẹnu rẹ̀ lórí ẹ̀sùn ìfipábánilòpọ̀ O ṣójú mí kóró bí wọ́n ṣé fí àdó olóró pa Dele Giwa lọdún 1986- Soyinka Ta ni Funmilayọ Ransome-Kuti?
Kabiyesi ni inu awọn lọbalọba ni Ọsun ko dun rara, paapa awọn ọba to wa lati ilẹ Iwo ati ilu Ọgbaagba, awọn kan n fi ọgbọn-gbọn tu wọn ninu ni, ti Oluwo ba si dakẹ, to rọra n ba isẹ rẹ lọ, awọn yoo ri aaye tọwọbọ ọrọ naa, ti alaafia yoo fi jọba laarin wọn.
Ìdílé Pius Adesanmi ti gbé Boeing lọ sílé ẹjọ́ Adájọ́ Dogo tí wọ́n jí gbé ti gba ìtúsílẹ̀ Ojọ kẹtadinlọgbọn, oṣu keji, ọdun 1972 ni a bi oloogbe Pius Adesanmi.
 Ó jẹ ́ orisà tí ìran rẹ ̀ kún fún ìbẹ ̀ rù .
NYSC Camp, After coronavirus: Ìjọba kéde ọjọ́ ìwọlé àwọn àgùnbánirọ̀ sí ìpàgọ́ lẹ́yìn Covid 19- Minista ọ̀rọ̀ ọ̀dọ́ Nàìjíríà
Gómìnà ìpínlẹ̀ Kaduna, El-Rufai fi ipò míì dá Sanusi lọ́lá Stolen phone: Fóònù mi ni mo lọ́ tún ṣe lọlọ́pàá bá he mí pé mo jí fóònù- Gbajúgbajà agbóhùnsáfẹ́fẹ́ nílùu Ìbàdàn Gómìnà ìpínlẹ̀ Kaduna fún Sanusi ní ipò tuntun Ọpọ igba lo ti sọ wi pe oun ko jẹbi ẹsun ti wọn fi kan oun,amọ ẹsun naa gbe de ilẹ ẹjọ ni ibi to ti ri ẹwọn he.
Ariwo ta lóde nítorí kò sí ọtí waini,oòrùn ayọ̀ ti wọ̀;ayọ̀ di àwátì ní ilẹ̀ náà.
Sugbọn o yẹ ko ye wa pe awọn ara ijọhun gbọn pupọ, o si ni idi ti wọn se gbe awọn eewọ yii kalẹ lati dari awujọ wa, eyi ti ọpọ wọn wa fun aabo lọwọ ewu.
Anas Aremeyaw lo ṣaaju awọn to ṣe iwadii naa nibiti ọwọ si ti tẹ apoogun oyinbo to jé ọga agba nile iwosan nla ni Ghana, Thomas Osei ati Divine Kumordzi to jẹ oṣiṣẹ eleto ilera.
Nígbà tí àgbàrá bì lù ú, lẹsẹkẹsẹ ni ó wó, ó sì wó kanlẹ̀ patapata.
Lẹ́yìn èyí, Jesu rí ọkunrin náà ninu Tẹmpili, ó wí fún un pé, “O rí i pé ara rẹ ti dá nisinsinyii, má dẹ́ṣẹ̀ mọ́ kí ohun tí ó burú ju èyí lọ má baà bá ọ.
Aarẹ ile aṣofin agba, Sẹnetọ Saraki ni igbesẹ ti ofin la kalẹ ni ki ijọba apapọ tẹle lori ọrọ naa.
Fijilanté ṣèṣì yìnbọn pa Sunday ní Ondo, wọ́n ní wọ́n rò pé ẹranko ni!
”Ogbeni Habibu Aliyu Kila, ti o
délànà ní tirẹ ̀ ní etí ilé-ifẹ ̀ ni àwọn Ẹ ̀ gbá tó kọ ́ kọ ́ dé tẹ ̀ dó sí .
Koda, o fi ẹsun kan pe kọmisana ọlọpaa nipinlẹ Ondo wa nibi iṣẹlẹ naa.
Yankari Reserve: Erin pa ènìyàn méjì ní ìlú Bajama
Awọn iroyin ti ẹ lee nifẹẹ si: Okunrounmu: Ijọba Buhari jẹ ijiya Ọlọrun fun Naijiria Osisẹ Jamb: Ọga mi lo mi 36m, kii se ejo O fikun pe kii se pe wọn yinbọn mọ ọkọ ofurufu naa, ati wipe akọsilẹ to wa nilẹ saaju isẹlẹ naa fihan wipe o seese ko jẹ wipe baalu naa ni iyọnu lo sokunfa ijamba naa.
Sise ifilole igbimo tuntun nile igbimo asofin 
Kí o ka àwọn ọkunrin wọn láti ẹni ọgbọ̀n ọdún títí dé aadọta, àwọn tí wọ́n lè ṣiṣẹ́ ninu Àgọ́ Àjọ.
Àwọn ọmọ Gadi sì tún àwọn ìlú olódi wọnyi kọ́: Diboni, Atarotu ati Aroeri, 
 O so pe ki o to di osu kejila odun yii, ni ise akanse yoo bere lori oko oju irin.
Wọn ni awọn mejeeji ni ki Kenny ta idije ẹgbẹ agbabọọlu wọn fun ti Sweden.
Ilẹ̀ yín yóò dára ọ̀nà yín yóò sunwọ̀n, iwájú ni ẹ ó máa lọ, ẹ kò ní di èrò ẹ̀yìn, nǹkan yín kò ní bàjẹ́, rere ni ẹ o maa rí láéláé.
Ní ọdún kejidinlogun, ó kó àwọn ẹgbẹrin ó lé mejilelọgbọn (832) eniyan ní Jerusalẹmu.
Ó bá tún wí fún wọn pé, “Ẹ bù ninu rẹ̀ lọ fún alága àsè.
Bí a kò bá sì jí Kristi dìde, a jẹ́ pé lásán ni igbagbọ yín, ẹ sì wà ninu ẹ̀ṣẹ̀ yín sibẹ.
Awọn ijoye naa to ko ara wọn jọ labẹ orukọ' Awọn afọbajẹ ti ọrọ ilu kan gbọn-gbọn', beere fun igbesẹ yii ninu iwe ẹsun kan ti wọn fi ránṣẹ si gomina ipinlẹ Osun, Adegboyega Oyetola.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Funmi Adewara: Tele Medicine' ní a fi ń ṣàyẹ̀wò èèyàn ìdá ọgọtá láti dènà ìtànkálẹ̀ Covid 19 Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Funmi Adewara: Tele Medicine' ní a fi ń ṣàyẹ̀wò èèyàn ìdá ọgọtá láti dènà ìtànkálẹ̀ Covid 19 22 Agẹmo 2020 Inu ile la ti n tọju àwọn to ni Covid 19 ti itọju wọn ko lagbara ju- Dokita Adewara Patient Appointment Screen, Tele Medicine, Mobile Health àti àwọn ipede tuntun mii ni arun Coronavirus to n ba gbogbo agbye finra yii ti bi lasiko yii.
Gẹgẹ bi atẹjade naa ṣe sọ, eredi igbesẹ ati ti ọja lawọn ọjọ ti a la kalẹ wọnyii wa lati lee fi sami ayajọ ọdun Aheregbe ati Amole.
Cannabis: Akeredolu késí ìjọba Nàíjíríà láti fi òfin ti àmúlò igbó lẹ́yìn
 A o tẹsiwaju lati maa kilọ fun fun awọn eeyan lati ṣọra ṣe, nitori apejọpọ elero pupọ lee jẹ ki ajakalẹ arun ọhun burẹkẹ sii.
Salima ni baba àwọn ará Bẹtilẹhẹmu, Netofati, ati ti Atirotu Beti Joabu; àwọn ará Soriti ati ìdajì àwọn ará Manahati.
Garba jẹ oyè náà láàrin ọdún 1989 sí ọdún 1990.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: 'Ẹ dìbò fún Buhari ní 2019 kí Yorùbá le gbàjọba ní 2023' Àwọn àpẹẹrẹ pé o ti ń darúgbó Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Ọlọ́run kò ní jẹ́ kí àwa dìbò fún Buhari' O salaye pe awọn ajinigbe ọhun fẹsẹ fẹ nigba ti wọn ri awọn agbofinro ninu igbo ti wọn wa pẹlu akẹẹkọ gboye naa, ṣugbọn o ni wọn ko awọn ohun ti wọn gba lọwọ awọn agunbanirọ ọhun lọ.
Oyo state: Rauf Adeniyan, igbákejì gómìnà ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́ ní àwọn ọ̀tá ìdàgbàsókè ló ń gbé ìròyìn ààwọ̀ láàrín òun àti gómìnà Makinde
Ìjọba Ọyọ: Igba náírà péré làwọn ọlọ́kadà yóò máa san lójúmọ́ fáwọn adarí ibùdókọ̀ tuntun
" Àwọn akẹ́kọ̀ọ́ da ìdánwò WAEC rú, wọn gún infijilátọ̀ ní 'compass' Irinwó lé méje èèyàn ló gbàwòsàn lọ́wọ́ Covid-19 lọ́jọ́ Àbámẹ́ta, 453 míì tún lùgbàdì rẹ̀ Aya gómìnà Kwara fẹ́ ran tìyá- tọmọ olójú búlúù lọ́wọ́ Coronavirus cases in Africa- Ó tí lé ni mílíọ̀nù kan ènìyàn to ti lùgbàdì ààrùn Covid-19 Kini awọn ọmọ Naijiria bii Fayooṣe ati Imo Ugochinyere ti sọ?
Okwaraji kú ni ọjọ́ kejila, oṣù kẹjọ ọ́dun 1989.
Ẹta- Igbọraẹniye ni lati wa larin awọn ipinlẹ to fi ẹgbẹkẹgbẹ pẹlu ara wọn laarin aala kan naa.
ní ọdún 1960 , thi ṣíwájú ìfipá gba ìjọ ́ ba lọ ́ wọ ́ diệm , ń sọ wípé ológun dásí òṣèlú .
El-Zakzaky: Arúfin ni ijọba Muhammadu Buhari gan-an
Ìyẹ́ keji Kerubu kinni ati ìyẹ́ kinni Kerubu keji sì kan ara wọn ní ààrin yàrá náà.
Ó gba gbogbo wọn níyànjú pé kí wọ́n fi gbogbo ọkàn wọn dúró ti Oluwa pẹlu òtítọ́.
#EndSARS: Àwọn olùwọ́de kọ etí ikún sí àṣẹ ijọba, wọ́n tẹ̀sìwájú ìwọ́de l'Abuja Kanye West, Ozil, Boyega, àti àwọn gbajúmọ̀ ilẹ̀ okèèrè tó ṣàtìlẹyìn fún ìpolongo #ENDSARS Ọba Lamidi Adeyẹmi, òṣìṣẹ́ adójútòfò àti Abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò kó tó jọba Ṣé Èdùà dá ààtàn isó ni?
EFCC lawọn ṣebi ẹni gba lati juwọ silẹ ni wọn ba fi gbe idaji owo naa wa ti wọn si ṣeleri lati mu iyoku wa ti ọrọ ba yanju.
Bi o tilẹ jẹ pe Ọrẹdẹin ko du ipo oselu kankan nigba naa sibẹ, o lagbara ju awọn to wa nipo asẹ lọ.
    Nígbà tí o ṣe, ọmọ araye bọ́ sí aarin ọmọ àti bàbá yìí, ọkùnrin kúkúrú bìlísì kan lọ sí ọdọ bàbá ó sọ̀rọ̀ báyìí fún un o ni:
Ramoti ati Anemu, pẹlu àwọn pápá oko àyíká wọn.
Aarẹ orile-ede Ghana, Nana Akufo Addo naa ba ọkan jẹ lori ijakulẹ yi amọ ṣa o loun ni ireti pe Ghana yoo gberasọ pada.
O jẹ́ kí àwọn eniyan máa gùn wá lórí mọ́lẹ̀,a ti la iná ati omi kọjá;sibẹsibẹ o mú wa wá sí ibi tí ilẹ̀ ti tẹ́jú.
Nígbà tí obìnrin náà jókòó díẹ̀, ó díde, ó lọ bu omi tútú fún mi mu, omi náà tutu ju omi etí odó tí mo wà ni ìgbà mẹ́wàá, nígbà tí o sì wòye pé àárẹ̀ ti mu mi jù, ó lọ mú òògùn wá, oogun náà nínú ìgò kan báyìí, ìgbá tí ó sì bù díẹ̀ nínú òògùn náà sí inú galafi kan fún mi tí mo mu u, ṣe ni ara mi le gaú, ọkàn mi sọ jí.
Bí ẹ bá mú akọ mààlúù wá fún ọrẹ ẹbọ sísun, tabi fún ìrúbọ láti san ẹ̀jẹ́ tabi fún ẹbọ alaafia sí OLUWA, 
Ti ẹ ba fi opin si black Friday, yoo pa okoowo lara, ati awọn talika to yẹ ko ra nkan ni ẹdinwo."
Òkúta tí ó dàbí ìlẹ̀kẹ̀ ni wọ́n fi ṣe àwọn ìlẹ̀kùn mejeejila ìlú náà; ẹyọ òkúta kọ̀ọ̀kan ni wọ́n fi gbẹ́ ìlẹ̀kùn kọ̀ọ̀kan.
Egbinrin ọtẹ lawọn isẹlẹ to n waye nipinlẹ Plateau nitori baa se npakan, ni omiran nru.
Ikú apànìyàn nìkan ni ó sì lè ṣe ètùtù fún ìwẹ̀nùmọ́ ilẹ̀ tí ó ti di àìmọ́ nípa ìpànìyàn.
Folaṣade Adeyẹmọ mẹnuba oriṣi àwọn ọ̀rẹ́ lati ori ayelujara ti wọn nifẹ si oun lataari awọn fọto ti oun gbe sori erọ ayelujara ati bi wọn ṣe maa n padà sá fun oun ni kete ti awọn ba ti jọ pade lojukoju.
Àwọn oriṣa irọ́ tí àwọn baba wọn ń bọ, ti ṣì wọ́n lọ́nà.
idagbasoke ati ohun amayederun fun awon omo ipinle Nasarrawa lo je ohun logun.
Bi o ti le je pe, iko agbaboolu Roma jawe olubori ninu ifesewonse ese keji ipele keji si asekagba idije UEFA champions league, sugbon jijawe olubori ohun ninu ifigagbaga naa ko to fun iko agbaboolu Roma lati tesiwaju si ipele ti o keyin ninu idije naa.
’’Oloogbe naa je akoroyin fun  osise mohun-maworan ipinle naa, ki o to di pe o je iku nipe.
Ogbeni Bello Dambatta, ti o dari iko to n ri si isele pajawiri lo sibi isele naa, Head of Rescue Team, Borno State Emergency Management Agency (SEMA), fi oro ohun mule.
Minisita tun wa ro awon osise lati tubo maa satileyin fun ijoba ni eyi ti yoo je ki idagbasoke ba eto oro aje ati fun ojo iwaju orile ede Naijiria.
Wọn bi Musa Yar'adua ni ọjọ kẹrindinlogun oṣu kẹjọ ọdun 1951, o papoda lẹyin aisan pipẹ lọjọ karun oṣu karun odun 2010.
O ni ẹgbẹ awọn yoo ri pe awọn ọmọ ogun gba owo to yẹ ki wọn ba le ṣe iṣẹ wọn bo ti ṣe tọ ati bo ti ṣe yẹ Ajọ ti ko niiṣẹ pẹlu ijọba kan ti orukọ wọn n jẹ 'Enough is Enough' lo sagbatẹru ijiroro naa pẹlu ajọsepọ ile isẹ BBC,TVC NEWS,BudgiT,One ati Transition Monitoring Group.
Awon Agbaboolu owo-eyin(Defenders): Abdullahi Shehu (Bursaspor FC, Turkey); Tyronne Ebuehi (Ado Den Haag, The Netherlands); Olaoluwa Aina (Hull City, England); Elderson Echiejile (Cercle Brugge KSV, Belgium) ati Brian Idowu (Amkar Perm, Russia).
Fawọn Gomina mẹrin to ti jẹ ni ipinlẹ naa, eeyan kọọkan gẹgẹ bi isiro kan ti iwe iroyin kan gbe jade lọdun 2017, yoo maa gba miliọnu meji naira le diẹ lọdun.
Ọkan lara awọn igbimọ aṣẹjọba ipinlẹ naa ṣo pe ijọba ipinlẹ ọhun yi ipinnu ṣiṣi ilwe iwe naa pada nitori ijọba apapọ ko faye gba a.
Yatọ si Obasanjọ, olootu ijọba Canada Justin Trudeau, Taoiseach Micheál Martin ti Ireland ati Keir Starmer olori alatakọ nilẹ Gẹẹsi fi ọrọ ikini ranṣẹ loju opo Twitter Titi di igba ta fi n ko iroyin yi jọ, olootu ijọba ilẹ Gẹẹsi, Boris Johnson, aarẹ Russia Vladmir Putin ati aarẹ Naijiria Muhammadu Buhari ko ti fi ikini ranṣ si Biden ati Harris.
Oluranlọwọ aarẹ lori ayelujara, Bashir Ahmad fidi ọrọ naa mu lẹ loju opo Twitter rẹ pe Aarẹ Buhari gbe igbesẹ lẹyin ipade igbimọ ọlọpaa nile ijọba l'Abuja l'Ọjọbọ.
Ikede yii waye lẹyin ti ajọ NIMC fun awọn ileeṣẹ ibaraẹnisọrọ ni gbedeke ọsẹ meji, lati gbẹsẹ le gbogbo siimu ẹrọ ibaraẹnisọrọ ti ko ba ti ni nọmba NIN ninu akọsilẹ rẹ.
Ṣé n kò wá ní jẹ wọ́n níyà fún àwọn nǹkan tí wọ́n ṣe wọnyi?
Ó sọ majẹmu rẹ̀ fun yín, tíí ṣe àwọn òfin mẹ́wàá tí ó pa láṣẹ fun yín láti tẹ̀lé, ó sì kọ wọ́n sí orí tabili òkúta meji.
Jehu kọ ìwé ranṣẹ sí àwọn olórí ìlú ati àwọn àgbààgbà ati àwọn olùtọ́jú àwọn ọmọ Ahabu, ó ní: 
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ki lo fa Ija lọbalọba ni ilu Iwo Nigba to fi atẹjade sita lori ọrọ yii, akọwe eto iroyin si gomina, Taiwo Adisa ni irọ gbuu ni pe ilu Oyo lo yẹ ki Ileesẹ ọlọpaa naa wa nitori Makinde lo kọ lẹta lati beere fun Ileesẹ ọlọpaa naa, ti ọga agba ọlọpaa si fi ontẹ lu u pe ko wa nilu Agọ Arẹ, ti wọn si lo Ileesẹ asesiga ìjọun lati bẹrẹ Ileesẹ ọlọpaa naa.
Sugbọn lọdọ awọn kan, ohun to jẹ lo yoo ti wọn si ni ijiya tọ si Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Àwọn ohun tó yẹ́ kí o mọ̀ nípa Ọ̀gá DSS tuntun EFCC, mò ń bọ̀ wá yọjú síi yín - Fayoṣe Itse Sagay wọ gàu lórí ọ̀rọ̀ Adeosun Oríṣun àwòrán, @HMKemiAdeosun Àkọlé àwòrán, Awọn kan ni boya o fẹ lọ du ipo gomina ni ipinlẹ rẹ ipinlẹ Ogun ni Bi a ko ba ni gbagbe, ileeṣẹ iroyin Premium Times lo kọkọ gbee sita pe lẹyin ti awọn ṣe iwadi lori iwe ẹri ti Adeọṣun n gbe kiri fun eto isinruulu rẹ lawọn kẹẹfin pe ayederu gbaa ni.
OLUWA wà pẹlu Joṣua, òkìkí rẹ̀ sì kàn ní gbogbo ilẹ̀ náà.
Mo ti kọ́ rò pé tọ̀sán-tòru ni ìwọ OLUWA ń fi òpin sí ayé mi.
bi ẹ ba ji apoti ibo gbe tabi da wahala silẹ tọwọ ba ba yin, mi o lọwọ ninu iyẹn o.
Yollywood: Bákan náà ni àwòrán Sikiratu Sindodo tó ń ṣọjọ́ ìbi, gba orí ayélujára
Donald Trump ni Aarẹ orilẹ-ede Amẹrika kẹta ninu itan ti ọbẹ yoo maa ba nidi lati ọdọ awọn ile aṣoju-ṣofin lorilẹ-ede naa.
Oríṣun àwòrán, @Jidesanwoolu Wọn tiẹ tiraka lati gun emi naa lọbẹ lọrun, amọ ọwọ wọn yẹ, ti wọn si fi ọbẹ ya mi ni agbọn.
Àwọn ni wọ́n sì n gba iṣẹ́ olùkọ́ báyìí.
“Ẹni tí kò bá ṣe tèmi, ó lòdì sí mi.
Nítorí pé Ọlọrun ran àwọn ọmọ Lefi tí wọ́n ru Àpótí Majẹmu OLUWA lọ́wọ́, wọ́n fi mààlúù meje ati àgbò meje rúbọ.
Ninu awọn ọrọ t sọ lori iroyin kan, Ọbasanjọ ni wọn ti kilọ fun oun tẹlẹ pe ijọba Jonathan yoo kọ ọmọ oun obinrin meji lati ṣe iṣẹ idọti, oun si kilọ fun wọn.
Ipinnu Messi ko ṣẹyin rukerudo to n ṣẹlẹ lọwọ ni Barcelona papaajulọ lati igba ti Bayern Munich ti lu wọn laluki pẹlu ami ayo mẹjọ si meji ninu idije UEFA Champions League.
OLUWA ní, “Mo ṣetán tí n óo fi ọ́ lé àwọn tí o kórìíra lọ́wọ́, àwọn tí ọkàn rẹ yipada kúrò lọ́dọ̀ wọn pẹlu ìríra.
Oríṣun àwòrán, Reuters Ṣáájú lẹ́yìn tí ààrẹ ń lọ sí ilé ìwòsàn lọ́ja Ajé ló kéde pé kí àwọn ènìyàn má bẹ̀ru ààrùn náà rárá, ''ẹ má ṣe jẹ́ ki ìbẹ̀rù rẹ̀ gba àkóso ayé yín.
Koda o ni oun le ṣee lọfẹẹ, bakan naa lo bi awọn ololufẹ rẹ lati sọ ohun ti wọn fẹran ju ni ti wọn lati maa ṣe.
N óo san ẹ̀jẹ́ mi fún OLUWAlójú gbogbo àwọn eniyan rẹ̀,
Òkú ọmọ tuntun pòórá nílé ìgbókúpamọ́sí nílùú Akurẹ Oun pẹlu Zlatan t'oun naa jẹ olorin ni wọn fi panpẹ ọba mu u.
Yoruba films: Gbogbo bó ṣe lọ rèé lágbo òṣéré láàrín ọ̀sẹ̀ yìí
00 bn Ajọ eleti gbaroye lawujọ - N5.
kí ó sọ fún Aaroni pé, “Èyíkéyìí ninu arọmọdọmọ rẹ̀ tí ó bá ní àbùkù kankan kò gbọdọ̀ rú ẹbọ ohun jíjẹ sí Ọlọrun rẹ̀.
Gbogbo wọn lọ sí ilé OLUWA pẹlu àwọn alufaa ati àwọn wolii ati gbogbo àwọn eniyan, àtọmọdé àtàgbà wọn.
Maria Magidaleni, ati Joana, ati Maria ìyá Jakọbu ati gbogbo àwọn yòókù tí ó bá wọn lọ, ni wọ́n sọ nǹkan wọnyi fún àwọn aposteli.
Imọran yii waye lẹyin ti ọga ọlọpaa, Mohammed Adamu ti kesi gbogbo ileeṣẹ ọlọpaa kaakiri lati wa ni igbaradi ki wọn le koju ipenija to ba yọju.
O ni eyi ko fi ọna kankan jẹ mọ pe wọn mu aṣofin agba naa.
Bí ikú Ọmọ Ọlọrun bá sọ àwa tí a jẹ́ ọ̀tá Ọlọrun di ọ̀rẹ́ rẹ̀, nígbà yìí tí a wá di ọ̀rẹ́ Ọlọrun tán, ajinde ọmọ rẹ̀ yóo gbà wá là ju tàtẹ̀yìnwá lọ.
Wọ́n yipada sí oriṣa Baali, wọ́n dàbí ọrun tí ó wọ́, idà ni a óo fi pa àwọn olórí wọn, nítorí ìsọkúsọ ẹnu wọn.
Ó pín òkun níyà, ó jẹ́ kí wọ́n kọjá láàrin rẹ̀;ó sì mú kí omi nàró bí òpó ńlá.
" Oríṣun àwòrán, BBC Sport Ni ti pe boya ede aiyede ti wa laarin iyawo Ajimobi ati igbakeji gomina tẹlẹ, Omoetan ni oun ko le sẹ boya ija wa laarin awọn mejeji ṣaaju iṣẹlẹ naa.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: INEC sùn ọjọ́ gbígba káàdì ìdìbò síwájú Ìyá Leah Sharibu ké gbàjarè sí ìjọba Buhari Ìjọba kò ní ti afẹ́fẹ́ ìbánisọ̀rọ̀ Nàìjíríà pa - NCC Àwọn nọmbà yìí ló le fi bá iléèṣẹ́ ológun sọ̀rọ̀ lásìkò ètò ìdìbò #NigeriaDecides Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Ajọ naa fikun ọrọ rẹ pe, Ọgbẹni Magu gba ifiwepe lati ọdọ igbimọ naa nigba ti o n lọ si olu ileeṣẹ ajọ ọtẹlẹmuyẹ fun ipade kan.
Sinimá oríta nílé aṣojú-sòfin, NDDC bínú jáde ní ibùdó ìwádìí Awọn adari ajọ Niger Delta Development Commission, NDDC ti jade kuro ni gbọngan ti ile igbimọ aṣofin kekere ti n ṣe iwadii owo to le ni biliọnu mọkanlelọgọrin naira.
Ọgbẹni Olarinde ṣalaye pe kii ṣe gbogbo nnkan to wa ninu Bibeli lo ba ilana ẹsin Kristẹnu mu.
Lara awon to wa nibi ipolongo naa ni awon omo
Ní ọjọ́ náà, mo búra fún wọn pé n óo yọ wọ́n kúrò ni ilẹ̀ Ijipti, n óo sì mú wọn dé ilẹ̀ tí mo ti wá sílẹ̀ fún wọn, ilẹ̀ tí ó kún fún wàrà ati oyin, ilẹ̀ tí ó lógo jùlọ láàrin gbogbo ilẹ̀ ayé.
 Akẹ́kọ̀ọ́ ṣe ìdánwò àṣekágbá WAEC ní ibùdó ìtọ́jú aláàrún COVID-19 ní Gombe Ọrọ di iran awo dami ẹnu loni ni ipinlẹ Gombe nigba ti akẹkọṣedanwo kan to ni arun coronavirus joko ṣe idanwo pẹlu awọn akẹgbẹ rẹ ni ipinlẹ Gombe."
Iko agbaboolu Naijiria tojo ori won koju ogun odun lo(Nigeria’s U-20 team), Flying Eagles, yoo maa waako pelu iko agbaboolu Ghana, Niger Republic ati Benin Republic ninu idije WAFU U-20 ti yoo bere lojo kefa si ojo kerindinlogun osu kejila odun ti a wayii, niluu Lome, lorile-ede Togo.
A óo máa gbọ́ ohùn rẹ̀ láti inú ilẹ̀ bí ohùn òkú,a óo sì máa gbọ́ tí yóo máa sọ̀rọ̀ kẹ́lẹ́kẹ́lẹ́ láti inú erùpẹ̀.
"Ìdí tí ìjóba ìpínlẹ̀ Eko fí ṣí àwọn ilé ìwé kan padà Ṣé Nàìjíríà lẹ́mìí nkan tí Ghana ń ṣe fáwọn akẹ́kọ̀ọ́ ""Secondary"" tí yóò wọlé ní October yìí?"
O gbà mí lọ́wọ́ ọ̀tẹ̀ àwọn eniyan,o fi mí ṣe olórí àwọn orílẹ̀-èdè;àwọn orílẹ̀-èdè tí n kò mọ̀ rí sì ń sìn mí.
Ọna irinajo rẹ lo ti pade awọn ọdọ naa, to bẹrẹ si ni fi ṣe yẹyẹ.
Àkọsílẹ̀ ìran Jakọbu nìyí: Josẹfu jẹ́ ọmọ ọdún mẹtadinlogun ó sì ń bá àwọn arakunrin rẹ̀ tọ́jú agbo ẹran ó wà lọ́dọ̀ àwọn ọmọ Biliha ati àwọn ọmọ Silipa, àwọn aya baba rẹ̀.
ba yọ gbogbo awọn to ha si abẹ ile to da wo naa.
Nígbà náà ni mo sọ lọ́kàn ara mi pé, “Ohun tí ó ṣẹlẹ̀ sí òmùgọ̀ ni yóo ṣẹlẹ̀ sí èmi náà.
Ileeṣẹ ọlọpaa ti sọ pe awọn yoo fa ẹyẹ naa le awọn alaṣẹ ibugbe ẹranko to wa ni agbegbe naa lọwọ nibi ti yoo wa fun oṣu mẹta lati kọ́ bi yoo ṣe maa fo, ko to o di pe wọn yọnda rẹ.
    Báyìí ni mo kọ̀wé ti mo fi ránṣẹ́ sí Ìfẹ́pàtàkì.
Certificate Forgery: Ọmọ oyè yí ìwé ẹ̀rí láti dupò Oluwoye ti ilú Iwoye
Binta ni ọpọ igba ti oun ba wa ni ẹnu isẹ, ni oun maa n tako abala ere to ba gba ka si ara silẹ tabi wa ni ihooho, Ati pe ẹnu oun kii duro lati gba awọn ọjẹ wẹwẹ akẹẹgbẹ oun nimọran pe ki wọn dẹkun sisi ara silẹ, tori eyi ko bojumu fun ọmọluabi ati asa wa.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Sunday Shodipe: Ilé ẹjọ́ fi Sunday Shodipe, afurasí ìṣekúpani l'Akinyele pamọ́ sí ọgbà ẹ̀wọ̀n 16 Ògún 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 21 Owewe 2020 Oríṣun àwòrán, oyo nsight.
Kòṣẹlẹ̀rí ni Hajj ọdún 2020, wo ìyàtọ̀ tó wà nínú rẹ̀ sí ti tẹ́lẹ̀ Ẹ̀yin ẹlẹ́gbẹ́ òkùnkùn tẹ fẹ́ ṣe àjọ̀dún lónìí, lákọ la ń dúró dè yín - Iléeṣẹ́ ọlọ́pàá Ìjọba Akeredolu kò ní omi àánú lójú, a kò tọ́jú alárùn Coronavirus mọ́ - Dókítá Ondo Bí àwọn adarí ìjọba ṣe ń kó Coronavirus, ń kọ wá lóminú - Ìjọba àpapọ̀ Oríṣun àwòrán, Others Àkọlé àwòrán, A o gbé pápákọ̀ ofurufu Eko ati Abuja ti laipẹ- Hadi Sirika Ṣaaju ki awọn papakọ ọkọ ofurufu o to o di ṣiṣi pada, ajọ to n ṣe amojuto awọn papakọ ni Naijiria, FAAN, kede pe, ki awọn arinrinajo ti pe si papakọ, o kere tan, wakati mẹta ṣaaju akoko ti baalu wọn yoo gbera.
Arabinrin Funmilola sọrọ lori bi ọkọ rẹ ṣe ku, igbiyanju gbogbo ile lati doola ẹmi rẹ ati irinajo rẹ lati igba naa wa.
Àmọ́ ìkìlọ̀ nlá rèé o: ẹni bá fẹ́ lọ kó yàá mú owo lọ́wọ́ o, nítorí nkan rọra gbówó lórí díẹ̀ níbẹ̀.
Ìfọwọ́sowọ́pọ̀ nìkan ni ọ̀nà abáyọ sí ìṣòro Nàìjíríà- Olusegun Obasanjo Àwọn ohun kàyéèfì tó le mú kí ọmọbìnrin ní oyún ìju Ìdí tí àwọn ìpińlẹ̀ se ń ti ilé ẹ̀kọ́ ní ìhà ìwọ̀ Oòrun-Àríwá Nàìjíríà rèé Mínísítà dèrò àgọ́ ọlọ́pàá nítorí ẹ̀sùn kíkó owó ìrànwọ́ Covid-19 sápò Ìrìnàjò Tsafe sí Zamfara tí kílomita ìgba àti díẹ̀, èyí yóò gbà wọ́n ni wákàtí mẹ́tà kí wọ́n tó débẹ̀ nítóri ipò tí ọ̀nà náà wà nígbà ti Tsafe sí kankara jẹ́ kílòmítà mẹ́tàlélọ́gọ́rín Lẹ́yìn ọjọ́ mẹ́fà ti àwọn ọmọ náà ti wà ni ọwa àwọn ajínigbe.
Orilẹ-ede Naijiria ni Akubuike ti kekọọ imọ ofin, o si sisẹ nile ifowopamọ, ko to o ko lọ silẹ America.
O wa sisọ loju rẹ pe, inu ere tiata ni oun ti ya fọto naa nile iwosan, ko ko ko si ni ara oun le.
Lẹ́yìn ọdún kan, ìgbẹ́jọ́ Fayose lórí ẹ̀ṣùn àjẹbánu ₦2bn gbérasọ Iléẹ́jọ́ gbégi lé owó Ayodele Fayose Fayose: Kàkà kí n darapọ̀ mọ́ APC, màá.
Mo bọ́ lọ́wọ́ igbó mímu ṣùgbọ́n ìnira ilé Aafa Ọlọrẹ ti pọ̀jù- ọ̀dọ́ kan A jọ ṣe ìyàwó pọ̀, a jọ bímọ ní ọjọ́ kan náà, a tún jọ máa ń ṣàìsàn pọ̀ ni Lisabi Agbongbo Akala rèé, ẹni tó fi ìfẹ́, ìṣọ̀kan àti ìrẹ́pọ̀ gba ilẹ̀ Ẹ̀gbá lọ́wọ́ ìmúnisìn Àgbẹdọ̀!
Wọ́n n fi gbogbo ẹnu sọ̀rọ̀.
Inu ibanujẹ si ni baba, iya, ati aburo rẹ, to jẹ pe oun lo tun ṣe daadaa julọ ninu idanwo WAEC ọdun 2020 nileewe rẹ.
Wọ́n bi í pé, “Olùkọ́ni, kí ni kí a ṣe?
O ni ireti aàwọ ara to n dan, to si rẹwa.
Bakan naa ni Mailafia ni oun fẹran Aarẹ Buhari ati wi pe oun ṣe agbatẹru fun un, amọ awọn to wa ni iṣejọba rẹ ko fun aarẹ ni atilẹyin to nilo lati mu idagbasoke ba orilẹede Naijiria.
Oríṣun àwòrán, @AAjayiAgboola Awọn yoku ni le Oluji/Okeigbo, Owo, Idanre ati Ondo East.
Gbogbo igbesẹ ati wa nkan ṣe sii kan tun bi afikun ọkọ ti awọn eniyan ra ti wọn forukọ rẹ silẹ.
A kò gbọdọ̀ kọ́ ilé, a kò gbọdọ̀ dá oko, a kò gbọdọ̀ gbin ọgbà àjàrà.
Wọn bi i ni ọjọ kẹrinla, oṣu kọkanla, ọdun 1864.
Awọn eniyan naa to n fi ibinu wọn han pẹlu 'hashtag' #FreeOurGirls, eyi to tumọ si tu awọn ọmọbinrin wa silẹ, ni wọn n fi oriṣiriṣi nkan bi irun'mu, irun obinrin and fila kun awọn aworan rẹ lati ṣatilẹyin fun awọn ọmọbinrin naa.
Ti o ba n gba owo osu to kere julọ (₦18,000): Yoo gba sẹnatọ kan ni wakati kan ati isẹju kan lati gba iye owo osu naa.
OLUWA dá a lóhùn, ó ní, “Mú ẹgbọ̀rọ̀ abo mààlúù ọlọ́dún mẹta kan, ati ewúrẹ́ ọlọ́dún mẹta kan, ati àgbò ọlọ́dún mẹta kan, ati àdàbà kan ati ọmọ ẹyẹlé kan wá.
Idi iroyin ayọ yii ko yẹ lori bi aarẹ Muhammadu Buhari ti ṣe buwọlu sisan owo oṣu tuntun naa fun awsn oṣiṣẹ apapọ ti owo ti wọn n gba ko to iye ẹkunwo oṣu tuntun naa lọwọ yii.
Oríṣun àwòrán, Ayo Akanji Àkọlé àwòrán, Em aa binu si mi pe mi o ni le yóju, ọ̀rọ̀ Turkey ati Kurdish lo fàá Àwọn tí ìbàdan, ní ìpínlẹ̀ Oyo, Porthacourt àti Imo Oríṣun àwòrán, Tajudeen Olajide Àkọlé àwòrán, Micra lawọn ara Ibadan yoo gbe de Abuja lati yẹ ọkọ iyawo sí Oríṣun àwòrán, H cookey Àkọlé àwòrán, Awon tori omi o gbẹ́yìn Ọkọ ìyàwọ ti de nínú ọkọ bọginin rẹ̀ ti àwọn alábarin àti olólùfẹ́ rẹ̀ si n wọ́ tẹ̀le.
Nítorí náà, mo rí i pé kò sí ohun tí ó dára, ju pé kí eniyan jẹ ìgbádùn iṣẹ́ rẹ̀ lọ, nítorí ìpín tirẹ̀ ni.
Oríṣun àwòrán, Instagram/currentalhaja Lẹyin naa lo bẹrẹ si ni dupẹ ni mẹsan an mẹwaa lọwọ olowo-ori rẹ, Alaafin Oyo.
"Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Girl Child Day 2019: Inú mi dùn pé ọmọ obinrin nìkan ni mo bi -Tawakalitu Olawale Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Girl Child Day 2019: Inú mi dùn pé ọmọ obinrin nìkan ni mo bi -Tawakalitu Olawale 11 Ọ̀wàrà 2019 Oní ni ayájẹ ọjọ ọmọbinrin lágbàyé tí àkọle rẹ jẹ ""Ijígìrì ọmọbinrin: kò ni àkọsílẹ̀ kò sì ṣe dádúró"" Bí gbogbo aye ṣe ń se ayájọ ọjọ yìí, BBC Yoruba fi ọ̀rọ̀ wá Abileko Tawakalitu Olawale to bi kikida ọmọ obinrin nikan lẹ́nu wò láti le mọ ìrírí rẹ."
Titi di bi a ti ṣe n ṣe akojọpọ iroyin yii, Adams Oshiomole tabi alaṣẹ ẹgbẹ naa kankan loke ko tii fesi si igbesẹ yi.
 zardari ni opó-kùnrin benazir bhutto , eni to je alakoso agba ile pakistan ni emeji .
Akindele to wa sile ẹjọ pẹlu agbẹjọro meji ni, oun ko jẹbi awọn ẹsun naa.
Nebukadinesari Pàṣẹ pé kí Gbogbo Eniyan máa Sin Ère Wúrà tí ó gbé kalẹ̀.
Ṣé o dé láti pa wá run ni?
Bí mo ti gbójú sókè, mo rí ọkunrin kan tí ó wọ aṣọ funfun, ó fi àmùrè wúrà ṣe ìgbànú.
" Oríṣun àwòrán, Others Falana fikun pe awọn ofin ti ijọba gbe sita naa kii se tuntun, amọ ohun to yẹ ka tako ninu ofin ọhun ni bi ijọba se fun ajọ rẹ kan lagbara lati gba akoso awọn ileesẹ ti kii ba se tijọba, ti wọn ba kẹẹfin iwa sise magomago nibẹ.
Amotekun kò le ṣe èso rere nílẹ̀ Yorùbá àyàfi ni Èkó nìkan - Alao Akala Ṣé òtítọ́ ni pé nǹkan oṣù obìnrin le ba òògùn ìbílẹ̀ jẹ́?
Eniyan burúkú a máa jìn sinu ọ̀fìn ẹ̀ṣẹ̀ rẹ̀,a sì bọ́ sinu ìyọnu nítorí ẹ̀ṣẹ̀ rẹ̀.
9 66635 Orilẹede South Korea 1217 2.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ajayi: ṣé ìwọ mọ irúfẹ́ ọmọ tí Yorùbá ń pè bẹ́ẹ̀?
yàtọ ̀ sí àwọn tí a sọ ̀ rọ ̀ rẹ lókè yìí , ọ ̀ pọ ̀ lọpọ ̀ àwọn ẹ ̀ yà míìràn náà ló pọ ̀ ní Ẹ ̀ gbá tí wọ ́ n ti di ọmọ onílẹ ̀ tipẹ ́ .
 ltd ' láti sètò títa àwon isé òun sí orí cd pèlú títà rè ( makinde 2004 : 30 ) .
Bi itan igbe aye Tunde Idiagbon si ṣe lọ ree, gẹgẹ bi a ṣe ka a loju opo Wikipedia atawọn oju opo itakun agbaye miran: Ibẹrẹ itan igbe aye Tunde Idiagbon Oríṣun àwòrán, OTHERS Ọjọ Kẹrinla oṣu Kẹsan-an ọdun 1943 ni Hassan Dogo ati aya rẹ, Ayisatu iyabeji Idiagbon bi Tunde Abdulbaki Idiagbon sile aye nilu Ilorin, tii ṣe olu ilu ipinlẹ Kwara.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù #Zamfarakillings: Ìjọba pàṣẹ kí wọn dáwọ́ ìwakùsà ní Zamfara 7 Ìgbé 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 8 Ìgbé 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ọjọ́ Etí ni Abẹnugan Ilé Ìgbìmọ̀ Aṣòfin ìpìnlẹ̀ Zamfara fi léde àwọn jàgúdà tí pa ènìyàn 50 tó jẹ́ ọmọ ẹgbẹ JTF.
Gina to jẹ iya India Kager ṣafiwe ohun to ṣelẹ lẹyin iku George Flyod ni America pẹlu iku ọmọ tirẹ.
“Awon eto omo eniyan, ti o pon dandan, ti o se e fowo ra, eyi ti yoo mu alaafia ati idagbasoke waye”.
Gbogbo ohun tí mo sọ láti ọjọ́ tí mo ti ń bá ọ sọ̀rọ̀ ní ìgbà ayé Josaya títí di òní, ni kí o kọ.
Lẹnu ọjọ mẹta yí, itako ọrọ láàrin Obasanjo àti Buhari ti peleke sí i lẹyìn tí Obasanjo kọ leta sí Buhari lórí bí o tí ṣe n ṣètò ìlú.
O ku diẹ ki wọn o pe miliọnu mẹrinla (13.
Ó dàbí ọkunrin oníṣòwò kan tí ó ń wá ìlẹ̀kẹ̀ olówó iyebíye kan.
Àwọn ọmọ Seiri ni Lotani, Ṣobali ati Sibeoni; Ana, Diṣoni, Eseri ati Diṣani.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Coronavirus Cases in Africa: Àwọn àràmọ̀ndà ìbomú-bẹnu tó gbòde lásìkò Coronavirus yìí 24 Ìgbé 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 9 Èbibi 2020 Akojọpọ aworan alarambara nipa ọna ti awọn eniyan n gba ṣe ibomu-bẹnu nitori coronavirus Oríṣun àwòrán, Ololufe BBC Àkọlé àwòrán, Lati oke de ile ni wọn ti wọ asọ kan naa pẹlu ibomu.
Apapa - Oshodi Expressway / 3rd mainland Bridge, Ijọba ibilẹ Ikeja Somolu / Kosofe 35.
Wọ́n bèèrè lọ́wọ́ rẹ̀ pé: “Kí ni kí á ṣe sí ọ, kí ìjì omi òkun lè dáwọ́ dúró?
ní ọdún kẹtadinlọgbọn tí Asa ọba Juda gorí oyè, Simiri bá wọlé, ó fi idà ṣá Ela pa, ó bá fi ara rẹ̀ jọba dípò Ela.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: ‘Ìjìyà wà fún ríra ìbò lórílẹ̀-èdè Naijiria’ Àwọn lọ́balọ́ba ilẹ̀ Yorùbá péjúpésẹ̀ si àpérò ní Ilé Ifẹ̀ Orí kò òṣìṣẹ́ EFCC méjì yọ lọ́wọ́ ìjàmbá iná Adikwu, to figba kan jẹ ọlọpaa ri ki iṣẹ to bọ lọwọ rẹ lo ko awọn adigunjale to ṣọṣẹ ni ilu Ọffa sodi.
Awọn eniyan ri awọn ọlọpaa atawọn ẹṣọ ile aarẹ ti wọn duro gidigba lati ṣọ ile aarẹ eyi to wa ni olu ilu orilede naa, Monrovia.
Iwadii fikun un wi pe awọn ẹranko igbo miran bii amọtẹkun, kinihun maa n le eniyan lati pa wọn.
Oríṣun àwòrán, others Bayii ni esi idibo naa ṣe lọ: Ibrahim Olusegun Michael PHD.
Wọn fi ipá mu wa lati sọ pe a jẹbi Oríṣun àwòrán, PIUS UTOMI EKPEI Awọn ọmọbinrin naa ti wọn gbe lọ sile ẹjọ alagbeka kan to wa ni adugbo Old Parade Ground nilu Abuja ni ko ni agbẹjọro kankan to ṣoju wọn bi adajọ ṣe n ka ẹsun wọn sita.
O fi da awon omo ogun naa loju lati pese awon ohun elo ija ogun ati ohun elo amayederun fun won lai fi oro naa fale rara.
Awọn asọfin naa mu ofin ọhun lọkunkundun lẹyin iwadii ẹsun ibalopọ ti ileeṣẹ iroyin BBC ṣe, eyi to tu aṣiri awọn olukọ kan ni Fasiti ilu Eko ati Fasiti Ghana.
kò sinmi láti máa dúpẹ́ nítorí yín, mo sì ń ranti yín ninu adura mi.
Gẹgẹ bii ọmọ Naijiria to n pa ofin mọ, mo gba idajọ ile ẹjọ to ga ju lọ lai fi ohunkohun ṣe - Ademola Adeleke.
Ẹwẹ, Yemi Mustapha ni kete ti awọn de ti wọn si n ṣe eto ati ki gomina ku abọ ati ku oriire ni awọn tun lọ si ile ẹbi oloogbe naa lati bẹ wọn wo.
Nígbà tí àwọn ọmọ Israẹli wà ninu aṣálẹ̀, wọ́n rí ọkunrin kan tí ń ṣẹ́gi ní ọjọ́ ìsinmi; 
tí eniyan lè máa fi wà láàyè títí lae,kí ó má fojú ba ikú.
Ni agogo meji oru ọjọ Satide tii ṣe ọjọ kẹrindinlọgbọn, oṣu kẹwaa ni wọn tuu silẹ lẹyin ti awọn ajinigbe naa jii gbe lasiko to fi n rin irinajo bọ lati ilu Abuja lọ si ilu Akurẹ.
Ni ọjọ́ kan, ó pe ọ̀kan ninú àwọn ẹ̀gbọ́n rẹ ti ó sọ di alágbàṣe ninú oko rẹ tẹ́lẹ̀ ó si bu, ó pe e ni aláìní dé ojú rẹ.
Solomoni gorí oyè lẹ́yìn ikú baba rẹ̀, ìjọba rẹ̀ sì fẹsẹ̀ múlẹ̀ gbọningbọnin.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Rabaraba ogun naa ko si ti tan nilẹ di akoko yii nitori awọn aidaa to bi ogun abẹle nigba naa, si lawọn eeyan kan n tọkasi pe o si wa nilẹ di iwoyi.
O fikun un oro re pe:“A bu enu ate lu bi orile-ede Iran se sekolu si Israel.
AWỌN IROYIN TẸẸ LE NIFẸ SI NIPA RẸ Ta ni Naira Marley jẹ́ gan?
Nitorinaa ni wọn se ni awọn kọ jalẹ wi pe, ijọba ko gbọdọ fun Festus Adedayo ni ipo kankan.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Oluwo: Mo fẹ́ kí gbogbo ọmọ Nàíjíríà gbà mí lórí ìyà tí Oluwo fi jẹ mi, ni mó ṣe pe ẹjọ́ 3 Ẹrẹ̀nà 2020 Oríṣun àwòrán, Oluwo Agbowu tilu Ọgbaagba, Ọba Dikrullahi Akinrọpo ti salaye lori idi to fi gbe Oluwo tilu Iwo, Ọba Abdulrasheed Adewale Akanbi lọ sile ẹjọ lori ija to wa laarin wọn, lẹyin ti igbimọ lọba lọba ipinlẹ Ọsun ti dasi aawọ naa.
Ó sì fi àwọn olórí ẹ̀ṣọ́ tí ń ṣọ́ ẹnu ọ̀nà ààfin ọba ṣe alabojuto wọn.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Abìjà: Bàbá mi fi iṣẹ́ ọdẹ ti ń pa lémi lọ́wọ́ ni nítorí babaláwo ni Adajọ agba naa kọ lati yọju si ile ẹjọ naa, sugbọn ọgọọrọ awọn agbẹjọrọ agba(SANs) lo lọ si ile ẹjọ naa lati se atilẹyin fun agbẹjọro agba naa.
Afẹ́fẹ́ Gáàsì tó ń yọ́ọ́ jò pa Ajibola lẹ́nu iṣẹ́ jórin-jórin Ọkọ lé aya rẹ jáde nílé nítorí ìrísí ojú àwọn ọmọ rẹ méjì ní Ilorin Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'A ò tíì rí omi mu, ẹ ní ká máa fọwọ́ tóríi Coronavirus' Tani Tayo Amusan gan?
Ó sì lọ sọ́dọ̀ Akiṣi, ọba Gati.
Kí ni n óo san fún OLUWA,nítorí gbogbo oore rẹ̀ lórí mi?
Lolade ni Kaka ki n san owo gobọi fun Uber tabi Bold, niṣe ni mo maa lọ wọ ọkọ Danfo tabi Molue nitori ko si owo lasiko yii."
Nibi apero Mo Ibrahim to waye ni ọjọ abamẹta nilu Abidjan, ni o ti sọrọ yi.
OLUWA Ọlọrun ní, “Ní ti ilé Israẹli, kò ní sí ọ̀tá tí yóo máa ṣe ẹ̀gún gún wọn mọ́, láàrin gbogbo àwọn tí wọ́n yí wọn ká tí wọ́n sì ń kẹ́gàn wọn.
Mikaeli ati àwọn angẹli rẹ̀ ń bá Ẹranko Ewèlè náà jà.
 Ti ise oju opopona  naa ba pari , wakati ti awon eniyan maa n fi rin yoo  tun dinku jojo, bakan naa, ni  idagbasoke yoo tun deba  eto oro aje orile ede yii.
Tí o bá fetí sí gbogbo ohun tí òun pa láṣẹ fún ọ, tí o sì ń rìn ní ọ̀nà òun, tí ò ń ṣe ohun tí ó tọ́ lójú òun, tí o pa òfin òun mọ́ tí o sì ń mú àṣẹ òun ṣẹ, gẹ́gẹ́ bí Dafidi, iranṣẹ òun ti ṣe, ó ní òun óo wà pẹlu rẹ, arọmọdọmọ rẹ ni yóo máa jọba lẹ́yìn rẹ, òun óo fi ìdí ìjọba rẹ múlẹ̀ bí òun ti ṣe fún Dafidi; òun óo sì fi Israẹli fún ọ.
Àwọn ọmọ Israẹli ranṣẹ sí ẹ̀yà Reubẹni, ẹ̀yà Gadi ati ìdajì ẹ̀yà Manase ní ilẹ̀ Gileadi, àwọn tí wọ́n rán ni Finehasi, ọmọ Eleasari, alufaa, 
A ti sún ìgbẹ́jọ́ Ganduje, Tambuwal àti Ihedioha sí ọ̀la Àǹfààní wo ló wà nínú Brexit fún Nàìjíríà àtàwọn orílẹ́-èdè Afíríkà?
”Wọ́n dáhùn pé, “Ikú ni ó tọ́ sí i.
Nisoju mi ni wọn se fipa ba awọn mẹrẹẹrin lopọ.
Ní ọdún 1988 wọ́n dá ọjọ́ kíní ọsù Ọpẹ sí gẹ́gẹ́ bíi Ọjọ́ Àrùn Kògbóògù Àgbáíyé.
Ilé aṣòfin orílẹ̀-èdè UK ti faramọ́ fífí ìyà jẹ àwọn adarí Naijiria tọ lọ́wọ́ nínú rògbòdìyàn ENDSARS Ninu ọrọ kan ti o jade lati ile Oodua ti ṣe Aafin Ọọni nilu Ile Ife, ni wọn ti ni aworan Arẹmọ Ọọni ko tii jade sọwọ ẹnikẹni.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Iba Gani Adams: Bẹ́ẹ gbé Yorùbá síbẹ́, ó lè burú ju àwọn míì lọ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Iba Gani Adams: Bẹ́ẹ gbé Yorùbá síbẹ́, ó lè burú ju àwọn míì lọ 10 Òkùdu 2019 Aarẹ Ọna Kakanfo ti ilẹ Yoruba, Ọtunba Gani Adams ti ni ọrọ ijinigbe ko ṣe ajoji si ijọba kankan ni Naijiria.
Ẹ ti dòjé bọ oko, nítorí àkókò ìkórè ti tó,ẹ lọ fún ọtí waini nítorí ibi ìfúntí ti kún.
Oríṣun àwòrán, @SHEHUSANI Àkọlé àwòrán, isejọba Aarẹ Muhammadu Buhari bẹrẹ ni ọdun 2015, Naijiria jẹ gbese to to biliọnu mẹwaa naira.
Ọgbẹni Trump funra rẹ naa gba esi ayẹwo pe o ni Coronavirus nibẹrẹ oṣu kẹwa to si lo ọjọ mẹta nileewosan.
Lára rẹ̀ ni bi Sani ṣe gba ẹgbẹ̀run lọ́nà ogún dọla lọ́wọ́ oníṣòwò ọkọ kan, Alhaji Sani Dauda to jẹ oludári ASD Motors to si ti fun ni ẹgbẹ̀run mẹ́wàá dọ́la ko to lọ fi ẹjọ sun àjọ EFCC.
Àwọn ará Rómù sọ orúkọ rẹ̀ fún òsa Rómù tó únjẹ́ Júpítérì.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Michelle ni inu oun yoo dun lati ri ọmọ̀ naa laipẹ Amọṣa, baba ọmọ naa, iyẹn Ọmọọba Harry ni awọn ko tii jiroro lori orukọ ti ọmọ naa yoo jẹ.
Ẹmi rẹ ko lọ si i ṣugbọn ojoojumọ lo fi n sọkun awọn ọmọ rẹ meji ti aldugbo rẹ Celestine pa lasiko ipaniyan lẹyamẹya ọhun.
nítorí pé, àwọn ọmọ ogun Kitimu tí wọ́n wà ninu ọkọ̀ ojú omi yóo gbógun tì í.
O ni: Gbogbo èèyàn lo n gbe ọmọ wale lẹ́yìn ibimọ ṣugbọn irinajo tèmi ko ri bẹ́ẹ̀.
Ṣaṣa ni orileede agbaye ti eeyan yoo de ti ko ti ni ba ọmọ Naijiria.
" Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo Aderibigbe tun sọrọ siwaju pe, Seyi Makinde tun wa lẹẹkeji lati wa fi iwe pe aarẹ musulumi si ibi waasi aawẹ to seto, oun si ni aarẹ ni ki oun tẹle lọ soju oun, inu mọto Seyi si ni oun wọ lọ sibẹ.
 “A ti se ipade pelu awon egbe oselu ki eto idibo to waye rara, bakan naa ni a n ba awon ti oro kan soro, eyi ti a ni igbagbo pe, a niigbekele ati igbora eni ye.
Ebi kò ì tí à mí nísisìyí, ìgbà tí a bá simi díẹ̀ n óò wáá jẹun.
Lasiko irinajo wa naa, a ri kanga agboole Seriki Abass, ti wọn kọ lọdun 1847 eyi ti wọn pe ni Brazilian Barracoon.
Alukoro ajọ ọlọpaa ipinlẹ Ọyọ, Fadeyi Oluwagbenga fi idi ọrọ naa mulẹ.
Mo ba wọn jọsin nile ijọsin atibẹrẹpẹpẹ ẹbi mi, St Paul's Anglican Church, Ayegbaju, Ile-Ife loni lati fi ọpẹ fun Oluwa ati lati kasẹ ayẹyẹ ọdun marun ti mo pe lori itẹ."
Àwọn èdè àjèjì yìí kì í ṣe àmì fún àwọn tí ó gbàgbọ́, bíkòṣe fún àwọn tí kò gbàgbọ́.
Ìjọ Àgùdà dìbò pé kí àwọn baálé ilé tó ní ìyàwó má a jẹ àlùfáà ìjọ Atiku fikun ọrọ rẹ pe inu oun ko bajẹ lori idajọ ile ẹjọ, o ni oun ko ronu nipa ara oun bi ko ṣe pe nipa Naijiria l'oun ro ni gbogbo igba.
Bí wọn bá gbèrò ibi sí ọ,tí wọ́n sì pète ìkà, wọn kò ní lè ṣe é.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Osun Election Results: Wọ́n ti ka ìbò Ọṣun tan, ìkéde INEC lo kù 23 Owewe 2018 Àkọlé àwòrán, Abajade èsì ìdìbò Ọṣun bí INEC ṣe kàá sita Onikaluku n dúró de ìkéde ajọ INEC lórí idibo Ọṣun.
Rape: Oluwaseun Osowobi ní Commonwealth fún lámì ẹ̀yẹ ọ̀dọ́ tó pegedé jùlọ ní 2018
Nígbà tí wọ́n rí ìrànlọ́wọ́ gbà, wọ́n ṣẹgun àwọn ará Hagiriti ati àwọn tí wọ́n wà pẹlu wọn, nítorí wọ́n ké pe Ọlọrun lójú ogun náà, ó sì gbọ́ igbe wọn nítorí pé wọ́n gbẹ́kẹ̀lé e.
Barrister lo bi gbogbo oníṣẹ́ fújì -Oṣupa
" fún àpẹẹrẹ , "" csd g12 "" tọ ́ ni sí "" ààmì kejìlá "" lábẹ ́ àpapọ ̀ ( àdàkọ ìṣẹ ́ tí kìí ṣe tìrẹ ) àti "" csd u1 "" tọ ́ ni sí "" ààmì àkọ ́ kọ ́ "" làbẹ ́ "" oníṣẹ ́ "" ( ìbẹ ́ èrè oníṣẹ ́ ) ."
“Majẹmu ìyè ati alaafia ni majẹmu mi pẹlu Lefi.
Nípasẹ̀ àwọn ọmọ rẹ ni n óo ti bukun gbogbo orílẹ̀-èdè ayé, nítorí pé o gbọ́ràn sí mi lẹ́nu.
Ijoba orile ede Naijiria ti ni ise akanse lori ina mona-mona ko ni pe bere , ni eyi ti won yoo maa lo odo nla , ni eyi ti yoo wa ojutuu si Isoro ati ipenija to maa n waye lori ina mona-mona ni jake-jado orile ede Naijiria.
Ọkùnrin kan rí ẹ̀wọ̀n ọdún mẹ́rin he lẹ́yìn tó jí ẹ̀rọ ìléwọ́ iPhone ní ìpínlẹ̀ Ogun A ti gbé ìwádìí dìde lórí ìpànìyàn tó wáyé lásìkò ìwọ́de EndSARS- Ilé ẹjọ́ àgbáyé, ICC Àwọn ọ̀dọ́ dáná sun ọkọ̀ akérò tó ṣekúpa ọlọ́kadà ní Ibadan Oṣú mẹ́fà ni òṣìṣẹ́ ìjọba tó bá bímọ yóò máa lò nílé kó tó wọṣẹ́ padà- Seyi Makinde A kó ní sanwó oṣú ASUU láìjẹ́ pé wọ́n gba IPPIS- Ìjọba Àpapọ̀ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Orlando Owoh: Èmí àti Oladipupo Owomoyela jọ lọ ẹ̀wọ̀n Alágbọn- Caroline Owoh, aya Orlando Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Alaafin: Wo arẹwà mẹ́jọ̀ tó ń ṣìkẹ́ Ọba Adeyemi13 Ògún 2020 Alaafin Oyo: Kíni 'Ẹ̀lẹ̀ daddy' Olorì Abbey Adeyemi ṣe tí ojú òpó ayélujára rẹ̀ fi ń yeruku lálá?
Jesu bá sọ fún àwọn eniyan ati àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ pé, 
 kò sí bátànì kan pàtó tí alápìíìrì gbọ ́ dọ ̀ tẹ ̀ lé nínú eré nítorí pé bí ó bá ṣe wuni ni a ṣe ń ṣèmọ ̀ le ẹni ní àpẹẹrẹ ìsàlẹ ̀ yìí , alámọ ̀ ni eléré àpíìrì yìí fi bẹ ̀ rẹ ̀ erée rẹ ̀ .
Njẹ ẹya ẹjẹ SS lee yipada?
Bí ó bá jẹ́ pé ìwé tí mo kọ bà yín ninu jẹ́, n kò kábàámọ̀ rẹ̀.
Miyazaki so pe, awon onraja ati awon oludokowo nilo aabo ti o peye latari ati maa se fara kasa awon akoba ti ohun ayederu ti se fun eto oro-aje, eto oja idokowo ati ajosepo eto idokowo lagbaye.
Ẹ̀yin tí ẹ̀ ń retí ọjọ́ OLUWA, ẹ gbé!
Bakan naa la ri ninu ere ori itage Edo yi pe Adams Oshiomole to ti kọkọ kẹyin si Ize Iyamu to ko ipa ribi ribi nigba ti Oshiomole fi dupo Gomina ti wa pada wa fontẹ lu Iyamu gẹgẹ bi ayanfẹ rẹ bayi.
Ọ̀pọ̀ òṣèré tíátà tó ń sàìsàn ni kò ṣe dáadáa fẹ́gbẹ́ - Jide Kosọkọ Seyi Makinde, yé é sọ̀rọ̀ mi láìdà - Gomina Ajimobi Igbakeji adari àjọ SERAP, Ọgbẹni Oluwadare, tó ba BBC yoruba sọ̀rọ̀ sàlàyé pé, àjọ náà ṣe ètò ìwádìí naa ní ẹkun mẹfẹfà to gbé orilẹ̀-èdè Nàìjíríà ro láàrin àwọn eeyan ti ọjọ ori wọn jẹ méjìdínlogun sóke ní ìpínlẹ̀ mẹ́fà àti olulu orilẹ̀-èdè Naijiria ti ṣe Abuja.
Nítorí tiyín gan-an ni OLUWA ṣe bínú sí mi, tí ó sì fi ibinu búra pé, n kò ní kọjá sí òdìkejì Jọdani, n kò sì ní dé ilẹ̀ dáradára náà, tí OLUWA Ọlọrun yín fun yín.
Ọwọ́ sìkún ọlọ́pàá tẹ afurasí lórí ẹ̀sùn ìpaǹìyàn ni Port Harcourt ìjàmbá ọkọ lọnà Èkó gba ẹmí Èniyàn márùn ún!
Nítorí náà Amasaya dá àwọn ọmọ ogun Efuraimu tí ó gbà pada sílé wọn.
Awọn ọmọ ẹgbẹ igbimọ yii ni Ile Igbimọ Aṣofin yii ti ṣagbeyẹwo wọn ni ọjọ Aje, ọjọ kẹrinla oṣu karun-un ọdun 2018 yii, gẹgẹ bi ibeere Gomina ṣugbọn wọn ko pinnu lori rẹ.
Jakọbu bá bẹ̀rẹ̀ ìrìn àjò rẹ̀ láti Beeriṣeba.
Efunsetan Aniwura: Àwọn fíìmù òde òní ń kọ́mọ lólè àti ọ̀pọ̀ ìwà burúkú
Àkọsílẹ̀ yìí jẹ́ ti Naomi Adam àti Sarah Samuel, Rhoda Peter, Sarah Job àti Margaret ti wọn jẹ mẹ́rin nínú awọ́n tí orí kọ́ yọ̀ nínú oṣù karun un, ọdún 2017.
Ko si yẹ ki ẹnikẹni ro pe o ti tan fun oun, ti Eledua ba fi dara to wu u.
D'Banj: A dúpẹ́ fún ìfẹ́ yín
Ẹ wo bi eto isinku naa ṣe lọ ninu fidio yii: Lara awọn to si kopa nibẹ ni gomina ipinlẹ Kogi, to jẹ ilẹ abinibi Tolulope, Yahaya Bello.
"O nilo ikọni, idari, ọrọ pe o gba ẹsin kọ leleyii, Ọlọrun gbudọ tun un bi tori eeyan ṣaa ni mi.
Àwọn ọmọ ogun Juda sì kó ọpọlọpọ ìkógun.
Ìtẹ́ náà ní àtẹ̀gùn mẹfa, ère orí ọmọ mààlúù sì wà lẹ́yìn ìtẹ́ náà.
Titi di bi a ṣe n sọrọ yii alagba Ọlayiwla Adigun ṣi n duro lori pe oriṣa Ọṣun ko si ni ojubọ rẹ ms bayii, bẹẹni baba Ataọja pẹlu n faake kọri pe oun ko ta oriṣa Ọṣun.
Ogún lọ́gọ̀ àwọn olùkọ́ni nílu òyìnbó ni wọ́n jẹ́ ọmọ ilẹ̀ Yorùbá sùgbọ́n pẹ̀lú gbogbo akitiyan wọn kò sí ọ̀kan soso nínú isẹ́ ìwádìí wọ́n pẹ̀lú aroko tí ó wà ní èdè Yorùbá
“Lẹ́yìn náà, mú àgbò keji, kí Aaroni ati àwọn ọmọ rẹ̀ gbé ọwọ́ lé e lórí.
Oríṣun àwòrán, Google Àkọlé àwòrán, Aworan ayẹyẹ Google Oríṣun àwòrán, Google Lọpọ igba ni ohun oyinbo a maa ṣi orukọ adugbo Naijiria pe ti ẹlomiran ko si ni mọ pato ohun ti o n sọ.
aarin(Midfielders): Mikel John Obi (Middlesbrough FC,
Kí ni àwọn eniyan wọnyi ṣe?
Ẹkùn lúgọ de Ọ̀bọ, ó fi ọgbọ́n tan ki ó lè sún mọ́ òhun.
Wọ́n wólẹ̀, wọ́n sin OLUWA, wọ́n sì tẹríba fún ọba.
Àwọn àmì tí o fi le mọ ẹni tó fẹ́ pokùnso: Ẹlẹ́rìí: Ọ̀pọ̀ àwọn tó fẹ́ gba ẹmi àrà wọ́n sába máá n wa ẹlẹ́rí, láti fi àmì ìkìlọ̀ sílẹ̀, wọ́n ma a ń wá ẹni ti wọ́n yóò sọ fún pé, àwọn fẹ́ gba ẹmi ara wọ́n.
Iṣẹ iwadi fi han wi pe lati igba ti awọn ile ẹkọ ti di titi nitori aarun Corona ni awọn eeyan naa ti sọ ọgba ile ẹkọ ijọba di ile itaja.
Mẹtalelọgọfa ninu wọn lo wa lati ipinlẹ Eko eyi si lo pọju ninu gbogbo ipinlẹ lọjọ Iṣẹgun.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Bàálù to gbe Yemi Oṣinbajo já lulẹ̀ ní Kogi 2 Èrèlè 2019 Oríṣun àwòrán, LAOLU AKANDE Iroyin to n tẹwa lọwọ ni pe ọkọ baalu Igbakeji Aarẹ Naijiria, Yẹmi Ọṣinbajo ja lulẹ ni ilu Kabba nipinlẹ Kogi laipẹ yii.
Nítorí OLUWA ti yan Sioni;ó fẹ́ ẹ fún ibùjókòó rẹ̀:
Nígbà tí ó ṣe, Àǹjànnú-ìbẹ̀rù gbé ẹsẹ̀ ọ̀tún bàbá mi kúrò ní ilẹ̀ tán pátápátá, ó sì ń gbé e lọ sí ibi èjìká, bàbá mi fi ẹsẹ̀ osì ti ilẹ̀ bí ẹbọra náà ti ń tì í lọ sí ibi kòtò kí onítọ̀hún baà ṣubú sí inú kòtò kí ó kún inú kòtò bámúbámú - ṣùgbọ́n eléyìínì kò ṣeé ṣe; nítorí kí òun tóó ti bàbá mi dé inú kòtò, bàbá mi ti gba ẹsẹ̀ rẹ̀ ọ̀tún sílẹ̀ ó sì ti fi méjèéjì ti ilẹ̀, nígbà tí Àǹjànnú-ìbẹ̀rù si bẹ̀rẹ̀ báyìí tí ó gbá bàbá mi kúrò ni ilẹ̀ tán pátápátá tí ó sọ ọ́ sí iwájú pẹ̀lú agbára, ẹsẹ̀ ni bàbá mi fi ti ilẹ̀ tí ó dúró gbọnin, nígbà tí ó sì wọ ẹbọra náà lójú ó bú sí ẹ̀rín ó wí pé, ‘Ẹ̀hìn ológbò kì í balẹ̀, èèwọ̀ ni – gbogbo àwọn iwin sì pariwo.
Oríṣun àwòrán, Alamy Àkọlé àwòrán, Opo emi lo sonu nibi eto isinku ogagun Soleiman ti won tun fi sun isinku naa siwaju Orílẹ̀-èdè Iran ti kọlu ibùdó ọmọ ogun America méjì ní Iraq- America Lati ọjọ Ẹti to kọja ti Amẹrika ti pa Soleimani, olori ikọ ogun Iran ni agbaye ti wa ni inu fuu-aya fuu lori pe o ṣeeṣe ki ogun waye laarin orilẹ-ede mejeeji.
Agbẹnusọ awọn ọlọpaa sọ fun akọroyin BBC pe asiko ti to ki ijọba gbajumọ ọlọpaa agbegbe to maa ni oye iṣẹlẹ lori eto aabo agbegbe kọọkan ati ọna abayọ ki awọn iṣẹlẹ bayii to maa gba ẹbọ ni Naijiria.
Lara awọn to ba iṣẹlẹ ọhun lọ ni okunrin mẹrin, obinrin meje ati ọmọde meji.
O si daju wi pe bi iṣakoso Naijiria ṣe n lọ bayii kii ṣe oun to ṣanfaani fun awọn ọmọ Naijiria."
Ẹ ṣá jẹ́ kí á gbà fún wọn, wọn yóo sì máa bá wa gbé.
"damascus ( ' ) , ni siria won unpe ni "" al sham "" ( ' ) , ati bi "" ilu jasmine "" ( "" "" ) , ni oluilu ati ilu keji totobijulo ni síríà ati ikan ninu awon igberiko 14 ni orile-ede na ."
Ṣugbọn Jehoṣafati sọ fún ọba Israẹli pé, “Jẹ́ kí á kọ́kọ́ bèèrè lọ́wọ́ OLUWA ná.
Ọmọ Nàìjíríà kan gbé Fásitì Oxford lọ sílé ẹjọ́ tàko oríkí ọrọ 'Mortgage' nínú ìwé àtúmọ̀ ọrọ Ọwọ́ ọlọ́pàá tẹ àwọn olè tó kó góòlù àti ẹgbẹ̀lẹ́gbẹ̀ mílíọ̀nù lọ nílé MKO Abiola l'Eko Ó sàn kí ẹ pa mí ju kí ẹ ba oko tí mo gbin igbó sí jẹ́ lọ- Afurasi Clement sí NDLEA Mo ṣetán láti fi ẹ̀ṣẹ́ dín dòdò ìyà fún Anthony Joshua- Efe Ajagba Ara ló ń ta àwọn ẹgbẹ́ NURTW tó ń pariwo mi kiri, APC ni wọ́n bá lọ nígbà náà l'Oyo- Auxiliary Oríṣun àwòrán, others Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí MKO Abiola: Ọwọ́ ọlọ́pàá tẹ àwọn olè tó kó góòlù àti ẹgbẹ̀lẹ́gbẹ̀ mílíọ̀nù lọ nílé Abiola l'Eko4 Owewe 2020 6:18 Fídíò, Akomolede: Bolaji Faleke ni Olùkọ́ tó ń kọ́ wa ní àṣà oge ṣiṣe lórí BBC Yorùbá, Duration 6,181 Owewe 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Awọn nkan to yẹ ki o mọ nipa Laycon Ilu Eko ni wọn bi Leycon si.
Makiri, láti inú ẹ̀yà Manase ni mo fún ní ilẹ̀ Gileadi.
"Oríṣun àwòrán, @DrJoeOdumakin Àkọlé àwòrán, 'Eredi ikọlu awọn agbebọn si awọn ile ẹkọ awọn akẹkọbinrin ni lati dawọn lẹkun lilọ si ileewe' ""Ajọṣepọ wa laarin eto abo ati eto ẹkọ nitori ẹni ti ko ba ni aabo to peye ko lee ronu ati lọ kẹkọ."
 Lára àwọn ti ọlọ́pàá mú ni ọlọdẹ àti àwọn to n siṣẹ́ ní eka owó, sùgbọ́n ǹkan ti a fẹ wadi ni pe, kí ni ìdí ti wọ́n fi kó owó pamọ si ọfíísi fún odidi ọjọ márùn láì ko lọ si ilé ìfowopamọ.
Oríṣun àwòrán, Yusuf_satia/instagram Omijé bọ́ níbi ìsìnkú Ogun Majek Ọkọ̀ wa wọ'gbó lọ lẹ́yìn táwọn dánàdánà dàbọn bò wá- Toyosi Adesanya Ǹjẹ́ o mọ àwọn òṣèré bí Oyin Adejọbi, Funmi Martins àtàwọn míì tó ti dágbére fáyé?
Kabiyesi, bí mo ti ń lọ lọ́nà lọ́sàn-án gangan, mo rí ìmọ́lẹ̀ láti ọ̀run tí ó mọ́lẹ̀ ju ti oòrùn lọ, tí ó tàn yí èmi ati àwọn tí ń bá mi lọ ká.
OLUWA wí fún un pé, “Orílẹ̀-èdè meji ni ó wà ninu rẹ,a óo sì pín àwọn oríṣìí eniyan meji tí o óo bí níyà,ọ̀kan yóo lágbára ju ekeji lọ,èyí ẹ̀gbọ́n ni yóo sì máa sin àbúrò.
#sackFestusAdedayo: Àwọn ọmọ Naijiria kẹ̀yìn si ìyànsípò Festus Adedayo
Pilatu bá dá Baraba sílẹ̀ fún wọn.
"Pupọ ninu wọn lo ni funra awọn lawn gbe wọn lọ sibẹ tori wọn jẹ alaigbọran tabi ole, onipanle ọmọ ti wọn si fẹ ki wọn lọ kọ keu""."
Nígbà tí ó di ọdún karun-un ìjọba rẹ̀, Ọlọrun fi ìyà jẹ ẹ́ nítorí aiṣootọ rẹ̀.
 ibudo rẹ jẹ ibudo ọkọ oju-omija ti o tobi julọ ni okun adriatic .
 ni 2005 , ohun ni obinrin akoko to di oga agba awon osise brasil , nigbati aare luiz inácio lula da silva yan sipo na .
Ọpọ eeyan si ti sọ pe òṣì lo n mu ki awọn eeyan o ma a tọrọ baara, paapa awọn ọmọde ti awọn obi wọn maa n fi si abẹ ẹ̀kọ́ almajiri, nitori a ti jẹun.
Ọkàn rẹ̀ kì í balẹ̀ lóru, asán ni èyí pẹlu.
Ó bá ọba tí ó ń bá Gehasi iranṣẹ Eliṣa sọ̀rọ̀; ọba fẹ́ mọ̀ nípa àwọn iṣẹ́ ìyanu Eliṣa.
Ọba yan àwọn ọ̀gágun lórí àwọn eniyan, ó sì pe gbogbo wọn jọ sí gbàgede ẹnubodè ìlú.
Ilu Eko ati ilẹ Amẹrika lo ti lo igba ewe rẹ, ko to di pe wọn gba ilẹ Gẹẹsi lọ nigba ti Olukẹmi wa lọmọ ọdun mẹrindinlogun.
Ọga Agba ajọ naa, Abike Dabiri-Erewa sọ pe awọn aṣatipo to le ni ẹgbẹrun lọna ọgbọn nijọba Naijiria ti da pada sile.
Ẹni ọdún mẹẹdọgbọn ni Jehoiakimu nígbà tí ó jọba.
Lootọ gẹgẹ bi wọn ṣe sọ ọ, ilana Covid-19 ni wọn tẹle.
" Àwọn ọmọ orílẹ ̀ èdè nàìjíríà tí àríwá kò fìgbàkan gba ti ọ ̀ làjú tí wọ ́ n sì ń pèé ni "" ilimin boko "" ( "" ẹbu ẹ ̀ kọ ́ "" ) tí wọ ́ n sí máa ń pe ilé ìwé ní "" makaranta boko "" ."
je ikefa re ti yoo waye niluu Abuja.
Wọn ni ti gbogbo eeyan lo n ṣe.
MI naa tun dahun pe ti 'eniyan Ọlọrun' ba ṣe iṣẹ ibi, 'eniyan Satani' ni.
31 Ẹrẹ̀nà 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 2 Ìgbé 2020 Arun Coronavirus ko mọ ọmọde, bẹ ni ko mọ agbalagba, bo ṣe n pa olowo lo n kọlu ẹni ti ko ni.
Ayálégbé wa tó fi tipá já àbálé mi ṣe àkóbá fún ìgbé ayé mi - Foluke Daramola Ìjà Awolọwọ, Akintọla àti ogun 'Wẹtiẹ', ẹ̀kọ́ wo ló kọ́ wa?
Laipẹ́ yii, olusọ̀aguntan ijọ RCCG, pasitor Adeboye sọ ni gbangba fun awọn ọmọ ijọ rẹ̀ wipe, ẹni ti ko ba san idamẹwa ko ni lọ si ọ̀run.
Abrahamu bá sọ fún àwọn ọdọmọkunrin tí wọ́n tẹ̀lé e, ó ní, “Ẹ dúró ti kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ níhìn-ín, èmi ati ọmọ yìí yóo rìn siwaju díẹ̀, láti lọ sin Ọlọ́run, a óo sì pada wá bá yín.
Wọ́n ti pa ẹni to yìnbọn pa ará Texas márùn ún -ọlọ́pàá Gbogbo ọjà di títì pa nílùú Akure, ṣugbọ́n nítorí kí ni?
Oríṣun àwòrán, Twitter Ijọba Gombe sọ pe aimọkan lo mu ki awọn eeyan naa ṣe iwọde.
Ṣugbọn Ọlọrun yóo ta wọ́n lọ́fà;wọn óo fara gbọgbẹ́ lójijì.
Lara awon eru ti ile ise Asobode ekun yii  tun ri gba ni a ti ri oko ayokele (Toyota Corolla) ti owo  re le die ni Milioni Meta Naira, oko ayokele (Toyota Highlander) ti owo
Ninu gbogbo ìpọ́njú wa, mo ní ayọ̀ lọpọlọpọ.
Akitiyan ọmọ'ṣẹ́ mi tó wà lára àwọn tó jí ìbejì mi gbé kò kéré nígbà tí á n wá wọn- Akeugbagold Bakan naa ni Minisita fun eto ẹkọ, Mallam Adamu Adamu wa paṣẹ fun awọn adari ajọ naa lati bẹrẹ igbesẹ lati gba gbogbo owo ti wọn fi ọna ẹru gba pada lọwọ wọn.
Pẹpẹ bàbà tí Besaleli ọmọ Uri, ọmọ Huri ṣe, wà níbẹ̀ níwájú àgọ́ OLUWA.
Ọjọ Ẹti nikan ni ejo naa maa n fi aaye gba omi pipọn.
Ìdìbò abẹ́lẹ́ fún ìpo gomina yoo wáyé lóni Idibo abẹle lati yan oludije fun ipo gomina labẹ asia ẹgbẹ oṣelu APC yoo waye lawọn ipinlẹ to ku ni Naijiria loni ọgbọn ọjọ, oṣu kẹsan an yatọ si ti ipinlẹ Imo ati ti Eko ti wọn sun si ọjọ kini, oṣu kẹwaa, ọdun yii.
orile ede yii ku ori-ire fun ayẹyẹ ayajo odun awon osise lorile ede Naijiria.
Fun akẹẹgbẹ rẹ nipinlẹ Eko, Gboyega akọsile sọ pe ipinlẹ Eko ko tii ni erongba kankan lati darapọ mọ eto naa.
10 Ọ̀wàrà 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 24 Ìgbé 2020 Ṣe eyin naa mọ orukọ ẹ̀ṣọ́ ara aya yín?
Amule iko naa, Ikechukwu Ezenwa ati Daniel Akpeyi nireti wa pe, won yoo darapo mo won leni ti n se ojoRu(Wednesday).
OLUWA, gbọ́ láti ọ̀run, kí o ṣe ìdájọ́ àwọn iranṣẹ rẹ.
Ọ̀rọ̀ tí OLUWA sọ nípa ilẹ̀ Moabu nìyí: Nítorí tí a wó ìlú Ari ati Kiri lulẹ̀ ní òru ọjọ́ kan ṣoṣo,ó parí fún Moabu.
Àkọsílẹ̀ bí wọn ṣe pín ilẹ̀ Kenaani, tí ó wà ní apá ìwọ̀ oòrùn odò Jọdani fún àwọn ọmọ Israẹli nìyí.
Nítorí náà, n óo sọ iná sí ààfin Hasaeli, yóo sì jó ibi ààbò Benhadadi kanlẹ̀.
Ó bá rọra dá àwọn nìkan mú lọ sí ìlú kan tí ń jẹ́ Bẹtisaida.
"Awa ọdọ nilẹ Yoruba n bu ẹnu atẹ lu igbesẹ ti ijọba gomina Abiọla Ajimọbi tipinlẹ Ọyọ gbe lati wo ileesẹ redio Fresh Fm, eyi to si lewu fun alaafia orilẹ-ede yii.
Pinnick: Danny Jordaan láti South Africa ló rọ́pò rẹ̀
sibẹsibẹ, a máa tọ́jú oúnjẹ rẹ̀ ní àkókò ẹ̀ẹ̀rùn;a sì máa kó oúnjẹ jọ, ní àkókò ìkórè.
Ijoba orile ede Naijiria ti ni
Ọgọrọ awọn ololufẹ Arsenal ni wọn yabo oju opo ayelujara papaajulọ Twitter, nibi ti wọn ti sọ pe ki Emery kọwọ fipo rẹ silẹ tabi ki Arsenal juwe ile fun un.
“Ní ọdún kinni ìjọba Dariusi ará Mede, mo dúró tì í láti mú un lọ́kàn le ati láti bá a fi ìdí ìjọba rẹ̀ múlẹ̀.
Ọmọ adáṣọ bù á lẹ̀ jẹ
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Kogi àti Bayelsa: Gomina Yahaya Bello ti Kogi àti David Lyon ti Bayelsa gba ìwé ẹ̀rí INEC 21 Bélú 2019 Oríṣun àwòrán, others Àkọlé àwòrán, Gomina Yahaya Bello gba iwe ẹri mo yege lọwọ ajọ eleto idibo Ajọ eleto idibo INEC ti fun gomina ti wọn kede pe o jawe olubori ninu idibo ipinlẹ Kogi, Yahaya Adoza Bello ni iwe ẹri lati pada sipo gomina.
Orísìíríṣìí ìtàn atẹnudẹ́nu ló dárúkọ rẹ̀, àmọ́ kòsí ẹni tó mọn òdodo ọ̀rọ̀.
 Ṣùgbọ ́ n a rí àwọn ìlú díẹ ̀ tí wọn gbọ ́ èdè ara wọn bí ó tilẹ ̀ jẹ ́ pé ìyàtọ ̀ wà díẹ ̀ díẹ ̀ nínú wọn .
Laduntan Oyekanmi di ìyálóde tuntun fún ilẹ̀ Ibadan Ìtàn tó wà nídi òwe ‘Sebótimọ Ẹlẹ́wà Sàpọ́n’ Taiwo Akinkunmi, ọmọ Ibadan tó ya àsìá Nàíjíríà Ogedengbe Agbógun Gbórò, Akọni tó ń dẹ́rù ba ikú.
Ninu ọrọ tirẹ, Alaga Igbimọ to n ri si fun ọrọ iroyin ati Ilana Imuṣẹṣe ninu Ile, Aṣofin Tunde Brahimoh ṣalaye pe ofin yii yoo le la awọn ilu lọyẹ, ti wọn lero pe gbogbo awọn ti wọn n ṣe wre nita gbangba nikan ni o ni arun ọpọlọ.
Bakan naa ni Obasanjo tun laago ikilọ fun awọn olori orilẹ-ede ede ni ilẹ Afirika pe, ki wọn tete dawọle ọgbin oúnjẹ lọpọ yanturu lẹyin arun Coronavirus.
Wọ́n bi í pé, “Báwo ni ojú rẹ́ ti ṣe là?
olote naa labe igi ti won sapamo si niluu Baga.
ṣugbọn awọn oṣiṣẹ kọ jalẹ pe ẹgbẹrun lọna ọgbọn naira lawọn yoo gba gẹgẹ bi owo
Alufaa yóo gbà á, yóo fa ọrùn rẹ̀ tu, yóo sì sun ún lórí pẹpẹ, lẹ́yìn tí ó bá ti ro ẹ̀jẹ̀ rẹ̀ sí ara pẹpẹ tán; 
Sùgbọ́n èyí ńta ni lára ní irú orílẹ̀èdè ẹkùn ìwọ̀ oòrùn Áfíríkà níbi tí fífi ipá bá ni lopọ̀ ti fẹ jú síbẹ̀ síbẹ̀, wọ̀n kìí fibẹ̀ẹ́ sọ̀rọ̀ nípa ẹ̀.
Coronavirus Update: Èèyàn mẹ́sàn án míràn tún ni Coronavirus nípìnlẹ́ Eko, ó di èèyàn 111 tó níi ní Nàìjíríà Oríṣun àwòrán, Getty Images Eniyan mẹrinla miran tun ti ni aarun coronavirus ni orilẹ-ede Naijiria.
Lootọ a ko lee ri angẹli ni ipo isejọba nitori gbogbo awọn olori orilẹede kaakiri agbaye naa lo ni tiwọn lọwọ nitori ibi gbogbo la n dana alẹ, ọbẹ kan dun ju ara wọn lọ ni."
Ọrọ Yoruba kan lo ni ‘asun fọn-fọn n tifọn, asun-maparada ni ti igi aja’, bẹẹ́ ni ọrọ ri fun ọkunrin ajinigbe naa, ti ẹnikẹni ko tii mọ orukọ rẹ.
ẹyẹ àkọ̀, ati oniruuru yanjayanja, ẹyẹ atọ́ka, ati àdán.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Nigeria governor's Forum: Kò sí Móṣáláṣí lórí ilẹ̀ náà, kòròfo ilẹ̀ lásán ni 9 Owewe 2019 Oríṣun àwòrán, @others Àkọlé àwòrán, Emi ko wó Mọṣalaṣi kanakn ni Rivers Lori ọrọ Gomina Wike ati Mọṣalaṣi ti wọn ni o wo ni ipinlẹ Rivers ni ootọ ọrọ ti n fojuhan.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Timi Frank: Àjọ UN, EU ẹ báwa kìlọ fún Ààrẹ Buhari 14 Ọ̀pẹ̀̀ 2018 Oríṣun àwòrán, Google Àkọlé àwòrán, Igbákejì Akọ̀wé ẹgbẹ́ òsèlú APC tẹ́lẹ̀rí, Timi Frank ní Buhari ń ni àwọn ẹgbẹ́ alátakò,PDP lára.
Lara awọn ojusẹ rẹ ni yiyan ati amojuto awọn oṣiṣẹ ileeṣẹ aarẹ to ṣe koko, ṣiṣe ilana ti awọn oṣiṣẹ ileeṣẹ aarẹ yoo ma gba ṣe iṣl wọn, amojuto bi awọn eniyan ṣe n wọ ile aarẹ, Aso Villa si, amojuto iwọlejade iroyin nileeṣẹ aarẹ mimojuto awọn nkan to le ṣe anfaani tabi pa aarẹ lara, iduna-dura pẹlu ile aṣofin, ati awọn ẹka ileeṣẹ ijọba to kú lati ṣe amulo ilana iṣejọba aarẹ, ati gbigba aarẹ nimọran lori oriṣiriṣi iṣẹlẹ.
Ní àkókò kan àwọn ọmọ Israẹli fi ìṣákọ́lẹ̀ rán an sí Egiloni, ọba ilẹ̀ Moabu.
Ọgbẹni Shittu ṣalaye pe awọn ọdọ tí aje iwa ibajẹ naa ba ṣi mọ lori yoo jẹ iyán wọn niṣu kete ti Amọtẹkun ba gberasọ tan loṣu kẹta ọdun 2021.
n gbe kaakiri lati fi ba oruko aare Muhammadu Buhari jẹ.
Ọga Agba ajọ EFCC naa fi kun un wi pe awọn ko ni gba iwa ibajẹ laaye nigba kankan nitori awọn yoo tẹsiwaju lati maa gbogun ti iwa ibajẹ.
Èyí ni Aaroni yóo máa wọ̀ nígbà tí ó bá ń ṣe iṣẹ́ alufaa rẹ̀, yóo sì máa gbọ́ ìró rẹ̀ nígbà tí ó bá ń wọ ibi mímọ́ lọ níwájú OLUWA ati ìgbà tí ó bá ń jáde, kí ó má baà kú.
Itankalẹ ajakalẹ arun coronavirus ti mu ki okuta o ba ọja eporsbi l'agbaye.
Ṣugbọn àwọn kan ninu wọn lọ sọ́dọ̀ àwọn Farisi, wọ́n lọ sọ ohun gbogbo tí Jesu ṣe.
Iwe iroyin City People ti fun ni ami ẹyẹ ri gẹgẹ bii ẹni to ṣe daadaa fun awọn ara ilu.
Kò gbọdọ̀ fi opó ṣe aya tabi obinrin tí ó kọ ọkọ rẹ̀ sílẹ̀, tabi obinrin tí ó ti mọ ọkunrin, tabi aṣẹ́wó; kò gbọdọ̀ fẹ́ èyíkéyìí ninu wọn.
Wọ́n fún obìnrin kan lọrùn pa, awuyewuye ti ń wáyé Nigba ti o n ṣalaye bi wọn ṣe pa aṣiwaju ẹgbẹ okunkun naa, Kọnẹẹli Ọladipọ ni, yatọ si pe wọn yinbọn pa Ebila lasiko to fi n gbiyanju lati sa mọ awọn agbofinro lọwọ leti bebe odo Kudẹti, awọn ni ẹri pe ọpọlọpọ awọn ọmọ ẹgbẹ okunkun onemillion boys to wa pẹlu rẹ naa fi ara gbọta ibọn.
Siwaju si, akowe agba fun ijoba apapo , ogbeni Boss Mustapha, ti o fimo oga agba awon osise, Abba Kyari abbl.
Oríṣun àwòrán, Reuters Àkọlé àwòrán, Pẹlu bi orilẹede Britain ṣe dibo ninu idibo to kọja, o da bi ẹ ni pe wọn n fẹ Brexit.
Ó ṣiṣẹ́ lábẹ́ ìjọba ìpínlè ìwọ̀-oòrùn àtijọ́ ní ilẹ̀ Nàìjíríà.
Ooni sọ eyi lẹyin ti o gbalejo ẹgbẹ ọdọ National Youth Council of Nigeria ni aafin rẹ to wa ni Ile Ifẹ, ni ipinlẹ Osun.
Ninu iwe kan aarẹ Naijiria buwọlu funrarẹ, Buhari gb'oriyin fun ọgbọn ato oye aarẹ China.
lasiko ti o n ki awon omo orile ede Naijiria ku odun tuntun.
Fidio naa safihan Ayinde nibi to ti n mu gari Ijẹbu pẹlu ẹja dindin ati ede nibi ayẹyẹ igbeyawo kan nilu Ijẹbu Ode.
Ní gbogbo àgbáyé, níbi tí a ti lè rí àwọn Mùsùlùmí àti Kìrìstẹ́nì tí wọ́n ngbé pọ̀ ní ìlú kannáà, kòsí ibi tí ìrẹ́pọ̀ wà tó ti ilẹ̀ Yorùbá!
"Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Bí ẹ ṣe mọ̀wé tó, ẹ wá dánrawò níbí pẹ̀lú ""Àpólà Ọ̀rọ̀ Orúkọ - Noun Phrase ""Nigba to di Ọjọru, ni wọn ni ka ko asọ wa dani, ti wọn si ni ki wọn se oju mi loge fun mi nibudo ẹkọsẹ asaraloge ti mo ti n kọsẹ."
nile, loko ati opopona jake jado agbegbe rẹ.
Ṣé tí ogún ẹ̀ni bá dáni lójú a fi ń gbárí ni?
"Amọ, nigba ti wọn ko gbọran si aṣẹ naa ni ""ọkan lara wọn ṣẹwọ si awọn yooku rẹ, loju ẹsẹ naa si ni wsn bẹrẹ si ni yin afẹfẹ oloro naa."
Festac / Amuwo-Odofin Link Bridge Ijọba ibilẹ Amuwo Odofin 19.
4 Bẹ́ẹ̀ni, ẹnikẹ́ni tí ó bá fi dòjé rẹ̀ tí ó sì kórè, òun náà ni Ọlọ́run pè.
Nítorí nígbà tí a jẹ́ aláìlera, ní àkókò tí ó wọ̀, Kristi kú fún àwa tí kò ka Ọlọrun sí.
Máa gbé kẹ̀kẹ́ rẹ lọ, àwọn akọròyìn kọ̀ ìpàkọ́ sí Femi Fani Kayọde Bakan naa ni o ti kopa ninu fiimu Hollywood bii Moby, Guns N' Roses, Armin Van Buuren, LMFAO's Sexy ati I Know It.
Oorun sisun jẹ ọkan lara awọn nkan to ṣe pataki ti gbogbo eniyan maa n ṣe ni alẹ, oorun sisun si ni anfaani lọpọlọpọ to n ṣe fun ilera.
kí alufaa wò ó bóyá ó dára tabi kò dára; iye tí alufaa bá pè é náà ni iye rẹ̀.
1 Oliver Cowdery, lõtọ́, lõtọ́, ni mo wí fún ọ, pé dájúdájú bí Olúwa ti wà láàyè, ẹnití í ṣe Ọlọ́run àti Olùràpadà rẹ, àní bẹ́ẹ̀ dájú ni ìwọ yíò gba ìmọ̀ ohun-kohun tí ìwọ yíò bá bèerè nínú ìgbàgbọ́ pẹ̀lú ọkàn òtítọ́, ní gbígbàgbọ́ pé ìwọ yíò gbà ìmọ̀ nípa àwọn àkọsílẹ̀ fífín ti àtijọ́, tí wọn jẹ́ ti igbàanì, tí wọn ní àwọn abala wọ̃nnì lára ìwé mímọ́ mi nínú, nípa èyí tí a ti sọ̀rọ̀ nípasẹ̀ ìṣípayá Ẹ̀mí mi.
"O ṣeeṣe ko jẹ aṣita ibọn lo ba awọn to ku, nitori pe awọn ọmọ kekere ti ọjọ ori wọn wa laarin ọdun mẹwaa si mẹẹdogun ni ibọn ba.
fun ọrọ ilẹ abẹle, Ogbeni Rauf Aregbesola, ogbeni Jim Ovie, ogbeni Wale
Gege bi asofin Ayo Da-Silva,” Opolopo awon oloselu lo ti jade labe asia egbe oselu “APC ati PDP”, ni eyi ti won ti n tuko orile-ede Naijiria fun ojo pipe, sibesibe ebi si n pa awon ara ilu, awon omo wa ko nise lowo, bee si ni awon obinrin wa ti di asewo kale.
Ẹ̀yin ọmọ Israẹli,ẹ pada sọ́dọ̀ ẹni tí ẹ ti ṣàìgbọràn sí lọpọlọpọ.
Nígbà tí àwọn iranṣẹ Hadadeseri rí i pé Israẹli ti ṣẹgun àwọn, wọ́n bẹ Dafidi, wọ́n sì bẹ̀rẹ̀ sí sìn ín.
Elija bá súnmọ́ gbogbo àwọn eniyan, ó wí fún wọn pé, “Yóo ti pẹ́ tó, tí ẹ óo fi máa ṣe iyèméjì?
Wọn ti lero pe bi awọn ṣe parapọ ba ọpọ dukia jẹ, ti wọn si ṣe ọpọ iwa jagidijagan lasiko naa, ti ko si si ẹni to mu wọn sii, ni awọn ṣe lee maa hu iwa kotọ naa lọ."
“Ṣugbọn ẹ̀yin ọlọ́rọ̀ gbé,nítorí ẹ ti jẹ ìgbádùn tiyín tán!
pe eto idibo to waye ni irọwọ ati irọsẹ loju gbogbo agbaye, ki enikan si tun maa
Nítorí náà, Ajana gba onídùró Melaye pẹ̀lú mílíọ̀nù mẹ́wàá Náírà.
Uzoka jẹ okan lara awọn ti wọn yoo kọkọ fi ọbẹ gun pa ni orilẹ-ede naa ni Ọdun 2018.
Lara awọn to ku ọhun ni ọkunrin meji ati obinrin mẹta.
 kò tíì yé ni bóyá oríṣi àjẹsára náà tí à n gba ẹnu lò léwu láti lò nígbàtí ènìyàn bá wà nínú oyún .
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Awọn ọmọ Chibok- 'Mẹ́ẹ̀dógún lókù tó wà láàyè' 14 Ìgbé 2018 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Loni lo pé ọdún mẹ́rin geere ti wọn ko ọ̀rìnlérúgba o din mẹ́rin ọmọbìrin ni ileewe girama to wà ni Chibok Akọ̀ròyìn kan to ní àjọse pẹlu ikọ̀ Boko Haram ti sọ pe, mẹ́ẹ̀dógún péré ló kù tó wà láàyè ninu ọmọ méjìléláàádọ́fà to si wà láhàámọ́ awọn Boko Haram ninu awọn ti wọ́n jí gbé ni ilu Chibok.
Ìtumọ̀ iye àmì náà ni ọtalelẹgbẹta, ó lé mẹfa (666).
Oríṣun àwòrán, @PoliceNG O ni iru igbesẹ bẹẹ yoo koba irufẹ ijọba bẹ ẹ to jẹ pe ara ilu lo dibo yan an sipo, paapa nilẹ Iwọ-oorun Gusu Naijiria .
A ti fi ayé lé àwọn ẹni ibi lọ́wọ́,ó ti di àwọn adájọ́ rẹ̀ lójú.
INEC lẹ orúkọ àwọn olúdíje sípò gómìnà ní Ọsun 'Ayélujára la fi rí ọmọ wa tó sọnù!
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ado Ekiti Blind Couple: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú Ifipabanilopọ: Ni ọpọ igba ti isẹlẹ ifipanilopọ ba waye, asa awujọ ni lati sọ fun obinrin ti wọn ba fipa ba lopọ pe ko panu mọ.
Nígbà ti wọn pàdé bàbá mi, ó kí wọn àwọn náà si dá a lóhùn bí ó ti yẹ kí ẹni tí a kò mọ̀ rí dá ni lóhùn mọ.
Ayọ̀ọlá: Ẹ mú oní múrí kan wá.
Ìgbà mẹ́ta ọ̀tọ̀ọ̀tọ̀ tí ìjọba Nàìjíríà ti gbẹsan lára orilẹ-ède mí tó dẹ́yẹsí i Egbẹ́ MULAN sọ pe sisọrọ lodi si Anabi Muhammed ti Olorin Yahaya se yii ko tọ suna ninu ẹsin Islam rara ati pe idajọ Sharia tẹ̀ awọn lọrun ninu ilana ofin.
Aláàfin Ọyọ: Pọ́ńbélé Yorùbá ni mí, n ò sì ní tijú rẹ níbikíbi
“Ijiroro ipile keyin lori ona lati samulo papa isere Stephen Keshi fun
Lati ibẹrẹ pẹpẹ iṣẹ rẹ lo ti nifẹ lati maa gbẹjọro fun awọn ti ijọba apapọ tabi ipinlẹ ba fi ẹsun iwa ọdaran kan.
lana ode yii (Ọjọ Iṣẹgun) ni wọn ṣẹṣẹ bu owo le owo ina mọnamọna o.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Omar Al-Bashir ti wọ́n gbajọba lọ́wọ́ ẹ ló di wàhálà Wọn ni wọn jẹbi ẹsun 2, 3, 4.
"Oríṣun àwòrán, @followlasema Oshiomole ṣì ni alága ẹgbẹ́ òṣèlú APC - ilé ẹjọ́ kòtẹ́milọ́rùn Ilé ẹjọ́ ti sún ìgbẹ́jọ́ pásítọ̀ ìjọ Sotitobire si Ọjọ́bo̩ Èèyàn 17 àti ọ̀gá iléẹ̀kọ́ kan bá ìṣẹ̀lẹ̀ ìbúgbàmù lọ l‘Eko Èyí ni ohun tí a mọ̀ nípa afurasí aláàrùn coronavirus nípìnlẹ̀ Enugu O ni ""Mo pinu lati lọ sọ fun alufaa ijọ nipa gaasi to n run, ṣugbọn ki n to de ẹnu ọna ile ijọsin naa, gaasi ọhun ti gba gbogbo agbegbe naa, to si to gbana lẹyin iṣẹju diẹ si."
Ìlú tí ó fún gbogbo àwọn orílẹ̀-èdè ní ọtí àgbèrè rẹ̀ mu, tí ó mú ibinu Ọlọrun wá, ó ti tú!
”Amosa, ko sọro nipa bi awon
Bí ó bá ṣe bẹ́ẹ̀, ó ti ba ẹ̀wù titun jẹ́, aṣọ titun tí ó sì fi lẹ ògbólógbòó ẹ̀wù kò bá ara wọn mu.
Agbẹ́jọrò náà ní gẹ́gẹ́ bi àgbẹnusọ ọlọ́pàá ìpińlẹ̀ Ipinlẹ Oyo ni, Olugbega Fadeyi ṣe sọ, ó ni area Commander ti òun pè sàlàyé pé, kìí ṣe ọlọ́pàá ló yìn ìbọ̀n nílú Ogbomosho.
Ninu atẹjade kan to fi sita loju opo twitter rẹ ni ọsan ọjọ Ọjọru, Davido ni oun ti tun ayẹwo arun Coronavirus ṣe o, ṣaka bayii si ni ara oun ya.
Bi eto yii ba ti bẹrẹ, awọn eeyan maa n peju pesẹ si ipagọ RCCG yii lojukoroju ni ṣugbọn asiko Covid-19 yii, ijọba ti kede pe ile ijọsin kankan ko gbudọ korajọ ti Pasitọ Adeboye naa si sọ fun awọn ọmọ ijọ pe ko ni si ipade adura nla ojukoroju lọdun yii afi lori amohunmaworan ati lori ayelujara.
Ewe, ogagun Texas fikun oro re pe, lara awon omo ogun olote naa sa wo gbo, sinu igbo aginju ti o sun mo won, bee si ni ise n lo lowo lati pa awon ti o sawo igbo naa re patapata.
Ó wà ní apá ìlà oòrùn ọgbà Edẹni.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Baba Suwe: Ó lé ní ọdún méjì tó fi sàìsàn láì kópa nínú tíátà 19 Èrèlè 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 1 Agẹmo 2020 Oríṣun àwòrán, Babasuwe_official instagram Odu ni Babatunde Omidina , ti ọpọ eeyan mọ si Baba Suwe ni agbo ere tiata, kii si se aimọ fun oloko.
''A o ṣa gbogbo ipa lati mu awọn to wa nidi iwa koju ofin'' Ninu idibo bẹnu to waye lagbegbe ohun lai pẹ yi, awọn oludibo faramọ idasilẹ ijọba tiwantiwa fun awọn musulumi to pọ ni guusu Philippines.
Gbogbo àwọn orílẹ̀-èdè tí o dá ni yóo wá,OLUWA, wọn óo máa forí balẹ̀ níwájú rẹ:wọn óo sì máa yin orúkọ rẹ lógo.
OLUWA fún mi ní àwọn tabili òkúta meji náà, tí Ọlọrun fúnrarẹ̀ fi ọwọ́ ara rẹ̀ kọ.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Ẹka eto ilera ni Naijiria ko ri owo na fun ọjọ pipẹ, loorekoore lawọn oṣiṣẹ maa n gun le iyanṣẹlodi fun ẹkunwo.
”Elija pàṣẹ fún iranṣẹ rẹ̀ pé kí ó lọ sọ fún ọba, kí ó kó sinu kẹ̀kẹ́ ogun rẹ̀, kí ó sì sọ̀kalẹ̀ pada sí ilé kí òjò má baà ká a mọ́ ibi tí ó wà.
Láti ìgbà àtijọ́,ni mo tí ń sọ àwọn nǹkan tí kò ì tíì ṣẹlẹ̀.
Ifiyajẹni lọna aitọ O ṣeeṣẹ ki ẹni ti wọn ti fi iya jẹ̀ẹ lọna aitọ ma a tọ si ile.
Má ṣe kó mi lọ pẹlu àwọn eniyan burúkú,pẹlu àwọn tí ń ṣe iṣẹ́ ibi,àwọn tí ń bá àwọn aládùúgbò wọnsọ ọ̀rọ̀ alaafia,ṣugbọn tí ètekéte ń bẹ ninu ọkàn wọn.
5 Máa gbàdúrà nígbà gbogbo, kí ìwọ lè di aṣẹ́gun; Bẹ́ẹ̀ni, kí ìwọ o lè ṣẹ́gun Sátánì, àti pé kí ìwọ lè bọ́ lọ́wọ́ àwọn ìránṣẹ́ Sátánì tí wọ́n di iṣẹ́ rẹ̀ mú.
Dafidi pa àṣẹ OLUWA mọ́, ó sì lọ sí ibi ìpakà Arauna, gẹ́gẹ́ bí Gadi ti sọ fún un.
Nigba ti Ojelade dagba oun naa tun se ere eegun lọ silu miran nibi to ti ko si wahala nitori pe ko juba awọn agba Ọjẹ ko to bẹrẹ idan pipa.
O ba BBC sọrọ nipa bo ṣe maa n ran awọn obinrin lọwọ lori eto rẹ, koda bo ṣe maa n lọ kọ wọn ni ere idaraya to lee mu ara wọn dide fun ibalopọ.
Má ṣe jẹ́ ọlọ́gbọ́n lójú ara rẹ, bẹ̀rù OLUWA, kí o sì yẹra fún ibi.
Arìnrìnàjò sí Libya ní iṣẹ́ agbẹjọ́rò ló wù òun, àmọ́ iṣẹ́ aṣẹ́wó ló mú ṣe ní Libya
Saraki ṣe àdúrà fún Fayẹmi Ààrẹ ilé ìgbìmọ̀ aṣòfin àgbà, Bukola Saraki ti fi àtẹ̀jáde síta lójú òpó Twitter láti kí Kayọde Fayẹmi kú oríire ìdìbò ìpínlẹ̀ Ekiti.
Dafidi sán aṣọ mọ́dìí, ó sì ń jó pẹlu gbogbo agbára níwájú OLUWA.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ṣé lọ́ọ̀ọ́tọ́ ni Kẹmi Adeọṣun kò ní ìwé ẹ̀rí?
'Báyìí la ṣe rìn ín láti pápákọ̀ òfurufú Abuja sí Eko bí ìrìnà òfurufú abẹ́lé ṣe bẹ̀rẹ̀' Kí ló mú Obasanjo ti ilẹ̀kùn mọ́ ẹbí, òṣìṣẹ́, ojúlùmọ̀ ní ibi òkú àna rẹ̀?
Boko Haram, ISWAP in Borno: Islamic State West Africa Province ni àwọn mọ̀ọ́mọ̀ pa ṣọ́jà méje náà ni
 Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Yoruba Culture: ọjọ́ méje ni wọ́n fí n rẹ ẹ̀kú Danafojura kó tó jáde Ijoba APC ni Igboho tẹle pẹlu awọn Fẹlẹ, débi pé lórí ẹsẹ aimọdi, ẹ rán mí lọ síbi tí ń ko fẹ́, mo lọ, mo bọ.
Huramu mọ ìkòkò, ó rọ ọkọ́, ó sì ṣe àwọn àwo kòtò.
Lẹyin naa lo si bẹrẹ iṣẹ olukọni ni Fasiti Bahauddin Zakariya, nilu Multan, titi di igba ti wọn fi ofin gbe e.
Ṣé OLUWA kò ní mú sùúrù mọ́ ni?
 Ni ibamu pelu isele naa, amugbalegbe aare pataki lorii eto iroyin ati
Ẹnikẹ́ni tí ó bá tàpá sí àṣẹ rẹ, tí ó sì kọ̀ láti ṣe ohunkohun tí o bá sọ fún un, pípa ni a óo pa á.
Edẹni, Miniamini, ati Jeṣua, Ṣemaaya, Amaraya, ati Ṣekanaya, ń ràn án lọ́wọ́ ní gbogbo ìlú àwọn alufaa, wọ́n ń pín àwọn ẹ̀bùn náà láì ṣe ojuṣaaju àwọn arakunrin wọn, lọ́mọdé ati lágbà ní ìsọ̀rí-ìsọ̀rí; 
“Mo fẹ́ kí ẹ mọ̀ pé a ti rán iṣẹ́ ìgbàlà Ọlọrun yìí sí àwọn tí kì í ṣe Juu.
Inec kede ọjọ idibo titi di 2055 Inec yoo bẹrẹ iwadi lori oludibo Kano Atẹjade kan ti Paul Ejime, agbẹnusọ fun agbarijọpọ awọn eleto idibo nilẹ Afrika, Econec, fi ṣọwọ si awọn oniroyin ni aarẹ Ghana tẹlẹri John Mahama ṣoju ajọ Commonwealth ti aarẹ ana orilẹede Naijiria, Goodluck Jonathan si ṣoju ibudo iwadi lori ifidimulẹ eto oṣelu arawa nilẹ Afrika nibi ipade naa.
” Lẹ́yìn tí ó ti sọ̀rọ̀ náà tán, ó ṣí ìlẹ̀kùn, ó sá lọ.
Aare Muhammadu Buhari ti ba awọn omo ile igbimo asofin agba ti egbe APC se ipade nile aare to wa niluu  Abuja.
Sibẹsibẹ inú OLUWA kò rọ̀,bẹ́ẹ̀ ni kò dá ọwọ́ ìjà rẹ̀ dúró.
Ewe, ireti wa pe won yoo
O sọ pe lati mu ki eyi ṣeeṣe, o ni ijọba Ekiti ti n ba awọn to yẹ sọrọ.
ede Sudan ti ya jẹ $1.
Kwara Commissioners: Àgùnbánirọ̀ obìnrin, ẹni ọdún mẹ́rìndínlọ́gbọ̀n di kọmíṣọ́nnà ní Kwara
Wọ́n fi kòbókò na àwọn mìíràn.
Ni temi o, ijọba apapọ gan an lo n fa iyanṣlodi yii siwaju.
Mo ti gé àwọn igi kedari rẹ̀ tí ó ga jùlọ lulẹ̀,ati àwọn ààyò igi firi rẹ̀.
Gbogbo nǹkan láyé yìí ló ní àkókò ati ìgbà tirẹ̀:
Oríṣun àwòrán, @SaifRikiji Enwonwu ni oun paṣẹ fun awọn ọlọpaa lati kuro ni agbegbe naa, ki ifẹhonu han ma ba a da rogbodiyan silẹ.
Ṣugbọn jẹ́ kí inú gbogbo àwọn tí ó sá di ọ́ ó dùn,kí wọn ó máa kọrin ayọ̀ títí lae.
Awon miran ti won yan ni oloye ni: Mohammed Ibrahim lati ile ise iwe iroyin New Nigerian Newspapers gege bi igbakeji alaga ati Sola Ojo lati ile ise iwe iroyin The Sun Newspapers gege bi akowe nigba ti Asma’u Halilu tile Akede Naijiria, Voice of Nigeria je okan lara awon omo egbe.
Bakan naa ni oju ọna si Isalu Ọrun, Ibujoko Olowo Aye ati odo ewe gbese ati Ọgbun Ainisalẹ wa ninu Igbo Olodumare gẹgẹ bi Fagunwa ti se apejuwe rẹ.
4 146679 Orilẹede Nepal 1594 5.
Nítorí pé lọ́kàn rẹ̀ a máa pọ́n ara rẹ̀,pé kò sí ẹni tí ó lè rí ẹ̀ṣẹ̀ òun,ká tó wá sọ pé yóo dá òun lẹ́bi.
Ọpọlọpọ wọn ko sin Satani: Iyalẹnu to wa nibẹ ni pe ọpọlọpọ awọn to jẹ olufọkansin ninu ijọ naa kii jọsin fun Satani - wọn ko gbagbọ ninu ọlọrun kankan.
“Ẹnikẹ́ni tí ó bá lu baba tabi ìyá rẹ̀, pípa ni kí wọ́n pa òun náà.
Sowore: Ilé ẹjọ́ pàṣẹ kí ìjọba àpapọ̀ san ₦1m owó ẹ̀bẹ̀ fún ẹgbẹ́ ajijagbara Sowore, torí ìwọde wọn tí wọ́n dà rú
Sudan bẹ Ààrẹ Trump pé kó yọ ọ́ kúrò nínú àwọn orílẹ́-èdè agbésùnmọ̀mí Wo àwọn ti ọmọ Nàìjíríà ń retí kí Buhari fọwọ́ òfin mú- èrò àwọn èèyàn ṣọ̀ọ̀tọ̀ọ̀ Òṣìṣẹ́ iná gún olùdarí Maesk Nigeria àti aya rẹ̀ lọ́bẹ mọ́lé, ìyàwó dèrò ọ̀run Ta ni Funmilayọ Ransome-Kuti?
Ẹnikan to n gbe agbegbe ti ile naa ti wo ṣalaye pe wọn si n kọ ile naa lọwọ ni Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Amọ koda bi oogun Coronavirus tilẹ yọju, ọpọ ni ko ṣi tii le pada sẹnu iṣẹ wọn lẹkunrẹrẹ.
Lai Mohammed fèsì sí ọrọ Obasanjo Exclusive: Buhari ní àìlera lẹ́mìí, lára, àti lọ́kàn- Obasanjo Day 8: Bode George dá sí aawọ̀ Buhari, Obasanjo #BBCNigeria2019 Èmi kò ṣeku-ṣẹyẹ, àyípadà ìṣàkóso Nàìjíríà ni mo faramọ́ - Ọbasanjọ Èmi àti Ọbasanjọ leè yapa nínú òṣèlú, àmọ́ mo ń bọ̀wọ̀ gidi fun - Buhari Amofin Jiti Ogunye bẹnu ẹ̀tẹ́ lú owó inakuna to pọju laarin awọn oloṣelu lasiko yii.
Spanish flu and other pandemic: Ẹ fọkàn balẹ̀, àwọn àjàkálẹ̀ àrùn kan rèé to burú ju Coronavirus lọ
Ó wí pé, “Kabiyesi, ṣé o ti kéde pé Adonija ni yóo jọba lẹ́yìn rẹ ni?
kí o sì bẹ̀rẹ̀ sí yọ̀ fún ohun tí OLUWA fún ìwọ ati ìdílé rẹ, kí àwọn ọmọ Lefi ati àwọn àlejò tí ń gbé ààrin yín náà sì máa bá ọ ṣe àjọyọ̀.
"Ó ṣe ni láànú pé gbogbo akitikyan ààrẹ ní àwọn kan yí dànù tí wọn sì kọ̀ jálẹ̀ láti gba ẹkùn ìwọ̀-òòrún- guusu pada sí àyé ìmunísìn ní bi tí àwọn àìkúkú joyè ó sàn ju ẹnu mi ò kálùú.
Èmi Paulu ni mo wí fun yín pé bí ẹ bá kọlà, Kristi kò ṣe yín ní anfaani kankan.
Ajo to n ri si boolu afesegba nile Afrika (CAF) ti panupo pelu ajo to n ri si boolu afesegba ni Naijiria (NFF) lati sajoyo ayeye odun mẹ́rìnlélógójì agbaboolu iko Super Eagles teleri Taribo West lojo Aje(Monday).
Nígbà tí ó sọ̀rọ̀ báyìí, ojú ti gbogbo àwọn tí ó takò o.
 Ṣugbọn ko si iwadii imọ ijinlẹ kankan to fara mọ ero yii, iwa abuku si ni wọn lo jẹ fawọn obìnrin."
apere buruku lojo iwaju pe, leyin igba ti awon igbimo ti oro kan, naa ti fenuko
Ibi tí mo tí ń ronú yìí ni mo ti rí àgbọ̀nrín kan tí ó ń kọjá lọ mo sì ké sí i mo ní, Àgbọ̀nrín ò, jọ̀wọ́ yọ mí nínú ìhámọ́ yìí o.
Àtẹ̀jáde ọ̀hún tun sọ pé wọ́n ti ní kí àwọn iléeṣẹ́ tọ́rọ̀ kàn san owó ìtanràn tó bá ìkọ̀ọ́kan àwọn ẹ̀sùn tí wọ́n fi kàn wọ́n.
Nítorí náà, fi igi goferi kan ọkọ̀ ojú omi fún ara rẹ.
Wo àwọn oúnjẹ márùn ún tó ń mú kí àtọ̀ ọkùnrin dára síi Abiru wọlé àtúndi ìbò Sẹnẹtọ l'Eko, olùdíje méjì ṣojú APC ní Imo, òṣìṣẹ́ INEC méjì sọnù ní Zamfara Ọmọbìnrin tó tayọ nínú ìdànwó WAEC ọdún 2019 pẹ̀lú A1 méje ti kú Kí lo mọ̀ nípa ìbẹta kan ṣoṣo tí Alaafin Oyo bí?
Ọdun kan sẹyin lo ko wa si ipinlẹ Eko, lati bẹrẹ iṣẹ orin kikọ, Lasiko ti Ebuka fi ọrọ wa lẹnu wo lori irinajo ifẹ oun ati Neo, Vee sọ pe nigba ti awọn ba pada si aarin ilu, ni wọn yoo mọ ibi ti ori n gbe ẹsẹ lọ fun wọn.
Ojú yóo ti Kiriataimu nítorí ogun óo kó o;ìtìjú yóo bá ibi ààbò rẹ̀, wọn óo wó o lulẹ̀;
agbofinro naa ti mura sile fun eto idibo yii.
’ Ọba náà tún ṣe ìbéèrè, ó ní, ọ̀nà wo ni ìwọ gbà tí ìwọ fi pa Àǹjànnú-ìbẹ̀rù?
Eléré ìdárayá Cameroon mẹ́jọ di àwátì Àwòrán ìrántí ní ìdíje Madrid, Juventus A gbìyànjú láti bá àwọn onímọ̀ nipa eré ìdárayá sọrọ lórí òun to máa n je ki àwọn eléré ìdárayá f'ẹsẹ fẹ kété ti wọn ba ti dé ìlú òkèèrè.
Lọjọ aje, ẹgbẹ oṣelu PDP fẹsun kan pe wọn n pete lati fun Adeleke ni majele ni.
Lọ gbógun ti àwọn ará Amaleki, kí o sì run gbogbo nǹkan tí wọ́n ní patapata.
Bẹ́ẹ̀ ni àwọn ìjọ túbọ̀ ń lágbára sí i ninu igbagbọ, tí wọ́n sì ń pọ̀ sí i ní iye lojoojumọ.
Ṣé lóòtọ́ ni àdó olóró bú níléeṣẹ́ ìjọba South Africa tó wà nílùú Abuja?
Lẹyin gbogbo igbesẹ yii, ileefowopamọ rẹ yoo fi awọn numba kan ranṣẹ si ori ẹrọ ibanisọrọ alagbeka rẹ.
Pẹ̀lẹ́ bí ẹ gbóhùn àríri, abínú fọhùn bí ènìyàn
Àkọlé àwòrán, Mo ṣeleri lati fi ootọ inu sin awọn eniyan to dibo yan mi sipo.
Lẹyin naa lo morile Alimoso pẹlu Modina, Osadebey, Isiaka, Bakare, Wahab Oduntan ati Lukman, ti wọn si tun pada si Ileesẹ naa ni aago mẹsan alẹ.
Lẹyin eyi ni awọn agba ọjẹ ninu iṣẹ oṣere nilẹ Yoruba bii Mr Latin, Jide Kosọkọ àti Mama Rainbow sọ̀rọ̀ lórí ìjà Toyin ati Lizzy, wọn n gbiyanju lati dasi aawọ naa.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Lagos State Assembly: Ó takò òfin kí àwọn obí jẹ̀yà ti ọmọ ba darapọ̀ mọ́ ẹgbẹ́ òkùnkùn 12 Ògún 2020 Oríṣun àwòrán, Others Awọn ajafẹtọ ọmọniyan ti bu ẹnu atẹ lu igbesẹ Ile Igbimọ Aṣofin ni ipinlẹ Eko lati buwọlu abadofin ti yoo faaye gba ki awọn obi pin ninu iya ti ọmọ wọn to ba n ṣe ẹgbẹ okunkun yẹ ko jẹ.
Iko agbaboolu orile-ede ti o ba gba ife-eye idije WAFU yoo pegede fun idije boolu afesegba ile Afrika(2019 U-17 African Cup of Nations), ti yoo waye lorile-ede Tanzania.
Igbimọ onidajọ tun daba pe, yatọ si pe wọn yọ adajọ Tokode nipo, o tun gbọdọ da gbogbo owo osu ati ajẹmọnu gbogbo to gba lọna lọna ti ko bofinmu laarin ọjọ keji osu kejila ọdun 2015 ti wọn bura fun un gẹgẹbi adajọ ileẹjọ giga si asiko ti wọn yọọ nipo pada fun ijọba.
Ó ní, “Ẹ fetí sí mi, gbogbo ẹ̀yin ará Juda ati ti Jerusalẹmu ati ọba Jehoṣafati, OLUWA ní kí ẹ má fòyà, kí ẹ má sì jẹ́ kí ọkàn yín rẹ̀wẹ̀sì nítorí ogun ńlá yìí; nítorí pé kì í ṣe ẹ̀yin ni ẹ ó ja ogun ńlá yìí, Ọlọrun ni.
Lara awọn ohun ti wọn n beere lọwọ ọpọ awọn eeyan naa, ti pupọ wọn ko niwe ẹri iwe ni, iwe iforukọsilẹ wọn, ati kaadi idanimọ wọn.
maa dari ipade awon gomina ti ekun Gusu lorile ede Naijiria.
Nínú ihò kejì yìí, àgbàrá òjò tún lé mi jáde, òjò náà pọ̀ tó bẹ́ẹ̀ ẹ̀fúùfù sì fẹ́ tó bẹ́ẹ̀ gẹ́ẹ́, n kò ì tí ì bá irú rẹ̀ pàdé láti ọjọ́ tí mo ti sìnà sí ibẹ̀.
Gbogbo apapọ awọn eeyan ti yoo jẹ anfaani eto naa ni isọri akọkọ, tii se ipinlẹ mejila si jẹ ẹgbẹrun lọna mẹrinlelaadọta.
6 115360 Orilẹede Georgia 1694 42.
"Osinbajo ni ""lootọ iyatọ le wa laarin awn ọmọ Naijiria ni ti ẹsin tabi ẹya ṣugbọn oṣuṣu ọwọ kan naa ni wa""."
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Yoruba Films: Ireoluwa ṣ'ọjọ́-ìbí, Mide àti ọkọ rẹ̀ lẹ̀pọ̀, Iyabo Ojo f'aṣọ ilẹ̀ Afirika dárà 15 Ògún 2020 Oríṣun àwòrán, Instagram Ọjọ nii pẹ, ipade kii jinna.
Ìpínlẹ̀ Osun kéde ọjọ́ táwọn iléèwé yóò ṣí padà Victoria Rubadir ọmọ Kenya ló gba àmì ẹ̀yẹ Komla Dumor BBC World News.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù WHO: Naijiria n koju itankalẹ Lassa to ti i l'agbara ju 28 Èrèlè 2018 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Minisita feto ilera ni ajumọse ni igbesẹ lati gbogun ti iba ọrẹrẹ Akọsilẹ ti ajọ to n ṣ'amojuto aarun ni Naijiria fi sita lọsẹ yii ti jẹ ko di mimọ pe okoolelọọdunrun din mẹta eeyan l'ayẹwo ti fidirẹmulẹ pe o ni aisan iba lassa, gẹgẹ bi Bi o tilẹjẹ wipe igba akọkọ kọ niyi ti aisan naa yoo bu jade ni Naijiria, ṣugbọn ko ti lagbara to bayi ri.
Alessia Afi Dipol Ọjọ ori: Mejilelogun Orilẹẹde: Togo Ere idaraya: Alpine Skiing Pẹlu bi ko se tan mo ile Togo,Alessia Afi Dipol yan lati soju ilẹ naa.
O ni ara awọn agbekalẹ ti awsn eeyan kan ti ko mọ nipa ọrọ ọba jijẹ nilẹ Yoruba maa n sọ kaakiri ni eyi lati lee gbin ẹru ati ọwọ yii ipo ọba ka.
Ẹgbẹ́ òṣìṣẹ́, ìjọba ṣèpàdé lórí owó oṣù sísan l'Ọ́ṣun Nibayii, ajọ to n mojuto akoso ileeṣẹ ọlọpaa lorilẹede Naijiria, ti ke gbajare sita pe 'ọyọkun ọlọpaa ti pọju nigbeoro.
Ọwọ́ ọlọ́pàá tẹ ọkùnrin mẹ́rin pẹ̀lú orí èèyàn ní ìlú Akure Mọ síi nípa ohun tó ṣẹlẹ ní àwọn ibi tí wọn ti ṣilẹkùn ilé ìwé padà lẹyìn Covid 19 A óò dá ẹnikẹ́ni tó bá gbé ìwé àti àṣírí ìjọba síta lórí ayélujára lọ́nà àìtọ́ dúró - Ìjọba àpapọ̀ Ọkunrin to ba ni ibalopọ pẹlu obinrin to n ṣe nnkan oṣu yoo ku: Igbagbọ kẹrin nipa nnkan oṣu obinrin ti ko fi idi mulẹ ni pe, ọkunrin to ba ni ibalopọ pẹlu obinrin to n ṣe nnkan oṣu lọwọ yoo ku.
Ṣugbọn bí a bá jẹ́wọ́ ẹ̀ṣẹ̀ wa: olóòótọ́ ati olódodo ni òun, yóo wẹ àìṣedéédé gbogbo nù kúrò lára wa.
Toyin Abraham: Oríṣun àwòrán, Toyin_abraham Mama Ire, gẹgẹ bi ọpọ eeyan se maa n fi orukọ ọmọ pe Toyin Abraham, jẹ ilumọọka osere tiata lde oyinbo ati Yoruba.
Bi apa karun un eto naa ṣe ti wa sopin bayii, agbeyẹwo awọn to ti jawe olubori lati ẹyin wa ree, pẹlu iye ẹbun owo ti wọn mu lọle.
"Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, #Oshimole: Àwọn aṣáájú APC kò mọ ohun ti wọ́n n ṣe lásìkò yí Ninu ọrọ ti ọkan ninu awọn amugbalẹgbẹ oludije ẹgbẹ oṣelu APC naa ba BBC news Yoruba sọ, ""ko si Alhaji Abdulraham pẹlu ikọ ipolongo naa lasiko ti ikọlu naa waye; ṣugbọn a lee sọ wi pe, Tunji Ajulo Opin to jẹ oludije fun aga ile aṣoju-ṣofin lẹkun Ekiti, Oke Ẹro, Isin ati Irẹpọdun ni ipinlẹ Kwara lẹgbẹ oṣelu APC ni wọn n lepa."
Wọ́n gba àwọn ìlú kéékèèké agbègbè rẹ̀ pẹlu.
Lẹyin naa ni awọn ọlọpaa mu olukọ yii, igbakeji rẹ ati almojuto ti wọn si juwọn si atimọle.
Gamalieli ọmọ Pedasuri, kó àwọn akọ mààlúù meji ati àgbò marun-un, òbúkọ marun-un ati ọ̀dọ́ àgbò marun-un, ọlọ́dún kọ̀ọ̀kan sílẹ̀ fún ẹbọ alaafia.
Gẹ́gẹ́ bi o ṣe sọ o yẹ ki ìjọba tètè wá wọ̀rọ̀kọ̀ fi sàdá ki ọ̀rọ̀ maa ba bẹyìn nítori pe, lọ́wọ́ bayii àwọn ọdàran yìí kan n fi àdá àti okúta dẹrùba àwọn ènìyàn, sùgbọ́n ti o ba yá wọ́n o bẹ̀rẹ̀ si ni lo ibọn.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Fàyàwọ́ ọmọnìyàn kó ọmọ ilé ìwé ọgọ́rùn ún Kíni ẹ mọ̀ nípa àwọn gbajúgbaja Yollywood?
Ile ẹjọ naa gbe igbesẹ yii lẹyin ti wọn fagile ẹsun ti Olusola Eleka ati ẹgbẹ oselu PDP pe lati tako Fayemi to wọle ni Ekiti.
kí o baà lè ní làákàyè,kí ọ̀rọ̀ ẹnu rẹ lè kún fún ìmọ̀.
Ọmọ-ẹ̀yìn tí Jesu fẹ́ràn sọ fún Peteru pé, “Oluwa ni!
Ẹ kíyèsí ọgbọ́n Ọlọrun, nítorí pé, ta ló lè tọ́ ohun tí ó bá dá ní wíwọ́?
Awọn arugbo, ati awsn to ba ni aisan kan to n ba wọn finra ninu ara bi i ikọ semi-semi, itọ ṣuga ati aarun ọkàn, ni aarun covid-19 le da gunlẹ julọ.
Kini awọn ohun ti igbimọ Inec yoo mojuto?
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Akomolede ati Aṣa: Mọ̀ síi nípa ìró afárànma àti agbárànmọ́ fáwẹ́ẹ̀lì Yorùbá 4.
Fowler kò sí lábẹ́ ìwádìí kankan-Garba Sheu Jesu orí ayélujára kan rèé tó wa fun isoji ni Afirika Ohun mẹ́fà tí kò yẹ́ kí o gbàgbé nípa Gómìnà Ambode Wo àwọn eléré ìdárayá mẹ́ta tí àjọ FIFA ti fòfin dè títí ayé Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Ọjọgbọn Gambari lọ si gbajugbaja ileewe King's College nipinlẹ Eko.
Eyi ja si pe ida mẹrindinlogun ninu ọgọrun un pere ni abo to maa ba ijọba Buhari ṣiṣẹ ni saa keji ijọba rẹ yii.
Gbèsè Nàìjíríà yóò di $50b tí wọ́n bá tún yáwó- Shehu Sani Àwọtẹ́lẹ̀ ọkùnrin àti Ìdọ̀tí Kilo méje ṣekú pa Ìgalà Ẹ wo iye t'óúnjẹ dà báyìí lọ́jà lẹ́yìn tí ìjọba ti ibodè Ẹ̀wọ̀n oṣù mẹ́ta àti #3,000 ni awakọ̀ tí kò bá ní ‘speed limiter’ yóò fi jura- FRSC Kin lo tun ṣẹlẹ lasiko abẹwo Trump ni Afghanista?
Afolayan ni oun kọ lati fi ogun silẹ de ọmọ oun nitori oun gbagbọ pe wọn maa ṣoriire ju oun lọ ti wọn fi maa ni ọ̀rọ̀ pupọ.
Bibori ninu idije yii ti fun Ghana loore ofe lati kopa ninu idije agbaye ti oje wewe ti ko tii pe omo odun metadinlogun to m bo lona.
Amọ ọgbọn okoowo Mercy ti sun siwaju bayii tori o ti mu asọ ẹbi tita mọ ọja rẹ, bo si se n ta asọ fun awọn oniyawo, lo n ta tawọn ọljọ ibi ati tawọn oloku agba.
Ri i daju pe ayika rẹ wa ni imọtoto.
"Ẹ fi ọlọ́pàá wa sáàrin ọlọ́pàá yín ní South Africa fún ààbò àjèjì - ìjọba Nàíjíríà bèèrè OPC, Miyetti Allah, agbófinró yóò wà nínú ìgbìmọ̀ aláàbò nílẹ̀ Yorùbá Ìbò abẹ́nú PDP ní Kogi gbérasọ, olùdíje 5 fipò sílẹ̀ fún Idris Wada Ẹkúnrẹ́rẹ́ èróngbà ọ̀jọ̀gbọ́n Wole Soyinka lóri ìgbésẹ̀ Boris Johnson Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fọ́nrán ohùn, Soyinka fí kún pé ìjọba ilẹ̀ Gẹẹsì ń fi àpẹrẹ ""ti kò dára lélẹ̀"" Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ọ̀rọ̀ lórí Brexit Àṣojú ìjọba ti sọ pé ààyè yóò pọ̀ fún àwọn ọmọ ilé aṣofin láti jíròrò lóri ọ̀rọ̀ náà, bótilẹ̀ jẹ pé o yé kí ilé jòkó lóri ọ̀rọ̀ náà lọjọ iṣẹ́gun."
Alhaja Kudirat Abiola, akọni obìnrin, tó gba ọkùnrin mẹ́fà kí wọ́n tó leè pa á Bí Gómìnà Makinde bá ṣẹ̀ mí, lẹ́tà lásán ló jẹ mí- Aláàfin Ọ̀yọ́ Buhari yóò báwọn ọmọ Nàìjíríà sọ̀rọ̀ lọ́la 'June 12' tí ṣe àyájọ́ ìjọba àwarawa Èèyàn 104 kó covid-19 ní iléeṣẹ́ kan ṣoṣo ní Sagamu- Ìjọba Ogun Wèrè tí mò ń ṣe ní Facebook ló pawó fún mi-Esabod Ṣugbọn Obaseki ti sọ pe ni oun ko ni pe ẹjọ kotẹmilọrun lori igbesẹ igbimọ naa.
Buhari pàṣẹ́ kí ojú ọ̀nà Apapa gba ìdáǹdè ní kíákíá Háà!
Seraaya, ọmọ Hilikaya, ọmọ Meṣulamu, ọmọ Sadoku, ọmọ Meraiotu, ọmọ Ahitubu, olórí ilé Ọlọrun, 
Ronaldo, Messi ẹ yàgò lọnà fagbábọ́ọ̀lù Nàìjíríà tó n gbowò julọ!
Amuneke so lasiko to n ba ile-ise akoroyin Complete Sports soro pe, “Iko ohun lapaapo gbodo tara giri, ni tori pe, ipa awon agbaboolu naa ko dara to rara bi o ti le wu ko mo ninu awon ifesewonse won.
Bẹẹ lọmọ sori ni Hong ati Japan ti iye eeyan to ko aisan naa ko pọ to tawọn orileede to jina rere si China lọ.
Ni bayii, Djokovic yoo lo koju Marin Cilic nipele ti o kan.
Bi ẹ ko ba ni gbagbe, Wolii Alfa Sọtitobirẹ n jẹjọ pẹlu awọn mẹfa miran lori ẹsun ijọmọgbe ti wọn fi kan an nipa ọmọdekunrin jojolo Gold Kọlawọle to sọnu ni ile ijọsin rẹ loṣu kọkanla ọdun 2019.
Bí ó bá jẹ́ pé ẹ mọ̀ mí, ẹ̀ bá mọ Baba mi.
A saba maa n jẹ ogun awọn eeyan to jẹ ẹjẹ wa bii obi, ẹgbọn tabi ibatan wa, ti a si maa n jẹ ogun imọ lati ọdọ olukọ tabi awọn asaaju ẹsin wa.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Fayoṣe fẹ́ kí EFCC sàn owó Ìtanràn N20 biliọnu fún òun 9 Owewe 2018 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 5 Ọ̀wàrà 2018 Oríṣun àwòrán, EFCC/Fayose/Twitter Àkọlé àwòrán, Ẹ̀nu kun EFCC lórí ìkéde tó fi síta nípa Fayose níkété tí wọ́n kéde èsì ìbò gómìnà Ekiti Gomina Ayodele Fayose ti ipinlẹ Ekiti ti kowe si ile isẹ EFCC, Ajọ to n gbogun ti iwa ijẹkujẹ lorilẹ-ede yii, lori ẹsun pe won ba oun loruko je ti wọn si kowe majade nilu si awọn ile isẹ alaabo.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù UEFA: Real Madrid yóò kojú Bayern, Arsenal àti Athletico yóò wáákò 13 Ìgbé 2018 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Aṣekagba yoo waye nilu Kiev ni ọjọ kẹrindinlọgbọn oṣu karun Àwọn alaṣẹ ajọ ere bọọlu ilẹ Yuroopu, UEFA ti gbe ilana ifẹsẹwọnsẹ ipele to kangun si aṣekagba jade.
O sọ àwọn ìlú di òkítì àlàpào sì ti pa àwọn ìlú olódi run.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Widows Day 2019: Mo máa ń sá kiri wá owó ilé ni -Opó Eyi lo mu ki alaga ẹgbẹ oṣelu APC ni ipinlẹ Ọṣun, Gboyega Famodun o ke sawọn ọmọ ẹgbẹ oṣelu naa lati wọ inu adura lọ bayii ki nnkan lee ṣe ẹnuure bọ fun wọn lati ile ẹjọ naa.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Idije Super Cup Liverpool lo gba ife ẹyẹ UEFA Champions League ni saa bọọlu to lọ nilẹ Yuropu nigba ti Chelsea gba ife Europa League.
Iya ma n fun ọmọ rẹ ni ajẹ, ẹlomii si wa to yẹ pe lati ọrun lo ti gba ajẹ.
Nígbà tí wọ́n gbọ́ pé, Simiri ti ṣọ̀tẹ̀ sí ọba ati pé ó ti pa á, lẹsẹkẹsẹ ni gbogbo Israẹli fi Omiri olórí ogun, jọba Israẹli ninu àgọ́ wọn ní ọjọ́ náà.
Ninu wọn ni a óo ti rí òkúta igun ilé, tí a lè pè ní olórí, aṣaaju, ati aláṣẹ, láti ṣe àkóso àwọn eniyan mi.
Eyi ko si ninu Alukurani sugbọn o jẹ ara awọn ọrọ to de lẹyin lẹyin ti wọn maa fi n ṣe apejuwe awọn onimọ.
Ni igba naa, ileeṣẹ to n pin ina ọba lorilẹede Naijiria, TCN ṣalaye pe nnkan bii ẹgbẹrun kan o le ọtalelẹgbẹta o din meji mẹgawaati (1658 megawatts) ni wọn padanu ninu agbami akojọpọ ina mọnamọna to wa fun lilo ni Naijiria nigba naa.
Kí àwọn tí ó bá wà ninu abúlé má sá wọ inú ìlú lọ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Idibo ko ni waye ti wọn ko ba mu ọkọ mi jade Ẹsun ti wọn ba si fi kan ẹni naa ni yoo sọ iru oniduro ti adajọ yoo sọ pe ko mu wa.
Òun náà ni Ẹlẹ́dàá fún láṣẹ láti fún àwọn ẹ̀dá mìíràn gẹ́gẹ́ bí ẹyẹ, ewéko, ẹranko, igi àti bẹ́ẹ̀ bẹ́ẹ̀ lọ ní orúkọ tí wọn yóò máa jẹ.
“ ‘Ẹni ìfibú ni ẹnikẹ́ni tí ó bá bá ẹranko lòpọ̀.
17 Ògún 2019 nnkan yan nibi ayẹyẹ Ajọdun Ọṣun Osogbo to waye nilu Osogbo, ipinlẹ Ọṣun ni ọjọ Ẹti.
Osisẹ Agba ni Ile Iwe Giga lorilẹede India ti tọrọ aforiji lọwọ awọn eniyan, lẹyin ti aworan awọn akẹẹkọ to fi paali bori ja rainrain lori ẹrọ ayelujara.
Nínú orin nàá ló ti sọ nípa bí 'maga', èyí tó túmọ̀ sí 'mumu' tàbí 'ọ̀dẹ́', tó bọ́ sọ́wọ́ àwọn ọmọ yahoo ṣe ń se.
Nínú ìdájọ́ rẹ, adájọ́ ni ikọ olupẹjọ fi ẹri tó dájú hàn pé Arogundade lo gbẹmi Ọlọpaa naa, to sì ni kí wọn yẹ igi fún un, títí tí ẹ̀mí yóò fi bọ lára rẹ.
"Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Àjọ INEC ti yọ orúkọ ẹgbẹ́ òṣèlú 74 kúrò l'ágbo òṣèlú Nàìjíríà Mò ń tọ̀ s'ára ni mo fi gba ara à mi l'óko ẹrú ní Omar ""Èmi náà kọ́, àṣìṣe ló mú kí ń gún ọkọ mi pa láàrin ọjọ́ 51 taa fẹ́ ara wa"" Lateef Adedimeji rèé tó mú omi lójú àwon òbí rẹ̀ lọ́jọ́ ẹ̀yẹ Ẹ wo àwòrán ìgbé àyé ààrẹ ilẹ̀ Kenya tẹ́lẹ̀rí, Arap Moi tó papòpà Ọlọ́pàá fẹ̀sùn ìpànìyàn kan ìyawo olóòtú ilẹ̀ Lesotho pé ó pa ìyáálé rẹ̀ Naijiria ati Ilẹ Amerika buwọ́lu ìwé àdéhùn lórí owó ìlú tí Abacha lù ní póńpó Kii wọpọ ki tọkọtaya dijọ maa se ọjọ ibi wọn ni ọjọ kanna, idi si ree ti ọrọ ajọsepọ Saheed ati Fathia fi yatọ pupọ, bi o tilẹ jẹ pe wọn ko jọ gbe papọ mọ."
Kaka ki ọrọ naa ni iyanju wọn ni niṣe ni awọn ọlọpaa ṣina ibọn bo ilẹ eyi to ti mu ki ọpọ awọn ọdọ naa ba ara wọn nile iwosan.
OLUWA Ọlọrun àwọn ọmọ ogun ti fi ara rẹ̀ búra, ó ní: “Mo kórìíra ìwà ìgbéraga Jakọbu, ati gbogbo àwọn ibi ààbò rẹ̀; n óo mú ọwọ́ kúrò lọ́rọ̀ ìlú náà ati gbogbo nǹkan tí ó wà ninu rẹ̀.
"Wọ́n ní kí ọ̀gá àgbà ""Ede Poly"" lọ rọ́kún nílé lórí ẹ̀sùn pé ó kan bẹ́ẹ̀dì sí ọ́fíìsì Arabinrin Olufunlayo Banire to jẹ oludasilẹ ajọ to n pese iranlọwọ nipa Rhesus naa ba BBC sọrọ lori koko yii ati ipenija rẹ fun obinrin, O gba ijọba Naijiria ni imọran lati pese abẹrẹ to yẹ lọfẹẹ fawọn obinrin."
Fake News: BBC Kò ṣe ètò ìrànwọ́ ìwé kíkà lásìkò yìí 'Ohun tó ṣẹlẹ̀ sí Ezekwesili kò le ṣẹlẹ̀ sí mi' #BBCNigeria2019 Tani Ọjọgbọn Mahmood Yakubu ti yóò ṣètò ìdìbò 2019?
osise ile ise aladaani ti ki I se ti ijoba, Bill ati Melinda Gates Foundation.
Ó bá lọ sí iwájú díẹ̀, ó dojúbolẹ̀, ó ń gbadura pé bí ó bá ṣeéṣe kí àkókò yìí kọjá lórí òun.
Nígbà tí Gideoni gbọ́ bí ó ti rọ́ àlá yìí, ati ìtumọ̀ rẹ̀, ó yin OLUWA.
Wo orúkọ àwọn ẹ̀yà ara rẹ̀ ní èdé Yorùbá Ẹ yé parọ́ kiri!
 Awọn to ṣeto naa yombo iṣẹ Chimamanda ninu “The Half of a Yellow Sun” pe o lagbara.
Àkọlé àwòrán, Saaju abẹwo yii ni Trump ti fihan pe oun wa lẹyin Boris Johnson pe ko gba ipo Theresa May.
Nígbà tí Hesekaya rí i pé Senakeribu ti pinnu láti gbógun ti Jerusalẹmu, 
"Omotoso wa pari ọrọ rẹ pe ""orukọ ti wọn n jẹ naa ni mo ro pe wọn maa jẹ lọ, a ko le yi orukọ wọn pada."
Agbẹnusọ fún àjọ ọlọ́pàá Ìpínlẹ̀ Eko, Chike Oti, sọ wipé àwọn ikọ̀ ọ̀tẹlẹ̀múyẹ́ àjọ náà ni ó mu u, ti ó sì jẹ́wọ́ wípé òun ti ń ṣiṣẹ́ agbẹjọ́rò fún ọdún mẹ́ta láà ní ìwé ẹ̀rí kankan.
Abenugan fun ile igbimo asofin ipinle Eko, asofin
2nd wave Coronavirus Update: England kéde ìséde ọ̀sẹ́ mẹ́rin níràn láti dẹ́kun ìtànkálẹ̀ Covid 19
Àgàgà àwọn tí wọ́n fi ata sí dáadáa.
 nínú àwọn tí ó kú , mẹ ́ fà ńbọ ̀ lati telford , shropshire , marún ńbọ ̀ lati west midlands - ìkan lati oldbury , àwọn tókù lati wolverhampton .
Aṣaájú olùwọ́de EndSARS 50 dèrò iléẹ́jọ́ lórí ìfẹ̀hónúhàn àti ìdàlúrú Ajàfẹ́tọ ọmọniyàn kan, Kenechukwu Okeke ti fẹ̀sùn ìwà ọ̀daràn kan àádọ́tà èèyàn nílé ẹjọ́ Májísíreeti kan nílùú Abuja.
Awọn alaṣẹ sọ pe inu igbo nla kan ni ipinlẹ Zamfara ni wọn ti gba ominira, awọn oṣiṣẹ eleto aabo lo ko wọn pada si Katsina lowurọ ọjọ Ẹti.
ọlọpaa lee fi panpẹ ọba si ọ lọwọ bi wọn ba rii pe onijagidijagan ni ọ tabi o ṣeeṣe ki o fẹ salọ.
Alaga ẹgbẹ naa, Ogbeni Ademola Babalola ṣapejuwe iṣẹlẹ naa pe ko dara to.
Burna Boy dàgbà sí ìhà ìlà-oorun Gúúsù Nàìjíríà tí o sì bẹ̀rẹ̀ iṣẹ́ orin ti o pè ni Fruity Loops.
Yika awọn oju opo ayelujara si ni wọn ti n k awo orin naa, to fi mọ awọn ori tẹlifisan ati redio.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Coronavirus in Nigeria: Ayodeji Osowobi ṣàlàyé bí ó ti jàjà bọ́ lọ́wọ́ àrùn covid-19 Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Coronavirus in Nigeria: Ayodeji Osowobi ṣàlàyé bí ó ti jàjà bọ́ lọ́wọ́ àrùn covid-19 8 Ìgbé 2020 Arun Coronavirus ti pa ẹgbẹgbẹrun eniyan kaakiri agbaye, ti o si ti sọ ọpọ di alailara.
Amọ, o fikun ọrọ rẹ pe ileeṣẹ ijọba to n ri si eto ibaraẹnisọrọ to n ṣagbatẹru eto kaadi idanimọ NIN naa ti n ro ọna mii ti wọn le gbe ọrọ naa gba ti ko fi ni da ajakalẹ arun silẹ.
Ṣugbọn ìdájọ́ yóo bẹ̀rẹ̀, a óo gba àṣẹ kúrò lọ́wọ́ rẹ̀, a óo sì pa á run patapata.
Ẹ lọ kọ́ ìtumọ̀ gbolohun yìí: Ọlọrun sọ pé, ‘Àánú ṣíṣe ni mo fẹ́, kì í ṣe ẹbọ rírú.
"Nínú ọ̀rọ̀ rẹ̀ ó ní ""Mo sàkíyèsí pé agbègbè Akobọ̀ lo máa n jòkó si to si ti lọ máa n ra igbó, ọ̀rẹ́ mi lo ti maa n ri nibi ojú irin to wa lọ́nà Barack tẹ́lẹ̀ to ti lo ti ma ń ra igbó."
Nítorí náà, bí òfin tí ẹnìkan rú ṣe ti gbogbo ọmọ aráyé sinu ìdájọ́ ikú, bẹ́ẹ̀ náà ni iṣẹ́ rere ẹnìkan yóo yọ gbogbo ọmọ aráyé ninu ìdájọ́ ikú sí ìyè.
Ogwuetiti Obiuto – Onyeka Nwelue – Nigeria
Nítorí ìjọba Ọlọrun kì í ṣe ti ọ̀rọ̀ ẹnu: ti agbára ni!
awon adari to di ipo lo mu ni gbogbo ipele ti won ba wa nimoran lati maa tẹti
Eji Gbadero lowo, o gbajumọ, ọmọ jaye-jaye ni, laarin ọdun 1960 si 1970 lọ soke, Eko kan, Gbadero kan ni, lọtun losi si ni awọn olorin maa n ki i, koda, Ebenezer Obey ati Yusuf Olatunji gan wa lara awọn olorin to kii, eyi to n sọ bo ṣe jẹ ilumọọka si nigba naa.
Ṣugbọn Oloye Lekan Balogun ni ko si ohun to buru kankan ninu iwe tawọn fi ṣọwọ si Olubadan, o ni awọn kan pe akiyesi rẹ si awọn nnkan kan to ṣe, ti ko dara ni.
"Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Aare Muhammedu Buhari ti setan lati yan ise fun awon minisita tuntun Ìjọba Buhari ń lo agbára láti jà ìjà ẹsìn- Jiti Ogunye Òpópónà márosẹ̀ Eko sí Ibadan tún dí pa lásìkò tí ọkọ̀ epo dànù Ọkùnrin méjì, obìnrin mẹ́ta jáde láyé ní Mecca lásìkò Hajj 2019 - NAHCON Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Iya Adura Esther Ajayi sọ àṣírí owó rẹ̀ tó fi ń ṣàánú ""A gbe igbesẹ naa pẹlu igbagbọ nla ati ọwọ taani fun awọn eeyan iyi ati ẹlẹgbẹjẹgbẹ ti wọn da si ọrọ yii, a si lero pe wọn yoo wa ọna lati yanju awọn aawọ to wa nilẹ nitubi n nubi, paapa lori bi wsn se ti asaaju wa mọle lati bii ọdun mẹrin sẹyin."
Ẹni ọdun mọ̀kandinlogoji ni ara ilẹ Eritrean to n gbe ni Norway.
Oríṣun àwòrán, BBC/Boko Haram Àkọlé àwòrán, Awọn Adunkoko mọni Boko Haram sefilọlẹ idunkuuku laja wọn lọdun 2009 Awọn eeyan mẹtalelogun to n dari bọ lati ibi isinku kan nipinlẹ Borno ti ko agbako iku lọwọ ikọ agbesunmọmi Boko Haram.
”Ó ní òun kò lè kà ánítorí pé wọ́n ti fi èdìdì dì í.
O salaye pe, oun foju sona lati tun fowosowopo pelu olori orile-ede naa, ni iyanju ati mu igberu ba ajosepo ni eka eto-abo, oro-aje ati imo ero, ati lati tun ni ajosepo ni eka awon aladani.
Ṣugbọn ní tiwa ibi ńláńlá ni a fẹ́ fà lé orí ara wa yìí.
Ṣugbọn Peteru ń tẹ̀lé wọn lókèèrè.
Ere yii maa n se afikun okun ati agbara fun awọn to n see nitori wọn yoo laagun, to si tun n mu ki ifẹ wa pẹlu.
Bi ọmọ o jọ ṣokoto, yoo jọ kijipa Emir Sanusi Lamido Sanusi kọ ni Emir akọkọ ti wọn yoo rọ l'oye.
“Ìwọ ọmọ eniyan; àwọn ọmọ Israẹli ti di ìdàrọ́ lójú mi.
Ni wọn igba to jẹ pe arise ni arika, arika si ni baba iregun, ohun ta ba fi oni ṣe, itan ni yoo da lọjọ ọla, idi ree ta fi ṣe akojọpọ itan igbe aye agba oselu to di oloogbe naa.
Ìjọ́ mí ní Italy ni mo fi ń ṣèrànwọ́ fáwọn aṣẹ́wó ọmọ Nàíjíríà tó há - Taribo West Bí ìrìnàjó ààrẹ ọlọ́dún méje nílẹ̀ Mali, Keita, ṣe lọ rèé Adamu Adamu, Minista ètò ẹ̀kọ́ ti fi òfin àátẹ̀lẹ́ síta kí àwọn ilé ìwé lè wọlé Ẹgbẹ́ akẹ́kọ̀ọ́ gíga n‘Ibadan ṣèwọ́de lọ iléeṣẹ́ ọlọ́pàá lórí afurasí tó dàwátì Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Sunday Igboho: Ẹ fi Ògún búra fún wa láti jà fún ilẹ̀ Yorùbá láì gbé Amotekun sábẹ́ ìjọba Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Akinyele Killings: Ilé iṣẹ́ ọlọ́pàá Ibadan fẹ́ fi owó kún móríya ẹni tó bá rí Sunday Shodipe23 Ògún 2020 5:58 Fídíò, Akomolede ati asa Yoruba: Ẹ wá kọ́ nípa àpòtí ìṣura èdè wa lórí BBC Yorùbá, Duration 5,5820 Ògún 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Yatọ si eyi, o tun le sọ awọn ede Afrika miran.
Àwọn ọmọ Gadi ati àwọn ọmọ Reubẹni dáhùn, wọ́n ní, “A óo ṣe ohun tí OLUWA bá pa láṣẹ.
Awọn iroyin ti ẹ le nifẹsi: Ijọba kede iye ọmọ to sọnu ni Dapchi Eeyan meji ku nibi iwọde DR Congo Manchester City gba ife ẹyẹ Carabao Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ibadan Poly: Àwọn aláṣẹ ní kí àwọn akẹ́kọ̀ọ́ fún ìsìnmi nítorí jàgídíjàgan 4 Ìgbé 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 5 Ìgbé 2019 Oríṣun àwòrán, Ibadan Poly Awọn alasẹ ileewe giga gbogboniṣe Polytechnic Ibadan ti gbe ilẹkun ileewe naa ti pa.
Oríṣun àwòrán, @fatimah_jiyah Àkọlé àwòrán, Aliyu Ahman Bahago Pategi naa ko gbẹyin ninu idije to wa nilẹ yi Ta ni yoo ja mọ lọwọ Ti a ba fi bi nnkan ti se ma n sẹlẹ lateyin wa wo,Bukola Saraki to jẹ Baba Isale fun awọn oloselu ipinlẹ Kwara a ma yan oludijk kan laayo leni ti awn oludije to ku yoo si gbaruku ti ninu idibo.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ọlọ́pàá àti Shiites tún fìjà pẹ́ẹ́ta Ẹ má tẹ́wọ́gba ògbólógbòó olósèlú - Soyinka Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fọ́nrán ohùn, Ọmọ Nàíjíríà: Àrímáleèlọ ni àríyá alẹ́ sátidé BB Naija Awon òbí náà paapaa, fara kasa nínú ìṣẹlẹ ọhun eyi to se akoba fun mimi soke silẹ wọn, bi o tilẹ́ jẹ pe ara wọn pada ya.
Ikọ ajinigbe gba mi ṣiṣẹ lati maa pa awọn eeyan, bi a ba si ni ka ka ni meni meji, mo ti gbẹmi eeyan marun un.
Atẹjade ti wọn fi sita naa ni Abiodun Agbele to fi'gba kan jẹ isọmọgbe gomina ana nipinlẹ Ekiti, Ayodele Fayose ti salaye bi oun ti ṣe ṣeto gbigbe owo fun Obanikoro.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù #BeyondFakeNews: Soyinka ní ọ̀pọ̀ ìgbà ni ìròyìn òfégè ti pa òun 9 Sẹ́rẹ́ 2019 Àkọlé àwòrán, Ọrọ lori ayederu iroyin Ọjọgbọn Wole Soyinka ṣi aṣọ loju ọrọ nibi ipade BBC ti ṣe l'Abuja lati tu aṣiri iroyin ofege, nigba ti o sọ pe ọpọ igba ni awọn kan ti gbe ayederu iroyin sita pe oun ti ku.
Akomolede ati Asa: Mọ̀ si nípa àwọn ọ̀nà tí Yorùbá ń gbà ran ara wọn lọ́wọ́
“Mo ti yan àwọn ọmọ Lefi láàrin àwọn eniyan Israẹli dípò àwọn àkọ́bí ọmọ Israẹli.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Mike Ifabunmi: Òrìṣà ló gbè wà jù ni Brazil NEMA ṣalaye pẹlu apẹẹrẹ bi owo ti o le ni bilonu meji naira (N2.
Ikọ alatilẹyin rẹ n fọwọ sọya pe oun ṣi ni aarẹ Egypt tori naa ko si labẹ ile ẹjọ.
nítorí náà, ẹ̀ṣẹ̀ tí ẹ̀ ń dá yìí;yóo dàbí ògiri gíga tí ó là, tí ó sì fẹ́ wó;lójijì ni yóo wó lulẹ̀ lẹ́ẹ̀kanṣoṣo.
"Ọ̀gá àgbà FRSC Ondo jáde láyé Ọba Saudi fìwé pe Ààrẹ Buhari fún ìjọ́sìn Umrah Idí tí àwọn dókítà ọpọlọ kò fi faramọ́ lílo igbó fún ìtọ́jú àìsàn Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, FRSC o gbọdọ ni ju 500 naira lọwọ "" Ìfojúsù wà ni pe kí àwọn àwakọ̀ to kójú òsùwọn máà wakọ̀ ní àwọn ojú pópó wa pẹ̀lú ìwé ìrìnà to jẹ ojúlówo ni ipinlẹ̀ Eko."
BBC Yoruba wa n bawọn oloriire ọhun dawọ idunnu, ta si n gbadura pe wọn yoo ri ẹmi loo.
Ara wọn nìkan ni wọn yóo lè gbàlà.
Àwọn ọmọ Israẹli ṣe bí OLUWA ti pàṣẹ fún Mose, wọ́n pàgọ́ ní ìsọ̀rí-ìsọ̀rí.
Nígbà tí wọ́n jáde, wọ́n súre fún àwọn eniyan náà, ògo OLUWA sì yọ sí gbogbo wọn.
 “Bakan naa, ni ijoba tun ti pase fun ajo to n
Inú bí wọn nítorí wọ́n ń kọ́ àwọn eniyan pé àwọn òkú yóo jí dìde.
“Kí ló dé tí ẹ̀yin fúnra yín kò fi lè mọ ohun tí ó tọ̀nà?
Bàbá tí ó sì bí-i ni Ìfòyà tí-í ṣe ọkọ Ìfẹ́dàrú ọmọ ilé Àìbalẹ̀-Ọkàn níbi tí Inúnibíni ti-í ṣe Mọ́gàjí-i wọn.
Makinde ni Jimoh Isiaq pada ku lẹyin ti wọn gbe e lọ si ile iwosan fasiti Bowen University ni Ogbomosho.
Òfin rẹ níye lórí fún mi,ó ju ẹgbẹẹgbẹrun wúrà ati fadaka lọ.
0 91 Orilẹede Dominican 0 0.
Àpapọ̀ gbogbo àgọ́ Efuraimu ní ìsọ̀rí-ìsọ̀rí jẹ́ ọ̀kẹ́ marun-un ó lé ẹgbaarin ati ọgọrun-un (108,100).
Ninu ibẹrubojo ni awọn eeyan n lọ ko nkan sile ti ọpọ ọja si ti tan lori igba nile itaja bayii.
 A ni lati maa tere omi kiri lawọn odo ni”.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Awọn dokita iṣegun Naijiria n kerora lori ẹka ilera 23 Ẹrẹ̀nà 2018 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Awọn dokita iṣegun Naijiria n kerora lori ẹka ilera Ni ọjọọbọ ni gbajugbaja oludokoowo ni, Ọgbẹni Bill Gate na ijọba apapọ orilẹede Naijiria ni pasan ọrọ wi pe ijọba Aarẹ Muhammadu Buhari ko se e to lẹka eto ọrọ aje, ẹkọ ati ilera.
Kò gbọdọ̀ wọ inú àgọ́ wá mọ́.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ẹ̀mí kan náà ló n darí ìrìnàjò wa táa fi jọ kọ́lé papọ̀- Ìbejì Ijamba loju popo: Nipasẹ ọna ti ko dara, Aletilapa awakọ, ọpọlọpọ ijamba oju popo ni o n waye loju popo ni ipinlẹ Eko.
Kaakiri origun mẹrẹrin agbaye ni awọn eeyan ti bu ẹnu atẹ lu iṣẹlẹ yii eleyi to sọọ di ọkan pataki ninu ohun ti awọn eeyan fi ṣe odinwọn eeyan ti wọn dibo fun lasiko idbo apapọ orilẹede Naijiria lọdun 2015.
Ọba ni mo ti jẹ́ tẹ́lẹ̀ rí mo sì ní ìyàwó kan ti mo gbọ́ kẹ̀lé dé góńgó, àṣé ògbálógbòó àjẹ́ ni.
Ọba Ogunoye yii, tii se Ọlọwọ tilu Ọwọ kẹtalelọgbọn, ni ayẹyẹ etutu jijade sita rẹ bẹrẹ ni kutu hai ọjọ Ẹti, eyi to se oju ogunlọgọ awọn ọmọ ilu naa.
Owó tí wọ́n ti fi kún àbá ìsúná wọ́n ti tó bílíọnù méjìdínlógún o lé ọwọ́ mẹ́sàn naira èyí sì wáyé láàrin Fasiti olùkọni àgbà fún iṣegun ti Benin gẹgẹ bi wọn ṣe fí bílíọnù kan ó lé ọwọ kan lé (1.
Eyi ni fidio wahala awọn ọlọpaa lasiko coronavirus eleyi to mu ẹmi ọpọ lọ pẹlu.
Rogbodiyan NURTW: Ọlọpa gbe Ọlorunwa satimọle
Lẹ́hìn tí ìyàwó mí sìn mí sí ọ̀nà díẹ̀ mo kí i mo wí pé: ‘Máa padà lọ sí ilé, ìyàwó mi, àpé, máa wo ilé dè mí o, èmi náà kò ní pẹ́, ìrẹsì ni kì o sè dè mí, nítorí àkàṣù ẹ̀kọ ni mo jẹ lánàá, bẹ́ẹ̀ ni mo jẹ ni ọkà ni mo jẹ ní ìjẹta; n ó gbìyànjú àti pa ẹran bọ̀, bí ọwọ́ bá sì ba àparò, a jẹ́ pé nǹkan náà yóó ṣe ẹnu re.
Nibẹ naa lo ti ka iwe alakọbẹrẹ ati iwe ipele girama.
Ẹni tí kò ka ẹni ẹ̀kọ̀ sí,ṣugbọn a máa bu ọlá fún àwọn tí ó bẹ̀rù OLUWA;bí ó bá jẹ́ ẹ̀jẹ́, kì í yẹ̀ ẹ́;bí ẹ̀jẹ́ tí ó ti wù kí ó nira tó.
Wọn ni tẹni ba dakẹ, ti ara rẹ yoo ba dakẹ, eyi lo tun mu ki awọn obinrin yii kesi akẹẹgbẹ wọn bii ẹgbẹrun lọna ogoje ninu ẹgbẹrun lọna aadọjọ ti wọn fi oju sun lori itakun agbaye, lati buwọlu ibeere wọn ọhun eyi ti wọn gbe siwaju awọn olori orilẹede lagbaye.
Bí o wíire, ayé á ní o kò wíire
    Nígbà tí ó lọ tán mo fi ìwé náà han àwọn ọ̀rẹ́ mi, nígbà tí wọ́n yẹ̀ ẹ́ wo, wọ́n ní ìwé náà kò burú, wọ́n ní ki n máa kọ̀wé síi dáadáa ki n mo sì ṣe yọ ọ́ lẹ́nu nípa ọ̀ràn náà mọ́, wọ́n ní ó lè fẹ́ mi nígbà tí ó ba ṣe bí mo bá lè mú sùúrù díẹ̀ nítorí bí a bá ti ṣe ń kọ̀wé sí ara wa ni a ó túbọ̀ máa fẹ́ràn ara wa àti pé nígbà tí ìwé bá pọ̀ díẹ̀ láàrin ara wa mo lè tún rọra bá ẹnu lu ọ̀rọ̀ náà lẹ́ẹ̀kan sí i.
Coronavirus ló lé mi kúrò níléèwòsàn UCH n'Íbàdàn- Ogun Majek Ta a ni yóò rọ́pò Abba Kyari gẹ́gẹ́ bi olórí òṣìṣẹ́ Buhari?
Mathilde-Amivi Petitjean Ọjọ ori: Mẹtalẹlogun Orilẹẹde: Togo Ere idaraya: Cross-Country Skiing Mathilde-Amivi Petitjean ti fi saaju jẹ okan lara ọmọ iko ere idaraya ori yiyin fun orilẹẹde France ki o to sun lati soju Togo ilẹ abinibi rẹ.
O tun ṣeeṣe lati ṣe ayẹwo boya o ti lugbadi coronavirus tabi bẹẹkọ nipasẹ foonu rẹ Koda, o le tun gba 'sample' ẹnu itọ ara rẹ fun ayẹwo lai de ile iwosan ki o si ri esi gba laarin ọjọ meji pere.
Nítorí nígbàkúùgbà tí ẹ bá ń jẹ burẹdi yìí, tí ẹ sì ń mu ninu ife yìí, ẹ̀ ń kéde ikú Oluwa títí yóo fi dé.
Ó ti mọ ẹni tí yóo fi òun lé àwọn ọ̀tá lọ́wọ́; nítorí náà ni ó ṣe sọ pé, “Kì í ṣe gbogbo yín ni ó mọ́.
Ewe, esi ami dogba-dogba ninu ifesewonse ti yoo waye laarin iko ohun ati orile-ede Swiss lojo Aiku(Sunday), ti to fun Belgium lati pegede sipele ti o kan ninu idije naa.
osu kárùn ún (April 29 to 4th of May) odun  2019,  niluu Abuja.
Àwọn afurasí ajínigbé pa Olufon ti Ifon nípìnlẹ̀ Ondo, Oba Isreal Adewusi Ó ti di ẹ̀ṣẹ̀ láti bẹ̀bẹ̀ fún afipábánilòpọ̀ nípìnlẹ̀ Ekiti- Ìjọba ìpínlẹ̀ Ekiti Ìbálòpọ̀ ọ̀lọ́jọ́ méje mú kí ilé ẹjọ́ tú ìgbéyàwó ọdún mẹ́wàá ká ní Ibadan Kí lo mọ̀ nípa ìbẹta kan ṣoṣo tí Alaafin Oyo bí?
Ajọ naa sọ eyi di mimọ nilu Eko.
Nnkan ti owo naa le se pọ.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Háà, èyí tún ga!
Idan naa ni wọn pe ni Houdini eyi tii ṣe idan kan to gbayi ju lagbaye ti gbajugbaja apidan Harry Hudini ti ṣe ri l'oun naa fẹ tun ṣe.
O mú kí ìkórè oko pọ̀ yanturu ní òpin ọdún;gbogbo ipa ọ̀nà rẹ sì kún fún ọpọlọpọ ìkórè oko.
Amọ ninu oṣu kẹjọ ọdun 2005, ni ẹgbẹ oselu PDP fi ikede sita pe Bamidele Olumilua kii ṣe ọmọ ẹgbẹ oun mọ, nigba to si di ọdun 2006 ni oloogbe naa dara pọ mọ awọn agba ilu kan lati da ẹgbẹ oselu Action Congress, AC silẹ.
Ijo, ilu ati iṣẹse lo balẹ sibi ayẹyẹ naa.
Ọkunrin naa ni lẹyin eyi ni wọn tun bẹrẹ si yẹ gbogbo ile awọn wo, ti wọn si n ko ohun gbogbo ti ọwọ wọn ba ba, ti wọn si gun ẹgbọn oun ni ọbẹ lọrun.
Nítorí àwọn ọkunrin tí ẹ mú wá yìí, kò ja ilé oriṣa lólè, bẹ́ẹ̀ ni wọn kò sọ ìsọkúsọ sí oriṣa wa.
Nígbà tí mo sọ bẹ́ẹ̀, ó rẹ́rìn-ín, ọkan mi sì bẹ̀rẹ̀ si rò pé ó ń fẹ́ ki n fẹ́ òun ni.
Bi ẹ ko ba gbagbe, o ti le ni ọsẹ kan ti awọn ọdọ kaakiri Naijiria ti gunle ifẹhonuhan, lori bi awọn oṣiṣẹ ẹka to n gbogun ti iwa idigunjale ni ileeṣẹ ọlọpa, SARS, ṣe pa awọn eeyan lọna aitọ.
O ni lẹyin ipade ti wọn ṣe pẹlu ijọba apapọ ni wọn pinnu lati da iyanṣẹlodi ọhu duro fun oṣe meji lati wo ibi ti ọrọ awọn ati ijọba yoo yuọri si.
- Ìjọba àpapọ̀ Adajọ to n gbọ ẹjọ naa ti kede ọjọ kẹrinla, oṣu kẹsan an, ọdun 2020 gẹgẹ bi ọjọ ti awọn agbẹjọro olupẹjọ ati olujẹjọ yoo gbe apilẹkọ awijare wọn kalẹ niwaju ile ẹjọ naa ki Adajọ lee ṣe idajọ to ba yẹ.
EFCC: Ìwádìí iléeṣẹ́ Alpha Beta Consulting Ltd ṣì ń tẹ̀síwáju lórí ẹ̀sùn N100b
Ó fi àwọn ọmọ rẹ̀ rú ẹbọ sísun ní àfonífojì ọmọ Hinomu.
Iku baba yeye ni ẹya Yoruba lagbara lati gbe igbesẹ lati gba ara rẹ silẹ bi eto abo ko baa gbe pẹẹli si lẹkun naa.
Balogun, gbe jade niluu Abuja  .
O ni gomina ipinlẹ Ọsun nikan lo ni asẹ lati ni ki oun lọ rọọkun nile na, to si dabi ẹnipe wọn ti ni nkan ninu si oun.
" Bí Hushpuppi ṣe tiraka rèé l‘Eko, kí ọlà ‘òjijì’ tó dé Gómìnà ìpínlẹ̀ Ondo, Rotimi Akeredolu ti móríbọ́ lọ́wọ́ àrùn Covid-19 A kò fi ọwọ́ òfin mú adelé alága EFCC Magu, ẹ yé parọ́ kiri- DSS Èèyàn 7 kú, 21 di àwátì lásìkò tí ọkọ̀ ojú omi dojúdé ní Eko àti Benue Nwajiuba sọ pe aye oṣu kan wa fun awọn ile iwe atawọn ipinlẹ to ba nifẹ si ṣiṣe idanwo naa lati pese awọn ile iwe wọn silẹ fun idanwo ọhun.
Oríṣun àwòrán, Facebook/James Stephen Ajibola Àkọlé àwòrán, Gbogbo awọn ipade apero ti a ti n ṣe bọ wa ko yatọ nipaṣe aba ti wọn n da James Ajibola naa sọ pe, o ṣe pataki lati ṣe apero ṣugbọn ohun to jẹ ẹdun ọkan ni pe ''oṣelu ni awọn ijọba Naijiria n fi ipade apero ṣe.
Awọn atipo naa tiẹ salaye nipa iru lasigbo to n koju wọn.
Ìyàwó igbákejì ààrẹ ológun Naijiria tẹ́lẹ̀, Oladipo Diya ti jẹ Ọlọrun nípè Ọmọ Nàìjíríà 292 láti Saudi Arabia gúnlẹ̀ sí Abuja Ìjẹkújẹ àwọn adarí ìjọba ló sọ mí di alárìnkiri nílẹ̀ òkèèrè-Oluwo Àjọ NAFDAC ti bẹ̀rẹ̀ àyẹ̀wò àgbò mẹ́rin tí wọ́n ṣe ní Nàìjíríà fún Covid-19 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Ọ̀pọ̀lọ́ àti akàn tí o sì wá gẹ́gẹ́ bí aṣojú àwọn ẹja hùwà ọmọlúàbí gan-an.
Jesu wá tún pa òwe yìí fún wọn.
 Oríṣun àwòrán, Reuters Àkọlé àwòrán, wọn panapana de ibẹ ni bi i wakati mẹta lẹyin ti ọkọ naa ja lulẹ Olootu orilẹ-ede naa, Abiy Ahmed fi sori Twitter pe ''oun ba awọn mọlẹbi to padanu eniyan wọn kẹdun iku awọn to ku sinu ijamba naa."
'Iru ba iyawo mi to n rọbi lọwọ, bẹẹ si ni ko si oogun fun un.
Nígbà tí Naamani rí i pé ẹnìkan ń sáré bọ̀, ó sọ̀kalẹ̀ lórí kẹ̀kẹ́ ogun tí ó gùn láti pàdé rẹ̀, ó bèèrè pé, “Ṣé kò sí nǹkan?
Mo je omo egbe ANC sugbon mi o dibo fun wọn .
O si da ẹbi aijade dibo daada awọn ara ilu ru ọrọ ihalẹ ti aarẹ Buhari sọ saaju idibo.
" Sùgbọ́n, nínú ọ̀rọ̀ tirẹ̀, ọmọ ẹgbẹ́ míràn to tún bá BBC Yoruba Otunba Deji Osibogun to tún jẹ́ aṣojú ẹgbẹ́ Yoruba Kọ̀yà, se atilẹyin fun Alintoye.
Oríṣun àwòrán, Wale Akorede/Facebook Àkọlé àwòrán, Wale Akorede Okunnu jẹ ọmọ bibi ilu Ogbomoṣo ni ipinlẹ Oyo ṣugbọn ilu Ibadan ni wọn bi i si.
Nítorí náà, wọ́n pada lẹ́yìn àwọn ọmọ Israẹli, wọ́n bẹ̀rẹ̀ sí sá lọ sí ìhà aṣálẹ̀, ṣugbọn ọwọ́ bà wọ́n, nítorí pé ààrin àwọn jagunjagun tí wọ́n yipada sí wọn, ati àwọn tí wọn ń jáde bọ̀ láti inú ìlú ni wọ́n bọ́ sí.
Lọ́wọ́ àwọn ọmọ onílẹ̀ ni tabi lọ́wọ́ àlejò?
Joshua àti Ruiz gbà láti jàjà mííràn lóṣù kọkànlá Owó wọgbó!
Abẹwo naa eyi to ti n fa awuyewuye lori ayelujara ni Rashidi Ladoja ti wa kede pe ko ni nnkan se pẹlu eto idibo ọdun 2023.
Money laundering: Inú ọ̀pọ̀ páálí oúnjẹ́ Nódù ní afurasí kan kó ọ̀pọ̀ ike ATM sí
Kenya Covid-19 fund: Aàrẹ pàṣẹ pé kí ìwádìí bẹ̀rẹ̀ lórí àwọn tó lu owó ìtọ́jú aláìsàn ní póńpó
Oríṣun àwòrán, Bashir Ahmad Àkọlé àwòrán, Aarẹ Buhari ni afojusun abadofin naa ni lati tubọ fi ẹsẹ eto ọrọ aje Naijiria rinlẹ daradara O fi kun un pe iṣuna to din diẹ ni triliọnu mẹsan naira naa ni wọn pin si owoona atigbadegba (Recurrent N4.
Ọmọ márùn-ún sọnù ní Otto l‘Eko, àwọn ìyá wọn kò jẹ́ èèyàn mọ́ lẹ́yìn ọdún kan Coronavirus bí èso rere nílẹ̀ Adúláwọ̀, wo díẹ̀ lára èso náà.
Ireti wa wi pe ilana karakata tuntun fun Afirika yii yoo sina ayọ fun eto karakata nilẹ Afirika nipa yiyọ awọn ohun to lee dena jija geerege eto karakata nilẹ Afirika ti yoo si tun fi aaye silẹ fun kiko epo rọbi kaakiri lẹkun naa.
Moradekẹ iya mi, Ọlọrun yoo wo ọgbẹ ọkan yin san ati awọn ana mi.
nibi yii,  awon abenugan mọ́kànlélọ́gbọ̀n lo wa
O wa ro awon akoroyin lati mojuto ise won bi o se to ati bi o se ye.
Awọn koko ẹsun ti iwe iroyin itakun agbaye naa fi kan Obasa ree: Òṣèré tíátà míì ń ṣàìsàn láti ọdún kẹta, ó bẹ̀bẹ̀ f'ówó Oluwo bẹ Ìjọba àpapọ̀ láti ṣe òfin tí yóò mú àdínkù ba ìwà ìfipá báni lòpọ Ọjà Ọba ní Akure ni ọwọ́ ọloọ́pàá ti tẹ aláàrùn Covid-19 tó sá kúrò ní ilé àyẹ̀wò – Akeredolu Ìdájọ́ ikú ni a fẹ́ fún àwọn afipábánilòpọ̀ - Ẹgbẹ́ ajàfẹ́tọmọnìyàn Ṣé lóòtọ́ ni òjòjò dá Abiola Ajimobi wólẹ̀?
Oríṣun àwòrán, Others Ṣugbọn, igbẹjọ miran tun waye lori ẹsun naa ni ilu Abuja ti ariya naa ti waye, ti awọn oṣiṣẹ eleto aabo si duro wamu-wamu nibi igbẹjọ naa to waye ni kootu alagbeka to wa ni gbagede Eagle Square.
Iyawọ ààrẹ fi kún pé nínú ìwòye òun, ìpínlẹ̀ Kano ló buru jù nínú àwọn ìpínlẹ̀ ti kò jẹ ànfani owó náà.
Hesekaya ọmọ rẹ̀ sì jọba lẹ́yìn rẹ̀.
Bákan náà lo fi kun pé àwọn ti mú ọmọ ìyá meji ti iṣẹ́ ti wọ́n jẹ ki wọ́n ma fi àtẹjisẹ ori ayelujar ránṣẹ lati tan awọn ti ko mọ pé wọ́n fẹ́ gbá awọn ni.
Kí á yin orúkọ OLUWA,láti ìsinsìnyìí lọ títí laelae.
Yatọ si eyi, Akufa tun le waye ti ẹbi ko ba ṣe awọn etutu to yẹ ni sise tabi wọn ko ṣe e daadaa, nigba ti ẹni akọkọ ku gẹgẹ aṣa.
Olóòótọ́ kì í tọ ọ̀nà ibi,ẹni tí ń ṣọ́ra, ẹ̀mí ara rẹ̀ ni ó ń pamọ́.
ona ti awon eniyan yoo se lee dibo fun wọn.
Nigba to n gbe aba isuna naa ka iwaju ile, aarẹ Buhari ni ipenija nla to n koju ijọba oun bayii ni ọna lati ri owo gbọ bukata eto isuna naa.
Lẹ́yìn tí a sì kí ara wa tán ni ó wí fún mi pé gba ni ó ránṣẹ́ pé ki n wa fi ojú kan òun ní wéréwéré.
Bí ọba Israẹli ti ń rìn lórí odi ìlú, obinrin kan kígbe pè é, ó ní, “Olúwa mi, ọba, ràn mí lọ́wọ́.
O ni pe adari tẹlẹri fun ọmọ ẹgbẹ to kere julọ ni Ile Igbimọ Asofin, Sẹnatọ Biodun Olujimi ti ẹgbẹ oselu PDP pe oun lo wọle ninu idibo naa si Ile Igbimọ Asofin gẹgẹ bi asofin to n ṣoju guusu ipinlẹ Ekiti.
Ó fi ìdí ayé múlẹ̀;kò sì ní yẹ̀ laelae.
Òmùgọ̀ ni àwọn olórí wọn ní Soani;ìmọ̀ràn wèrè sì ni àwọn ọ̀jọ̀gbọ́n ìgbìmọ̀ Farao ń fún eniyan.
Nígbà tí o bá ń bọ̀, bá mi mú agbádá tí mo fi sọ́dọ̀ Kapu ní Tiroasi bọ̀.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Isho Pepper pẹ̀lú àfihàn àwọn ìyàwó tó jẹ́ igi lẹ́yìn ọgbà fun un níní iṣẹ́ tíátà 26 Èbibi 2020 Oríṣun àwòrán, Other Yoruba ni igba ko lọ bi orere, ako o tọ lọ bi ọpa ibọn, nitori saa laa ni, ẹnikan ko lo ile aye gbo.
Lo ba fun wọn ni imọran pe ki awọn naa o ma a na ẹni to ba le wọn, bu ẹni to ba bu wọn, pa ẹni to ba pa wọn.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Ni ọjọ karundinlọgbọn, oṣu kẹfa ni o ti fidimulẹ pe Liverpool ni olubori liigi Premiership ti ilẹ Gẹẹsi lọdun yii nigba ti o si ku ifẹsẹwọnsẹ meje ki saa liigi tọtẹ yii pari.
Pasuma: Mọ dúpẹ́ lọ́wọ́ Ọlórun fún oríire ọjọ́ ìbí òní
Asofin Owoẹyẹ rọ awọn ọdọ lati jinna si iwa ọdaran naa tabi iwa ipa yoowu si awọn obinrin.
Ẹwẹ, agbẹnusọ fun ajọ EFCC ṣalaye pe, ẹsun nii ṣe pẹlu jibiti ori ayelujara lo jẹ ki ajọ naa tun mu Mompha yatọ si ẹsun to wa niwaju ileẹjọ tẹlẹ.
tí ẹnìkan ninu yín wá sọ fún un pé, “Máa lọ ní alaafia, Ọlọrun yóo pèsè aṣọ ati oúnjẹ fún ọ,” ṣugbọn tí kò fún olúwarẹ̀ ní ohun tí ó nílò, anfaani wo ni ọ̀rọ̀ tí ó sọ ṣe?
Ọjọ keji ọjọyii nigbe aye Olumuyiwa kii ṣe itan didun rara tori iye awọn to wa ke e lọna ti wọn si bẹrẹ si ni lu u bi i bara.
Ó béèrè aṣọ gbogbo tí o mu lọ, onítọ̀hún dáhùn, o ní aṣọ ìyàwó mi ni.
“Nítorí náà, gbọ́ nisinsinyii, OLUWA ni ó jẹ́ kí àwọn wolii wọnyi máa purọ́ fún ọ, nítorí pé ó ti pinnu láti jẹ́ kí ibi bá ọ.
Lẹyin eyi lo tẹlẹ Baba rẹ ati ẹbi lọ si ẹka eto aabo ara ilu nitori ọpọlọpọ ikọlu to n ṣẹlẹ.
Bẹ́ẹ̀ níí máa ń kìlọ̀ fún ọba Israẹli tí ọba Israẹli sì ń bọ́ kúrò ninu tàkúté ọba Siria.
Mo wá wọ̀ ọ́ ní aṣọ tí wọ́n ṣe ọnà sí lára, mo wọ̀ ọ́ ní bàtà aláwọ.
Ó wá fi ọgbọ́n wádìí gbogbo ibi tí ò ń lọ, ati gbogbo ohun tí ò ń ṣe ni.
yóo wí fún OLUWA pé,“Ìwọ ni ààbò ati odi mi,Ọlọrun mi, ẹni tí mo gbẹ́kẹ̀lé.
olúṣèyí abiọ ́ dún mákindé ni a bí ní ọjọ ́ karùndínlọ ́ gbọ ̀ n oṣù kejìlá , ọdún 1967 ( 25 december 1967 ) .
” ’ Kí baba ọmọbinrin tẹ́ aṣọ ìbálé rẹ̀ sílẹ̀ níwájú àwọn àgbààgbà, kí ó sì wí pé, ‘Èyí ni ẹ̀rí pé ó bá ọmọ mi nílé.
Mo sọkún títí ojú mi fi pọ́n,omijé sì mú kí ojú mi ṣókùnkùn,
Àkọsílẹ̀ àwọn nǹkan yòókù tí Amasaya ṣe, láti ìbẹ̀rẹ̀ dé òpin, wà ninu ìwé àwọn ọba Juda ati Israẹli.
Ile funfun balawu lorile-ede Amerika so pe oniruuru ipade ti o ba waye laarin orile-ede ohun ati North Korea,  ni lati fopin si sise eto tabi ifilole ohun ija oloro, leyin ti awon omo egbe lati Pyongyang sabewo si South Korea lojo Aiku(Sunday) pe, ijoba won faye ijiroro po sile pelu Amerika.
Gege bi iwe iroyin Herald, aare orile-ede Zimbabwe Emmerson Mnangagwa so pe, aawo ti o wa laarin orile-ede naa ati ilu UK ti dopin.
Odun 1945 ni Aduku darapọ mọ iṣẹ ologun ni Naijiria to si ja ọpọlọpọ ogun ati ipese iṣẹ aabo gẹgẹ bii ọmọ ogun ilẹ Naijiria tootọ.
nị ́ gbà tí sàláwà ń bá ilé iṣẹ ́ ìròyìn kan sọ ̀ rọ ̀ .
Wọn ni o dara fun eroja asaraloore iron, zinc ati protein.
Ẹ̀dínwó epo bẹntíró tí NNPC kéde kò kan ará ìlú Wo ohun tí òfin àgbáyé sọ nípa ọmọ tí a bí sí inú bàlúù Ìjọba buwọ́lu ẹgbẹ̀rún mẹ́wàá náírà owó ìrànwọ́ oṣooṣù fún ìyá Rashidi Yekini Ìjọba àpapọ̀, ẹ so ifilọlẹ ẹ̀rọ alatagba 5G rọ na - ilé asofin àgbà Alukoro ileeṣẹ ọlọpaa ni ipinlẹ naa, ASP Tee-Leo Ikoro ṣalaye fun BBC News Yoruba pe gbogbo awọn ọlọpaa ẹkun naa ni wọn ti ṣe ayẹwo fun lai da eeyan kan si ti wọn si n reti esi ayẹwo wọn bayii.
Oríṣun àwòrán, Human Rights Network Wọn lo ni arun ọpọlọ, to si n huwa ipa amọ dipo ki baba rẹ lọ tọju rẹ lati ọdun 1990, se lo pinnu lati ti ọmọ rẹ mọle."
Ilé aṣọ̀fin Nàìjíríà ń gbèrò ẹ̀wọ̀n f'áwọn olùkọ̀ tó bá dẹnu ìfẹ́ kọ akẹ́kọ̀bìnrin Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Seyi Makinde sọ eyi lasiko to n gbalejọ Abubakar Abdusalami ni ilu Ibadan.
Awọn mejeeji si n ti inu oko wọn bọ ni lasiko tawọn afurasi mẹrẹẹrin naa da wọn lọna ni deede aago marun irọlẹ.
O gbé agbára ogun wọ̀ mí;o sì mú àwọn tí ó dìde sí mi wólẹ̀ lábẹ́ ẹsẹ̀ mi.
Odi ìlú náà nípọn, ó sì ga.
Eyi ko sẹyin bi rogbodiyan kan ṣe waye lọdun naa, ti ẹmi ati dukia awọn eniyan si sọnù.
A kó dúnkoòkò mọ́ Ambode, isẹ́ wa là ń ṣe - Ilé Aṣòfin Eko Amẹ́rika dá akẹ́kọ̀ọ́ padá nítori Facebook Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
“Ẹ óo máa rú ẹbọ sísun sí OLUWA ní ìbẹ̀rẹ̀ oṣù.
Ati pe kò sí ǹkan to le de ba obinrin ti ọkọ yóò fi le e jáde, koda ko jẹ́ ajẹ tabi kó tilẹ̀ ya àgan kò le e kúrò nilé ọkọ rẹ̀ niwọn igba ti awọn ẹbi ba n fẹ tirẹ.
Iroyin to n tẹ wa lọwọ lasiko yii ni pe wọn ti ile ijọba pa ni GRA ni Ilorin ni Kwara.
ati Jokimu, ati àwọn ará ìlú Koseba, Joaṣi ati Sarafu, tí wọ́n fi ìgbà kan jẹ́ alákòóso ní Moabu, tí wọ́n sì pada sí Bẹtilẹhẹmu.
Ọkàn àwọn yìí ti ṣókùnkùn, ó sì ti yàtọ̀ pupọ sí irú ìgbé-ayé tí Ọlọrun fẹ́.
Toyin Abraham bí ọmọkùnrin jòjòló Òṣèré tíátà Toyin Abraham daya Kolawole Ajeyemi Wo àgbáríjọpọ̀ àwọn Arugbá Ọ̀ṣun Òṣogbo látìgbà tó ti bẹ̀rẹ̀ Buhari júwe ọ̀nà ilé fún Obono-Obla lórí ẹ̀ṣùn ayédèrú ìwé ẹ̀rí Àjẹ́ àti Aṣẹ́wó ní ìyá Rainbow - Òjòpagogo Awọn lẹgbẹlẹgbẹ-loyeloye ati ọkanọjọkan ẹlẹgbẹjẹgbẹ lawujọ ti n ṣe ikini fun Kabiyesi Ataọja ti ilu Ọṣogbo, Ọba Jimoh Oyetunji, ti Kabiyesi naa si n wure fun wọn.
O ni ohun ija ado oloro bii ''dynamite'' ni wọn fi ṣilẹkun ile ifowopamọ si naa, nibi ti wọn ti ji owo ko lọ.
Ìjọba ìpínlẹ̀ Eko ti kéde orúkọ àwọn ọlọ́pàá tó fi ìyà jẹ àwọn olùwọ́de #EndSARS Oríṣun àwòrán, Babajide Sanwo-Olu/twitter Gomina ipinlẹ Eko, Babajide Sanwo-Olu ti kede pe ọwọ ijọba ti tẹ diẹ lara awọn ọlọpaa to mu awọn oluwọde #EndSARS nipinlẹ Eko.
CNN sọ pe lọpọ igba lawọn gbiyanju lati ba ileesẹ ologun Naijiria sọrọ ati ileesẹ ọlọpaa.
“Oyegun tun so pe”ohun to se Pataki ni pe awon adari egbe APC ti wa lokan bayii ati  pe egbe yii wa leyin aare ati awon igbimo amusese naa”.
Aarẹ Buhari pàṣẹ pé kí wọ́n ṣàwárí àwọn oníṣẹ́ ibi tó pa èèyàn 65 ni Borno 1.
Gege bi oro re, eto ibasepo nile Africa yii je ona kan lara asa awon omo-ogun naa.
Àkọlé àwòrán, Àjọ ọlọ́pàá, Ìjọba ìpínlẹ̀ Ọyọ jẹ́jẹ̀ẹ́ láti ṣàwárí òòsà tó ń mu ẹ̀jẹ̀ nílùú Ìbàdàn Ọwọṣeni rọ awọn olugbe agbegbe naa lati ma bẹru nitori ijọba ati awọn agbofinro ko ni sinmi titi ti alafia yoo fi jọba ni agbegbe naa ati ipinlẹ Ọyọ l'apapọ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Àjẹ́, eégún, kí ni wọn ò pè mí tán tórí Vitiligo lára mi' Ajọ LASEMA sọ fun BBC Yoruba pe ẹmi meji ti ba iṣẹlẹ naa rin ti o si ti le ni ọkọ ọgbọn to jona.
Gege bi iroyin kan latodo ajo ti o n ri si oro  ounje ati eto-ogbin ninu ajo-isokan orile-ede agbaye, ti a mo si Food and Agriculture Organization, (FAO) (FAO), ogbele, ogbara, iseyo aarun eranko ati oogun lilo wa lara awon ajalu ti o n sakoba fun awon agbe ni awon orile-ede ti o ku die kaa to fun lodoodunIroyin so pe, laarin odun 2005 si odun 2015, isele ajalu sakoba fun eka eto ogbin ni awon orile-ede ti o ku die kaa to fun, ni eyi ti awon agbe ti padanu egbelemukun owo ti iye re to bilionu merindinlogorun owo dollars $96, eyi ti o ko sakoba fun ohun ogbin ati ipese ohun osin, eyi ti bilionu mejidinladota owo dollas $48 sele ni ile Asia.
Visa free: Àwọn Orílẹ-èdè tí wọn fún ọmọ Nàìjíríá lánfàní ìwé igbeluu ọ̀fẹ́
14 Àti pé àwọn wọ̃nnì tí wọ́n gbàá nínú ìgbàgbọ́, tí wọ́n sì ṣe iṣẹ́ òdodo, yíò gba adè kan ti ìyè ayérayé;
: 1) Boya wọn ko mu siga ri?
A ò bá máa wá ṣa  èrúnrún rẹ̀ nílẹ̀ lọ́kọ̀ọ̀kan.
Tí a fiṣọwọ́ ní 18:51 3 Ọ̀pẹ̀ 202018:51 3 Ọ̀pẹ̀ 2020 Àwòrán àwọn afurasí tí a fi léde kìí ṣe òfegè, ṣùgbọn a dọ́gbọ́n síi - Iléeṣẹ́ ọlọ́pàá Iléeṣẹ́ ọlọ́pàá lóun ò dọ́gbọ́n sí fọ́tò àwọn ọ̀daràn tó wà lórí Twitter.
Eyi yoo din awọn ọna ti ọkada n gba rin ku kaakiri ipinlẹ Eko.
Olalekan Jacob Ponle ti gbogbo eniyan mọ si Woodberry to jẹ ọkan lara awọn gbajuẹ ori ayelujara ti awọn ọlọpaa Dubai mu tẹlẹ pẹlu Ramoni Abass Hushpuppi.
Àkọlé àwòrán, Àwọn lọ́ba lọ́ba náà bá wọ́n pé níbi ìpàdé náà Ẹ̀wẹ̀, ní àkókò tí ikọ̀ oníròyìn wa kó ìròyìn yìí jọ, a kò tíì mọ àbájáde ìpàdé náà.
Obafemi Awọlọwọ Obafemi Awolowo jẹ ọkan gboogi lara awọn to ja fun ominira orilẹede Naijiria, ti o ''sọrọ soke'' nigba aye rẹ lori aṣemaṣe ti ijọba n ṣe nigba naa.
 Mahmoud MohammedOludari  igbimo ise ati ibanisoro Akanse – Festus
Àkọlé àwòrán, Adari ẹgbẹ oṣelu APC, Bọla Tinubu Àkọlé àwòrán, Gomina Ganduje ti ipinlẹ Kano nibi ibura wọle Gomina Gboyega Oyetọla Àkọlé àwòrán, Gomina Gboyega Oyetọla n tọwọ bọwe Àkọlé àwòrán, Gomina Rotimi Akeredolu ti ipinlẹ Ondo náà kò gbẹ́yìn Àkọlé àwòrán, Gomina ipinlẹ Eko, Akinwumi Ambode Àkọlé àwòrán, Gomina ipinlẹ Ọyọ lewaju, ti Ekiti tẹle e, Gomina Eko si n wo wọn lọọkan Àkọlé àwòrán, Gbajugbaja osere Yoruba Fadeyi Oloro niyii lẹgbẹ Ataoja ti Osogbo, Oba Jimoh Olanipekun pẹlu iyawo rẹ Àkọlé àwòrán, Gboyega Oyetọla bura wọle gẹgẹ bii gomina tuntun ipinlẹ Ọsun.
Awon to ku naa, ni won so pe , ile gbe won mi laaye nigba ti ile-riri Macalder sele ni Nyatike ti o je ogoji kilomita si ilu Migori.
BBC Africa Eye: Ìyá mi, bí mo bá rántí ikú rẹ lásìkò ìrọbí, àìbímọ tèmí ń pa mí kú díẹ̀díẹ̀
ajo naa sun siwaju da irẹwẹsi si won lokan, sugbon ki won tu jade lati lọ dibo
Iha wo lawọn eeyan kọ si i?
"''Gbogbo ileri ati afojusun fun awọn ọmọde ti a ba muṣe ti a si mu lokunkundun jẹ igbesẹ ti o tọ fun aabo ẹtọ awọn ọmọde, a si ni lati satilẹ̀yin fun wọn"" gẹgẹ bi Mohamed Fall, asọju ajọ UNICEF ni Naijiria ati alaga ajọ isọkan agbaye to n sabojuto ẹtọ awọn ọmọde ati ipolongo igbegidina awọn ẹtọ naa."
“Nítorí náà, mò ń ba yín rojọ́,n óo sì tún bá arọmọdọmọ yín rojọ́ pẹlu.
Gege bi aare Buhari se so ni gbagede Abubakar Tafawa Balewa, nipinle Bauchi.
Òṣùpá dà bí ọ̀sán, wọ́n sáré títí ilẹ̀ fi mọ́ síbẹ̀ ọkùnrin náà kò padà ó ń lé e lọ ó sì lé e títí wọ́n fi dé ibi ẹsẹ̀ òkè kan, ọkùnrin yìí tún tẹ̀lé e, bí ó ti gun òkè yìí dé orí lọ́hùn-ún tán, ọkùnrin yìí bá ara rẹ̀ láàrin ońiruurú ẹranko gbogbo inú ayé yìí wọ́n wà nínú ìgbìmọ̀ wọn.
Alami eye alaafia Johnson-Sirleaf di aare ni odun 2006, leyin odun keta ti orile-ede ohun bo lowo ogun abele elekeji, bakan naa ni won tun dibo yan fun saa elekeji ni odun 2011.
Wo ohun tó yẹ kí o mọ̀ nípa àwọn obìnrin méje ti Buhari fẹ́ yàn sípò minista Ajínigbé ń bèèrè fún epo, iṣu àti ọ̀tí Schinap gẹ́gẹ́ bí owó ìtanràn Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí kan sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ikogosi-Ekiti: Ilu ti omi tutu ti dapọ mọ gbigbona Awọn oye ti wọn fi da a lọla nigba aye rẹ ko kere rara: Balogun ilu Ileṣa Seriki Ajanaku ti Ijeṣa Ọgagun agba ikọ Ogun Ekiti Parapọ Obanla ti Ijeṣa (Oba-Ala Ogedengbe ti Ileṣa Kinni) Ìbí àti dídàgbà Ogedengbe: Ohun to wu ni lori ninu itan akinkanju yii ni wi pe ki wọn to bi i ni Ifa ti fọhun pe oun ni yoo jẹ olugbala ilu Ijeṣa.
Ẹ̀ka mẹfa ni ó yọ lára ọ̀pá fìtílà náà; mẹta lẹ́gbẹ̀ẹ́ kinni, mẹta lẹ́gbẹ̀ẹ́ keji.
Ẹ kò gbọdọ̀ mójú kúrò bí ẹni pé ẹ kò rí i.
Offa Robbery: Àwọn aráàlú ṣì n gbé nínú ìpaya lẹ́yìn ọdún kan
Ẹni tí ó wà lókè pẹ̀tẹ́ẹ̀sì kò gbọdọ̀ sọ̀kalẹ̀ wọlé lọ mú àwọn ohun ìní rẹ̀.
France Attack: Ọga Ọlọpaa ìlú Nice ní adúnkookòmọ́ni ló gún àwọn èèyàn náà pa
Òun ati àwọn àgbààgbà Israẹli ṣáájú wọn, wọ́n lọ sí Ai.
Dafidi sá àsálà, ó sá lọ sí ọ̀dọ̀ Samuẹli ní Rama, ó sọ gbogbo ohun tí Saulu ti ṣe sí i fún un.
Igbimọ ipolongo idibo rẹ sọ ninu atẹjade kan pe, ''Aarẹ Trump ti wẹ yan kanin-kanin bayi, ohun to si ku ni ka gbajumọ eto ṣiṣe iṣẹ sin awọn eeyan ilẹ Amẹrika'' Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Trump impeachment: Trump kò fìdí janlẹ̀ tán, àmọ́ níbo ni yóò jásì?
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Èmi gan máa ń béèrè lọ́wọ́ ara mi pé ta ni Wole Soyinka gangan' Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
wọ́n dà á sílẹ̀ níwájú àwọn aposteli kí wọ́n lè pín in fún àwọn tí ó bá ṣe aláìní.
Ó bá pada lọ sọ́dọ̀ Elija, ó ń tẹ̀lé e, ó sì ń ṣe iranṣẹ fún un.
Iwadii kan lati fasiti Maryland ni orilẹ-ede America ṣafiwe odiwọn ooru ọjọ ati otutu lasiko ajakalẹ arun Covid 19.
Olajengbesi ni awọn n lọ si ile ẹjọ kotẹmilọrun ni ireti pe wọn yoo gbe ọrọ naa yẹwo daadaa lati se oun to tọ.
Àwọn eeṣin kò kọ ikú adigunjalè náà, tí wọ́n tó ọgbọ̀n níye ló ṣe ọṣẹ́ láwọn báńkì náà fún wákàtí méjì àti ààbọ̀ gbáko, èyí tó sọ ọ̀pọ̀ èèyàn di opó àti ọmọ òrukàn.
Kìí ṣe ebi, ìyà tàbí ìṣẹ́ ló mú kí wọ́n yabo àwọn ilé ìkẹ́rùsí - Femi Adeshina Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Kété tí wọ́n bá ti báa yín sùn tàn torí pé ẹ tóbi, ẹ gbà pé ìfẹ́ yẹn ti parí - Auntie Remi Ọlọ́yàn ńlá Ẹwẹ, ọga agba ọlọpaa fọhun pe awọn ọlọpaa ṣiṣẹ gẹgẹ bii akọṣẹmọṣẹ ti awọn kan si fi ẹmi wọn lelẹ fun alafia lasiko ifẹhonuhan to waye kaakiri awọn ipinlẹ kan lorilẹede Naijiria.
Saaju ni gomina Dickson tipinlẹ Bayelsa ti ni awọn gomina lati ẹgbẹ oṣelu PDP ko ni dije dupo alaga naa lasiko yii.
Idije naa ti wọn fi jaa loju waye laarin ikọ orilẹ-ede Iran ati Cambodia, ni papa iṣere Azadi, to wa ni Tehran,to jẹ fun igbaradi idije ife ẹyẹ agbaye to maa waye lọdun 2022.
Ẹ̀ka ìròyìn Channel One ò fi òtítọ́ ìtàkùrọ̀sọ yìí pamọ́, ṣùgbọ́n wọ́n tẹnu mọ́ ọn pé ọ̀rọ̀ náà kò ṣègbè lẹ́yìn akọ.
Ṣé ohun kan wà tí ó ṣòro fún OLUWA ni?
Ó bi Dafidi pé, “Ṣé ajá ni mí ni, tí o fi ń mú ọ̀pá tọ̀ mí bọ̀?
Ẹ máa gbadura nígbà gbogbo, kí ẹ máa fi gbogbo ẹ̀bẹ̀ yín siwaju Ọlọrun nípa agbára Ẹ̀mí Mímọ́.
Kíni à ń pe ni Euthanasia?
Lassa Fever: Ọ̀nà márùn ún láti dènà ìbà ọ̀rẹ̀rẹ̀
" Nitori naa, onimọ nipa eto ọrọ aje ni Naijiria, Temitope Kọlawole wa rọ awọn ọmọ Naijiria, lati bẹrẹ si ni ṣe ipesẹ ounjẹ wọn labẹle nitori ọwọngogo ti yoo gori awọn eroja ounjẹ lasiko yii.
Igbakeji aare ni, ki o to di odun 2050 orile ede Najiria ni yoo wa ni ipo keta laarin awon ti iye won po julo ni agbaaye leyin orile India ati China.
Ojutalayo soju fun,  je ko di mimo pe omo
Lẹ́hìn eléyìí, Baba-onírùngbọ̀n dìde níbi tí ó jókòó sí ó sí tọ́ka sí igi kan tí ó ní òdòdó tí ó sì dára púpọ̀, ó wí pé: Wo igi tí ó wà lọ́hùn-ún nì; igi tí ewẹ rẹ̀ dúdú mirinmirin, lẹ́hùn-ún ni; tún wo òdòdó rẹ̀ bí o ti lẹ́wà tó pẹ́lú.
Ọ̀kan lára àwọn ọba tọ́jọ́ orí wọn dàgbà jù ní ìpínlẹ̀ Oyo ti wàjà Oríṣun àwòrán, The Sun Newspaper Ọba Samuel Afolabi, Onilu ti ilu Ilua ni ijọba ibilẹ Kajola nipinlẹ Oyo ti ku lẹyin aisan ranpẹ.
Nigba to ba BBC sọrọ, Charly Boy fidi rẹ mulẹ lootọ l'oun gba owo lọwọ agbẹjọro Festus Kenyamo ti ẹgbẹ APC, ṣugbọn owo iṣẹ ti oun ṣe fun APC nipasẹ Kenyamo ni oun gba lọwọ rẹ.
Awọn iroyin miran ti ẹ le nifẹ si: Njẹ lootọ ni wipe Yusuf Buhari ti ku?
Hajiya Halima Seth (1963-2020) Oríṣun àwòrán, Instagram Iyawo eekan onimọ nipa Islam, Sheikh Abdulwahab Abdullah ni Halima Shitu jẹ.
Eyi ni idi ti ko fi si wahala laarin awọn ati awọn olubagbe ni agbegbe wọn.
Yàrá Inú Òfurufú – àpá kejì Ìrìnkèrindò Moravia
Ọwọ́ sìkùn ọba tẹ lára àwọn afurasí tó kọlu ilú Òffà
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Osun Guber Poll: PDP ní ìdájọ́ ilé ẹjọ́ gíga lórí ọ̀rọ̀ Adeleke kò fẹsẹ̀ múlẹ̀ 3 Ìgbé 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 4 Ìgbé 2019 Oríṣun àwòrán, Facebook/Ademola Adeleke Àkọlé àwòrán, Idibo gomina Oṣun Adeleke ni iwe ẹri tó yẹ lati dije dupo gomina- Amofin Salami Ẹgbẹ oṣelu PDP ti sọ pe ohun yoo lọ si sile ẹjọ kotẹmilọrun lori idajọ ile ẹjọ giga l'Abuja to fagile iyansipo Ademola Adeleke gẹgẹ bi oludije sipo gomina fẹgbẹ oselu PDP ninu idibo gomina to waye ninú Osu Kẹsan an, ọdun 2018 ni ipinlẹ Osun.
Eyi ni ife ẹyẹ nla miran to tun gba lẹyin Grand Slam to gba ni Rome ni 2016 ati Australian Open to gba ni 2017 ko too bimọ.
Bí ìlà oòrùn ti jìnnà sí ìwọ oòrùn,bẹ́ẹ̀ ni ó mú ẹ̀ṣẹ̀ wa jìnnà sí wa.
Kogi Election: Kí ló mú àwọn jàndùkú dáná sun Aṣáájú obìnrìn ẹgbẹ́ òṣèlú PDP mọlé ?
Ina eto ilera n ku lo, bẹẹ ni eto ọrọ
Sugbọn kia ni ijọ Katoliki kede loju opo Twitter rẹ pe iroyin naa ki se otitọ nitori ọjọ pẹ ti awsn ti ya aworan naa.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìjàmbá iná: Ọkọ̀ epo ló gbiná, tó ran ogún ọkọ̀ míì 28 Òkùdu 2018 Oríṣun àwòrán, Ọllabọ̀dé Akamọ Àkọlé àwòrán, Àwọn èèyàn àti ọkọ̀ tó há sínú súnkẹrẹ-fàkẹrẹ tó ń wáyé lásìkò tí ọkọ̀ epo náà gbinná, ló forí sọta àjálù náà Ọkọ̀ epo kan ti sàdédé gbiná, tí ọ̀pọ̀ ọkọ̀ ayọ́kẹ́lẹ́ tó lé ní ogún sì gbinná tẹle.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ondo APC: Àṣà ojú-àwo-làwo fi ń gbọbẹ̀ kò lè wáyé l'Ondo 19 Ẹrẹ̀nà 2018 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 5 Owewe 2018 Oríṣun àwòrán, Ondo APC Àkọlé àwòrán, Ọmọ ẹgbẹ́ òsèlú APC tako Oshiomole Àwọn ọmọ ẹgbẹ òṣèlú All Progressives Congress ní ìpínlẹ̀ Ondo ti tako ààrẹ gbogboogbò fún APC Adams Oshiomole fún àṣẹ lílo àṣà ìdìbò abẹ́nú ojú àwo làwó fí ń gbọbẹ.
”Ọdọmọkunrin náà dáhùn pé, “Láti inú àgọ́ àwọn ọmọ Israẹli ni mo ti sá àsálà.
Ó ní èyí sì gbà ọ̀pọ̀lọpọ̀ èrò kí àwọn tó fẹnukò lórí àwọn owó tí àwọn fi síta.
Bakan naa lo fi kun pe, owo epo Naijiria lo si dinwo julọ lẹkun iwọ oorun Afirika nitori N326 ni wọ́n ń ta jáálá epo ní Ghana, N211 ní Egypt, ní ìgbà tó jẹ́ N168 ní Saudi Arabia.
Fun apẹẹrẹ, eto sisi oju aanu wo awọn ẹlẹwọn yoo bẹrẹ, ta si se atunto aye wọn.
Ẹwẹ, awọn oluwoye idibo ko si nikalẹ, eyi to si fa ibẹru ṣiṣe mago-mago idibo.
Ọkùnrin kan lu ìyàwó rẹ̀ pa"" nítorí ó lọ síbi ayẹyẹ ìsọmọlórúkọ Látilẹ̀ ni mo ti fẹ́ràn orin ìjọ Kérúbù àmọ́ ẹlẹ́sìn mùsùlùmí àti krìstẹ́nì ni mí- Qdot Rògbòdìyàn bẹ́ sílẹ̀ láàrin àwọn ọlọ́kadà àti àwọn òṣìṣẹ́ ọgbà ẹ̀wọ̀n ní Ibadan Tí a bá yọwọ́ àwọn ọba alayé kúrò, kò ní sí Nàìjíríà mọ́- Alaafin Oyo Makinde, Dele Momodu ń ṣèdárò Àgbà Oyè Ilẹ̀ Ibadan, Harry Akande tó jáde láyé Ninu idahun rẹ, Abike Dabiri ni '' O ya mi lẹnu lati kaa wi pe mo ko Palliatives pamọ sile."
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Yorùbá rẹwà, kọ́ nípa àwọn ọ̀rọ̀ tí ìró ẹnu wọn jọra àmọ́ tí ìtumọ̀ wọn yàtọ̀ Coronavirus tún ti bẹ́ gìjà sí Ghana àti Gabon Ẹ yọmí kúrò ní àhámọ́!
Ijamba ọkọ ayọkẹlẹ ati ọkọ tirela ni ipinlẹ Ondo ti mu ẹmi eniyan marun un lọ, ti eniyan meji si farapa.
Ninu atejade ti egbe oselu ti o wa lori aleefa lowo-lowo, All Progressives Congress APC, eleyi ti adele akowe agba egbe naa, ogbeni Yekini Nabena bowolu.
Ní ọ̀pọ̀ ìgbà à ní àwọn ọtẹlẹ̀múyẹ ní àwọn bi a ti lọ ń ko àwọn aṣẹ́wó tàbi ọdaran.
Mò ń sọ fun yín pé lóòtọ́ ni Covid-19 wà, èyí ni àlàyé Okoye .
Ẹya Hausa ati Fulani ni awọn afurasi naa, gbogbo wọn lo si sọ pe awọn ko jẹbi ẹsun ti wọn fi kan wọn.
Siasia ni oun ti gbiyanju agbara oun lati wa owo ti yoo fi ṣe ẹjọ naa nile ẹjọ to n ri si awuyewuye to ba jẹyọ nibi ere bọọlu afẹsẹgba lagbaaye.
Bí àwọn adarí ìjọba ṣe ń kó Coronavirus, ń kọ wá lóminú - Ìjọba àpapọ̀ Àkójọ́pọ̀ àwòrán rèé lórí bí ìwọlé akẹ́kọ̀ọ́ ṣe lọ sí ní Oyo Bí Hushpuppi ṣe tiraka rèé l‘Eko, kí ọlà ‘òjijì’ tó dé Magu lọ farahàn níwájú ìgbìmọ̀ tó ń ṣ'àyẹ̀wò EFCC, DSS kò mú un- EFCC Domestic Violence: Obìnrin tó gún ọkọ rẹ̀ pa lórí ọ̀rọ̀ fóònù ní òun si ní ìfẹ́ ọkọ òun Oríṣun àwòrán, Other Obinrin kan, Rabi Rabi'u to gun ọkọ rẹ pa ti ṣalaye pe, ede aiyede to ṣẹlẹ laarin awọn mejeeji lori ta ni yoo kọkọ ti fooni bọ ina lo fa sababi iṣẹlẹ naa.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ǹǹkan márùn ún nínú ilé tó lè ṣe ikú pa ni 30 Bélú 2018 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 1 Ọ̀pẹ̀̀ 2018 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Efin to n jade latara ẹrọ amunawa ti ran ọpọ lọ si ọrun Yoruba bọ wọ ni a kii joko sile ka fi ọrun yin.
S Embassy Ẹgbé agbábóólù orílẹ-èdè Naìjíríà gba ẹbuǹ wúrà ilẹ Afrika Iwadii fihan pe awọn agbalagba kọọkan ti n ṣowo da gbese nitori wọn n ṣe paṣipaarọ owo wọn to ti dọti si tuntun ni odiwọn to keere niye.
Àwọn ajàfẹ́tọ̀ọ́ abo ní Russia máa ń sábàá lo gbàgede ẹ̀rọ alátagbà àti ẹ̀fẹ̀ láti tan ìmọ́lẹ̀ sí ìhùwàsí àti ìṣe àwọn tí ó ń ṣègbè lẹ́yìn ẹ̀yà ènìyàn kan.
Ṣé ẹ̀ ń dọdẹ ẹ̀mí àwọn eniyan mi ni, kí ẹ lè dá àwọn ẹlòmíràn sí fún èrè ara yín?
Arakunrin agbẹbọn naa gẹgẹ bi ohun ta gbọ farapa ninu ikọlu pẹlu awọn Ọlọ́pàa ti wọn si ti mu bayi si ahamọ.
Ó ní, “Afọ́jú kò lè fi ọ̀nà han afọ́jú.
Operation Amotekun: Amọ̀tẹ́kùn ṣetán láti gbérasọ, fọ́ọ̀mù ìgbaniṣíṣẹ́ ti dé!
Eeyan to le ni ẹgbẹrun mẹta lo ma n jọsin ninu ijọ naa ninu isin ọjọ Aiku.
Ẹkunrẹrẹ alaye yii wa ni oju opo Twitter ajọ NCDC.
Wọn ni ila irun naa a gbooro pe ila irun naa kò ni wọ́.
Àlàó ra obì àti ọtí fún Olófìn-íntótó Olófìn-íntótó mu bíà mẹ́ta.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Premier League: Arsenal àti Liverpool gbéná wojú ara wọn 7 Ọ̀wàrà 2018 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 4 Bélú 2018 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Arsenal àti Liverpool gbéná wojú ara wọn Eegun k'eegun ni ifẹsẹwọnsẹ Arsenal pẹlu Liverpool ninu idije Premier League lẹyin ti ere bọọlu naa pari si omi alayo kọọkan ni papa iṣere Emirates nilu London.
Bi orile ede Naijiria yoo se
Sadiya Umar Farouq: Èmi kò jí nínú owó oúnjẹ àwọn akẹ́kọ̀ọ́, irọ́ ni Bolaji Owasanoye, alága ICPC ń pa
”Ogbeni Shehu fikun oro re pe, bee si ni aare ko fi igba kan bo kan ninu, ninu ise akanse gbigbogun ti iwa ibajẹ to yan laayo.
Wọ́n bá ń pe ilẹ̀ náà ní “Akelidama” ní èdè wọn.
nítorí pé wọ́n tàpá sí òfin Ọlọrun,wọ́n sì pẹ̀gàn ìmọ̀ràn ọ̀gá ògo.
Nǹkan kò ṣẹnuure fáwọn obìnrin nínú ìgbìmọ̀ ìṣèjọba Buhari Ajínigbé ń bèèrè fún epo, iṣu àti ọ̀tí Schinap gẹ́gẹ́ bí owó ìtanràn Wo ohun tó yẹ kí o mọ̀ nípa àwọn obìnrin méje ti Buhari fẹ́ yàn sípò minista Ọlọ́pàá ti mú afurasí ajínigbé Hamisu Wadume Bo tilè jẹ pe, ilé ẹjọ́ lo gbaa fún un, Rauf Aregbesola, di gomina ipinle Osun ni odun 2010 sì ọdún 2018.
Àsìkò tó láti dóòlà Nàíjíríà, a ti gbé ẹ̀ṣùn ìbò lọ sílé ẹjọ́ tó ga jùlọ - PDP Ramil, omọ ogun ilẹ̀ ní Russia yìnbọn pa akẹgbẹ́ rẹ̀ mẹ́jọ!
Ṣugbọn o, o ni awọn kẹẹfin pe awọn ọkọ maa n yọ ọ wọle ni alẹ, awọn si ti dawọ rẹ duro.
SERAP: Ọ̀rọ̀ àwọn alájẹbánu ti kúrò lọ́rọ̀ yàrá, ó ti di ọ̀rọ̀ gbangba
Ologun Nigeria gbakoso ibuba Boko Haram ‘Itusilẹ yoo wa fawọn onde Boko Haram’ Awọn agbesunmọmi Boko Haram tẹlẹ gba idande Boko Haram tu awọn olukọni UNIMAID silẹ Mohammed Bulama to jẹ alaga ijọba ibilẹ naa ni awọn eniyan mọkanlelogun ni wọn kọkọ pa ki wọn to tun wa lọ kọlu awọn ara abule to n gbeja awọn ero.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ondo, Edo governorship election: Wo ìdí tí oò fi ní lè wọ Amẹ́ríkà bí o bá lọ́wọ́ sí rírú òfin ìbò 24 Agẹmo 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 15 Owewe 2020 Oríṣun àwòrán, Donald Trump/Instagram Ijọba ilẹ Amẹrika ti ni ko ni si fisa fun awọn kan to lọwọ ninu makaruru idibo inu osu kọkanla ipinlẹ Kogi ati Bayelsa ati gbogbo rogbodiyan to ti ba imurasilẹ idibo Edo ati Ondo ti yoo waye lọjọ satide ọsẹ yii ati ti ọjọ kẹwa oṣu kewa to n bọ yii rin.
Aye ijọhun ni wọn maa n ri ọjọ ori gẹgẹ bii ami fun ọrọ ti ẹda ni, ti ọpọ si maa n fi ikun titobi yangan ni awujọ.
Ijamba ọkọ naa kan ọkọ ayọkẹlẹ Camry kan ti nọmba rẹ jẹ KSF920 FF ti ọkọ akoyanrin tioa kan ti nọmba rẹ jẹ ENU 576 ZZ to ko okuta lọ rọ lu to si tẹ mọlẹ.
Mo dupẹ lọwọ Ọlọrun ati awọn ọmọ Naijiria fun aduroti wọn'' O ṣalaye pe lọdọ Risikatu loun ti kuro laarọ yii ati pe ko ni pẹ ti awọn yoo fi tun ṣe yigi pada'' Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ìdílé tí ọkọ da ọmọ síta tóríi ojú Búlùú tí wọ́n ní bá BBC sọ̀rọ̀ Laipẹ yii ni awọn eeyan n beere boya awọn mejeeji yoo pari ija laarin ara wọn.
' Lori ohun to wa laarin rẹ ati Saheed Balogun Funkẹ ni lootọ ni oṣere Saheed Balogun ti jẹ ololufẹ oun ri, o ni oun nifẹ Saheed nitori oun rii gẹgẹ bi oninukan eeyan nigba naa.
Pẹlu ikede yi, awọn ọdọ Naijiria yoo dara pọ mọ awọn akẹgb wọn lorileede Ghana ati Cameroon lati ṣe ayajọ ọjọ yi.
Awon adari lati inu egbe oselu
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Oyo 2019 Budget: Ìjọba Ọyọ gé ₦282bn owó ìsúná 2019 sí ₦181bn 4 Owewe 2019 Oríṣun àwòrán, Oyo Assembly Ile Igbimọ Asofin Ipinlẹ Ọyọ ti ge owo isuna ọdun 2019 lati biliọnu lọna ọrinlerugba ati meji naira (N282 billion) si biliọnu mọkanlelọgọsan (N181 billion) Naira.
Oríṣun àwòrán, Twitter/BBNaija Fun idi eyi Laycon yoo ni lati san owo ori lori owo to jẹ ninu idije yi ati apapọ iye ẹbun to ri gba ayafi eleyi ti ijọba ba yọnda fun labẹ ofin.
OLUWA wí pé, “Nítorí pé àwọn eniyan mi ṣe nǹkan burúkú meji:wọ́n ti kọ èmi orísun omi ìyè sílẹ̀,wọ́n ṣe kànga fún ara wọn;kànga tí ó ti là, tí kò lè gba omi dúró.
Ọ̀míràn dàbí iṣẹ́e bàsèjẹ́ àti ọmọọ̀ta.
Lẹ́yìn tí ó fá irun rẹ̀, tí ó sì pààrọ̀ aṣọ rẹ̀, ó wá siwaju Farao.
Wọn bi Shehu Usman Aliyu Shagari ni ọjọ kẹẹdọgbọn, oṣu Keji, ọdun 1925, ni abule Shagari to wa ni ipinlẹ Sokoto.
Ìkọlù sáwọn àjèjì kò tíì tán ní South Africa, ètò ń lọ láti kó ọmọ Nàíjíríà wálé Samuel Ajayi Crowther, òjíṣẹ́ Ọlọ́run tó gbé èdè Yoruba lárugẹ Ìdí rèé ti Nàìjíríà fí ń gbé inú òkùnkùn Omíyalé àgbàrà ti ya ṣọ́ọ̀bù ní Niger Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Nigeria models: Ẹ má bóra mọ́, ọmọ dúdú dùn lọ́mọbìnrin Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
O ni oloṣelu ti ba ijọba jẹ de gongo bẹrẹ lati ipele ijọba mẹtẹẹta.
Mo wá sí ọ̀dọ̀ àwọn tèmi, àwọn tèmi kò sì gbà mí.
Dokita Onu wa ro awon omo egbe naa lati ri daju pe, won jade lati wa awon alabasisepo jake-jado lojuna lati samulo ababo eto kamika epo robi ohun.
Wọ́n bèèrè ẹran, ó fún wọn ní àparò,ó sì pèsè oúnjẹ àjẹtẹ́rùn fún wọn láti ọ̀run.
Kì í ṣe àròsọ ti ara rẹ̀ ni ó fi sọ gbolohun yìí, ṣugbọn nítorí ó jẹ́ olórí alufaa ní ọdún náà, ó sọ àsọtẹ́lẹ̀ ni, pé Jesu yóo kú fún orílẹ̀-èdè wọn.
6 24578 Orilẹede Suriname 139 24.
Gomina ipinle Kano, Umar Ganduje pe awon olukopa ohun lati wa ojutu si awon isoro to koju iwa eni lawujo, esin, ebi, ile-iwe awon odo, ikose owo ati lilo awon ohun elo igbalode lati fi koju awon isoro to n koju eto aabo.
Okele tí ọ̀nà ọfun bá gbà ni ènìyàn n fi sí ọ̀nà ọ̀fun, òkèlè tí ó tóbi bí orí Ọmọdé kò ní ṣàì yọ di ni lẹ́nu, rọra máa bu òkèlè nígbà tí o ba ń jẹun.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Edo: Ẹran dida ati ibọn gbigbe deewọ 9 Èrèlè 2018 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ijoba ipinlẹ Ekiti ati Kogi ti fofin de didaranjẹ saaju ki ipinlẹ Edo to gbe igbesẹ yii Ijọba ipinle Edo ti fofin de asa dida ẹran lalẹ ati gbigbe ibọn rin laarin awọn darandaran.
5 54066 Ilẹ Australia 909 3.
'Àwọn akọ̀ròyìn sọ ilé ìjọba di ilé ọtí àti tẹ́tẹ́' Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí kan sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
Ọmọbinrin Araba ilu Oṣogbo, Oloye Ifayẹmi Ẹlẹbuibọn, ni Ifayẹmisi Ẹlẹbuibọn to ni oju opo ayelujara naa.
Bakan naa ni eto idibo gomina to waye ni ipinlẹ Ọṣun, rogbodiyan waye, paapa lẹyin ti eto idibo naa waye ati lasiko atundi ibo.
Ẹnikan nínú wọn tiẹ̀ sọ fún ikọ ìròyìn BBC pé, àǹfààní ńlá ni ìjáde wọn òní jẹ láti gba atẹgun sára.
 “Orile ede Najiria n tesiwaju;orile ede Naijiria tun n dara si i;orile ede wa tun n se aseyori si i; orile ede wa kun fun wara ati oyin, gbogbo wa la o je eso orile ede yii.
Iroyin fi idi rẹ mulẹ pe oku arabinrin yii ati ibi ọmọ tuntun to bi ni oku naa nikan ni wọn ba, ẹnikan ko si lee sọ ohun to gbe oku ọmọ tuntun naa kuro nile igbokupamọsi naa.
Covid-19 vaccine: Abẹ́rẹ́ tí àjẹsára Pfizer ṣe yóò di lílò láti ọ̀sẹ̀ tó ń bọ̀ ní UK
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ẹ wo àwọn ọmọ orílẹ̀-èdè Brazil tó wá síilẹ̀ Yorùbá láti mọ orisun wọn Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: A tún ti ṣàwárí omi àjèjì míràn ní Ilé-Ifẹ̀ - Ọọ̀ni Irú ẹ̀dá wo ni olówó yalumọ àkọ́kọ́ nílẹ̀ Yorùbá, Candido Da Rocha?
Ọmọ́wùmí- Ọmọ Àkàngbé Orímóògùnjẹ́ ni òun náà Ọmọ ọdún mẹ́jọ ni.
Àwọn ará abúlé náà sì jẹ́ onímọ̀ọ́tótó gbáà.
Ṣugbọn ẹnìkan lè sọ pé, “Ìwọ ní igbagbọ, èmi ní iṣẹ́.
O mú kí òkùnkùn ṣú, alẹ́ sì lẹ́,gbogbo ẹranko ìgbẹ́ sìń jẹ kiri.
A ti bẹ̀rẹ̀ ìwádìí lóri ọ̀rọ̀ naáà à ó mu ẹni náà a ó sì fi jofin Oríṣun àwòrán, Twitter Àkọlé àwòrán, Ajà fẹ́tọ ọmọniyan gbàgboro lAbuja lóri mimu obinrin sátimole nitori iwosọ Àwọn aja fẹtọ ọmọ ènìyàn ti gbà ìgboro pẹ̀lú ìfẹhonu han nílu Abuja ti ṣe olú-ìlú orilẹ̀-èdè naijiria lóri ọ̀rọ̀ bi ọlọpàá ṣe ń mú àwọn obinrin sátìmọle, wọn a tún dóju tiwọn nítori pé wọn wọ aṣọ pénpé lo si ilé ijo tàbi ilé ìtura.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ọgbà ẹ̀wọ̀n ni wọ́n ti já àbálé Esra lábẹ́ àwáwí àyẹ̀wò wúndíá Alẹ ọjọ Satide, ọjọ kejila, oṣu kejila ọdun 2020, ni ija naa waye ni gbagede SSE Arena, ni ilu London, nibi ti Joshua ti fi ẹṣe ja Pulev bọ bi apo irẹsi.
Pabambari rẹ ni ti awọn ọmọ OOdua kan to tun n fi ede oyinbo fi ami si ori ọrọ yii, Kayeefi.
Bí ọkunrin kan bá bá a lòpọ̀ nígbà tí ó bá ń ṣe nǹkan oṣù rẹ̀, ọkunrin náà yóo jẹ́ aláìmọ́ fún ọjọ́ meje, ibùsùn tí ọkunrin náà bá sì dùbúlẹ̀ lé lórí yóo jẹ́ aláìmọ́.
Ohun tí wọ́n rí bani lẹ́rù tóbẹ́ẹ̀ tí Mose fi sọ pé, “Ẹ̀rù ń bà mí!
Oríṣun àwòrán, Facebook/Remi Oladoye Àkọlé àwòrán, Inu igbo nla ti igi tiiki wa yi ni awọn ajinigbe naa maa n fara soko si lati sisẹ ibi wọn Bi wọn se n ja wọn lole lọwọ, kia ni awakọ tiwa, to ti mọ nipa isẹlẹ to n waye lọwọ naa, nitori ọmọ Efon Alaaye ni, ti fa ọkọ jade lati sẹri pada.
Aládugbọ Kisauni lo gbọ ohun ọmọ rẹ to n sunkun asùn-dákẹ lo fi bere pé ki lo ṣe ọmọ náà, igbayi ni o wa gbe isoro arabinrin yii sori ayelujara.
Ile ẹjọ kan lorileede Myanmar ti ran awọn akoroyin ile ise iroyin Reuters meji kan lẹwọn lórí pé wọn n se iwadi lori iwa ipa sise fun awọn eeyan Rohingyas.
Wọn ti ri awọn mẹẹrin gbe lọ sile iwosan lara wọn.
Godluck Ebele Jonathan Àkọlé àwòrán, Ààrẹ Goodluck Ebele Jonathan Goodluck Ebele Jonathan kawe gboye ni ile iwe giga fasiti ilu PortHarcourt, o gba oye ipele keji ati oye PhD ni fasiti kan naa.
O ni won yoo fi owo yii seto idanilekoo fawon agbe lori ona oko dida ni ona igbalode ati ona katakara ti yoo rorun pelu ere goboi.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Mo ń retí láti ọ̀dọ̀ bàbá mi nígbà tí mo gbọ́ pé ó bá ìjàmbá bàálù lọ Dagmawits Moges to jẹ Minisita fun eto irinna sọ fun awọn akọroyin pe gbogbo iwe aṣẹ to yẹ ki baalu naa ni, ni o ni, ti awọn ti o si wa ọkọ ofurufu ọhun tẹle gbogbo ilana to yẹ.
Ninu àwọn akọrin, Eliaṣibu nìkan ni ó fẹ́ obinrin àjèjì.
Ọmọ Ààrẹ lẹ́tọ̀ọ́ láti ṣe ìgbéyàwó yálà àwọn ará ìlú fẹ́ràn ìjọba bàbá rẹ̀ tàbí bẹ́ẹ̀ kọ́ - Aisha Buhari Ó yẹ kí Buhari dá owó epo padà sí ₦97 tàbí kó kọ̀wé fipò sílẹ̀ - Àwọn akẹ́kọ̀ọ́ Àbá àpérò 2014 CONFAB lojútùú sí àtúnṣe ìwé òfin Nàìjíríà- Afenifere sáwọn sẹ́nẹ́tọ̀ Wo ọ̀nà ìsanwó tuntun fún àwọn oníbárà iná mọ̀nàmọ́ná ní Eko (EKDC) Bí nǹkan ọkùnrin bá há sójú ara obìnrin, kìí ṣe Mágùn, ẹ má páyà Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Constitution Review: Afenifere rọ àwọn aṣòfin láti lo àbá 2014 CONFAB fún àtúnṣe ìwé òfin Nàìjíríà8 Owewe 2020 6:30 Fídíò, Akomolede ati Aṣa lori BBC: Mọ̀ si nípa oríṣìí ẹ̀ka ìsọ̀rí ọ̀rọ̀ àti ìwúlò wọn, Duration 6,308 Owewe 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Iwakuwa Awakọ-akero jẹ iwa ti o se iku afawọfa loju popo 8) Ipaniyan: Eyi ni nigba to ba kuku gbẹmi ololufẹ rẹ patapata.
Nígbà tí Jesu dé Jẹriko, ó ń la ìlú náà kọjá.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Njẹ o ṣeṣe ki esi idibo jade lalẹ ọjọ idibo?
Bakan naa ni Aare yoo forojomitooro oro pelu awon eniyan ipinle Benue  ki o to tun lo sayewo si ibudo awon asatipo.
Ile ẹjọ giga apapọ kan ni ilu Abuja fagile oniduro rẹ ni ọjọbọ leyin eyi to ni ki wọn lọ gbe pada si ahamọ ọlọpaa.
N se ni wọn jọ ara wọn bii imumu Àkọlé àwòrán, Ọlọrun ma pa ibeji mi fun mi, ni adura ti baba yii n se lasiko to n bawọn ibeji rẹ ya fọto Àkọlé àwòrán, Awọn ibeji yii ma wu ni o, ejirẹ ara isokun Àkọlé àwòrán, Asọ kan naa, awọ kan naa, ila kan naa, koda, bakan naa ni awọn ibeji yii n wo.
Shiite: Bí Buhari kò bá tú ZakZaky silẹ̀, apa APC kò níí káa mọ́
 bàbá rẹ ̀ jẹ ́ mùsùlùmí tí ó sì nífẹ ̀ ẹ ́ sí gbogbo ẹni tí ó bá jẹ ́ onímọ ̀ , yàlà nínú ẹ ̀ sìn ni tàbí ìmọ ̀ tó ṣe pàtàkì mìíràn , tí ó sì ma ń sapá rẹ ̀ láti ràn wọ ́ n lọ ́ wọ ́ nígbà gbogbo pẹ ̀ lú owó àti ìgbìyànjú rẹ ̀ .
"Tí ènìyàn bá dàgbà nile obi nílẹ̀ Afirika, àwọn ǹkan wà ti oò le ni ore-ọ̀fẹ́ láti ṣe tabi sọ, botilẹ jẹ́ pe mo ti pé ọmọ ọdun marùnlélọ́gbọ̀n mi o ṣì lẹ́tọ lati dide lori ẹ̀sẹ̀ mi lòdì sí ǹkan ti àwọn òbí mi ba sọ ""Àwọn obí ni Afrika lo burú jùlọ ni gbogbo àgbàyé."
Gege bi Aare ajo NFF, Amaju Pinnick se so lasiko to n ba awon akoroyin soro nilu Abuja,”Ipade naa ni ireti wa tele pe yoo waye ninu osu kokanla odun 2017 si osu keta odun 2018.
Bí àwọn ará Juda bá tilẹ̀ ṣẹgun gbogbo ọmọ ogun àwọn ará Kalidea, tí wọ́n gbógun tì wọ́n, títí tí ó fi jẹ́ pé àwọn tí wọ́n ti fara gbọgbẹ́ nìkan ni wọ́n kù ninu àgọ́ wọn, wọn yóo dìde sí àwọn ará Juda, wọn yóo sì sun ìlú yìí níná.
Ninu ẹ̀yà Dani, àwọn tí wọ́n tó ẹni ogún ọdún, tí wọ́n tó lọ sójú ogun, gẹ́gẹ́ bí àkọsílẹ̀ wọn ní ìdílé-ìdílé 
Ni ayé òde òni, ọ̀pọ̀lọpọ̀ ọ̀dọ́ má a nkúrò ni ilé lati wá iṣẹ́ lọ si ilú miran.
Esau kan náà ni ń jẹ́ Edomu.
  “O se daradara ninu ifesewonse pelu England, a si n sise si lati tun bo ran lowo si, eleyi ti o sokunfa idi ti a fi ran akonimoomu iko yii lo si Deportivo La Coruna lati lo ran lowo ninu awon kudie-kudie miiran ti o ba ku.
“Omijé yóo máa dà pòròpòrò lójú miláì dáwọ́ dúró, ati láìsinmi.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Àwọn ọ̀nà tí obìnrin fi le gbádùn ìbálòpọ̀ Busayo Akogun Broadcast Journalist, BBC Yoruba 2 Ògún 2018 Oríṣun àwòrán, Laurene Boglio Onimọ kan nipa ibaṣepọ ọkunrin ati obinrin ti jẹ ko di mímọ̀ pé oriṣiriṣi ọna ni obinrin fi le gba ìtura lasiko ibalopọ̀.
O fi da awọn olokow South Africa loju pe ni gbogbo ileeṣẹ wọn ni awọn agbofinro a mojuto ti ilẹ ba ṣe mọ ni ọla ọjọ Aje.
Ẹ o ni le yin in kuro loju fidio to wu ni lori pẹlu ẹkọ ede Yoruba.
"Ìṣòro Nàíjíríà kọjá kí Bobrisky àtàwọn ẹlẹgbẹ́ rẹ̀ dá ní ilé ìgbọ̀nsẹ̀ lọ́tọ̀"" Ìṣòro Nàíjíríà kọjá kí Bobrisky àtàwọn ẹlẹgbẹ́ rẹ̀ dá ní ilé ìgbọ̀nsẹ̀ lọ́tọ̀"" Ìjọba ṣe àdínkù iye asòfin àpapọ̀ kó leè fi €1bn pamọ́ lọ́dún mẹ́wàá Mo gbàgbọ́ pé ọmọ mi kò kú, mo ṣì ń wá a - Bàbá Akẹ́ẹ̀kọ́ fásitì Akungba Ti awọn aṣofin naa ba gba abadofin yii wọlẹ, o tumọ si pe yoo jẹ eewọ fun olukọ Fasiti lati dẹnu ifẹ kọ awọn akẹkọ lorilẹede yii."
Wọn ṣee lati bẹrẹ si ni mọ aisan foniku fọla dide ati idojukọ awọn to n ṣaisan yii lagbaye.
Nigba to n ba BBC Yoruba sọrọ, igbakeji akọwe ipolongo fun ẹgbẹ oselu PDP lorilẹede yii, Ọgbẹni Diran Ọdẹyẹmi ni laipẹ lai jinna ni awọn araalu funra wọn yoo mọ iyatọ laarin akoko ti ẹgbẹ oselu PDP n se akoso ile asofin apapọ ilẹ wa ati akoko ti APC n dari rẹ yii.
10 Agẹmo 2018 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Harry Kane ni ọ̀pọ̀ olólùfẹ́ eré bọ́ọ̀lù lérò pé yóò ''Golden Boot'' ní Russia Idije fun agbabọọlu ti yoo gba ami ẹyẹ fun ẹni to gba bọọlu sawọn ju ''Golden Boot'' ninu idije ife ẹyẹ agbaye ti gbona sii bayii bi idije naa ti wọ ipele to kangun si aṣekagba.
Awọn gende agbebọn kan ti kọlu Kọmiṣọ́nna fọrọ ilẹ ati ilegbe nipinlẹ Ọyọ, Amofin Abdulraheem Abiodun lalẹ Ọjọru ana.
jegbadun eto alaafia, aabo, aseyori, idagbasoke ohun amayederun, orile ede ti a
Lojoojumọ ni kí o máa fi akọ mààlúù kọ̀ọ̀kan, rú ẹbọ ìmúkúrò ẹ̀ṣẹ̀, gẹ́gẹ́ bí ètùtù.
Àwọn eniyan ìyá rẹ̀ bá sọ gbogbo ọ̀rọ̀ yìí ní etígbọ̀ọ́ gbogbo àwọn ará ìlú Ṣekemu, wọn sì gbà láti tẹ̀lé Abimeleki tayọ̀tayọ̀.
sibẹsibẹ ọrùn rẹ̀ kò mì,apá rẹ̀ sì ń lágbára sí i.
“OLUWA àwọn ọmọ ogun, Ọlọrun Israẹli ní òun ti ṣẹ́ àjàgà ọba Babiloni.
Gẹ́gẹ́ bí ẹgbẹ́ ajìjàǹgbara àgbáyé tí ọ̀rán kàn, a tọrọ ìdánilójú ìjọba Myanmar láti ríi dájú wípé Abala 66 (d), tí ó yẹ kí ó sún ìtẹ̀síwájú ẹ̀rọ ayárabíàṣá síwájú, tí kò ní jẹ́ lílò fún ìpalẹ̀mọ́ ọmọ ìlúu Myanmar tí ó fẹ́ sọ èròo ọkàn-an wọn àti lọ́wọ́ sí ètò ìṣèlú ìjọba àwa-arawa ní Myanmar.
Ọkùnrin náà tálákà púpọ̀ ó sí ní ìyàwó kan.
Ẹka NOUN kan wa ni inu ọgba ẹwọn Kirikiri.
O sọ ọrọ yii lasiko ti gomina ipinlẹ Katsina, Aminu Masari tẹwọgba wọn lẹyin ti wọn gba ominira.
Lẹ́yìn tí wọ́n ti rìn fún ọjọ́ meje, kò sí omi mímu mọ́ fún wọn ati fún àwọn ẹranko tí wọ́n ru ẹrù wọn.
OLUWA wí pé: “Bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé àwọn ará Siria lágbára, tí wọ́n sì pọ̀, a óo pa wọ́n run, wọn yóo sì parẹ́.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Wọ́n fi agídí sé ọmọ Naijiria mọ́lé ní China nítorí àrùn Coronavirus Lọdun 2002, wọn yan-an gẹgẹ bi oludari igbimọ alakoso fun ileeṣẹ aladani Unilever Nigeria, ko tun to o darapọ mọ igbimọ alakoso ileeṣẹ eporọbi Exxon Mobile Nigeria.
Ìlù bàtá lo ń jó, wọ́n bẹ̀rẹ̀ síío lu ìlù báyìí, ‘Wèrádìran, ó jẹ gọngọ gbèsè, gbèsè, o jẹ gongo; nítorí wúndíá ó jẹ gọngọ gbèsè, ó jẹ gọngọ; nítorí adéblébọ̀, ó jẹ gọngọ gbèsè, gbèsè, o jẹ gongo; nítorí afẹ́ ayé ó jẹ gọngọ gbèsè, gbèsè, o jẹ gongo; nítorí àìnírònú ó jẹ gọngọ gbèsè, gbèsè, o jẹ gongo; nítorí fáàrí, ó jẹ gọngọ gbèsè, gbèsè, o jẹ gongo abbl.
Gbogbo àwọn ríkèé ríkèé ara rẹ ní àlẹékún agogo tí agogo ńlá inú ọpọlọ máa ń mójú tó.
Akọsilẹ sọ fun wa pe iwaju ile ẹjọ ti Morohunfolu ti lọ gba ẹjọ ro, ni wọn ti yin ìbọn fun, ti Oyinkan si di opo ọsan gangan.
Credit Joshua Akinyemi Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Tí iye iná tí ẹ rí gbà bá kéré ju owó tí ẹ rà á lọ, ẹ ti jẹ gbèsè tẹ́lẹ̀ ni - Iléeṣẹ́ apínnáká Ẹ gbọ́ Ohun tí Desmond Elliot àti Mojisola Alli-Macaulay sọ lórí ayélujára táwọn ọmọ Nàìjíríà fi ìbínú Mo pinu láti dá Iphone tì mo mú padà kí ọlọ́pàá tó mú mi Àwọn olóṣèlú Nàìjíríà márùn ùn tó sọ̀rọ̀ tí ará ìlú fà ìbínú yọ Gómìnà Seyi Makinde fẹ́ kó bọ́ọ̀sì elérò ọgọ́rùn-ún bóòde láti máa ná Ibadan sí ìpínlẹ̀ míì Oríṣun àwòrán, Seyi Makinde Ijọba ipinlẹ Oyọ ti ni awọn yoo lo ọkọ tuntun to le lọgọrun naa lati fi maa na gbogbo awọn ipinlẹ to wọ ipinlẹ Oyo.
Ni bayii, wọn ti ṣi ọna silẹ fun awọn eniyan lati kọja, amọ sunkẹrẹ fakẹrẹ wa diẹ ni opopona naa.
Lori amohunmaworan ileesẹ kan l'abẹle, lo ti sọ bẹ ẹ, nitori bi iroyin ṣe n lọ kaakiri pe awọn sọja n pa araalu nijọba ibilẹ Oyigbo, ti gomina kede àṣẹ konile-o-gbele fun, lati ọjọ mejila sẹyin.
Ẹyọ ẹnìkan wọn kò sì sùn,bẹ́ẹ̀ ni wọn kò tòògbé.
Obìnrin kan pa ara rẹ̀ nítorí pé ọ̀kọ̀ rẹ ń dẹ́yẹ síi pé o dúdú jù Irú kí lèyì?
Bí baba rẹ̀ kò bá ní arakunrin, ẹ fi ilẹ̀ ìní rẹ̀ fún ìbátan rẹ̀ tí ó bá súnmọ́ ọn jùlọ ninu ìdílé rẹ̀.
Àwọn eniyan yóo wí nígbà náà pé,“Nítòótọ́, èrè ń bẹ fún olódodo;nítòótọ́, Ọlọrun ń bẹ tí ń ṣe ìdájọ́ ayé.
Buhari borí ìdìbò abẹ́lẹ́ fun ìdíje ààrẹ̀ lẹgbe APC Ìgbésẹ̀ ìdìbò abẹ́lẹ́ ti bẹ̀rẹ̀ nínú ẹgbẹ́ òṣelu All Progressives Congress ki wọn fi yan awọn oludije ọmọ ẹgbẹ fun ipo gomina àti aarẹ fun idibo 2019.
O fikun wi pe ahesọ ni gbogbo ohun ti awọn eniyan n sọ wi pe nitori Omisore se iranwọ fun ẹgbẹ Oselu APC ni ẹkun idibo Guusu Ile-Ife ati ijọba ibilẹ Ariwa ipinlẹ Ọsun.
“Ìwọ ọmọ eniyan, pa àlọ́ kan kí o sì fi òwe bá àwọn ọmọ Israẹli sọ̀rọ̀.
"Rosie Campbell, oludari Global Institute for Women's Leadership to wa ni fasiti Kings College ni London sọ pe ''ko si ọkunrin tabi obinrin ti wọn bi isejọba mọ'' ''Sugbọn bi awujọ ti se re wa, ohun to seese ni ki awọn obinrin to jẹ olori ni oju anu ju awọn ọkunrin lọ'; Ipenija to wa ninu ka maa se oselu ọkunrin lo lagbara"" Awọn ọkunrin adari oriẹ-ede n kọ?"
Sọ fún wọn pé, ‘Ṣé ẹ sọ pé ẹrù wúwo ni baba mi dì rù yín?
93% Atunse oju ọna ati lila awọn opopona tuntun si ni yoo ko ọpọ owo isuna ti wọn bu fun ẹka naa lọ , ti biliọnu marundinlogoji ati diẹ, N35.
Ọkùnrin kan tún pa ọmọ rẹ méjì àti ìyá tó bíi Ọ̀rọ̀ Soyinka àti Obasanjo papọ̀ lórí pé Buhari n ṣe ìpínyà Nàìjíríà Iléèwé míràn tún dàwó ní ìpínlẹ̀ Eko Ilé ìjọsìn lè bẹ̀rẹ̀ ìsìn àárín ọ̀sẹ̀ padà, Mọ́sáláṣí àti Ṣọ́ọ̀ṣì lé gba iye èèyàn tó wù wọ́n ṣùgbọ́n.
Ẹni to jẹ pe dipo ki o dá ẹṣẹ, ki ẹri ọkan o le ma a jẹ awọn eeyan, o kuku fi aaye gba titẹ ifẹ ara ẹni lọrun.
 abdullah ti fe rania niyawo lati 1993 .
Ootọ eleyi lasan lee jẹ ki awọn eeyan gba iroyin naa gbọ.
Iyaafin Dabri tun tesiwaju pe” adanu ni iku Badru je fun awon obi re, nitori pe oun nikan ni omo ti iya re bi”.
Ile –ise olopaa wa dupẹ lowo
Ènìyàn 33,616 ló ti lùgbàdì ààrùn Coronavirus ní àpapọ̀ ní Nàíjíríà Bí ẹgbẹ́ One Million Boys ṣe bẹ̀rẹ̀ rèé àti ọṣẹ́ tó ṣe n'Ibadan Ǹjẹ́ o mọ̀ pé irú àwọn ìnàkí yìí wà ní Nàíjíríà?
” Ó fẹ́ fi ọgbọ́n yọ ọ́ lọ́wọ́ wọn, kí ó lè fi í ranṣẹ sí baba wọn pada.
Alaga egbe APC , Adams Oshiomhole ati akowe agba fun ijọba apapọ, Boss Mustapha,wa nibi ipade naa.
Bí ó tilẹ̀ pupa bí aṣọ àlàárì,yóo di funfun bí irun ọmọ aguntan funfun.
Àwọn àgbààgbà mú òkúta onikisi wá ati òkúta tí wọn yóo tò sí ara efodu ati sí ara aṣọ ìgbàyà, 
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo Ki lo maa n fa Akufa?
Fulani nìkan kọ́ ló ń pa ènìyàn ní Naijiria -Tinubu Oun pẹlu igbakeji rẹ, Patrick Kluivert ni wọn jijọ n fi ipo silẹ bayii.
Nígbà tí ó jẹ́ pé, à ń kéde pé Kristi jinde kúrò ninu òkú, báwo ni àwọn kan ninu yín ṣe wá ń wí pé kò sí ajinde òkú?
Wòlíì Kasali ní Dolapo Awosika kò lé ìyàwó òun jáde Ìtàn ayé Taiwo Oredein rèé, àgbà òṣèlú tó parí ayé rẹ̀ sọ́gbà ẹ̀wọ̀n Ìtàn ìgbé ayé Bode Thomas rèé, ó kọ́ wa láti máa kó ẹnu wa ní ìjánu Ere yii maa n jẹ ki ọpọlọ ọmọde ati agba to n ta ji pepe, o n dani laraya, mu ki ifẹ wa, ti yoo si tun fikun imọ isiro awọn to ba n taa.
Bí ó bá jẹ́ pé nítorí ohun tí ó ṣe ni Ọlọrun fi dá a láre, ìwọ̀nba ni ohun tí ó lè fi ṣe ìgbéraga.
Minista ṣalye pe lọwọlọwọ yii, awọn mọkanlelogun ni wọn ti ya sọtọ niyara ifinipamọsi kaakiri ipinlẹ mẹrin ti wọn ti furasi iṣẹlẹ ọhun.
O ni akoko ninu ise akanse naa ni eyi ti won yoo jo se papo pelu ile ise ijoba apapo to n pese omi nipa sise agbekale ona omi igbalode fi won oko ni Ikenne ati ni Ijebu ode to je ibudo eto ogbin gboogi.
Mọ̀ síi nípa Oyedele Adedokun tó ya àwòràn Donald Trump tó lu ayélujára pa
Esi iwadii Africa Eye ló jẹ ki gbogbo agbaye dide si iranlọwọ Cameroon lati gbogun ti awọn agbesunmọmi atawọn oniṣẹ ibi.
Ipese ina mọna-mọna Ileri: Iṣakoso ẹgbẹ oṣelu APC yoo ri daju pe ipese ina mọna-mọna dara si ti yoo to ogoji ẹgbẹrun laarin ọdun mẹẹrin si mẹjọ.
Ṣugbọn mo tún ń ranti nǹkankan,mo sì ní ìrètí.
Wo ohun tí Adájọ́ ṣe sí àṣùwọ̀n ìfowópamọ́sí Wòlíì Sotitobire Afárá Third mainland gba ẹ̀gbọ́n Obasanjọ dúró lórí ọ̀rọ̀ tó sọ lẹ́yìn ikú Kashamu- Kehinde Akinyemi Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Working religious women: Ẹ̀lẹ́hàá kìí ṣe ọ̀lẹ- Aminat Adegoke Lilo sọ òtítọ́ fún Ebuka lórí ìbáṣepọ̀ òun àti Eric: Ọkan lara awọn olukopa ninu idije BBNaija 2020, Boluwatife Aderogba, ti ọpọ eeyan mọ si Lilo ti sọ pe oun kabamọ ibaṣepọ oun ati Eric lori eto agbelewo naa.
igbamu ti omo odun metalelogbon, Wilder koko naa lo japa Breazeale wale ti ko
Lara awọn ti o daju fun tita ati rira ni awọn wọnyi: Arsenal - Pierre-Emerick Aubameyang: Àkọlé àwòrán, Adehun pẹlu Olivier Giroud ati Michy Batshuayi se koko fun Aubameyang Ẹgbẹ agbabọọlu Arsenal ti fun Borussia Dortmund pari ọrọ pẹlu Pierre-Emerick Aubameyang sugbọn ọrọ lilọ rẹ da le lori Olivier Giroud ati Michy Batshuayi ti Dortmund.
O fikun ọrọ rẹ pe dandan ni ọjọ karun-un, oṣu Kẹsan ti wọm kede.
Ilé ìsìn nlá kan wà láarin abúlé gangan.
Okunrin kan kú lójijì lẹ̀yin ọjọ̀ díẹ̀ to jẹ milionu kan dọ́là Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Usaya, ará Aṣiteratu, Ṣama, ati Jeieli, àwọn ọmọ Hotamu, ará Aroeri, 
 Ati pe a fi n ta awon eniyan ji lati tete lo gba kaadi idibo won ki won si jade wa dije tabi dibo bi emi ba se dari won.
Nítorí èyí ni mo ṣe ń fi ìkúnlẹ̀ gbadura sí Baba, 
Aliko Dangote to ni ile iṣẹ orisiriṣi sọ pe ''nigba ewe,miliọnu akọkọ to ba ni yoo ma jọ ọ loju.
 Amosa , won ko kede asiko ti
Ní ọjọ́ kinni oṣù kejila, ọdún kejila tí a ti wà ní ìgbèkùn, OLUWA bá mi sọ̀rọ̀.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Oba Adedokun Abolarin ti Oke Ila: Ó ya ọ̀pọ̀ tó súnmọ́ mi lẹ́nu bí mo ṣe ń kọ́ Lowurọ oni ti i ṣe ọjọ Kẹrindinlọgbọn, oṣu Kọkanla, oju opo ayelujara Twitter gbọn akanti rẹ yọ kuro loju opo wọn tori o tako ilana Twitter ati Instagram.
Nígbà tí ó di àfẹ̀mọ́júmọ́, Samuẹli pe Saulu lórí òrùlé, ó ní, “Dìde kí n sìn ọ́ sọ́nà.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Dókítà Òbílàdé: Ẹni tó bá lo Tramadol lálòjù leè sùn, kó má jí mọ́ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Dókítà Òbílàdé: Ẹni tó bá lo Tramadol lálòjù leè sùn, kó má jí mọ́ 11 Ògún 2018 Ninu ifọrọwerọ pẹlu Onisegun Oyinbo kan pẹlu BBC Yoruba, Dokita, Kunle Obilade ni iwọnba oogun Tramadol lee din ara riro ku, amọ aloju rẹ lewu pupọ.
O ní ìdí ti èyí kò fi wáye ní ọdún tó kọja ní pé ìjọba kò ti rí àrídájú bóyá àjọ náà yóò le ṣe ojúṣe wọn ti ìgbéṣẹ̀ náà bá wáyé.
Agbẹnusọ fun ile iṣẹ ọlọpaa nipinlẹ Eko Bala Elkana sọ pe awọn yoo iwadii lori iṣẹlẹ ọhun.
Lorim ọrọ obu irẹsi to n fa awuyewuye laarin ijọba ipinlẹ Ọyọ ati ijọba apapọ nipasẹ ileeṣẹ wọlewọde ilẹẹwa lọwọlọwọ, gomina ipinlẹ Ọyọ ni kokoro lo bo awọn ẹgbẹsan apo irẹsi ti wọn gbe fun wọn ati pe nigba ti ọrọ ti ri bo ṣe ri, o di dandan ko oun jabọ bi ọrọ ṣe jẹ fawọn eeyan ipinlẹ Ọyọ.
“A ti gbọ́ igbe ìdágìrì ati ti ẹ̀rù,kò sì sí alaafia.
 níbi tí orísirísi ọgbọ ́ n bá ti parapọ ̀ , ìlọsíwájú kò ní jìnnà si irú agbègbè bẹ ́ ẹ ̀ .
Ẹni tí ó bá ṣẹgun, tí ó forí tì í, tí ó ń ṣe iṣẹ́ mi títí dé òpin, òun ni n óo fún ní àṣẹ lórí àwọn orílẹ̀-èdè, ọ̀pá irin ni yóo fi jọba lórí wọn, bí ìkòkò amọ̀ ni yóo fọ́ wọn túútúú.
Fan Zhendong omo orile-ede China dipo kinni mu lagbaye fun atejade  ipo ate osu merin otooto lera won bayii.
Ninu awọn ere bọọlu mii to wa lonii, France yoo waako pẹlu Norway to ṣeya fun Naijiria.
Orílẹ̀-èdè Chad pé ọgọ́ta ọdún, àwọn ara ìlú ń pariwo lábẹ́ Aàrẹ Deby tó gba 'Field Marshal' Ìyàwó Bukola Saraki fún tìyá-tọmọ olójú búlúù ní N250, 000!
ero náà ko yí dáádáa .
Oríṣun àwòrán, Getty Images Láì dénà pẹnu àwọn tó n tọ́jú àwọn alárùn yìí ló léwu fún jù.
yóo tù yín ninu, yóo fi ẹsẹ̀ yín múlẹ̀ ninu oríṣìíríṣìí iṣẹ́ ati ọ̀rọ̀ rere.
Ayọ̀ ń bẹ fún ẹni náà,tí ó gbẹ́kẹ̀ rẹ̀ lé OLUWA,tí kò bá àwọn onigbeeraga rìn,àwọn tí wọn ti ṣìnà lọ sọ́dọ̀ àwọn oriṣa.
Lara eto yi lo sọ pe awọn yoo ti sọ agadagodo pa si awọn ibudo ere idaraya to fi mọ ibudo iko nkan iṣẹmbaye lariwa orileede naa.
Risikat olójú búlù dí aya Wasiu ní ìlànà Islam, tẹbí tará péjú síbẹ̀ Aàrẹ Marcelo Rebelo de Sousa ẹni ọdùn 71 bẹ́ sómi láti dóòlà obìnrin méjì tó fẹ́ rì sómi Ó ń bọ̀ lọ́nà!
Ó bẹ̀rẹ̀ sí kọ́ ilé náà ní ọjọ́ keji oṣù keji ọdún kẹrin ìjọba rẹ̀.
Iwadii fi han pe awọn ọmọbinrin to wa lagbaye le diẹ ni biliọnu kan.
" Àkọlé àwòrán, Esther ni awọn ti ko ba le fi igbeyawo naa silẹ gbọdọ wa ọna lati laa kọja O ti to ọdun diẹ bayii ti Esther ti fi ọkọ rẹ silẹ, bo tilẹ jẹ pe ko rọrun, ṣugbọn igboya lo fi gbe igbesẹ to gbe.
Ijọba ipinlẹ Eko lo kede igbesẹ naa loju opo Facebook rẹ.
 awon iwe kiko re da le lori ituyewo asa ati isolori oloselu .
Kí ni àwọn ẹ̀ṣẹ̀ àti ẹ̀sùn tó ń da Oshiomole láàmú?
O fi ìwà àjẹ́ tan gbogbo orílẹ̀-èdè jẹ.
Wọ́n sì da òrùka wúrà meji mìíràn, wọ́n dè wọ́n mọ́ ìsàlẹ̀ èjìká efodu náà níwájú, lókè ibi tí ó ti so pọ̀ mọ́ àmùrè rẹ̀.
Ọgọrun-un ọ̀dọ́ akọ mààlúù, igba (200) àgbò, ati irinwo (400) ọ̀dọ́ aguntan ni wọ́n fi rú ẹbọ ìyàsímímọ́ náà.
Gege bi ajo naa pe, o le ni ogorun milionu awon eniyan kaakiri lagbaye, ti won si n gbe igbe aye osi, toripe, won niloo lati sanwo fun itoju ilera ara won.
Ọrọ yii n ja ranyin nilẹ to n bi oriṣiiriṣii nkan lori ayelujara.
Gbogbọ igbiyanju Valencia lati ta ọmi ninu ere bọọlu ọhun, ja si ayọ nigba ti Daniel Wass tayo naa fi di 2-2.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Kòkòrò ajokorun da ìpòruru sí ọkan àwọn àgbẹ̀ Nàìjíríà 27 Èbibi 2018 Àkọlé àwòrán, Kòkòrò ajokorun le sọ àgbẹ̀ di ẹdun arinle toba ya wọ oko.
Kabiyesi ni inu maa n bi awọn eniyan pe oun n ṣakọ, o ni ṣe bi iwọ ba jọba oo ni ṣakọ?"
 Won wa n pe ijoba orile ede Kenya lati  seto ofin ti yoo  mojuto  oro wiwa gusa  ati eto aabo to peye fun awon to n wa gusa lorile ede  yii.
Ṣugbọn n óo fi Ijipti lé aláìláàánú akóniṣiṣẹ́ kan lọ́wọ́ìkà kan ni yóo sì jọba lé wọn lórí,bẹ́ẹ̀ ni Oluwa, OLUWA àwọn ọmọ ogun wí.
Kọmisọnna Ọlọpaa ni ipinlẹ Eko, Edgal Imohimi, dupẹ lọwọ awọn ara ilu fun suuru wọn ati wi pe wọn yoo gbe ọmọ ọdọ naa lo si ile ẹjọ laipẹ.
"Ọjọ mọkanlelogun ni awọn ẹsọ Amotekun yoo fi gba idanilẹkọ amọ loore koore la maa se idanilẹkọ fun wọn lori eto aabo.
Atẹjade kan ti ileesẹ ologun ilẹ wa fisita ni ẹkọ wọn se ajeji, ti awọn si ti n sọ wọn tọwọ-tẹsẹ, ki iwa wọn to bọwọ sori.
Baba Fadeyi Oloro gba alejo BBC Yoruba nile rẹ.
Ẹ ti ń sáré ìje dáradára bọ̀.
Ṣugbọn ẹ̀rù rẹ̀ ń bà wọ́n; wọn kò gbàgbọ́ pé ó ti di ọmọ-ẹ̀yìn Jesu.
A kò ní fi àwọn ọmọ wa obinrin fún àwọn ọmọ àwọn àlejò tí ń gbé ilẹ̀ wa, bẹ́ẹ̀ ni a kò ní fẹ́ àwọn ọmọbinrin wọn fún àwọn ọmọ wa.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Amọ ko si ohun to tẹyin iwadii naa bọ to loju tu.
( 5ii ) Òrò-ìse Àsínpò : lóòótó àwon tètèdé onígíràmà ti máa ń fún gbólóhùn abódé ní oríkì pé òun ni àkójopò òrò tí ó òrò-ìse kan nínú .
Iyiosa gba pe iwa yii ko ṣẹṣẹ bẹrẹ bikoṣe pe ki onikaluku ṣetan lati fopin sii bayii: Eghosa naa sọrọ lori iriri rẹ lọdun 2015 ni fasiti Eko bi olukọ kan ṣe féèlì akẹkọọ kan lẹẹmeji nitori pe o fẹ baa sun pe idajọ Olorun lo de loju rẹ: Khadijah, obìnrin àkọ́kọ́ tó dẹnu ìfẹ́ kọ àyànfẹ́ rẹ̀ Ìpínlẹ̀ Ekiti ló bàjẹ́ jùlọ ní Naijiria- Afe Babalola Àwọn ọmọ Naijiria yarí lórí ọ̀rọ̀ owó 'tollgate' tí ìjọba kéde rẹ̀ South Africa: Báwo ni ìkọlù sáwọn àjèjì ṣe wọ́pọ̀ tó?
Iwe ipe awọn ọlọpaa yii, ti igbakeji Kọmisọna ọlọpaa lolu ileesẹ ọlọpaa ilẹ wa nilu Abuja, Kolo Yusuf fọwọsi, lo pasẹ fun tọkọtaya naa lati yọju si wọn lọjọ Iṣẹgun to n bọ, eyiun ọjọ Kẹtalelogun osu Keje ọdun 2019.
Wọ́n bá kó àwọn arakunrin wọn jọ, wọ́n sì ya ara wọn sí mímọ́.
Odunlada Adekola: Ijo ni Odunlade Adekola fi bẹ ni tiẹ ninu fidio kan to fi soju opo Instagram rẹ.
Ni Naijiria, ọkunrin lo nse eto akoso ju.
Àwọn to fẹ ẹ to miliọnu kan ati ẹgbẹrun lọna igba lo si ti kú.
Dokita Onu se lalaye pe, ”Sise amulo kemika epo robi yoo tun mu igberu ba ile-ise to n mojuto oro kemika.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Lateef Adedimeji: Owó wa kò bá máa jóná ṣùgbọ́n aàyè ọpẹ́ ń yọ fún wa Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
’ OLUWA bá bèèrè pé, ‘Ọgbọ́n wo ni o fẹ́ dá?
Koda Olori Memuna Adeyẹmi funrarẹ sọ eyi gẹgẹ bi ara ọrọ imoore to kọ ṣọwọ si alaafin loju opo Instagram rẹ.
Bayii, ọpọ awọn ọmọ ẹgbẹ oṣelu Conservative ni mo fẹ kuro ni Brexit laijẹ pe erongba wọn wa si imuṣẹ.
Ó dá mi lójú pé bí mo bá ń yọ̀, inú gbogbo yín ni yóo máa dùn.
Ọmọ ọmọ ni adé arúgbó,òbí sì ni ògo àwọn ọmọ.
Ewe, lataari awon esi ifesewonse olojore pelu iko agbaboolu Seychelles ati Egypt, ti iko Super Eagles jawe olubori ninu re, eyi sokunfa idi ti won fi leto lati wa soke dipo keta mu lori tabili naa.
Aworan ìsàlẹ̀ yii se afiwe asiko ti yoo gba lati lọ lati ibi kan si omiran laarin ilu si igba ti ko si lílọ bibọ.
Eko -397 FCT-357 Kaduna-81 Plateau-63 Katsina-46 Sokoto-32 Oyo-28 Ogun-21 Kano-19 Rivers-18 Osun-13 Edo-12 Niger-12 Bayelsa-11 Borno-11 Bauchi-8 Jigawa-2 Ondo-2 Èèyàn mẹ́rin kú, 999 tuntun míràn tún lùgbàdì Covid-19 ní Naijiria Ajọ to n gbogun ti ajakalẹ aarun ni Naijiria, NCDC, ti kede pe eeyan 999 miran ti kun iye awọn to ti ni aarun COVID-19 ni Naijiria.
Oríṣun àwòrán, @ericotrips Oṣu mẹta to tẹle eyi yoo wa fun atunṣe ọna to lọ si Lagos Island lori afara naa.
Ṣugbọn ko darukọ awọn ipinlẹ naa.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ondo disability: Kò sí ẹni tí àkàndá kò lè ya ilé rẹ̀- Ayọdele Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Owo osu ọna meji ko lẹtọ 'Ọkọ mi yọ kindinrin mi lati rọpo owo ori' Iya ọmọ yii ṣalaye pe o ti ṣe diẹ ti ọmọ oun ti n ni arun ọpọlọ to ti n farahan diẹdiẹ sẹyin.
Nigba to n ba ikọ iroyin BBC sọrọ, ọkan ninu awọn akẹkọ ileẹkọ naa, to fi orukọ bo ara rẹ ni asiri, fidi rẹ mulẹ pe ọrọ kan tawọn akẹkọ kan n fi ransẹ loju opo ikansiraẹni instagram eyi tawọn akẹkọ musulumi ri bi eyi to n tabuku Anọbi Muhammed lo sokunfa aawọ naa.
Lọ sí ojú òpò website https://9mobile.
Òwe Yorùbá ni “Ọbẹ̀ tó dànù, òfò onilé, òfò àlejò” Àpẹrẹ pataki ni ọna àti ilé-iwosan ti ó bàjẹ́.
’ rèé Afọnja, ẹni tó finú wénú ní Ilọrin, àmọ́ tó jẹ iwọ Iya Gold jẹ ko ye wa pe, ohun to n kọ oun lominu ni idi to fi jẹ pe ọmọ toun lo di awati, laarin awọn ọmọ to pọ ti wọn fẹrẹ to igba lọwọ awọn olukọ ọmọde ijọ naa.
Yàrá kan wà ní ẹnu ọ̀nà àbáwọlé tí ìbú rẹ̀ jẹ́ ogún igbọnwọ (mita 9).
Ó fi wọ́n lé àwọn orílẹ̀-èdè mìíràn lọ́wọ́,títí tí àwọn tí ó kórìíra wọn fi jọba lé wọn lórí.
'A sọ fún ọlọ́kadà pé omi kún, omi kún, ṣùgbọ́n ó kọ etí ikún' #Adewura Ni ifesi, alaga ajọ CCB naa ti gboriyin fun aarẹ pe o jẹ ẹṣin iwaju ti tẹyin n wo sare pẹlu bi o ṣe kede dukia rẹ ni ilana to ba ofin mu.
Wo àwọn ìlérí tàwọn Gómìnà tuntun ṣe nínú ìbúra wọn Dapọ Abiọdun ree, ẹni tó dépò gómìnà ní àyájọ́ ọjọ́ ìbí rẹ̀ Rochas Okorocha, káàbọ̀ sí àwùjọ àwọn gómìnà tí EFCC ń wá - Fayose Ará ìlú dájọ́ oró fún ọkùnrin to bẹ́ orí ẹ̀gbọ́n rẹ̀ ní Cross River Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Tí ó bá di ìgbà náà, obinrin meje yóo rọ̀ mọ́ ọkunrin kan ṣoṣo, wọn óo máa bẹ̀ ẹ́ pé, “A óo máa bọ́ ara wa, a óo sì máa dá aṣọ sí ara wa lọ́rùn.
Gomina El-Rufai dupẹ lọwọ Malam Sambo fun bi o ti gba pe ki Sanusi di alakoso igbimọ alaṣẹ fasiti ipinlẹ Kaduna tuntun ọhun.
ó bẹ̀rẹ̀ sí fọ́nnu fún wọn bí ọrọ̀ rẹ̀ ti pọ̀ tó, iye àwọn ọmọ rẹ̀, bí ọba ṣe gbé e ga ju gbogbo àwọn ìjòyè ati àwọn olórí yòókù lọ.
Àgọ́ yìí sì wà pẹlu wa títí di àkókò Dafidi.
Kò séwu nínú ìdìbò tó ń bọ̀ l'Ondo àfi gìrì àparò- Akeredolu APC kò ni ṣe ìdìbò nípínlẹ̀ Ondo ti ìgbìmọ̀ bá yọ mi kúrò nínú ìdíje- Segun Abraham Ninu ọrọ ti Eyitayo Jeged sọ fun BBC Yoruba, o ni awọn ti gba iyọnada ṣaaju lọdọ ọlọpaa ki awọn to bẹrẹ ipolongo.
Gbọ́ igbe kan ní Horonaimu,igbe ìsọdahoro ati ìparun ńlá!
Ṣebí nítorí Rakẹli ni mo fi sìn ọ́?
Ṣebí mo lè wẹ̀ ninu wọn kí n sì mọ́!
Ọpọ igba lorukọ rẹ ti jade pẹlu eebu to pọ lori ẹrọ ayelujara lori ọrọ ẹnu rẹ.
Oríṣun àwòrán, Instagram/official_MajekFashek Bakan naa lo sọ pe awọn ẹbi ko tii mu ọjọ isinku fun Majek.
igi Sipirẹsi ni yóo máa hù dípò igi ẹlẹ́gùn-ún,igi Mitili ni yóo sì máa hù dípò ẹ̀gún ọ̀gàn,yóo jẹ́ àmì ìrántí fún OLUWA,ati àpẹẹrẹ ayérayé tí a kò ní parẹ́.
Ounjẹ alẹ́ fùn idupẹ lọdọọdun ni America, Kini o tumọ si?
Wayi o, WCS ni iṣẹ ti bẹrẹ pẹlu ajọṣepọ ijọba Naijiria atawọn ti ọrọ kan, lati daabo bo awọn ẹranko ọhun.
0 19 Erekusu Falkland Island 0 0.
Oríṣun àwòrán, Reuters Àkọlé àwòrán, Ààrẹ Trump tapa si àbájáde ìpàdé G7 Trump fí ọrọ̀ ìyípadà náà lédè lójú òpó Twitter pẹlú àlàyé pé àwọn orílè-èdè tó kù n fí owo orí ọjà tó ga lè Amẹrika.
O hande pe lati ibẹrẹ idije naa ni Liverpool ti n sa gbogbo ipá wọn lai ṣaarẹ pe ki ipinnu gbigba ẹyẹ Premiere League lè ṣẹ.
Isede yoo maa wa lati aago mẹjọ alẹ si mẹfa idaji.
Lẹ́hìn èyí ni igi tèmi tún wáá lọ foríbalẹ̀ lẹ́ẹ̀kejì, bí orí rẹ̀ sì ti balẹ̀ báyìí, mo bẹ́l sílẹ̀ kí ó tóó tún dìde.
Lara awọn akẹkọọ to wa ni kilaasi baba Aderibigbe lọdun naa lọhun ni Oluwaseyi Abiodun Makinde, ẹni to di gomina ipinlẹ Oyo lonii.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Wọn ti ju ọkunrin kan si ẹwọn ọdun mẹẹdogun Awọn alaṣẹ ijọba Naijiria ni awọn afurasi ọmọ ẹgbẹ Boko Haram to le ni ẹgbẹrun mẹfa lo wa ni ahamọ jakejado orileede Naijiria.
“Ẹ kò gbọdọ̀ máa wo kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ tabi akọ mààlúù arakunrin yín, tí ó wó lulẹ̀ lẹ́bàá ọ̀nà, kí ẹ sì mójú kúrò bí ẹni pé ẹ kò rí i.
6 miliọnu lati ṣatunṣe ibudo itọju ajakalẹ arun to wa ni Olodo.
Aago mejila ọsan ọjọ Aiku, ọjọ kejidinlọgbọn, oṣu kẹfa, ọdun 2020 ni eto isinku Sẹnetọ Abiola Ajimobi yoo waye.
NNPC kéde Mele Kyari gẹ́gẹ́ bí aṣojú Nàìjíríà tuntun l'ájọ OPEC Ajọ elepo rọbi lorilẹ-ede Naijiria, NNPC ti kede yiyan Mallam Mele Kyari gẹgẹ bii aṣoju tuntun fun orilẹ-ede Naijiria ni ajọ awọn orilẹede to n wa epo rọbi lagbaye, OPEC.
Eliṣa bá sọ fún un pé kí ó mú ọrun ati ọfà, ó sì mú wọn.
TÍ Ó NÍ ÀWỌN ÌFIHÀN TÍ A FIFÚN JOSEPH SMITH, WÒLÍÌ NÁÀ
Ṣugbọn bí olúwarẹ̀ kò bá mọ̀ọ́nmọ̀ pa á, tí ó jẹ́ pé ó ṣèèṣì ni, irú ẹni bẹ́ẹ̀ lè sálọ sí ibìkan tí n óo yàn fún yín.
Oríṣun àwòrán, Instagram/KolawoleAjeyemi Ọkọ Toyin, ẹni to sọrọ naa loju opo Instagram rẹ, @kolawoleajeyemi ni ṣe irora, omije ati ọpọ nkan miran ti ko see sọ, ti aya oun la kọja nigba to fẹ bi ọmọ ti Ọlọrun fi tawọn lọrẹ ni k'oun sọ ni, o ni ẹnu oun ko le sọọ tan.
Iwe iroyin olojojumo ThisDay ti o fi ilu Eko se ibujokoo so pe, ile-ise Telelogy Holding ati ile-ise Smile Communications ti o fi orile-ede South Africa se ibujokoo  ni awon ile-ise meji ti o ku ti won n fi iga gbaga lati ra ile-ise naa.
Isaaki jẹ́ ẹni ọgọsan-an (180) ọdún nígbà tí ó kú.
Idajọ ile ẹjọ kotẹmilọrun yii ni yoo si sọ boya Adeleke yoo ko lọ ile ijọba tabi idakeji rẹ.
Ó pín ilẹ̀ wọn fún àwọn eniyan rẹ̀,nítorí pé ìfẹ́ rẹ̀ tí kì í yẹ̀ wà títí lae;
Ninu aayan wa lọsẹ yii lati mọ bi awọn ọmọ Kaarọ Oojire ti gbọ Yoruba si, a ni ki wọn fi ami si ori iro ọrọ ‘Irokotọla', sugbọn ẹnu ko gba iroyin.
lati  dipo isejoba mu lorile ede yii.
Ẹ óo máa jẹun, ṣugbọn ẹ kò ní yó; Ẹ óo máa ṣe àgbèrè ẹ̀sìn, ṣugbọn ẹ kò ní pọ̀ sí i; nítorí ẹ ti kọ èmi Ọlọrun sílẹ̀ ẹ sì yipada sí ìwà ìbọkúbọ.
Loju opo Twitter, awọn ẹbi rẹ, ara ati ọrẹ ko ye se idaro rẹ, ti awọn kan si n beere wipe ṣe ki ṣe pe aye ti gbagbe ilumọọka akọrin yii?
Tí kì í jẹ́ kórí ìlemèrè ó bàjẹ́.
ajọ NCDC, mọkanla ninu awọn ijọba ibilẹ mejidinlogun ta n wi yii ti wọn ti n ko arun Coronavirus ju si lo wa ni ipinlẹ Eko.
Gbogbo ilé ẹkọ́ yóò sì wà ní títì pa, nígbà ti ilé iṣẹ́ tó n rí sí ètò ẹ̀kọ́ yóò máa ṣetò pẹ̀lú àwọn ilé iwé lórí àwọn ìlànà ti wọ́n lè tèlé nítori àwọn ọmọ akẹ́kọ̀ọ́ jáde ti J.
Ìyàwó mi ṣẹ̀ṣẹ̀ bímọ tuntun, kò si oúnjẹ fún wa torí ìgbélé Coronavirus- Yakubu Coronavirus ló lé mi kúrò níléèwòsàn UCH n'Íbàdàn- Ogun Majek Wo àwọn ohun tó yẹ kí o mọ̀ nípa àrùn Coronavirus àti ìbálòpọ̀ akọ àt'abo Ó yẹ kí ìjọba gbé ilé ìwé tì pa títí di ọdún 2021- ASUU Ṣugbọn o ni NIPRD ti gba ijọba Naijiria nimọran pr ko si ẹri pe àgbo naa le dena tabi wo Covid-19 san.
Ifipabanilopọ ma n fa ọgbẹ ọkan
Ẹgbẹẹgbẹrun ọ̀tá tó yí mi kákò le bà mí lẹ́rù.
waye ni Vienna lorile ede Austria lojo Aje , osu kejila, ojo kejidinlogun ati
Oba Olayode: Egbo to ti fẹẹ́ jiná ni ẹ tún ń fi èékáná te yìí
Mo ti sa gbogbo agbára mi láti tọ́jú ọ̀kẹ́ marun-un (100,000) talẹnti wúrà kalẹ̀ fún kíkọ́ ilé OLUWA, aadọta ọ̀kẹ́ (1,000,000) talẹnti fadaka, ati idẹ, ati irin tí ó pọ̀ tóbẹ́ẹ̀ tí ẹnikẹ́ni kò lè wọ̀n.
 ní ọdún 1975 Ọlá balógun gbé fíìmù kan tí ó pè ní  Àjàní Ògún "" ."
Ààrẹ Buhari kẹ́dùn pẹ̀lú ẹbí àwọn èèyàn 207 tí wọ́n pa lọ́jọ́ Àjíǹde Omotola Jalade ní Nàìjíríà dàbí ọ̀run àpáàdì lábẹ́ ìjọba Buhari Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Helen Paul sọ idi tó fi gba orúkọ ní kékere Arsenal si wa ni ipo kẹrin lori tabili Premier League, ṣugbọn Chelsea yoo gba ipo naa mọ wọn lọwọ ti wọn ba jawe olubori ninu ifẹsẹwọnsẹ ti wọn lọjọ Aje.
egbe awon osise orile ede Naijiria(Nigeria Labour Congress) se ni ipinle Benue.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Rivers Police:wọ́ ọlọ́pàá ti tẹ àwọn afurasí tó lọ gbin ǹkan abúgbàmù sí ṣọ́ọ̀ṣì bàbá gómìnà Wike 2 Bélú 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 29 Bélú 2020 Ijọba ipinlẹ Rivers ti fi panpẹ ofin mu eeyan meji kan toripe wọn lọ gbe nkan oloro abugbamu si ijọ baba gomina ipinlẹ naa, Nyesome Wike iyẹn Christian Church International.
Pupọ ninu awọn eeyan to ba wa sọrọ ninu awọn to forukọ silẹ ṣalaye wi pe, ilepa ati ja fun ẹtọ ọmọniyan lo sun wọn de ibi iforukọsilẹ fun ikọ Amọtẹkun.
Ẹnikẹ́ni tí ó bá bọ́ lọ́wọ́ idà Hasaeli, Jehu ni yóo pa á, ẹnikẹ́ni tí ó bá sì bọ́ lọ́wọ́ idà Jehu, Eliṣa ni yóo pa á.
feyinti In-Tae Lee , lo so pe ijoba orile ede Korea ti n gbiyanju lati wa ona ti
" Iná èèsì kìí jóni lẹ́ẹ̀mejì - Ọbásanjọ́ Ọbásanjọ́, Fálaè sè‘pàdé lóríi Bùhárí Buhari kéde pé òun yóò se sáà kejì nípò Gómínà Ìpínlẹ̀ Osun nígbà kan rí, Olagunsoye Oyinlola àti igbákejì gómínà Ìpínlẹ̀ Oyo nígbà kan rí, Taofeek Arapaja wà nínú ìpàdé náà.
Nítorí ó ní,“Agbára mi ni mo fi ṣe èyí,ọgbọ́n mi ni mo fi ṣe énítorí pé mo jẹ́ amòye.
Fún ọdún meje yìí, ẹnìkan kò ní ṣẹ́ igi ìdáná lóko, bẹ́ẹ̀ ni wọn kò ní gé igi ninu igbó kí wọ́n tó dáná; ohun ìjà ogun ni wọn yóo máa fi dáná.
Oríṣun àwòrán, Ekiti state government Ninu ọrọ to ba awọn oniroyin sọ lẹyin ipade naa, Ọọni Ogunwusi ṣalaye pe gbun-gbun-gbun gbogbo ti pari.
Ile -ise New Partnership for Africa’s Development (NEPAD), ti pari eto idanileko fun awon omo orile-ede Nigeria ti won le ni oodunrun .
Wọn ja ilẹkun to wa ni oju ọna wọle, wọn si bori awọn ẹsọ alaabo to wa lẹnu iṣẹ lasiko naa, ki wọn to tu awọn ẹlẹwọn silẹ.
Ọrọ yii jẹ jade ni ilu eko nibi ipade oniroyin pẹlu awọn adari meji lati awọn ile iṣẹ to wa ninu ẹgbẹ naa iyẹn PENOP ati ARM Pension nibi ti wọn ti fi hande pe aṣ taara latọdọ ajọ to n risi ọrọ owo ifẹyinti awọn oṣiṣẹ ni Naijiria (PENCOM).
Yoruba ni fi ọrẹ rẹ han mi; maa sọ iru eeyan ti o jẹ ati pe ki gbogbo akẹkọọ maa ranti iru ọmọ ẹni ti awọn n ṣe.
Ṣugbọn ni bayii oun funra rẹ lo tu iroyin ayọ yii fun awọn oṣiṣẹ ileeṣẹ redio rẹ pe.
Ẹnikẹ́ni tí ó bá sì fi ara kan ibùsùn tabi ìjókòó rẹ̀, yóo di aláìmọ́; kí ó fọ aṣọ rẹ̀, kí ó sì wẹ̀, yóo jẹ́ aláìmọ́ títí di ìrọ̀lẹ́.
Ìgbà tí ilẹ̀ ṣu, tí ayédèrú-ẹ̀d[‘a sọ fún mi pé kí a jọ lọ, ó mú dé ibi kan báyìí, o fi mi síbẹ̀, o ní òun ń padà lọ sí ibi tí òun ń gbé ní ìlú náà, ki ń máa wòran, n o fi ojú mi rí ìyàwó mi àti ọ̀rẹ́ rẹ̀ ọkùnrin.
Adebanjo ni oun yoo sa gbogbo agbara oun lati wa ojutu si aawọ naa nitori ilẹ Yoruba ko gbọdọ bajẹ."
Lẹ́yìn náà, kí ìwọ ati àwọn ọmọ rẹ wọlé, nígbà tí ẹ bá sì ti ti ìlẹ̀kùn yín tán, ẹ bẹ̀rẹ̀ sí da òróró náà sinu àwọn ìkòkò náà, kí ẹ sì máa gbé wọn sí ẹ̀gbẹ́ kan bí wọ́n bá ti ń kún.
Dangote vs Arsenal: Dangote lóun ṣì máa ra Arsenal ní 2021
 Àwọn tí ó ṣe àwárí plánẹ ́ tì kékeré yìí ni s.
Ni báyìí, agbẹjọro fún olórí ẹni afẹsunkan, Olusola Oke tí ṣàlàyé fún ilé ẹjọ́ báyìí pé, àwọn ẹlẹri ogun tí dé lati jẹri, ṣùgbọ́n, mẹta péré ni yóò farahàn niwaju adajọ loni.
Igba akọkọ niyi ti Juwon yoo maa kopa ninu ere Tiata gẹgẹ bi iya rẹ ṣe fi sita loju opo Instagram rẹ.
Ó wà ní àkọsílẹ̀ pé, “Nítorí rẹ a wà ninu ewu ikú lojoojumọ,wọ́n sì ṣe wá bí aguntan tí wọ́n fẹ́ lọ pa.
Gẹ́gẹ́ bi ṣẹṣẹ de Soyombo ni wọ́n gba ẹgbẹ̀run lọ́na ogun náira fun aṣọ oorun, miliki, tea, towẹẹli àti awon nkan miran ti apapọ owo rẹ̀ ko le ju ẹgbẹrun mẹẹdogun naira lọ.
nikan ni o lee da awon eniyna pada si aye irorun ati ominira.
Lataari ise takun-takun iko agbaboolu Manchester City ninu ifesewonse ti o waye lopin ose, eleyi ti iko ohun gbo ewuro si iko agbaboolu Southampton loju ninu idije EPL pelu ami-ayo mefa sookan(6-1), esi ifesewonse naa pelu opo yanturu ami-ayo lo seranwo fun iko Pep Guardiola lati bo si oke tente tabili idije EPL bayii.
“Mo pàṣẹ fun yín nígbà náà, mo ní, ‘OLUWA Ọlọrun yín ti fi ilẹ̀ yìí fun yín bíi ohun ìní; gbogbo àwọn akọni ninu àwọn ọkunrin yín yóo kọjá lọ pẹlu ihamọra ogun ṣiwaju àwọn ọmọ Israẹli, arakunrin yín.
Ọjọ́ kẹwàá oṣù Ẹrẹ́nà ọdún 2019
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Pneumonia: Dókítà ní kòkòrò àìfojúrí ló ń fàá Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Ooni: Ọọni àti Buhari tún ṣèpàdé fún ìgbà kejì láàrin ọ̀sẹ̀ kan
"Orúkọ àwọn orílẹ̀èdè tí yóò kópa ní AFCON 2019 rèé Ileẹjọ f'ofin de ọdun oro nipinlẹ Ogun Àwọn àṣà àti ìse tó yọ obìnrin sílẹ̀ nílẹ̀ Yorùbá ""Miò faramọ́ ìyànsípò Festus Adedayo"" Lánàá òde yìí ni Aisha tún fi ohun rẹ̀ síta lóri ìyànsípò agbẹ́nusọ fún ààrẹ ilé ìgbìmọ aṣòfin agbà Ahmed Lawan tó fẹ yan Festus Adedayo sípò."
Nígbà tí Hasaeli pàdé rẹ̀, ó sọ pé, “Iranṣẹ rẹ, Benhadadi, ọba Siria, rán mi láti bèèrè lọ́wọ́ rẹ bóyá òun óo yè ninu àìsàn òun.
Obasanjọ sojú abẹ níkòó lórí ọ̀rọ̀ ìkólù Ódè.
Bí ó ti lẹ̀ jẹ́ wí pé Ààrẹ Buhari sọ pé Ọbasanjọ ní ẹjọ́ láti jẹ́ lóri òbítíbitì owó tó ná lásìkò ìṣàkósò ọlọ́dún mẹ́jọ rẹ̀, Ọbasanjọ ti ní ẹ̀sùn nàá kò ní ẹsẹ̀ nílẹ̀, tó sì ti ní kí ìṣàkóso Buhari tẹ̀síwájú láti tanná wá ìdí òun.
PFN: Fatoyinbo kọ̀ láti yọjú ni ìwádìí wa kò ṣe parí Ilé iṣẹ́ márùn ún tí wọ́n dárukọ kìí ṣe túntun- Garba Sheu FRSC dá N443,180 padà fún ẹbí ẹni to ní ìjàmbá mọ́tò Ọlọ́pàá Germany ń wádìí àfurasí mẹ́rin nínú àwọn tó kọlu Ekweremadu ni Germany Olamilekan Adegbitẹ O jé kòmisona fun eto ìṣe àti ohun amayederun tẹ́lẹ̀ rí ní ìpínlè Ogun.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù BBC Gov Debates: Ìṣẹ̀lẹ̀ mánigbàgbé níbi ìfọ̀rọ̀wérọ̀ BBC Yorùbá l'Ọyọ 2 Èrèlè 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 4 Èrèlè 2019 Àkọlé àwòrán, ìfọ̀rọ̀wérọ̀ BBC Yorùbá Ni kete ti oju opo facebook BBC News Yoruba ti ṣi silẹ fun akanṣe Facebook Live ipade ifọrọwerọ awọn oludije gomina ipinlẹ Ọyọ ni oniruuru eto ti a le gbadun ti bẹrẹ.
Wọ́n mú ọrẹ ẹbọ ati turari lọ́wọ́ wá sí Tẹmpili OLUWA.
Àwọn ọkunrin tí wọn bá rú òfin mi, tí wọn kò sì tẹ̀lé ìlànà majẹmu tí wọn dá níwájú mi, n óo bẹ́ wọn bíi ẹgbọ̀rọ̀ mààlúù tí wọn bẹ́ sí meji, tí wọ́n sì gba ààrin rẹ̀ kọjá.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Yomi Lanso wipe ka jọ gbadun laye Ninu ọrọ ti wọn ba awọn oniroyin sọ, Ọjọgbọn Ango Abdullahi to jẹ alaga ẹgbẹ agba oke ọya Naijiria ni nibi ti ọrọ de duro bayii, ko daju pe ẹmi awọn darandaran Fulani de mọ ni apa guusu orilẹ-ede Naijiria ti wọn wa.
Agbábọ́ọ̀lù Super Falcons tẹ́lẹ̀, Chiejine jáde láyé lẹ́ni ọdún 36 PFN: Fatoyinbo kọ̀ láti yọjú ni ìwádìí wa kò ṣe parí Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí kan sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
Ogun ebi ni Nàìjíríà ń bá fínra lọ́wọ́, ogun coronavirus kò gbọdọ̀ kún un-Oluwo Ìjọba àpapọ̀ fi Austria, Sweden kún àwọn orílẹ̀èdè tí kò lè wọ Nàìjíríà Èyí làwọn ayẹyẹ nlá tí kò ní wáyé nítorí coronavirus Peter Fatomilola ní àìsí ẹ̀kọ́ ń mú káwọn òṣèré tíátà ó máá ṣe oun tí kò tọ́.
“Bọ̀wọ̀ fún baba ati ìyá rẹ.
Awọn eleto abo to wa nibẹ gbe wọn jade ni gbogbo rẹ ba di pẹ n tuka nile ijọsin Wọn kọ wọn o lọ awọn ebi Osadebe duro si enu ilooro sọọsi pe awọn o ni lọ afi ti wọn ba fopin si isopọ Ninu ọrọ rẹ Osadebe ti ko le sọrọ daada ni Gloria gbẹtin bẹbọ jẹ fun oun, isẹlẹ to waye yii si ja oun laya pupọ.
Kogi Robbery: Wọ́n sin ọ̀gá ọlọ́pàá táwọn Ọlọ́ṣà pa ní ìpínlẹ̀ Kogi láàrín ọ̀pọ̀ omijé Oríṣun àwòrán, oyo insight Ọga ọlọpaa ni ileeṣẹ ọlọpaa t'awọn Adigunjale ti ṣọṣẹ ni ipinlẹ Kogi ti wọ kaa ilẹ sun ni ilu Ibadan Agbegbe Olunde ni ilu Ibadan ni wọn gbe sin Ọgbẹni Adebọla Tajudeen si.
Báyìí ni Àrẹ̀mọ Ooni Adeyeye Ogunwusi ṣe wọ ṣọ́ọ̀ṣì fún ìgbà àkọ́kọ́ láti bá bàbá rẹ̀ ṣe ìdúpẹ́ ìwúyè Ọmọ Risikat olójú búlúù méjèéjì jẹ̀bùn oríire àti ìfà ńlá Ta ni obìnrin tó fẹ́ bá Dino Melaye ṣe ìgbéyàwó lọ́jọ́ kejì Kérésì?
Wọ́n fi aṣọ funfun onílà tẹ́ẹ́rẹ́tẹ́ẹ́rẹ́, ti aláwọ̀ aró, ti elése àlùkò ati aṣọ pupa tí wọ́n ṣe iṣẹ́ ọnà sí lára ṣe àmùrè gẹ́gẹ́ bí OLUWA ti pàṣẹ fún Mose.
Adejumọ fikun pe Sunday Omobolanle ni baba naa n jẹ tẹlẹ, ko to lọ si Mecca, to si yi orukọ rẹ pada si Yekeen.
Nitori isẹlẹ yii, se ni adugbo Iwo Road di pa, ti ọ̀pọ̀ ero si n fi ẹsẹ rin, nigba ti awọn ọlọkọ to n rin irin ajo bọ lati awọn ilu miran ha sinu sunkẹrẹ fakẹrẹ ọkọ fun ọpọ wakati, ti ohun gbogbo si dẹnu kọlẹ lagbegbe naa.
"Gbogbo eeyan lo mọ awa Yoruba pe a ko ni mọra, ta si tun ni ifarada nipa awọn ara oke ọya, paapaa lasiko ti wọn ba tọ wa nija.
Abiola Ajimobi: Ọba Adeyemi daro ikú gómìnà àná ní Oyo Alaafin Oyo, Ọba Lamidi Olayiwola Adeyemi Kẹta ti kẹdun lori iku Gomina ana nipinlẹ Oyo, Abiola Ajimobi.
Ọkọ agbepo kan to lana ni wọn ni o fa ina naa ti o ṣakoba fọja Ochanja titi de agbegbe Upper Iweka.
Ìtàn Gbọnka àti Timi, akọni méjì tó borí Aláàfin Ṣango Òkè Idanre rèé tí odidi ìlú kan ló ń gbé lórí ẹ̀ Lisabi Agbongbo Akala rèé, ẹni tó fi ìfẹ́, ìṣọ̀kan àti ìrẹ́pọ̀ gba ilẹ̀ Ẹ̀gbá lọ́wọ́ ìmúnisìn Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
 Fanwo ṣalaye pe ajọ NCDC fẹ fi tipatikuuku jẹ ki ipinlẹ Kogi ni arun Coronavirus ti ko si yẹ ko ri bẹ."
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù RCCG Congress 2020: Pásítọ̀ ní owó Naira yóò sì tún gbé pẹ́ẹ́lí lẹ́ẹ̀kàn síi 12 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Oríṣun àwòrán, @thehgcongress Alabojuto gbogbogbo fun ijọ Redeemed Christian Church of God, RCCG, Pasitọ Enoch Adeboye ti sọ pe owo Naira yoo si tun pada niyi lawujọ awọn owo orilẹ-ede to gbe pẹẹli julọ lagbaye.
(àkókò náà jẹ́ àkókò ìkórè, odò Jọdani sì kún dé ẹnu), ṣugbọn bí àwọn alufaa tí wọ́n gbé Àpótí Majẹmu ti dé etídò náà, tí wọ́n sì fi ẹsẹ̀ wọn kan omi, 
idagbasoke ba eto okoowo agbaye nipa lilo imọ ẹrọ igbalode .
Nígbà tí ó yá, ó rán ẹrú rẹ̀ kan sí àwọn alágbàro náà.
Ọdun mẹrindinlogun si ni Oyo fi ba Ekiti jagun.
Lẹsẹkẹsẹ àrùn ẹ̀tẹ̀ náà bá kúrò lára rẹ̀, ara rẹ̀ sì dá.
Ti a ko gbagbe, Ọjọ Kẹwa, Osu Karun un ọdun 2018 ni ijọba kọ iwe lo gbe ile rẹ fun igba diẹ si ọjọgbọn Uwakwe fun iwadii ẹsun jẹgudujẹra ti wọn fi kan an ati awọn meji miran.
Nítorí ẹ̀ṣẹ̀ ojúkòkòrò rẹ̀, inú bí mi,mo jẹ ẹ́ níyà, mo fojú pamọ́, inú sì bí mi;sibẹ ó túbọ̀ ń ṣìnà sí i ni, ó ń ṣe tinú rẹ̀.
5 owó naira ni ọọfiisi àjọ INEC ni Zamfara 10 Ọ̀wàrà 2019 Oríṣun àwòrán, Efcc Àkọlé àwòrán, Aduru owo yii lo wa nipamọ ni iyara kan!
Wọn ti fi panpẹ ofin mu minisita to n ri si ọrọ awujọ ni Indonesia lẹyin ti wọn fẹsun kan pe o gba riba $1.
Oríṣun àwòrán, AFP Àkọlé àwòrán, Darandaran yii n dari awọn ẹran rẹ lode ilu Mdhila, ọkan lara awọn ibuwa nnkan alumọni ni orilẹede naa , nibi tawọn oṣiṣẹ ti pada s'ẹnu iṣẹ lẹyin igba ti wọn da'ṣẹlẹ fun oṣu kan.
Ìjọba rẹ̀ bẹ̀rẹ̀ láti Babeli, Ereki ati Akadi.
siwaju si  ọjọ kẹ́rìndínlógún, osu keji odun 2019 , ti
Awọn onimọ ni ki Obinrin o jẹ funfun, nigbati Ọkunrin yoo jẹ dudu rẹ.
Èmi Paulu, aposteli Kristi Jesu nípa ìfẹ́ Ọlọrun, ni mò ń kọ ìwé yìí sí àwọn eniyan Ọlọrun tí ó wà ní Efesu, àwọn tí wọ́n jẹ́ olóòótọ́ sí Kristi Jesu.
 ipa àjẹsára náà a má a pẹ ́ títí fún ọ ̀ pọ ̀ lọpọ ̀ ọdún .
Solomoni kó kẹ̀kẹ́ ogun ati àwọn ẹlẹ́ṣin jọ; àwọn kẹ̀kẹ́ ogun jẹ́ egbeje (1,400) àwọn ẹlẹ́ṣin sì jẹ́ ẹgbaafa (12,000); ó kó wọn sí àwọn ìlú kẹ̀kẹ́ ogun rẹ̀ ati sí ọ̀dọ̀ ara rẹ̀ ní Jerusalẹmu.
Muyiwa Ademola Ọdun 1991 lo bẹrẹ ere tiata, lati igba naa lo si ti lami laaka ninu awọn ere akọnilọgbọn to ma n gbe jade.
- Sanwoolu Àṣé àṣírí wà nínú Hijabu tí Aisha Yesufu ń wọ̀ lọ ìwọ́de Ṣé Èdùà dá ààtàn isó ni?
Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Whatsapp: Àwọn gbéwiri s'àtakò sí Whatsapp, yára ‘Update’ rẹ̀14 Èbibi 2019 WhatsApp: Àwọn fóònù wọ̀nyìí kò ni lè ṣe WhatsApp láti ọdún 202031 Ọ̀pẹ̀̀ 2019 Facebook mú àyípadà bá àtẹ̀jíṣẹ́ síra ẹni lórí òpó Instagram, wo àwọn ǹkan tó kàn ọ níbẹ̀5 Owewe 2020 Uganda: Á lo owọ́ orí náà láti san gbèsè táa jẹ31 Èbibi 2018 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 3 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 5 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Ìwọ̀n tí wọ́n fi nwọnsẹ̀ àwọ́n géndé, láìí ṣe t’ọmọdé, máa nṣábàá bẹ̀rẹ̀ láti 7 dé 12, ìyen fún génde ọkùnrin.
Eyi ri bẹ ẹ lyin ti ajọ to n gbogun ti aarun ni Naijiria, Nigeria Centre for Disease Control (NCDC) kede esi ayẹwo eeyan igba le mọkandinlọgbọn lọjọ kẹẹdọgbọn, oṣu Karun, ọdun 2020.
"O ni, ""A ba obi awọn ọmọ to n lọ si ile ẹkọ girama to jẹ ti ijọba ipinlẹ Ọyọ sọrọ, a si ṣe awari ẹ pe, gbogbo wọn n tiraka lati san ẹgbẹrun mẹta naira ti ijọba ana n gba lọwọ wọn."
Mobolaji Anthony Way (Lati papakọ ofurufu Murtala Mohammed si abẹ afara to wa niwaju ile iwosan LASUTH) 2.
Amọ, awọn mejeeji ni awọn ko jẹbi ẹsun ti wọn ki kan wọn.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Kìí ṣe ọmọbìnrin nìkan ni Ọlọ́run pàṣẹ fún láti pa ìbálé mọ́ Ariwo waye lori igbesẹ rẹ, paapa nigba ti iroyin sọ pe orukọ Minisita fun ina mọna-mọna, Babatunde Fashola ni wọn fi gba baalu naa.
Oríṣun àwòrán, @mko_abiola MKO Abiọla kede ara rẹ bii aarẹ fun Naijiria, ti wọn si sọ ọ si ahamọ.
Bẹẹ si ni ọga ọlọ́pàá tí tí ìbínú àwọn èèyàn sókè nígbà tó kéde pé káwọn agbofinro máa lo ọwọ líle àti ọna ti ko bófin mú, fìyà jẹ àwọn èèyàn tó ba tako òfin náà.
Láti ìgbà tí obìnrin náà ti wọlé kò tilẹ̀ fẹ́ kí ìyáálé rẹ̀ ní nǹkan kan pọ̀ pẹ̀lú ọkọ mọ́, kò fẹ́ kí ọkọ bá a sọ̀rọ̀, kò fẹ́ kí ọkọ bá a ṣiré, kò fẹ́ kí ọkọ ṣe nǹkan kan fún obìnrin náà mọ́.
Àwọn ẹrú náà bá lọ sí ìgboro, wọ́n kó gbogbo àwọn tí wọ́n rí wá, ati àwọn eniyan rere, ati àwọn eniyan burúkú.
Sara-Jayne King: Ọ̀nà ayé mi dàrú torí òbí mi ta mí nù fún alágbàtọ́
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Wọle Soyinka: Ti mo ba dara pọ m'ẹgbẹ Obasanjọ, wọn gbọdọ yẹ mi lọpọlọ wo Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Wọle Soyinka: Ti mo ba dara pọ m'ẹgbẹ Obasanjọ, wọn gbọdọ yẹ mi lọpọlọ wo 19 Èrèlè 2018 Ọjogbọn Wole Soyinka ba BBC Yoruba sọrọ lori ọrọ oselu ni Naijiria.
Nítorí ayé yóo kún fún ìmọ̀ ògo OLUWA, gẹ́gẹ́ bí omi ti kún inú òkun.
Ó ní, Ìyábọ̀, àbúrò mi tí ẹ̀ ń pè ní Bùrọ̀dá Eréko ni ó ń ṣàìsàn púpọ̀; àwọn oníṣègùn òyìnbó tí ó yẹ̀ ẹ́ wò sọ pé kò dájú pé ó lè yè, nítorí àìsàn ikú ni àìsàn náà.
" Ọdun mẹrin abọ ni adehun naa ti wọn ṣe pẹlu agbabọọlu ọmọ orilẹede Cotedivoire naa.
Dájúdájú, ó ti dojú kọ mí,ó sì bá mi jà léraléra tọ̀sán-tòru.
Àjọ NCDC kéde ènìyàn 779 tó tún ṣẹ̀ṣẹ̀ ní Coronavirus ní Nàìjíríà Mí ò tíí ní ìpinnu lóri ìdíje ààrẹ ọdún 2023 Peter Okoye, ìyàwó àti ọmọ lùgbàdì ààrùn Coronavirus Oríṣun àwòrán, Nigeria Defence News Nibi ti wọn f'ogun awọn irinṣẹ ti Naijiria ra yii gbari de, wọn tun kede pe bi orilẹede Afirika kankan ba wa to ti gbe iru igbesẹ lilo rọbọọti fun iṣẹ ni papakọ ofuru wọn, ẹ jẹ ka mọ."
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Wọn nwa awọn ọmọde ninu isẹlẹ ina Russia Eeyan mẹrin ku ninu ijamba ọkọ l'Eko Awọn ọlọpaa lo afẹfẹ tajutaju lati tu awọn mọlebi to yi ago ọlọpaa naa kaa, lẹyin ti wọn gbo iroyin ijamba ina naa.
O sọrọ akin nigba ti o pe ipade awọn oniroyin ni Delhi to si gba pe oun ti padanu ipo ti ẹbi rẹ ti dimu ni Uttar Pradesh ni Amethi lati ọdun 2004.
" ní àwọn ìlú , àwọn ẹ ̀ fọ ́ n ẹ ̀ yà "" aedesaegypti "" ni ó sábà maa ń tàn káàkiri ."
Ẹni tí ó sọ fún ẹlẹ́ṣẹ̀ pé ọwọ́ rẹ̀ mọ́,àwọn eniyan yóo gbé e ṣépè,àwọn orílẹ̀-èdè yóo sì kórìíra rẹ̀.
Banki apapọ Naijiria naa kede pe oun yoo lo owo to le ni Tiriliọnu kan Naira, lati ya awọn olokoowo ti ajakalẹ arun naa ba okoowo wọn jẹ.
Nigbati 44,500 ọkunrin po ju obinrin lọ ni ile iwe girama ọlọdun mẹta alakọjade.
Oríṣun àwòrán, Bashir Ahmad Àkọlé àwòrán, Aarẹ Buhari sọ pe oun ko ni ibaṣepọ to dara pẹlu ile aṣofin labẹ Saraki ati Dogara lasiko to ṣinu aawẹ pẹlu awọn olori ile aṣofin Eyi lo mu ki a fẹ ṣe agbeyẹwo diẹ lara awọn igba ti Aarẹ Buhari ati awọn ọmọ ile aṣofin ti jọ gbena woju ara wọn ri Ofẹ ẹ jẹ wi pe lati ibẹrẹ ile aṣofin kẹjọ ni aarin awọn ọmọ ile aṣofin apaọ mejeeji ati ẹka iṣakoso, paapa, aarẹ Muhammadu Buhari ko ti gún.
Koda, aarẹ Muhammadu Buhari funrarẹ ko ṣai mẹnu le ọrọ yii nibi ipade idagbasoke Afirika to lọ ṣe ni Japan.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Coronavirus in Nigeria: Ìwádìí fihàn pé ọ̀pọ̀ aráàlú ni kò gbà pé àrùn Covid-19 wà Ẹgbẹ́ ọmọlẹ́yìn Kristi kéde àdúrà nítórí àrùn Coronavirus Oríṣun àwòrán, Rccg Saaju la ti sọ fun yin pe ẹgbẹ awọn ọmọlẹyin Kristi ni Naijiria, CAN ti dari awọn ile ijọsin, lati ya ọjọ kejilelogun ati ọjọ kọkandinlọgbọn oṣu kẹta sọtọ fun adura nitori arun Coronavirus.
Gẹ́gẹ́ bi ọ̀rọ̀ ti ó sọ wi pé “Ni ilú afọ́jú, olójú kan lọba”, laarin Ìjọba àpapọ̀, nitori iwà-ibàjẹ́ ọ̀pọ̀lọpọ̀ ọdún, a lè sọ wi pé àwọn ipinlẹ̀ Ìwọ̀-Oòrùn, Èkìtì, Èkó, Ògùn, Ondó, Ọ̀ṣun àti Ọ̀yọ́ ṣe dáradára nipa ipèsè ohun amáyédẹrùn.
Nítorí OLUWA wí pé,“Mo ṣetán wàyí, tí n óo sọ àwọn tí wọn ń gbé ilẹ̀ yìí nù bí òkò.
UFC 243: Isreal Adesanya sán bàǹtẹ́ ìyà fún Robert Whittaker pẹlu 18-0
Ṣugbọn ọpọ mọ pe ilu Daura lo ti wa.
bo ti wu ko ri, a ni lati gba bi isẹlẹ yii se ri, pupo ninu wa lo ti lọ si ilu
Ko tan sibẹ, awọn akẹkọọ girama naa se iwọde tako ilana ijọba Ajimobi ni ẹka eto ẹkọ, eyi to mu ki igboro mi titi, ti awuyewuye si waye lasiko naa lẹka eto ẹkọ.
Nítorí nígbà tí ó bá ṣubúkò ní sí ẹni tí yóo gbé e dìde.
OLUWA sọ láti ẹnu àwọn wolii, iranṣẹ rẹ̀, pé, 
 a lè gbọ ́ orin rẹ ̀ lọ ́ pọ ̀ ìgbà ní ilé iṣẹ ́ ẹ ̀ rọ asọ ̀ rọ ̀ mágbèsì káàkìri ilẹ ̀ yorùbá .
Bakan naa ni won tun se idasile awon igbimo alaba-sise po lori oro eto ogbin, irina-oko, ile-ise ipese nnkan ati eka ile-ise amuna wa, eyi ti minisita ile-ise kookan yoo dari re.
"Ṣe ""I am a Tiger"" ni itumọ ""Ayamatanga""?"
Ìtọ́ni ọlọ́gbọ́n jẹ́ orísun ìyèa máa yọni ninu tàkúté ikú.
27 Bélú 2020 Ìbẹta, Oba Lamidi Adeyemi, Alaafin Oyo pé ọdún méjìlá; nkan tó yẹ kí o mọ̀ nípa wọn nìyíì26 Bélú 2020 Operation Falcon: Omi tẹ̀yìn wọ̀gbín lẹ́nu fáwọn ọmọ Nàìjíríà mẹ́ta tó lu èèyàn 50,000 ní gbájúẹ̀ jákèjádò àgbáyé26 Bélú 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Ọjọ́ Iṣẹgun ati Ọjọru ni ìjọba Naijiria kéde fun ìsinmi.
Nígbà tí Hẹrọdu rí i pé àwọn amòye tan òun jẹ ni, inú bí i pupọ.
Jẹ́ kí ìdáláre mi ti ọ̀dọ̀ rẹ wá;kí o sì rí i pé ẹjọ́ mi tọ́.
Mo jẹ́ baba fún talaka,mo gba ẹjọ́ àlejò rò.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Boko Haram: Ikọ̀ afẹ̀jẹ̀wẹ̀ kọlu Gómìnà Borno lẹ́ẹ̀kejì pẹ̀lu kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ aládòó olóró 26 Owewe 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 29 Owewe 2020 Oríṣun àwòrán, Getty Images Iroyin ti n jẹ jade nipa ọna ara ti ikọ Boko Haram fi ṣe ikọlu si Gomina ipinlẹ Borno, Babagana Zulum ni igba keji.
Nigba to n ba ajo-igbimo eleto ilera soro, ki o ti di akoko idibo, Omowe  Tedros seleri lati maa gbe igbese kiakia lori awon ajakale aarun pajawiri to le waye lojo iwaju.
Sugbọn Ajimobi tẹsiwaju lati dije fun ipo Sẹnatọ naa, bi o tilẹ jẹ pe o ti lọ sile aṣofin agba ri , ko to di gomina ipinlẹ Ọyọ.
Ọ̀pọ̀lọpọ̀ àwọn tó nlo Roomba yìí a máa fi àkókò ìgbálẹ̀ sí ìgbà tí wọn ò bá sí n'lé.
Ko tii pe ọdun kan ti o gba Ami ẹyẹ akọkọ gẹgẹ bi Ajagun-wakọ obinrin akọkọ ti ikọ ọmọogun Naijiria, ti o fi fi aye silẹ.
Ilu Numana jẹ ọkan lara awọn ilu to ti lugbadi ikọlu daran-daran lẹkun Guusu Kaduna.
Funke Akindele tọrọ àforíjì, Lateef Adedimeji d'obìnrin, Bàbá Ire kó ìrẹsì lọ Ogbomoṣo Yoruba Films: Funke Akindele tọrọ àforíjì, Lateef Adedimeji d'obìnrin, Bàbá Ire kó ìrẹsì lọ Ogbomoṣo Oríṣun àwòrán, Instagram Awọn oṣere tiata Yoruba ṣi n dara papaa julọ loju opo Instagram wọn, bo tilẹ jẹ pe konle-o-gbele wa nita.
Adam Lamhamedi Ọjọ ori: Mejilelogun Orilẹẹde: Morocco Ere idaraya: Alpine Skiing Adam Lamhamedi ti baba rẹ jẹ ọmọ Morocco ti  iya rẹ si jẹ ọmọ Canada se oun manigbagbe nigba ti o di ọmọ ilẹ Afrika akoko to gba ami ẹyẹ goolu nibi idije Winter Youth Olympic Games ni Austria lọdun 2012.
 Mo dàgbà nkọ̀ S'oge mó , owó ni kò sí.
irufẹ igbesẹ bẹẹ tilẹ tun ti fa ipalara fun ọjọ ọla ọmọ wọn.
Ẹ fi gòjé yin OLUWA,ẹ fi hapu olókùn mẹ́wàá kọ orin sí i.
Dokita Bukola ni lati igba ti iṣẹlẹ naa ti ṣẹlẹ ni arabinrin naa ti n gba iwosan.
Nigba ti o n gba abọ iwadi naa ti olori igbimọ ọhun Amal Pepple gbe fun un, Aarẹ Buhari ni oun yoo ṣa agbara oun lati ri wi pe ilé aṣòfin mú ayípadà bá owó oṣù ti àwọn òṣìṣẹ́ n gba.
Díaz tún jẹ́ olùkópa nínú ẹgbẹ́ Ohùn Àgbáyé fún ọdún mẹ́wàá.
Lọwọlọwọ, apapọ awọn to ti ni aarun naa ti pe 75,062, eeyan 66,775 ti ri iwosan, 1, 200 si ti ku.
awon atunse to si n lo lowo ni papa ofurufu to wa niluu eko ati ni ilu Abuja,
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: 'Ọ̀jọ̀gbọ́n Akindele kò ṣẹ̀ṣẹ̀ máa bèèrè fún ìbálòpọ̀' Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fọ́nrán ohùn, Akẹ́kọ̀ọ́ dókítà: Fásitì Ìbàdàn gbọdọ̀ dín owó iléẹ̀kọ́ wa Àjọ náà ní àwọn yóò lo ìlànà òfin láti fi kàn án nípá fún wọn láti ṣe bẹ́ẹ̀.
Ẹkunrẹrẹ ohun ti oju awọn obinrin mejeeji naa ri ni orilẹede Oman ree.
Lọjọ isẹgun ni agbẹnusọ fún adele Ààrẹ, Laolu Akande, fi ọrọ síta loju opo Twitter pé Adele Aarẹ Yemi Osinbajo ti pasẹ fun ọgá ọlọpaa lati se atunto SARS.
Awọn iroyin miran ti ẹ le nifẹ sii: Olusegun Obasanjo: Ọmú ìyá mi ti mo fi ń mùkọ ni kekere, ló jẹ ki ń lókun 'Ọmọdé tó fẹ̀ràn sínsín èèyàn jẹ ní Ikorodu ni wá' Sola Sobowale: Iṣẹ́ tí Ọlọ́run kọ mọ́ mi ni mò ń ṣe Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Ó lọ sí ìdí pẹpẹ bàbà tí ó wà níwájú OLUWA ninu àgọ́ àjọ, ó sì fi ẹgbẹrun (1,000) ẹran rú ẹbọ sísun lórí rẹ̀.
Johanu yìí wọ aṣọ tí a fi irun ràkúnmí hun, ọ̀já ìgbànú aláwọ ni ó gbà mọ́ ìdí.
Kíá, bí ó ti lọ tán, ẹni tí ó gba àpò marun-un lọ ṣòwò, ó bá jèrè àpò marun-un.
Adajọ naa, ti wọn pe orukọ rẹ ni Abdul Jogo la gbọ pe wọn ji gbe lọ pẹlu awakọ rẹ loju ọna Ibilo si Isua de Akoko, leti aala ilẹ ipinlẹ Ondo si Edo.
- Ọọ̀ni Ife Kí a tó dá ẹjọ́ Pásítọ̀ ìjọ Sọ titobi rẹ, ó di 2020- Adájọ́ ní Akurẹ Ọpọ ni ko mọ ijọ kan torukọ rẹ n jẹ Sotitibire Miracle Centre nilu Akure tẹlẹ, ṣugbọn okiki ile ijọsin ọhun kan lẹyin ti ọmọ ọdun kan o le diẹ dede poora nile ijọsin naa.
“Ẹ ranti bí OLUWA Ọlọrun yín ti bukun yín ninu gbogbo ohun tí ẹ dáwọ́lé, ó sì ti tọ́jú yín ní gbogbo ìgbà tí ẹ̀ ń rìn kiri ninu aṣálẹ̀ ńláńlá yìí.
Koríko a máa rọ, òdòdó a sì máa rẹ̀;ṣugbọn ọ̀rọ̀ Ọlọrun wa dúró títí lae.
Bakan naa ni lawọn kan naa tun kọlu Azeezat Shomuyiwa ti wọn fọ okuta mọ lori pẹlu oyun oṣu meje ninu rẹ.
Ojúlówó òróró ìpara kan, olówó iyebíye ni ó wà ninu ìgò náà.
Oríṣun àwòrán, others Gbajabiamila ni Minisita naa yoo foju wina ofin to ba kọ lati fi orukọ awọn aṣofin ọhun lede ní kiakia.
Nígbà tí a wọ Romu, wọ́n gba Paulu láàyè láti wá ilé gbé pẹlu ọmọ-ogun kan tí wọ́n fi ṣọ́ ọ.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Kíni òdiwọ̀n ọti ti o yẹ ki ènìyàn maa mu ẹmu Omonhinmin tún fi kun pé ẹmu dara púpọ̀ fún ara, sùgban èyí kò túmọ̀ sí pé kí ènìyàn wá mu ni àmujù O ní ó dára ki obinrin mu ife kanb lóòjọ́ nígbà ti àwọn ọkùnrin le mu bi ife méjì láàrín ọjọ́ kan.
Wọ́n kígbe níbẹ̀ ṣugbọn kò dá wọn lóhùn,nítorí ìgbéraga àwọn eniyan burúkú.
8 616 Erekusu Barbados 7 2.
Orin nàá gbajúmọ̀ púpọ̀ lásìkò nàá, débi pé, ó gba àmì ẹ̀yẹ Nigeria Entertainment Award, gẹ́gẹ́ bi orin tó tayọ jù lọ ní 2008.
Aare Vladimir Putin kedun pelu awon ebi ati ara awon ti won ku sinu ijamba.
Bàbá ẹni ọgọ́ta ọdún dèrò ilé ẹjọ́ nítorí ó wọ inú oko Obasanjo láì gba àṣẹ Wo ohun tó ń fa àfikún epo lóòrèkóòrè ní Nàìjíríà Gbajabiamila balẹ̀ sí Ghana láti pẹ̀tù sááwọ̀ láàrin Nàìjíríà àti Ghana Isiaka Busari, Mighty Joe tó jẹ́ adigunjalè tó rọ́pò Ọyenusi lẹ́yìn tí wọ́n pa á E wo ọmọ Yorùbá àkọ́kọ́ tó jà fún ẹ̀tọ́ àwọn aláwọ̀dúdú ní America!
Sibẹsibẹ Juda tí òun pàápàá jẹ́ alaiṣootọ, kò bẹ̀rù, òun náà lọ ṣe àgbèrè.
Iwadii awọn ọlọpaa lo si fihan pe, irinajo arabinrin yii jọ mọ lilọ si ile ijọsin Segun to wa ni ilu Ikoyi-Ile nipinlẹ Osun.
Iṣẹlẹ aburu ti ko ye ni yii waye ni ilu akure ni ipinlẹ Ondo.
Ninu ọrọ ti awọn ọdọ naa sọ, wọn ni ijọba gbọdọ fi opin si iṣẹ awọn ọlọpaa SARS ni Naijiria.
“Iyọ̀ dára, ṣugbọn bí iyọ̀ bá di òbu, báwo ni yóo ṣe tún lè dùn mọ́?
" Wọ k'ilu mọ oṣere sinima naa ni, bi Toyin ko ba dẹkun ibajẹ lori ọrọ oun, ija ṣẹṣẹ bẹrẹ laarin wọn ni.
Nítorí onírúurú àwọn ẹ̀dá abàmì gbogbo ni wọ́n máa ń ṣire kiri ní òru, àti èyí tí ó kéré àti èyí ti ó tóbi, àti èyí tí ó ni ojú àti èyí tí kò ní, olórí-méjì àti olórí-mẹ́ta èyí tí ó wà ní ìhòòhò àti èyí tí ó fi ewé bora, èyí tí ó da bi ìjímèrè àti èyí tí ó ní ìwo lórí bí ẹranko: onírúurú àwọn nǹkan báwọ̀nyí kún igbó náà dé ẹnu, nígbà tí ó bá sì di orù ggbogbo wọn a máa ṣiré wọn a máa sáré kiri.
pé kí wọ́n ya ọjọ́ kẹrinla ati ọjọ́ kẹẹdogun oṣù Adari sọ́tọ̀, 
Oríṣun àwòrán, @AbdulfataAhmed Àkọlé àwòrán, Gomina Fatai Ahmed n gbero lati lo ile asofin agba lẹyin saa rẹ gẹgẹ bi Gomina Bukola Saraki to jẹ Gomina saaju ri wa lati ẹkun gbungbun Kwara.
Bi o ṣe n ṣe ere ede Yoruba naa lo n ṣe sinima ede Oyinbo ati Igbo.
O fikùn pé, ara àwọn àfojúsùn òun gẹ́gẹ́ bíi Gómìnà ni lati mú amugbooro bá eto ọrọ aje nipinlẹ Ondo, èyí tó tọ́ tí fò sókè ga láti mílíọ̀nù lọ́nà eedegberin náírà si biliọnu méjì náírà báyìí.
Ooni Ile Ife pàdánù Màmá àgbá Lọjọ Aje ni igbẹjọ miran tun waye nile ẹjọ giga to n gbọ ẹjọ ti ijọba fi kan Wolii Alfa Sọtitobirẹ nilu Akurẹ, Nibẹ ni ọkan lara awọn oṣiṣẹ ajọ naa ti wọn pe gẹgẹ bii ẹlẹri olupẹjọ nibi igbẹjọ naa ti ṣalaye nipa idi to fi jẹ pe ajọ DSS lo n ṣe ẹjọ naa.
“Gbogbo àwọn ọmọ rẹ ọkunrin, ni OLUWA yóo kọ́ wọn yóo sì ṣe ọpọlọpọ àṣeyọrí.
Eyi n ba ni ninu jẹ, yoo si dara kẹ jẹ kawọn eeyan se idaro oloogbe to ba se wu wọn, ki wọn si fi Ọlọrun silk lati se idamọ awọn eeyan eke ati awọn olootọ ẹda."
Má jẹ́ kí ẹ̀rù mi bà ọ́,bẹ́ẹ̀ ni n kò ní le kankan mọ́ ọ.
Gomina Makinde sọ eyi lasiko ti wọn n se ibura wọle fun awọn aṣofin ipinlẹ ti wọn dibo yan si Ile Igbimọ aṣofin ipinlẹ naa.
Àsìá ilẹ ̀ kìrìbátì jẹ ́ àsìá oŕilẹ ̀ -èdè .
Eyi tun tumọ si pe, o le nira fun nnkan ọmọkunrin awọn ọkunrin kan lati dide tabi duro fun igba pipẹ lasiko ibalopọ.
Lesotho vs Nigeria: Nàìjíríà lu Lesotho lu lálùbolẹ̀ mọ́lé wọn
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Kayefi BBC Yorùba: Bàbá ọmọ, Mọ́ṣúárì, Ọlọ́pàá kẹ́jọ́ rò nípa òkú ọmọ tó pòórá Buhari di alága àjọ Ecowas Olórí l‘Afirika, ẹ dìde tako òṣèlú ẹ̀tanú ní Benin - Obasanjo àti Kufuor Osinbajo ta kété sí ọ̀rọ̀ 'Ruga Settlement' Omotola Ekehinde, Ezekwesili, Funmi Iyanda dá sí ẹ̀sùn ìfipábánilòpọ̀ Fatoyinbo COZA: Mi ò fípá bá obìrin lò pọ̀ rí láyé mi - Pásítọ̀ Fatoyinbo Nibi ipade ti awọn aarẹ n ṣe yii, wọn yoo ṣe ayẹwo ibi ti awọn minisita naa ba iṣẹ de.
Wọ́n dé ilẹ̀ náà, wọ́n sì gbà á; ṣugbọn wọn kò gbọ́rọ̀ sí ọ lẹ́nu, wọn kò sì pa òfin rẹ mọ́.
Ko tan sibẹ o, eso yii tun jẹ ara eso ti ko se ko pamọ fun igba pipẹ, eyi to n mu ka maa jẹ eso rẹ ni ajaabalẹ.
Baalu eleyi yatọ si 737 Max to jabo ninu ijamba ofurufu meji kan to waye laipẹ yi.
"Ruiz to jẹ ọmọ orilẹede America ati Mexico, ninu ọrọ to sọ lẹyin idije naa sọ pe ""ala mi ti wa si imuṣẹ bayii."
E̩nì kò̩ò̩kan ló ní è̩tó̩ tó dó̩gba láti s̩e is̩é̩ ìjo̩ba ní orílè̩‐èdè rè̩.
Gbogbo eniyan sì ń sọ̀rọ̀ rẹ̀ ní rere.
Ṣugbọn Rehoboamu kọ ìmọ̀ràn àwọn àgbà.
Childhood Games: Ewo nínú àwọn eré ìdárayá ilẹ̀ Yorùbá tẹ ṣe ní kékeré wo lẹ fẹ́ràn jù?
Ìyá mi ń bẹ lónìí, ṣùgbọ́n bàbá mi kò sí, ṣùgbọ́n ọ̀ràn ikú bàbá mi dùn mí gidigidi.
ti salaye pe isejoba Gomina Seyi Makinde ko ni faaye gba dida idoti soju popo mọ.
Mibayii iye awọn to ti jalaisi nipasẹ ajakalẹ arun naa lorilẹede Naijiria ti di ẹgbẹrin ati mẹtalelọgbọn.
A ti yanjú ìṣẹ̀lẹ̀ ìjàmbá ọkọ̀ agbépo tó dànù lágbègbè AIT, Alagbado - LASEMA Cardi B ṣàlàyé ohun tó gbé fọ́tò ìhòhò rẹ̀ d'órí ayélujára Instagram Ìdí táwọn olùwọ́de EndSARS fi kọ oúnjẹ àti ọtí ẹlẹ́rìndòdò tí MC Oluomo gbé wá rèé Wo nọ́mbà tí o le è pè láti gba owó gbà-má-bínú tí ọlọ́pàá bá fìyà jẹ ọ́ lọ́nà àìtọ́ l'Eko Wo ìgbésẹ̀ mẹ́ta tí Gómìnà Obiano gbé lórí ọ̀rọ̀ SARS ní Anambra Kini o ti kọkọ ṣẹlẹ?
Ibi ni n óo ṣe yín, n kò ní ṣe yín ní oore.
Aarẹ Oluṣegun Obasanjo lo yan Ribadu sipo gẹgẹ bi alaga akọkọ fun ajọ EFCC.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Novak Djokovic: Ògbóǹtarìgì agbábọ́ọ̀lù tẹníísìì Novak Djokovic ti lùgbàdì coronavirus 23 Òkùdu 2020 Oríṣun àwòrán, Instagram/djokernole Gbajugbaja agbabọọlu tẹnisii, Novak Djokovic ti lugbadi aarun coronavirus.
Àwọn ará Kalidea kan wá siwaju ọba, wọ́n fi ẹ̀sùn kan àwọn Juu pẹlu ìríra, wọ́n ní, 
Awọn ọmọde ti ọjọ ori wọn ko to ọdun maarun lo wa ninu ewu ju: L'ọdun 2017, awọn lo ko ìdá mọkanlelọgọta(266,000) ninu awọn ti ibà pa l'agbaye.
O Fagunwa kú, dúkìá rẹ̀ sì ń fọhùn síbẹ̀, ilé rẹ̀ rèé Samuel Ladoke Akintọla jẹ́ Agbẹjọ́rò àti Akọ̀ròyìn tí ọ̀rọ̀ dá lẹ́nu rẹ̀ Ayinla Ọmọwura, orin èébú àti oríyìn lo fi di ọ̀rẹ́ àwọ̀n obìnrin Taiwo Akinkunmi, ọmọ Ibadan tó ya àsìá Nàíjíríà Lọ́sẹ̀ yìí, ilú Akure ní ìpínlẹ̀ Ondo ni BBC Yorùbá tún ti rí Kàyééfì yii o.
Awọn ọlọ́pàá ti mu àwọn ole ti won jalè ni Ọfa ti wọn ṣe ikú pa ọpọlọpọ ènìyàn.
Eyi tumọ si pe wọn ko lanfani ati lọ sileewe girama bayii.
Laycon Oríṣun àwòrán, BIG BROTHER NAIJA Laycon, ti ọpọ gbagbọ pe oun ni yoo jawe olubori ninu eto Big Brother Naija fun ọdun 2020, naa ti jẹ ọpọlọpọ ẹbun nibi awọn idije to waye.
Dafidi bá dáhùn pé, “Àwọn ọmọ Lefi nìkan ni wọ́n gbọdọ̀ ru Àpótí Majẹmu OLUWA, nítorí àwọn ni Ọlọrun yàn láti máa rù ú, ati láti máa ṣiṣẹ́ ìsìn rẹ̀ títí lae.
O fi sori oju opo Ayelujara rẹ aarẹ fẹnuko lori igbesẹ naa lẹyin ipade kan to waye laarin minisita feto ilera, oun atawọn akọṣẹmọṣẹ miran lati ṣe agbeyẹwo ọwọja arun Coronavirus lori ere idaraya naa.
Ki se wi pe o jale tabi o wuwa odaran sugbọn o se oun manigbagbe kan pẹlu bi o ti se jẹ obinrin orileede Japan akọkọ ti yoo de asekagba idije Grand slam lawn tennis ti o si gba ife ẹyẹ naa.
Orí ìdúró ni mo ti wo ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ Nàìjíríà àti Hungary tán- Mínísítà Háà!
Oríṣun àwòrán, Femi Joseph Àkọlé àwòrán, Afurasí alásè gún ọ̀gá rẹ̀ pa Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ọ̀kùnrin ọdún 75 gbẹ́mìí mì nínú odò Ọ̀sà l'Eko Ganduje: Mi Ò gba rìbá lọ́wọ́ ẹnikẹ́ni rí láyé mi Kí ló fà á tí àwọn ọmọ Obasanjo ń ta kò ó ní gbangba?
Agbenusọ fun ile isẹ ọlọọpa ni ipinlẹ Ondo ni iwadii ti bẹrẹ ni pẹrẹwu lori isẹlẹ naa.
Àpótí Ẹ̀rí Bọ́ Sọ́wọ́ Àwọn Ará Filistia.
38 Gbàdúrà nígbà gbogbo, èmi yíò sì tú Ẹ̀mí mi sí orí rẹ, àti pé púpọ̀ ni ìbùkún rẹ yíò jẹ́—bẹ́ẹ̀ni, àní ju bí ìgbà tí ìwọ rí àwọn ohun ìṣúra ti ayé ati àwọn ohun àìtọ́ gbogbo ní ìwọ̀n bí ó ṣe tó.
Ní tèmi, olùpọ́njú ati aláìní ni mí;ṣugbọn Oluwa kò gbàgbé mi.
- CAN Oríṣun àwòrán, Catholic Church of Nigeria Ẹgbẹ́ ọmọlẹ́yìn Kírístì ni Nàìjíríà (CAN) ti rọ àwọn ìjọ ni gbogbo ìpinlẹ̀ Nàìjíríà, tó fi mọ ìlú Abuja, láti tẹ̀lé gbogbo ìlànà ìjọba lórí ọ̀rọ̀ Covid-19.
’ ‘A fi ọrọ yii sita ki awọn araalu le mọ otitọ nipa iṣẹlẹ naa, ki wọn si dẹkun ati ma a wu iwa aitọ.
Nítorí náà Eleasari ati Itamari ní ń ṣe iṣẹ́ alufaa ní ìgbà ayé Aaroni, baba wọn.
Ṣugbọn ọrọ rẹ yii kọ ẹyin si awọn iroyin to n ti ipinlẹ naa jade wipe, lẹnu ọjọ mẹta yii, awọn awọn janduku oju popo ti pa awọn awakọ ati arinrinajo ni popona Ibadan si Ife, ati oju ona Iwaraja ni agbegbe Ilesa.
Kí n tó fura,ìfẹ́ tí ṣe mí bí ẹni tí ó wà ninu ọkọ̀ ogun,tí ara ń wá bíi kí ó bọ́ sójú ogun.
Jehoṣafati dojúbolẹ̀, gbogbo àwọn ará Juda ati àwọn ará Jerusalẹmu náà bá dojúbolẹ̀, wọ́n sì sin OLUWA.
Namibia yii naa lo wa ni ipo kẹwa lagbaye ninu abọ iwadi nipa alafo to n bẹ laarin akọ ati abo lọdun 2018, to si n lewaju orilẹede Germany ati ilu Ọ́ba, UK.
Jesu wá kìlọ̀ fún wọn gan-an pé kí wọn má jẹ́ kí ẹnikẹ́ni mọ̀.
CP Odumosu Akeem - CP Edo Command Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 3 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 5 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Nigba ti wọn beere lọwọ awọn ọmge naa pe, ki lo se wọn, ni wn ba salaye pe awọn alọkolohunkigbe meji lo fi ibọn gba ohun ini awọn, ti wọn si tọka ọna tawọn ole ọhun morile fun awọn ọlọpa.
Atejade ohun wa n ro awon orile-ede laagbaye lati fungun mo olori orile-ede DRC lati fori alefa sile, tori pe, fifi ori alefa ohun sile, yoo faye gba akokun eto ijoba tiwa-n-tiwa lorile-ede naa.
''Bí Ààrẹ bá fẹ mo òun ti a n ṣe, ara rẹ ni abadofin náà'' Oríṣun àwòrán, facebook/Dino Melaye Àkọlé àwòrán, Senato Dino Melaye ni oun fẹ kí Ààrẹ Buhari tọrọ aforijin lọwọ ilé Lẹnu ọjọ mẹta yìí, Senato Dino Melaye àti ilé iṣé ọlọ́pàá, to fi mọ Gómìnà ipinle rẹ Kogi, ti n bá ará wọn fà wàhálà.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Deji Adenuga : Ìdí tí mo fí jó èèyàn mẹsan mọ ilé 30 Ìgbé 2019 Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Deji Adenuga : Ìdí tí mo fí jó èèyàn mẹsan mọ ilé Arakunrin ti ọlọpaa ṣe afihan rẹ nitori pe o dana sun mọlẹbi ọrẹbinrin rẹ mẹsan mọle ti salaye ohun to mu hu iru iwa bẹ.
Àánú àwọn ọmọ Bẹnjamini bẹ̀rẹ̀ sí ṣe àwọn ọmọ Israẹli nítorí pé OLUWA ti dín ọ̀kan kù ninu ẹ̀yà Israẹli.
Eliṣa dáhùn pé, “O kò gbọdọ̀ pa wọ́n, ṣé o máa pa àwọn tí o bá kó lójú ogun ni?
Ibanuje d'orí agbà k'odò, Ruiz fi ẹ̀ṣẹ́ sọ Anthony Joshua di ọmọ ológo àná Eyi ni ọrọ aṣoju ileeṣẹ to n ṣe ajọṣepọ pẹlu ile iwe kan ni agbegbe Ajegunle to gba obi laye lati maa fi ike san owo ile iwe àwọn ọmọ.
Báwó ni òògùn dexamethasone ṣe ń ṣiṣẹ́ lára Ohun méje tí o kò gbọ́ rí nípa aláìsàn arunmọ-léegun- Dókítà Igbekele A o gbiyanju lati se atupalẹ diẹ ninu wọn ni meni meji.
Ó bi wọ́n pé, “Ìba oúnjẹ wo ni ẹ ní?
Ẹnikẹ́ni tí ó bá súnmọ́ ibi mímọ́, pípa ni kí wọ́n pa á.
 O ti sere ati fiimu lorisiirisii lede oyinbo ati ni ede abinibi re bii “No Pain No Gain”  ati “Nkan Adun.
Jesu bá wò wọ́n lójú, ó ní, “Ǹjẹ́ kí ni ìtumọ̀ àkọsílẹ̀ yìí,‘Òkúta tí àwọn ọ̀mọ̀lé kọ̀ sílẹ̀,òun ni ó di òkúta pataki ní igun ilé.
Wolii ará Juda náà bá mú kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ gùn, ó ń lọ.
BBC Yoruba ṣe akojọpọ diẹ lara awọn ẹsun iwa ibajẹ ti ajọ EFCC ṣagbatẹru rẹ lati igba ti Ibrahim Magu jẹ alaga ajọ naa.
Àjọ ìṣọ̀kan àgbáyé UN ti fọmọ ogun apẹ̀tù-síjà ránṣẹ́ sí Mali Adebo bórí l'Oyo, Oluomo ní ìpínlẹ̀ Ogun gẹ́gẹ́ bí adarí ilé aṣòfin Ààrẹ Buhari ṣẹ̀ṣẹ̀ tẹ́wọ́ gba ìwé ìfẹ́yìntì Onnoghen Ìpínlẹ̀ Oyo gba ipò ìkíní mọ́ Edo lọ́wọ́ nínú fífí ọmọdé ṣ'ẹrú Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, BBC Africa Eye: Akọroyin fẹ ìdí àwọn oníṣẹ́ ibi ọmọ ogun síta Koda, ko si idije ife ẹyẹ bọọlu ajọ FIFA kankan ti irufẹ eyi ti ṣẹlẹ.
ati egbe osise fikun-lukun loorekoore , ni eyi ti yoo tun je ki ilosiwaju ba
"Mo sọ fún wọ́n pé mi ò lé fún wọ́n ni iye owó náà, wọ́n gbé wá silẹ̀ si ìdajì mílíọnu Naira, mó ni mí olè sán-án, wọ́n padà ni kí ń san ẹgbẹ̀run ogójì náírà dín ni ọ̀dúnrun owó.
O ni: “Iru iwa tabi igbagbo abe dida fomobinrin ko je itewogba rara nitori ko nii fi se igbagbo, esin , iran, asa tabi ise iru awon eniyan ti won n see.
Liverpool to wa loke tente tẹlẹ lo ti wa nipo keji ti Man City si n fi ami ayo kan siwaju.
 síbẹ ̀ síbẹ ̀ , ọ ̀ pọ ̀ àwọn ìletò kòsí mọ ́ .
Nítorí náà, OLUWA bínú sí àwọn ọmọ Israẹli, ó sì run wọ́n kúrò níwájú rẹ̀, ṣugbọn ó fi Juda nìkan sílẹ̀.
O ni awọn eroja ara bii vitamin E, zinc ati protein eleyii ti o fun awọn agọ ara awọn eniyan lati ṣiṣẹ.
Awon to kopa ninu eto naa gba pe ti odun yii tun dun ju ti ateyinwa lo nitori pe awon alawo funfun naa kopa nibe yato si ti ateyin wa.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, BBC Africa Eye tú àṣírí ìfìyàjẹni àwọn òṣìṣẹ́ aláàbò Farotimi sọ fun BBC Yoruba pe, Aarẹ Buhari ko tẹle ofin lo jẹ ki wọn maa pa eeyan ninu ijọba rẹ, ti ko si ṣe bi ẹni pe nkan babara n ṣẹlẹ.
Àlàyé rèé lórí ááwọ̀ Femi Fani-Kayode àti Tunde Bakare Ọmọ ẹgbẹ́ òkùnkùn mẹ́ẹ̀dógún wọ gàù ọlọ́pàá ségí ní Eko Àwọn àjàkálẹ-àrùn tó ti wáyé rí ṣáájú Coronavirus Ta ni Ọ̀jọ̀gbọ́n àkọ́kọ́ nípa ìmọ̀ ọ̀daràn ní Nàíjíríà, Femi Odekunle tí Covid-19 pa?
ng Awọn ile iwe ti ko ba ni agbra lati pese awọn ilana aatẹle yii ni oore ọfẹ lati ṣi fi awọn akẹkọọ wọn sile nile obi ati alagbatọ wọn.
Pẹlu ìrànlọ́wọ́ àwọn tí ń bọ oriṣa àjèjì kan, yóo bá àwọn ìlú olódi tí wọ́n lágbára jùlọ jà.
O gba awọn ọdọ bii tirẹ ni imọran lati tọju iwa wọn daadaa nitori iwalẹwa ọmọ eniyan.
Ṣugbọn ẹ̀ ń lérí, ẹ̀ ń fọ́nnu; irú ìlérí báyìí kò dára.
Sibẹsibẹ ò ń bèèrè pé, ‘Kí ni Ọlọrun mọ̀?
Kí ọkọ̀ méjì má tíì kọlu arawọn làá ti gbọ́ pé wọ́n gbiná wọ́n sì jóná ráú-ráú lójú òpópónà.
O ni Eeyan meji lo padanu ẹmi wọn ninu iṣẹlẹ naa ṣugbọn a ko tii le sọ awọn ileeṣẹ to ni awọn ọkọ mejeji."
7 Bélú 2020 EndSARS Protest Update: Sowore ní ikọ̀ ọlọ́pàá yìnbọn fún òun lọ́jọ́ Ajé12 Bélú 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 3 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 5 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Mùsùlùmí ni mí ṣùgbọ́n ìrírí àkọ́kọ́ mi rèé nípa ọdún Kérésìmesì ní Canada, Muhammad Hussain ṣàlàyé 25 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Oríṣun àwòrán, Mohammad Hussain Àkọlé àwòrán, Mohammad Hussain pẹlu awọn akẹgbẹ rẹ nibi ti wọn ti n palẹmọ de ọdun Keresi Iriri akọkọ arakunrin ẹlẹsin musulumi kan nigba ọdun keresi to fi soju opo Twitter ti di ohun tawọn eeyan n pin kaakiri.
Jeṣua, Bani, ati Kadimieli, Ṣebanaya, Bunni, Ṣerebaya, Bani, ati Kenani dúró lórí pèpéle àwọn ọmọ Lefi, wọ́n sì gbadura sókè sí OLUWA Ọlọrun wọn.
"Tí òṣèré tíátà yóò fi kú, eré ni wọn yóò ló ń ṣe - Ibrahim Chatta Ẹ wo nkan tí àwọn akẹẹgbẹ́ Lateef Adedimeji sọ nípa f'ọ́tò ìgbéyàwó òun àti Adebimpe tó jáde Ọkọ Funke Akindele kó eléré àti òṣìṣẹ́ jọ fi ṣe ""Surprise Pato"" fún un lọ́jọ́ ìbí rẹ̀ Ọdún méjì, wàhálà méjì lójúbọ Osun Osogbo, Kí ni apẹ̀rẹ̀ ikòlẹ̀sí ti Eko fi yàtọ̀ sí ti Ekiti tí ọ́ọ́físà mú wa mọ́lẹ̀?"
Obaseki - BBC News Yorùbá BBC News, YorùbáFò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù AFCON Qualifier: Kò séwu fún gbogbo àwọn tí yóò kópa nínú ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ Naijiria àti Sierra Leone ní Benin - Obaseki 1 Bélú 2020 Oríṣun àwòrán, @daily_trust Gomina ipinlẹ Edo, Godwin Obaseki ti sọ pe abo to peye yoo wa fun gbogbo awọn agbabọọlu atawọn ero iworan ti yoo wa nibi ifẹṣewọn laarin ikọ Super Eagles ati Leone Stars ti orilẹ-ede Sierra Leone lọsẹ to n bọ.
Ìyá Siasia kúrò lákàtà àwọn ajínigbé lẹ́yìn oṣù méjì ààbọ̀ Fábàdà!
“Yan ọkunrin mejila láàrin àwọn eniyan náà, ẹnìkọ̀ọ̀kan láti inú ẹ̀yà kọ̀ọ̀kan.
Agbẹnusọ ajọ naa, Kayode Adegoke, kede awọn ilana tuntun yii lọjọ Iṣẹgun, ninu atẹjade kan pe ilana kikọkọ fi orukọ silẹ ni ajọ naa yoo ma lo bayii.
dì wọ́n lámùrè, kí o sì dé wọn ní fìlà.
Ẹni tí ó bá lọ lóyún, tí ó lọ bímọ, kí ó tó gbé ìyàwó, ó sọ epo di àbàwọ́n nìyẹn.
Ile-igbimo asofin ni won ti gbe igbese lojoRu ose yii lati sewadii lori bi won se yo ise akanse oko oju irin ti ila oorun kuro nibe, ni eyi ti won fe se atunse lori re ni  jake jado orile ede Naijiria.
Tolulope Arotile: Wo àbájáde ìwaádìí iléeṣẹ́ ológun òfúrufú lórí ikú awakọ̀-òfúrufú jagun obìnrin àkọ́kọ́ ní Naijiria Wọn ni awakọ ọhun, Nehemiah Adejoh ko ni iwe aṣẹ lati wa ọkọ loju popo.
Iroyin kan fi ye wa pe koda, Adekunle tun ti fọwọsi iwe adehun kan fun sise Rọbọti, eyi ti owo rẹ to aimọye miliọnu dọla.
Irú ìbéèrè wo ni mo le bí àwọn elétò ìlera mi?
 Ó gbé ipò kẹfà nínú ìfẹsẹ ̀ -wọnsẹ ̀ ti 200 metres nínú id ̀ íje 1994 commonwealth games .
Lara ohun ti wọn kọ nipa rẹ loju opo BB Naija, wọn ni o figba kan fẹ gbẹmi ara rẹ.
Gẹgẹ bi ikede ti ajọ naa fi sita, owo itanran ti wọn yoo san wa laarin miliọnu meji si miliọnu mẹta Naira.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Awakọ̀ 3rd Mainland Bridge: Ìjọba ko yanjú súnkẹrẹ fàkẹrẹ ọ̀nà Apapa Iṣoro nla ni sunkẹrẹ-fakẹrẹ ọkọ n ko o ba awọn to n gbe ni agbegbe Apapa, ti wọn si n fi ojoojumọ fi ibanujẹ han lori awọn ọna ti ko dara.
Lọna ati lee mu ala rẹ dohun, Ọjọgbọn Balogun lọ kọ bi wọn ṣe n ṣe iṣẹ agbẹ Amẹrika fun oṣu mẹfa ki o to wa bẹrẹ ti ara rẹ gan an.
“Nígbà tí ó fẹ́rẹ̀ tó àkókò tí ìlérí tí Ọlọrun ṣe fún Abrahamu yóo ṣẹ, àwọn eniyan náà wá túbọ̀ ń pọ̀ níye ní Ijipti.
Ìran tí Ọbadaya rí nìyí, OLUWA Ọlọrun sọ nípa Edomu pé:A ti gbọ́ ìròyìn láti ọ̀dọ̀ OLUWA,ó sì ti rán iranṣẹ rẹ̀ sí àwọn orílẹ̀-èdè pé:“Ẹ múra, ẹ jẹ́ kí á lọ bá Edomu jagun!
” Àwọn ọba mẹtẹẹta náà bá lọ sọ́dọ̀ rẹ̀.
Aba yi ko sẹyin bi asofin agba, Magnus Abe ati awọn mejilelogun miran, se gbe ọrọ naa ka'lẹ, gẹgẹ bi ọrọ pajawiri, lati se ofintoto lori bi ile-isẹ ifowopamọ apapọ se n yọ owo layọju ati lọnọ aitọ lọwọ awọn eniyan.
Nígbà tí jamba bá ń ṣẹlẹ̀ káàkiri,yóo máa dé ba yín.
Bakan naa ,gomina ipinle Eko ,
Iwe igbọraẹniye ọhun lo wa lati wa ojutu si bi awọn ọmọ ilẹ South Africa se maa n kọlu awọn ajeji to wa lorilẹede wọn.
Ìwọ lágbára lórí ẹyẹ ojú ọ̀run àti lórí ẹja inú òkun, lórí eweko orí ilẹ̀ àti lórí àwọn kòkòrò kéékèèkéé.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ààrẹ Buhari: Irọ́ ni pé Leah Sharibu ti kú sí àhámọ́ Boko Haram 10 Èrèlè 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 11 Èrèlè 2019 Oríṣun àwòrán, Google Àkọlé àwòrán, Ààrẹ Buhari: Irọ́ ni pé Leah Sharibu ti kú sí àhámọ́ Boko Haram Lẹyin to ku ọsẹ kan ki idibo gbogboogbo ko waye ni orilẹede Naijiria, iya Leah Sharibu ti awọn ikọ agbesunmọmi Boko Haram jigbe lọdun to kọja ti ke gbajare si ijọba apapọ.
Okunnu wa tún gba àwọn aráàlú nímọ̀ràn láti máa tẹle asẹ ìjọba, pàápàá gẹ́gẹ́ bo se kan amojuto itankalẹ àrùn Coronavirus àti igbele, nítorí àlàáfíà wà àti ti gbogbo ìlú lọ ja ju.
Ẹ ṣọ́ra gidigidi, ẹ má gbàgbé majẹmu tí OLUWA Ọlọrun yín ba yín dá, ẹ má sì yá èrekére fún ara yín, ní àwòrán ohunkohun, nítorí pé, OLUWA Ọlọrun yín lòdì sí i.
wa bayii ni isuna, eleyi ti a si ti jiroro lori re ninu ipade yii, ti o fi mo
APC Ekiti pàṣẹ lọ rọ́ọ́kún nílẹ̀ fún àna Tinubu àti Babafemi Ojudu Ẹ gbọ́ òhun tí àwọn olùdíjé sípò gómìnà nípínlẹ̀ Ondo sọ nípa Bàbá ìsàlẹ̀.
Oṣu Kẹwaa, ọdun 2017, ni wọn yọ Lawal kuro nipo lẹyin ti wọn fi ẹsun kan pe o na N544m ni inakuna lati fi ge koriko.
Ajihinrere Mike Bamiloye ni,ọrọ naa ko ni itumọ kankan lodi si oriṣiriṣi itumọ ti awọn eeyan n fun un.
O ni otitọ nipe iṣede kaakiri orilẹede Naijiria yoo mu idiwọ ba awọn onimọtọ atawọn mii ti iṣẹ wọn jọ mọ ki wọn maa rinrin ajo.
Ọjọ kọkandinlogun, oṣu Keji, ọdun 2018 ni ikọ agbesunmọmi Boko Haram ji awọn akẹkọbinrin naa gbe nileewe wọn to wa ni ilu Dapchi, nipinlẹ Yobe.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Yoruba Language: BBC Yoruba ń gbìyànjú kí èdè má parun Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Yoruba Language: BBC Yoruba ń gbìyànjú kí èdè má parun 24 Ọ̀wàrà 2018 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 29 Èbibi 2020 Ọ̀rọ̀ kìí tóbi títí ká fi ọ̀bẹ bù ú.
2 x General Purpose Machine Gun.
Kí èyí lè jẹ́ ohun ìrántí fun yín, nígbà tí àwọn ọmọ yín bá bèèrè lọ́wọ́ yín ní ọjọ́ iwájú pé, ‘Báwo ni ti àwọn òkúta wọnyi ti jẹ́ rí?
Iranṣẹ náà bá bẹ̀rẹ̀ sí wo àpò wọn, ó bẹ̀rẹ̀ lórí àpò èyí àgbà patapata, títí dé orí ti àbíkẹ́yìn wọn, wọ́n bá ife náà ninu ẹrù Bẹnjamini.
 bí a ti rí àwọn tó jẹ ́ pé wọn kò ní ẹ ̀ sìn méjì ju ẹ ̀ sìn ìbílẹ ̀ ni a rí àwọn mìíràn tó wà nínú àwọn ẹ ̀ sìn ìgbàlódé wọ ̀ nyí síbẹ ̀ tí wọn tún ń nípa nínú bíbọ àwọn òrìṣà inú ẹ ̀ sìn ìbílẹ ̀ .
kí ó tó já Ààrẹ Algeria kò ní pẹ́ kọ̀wẹ́ fipò sílẹ̀ Ahmed Musa gbàmì ẹ̀yẹ agbábọ́ọ̀lù tó pegede ní ọdún 2018 Àwọn olùgbé Fiditi pé fún ìrànlọ́wọ́ lórí àwọn òrùlé tí atẹ́gùn ojó ṣí lọ Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Dokita Akerele ni bo tilẹ jẹ pe lilo igbo gẹgẹ bii oogun dara, abojuto ọrọ oogun lilo ni orilẹede Naijiria ko dara to.
Awọn nkan to ka silẹ re e pe aarl ti ṣe lati din ajakalẹ arun naa ku ni Naijiria: Ka le mu adinku ba laarẹ ṣe paṣẹ ki wọn o fofin de awọn arinrinajo lati orilẹ-ede mẹtala, to ni ju ẹgbẹrun eniyan to ni arun naa lọ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Àgbà ni Obasanjo, oun tó ń sọ yé e, ìjọba ni kó tají - Wale oke Muhammadu Buhari Àkọlé àwòrán, Ààrẹ Muhammadu Buhari Ààrẹ Muhammadu Buhari ni ààrẹ ikeeje ati ikẹẹdogun ti orilẹede Naijiria ti wn yoo bura wọle fun ni ọjọ kọkandinlogun oṣu karun-un dun 2019.
Ijoba orile-ede Cameroon fesun kan awon egbe naa pe, won n da laasigbo sile ni ekun apa ariwa ila-orun ati iwo orun-gusu , agbegbe ti a mo si elede Geesi ohun ni laasigbo ti n waye laarin awon alatileyin ijoba ati awon elede Geesi naa.
si gbọdọ ṣisẹ yi ni pipe gẹgẹ bi ọlọpaa ti o n ṣo owo ilu.
Ikédé ìjọba tó wáyé lọ́jọ́ ajé yìí kò kan àwọn tó ti ni físà ilẹ̀ Amẹrika lọ́wọ́ tẹ́lẹ̀.
Ìtàn fi yé wa wi pé Yorùbá ka ọ̀rọ̀ obinrin si ni àṣà Yorùbá  bi ó ti ẹ jẹ wi pé obinrin ki jẹ Ọba nitori ni àṣà ilú, ọkunrin ló njẹ olóri.
Bakan naa tun ni ijọba Naijiria n beere lọwọ ilẹ South Africa pe ko fi awọn ọlọpa Naijiria sinu awọn ọlọpa ilẹ South Africa, ki wọn si tun wa lara awọn asoju ilẹ wa ni South Africa.
Wọn yóo wá di agbo kan lábẹ́ olùṣọ́-aguntan kan.
Olaniyi Olaniyan - BBC News Yorùbá BBC News, YorùbáFò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Mò ń fi lẹ̀kẹ̀ ya àwọnran láti jèrè ǹkan méjì - Olaniyi Olaniyan Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Mò ń fi lẹ̀kẹ̀ ya àwọnran láti jèrè ǹkan méjì - Olaniyi Olaniyan 9 Ìgbé 2019 Botilẹ jẹ pe Olaniyi Sunday Olaniyan bẹ̀rẹ̀ iṣẹ́ àwòràn yíyà rẹ̀ ni ibi kékére sùgbọ̀n lónìí, ó jẹ́ ọkan lára àwọn to ń ṣe ǹkan àrà ọ̀tọ̀.
Àwọn ọmọ Ara jẹ́ ẹẹdẹgbẹrin lé marundinlọgọrin (775)
Sibẹsibẹ àwọn eniyan ṣì ń rúbọ ní àwọn ibi ìrúbọ, ṣugbọn OLUWA Ọlọrun wọn ni wọ́n ń rúbọ sí.
Idajo meji to waye lojo Eti lori oro naa.
Idà ni yóo ṣá a ní apá, yóo sì bá a ní ojú ọ̀tún, apá rẹ̀ óo rọ patapata, ojú ọ̀tún rẹ̀ óo sì fọ́ patapata.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Bakare Mubarak: ọ̀pọ̀ èèyàn ló máa ń fẹ́ dúró sí ẹgbẹ́ mí tójú si máa n tì mí Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Bakare Mubarak: ọ̀pọ̀ èèyàn ló máa ń fẹ́ dúró sí ẹgbẹ́ mí tójú si máa n tì mí 14 Sẹ́rẹ́ 2020 Mo fẹran Iyán ati ọbẹ ẹfọ riro pupọ- Bakare Mubarak Arinrinoge to ga julọ nilẹ Adulawọ, Mubarak Bakare ba BBC lalejo nibi to ti sọ bi oun ṣe bẹrẹ irin ajo rẹ lẹnu iṣẹ arinrinoge.
Ó tún pe ara rẹ̀ ní Mesaya, Ọba.
Ile-ise to n mojuto oro epo robi
Ọ̀lẹ ti ọwọ́ bọ àwo oúnjẹ,ṣugbọn ó lẹ kọjá kí ó lè bu oúnjẹ kí ó fi bọ ẹnu.
Ó kọ ọ̀rọ̀ náà sinu ìwé òfin Ọlọrun, ó gbé òkúta ńlá kan, ó sì fi gúnlẹ̀ lábẹ́ igi Oaku, ní ibi mímọ́ OLUWA, 
2m) to din diẹ ni ida mẹtadinlaadọta (46.
Ṣùgbọ́n ki ni kan ba aja o jẹ́, apá ẹranko náà gùn ju itan lọ, àwọn ọkùnrin mẹ́ta t;i wọ́n jẹ́ aṣáájúnínú àwọn ọmọ ọba yìí kò ní obìnrin.
Public Anger: Irú ọ̀rọ̀ wò láwọn olóṣèlú Nàìjíríà márùn ùn yí sọ tó mú ìbínú ará ìlú wa?
Gbogbo ilẹ tó yí oke Arafat ká ní ilẹ mimọ.
Èyí yóo tẹ́ Ọlọrun lọ́rùn ju akọ mààlúù lọ,àní, akọ mààlúù tòun tìwo ati pátákò rẹ̀.
Ahmed Rufai ati awon oga agba ile-ise ijoba apapo.
Ṣugbọn ni ti eleyi, akẹkọọ kan lo gbe lọ si ile ẹjọ pẹlu alaye pe aye ati ilu gan ti yi pada ti ọpọlọpọ si ti f'ofin gba a kaakiri agbaye.
Ọkunrin náà ati obinrin náà wà ní ìhòòhò, ojú kò sì tì wọ́n.
Àwọn ọmọ ènìyàn kò jẹ́ wí pé ibi tí àwọnn dé yìí tó, wọn a máa wí pé ó kù díẹ̀ títí ọjọ́ ikú wọn.
Ó ru agbelebu rẹ̀ jáde lọ sí ibìkan tí ó ń jẹ́ “Ibi Agbárí,” tí wọn ń pè ní “Gọlgọta” ní èdè Heberu.
"Àwọn àwòrán ìrántí tó ń sàmì ogójì ọdún tí Ọba Adesoji Aderemi jáde láyé Ìdí tí ìjóba ìpínlẹ̀ Eko fí ṣí àwọn ilé ìwé kan padà Wo awọn Aàrẹ nílẹ̀ Áfríkà to ti gba oyè ""Field Marshal"" rí Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!"
Auxiliary: Alága àjọ Park Management System, gbé àwọn tó ń ja ìjọba lólè ní ibùdókọ̀ lọ sí ilèẹjọ́
Adájọ́ àgbà ìpínlè Kogi jẹ́ Ọlọ́run nípè nílé ìtọjú àwọn àláàrùn Covid-19 Ẹ wo àwòrán bí ìsìnkú Abiola Ajimobi ṣe lọ!
Àhámọ́ EFCC ni Mohammed Adoke yóò ti ṣe kérésì ‘Pussypedia’ rèé, ojú òpó tó ń mú àdínkù bá ìṣòro ìmọ̀ nípa ẹ̀yà ara obìnrin Wọn pa ọlọ́pàá kan níbi tí wọ́n ti dáná sun ìjọ Sotitobire l'Akurẹ - Police PRO Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Èyí ni ìtàn bí ẹni tí mó gbọ́njú mọ̀ bíi bàbà ṣe fipá bá mi lájọṣepọ̀ Maha ti a fi orukọ bo ni aṣiri ti le ni ogun ọdun, o si jẹ akẹkọọjade ni fasiti kan, wa lati Ariwa orilẹede Sudan.
Wọ́n tún pe ọkunrin náà tí ó ti fọ́jú rí lẹẹkeji, wọ́n wí fún un pé, “Sọ ti Ọlọrun!
Nítorí kí ọ̀ràn mi má ba dà bí àṣejù, ki wọ́n má ba sọ olúwaarẹ̀ lórúkọ, wọn a si wí pé olúwaarẹ̀ kì í ṣe ọmọlúwàbí, eléyìínì náà ló jẹ́ kí n ṣe ojú ayé ní tèmi, nítorí kíkí tí mo kí i kò ti inú ọkàn mi jáde.
Ninu atejade kan lati ile-ise re, o tesiwaju wi pe alekun yoo  de ba eto abo ninu ile igbimo asofin naa.
Nǹkan díẹ̀ tí olódodo nídára ju ọ̀pọ̀ ọrọ̀ àwọn eniyan burúkú.
"Èsì àyẹ̀wò tí àjọ NCDC gbé síta fihàn pé ènìyàn 265 ló tún ti ní ààrùn Covid-19 ní Nàìjíríà Wo ohun tí a mọ̀ nípa iléeṣẹ́ ""ISON Xperiences"" tí òṣìṣẹ́ 78 ti kó àrùn coronavirus ní Ìbàdàn 'Ìbọn dún láàfin Ọ̀ọ̀ni ilé ifẹ̀ lóòtọ́, ṣùgbọ́n kò séwù' Òṣèré tíátà, Ọmọba Femi Oyewunmi tí ọ̀pọ̀ mọ̀ sí Laditi ti jáde láyé ₦22."
Toun ti bẹẹ gbogbo awọn ẹgbẹ okunkun lo m an deru ba awọn eeyan bi wọn ba darukọ wọn.
Àwọn akẹgbẹ́ ẹ̀ṣọ́ àjọ FRSC mẹ́ta tí àrá sán pa l'Ogun gbọdọ̀ ṣ'ètùtù- Elebuibọn Oríṣun àwòrán, Twitter/FRSC Twitter Ikilọ ni iṣẹlẹ ara to san pa awon ẹṣọ alaabo oju-popo (Federal Road Safety Corps) meta, ti opo si farapa nipinlẹ Ogun.
“Nígbà tí gbogbo eniyan bá ń ròyìn yín ní rere, ẹ gbé, nítorí bẹ́ẹ̀ ni àwọn baba wọn ṣe sí àwọn èké wolii.
Wọn yóo ṣírò àkókò tí ó ti lò lọ́dọ̀ olówó rẹ̀ bí àkókò tí alágbàṣe wà lọ́dọ̀ rẹ̀.
Fulani nìkan kọ́ ló ń pa ènìyàn ní Naijiria -Tinubu 'Kristẹni lo n fara kaaṣa ikọlu fulani ju' 'Iha kokanmi Buhari lewu fun Nigeria' NBC fọwọ́ sí ìdásílẹ̀ ilé iṣẹ́ Fulani Radio Gani Adams kilọ f'awọn darandaran Nigba ti BBC News Yoruba tun gbiyanju ati gbọ tẹnu awọn gomina, paapaa nipasẹ ẹni to jẹ alaga ajọ awọn gomina lorilẹ-ede Naijiria, (Governors forum) Gomina Kayọde Fayẹmi ti ipinlẹ Ekiti, agbẹnusọ rẹ, to ba wa sọrọ lori tẹlifoonu ṣalaye pe, akọkọ igba kọ niyi ti ẹgbẹ kan yoo dide nihin tabi lọhun lati gbe aṣẹ kalẹ to si jẹ pe asan lasan ni.
 Ìyàtọ ̀ maa ń wà ní àwọn bacterial tí ó wọ ́ pọ ̀ , tí ó sì maa ń pọ ̀ sí tó bí ọgọ ́ rún sí ẹgbẹ ̀ rún ni ojú ara .
Kí á máa wo Jesu olùpilẹ̀ṣẹ̀ ati aláṣepé igbagbọ wa.
Nígbà tí wọn kò tíì pọ̀ pupọ,tí wọn kò sì jẹ́ nǹkan,tí wọ́n jẹ́ àjèjì níbẹ̀,
O wa lati ile olorogun, oun si ni ọmọ kẹfa ti wsn bi ninu ẹbi rẹ.
Lasiko to ṣe abẹwo ibanikẹdun si awọn eeyan Maiduguri, n ṣe ni awọn ara ilu n pariwo pe awọn ko fẹ ẹ mọ.
Èdùmàrè á jẹ́ ki ọdún na a tura o.
Ohun ti mo so lọdun 1984 lo n sele bayii.
Lẹ́yìn náà, yóo wá sí ibùdó, ṣugbọn ẹ̀yìn àgọ́ rẹ̀ ni yóo máa gbé fún ọjọ́ meje.
Buhari so pe ibasepọ laarin Naijiria ti orileede China laarin ọdun mẹta sẹyin ti se okunfa sise isẹ lori awọn nnkan amayerọrun orisirisi ti owo wọn le ni billionu maarun dola.
Awọn agbesunmọmi yii kọlu ọkọ ọmọ ogun ilẹ̀ Naijiria lasiko ti wọn n wọ aarin igbo Sambisa ni ariwa iwọ oorun Naijiria.
kan naa pẹlu aga onike mẹwaa to jẹ ti ijọ naa.
ẹgbẹ oṣelu naa fun ipo Gomina, Ọgbẹni Babajide Sanwo-Olu ati igbakeji rẹ
Gbajúmọ̀ gbọdọ̀ jẹ́ àwòkọ́ṣé rere torí bí ìràwọ̀ ṣe ń kú, ni òmíràn ń tàn - Foluke Daramola Small Doctor: Mo kórira igbó, ọtí àti sìgá nítorí màmá mi lòdì si Tọwọ́ tẹsẹ̀ laá fi gba ìrànwọ́ owó ẹ̀kọ́ Almajiri ní ìpinlẹ̀ Oyo- Alága Subeb Ẹlẹ́wọ̀n tẹ́lẹ̀ gboyè ìmọ̀ ìjìnlẹ̀ méjì lọ́gbà ẹ̀wọ̀n Eyi tumọ si wi pe Naijiria yoo bẹrẹ si ni fun awọn eniyan to wa ni ilẹ̀ okeere, ti wọn fẹ wa fẹyinti si orilẹ-ede Naijiria ni Iwe Irinna.
Bẹ́ẹ̀ ni Hiramu ṣe tọ́jú gbogbo igi kedari ati igi sipirẹsi tí Solomoni nílò fún un.
Ṣugbọn gbogbo fadaka ati wúrà ati àwọn ohun èlò idẹ ati ti irin jẹ́ ohun ìyàsọ́tọ̀ fún OLUWA, inú ilé ìṣúra OLUWA ni a óo kó wọn sí.
"Arabinrin Ehuriah sọ fun BBC pe ""ojoojumọ ni iru nkan bayii n ṣẹlẹ to ṣe pe tọkọ taya yoo fẹ rinrinajo lọ oke okun to si ṣe pe iwe ti ṣọ́ọ̀ṣì ti ko láṣẹ fun wọn ni wọn yoo na siwaju""."
O jọ bi ẹni pe awakọ naa ko fẹ fun ọlọpaa naa ni owo to ju ẹgbẹrun kan Naira lọ ti o si mu ki ọlọpaa naa pasamọ pe ''Ki wọn ma ji mọto gbe, ki wọn ma jale, Olorun gaan faramọ '' Fọnran naa re: Ọpọ Naijiria lo lodi si ohun ti ọlọpaa naa sọ lori ẹrọ ayelujara, ti wọn si n kesi ijọba lati ṣe atunto ileeṣẹ ọlọpaa.
 Ìtàn sọ wí pé ọmọ Ọ ̀ rányàn ni ṣàngó i ṣe àti pé Ọya , Ọ ̀ ṣun ati Ọbà jẹ ́ ìyàwó rẹ ̀ .
Nígbà tí Jesu wà ní agbègbè Jerusalẹmu ní àkókò Àjọ̀dún Ìrékọjá, ọpọlọpọ eniyan gba orúkọ rẹ̀ gbọ́ nígbà tí wọ́n ṣe akiyesi àwọn iṣẹ́ ìyanu tí ó ń ṣe.
Nígbà tí mo bá kó wọn pada láti inú oríṣìíríṣìí orílẹ̀-èdè, tí mo kó wọn jọ láti ilẹ̀ àwọn ọ̀tá wọn, n óo fi ara mi hàn bí ẹni mímọ́ lójú ọpọlọpọ orílẹ̀-èdè.
O kò fi ìfẹnukonu kí mi.
Samuel Ajayi Crowther: Baba nlá Herbert Macaulay, tó túmọ̀ Bíbélì sí Yorùbá
Kò ní iye ìgbà tí ó ti tù mí ninu, ninu ìṣòro mi.
Bakan naa, lo tun  salaye pe oun ati awon gomina ekun Gusu yii
Ní ìlú tiwa ṣá o, àti Kìrìstẹ́nì o, àti Mùsùlùmí o, àti Abọ̀ìṣà o, àjọjẹ lẹran Iléyá!
Pẹlu bi gbogbo oju ọjọ ṣe ri ni ilẹ naa, ọpọ awọn olutaja ọti ni wọn ṣi ṣọọbu wọn kalẹ ti wọn n reti onibara.
Bí mo bá tilẹ̀ wí pé mo ní ìrètí, tí mo sì ní ọkọ ní alẹ́ òní, tí mo sì bí àwọn ọmọkunrin, 
Ẹ̀tàn ni ojú dáradára, asán sì ni ẹwà,obinrin tí ó bá bẹ̀rù OLUWA ni ó yẹ kí á yìn.
Bí o bá pàdé ẹnikẹ́ni lọ́nà, má ṣe kí i, bí ẹnikẹ́ni bá kí ọ, má dáhùn.
Bakanna ni wọn maa n ṣe iwadi ti wọn naa lori awọn iṣẹlẹ iwa ọdaran.
Ijọba ti pinnu láti gbé ìgbẹ́sẹ̀ to nípọn lóri ẹni to ba ń sùn lẹ́nu iṣẹ́.
Nígbà tí wọ́n dé ita ibẹ̀, ọba pàápàá wà nínú ilé, nígbà tí ó sì yọ sí bàbá mi, ẹ̀rù ba bàbá mi.
Ṣugbọn baba ati ìyá rẹ̀ kò mọ̀ pé ọ̀rọ̀ náà ní ọwọ́ OLUWA ninu, nítorí pé OLUWA ti ń wá ọ̀nà láti mú àwọn ará Filistia nítorí pé, àwọn ni wọ́n ń mú àwọn ọmọ Israẹli sìn ní àkókò yìí.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Coronavirus protest: Àwọn Dókítà fáríga nípìnlẹ̀ Ondo,wọn ní kí Gomina san owó oṣù mẹ́ta tó jẹ wọ́n!
Ẹni tí OLUWA bá yàn ni yóo jẹ́ ẹni mímọ́; ẹ ti bẹ̀rẹ̀ sí kọjá ààyè yín, ẹ̀yin ọmọ Lefi!
Ní alẹ ọjọ kẹfa oṣu kẹrin ọdun 1994, ni àwọn kan yin baa lu to n gbe aarẹ Rwanda to jẹ ẹya Hutu nibọn Juvental Habyarimana bi o ṣe n fẹ ba ni papakọ ofurufu ni Kigali.
INEC ti se gudu gudu meje, yaya mẹfa ,awon ile-ise eleto aabo naa se daadaa pẹlu.
Àwọn ọmọ Israẹli kò ní dúró ní ilẹ̀ OLUWA mọ́; Efuraimu yóo pada sí Ijipti, wọn yóo sì jẹ ohun àìmọ́ ní ilẹ̀ Asiria.
Ọpọlọpọ lo n gba imọran pe asiko ti to ki a pada sidi awọn aṣa Yoruba to fini lọkan balẹ, bii ti iwadii ṣaaju igbeyawo ti ẹbi afẹsọna maa n ṣe.
Ọpọ ileewe alakọbẹrẹ to jẹ ti aladini naa ko wọle kaakiri ilu Eko.
Enhakore yìí sì wà ní Lehi títí di òní olónìí.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Eid el Kabir: Àwọn ohun mẹ́sàn án tí Mùsùlùmí gbọdọ̀ ṣe nínú oṣù Dhual rèé 7 Agẹmo 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 24 Agẹmo 2020 Oríṣun àwòrán, Getty Images Anabi Muhammad (SAW) sọ pe ko si ọjọ kankan to ṣe koko julọ ninu ọdun kan ju ọjọ mẹwaa akọkọ ninu oṣu Dhu al- Hijjah.
Mauricio Pochettino: Ṣé Pochettino lè gba ife ẹ̀yẹ UEFA Champions League tí PSG ń wá fún wọn?
Ogunlọgọ awọn obirin ni wọn sọ wipe awọn soja tu wọn sihoho, ti wọn si tun tẹ ẹtọ wọn loju mọlẹ.
Nígbà tí wọ́n sọ fún ọba pé Eliṣa wà ní Damasku, 
Bẹ́ẹ̀ ni n óo ṣe fi òpin sí ìṣekúṣe ní ilẹ̀ náà; èyí óo sì kọ́ gbogbo àwọn obinrin lẹ́kọ̀ọ́, pé kí wọ́n má máa ṣe ìṣekúṣe bíi tiyín.
Akoroyin wa ti iṣẹlẹ naa soju rẹ ni ko si eeyan kankan to padanu ẹmi ninu iṣẹlẹ naa ṣugbọn ọkọ mẹfa kolu ara wọn ninu ijamba naa Ọkọ agbepo kan la gbo pe o ya lọ ba awọn awakọ ti o si kọlu ọkọ mẹfa loju popo.
Ẹṣin ati àwọn tí wọn ń gùn wọ́n yóo ṣubú, wọn óo sì fi idà pa ara wọn.
Ẹwẹ, awọn miran n pariwo pe arumọjẹ lasan lawọn ijọba n fẹ fi ọrọ naa ṣe ati pe wọn ti fẹ maa mu araalu ni mugun niyẹn o.
Nígbà tí àwọn ọmọ ogun Israẹli pada dé, wọ́n lọ kó ìkógun ninu ibùdó àwọn ọmọ ogun Filistini.
Irú ẹni bẹ́ẹ̀ ti gbàgbé ìwẹ̀mọ́ ẹ̀ṣẹ̀ rẹ̀ àtijọ́.
Bó ṣe ń lọ ń dùn mọ mi ṣùgbọ́n mi ò kànlẹ̀ ní ìmọ̀lára ìtẹ́lọ̀rùn ìbálòpọ̀.
Ipinle Kwara yoo tubo tepele mo ipinnu re lati mu iwuri ba eko ati imo nipa isiro ,ni ona ti  idagbasoke yoo se de ba  ipinle naaIgbakeji gomina ipinle Kwara, alagba Peter Kisira lo soro yii nigba ti o n gba igbimo egbe awon onisiro lorile ede Naijiria lalejo ni ofiisi re.
Premature babies: Ọ̀nà tí orin gbígbọ́ fi ń ṣèrànwọ́ f'ọpọlọ ọmọ ìkókó rèé
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Osun tribunal: APC ní ìdájọ́ ilé ẹjọ kò lẹ́sẹ̀ ń lẹ̀, Ó ń gba ilé ẹjọ́ kòtẹ́milọ́rùn lọ 22 Ẹrẹ̀nà 2019 Oríṣun àwòrán, Gboyega Oyetola Àkọlé àwòrán, Ninu atẹjade kan ti ẹgbẹ oṣelu naa fi sita ni o ti ṣalaye pe idajọ naa ko ba ofin mu rara Ijọba ipinlẹ Ọṣun pẹlu ti fi atẹjade sita pe wọn gomina Oyetọla ti gba ile ẹjọ kotẹmilọrun lọ ati pe pẹlu eyi, Oyetọla ṣi ni gomina ipinlẹ Ọṣun.
Iku lo gbẹyin iṣẹ akin ti Ogbeni Ilori lọ ṣe yii nitori wọn ni awon afurasi Fulani kan ya bo wọn ti wọn si yinbon fun wọn.
Bíbéèrè fún ìbálòpọ̀ gbogbo ìgbà sọ ìyàwó ilé dèrò ilé ìwòsàn Ẹ ta kété sí àjọṣepọ̀ tí kò bá fún yín láyọ̀ torí ẹ̀mí kò ní ààrọ̀ - Àwọn òṣèré tíátà gbarata lórí ìdájọ́ ikú Rárá o, ẹ kò gbọdọ̀ sìnkú akẹ́kọ̀ọ́ LASU tí wọn fi ṣe òògun owó - Ìjọba Eko yarí Ta ni Nana Akufo- Addo to wọle ibo aarẹ Ghana lẹẹkeji?
Méjì nínú àwọn aláìsàn nàá padà jẹ́ Ọlọ́run nípè, tí ẹnì kẹta padà sí ibùdó ìtọ́jú nàá ní ìlú Mbandaka.
Yorùbá ni “Ohun ti a kò bá jiyà fún, ki i lè tọ́jọ́”.
Ẹbí Abiola Ajimobi kéde bí ètò ìsìnkú rẹ̀ yóò ṣe rí pé.
Hanuni ati àwọn tí ń gbé Sanoa tún Ẹnubodè Àfonífojì ṣe, wọ́n tún un kọ́, wọ́n sì ṣe àwọn ìlẹ̀kùn rẹ̀.
Wọ́n ń sọ pé, “Ìwọ, Mesaya, sọ ẹni tí ó lù ọ́ fún wa!
Ifesinachi ti na papa bora bayi.
Bí a ṣe hun ọ̀rọ̀ pọ̀ nínú gbólóhùn ṣe pàtàkì kíkà iye ìró èdè nínú gbólóhùn kò fi ibi kankan ní ìtúmọ̀.
”Bakan naa, leyin awon ile ti o
Itakete si ara ẹni lawujọ Oríṣun àwòrán, Getty Images Awọn ọna miran ti a le fi dena itankalẹ arun yi ni ki a ri wi pe a tẹle ilana ki awọn eeyan ma talanga sirawọn ti wọn ba wa nita tabi laarin eeyan.
redio ati mohun-maworan nipa ilodi si pe ki eniyan ni awon irinse bi I ibọn ati
Ọ̀tọ̀ ni ẹwà oòrùn, ọ̀tọ̀ ni ti òṣùpá, ọ̀tọ̀ ni ti àwọn ìràwọ̀, ìràwọ̀ ṣá yàtọ̀ sí ara wọn ní ẹwà.
Àwọn èrò nígboro Eko fẹ́ lu obìnrin kan pa, pé ó mú nǹkan ọmọkùnrin pòórá Morenike ni asiko ti to ki awọn ọmọ obinrin wa mọ pe ko si ipo ti wọn ko lee de laye wọn ati pe ko si iṣẹ ti wọn ko le ṣe.
Wọn fi igba kan sọ wipe ohun ni yoo kopa gẹgẹ bi T'Challa ninu ere sinima, Black Panther to gbode kan bayi.
Ó ń sọ fún àwọn ọ̀gbun ati àwọn àfonífojì pé, èmi fúnra mi ni n óo kó ogun wá ba yín, n óo sì pa àwọn ibi ìrúbọ yín run.
Àwọn ni irú-ọmọ àwọn baba-ńlá ayé àtijọ́.
Àwọn ẹlẹ́rìí ni wọ́n gbọdọ̀ kọ́kọ́ sọ òkúta lu ẹni náà, lẹ́yìn náà ni gbogbo eniyan yóo tó kó òkúta bò ó, bẹ́ẹ̀ ni ẹ óo ṣe yọ ẹni burúkú náà kúrò láàrin yín.
0 27 Solomon Islands 0 0.
Panpẹ ajo to n gbogun ti iwa ibaje lawujo, EFCC, ti  ilu Ibadan, ni ipinle Oyo , ekun Gusu orile
OLUWA wí fún mi nígbà náà pé, ‘Gbogbo ohun tí wọ́n sọ patapata ni ó dára.
Pẹlu iranlọwọ ofin tuntun yii, wọn yoo ṣe idasilẹ akọsilẹ orukọ awọn to ba fi ipa banilopọ; wọn ki yoo pa aṣiri mọ nipa ẹni ti wọn fi ipa balopọ.
Ọkunrin kan, tí ń jẹ́ Ṣeba, ọmọ Bikiri, láti agbègbè olókè ti Efuraimu, ni ó ń dìtẹ̀ mọ́ Dafidi ọba.
Alaga ajọ naa, Ọjọgbọn Shehu Risqua sọ fun awọn akọroyin pe ibudo idibo ọrinlerugba din ẹyọkan ni idibo naa yoo ti waye.
Wọn ti ni ki awọn Họnọrebu mẹtẹẹta yii má rin ni sakani ile igbimọ aṣofin Ondo mọ ni Akurẹ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Asa Trokosi nibi ti ọmọde ti n jiyan ẹsẹ mọlẹbi rẹ , wọpọ ni Ghana, Togo ati Benin.
"Oríṣun àwòrán, @followlastma ""VIO nikan lo lee da mọto duro lati beere awọn nnkan bii iwe ọkọ ati boya mọto dangajia tabi ko dangajia."
O wa so fun awon alase ile-ise iwadii naa lati tesiwaju lori iwadii nipa egbogi ibile, agbegbe ti o ya soto fun ra re, bakan naa ki o tun mu eto idanilekoo lokunkun dun, ni iyanju ati tan imo ati oye naa ka.
Ninu atẹ́jade kan to fisita, ijọba ipinlẹ Osun ti kẹdun lori iku agba oselu naa, ẹni to sapejuwe bii awokọse fun onirẹlẹ, ẹni ti ko mọtara rẹ nikan ati olootọ eniyan.
Oríṣun àwòrán, Sunday Adeyemo Irọlẹ si ni wọn wọ igbo naa titi di owurọ ọjọ keji, ti wọn n wa awọn afurasi ọdaran naa kiri inu igbo to fẹ naa.
"Funke Akindele-Bello gbe nkan mẹta ṣe lẹẹkanṣoṣo Ní ilé gbájúgbàja òṣèré Funke Akindele Bello ti gbogbo ènìyàn mọ sí ""Jennifa"" ohun mẹtalọkan lo jẹyọ níbẹ̀."
Wọn kò gba ohun tí àwọn obinrin náà sọ gbọ́.
Ẹni tí kì í tètè bínú sàn ju alágbára lọ,ẹni tí ń kó ara rẹ̀ níjàánu sàn ju ẹni tí ó jagun gba odidi ìlú lọ.
Kmhmu’ ní àríwá àti àárín gbùngbùn Laos;; 
Èyí ni wọn fi tún ṣàfihàn èso burúkú tó ń bí láyé àwọn ọ̀dọ́ tó ń muú, pàápàá jùlọ, lẹ́kùn àríwá Nàìjíríà.
"Ó ní, ""A ó ránṣẹ́ si gbogbo àwọn òṣìṣẹ́ àjọ wa tí o wà ní gbogbo pápákọ̀ òfurufú pe kí wọn fojú sita, kí wọn tún máa lo ẹ́rọ tàmómítà tí wọ́n fi ń wo bí ǹkan ṣe ngbóná sí láti ṣ'àyẹ̀wò fun àwọn èrò."
Èmi óo máa ṣe àṣàrò lórí ẹwà ògo ọlá ńlá rẹ,ati iṣẹ́ ìyanu rẹ.
Ní agogo mẹsan-an òwúrọ̀ ni wọ́n kàn án mọ́ agbelebu.
Angel Gomes: Angel Gomes, agbábọ́ọ̀lù Manchester United ṣàlàyé ohun gan tó gbé e dé ṣọ́ọ̀ṣì T.
Bakan naa lawọn amofin yoku naa gbee nidi lori eyi.
gbogun ti awon omo ogun olote ti o ba ku nibi-kibi ti won n ba fori pamo si,
Nígbà tí ó dé ìdí rẹ̀ kò rí ohunkohun àfi ewé, nítorí kò ì tíì tó àkókò èso.
Gbogbo àwọn ọmọ Lefi tí wọ́n jẹ́ akọrin: Asafu, Hemani, Jedutuni, àwọn ọmọkunrin wọn ati àwọn ìbátan wọn dúró ní apá ìhà ìlà oòrùn pẹpẹ.
Lati igba ti iroyin naa ti jade sita lo ti n ṣe ọpọlọpọ ni haa-hin nitori idẹyẹsi naa.
Jakọbu sọ pé, “Oòrùn ṣì wà lókè, kò tíì tó àkókò láti kó àwọn ẹran jọ sójú kan, ẹ tètè fún àwọn aguntan ní omi mu, kí ẹ sì dà wọ́n pada lọ jẹ koríko sí i.
"Njẹ o mọ oju yi ni ""Yollywood"" Ayefẹlẹ: Ìjọ̀ba ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́ kò fẹ́ òótọ́ ní wọ̀n ṣe fẹ́ wó iléèṣẹ́ rédíò mi Okòwò wo ni ẹ̀gbẹ̀rún mẹ́wàá tó ó ṣe?"
Akala ni awọn eeyan Ogbomọsọ nikan lo lee yọ alaga ijọba nipo, kii se Kọmisọna kankan pẹlu afikun pe ki lo de to jẹ igba ti ọmọ oun kuro ni APC, ni tiẹ yatọ si ti ara yoku.
fún BBC Yorùbá fún ayẹyẹ ọdún méjí - Mike Ifabunmi láti Brazil Ṣé Liverpool ṣì leè tẹ̀síwájú ní ìdíje Champions league?
Nigba to n salaye loju opo twitter rẹ, @adetutuoj8811, lori ohun ti oju rẹ n ri lawujọ nitori pe o kọ ila, Adetutu ni yẹyẹ, ẹsin ati itiju naa pọ debi gẹẹ, ti oun ko fi lee tẹsiwaju lẹnu ẹkọ oun.
Sagay sọ pe awọn gomina ọhun ko nilo lati kọkọ gba aṣẹ lọwọ Malami ki wọn to wa ọna ati daabo bo agbegbe wọn.
Èèyàn 20 ni coronavirus pa l'Ọ́jọ́bọ nìkan O ti lé ní ènìyàn mẹ́wàá tí ina jó gúrúgúrú nínú ìjàmbá tó wáyé ní Delta Wo ohun tí ìrìnàjò ààrẹ Buhari fún ìgbà àkọ́kọ́ lásìkò Coronavirus lọ sí Mali yóò bá bọ̀ Ẹgbẹ́ Boko Haram pa àwọn òṣìṣẹ́ UN márùn ún tó wá ṣiṣẹ́ ìrànwọ́ ní Nàìjíríà Kini ẹjọ Woodberry ti wọn danu yii tumọ sí?
Lẹyin ti ẹgbẹ oṣiṣẹ TUC sọ pe ipo ti Naijiria wa lawujọ awọn orilẹ-ede fihan pe Naijiria ti kuna lati dagbasoke lẹyin to ti gba ominira fọdun mejidinlọgọta.
Ojuse awọn olori ẹka ẹsin ati oselu gbogbo lorilẹede Naijiria.
Láti káàkiri àgbáyé sì ni wọ́n ti wá.
" Bayero Emir ìlúu Kano, ìyá rẹ̀ ọmọ Emir Kẹjọ ni ìlú Ilorin!
Ní ọjọ́ kan, ó ranṣẹ sí Joabu, pé kí ó wá mú òun lọ sọ́dọ̀ ọba, ṣugbọn Joabu kọ̀, kò lọ sọ́dọ̀ rẹ̀.
O pin ẹran Tọki ati ounjẹ alẹ miran ti wọn pese silẹ fawọn ọmọ ogun to wa nibẹ, koda o ya fọto pẹlu ọpọ ninu awọn omọ ogun to wa nibẹ.
O fẹnukọ lọdọ awọn ọmọ Naijiria nigba to ni awọn janduku ji paliatifu ti oun fẹ pin fun awọn araalu lọjọ ibi rẹ eyi to jẹ ọjọ kẹẹdọgbọn oṣu kẹwa ọdun 2020.
Ó pàṣẹ fún wọn pé kí wọn má mú ohunkohun lọ́wọ́ ní ọ̀nà àjò náà àfi ọ̀pá nìkan.
Òkìkí rẹ kàn dé ọ̀run, ìjọba rẹ sì kárí gbogbo ayé.
Iroyin ẹlẹjẹ yìí tàn ká gbogbo orílẹ̀-èdè Naijiria.
Ká ní ọmọ Buhari fẹ́ mi, màálù 150 ní màá fi dána - Olólùfẹ́ míì tó tún yọjú Tinubu, yé é sọ̀rọ̀ abẹ́lẹ̀, bọ́ sí gbangba láti bèèrè àtúntò Nàíjíríà lọ́dọ̀ Buhari - Afẹnifẹrẹ Wo àwọn ìlànà tuntun ti o gbọdọ tẹlèé rèé ki ó to le wọkọ̀ òfurufú lọ sókè òkun Fuel Price Increase: Ìjọba Buhari ń fi ara ní àwọn èèyàn púpọ̀ jù Awọn eeyan ipinlẹ Ọyọ gbarata lori alekun owo epo bẹntiro Gbogbo awọn eniyan to n lo epo bẹntiro fun iṣẹ oojọ ati igbokegbodo ọkọ ti gbarata lori aleekun ti ijọba mu ba iye ti wọn n ta jala epo kan jakejado orilẹede yii.
Kasonde sọ fun BBC pe ileewe naa ko tii sin Matfishi, o ni awọn n gbero lati fi oogun ti ko ní jẹ kí oku rẹ bajẹ si ara ẹja naa ki awọn le maa rii wo lọ.
Bakan naa, lo tun rọ awọn eeyan to ni arun ikọ ife lati maa lọ fun itọju deede, ki wọn maa lo oogun ati abẹrẹ wọn bo ti yẹ, ki iwosan lee tete de bawọn, tori ikọ ife kii pa ẹni to ba tọju ara rẹ.
Oníṣẹ́ àdáni 250,000 ni ìjọba ṣe ìlànà yìí fún Ẹ má gbìyànjú láti bo àṣírí ìpànìyàn tó wáyé ní Lekki, á ní ẹ̀rí tó dájú - Amnesty International Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Kété tí wọ́n bá ti báa yín sùn tàn torí pé ẹ tóbi, ẹ gbà pé ìfẹ́ yẹn ti parí - Auntie Remi Ọlọ́yàn ńlá Kini idi ti ilẹ America ko fi ṣe atilẹyin fun?
Àwọn ọmọ Elamu keji jẹ́ ẹgbẹfa ó lé mẹrinlelaadọta (1,254)
Ó rò pé yóo yé àwọn arakunrin òun pé Ọlọrun yóo ti ọwọ́ òun fún wọn ní òmìnira.
O fikun pe ọjọ Aje lawọn yoo fẹnu ọrọ jona lori igbesẹ gbigbe aba sisan owo osu tuntun naa de ile asofin apapọ, pẹlu afikun pe ijọba yoo rọ awọn ijọba ipinlẹ lati wa owo fi san alekun owo osu naa.
Aare fi mule pe, ijoba ko ni sinmi di igba ti won ba to fi oju awon obayeje ati awon ti o n satileyin fun won patapata jofin.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Àṣà àti ìgbàgbọ́ Yorùbá ni pé òbí wọn máa ń padà wá sáyé Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Lockdown updates: Naira Marley gbóríyìn fún Jude Chukwuka pẹ̀lú #1 míliọnù Ilu Eko gbona mọ awọn ọmọ ẹgbẹ one million boys gidi lasiko naa, eyi si lo mu ki Ebiola sa wa silu Ibadan, lati wa fi ori ara rẹ pamọ.
Agboola Ajayi ni aikunjuwọn Abẹnugan naa farahan pẹlu bii Adajọ Agba ni ipinlẹ Ondo ṣe da iwe ti wọn kọ si lati bẹrẹ igbesẹ lati yọ oun ni ipo pada.
Ni ọjọ Aje ni ajọ to n gbogun ti iwa ijẹkujẹ lorilẹede Naijiria, EFCC, gbe Fayoṣe lọ si ile ẹjọ giga apapọ to wa ni Ikoyi nilu Eko lori ẹsun ikowojẹ ati ṣiṣe owo ilu baṣubaṣu ati gbigbowo rin lọna ti ko bofinmu, eleyi ti gomina ana ọhun dahun si pe oun ko jẹbi.
Ẹnìkọ̀ọ̀kan ninu àwọn tí wọn ń ṣiṣẹ́ náà fi idà kọ́ èjìká bí ó ṣe ń mọ odi lọ.
Ní’hà ibòmíì, ilẹ̀ ṣú fún wákàtí mọ́kànlélógún.
Ńṣe ni ó máa ń náwó bí ẹlẹ́dà.
Lara awọn ere ti oloogbe Osuntoun ti kopa ni Koto Orun, Aye Akamara, Koto Aye, ti gbogbo rẹ jẹ latọwọ oloogbe Ajilẹyẹ.
Àlá àwọn òjíṣẹ́ Olúwa tó fẹ́ jẹ ààrẹ Nàíjíríà leè má ṣẹ lógún ọdún - Abiara N kò fẹ́ ṣiṣẹ́ aṣẹ́wó ló mú mi máa wa ọkọ̀ taxi - Obìnrin tó ń wa Uber Ọba Lamidi Adeyẹmi, òṣìṣẹ́ adójútòfò àti Abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò kó tó jọba Kíni ìwọ mọ̀ nípa Funmilayọ Ransome-Kuti?
Àwọn ìròyìn tí ẹ lè nífẹ̀ẹ́ sí: 'Èèwọ̀' gààrí fún àwọn èèyàn ipínlẹ̀ Ondo Agbébọn jí alága káńsù tẹ́lẹ̀ gbé Alárùn ọpọlọ lu àwọn nọ́ọ̀sì àti dókítà agba níléèwòsàn ní àlùdákú Ọmọkùnrin tó pa ọmọ igbákejì Gómìnà Ondo gba ìdàjọ́ ikú ‘Ẹni mẹ́rin àti Àlága ADC nípìnlẹ̀ Ondo ni wọ́n jígbé lọ’ Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
awon eniyan mo wi pe  lootọ ni MKO Abiola
Ẹ wo ọba kan nílẹ̀ Yorùbá, tí kò ṣe ètùtù tàbí náwó ànájù, kó tó jọba Irọ́ ni pé ọba tuntun má a ń jẹ ọkàn ọba tó bá wàjà ní ìpèbí - Elebuibon Àwọn ìṣẹ̀lẹ̀ ńlà lọ́sẹ̀ tó kọjá tó fi mọ́ bí Covid-19 ṣe gbẹ̀mí èèyàn 23 lọ́jọ́ kan ṣoṣo Èèyàn 1,598 míì tún ti lùgbàdì covid-19 ní Nàijíríà, 1,420 ló ti kú báyìí Mo ti ní ìyàwó àfẹ́sọ́nà, ayẹyẹ ìgbeyàwó mi ń bọ̀ láìpẹ́ - Lateef Adedimeji Ọwọ́ tẹ ènìyàn méjì tó ń ta ayédèrú aṣọ iṣẹ́ ikọ̀ Àmọ̀tẹ́kùn ''O pa mi lẹrin nigba ti mo gbọ ọrọ awọn ọdọ ti wọn n pe ara wọn ni ẹgbẹ awọn ọkunrin to lahun,'' Akeugbagold lo sọ bẹẹ.
Àwọn ọ̀rọ̀ ọlọ́gbọ́n tún nìwọ̀nyí:Kò dára láti máa ṣe ojuṣaaju ninu ìdájọ́.
Abayomi tun fikun pe Gomina tẹlẹ ri ọhun ni ọpọlọpọ ẹya ara rẹ ti daṣẹ silẹ, nitori oró aarun Covid-19."
Loke okun, o mu ajo iṣẹ pọn pẹlu Royal Court Theatre, London nibi ti o ti kọ ọpọlọpọ iwe to si ṣe agbejade rẹ ni Naijiria ati loke okun.
Falz tó jẹ́ olórin tàka-súfèé ti kéde pé òun ń wá obìnrin rere lọ́ọ̀dẹ̀ òun
Ayọ̀ọlá: Ǹ jẹ́ ẹ ní ṣúgà
ijiroro  ti  ile igbimo asofin fẹnuko le lori lojo Isegun
Bí ó bá wí pé àwọn ẹran tí ó ní funfun tóótòòtóó ni yóo jẹ́ owó ọ̀yà mi, gbogbo ẹran inú agbo a sì bí onífunfun tóótòòtóó.
Òun ni ó kéré jù láti gba oyè ní yunifásítì .
Nítorí náà, mo ṣe ìlérí fún wọn ninu aṣálẹ̀ pé n óo fọ́n wọn káàkiri láàrin àwọn orílẹ̀-èdè yòókù, 
Lẹ́yìn náà, gbogbo àwọn ọkunrin tí wọ́n mọ̀ pé àwọn iyawo wọn ń sun turari sí àwọn oriṣa ati àwọn obinrin tí wọ́n pọ̀ gbáà tí wọn wà nítòsí ibẹ̀, ati àwọn tí wọn ń gbé Patirosi ní ilẹ̀ Ijipti, wọ́n bá dá Jeremaya lóhùn, 
Lẹyin to foribalẹ fawọn ọba alade naa tan, ni Anthony Joshua wa ya fọto pẹlu awọn ololufẹ rẹ ti wọn wa foju gaanni rẹ.
O wa ni ile ẹjọ ṣe idajọ to yẹ nipa dida ẹjọ are fun Balogun.
”Ó dá a lóhùn pé, “Ọmọ Lefi, láti Bẹtilẹhẹmu ní ilẹ̀ Juda ni mí, ibi tí n óo máa gbé ni mò ń wá kiri.
ibi-ile ti a mo loni bi burkina faso t je titedo kutukutu , larin odun 14,000 ati 5000 sk , latowo awon ode asako ni apaariwaiwoorun ibe , ti awon ohun amulo won bi ihale , igbele ati oriofa won je wiwari ni 1973 latowo simran nijjar .
Mercy Aigbe kò mọ ọ̀dá owó, ọkọ̀ ayọ́kẹ́lẹ́ tuntun ló fà yọ lásìkò Coronavirus Àwọn ǹkan ti ọ̀pọ̀ ko mọ nípa Baba Suwe Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Yollywood: Sinimá Ajé Ọjà tún so Fathia àti Saheed Balogun pọ̀ nínú Sinimá Nigba to n sọrọ lori ibi ti imisi ti n wa nipa awọn fidio to maa n fi si ori ayelujara, agba Inaki ni iriri ti oun ba ri ni awujọ ni oun maa n fi ṣe ọrọ isiti, ti awọn eeyan si maa n fi fidio ransẹ si oun nigba miran.
Àṣeyọrí Anthony Joshua fi hàn pé owó tí à ń ná lórí eré ìdarayá kò lọ lásán - Dapo Abiodun Ohun mẹ́wàá pàtàkì nípa Maradona àti ìbáṣepọ̀ rẹ̀ pẹ̀lú ẹlẹ́sẹ̀ ayò Diego Costa rèé Lóòtọ́ ni mo yìnbọn níbi yánpọnyánrin tó wáyé ládúgbò mi-Seun Kuti Wo àwọn Ọba aládé méje tó jẹ́ obìnrin nílẹ̀ Yorùbá Mi ò le tòṣì láéláé!
Sugbọn sa, kọmisana eto ilera nipinlẹ naa, Ahmed Gana sọ fun BBC pe awọn eeyan naa ko fi apẹẹrẹ aarun naa han ni wọn ko ṣe nilo oogun.
Ẹni ogoji ọdún ni nígbà tí wọ́n fi jọba lórí Israẹli, ó sì wà lórí oyè fún ọdún meji.
Àkọlé àwòrán, Ibi gbogbo ni wọn ti nko adiẹ alẹ taa ba nsọrọ bibi awọn ibeji to lẹpọ Iranwọ owo isẹ abẹ de fun awọn ibeji naa nigbati olori ile asoju-sofin, Hon Yakubu Dogara se agbatẹru isẹ abẹ naa, ki eyi ibeji to nmi daada naa lee gbe ile aye.
Bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé n kò lẹ́bi,sibẹsibẹ ọ̀rọ̀ ẹnu mi yóo di ẹ̀bi rù mí;bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé n kò lẹ́ṣẹ̀,sibẹsibẹ yóo fihàn pé ẹlẹ́ṣẹ̀ ni mí.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Enyimba, Akwa United gunlẹ fun idije ife ẹyẹ CAF 5 Ẹrẹ̀nà 2018 Oríṣun àwòrán, @EnyimbaFC Àkọlé àwòrán, Enyimba wa lara awọn odu ẹgbẹ agbabọọlu ni Afirika Ikọ agbabọọlu Eyimba ti orilẹede Naijiria ti gunlẹ si ilu Cotonou lorilẹede Benin fun abala komẹsẹ o yọ akọkọ ninu idije CAF Confederations cup ti yoo waye ni papa isire Stade de l'Amitié de Kouhounou, Cotonou lọjọọru.
 Àròsọ ni ó ti wọkọ ̀ lọ sí ifẹ ̀ láti lọ ṣe ìwádìí owó náà .
 Akọroyin ọmọ orilẹede Senegal ni mi mo si ni lati ba ọ sọrọ Oríṣun àwòrán, George Wafula/BBC Eyi ṣẹlẹ ni o ku ọsẹ diẹ ṣaaju idibo aarẹ ni Senegal bẹẹ si ni ẹni ti iroyin naa n ba wi Ọgbẹni Sonko jẹ ọkan lara awọn to n gbena ibo yii woju aarẹ Macky Sall.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Murphy Elégungun Rọba: Mo fẹ́ di ẹnití egungun rẹ̀ rọ̀ jùlọ ní àgbáyé Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Murphy Elégungun Rọba: Mo fẹ́ di ẹnití egungun rẹ̀ rọ̀ jùlọ ní àgbáyé 23 Sẹ́rẹ́ 2019 Ọba afinidara ni Ọlọrun, bo se da dudu, naa lo da funfun, o da ẹni ti eegun rẹ le koko, to si tun da ẹni ti eegun rẹ rọ bii rọba.
Ẹ sinmi ariwo Saraki, ẹnikẹ́ni ló le è di ààrẹ aṣòfin àgbà Kọ́ ilé lọ́nà àìtọ́, ko rẹ́wọ̀n he - Buhari Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Kidnapped Girl: Iyá Ikimot ní lẹ́yìn ọ̀pọ̀ ìdààmú àti owó láti wá ọmọ náà, òun sọ ìrètí nù O ni ohun to buru jai ni lati ma a lo ẹrọ ayelujara lati fi tabuku oun lawujọ.
ni gbagede ikabo niluu Abuja(National Collation centre in Abuja).
Mo kábámò pé mo fipá bá Ìyá ẹni ọgọrin ọdún sún ní Kano- Muhammad Zulfara'u Ìfipábánilòpọ̀ kìí ṣe ìwà ọmọlúwàbí, àwọn òṣèré tíátà pariwo síta Iyabo Ojo, Toyin Abraham, Mercy Aigbe, ta làwọn òṣèrébìnrin yìí gbè lẹ́yìn lórí ọ̀rọ̀ ìfipábánilòpọ̀?
Ẹgbẹrun meji ati ẹgbẹrin le marundinlaadọta ni apapọ awọn eniyan to ti ni ifarakanra pẹlu awọn to ni aisan naa, tawọn naa si ti wa labẹ amojuto.
Èdè yorùbá àjùmọ ̀ lò ni ó pa gbogbo ẹ ̀ yà yorùbá pọ .
" Omije Ṣugbọn, iranlọwọ Okina ko jina si: Ibatan rẹ kan lati Eko ṣe koriya fun un.
Àwọn tí wọ́n gbójú lé ẹṣin;tí wọ́n gbẹ́kẹ̀lé kẹ̀kẹ́ ogun nítorí pé wọ́n pọ̀,tí wọ́n gbójú lé ẹṣinnítorí pé wọ́n lágbára!
Nitori pe awọn ileeṣẹ abẹle ko ni le fi iga gbaga pẹlu ọja to n wọle lati ilẹ okeere, lori iye ti wọn n ta a.
Dipo ki awọn to n lọ lati ipinlẹ Ọyọ ṣẹṣẹ lọ gbera lati ilu Eko, papakọ ofurufu to n bẹ nilu Ibadan ni wọn o ti maa gbẹrẹ bayii.
Ǹkan ìṣeré ìbálòpọ̀ ń ṣiṣẹ́ bákan náa lára ni tẹ́lẹ̀ ṣùgbọ́n àwọn ilé iṣẹ́ ti ń wo onírúurú ìpele tí ara fi ń wà lọ́nà báyìí láti ṣe ọ̀tọ̀tọ̀.
Ẹmi marun un sọnu ninu ija Kaduna Oríṣun àwòrán, AFP Àkọlé àwòrán, Ọpọ igba ni ija igboro maa nbẹ silẹ ni Kaduna, ti wọn si maa njo awọn ile ijọsin ni ina Saaju la ti kọkọ mu iroyin wa fun yin pe, eniyan marun ti padanu ẹmi wọn, ti ọgọọrọ mii si farapa ninu isẹlẹ to waye lagbegbe Kasuwan nipinlẹ Kaduna.
Ṣugbọn oluranlọwọ rẹ kan sọ wi pe, o wa ninu ipade, ati wi pe irọle ni yoo le ba akọroyin naa sọrọ.
Ọkan ninu awọn mẹsan an to ku ninu Ile Ẹgbọn Agba, Big Brother Naija n lọ sile loni gẹgẹ bi awọn oluworan ba ṣe dibo fun wọn si.
Awọn olukopa to ba fẹ ẹ kawe ni Hungary le mu to eto ẹkọ meji, bo ba ṣe wu wọn.
Bakan naa, ẹlẹsẹ ayo ẹgbẹ agbabọọlu Juventus, Paulo Dybala naa ti lugbadi arun ọhun.
Ọọniriṣa, Alayeluwa Adeyẹye Ogunwusi Ọjaja II ati Sultan ti ilu Sokoto, Sa'ad Abubakar kẹta ṣalaye pe ohun to banininu jẹ gidi ni pe awon avbenipa lee gba ẹmi ọbalaye lorilẹede Naijiria.
Gbogbo àwọn ègún tí a kọ sinu ìwé yìí yóo ṣẹ sí i lára, OLUWA yóo sì pa orúkọ olúwarẹ̀ rẹ́ kúrò láyé.
Nígbà ti o dé ẹ̀gbẹ́ mi, mo wa bẹ̀ẹ́ ki ó bá mi ti móto mi, o sì bá mi tìí, mo wá ni ki ó jọ̀ọ́ kó bámi tìí díẹ̀ sí pé màá fún ní ǹkan kan."
Anthony Joshua - Igbanu mẹta lẹka ẹṣẹ kikan to lami laaka lo wa lo lọwọ rẹ nikan Oríṣun àwòrán, Instagram/anthonyjoshua Ti a ba n sọrọ awọn afi ẹṣẹ ku bi ojo lagbaaye, ọrọ ko tii tan ti a ko ba darukọ Anthony Oluwafemi Joshua.
Ṣugbọn ṣa, Baba Keresi jẹ ọna lati dun ara ẹni ninu, eyi to jẹ ọkan pataki lara afojusun wọn.
awon adari ile ise agbofinro ati ajọ eleto aabo se kuna lati wa fun ipade naa,
Ọba dáhùn pé, “N óo máa mú Kimhamu lọ, ohunkohun tí ó bá sì bèèrè, ni n óo ṣe fún un.
Ní àkókò ìjà yìí, gbogbo àwọn ẹbọra òde ọ̀run bẹ̀ẹ́, ṣùgbọ́n òun kò gbọ́, ó lé ọmọ rẹ̀ wá sínú ayé kí ó bà lè ní ìpín nínú ìbànújẹ́ ti n tẹ̀lẹ́ ọmọ ènìyàn kiri títí ọjọ́ ayé wọn.
Gẹ́gẹ́ bi adájọ àgbà Nnamdi Dimgba ṣe sọ, níwọ̀n ìgbà ti olùjẹjọ náà ti pa iléri rẹ̀ mọ láti dá Bílíọnù kan àbọ̀ naira pada, nítori naa ko si ẹni to le gbe lọ si ilé ẹjọ́ mọ́.
Gbogbo wọn wá bi í pé, “Ṣé ìwọ wá ni Ọmọ Ọlọrun?
Abimeleki tún wí fún un pé, “Wo gbogbo ilẹ̀ yìí, èmi ni mo ni ín, yan ibi tí ó bá wù ọ́ láti gbé.
O si fi ika hanu pe to ba jẹ pe awọn obi oun lagbara lati ran oun lọ sile iwe ni, oun ko ba ti dawọle isẹ adigunjale to wa gba ẹmi oun naa O ni iya ẹsẹ ti oun sẹ ni oun fẹ ku le lori yii, ọrọ Ọlọrun si lo sẹ mọ oun lara pe, ẹni to ba fi ida pa eniyan, lati ipa ida naa ni yoo fi ku, amọ ki Ọlọrun fori jin oun .
'Ìdí tí a ò fi pa àwọn ajínigbé tó gbé àwọn akẹ́kọ̀ọ́ Kankara nìyìí' Àwọn agbébọn tún gbìyànjú láti gbé akẹ́kọ̀ọ́ ilé Keu 80 ní Katsina Mo gbóríyìn fún Buhari bó ṣe dóòlà ẹ̀mí àwọn akẹ́kọ̀ọ́ tí wọ́n jí gbé ní Kankara Iléeṣẹ́ ológun ti yabo ibùdó àwọn jàndùkú tó jí àwọn akẹ́kọ̀ọ́ gbé níléèwé katsina- Garba Shehu Òṣèré tíátà Yorùbá yìí la orí mọ́lẹ̀ nígbà tó ń ṣe sinimá lọ́wọ́ Wo ìdí tí ọmọ ọdún mẹ́wàá ṣe ti àbúrò rẹ̀ ọmọ ọdun kan àbọ̀ sínú kàǹga Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Pásítọ̀ ló sọ fún mi pé Ọlọ́run pè mí láti di Olokun tó ń bọ omi' Àrẹ̀mọ Ooni Adeyeye Ogunwusi ti wọ Ààfin Ile Ife fún ìgbà àkọ́kọ́ Oríṣun àwòrán, Ooni Palace Ọọni ti Ile Ife to tun jẹ Arole Oodua, Ọọni Adeyeye Enitan Ogunwusi, Ọjaja II ti fi oju ọmọ wọn han faraye fun igba akọkọ lọjọ Iṣẹgun ọsẹ.
Saaju ki wọn to fọwọ bọ adehun naa ni Aarẹ orilẹẹde Naijiria Muhammadu Buhari ti yọwọ ninu re.
Àwọn ọmọ Israẹli bèèrè pé, “Èwo ninu gbogbo ẹ̀yà Israẹli ni kò wá sí ibi àjọ níwájú OLUWA?
Atẹjade NUJ wa n beere pe se aarẹ Buhari ti padanu ohun rẹ ni, tori awọn ọmọ Naijiria n reti ọrọ rẹ nibayi ti Naijiria joko le agba ẹtu, to lee bu nigbakugbaa.
Oríṣun àwòrán, Instagram Ninu ọrọ wọn, awọn alaṣẹ oju ọpọ Twitter ni ibanujẹ ọkan lo jẹ fun awọn pẹlu bi awọn gbajuẹ ṣe gba owo lọwọ awọn eniyan.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Ẹwẹ, Arakunrin Babablola Ogunbuyide to jẹ gẹgẹ bi ọrẹ ati ọmọ si Baba ọbasanjọ naa ṣẹ apejuwe rẹ ẹni rẹrẹ ti Olorun ṣẹda rẹ.
O fi kun pe awọn ajikusa wa naa ti ba odo ọṣun jẹ pẹlu oniruru awọn eroja to jẹ majele fun agọ ara.
 awon oloye egbe yoo se ise lori abajade won, ni eyi ti yoo mu idajo rere wa.
Sugbọn gomina ipinlẹ Kwara, AbdulFatai Ahmed, ti wa fesi pada pe ọ̀rọ naa ko ri bẹẹ rara nitori aabo to peye si n bẹ fun awọn oludibo.
Oríṣun àwòrán, Other O sa ipa rẹ lati mu agbega ba iṣẹ ọkọ rẹ, tii ṣe ere tiata, ti ọpọ eeyan si mọ gẹgẹ bii Iyawo Alalubosa tabi Ayoni, nitori ipa to ko ninu ere naa Iyawo Alalubosa.
Lọkọlaya Harry and Meghan ti sọ pe o di ẹyin igba ti wọn ba ti yayọ ọmọ tuntun naa pẹlu awọn mọlẹbi wọn ki wọn to kede ibi rẹ fun aye gbọ.
N óo fi òpin sí ẹ̀rín ati ìró ayọ̀ ní ibí yìí, n óo sì fi òpin sí ohùn iyawo àṣẹ̀ṣẹ̀gbé ati ti ọkọ iyawo.
"mo wa lara awọn apaniya, "" ẹni ọdun aadọrin ọun lo sọ bẹ."
Sam Kayode Olùṣírò owó ọmọ Nàìjíríà tó tún ń ṣe iṣẹ́ olùṣọagùtàn lẹ́kọ̀ọ̀kan ni ilẹ ọba (UK) Sam Kayode gba ìdájọ láti lọ sí ẹwọ̀n ọdún mẹ́rìnlá, fún ẹsùn jíjí, mílíọ̀nù mẹ́rin ó le ọwọ́ kan Pọ́ùn nínú oṣù kẹfà ọdún 2016.
Bẹ́ẹ̀ ni Èṣù-kékeré fi ara pa, tí eyín rẹ̀ méjì ká, tí òrùka rẹ̀ kan sọnù, tí ó si fi ẹsẹ̀ dá, tí ó ń rìn bí onísòbìyà kiri.
Bótílẹ̀ jẹ́ pé ìgbìmọ̀ náà nawọ́ ẹ̀sì ìwádi rẹ̀ fun INEC latí oṣù tó kọ́já, àwọn èèyàn ko tíì mọ ẹ̀sì náà.
 ní united kingdom , cellulitis ni ìdí tí wọ ́ n fi dá 1.
Àwọn baba wa tí wọ́n tẹ̀lé Joṣua gba ilẹ̀ àwọn orílẹ̀-èdè tí Ọlọrun lé kúrò níwájú wọn, lẹ́yìn náà wọ́n gbé àgọ́ náà wá.
Olórí Alufaa bá bi í pé, “Ṣé bẹ́ẹ̀ ni ọ̀ràn náà rí?
Oyeleye ni awọn gomina naa ti sọ ọ nibi eto ifilọọlẹ pe Amọtẹkun kii ṣe ọlọpaa tabi sọja o, ọlọpaa ibilẹ lasan ni wọn jẹ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Mo fọ́ lójú ṣùgbọ́n mo mọ gbogbo irinṣẹ́ tí mo fi ń ṣe mọkalíìkì' Nigba ti akọroyin BBC beere pe ṣebi nigba ti wọn wa ninu ikọ figilante fun apẹẹrẹ wọn maa n gbe ibọn, esi ti o fọ ni wi pe ṣe bi ibọn ṣakabula lasan ti wọn fi n pa ẹran ninu igbo niyẹn.
Bẹẹ gẹlẹ ni Kilaasi Akomolede Yoruba wa yoo ṣe ri lonii ki ẹ lọ wo fidio naa loke fun itan aladun ati akọniloye yii.
Ẹni tí ó bá ṣẹgun ni n óo fi ṣe òpó ninu Tẹmpili Ọlọrun mi.
"- Ẹgbẹ́ àgbẹ̀ kìlọ̀ ""Ilẹ̀ Nàìjíríà kii se UK, Amẹ́ríkà àti Faranse."
Èdè Yorùbá pín sí orísirísi ẹ̀ka ní àkọ́tán, ó sì ti di gbajúgbájà ni orílẹ̀ èdè Nìgeria àti àgbáláayé lá papọ̀.
Algeria lo ṣẹ Naijiria leegun ẹyin ninu ifẹsẹwọnsẹ to kangun si aṣekagba.
Ìya fólúké yìí ni ó mú kọ́kọ́rọ́ séèfù jáde tí ó ṣí i tí wọn kò sì bá nnkan kan ní ibẹ̀.
Ó kó wọn lọ sí Babiloni, wọ́n sì ń sin òun ati àwọn ọmọ rẹ̀ títí di àkókò ìjọba Pasia; 
adinku ba owo to n wọle ju bi a ṣe lero lọ, eleyii to ṣe akoba die fun
Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Lílo oògùn Sniper fún ìtọ́jú oúnjẹ leè yọrí sí ikú àìtọ́jọ́ - NAFDAC kìlọ̀2 Bélú 2020 WAEC 2020 result checker: Wo nkan tí yóò ṣẹlẹ̀ sí àwọn akẹ́kọ̀ọ́ tí àjọ WAEC gbẹ́sẹ̀ lé èsì ìdánwò wọn3 Bélú 2020 How to apply for Nigeria Youth Investment Fund: Wo ibi láti mọ̀ síi nípa àwọn ọ̀dọ́ tó máa ri owó náà gbà3 Bélú 2020 Fídíò, Soyinka Cancer: Àṣe ara mi ni iso ti n run gbogbo bí mo ṣe n ṣèrànwọ́ lórí jẹjẹrẹ27 Bélú 2019 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 3 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 5 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Barister lo bi gbogbo oníṣẹ́ fújì -Oṣupa Alukoro fun ajọ FRSC fikun ọrọ rẹ pe ajọ naa sọ fun akọwe ile igbimọ aṣofin agba lati awọn nọmba ọhun nitori oun lo sun mọ wọn ju.
Oyetọla ko ṣai fẹnu ba a wi pe awọn eniyan ipinlẹ naa jẹ akinkanju, olufẹ aṣa ati ẹni ti igbagbọ wọn ranmọ oye awón baba n la wọn fun nini lpinlẹ ''Ọmọluabi'' Gomina naa sọ wi pe gbogbo eto isejọba lpinlẹ naa lo da lori oun ti ara ilu n fẹ.
" Lọjọru to kọja ni iroyin kàn pe Adebayọ Shittu to ti fi igba kan jẹ minisita fun eto ibaraẹnisọrọ l'orilẹede Naijiria, sọ pe oun yoo ṣiṣẹ tako oludije ẹgbẹ oṣelu All Progressives Congress, APC, Adebayọ Adelabu, ninu eto idibo gomina ti yoo waye nipinlẹ Ọyọ l'ọdun 2019.
Liverpool lo wa loke tente tabili EPL, nigba ti ifẹsẹwọnsẹ to ku si jẹ mọkanla.
àwọn ẹyẹ ojú ọrun, àwọn ẹja inú òkun,ati gbogbo nǹkan tí ó ń lúwẹ̀ẹ́ ninu òkun.
Apá kejì yìí kò ní ṣòro fún ọ láti kọ nítorí bàbá mi pàápàá ti fi ọwọ́ ara rẹ̀ kọ èyìínì sílẹ̀, kí ó tóó kú, ìwé tí ó kọ ọ́ si kò si lọ́wọ́ mi nísisìyí, ó wà ní ilé, ìgbà tí mo bá sì mú un dé ni òwúrọ̀ ọ̀la, n ó fi ara mi sí ipò bàbá mi n ó máa kà á fún ọ, ìwọ yóó sì máa kọ ohun tí mo bá ń sọ sílẹ̀ bí ẹni pé bàbá mi ni ó tọ̀ ọ́ wá sí ilé tí ó ń sọ ìtàn ìgbésí-ayé ara rẹ̀ fún ọ.
Nítorí náà, n kò ní fi ìyà jẹ Jerusalẹmu nígbà tí ó wà láàyè, n óo jẹ́ kí ó kú ní alaafia.
Ọlọrun ti fi ẹ̀mí rẹ̀ sinu rẹ̀, ó sì ti fún un ní ọgbọ́n, òye, ati ìmọ̀ ninu oríṣìíríṣìí iṣẹ́ ọnà, 
Sise ayẹwo lera lera Oríṣun àwòrán, Getty Images Awọn onimọ ti BBC ba sọrọ fidi ọrọ yi mulẹ pe sise ayẹwo fawọn eeyan ni ọna kan gbogi la ti mu adinku ba itankalẹ Coronavirus.
Alaisan naa wa labẹ itọju ni ileewosan fun wiwo ajakalẹ aarun to wa ni Yaba, nilu Eko,  Wọn ti kọkọ fura aarun yii lorilẹ-ede Egypt ati Algeria, ṣugbọn ko tii yọju ni agbegbe ilẹ olooru ."
Ki iṣẹ wọn le ba so eso rere, awọn ileesẹ ọlọpa ipinlẹ ni i awọn irinṣẹ to ba igba mu to fi mọ awọn akanṣe ibudo ikọṣẹ l'orilẹede naa.
Nítorí bẹ́ẹ̀ ni o ṣe jẹ wọ́n níyà,o sì pa wọ́n run,o sì ti sọ gbogbo ìrántí wọn di ohun ìgbàgbé.
Ronaldo ni Liverpool lo to gbangba sun lọyẹ, o si gbagbọ pe didun ni ọsan yoo so fun wọn nigba ti wọn ba koju Tottenham ni papa iṣere Wanda Metropolitano lọjọ nirọlẹ ọjọ Abamẹta.
Baba rẹ si ti wa ni ẹka ileesẹ ọlọpaa to n wadii ẹsun iwa ọ̀daràn, ni Panti ni ipinlẹ Eko.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Corornavirus: Ṣe lilo ìbọ̀wọ́ le dènà ààrùn Coronavirus Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Corornavirus: Ṣe lilo ìbọ̀wọ́ le dènà ààrùn Coronavirus 28 Ìgbé 2020 O ṣeeṣe ki iwọ naa ti ri tabi gbọ nipa pé bi ènìyà ba ti lo ìbọ̀wọ́ ewu Corornavirus ti fòó.
Mo rí i ó súnmọ́ àgbò náà, ó fi tìbínú-tìbínú kàn án, ìwo mejeeji àgbò náà sì ṣẹ́.
Ko yọ ọmọde silẹ, ko si yọ agba silẹ gẹgẹ bi akọroyin BBC ṣe ṣe alabapade awọn ọdọmọbinrin ibeji kan to jẹ ọmọ ọdun mọkanla ti wn si ti n lu ilu lati ọdun mẹta.
Ko pẹ ti Minisita to n ri si iroyin ati aṣa, Lai Muhammed naa tẹnu bọ ọ̀rọ̀ yii lawọn ọmọ Naijiria naa tu kẹkẹ ọrọ silẹ.
Nibayii, ọkunrin to wa mu iya mi lọ agọ ọlọpaa ni ọjọ naa ni o wa n ṣe iwadi iku rẹ bayii.
Eniyan marundinlọgọtalenigba ninu awọn to ni arun ọhun ni Naijiria ti ri iwosan gba, ṣugbọn mẹrinlelogoji eniyan ti filẹ ṣaṣọ bora.
pe ki Olorun tu ebi oloogbe naa ninu.
Ekiti Election: Èyí ń rán wa létí pé iná èèsì kò gbọdọ̀ jó wa ní ẹ̀ẹ̀kejì
Ọ̀rọ̀ yìí jẹyọ nígbà ti àbúrò aya ààrẹ gbégbà ìbò ìdìbò abẹ́lé fún ìpò Gomina ni ìpínlẹ̀ Adamawa sùgbọ́n ti kò wọle.
Oríṣun àwòrán, Lulu Jemimah Àkọlé àwòrán, Lulu Jemimah Ìgbà tó ṣe àbẹ̀wò sí Uganda l'óṣù Kẹjọ fún ayẹyẹ ọjọ́ ìbí ọdún kéjìlélọ́gbọ̀n rẹ̀, ní eròngbà nàá wọ́ ọ́ l'ọ́pọlọ.
Ìwọ wá ń sọ pé, ‘Bí ẹnikẹ́ni bá pa ọ̀rọ̀ mi mọ́, kò ní tọ́ ikú wò laelae.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Awọn daran daran fi ọbẹ ge baba mi lori - ọmọ ọdun mọkanla Ipaniyan wọpọ l'awọn ipinlẹ bi i Kaduna, Plateau ati Benue.
Ninu ọrọ rẹ, o tẹnu mọ pe Ile Igbimọ Aṣofin Ipinlẹ Eko ti ṣe gudugudu meje yaaya mẹfa pẹlu awọn ofin loriṣriṣi ti wọn n ṣe lati fi ẹsẹ iṣakoso ijọba onipele-si-ipele (federalism) mulẹ ni orilẹ-ede Naijiria.
Fẹla gba oriṣiriṣi ami ẹyẹ kakakiri agbaye ninu orin kikọ, bẹẹ naa ni o ja takuntakun lati ri pe ijọba ṣe ojuṣe wọn fawọn ara ilu nigba aye rẹ.
pé yóo fi àánú bá àwọn baba wa lò,ati pé yóo ranti majẹmu rẹ̀ mímọ́
Bí ìyàwó rẹ bá lóyún tàbí bímọ ní ìpínlẹ̀ Oyo, wo bí o ti ṣe lé gba ìsinmi ìtọ́mọ (Paternity leave) Ẹ̀bùn #500,000 wà fún ẹni tọ bá ba wa rí afurasí ikú Akinyẹle tó sọnù- Iléeṣẹ́ Ọlọ́pàá Wo àmúyẹ kí o tó lè di ọmọ ogun ilẹ̀ Nàìjíríà pẹ̀lú fọ́ọ́mù tó jáde yìí Ṣé òótọ́ ni pé ìgbẹ́ erin le è wo arùn Coronavirus sàn?
Ìdílé Barrister àti K1 Wasiu Ayinde sọ àsọyépọ̀ nílé Obey Commander2 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Fídíò, Boko Haram: Oluwatobi Adeigba, Ọkọ mi ń lọ siṣẹ́ fún àjọ INEC ló kàgbákò ikú - Opó Adeigba2 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Kimhamu ọmọ mi nìyí, jẹ́ kí ó máa bá ọ lọ, kí o sì ṣe ohun tí ó bá tọ́ ní ojú rẹ fún un.
Bí o ti rí amọ̀ tí ó dàpọ̀ mọ́ irin, bẹ́ẹ̀ ni àwọn apá kinni keji yóo máa dàpọ̀ ní igbeyawo, ṣugbọn wọn kò ní darapọ̀, gẹ́gẹ́ bí irin kò ti lè darapọ̀ mọ́ amọ̀.
Òun yìí ni Ọlọrun jí dìde kúrò ninu òkú.
Ijọba ipinlẹ Oyo fi sita loju opo Twitter wọn pẹlu alaye ni sisẹ n tẹle lori bi wọn ṣe na owo naa.
Àwọn aláṣẹ sì ń fi ìkanra mú gbogbo ìhàlẹ̀ tí wọ́n ń rí.
Lára ilẹ̀ ẹ̀yà Reubẹni tí ó wà ní ìhà ìlà oòrùn, ní ìkọjá Jọdani níwájú Jẹriko, wọ́n fún wọn ní Beseri tí ó wà ní ara òkè, ati Jahasa, 
Lọgan ti ajọ naa si kede ainile tẹsiwaju pẹlu ipolongo ibo, ni awọn ẹgbẹ oṣelu kan ti n fi ibinu han si igbesẹ ajọ naa.
Tunbosun Ogunbanwo to jẹ adari ẹka imọsilara awọn ara ilu ni ileeṣẹ ijọba to n mojuto ilera ni Eko fidiẹ mulẹ pe eniyan mọkanla lo ti doloogbe lataari arun yii.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Nigeria Stowaway: Baalu tó ń lọ Owerri ni Ọdọmọkunrin náà fẹ́ gán- Airpeace 27 Ọ̀pẹ̀̀ 2019 Àkọlé àwòrán, Agbófinro mú ọkùnrin to n gun baalu to fẹ́ gbera Ìdàrúdàpọ̀ bẹ́ silẹ̀ lónìí ní pápákọ̀ òfurufu ilú Eko nígbà tí ọkùnrin kan ti wọ́n ò tii dárukọ sárẹ gun bààlú Air Peace to n gbéra.
Ìdí tí ó fi fẹ́ràn rẹ̀ nip é nígbà tí Ọ̀sanyìnnínbí ń ṣe òkú ìyá rẹ̀, ó fún un ní ọgọ́rùn-ún náírà (N100.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Mílíọ̀nù Márùn-ún ènìyàn n bẹ nínú ewu ìyàn 3 Èbibi 2018 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 4 Èbibi 2018 Oríṣun àwòrán, STEFAN HEUNIS/AFP/Getty Images Àkọlé àwòrán, Àwọn ọmọ wẹ́wẹ́ tó dín díẹ̀ ni mílíọ̀nù méjì ń gbé nínú aìjẹun-kanu Ówọ́n gógó oúnjẹ, ọ̀gbẹlẹ̀ àti rògbòdìyàn tí lé ọ̀pọ̀lọpọ̀ ènìyàn sínú ebi àti ìyàn.
Wọ́n ń pọ́n àwọn ọmọbinrin rẹ̀ lójú,òun pàápàá sì ń joró lọpọlọpọ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Adamawa election result: Olùdíje PDP já ipò gómìnà gbà mọ́ gómínà Bindow lọ́wọ́ 29 Ẹrẹ̀nà 2019 Oríṣun àwòrán, @AjammaS Àkọlé àwòrán, INEC kede Ẹgbẹ alatako, APC gẹgẹ bii olubori ibo gomina ipinlẹ Adamawa Oludije fun ipo gomina ninu ẹgbẹ oṣelu Peoples Democratic Party, Ahmadu Fintiri, ti jawe olubori gẹgẹ bi gomina ipinlẹ Adamawa.
O tun fi kun wipe ṣẹnetọ naa fi ọrọ silẹ wipe ni tootọ ni oun fi orukọ silẹ fun idanwo naa, ṣugbọn pe oun ko kọ ọ.
Irúgbìn mìíràn bọ́ sí orí òkúta tí erùpẹ̀ díẹ̀ bò lórí.
Ó kéré jù, òṣìṣẹ́ yio lo wákàtí mẹfa lati lọ àti bọ ni ibi iṣẹ́ nitori sún-kẹrẹ fà-kẹrẹ ọkọ̀.
salaye awon ohun amayederun ti won fe ki ijoba se fun un won , ni eyi ti won fi
0 1102096 Orilẹede Germany 21064 25.
Lati nnkan bi ọgọrun ọdun ti ileto naa ti wa, ko si ina ẹlẹntiriiki ni ilu naa.
Bàbá pokùnso ní àhámọ́ lórí ẹ̀ṣùn pé ó bá ọmọ rẹ̀ lòpọ̀ Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí kan sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
Nítorí náà, ẹni tí ó bá mọ rere í ṣe tí kò ṣe é, ẹ̀ṣẹ̀ ni ó ń gbà.
Àṣẹ pé kí Wọ́n Pa Àwọn Olùṣọ́-Aguntan Ọlọrun.
Iliya Kure to je alakoso DEVCOMS ninu oro tire so erongba agbekale igbimo ipolongo yii ki ifitonileti ati idanilekoo to ye le wa fun awon eniyan loorekoore paapaa nigberiko gbogbo ki awon obinrin le nimo kikun lori pataki ifetosomobibi.
Ile igbimo asoju –sofin niluu Abuja, ti bọwọlu
Idunnu wa kọ ni lati tun da kun wahala to wa nile.
O tun sọrọ pataki ati ipa ti aṣa n ko lawujo Yoruba.
Bi ọjọ se n gori ọjọ, ti osu si n gori osu,
Idi si niyii ti ajọ NCC ati awọn eeyan mii ni ẹka ibaraẹnisọrọ ṣe fẹnuko pe o ti di dandan lati mu ki akoyawọ ati ootọ wa ninu eto iforukọsilẹ siimu.
Àlọ́ oooooooooo Báwo ni ìlù gángan se bẹ̀rẹ̀ ?
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Iya n ronu; ọmọ n roka lo ri ni Mozambique.
Ibi tí mo tí ń ronú báyìí ni mo ti wo iwájú tí mo rí òkúta ńlá kọ̀bìtì kan.
Láti ìgbà yìí lọ èmi yóo lọ sọ́dọ̀ àwọn orílẹ̀-èdè mìíràn.
Ẹru ipinya n ba awọn lọkọlaya yii pe ki orilẹ ede Sri Lanka ma tun bẹrẹ ogun mọ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Abule Ado explosion: Irọ́ ńlá ní NNPC pa lórí ìbúghbàmù Abule Ado níbí tí ẹ̀mí èèyàn 23 Ohun ti ọpọ lagbegbe naa n sọ ni oe, aṣemáṣe olopaa nipa jijẹ ki afunrasi naa o lọ mọ wọn lowo, ti wọn ko si tun fi to ara ilu leti kun ara oun to ṣokunfa iku to pa Funmilayọ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Transfer Window: Èrò olólùfẹ́ eré bọ́ọ̀lù ṣọ̀ọ̀tọ̀tọ̀ lórí Iwobi, Lukaku àti Luiz 9 Ògún 2019 Oríṣun àwòrán, Arsenal FC Agbabọọlu Arsenal to jẹ ọmọ Naijiria, Alex Iwobi wa lara awọn agbabọọlu to darapọ mọ ẹgbẹ agbabọọlu miiran l'Ọjọbọ to jẹ gbedeke ọjọ ti ẹnikẹni le ra agbabọọlu tuntun ṣaaju saa bọọlu mii to bẹrẹ lonii ọjọ Ẹti nilẹ Gẹeṣi.
Ṣugbọn wọ́n mú ọba Ai láàyè, wọ́n sì mú un tọ Joṣua wá.
Àwọn gómìnà tẹ́lẹ̀rí tó ti dèrò ẹ̀wọ̀n Wo bí o ṣe le è gba páálí ìrìnnà àti bí ò ṣelè di ọmọ orílẹ́èdè Malta Ìbúgbàmú ọ̀pá epo béntíróò mú ẹ̀mí lọ ni Eko O ya ẹ jẹ ki a gbe wọn yẹwo leni eji.
Onídàájọ́ yóo fà ọ́ fún ọlọ́pàá, ọlọ́pàá yóo bá gbé ọ jù sẹ́wọ̀n.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Naijiria gbe ile-ẹkọ giga fasiti ti Alabama re ile-ẹjọ 28 Èrèlè 2018 Oríṣun àwòrán, ALABAMA STATE UNIVERSITY Àkọlé àwòrán, Ile-ẹkọ naa sọwipe awọn jẹ ijọba orilẹede Naijiria ni $202,000 Ijọba orilẹede Naijiria n gbe ile-iwe giga fasiti Alabama State University lọ si ile-ẹjọ pẹlu ẹsun wipe wọn si owo iranwọ awọn akẹẹkọ wọn lọ.
APC: Mí ò tíí ní ìpinnu lóri ìdíje ààrẹ ọdún 2023-Tinubu
Njẹ lootọ ni Fayọse tọrọ idariji l'ọwọ Buhari?
Àkọlé àwòrán, Ifipabanilopo ni esun ti awon eniyan Naijiria setan lati gobgun ti bayii 'Pasitọ rẹ kìí ṣe Olorun rẹ' ni àkọ́lé ìwọ́de kan ni Abuja.
O ni ninu ile ti ifẹ ba wa, ko si nkankan to jẹ pe wọn gbe ori ọkurin fun alagbafọ.
Oríṣun àwòrán, @HQNigerianArmy Amọ mo si nigbagbọ ninu awọn osisẹ ologun, ọlọpaa atawọn osisẹ agbofinro yoku lati ipasẹ abọ ti wọn n jẹ fun mi, sugbọn mo ro pe o yẹ ki wọn si lee se ju bayii lọ.
2 Èbibi 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 8 Èbibi 2020 Àwọn agbarijo pò dokika ni ile ise ìwòsàn tí ilé ìwé àwọn dókítà ni Ipinle Ondo (UNIMED) ni wọn ti fi ehonu wọn lónìí ní bí ijoba Akeredolu kò ti ṣe san owó oṣù wọn láti bíi oṣù merin àbọ̀ seyin.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Fídíò òògùn ikọ́ Codeine: Àpọ̀jù rẹ̀ ń ya ọ̀dọ́ ní wèrè Gẹ́gẹ́ bíi àwọ̀ǹ òògùn olóró yòkúù, èròjà codeine jẹ́ mọ̀lẹ́bí kan náà pẹ̀lú heroine.
Kaakiri awọn ipinlẹ Naijiria ni irufẹ igbẹjọ yi ti n waye ni idahun si ipe arailu si iwa aitọ t'awọn agbofinro paapa ikọ SARS n hu si ara ilu.
Kọ orúkọ Aaroni sí ọ̀pá tí ó wà fún ẹ̀yà Lefi, nítorí pé ọ̀pá kan ni yóo wà fún olórí kọ̀ọ̀kan.
Ṣé nítòótọ́ ni Ọlọrun sọ pé ẹ kò gbọdọ̀ jẹ ninu èso àwọn igi ọgbà yìí?
" Bakan naa lo rọ awọn ọdọ to n ṣe iwọde lati ṣe e ni ibamu pẹlu ofin Ọlọrun, ati ofin orilẹ-ede.
O ni awọn ọkọ oju omi akero meji kọlu ara wọn lagbegbe ijọba ibilẹ Ojo.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Kidnapping: ASUU kọminú lórí ọwọ́jà ìjínigbé, pè fún àbò fáwọn olùkọ́ fásitì 17 Èbibi 2019 Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Kidnapping: ASUU kọminú lórí ọwọ́jà ìjínigbé, pè fún àbò fáwọn olùkọ́ fásitì Awọn olukọ fasiti lorilẹede Naijiria ni pẹlu bi nnkan ṣe n lọ yii o ṣeeṣe ki awọn gunle iyanṣẹlodi lati fi ẹhonu han lori bi jiji awọn olukọ fasiti gbe ṣe wa di tọrọ fọnkale lorilẹede Naijiria.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù 2020 International day for Rural Women, Garri Ondo: Owó tà ń ná láti ṣe Garri tà kìí ṣe kékeré Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ 2020 International day for Rural Women, Garri Ondo: Owó tà ń ná láti ṣe Garri tà kìí ṣe kékeré 8 Èbibi 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 15 Ọ̀wàrà 2020 Garri olóyọ̀ ti dé'lẹ̀!
’ ” (Èyí ni láti mú Kristi sọ̀kalẹ̀.
Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Fídíò, Akomolede Yoruba: Ìtàn ọ̀rẹ́ tó fi ògùn gba ọkọ ọ̀rẹ́ rẹ̀ nílùú òyìnbó rèé15 Owewe 2020 Fídíò, Yoruba Language: Akomolede ati Asa Yoruba tọ̀sẹ̀ yí rèé lẹ́nu olùkọ́ wa30 Ògún 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Wọ́n ni gbogbo akitiyan láti bá olùgbaninímọ̀ràn rẹ̀ lórí ọ̀rọ̀ tó kan ìròyìn, Oluyinka Akintunde sọ̀rọ̀ lórí èyí, pàbó ló já sí.
Ogbeni Usaini ṣalaye fún mi lori ọkan lára wón ti mo duro tì pé: kò lè sùn si orí ibùsùn nítori pe O ti ba ibùsùn rl jẹ́, o ti fọ́ fèrèsé láti fi ṣe ọṣẹ́ fún ara rẹ̀ ."
Wọ́n pé ọdún méjìlá báyìí Wiro ni iwa to butu jai ni ẹni to ju ọmọ naa nu swa, paapaa lasiko ti ọpọ awọn lọkọ-laya kan ko ri ọmọ gbe jo.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Abdulfatah Ahmed: Àwọn Kwara fẹ́ dán ilé ọkọ kejì wo ni lásìkò yí Facebook tun ti gba imọran lori awọn ohun to nii ṣe pẹlu ofin ati ilana eto iṣuna ori ayelujara naa lọdọ awọn adari eto iṣuna ilẹ Amẹrika.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fọ́nrán ohùn, NUJ: A fẹ mọ ẹsẹ awọn akọroyin tẹ da duro Odusile ni ẹgbẹ akọroyin yoo tanna wadi isẹlẹ naa lati mọ ohun tawọn ileesẹ ọhun ri lọbẹ, ti wọn se waaru ọwọ.
Ẹbi Gomina àná ni ipinlẹ Oyo, Senetọ Abiola Ajimọbi ti jade sita wa sọ pé irọ ni pe Ajimọbi ku!
 O wa fi asiko ohun ro gbogbo won
Atali Elimgbu community: Ọ̀lọ́pàá ní àbò ara ẹni ló mú ọlọ́páà pa ọdọ́ kan ní Port Harcourt
láti gba ẹ̀kọ́, tí yóo kọ́ni lọ́gbọ́n,òdodo, ẹ̀tọ́ ati àìṣojúṣàájú,
N óo dá ire tìrẹ náà pada pẹlu tiwọn.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Busola Dakolo: Ẹ̀sùn tí mo fi kan pásítọ̀ ìjọ COZA ṣì dúró digbí 7 Ògún 2019 Oríṣun àwòrán, Busola dakolo Busola Dakolo sọ fun BBC lọsan Ọjọru pe oun ko tọwọ bọ iwe kankan to tako ẹsun ifipabanilopọ to fi kan Pasitọ agba ijọ Commonwealth of Zian Assembly, Biodun Fatoyinbo.
Ọpọ lo gbagbọ pe Messi lo le ran Man City lọwọ lati gba ife ẹyẹ UEFA Champions League eyi ti wọn ko tii gba ri ninu itan wọn.
Wọn tun sọ pe awọn ko ni ta iwe iroyin kankan titi di ago mẹwaa aarọ ati pe bi ẹnikẹni ba tapa si aṣẹ yi awọn yoo foju rẹ jofin.
fíìmù jẹ ́ ọ ̀ rọ ̀ kàn tí a fi kó àwòràn papọ ̀ .
” Gehasi bá dìde, ó bá a lọ.
Ootọ si ni awọn ọlọpaa mu, ti wọn si tun gba dukia rẹ.
Ọjọ Iṣẹgun ni fidio kan jade to ṣafihan bi Sẹnetọ naa ṣe n lu obinrin kan nile itaja eroja ibalopọ Ọgbẹni Frank Mba ni awọn ọlọpaa ti kan si arabinrin ti iṣẹlẹ naa ṣẹlẹ si pẹlu awọn igun miran ti ọrọ kan igbesẹ iwadii si n lọ .
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Widows Day 2019: Mo máa ń sá kiri wá owó ilé ni -Opó Bakan naa ni Madagascar ti gbena woju orilẹ-ede Burundi ninu idije to n lọ lọwọ yii.
Ṣùgbọ́n àwọn mẹ́fà tí ó kù jẹ́ tèmi, Ọlọ̀run Ọba sì ti pa á láṣẹ fún mi pé kí n máa fi wọ́n ṣe àpẹẹrẹ fún àwọn ọmọ aráyé ti wọ́n bá dé sàkáání mi.
A gbọ́ pé ilé ìwòsàn kan ní Ìkòyí ni olórin náà kú sí lẹ́yìn tí ó dákú ní ọjọ́ Àbámẹ́ta.
Aworan bí Drogba ati awọn akẹgbẹ rẹ tí ṣe kunlẹ bẹ awọn ologun láti gba alaafia laaye jẹ nkan ti awọn Ileese amohunmaworan kaakiri fi n hàn n'ilẹ wọn.
Ninu oro ogbeni Ralph Nduul, to n mojuto sise iwadii ati iseto nile ise BSEMA, fi mule pe, awon ti duro digbi fun oniruuru ikolu omiyale ti o le waye.
Ó wọ́ gbogbo omi òkun jọ bí òkìtì;ó pa gbogbo omi inú àwọn ibú pọ̀ bí ẹni pé ó rọ ọ́ sinu àgbá ńlá.
"Ọpọ wa lo maa n bọ asọ ibori (Hijab) wa lati darapọ mọ awọn akẹẹgbẹ wa lasiko ta ba n jo.
Ẹni tí ó bá ti ń rí ǹkan oṣù rẹ̀, tí ó bá bá ọkùnrin ṣ’erékéré, oyún ni yóò ní.
Lọdun 1952 lasiko ti ijọba amunisin oyinbo n lọ si opin ni awọn ọdọmọdekunrin kan ṣe idasilẹ awọn ẹgbẹ yii.
A Fi Ọba Ijipti Wé Diragoni.
Detective Fashola"" ati Kamẹra iṣẹlẹ iyinbọnpaniyan Lekki Ọrọ ti Minisita to n ri si ọrọ iṣẹ ode ati ileegbe Naijiria Babatunde Fashola ba sọ, a maa saba mu iriwisi wa lati ọdọ awọn ọmọ Naijira."
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ọlọ́pàá Ondo: A bá òkú ọmọ igbákeji gómínà tẹ́lẹ̀rí nílé ọ̀rẹ́kùnrin rẹ̀ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Ọlọ́pàá Ondo: A bá òkú ọmọ igbákeji gómínà tẹ́lẹ̀rí nílé ọ̀rẹ́kùnrin rẹ̀ 8 Agẹmo 2018 Isẹlẹ ibanujẹ ti sẹ ni ile Igbakeji Gomina Ipinle Ondo, Alhaji Lasisi Olubọyọ lẹyin ti wọn ba oku ọmọ rẹ, khadijat ni ile ọrẹkunrin rẹ, Adeyemi Alao ni ipinlẹ Ondo.
Ninu awijare rẹ, Koh ni Uzoka lo tọja oun.
Ami ayo meji si ẹyọ kan ni Brighton ti wọn lọ ba nilẹ fi gbẹyẹ mọ wọn lọwọ.
Ọkunrin náà dá a lóhùn pé, “Wọ́n ti kúrò níhìn-ín, mo gbọ́ tí wọn ń bá ara wọn sọ pé, ‘Ẹ jẹ́ kí á lọ sí Dotani.
Lara awọn eekanlu naa lati ri Femi Fani-Kayode, ẹni to sọ loju opo Twitter rẹ pe o ba oun lọkan jẹ lati gbọ iku ọkunrin naa.
Fun àpẹrẹ, bi àwọn ọmọdé bá njá, àgbàlagbà ti ó bá wà ni ilé ni yio là wọ́n, bi àwọn iyàwó-ilé bá njà, olóri ẹbi tàbi Àrẹ̀mọ ni yio la ijà.
akin lati fi opin si iwa tani yoo mu mi ti o n sele ki o to de ijoba ni odun
Obìnrin Mùsùlùmí ṣe ilé àlúfà ní ọ̀ṣọ́ fún Kérésìmesì Àwọn gómìnà nílẹ̀ Yorùbá ti kùnà láti pèsè ààbò tó péye fún aráàlú - Ẹgbẹ́ Majeobaje Amẹ́ríkà yarí pé àwọn agbégbọn tó jí akẹ́kọ̀ọ́ 344 gbọ́dọ̀ fojú winá òfin Bi afẹfẹ alafiaa ti ṣe n fẹ lu ijọba ati awọn obi tọmọ wọn jajabọ lọwọ ajinigbe ni Katsina, ijọba Amẹrika ti n kesi awọn tọrọ kan pe, ki wọn maa gbagbe lati tọ pinpin awọn to wa nidi iṣẹlẹ yi.
Ọba ka ìwé majẹmu tí wọ́n rí ninu ilé OLUWA sí etígbọ̀ọ́ wọn.
Ọkùnrin kan tó yasó nínú ọkọ̀ Uber rí ẹ̀wọn he Toyin Abraham tú àṣírí ohun tí ọlọ́pàá Náìjíríà sọ mọ́lẹ́bí rẹ̀ kan dà Ajọ LASEMA ni o dabi pe awakọ agbepo naa n sare ni ko to ṣubo.
Awo orin rẹ tuntun to ko jade fun un ni anfani lati BBC News Yoruba sọrọ lori ohun to n fun un ni Imisi lati gbe awọn orin agbọgbarimu jade ni gbogbo igba.
Òjò kò ní rọ̀, ilẹ̀ yóo sì le bí àpáta.
26 Àti nísisìyí, kíyèsíi, àwọn kan wà tí a pè láti kéde ìhìnrere mi, sí àwọn Kèfèrí àti sí àwọn Júù.
Kẹ si maa wo, irufẹ ida ti baba rẹ mu ni ọgbọn ọdun o le diẹ sẹyin, naa ni Ọba Ogunoye naa tun mu yii.
Oniruuru awuyewuye ati edeaiyede lo ti n wọ ts idibo abẹnu ọhun lẹyin lẹgbẹ oṣelu APC eyi to ti mu ki wọn paṣẹ ki alaga ẹgbẹ oṣelu, Adams Oshiomhole naa lọ rọọkun nile pẹlu.
Wo àwọn irọ́ tí wọ́n ń pa fún ọ nípa àrùn Coronavirus Ayẹyẹ naa ti wọn pe ni 'Ibadan Week Celebration' ni wọn ti sun siwaju bayii nitori arun Coronavirus ọhun.
”Nítorí pé láti Sioni ni òfin yóo ti máa jáde,ọ̀rọ̀ OLUWA yóo sì máa jáde láti Jerusalẹmu.
Abíóyè: Ọmọ tí a bí lásìkò tí bàbá rẹ̀ wà lórí oyè
Ìpínlẹ̀ méjìlá nínú ewu àgbárá òjò ní Nàìjíríà Kíni ẹ mọ̀ nípa àwọn gbajúgbaja Yollywood?
Wọn ni ijọba ni lati jẹ ki awọn ara ilu ri wi pe ko si erongba kankan to yatọ si mimu idagbasoke ba awọn eeyan pẹlu igbesẹ dida Ruga settlement silẹ.
Ni ọjọ Aje, ọjọ kini, oṣu kẹfa, ọdun 2020 ni Majek Fashek jade laye lẹni ọdun mẹtadinlọgọta.
"Ẹyin eniyan mi ẹ jọwọ, ẹ jẹ kani suru fun awọn ijọba ba wa nitori fun anfaani ara wa ni.
Baale ati Mogaji ti Olubadan fi je lona ti ko ba ofin mu lati lọ ko ọ sile/ pe
Àwọn ọmọ wọn yóo dá yàtọ̀ láàrin orílẹ̀-èdè,a óo dá arọmọdọmọ wọn mọ̀ láàrin àwọn eniyan,gbogbo àwọn tí ó bá rí wọn,yóo gbà pé èmi OLUWA ti bukun wọn.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ilé ẹjọ́ tú ìgbéyàwó ọdún mẹ́wàá ká nítorí ẹ̀sùn ìbálòpọ̀ ọlọ́jọ́ gbọọrọ àti òògùn owó 26 Bélú 2020 Oríṣun àwòrán, Getty Images Ile ẹjọ ibilẹ Mapo nilu Ibadan, ti tu igbeyawo ọlọdun mẹwa kan, nitori ẹsun ibalopọ alainigbedeke, ati oogun owo.
“Ọmọ eniyan, mo ti fi ọ́ ṣe olùṣọ́ fún ilé Israẹli.
Bótilẹ̀ jẹ́ pe ilé ilé iṣẹ́ to ń se ohun mímu náà Revin Zambia kò ti fèsì lóri ọ̀rọ̀ náà.
Àwọn ọmọ ènìyàn ti yípadà, ọlọ́gbọ́n bẹ̀rẹ̀ sí dé inú wọn, ojọ́ pẹ́ tí mo ti fi ìhín ṣe ibùgbé, ẹni kan kò gbìyànjú àti yí mi lọ́kàn padà rí, ṣùgbọ́n mo ti kíyèsí i láti ọjọ́ ti Ọlọ́run ti ṣe ẹ̀dá mi pé, onísùúrù kò le kábàámọ̀ láé àfi ẹni tí ó fi òmùgọ̀ ba sùúrù jẹ́: láti oní lọ, n kò ní hùwà ìbàjẹ́ si ọmọ aráyé mọ́, n kò ní kanra si àwọn ọmọ ènìyàn, n kò ní fajúro si àwọn ẹranko, n kò sì ní hùwà ibajẹ́ ọ sí àwọn ewéko inú igbó, nítorí ọ̀rọ̀ rẹ ti yí mi lọ́kàn padà, n kò ní hùwà ará oko mọ́.
Ò máa san ẹ̀san fún eniyangẹ́gẹ́ bí iṣẹ́ rẹ̀ bá ti rí.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù UNICEF: Nàìjíríà ti bí ìkókó 26, 039 lónìí ọjọ́ kíní, oṣù kínií, ọdún 2020 1 Sẹ́rẹ́ 2020 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, UNICEF ni awọn ọmọ tuntun ti a maa bi ni Naijiria a tó ìdá meje ninu ọgọrun un gbogbo ikoko ti a maa bi lagbaye Ajọ ìṣọ̀kan àgbáyé lórí ọrọ awọn ọmọde, UNICEF ti kede pe Naijiria a bi ikoko mọkandinlogoji le ni ẹgbẹrun mẹrindinlọgbọn lonii.
Ebuka ni yoo ṣi gbalejo eto apejọpọ ọjọ Aiku naa ni ile ẹlẹgbọn agba BBNaija naa Oríṣun àwòrán, others Wo díẹ̀ lára àwọn tí yóò kópa nínú ìdíje BBNaija ọdún yìí Idije BBNaija ọdun 2020 ti gberasọ, oriṣiriṣi oju tuntun ti awọn ololufẹ BBNaija ko tii ri ri ni yoo si pe jọ sinu ile BBNaija lọdun yi.
tabi tí ijamba bá ṣe ní ọwọ́ kan tabi ẹsẹ̀ kan, 
Gwandu ni gbogbo ẹhonu araalu ni awọn alaṣẹ ileeṣẹ ọlọpa yoo mojuto ni ibamu pẹlu ipinnu ọga agba awọn ọlọpa lati mu atunto ati atunṣe ba ikọ ọlọpaa kogberegbe FSARS lati lee bẹrẹ si ni ṣe iṣẹ wọn bi o ti tọ ati bi o ti yẹ.
Lọ sọ fún Jeroboamu pé, ‘OLUWA Ọlọrun Israẹli ní, “Mo gbé ọ ga láàrin àwọn eniyan náà, mo sì fi ọ́ jọba lórí Israẹli, àwọn eniyan mi.
O damiloju pe o n jẹgbadun.
    Báyìí ni ìyàwó mi náà ka tirẹ̀, ìgbà tí wọ́n sì kọrin dídùn tan ní ìsìn ìgbéyàwó náà ti parí ti pári ti a lọ sí ilé ti wọ́n fún wa.
Ni owurọ Ọjọ Isinmi, ni agbegbe Andhra Pradesh ni Vijayawada ni iṣẹlẹ naa ti waye.
Agbaboolu owo eyin Juventus Medhi Benatia, gba ami ayo meji wole, bee si ni  Douglas Costa gba ami ayo miiran wole.
Àkọlé àwòrán, Awọn ara Eko pejọ si ibi iburawọle fun Gomina tuntun ati igbakeji rẹ.
Ajọ naa fi ẹsun kan wọn pe wọn tapa si ofin to de igbohunsafẹfẹ, nipa ṣiṣe afihan awọn fidio ti wọn ko ṣe iwadii rẹ.
Ẹ̀mí bá gbé mi dìde, ó mú mi wá sinu gbọ̀ngàn inú; ìtànṣán ògo OLUWA sì kún inú Tẹmpili náà.
ni pipe, eleyii ti awa naa yoo ṣagbeyẹwo wọn ni kikun.
Ninu atẹjade kan to fi si oju opo twitter rẹ, Sanwo-Olu gbadura fun alaafia, ilọsiwaju ati igberusi fun awọn musulumi bi wọn ṣe n ṣajọyọ naa.
Ìròyìn ibi kì í bà á lẹ́rù,ọkàn rẹ̀ dúró ṣinṣin, ó gbẹ́kẹ̀lé OLUWA.
Natani bá tọ Batiṣeba ìyá Solomoni lọ, ó bi í pé, “Ṣé o ti gbọ́ pé Adonija ọmọ Hagiti ti fi ara rẹ̀ jọba, Dafidi ọba kò sì mọ nǹkankan nípa rẹ̀.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Zlatan: Ọ̀rẹ́ ni mo sìn lọ ‘studio’ tí mo fi bẹ̀rẹ̀ orin lẹ́yìn tí mo kùnà ìdánwò WAEC Ẹ̀wẹ́, òǹkòwé náà sàlàyé pé, Adedibu fi ìwà jọ akọni lójú ogún ilẹ ìbàdan kan, ti orúkọ rẹ̀ tàn ká ilé, tàn ká oko, eyiun Iba Oluyole.
Àkàrà tú sépo, Trump ló kọ èsì ìlera ara rẹ̀ Trump yọ Tillerson kuro nipo Ìpè orí fóònù tó mú kí America fẹ́ yọ ààrẹ Trump rèé Donald Trump ní àwọn ọmọ ogun IS yi wà lára àwọn tó burù julọ nínú ìkọlù Aarẹ Trump ninu ọrọ rẹ fidiẹ mulẹ pe awọn Taliban ti ṣetan lati bawọn sọrọ bayii.
Ewe, bakan naa si ni, rogbodiyan latodo awon omo-ogun olote ko gbeyin ni erongba lati dena ayeye ohun.
ẹ óo kọrin òwe bú ọba Babiloni pé:“Agbára aninilára ti pinìpayà ojoojumọ ti dópin.
Èdùmàrè tó dá ẹ̀dá ọmọ èèyàn tó pàṣẹ pé ká máa bí síi ká sì máa rẹ̀ síi, Òun náa ló ṣe ọpọlọ ọmọ ènìyàn yàtọ̀ sí ti ẹranko lásán.
 Àjàpadé jẹ ́ ọmọ rere , ó sì fẹ ́ ràn láti máa ṣeré káàkiri ààfin Òdùduwà , àwọn ènìyàn a sì máa pè é ní  Àjàpadá Ọmọ Ẹkùn ."
O ni bi awọn ewe ẹfọ yii ti dudu were were lo jẹ ki o ṣe anfaani fun ara.
Oríṣun àwòrán, AFP Àkọlé àwòrán, Kíni ìdí tí àwọn ẹbí àwọn ọmọ Chibok fi ń tọ woli lọ?
Loore koore ni awọn ajọ pajawiri n kilọ pe ki awọn eeyan sọrọ tita afẹfẹ gaasi ni itosi ibi tawọn eeyan n gbe.
June 12: Lekan Alabi ní kí ọmọ Naijiria rántí àwọn akọni ìjọba àwa-arawa
Bí wọ́n bá ti dé àwọn ẹnu ọ̀nà gbọ̀ngàn inú, wọn yóo wọ aṣọ funfun.
Bẹẹ ba gbagbe, o to ọsẹ meji ti igbakeji gomina nipinlẹ Ondo yii kan naa, Agboola Ajayi, kuro ninu ẹgbẹ oselu APC to n se ijọba lọwọ nibẹ, lọ sinu ẹgbẹ alatako PDP.
Ìjọba ìpínlẹ́ Kaduna: A kò dá olùkọ́ míì dúró
O ṣalaye pe ọmọ iya oun ti ko kuro nile ọkọ rẹ ni nkan bi oṣu mẹ ta sẹyin nitori ede aiyede to ti n waye laarin wọn.
Usaya ní ọpọlọpọ ọmọ ogun, tí wọ́n tó ogun lọ, ó pín wọn ní ìsọ̀rí-ìsọ̀rí gẹ́gẹ́ bí ètò tí Jeieli akọ̀wé, ati Maaseaya, ọ̀gágun ṣe, lábẹ́ àkóso Hananaya, ọ̀kan ninu àwọn ọ̀gágun ọba.
O ṣalaye pe yoo waye nipinlẹ Adamawa, Bauchi, Benue, Kano, Plateau ati Sokoto ati ni gbogbo ibudo idibo ti ibo ile igbimọ aṣofin naa ko ti kẹsẹ jari kaakiri orilẹede Naijiria.
Ó tún wí fún wọn pé, “Ẹ fi ara balẹ̀ ro ohun tí ẹ bá gbọ́.
Iye àwọn ọmọ Geriṣoni ní ìdílé-ìdílé, gẹ́gẹ́ bí ilé baba wọn, 
Oni, ọjọ Karun oṣu Kẹrin ọdun 2019 gan an lo pe ọdun kan geerege ti awọn adigunjale yabo ilu Ọffa, ti wọn si ja ileefowopamọ maarun ọtọọtọ lole.
Ṣugbọn nisinsinyii, ìjọba rẹ kò ní jẹ́ títí lae, nítorí pé, o ti ṣe àìgbọràn sí OLUWA.
 lápapọ ̀ , àwọn agbègbè yí ń jẹ ilẹ ̀ yorùbá .
ki gbogbo awon omo orile ede Naijiria fokan balẹ, nitori pe won ko ni pẹ maa
Àwọn ọmọ ogun tí wọ́n wà lábẹ́ wọn jẹ́ ọ̀kẹ́ mẹẹdogun ó lé ẹẹdẹgbaarin ati ẹẹdẹgbaata (307,500), wọ́n lágbára láti jagun, ati láti bá ọba dojú kọ àwọn ọ̀tá rẹ̀.
Ó wí fún un pé, “Rabi, a mọ̀ pé olùkọ́ni láti ọ̀dọ̀ Ọlọrun wá ni ọ́, nítorí kò sí ẹni tí ó lè ṣe àwọn iṣẹ́ ìyanu tí ò ń ṣe wọnyi àfi ẹni tí Ọlọrun bá wà pẹlu rẹ̀.
O ni pipada si eto abo civil defence bi o senwa lati ipile ni ojuutu si isoro yii.
Bakan naa ni wọn ti fi ofin de gbogbo nkan to ni i ṣe pẹlu ẹgbẹ akẹkọọ nileewe naa.
Wọnyi ni awọn sẹnẹtọ mẹrin ọhun to papoda laarun oṣu mẹfa tun to fori sọ asiko ajakaklẹ aarun coronavirus lorilẹede Naijiria.
00 ) níbi tí kò ti sí ẹni tí ó tún fún un ju náírà márùn-ún lọ .
han lati da okoowo sile lorile ede Naijiria, paapaa julo iru eyi to n sẹlẹ  bayii laarin orile ede Naijiria ati orile ede
Iroyin ni awọn miran ninu awọn ọmọ ogun ṣi wa ni ile iwosan fun itọju bayii.
Ó wá bù ẹnu àte lu irú ìwà bẹ́ẹ̀ pé àwọn òsìsẹ ìjọba lọ́wọ́ sí gbigba ilẹ̀, ó ní ilé ẹjọ́ tí dájọ, to sì gbé fún àwọn ará ìlú náà.
Bí ẹ ti gbé ara yín fún ìwà èérí ati ìwà tinú-mi-ni-n-óo-ṣe, tí a sì fi yín sílẹ̀ kí ẹ máa ṣe bí ó ti wù yín, bẹ́ẹ̀ náà ni kí ẹ wá fi ara yín jìn fún iṣẹ́ rere, kí ẹ sìn ín fún iṣẹ́ mímọ́.
 Ile ise ijoba apapo to n mojuto oro eto ilera ati ile ise Human Virology ti n satileyin tele fun awon eniyan lori riri oogun naa ni Naijiria ni eyi ti won ko tii ri ariwisi boya won ti baje tabi bee ko”.
Agẹṣin Adimula tilu Ila Ọrangun ni bi wọn ba bi ọmọ lori oye, akọkọ ni pe kii ṣe bi gbogbo eeyan yooku yoo ṣe ri ọmọ tuntun naa ni Kabiyesi tabi awọn Afọbajẹ yoo ṣe rii.
Ẹrọ keji ni ẹrọ Ventilator, to n seranwọ lati jẹ ki alaisan lee mi jalẹ daadaa.
'Bíbélì kò ní kí tọkọ taya lu ara wọn pa' Ṣé o mọ ìgbésẹ̀ ìkọ̀sílẹ̀ lábẹ́ òfin Naijiria?
Ẹfunsetan Aniwura, obìnrin tó ju ọkùnrin lọ Ọ̀rọ̀ǹpọ̀tọ̀niyùn, Aláàfin obìnrin àkọ́kọ́ rèé, tó ní nǹkan ọkùnrin Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Mike Ifabunmi: Òrìṣà ló gbè wà jù ni Brazil Egungun, Ẹyọ, Gẹlẹdẹ, ati bẹẹ bẹẹ lọ pelu awon nkan ara ti wọn fi hande nibi ọdun naa.
Á wá dàbí pé wọ́n ń kíni káàbọ̀ sí inú igbó àwọn.
Iyabo Ojo sọ̀rọ̀ nípa iṣẹ́ abẹ tó ṣe, Nkechi Blessing ra ǹkan irinsẹ fún arọ Toyin Abraham àtàwọn ọ̀dọ́ sọ̀kò èèbú síra wọn torí ìwọ́de #EndSARS Ìbò aráàlú pẹ̀lú ẹ̀yà yókù lá fi yanjú àtúntò Nàíjíríà - YCE Nitori naa aarẹ ẹgbẹ FIBAN Desmond Nwachukwu ti wa pasẹ ki awọn ọmọ ẹgbẹ naa jeburẹ ki wọn si bẹrẹ si ni lo orin KWAM 1 lori eto wọn.
Nepal ní ọ̀wọ̀ ẹyẹ oríṣi 876, tí ọ̀kan ṣoṣo nínúu wọn sì jẹ́ irú èyí tí kò sí ní ibòmíràn lórí ilẹ̀ ayé (Spiny Babbler).
Ẹgbẹ Shiite tun sọ pe ninu irora ti ko ṣe fẹnu sọ ni iyawo El-Zakzaky wa nitori ọta ibọn tawọn ologun yin mọ si mwa lara rẹ.
Olugbe Opeji kan, Babatunde Adesola sọ fun BBC pe nnkan ibẹru nla o jẹ fun awọn lati ri ọpọlọpọ awọn Fulani darandaran wọ ilu wa.
”Gege bi minisita ajo to n ri si oro ile-okere, ogbeni Geoffrey Onyeama se so, O ni: lati igba ti won ti se ifilole ajo oro ile-okere lodun 1957 seyin, ojuse ati ilana re ni lati daabo bo ibasepo orile-ede Naijria ati orile-ede yooku, ati lati pese ilana lati fayegba awon orile-ede miran .
Lẹ́yìn ìwádìí, àwọn ọlọ́pàá ṣe àrídájú wípé ọmọ-ọ̀dọ̀ kan láti ilẹ̀ òkèèrè tí ó ń bẹ̀rù wípé ọ̀gá òun yóò lé òun ni ẹnu iṣẹ́ bí ó bá mọ̀ wípé òun ní oyún ni ìyáa rẹ̀.
Àjẹsára dídáranjẹ ̀ ọpọlọ ti japaníìsì jẹ ́ àjẹsára tí ń dáàbò bo ni lọ ́ wọ ́ dídáranjẹ ̀ ọpọlọ ti japaníìsì .
Bi awọn kan ṣe n kan saara si, ni awọn kan n bu ẹnu ẹtẹ lu u, paapa lẹyin ti ìwé iroyin Daily Trust, pé akiyesi si awọn orukọ naa ti ko ni orúkọ aarẹ Naijiria nigba kan, Olusegun Obasanjo ninu.
Nígbà tí Saulu rí àwọn ọmọ ogun Filistini, àyà rẹ̀ já, ẹ̀rù sì bà á lọpọlọpọ.
Ẹrin Ijesa, Ọ̀ṣun Oṣogbo, àwọn ibùdó ìgbafẹ́ tí ó yẹ kí o mọ̀ Ǹjẹ́ o mọ àwọn ǹkan èlò ilé tó léwu fún ẹ̀mí?
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Magawa: Èkúté tó sàwárí bọ́mbù ilẹ̀ gbàmi ẹ̀ye wúrà PDSA 25 Owewe 2020 Oríṣun àwòrán, PDSA/PA Àkọlé àwòrán, Magawa gba ami ẹyẹ wura lẹtin to sàwárí ọmi-ilẹ ni cambodia Èkúté ńlá kan to dà bi òmìràn ti gba àmì ẹ̀yẹ wúrà fún iṣẹ́ rẹ̀ láti ma ṣe awári imọ-ilẹ Magawa a maa ti fimu filẹ̀ lati ri imọ-ilẹ Mọ́kandinlógójì àti ti àwọn méjìdinlagbọ́n ti kò bu gbàmu mọ lọ́wọ́ ri lati igba tó ṣe iṣẹ́ to yàn láàyò yìí.
Jehoṣafati, ọmọ Ahiludi ni olùtọ́jú àwọn ìwé àkọsílẹ̀.
Èniyan 81 ló ti ní àrùn Coronavirus ní Naijiria Gómìnà ìpínlẹ̀ Kaduna ti ní àrùn Coronavirus Àfẹ́sọ́nà Davido, Chioma nàá ti ní ààrùn Coronavirus Coronavirus: Njẹ́ jíjẹ́ aláwọ̀ dúdú le gbà ọ́ sílẹ̀ lọ́wọ́ ààrùn Coronavirus?
Nítorí Ọlọrun yóo mú gbogbo nǹkan tí eniyan bá ṣe wá sí ìdájọ́, ati gbogbo nǹkan àṣírí, ìbáà ṣe rere tabi burúkú.
Boss Mustapha to jẹ alaga ikọ amuṣẹya lori ọrọ ajakalẹ arun COVID-19 ni Naijiria ṣalaye lasiko ijiroro igbimọ naa lọjs Aje nilu Abuja pe nnkan lee da bi ẹni pe o ti n lọlẹ lẹnu lọwọlọwọ yii lori ọwọja ajakalẹ arun naa ṣugbọn O ni ẹyẹ ina gbigbona lọrọ arun naa ni Naijiria bayii, O kan fi eeru tutu boju ni.
Nítorí náà ni àwọn tí wọn ń gbé inú àwọn ìlú olódi náà ṣe di aláìlágbára,tí ẹ̀rù sì bà wọ́n gidigidi.
Sẹnatọ Saraki, ni oniruuru abajade iwadi lo n fidi rẹ mulẹ wipe nkan o ọjọ iwaju ilẹ Afirika ni ifọwọsowọpọ awọn eniyan rẹ, paapaa julọ lati lee ṣ'eto ọjọ ọla to gun rege fun awọn ọdọ.
School) to wa ni agbegbe Oluyole Estate ni ijoba Ibile Iwo-oorun Gusu, Ibadan
Awọn ẹgbẹ ajafẹtọ ọmọniyan ti ko din ni metalelaadọta ni wọn ti ṣetan bayii lati fi ehọnu han ni Ọjọ Karun un, Oṣu Kẹsan, ọdun yii.
eto isuna ati eto ọrọ aje , ogbeni James Owolabi, ni eto yii wa lara ohun akọkọ
Hicks ẹni ọdun mọkanlelọgbọn jijọ ba aarẹ Trump rin ninu ọkọ baalu rẹ Air Force One lọ si Ohio nibi ti itakurọsọ laarin Trump ati Biden ti waye.
Oríṣun àwòrán, Others Ere olokun: Awọn obinrin lo fẹran lati ma a ṣe ere yii.
Fadeyi fi kun ọrọ rẹ pe ọlọpaa ko yinbọn fun ẹnikẹni nibẹ tako iroyin to gba ori ayelujara kan wi pe ọlọpaa yinbọn nibẹ.
Ọ̀ògùn ikọ́ codeine ń pa iran kan run lọ ní Nàíjíríà
Israẹli ń ṣe agídí bí ọ̀dọ́ mààlúù tí ó ya olóríkunkun; ṣe OLUWA lè máa bọ́ wọn bí aguntan nisinsinyii lórí pápá tí ó tẹ́jú.
Daju daju, gbogbo agbaye lo n ṣelede lẹyin ẹniire to lọ, arẹwa obinrin, aya pasitọ ijọ Trinity House lorilẹede Naijiria, Ibidunni Ighodalo.
Bo tilẹ jẹ pe wọn dẹkun wọn lati ba ileeṣẹ iroyin sọrọ, ọpọ awọn oṣiṣẹ eto ilera nilẹ Gẹẹsi ti sọ ẹdun ọkan wọn fun ileeṣẹ iroyin BBC nipa bi aini irinṣẹ to peye ṣe n jẹ wọn niya.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ọmọ́táyọ̀ Olútóyè: Àwọn ǹkan tó yẹ kí ẹ mọ̀ nípa Ọ̀jọ̀gbọ́n obìnrin àkọ́kọ́ nínú ẹ̀kọ́ èdè Yorùbá lágbàyé 29 Ògún 2019 Oríṣun àwòrán, @others Àkọlé àwòrán, Iṣẹ tokunrin n ṣe, obirin naa le ṣe e Abi Ọjọgbọn Omọtayọ Olutoye ni ọjọ karundinlogun, oṣu kẹwa, ọdun 1935, ni ilu Eko, bi o tilẹ jẹ pe, ọmọ bibi ilu Ilogbo, ni ipinlẹ Ekiti ni.
Ó bá lọ dá ọgbọ̀n owó fadaka pada fún àwọn olórí alufaa ati àwọn àgbà.
Asuu Àkọlé àwòrán, Bi awọn kan ṣe n sọ pe odaa bẹ, lawọn miran n sọ pe ko yẹ ko ri bẹẹ nitrori akoko awọn akẹkọọ n lọ lai duro.
Yemi Solade Gbogbo ọjọ kọkanlelọgbọn oṣu kini ni ayẹyẹ ọjọ ibi gbajugbaja oṣere, Yemi Solade.
Adajọ ile ẹjọ igbẹjọ idibo Naijiria ti ni ki wọn lọ tun ibo naa di ni ẹkun iwọ oorun ipinlẹ Kogi.
Oríṣun àwòrán, @YACMediaProd Nigba to ku iṣẹju marun un ki ifẹsẹwọnsẹ naa wa sopin ni Bruno Fernandes ṣe bi ọkunrin, to si da goolu kan pada sinu awọn Chelsea, ṣugbọn o ti bọ sori.
Kì í ṣe ibi tí ò ń gbé nìkan, ṣiṣẹ́, san owó orí àti ṣe àkóso ibi tí ó ti ní ipa, àmọ́ ìfàsẹ́yìn fún ẹ̀tọ́ ọmọnìyàn nínú ibi tí ìjọba àwa-arawa ti fi ẹsẹ̀ rinlẹ̀ lè di lílò fún ìrúfin ẹ̀tọ́ ní àwọn agbègbè tí ẹ̀tọ́ ọmọnìyàn kò fi bẹ́ẹ̀ fi ẹsẹ̀ múlẹ̀.
Ẹ̀rù ba Jehoṣafati gidigidi, ó sì bẹ̀rẹ̀ sí wá ojú OLUWA, ó kéde jákèjádò ilẹ̀ Juda pé kí wọ́n gbààwẹ̀.
O sọ pe asiko yii ni wọn ṣẹṣẹ mọ irora ti awọn ọmọ Naijiria maa ni ti iru iṣẹlẹ bayii ba ṣẹlẹ si wọn.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Champions League: Ronaldo ní Tottenham yóò jẹ moyó ìyà lọ́wọ́ Liverpool 31 Èbibi 2019 Oríṣun àwòrán, Twitter/UEFA Champions League Àkọlé àwòrán, Champions League yoo yeruku lala Ọ ní wọn á jìyà nínú àṣekágba ìdíje UEFA Champions League.
Coronavirus: Odaran tíì kí bá ṣé ọmọ orílẹ̀èdè Ethiopia yóò padà sí ìlú abinibi rẹ
Bisọbu Oyedepo lo jẹ ojiṣẹ Ọlọrun kẹta, ti yoo rọ Aarẹ Buhari lati kọwe fipo silẹ lẹyin ti bisọọbu agba fun Ijọ Aguda l'Abuja, John Cardinal Onaiyekan, ati akẹẹgbẹ rẹ tẹlẹ nipinlẹ Eko, Cardinal Anthony Olubunmi Okogi, sọ fun Aarẹ Buhari lati fipo silẹ lẹyin to kuna lati daabo bo awọn ọmọ Naijiria.
Nítorí bí eniyan bá lè di ajogún nípa òfin, a jẹ́ pé kì í tún ṣe ìlérí mọ́.
"Ko si ọna ti yoo gba wọle ti a ko ni mọ, 'tori o tako ofin lati ko wọn wọle.
LAUTECH Crisis: Makinde ní kí ìpínlẹ̀ Ọyọ gba àkóso fásitì náà ni ọ̀nà àbáyọ
Ọmọ ọdun méje gbé bàbá rẹ̀ lọ àgọ́ ọlọ́pàá Ìbálòpọ̀ ọkùnrin sí ọkùnrin kò lòdì s'ofin Tó o bá ṣàdéhùn ìfẹ́ tó ò mú u ṣẹ, ẹ̀wọ̀n lo fi ń ṣeré Oríṣun àwòrán, AFP Àkọlé àwòrán, Awọn alatil;ẹyin Modi ni Assam ti wọn ti n yọ ayọ esi idibo silẹ Ọpọ lo gba pe olori gidi ni Narendra Modi ṣugbọn awọn mii ni o bu epo si ina ẹlẹyamẹya ti ko pọ ni India to bayii tẹlẹ.
Oke-Oluokun ni Ila- oorun, Gusu Ibadan ni ipinle Oyo.
Máa gbé kẹ̀kẹ́ rẹ lọ, àwọn akọròyìn kọ̀ ìpàkọ́ sí Femi Fani Kayọde Ọba Adegbite Adedoyin kawe gboye imọ anofin ta si gbọ pe o lọwọ si idasilẹ ile ẹkọ girama to le ni mẹjọ laarin ọsun 1978 si 1982.
Ṣugbọn wọn kò gbọ́ràn, wọn kò fetí sílẹ̀, wọn kò dáwọ́ ibi ṣíṣe dúró, wọn kò sì yé sun turari sí oriṣa mọ́.
nnkan jẹ”Aare  Buhari gbosuba fun igbakeji re , ojogbon  Yemi Osinbajo, fun ise ribi-ribi to n se
Gomina fi idunnu re han lati tewo gba adari ijoba orile ede Britain ni alejo, o so pe ibasepo to wa laarin orile ede Naijria ati Britain ti wa lati ọjọ pipẹ.
(Ṣe àfiwé Málákì 4:5–6; bákannáà ìpín 27:9; 110:13–16; àti 128:18.
Amotekun yóò gba owó oṣù kẹtàlá ní ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́ - Seyi Makinde Maina dákú fún ọ̀pọ̀ ìṣẹ́jú, iléejọ́ sáré so ìjókòó rọ̀ Wo ìròyìn tó pọ̀ jùlọ táwọn èèyàn ń wá ní Google lọ́dún 2020 Obasanjo àti Gani Adams tẹ́ mi pẹ̀lú bí wọn ṣe tahùn síra wọn - Adebanjo Bakan naa, Ọọni sọ pe Covid-19 ti sọ ọpọ ọdọ atawọnobi wọn di alainiṣẹ lọwọ atipe ifasẹyin ọrọ aje yii tun jẹ iṣoro mii to ṣakoba fun awọn ọdọ Naijiria.
Ilé ẹjọ́ Kano: Ganduje kò lẹ́tọ̀ọ́ láti yan Emir Ṣáájú ààwẹ̀ Ramadan, àwọn ọlọ́pàá Sharia ń mú aṣéwó àti ọ̀daràn nípínlẹ̀ Kano Ganduje fún Aminu Ado Bayero ní ìwé ìyannisípò gẹ́gẹ́ bí Emir ìlú Kano Dangote, Fayemi pari ìjà láàrin Ganduje àti Emir Sanusi Bakan naa ni ọmọ ṣori ni ipinlẹ Ogun lọdun yii: Kò ní sí ayẹyẹ ọdún Ojúde Oba lọ́dún yìí- Awujale ilẹ̀ Ijebu Ọba Sikiru Adetona ti ilẹ̀ Ijebu ti kéde pé ayẹyẹ ọdún Ojude Oba kò ní wáyé lọ́dún yìí.
Wọ́n ṣe àwọn ọ̀pá ìdábùú rẹ̀, wọ́n sì tún odi rẹ̀ kọ́ ní ìwọ̀n ẹgbẹrun igbọnwọ (mita 450), sí Ẹnubodè Ààtàn.
Oríṣun àwòrán, María Conejo/BBC A gbọ pe ọmọbinrin naa n gbe pẹlu aburo baba rẹ, Esther Ogungbemi, nilu Ilare, to wa ni ijọba ibilẹ naa.
Tí a fiṣọwọ́ ní 11:36 12 Sẹ́rẹ́ 202111:36 12 Sẹ́rẹ́ 2021 Ẹ dákẹ́ àhesọ ọ̀rọ̀, ohun tó pa ẹ̀gbọ́n àti àbúrò Orisabunmi rèé - Mọ̀lẹ́bí gbarata Mọlẹbi Orisabunmi ni ofuutu fẹẹtẹ, aasa ti ko ni kaun ni ahesọ ọ̀rọ̀ nipa iku to pa tẹgbọn taburo Orisabunmi, yoo si dara ki awọn eeyan kọ ẹyin si.
Ọwọ́ tẹ afurasí 8 tó jí akẹ́kọ̀ọ́ Chibok gbé Boko Haram pa olùkọ̀ 2,295 ni àríwá Nàíjíríà kọ́lẹ́rà pa èèyàn 50 ní Borno,Yobe àti Adamawa Ọlọpa kan yinbọn mọ ọga rẹ nitori obinrin Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, FFK: Buhari ló ń fún àwọn Fulani láàyè láti máa pa ènìyàn' Awọn ẹgbẹ ti wọn n ja fun itọju nkan ayika ati nkan adayeba ni Naijiria ti n sọ fun awọn agbofinro lati tu igun yii silẹ.
Yakubu fikun pe, awọn yoo fi ọsẹ kan se afihan orukọ awọn oludibo, bẹrẹ lati ọjọ kẹfa Oṣu kọkanla ọdun yi titi di ọjọ kejila Oṣu kọkanla Oríṣun àwòrán, @inecnigeria Ireti INEC ni pe, ayẹwọ orukọ yi yoo fun awọn ara ilu lanfaani lati mọ boya aisedede kankan wa ninu orukọ wọn.
Atẹjade naa ni ni kete tawọn adigunjale naa sisẹ laabi ọhun tan, ni wọn fẹsẹ fẹ lori ọkada wọn amọ ti Adebayo atawọn araalu gba ya wọn pẹlu ọkọ rẹ titi to fi le wọn de adugbo dandaru.
Nígbà tí ó sì di òwúrọ̀ ọjọ́ kan báyìí, ògbólógbòó àjẹ́ kan dí wa mọ́ ilé, bẹ́ẹ̀ ni eléyìíní gbóna ju àwa lọ, ẹ̀dá burúkú náà bá wa fi ìjà pa ẹẹ́ta, ó lé wa kúrò nínú ilé a si sáré dé Igbó Olódùmarè koko.
Ó ń rìn káàkiri àwọn òkè bí ibùjẹ rẹ̀,ó sì ń wá ewéko tútù kiri.
Idajọ iku Ọpọlọpọ igba ni wọn gbiyanju lati pa a, igba mii loju popo ti ẹmi awọn mii lọ si i.
Wọ́n á tún máa lé ọmọọmọ wọn kiri ní àdúgbò
O to ogoji ọdun ti Soyinka ti n kọ iwe naa, ko to o gbe jade lọdun 2020.
 Bi awọn onilu gangan ati bata se n lu ilu lọ niwaju arugba naa, ni awọn agbofinro n sọ ọ loju lẹsẹ, ti wọn ko si jẹ ki ẹnikẹni sunmọ ọdọ rẹ."
Ènìyàn 653 míràn tún kún iye àwọn tó ní COVID-19 ní Nàìjíríà Nǹkan mẹ́sàn án tí Mùsùlùmí gbọdọ̀ ṣe nínú oṣù Dhual- Hijjah Iléeṣẹ́ ológun òfurufú Nàìjíríà fa àwọn mẹ́ta tí ọwọ́ tẹ̀ lórí ikú Tolulope Arotile lé Ọlọ́pàá lọ́wọ́ Èèyàn 20 ni coronavirus pa l'Ọ́jọ́bọ nìkan Ilé ẹjọ́ wọ́gilé ìgbẹ́jọ́ Olalekan 'Woodberry' Pọnle Pataki Afara 'Third Mainland Bridge' ati itan rẹ: Afara yii jẹ eyi ti wọn tun n pe ni Ibrahim Babangida Boulevard, ọjọ ibi Babangida lọjọ kẹtadinlogun, oṣu kẹjọ lọdun 1990 ni wọn ṣii.
Gbé pẹpẹ ẹbọ sísun kalẹ̀ níwájú ẹnu ọ̀nà àgọ́ mímọ́ ti àgọ́ àjọ náà.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Kano Govnorship Re-run: Gómìnà Ganduje ní òun yóò fara mọ́bí èsì ìdìbò bá ṣe jẹ́ 22 Ẹrẹ̀nà 2019 Gomina ipinlẹ Kano, Abdullahi Ganduje ti sọ fun BBC pe oun yoo gba kadara ti oun ba fidirẹmi ninu atundi ibo gomina ti yoo waye jakejado ijọba ibilẹ mejidinlgbọn to wa nipinlẹ naa.
 Ṣíṣàyẹ ̀ wò bóyá àjẹsára náà ṣiṣẹ ́ lè wáyé nípa ṣíṣe àwọn àyẹ ̀ wò ẹ ̀ jẹ ̀ .
Sibẹsibẹ, n óo ranti majẹmu tí mo bá ọ dá ní ìgbà èwe rẹ.
Ẹ jẹ́ kí àwọn ọmọ yín mọ̀ pé àwọn ọmọ Israẹli kọjá odò Jọdani yìí lórí ilẹ̀ gbígbẹ.
Nàìjíríà làwọn ní ìfẹ́ sí ìpèsè abẹ́rẹ́ àjẹsára Covid-19 tí Russia ṣe Àwọn dókítà yóò bẹ̀rẹ̀ ìyanṣẹ́lódí lọ́jọ́ Ajé Wo ohun tí ilé ẹjọ́ ní kí wọ́n ṣe fún Sunday Shodipe, afurasí ìṣekúpani l'Akinyele Níbo lọ̀rọ̀ dé dúró nípa iṣẹ́ àwọn tó n wa iṣẹ́ N-Power?
O salaye pe, “ile-igbimo asofin ti fenuko lori ipnnu ohun pe, isele ti o n waye naa je ipenija eto-abo nla fun ijoba ati awon ajo eleto abo lorile-ede Naijiria.
Ko daju pe awọn ọmọ ẹgbẹ Republican to jẹ ẹgbẹ Trump yoo dibo lati yọ aarẹ to jẹ ọmọ ẹgbẹ wọn.
Idajo naa ti ile ẹjọ kotemilọrun fi sọwọ sọ pe ọrọ naa ko jẹmọ ẹsun ti wọn fi kan an ni ọdun 2011.
Ẹnu alágbèrè obinrin dàbí kòtò ńlá,ẹni tí OLUWA bá ń bínú sí níí já sinu rẹ̀.
Bakan naa, ile iṣẹ ijọba to n ṣe amojuto yii naa le yọ alaga igbimọ ijọ to ba se aṣemaṣe, to si tun ni agbara lati yan ẹlomiran dipo.
Amọ, ohun ti Ọba Akiolu sọ nigba to sa kuro laafin ni wi pe oun ko pada si ibẹ mọ,oun lọ si Banana Island, ni Ipinlẹ Eko, titi ti ohun gbogbo yoo fi pada sipo.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ó ti di igba mílíọ̀nù ènìyàn ó dín díẹ̀ tó wà lórílẹ́èdè Nàìjíríá Ó Jẹ́ kó di mímọ̀ pé láti àádọ́ta ọdún sẹ́yìn ni iye ènìyàn tó wà ní àwọn ìlú ńlá ti pọ̀ gan láì sí ìgbéga tó báa mu ní ti àwọn ohun amáyérọrùn.
Ko din ni miliọnu mọkandinlọgọta eeyan to ti ko ajakalẹ arun COVID-19 lagbaye lati igba ti eegun rẹ ti kọkọ ṣẹyọ.
Eniyan mẹjọ lo kọkọ ba iṣẹle yii rin ninu awọn ogun eniyan to kọkọ kọlu.
Buhari ni ki gbogbo minista ju awa iṣẹ wọn silẹ fawọn akọwe agba ile iṣẹ ijoba apapọ ti ẹni kọọkan wọn n ṣe minista le lori.
Lẹyin ti Oluwo fi iya jẹ Agbowu tan, ni igbimọ lọba-lọba ipinlẹ Osun paṣẹ pe ki Oluwo lọ ọ rọkun nile fun oṣu mẹfa.
Hearn fikun ọrọ rẹ pe o ti di dandan fun Joshua lati gbẹsan bayii nigba ti awọn mejeeji ba koju ara wọn fun igba keji ninu oṣu kọkanla tabi ekejila Irọ́ ńlá!
" Kí ló ṣokùnfà afárá tó já tó pa ènìyàn kan ní Ilorin?
Nígbà tí ó wọlé ó dúró níwájú Eliṣa.
Bẹẹ si ni o da bii pe ipa ti o ko ninu sinima eleyii tun yi lori ju ti akọkọ lọ.
Ó fi ìlànà lélẹ̀ fún ìdílé Jakọbu;ó gbé òfin kalẹ̀ fún àwọn ọmọ Israẹli.
O ni awọn gomina ilẹ Oodua ko ni tẹti ninu ojuṣe wọn titi ti ipenija eto aabo yoo fi di ohun igbagbe ni ẹkun iwọ oorun guusu Naijiria, eyii lo si mu ki gbogbo awọn gomina naa fi orikori lati ṣe ifilọlẹ Amọtẹkun.
Àkọlé àwòrán, Akọ̀ròyìn BBC tẹkọ̀létí lọ sí ilé oúńjẹ kan tí wọ́n sí lẹ́yìn tí mínísítà ètò ọ̀gbìn àti ìdàgbàsókè igbèríko, Sabo Nanono sọ pé èèyàn le jẹ oúnjé ọgbọ̀n náírà yó.
3 Ọ̀wàrà 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ọlọpaa n wa awon Ajinigbe náà Awọn Ọlọpaa ni Ipinlẹ Kaduna ti fi idi ijinigbe awọn ọmọ ileewe mẹfa mulẹ.
Àsìkò tó ki àwọn èrò ji lati bá àwọn olè wọnyi wi, nitori àwọn Òṣèlú Òkè-Òkun nibiti wọn nkó owó ilú lọ, kò fi owó ilú wọn tọ́jú ara wọn, wọn nwọ ọkọ̀ pẹ̀lú àwọn ará ilú, àyè kò si fún wọn lati ja ilú ni olè bi ti àwọn Òṣèlú Nigeria.
ile igbimọ asofin lorile ede Naijiria , Femi Gbajabiamila, ti ni oun yoo sisẹ papọ
Ẹka ẹkunrẹrẹ rẹ nibi Ọjọ 22, Osu Keji Ijọba ipinlẹ Yobe sọwipe awọn o sọ bẹẹ mọ, wọn si bere fun idariji nitoriwipe kosi ọmọ kankan ti wọn gba la.
Wọ́n ń sin OLUWA wọ́n sì ń fi orúkọ rẹ̀ búra wọ́n sì tún ń fi oriṣa Milikomu búra; 
Kí wọn tó dé ìsàlẹ̀, àwọn kinniun ti bò wọ́n mọ́lẹ̀, wọ́n sì fọ́ egungun wọn túútúú.
 Ìtàn tó tọ ́ ka sí Ọ ̀ kànbí gẹ ́ gẹ ́ bí ọmọ kan ṣoṣo tí odùduwà bí náà gbà pé Ọ ̀ ràńyàn ni àbígbẹ ̀ yìn ọ ̀ kànbí .
Eniyan mejilelokolenigba ninu awọn to ni arun ọhun ni Naijiria ti ri iwosan gba, ṣugbọn marundinlogoji ti filẹ ṣaṣọ bora.
Awọn dokita alawọ funfun aye igba naa wá bẹrẹ si ni lo taba fun itọju oriṣiriṣi aisan.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Gbogbo ẹ̀yin ọ̀ba abẹ́ mi, tí ẹ̀ ń ta ilẹ̀ ìlú, ẹ kò ní fara re lọ - Oluwo Ìjọba Ọ́ṣun, Oluwo kò yẹ lẹ́ni tó leè darí ìlú, ẹ bá wa le kúrò lórí ìtẹ́ - Olú ti Ilé-Ogbó Ọjọ́ orí wo ló yẹ kí ikùn ẹ̀dá bẹ̀rẹ̀ sí tóbi?
A wo èdè àmúlò nígbà tí a bá ń sọ̀rọ̀ àti igba ti a ba kọ èdè Yorùbá silẹ.
Akintola tako igbesẹ ẹgbẹ AG pẹlu idari Awolowo lori asopọ pẹlu ẹgbẹ oṣelu mii, Akintola ni awọn ẹya Igbo ni wọn n jẹ anfaani eto ọhun ju.
Nítorí ó wà ní àkọsílẹ̀ pé, ‘Ìwọ kò gbọdọ̀ sọ̀rọ̀ burúkú sí aláṣẹ àwọn eniyan rẹ.
Awọn kan to wa sibi ipade naa tilẹ fẹ yọju wo orukọ naa ki wọn le lọ fẹdọ lori oronro sun ṣugbọn lakoko yii, mi o ni gba ki ẹnikẹni ti mi lati gbe orukọ jade""."
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Yoruba Films: Mr Latin ní òṣèré tó bá ya sinimá lásìkò Coronavirus yìí, òun ò lọ́wọ́ ń bẹ 15 Èbibi 2020 Oríṣun àwòrán, Instagram/Mr Latin Ere Sinima jẹ ara ẹka iṣẹ aayan laayo lawujọ to ṣe pataki, to si tun ma a mu owo wọle fun awọn osere tiata ati ijọba pẹlu.
Àwọn ni wọn óo máa fi ọ̀rá ati ẹ̀jẹ̀ rú ẹbọ sí mi.
 ) ti gbé ìlànà ẹ ̀ kọ ́ yorúbá fún iloé-ẹ ̀ kọ ́ sẹ ́ kọ ́ ńdírì jáde ni ó ti di dandan láti wá ìwé tí yó ṣe àlàyé yékéyéké lórí àwọn iṣẹ ́ tí ó jẹ yọ nínú ìlànà ẹ ̀ kọ ́ tuntun yìí .
Àwọn ẹ̀mí èṣù jáde kúrò ninu ọpọlọpọ eniyan, wọ́n ń kígbe pé, “Ìwọ ni Ọmọ Ọlọrun.
Ọgbẹni Thompson Akpabio lati ẹgbẹ oṣiṣẹ, Nigeria Employer Consultative Association (NECA) sọ pe wọn yoo nilo alaye kikun lori lori abala keji abadofin naa to sọ nipa bi wọn yoo ṣe maa ṣakoso eto naa.
Mi o raaye to bi o ṣe yẹ nigba ti mo wa pẹlu ikọ Chelsea.
Wayii o, Gomina Sanwo-Olu ti kede pe oun yoo bawọ̀n eeyan ipinlẹ́ Eko sọ̀rọ̀ ni aarọ ọjọbọ oni.
Kibusaimu ati Beti Horoni, gbogbo wọn jẹ́ ìlú mẹrin.
Bí ilẹ̀ ìní olukuluku ẹ̀yà àwọn ọmọ Israẹli bá ti tóbi tó, bẹ́ẹ̀ ni iye ìlú tí wọn yóo fi sílẹ̀ fún àwọn ọmọ Lefi yóo pọ̀ tó.
Ẹ̀ wo bí àwọn ẹ̀ṣọ́ ojú etí òkun ṣe ń ṣiṣẹ́ l'Eko World water day: Ẹrin Ijesa, Ọ̀ṣun Oṣogbo, àwọn ibùdó ìgbafẹ́ omi tí ó yẹ kí o mọ̀ Kí lo fẹ́ mọ̀ nípa D.
Èyí ni yóo jẹ́ àmì fún ọ pé gbogbo ohun tí mo sọ ni yóo ṣẹ.
bi aare Buhari se sọ, “Ijọba ko ni faaye gba iwa ipaniyan tabi titẹ ẹtọ
Àwọn ìṣẹ̀lẹ̀ yìí ló mú kí BBC News yoruba ṣe ìwádìí ǹkan ti ó fàá tí àwọn ǹkan wọ̀nyìí fi ń peléke síi lójoojúmọ́.
“Àwọn wọnyi ni ẹ óo kà sí ohun ìríra, tí ẹ kò gbọdọ̀ jẹ ninu àwọn ẹyẹ: idì, igún, ati oríṣìí àṣá kan tí ó dàbí idì, 
Ẹ wá sin OLUWA Ọlọrun yín níbẹ̀, kí ibinu rẹ̀ lè yipada kúrò lọ́dọ̀ yín.
Amofin agba Olumide Fusika, to jẹ agbẹjporo fun Sowore rọ ile ẹjọ na lati tu silẹ lẹyin ti wọn ti wọn gba beeli rẹ lọsẹ to kọja.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Bunmi Ojo: Ó ń wòran bọ́ọ́lù lọ́wọ́ ni àgbébọn sekú pàá 11 Ògún 2018 Oríṣun àwòrán, Facebook/Bunmi.
Awọn oṣere mẹwaa to ti ku amọ ti iṣẹ wọn n fọhun sibẹ: Oyin Adejobi: Oríṣun àwòrán, others Baba Oyin Adejobi jẹ agba ọjẹ oṣere tiata nigba aye rẹ, to si dabira ni agbo oṣere tiata pẹlu ọpọ awọn ere akọnilọgbọn.
Ọlọrun ranti Abrahamu, nígbà tí ó pa àwọn ìlú tí ó wà ní àfonífojì náà, níbi tí Lọti ń gbé run, ó yọ Lọti jáde kúrò ninu ìparun.
Mo ti ṣètò ibìkan ninu ilé náà fún Àpótí Ẹ̀rí OLUWA, tí tabili òkúta tí wọ́n kọ majẹmu sí wà ninu rẹ̀, majẹmu tí OLUWA bá àwọn baba ńlá wa dá nígbà tí ó ń kó wọn jáde láti ilẹ̀ Ijipti.
O maa maa ṣafikun si awọn ofin to fi n dari ololufẹ rẹ, o maa maa ṣọ ọ lọwọ-lẹsẹ pẹlu ara gbigbona.
Ohun tí Paulu Ṣe ní Erékùṣù Mẹlita.
Ìgbẹ̀yìn ọkùnrin tó pa obìnrin 93 ni America Abiy Ahmed gba àmì ẹ̀yẹ̀ ti àláfíà lágbàáyé gẹ́gẹ́ bí ọmọ Africa Ìdẹ̀ra dé l'Eko!
Ní ọdọọdún ni Elikana máa ń ti Ramataimu-sofimu lọ sí Ṣilo láti lọ sin OLUWA àwọn ọmọ ogun, ati láti rúbọ sí i.
Atẹjade ti alukoro ileeṣẹ ọlọpaa ipinlẹ Eko, Bala Elkana fi sita ṣalaye pe Busayo Owoodun lorukọ obinrin tọta ibọn ba naa.
tóbẹ́ẹ̀ tí kò ní fún ẹnikẹ́ni jẹ ninu ẹran ara ọmọ rẹ̀ tí ó bá ń jẹ ẹ́; nítorí pé kò sí nǹkankan tí ó kù fún un mọ́, ninu ìnira tí àwọn ọ̀tá yín yóo kó yín sí nígbà tí wọ́n ba dó ti àwọn ìlú yín.
Toyin Abraham fi orin yẹ́ Iyabo Ojo sí níbi ìsìnkú ìyá rẹ̀, Falz di ẹni tí wọ́n fí òpópónà ṣọ orí rẹ̀ Oríṣun àwòrán, Getty Images Ipo wo ni awọn ilu igberiko Borno wa bayii?
A gbọ wipe lasiko ti baalu ayarabiaṣa naa fẹ ẹ ba lo ja lojiji.
Wọn kò dá iná ẹ̀yẹ fún un gẹ́gẹ́ bí wọ́n ti máa ń ṣe níbi ìsìnkú àwọn baba rẹ̀.
Minisita eto abo Delfin Lorenzana to ṣe apejuwe iṣẹlẹ ohun gẹgẹ bi iwa to ''buru gba'' rọ awọn ara ilu lati pawọpọ dẹkun iru iwa agbesunmọmi bayi.
"Ẹsẹ mi apa ọtun ni mo ti ni ipenija.
Aaroni gba wúrà náà lọ́wọ́ wọn, ó lo irinṣẹ́ àwọn alágbẹ̀dẹ, ó fi wúrà náà da ère ẹgbọ̀rọ̀ mààlúù kan.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ọjà Enugu dahoro tórí ókú ọ̀pọ̀ ẹyẹ igún tó balẹ̀ 22 Agẹmo 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Aworan ẹyẹ igun Awọn oku ẹyẹ igunugun ti wọn ri kaakiri ilẹ lọja Eke-Ihe ni ijọba ibilẹ Awgu ti di ọrọ to n tan kalẹ laarin awọn araalu latari fidio kan to wa lori ẹrọ ayelujara lati ọjọ aiku.
Igbakeji adari ajọ SERAP, Ọgbẹni Kola Oluwadare to ba BBC Yoruba sọrọ, rọ awọn ara ilu lati lọ sọ tẹnu wọn nigba ti awọn aṣofin ipinlẹ Oyo ba n gbe aba naa yẹwo.
Àwọn ará ìlú ń fẹ́ ohun tuntun àti àtúntò tòótọ́.
 Òun ni ó gba Ẹ ̀ bùn nobel ti 2006.
Lọdun 1924, o tẹ akọsilẹ ọrọ kan jade nipa bi awọn obinrin kan kii ṣe ni imọlara adun tabi fihan pe wọn n gbadun ibalopọ.
Ẹ rọ́ àlá mi fún mi, n óo sì mọ̀ dájú pé ẹ lè sọ ìtumọ̀ rẹ̀.
Yọ́ ojúlówó wúrà bò ó, kí o sì yọ́ ojúlówó wúrà sí gbogbo etí rẹ̀ yípo.
 Iya wọn si fesi fun wọn wipe, ""Ẹ bẹrẹ si ni yọ ogiri naa ni ẹyọ kọọkan, titi yoo fi wo palẹ."
NBS sọ pe iṣẹlẹ naa ko ṣeyin ajakalẹ arun Coronavirus to n ba gbogbo agbaye finra.
Gege bi atejade naa se so,“A dupe pupo lowo Ronaldo, leni ti o sise takun-takun ni gbogbo akoko re ti o lo pelu wa nibi.
Awọn ọlọpàá ti wọn pè wá wo ohun to ṣẹlẹ̀, kọ́kọ́ pa awọn ẹranko míràn to wà nínú àgò tó fara ti kìnìún náà.
gbe  maa  sagbeyewo awon irinse ati  ohun elo oju ọna ati ile kikọ”Ademola Adepoju.
Ẹgbẹrun un mejilelogoji ati aabọ naira(N42,500) lawọn ẹro gbọdọ san gẹgẹ bi owo ayẹwo fun covid-19 ti wọn ba de Naijiria eleyi ti ọpọ wọn koro oju sí.
òun OLUWA ní òun óo mú ibi wá sórí ibí yìí ati àwọn eniyan ibẹ̀ gẹ́gẹ́ bí a ti kọ ọ́ sinu ìwé tí a kà sí ọba Juda létí.
Ọlọrun mi, mo kígbe pè ọ́ lọ́sàn-án,ṣugbọn o ò dáhùn;mo kígbe lóru, n ò sì dákẹ́.
Ohun to yipada ni ọna ti a n gba pin in; awọn ajọ kan wa to n pin in tẹlẹ ṣugbọn nkan ti yi pada bayii a si ti ni ajọ mii ti yoo maa pin in.
Ó bá sọ fún mi pé, “Ègún tí yóo máa káàkiri gbogbo ilẹ̀ náà ni a kọ sinu ìwé yìí.
 itundajo awon opin 1980 pipinlabe awon agbegbe ile ghana si adugbo 110 , nibi ti awon ile-igbimo ibile adugbo kookan ti le dojuko isoro imojuto ibile ti won .
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Iná Ibadan: Gbogbo dúkìá tó wà lókè ilé alájà kan náà ló jóná tán Idáduro awọn alága ìjọba ìbílẹ̀ yìí wáye lẹ́yin wákati díẹ ti àwọn ọmọ ilé ìgbìmọ aṣòfin dábàá pe ki wọ́n da wọ́n duro.
Oríṣun àwòrán, @akandeoj O se eyi pẹlu bo se ko awọn mejeeji lẹyin lasiko ifilọlẹ owoya naa, ti wọn si dijọ farakinra pẹlu awọn ọlọja ipinlẹ Eko naa.
Nítorí pé lọ́dọ̀ rẹ ni orísun ìyè wà;ninu ìmọ́lẹ̀ rẹ ni a ti ń rí ìmọ́lẹ̀.
Ẹ̀rọ ayàwòrán ara ọlọ́pàá fihàn pé ìgbà ogún ni George Floyd pariwo, kó tó kú Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, George Floyd: Àwọn ọlọ́pàá darapọ̀ mọ́ àwọn olùwọ́de lórílẹ̀èdè Amẹ́ríkà Ọlọ́pàá kọ́ lo pa olórí àwọn ''One Million Boys'' Ebila n'Ibadan- Ọ̀gá ọlọ́pàá Oyo Ẹ wo ọ̀nà tí ìjọba Nàìjíríà fẹ́ gbà san owó àwọn olùkọ́ iléèwé aládàni tí kò rówó oṣù gbà Bí òṣìṣẹ́ Amotekun bá fi orúkọ sílẹ̀ lórí ayélujára, àwọn ọ̀daràn yóò tètè fojú hàn - Oludari Amotekun l'Oyo Kí ló fa ìjà láàrin Wunmi Toriola àti Seyi Edun?
nítorí náà, ọkàn wa ti rẹ̀wẹ̀sì;ojú wa sì ti di bàìbàì.
"Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Oba Adedokun Abolarin ti Oke Ila: Ó ya ọ̀pọ̀ tó súnmọ́ mi lẹ́nu bí mo ṣe ń kọ́ ""Iyalẹnu si lo jẹ bi Niyi ṣe sọ fun mi pe ki a tẹsiwaju pẹlu ibalopọ naa, lai fi ti ẹjẹ to ṣi n jade lara mi ṣe."
Ó gba gbogbo ilẹ̀ Israẹli pada láti ẹnubodè Hamati títí dé Òkun Araba, gẹ́gẹ́ bí ọ̀rọ̀ tí OLUWA Ọlọrun Israẹli sọ láti ẹnu wolii rẹ̀, Jona, ọmọ Amitai, ará Gati Heferi.
O fikun ọrọ rẹ ijọba Ekiti yoo pade kede ipinnu rẹ lori ọrọ naa lẹyin ti gbogbo ipinlẹ Yoruba ba ti fẹnuko tan.
pé bí inú eniyan burúkú bá ń dùn,tí ẹni tí kò mọ Ọlọrun bá ń yọ̀, fún ìgbà díẹ̀ ni.
Mo ké sí i, mo ní Èkúté ò!
Nítorí ìwọ, OLUWA, ti mú inú mi dùn nípa iṣẹ́ rẹ;OLUWA, mò ń fi ayọ̀ kọrin nítorí iṣẹ́ ọwọ́ rẹ.
com/yoruba/afrika-45109762 Ìyá ìbarùn-ún: Mo rò pé 'scan' ń pa irọ́ niní oyún pé márùn-ún ni màá bí Àkọlé àwòrán, Ìyá ìbarùn-ún: Mo rò pé 'scan' ń pa irọ́ niní oyún pé márùn-ún ni màá bí Pẹlu bi nnkan ṣe ri ni ilu bayii, ọpọ ni ko fẹ bimọ mọ.
Ó ní orúkọ òun nìyí títí ayérayé, orúkọ yìí ni wọn óo sì máa fi ranti òun láti ìrandíran.
komisona lati ekun re ,pe ki won mojuto eto aabo ,ki won si dena iwa odaran
Ọkan to ba ni lọkan jẹ gidi gan an ni iriri ti gbajugbaja oṣere, Toyin Abraham fi sita nipa ọrẹ bii mọlẹbi rẹ kan, Adenike Adekanle ti aṣita ọta ibọn ọlọpaa sọ ọ di alaabọ ara lọdun 1996.
Tacha tọrọ àforíjí, ó da gbogbo ẹ̀bi lé ara rẹ̀ lórí Ẹ ṣé mo dúpẹ́ fún àdúrótì àti ìfẹ tí ẹ ní sí mi - Toyin Abraham MC Oluọmọ ti di Alága àwọn awakọ̀ ní ìpínlè Èko.
17 Àti nígbanáà, kíyèsíi, gẹ́gẹ́bí ìfẹ́ inú rẹ, bẹ́ẹ̀ni, àní gẹ́gẹ́bí ìgbàgbọ́ rẹ ni a ó ṣe é fún ọ.
Gbẹ̀san mi lára àwọn tí wọn ń ṣe inúnibíni sí mi.
44 usd fún ìwọ ̀ n egbògi náà kanṣoṣo ní ọdún 2014 .
Awọn to se agbatẹru fidio naa lero pe, awọn eeyan jakejado agbaye naa yoo wo fidio yii, ti wọn yoo si fi ohun tiwọn naa si pẹlu.
Covid 19 Palliative: Mínísítà dèrò àgọ́ ọlọ́pàá nítorí ẹ̀sùn kíkó owó ìrànwọ́ Covid-19 sápò
Ní ìbẹrẹ̀ pẹ̀pẹ̀, ọjọ́ mẹ́fà ni à ń sọ ọmọ lórúkọ ìbáà jẹ́ ọmọkùnrin tàbí ọmọbìnrin.
” Wọ́n bá mú un wá sí Jerusalẹmu, ibẹ̀ ni ó sì kú sí.
"Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ẹgbẹ́ ajàfẹ́tọ̀ọ́ ẹni yóò bẹ túbú ọlọ́pàá wò Àwọn olólùfẹ́ eré bọ́ọ́lù dábírà ní Russia Wọ́n yọ 'aṣofin olóorun' nílé aṣòfin Èkìtì O ní ""mo ránti pé nígbà kan, àwọn ènìyàn ń pariwo pé wọ́n fún àwọn ènìyàn ẹkùn ibì kan níṣẹ ju àwọn ẹkùn míràn lọ, sùgbọn ọ̀pọ̀ àwọn ǹkan wọ̀nyìí tí ó bá dé détigbọ́ ààrẹ, Buhari kò lè káwọ́ gbera lórí rẹ̀."
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Revolution Now: Ilé ẹjọ́ dá Omoyele Sowore padà sí àhámọ́ DSS 30 Owewe 2019 Oríṣun àwòrán, @Tony_Nwajei Àkọlé àwòrán, Ile ẹjọ kọ lati da Sowore ati Bakare silẹ Ile ẹjọ giga to wa l'Abuja ti da Omoyele Sowore pada si ahamọ ajọ ọtẹlẹmuyẹ DSS, titi di igba ti ile ejọ ọhun yoo tẹti si ipẹjọ beeli rẹ.
Tí ẹ bá pa òfin OLUWA Ọlọrun yín mọ́ bí mo ti fun yín lónìí, tí ẹ̀ fẹ́ràn rẹ̀, tí ẹ̀ ń rìn ní ọ̀nà rẹ̀, tí ẹ sì ń pa àwọn òfin, ìlànà ati ìdájọ́ rẹ̀ mọ́, ẹ óo wà láàyè, ẹ óo sì máa pọ̀ sí i.
Ọga Ọlọpaa lorilẹ-ede Naijiria ti fun awọn eleto aabo ni aṣẹ lati ri pe eto aabo gbona jainjain si i ni awọn ipinlẹ kaakiri orilẹ-ede Naijiria ati ilu Abuja.
Nigba to n ba BBC Yoruba sọrọ lori isẹlẹ yii, osisẹ alarina fun ileekọ fasiti Ibadan, Ọgbẹni Tunji Ọladẹjọ fi idi isẹlẹ naa mulẹ pẹlu afikun pe awọn adigunjale naa gba ọpọ ẹrọ ilewọ alagbeka lọwọ awọn akẹkọbinrin naa.
"Ẹwẹ, o sọ ninu ọrọ kan pe "" iṣẹlẹ yii ko ni di awọn orilẹede ati ajọ agbaye lọwọ iranwọ ti wọn n ṣe fun ọgọọrọ awọn ọmọ Naijiria to nilo iranwọ ni apa Ila Oorun Ariwa orilẹede Naijiria""."
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Èmi àti Bọla Tinubu fẹ́ lo ‘German Mercenaries’ láti gbé MKO Abiọla kúrò lẹ́wọ̀n - Dele Momodu Buhari, ṣí ìwé àkọsílẹ̀ orúkọ àwọn gómìnà tó jẹ̀bi ìkówójẹ, káráyé mọ̀ wọ́n - SERAP O dùn mí pé Buhari kò yàn mí sípò Mínísítà lẹ́ẹ̀kejì àmọ́ mò gbà kádàrá - Adebayo Shittu Makinde, jọ̀ọ́ kéde Aug 20 ọdọọdún bíi ọjọ́ ìsinmi fún ìṣẹ̀ṣe - Àwọn oníṣẹ̀ṣe Ọyọ Alaafin wa kesi awọn ọba alaye yoku nilẹ Yoruba lati maa gbe awọn asa ajogunba wa, ede, ati ise Yoruba larugẹ, ni gbogbo ilu ti wọn ba jọba le lori.
ewì ayaba jẹ ́ ewì tí a mọ ̀ mọ ́ àwọn ìyàwó ọba nìkan .
Oríṣun àwòrán, @followlasg Àkọlé àwòrán, Bakan naa ni Bola Tinubu sapejuwe Lateef Jakande bii alakoso to dantọ lasiko to nira lati dari Naijiria.
‘Nàìjíríà ló ní akúṣẹ̀ẹ́ tó pọ̀ jùlọ lágbàyé’ Ààrẹ Muhammadu Buhari yóò gba Theresa May tó jẹ́ olóòtú ìjọba ilẹ̀ Gẹ̀ẹ́sì níle ìjọba l'Abùja lónìí.
"O ni ""mo ba bẹ ẹgbọn mi kan to wa nile, a si jọ lọ si ibi ti ole ti n ja yii""."
Nítorí náà, Ahasi gbé pẹpẹ idẹ náà sí apá òkè pẹpẹ tirẹ̀.
Oríṣun àwòrán, Dogara media office Àkọlé àwòrán, Àwọn ìbejì tí wan yà sọ́tọ̀ Iroyin to tẹ wa lọwọ sọ pe miliọnu naira ni owo ti wọn san fun iṣẹ abẹ lati ya awọn ọmọ naa.
Ẹ wo nkan tí àwọn akẹẹgbẹ́ Lateef Adedimeji sọ nípa f'ọ́tò ìgbéyàwó òun àti Adebimpe tó jáde Kò ní sí ayẹyẹ ọdún Ojúde Oba lọ́dún yìí- Awujale ilẹ̀ Ijebu Wo ìgbésẹ̀ méjọ tí ilé aṣòfin ìpínlẹ̀ gbọdọ̀ tẹ̀lé láti yọ igbákejì gómìnà Kòṣẹlẹ̀rí ni Hajj ọdún 2020, wo ìyàtọ̀ tó wà nínú rẹ̀ sí ti tẹ́lẹ̀ Amọ, ayẹwo naa tun fihan pe awọn akẹgbẹ rẹ ọmọ Naijiria ti wọn jọ wa ni Genk, Stephen Odey ati Cyrul Dessers ko ni arun ọhun.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Ohun tóo gbúdọ ṣe lọ́dún yìí bí o bá fẹ́ kí Ọlọ́run bá ọ rìn' Ọgbẹni Ologbondiyan ni ijọba ko ni ifẹ araalu ninu pẹlu igbesẹ yii lẹyin owo ori gọbọi tawọn eeyan n san ati ọwọ gogo ọja.
O si n dije fun ipo aṣofin nijọba ibilẹ Brooklyn City Council ni Minnesota.
A ti rí ìrora látàrí àwọn àfilé ìdíyelé, ǹjẹ́ o mọ ìṣòro tí ó ń fà fún àwọn ará ìlú?
fun awọn eniyan pe, awọn agbofinro wa ti gbaradi lati pese eto aabo.
Òní ni Shi'ite fẹ́ ṣe ìwọ́de ikú ọmọ ọmọ Anọ́bì ní èyí tí ó lòdí sí àṣẹ agbófinró Ronaldo, Messi ẹ yàgò lọnà fagbábọ́ọ̀lù Nàìjíríà tó n gbowò julọ!
Ìjọba ìpínlẹ̀ Zamfara ti gbé iléèwé mẹ́wàá tìpa Ṣé lọ́òtọ́ ni ọlọ́pàá dàwátì torí àti dóòlà aráa India méjì tí wọ́n jígbé?
Lẹ́yìn náà, ó bi í pé, “Jọ̀wọ́, kí ni orúkọ baba rẹ?
“Awon omo ogun se ikolu si ipago omo ogun olote Boko Haram ti o wa lagbegbe Benisheikh, nipinle Borno.
Oríṣun àwòrán, LASEMA Osanyintolu sàlàyé pé, ilé igbé márùnlélógún, àwọn sọ́ọ̀bù mẹ́rìndinlógún àti ilké iwé alákọ̀bẹ̀rl kan wà lára àwọn dúkíà tó ti bá iṣẹ́lẹ̀ náà rìn lọ́wọ́lọ́wọ́ Àwọn ǹkan míran tó tún bàjẹ́ nibẹ̀ ni ilé alájà mẹ́rin tó fi mọ ilé itura kan, ọkọ tó n gbé afẹ́fẹ́ gáàsì, kẹ̀kẹ́ márúwá, ọkọ ẹru kan.
“Ọjọ́ kẹwaa oṣù keje ni ọjọ́ ètùtù.
Ti a o ba gbagbe pe alaga egbe PDP Secondus naa ti pe lati yo alaga ajo eleto idibo lorile ede Naijiria latari bi won se sun eto idibo to yẹ ko waye lojo Abameta siwaju.
 wọ ́ n yàn-án ní ayàwòrán àkọ ́ kọ ́ fún olorì tí ó sì gba ẹgbẹ ̀ rún àti igba pọ ́ nhùn fún iṣẹ ́ rẹ ̀ .
Ọ̀rọ̀ pàtàkì ni a wá láti bá ọ sọ lónìí, bí o fẹ́ bí a kọ̀ o nílati gbọ́ ọ̀rọ̀ náà bí o ko bá sì gbọ́ ní ojú bọ̀rọ̀, a o wí fún ọ ni ojú líle.
Oríṣun àwòrán, @AishaBuhari Àkọlé àwòrán, Ọmọ Mamman Daura: Aisha Buhari ń wù ìwa ipá sí wa!
Lizzy Anjorin: Kò sí òṣèré tíátà lóbìnrin tó ní dúkìá jù mí lọ
Segun, Máàkì tóo ní kọ́ ni yóò ṣé atọ́nà oríire rẹ láyé Sowore: olùdíje Ààrẹ tó fẹ gbà Nàìjíríà padà fún àwọn ọdọ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Bí ìrẹsì tèmi Ayinde bá ń pàkùta, kò tọ́ sẹ́nu aláàrù Barrymaade' Saraki ni awọn ile wọnyii kii ṣe ohun ti a n fi bo, ati wi pe awọn ile ti oun sọ fun ijọba pe o wa ni ikawọ oun ni awọn ile wọnyii lasiko ti oun wa ni isejọba.
Wọn ko si ranti pe ohun ti ọkunrin lee se, awọn obinrin gan lee se daradara ju ọkunrin lọ.
Awọn janduku naa tun ṣakọlu si afin ọba ilu Eko, ile itaja Shoprite, ileeṣẹ ọkọ oju omi ni Marina ati ile iya Gomina ipinlẹ Eko to wa ni Akerele.
Àwọn ará Samaria sì tú jáde láti lọ kó ìkógun ní ibùdó ogun àwọn ará Siria.
OLUWA fi àìsàn ṣe ọmọ tí aya Uraya bí fún Dafidi.
Fi eléyìí ṣe àríkọ́gbọ́n, ìwọ ọ̀rẹ́ mi, bí ènìyàn le púpọ̀ ọmọ aráyé á bú u, bí ènìyàn rọ̀ púpọ̀ ọmọ aráyé á bú u, ṣùgbọ́n bí ènìyàn bá wà ní ìwọ̀n-túnwọ̀nsì, bí olúwaarẹ̀ tilẹ̀ gba èébú àwọn òmùgọ̀ inú ayé, olúwaarẹ̀ yóò ní iyì lójú àwọn ọlọgbọ́n, òun kò sì ní gba èébú Ọlọ́run Ọba.
Nítorí òkúmọ yìí wá sinu asán, ó sì pada sinu òkùnkùn.
Akole ipade ijiroro elekerin igbimo ohun ni, “ je ki owo wa mu igberu ba sise itoju awon alarun kogbogun HIV”.
Sanyeri, lasiko to n kopa lori eto BBC Yoruba ṣalaye pe, ọjọ pẹ ti oun ti n jẹ Sanyeri, lati igba ti oun ti bẹrẹ ere tiata laarin ọdun 1992 di 1993.
" It however added … the government will however not hesitate to act on the recommendations of the Ezes' Council as long as it would be in the interest of the State…"" Lẹ́yìn náà ni ìjjọba gbé atẹjade kan sita pe ọ̀rọ̀ náà ko ri bẹ́ẹ̀ "" A ò ní ọ́wọ́ nínú yíyọ àwọn ọba mẹ́rin ti gbigbe àwọn ààdọta lọ siwaju igbimọ àwọn Ezes lati jẹjọ, Ẹ̀wẹ̀ fikun pé ìjọba kò ni kọ ìmọran àwọn ǹkan to tọ láti ṣe fun igbimọ àwọn Eze níwọn ìgbà ti yóò ba ti mú ìlọsíwáju ba ìpínlẹ̀ Imo Oríṣun àwòrán, Alamy Àkọlé àwòrán, Eze Njemanze lo ọdun mẹ́tàdínlọgbọ̀n titi to fi kún ni ọdun 2016 lẹ́yìn ọdun mẹ́rìnlélọ́gọ́rin Nítori náà gẹ́gẹ́ bi ó ṣe sẹlẹ̀ ní Kano, bẹ́ẹ̀ ni ijọba Okorocha se pin awon lọbalọba si àgbégbe márun ti onikaluku si ni ọba ti wọn."
Tani kò fẹ́ d’àgbà oní làákàyè?
  A ti ṣe ofin yii, ohun ti a n ṣe niisinyi ni lati yẹ ofin yẹn wo, lati wo awọn ibi kan, apẹẹrẹ boya awọn kan ni ki o ni anfani si eto yii tabi gbogbo ara ipinlẹ Eko.
Wayi o, awọn obi ti fariga pe awọn ko ni owo kankan lati san, bakan naa ni awọn ko tilẹ ni iwe ẹri kankan lati fi silẹ.
Ọmọ ẹgbẹ oṣelu Peoples Democratic Party (PDP) nii ṣe.
Ni kete ti o ba si ti lee kọ fun igba mẹta, ẹlẹkọ ọrun yoo polowo fun un ni.
Lori awọn ọpọ nkan to ṣẹlẹ yii ni oun ni ireti pe oun yoo ni ajọṣepọ to dara pẹlu awọn aṣofin to n bọ.
 micheal ti olóòṣà , tí ó sì parí rẹ ̀ ní ilé-ẹ ̀ kọ ́ alákọọ ́ bẹ ̀ rẹ Àgọ ́ Òwu ní Ṣógúnlẹ ̀ ní ìpínlẹ ̀ Èkó .
Egbe awon agbe ti a mo si,All Farmers Association of Nigeria (AFAN) eka ipinle Anambra ti so pe, ki won fun awon agbe ni eso lasiko ni awon ekun mefeefa lorile-ede Naijiria, alaga awon agbe eka ipinle Anambra  Nnamdi Mekoh, ni o pe ipe yii lasiko ifoworo wani lenu wo pelu awon oniroyin nilu Awka.
Báálẹ̀ fẹ́ ìyàwó méjì, Olorì Táwàkálítù Adédèjì Balógun- Elétǔ àti Olorì Ọmọlará Adédèjì Balógun- Elétǔ pẹ̀lụ́ àwọn ọmọ alálùbáríka
Marunlelọgọrin ninu wọn lo wa lati ipinlẹ Eko nikan nigba ti mẹtalelogun wa lati olu ilu Naijiria, Abuja.
tabi tí ó fi ọwọ́ rẹ̀ lù ú pẹlu ibinu tí ẹni náà sì kú.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù World TB Day: Funkẹ Dosumu ni ikọ́ ife kìí pani, ta bá lo òògùn rẹ̀ déédé Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ World TB Day: Funkẹ Dosumu ni ikọ́ ife kìí pani, ta bá lo òògùn rẹ̀ déédé 24 Ẹrẹ̀nà 2019 Oni yii, tii se ọjọ́ Kẹrìnlélógún oṣù Kẹta ni ajọ isọkan agbaye ya sọtọ gẹgẹ bii ayajọ lati gbogun ti arun ikọ ife.
Asiko awẹ Ramadan ni wọn ma n kọ iru orin yii lati ile kan si ile mii.
Fifi eto si iṣẹ ati ifaayesilẹ ṣe pataki: Ọpọ lo ti sọ fun wa pe awọn n sisẹ fun wakati to pọ tawọn ba wa nile ju ki awọn wa ni ibi isẹ lọ.
Orilelẹede South Africa ti n reti ikọwe fiposilẹ rẹ.
Ọdún mẹtala ni Solomoni fi parí kíkọ́ ilé ti ara rẹ̀.
A run gbogbo wọn patapata gẹ́gẹ́ bí a ti ṣe sí Sihoni, ọba Heṣiboni, tí a run gbogbo àwọn ìlú rẹ̀, ati ọkunrin, ati obinrin, ati ọmọde.
Ìwọ ọ̀rẹ́ mi, bàbá mi fẹ́rẹ̀ ma ì tí ì pa’ri ọ̀rọ̀ yìí tan nígbà tí àwọn méjéèjì ti kọlu ara wọn, ìjà náà si pọ̀ gidigidi, ènìyàn pàdé àǹjànnú, gbogbo igbó ń pariwo, bí Èṣù-kékeré ti le bẹ́ẹ̀ náà ni Olówó-ayé le, bàbá mi, ọkùnirn náà, ẹni ti ń bẹ ni inú ayé tí ń ja ìjàkadì pẹ̀lú èrò ọ̀run alákeji.
Ejò bi obinrin náà pé, “Ngbọ́!
"Meji ninu awọn ole naa ti wọ inu ile Ilori ti ọkan ninu wọn si n ṣọna ni ita.
Àkọlé àwòrán, Òkò ọ̀rọ̀ ṣáájú ìdìbò 2019 Tinubu sọrọ yii lẹyin to ṣepade idakọnkọ pẹlu Aarẹ Muhammadu Buhari nilu Abuja.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ààrẹ Buhari ti gba Ààrẹ Macron ti orílẹ̀èdè France lálejò nilu Abuja Awọn oṣiṣẹ pana-pana ti n ṣe iṣ lọ ni pẹrwu lati gbiyanju dida ọwọ ina naa duro.
Gẹgẹ bii akọṣẹmọṣẹ oniroyin, afojusun rẹ nigba naa ni lati maa ṣe awọn iroyin to kan iha ariwa ati lati daabo bo ifẹ wọn.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Coronavirus in Nigeria: Ẹ wo bí ẹ ṣe lè ṣe hand sanitizer"" nínú ilé yín Corona in Nigeria: Ìjọba ìpínlẹ̀ Ogun gbé àgádágodo sẹ́nu ibodè rẹ̀ tóri àrùn Coronavirus Oríṣun àwòrán, @dabiodunMFR Àkọlé àwòrán, O nio jẹ ọna lati ṣadinku ba kiko arun Coronavirus wọ ipinlẹ ọhun lati awọn ipinlẹ bi ipinlẹ Eko Ijọba ipinlẹ Ogun, labẹ iṣakoso Gomina Dapo Abiodun ti pasẹ pe ki wọn ti gbogbo ibode to wọ ipinlẹ naa lati dẹkun itankalẹ arun Coronavirus."
Ni ọdun 1964, Olatunji ṣiṣẹ pọ pẹlu aarẹ akọkọ lorilẹede Tanzania, Julius Nyerere ati Malcolm X lati fopin si ofin ẹlẹyamẹya lorilẹede Amerika.
“Tabi, kí obinrin kan ní naira mẹ́wàá, bí ó ba sọ naira kan nù, ṣé kò ní tan iná, kí ó gbálẹ̀, kí ó fẹ̀sọ̀ wá a títí yóo fi rí i?
Coronavirus Cases in Africa:Ẹ wo bí ìpínlẹ̀ Eko, Ondo àti Oyo yóò ṣe dá ilé ìjọ̀sìn padà
Ọna lati ṣe koriya fun awọn oludibo ni nitori pe ti eeyan ba jade lati dibo,ojuṣe rẹ pataki ni o ti ṣe yẹn.
Fatima Ganduje, ìyàwó ọmọ Ajimọbi ní iró ni pé Bàbá ọkọ òun kú!
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Iṣẹ́ Kudirat Abiọla ṣì ń fọhùn síbẹ̀, lẹ́yìn ọdún 23 tó papòdà Irọ́ ńlá!
James Milner lo gbayo keji wọle fun Liverpool ki agbabọọlu Arsenal tẹlẹ Alex Oxlade Chamberlain ati Divock Origi to gbayo ẹlẹkẹta ati ẹlẹẹkẹrin sile Arsenal.
Ẹni tí ó bá lọ́lá jùlọ láàrin yín ni kí ó ṣe iranṣẹ yín.
A kò fi ohun ìkọsẹ̀ kankan siwaju ẹnikẹ́ni, kí àwọn eniyan má baà rí wí sí iṣẹ́ wa.
Ẹ kún fún irọ́ pípa, ìkà ń bẹ ninu yín,iṣẹ́ burúkú sì ń bẹ lọ́wọ́ yín.
Ninu osu kinni odun ti a wa yii ni olori ijoba orile-ede Israel, Benjamin Netanyahu kede sise amulo erongba re lati ko awon arinrinajo ti won woo rile-ede naa lona aibofinmu, ni eyi ti o fun won anfaani lati kuro funra won wooro-wo, tabi ki won gbe won sewon gbere.
Nínú ọ̀rọ̀ rẹ tó fi síta lórí rẹ́díò Biafra, Nnamdi Kanu ní òhun kò mọ̀ọ́mọ̀ sá nílùú bí kìí bá ṣe wí pé iléesé ọlógun Nàìjíríà fẹ́ pa òhun lo mu ki oun sa nilu.
"Ṣaaju ni Odion Ighalo, to n gba bọọlu fun Manchester United nilẹ Gẹẹsi, ti kọkọ sọ pe ""itiju nla gbaa"" ni ijọba Naijiria jẹ lẹyin ikọlu Lekki."
Joṣua ṣe bí Mose ti pàṣẹ fún un, ó bá àwọn ará Amaleki jagun.
Kí OLUWA pèsè ọpọlọpọ èso sórí ilẹ̀ wọn,kí ó sì kún fún àwọn èso tí ó dára jùlọ láti ìgbà dé ìgbà.
O sapejuwe ere bebi ori ero amohun-maworan gege bi ohun to n dagbasoke kiakia, ti awon eniyan si nife si, leyi ti yoo si tete dagbasoke ni Naijiria, paapajulo ti o ba ba ilana Asa ati ise orile-ede yii mu.
Elebuibon sọ pe iyalẹnu lo jẹ fawọn to wa nibẹ lọna naa pe oun fi ọfọ da ẹjẹ jade duro.
ati àwọn ọmọ rẹ̀ ọkunrin mejeeji.
san owo naa fun awon osise bayii.
OLUWA sọ fún Aaroni pé, “Ìwọ, ati àwọn ọmọ rẹ, ati ìdílé baba rẹ ni yóo jìyà ẹ̀ṣẹ̀ tí wọ́n bá dá ní ibi mímọ́.
Stadium ti o wa niluu Asaba, nipinle
₦750m ni Akeredolu ń gbà lóṣù fún ‘Security Vote’ àti ₦150m owó oṣù - Agboola Ajayi fèsì INEC kéde agbègbè ẹsẹ̀ odò 270 ti èrú ìbò ti le wáyé ní ìpínlẹ̀ Ondo Ọ̀pọ̀ aráàlú Owo wà nílé ìwòsàn, síbẹ̀ APC àti PDP kò gba ẹ̀bi Ẹ gbọ́ òhun tí àwọn olùdíjé sípò gómìnà nípínlẹ̀ Ondo sọ nípa Bàbá ìsàlẹ̀.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìfipábọ́mọlòò Kaduna: Ọlọ́ọ̀pá m'áwọn tó ń fipá bá èèyàn 500 àtàwọn ọmọdékùnrin lò pọ̀ 27 Owewe 2019 Oríṣun àwòrán, Nigerian Police Eeyan bi ẹẹdẹgbẹta tawọn ọmọde wa lara wọn lo gba ominira lẹyin tawọn ọlọpaa yabo ile kan lagbegbe Rigasa nipinlẹ Kaduna l'Ọjọbọ.
Ọga ọlọpaa tun tẹnumọ igbaradi ileeṣẹ ọlọpaa lati fi orukọ rere pe ileeṣẹ ọlọpaa Naijiria to fi mọ aato nilana ikọṣẹmọṣẹ fun ṣiṣe iṣẹ wọn fun awọn araalu.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Lori ejo to mi owo: Ajọ JAMB fun osisẹ n'iwe lọ gbe'le ẹ 12 Èrèlè 2018 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, osise ajo jamb wipe ejo gbe owo mi Ajọ JAMB ti kede lana wipe ohun ti fun oṣiṣẹ rẹ̀ Philomina Chieshe niwe lọ gbélé ẹ látàrí ìṣẹ̀lẹ̀ ejò miwó-miwó ti wọ́n lo mi mílíọ́nù mẹ́rìndínlógóji naira lọ́ọ̀físì ìgbìmọ̀ aláṣẹ àjọ nàá tó wà ní Makurdi ní ìpínlẹ̀ Benue.
Awọn iroyin miran ti ẹ le nifẹ si: ‘Aawọ abẹnu lee koba APC ni 2019’ Dino Melaye tun k'ọrin miran Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
A si n fi asiko yii dupẹ lọwọ yin fun isẹ takuntakun alailẹgbẹ ti ileesẹ yin n se laarin wa.
Ẹ gbé Etete, Adoke àtàwọn míràn lórí ọ̀rọ̀ epo Malabu - Iléẹjọ́ Ìbálòpọ̀ ọ̀lọ́jọ́ méje mú kí ilé ẹjọ́ tú ìgbéyàwó ọdún mẹ́wàá ká ní Ibadan Bobrisky dárò pé EFCC gbé Mompha, ọ̀dọ́mọdé olówó tó ń lo aago ₦20m Fatai Rolling Dollar, Ọmọ ìdílé oyè tó gbé igbá orin tí Ebenezer Obey ń ṣiṣẹ́ lábẹ́ rẹ̀!
Ṣé o ti gbọ́ ohun ti Ọọni Ifẹ́ àti Soyinka parí ọ̀rọ̀ Yorùbá sí?
Coronavirus Updates: Báwo ló ṣe n tànkálẹ̀ l'Afrika?
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Senator Elisha Abbo: Ilé aṣòfin àgbà gbé ìgbìmọ̀ kalẹ̀ lórí Sẹ́nétọ̀ tó lu obìnrin l'Abuja 3 Agẹmo 2019 Oríṣun àwòrán, SenateNGR Ileegbimọ aṣofin agba lorilẹede Naijiria ti kede pe oun yoo ṣe iwadii ẹsun lilu ọmọbinrin kan nile itaja nilu Abuja eyi ti wọn fi kan Sẹnetọ Elisha Abboni alẹ ọjs iṣẹgun ọjọ keji oṣu keje ọdun 2019.
National Blindness and Visual Impairment Survey, 2005-2007 tun fihan pe ida
Ikolu awon omo-ogun olote naa ti ijoba Syria ti bere lati ose meji bayii, ni ikolu ti o lagbara julo lati odun mejo seyin ti won ti n kolu awon omo ogun olote naaEwe, gege bi egbe ajafeto ara ilu ni Syria se so,”Egberin eniyan loti salaisi bayii ninu ikolu ohun latari ibugbamu ado oloro.
Kì í jẹ́ kí eniyan burúkú ó wà láàyè,ṣugbọn a máa fún ẹni tí ìyà ń jẹ ní ẹ̀tọ́ rẹ̀.
Bákan náà ni ó ṣe sí ẹja, ó fún olukuluku bí ó ti ń fẹ́.
Ile –ise aare ti so pe erongba lati da ibugbe awon daran-daran (Ruga)sile yoo fopin si wahala ati laasigbo to maa n waye laarin awon daran-daran  ati agbe, nipa ni awon daran-daran se maa n daran won kaakiri lati je ohun ogbin awon agbe.
Ile-ejo ologun lorile-ede Somalia ti dajo iku fun okunrin kan latari lilowo ninu ibugbamu ado-oloro ti o seku pa ogunlogo awon eniyan ninu osu kewaa odun to koja.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Akomolede ati Aṣa lori BBC: Mọ̀ si nípa oríṣìí ẹ̀ka ìsọ̀rí ọ̀rọ̀ àti ìwúlò wọn O ni àwọn mu ẹni ti wọn fẹsun.
Ní àkókò náà, Ọlọrun kò fún un ní ogún ninu ilẹ̀ náà, bí ó tilẹ̀ ṣe ẹsẹ̀ bàtà kan, kò ní níbẹ̀.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Ǹjẹ́ àrùn Coronavirus leè wà lára èèyàn títí lái?
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ẹ wo àrà àwọn ọmọ kékeré ń fi ẹ̀kọ́ kọ̀mpútà dá Àwọn ti ìlé iṣẹ́ BBC Yorùbá n gbe yẹwo fi sami ayẹyẹ ọmọ wẹ́wẹ́ t'orílẹ̀-èdè Nàìjíríà tó tí làmìlaaka nínú ǹkan ti wọ́n yàn láàyò lagbaye ni: Jeremaiah Owura Addo (GHANA) Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Jeremiah Addo: Ọmọ ọdún méjì tó ṣeeṣe kò mọ̀wé jù l'ágbàáyé Ọmọ yìí gan an ni à bá sọ pé orí rẹ̀ pé bii ti alájọ Ṣomolu.
Ní tèmi, a ti fi mí rúbọ ná.
Ofin tuntun naa, ti wọn fi ransẹ si gbogbo ẹka ileesẹ ọlọpaa ilẹ wa lo pasẹ peayipada nla ti ba ẹka Sars nileesẹ ọlọpaa.
Aare Buhari sapejuwe Oba Tejuoso gege bi ogidi omo Yoruba to je olori rere to feran awon ara ilu to n joba le lori.
Ibeere ti Ọjọgbọn Akinyẹmi beere lori eyi ni wipe, njẹ Cyril Ramaphosayoo lee tan ẹhonu awọn alagbra wọnyii bi ti wọn ko si ni daa ni agbo si ina?
wọn yóo gbé ejò lọ́wọ́, wọn yóo mu òògùn olóró, ṣugbọn kò ní ṣe wọ́n léṣe; wọn yóo gbé ọwọ́ lé àwọn aláìsàn, ara wọn yóo sì dá.
Ajọ WHO ṣalaye pe ko tii si oogun tabi abẹrẹ to le wo aarun coronavirus lọwọlọwọ bayii.
O ni ewu ni ti oniduro ko ba mọ ẹsun ti wọn fi kan ẹni to n jẹjọ.
Oríṣun àwòrán, other Osisẹ Alukoro fun ilé ìwòsàn náà, ọgbẹ́ni Abdullahi fìdí rẹ̀ múlẹ̀ fún BBC Yoruba pé, lóòtọ́ ni ìṣèlẹ̀ náà wáyé.
 Arẹwa ile Spain yii ni iyawo baba awon omo re meta to ku (Cristiano Ronaldo Jr, 7; ati ibeji Eva ati Mateo Ronaldo (1).
Tí a fiṣọwọ́ ní 8:26 10 Ọ̀pẹ̀ 20208:26 10 Ọ̀pẹ̀ 2020 Obasanjo àti Gani Adams tẹ́ mi pẹ̀lú bí wọn ṣe tahùn síra wọn - Adebanjo Laipẹ yii ni Oloye Adebanjo pẹtu si ija to wa laarin awọn mejeeji nile rẹ ti Obasanjo ati Adams si sọ ohun to n dun wọn nibi ipade ọhun.
Labẹ asia ẹgbẹ Alliance for Democracy, AD, lo ti bẹrẹ irinajo oṣelu rẹ, ti o si sun lọ si ACN ki o to pada kangun sinu ẹgbẹ oselu APC, nibi to ti wa jẹ olori ile lọjọ Iṣẹgun, ọjọ Kọkanla oṣu Kẹfa ọdun 2019.
"Eewọ ni koda nile alaye ka maa ro iku ro ọta ẹni""."
Oríṣun àwòrán, Facebook Eyi ko ṣẹyin bi Ajọ INEC ṣe kede gomina ipinlẹ Ondo, Oluwarotimi Akeredolu gẹgẹ bi ẹni to jawe olubori ninu idibo sipo gomina nipinlẹ Ondo.
08trn kalẹ̀, ó ń wá owó tí yóò fi gbọ́ bùkátà rẹ̀ N kò sọ fún ìyá mi kí ń tó lọ sílé BB Naija - Laycon Ìdí tí Gúúsù Akure, Owo àti ìwọ̀orun Ondo yóò fi sọ ẹni tí yóò jáwé olúborí nínú ìbò gómìnà Ondo Kẹ̀rẹ̀ kẹ̀rẹ̀ Okonjo-Iweala ń súnmọ́ ipò olórí WTO bọ̀ Bode George ní Fayose gọ̀, ó fẹnu họra, Fayose ní ''ẹ ò lè pa mí bí ẹ ṣe pa Bola Ige Ènìyàn 5, ilé 25 ilé ìtajà 16 àti àwọn ǹkan mírà lo bá ìṣẹ̀lẹ̀ iná náà rìn.
9th Assembly: Aráàlú ní àwọn ń fẹ́ ìpèsè àwọn ohun èèlò amáyédẹrùn
Igi oko dori kodo, ojojo n se ewebẹ ọja, omi n bọ loju alawọ dudu ati funfun, ti koowe si ke lai ha.
Ẹwẹ, ni ọjọ kejidinlogun, oṣu kẹjọ, ọdun 2020, Keita ati olootu ijoba Mali Boubou Cisse, ni awọn ọmọ ogun gbe lasiko ti wọn ditẹ gba ijọba.
Ikú Kofi Annan dorí àwùjọ àgbáyé kodó Kíni iyatọ tó wà láàrin FSARS àti SARS?
'Àwa ọmọ Nàìjíríà tó farapa fẹ́ wálé láti Lebanon, ìjọba kó wa pamọ́' Ọlọ́run nìkan ló mọ bí ìrìnàjò ìfẹ́ ẹ̀dá á ṣe rí láyé, ọ̀dọ́ Aláàfin ní orí gbémí yà sí, ó sì tẹ́milọ́rùn- Olorì Aanu Èèyàn 334 ló gbàwòsàn lọ́wọ́ Covid-19 l'Ọjọru, 453 míì tún lùgbàdì rẹ̀- NCDC Wọ́n dájọ́ ikú nípa sísọ̀kò pa ẹni ọdún 61 ní Kano Gomina ipinlẹ Benue, Samuel Ortom ni ijọba gbọdọ wa wọrọkọ fi sada ni ẹka eto aabo nitori aisi aabo to peye naa ti fa ifasẹyin fun idagbasoke orilẹ-ede Niajiria.
Sowore ni ko si anfaani kankan ti abadofin naa le ṣe fun araalu bi ko ṣe pe ko daabo bo awọn to wa ni ijọba.
Mose ati àwọn ọmọ Israẹli ṣẹgun Sihoni nígbà tí wọ́n jáde kúrò ní Ijipti.
Ọga ajọ INEC to n ri si eto iroyin ati ilanilọyẹ, Ọgbẹni Festus Okoye lo fọrọ naa lede lẹyin ipade to ṣe pẹlu awọn lọgalọga ajọ INEC lori ibo gomina to waye lọjọ Abamẹta to kọja.
Èyí yóo di ìlànà fún wọn títí lae: fún òun ati arọmọdọmọ rẹ̀ ní gbogbo ìran wọn.
Iná ẹ̀lẹ́ńtíríkì pa ẹlẹ́wọ̀n máàrún lọ́gbà ẹ̀wọ̀n l'Eko Nǹkan mẹ́wàá tó yẹ ní mímọ̀ nípa fásitì ẹ̀kọ́ ìrìnà òní $50m ní Nàìjíríà Ọlọ́pàá South Africa rí ẹ̀wọ̀n ọgbọ̀n ọdún he torí ikú ọmọ Nàìjíríà Àwọn agbébọn pa ènìyàn mẹ́rinlá lásìkò ìjọsìn Dino ní ìyàwó ni Adeyemi jẹ́ f'óun lágbo òṣèlú, Adeyemi l'ọ́mọ ọ̀dọ̀ ni Dino jẹ́ Bi o tilẹ jẹ wi pe ofin laa kalẹ pe awọn aṣofin yoo ni ileeṣẹ agbegbe lawọn ẹkun idibo wọn sibẹ ọpọ ni ko mọ ibi ti awọn ileeṣẹ wọnyii wa.
Adesanmi lọ sile iwe Titcombe College niluu Egba, bẹẹ lo tun kawe nile iwe giga
Mo bínú sí wọn mo sì gbé wọn ṣépè, mo na àwọn mìíràn, mo sì fa irun wọn tu.
Ilé isẹ́ Àjọ INEC gbaná ní ìpínlẹ̀ Plateau Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí kan sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
Trump ń lérí láti ti ojú òpó ìkànsíraẹni ayélujára pa nílẹ̀ Amẹrika Aarẹ ilẹ Amẹrika, Donald Trump ti n gbaradi lati tọwọ bọwe aṣẹ kan to ni ṣe pẹlu iṣakoso awọn ileeṣẹ to n risi oju opo ikansiraẹni lori itakun agbaye.
ọdun 2018 onitiriliọọnu kan le diẹ naira pẹlu iko ọgọta ninu ida
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ọbasanjọ: O dun mi pe awọn obi mi ko ri aseyọri mi 5 Ẹrẹ̀nà 2018 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ọbasanjọ ti jẹ olori ijọba ologun ni Naijiria ri, ko to tun jẹ aarẹ alagbada fun saa meji Aarẹ ana lorilẹede Naijiria, Oloye olusẹgun Ọbasanjọ ti nfi ika hanu pe bi awọn obi oun ko se pẹ laye lati ri pe oun se aseyọri ndun oun jọjọ.
Wọn á kó àwọn àgọ́ wọn ati àwọn ẹran ọ̀sìn wọn lọ́wọ́, wọn á sì bo àwọn ọmọ Israẹli bí eṣú.
Iya to jẹ Adeeko kii ṣe diẹ, ọpọ igba si ni kii ri ounjẹ alẹ jẹ, ṣugbọn ni igbẹyingbẹyin, o ru u la o si kawe gboye.
Ministerial List: Buhari tí dájọ tí yóò búra wọle fún àwọn mínísítà rẹ̀
Aare Muhammadu Buhari ti bọwọlu iwe isuna ọdun 2019ti iye rẹ le ni
’ Yóo ṣe bí ẹ ti wí.
Awon ipò náà ni Minisita fun eto ọrọ araalu, ajalu ati idagbasoke awujọ, Minisita fun eto amuṣagbara, Minisita fun igboke-gbodo ọkọ ofurufu, Minisita fun akanṣe iṣẹ ati ọrọ okeere, Minisita fun ọrọ awọn ọlọpaa.
Adisa sàlàye pé ìdájọ yìí yóò fun àwọn òṣìsẹ́ ijọba ìbìlẹ ni ore-ọ̀fẹ́ láti pada sẹnu iṣẹ́ nítori gbogbo ìgbà ti hílahilo àwọn alága ìjọba tẹlẹ̀ri ti bẹ̀rẹ̀ ni gbogbo òṣìṣẹ́ ti ni àwọn ko fẹ fi ẹmi awọn sòfò ti wọ́n si ti gbe ilé Joko.
Wọ́n ní, ‘Ẹ kò rí ọkunrin yìí, oníjẹkújẹ ati ọ̀mùtí, ọ̀rẹ́ àwọn agbowó-odè ati àwọn ẹlẹ́ṣẹ̀.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Omolola Arohunmolase Welder: Mo ti fí iṣẹ́ 'Welder' gbayì láwùjọ, tó mo fi tọ́ ọmọ yanjú Ninu atẹjade kan to fi soju opo twitter rẹ ni aarẹ ti ṣalaye lori igbesẹ yii.
" Esi ti awọn naa si maa n fọ pada ni pe, o ni ohun ti ọba se, ki wọn to pa a, nitori ti ko ba si ẹsẹ, ẹsẹ kii dede sẹ""."
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Sàká: Oun tí orí bá yàn fún ẹ̀dá ni kó ṣe Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Sàká: Oun tí orí bá yàn fún ẹ̀dá ni kó ṣe 15 Ìgbé 2018 Gbajúgbajà òṣèré tíátà, Afeez Ayétòrò tí ọ̀pọ̀ mọ̀ sí Sàká ṣàlàyé nínú ìfọ̀rọ̀jomitoro ọ̀rọ̀ rẹ̀ pẹ̀lú BBC wí pé oun ti orí bá yàn fún ẹ̀dá ni kó ṣe.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Kwara Coronavirus death: Aminu Adisa Logun ti d'olóògbé lẹ́yìn tó lùgbàdì àrùn Covid-19 7 Agẹmo 2020 Oríṣun àwòrán, Kwara COS Olori oṣiṣẹ ijọba ipinlẹ Kwara, Aminu Adisa Logun ti dagbere faye lẹni ọdun mẹtalelaadọrin lẹyin to lugbadi arun Covid-19.
Eyi ni ọrọ ọkan lara awọn afọbajẹ ilẹ Yoruba kan, Oloye Fagbenle Adedayọ Agẹṣin Adimula ati afọbajẹ ilu Ila Ọrangun ọkan lara awọn ilu iṣẹmbaye ilẹ Yoruba.
 a fún ni ní ìwé-àṣẹ láti lò wọ ́ n ní àwọn orílẹ ̀ -èdè tó ju 60 lọ .
Òkùnkùn bo orúkọ rẹ̀, ẹnìkan kò sì ranti rẹ̀ mọ́.
dupẹ pe Ọlọrun jẹ ki o ṣeeṣe fun wa lati kọ mọṣalaṣi tuntun yii,
Kò sí ẹnìkan tí ó lè dá a lóhùn ọ̀rọ̀ yìí.
Gomina Lalong wa rọ awọn ọmọ ipinlẹ naa lati gba alaafia laye, ki eto ijọba tiwantiwa le gbooro si lagbegbe naa.
Ethiopia: Abiy Ahmed di olóòtú ìjọba
A gbọ́ pé Abraham,ni èèyàn kẹwàá tí wọn yóò yìnbọn pa ní ìlú London ní ààrin ọ̀sẹ̀ méjì.
 O di gbajugbaja onkọwe lẹyin to gbe iwe alase rẹ: “Kitchen Confidential: Adventures in the Culinary Underbelly” sita lodun 2000.
Ọmọ-ẹ̀yìn kan wà ní Jọpa, tí ó jẹ́ obinrin, orúkọ rẹ̀ ń jẹ́ Tabita, tabi Dọkasi ní èdè Giriki.
“Igi rere kò lè so èso burúkú.
Àwọn ọmọ ọga Bello náà, ti wọn wa lati ilu Ilorin, ní wọn ti kẹ́kọ̀ọ́ gba òye imọ ìjìnlẹ̀ nílé ẹ̀kọ́ fasiti, kí wọn to jogún isẹ ti baba wọn ń ṣe, kódà agbẹjọro ni Femi, tíì ṣe àgbà wọn.
Naijiria loju pe ijoba yoo tubo  maa  mojuto ojuse won nipa didaabo bo ẹtọ  gbogbo omo orile ede Naijiria.
Ẹ̀mí gbé mi, ni angẹli yìí bá gbé mi lọ sinu aṣálẹ̀.
Amọ ọkan lara awọn oṣere to yẹ ko kopa ninu ere naa ko wa, ni wọn ba ni ki n rọpo rẹ, bi mo ṣe bẹrẹ iṣẹ tiata nìyẹn.
Bayii Sanwo Olu ti kede pe ki wọn lọ tu wọn silẹ ni ẹyẹ o sọka.
OLUWA, ìwọ ni ìpín mi, ìwọ ni mo yàn;ìwọ ni ò ń jẹ́ kí ọ̀ràn mi fìdí múlẹ̀.
Oríṣun àwòrán, Arotile Lasiko to n ba àwọn akọroyin sọrọ, baba rẹ, Onimọ ẹ̀rọ Akintunde Arotile, sọ pe oun ba ọmọ òun sọrọ ni ọsan ọjọ to kú, ki oun to pada gbọ iroyin ikú rẹ.
34 ninu osu kejila odun 2017 si N183.
Amasa bá lọ kó àwọn eniyan Juda jọ, ṣugbọn kò dé títí àkókò tí ọba dá fún un fi kọjá.
Ọjọ́ mẹfa ni ẹ óo fi máa rí oúnjẹ kó, ṣugbọn ní ọjọ́ keje tíí ṣe ọjọ́ ìsinmi, kò ní sí níbẹ̀ rárá.
@onos_147 ni to ba jẹ ọmọ ipinlẹ Edo ni Aisha ni, Fatimah ko ba ti ge ni imu.
Britain benu ate lu ikolu Iran si orile-ede Israel, bee si ni won fe ki orile-ede Russia lo ipo re silu Syria lati da ikolu duro bi o ti le wu ko mo.
Wọ́n fi idà pa gbogbo àwọn ará ìlú náà láìku ẹyọ ẹnìkan, wọ́n sì sun ìlú Hasori níná.
O ni ere Fuji ti wa saaju ki oun ati Ayinde Barrister to bere orin kiko rara.
Oríṣun àwòrán, others Àkọlé àwòrán, Àwọn ọmọ Naijiria to ti kú lóri pápá lásìkò ìfẹsẹwọ́nsẹ Michael Umanika: Agbábọọlu Naijiria fún Zagatala PFK lo dójubolẹ lori pápá lásìkò ti wọ́n ṣe ìgbáradi láti lọ fun idíje.
Èmi náà óo sì yan ìjìyà fún wọn,n óo jẹ́ kí ẹ̀rù wọn pada sórí wọn.
Lẹ́yìn náà ni ó ṣẹ̀ṣẹ̀ wá wí fún àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ pé, “Ẹ jẹ́ kí á tún pada lọ sí Judia.
Gbogbo ayé ló fẹ́ wo ikú ẹ̀sín ti Bádérù máa kú.
Ati ọmọde ati agba, ati ọkunrin ati obinrin, lo si wa ninu wọn.
O le fa ki ẹni naa ma daku ti ẹjẹ rẹ ko ba pọ to ti awọn ẹya ara rẹ naa si le kọ lati ma sisẹ.
’N óo sì pe àwọn orílẹ̀-èdè tí n kò náání ní ‘Àyànfẹ́ mi.
Bẹ́ẹ̀ ni Eleasari alufaa ati Joṣua ọmọ Nuni ati àwọn àgbààgbà ninu ẹ̀yà àwọn eniyan Israẹli ṣe ṣẹ́ gègé láti pín ilẹ̀ náà ní Ṣilo níwájú OLUWA, ní ẹnu ọ̀nà àgọ́ ìpàdé; wọ́n sì parí pípín ilẹ̀ náà.
Ganiyu ṣalaye pe eniyan mẹta ni ọkọ ajagbe naa ṣe akolu si ṣugbọn ti eniyan kan si gbẹmi mii loju ẹsẹ.
Suhaila Ibrahim El-Zakzaky, ninu fidio to fi sita loju opo Twitter rẹ salaye pe, iwọde ẹgbẹ naa to da lori pe ki wọn tu El-Zakzaky silẹ, ṣi n tẹ siwaju Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Da ẹran jẹ̀ nígboro, ko fẹ̀wọ̀n oṣù méje jura tàbí san ₦200,000 - Ilé aṣòfin Ọyọ dábàá Kí ni Oluwo lọ ṣe ní Aso Rock lẹ́yìn lẹ́tà rẹ̀ sí ààrẹ Buhari?
Ta ni Olodumare, tí a óo fi máa sìn ín?
A sì ti fi àáké lé gbòǹgbò igi báyìí.
Nibayii, Ikekweazu fi aridaju rẹ han ni ọjọ Iṣẹgun nibi ipade ikọ amuṣẹya aarẹ nipa Covid-19, PTF.
Lala maa lu ni alẹ oni nigba ti Bafana Bafana ẹgbẹ agbabọọlu South Africa maa gbena woju Super Eagles ti Naijiria.
”Joṣua bá dojúbolẹ̀, ó sin OLUWA, ó sì bèèrè lọ́wọ́ rẹ̀ pé, “Kí ni o fẹ́ kí n ṣe, OLUWA mi?
Ǹjẹ́ Balaki bá àwọn ọmọ Israẹli ṣe ìjàngbọ̀n kan tabi kí ó bá wọn jagun rí?
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù APC Kwara: Abdulrahman ṣì ni olùdíje wa fún ipò Gómìnà 20 Ọ̀pẹ̀̀ 2018 Oríṣun àwòrán, APC KWARA Àkọlé àwòrán, Igbimọ amuṣẹya ẹgbẹ lo ṣe idibo abẹnu to gbe Abdulrahaman Abdulrazaq wọle gẹgẹ bi oludije ipo Gomina Akowe ipolongo apapọ ẹgbẹ APC, Lanre Issa Onilu ti tako idajo ile ẹjọ giga kan nilu Ilorin to ni igbimọ ẹgbẹ labẹ akoso Ishola Blogun Fulani ni ojulowo igbimọ ẹgbẹ.
Biden ti ni ọpọlọpọ iriri ni Washington.
Ọkunrin to ba n tẹnbẹlu iwa ipa si obinrin, okunrin naa a wu iwa ipa si obinrin niyẹn.
Mo sọ fun yín, ó tilẹ̀ ju wolii lọ.
Gẹgẹ bi a ṣe ka a loju opo Wikipedia atawọn oju opo miran lori ayelujara, ọta ìbọn kan ṣoṣo lo sokunfa ogun Agbekoya, eyi to mu ọpọ ẹmi lọ.
Lẹ́yìn tí o bá ti kórè tán, o kò gbọdọ̀ pada lọ tún kórè àwọn ohun tí o bá gbàgbé.
A dúpẹ́ lọ́wọ́ rẹ, Ọlọrun wa, a sì yin orúkọ rẹ tí ó lógo.
 Mo je aare egbe yii fun igba meji otooto, koda won tun fe ki n tesiwaju, eleyi ti mo so fun won pe enikan kii je kile fe.
Akeugbagold tún kesi àwọn agbofinro láti tètè bá òun ṣe ìwádìí nípa ibi tí àwọn ọmọ náà wá, kí wọn sì bá òun kò wọn wálé.
Oríṣun àwòrán, AFP Àkọlé àwòrán, Ọjọ buruku ni ọjọ ti awọn afunrasi pa alufa ijọ aguda nipinlẹ Benue.
Nígbà tí ó yá, Opa fi ẹnu ko ìyá ọkọ rẹ̀ lẹ́nu, ó sì dágbére fún un; ṣugbọn Rutu kò kúrò lọ́dọ̀ ìyakọ rẹ̀.
Ìrun àpapọ̀ dèèwọ̀ lọ́jọ́ Jímọ̀, kò sí oúnjẹ alẹ́ Olúwa mọ́ fún Kristiẹni Háà, Coronavirus ba ọjọ́ ìbí mi jẹ́ tán, díẹ̀ ló kù, mo yára ṣàtúnṣe sí i - Obasanjo Ẹ wo ọpọ eré ìdárayá nílẹ̀ Yorùbá tó ti ń di ohun ìgbàgbé Coronavirus tún ti ṣe ọṣẹ́ lórí iṣẹ́ líla ojú ọ̀nà relùwe láti Eko sí Ibadan - Ìjọba àpapọ̀ A n ṣé àyẹwò ẹni tá fúnra sí pé o ní Coronavirus l'Eko-Kọmísánà ìlera Bi o tilẹ jẹ pe Coronavirus ti na ọwọja rẹ de awọn orilẹede kan nilẹ Afrika, sibẹ awọn alasẹ lawọn orilẹede nilẹ adulawọ lo n tiraka lati pana ọpọ ayederu iroyin to rọ mọ Coronavirus.
Bakan naa ni ileẹjọ tu beeli rẹ tu beeli rẹ ka nitori o rufin to de beeli rẹ.
Ẹgbẹ́ òṣèlú AA kò gbọdọ̀ kópa nínú ìdìbò gómìnà ní Kogi, Bayelsa - Ilé ẹjọ́ Yahaya Bello, Gomina ìpínlẹ̀ Kogi kéde Onoja ní ìgbákejì tuntun Omi ìṣẹ̀ńbáyé tó ń dà ní Ówù rèé, èyí tó ga jùlọ ní Afirika Buhari o, pèsè ohun tó yẹ sí ọgbà ẹ̀wọ̀n, kí àyípadà orúkọ wọn léè pegedé Àwọn agbébọn fọ́ ọgbà ẹ̀wọ̀n ni Minna Ile isẹ akoroyinjọ ni Naijiria (NAN) sọ pe, ọga agba fun ile iṣẹ to n sakoso awọn ọgba ẹwọn ni Naijiria, ọgbẹni Jafar Ahmed lo fidi iṣẹlẹ yii mulẹ fawọn akọroyin nilu Koton Karfe.
Adetutu Alabi jẹ ọkan ninu awọn obinrin ti asa ila kikọ ti ko ba lati ka iwe, pẹlu ọpọ ipa ti ko see sọ miran to tun ni lori rẹ.
Lọwọ-lọwọ bayii, wọn ti n gbe awọn eeyan to sese ninu ijamba ibugbamu naa lọ sile iwosan, ninu eyi ti a ti ri sisita ijọ Katoliki kan ati akẹkọ mta.
‘A gba ìjọba láti dá ìjọba tiwantiwa padà’ Ile iṣẹ ologun ni orilẹede Gabon sọ wi pe awọn ti gba ijọba ti ile Gabon to kun fun ọpọlọpọ ohun alumọni epo rọọbi.
Ibadan (Ibadan Polytechnic satellite campuses) lati da duro gege bii ile eko
Ẹ wo Àwọn Ọ̀rọ̀ Àdéhùn Ìlò fún ẹ̀kúnrẹ́rẹ́.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ijamba ọkọ: Ẹmi 18 bọ ni marosẹ Ibadan si Eko 19 Ẹrẹ̀nà 2018 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Taya ọkọ kan to fọ lori ere lo fa sabi ijamba ọkọ naa Eeyan mejidinlogun la gbọ pe o padanu ẹmi wọn ninu ijamba ọkọ to waye lagbegbe adugbo Alapako si Ogunmakin ni opopona marosẹ Ibadan silu Eko.
Apetan orukọ gbajumọ oṣere tiata naa ni Olusola Isola Ogunsola, tii ṣe ọmọ bibi ilu Abeokuta, to jẹ olu ilu ipinlẹ Ogun bayii.
Lọdun 1984, Maradona fi ikọ agbabọọlu Boca Juniors silẹ lọ si Napoli lorilẹede Italy.
Ki n ma sà bá ọ̀rọ̀ yìí lọ bí ilẹ̀ bí ẹní, èèmeje ni obìnrin yìí gbé Òmùgọ̀diméjì lulẹ̀ lójú wa, ìgbà tí wọ́n sì jàjà gba ọba sílẹ̀ lẹ́ẹ̀keje yìí ṣe ló gba iré dà sílẹ̀ tí obìnrin yìí náà gbá tẹ̀lé e.
Lasiko ti Fayose n ṣe ifọrọwanilẹnuwo pẹlu Dele Momodu lo sọ bẹẹ.
Ṣugbọn nígbà tí wọ́n dé ọ̀dọ̀ Jesu wọ́n rí i pé ó ti kú, nítorí náà wọn kò dá a lójúgun.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ere ki laja n ba ẹkun se?
Ogbẹni Akinrọpo sọrọ nipa iriri rẹ pé ki òbí má nigbagbọ pé ẹnikan kò le ṣe ọmọ wọn nibi nitori pe ayé ti dorikodo, àṣà ti n sọnu.
Brian ni ''gbogbo awọn oṣiṣẹ lo ṣi n wa sibi iṣẹ bo tilẹ jẹ ko si alejo kankan.
Bí Satani bá gbógun ti ara rẹ̀, tí ó ń bá ara rẹ̀ jà, kò lè fi ẹsẹ̀ múlẹ̀, a jẹ́ pé ó parí fún un.
Àwọn tí wọ́n wà pẹlu mi rí ìmọ́lẹ̀ náà, ṣugbọn wọn kò gbọ́ ohùn ẹni tí ó ń bá mi sọ̀rọ̀.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, World Radio Day: Àwọn òṣìṣẹ́ rédíò ní àwọn ń pa ìsòro àwọn mọ́ra ni láti mú inú aráàlú dùn Fadeyi wa fidi rẹ mulẹ pe Kọmisana ọlọpa nipinlẹ Ọyọ ti pasẹ pe ki iwadi bẹrẹ lọgan lori ohun to fa rogbodiyan to waye lagbegbe Soka ọhun, ni kete ti iwadi naa ba si ti pari lawọn yoo kede fun araye gbọ.
Mo gbọ́ ohùn olùfẹ́ mi, wò ó!
Ki lo fa ṣababi ija naa?
Alákòso orín Wasiu Ayinde Mashall, Adebayo Olasoju to ba BBC Yoruba sọrọ lórí fóònù ṣàlàyé pé, ọ̀rọ̀ tó ṣẹlẹ kìí ṣe èyí tó yẹ ki ó jáde rárá nítóri, ọmọ iṣẹ́ K1 ni MC Murphy.
O ni ohun to jẹ ki orukọ arun coronavirus o gbode kan ni pe, 'aisan alariwo'ni.
Gómìnà rè sodò nì Kenya nígbà tó ń ya fọ́tò ara rẹ̀
Níbẹ̀ ni a óo ti dẹ́rù bà wọ́n gidigidi,nítorí Ọlọrun ń bẹ pẹlu àwọn olódodo.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Kii ṣe aniani pe ọpọ awọn opopona ni ilu Eko ni ko dara fun lilọ-bibọ ọkọ to ja geere.
Arsenal ṣe Valencia b'ọ́ṣẹ tií ṣ'ojú Man City àti Arsenal yóò síde Premier League Àṣẹ̀yìnwá àṣẹ̀yinbọ̀ Aubameyang ló gbá bọ́ọ̀lù sáwọn lẹ́yìn to gé Ainsley Maitland - Niles àti Martin Dubravka légèé tán.
Ó ní, “Ẹni ìyìn ni OLUWA lónìí, nítorí pé ó fún Dafidi ní ọlọ́gbọ́n ọmọ, láti jọba lórí orílẹ̀-èdè ńlá yìí.
Bí ìlẹ̀kùn ṣe ń ṣí síhìn-ín, sọ́hùn-ún, lórí ìdè rẹ̀,bẹ́ẹ̀ ni ọ̀lẹ ń yí síhìn-ín, sọ́hùn-ún, lórí ibùsùn rẹ̀.
Ó fara pamọ́ bíi kinniun tí ó wà ní ibùba;ó fara pamọ́ láti ki aláìní mọ́lẹ̀;ó mú aláìní, ó sì fi àwọ̀n fà á lọ.
Oríṣun àwòrán, RARIYA Àkọlé àwòrán, Oṣu Kejila, ọdun 1988, ni iya to bi Aarẹ Buhari, Zulaihat Adamu Hardo, ku Ẹya Fulani ni iya Aarẹ Buhari, Zulaihat, lati ilu Daura nipinlẹ Katsina.
”Wọ́n bá dá a lóhùn pé, “Rárá o!
Yóo gé àwọn tí ó ga fíofío lulẹ̀,yóo sì rẹ àwọn agbéraga sílẹ̀.
Olùfẹ́ mi bá mi sọ̀rọ̀, ó wí fún mi pé,“Dìde, olùfẹ́ mi, arẹwà mi,jẹ́ kí á máa lọ.
Ijọba ati awọn ọba alade naa ti bẹrẹ si ni ba wọn lọwọ si ọ̀rọ̀ ọhun.
Aare tun wa ro awon omo orile ede Naijiria to wa nipo adari lati fi iwa Ribadu se awokose , ki won si ri ise- ijoba gege bi ise ti awon eniyan ni igbekele ninu won.
A jẹ́ pé bí ó ṣe nyí òòrùn po, nígbà míràn á kọ́ orí (àríwá) sóòrùn, nígbàmíì á kọ ìdí (gusu) síi.
" Aarẹ tuntun ti wọn sẹsẹ dibo yan fun ajọ to n ri si akoso awọn orilẹede nilẹ Yuroopu, Ursula von der Leyen - ti yoo gba ọpa asẹ lọjọ kinni, osu Kọkanla ọdun 2019 - tun ti tẹnumọ ipinnu ajọ isọkan ilẹ Yuroopu lori ọrọ yii.
Taribo West: Àwọn aláìní ní Italy ní mò ń fi owó ìjọ mi ràn lọ́wọ́
Oludije fun ipo aarẹ ẹgbẹ Barcelona sọ pe o ti han gbangba bayii pe Messi fẹ lọ ba akọnimọọgba rẹ tẹlẹ, Pep Guardiola ni Man City.
“Bèèrè àmì tí ó bá wù ọ́ lọ́wọ́ OLUWA Ọlọrun rẹ–ìbáà jìn bí isà òkú, tabi kí ó ga bí ojú ọ̀run.
Ohun mẹ́fà tí àgbáyé kò mọ̀ nípa Majek Fashek tó d'olóògbé nìyí WAEC ti ṣetán fún ìdánwò àṣekágbá girama Wo àwọn ìjọba ìbílẹ̀ 20 tí àrùn coronavirus pọ̀ sí jùlọ ní Nàìjíríà Ẹ gbọ́ ọ̀rọ̀ lẹ̀nu bàbá Uwa, akẹ́kọ̀ọ́ fásitì tí wọ́n fipábálòpọ̀ tó dèrò òrun Ọpẹlọpẹ awọn araalu to n fun mi lowo, oun ni mo fi n gbọ bukata ara mi, ko si apọnle kankan fun wa."
Ilé Ẹjọ́ Àgbà di ìdálẹ́jọ́ tí wọ́n ṣe ní oṣù Igbe tí ó kọjá àmọ́ a dá wọn sílẹ̀ lẹ́yìn ìdáríjì ààrẹ ní àsìkò Ọdún Tuntun ìbílẹ̀ orílẹ̀ èdè náà.
Mose gba owó ìràpadà náà lórí àwọn tí iye àkọ́bí àwọn ọmọ Israẹli fi pọ̀ ju àwọn ọmọ Lefi lọ.
Ọmọ ti ẹya ba bi, ẹya nii jọ.
Àwọn àjẹsára náà kò léwu láti lò .
anguidae jẹ ́ orúkọ àwọn ẹbí tí ó tóbi tí ó jẹ ́ ti aláǹgbá ti northern hemisphere .
Ajọ to n ri ri irina ni yoo fi iwe irina awọn eeyan pamọ titi digba ti ọjọ mẹrinla naa yoo fi tan.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Iléejọ́ Cameroon: Wọ́n Jẹ̀bi ẹ̀sùn ìṣelòdì sí ìjọba 26 Èbibi 2018 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Àwọn ajìjàǹgbara náà ǹ jà fún òmìnira pátápátá fún àwọn olùgbé Cameroon lẹ́kùn ti wọn ti n sọ èdè Gẹẹsi Ileẹjo ti ran awọn ajijangbara meje lọ sẹwọn fún ọdun mẹwaa si mẹẹdogun lori ẹ̀sùn iṣelodi si ijọba ati idunkooko-mọ-ni.
Awọn ijọba ibilẹ ti APC ti moke ninu mẹsan to ti jawe olubori bayii ni, Akoko North West, Akoko North East, Akoko South East ati Akoko South West.
Lasiko ti Baba Aduku sọrọ lẹyin to gba ami ẹyẹ o kare ti ileeṣẹ ologun fun un lo sọ pe ara oun ṣi le daadaa koda lori ibusun paapaa ni eyi to pa ọpọ lérin in nigba naa.
Ninu esi rẹ si abadofin naa, Alakoso agba fun Ọrọ Irinajo-afẹ, Aṣa ati Iṣe ni Ipinlẹ Eko, Ọgbẹni Steve Ayọrinde ṣalaye pe o ṣe pataki ki iru ajọ yii wa lati fi mu aṣeyọri ba ba igberu ti o n ba ẹka irinajo-afẹ ni Ipinlẹ Eko ti Gomina Akinwunmi Ambọde n ṣe bayii.
Obinrin náà lóyún, ó sì bí ọmọkunrin kan.
Lateef Adedimeji: Owó wa kò bá máa jóná ṣùgbọ́n aàyè ọpẹ́ ń yọ fún wa
"Koda, a gbọ pe wọn pin ẹran ara rẹ yẹlẹ yẹlẹ ni, ti wọn si kun ni ijanja, idi si ree ti wọn se maa n pe awọn ara Ogbomoso nigba miran pe ""Ogbomoso a pọba jẹ."
Ṣugbọn ọkunrin náà gbọdọ̀ mú àgbò kan tọ OLUWA wá ní ẹnu ọ̀nà Àgọ́ Àjọ, kí ó fi rú ẹbọ ìmúkúrò ẹ̀bi fún ara rẹ̀.
Ile igbimo asofin tun ti fenuko  lati maa jokoo fun ojo meta gbako lati fehonuhan lori eto aabo to n se seke-seke lorile ede yii.
Ọlọrun ṣèlérí láti Dá Ibukun Jerusalẹmu Pada.
Igba tiru iyalọmọ bẹẹ ba si de ile iwosan, nitori ori ọyan rẹ to ti bẹ, ti wọn ba tẹ ọyan rẹ fun omi, ni ẹjẹ yoo maa jade dipo omi ọyan.
“Ní tìrẹ, ìwọ ọmọ eniyan, àwọn eniyan rẹ tí ń sọ̀rọ̀ rẹ lẹ́gbẹ̀ẹ́ ògiri ati lẹ́nu ọ̀nà àbáwọlé wọn, wọ́n ń wí fún ara wọn pé: ‘Ẹ jẹ́ kí á lọ gbọ́ ohun tí OLUWA wí.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Àwọn olúlùfẹ́ fí ìbòjú fi ẹnu ko ara wọn ní Philippine Eyi ni nkan ti kọmisana fun eto iroyin nipinlẹ Eko, Gbenga Omotoso sọ fun BBC lọjọ Ẹti.
Jẹ́ kí ojú ó ti àwọn alátakò mi, kí wọn parun;kí ẹ̀gàn ati ìtìjú bo àwọn tí ń wá ìpalára mi.
Ọrọ yii mu ki awọn eeyan ṣi iwe kan iru igbeṣẹ bayi ti Gomina ipinlẹ Kwara nigba kan ri Bukola Saraki hu pẹlu yiyọ adajọ agba ipinlẹ naa Adajo Elelu Habeeb.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Burundi president: Wo àwọn ohun tó yẹ kí o mọ̀ nípa Pierre Nkurunziza, ààrẹ orílẹ̀-èdè Burundi tó dolóògbé 9 Òkùdu 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 11 Òkùdu 2020 Pierre Nkurunziza ni Aarẹ ti idibo wọle rẹ fun saa kẹta da fa ki n fa a silẹ.
Laarin irọlẹ si idaji si ni gbogbo awọ̀n olokoowo pataki yii maa n jẹ eniyan.
Ṣugbọn kí àwọn àlejò náà tó sùn, gbogbo àwọn ọkunrin ìlú Sodomu ti dé, àtèwe, àtàgbà, gbogbo wọn dé láìku ẹnìkan, wọ́n yí ilé Lọti po.
    Ọkùnrin yìí gbé pẹ̀lú ìyàwó rẹ̀ fún odidi oṣù mẹ́fà kí ó tó rántí ilé.
Cameroon Atrocity, BBC Africa Eye: Ẹwọ́n ọdún méjìlá ni wọ́n fún àwọn sója mẹ́rin tó pa ìyá àti ọmọ méjì ní Cameroon
”Ọba dáhùn pé, “Ó dára, mò ń gbọ́.
Amọ nibayii, awọn adari ẹgbẹ JOHESU naa ti wa paṣẹ fun wọn lati pada si ẹnu iṣẹ kaakiri orilẹede Niajiria.
Bí ìwọ̀n pẹpẹ náà ti rí nìyí; irú ọ̀pá kan náà tí ó jẹ́ igbọnwọ kan ati ìbú àtẹ́lẹwọ́ (ìdajì mita kan) kan ni ó fi wọ̀n ọ́n.
Egypt rán ènìyàn 700 lọ ẹ̀wọ̀n lórí ìfẹ̀hónúhàn 2013
Ṣebí ẹ̀mí tí ó jẹ́ iranṣẹ ni gbogbo àwọn angẹli.
1 89183 Orilẹede Belarus 1238 13.
Aarẹ Lebanon ti ṣaaju sọ pe ohun to fa sababi ibugbamu ọhun ni ibugbamu nkan oloro toonu ammonium nitrate to fẹrẹẹ to ẹgbẹrun mẹta (2,750) ti wọn ko pamọ lọna aitọ fun ọpọlọpọ ọdun.
Ẹni tí ó bá fẹ́ràn ayé kò ní ìfẹ́ sí Baba.
mona-mona wa niluu Delhi lorile ede India , ni orile ede naa wa ya orile
Ile isẹ ọlọpaa ni ipinlẹ Rivers ti fi panpẹ ọba mu ọmọ ile iwe girama ni ilu Port Harcourt to fi tajutaju si ara awọn ọmọ kilasi rẹ.
"Mo fẹ́ máa kọ ""Classical"" lédé Ijebu, Hausa, Igbo Pidgin - Abiodun Koya Ǹjẹ́ o tilẹ̀ mọ Samuel Okwaraji, agbábọ́ọ̀lù Nàìjíríà tó 'ṣubú lójú ìjà' Ṣé ẹ̀ṣẹ́ nìyí tàbí kùmọ̀?"
Iléeṣẹ́ China kan ti fagídí mú àwọn òṣìṣẹ́ rẹ̀ mu ìtọ̀
Onnoghen jẹ̀bi ẹ̀sùn tí wọ́n fi kàn án, ó pàdánù owó rẹ̀ Kò tọ̀nà láti gbé adájọ́ Onnogben lọ síwájú CCT - Adájọ́ fẹ̀yìntì Ọjọ kejidinlogun oṣu Kẹrin si ni igbimọ to n gbọ ẹjọ naa, CCT, sọ pe o jẹbi ẹsun naa, ti wọn si fi ofin de e pe ko ma di ipo ilu mu fun ọdun mẹwaa.
Ajọ INEC kọ lati darukọ oludije APC to bori nitori awọn meji Ifeanyi Araraume ati Frank Ibezim lo duro gẹgẹ bi oludije ẹgbẹ naa ninu idibo ọjọ Abamẹta.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Àṣìṣe ọlọ́pàá àti Adájọ́ sọ mí di ẹni tí wọ́n dájọ́ ikú fún, ọpẹ́lọpẹ́ Fayoṣe tí ko buwọlu Ohun tójú àwọn èèyàn tún rí tí wọ́n figbé ENDSARS bọnu Lọwọlọwọ, awọn ọmọ Naijiria tun ti wu ọna ti awọn ọlọpaa kogberegbe SARS fi n huwa si awọn araalu sita.
 Nigba ti Emir ilu Daura naa n
Mo fẹ́ lọ san ẹ̀jẹ́ kan tí mo jẹ́ fún OLUWA.
Elégbèje ko sì sí àníàní pé bí a bá ti lè ká ọ̀kan nínú èso igi ìrònú jẹ ọ̀nà àti wò ọ́ nínú àìsàn jẹunjẹun yìí kò ní ṣàì yé ni, ohun tí mo bá wá nì yí, Ìbẹ̀nbẹ́-olókùnrìn, ọkùnrin, o kú u jíjẹ, o kú u mímu.
Bo tilẹ jẹ pe o ni itakurọsọ n lọ lọwọ laarin NUPENG ati ijọba Eko, Momoh sọ pe iyanaṣẹlodi ọhun yoo tẹsiwaju titi di igba ti ijọba Eko yo gbe igbesẹ ọna abayọ si iṣoro ti wọn n doju kọ.
asa lorile ede Naijiria, Lai Mohammed lo soro yii lojo Aje pelu awon akoroyin
Níto’ri nígbà tí mo dé òkè tán atẹ́gùn kò fẹ́ mọ́, ìtàkùn dúró bí ó ti wà rí, àwọn igi kò sì fi orí balẹ̀, ṣé èmi ìbá mọ̀ kí n tètè bẹ́ sílẹ̀ bí atẹ́gùn bá fẹ́ ṣùgbọ́n nígbà tí igi ti wà ní ìdúró, àti sọ̀ kalẹ̀ kò lè ṣàìjẹ̀ ìṣòro fún mi.
esi ibo ẹgbẹrun mẹrindinlogun-le-meje (16,007) ti akẹgbẹ rẹ lati ẹgbẹ
Ko tan sibẹ o, iwadii ijinlẹ kan tun sọ pe, wiwo fidio ibalopọ - to ṣaba ma n waye pẹlu titẹ ara ẹni lọrun, ma n ni ipa ti ko dara lara ọpọlọ.
Njẹ ẹ mọ pe SARS ni baba?
"O fi iroyin naa to awọn ọmọ Naijiria leti lori Twitter ni Ọjọbọ niga to ni ""Ọjọ ibanuje ni ọjọ yii jẹ fun aye mi."
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Osun Osogbo: OSUCCIMA ní òun yóò lo ọdún Ọṣun Osogbo pèsè iṣẹ́ àti àgbéga okoòwò aládàáni 5 Ògún 2019 Oríṣun àwòrán, Osun Osogbo Festival Nibayii ti ajọdun Ọsun Osogbo n bẹrẹ loni ọjọ Aje pẹlu eto 'Ìwọ́ Popo', ti wọn fi n fọ ilu mọ ni ilana ibilẹ wa, wọn ti gba awọn ileesẹ nlanla nimọran lati fi ọwọ sowọpọ nidi sise agbelarugẹ ajọdun naa.
Idajọ naa ti kuro nile ẹjọ majisireeti lonii eyi ti yoo waye ninu oṣu keji yoo waye nile ẹjọ giga ipinlẹ Ondo.
Arẹwà Ibidunni Ighodalo wọ káà ilẹ̀ lọ nílùú Eko Oníṣòwò kan wó ọ́fíìsì Nàìjíríà ní Ghana lulẹ̀, ìjọba Nàìjíríà faraya Ìséde ká mi mọ́ orí afára Kara ni mo ní kí n sùn, ki ọkọ̀ mi tó jóná Apẹrẹ ti a ri lati fi kin ọrọ yi lẹyin ni bi Gomina Godwin Obaseki ko ti se jẹ ki ọjọ pẹ rara ki o to sare lọ darapọ mọ ẹgbẹ oselu PDP lẹyin ti APC ni pe awọn ko fun un ni tikẹẹti ẹgbẹ mọ.
Igba akọkọ laarin ogun ọdun ni yii, ti Naijiria a de ipele ikẹrindinlogun ninu idije ife ẹyẹ agbayeSuper Falcons gòkè odò bọ́ sípele ìkẹrìndínlógún ní France.
Adájọ Abdul'Aziz Waziri tun dájọ pe ilé ẹjọ náà kò le gbọ ẹjọ ti ẹgbẹ́ òṣèlú Movement for the Restoration and Defence of Democracy (MRDD) pè.
 Ìkọ ́ ni nílé ẹ ̀ kọ ̣ ́ gíga yàtọ ̀ gédégédé sí ti ilé ẹ ̀ kọ ́ girama tàbí alákọ ̀ ọ ́ bẹ ̀ rẹ ̀ .
Gege bi O ti so, ipinle Gombe lo n pese egbon-owu ti o darajulo, sugbon itan ti yi pada bayii.
O ti kọ ọpọlọpọ arosọ, iwe akagba to fi mọ iwe itan kekeeke lede Yoruba.
Jẹ́ kí àwọn alufaa rẹ wọ ẹ̀wù òdodo,kí àwọn eniyan mímọ́ rẹ sì máa kọrin ayọ̀.
OLUWA sì dúró ní ẹnu ọ̀nà Àgọ́ Àjọ ninu ọ̀wọ̀n ìkùukùu, ó sì pe Aaroni ati Miriamu, àwọn mejeeji sì jáde siwaju.
 ohun ni alaga ile-ise igbimo abo orile-ede , akowe agba egbe awon osise ile korea , egbe oselu to unsejoba lati 1948 , ati alase gigajujo akogun awon eniyan korea , to je akogun ekerin to tobijulo lagbaye .
Ìbátan Elimeleki yìí dáhùn, ó ní, “Bí ọ̀rọ̀ bá rí bẹ́ẹ̀, n kò ní lè ra ilẹ̀ náà pada, nítorí kò ní jẹ́ kí àwọn ọmọ tèmi lè jogún mi bí ó ti yẹ.
Akọroyin naa ni Abu Abdullah Ibn Umar-Al-Barnawi ni wọn fi rọpo rẹ.
Ẹnikẹni ti a ba ri to jẹ ẹya Igbo, la o fi iya jẹ lai si aanu.
Wọ́n kọ sinu ìwé náà pé: “Ẹ̀yin eniyan Israẹli, ẹ pada sọ́dọ̀ OLUWA, Ọlọrun Abrahamu, Isaaki, ati Israẹli, kí ó lè pada sọ́dọ̀ ẹ̀yin tí ẹ kù tí ẹ sá àsálà, tí ọba Asiria kò pa.
Ki lo ti ṣẹlẹ tẹlẹ ni Jos?
4 Ògún 2020 Oríṣun àwòrán, others Kii ṣe pe o ṣa dede wu igbakeji gomina ipinlẹ Ondo, awọn eeyan ni wọn n gun un ni kẹṣẹ pe ko fi ẹgbẹ oṣelu naa silẹ.
"Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: 'Penis Fish"", ẹ̀ja tuntun tó rí bí ǹkan ọmọkùnrin lùwẹ̀ jáde lórí òkun Kò sí ọkùnrin tí yóò fún obìnrin tó halẹ̀ bíi tèmi lówó - Lizzy Anjorin Gómìnà Kwara kéde àgùnbánirọ̀ àtàwọn míì gẹ́gẹ́ bí kọmíṣọ́nnà tuntun Táyà ọkọ̀ agbépo tó fọ́ fa ìjàmbá ọ̀kọ̀ l'Ékò, èèyàn kan farapa Boris Johnson àti ẹgbẹ́ rẹ̀ wọlé ìbò, Trump àtàwọn ààrẹ míì kíi kú oríire ""Niṣe lo duro l'ẹgbẹ kanga naa, ko to o di wi pe o fi ẹsẹ kọ, to si ṣubu sinu kanga."
Lọdun 1846, ti aarun onigbameji tun bẹ silẹ ni Mecca, eeyan to le lẹgbẹrun un mẹẹdogun lo padanu ẹmi wọn.
Ṣaworo tí ó wà lọ́rùn ẹsẹ̀ wọn a sì máa dúnbí wọ́n tí ń gbésẹ̀ lọ́kọ̀ọ̀kan.
 bo se tọ ati bo se yẹ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ọọni ogunwusi bẹrẹ abẹwo si orilẹede Brazil Awọn akọni mejeeji yii gba awọn ọdọ Naijiria lati ji dide si iṣẹ ati iwa ọmọluwabi to yẹ ki a mọ ọdọ mọ.
Ese Bibeli ohun so pe, “Gbogbo iwe-mimo ti o ni isimi Olorun, ni o si ni ere fun eko, fun ibani-wi, itoni, fun ikoni ti o wa ninu ododo”.
O ni wọn bẹrẹ si ba gbogbo mọto to wa nibẹ jẹ, to fi mọ ọkọ meji ti iya oun ni, ti wọn dana sun.
Ó kọ́ àwọn ìlú olódi ní agbègbè Aṣidodu ati ní ibòmíràn ní ilẹ̀ àwọn ará Filistia.
"Wo awọn Aàrẹ nílẹ̀ Áfríkà to ti gba oyè ""Field Marshal"" rí Kò yẹ kí ìjọba máa ní àwọn mẹ̀kúnú lára lásìkò Coronavirus yìí- Rewane Ẹ wo bí ìsìnkú Adegbenro, Kọmíṣọ́nnà l‘Ondo ṣe lọ."
Ere itagbangba yii waye ni ojo Abameta ni Congress Hall, Transcorp Hilton, niluu Abuja.
Coronavirus: Arsenal padà sórí pápá, Premier League lè bẹ̀rẹ́ padà lóṣù kẹfa Coronavirus: Kíni àwọn àmì tuntun tó n fihàn?
Ìwádìí nípa ìtàn ìṣẹ ̀ dálẹ ̀ àwọn ìlú tí iṣẹ ́ yìí dé fi hàn gbangba pé mọ ̀ lẹ ́ bí ni ifẹ ̀ , ifẹ ̀ ẹ ́ tẹ ̀ dó pẹ ̀ lú Òkè-igbo , àti ifẹ ̀ wàrà .
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ondo missing baby: Òkú ọmọ tuntun di àwátì nílé ìgbókúpamọ́sí ìjọba nílùú Akurẹ 19 Èbibi 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 20 Èbibi 2019 Oríṣun àwòrán, Shutterstock Àkọlé àwòrán, Iya ọmọ ati ọmọ rẹ to dakẹ lasiko ibi ni wọn gbe wọ ile igbokupamọsi ileewosan nla Ondo state specialist Hospital nilu Akurẹ ki oku ọmọ tuntun naa to poora Ariwo eemọ ree, ẹ maa woo niran ni ọpọ awọn ero to de gbagede ileewosan nla Ondo state specialist Hospital nilu Akurẹ ni ọjọ abamẹta nibi ti okiki ti kan pe oku smọde jojolo kan ti wọn gbe si inu ile igbokupamọsi, ileewosan naa ti poora.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Igboho, Ajimobi, Makinde àti àwọn ọlọ́pàá ṣe bẹbẹ kí n tó rí ìbejì mi gbà padà O ni ìṣẹ̀lẹ̀ bí wọn ṣe jí àwọn ìbejì òun gbé tí jẹ kò yẹ òun gbé a ti ní ìṣòro pupọ lórílẹ̀ èdè Nàìjíríà, ju bí a ṣe ríi lọ, paapa nípa eto aabo.
Wọ́n fi ọ̀rọ̀ náà sọ́kàn, wọ́n ń bá ara wọn jiyàn nípa ìtumọ̀ jíjí dìde kúrò ninu òkú.
Ẹ rìn yí Sioni po; ẹ yí i ká;ẹ ka àwọn ilé ìṣọ́ rẹ̀;
Amọ, ko ye ẹnikẹni idi ti dokita naa fi jade lati sọ eyi, ati wipe ile isẹ aarẹ, White House ko tii fesi si ọrọ ti dokita naa sọ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù BBC Gov Debates: Àwọ́n olùdíje ìpínlẹ̀ Ogun ṣe tan láti jíròrò 8 Èrèlè 2019 Àkọlé àwòrán, ìpàdé ìfọ̀rọ̀wérọ̀ BBC Yorùbá Ka wi i bẹẹ ka ba a bẹẹ niyi ọmọluabi.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Premier League Top Scorer: Aubameyang, Mane àti Salah gba Golden boot 12 Èbibi 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 13 Èbibi 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Pierre-Emerick Aubameyang(Arsenal), Agbabọọlu ọmọ Senegal Sadio Mane(Liverpool) àti Mohmmed Salah (Liverpool) Ọmọ ilẹ̀ Afíríkà mẹ́ta ló gbà àmi ẹyẹ Golden boot ninu idije Premier League to kásẹ̀ nílẹ̀ lónìí,.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Ohùn gooro ló gbé mi dé ọ̀dọ̀ ààrẹ̀ Bush, Obama, Obasanjo, Goodluck, Buhari' Kilo fa awọn ilana tuntun ?
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Omotola Jalade ní Nàìjíríà dàbí ọ̀run àpáàdì lábẹ́ ìjọba Buhari Ọ̀rọ̀ǹpọ̀tọ̀niyùn, Aláàfin obìnrin àkọ́kọ́ rèé, tó ní nǹkan ọkùnrin Baṣọ̀run Gáà, tó yan ọba mẹ́rin, pa ọba mẹ́rin àmọ́ ọba karùn-ún ló pa á Idi ree ti abiyamọ yii ati ọkọ rẹ fi morile ile iwosan ijọba kan ni ilu Nairobi, lorilẹ-ede Kenya, nibi ti wọn ti gbọ pe ọmọ to ni nkan ọkunrin ati obinrin ni wọn bi, ti dokita si gba wọn niyanju lati wa se isẹ abẹ, ki ọmọ naa le di ọkunrin nitori nkan ọkunrin to wa lara ọmọ naa lagbara ju ti obinrin lọ.
Irrawaddy Náà sọ wípé òun kò ṣe àṣemáṣe ju jíjábọ̀ọ ìwọ̀yáàjà tí ó bẹ́ sílẹ̀ ní sàkání náà láti ìbẹ̀rẹ̀ ọdún-un 2019.
”Alhaji Mohammed so pe ijọba orile ede Naijiria ti kede ifilọlẹ gbigbokun ti iroyin eke, ni eyi lati tun jẹ ki awọn omo orile ede Naijiria mo nipa ewu ti o wa nibe, o so pe”ewu buruku lo wa ninu iroyin eke, ki i se nipa ti ijọba tiwa-n-tiwa nikan , o tun ni i se pelu alaafia ati eto aabo orile ede yii.
Oríṣun àwòrán, Osun Osogbo Festival O ni eyi yoo seranwọ fun awọn asaaju awujọ, asaaju ẹgbẹ oselu, awọn ọmọ Naijiria loke okun, awọn onileese nlanla atawọn olokooowo aladani ti ko lee wa sibi ajọdun Ọsun Osogbo lọdun yii, ni anfaani lati kopa latipasẹ awọn ẹrọ igbalode naa eyi ti yoo dena ẹnawo ati fifi akoko sofo.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù #SagamuOnFire: Àwọn ẹbí Tiamiyu bèrè fún ìwádìí tòótó lórí ikú ọmọ wọn 25 Èrèlè 2020 Oríṣun àwòrán, Twitter Àkọlé àwòrán, Gomina ipinlẹ Ogun, Dapo Abiodun ṣe àbẹwò ìbánikẹ́dùn sí àwọn òbí Tiamiyu Kazeem tí àwọn ọlọ́pàá pa.
Bí ó ti ń lọ lọ́nà, tí ó súnmọ́ Damasku, iná kan mọ́lẹ̀ yí i ká lójijì; 
Àwọn marun-un tí wọ́n lọ ṣe amí ilẹ̀ náà bá wọlé, wọ́n gbé ère dídà, wọn mú ẹ̀wù efodu, wọ́n sì kó àwọn ère kéékèèké ati ère fínfín.
Ó tún jẹ́ akọrin-ṣeré àti àdánìkànkọrin tí ó gbajúmọ̀, ó sì máa ń kọ orin àdánìkànkọ nípa àṣà Roma tí ó jẹ́ orírun rẹ̀.
Oríṣun àwòrán, @Equityoyo Mutiat ni o ti ṣu oun lati maa reti ọjọ ti awọn yoo le kọ idanwo.
tawọn si n duro de abọ nipa isẹlẹ ọhun lati ọdọ awọn kọmisana fun ajọ eleto idibo lawọn ipinlẹ naa.
" Akeugbagold fikun pe afurasi naa n fo fayọ lasiko ti wọn tu awọn ọmọ naa silẹ ni, ti ko si si ẹni to fura si pe ejo rẹ lọwọ ninu iṣẹlẹ naa.
Bakan naa ni Erica to wa lara awọn olukopa ogun to bawọn bẹrẹ idije naa ti dero ile lẹyin ti wọn le kuro lọjọ Kẹfa oṣu Kẹsan, 2020.
Ọ̀yẹ̀ yóò là fún abẹ́rẹ́ ìfètòsọ́mọbíbí fáwọn ọkùnrin láìpẹ́ Loṣooṣu ni Marie Stopes maa n ko rọba idaabobo bii miliọnu kan abọ si meji wọ orilẹ-ede Uganda.
Njẹ abadofin naa ti di ofin?
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Kayefi BBC Yorùba: Bàbá ọmọ, Mọ́ṣúárì, Ọlọ́pàá kẹ́jọ́ rò nípa òkú ọmọ tó pòórá Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Titi ti o fi ku, oun ni alaga igbimọ ile to n ri si ọrọ awọn oṣiṣẹ ati eto igbaniṣiṣẹ.
Olóòlù kò ni kọ́ja agboolé rẹ̀ fún ọdún eégún ìlú Ibadan tọdún yìí Trump nílò láti káwọ́ pọ̀nyìn jẹ́jọ́ nítori ọgagun Soleimani tí Amẹ́ríkà pa-Iran Ìgbòkègbodò ọkọ̀ akérò àti ọkọ̀ òfurufú bẹ̀rẹ̀ padà jákèjádò Nàìjíríà!
Bí ó bá jẹ́ pé a tẹ́ pẹpẹ tí yóo mú wa kọ OLUWA sílẹ̀, tabi pé a tẹ́ pẹpẹ fún ẹbọ sísun, ati ẹbọ ohun jíjẹ, ati ẹbọ alaafia, kí OLUWA gbẹ̀san lára wa.
olopaa Ibrahim Idris, sọ pe ki awon olopaa kuro ni ona oju popo .
Ohun tí OLUWA sọ nípa àwọn ará Amoni nìyí: Ó ní,“Ṣé Israẹli kò lọ́mọ ni?
Nínú wọn ni Tonye Cole, Ade Shounbi, Ade Odunsi àti Omamofe Boye àti bẹ́ẹ̀-bẹ́ẹ̀ lọ.
Fake money: Àgbà òṣèré sinimá ní ìfẹ́ owó, àti ṣekárími ló ń dá wàhálà sílẹ̀ láwùjọ
02 ti o pajude si N15.
Wọn fẹsun kan Juliari Batubara lẹtin ti awọn ọlọpaa ṣawari orisiriṣi apo ti owo ọhun wa ni ikawọ rẹ.
Patrick Areghan to jẹ oludari ajọ naa ni Naijiria sọ ninu atẹjade kan pe igbesẹ naa waye nitori pe awọn fura pe awọn akẹkọọ náà ṣe mago-mago lasiko idanwo.
Aare Buhari tun so pe bi awon
Àwọn Ọmọ Israẹli Ṣẹgun Sihoni Ọba.
 fún iṣẹ ́ ribiribi wọn fún ìlú ni a ṣe sọ ibùdó náà lórúkọ wọn - ajẹ ̀ bú-olóde .
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Nigeria 2019: INEC ìpínlẹ̀ Rivers ṣetán láti kéde èsì ìdìbò Rivers 2 Ìgbé 2019 Oríṣun àwòrán, @pius Àkọlé àwòrán, Wamu wamu ni awọn agbofinro duro nibudo ikede idibo Rivers Ilana ofin ti INEC la kalẹ fun kika ibo naa jẹ eyi ti wọn kọkọ fara balẹ ṣalaye ṣaaju kika ibo.
Wọn le to ọgọta si ọgọrun, eyi to ma n mu ko nira lati da ẹnikẹni ninu wọn mọ.
O ni awọn adigunjale naa fẹsẹ fẹ, ti wọn si fi ọkọ ti wọn gbe wa silẹ nigba tawọn ọlọpaa de ibẹ, ti wọn si kọju ija kọ wọn.
Wò ó, bí iranṣẹkunrin ti máa ń wo ojú oluwa rẹ̀,tí iranṣẹbinrin sì máa ń wo ojú oluwa rẹ̀,bẹ́ẹ̀ ni à ń wo ojú OLUWA, Ọlọrun wa,títí tí yóo fi ṣàánú wa.
Oríṣun àwòrán, EPA Àkọlé àwòrán, Ooru amuju, to ti wọ Sẹlisiọ̀si marundinlaadọta, lo mu ki ọkunrin ara Egypty yii ati ẹsin rẹ bẹ sinu odo nla kan, lati gba itura ni ilu Cairo lọjọ Ẹti Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ibọn n dun lakọ lakọ lorilẹede Libya, nigba ti awọn ọmọ ogun to n satilẹyin fun ijọba ti gbogbo agbaye gbaruku ti, n waako pẹlu awọn ọmọ ogun to n se atilẹyin fun Khalifa Haftar ni ilu Tripoli l‘Ọjọbọ Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Bi o tilẹ jẹ pe ogun n l lọwọ lawọn agbegbe kan lorilẹ ede Libya, amọ eni agbegbe miran nilu Tripoli, ogun naa ko di awọn ọdọkunrin yii lọwọ lati se idije bọọlu alapẹrẹ lọjọ Aje Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Awọn baalu yii lo n fo kaakiri ori papa Loftus Versfeld lasiko ti wọn n se ibura fun aarẹ Cyril Ramaphosa ti orilẹede South Africa lọjọ Abamẹta Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Gbogbo ireti awọn ọmọ ẹgbẹ to jẹ isẹda kannaa, ti wọn n fẹ ara wọn lorilẹede Kenya lo ja si pabo, nigbati ile ẹjọ to ga julọ faake kọri lati wọgile awọn ofin to de ki akọ ati akọ tabi abo ati abo maa fẹ ara wọn lọjọ Ẹti Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Obinrin kan ree lọjọ Satide nilu Dakar, lorilẹede Senegal, to ni ki wọn fi ọda se aworan egbo si oun lori, lati tako hihu iwa ipa sawọn obinrin lorilẹede naa.
Bakan naa lo ni France to ń gba alèjò ayẹyẹ náà wà ni ipò kaàrún tọ jẹ ipele kéta si aṣekágbá.
Ajisebutu so wipe iwadi nlọ lọwọ-lọwọ nipa iku ọga ọlọpa naa.
Àwọn ọmọ Nàìjíríà 320 yóò padà wálé láti South Africa lọ́jọ́rú - Adama Ìdí rè é tí mo ṣe lọ sí South Africa fún àpérò ọrọ̀ ajé - Ezekwesili ṣàlàyé Àwọn ṣẹ̀ṣẹ̀dé South Africa yóò gba ìrànwọ́ owóyàá àti káádì ìpè - Dabiri Ibeere nla ni pe igba melo ni ikọlu sawọn ajeji ti waye ni South Africa?
Lodun 1904 ni ekun yii dojuko iru ogbele yii seyin.
Ìrànwọ́ ikú fàwọn tó bá wà lórí àkéte àìsan tó leè já sí ikú ti di òfin tuntun tí wọ́n fẹ́ fọwọ́ sí!
Ní àkókò Hẹrọdu, ọba Judia, alufaa kan wà tí ń jẹ́ Sakaraya, ní ìdílé Abiya.
“Ẹ kò gbọdọ̀ jalè, ẹ kò gbọdọ̀ fi ìwà ẹ̀tàn bá ara yín lò; ẹ kò sì gbọdọ̀ parọ́ fún ara yín.
 nigba ti won ba de si orile ede Russia.
Iroyin so pe, ikolu orisirisi ohun sekupa opolopo awon olugbe agbegbe ti ikolu naa ti waye, leyi ti o si sokunfa fifi ilu naa sile.
Ogbeni Hassan Bello ti o je akowe agba igbimo ti o n ri si awon eru oju-omi so pe, gege bi ajo asamoju to, ajo ohun ti setan bayii lati se agbekale ilana kan ti yoo setileyin fun eto kaara-kata ni awon enu ibode awon orile-ede nile Africa.
Igbakeji alukoro fun ile iṣẹ ọlọpaa Naijiria, Ọgbẹni Adeniran Aremu to ba BBC Yoruba sọrọ ṣalaye pe ile iṣẹ ọlọpaa yoo gbe igbesẹ to ba yẹ lẹyin to ba pari iṣẹ iwadi lori fọnran ọhun.
Gbogbo awọn ohun elo amuletutu (Air conditioning system) lo gbọdọ wa ni pipa nigba gbogbo.
Wo ohun tí yóò ṣẹlẹ̀ ní ìpàdé àwọn èèkàn Yorùbá láti mú kẹ́ẹ dìbò fún Tinubu ní 2023 Kí làwọn nǹkan tó lè rán ọkùnrin sí ọ̀run alákeji lásìkò ìbálòpọ̀ pẹ̀lú obìnrin?
Ni ti CNN, lai Mohammed ṣalaye pe iwadii ofege ni wọn ṣe, eyii to yẹ ko jẹ ohun itiju fun wọn gẹgẹ bii ileeṣẹ iroyin to kari aye.
Ọjọ diẹ ṣaaju ọjọ naa ni Ojukwu sa kuro ni ilu; o wa baalu lọ si orilẹ-ede Cote d'Ivoire, to si fi igbakeji rẹ, Philip Effiong, silẹ lati mojuto jijọwọ ara wọn fun ijọba Naijiria.
Ẹni to bori: South Africa Morocco vs Tunisia.
Saudi fẹ́ gbẹ̀mí 23 ọmọ Nàìjíríà tó gbé òògùn olóró Ìkọlù ibùdó epo rọ̀bì Saudi Arabia yóò kóbá jíjẹ-mímu àwọn èèyàn rẹ̀ - Buhari Ìjọ̀ba Saudi ti tú Zainab tí wọ́n fẹ̀sùn òògùn olóró kàn sílẹ̀ Ìjọba Borno bẹ àwọn ọgbọ̀n Alfa Saudi lọ́wẹ̀ láti rẹ́yìn Boko Haram Awọn alaṣẹ naa mẹnuba awọn koko wọnyii pe: Iṣẹlẹ kan ṣẹlẹ lọdun 2015 nigba ti ọkunrin kan ṣaa deede n pariwo le aafa Sheik Ali Al Hadaify lori lasiko to n pe irun lọwọ ninu mọṣalaṣi nla naa.
Ninu atẹjade kan to fi sita lori Twitter lọjọ Aiku, Onyeama sọ pe awọn n beere fun igbesẹ kiakia lati ọdọ ijọba orilẹ-ede Ghana, lati wa awọn to ṣe ikọlu naa sita, ki wọn o si tun pese aabo fun dukia ati ẹmi awọn ọmọ Naijiria to wa ni Ghana."
Adanna ni irufẹ awọn eso yii ni ohun aṣara loore kan ti wọn n pe ni ''fibre'' ninu.
 Awon mejeeji pade latigba odo won wa ki o to fiṣe silẹ nitori ololufẹ ẹ.
Ẹjọ naa kan awọn oṣiṣẹ ajọ ọtẹlẹmuyẹ M16 ati FBI nilẹ Amẹrika, bẹẹ naa ni o kan aarẹ ilẹ Naijiria kan tẹlẹ, pẹlu awọn oṣiṣẹ kan ile iṣẹ epo mejeeji.
Minisita fun ọrọ to je ofurufu, Hadi Sirika lo sọrọ yii nigba to n ba  awọn  akọroyin sọrọ  nibi ipate baalu ofurufu to waye ni Farnborough to wa ni UK.
 a gbani nímọ ̀ ràn láti gba àfikún ìwọ ̀ n àjẹsára náà láàárín ọdún kọ ̀ ọ ̀ kan sí méje-méje , bí a bá wo bí àrùn náà ti wọ ́ pọ ̀ tó ní agbègbè náà .
Ṣugbọn ó la ààrin wọn kọjá, ó bá tirẹ̀ lọ.
Abiola Ajimobi: Gómìnà kòṣẹlẹ̀rí àkọ́kọ́ tó fi ọba 21 jẹ lọ́jọ́ kan ṣoṣo nílẹ̀ Ibadan Oríṣun àwòrán, Instagram/ abiola ajimobi Abiola Ajimobi, Gómìnà tí ọ̀rọ̀ kìí kú mọ lára, à fi kó fèsì Iku pa Abírí, Abírí ku, iku pa Abìrì, Abìrì rọrun, iku pa akọ̀kọ́, omi akọ̀kọ́ danu, ko si ẹni ti ko ni ku, ko si ẹni ti oko baba rẹ ko ni di igboro.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Bẹẹ si ni gbogbo ijiroro to waye lọjọ Aje lati yanju aawọ naa lo ja si pabo, ti wọn ko si fẹnu ọrọ jona lori awọn koko ọrọ kan ti orilẹ-ede Egypt ati Sudan n kọminu le lori.
Bawọ lawọn oludije yi ṣe n rọwọ mu si jakejado Amẹrika?
 pinckney wà nínú wọn ) nígbà tí wọ ́ n únṣe ìsìn àdúrà nínú Ṣọ ́ ọ ̀ ṣì emanuel african methodist episcopal ni ilu charleston , south carolina , ni ìrọ ̀ lẹ ́ ọjọ ́ 17 oṣù kẹrin , ọdún 2015 .
Ohun tí n óo fi mọ̀ pé olóòótọ́ ni yín nìyí: mo fi orúkọ Farao búra, ẹ kò ní jáde níhìn-ín àfi bí ẹ bá mú àbíkẹ́yìn baba yín wá.
Ninu ibugbamu afefe gaasi naa ti o waye lojo Abameta(Saturday), eniyan kan padanu emi re ti ile itaja marundinlogun si jona rau-rau.
Torinaa bi o ṣe padanu eeyan pups layika rẹ fihan pe pẹlu gbogbo agbara to ni ninu oṣelu, oun naa ti ni ifọwọkan ajalu to kan awọn eeyan laye oun naa ri.
aare odun 2019, o ni oun yoo nifẹẹ lati tubọ maa se isẹ papọ pelu adari orile
Sugbọn esi to fun wọn ni pe eeyan ẹlẹ́ran ara ni oun.
''Lati ilẹ ni baba mi ti sọ fun mi pe n ko ni lọ si ile iwe nitori iṣẹ Ifa akọsẹkaye mi sọ pe mo gbọdọ ṣe.
Mo mọ ẹni tí o jẹ́.
Mo fun yín ní ilẹ̀ tí ẹ kò ṣe làálàá fún, ati àwọn ìlú ńláńlá, tí ẹ kò tẹ̀ dó, ẹ sì ń gbé ibẹ̀.
”Dakingari wa ro awon eniyan ni agbegbe naa lati maa fi to awon eso onibode leti ti bi won ba ti ko firi awon onifayawo.
Ati pe oun n duro de abajade iwadii ijọba Naijiria lori ẹsun ifiyajẹni ti wọn fi kan awọn ọlọpaa.
Ekeji ṣú aya rẹ̀ lópó, ṣugbọn òun náà kú láì ní ọmọ.
Orangun to jẹ alaga igbimọ to n pẹẹtu si aawọ laarin Oluwo ati awọn ọba mẹjọ to wa ni ikawọ rẹ sọ wi pe awọn to mọ bi ọrọ naa ṣe ṣẹlẹ n bẹru lati sọrọ sita.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Akomolede ati Aṣa: Mọ̀ síi nípa ìró afárànma àti agbárànmọ́ fáwẹ́ẹ̀lì Yorùbá Bi o tilẹ jẹ pe o fa ẹtanu rẹ laarin awọn eeyan kan; sibẹ oun ri i gẹgẹ bi igbesẹ to tọ gẹgẹ bi oogun to yẹ ni lilo to dabi ọna abayọ lati wo wahala igba naa.
Wọ́n ti di ẹrù wúwo fún mi,n kò lè gbé e mọ́, ó sú mi.
Ni bayii awọn iranṣẹ Ọlọrun pẹlu ti da si ọrọ naa pẹlu ipe si aarẹ Buhari lati wọgile eto ọhun patapata.
Ní ìparí, àwọn ẹ̀yà tí wọ́n wà lábẹ́ ọ̀págun Dani ṣí, wọ́n tò ní ìsọ̀rí-ìsọ̀rí.
Oríṣun àwòrán, Instagram/ abiola ajimobi Ṣé lóòtọ́ ni òjòjò dá Abiola Ajimobi wólẹ̀?
Coronavirus: Nítorí àrùn Coronavirus ìjọba àpapọ̀ ní káwọn arìnrìnàjò láti orílẹ̀èdè Amẹ́ríkà, Gẹ̀ẹ́sì, Faransé àtorilẹ̀èdè mọ́kànlá míràn o gbélé wọn Gẹgẹ bii ara eto lati tete wawọ ọwọja arun Coronavirus wọlẹ, ijọba orilẹede Naijiria ti gbẹsẹle irinajo lati awọn orilẹede Mẹtala kan wọ orilẹede Naijiria.
Iroyin ni awọn ọmọ naa ti di awati lati Ọjọbọ, oṣẹ to kọja ti wọn ko si tii ri wọn titi di asiko ti a n ko iroyin yii jọ.
Ṣé èmi, ati ìyá rẹ, ati àwọn arakunrin rẹ yóo wá foríbalẹ̀ fún ọ ni?
Oyo to jẹ ila Gusu orile ede Naijiria.
Pààlà yípo òkè náà fún wọn, kí o sì kìlọ̀ fún wọn pé, kí wọ́n ṣọ́ra, kí wọ́n má ṣe gun òkè yìí, tabi fi ọwọ́ kan ẹsẹ̀ òkè náà.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ House on water: Ǹjẹ́ ìwọ lè gbé ilé tó wà lórí omi?
Ogoji ọjọ́ ni èṣù fi dán an wò.
Dokita Stella Immanuel ninu fọnran fidio yii darukọ oogun hydroxychloroquine, zinc ati Zythromax gẹgẹ bi awọn oogun ti ohun ti fi tọju alaisan Covid-19 to le ni ọọdunrun.
Àwọn ìlú ńláńlá ati ìlú kéékèèké tí ó wà ninu ilẹ̀ yìí jẹ́ ìpín ẹ̀yà Gadi gẹ́gẹ́ bí iye ìdílé wọn.
Nígbà tí à ń wo Kipru lókèèrè, a gba ẹ̀gbẹ́ ọ̀tún ibẹ̀ kọjá, a bá ń bá ọkọ̀ lọ sí ilẹ̀ Siria.
Lẹ́yìn tí Jesu ti parí gbogbo àwọn òwe wọnyi, ó kúrò níbẹ̀.
Àwọn ará Edomu bá ọ ṣòwò nítorí ọpọlọpọ ọjà tí ò ń tà.
E yé ṣíra yín s'íhòhò nínú fíìmù, àṣà burúkú ni- Efusetan kìlọ̀ fáwọn òṣèré Ẹ wo márùn ún lára àwọn tí ilé ẹjọ́ ti yọ kúrò nípò lẹ́yìn ìdìbò ọdún 2019 Wo ọ̀nà láti gbógun ti àìsàn Ibà lásìkò yìí Ilééṣẹ́ Facebook leè mọ ìgbà tí àwọn tó wà lójú òpó wọn ń ní ìbálòpọ̀ Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí 2 sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 2:23 Fídíò, Water Generator: Ó leè ṣiṣẹ fún wákàtí mẹfà, kó tó sinmi, Duration 2,2310 Òkùdu 2020 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
Oríṣun àwòrán, Facebook/Pius Adesanmi Àkọlé àwòrán, Iku mu Pius Adesanmi lọ O tun tẹsiwaju nigba to gboye miran ninu ẹkọ ede Faranse ni fasiti ilu Ibadan.
Buhari, o kò ṣe bẹbẹ kankan láì jẹ́ pé o gba Leah Sharibu náà sílẹ̀ Wo àwọn nǹkan to tún nílò NIN fún yàtọ̀ fún ìforúkọsílẹ̀ síìmù Ilé aṣòfin àgbà yọ gómìnà nípò, ẹni tó fi owó ìlú rán ọmọ lọ sí Amẹ́ríkà Amẹ́ríkà yarí pé àwọn agbégbọn tó jí akẹ́kọ̀ọ́ 344 gbọ́dọ̀ fojú winá òfin Nigba to n fidi iroyin ayọ naa mulẹ fun BBC Yoruba, ọkọ iya Kaosara oloju buluu, Abdulwasiu ni lootọ ni oriire naa wọle ti idile oun.
Barca na Manchester United pẹu ami ayo kan si odo ni ọjọru.
“Bee si ni mo fe dupe pupo lowo awon igbimo lati ile-ise aladani, awon olokoowo ati awon toro kan miiran ti won gba lati mu atunse ohun wa si imuse ni kete ti ijoba apapo ba bonte lu iwe abadofin naa.
com Arakunrin ẹni ọdun mẹrindinlọgbọn kan ni wọn fi ẹsun kan pe o pa baba rẹ, alagba Christopher Ogum ni ilu Umuomaku nijọba ibilẹ Orumba South nipinlẹ Anambra Ṣọfẹli ikọle ni wọn ni o fi pa baba rẹ ti wọn ni ọjọ́ ori rẹ jẹ aadọrin ọdun ti o si sare sin in ni oloku oru sinu saare kan ti ko gbẹ jin pupọ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Sogidi Lake: Kòṣẹja-kòṣèèyàn lá bá nínú adágún odò náà -Ojedele Rògbòdìyàn yìí náà tún wa lára ohun tó mú kí àwọn ológun gba ìjọba Nàìjíríà lọ́dún 1966, tí wọn sì gba ẹ̀mí oloye Samuel Ladoke Akintola, bẹ́ẹ̀ si ni Oloye Obafemi Awolowo wa ni ọgbà ẹ̀wọ̀n lásìkò náà.
Obinrin tí kò bá tíì mọ ọkunrin rí ni ó gbọdọ̀ fẹ́ níyàwó.
Kì í ṣe pé a kò ní ẹ̀tọ́ láti jẹun lọ́dọ̀ yín; ṣugbọn a kò ṣe bẹ́ẹ̀ kí á lè fi ara wa ṣe àpẹẹrẹ fun yín, kí ẹ lè fara wé wa.
Latari eyi, wọn ti kọrin ni Athens, Sweden, UK, Germany, Spain, Italy, Switzerland atawọn orilẹede mii kaakiri agbaye.
Àkókò náà dé wàyí, tí ẹn8i méjì pa ara pọ lójú gbogbo ayé tí wọ́n di ọkan ṣoṣo.
Nítorí pé nígbà tí ẹ rán mi sí OLUWA Ọlọrun yín pé kí n gbadura fun yín, gbogbo ohun tí OLUWA Ọlọrun yín bá wí ni kí n sọ fun yín, ẹ ní ẹ óo sì ṣe é.
"Iṣẹ́ àkànṣe tí kò parí ni Buhari ń bọ̀ wá ṣí l‘Eko - Aráàlú figbe ta ""Obìnrin mẹ́jọ nínú mẹ́wàá tó n lo wíìgì ló pá lórí"" Pẹ̀lú abẹ̀rẹ̀ àjẹsára yìí, ẹ̀fọn kankan kò lè mú àìsàn ibà wá O rọ awọn ile isẹ imọ ẹrọ ibanisọrọ ati eyi to n se 'Sim Card lati fi aabo ilu saaju ohunkohun, ki wọn ba le ri wi pe `aabo awọn ara ilu jọ wọn loju, ki itẹsiwaju le ba orilẹede Naijiria."
Bi atupalẹ́ eto isuna naa se lọ ree ati ipin owo ti ẹka kọọkan ko ninu aba isuna ọhun.
Gomina naa ni: ni ipade naa jẹ akitiyan ijọba lati le gba ẹ̀mí awọn ọmọ naa la.
Àwọn kinniun ti bú mọ́ ọn,wọ́n bú ramúramù.
iwadii lekunun rere lori isele buruku naa nigba ti awon to se isẹ lati du ẹmi
Mò ń sọ fun yín dájúdájú, níbikíbi tí a bá ń waasu ìyìn rere ní gbogbo ayé, a óo máa sọ nǹkan tí obinrin yìí ṣe ní ìrántí rẹ̀.
Nígbà tí wọ́n pada dé ibùdó, àwọn àgbààgbà Israẹli bèèrè pé, “Kí ló dé tí OLUWA fi jẹ́ kí àwọn ará Filistia ṣẹgun wa lónìí?
Eyi mu ki ero pọ nita ile rẹ ti wọn si n wọ loju titi.
ati pé, ‘Kí á fẹ́ràn ẹnìkejì wa bí a ti fẹ́ràn ara wa’ tayọ gbogbo ẹbọ sísun ati ẹbọ yòókù.
Nígbà tí mo rí àwọn àlejò wọ̀nyí ti pọ̀ tó, tí mo sì wo owó ti Baba-onírùngbọ̀n-yẹ́úkẹ́ ti ń ná fún mi láti ìgbà tí mo ti dé, ẹnu yà mí gidigidi.
Eekan lára àwọn to doloogbe lọdun to n kogba wọle yii ni Ọbabinrin Soul to jẹ Ọlọrun ni pe lọmọ ọdun mẹrindinlọgọrin loṣu kẹjọ ọdun.
Obinrin naa ta ọmọ rẹ lẹyin to ti ni oyun osu mẹfa ninu.
Amofin Ajulọ la gbọ pe o fi aworan kaadi idanimọ wọn si ori ayelujara lẹyin to ni oun ṣe kongẹ wọn ni agbegbe Akoko ni ipinlẹ Ondo.
Awọn ẹka ti wọn fi ṣe gbèdége ayẹwo ni ẹka ọlọpàá, ẹka ètò iná ọba, èto idajọ àti ètò ẹkọ́ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Kidnapped Girl: Iyá Ikimot ní lẹ́yìn ọ̀pọ̀ ìdààmú àti owó láti wá ọmọ náà, òun sọ ìrètí nù Àkọlé àwòrán, SERAP: Ìwàdìí ní ẹ̀ka iṣẹ́ ọlọ́pàá àti ìdájọ́ ló kúndùń ìwà àjẹbánu jùlọ Ibèèrè náà gẹ́gẹ́ bi ó ṣe sọ ni pé, Ẹ̀ka wó ni àwọn ènìyàn léro pé wọn le gbà rìbá ni ọwọ wọn?
"Lootọ ọdọọdun ni awọn musulumi jakejado agbaye máa n peju sí orilẹede Saudi láti kópa nínú ìjọsìn fun eto Hajj sugbọn iye ọjọ ti wọn fi n ṣe eto Hajj yii gan kò fẹ jù ọjọ márùn ùn lọ, Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ọdún Orò ń sọ àwa obìnrin sí ìgbèkùn, ẹ̀wọ̀n, tó sì ń tẹ ẹ̀tọ́ wa lójú - Àwọn obìnrin Ikorodu faraya Èèyàn mẹ́rìnlá tí ọpọlọ wọ́n pé la buwọ́lù bíi kọmísọ́nà l‘Oyo - Olórí ilé aṣòfin kan sáárá Èmi àti Saheed kìí ṣe ọmọdé, a ti jọ ṣe Sinimá papọ̀, èyí túmọ̀ sí pé ìjà ti parí - Fathia Balogun ""Mo fẹ́ pa ara mi torí ojú àbùkù tí wọn ń fi wò mí pé mo fi iṣẹ́ abẹ bímọ"" Fulani kò leè dúró, táa bá lo ohun ta jogún lọ́dọ̀ àwọn bàbá wa - Sunday Igboho Ọna làti ṣètò fawon obitibiti èèyàn tó máa n kópa nínú ìjọsìn yíi, ni àwọn aláṣẹ ilẹ Saudi se fi ọjọ pupọ sílẹ saaju àti lẹyìn eto Hajj, kí gbogbo ètò bàa lè lọ ní irọwọrọsẹ."
Ṣugbọn nkan ti o si n jẹ kayeefi si awọn ọmọ Naijiria ni pe, Aarẹ Buhari, tabi ijọba apapọ ko ti i sọ nkankan lori ọrọ Magu.
Ọmọbinrin náà jẹ́ ọkan lára àwọn akópa nínú idije oge Fasiti Ghana.
O fikun ọrọ pe agbẹjọro sọ fun Fatoyinbo wi pe ko maa yọju si igbimọ naa nitori aarẹ ajọ PFN, Bisọpu Felix Omobude ti sọ tẹlẹ pe oun o mọ Fatoyinbo ri.
Ohun gbogbo tí a gbọ́ pé o ṣe ní Kapanaumu, ṣe wọ́n níhìn-ín, ní ìlú baba rẹ.
Ìrẹ̀sì kò gbọdọ̀ wọlé níbáyìí ta ṣí ẹnu bodè padà - Ìjọba àpapọ̀ Jide Kosoko forin sẹ́nu pé òun ni igi lẹ́yìn ọgbà Mr Latin lórí ipò ààrẹ TAMPAN tó wà Ó pé ọdún mẹ́wàá tí Barrister kú; wo ǹkan tó yẹ láti mọ̀ nípa rẹ̀ gẹ́gẹ́ bíi olórin, tẹ̀wé-tẹ̀wé, akọ̀wé àti sọ́jà Àìmọ̀kan ló mú mi hu ìwà tí mo hù kọjá sẹ́yìn, Jonathan dárí jì mí - Dino Melaye Njẹ anfaani to wa ninu bi ijọba ṣe ṣi bọda pada?
    Nígbà tí o ṣe a kò gbọ́ ọwọ́ odó mọ́, kò sì ju ìṣẹjú kan tí ọwọ́ odó dákẹ́ tí ariwo ta ni ẹ̀yìnkùnlé pé ọba ń jà tí a bẹ̀rẹ̀ síí gbọ́ gìrìgìrì ẹsẹ̀.
Mo bá wá sí Jerusalẹmu mo sì wà níbẹ̀ fún ọjọ́ mẹta.
Ní ọ̀pọ̀ ìgbà, ọ̀pọ̀ ló n kọ ibi ara si fífi ọṣẹ fọ̀wọ́ lai mọ pe lẹyin ọṣẹ náà, o ṣeeṣe ki kòkòrò àifojuri náà tún pada si ọwọ ẹni ti ìmọtoto tó yẹ ko ba si fun fóònù.
O ye mi-ko ye ẹ lori ọrọ yi mu ki awọn kan máa sọ pe ẹka alaṣẹ n dunkooko mọ ẹka idajọ ti ọrọ naa si ti mu alaye orisirisi wa lodo awọn amofin.
Ṣé o ti kọ̀ wá sílẹ̀ patapata ni?
Awọn iroyin ti a n gbọ latọdọ awọn oniroyin to wa labẹle lawọn to wa nibi eto isinku ni wi pe wọn ti sin oku rẹ ni bonkẹlẹ lai jẹ ki awọn oniroyin wọle.
Gbajugbaja osere, Yemi Elesho ti sọ iriri reki o to di ilumọọka ni ẹka amuludun
Onímọ míràn Chukwuma Osakwe to jẹ́ ọjọgbọ̀n nínú ìmọ itan àwọn ológun sàlàyé pé àwọn orílẹ̀-èdè ti wọ́n ti jé ki ìjà ẹsìn pin wọ́n tẹ́lẹ̀ yóò túbọ kojú ìṣòrò ìjà ẹ̀sìn àti wàhálà ètò ààbò.
OLUWA, ṣé o kò ní ṣe nǹkankan sí ọ̀rọ̀ yìí ni?
Abameta(Saturday) fun ifesewonse olorejore ti o waye lati fi buyi fun Gomina Akinwunmi Ambode ti yoo fi ori aleefa
Ẹ̀rọ CCTV tú àsírí ọkùnrin ẹni ọgbọ̀n ọdún tó fi ipá bá ọmọ ọdún mọ́kànlá lòpọ̀ Ó ń bọ̀ lọ́nà!
"Ó ní ""Aarẹ, mo dúpẹ́ pé mo ni oore ọ̀fẹ́ láti sin ilẹ̀ baba mi gẹ́gẹ́ bi ipò ti mo dìmú."
'Àṣírí ọkọ mi tú sími lọ́wọ́, ṣé mo le dáríjì í?
 Aini isokan lataari ero ati oro alufansa ti awon kan n so n fa Naijiria seyin ni.
"Àkọlé àwòrán, Ibi ti nkan de duro lori aarun polia ni ilẹ Africa ""Awọn obi mi sọ fun mi pe lasiko naa, awọn ileewosan gan-an ko mọ nipa itọju rẹ, de bi i pe ti wọn ba fun ọmọ ni abẹrẹ, o npa wọn ni."
"Nigba to n sọ idi ti wọn ṣe n pe ni Oluomo, MC ni ""Oju popo ni mo gbe dagba, a ko ara wa jọ lati dẹkun iwa ole jija ni Oshodi, ni ọba mẹrinla ṣe fi mi jẹ oye Oluomo ni Isọlọ, orúkọ yii si lo ro mi, ti mo fi de ibi giga."
Gomina Makinde sọ ọrọ yii lasiko to ṣe abẹwo silu Saki pẹlu afikun pe awọn agbesunmọmi naa, to fi mọ awọn janduku agbebọn lati orilẹ-ede Mali ati awọn orilẹ-ede mii ni Iwọ Oorun Afirika, n wọle lati ibode to wa ni Saki.
Amọṣa, alukoro ileewe fasiti UNIOSUN, Ọgbẹni Adeyẹmi pẹlu ṣalaye fun BBC pe awọn alaṣẹ ileewe naa ti n gbe igbesẹ lori rẹ.
Nítorí wípé kò sí iṣẹ́ fún wọn, àwọn abódiakọ-akọ́diabo ènìyàn  kò ní ṣíṣe ju kí wọn ó ṣe òwò nọ̀bì láti rí oúnjẹ òòjọ́.
Eko: Ọjọ Iṣẹgun ni ipinlẹ Eko sọ abadofin ikọ amọtẹkun di ofin gẹgẹ bi ọkan lara ikọ to n boju eto aabo ni ipinlẹ Eko, labẹ ofin Lagos State Neighborhood Safety Corps Agency Law, 2019.
Mo láyọ̀ nígbà tí mo rí ètò tí ó wà láàrin yín ati bí igbagbọ yín ti dúró ninu Kristi.
Iye awon oludibo to yẹge lati dibo jẹ-                    604,240 Ademola Adepoju.
Ǹjẹ́ nisinsinyii, OLUWA, mo bẹ̀ ọ́, gba ẹ̀mí mi, nítorí pé, ó sàn fún mi láti kú ju pé kí n wà láàyè lọ.
Àwọn ologun dóòlà akẹ́kọ̀ọ́ mẹ́fà lọ́wọ́ àwọn ajínigbé ní Kaduna Dino Melaye fìdí rẹmi, Smart borí nílé ẹjọ́ kòtẹ́milọ́rùn A fẹ́ kí a máa tẹ àwọn afipábánilòpọ̀ lọ́dàá ni báyìí - Ìjọba Ekiti Ni afikun ni awọn bii Malam Sidique to wa kirun ni Aso Rock naa ke si ijọba lati wa wọrọko fi ṣada lori iroyin ẹlẹjẹ to n gab ori ayelujara kan lasiko yii.
Ẹ̀yin tí ẹ̀ ń gbé Saanani, ẹ má jáde kúrò níbẹ̀, nítorí ẹkún àwọn ará Beteseli, yóo fihàn yín pé kò sí ààbò yín lọ́dọ̀ wọn.
Awọn asofin naa lo n fi apa janu pe ile ko fun awọn ni aaye lati gbọ aroye awọn.
Bi obinrin naa ba si fi ọrọ yii se apamọra, ti ko si tun lọ sile iwosan fun ayẹwo ati itọju ara rẹ, ewu n bẹ loko longẹ.
Kò sí alufaa kan tí ó gbọdọ̀ mu ọtí waini nígbà tí ó bá wọ gbọ̀ngàn inú.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo Ọmọ ọdọ naa, Thaddaeus Jaja jẹwọ fun awọn ọtẹlẹmuyẹ lẹyin ti ọwọ tẹ tan pe oun dana sun oku oun, lẹyin naa ni oun ta ọkọ rẹ ni miliọnu meji naira dinj diẹ.
Wọ́n mú Johanu lọ́wọ́ kí wọn lè máa rí i rán níṣẹ́.
Greenland ni erékùsù ti o tobi jù lọ lágbayé.
Àwọn ọ̀tá ti dáná sun ún, wọ́n ti gé e lulẹ̀;fi ojú burúkú wò wọ́n, kí wọ́n ṣègbé!
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Larisa: Má jẹ́ kí ọjọ́ orí rẹ dí ẹ lọ́wọ́ láti bẹ̀rẹ̀ ohunkóhun to wù ọ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Larisa: Má jẹ́ kí ọjọ́ orí rẹ dí ẹ lọ́wọ́ láti bẹ̀rẹ̀ ohunkóhun to wù ọ 23 Ọ̀pẹ̀̀ 2018 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 26 Ọ̀pẹ̀̀ 2019 Abule Kalinova ni Larisa ti n ṣe iṣe olukọni ko to di ilumọọka arinrin oge.
ni atunṣe naa yoo le jẹ ki ikọ naa tubọ le polongo ojuṣe ati iṣẹ wọn
Ṣugbọn Abramu dá a lóhùn pé, “Ṣebí ìkáwọ́ rẹ ni ẹrubinrin rẹ wà, ṣe é bí ó bá ti wù ọ́.
Àṣà Sharia ní ilé ẹjọ́ kòtẹmilọ́rùn tirẹ̀, ti wọ́n si máa n gbọ́ ẹjọ́ to níṣe pẹ̀lú ẹsìn, ìwà ọ̀daran àti láàrìn àwọn mùsùlùmí síra wọ́n.
''Lootọ ni pé àwọn ọdọ ẹgbẹ náà kò mọ sí èrò mí ṣùgbọ́n mi o gbèrò láti ṣe àkóbá fún wọn.
Àríyànjiyàn Osinbajo àti PDP Mi ò kọ̀wé fipò sílẹ́ - Osinbajo Keyamo àti Fani-Kayode faraya 'Buhari, máa múra sílẹ̀ láti fẹ̀yìntì' Ajafẹtọ ọmọniyan yii gbe awọn ẹka aṣeyọri Naijiria sori oṣuwọn lati ogun ọdun sẹyin ti a ti n ṣe ijọba alagbada.
Frank Lampard to n tukọ Derby County lo jọ pe ade naa yoo ṣi mọ lori.
OIC tun pinnu lati maa ṣe igbelarugẹ eto ẹkọ imọ-ijinlẹ ni gbogbo orilẹede to jẹ ọmọ ẹgbẹ naa.
Ọmọ Downsydrome ti mo bí ló fún mí láǹfàní láti de ilú Oyinbo Ìdí tí mi ò fi lègbà kí ẹnikẹ́ni fọwọ́ tẹ ara mi gẹ́gẹ́ bí olórin-Sola Allyson Ọlọ́pàá, adájọ́ àtàwọn aṣọ́bodè ló gba rìbá jùlọ ní Nàìjíríà-NBS Ìròyìn nípa ìyàwó túntún fún ọkọ mi kò mì mí lọ́kàn rárá-Aisha Buhari Cuppy sọrọ loju opo Instagram rẹ, ẹrẹ pe ni gbogbo igba ni lawọn ọkan mimọ maa n bori, iyẹn ni pe Joshua lọka mimọ.
Obìnrin kò gbọdọ̀ jáde alẹ́ mọ́ ní Kano Ààrẹ Buhari buwọ́lu ẹ̀dínwó ìdánwò NECO àti JAMB Isaac Adewọle: Minsita fun eto ilera Oríṣun àwòrán, @Isaac Adewole Àkọlé àwòrán, Iyanṣẹlodi ti pọ ju lasiko iṣejọba yii Koko ọrọ ti awon eniyan fi binu si minista fun eto ilera julọ lori ayelujara ni nigba ti o ni: kii ṣe gbogbo oniṣegun oyinbo lo maa fi ṣe iṣẹ ṣe, awọn mii a lọ ṣiṣẹ agbẹ.
Kilode ti wọn fi di titipa, sebi oogun ikọ nikan lo yẹ kijọba wọgile?
Lọdun 2014 lo di olori awọn obinrin ni ẹgbẹ oṣelu APC.
Wo ninu awọn to ti si ileewe pada ati bi wọn se n daabo bo awọn akẹkọọ: China China nibi ti arun yi ti jẹyọ ti da awọn akẹkọọ pada sile iwe lẹyin ti wọn jajabọ lọwọ arun naa.
Yóo jẹ́ aláìmọ́ bí ìgbà tí ó ń ṣe nǹkan oṣù rẹ̀.
Ẹ kò fetí sí ọ̀rọ̀ OLUWA, ẹ kò pa òfin, ati ìlànà rẹ̀ mọ́.
Gbogbo nǹkan wọnyi ni mo fi sọ́kàn.
"O ni ""mo dupẹ lọwọ gbogbo ẹyin milọnu kan ati abọ to n fifẹ han si mi."
Oríṣun àwòrán, @NLCtoday Onwoye awujọ naa ni, ijọba gbọdọ se amojuto awọn ile ti wọn n ko awọn ẹlẹwọn pamọ, ti wọn ko si ni kun akunfaya mọ.
Baba Tolu ni nigba ti oun de ile, iya rẹ lọ gbadura lori oke.
Claim : Eyi ni igbese ti awọn eniyan maa n gbe
Ni ifọwọsowọpọ la o js mu ki oorun ipinlẹ Ondo o tubọ maa tan sii.
Gẹgẹ bi Alufa Kumuyi ṣe sọ, awọn amuyẹ yii ni Bibeli Mimọ Atọka naa ni: Ọdun mẹẹdogun lo gba ki wọn o to o tẹ sita Kii ṣe pe Alufa Kumuyi kọ bibeli miran, amọ, o sọ pe oun ṣe ogbufọ ede oyinbo ni, sugbọn ni ede Yoruba to rọrùn lati kà fún ẹnikẹni Ẹgbẹ awọn oluka Bibeli, Bible Society of Nigeria, lo ba Kumuyi tẹ bibeli naa sita Kumuyi sọ pe o jẹ ọkan lara awọn Bibeli òde oni, to ṣe e gbarale, to si rọrun julọ lati kà Ẹgbẹrun mẹta ati ọtalelẹgbẹrin din mẹwaa Naira (₦3,750) ni wọn n ta ẹyọ kan Bibeli naa Bibeli naa jẹ kikọ ni ilana èdè Yoruba ode oni, nípa ṣíṣe agbeyẹwo awọn ọrọ akọtọ ati gbolohun ede Yoruba to ti yi pada kuro ni ti àtijọ́ Ilana lori bi a ṣe n pe ọrọ Yoruba kọọkan, ati itumọ awọn ọrọ to ta koko Kumuyi sọ pe Bibeli naa wulo fun ẹ̀kọ́ Bibeli ati iwaasu, bẹẹ ni ko yi ohunkohun pada ninu Bibeli to ti wa tẹlẹ.
Agbẹnusọ Ile Igbimọ Aṣofin Ipinlẹ Eko, Aṣofin Mudashiru Ọbasa, ẹni ti Aṣofin Sanai Agunbiade, Olori Ọmọ Ẹgbẹ Oṣelu to pọ ju ninu Ile naa ṣoju fun sọ pe iru eto ironilagbara yii ṣe pataki lati maa mu inu awọn ara ilu dun lati le ni imọlara mudunmudun ijọba tiwantiwa.
N kò ní inú dídùn sí ẹ̀jẹ̀ mààlúù tabi ti ọ̀dọ́ aguntan tabi ti òbúkọ.
igbimo asofin wa bura fun Omo –Agege gege bi igbakeji abenugan fun ile igbimo
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù RRS: Ọwọ́ tẹ olè tó gbé òrùka ìgbéyàwó obìnrin kan mì ní Eko 16 Òkùdu 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 17 Òkùdu 2019 Oríṣun àwòrán, RRS Àkọlé àwòrán, RRS mu Taofeek Adebayo ati Toheeb Tijani ni Oshodi Ọwọ ọlọpaa ti ba ole oju popo kan ti wọn fẹsun kan wi pe o gbe oruka igbeyawo arabinrin kan mii lẹyin to fi ibọn gba a lọwọ rẹ ni ọjọ Ẹti.
Orileede Germany faye gba ki eto ijọsin yala ni Mọsalasi tabi sọọsi bẹrẹ pada ni ọjọ Kẹrin osu Karun, sugbọn awọn olujọsin gbọdọ takete si ara wọn niwọn ẹsẹ bata marun un.
Ilana ẹsin musulumi ni wọn fi sin oku agba osere ọhun, ti awọn ọmọ rẹ si n sọkun pe o digbo se.
Bákan náà, ó tún ṣe oriṣa Aṣera kan.
Ẹnìkan yóo fò bí ẹyẹ idì, yóo na ìyẹ́ rẹ̀ sórí Bosira, ní ọjọ́ náà ọkàn àwọn ọmọ ogun Edomu yóo dàbí ọkàn obinrin tí ń rọbí.
Ati pe ijọba ko gbero lati fi agidi gba ilẹ lọwọ ẹnikẹni ni Naijiria fun awọn Fulani.
COVID-19 variant tó wà ní Nàìjíríà tún yàtọ̀ sí ti UK
''Olóde'' ni Yorùbá ń pe coronavirus, iléeṣẹ́ Yemkem ti rí òògùn rẹ̀ báyìí- Olùdásílẹ̀ Yemkem Lẹ́yìn ìfẹ̀yìntì ọdún márùn-ún, báágì àti bàtà ló kàn Nigba to n sọrọ lori agbekalẹ ibudo ikẹkọ kẹkẹ naa fun BBC Yoruba, Lekan Kuyoro tii se oludari ibudo naa ni, bii ere, bii ere lawọn n fi kẹkẹ sere nigba to bẹrẹ, ti awọn ko si mọ rara pe ọjọ iwaju rere yoo wa fun ere naa.
Ife kan wà ní ọwọ́ OLUWA,Ibinu Oluwa ló kún inú rẹ̀,ó ń ru bí ọtí àní bí ọtí tí a ti lú,yóo ṣẹ́ ninu rẹ̀;gbogbo àwọn eniyan burúkú ilẹ̀ ayé ni yóo sì mu ún,wọn óo mu ún tán patapata tòun ti gẹ̀dẹ̀gẹ́dẹ̀ rẹ̀.
 Àbùdá kan gbòógì tí ọ ̀ rọ ̀ tàbí gbólóhùn pọ ́ nna máa ń ní ni àì ní ìtumọ ̀ kan pàtó .
FAME Musician of the Year, Best Fuji Artiste at the Nigerian Music Awards Oríṣun àwòrán, Instagram/kwam1-official Best African Artiste at the WOMAD Festival in Reading 1996 The Headies - Hall of Fame 2013 City People Lifetime Achievement Award - 2014 Wasiu Ayinde ti gbe ọpọlọpọ awo orin jade, bẹ ẹ si ni awọn eyi to kọ ni ode ere, sugbọn to gbe jade sori fọnran.
Wọ̀nyí ni àwọn ẹjọ́ tó làmìlaaka ti EFCC ṣe lásìkò Ibrahim Magu Fọwọ́ kan obìnrin lọ́nà àìtọ́, kí o rẹ́wọ̀n ọdún mẹ́rìnlá he- Àwọn aṣòfin yarí Kò ní sí ayẹyẹ ọdún Ojúde Oba lọ́dún yìí- Awujale ilẹ̀ Ijebu Kòṣẹlẹ̀rí ni Hajj ọdún 2020, wo ìyàtọ̀ tó wà nínú rẹ̀ sí ti tẹ́lẹ̀ Ẹ̀yin ẹlẹ́gbẹ́ òkùnkùn tẹ fẹ́ ṣe àjọ̀dún lónìí, lákọ la ń dúró dè yín - Iléeṣẹ́ ọlọ́pàá Àkọlé àwòrán, Àwọn ọlọ́pàá kò kọbiara si ọ̀rọ̀ ipá lásìkò ìgbéle Covid -19 ni ìwà ipá ṣe pọ̀ - Ajàfẹ́tọ obìnrin Ṣaaju ni Ajafẹtọ ọmọniyan kan ti fẹsun kan ọlọpaa ipinlẹ Oyo pe wọn ko ṣe to bo ti yẹ.
Amọ ko si ewu fun lati kuro nile ijọba titi ti saa rẹ yoo fi buse ni ọsẹ kan si asiko yii nitori o see se kawọn asofin agba ma tete joko pada lati wa gbọ igbẹjọ rẹ.
Àmọ́ ọ̀rọ̀ ìyànjù tí ọ̀pọ̀ gbé kalẹ̀ ni pé àti igun kínií àti ìkejì, aráàlú ń wò wọ́n láti mọ ibi tí wọ́n bá orilẹ-ède yìí de.
ìkúnlápá tí àwọn Ọlọ ́ pàá ń ṣe fún ọ ̀ gbẹ ́ ni aníní ni a gbàgbọ ́ wípé ó jẹ ́ kí ìwà ìdún-kokò àti ìṣẹ ̀ rùbàlú rẹ ̀ ó peléke sí nị ́ 1986 , nígbà tí ọwọ ́ tẹ méjì lára àwọn abẹ ́ ṣin-káwọ ́ rẹ ̀ tí wọ ́ n sì fojú balé ẹjọ ́ tí ilé ẹjọ ́ sì fì ìyà tó tọ ́ jẹ wọ ́ n pẹ ̀ lú ìrànlọ ́ wọ ́ àwọn ọlọ ́ pàá nípa fí fìdí òkodoro ẹjọ ́ múlẹ ̀ nílé ẹjọ ́ láì wo ọ ̀ pọ ̀ lọpọ ̀ owó àbẹ ̀ tẹ ́ lẹ ̀ tí aníní ti fún wọn .
Àwọn olùfẹ̀hónúhàn náà ń bínu sí ìhà ti àwọn ìjọba ń kọ sí ìṣẹ̀lẹ̀ to wáyé náà.
ile-ise awon agbofinro mulẹ gẹgẹ bi oludari ile-ise naa, iyen Mohammed Adamu
5m ni ilẹ̀ Ireland fẹ́ fún Nàíjíríà lára owó tí olórí ológun tẹ́lẹ̀ jí kó
Lẹ́yìn tí ejò bá ti buni jẹ tán,kò ṣàǹfààní mọ́ kí á máa pọfọ̀ sí ejò.
Wọn óo tún àlàpà ahoro àtijọ́ kọ́,wọn óo tún gbogbo ilé tí ó ti wó lulẹ̀ kọ́,wọn óo sì tún ìlú tí a ti parun láti ọdún gbọọrọ kọ́.
" Obasanjo, Gowon, Muhammed- wo àwọn olóri Nàìjíríà lọ́dọ̀ọ́ Ọ̀pọ̀ èèyàn ló sá fún mi nígbà tí mo dùbúlẹ̀ àìsàn- Ògògó Bí ọwọ́ ọlọ́pàá Sharia Kano ṣé tẹ ọkùnrin 26 tó mura bi obìnrin Àwọn abiyamọ figbe ta lórí ọmọ ọdún kan ti wọn wá nílé ìjọsìn l'Akure Oluwo ṣalaye pe, ikọsilẹ naa ko ṣẹyin pe ọrọ awọn mejeeji ko ye ara wọn mọ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Brain Squad: Àwọn ọmọdébìnrin Nàìjíríà ṣe App"" ìrànwọ́ owó iléèwè Ati pe ẹnikẹni ko gbọdọ ba olori Chanel Chin tẹlẹ dowopọ mọ lorukọ Olori Oluwo ti ilẹ Iwo, Oba Telu1."
Eyi lo mu ki aayo Alaafin tilu Oyo tẹlẹ, Olori Anu fi n kigbe gbami-gbami fun araye nipa awọn ewu to ni oun n la kọja.
O tenumo pe,”Inu mi dun pupo lati wa ni bi, paapajulo lati je akonimoogba tuntun iko yii, bio tile jepe idojuko nla ni eyi je, sugbon mo n fojusona lati bere ise ni kiakia.
"Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Osinbajo yẹ́ Woli Arole sí níbi ìṣíde ""The Call"" Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!"
 Ó sí ìbùsọ ̀ òwò ní monrovia , kó tó di pé ó kọjú sí ìṣèlú .
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Àṣìṣe ọlọ́pàá àti Adájọ́ sọ mí di ẹni tí wọ́n dájọ́ ikú fún, ọpẹ́lọpẹ́ Fayoṣe tí ko buwọlu Olupẹjọ jẹ ko di mimọ fun ile ẹjọ naa pe Ọladeji ti Sunday pa lẹyin to sa kuro lahamọ ọlọpaa ni wọn ṣi tori rẹ gbe e wa siwaju ile ẹjọ.
Ninefe jẹ́ ìlú tí ó tóbi, ó gbà tó ìrìn ọjọ́ mẹta láti la ìlú náà já.
Òkúta yìí ni wọ́n fi nkọ́lé, tí wọ́n sì fi nkọ́ gbogbo àwọn odi tí wọ́n fi nyí ilèe wọ́n po.
Oríṣun àwòrán, SOB Agunbiade Nigba to n ba BBC Yoruba sọrọ SOB Agunbiade ni ohun tawọn eeyan n pin kaakiri gẹgẹ bi iroyin yii jẹ amọọmọṣe awọn kan lati gbẹ oun lẹsẹ gẹgẹ bi oloṣelu ni.
ojogbon Yemi Osinbajo ti ni eto idibo odun 2019 ni yoo so bi ojo iwaju orile
” Rakẹli bá dá a lóhùn, ó ní: “Bí o bá fún mi ninu èso mandiraki ọmọ rẹ, ọ̀dọ̀ rẹ ni Jakọbu yóo sùn lálẹ́ òní.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ile asofin Kwara: Owo ifẹyinti d'opin f'awọn gomina ana 27 Èrèlè 2018 Oríṣun àwòrán, @kwhanigeria Àkọlé àwòrán, Aarẹ ile asofin agba ni Naijiria jẹ gomina tẹlẹri nipinlẹ Kwara Ile asofin ipinlẹ Kwara ti fontẹ lu atunṣe aba ofin kan to n tako igbesẹ sisan owo ifẹyinti f'awọn gomina ana atawọn igbakeji wọn pẹlu awọn eeyan mii to dipo oṣelu mu lẹyin ti saa wọn ba pari.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Mistura Oseni Akintunde: Ara múmú kìí ṣe oríṣun ìfipábánilòpọ̀, ìran àwòjù ló ń fà á Lọwọ-lọwọ, oun ati awọn ẹgbẹ́ ọmọ rẹ obinrin lo jọ n joko ṣe idanwo WAEC.
Nígbà tí ó tó àkókò àti máa jẹun òkèlè bàbá mi tóbi ju òroǹbó lọ ó sì ń jẹun ní ìgbà tí mààlúù bá ń jẹ koríko.
Ìṣirò ohun tí wọ́n lò fún kíkọ́ àgọ́ ẹ̀rí wíwà OLUWA nìyí: Mose ni ó pàṣẹ pé kí ọmọ Lefi ṣe ìṣirò àwọn ohun tí wọ́n lò lábẹ́ àkóso Itamari ọmọ Aaroni, alufaa.
Naijiria ti loo ri figba alejo idije ere bii ti All African Games lọdun 2003 ti wọn kọkọ fi ṣide.
yóo ti ìka bọ inú òróró tí ó wà ní ọwọ́ òsì yìí, yóo sì wọ́n ọn sílẹ̀ níwájú OLUWA nígbà meje.
Orilẹede India nikan eyi ti pọ ju ti Naijiria lọ.
Shittu ni wọn ni o sàlàyé siwaju pe, òun ko nílò lati se ìsìnru ọlọdun kan ọun nitori pe, ni kété ti oun ti pari ni Fásitì ni oun ti wọnú òsèlú, èyí to túmọ̀ si pe, ipò òsèlu ti òún dìmú ti rọ́pò ìsìnrú ìlú to yẹ ki oun se.
O sọ ọrọ yi loju opo Twitter rẹ .
Gomina ipinlẹ Ondo, Rotimi Akeredolu ti kesi awọn ọmọ Naijiria lati lo asiko ọdun salah yii lati fi gbadura fun alaafia lorilẹede Naijiria.
Kíyèsí i, wọn ìbáà jókòó,wọn ìbáà dìde dúró,èmi ni wọ́n máa fi ń kọrin.
Pẹlu iforowero ti Obasanjọ se rẹpẹtẹ, o fi we awọn ohun to ba isẹ isejọba rere jẹ bii isẹ, aisi abo, amojuto to mẹhẹ fun ọrọ aje, aibikita si isẹ ẹni, gbigba ọjẹgẹ laye ati bẹẹ bẹẹ lọ.
Oluwa mi mú mi búra pé n kò gbọdọ̀ fẹ́ aya fún ọmọ òun láàrin àwọn ará ilẹ̀ Kenaani tí òun ń gbé.
Níbo ni ẹni tí ń gba owó orí wà?
Igbe ìparun ńlá láti ilẹ̀ àwọn ará Kalidea!
 Wọn rọ awọn onibaara lati ṣadinku lilo awọn ohun eelo yii, lati tubọ maa ṣgbe fun awọn ti le maa lo lera lera, dipo ki a kan lo ọkan lẹẹkan ṣoṣo, ki a si ṣe bẹẹ sọ ọ nu, pe gbogbo eyi lo n fa ọpọ awọn idọti onike bayii laarin ilu.
Inú wa kò dùn mọ́;ijó wa ti yipada, ó ti di ọ̀fọ̀.
Ibọwọ fún òfin ilẹ̀ wa Ohun àrà kẹta tí Umar Yar'adua ṣe lórí aleefa ni pé ó jẹjẹ pé òun yóò máa bù ọwọ ńlá fún òfin ilẹ̀ wa yàtò si bí àwọn aṣáájú tó síwájú rẹ tí ń ṣe.
Ọlọrun mú yín bí ọmọ ni.
Wenger tí ó ti lo ọdún mọ́kànlélógún gẹ́gẹ́bí adarí Arsenal nlọ 'lé bí ó tilẹ̀ jẹ́ pẹ́ ó ṣì níi ọdún kan tí àdéhùn iṣé rẹ̀ yóò parí.
Awọn orilẹ-ede to sun mọ wọn bii Sudan, South Sudan, Kenya, Djibouthi ati Eritrea ṣeeṣe ki wọn jẹ anfani tori ọpọlọpọ wọn ni ko gbadun ina.
O ni idigunjale, jijinigbe, ipaniyan, ẹgbẹ́ okunkun ni koko pataki ohun tijọba fẹ ki SARS fopin si lawujọ.
ó bá ní, “OLUWA ní òun óo sọ àwọn odò gbígbẹ wọnyi di adágún omi.
Awọn ọlọpa ni ọwọ palaba awọn igara ọlọsa mẹrin naa, ti wọn ti nfi oju awọn eeyan ipinlẹ ọhun han eemọ fun igba di segi nitori isẹ iwadi ijinlẹ ati ọtẹlẹmuyẹ to yaranti.
Ìtura lati orí ọmú (Nipple Orgasm) Fifi ọmú ati orí ọmú ṣere maa n mu ki ọpọlọ jí, to si maa n mu ki idọ gbá yágí-yágí, paapa ti wọn ba mu u.
Àwọn ni ọmọ Josẹfu ní ìdílé-ìdílé.
‘Isẹ́ tíátà pé mi láì mú nkàn míì mọ’ Mercy Aigbe: Èmi ni ìyá onílé tuntun 'Ẹ dá owó padà f’áwọn ẹbí MKO Abiọla' Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí kan sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
Oríṣun àwòrán, Instagram/BBNaija Oni lonii jẹ, ẹni a bẹ lọwẹ.
Aarẹ ilẹ orilẹede Naijiria, Muhammadu Buhari yoo ma gbalejo Aarẹ ilẹ orilẹede Faranse, Emmanuel Macron fun ijiroro lori eto abo ati igbesunmọmi lorilẹede Naijiria.
Tí o bá rí àpẹrẹ mẹ́fà yìí, sá àsálà fún ẹ̀mí rẹ̀!
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Buhari: A lágbára láti san gbogbo gbèsè tí a jẹ 31 Ògún 2018 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 4 Owewe 2018 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ààrẹ Muhammadu Buhari wa lorílẹ̀èdè China làti lọ se ìpàdé tó dá lórí ìbásepọ̀ láàárín ilẹ̀ Afirika ati China.
 ) ( the pencil has a fine point .
Ẹ má máa gbèrò ibi sí ara yín, ẹ má sì fẹ́ràn ìbúra èké, nítorí gbogbo nǹkan wọnyi ni mo kórìíra.
Àwọn ọfà rẹ mú, wọ́n gún àwọn ọ̀tá ọba lọ́kàn,àwọn eniyan ń wó lulẹ̀ níwájú rẹ.
Mo tún rí ohun asán kan láyé:
"Ẹlomiiran ti iṣẹlẹ naa ṣoju ẹ sọ fun BBC pé ""o ba mi lojiji lati ri ọkọ baalu naa bo ṣe gbina ni iṣẹju perete to yẹ ki oun wọ ọkọ baalu mii lati rinrin ajo""."
Bakan naa lo ni oun yoo maa wẹ fun aja awọn, Zyron ni ọsọọsẹ, oun yoo si maa ko igbẹ rẹ pẹlu, to fi mọ titun ibugbe rẹ se.
Koda, iroyin sọ pe aarin oru ni wọn fi sa kuro nilu Oyo lọ si Eko.
Onyeama , ti o je oludari eka to n ri si oro ala laarin orile ede meji, Nura Abba Rimiwa fi
A kọ orúkọ kan sára ẹ̀wù ati sí itan rẹ̀ pé: “Ọba àwọn ọba ati Oluwa àwọn olúwa.
fun ajo agbaye  (United Nations) Tijjani
"Àmọ́, Onímọ̀ kan nípa ìdíyelé ilẹ̀ àti ilé, tó bá BBC Yoruba sọ̀rọ̀ sọ pé ""owó nàá pọ̀ kọjá bó ṣeyẹ láti fi kọ́ ìlé alájà mẹ́wàá nàá, tó fi mọ́ àwọn tó wà lẹ́gbẹ̀ẹ́ rẹ̀."
Èmi, Alàgbà, ni mo kọ ìwé yìí sí ọ, Gaiyu olùfẹ́, ẹni tí mo fẹ́ràn nítòótọ́.
àwọn ọmọ Basiluti, àwọn ọmọ Mehida, ati àwọn ọmọ Haṣa,
O ni Ajimọbi ti ṣelẹri lati yanju aawọ ẹgbẹ oṣelu APC lasiko ipade apapọ ẹgbẹ ti NEC to m bọ lọna.
- iléeṣẹ́ ológun kìlọ̀ Àjọ FCTA fòfin de ìwọ́de nílùú Abuja Ọba Lamidi Adeyẹmi, òṣìṣẹ́ adójútòfò àti Abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò kó tó jọba Ṣé Èdùà dá ààtàn isó ni?
” Wọ́n bá tì í jáde.
Amọṣa iran ko tii pari bi ẹ ko ba tii wo awọn ohun ti oju ri wọnyii nibi ajọdun naa.
Coronavirus in Nigeria: Ìpínlẹ̀ Kaduna ní èèyàn 37 nínú àwọn 122 tí Covid-19 ṣẹ̀ṣẹ̀ ràn ní Naijiria Esi ayẹwo coronavirus lati ipinlẹ mọkanla ti ajọ NCDC fi sita ni Ọjọru, ọjọ keji, oṣu Kejila dun 2020, (02-12-2020), fihan pe, eeyan marundlaadọjọ tun ti ni aarun naa ni Naijiria.
 Ẹnití ó kọ ́ kọ ́ ṣàpèjúwe àrùn náà ni weil ní ọdún 1886 ní germany .
Ṣugbọn Ahabu tún bi í pé, “Ìgbà mélòó ni n óo sọ fún ọ pé, nígbà tí o bá sọ̀rọ̀ fún mi ní orúkọ OLUWA, kí o máa sọ òtítọ́ fún mi?
Ewe, obinrin akoko lorile-ede Nigeria Aisha Buhari lo asiko ayeye naa, lati benu-ete lu jiji awon awon eniyan gbe ati iwa laabi miiran ti won se si awon obinrin ati awon omodebinrin.
Igbakeji minisita fun eto isuna lorile-ede Egypt Ahmed Kouchouk so pe, orile-ede Egypt ti setan  lati ta eto eya-wo ti o le ni bilionu meta dollars $3-4 billion laarin odun 2018 si 2019, eyi ti yoo bere ninu osu keje odun ti a wa yii.
O ni oun ti fa ọrọ ẹsun naa le awọn agba igbimo ijọ lati ṣe iwadii to yẹ ati awọn ẹni iwaju ti oun n wo.
O ni lara asa Yoruba ni ki awọn oni ifa ati awọn agba ṣe irubọ, ki wọn wo ikọṣẹ-jaye ọba ti o fẹ jẹ, kikọ ọba ni bi wọn ṣe n sọrọ lawujọ ati bi ihuwasi to mu ọba yatọ si awọn ẹlomiran, eyi to mu ki wọn ma a pe e ni alaṣẹ ekeji orisa.
”Lara awon to tun soro nibe ni
Bakan naa, nile-ise olopaa fi mule pe, Kọmiṣọna olopaa miiran ni yoo maa dari eka FSARS ti atunto sese de ba ohun.
Ènìyàn ọgbọ̀n lé ẹ̀ẹ̀dẹ́gbẹ̀ta ló ti fojú hàn, tí àyẹ̀wò sì ti fìdí méjìdíláàdọ́ta múlẹ pé wọn ni ààrùn náà.
Bàbà dídán ni Huramu fi ṣe àwọn ìkòkò ati ọkọ́ ati àwokòtò ati gbogbo ohun èlò inú ilé OLUWA tí ó ṣe fún Solomoni ọba.
Mo wò yíká, ṣugbọn kò sí olùrànlọ́wọ́, ẹnu yà mí pé, n kò rí ẹnìkan tí yóo gbé mi ró;nítorí náà, agbára mi ni mo fi ṣẹgun,ibinu mi ni ó sì gbé mi ró.
Àrà méèrírí , ẹ wo ọkùnrin tí eegun rẹ̀ rọ̀ bíi rọ́bà, tó ń ká bíi ẹja Ilé kẹta da wó l'Eko láàrin ọsẹ méjì Oluwaseun ni afojusun oun ti oun fi da ajọ STER (Stand To End Rape) silẹ ni lati ri daju pe, asa ifipabanibalopọ ko maa waye ni ojoojumọ mọ ni awujọ wa.
Fun ọpọlọpọ ọdun lo ti fi nu bata fun awọn eeyan lẹgbẹ ọna lati fi tọju ara rẹ, lati kekere ni Ọgbẹni Chekole ti fi wa iṣẹ kiri loju titi.
Ẹ kò gbọdọ̀ fi orúkọ mi búra èké, kí ẹ má baà ba orúkọ Ọlọrun yín jẹ́.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Omolola Arohunmolase Welder: Mo ti fí iṣẹ́ 'Welder' gbayì láwùjọ, tó mo fi tọ́ ọmọ yanjú Oluyole si tun jẹ ọkan lára àwọn tí wọ́n ń wò bí ẹni to gbé ilẹ̀ Ibadan ró.
Amọṣa, bi awọn akẹkọ yii ṣe n pada si ẹnu ẹkọ wọn o daju pe Leah Sharibu ti wọn ji gbe pẹlu awọn akẹgbẹ ṣi wa lahamọ awọn agbebọn naa.
Ninu oro won, agbenusoro ajo NFF, Toyin Ibitoye.
NCDC ni awọn meji ninu wọn ṣẹṣẹ rinrin ajo de lati oke okun ni.
” Eniyan wá ń fi ẹnu ko ère mààlúù lẹ́nu!
Ṣugbọn OLUWA kò sí ninu ìṣẹ̀lẹ̀ náà.
Òkè àti pẹ̀tẹ́lẹ̀, òòrùn àti òṣùpá, àwọsánmọ̀ àti erùpẹ̀ ilẹ̀, gbogbo ìwọ̀nyí jẹ́ ìyanu.
Ẹ yipada, ẹ̀yin alaiṣootọ ọmọ,n óo mú aiṣootọ yín kúrò.
Mimiko fẹ du ipo sugbọn ẹgbẹ ni awọn ko fọwọsi erongba rẹ.
"O menuba pe: ""Gbogbo awọn to ṣẹlẹ si ko seyi ti ko lẹjẹ lọrun ninu gbogbo wọn."
Owe yii lo wa si ọkan onimọ nipa ẹṣin Islam, Sheikh Taofeeq Akeugbagold ti wọn ji ibeji rẹ gbe lọ laipẹ yii, to ṣe n fi ika hanu loju opo Facebook rẹ lọsan ọjọ Aje.
Kọmisana feto iroyin Funke Egbemode sọ pe, ijọba to n gbaroye araalu ni awọn jẹ, nitori naa, lawọn fi yi ipinu pada lori isin aisun ọjọ ọdun tawọn wọgile saaju.
Orilede Tanzania nikan lo ti mu ipinu yi di mimuṣẹ.
Coronavirus tún ti ṣe ọṣẹ́ lórí iṣẹ́ líla ojú ọ̀nà relùwe láti Eko sí Ibadan - Ìjọba àpapọ̀ Àrùn Coronavirus fa'lẹ̀ya láwọn ìletò aláwọ̀dúdú ní Amẹ́ríkà Coronavirus in Osun: Iṣẹ́ labiyamọ ń ṣe o, Davido pariwo síta lórí bó ṣe ń tọ́jú ọmọ tí Chioma fi sílẹ̀ fún Oríṣun àwòrán, davido Gbajugbaja akọrin takasufe ni, David Adeleke ti ọpọlọpọ mọ si Davido ti pariwo sita pe nnkan ko rẹrin lori titọju ọmọ ti oun ti iyawo rẹ Chioma bi fun latigba ti iya rẹ ti wa ni igbele iyasọtọ.
Gẹ́gẹ́ bi Seriki Fulani ìpińlẹ̀ Oyo Alhaji Salihu Abdulkadir ṣe sọ àwọn Amọtẹ́kùn já wọ bùba àwọn ajínígbe ní ìbi ọ̀tọ̀ọ̀tọ̀ méjì ní agbègbè náà.
A lè fi òwe Yorùbá ti ó ni “A ò mọ èyi ti Ọlọrun yio ṣe, kò jẹ́ ki á binú kú”, tu ẹni ti ó bá ni ìrẹ̀wẹ̀sì ninú, pé ọjọ́ ọ̀la yio dára.
Bakan naa ni ọkọ oju'rin gba ọmọbinrin kan to jẹ agunbanirọ agbegbe Ikẹja l'oṣu Kẹta ọdun 2018 bakan naa.
Ẹgbẹ́ Onímọ̀-nípa-ẹyẹ ṣe ìrìnàjò láti  Kathmandu sí Chitwan ní àná.
Absalomu ranṣẹ pe Joabu lẹẹkeji, Joabu sì tún kọ̀, kò lọ sọ́dọ̀ rẹ̀.
Àwọn olórin Nàìjíríà kẹ́dùn ikú ọmọ DBanj Nígbàti BBC Yorùbá fí ọ̀rọ̀ wá àwọn ọmọ Nàìjíríà tó tí sẹ alábápàdé ẹ̀ka ọlọ́pàá SARS tẹ́lẹ̀ rí ní wọn sàlàyé ǹkan ti ojú wọn ti ri .
Baana, ọmọ Ahiludi, ni alákòóso ìlú Taanaki, ati ti Megido, ati gbogbo agbègbè Beti Ṣeani, lẹ́bàá ìlú Saretani, ní ìhà gúsù Jesireeli ati Beti Ṣeani; títí dé ìlú Abeli Mehola títí dé òdìkejì Jokimeamu.
Ní ọjọ́ kinni oṣù kọkanla, ní ogoji ọdún tí wọ́n ti kúrò ní Ijipti, ni Mose bá àwọn eniyan Israẹli sọ ohun tí OLUWA pàṣẹ fún un láti sọ fún wọn; 
Wo bí wúrà ti dọ̀tí,tí ojúlówó wúrà sì yipada;tí àwọn òkúta Tẹmpili mímọ́ sì fọ́nká ní gbogbo ìkóríta.
Wọn ṣapejuwe aarẹ Lukashenko gẹgẹ bi aarẹ apaṣẹwaa to ṣẹ tun wa nilẹ Yuroopu bayii.
Pẹlu ipá ati ọwọ́-líle ni ẹ fi ń ṣe àkóso wọn.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Coronavirus symptoms: Ó ti di Ọgbọ̀n èeyàn báyìí tó ti ní àrùn Coronavirus ní Nàìjíríà 22 Ẹrẹ̀nà 2020 Oríṣun àwòrán, Others Àkọlé àwòrán, Ẹlòmíràn tún ti lùgbàdì àrùn Corona Virus nílùú Abuja àti Eko Ìròyìn tó ń tẹ̀ wa lọ́wọ́lọ́wọ́ ní wí pé Ajọ to n gbogun ti ajakalẹ arun lorilẹede Naijiria, NCDC tun ti kede pé ènìyàn mẹta miran tun ti ko arun coronavirus niluu Eko O ti di eeyan ọgbọn bayii to ti lugbadi arun naa lorilẹede Naijiria.
Iwadi kan nilẹ Amẹrika lo fi idi eyi mulẹ.
 Ọ ̀ kànbí ni àkọ ́ bí odùduwa .
Ìwọ ni o yọ mí nígbà tí mo wà ninu ìpọ́njú,ṣàánú mi, kí o sì gbọ́ adura mi.
Maa tesiwaju lati  fokan yin bale , gege bi okan lara yin, , lati maa kaare nipa fifowosowopo pelu awon ajo eleto –aabo , lati   se iwadiii , ki a si tun foju awon asebi yii jofin fun iwa ailaaanu fun emi eniyan ti won hu.
Ọkùnrin kan di èrò ọ̀run nítorí pé o fi ẹ̀sùn kan alájọgbélé rẹ̀ pé o n yan ìyàwó ẹnìkan lálè Èèyàn mẹ́tàlélógóje míì ṣẹ̀ṣẹ̀ kó COVID-19 ní Nàìjíríà Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Oyenusi ló mú mi wọ ẹgbẹ́ adigunjalè kó tó di pé mo b'Ólúwa pàdé' Bakan naa ni ẹni to n dari igbimọ amuṣẹya lori ọrọ coronavirus ni ipinlẹ Ekiti Ọjọgbọn Bọlaji Aluko pẹlu sọ pe awọn ko ṣetan lati wo aago alaago sare.
Olubadamọran nigba kan ri fun ileeṣẹ Amerika sọ fun BBC pe ipinnu ilẹ Amerika lasiko yii fihan pe ko si ajọṣepọ to fẹ dan mọran laarin ijọba Buhari ati ileeṣẹ Amerika to wa ni Naijiria.
Ẹ jọwọ ẹ dariji mi lori ọrọ yii, bi a ṣe n wa ọna ki orilẹ-ede wa le ni itẹsiwaju.
Bí wọ́n ti ń tọ́jú oúnjẹ lọ́wọ́, Peteru bá rí ìran kan.
Ramaphosa so pe, “erongba atunto ohun ni lati mi igberu ba isakoso ijoba, nipa sise amulo awon igbese ti o ye, lati le maa yanju awon oro ti o n lo lorile-ede naa”.
Àfi Ọlọ́run ọba nìkan lo lè mọ̀ bí ọkàn mi ti rí láti ìgbà tí mo ti fi yín silẹ̀.
Awọn alaṣẹ ajọ ọlọpaa ko ni faaye gba aṣilo agbara rara.
lowo lati gbogun ti airisẹ .
Lati oṣu kẹrin ọdun 2019 ni Naijiria ti sọ ẹgbẹrun ọgbọn naira di owo oṣu oṣiṣẹ to kere julọ ni Naijiria.
F Odunjo tun jẹ ọmọ ẹgbẹ olukọ nilẹ wa Naijiria fun ọpọlọpọ ọdun, o jẹ akọwe ẹgbẹ naa laarin ọdun 1942 si 1951.
Wọn ni ko si ẹni to le fidi ẹsun ijọmọgbe ti wọn kan alufaa Babatunde mulẹ, wọn ni awọn mii tiẹ sọ pe pasitọ ọhun ri ọmọ naa mọlẹ laaye ni.
Lara awọn asofin to kọwọrin pẹlu Pelosi ni awọn agba asofin to jẹ adulawọ.
Jaeli bá jáde lọ pàdé Sisera, ó wí fún un pé, “Máa bọ̀ níhìn-ín, oluwa mi.
“Àwọn baba wa ní àgọ́ ẹ̀rí kan ní aṣálẹ̀.
Ní ọjọọjọ́ ìsinmi, kí ẹnìkọ̀ọ̀kan yín máa mú ọrẹ ninu ohun ìní rẹ̀, kí ó máa fi í sọ́tọ̀ gẹ́gẹ́ bí Ọlọrun bá ti bukun un.
Umai Emery: Villarael yan akọ́nimọ̀ọ́gbá Arsenal tẹ́lẹ̀, Emery gẹ́gẹ́ bí akọ́nimọ̀ọ́gbá rẹ̀ tuntun
“Ọlọrun ni ọba, òun ló sì tó bẹ̀rù,ó ń ṣe àkóso alaafia lọ́run.
Bákan náà, nígbà tí àkókò bá tó,n óo tú ẹ̀mí mi jáde sára àwọn iranṣẹkunrin ati àwọn iranṣẹbinrin yín.
Thomas John yoo jẹ adele alaga gẹgẹ bi ilana abala ofin 11(3) ati 2(1) ti ajọ NNPC eyi to tumọ si pe yoo bẹrẹ iṣẹ loju ẹsẹ.
Afọnja, ẹni tó finú wénú ní Ilọrin, àmọ́ tó jẹ iwọ Ìgbín ní èmi àti ìyá mi máa ń he kiri, ká tó lee jẹun - Lizzy Anjọrin Ẹ wo báwọn òṣèré tíátà kan yóò ṣe rí lọ́jọ́ ogbó Ìtàn tó rọ̀ mọ́ òwe ‘aṣọ kò bá Ọ́mọ́yẹ mọ́.
Ayọ̀ ń bẹ fún àwọn tí ebi òdodo ń pa, tí òùngbẹ òdodo sì ń gbẹ,nítorí Ọlọrun yóo bọ́ wọn ní àbọ́yó.
Awọn yoku ni Uganda, Morocco, Ghana, Kenya, eSwatini ati Malawi.
“Kabiyesi, ìtumọ̀ rẹ̀ nìyí: Àṣẹ tí Ẹni Gíga Jùlọ pa nípa oluwa mi, ọba ni.
Idi ree ti igbimọ awọn gomina ipinlẹ ni Naijiria fi dide lati kede pe nnkan ko fararọ, nitori ọwọja iwa fifi ipa bawọn obinrin lopọ ati hihu iwa ipa si awọn abo ati ọmọde to n gogo yika Naijiria.
Nítòótọ́ ni wọ́n ń wá mi lojoojumọ,wọ́n sì fẹ́ mọ ìlànà mi,wọ́n ṣe bí orílẹ̀-èdè tí ó mọ òdodo,tí kò kọ òfin Ọlọrun wọn sílẹ̀.
Bú ààrẹ láwọn orílẹ̀èdè márùn-ún yìí kí o rugi oyin Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Koda, o rọ wọn lati ṣe ajọpin ounjẹ de ọdọ awọn alaini.
Fidio kan eyi to gbalẹ bi iso ẹwa lori ayelujara lo ṣafihan bi wọn ṣe yi iya arugbo naa ka, ti wọn si n lo awọn nnkan lati gba a lori.
Ẹ̀rí yìí ni a tẹ̀ jáde nínú àtúntẹ̀ ti 1835 ti Ẹ̀kọ́ ati àwọn Májẹ̀mú bíi ẹ̀rí kíkọ ti àwọn Àpóstélì Méjìlá:
 Adari ile –ise naa soro yii lasiko ti ikọ awon
atunse ba deba bi awon aare orile ede Naijiria se n yan awon adari sipo yoo din
Kebe n Kwara, ẹni to ni ko yẹ ki orilẹede Naijiria tii gba ominira, wa gba awọn araalu nimọran lati sugba ijọba Buhari nitori pe ilu ko rọ̀run nigba ti Buhari gba ijọba pẹlu afikun pe iwa ajẹ́banu ko lee tan lara awọn ọmọ Naijiria.
 Ninu ikede ilu-o-fara ro ni odun 2016 ti o to osu mewaa, ogoro awon omo orile-ede Ethiopia ni awon ologun fi owo sinkun mu, ti won si ko won si atimole.
Olódodo ni ọ́, OLUWA,ìdájọ́ rẹ sì tọ́.
Oríṣun àwòrán, PrOMAISODOR GHANA Lẹyin ti awọn adajọ ṣe itọwo abọ irẹsi jọlọọfu ti wọn gbe wa, awọn mẹtẹẹta lo panupọ ṣalaye pe irẹsi jọlọọfu ti ghana lọba.
O lọ sile ẹkọ alakọbẹrẹ Patrick Mimọ ladugbo Oke Paadi nilu Ibadan amọ O pari ẹkọ alakọbẹrẹ rẹ ni ile ẹkọ Ibadan City Council, ICC Orita Aperin nilu Ibadan.
Èṣi àyẹ̀wò jáde, Gómìnà Bauchi ti ní aàrùn coronavirus báyìí 'Ẹ dárí ẹ̀ṣẹ̀ mi jìnmí, àmọ́ èmi nìkan kọ́ ló ṣẹ̀,' Ajimobi bẹ ọmọ ẹgbẹ́ APC l'Oyo Ọpọ ọmọ Naijiria ni wọn ki baba ku ajaye, bẹẹ ni wọn ki i ku oriire loju opo Twitter.
Ajọ FIFA fofin de Siasia pe ko gbọdọ ni ohun kankan ṣe mọ pẹlu ere bọọlu, amọ o ni oun ko mọwọ, bẹẹ ni oun ko mẹsẹ lori ọrọ naa.
O lo sọ pe ''boya eniyan ni aarun HIV tabi ko ni, iku kan naa ni yoo pani.
Awọn ipinlẹ to ku ni: Apapọ awọn to ti ni l'orilẹ-ede Naijiria jẹ ẹgbẹrun meje, ati ẹẹdẹgbẹta le mẹrindinlọgbọn (7526).
Nisinsinyii, ẹ rò pé ẹ lè dojú ìjà kọ ìjọba OLUWA, tí ó gbé lé àwọn ọmọ Dafidi lọ́wọ́; nítorí pé ẹ pọ̀ ní iye ati pé ẹ ní ère ẹgbọ̀rọ̀ mààlúù tí Jeroboamu fi wúrà ṣe tí ó pè ní ọlọrun yín?
Iwin yóo rí ibi máa gbé,yóo sì rí ààyè máa sinmi níbẹ̀.
"Gomina Sanwo-Olu sún ọjọ ""ṣiṣẹ lati ile"" síwájú fún àwọn òṣìṣẹ́ ìjọba Ẹ ṣọ́ra o, ayédèrú abẹ́rẹ́ àjẹsára COVID-19 gbòde ní Nàìjíríà, NAFDAC pariwo síta Dókítà 66 síṣẹ́ abẹ fún ìbejì tó lẹ̀pọ̀ nílé ìwòsàn fasiti Ilorin Àwọn agbébọn tó ń gba ojúgbó wọlé máa ń tó 1000 lẹ́ẹ̀kan náà - Amotekun Mo ti ní ìyàwó àfẹ́sọ́nà, ayẹyẹ ìgbeyàwó mi ń bọ̀ láìpẹ́ - Lateef Adedimeji Ìdí tí àwọn èèyàn kan kò fí le ni àrùn Coronavirus Eeyan 168 lo ni covid-19 nipinlẹ Rivers, mọkandinlaadọta l'Ogun, ọgbọn lati ipinlẹ Oyo, mọkanla l'Ondo nigba ti eeyan meje karun naa l'Ekiti."
Mo ti sọ fun yin pe Lecon n gbe owo ile BB Naija bọ wa sile, o si ti de bayii.
Mo ti pinnu láti máa tẹ̀lé ìlànà rẹ nígbà gbogbo,àní, títí dé òpin.
 Ṣùgbọ ́ n kì í ṣe ọ ̀ kan náà ni wọ ́ n ní òórọ ̀ ọjọ ́ bí a ti sọ ṣáájú .
Kọmisọna fun eto ẹkọ wipe, awọn n ṣiṣẹ pọ pẹlu Ajọ awọn Olukọ Lapapọ (National Teachers Institute) lati bawọn kọ ọgọrun olukọ, pẹlu ireti wipe eleyi yoo mu ilọsiwaju ba eto ẹkọ ni ipinlẹ naa.
Niluu Eko fun apẹẹrẹ, awọn olufẹhonukan bọ si oju titi ṣugbọn awọn ọlọpaa yin tajutaju soke lati tu wọn ka.
O sọ pataki ṣaworo to wa leti ilu ti kii ba wọn re ode ibanujẹ pẹlu ṣẹkẹrẹ.
Èyí tí ó ṣìkejì ni pé, ‘Kí ìwọ fẹ́ràn ẹnìkejì rẹ bí o ti fẹ́ràn ara rẹ.
“Bí ẹnìkan bá yá ẹran ọ̀sìn kẹ́ran ọ̀sìn lọ́wọ́ aládùúgbò rẹ̀, tí ẹran náà bá farapa tabi tí ó kú, tí kò sì sí olówó ẹran náà níbẹ̀, ẹni tí ó yá ẹran náà níláti san án pada.
Ta ló dàbí OLUWA Ọlọrun wa,tí ó gúnwà sí òkè ọ̀run,
OLUWA Ọlọrun yóo fọn fèrè ogunyóo sì rìn ninu ìjì líle ti ìhà gúsù.
Ó fi aṣọ aláwọ̀ aró rán ẹ̀wù àwọ̀kanlẹ̀ sí efodu náà, 
Eyi lo mu ko kọ iwe ẹsun mọ ajọ EFCC, nile ẹjọ, botilẹjẹ pe igbẹjọ si n lọ lori ọrọ ti ẹ naa.
Mo di ẹni ẹ̀sín láti àárọ̀ títí di alẹ́,gbogbo eniyan ń fi mí ṣe yẹ̀yẹ́.
Nítorí náà a mú ọrẹ ẹbọ: ohun ọ̀ṣọ́ wúrà, ẹ̀wọ̀n, ẹ̀gbà ọwọ́, òrùka, yẹtí, ati ìlẹ̀kẹ̀ wá fún OLUWA lára ìkógun wa, láti fi ṣe ẹbọ ètùtù fún wa níwájú OLUWA.
Ọmọ mi, ṣọ́ra fún ohunkohun tí ó bá kọjá eléyìí, ìwé kíkọ́ kò lópin, àkàjù ìwé a sì máa kó àárẹ̀ bá eniyan.
Bí wọ́n ṣe wà bí aláìsí.
Gẹ́gẹ́ bí ààrẹ orílẹ̀-èdè Madagascar Andry Rajoelina ṣe sọ ewé artemisia annua ti hausa n pè ni Tazargade ti yorùba sì n pé ní Ewe Egbin Zulu Sáájú àsìkò yìí ní ní àwọn onímọ̀ ti n ṣe ìwádìí ewé náà fún àwọn èròjà ìtójú àìsàn míràn bíi àìsàn ibà, Cancer àti HIV.
Ọdun 1997 ni Oyetola ti darapọ mọ sise oselu, O pẹlu awọn to da ẹgbẹ oselu Alliance for Democracy AD silẹ ni ọdun 1998, ki o to di alaga ẹgbẹ oṣelu ACN to di APC bayii.
Kí wọ́n dúró pẹlu rẹ níbẹ̀.
Idi ree ti BBC Yoruba, lori eto Laa han mi se n la wa lọyẹ lori awọn ohun to yẹ́ ka se lati dena itankalẹ arun Coronavirus.
Ọsinbajo pe fun ọlọpa agbegbe Osinbajo: Ẹ dìbò fún Buhari, kí ẹ̀yà Yorùbá lé gbàjọba ní 2023 Dúkìá mi ò lé kan o, mo ti dá fọ́ọ̀mù padà bó ṣe wà tẹ́lẹ̀ - Buhari, Osinbajo Ta ni olórí ogun Ethiopia, Saere Mekonnen to kú sínú ìdìtẹ̀-gbàjọba?
Kódà àwọn kan a máa lá a ní gbẹrẹfu.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, John Amanam: Ìfẹ́ tí mo ní sí àbúrò mi ló sọ mi dí ẹni tó ń ṣe 'Prosthetic' báyìí Lọdun 1982 ni wọn fi jẹ Owa 'Tapa ti Itapa Ijesha ni ipinlẹ Osun ni iwọ oorun guusu Naijiria.
Lẹ́yìn náà, wọn á fún àwọn aguntan wọ́n lómi mu, wọ́n á sì yí òkúta náà pada sẹ́nu kànga.
Ṣìṣeṣìṣe Troost-Ekong ṣokùnfà ìyà àjẹsùn fún Nàìjíríà lọ́wọ́ Algeria Àwọn olówó Naijiria 5 tí owó wọn ju owó ìsúnná Naijiria lọ!
Gẹgẹ bi oludije fun ipo Aarẹ lati ibẹrẹ wá lo ti ni awọn igbakeji yii: Ọmọwe Chuba Okadigbo (2003) Edwin Ume-Ezeoke (2007) Pásítọ̀ Tunde Bakare (2011) Ọjọgbọn Yemi Osinbajo (2015) Idibo ti ọdun 2015 jẹ eyi to laami laaka gẹgẹ bi Aarẹ Muhammadu Buhari ati igbakeji rẹ Ọjọgbọn Yemi Oṣinbajo ṣe polongo pẹlu ileri 'ayipada' ni ibo to le ni miliọnu mẹẹdogun lati jawe olubori ninu idibo naa.
”Wọ́n wá bẹ̀rẹ̀ sí bá ara wọn jiyàn, wọ́n ń wí pé, “Bí a bá sọ pé, ‘Láti ọ̀run ni,’ yóo bi wá pé, ‘Kí ló dé tí ẹ kò fi gbà á gbọ́?
waye lasiko iwode iko omo ogun oju ofurufu ohun, leyin ti won kofiri awon omo ogun
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Presidency: Aarẹ Buhari kẹdun ikú àwọn eniyan to kagbako Boko Haram 28 Agẹmo 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 29 Agẹmo 2019 Oríṣun àwòrán, @Presidnecy Àkọlé àwòrán, Ironu dori agba kodo Aarẹ Mohammadu Buhari bu ẹnu ẹ̀tẹ́ lu ikọlu awọn alakatakiti ẹsin Islam, Boko Haram ni Borno Mallam Garba Shehu to jẹ olubadamọran fun aarẹ Buhari lori ọrọ iroyin ati ifitonileti gbogbo sọ ninu atẹjade kan to fi sita pé nkan ibanujẹ lo ṣẹlẹ yii.
Ọ̀rọ̀ kún inú mi bí ọtí inú ìgò,ó fẹ́ ru síta bí ọtí inú ìgò aláwọ.
Ọpọ ẹbí lo ń wa owó ìtanràn bayii bii ti oloselu Zamfara ti àwọn ọlọpaa ṣì ń wa iyawo rẹ ati ọmọ mẹfa ti àwọn ajinigbe ji bayii.
gbosuba fun awon olopaa ti ekun naa fun gudu gudu meje yaya mefa ti won n se
Igba miran, eni to ba n fẹ eeyan kan le maa se oju aye lasan to jẹ pe o n fi ẹjẹ sinu tu itọ funfun sita ni.
ó bẹ̀rẹ̀ sí lépa wolii ará Juda náà.
Iwa jẹgudujẹra: Aarẹ Buhari ni igbogunti iwa jẹgudujẹra ti sọ eso rere pẹlu bi awọn ti se ri ọpọlọpọ owo gba pada lọwọ awọn ọbayejẹ lawujọ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Leah Sharibu ti lo irínwó ọjọ́ ní àhámọ́ Boko Haram 14 Èbibi 2019 Oríṣun àwòrán, Google, BBC Àkọlé àwòrán, Akara oyinbo fun ọjọ ibi Leah Sharibu Leah Sharibu ti awọn agbesunmọmi Boko Haram jigbe ni ọdun to kọja, ti pe ọmọ ọdun mẹrindinlogun ni panpẹ wọn.
Mo ní, “Èmi óo jẹ́wọ́ ẹ̀ṣẹ̀ mi fún Oluwa,”o sì dáríjì mí.
Tabi agbègbè wọn tóbi ju tiyín lọ?
Oludije dupo gomina  labe asia egbe  All Progressives Congress APC ni ipinle Kwara ,
Koda, Iya Onile naa ni oun ti fi ọrọ Lisa to ọlọpaa leti tẹlẹ nitori ko tun tete san awọn owo ina tai awọn to n tun ile ṣe.
Níbikíbi tí OLUWA Ọlọrun yín bá yàn, ni ẹ ti gbọdọ̀ máa jẹ wọ́n níwájú rẹ̀, ní ọdọọdún; ẹ̀yin ati gbogbo ilé yín.
Òkùnkùn birimùbirimù ń bọ̀ ní Nàìjíríà!
Owó oúnjẹ ni mo lọ ọ gbà, oyún ọmọ tí mo jù sí àkìtàn ni mó gbé wálé- Dupe, ìyá Muiz Kọ́ sí i nípa àwọn oúnjẹ aṣaralóore tó yẹ kí Aláboyún máa jẹ Ohun mẹ́wàá pàtàkì nípa Maradona àti ìbáṣepọ̀ rẹ̀ pẹ̀lú ẹlẹ́sẹ̀ ayò Diego Costa rèé Ọmọbìnrin tó tayọ nínú ìdànwó WAEC ọdún 2019 pẹ̀lú A1 méje ti kú Ọ̀rọ̀ àsọkẹ́yìn Diego Maradona ìlúmọọká agbábọ́ọ̀lù rèé kó tó dágbére f'áyé Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Oba Adedokun Abolarin ti Oke Ila: Ó ya ọ̀pọ̀ tó súnmọ́ mi lẹ́nu bí mo ṣe ń kọ́ Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Adeyeye Ile Ife: Kílódé tí Ọọni Ife, Oba Ogunwusi kò fi gbọdọ̀ rí ọmọ rẹ̀ tuntun títí di ẹ̀yìn oṣù mẹ́fà?
Akinṣemọla ni ọjọru to jẹ Ọjọ Kẹsan, Oṣu Kẹsan, ọdun 2020 ni o yẹ ki Paul Sodje pe ẹni ọdun marundinlọgọta.
Bakan naa ni Alaafin ilu Oyo ni oun fun awọn to ji awọn nkan gbe lasiko naa ni gbedeke lati da wọn pada, eleyii ti o ni wọn tẹle to si jẹ ki alaafia jọba ni ipinlẹ Oyo.
ati àwọn ẹ̀wù tí a dárà sí, ẹ̀wù mímọ́ Aaroni alufaa ati ẹ̀wù àwọn ọmọ rẹ̀ tí wọn yóo máa fi ṣe iṣẹ́ alufaa wọn, 
Aṣoju ṣofin Abdulmumini fikun ọrọ rẹ pe Gbajabiamila lawọn ọmọ ile igbimọ aṣoju ṣofin lati iwọ oorun gusu naa fẹdibo fun un.
 Ewe, lara awon ti o wo ere ohun ni, aare ana fun orile-ede Naijiria Olusegun Obasanjo.
“Ohun iwuri gidi ni ti abadofin fun ṣiṣe ẹkọ ede Yoruba ni kannpa fun awọn ile-iwe alakọbẹrẹ, ile-iwe girama ati awọn ile-ẹkọ giga miiran ni Ipinlẹ Eko, ti Ile Igbimọ Aṣofin yii sọ di ofin”.
O fi kun un pe ninu awọn ẹlẹwọn marundinlọgbọn to forukọ silẹ ni ileewe naa lọdun 2015, oun nikan lo pari.
Aláìmòye ènìyàn wi pe onífẹ̀ẹ́kúfẹ̀ẹ́ni obìnrin tí ó tìkara rẹ̀ fẹ́ ọkùnrin bẹ́ẹ̀ ni kí obìnrin tóó ṣe irú èyí, iná ìfẹ́ ọkàn rẹ̀ a máa lágbára ju iná ìléru.
Gomina ipinlẹ Ogun sisọ loju ọrọ yii lasiko to n gbalejo Laycon ni ọọfisi rẹ to wa ni Oke Mọsan nilu Abeokuta.
"Jane, ẹni ọdun mẹrindinlọgbọn, lasiko to n ba BBC sọrọ ni, ""ọkan mi balẹ lati wa si agbo ijo to wa fun obinrin nikan lai lọwọ awọn ọkunrin ninu, mo wa pẹlu ọrẹ mi obinrin, eyi to mu ki inu mi dun lati wa pẹlu ẹni to loye nipa oun."
Ninu ọrọ re to kọ loju opo Twitter rẹ, Fani-kayode ni sugbọni kii se Buhari nikan lo lẹbi ọrọ naa.
Ìgbà tí a sì pa ẹran púpọ̀ nígbà kan ó yó ní ìgbà kín-ín-ní ọjọ́ ayé rẹ̀.
Onigbọwọ Day, Lou DiBella lo kede iku rẹ nigba ti o wa pẹlu awọn ẹbi ati ọrẹ rẹ.
omi tí ń ṣàn bọ̀ láti òkè dúró, ó sì bẹ̀rẹ̀ sí wọ́jọ pọ̀ bí òkítì ńlá ní òkèèrè ní ìlú Adamu tí ó wà lẹ́bàá Saretani.
Koda, o tun polongo fidio orin D'banj loju opo ayelujara rẹ.
Òkìkí Jesu sì kàn ká gbogbo ìgbèríko ibẹ̀.
Sugbọn gba mi bi mo ti ri nitori mo nifẹ rẹ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ember Month Security: Ọwọ́ pálábá àwọn ọmọ ẹlégbẹ́ òkùnkùn 15 ségí ní ìpínlẹ̀ Eko 13 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 30 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Oríṣun àwòrán, Lagos Police Ijọba ipinlẹ Eko ni ọwọ awọn ti tẹ awọn ọdaran ti wọn n da agbegbe Ikorodu ati Lekki/Ajah laamu nipinlẹ Eko.
Èyí àbíkẹ́yìn rí èso igi kan rà, èso igi yìí kìí bàjẹ́, ó le koko ṣùgbọ́n kò sí àìsàn kan ní ayé yìí tí eso igi náà kò le wò, bí aláìsàn bá ti gbóòórùn rẹ ṣá, kí aláìsàn dìde ni.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Premier League: Nàn sẹ́ni ọ́ gọ̀ ni Chelsea fi ṣe fún Watford 5 Èbibi 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Chelsea fakọyọ O fẹ dabi ẹni pe Chelsea ni ipo lati dije fun UEFA Champions League ni saa to n bọ yoo ja mọ lọwọ laarin awọn wọn ati Arsenal ati Manchester United.
Kí ẹ lè mọ bí nǹkan ti ń lọ sí lọ́dọ̀ mi, ati ohun tí mò ń ṣe, Tukikọsi yóo sọ gbogbo rẹ̀ fun yín.
ẹ̀rù kò bà ọ́ ni ndan?
OLUWA Ọlọrun Israẹli sọ fún mi pé, “Gba ife ọtí ibinu yìí lọ́wọ́ mi, kí o fún gbogbo àwọn orílẹ̀-èdè tí n óo rán ọ sí mu.
Ni orilẹede Egypt, ko din ni miliọnu mẹwa awọn eeyan orilẹede Egypt ti o jẹ Kristẹni, pupọ ninu wọn lo si jẹ ẹya Coptic Christian.
A Gbé Àpótí Majẹmu kúrò ní Kiriati Jearimu.
Wọn tun fi kun un pe ko si idi to fi yẹ ki ijọba kan owo naa ni ipa fun awọn akẹkọọ niwọn igba to jẹ wi pe wọn ti ni ki ileewe kọọkan o maa pese awọn ilana ati ohun elo fun ayẹwo awọn akẹkọọ ṣaaju iwọle wọn.
tabi bí ẹnìkan bá ṣèèṣì sọ òkúta láì wo ibi tí ó sọ òkúta náà sí, tí òkúta náà sì pa eniyan tí kì í ṣe pé ó ti fẹ́ pa olúwarẹ̀ tẹ́lẹ̀, tí kò sì kórìíra rẹ̀, 
Ẹ lè fi wọ́n sílẹ̀ fún àwọn ọmọ yín nígbà tí ẹ bá kú, kí wọn lè jogún wọn títí lae.
Africa Eye: Olùkọ́ méjì ní fásitì Eko àti Ghana lùgbàdì ọ̀fíntótó BBC lórí ìwà ìbàjẹ́ Bí Kunle Ọlasọpe, ìlúmọ̀ọ́ká agbóhùnsáfẹ́fẹ́ ṣe lo ìgbésí ayé rẹ̀ rèé Inú máa ń bí mí láti gbọ́ pé ẹ̀yà kan kò leè darí Nàíjíríà -Tunde Bakare Músò!
Wọn yóo wá mọ̀ pé èmi ni OLUWA Ọlọrun, nígbà tí mo bá ti ipasẹ̀ yín fi bí orúkọ mi ti jẹ́ mímọ́ tó hàn wọ́n.
Awon eniyan yii ti koju isoro  lorisiirisii nipa eto abo ti won ti sa lo kuro nile won ni eyi ti won ko le seto ogbin, kawe tabi mojuto ilera won ti won ti padanu awon ohun ini won”.
2019 Budget: Ètò àbò, ètò ẹ̀kọ́, gbégbá orókè nínú àbádòfin N8.
Ní ọjọ́ 8 oṣù Ọ̀pẹ, ẹbíi rẹ̀ ti  ṣe àgbékalẹ̀ ìpolongo –“100 ọjọ́ fún Alaa”  kí àtìmọ́lée rẹ̀ ó ba wá s'ópin ní mọnawáà.
Ẹni tí ń gbé irúgbìn lọ sí oko tẹkúntẹkún,yóo ru ìtí ọkà pada sílé tayọ̀tayọ̀.
Àkọlé àwòrán, Awọn kabiyesi, lade-lade ati loyeloye naa wa nibẹ.
O ni bi a se n gbe ise agbase sita naa n faa Adekunle Akinlade Àkọlé àwòrán, #BBCGOVDEBATE: Ẹṣẹ Mẹ́ta ni ètò ìjọba fi lélẹ̀ ní Ogun Akinlade ni ki ijoba to wa lode to de nnkan buru ju bayii lọ lóri abo.
A ti wá pinnu, gbogbo wa sì fohùn sí i, a wá yan àwọn eniyan láti rán si yín pẹlu Banaba ati Paulu, àwọn àyànfẹ́ wa, 
Oloye Ẹlẹbuibọn ni ara ọna ti awọn ẹlẹsin okeere fi ba ẹsin abalaye jẹ niyi ki awọn eeyan lee maa fi oju ibajẹ wo ẹsin naa.
17 Èbibi 2018 Oríṣun àwòrán, @NigerianSenate Àkọlé àwòrán, Ẹnu ko sin lara Ile igbimọ aṣọfin apapọ paapa julo lori iye owo ajemonu ti wọn n gba Ẹ gbọ́ ná, iru ẹ́mi wo la lee fi mílíọ́nù mẹ́tàlélọ́ọ̀dúnrún náírà dáàbò bo lorílè-èdè Nàìjíríà?
Oríṣun àwòrán, Twitter/NFF Àkọlé àwòrán, Iku pa agbabọọlu Super Falcons tẹlẹ NFF ṣalaye pe Ọjọru ọsẹ yii ni agbabọọlu naa dagbere faye.
Bẹ́ ẹ̀ sì ni tó bá jẹ́ ti kí a gbani wọlé sí ẹ̀ka ìtọ́jú tó lágbára jùlọ, ìdá ọgọ́rùn nínú àwọn tó kú ti lé ní ẹni ọdún márùnlélọ́gọ́ta.
Tinubu ati Fashola ṣe saa meji pe perepere, ṣugbọn saa kan ni Jakande ati Ambode ṣe .
Amọṣa kabiyesi Ọọni ti ilẹ Ifẹ ti ṣalaye pe ko si ohun to jọọ eyi rara.
Plateau-60 FCT-33 Kaduna-26 Rivers-18 Lagos-17 Enugu-9 Kwara-9 Ondo-9 Nasarawa-6 Gombe-5 Anambra-5 Delta-4 Abia-4 Imo-3 Edo-2 Ogun-2 Oyo-2 Osun-2 Bauchi-1 Kano-1 NCDC ní ènìyàn 252 míràn ló tún fara kásá Covid-19 ní Nàìjíríà Bí ọjọ́ ṣe n gorí ọjọ́ ló dàbí pe ọwọ́jà àjàkálẹ̀ ààrùn coronavirus ń rọ́lẹ̀ síi ni orílẹ̀-èdè Náìjíríà.
Òun náà sì dá mi lóhùn, ó ní, Ìwọ ta ní ń pè mí lórí igi?
Ní ọjọ́ kẹsan-an oṣù kẹrin, ìyàn náà mú láàrin ìlú tóbẹ́ẹ̀ tí àwọn eniyan kò fi rí oúnjẹ jẹ mọ́.
A ko ṣẹṣẹ ma ṣe apero, ko si le tan iṣoro wa bi awọn olori ko ba ṣetan lati ṣe amulo abajade wọn'' O ṣalaye pe ko boju mu bi awọn ẹya kan ti ṣe n da jẹ gbogbo mudunmudun ijọba awarawa, ti awọn to ku ko si ri anfaani ilu jẹ.
Arákùnrin tó bá wọ́n ṣàgbékalẹ̀ òfin ẹgba jíjẹ lórí ìwà àgbèrè kó sínú àgbèrè Mo ń bá ọ́kùnrin 15 sùn lọ́ọ̀jọ́ láti sàn owó ọ̀gá mi- Ngozi O tó gẹ́!
Nitori awọn afẹhọnuhan ko jẹ ki awọn ọkọ raye kọja kaakiri ipinlẹ naa.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Paystack Shola Akinlade: Ìgbésẹ̀ 5 yìí ni mo gbé tíléeṣẹ́ Stripe fi dókòwò $200m pẹ̀lú mi Oloye Elebuibon ni ọkan oun balẹ pe awọn ọmọ oun ko kẹyin si Ifa sise.
Ọgbẹni Adeleke Adegboyega, Alaga Ẹgbẹ Alupupu Ọkada labẹ Ẹgbẹ awọn Ọlọkọ (NURTW) ẹka ti Agboyi-Ketu bẹbẹ fun atunṣe awọn ọna ọkọ ki irn awọn ọkọ loju popo le maa lọ geere.
Kí ẹnikẹ́ni má ṣe máa wá ire ti ara rẹ̀ bíkòṣe ire ẹnìkejì rẹ̀.
Throughout his tenure as an American Ambassador to Nigeria, Amb.
Ìròyìn òfégè: ìwádìí lórí ayédèrú ìròyìn l'Afirika fún ọdún kan
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ọdọmọde to n seranwọ fun awọn ọmọ ita ni Calabar 19 Èrèlè 2018 Oríṣun àwòrán, STREET PRIESTS Àkọlé àwòrán, Pupọ ninu awọn ọmọ̀ ti Okina ran lọwọ lo wa lati ibudo awọn ogunlende Ninu ọpọlọpọ lẹta ti a maa n ri i gba lati ọdọ awọn oniroyin ni ilẹ Afirika, onkọwe Adaobi Tricia Nwaubani ṣe agbeyẹwo bi ọdọmọkunrin kan ṣe n tun aye awọn ọmọde to n gbe lawọn ojupopo.
JJ Omojuwa ni asiko ti to bayi ki awọn olori orileede Naijiria se ojuse wọn bo ti se to ati bo ti se ye.
Ìtàn Aláàfin Aole rèé, tó gbé ìran Yòrùbá ṣépè Má bọ́ sọ́wọ́ gbájúẹ̀, wo ìlànà FRSC láti gba nọ́mbà àdáni fún ọkọ̀ rẹ Kónílé-ó-gbélé Covid 19 ló tú àṣírí àwọn àfipábánilòpọ̀ láwùjọ- Mínísítà ọ̀rọ̀ àwọn obìnrin Kí ni ilé ìgbìmọ̀ aṣòfin ṣe tó ti ran aráàlù lọ́wọ́?
Awujale: Gómìnà Amosun kò fẹ́ràn àwọn ará Ìjẹ̀bú
”Ó bá dáhùn pé, “Àwọn ìwo wọnyi dúró fún àwọn tí wọ́n fọ́n Juda ká patapata, tóbẹ́ẹ̀ tí kò ku ẹnìkan mọ́.
Ohun to wa ku ni ki onikalulku lo ẹtọ yi lọna ti ko fi ni koja ofin to fi aaye gba wọn.
Bi awọn kan ṣe ni ìrírí kọja ẹgbẹ abewú naa ni awọn mii ni asiko ti to ki awọn arugbo lọ fadagba ètò rọ sibi kan.
Ọkọ mi kò kú, ó ń palẹ̀ ọjọ́ ìbí 78 rẹ̀ mọ́ lọ́wọ́
Ṣugbọn kí ẹ máa ṣiṣẹ́ fún OLUWA Ọlọrun, ati fún gbogbo eniyan Israẹli.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Akomolede ati Asa lori BBC: Olùkọ́ Kikelomo Ogunboye tan ìmalẹ̀ sí ìwà olè ọ̀gá ọlọ́pàá Buhari le sọ ipò ààrẹ́ nù tí kò bá yọjú sáwọn aṣòfin - Amòfin Ẹgbẹ́ òṣèlú alátakò takú láti gba èsì ìbò ààrẹ ní Ghana Ọ̀pọ̀ nkan tó n ṣẹlẹ̀ kò jẹ́ kí n gbàgbọ́ pé Naijiria wà ní abẹ́ ìdarí ẹnikẹ́ni - Wole Soyinka Ọmọ ẹgbẹ́ òkùnkùn ṣoro ní Ijebu Ode, ọ̀pọ̀ ẹ̀mí sọnù Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Minisita to n ri si Asa ati ifitonileti lorile-ede Naijria, ogbeni Lai Mohammed, ti pe fun ifowosowopo pelu orile-ede China lati mu idagbasoke ba ile-ise to n se bebi lorile-ede yii.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Blacksmith: èmí ni ìran keje tó jogún iṣẹ́ àgbẹ̀dẹ yii- Alatiṣe Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Gbogbo àwọn eniyan náà bá bọ́ yẹtí wúrà etí wọn jọ, wọ́n kó wọn tọ Aaroni lọ.
Bí Ọlọrun bá pe àwọn tí ó sọ ọ̀rọ̀ rẹ̀ fún ní ọlọ́run, 
Pasitọ Alfred Femi Ajifowowe lo sọrọ yii fun BBC Yoruba.
Naijiria lati yago fun biba opa epo jẹ, nitori iru iwa bayii lewu pupọ, o si
Ẹ jẹ́ kí n sálọ sibẹ, ṣebí ìlú kékeré ni?
Ati pé, ǹjẹ́ àwọn oriṣa àwọn orílẹ̀-èdè náà gbà wọ́n sílẹ̀ lọ́wọ́ ọba Asiria?
Ọpọlọpọ ninu wọn sọ pé, “Ó ní ẹ̀mí èṣù, orí rẹ̀ ti dàrú.
 Ni ipari, O menuba ise akanse ti won n se pelu ifowosopo awon alaga ijoba ibile kookan lati ta awon agbe ji ki won le bere ise oko bi o ti ye ki ere pupo le wole fun won lodun yii nipa gbigbin awon eso to kunju owo ti ENADEP ti pese sile fun  tita lowo pooku kidagbasoke le ba eto ogbin ipinle Enugu.
"Wọn sọ pe awọn kan wà to ni Covid-19, sugbọn ti ko fi àpẹẹrẹ kankan han, tí wọn si le ko ran elomiran.
“Bí ibìkan lára ọkunrin tabi obinrin bá déédé ṣẹ́ funfun, 
Argentina di ipo karun un mu, Croatia dipo ogun mu, bee si ni Iceland wa ni ipo méjìlélógún.
Àwọn tí ó ti wí fún pé: Ìsinmi nìyí,ẹ fún àwọn tí àárẹ̀ mú ní ìsinmi;ìtura nìyí.
 níbẹ ̀ , wọ ́ n ń lò ó gẹ ́ gẹ ́ bí tí ìjọba ń mú lò .
bí àwọn èròjà tí a kà sílẹ ̀ wọ ̀ nyí bá ti dé ọwọ ́ àwọn àgbà Òjẹ ̀ , a ó mú ọkùnrin tí kò sé kò yẹ ̀ gíga òkú Òjẹ ̀ náà lọ sínú igbó ìgbàlẹ ̀ .
Ipago ohun ni won si lojo-Aje(Monday),  ti awon agbaboolu mejo si gunle lojo kannaa kii awon miran o to wa darapo mo won lojo keji.
Ohun tí à ń sọ hàn kedere nígbà tí a rí i pé a yan alufaa mìíràn gẹ́gẹ́ bí àwòrán Mẹlikisẹdẹki, 
wa se iwadii lofintoto idi ti awon osise omo ogun Naijiria se sekupa osise
Lọdun 2016, ijọba apapọ gba ẹgbẹrun lọna igba eeyan siṣẹ labẹ asia N-Power, bẹẹ lo tun gba ẹgbẹrun lọna ọọdunrun eeyan mii lọdun 2017.
ẹni ọdun mẹẹdọgbọn yii ti ṣe ọpọlọpọ orin to gbode kan jade lagbo orin ni Naijiria bii 'Issa Goal' ati eyi to ṣẹṣẹ gbe jade yii 'Soapy'.
 reinmuth se awari planeti yii ni ojo karun osu kewa odun 1931 ni heldeberg .
Ṣugbọn Ọlọrun jí i dìde kúrò ninu òkú.
FIFA ti sọ tẹlẹ pe Amaju Pinnick ni oun damọ gẹgẹ bi aarẹ.
Ó máa ń lò tó ọjọ́ márùn-ún tàbí ọ̀sẹ̀ kan ní ifẹ̀ ní ilé Orímóògùnjẹ́ kí ó tó padà sí Gbọ̀ngán.
Àṣẹ tí OLUWA pa ni pé, ‘Kí olukuluku yín kó ìwọ̀nba tí ó lè jẹ tán, kí ẹ kó ìwọ̀n Omeri kan fún ẹnìkọ̀ọ̀kan ninu àgọ́ yín.
Ṣugbọn Rutu dáhùn, ó ní, “Má pàrọwà fún mi rárá, pé kí n fi ọ́ sílẹ̀, tabi pé kí n pada lẹ́yìn rẹ; nítorí pé ibi tí o bá ń lọ, ni èmi náà yóo lọ; ibi tí o bá ń gbé ni èmi náà yóo máa gbé; àwọn eniyan rẹ ni yóo máa jẹ́ eniyan mi, Ọlọrun rẹ ni yóo sì jẹ́ Ọlọrun mi.
Ẹ kò gbọdọ̀ fi ohunkohun tí ń fi àyà fà lórí ilẹ̀ sọ ara yín di ìríra; ẹ kò gbọdọ̀ kó ẹ̀gbin bá ara yín, kí ẹ má baà di aláìmọ́.
Alakoso egbe yii Chukwuemeka Eze na tun ni awon egbe meteeta yii fowosowopo lati se idanilekoo yii lati lee dena awon ijamba to n maa sele lasiko  eto idibo.
Lati le ṣe akojọpọ awọn itan wn yi,ile iṣẹ BBC lo awọn oṣiṣẹ wọn kaakiri ati awọn amoye lati yẹ iwe iroyin,ori ayelujara kaakiri fun oroyin to ni ṣe pẹlu iṣeku pa awọn obinrin.
Ìṣọ̀kan Yoruba lo yẹ ki a máa lé bayii.
Ní ìgbà kan, ológun kan wọ inú igbó iwin kan.
Eyitayo Jegede Oríṣun àwòrán, Google Àwọn iṣẹ́ mi ko ní ní àlébù kankan Eyitayo Jegede to jẹ oludije ipo gomina ni ipinlẹ Ondo labẹ asia ẹgbẹ oṣelu Peoples Democratic Party, PDP fesi si idahun awọn eeyan pe iṣẹ akanṣe ti awọn fẹ dawọle yoo fun tagba tọdọ ni iṣẹ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù MURIC pè fún ìwọ́de lẹ́yìn Jumat láti tako ìgbésẹ̀ ISI lórí Hijab wíwọ̀ 12 Agẹmo 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 13 Agẹmo 2019 Ọrọ lori gbigba ibori Hijab lori awọn akẹkọ ileewe girama ISI ni fasiti Ibadan ti fa ọpọ awuyewuye sẹyin.
’’Ninu oro tire,Onimo ero, Seyi Makinde je ki o di mimo pe
Oríṣun àwòrán, Getty Images Ninu ọrọ ti o sọ ṣaaju ifẹsẹwọnsẹ ọhun, olukọni ẹgbẹ agbabọọlu Liverpool, Jurgen Klopp jẹ ko di mimọ pe awọn agbabọọlu oun yoo da ọpọlọpọ wahala silẹ fun Manchester United nitori pe bi awọn agbabọọẹu oun ba gba bọọlu daradara, awọn agbabọọẹu Manchester united yoo maa sa kijokijo lati di oju ile wọn ni o.
Atiku tun fikun ọrọ rẹ pe, Buhari ko bọwọ fun aṣẹ ile ẹjọ lorilẹede Naijiria, bẹẹ lo tun fẹsun kan-an lori rira ọkọ ofurufu Tucano.
Èmi ni mo mọ bí eniyan tií rí ìpọ́njú,tí mo mọ bí Ọlọrun tií fi ibinu na eniyan ní pàṣán.
Láìṣe àní, àní, OLUWA Ọlọrun ní, “N óo ṣe sí ọ, bí ìwà rẹ.
Àkọlé àwòrán, Kilomita marunlelaadọta ni afara naa 2.
Labẹ akoso Adebajo, Stationery Stores ni awọn ilumọọka agbabọọlu bi Haruna 'Master Dribbler' Ilerika, Yomi Peters, Julius Akpele, Peter Rufai, Ike Shorounmu, Yakubu Mambo ati Mudashiru Lawal.
Mo wí ní ọkàn ara mi pé, Ọlọrun yóo dájọ́ fún olódodo ati fún eniyan burúkú; nítorí ó ti yan àkókò fún ohun gbogbo ati fún iṣẹ́ gbogbo.
awọn kudiẹkudiẹ to jẹyọ ninu eto iṣuna owo ọdun 2018, ki o si
Ẹ Múra Sílẹ̀ De Ìpadàbọ̀ Oluwa.
A ti mọ òbí 40 nínú 108 t'ọ́mọ wọn bọ́ ní ayédèrú ibùdó atúnwàṣe Ilorin - Ọlọ́pàá Kwara Mo pàṣẹ pé kí ọ̀gá owó ìfẹ̀yìntì tẹ́lẹ̀, Maina sì wà látìmọ́lé- Adájọ́ Ó rẹ ẹni ọdún 49 tó ri ẹ̀wọ̀n ọgọ́ta ọdún he lẹ̀yìn tó bá ọmọ ọdún méjì lòpọ̀ Ìgbà tí òògùn ẹ̀jẹ̀ ríru lè ṣiṣẹ́ jù rèé- Onímọ̀ Wọ́n ti ṣí ilé oúńjẹ oní ọgbọ̀n náírà (N30) ní Kano Alonge sọ pe Igbeneghu ko tii yọju si agọ ọlọpaa ọhun, bo tilẹ jẹ pe wọn fi iwe naa ranṣẹ sii nipasẹ Fasiti Eko.
Bí a ti ṣe ń pe “wine” ní èdèe Putonghua náà ni à ń pe “9”.
O ní àwọn ekute náa le wọ́ ènìyàn fun ara rẹ̀ lọ, síbẹ̀ ko si ètò kankan láti mu atuṣe wa, nitori gbogbo igbo ayika ibẹ lo kún fọ́fọ́.
Kemi Adeosun ni iroyin ni ko si ni Naijiria mọ.
Ogbeni Oshiomole soro yii lasiko to n ba awon akoroyin  soro ni ile-ipolongo egbe won, to wa niluu Abuja leyin ipade to se pelu asoju orile ede Britain fun orile ede Naijiria,Paul Arkwright.
O wa lara ikọ agbabọọlu Naijiria to gba ife ẹyẹ AFCON 2013 lorilẹede South Africa.
Oríṣun àwòrán, @DAWNCommission Gẹ́gẹ́ bi abala kẹrindinlogoji abadofin náà ṣe sọ, ẹnikẹni to ba gbiyanju lati di Amọtẹkun lọ́wọ́ láti ṣe ojuṣe wọ́n, lù u tàbi pa a lára lọnà àitọ lẹ́nu iṣẹ́, ti ṣẹ lábẹ́ òfin, yóò si fi ẹwọ̀n àti ẹgbẹrun lọ́na igba àti ààbọ̀ naira jura."
ọgọrọ awon alatileyin egbe naa  lo wa ni papa isere ti Adokiye Amesimaka nibi
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù AFCON: Cameroun kò ní leè gbàlejò ìdíje nítorí àwọn kùdìẹ̀-kudiẹ kan 1 Ọ̀pẹ̀̀ 2018 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Àjọ CAF ní àyè wà fún Cameroun láti gbàlejò ìdíje AFCON láìpẹ́ bí ó bá tètè tún ilé rẹ̀ tò Orilẹede Cameroun ko ni lee gbalejo idije ife ẹyẹ agbabọọlu orilẹede Afirika, AFCON ti yoo waye ni ọdun 2019 mọ.
Adágún omi kan wà níbẹ̀ tí ń jẹ́ Betisata ní èdè Heberu.
Ṣugbọn kinni ọhun ti wa di nla bayii debi wi pe awọn gbajugbaja oṣere to fẹran iṣẹ wọn n gboṣuba fun wọn.
Bó tilẹ̀ jẹ́ pé ìròyìn òfegè ni pé Buhari fẹ fẹ́ Sadiya, síbẹ̀ àwọn ọmọ Nàìjíríà ń ṣètò ìyàwò náà lórí ayélujára Ìbéèrè àti ìdáhùn pẹ̀lú Seyi Awolowo ti BBNaija lórí BBC Yorùbá Ìran Yorùbá: Àṣà ju àṣà lọ!
Wọ́n lé e kúrò láàrin àwọn eniyan, ó sì bẹ̀rẹ̀ sí jẹ koríko bíi mààlúù.
Yollywood: Odunlade fẹ́ j'ọba, Bolanle Ninalowo fun ìyàwó rẹ̀ ni ẹ̀bun kanka, Pá Kasumu rebi àgbà ree
O fidiẹ mulẹ pe nitootọ ni iku awakọ kọmiṣọnna naa ba ni ninu jẹ ṣugbọn ọ́dílí to jẹ ọlọpaa to n ṣọ kọmiṣọnna ṣi n agb itọju nile iwosan ijọba bayii.
Lai Mohammed ni iye owo epo yii fihan pe, iye owo ti wọn ta epo bẹntirol ni Naijiria lo ṣi kere ju ni ilẹ Afrika, bi o tilẹ jẹ pe awọn ti yọ owo iranwo kuro lori rẹ.
O ṣalaye ipinnu rẹ fawọn eniyan ipinlẹ Ọṣun ni ẹkunrẹrẹ.
79 Áà Ọlọ́run, Bàbá Ayérayé, àwa béèrè lọ́dọ̀ rẹ ní orúkọ Ọmọ rẹ, Jésù Krístì, láti súre àti lati ya wáìnì yìí sí mímọ́ sí ẹ̀mí gbogbo àwọn ẹnití ó mu nínú rẹ̀, pé kí wọ́n lè ṣeé ní ìrántí ti ẹ̀jẹ̀ Ọmọ rẹ, èyítí a ta sílẹ̀ fún wọn; pé kí wọ́n lè jẹrìí sí ọ, Áà Ọlọ́run, Bàbá Ayérayé, pé wọ́n nrántí rẹ̀ nígbàgbogbo, pé kí wọn lè ní Ẹ̀mí rẹ̀ láti wà pẹ̀lú wọn.
Awọn ohun mi to ti ṣẹlẹ lọjọ ti Adamu gba ipo Awọn kan ti kọkọ ro wi pe ijọba apapọ yoo fi kun akoko ti ọga ọlọpaa Ibrahim Idris yoo lo lẹnu iṣẹ nitori igbaradi eto aabo fun idibo gbogbogbo ọdun yii.
” Ó sì tún sọ siwaju sí i pé, kí olukuluku fetí sí ohun tí òun wí dáradára.
Ṣé àwọn odò Abana ati odò Faripari tí wọ́n wà ní Damasku kò dára ju gbogbo àwọn odò tí wọ́n wà ní Israẹli lọ ni?
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Queen Badra Olaitan: Ọ̀pọ̀ nnkan tó bàmí nínú jẹ́ ni ojú mi rí lọ́dún 2020 8 Bélú 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 9 Bélú 2020 Oríṣun àwòrán, Instagram/@queenola2 Yoruba ni oju ẹni maa la, a ri to, oju ẹni maa la, a ri iyọnu, bẹẹ si ni ẹni ti yoo ba ga, ẹsẹ rẹ yoo tiirin.
Oba Ogunwusi to wipe awọn lọbalọba ni akọkọ-kan awọn eniyan, wa kesi awọn ọba lati mase ka'wọ gbera, sugbọn ki wọn fọwọsowọpọ pẹlu ijọba orilẹede yi lati mu itẹsiwaju ba ọr aje orilẹede yi.
Idibo sipo gomina yoo waye ni ọjọ kẹwaa, oṣu Kẹwaa, ọdun 2020.
Ọdun ileya jẹ ọdun nla fun àwọn musulumi ododo kaakiri agbaye.
Coronavirus: Mẹ́rin nínú àwọn mọ́kànlá láti Sokoto tí wón mú l'Oyo ló ní àrùn Covid-19 Àkọlé àwòrán, Gomina Seyi Makinde ni oun ko ni yọnda wọn fun ijọba ipinlẹ Sokoto, ayafi ti wọn ba kọkọ ṣayẹwo Coronavirus Mẹrin ninu awọn eeyan mọkanla to n ti ipinlẹ Sokoto bọ ṣugbọn ti awọn agbofinro mu lẹnu ibode ipinlẹ Oyo si Osun lo ni arun Coronavirus.
Àwọn ọmọ tí Josẹfu bí ní Ijipti jẹ́ meji.
Ìtura alápapọ̀ (Blended Orgasm) Obinrin le gba iru itura yii ti ọkunrin ba fi ọwọ kàn ju ẹya ara rẹ̀ kan lọ lẹ́ẹ̀kan naa.
n kò ní já ọmọ Nàíjíríà kulẹ̀ - Buhari A ó wọ́gilé èsì ìbò tẹ bá dì láì lo ẹ̀rọ ayẹkáádì wò - INEC Àwọn olóṣèlú kan fẹ́ da ìbò gómìnà rú- Burutai Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Nigeria Elections 2019:Ìbò la ní kí ẹ dì, àwa kò bá tìjà wá Awọn meji yoku Peter Ige ati Emmanuel Agim ti wọn wa ninu igbimọ ẹlẹni mẹta naa faramọ idajọ ọhun.
Pa á, kí o sì sin ín.
Níbẹ̀ ni wọ́n rí ọkunrin Juu kan, tí ó ń pidán, tí ó fi ń tú àwọn eniyan jẹ.
Lara awọn ti wọn dijọ kọ iṣẹ tiata lọdọ Akin Ogungbe lasiko naa ni Jimoh Aliu, Charles Olumo (Agbako), oloogbe Afolabi Afolayan (Jagua), ati Femi Adeyemo (Baba n gba life).
nítorí pé nítorí rẹ̀ ni ọpọlọpọ àwọn Juu ṣe ń kúrò ninu ẹ̀sìn wọn, tí wọn ń gba Jesu gbọ́.
 Ọ ̀ pọ ̀ àwọn èèyàn angola ni wọn ń ṣe àtìpó ní brazil .
”Ṣugbọn Jesu kò dá a lóhùn.
 Oba Gbadebo wa tun fi kun oro re pe ki awon osise eleto aabo
Cosmic Crisp apple: kò le bàjé nínú ẹ̀rọ amóhun tutù fún ọdún kan
Adura tí wolii Habakuku kọ lórin nìyí:
Awọn kan bu ẹnu ẹtẹ lu Aarẹ Muhammadu Buhari pe 'ko ni ko awọn ọlọpa ati ọmọ ogun lọ si ipinlẹ Zamfara bo ṣe ko wọn lọ si Ekiti lasiko eto idibo gomina to waye nibẹ.
    Nígbà kan ẹyẹ ẹ̀gà kan tí ó kọ ilée sí orí àgbàdo kan jáde la’ti kọ̀ wá oúnjẹ, o sì fi àwọn ọmọ rẹ̀ sọ ilé kí o bà máa gbọ́ ohun tí olóko yyóò wí nípa ọjọ́ ti yóò ya àgbàdo kí àwọn ba lè tètè sálọ.
Idi ni yi ti Ọ̀bọ fi bẹ̀rẹ̀ si kólòlò ti ó ndún bi “Àmin” titi di ọjọ́ òni.
Ìdí nìyí tó fi se pàtàkì fún gbogbo tolórí-tẹlẹ ́ mù , tòǹga-tòǹbẹ ̀ rẹ ̀ ki kúlukú ní ètò kan gbòógì lọ ́ nà bí yóò se máa náwó rẹ ̀ .
Ileeṣẹ naa ninu atẹjade kan ti Stanley Olisa fi sita sọ pe igbesẹ naa nira fawọn ṣugbọn ko si ohun tawọn le ṣe ju pe ki awọn din owo oṣu ku tabi kawọn le awọn eeyan lẹnu iṣẹ.
Eleyi wọ́pọ laarin àwọn Òṣèlú, Ọ̀gá Òṣìṣẹ́ Ìjọba àti àwọn ti ó ri owó ilú kó jẹ.
Ṣé o kò mọ̀ wí pé níwọ̀n ìgbà tí ọmọ Jese bá wà láàyè, o kò lè jọba ní Israẹli kí ìjọba rẹ fẹsẹ̀ múlẹ̀?
”Olokoowo omo orile-ede Naijiria, Emeka Offor so pe, awon alabasisepo ohun ti setan lati da ile-ise epo robi ati ina mona-mona sile.
Osoba: Àwọn tó ń bèèrè fún àtúntò ń jà fún ikùn ara wọn ni
Oluranlọwọ fun Kashamu lori ọrọ to jẹ mọ iroyin, Austin Oniyokor sọ wi pe awọn adari ẹgbẹ lo parọwa si Kashamu lati dije dupo naa lẹyin Adeleke Shittu jọwọ ipo rẹ lẹyin idibo abẹle.
Ko si ẹni ti ijọba ko le da silẹ.
Ní ọ̀pọ̀ ìgbà tí a ba sá kúrò ni àhámọ ti àwọn ará ìlú sì gbọ́ pé ahamọ Boko Haram ni a ti wa, wọ́n fà wá le wọ́n lọ́wọ́ pada, nítori wọn ò fẹ́ ni ǹkan ṣe pẹ̀lú wọn.
Ọpọlọpọ ololufẹ ere bọọlu yoo ranti wipe, ọkan ṣoṣo bi iru aṣekagba yii lo ti waye sẹyin ri, iyẹn ni ọdun 2008.
N óo gbà ọ́ lọ́wọ́ àwọn eniyan burúkú, n óo sì rà ọ́ pada lọ́wọ́ àwọn ìkà, aláìláàánú eniyan.
Àwọn ọ̀gágun tí ó ti fẹ̀yìntì tàbí àwọn tí wọn ṣe àtìlẹ́yìn fún láti dé orí ipò ni ó ti ń tukọ̀ orílẹ̀-èdè Nàìjíríà láti ọdún 1999 tí ìjọba tiwantiwa ti padà.
Bí ẹnìkan bá kíi, oúnjẹ dé, nítorí jíjẹ ni wọn ń jẹ òkú ara wọn ṣùgbọ́n wọn ko kẹ́ déédéé pa ara wọn jẹ.
Jesu bá sọ fún àwọn eniyan náà pé, “Ẹ jáde wá mú mi pẹlu idà ati kùmọ̀ bí ìgbà tí ẹ wá mú olè.
“Ẹ kò gbọdọ̀ jẹ ohunkohun tí ó bá kú fúnrarẹ̀, ẹ lè fún àwọn àlejò tí ń gbé ààrin yín, kí ó jẹ ẹ́, tabi kí ẹ tà á fún àjèjì, nítorí pé, ẹ̀yin jẹ́ ẹni mímọ́ fún OLUWA Ọlọrun yín.
Ẹ̀yin ẹ̀ṣọ́, ẹ kò gbọdọ̀ fààyè gba jíjí àpótí ìdìbò ní Kogi àti Bayelsa- Buhari Ọlọ́pàá kan jáde láyé, èèyàn méjì fara gbọta lásìkò ìdigunjalè ní Falomo l‘Eko ‘Ilé ẹjọ́ kò gbé ẹ̀sùn ìfipánílòpọ̀ yẹ̀wò, à ń lọ sí ilé ẹjọ́ - Busola Dakolo Ètò ìdìbò gómìnà ìpínlẹ̀ Kogi àti Bayelsa m bọ̀ lọ́nà- INEC Oríṣun àwòrán, facebook/Alex Akinyele Àkọlé àwòrán, Alex Akiyele jade laye lọjọ karundinlogun, oṣu kọkanla, ọdun 2019 Ni ọdun 1967, Akinyele ṣiṣẹ ni ileeṣẹ ijọba to n risi wọlewọde orilẹ-ede ni ipinlẹ Eko.
Oríṣun àwòrán, NUJ national Headquater O wa beere pe ki wọn tu akọroyin kan, Tom Oga Uhia, tii se oludasilẹ iwe iroyin Power Steering Magazine to wa lahamọ silẹ.
Áà, Ọlọrun mi, ranti ohun tí Tobaya ati Sanbalati ati Noadaya, wolii obinrin, ṣe sí mi, ati àwọn wolii yòókù tí wọ́n fẹ́ máa dẹ́rù bà mí.
Oríṣìíríṣìí ọ̀rọ̀ kẹ́lẹ́kẹ́lẹ́ ni àwọn eniyan ń sọ nípa rẹ̀.
Ọ̀gọ̀rọ̀ èèyàn lórí ayélujára bú Dalung lórí owó IAAF Bakan naa ni Olori Ajọ to n risi eto idibo lorilẹ-ede Malawi, Jane Ansah, ti parọwa fun ki gbogbo nkan wa ni irọwọrọsẹ lorilẹ-ede naa.
Kí OLUWA dájọ́ láàrin èmi pẹlu rẹ, kí ó gba ọ̀rọ̀ náà yẹ̀wò, kí ó gbèjà mi, kí ó sì gbà mí, lọ́wọ́ rẹ.
Iṣẹ ilẹ gbígbá, fifọ gọ́tà, didari ọkọ̀, ati oju ọna sise, wa lara isẹ tawọn ọdọ yoo ṣe fun oṣu mẹta, ₦20,000 si ni owo oṣu wọn.
ẹ̀yin ni ẹ jẹ ẹran ara àwọn eniyan mi, ẹ bó awọ kúrò lára wọn, ẹ sì fọ́ egungun wọn sí wẹ́wẹ́, ẹ gé wọn lékìrí lékìrí bí ẹran inú ìsaasùn, àní, bí ẹran inú ìkòkò.
Ni àwọn ọmọ-ẹ̀yìn Kristi bá pinnu pé olukuluku àwọn yóo sa gbogbo agbára rẹ̀ láti fi nǹkan ranṣẹ sí àwọn onigbagbọ tí ó ń gbé Judia.
Oríṣun àwòrán, Adegboyega Ajani Idi ree to fi yẹ ka tete san sokoto wa ko le lati gbogun tiwa ajẹbanu naa.
Ìjìyà yìí dé bá Juda láti ọ̀dọ̀ OLUWA, láti pa wọ́n run kúrò níwájú rẹ̀, nítorí ìwà ẹ̀ṣẹ̀ Manase ọba, 
Gomina ipinlẹ Ondo, Rotimi Akeredolu lo sọ bẹ ẹ lori awuyewuye to n waye laarin oun ati igbakeji rẹ.
Gerard Pique, to jẹ ogbontarigi onkorin yoo maa ṣatilẹyin fun ololufẹ rẹ lati ódun to ti pẹ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Coronavirus in Nigeria: Wo àwọn ohun tó yẹ kí o mọ̀ nípa ọ̀nà láti dáàbò bo ara rẹ lọ́wọ́ Coronavirus 28 Èrèlè 2020 Oríṣun àwòrán, Getty Images Aarun Coronavirus ti wọ orilẹede Naijiria bayii, eyi kii sii ṣe iroyin tuntun mọ bayii.
O fi kun pé, ìyàtọ to wa láàrin èsì ìdìbò ẹni to wọle àtí ẹni to fi ìdi rẹmi kéré gbáà si àwọn to forúkọ silẹ̀ nibi ti àtúndi ìbò ti waye, nítoripe wọn kò fún àwọn ènìyàn míràn láàyè láti dibo nígbà ti ẹ̀ri wà pe àwọn ẹgbẹ́ alátako ń díbo ní àìmọye ìgbà.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ìdílé tí ọkọ da ọmọ síta tóríi ojú Búlùú tí wọ́n ní bá BBC sọ̀rọ̀ Ọpọlọpọ ipinlẹ ni Ariwa Naijiria ti gbiyanju lati fi opin si ti tọrọ baara.
Alukoro ileeṣẹ ọlọpaa ni ipinlẹ Ondo, Fẹmi Joseph to fi idi iṣẹlẹ naa mulẹ to si ni awọn ọlọpaa yoo gbe awọn oṣiṣẹ ileewosan naa ti ọrọ ọhun kan fun ifọrọwanilẹnuwo laipẹ.
Ó sì ń jà bí ìjì líle.
Gomin aipinlẹ Oyo, Seyi Makinde Oríṣun àwòrán, Twitter/@seyiamakinde Gomina ipinlẹ Oyo naa kede3 loju opo Twitter rẹ pe oun lugbadi arun Coronavirus ni nkan bii ọgbọnjọ oṣu kẹta.
Leah Sharibu pé ọmọ ọdún 16 ní àhámọ́ Boko Haram Wọn ji akẹkọbinrin to le ni ọgọrun un gbe ni Government Girls Science and Technical school nipinlẹ Yobe loṣu keji ọdun 2018Dapchi School ṣí padà lẹ́yìn oṣù mẹ́sàn án.
Nígbà tí mo bá wà láàrin àwọn aláìlera, èmi a di aláìlera, kí n lè jèrè àwọn aláìlera.
Ọpọlọpọ eniyan ni wọ́n ti kọ ìròyìn lẹ́sẹẹsẹ, nípa ohun tí ó ti ṣẹlẹ̀ láàrin wa; 
"Oríṣun àwòrán, Instagram/ Toyin Abraham Toyin ni ""Mo wo ara mi, mo si ronu nipa aye yii ati ohun gbogbo to wa ninu rẹ, O si han si mi pẹlu ẹdun ọkan pe asan ni aye, omulẹ mofo."
Òtítọ́ ni pé àwa náà jẹ́ aláìlera pẹlu rẹ̀, ṣugbọn a óo wà láàyè pẹlu rẹ̀ nípa agbára Ọlọrun ninu ìbálò wa pẹlu yín.
Ṣugbọn èmi dàbí igi olifi tútùtí ń dàgbà ninu ilé OLUWA,mo gbẹ́kẹ̀lé ìfẹ́ Ọlọrun tí kì í yẹ̀, lae ati laelae.
Olori Damilola Adeyemi: Oríṣun àwòrán, Damilola Adeyemi Olori Damilola ni iyawo kekere laarin awọn arẹwa Alaafin bayii, oun si ni oju baba ati afẹfẹ tuntun ti Alaafin n mi simu.
21 Èbibi 2018 Àkọlé àwòrán, Wákàtí a má jó bi pé kò sáré rárá nínú àwẹ̀.
OLUWA jẹ mí níyà pupọ,ṣugbọn kò fi mí lé ikú lọ́wọ́.
"Mi ò ṣẹ̀ máa pín ǹkan lọ́wọ́ ara mi fún aráàlù, ilé mi gangan kọ́ ni wọ́n ti jí ""Palliative"" kó - Họ́nọ́rébù Agunbiade Ẹ má à gbìyànjú láti bo àṣírí ìpànìyàn tó wáyé ní Lekki, á ní ẹ̀rí tó dájú - Amnesty International Ọmọ Nàìjíríà kan gbé Fásitì Oxford lọ sílé ẹjọ́ tàko oríkí ọrọ 'Mortgage' nínú ìwé àtúmọ̀ ọrọ Ènìyàn 5, ilé 25 ilé ìtajà 16 àti àwọn ǹkan mírà lo bá ìṣẹ̀lẹ̀ iná náà rìn."
Coronavirus: A kò nílò láti ti àwọn ilé ìwé àti ilé ìjọsin wa pa- Minista ètò ìlera
Mo fún Esau ní òkè Seiri bí ohun ìní tirẹ̀, ṣugbọn Jakọbu ati àwọn ọmọ rẹ̀ lọ sí ilẹ̀ Ijipti.
Tọmọdé tàgbà ló sì mọ̀ wí pé ní àgbàlá Olόwό-Ìbínú ni igi owó ti ńso.
2019 Guber election: Mi ò fara mọ èsi ìdìbò Ọyọ́ ‘Kò tọ́sí Adeleke láti díje dupò gomina Ọṣun’ Ààrẹ Abdulaziz Bouteflika ti kowe fipo silẹ Magu,'estimated billing' àti àwọn ohun míràn tí ilé aṣòfin Nàìjíríà kò rí yanjú Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ojojúmọ ní mọ ń kẹ́kọ̀ọ́ lára ọmọ mi to jẹ akanda Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Àyà mi kọ́kọ́ máa ń já nígbà ti mo ṣẹ̀ṣẹ̀ bẹ̀rẹ̀ -Alaga iduro ọkùnrin Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Ọkọ arabinrin to n rọbi naa, Edmond sọ iriri rẹ fun Ileeṣẹ Iroyin BBC ati bi o ṣe ṣẹlẹ.
Lẹyin ọpọlọpọ lilu yii ni mama naa daku, ti wọn si fun un ni agbo kan mu ki wọn to gbe e lọ si ile rẹ nibi to ku si.
Ijọba ko pese rẹ fun wọn Kọmisana feto ẹkọ salaye pe, isẹju mẹẹdọgbọn pere ni wọn yoo fi maa se idanilẹkọọ fawọn akẹkọọ lori isẹ kọọkan, ti wọn yoo si se isẹ mẹfa laarin wakati meji aabọ lojumọ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ogbomsho shooting, End Sars, End SWAT: Isiaka fi ọmọbìnrin kan àti ìyàwó tó lóyún sínú síl Abayomi ni ninu eniyan 441 to wa ni ileewe naa, ni 181 ninu wọn ti ko arun Covid-19 ọhun.
Òkìkí rẹ̀ kàn ká gbogbo ìgbèríko.
Eniyan bíi yín ni àwa náà.
Nígbà tí ìjì líle bá ń jà, a gbá ẹni ibi lọ,ṣugbọn olódodo a fẹsẹ̀ múlẹ̀ títí lae.
"Oju buluu ti Risikat ni ṣeeṣe ko jẹ ṣegeṣege to maa n waye ninu ẹyinju, gẹgẹ bi Dokita Yetunde Oladipo ṣe sọ fun wa.
Inú bí Dafidi nítorí pé Ọlọrun lu Usa pa, láti ọjọ́ náà ni a ti ń pe ibẹ̀ ní Peresi Usa títí di òní.
Oríṣun àwòrán, Instagram/abiola ajimobi APC: Ajimobi di adelé alága àpapọ̀ ẹgbẹ́ òṣèlú Ajọ Amuṣẹya ẹgbẹ oṣẹlu APC, NWC ti kede Sẹnetọ Abiola Ajimobi gẹgẹ bi Alaga ẹgbẹ tuntun ni Ila Orun orilẹede Naijiria.
Osinbajo ni Ẹ ku ọjọ ibi, Ọjọgbọn!"
Nigba to n salaye idi ti eyi yoo fi ri bẹẹ, Oloye Bello ni ọrọ owo tijọba n fun awọn , eyiun Oluwo, awọn ijoye ati Baalẹ lo fa jaadi yii nitori pe Oluwo fẹ maa da owo naa na.
’ Oluwa bá dá mi lóhùn pé, ‘Dìde kí o máa lọ sí Damasku.
Nítorí náà, mo dojú ìjà kọ àwọn wolii tí wọn ń sọ ọ̀rọ̀ tí wọn gbọ́ lẹ́nu ara wọn, tí wọn ń sọ pé èmi ni mo sọ ọ́.
Wàyí ò, omi òkun ti fọ́ ọ sí wẹ́wẹ́,o ti rì sí ìsàlẹ̀ òkun.
Ibo ni n óo yà sí?
Kí ló mú Obasanjo ti ilẹ̀kùn mọ́ ẹbí, òṣìṣẹ́, ojúlùmọ̀ ní ibi òkú àna rẹ̀?
Oun ni omọ Awowlọwọ to dagba ju ki iku to mu un lọ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ibadan Tanker Fire Accident: Ṣúnkẹrẹ fàkẹrẹ gbalẹ̀ lẹ́yìn ìjàmbá ọkọ̀ epo 18 Ìgbé 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 19 Ìgbé 2019 Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ibadan Tanker Fire Accident: Ènìyàn méji ló kú nínú ìjàmbá ọkọ̀ agbépo Ẹni to ba jẹ ori ahun, yoo sunkun lọsan Ọjọbọ nilu Ibadan, nigbati ọkọ agbepo kan dede ṣubu ni agbegbe Sawmill-Iwo Road lopopona marosẹ Eko si Ibadan.
Oriṣiiriṣi awọn nkan lo maa n saaba wu oloyun jẹ nipo iloyun.
World Happiness Day: Orílẹ̀èdè Austria ló gba ipò Australia nínú àwọn èèyàn tó láyọ̀ jùlọ
Bayii, wọn ti ṣafikun si gbedeke asiko too le san owo ori lai san ele sii fun oṣu mẹfa.
Naijiria jawe olubori nigba mejila ọtọọtọ, ti South Africa si jawe olubori nigba kan.
Oluwo ko ṣai sọ nipa Olori mii to n bọ laafin Iwo lẹyin ti o ti kọ Olori tẹlẹ, Chanel Chin silẹ.
Ọjọ Aje ni wọn gbe Adeyemi lọ ile ẹjọ kekere to wa ni Oke Eda, Akure, lori ẹsun pe o gbèrò lati pa Khadijat pẹlu awọn afurasi miran ti wọn ti fẹsẹ fẹ.
Abilekọ Oluwatoye ni ko si oun to buru ninu ki ọkọ mu ọyan aya iyawo rẹ lasiko to ba n t'ọmọ lọwọ, nitori ko si ewu kankan fun ọkunrin bẹẹ.
''A kò gbà pé Eyitayo Jegede fìdírẹmi, Àjọ INEC ló ṣe aṣemáṣe'' Awọn ololufẹ ẹgbẹ oṣelu PDP ti ni awọn ko gba wi pe Eyitayo Jegede fidirẹmi, amọ ajọ eleto idibo INEC lo ṣe magomago fun wọn.
Nítorí náà, OLUWA Ọlọrun ní, “N óo fi ibinu mú kí ìjì líle jà, n óo fi ìrúnú rọ ọ̀wààrà òjò ńlá, n óo mú kí yìnyín ńláńlá bọ́ kí ó pa á run.
Òkè Ìrònú ń bẹ létí odi ọ̀run.
Dajudaju, ko ba ti wu awọn dokita Naijiria to lati duro sile ni orilede wọn ṣugbn wọn ni ijọba ko wu awọn lori.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Thai Deer: Pátá awọtẹlẹ, rọba àti ìdọ̀tí kilo méje ṣekú pa Ìgalà 28 Bélú 2019 Oríṣun àwòrán, The Protected Area Regional office 13 (Phrae) Àkọlé àwòrán, Wọn ba orisirisi idọti ninu Igala naa ti wọn ṣokunfa iku rẹ Igala kan ti wọn ri oku rẹ ni ọgba iko-ẹranko-si kan lariwa orile-ede Thailand ni awọn alaṣẹ ti ba idọti to to iwọn kilo meje ninu rẹ.
” Ati òwe kan tí wọn máa ń pa pé, “Ẹlẹ́dẹ̀ tí wọ́n fọ̀ nù yóo tún pada lọ yíràá ninu ẹrọ̀fọ̀.
O ṣalaye siwaju sii pe ohun ti aba yii wa fun naa ni lati dena ifẹmi ṣofo awọn Naijiria lori ọrọ ikorira tawọn kan sọ eleyii to da rogbodiyan silẹ.
Nítorí pé Siria, pẹlu Efuraimu ati ọmọ Remalaya ti pète ati ṣe ọ́ ní ibi.
Iwa ipa ko le gba awọn akẹkọ Dapchi pada O ni wọn da awọn akẹkọbinrin naa silẹ ni nkan bi aago mẹta oru pẹlu iranlọwọ awọn ọrẹ orilẹede Naijiria, ati pe ijọba ko san kọbọ fun itusilẹ wọn.
Igbimo Coker Commission of Inquiry ni Oloye Awolowo jẹbi lori isubu ajo naa nitori ko tẹlẹ ilana to tọ fun ẹni to ba di ipo ilu mu lati tẹle (Coker Commission, 1962; Magid, 1976: 73).
 bí èyí bá wáyé , ewu ṣíṣẹ ̀ jẹ ̀ àti àwọn ìṣoro kídìnrín maa ń pọ ̀ si .
Ejiofor, tun so pe opolopo  awon eniyan to wa ni okeere lo n tun ilu won se, o wa ro won “ lati maa lowo ninu eto idagbasoke orile ede Naijria’’.
Ẹ̀wẹ̀, àgbẹnusọ ilé iṣẹ́ tó ọ̀rọ̀ abẹ́lé, Mohammed Manga sàlàyé pé, owó ayípada ibudó tuntun láti ọ̀ds ìjọba kò ju ẹgbẹ̀rún lọ́nà ọ̀gbọ̀n náírà lọ Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Ariwo gbaye kan lori rẹ nitori lara awọn oriṣa to gbajugbaja julọ ni ilẹ Yoruba ni Ọṣun wa koda ilu mẹta ọtọọtọ ni wọn ti n ṣe ọdun ọṣun oṣogbo - ilu Osogbo, ilu Ifẹ ati ilu Ifaki Ekiti.
O ni awon ile-eko naa yoo wa
Governorship Election Results: Àgbùnbánirọ̀ tó bá INEC ṣiṣẹ́ kú nínú ìjàmbà ọkọ̀ ojú omi l'Ondo Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, APC jáwé olúborí nípínlẹ̀ Ekiti Iroyin fihan e ọmọ Naijiria meji wa lara awọn to ku ninu baalu orilẹ-ede Ethiopia kan, Boeing 737 to ja lulẹ loju ọna rẹ lati Addis Ababa si Nairobi.
" Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Blind DJ: Etu Omotayo kò ríran àmọ́ ó le to irinṣẹ́ eléré pọ̀ láti kọrin láì sí ìrànwọ́ Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Peers of Heaven: Ààrẹ ẹgbẹ́ Emèrè ní àwọn ti wà tipẹ́, wọn kò pariwo síta ni18 Ògún 2020 Ondo Election: Akeredolu f'ògún ikọ̀ Àmọ̀tẹ́kùn Ondo gbárí fún ìdìbò tó ń bọ̀12 Ògún 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Latari bi awọn ọmọ janduku kan ṣe wọ Ile Igbimọ Aṣofin-agba orilẹ-ẹde Naijiria ni ilu Abuja ti wọn si ji ọpa aṣẹ Ile Aṣofin naa lọ, Ile Igbimọ Aṣofin Ipinlẹ Eko ti bu ẹnu lu iwa naa pe o jẹ ohun idojuti patapata fun eto oṣelu tiwantiwa ni orilẹ-ede Naijiria.
Ẹ kò gbọdọ̀ jẹ ajá mọ́' Seyi Makinde, fún mi ní ₦156m lórí iṣẹ́ ọpọlọ mi to lò láì tọ́ - Agbaṣẹ́ṣe Ta ló da 'ewé' bo N4.
Lẹyin naa lo gba ẹrọ ibanisọrọ ti wọn si fẹsẹ fẹ.
Eyi to n se afihan pe oku naa jẹ ọlọrọ nigba aye rẹ.
 Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Bakare Mubarak: ọ̀pọ̀ èèyàn ló máa ń fẹ́ dúró sí ẹgbẹ́ mí tójú si máa n tì mí ""Nítori ìdí èyí kò si Gómìnà yálà ẹyọ kan tàbi lápapọ̀ to ni ẹ̀tọ tàbi agbára láti ṣe ìdásílẹ̀ ilé iṣẹ́ tàbí àjọ kankan to níṣe pẹ̀lú èètò ààbo."
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ìbẹ̀rù nípa Amotekun ló ń mú káwọn èèyàn kan máa wí ìwíkùwí - Soyinka Wo àwọn àdúgbò tí ìpínlẹ̀ Eko ti fòfin de ọ̀kadà àti Marwa Àwa ò ri lẹ́ta kankan gbà láti ọ̀dọ̀ Malami lóri ọ̀rọ̀ àwọn alága Kansu - Makinde Àwọn nkan tó yẹ kí o mọ̀ nípa ìgbẹ́jọ Trump tí yóò blrẹ̀ l'ọ́dọ̀ àwọn Sẹ́nétọ̀ Mí ò le nífẹ̀ẹ́ obìnrin Nàìjíríà kankan mọ lẹ́yìn ti mo ti tọ́ obìnrin òyìnbó wò- Issa Oji le lugba eeyan lo ti lugbadi aarun naa eyi to n ran lati ọunjẹ inu okun.
”Jesu wí fún un pé, “Máa bọ́ àwọn ọ̀dọ́ aguntan mi.
Loju opo Twitter awọn eyan ti n bẹnu atẹ lu igbese yi.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Cerebral Palsy: àrùn tó n gba omijé lójú ẹni láìnídìí Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Cerebral Palsy: àrùn tó n gba omijé lójú ẹni láìnídìí 7 Agẹmo 2019 Odun 2016 ni wọn ni mo tun ni arun jẹjẹre mọ cerebral palsy mi -Steph Oriṣiiriṣii àrùn lo n yọ ẹda lẹnu ti ko jẹ ki eniyan le ṣe ohun to wuu ni ọpọ igba.
Oríṣun àwòrán, EPA Iṣẹlẹ yi n waye saaju abọ igbẹjọ ẹsun pipa Olootu ijọba tẹlẹ, Rafik Hariri lọdun 2005.
Adamu tún bá aya rẹ̀ lòpọ̀, ó lóyún, ó sì bí ọmọkunrin kan.
Ó fi kun pé, àjọ ọ̀hún ti yọọ́ kúrò lára àwọn tó ń tèlé mótò abẹnugan, àjọ náà fi kun pé kedere ni àwọn yóò ṣe gbogbo ìwádìí àti ìdája ọ̀rọ̀ náà.
Inú mi dùn nígbà tí wọ́n wí fún mi pé,“Ẹ jẹ́ kí á lọ sí ilé OLUWA.
"alángba àpáta galápagos ( "" microlophus albemarlensis "" ) , tí wọ ́ n tún mọ ̀ sí alángba àpáta albemarle , jẹ ́ ẹ ̀ yà alángba àpáta tí ó wọ ́ pọ ̀ ní erékùṣù galápagos níbi tí ó ti wà ní ọ ̀ pọ ̀ lọpọ ̀ erékùṣù ìwọ ̀ oòrùn archipelago : àwọn erékùṣù ńlá , isabela , santa cruz , fernandina , santiago àti santa fe , àti àwọn ọ ̀ pọ ̀ lọpọ erékùṣù kékèké : seymour , baltra , plaza sur , daphne major àti rábida ."
Àṣé bí ọkùnrin afọ́jú náà ṣe nkàwé lọ, ó tún fi etí sílẹ̀ sí ìkéde awakọ̀ èrò.
Mo tún sọ fún àwọn eniyan náà pé, “Kí olukuluku ati iranṣẹ rẹ̀ sùn ní Jerusalẹmu, kí wọ́n lè máa ṣọ́ ìlú lálẹ́, kí wọ́n sì máa ṣiṣẹ́ ní ojú ọ̀sán.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Dele: 'Oṣù mẹ́jọ ni wọ́n tí yọ ina wa ló jẹ́ kí Dele lọ ṣe iṣẹ́ àmúrelé nídìí ẹ̀rọ ATM 25 Èrèlè 2020 Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Dele, ọmọdé tó ń fi iná ẹ̀rọ ATM ṣe iṣẹ́ àmurelé sọ ìdí tó fi kára mọ́ ẹ̀kọ́ rẹ̀ fún BBC Yorùbá Rasheed Fathia Dele ni iṣẹ nọọsi ni oun fẹ ṣe lọjọ waju lo jẹ ki oun mura si ẹkọ oun.
O ni o yẹ ki a ronu lori idagbasoke awọn ewe Naijiria ati ipese ọjọ iwaju rere fun awọn ọmọ wa.
Kí á tó dá àwọn òkè ńlá sí ààyè wọn,kí àwọn òkè kéékèèké tó wà, ni mo ti wà.
Paroparo ni awọn ojupopo da ni ọsẹ mimọ Lai fi gbogbo nkan to n ṣẹlẹ ṣe, ongbẹ sọọsi si n gbẹ ọpọlọpọ Kristẹni - ọjọ isinmi to kọja dun wọn pupọ nitori o jẹ ayajọ ọjọ Isinmi Ọpẹ.
Nígbà tí Atalaya gbọ́ ariwo àwọn tí wọn ń ṣọ́ ààfin ati ti àwọn eniyan, ó jáde lọ sí ilé OLUWA níbi tí àwọn eniyan péjọ sí.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Temitope Akinnusi: Ọ̀pọ̀ iléeṣẹ́ ló takú láti gbà mí síṣẹ́ torí mo ní ojú kan O to ida ogoji dokita Naijiria to wa ninu ẹgbẹ yii ti wọn n beere fun ẹkunwo owo oṣu, itọju to peye lẹnu iṣẹ, atunṣe to yẹ si awọn ile iwosan Naijiria paapaa lasiko Coronavirus yii Aarẹ ẹgbẹ yii, Dokita Aliyu Sokomba sọ fun ileeṣẹ iroyin AFP pe awọn dokita to n tọju alaisan coronavirus naa yoo darapọ mọ wọn lasiko yii laiyọ ẹnikẹni silẹ Ki lo ti ṣẹlẹ sẹyin?
Orilẹ-ede Egypt gba ami ayo bọọlu kan sáwọ̀n Zimbabwe ti wọn ko si ri da pada.
Àbá yìí wà nínú àbájade ìwádìí ti àjọ náà ṣe ti àlága wọn Muhuyi Magaji si fọ́wọ́ si.
Gba ara rẹ là kí o sì gba àwa náà là!
Àwọn ìṣẹ̀lẹ̀ tí ó níláti ṣẹlẹ̀ láìpẹ́ nìyí, tí Ọlọrun fún Jesu Kristi, pé kí ó fihan àwọn iranṣẹ rẹ̀.
Bí a kò ti ṣe lè ka iye ìràwọ̀ ojú ọ̀run, tí a kò sì lè wọn yanrìn etí òkun, bẹ́ẹ̀ ní n óo ṣe sọ arọmọdọmọ Dafidi ati arọmọdọmọ Lefi alufaa, iranṣẹ mi, di pupọ.
“O óo fẹ́ iyawo sọ́nà, ẹlòmíràn ni yóo máa bá a lòpọ̀.
Ṣugbọn sisọ ọrọ odi si Anabi Muhammed ko tọna rara ninu ẹsin Islam.
Otito oro ni pe lati odun 1999 ti a ti pada si ijoba tiwa-n-tiwa , ila-Gusu ti se odun mejo (1999-2007) Ariwa ti se odun marun un(2010-2015).
O n kopa ninu ọpọlọpọ ere idaraya pẹlu ere sisa lori yinyin.
 Wọn sare gbe e lọ sile iwosan, amọ gbogbo ileewosan ti wọn gbe e de lo sọ pe awọn ko ni aporo ejo lati lo fun un, nitori pe awọn eniyan kii ṣaba wa gba a.
Ó bá dáhùn pé, “Mò ń jowú nítorí OLUWA, Ọlọrun àwọn ọmọ ogun, nítorí pé àwọn ọmọ Israẹli ti da majẹmu rẹ̀, wọ́n ti wó pẹpẹ rẹ̀ lulẹ̀, wọ́n sì ti fi idà pa àwọn wolii rẹ̀.
Bí ẹ bá yá eniyan lówó tí ó jẹ́ ẹni tí ẹ nírètí pé yóo san án pada, kí ni fáàrí yín.
Aarẹ ni eto abo ati idagbasoke ọmọniyan wa lara koko ohun ti iṣuna naa yoo mu gbọ julọ.
Makinde o mikan, o tẹra mọ ipinnu rẹ o si kuro ni ẹgbẹ oṣelu PDP lọ si ẹgbẹ
Ọpọlọpọ miliọnu eniyan, paapa awọn obinrin ni Asia ati Afrika lo n gba oriṣiriṣi ọna lati di eniyan pupa.
Ìjọba maa n gbé omi wá fún wa tẹ́lẹ̀, ṣùgbọ́n, wọ́n ti dáwọ́ rẹ̀ dúró.
Wo bi wọ́n ṣe n ṣe àmójútó ilé ìjọsìn Prophet Israel Oladele, CCC Genesis Global Kà nípa ibi tí wọ́n bí Àrẹ̀mọ tuntun Ọọ̀ni Ife sí, àti orúkọ tó ń jẹ́ Ẹ̀tanú pé Olùṣọ́ Genesis kò fẹ́ Laide Williams-Oni ló ṣe rán an lọ́ sí ẹ̀wọ̀n ọdún kan - CCC Genesis Global Taribo West wọ gàu lọ́wọ́ ọmọ Nàìjíríà lẹ́yìn tó sọtẹ́lẹ̀ pé Trump yóò wọlé ìbò ààrẹ Amerika Kilo gbe e de ijọ Celestial?
Ile Asofin Eko: Ọjọ́ Kẹrin oṣù Kejì ni Ambọde yóò yọjú síwájú ilé
O fikun ọrọ rẹ wi pe ohun to f'oun bayii ni lati dari wale ki o di ọjọ Satide.
Ni bayii, gege bi ile-ise agbofinro ni Russia, won ni awon ti mu awon merin kan ti won ro pe o le lowo si isele ijamba ina ohun, ti o fi mo awon olutaja ati eni ti o ni ile itaja naa.
Eyi ṣẹlẹ nitori Trump kọ lati ṣe iṣẹ rẹ botitọ ati boti yẹ, mo si gba pe ẹsan 'karma' n ṣiṣẹ lootọ.
N óo máa rìn fàlàlà,nítorí pé mo tẹ̀lé ìlànà rẹ.
Oríṣun àwòrán, Reuters Goolu ti Lucas Perez jẹ nipa gbe e silẹ gba a sile ni iṣẹju karun abala kini ni ikọ Alaves fi lewaju ninu ifẹsẹwọnsẹ naa.
Mo bẹ̀bẹ̀ kí OLUWA dáríjì mí nígbà tí mo bá tẹ̀lé oluwa mi lọ sinu tẹmpili Rimoni, oriṣa Siria láti rúbọ sí i.
Kí ló dé tí o fi ń ṣe ojúkòkòrò sí ọrẹ ati ẹbọ tí mo bèèrè lọ́wọ́ àwọn eniyan mi, tí o sì gbé àwọn ọmọ rẹ ga jù mí lọ; tí wọn ń jẹ àwọn ohun tí ó dára jùlọ lára ohun tí àwọn eniyan mi bá fi rúbọ sí mi ní àjẹyọkùn?
Igbẹkẹle rẹ̀ já sí asán,ìmúlẹ̀mófo ni, bí òwú aláǹtakùn.
Lọdun 2018 ni wọn yọ ọwọ kilanko Kashamu kuro ni ẹgbẹ oṣelu PDP ko to gba ile ẹjọ lọ ni Abuja ti wọn si yi i pada loṣu kẹwaa, ọdun 2018.
Ìgbà tí a máa dé ọ̀hún iwin ti yọ ojú Gọ̀ǹgọ̀ṣútàkìtì, wọ́n sì de Ìnàkí-gorí-ìtẹ́ sí ẹ̀bá ọ̀nà, wọ́n fún un lókùn daindanin ṣe ni ó ń ṣẹ́jú pàkò bí ejò ọka.
ìdámẹ́ta yóo wà ní ààfin ọba, ìdámẹ́ta tó kù yóo máa ṣọ́ Ẹnubodè Ìpìlẹ̀; gbogbo àwọn eniyan yóo sì péjọ sí gbọ̀ngàn ilé OLUWA.
Ṣugbọn John ko le ṣe oun to fẹ nitori pe o ti fi ara pa pupọ.
Oludije to da duro ni lai si ẹgbẹ oṣelu kankan.
O ni  “A ni igbagbo pe, a o bori ogun  iwa ibaje yii.
Ò máa dúró ti àwọn tí ó dúró tì ọ́,ò sì máa ṣe àṣepé fún àwọn tí ó pé;
Ẹni ọdun mọkanlelogun kan, 'Lekan the Engine' Muibi to jẹ mọkaliiki ni Ooṣa ni Joshua jẹ si oun.
Auxiliary korò ojú sí àwọn ọmọ ẹ̀yìn rẹ̀ tó ń dàlú rú Ọlọpa mu asaaju ẹgbẹ NURTW APC ni Auxilliary ṣiṣẹ́ fún lásìkò ìdìbò gómìnà 2019 kìí ṣe PDP-Oyo NURTW Ta ló leè rò pé ọmọ mẹ̀kúnnù bí èmi leè dé ipò alága NURTW?
Nígbà tí Judasi jáde, Jesu wí pé, “Nisinsinyii ni ògo Ọmọ-Eniyan wá yọ.
To si jẹ pe ọpẹlọpẹ awọn eeyan to sugbaa rẹ, lati yọ ọ jade ni abẹ Maruwa, lo fi tete di eero ileewosan.
Ẹwẹ nigba ti ọlọjọ yan lati wa mu u, aarẹ Nkurunziza jẹ Ọlọrun nipe lọjọ kẹsan oṣu kẹfa ọdun 2020.
Nítorí odò Diboni kún fún ẹ̀jẹ̀,sibẹsibẹ n óo jẹ́ kí ohun tí ó jù bẹ́ẹ̀ lọ dé bá a.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Sunday Ayẹni: Damilọla, aya ọmọ mi fìgbónára sọ mi sókùnkùn alẹ́ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Sunday Ayẹni: Damilọla, aya ọmọ mi fìgbónára sọ mi sókùnkùn alẹ́ 6 Ògún 2018 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 7 Ògún 2018 Ibanujẹ nla ni ki majesin toju òbí rẹ̀ rọ̀run!
Ko pẹ lẹyin ti iroyin kan lọsẹ to kọja jade pe ijọba ti fofin de ile iṣẹ Aamin.
alaafia bayii, ki awon arinrinajo maa rin yan fala-fala ni bayii, nitori pe
Ìgbà tí a bá ń gún iyán tí a bá ń ro ọkà ni ìgbà ìsìnkú, à ń o wó dànù ni, ẹni tí ó ti kọjá ti kọjá.
PDP, APC di ẹgbẹ́ aládúrà nítorí ìdájọ́ èsì ìdìbò Ọṣun Atiku n ṣé iranran lórí ìbò 1.
APC primary: Uche Nwosu kùnà ní wọ́ọ̀dù kan Kanye West pa orúkọ dà sí 'Ye' Seyi Makinde (PDP) sọ̀rọ̀ lóri ìpinnu rẹ̀ ni Ibadan Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ọọni Ile-Ifẹ: Gbogbo olùdìbò ló ní agbára ti rẹ̀.
Kii kuku ṣe pe a fi ṣe ti puruntu nikan amọ yoo jẹ amulumọla ọdọ to le kọ tabi lagbara ati puruntu.
orile ede  Burundi  lojo Abameta yii.
Ministerial List: Mo setan lati yan ise fun awon minista mi- Aare Buhari
Ní ọjọ́ keji Hasaeli mú aṣọ tí ó nípọn, ó rì í bọ omi, ó sì fi bo ojú Benhadadi títí ó fi kú.
Mo ti beere igbesẹ to yẹ ki n gbe, eyi ti yoo bu iyi fun Kristi ati iṣẹ to yan fun mi lati ṣe.
Nígbà tí wọ́n jẹun tán, wọ́n bi í pé, “Níbo ni Sara aya rẹ wà?
Dáàbò bò wá, OLUWA, pa wá mọ́ laelaekúrò lọ́wọ́ irú àwọn eniyan báwọ̀nyí.
Ariwo to pa nitori idunnu mu ki awọn eniyan o pe le wọn lori, wọn si doola aburo rẹ.
Gomina Ipinle Oyo, Seyi Makinde ti seleri lati gbe ofin  ma-se-ba-mi-wi sẹgbẹ , fun iwadii lodo ajo to
Àwọn ni n óo lò láti wò ó bí àwọn ọmọ Israẹli yóo máa tọ ọ̀nà tí mo là sílẹ̀, bí àwọn baba ńlá wọn ti ṣe.
Jeremaya bá wí fún Sedekaya, ó ní, “Bí mo bá sọ fún ọ, o kò ní pa mí dájúdájú?
Akọkọ, ijọ apapọ ti tu ikọ SARS ka, ṣugbọn emi funra mi yo ṣe abẹwo sawọn ọfiisi SARS gnogbo to wa ni ipinlẹ Anambra lati rii daju pe wọn tu ẹnikẹni ti wọn ba fi sinu ahamọ silẹ.
O ni owo oṣu marun gbako ni ijọba gbẹsẹ le laisan fawọn oṣiṣẹ fasiti ni Maiduguri, nigba ti Akowe owo Fasiti Michael Opara, si n di owo awọn olukọ ibẹ, nitori wọn kọ lati fi orukọ silẹ fun IPPIS.
Gẹgẹ bi aarẹ Filipe Nyusi ti salaye, oun ri ọpọ oku eeyan ti wọn le tente loju oniruuru odo lasiko ti oun foninu baalu rin kaakiri orilẹede naa.
Bọ́ọ̀sì ìrìnà 106 tuntun yóò máa ná Ibadan sí Eko àtàwọn ìpínlẹ̀ míì - Seyi Makinde Àkùkọ dojú ìjà kọ ọlọ́pàá, ikú ló já sí fún agbófinró Ṣé o mọ̀ pé o leè forúkọ̀ iléeṣẹ́ rẹ̀ sílẹ̀ lọ́fẹ̀ẹ́?
Àwọn Òfin tí ó Jẹmọ́ Àrùn Ara.
Àwọn obìnrin ilé ìgbìmọ̀ aṣòfin Amẹrika fọnmú sí ọ̀rọ̀ Trump Èrò àwọn ọmọ Naijiria yàtọ̀ lórí ohun ìní Seyi Makinde A ó gbé'gbésẹ̀ lẹ́yìn ìwádìí fídíò tí Dino ti ń náwó lójú agbo- Ọlọ́pàá Agbẹnusọ awọn agbofinro ni ẹkun yii, Yyopev Mathias ni nkan bii aago mẹrin irọle ana ni awọn gba ipe lori ile to wo naa.
Oríṣun àwòrán, Twitter/Aguero/Kane Ko si ẹgbẹ agbabọọlu kan to ti gba ami ẹyẹ mẹrin ri ni saa kan ninu itan ere bọọlu nilẹ Gẹẹsi.
Àwọn kan yóo sá àsálà ní òkè Sioni,ní Jerusalẹmu, gẹ́gẹ́ bí OLUWA ti sọ,àwọn tí OLUWA pè yóo sì wà lára àwọn tí wọn yóo sá àsálà.
 Ìtàn wí pé , bí òjù bá ti ń rò , àgbàré òjò yíò kó ìdòtín láàti òkè yìí lo sí ìsàlè-òbà , àwon ará ìsàlè-òbà yóò wá a wí pé , àgbàrá òrè ló kó ìdòtí wá sí àdúgbò àwon .
"'Orísúnmibáre ni àìsàn 'Polio' tó kọlù mí ní kékeré' Wo àwọn ọmọ ilé ìgbìmọ̀ aṣòfin l'Abuja tó sùn fọnfọn lásìkò ìjókòó ilé 'Sanwo-Olu kò ní ṣ'àyẹ̀wò covid-19 míì nítorí kọmíṣọ́nà ètò ìlera ṣẹ̀ṣẹ̀ k'árún náà' Ọkọ Funke Akindele kó eléré àti òṣìṣẹ́ jọ fi ṣe ""Surprise Pato"" fún un lọ́jọ́ ìbí rẹ̀ Ninu alaye to ṣe nipa afikun owo naa, Ileesẹ Multichoice ni owo ọjà to gbowo lori, owo ori ọjà, ati agbara owo naira to dinku lo fa a."
Oríṣun àwòrán, Facebook/Oyo State House of Assembly Àkọlé àwòrán, Ayẹwo fawọn kọmiṣọna tuntun Diẹ lara wọn to sọrọ lẹyin ti ile fọwọ si iyansipo wọn gẹgẹ bi kọmiṣọna sọ pe, awọn ri iyansipo awọn gẹgẹ bi anfani lati sin awọn eeyan ipinlẹ Oyo ati lati kopa ninu iṣejọba rere, eyi ti Gomina Ṣeyi Makinde ṣeleri fawọn eeyan ipinlẹ naa.
O ṣalaye pe ami pe o ni i ko fara han lara rẹ to si ni oun yoo tẹle ofin iyaraẹnisọtọ.
Lọjọ Satide, ọjọ kọkanlẹlọgbọn osu kẹta ọdun yi, Oba alade naa fe gbe igbese manigbagbe, eyi to see se ki o gbegidina isọkan laarin awọn Musulumi ile Yoruba .
7 76718 Orilẹede Libya 1273 19.
Gbogbo oju opo ayelujara lo ti kun bayii fun fọto awọn oṣere tiata, ti wọn parada di arugbo bẹ si ni awọn ọmọ Naijiria naa ti dara pọ mọ eyi.
Oholiabu, ọmọ Ahisamaki, ti ẹ̀yà Dani, wà pẹlu rẹ̀.
”Igbakeji abenugan ile igbimo asoju  naa, Ahmed Idis Wase naa tun fi ibinu rẹ han
Ẹnikẹfa wọn la gbọ pe o ti na papa bora.
Maapu Ijọba Mansa Musa Bi ijọba rẹ ṣe tan kalẹ to, bẹẹ naa ti alumọni goolu ati iyọ pọ yanturu ni ijọba rẹ.
Ẹsira gbọ́ pé Àwọn Ọmọ Israẹli ń fẹ́ Àwọn Ọmọbinrin tí wọn kì í ṣe Juu.
O ni 'Musulumi ni, o si n gba aawẹ Ramadan lọwọ.
O mẹnuba idojukọ ti oun ni ki wọn to gba pe ki oun fẹ Ramla ni Somalia.
Ẹ máa retí oore-ọ̀fẹ́ tí yóo jẹ́ tiyín nígbà tí Jesu Kristi bá tún dé.
Nígbà tí abo kinniun náà rí i pé ọwọ́ tẹ ọmọ òun,ati pé igbẹkẹle òun ti dòfo,ó mú òmíràn ninu àwọn ọmọ rẹ̀,ó tọ́ ọ di ọ̀dọ́ kinniun.
Ṣugbọn o ni ọkọ ti awọn adigunjale naa ko owo ti wọn ji si ṣagbako ijamba nigba ti wọn n gbiyaju ati salọ, awọn ara ilu kan si kọlu awọn adigunjale naa ti wọn si ji owo ti awọn ole ọhun ko.
Alukoro ile iṣẹ ọlọpaa Ọgbẹni Frank Mba lo kọkọ fi lede loju opo Twitter awọn ọlọpaa pe eeyan le fi irẹlẹ beere lati kọkọ yẹ agbofinro wo ko to yẹ ẹni naa wo.
Nítorí náà jọ̀wọ́ gba ẹ̀bùn yìí lọ́wọ́ iranṣẹ rẹ.
Ọkọ̀ tírélà 3 kọlu ọkọ̀ ìgboro, obìrin 2 kú, 6 farapa yánnayànna Mi ò fẹ́ ìrànwọ́ ẹgbẹ́ òṣèré, àwọn kọ́ ló kóbá mi- Chief Kanran Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí 12:41 Fídíò, Baby abandoned on dunmpsite: Mo ti bímọ mẹ́rin tẹ́lẹ̀ fún bàbá méjì nínú òṣí- Dupe Ogbomọṣọ, Duration 12,414 Owewe 2020 6:18 Fídíò, Akomolede: Bolaji Faleke ni Olùkọ́ tó ń kọ́ wa ní àṣà oge ṣiṣe lórí BBC Yorùbá, Duration 6,181 Owewe 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 3 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 5 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
“Bí ẹnikẹ́ni bá bá aya aládùúgbò rẹ̀ lòpọ̀, pípa ni kí wọ́n pa olúwarẹ̀ ati obinrin tí ó bá lòpọ̀.
Ipade naa kii ṣe akọkọ ti awọn mejeeji yoo jọ ṣe ṣugbọn ohun to ya awọn eeyan lẹnu nipa ipade naa ni pe Gomina Ibikunle Amosun kọwọrin lọ ipade naa pẹlu oludije ipo Gomina lẹgbẹ oṣelu APM, Adekunle Akinlade.
láti odò Ṣihori, ní apá ìlà oòrùn ilẹ̀ Ijipti, títí lọ sí apá àríwá ní ààlà Ekironi tí ó jẹ́ ti àwọn ará Kenaani, (Marun-un ni ọba àwọn ará Filistia, àwọn nìwọ̀nyí: ọba Gasa, ti Aṣidodu, ti Aṣikeloni, ti Gati, ati ti Ekironi) ati ilẹ̀ àwọn Afimu ní ìhà gúsù.
Nise ni ọ̀pọ̀ àwọn ọmọ Nàìjírìa tí n sọ èrò wọn lórí fọnrán náà, tí wọn sì bẹnu àtẹ́ lu ìgbèsẹ̀ gómìnà Kano.
" Amugbalẹgbẹ fun aarẹ wa kadi ọrọ rẹ nilẹ pe ololufẹ Naijiria ni aarẹ Muhammadu Buhari, ti oun si mọ ọbuda ati isẹ rere rẹ daradara.
 Ọgbẹni Mandela gba ominira kuro l'ọgba ẹwọn lẹyin ọdun mẹtadinlọgbọn."
Gomina Ipinle Oyo, Onimo ero Seyi Makinde ti ro gbogbo
Tammy Abraham dáná sun Wolves, ni Twitter bá ń lọgun rẹ̀ tan-tan Egbé agbábọọlù Super Eagles gbàgbé ohun eèlò wọn - Ọlajiire Bi o tilẹ jẹ wi pe ọdẹdẹ Chelsea ni Stamford Bridge ni ifẹsẹwọnsẹ naa ti waye, ko gbe Tammy Abraham atawọn ọmọ ikọ Frank Lampard yooku.
Ṣugbọn kò lè rí i nítorí ọ̀pọ̀ eniyan ati pé eniyan kúkúrú ni.
Usaya ọba di adẹ́tẹ̀ títí ọjọ́ ikú rẹ̀.
Amọ, awọn adari ẹgbẹ Afenifẹre ni ki Tinubu ma fi ṣe ọrọ ẹnu nikan, ko bọ si gbagede lati beere fun atunto Naijiria, ki ohun ini ati bi owo ṣe n wọle labẹle ba le kaakiri ọpọlọpọ eniyan.
Àwọn Eniyan Jerusalẹmu kígbe sókè fún ìrànlọ́wọ́.
Inyamkume to je oga agba ajo to n mojuto isele oju ojo ati atunto, CCMAI lo parowa yii nilu Abuja.
Ikede naa waye lẹyin ti àwọn afurasi ọmọ ẹgbẹ to n polongo fun idasilẹ orilẹ-ede Biafra, IPOB, já iwọde EndSars gba, eyi to yọri si iku sọja mẹfa, ati ọlọpaa mẹta.
Wọn yoo si na biliọnu marun un naira le ni ọọdunrun lori atunṣe awọn ọọfiisi ati ile inu Aso Rock to jẹ ileejọba ni Abuja to jẹ olu ilu Naijiria.
Àwọn òyìnbó dá mi lóhùn pé òtítọ pọ́nbélé ni mo sọ, n kò parọ́ rárá.
Ní ọjọ́ kẹrinla, oṣù kinni ni wọ́n pa ọ̀dọ́ aguntan Àjọ Ìrékọjá.
Ṣé kò wá sí ẹnikẹ́ni láàrin yín tí ó gbọ́n tó láti dá ẹjọ́ fún ẹnìkan ati arakunrin rẹ̀ ni?
Minisita to n ri si eto irinna
Ogunlọ́gọ̀ wà ní àfonífojì ìdájọ́,nítorí ọjọ́ OLUWA kù sí dẹ̀dẹ̀ níbẹ̀.
0 426 Agbegbe St Vincent and the Grenadines 0 0.
Wọ́n kọ ọ́ sinu ìwé Jaṣari pé, oòrùn dúró ní agbede meji ojú ọ̀run, kò sì tètè wọ̀ fún bí odidi ọjọ́ kan.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ondo Land Death: Opó àti àbúrò olóògbé ní aáwọ̀ ilẹ̀ ló fá ikú òjijì fún Olayinka Olabode Amọ gomina ipinlẹ Delta, Ifeanyi Okowa, ti sọ ṣaaju pe oun ko ni pa ofin yii rẹ nitori Delta kii ṣe Eko.
"Àkọlé àwòrán, ""A ti joko jiroro lori ọrọ to nii se pẹlu owo osu, amọ a pinnu nibi ipade naa lati sun ijiroro naa siwaju di ọjọ Aje, ka to lee fi ẹnu ọrọ jona nipa aawọ to wa nilẹ."
Fayose ko kẹrẹ ninu ijo Shaku-shaku Oríṣun àwòrán, @GovAyoFayose Àkọlé àwòrán, Iyawo yoo bi isun, yoo bi iwalẹ Oríṣun àwòrán, @sleem_nation Àkọlé àwòrán, Iya ati baba mo mi lọ, ẹfi adura sin mi o Oríṣun àwòrán, @Emmadex Àkọlé àwòrán, Tomilọla, ile ọkọ ya, ki ẹlẹda awọ̀n obi rẹ sin ọ lọ Oríṣun àwòrán, @MonteOzAfrica Àkọlé àwòrán, Iyawo dun lọsingin, ọkọ tun mi gbe BBC News, Yorùbá Ìdí tí ẹ fi le è nígbàagbọ́ nínú ìròyìn BBC Ìlànà Lílò Nípa BBC Òfin Àṣírí Cookies Kàn sí.
Jolaade ni oun kii lo idan abi alupayide amọ erongba oun ni lati di onimọ ẹrọ ayarabiasa lagbaye, to maa idasilẹ oniruuru akanse isẹ lori ayelujara.
Ní ọjọ́ kan náà, tíí ṣe ọjọ́ kẹrinlelogun oṣù kẹsan-an, OLUWA tún rán Hagai, pé kí ó 
Ìjà náà pọ̀ gidigidi ṣùgbọ́n àsẹ̀yìnwá àsẹ̀yìnbọ̀, Olódùmarè ṣẹ́gun, èyi ló sì mú kí a lé Èṣù kúrò ní òde ọ̀rùn tí o fi di pé o ń gbé ọ̀run Àpáàdì di òní olónìí.
Orukọ oloogbe naa ni Funkẹ Ọlakunrin, tii se ẹni ọdun mejidinlọgọta.
Olúránlọ́wọ́ fún Dino Melaye - BBC News Yorùbá BBC News, YorùbáFò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Irọ́ ni ọ́lọ́pàá npa nípa Dino - Olúránlọ́wọ́ fún Dino Melaye 26 Ìgbé 2018 Oríṣun àwòrán, @dinomelaye Àkọlé àwòrán, Iléesẹ́ ọlọ́pàá ní orílẹ̀èdè Nàìjíríà kéde pé òun ń wá sẹ́nètọ̀ tó ń sojú ẹkùn ìdìbò ìlà oórùn Kogí, Dino Mélayé Oluranlọwọ pakati kan fun sẹnatọ to n soju ẹkun iwọ oorun Kogi, Dino Melaye sọ wipe irọ patapata ni awọn ọlọpaa n pa wipe sẹnatọ naa fo bọọlẹ ninu ọkọ ni olu ilu Naijiria, Abuja.
Oríṣun àwòrán, Others Asofin Fagbenro ni awọn mọlẹbi Barakat nilo atilẹyin to yẹ ati eto idẹrun ti yoo din ironu wọn ku lasiko yii ti wọn n sọfọ iku ọmọ wọn.
Kí èpè wọn mọ́ mi, OLUWA, bí n kò bá sọ ọ̀rọ̀ wọn ní rere níwájú rẹ, bí n kò bá gbadura fún àwọn ọ̀tá mi ní àkókò ìyọnu ati ìdààmú wọn.
Ayọ̀ọlá: Ó da, ṣé ẹní bàbá dúdú
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Gbogbo ipá kò tíì pin lórí ọmọ ọdún méjì tó kó sí àǹga 28 Ọ̀wàrà 2019 Oríṣun àwòrán, BBC Sport Àkọlé àwòrán, Ebi ọmọ to ja si kọnga Ni bayii, awọn adoola ẹmi ẹni ko tii ri ọmọ ọdun meji ti o ja si inu kọnga gbe jade ni ilẹ India.
Koda, wọ̀n se akawe awọn idajo ile ejo Supreme Court to jọ eyi.
Kọmisọnna fajọ NCC, Sunday Dare lo fi ọrọ naa lede ni ilu Port Harcourt lasiko to n se ilanilọyẹ fun awọn eniyan ni agbeegbe naa.
Ìdí rèé tí ìforúkọsílẹ̀ rẹ kò ṣè wọlé lójú òpó N-Power Oríṣun àwòrán, @NPOWER_NG TWITTER Àkọlé àwòrán, Aworan awọn ọdọ to n gba idanilẹkọ labẹ N-Power Iroyin to gbode nilẹ oni to mọ bayi ni pe pupọ awọn eeyan to forukọ silẹ loju opo igbanisiṣẹ ijọba Naijiria N-Power 2020 ni iforukọsilẹ wọn le ma wọle.
Bakan naa lẹjọ tun kan awọn ọmọ igbimọ ti wọn gbe kalẹ lori rira ọkọ bọọsi naa, iyẹn họnọrebu Fatai Mojeed, Gbolahan Yishawu, A.
Kò sí ẹni tí yóo fara mọ́ àbá yín yìí.
Won tun fi aaye sile fun awon arugbo ati alaboyun lati kọkọ dibo won ni
" O ni wọn maa n ṣe iṣẹ wọn bi iṣẹ, ṣugbọn ijọba n ba ojuṣe rẹ ku to ba ti to asiko lati san owo oṣu fun wọn.
Nikẹhìn, ọmọ náà túnúnbá fún bàbá rẹ̀ ati àwọn ọmọ-ogun rẹ̀.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Amọ ẹranko ti awọn eniyan bẹru julọ ni ẹkun.
Wọn ko sọ idi ti wọn fi tako Okonjo-Iweala.
Aisha Umar jẹ ẹni ọdun marunlelogun, onisowo ni lati ipinlẹ Sokoto.
Ní ìrọ̀lẹ́ ọjọ́ kan báyìí nínú ọkọ̀-ojúurin abẹ́lẹ̀ ní ìlú Paris, ọ̀gbẹ́ni afọ́jú kan fẹ̀lẹ̀ jókòó sórí ìjòkó tó kọjú sí mi.
Bí òkúta tí eniyan là, tí ó fọ́ yángá-yángá sílẹ̀,ni a óo fọ́n egungun wọn ká sí ẹnu ibojì.
ofurufu, ti eka Erekusu Channel, ogbeni John
Adajọ Victoria Bob Manuel to paṣẹ yii ṣe bẹẹ lẹyin atotonu lati ọdọ awọn agbẹjọro ijọba ati tawọn afunrasi naa.
O sọ ninu ọrọ rẹ pe ''Gbogbo ogo fun Ọlọrun, baalu ayarabiaṣa to gbe wa lati ilu Abuja ja lulẹ nigba to fẹ ẹ ba silẹ nilu Kabba, nipinlẹ Kogi.
Àwọn Ọmọ Israẹli Kọrin Arò ní Ìgbèkùn.
Wọ́n lò wọ́n láti kọ́ ìlú Pitomi ati Ramesesi tíí ṣe àwọn ìlú ìṣúra fún Farao.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Linda Ikeji: Sholaye ni bàbá ọmọ mi, ṣùgbọ́n a ti túká 14 Ọ̀pẹ̀̀ 2018 Oríṣun àwòrán, officiallindaikeji/Instagram Àkọlé àwòrán, Linda ati ọkọ rẹ tuka Ilumọka oniroyin ayelujara Linda Ikeji ti ṣafihan ọmọkunrin jojolo rẹ lori ayelujara, bẹẹ ni o si fidi rẹ mulẹ pe jayejaye oun ko ni nnkankan ṣe mọ pẹlu baba ọmọ naa ti orukọ rẹ n jẹ Sholaye Jeremi.
 Ìdí rèé tí yoòbá fi máa ń sọ wí pè ,  adìyẹ ìrànà kì í ṣ ' ọhun à jẹ gbé "" ."
Nítorí ohun tí ojú rẹ̀ ń rí ati ohun tí etí rẹ̀ ń gbọ́ ń ba ọkàn ọkunrin olódodo yìí jẹ́ lojoojumọ bí ó ti ń gbé ààrin àwọn eniyan burúkú yìí.
sugbon papa sibe mimi kan ko mi kuro nitpri o si duro digbi sipo re.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Mexican Octogenarian: Kò sígbà táa dá aṣọ, ti a kò rílẹ̀ fiwọ́!
Ni opin ọdun 2017, o ti ṣe eto ajẹsara fun awọn eniyan ti o le ni miliọnu mẹta, ṣugbọn eyi ko da itankalẹ arun naa duro.
Ti a ba fayegba iru igbese bayii ko tesiwaju, eyi lee dena ojuse awon ara ilu lati dibo yan oludije ti won fe sipo.
Duro Ladipọ si gba ami ẹyẹ latọwọ aarẹ Naijiria nigba naa, Ọmọwe Nnamdi Azikwe lasiko ọdun keresi kan to waye ni ibudo iko nkan isẹnbaye lọjọ si to wa ni Onikan, nilu Eko Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Akomolede àti Aṣa: Ọ̀rọ̀ Ẹ̀yán ni Bunmi Femi Amao ń kọ́ wa lórí ètò Akọ́mọlédè àti Àṣà lóri BBC Yoruba Ifẹ to ni si asa isẹmbaye yii si lo tii titi de idi tiata, ti ọpọ ere rẹ naa si maa n se agbelarugẹ awọn ohun ajogunba wa nilẹ Kaarọ oojire Lẹyin ti Duro Ladipọ ka iwe tan nilu Osogbo, lo wa si Ibadan, lati se isẹ Olukọ lọdun 1960, Idi isẹ olukọ lo ti dara pọ mọ ẹgbẹ osere tiata Mbari Mbayọ pẹlu iranlọwọ oyinbo alawọ funfun kan lati Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Contortionist: Mo lè gbé ìfun mi pamọ́ ki n tún se èémí!
Aṣeyori Bernie Sander jẹ ǹkan to ya ni lẹ́nu diẹ.
Lọwọ lọwọ bayii, ọmọ mẹta ni Ọba Oke fi jinki wọn, ti wọn si tun n sisẹ olukọ.
Bí àwọn CNN-FDD ṣe gbé oyè náà ní yẹpẹrẹ tó ipò agbára Nkurunziza gẹ́gẹ́ bí adarí ayérayé tó ga jù ti jẹ́ kí ó nira fún ẹnikẹ́ni láti kọ ohunkóhun tí ó bá yàn láti ṣe, títí mọ́ ìgbésẹ̀ rẹ̀ láti ṣe àyípadà òfin sáà méjì fún ipò adarí tí ó wà nínú ìwé òfin orílẹ̀-èdè náà.
N óo yọ ọkàn òkúta kúrò láyà wọn, n óo sì fún wọn ní ọkàn ẹran; 
Kí ojú rẹ lè máa wà lára ilé ìsìn yìí tọ̀sán-tòru, níbi tí o sọ pé o óo yà sọ́tọ̀ fún orúkọ rẹ.
Ni bayii, ọrọ ọhun ti yii kan oriade o.
Gẹgẹ bi ọrọ ti awọn oṣoju mi koro sọ, ibugbamu naa waye laarin ago mẹjọ si mẹsan an owurọ ọjọ Isinmi.
Elebuibon ni o le ju ọdun mẹwaa lọ nitori ẹkọ kikọ nipa Ifa ko le tan laelae.
yoo wa ninu igbimo rẹ  .
Wike kò wó Mọṣáláṣi rárá o -Fayẹmi lórúkọ gbogbo Gómìnà Bakan naa lo tun ṣalaye pe awọn ọlọpaa ti tilẹkun mọ ọmọlẹyin Shiite ni olu ileeṣẹ ẹgbẹ IMN ni ilu Ṣokoto lati kawọn lọwọ ko ki mọ maa baa jade lọ ṣe iwọde wọn.
Èyìínì ni pé Àgùntàn-ìnàkí ni ó fi ọwọ́ ara rẹ̀ ṣe ara rẹ̀.
Oríṣun àwòrán, Guru Maharaj O ní sáájú ni ilẹ̀ náà ti ń dá wàhálà sílẹ̀ láàrin Guru Maharaj àti Adegoke Amao pẹ̀lú Ṣoara Atere.
Lẹyin naa lo rọ awọn ẹgbẹ oṣelu lati maa yanju awọ to ba wa laarin wọn gẹgẹ bi ọmọ iya dipo ki wọn maa yọ ile ẹjọ lẹnu.
Ó tẹ́ bàbá mi lọ́rùn pé ká mu gàárì nílé ju kí ebi pa ará ìta lọ - Ọmọ Gbenga Adeboye Àwọn tó jí ìbejì mi gbé ti pè mí ṣùgbọ́n N50 mílíọ̀nù tí wọ́n ń béèrè pọ̀ ju agbára mi lọ-Akeugbagold Èèyàn 196 míràn tún ti ní àrùn Coronavirus ní Nàíjírìa Iléeṣẹ́ aṣọ́bodè yarí, kò gba ìrẹsì tó bàjẹ́ padà lọ́wọ́ Ṣeyi Makinde Gomina ipinlẹ Eko, Babajide Sanwo-Olu ni nipele nipele ti aṣọ alubọsa n wa ni wọn yoo maa ṣe eto ati ilana ti wọn n gbe kalẹ naa.
Bẹ́ẹ̀, bí ti irú wọn ti níláti rí nìyí.
Láti tẹ́ aṣálẹ̀ lọ́rùn,ati láti mú kí ilẹ̀ hu koríko?
 gbajúgbajà ni nínú iṣẹ ́ yìí .
Opeyemi Ayeola: Inú sinimá ni ọkọ mi ti rí mi, ọdún mẹ́ta ló fi wá nọ́mbà mi, kó tó fẹ́ mi
Ògo Efuraimu yóo fò lọ bí ẹyẹ, wọn kò ní lóyún, wọn kò ní bímọ, bẹ́ẹ̀ ni ọlẹ̀ kò ní sọ ninu wọn!
'À ń bẹ Ààrẹ Buhari kó pèsè ààbò fún àwa ọ̀dọ́bìnrin' Ìdílé Pius Adesanmi ti gbé Boeing lọ sílé ẹjọ́ A kò lè gba àwọn jandùkú Fulani láàyé nílẹ̀ Yoruba -Awọn gómínà Lẹ́yìn àṣẹ ilé ẹjọ́, AIT àti RayPower padà s'afẹ́fẹ́ Michael Gove naa ti kede pe ipo naa wu oun ni UK.
Dokita Stella tun ni oju opo ile ijọsin rẹ,Fire Power Deliverance Ministries nibi ti o ti n ṣe iwaasu loore koore nilana Kristẹni.
Buhari ni : “A fi edun okan wa han si  ebi awon eniyan ti won pa nibi isẹlẹ buruku to
" Ọ̀dọ́mọkùnrin náà tó fi Boko Haram sílẹ̀ bá BBC sọ̀rọ̀, ṣùgbọ́n kò fẹ́ ká dárúkọ rẹ̀.
Bí iná tíí jó igbó,àní, bí ọwọ́ iná sì ṣe ń jó òkè kanlẹ̀,
 iye owó rẹ ̀ lójú pálí jẹ ́ 4.
O ba Sheikh Mohammed Mutumba lojiji lẹyin ọsẹ meji igbeyawo wọn lati ri i pe ọkunrin ni iyawo oun, Swabullah Nabukeera to tin n wọ hijab lati ọjọ yii ati wi pe orukọ rẹ gangan ni Richard Tumushabe.
Ọba dá a lóhùn pé, “Ṣe bí Joabu ti ní kí o ṣe.
Ẹni tí ó bá gba ìtọ́ni wà ní ọ̀nà ìyè,ṣugbọn ẹni tí ó bá kọ ìbáwí yóo ṣìnà.
Gbogbo àwọn tí ń tẹ̀lé Jesu ni mò ń lé kiri: ẹni tí mo bá sì bá ninu wọn pípa ni.
Kò ní sí ẹnikẹ́ni tí yóo lè dojú kọ yín, OLUWA Ọlọrun yín yóo mú kí ẹ̀rù yín máa ba gbogbo àwọn olùgbé ilẹ̀ tí ẹ óo máa rìn kọjá, jìnnìjìnnì yín yóo sì máa bò wọ́n, gẹ́gẹ́ bí OLUWA ti ṣe ìlérí fun yín.
O ni lẹyin eyi ni Alaafin Aolẹ yin ọfà mẹta, ti kii ṣe ọfà lasan, si origun mẹta yika ilẹ Yoruba.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Osun Osogbo festival 2019: Báwo ni àjọ̀dún Ọ̀ṣun Òṣogbo ṣe lọ lọ́dún yìí?
'Mi ò mọ̀ pé mo lóyún àfìgbà t'ọ́mọ ń rún'ra' Bidemi Kosọkọ di ìyá ìkókó Njẹ àwọn èèyàn kò tí gbàgbé Dagrin, akọrin ‘Rap’ bí?
Ó bá di ọwọ́ baba rẹ̀ mú láti gbé e kúrò lórí Efuraimu kí ó sì gbé e lórí Manase.
Wọn ìbáà gbààwẹ̀, n kò ní gbọ́ igbe wọn.
Ẹri pe ileeṣẹ ti o n ba a ṣiṣẹ yoo yọnda rẹ lati lọ ọ kẹkọọ Awọn ẹka eto ẹkọ Imọ ijinlẹ akọkọ 'undergraduate' •Engineering, •Geology, •Agriculture, •Science, •Mathematics, •Languages, •Environmental sciences, •Sports, Law, •Social Sciences, •Biotechnology, •Architecture, •Medicine (perete), •Pilot Engineering, •Neurologis.
Idi ree ti gbajumọ osere tiata lobinrin kan, Bukunmi Oluwasina fi n se jaginni yodo si oore nla kan to wọle tọọ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù WASSCE: Ìpínlẹ̀ Delta fòfin de olùkọ́ 41 tó ṣe màgòmágó nínú ìdánwò 11 Owewe 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 22 Owewe 2020 Oríṣun àwòrán, Google Ipinlẹ Delta ti fofin de awọn olukọ ile iwe girama mọkanlelogoji ti wọn ṣe magomago ninu idanwo aṣekagba ti wọn ṣẹṣẹ pari.
tẹnumọ pe ọrọ aabo ara ilu ati awọn nnkan ini wọn jẹ ojuṣe pataki fun
Aṣofin Tunde Braimoh ṣapejuwe Ọba Eko gẹgẹ bi ẹni ti oriire n ba rin, ti ti o si ti ko ọpọlọpọ ibukun ba ipinlẹ Eko ni gbogbo ọna, o fi ti bi ero ṣe pọ si bayii ni ipinlẹ Eko ṣe apẹẹrẹ, “ ni asiko ti Ọba wa maa gun ori aleefa, miliọọnu mẹsan pere ni onka awọn eniyan to wa ni Ipinlẹ Eko, ṣugbọn ni bayii onka awọn to wa ni ipinlẹ yii ti le ni miliọọnu mejilelogun, eleyii jẹ ara ibukun ti kaabiyesi mu wọ ipinlẹ yii”.
 Greatest Of All Time🔵🔴 Born in La Masia.
 Nigba ti akowe ajo EFCC ohun, Ola
N óo fi ojurere wò yín, n óo mú kí ẹ máa bímọlémọ, kí ẹ sì pọ̀ sí i, n óo sì fi ìdí majẹmu mi múlẹ̀ pẹlu yín.
Ni oṣu kinni, ọdun 1980 ni wọn bi i ni ilu Wimbledon lorilẹ-ede Gẹẹsi ṣugbọn ọmọ orilẹ-ede Naijiria ni awọn obi rẹ, Dokita Fẹmi Adegoke ati Ọjọgbọn Feyi Adegoke ni orukọ wọn Buhari, pe ìpàdé àpérò ọmọ Nàíjíríà fún àgbékalẹ̀ òfin tuntun - Afe Babalola Ọkọ̀ akẹ́rù Dangote rọ́lu BRT lọ́nà Ikorodu, èèyàn kan kú, 59 farapa, ẹsẹ̀ dẹ́rẹ́bà gé Owó dé!
Nítorí bẹ́ẹ̀ ni ìfẹ́ Ọlọrun pé nípa ìwà rere yín, kí kẹ́kẹ́ pamọ́ àwọn aṣiwèrè ati àwọn òpè lẹ́nu.
Nígbà tí kò sí owó mọ́ rárá ní ilẹ̀ Ijipti ati ilẹ̀ Kenaani, gbogbo àwọn ará Ijipti tọ Josẹfu lọ, wọ́n wí pé, “Fún wa ní oúnjẹ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Election Tribunal: Ẹ̀rù tó ń ba APC ni wọ́n ṣe kọ̀wé sáwọn ọ̀tẹlẹ̀múyẹ́ 25 Ẹrẹ̀nà 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 26 Ẹrẹ̀nà 2019 Oríṣun àwòrán, @OfficialPDPNig Ẹgbẹ oselu alatako gboogi nil Naijiria, PDP, ti fesi pada lori bi ẹgbẹ oselu to n sejọba lọwọ, APC se figbe ta, lẹ́yìn tí ẹgbẹ́ PDP jáde láti sọ pé àwọn ní ẹ̀rí tí àwọn gbà láti ojú òpó INEC pé, Atiku Abubakar fi ìbò tó lé ní mílíọ̀nù kan jáwé olúborí.
O ni nitori pe oun kuro ninu igbeyawo oun ni wọn ṣe n dunkooko mọ ẹ̀mí oun, oun si wa n pariwo pe, Alaafin lo wa nidi rẹ, bi ibi ba sẹlẹ si òun.
Nítorí náà n óo mú kí àwọn ọ̀run wárìrìayé yóo sì mì tìtì tóbẹ́ẹ̀ tí yóo sún kúrò ní ipò rẹ̀,nítorí ibinu OLUWA àwọn ọmọ ogun ní ọjọ́ tí inú rẹ̀ bá ru.
ly/2rHOXzO Oríṣun àwòrán, Yinka Ajia Ẹ ku oju lọna ipade yii o pẹlu BBC Yoruba!
Njẹ ọna abayọ ti wa si aisan Coronavirus?
A gbọ wipe awọn eeyan to n fọ ọpa epo lo tun se okunfa akọtun ibugbamu ọpa epo yii.
Ajọ to n mojuto eto naa, National Identity Management Commission, NIMC ti ṣe 'App' kan ti yoo fun wọn ni anfaani lati gba kaadi idanimọ NIN, tabi fi rọpo kaadi naa.
Oríṣun àwòrán, Alaafin Oba Adeyemi III Kii ṣe ori iṣejọba gomina Gboyega Oyetọla ni igbesẹ yii ti bẹrẹ bikoṣe lati ori Rauf Arẹgbẹṣọla to ṣiwaju rẹ.
Ayeye isiso loju eegun ohun ni o waye lati se ikinni kaabo awon iko orile-ede kookan ti yoo maa kopa ninu idije ohun pelu orin, ilu ati ijo latowo egbe onijo Munujali.
Ọmọ ọdún 23 jẹ́wọ́ bó ṣe pa ẹ̀gbọ́n ìyá rẹ́, ẹni ọdún 60 nípinlẹ̀ Ogun Wo nǹkan tí ìjọba àpapọ̀ yóò ṣe fáwọn tó ń ta 'pẹlẹbẹ', 'pàrágà' àti 'fònàgáú' Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 3 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 5 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Gonzalo Higuain, Pedro àti Marcos Alanzo nígbà ti N'Golo Kante fara ṣeṣe, won fi Olivier Giroud, Willian, Ruben Loftus-Cheek àti Emerson Palmeri rópò wọn, Nígbà ti Eintracht Frankfort ṣe ayipada ẹnikan pere.
Ẹ kọwe fí ipò silẹ Bi ẹ ko ba ní gbagbe kò tíì pé ọsẹ meji ti aṣofin Clement Akanni to n ṣoju ẹkun idibo Ila to jẹ agbegbe ọkan lara awọn àgba ẹgbẹ oṣelu APC lorilẹ ede Naijiria, oloye Bisi Akande, pẹlu ti dagbere fun ẹgbẹ oṣelu naa to sì gba ẹgbẹ oṣelu PDP lọ.
Florence Ajimobi tahùn sí igbákeji gómìnà Oyo lórí ikú ọkọ rẹ̀, Gbogbo wa làó kú"" Kìí ṣe ẹ̀bi wa pé ètò ìsìnkú Abiola Ajimobi falẹ̀ - ìjọba ìpínlè Oyo Orúkọ ìnagijẹ mẹ́jọ tí wọ́n fi ń pe Abiola Ajimọbi nígbà ayé rẹ̀ Àwọn aṣòfin Naijiria ṣọ̀rọ̀ ìwúrí nípa Ajimobi Nínú àtẹ̀jáde tí ilé ìfowópamọ́ ọ̀hún fi síta lọ́jọ́ Àìkú, sàlàyé pé ó ye òun yékéyéke pé àsìkò yìí kò rọgbọ fún àwọn oníbara òun rárá."
Ogunjọbi dije lẹẹmeji fun ipo aarẹ ajọ NFF, ṣugbọn o fidi rẹmi lẹyin ti Amaju Pinnick wọle lẹẹmejeeji.
Olivier Giroud fi àràmọ̀ndà góòlù méjì ṣayẹyẹ ìfẹsẹ́wọnsẹ̀ ọgọ́rùn ún tó gbá fún France Gómìnà Seyi Makinde bá ẹbí Isiaq Jimoh tó kàgbákò ikú òjijì dárò Duro Ladipọ, ìlúmọ̀ọ́ká òṣèré tíátà àti ọmọ àlúfà tí kò gbàgbé àṣà ìbílẹ̀ N kò sọ fún ìyá mi kí ń tó lọ sílé BB Naija - Laycon Ó sàn fún mi kí n máá tíì lọ́kọ báyìí ju kí n lọ́kọ ṣùgbọ́n.
" Alayee re e lori nkan ti Ọjọ́ Black Friday jẹ ni agbaye Black Friday ni orukọ ti wọn n pe ọjọ Ẹti to ba tẹle ọjọ idupẹ 'Thanksgiving Day' nilẹ Amerika.
Ta lo pa Abimbọla ati Mubarak l'Ogun?
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Mummy calm down: Ìyá Ore sọ pé gbogbo ìgbà tí óun bá n bá a wí ló ma n ṣe àwàdà Ko tan sibẹ, aya gomina ipinlẹ Kwara tun kede pe oun ti n gbe igbesẹ lati ri daju pe aarin obìnrin naa ati ọkọ rẹ gun pada, ki wọn si di idile alayọ.
Nigba to ngbe idajọ rẹ kalẹ lori ẹjọ naa to ti bẹrẹ lati ọjọ keje osu kejila ọdun 2010, adajọ Gabriel Kọlawọle ni awọn olupẹjọ fi idi ẹri wọn mulẹ kọja iyemeji.
 Ó lọ sí ilé-ìwé ti àwọn olùkọ ́ ni ti  local authority teacher training college "" ní ìlú Ọ ̀ yọ ́ láti inú ọdún 1961 di ọdún 1962 ."
"O daju pe iwa janduku to waye lọjọ kẹsan to ṣokunfa atundiu ibo ko to ti ọjọ kẹtalelogun ti ajọ Inec si ṣebi ẹni pe awọn ko ri nnkankan ti wọn si kede esi ibo naa.
Ìkádìí O darapọ mọ ilẹeṣẹ ijọba Ipinlẹ Ọṣun nibi to ti ṣiṣẹ fun ọdun mẹrindinlogun labẹ akoso ijọba oloogun mẹta ati ijọba alagbada Olagunsoye Oyinlọla.
Iye ibo ti wọn di jẹ –
Bó ti wù kí eniyan fi ẹṣin yí ẹ̀rọ ìpakà lórí ọkà alikama tó,ẹ̀rọ ìpakà kò lè lọ ọkà kúnná.
O daju wi pe baalu rẹ ko ti le gunlẹ si China ti awọn ọmọ Naijiria fi n ke irọra lori ai ri kaadi idibo PVC gba ti awọn kan si so ninu ifọrọwanilnuwo pẹlu BBC Yoruba pe awọn kan n gba ẹgbẹrun meje Naira lọwọ awn eeyan ki wọnn to le gba kaadi.
Arabinrin Dabiri-Erewa ni ilu Eko lawọn eeyan naa yoo maa gba lọ silu Abuja taarata nibi ti wọn yoo ti fi wọn si igbele ọjọ mẹrinla lati mọ boya wọn laarun coronavirus tabi wọn ko ni.
Àkọsílẹ̀ wà ninu Ìwé Mímọ́ nípa mi pé,Ọlọrun, mo dé láti ṣe ìfẹ́ rẹ.
Lati ogunjo osu kinni odun yii ti Donald Trump bere ise gege bii aare ile America lo ti n sise ni Washington titi di ojo eti to koja to bere abewo sile okeere nipa lilo si Saudi Arabia.
1–6, Àwọn òṣiṣẹ́ nínú ọgbà ajarà yíò jẹ èrè ìgbàlà; 7–14, Wá ọgbọ́n, kígbe ironúpìwàdà, ní ìgbẹ́kẹ̀lé nínú Ẹ̀mì, 15–22, Pa àwọn òfin mọ́, kí o sì ṣe àṣàrò ọ̀rọ̀ Olúwa; 23–27, Má ṣe sẹ́ ẹ̀mí ìfihàn àti ìsọtẹ́lẹ̀; 28–30, Àwọn tí wọ́n gba Krísti di ọmọ Ọlọ́run.
Nítorí àwọn tí ó ń hùwà gẹ́gẹ́ bí ẹni tí ẹran- ara ń lò a máa lépa ìtẹ́lọ́rùn fún ẹran-ara; ṣugbọn àwọn tí Ẹ̀mí ń darí a máa lépa àwọn nǹkan ti Ẹ̀mí.
Jọ̀wọ́ ràn mi lọ́wọ́ èkúté ti ń ṣiré kiri; kò sí ẹni tí ó kéré níwájú Ọlọ́run Ọba àfi alábòsí ènìyàn tí ó pe o olè ki ó wáá jà tí ó lọ tún lọ wí fún olókko kí ó wáá ṣọ́ oko, olóko dúpẹ́ olè dúpẹ́ bẹ́ẹ̀ ni ìdájọ́ alábòsí di ọ̀run alákeji.
Anthony Joshua ti na Joseph Parker nibi ìdijé ẹ̀ṣẹ
Wasiu Ayinde: Èmi kìí ṣe Mayegun olórin àmọ́ mo fẹ́ jẹ́ olùlàjà nílẹ̀ Yorùbá
Awọn to dan wo ninu ki wọn farapa tabi ki wọn padanu ẹmi wọn.
Àwọn tó ń wojú ọjọ́ rí ihò dúdú tó tóbi jù láyé àtọ̀run
Nibayii eeyan 856 lo ti ṣe alaisi nipasẹ ajakalẹ arun naa lorilẹede Naijiria.
Nítorí tí mo bá ti dáríjì eniyan, (bí nǹkankan bá fi ìgbà kan wà tí mo fi níláti dáríjì ẹnikẹ́ni), mo ṣe é nítorí tiyín níwájú Kristi.
Ó kó gbogbo àwọn pẹpẹ ìrúbọ ati àwọn pẹpẹ tí wọ́n ti ń sun turari ní gbogbo àwọn ìlú Juda jáde.
O ni lẹyin wakati diẹ ti oju oun ṣi wu sibẹ ti ojú n ta oun ni oun ṣẹṣẹ gba pé kii ṣe idọti lasan ni o ko si ẹyinju oun.
Oríṣun àwòrán, @adetutuoj8811 Koda o ni ọkan tiẹ wa, ti oun ba jade fun ọdun meji, gbedeke to si fi lelẹ ni pe alẹ ni awọn yoo maa pade, ti oun si fara daa, toripe ọmọ ọdun mẹrin ni oun wa, ti iya oun fi ku, ajọ alaanu kan si lo wo oun dagba.
Ẹni tí ó ní ẹ̀mí èṣù lè la ojú afọ́jú?
Agbẹnusọ aarẹ Muhammadu Buhari, Garba Shehu to fi eyi lede ni ori ẹrọ ikansiraẹni Twitter rẹ, sọ wi pe ọjọ mẹwa ni Buhari yoo lo lati lọ se ayẹwo ara rẹ.
''A ko fẹ wa ọwọ mọ nnkan ìní awọn ọmọ orile-ede Naijiria kankan sugbọn a o ri wi pe a tele ilana to tọ sugbọn o seese ki o pẹ diẹ'' Bakan naa ni Theresa May mẹnu ba pataki kikoju ipenija aabo ati ìfọwọ́sowọ́pọ̀ láti kojú ìpeníjà Boko Haram.
Eyi waye nitori pe ọwọngogo owo ọkọ ti pọju nitori ẹkun omi to ti gba gbogbo oju titi tan.
Opọ ẹmi ati dukia lo ti ba iwa ipa ati igbesunmọmi awọn Boko Haram rin ni Naijiria ni eyi ti ọpọ si ti di alarinkiri ati aṣatipo lagbaye.
Ìlú Ògbàgì jẹ ́ ọ ̀ kan nínú àwọn ìlú pàtàkì tó wà ní agbègbè àríwá Àkókó ní Ìpínlẹ ̀ oǹdó .
O pari ọrọ rẹ pẹlu imọran pe ki ẹnikẹni to ba bimọ fun ọkọ oun, o yọju si gbangba.
Ẹ jọ̀wọ́ nítorí Ọlọ́run, ẹ má jẹ́ kí oore di ibi mọ mi lọ́wọ́."
O fi igba kan jẹ aarẹ adari ẹka imọ iṣegun ni fasiti Maitama Sule ni ilu Kano ki o to jade laye.
Ọ̀rẹ́kùnrin pa ọmọ igbákeji gómínà tẹ́lẹ̀rí Wo Ọ̀jọ̀gbọ́n Eleka tó ń díje fún ipò gómìnà Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, FFK: Buhari ló ń fún àwọn Fulani láàyè láti máa pa ènìyàn' Ẹ̀wẹ̀, àwọn ọ̀dọ́ Nàìjíríà náà kò dákẹ́ bí ó ti lẹ jẹ́ pé wọ́n ń dárò ọdọbinrin naa, lọ́gán ni wọ́n fun Yọmi Shogunlẹ lesi ni oju opo Twitter rẹ.
Gege bi ajo to n mojuto Isele
, Duration 5,5712 Òkùdu 2020 4:51 Fídíò, Lateef Adedimeji: Owó wa kò bá máa jóná ṣùgbọ́n aàyè ọpẹ́ ń yọ fún wa, Duration 4,5119 Ògún 2019 BBC News, Yorùbá Ìdí tí ẹ fi le è nígbàagbọ́ nínú ìròyìn BBC Ìlànà Lílò Nípa BBC Òfin Àṣírí Cookies Kàn sí.
Jesu jáde kúrò níbẹ̀, ó lọ sí agbègbè Tire ati Sidoni.
O korin pelu awon eekan bii Taj Mahal atiToumaniDiabatélati gbe orin bii Kulanjan, jade, eyi ti itakun agbaye re gba pe Obama to je aare ile Amerika tele ni oun feran.
Ki ijoba yii to de lodun meta seyin , awon agbegbe  ati ijoba ibile to wa ni ila-oorun ti omo –ogun Boko Haram ti n je gaba le lori po pupo.
Ajọ to n mojuto gbigbogun ti ajakalẹ arun nilẹ Amẹrika, CDC ti ṣaaju fi ikilọ sita pe sanitaisa to ni ọti ninu ni agbara lati ba iwe itẹka ibo jẹ.
"Oríṣun àwòrán, Bola Ahmed Tinubu Bakan naa ni gomina ipinlẹ Eko tẹlẹ tun woye pe ""awọn eeyan to ni agbekalẹ eto aabo Amotekun yoo fa isọkan orilẹede Naijiria ya pẹrẹ-pẹrẹ lo jẹ ẹwa ede to lewu lati ẹnu awọn eeyan to yẹ ki oye ye julọ."
Kíni ẹ mọ̀ nípa Ọmọ́táyọ̀ Olútóyè, Ọ̀jọ̀gbọ́n obìnrin àkọ́kọ́ nínú ẹkọ́ èdè Yorùbá lágbàyé À ti fi àwọ̀n ọlọ́kadà 123 láti Jigawa sílẹ̀ -Ọlọpaa Àwọn jàǹdùkú pa fadá ní Taraba-Iléeṣẹ́ ọlọ́pàá Ọkọ̀ òfúrufú ọlọ́pàá yóò bẹ̀rẹ̀ sí ní káàkiri Naijiria - Ọgá Ọlọ́pàá Aarẹ ilẹ Amerika, Donald Trump ti fi sita loju opo twitter rẹ pe gbogob nkan to n ṣẹlẹ ni wọn fi n to oun leti bo ṣe n lọ ni Texas.
Ninu ọrọ to ba awọn onwoye kaakiri ti wọn wa lati mojuto bi nnkan ṣe nlọ nibi idibo naa sọrọ nilu Ado Ekiti ni ajafẹtọ naa ti ṣalaye ọrọ yii.
Aare orile ede Naijiria Muhammadu Buhari ti dibo gomina ti  odun 2019 ati ile igbimo asoju  , ni eyi ti o waye jake –jado orile ede Naijiria.
Awọn ilu miran ti awọn eeyan alawọ dudu pọ si bii Detroit, Milwaukee, New Orleans ati New York, lo ti di ibuba fun arun naa.
Àwọn ìròyìn mìíràn tí ẹ lè nífẹ̀ẹ́ sí: 2019 elections: Ìgbésẹ̀ méje fún ìdìbò 2019 tí ó yẹ kí o mọ̀ Saraki: Ọ̀gá ọlọ̀pàá Idris ń lépa ẹ̀mí mi ‘Aawọ abẹnu lee koba APC ni 2019’ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 2019 election: Àwọn olùdíje fún ipò gómìnà nípínlẹ̀ Kwara sọ̀rọ̀ lórí ohun tí wọ́n fẹ́ ṣe Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Ọdun 2016 ni rogbodiyan bẹrẹ ni agbegbe naa.
O sapejuwe awon ti o n  soro yii gege bi” Alaimokan ati alailesin.
Ondo, Oyo, Kwara lori gbedeke 30,000 owo osu osisẹ Komisona feto iroyin ni ipinlẹ Ondo, Donald Ojogo, lasiko to n ba BBC Yoruba sọrọ salaye pe, ijọba ipinlẹ Ondo ti gbe igbimọ kan kalẹ lati se ayẹwo awọn osisẹ to wa ni ipinlẹ Ondo, boya awọn yoo le san owo osu tuntun fawọn osisẹ naa.
Lẹ́yìn náà, OLUWA Ọlọrun wí pé, “Nisinsinyii tí ọkunrin náà ti dàbí wa, tí ó sì ti mọ ire yàtọ̀ sí ibi, kí ó má lọ mú ninu èso igi ìyè, kí ó jẹ ẹ́, kí ó sì wà láàyè títí lae.
Ṣugbọn ó ti mọ ẹ̀tàn wọn.
Ṣìṣeṣìṣe Troost-Ekong ṣokùnfà ìyà àjẹsùn fún Nàìjíríà lọ́wọ́ Algeria Aago Naijiria ti kún àkúnwọ́sílẹ̀ - Tunde Bakare Àwọn olówó Naijiria 5 tí owó wọn ju owó ìsúnná Naijiria lọ!
Aarẹ orileede Naijiria, Muhammadu Buhari ti pasẹ fun awọn ẹsọ eleto aabo lorilẹede Naijiria, lati dẹkun bi awọn eniyan kan se n ko ohun ija wọ orilẹede Naijiria lọna ẹburu.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù First Lady: Kí ló mú Aisha Buhari gbà oyè tó kọ tẹlẹ?
Ìrẹ̀lẹ̀-ẹ́ wá ati ọ̀rẹ́-ẹ rẹ̀ Ṣebíotimọ ṣùgbọ́n ariwo Ìgbéraga àti ìbátan rẹ̀ Àṣejù ti pọ̀ jù nítorí náà wọn kò pẹ́ púpọ̀ kí wọ́n tό-ό lọ; wọ́n lọ bá ọ̀re-ẹ́ wọn Ayọ̀ àti Inú-dídùn níbi ti wọ́n ti ńta ayò ní ìgboro.
Ṣugbọn yóo sọ fun yín pé, ‘Èmi kò mọ̀ yín rí.
Ọ̀pọ̀ ènìyàn ló sì ti ń sọ ẹni ti wan ni lọ́kan pé yóò lọlé, sùgbọ́n bí o ṣe bá àwọn lan lójiji pé Eric àti Tochi ló lọ sílé, àwọn míràn ni kò ya àwọn lẹ́nu pé èyí ṣẹlẹ̀.
Ní èrò tèmi o, wọ́n bu ẹwà kún ìlú Èkó rẹpẹtẹ!
Nínú fídíò yìí láti rí Lizzy tó n jó sí orin ìgbéyàwó tí àwọn alága ìdúró/ìjókòó n kọ.
Akitiyan ìjọba láti mú kí àwọn ọmọ Nàìjíríà san owó orí Ẹ fẹ mọ iye to gba abi, lalai deena pẹnu, Ibrahim Salisu Iriyos gba ẹgbẹrun marun un Naira gẹgẹ bi agbabọọlu ti o gba owo julọ fun ẹgbẹ Super Stars.
Nínú àtẹ̀jáde kan tó fi síta l'ọ́jọ́bọ̀ lójú òpó Twitter, Kachikwu ṣàlàyé pé ohun tí òun sọ ni òun wà lára àwọn akẹ́kọ̀ọ́ tó lákè nígbà tí òun parí ẹ̀kọ́ ìmọ̀ nípa òfin ná yunifásitì Nigeria, Nsukka.
''Ìséde káàkiri Nàìjíríà lọ̀nà àbayọ sí ìtànkálẹ̀ coronavirus, bí bẹ́ẹ̀ kọ́ àpá kò ní ká covid-19 mọ́''- Onímọ̀ Nàìjíríà tún ní àkọsílẹ̀ ènìyàn 108 tó ní ààrùn coronavirus Ǹjẹ àgbo lè ṣe òògùn coronavirus?
"Ajafẹtọ ọmọniyan kan ni Naijiria, Nkasi Wode, sọ pe ""niṣe ni Boko Haram ati awọn janduku n ṣiṣẹ ni Iwọ oorun Ariwa ati Ila oorun Ariwa Naijiria, lai si idiwọ kankan""."
Ninu ipade igbimo ijoba apapo to waye nile-ise aare lojoBo(Thursday), ogbeni Faki so di mimo pe, ki i se nitori aaye ti o sofo ni apapo igbimo ohun fi yan aare Buhari gege bi eni ti osuwon re kun julo ninu isejoba awon aare ti o n koju iwa-ibaje nile Afrika.
Ogbeni Hadi Sirika pari oro re pe, orile-ede Naijiria nilo olotito akinkanju ati eni ti o se fokan tan adari bi aare Buhari.
Minisita Aarẹ Muhammadu Buhari ti ran awọn aṣoju si aarẹ South Africa lati fi ẹdun ọkan rẹ han ati lati wa nnkan ṣe si ikọlu ati ikoriira awọn ọmọ Naijiria to n gbe ni South Africa.
“Ẹ kò gbọdọ̀ jẹ ọ̀rákọ́ràá, ìbáà jẹ́ ti mààlúù tabi ti aguntan tabi ti ewúrẹ́.
Mo wá gbọ́ ohùn angẹli tí omi wà ní ìkáwọ́ rẹ̀ tí ó sọ pé, “Olódodo ni ọ́ fún ìdájọ́ rẹ wọnyi, ìwọ tí ó wà, tí ó ti wà, ìwọ Ẹni Mímọ́!
To a man, who has been exemplary in life and his commitment to Nigeria,To a man who has a great sense of humour,To a man who genuinely loves the Nigerian people and to a man I am privileged to call Boss, Happy 76th Birthday!
Bade lati ipinle  Kaduna adari aato ile ,
"Nitori naa, awọn ẹka ileeṣẹ ọlọpaa to n gbogun ti ẹgbẹ okunkun, ijinigbe, ati idigunjale si ti wa ni imurasilẹ lati tu ipejọpọ bẹ ẹ ka.
Wọn kò mọ̀ pé Josẹfu gbọ́ gbogbo ohun tí wọn ń wí, nítorí pé ògbufọ̀ ni wọ́n fi ń bá ara wọn sọ̀rọ̀.
Awon gomina merin lo wa nibi ipade ohun.
Ẹgbẹ oṣelu PDP kọwe mọ wipe kò yẹ ko wa lara igbimọ naa nitori wipe ọmọ ẹgbẹ oṣelu APC ni ọkọ rẹ ati wipe, o ti kọwe fi igbimọ naa silẹ ni Ọjọru.
Lati le mu iyatọ ba bi ijọ Aguda ti ṣe n fọwọ mu awọn ẹjọ to ni ṣe pẹlu ibalopo ọmọde ni wọn ṣe mu iyipada ofin yi wa.
Asiri bí Elikana, Elikana bí Ebiasafu, Ebiasafu sì bí Asiri.
Ẹgbẹrun marundinlogun o le ọọdunrun ati mẹtalelọgbọn lo ti ri iwosan, ṣugbọn ẹgbẹrin o le ẹyọkan ẹmi lo ti baa rin.
Borno Zabarmani Rice Farmer Massacre: Àwọn àgbàgbà Òkè Ọya ní ẹ̀mí èèyàn kò níyì mọ́ lábẹ́ ìṣèjọba Buhari
Ileesẹ BBC World Service ati ileesẹ MTN ti setan lati maa mu iroyin yi wa si eti igbọ yin lọfẹ lede Yoruba, Pidgin Igbo ati Hausa.
#Adewura Latifa Bello: Ọlọ́pàá ní àwọn kò tíì lè fídí rẹ̀ múlẹ̀ pé òun ni
O wa gba awọn awọn ọmọ ẹgbẹ ANC nimọran lati sọọse ki omi maa baa tẹyin wọ igbin wọn lẹnu.
Ṣugbọn sibẹsibẹ, a kò gbọdọ̀ fi àwọn ọmọ wa fún wọn.
pé kí ó sọ fún àwọn ọmọ Israẹli pé, “Bí ẹnìkan bá jẹ́jẹ̀ẹ́ pataki kan láti fi odidi eniyan fún OLUWA, tí kò bá lè mú ẹ̀jẹ́ rẹ̀ ṣẹ, iye tí ó níláti san nìyí: 
Àwọn ọba Yorùbá kan rèé tí wọ́n rọ̀ lóyè, tí ọba míràn jẹ lójú ayé wọn Ajá kìí rorò kó ṣọ́ ojú'lé méjì, kò tọ́ ọ́ sí Alaafin láti dásí ọ̀rọ̀ ọba l‘Ekiti - Peter Fatomilọla Minisita fere idara jẹ ko di mimọ pe lẹyin ti wọn gbe kalẹ niwaju aarẹ lo jẹ ko gbe aṣẹ naa kalẹ lati dena itankalẹ arun naa.
Jonathan, Igbakeji Aarẹ ojogbon Yemi Osinbajo, Abenugan ile Igbimọ Asofin,
Hakeem ni ohun didun, to si tun jẹ ẹlẹyinju aanu, ẹni to n kopa ribiribi si eto idagbasoke ilẹ Afirika.
(Nítorí pé àwọn ọmọ ẹ̀yìn Atalaya, obinrin burúkú n nì, ti fọ́ ilé Ọlọrun, wọ́n sì ti kó gbogbo ohun èlò mímọ́ ibẹ̀, wọ́n ti lò ó fún oriṣa Baali.
Oriṣiriṣi eegun lo wa nilẹ Yoruba ṣugbọn ọtọ ni ti eegun Danafojura to n jade ni ilu Ogbomọsọ ni ipinlẹ Oyo ni guusu Naijiria.
Nítorí náà, ṣọ́ra, o kò gbọdọ̀ mu ọtí waini tabi ọtí líle, bẹ́ẹ̀ ni o kò gbọdọ̀ jẹ ohunkohun tí ó jẹ́ aláìmọ́.
Ko to darapọ mọ ileeṣẹ NNPC, Baru ṣiṣẹ nile iṣẹ Jos steel Rolling Company laarin ọdun 1988 si 1991.
Ẹgbẹ osisẹ lorilẹede Naijiria,NLC ti ni idi ti awọn fi kọ ẹgbẹrun lọna mẹtadinlọgbọn(27,000) Naira ti ijọba fi ọwọ si gẹgẹ bi gbendeke owo osu awọn osisẹ lorilẹede Naijiria ni wi pe ijọba ko mu adehun wọn sẹ.
Hasaeli ọba Siria kò fi àwọn ọmọ Israẹli lọ́kàn balẹ̀ ní gbogbo àkókò ìjọba Jehoahasi.
kí ẹ lè máa bẹ̀rù OLUWA Ọlọrun yín, ẹ̀yin ati arọmọdọmọ yín, kí ẹ lè máa tẹ̀lé àwọn ìlànà ati òfin tí mo fun yín lónìí, ní gbogbo ọjọ́ ayé yín, kí ẹ lè pẹ́ láyé.
Ọ̀pá afẹ́fẹ́ gáásì NNPC tó dálu ló fa ìbúgbàmù l'Eko, ilé 50 àti ọ̀pọ̀ ẹ̀mí ṣòfò Ijamba ina to sadede bẹ silẹ lọsan ọjọ Aiku lagbegbe Ado Soba, Abule Ado nijọba ibilẹ Amuwo Ọdọfin ti mu ẹmi lọ, to si tun ba ile to le ni aadọta jẹ kanlẹ.
asofin , Ike Ekweremadu naa tun so pe awon ijoba ibile naa ni lati da duro ni
Ẹ̀yin ìdílé Jakọbuẹ wá, ẹ jẹ́ kí á rìn ninu ìmọ́lẹ̀ OLUWA.
“Àjàgà wúwo ni Solomoni baba rẹ gbé bọ̀ wá lọ́rùn.
”Aare tun wa se ikilo pe  “opolopo igbese ni a n gbe lati dekun iwa ibaje, ni eyi ti o si n so eso rere.
Ami ayo meji si odo ni Arsenal fi gbẹyẹ mọ Manchester United lọwọ ninu ifẹsẹwọnsẹ naa.
Àwọn oṣiṣẹ to n sisẹ lori afara naa ti la ọna kan nibẹ fun eyi.
Awọn agbẹ naa ke gbajare pe pẹlu bi wọn ṣe pa ọkan lara wọn, ti wọn fipa ba awọn ọmọ wẹwẹ wọn lopọ ti wọn si ba oko wọn jẹ, sibẹ sibẹ, awọn daran daran yii ṣi n da ilu awọn laamu eyi to si n gba orun loju wọn.
Eeyan ẹgbẹrun mẹwa pere ni yoo kopa ninu Hajj ọdun 2020, tosi jẹ pe pupọ ninu wọn ni yoo jẹ awọn ọmọ ilẹ Saudi ati awọn ajoji to n gbe nibẹ.
Boukar Mani Orthe sọ pé àwọn agbébọn bíi àádọ́ta ni wọ́n kọlu ìlú náà, tí wọ̀n sì gbé àwọn ọmọbìnrin náà lọ.
Tẹẹ ba ni awọn ẹlẹyamẹya to buru pupọ lawọn to gbe fọnran aworan naa jade, mo setan lati tọrọ aforijin toba wu yin ki n se bẹẹ."
Nígbà náà ni wọ́n tún ń wá ọ̀nà láti mú un, ṣugbọn ó jáde kúrò ní àrọ́wọ́tó wọn.
Àwọn olùkọ fásitì bẹ̀rẹ̀ ìyanṣklódì náà ní láti jà fún àìṣe àmúṣẹ àwọn àdéhùn lórí ìtọjú àwọn òṣìṣẹ́.
Bó tilẹ̀ jẹ́ pé ìròyìn òfegè ni pé Buhari fẹ fẹ́ Sadiya, síbẹ̀ àwọn ọmọ Nàìjíríà ń ṣètò ìyàwò náà lórí ayélujára Olùkọ́ àgbà tó fipá bá ọmọ ọdún 13 lò yóò fojú ba ilé ẹjọ́ ni Benue Ẹṣẹ wo ni Ambode ṣẹ̀ tí ilé aṣòfin Eko fẹ́ fí ọlọ́pàá mú u?
Nígbà tí ó dé ọ̀dọ̀ Simoni Peteru, Peteru bi í pé, “Oluwa, ìwọ ni o fẹ́ fọ ẹsẹ̀ mi?
Kenaani yìí kan náà ni baba ńlá àwọn ará Jebusi, àwọn ará Amori, àwọn ará Girigaṣi, 
a wí fún un pé, a kò ní lọ, àfi bí arakunrin wa bá tẹ̀lé wa, nítorí pé a kò ní rí ojú rẹ nílẹ̀ bí kò bá bá wa wá.
Ó bá dìde lórí adura, ó lọ sọ́dọ̀ àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀, ó rí wọn tí wọn ń sùn nítorí àárẹ̀ ìbànújẹ́.
Ilé asofin àgbà pàrọwà yìí lásìkò ìjíròrò lórí abá kan, tí asofin Uche Ekwunife gbé wa ṣíwájú ilé, èyí tó fi ń pe àkíyèsí àwọn asofin àgbà si ipo ti ifilọlẹ ẹ̀rọ 5G náà dé dúró.
‘ASUU da ìyanṣẹ́lódì dúró' Lẹyìn tí mo figbe ta, INEC mú PVC mi wá bá mi nílé - Gani Adams Ọ̀pọ̀ àwọn ará ìlú ló ti ń wọ tìkẹ́tìkẹ́ báyìí lọ si gbọ̀ngàn Olusegun Obasanjọ Libaray ní ìlú Abeokuta, ní bi tí wọn ó ti máá fí ojú ajé kan onisọ.
Orúkọ ọmọ rẹ̀ kinni ni Geriṣomu, (ìtumọ̀ rẹ̀ ni pé, “Mo ti jẹ́ àtìpó ní ilẹ̀ àjèjì.
Nítorí níbi tí ìṣúra rẹ bá wà, níbẹ̀ náà ni ọkàn rẹ yóo wà.
O ni awọn ọmọbirin naa sa wọ igbo, nibi ti wọn sapamọ si.
Ẹ̀rù Solomoni ba Adonija tóbẹ́ẹ̀ tí ó fi sá lọ sinu Àgọ́ OLUWA, tí ó sì di ìwo pẹpẹ mú.
0 15 Marshall Islands 0 0.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Farms to You: Irú ajílẹ̀ wo ló yẹ fún lílò lásìkò yìí- Aisha Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
ati Mejakoni, ati Rakoni pẹlu agbègbè tí ó dojú kọ Jọpa.
8 5811 Orilẹede Guadeloupe 151 37.
'Àwọn oníṣòwò lẹ̀ka ètò ẹ̀kọ́ nìkan ló lè forúkọ sílẹ̀ báyìí fún ìrànwọ́ ìjọba àpapọ̀ Nàìjíríà' Ọgbẹni Ogunwuyi ni nigba to ba ya ni eto naa yoo kan awọn mii ti ọwọja coronavirus ṣe ipalara fun bakan naa.
OLUWA ti mú kí àwọn ọmọ ogun Siria gbọ́ ìró ẹsẹ̀ kẹ̀kẹ́ ogun ati ẹṣin ati ọpọlọpọ àwọn ọmọ ogun.
Fifi dandan le pe ọmọ ilu kan lo gbọdọ jẹ ọga ileewe ilu rẹ.
 Ó gba Ọ ̀ pa àṣe ní ọjó keje oṣù kejìlá , ọdún 2015 .
Oríṣun àwòrán, @aishambuhari Sugbọn awọn agbofinro naa ko lee ṣe ohunkohun nipa rẹ nitori pe ẹni ti aje ọrọ naa ṣi mọ lori jẹ ọmọ Mamman Daura.
nítorí ọ̀rẹ́ mi kan ti ìrìn àjò dé bá mi, n kò sì ní oúnjẹ tí n óo fún un’; 
Bakan naa, gbajugbaja oserebinrin, Alhaja Fausat Balogun, ta a mọ si Madam Sajẹ, naa ti ni eniyan to se e gbarale ni Dagunro nigba aye rẹ.
Lẹ́yìn tí Ade Love papoda tán, ní àwọn ọmọ bibi rẹ mẹ́rin náà, tí mẹta nínú wọn jẹ ọkùnrin nígbà tí Mojisola nìkan jẹ obinrin, jogún isẹ baba wọn, tíì ṣe ère tíátà.
Kí a yọ epo kúrò nínú àlìkámà, a ti bere ìbéèrè lowo awon onímò.
O fikun oro re pe, opolopo awon omo orile-ede Naijiria ni o n keeko lorile-ede Canada ni erongba lati wa se amulo awon imo naa lorile-ede Naijiria.
"Ọkọ kọ̀ mí, mo fẹ́ jẹ májèlé torí mo bímọ tó ní ojú ara takọtabo Èèyàn méjì tó ń gbọ́n epo bá ìṣẹ̀lẹ̀ ọkọ̀ epo tó gbiná rìn n‘Ibadan Àpẹrẹ lásán ni ẹsẹ̀ wíwẹ̀, ìwà ìrẹ̀lẹ̀ ni kókó - Àlùfá àgbà Akinyemi Nigba naa lo fi hande wi pe oun ko korira afipabanilopọ to jẹ baba oun to fipa ba iya rẹ lo pọ lọjọ kinni ana ṣugbọn o ni ""mo ti dari ji baba mi"" tori o ṣe ko ṣe, oun lo ṣe ọlọkọ to wa mi wa si aye."
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù How to apply for Nigeria Youth Investment Fund: Wo ibi láti mọ̀ síi nípa àwọn ọ̀dọ́ tó máa ri owó náà gbà 29 Ọ̀wàrà 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 3 Bélú 2020 Oríṣun àwòrán, @Emefiele Banki apapọ Naijiria ti a mọ si Central Bank ti ṣalaye lẹkunrẹrẹ lori irufẹ awọn to maa ri gba ninu owo iranwọ ti o jade yii.
Atẹjade kan ti ileeṣẹ to n ri si karakata owo epo lorilẹede Naijiria, PPMC fi sita ṣalaye pe igbesẹ naa wa lati tubọ mu ki ọja rẹ tubọ ta si ni ibamu pẹlu aṣẹ ajs to n ri si idiyele owo epo lorilẹede Naijiria, PPPRA gbe kalẹ lori iye ti wọn yoo maa ta epo lorilẹede Naijiria.
''Baba mi ko fẹ ki n ṣiṣẹ tiata, o ni iṣẹ tiatia yoo jẹ ki n maa ṣe oogun,'' Elesho lo woye bẹẹ.
ẹ óo mọ òtítọ́, òtítọ́ yóo sì sọ yín di òmìnira.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Osinbajo àti PDP ń jiyàn lórí ìkówójẹ́ lábẹ́ àwọn adarí wọn 7 Èbibi 2018 Oríṣun àwòrán, @ProfOsinbajo/@OfficialPDPNig Àkọlé àwòrán, Bùhárí kò lè fọwọ́ sọ̀yà pé òun kógojá nígbà tí àwọn tó ba ni ẹ̀sùn ìkówòjẹ kìí jẹ́jọ́ mọ́ bí wọ́n bá ti darapọ̀ mọ́ ẹgbẹ́ òṣèlú APC Ọ̀rọ̀ ti ń di èyí tí à ń gbà bí ẹni gba igbá ọtí, láàárín igbákejì ààrẹ orílẹ̀-èdè Nàíjíríà, Yẹmí Osinbajo, ati ẹgbẹ́ òṣèlú PDP, lórí ìdánimọ̀ ati orúkọ àwọn tó da owó ìlú si àpò arawọn.
Èyí sì lòdì sí ìlànà tó wà nílẹ tẹ́lẹ̀, torí àkọ́bí Aláàfin gbọ́dọ̀ kú pẹ̀lú rẹ ni.
Oríṣun àwòrán, TWITTER/NPOWER_NG Wo bi o ṣe le fi orukọ silẹ Gbogbo ẹni to ba koju osuwọn ni lati lọ si oju opo ayelujara ileeṣẹ ijọba apapọ to wa fun eto ẹkọ ni www.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fọ́nrán ohùn, Onimọ nipa ile kikọ sọwipe ijọba nilo awọn onimọ nipa owo ori ile Wọn ti ko awọn ti wọn farapa lọ si ile iwosan ijọba ni Gbagada nipinlẹ Eko.
Nígbà tí ó di òwúrọ̀, Jakọbu rí i pé Lea ni wọ́n mú wá fún òun.
Ninu ọrọ rẹ pẹlu BBC Yoruba, amofin naa ni oun ti ajọ CDHR nilo lati ọdọ ẹni ti ileeṣẹ okeere naa da pada lẹnu ọna, ni ẹri bii fidio tabi aworan ti yoo fi ohun to ṣẹlẹ han.
"Iroyin wipe ti aarẹ Zuma ko ba kọ'we f'ipo s'ilẹ, awọn asofin lorilẹede naa yoo d'ibo mi o ni igbẹkẹle ninu rẹ, (vote of no confidence)""."
Kete ti wn gbọ ni wn fọn sori ayelujara lati da si ọr naa.
Àwọn ènìyàn tilẹ̀ ni òun ló yẹ kí ó gba àmì ẹ̀yẹ ọmọ tó jáfáfá jù lọ lágbàyé.
Nítorí náà, gbogbo ẹ̀gbẹ́ ní ń dùn mí,gbogbo ara ní ń ro míbí obinrin tí ń rọbí lọ́wọ́.
Nítorí bí wọ́n bá ti bọ́ lọ́wọ́ ìbàjẹ́ ayé nípa mímọ Oluwa ati olùgbàlà wa, Jesu Kristi, tí wọ́n tún wá pada sí ìwà àtijọ́, tí ìwà yìí bá tún borí wọn, ìgbẹ̀yìn wọn á wá burú ju ipò tí wọ́n wà lákọ̀ọ́kọ́ lọ.
NEMA: Ǹkan méje ló ń fa omíyale ní orílẹ̀-èdè Nàìjíríà
 jonston jẹ ̀ bi àìmọ ́ mọ ̀ pànìyàn , ó sì gba ẹ ̀ wọ ̀ n ọgbọ ́ ̀ oṣù pẹ ̀ lú ìdánidúro ọkọ ̀ wíwà fún ọdún marún .
Lara awọn adugbo to gbajumọ nilu Eko si ni Oshodi, bii eeyan ba si de Eko, lai mọ adugbo Oshodi, onitọhun ko mọ Eko rara.
Ipinlẹ Ekiti lo ṣe daadaa ju nipa wiwo alafo to wa laarin akọ sabo ni gbogbo ipele eto ẹkọ.
Ìfẹ́ yín dàbí ìkùukùu òwúrọ̀, ati bí ìrì tíí yára á gbẹ.
Ṣugbọn àwọn orílẹ̀-èdè wọnyi kò mọ èrò OLUWA, ìpinnu rẹ̀ kò sì yé wọn, pé ó ti kó wọn jọ láti pa wọ́n bí ẹni pa ọkà ní ibi ìpakà.
Ṣugbọn bi wọn ṣe kọja Cedi Plaza ni Abuja ni wọn pade awọn ọlọpaa.
BBC Yoruba n gba ẹyin ọdọ asiko yii naa nimọran lati fi irun dudu ṣiṣẹ si idagbasoke ede ati aṣa Yoruba ko ma baa parun lasiko ti yin, ki awọn eeyan le ri ipa rere ti yin naa sọ nigba ti agba tabi ọlọ́jọ́ ba de.
1 298 Erekusu Saint Lucia 2 1.
Alli-Macaulay ni ti awọn omo Naijiria ba ti fa igbo tan ni wọn ma n lọ si ori ẹrọ ayelujara lati lọ sọ isọkusọ.
Mọkanlelogun lara wọn ni i ṣe pẹlu idibo, mẹfa si jẹ ti ibọn yinyin, eyi to yọri si iku eeyan marun-un.
Peteru bẹ̀rẹ̀ sí wí fún un pé, “Wò ó ná, a ti fi ohun gbogbo sílẹ̀ láti tọ̀ ọ́ lẹ́yìn!
Igbimọ oluwadi fẹ ki wọn o da awọn oṣiṣẹ JAMB to ja'le duro
Bí o bá ń se N-Power tóo sì ti ríṣẹ́ sí ibòmíràn, olè ni ọ́!
Wayii o, eyi ti o je iyalenu be ni, orile-ede Tanzania ti o lanfani ati wa soke die si lataari pipegede fun ifesewonse idije boolu ile Afrika leyin odun  mọ́kàndínlógójì seyin ti orile-ede naa ti kopa gbeyin fun idije AFCON.
Awọn onimọ sayẹnsi ti sọ pe irọ ni iru iroyin naa.
Eyi ti awọn esi idije miiran ninu Europa liigi: Atlético Madrid 3-0 Lokomotiv Moscow Borussia Dortmund 1-2 FC Red Bull Salzburg CSKA Moscow 0-1 Lyon Lazio 2-2 Dynamo Kiev Marseille 3-1 Athletic Bilbao RB Leipzig 2-1 Zenit St Petersburg Sporting Lisbon 2-0 Viktoria Plzen.
NIMC: NIMC, NCC, NITDA àti GBB gbọ́dọ̀ ṣiṣẹ́ papọ̀ kí ètò aàbò Nàìjíríà lè dára síi
Òkè àti pẹ ̀ tẹ ́ lẹ ̀ , oòrùn àti òsùpá , àwọ ̀ sánmọ ̀ àti erùpẹ ̀ ilẹ ̀ , gbogbo ìwọ ̀ nyí jẹ ́ ìyanu.
O ni pupo ninu awn iṣẹlẹ iṣekupa awn obinrin ni ko lu sita.
Mó lùgbàdì ààrùn Covid-19 àyẹwò sì fìdí rẹ̀ múlẹ̀.
Oba Atobatele Arugba naa jọba laarin ọdun 1837 si 1859, to si lo ọdun mejilelogun nipo.
Àwọn ọmọ ogun tí àwọn ará Bẹnjamini kó jọ ní ọjọ́ náà jẹ́ ọ̀kẹ́ kan ati ẹgbaata (26,000) àwọn ọkunrin tí wọn ń lo idà; láì ka àwọn tí wọn ń gbé Gibea tí àwọn náà kó ẹẹdẹgbẹrin (700) akọni ọkunrin jọ.
Gege bi alaga ero ayelujara Twitter, Omid Kordestani, se so,“ inu mi dun pupo lati ki @NOIweala ati @authorzoellick kaabo saarin igbimo awon oludari @twitter.
Ọjọ mọkanlelaalọgọrin ni awọn olukopa fi wa ninu ile Big Brother, nibi ti wọn ti kopa ninu oriṣiriṣi idije, faaji, ariya, ati bẹẹbẹ lọ.
Júpítérì jẹ́ kìkósọ́tọ̀ bíi òmìrán ẹ̀fúùfù lápapọ̀ mọ́ Sátúrnù, Úránù àti Nẹ́ptúnù.
2019 Flood Alert: Àṣírí ọ̀nà tí ẹ le gbà dèna omí yale rèé.
Lẹ́yìn gbogbo sinimá oríta ní Ondo, Akẹti jáwé olúborí ní APC Èsi idibo lati yan ẹni ti yoo dije du ipo gomina fun ipinlẹ Ondo labẹ ẹgbẹ oṣelu APC ti jade.
Ajọ eleto idibo ni ipinlẹ Ekiti ti kede pe awọn ti n ka ahesọ ọrọ kan to gba awọn oju opo ikansira ẹni lori itakun agbaye kan, nibiti wọn ti n kede esi ibo gomina ni ipinlẹ Ekiti lọna ti ko bofin mu.
urdu jẹ orukọ ọkan ninu awọn ede ti a sọ ni south asia .
Àwọn dókítà Eko bẹ̀rẹ̀ ìyanṣẹ́lódì lórí owó oṣù àti ètò adójútòfò fún ìtọ́jú Coronavirus Alaga ẹgbẹ awọn to ni ileewe aladani ni Naijiria, National Association of Private school Owners, ti fidirẹmulẹ pe lootọ ni ijọba apapọ fẹ ẹ san owó oṣù awọn oṣiṣẹ wọn.
‘Olùkọ́ fipá bá akẹ́ẹ̀kọ́ girama lòpò nítorí máàkì’ Buhari, kò sí iṣẹ́, owó àti Oúnjẹ́ - Ọmọ Nàíjíríà figbe ta Ìtàn ìgbé ayé Abdulrahman Abdulrazak, gómìnà Kwara Ọ̀rọ̀ Aisha Buhari sí Ramaphosa wú ọ̀rọ̀ síta lẹ́nu àwọn ọmọ Nàìjíríà Idahun si ibeere toni: Ige ni ọmọ ti o fi ẹsẹ̀ wa si ayé.
 Àmọ ́ , ànìyàn ẹgbẹ ́ òṣèlú náà ló dá lórí ìṣèjọba àwùjọ àwa-arawa ló mú yàtọ ̀ sí àwọn ẹgbẹ ́ òṣèlú tó kù .
 gbogbo ilẹ benue-congo ni wọn tí máa ń lò ó .
Giroud fakọyọ lopolopo, leyin ti o gba ami aayo meta sagbon.
Nibayii, orilẹede mẹtala ni aarẹ Trump ti fi ofin to lagbara de bayii nipa wiwa si orilẹede Amerika.
ní ìgbà yẹn , ó ṣe pàtàkì kí gbogbo ọkọ ̀ tí wọ ́ n kọ ́ ní ọdún 1988 kí ó ní ohun tí ó lè dínwọ ́ eré sísá kù .
fi anfaani yii dupe lowo igbakeji mi, nitori pe, o mọ ohun ti a n la kọja, ni
Usman Yahaya to jẹ́ bàbá Dayo ni bí àwọn ṣe bi Dayo ni iya oun ti gbà ọmọ náà láti tójú, ṣùgbọ́n àsìkò to bẹ̀rẹ̀ si ni lọ ilé ẹkọ, òun ṣe àkíyesi pé kò dẹrùn fun láti kọ iwé.
Bakan náà ní ẹgbẹ́ tó n ri sí ìjọ ìgbàlóde (PFN) sọ lọ́sẹ̀ tó kọ́ja pé ó kọ̀ láti yoju sí ìpáde ti àwọn pèé sí fún ìfọ̀rọ̀wánilẹ́nuwò.
A fi Òróró Yan Jehu ní Ọba Israẹli.
Wo àwọn àsọtẹ́lẹ̀ ìgbà tó yẹ kí ayé parẹ́ àtàwọn tó sọ àsọtẹ́lẹ̀ náà Lẹ́yìn tí mo gbé ayé mi yẹ̀wò, mo ríi pé asán layé - Toyin Abraham Oníṣòwò kan wó ọ́fíìsì Nàìjíríà ní Ghana lulẹ̀, ìjọba Nàìjíríà faraya Ó di gbéré!
Mi o ro pe o mọ itumọ rẹ.
Ọkùnrin náà wí fún Ewédayépọ̀ pé oògùn aporó ní ń bẹ nínú akèǹgbè náà àti wí pé títí á ó fi dé ilé ni kí ẹnì kọ̀ọ̀kan wa máa mu ìdajì ṣíbí nínú rẹ̀ lójoojúmọ́ àti pé bí a bá ti ń ṣe èyínì kò sí oró ejò tí ó lè mú wa.
Nígbà tí ó di alẹ́, Paulu rí ìran kan.
Ẹsun keji to kọ Trump lẹsẹ ni pe o di ile aṣofin lọwọ iṣẹ nipa kikuna lati fọwọ sowọpọ pẹlu ile naa lori eto iwadii ati yọ aarẹ naa nipo pẹlu pipaṣẹ pe awọn eeyan kan ko maṣe farahan lati jẹri niwaju ile naa.
Wọn kò ní ní ìpín láàrin àwọn arakunrin wọn.
EFCC fẹ gbegidina ibo rira ni 2019 EFCC p'oṣiṣẹ banki l'ẹjọ Agbẹjọro fun ajọ EFCC, Ọmọwe Obi sọ fun ile ẹjọ pe Alao Akala ati Ayọọla dijọ gbinmọ pọ lati gbe awọn owo naa jade kuro ninu apo ajọni ijọba ipinlẹ Ọyọ atawọn ijọba ibilẹ nipinlẹ naa.
Lara  awọn  to wa nibi ayeye naa ni  awọn  akọroyin ilẹ okeere,  awọn  eniyan jankan-jankan,  awọn  ti  ọrọ  naa kan,  awọn  to n se baalu ofurufu  ati asoju ijọba orilẹ ede  yii.
Orúkọ wọn nìwọ̀nyí: láti inú ẹ̀yà Reubẹni, ó rán Ṣamua ọmọ Sakuri; 
 Abe dida maa n nipa buruku ninu igbeyawo iru omo bee lojo iwaju ni eyi ti ko je itewogba mo lasiko olaju yii”.
Nítorí kí ọmọ náà tó mọ bí a tí ń pe ‘Baba mi’ tabi ‘Mama mi’, wọn óo ti kó àwọn nǹkan alumọni Damasku ati ìkógun Samaria lọ sí Asiria.
Kò si bi owo ilú, òbi, tàbi ẹbí ti lè pọ̀ tó, bi enia kò bá ṣiṣẹ́ kun á parun.
orile ede Naijiria ati awon mẹ́tàlá miiran , pelu awon ti ki i se omo Ologun sugbon
Ṣugbọn nisinsinyii, ó ti ṣèlérí pé, “Lẹ́ẹ̀kan sí i kì í ṣe ilẹ̀ nìkan ni n óo mì, ṣugbọn n óo mi ilẹ̀, n óo sì mi ọ̀run.
O ni oun ṣetan lati tẹsiwaju nipa ṣiṣe bẹẹ, bakanna lo ni oun ko ni kaarẹ nitori ohun tawọn eeyan kan n sọ kiri.
Ọba bá kọjú sí Itai ará Gati, ó sì bi í pé, “Kí ló dé tí o fi ń bá wa lọ?
Ni Paris ni Neymar ti gba bọọlu fun ikọ agbabọọlu Paris St-Germain (PSG).
Ahmed, ẹni to kede pe ijọba ti pasẹ pe ki wọn si awọn ẹnu bode mẹrin kan pada nilẹ wa lọgan, tun salaye nipa awọn ọja ti ko ni le wọle sorilẹede yii lati oke okun.
Aṣẹ ti ọga ọlọpaa gbe jade naa ni wi pe gbogbo awọn ọlọpaa to ba n ṣiṣẹ ni ẹka naa, ki wọn jawọ ninu rẹ.
A gbọ pe Igboho ati ọkunrin kan ti wọn pe orukọ rẹ Babatunde Arowolo, ti gbogbo eeyan mọ si Bako, lo de lasiko lati gba awọn eeyan adugbo naa silẹ, ni kete ti aawọn ọmọ onilẹ naa si foju gaani rẹ, ni wọn ba juba ehoro.
Arsenal jẹwọ ọmọ ọkọ fun Tottenham ni abala ikeji ifẹsẹwọnsẹ naa ṣugbọn pẹlu gbogbo kirakita wọn, goolu kan ṣoṣo ti Aubameyang gba wọle nikan ni wọn ri dimu eyi to ko wọn yọ ninu itiju naa.
O ni awọn ṣe amulo ọgbọn inu ati bi awọn ọdẹ ati ẹgbẹ bii OPC ṣe mọ ọna gbogbo ninu aginju ọhun, lati fi ṣe awari awọn amokunṣika ti wọn fara sinko sinu igbo naa.
 ojuibigiga pipojulo iji yi je bi 8 km loke ayika awon ori isujo .
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Nigeria 2019 Elections: Issa Onilu ní APC kò ní fi èrú gba ìbùkún lásìkò ìbò Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Nigeria 2019 Elections: Issa Onilu ní APC kò ní fi èrú gba ìbùkún lásìkò ìbò 20 Èrèlè 2019 Agbenusọ fun ẹgbẹ́ òṣèlú APC, Lanre Issa-Onilu ní, kò sí òótọ́ kankan nínú ẹ̀sùn tí olùdije ẹgbẹ́ òsèlú PDP, Alhaji Atiku Abubakar fi kan APC.
Oríṣun àwòrán, Instagram Oríṣun àwòrán, @BBNaija Koda, ọpọ awọn ololufẹ ikọọkan awọn oludije wọnyi lo ti n dibo fun ẹni ti ọkan wọn fẹ pe ko moke lori ayelujara, ti gbogbo eeyan si n foju sọna pe taa ni owo naa yoo ja mọ lọwọ.
Olootu iroyin lori eto ọrọ aje fun ile isẹ BBC, Mathew Davies, ni iwoye wa pe adehun yi yoo mu adiku ba ainise to peleke laarin awọn ọdọ ti lawon orilẹẹde Afrika.
Lisa gbe igbesẹ lati tun iyara rẹ ṣe!
Ẹ̀yin mùsùlùmí, ẹ yàgò fún ìwà ipá- Buhari Ìpínlẹ̀ Ogun, Eko ti gbáradì fún ẹ̀kún omi yalé Ẹgbẹ́ òṣèlú PDP ní ìpínlẹ̀ Bayelsa jáwé olúbori nínú ìdìbò ìjọba ìbílẹ̀ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Shiite: Ẹ̀mí àti ara wa kọ ohun tí ìjọba ń ṣe sìwa láti 2015 Babajide Raji Fashola tó jẹ́ gómìnà ìpínlẹ̀ Eko nígbà kan rí, mọ ere Okwaraji si ìwáju National Stadium láti maa ṣe ìránti rẹ̀ ńtori pé pápá iṣèré yìí náà ló ti kú.
Wọ́n lẹ́nu, ṣugbọn wọn kò lè sọ̀rọ̀,wọ́n lójú, ṣugbọn wọn kò lè ríran.
Aare  orile ede Naijiria Muhammadu Buhari ti de si New York fun ipade apero ti ajo gbaye , eleyii ni yoo je ipade apero  ikẹ́rìnléláàdọ́rin(74) iru rẹ ti yoo waye.
Biden pada yan gẹgẹ bi igbakeji ti awọn mejeeji si jijọ dije dupo aarẹ ti wọn si ti wa jaweolubori bayi.
Nàìjíríà ní ìgboyà láti kojú ilẹ̀ South Africa - Foluṣọ Philips A fẹ́ ìdájọ́ òdodo lórí ìsẹkúpani- àwọn akẹ́kọ̀ọ́ Àwọn ọmọ Naijiria sọ̀rọ̀ lórí ìgbẹ́jọ́ tó da ẹjọ́ Atiku nù!
jọ̀wọ́, gbọ́ láti ilé rẹ ní ọ̀run, dáríjì wọ́n, kí o sì ṣe ẹ̀tọ́ fún olukuluku gẹ́gẹ́ bí ìwà rẹ̀, nítorí ìwọ nìkan ni o mọ ọkàn ọmọ eniyan.
Ni wọn ba mu u lọ sinu koto awọn ologun lẹyin ibi ti wn ti n yẹ ọkọ wo wọn si ṣe e yana yana ni ti ibalopọ gẹgẹ bi iroyin ṣe sọ.
ìjọba ìpínlẹ̀ Ondo - BBC News Yorùbá BBC News, YorùbáFò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù First symptom of Coronavirus: Àwọn èèyàn kò bìkítà sí àlàkalẹ̀ ìjọba lórí àrùn Covid-19 - ìjọba ìpínlẹ̀ Ondo 26 Òkùdu 2020 Oríṣun àwòrán, @RotimiAkeredolu Àkọlé àwòrán, Eeyan mẹrinlelogoji miran lo ṣẹṣẹ ni Coronavirus ni ipinlẹ Ondo Ijọba ipinlẹ Ondo ti sọ pe awọn eeyan ipinlẹ naa ko gbagbọ pe Coronavirus wa lode lo jẹ ki arun naa maa pọ si ni ipinlẹ ọhun.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìjàmbá ọkọ̀ ojú'rin tó ṣubú wáyé ní Agége l'Eko 10 Sẹ́rẹ́ 2019 Oríṣun àwòrán, @rrslagos767 Iroyin to tẹ wa lọwọ sọ pe ijamba ọkọ oju'rin kan waye ni Agege nipinlẹ Eko.
Kí ló dé, tí ò ń pariwo bẹ́ẹ̀?
Àwọn ọmọ Israẹli kúrò ní Ramesesi ní Ijipti ní ọjọ́ kẹẹdogun oṣù kinni, ní ọjọ́ keji Àjọ̀dún Ìrékọjá pẹlu ọwọ́ agbára OLUWA, níṣojú àwọn ará Ijipti, 
Awọn naa ni: Adajọ Doris Okuwobi to je alaga ti wọn bura fun lẹyin eyi ti awọn ọmọ igbimọ naa kọja lọ si ile LASWA to wa ni Falomo ni Ikoyi.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Kàyééfì BBC Yorùbá: Ẹ̀kúnrẹ́rẹ́ àlàyé lórí ááwọ̀ tó wáyé láárin Oluwo ati Agbowu Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Ìròyìn Kàyééfì BBC Yorùbá: Ẹ̀kúnrẹ́rẹ́ àlàyé lórí ááwọ̀ tó wáyé láárin Oluwo ati Agbowu 27 Ẹrẹ̀nà 2020 Orangun Ila, Oba Wahab Adeniji Oyedotun, ti ni awọn to wa nibẹ nigba ti ija bẹ silẹ laarin ìlú Iwo, Oba Abdulrasheed Akanbi àti ọba Agbowu ti Ogbaagbaa,Dhikrulahi Akinropo ti kọ lati sọ otitọ lori bi ọrọ naa ṣe sẹlẹ.
Olódodo yóo jèrè òdodo rẹ̀; bẹ́ẹ̀ sì ni eniyan burúkú yóo jèrè ìwà burúkú rẹ̀.
Ohola tún lọ ṣe àgbèrè lẹ́yìn tí ó ti di tèmi, ó tún ń ṣẹ́jú sí àwọn ará Asiria, olólùfẹ́ rẹ̀: 
 Ninu atejade kan to wa lati ofisi igbakeji aare ,  o so pe ojogbon Osinbajo yoo maa soro lori
Mo dúró lórí ilẹ̀ tí ó tẹ́jú;láwùjọ ọ̀pọ̀ eniyan ni n óo máa yin OLUWA.
Bi awọn ipinlẹ to ni Coronavirus ni Ọjọ Abamẹta ṣe lọ ree: Ondo-42 Plateau-25 Rivers-16 Ebonyi-10 Abia-9 Ogun-9 FCT-9 Osun-7 Katsina-6 Kaduna-6 Ekiti-4 Taraba-4 Edo-3 Anambra-2 Akwa Ibom-2 Kano-1 Ènìyàn 100 ló kó àrùn Coronavirus ní Nàìjíríà ní Ọjọ́ Aiku Ajọ to n gbogun ti ajakalẹ arun lorilẹede Naijiria, NCDC ti kede pe eeyan 100 miran ti lugbadi arun Covid-19 ni Naijiria.
Diakoni kò gbọdọ̀ ní ju aya kan lọ; ó sì gbọdọ̀ káwọ́ àwọn ọmọ rẹ̀ dáradára ati gbogbo ìdílé rẹ̀.
Amọṣa nibo ni Makinde ti ko arun yii naa?
Bo tile je pe ojo n rọ ni awon
 Ọba Ogunwusi fikun pe  Aafin yii jẹ ti atijọ, eyi to ti le ni ẹgbẹrun mẹwa ọdun, bẹẹ ni mo tun ni awọn ile to ju ọọdunrun, irinwo ati ẹẹdẹgbẹta ọdun lọ ninu aafin yii, ti wọn ti di nkan isẹmbaye to jẹ apeyawawo fun gbogbo agbaye.
Agbẹnusọ fun ile iṣe ọlọpaa ni orile ede Naijiria, Moshood Jimoh, ti ó fi ọrọ naa to awọn oniroyin leti, sọ pe, yatọ si awọn afurasi ti ọwọ awọn ọlọpaa ti tẹ, wọn ti gbe orukọ awọn to ku lọ iwaju INTERPOL ki wọn baa le tete ri wọn mu.
"Iya Kazeem Tiamiyu - BBC News Yorùbá BBC News, YorùbáFò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Sagamu: Ògo ọjọ́ iwájú ìdílé wa ni Kazeem tí àwọn SARS ṣekúpa - Iya Kazeem Tiamiyu Olumide Owaduge Broadcast Journalist 26 Èrèlè 2020 Oríṣun àwòrán, @dabiodunMFR Àkọlé àwòrán, O ṣalaye pe ọmọ ọhun kii ṣe onijọgbọn, bẹẹ ni ki i ṣe ọmọ "" Yahoo."
Gbogbo ọmọkunrin tí ó bá ti pé ọmọ ọjọ́ mẹjọ láàrin yín gbọdọ̀ kọlà abẹ́, gbogbo ọmọkunrin ninu ìran yín, kì báà ṣe èyí tí a bí ninu ilé yín, tabi ẹrú tí ẹ rà lọ́wọ́ àjèjì, tí kì í ṣe ìran yín, 
Àwọn ìròyìn mìíràn tí ẹ lè nífẹ̀ẹ́ sí: Ọlọpa mu asaaju ẹgbẹ NURTW Ajínigbépawó jí akọ̀wé NURTW gbé l'Óǹdó Àṣà ìbálé lálẹ́ ìgbeyàwó ń dọdẹ àwọn obìnrin òde òní Àfi ìgbà tí mo bọ́ sọ́wọ́ ọ̀tá mí nínú ìrìnàjò ìfẹ́- Roshan Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, afin pupa Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Akitiyan ọmọ'ṣẹ́ mi tó wà lára àwọn tó jí ìbejì mi gbé kò kéré níg Gbajugbaja onimọ nipa ẹṣin Islam, Sheikh Taofeeq Akeugbagold ti sọrọ nipa iru eeyan ti amugbalẹgbẹ rẹ, Opeyemi Oyeleye jẹ, ẹni tii ṣe afurasi tawọn Ọlọpaa lo ṣe kokari bi wọn ṣe ji ibeji rẹ gbe lọ.
Ramadan: Sultan pàṣẹ fún àwọn mùsùlùmí láti ṣ'ọdẹ òṣùpá lónìí
Asínwín obínrin ń ṣe fáàrí; wèrè ọkùnrin ń fá irùngbọ̀n; aboyún ń bímọ pẹ̀lú àǹfààní; abiyamọ ń rìn tayọ̀-tayọ̀; àwọn oṣó ń túúbá, àwọn àjẹ́ ń tọrọ àforíjì.
Ṣugbọn o ti gbé mi ga, o ti fún mi lágbára bíi ti ẹfọ̀n;o ti da òróró dáradára sí mi lórí.
Ẹnu òmùgọ̀ ni yóo tì í sinu ìparun,ọ̀rọ̀ ẹnu rẹ̀ ni yóo sì ṣe tàkúté mú un.
Ohun tí à ń retí lọ́dọ̀ ìríjú ni pé kí ó jẹ́ olóòótọ́.
Iléeṣẹ́ ọmọogun Nàìjíríà ní fídíò tó ti pẹ́ ní fídíò ọmọogun tí kò fẹ́ kojú Boko Haram
25 Àti pé níwọnbí wọn bá ṣe àṣìṣe kí á lè sọọ́ di mímọ̀;
Ọpọlọpọ awọn eniyan lo ni awọn Fulani darandaran lo se isẹ ibi naa ni opopona Ore ni ipinlẹ Ondo.
Ṣugbọn bí ọmọ náà ti fa ọwọ́ rẹ̀ pada, arakunrin rẹ̀ bá jáde.
Ikọ BBC to se abẹwo si agbegbe naa lọjọru jabọ pe awọn agbofinro ti kalẹ si agbegbe naa, ọpẹlọpẹ wọn ohun ti a n wi yii, kọ ni a ba maa wi.
Adari Ajọ FRSC nipinlẹ naa, Ahmed Umar lo sọ bẹ fun BBC lati mọ iru iku to pa awọn oṣiṣẹ naa.
Saulu lọ pàdé rẹ̀, ó sì kí i káàbọ̀.
Awọn dokita le ya aworan ẹdọfooro lati wo bi o ṣe gbọgbẹ si.
Lara ohun to si mu ki awọn obinrin jẹ eniyan ọtọ ni ṣíṣe nnkan oṣu, eyi ti yoo mu ki wọn loyun ati bímọ.
“Sibẹsibẹ, ẹ kọ̀, ẹ kò lọ, ẹ ṣe orí kunkun sí àṣẹ tí OLUWA Ọlọrun yín pa fun yín.
Ayẹyẹ ya Àkọlé àwòrán, Awọn ijoye ati agbaagba ilu nile Ibo naa joko pẹlu ṣe ayẹyẹ yii BBC News, Yorùbá Ìdí tí ẹ fi le è nígbàagbọ́ nínú ìròyìn BBC Ìlànà Lílò Nípa BBC Òfin Àṣírí Cookies Kàn sí.
Deaf parents and siblings: Láàrín ìdílé ẹlẹ́ni márùn ún yìí, ọmọ kan ṣoṣo ló léè sọ̀rọ̀
Polaris Bank Nigeria: Ẹ̀rù ń bà wá o
Ẹwẹ, l'Ọjọbọ ni ajọ INEC ṣi aṣọ loju ọrọ yii nigba to sọ fun igbimọ igbẹjọ ibo aarẹ l'Abuja pe oun ko ni ''server'' ti Atiku ati PDP n beere fun.
Iwájú ọkọ̀ wọ inú iyanrìn, kò ṣe é yí.
A fi ọwọ́ọ ṣìgún òfin mú Alaa a sì mú u kúrò ní ilé ẹbíi rẹ̀ nínú oṣù Belu ọdún 2013.
Èyí tí o tilẹ̀ tún pa ni lẹ́rìn-ín ni pé n kò kí Inúlayéwà tó túmọ̀ àlá náà fún mi mọ́, bí ó ba kọjá n kò jẹ́ ki i, bí ó fi ẹsẹ̀ kọ n kò jẹ́ wí pé kí o pẹ̀lẹ́, bẹ́ẹ̀ ni mo tún ṣe títí ilẹ̀ ọjọ́ náà fi ṣu.
Rashidi Ladoja: Èmi kìí ṣe olóṣèlú mọ́, n kò sí nínú ẹgbẹ́ òṣèlú kankan
Wọn yóo mọ̀ pé Juu hánún-hánún ni ọ́ àtipé ò ń pa Òfin Mose mọ́.
Buhari sisọ loju ọrọ yii lasiko to nka ọrọ apilẹkọ rẹ gẹgẹbii alejo pataki nibi ayẹyẹ ọdun kọkanlelọgọta ti orilẹede Ghana gbominira eyi to waye nilu Accra.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ghana Election 2020: Ẹ dín iye ìgbà tẹ n gorí obìnrin kù kẹ́ẹ lè lágbára.
Itan sọ wipe yatọ si wi pe o jẹ aarẹ, Ojo Aburumaku tun pada wa jẹ Sọun ti ilu Ogbomọsọ.
Ọmọ ilẹ Australia, Nick Kyrgios ni tiẹ sọ pe igbesẹ lati maa kopa ninu idije tẹniisii lasiko ajakalẹ aarun covid-19 yii.
Simoni dáhùn pé, “Ẹni tí ó fún ni owó pupọ ni.
Nígbà náà ni o óo tó lè fi ìgboyà gbójú sókè láìlẹ́bi;o óo wà láìléwu,o kò sì ní bẹ̀rù.
Won ro awon eniyan Cuba lati yan okan ninu awon meji ti won fi oruko won si iwe idibo fun ti apapo ati ti elekunjekun.
Gbogbo àwọn ọmọ ogun Kalidea, tí wọ́n wà pẹlu olórí àwọn tí wọn ń ṣọ́ ọba wó gbogbo odi Jerusalẹmu lulẹ̀ patapata.
Ọ̀gbẹ́ni Olówó-ayé ń bẹ, ènìyàn pàtàkì ni; Ènìyàn-ṣe-pẹ̀lẹ́ náà wà láàárin wa, ènìyàn pàtàkì ni; èmi náà sì nìyí, Ìjànbáforítì baba erin; Ọlọ́run ń bẹ fún wa, à ń lọ.
Iroyin to n tẹ wa lọwọ bayii ti wa fidi rẹ mulẹ pe, se ni awọn ọkọ duro lai lee lọ siwaju abi sẹyin lopopona marosẹ to wọ Ibadan si Eko ati eyi to lọ lati Eko si Ibadan nitori ọna ti wọn ti pa naa.
"Wọ́n fi ẹ̀sùn kàn án wí pé, ó ní ""àtẹ́lẹwọ́ òun ni Ààrẹ nàá wà."
"Gẹgẹ bo ṣe sọ, o ni ""idunnu wa ni lati ṣagbatẹru igbaradi idije AFCON 2021 laarin ikọ Super Eagles ati Leone Stars ni papa iṣẹre Ogbemudia."
Nígbà náà ni Judasi, ẹni tí ó fi í fún àwọn ọ̀tá, bi í pé, “Àbí èmi ni, Olùkọ́ni?
Ko si sẹni to tako ijọba gomina Ayodele Fayose nigbanaa, ki wa ni pataki ọba mẹrindinlogun ti Alaafin n tọkasi pe o wa ninu ilana pẹlupẹlu?
 Ó fẹ ́ rẹ ̀ jẹ ́ gbogbo àwọn tí kò ní agbára àti kojú àrùn náà lẹ ́ yìn tí wọ ́ n bá gba ìwọ ̀ n egbògi náà kanṣoṣo ni wọn yóò ní agbára yìí lẹ ́ yìn ìwọ ̀ n egbògi náà kejì .
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Póópù Francis kúnlẹ fí ẹnu ko ẹsẹ̀ àwọn adarí orílẹ̀ède South Sudan Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Póópù Francis kúnlẹ fí ẹnu ko ẹsẹ̀ àwọn adarí orílẹ̀ède South Sudan 12 Ìgbé 2019 Olori ijọ Aguda, Poopu Francis fi ẹnu ko ẹsẹ awọn adari orilẹede South Sudan nigba ti wọn lọ ki ni ibudo rẹ ni Vatican.
Owo ti a n pa lọdun, ko to miliọnu meji ti NIPOST sọ pe ka mu wa.
Eyi wa tako nọmba ti awọn eeyan kan n gbe kaakiri tẹlẹ pe miliọnu mẹtala lawọn majeṣin ti ko si ni ileewe lọwọ bayii.
Adelé Ọba Alade Idanre fẹ̀sùn kan Owa ìlú Idanre pé ó bẹ àwọn jàǹdùkú lọ́wẹ̀ láti fi ìjà jẹ òun Oríṣun àwòrán, @HighTableAfrica Rogbodiyan bẹ silẹ ni ilu Alade Idanre, iyẹn ni ipinlẹ Ondo lori ẹni to yẹ ko gori itẹ Ọba Olusegun Akinbola to di oloogbe lọjọ kẹrindinlogun,oṣu Kẹwaa, ọdun 2020.
Láìṣe àníàní, ìwọ alágbára ọkùnrin, ìwọ kò si láarin àwọn aláìmoye.
ti lo lori aleefa , ti so pe ohun to wa lokan ohun ni lati ri i pe eto idibo ti
Gbogbo rẹ yoo ku si bii ẹgbẹrun mẹwa o din diẹ naira lati jẹ Pizza ti ko yatọ si ti ilẹ gẹẹsi lorilẹede Naijiria.
Iroyin to n kan BBC lọwọ ni pe awọn ọmọ ijọ COZA nikan ni wọn n jẹ ko wọle inu ile ijọsin laarọ yii lati jọsin.
“Eleasari alufaa ati Joṣua ọmọ Nuni ni yóo pín ilẹ̀ náà fun yín.
Sunday Igboho kàn ń gbé ‘Camera’ lẹ́yìn kiri, kí wọ̀n lè rò pé ó ń jà fún Yorùbá - Gani Adams ''Ẹ ràn wá lọ́wọ́, ọmọ 18 pẹ̀lú ìyàwó mẹ́rin ni ọkọ wa tí ìbọn ''Customs'' pa fi sílẹ̀ lọ'' ₦750m ni Akeredolu ń gbà lóṣù fún ‘Security Vote’ àti ₦150m owó oṣù - Agboola Ajayi fèsì Àjọ EFCC ti mú ọ̀dọ́kùnrin mẹ́wàá lórí ẹ̀sùn jìbìtì lílù lórí ayélujára ní Oyo Ẹgbẹ́ tó ń fẹ́ Oduduwa Republic kọ̀wé ẹ̀hónú sí UN, EU, AU àti ìjọba Gẹ̀ẹ́sì Ileeṣẹ ọlọpaa ni mẹwaa lawọn adigunjale naa, awọn ọkọ ti wọn si lo fi fọ banki naa ni ọkọ ayọkẹlẹ Volkswagen Golf pẹlu nọmba GED 906 AA, Acura MDX Jeep pẹlu nọmba LSR 327 CD, ati Toyota Camry to ni nọmba No GED 106 ER.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Presidency: $500 mílíọ́nù ni a ti ná lórí nǹkan ogun nínú owó tí a gbà nínú àṣùwọ̀n àpapọ̀ 30 Bélú 2018 Oríṣun àwòrán, Nigeria Presidency Àkọlé àwòrán, Agbẹnusọ fún Ààrẹ Buhari ti ní ohun kò lè sàlàyé bí ìjọba se ná bílíọ́nú kan Naira tí ìjọba àpapọ̀ yọ nínú àpò ìsúná lọ́dún 2017 Ileeṣẹ aarẹ lorilẹ̀ede Naijiria ti sọ wi pe oun o mọ oun pupọ lori bi ijọba se na iye owo biliọnu kan Naira ti ijọba yọ ninu apo isuna lọdun 2017, fun ipese ohun ija fun ile isẹ ologun Naijiria.
O ni wọn n fọrọ wa onibara oun lẹnuwo nitori awọn kudiẹkudiẹ to wa ninu awọn owo ti ajọ naa gba lọwọ awọn ti wọn mu, iyatọ wa lara iye ti o kede ati iye to wọ apo ìjọba.
Gbogbo eyi ni o yẹ ki awọn ara ilu ni agbọye rẹ.
Naa lo difa fun awọn Amọtẹkun ti awọn gomina gbe kalẹ lati maa ran awọn ọlọpaa lọwọ.
" O ni ipinlẹ Eko ti lamilaaka ninu awọn igbesẹ lati koju iwa ipa si awọn obinrin atawọn ọmọde pẹlu bi ikọ ti wọn gbe kalẹ lori rẹ ti se gbe awọn ilana kalẹ leyi ti o mu irọrun ba fifi iroyin nipa isẹlẹ iwa ipa labẹle to awọn ileesẹ to yẹ leti ati mimu ijiya to tọ ba awọn to ba hu iwa ọhun.
 Òun ni omo nigeria àkókó tó kókó ní káà .
se ipade po pelu awon adari orile ede agbaye lasiko apero naa.
Ghana elections result 2020: Èsì ìdìbò tó gbé aàrẹ tuntun wọlẹ́ ní Ghana rèé.
Kì í sìí ṣe pé à-rú-tún-rú ni yóo máa fi ara rẹ̀ rúbọ, bí Olórí Alufaa ti ìdílé Lefi ti máa ń wọ Ibi Mímọ́ jùlọ lọ ní ọdọọdún pẹlu ẹ̀jẹ̀ tí kì í ṣe ẹ̀jẹ̀ ara rẹ̀.
Ijipti dàbí ọmọ mààlúù tí ó lẹ́wà,ṣugbọn irù kan, tí ó ti ìhà àríwá fò wá, ti bà lé e.
Ìjọba rí i wípé ó tó àsìkò láti sún owó ìwé ẹ̀rí ọmọ-ìlú-fún-ìrìnnà, ó sì ti yọ ọwọ́ọ Kílàńkóo rẹ̀ kúrò nínú kíkó  owó lé e lórí, kí ó ba lè ṣe, fún àpẹẹrẹ, pèsè omi, ináa mànàmáná àti àwọn ohun amáyérọrùn mìíràn.
Nnkan ko ṣẹnu fun ikọ agbabọọlu Naijiria ninu ifẹsẹwọnsẹ akọkọ ti wọn gba lẹyin ti Norway fiya jẹ wọn pẹlu ami ayo mẹta sodo.
Àwọn òmùgọ̀ gbé àtùpà, ṣugbọn wọn kò gbé epo lọ́wọ́.
 O tẹsiwaju pe ""Aworan ti aya Aarẹ fi lede lori ayelujara kii ṣe lati fi yọ suti ete si awọn ọmọ Naijiria, ṣugbọn o jẹ ọna lati fi ẹmi imoore han si awọn to ba idile rẹ ṣajọyọ igbeyawo ọhun."
Ó ní:“Ó dùn mọ́ mi pé níwájú yín ni n óo ti sọ ti ẹnu mi.
“Gbogbo àwọn olórí láti apá àríwá wà níbẹ̀, ati gbogbo àwọn ará Sidoni, tí wọ́n fi ìtìjú wọlé lọ sí ipò òkú pẹlu àwọn tí wọ́n kú lójú ogun.
Àwọn ọmọ Sibeoni ni Aya ati Ana.
Ko si ani ani pe awọn ọmọde le ko arun Coronavirus .
Ṣugbọn nígbà tí wọn fi ìwọ̀n Omeri wọ̀n ọ́n, àwọn tí wọ́n kó pupọ jù rí i pé, ohun tí wọ́n kó, kò lé nǹkankan; àwọn tí wọn kò sì kó pupọ rí i pé ohun tí wọ́n kó tó wọn; olukuluku kó ìwọ̀n tí ó lè jẹ.
Ohun tí Joṣua ṣe fún wọn ni pé ó gbà wọ́n lọ́wọ́ àwọn ọmọ Israẹli, kò jẹ́ kí wọ́n pa wọ́n.
Nígbà tí Akin Olúṣínà àti Ilésanmí dé ọ̀dọ̀ Ọ̀sanyìnnínbí tí ó rò pé oògùn ni wọ́n wá ṣe ní ọ̀dọ̀ òun, àwọn ẹbọ tí ó kà fún wọn ni ìyá ewúrẹ́ kan, ẹgbẹ̀rún náírà ìgò epo kan, iṣu mẹ́ta àti ìgàn aṣọfunfun kan.
Ashikeni menuba awon ajo to fowosopo pelu won lati se ise yii bii ajo ilera agbaye, WHO, ati ajo UNICEF  ti won fi owo iranwo sile fun aseyori eto abere ajesara naa.
"Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Akomolede ati Asa: Mọ̀ si nípa àwọn ọ̀nà tí Yorùbá ń gbà ran ara wọn lọ́wọ́ Àwọn kan ní ìpínlẹ̀ Kwara já ilé ìkó-ǹkan-sí wọ́n pín "" CaCovid Palliative"" fáwọn èrò ní Ilorin Ọpẹ́lọpẹ́ àwọn ẹ̀sọ́ aláà[bò àwọn Jàǹdùkú tún yabo ilé tí ""Covid 19 Palliative"" waà Ọpẹlọpẹ awọn ẹṣọ alaabo, awọn janduku tun yabo ile igbe ohun iranwọ Covid-19 si ni Ilorin EndSars Protest: Aworan lori ayelujara safihan ọgọọrọ eniyan to n gbe igbe ohun iranwọ Covid-19 si ni Ilorin Ijọba Kwara ni awọn ti gbọ pe awọn janduku naa n bọ wa ko ohun iranwọ Covid -19 Ẹṣọ alaabo nipinlẹ Kwara ti bori awọn janduku to ṣekọlu si ile igbohun iranwọ Covid-19 si ni agbegbe Ilorin Cargo nipinlẹ Kwara."
27 Ọ̀wàrà 2020 Oríṣun àwòrán, Twitter/jidesanwoolu Gomina Babajide Sanwo-Olu ti ni ijọba apapọ ati ti ipinlẹ Eko yoo ṣapa lati ri pe ẹnikẹni to lọwọ si ipaniyan Lekki yoo foju wina ofin.
Nígbà tí ó bá wà ní ahoro, yóo ní irú ìsinmi tí kò ní rí ni àkókò ìsinmi yín, nígbà tí ẹ̀ ń gbé inú rẹ̀.
Eyi ko si sẹyin bi ile ẹjọ kotẹmilọrun ni Abuja ti ṣe wọgile eto igbaniṣiṣẹ ti wọn fi gba wọn wọle ni 2019.
Ìjọba ilẹ̀ Turkey yí ilé Ìṣẹ̀mbáyé tó ti lo ọdún 1,500 padà sí Mọ́ṣáláṣí Hagia Sophia: Ìjọba ilẹ̀ Turkey yí ilé ìṣẹ̀mbáyé padà sí Mọ́ṣáláṣí Ijọba ilẹ Turkey ti yi ile iṣembaye kan ti orukọ rẹ n jẹ Hagia Sophia si Mọṣalaṣi.
Òun ni olùdásílẹ̀ àjọ kan tó ń poun réré ọ̀rọ̀ àìrọ́mọbii tí a mọ̀ sí Ibidunni Ighodalu Foundation tó sì tún n ń ran àwọn tó kù díẹ̀ káàtó fún láwùjọ lọ́wọ́ láti ṣe IVF Ọ̀gá àgbà Ọlọ́pàá wọ́ ọ̀rọ̀ Aisha Buhari tì sẹ́gbẹ̀ẹ́ kan Wo àwọn òṣèré tíátà Yorùbá tó bí ìbejì Bí wọ́n ṣe kó mi mọ́ rògà ìròyìn òfégè kan tó leè kóbá olùdíje Ààrẹ ẹgbẹ́ alátako Àjọ ọlọ́pàá, Ìjọba ìpínlẹ̀ Ọyọ jẹ́jẹ̀ẹ́ láti ṣàwárí òòsà tó ń mu ẹ̀jẹ̀ nílùú Ìbàdàn Ìgbà mọ́kànlá ọ̀tọ̀ọ̀tọ ló gbìyànjú àti di ọlọ́mọ láyé nípa ṣíṣẹ ọ̀nà àti rọ́mọbí ìgbàlódé IVF Ibidunni àti Ituah ní ọmọ méjì papọ̀ Ilé iṣẹ́ rẹ̀ Elizabeth R ló maa ń ṣe ilú Eko lóge lásìkò ọdún kérésì Ẹ̀wẹ̀, ọkọ rẹ̀ Ituah Ighodalo lẹ́yìn tó gba ipè pé ọkọ rẹ̀ kú lótún ṣe ètò ìsìnkú fún ẹnikan lówòrọ̀ òní ojọ́ àìkú.
Orilẹede Italy ma n jẹ burẹdi ati iyẹfun ti wọn fi idin se: Oríṣun àwòrán, Anja Barte Telin Àkọlé àwòrán, Jijẹ burẹdi onidin jẹ eewọ nilẹ Europe nitori ipa rẹ lara awọn eniyan.
O ti mú kí àwọn ọ̀rẹ́ kòríkòsùn mi fi mí sílẹ̀;mo sì ti di ẹni ìríra lọ́dọ̀ wọn:mo wà ninu àhámọ́, n kò sì lè jáde;
N o yan ise won fun won ni kete ti a ba ti se ifilole awon alase leyin ibura wole won gege bi aare se so ninu atejade kan lale ojo Isegun.
Gẹgẹ bii agbabọọlu, Amuneke ko ṣee fọwọ rọ sẹyin ninu ikọ Super Eagles, oun lo jẹ goolu mejeji ni AFCON 1994 lorilẹede Tunisia nibi ti Naijiria ti fi ami ayo meji si ẹyọkan pẹlu Zambia gba ipo keji nilẹ Afirika.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Yorùbá dùn lédè, ẹ máa sọọ́ Ẹfunroye Tinubu - Ògbóǹtagí oníṣòwò, olówò ẹrú àti afọbajẹ Samuel Ajayi Crowther, òjíṣẹ́ Ọlọ́run tó gbé èdè Yoruba lárugẹ Mọrèmi Àjàṣorò, akọni obìnrin tó gba Ilé Ifẹ̀ sílẹ̀ lóko ẹrú Ọ̀rọ̀ǹpọ̀tọ̀niyùn, Aláàfin obìnrin àkọ́kọ́ rèé, tó ní nǹkan ọkùnrin Amọ adinku lee ba awọn ipa yii ti obinrin ba n jẹ ounjẹ asara loore, to si tun n se ere idaraya bo se yẹ.
Nigba ti mo si bẹrẹ si pe awọn ọrẹ mi ọkunrin lati wadi idi ti eyi fi ri bẹẹ, wọn ni awọn lee pọn ọmọ sẹyin ninu ile sugbọn awọn ko lee se bẹẹ ni ita gbangba.
Nibayii, wọn ti mu ike omi eso to mu ti wọn ni o n run oogun apakokoro lọ si yara ayẹwo ti wọn si n ṣe iṣẹ lori rẹ.
olu  ile-iṣẹ igbimo naa to wa niluu Abuja.
Nítorí náà, Ọlọrun mú kí afẹ́fẹ́ kan fẹ́ sórí ilẹ̀, omi náà sì bẹ̀rẹ̀ sí fà.
Kí gbogbo aráyé lè mọ̀ pé, OLUWA lágbára, kí ẹ sì lè máa bẹ̀rù OLUWA Ọlọrun yín títí lae.
O ni bi aarẹ Buhari ṣe dakẹ lori iṣẹlẹ naa fihan pe iṣẹlẹ naa lọwọ kan awọn araata ninu lati da oju ilẹ Yoruba de'lẹ.
Kollington tun salaye pe awọn ololufẹ awọn lo maa n da ija silẹ laarin oun ati Barrister nitori iwa gbọyi-sọyi ti wọn maa n se, ti wọn si maa n ti awọn lati fi orin owe bu ara awọn.
Bẹ́ẹ̀ gan-an ni ọlọ́rọ̀ yóo parẹ́ lẹ́nu iṣẹ́ ọwọ́ rẹ̀.
Minisita fun imo sayensi ati ẹrọ lorile ede Naijiria, omowe Ogbonaya Onu lo soro yii nibi ifilole  igbimo awon minisita, to waye niluu Abuja.
 Àwọn eniyan ni lati ṣọra pelu ọgbẹ ́ ati egbo tàbí àwọn ohun miran ti o le mu ara ṣe ẹ ̀ jẹ .
Ó bá yan àwọn mejila, ó pè wọ́n ní aposteli, kí wọn lè wà pẹlu rẹ̀, kí ó lè máa rán wọn lọ waasu, 
Siwaju si, awon adari tẹlẹri lorile-ede Naijiria bi: ogagun Yakubu Gowon, Ibrahim Babangida ati Adajo Agba tẹlẹri, CJN Mariam Muktar kọ iwe ransẹ wi pe, awọn ko ni le kopa ninu ipade naa.
Gege bi  iroyin, ti agbenusoro  ile-ise iko omo oogun naa ogagun Texas Chukwu, gbe jade pe afurasi iko omo oogun olote naa wa  ni ipo mẹ́rìndínlọ́gọ́rùn ún ninu awon ti won gbe oruko sita lati sawari won.
MICHAEL ANYIAM OSIGWE AMAA 2018 Ami eye fun omo ile Adulawo to n gbe loke okun
Ṣugbọn ki ti ẹ ni ti awọn alufaa olokiki ti ọrọ agbere n jẹyọ lori wọn?
" Makinde tẹsiwaju pe ojuṣe oun gẹgẹ bi gomina ni lati dabo bo awọn eeyanb ipinlẹ naa, ati pe ijọba rẹ yoo ṣe gbogboi ohun to yẹ ni ṣiṣe lati dena arun Coronavirus.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Gẹgẹ bi ikede ti ọmọọmọ rẹ kan fi sita, Shagari ku lẹyin aisan ra npẹ sileewosan gbogboogbo to wa nilu Abuja.
Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Oyinkan Abayomi: Ajàfẹ́tọ̀ọ́ ẹni tó dá ẹgbẹ́ òṣèlú obìnrin àkọ́kọ́ sílẹ̀, tó tún jà fún ètò ẹ̀kọ́, ìṣèlú àti òmìnira obìnrin5 Bélú 2020 Ìtàn Mánigbàgbé: Ìnà ẹgba mẹ́sàn-án ni Jesu Oyingbo fi ń kí ọmọ ìjọ ọ́kùnrin tuntun káàbọ̀31 Èbibi 2020 Ìtàn Mánigbàgbé: Èyí ni àwọn Ọba ilẹ̀ Yorùbá mẹ́jọ tí wọn lé kúrò lórí oyè10 Ọ̀wàrà 2020 Ìtàn Mánigbàgbé: Duro Ladipọ fi òjò àti àrá ńlá sàmì ìpapòdà rẹ̀11 Ọ̀wàrà 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Loju ọpọlọpọ, ọga ni ninu ka sọ ọrọ ibalopọ fun awọn obinrin.
Wọ́n kọ ìwé náà ní orúkọ ọba, wọ́n sì fi òrùka ọba ṣe èdìdì rẹ̀.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Mama Arsenal: Màmá àgbà yìí máa ń lọ sí ìbùdó tí wọ́n ti ń wo bọ́ọ́lù láti wòran Ẹsun miran tun ni pe, Magu n dari owo ti won ba gba lọwọ awọn to n huwa ajẹbanu sibo miran.
Bi eeyan ko ba sun deedee awọn 'cell' ọpọlọ wa yoo máa ku diẹ diẹ.
Ọkà ibi ìpakà yín ati ọtí ibi ìpọntí yín kò ní to yín, kò sì ní sí waini tuntun mọ́.
Nítorí náà, Adonisedeki ọba Jerusalẹmu ranṣẹ sí Hohamu ọba Heburoni, Piramu ọba Jarimutu, Jafia ọba Lakiṣi ati Debiri ọba Egiloni, pé, 
Oò nílò ìwé ẹ̀rí WAEC láti dí ààrẹ tàbí gómìnà - Keyamo Àyẹ̀wò òkú tú àṣírí bí òṣìṣẹ́ NSCDC tí ọlọ́pàá lù ní Abuja ṣe kú Ọlọ́pàá gbé àwọn tó yìnbọn lu olólùfẹ́ ní Ajegunle Meji ninu awọn oku yii ti mo ri ni wn ge ori wọn, wọn yin ọkan ni ibọn ti wọn si fi abẹ la ọrun rẹ."
- Ìwádìí BBC Yánpọn yánrin lórí ikú ọmọ Alága ẹgbẹ́ Afenifere, Fasoranti Oríṣun àwòrán, OTHER Àkọlé àwòrán, Alagba Reuben Fa#soranti ati Oloogbe Funke Olakunrin Pẹlu iroyin ojiji ti ọpọlọpọ n sọ nipa iku ọmọ alaga ẹgbẹ Afenifere ti ilẹ Yoruba, ọpọ gbọ yii sọ yii lo ti n jẹ jade lori boya Fulani daran daran tabi awọn agbebọn lo pa Funkẹ Ọlakunrin.
Funra rẹ lo kọkọ tu owo jọ lẹyin to ṣiṣẹ fun ọpọlọpọ ọdun ko to tun bẹrẹ ile iwe pada Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Working religious women: Ẹ̀lẹ́hàá kìí ṣe ọ̀lẹ- Aminat Adegoke Adebayọ Faleti lo tumọ orin ogo orilẹ-ede Naijiria si ede Yoruba to si tun fi igba pipẹ kọ akọsilẹ akanṣe fun awọn eekan oloṣelu bii Bola Ige, Oloye Ọbafẹmi Awolowo, Ernest Shonekan si ede Yoruba.
Ninu ọrọ to ba BBC News Yoruba sọ lori agbekalẹ igbimọ naa, gomina Gboyega Oyetọla ni ara igbesẹ lati rii pe ebi ko pa awọn olugbe ipinlẹ Ọṣun lasiko ti ofin koniogbele yoo fi wa nikalẹ nipinlẹ ọhun ni wọn Coronavirus in Osun: Ọọ̀ni ile Ifẹ̀ yóò gbé orò bí ìgbà ìwáṣẹ̀ láti lé 'ẹbọra Coronavirus,' 'kúró nílùú Oríṣun àwòrán, Ooni Enitan Ogunwusi Gbogbo agbaye ti n damu lori arun yii fun ọpọlọpọlọ oṣu bayii laisi ọna abayọ kan to dan mọran.
 e wo ( 23 ) àti ( 24 ) .
Bakan naa lo ni ti oun ba pada sípò, oun yoo túbọ̀ yan oloselu sẹnu isẹ si.
Kì í ṣe gbogbo eniyan ni ó rí i bíkòṣe àwọn ẹlẹ́rìí tí Ọlọrun ti yàn tẹ́lẹ̀, àwa tí a bá a jẹ, tí a bá a mu lẹ́yìn tí ó jinde kúrò ninu òkú.
“Wọn kò gbọdọ̀ sọ ara wọn di aláìmọ́ nípa sísúnmọ́ òkú, ṣugbọn wọ́n lè sọ ara wọn di aláìmọ́ bí ó bá jẹ́ pé òkú náà jẹ́ ti baba wọn tabi ìyá wọn tabi ti ọmọ wọn lọkunrin ati lobinrin tabi ti arakunrin wọn tí kò tíì gbeyawo tabi arabinrin wọn tí kò tíì wọ ilé ọkọ.
Joṣua pè wọ́n, ó ní, “Kí ló dé tí ẹ fi tàn wá jẹ, tí ẹ wí fún wa pé, ọ̀nà jíjìn ni ẹ ti wá, nígbà tí ó jẹ́ pé ààrin wa níbí ni ẹ̀ ń gbé?
N óo bá ọ lọ sí Ijipti, n óo sì tún mú ọ pada wá, ọwọ́ Josẹfu ni o óo sì dákẹ́ sí.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Éégún tó wà nídí Yoruba Bollywood, Samo Baba f'ojú hàn o!
Bi Runṣewe ṣe ni pe Bobrisky n ba oju orilẹ-ede Naijiria loju jẹ naa ni Bobrisky n da a lohun pe, o keere si nọmba nitori awọn to ju u lọ lagbo iṣejọba loun n ba dowo pọ.
Igbesẹ ko ṣẹyin bi Amẹrika naa ti ṣe fi orukọ Kudirat Abiola iyawo MKO Abiola pori opopona kan ni New York.
Ṣugbọn àwọn mẹ́wàá kan ninu wọn sọ fún Iṣimaeli pé, “Má pa wá, nítorí a ní ọkà wíítì, ọkà baali, ati òróró ati oyin ní ìpamọ́ ninu oko.
Ọjọ Keje, oṣu Kẹrin, ọdun 1927 ni wọn bi Olatunji si abule Ajido lẹba ilu Badagry, to si jẹ ojulowo ọmọ bibi ilẹ Yoruba.
Wọ́n ti mọ odi rẹ̀, wọ́n sì ti fẹ́rẹ̀ parí ìpìlẹ̀ rẹ̀.
Ọ̀pọ̀lọpọ̀ awọn eeyan ni ẹru n ba lati igba ti ajakalẹ̀ arun COvid 19 ti bẹ́ silẹ̀ pe eto ilera ilẹ̀ Adulawọ ko dara t ni eyi to le mu ki ọsẹ́ Covid 19 lagbara ju Awọn eniyan ilẹ̀ Afirika le ni bilionu kan ni eyi ti awọn to lugbadi ajakale arun Covid 19 nibẹ̀ ko ju miliọnu kan ati abọ gẹ́gẹ́ bii akọsilẹ̀ fasiti John Hopkins.
Lojoojumọ, ninu Tẹmpili ati láti ilé dé ilé, wọn kò dẹ́kun láti máa kọ́ eniyan ati láti máa waasu pé Jesu ni Mesaya.
Ọ̀nà tí a fi lè mọ àwọn ọmọ Ọlọrun yàtọ̀ sí àwọn ọmọ Èṣù nìyí: gbogbo ẹni tí kò bá ṣe iṣẹ́ òdodo tí kò sì fẹ́ràn arakunrin rẹ̀ kò wá láti ọ̀dọ̀ Ọlọrun.
Wọn a ti àwọn aláìní kúrò lójú ọ̀nà,gbogbo àwọn talaka a sì lọ sápamọ́.
Ọ̀nà táwọn èèyàn sì fi ń gba ìwòsàn nígbà náà ni kí wọn takete sì ara wọn, tàbí kí wọn dá wa ninu ile, wọn.
Barcelona fàgbà han Deportivo láti gba ife ẹ̀yẹ
“Gbogbo àwọn kòkòrò tí wọn ń fò jẹ́ aláìmọ́ fun yín, ẹ kò gbọdọ̀ jẹ wọ́n.
Ní inú oje òdòdó ni kòkòrò oyin ti ń yọ àdídùn ṣe oyin.
O óo tún rí nǹkan ìríra tí ó ju èyí lọ.
ile-ise eleto aabo se pelu aare ni adari ile-ise omo ogun oju omi, Vice Admiral
8 mílíọ ́ nù tí wọn ní ìpàdánù ìríran .
Kí ló dé tí ò ń fọ́nnu nípa agbára rẹ,ipá rẹ ti pin, ìwọ olóríkunkun ọmọbinrinìwọ tí o gbójú lé ọrọ̀ rẹ,tí ò ń wí pé, ‘Ta ló lè dojú kọ mí?
Nitori naa igbimọ iwadii yi yoo ko gbogbo ọrọ jọ ki a ba le ṣe atunṣe ati itanran to yẹ'' Bẹẹ naa lo ni oun ni igbagbọ pe iyipada rere ni yoo tẹle ohun to ṣẹlẹ lẹnu ọjọ mẹta yi.
Ninu ọrọ to ba BBC News Yoruba sọ, olori tuntun ti wọn ṣẹṣẹ yan fun ile naa, Ọlamide George ni ilu Ibadan ni awọn sare wa fi ara sinko si nitori abo ẹmi wọn.
O ni ọdun to lọ ni gbogbo wọn lapaapọ ṣẹṣẹ ri to awọn arinrinajo to to miliọnu mẹtadinlogun laaarin ọdun kan.
Lẹ́yìn náà, a óo wá gba gbogbo Israẹli là.
Alaye adajọ naa ni pe o lewu lati gba oniduru afurasi alujibiti ọhun nitori pe o le e fi ẹsẹ fẹ, ki wọn ma ri mọ.
Wọ́n mú kí ọkàn mi balẹ̀.
 david bámigbóyè dá sílẹ ̀ ní ọdún 1973 ní wọ ́ n kéde rẹ ̀ lẹ ́ yìn tí wọ ́ n ti pinu láti dá ilé-ẹ ̀ kọ ́ náà sílẹ ̀ sí ìpínlẹ ́ ̀ kwara lọ ́ dún 1971 .
Dafidi bá dìde kúrò ní ilẹ̀, ó wẹ̀, ó fi òróró pa ara rẹ̀, ó pààrọ̀ aṣọ rẹ̀, ó sì lọ sí ilé OLUWA láti jọ́sìn.
Dafidi pe Sadoku ati Abiatari, àwọn alufaa, pẹlu àwọn olórí àwọn ọmọ Lefi mẹfa, Urieli, Asaaya, ati Joẹli, Ṣemaaya, Elieli, ati Aminadabu, 
Oríṣun àwòrán, BSodiq Traffic violation One Way: A ti ṣetán látu lu ọkọ̀ 44 tí a gbẹ́sẹ̀lé ní gbàǹjo - Ìjọba ìpínlẹ Eko Ijọba ipinlẹ Eko ti kede pe awọn yoo ta ọkọ mẹrinlelogoji ti wọn gbẹsẹle lọwọ awọn eeyan to tapa s'ofin to rọ mọ irinajo oju popo ni ipinlẹ naa.
”Siba dá a lóhùn pé, “Mẹfiboṣẹti dúró sí Jerusalẹmu; nítorí ó dá a lójú pé, nisinsinyii ni àwọn ọmọ Israẹli yóo dá ìjọba Saulu baba-baba rẹ̀ pada fún un.
"Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Oba Adedokun Abolarin ti Oke Ila: Ó ya ọ̀pọ̀ tó súnmọ́ mi lẹ́nu bí mo ṣe ń kọ́ Ìhà ti Fatai yara kọ sí eyi ni pe o bẹ̀rẹ̀ si kọ ara rẹ bí wọn ṣe ń lu ohun èlò orin ""jita"" eyi to bẹ̀rẹ̀ lọdun 1955 pẹlu jita tí kii lo batiri tabi iná ayafi afẹ́fẹ́."
ṣe ẹ ranti pe nigba ti twitter kọkọ bẹrẹ, iwọnba ogoje ọrọ pere nikan lo lee gba ni atẹjade kan.
Nitorin naa wọn fi ikilọ sita loju opo wọn ni Twitter ki awọn eeyan sọra fawọn onijibiti to n gbe iroyin ẹlẹjẹ yi ka.
Ileeṣẹ TCN lo fi atẹjade naa sita.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Toma Unu: Ọmọbìnrin tó ń fi ẹsẹ̀ rẹ̀ ya àwọran nítori pe ó ni ìpènija ọpọlọ Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Gẹgẹ bi ọmọ naa ṣe sọ, lati igba kekere rẹ ni baba naa ti ma n ba lopọ̀.
Nítorí náà, níwọ̀n ìgbà tí ẹ ti gba ìjọba tí kò ṣe é mì, ẹ jẹ́ kí á dúpẹ́.
Mikel dupẹ lọwọ Naijiria fun anfani lati ṣoju orilẹede rẹ ninu oniruuru idije ere bọọlu.
Wọn ni ounjẹ kanna lawọn maa n jẹ ninu ile, aya, ọmọ abi owo ko si lee ya awọn.
Ìlú Jamani ni wọ́n ti kọ́ àṣà yìí, ó dẹ̀ hàn gedegbe bẹ́ẹ̀ nítorí pé ọjà-kérésìmesì-Jamani ni wọ́n npèé.
" Theladyjokelet loju opo tiẹ naa wa n fi ika hanu lori ihuwasi awọn osere tiata Yoruba naa, eyi to ni o n ba oun ninujẹ.
leti , ki won tun lee fi kun awon agbofinro to wa nilẹ.
Mò ń jẹ eérú bí oúnjẹ,mo sì ń mu omijé mọ́ omi
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, #Oshimole: Àwọn aṣáájú APC kò mọ ohun ti wọ́n n ṣe lásìkò yí Titi di bi a ti ṣe n ṣe akojọ iroyin yi, ẹgbẹ APC ko ti fesi si idajọ ti ile ẹjọ yi gbe kalẹ.
Ati pe o ti pada si ileewe."
Ninu ọrọ rẹ, alakoso eto igbayegbadun fawọn opo naa, Amofin Funmi Lamuye ni asiko to fun awọn ti eledumare ba ṣẹgi ọla fun lawujọ lati maa ranti awọn to ku diẹ kaato fun, paapaa julọ awọn opo.
Apata fidi ẹ mulẹ pe ẹgbẹ awọn agbẹjọro ti ṣetan lati ṣatilẹyin fun iwọde alaafia to n lọ lọwọ naa.
A fẹ́ lo ẹ̀jẹ̀ àwọn èèyàn tó ye àrùn Coronavirus láti fi ṣe ìwòsàn fún àwọn tó wà lórí àárẹ- UK Àwọn tó jí kọmíṣọ́nnà gbé l'Ekiti ń bèèrè fún N30 mílìọnù kí wọ́n tó le è tú u sílẹ̀ Ọga Bello, lásìkò to ń koro ojú sì bí àwọn ère itage ni èdè Yorùbá kan ṣe ń kùn fún ọpọ èdè gẹ̀ẹ́sì, ó ní, èyí dá lórí irú ipò tí èèyàn kan bá fẹ́ ṣe nínú eré.
Ronaldo ati Juventus fidi rẹmi nitori Ajax lo jawe olubori pẹlu ami ayo si ẹyọkan ni papa iṣere Juve.
Nnkan to yẹ ki wọn beere ni pe ta lo yan Iyalọja naa.
Ballon D'or 2019: Ronaldo ló dáńtọ́ jùlọ (GOAT), bó tilẹ̀ jẹ́ pé Messi ló gb'àmì ẹ̀yẹ Ballon D'or
Nítorí pé ọpẹ́ mélòó ni a lè dá lọ́wọ́ Ọlọrun nítorí yín, lórí gbogbo ayọ̀ tí à ń yọ̀ nítorí yín níwájú Ọlọrun wa?
 bi apejuwe ọbẹ ila , ọbẹ ewedu , ọbẹ ọgbọnọ tabi eyi ti a nọ si apọn .
Nibayii, ẹgbẹ afẹnifẹre ilẹ Yoruba naa ti da wọn lohun pe, eyi ko lee tu irun kan lara iduro ṣinṣin ẹya Yoruba.
UN: Ìkọlù Boko Haram, darandaran pẹ̀lu ááwọ̀ ósèlú ń dẹ́rù bà wá
Oríṣun àwòrán, Iamnino_b Àkọlé àwòrán, Odunlade fẹ́ j'ọba, Bolanle Ninalowo fun ìyàwó rẹ̀ ni ẹ̀bun kanka, Pá Kasumu rebi àgbà ree Pa Kasunmu faye lẹ Gbajugbaja oṣere tiata Kayode Odumosu ti gbogbo eeyan mọ si Pa Kasumu lọsẹ yi dagbere faye.
1 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 2019: Marlian, òfégè ìgbéyàwó Buhari, Fatoyinbo àtàwọn ìṣẹ̀lẹ̀ ńlá tó mi ìgboro tìtì ní 201929 Ọ̀pẹ̀̀ 2019 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 3 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 5 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Ọrẹ tirẹ̀ ni: àwo fadaka kan tí ìwọ̀n rẹ̀ jẹ́ aadoje (130) ṣekeli, abọ́ fadaka kan tí ìwọ̀n rẹ̀ jẹ́ aadọrin ṣekeli.
Oluwo ke gbajare bẹẹ nibi eto idije kan fawọn akẹkọ ile ẹkọ girama to waye ni ẹkun idibo iwọ oorun ipinlẹ Ọsun, eyi ti ẹgbẹ alaanu kan se agbatẹru rẹ.
Lara awon to wa nibi ipade apero naa ni ojogbon Amos Sawyer, ti o je Aare fidehe teleri  lorile-ede Liberia, ni yoo soju fun ajo ECOWAS, nigba ti Aare teleri lorile-ede South Africa,  Kgalema Motlanthe yoo soju fun ajo AU.
Ta ni lè dárí ẹ̀ṣẹ̀ ji ni bíkòṣe Ọlọrun nìkan?
Lati ọwọ Abigail Ireland ni Stockport Iroyin BBC Ikọ eleto aabo O ṣeeṣe ki Coronavirus ni ipa to pọ lara awọn arugbo ati awọn to ni ailera miran lara tẹlẹ bii aisan ọkan, aisan ẹdọ-foor ati itọ ṣuga Ko si ẹri aridaju kankan pe awọn alaabọ ara to ni ilera pipe laini ailera tẹlẹ wa ninu ewu coronavirus ju awọn miran lọ Ṣe awọn to ti ni otutu aya Niumoníà tẹlẹ wa ninu ewu ami coronavirus?
“Ṣugbọn bí wọn bá jẹ́wọ́ ẹ̀ṣẹ̀ wọn, ati ẹ̀ṣẹ̀ àwọn baba wọn, nípa ìwà ọ̀dàlẹ̀ tí wọ́n hù sí mi, ati lílòdì tí wọ́n lòdì sí mi, 
Èèyàn 20 mííràn tún ti lùgbàdì ààrùn Coronavirus ní Naijiria Ìrìnàjò Toyin Abraham, láti orí gbèsè jíjẹ, ó di onílé, onimọto àti aya lọ́ọ̀dẹ̀ ọkọ Òfìfo ṣọ́ọ̀ṣì pa aṣọ dà fún àwọn Páṣítọ̀ Nàìjíríà Bí ẹni forí ọká họmú ni ti ìjọba bá dẹ́kun òfin koníléógbélé báyìí-WHO Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí kan sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
OLUWA Yóo Ṣe Ìdájọ́ Àwọn Orílẹ̀-Èdè.
Nígbà tí Labani gbọ́ ìròyìn ayọ̀ náà pé, Jakọbu ọmọ arabinrin òun dé, ó sáré lọ pàdé rẹ̀, ó dì mọ́ ọn, ó fi ẹnu kò ó lẹ́nu, ó sì mú un wá sí ilé.
O kò ní ṣàìmọ̀ pé gbogbo àwọn tí wọ́n wà ní agbègbè Esia ti sá kúrò lọ́dọ̀ mi, tí ó fi mọ́ Fugẹlọsi ati Hemogenesi.
Ṣé òfin kónílé-ó-gbélé lè mú àdínkù bá ìtànkálẹ̀ Coronavirus?
Ṣugbọn bí ibi tí ó pá ní orí rẹ̀ tabi iwájú rẹ̀ yìí bá lé, tí ó sì pọ́n, ẹ̀tẹ̀ ni ó fẹ́ bẹ̀rẹ̀ sí jẹ jáde níbi tí orí tabi iwájú rẹ̀ ti pá.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Trump picture: ọjọ́ tí Trump kí mi kú iṣẹ́ lórí 'twitter' ní inú mi dùn jù- Oyedele Awọn miran sọ ootọ ọrọ funra wọn lati tubọ tẹ ipa mọ iṣẹ aje wọn bayii ti ọmọ aarẹ ba le maa ya aworan kiri.
o dangajia julo jake-jado ile Afrika, o wa lara akonimoogba marundinlogbon ninu
ibeere miran tun ni :Eto oro aje orile ede yii gbera le epo robi pupo, ona
falciparum ba fa, ni ' artemisinin-based combination therapy (ACT).
Itan Omi Erin Itan omi gbigbona ati tutu ni Ikọgosi Ekiti Àlàyé rèé lóríi ìdí tí wọ́n fi ń pe aya ní ìyàwó Mọ̀ síi nípa Shina Rambo tó pàdé Jesu lọ́gbà ẹ̀wọn lẹ́yìn tó ti jalè Produced by Yemisi Oyedepo, Funmi Jokotade & Damilola Oduolowu Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Ooni Ile Ife: Ooni Adeyeye Ogunwusi àti Olòrì Naomi gbé Àrẹ̀mọ tuntun wọ ṣọ́ọ̀ṣì21 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 SERAP ké sí ààrẹ Buhari lórí èròngbà àwọn NCC àti NIMC lórí ìforúkọsílẹ̀ NIN20 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Dino Melaye Marriage Proposal: Se lóòtó ni sẹ́nátọ̀ Dino Melaye fẹ́ gbé ìyàwò tuntun19 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Inter-tribal Marriage: Bàbá mi kọ̀ láti bá mi sọ̀rọ̀ torí ọ̀kọ akáta tí mo mú wálé20 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí 3 sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 2:23 Fídíò, Water Generator: Ó leè ṣiṣẹ fún wákàtí mẹfà, kó tó sinmi, Duration 2,2310 Òkùdu 2020 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
Eleyi lo maa sọ ikọ agbabọọlu ti yoo pegede fun ipele to kangun si aṣekagba.
Kí OLUWA bukun ọ nítorí ohun tí o ṣe fún mi lónìí.
Igbimọ iṣakoso ileeṣẹ naa ti fi ẹsun aṣemaṣe lẹnu iṣẹ kan ọjọgbọn Yusuf, eleyi to mu ki wọn ni ko lọ rọọ kun nile laipẹ yii ṣugbọn ti akọwe agba naa kuna lati tẹle.
aládùígbò ni odùduwà àti alárẹ ̀ jẹ ́ ni apá ilẹ ̀ lárúbáwá .
Alhaja Fatimah Aṣabi sọ fun ik iroyin BBC pe eeyan oun mẹta lo wa ninu iṣẹlẹ naa ti wọn ko si tii ri meji ninu wọn.
Àwọn Juu meje kan tí wọn jẹ́ ọmọ Sikefa Olórí Alufaa wà, tí wọn ń ṣe bẹ́ẹ̀.
Iye awọn eeyan to ṣẹṣẹ ko arun naa ni ipinlẹ kọọkan ree: Eko -281 Abia-48 Oyo-45 FCT-38 Ogun-37 Enugu-31 Ondo-23 Plateau-21 Edo-19 Delta-18 Rivers-18 Bayelsa-17 Akwa Ibom-17 Kaduna-14 Kano-12 Bauchi-9 Gombe-4 Osun-3 Benue-3 Nasarawa-3 Kwara-3 Ekiti-2 Borno-1 Èèyàn 745 ló lùgbàdì àrùn Coronavirus ní Naijiria ní Ọjọ́bọ̀ Oríṣun àwòrán, Others Eeyan 745 tuntun mii lo ṣẹṣẹ lugbadi arun Coronavirus ni Naijiria.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Lagos building collapse: Àwọn òbí ń kérora lórí ikú àwọn ọmọ wọn nínú ìjàmbá ilé tó wó Loju opo Twitter awọn eeyan ti n ṣalabapin fidio iṣẹlẹ naa Ninu fọnran fidio ta ri loju opo ayelujara niṣe lawọn eeyan pe jọ laibikita itankalẹ arun Covid-19.
ilopo meji ti de ba owo ti a n fi pamo sapo okeere ,a ti n fokan awon onisowo bale, owo ile wa naa tun gbe peeli si ilaarin odun kan.
Ṣugbọn igi ọ̀pọ̀tọ́ dá wọn lóhùn pé, ‘Ṣé kí n pa èso mi dáradára tí ó ládùn tì, kí n wá jọba lórí yín?
Minisita feto abo nilẹ Amẹrika, Jim Mattis ati akẹgbẹ rẹ nilẹ Indonesian, Ryamizard Ryacudu se ayẹwo awọn ọmọogun ilẹ Indonesia.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Bi ìyàwọ mi ṣe n jábọ́ sí kọ́tà ló jẹ́ kí n kọ́ka fura pé kò ríran mọ́- ọkọ Dorcas Kassim ni yatọ si eleyi, o ṣi n gun ori akasọ lọ sun si yara rẹ o si n sọkalẹ wa funrarẹ.
N óo sì sọ ibẹ̀ di àlàpà títí ayé.
Kí ni ìtumọ̀ ọ̀rọ̀ yìí tí ó sọ pé, ‘Ẹ óo wá mi, ẹ kò ní rí mi, níbi tí mo bá wà, ẹ kò ní lè dé ibẹ̀?
Sugbọn nkan to damiloju ni pe eeyan le kapa ifoya rẹ.
Bí ẹ bá pa òfin mi mọ́, ẹ óo máa gbé inú ìfẹ́ mi, gẹ́gẹ́ bí mo ti pa òfin Baba mi mọ́, tí mo sì ń gbé inú ìfẹ́ rẹ̀.
Anasi Olórí Alufaa ati Kayafa ati Johanu ati Alẹkisanderu ati àwọn ìdílé Olórí Alufaa wà níbẹ̀.
Ẹgbẹ́ Akọ́mọlédè: A kan sáárá sí ìpínlẹ̀ Eko fún sísọ èdè Yorùbá di dandan nílé ẹ̀kọ́
'Ọlọpaa ni Harris' Ju ọpọlọpọ oludije igbakeji aarẹ lọ, Harris ni ibẹrẹpẹpẹ gẹgẹ bii agbofinro eyi si jẹ jade daadaa ninu awọn ibeere ti wọn bi i lasiko ifọrọwerọ.
Ààlà ilẹ̀ wọn, ní ìhà gúsù lọ láti òpin Òkun Iyọ̀, 
”Mo dáhùn, pé, “Ọ̀pá igi Alimọndi ni.
Nigba to n fidi isẹlẹ naa mulẹ, osisẹ alarina fun ileesẹ ọlọpaa ipinlẹ Oyo, Olugbenga Fadeyi ni aago marun idaji Ọjọru ni wọn pa obinrin naa.
Ondo Murder: Awọn ọlọ́pàá kò tíì mọ ibi tí wọn sin òkú ọmọ náà sí
Liigi orilẹede Spain: ko ni si igbaradi kọkan ayafi igba ti wọn ba gbe ẹsẹ kuro lori awọn eto to wa nilẹ.
Àpò òfìfo ni a bá nígbà tí a gbàjọba lọ́dún 2015, ṣùgbọ́n a ti ṣiṣẹ́ ribiribi - Ìjọba àpapọ̀ Ọwọ́ Interpol àti ọlọ́pàá Nàìjíríà ti tẹ ọmọ Nàìjíríà mẹ́ta tó lu èèyàn 50,000 ní gbájúẹ̀ Àwọn Olúkọ ìpínlẹ̀ Oyo fakọyọ lórí ètò Akọ́mọlédè àti Àṣà púpọ̀ Iléeṣẹ́ ọlọ́pàá palẹ̀ òkú ọmọ ọjọ́ kan mọ́ lẹ́yìn t́i wọ́n jùú sórí ààtàn Omotara kan ìdin nínú iyọ̀, àwọn ọmọ ilẹ̀ Faranse náà bínú síi nítorí alágbe tó fi ṣe yẹ̀yẹ́.
Akeredolu, ni owo osu to fẹ pari yii ni ijọba oun jẹ awọn oṣiṣẹ ipinlẹ naa, ti oun yoo si san.
"Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ìlú méjì kọjú ìjà síra wọn l‘Ondo torí aáwọ̀ ilẹ̀, ọba kan wà ní ‘Coma’, èkejì fo ògiri jáde Ọmọ Naijiria hú ẹ̀sùn ìfipá bánilòpọ̀ tí wọ́n fi kan Fatoyinbo síta lẹ́yìn tó lọ sí Shiloh Ìdí rèé tí mo fi yan ikọ̀ PMS rọ́pò NURTW nípìnlẹ̀ Oyo - Seyi Makinde Ìwọ́de ńlá yóò bẹ́rẹ̀ lọ́jọ́ táwọn gómìnà bá yá ₦17trn nínú owó ìfẹ̀yìntì òṣìṣẹ́ - NLC ""Buhari, Olóṣèlú àtàwọn òjíṣẹ́ Ọlọ́run ló mú àjẹbánu gogò ní Nàíjíríà"" Ooni Adeyeye ti Ile Ife fẹ sèrànwọ́ owó iléèwè fún akẹ́kọ̀ọ́ 5 mílíọ̀nù ní Nàìjíríà Ọkùnrin kan rí ẹ̀wọn he lẹ́yìn tó lu obìnrin ní jìbitì ìfẹ́ tí iye rẹ̀ tó $15,000 lórí ayélujára Fr Mbaka, ọmọ ìjọ rẹ̀ kọ̀lu akọ̀ròyìn BBC, wọ́n lù wọ́n ní àlùdojúbolẹ̀ Háà!"
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Àṣìṣe ọlọ́pàá àti Adájọ́ sọ mí di ẹni tí wọ́n dájọ́ ikú fún, ọpẹ́lọpẹ́ Fayoṣe tí ko buwọlu Kini BBC ba bọ ni agbegbe New Garrage?
Ni abala to gbeyin ninu egbe A, orile-ede Ghana yoo koju Guinea ni papa isere Stade de l’Amitie in Libreville lojo Abameta to m bo.
O miran tun ni ki obinrin o ma ni ile ọmọ tabi ko ma le bímọ, ki oun naa o ma sọ fun afẹfẹsọna rẹ saaju igbeyawo.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ọpọlọpọ ọmọ orilẹede South Africa lo ti n reti ikọwe fi ipo silẹ Jacob Zuma Pẹlu bi ọgbẹni Jacob Zuma se kọwe fipo silẹ, Cyril Ramaphosani adele aarẹ titi ti ile asofin apapọ orilẹede SouthAfrica yoo fi buwọlu u gẹgẹbi aarẹ.
Pásítọ̀ Enoch Adeboye darapọ̀ mọ̀ #ENDSARS, ó fún ìjọba Nàìjíríà ní ìmọ̀ràn ọ̀nà àbáyọ Kìí ṣe gbogbo ohun tí dókìtà ni kí n má jẹ torí àìsàn jẹjẹrẹ ni mo tẹ̀lé- Soyinka Mi ò mọ̀ nípa àwọn tọ́ọ̀gì tó da ìwọ́de EndSARS Alausa rú, mo ṣì wà lẹ́yìn yín digbí!
Man City ti fàgbà han Fulham pẹ̀lú 2-0 Awakọ̀ òfúrufú Ethiopian Airlines pariwo 'lọ sókè!
Ṣugbọn iṣẹ́ wọn ni láti máa ran àwọn ọmọ Aaroni lọ́wọ́ ninu iṣẹ́ ìsìn ilé OLUWA, láti máa ṣe ìtọ́jú àgbàlá ati àwọn yàrá ibẹ̀, láti rí i pé àwọn ohun èlò ilé OLUWA wà ní mímọ́, ati láti máa ṣe àwọn iṣẹ́ mìíràn tí ó yẹ ninu ilé OLUWA.
Buhari ti rọ awon adari lati ekun ila Gusu, pe ki won tubo gbiyanju lati fopin
Nínú ọ̀rọ̀ rẹ̀, ó jọ bi ẹni pé, Lizzy ti n fẹ́ ọkùnrin náà láti bíi ọdún mẹ́rìnlá sẹ́yìn, ṣùgbọ́n wọ́n ṣẹ̀ṣẹ̀ ṣe ètò tó tọ́ àti èyí tó yẹ̀ ni lóri ìrìnàjò ìfẹ́ wọ́n.
“Bo tile jẹ pe eto idibo to
"ní ọdún 1992 , ládi ládébò , ọ ̀ kan nínú àwọn tó ṣẹ ̀ ṣẹ ̀ bẹ ̀ rẹ ̀ sí ní ṣe fíìmù sí fídíò gbá oyè méjì lórí fíìmù rẹ ̀ méjì : "" Èèwò "" àti "" vender "" ."
Nígbà tí àwọn ọmọ ogun Gideoni fọn ọọdunrun (300) fèrè wọn, Ọlọrun mú kí àwọn ọmọ ogun ọ̀tá wọn dojú ìjà kọ ara wọn, gbogbo wọn bá bẹ̀rẹ̀ sí sá lọ sí apá Serera.
Ohun tó yẹ kí o mọ̀ nípa àgbo Covid-19 ti Madagascar n lò Ọ̀pọ̀ lo tí ń bèrè àwọn èròjà tó wà nínú àgbo ti orílẹ̀-èdè Madagascar ní ó lé wo ààrùn coronavirus.
òkú rẹ̀ kò gbọdọ̀ sun orí igi náà.
Iye awọn eeyan to ṣẹṣẹ ko arun naa ni ipinlẹ kọọkan ree: Eko-285 Rivers-68 FCT-60 Edo-60 Enugu-56 Delta-47 Ebonyi-42 Oyo-41 Kaduna-19 Ogun-18 Ondo-16 Imo-12 Sokoto-11 Borno-9 Nasarawa-8 Abia-5 Gombe-5 Kebbi-5 Kano-4 Yobe-3 Ekiti-3 Osun-2 Báwó ni òògùn dexamethasone ṣe ń ṣiṣẹ́ lára Ilé ẹjọ́ yẹ àga mọ́ Ọba Ìkirè nìdí lẹ́yìn ọdún 27 lórí ìtẹ́ Wo ọ̀nà tí àwọn ‘ẹ̀lẹ̀ Daddy’ gbà dé ààfin Ọyọ Ìjọba tó wà lóde yìí kò ní ìfẹ́ aráàlú la ṣe dá ẹgbẹ́ NCF sílẹ̀ - Femi Falana Eeyan 684 tuntun mii lo ṣẹṣẹ lugbadi arun Coronavirus ni Naijiria.
Oloye Olumẹgbọn, tii se ọkan lara awọn afọbajẹ nilu Eko, nii tun se Fatai Olumegbon olori oye Idejo ni aafin ọba Eko to wa ni Iduganran.
A ti gba kamu nitori kan si nkan ti a lee se.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Elisha Abbo: Àwọn alátakò mi nínú òsèlú ló gbé fídíò mi síta 2 Agẹmo 2019 Oríṣun àwòrán, Elisha Abbo Sẹnetọ kan to n soju ẹkun idibo ariwa Adamawa, Elisha Abbo ti di olokiki latari bi fidio kan ṣe ṣe afihan bo ṣe lu arabinrin abiyamọ kan bolẹ ninu ṣọọbu kan, ti wọn ti n ta awọn nkan ibalopọ, Banex Plaza ni Abuja.
Lagos tanker accident: Ọkọ̀ àjàgbé agbépo kan tún dànù l'Eko
Ọọni ile ifẹ gunlẹ si Brazil Àjọ̀dún ìlù bẹ̀rẹ̀ nílú Abẹ́òkúta Kini 'pen' l'ede Yoruba?
Ọba fara gbọgbẹ́ ninu ogun náà, nígbà tí àwọn ogun Siria sì lọ tán, àwọn balogun rẹ̀ dìtẹ̀ mọ́ ọn nítorí pé ó pa ọmọ Jehoiada alufaa, wọ́n sì pa á lórí ibùsùn rẹ̀.
Ọba Adekola Ogunoye jọba lẹ́yìn Olagbegi, tó sì waja losu kọkànlá ọdún 1992, o si jọba fún ọdún mẹẹdọgbọn gbáko.
Ṣugbọn mo mọ̀ yín, mo sì mọ̀ pé ẹ kò ní ìfẹ́ Ọlọrun ninu yín.
Yóo san ẹ̀san ẹ̀ṣẹ̀ wọn fún wọn,yóo pa wọ́n run nítorí ìwà ìkà wọn.
asoju-sofin to n soju nile-igbimo asoju-sofin agba niluu Abuja, Temitope
Koda, awọn ile ijo naa ko ba ofin mu nitori pe aarin adugbo ti awọn eniyan n gbe ni wọn wa.
Ìbúgbàmù Somalia: Àwọn ọmọ ilé ìwé farapa nínú ìbúgbàmù
Ó yọ ninu ewu òkun, ṣugbọn Ọlọrun ẹ̀san kò gbà pé kí ó yè.
Jonatani bá rápálá gun òkè náà, ọdọmọkunrin tí ó ń ru ihamọra rẹ̀ sì tẹ̀lé e.
Ìwọ jẹ́ kí n sọ̀rọ̀ díẹ̀ nípa ọ̀kan nínú àwọn ìwà buburú tí wọ́n máa ń hù, jẹ́ kí a sọ̀rọ̀ nípa ilara wọn.
Dokita Faduyille sọ pe o yẹ ki gbogbo eeyan to wa nibi isinku naa yara wọn sọtọ ninu igbele fun ọjọ mẹrinla ki wọn si ṣe ayẹwo lati mọ boya wọn ko ni aarun naa.
'Awọn agbabọọlu Super Eagles kan n gba‘bọde fun Naijiria'
Ilu Abuja ni awọn to ni i pọ si ju pẹlu eeyan mọkandinlọgọrin, nigba ti eeyan mọ́kàndínlọ́gọ́ta ni ni ipinlẹ Eko, ti Kaduna atawọn ipinlẹ mejila miran si n tẹle lẹyin.
Wọ́n dóti ìlú náà títí di ọdún kọkanla ìjọba Sedekaya.
kan,nipa bi won se n se ijọba won n se owo ilu-kumo-kumo, won ti sọ iwa rere
Ṣé ẹ̀yin mọ idí ti Abass Akande fi n jẹ Obesere?
Láti ìran dé ìran ni a óo máa yin iṣẹ́ rẹ,tí a óo sì máa sọ̀rọ̀ iṣẹ́ agbára ńlá rẹ.
Iwin yìí wọ ẹ̀wù péńpé tí ó dà bí ẹ̀wù ọdẹ pẹ̀lú ṣòkòtò kékeré kan tí kò ju orúnkún lọ, gbogbo ìwọ̀nyí kún fún ẹ̀jẹ̀ ó ń pọ́n kankan.
Ẹsun ti wọn fi kan wọn ni iwaju adajọ Olufunke Sule Amzat ni lilẹdi apo pọ lati huwa ọdaran ati kikojọ labẹ asia ẹgbẹ to lodi s'ofin eleyi ti wọn fura si pe o jẹ ẹgbẹ okunkun aiye.
Iroyin fi lede wipe ẹgbẹ awọn osisẹ̀ labẹ̀ NLC, TUC ati JNC to pe fun iyansẹ̀lodi ọlọ̀jọ̀ mẹ̀ta onikilọ̀ naa, so fun awọn osisẹ̀ ni ipinlẹ̀ Ọ́yọ̀ lati fi kọ́kọ́rọ́ ti ile-isẹ́ wọn fun ọjọ mẹ́ta, eleyi ti o bẹ́rẹ́ loni.
Beckham, àgbábọ́ọ́lù tẹ́lẹ̀ rèé tó ń sọ èdè Yorùbá Kingston lọmọ Áfíríkà tó gba ohun tí Hulk Hogan kò rí gbà Àwọn aṣòfin kò ní gba k'ẹ́gbẹ́ yan olórí fún wọn- Dogara ''Buhari, Zamfara là fẹ kí o lọ, kìí ṣé Jordan'' Agbabọọlu ti orukọ rẹ n jẹ Son lo gba goolu kan ṣoṣo ninu ifẹsẹwọnsẹ ọhun wọ le.
Hubert Ogunde rèé, baba àwọn òsèré tíátà Pervez Musharraf, Àarẹ ológun Pakistan nígbà kan rí gbọ́jọ́ ikú Ẹ̀wọ̀n tí mo lọ ni ẹ̀san ìwà tí mo hù gẹ́gẹ́ bíi olórí ológun- Buhari Adájọ́ ẹ tú wa ká, ìyàwó mi n gbé ààlè wá sórí ibùsùn wa- Ọkọ ìyàwó Iroyin ni Adewale bẹ Lateef lọwẹ lati gba ẹmi arabirin Sikirat to si fun un ni ẹgbẹrun mẹfa naira owo iṣẹ.
Wọ́n wá gba ìwé pada fún Sila ati Timoti pé kí wọ́n tètè wá bá a.
Ohun to si jẹ awọn ara ilu logun nipa ọrọ yi ni bi awọn oṣiṣẹ ile iṣẹ mọnamọna ti ṣe n bu owo gọbọi fun awọn ti ko ni ẹrọ to n ka iye owo ina ti wọn kò lo 'pre paid meter'.
 wọn wà ní àgbègbè Èbìrà ní ìpínlè kogi , kwara , edo , àti béè béè lo .
Ajo EU so pe, lilo igbese idajo iku ku die kaato lorile-ede naa.
O ti fi da awọn eeyan loju pe awọn yoo gbe igbesẹ to tọ kiakia.
Ọ̀jọ̀gbọ́n Simon Mallam wa nínú àwọn mẹ́fà tó ti kú nínú ìjàmbá iná gáàsì- Ìjọba Kaduna Obabinrin Elizabeth II ṣàfihàn àwòrán orí adé mẹ́ta tó lè jé lẹ́yìn rẹ̀ Èmi ní mo fún Afeez Abiodun ní orúkọ 'Ọwọ' tó ń jẹ́ -Yemi My Lover Obabinrin Elizabeth II ṣàfihàn àwòrán orí adé mẹ́ta tó lè jé lẹ́yìn rẹ̀ Bakan naa ni akowe ati alukoro ẹgbẹ oṣelu PDP, Kola Ologbondiyan sọ pe igbesẹ ijọba lati fowo kun owo ina yoo dakun iṣoro awọn araalu.
Ọjọ́ mẹ́jọ-mẹ́jọ, ìyẹn ọ̀sọ̀ọ̀sẹ̀, ni ètò náà njáde.
Ta ni ó tó takò ó pé kí ó má ṣe ohun tí ó bá wù ú?
Wọ́n gbéra láti ibẹ̀, wọ́n lọ pa àgọ́ sí àfonífojì Seredi.
Àrẹ̀mọ Ooni Adeyeye Ogunwusi ti wọ Ààfin Ile Ife fún ìgbà àkọ́kọ́ Èyí ni ìtàn Ọkùnrin tó rí ẹ̀wọ̀n he nítorí àkùkọ aládúgbò rẹ̀ tó pa Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Gómìnà ìpínlẹ̀ Benue, Samuel Ortom ti parí ìjà láàrin akọ̀ròyìn Channels TV, Pius Angbo àti Ifeyinwa Angbo, ìyàwó rẹ̀8 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Ronke Oshodi-Oke: Ọkọ mi kò mọ̀ pé òṣèré ni mi nígbà tí a pàdé- Ojo8 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 5:03 Fídíò, Omolola Arohunmolase Welder: Mo ti fí iṣẹ́ 'Welder' gbayì láwùjọ, tó mo fi tọ́ ọmọ yanjú, Duration 5,039 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 4:11 Fídíò, Oba Adeyeye Ogunwusi: Ojú mi ti rí lọ́pọ̀ lọpọ̀, ọ̀pọ̀ èèyàn ni kò tilẹ̀ gbàgbọ́ pé mo lè jọba- Ooni, Duration 4,117 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí 2 sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
Paulu Ń Waasu Kristi Tí Wọ́n Kàn Mọ́ Agbelebu.
gẹ́gẹ́ bí ìyìn rere tí a fi lé mi lọ́wọ́, ìyìn rere Ọlọrun Ológo, tí ìyìn yẹ fún.
”Ewe, Rohr fikun un oro re pe, oun yoo seto apapo agbaboolu márùndínlógójì  ti yoo kopa ninu idije naa fun ajo NFF lojo kerin in osu karun un odu ti a wa yii.
 Ìbéjì ni wọ ́ n fi eẹgún bí .
Ohun ti oju Musa Adamu, olugbe ilu Mallamawa ri lasiko tawọn agbebọn ṣigun bo abule rẹ fọjọ meji kọja afẹnusọ.
Ni bayii, ẹgbẹ kan to n ja fun ẹtọ awọn musulumi, MURIC ti pe fun iwọde lati fi ẹhonu han lori ọrọ naa.
Kí OLUWA gbẹ̀san lára àwọn ọ̀tá Dafidi.
Hukoku ati Rehobu, pẹlu àwọn pápá oko àyíká wọn.
 irú ìsọmọlórúkọ yìí gbọ ́ dọ ̀ jẹ ́ èyí tí a ṣe tìlù tìfọn .
Kìnìún mẹ́rìnlá bọ́ sígboro Ida ogun ninu ida ọgọrun owo iyọnda rẹ lo ṣo pe ki wọn fun ẹbi Leah, iye kan naa lo ni ki wọn fun idile Hauwa Liman ati Hussaini Ahmed Khoisan, awọn oṣiṣẹ oluranlọwọ ti Boko Haram pa.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Beard Woman: Irungbọ̀n mi máa ń dójú tì mí láti jáde lọ ra nǹkan ní ọ̀sán gangan 29 Sẹ́rẹ́ 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 23 Ìgbé 2020 Njẹ ẹyin ti ni iriri eleyi ti awọn agbofinro sọ pe ki ẹ bọra silẹ lati le e ri aridaju pe lootọ obinrin ni yin?
 eléyìí ni wọ ́ n ń sọ ní orílẹ ̀ -èdè turkey .
O óo máa táràrà lọ́sàn-án gangan bí afọ́jú.
Boko Haram ti n se atipo.
5m nínú ẹ̀bùn BBNaija season rẹ̀ Lẹyin ti olukopa eto agbelewo BBNaija, Lekan Agbeleshebiọba ti ọpọlọpọ mọ si Laycon bori pẹlu ẹbun ti akojọpọ iye rẹ to miliọnu marundinlaadọrun naira, N85m ni okiki rẹ ti kan kalenkako ti ọpọlọpọ si ti n kii ku oriire.
Ọmọ Yahoo tú àṣírí ara rẹ̀ fún, bí wọ́n ṣe ń ṣe é BBC Yorùbá Ènìyàn 27 lo ti bá iṣẹ̀lẹ̀ ọkọ̀ ofúrufú tó já rìnrìn ajò Pasuma kìí ṣe ọkọ mi o!
Nigerian Celebrities: Ẹ wo àwọn ìlúmọ̀ọ́ká olórin, òsèré tó ti sàtìmọ̀lé rí!
Oríṣun àwòrán, Tope alabi O tún wa gba àwọn ọdọ tó nifẹ láti máa kọrin ẹ̀mí nímọ̀ràn pé, isẹ orin kíkọ yóò rọrùn fún wọn tó bá wù Ọlọ́run fún onitohun láti kọrin, àmọ́ ó fikùn pé, orin ẹ̀mí kíkọ kii se isẹ ti èèyàn leè ṣe ayojuran si.
"O ni ""nọmba ẹrọ ibaraẹnisọrọ ti wọn fi si ori iwe ipolongo ariya naa ni wọn fi tọpasẹ wọn, ti ọwọ fi tẹ wọn""."
Lẹ́yìn tí gbogbo àwọn àgbààgbà ti péjọ, àwọn alufaa gbé Àpótí Ẹ̀rí náà.
N óo máa yìn ọ́ tọkàntọkàn OLUWA,lójú àwọn oriṣa ni n óo máa kọrin ìyìn sí ọ.
 o tobi to lati gba planeti meji tabi meta to ni diamita aye .
Guinea Bisau ti fi idunnu re han si orile ede Naijria fun atileyin ti won se lasiko iforukosile  ati igbaradi fun eto idibo.
Oríṣun àwòrán, Ademola adeleke Àkọlé àwòrán, Titi di asiko yii, ileeṣẹ ọlọpaa ko tii sọ ohunkohun lori ọrọ naa Ki ni ileeṣẹ ipolongo ibo fun Adeleke sọ?
Ewe, olugbani-nimoran lori eto aabo nile ise aare Trump, John Bolton so lojo isegun pe, oun ko ro pe awon aworan ati fonron ti o ro mo iku Khashoggi ti awon ara ile Turkey n pin kaakiri ero ayelujara, boya iku naa niise pelu omooba ile Saudi, Mohammed bin Salman.
Terry Waya ni igba ti Kiddwaya wa ba oun pe o fẹ lọ kopa nilee ẹlẹgbọn agba, oju ti oun fi wo o gan, ṣe lo pa ẹnu mọ.
Lójú kan náà òun ati gbogbo ìdílé rẹ̀ sì ṣe ìrìbọmi.
Oríṣun àwòrán, @ProfOsinbajo Àkọlé àwòrán, ''AyanYemi ọmọ Ayanbajo''.
Bí ẹ rí abirun dúdú lórí
Iroyin kan fikun pe ọps dukia ni wọn baana lasiko ija igboro to jẹ ti oselu naa, ko si din ni ọkọ ayọkẹlẹ mẹẹdogun to bajẹ.
Oríṣun àwòrán, Lulu Jemimah Lulu sọ pé ''ara n yá mi láti mú àfojúsùn mi láti jẹ́ ọ̀mọ̀wé ṣẹ.
‘Ìwà ìdúnkòokòmọ́ni, ọ̀yájú sàwọn olùdìbò ló kún inú àtúndì ìbò Ọ̀sun’ Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí 2 sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
Bi fidio naa se lọ ree: Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Àwọn abawọn òhun gẹ́gẹ́ bó ṣe sọ wá láti ẹnu Ààrẹ Olusegun Obasanjọ ti wọn ti jọ ṣe ìjọba fún ọdun mẹ́jọ, ó fi kún pé àwọn ǹkan tó sọ nípa Atiku ní àwọn ènìyàn gbàgba pé ó jẹ òtitọ nítori pe wọn gbàgba pé ó mọ̀ọ́ dárádára Obasanjo fi kún pé Atiku kò ṣe gbara lé àti pé ajinilẹ́sẹ̀ ni Atiku lásiko ti àwọn jọ ṣe ijoba.
Ẹwẹ, o ni wọn lee gba awọn eniyan niyanju ti wọn ba nifẹ si wiwo isin naa lori ayelujara lati ṣe bẹẹ.
Àfi kí wọ́n máa bá arawọn jà lójoojúmọ́.
 Ọjọ ́ yìí ni a gbé adé fún mọnígbùwà .
O pe awon omo bibi iran Igbo lati koju idojuko kiku ti ede ati asa Igbo fe maa ku lasiko yii nitori pe awon eniyan ti n gbagbe ile nipa gbigbe ati sise ise leyin odi.
Amọ Mailey ninu awọn orin rẹ tuntun fi Ruggedman ṣe yẹyẹ lori ọrọ naa.
Infantino lo gba eku ida lọwọ Sepp Blatter lọdun 2016 to si ti mu afikun ba iye awọn agbabọọlu ti yoo figagbaga fun ife ẹyẹ agbaye ti yoo waye lọdun 2026.
Asole Real Madrid, Navas kopa ribiribi ninu ifesewonse naa, leyin ti o dena boolu lorisirisi lati ma wonu agbon re.
COZA RAPE Allegation: Ìdí rèé tí mi ò fi yọjú sí ìgbìmọ̀ àjọ PFN- Fatoyinbo
’ rèé Afọnja, ẹni tó finú wénú ní Ilọrin, àmọ́ tó jẹ iwọ Ninu esi rẹ, Soworẹ ni o si eyi kii ṣe igba akọkọ ree t'oun yoo darapọ mọ awọn to n ṣewọde.
Wọn ni eyi ja si wi pe ọdun 1961 ni apa ibi ti Atiku Abubakar ti wa dara pọ mọ orilẹede Naijiria.
Ẹrú ni ọ́ nígbà tí a fi pè ọ́?
Wo àwọn nkan tí o le ṣe gẹ́gẹ́ bi aláboyún lásìkò àjàkálẹ̀ ààrùn Covid-19 Lóòtọ́ lò n lo ìbomú-bẹnu, ṣùgbọ́n ṣe bóṣeyẹ kí o wọ̀ ọ́ ló ṣe n ṣe?
Àwọn kan ti yan ìṣàjọyọ̀ àjọ̀dún náà ní ìkọ̀kọ̀.
Nibi ipade igbimọ abo ileewe naa ni wọn ti gbe igbesẹ yii.
 Iwa ojowu to wa lara Obasanjo  si aare Buhari ni ko je ko mọ pe awon eniyan ni
Ìpínlẹ̀ Eko, Ọṣun àti Ondo yóò bẹ̀rẹ̀ sí ní lo ‘Drone’ fún ààbò A kò jáde ṣe ìwọ́de ìtagbangba mọ́, inú ọkàn wa lá ti máa ṣe ìfẹ̀hónú hàn - Revolution Now Ẹ yàgò fún gbájúẹ̀, a kò tíì gba ẹnikẹni fún iṣẹ́ tíṣà - Ìjọba Ọyọ lọgun Nigba to n fi idi isẹlẹ naa mulẹ, osisẹ alarina fun ileesẹ ọlọpa ipinlẹ Ondo, Fẹmi Joseph salaye pe awọn osisẹ ọlọpa ti n finmu finlẹ lati se awari awọn olubi ẹda to sisẹ laabi ọhun.
Ipele idije Champions league yi tun jẹ ọkan ninu awọn meji ninu eyi ti FC Porto ati Liverpool FC yoo pade ara wọn.
Nítorí náà, Abramu kó àgọ́ rẹ̀ wá sí ibi igi Oaku ti Mamure, tí ó wà ní Heburoni, níbẹ̀ ni ó ti tẹ́ pẹpẹ fún OLUWA.
Biden ni Donald Trump gbọdọ fun oun ni aye lori bi yoo ṣe gbe ipo silẹ ni ọdun to n bọ lai si idẹna kankan.
Oludari agba eka iforotonileto ati igbodegba ile-ise omo ogun naa, ogagun Ibikunke Daramola lo jabo oro ohun fun awon akoroyin lojoRu(Wednesday.
 the only all-african state not in the au is morocco nikan ni orile-ede alominira ti ki i se omoegbe isokan afrika .
    Báyìí ni àwọn Èdídàrẹ́ ka ìgbàgbọ́ wọn lórí oúnjẹ.
Aisan ọkan ti n ba oloogbe Isa Funtua finra tẹlẹ ni eyi to ti n gab itọju loorekoore nipa rẹ tẹlẹ.
Amaechi ni Eredi fasiti yi ni ki wọn le ṣagbekalẹ awọn onimọ lẹka irinna Naijiria.
O sọ wá di ẹni àmúpòwe láàrin àwọn orílẹ̀-èdè,ati ẹni yẹ̀yẹ́ láàrin gbogbo ayé.
“A o ni gba enikankan laaye lati lọ dibo pelu awọn  ẹsọ agbebọn ,eleyii tapa si ofin eto idibo.
"Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Rape cases in Nigeria: Ọmọ ọdun 5 àti 14 ni Kalu wà nígbà tí obìnrin fipá ba lòpọ̀ Obinrin naa kọ silẹ ninu iwe akọsilẹ ileeṣẹ ọlọpaa pe ""ọkunrin ọhun, lẹyin to fipa ba mi lopọ tan, tun ni ki n mu okó rẹ, ti mo si ge oko naa jabọ""."
"O ni, "" Ibi ti mo joko si naa niyẹn pe ọla ni ọjọ Aje, gbogbo nnkan le lọju pọ ni ibi alata."
Atẹ́gùn náà pọ̀ gidigidi ó fẹ́ síhìn-ín ó fẹ́ sọ́hùn-ún, àwọn igi àti ìtàkùn sì bẹ̀rẹ̀ sí kọlu ara wọn.
ariwo ti awon eniyan maa n pa ku, pe ijoba ko yan asoju kankan lati ẹkun wọn.
Joshua Kimmich lo gba ami ayo kinni wole, ti Karim Benzema si da ami- ayo ohun pada niseju mejo si ami ayo akoko.
Fidio kan ti wọn pin káàkiri lori ẹrọ ayélujára Weibo ni ìlú China fihàn tí oṣiṣẹ kunrin kan ti duro láàrin ibìkan ti wọn ti n lu ni kumọ.
Ninu eto naa ni Katung Aduwak, ẹni ọdun mẹrindinlọgbọn ti jawe olubori nibẹ.
Ẹwẹ, Gomina ipinlẹ Anambra, Willie Obiano ti ṣe agbekalẹ́ igbimọ kan ti yoo tọpinpin ọrọ ina yi.
Dafidi ní, “Ẹnikẹ́ni tí ó bá kọ́kọ́ pa ará Jebusi kan ni yóo jẹ́ balogun fún àwọn ọmọ ogun mi.
Kò dára kí eniyan wà láìní ìmọ̀,ẹni bá ń kánjú rìn jù a máa ṣìnà.
LASTMA: A ṣèlèrí láti fi òṣìṣẹ́ yìí jófin tó bá ṣẹ̀
Itan rẹ dàbí ohun ọ̀ṣọ́,tí ọlọ́gbọ́n oníṣọ̀nà ṣe.
Tottenham tẹ̀yìn gbéru Ajax Bukola Saraki kò kọjá òfin - EFCC Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Pierre-Emerick Aubameyang ló gbá àmì ayò méjì nínú mẹ́ta ti Arsenal fi bori Lasiko yii ni àwọn agbabọọlu Arsenal naa ti pakiti mọlẹ, ti Pierre-Emerick Aubameyang si da ayo kan pada fun Valencia laarin iṣẹju mẹtadinlogun ti idije ọhun bẹrẹ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Arafat Day: Wo àwọn ohun márùn-ún tí ayájọ́ òní fi lọ́lá jùlọ nínú Islam 10 Ògún 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 30 Agẹmo 2020 Oríṣun àwòrán, Hujjaj in Masjid al Namirah, Arafat Ọjọbọ oni, tii se Ọgbọnjọ osu Keje ọdun 2020 ni ọjọ Arafa fun ọdun yii.
Wọ́n sì ṣe àlàyé pé ẹgbẹ̀rún lọ́nà ọgbọ̀n naira tí àjọ náà ń béérè fún kò tó láti gbọ́ bùkátà àwọn òṣìṣẹ́.
A dàbí ẹni tí ń kú lọ, sibẹ a tún wà láàyè.
Ọga akọrin RCCG : Fẹla lo ṣe iwuri fun mi
Wọ́n ń bèèrè pé, “Kí ló dé tí à ń gbààwẹ̀, ṣugbọn tí OLUWA kò rí wa?
Oṣù tí ó ń bọ̀ ni ó sààmì ọgbọ̀n ọdún tí ìpaninípakúpa Tiananmen Square wáyé.
Igbo Olodumare rèé, níbi tí Ìgbín ti tóbi ju Ìjàpá lọ Ìdílé márùn-ún tó gbajúmọ̀ fún òwò ẹrú nílẹ̀ Yorùbá Wo ìtàn ayé gbajúmọ̀ adigunjalè méje nílẹ̀ Yorùbá Iru ẹda wo ni Alaafin Adeyemi jẹ?
Ọdun 2013 ni ẹni ọdun marundinlaadọrin naa di olori ẹgbẹ oṣelu Malawi Congress Party, lai ni iriri kankan nipa oṣelu.
Mo parí iṣẹ́ àṣepatì 239, iṣẹ́ 236 míì ń lọ lọ́wọ́- Seyi Makinde Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
8 Ẹrẹ̀nà 2020 Oríṣun àwòrán, Twitter/manchester united Àkọlé àwòrán, O ti di igba mẹta ọtọtọ ni saa yii ti Man U ti n digbaju ru Man City.
Àjọ Ìlere Àgbáyé àti ilé-iṣẹ ́ Ìṣàkóso àti Ìdènà Àrùn gba ni nímọ ̀ ràn pé kí a fún gbogbo ọmọdé ní àjẹsára ìkọ ́ ọfe , àti pé kí a fikún àwọn àjẹsára tí à ngbà lóòrèkóòrè .
 Dariji mi fun awọn asiko ti mo pariwo mọ ọ, nitori ẹrù isẹ iranṣẹ àti bukaata ile wọ̀ mi lọrun.
Sugbọn nigba ti yoo fi di asalẹ ọjọ ẹti ni o fi ikede soju opo Twitter ti ile ise Aarẹ Naijiria naa si kede ifiposilẹ rẹ Àwọn ìwé ẹ̀rí wo lo nílò kí o tó gba oyè òṣèlú?
Awọn  eniyan metalelogbon lo padanu emi  wọn , pelu  awọn  ọlọpaa  mesan an , nigbati  awọn  adigunjale wa si  ilu Offa, ti  wọn  si  kolu  awọn  ile-ifowopamo ati ago ọlọpaa  to wa niluu naa.
Oríṣun àwòrán, Olasunkanmi Marshal/Facebook N kò jẹ Mayegun láti bùgá, mo wá tún ilẹ̀ Yorùbá ṣe ni - Wasiu Ayinde Mo le búra pé kò sí ìbáṣepọ̀ láárin Olorì Badrat àti Wasiu Ayinde - Olori Folashade Barrister ló sọ mí di èèyàn ńlá - Ayinla Kollington Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Bí ìrẹsì tèmi Ayinde bá ń pàkùta, kò tọ́ sẹ́nu aláàrù Barrymaade' Alhaji Adisa Oseifa to jẹ ọrẹ korikosun Barrister naa wa nikalẹ nibi Ipade ọhun.
Dokita adigunjale ta n sọrọ rẹ yii jẹ oninu fufu ẹda, to si gberaga pupọ, koda se lo pariwo mọ ọlọpa to wa mu pe oun ko fẹ bo se n ba oun sọrọ, nitori to ba jẹ pe oun gbe ibọn dani ni, oun ko ba ti fi ibọn pa Lasiko ti ina idigunjale n jo fun Oyenusi, Oyenusi maa n janu pe ibọn ko ni agbara lori oun, tawọn eeyan si ri ogbologbo adigunjale naa bii Adigunjale akọkọ to gba ipo kinni yika orilẹede Naijiria.
nítorí ó ń kọ́ àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀, ó ń wí fún wọn pé, “A óo fi Ọmọ-Eniyan lé àwọn eniyan lọ́wọ́, wọn yóo pa á, ṣugbọn nígbà tí wọ́n bá ti pa á tán, yóo jí dìde lẹ́yìn ọjọ́ mẹta.
Koda, ko kẹkọọ pari ti ko fi lọ mọ.
Ka tilẹ wa sọ pe pẹlu owo ọkọ, ki iyẹn jẹ ẹgbẹrun marun.
OLUWA àwọn ọmọ ogun ní:“Wò ó!
O kede ipinnu ohun ninu osu kejila odun ti o koja pe oun yoo pada sini kopa, bi o tile jepe iko naa ko pegede fun idije boolu agbaye ti yoo waye lorile-ede Russia ninu odun ti a wa yii.
Ó ti gbé Olùgbàlà dìde fún waní ìdílé Dafidi, iranṣẹ rẹ̀;
Bakan naa ni ilẹ Amẹrika ni awọn yoo tun fi ẹgbẹrun mẹta kun ikọ ọmọ ogun ti wọn yoo ran lọ si aarin gbungbun iha Guusu gẹgẹ bi ikọ olu lalakan fi n ṣọri.
Operation Amotekun: Atiku ní ẹ̀ṣọ́ alábòò Amọtẹkun yóò ṣ'èrànwọ́ lórí ètò ààbò tó mẹ́hẹ
Ǹjẹ́ bí ó bá fẹ́ràn mi kò ni wí pe àáró mi sọ òun gan?
"Irú ọ̀rọ̀ bẹ́ẹ̀ kò ní òtítọ́ nínú, tò sì jé ohun ìṣìnà pátápátá.
Shuijin salaye pe, lati bi odun meje ti ajosepo ti wa laarin Nigeria ati orile-ede China, orile-ede mejeeji ohun  ti ni idagbasoke ti o lagbara.
Àwọn kókó ohun tó wà nínú lẹ́tà tí Aláàfin kọ sí Fayemi rèé Ṣé lóòtọ́ ni Ọọ̀ni ilé ifẹ̀ ti parí aáwọ̀ lọ́balọ́ba l'Ékìtì?
Ẹgbẹ ẹlẹni mẹtadinlaadọta to nsọ ede Gẹẹsi ni orilẹede Cameroon to ya kuro lati orilẹede wọn lati wa gbe ni Naijiria pẹlu adari wọn, Julius Sisiku Ayuk Tabe ni wọn ko kuro ni orilẹede Naijiria lọ si orilẹede Cameroon lẹyin ti wọn ko wọn ni ilu Abuja ni ibẹrẹ osu kini ọdun yii.
Ìdí rèé tí ilẹ̀ Afirika fi gbọdọ̀ kópa nínú dídán abẹ́rẹ́ coronavirus wò Èèyàn 328 tuntun míì ló lùgbàdì àrùn Coronavirus lọ́jọ́ Ẹti ní Naijiria Èdè Gẹ̀ẹ́sì tí pọju nínú tíátà Yorùbá tá n gbé jáde lóde òní - Afeez Ọwọ Odunlade àti Femi Adebayọ: Wo ohun tó yà wá sọ́tọ̀ nínú àwọn arẹwà ọkùnrin Lara ohun to sọ fawọn ololufẹ rẹ ni ipa to ko ninu ere sinima Naijiria paapaa julọ nipa ṣiṣe atọna fawọn elere sinima to ti wa gun oke agba loni.
bákannáà ní ọ ̀ rọ ̀ sìsọ lásán yìí jẹ ́ ìyanu , èyítí , mo sì gbọ ́ ní ìjọ ́ sí ni mo ní kí nbá yín sọ lónǐ , ẹ ̀ nyin ọmọ ènìà .
Gomina tun pase  pe ki  won ti awon ile-ise ijọba ati awon oja to wa laarin ilu pa, ki awon ara ilu si wa ninu ile won, lati fi le takubu aare to fe wa si ipinle naa.
Wo bí ètò ìdìbò abẹ́lé ẹgbẹ́ òṣẹ́lú PDP ṣe ń lọ ní ìlú Akure Idibo ọhun waye lati ori ijọba kan si omiran.
Ilu Makun ni ipinlẹ Ogun ni wọn ti bi Adebayo Ogunlesi ti o si ti wa di ilumọka agbẹjọro ati ouldukowo lagbaye Pupo ninu awọn arinrinajo to ba gba papakọ ofurufu Gatwick kọja nilẹ Gẹẹsi a maa kan saara si bi wọn ti ṣe ṣe eto papakọ ofurufu naa.
Ṣugbọn bí ó bá jẹ́ pé nípa Ẹ̀mí Ọlọrun ni mo fi ń lé àwọn ẹ̀mí èṣù jáde, a jẹ́ pé ìjọba Ọlọrun ti dé ba yín.
Wọ́n to ìlẹ̀kẹ́ láti orúnkún lọ sí ìsàlẹ̀, ìgbà tí ó kù díẹ̀ kí wọ́n tò ó dé ọrùn ẹsẹ̀, wọ́n dáwọ́ rẹ̀ dúró, wọ́n sì wá mú ẹ̀gbà ide, wọ́n tò ó yí ọrùn ẹsẹ̀ po, wọ́n ge idẹ pẹlẹbẹ pẹlẹbẹ wọ́n so ó mọ́ ẹ̀gbà wọ̀n-ọnnì, eléyìí nì sì ń dún woro-woro bí wọ́n ti ń sáré kọjá lọ.
Dánáfojúrà nìyí, abàmì eégún tí ń gbé inú iná ṣọlá Funke Akindele jẹ àkàndá ẹ̀dá- Adaku inú eré Jẹnifa Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí 3 sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
O fikun pe koda ti oun ba rinrinajo lọ si oke okun, isẹ ni oun tun maa n se bii aago, ti oun yoo si maa ra orisirisi eroja ti oun fẹ wa ta lorilẹede yii nitori ọna kan ko wọja.
Lai wo eyi, atilẹyin ti Biden n ri laarin awọn oludibo alawọdudu pọ jọjọ lasiko idibo aarẹ ti o fẹ waye yii ṣugbọn laipẹ yii , tun sọ ọrọ to da ilẹ ru lori eto ori rdio kan to ti sọ pe iwọ too ba niṣoro pe o fẹ mọ boya emi ni waa dibo fun tabi Trump, iyẹn nipe oo ki n ṣe alawọdudu."
CSKA Mosco - Ahmed Musa: Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ẹgbẹ agbabọọlu Leicester City ti gba fun Ahmed Musa lati lọ si CSKA Moscow Awọn ẹgbẹ agbabọọlu CSKA Moscow ti Russian liigi ti kede pe ọmọ ẹgbẹ agbabọọlu Naijiria, Ahmed Musa ti tun darapọ mọ wọn fun igba diẹ.
Ìgbà tí a dé aginjù yíì ló tún di kí a máa rí àwọn iwin.
WCS ni ẹrọ ayaworan ti wọn ri mọlẹ ninu aginju ọhun, lo ya aworan awọn Inaki naa, ti diẹ lara wọn si ni ọmọ lọwọ.
Ayọ̀ abara tíntín, àwo orin tuntun ni ọmọ ti Burna Boy bí, bí àwọn olólùfẹ́ rẹ ṣe ń ki náà ni àwọn ọ̀rẹ́ àti ojúlùmọ̀ náà ń kíi kú oríire.
Lojo-Ru, ile-ejo kan fi awon osise ijoba kan satimole, latari bi won ko se tele ase ile-ejo naa,latiAwon agbejoro fun ogbeni Miguna fi mule pe, oko oju ofurufu Emirates lo gbe Miguna kuro ni ilu Nairobi.
O kò gbọdọ̀ bá arabinrin baba rẹ lòpọ̀, nítorí pé, ẹbí baba rẹ ni ó jẹ́.
Àwòrán àbẹwo Macron si Afrika Shrine Ọgọ̀rọ̀ èèyàn s'ayẹyẹ ọjọ́ ìbí ọgọ́rin ọdún fún Fẹla Messi ló gb'àmì ẹ̀yẹ Ballon D'or lóòtọ́ọ́, àmọ́ Ronaldo ló dára jùlọ (GOAT)- Mendes Ilé ẹjọ́ Eko pàṣẹ, EFCC mú u ṣẹ, Ìjọba gbẹ̀sẹ̀ lé ilé Saraki ní Ilorin Tani Oyedele Adedokun?
Nítorí láti ọ̀dọ̀ Ẹ̀mí Mímọ́ ni a ti fún ẹnìkan ní ẹ̀bùn ọ̀rọ̀ ọgbọ́n, a sì fún ẹlòmíràn ní ẹ̀bùn ọ̀rọ̀ ìmọ̀ láti ọ̀dọ̀ Ẹ̀mí kan náà.
Ayọ̀ọlá: Kínni ẹ ni ní títà tí mo lè fi mu gàrí
Buhari ti ni orile ede Naijiria yoo tubo maa fọwọsowọpọ pẹlu awon to wa ni
Tunde Kelani ni ko tii pe osu kan ti awọn peju se ayẹyẹ ọjọ ibi fun Oniluola, ti awọn ko si mọ pe ọlọjọ ti n sunmọ.
Omijé fẹ́ bọ́ lójú mi tí mo bá ṣàfiwé SARS tí mo dá sílẹ̀ àti SARS tó wà níta báyìí- Fulani Kwajafa Ohun tí ojú ìyàwó mi rí lọ́wọ́ SARS kò ṣe é fẹnusọ- Poju Oyemade Kìí ṣe gbogbo ohun tí dókìtà ni kí n má jẹ torí àìsàn jẹjẹrẹ ni mo tẹ̀lé- Soyinka Wo ìsọ̀rí àwọn tó jẹ́ kí ìwọ́de End SARS / end SWAT lárinrin àti ìtumọ̀ Iya Isiaka, Ramota Jimoh ke si araye lati ṣaanu oun ki iku Isiaka ma ja si asan lori iwọde titako iwa ifiyajẹni lọna aitọ awọn agbofinro.
Amọsa ohun to tubọ kọ awọn eniyan lominu ko ju bi o se jẹ wipe pupọ ninu awọn gomina ana wọnyii ti wọn se ofin yii gbe lẹyin ni wọn tun fo fẹrẹ gba aga ipo oselu miran lọ bii ile asofin agba, Minisita ati bẹẹbẹẹlọ.
'Oriṣiriṣi ọkunrin ni mo ba sun lọna ati jẹ ni Russia'
Gẹgẹ bi iroyin naa ti wi, nigba ti BBC Yoruba kan si agbẹnusọ fun ileesẹ ọlọpa nipinlẹ Ọyọ, Olugbenga Fadeyi lati gbọ tẹnu rẹ, o ni ka pe oun pada laipẹ.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Pásítọ̀ bẹ́'rí ọmọ ìjọ ní ìpínlẹ̀ Ògùn Afẹ́fẹ́ òjò líle ṣọṣẹ́ nípinlẹ Kwara Ẹmi mẹrin sọnu sinu ijamba afara Kara Ghana ti mu àwọn afurasí ajínigbé ọmọ Naijiria mẹ́ta Ninu awọn ọkọ to farakasa la ti ri ọkọ akero kan to fi mọ awọn ọkọ ayọkẹlẹ miran.
   Bakan naa, eniyan mokanla miiran tun farapa yanayana ni gbagede igbafe lagbegbe Jacksonville lojo Aiku(Sunday).
Bí ìmọ́lẹ̀ tí ó wà ninu rẹ bá wá di òkùnkùn, báwo ni òkùnkùn náà yóo ti pọ̀ tó!
Bí ọkunrin kan bá bá ẹranko lòpọ̀, pípa ni kí ẹ pa òun ati ẹranko náà.
Èyí ni ohun tí a mọ̀ nípa afurasí aláàrùn coronavirus nípìnlẹ̀ Enugu Aṣíwájú ni Nàíjíríà nínú ìdènà Coronavirus, ohun márùn-ún rèé tí àgbáyé ń kọ́ lára wa Àǹkóò àrùn coronavirus dé orílẹ̀èdè Togo Lọdun to kọja to pe ọdun mẹrindinlọgbọn, Pogba ṣe ikowojọ owo to le ni ẹgbẹrun meje Pọhun, fun ajọ kan to n pese omi to mọ fun awọn to nilo o rẹ.
Ṣugbọn àwọn ọmọ yín tí ẹ sọ pé ogun yóo kó, ni n óo mú dé ilẹ̀ náà; ilẹ̀ tí ẹ kọ̀ sílẹ̀ yóo sì jẹ́ tiwọn.
O ṣalaye pe ẹni to fẹ ẹ ṣe oniduro gbọdọ mọ ẹni to n jẹjọ daadaa, titi de ile ati ẹbi rẹ.
Kìí mú ojú kúrò lára àwọn olódodo,ṣugbọn a máa gbé wọn sórí ìtẹ́ pẹlu àwọn ọba,á gbé wọn ga,á sì fi ìdí wọn múlẹ̀ títí lae.
” Dafidi bá tú wọn kúrò lára rẹ̀.
gbodo gbiyanju lati maa je asiwaju rere nile Afirika.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Akọsilẹ fihan pe lasiko eto idibo gbogbogboo to waye ni ọdun 2019, awọn obinrin to kopa ninu ibo sile asofin agba jẹ ojilerugba o din mẹjọ (232), tile asoju-sofin jẹ ojilelẹẹdẹgbẹrun o din mẹjọ ( 532), nigba ti mejilelọgbọn (32) tiraka lati di gomina ipinlẹ.
Michelle Obama, Theresa May, Bíṣọ́ọ̀bù Curry ránṣẹ́ ìkíni kú oríire sí Harry àti Meghan Lẹyin ti aafin ilẹ Gẹẹsi ti kede ibi ọmọ ọkunrin tuntun fun ọmọọba Harry ati aya rẹ Meghan, wọn ti gbe iwe ikede ibi rẹ siwaju aafin Buckingham palace bayii.
N óo tún fún un ní ìràwọ̀ òwúrọ̀.
Òtítọ́ inú òfin ilẹ̀ Nàìjíríà nípa asòfin tó bá jẹ́ ọmọ orílẹ̀èdè méjì?
Ìgbín ní èmi àti ìyá mi máa ń he kiri, ká tó lee jẹun - Lizzy Anjọrin Ìtàn tó rọ̀ mọ́ òwe ‘aṣọ kò bá Ọ́mọ́yẹ mọ́.
Wọ́n ń tún fẹ́ẹ́ padà sí ipò wọn ìṣáájú, nígbà tí ó sì fi máa tó ọdúun mẹ́ta lẹ́hìn èyí  igbe ti gba gbogbo inu ayé kankan.
"Kikuna lati mu awọn apaniyan naa sita, ko ni ṣi nkan mii fun wa lati ṣe ju pe ka daabo bo awọn eniyan wa lọ, ka si le gbogbo awọn ọdaran Fulani darandaran kuro laarin wa.
Ẹwẹ, Fathia gbe fiimu kan jade laipẹ eyi to mu ohun ati Saheed Balogun ko'ra wọn loore koore gẹgẹ ajumọ ṣere ifẹ pọ lori itage.
Ri dáju pé ò kí ń wo fọ́nran orin, eré tàbi ǹkan míràn pẹlú dátà rẹ, ọ̀nà abáyọ ni láti kọ́kọ́ gbàá sílẹ̀ kí ó to wòó, pàápàá jùlọ ti ó ba ri ànfàni Wi-Fi.
Mo dáríjì àwọn IPOB tó nà mí ní Germany nítorí wọn o m'ohun tí wọ́n ń ṣe- Ekweremadu Ọlọ́pàá Ogun gb'ọmọ Ìmáàmù lọ́wọ́ ajínigbé, ṣùgbọ́n wọ́n gbé ọkọ̀ ojú omi ọlọ́pàá lọ Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
O tẹ siwaju pe, pẹlu eniyan bii miliọọnu mẹfa ati ẹgbẹrun lọna ẹgbẹfa-le-mẹsan-an ati marundinlọgọfa (6,609,115) ti wọn wọn lẹtọọ ati dibo ni Ipinlẹ Eko, o ṣe pataki lati ṣe idasilẹ alekun awọn ibudo idibo kekere yii, lati le ṣadinku akoko ti awọn ondibo yoo maa lo lati dibo.
gbogbo bi igbẹjọ pẹlu Alfa Babatunse si se n lọ si lati sawari ọmọ naa ni BBC n mu wa fun yin.
Àbẹ́wò ọlọ́jọ́ mẹ́ta Trump sí UK nínú àwòrán Ganduje ń bèèrè bí Emir Sanusi ṣe se owó ìlú mọ́kumọ̀ku ‘Buhari gbà wá o, Seyi Makinde n fi jàǹdùkú halẹ̀ mọ́ wa láti kúrò lọ́ọ́fìsì’ Ẹ dákẹ́ àhesọ ọ̀rọ̀, n kò bí ìbẹta - Yinka Ayefẹlẹ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Odebiyi: ìgbà gbogbo ni Bàbá mi ń polówó iṣẹ́ mi fáráyé Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Boya eyi si lo faa, ti awọn ohun to jọ mọ imọ ijinlẹ nipa isẹda ẹya ara obinrin ko se fi bẹẹ wọps lori itakun agbaye.
Ofin orilẹede Naijiria, ẹka Section 29 (4) (b) ti ọdun 1999 fi lede wi pe obinrin ti wọn ba ti gbe ni iyawo ti da agbalagba niyẹn.
Bi iya Taiwo se wọle wa, lati da ọmọ rẹ lohun, ni Taiwo yii fi igi nla, ẹrọ ilọsọ (iron) ati ẹrọ to n tan ina si idi Kọmputa, (UPS) gbaa lori lọna ati ri daju pe iya rẹ ko ye isẹlẹ naa.
Naira Marley, Burna Boy àti Rema ló kó àmì ẹ̀yẹ tó pọ̀jù ló ni MVP Ibo gomina Ipinlẹ Sokoto Oludije ibo gomina fẹgbẹ oṣelu APC nipinlẹ Sokoto, Ahmad Aminu Waziri lo pe gomina Aminu Waziri Tambuwal to jawe olubori ninu ibo gomina ipinlẹ naa.
Apá ìwọ̀ oòrùn tí ó jẹ́ ẹgbaa meji ó lé ẹẹdẹgbẹta (4,500) igbọnwọ (mita 2,250), yóo ní ẹnubodè mẹta.
“Ninu gbogbo ilẹ̀ tí ó wà ní ìkáwọ́ yín, ẹ gbọdọ̀ fi ààyè sílẹ̀ fún ẹni tí ó bá fẹ́ ra ilẹ̀ pada.
Àánú wọn ṣe Jesu, ó bá fi ọwọ́ kàn wọ́n lójú.
•Sise bẹẹ yoo mu ki o gbe ọ lọ si ibi ti o ti jẹri pe lootọ iwọ lo ni e-mail •Bi o ba se eyi tan, o ni lati kọ nọmba idanimọ ile ifowopamọ BVN rẹ ati ọjọ ibi rẹ (dd/mm/yr) •Abala iroyin nipa rẹ ati oju opo ikansiraẹni:kọ orukọ baba rẹ, orukọ rẹ bo ti se wa lori nọmba BVN rẹ •Abala iwe ẹri ẹkọ ati eto miran: labala yi, o le kọ ọ sibẹ boya o kawe gboye tabi o lọ si ile ẹkọ rara.
Mo wòye pé a kò lè fi ìyà ayé yìí wé ọlá tí Ọlọrun yóo dá wa ní ayé tí ń bọ̀ wá.
Igbayi lo to o ye mi pe gbogbo awọn apẹrẹ ti mo n ri lati bi oṣu melo kan, ati bi ara mi kii ṣe fi gbogbo igba ya jẹ apẹrẹ aarun HIV.
Wo ohun tó yẹ kí o mọ̀ nípa olórin tí wọ́n dájọ́ ikú fún ní Kano Oríṣun àwòrán, Idris Ibrahim Ọjọ Aje, ọjọ kẹwaa, oṣu Kẹjọ, ọdun 2020 ni ile ẹjọ kan ni Kano se idajọ iku fun ẹnu ọdun mejilelogun kan lori ẹsun pe o bá orúkọ Anọbi Muhammed jẹ́.
OLUWA, kọ́ mi ní ìlànà rẹ,n óo sì pa wọ́n mọ́ dé òpin.
 Aadọrun atipo ri s'omi ni Libya Ipinlẹ Ọsun gba awọn ọmọ rẹ pada lati Libya O tẹ siwaju wipe, 'A ti mulẹ ki a to kuro lorilẹede Naijiria."
gbogun ti iwa adigunjale ati odaran lorile ede Naijiria iyen Special Anti
L'Ọjọbọ ni Oluwo fun ile ifowopamọ Access Bank ni ọjọ kan pere, lati ṣe awari oṣiṣẹ rẹ to ṣ'okunfa bi ẹgbẹlẹgbẹ owo fi ranṣẹ si mama rẹ ṣe poora, ki wọn si da owo naa pada ni kiakia.
(Ninth player to reach 150 English Premier League goals).
Adajọ Ilelah tun fikun pe ọlọpa lo kuna lati fi idi ẹri to giriki mulẹ pe lootọ ni Abbo fiya jẹ Warmate.
Ìwọ ni OLUWA fi òróró yàn ní ọba wọn.
yóo sì di eruku lẹ́búlẹ́bú lórí gbogbo ilẹ̀ Ijipti, yóo di oówo tí yóo máa di egbò lára eniyan ati ẹranko, ní gbogbo ilẹ̀ Ijipti.
Nisinsinyii ẹ mọ Ọlọrun, tabi kí á kúkú wí pé Ọlọrun mọ̀ yín.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Buhari buwọ́ lu òfin ọ̀dọ́ leè dupò 'Àwọn ọba, olóṣèlú ń ṣe ẹgbẹ́ òkùnkùn' Sé Dino Melaye ti bọ́ sẹ́gbẹ́ PDP ni ?
" Pẹlu ero pe adigunjale ni awọn eeyan wọnyii ni mo fi ni ki awọn ọlọpaa o gba tẹle wọn ti wọn si mu wọn.
Aarẹ Buhari ni adinku ti de ba ọwọja wahala awọn ikọ agbebọn Boko Haram naa, lati igba ti oun ti de ori oye ni ọdun 2015.
Ko fi bẹẹ si ẹnikan to mọ eredi ti ija fi bẹ silẹ ni ọja naa, titi di asiko ti a ṣe akojọpọ iroyin yii.
Àwọn tí o ń lu ìlù tí wọn ń jó ni wọ́n wà níwájú pátápátá.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Boko Haram 601 parí iléẹ̀kọ́, ìjọba yóò san ₦20,000 lóṣù fún ẹnì ìkọ̀ọ̀kan Aráàlú faraya torí èèyàn 63 tó dèrò ọ̀run ní Gúúṣù Kàdúná láàrin ọ̀sẹ̀ kan Hospital Wedding: Oṣù kan péré ni Tash fi ṣe ìgbéyàwó pẹ̀lú Simon kó tó kú Èèyàn 11 kú, èèyàn 438 míràn tún kó COVID-19 ní Nàìjíríà l'Ọ́jọ́ Àbámẹ́ta Bí o ṣe lè forúkọ silẹ̀ fún ètò N75BN Nigerian Youth Investment Fund"" rèé."
“Kí ó lè dára fún ọ, ati kí o lè pẹ́ lórí ilẹ̀ náà.
"Oríṣun àwòrán, Instagram/sanyeri12 ""Ere apanilẹrin ni ode inawo ni emi ati Kamilu Compo maa n lọ ṣe nigba ta kọkọ de Eko, ta si n ri owo diẹ-diẹ, kii ṣe agbe taarata amọ a a fi awada tọrọ owo."
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Bose Okeowo: Àárẹ̀ kékeré ló sọ mi dí aláàbọ̀ ara yìí ṣùgbọ́n.
Bí bàbá-à mi sì ṣe sọ ìtàn yìí fún mi ni ń ò ṣe sọ́ fún-un yín lónìí yìí ẹ̀yin ọ̀rẹ́-ẹ̀ mi.
Modekai di eniyan pataki ní ààfin; òkìkí rẹ̀ kàn dé gbogbo agbègbè, agbára rẹ̀ sì ń pọ̀ sí i.
Bí ó bá jẹ́ pé ẹ̀yà kan ṣoṣo ni gbogbo ara ní, níbo ni ara ìbá wà?
O sọ pe ọrẹ ni Adamu Adamu ati Hammed Ali jẹ si Aarẹ Buhari.
Ẹnikẹ́ni tí kò bá gbọ́ràn sí wolii náà lẹ́nu, píparun ni a óo pa á run patapata láàrin àwọn eniyan Ọlọrun.
Kí Ọlọrun, tí ó yan Jerusalẹmu gẹ́gẹ́ bí ibi ìsìn rẹ̀, pa ẹni náà run, kì báà ṣe ọba tabi orílẹ̀-èdè kan ni ó bá tàpá sí òfin yìí, tí ó sì ń wá ọ̀nà láti wó ilé Ọlọrun tí ó wà ní Jerusalẹmu.
Lẹ́yìn náà ni Dafidi ati gbogbo àwọn eniyan tí wọ́n wà pẹlu rẹ̀ gòkè odò Jọdani.
Ooni ti Ile Ifẹ nibi ojumọ gbe mọ wa sile aye ree to gunwa lori itẹ awọn baba nla rẹ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Abule Ado explosion: Irọ́ ńlá ní NNPC pa lórí ìbúghbàmù Abule Ado níbí tí ẹ̀mí èèyàn 23 Eyi tumọ si pe idajọ di oṣu to m bọ ko to waye lori awọn maraarun.
Aṣofin Gbolahan Yishawu, to n ṣoju ẹkun idibo Eti Osa keji lo daba yii, to si sọ pe ijọba daba lati na biliọnu mẹtadinlogun naira (₦17b) lati ra awọn ọkọ wọn yii, ninu aba isunna ọdun 2017 ṣugbọn ile ko buwọlu.
 e jé kí á wá wo bí gírámà yìí se ń sisé .
 Èyí ló fà á tí wón fi ńpe ilé yìí ní ilé búoyè .
oloro pa awon alaisẹ ni ipinle Borno.
Wọn kò gbọdọ̀ fẹ́ opó tabi obinrin tí ọkọ rẹ̀ kọ̀ sílẹ̀, àfi wundia tí kò tíì mọ ọkunrin láàrin àwọn eniyan Israẹli tabi opó tí ó jẹ́ aya alufaa.
Láìpẹ́, ìkùukùu bo gbogbo ojú ọ̀run, afẹ́fẹ́ bẹ̀rẹ̀ sí fẹ́, òjò ńlá sì bẹ̀rẹ̀ sí rọ̀.
O ni eyi se afihan aigboraẹniye to wa ninu ijọba to wa lode.
Ilé-iṣẹ́ Agbóhùnsáfẹ́fẹ́ Ìbílẹ̀ Fagilé Ìfọ̀rọ̀wọ́rọ̀ pẹ̀lú àwọn ajìjàǹgbara LGBT lẹ́yìn ìhalẹ̀mọ́ sí olóòtú
Dájúdájú àwọn ọba mẹtẹẹta wọnyi ti bá ara wọn jà, wọ́n sì ti pa ara wọn, ẹ jẹ́ kí á lọ kó ìkógun ninu ibùdó-ogun wọn.
“Èmi kò ní fi yín sílẹ̀ bí aláìlárá.
Turnout : Eyi ni lati se akawe oye awọn eniyan
ìdí ni pe mo ti ri ti wọ́n ti lùú, mo ri ti wọ́n daa dúro, mo ti ri bi ẹjẹ̀ ṣe bòo', mo ri nibi to ti n sunkún, ẹmi gan náà yóò mu sunkun, èèyan ẹlẹran ara bi ti gbogbo aye ni.
Ẹni tí ó bá sì gbà mí, ó gba ẹni tí ó fi iṣẹ́ rán mi.
 Ìwà ìrẹ ̀ lẹ ̀ tí wikipedia fẹ ́ níṣe pẹ ̀ lú gbogbo àwọn olóòtú nígbà tí wọ ́ n bá ń bá ara wọn sọ ̀ rọ ̀ ní wikipedia , pẹ ̀ lú ọ ̀ rọ ̀ ní ojú ewé ọ ̀ rọ ̀ oníṣẹ ́ àtí ojú ewé ọ ̀ rọ ̀ àyọkà àti gbogbo ìjíròrò tàbí nípa àwọn ẹlẹgbẹ ́ rẹ tí ó jẹ ́ olùkọ wikipedia .
Ẹni tó n baa dije gẹgẹ bii igbakeji, iyẹn ọjọgbọn Durotoye Adeolu gan an lo tẹwọ gbà awọn aṣofin mẹta yii.
Nítorí náà, ìsinmi ọjọ́ ìsinmi wà nílẹ̀ fún àwọn eniyan Ọlọrun.
“Dìde, lọ sí ilé amọ̀kòkò, níbẹ̀ ni óo ti gbọ́ ọ̀rọ̀ tí mo fẹ́ bá ọ sọ.
Nítorí àwọn tí ó bá ń gbin nǹkan ti Ẹ̀mí yóo ká àwọn nǹkan ti Ẹ̀mí, tíí ṣe ìyè ainipẹkun.
Amọ asofin Owoeye ni ki Davido ma ti yọ ju nitori pe idaj naa ko tunmọ si pe Adeleke ti gba idajo lori ọrọ yi.
Erongba  ilana ohun ni lati tete mu igberu ba eka eto ogbin, nipa pipese eyawo fun awon olokowo nlanla, o kere tan owo ti o to aadota milionu Naira,  pelu ere ti ko ga ni lara, bi iko mesan-an ninu ida ogorun.
ENDSARS Protest: Akẹ́kọ̀ọ́ àti ọ̀gá iléèwé ń kérora torí ìdánwò NECO tó ṣún síwájú
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ayédèrú Ọ̀ṣun ni wọ́n ń bọ lónìí, kìí ṣe ojúlówó - Bàbá Ọlọ́ṣun tún figbe ta Ọ̀ṣun Oṣogbo 2019 gbéra, àwòrán bí ọdún ṣe ń lọ rèé Àṣìkà ìṣirò èsì ìbò ààrẹ nípìnlẹ́ẹ̀ 11, ló fa ìjákulẹ̀ mi - Atiku El-Zakzaky fi India sílẹ̀, níbo ni yóò dé sí ní Nàìjíríà?
Gideoni dá wọn lóhùn, ó ní “N kò ní jọba lórí yín, bẹ́ẹ̀ ni ọmọ mi kò ní jọba lórí yín, OLUWA ni yóo máa jọba lórí yín.
OLUWA yóo da wèrè, ìfọ́jú, ati ìdàrúdàpọ̀ ọkàn bò ọ́.
Idajọ ile ẹjọ waye lẹyin ti Fatoyinbo gbe ẹjọ kotẹmilọrun lati fi ẹsun kan Busola wi pe o ba orukọ oun je, ti o si puro mo oun lori esun ti busola fi kan oun.
Wo àwọn oúnjẹ márùn ún tó ń mú kí àtọ̀ ọkùnrin dára síi Wo àwọn ohun tí Amotekun kò ní le è ṣe mọ́ ní ìpínlẹ̀ Oyo.
Akeugbagold fikùn pé, òun ti ko awon nkan ti oun leè tá jáde, pé kí wọn lu wọn ní gbanjo, láti tètè rí owó gba.
    Nígbà tí ó rí ọkùnrin yìí, ó rẹ́rìn-ín músẹ́, eyín ẹnu rẹ sì funfun tó bẹ́ẹ̀ tí ó fẹ́rẹ̀ lè sọ ọmọkùunrin di wèrè, nígbà tí ó sì wo ọkùnrin náà lójú ó ṣe bí obìnrin àfẹ́sọ́nà ti n tíjú ọkọ rẹ̀ tuntun.
ko ga ju ọkan lọ lasiko ijọba rẹ, sugbon iwa oju-saaju lo n wu bayii ni awon apa kan lorile ede yii.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Akọ́mọlédè àti Àṣà lórí BBC Yorùbá: Kọ̀ síi nípa iṣẹ́ tí oúnjẹ ń ṣe lára níbí Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí India Wedding: Ìyàwó kan ní India wọ sòkòtò fún ayẹyẹ ìgbéyàwó rẹ̀- Wo ìdí tó fi ṣe bẹ́ẹ̀25 Bélú 2020 Senator Ishaku Abbo: ìdí rèé tí mò fi fi kọ̀wé fi PDP sílẹ̀ darapọ̀ mọ́ ẹgbẹ́ òṣèlú APC25 Bélú 2020 Maina N2bn Fraud: Agbẹjọ́rò Maina yọ ọwọ́ nínú ìgbẹ́jọ́, Ó lóun kò ṣé mọ̀25 Bélú 2020 Free Pad: Scotland ti di orílẹ̀-èdè àkọ́kọ́ tó bẹ́rẹ̀ pínpín páàdì ǹkan osu fún gbogbo obìnrin lọ́fẹ̀ẹ́25 Bélú 2020 Fídíò, International Day for Elimination of Violence against Women: Àlùfáà Joel Olugbenga: Bíbélì kò ní kéèyàn dúró títí ọkọ rẹ̀ yóò fi lù ú pa25 Bélú 2020 Elon Musk, Ọ̀gá àgbà iléeṣẹ́ SpaceX, Tesla CEO ń bá Bill Gates du ipò ẹni tó lówó jùlọ ṣèkejì lágbayé26 Bélú 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Ogun ati ìyàn ni yóo pa wọ́n run, òkú wọn yóo sì di oúnjẹ fún àwọn ẹyẹ ati àwọn ẹranko.
Nígbà tí Solomoni gbọ́ pé Joabu ti sá lọ sinu Àgọ́ OLUWA, ati pé ó wà lẹ́gbẹ̀ẹ́ pẹpẹ, Solomoni rán Bẹnaya kí ó lọ pa á.
Bí o tilẹ̀ fò lọ sókè bí ẹyẹ idì,tí ó tẹ́ ìtẹ́ rẹ̀ sí ààrin àwọn ìràwọ̀,láti òkè náà ni n óo ti fà ọ́ lulẹ̀.
Kò sóhun tó ń jẹ́ 'Captivus' nílẹ̀ Oodua, mágùn ni mágùn ńjẹ́ - Babaláwo Ni ọjọ diẹ sẹyin, fidio kan lu ayelujara pa nibi ti ọkunrin ati obinrin kan ti lẹpọ nibi ibalopọ, ti nnkan ibalopọ wọn ko si lee yọ kuro ninu ara wọn.
Ọkàn mi kò ní alaafia,mo ti gbàgbé ohun tí ń jẹ́ ayọ̀.
Àwọn mààlúù wọn ń gùn,wọ́n sì ń bímọ ní àbíyè.
 hughes gbajumo fun awon iwe re to ko nigba harlem renaissance .
Ọlọrun ni ó sọ fún un pé,“Ìwọ ni Ọmọ mi,lónìí ni mo bí ọ.
Ilé aṣòfin Amẹ́ríkà yarí Oríṣun àwòrán, Getty Images Olori ile aṣofin ilẹ Amẹrika, Nancy Pelosi ti bẹrẹ igbesẹ lati mu ki igbakeji aarẹ, Mike Pence ṣiṣẹ lori yiyọ aarẹ Donald Trump nipo.
 oju meji Ọgbọọgba lo sì nì .
“Nítorí pé èmi, OLUWA àwọn ọmọ ogun ni mo sọ ọ́ pé láìpẹ́, n óo tún mi ọ̀run ati ayé jìgìjìgì lẹ́ẹ̀kan sí i, ati òkun ati ilẹ̀.
Ọlọrun ti fi ìlú yín sílẹ̀ fun yín!
Awọn miran gbagbọ pe jijẹ Ṣokoleeti dudu tabi to ti jona diẹ maa n fi kun adùn ibalopọ: Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Awọn onimọ sayẹnsi ni jijẹ ṣokoleeti dudu yoo jẹ ki ina ifẹ romjo sii Ọpọlọpọ lo gbagbọ pe ti awọn ba n jẹ ṣokoleeti ti o jẹ ohun adidun lati inu kòkó maa n jẹ ki ololufẹ meji tubọ gbadun ara wọn sii.
Wọ́n ṣẹgun ìlú Aṣikeloni ati Ekironi ati àwọn ìlú tí ó wà ní agbègbè wọn.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Beauty tips: Ṣé ẹ gbà pé obìnrin lè kun ojú láàrín ìṣẹ́jú mẹ́ta?
Awọn mejeeji naa, ti wọn lọ lo isinmi wọn ni orilẹ-ede Amẹrika lo se alabapin awọn aworan ti wọn ya pẹlu baba wọn nibẹ.
Oríṣun àwòrán, Facebook/Ibrahi Magu Laolu Akande wa salaye pe, igbakeji aarẹ ni oun ko ni faaye gba irufẹ awọn iroyin eke yii lati si i oun lọna nidi sise isẹ ilu bo se yẹ.
Ọmọ ọdún 23 jẹ́wọ́ bó ṣe pa ẹ̀gbọ́n ìyá rẹ́, ẹni ọdún 60 nípinlẹ̀ Ogun Wo nǹkan tí ìjọba àpapọ̀ yóò ṣe fáwọn tó ń ta 'pẹlẹbẹ', 'pàrágà' àti 'fònàgáú' Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
“Mo fi ara mi búra, dájúdájú, tipátipá, pẹlu ibinu ati ọwọ́ líle ni n óo fi jọba lórí yín.
Nibayii, o tumọ si pe gbogbo awọn mẹtẹẹta to wa ninu ẹlikọpita naa lo ti ku.
Ìjà orogún méjì ní London, Arsenal àti Tottenham ta ọ̀mì Kọmiṣọna Omotosho ṣalaye pe iwa ọdaran ti dinku nipinlẹ Eko lati igba ti ijọba ti da ajọ pataki kan silẹ.
" Nigba to n sọrọ lori ajọsepọ rẹ pẹlu gbajugbaja oṣere tiata lobinrin kan, Iyabo Ojo, ti ẹnu n kun awọn mejeeji pe ọrọ ifẹ ikọkọ wa laarin wọn; Muka Ray ni awọn mejeeji dijọ n ṣíṣẹ papọ ni amọ araye ro pe awọn n fẹ ara awọn ni.
 Ẹ ba awọn akọwe agba ati olri ileeṣẹ gbogbo to wa labẹ yin ṣiṣẹ pọ daadaa."
Àwọn eniyan burúkú bíì rẹ, ni ẹ̀ṣẹ̀ rẹ lè pa lára,àwọn ọmọ eniyan ni òdodo rẹ sì lè jẹ́ anfaani fún.
Ṣugbọn oluranlọwọ fun Sẹnẹtọ Adeleke lori eto iroyin, Bamidele Salami to ba BBC Yoruba sọrọ ṣalaye pe idajọ naa ko lẹsẹ nilẹ rara ati pe ajọ idanwo iwe mẹwaa ti a mọ si WAEC ti bura nile ẹjọ pe Ademola Adeleke ṣe idanwo aṣejade naa.
Nítorí náà, bíi kinniun ni n óo ṣe si yín, n óo lúgọ lẹ́bàá ọ̀nà bí àmọ̀tẹ́kùn; 
Bí mo bá sọ pé n óo gbé orílẹ̀-èdè kan dìde, n óo sì fi ìdí rẹ̀ múlẹ̀; 
jẹ́ ẹgbaa mẹtadinlogun ó lé egbeje (35,400).
Lori ẹrọ ayelujara, akẹkọ naa ti orukọ rẹ n jẹ Ṣẹgun gbe awọn maaki rẹ to ti gba sẹyin ninu idanwo JAMB lati igba to ti n ṣe e sita.
Lẹyin naa lo kilọ fun un pe ko gbọdọ sọ fun ẹnikẹni, ti ko ba fẹ ẹ ku.
Lẹyin ti ọwọ tẹ wọn tan, ni awọn oṣiṣẹ aṣọbode tun rii wi pe oogun Tramadol tun kun inu agolo ikẹru si, ti wọn n pe ni ''container'' bamu.
" Oríṣun àwòrán, @victoryomogiate Victory ni ki ẹnikẹni mase da oun lẹjọ nitori wọn ko mọ isoro ti oun n la kọja lati bi ọdun kan sẹyin, to si tun fi aworan ti oun ati Cute Abola ya soju opo Twitter rẹ́, lasiko ti ọrọ wọn wọ.
Lára àwọn ọmọ Asafu wọ́n yan Sakuri, Josẹfu, Netanaya, ati Asarela; wọ́n wà lábẹ́ àkóso Asafu, wọn a sì máa sọ àsọtẹ́lẹ̀ lábẹ́ àkóso ọba.
 Makinde ni ohun to tọ ni pe ki onikaluku tẹle sayẹnsi."
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ogoni 9 execution anniversary: Ta ni Ken Saro-Wiwa tí ìjọba ológun sekúpa?
yara –ikawe fun eka  imo irin ati ile eto
OLUWA yóo ta okùn ìdàrúdàpọ̀ lé e lórí,yóo sì na ọ̀pá ìdàrúdàpọ̀ lé àwọn ìjòyè rẹ̀ lórí.
Ninu esi idibo awọn ijọba ibilẹ ti wọn kọkọ ka, APC moke ninu ijọba ibilẹ mejidinlogun to wa ni Ondo.
Bẹ́ẹ̀ ni n óo ṣe sí ìlú yìí ati àwọn tí wọn ń gbé ibẹ̀.
Ọmọ Mamman Daura ni Fatima Daura to jẹ ọmọ ẹgbọn aarẹ Buhari.
Ọ̀rẹ́ mi tíó ń gbé etí ilé mi kò ní eépìnní rí, baba ìyàwó rẹ̀ ní ó sọ ọ́ di ènìyàn, tí ó fi owó ńlá dúró fún un lọ́dọ̀ Òyìnbó,ìgbà tí mo sì rí tọkọ-taya náà láì pẹ́ yìí, ṣe ni àwọn mejèèjì fẹ̀hìntì sí inú mọ́tò ayọ́kẹ́lẹ́ tí wọ́n ń lọ gẹ́gẹ́ bí ọba.
Ẹni tí ó bá fèsì tí ó tọ́dàbí ẹni tí ó fi ẹnu koni lẹ́nu.
Awọn iroyin miran ti ẹ le nifẹ si: Dino Melaye f'oju ba'le ẹjọ Yusuf Buhari pada de lẹyin itọju lẹyin odi Ijọba apapọ taare ọga ọlọpa si Yobe Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Bakan naa si ni ero igbalode fonran se afihan opo eniyan ti won sa asala fun emi won lati gba eba ona pajawiri jade loIroyin miran tun fi mule pe, awon eniyan miran tun fo ferese ile ohun jade lati sa asala fun emi won.
O fi kun pe ẹni keji ni ọmọkunrin kan ti ọjọ ori rẹ ti le ni aadọta ti ko rinrinajo lọ si ibikibi.
Ati pe eyi ni lójùnà àti mú ìjọba awa ara wa gbẹ̀rú síi.
Ara rẹ ko ni jọlọ daada: Omi maa n jẹ ki ara tutu to si maa mu ki awọn sẹẹli awọ ji pepe, ki si dabi ti ọmọ tuntun.
Kii ṣe ootọ pe ere yii lo gbe ogo mi jade'' Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Gbajúgbajà òsèré tó tún mọ́ ọbẹ̀ sè Nipa ọjọ manigbagbe nigbesi aye osere yii, Iya Oṣogbo ni ọjọ ti ololufẹ ere awọn kan fẹ ẹ fi ọkọ gba awọn da si gọta nilu Ibadan ni nitori inu rẹ to dun julọ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Owu Water Falls: Ọba Oyewole ni ibùdó ìrìn àjò afẹ́ gidi ni àmọ́ ọ̀nà ibẹ̀ burú jáì Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Owu Water Falls: Ọba Oyewole ni ibùdó ìrìn àjò afẹ́ gidi ni àmọ́ ọ̀nà ibẹ̀ burú jáì 29 Ọ̀wàrà 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 1 Ògún 2020 Awamaridi ni isẹ Olodumare, to ba se ojo, a se ọda, a se ọkan a mu bi otutu, a se omiran, a mu bi ọyẹ.
@peterparne ni tiẹ sọ pe awọn meji lo n tako alaafia ati iṣọkan orilẹede Naijiria lẹyin to kọkọ ki wọn ku iṣẹ.
Demilade Adepegba: Mo má a ń gbàgbé fèrè ni, tí mo bá wà nílé ìwé
O fi kun un ọrọ rẹ pe ọmọ naa ti n gba itọju nileewosan bayii, ti iwadii si n lọ.
Nítorí pé ọba gbẹ́kẹ̀lé OLUWA;a kò ní ṣí i ní ipò pada,nítorí ìfẹ́ Ọ̀gá Ògo tí kì í yẹ̀.
Yóo dàbí obinrin tí wọ́n tú sí ìhòòhò,tí ó jókòó ní ilẹ̀ẹ́lẹ̀.
Àwọn ìlú rẹ̀ yóo di àkọ̀tì títí laewọn yóo di ibùjẹ àwọn ẹran,níbi tí àwọn ẹran yóo dùbúlẹ̀,tí ẹnikẹ́ni kò sì ní dẹ́rùbà wọ́n.
isipopada lati isejoba ologun si ijoba tiwa-n-tiwa jẹ okan lara aseyori
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Wo ìtumọ̀ àti pàtàkì ọ̀pọ̀ oyè ẹ̀ṣìn nínú Islam 5 Òkùdu 2020 Oríṣun àwòrán, others Àkọlé àwòrán, Mùsùlùmí tó ń gbèrò láti lọ hajj ni Alhaji, Alhaja - Onímọ̀ Kii ṣe ohun tuntun rara lati ri apemọ orukọ Alhaji ati Alhaja lẹyin orukọ awọn eeyan to ba ṣẹṣẹ ti ilẹ mimọ hajj de.
Oríṣun àwòrán, @seyiamakinde O fikun pe kìí ṣe gbogbo ẹní to ba kéré lọ́jọ́ orí náà ni ọpọlọ rẹ̀ kéré, nítorí náà, tọ̀wọ̀-tọ̀wọ̀ ní òun yóò máa fi ba gbogbo àwọn àgbààgbà ilé isẹ̀ náà ṣe.
Kí ló wà láàrin Olorì Badra àti Bobrisky, tí ọ̀rọ̀ wọn fi wọ̀?
Baruku ń kọ ohun tí Jeremaya ń sọ sílẹ̀ bí Jeremaya tí ń sọ̀rọ̀.
Agneroh: Ohun gbogbo tí ẹ bá rí lórí ẹ̀rọ ayélujára kọ́ ni òtítọ́
Olόyè Ògbójú kò náání ẹnikẹ́ni lόde ayé, ό sì burú tό bẹ́ẹ̀ gẹ́ẹ́ tí kò sí ẹni tí ό ńsọ̀rọ̀ Ọkùnrin náà dára nílé lόko.
Egbe osise lorile ede Naijiria ti pinnu lati bere iyanselodi alailojo ni ojo kefa osu kokanla, odun ti a wayii, ti ijoba apapo ba kunna lati mu ipinnu won se nipa sisan ekunwo ogbon egberun naira, ni eyi ti won fenuko le lori.
Iranwọ ti mo ṣe ko le fd ọwọ ago pada sẹyin gẹgẹ bi Mukankuranga ṣe sọ Oríṣun àwòrán, Natalia Ojewska Àkọlé àwòrán, Ruwanda Genocide: Obi ni mi - mo pa obi awọn ọmọ wẹwẹ O jẹ ọkan lara awọn obinrin ẹgbẹrun mẹrindinlọgọrun ti ijọba ju sẹwọn fun ipa wọn ninu ipaniyan abẹle Ruwanda- awọn miran pa agbalagba bi ti Mukankuranga awọn miran p ọmọ wẹwẹ, nigba ti awọn kan fi anfani naa fipa bawọn eniyan lopọ ti wọn si tun gbẹmi wọn.
Wọ́n bá bẹ̀rẹ̀ sí wá ọ̀nà láti mú un, ṣugbọn ẹnikẹ́ni kò fi ọwọ́ kàn án nítorí àkókò rẹ̀ kò ì tíì tó.
Nígbà tí Lamẹki di ẹni ọdún mejilelọgọsan-an (182), ó bí ọmọkunrin kan.
'Ọkọ mi yọ kindinrin mi lati rọpo owo ori' Ìjí líle, Cyclone Fani, kọlu Ìlà-Oòrùn India Ọlọ́wọ́ idán Houdini kò yè é o, ó bómi lọ!
Àjọ tó ń mójútó àyíká l'Eko mú 123 ọlọ́kadà tó ń bọ̀ láti Jigawa Ibeere nla ti awọn eniyan ipinlẹ Eko n beere ni pe kini gbogbo wọn fẹ wa ṣe ni Eko?
Ẹni tí ó fẹ́ ìtọ́sọ́nà, ó fẹ́ ìmọ̀, ṣugbọn ẹni tí ó kórìíra ìbáwí òmùgọ̀ ni.
6m lórí ètò BBNaija torí pó sọ̀rọ̀ ìwúrí nípa Nàíjíríà Bí mo ṣe dúró ti Toyin nílé ìgbẹ̀bí jẹ́ kí ń mọ̀ pé ó yẹ kí ọkùnrin máa bọ aya wọn - ọkọ Toyin Abraham Iṣẹ́ ọpọlọ ló yẹ ká ṣe nínú tíátà, kìí ṣe àfihàn ara bíbó àbí ìhòòhò wa - Binta Mọgaji O fikun pe lara awọn eeyan meji si mẹta ti oun mọ, to n nawo fi gbọ bukata ẹgbẹ to n ja fun ifẹsẹmulẹ ijọba alagbada lorilẹede Naijiria (Nadeco) nigba naa, ni Bọla Tinubu wa.
"Iwe ìpéjọ sọ pe o ti ṣa lọ.
PDP: Ilé aṣòfin àti Gómìnà Kwara kùnà pẹlú yíyọ àwọn alága ìjọba ìbílẹ̀
Kii din ni 3,600 owó Bitcoin tuntun to n jade lojumọ.
Osanyintolu ni iṣẹlẹ naa waye ni agbegbe Aso-Odo, Badagry ni ipinlẹ Eko ni Ọjọ Iṣẹgun.
Ogbeni Onyeama  so pe ,oun lọ soju aare orile ede Niajiria,Muhammadu Buhari ni orile ede Sao Tome ati  Principe  nipa ona ti won yoo gba lati pese  eto iranwo ise akanse fun  orile ede naa .
Ṣeyi Makinde fòfin de ẹgbẹ́ NURTW Ọyọ, ó gbàkóso gáréjì ọkọ̀ Èèyàn méjì tó ń gbọ́n epo bá ìṣẹ̀lẹ̀ ọkọ̀ epo tó gbiná rìn n‘Ibadan Wo àwọn ìlérí tàwọn Gómìnà tuntun ṣe nínú ìbúra wọn Sìgá mímu ń di èèwọ̀ oògùn ìlera pípé lagbaye Ki i tun ṣe eyi nikan, àwọn ijọba China ni afara ori omi to gun ju ni agbaye to wa ni orilẹ-ede China kò ná wọn ju triliọnu meje o le diẹ lọ.
Nígbà tí ó yá Lamẹki pe àwọn aya rẹ̀, ó ní:“Ada ati Sila, ẹ tẹ́tí sílẹ̀,ẹ̀yin aya mi, ẹ gbọ́ mi ní àgbọ́yé:Mo pa ọkunrin kan nítorí pé ó pa mí lára,mo gba ẹ̀mí eniyan nítorí pé ó ṣá mi lọ́gbẹ́.
””Opolopo orile-ede jake-jado lo tin se amulo kemika epo robi, bi a ba wo bi a se n pese ohun ipese gassi to lorile-ede yii, asiko ti wa to wayii fun orile-ede Naijiira lati darapo mo won.
Ṣugbọn ipẹyinda iṣẹlẹ yii ni pe, awọn ololufẹ Wunmi Toriola ati Seyi Edun sakiyesi pe aawọ abẹnu ti n waye laarin awọn oṣere tiata mejeeji, eyi to si fi idi mulẹ lasiko ti Seyi Edun ṣe ọjọ ibi.
Gbogbo ilu ni wọn sọ ina si, ti wọn si ko awa ti wọn mu lẹru gba ilu Isẹyin lọ, eyi to to ogun maili si ilu wa, ti mo si juwọ si ilu abinibi mi pe, o digbose, o tun di aye atunwa.
Aare orile-ede South Africa, Cyril Ramaphosa ti yan gomina teleri fun ile-ifowopamo agba orile-ede ohun, Tito Mboweni gege bi minisita tuntun ti yoo maa mojuto eto isuna lati ropo Nhlanhla Nene ti won fi esun iwa ibajẹ kan.
Kehinde ni o yẹ ki ijọba ṣe awọn nkan ti Abiola ku fun si ilu.
Mose sọ fún àwọn ọmọ Israẹli pé, “Èyí ni ilẹ̀ tí ẹ óo fi gègé pín.
Tori ìdí èyi gàn ni mo ṣe ṣe àkojọ àwọn orin to ni ṣe pẹlu imọ ìṣiro fun àwọn ọmọ ilé-iwé alakọbẹ̀rẹ̀."
Àwọn ọmọ Naijiria fèsì sí Osinbajo tó ṣetán láti wàákò pẹ̀lú Timi Frank Ìpè orí fóònù tó mú kí America fẹ́ yọ ààrẹ Trump rèé Ẹ̀yin baálé ilé, ẹ yé sá tẹ̀lé mi kiri mọ́!
Wayi o, gbogbo awọn akẹẹgbẹ rẹ lagbo tiata ni wọn ti n dawọ idunnu pẹlu rẹ, ti wọn si n ki pe o ku ewu ọmọ.
Ọjọ Iṣẹgun ni Aaarẹ gbe aba iṣuna to le ni tiriliọnu mẹwaa lọ siwaju ile aṣofin agba l'Abuja.
Àkọlé àwòrán, A ò ṣe àyọnusọ lóri ọ̀rọ̀ abẹ́lé Nàìjíríà-UK Ǹjẹ o mọ bí 'April Fool's Day' se bẹ̀rẹ̀?
Kí ẹni tí wọ́n fẹ́ wẹ̀ mọ́ náà fọ aṣọ rẹ̀, kí ó fá irun rẹ̀, kí ó sì wẹ̀, yóo sì di mímọ́.
Àwọn kan ninu àwọn ọmọ Lefi jẹ́ akọ̀wé, àwọn kan wà nídìí ètò ìsìn, àwọn mìíràn sì jẹ́ aṣọ́nà.
Aṣoju Kanye West to ba ileeṣẹ iroyin CNN sọrọ ni owo naa wa idile Floyd, Ahmaud Arbery ati Breonna Taylor.
Israel Adesanya fi ẹ̀ṣẹ́ mú ẹ̀jẹ̀ jáde nímú Whittaker láti gba àmì ẹ̀yẹ UFC Tottenham tasẹ̀ àgẹ̀rẹ̀ bí Tacha fara káásá ìyà lọ́wọ́ Brighton Ta ni yóò gba ₦60m lónìí láàrin olùdíje márùn-ún tó kù nílé BBNaija?
4)Pàtàkì ọjọ Arafat: Ọjọ àpéjọ ní ọjọ yií jẹ fawọn Alalaaji, tí àkọsílẹ sí wa pé ẹni tí kò bá b'awọn lọ sí Arafat kò ní Hajj.
Ajọ NAFDAC ni awọn yoo ṣe ayẹwo agbo coronavirus ti Madagascar fi ranṣẹ si Naijiria ni kiakia.
Ọmọogun mu darandaran fulani mẹfa, wọn pa mẹwa ni Adamawa
Àwọn ìṣẹ̀lẹ̀ mánigbàgbé tó wáyé nínú oṣù Kẹ́wàá ọdún 2020 Àwọn ọmọ Nàìjíríà yarí lórí èròngbà ilé aṣòfin pé kí àjọ FRSC má a lo nkan ìjagun Àwọn ìwàásù akọnilẹ́nu hàà tí Prophet Israel Oladele CCC Genesis Global ti ṣe rèé Báàgì Ghana Must Go pàwọ̀dà, ó di ohun táwọn ránsọ ránsọ fi ń dárà orísirísi Wòlíì míì, tún wọ gàù lẹ́yìn tó tàpá sí ìlànà béèlì tí wọ́n fún un nílé ẹjọ́ Iléeṣẹ́ ológun ní ó bàwọn lọ́kàn jẹ́ bí Sanwo-Olu ṣe ni kìí se òun ló pe sójà si Lekki Àdari ẹka ọmọ ologún 81 Brigade ní Victoria Island Brig.
Bákan náà, ó lè lo aṣọ aláwọ̀ aró ati elése àlùkò, ati aṣọ pupa ati aṣọ onílà tẹ́ẹ́rẹ́tẹ́ẹ́rẹ́ láti ṣe oríṣìíríṣìí iṣẹ́ ọnà.
Oríṣun àwòrán, @Hushpuppi Àkọlé àwòrán, Gal Pissetzky tó ń ṣojú Hushpuppi fẹ̀sùn ajínigbé kan FBI lórí ọ̀rọ̀ Ramọni Abass FBI jí Hushpuppi gbé ní Dubai ni- Agbẹ́jọ́rọ̀ Ramọni Igbalode Gal Pissetzky to n ṣoju fun Ramoni Abass Igbalode ba BBC sọrọ lori ohun to n ṣelẹ bayii lori ọrọ Hushpuppi.
Mọ̀ síi nípa ǹkan tí o lè ṣe láti dènà ibà Lassa Tinubu kò ṣékú, kò ṣé ẹyẹ, o n dibọn ní lórí ọ̀rọ̀ ikọ̀ Amotekun - Fani Kayode Mọ̀ síi nípa ǹkan tí o lè ṣe láti dènà ibà Lassa Sanwo-Olu pèsè ìpàgọ́ tó wà ní Igando fáwọn tí iná jólé wọn ní Abule Egba láti gbé Lẹ́yìn bi ọ̀ṣẹ̀ mẹ́ta ti ọ̀pọ̀ ènìyàn ti n reti ki Asiwaju ẹgbẹ́ APC fèsi lóri ìdásílẹ̀ ètò àbò Amọtẹkun, ọjọru ọsẹ̀ yìí lo ṣẹ̀ṣẹ̀ sọ ààyè tó tò sí lórí ọ̀rọ̀ náà.
Èmi óo san ẹ̀jẹ́ mi fún ọ, Ọlọrun;n óo sì mú ẹbọ ọpẹ́ wá fún ọ.
“ ‘Ẹni ìfibú ni ẹnikẹ́ni tí ó bá yá ère gbígbẹ́ tabi ère tí wọ́n fi irin rọ.
Fìlásayépọ̀ wá sọ fún mi lẹ́yìn náà pé òun lé bá mi ṣe e kí iwin inú fìlà òun lọ bá mi kí obìnrin náà wá, Ẹ̀yin ọ̀rẹ́ mi, wéré ni mo dọ̀bálẹ̀ fún Fìlásayépọ̀, èmi ni mo mà sì jẹ́ olórí gbogbo wọn o!
Ohun ìní ọlọ́rọ̀ ni ààbò rẹ̀,ṣugbọn àìní talaka ni yóo pa talaka run.
Oòrùn yọ kí ó tó kọjá Penueli, nítorí pé títiro ni ó ń tiro lọ nítorí itan rẹ̀.
Obinrin naa fi ọmọ ọdun meji saye lọ.
Ela ọmọ rẹ̀ sì gorí oyè lẹ́yìn rẹ̀.
Ẹni tí Oluwa kò ka ẹ̀ṣẹ̀ sí lọ́rùn sì ṣoríire.
8 3095 Orilẹede Central African Republic 63 1.
Esau rí i pé Isaaki ti súre fún Jakọbu, ó sì ti rán an lọ sí Padani-aramu kí ó lọ fẹ́ iyawo, ati pé nígbà tí ó ń súre fún un, ó pàṣẹ fún un pé kò gbọdọ̀ fẹ́ ninu àwọn ọmọbinrin ará Kenaani.
 Àlàyé wáyé lórí ọ ̀ nà ìgbékalè ọ ̀ ràn nínú fíìmù àgbéléwò yorùbá , bákan náa ni a sì tún se àyèwò ipa tí fíìmù àgbéléwò ajemọ ́ ọ ̀ ràn dídá ń ní lórí àwọn òǹwòran , òsèré lọ ́ kùnrin-lóbìnrin àti àwùjo lápapọ ̀ .
Wò ó bí ó ti ń sọ̀rọ̀ ní gbangba tí wọn kò sì sọ ohunkohun sí i.
Tí OLUWA àwọn ọmọ ogun ti súre fún pé, “Ibukun ni fún Ijipti, àwọn eniyan mi, ati fún Asiria tí mo fi ọwọ́ mi dá, ati fún Israẹli ìní mi.
Gẹgẹbii aṣiwaju to dara, ẹtọ ọ wa ni lati rii daju wi pe anfani ati j'eeyan wa nilẹ fun wọn nilẹ baba wọn.
Nigba naa lo fi aworan awọn ọmọbirin ti o fẹsun kan pe wọn n bẹ oun lati bawọn ṣe ere ifẹ ki oun baa le fun wọn lowo han.
Bẹẹ lọrọ ri fun olukọ kan tẹlẹ ni fasiti Eko, Azeez Baruwa, tileeẹjọ giga Eko ni ko yara lọ na naju lọgba ẹwọn fun ọdun mọkanlelogun.
Gbogbo eyi lo gbọdọ ṣe laarin wakati mejidinlaadọta, ti ko ba fẹ lọ sile ẹjọ.
 bákan náà ni ó tún gbé orin rẹ ̀ dé ọ ̀ pọ ̀ Ìpínlẹ ̀ orílẹ ̀ èdè amẹ ́ ríkà .
Oun ni minisita tẹlẹri fun ọrọ iroyin, lẹyin naa lo di alaga fun ajọ ere idaraya orilẹ-ede yii.
to n mojuto idije AFCON, Amaju Pinnick wa so pe, ojuse ajo CAF ni lati se ohun
Awọn ijọba ibilẹ yii ni wọn ni o n pese ida ọgọta awọn to lugbadi Covid19 ni ipele isede yii lorilẹede Naijiria.
Ọmọ mẹjọ ni Obedi Edomu bí nítorí pé Ọlọrun bukun un.
Fasoranti: Osinbajo ìṣẹ̀lẹ̀ ààbò tó mẹ́hẹ kò mọ níbì kan, káàkiri Nàìjíríà ni
Agbebọn pa ọmọ ogun mejila Akọwe ẹgbẹ ọmọlẹyin Kristi, CAN jade laye Ikọ̀ Lafiya Dole gbógun ti Boko Haram Awọn akọroyin sọpe o ṣeeṣe ki ipaniyan naa ni i se pẹlu eto idibo oṣẹ to n bọ.
Ṣùgbọ́n àwa náà ti mọ̀ pé ẹni tí ó à olórí ejò fa ìjàngbọ̀n lẹ́sẹ̀, ẹni tí ó bá ti hu irú ìwà tí àwa hù nì, ojú olúwaarẹ̀ yóò rí nǹkan.
Àwọn ẹran ọ̀sìn ń kérora,àwọn agbo mààlúù dààmú,nítorí pé kò sí pápá oko fún wọn;àwọn agbo aguntan pàápàá dààmú.
Lọwọlọwọ, apapọ awọn to ti ni aarun naa ni Naijiria bayii ti pe 77,933, eeyan 67,784 ti ri iwosan, nigab ti awọn 1,218 ti dagbere faye.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ìwọ́de EndSARS ló ń sọ pé inú ń bí àwọn ọ̀dọ́, ìjọba, ẹ náání wọn - Obasanjo Ẹni iyì àti akíkanjú tó ṣe gbẹ́kẹ̀lé làwọn èèyàn Akure, ilú ìyá mi - Seyi Makinde Ẹ̀yin ọ̀dọ́ ti rí èrè ìwọ̀de yín lórí EndSARS àmọ́ ẹ ṣọ́ra, kẹ má baà sọ èrè náá nù - Tinubu Owó ìrànwọ́ Covid-19 dé, ìjọba fẹ́ san ₦75bn fún 54,000 olókoòwò Ìjọba ìpínlẹ̀ Eko ti iléèwé pa nítorí ìwọ́de #EndSARS Ìrẹ̀wẹ̀sì ń bá wa torí ìdánwò NECO tẹ ń ṣún síwájú lọ́pọ̀ ìgbà - Akẹ́kọ̀ọ́, ọ̀gá iléèwé Agbára ìgbìmọ̀ ìdájọ tí mo gbé kàlẹ̀ yóò dé ọ̀dọ̀ àwón ólọ́pàá tó ti kúrò lẹ́nu iṣẹ́ tẹ́lẹ̀- Sanwo Olu Wo àwọn orílẹ̀èdè míràn tó ń fojú winá ìwọ́de bíi ti ENDSARS O ni awọn ko ti le sọ pato iye awọn to sa níbẹ ati pe awọn yoo fi to ara ilu leti ni kete tàwọn ba pari iwadii.
Oṣere tiata kan ree, Goriola Hassan to sọ pe, oun ko ṣe etutu kankan, ki oun to jẹ ọba ilẹ Uba Imobi nilẹ Ijẹbu nipinlẹ Ogun.
Greece: Orilẹede Greece naa si papakọ ofurufu rẹ fun awọn arinrinajo, amọ wọn ko fun orilẹede Amerika, Brazil ati Russia ni anfaani lati wọ ibẹ nitori arun Coronavirus.
Láti Òkè Abarimu wọ́n lọ sí pẹ̀tẹ́lẹ̀ Moabu lẹ́bàá odò Jọdani létí Jẹriko.
Zainab Aliyu: Mo sọkún títí, ojé tán lójú mi ní àhámọ Saudi
 } ati ti awon alapaosi won ( − 1 , − 2 , − 3 , .
Wọn fikun wi pe awọn to wa ninu ọkọ naa n lọ si ipagọ awọn ẹlẹsin Kristẹni, ki iṣẹlẹ naa to waye Òkú èèyàn mẹ́jọ ni wọ́n yọ níbi ìṣẹ̀lẹ̀ ìjàmbá ọkọ̀ nílùú Eko lọ́jọ́ Aje Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Mo máa n forin mi kìlọ̀ ìwà ìbàjẹ́ láwùjọ ni -Hameen Oku eeyan mẹjọ ni wọn ti yọ jade ninu omi bayii nibi ijamba ọkọ oju omi kan to waye ni ọjọ Satide.
A ní ìdánilójú ninu Oluwa nípa yín pé àwọn ohun tí a ti sọ, tí ẹ sì ń ṣe, ni ẹ óo máa ṣe.
Akure Anglican Bursar: Àwọn agbébọn gbé owó sálọ lẹ́yìn tí wọ́n pa akápò ìjọ Anglican
Ó bá fa ọmọde náà lọ́wọ́, ó wí fún un pé, “Talita kumi” ìtumọ̀ èyí tíí ṣe, “Ìwọ ọmọde yìí, mo wí fún ọ, dìde.
Gbagede Independence Square ni ọpọ ọmọ orilẹede naa peju si, ti wọn n fo fẹrẹ fun ayọ, ti inu wọn si n dun pe awọn bori aarẹ Keita.
Ikọ̀ ẹlẹ́sìn Hàkíkà rèé, níbití wọn ti ń pààrọ̀ ìyàwó láàrín ara wọn Irú ẹ̀dá wo ni aṣòfin Bukola Saraki jẹ́?
Ẹ wẹ̀, kí ara yín dá ṣáká.
Atẹjade kan ti ọmọ oloogbe naa, Folabi Fasanmi fisita lo kede ipapoda ọkan lara asaaju ẹgbẹ Afenifere naa ni alẹ ọjọru Gẹgẹ bi atẹjade naa ti wi, ọdun mẹrinlelaadọrun lo lo loke eepẹ, ki ọlọjọ to de.
ni ipinlẹ Niger ,Egbe APC  ni iye ibo  612,371 nigba
Bi awọn ipinlẹ to ni Coronavirus ṣe lọ ree: Kaduna-63 FCT-51 Plateau-38 Eko -33 Delta-25 Gombe-21 Adamawa-21 Edo-20 Katsina-17 Akwa Ibom-11 Ekiti-10 Rivers-9 Ondo-5 Ebonyi-4 Cross River-3 Ogun-3 Sokoto-2 Imo-2 Nasarawa-2 Èèyàn 329 ni ààrùn coronavirus tún ṣẹ̀ṣẹ̀ ràn ní Nàìjíríà - NCDC Ọọdunrun ati mọkandinlọgbọn eeyan ni ajọ NCDC tun kede pe o ti ni Covid-19 ni Naijiria.
Jesu dá wọn lóhùn, ó ní, “N óo bi yín léèrè ọ̀rọ̀ kan, ẹ dá mi lóhùn, èmi náà óo wá sọ irú àṣẹ tí mo fi ń ṣe nǹkan wọnyi.
Irọlẹ Ọjọbọ ni iroyin kan jade pr Minisita ọhun, Lai Mohammed sọ pe miliọnu mẹta ataabọ Naira ni ijọba fi n fun El-Zakzaky l'ounjẹ loṣooṣu lati igba to ti wa lakata wọn.
Ó tún fi kún un pé,“Kí OLUWA Ọlọrun mi bukun Ṣemu,ẹrú rẹ̀ ni Kenaani yóo máa ṣe.
Àwa tí a ti mọ ìwà yìn kò bìkítà fún yín mọ́, ìwà búburú yín kò jẹ́ kí ẹ to nǹkan lójú wa.
"Bi ẹnikẹni ko ba ni ìdá meji lẹyin ọjọ kẹta, wọn yoo da idibo duro fun ọjọ kan lati faaye silẹ fun adura gbigba, ijiroro ati ""iwaasu ranpẹ"" lati ẹnu cardinal ti oyè rẹ ga ju."
Ǹjẹ́ a máa rí nǹkan bí eniyan ṣe rí i?
"m ni ojú mi déédé fọ́ níbi tí mo ti ń darí ọkọ̀ ni Ọrẹgun Ikẹja -LASTMA Yesufa Mo ti kó kúrò nílé Olu Jacobs rí lẹ́ẹ̀mejì- Joke Silva ""Mo fẹ́ pa ara mi torí ojú àbùkù tí wọn ń fi wò mí pé mo fi iṣẹ́ abẹ bímọ"" Èmi àti Saheed kìí ṣe ọmọdé, a ti jọ ṣe Sinimá papọ̀, èyí túmọ̀ sí pé ìjà ti parí - Fathia Balogun Wọ́n ta ère Ọ̀ṣun Osogbo sí Togo - Bàbá Ọṣun figbe ta Binta wa rọ awọn akẹẹgbẹ rẹ lati maa se ere to mu ọgbọn lọwọ, ti yoo se agbelarugẹ asa ati ise wa, ti yoo si kọ awọn araalu lẹkọ gidi, nitori awokọse rere lo yẹ ki awọn onitiata jẹ lawujọ wa."
Bí ààwẹ náà ṣe ń tẹ̀síwájú, tí gbogbo àwọn súgà inu ẹ̀dọ̀ ba ti tán, ọ̀rá ara ni yóò fi ààbọ si láti pése agbára fún ara ninu ààwẹ Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Lẹyin àwọn ọjọ díẹ̀ ti ààwẹ ba ti bẹ̀rẹ̀ to sábà máa ń nira, nágbà ti ara bá ti n sinlẹ̀ fún mimọ pe ara ń gba ààwẹ ti ara yóò ti mọ pe oun gba ààwẹ.
Wo àwọn Gómìnà Naijiria tí àrùn Covid-19 ti bá fínra Kí ló pa àwọn òṣìṣẹ́ àjọ FRSC mẹ́ta lẹ́ẹ̀kan náà ní Ogun, ṣe iná gbé wọn ní, tàbí àrá?
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Peters Ijagbemi dá àrá lórí ètò 'Ṣé o láyà' ti BBC Yorùbá lọ̀sẹ̀ yìí Ajọ to n gbogun ti iwa ibajẹ lorilẹ-ede Naijiria EFCC n ṣewadii Minisita tẹlẹri naa, Dieziani Alison-Madueke fun ẹsun iwa ibajẹ ati jẹgudujẹra lasiko to wa ni ipo.
Bakan naa ni Ladoja kọ lati jẹ ki Baba iṣalẹ rẹ fi orukọ silẹ fun awọn Kọmisọnna ti wọn yoo jọ ṣe ijọba.
Amọ yii ko ba ọpọ eeyan lara mu lori ayelujara.
Nígbà tó yá ló bá yára palẹ̀ ìwé rẹ̀ mọ́, ó mú ọ̀pá rẹ̀, ó dìde ó rìn tààrà jáde kúrò nínú ọkọ̀ náà láìsí ìràlọ́wọ́ ẹnikẹ́ni.
Ijọba Ondo fesi si isẹlẹ yii.
Bí ìbátan ọkọ Rutu tí ó súnmọ́ ọn, tí Boasi sọ nípa rẹ̀ ti ń kọjá lọ, ó pè é, ó ní, “Ọ̀rẹ́, yà sí ibí, kí o sì jókòó.
Àwọn ìròyìn mìíràn tí ẹ lè nífẹ̀ẹ́ sí: Pásítọ̀ bẹ́'rí ọmọ ìjọ ní ìpínlẹ̀ Ògùn Ọlọ́pàá gbé àwọn tó yìnbọn lu olólùfẹ́ ní Ajegunle Ṣé ìfipágbàjọba àwọn ológun kò maa pọ̀ si l'Afirika?
Matt Hancock tó jẹ akọwe nipa ọrọ aṣa ni o ya oun lẹnu lati ri awọn ile iwe ti wọn ti n fofin de lilo foonu nile iwe.
Ẹlòmíràn a wí pé orí òun tóbi jù òun ń fẹ́ kí ó túbọ̀ kéré sí i, òmíràn a wí pé etí òun tóbi ju bí òun ti fẹ́ òun kò fẹ́ irú etí bẹ́ẹ̀ mọ́, ẹlòmíràn a wí pé ẹsẹ̀ òun tẹ́ẹ̀rẹ́ ju bí ó ti yẹ òun ń fẹ́ kí ó tóbi díẹ̀ sí i.
ọ̀tun ni wọ́n láràárọ̀,òtítọ́ rẹ̀ pọ̀.
OLUWA Ọlọrun àwọn baba wa: Abrahamu, Isaaki ati Israẹli, jẹ́ kí irú ẹ̀mí yìí túbọ̀ máa wà ninu àwọn eniyan rẹ títí lae, kí o sì jẹ́ kí ọkàn wọn máa fà sí ọ̀dọ̀ rẹ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Mama Arsenal: Ẹgbẹ́ kan ti fún màmá ní ẹ̀bùn owó Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Mama Arsenal: Ẹgbẹ́ kan ti fún màmá ní ẹ̀bùn owó 6 Agẹmo 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 23 Agẹmo 2020 Bi a ba ku, iṣe o tan ni Yoruba maa n wi.
Amọ eewọ ni fun awọn obinrin oloyun, ki wọn ma ba a bi ọmọ ti ọpọ́n ori rẹ yoo jọ ti tata.
O ni ''ko yẹ ki awọn olosẹlu maa ka sisan owo osu gẹgẹ bi aseyori nitori ẹ̀tọ́ ni ki wọn gba owo lẹyin isẹ.
Sugbọn lati igba ti Shogunlẹ ti n sọrọ yii, ni awn ọmọ Naijiria ti n gba ọrọ naa mọ ara wọn lọwọ, ti wn si n fi ero wọn han nipa rẹ loju opo Twitter wọn bẹẹ naa ni wn n fesi si ohun ti Shogunl sọ loju opo Twitter rẹ.
Ẹwẹ, ṣaaju eyi, ninu ọrọ ikinikaabọ, Aṣofin Tunde Braimoh, Alaga Igbimọ to n mojuto Iroyin ati Ọgbọn Iṣelu ninu Ile Igbimọ Aṣofin yii, kan saara si agbẹnusọ Ile naa fun abuda aṣiwaju rere ti o ni, eleyii ti o fi ṣeeṣe ki Ile naa fi ṣe aṣeyori to pọ bayii.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Arteta ni o da oun loju pe balogun Arsenal yoo buwọlu iwe adehun tuntun lati wa pẹlu ikọ agbabọọlu naa siwaju sii.
Orílẹ̀-èdè mẹ́wàá tí ẹgbẹ́ alákatakítí Islamic State n fínna mọ́ ní àgbáyé Ó ṣeéṣe kí ènìyàn 12,000 máa kú lójoojúmọ́ lẹ́yìn Covid-19 Ìtàn ayé Henry Fajemirokun, olówó tó fi owó mọ Olúwa àti ènìyàn Mi ò tíì gba ìwé ìfitónilétí pé wọ́n fẹ́ yọ mí nípò igbákejì gómìnà ìpínlẹ̀ Ondo- Agboola Ajayi Dr Anu: Ìjọba àpapọ̀ ti mú obìnrin tí àwọn èèyàn fi ẹ̀sùn kàn pé ayédèrú ìdí ló n ṣe Oríṣun àwòrán, Medcontour/FCCPC Ijọba Naijiria ti fi ofin gbe dokita kan, Anu Fela (Medcontour), wọn si ti gbe e lọ si ile ẹjọ giga ijọba apapọ ni Ikoyi nilu Eko.
lohun lori awọn ẹsun to nii ṣe pẹlu awọn kudiẹkudiẹ ti wọn ṣakiyesi
Iléeṣẹ́ ológun àti ẹgbẹ́ Shiite tún kọlu ara wọn Aṣòfin ìpínlẹ̀ Èkìtì tí wọ́n yìnbọn fún ti dolóògbé 'Súnkẹrẹ-fàkẹrẹ ọkọ̀ ló kó mí yọ lọ́wọ́ ìjàmbá ọkọ̀ òfurufú' Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Mike Ifabunmi: Òrìṣà ló gbè wà jù ni Brazil Agbẹnusọ fún Fayoṣe, Lere Ọlayinka ló fìdí èyí múlẹ̀ fún BBC Yoruba.
E̩nì kò̩ò̩kan ló ní è̩tó̩ sí ètò nínú àwùjo̩ rè̩ àti ní gbogbo àwùjo̩ àgbáyé níbi tí àwo̩n è̩tó̩ òmìnira tí a ti gbé kalè̩ nínú ìkéde yìí yóò ti jé̩ mímús̩e̩.
a ṣe àgbéjáde àjẹsára ikọ ́ ọfe ní ọdún 1926 .
6 3483531 Orilẹede Iran 56621 69.
Nitori awọn ọrọ nlanla ti o maa n sọ ninu sinima, lo faa ti awọn eeyan fi n pee ni orukọ yii.
Ẹka ẹkunrẹrẹ rẹ nibi Ọjọ 20, Osu Kẹta Ajọ Amnesty International sowipe ijọba orilẹede Naijiria ko kọbi ara si ikilọ wipe awọn ikọ Boko Haram fẹ se ikọlu si ilu Dapchi ni wakati diẹ si igba ti awọn ẹsinokọku naa wa ji awọn ọmọbinrin naa gbe.
Fún àwọn òṣèré soca, kí ni kan ní í máa mú ni jáwé olúborí nínú Ìwọ́de Ojúnà, kò ju, dídáńgájíá ní oríi òpópónà.
the team of his plan to call him up for the Seychelles game.
Àwọn mìíràn a máa pè é ní àlejò nítorí pé wọ́n kà á sí àlejò tó wá bá ni; ṣùgbọ́n wọn kò kà á sí àlejò tí yóò tún padà, bí kò ṣe èyí tí yóò máa bá ni gbé lọ títí.
Eyi lo mu ki onimọ nipa ihuwasi ati ise ọmọniyan, Samuel West sọ wi pe, ounjẹ jijẹ jẹ ohun abalaye to n se afihan ihuwasi eniyan ati ibi ti eniyan ti ṣan wa.
Oloye Adegboye Onigbinde lo ṣe akọni ikọ Super eagles nigba naa lorilẹede South Korea ati Japan.
Ninu ọrọ rẹ, Femi Hamzat ni oun gbagbọ pe Sanwo-Olu ni okun ati agbara lati mu itẹsiwaju ba ipinlẹ Eko.
O ni ko si ẹni ti ko ni aleebu tiẹ lara, ṣugbọn daadaa Ajimọbi tayọ ohun ti awọn eeyan le maa wo lara rẹ gẹgẹ bii aleebu.
O ni awọn kokoro kan ti a ko lee fi oju ri lo n fa aisan naa, ti a si lee ko awọn kokoro kekeke naa latinu afẹfẹ buruku, eefin, eedu, tabi ka lo ife ati ifọyin ẹni to ba ni aisan naa.
Lati nnkan bi ọjọ diẹ sẹyin ni awọn ọgagun lati orile¬-ede meji naa ti n ṣepade lati yanju awọ yii, ṣugbọn igbiyanju lati pari iru awọ bayii latẹyinwa ko so eso rere.
Bakan naa ni Ikọ ọmọogun Naijiria fikun wi pe, gbogbo eto ti to lati ri wi pe ko si ikọ Boko Haram mọ ni agbegbe naa.
Ìtàn Gbọnka àti Timi, akọni méjì tó borí Aláàfin Ṣango Lisabi Agbongbo Akala rèé, ẹni tó fi ìfẹ́, ìṣọ̀kan àti ìrẹ́pọ̀ gba ilẹ̀ Ẹ̀gbá lọ́wọ́ ìmúnisìn Idi si ree ti BBC Yoruba fi wọ inu itan lọ, paapa pẹlu awọn akọsilẹ to wa lori itakun agbaye, se itan kii ku, lati selanilọyẹ lori awọn isẹlẹ to ti waye sẹyin nipa ọpọ ọba ti wọn ti rọ loye, ti awọn miran ninu wọn, ko si pada sori oye mọ titi di ọjọ iku wọn.
Wọ́n kàn ń fi orúkọ òun sọ àsọtẹ́lẹ̀ èké ni, kí òun lè le yín jáde, kí ẹ sì ṣègbé, àtẹ̀yin àtàwọn wolii tí wọn ń sọ àsọtẹ́lẹ̀ fun yín.
Erica wa kesi Nengi pé ti o ba nífẹ̀ Kiddwaya, ore-ọ̀fẹ́ wà fún láti sọ ni àsìkò yìí nítori pé, bi ó ṣe ń ṣe ni àyíka rẹ̀, kò tẹ́ òun lọ́rùn rárá.
jẹ ̀ dọ ̀ jẹ ̀ dọ ̀ c jẹ ́ àrùn tí ó jẹ ́ pé ẹ ̀ dọ ̀ ni ó kọ ́ kọ ́ máa n ṣe àkóbá fún .
Oríṣun àwòrán, other Nigba ti o kan Sẹnetọ Oṣinọwọ lati sọrọ, awọn ọrọ to jade lẹnu 'Pepperito' gẹgẹ bi ọpọ awọn ololufẹ rẹ ṣe maa n pe e dabi ti ẹni to ti riran iku ara rẹ ni Se lo dabii pe o wa n fi ọgbọn sọ fawọn eeyan irufẹ nkan to fẹ bi oun pẹlu ba rewalẹ asa.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù INEC ń pe àwọn èèyàn lórí fóònù láti wá gba káàdì ìdìbò wọn 16 Ìgbé 2018 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 11 Owewe 2018 Oríṣun àwòrán, @inecnigeria Àkọlé àwòrán, INEC ní gbígba àwọn káádì ìdìbò tó wà nílẹ̀ ló ń fà bíi ìgbín pẹ̀lú onírúurú ìpolongo àti ìtanijí INEC ipinlẹ Ọyọ ń fúnra wọn pe àwọn èèyàn lati wa gba kaadi idibo wọn.
Haa-hin in ni iroyin naa ṣe ọpọ onwoye nitori pe ko si ẹni lee ro pe ẹgbẹ kan to wa lori alefaa lee kẹyin si aṣoju wọn ninu iṣejọba.
Ortom sọ pe ''eebu lo jẹ si awọn eeyan ipinlẹ Benue ati pe awọn lodi si'' Fayọṣe ṣe abẹwo si Ortom Gani Adams kilọ f'awọn darandaran Sé agbésùmọ̀mí ní àwọn darandaran?
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Àádọ́ta Náírà tí báńkì ń yọ nínú owó ìpamọ́ oníbàárà kò tọ̀nà - Iléejọ́ Agbébọn tún gbẹ̀mí àgbẹ̀ míì lọ́nà oko lágbègbè Ibarapa Sanwo-Olu, El-Rufai fara pamọ́ torí COVID-19 lẹ́ẹ̀kejì Àwọn agbófinró Nàíjíríà yóò rojọ́ níwájú iléẹjọ́ àgbáyé ICC Wo ìgbéyàwó olówó iyebíye tí awakọ̀ Kabúkabú ti jẹ̀bùn ọkọ N3.
O sọju abẹ niko pe igbeyawo ko gbọdọ la ẹmi lọ mọ, ẹ le yẹra funra yin ki alaafia fi jọba.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Mo lé fi òjò dá àrà tò wù mi f'áwọn oníbárà mi lásìkò tó wù mí 27 Ògún 2018 Àkọlé àwòrán, Ǹjẹ́ o mọ pe eniyan máa n pe ojo?
Sanwo-Olu lo sọ ọrọ naa loju opo Twitter rẹ lẹyin to ṣabẹwo si awọn eeyan naa ni ilu Eko.
" Awọn ipẹẹrẹ ọmọ ologun maarun la gbọ pe wọn ji owo naa gbe.
Isaaki wí pé, “Ṣé o rí i báyìí pé mo ti darúgbó, n kò sì mọ ọjọ́ ikú mi.
Ileeṣẹ ọlọpaa ni ipinlẹ Adamawa ti mu ẹyẹ igun kan si atimọle bayii ni ipinlẹ naa.
Bí ọkunrin kan bá ní ọgọrun-un aguntan, tí ọ̀kan ninu wọn bá sọnù, ǹjẹ́ ọkunrin náà kò ní fi aguntan mọkandinlọgọrun-un yòókù sílẹ̀ lórí òkè, kí ó lọ wá èyí tí ó sọnù?
Ọkùnrin kọ́ ló ra jeep fún Iyabo Ojo, òógùn ojú mi ni mo fi rà á fun"" Ninu akọsilẹ naa to fi si ori ayelujara Facebook, Mike Bamiloye sọ pe, oun ko ni ohunkohun bi i owo ati dukia, nigba ti Gloria gba lati fẹ oun, bo tilẹ jẹ pe awọn ẹbí wa gba wa ni imọran pe, ki a ma ṣe bẹ ẹ."
 nínú ìbásepò wọn , àwon òrò náà n sisẹ ́ lórí ara wọn to fi jẹ ́ pé àwon ọ ̀ wò kan a gbà àwọn mìíràn yóò sì fún wọn ní àwọn àbùdá kan .
Aládúgbò ti ọmọ Nàìjíríà jábọ́ látorí ilé alájà méjì
“Obinrin tí o rí ni ìlú ńlá náà tí ó ń pàṣẹ lórí àwọn ọba ilẹ̀ ayé.
O wi siwaju sii pe loni ni awọn yoo mọ nipa boya ọmọ ẹgbẹ agbabọọlu Borrusia Dortmund, Pierre-Emerick Aubameyang yoo darapọ mọ wọn tabi bẹẹkọ.
Seriki Williams Abass: Ọba Badagry tó jẹ́ ẹrú, tó tún padà di olówò ẹrú
Amọ ṣa ijọba ipinlẹ ibi to ba ti jẹ owo bi apẹrẹ ti Laycon to waye ni Eko yi ni o lẹtọ lati gba owo naa lori apapọ owo ti Laycon ba pa wọle lọdun .
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Viral Diarrhea: Òjò ló lè mú kí ìtànkálẹ̀ àrun ìgbẹ́ ọ̀rìn má tètè dópin ni Eko- Iléeṣẹ́ ìlera 11 Bélú 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Arun igbẹ ọrin yii bẹ silẹ laipẹ ni ipinlẹ Eko ni eyi ti wọn ni Oluwa ti n gbakoso Ileeṣẹ ijọba ipinlẹ Eko to n mojuto eto ilera ni ẹni mọkanla lo ti ba arun igbẹ ọrin to n tankale yii rin.
Sẹnetọ Abbo ṣalaye pe iya oun ni awọn agbebọn naa kọkọ beere lọwọ baba oun nigba ti wọn wọle wa pẹlu ibọn AK47 lọwọ wọn ki awọn aburo oun to sọ fun wọn pe iya oun ti jade laye.
O sọ pe o ṣeni laanu pe ko si ẹnikan to ronu pe iru ipade itagbangba yii le ṣakoba fun eto ilera araalu pẹlu bi arun covid-19 sẹ wa nita bayii.
Akintoye lo rọpo oloogbe Abraham Adesanya to n dari iran Yoruba to doloogbe loṣu kẹrin, lọdun 2008.
Òkúta ńláńlá, olówó ńláńlá, onígbọ̀nwọ́ mẹjọ ati onígbọ̀nwọ́ mẹ́wàá ni wọ́n fi ṣe ìpìlẹ̀ ilé náà.
 damasku je gbangan asa ati esin pataki ni lẹ ̀ fántì .
Ni bayii, o wa yẹ ka mọ itan igbe aye akọni yii ati ipa to ko ni ilu rẹ, boya rere ni abi buburu.
” Aṣofin Ọbasa tun fi kun ọrọ rẹ.
Ṣé ó tọ̀nà kí obìnrin máa bímọ sílé?
Jerusalẹmu ti dẹ́ṣẹ̀ burúkú,nítorí náà ó ti di eléèérí.
Ajọ NCDC naa fi lede loju opo ikansiraẹni Twitter wọn ni alẹ Ọjọbọ.
Wayi o, Flying Eagles yoo koju Qatar, USA ati Ukraine nipele kerin ninu idije boolu agbaye FIFA U20 World Cup.
Nígbà náà ni Samuẹli mú ìwo tí òróró wà ninu rẹ̀, ó ta òróró náà sí i lórí láàrin àwọn arakunrin rẹ̀, Ẹ̀mí OLUWA sì bà lé Dafidi láti ọjọ́ náà lọ.
Yí ẹ̀gàn wọn pada lé wọn lórí, kí o sì fi wọ́n lé alágbèédá lọ́wọ́ ní ilẹ̀ tí wọ́n kó wọn lẹ́rú lọ.
Oloogbe naa koko je  oludari ile ise  NNDC ana ,aare nigbagbo pe iwa adari ati akoni oloogbe pasito Aginighan fun idagbasoke ekun ila Gusu je ” eyi ti ko lee fọwọ ro seyin , ati iwa akin re nigba oselu si awon eniyan re.
Ọpọ ere ti baba Suwe ba ti kopa, naa ni Ọpọbẹ maa saba n kopa ninu rẹ.
Kò sí ìfòyà, ọkọ̀ bààlù wà tí ìjọba ba ti afárá 3rd Mainland lósù yìí Wole Soyinka rèé láti kékeré 'Orúkọ pásítọ̀ ni Magu fi ra ilé N573 mílíọ̀nù sì Dubai - PCARA Iléeṣẹ́ Ọlọ́pàá ṣetán láti bẹ̀rẹ̀ ètò ìgbanisíṣẹ́ lákọ̀tun Olayanju ni ko si ohun to nira ninu fifi orukọ silẹ lori ayelujara nitori ko si ibudo itakun agbaye ti wọn ba lọ lati fi orúkọ silẹ, ti wọn ko ni seranwọ lati ba wọn ṣe.
Ìbá sàn kí n kúkú wà lọ́hùn-ún.
Nitori iyasọtọ yi, Cristianno Ronaldo ko ni le kopa fun ẹgbẹ agbabọọlu rẹ Juventus lọjọ Kẹtadinlogun oṣu Kẹwa pẹlu Crotone.
9 Àti, nítorínáà, ohunkóhun tí ìwọ bá bèerè ní ọwọ́ mi pé kí èmi ó sọ fún ọ nípa ọ̀nà yìí, èyí ni èmi yíò fi fún ọ, ìwọ yíò sì ní ìmọ̀ nípa rẹ̀.
Bawo ni arun Coronavirus ṣe buru to?
Nítorí náà, Ìrìnkèrindò, ìwọ ọmọ Oyíndayépọ̀, bá mi wá èso igi ìrònú lọ.
Àsàkẹ́: Ó jẹ́ ọ̀kan nínú àwọn ìyàwó Àkàngbé Orímóògùnjẹ́.
2m ọmọdé kò ṣe lọ sílé ẹ̀kọ́ - SERAP ké tọ iléẹjọ́ àgbáyé Buhari, ṣí ìwé àkọsílẹ̀ orúkọ àwọn gómìnà tó jẹ̀bi ìkówójẹ, káráyé mọ̀ wọ́n - SERAP Buhari gbọ́dọ̀ bẹ̀rẹ̀ ìwádìí Ganduje láàrín ọjọ́ mẹ́rìnlá-SERAP 'Iléèṣẹ́ ọlọ́pàá ló gbégbà orókè nínú ìwà jẹgudujẹra ní Nàìjíríà' Ninu iwe yi ti wọn tun fi ṣọwọ si Minisita eto idajọ Naijiria SERAP ni ko ba ofin ilẹ Naijiria mu ki awọn Gomina maa foju si owo ifẹyinti awọn oṣiṣẹ lara ni gbogbo igba.
Mose ati Aaroni bá bu eérú ninu ẹbu, wọ́n dúró níwájú Farao.
"Triumph lori Twitter da si ọrọ naa nigba to ni ""Anfani wo ni owo oju opopona yoo ṣe awọn ọmọ Naijiria nigba ti ọpọlọpọ ọna ijọba apapọ ti dẹnu kọlẹ?"
Ṣugbọn nígbà tí èmi kọsẹ̀, wọ́n kó ara wọn jọ,wọ́n ń yọ̀,wọ́n kó tì mí;pàápàá jùlọ, àwọn àlejò tí n kò mọ̀ ríbẹ̀rẹ̀ sí purọ́ mọ́ mi léraléra.
”Nígbà náà ni àwọn eniyan wá, wọ́n ṣùrù mọ́ Jesu, wọ́n mú un.
Gbogbo awọn alatilẹyin igun mejeeji ti ji de ile ẹjọ ni kutukutu owurọ oni ti wọn si n reti ohun ti yoo gbẹyin ẹjọ naa.
Owo naa le ni biliọnu kan Dọla (1.
Bi èèyàn yóò bá kópa nínú Hajj, o di dandan fún àwọn ọkùnrin láti wọ asọ yí nikan lásìkò tí wọn yóò fi ṣé ìjọsìn.
Aare orile ede Naijiria, Muhammadu Buhari ti fokan awon omo orile ede South Sudan balẹ pe orile ede Naijiria ti setan lati se satileyin fun orile ede naa, lori eto ọrọ iselu ati ọrọ aje.
Ẹ̀yin ni a ti dáàbò bò nípa agbára Ọlọrun nípa igbagbọ sí ìgbàlà tí a ti ṣe ètò láti fihàn ní ọjọ́ ìkẹyìn.
Wole Soyinka sọ ìdí tó fi ni òun a fi màálù Fulani ṣe súyà fáwọn èèyàn abúlé
Oríṣun àwòrán, Dbanj Àkọlé àwòrán, Oṣu kẹfa, ọdun 2018 ni Daniel, ọmọ ọkunrin DBanj ku lẹyin oṣu diẹ to ṣe ọjọ ibi ọdun kan rẹ.
 Ile iwosan kan lorile-ede Canada ni won ni o ku si lojo Bo to koja.
bojuto agbegbe ,ti awon eniyan agbegbe naa yoo si maa san owo ti ko ga jara lo
Mo sì rí i tí kẹ̀kẹ́ ogun àwọn ọ̀tá ati àwọn ẹlẹ́ṣin wọn ń lépa rẹ̀.
agbateru idije ohun yoo ja mo lori.
Oríṣun àwòrán, Twitter/governor Borno Èèyàn 145 tún ti ní COVID-19 ní Nàìjíríà Ẹ̀yin ọmọ ogun, ẹ lọ dojú ìjà kọ àwọn ọmọ ẹgbẹ́ Boko Haram títí ti ẹ ó fi rẹ́yìn wọn - Buhari Olorì Aláàfín tẹ́lẹ̀, Anuoluwapo Adeyemi gba àmì ẹ̀yẹ lórí ipa tó kó nínú oge ṣíṣe Kàyééfì!
Iyabo Ojo gé okùn àjọṣepọ̀ rẹ̀ pẹ̀lú olóṣèlú nínú ẹgbẹ́ APC ati PDP Mo ti tọrọ aṣọ àti yẹtí etí rí, kí n tó leè ṣe àwo orin - Tope Alabi 'Bí ìgbà èèyàn bọ́ aṣọ lára àgbàdo lọ̀rọ̀ àwa apálórí' Produced By Yemisi Oyedepo & Damilola Oduolowu Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí US presidential election 2020: Kíni Kọ́lẹ̀jì ìdìbò, àwọn ìpińlẹ̀ tó le gbé olùdíje wọlé àti àwọn ǹkan ti o yé kí o mọ̀ nípa ìdìbò ilẹ̀ Amerika.
ṣugbọn ní àkókò ooru, wọn a yọ́,bí ilẹ̀ bá ti gbóná,wọn a sì gbẹ.
rẹ, ọdun yii naa si ni eto idibo gbogboogbo yoo waye.
EarPod yìí, iPod àti iPone ni wọ́n ṣe é fún.
 Ọjọ kan tiẹ wa, ti ewe oogun mi fẹ sunko, ọwọ awọn ọlọpaa ati ologun fẹ tẹ mi, a yaa bọ sagbo awọn eeyan to n ṣe inawo, a fọn owo soju agbo, ọpọ eeyan àtàwọn ọlọpaa gan n sa owo, la ṣe ri ọna sa lọ.
Bí nǹkan bá ṣe mí àtàwọn ọmọ mi, Aláàfin ni kẹ mú o - Olorì Anu figbe ta Oríṣun àwòrán, Instagram/queen__aanu Saaju la ti sọ fun yin pe, Olori Anu ti bọ soju opo Instagram ni irọlẹ Ọjọru lati kede fun araye pe oun ti kuro ninu aafin.
Aṣeyọri orin yii jẹ apapọ iṣẹ iyi ti olorin Naijiria, Wizkid ni lọja orin.
O ti gba ami ẹyẹ pupọ nile, ati loke okun bii ti: Ami ẹyẹ Adari rere ni fasiti Pittsburgh USA, ami idanimọ fun iṣẹ rere ti fasiti Stanford University, America; ami ẹyẹ ògo lẹnu iṣẹ akanṣe ẹni ni fasiti Pittsburgh, America.
Agbẹnusọ fún ààrẹ Muhammadu Buhari,Garba Shehu sàlàyé pé àwọn sì ń wo fọ́nràn náà wò bóyá ohun Leah ni Nínú fọ́nrán náà Leah ń bẹ ààrẹ Muhammadu Buhari lati ṣàánú nítori ìdílé òhun Ìròyin fi han pé wọn fi Sharíbù sáhàmaọ́ nítori o kọ̀ la'ti ṣẹ́ ìgbàgbọ́ rẹ̀ nínú ẹ̀sin Kristiẹni.
Sibẹsibẹ ó fi ìṣúra dáradára kún ilé wọn–ṣugbọn ìmọ̀ràn ẹni ibi jìnnà sí mi.
Neil Armstrong lo si koko je eni akoko to fi ese rin ni ori osupa, ti opolopo awon aworawo si ma n se odun yii kaakiri agbaye ni odoodun.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Eeyan mẹwa to mu 'Yọllywood' lamilaaka 21 Èrèlè 2018 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 17 Ògún 2018 Oríṣun àwòrán, AFP Nollywood ni ẹgbẹ awọn osere lorilẹ-ede Naijiria, ninu eyi ta ti ri awọn ogbontagiri osere tiata to ti laamilaaka ninu isẹ ti wọn yan laayo.
O ni ohun ti o kan bayii ni lati rii pe wọn fi gbogbo awọn koko to wa ninu eto naa si iṣe.
 “Ajiroro nibi ipade igbimo amusese ijoba apapo lonii, ifenuko lati se iadasile eto kara-kata alailowo ori ninu laarin awon orile-ede nile Africa, ni bayii, ti a ti fidi oro ohun ti sibi kan, kii se fun ile-ise ti o n ri si eto idokowo, kara-kata ati ile-ise nikan, amo, pelu ajosepo ile-ise to o n ri si oro ile-okeere ati ile-ise ti o n ri si eto idajo, Aare tun se ifilole igbimo kan ninu osu keji odun 2017, eyi ti yoo faye gba awon eka ladani lati fowosowopo se ise naa.
O kò pa òfin tí OLUWA Ọlọrun rẹ fún ọ mọ́.
Nígbà tí ọba gbọ́ ọ̀rọ̀ yìí, ọkàn rẹ̀ dàrú lọpọlọpọ, ó sa gbogbo ipá rẹ̀ títí ilẹ̀ fi ṣú láti gba Daniẹli sílẹ̀.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù ASUU strike : Ìdí tí àwọn olùkọ́ kò ṣe tíì f'òpin sí ìyanṣẹ́lódì 8 Sẹ́rẹ́ 2019 Oríṣun àwòrán, Frédéric Soltan Ijọba orileede Naijiria ti kede pe awọn ti yanju awọn olukọni ile ẹkọ fasiti ti wọn gun le iyanṣẹlodi.
" Osere tiata ọhun wa rawọ ẹbẹ sawọn eeyan pe ki wọn maa tiraka lati rin jinna si ohunkohun to ba lee fa wahala ba aye wọn tabi ge ẹmi wọn kuru, to si tun rọ wọn lati ta kete si ija, ki wọn si tun kẹyin si awọn eeyan to ba lee ru ibinu wọn soke.
 Ìpolongo nípa gbígba àjẹsára ni a tún lè lò láti fi ṣàkóso ìtànkálẹ ̀ àrùn náà .
Jiti Ogunye: Ẹgbẹ́ tó ní Asojúsòfin tó pójú ló lè yan Ààrẹ Ilé Asòfin àpapò
Èmi ni Alfa ati Omega, ìbẹ̀rẹ̀ ati òpin.
Oríṣun àwòrán, Wumi toriola Lootọ ni Wunmi Toriola ki Seyi ku ọjọ ibi amọ ọpọ ololufẹ Seyi ni ikinni naa ko dabi ti tẹlẹ, ti wọn si n fura pe ejo ti gba aarin awọn oṣere mejeeji kọja.
gbogbo agbaye tewogba, bee si ni mo daju pe, wa se aseyege.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù ASUU- Tírílíọ̀nù 1.
Goṣeni, Holoni, ati Gilo; gbogbo ìlú ati ìletò wọn jẹ́ mọkanla.
Atẹjade kan ti oludari agba fun ajọ Lasema nipinlẹ Eko, Oluwafẹmi Oke-Osanyintolu to fi idi isẹlẹ naa mulẹ fun BBC Yoruba salaye pe ọkunrin kan lo ha sabẹ awoku ile naa.
“Àwọn ọmọ Israẹli gbọdọ̀ kó àwọn nǹkan ìrúbọ náà fún àwọn ọba Israẹli.
Arun Coronavirus lo tun mu ọmọ bibi ipinlẹ Ogun naa lọ lẹni ọdun mejilelọgọta lẹyin ti arun Coronavirus ba a finran.
Ilẹ̀ sì bẹ̀rẹ̀ sí í mì tìtì, gìrìgìrì ẹsẹ̀ àwọn méjèéjì ju ti ènìyàn mẹ́eàá lọ wọ́n fẹ ojú toto, wọ́n di mọ́ ara wọn bí ìgbà ti ìtàkùn bá dìi mọ́ igi oko, àwọn méjèéjì sì ń mí hẹlẹhẹlẹ bí ajá ọdẹ, Ọjọ́ ńlá ni ojọ́ náà fún ẹbọra kékeré inú ọ̀gán, orúkọ ẹni ti ń jẹ́ Èṣù-kèkerè-òde.
Ọlọ́pàá mú afurasí 31 tó ń dúnkokò máwọn ọmọdé lórí ayélujára Bàbá ọlọ́mọ méjì fi ipá bá ọmọ ọdún mẹ́rin lò pọ̀; Adájọ́ rán an ní ẹ̀wọ̀n gbére Wo ìgbà mẹ́rin tí ìjọba ti tú ikọ̀ ọlọ́pàá SARS ká sẹ̀yín ṣùgbọ́n.
Eyi to ni o ti mu idagbasoke ba ipese oúnjẹ ni Naijiria, ati idunnu ba awọn eeyan naa.
Sìgá mímu ń di èèwọ̀ oògùn ìlera pípé lagbaye Deji dáná sun ẹbí olólùfẹ́ rẹ̀, lèèyàn 8 bá dèrò ọ̀run Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí kan sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
kódà Ọba bìnrin  elibabeth ' tí ó tó láti ṣe ìtóka ni a mọ ̀ pé ó ní agbára lórí ilẹ ̀ gẹ ̀ ẹ ́ sì ."
" Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Africa Eye: Wo ìtàn ìyá kan ìyá kan àtàwọn olè ajọ́mọgbé tó n ta ọmọ ní Kenya Iroyin sọ pe agbenusọ ileesẹ ọlọpaa ni ẹkùn Kampala, Luke Owoyesigyire ní o se e ṣe ki wọn o ṣe ayẹwo aarun Covid-19 fun awọn afurasi naa.
SARS: Ẹgbẹ́ agbábọ́ọ̀lù Remo Stars ní ikọ̀ SARS ló pa agbábọ́ọ́lú òun
Ọkan lara awọn gbajugbaja agbabọọlu Barcelona, adilemu, Gerard Pique ke gbajari pe abuku nla kan Barca, o ni omi ti tẹyin wọ igbin lẹnu.
Botilẹ jẹ pe ko si igba kankan ti Instagram fi atẹjade sọwọ pe nkan bayii ni Tunde Ednut ṣe sibẹ, ìgbà meji ọtọọtọ ni wọn ti gbọn yọ loju opo naa.
Borno Zabamari Massare: Àjọ NCC fẹ́ tú ìwé owó àwọn olúpèsè ìtàkùn ìbánisọ̀rọ̀ wo
Bẹẹ lọrọ ri fun afurasi ajinigbe kan ti ẹnu ko sin lara rẹ lẹnu ọjọ mẹta yii, Hamisu Bala, ti gbogbo eeyan mọ si Wadume, ẹni to kede pe ẹgbẹ oselu APC fun oun ni miliọnu mẹtala naira lasiko eto idibo apapọ to kọja.
Olukọ wa fun toni ni Iyaafin Idowu Peters lati Ogba Junior Grammar School.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Islamu faaye gba okunrin lati niyawo mẹrin to ba wuu O ni ''obinrin ni mi, mo si mọ bo ti ṣe ri lara ti obinrin ko ba fẹ ki ọkọ rẹ fẹ iyawo mii.
 Ni ti @Ciefbucha, o ni ""Mo kọkọ ro pe ìjọba ni ìṣòro wa nilẹ yi ni, ṣugbọn o ti hàn sí gbàgede pe awa ara ilu gan ni ìṣòro ara wa nitori a ko le tẹle ofin ti wọn là kalẹ fún ànfàní ara wa."
Sugbọn nigba ti yoo fi di ọjọ kẹtala, oṣu Kínní, aarun naa ti di ti gbogbo agbaye, nitori pe orilẹ-ede bi Thailand, Japan, South Korea àti America ṣe bẹ̀rẹ̀ si i ni akọsilẹ ti wọn naa.
L'ọjọbọ l'olootu ijọba Ardern kede fifi ofin de lilo awọn ibọn atamatase lorileede naa.
Agbẹjọro naa ni, igbeyawo abalaye ti ilẹ Yoruba nikan lo faye gba ki ọkunrin o ni iyawo pupọ, nigba ti ẹsin musulumi labẹ ofin sọ wi pe, eniyan le fẹ mẹrin ti o ba si le ṣe deede laarin awọn iyawo ohun.
Canada Awọn ọlọpaa ni Canada lo gbowo julọ lagbaye.
Falayi pasẹ fun iyawo rẹ nigba to dele pe ko pọn ọmọ naa sẹyin lọ sile ẹnikan to darukọ fun-un.
Ọ̀gbẹ́ni Bichi ti kẹ́kọ̀ọ́ nípa ṣíṣe àtúpalẹ̀ àbọ̀ ìwádìí iṣẹ́ ọ̀tẹlẹ̀múyẹ́, tó fi ma nípa ètò ìgbanisíṣẹ́ ọ̀tẹlẹ̀múyẹ́ ní ilẹ̀ Gẹ̀ẹ́sì.
Ṣugbọn o pada si Democrat lọdun 2018 bibi to wa di akoko yii.
Wọ́n ti sún ìdájọ́ àwọn sójà tó pa ìyá àti ọmọ ní ọdun 2018 sí oṣù tó m bọ̀ Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí NUJ ìpínlẹ Oyo bà àwọn ọmọ ẹgbẹ́ tó lọ ìpàdé tí Femi Fani Kayode pè ní Ibadan wí7 Owewe 2020 6:18 Fídíò, Akomolede: Bolaji Faleke ni Olùkọ́ tó ń kọ́ wa ní àṣà oge ṣiṣe lórí BBC Yorùbá, Duration 6,181 Owewe 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Ọmọlufa jẹ onirẹlẹ obinrin, o ni itẹriba, to si maa n gba imọran iya rẹ amọ onijagidi jagan ẹda, olori kunkun, alailẹkọ ati onipanle eniyan ni aburo rẹ, to n jẹ Ọmọyẹni, eyi ti apekuru rẹ n jẹ Ọmọyẹ.
Ọkọ̀ akẹ́rù Dangote rọ́lu BRT lọ́nà Ikorodu, èèyàn kan kú, 59 farapa, ẹsẹ̀ dẹ́rẹ́bà gé Àwọn ọmọ Nàíjíríà ló ṣiṣẹ́ takò mí ní Ireland kí ń má baà wọlé ìbò Káńsélọ̀ - Yemi Adenuga Láti January lọ, gbogbo ẹni tó bá ra ọjà lórí ayélujára yóò máa sanwó orí - FIRS Aṣojú Seyí Makinde lásan ní mo jẹ, òṣìṣẹ́ gbọdọ̀ bọ̀wọ̀ fún mi - Ọ̀dọ́mọdé Kọmísánà Afẹ Babalọla wa rọ aarẹ Muhammadu Buhari lati pe ipade apero apapọ awọn ọmọ Naijiria, ta si mu awọn asoju lai lo ẹgbẹ oselu kankan.
Wo ohun tí Adájọ́ ṣe sí àṣùwọ̀n ìfowópamọ́sí Wòlíì Sotitobire Ẹ má gbàbọ̀de kankan láti tú Wolii ìjọ Sotitobire sílẹ̀ o!
Wọ́n lé ọ̀gá ọlọ́ọ̀pá l’Eko nítorí ìwà ìbàjẹ́ Kí lo mọ̀ nípa Eniọla Badmus?
Wọ́n ní ìgbàyà tí ó dàbí ìgbàyà irin.
Ẹ̀gbọ́n-bìrin méjèèjì Abd El Fattah, Mona àti Sanaa Seif, jẹ́ agbèjà ẹ̀tọ́ ọmọnìyàn bákan náà tí wọ́n sì ti ṣe ìpolongo alátakò ìjìyà mẹ́kúnnú lọ́wọ́ọ àwọn ológun ní ìlú náà.
"Ikú Khaleel lo yẹ kó jẹ́ àṣemọ láti dẹ́kun pípa àwọn ọmọ wa níbikíbi lágbàyé pàápàá jùlọ ni Ariwa Cyprus.
Eyi mu ki o nireti pe wọn yoo si ri ọkọ rẹ laaye.
Ìfọwọ́sowọ́pọ̀ nìkan ni ọ̀nà abáyọ sí ìṣòro Nàìjíríà- Olusegun Obasanjo Buhari, o ṣẹ ilẹ̀ Yorùbá púpọ̀, ló àyájọ́ ìbí rẹ̀ láti tọrọ àforíjìn - PDP Ìtura ìgbà díẹ̀ ni bọ́dà tí ìjọba ṣí padà, kò lóòre nínú - Onímọ̀ ọrọ̀ ajé Wo ìdí tí ààrẹ Buhari kìí fi ṣe ẹ̀dà Jubril láti Sudan Àwọn ohun kàyéèfì tó le mú kí ọmọbìnrin ní oyún ìju Bakan naa lo fikun pe ijọba apapọ ko san eepinni fawọn ajọmọgbe naa, idunadura lasan ni awọn se.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Kengbe Ilorin: Àṣà ẹ̀yà Fulani, Bariba àti Gambari tó dàpọ̀ mọ́ ti Yoruba Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Wọn ni $470m ni Gomina na lati gbe ara rẹ ati awọn ọmọ ẹgbẹ APC lọ wo idije AFCON ni Egypt.
Oríṣun àwòrán, @GboyegaOyetola O wa rọ gomina Makinde lati mase gunle iwa ibanilorukọjẹ abi igbiyanju lati ru awọn osisẹ fasiti Lautech laya soke, to fi mọ awọn eeyan ipinlẹ Ọyọ lapapọ.
N kò ní inú dídùn sí ikú ẹnikẹ́ni, nítorí náà, ẹ yipada kí ẹ lè yè.
Laarin agogo mẹsan owurọ titi di aago mẹta ọsan ni ayẹwo orukọ naa yoo ma waye lojumọ.
awon obinrin to wa ninu oselu tun le sii.
Nítorí pé ibi gíga ni ó ń gbé;yóo mú kí ìdájọ́ òtítọ́ ati òdodo kún Sioni.
Odunlade fẹ́ j'ọba, Bolanle Ninalowo fun ìyàwó rẹ̀ ni ẹ̀bun kanka, Pá Kasumu rebi àgbà ree Bí Coronavirus ṣe ń tàn kálẹ̀ náà ní ìròyìn èké nípa rẹ̀ ń pọ̀ si Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Obasanjọ: Ọbasanjọ ní òhun yóò fi ìyókù ayé òun san oore Ọlọrun ni Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Fadeyi Oloro: Ọfọ̀, àyájọ́ kò ràn án lọ́jọ́ tí 'ṣó o láyà' bá a lálejò Abẹsẹkubiojo Kiwi Middleweight fun UFC yoo koju Romero nínú ija oni pele marun ni Las Vegas ní ọla ode yìi, eyi ti yoo jẹ ijà akọkọ láti igba ti o ti doju Robert Whittaker boleẹ̀ninu oṣu kẹwàá ọdun to kọja, eyi túnmọ si pe ìpo Middleweight náà tọ si ti o ba na Romero Romero máà n fi ara rẹ han bi ẹni to le koko ti ko si si ẹni to le bori rẹ lati igba to ti yan iṣẹ́ náà láàyò.
Alaga ẹgbẹ ni oun tabi gomina ko si ni ilu Ibadan nigba ti o ṣẹlẹ ṣugbọn nkan ti wn ṣalaye fun oun ni pe taya ọkọ lo fọ lori ere, arakunrin naa lo si n wa ọkọ to wa jẹ pe ẹgbẹ ọdọ rẹ ni taya ti fọ.
Ṣugbọn Dafidi ati àwọn ọkunrin rẹ̀ ti wà ní aṣálẹ̀ Maoni tí ó wà ní Araba lápá ìhà gúsù Jeṣimoni.
9 50157 Orilẹede Naijiria 1405 0.
ṣugbọn tí kò tún wu ọkọ titun náà, tí òun náà tún já ìwé ìkọ̀sílẹ̀ fún un, tí ó sì tún tì í jáde kúrò ninu ilé rẹ̀, tabi tí ọkọ keji tí obinrin yìí fẹ́ bá kú, 
Mercy ló gbadé BBNaija ọdún 2019 Keisha sàlàyé ìdí tó fi sunkún ní ìyàrá ìrántí nílé ẹlẹ́gbọ̀n ọ́n àgbà, ayé pariwo Oríṣun àwòrán, Others Ka3na àti Lilo ló kọ́kọ́ dágbére fún ètò Big Brother Naija 2020 Ka3na àti Lilo ló kọ́kọ́ dágbére fún ètò Big Brother Naija 2020 Lilo ati Ka3na ni eeyan meji akọkọ ti wọn le kuro ninu eto Big Brother Naija season 5 lockdown, lẹyin ọsẹ meji ti wọn ti lo.
Bí a bá ní ìwúrí, ẹ̀yin náà yóo ní ìwúrí; ìwúrí yìí yóo sì kọ yín ní sùúrù nígbà tí ẹ bá ń jẹ irú ìyà tí àwa náà ń jẹ.
elo oju ogun ti ijoba ti pese, ti to fun wa lati wu wa loril”Ogagun Akinroluyi tun fikun oro
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Anthony Obiagbaoso Enukeme: Àkójọpọ̀ àwòrán àràǹbarà nípa ìsìnkú ọlọ́rọ̀ ọmọ Nàíjíríà 16 Ògún 2020 Anthony Obiagbaoso Enukeme ni alaṣẹ agba fun ileesẹ elepo rọbi Tonimas oil, ọmọ bibi ipinlẹ Anambra nii se.
Ó tún sọ pé,“O ti wà láti ìṣẹ̀dálẹ̀ ayé, Oluwa,ìwọ ni o fi ìpìlẹ̀ ayé lélẹ̀.
Nígbà náà ni Abrahamu dojúbolẹ̀, ó búsẹ́rìn-ín, ó sì wí ninu ara rẹ̀ pé, “Ọkunrin tí ó ti di ẹni ọgọrun-un (100) ọdún ha tún lè bímọ bí?
Ọba bá pe gbogbo àwọn iranṣẹ tí wọ́n wà lábẹ́ àwọn gomina ìpínlẹ̀ jọ, gbogbo wọn jẹ́ ojilerugba ó dín mẹjọ (232), ó sì pe gbogbo àwọn ọmọ ogun Israẹli jọ, gbogbo wọ́n jẹ́ ẹẹdẹgbaarin (7,000).
Nígbà tí mo fi wà ní Geṣuri, ní ilẹ̀ Siria, mo jẹ́ ẹ̀jẹ́ fún OLUWA, pé bí ó bá mú mi pada sí Jerusalẹmu, n óo lọ sìn ín ní Heburoni.
Àkókò tí mo ń sọ̀rọ̀ rẹ̀ yìí, ẹ̀rù kò tilẹ̀ tún wáá bà mí mọ́ nítorí ọkan mi ti ń kúrò nínú ayé mo sì ti bẹ̀rẹ̀ sí ronú òde ọ̀run.
Oríṣun àwòrán, Facebook/Barrister fans page Àkọlé àwòrán, ṣe ẹyin ranti orin kekere arosọ?
“O ti gbọ́ bí wọn tí ń pẹ̀gàn mi, OLUWA,ati gbogbo ète wọn lórí mi.
Ki eniyan  maa jo ninu afefe jẹ ọkan lara ijo ti o wọpọ laarin awọn abarapa ni orile ede Kenya.
ile-ise to n ri si ile kiko ati oju popo (Nigerian Building and Roads Research
Ní Heburoni, níbi tí Dafidi ti jọba fún ọdún meje ati ààbọ̀, ni wọ́n ti bí àwọn mẹfẹẹfa fún un.
idagbasoke si n wọle, nitori naa, ko  si iye owo to pọju lati fi se atunse si eto ọrọ
Bakan naa lo ni ki wọn si awọn to ku ni ọjọ kọkanlelọgbọ̀n osu kejila ọdun yii.
Sibẹ, ijọba Naijiria ti sọ lọpọ igba pe awọn run Boko Haram jegejege ki awọn agbesunmọmi ọhun to tun turi jade fun iwa ipa to n pọ sii.
Ninu fọnran fidio kan ti o ti gbode kan ni arakunrin naa Pawan Kumar ti sọ pe ohun ṣeṣi dibo fun ẹgbẹ to wa lori oye, Bharatiya Janata Party (BJP).
IRAN -Aarin gbungbun Ila Oorun Afrika ni o wa.
Yahoo Yahoo: Dating , Construction, awọn tó ń ṣe credit card
O ni ''púpò nínú àwọn to salo kò mò wí pé òun to wa leyin ẹfa ju èje lọ.
Bẹ́ẹ̀ náà ni ó ń ṣe láàrin ọjà, ó ń bá ẹnikẹ́ni tí ó bá wà nítòsí sọ̀rọ̀.
O gbọdọ̀ ṣe ẹ̀dà iwé yìí ti o ba ti forúkọ silẹ tan lóri ayélujara: (a) Iwe ti o fi han ọmọ ipinlẹ ti o jẹ́; (b) Alága ìjọba ìbilẹ̀ rẹ̀ gbọdọ̀ tọ́wọ́bọ̀wé ìjẹ́ri si tabi ọgá ológún kan (d).
Akeredolu, tó ò bá fa àkóso Ondo lé mi lọ́wọ́ láàrin ọjọ́ 21, o tàpá sófin - Igbákejì gómìnà Oríṣun àwòrán, @RotimiAkeredolu Ọrọ ti n ba ọrọ bọ nipinlẹ Ondo lori bi ajọsepọ to wa laarin gomina Rotimi Akeredolu ati igbakeji rẹ.
Iléesẹ́ ọlọ́pàá Uganda mú akọrin Naijiria, Omah Lay fún rírú òfin ìlànà Covid-19 Oríṣun àwòrán, @canadian_chops Ileesẹ ọlọpaa orilẹ-ede Uganda ti mu gbajugbaja akọrin takasufe, to jẹ ọmọ Naijiria, Omah Lay, ati awọn eeyan meji mii, fun titapa si ilana Covid-19.
Maradona gbarada nigba to gba ami ẹyẹ liigi ọjẹwẹwẹ Argentina pẹlu ẹgbẹ agbabọọlu Boca Juniors lọdun 1982.
 Lati ijeta ni a ti n gbadura kikan-kikan pe ki Olorun je ki won si I fun wa ki a le wonu re wo”.
5M ti pọ̀ jù fún owó fọ́ọ̀mù ìdìbò abẹ́lẹ́ sípò gómìnà APC - SERAP 'Ọkọ mi yọ kíndìnrín mi láti fi rọpò owó ori' Pásítọ̀ ń sanwó wáàsí mi lórí rédíò, ó fi ń ṣe ìwàásù ní ṣọ́ọ̀ṣì - Akeugbagold O ni Ni kete ti wọn ke si wa, ni awọn oṣiṣẹ wa lọ si ibẹ, ti a si gba awọn ọdaran naa mu lọrun ọwọ pẹlu ori eeyan ati awọn ẹya ara eeyan miran."
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, World TB Day: Funkẹ Dosunmu ni ikọ́ ife kìí pani, ta bá lo òògùn rẹ̀ déédé O ni oun sa kuro ni agọ Boko Hram naa pẹlu ọmọ oun ati awọn obinrin mẹjọ miran, amọ awọn yoku ku sinu igbo nitori aisan ati ebi.
 Gege bi aare Buhari se so lana pe, oun yoo tun pada se ipade pelu awon ogagun naa lati ri daju pe awon wa ojutu si oro awon onise ibi ohun.
Ẹwẹ, amofin Ẹbun-Ola Adegoruwa pẹlu kin ọrọ naa lẹyin.
Ó pe gbogbo àwọn alufaa ati àwọn ọmọ Lefi jọ, ó sọ fún wọn pé, “Ẹ lọ sí àwọn ìlú Juda, kí ẹ máa gba owó lọ́wọ́ gbogbo àwọn ọmọ Israẹli láti máa fi tún ilé OLUWA Ọlọrun yín ṣe ní ọdọọdún.
Ẹnìkan ṣoṣo ni ó fúnni lófin, tí ó jẹ́ onídàájọ́.
"Mama Ṣakirat ti o jẹ iya ẹgbẹ awọn elewe ọmọ ni ọja Ikorodu, ipinlẹ Eko, Naijiria ni ""ṣe ẹ rí eku tí ẹ̀ ń pè yẹn, oúnjẹ tó dára ni"", emi maa n jẹ ẹ daadaa."
Àwọn ọkọ̀ ojú omi tí wọ́n kún fún ọmọ ogun yóo wá láti Kitimu,wọn yóo borí àwọn ará Aṣuri ati Eberi,ṣugbọn Kitimu pàápàá yóo ṣègbé.
Nigba ti BBC Yoruba beere lọwọ ọgbẹni Adewole pe ṣe biba awọn foonu naa jẹ ko ni da bi iwa basejẹ lati ọdọ ile ẹkọ naa, o sọ pe: ''Bi eeyan ba fi owo iyebiye ra nnkan ti yoo ṣe ipalara f'awujọ, ṣe a ma ni tori bẹẹ a ko ni gba a lọwọ rẹ tabi ki a baa jẹ ki o to le ṣe ipalara f'awujọ?
Ileeṣẹ ọlọpaa ni Kano ti ṣe ayẹwo fun awọn eniyan to le ni ẹgbẹrun mẹtala ti wọn fẹ darapọ mọ wọn, Agbẹnusọ ileeṣẹ awọn ọlọpaa nipinlẹ naa, DSP Abdullahi Haruna lo fi ọrọ naa lede lasiko ayẹwo naa ni Ọjọ Ẹti ni ilu Kano.
O fi kun un pe, ara ohun to yẹ ki ijọba ṣe bayii ni ifikuluku, ipẹtu-saawọ ati ifidaniloju pe nnkan yoo di ṣiṣe lori ẹhonu wọn.
Egbe ohun, SWAN ni igbagbo pe, iyansipo dokita ohun yoo se anfani fun orile-ede yii lati dojuko awon isoro to n koju eto ilera awon agbaboolu.
Uzor Kalu,lo soro yii lasiko to n ba awon akoroyin soro niluu Abuja pe,ile
Oríṣun àwòrán, Others O ni ko si otitọ ninu iroyin pe, ijọba n fun ẹni kọọkan ninu wọn ni N100,000, wi pe N20,000 ni awọn n san fun wọn.
Tí ìrandíran ọmọ adáríhunrun yóò ma jẹ àǹfààní rẹ̀
Mo ti hùwà òmùgọ̀, ohun tí mo ṣe burú pupọ.
 orin tó gbalágboko ni pẹ ̀ lú .
Ipinlẹ Bayelsa jẹ ọkan lara awọn ipinlẹ ni guusu Naijiria ti a da silẹ lọdun 1996.
Ni ipari won ni ki awọn musulumi tubọ maa gbe ni alaafia ninu atejade naa ti Amofin Muhammad Sani Garba fọwọ si gẹ́gẹ́ bii alaga MULAN.
Kiko ọgọrun eeyan pamọ fun iyasọtọ ati itọju: Ko din ni ọgọrun eeyan to ba ọmọ ilẹ Italy to ko arun Coronavirus wọ Naijiria, ti ijọba ko si ipamọ fun ayẹwọ ati itọju.
Ọjọ diẹ ṣaaju ọjọ naa ni Kyari pada si orilẹ-ede Naijiria nibi to ti lọ duna-dura okoowo kan pẹlu ileeṣẹ Siemens AG.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Toyin Abraham: Ó dára ká ní àròjinlẹ̀ pé ayé ni Ọlọ́run fi ju ẹ̀dá lọ 21 Òkùdu 2020 Oríṣun àwòrán, Instagram/toyin abraham Yoruba ni lowe lowe ni a n lu ilu agidigbo, ọlọgbọn lo n jo, ọmọran si lo n mọ ọ.
Tí igun òṣèlú kọ̀ọ́kan sì máà n gbìyànjú láti ta ara wọn yọ.
“Lọ sí òkè Abarimu tí ó dojú kọ ìlú Jẹriko, ní ilẹ̀ Moabu.
Yóo sá lójú ogun,a óo sì kó àwọn ọmọkunrin rẹ̀ lọ máa ṣiṣẹ́ tipátipá.
Ẹgbẹ oselu naa to se ijọba laarin ọdun 1999 si 2015 ni pẹlu ọrọ ti gomina ipinlẹ Yobe, Alhaji Ibrahim Geidam sọ lori isẹlẹ ijinigbe naa wipe kiko ti awọn alasẹ ileesẹ ọmọogun ko awọn ọmọogun kuro ni agbegbe naa lo silẹkun gbaragada silẹ fun awọn ikọ adukukulaja naa lati wọle se ọsẹ wọn.
Jesu wí fún wọn pé, “Ẹ mú wá ninu ẹja tí ẹ ṣẹ̀ṣẹ̀ pa.
"Báyìí ni 50 Kobo ṣe dá ìfẹ̀hónú ""Ali Must go"" sílẹ̀ tó mú ọ̀pọ̀ ẹ̀mí akẹ́kọ̀ọ́ lọ Àwọn olóṣèlú Nàìjíríà márùn ùn tó sọ̀rọ̀ tí ará ìlú fà ìbínú yọ 'Ọlọ́pàá kò yìnbọn pa olùwọ́de EndSARS kankan' Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Kété tí wọ́n bá ti báa yín sùn tàn torí pé ẹ tóbi, ẹ gbà pé ìfẹ́ yẹn ti parí - Auntie Remi Ọlọ́yàn ńlá Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!"
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìkọlù UK: Agbébọn pa ọmọ asòfin àpapọ̀ Nàíjíríà kan 28 Ẹrẹ̀nà 2018 Oríṣun àwòrán, Facebook/ Dolapo Badru Àkọlé àwòrán, Abraham Badru ni ọmọ kansoso tí ìyá rẹ̀ bí Àwọn agbébọn ti pa ọ̀dọ́kùnrin kan, Abraham Badru, ẹni ọdún mẹ́rìndínlọ́gbọ̀n, tíí se ọmọ Asòfin Dọlápọ̀ Badru, tó ń sojú ẹkùn ìdìbò erékùsù ìpínlẹ̀ Èkó ní ilé asojú sòfin ní Àbújá.
O ni abala ojilerugba o din mẹsan ofin iwa ọdaran ilẹ wa lo sọrọ nipa awọn iwa kotọ lawujọ.
Aminu ni awọn yoo tẹsiwaju lati maa ja fun Nazir ki wọn le tu u silẹ.
Bí mo bá lọ sọ fún Ahabu pé o wà níhìn-ín, tí kò bá rí ọ mọ́, pípa ni yóo pa mí; bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé láti ìgbà èwe mi ni mo ti bẹ̀rù OLUWA.
Ọọni: Ilẹ̀ ifẹ̀ ní ìran Ìgbò tí ṣẹ wá kìí ṣe ilẹ̀ juu
Ilé aṣòfin ti buwọ́lu Tanko Muhammad gẹ́gẹ́ bi adájọ́ àgbà Nàìjíríà CAN kò rán ẹnikẹ́ni lọ ṣọ́ọ̀ṣì COZA, iṣẹ́ ara wọn ní wọ́n lọ jẹ́ -Samson Ayokunle Yinka Ayefele di bàbá ìbẹta Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
''Àwọn ọmọ wa ma ń wọ ọkọ̀ ojú omi láìsí ẹ̀wù ìdàábòbò nítorí àti kàwé'' Alagba S.
Abewo aare Macron ohun lotun mu itunmo otun wa sile igbafe naa, bee si ni, aare ohun fikun oro re pe, orile-ede Naijiria se pataki bi igberu ba fe ba asa ati ise nile Afrika.
Nítori àwọn àtúgbẹ́yẹ̀wò, o níra láti ṣe àkójọpọ fún àwọn ọkọ́ naa Orisun: Johns Hopkins University atawọn ajọ eto ilera ilu Iye akọsilẹ to waye gbẹyin 15 Oṣù Ṣẹ́rẹ́ 2021 20:44 WAT+3 Kí lawn ọmọ Naijiria n reti lẹnu Aarẹ?
Lojiji ni awọn agbebọn kan ya wọ ilu Dongon ti wọn si fi ọpọ ẹmi ṣòfò.
Ẹ̀yin tí ẹ fẹ́ràn OLUWA, ẹ kórìíra ibi;OLUWA á máa dá ẹ̀mí àwọn olùfọkànsìn rẹ̀ sí,a sì máa gbà wọ́n lọ́wọ́ àwọn eniyan burúkú.
Bi arun ọhun ṣe n ṣoro ni Europe, lo n pọ si ni America.
"Oríṣun àwòrán, Event Plus BBC Yoruba ṣe akọjọpọ awọn fọto oriṣiriṣi nipa awọ oju wọn fun un yin: Ohun ti dokita ti BBC ba sọrọ sọ niyii: ""O ṣee ṣe ki Risikat Azeez atawọn ọmọ rẹ mejeji ni ohun to jọ mọ irufẹẹ ""Àfín"" kan ti oyinbo n pe ni ""Ocular Albinism"" eyi to jẹ nkan teeyan n ni lati iran de iran to si jẹ ohun to maa n mu adinku ba awọ lẹyin oju eeyan""."
OLUWA ti sọ fún mi pé kí n bukun wọn,Ọlọrun pàápàá ti bukun wọn, èmi kò lè mú ibukun náà kúrò.
Arabinrin Bello fikun pe, ko si ohun mii ti wọn n fi owo ti wọn ri gba ṣe yatọ si amojuto ile ti wọn ko tii kọ tan.
olusakoso ile-ise to n mojuto owo ifeyinti lorile ede Naijiria.
Góòlù pọ̀ ní ìlú Madaka ṣùgbọ́n wọn kò ní ọ̀nà fún ọgọ́rùn ún ọdún Àìsàn ìtọ̀ súgà kò túmọ̀ sí pé èèyàn ti gba ọjọ́ ikú- Dókítà Wilson Kí láwọn ohùn àmúyẹ tí kọmẹńtátọ̀ tó dáńtọ́ gbọ́dọ̀ ní?
Baba àwọn aláìníbaba ati olùgbèjà àwọn opó ni Ọlọrun,ní ibùgbé rẹ̀ mímọ́.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Uber Lady: Bùkátà pọ̀ lọ́rùn mi ní mo ṣe ń wa taxi akérò Awọn nkan miran ti o ba ikede yi wa ni wọn yi: Awọn ọlọkọ baalu yoo bẹrẹ isẹ lorile-ede Naijiria nikan Awọn akẹkọọ ile ẹkọ to fẹ se idanwo asekagba ni ile iwe alakọbẹrẹ ati girama yoo pada si ile ẹkọ Ni awọn ijọba ibilẹ ti ọwọja arun yi ko pọ, lilọ bibọ ọkọ yoo maa waye ‘Ọ̀pọ̀lọpọ̀ ni inú wọn kò dùn sí bí Hajj kò ṣe ní wáyé lọ́dún yii’ Ìbánújẹ́ gbọkàn àwọn èèyàn nílé abílékọ ọlọ́mọ mẹ́ta tí wọ́n ṣẹ̀ṣẹ̀ pa ní Ibadan Ẹ wo ìṣẹ̀lẹ̀ nípa ẹ̀sùn ìfipábánilòpọ̀ tí wọ́n fi kan D'banj ní sísẹ̀-n-tẹ̀lé Eji Gbadero, ọmọ Ibadan àti jayé-jayé ọmọ ónílẹ̀ ti wọn yẹgi fun l'Eko Bàbá ẹni ọdún 61 bá ọmọ rẹ̀ lopọ̀, ó fún un lóyún l'Eko Awọn garaji ọlọkọ ni lati pese ọsẹ ifọwọ, aaye ti awọn ti o fẹ wọ ọkọ yoo duro si ti wọn ko si ni gbe ju ida meji iye ero ti wọn n gbe tẹlẹ Ilana to de awọn ile igbafẹ, ile ounjẹ, si wa nilẹ.
Ogbeni Bolaji Tunji salaye pe, gomina Ajimobi ro Onimo ero Seyi Makinde lati ri
Ọmọ osu mẹrin ni Coronavirus nilẹ Cambodia: Bakan naa ni orilẹ-ede Cambodia tun ti fidi eniyan mẹẹrin miran to ni arun naa lara mulẹ.
Ninu ọrọ kan to sọ, Bibeli naa to pe ni Bibeli Mimo Atoka, Kumuyi sọ pe, oun sisẹ pọ pẹlu awọn onimọ èdè Yoruba fun ọdun mẹẹdogun, fun iwadii to yẹ, ki kikọ ati títẹ̀ rẹ to o pari.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ìtàn tó wà nídi òwe ‘Sebótimọ Ẹlẹ́wà Sàpọ́n’ Mo fẹ́ ọkọ mi torí bó se ń kọrin, kìí se torí owó - Ìyàwó Aràrá Mo fẹ́ kí àyẹyẹ ìgbeyàwó mi dùn ni mo se bú sẹ́kún - Ọkọ ìyàwó ẹlẹ́kún Ṣẹ̀ s’ófin ìrìnà l‘Eko, ko fi ẹ̀wọ̀n ọdún mẹ́ta jura - Ìjọba Eko Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Òkè Ìdànrè: Òkè tó kéré jùlọ jẹ́ ẹsẹ̀ bàtà 3000 Shogunlẹ, ẹni to bo ọrọ yii loju boro, lasiko to n dahun ibeere kan ti ẹnikan ju si loju opo naa, fi kun pe, bi o tilẹ jẹ pe iwa ibalopọ ninu ọkọ ko sẹ si ofin Naijiria, sibẹ, awọn gbedeke kan rọ mọ isẹlẹ yii.
Àwọn akẹ́kọ̀ọ́-binrin Naijiria òhun, lo gba ipò kínní láàrin ẹgbàá oludije tó ṣe àfihàn iṣẹ ọwọ wọn níbi ìdíje náà.
3bílíọ́nù tó farapamọ́ fọ́dún mẹ́wàá 28 Ìgbé 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 15 Èbibi 2020 Oríṣun àwòrán, Aketi Àkọlé àwòrán, Owó gọbọi wá nídìí oko-owo igbó gbingbin, Ìpínlẹ̀ Ondo kò ní pẹ gba àṣẹ láti gbin - Akeredolu Ijọba ipinlẹ Ondo ni awọn ti ṣawari owo kan to le ni biliọnu mẹrin naira to pamọ sinu aṣuwọn ifowopamọsi idakọnkọ kan fun odindi ọdun mẹwaa.
Lo gbaye kan lori ikanni ayelujara bayii lori iroyin olukọ miran ni fasiti Ọbafẹmi Awolọwọ ile ifẹ, OAU ti wọn ni aje tun ṣi mọ lori bayii o lori pe oun naa tun fẹ ba akẹkọọ lajọṣepọ ko to lee fun un ni maaki.
Oríṣun àwòrán, @thisislagos1 Bakan naa, aarẹ ile asofin agba, to jẹ ọmọ bibi ipinlẹ Kwara, Dokita Bukọla Saraki, naa ti daro lori iku awọn eeyan naa.
Ohun tí wọ́n fi ń ṣe báàgì, bàtà ni wọ́n ń tà bíi ‘pọ̀ǹmọ́’— NAFDAC Owó tí Dino nà kò tilẹ̀ tó ra epo sí gẹnẹrétọ̀ tí a fi kọrin - Ayefele 'Nàìjíríà, ṣọ́ra, ogun ń sọ ilé ọlá di ahoro!
Ó yá, ẹṣin, ẹ gbéra,kí kẹ̀kẹ́ ogun máa sáré kíkankíkan!
Ṣugbọn yóo jẹ́ aláìmọ́ títí di ìrọ̀lẹ́ ọjọ́ náà.
Níbi tí ó ti ń bínú sí àwọn alufaa, àrùn ẹ̀tẹ̀ yọ níwájú rẹ̀, lójú àwọn alufaa ninu ilé OLUWA.
Ọba Adeyẹmi, lasiko to n sọrọ salaye pe awọn alalẹ ati iran to n bọ lọjọ iwaju ko ni forijin oun, ti oun ba kọ lati maa se ajọdun Sango lọdọọdun, gẹgẹ bii ọkan lara awọn ọba to ti jẹ ri nilu Ọyọ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ìgbésí ayé àwọn ọmọdébìnrin wọ̀nyìí di ọ̀tun láti 2008 Eyi lo fi bẹrẹ iwọde ojoojumọ ṣe lodi si iwa Alake ati Ajẹlẹ yii.
Oríṣun àwòrán, Twitter Àkọlé àwòrán, Ajọ awọn oṣiṣẹ olukọ ile ẹkọ giga Amọ ijọba ni idi ti awọn fi gbe e kalẹ ni lati gbe ogun ti iwa ibajẹ ati jẹgudujẹra to wa ni ẹka oṣiṣẹ ijọba lorilẹede Naijiria.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Sarri: Ìbéérè márùn ùn yìí ni Chelsea ní láti dáhùn 16 Òkùdu 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Maurizio Sarri nigba ti wọn gba ife ẹyẹ Europa League Bi Maurizio Sarri ṣe fi Chelsea silẹ lọ Juventus, ẹgbẹ agbabọọlu naa n ti n wa akọnimọọgba kejila ti ṣe akoso lati igba ti Roman Abramovich ti ra Chelsea.
Bakan naa , aare yoo tun maa
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Òtítọ ní Obasanjo sọ, Buhari n fí agbára fún ẹlẹ́yàmẹ̀yà ní Nàìjíríà-Soyinka 9 Òkùdu 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 15 Owewe 2020 Oríṣun àwòrán, CHARLES IGBINIDU/Twitter Onkowe Ọjọgbọn Wole Soyinka ti ṣe atilẹyin fun ọrọ ti aarẹ ana Olusegun Obasanjo sọ wi pe ogun ẹlẹyamẹya gbinlẹ si labẹ ijọba Aarẹ Buhari.
Alufaa kò gbọdọ̀ jẹ ohunkohun tí ó bá kú fúnrara rẹ̀, tabi tí ẹranko burúkú bá pa; kí ó má baà fi òkú ẹran yìí sọ ara rẹ̀ di aláìmọ́.
Jesu dá wọn lóhùn pé, “Àwọn ọ̀rẹ́ ọkọ iyawo kò lè máa ṣọ̀fọ̀ níwọ̀n ìgbà tí ọkọ iyawo bá wà lọ́dọ̀ wọn.
Neo Amọṣa lẹyin eto alalẹ ọjọ Aiku nibi ti wọn ti maa n kede ẹni ti ile ya fun ni olugbalejo eto naa, Ebuka Obi-Uchendukede orukọ Kaisha gẹgẹ bi awọn olukopa ti awọn to n wo eto naa dipbo fun pe ki wọn maa gba ile wọn lọ.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Àwọn iròyin ẹlẹ́jẹ̀ márùn ún tó fẹ́ẹ̀ tú Nàìjíríà ká Bó ṣe ń wáyé ní Oyo, ló tún ń ṣẹlẹ̀ ní Kano, ilé ẹjọ́ júwe ilé fún Emir mẹ́rin tí Ganduje yan Ẹ wo àwọn ọ̀dọ́mọdé Naijiria tó ń ṣe bẹbẹ nínú isẹ́ aládaní nílé Àwọn agbébọn kọlu Kọmísánà fọ́rọ̀ ilẹ̀ àti ilégbèé ní Ọyọ, awakọ̀ dèrò ọ̀run Èwo nínú àwọn amóhùnmáwòrán yìí lẹ rántí?
”OLUWA Ọlọrun Israẹli ló sọ bẹ́ẹ̀.
Ṣugbọn nigba ti BBC Yoruba kan si Ileesẹ ọlọpaa ipinlẹ Oyo lati fi idi iṣẹlẹ naa mulẹ, alukoro ọlọpaa nipinlẹ Ọyọ, Olugbenga Fadeyi ni iṣẹlẹ naa ko tii de etigbọ awọn agbofinro rara.
Lẹ́yin o rẹyin ọ̀gbẹ́ni Amusan gbà pé , o di dandan ki òun ló tún ẹ̀kọ Yoruba kọ nítọri pe imọ oun kù díẹ̀ káàto nínú àwọn ibéèrè ti a bii Òfìfo ṣọ́ọ̀ṣì pa aṣọ dà fún àwọn Páṣítọ̀ Nàìjíríà Àwọn Alákòso gárèjì ló kó ìbọn àti àdá tọ ọlọ́kadà wá ní Soka-Alága ẹgbẹ́ ọlọ́kadà Ọyọ Èèyàn 17 mííràn tún ti lùgbàdì ààrùn Coronavirus ní Naijiria Funke Akindele jẹ àkàndá ẹ̀dá- Adaku inú eré Jẹnifa Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí kan sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
Kí ló wá fa ẹjọ́ o Alákọ̀wé?
 o je akowe agba keji aparapo awon orile-ede lati april 1953 titi di ojo to se alaisi ninu ijamba baalu ni september 1961 .
Ẹgbẹ́ agbabọọlu Arsenal, Brighton ati West Ham ti si ibudo igbaradi wọn silẹ fun awọn agbabọọlu lati ma a da ṣe igbaradi.
Ogunjobu gba bọọlu fun gbajugbaja ẹgbẹ agbabọọlu un ni Shooting Stars ti ilu Ibadan.
 ní latin america àti àwọn apábibìkan ní west africa , ohun tí a mọ ̀ ni wípé Ọkùnrin nìkan ló lẹ jẹ Àràbà Ọ ̀ rúnmìlà , nígbà tí àwọn apá ibìkan ní west africa bákan náà sọbwípé ipò yí náà tọ ́ sí àwọn obìnrin pẹ ̀ lú .
Bakan naa, ni iroyin miran tun so pe, saa keji iforowanilenuwo ohun tun bere pada lojoBo(Wednesday), lagogo mejo owuro.
Akanṣe eto BBC Africa to maa n tu aṣiri awọn nkan ikọkọ tabi to fara sin to si n ṣakoba fun araalu ati ijọba ti fi fidio to wa loke yii tu aṣiri kan ni Naijiria.
Dípò bẹ́ẹ̀ ó ṣe gẹ́gẹ́ bí ó ti wà ní àkọsílẹ̀, “Èmi ni ẹ̀gàn àwọn ẹni tí ó ń gàn ọ́ rẹ́ lára.
un ,eyi ti oba Abdulaziz Al Saud yoo
Mo mọ̀ pé gbogbo ohun tí Ọlọrun ṣe, yóo wà títí lae.
Eyi to pọ ninu ọrọ wọn ni ki wọn kọkọ ri awọn ọmọ yi lalaafia.
Gege bi aare se so: “Ipinnu ayeye yii ni lati ri daju pe igbe aye alaafia ati isokan joba laarin awon omo orile-ede Naijiria.
Ọkùnrin náà sì lo ń kó igbaju bo ọmọkùnrin rẹ tó kùnà nínú idanwo náà, ó ní kó naani owo ribiribi tí òun na lè lórí nílé ìwé.
Amúlò òfin náà yóò bẹ̀rẹ̀ láti osù kọkànlá ọdún 2021, èyí yóò sì sọ New Zealand di ọkan lára àwọn ìlú díẹ̀ tí fààyè gbà kí wọ́n ràn èniyàn lọ́wọ́ ikú.
Àwọn ọmọ Adini jẹ́ ọtalelẹgbẹta ó dín marun-un (655).
Alaafin ni inu awọn ọba naa ko dun nitori pe goimna Fayemi fi ọba to kere ni ipo jẹ adari ẹgbẹ awọn lọbalọba nipinlẹ naa, idi si niyi ti wọn ṣe gbe igbesẹ ti wọn gbe.
Mo pàṣẹ pé kí ọ̀gá owó ìfẹ̀yìntì tẹ́lẹ̀, Maina sì wà látìmọ́lé- Adájọ́ Àjọ AMCON gbẹ́sẹ̀lé gbogbo ǹkan ìní Jimoh Ibrahim tó lé ní N69 bíliọ̀nù Mí o fẹ́ kí wọ́n tún jí mi gbé léèkejì- Falae ké gbàjarè!
Bẹẹ loun pẹlu tun beere Sowore.
Ṣé kí eniyan lè doríkodò bíi koríko etí odò nìkan ni?
” Kíá, ó bá dìde, ó ń tẹ̀lé e.
Nígbà tí Òjòlá-ìbínú bẹ̀rẹ̀ sí ọ̀rọ̀ í sọ ọ̀nà ọ̀fun rẹ̀ bẹ̀rẹ̀ sí kù bí òjò,ojú rẹ̀ sì dàbí ìlẹ̀kẹ̀ pupa.
Ni bayii, oku arabinrin naa ni wọn ti gbe lọ si ile igbokupamọsi ti ile iwosan gbogboogbo Ijọba ni Ifọ, Ipinlẹ Ogun.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Omi ìṣẹ̀ńbáyé tó ń dà ní Ówù rèé, èyí tó ga jùlọ ní Afirika Àlá àwọn òjíṣẹ́ Olúwa tó fẹ́ jẹ ààrẹ Nàíjíríà leè má ṣẹ lógún ọdún - Abiara Ìbẹ̀rẹ̀ mi kò rọrùn rárá, omi máa ń bọ́ lójú mi tí mo bá rántí àkókò náà - Small Doctor Ẹ̀kún omi lé ọ̀pọ̀ onílé ní àdúgbò Isheri ní Eko Kèǹgbè lílù ní Ilọrin rèé, orin ìgbéyàwó, àwàdà àti ẹ̀ẹ̀kẹ́ èébú Àwọn ajínigbé jí adájọ́ gbé, ẹ̀mí ọlọ́pàá tó ń ṣọ ọ́ lọ sí i Omolola ni airin lọwọọwọ nii jẹ ọmọ ejo niya, amọ ti awọn obinrin ba dide tako awọn iwa ipa ti awọn ọkunrin n hu si wọn ni awujọ, adinku yoo ba iya to n jẹ wọn.
'Omi mimọ' ti wọn gbe kalẹ ni wọn sọ di aimọ, nipa kiki nkan si oju ara obinrin.
Lagos Flood: Wọ́n ṣì ń wa àwọn ọmọ méjì tí àgbàrá òjò wọ́ lọ ní Ketu l'Eko
Saraki tako ìròyìn tó ní àjẹmọ́nú Sẹ́nétọ̀ yóò di ₦15m Ọsinbajo kó Ambọde, Sanwo-Olu lẹ́yìn láti pín owóyàá l‘Eko Fayoṣe ní ìbéèrè mẹ́rin fún Buhari lórí ìwé ẹ̀rí rẹ̀ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ìnú mi kìí dùn nígbà trí mo ń ṣiṣẹ́ ni bánkì tó ìgbà ti mo bẹ̀rẹ̀ mẹkáníìkì Joseph ni iwadii ti n lọ lọwọ lati ri awọn ajinigbe naa ati lati doola ẹmi awọn ti wọn jigbe naa.
Ewe, ifigagbaga ohun ni yoo fun akonimoogba agba iko Super Eagles, Gernot Rohr  ni aaye lati mo agbaboolu ti o kaaju osuwon julo lati lo ninu idije agbaye naa, ni paapajulo ekaa awon asole, yoo fun n lanfani lati mo asole ti o darajulo ti yoo je eni akoko lati yan.
Nígbà tí Jesu gbọ́ ọ̀rọ̀ yìí, ẹnu yà á.
Òkú àwọn eniyan yìí yóo di oúnjẹ fún àwọn ẹyẹ ati fún àwọn ẹranko, kò sì ní sí ẹni tí yóo lé wọn.
Àwọn ọmọ àwọn iranṣẹ Solomoni nìyí:àwọn ọmọ Sotai, àwọn ọmọ Hasofereti, ati àwọn ọmọ Peruda;
O ni lorileede Naijiria iyatọ wa laarin ki eeyan bẹru Ọlọrun ati ki eeyan maa tẹle ẹsin kan.
Nígbà tó ń sọ̀rọ̀ lórí bí ìjọba ṣe de òkun lórí àṣẹ konile ó gbélé, ó ní igbese ìjọba náà lo fihan pe, ijọba tó ń gbọ igbe aráàlú lo wà nita, eyi tó fún wọn láǹfààní láti jáde síta lọ wà jíjẹ àti mímú.
Ọjọ́ kẹrìnlá, oṣù keje, ọdún 2020 ni ojú òpó ìgbànisíṣẹ́ náà sí sílẹ̀ tí yóò sì pari ni ọjọ́ kẹtàlélógún, oṣù kẹjọ, ọdún 2020.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Èmi gan máa ń béèrè lọ́wọ́ ara mi pé ta ni Wole Soyinka gangan' Oṣu kẹrin, ọdun 1978 ni Funmilayọ jade laye.
Ita-gbangba awọn alenulọrọ yii ni Igbimọ to n ri si eto Iroyin, Aabo ati
Lẹyin ti iṣejọba Naijiria yi pada lọdun 1975 Soyinka pada wale lati tẹsiwaju iṣẹ rẹ ni fasiti Ile Ifẹ.
Nígbà tí a dé Jerusalẹmu, àwọn onigbagbọ gbà wá tayọ̀tayọ̀.
Ó sì mú akọ mààlúù meji, àgbò marun-un, òbúkọ marun-un ati ọ̀dọ́ àgbò marun-un, ọlọ́dún kọ̀ọ̀kan wá fún ẹbọ alaafia.
Ilẹ̀ Tí Wọ́n Pín fún Ẹ̀yà Simeoni.
O si da oun loju wí pé ni igba ti Olόyè Ògbójú bá pa ipò dà, gbogbo owó-o rẹ̀ yόò di ti Ìdààmú-Ayé.
Ìfẹ́ tí o ní sí mi, kò ṣe é fi ẹnu sọ,ó ju ìfẹ́ obinrin lọ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ta ni Ọjọgbọn Adebanji Akintoye tó borí Tinubu láti di olórí àwọn Yoruba?
Esi ibo gomina ni ipinlẹ Ekiti lati ijọba ibilẹ kọọkan: 1) Ijọba ibilẹ Ìlejeméje: APC - 4,153, PDP- 3,937 2) Ijọba ibilẹ Osí: APC - 12,342, PDP - 11,145 3) Ijọ̀ba ibilẹ Ifẹlodun/Irẹpọdun: APC- 13,869, PDP- 11,456 4) Ijọba ibilẹ Ọyẹ́: APC - 14,995, PDP - 11,271 5) Ijọba ibilẹ Ẹ́fọ̀n: APC - 5,028, PDP - 5,192 6) Ijọba ibilẹ Mòbà: APC - 11,837, PDP - 8,520 7) Ijọba ibilẹ Ìjerò: APC - 14,192, PDP - 11,077 8) Ijọba ibilẹ Gbọnyin: APC - 11,498, PDP - 8,027 9) Ijọba ibilẹ Emùré: APC - 7,048, PDP - 7,121 10) Ijọba ibilẹ Ìkẹ́rẹ́: APC - 11,515, PDP - 17,183 11) Ijọba ibilẹ Iwọ-Oorun Ekiti: APC - 12,648, PDP - 10,137 12) Ijọba ibilẹ Ìkọ̀lé: APC - 14,522, PDP - 13,961 13) Ijọba ibilẹ Isẹ/Ọrun: APC - 11,908, PDP - 6,297 14) Ijọba ibilẹ ila oorun Ekiti: APC - 12,778, PDP - 11,564 15) Ijọba ibilẹ iwọ oorun Guusu Ekiti: APC - 11,015, PDP 8,423 16) Ijọba ibilẹ Ado: APC - 28,111, PDP - 32,810 Oríṣun àwòrán, @APCNigeria Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Eyi lo mu ki ijọba gbe owo epo bẹntiro lọ si N141 lati N65, lẹyin naa lawọn eeyan bẹ sita ti wọn si bẹrẹ ifẹhonuhan kaakiri orilẹede Naijiria.
Ọpọ eeyan lo ti n bere pe Kí ló ṣe ikú pa Adewura Latifat Bello lẹ́yìn ọ̀sẹ̀ méjì tí wọ́n ń wá a?
A - Agbonmagbe Tosin Omowumi 13APCAdegboyega Isiaka Oyetola - Benedict Olugboyega Alabi 14APGAOluwatoki Adetokunbo Adedayo A.
Ìlú Èkó ni genevieve nnaji ti dàgbà .
Àkọlé àwòrán, Àwọn ọlọpaa ati akanṣe SWAT di ẹnu ọna Sinagọọgu naa pa Ẹsun mọkandinlọgbọn ni wọn fi kan ọkunrin ọmọ ọdun mẹrindinlaadọta yii bii didena ijọsin ati igbagbọ ẹlomii àti ipaniyan.
Nígbà tí a dé Masedonia, ọkàn wa kò balẹ̀ rárá.
Ti aisan lukuluku ba mu adiyẹ lati ori, a lọ si ibi ọna ọfun, eleyii ti yoo mu ki ati riran ni wọn lara.
Da Rocha sunmọ isejọba Gẹẹsi, o jẹ olotitọ eniyan, o korira irọ pipa, o lẹmi iwa ikora ẹni nijanu, bẹẹ ni ko lọwọ ninu oselu sise Da Rocha bẹru Ọlọrun, ọmọ ijọ Aguda, Katoliki nii se, to si maa n fi owo r se annu fawọn alaini Candido Da Rocha jẹ Ọlọrun nipe lẹni ọdun mejidinlaadọrun (88), ti wọn si sin si itẹ oku to wa ni Ikoyi.
"Wàhálà orun Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Nígbà tí agogo rẹ sọ fún o wípé kí o lọ sùn sùgbọ́ ara rẹ sọ wípé ""rara"" Àwọn tí wọ́n ṣe isé àsìkò ọ̀tọ̀tọ̀ àti àwọn èlọ̀míràn ti wọ́n ní kọ́núńkọ́họ láàárín àsìkò ara wọn àti àsìkò ìbagbépọ̀ le ní ńǹkan tí wọ̀n pè ní 'social jet lag'."
Awọn kan ti ọrọ naa soju ni, wọn ge apa rẹ jabọ ninu ikọlu yi.
Leyin odun mejilelogun ti akonimoogba agba iko agbaboolu Arsenal, Arsene Wenger ti n tuko iko agbaboolu ohun, Wenger ti kede bayii lati fi iko naa sile lopin saa to n lo lowo yii.
Ọbinrin yii ti wa ni akolo ọlọpaa bayii, nibi ti wọn yoo ti gbee lọ si ileẹjọ laipẹ.
Idi ni yi ti Canada ṣe n ṣiṣẹ pọ pẹlu Amerika lori ọrọ yii, lati fi opin si bi awọn ọmọ Naijiria ṣe n fi iwe irinna Amerika wọn wọ Canada.
68 Ẹnikẹ́ni tí ó bá kéde púpọ̀ tàbí kéré jù èyí, irú ẹni bẹ́ẹ̀ kìí ṣe ti èmi, ṣùgbọ́n ó jẹ́ alátakò sí mi, nítorínáà kìí ṣe ti ìjọ mi.
''Ijọba ko gbagbe awọn ọlọpaa ni Naijiria.
O ni labẹ ofin owo ori sisan pin si meji.
Idi ree ti ọpọ awọn oṣere tiata lobinrin fi n lo ipara ibora ki wọn lee pupa ni awọ, ti oju wọn yoo si dun wo ninu ere.
 kakiri ise re o je agbejero fun eto araalu ati ija omoniyan .
Ọba bi í pé, “Ṣé alaafia ni Absalomu, ọmọ mi wà?
Kì í ṣe idà tabi ọfà ni ẹ fi ṣẹgun àwọn ọba ará Amori mejeeji, agbọ́n ni mo rán ṣáájú yín tí ó sì lé wọn jáde fun yín.
Ninu ifọrọwanilẹnuwo pẹlu agbẹnusọ fun agba ọjẹ osere naa, Isaac Haastrup,BBC Yoruba fidi ọrọ iku rẹ mule ati wi pe wọn ti gbe oku rẹ lọ si ile igbokupamọsi ni ile iwosan Wesley Guild, nilu Ilesha.
Oríṣun àwòrán, Bukola Saraki/Twitter Àkọlé àwòrán, ọ̀pọ̀ gbágba pé èrò ọkàn Bukola Saraki ni láti di Ààrẹ ilé aṣòfin Àgbà l'Abuja A gbọ pe ẹgbẹ oṣelu APC fẹ yan Aarẹ ile igbimọ aṣofin Agba l'Abuja lati Ila-Oorun Ariwa orilẹ-ede naijiria.
Mercy Aigbe ṣá ọmọ rẹ̀ sínúu fíìmù tuntun, wo itú tí ọmọ ọdún mẹ́wàá náà pa 'Àgbàrá òjò wọ́ ọmọ méjì lọ ní Ketu l'Eko lálẹ́, a ṣì ń wá wọn di òní' Ọkọ mi kò fẹ́ràn oúnjẹ òyìnbó àfi ti ìbílẹ̀ - Lizzy Anjorin Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Mayowa Omoniyi: Kò sí orin Obey, Sunny Ade abí tàkasúfèé tí ń kò le ta gìtá sí Gẹgẹ bi ẹni ti isẹlẹ naa soju rẹ ti sọ fun BBC Yoruba, bi awọn ọlọpaa naa ti n bọ lati Ibadan, oju wọn kọrẹ lọwọ, bi wọn si se wọ ilu Ogbomoso ni wọn kọju oro sawọn araalu ti ko mọwọ mẹsẹ.
Àwọn ọmọ Juda gbéra, wọ́n lọ gbógun ti àwọn ará Kenaani ati àwọn ará Perisi.
Wo àwọn ńkan tí o mọ nípa Oloye M K O Abiọla 2019 Elections: NBC na Channels TV àti ilé iṣẹ́ ìròyìn 44 ní pàsán Ninu ojo, ninu ẹrun, iṣẹ́ iṣẹ́ ni, bẹẹ ni tawọn oniroyin n ri paapaa ju lọ ni akoko yii to jẹ wi pe laarin iṣẹju aaya ni awọn eniyan fi n ka iroyin bayii.
Wike má gbé jàgídíjàgan wá sí Ondo, APC kò ní ṣ'èèrú nínú ìdìbò gómìnà tó ń bọ̀- Kalejaye Èèmọ̀!
Ẹ sáré ní ọ̀nà tí ẹ óo fi rí ẹ̀bùn gbà.
Nuhu fikun pe, lẹyin ọpọ agbeyẹwo ati aato, diẹ diẹ ni ìjọba yoo si awọn papakọ ofurufu yoku labẹle pada.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Àṣírí ńlá tó ń bẹ láàrín Alaafin àtàwọn onílù rẹ̀ rèé Oyedepo àti ìjọba ń tahùn síra lórí bí ìjọba ṣe ń gba àkóso àwọn ilé ìjọsìn EFCC tún gbé Mompha lórí ẹ̀ṣùn lílu jìbìtì lórí ayélujára Ọlọ́pàá méjì wọ gàù lóri bí afurasí apanìyàn l‘Akinyele ṣe sá lọ Ìrìnna ọkọ́ òfúrufú s'ílẹ̀ òkèèrè bẹ̀rẹ̀ padà ní Nàìjíríà Jegede (PDP) ti yan Aṣojúṣòfin Ikengboju gẹ́gẹ́ bí ìgbákejì rẹ̀ tí wọ́n yóò jọ díje dupò Oniruuru ilu ni a ni ni ilẹ Yoruba ti olukuku si ni isẹ ọtọọtọ ti wọn n ṣe, bi a ṣe ni eyi ti a n lo fun ayẹyẹ bẹni ti orisa wa, bakan naa ni eyi ti a n lo fun ayẹsi ọba laafin.
Aare Muhammadu Buhari ti so pe, ko si eya kankan ti oun yoo foju tembelu tabi yo sile labe akoso ijoba re.
Labẹ ofin America, Aare Donald Trump ko lasẹ lati yi ọjọ idibo naa pada siwaju tabi ko sun un sẹyin rara.
Ó dàbí òróró iyebíye tí a dà síni lórí,tí ó ṣàn dé irùngbọ̀n;bí ó ti ṣàn dé irùngbọ̀n Aaroni,àní, títí dé ọrùn ẹ̀wù rẹ̀.
Yẹyẹ ni Duke of Ikorodu fi ọrọ naa ṣe nigba to sọ pe ọkunrin ọun dabi ọmọ ọdun mẹẹdogun loju oun.
Kọmisọnna fun eto ilera naa kesi awọn eniyan lati ni lọkan wi pe arun Coronavirus si n ba ọpọlọpọ eniyan finra, nitori naa ki wọn mu ilera ara wọn lọkunkundun.
Bẹẹ, ọrọ lo ko moko-moro wa ni ọrọ ohun to n ṣẹlẹ nile igbimọ aṣofin ati ninu eto oṣelu ipinlẹ Ondo lati bii ọjọ mẹta sẹyin.
Ṣùgbọ́n Simisola Bolatito Ogunleye (Simi), David Adedeji Adeleke (Davido) àti Omawumi Megbele (Omawumi) lọ gbegba oroke níbi ayẹyẹ náà.
Nítorípé láti abúlée Youlegave dé òkúta Robin Hood, bí onírìnàjò bá ṣe npọ́n òkè náà ni yó ṣe máa sọdá afárá kọjá àwọn odò kékeré.
Nítorí pé Memfisi yóo di òkítì àlàpà,yóo di ahoro, kò sì ní sí ẹni tí yóo máa gbé ibẹ̀.
Bakan naa ni orile ede mejeeji naa yoo tun
Ileeṣẹ BBC gba'lejo ife agbaye FIFA nipinlẹ Eko
Awọn oyinbo pọtugi n pin Oshodi ninu ere ti wọn ba jẹ ninu okowo wọn, eyi to sọ di olowo ati ọlọrọ nigboro Eko.
Ẹwẹ, ọkan lara awọn oloye ẹgbẹ ẹlẹsin Shia, ta a tun mọ si Islamic Movement of Nigeria, IMN, Mohammed Ibrahim Gamawa, ṣalaye pe awọn ọmọ ijọ El-Zakzaky paapa maa n da owo lati fi ra awọn nkan ti olori wọn nilo lahamọ.
Ẹ̀yin ará, ẹ má fi ojú fo èyí dá, pé níwájú Oluwa ọjọ́ kan dàbí ẹgbẹrun ọdún, ẹgbẹrun ọdún sì dàbí ọjọ́ kan.
“Nígbà tí o bá ń wọ inú Àgọ́ Àjọ lọ, ìwọ, ati àwọn ọmọ rẹ, ẹ kò gbọdọ̀ mu ọtí waini tabi ọtí líle, kí ẹ má baà kú; èyí yóo jẹ́ ìlànà títí ayé fún arọmọdọmọ yín.
Ẹ̀yin ẹ yan ọkunrin kan láàrin yín tí yóo sọ̀kalẹ̀ wá bá mi jà.
awon oludije labe egbe oselu APC naa lọ fidii rẹmi.
Olólùfẹ́ mi ṣèèsì fi ọkọ́ gbá mi sí gọ́tà, mo rò pé ọlọ́jọ́ dé ni - Iya Osogbo Bí ìrìnàjó ààrẹ ọlọ́dún méje nílẹ̀ Mali, Keita, ṣe lọ rèé Láì san owó oṣù tẹ jẹ wá, kò sọ́rọ̀ kankan - ASUU sọ fún ìjọba Ìjọ́ mí ní Italy ni mo fi ń ṣèrànwọ́ fáwọn aṣẹ́wó ọmọ Nàíjíríà tó há - Taribo West Ọlọ́pàá méjì wọ gàù lóri bí afurasí apanìyàn l'Akinyele ṣe sá lọ Ile ișẹ ọlọpaa ipinlẹ Oyo ti bẹrẹ ifọrọwanilẹnuwo pẹlu ọlọpaa meji ti Sunday shodipe, ọdaran to n dẹmi awọn ẹniyan legbodo lagbegbe Akinyele, bọ mọ lọwọ.
Ati pe 'bo ku ọkunrin kan ṣoṣo ti yoo tako ijọba apaṣẹ wa a Buhari ati ẹgbẹ oṣelu APC, Ayọdele Fayoṣe ni yoo jẹ ọkunrin naa'.
Bakan naa, igbimo to n mojuto iwa-ibaje ninu ajo CAF ohun, tun fofin de awon adari ifesewonse mewa miiran fun irufe esun naa, eleyi ti ofin de awon miiran fun odun meji, bee si ni awon miiran gba odun mewa.
Ọpọ orillẹede agbaye lo ti kuna lati pese aabo to peye fawọn oṣiṣẹ eleto ilera lẹnu iṣẹ wọn.
Àwọn míràn ninu igbẹjọ náà ni Ọga agba ọlọpàá àti mínísita fun ọ̀rọ ọlọpàá.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Oúnjẹ ibìkan jẹ́ èèwọ̀ ibòmíì ni ọ̀rọ̀ ọmú ńlá' Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 3 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 5 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ sí: Ilé ìgbìmọ̀ aṣòfin Ekiti yọ abẹnugan rẹ̀ Àyájọ́ ọmọbìnrin gba gbogbo ayélujára tán BBC Yorùbá sàbẹwo sí ilé iṣẹ́ Suncity FM Atiku Abubakar jẹ igbakeji aarẹ lasiko ti Ọbasanjọ fi jẹ aarẹ Naijiria laarin ọdun 1999 si 2007.
18 Ẹrẹ̀nà 2018 Awọn iyatọ to wa ni ara Ọkunrin ati Obinrin ,paapa ọwọ ati ẹsẹ lo ma n sokunfa bii otutu se n mu Obinrin ju Ọkunrin lọ.
Akinyemi sọ pe Baba Iyabo ko kabamọ ọrọ to sọ ninu atẹjade naa.
Lẹyin ti iṣẹlẹ ti Senetọ Abbo ti gba obinrin kan to n tọmọ leti nile itaja nkan ibalopo ni Abuja ni ọrọ yii ti di kari ayeẸ má bínú, mo kábàmọ́ pé mo na obìnrin -Elisha Abbo.
Nítorí n kò mọ bí wọ́n ṣe ń pọ́n eniyan,kí Ẹlẹ́dàá mi má baà pa mí run ní kíá.
Ọrọ nla yii lagbara gan, a ko sile da nikan gbe.
- Olukoya ti ìjọ MFM Ẹni mẹ́ta wọ gbaga ọlọpàá nítori ajílẹ̀ tí wọ́n kó tà ní ọja Daleko ní Mushin Ẹ̀yin ọ̀tá mi, ẹ lọ dì mọ́ òpò ina lọ́dún 2020- Ayodele Fayose Ìjọba Gomina Raman Razak padà wólé arúgbó ní Ilọrin!
Oríṣun àwòrán, @others Àkọlé àwòrán, Elisha Abbo: kí ẹnikẹni ma halẹ̀ mọ Kayọde mi, ẹjọ wà nile ẹjọ́ Bi Senetọ Olurẹmi Tinubu to n ṣoju ẹkun kan nipinlẹ Eko ati Seneto Abbo ṣe tahùn sira wọn lasiko iwadii ọhun lo tun ti di apero fawọn ọmọ Naijiria.
7 24269 Erekusu Bahamas 175 45.
"Olukọni naa ni ko si wahala, sugbọn ko si owo kankan lọwọ mi, mo si yara tete jẹwọ ipo ti mo wa fun wọn pe, inu ahoro kan ni mo n gbe, ko si si owo kankan lọwọ mi.
Botilẹjẹ pe Mamora sọ pe oun ko le sọ iye ti Naijiria yoo san fun awọn agbo naa ni pato , o sọ pe kii ṣe ọ̀fẹ́ ni Madagascar ko fun Naijiria.
(Goal) Ṣé ẹ̀mí ilé aṣòfin lè gbé ṣíṣe ìwádìí 16 bn owó àgbàṣe iná ọba Nàìjíríà?
Linda Ikeji: Sholaye ni bàbá ọmọ mi, ṣùgbọ́n a ti túká
Lẹyin ikọlu lorisirisi ni South Africa ni Naijiria ni ki awọn ọmọ rẹ ti wọn ba fẹ pada sile ki wọn maa bọÀbábọ̀ mi sí orílẹ̀èdè South Africa rè é - Aṣojú Buhari.
Ọlọ́gbọ́n yóo jogún iyì,ṣugbọn ojú yóo ti òmùgọ̀.
Amọṣa, titi di bi a ṣe n sọrọ yii, ọrọ naa ko tii jẹ rodo lọ momi.
O ṣalaye pe igbeṣẹ yi jẹ oun to dun mọ awọn ninu ati pe awọn fẹ ki awọn orile-ede miran naa tẹle apẹrẹ Amerika yi.
Ó ń jẹ koríko bíi mààlúù, ìrì sì sẹ̀ sí i lára, títí ó fi mọ̀ pé Ọlọrun tí ó ga jùlọ, ni ó ní àṣẹ lórí ìjọba eniyan, tí ó sì ń gbé e fún ẹni tí ó bá wù ú.
Kato wi ka to fọ ọ, o ti ṣe'pinu pe ohun yoo fun eeyan mẹwa ni miliọnu Naira kọọkan ti @atiku ba wole gẹgẹ bi Aarẹ orileede Naijiria!
Koda, wọn dori agbelebu kodo, ti wọn si ka Adura Oluwa lati ipari.
Rape: Ọmọ tí wọn ń fipá bá lòpọ̀ yóò máa ní ìrora ọkàn nígbà gbogbo
Awọn obi awọn ọmọ Chibok lasiko ti wọn n ba Adaobi Tricia Nwaubani sọrọ ni ọrọ awọn kii se oju lasan mọ ni awọn se gba ọdọ Pasito ati Woli T.
Lọdun 2015,Femi Gbajabiamila koju Yakubu Dogara fun ipo olori ile amọ Dogara lo jawe olubori.
 bákan náà , tẹ ̀ gbón tàbúrò ni ìyá tí ó bí wọn .
Àwọn ọmọ àyànfẹ́ arabinrin rẹ kí ọ.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: 'Ọjọ́ lọjọ́ tí mo mọ̀ pé wọ́n bí mi láà ní ojú ara obìnrin àti ilé ọmọ' Ọmọ ti lọ kí baba, Fayemi bẹ Aláàfin wo l‘Ọyọ, wọ́n jírórò lórí lẹ́tà Coronavirus dá rúkè-rúdò sílẹ̀ ní pápákọ̀ òfurufú l‘Amẹrika, ọ̀pọ̀ ń forí gbárí Òṣèré tíátà Yorùbá mẹ́ta gbàmì ẹ̀yẹ pé wọ́n pegedé Òkú ṣùn nínú ìbúgbàmú tó wáyé l‘Eko Àwọn kókó ohun tó wà nínú lẹ́tà tí Aláàfin kọ sí Fayemi rèé Koda, ọpọ mọto ti wọn gbe kalẹ si adugbo naa lo bajẹ tan pata, ti ọpọ eeyan si di alainile lori.
Nítorí náà, n óo máa yìn ọ́ láàrin àwọn orílẹ̀-èdè,n óo máa kọ orin ìyìn sí orúkọ rẹ.
Ṣugbọn ti imọ nipa awọn ti ko ba fi apẹrẹ arun yi han ba pọ si, o ṣeeṣe ki a mu adinku ba iye awọn to ku latari arun Coronavirus.
Angẹli OLUWA sọ fún Satani pé, “OLUWA óo bá ọ wí, ìwọ Satani!
Seun Egbegbe lo ọdún méjì àti oṣù méje lẹ́wọ̀n láì tìí san béèlì rẹ̀ Ẹ wo ojú owó ìrẹ̀sì báyìí lẹ́yìn tí ìjọba ti ibodè pa Bobrisky dárò pé EFCC gbé Mompha, ọ̀dọ́mọdé olówó tó ń lo aago ₦20m À ń gbé ìjọba ìpínlẹ̀ Ọyọ lọ si ilé ẹjọ- Ẹgbẹ́ Fulani darandaran Bayii, Ijọba Ipinlẹ Ondo ti fofin de tita ẹran maaluu ni agbegbe naa titi ti iwadii yoo fi pari lori iṣẹlẹ naa.
“Kí ó kọ́kọ́ wẹ̀, lẹ́yìn náà, kí ó wọ àwọn aṣọ mímọ́ nnì: ẹ̀wù funfun mímọ́, pẹlu ṣòkòtò funfun, kí ó fi ọ̀já funfun di àmùrè, kí ó sì dé fìlà funfun.
O sọ gẹgẹ bi iroyin naa ti ṣe sọ, o ni lailai fi ti oṣelu ṣe, oun yoo palẹmọ awọn ọkọ agbepo nla to n ṣokunfa idiwọ lilọ bibọ lagbegbe naa.
to wa laarin awon oluko fafiiti ati ile-eko gbogbonse lorile ede Naijiria.
A ti ẹ gbọ pe ileewe girama St.
‘Aawọ abẹnu lee koba APC ni 2019’ Awọn aṣofin ati awọn oluwọde yi ya wọ ile-ẹjọ naa l'Abuja ti wọn si i fẹhonuhan lori bi ijọba ṣe gbe aṣofin Dino Melaye lọ sile ẹjọ.
“Ṣugbọn bí eniyan burúkú yìí bá bí ọmọ, tí ọmọ yìí rí gbogbo ẹ̀ṣẹ̀ tí baba rẹ̀ ń dá, tí ẹ̀rù bà á, tí kò sì ṣe bíi baba rẹ̀, 
Naijiria fi ìgbájú mẹ́ta lé Cameroon kúrò ní AFCON Wo àwọn ẹranko tí wọ́n máa figagbaga ni Egypt nínú AFCON 2019 Kí ló mú ọmọ Nàìjíríà mẹ́sàn án forí la ikú nínú ìkọlù Libya?
A ó gbé'gbésẹ̀ lẹ́yìn ìwádìí fídíò tí Dino ti ń náwó lójú agbo- Ọlọ́pàá Àwọn obìnrin ilé ìgbìmọ̀ aṣòfin Amẹrika fọnmú sí ọ̀rọ̀ Trump O ti lé ni òkú ẹni mẹ́wàá ti wọ́n ti ri yọ nínú ilé to dà wó ni Jos Èrò àwọn ọmọ Naijiria yàtọ̀ lórí ohun ìní Seyi Makinde Ojú gbooro o"" ni ogidi ikini fun onidiri eyi ti awọn kan ni o tumọ si pe ojú a ríran la ilà irun naa daadaa."
Ni ipinlẹ Ogun, awọn igbimọ amuṣẹya naa gbe abadofin naa kalẹ lati le wa ọna abayọ so eto aabo to mẹhẹ,ti awọn igbimọ amuṣẹya naa si pa ohun pọ fẹnu ire pe e.
Wọn ko mọ wipe ẹṣin-ò-kọkú kan to to ado oloro mọra ti darapọ mọ wọn bi pe akọroyin naa ni oun.
Kò sí ẹni tí a lè fi wé ọ;bí mo bá ní kí n máa polongo ohun tí o ṣe,kí n máa ròyìn wọn,wọ́n ju ohun tí eniyan lè kà lọ.
Ọrẹ tirẹ̀ ni àwo fadaka kan tí ìwọ̀n rẹ̀ jẹ́ aadoje (130) ṣekeli, abọ́ fadaka kan tí ìwọ̀n rẹ̀ jẹ́ aadọrin ṣekeli.
40 Ẹ̀yin yíò sì wólẹ̀, ẹ ó sí bu ọlá fún Bàbá ní orúkọ mi.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Mo ti fẹsẹ̀ rìn kúrò ní Nàíjíríà àmọ́ ń kò tíì dé ibi tí mò ń lọ - DJ Switch Àwa olóṣèlú yóò fi ẹ̀mí wa ṣòfò, tá ba jẹ́ kí ìwọ́de ọ̀dọ́ míì tún wáyé - Lawan Nígbà wo gan-an ni ẹgbẹ́ òṣèlú APC yóò ṣe ìpàgọ́ àpapọ̀?
Ninu iṣẹlẹ taa n wi yi, o kere tan eeyan mẹtadinlogun lo padanu ẹmi wọn.
Buhari, Makinde, Sanwo-Olu kẹ́dùn pẹ̀lú ẹbí Tola Oyediran, àkọ́bí lóbìnrin tí Obafemi Awolowo bí tó papòdà Wo àfiwé owó oṣù Ọlọ́pàá Nàìjíríà pẹ̀lú akẹgbẹ́ wọn lókè òkun Àwọn akẹ́kọ̀ọ́ 181 pẹ̀lú Olùkọ́ lùgbàdì Covid 19 níléèwé aláàdáni kan nípinlẹ̀ Eko Ileesẹ ologun wa fọwọ sọya fun ifẹsẹmulẹ aabo ati alaafia to peye yika Naijiria, to si n beere atilẹyin araalu fun aseyọri akanse eto naa.
Agbaboolu ati akonimoogba agba iko Super Eagles teleri, Samson Siasia so pe, ko si nkan ti o se pataki ninu ife ti oun ni si balogun iko Super Eagles, Mikel Obi.
  Minisita fun ọrọ isẹ lorile ede Naijiria,
Labẹ pe ibẹrẹ kọ l'onisẹ, afi ẹni ba laa ja, awọn ti o fi ẹgbẹ oselu APC silẹ fun Oshiomole bi Aarẹ ile asofin agba tẹlẹ ri Bukola Saraki ni wọn wa n gba Godwin Obaseki lalejo ninu ẹgbẹ oselu PDP bayi.
" Oríṣun àwòrán, Instagram/lizzyanjorin Lizzy fi kun pelọjọ Kẹtadinlọgbọn osu Keje naa ni ẹnikan n dunkoko lati pa oun, ti oun si gbe soju opo Instagram oun, amọ ẹtahoro awọn osere lo sọ le ohun ti mo fi sita yii, ti ọpọ wọn ko si fọhun lati ja fun mi, awọn ololufẹ mi ko si ba wọn ja le lori.
”“mo nigbagbo pe asofin Ndoma-Egba yoo lo opolopo iriri to ni fun ipade egbe naa ti yoo waye ni ojo kẹ́tàlélógún, osu kefa, odun 2018.
Kí ló mú kí ọkọ̀ kan tó jóná ráùráú lórí afárá Ojuelegba?
Bakan naa, iwe ofin orilẹ-ede Naijiria laa kalẹ igbesẹ to yẹ fun yiyọ adajọ agba nipo."
O ni iru adehun yii jẹ ọna abayọ, amọ o ku ki ijọba gbe igbesẹ lati ri pe awọn mẹkunnu ko farakasa eto yii, tori pe wọn lee ma lowo lati san bii awọn olowo.
Kò sí ẹranko búburú kankan nínú igbó ọ̀hún àyàfi àwọn kòkòrò bí agbọ́n àbí àkekèé nìkan.
Awon oluko, ti won bere iyanse-lodi lojo-Bo so ninu atejade kan pe, awon n bere fun irorun awon osise ijoba bi: eto eyawo fun oko ayekele ati  eto ilera madoju-tofo to peye fun awon osise.
Ọmọ Nàìjíríà kan gbé Fásitì Oxford lọ sílé ẹjọ́ tàko oríkí ọrọ 'Mortgage' nínú ìwé àtúmọ̀ ọrọ Ọwọ́ ọlọ́pàá tẹ àwọn olè tó kó góòlù àti ẹgbẹ̀lẹ́gbẹ̀ mílíọ̀nù lọ nílé MKO Abiola l'Eko Ó sàn kí ẹ pa mí ju kí ẹ ba oko tí mo gbin igbó sí jẹ́ lọ- Afurasi Clement sí NDLEA Mo ṣetán láti fi ẹ̀ṣẹ́ dín dòdò ìyà fún Anthony Joshua- Efe Ajagba Ara ló ń ta àwọn ẹgbẹ́ NURTW tó ń pariwo mi kiri, APC ni wọ́n bá lọ nígbà náà l'Oyo- Auxiliary Oríṣun àwòrán, others Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí MKO Abiola: Ọwọ́ ọlọ́pàá tẹ àwọn olè tó kó góòlù àti ẹgbẹ̀lẹ́gbẹ̀ mílíọ̀nù lọ nílé Abiola l'Eko4 Owewe 2020 6:18 Fídíò, Akomolede: Bolaji Faleke ni Olùkọ́ tó ń kọ́ wa ní àṣà oge ṣiṣe lórí BBC Yorùbá, Duration 6,181 Owewe 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Awon osere bii Kate Henshaw, Rahama Sadau, Dakore Egbuson atawon mii loruko won jade.
Ṣugbọn ẹni tí ó fi Ọmọ-Eniyan lé àwọn ọ̀tá lọ́wọ́ gbé!
Eyi ni igbesẹ tuntun to n jẹyọ latara aawọ laarin awọn ile iṣẹ to jẹ ti ilẹ Britain nilẹ yii ati ijọba Naijiria lori òwò gaasi kan ti ko pari to ti waye latọdun 2010.
Gbogbo awọ̀n eeyan wa, paapaa julọ awọn to jẹ̀ obinrin ni wọn kọlu.
Oríṣun àwòrán, AFP Lọdun 2001 ni awọn adari ilẹ adulawọ seleri lati maa mu ida meẹdogun ninu ọgọrun un ninu owo isuna wọn lọdọọdun wa fun iwadii nni eyi ti won ko muṣẹ.
Awọn eeyan kan to ms agba oṣelu ọmọ bibi ilẹ ibadan naa ti wọn si mọ pe kii ṣe ẹni ti a lee pa ohun ms agogo rẹ lẹnu pẹlu n miri pe o ṣeeṣe ko ri bẹẹ nitori o to ọjọ mẹta ti wọn gburo rẹ nita gbangba.
Pasitọ Adeboye paṣẹ lọjọ Aiku, ọjọ kẹwaa oṣu kini ọdun 2021 pe ki gbogbo awọn ọmọ ijọ naa lagbaye gba awẹ ọjọ mẹtalelọgọta naa.
World Toilet Day: 'Ìgbẹ́ tí wọ́n ń yà síbí kìí jẹ kí oníbàárà wá sọ́dọ̀ wa' Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Lóṣù mẹ́ta sẹ́yìn, mò ń wa ọkọ̀ taasín, ṣùgbọ́n wọ́n sọ mí di afọ́jú lọ́san gangan' Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Torinaa, Ogunwusi gori oye ni ọjọ kẹrindinlọgbọn lẹyin ọpọlọpọ fa ki n fa a ija oye to gbona janjan laarin gbogbo awọn Arẹmọ oye to wa lasiko naa.
” Omowe Abari ninu oro tire salaye igbese ajo naa nipele kookan lori ipese idanilekoo to ye fawon oludibo ati ipolongo igbiyanju ati awon abadofin ijoba fun idagbasoke Naijiria tai imo eto omoniyan won.
Deji Adeyanju vs Charley boy: Charly Boy l'óun kò gbowó, Deji ní ó já òun kulẹ̀
Visa: Àwọn ọmọ Naijiria yóò má a san àfikun owó láti wọ Amẹrika 27 Ògún 2019 Oríṣun àwòrán, @ClemsonTigerNet Orilẹede Amerika ti polongo afikun iye owo iwe irinna (Visa) fun ẹnikẹni lati orilẹede Naijiria, to ba fẹ wọ ilẹ Amerika.
Gbangba fẹ dẹkun ti kedere yoo si bẹwo nipinlẹ Kwara pẹlu ibo atundi ti yoo waye nibẹ lọjọ abamẹta.
6 Kíyèsíi, ayé ńbàjẹ́ nínú àìṣedéédé; ó sì di gbígbọdọ̀ ṣe pé kí àwọn ọmọ ènìyàn rú sókè sí ironúpìwàdà, àti àwọn Kèfèrí àti bákannáà ìdílé Isráelì.
"MKO Abiola, iṣẹ́ aṣẹ́gità ló fi bẹ̀rẹ̀ okoòwò Onimọ ẹsin Islam yii ni ""fun igbadun ara ile kọ leleyii rara o, igbarun gbaa ni."
6 5665 Orilẹede Namibia 152 6.
Ayodele sọ eyi lasiko ọdun tuntun nigba to n sọrọ nipa Aarẹ Muhammadu Buhari; Igbakeji aarẹ, Yemi Osinbajo ati adari ẹgbẹ oṣelu APC, Bola Tinubu pẹlu ẹka ijọba miran.
Ìdí ni pé, wọn kò wá ìdáláre níwájú Ọlọrun nípa igbagbọ, ṣugbọn wọ́n gbẹ́kẹ̀ lé iṣẹ́ ọwọ́ wọn.
Alagba Mangosuthu Buthulez la gbọ pe awọn ọpọ ero kan pa ohun mọ lẹnu nigba ti awọn ọkunrin kan ya wọ agbegbe naa ti wọn si n ke sawọn ajoji lati fi orilẹede wọn silẹ.
Bí ẹ̀yin fúnra yín ti jẹ́ aláìgbọràn sí Ọlọrun nígbà kan rí, ṣugbọn tí ó wá ṣàánú yín nígbà tí àwọn Juu ṣàìgbọràn, 
kí ó tó já Gómìnà mẹ́rin yóò jẹ́jọ́ lẹ́yìn sáà wọn - EFCC Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Èré Ọṣun: Àtáója ní wọn kò jí ère Ọṣun, ó sì wà níbi tó wà Ko da awọn bi aadọta eeyan lo sa asala lọ si ago ọlọpaa nigba tawọn ọmọ ilẹ South Africa doju ija kọ wọn lọganjọ oru.
Àwọn kan wá dìde, wọ́n ń jẹ́rìí èké sí i pé, 
ó sọ wá di alààyè pẹlu Kristi nígbà tí a ti di òkú ninu ìwàkíwà wa.
nígbà tí wọ́n bá mọ ẹ̀ṣẹ̀ tí wọ́n dá, tí wọ́n sì rí àṣìṣe wọn, gbogbo ìjọ eniyan náà yóo fi ọ̀dọ́ akọ mààlúù kan rú ẹbọ ìmúkúrò ẹ̀ṣẹ̀, wọn yóo fà á wá síbi Àgọ́ Àjọ.
Àwọn ohun tó yẹ́ kí o mọ̀ nípa Ọ̀gá DSS tuntun Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ọṣun Decides: ADC, ADP, APC àti SDP soju abẹ níkòó lórí ìwà ìbàjẹ́ Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
O ní gbogbo rògbòdìyàn tó n ṣẹlẹ̀ nílùú kìí ṣe tuntun bákan náà ni kìí ṣe ìṣòro tí kò ṣee bori, sùgbọ́n ó nílò ìfowọ́sowọ́pọ̀ àwọn ará ìlú bákan náà ni ìfarajì àwọn olórí.
Olootu ijọba orileede Pakistan Imran Khan, loju opo Twitter rẹ, gbosuba kare fun Naeem to si kede pe awọn yoo fi ami ẹyẹ to ga julọ da lọla.
Ẹ̀yin olùkọ́, ìlànà àkànṣe owó oṣù tuntun dé fún yín Saaju la ti kọkọ mu iroyin wa fun yin pe aarẹ Muhammadu Buhari ti kede ilana akanse owo osu fawọn olukọ lorilẹede yii.
ede Naijiria lati fun awon oludije ni anfaani lati wa so tenu won.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ronke Oṣodi: òótọ́ ọ̀rọ̀ máa ń korò gan ni f'áwa èèyàn Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Wọ́n mú mààlúù meji tí wọn ń fún ọmọ lọ́mú lọ́wọ́, wọ́n so kẹ̀kẹ́ ẹrù náà mọ́ wọn lọ́rùn, wọ́n sì ti àwọn ọmọ wọn mọ́lé.
Lati ibẹ, yan eto ti o ba koju oṣuwọn fun.
Ìjọba ìpínlẹ̀ Osun tí búwọlù ìlànà àyẹyẹ Ọṣun-Oṣogboo ọdún 2020 Ọwọ́ tẹ Bàbá ọgọ́rin ọdún tó fipá bá ọmọ ọdún márù'n ún lò pọ̀, Adájọ́ kọ láti gba onídúrò rẹ̀ Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Immaculate Okochu: Arẹwà orí ìpolówóo Cold Stone Creamery ṣàgbàkò ikú nínú ìjámbá ọkọ̀ nígbèéyàwó ku díẹ̀14 Ògún 2020 Unilag VC: Folasade Ogunsola ni obìnrin àkọ́kọ́ tó jẹ ọ̀gá àgbà fún ibùdó ẹ̀kọ́ṣẹ́ ìṣègùn Fáṣítì Eko24 Ògún 2020 Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí 3 sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 2:23 Fídíò, Water Generator: Ó leè ṣiṣẹ fún wákàtí mẹfà, kó tó sinmi, Duration 2,2310 Òkùdu 2020 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
, Duration 5,5712 Òkùdu 2020 8:23 Fídíò, Osusan Oluwatobi tricycle accident: 'Ìgbà tí mo máa fi lajú sáyé padà, ọ̀fọ̀ ikú mi ní wọ́n ń kígbe', Duration 8,2324 Ògún 2020 BBC News, Yorùbá Ìdí tí ẹ fi le è nígbàagbọ́ nínú ìròyìn BBC Ìlànà Lílò Nípa BBC Òfin Àṣírí Cookies Kàn sí.
Ó ní se ni òun yóò wọ́ ilé isẹ́ BBC lọ sílé ẹjọ́ bí wọn ò bá san gbèsè owó tí wọ́n jẹ ẹ́.
Oríṣun àwòrán, Twitter O sọ pe ''ti o ba ti lo hydroxychloroquine ti ara rẹ si ti ya.
Ọkunrin kan wà tí ń jẹ́ Jairu, aṣaaju kan ni ní ilé ìpàdé ibẹ̀.
Oríṣun àwòrán, Alaafin of Oyo ''Bi a ba fẹ jẹ mudunmudun ohun ta ṣiṣẹ fun, o di dandan ki a mu aabo ni pataki.
Bakan naa ni ijinigbe n waye ni ẹkun aringbungbun gusu orilẹede Naijiria nibi ti iwapo rọbi ti n waye-eyi ko ni ohunkohun n ṣe pẹlu Boko Haram.
Nítorí kì í ṣe àìní àwọn onigbagbọ nìkan ni iṣẹ́ ìsìn yìí yóo pèsè fún, ṣugbọn yóo mú kí ọpọlọpọ eniyan máa dúpẹ́ lọ́wọ́ Ọlọrun.
Nígbà tí ìwà òmùgọ̀ bá kó ìparun bá a,ọkàn rẹ̀ a máa bá OLUWA bínú.
Jesu bá bẹ̀rẹ̀, ó ń fi ìka kọ nǹkan sórí ilẹ̀.
Bí ilẹ̀ tíí mú kí ewéko hù jáde,tí ọgbà sì ń mú kí ohun tí a gbìn sinu rẹ̀ hù,bẹ́ẹ̀ ni OLUWA Ọlọrun yóo mú kí òdodo ati orin ìyìn yọ jádeníwájú gbogbo orílẹ̀-èdè.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ìdílé tí ọkọ da ọmọ síta tóríi ojú Búlùú tí wọ́n ní bá BBC sọ̀rọ̀ Ta lẹni ti o tapa si ofin bawo lo si sẹ kan awọn ẹsọ Aisha Buhari?
Ìjọba Ọ́ṣun, Oluwo kò yẹ lẹ́ni tó leè darí ìlú, ẹ bá wa le kúrò lórí ìtẹ́ - Olú ti Ilé-Ogbó Ija eerin meji: Oluwo ati Ọọni Ani sẹ, Ọọni ran alaabo rẹ simi - Oluwo Ìgbà mẹ́rin tí ọ̀rọ̀ Oluwo dá awuyewuye sílẹ̀ Ọ̀rọ̀ èmi àti Olorì Chanel Chin kò yé ara wa mọ́ nínú ilé- Oluwo Ìwà ọ̀dàlẹ̀ ni bí ẹ kò bá gbé iléèwé ìkọ́ṣẹ́ olùkọ́ni kalẹ̀ sí ìlú Ìwó- Oluwo Àwọn ọba tó wà lábẹ́ mi ń talẹ̀ nítàkutà- Oluwo Ìjọba Ọṣun ti dásí ìjà láàrin Oluwo àti Agbowu Lẹyin abọ igbimọ naa, ni igbimọ lọbalọba ọhun ba pe ipade pajawiri, eyi to waye nibujoko ijọba ipinlẹ Ọsun to wa ni Abẹrẹ.
Kí gbogbo àwọn tí ń wá ọ máa yọ̀,kí inú wọn sì máa dùn nítorí rẹ;kí àwọn tí ó fẹ́ràn ìgbàlà rẹmáa wí nígbà gbogbo pé, “OLUWA tóbi!
Boko Haram ṣọṣẹ́ ní Borno, wọ́n sé àwọn èèyàn mọ́lé ní Kukawa Agbègbè Kukawa ni ipinlẹ Borno ni àwọn oníṣẹ́ ibi yìí ti ṣọṣẹ́ báyìí Iroyin to n tẹ wa lọwọ sọ pe ni ila oorun ariwa Naijiria ni awọn oniṣẹ ibi yii kọlu ni ipinlẹ Borno.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Kwara: Fọ́fọ́fọ́ ni mọ́ṣáláṣí kún tí ìlànà ìjìnàsíraẹni 'social distancing' sí forí Gomina ipinlẹ Eko, Babajide Sanwo-Olu sọ pe igbesẹ ṣiṣi awọn mọṣalaṣi yi jẹ apẹrẹ pe Naijiria n tẹsiwaju ninu idoju ija kọ arun Covid-19.
Ọ̀lẹ ń wí pé, “Kinniun kan wà lọ́nà!
"Àlàyé rèé lóríi ìdí tí wọ́n fi ń pe aya ní ìyàwó Khafi wọ gàu lẹ́nu iṣẹ́ lórí ẹ̀sùn ìbálòpọ̀ ní BB Naija Àlàyé rèé lóríi ìdí tí wọ́n fi ń pe aya ní ìyàwó ""Nigba ti asiko ba to ti mo ba lọ, mo bẹ yin, ẹni ti o to gbangba sun lọyẹ ni ki ẹ yan sipo."
 ó tún fúni níròó nípa àwọn fíímù , àwọn òṣèré , àti àwọn ènìyàn míiràn pẹ ̀ lú .
O ni bi awọn ọmọ ogun Naijiria se n se ojo lo yẹ ka fi bi ara wa leere pe ohun ija taa lo ni agbara ju laarin awn ologun Naijira ati awọn adunkooko mọni.
Ayẹyẹ ọdun awọn ọmọ bibi ilu Ibadan Oríṣun àwòrán, IbadanCity ANNOUNCER Lẹyin awuyewuye to tẹle ipade ita gbangba ti ẹgbẹ oṣelu PDP ṣe nilu Ibadan, ni ẹgbẹ ọmọ bibi ilu Ibadan, CCII, wọgile aṣekagba ayẹyẹ ilu ibadan ti wọn pinnu lati ṣe tẹlẹ.
Nigeria swearing-in: Ètò ìbúrawọlé káàkiri Nàìjíríà
Nítorí náà, ẹ máa yọ̀, ẹ̀yin ọ̀run ati ẹ̀yin tí ẹ̀ ń gbé inú wọn.
Dangerous Animal: Ẹ wo àwọn ajá mẹ́wà tó máa ń hùwà ipá tí ẹ kò gbọdọ̀ sìn nílé
Ọpọlọpọ àwọn darandaran ni wọ́n ti ba ọgbà àjàrà mi jẹ́,wọ́n ti tẹ oko mi mọ́lẹ̀,wọ́n sọ oko mi dáradára di aṣálẹ̀.
Aṣofin Tunde Braimoh ti o n ṣoju ẹkun idibo Koṣọfẹ keji ninu IIe Igbimọ Aṣofin Ipinlẹ Eko ti ṣapejuwe Ipade apero oloṣu mẹta-mẹta ti Ile Igbimọ Aṣofin Ipinlẹ Eko maa n ṣagbatẹru rẹ kaakiri ẹkun idibo ogoji ti o wa ni ipinlẹ naa gẹgẹ bi eyi ti o ti n so eso rere lati fi mọ ero ọkan awọn ara ilu, ti o si ti n ni aṣeyọri ninu idagbasoke ilu bayii.
Akwa-Ibom:Mílíọ́nù mẹ́wàá Náírà ni ilé ẹjọ́ ni kí Kábíyèsí san gẹ́gẹ́ bí owó ìtaran ilẹ̀ tí ó gbà lọ́nà àìtọ́
Ikini naa ni ti ajọ agbowo ori ni ipinlẹ Eko to kii pe o ku oriire naa ṣugbọn ko maa gbagbe lati san owo ori rẹ bi o ti tọ lọdun 2021.
''Idanwo aṣekagba yii ni awọn fẹ fi mọ boya ko ni si ẹni ti yoo lugbadi arun naa lasiko idanwo to n lọ lọwọ.
com Lẹyin naa ni ki o fi okun ibomu naa kọ eti rẹ mejeeji.
" "" awo "" "" jẹ ́ tó níṣe pẹ ̀ lú àkọ àti abo ní ó bá ń kọ ́ ṣẹ ifá dídá ."
Eric ati Tochi ni wọ́n lé kúrò nílé ẹlẹ́gbọ̀n àgbà BBNaija lọ́sẹ̀ yìí Láti ìgbà ti ilẹ̀ ti mọ́ lówùrọ òni ni àwọn ọmọ Naijiria tí n fójú sọ́na wípe tani- ẹgban àgbà yóò lé lọ sílé.
Lẹyin ti okiki iroyin kan lọjọbọ pe, awọn eeyan kan kọlu ibudo iko nnkan awọn ohun elo iranwọ lasiko ajakalẹ arun COVID-19 pamọ si nilu Eko, awọn eeyan kan naa tun ti ṣe bẹẹ nipinlẹ Osun bayii.
Nígbà tí a dá ọjọ́ tán báyìí, ọba bẹ̀rẹ̀ síi ṣe ìtọ́jú mi ni onírúurú ọ̀nà, ó fún mi ni àpò owó kan láti fi ṣe ìpèsè ìrìnàjò náà, mo di ẹni tti ń wọlé tí ń jáde ni ààfin ọba.
Koda, wọn ni owo to ti fi magoago gba lọwọ awọn eeyan n lọ si nnkan bi miliọnu kan dọla.
Ìbá wù mí kí o jẹ́ ọmọ ìyá mi ọkunrin,kí ó jẹ́ pé ọmú kan náà ni a jọ mú dàgbà.
O ni iṣẹlẹ naa waye nigba ti ileeṣẹ ina mọnamọna ṣẹṣẹ mu ina de lagbegbe tawọn n gbe, ti esu si lo oun.
( 1 ) Ẹka ìdílé àríwá ila Òòrun wa láti akkadian , nítorí èdè to ti paré tó jẹ ́ ayé òlàjú tó ti kọjá lọ ti àwọn assyrians àti babylonians nígbà to ṣi jẹ pé akkadian wà ní lílò fún nǹkan bi Ọdún meji miliniọnu títí di àkókò ayé jésù hetzron pin àríwá ìwọ ̀ oòrùn semitiki si àringbùngbùn àti gúṣù àríwá ṣi ẹ ̀ ka .
Bọde George naa ṣalaye fun BBC Yoruba pé àwọn to pa Adeniyi Aboriṣade lọsan gangan lọjọ naa kò bojú rárá.
” Ó dáhùn pé, “Agbọ̀n òṣùnwọ̀n eefa kan ni.
Ninu iriwisi tire, Dokita Dipo Awojide ni adura pe ki irufe isẹle bayi ma waye mọ ko le tan ọrọ to wa nile yi bi kò ṣe pe ki ijọba wa wọrokọ fi ṣada lori ipenija ijmaba ina ọkọ agbepo.
Èmi nìkan kò lè ṣe àkóso àwọn eniyan wọnyi; ẹrù náà wúwo jù fún mi.
Ohun tí ẹ óo ṣe sí wọn nìyí: ẹ wó gbogbo pẹpẹ wọn lulẹ̀, ẹ rún àwọn òpó wọn, ẹ gé àwọn oriṣa Aṣera wọn lulẹ̀, kí ẹ sì sun gbogbo àwọn ère wọn níná.
Ọmọ Mínísítà àná, Adewole bọ́ s'ọ́wọ́ ajínigbé Ọmọ ọkunrin minisita tẹlẹ ri fun eto ilera Isaac Adewole, iyẹn Dayo Adewole ti bọ sọwọ̀ awọn ajinigbe.
"Nínú ọrọ rẹ ó gboríyìn fún aláàfin gẹ́gẹ́ bi abẹ ẹsẹ eni ti òun ti n kẹ́kọ̀ọ́, ẹni tó kami lati maa ní afojúsùn O ní kábíyèsí ló kọòun pé ẹni ti kò ba ni ìwòye ni wọ́n n pè ń pè ni aláìniwòye ọjọ́ ìwáju '' Kábíyèsí ni ẹni náà dàbí ọkọ ojú omí ti kò sí atukọ níbẹ̀"" Oríṣun àwòrán, Anu Adeyemi/Instagram Àkọlé àwòrán, Olorì Anu Adeyemi ń ṣe ọjọ ìbí, ẹgbẹ́ ǹkan tò sọ sí Kábíyésì Olorì ní ọ̀na sí aṣeyọrí kò rọgbọ rárá, sùgbọ́n ìpinnu ọkan àti àforítì gangan ni èròjà fún àṣeyọrí"" ""Baba kí ẹ pẹ́ lórí itẹ àwọn babanla yín, Ọdún tuntun yìí a sàn wá si ohun rere àti igbé aye ọtun ti yóò tì mi sí ibi gíga."
O ti bá mi sọ ọ̀fọ̀ mi di ijó,o ti bọ́ aṣọ ọ̀fọ̀ kúrò lára mi,o sì ti dì mí ní àmùrè ayọ̀,
Ẹni to bori: Namibia Guinea vs Morocco.
fun ile-eṣẹ, idokoowo ati karakata, Minisita fun iṣẹ ode ati ile gbigbe, Minisita
Kìí ṣe owó bàbàrà lọ títí o, àmọ́ ó jọ̀ọ́ lójú púpọ̀ púpọ̀.
7 87930 Orilẹede Senegal 338 2.
 Ko ni nnkankan ṣe pẹlu Igbimọ Alakoso Ijọba
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ibadan Accident: Èèyàn méjì kú, ẹnìkan wà nílé ìwòsàn Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Ogagun Umar Mohammed so pe won ri oku ogagun yii ni inu koto kan ti won ko lo mo on to wa ni Guchwet , ni  eyi to wa ni Gusu Jos.
Nígbà náà ni wọ́n pada lọ sọ́dọ̀ Balaki, wọn sì sọ fún un wí pé Balaamu kọ̀, kò bá àwọn wá.
”Orji,tun wa ro awon akoroyin lati tubo maa la awon eniyan lọyẹ lori eto idibo.
Ajọ naa ṣalaye lori ikanni twitter rẹ pe, iwe afihan pe lootọ ni aarẹ ṣe idanwo lawọn fun un.
Lara awọn nnkan miiran ti awọn ara ilu tun beere fun nibi ipade awọn alẹnulọrọ yii ni pipese omi ẹrọ kaakiri agbegbe Agboyi-Ketu.
Wọ́n á so àgbàdo mọ́ ìdí, adìẹ á sì máa lé wọn kiri
Kò jẹ́ kí ẹnikẹ́ni gbé ohunkohun la àgbàlá Tẹmpili kọjá.
Ẹ̀mí rẹ̀ gùn, ó lọ́rọ̀, ó sì lọ́lá, ó sì di arúgbó kàngẹ́kàngẹ́ kí ó tó kú, Solomoni ọmọ rẹ̀ sì jọba lẹ́yìn rẹ̀.
Ọ̀wọ́ngógó epo bẹntirò: NNPC ni 'ìròyìn ẹlẹ́jẹ̀' ni ‘Ìjọba Buhari kò lé è dá ààbò bo àwọn ará ìlú’ Omotola Jalade ní Nàìjíríà dàbí ọ̀run àpáàdì lábẹ́ ìjọba Buhari Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Èmi ò kí ń lu ìyàwó mi' O fi kun wi pe, awọn gbọdọ fi ọgbọn se e ni, ti awọn ba setan lati yọ owo iranwọ ti ijọba n san lori epo bẹntirol nitori owo naa ti pọju fun ijọba lati ma a san ati wi pe owo ohun ti posi ba yii.
Oríṣun àwòrán, ooni adeyeye ogunwusi Iwu ni òun ti sepade pẹ̀lú Minisita fún imọ ṣayẹnsi àti iṣẹ ẹ̀rọ pẹ̀lú Minisita feto ìlera láti sọ fún wọn pé, òun ti rí àwọn egbògi kan tó leè ṣe ìwòsàn fún arun Coronavirus tàbí arun-karun tó bá ń ṣe idiwọ fún mimi jalẹ.
Femi, tíì ṣe ọmọ àgbà ọjẹ osere tíátà, Adebayo Salami, wá fìdí rẹ múlẹ̀ pé, orúkọ Baba òun là ọ̀nà pupọ fún òun nínú isẹ tíátà nítorí láti kékeré òun ti ń kó isẹ tíátà lára wọn.
Àkọlé àwòrán, Onikaluku ni eka Filani n dibo yan eni to fe Bakan naa lo ṣalaye pé awọn oludibo 1007 to jẹ aṣoju lo n kopa ninu idibo naa nibiti ko ti si wahala kankan ti gbogbo rẹ n lọ bi o ti yẹ.
Oríṣun àwòrán, Facebook/Mike Bamiloye Bamiloye sọ pe iyawo to n ṣe ojuṣe rẹ ni Gloria jẹ, debi i pe oun ko ni ìdí kankan lati jẹun nita.
Awọn oludije mọkanla miran ni wọn yoo jijọ figagbaga.
Aarẹ Naijiria Muhamadu Buhari ṣẹṣẹ fọwọ si adehun okoowo kan naa yii ni nibi ipade apero ajọ iṣọkan ilẹ Afrika to waye ni orilẹede Niger lọjọ Aiku.
ṣugbọn ní tiwa, Ọlọrun kan ni ó wà, tíí ṣe Baba, lọ́dọ̀ ẹni tí gbogbo nǹkan ti wá, ati lọ́dọ̀ ẹni tí àwa ń lọ.
Gomina sọ pe ''ẹgbẹrun un lọna ọgọrin eeyan ti wọn ko rọwọ họri ni wọn ti janfaani eto ilera to peye laisan kọbọ labẹ eto OHIS ni bii ọdun kan sẹyin.
"Oríṣun àwòrán, @NLCHeadquarters ""Owo ti wọn n fi pawọn fun ifẹyinti awọn osisẹ ni owo yii, ko si wa fun yiya rara."
Wọ́n tún san ìdámẹ́wàá gbogbo nǹkan tí wọ́n ní.
Femi Falana ni awọn ti kọ iwe ẹhonu sijọba ipinlẹ Ọyọ lori ọrọ naa, ti awọn yoo si gbe ileeṣẹ Henkel Nigeria limited lọ si ile ẹjọ fun aibikita wọn fun awọn oṣiṣẹ ile isẹ naa.
Awọn ọkunrin naa tun n tẹle wa titi ta fi filu naa silẹ lọ gba iwosan ati iranwọ ọlọpaa.
Àwọn ọmọ Juda ati àwọn ọmọ Israẹli pọ̀ bíi yanrìn inú òkun, wọ́n ń rí jẹ, wọ́n ń rí mu, wọ́n sì láyọ̀.
Ó ní ọpọlọpọ ọkọ̀ ojú omi Taṣiṣi tí wọ́n máa ń bá àwọn ọkọ̀ ojú omi Hiramu lọ sí òkè òkun.
Ìbá ti dára tó, kí ìgbàlà Israẹli ti Sioni wá!
Nínú ìṣèjọba yìí, Èmi àti Ààrẹ Buhari lọlọ́rọ̀, kìí ṣe ọmọ Nàìjíríà-Ibrahim Gambari, olórí òṣìṣẹ́ lọ́fíìsì ààrẹ Aláàfin gbé àṣẹ kalẹ̀ láti dènà àtúnṣẹ̀ ìṣẹ̀lẹ̀ 'Soka'nílùú Ọ̀yọ̀ Mo kábàámọ̀ pé n kò kàwé, kí n tó bẹ̀rẹ̀ iṣẹ́ tíátà - Sanyeri Ìdí táwọn apòògùn Nàìjíríà fi tako oògùn Coronavirus láti Madagascar Atẹjade naa ni gbogbo ipinlẹ tó wa ni Naijiria ni wọn ti rọ lati lo gbogbo akọsilẹ to wa nikawọ wọn lati tọ ipaṣẹ ilegbe awọn akẹkọọ to wa lawọn ile ẹkọ alakọọbẹrẹ ijọba.
 Ọwa Obokun wa rọ Ile Igbimọ Aṣofin naa lati fọwọsowọpọ pẹlu Igbimọ Aṣofin Apapọ lati ṣatunṣe si iwe-ofin orilẹ-ede yii ki awọn lọbalọba naa le ni ipa ti wọn ninu iṣakoso ilu ati iṣelu lorilẹ-ede yii.
Akọroyin BBC Yoruba to wa nibi ifilọlẹ eto aabo naa fi to wa leti pe, aago mẹsan ni eto naa yẹ ko bẹrẹ, ti wọn si n reti awọn alejo pataki lọwọlọwọ.
” Esau sì dá a lóhùn pé, “Èmi nìyí.
" Nigba to n gba awọn adari wa nimọran lori bi ọjọ ọla Naijiria yoo ṣe dara, Akeugbagold rọ wọn lati pese iṣẹ fun awọn ọdọ, ki wọn si fun wọn ni owo lati da iṣẹ tara wọn silẹ, ki wọn ma baa huwa ọdaran.
”Oludari VON so pe ipade naa ko so nipa ona ti eya Igbo yoo gba je aare lodun 2023 tabi gbosuba fun Muhamadu Buhari lori iyanju re fun awon  atunse to se si awon ibi to baje ni iwo-oorun.
Ó lẹ́wà gan-an ni, ó wọ aṣọ darádára, ara rẹ̀ tutu nini, ó mọ́ tónítóní, ara rẹ̀ ń dán bí ara ọmọ kékeré, eyín rẹ̀ funfun bí asọ àlà, ojú rẹ̀ gún bí ojú òṣùpá, ẹyínlójú rẹ̀ mọ́lẹ̀ kedere, ẹ̀yà ara rẹ̀ wà ní ìwọ̀ntun-wọ̀nsì, wọn bá ara ṣe dọ́gbadọ́gba, ó ró aṣọ, ó wé gèlè, ó mú ìbòrùn lọ́wọ́, o fi yẹrí sí etí, o fi òrùka sí ọwọ́ ó sì wọ sálúbàtàtà idẹ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù BBC and MTN: ọ̀fẹ́ ni ẹ o máa gbọ́ ìròyìn Yorùbá, Pidgin, Igbo àti Hausa lórí 'MyMTN App' yìn!
Àlejò kankan tabi alágbàṣe kò gbọdọ̀ ba yín jẹ ẹ́.
Oríṣun àwòrán, OSatuyi Àkọlé àwòrán, Ẹ̀dínwó epo bẹntírò ti NNPC kede kò kan ará ilú Ajọ PPPRA ṣalaye ninu atẹjade naa wi ẹdinwo epo bẹntiro naa wa ni ibamu pẹlu idasilẹ ṣiṣe ayẹwo owo epo rọbi oṣu kẹta ọdun yii.
ó ní kí ọba ṣí fèrèsé, kí ó kọjú sí ìhà ìlà oòrùn, ọba sì ṣe bẹ́ẹ̀.
Ṣugbọn sibẹ ojuṣe awọn to jẹ ẹni rere ninu wọn ati ijọba pẹlu ni lati hu awọn oniṣẹ ibi aarin wọn jade, bi bẹẹ kọ, ọrọ ọhun ti di má fi oko mi ṣe aala, eleyi to jẹ pe ọjọ kan bayii leeyan n kọọ.
Aṣofin Ọbasa sọrọ yii ninu ọrọ ikini ku ọdun rẹ fun ayẹyẹ itunu aawẹ Ramadan (Eid-l-Fitri) ti ọdun 2018 yii, eleyii ti Alukoro agba rẹ, Ọgbẹni Musbau Rasak fọwọ si.
Mo bi wọ́n léèrè pé irú ibi pẹpẹ ìrúbọ wo ni ẹ tilẹ̀ ń lọ ríì?
Irin kilomita marun un ni wọn ma n rin ki wọn to tilẹ rin omi rara fun abọ fifọ, aṣọ fifọ ati lilo ninu ile.
a Eda Onile Ola ati bẹẹbẹẹ lọ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Governor's Pension: Kwara fẹ́ ṣé bí Èkó, ó dẹ́kun sísan owó ìfẹ̀yìntì fáwọ̀n Gọ́mìnà àná àti igbákejì wọn 10 Bélú 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 13 Bélú 2020 Oríṣun àwòrán, Facebook/Saraki/Abdulrahaman Ipinlẹ Kwara ti ṣetan lati ba ipinlẹ Eko ko anko, nipa yiyi ofin to ya owo ifẹyinti sọtọ fawọn Gomina tẹlẹ ati igbakeji wọn.
O sọ pe bẹẹ na ni ọrọ ri fun ẹkùn Niger Delta pẹ̀lú wàhálà àwọn ajìjagbara tí wọ́n ń kojú lónìí.
Má ranti ẹ̀ṣẹ̀ tí mo ti ṣẹ̀ ní ìgbà èwe mi,tabi ibi tí mo ti kọjá ààyè mi;ranti mi, OLUWA, nítorí ìfẹ́ rẹ tí kì í yẹ̀,ati nítorí oore rẹ.
O ṣalaye pe ẹbí, ara ati ọrẹ lo da owo ti awọn fi ṣeto ayẹyẹ igbeyawo naa lọdun 1988,to fi mọ eyi ti wọn fi gba ile.
Àkọlé àwòrán, Awọn ọdọ Eko ni igbesẹ yii jẹ fifi ọwọ rẹ ijọba awa ara wa nimu ati pe lati igba ti ile igbimọ aṣofin yii ti bẹrẹ iṣẹ, ko si ofin kankan ti wọn ṣe to ba ifẹ awọn ọmọ Naijiria mu.
Mi ò gbèrò láti lọ fún sáà kẹ́ta gẹ́gẹ́ bí ààrẹ - Buhari Ọmọ Nàìjíríà yarí lórí àbá láti mójútó ayélujára, ilé aṣòfin láwọn ń tẹ̀síwájú lórí ẹ̀ Alaga ajọ PFN rọ alakoso fasiti ti wọn ti fẹ ṣe apero naa, Ọjọgbọn Charles Igwe wi pe ko ma ṣe gba wọn laye, bi ko ba fẹ ri ibinu Ọlọrun.
Baakana, ijọba orilẹ-ede Somalia ti kede pe wọn ti gbalejo arun Coronavirus lorilẹ-ede wọn.
Ohun ti igbimọ to n mojuto ọrọ ajakalẹ arun Covid-19 ni Naijiria sọ ni yi ni Ọjọbọ tii se ọjọ kọkanlelogun, osu Karun un.
Ọwọ́ ọlọ́pàá tẹ ọmọ Britain tó ń ta kẹ́míkà gẹ́gẹ́ bi omi ìyanu BBC tun rii pe àwọn orilẹ-ede bii India, Denmark, Iran, Srilanka, Russia ati ilẹ̀ Europe ni wọn fi n parọ fawọn ọmọ wọnyii pe wọn a ko wọn lọ lati maa gba bọọlu jẹun.
”Aare ni gbigbokun ti iko olote ti di ohun to n sele ni agbaye bayii, nitori naa ni awon orile ede ti o n koju iru isele naa se n fowosowopo lati gbogun ti iko olote.
Orilẹ-ede Belgium ti jẹ gbajugbaja fún awọn ọlọsin ẹyẹle at'awọn ololufẹ ẹyẹle.
Won koi ti kede igba tabi akoko ti eto idibo orile-ede naa yoo waye, amo, won ti so pe, eto idibo yoo waye ki odun yii to pari.
Ki wa ni orilẹede Naijiria n da bayii?
Ọrọ ti wọn n sọ tun wa a peleke, lẹyin ti iroyin kan jade pe wọn fẹ ẹ gba Kyari wa sileewosan nilu Eko fun itọju, dipo ilu Abuja to n gbe.
Àjẹsára àwàlù eyín di ohun tó wà fún lílò ní ilẹ ̀ amẹ ́ ríkà ní àwọn ọdún 1940 .
Nígbà tí Ain àti Ilésanmí ti Ìbàdàn tí wọ́n ti ń bọ̀ dé Ilé-Ifẹ̀, wọ́n lọ sí ilé fáwọlé Nígbà tí Orímóògùnjẹ́ ń ṣàìsàn lọ́wọ́ tí fọláṣadé 9tí àwa tún mọ̀ sí fìlísíà) wá sí Ifẹ̀, ó lò tó ọjọ́ mẹ́ta dípò méjì tí ó máa ń lò tẹ́lẹ̀.
Àwọn ọ̀dọ́ dáná sun àgọ́ ọlọ́pàá lorí ẹ̀sùn pé ọlọ́pàá SARS pa ọ̀dọ́kùnrin kan Ẹwẹ, awọn ọdọ dana sun ilẹ iṣẹ ọlọpaa nilu Iwo nibi ifẹhonu wọn lẹyin ti ọlọpaa SARS yinbọn pa Nafiu.
Ṣeṣani kò bí ọmọkunrin kankan, kìkì ọmọbinrin ni ó bí; ṣugbọn Ṣeṣani ní ẹrú kan, ará Ijipti, tí ń jẹ́ Jariha.
Mélòó-mélòó wá ni àwọn nǹkan ti ayé yìí?
O ni ki awọn eniyan maa kuro ninu ẹgbẹ  kan si ẹgbẹ  miiran, ko jẹ ohun tuntun ninu oselu.
Ẹwẹ, ẹgbẹ oṣelu alako PDP ti kepe ile igbimọ aṣofin agba l'Abuja lati pe ipade pajawiri lori ọrọ naa.
Láti ìgbà náà ni Edomu ti di òmìnira kúrò lọ́wọ́ Juda.
Alaafin: Olori Aanu Adeyemi ṣàlàyé ìdí tó ṣe gẹ́ Oba Lamidi Adeyemi ti ìlú Oyo Àjọ JAMB kéde ìlànà ìgbà ni wọlé tuntun fún àwọn ilé ẹ̀kọ́ gíga Ọwọ́ ikọ̀ aláàbò STF tẹ afurasí mẹ́jọ tó lọ́wọ́ nínú ìpànìyàn lemọ́-lemọ́ọ Gúúsù Kaduna Èèyàn 290 míràn ló ṣẹ̀ṣẹ̀ fara káásá àrùn Covid-19 ní Nàìjíríà, 160 gbàwòsàn Belarus ni orilẹede to gbona ju paapaa lasiko ogun agbaye keji.
nítorí pé apànìyàn náà gbọdọ̀ dúró ní ìlú ààbò rẹ̀ títí tí olórí alufaa yóo fi kú, lẹ́yìn náà, ó lè pada sí ilẹ̀ ìní rẹ̀.
Ó kọ ibùgbé rẹ̀ ní Ṣilo sílẹ̀,àní, àgọ́ rẹ̀ láàrin ọmọ eniyan.
Lẹyin naa lo lọ si Daura.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Cristiano Ronaldo fi Real Madrid sílẹ̀ Ta ni yóò gba ''golden boot'' ní Russia?
Lalẹ ọjọru ọjọ kẹrindinlogun oṣu kẹsan ni oṣerebinrin yii rọraa fidio kan soju opo ayelujara rẹ to fihan pe o ti gba oruka igbeyawo.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Cancer: Àṣe ara mi ni iso ti n run gbogbo bí mo ṣe n ṣèrànwọ́ lórí jẹjẹrẹ Naijiria to jẹ orilẹ-ede ilẹ alawọdudu ti ero pọ si julọ naa lo ọgbọn atẹyinwa wọn ti wọn fi bori arun polio nipa lilọ kaakiri abule lọ fun awọn ọmọ ni abẹrẹ ajẹsara.
Buhar ti de si orile ede Niger Republic fun
Yóo mú kí ìdáláre rẹ tàn bí ìmọ́lẹ̀;ẹ̀tọ́ rẹ yóo sì hàn kedere bí ọ̀sán gangan.
Eyi si maa n jẹ iyalẹnu fun ọpọlọpọ pe bawo ni Ọba Adeyemi ṣe n ṣe e, ati pe kini aṣiri ibeji rẹ.
Ìdúnàdúrà ṣì n lọ láti dóòlà ọmọ Ọffa mẹ́fà lọ́wọ́ ajínigbé- ODU Irọ funfun báláwú ni, Boko Haram kò dawa lọnà rárá -Ọmọ ogun Naijiria Akitiyan ìjọba láti mú kí àwọn ọmọ Nàìjíríà san owó orí Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Agbara ti iro kọọkan ni lori ikeji rẹ wa lara ohun ti a n gbe yẹwo.
 Eyi ni ọrọ Dokita Pascal Vahwere, ọkan lara awọn dokita to n gbogun ti arun naa ni orilẹede Democratic Republic of Congo, DRC."
 Àyípadà kọ ̀ ọ ̀ kan le ní agbènọ ́ mbàga tọ ́ gbọ ́ dọ ̀ jẹ ́ nọ ́ mbà odidi aláìjẹ ́ olódì , èyun pé , nọ ́ mbà àdábá kan .
À lágbára láti san gbogbo gbèsè tá jẹ Day 29: Kí lo mọ̀ jù nípa Atiku Abubakar?
Èmi kọ́ ni Jobu ń bá wí, ẹ̀yin ni,n kò sì ní dá a lóhùn bí ẹ ṣe dá a lóhùn.
Amọ o ṣalaye pe oun si ni lati wo awọn ẹgbẹ agbabọọlu mi ki oun to pinu eyi ti oun maa darapọ mọ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Mercy Aigbe: Iṣẹ́ ọwọ́ mi ni mó n jẹ, gómìnà àbi ààrẹ kò gbọ́ bùkátà mi 17 Agẹmo 2019 Oríṣun àwòrán, Mercy aigbe Gbaju-gbaja oṣere tiata, Mercy Aigbe ti sọrọ sita lati wẹ ara a rẹ mọ, ninu ahesọ ọrọ kan to n lọ nigboro pe 'ọkunrin lo fi n gbe bukaata ara rẹ.
Òfò ṣ'ẹ̀dá: Ẹ̀fọn Norwich já bàálùu Man City Tammy Abraham dáná sun Wolves, ni Twitter bá ń lọgun rẹ̀ tan-tan Agbabọọlu ikọ Chelsea tẹlẹ, Juan Cuadrado lo kọkọ gba gooolu wọle fun Juventus ki Blaise Matuidi to fi ori gbe ikeji wọle fun goolu Juventus keji.
- Ilé ẹjọ́ ìpínlẹ̀ Ondo Ilé ìwòsàn kan rèé tó ń fi àtùpà gbẹ̀bí aláboyún Lẹ́yìn èyí ni ilé iṣẹ́ ọlọ́pàá dá àwọn ẹsọ́ aláàbò sí ibi ìṣẹ̀lẹ̀ náà, sùgbọ́n nígbà ti wọ́n dé bẹ̀, àwon ọmọ lẹ́yìn eégún kọjú ìjà sí àwọn ọlọ́pàá pẹ̀lú ìbọ̀n.
O ni  ju milionu kan le mefaAtiku sọ pe oun ni o jawe
Aadọta ninu àwọn ọmọ àwọn wolii náà sì dúró ní òkèèrè, wọ́n ń wò wọ́n.
Ẹwẹ, Kọlawọle naa yii pada wipe oun ko ti Oluwo tabi se e ni ohunkohun, bi o tilẹ jẹ wipe o gba wipe nkankan pa oun pọ pẹlu Oluwo lakoko to nse isẹ rẹ.
- Olùgbé Opebi l'Eko Akeredolu ń fẹ́ kí wọ́n dìbò fún òun ló jẹ́ kó ṣàdínkù owó ilé ìwé AAUA - Akẹ́kọ́ọ̀ AAUA Wo àṣẹ tuntun tí Buhari gbé síta nípa owó iná ọba Oríṣun àwòrán, others Àkọlé àwòrán, awọn gbajgbaja osere naa ree Lágbo òṣèré bákan náà nínú ọ̀sẹ yiìí ni àwọn àwọn àgbáríjọ àwọn oṣerẹ agbálewò ti kìí ṣe ti Yoruba níkan ti ko àrawọn jọ.
Ó wí ninu ara rẹ̀ pé, “N óo fi Mikali fún Dafidi kí ó lè jẹ́ ìdẹkùn fún un, àwọn Filistini yóo sì rí i pa.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Arsenal vs Liverpool: Arsenal fìyà bẹ̀rẹ̀ sáà bọ́ọ̀lù tuntun fún Liverpool pẹ̀lú Community Shield 19 Agẹmo 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 30 Ògún 2020 Oríṣun àwòrán, Getty Images Aṣe igi ti a ba foju rena, lo maa n gun ni loju ni tootọọ.
Abala 22 ìwé òfin ọdún 1999 pèsè fún ẹ̀tọ́ òmìnira ìròyìn àti Abala 39 fi lélẹ̀ wípé “gbogbo ènìyàn ni ó ní ẹ̀tọ́ sí òmìnira ọ̀rọ̀ sísọ, títí kan òmìnira láti gbá ìròyìn mú àti gba ọgbọ́n àti ìwífun láì sí ìdíwọ́…”
OLUWA, mo kórìíra àwọn tí ó kórìíra rẹ;mo sì kẹ́gàn àwọn tí ń dìtẹ̀ sí ọ?
Paṣeda ni tirẹ náà fi àra mọ ọ̀rọ̀ Ogunbanjọ lati yan kọmisọna àkànda ẹdá Akinlade ni ijoba amosun ti fowo si iwe adojutofo ilera fun ipinle Ogun, isejoba oun yoo si tun tẹsiwaju lori re.
Ilé ẹjọ́ tó ga jù ní kí gómìnà tẹ́lẹ̀, Jolly Nyame lọ fẹ̀wọ̀n ọdún 12 ṣara rindin
Minisita fun eto inawo Ken Ofori –Atta lo soro yii lasiko ti won gbe eto isuna wa sile igbimo asofin to wa ni Accra.
0 98038 Orilẹede Yemen 639 2.
Aisaya jáde kúrò lọ́dọ̀ ọba, ṣugbọn kí ó tó jáde kúrò ní àgbàlá ààfin, OLUWA sọ fún un pé, 
Kogi Loan: Owó àkànṣe ìṣẹ́ ìjọba àpapọ̀ tíjọ́ba Kogi ṣe la fẹ́ dá padà
Onímọ̀: Bí òbí bá ń mú sìgá, ọmọ rẹ̀ leè sàìsàn ọ̀nà ọ̀fun lọ́jọ́ iwájú
Ninu atẹjade naa, o ṣalaye pe lẹyin ipade awọn ajafẹtọmọniyan pẹlu ọga ọlọpaa ati ileeṣẹ to n mojuto ọrọ ọlọpaa ni wọn pinnu lati ṣamuṣẹ ohun tawọn oluwọde n beere.
 Àwọn ènìyàn tó ń gbé ibẹ ̀ tó 1,278.
Ọkọ baalu Azman naa lo bẹrẹ si ni ṣe efin lẹyin ti obnrin to wọ ọkọ ofurufu naa fa shisha ti ko si pa ina rẹ daadaa ko to wọ ọkọ ofurufu.
Ọpọlọpọ eniyan mú ẹ̀bùn wá fún OLUWA ní Jerusalẹmu, wọ́n sì mú ẹ̀bùn olówó iyebíye wá fún Hesekaya, ọba Juda.
Nítorí ọjọ́ OLUWA súnmọ́lé; OLUWA ti ṣètò ẹbọ kan, ó sì ti ya àwọn kan sọ́tọ̀, tí yóo pè wá jẹ ẹ́.
Èmi náà yóo máa pàtẹ́wọ́, inú tí ń bí mi yóo sì rọ̀, èmi OLUWA ni mo sọ bẹ́ẹ̀.
"Bakan naa ni isede ọhun tun faaye gba awọn ọdaran to n ko siga wọle labẹlẹ nitori awọn to n mu u koro oju si ofin ""ma u siga""."
OLUWA yóo mú jìnnìjìnnì ati ìrẹ̀wẹ̀sì ọkàn ba yín, yóo sì mú kí ojú yín di bàìbàì.
O gba oye ọmọwe ninu ẹkọ nipa Ogun ni King's College ti fasiti London nilu Ọba.
Ẹ mu àmuyó, ṣugbọn kì í ṣe ọtí.
6) Pa awọn aṣẹ to ni ṣe ki foonu rẹ maa ṣatunṣe sawọn nkan ti o n wọ ori foonu rẹ bii fidio to maa bọ sinu rẹ ni kete to ba ti de ori ẹrọ ibanisọrọ rẹ.
Champions League: Barca da yẹpẹ sí gaàrí Man U ní Old Trafford
Ṣugbọn n kò ní ṣe bẹ́ẹ̀, kí ẹnikẹ́ni má baà rò nípa mi ju ohun tí ó rí ninu ìwà mi ati ohun tí ó gbọ́ lẹ́nu mi lọ.
Nítorí wọ́n fi ojú fo èyí dá pé, láti ìgbà àtijọ́ ni àwọn ọ̀run ti wà, ati pé láti inú omi ni ilẹ̀ ti jáde nípa àṣẹ Ọlọrun.
O fi mulẹ pe Gomina ni yoo
Prystaiko fikun wi pe awọn to wa ninu ọkọ ofurufu naa lẹ ni aadọsan eniyan.
Ṣugbọn ní ìkáwọ́ rẹ ni ìdáríjì wà,kí á lè máa bẹ̀rù rẹ.
Ọ̀pọ̀ ọmọ Nàìjíríà ló ni ìdájọ́ to yẹ ni láti le Erica kúrò nínú ilé.
Ọ̀pọ̀ ọmọ Nàìjíríà ń fẹ́ kí òfin kónílé-ó-gbélé kásẹ̀ nílẹ̀ ní Nàìjíríà Oríṣun àwòrán, Twitter Ọpọlọpọ ọmọ Naijiria ti fi ẹro wọn han lori ẹrọ ayelujara lori ohun ti wọn lero pe Aarẹ Buhari yoo sọ lori arun Coronavirus.
Azeez Popoola Adeduntun - O yege7.
Ṣugbọn nigba ti ẹbẹ pọ, adajọ din ẹwọn naa ku si oṣu kan, tabi ẹgbẹrun mẹta fun owo itanran.
Mexican Octogenarian: Kò sígbà táa dá aṣọ, ti a kò rílẹ̀ fiwọ́!
BBC Yoruba tu pẹrẹpẹrẹ bo ṣe jẹ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ọlọ́pàá Eko: Afurasí náà ní ẹnìkan ló bẹ òun lọ́wẹ̀ láti lọ gba ilẹ̀ onílẹ̀ 25 Òkùdu 2019 Oríṣun àwòrán, Nigerian Police Àkọlé àwòrán, Awọn ọlọpaa ba ibọn agbelẹrọ mẹẹrin ati ọta ibọn mejidinlogoji ninu ọkọ bọọsi naa.
Ọjọ Aiku ni iṣẹlẹ naa ṣẹlẹ ninu ile ti Akinola n gbe pẹlu iya rẹ naa, Alice Akinola, ati ọmọdekunrin miiran kan.
”Maria bá yipada sí i, ó pè é ní èdè Heberu pé, “Raboni!
Ọwọ́ tẹ babaláwo àti adigunjalè márùń ni Imo - Olọpàá Kí ni pàtàkì nọ́mbà 615 láàrín àwọn èèyàn ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ̀ Àwọn mẹ́rin t'íjọba Buhari k'etí ikún s'àṣẹ òmìnira iléẹjọ́ lórí wọn rèé Ilé ẹjọ́ kọ̀ láti tú Omoyele Soworẹ sílẹ̀ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Olojo festival: Fídíò bí èrò ṣe darapọ̀ mọ́ Ọọ̀ni láti ṣọdún Ọlọ́jọ́ nílé Ifẹ̀ nìyí Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Lára àwọn idi ti ọmọ lè fi rù ni: àìsàn, ebi, òùngbẹ, ìṣẹ́, ai ni alabojuto, òbí olójú kòkòrò, ai ni òbí àti bẹ ẹ bẹ lọ.
Ẹ jẹ́ kí á tẹ̀síwájú nípa kíkọ́ ẹ̀kọ́ tí ó jinlẹ̀.
Wọ́n bá tún bèèrè pé, “Ó dára, ta ni ọ́?
Bẹ́ẹ̀ ni òmùgọ̀ àwon ènìyàn pọ̀ tó?
Gbajugbaja elere sinima yii, Yemi Ayebo ni BBC Yoruba gba lalejo lori eto wa loju opo Facebook.
" Ṣaaju ninu ọrọ rẹ ni Emir ilu Kano, ti pe fun, 'ajọṣepọ ati ajumọkẹgbẹ pọ lati finuwenu lori gbigbogun ti iṣoro to n koju eto ẹkọ, igbanisiṣẹ ati idagbasoke ilu laarin awọn ọdọ lorilẹede Naijiria nitori nipasẹ eyi ni ọna abays fun iṣoro atigbadegba to n koju orilẹede Naijiria lee ti yọju.
Kini Fatima sọ pe o ṣẹlẹ gangan?
Fun Prince Adewale Amidu, o ṣọrọ lori bi Ààrẹ Buhari ṣe sọ pe bi awọn orilẹ-ede miran naa ṣe n ṣe niyẹn nitori coronavirus.
 O ni ki won dibo fun olotito ati eni to ni
kí ẹ fi iná sinu wọn, kí ẹ sì gbé wọn lọ siwaju OLUWA.
 Àwọn asunrárà ọkùnrin tí ó máa ń fi rárà ṣe iṣẹ ́ ṣe ni wọ ́ n máa ń ya ilé kiri láti sun rárà .
Bakan naa lori ọrọ yiyẹ aṣẹ irinna wo kete ti eeyan ba ti de orilẹ-ede Naijiria eyi ti wọn pe ni Visa on Arrival"", O ni yoo jẹ anfani nla fun awọn oniṣowo ọmọ Afirika to ba n bọ lati wa ṣe owo lọna to tọ ki wn le gberu sii."
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Anambra Rape: Ìdí ti mo fi bá ọmọ ọdún méje lòpọ̀- Ejike Kanu 7 Ọ̀wàrà 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 8 Ọ̀wàrà 2020 Oríṣun àwòrán, Hamisu Mallamawa Àkọlé àwòrán, Iwaju ile Musa Ọkùnrin ẹni ọdún mẹ́tàlélọ́gbọ̀n kan ni wọ́n ti fí pánpẹ́ ọba mú nítorí ó fipá bá ọmọ ọdún méje tó jẹ́ aládùgbò rẹ̀ lòpọ̀.
Ọrọ lori iṣejọba ajumọlo ninu ẹgbẹ oṣelu AG lo mu ki edeaiyede ṣẹlẹ laarin Akintola ati Awolowo.
O ni àwọn òbi Ani ko faramọ ìbáṣepọ̀ àwọn nítori òun dàgbà jù ú lọ, o sì yẹ kó fẹ́ ìyàwó kan ni abule wọ́n ni ìpínlẹ̀ Ebonyi.
,United Nations , António Guterres ,ni won yoo jọ maa sọrọ lasiko iside ipade ọhun.
Alaye wọn ni pe awọn eeyan to dipo nla mu ninu ijọba ko le maa gbadun, ki wọn wà ni k'ara ilu maa ṣe ifarada.
Nítorí pé, talaka kò ní tán lórí ilẹ̀ yín, nítorí náà ni mo ṣe ń pàṣẹ fun yín pé kí ẹ lawọ́ sí arakunrin yín, ati sí talaka ati sí aláìní ní ilẹ̀ náà.
oba ilu Jebba  ni aarin gbungbun orile
Àwọn Farisi ati àwọn amòfin kan tí wọ́n wá láti Jerusalẹmu péjọ sí ọ̀dọ̀ Jesu.
Aare ni orile ede Naijiria ati Equatorial Guinea
Kò sí àkọsílẹ̀ ìbẹ̀rẹ̀ tabi òpin ìgbé-ayé rẹ̀.
Osun-Osogbo Festival 2020: Ìjọba ìpínlẹ̀ Osun tí búwọlù ìlànà àyẹyẹ Osun-Osogbo ọdún 2020 Oríṣun àwòrán, Others Ìjọba ìpínlẹ̀ Osun ti buwọlu ìlànà ti yóò fí ṣe ayẹyẹ ọdún Osun-Osogbo ọdún 2020.
Ọpọlọpọ awọn ajọ alaanu si bẹrẹ si fi ounjẹ, oogun, ati nkan ijagun (bi awọn kan ṣe sọ) ranṣẹ si Biafra.
Oríṣun àwòrán, @kekeTony Àkọlé àwòrán, Ṣadede ni aworan awọn ọlọpaa ti wọn na ika 4+4 yi lu sita loju opo ayelujara Aṣa yi gbalẹ laarin awọn alatilẹyin APC ti awọn ọmọ ogun kan ati ọlọpaa naa si ba wọn da ninu aṣa naa.
Bo tilẹ jẹ pe ilu London ni wọn bi Vee si, ọdun 2019 lo tẹkọ leti lọ si lati tẹpa mọṣẹ orin to yan laayo.
Ẹya Covid-19 tuntun ti jẹyọ ni Demark bakan naa ni wọn ri ni Australia, Italy ati Netherlands.
Bi orile ede Naijiria se n mura
Ẹni tí ó bá gbin aiṣododo yóo kórè ìdààmú,pàṣán ibinu rẹ̀ yóo sì parun.
Awọn iroyin ti ẹ lee nifẹẹ si: NYSC ko awọn agunbanirọ kuro nileewe l'Ọsun APC ati PDP ko ni Ijọba ipinlẹ Eko, labẹ Gomina Akinwunmi Ambode wa parọwa si awọn tọrọ naa kan lati kọpa ninu agbekalẹ aba kan nile asofin ipinle naa, lati le mu ki awọn eniyan fi ero wọn han lori abadofin owo ori ilẹ ati ile ni ipinle Eko.
Koda, o tun ṣẹṣẹ fakọyọ ninu ija to ja kẹyin ni, nibi to ti ṣe Paulo Costa bi ọsẹ ti n ṣe oju, ninu ija to waye niluu Abu Dhabi lorilẹede UAE laarọ lọjọ Aiku.
Àmọ́di ńlá tí ó ń fẹ́ pa mí!
Ó dá mànàmáná fún òjò,ó sì mú ìjì jáde láti inú ilé ìṣúra rẹ̀.
Oríṣun àwòrán, Ogun State Governor's office Àkọlé àwòrán, Ni aye atijọ, awọn ìlú nilẹ Yoruba ati kaakiri ilẹ Afrika maa n lo ìlù lati ba ara wọn sọrọ.
O ni kii ṣe ọna tabi erongba lati dẹru ba ijọba to n bọ.
Wọn kò pa àwọn eniyan ilẹ̀ náà run,gẹ́gẹ́ bí OLUWA ti pa á láṣẹ fún wọn,
Ṣugbọn bí o bá dín iṣẹ́ líle baba rẹ yìí kù, tí o sì mú kí ìgbé ayé rọ̀ wá lọ́rùn, a óo máa sìn ọ́.
"O yẹ ki a jẹ́ ki awọn aṣa wa ba igba mu ko le maa wu awọn eniyan.
ninu awọn kristiani ti Ọdọ Àjọ-Ọdọ onigbagbọ , imọran miiran ni kristius victor .
Mo kó gbogbo ayé,bí ẹni kó ẹyin ẹyẹ tí ó kọ ẹyin rẹ̀ sílẹ̀, tí ó fò lọ,kò sí ẹnìkan tí ó lè ṣe nǹkankan,kò sí ẹnìkan tí ó lanu sọ̀rọ̀,bẹ́ẹ̀ ni ẹnikẹ́ni kò gbin.
Ṣugbọn OLUWA dá mi lóhùn, ó ní,“Má pe ara rẹ ní ọmọde,nítorí pé gbogbo ẹni tí mo bá rán ọ sí ni o gbọdọ̀ tọ̀ lọ.
Níbi tí adura Dafidi ọmọ Jese parí sí nìyí.
Ileeṣẹ ọmọogun naa wa kesi awọn eniyan lawujọ, paapaa awọn agbegbe to wa ni eti omi lati ri wi pe aabo ẹmi ati dukia jẹ wọn loju.
Babachir Lawal bọ lọwọ EFCC Bukola Saraki kò kọjá òfin - EFCC EFCC tun gbe Akala yọju sile ẹjọ EFCC fẹ gbegidina ibo rira ni 2019 EFCC kó akẹ́kọ̀ọ́ fásitì UNIOSUN Ajọ EFCC ni wọn lọ ṣe iwadii owo naa ni kete ti wọn ri iwe ẹsun gba lati ọwọ oṣiṣẹ fifihẹ kan ti INEC lo lasiko idibo to kọja.
Ní ìrọ̀lẹ́, nígbà tí Jakọbu ti oko dé, Lea jáde lọ pàdé rẹ̀, ó sọ fún un pé, “Ọ̀dọ̀ mi ni o gbọdọ̀ sùn ní alẹ́ òní, èso mandiraki ọmọ mi ni mo fi san owó ọ̀yà rẹ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù World tour- Jessica Nabongo ni obìnrin akọkọ nilẹ Africa tí yóò rin àgbaye tan 10 Ọ̀wàrà 2019 Oríṣun àwòrán, Jessica Nabongo Àkọlé àwòrán, World tour- Jessica Nabongo ni obìnrin akọkọ nilẹ Africa tí yóò rin àgbaye tan Ninu ọdun yii ni Jessica Nabongo mu ero rẹ ṣẹ gẹgẹ bi obinrin akọkọ ni ilẹ Adulawọ ti yoo rin gbogbo orilẹ-ede agbaye.
Nigeria Ni ibẹrẹ oṣu kẹwaa ọdun 2020 ni iwọde fopin si iwa kotọ ọlọpaa ti ọmọ si #ENDSARS bẹrẹ ni Naijiria.
Awọn awroan yii wa lati ọwọ: AFP, Reuters, PA and Getty Images Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Peteru tún sẹ́, ó búra pé, “N kò mọ ọkunrin náà.
ifá jé òrìsà kan pàtàkì láàrin àwon yorùbá .
Eniyan rere ń mú ohun rere wá láti inú orísun rere ọkàn rẹ̀.
Awọn kan n sọ ahesọ pe arun onigbameji ni awọn eeyan gbagbọ pe o ṣokunfa iku rẹ.
“Ibà-ẹ̀fọn àti àmìi rẹ̀ ní ọdún yìí ti yàtọ̀ nítorí ìdí èyí ni o fi ní láti tọ oníṣègùn rẹ̀ lọ ní kété tí o bá ti ní ibà náà” – gẹ́gẹ́ bí ògbólògbó onímọ̀ ìlera ti Ilé-ìwòsàn Bangabandhu ti sọ.
Nigba ti BBC kan si ṣẹnetọ naa, o ni iṣẹlẹ naa ti waye lati ọjọ Kọkanla oṣu Kẹta ọdun 2019 bo tilẹ jẹ wipe awọn iroyin to n sọrọ nipa isẹlẹ naa ni ọjọ Kọkanla oṣu Karun un ọdun 2019 lo waye.
Lara oriki Alaafin ni, Iku baba yeye, Adeyẹmi Alowolodu, ojo pa sẹkẹrẹ ma dẹ, ọmọ Atiba, ọmọ iku ti iku ko gbọdọ pa, ọmọ arun ti arun ko gbọdọ se.
Ibanujẹ dori agba Messi kodo lẹyin ti ijakulẹ Barcelona pẹlu Osasuna gba ife ẹyẹ La Liga mọ Barcelona lọwọ lalẹ Ọjọbọ.
” Ẹ̀rù ba Hamani gidigidi níwájú ọba ati ayaba.
naa lati fi maa ṣamojuto awọn ojuṣe ijọba ibilẹ ni ti gbigba oṣiṣẹ sẹnu
O fi kun pe ki gbogbo àwọn ọmọ ẹgbẹ́ àti àwọn olólùfẹ wọ́n ma gbe ìgbésẹ̀ kankan titi gbogbo àwọn ti ijọba ibilẹ Oyo pe ki wọ́n wa jẹ́jọ ni ọjọ káàrun osù keji ọdun yií yóò fi wá sọ ti ẹnu wọ́n.
oniwaadi,olukọ ati gbogbo awon to ko ipa Pataki lati gbougun ti aisan iba
Dafidi pàṣẹ fún àwọn olórí ninu àwọn ọmọ Lefi pé kí wọ́n yan àwọn akọrin láàrin ara wọn, tí wọn yóo máa fi ohun èlò orin bíi hapu, dùùrù, ati aro dá orin ayọ̀.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ìbádọ́gba nínú ìsèlú àti iṣẹ́ láwùjọ ṣe pàtàkì fún ìdàgbàsóké Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Nikodemu bi í pé, “Báwo ni a ti ṣe lè tún ẹni tí ó ti di àgbàlagbà bí?
World Toilet Day: 'Ìgbẹ́ tí wọ́n ń yà síbí kìí jẹ kí oníbàárà wá sọ́dọ̀ wa' Nínú kó o fi omi fọ ìdi tàbí lo tííṣù fi fá a, Èwo ló rọrùn?
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ọba mẹ́wàá tí wọ́n ti lé kúrò nípò: Alaafin, Ọlọ́wọ̀, Elérúwà , Awujalẹ àti .
Ati pé ìlànà náà ki ṣe bi ọlọpàá ṣe ń ṣe àwọn afúrasi to ba wà ní àyíká wọ́n  Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fọ́nrán ohùn, Joe Igbokwe kò yẹ́ fún ipò ti wọ́n fún nípìnlẹ̀ Eko - Babatunde Gbadamosi Awọn ọlọpàá náà ní Insp."
Danbatta salaye pe, ile-ise Etisalat yoo si wa sibe, amo bi oro pasiparo owo se ri bayii, ajo NCC yoo tesiwaju lati se amojuto ti yoo ri daju pe,awon ile-ise ero ibara-eni soro yoo ni igberu ninu oja idokowo”.
Nígbà tí àwọn onigbagbọ mọ̀, wọ́n sìn ín lọ sí Kesaria, wọ́n fi ranṣẹ sí Tasu.
Afọ́jú tí ó ń fọ̀nà hanni ni wọ́n.
O ni, kii ṣe pe wọn ji olorin ọhun gbe gẹgẹ bi iroyin ẹlẹjẹ ti awọn kan n gbe kiri lori itakun agbaye, ṣugbọn ahamọ ọlọpaa lo wa.
O ni ko si idi pataki kan pato fun oun lati rawọ ébẹ si awọn ọmọ Naijiria latari ikọlu ti o waye ni ilẹ naa.
- Trump Ọ̀pọ̀ ewébẹ̀ àti èso aṣaralóore tó wà ní àyíká àmọ́ tí ẹ kò kà kún rèé Omi ara Ọ̀pọ̀lọ́, ẹ̀jẹ̀ Ẹlẹ́dẹ̀ àti wáìnì tí wọn fi Èkúté ṣe ń mára jípépé, ẹ máa mú Gẹgẹ bi onimọ nipa iloyun ati ibimọ obinrin, Ọjọgbọn Adetunji Adeniji, lati Fasiti Ladoke Akintola, nilu Ogbomoso, ṣe sọ fun iwe iroyin Tribune, , bi obinrin ba ṣe tin-in-rin tabi sanra si naa ma n ni ipa lara rẹ ati oyun ọmọ to ba ni.
10 Nísisìyí, bí ìwọ bá ti mọ èyí ìwọ ìba ti túmọ; bí ó tilẹ̀ rí bẹ́ẹ̀, kò tọ̀nà pé kí o túmọ̀ ní ìsisìyí.
Bí ó bá jẹ́ pé owó ni wọ́n fi yá ẹran náà lọ tí ó fi kú, a jẹ́ pé orí iṣẹ́ owó rẹ̀ ni ó kú sí.
Agbára àwọn ẹṣin wọnyi wà ní ẹnu wọn ati ní ìrù wọn.
"Orukọ ""Rainbow"" ti wọn n pe Idowu Philips wa latinu Oṣumare to jẹ ""Rainbow"" ni ede Gẹẹsi."
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Adebola Ademilua: Àìrísẹ́ ṣè lẹ́yìn ìwé kíkà ló sọ mi dí ìyá onírú, mo dúpẹ́ tèmi 5) Aja lo l'ẹru lati ọwọ oloogbe Oladẹjọ Okediji.
Ohun kan to kan awọn aṣofin lominu ni iye ti wọn kọ sinu rẹ pe Naijiria yoo fi seto gbese to le ni triliọnu mẹta naira ati erongba lati ya owo to le ni triliọnu marun un lati fi seto isuna.
o tun wa ro won lati se iru atileyin bẹẹ fun gomina tuntun naa , ki o le se
“ ‘O kò gbọdọ̀ ṣe ojú kòkòrò sí aya ẹlòmíràn, tabi ilé rẹ̀, tabi oko rẹ̀, tabi iranṣẹkunrin rẹ̀, tabi iranṣẹbinrin rẹ̀, tabi akọ mààlúù rẹ̀, tabi kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ rẹ̀, tabi ohunkohun tíí ṣe ti ẹlòmíràn.
Ó kó wọn lọ sí Baala ní Juda láti gbé àpótí ẹ̀rí Ọlọrun wá sí Jerusalẹmu.
’ rèé Afọnja, ẹni tó finú wénú ní Ilọrin, àmọ́ tó jẹ iwọ Ẹfunsetan Aniwura, obìnrin tó ju ọkùnrin lọ Ọ̀rọ̀ǹpọ̀tọ̀niyùn, Aláàfin obìnrin àkọ́kọ́ rèé, tó ní nǹkan ọkùnrin Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Kayeefi: Facebook ni Wolii Arole Jesu fi tàn an wọ agbo, orí rẹ̀ ni wọ́n fi s'owó Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Toke Makinwa, Banana Island house & Festus Fadeyi: Toke Makinwa fọhùn síta; Jude tí Amcon náà dá a padà pé.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Domestic Violence: Ìjà láàrin lọkọlaya sọ aya dèrò ọ̀run Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Ninu ọrọ ti agbẹnusọ ileeṣẹ ologun fi sita, Brig.
N óo máa ṣírò iṣẹ́ rere rẹ,n óo máa ròyìn iṣẹ́ ìgbàlà rẹ tọ̀sán-tòru,nítorí wọ́n pọ̀ tóbẹ́ẹ̀ tí n kò lè mọ iye wọn.
Ta ní ń bọ̀ láti inú aṣálẹ̀ yìí,tí ó fara ti olùfẹ́ rẹ̀?
Eyi ni awọn ọrọ miran tawọn ọmọ Naijiria sọ si Keyamo lori: Ẹwẹ Aarẹ Buhari, igbakeji aarẹ tẹlẹ, Alhaji Atiku Abubakar ti ranṣẹ ikini ku oriire si Anthony Joshua, Koda Sẹnetọ ana, Dino Melaye gan ko gbẹyin Ninu ọrọ tirẹ, Aarẹ Buhari gbosuba fun un pe o ja igbanu ẹyẹ rẹ gba pada lọwọ Andy Ruiz.
Nígbà tí ilẹ̀ ń ṣú lọ tí ó kù díẹ̀ kí wọ́n ti ìlẹ̀kùn ẹnu ibodè ni wọ́n jáde lọ, n kò sì mọ ibi tí wọ́n lọ.
Aya Femi Amao n ṣiṣẹ nile ẹkọ Graceland Heights School ni Wọfun Olodo ni Iyana Church nilu Ibadan nipinlẹ Oyo.
“Ẹnikẹ́ni tí ó bá pa eniyan, pípa ni wọn yóo pa òun náà.
O óo kọ́ ilé, o kò sì ní gbé inú rẹ̀.
Koda, orisun ọrọ aje wa gan n fa isoro, tawọn ẹya ti epo rọbi pọ si naa si n dunkooko pe awsn fẹ ya kuro ni Naijiria lati lee se akoso ohun alumọni ti ọba oke fi jinki awọn.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Nazir Sarkin Waka: 'Mo ṣetán láti lo gbogbo ayé mi tókù lẹ́wọ̀n' 5 Bélú 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 6 Bélú 2020 Oríṣun àwòrán, Nazir Sarkin Waka 'Mo ṣetán láti lo gbogbo ayé mi tókù lẹ́wọ̀n' Arakunrin olorin ọmọ Naijiria kan, Nazir Sarkin ti ni oun ṣetan lati lo gbogbo igbesi aye oun lẹwọn nitori ohun to gbagbọ.
Lori ibeere yii, Fatomilola sọ pe oye to lagbara ni ipo ọba laye atijọ, sugbọn awọn ọba ode oni ko lẹnu ọrọ mọ, nitori pe oloṣelu lo n fi wọn joye.
Wèrè tí mò ń ṣe ní Facebook ló pawó fún mi-Esabod Àwọn ọlọ́pàá kò kọbiara si ọ̀rọ̀ ìwà ipá lásìkò ìgbéle Covid -19 ni ìwà ipá ṣe pọ̀ - Ajàfẹ́tọ obìnrin Ẹwẹ lati ọdun to kọja ti awọn aṣofin yii ti bẹrẹ iṣẹ, ọpọ igbesẹ ni wọn ti gbe ọpọ aba ofin si ni wọn ti da ṣugbọn ibeere to n jẹyọ ni wi pe bawo ni awọn aba ọhun ṣe kan ara ilu to si ṣe wọn loore.
Bakare ni gbogbo irú etutu bẹ́ẹ̀ kò si mọ, ti ọpọ awọn Ọba Alade isinyii ko ki n ṣe pe ni ọna to tọ ati ọna to yẹ, nítori náà o lé maa si ǹkan ti yóò tẹ̀yin ìgbésẹ̀ yìí jáde.
Ìwúrí àti àyọ̀ nlá ni fún gbogbo ọmọ Yorùbá àti gbogbo Nàìjíríà lápapọ̀ lónìí!
Awọn alaṣẹ Fatimid ni Egypt sọ pe awọn ni ojulowo olori ẹsin musulumi, eyi to mu wọn tako ijọba Abbasid lorilẹ-ede Iraq ati Syria.
"Mo kọkọ n wo pe se ẹgbọn n ba aburo rẹ wi ni abi ibo ni mo ti se asise?
Mohammed Umar: Ta ni ọ̀gá àgbà tuntun fún EFCC?
Oríṣun àwòrán, ore_mommycalmdowr Nipa ti Oreofeoluwa Lawal-Babalola, iya rẹ ni ko i tii mọ nkankan nipa ohun ti fidio naa da silẹ, amọ oun to sọ fun iya rẹ ni wi pe 'Mummy, mo n ri ara mi ri lori ẹrọ ayelujara kaakiri'.
Kò sí ẹyọ kan tí ó rú Solomoni lójú, tí kò dáhùn pẹlu àlàyé.
 Ìwé mẹ ́ rindínláàdọ ́ rin ni wọ ́ n kó jọ sínú bíbéli .
Àwọn ìlú wọn tóbi, wọ́n sì jẹ́ ìlú olódi, odi wọn ga kan ọ̀run, àwọn òmìrán ọmọ Anaki sì wà níbẹ̀!
Kò ju ọjọ́ méje lẹ́yìn èyí tí a gbọ́ pé ọba náà kú.
Kylie Jenner to jẹ abikẹyin ninu idile wọn, di ọlọla ni pasẹ ohun elo amaradan ati asaraloge ti oun ta.
Bí adágún omi tíí gbẹ,ati bí odò tíí ṣàn lọ, tí sìí gbẹ,
bi a se mọ pe awon ile –iwe ati awon ibi ile idibo ni won n lo lati ka awon ibo
Ọjọ ti pe ti ọta awọn mejeeji ti bẹrẹ ṣugbọn lnu igba ti liigi Premiership di ilumọka yi, awọn alatilyin wọn ko fẹ ri imi ara wọn lakitan.
Ni ọjọ Iṣẹgun, ọjọ kẹta, oṣu kejila, ọdun 2019 ni gomina ipinlẹ Eko, Sanwo Olu Babajide, kede iyipada orukọ rẹ si papa iṣire Mobọlaji Johnson.
Olu ile-ise tuntun ohun je okan lara awon ise-akanse Aare Abdel-Fattah El-Sisi, pelu erongba ati se agbekale  olu-ilu, ti awon ile-ise ijoba ati awon ile-ise miiran yoo ko lo.
Naijiria na Tunisia pẹlu ami ayo kan sodo l'Ọjọru lati gba ipo kẹta.
Ileeṣẹ Otẹlẹmuyẹ CIA ti fọrọ wa awọn mẹrin to ku naa lẹnuwo ki awọn ọmọ ogun Amerika to ko wọn.
Láti ìgbà laelae ni wọ́n ti jẹ́ ọlọ̀tẹ̀ sí àwọn ọba agbègbè wọn.
Ìfọwọ́sowọ́pọ̀ nìkan ni ọ̀nà abáyọ sí ìṣòro Nàìjíríà- Olusegun Obasanjo Ìtura ìgbà díẹ̀ ni bọ́dà tí ìjọba ṣí padà, kò lóòre nínú - Onímọ̀ ọrọ̀ ajé Wo ìdí tí ààrẹ Buhari kìí fi ṣe ẹ̀dà Jubril láti Sudan Bukunmi Oluwasina, to sẹsẹ se igbeyawo laipẹ yii, wa ke sawọn ololufẹ rẹ, lati ba ke Halleluyah, nitori oun n jo kiri inu ile ni pẹlu isẹ ayọ ti oun gba naa lọdọ Funke.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ado Ekiti Blind Couple: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú Kinni Igboho tun sọ?
Nítorí náà, gbogbo àwọn ọmọ Lefi tí wọ́n jẹ́ ìran Aaroni alufaa gba ìlú mẹtala lọ́wọ́ àwọn ẹ̀yà Juda, ẹ̀yà Simeoni, ati ẹ̀yà Bẹnjamini.
Ẹ ṣe ọkàn yín gírí, ẹ̀yin ọmọ ogun Filistini!
Lọwọlọwọ, olukọ mẹta lo n jẹjọ lọwọ."
Arire ba ni se ni wọn, wọn kii si fi bo Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Mama Arsenal: Màmá àgbà yìí máa ń lọ sí ìbùdó tí wọ́n ti ń wo bọ́ọ́lù láti wòran Lara akiyesi wa tun ni pe, ko si oruka igbeyawo lọwọ Adebimpe tabi Lateef ninu fọto tuntun naa.
Blind DJ: Etu Omotayo kò ríran àmọ́ ó le to irinṣẹ́ eléré pọ̀ láti kọrin láì sí ìrànwọ́
Omo odun mẹ́tàdínllọ́gọ́ta ohun, bere sini n tuko Brazil lati osu kefa odun 2016, bee si ni O ran iko ohun lowo lati pegede fun idije boolu agbaye.
Ijọba ni awọn janduku agbebọn kan ti kan si awọn pe awọn lawọn ṣiṣẹ laabi naa ti wọn si ti bẹrẹ idunadura, pẹlu bi ikọ Boko Haram tun ṣe sọ tirẹ yii, ewo lewo ni ibeere to gbẹnu ọmọ kan.
NANS: Àwọn aráàlú ní se ló yẹ kí NANS bẹ̀bẹ̀ fún òpin ìyansẹ́lódì ASUU
Òṣìṣẹ́ ajàfẹtọ tó wà níbl sàlàyé pé ẹgbẹ̀lẹ́gbẹ̀ àwọn ará ìlú ló ti sá wá si àgó ogunléndé tí òun ti ń ṣiṣẹ́ ni Monguno.
Iṣimaeli, ọmọ Netanaya sọkún pàdé wọn láti Misipa.
Ọdọ Aarẹ orileede Naijiria ni aṣẹ wa lori ẹni ti wọn yoo yan ni ipo ọga fasiti lẹyin ti awọn igbimọ ayẹwo ti fasiti ba yan ti fi orukọ eeyan mẹta tabi mẹrin ṣọwọ si.
83 ninu ida ogorun eto oro-aje ju ti akosile saa kerin odun 2016.
 Won si n se idanimo fun awon ti won kagbako naa ni bayii sugbon olopaa Isreal ni akonimoogba ere idaraya boolu alafesegba wa ninu awon to doloogbe.
Sugbọn, eyi ko tumọ si pe Woodberry ti bọ patapata nitori wọn le fi ẹsun miran kan an.
Anania bá lọ, ó wọ inú ilé náà, ó fi ọwọ́ kan Saulu.
Nibi ipade kan pẹlu aarẹ orilẹede Guinea Bissau to mu agbo naa wa, Umaro Sissoco Embalo, aarẹ Buhari ni oun ko ni gbe igbesẹ lati sọ agbo naa di lilo fun ọmọ Naijiria titi di igba ti awọn eleto ilera ilẹ yii yoo fọwọ si.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Matthew ree nigba to wa ni ọmọde pẹlu iya rẹ, Daphne Ni ọjọ ti wọn pa iya mi, Daphne Caruana Galizia, o wa ọkọ lọ ile ifowopamọ lati lọ yanju ọrọ kan nipa apo ifowopamọ rẹ ti minisita kan ti ni ki ileeṣẹ naa ti pa.
Ayẹwo keji si fi idi rẹ mulẹ.
Sugbọn eyi ko di Buhari lọwọ lati ma polongo ibo fun ọdun 2019.
Ṣugbọn àwọn alágbẹ̀dẹ wọnyi wá láti dẹ́rùba àwọn orílẹ̀-èdè tí wọ́n fọ́n Juda ká, ati láti fọ́n àwọn náà ká.
25 Ìgbé 2019 Ṣíṣe ojú lóge jẹ ọkan lara ohun to ma n mu oju obinrin gun rege tabi dun un wo.
"Aabo to daju wa fun ọpa aṣẹ gidi.
Oríṣun àwòrán, Ooni of Ife Ọọni Ifẹ ni ọja Ejigbo Mẹkun ti wa lati ẹẹdẹgbẹta ọdun sẹyin, bi wọn si se se agbende rẹ pada ni ọdun yii se afihan ohun rere to n bọ.
Ọ̀gá Yakubu sọ pé àjọ INEC yóò fún gbogbo wọn ni ìwé èrí ní ọjọ ajé ti ṣe ọjọ kẹtàdinlọgbọ̀n oṣù kàrún ọdun 2019.
Dino kọ láti yọjú sílé ẹjọ́ fún ìgbà ìkejì N kò nílò ìwé ẹ̀rí Waec ní fásitì Amẹrika - Adeleke Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ọ̀gá Bello: Àìgbọ́n ló ń da àwọn òsèré tíátà tó ń jà lórí ayélujára láàmú Awọn ileẹkọ giga ti ọrọ kan ni ile ẹkọ giga gbogbonse Poly ipinlẹ Ọṣun ni ilu Iree, ileẹkọ giga imọ ẹrọ ni ilu Ẹsa oke ati ile ẹkọṣẹ olukọni to wa nilu Ila Ọrangun.
Ṣugbọn a jọ ń ṣiṣẹ́ pọ̀ pẹlu yín ni, kí ẹ lè ní ayọ̀.
Ipo wo gan ni ilera Gbadamọsi Babangida wa lọwọlọwọ?
Ọkọ ofurufu ilẹ Ukraine naa ni awọn eniyan mọkan dinlọgọsan an inu rẹ di ero ọrun pẹlu awọn oṣiṣẹ inu rẹ.
Oríṣun àwòrán, @SheunDam Gbogbo igbiyanju lati jẹ ki wọn sun igbẹjọ rẹ siwaju ko baa le lọ fun itọju loke okun ni ile ẹjọ ko gba rara.
Ewe, iroyin tun fi mule pe enikeni ko farapa ninu ikolu naa.
Ìkórira pé mo jẹ Mayegun ni wọn ṣe parọ́ pé mo ń fẹ́ olorì Aláàfin, kò rí bẹ́ẹ̀ rárá- Kwam 1 Adájọ́ pàṣẹ pé kí wọ́n o fi àwọn afurasí tó pa ọmọ Fasoranti sí ọgbà ẹ̀wọ̀n Nàìjíríà tún ní àkọsílẹ̀ ènìyàn 108 tó ní ààrùn coronavirus Kí làwọn ìdàmú tí Coronavirus n mú bá àgọ́ ara?
Àwọn ọmọ Israẹli bá sọ fún Mose pé, “A gbé!
AFCON 2019: Wo àbájáde èsì àsọtẹ́lẹ̀ rẹ
Oríṣun àwòrán, Nigeria police Ọlọpaa ni o sa lọ nibi ti awọn ti fẹ mu ni ọsẹ mẹta sẹyin ṣugbọn ọwọ baa.
Eyi ti kii ba awọn Kristiẹni kan lara mu.
Ọga agba ọlọpaa nigba to ṣe ibẹwo si wọn sọ fun wọn pe ki opo ibọwọ fun ẹtọ ọmọniyan lo se pataki julọ ninu ninu iṣẹ wọn.
Kí ó mú àwọn nǹkan wọnyi ninu ẹbọ alaafia náà, kí ó fi wọ́n rú ẹbọ sísun sí OLUWA: ọ̀rá rẹ̀, gbogbo ọ̀rá tí ó wà ní ìrù rẹ̀ títí dé ibi egungun ẹ̀yìn rẹ̀, ati gbogbo ọ̀rá tí ó bo gbogbo nǹkan inú rẹ̀ ati ọ̀rá tí ó wà lára ìfun rẹ̀, 
Oríṣun àwòrán, Gboyega Oyetola/Facebook Àkọlé àwòrán, Ààrẹ Muhammadu Buhari kò gbẹ́yìn lásìkò tí Oyetọla n polongo ìbò Bawo ni ìṣèlú Oyetọla Adegboyega ṣe bẹ̀rẹ̀?
23 Ìgbé 2020 Coronavirus: Báwo ni o ṣe le mọ̀ pé o ní àrùn Coronavirus?
o ni iye ibo  138,184 .
Oloye Ọbasanjọ sọ bẹẹ lasiko to n sọrọ ni ilu Bali, lorilẹ-ede Indonesia, nibi idanilẹkọ kan ti wọn fi sọri Babacar Ndiaye nibi ipade banki ayanilowo lagbaye IMF ati banki agbaye, World Bank.
Níbẹ̀ ni olukuluku yóo ti gba ohun tí ó tọ́ sí i fún oríṣìíríṣìí ìwà tí ó ti hù nígbà tí ó wà ninu ara, ìbáà ṣe rere, ìbáà ṣe burúkú.
Awọn igara ọlọṣa ti yinbọn pa ọkunrin ọlọdẹ kan lagbegbe Mọniya nilu Ibadan.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Sotitobire: Ọkọ mi kò mọ̀ Jegede PDP rí, kódà kò fa ẹnikẹ́ni kalẹ̀ dípò Akeredolu- Bisola Bawo ni wọn yoo ṣe ṣiṣẹ: Sanwo Olu ni oṣu mẹfa ni awọn igbimọ naa ni lati fi ṣiṣẹ.
8 12760 Orilẹede montenegro 741 118.
Yoruba Taboo: Èèwọ̀ ni fún ọba láti gbé Bibeli tabi Kurani dání dípò ifá- Elebuibon, Agẹṣin Àdìmúlà
 Ọpọ awọn ile ni wọn ti koju laasigbo kan si ekeji lati ọwọ awọn oṣiṣẹ ile wọn.
 Ẹrí rè é, Sanwo-Olu ṣèlérí lóòtó lórí súnkẹrẹ-fàkẹrẹ Apapa A kò fẹ́ Festus Adedayo ní ìjọba Buhari - Àwọn olólùfẹ́ APC yarí Orí mi wú, ọmọ Nàíjíríà 16 gbàmì ẹ̀yẹ nínu akẹ́kọ̀ọ́ fásitì 27 l‘òkè òkun Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Iná Ibadan: Gbogbo dúkìá tó wà lókè ilé alájà kan náà ló jóná tán ""Ìléri ti ìjọba ṣe fún wọ́n ni pe ayé wọn yóò ni ojúùtú, sùgbọ́n ìréti wọn ni pe kò ni pẹ́ rárá"" ""Inú mi kìí ba dùn ti mo ba rí orílẹ̀-èdè Nàìjíríà gẹ́gẹ́ bi èyí tii yóò ma ṣe ìdásilẹ̀ oníruuru ilé iṣẹ́ ni ọdun mẹ́wàá sasiko yii, tí ọ̀pọ̀ eeyan yóò si kúrò ninu iṣẹ́ to n bá wọ́n fíra."
 rògbòdìyàn kò yé sẹlẹ ̀ , bẹ ́ ẹ ̀ nì làásìgbò kò roko ìgbàgbé .
láti Bamotu wọ́n ṣí lọ sí àfonífojì tí ó wà ní ilẹ̀ àwọn Moabu ní ìsàlẹ̀ òkè Pisiga tí ó kọjú sí aṣálẹ̀.
Àwọn eniyan yóo wá láti ìlà oòrùn ati láti ìwọ̀ oòrùn, láti àríwá ati láti gúsù, wọn yóo jókòó níbi àsè ní ìjọba Ọlọrun.
Pàápàá ní àwọn ilé-oújẹ, gbogbo nkan tí ń bẹ níbẹ̀ á wá máa ṣe kánmi-kànmì-kánmi, á wọ̀nni lójú gbáà.
Hubert Ogunde rèé, baba àwọn òsèré tíátà Ẹ̀wọ̀n tí mo lọ ni ẹ̀san ìwà tí mo hù gẹ́gẹ́ bíi olórí ológun- Buhari Pervez Musharraf, Àarẹ ológun Pakistan nígbà kan rí gbọ́jọ́ ikú Yàtọ̀ sí Olúwó, wo àwọn Ọba alayé tó ti kọ ìyàwó rí láìpẹ́ nílẹ̀ Oodua Oríṣun àwòrán, Empics Àkọlé àwòrán, Tenientertainer: Olórin obìnrin tí kìí ṣi ìhòhò rẹ silẹ̀- Olólúfẹ Teni Ọ̀rọ̀ yìí wá di gbigbà bi ẹni gba igbá ọti nígba ti @Benita_Fairy kọ pé Teni fí han pé àwọnn obinrin ọlórin lé ṣe àṣeyori lái ṣí ìhòhò wọ́n sílẹ̀ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Iná PHCN tó dé lójijì ṣàkóbá ńlá ní Ibadan Ní kété to sọ èyí tan ni àwọn ènìyàn bẹ̀rẹ̀ si ni gbàá bi ẹni gba igbá oti, bi àwọn kan ṣe ni kìí ṣe ]oun nikan ni kìí ṣí ìhòhò rẹ̀ sílẹ̀ ní àwọn míràn ni iṣe ọkunrin lo n ṣe ni kìí ṣe ṣi ara silẹ̀, Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ondo disability day: Ijọba ẹ gbà wá ní ariwo tí àkàndá ẹ̀dá ń pa Oríṣun àwòrán, Oba Orin Àkọlé àwòrán, Teni: Olórin obìnrin tí kìí ṣi ìhòhò rẹ Mo ti gba pé ológun ni ọkọ mí- Aisha Buhari Wọ́n f'ẹ̀sùn ọkọ̀ jíjí kan Naira Marley; Ó ní òun ni Buhari yóò gbé ìjọba fún Òkété bórù mọ àwọn ọjọgbọ́n méji lọ́wọ́, UNIABUJA jù wọ́n síta Yàtọ̀ sí Olúwó, wo àwọn Ọba alayé tó ti kọ ìyàwó rí láìpẹ́ nílẹ̀ Oodua Sáàju ni Teni Apata lásìkò to ṣe àbẹ̀wò si ilé iṣẹ́ BBC ti sàlàyé ìdí ti kìí fi ṣi ìhòhò rẹ̀ silẹ̀ nígba gbogbo Teni sàlàyé pé níní ifẹ́ si ominira ara òun jẹ́ ọkan pàtakì idí ti òun kìí fi ṣi ìhòhò ara òun sílẹ̀.
Idokowo: Aarẹ Donald Trump ti gba Aarẹ Buhari niyanju lati mu idẹrun ba idokowo laarin orilẹede Naijiria ati ilẹ Amẹrika.
Omo Soun Ogbomoso II - BBC News Yorùbá BBC News, YorùbáFò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Oba Olayode: Egbo to ti fẹẹ́ jiná ni ẹ tún ń fi èékáná te yìí - Omo Soun Ogbomoso II Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Oba Olayode: Egbo to ti fẹẹ́ jiná ni ẹ tún ń fi èékáná te yìí - Omo Soun Ogbomoso II 26 Ọ̀wàrà 2020 Gbogbo awọn ti BBC Yoruba fọrọ wa lẹnu wo nipa bi Oba Olayode keji to ti jẹ Soun ti ilu Ogbomoso ri nigba aye rẹ ṣe waja lo fẹrẹẹ ma fẹ sọ bi o ṣe ṣẹlẹ tori o jẹ ibanujẹ ọkan fun wọn.
Ṣebí ìwọ ni o wí pé, ‘Kí ni Abimeleki jẹ́ tí a fi ń sìn ín.
Yakubu Nabena, to jẹ igbakeji akọwe ipolongo ẹgbẹ APC ṣalaye fun ikọ BBC pe, igbesẹ to yẹ kọ ni awọn to paṣẹ lọ gbele rẹ fun Oshiomole tẹle.
Okunnu: Ẹnu Ayinde Barrister ni mo ti gbọ́ orúkọ 'Okunnu' kí n tó máa jẹ́ẹ Oríṣun àwòrán, Instagram/Okunnu Gbajugbaja adẹrinpoṣonu oṣere tiata, Wale Akorede, ti ọpọ mọ si Okunnu sọ pe ọjọ ti pe tawọn eeyan ti n sọ pe orilẹede Naijiria yoo dara.
Ọdun 2019 ni idibo gbogboogbo yoo waye ni Naijiria.
OLUWA Ọlọrun yín yóo fún ẹ̀yin ati àwọn ọmọ yín ní ẹ̀mí ìgbọràn tí ó fi jẹ́ pé ẹ óo fẹ́ràn rẹ̀ tọkàntọkàn, ẹ óo sì wà láàyè.
Wo àànfàní ‘Masturbation’, fífún ara rẹ̀ ní adùn ìbálòpọ̀ Ẹ fura o, Boko Haram ti pàgọ́ sí Abuja, yóò ṣe ìkọlù láìpẹ́ - Iléèṣẹ́ Aṣọ́bodè lọgun Ká ní ọmọ Buhari fẹ́ mi, màálù 150 ní màá fi dána - Olólùfẹ́ míì tó tún yọjú Tinubu, yé é sọ̀rọ̀ abẹ́lẹ̀, bọ́ sí gbangba láti bèèrè àtúntò Nàíjíríà lọ́dọ̀ Buhari - Afẹnifẹrẹ Biggie pari ọrọ rẹ pe awọn iwa to wu lodi si ofin to so ile ẹlẹgbọn agba naa ro.
Lasiko to n kopa lori akanse eto BBC Yoruba, Adeola ni iṣẹ aserunlọsọ ni oun kọ nilu Abuja, ki wọn to sọ fun oun pe, awọn eniyan kan wa to lee gbe oun lọ silu oyinbo fun bii oṣu mẹta, lati le ri owo kojọ fun idasilẹ isẹ tara oun.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Lassa fever: Ìjọba Eko ní akẹ́kọ̀ọ́ fásitì Ebonyi tó wá kẹ́kọ́ ìmọ̀ òfin, ní wọ́n bá Lassa lára rẹ̀ 20 Èrèlè 2020 Oríṣun àwòrán, Getty Images Ọwọ ijọba ipinlẹ Eko ti tẹ awọn eeyan mẹtalelọgọta ti wọn ti ni ajọṣepọ pẹlu eeyan ti o ni aisan iba Lassa ni ipinlẹ Eko.
Awọn Yoruba ma n lo aadun ni ibi aṣeyẹ tabi igbeyawo laye atijọ.
Ìkógun tí ó kù ninu àwọn tí àwọn ọmọ ogun kó bọ̀ láti ojú ogun jẹ́ ọ̀kẹ́ mẹrinlelọgbọn ó dín ẹgbẹẹdọgbọn (675,000) aguntan.
Nítorí ó ti ranṣẹ sí wa ní Babiloni pé a á pẹ́ níbí, nítorí náà kí á kọ́lé, kí á máa gbé inú rẹ̀, kí á dá oko, kí á sì máa jẹ èso rẹ̀.
Ṣugbọn wọ́n hùwà ọlọ̀tẹ̀:wọ́n sì mú Ẹ̀mí Mímọ́ rẹ̀ bínú.
tí ènìyàn bá ṣe alábàápàdé àkọsílẹ ̀ kan tí wọ ́ n ṣe ní èdè tó ṣe àjòjì sí i , ọ ̀ nà àbáyọ tí yóò kọ ́ kọ ́ wá sọ ́ kan rẹ ̀ ni ìranwọ ́ ẹni tí yóò ṣe aáyan ògbufọ ̀ irú àkọsílẹ ̀ bẹ ́ ẹ ̀ .
oselu  ANC ni egbe oselu Democratic Alliance
Bí o sì tilẹ̀ jẹ́ pé wọn má a ń sun ẹran ènìyàn kí wọ́n tó jẹ ẹ́, síbẹ̀ wọn kò mọ ọ̀nà àti yan òkú tí ó bá kú tí kò ní fi bàjẹ́, ìgbà tí wọ́n bá sì gbé e sí ẹ̀yìn kùnlé tó bí ọjọ́ mẹ́ta èyí nì a bẹ̀rẹ̀ sí í rùn ṣùgbọ́n àkókò náà ni wọn má a ń sáré pe ọ̀rẹ́ wọn kí ó wá jẹ àṣè ní ilé wọn, wọ́n á ni àwọn n ṣe sàráà kí ẹ̀mí àwọn bà gbó.
Bí ẹ bá takété sí àwọn nǹkan wọnyi, yóo dára.
”Gege bi Luis Enrique se so: “O fihan pe ipele yii lagbara pupo, sugbon a si gbagbo pe a o pegede.
bi gomina ti yoo maa dari ipinle naa fun saa keji, gẹgẹ bi ajo  INEC  se
O paarọ orukọ ẹgbẹ agbabọọlu agba ti Naijiria lati Green Eagles si Super Eagles.
Bákan náà, ìje̩níyà tí a lè fún e̩ni tó dé̩s̩è̩ kò gbo̩dò̩ ju èyí tó wà ní ìmúlò ní àsìkò tí e̩ni náà dá è̩s̩è̩ rè̩.
Ni bayii, ijọba ilẹ Gẹẹsi ti gbẹsẹ le owo naa titi digba ti awọn alaṣẹ Jersey, ilẹ Amẹrika ati Naijiria ba sọ asọyepọ lori bi wọn yoo ṣe pin owo naa.
O wa fikun pe, awọn isẹlẹ ifipabanilopọ mejeeji tawọn obinrin to sun mọ oun pupọ se si oun yii, ko jẹ ki oun nigbagbọ mọ ninu ẹnikẹni.
Nítorí OLUWA ṣeun;ìfẹ́ rẹ̀ tí kì í yẹ̀ wà títí lae,òtítọ́ rẹ̀ sì wà láti ìran dé ìran.
Mo ti sọ nǹkan wọnyi fun yín kí ẹ lè ní alaafia nípa wíwà ninu mi.
Ó kọ́ ilẹ̀ rẹ̀, ó sì ṣa gbogbo òkúta ibẹ̀ kúrò.
Ondo, Edo governorship election: Wo ìdí tí oò fi ní lè wọ Amẹ́ríkà bí o bá lọ́wọ́ sí rírú òfin ìbò
Ki a kuro nibẹ lọ si iye gan an ni owo baluu ti yoo ba wa si orilẹede Naijiria bayii lati ilu London ni ilẹ Gẹẹsi.
CP Asuquo Amba - CP Ekiti Command xxvi.
Ó sì pẹ́ kí ó tó ríi bí.
Gege bi atejade ohun, aare Keita  yan Soumeylou Boubeye Maiga lati di ipo re mu gege bi oludari agba orile-ede naa, ti o fi mo awon omo egbe mẹ́tàlélọ́gbọ̀n labe isakoso re tiko se atunse kankan le lori.
Àwọn ọba Yorùbá kan rèé tí wọ́n rọ̀ lóyè, tí ọba míràn jẹ lójú ayé wọn Èèyàn kan láti ìpínlẹ Ọ̀yọ́ kún iye àwọn tó ní àrùn Corona Virus Ìjọba ti pápákọ̀ òfúrufú Eko àti Abuja pa nítorí coronavirus Aawakọ̀èrò, ọlọ́kadà farakásá àṣẹ ìjọba Ekiti láti dẹ́kun Coronavirus Báwo ni àrùn coronavirus ṣe ń wọ Nàìjíríà Àwọn ìbéèrè tó yẹ kí o bi ara a rẹ̀ kí ó tó gba ìròyìn kankan nípa coronavirus gbọ́ Báwo ni o ṣe le mọ̀ pé o ní àrùn Coronavirus?
Oríṣun àwòrán, Getty Images Nigba to n sọrọ lori isẹlẹ yii, Abiọla Akiọde tii se agbẹjọro ati ajafẹtọ obinrin woye pe, ni orilẹede Afirika, awọn obinrin gbọdọ kọkọ fi imọ sọkan lati ri pe ofin ti yoo fun wọn ni anfaani ọgbọọgba pẹlu awọn ọkunrin di mimusẹ ninu ijọba ta wa yii.
Ni nnkan bii agogo mọkanla kọja iṣẹju marundinlọgbọn ni itakun ina orilẹede Naijiria daku lọ gbọrangandan ti gbogbo orilẹede Naijiria si bọ sinu hilahilo ko sina.
Tabi ti awọn iyawo wọn ba n rọbi, nitori ko si ile iwe, ile iwosan tabi ina monamona ni erekusu yii Ẹfunroye Tinubu - Ògbóǹtagí oníṣòwò, olówò ẹrú àti afọbajẹ SSANU, NASU gbé fásitì Ibadan tì pa O dìgbà tí mo bá dórí àgá kí ń tó sọ ìpinnu mi - Fatai Owoseni Falana àtàwọn míì péjú síbi àpérò #RevolutionNow l'Eko Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí kan sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
ní ọdún 2008 wọ ́ n fi a.
Apànìyàn Texas tú àsírí ara rẹ̀ Kí lo lè mú ọmọ ọdún mẹrin yìnbon pá ọmọ ọdún méjì?
Ibadan Divorce: Abílékọ Idowu faraya ní kóòtù kọkọ-kọkọ n'Ibadan, Ó ní òun ò leè pín ọkọ òun pẹ̀lú ẹnikẹ́ni
O ṣeeṣe ko jẹ pe aisi okun tó ninu lo faa to fi ṣubu to si daku.
O gbàgbé gbogbo bí mo ti jẹ́ fún ọ, bí mo ti máa ń kẹ́ ọ, tí mo máa ń gẹ̀ ọ, ti mo máa ń sá sókè sódò nítorí rẹ, gbogbo ìtọ́jú rẹ, ti mo ṣe nígbà ìyàwó o kò rántí mọ́, ìnáwó àwọn òbí mi, kò já mọ nǹkan kan fún ọ!
Aare Cyril Ramaphosa menuba eyi ninu oro re, lasiko ti won n bura fun ni ibere osu ti a wa yii pe, “Erongba ijoba ni lati gba awon ile naa pada lai san owo gba mabinu, lojuna ati mu aleku ba eto ogbin, aleku ounje ati lati ri daju pe, a da awon ile naa pada fun awon ti ijoba amunisin gba a lowo won.
"Eti ijọba Oyo ti kun nipa iwa ipanle ti awọn ọmọlẹyin Auxiliary n ṣe, mo wa n fi akoko yii kesi oun ati awọn ọmọ ẹyin rẹ lati sinmi agbaja, bi bẹẹ kọ, ìjọba yoo gba ipo naa lọwọ rẹ nitori ko si ẹni to ga ju ofin lọ.
Ami ayo mẹrin sodo ni ẹgbẹ agbabọọlu South Korea fi jiya lọwọ France to n gbalejo idije ọhun ninu ifẹsẹwọnsẹ akọkọ wọn.
Awọn eeyan le lo nọmba yii lori oju opo whatsapp tabi atẹjiṣẹ Koda awọn to ba ni ẹsun lati fi kan ọlọpaa ti ki i ṣe SARS naa lanfani lati pe awọn nọmba yii.
O wa lati ile ti won gba pe ise orin kiko nise abinibi ile won ni Mali.
 Kofi Wilson ti wa ni Itali fun ọdun mẹta."
Arabinrin ayaba Tapenesi yìí bí ọmọkunrin kan fún Adadi, ó sọ orúkọ rẹ̀ ní Genubati.
Kí alaafia máa bá ọ gbé.
“Àwọn orílẹ̀-èdè tí ẹ óo gba ilẹ̀ wọn yìí a máa ṣe àyẹ̀wò, wọn a sì máa gbọ́ ti àwọn aláfọ̀ṣẹ, ṣugbọn ní tiyín, OLUWA Ọlọrun yín kò gbà fun yín pé kí ẹ ṣe bẹ́ẹ̀.
Mo gbadura pé, gẹ́gẹ́ bí ìwọ, Baba, ti wà ninu mi, tí èmi náà sì wà ninu rẹ, kí àwọn náà lè wà ninu wa, kí ayé lè gbàgbọ́ pé ìwọ ni ó rán mi níṣẹ́.
Abúlé ọ̀ hún dára púpọ̀ , àwọn ènìà ibẹ̀ sì fanimọ́ra gidigidi.
Ó ń retí kí àjàrà rẹ̀ so,ṣugbọn èso kíkan ni ó so.
‘Mo gbo ti o gba ipe lori ẹrọ ilewọ rẹ, pẹlu bi o ṣe sọrọ, o fihan pe ọga rẹ kan lo pe e lati wa si ile igbe awọn ajagun(Airforce base).
lati fi yin Ọlọrun logo , lati da emi oun ati awon eniyan mẹ́sán án  ti won jo wa ninu oko ofurufu naa, ni eyi ti  oko ofurufu naa bale lojiji lojo Abameta.
Arabinrin Lisa Hanna jẹ ẹni ọdun marundinlaadọta ọmọ ilẹ Jamaica.
Ṣugbọn àwọn ọmọ-ẹ̀yìn bá àwọn tí ó gbé wọn wá wí.
Messi ti gba goolu mẹrinlelaadọta sáwọn nigba ti Ronaldo ti gba mejilọgbọn sawọn.
Manoa wá mọ̀ nígbà náà pé, angẹli OLUWA ni.
Àìsàn dá Ààrẹ àná ni Zimbabwe, Robert Mugabe, dùbúlẹ̀
Máa fún wa ní oúnjẹ òòjọ́ wa lojoojumọ.
O beere pe kin ni yoo sẹlẹ si awọn oogun mii ti wọn n se ati awọn to n siṣẹ nibẹ?
Ni ọjọ Aje ni Ọọni Adeyẹye Ogunwusi gunlẹ silu Ado Ekiti lati lọ igi alaafia laarin awọn ipele lọbalọba mọkanla ti a mọ si pelupelu ti wọn fariga pe awọn ko fara mọ igbesẹ gomina ipinlẹ naa, iyẹn Kayọde Fayẹmi lati yan Alawẹ ti ilu Ilawẹ Ekiti gẹgẹ bii olori igbimọ lọbalọba ni ipinlẹ naa.
A gbọ pe meji lara awọn 'ẹlẹ daddy' ọhun, Olori Damilola ati Olori Anu, lo sa kuro ni aafin Oyo.
 Àwọn àhámọ ́ eukarioti ( àwọn àhámọ ́ tí wọ ́ n ní kóróonú ) ní krómósómù onígbọọrọ títóbi nígbàtí àwọn àhámọ ́ prokarioti ( àwọn àhámọ ́ tí kò ní kóróonú ) ní krómósómù olóòbírípo kékeré , bótilẹ ̀ jípé àwọn ìsàtì sí òfin yìí wà .
Ọmọ Oodua to n mu ori ẹni wu lorilẹ-ede Amẹrika ni Sikiru Adepoju, isẹ ilu lilu si lo mu ko laami-laaka.
Wọ́n sì bẹ̀rẹ̀ sí kọ́ ilé OLUWA àwọn ọmọ ogun, Ọlọrun wọn.
Bi o ti se le forukọsilẹ kopa ninu N-Power 2020 ree Labẹ eto igbanisisẹ N-Power ipele kẹta to n waye losu Kẹfa, awọn to ba fẹ jẹ anfaani yi yoo lọ si oju opo ayelujara www.
Mo ranti òfin rẹ àtijọ́,OLUWA, ọkàn mi sì balẹ̀.
sọ fún Serubabeli, gomina ilẹ̀ Juda pé òun OLUWA ní, “N óo mi ọ̀run ati ayé jìgìjìgì.
Kọmiṣọnna eto ẹkọ l'Ekiti sọ pe gbogbo awọn kọmiṣọnna eto ẹkọ kaakiri ilẹ Yoruba lo ṣepade lọjọ Iṣẹgun lori ọrọ idanwo WAEC.
Jesu dá wọn lóhùn pé, “Èmi náà yóo bi yín léèrè ọ̀rọ̀ kan.
Alága àwọn onílé náà wá pàrọwà sí ìjọba ìpínlẹ̀ Èkó àti ìjọba àpapọ̀ láti wá rànwọ́nlọ́wọ́ láti kojú àwọn ọ̀bọ náà, nítorí àwọn eranko náà ti jẹ oúnjẹ wọn, àtiwípé wọ́n ti ba dúkìá wọn jẹ́.
Nítorí pé ogoji ọdún ni àwọn ọmọ Israẹli fi ń rìn kiri láàrin aṣálẹ̀, títí tí àwọn ọkunrin tí wọ́n lè jagun, tí wọ́n jáde láti Ijipti fi parun tán, nítorí wọn kò gbọ́ ti OLUWA wọn.
O jẹ ọmọ ọdun mẹrindinlogoji ati ọkan lara awọn ti ajọ FBI fesun kan pe o lu jibiti.
Bala to jẹ aarẹ ẹgbẹ awọn ọdọ NYCN ni Oríṣun àwòrán, @shehu Àkọlé àwòrán, Shagari Dariji awon bii Ojukwu, Yakubu Gowon ati Micheal okpara nigba iṣejọba rẹ Lọjọ Aiku ni Bala sọ ọrọ yii nigba ti aarẹ Buhari n ṣabẹwọ ẹ pẹlẹ si ẹbi oloogbe.
Van Persie lo bu ẹnu atẹ lu bi Solskjaer ṣe n rẹrin lasiko ti o n dahun ibeere awọn akọroyin lẹyin ti Arsenal ṣina iya fun Man U tan.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ondo police: Ìwádìí ń tẹ̀síwájú lórí ìjínigbé náà 8 Bélú 2018 Àkọlé àwòrán, Agbẹ́nusọ́ fún ilé isẹ́ ọlọ́ọ̀pàá ní ìpínlẹ̀ Ondo ní lóòtọ́ ni ìsẹ̀lẹ̀ náà wáyé ní ọ́ná Ọ̀bà Àkókó àti pé ìjínigbé wọ́pọ̀ lágbèègbè náà.
"Ẹgbẹ osisẹ, ninu atẹjade kan ti Akọwe apapọ rẹ, Comrade Peter Ozo-Eson fi sita, kede pe o jẹ iyalẹnu bi awọn oṣiṣẹ alaabo ""ṣe kọlu awọn to ṣe iwọde Revolution Now l'ọjọ Aje, ti wọn si mu wọn lọ si ahamọ."
Ọgbẹni Oluwadare ni, eyi ko ni fun gomina lagbara lati fi ajọ naa dunkoko mọ awọn ẹgbẹ alatako ijọba rẹ.
Barrister gbe awọn orin to le ni aadọrin jade, bẹẹ naa lo tun gba ọpọlọpọ ami ẹyẹ ko to dagbere faye lọdun 2010.
Àbí ìwọ kọ́ ni o mú kí omi òkun gbẹ,omi inú ọ̀gbun ńlá;tí o sọ ilẹ̀ òkun di ọ̀nà,kí àwọn tí o rà pada lè kọjá?
Kunle Afolayan: èmi kò fẹ́ fi ogún sílẹ̀ fún ọmọ mi
Ó pa òwe kan fún wọn, ó ní, “Ẹ wo igi ọ̀pọ̀tọ́ ati gbogbo igi yòókù.
Oríṣun àwòrán, Facebook/Nigeria Airforce Adegboye ni awọn fẹ ki ikọ ọmọogun Naijiria ṣe iwadii finifini nitori ki awọn le gba wi pe lootọ ni iṣẹlẹ naa waye.
''Operation Burst'' ti mú Eji olórí ''One Million Boys'' tó gba ipò Ebila Ọkùnrin kan tún pa ọmọ rẹ méjì àti ìyá tó bíi Ọ̀rọ̀ Soyinka àti Obasanjo papọ̀ lórí pé Buhari n ṣe ìpínyà Nàìjíríà Mo mọ̀ọ́mọ̀ sin ọmọ-ọmọ mi, ìkókó jòjòló láàyè ni, nítorí wọ́n fipá bá ọmọbìnrin mi lòpọ̀ ló fi lóyún rẹ̀!
iwaju(Forwards): Ahmed Musa (Al Nassar FC, Saudi Arabia); Victor Osimhen (Royal
Mourinho fẹ́ kojú Wenger nínú ìdíje miràn yàtọ̀ sí EPL
Èmi ni mo ni ọgbà àjàrà tèmi,ìwọ Solomoni lè ní ẹgbẹrun ìwọ̀n owó fadaka,kí àwọn tí wọn yá ọgbà sì ní igba.
Ẹsun mọkanlelogoji si ni wọn fi kan an.
Ileeṣẹ aṣoju orilẹ-ede America ti sọ pe kii ṣe nkan idunnu tabi iwuri fun awọn oṣiṣẹ ileesẹ naa lati ma má fun awọn ọmọ Naijiria ni iwe irinna si America.
Oríṣun àwòrán, AP Àkọlé àwòrán, Wahala mu ki awọn ologun maa ṣọna gbogbo iloro ni gbogbo igba Ẹgbẹ oṣelu FLN to ti jọba ni orilẹede ẹlẹgb oṣelu kan lati igba ominira rẹ wa pin si ẹgbẹ modernisers ati conservatives; igba yẹn ni Bouteflika to jẹ ti conservative ba pada lati ibi to ṣako lọ.
Àwọn eniyan náà jẹ àsè àjọ náà fún ọjọ́ meje, wọ́n ń rú ẹbọ alaafia, wọ́n sì ń dúpẹ́ lọ́wọ́ OLUWA Ọlọrun àwọn baba wọn.
ekun naa, o wa rọ awon oba lati maa se kaarẹ nipa sise atileyin fun awon
" Ẹ ̀ wẹ ̀ , ìwé ìròyìn náà tún fi kun wípé : "" Óyẹ kí ìjọba ó fìdí rẹ ̀ múlẹ ̀ wípé orílẹ ̀ -èdè yì kò ní fara mọ ́ ètò-ẹ ̀ kọ ́ tí kò péye tí ètò ẹ ̀ kọ ́ orílẹ ̀ -èdè náà ń kojú ásìkò náà "" ."
Orilẹ-ede Canada lo gbalejo ti ọdun 2015.
Bakan naa ni ajọ eto ilera l'agbaye, WHO, sọ pe ko si ẹri pe oogun kankan ti wa fun iwosan Covid-19, lẹyin ti Oríṣun àwòrán, AFP Àkọlé àwòrán, Ààrẹ orílẹ̀èdè Madagascar, fi ọwọ́ sọ̀yà lórí àgbo nàá, kódà, ó mu lára rẹ̀ lójú gbogbo ayé lórí tẹlifísàn Ewe Artemisia ni eroja gboogi ti wọn fi ṣe agbo naa, ati awọn ewe miran to wa l'orilẹ-ede Madagascar.
Ajo ti o n ri si isiro lorile-ede Nigeria so pe, awon eka ti ki I pese epo-robi ni akosile idagbasoke olodoodun ti o pegede ni odun 2016.
Awọn obinrin kan ṣe bẹ ẹ ki wọn o le ri iṣẹ ṣe ni oko ireke.
Mudashiru Ọbasa fi mulẹ ninu ipade ile naa pe ko si idi kan ti awọn kan le
Ọwọ ọlọpaa ti tẹ Idris to yinbọn ni aarin ìlú.
Ori ayelujara ni wọn ti n dibo, ti wọn tun ti n san owo orí ninu eyi ti Banki agbaye ti fi kede pe orilẹ-ede Estonia jẹ ọkan lara awọn orilẹ-ede perete lagbaye to n lo ayelujara julọ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Coronavirus cure: Olùdásílẹ̀ Yemkem ní ''Olóde'' ni Yorùbá ń pe coronavirus, iléeṣẹ́ Yemkem ti rí òògùn rẹ̀ báyìí 16 Èbibi 2020 Oríṣun àwòrán, Facebook/Yemkem Int'l Ileeṣẹ Yemkem International to n fi ewe ati egbo ṣe oogun ati itọju awọn eeyan ti sọ pe awọn ti po ewe ati egbo pọ lati wo aarun coronavirus to n ba gbogbo aye finra lọwọ yii.
Awọn ọmọ Yoruba miiran wo lo n kopa pẹlu rẹ lori BBNaija?
9–11, Krísti dá ọ̀run àti ayé.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Lagos Building Collapse: Ilé alájà méjì wó lu ọmọ mẹ́rin ni Bariga 29 Agẹmo 2019 Àkọlé àwòrán, Ile ọhun da wo lasiko ti atunṣe fẹ bẹrẹ Ilé to wa ni ojule ọgbọn ni adugbo Ọsọsa ni Bariga ni ipinlẹ Eko lo wo ti awọn ọmọ mẹrin si farapa ninu ẹ.
 gbogbo àwọn wọ ̀ nyí náà ló parapọ ̀ di àwùjọ-ẹ ̀ dá .
Ipinlẹ Eko si ni iye eeyan to pọ ju to ṣẹṣẹ ni arun ọhun ti wa.
Ẹni ọgọta ọdún ni Isaaki nígbà tí Rebeka bí wọn.
Wolii náà bá wí fún ọba pé, “OLUWA ní, nítorí pé o jẹ́ kí ẹni tí mo ti pinnu láti pa sá lọ, ẹ̀mí rẹ ni n óo fi dípò ẹ̀mí rẹ̀, n óo sì pa àwọn eniyan rẹ dípò àwọn eniyan rẹ̀.
Awọn ọlọpaa nipinlẹ Kano sọ fun BBC pe awọn ti sọ Zaharadeen si gbaga.
Facebook ti n ba gomina banki ilẹ Gẹẹsi, Mark Carney fikunlukun lori rẹ.
Ninu ọrọ to ba awọn eeyan ipinlẹ Ọyọ sọ naa, Gomina Makinde ṣalaye pe ko gbọdọ si ileewe ti yoo ṣi fun ẹkọ kikọ bẹrẹ lati ọjọru, ọjọ kọkanlelogun, oṣu kẹwaa.
Ogunlọgọ eniyan lo ti di alainile lori l'awọn ilu bi Tundun Takari, Dan Tudu, Unguwar kwakwa, Unguwar Mai Kwari, atawọn mii ni ipinlẹ Katsina.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Trump picture: ọjọ́ tí Trump kí mi kú iṣẹ́ lórí 'twitter' ní inú mi dùn jù- Oyedele Ẹsun ti wọn fi kan Bogoro ti wọn fi yọ ọ nigba naa ni pe ọwọ rẹ ko mọ lori igba biliọnu naira kan ti ajọ naa gbe sita fun akanṣẹ iṣẹ ṣugbọn tawọn kan ṣe baṣubaṣu.
Alhaji Hassan lasiko Ifọrọwanilẹnuwo parọwa si awọn eniyan lati gba bẹẹ lọdun yii nitori ati dẹkun ajakalẹ arun Coronavirus ni.
Iroyin fi yewa pe, Obinrin kan ati ọmọ rẹ jona ti Aarẹ Buhari si ba gbogbo ebi ati ijọba ipinlẹ Anambra kẹdun pupọ.
"Oríṣun àwòrán, Twitter ""Bi aago mọkanla si mejila lo maa n lọ, o si maa n pada sile bi aago marun irọlẹ."
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Oluwo: Mo lè jẹ Ọba ní Ile Ife Ẹ̀mí ológun kan bọ́, ọ̀pọ̀ arìnrìn àjò bọ́ sọ́wọ́ ajínigbé Àwọn agbébọn gbé òṣìṣẹ́ Shell méjì, wọ́n tún pa àwọ̀n aláàbò wọn ní Rivers Champions league: A jurawa lọ, Liverpool kó àjọ ìyà lọ́wọ́ọ Barcelona Ṣé N30,000 le mú ìyàtọ̀ gorí N18,000 owó oṣù òṣìṣẹ́?
O ni awọn ọlọpa ti bẹrẹ iwadi lori isẹlẹ naa.
Ohun gan wa lara nkan to gbe wa jade.
Nígbà tí ẹni tí ó gba àpò marun-un dé, ó gbé àpò marun-un mìíràn wá, ó ní, ‘Alàgbà, àpò marun-un ni o fún mi.
Koda awọn iṣiṣẹ ajọ eleto idibo idibo INEC meji lo tun di awati ninu eto idibo naa.
“Bí mo ti ń lọ, tí mo súnmọ́ Damasku, lójijì, ní ọ̀sán gangan, ìmọ́lẹ̀ ńlá kan láti ọ̀run tàn yí mi ká.
Eto idanilekoo ohun ni igbimo to n samoju to awon eru ti o n wole latoju omi se agbateru re, eyi ti akori re dale, “Kara-kata ati irorun irina-oko lorile-ede Naijiria”.
O fí kun pé ìjọba to n bẹ lóde kò ni káàrẹ nínú dídabò bo àwọn ọmọ Nàìjíríà lábẹ́ àkóso bóti wù kórí, ìjọba yóò dàyà àwọn ẹni ibi bolẹ̀.
Abenugan ile igbimo asofin agba Bukola Saraki naa ti  fi oro ikedun re sinu ero twitter re.
Sibẹsibẹ òun ni yóo jọ̀gá lórí gbogbo ohun tí mo fi ọgbọ́n mi kó jọ láyé yìí.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fọ́nrán ohùn, Ondo; 1000 si 2000 naira lowo ori ilẹ fun mẹkunu Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ekiti Election: Ẹgbẹ́ awakọ̀ Ekiti pa ìjọba dà lẹ́yìn tí wọ́n kéde Fayẹmi Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Kí ni àwọn aguntan wọnyi ṣe?
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Osun Election 2018 : Ilé ẹjọ́ ní Adeleke kò lẹ́tọ̀ọ́ láti díje dupò gomina 2 Ìgbé 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 3 Ìgbé 2019 Oríṣun àwòrán, Ademola Adeleke/Facebook Àkọlé àwòrán, Adeleke ni oludije ẹgbẹ òṣèlú PDP nínú ìdìbò Gómìnà ìpínlẹ̀ Osun Ile ẹjọ giga to wa ni ilu Abuja ti fagile iyansipo Ademola Adeleke gẹgẹ bi oludije sipo gomina ni ẹgbẹ oselu PDP ninu idibo gomina to waye ninú Osu Kẹsan, ọdun 2018 ni ipinlẹ Osun.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Ohun tawọn dokita sọ ni pe ki eeyan lo ẹyọ kan tabilẹti oogun yi ṣaaju ibalopọ ṣugbọn awọn mii maa n lo ju bẹ lọ.
Aarẹ ana lorileede Zimbabwe Robert Mugabe ko le rin mọ.
orile ede Naijiria si n fa bi igbin ninu gbogbo idije won to waye pelu awon ikọ
Awọn oloye to wa pẹlu Olori Adenikẹ ni Agbaoye Tunde Elerewe, Akọwe fun Ọlọwọ, Oloye Amos Aladeṣẹyẹ, Oloye Mudongho pẹlu Iyalode Ẹhin Ogbe, Oloye Ọbademi.
Ijọba orilẹede naa ti kede pe awọn ti ri eeyan kan to ni arun naa bayii nibẹ.
O salaye pe ileesẹ BBC Yoruba tun ti seto ifọrọwanilẹnuwo fawọn eekan ilu nilẹ Yoruba ni ede abinibi, ninu eyi taa ti ri Oloye Olusẹgun Ọbasanjọ ati Ọjọgbọn Wọle Soyinka.
Lara awọn ti ọjọ ibi wọn ko ọni ọsẹ yii ni: Regina Chukwu ṣe ọjọ ibi.
Eyi ni isẹlẹ to waye ni Kenya, amọ nigba wo ni iru idajọ yii yoo waye ni Naijiria?
Bakare Mubarak: ọ̀pọ̀ èèyàn ló máa ń fẹ́ dúró sí ẹgbẹ́ mí tójú si máa n tì mí
Ènìyàn 653 míràn tún kún iye àwọn tó ní COVID-19 ní Nàìjíríà Aláwàdà ni ọmọ mi láti kékeré, kò ṣẹ̀ṣẹ̀ máa gbé mi mọ́ra- ìyá ‘Mummy calm down’ (Toluige Olokoobi Babalola) Wo ìyàtọ̀ tó wà láàrin Bíbélì Yorùbá tí Kumuyi kọ sí èyí tó wà nílẹ̀ tẹ́lẹ̀ Ìpínlẹ̀ Oyo kéde àdínkù owó orí nítorí Covid 19 Ìjọba àpapọ̀ kéde ọjọ́ tí ìdánwò NECO, NABTEB àti BECE yóò bẹ̀rẹ̀ Nibayii, eeyan 873 lo ti ṣe alaisi nipasẹ ajakalẹ arun naa lorilẹede Naijiria.
so ninu eto iroyin wọn pe  lati Kodomti ni
" O wa gba gbogbo ara ilu nimọran lati fimọ sọkan ju ti tẹlẹ lọ, ka si wo egbo ọkan wa san nitori ko ni dara, ka jẹ ki ohun rere tawọn baba nla wa fisilẹ fun wa bajẹ.
Agbegbe Secretariat niluu Abuja ni nkan bi ago mẹta ni ọlọpaa naa yinbọn lu Ifeanyi.
Bàálù to gbe Yemi Oṣinbajo já lulẹ̀ ní Kogi
Amọ awọn oṣiṣẹ pajawirii ajọ LASEMA atawọn nkan mii fun eto ilera ti wọn gbe lọ sibẹ.
Egbe awon osise lorile ede Naijiria
9 132 British Virgin Islands 1 3.
A kò ní tún rí àwọn oníṣọ̀nà fún iṣẹ́ ọnà kan ninu rẹ mọ́.
A lè fi bàntẹ́ wé pátá àwọ̀tẹ́lẹ̀ òde òní.
Ó pè é pé kí ó dìde kí àwọn máa lọ.
Eto naa waye níbi ti igbákeji ààrẹ Yemi Osinbajo ti sọ̀rọ lọ́ri àfojusùn ìjọba lóri gbigba owó ori wọlẹ́ láì wo owó ìná ojoojúmọ́ àti gbogbo owó tí ijọba yóò lò fún àwọn iṣẹ́ àkànse.
Kí wọ́n má baà mú àwọn eniyan náà dẹ́ṣẹ̀, kí wọ́n sì kó ẹ̀bi rù wọ́n nípa jíjẹ àwọn ohun mímọ́ wọn; nítorí èmi ni OLUWA tí mo sọ wọ́n di mímọ́.
Oríṣun àwòrán, Instagram/bintaayomogaji O ni iwa ara bibo to wọpọ laarin awọn osere tiata lọkunrin ati lobinrin lode iwoyi, ni ko ba oju mu.
Igbadun rẹpẹtẹ n bẹ ni Ilu Port ni Cittagong fun faaji ti ko lopin.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Constitution Review: Afenifere rọ àwọn aṣòfin láti lo àbá 2014 CONFAB fún àtúnṣe ìwé òfin Nàìjíríà 8 Owewe 2020 Oríṣun àwòrán, @ngoamazing2009 Ẹgbẹ ajijagbara ilẹ Yoruba, Afenifere ti rọ ile aṣofin agba l'Abuja lati lo aba to jẹyọ nibi apero CONFAB to waye lọdun 2014 fun atunṣe iwe ofin orile-ede Naijiria.
Oríṣun àwòrán, @AmnestyNigeria Bakan naa ni ẹgbẹ ajafẹtọ ẹni ọhun tun sisọ loju rẹ pe lati igba ti iwọde EndSARS ti bẹrẹ, eeyan mẹrindinlọgọta lo ti ba isẹlẹ naa lọ.
Cyril Ramaphosa, aarẹ tuntun fun orilẹede South Africa?
Ó ti gbìyànjú sẹ́yìn láti di ààrẹ àmọ́ orí kò ṣe ní oore.
Níbo ni ẹ̀ báà palẹ̀ mọ́ fún mi pé kí n ti máa sinmi?
Lẹhin ọjọ mọ́kànlélógún ni Ilofi (Ilé Oyè) nigbati gbogbo ètùtù ti ó yẹ ki Ọba ṣe pari, Ọba Adéyẹyè Ẹniitàn, Ògúnwùsi gba Adé  Aàrẹ Oduduwa ni ọjọ́ kẹtàlélógún oṣù kọkànlá ọdún Ẹgbàálemẹ͂dógún ni Òkè Ọra nibiti Bàbá Nlá Yorùbá Oduduwa ti kọ́kọ́ gba adé yi ni ọ̀pọ̀lọpọ̀ ọdún sẹhin.
Ó kọ orúkọ àfojúdi sára orí rẹ̀ kọ̀ọ̀kan.
Ṣùgbọ́n awọn tí ìyè wákàtí àwẹ̀ wọn kéré diẹ ni Australia ati Chile níbi tí wọn ti n gbà àwẹ̀ wákàtí mọkanla ati mẹwàá.
Oladejo Okediji àti ìgbé ayé ìtàn kíkọ rẹ̀ Tottenham na Man City bí olè tó jí ike owó Ẹ yàgò fún ìwà adìẹ dàmí lóògùn nù, màá fọ lẹ́yin lásìkò ìjà - Buhari Ninu atẹjade kan eleyi ti agbẹnusọ fun ọọni ile ifẹ, Moses Ọlafare fi sita, o ni ko si bi awọn ọmọbibi ilu ile ifẹ yoo ṣe gbaa lero tabi huu ninu iwa lati gbe majele lọ da si inu omi ti awọn akẹkọ n lo fun mimu.
Ó tì í ṣubú, ó sì ń fi ẹsẹ̀ tẹ̀ ẹ́ mọ́lẹ̀.
Bẹ́ẹ̀ ni ọba Ijipti rí sí gbogbo àwọn tí wọ́n bá gbẹ́kẹ̀ wọn lé e.
Nítorí náà kí ọba má ṣe ka ẹ̀sùn kankan sí èmi ati ìdílé baba mi lẹ́sẹ̀, nítorí pé, èmi iranṣẹ rẹ, kò mọ nǹkankan nípa ọ̀tẹ̀ tí Dafidi dì sí ọ.
Spiny Babbler, ẹyẹ tí a kò le è rí níbòmìrán àyàfi ní Nepal.
Oludari ajo NDLEA nipinle Cross River, ogbeni Anthonia Edeh so di mimo fun awon akoroyin wi pe, owo sinkun ti te awon afurasi merin kan seyin ti o ojo ori won koju mejidinlogun si omo ogoji odun lo, lojo keji osu karun odun ti a wayii, lasiko ti won pese egbogi oloro naa.
Bẹ́nìkan ò yẹ̀ wá lọ́wẹ̀ wò, Èdùmàrè kúkú ń rí wa ní kedere.
-Ọlọ́pàá Ẹ fori jin wa, ẹni ta a lo ku tẹlẹ, ko ku mọ.
Ati pe ko si ìdí kankan fun un lati dunnu lori laasigbo to deba oludije kankan, tabi baba-isalẹ fun oloṣelu.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù #NotTooYoungToRun: Seun Fakorede ẹni ọdún 27 di kọmísánà l'Oyo Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ #NotTooYoungToRun: Seun Fakorede ẹni ọdún 27 di kọmísánà l'Oyo 22 Ògún 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 23 Ògún 2019 Ọdọmọde ọmọ ọdun mẹtadinlogbọn gba kọmiṣọna nipinlẹ Oyo.
'Orísúnmibáre ni àìsàn 'Polio' tó kọlù mí ní kékeré' John Blake wà ní ICU, ọlọ́pàá tó yìnbọn fún un bẹ̀rẹ̀ ìsinmi tipá tipá 'Ó tẹ́mi lọ́rùn kí n pàdánù ẹsẹ̀ mi, ju kí ǹkan ṣe oyún inú mi' Bí ẹ ṣe mọ̀wé tó, ẹ wá dánrawò níbí pẹ̀lú Àpólà Ọ̀rọ̀ Orúkọ, Noun Phrase"" Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí 3 sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 2:23 Fídíò, Water Generator: Ó leè ṣiṣẹ fún wákàtí mẹfà, kó tó sinmi, Duration 2,2310 Òkùdu 2020 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn."
Lawuyi Ogunniran, àgbà ọ̀jẹ̀ òǹkọ̀wé Eégún Aláré dágbére fáyé!
fun ipo gomina lati inu  egbe oselu ( All
Ẹ̀yáwó yí jẹ́ àfikún un gbèsè $73 billion tí orílẹ̀èdè Nàìjíríà ti ń jẹ tẹ́lẹ̀.
Ẹ mú ọkàn gírí kí ẹ sì ṣe bí akikanju.
O ni idunnu lo jẹ fun oun pe awọn ọmọ oun n polongo Ifa kiri origun mẹrin agbaye.
Asaraya, ọmọ Hoṣaaya, ati Johanani, ọmọ Karea, ati gbogbo àwọn ọkunrin aláfojúdi kan wí fún Jeremaya pé, “Irọ́ ni ò ń pa.
" Ní bàyíì, wọ́n ti n dá àwọn ọ̀kọ̀ tó n wọ inú ìlú Ado-Ekiti, láti àwọn ìlú mi i padà, kí wọ́n máà bà fi ara gbọta.
Nítorí náà, mo pàṣẹ pé kí wọ́n kó gbogbo àwọn ọ̀jọ̀gbọ́n Babiloni wá sọ́dọ̀ mi, kí wọ́n wá túmọ̀ àlá náà fún mi.
dun lati wa sibi buyi fun Gomina Ambode.
Kí ni a óo sì ṣe si yín, ẹ̀yin ẹlẹ́tàn?
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Awọn ọmọ wẹwẹ to n gbe ni awọn agbagbe ti aisan ibà wa n bẹ ninu ewu nini aisan naa L'ọdun 2017, bi ilaji awọn to wa ni aye lo wa ninu ewu nini aisan iba.
Bakan naa, ọlọpaa to n ṣabojuto ọlọpaa to ba daran to fi mọ oludari agbegbe (Area Commander), oludari ẹkun (Divisional Police Officer / Sectional Head) naa yoo fori ko ẹjọ lori aimojuto to peye wọn yoo si fi jofin.
Ero VAR ohun lo n sise lati ran oludari ifesewonse lowo fun anfani sise atunyewo awon olokan-o-jokan isele lori papa.
Ààrẹ tí sọ̀rọ̀, ọ̀rọ̀ tó sì sọ ní náà ni abẹ́ gé Nítori idí èyí mo rọ gbogbo àwọn ìgbìmọ̀ amúṣẹ́yá tí wọ́n túka àti gbogbo ọmọ ẹgbẹ́ tókù láti fíyedénu kí wọ́n sì máá wo ọjọ́ iwáju rere tó wà níwájú Mó ti fara ṣiṣẹ́ fún ẹgbẹ́ bí àwọn ọmọ ẹgbẹ́ tó kù tàbi jù ẹlòmíràn lọ, sùgbọ́n síbẹ̀ kò nimi lára láti túbọ̀ faraji gẹ́gẹ́ bi ọlọ́dani, kò sì si ẹni to yẹ ko ní ìṣoro kankan lòdì si eyi.
 Iranṣẹ Ọlọrun ni Ọgbẹni Chakwera jẹ ni orilẹ-ede Malawi."
O ni ko yẹ ki iru ẹni to wa ni ipo bi Lizzy maa lo ẹrọ ayelujara lati bu ẹlomiran.
 lára wọn ni olóyè ebenezer obey àti okóyè orlando owoh tó ti dolóògbé .
Helikati, ati Rehobu pẹlu àwọn pápá ìdaran tí ó wà ní àyíká wọn, gbogbo wọn jẹ́ ìlú mẹrin.
Kasaure fi idaniloju yii han nigba ti o n fun aare orile ede Vanuatu Obed Tallis, ni iwe ise re.
Saulu bá wí fún mi pé, ‘Sún mọ́ mi níhìn-ín, kí o pa mí, nítorí pé mo ti fara gbọgbẹ́, mò ń jẹ̀rora gidigidi, ṣugbọn ẹ̀mí mi ṣì wà sibẹ.
com,  won ni bi o ti le je pe iko Flying Eagles gba ami ayo kinni sagbon, eleyi ti Henry Offia gba wole sugbon omi poju oka lo leyin ti iko Saudi fi ami ayo kan ohun da meji pada.
Ṣugbọn o sọ pe oun ti ṣe aṣeyọri pupọ lori lilo oogun yi pẹlu awọn alarun Covid-19.
Won da 21 QRW sile lati maa mojuto awon ipenija to n sele ni ekun Benue-Nasarawa.
  Ipo yin gege bi alamojuto ilu se pataki lopolopo lati dena ohun kan wonyii.
Bakan náà ni ẹlomiran to n gbe agbegbe Agege sàlàyé pe ni àgbègbè ti oun, ṣe ni oun gbọ iró ibọ̀n sùgbọ́n oun ko tilẹ̀ le jáde láti yoju sibẹ̀.
gbiyanju lati ri i pe ile igbimo asofin kesan an  jiroro lori eto ilana ati ofin ti yoo ni ipa
Awọn iwe ẹri pe o kawe.
Farao bá pe Abramu, ó bi í pé, “Èéṣe tí o fi ṣe báyìí sí mi?
 Ṣùgbọ ́ n ó ṣe pàtàki náà láti şàgbéyèwò àwon àbùdà tí ó jẹ ́ ti èsìn ìgbàgbọ ́ póńbélé .
Bakan naa ni Pasitọ Adeboye sọrọ tako awọn oju ọna to wa ni Naijiria ti ko dara ti o si ti jasi iku ọpọlọpọ eniyan.
Bí omi-dídì ilé ayé ṣe ń yọ́, òkun ń kún.
O kẹkọ jade nileewe Northern Virginia Community College lẹyin ọdun maarun, oṣu kan ati ọjọ mẹta ti Boko Haram ji awọn akẹkọbinrin to le ni igba gbe ni ilu Chibok.
Joshua Beckford: Ọmọ ọdún mẹ́rìnlá kàwé gboye jáde ni Fasiti Oxford Josh Posh: Irun mií tó ‘Posh’, làwọn èèyàn se ń pè mí ní Josh Posh Jeremiah Addo: Ọmọ ọdún méjì tó ṣeeṣe kò mọ̀wé jù l'ágbàáyé O ti bẹrẹ si ni kawe lati gboye ẹkọ iṣakoso oṣiṣẹ ọba ni fasiti Ghana to wa nilu Legon.
"Atẹjade naa ni ""Logun jẹ ipe Eledumare lalẹ ọjọ Iṣẹgun lẹyin wakati diẹ ti esi ayẹwo fi han pe o ti ni arun Covid-19."
Ogbeni Mohammed soro naa di mimo lasiko ipade apero ijoba ti o waye niluu Gusau, ti n se olu-ilu ipinle Zamafara lati wa ojutu si isoro to n koju eto aabo nipinle Zamfara.
•Ileesẹ to wa fun eto ipawowọle labẹle ni yoo maa gba owo wọle amọ wọn yoo gbẹkẹle eto ayẹwo iwe owo sisan.
Ṣe ò ń bẹrù Buhari ní?
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Seun Kuti: Gbogbo mọ̀lẹ́bí mi ló wọ bàtà ti Fẹla bọ́ sìlẹ̀ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Seun Kuti: Gbogbo mọ̀lẹ́bí mi ló wọ bàtà ti Fẹla bọ́ sìlẹ̀ 18 Ọ̀pẹ̀̀ 2018 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 2 Ògún 2019 Oni lọjọ ti oloogbe Fela Anikulapo Kuti pe ọdun mejilelogun ni kaa ilẹ, sibẹ sibẹ gbogbo agbaye ko lee gbagbe rẹ.
asoju tun wa tẹnumọ pe, o di dandan ki awon adari
N óo kó wọn wá láti ilẹ̀ àríwá,n óo kó wọn jọ láti òpin ayé.
Bi eeyan ko ba wo daada, o f le ma damọ pe oun lo bọ lẹ ninu ọkọ naa.
Mo ti bá ọmọ ọwọ́ mẹ́ta lòpọ̀ sẹ́yìn, ọmọ oṣù mẹ́ta ló ṣìkẹrin - Afurasí jẹ́wọ́ Yoruba ni aji ede jẹ, kii ji mọ ni ẹyọ kan, bẹẹ si ni bi ọsan ba dun , eeyan loo mu igba.
Àlọ́ oooooooooo Ṣẹ gbọ́ nípa Alájọ Ṣómólú, tó ta mọ́tò ra kẹ̀kẹ́?
N-Power Tech (Software): ₦20,000 - si ₦40,000 loṣu.
Nigba ti ma a si fi pe ọdun mejila, o ti dinku si ifoya nípa imọtoto, paapa nipa fifi ara ko àwọn nkan to n jade lara ẹlomiran: bi itọ́ to n jade lẹ́nu wọn ti wọn ba sọrọ, kokoro aifojuri to n tankalẹ ti wọn ko ba fọwọ́ wọn lẹyin ti wọn lo ile ìyàgbẹ́, ati gbogbo awọn kokoro aifojuri ti mo lero pe o yi mi ka.
Báwo ni ẹ ti rí i sí nisinsinyii?
Bi a ko ba mu gbogbo eleyi kuro, ọwọ wa ko le mọ fun ẹjẹ.
Ẹ bi í, kì í ṣe ọmọde, yóo fi ẹnu ara rẹ̀ sọ bí ó ti rí.
Awọn alaṣẹ naa n kọwọrin pẹlu awọn ọmọ ogun lati ilu Monguno lọ si Baga nipinlẹ Borno.
Ni wọn ba pinu lati ko ẹru wọn kuro ni ilu.
Wo bí àwọn ọmọ yìí ti ń ṣe é.
“Ta ni ń ti Edomu bọ̀ yìí,tí ó wọ aṣọ àlàárì, tí ń bọ̀ láti Bosira,tí ó yọ bí ọjọ́ ninu aṣọ tí ó wọ̀,tí ń yan bọ̀ ninu agbára ńlá rẹ̀.
Asoju patakiAare Buhari ti koko ran awon asoju pataki lo si ipinle naa lori isele yii.
O tun wa pe ijoba lati seto iranw fun won .
“Agbẹnusọ Ile Igbimọ Aṣofin IpinlẹTaraba, Aṣofin Peter Abeldiah ni wọn yan gẹgẹ bi igbakeji alaga, Agbẹnusọ Ile Igbimọ Aṣofin Ipinlẹ Delta Aṣofin Sherif Oborevwori ni o jẹ Akapo-owo, nigba ti Agbẹnusọ Ile Igbimọ Aṣofin Ipinlẹ Kogi, Aṣofin Ọmọọba Kolawọle Mathew jẹ Alamojuto Isuna-owo igbimọ naa”.
Abiodun ba iyawo oloogbe Susan Buruji-Kashamu ati awọn ẹbi, to fi mọ gbogbo ọmọ bibi ilu Ijebu-Igbo kẹdun lori iku ilumọọka naa.
Celestine ẹlẹ́wọ̀n: Òun àti ọmọ rẹ̀ ló wà lọ́gbà ẹ̀wọ̀n
O ni oun yoo gbe igbese lati ri I pe ofin to n mojuto ẹtọ awon obinrin  tun fese  mule si i.
Bi a ba da ọjọ, ọjọ a pe,bi a ba da osu, osu a ko,bi o  se ku iwọnba wakati diẹ ti awọn omo orile ede Naijiria yoo lo lati dibo fun awon asoju won fun ipo aare ati ile igbimo asoju sofin lonii to jẹ ọjọ Abameta, awon omo orile ede Naijiria ti setan lati dibo yan eni ti won fe.
Alaafia atidagbasoke ninu ere idaraya                                                                      Eyi je lilo ero asoromagbesi ati ona iroyin fi mu ilosiwaju ba eto iroyin ere idaraya.
Katsina lo gbẹyin ninu eto yii, 170,000 ni iye ọkunrin fi ma n po ju obinrin lọ ni ile iwe alakọbẹrẹ.
Abdullahi Lawal Oríṣun àwòrán, Twitter Ṣaaju iku rẹ, Abdullahi ni ọga agba ẹka ileefowopamọsi First Bank to wa ni ipinlẹ Kano.
Níbi ìgbádùn bá sì wà, dandan ni kí ẹ bá èmi kinní yìí níbẹ̀ 🙂
Àwọn Ìlànà fún Ìyàsọ́tọ̀ Aaroni ati Àwọn Ọmọ Rẹ̀.
Lara awon ti won tun gbe lo sile ejo lasiko naa ni oludari fun eto owo ati isakoso ile-ise ana fun ofiisi olugbani-nimoran fun aare ana Shuaibu Salisu,oga agba fun ile-ise to n mojuto oro epo robi lorile ede Naijria, Aminu Baba-Kusa ati awon oludari meji fun  ile-ise ati ile-iwosan Acacia Holdings and Reliance Referral .
Ṣugbọn àwọn tí Ọlọrun bá pè ni à ń yàn, bíi Aaroni.
Ọrọ ti Meadows sọ ọrọ naa n waye lasiko ti arun naa n gbilẹ si l'Amẹrika, paapaa bo eto idibo aarẹ ṣe ku ọjọ mẹsan.
A óo fìdí rẹ múlẹ̀, ninu òdodo,o óo jìnnà sí ìnira, nítorí náà ẹ̀rù kò ní bà ọ́.
Igbeyawo Gbami o ra mi, igbeyawo ọkọ kaalẹ, igbeyawo Aṣante ati bẹẹ bẹẹ lọ ni a kọ ni kilaasi yii.
Ikọ naa, to dojukọ ẹkun ila oorun ariwa orilẹede Naijiria, lo ti ran eeyan bii ọkẹ kan (20,000) sọrun ọsangangan, to si tun ti sọ awọn eeyan bii miliọnu meji di alaini ile lori.
Ogbeni Enwonwu, ti opo eeyan ri gẹgẹ bi oludasile ise ọna igbalode lorilẹẹde Naijiria ya orisi meta eda aworan Tutu.
A mọ èyí pé a kò ṣe òfin fún àwọn eniyan rere, bí kò ṣe fún àwọn oníwàkiwà ati àwọn alágídí, àwọn aláìbọ̀wọ̀ fún Ọlọrun ati àwọn ẹlẹ́ṣẹ̀, àwọn oníbàjẹ́ ati àwọn aláìbìkítà fún ohun mímọ́, àwọn tí wọn máa ń lu baba ati ìyá wọn, 
Sanwo-Olu sọ wi pe owo ti wọn yọ kuro ninu owo naa wa fun riran awọn onisowo ati awọn to ni dukia lọwọ lati din inawo wọn ku nitori bi eto ọrọ aje se ri ni akoko corona yii ni Ilu Eko ati agbaye.
 Inu mi dun fun ise ribi-ribi ti oloogbe naa ti gbese lasiko igbesi aye
iye àwọn ènìyàn tó tó bílíọ ̀ nù 0.
Akọrin takasufe Amerika Cardi B ti kede ipinya pẹlu ọkọ rẹ, Offset, ọdun kan lẹyin igba ti wọn ṣe igbeyawo.
67 biliọnù owó oúnjẹ àwọn akẹ́kọ̀ọ́ tí ICPC ní wọ́n se mọ́kumọ̀ku N kò mọ ẹni tó fẹ́ gba ìyàwó mi, àmọ́ wọn máa ń sọ pé ó rẹwà - Mike Bamiloye Àríyá yá!
ojogbon  Ibrahim Muhammad Ahmad, adari ile-eko
Àwọn agbo ẹran yóo tún kọjá níwájú ẹni tí ó ń kà wọ́n ninu àwọn ìlú tí wọ́n wà ní agbègbè olókè, ati àwọn ti pẹ̀tẹ́lẹ̀ Ṣefela ati àwọn ìlú tí wọn wà ní Nẹgẹbu, ní ilẹ̀ Bẹnjamini, ní agbègbè tí ó yí Jerusalẹmu ká, ati àwọn ìlú Juda.
Okina bẹrẹ si ni bẹ wọn wo lojoojumọ, a si maa mu nkan ipanu dani fun wọn.
Jesu wá bẹ̀rẹ̀ sí túmọ̀ gbogbo àkọsílẹ̀ nípa ara rẹ̀ fún wọn.
Oun lo n gbin agbado ọran sẹyinkule ẹlẹyinkule, ko gbọdọ ya a jẹ, bẹẹ ni ko gbọdọ tu u danu.
 Emi ko ni ohunkohun kankan lati fi tako yin, dipo bẹẹ, mo ri gbogbo ohun to ti sẹlẹ lati ẹyin wa gẹgẹ bii irubọ ti a gbọdọ se lati mu ki ẹgbẹ wa lọ siwaju.
àwọn ọmọ Resini, àwọn ọmọ Nekoda ati àwọn ọmọ Gasamu;
21 Ẹ gba orúkọ Jésu sí orí yín, kí ẹ sì sọ òtítọ́ pẹ̀lú ìronújinlẹ̀.
Awọn alasia: Isọri awọn miran to jẹ ki iwọde End SARS ni itumọ ni bi awọn eeyan kan ṣe n gbe asia orile-ede Naijiria lojuko iwọde naa.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ambode: Ilé aṣòfin Eko ní kí gómìnà àná wá wí tẹnu rẹ̀ lórí owó ọkọ̀ BRT 27 Ọ̀wàrà 2019 Oríṣun àwòrán, @AkinwunmiAmbode Ile igbimọ aṣofin ipinlẹ Eko ti kọwe pe gomina ana ni ipinlẹ naa, Akinwunmi Ambọde pe ko yọju niwaju igbimọ ile naa, to n ṣewadi awọn ohun kan to ṣokunkun lasiko iṣejọba rẹ.
Gbogbo eniyan lo si maa n pee ni ‘Baba Oloye’ gẹgẹ bii àpèjà rẹ̀.
Ìjọba yóò lo BVN àtàwọn ọ̀nà méjì míràn láti pín owó ìrànwọ̀ fún aráàlú Èyí tí a wò jùlọ 5:03 Fídíò, Omolola Arohunmolase Welder: Mo ti fí iṣẹ́ 'Welder' gbayì láwùjọ, tó mo fi tọ́ ọmọ yanjú, Duration 5,039 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 5:39 Fídíò, Akomolede ati Asa lori BBC: Olùkọ́ Kikelomo Ogunboye tan ìmọ́lẹ̀ sí ìwà olè ọ̀gá ọlọ́pàá Audu gẹ́gẹ́ bí àwòkọ́ṣe àsìkò yìí, Duration 5,398 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 4:11 Fídíò, Oba Adeyeye Ogunwusi: Ojú mi ti rí lọ́pọ̀ lọpọ̀, ọ̀pọ̀ èèyàn ni kò tilẹ̀ gbàgbọ́ pé mo lè jọba- Ooni, Duration 4,117 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 4:43 Fídíò, Promise Akinlade: ọmọ ọdún mọ́kànlá tó ń fi ìlù dárà bíi àgbàlagbà sọ̀rọ̀ nípa tálẹ́ǹtì rẹ̀, Duration 4,437 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 0:59 Gbọ́, Ìsẹ̀lẹ̀ jákèjádò orílẹ̀èdè àgbáyé láàárín ìṣẹ́jú kan, Duration 0,59wákàtí 5 sẹ́yìn 7:03 Fídíò, Olumuyiwa Bolade Adedeji Military Bruitality: Bí arákùnrin onípèníjà ara tí sọ́jà lù ṣe dé, Duration 7,035 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 4:45 Fídíò, Yoruba Films: Ẹ̀ẹ́ bẹ̀ mi kúrò láyé ni, mi ò lè kú - Fadeyi Oloro, Duration 4,4526 Èrèlè 2020 2:48 Fídíò, Esther Ajayi: Èmi náà ti borí ìṣòro rí ló ń mu mi ṣojú àánú, Duration 2,481 Ògún 2019 6:08 Fídíò, Adebola Ademilua: Àìrísẹ́ ṣè lẹ́yìn ìwé kíkà ló sọ mi dí ìyá onírú, mo dúpẹ́ tèmi, Duration 6,0827 Bélú 2020 5:55 Fídíò, Soyinka Cancer: Àṣe ara mi ni iso ti n run gbogbo bí mo ṣe n ṣèrànwọ́ lórí jẹjẹrẹ, Duration 5,5527 Bélú 2019 BBC News, Yorùbá Ìdí tí ẹ fi le è nígbàagbọ́ nínú ìròyìn BBC Ìlànà Lílò Nípa BBC Òfin Àṣírí Cookies Kàn sí.
Ó sọ fún angẹli kẹfa tí ó mú kàkàkí lọ́wọ́ pé, “Dá àwọn angẹli mẹrin tí a ti dè ní odò ńlá Yufurate sílẹ̀.
Ṣugbọn àánú tí Ọlọrun fún wa dípò ọpọlọpọ aṣemáṣe wa, ìdáláre ni ó yọrí sí.
Lẹ́yìn náà n óo mú Sedekaya ọba Juda, ati àwọn ìjòyè rẹ̀, ati àwọn tí àjàkálẹ̀ àrùn, ogun, ati ìyàn, bá pa kù ní ìlú yìí, n óo fi wọ́n lé Nebukadinesari, ọba Babiloni lọ́wọ́, òun ati àwọn ọ̀tá tí ń wá ọ̀nà láti pa wọ́n.
Ṣé eniyan lè fi ìwọ̀ mú un?
Ọ̀kan nínú àwọn àjọ̀dún tó rọ̀ mọ́n ẹ̀sìn náà ni àjọ̀dún òrìṣà Eostre.
Ẹ̀yin náà ẹ dà á rò.
Mo ti fi ṣe alákòóso àwọn eniyan mi.
Wọn fikun pe, igbeyawo jẹ ohun ọlọla ti awọn eniyan yẹ ki wọn bọwọ fun lai si inira fun wọn nipa pansaga, eleyii ti o le e sediwọ fun wọn nipa ṣiṣe ojuṣe wọn ni inu ile.
baptist boys ' high school jẹ ́ ilé ìwé girama ní abeokuta , Ìpínlẹ ̀ Ògùn , gúúsù-ìwọ oòrùn nàìjíríà .
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Coronavirus: Báyìí ni àwọn ṣọ́ọ̀ṣì ńlá nlá ní Nàìjíríà ṣe ń bá ìgbà coronavirus yí 8 Ìgbé 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 5 Èbibi 2020 Oríṣun àwòrán, Getty Images Nṣe ni àwọn sọọsi nlá nlá wà ní òfìfo, tí àwọn ilẹkun wọn naa si wa ni titi pa lasiko yii.
Ọmọ ẹlẹ́ja ò tú mù kẹkẹ
Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Obasanjo: Mo lòdì sí ìgbé ayé tí Gani Adams ń gbé látẹ̀yìnwá, ṣùgbọ́n n kò bá a jà - Obasanjo3 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Stella Obasanjo Motherless: A ti rí àwọn ọmọ tó sọnù ní ilé àwọn ọmọ òrukàn ní Abeokuta2 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Assistant Commissioner of Police: Àwọn afurasí ṣá ìgbákejì kọmísọ́nà ọ̀gá ọlọ́pàá láàké dójú ikú2 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 All times Yoruba novels: Ìwé àkàgbádùn láti ọwọ́ D.
aladani ti o n ri si idọti lojuna ati
Wo ojú Akeem t'Ọlọ́pàá mú pé ó fipá bá ọ̀dọ́mọbìnrin kan sùn létí odò l'Oṣun O ni awọn eeyan dẹyẹ si mi, wọn fi mi ṣe yẹyẹ, oju si n ti mi, ṣugbọn ni bayii inu mi dun tori ko sewu nibẹ.
Boyega ni oun ti setan lati wa lo asiko ni Naijiria lati fi gbe ere sinima to safihan asa, isese ati orisun igbe aye Naijiria han.
“ ‘Ẹni ìfibú ni ẹnikẹ́ni tí kò bá pa gbogbo àwọn òfin yìí mọ́, kí ó sì máa tẹ̀lé wọn.
Casuwi Csu Marzu Ǹkan to mú ounjẹ èyí yàtọ ni pe ó dàbi aràn.
ó sì fún ẹnìkọ̀ọ̀kan wọn, atọkunrin atobinrin, ní burẹdi kọ̀ọ̀kan, ati ègé ẹran yíyan kọ̀ọ̀kan ati àkàrà èso resini.
Oríṣun àwòrán, Instagram/ajimobi Itan igbe aye Abiola Ajimobi: Ọjọ nla ni ọjọ kẹrindinlogun, oṣu Kejila, ọdun 1949 ti alagba Ganiyu Ajimobi ati aya rẹ, Sikiratu Abeje bi Isiaka Abiola Akanji sile aye.
O ni gbogbo ẹru ẹbun ti ẹnikẹni lee ni lọwọ lati fun oun ki wọn fi sọwọ lọ gbe ile wọn naa titi di igba ti arun naa yoo dẹkun.
O wa fun jija ogun ofurufu.
Wọ́n wá ń bá ara wọn sọ pé, “Ọ̀rọ̀ rẹ̀ mú wa lọ́kàn bí ó ti ń bá wa sọ̀rọ̀ lọ́nà, ati bí ó ti ń túmọ̀ Ìwé Mímọ́ fún wa!
Ijọba orilẹede Naijiria ṣe iwadi to fi han wipe awọn janduku oṣiṣẹ papakọ ofurufu to wa ni Kano lo gbin oogun oloro naa sinu apo rẹ.
Sọ́ra, òògùn ikọ́ codeine lee yi ọ lórí Ọ̀rọ̀ ń bọ́ lóríi fídíò Codeine Ijọba àpapọ̀ fòfin de oògùn ikọ́ olómi codeine BBC lo gbe fidio ọ̀tẹlẹ̀múyẹ́ kan jade ti o fi ṣàfihàn ewu ńlá to wa ninu mímu àpọ̀jù iru oògùn ikọ́ báyìí ni Naijiria.
Akọrin, ọmọ ilé ìwé àti àwọn aládùúgbò péjọ ní  Kingston, Lionel Town, Ridge Red Bank àti White River  fún ìdánilẹ́kọ̀ọ́ ọlọ́jọ́ mẹ́rin nínúu oṣù Ẹrẹ́nà àti Igbe.
 Wọ́n fi kún pé  A rọ ààrẹ Muhammadu Buhari lati yara buwọlu àbádofin lóri àtunṣe to wáye nínú iwé òfin ilẹ wa, eyi to nii ṣe pèlu ètò ìdìbò, ní kété ti àwọn ilé ìgbìmọ aṣòfin bá ti gbe aba naa dé ìwáju rẹ̀.
O ṣapejuwe ipo ọba gẹgẹ bi ibi akọkọ ninu ijọba o si ni yoo maa jẹ ọna si ibi nkan ini Naijiria ni gbogbo igba.
Ọpọ awọn tọrọ naa soju wọn ni wọn n ke si ọlọpaa pe ko gbe orokun rẹ kuro lọrun ọkunrin ọun ati pé ko mira mọ.
Fatoyinbo sọrọ yii ninu atẹjade kan to fi sita lati ọwọ amugbalẹgbẹ rẹ, Ademola Adetuberu.
maa fi omi fọ ọwọ wọn ni gbogbo ibudo ọkọ , ti won si tun se ikilọ fun awon to
yii, ni ipinlẹ Gombe ,Ninu abajade esi ibo aarẹ ti
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Amọ, awọn eniyan to n gbe ni agbegbe ti awọn eranko yii pọ si n ran ẹsọ alaabo lọwọ lati le sawari ẹkun naa, ki wọn le fi ni alaafia lagbegbe naa.
Aare wa gbadura fun awon ti o padanu emi won sinu isele naa pe Olorun un yoo tewon si afefe rere.
Ẹni tí ó bá ṣẹgun ni yóo jogún nǹkan wọnyi.
Nigba ti Ileeṣẹ BBC kan si awọn ti ọrọ kan naa ni wọn fidiẹ mulẹ pe iroyin ẹlẹjẹ ni o.
Wọn kò pa majẹmu Ọlọrun mọ́,wọ́n kọ̀, wọn kò jẹ́ pa òfin rẹ̀ mọ́.
Jesu wá pè wọ́n sọ́dọ̀, ó fi òwe bá wọn sọ̀rọ̀ pé, “Báwo ni Satani ti ṣe lè lé Satani jáde?
Ẹni to bori: Senegal Madagascar vs Egypt.
Sugbọn wahala bẹ silẹ nigba ti ẹnikan to n wa kẹkẹ sadede kọlu abo kiniun rẹ lasiko to n mu gba atẹgun lọ loju popo, to si fi okun si lọrun bii aja.
Ohun tí a mọ̀ nìyí nípa gbọ́nmi síi omi ò tó lórí ọ̀rọ̀ oyè Babaloja-General ní ìpínlẹ̀ Oyo Ẹwẹ, oniruuru esun ni wọn fi kan an to fi mọ iku akọroyin Jamal Khashoggi ni olu ile ișẹ Saudi ni Istanbul lọdun 2018 ati erongba lati pa ọtėlẹmuyẹ Saudi Lan to wa ni Canada.
Ọpọ ololufẹ ere bọọlu papaa julọ awọn to n tele idije Premier Legaue sọ pe ifẹsẹwọnsẹ ọhun yoo yeruku lala nitori Liverpool fẹ gba ami ẹyẹ naa ni saa yii.
Rab ti fero ọkan rẹ han lori ọrọ Brexit.
Ebenezer Obey: Orin ṣì kù tí mo máa kọ, bí ń kò bá parí rẹ̀, ń kò ní kúrò láyé
“Nígbà tí OLUWA Ọlọrun yín bá lé wọn jáde fun yín, ẹ má ṣe wí ninu ọkàn yín pé, ‘Nítorí òdodo wa ni OLUWA ṣe mú wa wá láti gba ilẹ̀ yìí, bẹ́ẹ̀ sì ni nítorí ìwà burúkú àwọn orílẹ̀-èdè wọnyi ni OLUWA ṣe lé wọn jáde fún wa.
Nígbà tí Paulu gbé ọwọ́ lé wọn, Ẹ̀mí Mímọ́ bà lé wọn, wọ́n bá bẹ̀rẹ̀ sí fi èdè mìíràn sọ̀rọ̀, wọ́n ń sọ àsọtẹ́lẹ̀.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Sex party: Ìjọba gbé ilé ijó oníhòhò tì pa lórí ẹ̀sùn títàpá sí ìlànà àti dẹ́kun coronavirus 15 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Oríṣun àwòrán, Getty Images Ileeṣẹ ọlọpaa gbe ile ijo ibalopọ ti pa lori ẹsun pe wọn kuna lati tẹle ilana ati gbogun ti ajakalẹ arun coronavirus fun igba keji laarin ọsẹ kan.
ó ń bá àwọn Juu tí ó ń sọ èdè Giriki jiyàn.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Suicide Prevention: ìwọ́de yìí wáyé láti gbógun ti pípa ara ẹni A o maa mu ẹkunrẹrẹ iroyin naa wa fun yin laipẹ.
Ó kọ́ ìlú Beti Horoni ti òkè ati Beti Horoni ti ìsàlẹ̀.
Saulu bẹ̀rù Dafidi nítorí pé OLUWA wà pẹlu rẹ̀, ṣugbọn OLUWA kọ òun sílẹ̀.
” Gbogbo àwọn ọmọ Lefi bá kóra jọ sọ́dọ̀ rẹ̀.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Ìgbà tí mo máa fi lajú sáyé padà, ọ̀fọ̀ ikú mi ní wọ́n ń kígbe' Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Oju Serena Williams to jẹ ẹni ọdun mejidinlogoji naa wa lara gbigba ife ẹyẹ Margaret Court 24 ti Australia to jẹ Grand Slam ẹlẹni kan ṣoṣo.
ati àwọn tí ó wà ní ibùjẹ ẹran rí ìkógun pín:fadaka ni wọ́n yọ́ bo apá ère àdàbà;wúrà dídán sì ni wọ́n yọ́ bo ìyẹ́ rẹ̀.
Oludari ati aṣaaju awọn ẹka iroyin mejeeji yi ni ileeṣe BBC, Peter Okwoche sọ eyi di mimọ ninu ifọrọwanilẹnuwo pẹlu ile iṣẹ amohunmaworan Channels ni ọjọ abamẹta pe awọn ẹka iṣẹ iroyin yii yoo pese iroyin ni ede abinibi Yoruba ati Igbo fun awọn ọmọ orilẹede yii.
Ògbójú Ọdẹ ló npa ẹranko bi Erin, Ẹkùn, Kìnìún àti Ẹfòn, Ìmàdò, Ikõkò, nígbàtí àwọn to nṣe Ọdẹ etílé npa ẹranko ìtòsí ilé bi Ọ̀kẹ́rẹ́, Òkété, Ọ̀bọ àti bẹ̃bẹ lọ.
Mi o mọ idi ti tiẹ fi ri bẹẹ.
Leyin eto ibura fun aare tuntun naa, Sahle-Work Zewde ba awon omo ile –igbimo naa soro,ninu eyi ti o ro won lati faye gba alaafia.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: ìfipábánilòpọ̀: Má dákẹ́ - Oluwaseun Wọ́n ta ère Ọ̀ṣun Osogbo sí Togo - Bàbá Ọṣun figbe ta Baṣọ̀run Gáà, tó yan ọba mẹ́rin, pa ọba mẹ́rin àmọ́ ọba karùn-ún ló pa á Iya yii lo ta oun nidi kan lati pada wa sile lẹyin ọdun marun ti wọn ti ji oun gbe lọ silẹ ibo.
Kanye West ọmọ ilẹ́ America gbe awo 'Ye' sita ni eyi to ta pupọ lori itunes.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Iraq, Palestine wà nínú orílẹ̀-èdè mẹ́wàá tí ìwádìí BBC ti wáyé Orilẹ-ede Madagascar ko jawe olubori lati kopa ninu idije AFCON ri.
Nítorí náà àwọn eniyan mi yóo mọ orúkọ mi, wọn óo sì mọ̀ ní ọjọ́ náà pé, èmi tí mò ń sọ̀rọ̀, èmi náà nìyí.
Ninu ìmọ́lẹ̀ níwájú rẹ,ẹ̀yinná ati yìnyín ń fọ́n jáde,láti inú ìkùukùu.
" eyi túmọ ̀ sí "" ẹni ti o ti kẹ ́ sẹ járí ṣùgbọ ́ n "" gautama "" ni orúkọ ìdílé tí a bí i si ."
Nígbà tí ó di ìrọ̀lẹ́, ní déédé ìgbà tí àwọn obinrin máa ń jáde lọ pọn omi, ó mú kí àwọn ràkúnmí rẹ̀ kúnlẹ̀ lẹ́yìn odi ìlú lẹ́bàá kànga kan, 
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Chelsea ni tirẹ ta ọmi pẹlu Eintranct frankfurt ni orilẹede Germany Liverpool yoo koju Barcelona ni ọjọ iṣẹgun, Tottehnam yoo ba Ajax lalejo ni ọjọru ki o to kan Arsenal ati Valencia pẹlu Chelsea ati Eintranct frankfurt ni ọjọbọ ọsẹ to n bọ Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìpànìyàn l'Eko: Ilé ẹjọ́ dá ẹjọ́ ikú fún ọkùnrin tó pa ìyàwó rẹ̀ 8 Ẹrẹ̀nà 2019 Oríṣun àwòrán, Google Àkọlé àwòrán, Ìjọba ìpínlẹ̀ Eko fẹ̀sùn kan Lekan Shonde pé ó lu ìyàwó rẹ̀ pa, lẹ̀yín to fi ẹ̀sùn kan pé iyawo rẹ̀ pé óún yan àlè.
Ni ọdun yii ti wọn sọ pe o ṣeṣe ki awọn iwe idibo ti yoo wa lati ọwọ awọn ileeṣẹ ifiweranṣẹ pọ ju ti tẹlẹ lọ, wọn ti sọ pe o ṣeṣe ki iwe idibo ti wọn ko ni ka pọ ju ti atẹyinwa.
Ní ààrin òrùlé náà ni mo bá ọkùnirn títóbi kan tí orí rẹ̀ pá tí ‘rùngbọ̀n rẹ̀ sì pọ̀ tó bẹ́ẹ̀ tí ó gba ìdajì orí òkúta náà kankan, ó ń mu ìkòkò ńlá kan.
Gbogbo àwọn ọmọ Peresi tí wọn ń gbé Jerusalẹmu jẹ́ akọni, wọ́n jẹ́ ọtalenirinwo ó lé mẹjọ (468).
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Nigeria Air Force recruitment 2020: Ilé iṣẹ́ ọmọogun Nàìjíríà ti ṣí ojú opó rẹ̀ fún ìforúkọ silẹ̀ àti ọ̀nà ti ó le gbà ṣe ìfọ̀rọ̀wánilẹ̀nuwò orí ayélujára fún iṣẹ́ náà 25 Agẹmo 2020 Oríṣun àwòrán, Nigeria Airf Force Ilé iṣẹ́ ọmọ ogun òfurufú ti ṣi ojú òpó wọ́n fún ìforúkọ̀silẹ̀ àti ìgbaniasíṣẹ́ fún àwọn obinrin àti ọkùnrin, tó fẹ́di ọmọogun ojú òfurufú bí orílẹ̀-èdà Nàìjíríà ṣe n ṣelédè lẹ́yìn obìnrin akọ́kọ́ tó n wa ẹlikọputa ọmọogun Tolulope Arotile bí ó ṣe wọ káàlẹ̀ sùn.
Oríṣun àwòrán, @ayobamiolunloyo Lẹ́yìn ọdún kan tó gba òye ọmọwe ni wọn yàn Omololu ni Kọmiṣọnna feto idagbasoke ọrọ aje ni ẹkun ìwọ oòrùn Naijiria lapapọ.
Ọga ileeṣẹ naa, Noel Doyle, sọ pe wọn ko jere mọ ni wọn ṣe lu ileeṣẹ n ni gbanjo fun Dangote.
Angẹli náà tún ń bá ọ̀rọ̀ rẹ̀ lọ báyìí pé, “Ọba tí yóo tún jẹ ní Siria yóo jẹ́ ọba burúkú.
Oríṣun àwòrán, Twitter/NFF NFF kẹdun pẹlu ẹbi awọn oloogbe naa ati ẹgbẹ agbabọọlu Rangers Intl, ajọ naa gbadura pe ki Eleduwa tẹ wọn si afẹfẹ rere.
Bakanna, Abdullahi Zulkifli tun fi kun alaye re nigba ti o fi ye awon
ipolongo fun  Femi Gbajabiamila, ni ko si
Igba kan n lọ, igba kan n bọ, bi Iwobi ṣe fi Arsenal silẹ bẹẹ naa ni David Luiz gbera pa lati Chelsea wa si Arsenal.
Bakan naa ni mẹẹdogun lati ilu Ogun, mẹẹdogun ni ilu Bauchi, mọkanla ni Borno, mẹwa ni Gombe, mẹsan ni Sokoto, marun un ni Edo, marun un ni Jigawa, meji ni Zamfara, ẹyọkan ni Rivers, ẹyọkan ni Enugu, ẹyọkan ni Delta, ẹyọkan ni FCT ati ẹyọkan ni Nasarawa.
lorile ede Naijiria, kii se aarẹ Buhari.
BBC Arabic ati Arab Barometer ṣe iṣẹ iwadii lati fi mọ ero awọn eniyan yii nipa ẹsin ti wọn n sìn.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Eyi ni igba akọkọ ti orilẹede France yoo de ipele aṣekagba idije ife ẹyẹ FIFA lati ọdun 2006 Aarẹ orilẹede France, Ọgbẹni Emmanuel Macron ati Alayeluwa ọba Philippe ti orilẹede Belgium wa nikalẹ lati yẹ awọn agbabọọlu orilẹede wọn si.
Iye ènìyàn to lùgbàdì ààrùn náà ni ọjọ́bọ yìí tún pọwọ́ lọ sókè díẹ̀ si ju ti ọjọ́rú àti ọjọ́iṣẹgun lọ.
Láti ibẹ̀ lọ sí ìhà gúsù lẹ́bàá odò Jọdani, yóo parí sí Òkun-Iyọ̀.
Iroyin ti wọn kọkọ gbe sita ni ede oyinbo loṣu keji ọdun kọ lo da wahala silẹ.
Ileeṣẹ ọẹọpaa ni ipinlẹ Ọyọ ko tii sọ ohunkohun lori iṣẹlẹ yii lasiko ti a fi n ko iroyin yii jọ.
People’s Democratic Party (PDP), Ọgbẹni Jimi Agbaje ati igbakeji rẹ lọwọ,
Atiku ṣetán láti pèsè isẹ́ mílíọ́nù mẹ́ta lọ́dọọdún Ìdá 35% obìnrin ní ìjọba àti àwọn nǹkan míràn tí #Next Level bá dé Ará Kwara soríre bí mo se jáwé olúborí - Ọlawuyi Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, World Toilet Day: Aráàlú ní woléwolé yẹ kó bẹ̀rẹ̀ àyẹ̀wò ojúlé dé ojúlé Ninu ọrọ wọn, Ajọ naa ni igbese yii fihan pe awọn oloselu ko ka orilẹede Naijiria si, ati wi pe igbese yii le fa ifasẹyin fun idibo gbogboogbo lọdun to n bọ.
Bi wọn ṣe gbe The Wedding party apa kinni ati apa keji jade lasiko naa ni wọn ṣe gbe e jade.
eyin iko Liverpool loju, Van Dijk, pe yoo gba ami-eye naa, sugbon ibi ti won
Obinrin kan to n se kọndọ lẹyin ọkọ lorilẹede Kenya to si ni irungbọn bi ọkunrin, ti n sọ ohun ti oju rẹ ri lọwọ awọn ọlọpaa.
Bí ebi bá ń pa ọ̀tá rẹ, fún un ní oúnjẹ jẹ,bí òùngbẹ bá ń gbẹ ẹ́, fún un ní omi mu.
Fashola lo sọ eyi lasiko ti oun ati awọn gomina ni iwọ -oorun Naijiria n ba awọn ọmọ Naijiria sọrọ lori ipaniyan ti awọn ologun ṣe si awọn afẹhọnuhan ni Lekki.
Ó pàṣẹ pé kí wọ́n ṣe ọjọ́ náà ní ọjọ́ àjọ̀dún ati ayọ̀, tí wọn yóo máa gbé oúnjẹ fún ara wọn, tí wọn yóo máa fún àwọn talaka ní ẹ̀bùn.
Gbogbo awọn ti a ka sile yii to fi mọ Ahmad Pategi to jẹ ọmọ ile asojusofin agba fun Edu/ Moro/Patigi ni ẹkun ariwa Kwara naa ko gbeyin .
Nítorí ìwọ ni o lu gbogbo àwọn ọ̀tá mi bolẹ̀,tí o sì ṣẹgun àwọn eniyan burúkú.
"Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Sotitobire: Ọkọ mi kò mọ̀ Jegede PDP rí, kódà kò fa ẹnikẹ́ni kalẹ̀ dípò Akeredolu- Bisola O ni: ""Wọn ti buwọlu aṣẹ pe ki wọn ṣí gbogbo ibudo akojọ agunbanirọ to jẹ ibi ipagọ fawọn ti yoo kopa ninu eto naa lasiko yii."
” (Aṣálẹ̀ ni ọ̀nà yìí gbà lọ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Àbẹ̀wò Macron: Iṣẹ́ Fela kò le parẹ́ Ina naa ba ọpọ awọn to fẹran itan atayedaye ninu jẹ nitori ọjọ ori ile ijọsin naa.
Super Eagles, Gernot Rohr ti pe agbaboolu owo eyin iko Naijiria U20, Valentine Ozornwafor sinu iko re ti yoo
Kí ló fà á tí àwọn ọmọ Obasanjo ń ta kò ó ní gbangba?
"Báyìí ni àgbàọ̀jẹ̀ agbábọ́ọ̀lù Diego Maradona ṣe wọ káà ilẹ̀ lọ lólú ìlú Argentina Ohun mẹ́wàá pàtàkì nípa Maradona àti ìbáṣepọ̀ rẹ̀ pẹ̀lú ẹlẹ́sẹ̀ ayò Diego Costa rèé Àwòrán rèé nípa bí 'Hand of God' ṣé dí inagijẹ Diego Maradona Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Ọkọ mi wa ọkọ̀ tẹ ""Poly Bag"" lásán, àfi gbùùàà!"
À ń retí alaafia,ṣugbọn ire kankan kò dé.
Kò pé ni o kó àwọn jàndùkú wá láti Aboru wá si Mosan tí wan si bẹ̀rẹ̀ si ni ṣọṣẹ́, wọ́n jí ǹkan àwọn èèyàn, ọ̀ps àwọn míràn tilẹ̀ fi ilé wọ́n sílẹ̀ tí wọ́n sì sálọ.
OLUWA sọ fún mi pé, ‘Ẹ kò gbọdọ̀ da àwọn ará Moabu láàmú, tabi kí ẹ gbógun tì wọ́n; nítorí pé n kò fun yín ní ilẹ̀ wọn, nítorí pé mo ti fi ilẹ̀ Ari fún àwọn ọmọ Lọti gẹ́gẹ́ bí ohun ìní wọn.
Ninu fidio yii ni Norma Ka Mbele ti salaye bi awọn ọdọ mẹta ti fipa baa lopọ, ti ileesẹ ọlọpaa ko si ri ohun kankan se si.
Ajọ WHO n sẹ iranlọwọ fun akitiyanidoola ti ajọ NCDC n dari, pẹlu afojusun lati seto irolagbara fun amojuto, ifimu finlẹ, ayẹwo, to fi mọ amojuto awọn alaisan ati ikopa awọn araalu.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Mọ̀ nípa adelé adájọ́ àgbà tuntun, Ibrahim Tanko Muhammed 25 Sẹ́rẹ́ 2019 Oríṣun àwòrán, AsoRockVilla Àkọlé àwòrán, Ibrahim Tanko Muhammed Aarẹ Buhari ṣẹṣẹ yan adajọ agba tuntun lati dele gẹgẹ bi adajọ agba dipo adajọ Walter Onnoghen to ti jẹ adajọ orilẹede Naijiria.
Wọ́n kúrò níbẹ̀, wọ́n lọ pàgọ́ sí aṣálẹ̀ Sini.
Ninu ọrọ tirẹ, Ahmad Diallo ni ọdun to kọja loun ti n reti ki adehun naa bọsi nitori o da oun loju pe ẹgbẹ agbabọọẹu to ṣe rẹgi fun idagbasoke oun ni Manchester United jẹ.
Lara wọn ni Ẹniọla ati Dapọ.
Wọ́n ní, “Ìgbà tí ọmọ yìí wà láàyè, a bá Dafidi sọ̀rọ̀, kò dá wa lóhùn.
‘Kò sí ẹni tó fipá mú ẹ̀yà Igbo láti dìbò fún APC’ Digbí ni mo wà lẹ́yìn Amotekun, máà ṣèrànwọ́ mílíọ̀nú èèyàn fun - Nnamdi Kanu Kii ṣe igba akọkọ ti yoo dunkooko mọ awọn ẹya ti kii ṣe Yoruba lorilẹ-ede Naijiria niyii.
"Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: ""Apena fẹ́gbẹ́ Oṣugbo, Opa, Akala àtẹ̀yin awo, ẹ wa ọ̀pá àṣẹ Ọ́ba Akiolu jáde"" Òkú ọ̀dọ́ 15 ni mo kà ní Lekki amọ́ mo kábàámọ̀ pé a gbà kí ológun gbé okù wọn lọ - DJ Switch Àwọn jàńkùkú tún padà lọ fọ́ ShopRite Ilorin lónìí lásìkò ìṣéde Ikú Aráàlú 51, ọlọ́pàá 11, Sọ́jà 7 tó kú lásìkò ìwọ́de EndSARS dùn mí - Buhari Ẹ wo ọ̀rọ̀ àwọn Wòlíì tó ti sọ àsọtẹ́lẹ̀ saájú nípa làásìgbò EndSARS Májèlé olóró lẹ jí l‘Ekiti dípò èròjà oúnjẹ Covid-19 - Ariwo sọ lórí ayélujára Ẹ sọ́ra fún ìwà olè àti jàgídíjàgan nílẹ̀ Yorùbá-Sunday Igboho ₦147m la rí kójọ fún ìwọ́de, a kò fẹ́ owó mọ́, ìwọ́de ti parí - Feminist Coalition Ijọba Eko ni ọjọ kejilelogun osu Kẹsan ọdun 2020 ni Gomina Babajide Sanwo-Olu tẹwọgba awọn eroja ounjẹ naa latọwọ ajọ to n pese eto idẹrun arun Coronavirus, CACOVID."
Ǹjẹ́ Ọlọrun yóo gbọ́ igbe rẹ̀,nígbà tí ìyọnu bá dé bá a?
ifi-ọmọniyan se, ki won si je ki iwa naa ju ifẹ ọkan won lọ.
Máa pada bọ̀, kí á lè máa fi ọ́ ṣe ìran wò.
    Ẹnì kẹjọ ni Ìbẹ̀ǹbẹ́-Olókùnrùn tí mo ti sọ̀rọ̀ rẹ̀ fún yín tẹ́lẹ̀.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ikọ Super Falcons naa fun Naijiria ni ẹbun ọjọ ominira lẹyin ti wọn naa ikọ South Korea ninu idije Women's World Cup to n lọ lọwọ lorilẹede Faranse Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Adari ikọ Super Falcons, Thomas Dennerby fi idunnu rẹ han lẹyin ti ikọ rẹ jawe olubori Aworan yii wa lati ile isẹ Getty Images ati COPYRIGHT LUCIPOST Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 3 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 5 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Ewe, iko agbaboolu orile-ede Senegal dipo kinni won mu nile Afrika, ti orile-ede Tunisia, Morocco, Naijiria ati DR Congo si tele won leyin.
Ọ̀gá aṣọ́nà kọ̀ọ̀kan wà ní ẹnu ọ̀nà kọ̀ọ̀kan ní ẹ̀gbẹ́ mẹrẹẹrin: ní ìhà ìlà oòrùn, ati ìwọ̀ oòrùn, ati àríwá, ati gúsù; 
Awọn akẹẹkọ naa da paali boju pẹlu iho ni ẹgbẹ kan lati ma se jẹ ki awọn ọmọ naa ji ara wọn wo lasiko idanwo.
Oṣu mẹfa gbako ni ijọba fi gbe awọn ileewe tipa lẹyin ti ajakalẹ aarun covid-19 bẹ silẹ lorilẹede Naijiria.
Ó di ìgbà keji tí yóo fi èrú gba ohun tíí ṣe tèmi.
Ile iṣẹ ijọba yoo maa fọwọ si iwe aṣẹ fun ọlọdani lati le kopa.
Gba owó lọ́wọ́ àkẹ́kọ̀ọ́ ìjọba, ko rugi oyin - Seyi Makinde Iṣu ló wà nínú mọ́tò mi, kìí ṣe èèyàn ni mo sọ di iṣu - Afurasí Ajínigbé figbe ta Ìlú tí ọ̀daràn bá tí dẹ́ṣẹ̀ ló yẹ kí wọn tí gbẹjọ́ rẹ̀ -Agbẹjọ́rò Àgùnbánirọ̀ gbẹ́mìí mì látàrí 'Snipper' tó fi fọ irun rẹ̀ Awọn kan gba pé koko ipade naa ni ibaniwi fun Senetọ naa ati pe ohun ti o ṣe jẹ iwa idojuti fun gbogbo senetọ pata.
O ṣalaye pe lootọ ni ajọ OYRTMA fi ofin mu ọkọ meji lati fi fa awọn awakọ yoku leti ki wahala to bẹ silẹ Kí ló dé tí Ilé ẹjọ́ sún ìgbẹ́jọ́ Naira Marley sí ọ̀la?
Bakanna lo pasẹ pe ki gbogbo awọn adari ile isẹ ijọba farahan niwaju ile asofin ni kia kia .
"Baba Ogun Majek nílò ìranwọ owó yín lásìkò yìí, kí wọn leè gbádùn padà""."
Ẹ̀san OLUWA ni, ẹ̀san nítorí tẹmpili rẹ̀ tí wọ́n wó.
Bí wọn bá fẹ́, wọ́n lè jẹ́rìí sí i pé ọ̀nà àwọn Farisi ni mo tẹ̀lé ninu ẹ̀sìn ìbílẹ̀ wa, ọ̀nà yìí ló sì le jù.
Nítorí ọpọlọpọ ń hùwà bí ọ̀tá agbelebu Kristi.
Ko ni si aaye fun ọkọ ti ko ba ko àwọn ǹkan bii oogun tabi ounjẹ láti kọja ni ilú kan si omiran kò ni si aaye irin aajo láti ipinlẹ kan si omiran, bakan naa ni gbogbo eniyan gbọdọ maa lo ibomu-bẹnu ni ìgbà gbogbo.
Ẹni tí ń láwọ́ wà nínú gbajúmọ̀, ọwọ́ lílà kò le sọ ni di tálákà láéláé, nítorí àṣíi’rí ẹni ti ń lawọ́ kò le tú bí ayé kéré bí kò ju akèǹgbè lọ, ṣùgbọ́n, mọ̀ dájú pé ìnákùná yátọ̀ sí ọwọ́ lílà, nítorí onínàákúnàá ni ẹni tí ó sọ orí ara rẹ̀ nú tí o n fọnka sí ibi tí kò yẹ, àbámọ̀ ni ìgbẹ̀yìn irú ẹni bẹ́ẹ̀, ṣùgbọ́n síbẹ̀ náà, onínàákúnàá tún ní ìgbádùn tirẹ̀ lọ́tọ̀, onínàákúnàá lè jẹun sí inú ara rẹ̀, ṣùgbọ́n aláhun a máa gbé ọbẹ̀ ọjọ́ mẹ́wàá lé iná a tún máa fi omi si i.
Nígbà tí ọkùnrin náà sì ń sọ̀ kálẹ̀ òkè pẹ̀tẹ́ẹ̀sì rẹ̀ mo wí fún un, mo ní, ‘Baba-onírùngbọ̀n mi ọ̀wọ́n, jẹ́ kí n bá ọ kó díẹ̀ ni ‘rùngbọ̀n rẹ.
 Ti ọdun 2018 yii ni orilẹ-ede Naijiria ti darapọ mọ awọn orilẹ-ede miiran lagbaaye lati ṣayẹyẹ rẹ.
Òjò àrọ̀rọ̀dá: Àrá sán pa màálù mẹ́tàlélógùn ní Ekiti
London Tailor ni orukọ inagijẹ ti wọn fun arakunrin ẹni ọdun mẹtalelọgbọn, Olatunde Abolarinwa ti ifẹ oun ati iyawo rẹ dabii ti ẹlẹyẹle ni ti iyawo ko si mọ wipe ọkọ rẹ ko ni dagba, di ogbo, ferigi pau jẹ obi gẹgẹ bi wọn ṣe lero sira wọn.
ọdun 1985, o wọ ile iwe giga fasiti ilu Eko, nibi to ti gba oye Bachelor’s
Ọjọ́ karùn ún, oṣù Kẹrin ọdún 2019 ló pé ọdún kan ti ìdigunjalè iru eleyii waye ni nílùú Ọffa, ni ipinlẹ Kwara, ti wọn si ja ileefowopamọ maarun ọtọọtọ lole.
’Ṣugbọn àwọn ni ojú yóo tì.
Bakan naa, ọpọ lo ti n bu ẹnu ẹtẹ lu ijọba Aarẹ Keita lori bi ija ẹlẹyamẹya ṣe n pọ sii.
Tesiwaju si, orisirisi ipo ni o di mu nile ifowopamo agbaye lati odun 1982 si odun 2003 ati 2007 si odun 2011 abbl.
Naamani bá lọ sí odò Jọdani, ó wẹ̀ ní ìgbà meje gẹ́gẹ́ bí Eliṣa ti pàṣẹ fún un, ó rí ìwòsàn, ara rẹ̀ sì jọ̀lọ̀ bí ara ọmọde.
Ilé iṣẹ́ ọmọogun ni irọ́ tó jìnà sí òótọ́ ni ọ̀rọ̀ náà pé àwọn yìnbọ̀n tàbi pa ẹnikéni ní àsìkò sún, ẹ̀yí nìkàn kọ́, ó fi kun pé, ọ̀pọ̀ ẹ̀rí ló wà nígboro pé àwọn ko pa ẹnikẹ́ni.
Tabi ko kuku pa eeyan ni igbẹsan lori ajọṣepọ awọn mejeeji.
Iroyin naa fi kun un pe, diẹ diẹ imu ẹlẹdẹ wọn wọ ọgba tan, ti wọn raye sunmọ aafin, ti wọn si ni nọmba Kabiyesi lọwọ.
Iroyin naa sọ pe ọpọlọpọ wakati lo fi wa ni agọ ọlọpaa, ti wọn si tun ni ko pa gbogbo nkan to kọ nipa ẹsun rẹ lori ayelujara.
Wọn ni nibi ti wọn jọ fija pẹta ni ọta ibọn ti lọ ba obinrin oniṣowo kan ladugbo naa.
Nítorí orílẹ̀-èdè yóo gbé ogun ti orílẹ̀-èdè, ìjọba yóo dìde sí ìjọba, ilẹ̀ yóo mì tìtì ní oríṣìíríṣìí ìlú, ìyàn yóo mú ní ọpọlọpọ ilẹ̀.
O tun jẹ ọkan lara ọmọ igbimọ fun eto aabo ati ọtẹlẹmuyẹ fun ẹgbẹ oṣelu APC lasiko eto idibo ọdun 2015.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Iléèṣẹ́ ọlọ́pàá: ìwádìí bẹ́rẹ́ lórí ikú ọdaran tó tojú orun dójú ikú' Bawo ni ọwọ́ ṣe tẹ ẹ?
2019 Election: Bí Buhari ba le lọ Kóòtù ní ẹ̀ẹ̀mẹ́ta- Obasanjo Supplementary election: Ọlọpàá gbé ikọ kògbérégbè díde lọ si wọ́ọ̀dù ìdìbò Gama Ilé ẹjọ́ kéde Ademọla Adeleke gẹ́gẹ́ bíi gómìnà ìpínlẹ̀ Ọṣun Ní ipínll Kano, oniruuru ìṣẹ̀lẹ̀ ló wáye ti àwọn miran till pàdánu ẹmi wọn, ti ìdá ọgọrin nínu ìdá ọgọrun ibùdó ìdìbò sì ni kónukọhọ nínú.
National Electoral Commission INEC ti fun aarẹ orile ede Najiria, Muhammadu
Saraki tun sọ pe ki awọn alaṣẹ ile tun pin owo naa kan awọn ọmọ ṣẹnẹtọ to ku nigba to jẹ adari ile igbimọ aṣofin agba l'Abuja.
O ni kaka ti ijọba yoo fi wa ọna abayọ si isoro yii, o tẹwọn lọrun ki awọn akẹkọọ wa nile titi di ọdun to n bọ.
Minisita tun so pe awon odo nla meji naa,Oyan ati Ikere Gorge ti won fe lo lati maa fi pese ina mona-mona, ni eyi ti yoo je ki idagbasoke ba ina mona-mona lorile ede Naijiria.
Awọn eniyan jankan-jankan ni ẹka imọ ẹrọ lorilẹ-ede Naijiria ti da owo jọ pọ lati gbe ile isẹ ọlọpaa lorilẹ-ede Naijiria lọ si ile ẹjọ lori ẹsun pe wọn n fi iya jẹ wọn lọna aitọ.
Báwó ni òògùn dexamethasone ṣe ń ṣiṣẹ́ lára Ẹ̀kọ́ mẹ́jọ tó yẹ kí ilẹ̀ Afirika kọ́ lára àjàkálẹ̀ aàrùn coronavirus Coronavirus: Ewu wo làwọn òṣìṣẹ́ elétò ìlèra ń kojú ní Nàìjíríà?
Ọ̀dọ̀ fásitì jànkàn Oxford ló ti jáde Ẹlẹ́wọ̀n 44 kú sọ́gbà ẹ̀wọ̀n nítorí ooru tó mú púpọ̀ Ọwọ́ ọlọ́pàá ìpínlẹ̀ Kebbi tẹ bàbá àti ìyàwó rẹ̀ méjì fún pé wọn so ọmọ pọ̀ mọ́ ewúrẹ́ fún ọdún méjì Àmọ̀tẹ́kùn gbéra!
Ní 6 Oṣù Kẹrin 1830, lábẹ ìdarí láti ọ̀run wá, Wòlíì Joseph Smith ṣe ètò Ìjọ náà, báyìí sì ni Ìjọ òtítọ́ Jésù Krístì bẹ̀rẹ̀ sí ṣiṣẹ́ lẹ́ẹ̀kan síi bíi àgbékalẹ̀ kan láàrin àwọn ènìyàn, pẹ̀lú àṣẹ láti kọ́ni ní ẹ̀kọ́ ìhìnrere àti láti ṣe àbójútó àwọn ìlànà ìgbàlà.
Àwọn tó mọ̀ nípa ìpànìyàn Lekki yóò fojú winá òfin - Sanwo-Olu sí Becky Anderson Mo ti tọrọ aṣọ àti yẹtí etí rí, kí n tó leè ṣe àwo orin - Tope Alabi Amy Coney Barrett di adajọ́ àgbà nílé ẹjọ́ tó ga jùlọ l'Amẹrika Tani àwọn ọ̀dọ́ méjì tí yóò darapọ́ mọ́ igbimọ́ iwadii iṣẹlẹ́ Lekki ní Eko?
 Èyí fún wa ní ìlọ ́ po : 0 : 00 , 1 : 05.
Oludije ẹgbẹ oṣelu PDP fun ipo aarẹ Atiku Abubakar pe fun iṣọkan laarin awọn adajọ ki wọn baa le gbogun ti iwa aarẹ naa.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 2016 ni Angel kọ́kọ́ gbé àwo orin rẹ̀ síta láti fi bèrè ìdí tí òun fi yàtọ̀ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Aláàbọ̀ ara tó ń dari ọkọ̀ ojú pópó ní àìlera kìí ṣàrùn' Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 3 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 5 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Just been redeployed to the Ministry of Labour and Employment to work with my long-time big brother, H.
Gbogbo àwọn nnkan wọ̀nyí jẹ́ ànfàní tó wà ní àwùjọ-ẹ̀dá tí kò sì ṣe é fi sílẹ̀ láì mẹ́nu bà.
Àwọn ọmọ-ogun wá ń gbèrò pé kí àwọn pa àwọn ẹlẹ́wọ̀n, kí wọn má baà lúwẹ̀ẹ́ sálọ.
Bẹ́ẹ̀ ni ó ṣe ṣe ìtẹ́lẹ̀ mẹ́wẹ̀ẹ̀wá, bákan náà ni ó da gbogbo wọn, bákan náà ni wọ́n tó, bákan náà ni wọn sì rí.
Àwọn mààlúù yìí bá doríkọ ọ̀nà Beti Ṣemeṣi, wọ́n ń lọ tààrà láì yà sọ́tùn-ún tabi sósì.
Ọkọ kan ti jona rauru lori afara Ojuelegba nilu Eko.
Sanwo-Olu, El-Rufai fara pamọ́ torí COVID-19 lẹ́ẹ̀kejì Oríṣun àwòrán, Silverbirdtv Gomina ipinlẹ Eko, Babajide Sanwo-Olu ti yẹra fawọn eeyan fun igba diẹ naa.
Lẹ́yìn èyí mo tún rí angẹli tí ó ń ti ọ̀run sọ̀kalẹ̀ bọ̀.
"Gbeminiyi ni ""iwa pansaga iyawo mi ko lodiwọn, bẹẹ ni kii setọju mi, to si maa nsun ti oniruuru ọkunrin kiri."
Ojoawo Gbenga @gbengusgbengus ní ọ̀daràn pọ́ńbélé nìkan ni yóò já bọ́ láti inú ọkọ̀ ọlọ́pàá nígbà tí wọn bá múu.
Wo awọn nnkan miran ti awọn ọmọ Naijiria n sọ si Aarẹ.
Ta ló lè gbé àwọn òkè ńlá ati àwọn kéékèèké sórí ìwọ̀n?
Agbenusoro fun orile-ede ohun, Theresa May so oro ohun di mimo lojoBo(Thursday), leyin ti iko omo ogun Iran se ikolu si ibugbe iko omo ogun Israel.
Ọmọwe Yagboyaju ni ki gomina gbọ ọ̀rọ̀ naa ko kan feti gbọn ọn danu ni ko si yẹ ko tii ka a kun rara lasiko yii.
Awọn ọkunrin to wa nita ile naa ni BBC Igbo maa n kọ iroyin ti ko dara nipa Mbaka.
Amọ, sọja ọhun ni oun si fẹran iyawo oun lẹyin ti ọmọ mẹta ti wa laarin wọn.
Ọba ati Hamani lọ bá Ayaba Ẹsita jẹ àsè.
Oríṣun àwòrán, Others Loju opo ikansiraẹni ipinlẹ naa ni ijọba ti ni awọn ti bẹrẹ igbesẹ lati wa awọn eniyan meji ti wọn n wa naa lawari.
Jerusalẹmu ń sunkún pé,“Bojúwò mí, OLUWA,nítorí pé mo di ẹni ẹ̀gàn.
Awọn ipinlẹ naa niyii: Lagos-135 Edo-87 FCT-73 Rivers-67 Delta-62 Ogun-47 Kaduna-20 Plateau-19 Osun-17 Ondo-16 Enugu-15 Oyo-15 Borno-13 Niger-6 Nasarawa-4 Kebbi-3 Kano-2 Sokoto-1 Abia-1 Akojọpọ awọn to ti ni ti pe 28,167.
Ekpeyong ni sise awari iwadii awon oogun wonyi ti ru ireti opolopo soke.
O ra tikẹti rẹ lati Brazil lọ si France o si gba yara fun ni ile igbafẹ Hotel Sofitel Paris Arc Du Triomphe.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Kofi Annan ni o yẹ ki oun gbe igbeṣẹ ju eyi ti oun gbe nigba ija ẹlẹyamẹya Rwanda Ọdun 2001 lo gba ami ẹyẹ Nobel Prize fun wiwa alaafia gbogbo agbaye.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Buns ni ọmọ mi jẹ tán ní ṣọ́ọ̀ṣì, ló bá di àwátì' Nigba to n fi idi isẹlẹ naa mulẹ fun BBC Yoruba, osisẹ alarena fun ileesẹ ọlọpaa nipinlẹ Ọyọ, Olugbenga Fadeyi salaye pe lootọọ ni ikọlu ọhun waye.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Ọ̀nà àtijẹ kan ṣoṣo táa ní ni Màálù àwọn Fúlàní ti bàjẹ́' Amọṣa, agbẹjọro ijọba, ti amofin agba ipinlẹ Ondo, Adekọla Ọlawoye lewaju fun rọ ile ẹjọ naa lati fi iya to ba tọ jẹ wọn nitori awọn ẹri to ṣarajọ lori ẹjọ yii.
O rọ ajọ naa lati boju wo ẹbẹ rẹ fun ajọro bun mi-n-bun ọ niwọn igba ti oun ti bẹrẹ ijiya lori ẹṣẹ naa lẹyin ti awọn alaṣẹ fasiti naa ti yọọ ni iṣẹ.
Wọ́n kẹ́kọ̀ọ́ jáde ni ilé ìwé alákọ̀bẹ́rẹ̀ẹ́ ti ‘7th Day Primary School’ tí ó wà ní Abúlé Ọjà, wọ́n tẹ̀ síwájú sí ilé ìwé girama ní Jíbówú High School tí ó ń jẹ́ Premier College, Jíbówú tẹ́lẹ̀tẹ́lẹ̀ rí.
    Nítorí náà, ẹyin ọmọ ènìyàn, àwọn ọmọ ogun mi ti pé jọ ni onírúurú: kìnìhún kò níye, kò sì ẹni tí ó lè ka àwọn ẹkùn, ikooko pọ̀ lọ yanturu, Egbèje Erinmi lo n dúró bí ọmọ ogun àwọn ẹja, ọká àti erè la ẹnu sílẹ̀ dè yín hanha, àwọn igi tí kò le kúrò lójù kan ti ran àwọn iwin to ń gbe inú wọn wá jà lórúkọ igi, iwin inú ìrókò, iwin inuawusa, iwin inu ìbẹ́pẹ gbogbo àwọn iwin wọ̀nyí n dúró dè yín.
Ile -ẹjọ to ga julo lorile ede
Nítorí Johanu a máa wí fún Hẹrọdu pé, “Kò yẹ fún ọ láti gba iyawo arakunrin rẹ.
Amọ yatọ si ijo ati ọyaya tawọn araalu fi saba maa n pade aarẹ to ba wa bawọn lalejo, se ni awọn eeyan yii fi orin abuku pade aarẹ Buhari, ti wọn si n pariwo pe awọn ko fẹ, awọn ko nifẹ si.
Oun ní olùdásílẹ̀ ilé iṣẹ́ ìròyìn ti a mọ si Sahara Reporter tó bẹ̀rẹ́ ní ọdún 2006 nínú yara kékere kan ni Manhattan ni ilẹ̀ Amerika.
O ni ajọ INEC yoo tun ṣepade lati jiroro lori ọrọ idibo gomina nipinlẹ Rivers ti ajọ naa da duro lẹyin ti rogbodiyan bẹ silẹ kaakiri ipinlẹ naa.
Wọn a kó kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ aláìníbaba lọ,wọn a gba akọ mààlúù opó gẹ́gẹ́ bí ohun ìdógò.
Igbe aye olóògbé Pa Fatai Rolling Dollar dabii igba teeyan n wo sinima ni.
Oríṣun àwòrán, Twitter/@USEmbassyAbuja Àkọlé àwòrán, US Embassy Abuja Idẹnukọlẹ naa ti lapa lara wọn nilẹ Amerika pẹlu bi awọn agbaṣẹṣe ko ti ṣe riṣẹ gba ti ọpọ oṣiṣẹ ijọba ko si ribi rin irinajo nitori pe wọn ko ri owo osu gba.
Ọpọlọpọ ni iṣẹ́ ìyanu ati iṣẹ́ abàmì tí a ti ọwọ́ àwọn aposteli ṣe.
Yóo dà yín sẹ́gbẹ̀ẹ́ bí ọmọ tí ń mu ọmú,ẹ óo máa ṣeré lórí orúnkún rẹ̀.
Ni nkan bi ọsẹ meji sẹyin awọn ọmọ Naijiria ko mọ ẹni ti Lisa Hanna jẹ.
Wèrédìran ti ń gbé ilé Òmùgọ̀parapọ̀
Ojú yóo tì yín, fún àwọn igi Oaku tí ẹ nífẹ̀ẹ́ láti máa bọ.
  O ni bo ti tile je pe ,isẹ pupọ lo wa fun oun lati se sibẹ, oun ko ni
Àkọlé àwòrán, Àwọn òṣìṣẹ́ MMA2 Gẹ́gẹ́ bí wọ́n ṣe sọ ọ́ lọ́jọ́ ìṣẹ́gun, bẹ́ẹ̀ gẹ́lẹ́ náà ló rí lọ́jọ́rú tí wọ́n tú síta lówùrọ̀ kùtù hàì sí ẹnu ọ̀nà pápákọ̀ òfúrufú náà láì jẹ́ kí ẹnikẹ́ni wọlé.
Ìyàwó mi fi mí sílẹ̀ kó lọ sílé ọkùnrin míì nínú báráàkì kan náà, àmọ́ mò sí tún fẹ́ràn rẹ̀- Sọ́jà Wo àwọn ìṣesí ojoojúmọ́ mẹ́wàá tó le ṣàkóbá fún ọpọlọ rẹ Coronavirus: ''Ìjọba kò tíì pàṣẹ ìlànà ìtakété-síra-ẹni padà nínú BRT la ò ṣe máa tẹ̀le'' Wo àwọn Adelé-Ọba aládé méje tó jẹ́ obìnrin nílẹ̀ Yorùbá Ṣé lóòtọ́ ni Adajọ́ Àgbà Naijiria, Tanko Muhammad ti ní Covid-19?
julo ati igbakeji adari eto ile .
Paul sọ pé òun ni ó n tọ́jú bàbá òun nínú ẹ̀wọ̀n láti ìgbà tí ìlera rẹ̀ ti mẹ́hẹ̀.
Ninu àwọn ọmọ Elamu, Jeṣaya, ọmọ Atalaya, ni olórí;orúkọ aadọrin eniyan ni wọ́n kọ sílẹ̀ pẹlu rẹ̀.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Itaniji: Oluwo sọ ìtàn bí Orunmila ṣe jìyà nílùú Iwo àti ayọ̀ tó gbẹ̀yìn rẹ̀ torí sùúrù O wa n kọminu lori ija ojoojumọ to n waye nilu Ijebu Ode ati agbegbe rẹ lori ija agba laarin awọn ẹlẹgbẹ okunkun, to si fọwọ gbaya pe, ileesẹ ọlọpaa yoo kọju oro si wọn.
Gomina Ajimobi lo lọ si ile ẹjọ kotẹmilọrun, lẹyin ti adajọ ile ẹjọ giga ni ọdun to kọja ni Ajimobi ko lasẹ lati yan ọba mọkanlelogun fun ara rẹ.
Oun ni oníbodè Igbó Elégbèje, ó wọ sòkòtò péńpé kan báyìí, irun orí rẹ̀ gùn, o sì ba irun náà lọ si ẹ̀yìn, èyí ni nǹkan a nì bàrá ìdí bí o bá ń rìn lọ.
Tí a fiṣọwọ́ ní 13:07 29 Èbibi 201913:07 29 Èbibi 2019 Wo àwọn ààrẹ Nàìjíríà láti 1999 títí d'òní Video content Video caption: Wo àwọn ààrẹ Nàìjíríà láti 1999 títí d'òníWo àwọn ààrẹ Nàìjíríà láti 1999 títí d'òní Article share tools Facebook Twitter ṢàpínlòView more share options Share this post Copy this linkKà síwájú síi nípa àwọn ìtọ́kasí wọ̀nyí.
Aare ajo FIFA, Gianni Infantino ti salaye boolu afesegba ni Naijria gege bi ohun ti o ju oro esin lo,Geeg bi aare ajo FIFA, Infantino se so ninu ipade apapo AITEO-NFF Awards ti o waye nilu Eko, eyi ti ajo NFF sagbateru re,“Ere boolu afesegba ni Naijria je igbe aye awon odo.
Port harcourt Bole: Mi kò mọ́ pé bọ̀ọ̀lì títà lè gbé mi dé ipò yìí láyé mi!
Òkú ọmọ tuntun pòórá nílé ìgbókúpamọ́sí nílùú Akurẹ Fintiri fi ìdí gómìnà ìpínlẹ̀ Adamawa janlẹ̀ nínú ìdìbò gómìnà Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Nígbà tí mò ń wà Awolowo, Gowon, Babangida, mo fi ara mi sípo ọ̀wọ̀ tóri .
Bẹẹni, OOTỌ ni eyi, alaboyun, alaarẹ, ọmọde, àti arugbo ko le fi ẹjẹ silẹ̀.
Gomina Abiola Ajimobi pelu gomina ti ipinlẹ Ọyọ sẹsẹ dibo yan, Onimo ero Seyi Makinde jọ n jiroro lori  igbimo ti yoo se kokaari isiporọpo ni ile-isẹ gomina to wa ni agbegbe Agodi niluu Ibadan, ni ipinlẹ Ọyọ, ẹkun Gusu orilẹ ede Naijiria.
Biliọnu marun o le diẹ ni yoo pari afara Niger kejiI Ijọba Ọbasanjọ lo fi tipa-tipa gbe ilana idokowopọ laarin ijọba ati ẹka adani le awọn ọmọ Naijiria lori.
Àwọn Ènìyàn Mímọ́ Ọjọ́-ìkẹhìn ti ìbẹ̀rẹ̀ mọ rírì àwọn ìfihàn náà wọ́n sì rí wọn bíi àwọn ọ̀rọ̀ àfiránṣẹ́ láti ọ̀dọ̀ Ọlọ́run.
"Oríṣun àwòrán, @OfficialAPCNg ""A gbọdọ lo ọna to yatọ bayii nipa sisan owo osu to kere julọ nitori gbogbo owo ọja lo ti lọ soke lai si afikun fun owo osu awọn osisẹ, ti ohun gbogbo si wa loju kan soso."
CA Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Igbeṣe yii ni yoo bẹrẹ lati aago mejila orun, ọjọ Aiku, ọjọ kọkandinlọgbọn, oṣu kẹta ọdun 2020.
Oríṣun àwòrán, @followlasg Àkọlé àwòrán, Háà, ó ṣe!
Bí olórin ọmọ Nàìjíríà, Omah Lay se dèrò ọgbà ẹ̀wọ̀n ní Uganda Adajọ kan ni Uganda ti ni ki wọn fi olorin ọmọ Naijiria, Omah Lay, Temilade Openyi, ti ọpọ mọ si Tems ati Muyiwa Awomiyi si ọgba ẹgba ẹwọn di Ọjọru.
Lara ojuse igbimo naa ni lati sayewo finni-finni, ki won si tun yan awon to ba yege fun irinajo ile-mimo yii, Saraki so  pe, oun  fe maa ran awon musulumi ati kirisiteni lo sile mimo, nitori pe agbara ijoba ko ka a mo nitori eto oro aje wa to mehe.
Ó wí fún wọn pé, “Ẹ ju àwọ̀n sí apá ọ̀tún ọkọ̀, ẹ óo rí ẹja pa.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Sibahle Zwanen fi ìmọ̀ ìṣìro da orí ayélujára rú China: Aṣa ati iṣe ilẹ China ko faye gba keeyan maa di mọ ara wọn lawujọ rara.
O dara fun orisirisi itọju ara, gẹgẹ bi ipalara ina sugbọn ko yẹ ni mimu.
Awọn ọmọ Naijiria ti gbana jẹ lorii fidio yii to bẹẹ tawọn kan n wọn kobiewu epe fun gbajugbaja ori ayelujara yii.
EndSARS: Olatunde Abolarinwa London Tailor ní òun á ṣe baba fún mi, kò tilẹ̀ dúró ṣe bàbá àwọn ọmọ tirẹ̀ tóríi ìwà Ọlọ́pàá Mopol A kò lọwọ́ sí ìwé ìpẹ̀jọ́ tó tako ìdásílẹ̀ ìgbìmò ìwádìí aṣemáṣe ikọ̀ SARS- ọlọ́pàá Nàìjíríà Àwòrán àwọn afurasí tí a fi léde kìí ṣe òfegè, ṣùgbọn a dọ́gbọ́n síi - Iléeṣẹ́ ọlọ́pàá Àwọn Ọba alayé ní Naijiria ṣàbẹ̀wò sí Ọba Eko, Gómìnà Eko àti Bola Tinubu lẹyin ìwọ́de EndSARS Wọn ni ijọba Buhari ti tapa si ofin ilẹ Naijiria to sọ pe ojusẹ rẹ akọkọ ni lati daabo bo ẹmi ati dukia awọn ara ilu.
Mo n ro awon alase ile iwe ti ipinle, aladani ati ti apapo lati maa pese eto aabo to ye fawon akekoo nile iwe won ki okan obi ati alagbato le bale pe aabo wa fun awon omo won.
gomina ipinle Ekiti, ogbeni Kayode Fayemi  ku oriire iyansipo tuntun re
“Ó dùn mí pé mo fi Saulu jọba.
Bí ọ̀rọ̀ ìkà tilẹ̀ dùn ní ẹnu rẹ̀,tí ó sì fi pamọ́ sí abẹ́ ahọ́n rẹ̀,
Samuẹli pàṣẹ pé kí wọ́n mú Agagi, ọba Amaleki wá, Agagi bá jáde tọ̀ ọ́ lọ pẹlu ìbàlẹ̀ ọkàn, ó ní, “Dájúdájú oró ikú ti rékọjá lórí mi.
Lion Heart Genevive Nanji, ogbontarigi oṣere binrin Nollywood lo dari ere naa ni eyi to fihan pe o le ṣe iṣẹ aludari ere fun igba akọkọ.
Joṣua dìde ní òwúrọ̀ kutukutu ọjọ́ keji, ó pe gbogbo àwọn eniyan náà jọ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Akomolede ati Aṣa lori BBC: Mọ̀ si nípa oríṣìí ẹ̀ka ìsọ̀rí ọ̀rọ̀ àti ìwúlò wọn Awọn ti ile iwe girama lati ipele kini si ikẹta akọkọ yoo kẹkọọ lati aago mẹjọ si mọkanla owurọ, nigba ti awọn ti ipele kinni si ikẹta keji yoo lọ ile iwe lati aago mejila ọsan si mẹta.
Mo si kuku fi ara mi ji fun wọn.
 “Ifigagbaga yii lagbara pupo, sugbon nikeyin mo dupe pe mo jawe olubori.
Báyìí ni ẹbọra ńlá náà sọ̀rọ̀ fún wa, Ikú, ẹ̀dá tíkò ní ìtìjú ẹnikẹ́ni, tí kò jẹ̀ wí pé ènìyàn ńlá ni èyí òun kò ní í mú un lọ, ẹni tí ilẹ̀ rẹ̀ ń bẹ lagbedeméjì ayé òun ọ̀run.
Ọ̀rọ̀ àwọn wolii bá èyí mu, gẹ́gẹ́ bí ó ti wà ní àkọsílẹ̀ pé,
Gẹgẹbi awọn ọlọpa ti se e lalaye, Ade Lawyer ti wa ninu awọn ti ọlọpaa nwa lati bii ọdun marun sẹyin latari ipa rẹ ninu awọn ipaniyan oriṣiriṣi ni awọn ipinlẹ to wa ni ẹkun iwọ-oorun guusu orilẹede Naijiria.
" Femi ni òun máa ń fi iṣẹ àgbẹ̀ pawọda n'ilu Ilorin, lẹ́yìn iṣẹ́ tíátà, tí òun sì ń sìn àwọn ohun ọ̀sìn pẹ̀lú, tí òun sì tún máa ń bá àwọn èèyàn ta ilẹ̀ tàbí ra ilé, èyí tí kò ní jẹ́ kí wọn bọ sọwọ alagbeda.
Koda, a si lee ni idile ọlọla ati olowo lo ti jade, ọmọ ti wọn fi ọla ati owo tọ lati kekere ni Bode Thomas.
Emi ni akọwe fun aarẹ Musulumi nilẹ Yoruba, Alhaji Dauda Makanjuola, ti ọpọ eeyan n pe ni D-Damak, lẹyin ti mo fẹyinti ninu iṣẹ olukọ, ibẹ si ni mo ti pade Seyi Makinde, to wa fi ara rẹ han aarẹ musulumi gẹgẹ bii oludije fun ipo gomina labẹ ẹgbẹ oselu ẹlẹsin SDP ni ọdun diẹ sẹyin."
Nítorí Ìwé Mímọ́ sọ pé, “Má ṣe dí mààlúù tí ó ń tẹ ọkà lẹ́nu.
Palm Wine drinking: Àǹfààní tí ẹmu ń ṣe fún àgọ́ ara
Ẹ̀yin tí ẹ bẹ̀rù OLUWA, ẹ gbẹ́kẹ̀lé e,òun ni olùrànlọ́wọ́ ati aláàbò yín.
Gẹgẹ bi ohun ti ajọ to n gbogun ti ajakalẹ aarun lorilẹede Naijiria, NCDC sọ loju opo twitter rẹ ẹgbẹrun kan ati ọtalelẹgbẹta o le mẹrin 1664 lawọ ti aarun naa tun ṣẹṣẹ mu bayii o fi kun pe, eeyan ọrinleldunrun ati mẹj (388) ni ipinl Eko, ọtalelugb o le ẹykan (261) ni Kaduna, mẹtadinlaadọrun (87) ati ogun (20) lo ti ri iwosan bayii.
Akowe naa ni“O ye ki a maa gbadura fun awon agbaboolu yii, bo tile je pe won ti setan lati fagba han akegbe won, sibe won nilo Olorun lati ran won lowo.
Ṣaaju ni ijọba ipinlẹ ọhun ti ni ko si arun Coronavirus nilẹ oun, ṣugbọn ọrọ bẹyin yọ lẹyin ti àjọ NCDC ni irọ nla ni.
Awọn obinrin nireti wa pe wọn yoo lo ọgọrin ọdun laye, tawọn ọkunrin yoo si lo ọdun mẹrindinlọgọrin.
Oríṣun àwòrán, @MBuhari Àkọlé àwòrán, Awọn amoye sọ wi pe o ti pẹ ti awọn mejeeji ko tii gbọrawọn ye lori didari ọrọ ẹgbẹ APC Ṣaaju akoko yi, awọn mejeeji ti woju ara wọn nigba ti igbimọ amuṣẹya ẹgbẹ APC ti Odigie dari rẹ ko lati kin ayanfẹ Tinubu, James Faleke, lẹyin lati tẹsiwaju gẹgẹ bi oludije ninu idibo Gomina nipinlẹ Kogi.
”Ó dá wọn lóhùn pé, “Wọ́n ti kọjá sí òdìkejì odò.
O wa rọ awọn akẹgbẹẹ rẹ ti wọn jẹ aṣofin lati ṣe afọmọ awọn ile igbimọ aṣofin, nitori awọn ni o jẹ gbongbo fun ijọba tiwantiwa.
Ọgbẹni Monguno fifi opin si Almajiri kan gbogbo eeyan kii ṣe ijọba nikan lọrọ naa kan.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fọ́nrán ohùn, ọ̀rọ̀ lórí ọkọ̀ fún Fayose Bakan naa lo kan awọn oṣiṣẹ ile ẹkọ giga to wa lori ilana owo osu (CONTISS II) ati (CONTEDISS).
Nígbà tí mo gbọ́ bẹ́ẹ̀, mo jókòó, mo sọkún, mo sì kẹ́dùn fún ọpọlọpọ ọjọ́.
Sé ìgbé ayé yín dára si láti 2015?
 Àwọn náà ni Àdùkẹ ́ , Ọmọ ́ wùmí , oládípò àti bándélé .
Iwọ ni wọ́n sọ di oúnjẹ fún mi,nígbà tí òùngbẹ sì ń gbẹ mí,ọtí kíkan ni wọ́n fún mi mu.
orile ede agbaye ati pe egbe oselu APC ko ni se ayederu si eto idibo aare ti
Ileeṣẹ eleto ina ọba Ghana fi ikede yi soju opo ayelujara wọn lati tọrọ aforijin lọdọ ara ilu.
Ọjọ buruku esu gbomi mu ni aarọ Ọjọ Isẹgun ni ipinlẹ Eko lẹyin ti ọkọ oju irin kan pa eniyan mẹrin to wa ninu kẹkẹ maruwa.
ninu Ile Igbimọ Aṣofin yii ati pe mọaṣlaṣi naa ti duro bayii, afi atunṣe
'Àwọn Dókítà fẹ́ kẹ́yin s'awọ̀n alárùn lassa' Kíni ọ̀nà àbáyọ sí àìsàn Lassa Fever?
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ààrẹ Muhammadu Buhari #BBCNigeria2019 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Orile-ede China, n'ilu Yunnan ni ajakale àrùn yìí tí kọ́kọ́ bẹ silẹ, a sì leè ṣe àpèjúwe rẹ bíi alefọ ara tó ń wáyé ní pọpọlọ ìtàn, abiya àti ẹyin ọrùn, tó sì fẹ́ fara jọ ajakalẹ àrùn Justinian.
Àlejò àpàndodo ni Fayoṣe, a kò fìwé pèé - Afuye Yahaya Bello lẹ́ẹ̀kan síi ni APC ṣe ní ìdìbò abẹ́lé ní Kogi Gbogbo ọjà di títì pa nílùú Akure, ṣugbọ́n nítorí kí ni?
Ọrọ yi jẹyọ nigba ti ile ise ọmọogun n ba awọn akoroyin sọrọ.
Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Ooni Ile Ife: Ooni Adeyeye Ogunwusi àti Olòrì Naomi gbé Àrẹ̀mọ tuntun wọ ààfin Ilé Oòduà9 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Gómìnà ìpínlẹ̀ Benue, Samuel Ortom ti parí ìjà láàrin akọ̀ròyìn Channels TV, Pius Angbo àti Ifeyinwa Angbo, ìyàwó rẹ̀8 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Borno Zabamari Massare: Àjọ NCC fẹ́ tú ìwé owó àwọn olúpèsè ìtàkùn ìbánisọ̀rọ̀ wo10 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 APC NEC Meeting: Ẹkúnrẹ́rẹ́ ọ̀rọ̀ ìkini PDP sí APC bí àwọn adarí ẹgbẹ́ lápapọ̀ ṣe túká rèé8 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
‘Ilé ìwé tí kò bá ní ohun ìwòsàn yóò fẹ̀wọ̀n jura’ Àwọn Asòfin Naijiria yarí lórí ètò ìsúná 2019 Omoyele Sowore: Èrù ló ń ba àwọn NEDG láti pè mí 'Ó ku Shittu, ó ku Ọlọ́run lórí ohun tó fẹ́ fi san ẹgbẹ́ APC l'ẹ́san' Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 3 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 5 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
 ni ede ojojumo , a n lo awon aminomba bi akole ( fun apere nomba telifonu , nomba ile ) .
Coronavirus: Àjọ NYSC ké ètò ìfinimọ̀ fáwọn àgùnbánirọ̀ kúrú nítorí Coronavirus
diplomacy : n ; ( he solved the problem with diplomacy .
Oloye Ilaka ṣalaye pe, ijọba to ṣẹṣẹ gori aleefa ṣetan lati tele ofin ninu iṣejọba ipinlẹ Oyo.
Wọ́n dé sí etí odò kí ọba tó dé ibẹ̀.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ọmọ ọdún méjìlá yìí sọ bó ṣe di téélọ̀ táwọn àgbà ń bẹ́rí fún Bashorun Bọsun Ajuwọn lo pe ẹjọ ọhun lorukọ awọn alaga kansu naa.
Gbogbo àwọn ọdẹ sì sọ̀ lójú gbangba báyìí pé èmi nikan ni àwọn lè gbẹ́kẹ̀lé gẹ́gẹ́ bí olórí àwọn.
Ṣugbọn a kò fi ìgbà kankan gbà wọ́n láyè rárá, kí ó má dàbí ẹni pé ọ̀rọ̀ tiwọn ni ó borí, kí òtítọ́ ìyìn rere lè wà pẹlu yín.
Èèyàn mẹ́rin péré ló ní àrùn Coronavirus ni Ọjọ́ Satidé Dibu Ojerinde, akọ̀wé JAMB tẹ́lẹ̀ pàdánù ọ̀pọ̀ dúkìá sọwọ àjọ ICPC Ọ̀pọ̀ òjò lo ti rọ láàrin emi àti Olúwòó- Olorì chanel Nínú fídíò náà, ní ìyá àwọn ìbejì ọhun tí ń kígbe pé, káwọn ajọmọgbe náà ro tí ìrora tí òun là kọjá, lẹ́yìn idaduro ọdún méjìlá, kí òun tó ri àwọn ọmọ ọhun bí.
Ti a ko ba gbagbe, iroyin kan wi pe Olori Ijo Redeem, Enoch Adeboye ba alaga ẹgbẹ oselu APC, Ahmed Tinubu sọrọ lori saa keji fun Gomina Ipinlẹ Eko, Akinwunmi Ambode.
N kò ni yẹ majẹmu mi,bẹ́ẹ̀ ni n kò ní yí ọ̀rọ̀ tí mo ti sọ pada.
Ẹnikan ko tii mọ boya akọ tabi abo ni wọn yoo bi nitori wọn ko tii figba kan sọ iru ọmọ to wa ninu Meghan.
Lẹ́yìn oṣù meji, ó pada sọ́dọ̀ baba rẹ̀, baba rẹ̀ sì ṣe bí ó ti jẹ́jẹ̀ẹ́ pé òun yóo ṣe, ọmọbinrin náà kò mọ ọkunrin rí rárá.
Àwọn ẹrú ní ń jọba lé wa lórí,kò sì sí ẹni tí yóo gbà wá lọ́wọ́ wọn.
Lẹyin ti fidio naa ti wọn ti da seria iya fun Boluwatife Esther Adekunle jade ni alaṣẹ fasiti naa ti ni ki wọn lọ rọọ kun nile Akẹ́kọ̀ọ́ mẹ́fà tó lu akẹẹgbẹ́ wọn ní fásitì FUTA dèrò ilé Kìí ṣe gbogbo ohun tí dókìtà ni kí n má jẹ torí àìsàn jẹjẹrẹ ni mo tẹ̀lé- Soyinka Ẹni bá láyà kó fi àmì ohùn sí ọ̀rọ̀ Konko-jabele!
jẹ́ ẹgbaa mẹrindinlọgbọn ó lé egbeje (53,400).
Nítorí bí ẹ bá hùwà bí àwọn tí ẹran-ara ń darí, kíkú ni ẹ óo kú dandan.
Coronavirus lockdown: Bí àrùn Coronavirus ṣe dá gbogbo àgbáyé gúnlẹ̀ sójú kan náà nìyí
Lizzy Anjọrin: Ẹ jẹ ki a bẹrẹ pẹlu oṣere yii, Lizzy Anjọrin, lo fi ibeere lede lori oju opo Instagram rẹ pe kawọn ololufẹ oun sọ iru ọkọ ti oun n lo laarin ọdun 2012 si 2013.
Ko sẹyin isẹ agbaṣe oni aadọta biliọnu naira ti ijọba ipinlẹ Zamfara gbe fun wọn laarin ọdun 2012 si 2019.
Àwọn alákósó opó MMM lórí ẹ̀rọ ayélujara sọ wipe ńǹkan tí ó faà tí àwọn fi tií ni pe àwọn ko le maá bá etò sogúndogójì náà lọ laì sí ọ̀ga wọ́n tó dí olóògbẹ, Sergei Mavrodi.
Boríborí gbogbo rẹ̀, ẹ̀yin ará mi, ẹ má máa búra, ìbáà ṣe pé kí ẹ fi ọ̀run búra, tabi ilẹ̀, tabi ohun mìíràn.
"Àwọn aláànú dìde ìrànlọ́wọ́ fún tìyá-tọmọ olójú búlúù Olùrànlọ́wọ́ pàtàkì fún ọ̀rọ̀ ibojì òkú, àti àwọn ipò òṣèlú mìíràn tó jẹ́ kàyééfì ní Nàìjíríà Diezani gan an ní Hushmummy tó ń bú àwọn Yahoo boys- Àwọn Ọmọ Naijiria lórí Twitter A ti bẹ̀rẹ̀ ìwádìí lórí ibì tí owó tí àwọn adigunjalẹ̀ gbé ní banki Okeho wọ̀lẹ̀ sí- Ọlọ́pàá Ẹnikan lara wọn to fẹ ká fi orukọ bo oun ni asiri sọ pe ""igbẹ ewurẹ, ati ẹfọn lo kun ibi ti wọn ko wa si."
 #alwaysbelieve I wanna thank all the players, managers, teams and fans that I have met and made this journey one of a kind!
Akintola wọ agbo oṣelu Lẹyin to kẹkọọ gboye tan nilẹ Gẹẹsi gẹgẹ bi agbẹjọro, Akintola pada si Naijiria lọdun 1949.
O sọ pé ní àsìkò náà, nǹkan tí wọ́n ń fún awọn kò ju ẹgbẹ̀rùn mẹ́ta náírà lọ.
37 Àti lẹ́ẹ̀kansíi, gẹ́gẹ́bí ọ̀nà àwọn òfin sí ìjọ nípa ìlàna ìrìbọmi—Gbogbo àwọn tí wọ́n bá rẹ ara wọn sílẹ̀ níwájú Ọlọ́run, tí wọn sì níi lọ́kàn láti ṣe ìrìbọmi, tí wọ́n sì jade wá pẹ̀lú írobìnújẹ́ àti ìròra ọkàn, àti tí wọ́n jẹ́rìí níwájú ìjọ pé àwọn ti ronúpìwàdà lõtọ́ nínú gbogbo ẹ̀ṣẹ̀ wọn, àti tí wọ́n ní ìfẹ́ láti gba orúkọ Jésù Krístì sí orí wọn, pẹ̀lú ìpinnu láti sìn ín títí dé òpin, àti tí wọ́n ti fi hàn lõtọ́ nípa iṣẹ́ wọn pé àwọn ti gba lára Ẹ̀mí ti Krístì sí ìdáríjì àwọn ẹ̀ṣẹ̀ wọn, ni a ó gbà nípa ìrìbọmi sí inú ìjọ rẹ̀.
Hasaeli bá kó ogun rẹ̀ kúrò ní Jerusalẹmu.
Ohun to kọiwaju sẹni kan, ẹyin lo kọ si ẹlomii bi ilu gangan, awọn mii ni obinrin lo ni ile, obinrin naa lo ni ìlú ni eyi to fihan pé ko si nkan ti ọkunrin n ṣe tobinrin ko le ṣe.
"Abumere/BBC Àkọlé àwòrán, ""Nitori ati maa ta orin Jazz ati orin ilẹ Adulawọ ni a ṣe ṣi ile itaja rẹkọọdu yii silẹ."
 Àwọn ọmọ ogun ọlọtẹ tí olúbákin gbé díde kò lè sẹ ́ gun ti àbúrò rẹ ̀ Òródùdùjoyè .
Nigba ti wọn bii pe ki lo wa laarin oun ati Neo, Kaisha ni oun nifẹ Neo lootọ ni ibẹrẹ.
“Ǹjẹ́ nisinsinyii, OLUWA Ọlọrun, ìwọ nìkan ni Ọlọ́run, òtítọ́ ni ọ̀rọ̀ rẹ, o sì ti ṣèlérí ohun rere yìí fún iranṣẹ rẹ.
Owó iṣẹ́ alágbàṣe tọ́ sí i.
Nítorí náà, gbogbo wọn wá sí ibi ìyàsímímọ́ ère náà, wọ́n sì dúró níwájú rẹ̀.
“Nígbà tí ẹnikẹ́ni bá jẹ̀bi ọ̀kankan ninu àwọn ohun tí a ti dárúkọ wọnyi, kí ó jẹ́wọ́ ẹ̀ṣẹ̀ tí ó dá, 
Haram nibẹ ,ti won si tun ri awon irinse ija ogun oloro gba lowo won bii: a.
À ń kọ ìwé yìí sí gbogbo àwọn eniyan Ọlọrun tí ó wà ní ìṣọ̀kan pẹlu Kristi Jesu, tí wọ́n wà ní Filipi pẹlu gbogbo àwọn alabojuto ati àwọn olùrànlọ́wọ́ wọn.
Gẹgẹ ba se kaa loju opo Wikipedia, akikanju obinrin yii, Lúwòó Gbàgídà, ni Ọọni kọkanlelogun tilu Ile Ifẹ, tii se orirun gbogbo ọmọ Yoruba, to si jọba lẹyin Ọọni Giesi, Ọọni Lumọbi si lo jọba lẹyin rẹ.
“Gbogbo ohun tí àwọn ọmọ Israẹli bá yà sọ́tọ̀ fún mi, tìrẹ ni.
Awọn to ku ti ile fọwọ si iyansipo ni Ọgbẹni Raheem Abiodun Abdulraheem, Ọgbẹni Seun Asamu, Dokita Wasiu Olatunbosun ati ỌgbẹniAkinola Ojo.
Ètè rẹ dàbí òwú pupa;ẹnu rẹ fanimọ́ra,ẹ̀rẹ̀kẹ́ rẹ ń dán bí ìlàjì èso Pomegiranate,lábẹ́ ìbòjú rẹ.
Àwọn ìpínlẹ̀ tí a ti lè rí àwọn tó n sọ èdè Yorùbá nílẹ̀ Nàìjíríà norílẹ̀ èdè Bìní.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Orí ń ta àwọn olokowo ni Naijiria Ijọba ibilẹ ti Alake ti Ẹ̀gba n bojuto ni wọn n gba bu owó orí naa fawọn ọlọ́jà.
Inú àgọ́ ni ẹ óo máa gbé fún gbogbo ọjọ́ meje náà; gbogbo ẹni tí ó bá jẹ́ ọmọ Israẹli ni ó gbọdọ̀ gbé inú àgọ́, 
" 15 : 39 ] tabi "" lõtọ eyi ni Ọmọ Ọlọhun !"
Ìjọba Èkó figbé ìkìlọ̀ ta BBC ṣagbeyẹwo awọn eyi to wọpọ julọ ninu awọn arosọ naa to jinna si ootọ: Irọ ni pé àwọn to n jẹ eso ati ẹfọ ko le fi ẹjẹ silẹ Koko ọrọ to maa n fa ijiroro yii ni lori aṣaraloore to wa ninu ẹjẹ (iron).
Ṣá ti gbà mí láàyè kí n kọjá, 
Fidio kan to n ja ranin-ranin lori ayelujara ṣe afihan ofurufu to su jọ ati bi ibugbamu ọhun ṣe ba nnkan jẹ si.
Adele Agbẹnusọ fun ajọ EFCC, Tony Orilade ni ẹsun jibiti, ole ati lilo ẹrọ ayelujara lati fi gba owo lọwọ awọn eniyan ni awọn fi sun un.
Ó ṣẹgun àwọn ará Filistia, títí dé ìlú Gasa ati agbègbè tí ó yí i ká, ati ilé ìṣọ́ wọn, ati ìlú olódi wọn.
Ile ẹjọ kan lorilẹ-ede Amerika ti pa asẹ fun ile isẹ ipoogun Johnson & Johnson lati san biliọnu mẹjọ dọla fun arakunrin to sọ wi pe aisan oogun ọpọlọ ti wọn ta fun oun jẹ ki ọmu aya oun tobi si.
Ẹré bọ́ọ̀lù: Arsenal bọ́ mọ́ Dangote lọ́wọ́ láti rà
Ìgbéraga níí ṣáájú ìparun,ìrẹ̀lẹ̀ níí ṣáájú iyì.
naa ni asalẹ ojo Aiku  lẹyin ti won ka
E gbo bi o se salaye BBC tirẹ.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ikọ̀ Falconets yóò wàákò pẹ̀lú Spain 'Buhari/Osinbajo yóò jọ díje ni 2019' Sáà kan péré ni mo tọrọ lọ́dún 2019 - Atiku Ẹ o ranti wipe ti orin tilu ni awọn ololufẹ ikọ Al Nassr FC fi ki Musa kaabọ lẹyin to darapọ mọ wọn.
Ohun ti a gbọ ni pe, EFCC mu Mompha pada lọjọ Ẹti to kọja nigba to lọ si ọfiisi ajọ naa to wa ni Ikoyi niluu Eko lati gba aago ọwọ rẹ marun un, ẹrọ ibanisọrọ rẹ, iPhone 8 ati awo rẹ kan, ti ajọ naa gba lọwọ rẹ.
Nígbà wo ni n óo tó jí?
Ewe, alaga ipade ohun ni igbakeji aare Naijiria omoye Yemi Osinbajo, beesini igbakeji aare je eni akoko ti o soro ninu ipade naa, ti o si yanayana bi idagbasoke yoo se ba eto oro aje ile yii.
Ẹ kíyèsára kí ẹ má ṣàì bìkítà fún ẹni tí ń sọ ọ̀rọ̀ yìí, nítorí pé nígbà tí àwọn tí wọ́n ṣàì bìkítà fún Ọlọrun nígbà tí ó rán Mose ní iṣẹ́ sí ayé kò bọ́ lọ́wọ́ ìyà, báwo ni àwa ṣe le bọ́ bí a bá ṣàì bìkítà fún ẹni tí ó ń sọ̀rọ̀ láti ọ̀run.
 Awon toro kan yoo mo eyi ti won fe mulo ati eyi ti won fe yo kuro tabi satunse si bi o ti ye.
Àwọn iṣẹ́ náà nìwọ̀nyí: Òpó meji, àwọn ọpọ́n meji tí wọ́n dàbí abọ́ tí wọ́n wà lórí àwọn òpó náà, nǹkankan tí ó dàbí ẹ̀wọ̀n tí wọ́n fi dárà sára àwọn ọpọ́n tí ó wà lórí òpó náà, 
Oríṣun àwòrán, Nigeria Police Àkọlé àwòrán, Kọmiṣọna ọlọọpaa ti kede pe wọn n wa Inspẹkitọ Dania Ojo Bi iroyin ọrọ naa ṣe kan kakakiri ni awọn ọmọ Naijiria ti fi ẹhọnu wọn han lori ẹrọ ayelujara.
Nigba to n ba BBC Yoruba sọrọ, Olusola Oke, tii se agbẹjọro Babatunde salaye pe, igun olujẹjọ ti sọ saaju lasiko igbẹjọ to kọja pe, awọn ti kọwe ẹbẹ pe ki wọn gbe ẹjọ naa lọ sile ẹjọ giga ipinlẹ naa, idi si ree ti wọn ko fi gbe olujẹjọ wa sile ẹjọ lọjọru.
Joṣua gbéra ní òwúrọ̀ kutukutu, ó kó gbogbo àwọn ọmọ Israẹli wá ní ẹ̀yà kọ̀ọ̀kan, wọ́n bá mú ẹ̀yà Juda.
Ṣugbọn ní àkókò ìdánwò, yóo pèsè ọ̀nà àbáyọ, yóo sì mú kí ẹ lè fara dà á.
Ìwádìí tú àṣírí Dókítà tó pa ìyàwó rẹ̀, ó fẹ́ pa ọmọ wọn méjì, òun fúnrarẹ̀ tún pokùnso Ìjọba àpapọ̀ ti kéde ìsúnsíwájú ọjọ́ ìforúkọsílẹ̀ nọ́mbà NIN Ààrẹ Buhari: Kò ní sí lilọ bibọ ni Eko,Ogun ati Abuja fọjọ́ mẹ́rìnlá gbako Labẹ ikede ilana tuntun yi ti alaga igbimọ to n mojuto kikoju arun Covid-19 ni Naijiria Boss Mustapha sọ, gbogbo ile ounjẹ, ile igbafẹ ni wọn ni ko wa ni titi pa.
Ṣugbọn ẹni tí ó ń ṣe àgbèrè ń ṣẹ̀ sí ara òun tìkararẹ̀.
Ninu ọrọ tirẹ, Ọgbẹni Bankọle Bernad, Aarẹ Ẹgbẹ awọn Ile-iṣẹ to to nii ṣe pẹlu irinajo lọ si ilẹ okeere fi mulẹ pe dipo ki wọn maa ṣe atunṣe iṣẹ ti ile-iṣẹ ijoba fun Ọrọ Irinajo-afẹ, Aṣa ati Iṣe yii nipasẹ iru ajọ bayii, ki wọn da ile-iṣẹ kan silẹ ti wọn yoo kan forukọ rẹ silẹ labẹ ijọba ti yoo maa ṣe iru iṣẹ bayii.
Àrùn burúkú kan yóo kọlu ìwọ pàápàá, àrùn inú ni, yóo pọ̀, yóo sì pẹ́ lára rẹ títí tí ìfun rẹ yóo fi bẹ̀rẹ̀ sí tú jáde.
Ẹnu ya àwọn Juu, wọ́n ń sọ pé, “Báwo ni eléyìí ti ṣe mọ ìwé tó báyìí nígbà tí kò lọ sí ilé-ìwé?
Àwọn ọmọ Josẹfu ní ìdílé-ìdílé nìwọ̀nyí: Manase ati Efuraimu.
E̩nì kò̩ò̩kan ló ní è̩tó̩ láti dá ohun ìní ara rè̩ ní tàbí láti ní in papò̩ pè̩lú àwo̩n mìíràn.
Alaiṣootọ ni yóo fara gba ìyà tí ó tọ́ sí olóòótọ́ inú.
Kí ẹ máa gbọ́ràn sí àwọn aṣiwaju yín lẹ́nu, kí ẹ máa tẹ̀lé ìlànà wọn.
Ni ṣe ni Roys Akhimie bu ẹnu àtẹ lu gomina, tó sì sọ pé ìpèsè tó yẹ kí ìjọba ṣe fún àwọn èèyàn ìlú ló jẹ oun logun.
Agbenusọ fun ile iṣẹ ọlọpaa, Femi Joseph to ba BBC Yoruba sọrọ ni irọlẹ ana ni isẹlẹ naa waye ati wi pe awọn adigunjale ti maa n ṣọṣẹ ni agbegbe Ọba-Akoko to wa lọna Ọwọ si Akungba-Akoko.
Minisita ohun so pe”Akitiyan, aforiji, ise akinkanju, awon imoran lorisirisi oloogbe Baba Sala kopa ti ko se yesile ninu aseyori tile ise ere ori amohunmaworan se, ti o si tun mu igberu ba eto oro aje orile-ede Naijiria nipase mimu adinku ba awon ti ko ri ise, ”Alhaji Mohammed wa gbadura pe, Olorun yoo te oloogbe naa safefe rere, yoo si tun de awon ebi ati ara re ninu.
Oríṣun àwòrán, Olowu Idowu Henry Ṣugbọn igbakeji gomina naa fidi rẹ mulẹ fun BBC Yoruba pe ọrọ ko ri bẹ nitori ohun ko tii ri iwe kankan gba.
Wo àfiwé owó oṣù Ọlọ́pàá Nàìjíríà pẹ̀lú akẹgbẹ́ wọn lókè òkun Buhari, Makinde, Sanwo-Olu kẹ́dùn pẹ̀lú ẹbí Tola Oyediran, àkọ́bí lóbìnrin tí Obafemi Awolowo bí tó papòdà Báwo ni Donald Trump ṣè ń rí ọwọ́ mú sí nínú àkójọ èrò àwọn olùdìbò?
Ègbè Bàntẹ́ Bàntẹ́  Ó di gbì ikú dé Ègbè Bàntẹ́.
fi anfaani yii kẹdun pẹlu awon ẹgbẹ olootu akoroyin , ijoba ipinle Kano ati ẹbi
Lẹyin iṣẹlẹ naa ni awọn eeyan tu si igboro ti wọn si bẹrẹ si n dana sun awọn agọ ọlọpaa, ile ijọba ati dukia ilu.
'Mo máa tó dìde lórí àìsàn', Muyiwa Ademola sọ̀rọ̀ látorí àkéte àìsàn rẹ̀ Kóo tó gbàlejò láti UK, South Africa, wo àwọn kọ̀ndísọ̀n tí ikọ̀ PTF fi lélẹ̀ Àwọn Tíṣà Oyo kó owó tó wà fún àkóso iléèwé jẹ, ni wọ́n fi ń fọwọ́ kọ ìdánwò pẹ̀lú ṣọ́ọ̀kì - Seyi Makinde Wo àwòrán bí ọdún Keresimesi ṣe ń lọ káàkiri àgbàyé Ṣé òótọ́ ni àwọn ará Amẹ́ríkà máa ń hán an lọ́wọ́ kan tí wọ́n bá gbọ́ ọ̀rọ̀ ìbálòpọ̀?
Wahala bẹ́ sílẹ̀ nílùú Àbúja lọ́jọ́ ajé láàárín àwọn ọlọ́pàá àti àwọn ọmọ ìjọ ẹ̀sìn Shi'ite.
Ṣugbọn a já ọ lulẹ̀ sinu isà òkú, sí ìsàlẹ̀ ọ̀gbun.
Ìdí lèyí tí wọ́n fi npe òkúta yìí ní Ìgbésẹ̀ Robin Hood.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Orisabunmi: Èyí ni àlàyé lórí àsìkò ìkẹyìn olóògbé Orisabunmi àti ohun tó paá gan láti ẹnu Baba Ijesa 6 Sẹ́rẹ́ 2021 Oríṣun àwòrán, Instagram/themakingstv Kii ṣe iroyin mọ bayii pe gbajugbaja oṣere tiata ati sinima Yoruba, Iyaafin Fọlakẹ Arẹmu ti ọpọlọpọ eeyan mọ si Oriṣabunmi ti jade laye, amọṣa ohun ti o n ṣe ọpọlọpọ eeyan, paapaajulọ awọn ololufẹ wọn ni kayefi ni irufẹ iku to pa wọn.
Lọjọ Eti ni wọn ri oku rẹ niyara alejo nile itura kan ni France lasiko to n ṣiṣẹ lori ounjẹ kan fun CNN.
 kaa siwaju si ni ede gees>.
 paapaa julo aare Muhammadu Buhari ninu
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ọwọ́ ọlọ́pàá ti tẹ àwọn ọmọbìrin méjì tó pa b[pabá wọn 7 Ẹrẹ̀nà 2019 Oríṣun àwòrán, Pinellas County Sheriff's Office Àkọlé àwòrán, Linda Roberts ati Mary-Beth Tomaselli ti akisa aṣọ bọọ lẹnu ti wọn si fi ọwọ bo imu ati ẹnu rẹ ki o to wa ku Ọlọpaa ti mu awọn obinrin agbalagba meji to jẹ ẹgbọn ati aburo kan ni ni Florida ni orilẹede Amerika ti wọn fi ẹsun kan wipe wọn pa baba wọn to jẹ ẹni ọdun marundinlaadọrun nigba to ku ni ọdun 2015.
Ẹ̀yin ẹrú, ẹ máa gbọ́ ti àwọn tí wọ́n jẹ́ oluwa yín nípa ti ara, pẹlu ọ̀wọ̀ ati ìbẹ̀rù, pẹlu ọkàn kan gẹ́gẹ́ bí ẹni pé Kristi ni ẹ̀ ń ṣe é fún.
Ta ni ẹni náà ní òde ayé yìí, yálà dúdú, yálà funfun tí ó lé wí pe Bísọ́bù Phillips bá òun lo Yorùbá?
" Àwọn àkóràn kòkòrò tí ó maa ń fàá ni streptococci àti "" staphylococcus aureus "" ."
je ohun amusagbara fun idagbasoke orile-ede Naijriia Nigeria’s diversity will
”Wọ́n bàjẹ́, ohun ìríra ni wọ́n ń ṣe,kò sì sí ẹnìkan ninu wọn tí ń ṣe rere.
Inú bí OLUWA sí Amasaya gan-an, ó sì rán wolii kan sí i kí ó sọ fún un pé, “Kí ló dé tí o fi ń bọ àwọn oriṣa tí kò lè gba àwọn eniyan rẹ̀ lọ́wọ́ rẹ?
Eyi si lo mu ko maa kọminu pe ki lo de ti wọn gba owo oun ni papakọ ofurufu nilu Eko, ti wọn si fun oun ni iwe lati lọ se ayẹwo arun Coronavirus ni adugbo Lekki?
Ajọ EFCC tun sọ loju opo ayelujara Twitter rẹ pe Onidajọ Banjoko tun sọ pe Nyame jẹbi ẹsun pe o lu jibiti miliọnu marundinlaadọsan Naira (165m).
Oniruuru ipo ni Obasanjo ti di mu gẹgẹ bi ọgagun to si ti kopa ninu ọpọlọpọ eto to ni ṣe pẹlu ijagun nile ati lẹyin odi.
Ninu ifọrọwanilẹnuwo pẹlu ileeṣẹ iroyin kan ni ilu Eko ni Allwell ti ṣalaye pe ko si ohun to buru ninu pe oun n ṣe ayẹyẹ ọjọ ibi ọdun marundinlogoji lọdọọdun.
Nígbà tí Samuẹli kú, gbogbo àwọn ọmọ Israẹli kó ara wọn jọ láti ṣọ̀fọ̀ rẹ̀.
''Awọn Gomina ko lẹtọ si owo yii.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ẹ̀mí sòfò nínú ìjàǹbá ọkọ̀ ní Ìlasamàjà ‘Kò tọ́ s'Ọbásanjọ́ láti tọ́ka sí oníjẹkújẹ’ ‘Jí foonu ọkọ rẹ̀ wò, kóo fi ẹ̀wọ̀n jura’ Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Ìgbà tí ó dé, ó bu omi òkun bọ̀, wọ́n lo omi yìí, bàbá wọn sì ríran.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, What causes coronavirus: Akeugbagold sọ àṣírí ohun ti àrùn coronavirus ń dá lárá f Bakan naa ni ẹgbẹ awọn alaga ijọba ibilẹ, ALGON ni ipinlẹ Ọyọ pẹlu sọrọ ti wọn si woye pe, loju tawọn o, oloogbe Kẹhinde Ayọọla nikan lawọn ri gẹgẹ bii ọlọpọlọ pipe ti awọn ri tọkasi ni iṣejọba gomina Seyi Makinde.
Ìwé èsì àyẹ̀wò arùn Covid-19 lè di kòṣeémàní fáwọn tí o bá fẹ́ rìnrìn àjò sí ilẹ̀ òkèèrè Ni bayi ti awọn ọmọ Naijiria n reti ilana ti wọn yoo tẹle ti wọn ba fẹ rinrin ajo ọkọ ofurufu lọ silẹ okeere lẹnu ijọba, a ni ki a fi to yin leti ohun ti awọn ileeṣẹ ọkọ ofurufu kan ni ẹ gbọdọ ṣe.
Nítorí OLUWA ti sọ pé,gbogbo ilẹ̀ náà yóo di ahoro;sibẹ òpin kò ní tíì dé.
Ẹ wo ohun ti Judith la kọja ninu fidio yii ati bi o ṣe ri padadi iya aburo.
Àwọn ẹṣin rẹ̀ yára ju àṣá lọ.
A padà san owó ìtanràn fáwọn ajínigbé kí wọ́n to fi àwọn mẹ́tẹ̀ẹ̀ta sílẹ̀- Ẹbí Spaghetti, mílíìkì, Chivita àti Àǹkàrá sọ Rabiu dèrò ẹ̀wọn ni Eko Wọn wa rọ gbogbo awọn olugbe ilu Akurẹ lati tẹle aṣẹ yii.
Sibẹsibẹ, o wí pé, o mọ̀ mí o sì mọ orúkọ mi, ati pé mo ti rí ojurere rẹ.
Ọlọrun bá a sọ̀rọ̀ lójú ìran lóru, ó pè é, ó ní, “Jakọbu, Jakọbu.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Douye Diri: Ìgbìmọ̀ olùgbẹ́jọ́ ẹ̀hónú ìbò yẹ àga mọ́ Gómìnà Bayelsa nídìí 17 Ògún 2020 Oríṣun àwòrán, Others Ile ẹjọ to n gbọ ẹhonu ibo gomina nipinlẹ bayelsa ti wọgile ibo to gbe Gomina Douye Diri ati igbakeji rẹ, Lawrence Ewhrudjakpo wọle.
Idi niyii ti ọmọ eeyan fi ma n ṣe iyọnu awọn ajẹ, ki wọn o ma ba a da wọn laamu mọ.
Ile iṣẹ iroyin Naijiria ni Hawkins ni iku awọn ikoko yii le din ku ni 2020 ti onikaluku ba risi eto ilera alaboyun lẹgbẹ rẹ.
Ni ile iṣẹ Ọlopaa jẹ ko di mimọ pe iku wọn ko wa latọwọ ẹran kankan ti wọn pa fun jijẹ awọn eniyan bi ko ṣe iṣẹ ọwọ awọn ẹni ibi to fẹ da omi alafia ilu ru ni.
" Awọn Ọjọgbọn lorisirisi ti pejọ si fasiti Afe Babalola nilu Ado Ekiti lati ṣe ẹkunrẹrẹ iwadii lori awọn ewe ati egbo to le wo awọn aisan asekupani bíi Coronavirus, awọka, aromọleegun, arun jẹjẹrẹ ati bẹẹ bẹẹ lọ, ti wọn yoo si jẹ kijọba apapọ ati ajọ Nafdac mọ nipa bi awọn oogun ibilẹ naa yoo ti wulo si ati ipese wọn.
Joṣua jálù wọ́n lójijì, lẹ́yìn tí ó ti fi gbogbo òru rìn láti Giligali.
Tí a fiṣọwọ́ ní 5:16 10 Ọ̀pẹ̀ 20205:16 10 Ọ̀pẹ̀ 2020 ‘Sim Card’ títà àti ìforúkọsílẹ̀ rẹ̀ dèèwọ̀ ní Nàíjíríà - NCC Awọn aṣofin lo n beere pe ki lode ti ikọ Boko Haram atawọn janduku mii n fi ẹrọ ibanisọrọ ṣe iṣẹ aburu, ti ijọba ko si ri wọn mu?
“Ẹ̀yin eniyan, kí ló dé tí ẹ fi ń ṣe irú eléyìí?
Amọ, awọn onimọ sayẹnsi ti sọ pe o ṣe pataki fawọn ọmọ ilẹ Afirika naa lati kopa ninu didan abẹrẹ naa wo.
Arsenal ṣẹ́ṣó ìyà, búlálà ẹlẹ́nu mẹ́ta ni Leicester City fi lù wọ́n lálù bami Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ìbejì Àyànbìnrin tó ti ń di gbajúgbajà Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Afénifẹ́re: Oníkálukú ni yóò tẹ̀ka síbi tó wù ú tó bá yá 1 Èbibi 2018 Oríṣun àwòrán, YOUTUBE Àkọlé àwòrán, Odumakin àti Adebanjo: Àwọn Ọba kàn ń sọ tẹnu wọn ni o Ẹgbẹ Afénifẹ́re ṣe lòdì sí ọ̀rọ̀ àwọn Ọba ilẹ Yoruba kan.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Border closure: Ẹ wo iye t'óúnjẹ dà báyìí lọ́jà lẹ́yìn tí ìjọba ti ibodè 28 Bélú 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Niṣe lawọn ọmọ Naijiria n pariwo lori ọwọn gogo ounjẹ nitori ibode ori ilẹ ti ijọba apapọ ti pa lati oṣu kẹjọ.
Onidajọ ile ẹjọ giga naa, Samira Bature si ti dajọ pe ki Sẹnets Abbo san miliọnu lọna aadọta Naira fun arabinrin Warnate, lati fi tu u ninu.
Titi di akoko ti a ko iroyin yii jọ tii ṣe ọjọ ikẹtala, oṣu ikeje, ọdun 2019, Wole Soyinka ti pe ẹni ọdun marunlelọgọrin (85) ti gbogbo agbaye si n ṣe ayẹsi rẹ.
Ẹ kò gbọdọ̀ ṣiṣẹ́ rárá, ìlànà ni ó jẹ́ títí lae fún ìrandíran yín, ní gbogbo ibùgbé yín.
Èmi yìí sì ni olórí àwọn ẹlẹ́ṣẹ̀.
Àwọn ìlú náà ni: Gibeoni, Kefira, Beeroti ati Kiriati Jearimu.
”O ni ijọba aare Muhammadu Buhari ko ni “ maa wo iru igbese aibofinmu ti ajo eleto aabo gbe yii niran.
Ẹ̀kùn omi Katsina: Omi gbé òpó àti ọmọ mẹ́ta lọ
 Àwọn onímọ ̀ bíi abímbọ ́ lá , turner àti watkins ti ṣe áláyè pé àwọn ẹni tí wọ ́ n kó lọ orílẹ ̀ èdè  cuba ' , "" brazil ' àti america ' , wà níbẹ ̀ lónìí tí wọn ń gbé èdè àti àsà yorùbá lárugẹ ."
Ọjọ kẹtalelogun, oṣu Kẹjọ, ọdun 2015, lo kọkọ yan Kyari si ipo olori oṣiṣẹ, to si tun pada yan-an nigba to wọle saa keji.
Ọrọ gba ọna mi yọ nigba ti ọmọbinrin olori ẹgbẹ Shiite, Ibrahim El-Zakzaky to wa ni ahamọ sọ pe, ẹgbẹ awọn ko kede lati dawọ duro lori iwọde ti ẹgbẹ́ shiite n se.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ogun Assembly: Wọ́n ti ni kí àwọn alága ìjọba ìbílẹ̀ Ogun lọ rọọ́kún nílé 1 Òkùdu 2019 Àkọlé àwòrán, Irọ ló pa, a ti da awọn ti o yan sipo pada nitori ko tọna Awọn ọmọ ilé igbimọ Aṣofin ipinlẹ Ogun ti wọgile gbogbo iyansipo ti Gomina Amosun ṣe ko to fipo silẹ.
Igbakeji gomina Eko sọrọ nipa obinrin
Jesu wá kìlọ̀ fún wọn kí wọn má sọ fún ẹnikẹ́ni.
Gbajugbaja osere, Yomi Fabiyi ti kesi akẹgbẹ rẹ, Toyin Abraham wi pe ki wọn pari ija to wa laarin awọn mejeeji.
Wolii Aroye Jesu kọ ni oludasilẹ ijọ o ṣugbọn nigba ti oludasil ijọ papoda, wọn lọ ba baba kan niluu.
Wọn dóòlà ẹ̀mí ọ̀pọ̀ èrò níbi ìṣẹlẹ̀ ilẹ̀ rírì erékúṣù Lombok
Oludasilẹ ileeṣẹ Yemkem International, Akintunde Iṣhola Ayeni to ba BBC Yoruba sọrọ ṣalaye pe awọn ti fi ewe ati egbo tọju awọn alaarun covid-19 kan ti wọn si ti gbadun.
Ki ni ileeṣẹ iroyin Daily Trust sọ Akọroyin naa sọ pe Fani Kayode mu ileri rẹ ṣẹ ti o si pe awọn ọga ohun nileeṣẹ iroyin rẹ.
Jedaaya ọmọ Harumafi ló ṣe àtúnṣe abala tí ó tẹ̀lé tiwọn, ó tún apá ibi tí ó kọjú sí ilé rẹ̀ ṣe.
‘Won yoo ma lo imọ ekọ ti wọn gba ni ile iwe ti wọn lọ, lati fi ṣiṣẹ.
 Àáró , ìgbẹ ́ ọdún dídẹ , ìsingbà tàbí oko olówó , gbàmí-o-ràmí àti Èésú tàbí Èsúsú jẹ ́ ọ ̀ nà ìràn-ara-ẹni-lọ ́ wọ ́ .
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Vibrator -Ǹkan ìṣeré ìbálòpọ̀ mi ńpaná iṣẹ́ mọ́ mi lára' Alexandra Jones BBC Three 4 Bélú 2018 Oríṣun àwòrán, Eve Lloyd Knight Àkọlé àwòrán, Ǹkan ìṣeré ìbálòpọ̀ ti gbòde kan Ọmọ ọdún mọ́kànlélógún ni Leanne nígbà tó kọ́kọ́ ra ǹkan ìṣeré ìbálòpọ̀ rẹ̀ àkọ́kọ́.
Ṣe ara rẹ yẹ fún ìgbé-ayé eniyan Ọlọrun.
nasir ol molk mosque ( persian : مسجد نصیر الملک - masjed e nasir ol molk ) , tí wọ ́ n tún mọ ̀ sí mọ ́ ṣáláṣí aláwọ ̀ pupa fẹ ́ ẹ ́ rẹ ́ , jẹ ́ mọ ́ ṣáláṣí ìbílẹ ̀ ní shiraz , iran .
Kì í ṣe bẹ́ẹ̀ nìkan, ṣugbọn à ń yọ̀ ninu Ọlọrun nítorí ohun tí ó ṣe nípa Oluwa wa Jesu Kristi, ẹni tí ó sọ wá di ọ̀rẹ́ Ọlọrun ní àkókò yìí.
Nítorí tírà wà ní òkè àjà iyààrá mi, onírúurú ni gbogbo wọn, ọ̀sanyìn olohun kẹ́lẹ́kẹ́lẹ́ wà láàrin àwọn ṣìgìdì, àdó àti atọ́ kò gba òògùn mi mọ́, mo kó ogunlọ́gọ̀ sínú ìkòkò iyààrá mi – àwọn nǹkan wọ̀nyí ti pé sí mi lọ́dọ́ kí ọjọ́ lílọ wa tó pé.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Lai Mohammed: Kò sí ohun tó burú nínú kí ìjọba yá owọ láti fi ṣe àwọn ohun amáyédẹrùn 25 Bélú 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 16 Ògún 2020 Oríṣun àwòrán, Getty Images Minisita fun eto iroyin ati aṣa, Lai Mohammed ti sọ pe, ko si ohun to buru ninu ki ijọba ya owo lati fi ṣe awọn ohun amayedẹrun saarin ilu.
Nígbà tí ó lé wọn bá, ó wí fún wọn bí Josẹfu ti kọ́ ọ.
Ileeṣẹ amohunmaworan agbegbe Maiduguri ṣalaye pe bi wọn ṣe n pada bọ lati ibi isinku ni wọn ti kagbako awọn alakatakiti ẹsin Islam, Boko Haram.
Àmọ́ bó ti nítumọ̀ ìjìnlẹ̀ náà ló ni ti eréfèé.
Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Ronke Odusanya sọ̀rọ̀ lórí ìròyìn tó ní ó ti jẹ bàbá ọmọ rẹ̀, Jago run9 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Eniola Badmus kilọ fun awọn to n bu pe o ti sanra ju lati dẹyin lẹyin oun.
" Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Governorship Election Results: Seyi Makinde sọ ọ̀rọ̀ àkọ́sọ lẹ́yin èsì ìbò Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Johnson ti sọrọ akin lẹyin to jawe olubori tan, o ni laisi ani-ani, oun ṣetan lati mu ilẹ Gẹẹsi kuro ninu ninu ajọ EU loṣu to n bọ.
Johanu gbọ́ ninu ẹ̀wọ̀n nípa iṣẹ́ tí Jesu ń ṣe.
Ẹ gbé àpótí OLUWA lé orí kẹ̀kẹ́ ẹrù náà.
Ní àyájọ́ ọjọ́ òmìnira ti ọdún yìí, àwọn ọmọ orílẹ̀-èdè Mauritania fi ọkàn sí yíyàn tí a yan ẹgbẹ́ agbábọ́ọ̀lù orílẹ̀-èdè wọn sí àṣekágbá ìdíje Ife-ẹ̀yẹ ti àwọn orílẹ̀-èdè Ilẹ̀-Adúláwọ̀ (CAF) ju bí wọ́n ṣe ṣe sí àwọn ẹni ìgbàgbé, “àwọn ológun tí wọ́n wà nínú kòtò àìmọ̀… tí wọ́n ṣì ń dúró de ìsìnkú tí ó yẹni“, Kaaw Elimane Bilbassi Toure tí í ṣe olóòtú ibùdó ìròyìn orí ayélujára Le Flambeau ti Mauritania kọ.
Ó níláti yipada kúrò ninu ìwà burúkú,kí ó máa hu ìwà rere.
 o je kan ninu awon orile-ede agbaye to ni opolopo eya eniyan ati asapupo , eyi je nitori ikoreokere lati opo awon orile-ede .
Ewe, ninu iwe abadofin kan, ti egbe naa tesita lasiko ipade won ti o waye niluu Asaba, nipinle Delta.
O óo pa ìdílé oluwa rẹ, Ahabu ọba rẹ́, kí n lè gbẹ̀san lára Jesebẹli fún àwọn wolii mi ati àwọn iranṣẹ mi tí ó pa.
OLUWA, má fi ibinu bá mi wí;má sì fi ìrúnú jẹ mí níyà.
Láìsí igbagbọ eniyan kò lè ṣe ohun tí ó wu Ọlọrun.
Ṣé ẹ̀ṣẹ̀ kékeré ni o pe ẹ̀ṣẹ̀ àgbèrè ẹ̀sìn rẹ, 
Nígbà tí ó bá jáde,yóo máa rò mí kiri.
Ó wá ku obinrin yìí nìkan níbi tí ó dúró sí.
Buhari gb'alejo ife ẹyẹ agbaye FIFA nilu Abuja
Oríṣun àwòrán, Twitter/@RealAARahman Ọjọ́ ti pẹ́ tí Abddulraman ti dá ilé iṣe alágbàta epo ọkọ̀, First Fuels Limited sílẹ̀, ilé iṣé náà jẹ́ gbajúmọ̀ lórí ọrọ̀ epo ọkọ̀ ní gúúsù iwò oòrùn Nàìjíríà, tó jẹ́ ilẹ̀ Yorùbá.
” Ó bá sọ fún Joṣua pé, “Wò ó!
''Ma a bẹ awọn ọmọ ẹgbẹ lati da ọrọ Rasheed nu, nitori ko si otitọ kankan to sọ pẹlu ọrọ kubakugbe to sọ si ẹgbẹ FIBAN.
Aladesewa sọ pe ọwọ tẹ ọ̀kan ninu wọn nigba to n gbiyanju lati na papa bora kuro nibi iṣẹlẹ idigunjale kan, lẹyin naa lo mu awọn ẹgbẹ OPC lọ ibi kọlọfin wọn.
Wo ohun tó ṣelẹ̀ ní àgbáyé lọ́sẹ̀ tó kọjá Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Ó wá ń bá ọ̀rọ̀ rẹ̀ lọ títí ó fi di àfẹ̀mọ́júmọ́.
Yatọ si ami ẹyẹ fun odu agbabọọlu lọkunrin ati lobinrin, bakanna ni wọn tun se eto amiẹyẹ fun awọn eekan agbabọọlu lorilẹede Naijiria ti wọn ti fẹyin eleyi ti wọn pe ni 'Legends XI' Awọn agbabọọlfẹyinti ti anfani amiẹyẹ yii bọ si lọwọ ni, Anne Chiejine to jẹ asọle fu ikọ agbabọọlu obinrin orilẹede Naijiria, Super falcons nigbakanri, Augustin Eguavoen, Chirstian Chukwu, Uche Okechukwu, Felix Owolabi, Austin Okocha, Kanu Nwankwo to jẹ balogun fun ikọ agbabọọlu akọkọ ni ilẹ Afirika ti yoo gba ami ẹyẹ goolu ni idije bọọlu olympics pẹlu Dream team lọdun 1996 lorilẹede Amẹrika.
O ni ipade gbogbogboo ti won
Agbẹnusọ fun gomina Seyi Makinde, Ọgbẹni Taiwo Adisa ṣalaye fun BBC News Yoruba pe gomina ipinlẹ Ọyọ naa kii se dokita, ko si ni ifarahan awọn aisan to maa n ba arun coronavirus wa, nitorinaa ko lee ni ogun kankan to lo fun arun naa.
Ibeere ti ọpọ wa n beere ni pe, ṣebi ẹbun owo ni wọn fun Laycon, o ṣe tun wa di ogun oni owo ori sisan.
Onírúurú ikú ni yóò pa gbogbo àwọn olùgbée 20,000 Yau Ma Tei.
Rape: Bàbà ọmọ ọdún márùndínlọ́gọ́rin kó HIV ran ọmọ ọdún mẹ́rìnlá lẹ́yìn tó fi ipá báa lò
Àkókò mi kò ì tíì tó.
Kì í sá ṣe àwọn tí wọn ń sọ èdè mìíràn tí ó ṣòro gbọ́, ni mo rán ọ sí, àwọn ọmọ ilé Israẹli ni.
Aare Buhari wa kilo fun awon to n da wahala ija laarin awon agbe ati adaran sile ni apa ibikan lorile ede yii, pe owo ofin ko ni pe ba won.
igbimo naa, o tun wa seleri pe awon yoo se ojuse wọn bo se tọ ati bo se yẹ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Cairo: Ilé oúnjẹ fáwọn Yorùbá ní Cairo, Egypt Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Cairo: Ilé oúnjẹ fáwọn Yorùbá ní Cairo, Egypt 25 Agẹmo 2019 Lẹ́yin ti ikọ agbabọọlu Naijiria, Super Eagles ṣe aṣeyọri ti wọn gba lara awọn ami ẹyẹ bọ wale lati idije AFCON 2019 to waye lorilẹede Egypt, awọn nkan apawo wọle mii ṣi wa tawọn ọmọ Naijiria ń gbe ṣe lorilẹede naa.
SERAP ní ìjà ṣẹ̀ṣẹ̀ bẹ̀rẹ̀ ni lórí owó tí àwọn olóṣèlú ń bù fúnra wọn Kí ló dé tí ìjọba Èkìtì ń fí àwọn òṣìṣẹ́ ṣé ''helo-helo testing?"
Bakan naa ni gbajugbaja oṣere tiata, Ọmọtọla Jalade Ẹkẹinde naa sọ tirẹ si iroyin naa eleyii to ti ni iṣoro to n koju awọn to foju wina iṣẹlẹ ifipabanilopọ ni ọna ati fi idi ẹsun wọn mulẹ.
Jesu dáhùn pé, “Ẹ kò mọ ohun tí ẹ̀ ń bèèrè.
Àwọn ibudó ìdìbò ẹdẹ́gbẹ̀ta àtí mọ́rùndílógójì tó ti wà ni ìpińll Ondo láti ẹyìn wá ti fi hàn pé, PDP àti APC yóò jọ jàdu ìbò ní ìjọba ìbílẹ̀ yiìí ni.
Fadele: Dán an wò, lóbí ìyá ọ̀kẹ́rẹ́ ni a fi ọ̀rọ̀ ọ̀kadà náà ṣe
Bí wọ́n ti gbọ́ ọ̀rọ̀ yìí, Jesu nìkan ni wọ́n rí.
Ituah ní láti ǹkan bí wákàtí díẹ̀ sẹyìn, gbogbo ǹkan lo daru papọ.
Ekinni dàbí kinniun, ekeji dàbí akọ mààlúù, ojú ẹkẹta jọ ti eniyan, ẹkẹrin sì dàbí idì tí ó ń fò.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Ipinlẹ yi pẹlu Melbourne yoo kọkọ gba awọn ọsóọrọmọde lati wọle lẹyin naa lawọn to kere si wọn yoo bẹrẹ ẹkọ pada ni ọjọ kẹsan an, osu Kẹfa.
Èmi àti Sanyeri ti tọrọ oúnjẹ jẹ rí nílé oninawo torí ebi, ká tó di gbajumọ oṣere Ọ̀rẹ́ wa ni Lawrence jẹ́, àmọ́ ó gbẹ̀yìn dẹ́nu ìfẹ́ kọ abúrò wa - Joshua àti Damilola Bamiloye Mi ò to iṣẹ́ Regina Daniels rárá kí n tó fẹ́ ẹ láàrin ọ̀sẹ̀ mẹ́ta, mo sì tún le fẹ́ ìyàwó míì - Ned Nwoko Wo àwọn oúnjẹ márùn ún tó ń mú kí àtọ̀ ọkùnrin dára síi O ni amọ, o pada ye oun pe ko ni i bojumu ki obi mejeeji o ma a ṣe iṣẹ ti yoo ma gba akoko wọn.
Sugbọn ko ti i f'ojuhan boya West ti forukọ silẹ lati gbegba ibo, tabi boya o kan n fi ọrọ naa ṣawada ni.
Kí àwọn ọmọ Israẹli lè mọ̀ nípa ogun jíjà, pataki jùlọ, ìṣọ̀wọ́ àwọn tí wọn kò mọ̀ nípa ogun jíjà tẹ́lẹ̀.
Bàbá wa pàápàá kị̀ í bá wa ṣeré tó ti àbúrò rẹ̀ yìí.
Olówó-ayé kọjú si ọna rẹ̀, ó ń lọ, òun àti Ọlọ́run Ọba, nígbà tí ó si kù díẹ̀ kí ó la aginjù Ìdákẹ́rọ́rọ́ já ó de ibi odò kékeré kan ti ó ń ṣàn, tí ó ń dán, tí ó si tutù nini, ibẹ̀ ni bàbá mi sì dúró tí ó bu omi si ara, lẹ́hìn èyìínì ó jẹ ọ̀gẹ̀dẹ̀ pupa, ó mú obì nínú àpò ó da a sí ẹnu, ọkàn re sì balẹ̀ bí ọkàn ẹni tí ó jẹ pọ́n-ùn méjì ní gbèsè, tí Olódùmarè bò ní àṣírí, tí àǹfààní pọ́nun mẹ́wàá wọlé wá bá a.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Oluwo: Yóò nira fún ìjọba láti sanwó oṣù tí kò bá sí àtúntò 24 Ẹrẹ̀nà 2019 Oríṣun àwòrán, @ObaEmperortelu Oluwo ti ilu Iwo nipinlẹ Ọsun, Ọba Abdulrasheed Akanbi ti ke gbajare sita pe ti atunse ko ba ba isẹ ọba nipinlẹ naa, yoo nira fun ijọba lati san owo osu awọn osisẹ to kere julọ, ti i se ẹgbẹrun lọna ọgbọn naira.
Ṣugbọn bí wọn tí ń lọ, n óo da àwọ̀n lé wọn lórí, n óo mú wọn bí ẹyẹ ojú ọ̀run; n óo sì jẹ wọ́n níyà fún ìwà burúkú wọn.
Ó ní kí wọ́n kí i báyìí pé, “Alaafia fún ọ, ati fún ilé rẹ ati fún gbogbo ohun tí o ní.
kí o lè mọ òtítọ́ àwọn nǹkan tí wọ́n kọ́ ọ.
Pasito Ezekiel so pe“Pe orile ede Naijiria si wa ni okan, o ye ki a maa dupe lowo Olorun’’.
Mohammed Adoke Ọjọ kejidinlọgbọn oṣu Kejila ọdun 2015 ni ajọ EFCC fi iwe pe Mohammed Bello Adoke lori ẹsun magomago epo Malabu ti owo rẹ le ni biliọnu mẹfa naira.
Ìròyìn fihàn pé ó ti sẹlẹ̀ lẹ́ẹ̀mẹfà níbẹ̀rẹ̀ ọdún 2018.
" Oríṣun àwòrán, AFP Àkọlé àwòrán, Ọlọpa ni ko si ẹni lee sọ boya ọrọ ẹsin lo sokunfa wahala naa Biotilẹ jẹ wi pe awọn kan ti ọrọ naa soju wọn sọ fun BBC pe wahala bẹ silẹ nigba ti ọmọbirin ẹya Gwari kan yi ẹsin pada lati Kristẹni si Musulumi nitori ọrekunrin rẹ.
Alukoro ọlọpaa Gambo Isah tofi ọrọ yi sita ni ohun ko mọ ibi ti awọn akọroyin kan ti ri iroyin pe ohun sọ pe ọwọ ti tẹ awọn afurasi naa.
Papa iṣere Oworo Sports Centre ni a ti ṣe alabapade re e nibi ti oun ati awọn ajẹsẹ miran ti n gbaradi.
Akiṣi sì dáhùn pé, “Nítòótọ́ ni, mo mọ̀ pé o jẹ́ ẹni rere bí angẹli OLUWA, ṣugbọn àwọn olórí ogun ti sọ pé, o kò lè bá wa lọ sójú ogun.
Mo dupẹ pe o jẹ ọrẹ mi tootọ lasiko yii ati titi aye."
Láti ìgbà náà lọ, àwọn ọmọ Israẹli óo mọ̀ pé èmi ni OLUWA Ọlọrun wọn.
Ẹran tí ó ń jí gbé yìí wà lára ohun tí ó jẹ́ kí àwọn ènìyàn fura sí Ọ̀sanyìnnínbí pé òun ló jí owó Orímóògùnjẹ́ gbé níbi tí ó tí ń tọ́jú rẹ̀ nígbà tí ó ń ṣe àìsàn.
Sọ fún igbó ibẹ̀ pé èmi OLUWA Ọlọrun ní n óo sọ iná sí i, yóo sì jó gbogbo àwọn igi inú rẹ̀, ati tútù ati gbígbẹ, iná náà kò ní kú.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Akomolede ati asa Yoruba: Ẹ wá kọ́ nípa àpòtí ìṣura èdè wa lórí BBC Yorùbá Oriṣi ẹya litireṣọ Yoruba to wa ati ọna ti koowa n gba jẹyọ ni alagba Lawanson Olumuyiwa kọ wa ninu ti oke yii.
Lẹ́yìn náà ni àwọn ará Tekoa ṣe àtúnṣe apá ibi tí ó kọjú sí ilé ìṣọ́ tí ó yọgun jáde títí dé Ofeli.
" wages , salary , hire , pay , stipend , an animal which is also called "" ewújù , ' hedgehog , bush pig ."
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Háà, ó ṣe!
Eléyìí tún fún àwọn afọ́jú ní ànfàní àti kẹ́kọ̀ọ́ gboyè, tàbí láti ka ìwé ẹ̀sìn wọn bíi Bíbélì àbí Àlùkùránì.
Jakọbu bá súnmọ́ Isaaki baba rẹ̀, baba rẹ̀ fọwọ́ pa á lára, ó wí pé, “Ọwọ́ Esau ni ọwọ́ yìí, ṣugbọn ohùn Jakọbu ni ohùn yìí.
Nàìjíríà ní ìgboyà láti kojú ilẹ̀ South Africa - Foluṣọ Philips Àbọ̀ mi rèé láti orílẹ́èdè South Africa- Ààrẹ Muhammadu Buhari Nítorí ìkọlù àjòjì ní South Africa, èèyàn 5000 ló padánù iṣẹ́ wọn ní Nàìjíríà Òògùn olóró tí àwọn ọmọ Naijiria ń tà ló fa ìkọlù - South Africa Lẹyin ọjọ mẹta ti wọn ti n ṣe igbẹjọ naa ni ileẹjọ ni o jẹbi yinyin ibọn lu ọmọ Naijiria naa lẹyin ti ọlọpaa naa ja ọmọ Naijiria lole.
“N óo pa yín run, ẹ̀yin ọmọ Israẹli; ta ni yóo ràn yín lọ́wọ́?
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, BBC Yorùbá: Temidayọ Ọlọfinsawo ní kò rọrùn láti darí òṣìṣẹ́ ọlọ́pọlọ pípé Bode Thomas jẹ omiran ẹda, ẹni to ga, to si ṣigbọnlẹ bẹẹ, eyi to mu ki wọn fun ni orukọ inagijẹ 'Buldozer', bẹẹ si ni kii faaye gba ijakulẹ, to si maa n wa aseyọri ninu gbogbo ohun to ba dawọle Ile ẹkọ girama CMS ti Samuel Ajayi Crowther da silẹ ni Bode Thomas lọ, to si bẹrẹ isẹ lọgan to pari iwe mẹwaa rẹ bii akọwe nileesẹ Reluwe ilẹ wa Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ọja Arena Oshodi ni àwọn èèyàn ti ń r'aja Nigba to di ọdun 1939, ni Bode Thomas morile ilu London lati lọ kọ ẹkọ nipa imọ ofin, to si di agbẹjọro, to si di ojulowo lọya lọdun 1942, ko to pada wale lati wa da ileesẹ agbẹjọro tiẹ silẹ nilu Eko Bode Thomas, Frederick Rotimi William ati Remilekun Fani Kayode ni wọn dijọ da ileesẹ naa silẹ, ti wọn pe ni Thomas, Williams and Kayode law firm Ọdun 1946 ni Bode Thomas di agbẹjọro fun ẹgbẹ Ọmọ Oduduwa, to si tun jẹ ọkan lara awọn eeyan to da ẹgbẹ oselu Ọlọpẹ, taa mọ si ẹgbẹ Awolowo, Action Group silẹ O ṣójú mí kóró bí wọ́n ṣé fí àdó olóró pa Dele Giwa lọdún 1986- Soyinka Pius Adesanmi ní kò bá rọ́pò Wole Soyinka tí kò bá kú - ọmọ Naijiríà Soyinka: Ọ̀pọ̀ ìgbà ni ayédèrú ìròyìn ti pa mí Wole Soyinka rèé láti kékeré Ọdun 1949 ni Bode Thomas gba oye Balogun Oyo, eyi to lo lati fa oju awọn Ọba, ijoye ati eeyan jankan-jankan wa sinu ẹgbẹ oselu Ọlọpẹ, ti ero oun ati Oloye Obafemi Awolowo si saAba maa n yatọ lasiko ti wọn ba n jiroro ninu ẹgbẹ.
N óo gba àwọn aguntan mi lẹ́nu yín, ẹ kò sì ní rí wọn pa jẹ mọ́.
Bí ó ti ń mú un bọ̀, ẹ̀mí èṣù yìí bá gbé e ṣánlẹ̀, wárápá bá mú un.
Eeyan ire gbaa ni to si jẹ olufọkansin ilu.
Nígbà tí èmi Daniẹli rí ìran náà, bí mo ti bẹ̀rẹ̀ sí wá ọ̀nà láti mọ ìtumọ̀ rẹ̀, ni ẹnìkan bá yọ níwájú mi tí ó dàbí eniyan.
Aisha Buhari - BBC News Yorùbá BBC News, YorùbáFò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Hanan Buhari wedding: 'Cartoon' tí Bulama yà nípa ìgbéyàwó ọmọ mi kò bójúmu tó - Aisha Buhari 5 Owewe 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 8 Owewe 2020 Oríṣun àwòrán, Aisha Buhari Iyawo Aarẹ Naijiria, Aisha Buhari ti sọ pe katun ti gbajugbaja ayaworan, Mustapha Bulama ya, eyii to ṣafihan igbeyawo ọmọ rẹ, Hanan Buhari ti awọn ọmọ Naijiria si n ri sinu odo ko bojumu to.
Àpótí ẹ̀rí OLUWA náà wà níbẹ̀ fún oṣù mẹta, OLUWA sì bukun Obedi Edomu ati ìdílé rẹ̀.
Lọjọ Abamẹta Minisita feto ilera wọn kede pe eeyan 10,107 tuntun lo ko arun naa ti awọn to si ti gba tọwọ Covid-19 ku jẹ 8,153 Èèyàn 462 míràn tún lùgbàdì àrùn COVID-19 ní Nàìjíríà l'ọjọ́ Ẹtì Lọjọ ọdun Ileya,niṣe ni adinku ba iye awọn eeyan to lugbadi arun Covid 19 ni Naijiria.
Ẹlomiran ninu awọn ti wọn mu, Mohammed Ibrahim ni tiẹ sọ pe oun wa silu Eko lati ṣiṣẹ lẹyin t'oun ti ṣiṣẹ oko dida tan.
Agbenusoro ile igbimo ohun, ogbeni Titus Uba lo soro naa di mimo lasiko ijiroro awon omo ile igbimo asofin ohun ti o waye lojo isegun(Tuesday).
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Trump:Ẹ forijinmi lori atuntẹ twita mi 26 Sẹ́rẹ́ 2018 Oríṣun àwòrán, Donald Trump/Twitter Àkọlé àwòrán, Ẹ ma binu gbe mo se atuntẹ aworan naa Aarẹ ilẹ Amẹrika, Donald Trump ti tọrọ aforijin fun igba akọkọ lori bo se se atuntẹ fọnran aworan kan tawọn igun kan nilẹ Gẹẹsi gbe sori opo Twitter, eyi to n safihan iwa ipa awọn ẹlẹsin Islam, ti wọn se afihan rẹ lori tẹlifisan ITV nilẹ Gẹẹsi lọjọ ẹti.
Arsene Wenger nlọ lé Arsenal ja bi ẹlẹṣẹ - Wenger Mourinho tún fẹ́ bá Wenger pàdé l'ọ́jọ́ iwájú Mourinho sọ ninu fidio naa wipe, ọpọlọpọ oun lo ṣẹlẹ nigba yẹn lọun.
olódodo ni yóo wọ aṣọ tí ó bá kó jọ,àwọn aláìṣẹ̀ ni yóo pín fadaka rẹ̀.
Frank Mba to jẹ agbẹnusọ fawọn agbofinro lo fi lede pe awọn akọṣẹmọṣẹ ni ileeṣẹ ọlọpaa ti da si ilẹ iran Yoruba lati mu awọn ika eniyan yii.
Wá fi ẹnu kò mí lẹ́nu,nítorí ìfẹ́ rẹ dára ju ọtí waini lọ.
Ababọ ẹjọ ti wọn pe ni pe, ile ẹjọ giga Abuja dajọ are fun ọga ọlọpaa, Adamu ṣugbọn PSC faake kọri, ti wọn si gba ile ẹjọ kotẹmilọrun.
Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí EndSARS Ogbomosho: Gómìnà Makinde f'òkò kan pẹyẹ méjì nílé àwọn tó kàgbákò ìwọ́de EndSARS àti ààfin Soun13 Ọ̀wàrà 2020 10:43 Fídíò, Wole Soyinka sọ ìdí tó fi ni òun a fi màálù Fulani ṣe súyà fáwọn èèyàn abúlé, Duration 10,4323 Owewe 2020 Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí 2 sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
Ẹ gbọdọ̀ máa ṣe ohun tí ó tọ́, ati ohun tí ó yẹ lójú OLUWA; kí ó lè dára fun yín, kí ẹ lè lọ gba ilẹ̀ dáradára tí OLUWA ti búra láti fún àwọn baba yín, 
" Kẹmi Afọlabi to gbadura naa ni Kabbah, nibi ti adura ti maa n gba, wa se ladura pe Ọlọrun yoo gbọ adura awọn ololufẹ oun.
naa, ipade naa tun  fenuko pe: *Ile igbinmo asofin agba gbodo gbe igbese lori owo ti
Ireti ọpọ ni pe, igbesẹ naa yoo tete mu ki alaafia waye lori ọrọ naa; amọṣa ọrọ ko fẹ jọ bẹẹ bayii, kaka ki ewe agbọn aawọ ọhun si dẹ, ko ko ko lo n le si.
Irúfẹ́ àkiyèsí àti ìwádìí yí ni àwọn onímọ̀ ẹ̀dà-èdè ń pe gẹ̀ẹ́sì rè ní “duality” tàbí “double articulation” ìwádìí fihàn pé àwọn ẹyẹ àti ẹranko tí wọ́n ní ìró èdè kò pò, iye èdè tí òkọ̀ọ̀kan ní kò pọ̀ pẹ̀lú.
Wike ti PDP ló borí ìdìbò sípò gómìnà Rivers Ilé ẹjọ́ kòtẹ́milọ́rùn yá lórí ọ̀rọ̀ Adeleke- PDP Kíni ìlànà tí o dé yíyọ adájọ ilé ẹjọ kánkan ní Nàìjíríà?
Àbí, kí ní ń fa gbogbo àríyànjiyàn yìí?
Nitori naa lo ṣe pọn dandan lati beere oun ti Chelsea n fẹ gan.
O sọ pe, Mi o wo agogo nigbati mo gba ipe wipe ọja wa n jona ti mo si yara jade wa si ọja."
O ni lati igba iwaṣẹ ni Magun ti wa, ti awọn agba fi n ṣe iṣọra fun awon iyawo wọn, paapaa julọ, ti wọn ba ti n fura pe iru obinrin bẹẹ n rin awọn irin ti ko tọna.
” Aare Muhammadu Buhari wa ro awon ti yoo kopa nibi idanilekoo olojo meta naa lati fenuko lori ohun ti yoo ran ijoba apapo lowo nipa imo ero igbalode.
Iroyin taa gbọ ni wipe apapọ ikọ amuṣẹya alaabo ni agbegbe Ogere nipinlẹ naa lọjọ Iṣẹgun ọsẹ.
Akinwumi Adesina bọ́ lọ́wọ́ ẹ̀ṣùn jẹgúdújẹrá tí wọ́n fi kan - AFDB Iwadii tuntun ti Banki Idagbasoke ilẹ Afrika, AFDB gbe kalẹ ti ni adari Banki naa, Akinwunmi Adesina ko jẹbi ẹsun jẹgudujẹra ti wọn fi kan an.
Oba Olajide Olayode: Ó pe ọlọ́pàá láti yanjú aáwọ̀ ìlú lórí owó orí, bílísì bá dé
Messi ló gb'àmì ẹ̀yẹ Ballon D'or lóòtọ́ọ́, àmọ́ Ronaldo ló dára jùlọ (GOAT)- Mendes N kò mọ̀ pé ojú mi ṣì lè là mọ́ lọ́wọ́ ìgbájú- Boluwatifẹ FUTA Ìya lọ ṣọ́ọ̀ṣì, ló bá pàdánù ọmọ!
Saulu dá a lóhùn, ó ní, “Inú ẹ̀yà Bẹnjamini tí ó kéré jù ninu àwọn ẹ̀yà Israẹli ni mo ti wá, ati pé ìdílé baba mi ni ó rẹ̀yìn jùlọ ninu ẹ̀yà Bẹnjamini.
Kí làwọn nǹkan tó lè rán ọkùnrin sí ọ̀run alákeji lásìkò ìbálòpọ̀ pẹ̀lú obìnrin?
waye ni osu kárùn ún  .
Awon agbaboolu ti o tun gba oniruuru ami-eye miran ni: Rasheedat Ajibade, agbaboolu obinrin AITEO-NFF ti o darajulo “Player of the Year (Women)’’, Ikouwon Udoh, ami-eye agbaboolu ti o kere julo Young Player of the Year (Women)’’.
Janduku ji apoti ibo gbe ni Kwara Bí àtúndì ìbò ṣé ń lọ lọ́wọ́ ní ìpínlẹ̀ Kwara, ìròyìn tó ń dé sí etí ìgbọ́ BBC Yorùbá ní, àwọn jandùkú ti jí àpótí ìdìbò gbé ní ibùdó ìdìbò Olupodo ní wọ́ọ̀dù 1 Omù-Aran àti Federal Girls College Omu-Aran Woodu 2, sùgbọn àwọn ọlọ́ọpàá ti ríi gbà padà.
iroyin to lee da wahala sile laarin ilu kan si ikeji, ni eyi ti o le e mu ki awọn
Awọn mẹtẹẹta ni ẹnikeje, ikẹjọ ati ẹni ksan-an ti wọn le kuro lori eto ori tẹlifisan ọhun.
Ó ti tó ọdún mẹ́ta tí ó ti rí Akìn mọ.
50k) si naira meji (N2:00k), ti afikun aadọta kọbọ (50k) si gun owo oúnjẹ naa.
Ọmọ mi, jẹ oyin, nítorí pé ó dùn,oyin tí a fún láti inú afárá a sì máa dùn lẹ́nu.
Ó dá wa láre nípa oore-ọ̀fẹ́ kan náà, tí a fi ní ìrètí láti di ajogún ìyè ainipẹkun.
Àwọn alufaa tí wọ́n yàn láti máa fọn fèrè níwájú Àpótí Majẹmu Ọlọrun ni: Ṣebanaya, Joṣafati, Netaneli, Amasa, Sakaraya, Bẹnaya, ati Elieseri.
Ninu ọrọ rẹ, Ọgbẹni Abolarinwa gba awọn ọmọ Naijiria ni imọran lori igbesẹ ti wọn le gbe ki wọn maa baa fara kaasa ti rogbodiyan ba bẹ ṣẹlẹ.
Bẹẹ, o ti pẹ ti awọn agbesunmọmi alakatakiti ẹsin Islam boko haram ti n da ẹmi awọn eniyan legbodo.
Àwọn eniyan óo máa gbé ilẹ̀ wọn láìléwu, wọn óo sì mọ̀ pé èmi ni OLUWA nígbà tí mo bá ṣẹ́ ọ̀pá àjàgà wọn, tí mo bá sì gbà wọ́n lọ́wọ́ àwọn tí ó kó wọn lẹ́rú.
Nígbà ayé Ahasi, ọmọ Jotamu, ọmọ Usaya, ọba Juda, Resini Ọba Siria ati Peka ọmọ Remalaya, ọba Israẹli wá gbé ogun ti Jerusalẹmu, ṣugbọn wọn kò lè ṣẹgun rẹ̀.
Gẹ́gẹ́ bi àtẹ́jáde àjọ tó n gbógun ti àjàkálẹ̀ ààrùn ni Nàìjíríà (NCDC) ṣe fi síta lójú òpó twitter rẹ̀, ìpínlẹ̀ ìpínlẹ̀ Eko, Abuja àti Kaduna lo l;e ténté tábìlì.
Ṣugbọn ibinu Ọlọrun ti dé sórí wọn.
O tun fi kun un pe isinmi itọmọ ti ijọba n fun awọn obinrin to loyun tabi to n tọju ọmọ yoo kuro ni oṣu mẹrin si mẹfa fun awọn to n jẹ oṣiṣẹ ijọba ipinlẹ.
"Ẹni náà ni ọkùnrin tó gbé fóònù sọ pé ó lé ni ènìyàn ẹgbẹ̀run mẹ́rin tó ti wà nílẹ̀ láti inú oṣù kẹ̀ta, o ní wọ́n sọ pé tí òn bá le dúro àwọn yóò fi ìpè ránṣk ti àsìkò bá ti tó, sùgban ti kò bá le dúro àwọn lé wá ṣe fun nílé, sùgbọ́n yóò san ẹgbẹ̀rún lọ́nà ààdọ́ta náírà.
 Àwọn kan tún ń sọ tongan àti tokelau.
Naijiria ti fun ile-ise eto idajo lagbara lati tako iwa ipalara si omo orile
Láìpẹ́ kò sí ẹni tí yóo gbà pé oriṣa wa tóbi mọ́, oriṣa tí gbogbo Esia ati gbogbo àgbáyé ń sìn!
Fausat; ogbeni Kosoko Hakeem Adeyemi; dokita Balogun Sherifat Bolajoko; ogbeni Adeniji
Nígbà tí ó dé ọ̀dọ̀ Solomoni, ó sọ gbogbo ohun tí ó wà lọ́kàn rẹ̀ patapata fún un.
Ipòkípò tí ẹ bá wà lórí ilẹ̀ ayé mo fẹ́ kí ẹ gbé ìwà ìrẹ̀lẹ̀ wọ̀ bí ẹ̀wù.
Eyi lo mu ki BBC News Yoruba o ṣe akojọpọ awọn koko mẹta ti agba oṣelu naa mẹnu le.
Ọpọ lo pin fidio naa lori ayelujara ati Instagram.
Wọ́n ti yọ Donald Trump nípò gẹ́gẹ́ bí ààrẹ orílẹ̀-èdè Amẹ́ríkà ṣùgbọ́n ọ̀rọ̀ kò tíì tán síbẹ̀.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù BB Naija: Kí ló pa Elisha Abbo, Leycon àti Naira Marley pọ̀, tí àríyá yóò fi wáyé?
Àkọlé àwòrán, Ero pọ to ti jade lati wa yan oludije APC nipinlẹ Ọyọ nibiti oludije meje ti n dije Adebayọ Adelabu jẹ ọkan lara awọn ọmọọmọ gbaju-gbaja oloṣelu niluu Ibadan, Adegoke Adelabu, ti gbogbo eniyan mọ si Pẹnkẹlẹmẹẹsi.
Àkọlé àwòrán, Òní ní ìṣìnkú ìyálódé Ibadan Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 3 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 5 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
 Oríṣun àwòrán, Getty Images José Arnaiz Diaz lo kọkọ sọ bọọlu sinu awọn Barcelona lẹyin iṣeju marundinlogun ti ifẹsẹwọnsẹ naa bẹrẹ, ṣugbọn Messi da pada ni abala keji ifẹsẹwọnsẹ ọhun."
Fagunwa ló kọ́ Ògbójú Ọdẹ nínú Igbó Irúnmọlẹ̀, tí gbogbo àgbáyé mọ̀ ní ìwé kíkà àkọ́kọ́ ní èdè Yorùbá tó sì tún jẹ́ ọ̀kan lára àwọn ìwé tí kọ́kọ́ kọ l'édè ìbílẹ̀ Áfíríkà.
Oríṣun àwòrán, @RealAARahman Àkọlé àwòrán, Abdurrahman Abdurazaq to n du ipo Gomina ni Kwara wa lara awọn agbatẹru O to gẹ Bi wọn ba ti ṣe n lọgun oto gẹẹ, bẹ ni awọn oludibo lọmọde ati lagba yoo ma dahun pe ''Lilọ lẹ lọ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Slave Trade: Olórí ilé aṣòfin Amẹrika lọ Ghana láti bẹ ilé wò fún ayẹyẹ irinwó ọdún òwò ẹrú 31 Agẹmo 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 1 Ògún 2019 Oríṣun àwòrán, @hallaboutafrica Lọdun 1619, ọkọ oju omi kan fidi kalẹ si ibudo kan to jẹ ti ilẹ Gẹẹsi, eyi ti wọn n pa ni Virginia, to wa lorilẹede Amẹrika bayii, to si ko ogun ọmọ ilẹ adulawọ sinu rẹ.
 egbe yii ni omo-egbe milionu 72 ti o ti foruko sile ni odun 2004 .
Ọmọbìnrin ọdún 25 gún ọ̀rẹ́kùnrin rẹ̀ pa nítorí ó ní ko lọ ṣẹ́ oyún Isiaka Busari, Mighty Joe tó jẹ́ adigunjalè tó rọ́pò Ọyenusi lẹ́yìn tí wọ́n pa á Ọwọ́ ọlọ́pàá tẹ àwọn olè tó kó góòlù àti ẹgbẹ̀lẹ́gbẹ̀ mílíọ̀nù lọ nílé MKO Abiola l'Eko Ìjọba Nàìjíríà ti kéde pé kí ilé ìtura ṣí padà, kí ìlé ìwé máa palẹ̀mọ́ ìwọlé àwọn akẹ́kọ̀ọ́ Akinyele: Ilé ẹjọ́ fi Sunday Shodipe, afurasí ìṣekúpani l'Akinyele pamọ́ sí ọgbà ẹ̀wọ̀n Adajọ Majisireeti naa wa sun itẹsiwaju igbẹjọ naa si ọjọ kẹrindinlọgbọn, oṣu kẹwaa, ọdun 2020.
Òkúta kekeke ni wọn má n lẹ mọ àwọn opo mẹta tí wọn fí ṣe àpèjúwe Asetani.
3 368695 Orilẹede Bugaria 5405 76.
Ninu ifọrọjomitoro ọ̀rọ̀ kan pẹlu rẹ nigba aye rẹ eleyii ti aṣewadii ijinlẹ kan ninu imọ Litiresọ ilẹ Afirika, Karin Barber ṣe, awọn ohun iyalnu ni iru iṣẹ́ ti oloogbe yii ti ṣe silẹ ko to lọ.
Àwọn ohun ẹlẹ́mìí gbogbo gbo tí wọn kì í jáde lọ́sàn-án ni wọ́n jáde wá wòran, nítorí òkété j;ade, a sì rí òwìwí, bẹ́ẹ̀ ni àdán bá àwọn ẹyẹ wá.
Lọ́jọ́ Ẹtì ni Joshua tó ti gba bẹ́líìtì ẹ̀yẹ WBA,IBF ati WBO, gba àmì ẹyẹ nàá ní ìsọ̀rí àmì ẹ̀yẹ OBE, èyí tí wọ́n n pè ní Order of British Empire.
Ìwọ tí o pa oluwa rẹ!
O ni ọrọ naa jẹ eleyi to da lori ẹrọ ibaraẹnisọrọ - ọrọ ti ko lẹjabakan ninu.
Lọjọ iṣẹgun ti ọga ọlọpaa lorilẹede Naijiria Ibrahim Idris fẹyinti lẹnu iṣẹ ọba ni Muhammed gun ori ipo naa.
Nigeria 2019 election: 'Torí ǹkan tí mo fẹ́ ni mo ṣe máa dìbò'
Wọn yóo máa fi owó ra oko, wọn yóo máa ṣe ìwé ilẹ̀, wọn yóo máa fi òǹtẹ̀ tẹ̀ ẹ́; wọn yóo máa fi èdìdì dì í, àwọn ẹlẹ́rìí yóo sì máa fi ọwọ́ sí i, bẹ́ẹ̀ ni yóo máa rí ní ilẹ̀ Bẹnjamini.
ṣalaye pe atunṣe ti wọn n gbero lati ṣe naa yoo mu igberu ba ibaṣepọ to
Ariwo ta lórí ìtàkùn ayélujára ní ọjọ́ ajé, nípa ọ̀jọ̀gbọ́n Richard Akindele, ti ẹ̀ka ìmọ̀ nípa ìṣirò owó tí wọ́n ní, o ń bèèrè fún ìbálòpọ̀ ìgbà máàrún ọ̀tọ̀ọ̀tọ̀ lọ́wọ́ ọ̀kan lára àwọn akẹ́kọ́bìnrin tó fìdírẹmi nínú ìmọ̀ ẹ̀kọ́ kan tí ọ̀jọ̀gbọ́n náà ń kọ́.
Oríṣun àwòrán, Topealabi Bi ẹ o ba gbagbe, owurọ ọjọ aiku ọjọ kẹrinla oṣu kẹfa ni oloogbe Ibidun Ighodalo ku ninu yara rẹ nile igbafẹ kan ni ilu PortHarcourt latari ikọlu inu ọkan gẹgẹ bi wọn ṣe sọ ọ.
Ijoba ipinel Kaduna ti yi isinde, konle –gbele pada ni awon agbegbe ati ileto to wa ni ipinle Kaduna, leyi ti alaafia ti pada si ipinle naa.
Ẹ máa ṣàkíyèsí àwọn ìlànà mi, kí ẹ sì máa tẹ̀lé wọn.
 tọ ́ pẹ ́ Àlàbí lépa ẹ ̀ kọ ́ rẹ ̀ pẹ ̀ lú ìmọ ̀ sílàra àti ìfọkànsìn tí ẹ ̀ kọ ́ gbà .
Awọn ọlọpa mu afunrasi janduku merinlelaadota n'ipinlẹ Ọyọ
Àwọn ẹran tí wọ́n bá ya pátákò ẹsẹ̀, àwọn tí ẹsẹ̀ wọ́n là ati àwọn tí wọn ń jẹ àpọ̀jẹ.
" Nibi agbo ijo naa, se ni ipese abbo to peye wa, iwọnba awọn ọkunrin ti wọn si gba laaye lo wa ja awọn obinrin silẹ, ni kete ti wọn ba si se bẹẹ tan ni wọn yoo jade kuro nibẹ.
Gómìnà márùn ún tó fojú winá ìbínú bàbá ìsàlẹ̀ wọ̀n Àwọn ohun tuntun tí a mọ̀ nípa ìgbẹ́jọ́ Wòlíì Sotitobire Ṣé lóòtọ́ ni Sẹ́netọ̀ Bayo Osinowo ní ìfura ikú ara rẹ̀?
Àwọn òwe mìíràn tí Solomoni pa,tí àwọn òṣìṣẹ́ Hesekaya ọba Juda kọ sílẹ̀ nìwọ̀nyí.
Ẹnu mi yóo ròyìn iṣẹ́ rẹ tọ̀sán-tòru,nítorí a ti ṣẹgun àwọn tí ó fẹ́ pa mí lára,a sì ti dójú tì wọ́n.
Lẹ́yin ìwádìí iléesẹ́ BBC pẹ̀lú àjọṣepọ̀ Anas Arameyaw Anas, akọ̀ròyìn ọmọ Ghana kan, nijọba Ghana ṣe ìkéde tuntun.
Ọjọ kẹfa, oṣu Kẹrin, to jẹ ọjọ maarun ṣaaju ki awọn ologun to gbajọba ni awọn to n fi ẹhonu han ti wa niwaju olu ileeṣẹ ologun.
Ìlànà Ìkẹyìn tí Mose fún Wọn.
 “Lara awon to peju sivi ipade
A fẹ́ lo ẹ̀jẹ̀ àwọn èèyàn tó ye àrùn Coronavirus láti fi ṣe ìwòsàn fún àwọn tó wà lórí àárẹ- UK Ọlọ́run ló kọọ pé àwọn ọmọ mi yóò ṣiṣẹ tíátà, èmi kọ lo kàn-án nípa fún wọn - Ọga Bello Àwọn Òṣèré tíátà tó jogún isẹ lọ́wọ́ òbí wọn: Adelaja Ogunde: Oríṣun àwòrán, Adelaja ogunde Adelaja, tíi ṣe àgbà osere tíátà lọ jẹ ọmọ bibi oludasilẹ ère tíátà ni èdè Yorùbá, Herbert Adedeji Ogunde.
7 Kíyèsíi, èmi ńba ọ sọ̀rọ̀, àti bákannáà sí gbogbo àwọn tí wọ́n fẹ́ láti mú iṣẹ́ yìí jade wá àti láti ṣe àgbékalẹ̀ rẹ̀.
Nítorí náà, ẹ bẹ̀rù OLUWA, kí ẹ sì ṣọ́ra pẹlu àwọn nǹkan tí ẹ ó máa ṣe, nítorí pé OLUWA Ọlọrun wa kì í yí ìdájọ́ po, kì í ṣe ojuṣaaju, bẹ́ẹ̀ ni kì í sì í gba àbẹ̀tẹ́lẹ̀.
Jeremy Hunt ni òun gbà pé Boris Johnson á ṣiṣẹ́ dáadáa Ìtàn tó rọ̀ mọ́ òwe Ẹni tí kò ṣe bíi aláàárù l‘Oyingbo."
OLUWA wí pé, “Ọ̀kan ni gbogbo àwọn eniyan wọnyi, èdè kan ṣoṣo ni wọ́n sì ń sọ, wọ́n ṣẹ̀ṣẹ̀ bẹ̀rẹ̀ àwọn ohun tí wọn yóo ṣe ni, kò sì ní sí ohun kan tí wọn bá dáwọ́lé láti ṣe tí yóo dẹtì fún wọn.
N óo dojú kọ àwọn tí ń ṣe ségesège n óo jẹ wọ́n níyà.
pe  ẹsin wa , ede wa ati ẹya wa yatọ si
OLUWA Ọlọrun yín yóo rán agbọ́n sí wọn títí tí gbogbo àwọn tí wọ́n bá farapamọ́ fun yín yóo fi parun.
Nàìjíríà ló wà nípò kẹfà nínú ewu ikú àìtọ́jọ́ l'ágbàáyé nítorí nkan mímú tó ní ṣúgà
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ǹkan tí ẹ̀mí mímọ́ fi hàn mí kí n tó bẹ̀rẹ̀ orin ìfèdèfọ̀ rèé- Testimony Jaga O ni ijọba Buhari ko fi panpẹ ofin mu Sowore nitori o jẹ akọroyin, ṣugbọn nitori pe o gbe igbesẹ lati doju ijọba bolẹ.
Siwaju si, bi o se je pe Messi ko ni kopa ninu ifigagbaga ‘Clasico, bakan naa ni ko ni kopa ninu ifesewonse idije UEFA Champions League pelu iko agbaboolu Inter Milan ti yoo waye lojoRu(Wednesday).
Ẹ kọ wọ́n sí ara òpó ìlẹ̀kùn ilé yín, ati sí ara ẹnu ọ̀nà ìta ilé yín.
Amọ alẹ ọjọ naa ni Eniola kede loju opo Twitter ati Instagram rẹ pe ko si ohun to se ohun, saka ni ara oun da.
ti gba lati jọ maa samulo  eto iwe  asẹ fun isẹ akanse kan naa ni gbogbo awọn
O jẹ asiko idunnu fun un pẹlu bi o ba boju wo iye ọdun to ti fi ṣe laalaa ati gbogbo iṣoro to ti la kọja lati de ipo yii.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Akomolede ati Aṣa lori BBC:Wo ìrúfẹ́ ìgbeyàwó méje tó wà nílẹ̀ Yorùbá àti ojúṣe Alárinà Fasọla ni o bani ninujẹ pe owo ko si nita lasiko yii, ati pe ninu iwọnba ti ijọba n gbiyanju lati satunṣe si naa ni awọn kọlọransi kan tun n bajẹ.
Ewe, Titi Camara ati El Hadji
27 Òkùdu 2020 Oríṣun àwòrán, MTN Àkọlé àwòrán, Ire déé!
Aare Buhari soro ohun di mimo lasiko ipade apero olojo meta ti akori re da lori awon omo ogun olote ‘Boko Haram’ ohun, eleyi ti egbe kan to n ri si oro awon musulumi lati ile-iwe giga fafiti Bayero, nipinle Kano se agbekale lojo isegun(Tuesday).
Nkan iyalẹnu to wa nibẹ ni pe o darapọ mọ àwọn to n ṣe idanwo WAEC lọwọ lọwọ lati ṣe idanwo, lati le mu afojusun rẹ ṣẹ.
Ṣùgbọ́n, ó mà ṣe o, ìgbà tí àwọn oníṣègùn pàtàkì wọ̀n-ọnnì bá jí, tí wọ́n ronú tí wọn rí ìdí àìsàn yìí, wọn kò níí mọ̀ pé iṣẹ́ ọwọ́ Ẹlẹ́dàá àwọn ni.
    Lẹ́yìn èyí, obìnrin náà bèèrè bí mo ti ní ìyàwó mo sì wí fún un pé n kòì tìí ní, àti pé nǹkan bẹ́ẹ̀ kò tilẹ̀ tíì sí lọ́kàn mi, ohun tí ó lékè ẹ̀mí mi kò ju pe ki ń ṣe asáájú àwọn ènìyàn mi de Òkè Ìrònú ti ń bẹ nínú Igbó Elẹ́gbẹ́je.
Ọba yìí bá fi ọgbọ́n àrékérekè bá orílẹ̀-èdè wa lò.
Nítorí mo ti tẹ Juda bí ọrun mi,mo sì ti fi Efuraimu ṣe ọfà rẹ̀.
O tun lọ fasiti Dakar ati ti Parus, nibi to ti gboye nipa imọ ẹkọ International Relation, bẹẹ lo tun kẹkọọ gboye keji ninu imọ History.
New Zealand mosques: Ẹmi 49 ló tí bá ìṣẹlẹ̀ iyìnbọn Christchurch lọ
Oríṣun àwòrán, Facebook/Olubadan of Ibadan Balogun sọ di mimọ pe, awọn eeyan kan ni wọn n ti Olubadan lati ṣe ọpọ ohun to n ṣe, kii ṣe wi pe Olubadan fun ra rẹ gan lo n daa ṣe awọn ohun to n ṣe.
Okiki kan kari aye pe ojojo n se ogun Baba Suwe, ara ogun ko le, ti awọn ẹlẹyinju aanu si dide iranwọ lati doola ẹmi rẹ lọwọ iku ojiji.
ile-ise naa ba mu ni papa-n-dodo lati gba owo ti o kere si ogbon egberun.
Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Fídíò, Soyinka Cancer: Àṣe ara mi ni iso ti n run gbogbo bí mo ṣe n ṣèrànwọ́ lórí jẹjẹrẹ27 Bélú 2019 Professor Wole Soyinka láti kékeré13 Agẹmo 2020 Wole Soyinka: Pańpẹ́ ọba lọ̀nà àbáyọ sí ìwà ìbàjẹ́15 Èbibi 2018 Fídíò, Wọle Soyinka: Ti mo ba dara pọ m'ẹgbẹ Obasanjọ, wọn gbọdọ yẹ mi lọpọlọ wo19 Èrèlè 2018 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Ti wọn ba ni lo eleyii maa lo, ti wọn ba ni lo tọhun, ti wọn ba Ti mo ba fẹ fun ọmọ lọyan ti ọyan yẹn ko ba sẹ, o maa n su mi, igba mi maa sọkun, ara eeyan ko ni balẹ gẹgẹ bii abiyamọ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Coronavirus: Ǹjẹ́ adìyẹ Broiler ni ǹkan tó ń tan àìsàn COVID-19 kálẹ̀?
O ni eyi tako ominira to yẹ ko wa ati pe o dabi igba ti eeyan ba fẹ fipa gba nkan lọwọ ẹlomii ni.
Ekiti Election: Fayẹmi bá BBC sọ̀rọ̀ gẹ́gẹ́ bíi gómìnà tí Ekiti yàn
Ati wi pe kii ṣe ẹ̀rù lo mu ki oun ṣọ pe oun ko jẹbi ẹsun naa, ati pe ki ẹnikẹni to ba ni ẹri pe oun ba wọn kopa ninu rẹ jáde wa sọ.
Arabinrin naa sọ pe yoo wu oun ki awọn ọmọ oun naa di dokita ti wọn ba dagba.
Baldness: Àwọn tí irun wọ́n ti gbá rìfáàsì sọ ìrírí wọn àti àǹfàní tí wọ́n ń jẹ
Oríṣun àwòrán, Facebook/The Alaafin of Oyo Ọmọ ọba ni Lamidi Atanda, baba rẹ si ni Alaafin Adeniran Adeyemi, koda, ọmọ ọmọ ọba tun ni pẹlu nitori baba to bi baba rẹ, Alaafin Alowolodu Adeyemi naa jẹ Alaafin.
Alhaja Wuraola Asake Kola Daisi dagbere faye leni odun merindinlaadorun un.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Islamic State' ní Nàìjíríà bẹ́ àwọn Kristiẹni lórí ní ìpínlẹ̀ Bornu 27 Ọ̀pẹ̀̀ 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 28 Ọ̀pẹ̀̀ 2019 Oríṣun àwòrán, AFP Àkọlé àwòrán, Eto aabo to peye ti jẹ ipenija nla fun orilẹede Naijiria Ààrẹ Muhammadu Buhari ti rọ awọn ọm Naijria pe ki wọn ma ṣe jẹ ki awọn agbesunmọmi pin orilẹede niya lọna ti ẹsin.
tí inú rẹ̀ yóo yọ́, tí yóo sì gbàgbé ohun tí o ti ṣe sí i, n óo wá ranṣẹ pè ọ́ pada nígbà náà.
Dájúdájú púpọ̀ nínú yín ni kò mọ̀ mi tẹ́lẹ̀ rí, bí n kò bá sì níi purọ́, ẹ̀yin náà ṣàjèjì sí mi.
nígbà tí ìmọ́lẹ̀ rẹ̀ ń tàn sí mi lórí,tí mo kọjá ninu òkùnkùn pẹlu ìmọ́lẹ̀ rẹ̀;
Bákan náà ni ó ṣe èso pomegiranate ní ìlà meji, ó fi wọ́n yí iṣẹ́ ọnà àwọ̀n náà po, ó sì fi dárà sí ọpọ́n tí ó wà lórí òpó.
Baalu naa to jẹ Piper Malibu N264DB ni o sọnu ni ọjọ kọkanlelogun, oṣu kini nigba to n lọ lati ilu Nantes ni Faranselọ Cardiff.
Awọn afurasi meji yooku ti gba itusilẹ wọn.
fowo o  rogbodiyan, ihaholo bo le
daabo bo  awon ile naa fun ọjọ  iwaju, o tun wa gbosuba fun awon ara ilu  Itighidi bi won se n toju awon ohun adayeba
Ní àkókó tí akọ̀ròyìn BBC bẹ agbolé àwọn D'banj wò, kò sí olórin náà nílé bẹ́ẹ̀ sì ni kò sí ohun tó jọ pé ìyàwó rẹ̀ náà wà níbl.
O fi kun un pe o yẹ ki ijọba o ronu pe ajakalẹ arun COVID-19 ṣe ọpọẹọpọ ijamba fun awọn ọmọ Naijiria, bẹẹni gbogbo awọn ohun itura ti ijọba ṣeleri rẹ , ni araalu o ri, bi o tilẹ jẹ pe ijọba n pariwo pe awọn na ẹgbẹlẹgbẹ owo lori rẹ.
Àwọn iwé ìròyìn gbe jade wi pé Adébáyọ̀ Fálétí, ògúná gbòngbò ninú àwọn ti ó gbé èdè àti àṣà Yorùbá lárugẹ ni àgbáyé, re ibi àgbà nrè ni ọjọ́ ìsimi ọjọ́ kẹtàlélógún, oṣù keje, ọdún Ẹgbàálémẹ́tàdinlógún.
Ọmọ ń mú aboyún, ó dé orí ìkúnlẹ̀, ṣugbọn kò sí agbára láti bíi.
O ti jẹ Ọga ọlọpaa agbegbe, (area commander) ni agbegbe Oṣogbo ni ipinlẹ Ọṣun, ati Gusau ni ipinlẹ Zamfara.
Nígbà tí àwọn ọmọ ilẹ̀ Israẹli tí wọn ń gbé òdìkejì àfonífojì Jesireeli ní ìhà ìlà oòrùn odò Jọdani, gbọ́ pé àwọn ọmọ ogun Israẹli ti sá lójú ogun, ati pé Saulu ati àwọn ọmọ rẹ̀ ti kú; wọ́n sá kúrò ní ìlú wọn.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Lateef Adedimeji: Owó wa kò bá máa jóná ṣùgbọ́n aàyè ọpẹ́ ń yọ fún wa 6) Sharon Ikeazor: Sharon Ikeazor jẹ akọwe agba fun ajọ to n ri si owo ifẹyinti awọn oṣiṣẹ, iyẹn, Pension Transitional Arrangement Directorate (PTAD).
Awon osise ohun bere eto iyanselodi naa ni ojo kerin osu kejila odun 2017.
Ibo ni èrò ti yoo lo papakọ ofurufu naa wa?
Mo rin kaakiri ilu fun iṣẹ ṣugbn mi o lori rẹ.
Ìjọba ìlú pín sí ọ ̀ nà bíi mẹ ́ rin nígbà tí ọ ̀ kan wọn balẹ ̀ tán ni ibùdó titun yìí .
Èmi kọ́ ló pàṣẹ fún àwọn sọ́jà láti má a pa èèyàn ní Oyigbo - Nyesom Wike Banki Nàìjíríà, CBN ṣàlàyé nípa àwọn tó máa rí gbà nínú owó ìrànwọ́ N75b tíjọba gbé kalẹ̀ Kàyééfì!
Awọn iroyin ti ẹ lee nifẹẹ si: Àgùnbánirọ̀ t'ọ́lọ́pàá yìnbọn pa wọlẹ̀ sùn Kíni ẹ mọ̀ nípa àwọn gbajúgbaja Yollywood?
Wọ́n ń bọ̀ láti ọ̀dọ̀ àwọn olórí alufaa ati àwọn àgbà ìlú.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ọọni Ilẹ Ifẹ: Isọkan ni a nilo lorilẹede Naijiria 30 Sẹ́rẹ́ 2018 Oríṣun àwòrán, Ooni Palace Àkọlé àwòrán, Ooni pe fun ifọwọsowọpọ Nigeria Ooni ti Ilẹ-Ifẹ, Alayeluwa Adeyeye Enitan Ogunwusi - Ojaja 11, ti pe fun agbajọwọ ati isọkan awọn lọbalọba lati f'opin si ija ati asọ ni orilẹede Naijiria.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Bobrisky: Ìjọba ní kí àwọn ọmọ Naijiria yàgò fún Bobrisky 7 Ọ̀wàrà 2019 Oríṣun àwòrán, @bobrisky222 Ijọba apapọ ti kilọ fun awọn awakọ lati ma a sọra fun Bobrisky paapaa nipa ajọlo yara igbọnsẹ.
Igbesẹ Kẹsan: o lee lo awọn bọtini ayẹwo to wa nibẹ lati fi wa esi idibo ibudo ti o fẹ mọ ni kia masa werewere.
Ṣugbọn nígbà tí ohun tí ó pé bá dé, àwọn ohun tí kò pé yóo di ohun tí kò wúlò mọ́.
 obama gori oye ni ogun jo osu kinni odun 2009 .
Lori ẹsun wi pe wọn fẹ yọ ọba Olubadan ni ipo, Otun ti ilu Ibadan ni awọn ko sọ wi pe awọn fẹ yọ Olubadan.
Ẹ̀dá ẹyẹ yìí máa ń fò sókè lálá nínú àwọn àkókò kan nínú ọdún.
Gọngọ sọ, ẹlẹ́há pàdé àwọn tó lùú ní jìbìtì nílùú Eko lọ́jà Ibadan Ọ̀gá ọlọ́pàá Adamu Pàṣẹ́ iṣẹ́ àkànṣe nílẹ̀ Yorùbá Àwọn agbébọn jí ìyàwó bàbá Sẹ́nétọ̀ Abbo tó lu obìnrin nílùú Abuja gbé Ọlọ́pàá Ondo sọ ohun tí wọ́n mọ̀ nípa ẹni tó pa Ọmọ Fasoranti Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí 2 sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 2:23 Fídíò, Water Generator: Ó leè ṣiṣẹ fún wákàtí mẹfà, kó tó sinmi, Duration 2,2310 Òkùdu 2020 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
Àwọn ọmọ-ẹ̀yìn Johanu ròyìn gbogbo nǹkan wọnyi fún un.
Ile isẹ iroyin naa ti wọn da silẹ ninu iyara kolobo kan ni ilu Manhattan lọdun 2006 wa lati koju awọn iwa ibaje ni eto isejọba Naijiria.
Ṣiṣeṣisẹ ba adilemu, William Troost-Ekong, lo ba gba bọọlu sawọn Naijiria nigba ti ifẹsẹwọnsẹ ọhun de ogoji iṣẹju.
Bi awọn kan ṣe n gba tiẹ ti wọn n gbe lẹyin rẹ lawọn kan n ni kii ṣe m to ṣee fi yangan.
Gbogbo irun orí yín ni ó níye.
Ẹ̀yin náà ti fi ojú yín rí ohun tí OLUWA ṣe ní Baali Peori, nítorí pé, OLUWA Ọlọrun yín pa gbogbo àwọn tí wọn ń bọ oriṣa Baali tí ó wà ní Peori run kúrò láàrin yín.
 Ọ ̀ rọ ̀ nípa ìgbésí-ayé ayaba , àti ọba nínú ààfin .
Wọ́n yí ògo Ọlọrun tí kò lè bàjẹ́ pada sí àwòrán ẹ̀dá tí yóo bàjẹ́; bíi àwòrán eniyan, ẹyẹ, ẹranko ati ejò.
Bi a ṣe n sọrọ yii lilọ bibọ ọkọ lagbegbe na ti wa ni iduro.
Ilesanmi dun ju oye lọ Onwoye kan lori ọrọ aje ati oṣelu to fi ilu Eko ṣe ibujoko, Sam Olisha sọ fun BBC pe o ṣeni laaanu pe iru nkan bayi n ṣẹlẹ.
" Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ninu ijọba Buhari lawọn ole wa — Fayose Buhari jawọ ninu ilana okoowo Afrika Ààrẹ Buhari yóò ṣèbẹwò sí ìlu Ọba Ẹ̀tanú ló wà ní ìdí wàhálà darandaran Ààrẹ Mùhámádù Bùhárí tún ṣàlàyé àwọn àṣeyọrí ìjọba rẹ̀ fún ẹni ọ̀wọ̀ Welby.
ija  si ara won ki ojo idibo to de ni
Ó wọn àtẹ́rígbà ati ìloro rẹ̀, wọ́n sì rí bákan náà pẹlu àwọn yòókù.
Wọ́n dáhùn pé, “A rí i dájú pé OLUWA wà pẹlu rẹ, ni a bá rò pé, ó yẹ kí àdéhùn wà láàrin wa, kí á sì bá ọ dá majẹmu, 
Òun ni àkọsílẹ̀ wà nípa rẹ̀ pé: ‘Wò ó!
NFF President @PinnickAmaju, Nigeria Football Legend @Mathematical7 Segun Odegbami inspire Eagles to go all out today and win for Nigerians #SoarSuperEagles #WorldCup #Team9jaStrong #NGA pic.
Àlejò ni mí láyé,má fi òfin rẹ pamọ́ fún mi.
Ìgbà tí ilẹ̀ sì mọ́, ìyàwó mi kò ba ibi ojú ọ̀nà ibẹ̀ jáde, ibòmíràn ló bá jáde, ko sì tilẹ̀ rìn wá apá ibi tí mo wà rárá, ó lọ, o ń wá oùnjẹ.
Kí lo mọ̀ nípa fẹntilétọ̀, ohun eèlò aṣèrànwọ́ èémí Àwọn nǹkan tí obìnrin lè ṣe pẹ̀lú olólùfẹ́ oníwà ipá lásìkò ìgbélé Coronavirus yìí Coronavirus and OCD: 'Mo fi ogún ọdún gbáradì fún àjàkálẹ̀ ààrùn yìí' O fikun pe, ibatan oun kan lo kọ oun lati lo nkan miran pẹlu ọra, ki oun si fọn bii fere, ti oun si n lo iyarun.
Ẹsira ní: “Ìwọ nìkan ni OLUWA, ìwọ ni o dá ọ̀run, àní, ọ̀run tí ó ga jùlọ, ati gbogbo àwọn ìràwọ̀ tí ó wà lójú ọ̀run, ìwọ ni o dá ilé ayé ati gbogbo ohun tí ó wà ninu rẹ̀, ati àwọn òkun ati gbogbo ohun tí ó wà ninu wọn.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ikú tó ń pa ojúgbà ẹni.
Nígbà tí ó di ọjọ́ Ọ̀sẹ̀ ni ìyá wa ní tí a bá ń bọ̀ láti ilé- ìsìn, kí a yà ní ilè rẹ̀, kí a wádĩ kín ni ó ṣe é tí a kò fi rí ní àná, tí a kò sì tún fi rí i ní ilé- ìsìn.
Ní àkótán, ohun tí ó fẹ́ sọ ní wípé láti mú ayélujára wà ní ipò ọ̀fẹ́ àti ààbò, àwọn tí ó ń jà fún èyí nílò láti wá ọgbọ́n mìíràn dá.
O di akọwe fun Olotu Ijọba Nigeria nigba naa, Sir Abubakar Tafawa Balewa lọdun 1958, ko to o di pe o di minisita fun kata-kara ati ọrọ awọn ileeṣẹ lọdun 1959.
'EFCC mo dé' àti àwọn àṣà míì táwọn olóṣèlú fi dagbo rú ní 2018
Oju opo twitter kun fun ọrọ malegbagbe ti awọn eeyan sọ lori ọro ti oludamọran Aarẹ naa sọ.
Kòṣẹlẹ̀rí ni Hajj ọdún 2020, wo ìyàtọ̀ tó wà nínú rẹ̀ sí ti tẹ́lẹ̀ Ìjọba Akeredolu kò ní omi àánú lójú, a kò tọ́jú alárùn Coronavirus mọ́ - Dókítá Ondo Ẹ̀yin ẹlẹ́gbẹ́ òkùnkùn tẹ fẹ́ ṣe àjọ̀dún lónìí, lákọ la ń dúró dè yín - Iléeṣẹ́ ọlọ́pàá Agbẹnusọ ọlọpaa, Gambo Isah sọ fun ileeṣẹ iroyin AFP pe alupupu ni awọn agbebọ ọhun gun lọ ṣe iṣẹ ibi naa.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, FFK: Buhari ló ń fún àwọn Fulani láàyè láti máa pa ènìyàn' Ìtúsílẹ̀ dé f'áwọn ọmọ tó jìn sí kòtò!
Ondo Killing: Dejí sun ọmọ méje àtagbalagba meji mọ́lé nítorí pé ó ń bínú
Jesu wá tọ́ka sí èyí fún àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀, ó ní, “Mo ń wí fun yín gbangba pé opó talaka yìí dá owó ju gbogbo àwọn tí ó dá owó sinu àpótí lọ.
Bí Nàíjíríà ṣe jáwée jókòo jẹ́ fún South Afrika rèé Sanwoolu ṣe é dáa fún wa níbodè Lekki, Ikoyi - Awakọ̀ ní Lekki Kí ni Bode 'Thomas' ní ṣe pẹ̀lú ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ Nàìjíríà àti South Africa?
Nítorí náà, igikígi tí kò bá máa so èso rere ni a óo gé lulẹ̀, tí a óo sì fi dáná.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Jamb ni kawọn akẹkọ duro de esi idanwo wọn 17 Ẹrẹ̀nà 2018 Oríṣun àwòrán, AFP Ajọ Jamb to n ṣ'eto wiwọ ile-ẹkọ giga ti kes'awọn akẹkọ ti wọn kọ idanwo rẹ wi pe ki wọn ṣe suuru diẹ k'esi o fi jade.
ìlú kan rèé l'Abuja tí kò mọ̀ rárá nípa Covid-19 Àwọn òbí àti àbúrò mi kò le sọ̀rọ̀- Ifeoluwa Anthony Joshua ni ìwúrí ọmọ ọdún méje tó ń kàn'ṣẹ́ yìí ‘Ẹsẹ kikan kọ mi lati di alagbara’ 'Obinrin lo mu mi fẹran orin kikọ' Ẹ wo òtítọ́ ọ̀rọ̀ nípa bí àwọn agbébọn ṣe wó ile ní iléèṣẹ́ aṣojú Nàìjíríà ní Ghana Wọ́n ti pàṣẹ lọ rọọ́kún nílé fún òṣìṣẹ́ káńsù tó lú obìnrin kan ní ìpínlẹ̀ Ogun Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí 3 sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 2:23 Fídíò, Water Generator: Ó leè ṣiṣẹ fún wákàtí mẹfà, kó tó sinmi, Duration 2,2310 Òkùdu 2020 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
Nigba ti BBC Yoruba kan si agbẹnusọ ọlọpaa ni ipinlẹ naa, Abimbola Oyeyemi, o ṣalaye wipe, ikọ ọlọpaa mu ọmọkunrin kan ti wọn funra si wipe, ọmọ ẹgbẹ okunkun ni.
”Nígbà tí wọ́n gbọ́, wọ́n ní “Ọlọrun má jẹ́!
''Iwọde lo yẹ ki wọn ma ṣe ṣugbọn niṣe ni wọn gbegi dina ti wọn ko jẹ ki awọn eeyan kọja.
O bá àwọn orílẹ̀-èdè wí,o pa àwọn eniyan burúkú run,o sì pa orúkọ wọn rẹ́ títí lae.
 ( padà wá ní ọ ̀ sán yìí ) .
Nítorí pé ó ti fi ìjì tẹ̀ mí mọ́lẹ̀,ó sì sọ egbò mi di pupọ láìnídìí;
Wọ́n fi ìwé náà ranṣẹ sí àwọn gomina agbègbè ati àwọn olórí àwọn eniyan ati sí àwọn agbègbè kọ̀ọ̀kan ati ẹ̀yà kọ̀ọ̀kan ní èdè wọn.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, EndSars, EndSwat Protest: Òbí agbábọ̀ọ̀lù Gbenga Tiamiyu Kaka àtàwọn míì tí ọlapàá pa sọ̀r ''Lati igba ti mo ti wa ni kekere ni mo ti maa n ṣe akiyesi baba ati mama mi, ifẹ to wa laarin wọn pọju, ko si ẹni to le ya wọn,'' Ọgbẹni Akojede lo sọ bẹẹ.
Lọdun 2011 ti wọn kọkọ yan ẹlẹsẹ ayo UEFA.
Saraki ti fi idunnu re han bi eto idibo se n lọ bayii , ni eyi to je pe opolopo
O ni laipẹ yii ni ajọ naa fun awọn ẹgbẹ oṣelu tuntun ni iwe ẹri eleyi to ni yoo tun gba awọn obinrin laaye lati kopa lagbami oṣelu paapaa gẹgẹ bii alaga lawọn ẹgbẹ oṣelu tuntun ti wọn ṣẹṣẹ da sílẹ naa.
Ó ń rọ̀ wá láti má se kọjá agbára wa - BBC News Yorùbá BBC News, YorùbáFò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Sebótimọ Ẹlẹ́wà Sàpọ́n - Ó ń rọ̀ wá láti má se kọjá agbára wa 3 Ọ̀pẹ̀̀ 2018 Oríṣun àwòrán, AFP Àkọlé àwòrán, Òwe Sebótimọ Ẹlẹ́wà Sàpọ́n ló bẹ̀rẹ̀ lọ́dọ̀ obìnrin kan tó ń ta ẹ̀wà ní ìlú Abẹokuta.
Amy Coney Barrett di adajọ́ àgbà nílé ẹjọ́ tó ga jùlọ l'Amẹrika
FRSC: Awakọ̀ tó bá tàpá sófin ojú pópó yóò ṣọdún lẹ́wọ̀n
Mo ṣebí ẹni tí ó ń jẹun ni.
Lẹ́yìn gbogbo nǹkan tí Hesekaya ṣe, tí ó sin OLUWA pẹlu òtítọ́, Senakeribu ọba Asiria wá gbógun ti Juda.
Ohun ti wọn n beere ni pe ki ijọba gba awọn onipenija ara sii ninu awọn oṣiṣẹ ti kii ṣe awọn olukọ lawọn ileewe kaakiri ipinlẹ Oyo.
Ó sì gba Israẹli kalẹ̀ lọ́wọ́ àwọn tí wọn ń fi ogun kó wọn.
Ṣugbọn bí mo bá ṣe bẹ́ẹ̀ báwo ni Ìwé Mímọ́ yóo ti ṣe ṣẹ pé bẹ́ẹ̀ ni ó gbọdọ̀ rí?
Lẹ́yìn náà wọ́n pada lọ sí Samaria.
Ọlọrun sì dá a lóhùn, ó ní, “Nítorí pé ọgbọ́n láti mọ ohun tí ó dára ni o bèèrè, tí o kò bèèrè ẹ̀mí gígùn, tabi ọpọlọpọ ọrọ̀ fún ara rẹ, tabi ẹ̀mí àwọn ọ̀tá rẹ, 
kí Jeremaya dúró sí ẹnu ọ̀nà ilé OLUWA, kí ó sì kéde pé: “Ẹ gbọ́ ọ̀rọ̀ OLUWA, gbogbo ẹ̀yin ará Juda tí ń gba ẹnu ọ̀nà wọnyi wọlé láti sin OLUWA.
Saudi fẹ́ gbẹ̀mí 23 ọmọ Nàìjíríà tó gbé òògùn olóró Irọ́ ló pa, a kò mọ̀ ọ́ rí tàbí fún ọ ní ₦13m - APC tako afurasí ajínigbé Àlàyé rèé lórí bí wọ́n ṣe mú mi lẹ́rú ní 1837 - Ajayi Crowther Seun fakorede ní pàtàkì júlọ, isẹ́ ti gomìnà Ṣeyi Makinde gbé lé òun lọ́wọ́ ló ṣe pàtàkì júlọ ti òun si ti ṣetan láti ṣee dé ojú àmìn.
Orukọ Amuneke wọ iwe itan lẹyin to ṣagbatẹru bi orilẹede Tanzania ti pegede fun idije ere bọọlu ilẹ Afirika- AFCON 2019 fun igba akọkọ ni nnkan bi ọdun mọkandinlogoji(39 years).
Sùgbọ́n o, nínú ọ̀rọ̀ tí Fayose fi ránṣẹ́ fun ìgbà àkọ́kọ́ lórí ẹ̀rọ̀ ìkànsíraẹni twitter rẹ̀ ló ti sọ pé aláìlójútì, afipá gbà ìjọ̀ba ní ààrẹ Muhammadu Buhari.
Bákan náà ní wọ́n tun le gba òpópónà Victoria Island/Lekki/Epe/Ijebu-Ode-Benin/Ore.
“Bí ẹnìkan lásán ninu àwọn eniyan náà bá ṣèèṣì dẹ́ṣẹ̀, tí ó ṣe ọ̀kan ninu àwọn ohun tí OLUWA ti pa láṣẹ pé ẹnikẹ́ni kò gbọdọ̀ ṣe, tí ó sì jẹ̀bi, 
Awọn miran ṣi yi wa ti a ko le fidi oun to mu ki wọn pa wọn mulẹ tabi ẹni ti o pa wọn.
Ko si ẹni to le sọ nipato idi to fi jẹ pe tolotolo ni awọn ara America maa n pa fi sami ayẹyẹ idupẹ yii.
Alaga ajọ naa, ọmọwe Olufemi Damilola Oke-Osanyintolu lo fi soju opo ayelujara bi ọrọ naa ṣe ṣẹlẹ.
 Ṣùgbọ ́ n , lọ ́ nà kìíní ná , kò fẹ ́ rìn jìnnà púpọ ̀ sí àbùrò rẹ ̀ gẹ ́ gẹ ́ bí ìpinnu wọn pé àwọn kò gbọ ́ dọ ̀ jìnnà sára wọn bí ó ti lẹ ̀ jẹ ́ wí pé àwọn méjèè jì kò jọ fẹ ́ gbé ibùdó kan náà .
Ipenija aarun iba Ipade Commonwealth naa tun mu anfani ijiroro ati ijẹjẹ ọwọ iranwo lati koju aarun iba nilẹ Afrika.
Kíní ó sẹ̀lẹ̀ sí àkọwé yìí Naomi àti àwọn mẹ́ta tó ku tó fi mọ Rhoda Peter, Sarah Job àti Magaret Yama ní wọ́n tú sílẹ̀ ní inu oṣù Karun un, ọdún 2017 Ìjọba si rán wọn lọ fásitì Yola nínú oṣù kẹsan an, ọdun 2017 Naomi sàlàyé pé òun kọ àkọsílẹ̀ nítori pé òun fẹ ki ọmọ àti àwọn òbi oun ríí.
Nítorí náà, búra fún mi pé o kò ní pa ìdílé mi run lẹ́yìn mi, ati pé o kò ní pa orúkọ mi rẹ́ ní ìdílé baba mi.
Bi ajalu ba waye ni igba akọkọ, a le sọ pe amuwa Ọlọrun nii ṣe.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: N kò jà fún ìṣọ̀kan Yorùbá láti wá ipò tàbí orúkọ - Sunday Igboho Afurasí agbébọn 47 bọ́ sọ́wọ̀ ikọ̀ ‘Operation Burst’ l‘Oyo Iye àwọn tó ń ní Covid-19 ti ń pọ̀ ju ilé ìwòsàn lọ, tó bá yá ọwọ́ wa ò ní ka mọ́ - NCDC Kí ló ma n fa Àkúfà nílẹ̀ Yorùbá, àti ọ̀nà àbáyọ?
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Àyájọ́ òṣìṣẹ́: NURTW gba ẹ̀jẹ̀ lára àwọn òsìsẹ 1 Èbibi 2018 Àkọlé àwòrán, Awọn oṣisẹ naa ni gbogbo awọn ti wọn ṣe leṣe ni wọn ti gbe lọ sile ìwosan.
Ẹsira, akọ̀wé, dúró lórí pèpéle tí wọ́n fi igi kàn fún un, fún ìlò ọjọ́ náà.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Local Government Autonomy: Ìgbésẹ̀ àjọ NFUI kò bá òfin mu rárá 20 Èbibi 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Owó Nàìjíríà Onimọ nipa ofin, Deji Olabiwọnnu ni igbesẹ ajọ NFIU lati fofin de ijọba ipinlẹ pe ki wọn ma tọwọ bọ owo ijọba ibilẹ mọ ko tọna ṣùgbọ́n lootọ, odun to dara ni wọn ṣe.
 Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Bá wo ni coronavirus ṣe ń tàn kálẹ̀ ní àyíká wa?"
ataju lati fi le awon to n fehonu han ni awon oju popo ati aarin ilu.
Ṣisẹ ofin to pọju lọ Oríṣun àwòrán, Twitter/The Senate President Ile igbimọ aṣofin agba kẹjọ ṣiṣẹ lori abadofin to din meje lọọdunrun un(293) lati igba ti wọn ti bẹrẹ di oṣu karun un, ọdun 2019.
 Ó sebisé olùkóni ní ilé iwé ansa-ru-deen college tí ó wà ní ìlú sakí ní ìpínlè Òyó .
"Fasiti John Hopkins sọ pe ""titi di ọjọ kẹfa, oṣu Karùn-ún, eeyan mejidinlaadọjọ lo ni coronavirus lorilẹ-ede Madagascar, mokandinlọgọrun-un lo si ti ri iwosan."
Lẹyin ti Barcelona yọ wọn kuro ni idije UEFA Champions League, Everton fikun ijiya wọn pẹlu ami ayo mẹrin sodo.
Gbajugbaja ẹni ọdun mọkandinlọgbọn naa ti wa ni orilẹede Spain lati ọsẹ to kọja lẹyin to fi ẹgbẹ agbabọọlu rẹ tẹlẹ, Tianjin Teda tile China silẹ .
tí àwọn ọmọ ogun yín sì ṣetán láti ré odò Jọdani kọjá ní àṣẹ OLUWA láti gbógun ti àwọn ọ̀tá wa títí OLUWA yóo fi pa wọ́n run, 
Ẹnikẹ́ni tí ó bá ní ohun kan tí yóò ṣàǹfààní fún ẹgbẹ́ tí yòò sì mú ìmọ̀ kún ìmọ̀, kí ó má ṣe jáfara láti fi tó wa l'étí.
Onírúirú nkan ọ̀gbìn àti èso ni àwọn àgbẹ̀ náà ngbìn, wọ́n sì nsin oríṣìíríṣìí ẹranko.
"Gẹ́gẹ́ bi àtẹ̀jáde tí akọ̀wé Fayose Lere Olayinka fi síta, to pe àkọlé rẹ ni "" PDP gbọdọ̀ sọ pé kí ìgbákejì alága ẹgbẹ́ PDP nígbàkan ri olóyè Bode George lọ fẹ̀yìntì kí ẹgbẹ́ báa le ní ìlọsíwájú kí wọ́n sì jáwé olúborí nínú ìdìbò tó n bọ ní ìpińlẹ̀ Eko""."
N óo nawọ́ ìyà sí Edomu, n óo pa ati eniyan ati ẹranko inú rẹ̀ run.
 olú ilé ìjọba ìbílẹ ̀ náà wà ní iyemogun ni ìlú ilésà .
Wọn yóo kó ẹrù àwọn tí wọ́n ti kó wọn lẹ́rù rí; wọn yóo fi ogun kó àwọn ìlú tí wọ́n ti fi ogun kó wọn rí.
Àfẹ́sọ́nà Davido, Chioma nàá ti ní ààrùn Coronavirus Fíímù ṣíṣe dáwọ́ dúró, Joke Muyiwa di 'grandma', Lizzy Anjorin sọ pé coronavirus ko gbọdọ̀ díwọ́ ọjà títà Ìjọba ìpínlẹ̀ Eko bẹ̀rẹ̀ oúnjẹ pínpín fún àwọn èèyàn lásìkò ìgbélé Coronavirus Fidio yii kọni bi eeyan ṣe le ṣe hand sanitizer ninu ile ara rẹ pẹlu owo perete.
Mama Rainbow lọ si ileewe alakọbẹrẹ ni ipinlẹ Ogun, lẹyin naa lo kẹkọ gboye ni ileewe ẹkọṣẹ awọn nọọsi.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù BBC African Footballer: Salah tún fẹ́ gba àmì ẹ̀yẹ̀ lọ́dún 2019 14 Ọ̀pẹ̀̀ 2018 Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, BBC African Footballer: Salah gba àmì ẹ̀yẹ̀ lẹ́ẹ̀kan síi Àkọlé àwòrán, Mohammed Salah lo tun gbami ẹyẹ BBC Mohamed Salah lo gba ami ẹyẹ agbabọọlu ilẹ Afirika to pegede julọ fun ọdun 2018 (BBC African Footballer of the Year).
Ọpọlọpọ nǹkan tó lógo ni a sọ nípa rẹ,ìwọ ìlú Ọlọrun.
Àwọn ni ìjòyè tí wọ́n ṣẹ̀ láti ọ̀dọ̀ Oholibama, ọmọ Ana, aya Esau.
Burundi president: Wo àwọn ohun tó yẹ kí o mọ̀ nípa Pierre Nkurunziza, ààrẹ orílẹ̀-èdè Burundi tó dolóògbé
Bí ọ̀gbẹlẹ̀ ati ooru ṣe máa ń mú kí omi yìnyín gbẹbẹ́ẹ̀ ni ibojì ṣe ń gbé àwọn ẹlẹ́ṣẹ̀ mì.
Ṣugbọn àwọn ọmọ-ìbílẹ̀ ibẹ̀ kórìíra rẹ̀.
Balogun iko agbaboolu Super Eagles, Mikel Obi ti gboriyin fun iko Super Eagles, leyin ti iko ohun gbo ewuro si iko agbaboolu orile-ede tLibya lojo pelu ami-ayo merin sodo(4-0) lojo abameta(Saturday), ninu ifesewonse ipegede idije boolu afesegba AFCON to n bo lona lọdun 2019.
- Yinka TNT Wọn fi ẹsun kan pe niṣe lo mura bi abọriṣa Osun, ti oun ati ọmọbinrin kan to wa ni ihoho si jọ ni ibalopọ ninu ojubọ naa, l'oṣu Keje, ọdun 2020.
Adájọ́ Ojukwu ṣàlàyé síwájú pé, ẹnikẹ́ni tó bá nífẹ̀ẹ́ láti ra àwọn dúkìá náà gbọ́dọ̀ gbé igbesẹ láti ṣe bẹ́ẹ̀ láàrin ọ̀sẹ̀ méjì péré nígbàtí ìjọba àpapọ̀ kò si gbọ́dọ̀ jogún àwọn dúkìá náà lẹ́yìn ó rẹyìn.
Ẹni tí ó bá ń ṣe ohun èérí, kí ó máa ṣe ohun èérí rẹ̀ bọ̀.
gege bi mo se maa n so, ti a o ba pa iwa ibaje, o di dandan ki iwa ibaje pa wa.
4 Sẹ́rẹ́ 2019 Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Amina Zakari: Ojúṣe mi kìí ṣe láti ka ìbò Amina Zakari ti ọpọ eniyan ati paapaa julọ ẹgbẹ oṣelu alatako PDP ni awọn lodi si iyansipo rẹ ni ajọ eleto idibo INEC ti fesi.
Afẹ́fẹ́ ṣe ọwọ́ òdì sí wa.
Ẹ jẹ́ ki á ṣe ohun gbogbo ni ìwọ̀ntún-ìwọ̀nsì.
Bí o bá sọ wá sinu iná, Ọlọrun wa tí à ń sìn lè yọ wá ninu adágún iná, ó sì lè gbà wá lọ́wọ́ ìwọ ọba pàápàá.
O nigbagbọ ninu ki eniyan jẹ ounjẹ to se ara loore.
Eliasafu ọmọ Laeli ni yóo jẹ́ olórí wọn.
Ko tan sibẹ, opin yoo tun de ba bi ilẹ Gẹẹsi se jẹ ọmọ ẹgbẹ awọn ajọ nlanla to jẹ ẹka ajọ isọkan ilẹ Yuroopu to n se agbekalẹ ati amojuto ilana to rọ mọ oogun titi de idamọ wọn.
Èmi Paulu, ati Silifanu, ati Timoti, ni à ń kọ ìwé yìí sí ìjọ Tẹsalonika, tíí ṣe ìjọ Ọlọrun Baba ati ti Jesu Kristi Oluwa.
“Ta ló fún kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ ìgbẹ́ lómìniratí ó sì tú ìdè rẹ̀?
17 Nípa awọn ohun wọ̀nyí ni àwa mọ̀ pé Ọlọ́run kan wà ní ọ̀run, ẹnití ó jẹ́ àìlópin àti ayérayé, láti àìlópin dé àìlópin Ọlọ́run kan náà tí kò lè yípadà, ẹnití ó ṣe ẹ̀dá ọ̀run àti ayé, àti ohun gbogbo èyí tí ó wà nínú wọn;
Àwọn eniyan pataki ilẹ̀ náà yóo di ẹni ilẹ̀,ìbànújẹ́ yóo sì bá àwọn alágbàṣe.
iṣuna owo yii ṣe iṣẹ wọn daradara, ti wọn yoo fi le maa jabo iṣẹ wọn
- Sanwoolu Àṣé àṣírí wà nínú Hijabu tí Aisha Yesufu ń wọ̀ lọ ìwọ́de Kí ló ń ṣẹlẹ̀ láàfin Oyo táwọn èèyàn fi ń ki Alaafin ní mẹ́sàn án mẹ́wàá?
Rabuṣake gbọ́ pé ọba Asiria ti kúrò ní Lakiṣi, nítorí náà, ó lọ bá a níbi tí ó ti ń bá àwọn ará Libina jagun.
OLUWA kórìíra ìwà àwọn eniyan burúkú,ṣugbọn ó fẹ́ràn àwọn tí ń hùwà òdodo.
Àkọlé àwòrán, Alhaji Kayọde tó jáwé olúborí ní Kwara ti di oludije dupò gomina Seriki Yahaya ní ìbò 6, Abdulrahaman Abdulrazaq, ní ìbò 3, Garba Gobir ní ìbò 2, Akeem Oladimeji Lawal ní ìbò 27, Lukman Mustapha ní ìbò 11, Mashood Mustapha ní ìbò 5, Modibo Kawu ní ìbò 2, Mohammed Belgore, SAN ní ìbò 6, Professor ShuaibAbdulraheem ní ìbò 5, Mallam Saliu Mustapha ní ìbò 12, Yaman Abdullahi ní ìbò 7 ati Alh Tajudeen Makama ní ìbò 4, nigba ti Kayọde ni 891.
Ibi tí wọ́n wà kì í ṣe ibi tí ó dára láti gbé ní ìgbà òtútù.
Nítorí náà, a óo sin òun ati ogunlọ́gọ̀ àwọn eniyan rẹ̀ sí ààrin àwọn aláìkọlà, láàrin àwọn tí wọ́n kú lójú ogun.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Collapsed Building: Ilé alájà mẹ́rin wó l'Eko 13 Ẹrẹ̀nà 2019 Iye eeyan to ti jẹ Ọlọhun ni pe ninu ijamba ile to wo ni ipinlẹ Eko ti di ogun bayii, eyi jẹ ohun ti ijọba ipinlẹ̀ Ẹko sọ.
Wọn si tun fẹnu ko pe, awọn yoo ṣakitiyan lati ri pe ijọba awarawa fẹsẹ mulẹ.
Ifehonu-han ohun tun wa fun titako siseto idibo ile-igbimo asofin lojo-AbametaApapo egbe oselu alatako ohun ni, egbe ajafeto omoniyan, ati ege oselu Ivorian Popular Front, ti o je egbe oselu Aare teleri Laurent Gbagbo.
Ile ẹjọ dá awọn mẹfa yooku silẹ, nitori pe ko si ẹri to tako wọn.
8 Mo ti ní ìyàwó àfẹ́sọ́nà, ayẹyẹ ìgbeyàwó mi ń bọ̀ láìpẹ́ - Lateef Adedimeji 9 Covid-19: Ilé aṣojú-ṣòfin l'Abuja dábàá kí ìjọba sún ìwọlé àwọn akẹ́kọ̀ọ́ síwájú pẹ̀lú oṣù mẹ́ta 10 Ọwọ́ tẹ ènìyàn méjì tó ń ta ayédèrú aṣọ iṣẹ́ ikọ̀ Àmọ̀tẹ́kùn BBC News, Yorùbá Ìdí tí ẹ fi le è nígbàagbọ́ nínú ìròyìn BBC Ìlànà Lílò Nípa BBC Òfin Àṣírí Cookies Kàn sí.
Ṣugbọn kí ni wọ́n óo ṣe nígbà tí òpin bá dé?
Atẹjade ti fasiti ọhun fi sita tun ṣalaye pe, nigba ti ile iwe naa wa ni isinmi ni akẹkọọbinrin naa lọ ba a nibẹ.
com/yoruba/46733903 Mọrèmi: Ọọ̀ni ní láìsi Mọrèmi, kò leè sí ilẹ̀ Yorùbá Àkọlé àwòrán, Mọrèmi: Ọọ̀ni ní láìsi Mọrèmi, kò leè sí ilẹ̀ Yorùbá Iroyin yii da le ipa ti obinrin ko ninu ominira ati idagbasoke ọpọ awujọ lagbaye.
Ọdun 1938 ni wọn bi Fẹla nilu Abeokuta to jẹ olu ilu Ipinlẹ Ogun si idile Israel Oludọtun Ransome-Kuti to jẹ ọga ile iwe girama ati mama rẹ Oloye Funmilayọ Ransome-Kuti to jẹ ajafẹtọ ọmọniyan.
ijọba ńlá luba ti bẹ ̀ rẹ ̀ ní nǹkan bí ẹgbẹ ̀ rún kan ààbọ ̀ ọdún sẹ ́ yin 1,500 .
Ṣaaju asiko yii ni iya rẹ ti fura pe ojoojumọ ni nkan bii ohun ẹṣọ ohun n sọnu ninu ile.
Asofin Omisore soro ohun di mimo leyin ti o gba iwe-eri egbe naa, eleyi ti alaga egbe oselu SDP, ojogbon Rufai Alkali  fi kii kaabo pada sinu egbe oselu SDP nile egbe oselu ohun niluu Abuja.
Dìde, kí o rìn jákèjádò ilẹ̀ náà, nítorí pé ìwọ ni n óo fún.
Ni irọlẹ Ọjọru ni awọn afurasi ajinigbe naa gbe Umar Isah ni ile rẹ to wa ni Daura ni ipinlẹ Katsina ni nnkan bi ago meje aṣalẹ.
Àwọn ni wọ́n jẹ́ olórí alufaa ati olórí àwọn arakunrin wọn ní ìgbà ayé Jeṣua.
”Angẹli náà tún ní, “Àwọn ọba mẹta ni yóo jẹ sí i ní Pasia; ẹkẹrin yóo ní ọrọ̀ pupọ ju gbogbo àwọn yòókù lọ; nígbà tí ó bá sì ti ipa ọrọ̀ rẹ̀ di alágbára tán, yóo ti gbogbo eniyan nídìí láti bá ìjọba Giriki jagun.
Nítorí náà, ranti ohun tí o ti gbà tí o sì ti gbọ́, ṣe é, kí o sì ronupiwada.
Èyí jẹ́ majẹmu pataki tí mo bá ìwọ ati àwọn ọmọ rẹ dá.
A kì í gba ọ̀dàn lọ́wọ́ ọlọ́dàn
Yinka Ayefele di asojú Àjọ INEC Ayefẹlẹ bá BBC sọ̀rọ̀ lórí ilé orin rẹ̀ tí Ajimọbí ń tún kọ́ Ayédèrú Afenifere ló bá Buhari ṣépàdé - Odumakin gbanájẹ A kò lè gba àwọn jandùkú Fulani láàyé nílẹ̀ Yoruba -Awọn gómínà Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Obinrin Yorùbá ti ni àyè lati ṣe iṣẹ́ ti pẹ́, bi ó ti ẹ̀ jẹ́ wi pé àwọn iṣẹ́ obinrin bi oúnjẹ ṣí ṣe, ẹní hí hun, aṣọ hí hun, aró ṣi ṣe, òwú gbi gbọ̀n, ọjà ti tà (ẹ̀kọ́ ọrọ̀ ajé díẹ̀), oúnjẹ sí sè àti itọ́jú ẹbi ni obinrin nṣe.
Daniel ran ọmọ rẹ kan nileewe nilẹ Britain, nibẹ lo ti fẹ obinrin Irish kan to ba a wale pada si Naijiria nibi ti wọn ti tọ ọmọ meje.
Ẹsun ti wọn fi kan Marley ni pe o tapa si ofin isede coronavirus.
Inú séèfù yìí nì ó máa ń kó owó sí.
’Òru a gùn bí ẹni pé ojúmọ́ kò ní mọ́ mọ́,ma wá máa yí síhìn-ín, sọ́hùn-ún,títí ilẹ̀ yóo fi mọ́.
Ibrahim Chatta Lara awọn ti Ọlọrun gba fun ninu iṣe tiata Yoruba ni Ibrahim Chatta jẹ Laarin oṣẹ yii ni Chatta le ọdun kan si i nilẹ alaye.
Fáyóṣé fèsì lórí bí Buhari se ńdá Gaddafi lẹ́bi wàhálà darandaran
"Ohun ti Obasanjo sọ ninu atẹjade ọhun to da awuyewuye silẹ ni pe ""Buruji lo gbogbo ọgbọn alumọkọrọyi inu ofin lati bori awọn ẹsun ọdaran ti wọn fi kan an ni Naijiria ati loke okun, ṣugbọn ko le e sa mọ iku lọwọ."
63 Àwọn alàgbà nílati gba àwọn ìwé àṣẹ wọn ní ọwọ́ àwọn alàgbà míràn, nípa ìbò àwọn ọmọ ìjọ èyí tí wọ́n wà, tàbí nínú àwọn àpéjọpọ̀.
Ati pe ibudo ti awọn ileeṣẹ naa n ko awọn ọja wọn si ni ọwọ ti tẹ awọn oogun ikọ naa.
 wọ ́ n tún máa ń pe ẹgbẹ ́ eastern austronesian ní oceanic .
Bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé ẹ̀yà Juda di ẹ̀yà tí ó lágbára ju gbogbo ẹ̀yà yòókù lọ, tí wọ́n sì ń jọba lórí wọn, sibẹsibẹ ipò àkọ́bí jẹ́ ti àwọn ọmọ Josẹfu).
Gẹ́gẹ́ bí o kò ti mọ bí ẹ̀mí ṣe ń wọ inú ọmọ ninu aboyún, bẹ́ẹ̀ ni o kò mọ̀ bí Ọlọrun ṣe dá ohun gbogbo.
To ba n pẹ jẹun alẹ́, o le ni jẹjẹrẹ ọyan àti asétọ̀ Àwọn àpẹẹrẹ pé o ti ń darúgbó Ìgbẹ́ ọmọdé ń dènà ààrun jẹjẹrẹ, àìsàn ìtọ̀ súgà Abajade naa waye lati ara iwadii ti wọn ṣe laarin ẹgbẹrun mẹtadinlogoji ọkunrin ati awọn obinrin to le ni ọgọrin ẹgbẹrun.
Oṣu Kọkanla ọdun 2018 ni ẹgbẹ ASUU lọ fun iyanṣẹlodi, o si lọ fun oṣu mẹta, ko to o di pe o wa sopin lọjọ keje, oṣu Keji ọdun 2019.
Agbẹjọrọ ijọba ni ilu Los Angeles lo fi lede bẹẹ fun awọn oniroyin.
"Ọ̀rọ̀ ìjókòó ìgbìmọ̀ ìwádìí #EndSARS náà dé ìpínlẹ̀ Ogun Wo àfipábánilòpọ̀ ẹni ọdún 51 tí ìjọba ìpínlẹ̀ Ekiti tú làṣirí ní gbangba ""Àwọn sójà ní mo káàbò sí ilé ìṣerun àgbáyé tí wọ́n tí ń ṣerun bó ṣe wu wọ́n"" Sanitáísa leé ba ìwé ìtẹ̀ka ìbò jẹ́ - Àjọ CDC kìlọ̀ Ọga agba patapata awọn ọlọpaa, Muhammed Adamu sọ pe awọn ọlọpaa SWAT yoo bẹrẹ ẹkọ igbaradi ni kete ti wọn ba ti kede akojọ wọn lọsẹ to n bọ."
Oríṣun àwòrán, Mike bamiloye/facebook Àkọlé àwòrán, Bayii ni baba ati iya iyawo, Mike ati Gloria Bamiloye ṣe fi idunnu jo nibi idana ọmọ wọn, Darasimi Ohun ni ọmọbinrin kan ṣoṣo ni idile Mike-Bamiloye, oun naa si jẹ oṣere Kristẹni bii ti baba rẹ, iya ati awọn ẹgbọn rẹ ọkunrin meji.
Reuters ni wọn n pade pẹlu awọn ọga agba ọmọ ogun America ni Doha lati ọsẹ to kọja.
Inu mi dun pe n o ni awọn imọ ni BBC kun eyi ti mo ni tẹlẹ, eyi yoo si ran mi lọwọ lati le fikun lukun pẹlu awọn ero iworan mi labẹlě ni ẹkun ati jakejado agbaye nibikibi ti mo ba ti n ṣe iṣẹ mi Bi ẹnu rẹ se da șaṣa jẹ nkan to wu awọn onidajọ eto igbaniwọle naa lori, ati nipa bi o ṣ n sọ itan ilẹ Adulawọ labẹle ati ni gbangba, to fi mọ ori ayelujara.
Bakan naa ni igbimọ ọhun yoo maa bojuto bi ijọba yoo ṣe maa san owo gba-ma-binu fun ẹnikẹni ti ọlọpaa ba fiya jẹ lọna aitọ ni ipinlẹ naa.
Yatọ si eleyi to ṣẹlẹ ni Sudan, ifipagbajọba marun le lọgọrun lo ti kuna nilẹ Afirika nigba ti ọgọrun si ṣẹlẹ.
Gomina Akeredolu sọ eyi lasiko to jawe olubori ninu didbo sipo gomina ni ipinlẹ Ondo.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ko din ni ibudo ọmọogun ilẹ Amẹrika meji ti ado oloro lati orilẹede Iran kọlu.
 agogo náà tún jẹ ́ ọ ̀ kan nínú ohun èlò eré àpíìrì .
O kere tan eeyan ogoji la gbo pe o ku ninu isele naa ni ipinle Katsina.
Bo tilẹ jẹ pe ile igbimọ aṣoju naa fọwọ si pe ki Aarẹ wa wi tẹnu rẹ lori eto abo Naijiria, wọn ko tii sọ ọjọ ti Aarẹ yoo wa.
O ti fi ẹnu ara rẹ sọ lónìí pé, OLUWA ni Ọlọrun rẹ, ati pé o óo máa rìn ní ọ̀nà rẹ̀, o óo máa pa gbogbo ìlànà ati òfin ati ìdájọ́ rẹ̀ mọ́, o óo sì máa gbọ́ tirẹ̀.
ọpọlọpọ gba pe idije Egypt to ku lẹyin tun maa dun ju eyi lọ pẹlu ero pe Salah a da bira pẹlu bọọlu.
Lẹ́yìn èyí, Oluwa yan àwọn mejilelaadọrin mìíràn, ó rán wọn ní meji-meji ṣiwaju rẹ̀ lọ sí gbogbo ìlú ati ibi tí òun náà fẹ́ dé.
Omiri kú, wọ́n sì sin ín sí Samaria; Ahabu ọmọ rẹ̀ sì gorí oyè dípò rẹ̀.
Ọwọ́ ara mi ni mo fi kọ ìwé yìí si yín, ẹ wò ó bí ó ti rí gàdàgbà-gadagba!
"Ọpọ igba ni wọn ti beere lọwọ mi pe, kilode ti mi o fi ile silẹ fun.
Ó dára ní wíwò, iké oríṣiríṣi.
Olawale Akinola, ẹni to ṣe oju rẹ koro to fi mọ awọn ọlọpaa mẹrin.
Oluwa yipada, ó wo Peteru, Peteru wá ranti ọ̀rọ̀ Oluwa nígbà tí ó sọ fún un pé, “Kí àkùkọ tó kọ lálẹ́ yìí, ìwọ yóo sẹ́ mi lẹẹmẹta.
yii lati tun soro lori ibo odun 2019.
Awọn ọlọpaa tun se akiyesi pe ẹjẹ wa lara ọbẹ to wa ninu yara naa, ti wọn si tun ri korofo igo majele meji , agolo igo ohun mimu Red Bull mẹta ati ẹmu ti wọn fi n yọ eso kan.
Ọpọ lo ṣapejuwe igbesẹ naa gẹgẹ bi eyi ti ko ba oju mu, eyi to da bi iwa àpà.
Àwọn oúnjẹ tó n gbayì níbi ayẹyẹ báyìí Ẹ má mu gaarí mọ́ nítorí ìbà Lassa- Dókítà Boniface Mí ò le nífẹ̀ẹ́ obìnrin Nàìjíríà kankan mọ lẹ́yìn ti mo ti tọ́ obìnrin òyìnbó wò- Issa Oríṣìíríṣìí ẹ̀bùn tí àwọn olọṣèlú ń pín #BBCNigeria2019 Ṣugbọn to ba ti pẹ lara, awọn apẹẹrẹ naa yo yi si: ki ẹjẹ o maa jade lati imu, oju, eti, ẹnu, oju ara obinrin, iho idi, ati awọn iho miran ninu ara, lai nidii.
Amọ, ohun to sọ nipe awọn oloye kan buwọlu iwe ti awọn oloye naa kọ si Gomina ipinlẹ Oṣun, nigba ti awọn mii kọ lati buwọlu iwe naa.
Lójijì mo ṣe wọ́n,nǹkan tí mo sọ sì ṣẹ.
Ṣé Kristi náà ni ó wá pín yẹ́lẹyẹ̀lẹ báyìí?
’Tabi kí ó sọ fún un pé,‘Nǹkan tí ò ń mọ kò ní ìgbámú?
Nigba ti Maina yoo fi farahan nile ẹjs nigba miran, ori kẹkẹ ailera Wheelchair lo wa.
Àwọn Juu tí kò gbà pé Jesu ni Mesaya wá gbin èrò burúkú sí ọkàn àwọn tí kì í ṣe Juu, wọ́n rú wọn sókè sí àwọn onigbagbọ.
Ṣugbọn bí ó ti lé ẹ̀mí èṣù náà jáde ni odi náà bẹ̀rẹ̀ sí sọ̀rọ̀.
 Bo ti lẹ jẹ pe itankalẹ arun Ebola n pa ọpọ eniyan si, sibẹ awọn oṣiṣẹ eto ilera n la ewu ibinu awọn ajijagbara ati eniyan miran kọja nitori awọn ayederu iroyin to n tan kalẹ bi ina inu ẹẹrun, paapa lori ayelujara Whatsapp."
Esi ayẹwo aarun coronavirus ti ajọ to n gbogun ti aarun ni Naijiria, NDCD, kede ni alẹ ọjọ Ẹti fihan pe eniyan igba ati marundinlaadọta lo tun ti ni aarun naa ni Naijiria.
Fajemirokun tun n se iranwọ fun ọpọlọpọ eeyan miran to nilo atilẹyin rẹ nigba naa Owo ribiribi lo n gbe kalẹ fun amugbooro ẹka eto eto ati idagbasoke awujọ ati awọn ileẹkọ giga wa ni Naijiria.
Olówó ẹrú náà bá pè é, ó sọ fún un pé, ‘Ìwọ ẹrú burúkú yìí!
O kò gbọdọ̀ fi ẹ̀sùn èké kan ẹnikẹ́ni, o kò sì gbọdọ̀ pa aláìṣẹ̀ tabi olódodo nítorí pé, èmi, OLUWA kò ní dá eniyan burúkú láre.
Gẹgẹ bi ohun ti Ọgbẹni Adeniyi sọ fawọn akọroyin ni ilu Enugu, o ni n ṣe loun ronu si ọrọ awọn agba to ni iya meji ko gbọdọ jẹ okuugbẹ loun baa fi sare wa wọrọkọ fi ṣada.
Ṣugbọn Modekai gbọ́ nípa ọ̀tẹ̀ náà, ó sọ fún Ẹsita, ayaba, Ẹsita bá tètè lọ sọ fún ọba pé Modekai ni ó gbọ́ nípa ète náà tí ó sọ fún òun.
Igbakeji awọn ọmọ ile igbimọ aṣofin to pọju lọ, Aṣofin Oladiji Adesanmi lo buwọlu lẹta gbe ile rẹ naa pẹlu ifọwọsi abẹnugan ile.
“Àbí nǹkan ibi lè ṣẹlẹ̀ ní ìlú láìṣe pé OLUWA ni ó ṣe é?
"Folks, please, remember: ""I cast my vote…""  Any ""I casted my vote"" I see on my TL will be considered election violence."
O fi kun un pe oun kuro lara awọn ọba ti yoo maa ba awọn to ba wa nipo iṣejọba ta kangbọn nitoripe oun ko si lati maa tabuku tabi fi ẹrẹ yi awọn to ba wa nipo aṣẹ lara.
Ninu ọrọ rẹ, Babs ni iwadii lati Ajọ Ocean Conservancy f han pe ike rọba yoo pọ ju ẹja lọ ninu okun ni ọdun 2050.
Dokita Emmanuel Moses Rotimi to ni ile iwosan aladani, Delight Fertility Hospital ti sọrọ lori isoro to n koju awọn obinrin lasiko ti wọn ba dawọ lati ma a se nkan osu (menopausal stage).
“Ti a ba tele ilana ti
Ẹ̀ ṣeun ti ẹ dara pọ̀ mọ́ wa lónìí fún ìròyìn káàkiri Nàìjíríà níbi tí ètò ìbúrawọlé ti ń wáyé.
Ogun wá bẹ́ sílẹ̀ ní ọ̀run.
Bakan naa ni a ti pe awọn miran ti kii ṣe ọlọpa mọra lati ran wa lọwọ.
A mú ohun ìjà òdodo lọ́wọ́ ọ̀tún ati lọ́wọ́ òsì.
Ẹ wo àwọn ìròyìn tó ṣì ń gbóná fẹli fẹli lọ́sẹ̀ yìí Ẹ wo ìpínlẹ̀ 15 tó faramọ́ ìdásílẹ̀ àbúlé Ruga Ìtàn tó wà nídi òwe ‘Sebótimọ Ẹlẹ́wà Sàpọ́n’ Ìgbín ní èmi àti ìyá mi máa ń he kiri, ká tó lee jẹun - Lizzy Anjọrin Gomina Oyetọla ni, awọn ti yoo lee mu ki ilepa ijọba oun atawọn ileri ti oun ṣe faraalu o tete wa si imuṣẹ, loun n wa ati pe laipẹ lawọn eeyan naa yoo ṣarajọ.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Àwọn ibúdó àtìpó pọ̀ ní ẹnu ààlà Nàìjíríà àti Niger Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Àwọn ọmọ Jora jẹ́ aadọfa ó lé meji (112)
Kí ẹbọ ohun mímu jẹ́ ààbọ̀ òṣùnwọ̀n hini ọtí waini fún akọ mààlúù kan, ìdámẹ́ta òṣùnwọ̀n hini ọtí waini fún àgbò kan ati idamẹrin òṣùnwọ̀n hini ọtí waini fún ọ̀dọ́ aguntan kan.
Iroyin naa ni Adari ijọ naa fẹsun kan Aarẹ Buhari wi pe, ko ko ipa to jọju lati gbogun ti ẹgbẹ adunkokomọni Boko Haram.
Igbesẹ yii n waye loriọrọ kobakungbe ti Fani Kayọde sọ si akọroyin ileeṣẹ iroyin Daily Trust ni ilu Calabar, ni ipinlẹ Cross Rivers.
''Ti aarẹ Buhari ba buwọlu iwe ofin naa, eyi yoo mu ki awọn eniyan ni igbagbọ lori ijọba nipa ohun ti wọn sọ wi pe awọn yoo ṣe.
Ó fojú hàn gbangba pé, ààrin àwọn ọmọ tó jogún ilé náà kò gún.
Àwa Emèrè Onítẹ̀síwájú la ṣèpàdé nílé Elebuibon, kìí ṣe Oṣó àti Àjẹ́ Kò yé wa bí afurasí ṣe sálọ ní àhámọ́ àmọ́ ẹ ràn wá lọ́wọ́ lári ri mú padà - Ọlọ́pàá Oyo Dagunro ní ìtẹríba, tó sì ń gbé àṣà lárugẹ - Ọ̀gá Bello Oríṣi ẹbu ìwé ìdánwò ìṣìrò mẹ́ta ló dọ́wọ́ wa, àmọ́ wọn fi ń lu jìbìtì ni - WAEC Ṣugbọn Olodumare kọ wọn ni ọgbọn pe, etutu ati ẹbọ riru ni ọna abayọ - lilo iyọnu tabi ẹbẹ awọn ajẹ.
 ohun èlò ifá-dídá míìran ni ọ ̀ pẹ ̀ lẹ ̀ , èyí ló wọ ́ pọ ̀ jù fún ifá dídá ní ayé òde òní .
" Wọ́n ti ni kí àwọn alága ìjọba ìbílẹ̀ Ogun lọ rọọ́kún nílé Ará ìlú dájọ́ oró fún ọkùnrin to bẹ́ orí ẹ̀gbọ́n rẹ̀ ní Cross River Ohun tó wù kí ileẹjọ́ kòtẹ́milọ́rùn sọ, Adeleke kò lè di gómínà Ọ́ṣun - APC Sìgá mímu ń di èèwọ̀ oògùn ìlera pípé lagbaye Awọn akẹkọọ akẹgbẹ rẹ to ṣe iwọde lati fi ẹhonu han lori iku rẹ ni owurọ ọjọ Satide ko fojuure wo ileewosan ileewe naa rara.
Ẹni tí ó bá kú sí ààrin ìlú ninu ìdílé ìwọ Ahabu, ajá ni yóo jẹ òkú rẹ̀, ẹni tí ó bá sì kú sinu pápá, àwọn ẹyẹ ni yóo jẹ òkú rẹ̀.
Stealing: Ilé-ẹjọ́ ní kí Danladi, awakọ̀ tó jalè gbálẹ̀ kóòtù f'ọ́jọ́ méjì
Obìnrin kan gbé ara rẹ̀ níyàwó Èèwọ̀!
Ọ ̀ kan nínú àwọn ìtàn náà sọ pé : Ọwà iléṣà kìíní ajíbógun àti Ọba Ìjẹ ̀ bú-jẹ ̀ ṣà kìíni , agírgírì jẹ ́ tẹ ̀ gbọ ́ n tábúrò .
Eto idibo aarẹ naa, ti wọn ni Oloye MKO Abiola lo bori rẹ, nijọba ologun Babangida wọgile, eyi to fa laasigbo nla, paapaa nilẹ Yoruba.
Ọdun kan kọja, sibẹ mi o ri ẹnikankan to n jẹ Michelle Damsen"" boya mi o si ni mọ ọ lailai."
Wasiun Abiodun Onibọn woye pe ni ọdun 2010 ni wọn ṣe ofin tẹlẹ kii ṣe
Ọwọ́ ikọ̀ aláàbò STF tẹ afurasí mẹ́jọ tó lọ́wọ́ nínú ìpànìyàn lemọ́-lemọ́ọ Gúúsù Kaduna Èèyàn 290 míràn ló ṣẹ̀ṣẹ̀ fara káásá àrùn Covid-19 ní Nàìjíríà, 160 gbàwòsàn Wo bí ìgbéyàwó ọmọ bàbá olówó, Adama Indimi àti Prince Malik Ado ọmọ Ọba Ohinoyi ilẹ̀ Ebira ṣe lárinrin tó Asojú ìjọba orílẹ̀-èdè Lebanon ti kọ̀wé fipò silẹ̀ nítorí ìbágbàmù tó gbẹ̀mi ènìyàn 200 Kingsley ni oun yoo gbe ọmọ naa lọ sile awọn obi rẹ, ṣugbọn kaka ko ṣe bẹẹ ile ara rẹ lo gbe e lọ nibi to ti fi ipa ba lopọ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Tinubu: Nítorí Tinubu, àwọn ọmọge Sanwo-Olu da ìlù bolẹ̀ Lapade ni Olu ẹeda itan to jẹ akọni to n gbogun ti iwa ibajẹ ni awujọ lasiko naa.
Wasiu Ayinde: Ìkórira pé mo jẹ Mayegun ni wọn ṣe parọ́ pé mo ń fẹ́ olorì Aláàfin, kò rí bẹ́ẹ̀ rá Oríṣun àwòrán, others Ọba Fuji, Wasiu Ayinde Marshall, tí ọ̀pọ̀ èèyàn mọ si Kwam 1, tí sọ̀rọ̀ lórí ẹ̀sùn tí àwọn èèyàn kan fi kàn-án pé, ó ń ní ajọṣepọ pẹ̀lú ọkàn lára àwọn olórí Aláàfin tilu Ọ̀yọ́.
daju pe oun ko da ijoba se sugbon ki o maa gba imọran lọwọ awon to ba yẹ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Helicopter crash in Lagos: Àbájáde ìwádìí ẹlikọ́pítà to já ni Opebi laipẹ yii ti jáde 28 Ògún 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 21 Owewe 2020 Oríṣun àwòrán, LASEMA Ìgbìmọ̀ ìwádìí ìṣẹ̀lẹ̀ ìjàmba ti fi abájáde ìwádìí wọ́n síta lórí ẹlikọpítà to já ni Opebi nílùú Eko lọ́jọ́ kejìlélógójì, oṣù kẹjọ, ọdún 2020.
'Ojú mi gún régé nítòótọ́ ṣùgbọ́n ọ̀pọ̀ máa ń sá fún mi ni' Omoyele Sowore: Èrù ló ń ba àwọn NEDG láti pè mí Àwọn Asòfin Naijiria yarí lórí ètò ìsúná 2019 ‘Ilé ìwé tí kò bá ní ohun ìwòsàn yóò fẹ̀wọ̀n jura’ Ṣọla Kosọkọ-Abina gboriyin fawọn ọga agba elere tiata ti ko filọkulọ lọ oun lẹnu iṣẹ́ nigba to n sọ bi baba rẹ, Jide Kosọkọ ṣe bẹrẹ ere lọmọ ọdun mẹwaa péré ṣaaju ko to bi oun.
" Bayii ni Marie kọ ọ silẹ sinu iwe akọsilẹ rẹ lọdun 1952.
Bi ko ba ti ni, irọ nla gbaa ni.
Nígbà tí Eli gbọ́ igbe wọn, ó bèèrè pé, “Kí ni wọ́n ń kígbe báyìí fún?
O wa rọ ẹgbẹ OPC, New Era lati fọwọsowọpọ pẹlu ile iṣẹ ọlọpaa lori iṣẹ iwadii ti wọn n ṣe, lori iku arabinrin Olakunrin.
Foluke wá rawọ ẹ̀bẹ̀ pé káwọn ọmọ aráyé má ṣe sọ isẹ àánú di isẹ ibi mọ òun lọ́wọ́.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ile aṣofin: Jubrin maa pada bọ wale 13 Ẹrẹ̀nà 2018 Oríṣun àwòrán, @AbdulAbmJ Àkọlé àwòrán, Ọ́pọ igba ni Abdulmumini Jubrin ti sọrọ tako awọn asofin to jẹ ọkan lara wọn Ile asoju-sofin ni Naijiria ti pe alaga igbimọ ile tẹlẹ feto isuna, Abdulmumini Jubrin pada sibi ijoko rẹ lẹyin asẹ 'lọ rọọkun nile na' ti wọn pa fun-un.
Amọ, agbẹjọro Busọla Dakolo ti fesi pe ko si ootọ ninu ọrọ naa.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Funkẹ ni oun ''padanu gbogbo ohun ini oun si ọwọ ọkunrin yii ṣugbọn mo pinnu lati tẹsiwaju pẹlu gbigba tẹniisi ori tabili.
Ọmọ Yorùbá  tí kò bá ìdílé ọba tan, tí enì kan kò dé adé ní ìran rẹ̀ rí, tí ẹnikẹ́ni kò sì sọ ìtàn ìdílé rẹ̀ kan Ódùduà, tí ó tún fi ìlúrẹ̀ sílẹ̀ tí ó lọ sí ìlú òdì-kejì,tí ó dé ọ̀hún tán tí ó ńn ddu oyé wí pé òun fẹ́ẹ́ jẹ ọba, eléyìínì kò yàtọ́ sí ìnàkí àfi ti wí pé ara tirẹ̀ dán ju ti ìnàkí lọ.
kárbọ ̀ nù ( láti  èédú "" ) je ipilese kemika to ni ami-idamo c ati nomba atomu 6 ."
Coronavirus cases in Nigeria: Láì náání awuyewuye tó ń lọ láàfin rẹ̀, Aláàfin dẹ́rìn ín pẹ̀ẹ̀kẹ́ àwọn èèyàn ìlú Ọ̀yọ́ Alaafin pin ounjẹ loriṣiriṣi fun awọn eeyan rẹ.
 Òfin ìhun gbólóhùn ti a máa ń lò fún àpólà-ìse inú gbólóhùn alásínpò ise ni .
Ọọni wa lara awọn ọba ti aarẹ orilẹede Naijiria ko fi ọrọ rẹ ṣawada rara.
Aubameyang lo gba bọọlu si Mkhitaryan ko to gba bọọlu na sinu awọn Watford.
Wẹ̀ mí mọ́ kúrò ninu àìdára mi,kí o sì wẹ̀ mí kúrò ninu ẹ̀ṣẹ̀ mi!
Omilẹgbẹ awọn eeyan ree, ti wọn n sewọde ni Sudan, koda, se ni ilu kun fọfọ Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Awọn agbẹ ọlọgbin owu ree nilu Lesotho tawọn naa n sewọde tako awọn olokoowo China tori owo ọja wọn ti ko tẹ wọn lọwọ Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Agọ awọn atipo ree ni Libya, eyi ti ado oloro klu to si pa eeyan mẹrinlelogoji.
Fadeyi ni ilé ìṣẹ́ ọlọ́pàá ti bẹ̀rẹ̀ ìwádìí lórí ìṣẹ̀lẹ̀ túntun ti Mujeeb ti wọn pa tó ṣẹlẹ̀ yìí, láti rí idí aburú tó n f'ojoojúmọ́ wáyé níjọba ìbílẹ̀ Akinyele nílùú Ibadan.
Ṣááju àsìkò yìí o lé ni ènìyàn mílíọnu méji àti ọwọ́ mẹ́fà ló n ku lọ́dọ̀ọ̀dú ki wọn to gba abẹrẹ ajẹsara akọkọ bni ọdún 1960.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Nollywood: Toyin Abraham ń ta àgbo, Wumi Toriola, Ronke oshodi Oke ń ta ìpara ìbóra 22 Bélú 2019 Ọpọ oju to n pawo ninu awọn fiimu agbelewo wa lo jẹ ilumọọka fun ọpọ eeyan lorilẹede Naijiria.
“Àjèjé ọwọ́ kan kò gbẹ́rù dóri” àjùmọ̀ṣè wọn yìí mú ìlọsíwájú wá fún ìlú náà lọ́pọ̀lọ́pọ̀ “Abiyamọ kì í gbọ́ ẹkún ọmọ rẹ̀ kò má tatí were” ni ti àwọn ọmọ Ìjẹ̀bù - Jẹ̀ṣà sí ohunkóhun tí wọ́n bá gbọ́ nípa ìlú wọn.
Nítorí náà má gbojú fún wọn, bá wọn wí kí wọ́n lè ní igbagbọ tí ó pé.
12) yatọ si ọjọ kọ́kàndínlọ́gbọ̀n, osu kárùn ún (May 29) ti won maa n se tẹlẹ
leta ti alaga egbe PDP, Uche Secondus se kọọ si abenugan ile igbimo asofin
Wọ́n wọ aṣọ funfun, wọ́n dé adé wúrà.
Nítorí náà, èmi, OLUWA Ọlọrun fúnra mi, ni mo dójú le yín, n óo sì ṣe ìdájọ́ fun yín lójú àwọn orílẹ̀-èdè.
Ògo ni fún ẹni tí ó lágbára láti mu yín dúró gbọningbọnin, gẹ́gẹ́ bí ìyìn rere ati iwaasu nípa Jesu Kristi ti wí ati gẹ́gẹ́ bí àdììtú tí Ọlọrun dì láti ayérayé, ṣugbọn tí ó wá tú 
Dokita naa ni oyin mẹrẹrin lo ṣi wa laaye lasiko yii.
Kí ló mú Olorì Badrat Ajoke kúrò ní ààfin Oyo lọ́jọ́ Iléyá?
Akọrin ni Ledward, ileewe giga Carlifornia State lo lọ.
Ninu atejade kan eleyi ti akowe agba nile ise gomina, ogbeni Habib Aruna bowolu so pe, ogbeni Okunola yoo ropo iyaafin Folasade Sidikatu Adesoye to feyin ti lojo ketadinlogbon, osu kejila, odun ti a wayii.
Oríṣun àwòrán, Instagram/@nairamarley Àkọlé àwòrán, Naira Marley Wo àwọn ohun tó yẹ kóo mọ̀ nípa Naira Marley Ta ni Naira Marley jẹ́ gan an?
Ati pe Kabiesi funrarẹ n kọ awọn ọmọ ni iṣẹ eto ijọba ti a n pe ni 'Government' ni eyi ti wọn si n ṣe daadaa.
Ẹ̀yin tí ẹ ti jẹ́ àlejò ati ọ̀tá ninu ọkàn yín nípa iṣẹ́ burúkú yín 
Buhari sọ fun awọn Aarẹ tẹlẹri naa pe, gbogbo ohun ti awọn oluwọde n beere fun ni ijọba oun ti gbọ, awọn yoo si ṣiṣẹ le lori.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Wole Soyinka sọ ìdí tó fi ni òun a fi màálù Fulani ṣe súyà fáwọn èèyàn abúlé Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Wole Soyinka sọ ìdí tó fi ni òun a fi màálù Fulani ṣe súyà fáwọn èèyàn abúlé 4 Bélú 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 23 Owewe 2020 Wole Soyinka: Fraternity táwa bẹ̀rẹ̀ ní ìtàn tirẹ̀ ṣùgbọ́n .
"Mustapha ni ofin ti wọn yoo gbe kalẹ lawọn ijọba ibilẹ ọhun ni wọn pe ni ""isede pato""."
Kì í ṣe èso tí ó lè bàjẹ́ ni a fi tún yín bí bíkòṣe èso tí kò lè bàjẹ́, tíí ṣe ọ̀rọ̀ Ọlọrun tí ó wà láàyè, tí ó sì wà títí.
Wọ́n ń lé ọpọlọpọ ẹ̀mí èṣù jáde, wọ́n ń fi òróró pa ọpọlọpọ aláìsàn lára, wọ́n sì ń mú wọn lára dá.
Ọkọ Toyin Abraham pẹ́ ọ̀rọ̀ sọ lórí aáwọ̀ láàrin ìyàwó rẹ̀ àti Lizzy Anjorin Folashade Yemi-Esan, ohun tó yẹ kóo mọ̀ nípa adarí ẹ̀ka òṣìṣẹ́ ọba tuntun Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, South Africa: Àwọn ọmọ Nàìjíríà tó kù ní ìjọba SA ń kó ọ̀pọ̀ tó fẹ́ wále sí ọgbà ẹ̀wọ̀n Wumi Toriola ati Toyin Abraham Oríṣun àwòrán, Toriola Àkọlé àwòrán, Wumi Toriola Lara ọ̀rọ̀ to jẹ okunfa ija laarin Wumi Toriola ati Toyin Abraham ni awuyewuye pe ọrẹ Wumi iyẹn Seyi Edun gba ọkọ ti Toyin Aimaku n fẹ tẹlẹ, Adeniyi Johnson.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: 'Buns ni ọmọ mi jẹ tán ní ṣọ́ọ̀ṣì, ló bá di àwátì' Iná mọ̀nàmọ́ná lọ fún wákàtí 24 ní Ghana, lariwo bá sọ!
Gomina Dapo Abiodun fikun un wi pe Igbakeji Aarẹ Orilẹede Naijiria, Yemi Osinbajo naa ti fi ẹdun rẹ ranṣẹ si awọn eniyan ipinlẹ ọhun.
"'Penis Fish"", ẹ̀ja tuntun tó rí bí ǹkan ọmọkùnrin lùwẹ̀ jáde lórí òkun Àìsàn tó ń ṣe mí kìí ṣojú lásán!"
Ajo eleto idibo INEC lo soro yii lasiko ti egbe PDP
65 A kò gbọdọ̀ yan ẹnikẹ́ni sí ipò kankan nínú ìjọ yìí, níbití àkójọ ẹ̀ka dáradára ti ìkannáà wà, láì sí ìbò ìjọ náà;
Amọṣa ajọ ajafẹtọ kan to n gbogun ti ijẹkujẹ, SERAP ti ni awọn mẹrin kan ni ọta orilẹ-ede Naijiria.
O ni awọn ileejọsin maraarun ni wọn ti ti pa.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù India: Idán yíwọ, Chanchal Lahiri kú sómi gbe 17 Òkùdu 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 18 Òkùdu 2019 Àkọlé àwòrán, Chanchan Lahiri Apidan India kan ti wọ́n gbe ju sinu odo pẹlu ṣẹ́kẹ́ ṣẹkẹ̀ lọ́wọ́ lẹ́sẹ̀ pẹlu ero lati lefo pada lori omi ti gba ibẹ ku.
Oríṣun àwòrán, Diane Reeve A fẹ ki wọn o da a duro, ko maa ba a tun ko aarun naa ran awọn obinrin miran.
Èmi pàápàá ti yi ìwà mi padà, n kò hùwà bi ti ilé Òmùgọ́parapọ̀ mọ́, oṣù mẹ́ta mẹ́ta ni mò ń run orin nísisì yìí, oṣù mẹ́ta mẹ́ta ni mò ń ré èékán mi, ti mò ń wẹ̀, ti mo sì ń tọ́jú irun orí mi.
O ni: “A ti gba iyonda fun ise akanse ni Abuja fun ile ise to n pese omi eyi to je etalelaadorin milionu o le nigba owo naira fun ile ise ti yoo pese re.
Oṣu kẹta ọdun 2020 ni awọn ọdọ kan ni Kano ti kọkọ ṣe ifẹhonuhan lori iru ijiya to yẹ Yahaya nitori ọrọ odi to sọ si Anọbi.
igbimo asoju ati ile -adajo yoo da duro labe ofin nipa eto inawo won, ki eto
Lara ohun elo ti wọn ri gba pada lọwọ awọn afurasi naa ni ẹrọ amunawa kekere kan, aago ara ogiri mẹsan an, alupupu Bajaj kan, alupupu Hero marundinlaadoje ati alupupu TVS kan pẹlu nọmba iforukọsilẹ DGB 215QK.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Nigeria vs Benin: Àwọn ọmọ Nàìjíríà bu ẹnu ẹ̀tẹ́ lu NTA lórí ìgbóhùnsáfẹ́fẹ́ wọn 14 Bélú 2019 Oríṣun àwòrán, @Ammar_sunkanmi Àkọlé àwòrán, Awọn ọmọ Naijiria bu ẹnu atẹ lu NTA loju opo Twitter pẹlu ami #ShameOnNTA Awọn ọmọ Naijiria ti fi aidunnu wọn han lori itakunn ayelujara lori bi ileeṣẹ amohunmaworan orilẹ-ede yii, NTA, ṣe ṣafihan ifẹsẹwọnṣẹ laarin ikọ Supper Eagles ati ti Benin lana.
Bakan naa, o ni abala ofin kan wa to ṣalaye ilana ati yọ adajọ agba eyi to si ye yekeyeke.
 Ti ojo ba ro, o maa n je ki agbara san iyepe ile lo nitori pe ile maa n sa ni ti won ba ti sun nkan lori e.
" Bẹẹ ba si gbagbe, Sẹnatọ Abbo yii ni ẹnu n kun lati ọdun to kọja lori ẹsun pe o lu obinrin kan ninu ile itaja, ti fidio naa si gba ori ayelujara kan.
” Wọ́n ṣe bẹ́ẹ̀, ni wọn kò bá lè fa àwọ̀n mọ́, nítorí ọ̀pọ̀ ẹja.
Odunlade, Toyin dásí ìwọ́de #EndSARS, Mercy gbébọn Oríṣun àwòrán, Instagram/Kunle Afod Ọrọ ifẹhonuhan awọn ọdọ lori ati fi opin si ọlọpaa SARS ati SWAT ti ijọba ṣẹṣẹ yi orukọ wọn pada si ko yọ ẹnikankan silẹ mọ o.
Aminoni tí ìyá rẹ̀ ń jẹ́ Ahinoamu, ará Jesireeli, ni àkọ́bí.
Àkọlé àwòrán, Pipatẹ ọja lẹgbẹ titi jẹ nnkan ti o n kan awọn alaṣẹ lominu nitori ewu to wa nibẹ ti ọkọ ba yawọ Pipatẹ ọja lẹsẹ titi jẹ nnkan ti awọn alaṣẹ a ma lọgun tantan fun awọn ọlọja paapa lawọn adugbo ibi ti ọna ba ti họ.
Kò sí àjòjì darandaran kankan ní Nàìjíríà -NIS Ta ni Ààrẹ orílè-èdè Egypt, Morsi tó kù nílé ẹjọ́?
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ìtàn Olaniyi Balogun, ọ̀jọ̀gbọ́n tó fi Nàìjíríà sílẹ̀ lọ gba iṣẹ̀ àgbẹ̀ l'Ámẹ́ríkà Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Má jẹ́ kí ó ni ọ́ lára láti dá a sílẹ̀ kí ó sì máa lọ lọ́fẹ̀ẹ́, nítorí pé, ìdajì owó ọ̀yà alágbàṣe ni ó ti fi ń sìn ọ́, fún odidi ọdún mẹfa.
Ẹni tí ó ta talaka lọ́rẹ kò ní ṣe aláìní,ṣugbọn ẹni tí ó fojú pamọ́ fún wọn, yóo gba ègún.
ṣugbọn a ti ṣetán láti lọ sí ojú ogun nípa àṣẹ OLUWA.
Ẹ ranti pé ẹ ti jẹ́ ẹrú rí ní ilẹ̀ Ijipti.
 ní ọdún 1920 , ó rí ànfàní láti ṣiṣẹ ́ ní ilẹ ̀ nàìjíríà gẹgẹ ́ bí ọlọ ́ jà ní nwaniba , lópòópónà cross river .
Ileeṣẹ Bristow ni atunto ti awọn ṣe ni ileeṣẹ naa, lo fa ki awọn le awọn oṣiṣẹ to le ni ọgọrun naa.
Lẹyin idunadura ni wọn wa din owó naa ku si ọgbọn biliọnu naira le ni ọọdunrun ni eyi ti wọn fun MTN lọdun mẹta lati san.
akori re ni “ ọgọ́rùn ún ọdun ,ilakaka fun isẹ, iwa omoluabi
Àwọn eniyan burúkú a máa sá,nígbà tí ẹnikẹ́ni kò lé wọn,ṣugbọn olódodo a máa láyà bíi kinniun.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Nikesuliat: Ọ̀dọ́mọdébìnrin akéwì tó n fi ẹ̀ṣà kìlọ̀ ìwá lásìkò yìí Fọ ọwọ rẹ, ki o si fi oogun apakokoro fọ ọwọ rẹ.
Ìwọ ni baba ewúrẹ́, ìwọ ni baba wọn, ìwọ ni baba ọmọdé, ìwọ ni baba wọn, ìwọ ni baba àgbà, ìwọ ni baba wọn, ìwọ ni baba ènìyàn, ìwọ ni baba wọn, ìwọ ni baba ènìyàn, ìwọ baba wọn abbl.
Àwọn iranṣẹ ọba Asiria tún sọ ọ̀rọ̀ burúkú sí OLUWA Ọlọrun ati sí Hesekaya, iranṣẹ rẹ̀.
je lopolopo wi pe, pelu gbogbo oro isiti lati tako  amulo egbogi oloro lawujo paapaa julo laarin odo,
Buhari gb'alejo asoju orilẹede South Africa Alukoro ẹgbẹ́ àwọn ọmọ ilẹ̀ Nàíjììrà tí wọ́n ngbé orílẹ̀èdè South Africa Habib Miller sọ ọ́ di mímọ̀ pé ọmọkùnrin náà di olóògbé látàrí ìwà àífẹ́rí ẹ̀yà mìíràn tó gbòde kan nílẹ̀ náà.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Lizzy Anjorin vs Toyin Abraham: Àwọn àgbààgbà ẹgbẹ́ òṣèré tíátà fa ìbínú yọ 21 Owewe 2019 Oríṣun àwòrán, MRLATIN Awọn agbaagba ẹgbẹ oṣere tiata Yoruba ti jawe joko jẹẹ le Lizzy Anjọrin ati Toyin Abraham, awọn oṣere meji ti wọn n tahun si ara wọn lati bi ọjọ mẹta bayii lori ikanni ayelujara.
5 119640 Orilẹede Dominican Republic 2432 22.
Ọjọ Ẹti ọjọ kọkanla oṣu kejila ọdun 2020 yii ni deedee aago mẹrin irọlẹ ni iroyin sọ pe wọn pa oloṣelu ọhun lori alupupu, lẹyin to kuro ni oko rẹ pẹlu ẹni ti o ba n mojuto oko naa.
Koda iye owo gbajuẹ to n ṣe lati inu ẹwọn la gbọ pe o to miliọnu dọla kan.
 ohun gbogbo ń lọ ní mẹ ̀ lọ ̀ -mẹ ̀ lọ .
Ó tún lóyún, ó sì tún bí ọkunrin, ó ní, “Ọkọ mi gbọdọ̀ faramọ́ mi wàyí, nítorí pé ó di ọkunrin mẹta tí mo bí fún un”, nítorí náà, ó sọ ọmọ náà ní Lefi.
Lẹ́yìn náà, ó lọ títí dé Asimoni, ó tọ ipa odò Ijipti, ó sì pin sí Òkun Mẹditarenia.
Sibẹ wọn ti gbe koto si ẹgbẹ kọnga ti ọmọ naa ko si, wọn si n fi ẹrọ igbalode fa omi inu kanga naa sita.
Wọn ṣakiyesi wipe, ko si ounjẹ kankan ninu ile naa ti wọn si ri oku ọmọdekunrin naa ti ko ni omi kankan lara.
Ohun tí eniyan ń gbé gẹ̀gẹ̀, ohun ẹ̀gbin ni lójú Ọlọrun.
Ko ṣeku, ko ṣẹyẹ Lasiko ipolongo lati di oludije fun ẹgbẹ osẹlu Democrat, awọn alatako Biden wa lati igun apa osi, pẹlu Bernie Sanders ati Elizabeth Warren.
Bí a ti ṣe pín iṣẹ́ fún àwọn aṣọ́nà nìwọ̀nyí: Meṣelemaya, ọmọ Kore, ní ìdílé Asafu, ninu ìran Kora.
Bakan naa ni o ni ọkunrin ohun ba mọto Hinda Accord pelu ami idanimọ LSD 655 EV, to jẹ ti Kazeem Ajiboye jẹ pẹlu.
Titi di bi a ṣe n sọrọ yii ko tii si ẹni lee sọ bi iku rẹ ṣe jẹ.
Gbogbo èyí ṣẹlẹ̀ kí ọ̀rọ̀ tí OLUWA ti sọ láti ẹnu wolii nì lè ṣẹ pé, 
Amosa, ogbeni  Kassim ko sọrọ nipa isẹlẹ naa.
’ rèé Ìgbín ní èmi àti ìyá mi máa ń he kiri, ká tó lee jẹun - Lizzy Anjọrin Àríyá ò lópin láti ìgbà tí Nàìjíríà ti júwe ilé fún South Africa Wo ìdí tí àwọn obìnrin kan fi n yọ ilé ọmọ wọn kúrò Ọpọlọpọ awọn ọmọ Naijiria lo ti n sọ fun awọn agbofinro lati ṣe ohun to yẹ ki wọn gbajumọ eto aabo Naijiria.
Ẹnu ya àwọn eniyan, nígbà tí wọ́n rí i tí àwọn odi ń sọ̀rọ̀, tí àwọn amúkùn-ún di alára líle, tí àwọn arọ ń rìn, tí àwọn afọ́jú sì ń ríran.
Afọnja, ẹni tó finú wénú ní Ilọrin, àmọ́ tó jẹ iwọ Ǹjẹ́ ewu wà nínú lílò ẹ̀rọ FaceApp?
Ẹ̀yin ọmọde, mo kọ ìwé si yín, nítorí pé ẹ ti mọ Baba.
Ọpọ ọmọ ilẹ Amẹrika lo koro oju si bi Trump ṣe n sọrọ ko bakungbe ni gbogbo igba.
Nigbati ìnáwó rẹpẹtẹ fún igbeyawo bẹ̀rẹ̀, àwọn ẹlòmíràn bẹ̀rẹ̀ si jẹ igbèsè lati ṣe igbéyàwó pàtàki igbéyàwó ti Olóyìnbó ti a mọ si igbéyàwó-olórùka.
Ki lo fa sababi iku Kudirat gan an?
Nigeria yoo maa koju Croatia, Iceland ati Argentina ni ipele akoko ifigagbaga idije naa.
 Ọ ̀ rọ ̀ yìí dá yánpọn-yánrin sílẹ ̀ ní ààrin wọn2 .
Jesu ń rìn kiri ní gbogbo àwọn ìlú ati àwọn ìletò, ó ń kọ́ àwọn eniyan ninu àwọn ilé ìpàdé, ó ń waasu ìyìn rere ìjọba Ọlọrun, ó sì ń wo oríṣìíríṣìí àrùn ati àìlera sàn.
Lẹ́yìn náà ó mú mi wá sí ẹnu ọ̀nà ìta ibi mímọ́ tí ó kọjú sí ìlà oòrùn, ìlẹ̀kùn ẹnu ọ̀nà náà wà ní títì.
Ẹni to bori: Tunisia Namibia vs Algeria.
À ṣe àkójọ-èdè-fáyẹ ̀ wò láti ọdọ ̀ àwọn ọ ̀ kọrin .
Ẹ dìde, ẹ ya àwọn eniyan náà sí mímọ́; kí ẹ sì wí fún wọn pé, ‘Ẹ ya ara yín sí mímọ́ fún ọ̀la, nítorí pé OLUWA Ọlọrun Israẹli ti sọ pé àwọn ohun ìyàsọ́tọ̀ wà láàrin ẹ̀yin ọmọ Israẹli.
Ti mo ba fẹ ohunkohun lati kekere, mo gbọdọ sisẹ fun ni, eleyi si lo ran mi lọwọ lati sisẹ kara fun owo.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Abiola Ajimobi: Igbákeji ààrẹ sàbẹwò sí ìyàwó Ajimọbi 2 Ògún 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 8 Ògún 2020 Oríṣun àwòrán, others Ọjọ nii pẹ, ipade kii jinna, ki Ọba oke maṣe jẹ ka jẹ gbese.
Wọ́n ń wí pé, “Baali, dá wa lóhùn!
Àwọn ọmọ wolii náà lọ sọ ohun tí wolii tí ó wá láti Juda ṣe ní Bẹtẹli ní ọjọ́ náà fún baba wọn, ati ohun tí ó sọ fún Jeroboamu ọba.
Ọpọlọpọ lo ti fi si oju opo twitter wọn ohun to n ṣẹlẹ ni afara Otedola bayii Wọn ni ọkọ agbepo mejeeji naa ni epo rọbi wa ninu wọn.
ifowopamo agba lorile-ede Naijiria, Central Bank of Nigeria, CBN, eyi ti iye re
Pilatu bá tún wọ ààfin lọ, ó bi Jesu pé, “Ṣé ìwọ ni ọba àwọn Juu?
Àlààyé rèé lórí ìdí ta fi gbé ìlẹ̀kùn olú iléeṣẹ́ APC tì pa l‘Abuja Ohun tí ọlọ́pàá ń ṣe rèé láti sàwárí àwọn ‘mùjẹ̀-mùjẹ̀’ ní Akinyele Ohun tí a mọ̀ nìyí nípa àwọn tí yóò láǹfàní àti lọ sí Hajj lọ́dún yìí Wó ohun tó ṣokùnfà ọkọ̀ ojú omi to dójúdé l'Eko Nigba to n ṣalaye alakalẹ gbogbo ibi ti wọn na owo yii si kaakiri iṣọri iṣọri, kọmiṣọnna eto isuna ipinlẹ Oyo, Akinola Ojo sọ ipinnu ijọba ni pato.
Gbogbo àwọn eniyan bẹ̀rẹ̀ sí ké, wọn sì fi gbogbo òru ọjọ́ náà sọkún.
 Nitooto, egbe yii ti se awon ohun maleegbagbe lati igba ti a ti gori aleefa, bii, tita awon ipin idokowo olodun mejila ati Ologun odun ati fifun owo naira lagbara ki a to so fifi owo pamo si asunwon ile okeere wa lati ogun bilionu owo dola si ogoji bilionu dola, sugbon ise si po niwaju wa lati se ki a le fi mu gbogbo ileri wa se fun iran yii atawon to m bo.
Netaneli ọmọ Suari ni yóo jẹ́ olórí láti inú ẹ̀yà Isakari.
O ni orile ede Naijiria ti seto ilana owo to le ni bilionu meja dola lati fi satunse si awon ekun ti iko boko Haram bajẹ.
Bóyá ó sùn ni, ẹ sì níláti jí i.
Won kò fẹ́ kí ó kọ́ àwọn ọmọ wọn ni iṣẹ́ olè jíjà, ọ̀rọ̀ rẹ̀ tilẹ̀ ti sú wọn.
lasiko ipolongo ibo aare ti egbe PDP to waye niluu Port Harcourt,ni ipinle Rivers.
O tun fi idi rẹ mulẹ pe, ajọsepọ to dan mọran wa laarin awọn osere ori itage to wa ninu ẹgbẹ ANTP ati Tapan.
Lóòótọ́ ọ̀rọ̀ òtítọ́ ní agbára,ṣugbọn kí ni ẹ̀ ń bá mi wí lé lórí.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ìtàn rèé nípa bí Ogbomoso ṣe pa ọba, yọ nǹkan ọkùnrin rẹ jó kiri ìlú Aáwọ̀ oyè PDP gbé Fayose àti Seyi Makinde kọlu ara wọn, ìjà ń bọ̀ Ènìyàn mẹ́ta pàdánù ẹ̀mí wọ́n lọ́wọ́ àrùn Coronavirus ní Nàìjíríà ní Ọjọ́ọ̀rú Bí nǹkan ọkùnrin bá há sójú ara obìnrin, kìí ṣe Mágùn, ẹ má páyà Bàbálọ́jà márùn ún la ó ò ní l'Oyo tí Makinde bá lè buwọ́lu ìyànsípò YK Abass Ìjọba, e yé dẹ́yẹ sí wa mọ́, àwọn ẹlẹ́sìn ìbílẹ̀ ṣèwọ́de n'Ibadan Auxiliary gbé èèyàn mẹ́fà tó ń jáwèé ayédèrú fáwọn awakọ̀ lọ sí ilèẹjọ́ ní Ibadan Lara awọn eeyan to yọju lati gba isẹ naa la ti ri awọn ọmọ ẹgbẹ Agbẹkọya, ọdẹ, Fijilante, ọmọ ẹgbẹ OPC, awọn ọdẹ Soludero atawọn eeyan miran.
Amir:Akọkọ oye lẹyin Anọbi ree, o tumọ si asiwaju abi apasẹ, Amir si ni wọn sọ di Emir.
A fi bi igba ti eeyan n lọ sinu oṣupa ni ọkunrin yii bo imu, oju ati ẹnu rẹ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Egbò tó ti fẹ́ẹ̀ jiná ni ìtàn bí wọ́n ṣe pa Soun Ogbomoso, Ọba Olayode tẹ ń bèrè' Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Sẹnẹtọ Muhammed Sani Musa lati ipinlẹ Niger lo ṣagbatẹru abadofin naa.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Alleged incest: Ọkùnrin kan dèrò àtìmọ́lé lórí ẹ̀sùn fífi ipá bá ọmọ bíbí inú rẹ̀ méjì lájọṣepọ̀ ní ìlú Akure 3 Ògún 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 26 Èbibi 2020 Oríṣun àwòrán, Sola Ilesanmi Ọkunrin kan, Femi onifade, ti dero atimọle ajọ abo araẹni labo ilu, NSCDC lẹyin ti wọn fẹsun kan an pe o fipa ba awọn ọmọ rẹ obinrin meji lopọ.
A wí fún ún pé kí ó ṣe ìtọ́jú ìlú náà dáadáa àti wí pé àwa ó fi ibẹ̀ sílẹ̀ ní ìkáwọ́ rẹ̀ kí a lọ sí Igbó Elégbèje.
fun awon omo ile-iwe ,owo iranwo fun awọn ọlọja , ipese eto aabo ati awọn nnkan
Olaitan Shittu to jẹ aṣoju minisita ere idaraya lo fọrọ naa lede l'Ọjọru nigba to ṣabẹwo si Alhaja Yekini niluu Ijagbo nipinlẹ Kwara.
Idije to waye ni Ilu Abu Dhabi, ni orilẹede United Arab Emirates naa yẹ ko jẹ ija laarin Usman ati Gilbert Burns ni, amọ o lugbadi arun Coronavirus ni ko ṣe le kopa ninu ija naa.
Lopin ọsẹ to kọja ni iroyin gbe e pe gomina Abiola Ajimọbi da Yewande silẹ nigba to ku bi ọsẹ kan ti yoo kuro ni ipo gomina.
Gómìnà Willie Obiano lọ forí balẹ̀ f'órí adé Fayoṣe lo òpin ọ̀sẹ̀ lẹ́wọ̀n Iyaafin Ajibola Otubusin salaye pe orisirisi aisan l'oun ba finra fun ọdun marundinlogoji eleyi ti ko jẹ ki oun tiẹ lero pe oun le finu ṣoyun.
Angẹli náà bá sọ fún mi pé kí n lọ kéde pé OLUWA àwọn ọmọ ogun ní, “Mo ní ìfẹ́ ati ìtara tí ó jinlẹ̀ pupọ fún Jerusalẹmu ati Sioni.
Ajọ NCDC ṣalaye pe mẹta ninu awọn eeyan wa lati ipinlẹ Eko nigba ti ẹyọkan to ku wa lati olu ilu orilẹede Naijiria, Abuja.
Mímọ́ ni, ẹ sì gbọdọ̀ kà á sí mímọ́.
Oríṣun àwòrán, @NigAirForce Àkọlé àwòrán, Ijọba apapọ apapọ ti kede saaju wipe afikun ti de ba awọn ọmọogun to wa nilẹ lati wa awọn akẹkọ to sọnu Atẹjade kan ti minisita feto iroyin lorilẹede Naijiria, AlahajiLai Muhammed fisita ni, asẹ yii ko se lẹyin ipinnu ijọba lati fẹ eto awari awọn akẹkọ naa loju kọja ipinlẹ Yobe bọ si awọn ipinlẹ gbogbo to yii ka.
Ní àkókò tí Peka jọba Israẹli ni Tigilati Pileseri, ọba Asiria, gba ìlú Ijoni, Abeli Beti Maaka, Janoa, Kedeṣi, Hasori, ati ilẹ̀ Gileadi, Galili ati gbogbo ilẹ̀ Nafutali, ó sì kó àwọn eniyan ibẹ̀ lẹ́rú lọ sí Asiria.
Nibayii, ọjọ karun-un, oṣu Kẹsan an, ni irinajo baalu silẹ okeere yoo bẹrẹ pada.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ìtàn ìgbé ayé Isola Ogunsola, akọni mánigbàgbé òṣèré tíátà, olórin àti onílù Ma a pa ara mi si Cute Abiola lọrun bo ṣe já mi silẹ tori afẹsọna miran"" ""Àwọn akẹ́kọ̀ọ́ àgbà fipá bá ọmọkùnrin mi lòpọ̀ níléèwé Deeper Life, mò ń fẹ́ ìdájọ́"" Kí ló fa gbas-gbos láàrín Davido àti Burna boy lórílẹ̀èdè Ghana?"
Awọn akẹkọ fasiti Yusuf Maitama Sule ni Kano to fẹ ṣe iwọde naa lero wi pe ijọba yoo gbe igbesẹ kiakia lori ọrọ Zainab ki o ba le pada wa sile.
ISIS àti Boko Haram fẹ́ ṣoro lásìkò ìbò 2019 - Amẹrika Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Atiku ní òun kò dènà kí ọ̀dọ́ kankan dupò ààrẹ ní Nàìjíríà O fikun pe awọn iwe ilana isọwọsisẹ to de ikọ to n gbogun ti iwa idigunjale naa, ni yoo jade laipẹ.
Fani Kayode: Bùhárí ló lẹ̀bi Emir tí Olúwòó ń pe ara rẹ̀
Àwọn Yàrá Tí Wọ́n Kọ́ sí Ẹ̀gbẹ́ Àwọn Ògiri Tẹmpili.
Bakan naa lo sọ pe awọn obinrin kan ko ti ẹ jẹwọ ri pe awọ́n ma n se e tabi wọn ti ṣe e ri.
Wọn ni aifẹ kopa ninu eto ati dan abẹrẹ covid-19 wo le dena ati ri abẹrẹ ti yoo kapa aarun ọhun lagbaaye.
Awọn gbọngan ayẹyẹ gbọdọ ni iwe ẹri ti ijọba ipinlẹ Eko fun wọn ṣaaju ki ayẹyẹ kankan o to waye nibẹ, to fi mọ ontẹ ajọ to wa fun ọrọ abo nipinlẹ Eko.
Awọn to ku ni iṣẹ agbe, eto ẹkọ ati ilera.
", University of Illinois, Chicago (Criminal Law and Political Science, 1997) Ó ṣeéṣe kí àrùn Coronavirus tànkálẹ̀ gba inú afẹ́fẹ́- WHO Bí àrùn Coronavirus ṣe dá gbogbo àgbáyé gúnlẹ̀ sójú kan náà nìyí Lẹ́yìn tí wọ́n fi kakata hú gbogbo iṣú àti ẹ̀gẹ́ mí, wọ́n tún ṣá àwọn ọmọ mi ládàá-Guru Maharaj Ji Wo agbábọ́ọ̀lù Super Eagles Nàìjíríà àkọ́kọ́ tó lùgbàdì coronavirus Awọn ami ẹyẹ to ti gba Rising Star Super Lawyer, 2011 Top 100 Trial Lawyers Association of Trial Lawyers of America, 2010 Top 100 Trial Lawyers Association of Trial Lawyers of America, 2009 Top 100 Trial Lawyers American Trial Lawyers Association, 2007 Cum Laude John Marshall Law School, 2000 Honors University of Illinois, Chicago, 1997 ""10 Best Client Satisfaction"" attorneys by the American Institute of Criminal Law Attorneys ""Top 100 Trial Lawyers: Illinois"" by The American Trial Lawyers Association O si ṣeeṣe k Ramoni Abbas Olorunwa, ko ṣe to ogun ọdun l'ọgba ẹwọn, ti ile ẹjọ ba fi sọ pe o jẹbi awọn ẹsun ti wọn fi kan an."
Liverpool fi àjẹkù pàṣán Chelsea na Southampton mọ́lé Siasia ń gbèrò àti gbé FIFA lọ sí ilé ẹjọ́ Lampard wọ gàu!
Nítorí náà, mo wá pàdé rẹ,mo fi ìlara wá ọ, mo sì rí ọ.
Oríṣun àwòrán, Facebook/Seyi Makinde Gomina Ipinlẹ Oyo, Seyi Makinde ninu ọrọ ikẹdun iku onisoowo yii sọ pe ''baba to bi mi ma n gbadura pe ki n dabi Oloye Akindele ni, ti mo ba dagba tan'' Makinde sọ pe, Oloye Akindele lẹni to da owo to pọju fun ijọba lati koju ajakalẹ arun Covid 19.
Àwọn alufaa a máa dúró lojoojumọ láti ṣe iṣẹ́ ìsìn wọn, láti máa rú ẹbọ kan náà tí kò lè kó ẹ̀ṣẹ̀ lọ nígbàkúùgbà.
To ba wu u, ko yọju si wọn, to ba wu u, ko ma yọju.
8 Nítorínáà, má ṣe iyè méjì, nítorí ẹ̀bùn Ọlọ́run ni; ìwọ yíò sì dìí mú ní ọwọ́ rẹ, láti ṣe àwọn iṣẹ́ yíyanilẹ́nu: àti pé kò sí agbára tí yíò lè gbàá kúrò ní ọwọ́ rẹ, nítorí iṣẹ́ Ọlọ́run ni.
Oniruuru iṣoro lo koju ipese ẹbun ile naa nigbanaa nitori ọtọọtọ ni ibi ti awọn ti ọrọ kan ti fẹ ki ile wọn wa ki o to di pe olori iṣejọba nigbanaa dagbere faye.
Ọmọ ọdún mejì yìí kò dé iléèwé rí, àmọ́ ó mọ olú ìlú orílẹ̀-èdè ogójì àti àwọn ìṣẹ̀lẹ̀ mii tó wà láyé.
E̩nìké̩ni tí a fi è̩sùn kàn ni a gbo̩dò̩ gbà wí pé ó jàrè títí è̩bi rè̩ yóò fi hàn lábé̩ òfin nípasè̩ ìdájó̩ tí a s̩e ní gban̄gba nínú èyí tí e̩ni tí a fi è̩sùn kàn yóò ti ní gbogbo ohun tí ó nílò láti fi s̩e àwíjàre ara rè̩.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Noosi Morne to jẹ baba Zephany gangan nigba ti o n jade nile ẹjọ lẹyin ti Adajọ ti dajọ Miche Solomon to jẹ orukọ ti wọn sọ ọ ni kekere ni o n jẹ, amọ o sọ wi pe o tẹ oun lọrun ki awọn eniyan pe oun ni Zephany naa, nitori orukọ oun gangan niyẹn.
Ọgbni Toby sọ pe lori ki wọn kan fin ogun pako pako lo wu awọn nkan to n faya fa yii jade sita ninu ile naa.
Awọn gomina to n ji owo eto abo ti wọn si n jẹ gaba lori araalu 4.
Kí olukuluku wà ní ipò tí ó wà nígbà tí a pè é láti di onigbagbọ.
Àmọ́, diẹ lara mọlẹbi wọn tako idajọ iku naa, ti wọn si fẹ ki wọn da a duro na, nitori kikopa nibẹ le fi wọn sinu ewu coronavirus.
Nǹkan kékeré ni èyí jẹ́ níwájú OLUWA, yóo fun yín ní agbára láti borí àwọn ará Moabu.
N óo fi ebi pa wọ́n ní àpakú,iná yóo jó wọn ní àjórun,n óo sì fi àjàkálẹ̀ àrùn pa wọ́n run.
Nǹkan mẹ́wàá tó yẹ ní mímọ̀ nípa fásitì ẹ̀kọ́ ìrìnnà òní $50m ní Nàìjíríà Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Waris Kareem: Emmanuel Macron kan sáárá lórí àwòrán tó yà Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 3 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 5 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Jaeli bá mú òòlù kan, ati èèkàn àgọ́, ó yọ́ kẹ́lẹ́kẹ́lẹ́ lọ sí ibi tí Sisera sùn sí, ó kan èèkàn náà mọ́ ọn lẹ́bàá etí títí tí èèkàn náà fi wọlé, ó sì kú.
Oyo House: Ilé ìgbìmọ̀ Ìpínlẹ̀ Oyo buwọ́lu ìyànsípò kọmíṣọ́nà mẹ́rìnlá àtàwọn míì
Díẹ̀díẹ̀ ni Ọlọrun yóo lé àwọn orílẹ̀-èdè yìí lọ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Akomolede ati Aṣa lori BBC: Mọ̀ si nípa oríṣìí ẹ̀ka ìsọ̀rí ọ̀rọ̀ àti ìwúlò wọn Bẹẹ lawọn eeyan miran tun ki oriki iku pe o tun ti doro bi o se maa n daa: Ikú dóró ikú ṣìka pẹlu adura pe ki baba Sùn un re ó.
Ademọla Adeleke, Fayoṣe, Atiku sọ̀rọ̀ lórí ìdájọ́ ilé ẹjọ́ Ilé ẹjọ́ kòtẹ́milọ́rùn yá lórí ọ̀rọ̀ Adeleke- PDP Ilé ẹjọ́ ń retí ìwé ẹ̀rí Fásitì Sẹ́nétọ̀ Adeleke Ilé ẹjọ́ gba onídúró Sẹ́nétọ̀ Ademọla Adeleke Koda gbajugbaja olorin takasufe Davido ti Adeleke jẹ ibatan rẹ fi ikini soju opo Twitter rẹ lati ba Adeleke yọ lori ohun ti ile ẹjọ wi yi.
Amugbalẹgbẹ fun aarẹ, ẹni to foju laifi wo ọrọ ti Kanu n gbe kiri yii, tun se apejuwe ọrọ naa bii ero awọn omugọ, eyi ti ọpọ ọlọgbọn gan tun n gba a gbọ pẹlu.
Ó rán mi pé kí n máa tu àwọn tí ó ní ìbànújẹ́ ninu,kí n máa kéde ìdásílẹ̀ fún àwọn tí ó wà ní ìgbèkùn,kí n sì máa ṣí ìlẹ̀kùn ọgbà ẹ̀wọ̀n sílẹ̀ fún àwọn ẹlẹ́wọ̀n.
Àwọn ọmọ rẹ yóo pọ̀ bí erùpẹ̀ ilẹ̀, o óo sì gbilẹ̀ káàkiri sí ìhà ìwọ̀ oòrùn ati sí ìhà ìlà oòrùn, sí ìhà àríwá ati sí ìhà gúsù nípasẹ̀ rẹ ati àwọn ọmọ rẹ ni n óo bukun aráyé.
” Wọ́n bá ń tẹ̀lé e lọ, wọ́n gba ibi tí ó ṣe é fi ẹsẹ̀ là kọjá níbi odò Jọdani mọ́ àwọn ará Moabu lọ́wọ́, wọn kò sì jẹ́ kí ẹnikẹ́ni kọjá.
ile-ise epo robi(GMD NNPC), alaga ajo to n mojuto owo ori abbl.
Iroyin fi mule pe, bi pasipaaro re se wa ninu osu ti o koja be naa si lo duro soju kan, leyin ti pasipaaro Dola si Naira je ọ́ọ̀dúnrún o leni mọ́kàndínlọ́gọ́ta Naira(N359).
Ṣùgbọ́n Bísọbù Phillips fi hàn ni pé kì í ṣe gbogbo ọmọ Yorùbá ni o ń purọ́.
Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Amotekun: Miyetti Allah ní òun yóò péjú síbi ìpàdé ìta gbangba lọ́jọ́ Ajé láti sọ tẹnu òun22 Èrèlè 2020 Amotekun: Fatomilola ní gaga ọwọ̀ làwọn baba wa fi ń ṣọ́ ilé, òyìnbó ló sọ wá di ọ̀lẹ30 Sẹ́rẹ́ 2020 Amotekun Oyo: Ọwọ́ tẹ ènìyàn méjì tó ń ta ayédèrú asọ iṣẹ́ ikọ̀ Amọtẹ́kùn16 Sẹ́rẹ́ 2021 Operation Amotekun: Ẹgbẹ́ kan rọ Tinubu, láti sọ èrò rẹ lórí ọ̀rọ̀ Amọtẹkun18 Sẹ́rẹ́ 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Nítorí náà, ó yẹ kí àwa náà fi ẹ̀mí wa lélẹ̀ fún àwọn ará.
- Olukoya ti ìjọ MFM Àwọn òṣèré tíátà kan rèé, tí wọn fẹ́ ara wọn, tí ìgbeyàwó wọn sì pẹ́ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ọbẹ Ẹgusi sise ati jijẹ Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Agbo ẹlẹ́dẹ̀ kan wà níbẹ̀ tí ó ń jẹ lórí òkè.
Maryland flyover Ijọba ibilẹ Ikeja / Somolu 24.
Oríṣun àwòrán, Adégbóyèga Adébàjò Àkọlé àwòrán, Awọn agbabọọlu ẹgbẹ Stationery Stores wa kẹdun iku oludasilẹ ẹgbẹ wọn nigba to ku Bi awọn eeyan ṣe n gbadun ere bọọlu lati ẹsẹ awọn agbabọọlu Stationery Stores ni owo n ya wọle fun ile iṣẹ ti o n ba a jẹ orukọ.
Awọn ẹrọ alagbeka to ni oju gilasi ti kii fọ jẹ nnkan nla lagbo imọ tẹkinọlọgi.
Wo orin l'édè Yoruba àti Zulu tí Burna Boy fi fa ayélujára ya Ohun tí a rí nílé Ajimobi rèé lẹ́yìn ìròyìn òfégè pé ó jáde láyé Kini Arabinrin yii fẹ di ni ọjọ iwaju rẹ?
Sugbọn awọn onimó sayẹnsi ni agbaye tun ti n pariwo ajakalẹ arun miran ti wọn ni o m bọ lọna ti o ṣeeṣe ko di nla ni agbaye.
Abayọmi Aranmọlatẹ, Dr Laser: Vagino Plasty àti iṣẹ́ abẹ ẹwà Obìnrin ló jẹ mí lógún Wọ́n kò pa ẹnikẹ́ni sí ààfin Ṣọun Ogbomosọ, òkú tí àwọn ọdọ́ gbé wa ni ọlọ́pàá wọ́ jáde- Agbẹnusọ Ṣọ̀un Wo ìgbà mẹ́rin tí ìjọba ti tú ikọ̀ ọlọ́pàá SARS ká sẹ̀yín ṣùgbọ́n.
Ìyá wo ló bí yìnyín,inú ta ni òjò dídì sì ti jáde?
Bẹẹ bá gbàgbé, a ti mú ìròyìn wá fún yín ṣáájú lọ́jọ́ Aiku, nípa bí àwọn gende agbebọn tí yà wọ ilé Akeugbagold lalẹ ọjọ́ Satide, tí wọn sì gbé àwọn ìbejì rẹ kékeré lọ.
Igbakeji aarẹ tẹlẹ Joseph Boakai ti o fidirẹmi lọwọ Weah ninu idibo aarẹ 2017 lo ba lalejo.
so pe ida kan ninu ida meji owo oko ofurufu ni awon yoo gba lowo awon onibara
Orúkọ rere dára ju òróró olówó iyebíye lọ, ọjọ́ ikú sì dára ju ọjọ́ ìbí lọ.
O nigẹgẹ bi gbogbo eewọ ṣe ni atunbọtan naa ni igbesẹ ọba lati yẹ kuro loju opo iṣẹṣẹ ti eto ijẹọba nilẹ Yoruba dale naa ṣe ni atunbọtan.
Lọdun 2016, àwọn ọmọbìnrin ìbejì, ọmọ ọdún mẹẹdogun ku ni ilu Kumasi, lẹyìn tí wọn sun inu yàrá ti won fin ogún oloro apakokoro si.
Kò ṣẹ̀ṣẹ̀ tún ní pé à ń sọ ohunkohun mọ́.
Wọn ma n ji maalu ati eeyan gbe.
Bóyá Aarun náà yóò dín kù lásìkò erun(Summer)Ofinkin má ń wọ́pọ̀ lásìkò òtútù ju asiko èérún lọ, sugbon a kò tíì mọ bóyá ìtàn kalẹ rẹ yóò dín kù tó bá di igba ẹẹrun.
Mo sun ṣege ẹkun lọjọ akọkọ, ọjọ keji ati ọjọ kẹta, ki n to o gba kamu.
Ọ̀pọ̀lọpọ̀ òwe àti àṣayàn ọ̀rọ̀ tí a máa ń lò ni ó fi bí orúkọ ti ṣe pàtàkì sí hàn.
Ṣugbọn nígbà tí àwọn alágbàro náà rí ọmọ rẹ̀, wọ́n wí láàrin ara wọn pé, ‘Àrólé rẹ̀ ni èyí.
Jẹ́ kí n máa lọ, ìwọ náà ṣá mọ̀ bí mo ti sìn ọ́ tó.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Commonwealth: Ànfàní wo ni Nàìjíríà rí?
Ẹ̀ṣọ́ náà tún rí ẹyọ ẹnìkan, tí òun náà ń sáré bọ̀.
Wọ́n gbọ́ tí wọn ń fi oríṣìíríṣìí èdè sọ̀rọ̀, tí wọn ń yin Ọlọrun fún iṣẹ́ ńlá rẹ̀.
ami fun orile-ede France, aare Macron wa ro awon onigbagbo jake-jado agbaye
Ẹ má wọ bàtà, bẹ́ẹ̀ ni kí ẹ má mú ọ̀pá lọ́wọ́.
"Crystal Palace pàkúta sí gaàrí Manchester United ní Old Trafford Wilfred Ndidi, ọmọ Nàìjíríà pa iná ògo Chelsea ní Stamford bridge Manchester United dáná sun Chelsea bi ẹràn àgbò iléyá ""Ojú wa rí tó ní Egypt, bí wọ́n ṣe ń tẹ̀ wá lọ́mú, ni wọ́n ń gbá wa ní ìdí"" Toyin Abraham kìí bá èmi náà yọ̀, ni kò jẹ́ kí ń gbé e lárugẹ fún ayọ̀ ọmọ - Lizzy Anjorin Ọ̀pọ̀ èèyàn bẹnu ẹ̀tẹ́ lu Mercy Aigbe lórí bó ṣe ki Adeniyi Johnson Ìdí rèé tí mi ò fi yọjú sí ìgbìmọ̀ àjọ PFN- Fatoyinbo Adilemu, Joel Matip lo kọkọ fori kan bọọlu wọ le Arsenal, ki David Luiz to fa Mohamed Salah laṣọ nigba to fẹ gbayo sawọn, ni rẹfiri ba fọn feere pẹnariti."
'Mo fọ́ lójú ṣùgbọ́n mò ń tún àwọn ọkọ̀ tí iṣẹ́ rẹ̀ lè ṣe.
Iwadi ti Hanlon lati Mozambique se fihan wipe, orilẹede Mozambique ni orilẹede kẹta ni agbaye, ti wọn ti n gbe oogun oloro kuro lorilẹede naa lo si omiran pẹlu iranwo oju opo ikansiraẹni Whatsapp.
" Oṣú mẹ́fà ni òṣìṣẹ́ ìjọba tó bá bímọ yóò máa lò nílé kó tó wọṣẹ́ padà- Seyi Makinde Ọ̀rọ̀ ìjókòó ìgbìmọ̀ ìwádìí #EndSARS náà dé ìpínlẹ̀ Ogun ₦50 bílíọ́nù ni a pín fún gbogbo ìpínlẹ̀ ní Naijiria láti kojú àrùn Covid-19- Ìjọba àpapọ̀ Ẹ fún wa lówó oṣù wa tàbí kí a gùnlé ìyanṣẹ́lódì ọlọ́jọ́ gbọọrọ- Àwọn dokita ìpínlẹ̀ Ondo Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Kabex End SARS: Àwọn ìṣẹ̀lẹ̀ tó làmìlaaka tó wáyé nínú oṣù Kẹ́wàá ọdún 20206 Bélú 2020 Oyinkan Abayomi: Ajàfẹ́tọ̀ọ́ ẹni tó dá ẹgbẹ́ òṣèlú obìnrin àkọ́kọ́ sílẹ̀, tó tún jà fún ètò ẹ̀kọ́, ìṣèlú àti òmìnira obìnrin5 Bélú 2020 Yoruba movie: Ẹ wo ohun tí mama Ire, Toyin Abraham ní òun yóò máa fi ìyókù ọdún yìí ṣe6 Bélú 2020 Fídíò, Orlando Owoh: Ayé ti sú mi, àdúrà ikú ìrọ̀rùn ló wù mí- Christiana, Ìyá Orlando Owoh tó ti pé ọdún 1105 Bélú 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 3 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 5 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Jẹ́ kí wọn rí i péọ̀rọ̀ àwọn eniyan rẹ jẹ ọ́ lógún,kí ojú sì tì wọ́n.
Nàìjíríà làwọn ní ìfẹ́ sí ìpèsè abẹ́rẹ́ àjẹsára Covid-19 tí Russia ṣe Wo ọ̀nà ìsanwó tuntun fún àwọn oníbárà iná mọ̀nàmọ́ná ní Eko (EKDC) Àwọn dókítà yóò bẹ̀rẹ̀ ìyanṣẹ́lódí lọ́jọ́ Ajé Olórin Kano tí wọ́n dájọ́ ikú fún pe ẹjọ́ kòtẹ́milọ́rùn Eyi lo tun fidi imọran awọn agba Yoruba mulẹ pe iwọnba leeyan n da si ọrọ lọkọlaya mọ nitori.
Sri Lanka: Gauria ti di ololufẹ Roshan bẹ́ẹ̀ ọ̀tá ni wọ́n nígbà ogun abẹ́lẹ́ Sri Lanka
Ile iwe Ahmadu Bello lo ti lo ile -iwe giga fasiti ni ọdun 1979 to si kẹkọ gboye onimọ nipa eto oselu.
N kò jẹ́ kí òjò rọ̀ mọ́, nígbà tí ìkórè ku oṣù mẹta; mò ń rọ òjò ní ìlú kan, kò sì dé ìlú keji; ó rọ̀ ní oko kan, ó dá ekeji sí, àwọn nǹkan ọ̀gbìn oko tí òjò kò rọ̀ sí sì rọ.
Ẹni tó ni Ẹrú ló ni Ẹrù – Ìtàn Bàbá tó kó gbogbo ogún fun Ẹrú 
Jẹ́ kí adura mi wá sí ọ̀dọ̀ rẹ bíi turari,sì jẹ́ kí ọwọ́ adura tí mo gbé sókè dàbí ẹbọ àṣáálẹ́.
Kí ni kí n ti ṣe ọ́ sí, ìwọ Juda?
O sàpèjúwe ìwà to hù gẹ́gẹ́ bi èyí ti kò bá ìlànà ẹ̀kọ́ Islaamu mu.
Nígbà tí Dafidi jí ní òwúrọ̀, OLUWA rán wolii Gadi, aríran rẹ̀ sí i pé, 
Gẹ́gẹ́ bi ààrẹ Muhammadu Buhari ṣe sọ àjọsepọ náà yóò pèsè ìná mẹ́gà-wáàtì ẹgbẹ́run meje ní ọdun 2021 ti yóò si goke dé ẹgbẹ̀run mọkànlá ni ọdún 2023.
Kò sí ẹ̀rù ninu ìfẹ́; ìfẹ́ pípé a máa lé ẹ̀rù jáde, nítorí ìjayà ni ó ń mú ẹ̀rù wá.
Ó ṣe ìbéèrè lọ́wọ́ ọkùnrin náà ó sì wí báyìí pé: Ọ̀rẹ́, ńjẹ́ obìnrin náà ń bọ̀ láfẹ̀mọ́jú òní?
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ọmọ Yahoo tú àṣírí ara rẹ̀ fún, bí wọ́n ṣe ń ṣe é BBC Yorùbá Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Seyi Makinde: Ọ̀sẹ̀ àkọ́kọ́ ní December ni màá sìnkú ìyá mí
nítorí ẹni tí ó máa fi ọkàn ṣírò owó oúnjẹ ni.
Ìsẹ̀lẹ̀ iná Venezuela: Ẹ̀mí 68 bọ́ ní àgọ́ ọlọ́pàá Valencia
Àwọn tí wọ́n fi ọwọ́ sí ìwé náà tí wọ́n sì fi èdìdì dì í nìwọ̀nyí: Nehemaya, gomina, ọmọ Hakalaya, ati Sedekaya.
Ọmọ ọdún mẹ́wàá ń fọn fèrè lágbo àríyá Ìlú mímọ́ nibí, wọn kò gbọdọ̀ bímọ, sin òkú àbí ẹran síbẹ̀"" Kloe tó lọ sí BB Naija rèé, ó ní òun fẹ́ràn ọkùnrin tó bá dúdú Lẹ́yìn ìfẹ̀yìntì ọdún márùn-ún, báágì àti bàtà ló kàn Ọbasanjọ sọ àsírí sàgbàdèwe rẹ̀ Ìyá àgbà Ọlayinka, arúgbó tó ń ṣoge bí omidan Oluwo ni ipinlẹ Ọsun si n tiraka lọwọ ni, ti ko si dangajia to lati san owo osu to kere julọ tẹlẹ, tii se ẹgbẹrun lọna mejidinlogun naira, eyi to fihan pe omi n bẹ lamu fun wọn, ti yoo si nira lati san owo osu tuntun."
 Ọwọ ́ ọkọ rẹ ̀ , president nestor kirchner ni ó ti gba ìjọba lẹ ́ yìn ìgbà tí wọ ́ n ti dìbò yàn án wọlé ní ilẹ ̀ náà .
 nígbà tí ó bá tiní àkóràn , ìṣàkóso jẹ ́ ti aláámì láìsi ìwọ ̀ n tí ó jáfáfá kankan lòdì sí àkóràn náà .
Nígbà tí àwọn ọmọ Israẹli gbọ́ irú ìdájọ́ tí Solomoni ọba dá yìí, ó mú kí ó túbọ̀ níyì lójú wọn; nítorí wọ́n mọ̀ pé Ọlọrun ni ó fún un ní ọgbọ́n láti ṣe ìdájọ́ ní irú ọ̀nà ẹ̀tọ́ bẹ́ẹ̀.
Oríṣun àwòrán, Google Àkọlé àwòrán, Ọ̀pọ̀lọ̀pọ̀ àwọn olósèré ló ti ń tọrọ àánú láti ọwọ́ àwọn ọmọ Naijiria láti lè fi tójú Baba Suwe tó ń se àìsàn.
Ramadan: ọmọ ọdún mẹ́wàá sọ ìrírí rẹ̀ pẹlú Àwẹ̀
Àwọn iranṣẹ rẹ̀ bi í pé, “Kabiyesi, ọ̀rọ̀ yìí rú wa lójú, kí ni ohun tí ò ń ṣe yìí?
    “Nígbà tí mo padà dé ojú ọ̀nà olúkúlùkù t;un ẹrù dì dáadáa, lẹ́yìn náà a gbéra a kọjú sí ọ̀nà wa.
Abiy Ahmed di olóòtú ìjọba Ethiopia Olootu ijọba Ethiopia kọwe fipo silẹ Ko ti daju boya yoo salaye ojupọnna ti ijọba re yoo tọ nibi ayẹyẹ naa.
Lára wọn ni Mercy Aigbe tó ra ilé, tó gbe sí orí ìtàkùn àgbáyé àti Nkechi Blessing, tó sẹ̀sẹ̀ ra ọkọ̀ Toyota Venza pẹ̀lú Ọlátáyọ̀ Amọkade, tí gbogbo èèyàn mọ̀ sí Ìjẹ̀bú, tóun náà ra ọkọ̀ kan.
Bí Gómìnà Makinde bá ṣẹ̀ mí, lẹ́tà lásán ló jẹ mí- Aláàfin Ọ̀yọ́ Buhari yóò báwọn ọmọ Nàìjíríà sọ̀rọ̀ lọ́la 'June 12' tí ṣe àyájọ́ ìjọba àwarawa Èèyàn 104 kó covid-19 ní iléeṣẹ́ kan ṣoṣo ní Sagamu- Ìjọba Ogun Wèrè tí mò ń ṣe ní Facebook ló pawó fún mi-Esabod Eeyan 4,494 lo ti ri iwosan gba, nigba ti awọn 387 ti dero ọrun nitori arun ọhun.
Samuẹli dùbúlẹ̀ lórí ibùsùn rẹ̀ títí di òwúrọ̀ ọjọ́ keji.
Wọ́n gba ilẹ̀ ìní Sihoni, ọba Heṣiboni, ati ti Ogu, ọba Baṣani.
Ẹni tí ó jẹ́ alufaa tí ó ń wọ ẹ̀wù efodu nígbà náà ni Ahija, ọmọ Ahitubu, arakunrin Ikabodu, ọmọ Finehasi, ọmọ Eli, tíí ṣe alufaa OLUWA ní Ṣilo.
Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Vaccine rumours debunked: Àwọn ìròyìn òfegè nípa abẹ́rẹ́ àjẹsára Covid-194 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 11:29 Fídíò, EndSARS: Olatunde Abolarinwa London Tailor ní òun á ṣe baba fún mi, kò tilẹ̀ dúró ṣe bàbá àwọn ọmọ tirẹ̀ tóríi ìwà Ọlọ́pàá Mopol, Duration 11,295 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 3 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 5 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Rakẹli lóyún, ó sì bí ọmọkunrin kan.
'Àwọn agbábọ́ọ̀lù Super Eagles já wa kulẹ̀ ní ìdíje wọn pẹlúù Madagascar' Sọ àsọtẹ́lẹ̀ orílẹ̀èdè tí yóò borí ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ t'òní 'A fẹ́ kúrò ní Larubawa nítorí à kò gba ẹ̀sìn' Ọlọ́pàá ìpínlẹ̀ kọ́ ní ojútùú ìṣòro ìjínigbé ilẹ̀ Yoruba - Onímọ̀ ọ̀rọ̀ ààbò Ogedengbe Agbógun Gbórò, Akọni tó ń dẹ́rù ba ikú.
Ẹyin o rẹ yin ti ọwọ ọlọpa tẹ Ọlayẹmi lo to jẹwọ pe oun daa gẹgẹbii ọgbọn pe oun sun si ọgba agọ ọlọpa naa lẹyin ti ilẹ su oun silu Eko sugbọn to jẹ wi pe ilu Ilọrin ni oun gba lọ.
Kwara governorship: Gómìnà tí wọ́n yàn ní Kwara, Abdulrazaq ní òun yóò tún ìdigunjalè Offa yẹ̀wò
Oríṣun àwòrán, Reuters Ilakaka rẹ ati tawọn osise ilera miiran sokunfa bi Naijiria ti se ribi koju aarun yi ti ajọ eleto ilera lagbaye si sọ wi pe Naijiria ti jajabọ lọwọ ajakalẹ aarun naa logunjọ Osu kẹwa ọdun 2014.
“Mọṣalaṣi jẹ ile ijọsin akọkọ ti Ọlọrun pese
Wo àwọn ọ̀nà to fi leè ní owó lọ́wọ́ láti ipasẹ̀ iṣẹ́ amọ̀ Wòlíì Kasali ní Dolapo Awosika kò lé ìyàwó òun jáde Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
phpRi i pe ohun to ba yẹ lọ kọ sí gbogbo aaye ti wọn lò ṣe pataki to wa ninu fọọmu naa.
"O ni ""ipo Ọba ni Gomina wa, ko yẹ ko yára sọrọ""."
"Baba Ijesha bẹrẹ ifọrọwanilẹnuwo rẹ pẹlu gbajugbaja ọrọ to maa n sọ ninu ere ""Oyinbo sọrọ o fi Psychology sinu rẹ."
Jeremaya sọ fún gbogbo àwọn eniyan tí wọ́n dá a lóhùn, lọkunrin ati lobinrin pé: 
15 Ìgbé 2020 Lẹyin ti arun Coronavirus tan de Naijiria, oriṣiriṣi awọn ahesọ ọrọ lo ti n tan kalẹ lori itakun ayelujara.
 bíọlá ni orúkọ ẹni tí ó ń ta ọtí.
Nígbà tí a wá wọn tí a kò rí wọn, a lọ sọ́dọ̀ Samuẹli.
Iroyin fi han wipe, Onweniwe fi tipa gbe Nifẹmi lọ si oko kan ni Ogbese lẹyin ti wọn ni aawọ.
Gba àwọn tí wọ́n bá fẹ́ lọ pa sílẹ̀,fa àwọn tí wọ́n bá fẹ́ ta gbọ̀n-ọ́n-gbọ̀n-ọ́n,lọ sọ́dọ̀ àwọn apànìyàn pada.
Awọn ẹbi oloogbe ni Baba ko ṣaisan rara ki ọlọjọ to de.
Gbogbo wọn óo jẹ́ akikanju lójú ogun, wọn óo tẹ àwọn ọ̀tá wọn mọ́lẹ̀ ní ìgboro; wọn óo jagun, nítorí OLUWA wà pẹlu wọn, wọn óo sì dá àyà já àwọn tí wọn ń gun ẹṣin.
Ohun tí a rí nílé Ajimobi rèé lẹ́yìn ìròyìn òfégè pé ó jáde láyé Ọmọ atàpátadìde ni mí, télọ̀ ni bàbá mi- Abiola Ajimobi Ohun tí a mọ̀ nìyí nípa ìròyìn Ajimobi kú, kò kú, táyé ń gbé kiri Ninu atẹjade mii ti alaga ẹgbẹ ALGON, ọmọba Ayodeji Abass Aleshinloye fọwọ si, o jẹ ko di mimọ pe ajọgba ni awẹ ati adura naa ko ba jẹ nita gbangba ṣugbọn nitori akoko ti a wa yii, eyi ti Coronavirus n dari, ni wọn ṣe ni ki onikaluku gba a ni adagba.
"Bí nǹkan ọkùnrin bá há sójú ara obìnrin, kìí ṣe Mágùn, ẹ má páyà ""Ẹ fún ọ̀já kó le, lítà epo kan le tó ₦250 àbí ju ₦300 lọ"" Wọ́n ti dáwọ́ ìdánwò àbẹ́rẹ̀ àjẹsára Oxford dúró lẹ́yìn ti olùkopa kan ṣàìsàn Owó tí Kiddwaya bá rí ní BB Naija, ìdá kan fún Erica, ìkejì fọ́mọ aláìníyàá - Baba Kiddwaya O ni ""ami ẹye ọhun yẹ Trump gan ni nitori o gbiynaju lati jẹ ki alaafia wa laarin awọn orilẹ-ede kan agbaye ju awọn eeyan miran to ti gba ami ẹyẹ naa ṣaaju rẹ."
Ní àkókò náà, ọkunrin kan láti inú ẹ̀yà Lefi fẹ́ obinrin kan tí òun náà jẹ́ ẹ̀yà Lefi.
Oriṣiiriṣi ami ẹyẹ tilẹ Gẹẹsi ni Ramla ti gab bayii lẹnu kikan ẹ̀ṣẹ́.
Ẹka ẹkunrẹrẹ rẹ nibi Ọjọ 14, Osu Kẹta Aare Muhammadu Buhari gbera lọ si Dapchi lati lọ tu awọn obi awọn ọmọ naa ninu, atiwipe ijọba yoo doola ẹmi awọn akẹẹkọ naa.
Kàkà bẹ́ẹ̀ àwọn ẹ̀yà ara tí kò lágbára jẹ́ àwọn tí a kò lè ṣe aláìní.
Tàkúté ikú yí mi ká;ìrora isà òkú dé bá mi;ìyọnu ati ìnira sì bò mí mọ́lẹ̀.
"Boris tẹsiwaju pe, ""Inu awọn kan ko dun si iyapa yii."
Ọlọrun ti bojúwo àwọn eniyan rẹ̀.
Tí a fiṣọwọ́ ní 10:11 29 Èbibi 201910:11 29 Èbibi 2019 Gbàgede TBS l'Eko ń rọ́ kẹ̀kẹ̀ ní ìgbáradì de ìbúrawọlé Gbagede Tafawa Balewa Square ni eto iburawọle ti ipinlẹ Eko yoo ti waye.
Àwọn kẹ̀kẹ́ náà ń dán yinrinyinrin bí òkúta Kirisolite.
#67yearoldmother: Mo kojú ọ̀pọ̀lọpọ̀ àìsàn fún ọdún 35 lẹ̀yín ìgbéyàwò Háà ajé ò!
Ọwọ́ ti tẹ ọlọpàá mẹ́rìn to pa afurasí Nǹkan kò ṣẹnuure fáwọn obìnrin nínú ìgbìmọ̀ ìṣèjọba Buhari Àwọn ọmọ Yorùbá wo ni mínísítà ní ìjọba Buhari?
Sikiru Ayinde Barrister, Barry wonder gbajúmọ̀ olórin Fuji tó ṣiṣẹ́ sọ́jà, tẹ̀wé-tẹ̀wé àti akọ̀wé iléèṣẹ́
“Wọn óo mọ̀ pé èmi ni OLUWA, nígbà tí mo bá fọ́n wọn ká sí ààrin àwọn orílẹ̀-èdè mìíràn, tí mo tú wọn ká sórí ilẹ̀ ayé.
" Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Man U tún ṣubú dàánù lẹ́ẹ̀kan síi Man Utd Vs Man City: Ọ̀rẹ́ dì ọtá, ọtá dì ọ̀rẹ́ torí ife ẹ̀yẹ Omidan Bidemi Ajulo tẹ oju onibara rẹ kan si pẹpẹ lati ṣalaye bi obinrin to ba n lọ si ibi iṣẹ tabi ode ti ko fi bẹẹ́ gara ṣe le sare ṣe oju ara rẹ lọṣọ lai lo akoko gbọọrọ.
Ileesẹ ọlọpaa ipinlẹ naa sọ pe ọwọ ko tii tẹ ẹnikẹ́ni lórí iṣẹlẹ ọhun, ṣugbọn iwadii ti n lọ.
Oríṣun àwòrán, EPA Àkọlé àwòrán, Ni ibẹrẹ ọdun yi ni Volodymyr Zelensky gun ori alefa gẹgẹ bi aarẹ Ukraine Wọn ni o ṣeeṣe ki aarẹ Trump ti sọrọ nipa iranwọ òjìlénígba lé mewaa miliọnu dọla, nkan ija ogun ti ile asofin Amẹrika ti buwọlu, amọ ti ijọba Trump ko ti juwọ rẹ silẹ.
Progressives Congress (APC) ninu eto idibo gbogbo-gbo o ti o waye nipinle Zamfara.
Ìyàlẹ́nu ló jé lósàn ọjọ́ kejì tí ìsẹ̀lẹ̀ náà wáyé, nígbàti BBC Yorùbá sàbẹ̀wò sí ibùdó igbókúsí ilé ìwòsàn Mainland pé, àwọn ebí àwọn tó kú nínú ìjàmbá iná orí afárá ọtẹ́dọlá, tí kúrò níbẹ̀.
Iṣẹ iwadii BBC yii ṣafihan olukọ ni fasiti ijọba apapọ ni Eko ati ni Ghana ni eyi to ti n tu aṣiri oriṣiiriṣii sita bayii, Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Africa Eye: Olùkọ́ méjì ní fásitì Eko àti Ghana lùgbàdì ọ̀fíntótó BBC lórí ìwà ìbàjẹ́ Fasiti Eko to gba Omowe Boniface Igbeneghu to n kọ awọn akẹkọọ nipa ede ajoji tilẹ Yuroopu ni fasiti naa ti ni ko ṣiwọ iṣẹ na.
N óo gbé àsíá mi sókè sí àwọn eniyan,wọn óo gbé àwọn ọmọ rẹ ọkunrin mọ́ àyà wọnwọn óo sì gbé àwọn ọmọ rẹ obinrin sí èjìká.
Ọjọgbọn Abayọmi ni gbogbo awọn ero ọkọ to ba ọmọ orilẹede Italy naa to wọle sorilẹede Naijiria lati ilu Milan lorilẹede Italy ni ọjọ kẹrinlelogun oṣu keji ọdun yii ni wọn n wa bayii.
Coronavirus in Nigeria: Wòlíì 'Sọtítóbirẹ̀' fójú ba ilé ẹjọ́, fídíò ohun tójú rẹ̀ rí nílé ẹjọ́ nìyí
Bi esi tuntun naa ṣe lọ niyii: 92-Kano 36-FCT 30-Lagos 16-Gombe 10-Bauchi 8-Delta 6-Oyo 5-Zamfara 5-Sokoto 4-Ondo 4-Nasarawa 3-Kwara 3-Edo 3-Ekiti 3-Borno 3-Yobe 2-Adamawa 1-Niger 1-Imo 1-Ebonyi 1-Rivers 1-Enugu Lọwọlọwọ, o ti pe ẹgbẹrun meji le aadọsan eniyan to ti ni aarun naa ni Naijiria.
Iranṣẹ tí ó bá hùwà ọlọ́gbọ́n a máa rí ojurere ọba,ṣugbọn inú a máa bí ọba sí iranṣẹ tí ó bá hùwà ìtìjú.
Awọn orilẹede mẹẹdogun to wa ninu ajọ naa ti ni afojusun lati maa na owo kan naa nigba ti yoo ba fi di ọdun 2020.
Eyi lo mu ko gbe igbesẹ lati gba olukọ ede Yoruba fun awọn ọmọ rẹ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù NUJ: Kò yẹ kí akọ̀ròyìn fi ìròyìn tú àsírí ológun fún Boko Haram 7 Sẹ́rẹ́ 2019 Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fọ́nrán ohùn, NUJ: Ẹ̀yin Akọ̀ròyìn, ẹ sọ́ra nípa kíkọ ìròyìn tó léwu fétò ààbò Ẹgbẹ awọn akọroyin lorilẹede Naijiria, ti kesi awọn awọn ọmọ ẹgbẹ naa lati mu eto aabo ilu lọkunkundun nipa didẹkun kikọ iroyin ti o le jẹ ki eto aabo mẹhẹ lorilẹede Naijiria.
Bí èédú ti rí sí ògúnná, ati igi sí iná,bẹ́ẹ̀ ni oníjà eniyan rí, sí àtidá ìjà sílẹ̀.
Lionel Messi: ''Kò sí ohun to lè mú Messi dúró sí Barcelona mọ́''
“Lẹ́yìn ọjọ́ pípẹ́, oluwa àwọn ẹrú náà dé, ó bá bẹ̀rẹ̀ sí bi wọ́n bí wọ́n ti ṣe sí.
Bakan naa lo tun rọ ijọba aarẹ buhari lati tun ero rẹ pa lori iroyin kan to n jade kiri pe o n gbimọran ati fi kun owo ori awọn ọja rira lorilẹede Naijiria, VAT.
Ẹ máa yọ̀ ninu OLUWA, ẹ̀yin olódodo!
Kùrù-kẹrẹ Coronavirus ṣeéṣe kó dópin láàrín ọdún méjì - WHO Géńdé agbébọn yabo àgọ́ ọlọ́pàá n‘Ibadan, ẹ̀mí ọlọ́pàá kan bọ́ Ọba Ilorin ló pàṣẹ pé kí ń padà sọ́dọ̀ ọkọ mi - Risikat olójú búlúù NCDC kéde èèyàn 340 míràn tó ṣẹ̀ṣẹ̀ lùgbàdì Covid-19 ní Nàìjíríà A fí ara mọ́ ìdájọ́ ikú Sharia tó tọ́ sí Olórin Yahaya- ẹgbẹ́ Amòfin Mùsùlùmí ẹ̀ka ìpínlẹ̀ Kano Oludari agba fun ajọ Lasema tẹ siwaju ninu alaye rẹ pe idi eyi lo mu ki ọkọ akẹrun naa lọ rọ lu ọkọ ero kan to duro jẹjẹ rẹ, ti ile ẹru naa si jabọ.
Ṣugbọn ọkàn Farao tún le, kò sì jẹ́ kí àwọn eniyan náà lọ.
Ó jẹ́ aṣiwaju ní Israẹli fún ọdún meje.
Oríṣun àwòrán, Twitter/The Lagos State Govt Àkọlé àwòrán, Ibrahim ni ilu Badagry l'oun ti n lọ ba ẹgbọn to ti n gbe nibẹ tẹlẹ.
Ayé ò fẹ́ kí á ní
N óo sì dán wọn wò, bí a tíí dán wúrà wò.
Bi awọn kan ṣe n yọ ayọ ọjọ ibi, lawọn kan n palẹmọ fun ti wọn naa, bakan naa lawọn oṣere kan ko sai mẹnu ba ọrọ coronavirus gan an.
 19 : 20 ] [ heb .
Ẹ máa mu àmupara kí ẹ sì máa ta gbọ̀n-ọ́n-gbọ̀n-ọ́n, ife ìjẹníyà tí ó wà lọ́wọ́ ọ̀tún OLUWA yóo kàn yín, ìtìjú yóo sì bo ògo yín.
Ko le lanfani ati maa mura bii obinrin nipo adele Ọba.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù School resumption: Ilé aṣojú-ṣòfin l'Abuja dábàá kí ìjọba sún ìwọlé àwọn akẹ́kọ̀ọ́ síwájú pẹ̀lú oṣù mẹ́ta torí covid-19 wákàtí 7 sẹ́yìn Ile aṣoju-ṣofin l'Abuja ti sọ pe ki ijọba apapọ sun ọjọ iwọle awọn akẹkọọ pada kuro lọjọ Aje ọjọ kejilelogun, oṣu kinni, ọdun 2021 yii.
Wọ́n ṣùrù bò mí bí oyin,ṣugbọn kíá ni wọ́n kú bí iná ìṣẹ́pẹ́;ní orúkọ OLUWA, mo pa wọ́n run.
Agbára àti ìgboyà yìí, bí ó ṣe sọ, tí mú u láti lè sọ̀rọ̀ akin gẹ́gẹ́ bí atọ̀hùn-rìnwá àti ọmọ Tibet:
Gígùn apá àríwá àgọ́ náà jẹ́ ọgọrun-un igbọnwọ pẹlu, ogún ni àwọn òpó rẹ̀, àwọn ìtẹ́lẹ̀ wọn sì jẹ́ ogún pẹlu.
Nitori akoko ojo ko ti wọle de patapata.
Òun ni kò jẹ́ kí èmi fúnra mi wá sọ́dọ̀ rẹ.
Má ṣe burúkú jù, má sì jẹ́ òmùgọ̀.
Oríṣun àwòrán, Brodashaggi Ọba Ilorin ló pàṣẹ pé kí ń padà sọ́dọ̀ ọkọ mi - Risikat olójú búlúù Access Bank, dá ₦206,000 ìyá mi pádà lónìí, bí bẹ́ẹ̀ kọ́.
Ìgbà tí ó bá di alẹ̀ tí mo bá jẹun tán a fi oògùn burúkú sí inú omi tí mo máa mu bẹ́ẹ̀ ni n kò sì nì í mọ nǹkan kan ní tèmi.
Fulani Heardsmen: Afenifere ní àṣẹ tó bá wu àwọn àgbààgbà agbègbè àríwá Nàìjíríà kí wọ́n pa
Awọn eniyan to ju ẹgbẹrunmarundinlaadọta lo fọwọ si lori ẹrọ ayelujara Change.
 Mi o le se iye meji tabi ni iberu lati lo gege bi asole akoko ninu ifesewonse wa pelu orile-ede Croatia.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Òṣìṣẹ́ reluwé tó bá gbé owó gun tíkẹ́ẹ́tì, yóò gé ìka jẹ - Amaechi Àwọn adigunjalè pa èèyàn mẹ́fà ní báńkì kan nìpínlẹ̀ Ondo “Kò sí àgbègbè Nàìjíríà kánkan tó wà lábẹ́ àkóso Boko haram” Iroyin naa ni onibaara ti o jẹ Ọlọrun nipe naa jẹ ọkan lara awọn alagbe to maa n joko lẹba oju irin ni tesan Mushin.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Champions League Draw: Barcelona yóò kojú Man U ní ìpele 'quarter finals' 15 Ẹrẹ̀nà 2019 Oríṣun àwòrán, Twitter/Manchester UNited Àkọlé àwòrán, Idije Champions League Eegun kan eegun lọrọ ifẹsẹwọnsẹ ipele kọmẹsẹọyọ ẹlẹni mẹjọ(quarter finals) idije UEFA Champions League lẹyin ti wọn gbe Barcelona koju Manchester United.
Lasiko to n ba awọn oniroyin sọrọ, ni olu ile ẹgbẹ ASUU ni Fasiti Olabisi Onabanjo Ago Iwoye nipinlẹ Ogun ni adari ẹkun Eko ọjọgbọn Olusiji Sowande sọ pe ijọba apapọ jẹ awọn fasiti ni owo ti le ni igba biliọnu naira fun atunto awọn fasiti.
Ondo Election: Akeredolu f'ògún ikọ̀ Àmọ̀tẹ́kùn Ondo gbárí fún ìdìbò tó ń bọ̀
Ọmọ ogún ọdún kan tún di àwátì nílùú Akurẹ nípìnlẹ́ Ondo- PPRO Ajínigbé méjé ni a ti fi ṣìkún òfin mú ní ìpínlẹ̀ Ondo - Amotekun O ṣapejuwe iṣẹlẹ naa gẹgẹ bi ọgbẹ to wọ to jin, to si jẹ ibanujẹ.
Níbo ni ẹ óo kó ọrọ̀ yín sí?
Èmi ni OLUWA Ọlọrun yín,tí ó mu yín jáde láti ilẹ̀ Ijipti.
Wọ́n fi idẹ ṣe ọpọlọpọ agbè, wọ́n tò wọ́n ní ìlà meji sí etí agbada omi náà.
Ẹgbẹ́ òsìsẹ́ NLC ti kọ #27,000 owó osù òsìsẹ́ Gomina Fayemi jáwé lọ gbé ilé rẹ fún adarí fasiti Ekiti Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Murphy Elégungun Rọba: Mo fẹ́ di ẹnití egungun rẹ rọ jùlọ ní àgbáyé O ni gbogbo nkan ni awọn gbeyẹwo ko to di wi pe awọn fẹnuko lori gbedeke owo osu ti awọn fẹ ma a gba.
Mo ní ohun pupọ tí mo fẹ́ bá ọ sọ, ṣugbọn n kò fẹ́ kọ ọ́ sinu ìwé.
Ikede naa ni lẹyin ifitonileti ọlọjọ marundinlaadọta, akọwe ijọwe ijọba ti buwọlu adehun ti a fi yọ orilẹ-ede Sudan kuro lara awọn orilẹ-ede to n ṣagbatẹru iṣerubalu lagbaye."
"Shonibare ni, ""Arabinrin aṣẹwo kan ni o pe awọn ọlọpaa pe awakọ mi jọ ọkunrin kan ti o ja oun l'ole ni bii aago meta oru ni ọjọ kerin oṣu keta."
Ṣugbọn ní ọjọ́ náà gan-an ni Labani ṣa gbogbo ewúrẹ́ ati òbúkọ tí àwọ̀ wọn ní funfun tóótòòtóó, tabi tí ó dàbí adíkálà, ati gbogbo àwọn tí wọ́n ní funfun lára, ati gbogbo àwọn aguntan dúdú, ó kó wọn lé àwọn ọmọ rẹ̀ lọ́wọ́.
 Ọkúnrin ni olórí sáábà ń jẹ ́ .
Atẹjade ajọ WHO sọ pe O ṣẹṣẹ de pada lati ilẹ Gẹẹsi laipẹ yii nibi to ti lọ ṣe itọju aisan ara rẹ.
lorile ede Naijiria ni won ti rọ lati ran awon abarapa to wa lorile ede yii
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Buhari gb'alejo ife ẹyẹ agbaye FIFA nilu Abuja 8 Ẹrẹ̀nà 2018 Oríṣun àwòrán, @NGRPresident Àkọlé àwòrán, Aarẹ Muhammadu Buhari seleri iranwọ ati atilẹyin to ba yẹ fun ikọ agbabọọlu Super Eagles Aarẹ orilẹede Naijiria, Muhammadu Buhari ti gba'lejo ife ẹyẹ bọọlu agbaye ni ilu Abuja.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Donald Trump: Ilẹ̀ Amerika nìkan ni wọ́n ń bímọ sí láti gba ìwé ìgbéèlú 1 Ẹrẹ̀nà 2018 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 30 Ọ̀wàrà 2018 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ọ̀jọ́ méje ló ku kí ètò ìdìbò fún àwọn Ilé Ìgbìmọ̀ Asofin kékeré àti àgbà yóò wáyé ní ilẹ̀ Amerika.
Gbogbo odi ìlú yóo sì wó lulẹ̀.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Coronavirus: Opó afọ́jú kan sọ̀rọ̀ lórí ìnira tó ń kojú pẹ̀lúu coronavirus Awọn Gomina ariwa Naijiria wo lo ṣe lodi sii aṣa ẹkọ kewu Alumajiri?
Àabo ilẹ̀ Yoruba: Ọlọ́pàá ìpínlẹ̀ dára ṣùgbọ̀n ọ̀ràn lè tibẹ̀ jáde
" ní ọdún 2006 , "" fortune "" ṣe ìṣirò ọja sue , wọ ́ n sì ní wípé ó ju $ 400 million lọ ."
Sagbokoji, ìlú tó sún mọ́ ọ̀làjú pẹ́kípẹ́kí ṣùgbọ́n tí iná ẹ̀lẹ́ńtíríkì kò sí láti ọgọ́ọ̀rún ọdún
Ògiri tó gbé Nàíjíríà ró ń mì tìtì, ó sì le wó - Osinbajo figbe ta Laycon, kú oríire àmọ́ bá ń kó owó orí nínú ẹ̀bùn rẹ nílé BB Naija - Ìjọba Eko Boko Haram gbọ̀nà àrà yọ, kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ ló so àdó olóró mọ̀ láti kọlu Gómìnà Borno Ìṣòro jíjẹ́ ìyá n dáàgbé ló sọ mí di àtúnbí krístíẹ́nì - Remi Tinubu Kí ló ń fa wàhálà láàrín Kunle Afolayan àti Mike Ezuruonye lórí ayélujára?
"Dokita yọ góòlù àti owó ṣílè nínú obìnrin kan Ooni Ife fohùn ránṣẹ́ sí Boris Johnson, ó ní, ""bóo bá joun gbé, má johùn gbé"" WAEC gbé èsì ìdánwò WASSCE jáde EFCC kó akẹ́kọ̀ọ́ fásitì UNIOSUN O ni ko ba ofin mu ki awọn minisita naa ma mọ ibi ti wọn fẹ yan wọn si, bẹẹ si ni awọn asofin naa ko fi ọrọ wa wọn lẹnu wo, nitori wọn ti wa ni ipo isejọba tẹlẹri."
Níbo ni wọ́n sì ti wá?
6 mílíọ̀nù ni-APC Bí wọ́n ṣe ń ta káádì ìdìbò ní Kano nìyì Ilu Eko kẹ, laarin awọn ilu to rọrun lati gbe ju lagbaye!
 Àtí pé ìgbàgbọ wọn nípa ohun tí jésù jẹ ́ yàtọ ̀ díèdíẹ ̀ síbèsíbè gbogbo wọn gbà pé olùgbàlà ni jésù .
"Kìí ṣe ẹ̀bi wa pé ètò ìsìnkú Abiola Ajimobi falẹ̀ - ìjọba ìpínlè Oyo Peter Okoye, ìyàwó àti ọmọ lùgbàdì ààrùn Coronavirus Omolere pari ọrọ rẹ pe ""Kii ṣe Rauf Olaniyan ni wọn da pada lẹnu ọna gomina Abiola Ajimobi, bi ko ṣe ijọba ipinlẹ Oyo."
Ọmọ wo ló tún kù ní ara mi tí n óo ṣẹ̀ṣẹ̀ bí, tí yóo ṣú yín lópó?
Kódà ní ìta gbangba ńṣe ni oòrùn kanni látàrí gbọ̀ngbọ̀n.
 indonesia ní àwọn erékùṣù 17,508 .
”Nítorí pé OLUWA nífẹ̀ẹ́ rẹ,ilẹ̀ rẹ yóo sì dàbí iyawo lójú rẹ̀.
"Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: ""Jàǹdùkú gún ẹ̀gbọ́n mi lọ́rùn, jó ilé àti mọ́tò wa méjì, kòròfò la wà"" Olùwọ́de 12 kú ni Lekki, 38 lapapọ kú lọ́jọ́ Isẹ́gun, 56 ni àròpọ̀ àwọn tó bá ìwọ́de lọ - Amnesty International Osinbajo gbarata lórí ìṣẹ̀lẹ̀ Lekki, ó ní ìdájọ́ òdodo yóò wà Ooni Ogunwusi àti Wole Soyinka kòrò ojú sí ìṣẹ̀lẹ̀ Lekki Tollgate Ọ̀rọ̀ Nàíjíríà kúrò ní sinimá àwòrẹ́rìn-ìn, Buhari gbé ìgbésẹ̀ bíi òbí àti olórí - Obasanjo gbarata Ilẹ̀ Amẹ́ríkà wà lẹ́yìn àwọn olùwọ́de, Buhari dẹ́kun ìpànìyàn - Joe Biden Mọ̀ nípa DJ Switch, akíkanjú obìrin sàfihàn fídíò ìpànìyàn Lekki bó ṣe ń wáyé O ni ki ICC ""bẹrẹ iwadii ni kankan, lori iroyin to gbode nipa bi ijọba ṣe lo awọn tọọgi, ọmọ ogun atawọn oṣiṣẹ agbofinro, lati ṣẹru ba ati lati pa awọn oluwọde alaafia ni Abuja, Eko, Edo, Osun, Plateau ati ni Kano."
Ileeṣẹ iroyin Reuters sọ wipe awọn ọmọ Naijiri le nidaji awọn atipo to wa ninu ọkọjuomi naa.
Nípa igbagbọ ni Abeli fi rú ẹbọ tí ó dára ju ti Kaini lọ sí Ọlọrun.
O sọ pe awọn to wa ni ibẹ tilẹ sọ pe Adeleke ko si ni ile rara.
pé bóyá mo lè ti ipa bẹ́ẹ̀ mú àwọn eniyan mi jowú yín, kí n lè gba díẹ̀ ninu wọn là.
Ẹni ti wọn ṣapejuwe gẹgẹ bi ọkunrin olootọ, olufọkansin ati onigbagbọ gidi ninu isọkan Naijiria, ajọ isọkan ilẹ Afirika fun un ni ami idalọla wọn si gbe iṣẹ didari ipolongo lodi si iwa ajẹbanu nilẹ Afirika.
7 14,065 Sierra Leone 77 1.
Òun a máa wí báyìí pé: Mo jẹun ikùn mi rí ringingin bí ikùn ọmọ ẹyẹ, ikùn ńlá tí ó lé dodo sá wọ inú ilé lọ, ìbàdí mi tóbi ó rí jọ̀bọ̀tọ̀jọboto, ẹnu ọ̀nà kékeré kò gba ìyàwó mi mọ̀, nítorí ikùn ẹsẹ̀ rẹ̀ tóbi ju òpó ilé lọ, ìbàdí rẹ̀ sì tó ẹrù géńdé mẹ́fà, bẹ́ẹ̀ ni ẹ̀hìn ọrùin rẹ̀ tóbi tó ti ènìyàn mẹ́jọ.
Ó ń sọ̀rọ̀ bíi ti Ẹranko Ewèlè.
Ràkúnmí wọn jẹ́ irinwo ó lé marundinlogoji (435), kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ wọn jẹ́ ẹgbaata ó lé okoolelẹẹdẹgbẹrin (6,720).
Ọba yìí sì tún dáhùn, ó ni, Ta ni bàbá rẹ?
nibi ti ijọba naa ti na awọn owo kan ti Ile ko fọwọ si.
Wike, má gbé jàgídíjàgan wá sí Ondo, APC kò ní ṣ'èèrú nínú ìdìbò gómìnà tó ń bọ̀- Kalejaye Èèmọ̀!
Tsammani wa wi pe gbogbo ẹri ti Ajimọbi ko kalẹ ko lẹsẹ n lẹ rara lati tabuku alatako rẹ.
Gomina makinde nikan kọ lo daro kọmiṣọna fọrọ ayika atohun alumọni ni ipinlẹ Ọyọ naa, Ẹgbẹ oṣelu PDP ati APC pẹlu ko gbẹyin.
34 Àti lẹ́ẹ̀kansíi, lõtọ́ ni mo wí fún yin, Áà ẹ̀yin olùgbé orí ilẹ̀ ayé: èmi Olúwa ní ìfẹ́ láti sọ gbogbo nkan wọ̀nyi di mímọ̀ sí gbogbo ẹlẹ́ran ara;
Awọn ara ilé Idris to yinbọn fun àwọn eniyan sọ pe ara Idris ya.
Awọn inu ẹgbẹ naa nipinlẹ Oyo bi Ọjọgbọn Prof Dibu Ojerinde, Sẹnẹtọ Teslim Folarin, Họnọrebu Segun Odebunmi, Pa Akin Ojebode, Alhaji Laide Abass, Pa Adeleke atawọn mii.
Yàtọ̀ sí ìgbà tí ìnáwó pàjáwùrù bá wà ọjọ́ karùn-ún kànùn-ún ni Orímóògùnjẹ́ máa ń mú owó nínú séèfù rẹ̀ nígbà tí ó wà láyé.
Esi ayẹwo naa waye lẹyin ti ajọ to n ṣamojuto ajakalẹ arun, NCDC, kede esi ayẹwo eeyan 157 to tun ṣẹṣẹ ni i.
Igbakeji aare orile ede Naijiria , ojogbon Yemi Osinbanjo lo dari ipade igbimo ijoba apapo to waye lojoRu.
Shehu Sani: Irandiran àwọn ọmọ Naijiria ni yóò má a san gbèsè owo tí Buhari bá yá
Nígbà tí ọbabinrin Ṣeba rí i bí ọgbọ́n Solomoni ti jinlẹ̀ tó, ati ààfin tí ó kọ́, 
Onítọ̀hún tún lọ ó lọ wá abàmì ẹja wọ̀nyí wá.
 nígbà tí o bá tìwà nínu ènìyàn , àwọn àràn náà ń ṣẹ ̀ dá ìdin tí o ń jáde nínu àwọ ara .
"Bi mi o ṣe le jiyan mọ niyii, mo si bẹrẹ si ni sunkun.
wo àwọn nọ́mba ọlọ́pàá tí o lé pé láti mọ ọ̀nà àbáyọ Wọ́n kí irún Jimọ àkọ́kọ́ ní Hagai Sophia lẹ́yìn ọdún 85 ní Turkey Gẹgẹ bi ẹgbẹ awọn eeyan ẹkun Guusu Kaduna ti kede rẹ lọjọ Satide, eeyan mẹtalelọgọta lo ti dero ọrun laarin ọsẹ kan latọwọ awọn agbebọn.
Nibi ipade naa la ti se gbogbo agbeyẹwo ati eto aabo fun gbogbo awọn eeyan ti ọrọ kan, ti yoo kopa ninu eto idanwo naa."
Àwọn afọ́jú ati àwọn arọ bá wá sọ́dọ̀ rẹ̀ ninu Tẹmpili, ó sì wò wọ́n sàn.
Joabu bá pada lọ sọ́dọ̀ ọba, ní Jerusalẹmu.
Àwọn ọmọ-ẹ̀yìn Jesu gbàgbé láti mú burẹdi lọ́wọ́ àfi ọ̀kan ṣoṣo tí wọn ní ninu ọkọ̀ ojú omi.
Onkọwe naa nigba to se abẹwo si ile isẹ tuntun awọn ajọ to n gbogun ti iwa ibajẹ lorilẹede Naijiria, EFCC sọ wi pe ohun fẹ mọ bi wọn se n setoju awọn asebajẹ to wa ni panpẹ wọn si.
Kun Aguero ti akọnimọọgba Pep Guardiola gbe wọ gba pẹnariti ṣugbọn ẹsẹ goli lo gba bọọlu sawọn lo ba di ọmi 2-2.
"Awọn mii to tun n gbaruku ti Laycon ni Lateef Adedimeji, Olaniyi ""Sanyeri"" Afonja, Ufuoma McDermott, Broda Shaggy ati Lekan KingKong."
Ààré Muhammadu Buhari gbé ìlérí rẹ̀ le ǹkan mẹ́ta lásìkò ìdìbò 2015, pé kíkojú ètò ààbò, ìwà àjẹbánu àti mímú ìdàgbàsókè bá ètò ọrọ̀ ajẹ́ ló jẹ òun lógún.
Bo tilẹ jẹ pe awọn oṣojumi koro sọ pe awọn ọmọ ileeṣẹ ologun Naijiria lo pa awọn eeyan naa, ṣugbọn ileeṣẹ ọlọpaa ati ileeṣẹ ologun ti ni awọn ko mọwọ mẹsẹ ninu iṣẹlẹ ọhun.
Elija sọ fún ọba pé, báyìí ni OLUWA wí, “Nítorí pé o rán oníṣẹ́ láti lọ wádìí ọ̀rọ̀ lọ́wọ́ Baalisebubu, oriṣa Ekironi, bí ẹni pé kò sí Ọlọrun ní Israẹli láti wádìí lọ́wọ́ rẹ̀, nítorí náà, o kò ní sàn ninu àìsàn yìí, kíkú ni o óo kú.
Oríṣun àwòrán, Ibadan city announcer/ twitter Ki ni Aafin Olubadan sọ?
Ẹ dúpẹ́ lọ́wọ́ OLUWA, ẹ pe orúkọ rẹ̀,ẹ fi iṣẹ́ rẹ̀ hàn ní gbogbo orílẹ̀-èdè.
Bí o bá jẹ́ olódodo,kí ni ó dà fún Ọlọrun,tabi kí ni ó ń rí gbà lọ́wọ́ rẹ?
Àkọlé àwòrán, Ojọ̀gbọ́n Samuel Otubusin Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
' Koda o fikun pe, obinrin kan ti pe oun lori aago ri nigba ti oun ati ọkọ rẹ lẹpọ lasiko ere ifẹ ninu ile, ti oun si gba awọn mejeeji nimọran lati farabalẹ, titi ti ara wọn yoo fi walẹ.
Bẹẹ ba gbagbe, ọsẹ to kọja ni wọn di Maina ni apanyaka wa sile lati orilẹede Niger to salọ, ko ma baa fi oju wina igbẹjọ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù CJ Gold: ẹ̀rù kọ́kọ́ ba ìyá mi nígbà ti mo fẹ́ bẹ̀rẹ̀ iṣẹ́ ìjà jíjà Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ CJ Gold: ẹ̀rù kọ́kọ́ ba ìyá mi nígbà ti mo fẹ́ bẹ̀rẹ̀ iṣẹ́ ìjà jíjà 15 Ọ̀pẹ̀̀ 2018 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 17 Ọ̀pẹ̀̀ 2018 O ni ẹ̀rù máa n kọ́kọ́ ba òun ni nigba ti oun ba ṣẹṣẹ de gbagede ìjà.
Oye 'Imọlẹ Adinni' ni oṣere naa to tun jẹ Alhaja jẹ.
Gloria Adagbọn @gloria_adagbon ní, pẹ̀lú ìwà Dino táa mọ̀, a jẹ́ pé ká máa retí orin ‘àjekú ìyà’ míì láìpẹ́ ni.
Ó dàgbà, ó ga fíofío, láàrin àwọn igi igbó.
"Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Wo nǹkan tí yóò ṣẹlẹ̀ sí ọba tí wọ́n bá gbé ọ̀pá àṣẹ rẹ̀ lọ nílẹ̀ Yorùbá ₦147m la rí kójọ fún ìwọ́de, a kò fẹ́ owó mọ́, ìwọ́de ti parí - Feminist Coalition Wo ìròyìn, àwòrán àti fídíò èké nípa ìwọ́de EndSARS Super Eagles, ẹ máṣe gbá bọ́ọ̀lù fún Nàìjíríà mọ́ nítorí ìhà tí ìjọba kọ sí ìwọ́de EndSARS - John Ogu Ará Eko, ẹ pariwo ó tó gẹ́ẹ́ lórí làásìgbò tó gbòde torí ìwọ́de EndSARS - Sanwo-Olu Ọ̀tá Yorùbá ló lo ìwọ́de láti dojú ogun kọ wá - OPC ""Àwọn ọ̀tá Nàíjíríà tó fẹ́ dojú ìjọba bolẹ̀ ló wà lẹ́yìn ìwọ́de EndSARS"" Ó parí ni ohùn tó gbẹnu ọ̀pọ̀ ọmọ Nàíjíríà lẹ́yìn ọ̀rọ̀ Buhari Ninu atẹjade kan to fi sita lọjọ Ẹti, Akintoye ni asiko wa to bayii ki ajọ iṣọkan agbaye, ajọ orilẹede Yuroopu, ajọ iṣọkan ilẹ Afirika, AU, orilẹede Amẹrika ati ilẹ Gẹẹsi, lati dide wa fun atunto asopọ Naijiria ti wọn ṣe ni ọdun 1914."
Bakan naa lo ṣe lalaye pe, oun ati gbogbo alatilẹyin oun pata kii ṣe onijagidi jagan, ti wọn si kawe bẹẹ naa ni wọn ni ọpọlọ.
Nígbà tí wọn kò gbàgbọ́ sibẹ nítorí pé ó yà wọ́n lẹ́nu ati pé wọn kò rí bí ó ti ṣe lè rí bẹ́ẹ̀, ó bi wọ́n pé, “Ṣé ẹ ní nǹkan jíjẹ níhìn-ín?
Ọjọ́ meje ni a lò níbẹ̀.
Nígbà tí ó yá, gbogbo ìjọ eniyan Israẹli jáde kúrò ní Elimu, wọ́n lọ sí aṣálẹ̀ Sini tí ó wà ní ààrin Elimu ati Sinai, ní ọjọ́ kẹẹdogun oṣù keji tí wọ́n jáde kúrò ní Ijipti ni wọ́n dé aṣálẹ̀ náà.
30 Agẹmo 2019 Oríṣun àwòrán, Other Ọpọ aworan ati fidio to n ṣafihan ọkunrin kan to wo aṣọ bi Jesu Kristi, ti lu oju ayelujara pa lẹnu ọjọ mẹta yii kaakiri ilẹ Afirika.
Osuere Eunice - Ọmọ ẹgbẹ́ 9.
Ọ̀kan nínú àwọn ọkùnrin tí ó wá sí iwájú Aṣojú-Olódùmarè ṣe ìbéèrè rẹ̀ báyìí, ó ní Ìwọ ìránńsẹ́ Ẹlẹ́dàá ayé, ìwọ ìránńṣẹ́ Ẹlẹ́dàá ọ̀run, ohun tí ó ṣe ẹ̀dùn ọkàn mi ni èyí, ipò tálákà tí mo wà yìí súu mi, kì í ṣe èmi nìkan ṣoṣo ní ń bẹ nínú ayé, tèmi ṣe kúkú le tó bẹ́ẹ̀?
Oríṣun àwòrán, Getty Images Lẹyin igba diẹ, wọn pe Mubarak to ti n ṣe daadaa lẹ́jọ́[.
Alafojuri kan so fun awon akoroyin pe nkan bii aago kan abo osan asiko Florida ni isele naa sele nigba ti afara naa ja lule sori awon oko ti ina irinna oju popo ti da duro tele.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Champions League: Àwọn ohun tóyẹ kí ẹ mọ̀ nípa ti sáà yíí 17 Owewe 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Njẹ o ṣeeṣe ki ẹgbe agabọọlu Ilẹ Gẹẹsi jawe olubori ninu idije UEFA Champions League ti saa yii bi?
Bakan naa ni o fi kun-un oro re pe, “a gbodo sise papo lati ri daju pe, a ni igbekele ninu oja idokowo bi tateyin wa, eyi ti yoo mu igberu ati idagbasoke ba oja idokowo naa ati eto oro-aje orile-ede lapapo”.
Nítorí pé, o kọ òfin OLUWA, OLUWA ti kọ ìwọ náà ní ọba.
Iwaju ibudoko ọkọ oju irin Southgate ni wọn ti da a duro losu keji ọdun yi lẹyin ti ipe kan wole pe o n sọ ọrọ to korira ẹsin Islam.
Atnaf Berhane rántí wípé òún jẹ ìyà oró di aago méjì òru tí òún padà sí lẹ́yìn oorun díẹ̀.
Mekong Watch sọ wípé ohun ìṣẹ̀dá nìkan kọ́ ni a ní láti dáàbò bò àmọ́ àti àwọn “nǹkan àjogúnbá tí-a-kò-le-è-rí-dìmú” tí a lè pín àti rí lò.
Agbẹnusọ fun ile aṣofin, Emmanuel Agada, sọ fun BBC pe awọn ti bẹrẹ si ni ṣe ayẹwo awọn ilana ti yoo mu ko ṣeeṣe fun wọn lati yanju awọn awuyewuye to n jẹyọ lori iṣẹ awọn akọroyin.
lẹ́yìn ọdún meje, kí olukuluku yín máa dá ọmọ Heberu tí ó bá fi owó rà lẹ́rú sílẹ̀, lẹ́yìn tí ó bá ti sin oluwa rẹ̀ fún ọdún mẹfa.
Ibarapa Polytechnic Eruwa ni wọn yoo maa pe ni Adeseun Ogundoyin Polytechnic, Eruwa.
O gbọdọ ni kirẹẹditi márùn-ún ninu eyikeyi idanwo WASSCE/GCE/NECO/NABTEB, ti o ṣe lai ju ẹẹmeji lọ.
tí wọ́n bá rí i tí gbogbo ilẹ̀ náà ti di imí ọjọ́ ati iyọ̀, tí gbogbo rẹ di eérú, tí koríko kankan kò lè hù lórí rẹ̀, bíi ìlú Sodomu ati Gomora, Adima ati Seboimu, tí OLUWA fi ibinu ńlá parẹ́, 
Gbogbo àwọn tí wọ́n wà ninu ìpọ́njú, ati àwọn tí wọ́n jẹ gbèsè ati àwọn tí wọ́n wà ninu ìbànújẹ́ sá wá sọ́dọ̀ rẹ̀.
Ijoba ipinle Ekiti ti ni gbogbo
Àwọn ìpínlẹ̀ mẹ́fà míran yóò bẹ̀rl tiwọn ní sáà akọ́kọ́ nínú ọdún 2021.
Ẹ jẹ́ ki nsọ ìtàn náà fún-un yín; kí njù-ú sí i yín bí àkàṣu èdè àti ọ̀rọ̀.
Aare orile ede Naijiria Muhamadu Buhari ti ki gomina ana fun ipinle Ekiti , to tun je minisita fun ohun alumoooni ile ati irin lorile ede ede Naijiria Kayode Fayemi fun jijawe olubori gege bi oludije fun ipo gomina labe asia egbe All Progressives Congress (APC) ni ipinle Ekiti .
ng/ oju opo yii ni o ti le fi orukọ silẹ gẹ́gẹ́ bii ọmọ ogun ilẹ.
Ṣé wọ́n ní “ọ̀rọ̀ púpọ̀, irọ́ ní í mú wá” Tó tó ṣe bí òwe.
Tọkọtaya Otubusin wa fi gbogbo ogo fun Ọlọrun wi pe oun lo ṣe ohun iyanu yii fun wọn.
Bakan naa lo tun kesi ijọba atawọn araalu lati tete wa ojutu si ọrọ ifipanilopọ to n fi ojoojumọ peleke si, ti ijiya iku si tọ si awọn onisẹ ibi naa.
ìwọ Olùdámọ̀ràn ńlá, tí ó lágbára ní ìṣe; ìwọ tí ojú rẹ ń rí sí gbogbo ọ̀nà àwọn ọmọ eniyan, tí o sì ń san ẹ̀san fún olukuluku gẹ́gẹ́ bí ìwà ati iṣẹ́ ọwọ́ rẹ̀; 
'Ipò àpọ́nlé ni mo fi Gómìnà Abdulrahman sí ṣugbọn kò hùwa àpọ́nlé' Eré orí ìtàgé lásán ni ìgbéyàwó èmi àti Pasuma tí ẹ rí - Jaiye Kuti Èmi ní mo fún Afeez Abiodun ní orúkọ 'Ọwọ' tó ń jẹ́ -Yemi My Lover Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ṣé ẹ ti rí kí èèyàn ní àwọ̀ ara tó ń ṣí bíi ìpẹ́pẹ́ ẹja rí?
 O ni ipinnu oun ni lati seto idibo.
Ìtàn ìgbé ayé Isola Ogunsola 'I-sho Pepper', ògbóǹtagí òṣèré tíátà tó s'eré Yorùbá yíká Nàìjíríà Makinde ni gómìnà, èmi ni igbákejì rẹ̀; kò sí ìjà láàrin wa-Rauf Adeniyan, igbákejì gómìnà ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́ Oríṣun àwòrán, Darnella Frazier Àkọlé àwòrán, Iṣẹ ti bọ lọwọ ọlọpaa Minnesota mẹrin to pa ọmọ alawọdudu ni Canada George Floyd: Ọlọpaa mẹrin gba iwe idaduro lẹyin iku ọmọ alawọdudu ni Minnesota Adari ọlọpaa Minneapolis Madaria Arradondo sọ pé awọn ọlọpaa mẹrin to lọwọ ninu ǹkan to ṣeku pa ọmọ alawọ dudu George Floyd ti di oṣiṣẹ igba kan ri Fọran ṣafihan ọkunrin kan George Floyd to n pariwo pe oun ko le mi fun ọlọpaa alawọ funfun to de mọlẹ lasiko ti wọn n gbiyan ju lati mu Isẹlẹ yii tun muni ranti ọkunrin alawọ dudu miran Eric Garner to ku lẹyin ti ọlọpaa mu ni New York City lọdun 2014.
Premier League: Man City fìyà jẹ Cardiff láti padà sókè téńté
Láti agogo mejila ọ̀sán ni òkùnkùn ti bo gbogbo ilẹ̀ títí di agogo mẹta ọ̀sán.
Ẹgbẹ okunkun jẹ nkan to ṣaba wọpọ ni awọn ileewe giga lorilẹ-ede Naijiria, to si ti tàn dé ààrín àwọn tí kìí ṣe akẹkọọ naa, ati ileewe girama.
Angẹli náà tún dúró ní ọ̀nà tóóró láàrin ọgbà àjàrà meji, ògiri sì wà ní ìhà mejeeji.
Wọn ni awọn ti sọ fawọn dokita naa nipinlẹ Ondo lati mọ isẹ loju bẹrẹ lati ọjọ Aje, ọjọ Kẹfa osu Keje nitori aisi omi aanu loju ijọba gomina Akeredolu.
mélòó lafé kà nínú eyín adépèlé ni òrò àwon ohun ribi-ribi tí murtala gbése nígbà ti re .
Níwọ̀n ìgbà tí ayé bá ṣì wà, ìgbà gbígbìn ati ìgbà ìkórè kò ní ṣàìwà, bẹ́ẹ̀ náà ni ìgbà òtútù ati ìgbà ooru, ìgbà òjò ati ìgbà ẹ̀ẹ̀rùn yóo sì máa wà pẹlu.
Níwọ̀n bí mo ṣe jẹ́ Ọlọrun alààyè,mo fi ara mi búra.
Kò sí sì ẹni tó leè fi ọwọ rọ àwọn ọmọ Ade Love sẹ́yìn nínú isẹ ti wọn yàn láàyò náà, nítorí bí wọn tí ń ṣe ere tíátà ni èdè Yorùbá, naa ni wọn tún ń ṣe é ní èdè oloyinbo.
 nígbà tí kọ ́ là sọ ̀ kalẹ ̀ tí ó ń lọ , ó gbàgbé àpò rẹ ̀ ṣùgbọ ́ n wọ ́ n dá a padà fún un .
Aya Jeroboamu bá gbéra, ó pada sí Tirisa.
Báyìí ni o ṣe lè fi orúkọ oògùn tàbí àgbo rẹ sílẹ̀ lábẹ́ àjọ NAFDAC Báwo ní 'Aṣọ ẹbí' ṣe bẹ̀rẹ̀ ní ilẹ̀ Yorùbá?
Karakata Agbabọọlu: Bi o se nlọ
Ẹwẹ, Aarẹ Muhammadu Buhari ti kẹdun pẹlu idile oloogbe Tola Oyediran.
Kò sí omi fún àwọn eniyan náà níbi tí wọ́n ṣe ibùdó sí, wọ́n sì kó ara wọn jọ sí Mose ati Aaroni.
Lẹyin ti ile ẹjọ ba rii pe igbani-nimọran yii ko bi èso to yẹ ni wọn a ni ki lọkọlaya to n ja yii yẹra funra wọn fun igba diẹ, o pẹ tan, fun ọdun mẹta.
Nigeria at 59: Ẹ wo àwọn olóṣèlú méje pàtàkì tó jà fún òmìnira Nàìjíríà
Fọfọ ni gbọngan ibi ipade kun fun ero latoke de isalẹ gẹgẹ bi awọn ara ipinlẹ Ọyọ ṣe wa lati kaakiri ki wọn lee mọ nipa aato awọn oludije.
Omo bibi Yahaya Hamza to jẹ baba to tọ Nasir El Rufai dagba to jẹ gomina ipinlẹ Kaduna.
 dídùn àti dídùn ibẹ ̀ .
Idibo Osun: Gboyega Oyetola pegede ninu ìdìbò abẹ́nú APC ní Osun Ogbeni Gboyega Oyetola lo jawe olubori ninu idibo abẹlẹ ti ẹgbẹ oselu APC, ni igbaradi fun idibo gomina ti yoo waye ni Osu Kẹsan an, ọdun 2018.
Coronavirus: 'Gbogbo àgbáyé gbọ́dọ̀ pawọ́pọ̀ láti borí àrùn Coronavirus'
Agbẹnusọ Ileesẹ Ọlọpaa ni ipinlẹ Ondo, Tee-Leo Ikoro lo fi ọrọ naa lẹde fun BBC News Yoruba Tee-Leo Ikoro ni ileesẹ to n ṣe awọn ohun elo ti wọn fi n ṣe oju ọna lo fa ibugbamu naa, amọ kii sẹ ado oloro.
Gbọ́ tiwa, OLUWA, dáríjì wá, tẹ́tí sí wa, OLUWA, wá nǹkan ṣe sí ọ̀rọ̀ yìí, má sì jẹ́ kí ó pẹ́, nítorí orúkọ rẹ, tí a fi ń pe ìlú rẹ ati àwọn eniyan rẹ.
Ishaq Oloyede ní àjọ JAMB ń gbé ènìyàn ọgọ́rùn ún lọ ilé ẹjọ́ nítorí màgòmágó ìdánwò
Awọn ẹsun wo ni wọn ka si Ibrahim Magu lọrun.
Ilé tí ó wà ní ipò.
Amofin ati oloṣelu ni Aarẹ Akufo-Addo.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Emir of Kano: Soyinka ní ó dun òun pé Ganduje kò ní alámọ̀ran rere 12 Ẹrẹ̀nà 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 13 Ẹrẹ̀nà 2020 Oríṣun àwòrán, Emir ti Kano Ọjọgbọn Wole Soyinka ti bu ẹnu atẹ lu bi ijọba ipinlẹ Kano, labẹ iṣakoso Gomina Abdullahi Umar Ganduje, lori bo ṣe rọ Lamido Sanusi loye, gẹgẹ bi Emir ilu Kano.
Àkọlé àwòrán, Níbo láyé kọjú Àkọlé àwòrán, Níbo láyé kọjú Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
2 145560 Orilẹede Chech 8902 83.
Jakejado agbaye lawọn eeyan ti n sọ nipa lilo oogun yi lati koju ati fun itọju arun Covid-19.
Àkọlé àwòrán, Awọn ohun elo orin lọlọkan o jọkan ko gbẹyin nibi igbaradi naa.
Ṣé ohun tí ó dára ni, Ọlọrunpé kí o máa ni eniyan lára,kí o kórìíra iṣẹ́ ọwọ́ rẹ,kí o sì fẹ́ràn ète ẹni ibi?
Osun tribunal: APC ní ìdájọ́ ilé ẹjọ kò lẹ́sẹ̀ ń lẹ̀, Ó ń gba ilé ẹjọ́ kòtẹ́milọ́rùn lọ
“Wo Behemoti, ẹran ńlá inú omi,tí mo dá gẹ́gẹ́ bí mo ti dá ọ,koríko ni ó ń jẹ bíi mààlúù!
Itan sọ pe o le ni iyawo mọkandinlọgọrun ti Ogedengbe fẹ kaakiri ilẹ Yoruba.
Habib Muntazir, aládàádúró oníròyìn kan fi ẹ̀dùn ọkàn-an rẹ̀ hàn pé ìtàkùrọsọ ọ̀hún kò gbóòkàn:
Gẹgẹ bi ko ṣe fẹran lati maa duro loju kan, o gba ile, o si tẹsiwaju lọ si ilẹ Japan lati lọ jẹ Olukọ ede Gẹẹsi.
O ni gẹgẹ bii aṣẹ to wa lati ọdọ awọn ajọ to n mojuto owo ori epo, naira marundinlaadọjọ ṣi ni iye owo bẹntiroolu, ti ko si yi pada.
Olori ile aṣofin ipinlẹ Ọyọ, Aṣofin Michael Adeyẹmọ kú sí ilé ìwòsàn Jericho nílùú Ìbàdàn tí ìròyìn sì sọ pé àìsàn ọkàn ló paá.
Mo ṣebí àwọn abọ̀rìṣà náà ń ṣe bẹ́ẹ̀!
Oṣiṣẹ Huawei naa irinṣẹ naa ti wọn ma fi n sayẹwo oju gilasi ẹrọ alagbeka ṣeṣi jabọ sinu baagi agbekọpa oun bi ohun ti ṣe n kuro nibi ile isẹ T-Mobile kan.
Jakọbu gé ọ̀pá igi populari ati ti alimọndi, ati ti pilani tútù, ó bó àwọn ọ̀pá náà ní àbófín, ó jẹ́ kí funfun wọn hàn síta.
Ni wọn ba ni awọn ko ni gba wa laaye ti wọn si n ju ẹru wa nu.
Ẹ ṣe e ni soki lọbẹ oge laarin ọsẹ melo kan.
Nítorí pé ẹ̀rù jẹ̀jẹ̀ ni OLUWA, Ọ̀gá Ògo,Ọba ńlá lórí gbogbo ayé.
Bakan naa ni isẹlẹ ẹkun omi yii tun mu ẹmi ọmọ osu mẹta lọ.
SARS já wọ ilé àwọn akẹ́ẹ̀kọ́ fásitì Akungba Ìgbà wo ni àjọ ọ́lọ́pàá yóò káwọ́ SARS?
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Bi ìyàwọ mi ṣe n jábọ́ sí gọ́tà ló jẹ́ kí n kọ́kọ́ fura pé kò ríran mọ́- ọkọ Dorcas Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Bi ìyàwọ mi ṣe n jábọ́ sí gọ́tà ló jẹ́ kí n kọ́kọ́ fura pé kò ríran mọ́- ọkọ Dorcas 9 Ọ̀pẹ̀̀ 2019 Tete ṣe ayẹwo oju rẹ ko too pẹ ju- Ọjọgbọn Adeọla Onakoya Aisan Adakẹfọju-ẹni ti awọn oloyinbo n pe ni Glaucoma ni ọpọ awọn eniyan Naijiria ko ka kun pupọ nitori pe kii mu ariwo dani.
Elomiiran to tun jẹ ọmọ ijọ naa sọ pe ọpọ eeyan lo yabo ṣọọṣi Sotitobire lẹyin ti iṣẹlẹ ọhun ṣẹlẹ tan, o ni awọn eeyan naa sọ ina ṣọọṣi wọn si ba ṣọọṣi naa jẹ.
Àwọn alufaa fọn fèrè ogun, bí àwọn eniyan ti gbọ́ ìró fèrè, gbogbo wọn hó yèè!
Eniyan igba ati mọkandinlaadọta (249) si ti ku.
Ṣugbọn, OLUWA, ṣàánú mi;gbé mi dìde, kí n lè san ẹ̀san fún un.
Lara won to wa nibi ipade to waye ni ile- ijoba ohun ni awon oba, awon olori elesin ati awon eniyan pataki to wa ni ipinle naa.
Ṣe ni wọn gbe e sinu iho ti wọn ti gbẹ́ fun oku ẹgbọn rẹ.
- Lizzy Anjorin ''Inu mi bajẹ si iṣẹlẹ yii pẹlu bi awọn ikọ SARS ṣe n fi panpẹ mu awọn eniyan lai ni di.
Gómìnà ìpínlẹ̀ Ekiti, Kayode Fayemi nàá ti ni aàrùn Coronavirus Àwọn aṣekúpani tún ti pa ọmọ ọdún 16 ní Akinyele nípìnlẹ̀ Oyo Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Awọn awada to sọ bi ọrọ to kẹyin lori opo Twitter rẹ re e.
O pe akọle ipolongo naa ni ‘SIMPLE agenda manifesto’.
Ọlọ́pàá Ondo: A bá òkú ọmọ igbákeji gómínà tẹ́lẹ̀rí nílé ọ̀rẹ́kùnrin rẹ̀
Oguntola fi aidunnu re han nigba ti o so pe “afara
Wọ́n dàbí ìsun omi tí ó ti gbẹ, ati ìkùukùu tí afẹ́fẹ́ ń fẹ́ kiri.
Odunlade sọ pe Mercy ni olootu ere tiata ti oun kopa ninu rẹ, eyi ti akọle rẹ n jẹ ''DARA.
O sì ṣoro títí wọ ọdún 1959, nígbà tí ẹdinku bá iye èèyàn tó ń kú, tí wọn kò sì ju ìgbà lọ mọ nínú ọdún kan.
OLUWA ní: “Àwọn ará Israẹli ń dẹ́ṣẹ̀ kún ẹ̀ṣẹ̀, dájúdájú, n óo jẹ wọ́n níyà; nítorí pé wọ́n ta olódodo nítorí fadaka, wọ́n sì ta aláìní nítorí bàtà ẹsẹ̀ meji.
Ìran Abrahamu ni mí, láti inú ẹ̀yà àwọn ọmọ Bẹnjamini.
Láti ìgbà náà, ó ti farahàn tó ìgbà mẹ́wàá nínú ẹgbẹ́ agbábọ̀ọ̀lù Red Devils tí ó sì ti n pinu láti búwọ́ lùwé láti fikún àsìkò rẹ̀ nínú ẹgbẹ́ agbábọ̀ọ̀lù Manchester United.
Kristi kì í ṣe aláìlera ninu ìbálò rẹ̀ pẹlu yín.
Ṣugbọn bí ẹnikẹ́ni bá fẹ́ràn Ọlọrun, òun ni Ọlọrun mọ̀ ní ẹni tirẹ̀.
Ó yọ àwọn ìjòyè kúrò lórí oyè,ó gbé àwọn onírẹ̀lẹ̀ ga.
Ṣugbọn àwọn ọmọ Israẹli kò ní gbọ́ tìrẹ, nítorí pé wọn kò fẹ́ gbọ́ ọ̀rọ̀ mi.
Wọ́n dáhùn pé, “Ẹ jẹ́ kí á kúkú pe omidan náà kí á bèèrè lọ́wọ́ rẹ̀.
Iroyin kan ni o ti to ẹmi awọn eniyan mẹjẹ to ti lọ si iwọde yii ni Sudan.
nípa ẹni tí a ti rí oore-ọ̀fẹ́ gbà, tí a sì gba iṣẹ́ òjíṣẹ́ ní orúkọ rẹ̀, pé kí gbogbo eniyan lè gba Jesu gbọ́, kí wọ́n sì gbọ́ràn sí i lẹ́nu.
Yóo sá tẹ̀lé àwọn olólùfẹ́ rẹ̀, ṣugbọn kò ní lè bá wọn; yóo wá wọn káàkiri pẹlu ìtara, ṣugbọn kò ní rí wọn.
Helen Paul ni itan yii ko tilẹ ki n ṣe itan oun gbọọn lati ilẹ bi ko ṣe itan iya to bi i lọmọ, iya yii kan naa lo wa fi oye PhD to gba ji fun.
O woye pe, gbogbo awon ero ti won n se ayewo ara bi: MRI, CT scan ati ultrasound ati awon ohun elo miiran ni won ko sise mo tabi ti ko si won nile-iwosan naa.
O ku diẹ ko pe iṣẹju mẹsan an ni awọn aṣofin yii fi kunlẹ ni iranti iṣẹju mẹjọ ti ọlọpaa naa fi gbe orunkun le Floyd lọrun ti o si n pariwo pe oun ko le e mi.
O ni adura ti àwọn kan n gbà ni pe, ki arun naa ma ran àwọn ènìyàn dúdú, o ni ilé ìwòsàn, ilé oogun àti ile itaja ìgbàlode nikan ni wọ́n gba láti ṣilẹkun wọn.
N kò tíì yapa kúrò ninu àṣẹ tí ó ti ẹnu rẹ̀ jáde,mò ń pa wọ́n mọ́ ninu ọkàn mi.
” Nígbà náà ni Johanu gbà fún un.
Bakan naa lo sọ pe awọn ti fi akọsilẹ igbaradi wọn ranṣẹ si ijsba ṣaaju ki Saudi to fi ikede sita.
"Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Aṣọ òkè: Alákọ̀wé ní ọ̀nà láti wá oúnjẹ fáwọn tó ń ṣe aṣọ òkè ló ṣún òun débẹ̀ ""Inu ile yii ni gbogbo ọmọ ẹgbẹ ọlọkọ ero, boya alaaye ni abi oku ti bẹrẹ, ko sẹni to lee sẹ lori eyi."
Sise Amojuto lori reO ni oun nigbagbo pe awon oloye  egbe naa yoo  lo abajade lati fi se atona fun awon awuye-wuye to ba n waye ninu egbe.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Mí ò ya wèrè, mí ò burú, ọ̀nà àtijẹ là ń wá' ASD lo mú àbá wá wi pé Sẹnatọ le maa san owo náà díẹ̀diẹ̀ ti sẹnatọ naa si gba bẹ́ẹ̀, nígbà ti o délé o lọ fun ASD ni ẹgbẹ̀run méjìlá dọla ti ASD si fun un ni edà iwe fun owo to san.
Èèyàn mọ́kànlá kú lọ́jọ́ kan ṣoṣo ní Kano O kere tan, eniyan mọkanla lo di oloogbe niluu Kano lọkọ kan, ṣugbọn ko si ẹni to le sọ bo ya aarun coronavirus lo ṣeku pa wọn.
"Onimọ nipa ihuwasi eeyan naa, Omowe Rhoda sọ fun BBC pe, ẹnikẹni to n hu iru iwa bayii ni aisan ọpọlọ to n fa ohun ti awọn kan n wọn pe ni ""Pedophilia."
Josẹfu sọ fún àwọn arakunrin rẹ̀ ati gbogbo ìdílé baba rẹ̀ pé òun óo lọ sọ fún Farao pé àwọn arakunrin òun ati ìdílé baba òun tí wọ́n wà ní ilẹ̀ Kenaani ti dé sọ́dọ̀ òun.
Wumi Toriola Yoruba bọ, wọn ni bi ile da bi ko da, awọ ni ẹ wo.
Má bẹ̀rù, má sì ṣe jẹ́ kí ojú wọn já ọ láyà, nítorí pé ìdílé ọlọ̀tẹ̀ ni wọ́n.
Àwọn ìlú tó ń bá ilẹ ̀ faransé jà nígbà náà ni austria , prussia , russia , britain àti spain .
“Ọlọrun ti fi àṣẹ sí i pé, lẹ́yìn aadọrin ọdún lọ́nà meje ni òun óo tó dárí ẹ̀ṣẹ̀ àwọn eniyan rẹ ati ti ìlú mímọ́ rẹ jì wọ́n, tí òun óo ṣe ètùtù fún ìwà burúkú wọn, tí òun óo mú òdodo ainipẹkun ṣẹ, tí òun óo fi èdìdì di ìran ati àsọtẹ́lẹ̀ náà, tí òun óo sì fi òróró ya Ilé Mímọ́ Jùlọ rẹ̀ sọ́tọ̀.
 Bi o ti le je pe, iko agbaboolu Super Falcons padanu ifesewonse akoko ninu idije naa sowo iko kan naa(Banyana Banyana), sugbon won taraji lati gbesan ninu asekagba idije ohun.
Èyí ni yóo jẹ́ iṣẹ́ yín nítorí ẹ̀bùn ni mo fi iṣẹ́ alufaa ṣe fun yín.
Dafidi sọ fún Abiatari alufaa, ọmọ Ahimeleki, pé kí ó mú efodu wá.
Ẹ̀yin eniyan mi,ẹ wọ aṣọ ọ̀fọ̀, kí ẹ máa yí ninu eérú;ẹ máa ṣọ̀fọ̀, bí ẹni tí ń ṣọ̀fọ̀ ọmọ rẹ̀ kanṣoṣo;kí ẹ sì máa sunkún tẹ̀dùntẹ̀dùn,nítorí pé lójijì ni àwọn apanirun yóo bò yín.
Oluwo ilu Iwo nipinlẹ Osun tio gboṣuba kare fawọn aṣofin ipinlẹ Ogun pẹlu igbesẹ wọn eleyi ti yoo mu atunto ba ilana isinku awọn Ọba lagbegbe wọn.
A rii ti awọn janduku kan n ṣe ikọlu si awọn ara ilu ni agbegbe Oke-Are, awn ọlọpaa si gbe igbesẹ kia pẹlu ọkọ wọn ti wọn gbe lọ sibẹ lati koju iṣẹlẹ naa.
Bi iyawo aarẹ ṣe yan Funke sipo jẹ iyalẹnu fun ọpọ eeyan, sugbọn o ti n ba iyawo aarẹ ṣiṣẹ tẹlẹ ko to di akoko yii.
2 40023 Orilẹede Zambia 364 2.
Wọ́n kó àwọn ihamọra rẹ̀ sinu tẹmpili oriṣa wọn, wọ́n sì kan orí Saulu mọ́ ara ògiri tẹmpili Dagoni, oriṣa wọn.
Ni bayi, Eagles yoo lo ewu tuntun naa fun igba akoko ninu ifesewonse olorejore ti yoo waye laarin iko naa ati orile-ede Poland, ki won o to teko leti lo gba ifesewonse akoko pelu Croatia ninu idije agbaye.
Ó kọ́ àwọn ìlú olódi sí ilẹ̀ Juda nítorí pé alaafia wà ní gbogbo ilẹ̀ náà.
Ò ń gbéraga sí Ọlọrun ọ̀run.
Iko agbaboolu Real Madrid ti pegede sinu asekagba idije UEFA champions league fun igba keta lera won bayii.
Eliabu ọmọ Heloni ni yóo jẹ́ olórí wọn.
Ẹ kálọ, n óo pèsè ohun gbogbo tí ẹ nílò fun yín, ẹ ṣá má sun ìta gbangba níhìn-ín.
Àwọn orílẹ̀èdè tó ń ṣe bẹbẹ nínú ìdíje AFCON 2019 tó ń lọ ní Egypt Lai Muhammed yóò fojú ba'lé ẹjọ́ - ICPC Àwòrán apanilẹ́rìn-ín fún ọ̀sẹ̀ yìí, ìtọ́wò rèé Ẹwẹ lati igba ti orin tuntun yii, Soapy ti jade lawọn ọmọ Naijiria ko ti sinmi ẹnu lori ẹrọ ayelujara.
    Ìgbà tí ó di ọjọ́ kẹta mo múra ó di ilé Òmùgọ́parapọ̀ láti lọ̀ kí Wèrédìran.
Lẹyin ti esi wa jáde ni ọgba ẹwọn ti fi gbogbo awon to ti ni nkan ṣe pẹlu wọn naa lọ farapamọ fun ọjọ mẹrinla gẹgẹ bi ilana NCDC, ayẹwo wọn si n lọ loorekoore.
"Oríṣun àwòrán, @OGSG Banki Nàìjíríà, CBN ṣàlàyé nípa àwọn tó máa rí gbà nínú owó ìrànwọ́ N75b tíjọba gbé kalẹ̀ Wo àfipábánilòpọ̀ ẹni ọdún 51 tí ìjọba ìpínlẹ̀ Ekiti tú làṣirí ní gbangba ""Àwọn sójà ní mo káàbò sí ilé ìṣerun àgbáyé tí wọ́n tí ń ṣerun bó ṣe wu wọ́n"" Àlàyé rèé lóríi ìdí tí wọ́n fi ń pe aya ní ìyàwó Ẹ fún wa lówó oṣù wa tàbí kí a gùnlé ìyanṣẹ́lódì ọlọ́jọ́ gbọọrọ- Àwọn dokita ìpínlẹ̀ Ondo Atejade kan ti akọwe igbimọ naa Arabinrin Oluwatosin Ogundele fi sita ni igbẹjọ yi ko ni fi igba kan bọkan ninu ti yoo si mọlẹ kedere fara ilu."
Ó wọ ẹ̀wù tí a rẹ sinu ẹ̀jẹ̀.
awon ti o je osise to  n se ounje fun
Facebook yóò bẹ̀rẹ̀ ìnáwó orí ayélujára 'GlobalCoin' lọ́dún 2020
Gbogbo ọjà di títì pa nílùú Akure, ṣugbọ́n nítorí kí ni?
" níbi tí àtúnṣe bá sì ti pọn dandan , "" a kì í fòdù ọ ̀ yà sùn ká tó í nà án ládàá "" , wọn kò nì í bèsù bẹ ̀ gbà , wọn óò sì se àtúnṣe ní wéréwéré ."
Fadaka tí àwọn tí wọ́n kà ninu àwọn eniyan náà dájọ jẹ́ ọgọrun-un ìwọ̀n talẹnti, ati ẹẹdẹgbẹsan ìwọ̀n ṣekeli ó lé marundinlọgọrin (1,775), ìwọ̀n tí wọ́n máa ń lò ninu àgọ́ ni wọ́n fi wọ̀n ọ́n.
Ọmọ-ọ̀dọ̀ tí ó wà ní Hong Kong ju 370,000 lọ, òfin ṣì fi àyè gbà wọ́n kí ó máa gbé nínú ilé ọ̀gáa wọn.
Bí o ti wu tí obìnrin ṣe aláìgbọ́n tó, kò ní ṣàì fẹ́ràn ọmọ rẹ̀, bẹ́ẹ̀ ni bí a bá fẹ́ràn ọmọ ẹni, ọ̀rẹ́ ọmọ náà ọ̀rẹ́ ni yóò jẹ́ fún ni.
"O ni bi oun se n fi isẹ ikinni Barret jẹ fun aarẹ Buhari lo fesi pada pe ""Lindasay Barret, mo ranti pe emi ati ẹ pade loju ogun lọdun 1968."
Nítorí pé kí Ọlọrun tí ó dá gbogbo nǹkan, tí ó sì mú kí gbogbo nǹkan wà, lè mú ọpọlọpọ wá sí inú ògo, ó tọ́ kí ó ṣe aṣaaju tí yóo la ọ̀nà ìgbàlà sílẹ̀ fún wọn nípa ìyà jíjẹ.
Ìjà orogún awọn dokita àti oṣiṣẹ ilera.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Moses Melaye: Dino Melaye sùn ìta gbangba mọ́jú níléesẹ́ DSS Ọlọpaa to kawe jinlẹ ni ọgbẹni Ẹgbẹtokun pẹlu iwe ẹri imọ ijinlẹ akọkọ ninu imọ iṣiro, (B.
OLUWA wí fún un pé, lọ ka àwọn ọmọ Israẹli ati ti Juda.
Oríṣun àwòrán, V&A MUSEUM Àkọlé àwòrán, Bakan naa ni wọn si sọ wi pe awọn yoo da lara rẹ pada.
Yóo lọ sí ìhà gúsù sí Ribila ní ìhà ìlà oòrùn Aini títí lọ sí àwọn òkè tí wọ́n wà létí ìhà ìlà oòrùn Òkun-Kinereti.
Ọlọrun, ìyìn rẹ tàn ká,bí orúkọ rẹ ṣe tàn dé òpin ayé,iṣẹ́ rere kún ọwọ́ rẹ.
ati ilẹ̀ Araba títí kan odò Jọdani.
Ó fún un ní omi láti fi ṣan ẹsẹ̀ rẹ̀ ati ẹsẹ̀ àwọn ọkunrin tí wọ́n bá a wá.
Amọ ijọba ipinlẹ Oyo sọ pe ohun ti gbaradi fun ṣiṣi ileewe pada nipa riran awọn akọṣẹmọṣẹ ninu eto ilera ati ọrọ ayika lọ si awọn ileewe lati sọ bi eto ṣe le kẹsẹjari.
Yóo wó odi rẹ ati àwọn ilé dáradára tí ó wà ninu rẹ lulẹ̀.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Iwadi awọn onimọ ijinlẹ si ti fidi rẹ mulẹ pe, kii se gbogbo obinrin ti wọn ba gba ibale rẹ ni yoo se ẹjẹ loju ara, nigba ti awọn obinrin kan tiẹ wa ti wọn ko mu ibale wa lati ọrun, tabi ki ibale wọn ti seesi ja lasiko ti wọn wa ni kekere nitori erepa to lagbara tabi ere idaraya ti wọn se.
Funke Akindele ti di ìyábejì Àwọn arẹwà obinrin Yollywood, tá ló mọ iṣẹ́ rẹ̀ jù?
Àwọn ọmọ Binui jẹ́ ojilelẹgbẹta ó lé mẹjọ (648).
ní Ṣilo ní ilẹ̀ Kenaani, wọ́n sọ fún wọn pé, “OLUWA ti pàṣẹ láti ẹnu Mose pé kí wọ́n fún wa ní ìlú tí a óo máa gbé ati pápá oko fún àwọn ẹran ọ̀sìn wa.
Wo àwọn nkan tó yẹ́ kí o mọ̀ nípa 'Awawa Boys', ọ̀kan lára ẹgbẹ́ òkùnkùn tó n dá Eko rú Lẹ́yìn gbogbo sinimá oríta ní Ondo, Akẹti jáwé olúborí ní APC Wo ohun tó yẹ kí o mọ̀ nípa Laycon, akẹ́kọ̀ọ́jáde UNILAG tó ń kópa nínú BBNaija 2020 Iléeṣẹ́ ológun òfúrufú ti dárúkọ ẹni tó fi ọkọ̀ pa Tolulope Arotilẹ Wo àwọn tí Pondei fara jọ pẹ̀lú ààrẹ̀ níwájú ijẹ́jọ́ Ṣugbọn ṣa, awọn alaṣẹ ajọ TRACE, sọ pe awọn ko gba ọkọ lọwọ ọkunrin naa.
 E o ni anfaani lati dibo
bayii ni eyi ti o lo lati  Onitsha-Enugu ,
Ó wu OLUWA láti gbé òfin rẹ̀ gaati láti ṣe é lógo nítorí òdodo rẹ̀.
Ọlọ́pàá ń wa Ṣugbọn ijọ yii ti wọn darukọ rẹ ninu fidio to wa loke wa ni ilu Igboora, wọn si ni Woli kan to n dari wọn.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Ọjọ kejilelogun oṣu keji ọdun yii ni idije naa ko ba bẹrẹ tẹlẹ ki ajakalẹ arun covid-19 to bẹrẹ.
“Nítorí náà, kọ orin yìí sílẹ̀ nisinsinyii kí o sì kọ́ àwọn ọmọ Israẹli, kí orin náà lè jẹ́ ẹlẹ́rìí mi lọ́dọ̀ wọn.
OLUWA Ọlọrun àwọn ọmọ ogun ní, “Lọ bá Ṣebina, iranṣẹ ọba, tí ó jẹ́ olórí ní ààfin ọba, Kí o bi í pé: 
Ẹ̀yin ni Ẹ̀mí Mímọ́ ti fi òróró yàn, gbogbo yín sì mọ òtítọ́.
Ṣugbọn ọrọ ohun dabi ilu gangan an to jẹ pe ohun to kọju sẹnikan, ẹyin lo kọ sẹlominran.
Ẹrọ tí o ń lù kìkì lásán!
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ajimọbi: Pé Ayefẹlẹ jẹ́ àkàndá kò fún láṣẹ láti rú òfin Eeyan ko gbọdọ sọ pe t'ori oun jẹ alaabọ ara ko máa rufin-Abiola Ajumọbi Gbolohun yi jẹ ọkan ti awọn ọmọ kaarọ ojiire ko ni gbagbe lọdun 2018.
 ní ilẹ ̀ amẹ ́ ríkà iye owó rẹ ̀ kò tó 25 usd .
O wa lori ipo laarin ọdun 1811 si 1915.
Mú ẹran náà, kí o bó awọ rẹ̀, kí o sì gé e sí wẹ́wẹ́; 
Wọn wa tẹnumọ pe Oshiomole ṣi ni alaga olori awọn ati pe ''wamuwamu lawọn wa lẹyin rẹ'' Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
O ni boya awọn ẹbi oun ko ba wa ninu pe wọn n wa owo kiri bayii lati ba idande oun lọwọ awọn ajinigbe naa ni.
Onidajọ Ademọla Bọla gbe idajọ rẹ kalẹ pe ki wọn lọ yẹgi fun iranṣẹ Ọlọrun naa fun ṣiṣeku pa arakunrin kan ti oruks rẹ n jẹ Ayọ Ọlaniyi ni ileto kan to wa nitosi Okeigbo ni ipinlẹ Ondo.
Àgọ́ àwọn ọmọ ogun Midiani wà ní àfonífojì lápá ìsàlẹ̀ ibi tí wọ́n wà.
Wọ́n bọ́ ẹ̀wù rẹ̀, wọ́n wá fi aṣọ àlàárì bò ó lára.
“Nítorí náà, wí fún wọn pé èmi, ‘OLUWA Ọlọrun ní n óo kó wọn jọ láti ààrin àwọn ẹ̀yà ati orílẹ̀-èdè mìíràn tí mo fọ́n wọn ká sí, n óo sì fún wọn ní ilẹ̀ Israẹli.
23 Ẹrẹ̀nà 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Iyansipo naa ni o kan awọn lọga lọga to le ni aadọta to fi mọ ipo igbakeji ọga agba ọlọpaa ati awọn kọmisana ọlọpaa.
alaafia se farahan ni awon ilu kaakiri, o tun wa ro awon eniyan lati tubọ maa
ṣugbọn nítorí opó yìí ń yọ mí lẹ́nu, n óo ṣe ẹ̀tọ́ fún un, kí ó má baà fi wahala rẹ̀ da mí lágara!
Kachalla ni igbagbọ awọn obi naa ni pe awọn ọmọ yii nkoju awọn iriri to buru jai idi si niyi tawọn fi gbọdọ se aayan lati sawari wọn.
Bí ó ti ń lọ, ó dé ilé Mika ní agbègbè olókè ti Efuraimu.
O loju ọdọ to lee tayọ baba mi to ba dọrọ jijo bata.
Ọrọ pọ ninu iwe kọbọ ti ko ni ṣee kọ jade tabi ka tan, lẹnu kan de, ẹ wo fọnran yii lati wo gboogbo alaye bi Bosede Oguntunde lati ilu Ilorin, ẹni ọdun mẹtadinlaadọta koda to ti ni ọmọ-ọmọ ṣe di ẹni ti n pọ owó fún Woli Aroye Jesu ni ilu Igboora.
Ọlafare ni olori ẹsọ fi ọwọ sọ fun Oluwo lati jẹ ki Ọọni raye kọja si aye rẹ o si ni Oluwo gba lọgan, Ọọni si kọja si aye rẹ.
Ọjọgbọn Ṣoyinka tun rọ awọn ọmọ Naijiria pe, ki wọn mase gba gbogbo iroyin ti wọn ri lori ayelujara gbọ.
Loju opo Twitter rẹ ni o fi ikede yi si ninu fọnran fidio kan ti o ti kede fawọn eeyan ipinlẹ rẹ.
Oríṣun àwòrán, Other Laipẹ yii si lo ṣe ayẹyẹ ọjọ ibi rẹ loke eepẹ.
S Agboyi Ketu - Mile 12 Ajah - Oworonshoki Ijora - Ebute Ero Ikorodu - Oworonshoki Marina/C.
Wọ́n ti ṣí ilé oúńjẹ oní ọgbọ̀n náírà (N30) ní Kano Ta ni Funmilayọ Ransome-Kuti?
Ileesẹ to n dari ọrọ ilẹ sọ pe oun wadii orukọ wọn ninu akọsilẹ awọn to ni iwe ẹri, awọn ko ri aridaju pe wọn tẹle ilana to yẹ lati fi ra ilẹ naa.
Ẹlẹ́gbára náà bá dáwó dúró o ń wo gbogbo àgbègbè.
Bukola Saraki kò kọjá òfin - EFCC Osun Election Tribunal: Èyí ni òkodoro ìdájọ tí àwọn eniyan ìpínlẹ̀ Ọsun ti ń reti- Oyetola Ìgbà mélòó ni ikọ̀ Ilẹ̀ Gẹ̀ẹ́sì méjì wọ àṣekágbá Champions League rí?
Asa ka maa fi asọ ori ibusun han lalẹ ni aarọ ọjọ keji igbeyawo wọpọ lawọn agbegbe kan lagbaye, paapa ni Caucasus, ẹjẹ to ba si wa lara asọ ori ibusun naa lo n fi ẹri mulẹ pe ọkọ ba iyawo rẹ nile.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Wo itan omi gbigbona ati tutu ni Ikọgosi Ekiti 'Atunse ofin lo le dẹkun jẹgudujẹra' Niyi Akintọla: Atunse ofin lo le dẹkun jẹgudujẹra Niyi Akintọla ni ti atunse ko ba ba ofin Naijiria, iwọnba ni ijiya awọn oni jẹgudu-jẹra yoo maa jẹ.
mo wí fun yín gbangba lónìí pé, ẹ óo parun.
Oríṣun àwòrán, NAHCON Àkọlé àwòrán, Papakọ ofurufu Nnamdi Azikwe ni awọn arinrin-ajo naa yoo ti gbera Oríṣun àwòrán, NAHCON Àkọlé àwòrán, Àyẹwò fínífíní fún àwọn arinrin-ajo ṣe pàtàkì Oríṣun àwòrán, NASA Àkọlé àwòrán, Hajj je opo pataki ninu ẹsin Islam Oríṣun àwòrán, NAHCON Àkọlé àwòrán, Awọn osisẹ ile isẹ alalaji wa nikalẹ lati ri pe oun gbogbo lọ ni irọwọrọsẹ Oríṣun àwòrán, NAHCON Àkọlé àwòrán, Oko ofurufu ti yoo gbe awọn alalaji naa Oríṣun àwòrán, NAHCON Àkọlé àwòrán, Mínístà fún ìlú FCT Mohammed Bello ati alága àjọ tó n mójú tó ọrọ Alalaaji ní orílèèdè Nàìjíríà Abdullahi Mukhtar Muhammad ní papako òfurufú Nnamdi Azikiwe labuja Oríṣun àwòrán, NAHCON Àkọlé àwòrán, Aarẹ Buhari ni awọn mu eto aabo awọn ọmọ ilẹ Naijiria BBC News, Yorùbá Ìdí tí ẹ fi le è nígbàagbọ́ nínú ìròyìn BBC Ìlànà Lílò Nípa BBC Òfin Àṣírí Cookies Kàn sí.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Wo àwọn òṣèré Yorùbá tí Aisha Buhari yàn fún ìpolongo ìbò Nàìjíríà á bí ọmọ 25, 685 lọjọ́ kínni, oṣù kinni, ọdún 2019.
A kọjá ibi tí ilẹ̀ gbọọrọ ti wọ ààrin òkun tí wọn ń pè ní Salimone.
N1M ní iléẹ́jọ́ béèrè fún béèlì olùwọ́de EndSARS, Eremosele Adene Ile ẹjọ́ majisireeti kan ipinlẹ Eko ti gba beeli Eremosele Adene ti wọn fẹsun kan pe o ṣe onigbọwọ awọn oluwọde EndSARS nipinlẹ naa.
Oun ni ẹni akọkọ ọmọ Ẹya Hausa ti yoo kawe gboye ọjọgbọn ninu imọ ijinlẹ nipa ẹya ara.
Wọ́n fi ogun kó gbogbo àwọn ìlú náà nítorí pé ìkógun pọ̀ ninu wọn.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Dapo Ojora: Ẹ̀gbọ́n ìyàwó Bukola Saraki kú l'Eko, èdè aìyedè wà lórí bó ṣe kú 12 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Oríṣun àwòrán, Twitter/bukaola saraki Ni alẹ ọjọ Ẹti ni iroyin jade sigboro pe, ilumọọka ọmọ jayejaye ilu Eko ni, Dapọ Ọjọra ti jade laye.
Nígbà tó yá mo bá tún dé ibìkan tó dàbí ilẹ̀ olókùúta bákan.
Pẹlu ifẹsẹwọnsẹ yii bayii, ami ayo mẹrin ni Manchester United ti ni ninu ifẹsẹwọnsẹ meji ti wọn ti gba.
Àríyá ò lópin láti ìgbà tí Nàìjíríà ti júwe ilé fún South Africa Super Eagles kò ní já àwọn ọmọ Nàìjíríà kulẹ̀- Musa Kíló burú nínú kí Sanwo-Olu fún Super Eagles lówó?
N kò sọ̀rọ̀ bí onigbagbọ nípa ohun tí mo fi ń fọ́nnu yìí, bí aṣiwèrè ni mò ń sọ̀rọ̀.
 Eni ti o bere aye re gege bi akoroyin, ki o to di osere ori itage ati ori amohunmaworan, ti O si tun n sise takuntakun ni gbogbo igba lati mu igberu ba egbe osere Nollywood ni Naijiria.
 ohun tí a máa ń pè ní olórí fún àpólà kan ni òrò kan soso tí ó bá è dúró fún àpólà yen .
ifesewonse idije ile geesi ti o waye lopin ose.
Lẹyinorẹyin, ile ẹjọ giga kan nilu Eko ran lẹwọn ọdun mejila lọjọ karun un oṣu Kejila ọdun 2019.
Pẹlu bi o ti ṣe jẹ́ wi pe awọn to n wa itọju lo n san owo to pọju lati gba itọju,pupọ awọn mọlẹbi ti owo to n wọle fun wọn ko to dọla meji kii le gbọ bukata yi Oun to bani ninujẹ ni pe Naijiria ko ni akojọpọ iroyin to munadoko lori ọrọ yi lati ọdun 2009.
Àwọn ọlọ́pàá wá, wọn fẹ isẹ ṣe, ọ̀pọ̀ wọn sì ni kò ní irinsẹ láti fi ṣíṣẹ.
Ninu gbogbo nǹkan, mo ṣe é lófin pé n kò ní wọ̀ yín lọ́rùn, n kò sì ní yí òfin yìí pada!
Ìtàn ìgbésí ayé Oshodi, ọmọ Tápà léǹpe tó di akọni ní ìlú Eko Inú jìn!
ilana-ibagbepo ile india , to je ilana-ibagbepo togunjulo ati to kunrerejulo ti orile-ede alominira lagbaye , je gbigba bi ofin ni 26 january 1950 .
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Badagry ní ogún àjogúnbá tó pọ̀ yàtọ̀ sí òwò ẹrú Amọ nigba ti wahala wiwa ọmọ naa peleke, Falayi tun gbe Adediwura kuro nibẹ, to si gbe e lọ sile Ọba Asusumasa Atewogboye.
Aṣa igbeyawo nilẹ Oodua kii ṣe laarin ọkọ ataya nikan bikoṣe laarin gbogbo ẹbi mejeeji.
Ọkàn mi tí Ẹ̀mí ń darí sì jẹ́ mi lẹ́rìí pẹlu, pé, 
- Bode George Aya mi, dáríjìn mí fún bí n kò ṣe fi ìfẹ́ hàn sí ọ bó ṣe yẹ - Mike Bamiloye Wo owó tí Buhari bù fún ẹ̀ka kọ̀ọ̀kan nínú ìṣúná ọdún 2021 Kanu Ejike fipá bá ọmọ ọdún méje lò pọ̀ nínú sọ́ọ̀bù ìyàwó rẹ̀ Macaroni dari àwọn ènìyàn míran láti wọde lọ sí Alausa tii ṣe ilé iṣẹ́ ìjọba ìpínlẹ̀ Eko.
Nígbà tí wọ́n pada wá sọ ohun tí ó ṣẹlẹ̀ fún Jehu, ó ní, “OLUWA ti sọ tẹ́lẹ̀ láti ẹnu wolii Elija, iranṣẹ rẹ̀ pé, ajá ni yóo jẹ òkú Jesebẹli ní agbègbè Jesireeli.
Àwọn ni wọn yóo san owó fún àwọn gbẹ́nàgbẹ́nà ati àwọn tí wọn ń kọ́lé; 
Èyí ni yóo jẹ́ ìgbàlà mi,nítorí pé ẹni tí kò mọ Ọlọrun,kò ní lè dúró níwájú rẹ̀.
Amọ ṣa, kini iwulo awọn janduku oloṣelu yii lẹyin eto idibo?
Àwọn tí ń fọ́n irúgbìn pẹlu omi lójú,jẹ́ kí wọn kórè rẹ̀ tayọ̀tayọ̀.
tí kò gba owó èlé lọ́wọ́ ẹnikẹ́ni, tí ó yàgò fún ẹ̀ṣẹ̀, tí ó ń dá ẹjọ́ ẹ̀tọ́ láàrin ẹni meji, 
O ṣalaye pe oun di atipo ni America pẹlu ọmọ oun meji, lasiko ti ijọba Ọgagun Sani abacha, ni Naijiria fi ọkọ oun si ẹwọn, nitori ọrọ June 12.
A bi Ayo da Silva si ilu Eko, O lo sile iwe alokobere nipinle Edo, O teko leti lo sipinle eko lati tesiwaju fun eko girama, leyin re, o lo si ile-iwe eko gbogbonise nipinle Ogun, ogun state Polytechnic, niluu Abeokuta lati lo ko eko imo sayensi( Applied Chemistry), O si lo si ila oorun orile-ede Naijiria fun eto agunbaniro.
Ẹ̀yin amòfin ati ẹ̀yin Farisi, ẹ̀yin alárèékérekè wọnyi.
Ta ni o rò pé ò ń sọ̀rọ̀ ẹ̀gàn sí,tí o sì fi ń ṣe ẹlẹ́yà?
Nítorí ẹ fẹ́ràn ìjókòó iwájú ninu ilé ìpàdé.
N óo sọ ọ́ di olókìkí bí ọba tí ó lágbára jùlọ láyé.
"Tẹ ẹ ba gbagbe, mo sọ ninu fidio to lọ kaakiri ayelujara pe, Olori Alufaa, ati Biṣọpu ni mi ninu ijọ Brotherhood of the Cross and Star , nitori naa ni mo ṣe fa gbogbo nkan le Ọlọrun lọwọ.
Awọn ololufẹ naa Megan Watling ati Sasha-Lee Heekes ni ọgbẹ ọkan ni gbọngan naa da silẹ fun awọn.
Nígbà tí mo simi díẹ̀ lẹ́hìn èyí mo wáá dìde mo ń wọ́ ọ̀nà tí n óò bá padà lọ sí ibùgbé mi lọ́dọ̀ ọba Igbó Olódùmarè ṣùgbọ́n n kò rí ọ̀nà rárá, mo rìn síwá mo rìn sẹ́hìn kò tilẹ sí ibi tí ó jọ bí ẹni pé mo mọ̀.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, #NigeriaDecides: BBC ti wa ni gbogbo ìpínlẹ̀ Naijiria láti firoyin gbogbo tóo yin létí Guru Mahraji jana?
''Bi anfaani ba wa, ma tun se MMM lẹ́kan si'' Esi ti Olatunde Oladimeji fọ re nigba ti ikọ́ BBC Yoruba baa sọrọ lori iroyin to gbale kan pe olùdásílẹ̀ ìlànà sogúndogójì, MMM, Sergei Mavrod ti salaisi.
Ẹni ọdún mẹẹdọgbọn ni Jotamu nígbà tí ó jọba, ó sì wà lórí oyè ní Jerusalẹmu fún ọdún mẹrindinlogun.
O ni iwa awọn ọkunrin ilẹ Pakistan naa larinrin pupọ ti o si jẹ ọkan lara eyi ti o dara ju lọ.
heat : n ; ( fire gives heat .
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Border Closure: Mínísítà fétò ìṣúná ní fún ìgbà díẹ̀ ni wọn yóò fi ti ẹnu bodè pa 27 Bélú 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 28 Bélú 2019 Oríṣun àwòrán, @finance Àkọlé àwòrán, Border Closure: Mínísítà fétò ìṣúná ní fún ìgbà díẹ̀ ni wọn yóò fi ti ẹnu bodè pa Ijọba Aarẹ Muhammadu Buhari ti ni lootọ ni pe ibode ti awọn ti lo fa ki owo ọja o gbe pẹẹli soke si.
Amọ gbogbo nnkan pẹluu sababi ni, bi Ọlọrun ṣe sọ wi pe yoo ṣe ri niyii, a si ti gba fun Ọlọrun.
Wọn óo gba àṣẹ fún wakati kan, àwọn ati ẹranko náà ni yóo jọ lo àṣẹ náà.
Ṣáájú kí o tó fí orúkọ ẹni náà ránṣẹ, àyẹwò fínífíní yóò tí wáyé lọdọ àwọn ilé ìṣẹ́ ọ̀tẹlẹ̀múyẹ́ láti mọ irú ẹni tíì ṣe.
Nígbà tí Asuba kú, Kalebu fẹ́ Efurati, Efurati sì bí Huri fún un.
Nabena ni ajọsepọ awọn asaaju kan ninu ẹgbẹ oselu alatako, PDP pẹlu ilumọọka afurasi gbajuẹ, Ramon Olorunwa Abass, Hushpuppi mu ifura lọwọ.
Ṣugbọn ikọ Arsenal ṣiṣẹ takuntakun lati rii pe Liverpool ko na wọn mọle.
Díẹ̀ nínú ǹkan ti àwọn ènìyàn ń sọ rèé.
Makinde ni oun ati awọn to n ba oun ṣiṣẹ n ṣọ owo to wa ninu apo ijọba ati wipe, oun yoo gbe igbesẹ lati ṣe oun to yẹ ni kete ti wọn ba bura fun ou tan.
Ní ààrin àwùjọ ni n óo yìn ọ́.
Ibi ni ọkàn eniyan burúkú máa ń fẹ́,àwọn aládùúgbò rẹ̀ kì í sìí rí ojurere rẹ̀.
Coronavirus: Èèyàn kan péré ló ní àrùn aṣekúpani náà ní Nàíjíríà báyìí
Ìwé kíkà ló pín ọmọ tálákà yìí àti àwọn òbí rẹ̀ níyà
Òpópó ọ̀nà ṣófo,àwọn èrò kò rìn mọ́;wọ́n ń ba majẹmu jẹ́,wọn kò bìkítà fún ẹlẹ́rìí mọ́;wọ́n kò sì ka eniyan sí.
Iko ti o n ri si oro awon omo-wewe ninu ajo isokan orile-ede agbaye (UNICEF) so pe, ajo ohun ti gbe ganga-dero, ti o din nirinwo kaakiri awon ilu bi: Shendam ati Riyom ti o wa ni ijoba ibile ipinle Plateau, ni iyanju ati pese omi-mimu to mo-gaara.
” Sarai bá bẹ̀rẹ̀ sí fòòró ẹ̀mí Hagari, Hagari sì sá kúrò nílé.
Bakan naa ni Alaafin Adeniran Adeyemi keji, tii se baba ọba Lamidi Adeyemi, ẹni to jọba laarin ọdun 1945 si 1955, to si lo ọdun mẹwa pere lori oye, ki wọn to yọ nipo.
ohun jewo pe awon sekupa omo naa lati yo awon egun ara re.
”Ati pé,“Èmi nìyí ati àwọn ọmọ tí Ọlọrun fi fún mi.
Hesekaya gba àwọn ọmọ Lefi tí wọ́n ṣe dáradára ninu iṣẹ́ OLUWA níyànjú.
Nadabu ati Abihu kú nígbà tí wọ́n rúbọ sí OLUWA ninu Àgọ́ Àjọ pẹlu iná tí kò mọ́.
itoju ti won le lọ, ti won ba ni ipenija pelu ilera oju won.
Peteru bá sọ fún un pé, “N kò ní fadaka tabi wúrà, ṣugbọn n óo fún ọ ní ohun tí mo ní.
Coronavirus in Nigeria: Nàìjíríà yóò wo tí aráàlú bá bínú lórí àfikún igbele Covid-19 - Dele Momoodu Oríṣun àwòrán, dele momodu Gbajumọ akọroyin àti olóṣèlú kan, Dele Momoodu tí woye pe o ṣeé ṣe kí orílẹ̀ èdè Nàìjíríà wo, tí àwọn aráàlú bá fi bínú lórí àfikún igbele àrùn Coronavirus.
Timothy Owoẹyẹ ti ipinlẹ Ọsun ati pupọ lara awọn oṣiṣẹ ati akọwe ile igbimọ
“Bí arakunrin rẹ bá ṣẹ̀ ọ́, tètè lọ bá a sọ̀rọ̀, ìwọ rẹ̀ meji péré.
Nítorí náà, n óo tọ́jú àwọn ohun èlò sílẹ̀ fún un.
Ọmi ayo kọọkan ni Naijiria ta pẹlu Ukraine ninu ifẹsẹwọnsẹ to kẹyin ti wọn gba ni isọri wọn lati pegede fun ipele ẹlẹni mẹrindinlogun.
Ó di ìgbà tí ó bá kú.
Amọ ọmọ Yoruba kan ree, Akin Alabi to n lakaka lati gbe asa Yoruba larugẹ, paapaa nidi ki awọn ọmọde mọ nipa asa, ede, iwọsọ ati itan wa.
Wo ọ̀nà méje bí o ṣe lè dẹ́kun ikú òjijì: Aṣekudorogbo iṣẹ: ọkan lara iṣoro awa eniyan ni aye ode oni ni lati wa ounjẹ oojọ, eleyii ti o mu ki ọpọlọpọ eniyan miran ma a ṣe iṣẹ aṣekudorogbo.
125bn ni owo to pọ sikẹta ninu isuna Inec, ohun si ni wọn yoo lo lati ra awọn ohun eelo idibo ti ko gba ẹlẹgẹN6bn ni Inec yoo fi bọ awọn ọlọpa ninu eto idibo 2019 N5.
Sáájú ní wọn ti ń dágúnla pé àwọn olùkọ́ ati akẹ́kọ́ọ̀ kò ní lè kópa nítorí ìyanṣẹ́lódì tó ń lọ lọ́wọ́.
Oríṣun àwòrán, FACEBOOK/SALIU ADETUNJI Àkọlé àwòrán, Oba Adetunji ní Olubandan kọkanlelógoji , o gori oye ni ọdun 2016 lẹni ọmọ ọdun méji din ni ààdọrun Pẹlu ìgbésẹ̀ yìí wọn gomina ti ti fowokan ilana asa to ti wa tipẹ, ni ìha keji, gomina ni ko si n kan to yii itan pada, ko si nkan to yi iṣenabye pada, bakan naa ni asa o lọ si ibikan nilu Ibadan, bíkose pe àwọn ń mú ìdàgbàsoke ati igbelarugẹ ba àwọn ọlọye to ti wà nilẹ tẹ́lẹ̀ Olubadan ti ọrọ náà kan gbe gomina Ajimobi lọ si ile ẹjọ pe ki ó dá aṣẹ náà pada, bakan náà ni Gomina Oyo tẹlẹ ri Alhaji Rasheed Ladoja to jẹ ọkan lára àwọn Mọgaji ti wọn gbe ga kọ ipò náà to si lodi si ìgbésẹ̀ gomina pe oun kò le jẹ ọba lai ni ààfin Ninu oṣù kini ọdun 2018 ni ile ẹjọ giga ni ìpínlẹ Ọyo dájọ pe ìgbésẹ̀ gomina lòdi si òfin, bákan náà ni Gomina náà ti gbe ẹjọ lọ ile ẹjọ kòtẹmilọrun Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Oríṣun àwòrán, Reuters Àkọlé àwòrán, Idunu subu layo fun opolopo ni Liberia nibi ayẹyẹ ibura wọle Ohwefo White ni ti ẹ n fẹ ki aarẹ wọn tuntun mu idagbasoke ba liigi orilẹede Liberia, ko si tun ran awọn agbabọọlu to jẹ ọmọ Liberia lọwọ lati lọ si ilẹ okeere."
" àkọ ́ kọ ́ ní ọdún 1971 furfuryl alcohol dàpapọ ̀ ṣiṣẹ ́ pẹ ̀ lú bromine ní methanol sí "" 2,5-dimethoxy-2,5-dihydrofuran "" tí ó tún ara ṣàjọ sí dihydropyran pẹ ̀ lú àdàpọ ̀ sulfuric acid ."
O gbe Diakoni Janet Oluṣọla niyawo.
Oun gẹgẹ bii Sẹnetọ ilu California, bi ko tilẹ tii ṣaṣeyọri lawọn idije rẹ kọọkan, nibayii o ti di ilumọọka.
Aṣofin Ọbasa gboriyin fun iṣẹ akinkanju Gomina Akinwunmi Ambọde ni Ipinlẹ Eko.
Ninu atẹjade kan to fi soju opo ileeṣẹ to n mojuto ẹka eto iṣuna rẹ, ijọba Amẹrika sọ pe oun ti gbẹsẹ le ile ati gbogbo ohun ini to jẹ ti awọn afurasi naa to wa nilẹ Amẹrika.
Sowore: Ìdí tí mi ò fi lè ṣiṣẹ́ pẹ̀lú Mogbalu
''Obi mi niṣe la maa fi ọmọ ṣe yẹyẹ pe gbogbo ẹgbẹ rẹ lo ti lọ si yunifasiti, iwọ leleyi to wa nibi.
Iṣelẹ naa waye ni ijọba ibilẹ Charanchi, ni ipinlẹ ọhun, ni aarọ ọjọ Iṣẹgun.
Bóò ṣe lè yẹra fún ikú nígbà òjò - Onímọ̀ Ehi Iden Children's Day: Àwọn ọmọdé tó ń ṣe bẹbẹ láwùjọ Afíríkà 'À ń bẹ Ààrẹ Buhari kó pèsè ààbò fún àwa ọ̀dọ́bìnrin' Ẹ̀gbẹ́ òṣìṣẹ́ ní ìpínlẹ̀ Oyo so ìyanṣẹ́lódì rọ̀!
Àwọn ọba kò gbọdọ̀ ni àwọn eniyan mi lára mọ́, wọ́n gbọdọ̀ fi ilẹ̀ yòókù sílẹ̀ fún àwọn ọmọ Israẹli gẹ́gẹ́ bí ẹ̀yà wọn.
Fidio kan to fihan bi iyawo aarẹ, Aisha Buhari ṣe n fariga pe wọ́n tilẹkun mọ oun ninu ile ijọba to wa l'Abuja pẹlu bi awọn aṣọna si ṣe wa ninu ile ṣi n tu ọrọ sita kaakiri itakun ayelujara.
láti Aroeri tí ó wà ní etí àfonífojì Arinoni ati ìlú tí ó wà ní ààrin gbùngbùn àfonífojì náà, ati ilẹ̀ tí ó tẹ́jú ní Medeba títí dé Diboni; 
Olu ile-iseO salaye pe, igbimo amusese ohun ti so fun awon asoju ti yoo kopa nibi ipade naa lati sa ipa won nipa gbigbe olu ile-ise eto oro kara-kata naa wa sorile-ede Naijiria.
World Toilet Day: Ṣé lóòtọ́ ni ìlú Eko gba ipò gidi tórí ṣíṣe ìgbọ̀nsẹ̀ níta gbangba?
Ní ọjọ́ 20 oṣù Agẹmọ, àgbájọ àwọn ènìyànkéènìà gba ẹ̀mí àwọn àgbàlagbà mẹ́rin kan láì dá wọn lẹ́jọ́ ní agbègbèe Gumla ní Jharkhand, India lẹ́yìn tí a fi ẹ̀sùn-un àjẹ́ kàn wọ́n.
OLUWA ní:“Ṣugbọn nisinsinyii, ẹ̀yin ọmọ Jakọbu iranṣẹ miẹ̀yin ọmọ Israẹli, àyànfẹ́ mi.
Ọlọrun níláti jẹ́ olóòótọ́ bí gbogbo eniyan bá tilẹ̀ di onírọ́.
Ó yọ́ ojúlówó wúrà bo gbogbo inú rẹ̀.
Oríṣun àwòrán, Instagram/ abiola ajimobi O ṣe apejuwe Ajimọbi gẹgẹ bi ẹnikan ti o da yatọ laarin awọn akẹgbẹ rẹ ti o si ni igboya.
Oxfam: Olówó mẹ́ta ní Afirika lówó ju 650m aláìní lọ
Ó ti tán fún mí lọ́dún 2023- Ààrẹ Muhammadu Buhari Bàbá Adamu tó jẹ́ ọmọ ogun Nàìjíríà tó dàgbà jùlọ jáláìsí Ìjọba Gomina Raman Razak padà wólé arúgbó ní Ilọrin!
Ẹlẹ́mìí ni òun alára,nítorí pé kí ni ó lè ṣe?
Ọwọ́ ṣìkún ọlọ́pàá tẹ afurasí tó ń pa obìnrin ni Port Harcourt Lóju òpó Instagram rẹ̀ lo ti pàrọwà náà pé, òun kò nik ẹtọ́ botiwù kí o mọ láti tàbùkù ẹnikan tàbi dá ẹnikéni lẹbi nítori òun ko mọ ibi ti bàta ti n ta wọ́n lẹ́sẹ̀, sùgbọ́n ó ṣe pàtàkì láti fòpin si ààwọ náà ki wọn le tẹsíwáju pẹlu ayé wọ́n.
Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí 1:44 Fídíò, Ebola Virus: ìdí tí Ebola fi ń tàn kálẹ̀, Duration 1,4422 Òkùdu 2019 Ebola: Àwọn aláìsàn mẹ́ta sá kúrò níléwòsàn ní DR Congo24 Èbibi 2018 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
àwọn ọmọ Jaala, àwọn ọmọ Dakoni, ati àwọn ọmọ Gideli;
Koda awọn miiran ni akọnimọọgba tuntun fun ikọ agbabọọlu Chelsea, Frank Lampard ko mọ iṣẹ, wọn ni ki wọn le lọ.
Ipinlẹ Kwara, Eko, Ọyọ ati Ogun lo tun tẹlee eyi ti o yi iha ti ọpọ kọ si eto oṣelu lorilẹede Naijiria titi de oke okun pada.
Yatọ si ilu Abuja to ni eeyan 130 tuntun awọn ipinlẹ bi Imo ati Adamawa ko ni ju eeyan kọọkan lọ.
Omi yìí ni Mose, ati Aaroni ati àwọn ọmọ Aaroni fi ń fọ ọwọ́ ati ẹsẹ̀ wọn, 
Ìdí tí mo fi fẹ́ di Gómìnà Kogi - Dino Melaye Atiku ni kò tíì dópin fún Adeleke, PDP ni àwọn gba idájọ́ wọlé Mo sọ Dókítà dí òpùrọ́ lórí ayé mi - Steph Èyí ni ọ̀nà tí àwọn obìnrin n gbà kó ara wọn sí wàhálà nítorí ara bíbó Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí kan sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
Lẹ́yìn ọdún meji Pọkiu Fẹstu gba ipò Fẹliksi.
Àwọn olólùfẹ́ Mercy Aigbe kẹ̀yìn sí í pé ó ní káwọn ọmọge gbọ́n àpò baálé ilé tí wọ́n ń fẹ́ gbẹ Ìjà àgbà méjì!
College) to wa ni Garki , Area 3 Abuja,ni olu-ilu orile ede Naijiria , Excellence
Bi a ko ba gbagbe, ileeṣẹ ologun lọdun tokọja bẹnu àtẹ́ lu ìwádìí Amnesty International pe wọn fẹ tu Naijiria ka pẹlu abajade iwadii wọn pe o le ni ẹgbẹrun mẹta eeyan ti wọn ti lugbadi iku lataari aawọ laarin awọn agbe ati darandaran ni Naijiria.
"Wo àwọn Adelé-Ọba aládé méje tó jẹ́ obìnrin nílẹ̀ Yorùbá Omah Lay ti fojú balé ẹjọ́ ní Uganda Ìjọba Amẹrika yọ orúkọ Sudan kúrò nínú ìwé orílẹ̀-èdè tó ń ṣagbátẹrù ẹgbẹ́ agbésùnmọ̀mí Èyí ni àwọn aṣíwájú ìjọba tí ajé ìwà ìjẹkújẹ ti ṣí mọ́ lórí láàrin ọdún 1960 sí àsìkò yí O ni ""gomina ọhun, tohun ti igbakeji rẹ, Manir Yakubu sọ pe awọn agbebọn naa ti kan si wọn, ati pe idunadura ti n lọ lori bii awọn akẹkọọ naa yo ṣe pada wale."
Titi di asiko ti a fi n ko iroyin yii jọ awọn alaṣẹ ileewosan naa ko tii fi ọrọ sita lori rẹ.
Bi ẹ ba ranti, ọrọ laarin gomina Makinde ati awọn eekan PDP bii Fayose, Hon.
”Ẹ̀ṣẹ̀ yín ni ó pọ̀, ni a fi ká aṣọ ní ìdí yín,tí a sì jẹ yín níyà.
Ṣugbọn kí ẹ lè mọ̀ pé Ọmọ-Eniyan ní àṣẹ ní ayé láti dárí ẹ̀ṣẹ̀ ji ni,” ó bá wí fún arọ náà pé, 
“Mo ri kikowe fipo mi sile gege bi ona ati mu atunto ba eto ijoba-n-tiwa ti yoo si mu alaafia joba lorile-ede naa”.
Nítori àwọn àtúgbẹ́yẹ̀wò, o níra láti ṣe àkójọpọ fún àwọn ọkọ́ naa Orisun: Johns Hopkins University atawọn ajọ eto ilera ilu Iye akọsilẹ to waye gbẹyin 15 Oṣù Ṣẹ́rẹ́ 2021 20:44 WAT+3 Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ẹ̀mí kan náà ló n darí ìrìnàjò wa táa fi jọ kọ́lé papọ̀- Ìbejì Coronavirus: Àwọn ohun tí a kò tíì mọ̀ nípa àrùn Covid-19 Kí lo mọ̀ nípa fẹntilétọ̀, ohun èlò aṣèrànwọ́ èémí Ṣé òògùn Chloroquine lè dènà ààrùn Coronavirus bí?
Gomina ipinlẹ Osun naa fikun wi pe ẹnikẹni to ba si ni ẹru ti wọn ji sile rẹ yoo foju wina ofin nitori oni ni ayẹwo ojule si ojule yoo bẹrẹ.
Ọkọ tirela mẹta lo fa ijamba ọkọ naa lẹyin ti wọn kọlu ọkọ igboro to gbe awọn eniyan, eleyii ti ọmọ kekere kan wa ninu ọkọ naa.
 Ijọ Sotitobire: Òótọ́ àti irọ́ tó wà nínú iṣẹ̀lẹ̀ náà Kìí ṣe olórí ọ̀dọ́ ẹgbẹ́ wa ló kú o, ọkọ̀ gb'ókìtì, ọ̀dọ́ kan gba 'bẹ̀ lọ - PDP Oyo Àkìtàn ni mí, kò sí ohùn tí ara mi kò gbà -Fayose Wòlíì èké 'John of God' tó bá obìnrin 300 lò pọ́ gba ìdájọ́ ẹ̀wọ̀n ọ́dún 19 O tẹ siwaju pe Inu mi dun nitori Arsenal jẹ ọkan lara awọn ẹgbẹ agbabọọlu to tobi ju lagbaye.
Komisana ilera ni Ondo: Eku ọlọmu pupọ lo nfa iba Lassa
Oríṣun àwòrán, @AlaafinofOyo Yatọ si eyi, ipa kekere kọ ni Adeyemi n ko si idagbasoke orilẹede Naijiria, to si maa n kopa ti kii se keremi si awọn ohun to n lọ lorilẹede yii.
O ni ti ijọba ba tẹ awọn agbofinro lọrun, wọn ko ni ṣaa dede maa yinbọn pa alaiṣẹ tabi ki wọn maa gba owo aitọ lọwọ awọn ara ilu.
 wọn fẹ ̀ dé iòkè tangayika lábẹ ́ llnngh sungu tí í ṣe olorí wọṅ ní 1760-1840 .
tí a bá lo atóka ìbéèrè tan i tàbí kí ni láti bèèrè ìbéèrè nípa òrò-orúko olùwà , ààyè olùwà yìí kò ní í jé kòòfo .
Kí ni anfaani agbára wọn fún mi,àwọn tí wọn kò lókun ninu?
Ìtàn Mánigbàgbé: Bí Ẹfunroye Tinubu ṣe di ilú Ẹ̀gbá mú, ló ń pàṣẹ ní Eko
Bi o ti n kọrin naa lo n ṣe ere tiata.
Abrahamu tún sọ fún OLUWA pé, “Jọ̀wọ́, dárí àfojúdi mi jì mí, èmi eniyan lásán, nítorí n kò ní ẹ̀tọ́ láti bá ìwọ OLUWA jiyàn?
Ikọlu ọhun waye ni nkan bii osu meje lẹyin ti awọn agbebọn naa ti kọkọ kọlu ileewe yii kan naa ti wọn si ji igbakeji ọga agba ileewe naa, ati awọn akẹkọ mẹrin.
O ni ohun idunnu nla lo jẹ wi pe idajọ naa so eso rere fun Sẹnetọ Kọla Balọgun lẹyin ọpọlọpọ atotonu.
Bákan náà, ẹ̀yin ọ̀dọ́, ẹ máa tẹríba fún àwọn àgbà.
ti ẹda le ru fun iwa-laaye awọn ẹlomiran.
Nigba ti yoo si fi di ọdun 2017, ẹgbẹ ajijangbara alakatakiti yii, IS, ti padanu pupọ ninu awọn ibùba rẹ ni Syria ati Iraq.
Nígbà náà ni Gideoni tó mọ̀ pé angẹli OLUWA ni, ó bá dáhùn pé, “Yéè!
Mo ti rù láàrin ọ̀sẹ̀ kan, iṣẹ́ Eko kò dẹ́rùn - Sanwo-Olu Àìle è ka kéú ló sọ mí di Krìstíẹ̀nì - Adewale Ayuba A kò lè gba àwọn jandùkú Fulani láàyé nílẹ̀ Yoruba -Awọn gómínà Àkọlé àwòrán, Papa sere yii ko le duro mo legbe awon akegbe re nile okeere rara Arugbo ṣoge ri ọrọ papa iṣere Abuja yii.
Ibi mímọ́ yóo wà láàrin rẹ̀.
Agbẹjọro ijọba ni wọn ti si ogoji ninu awọn oku naa ti wọn si ti ko oku mẹrin to ku lọ fun ayẹwo bi o ti yẹ.
Opo ololufe ere boolu afesegba ni yoo maa fojusona fun
Àwọn ni yóo pada tọ̀ ọ́ wá, o kò ní tọ̀ wọ́n lọ.
Sọ bí o ti rí i fún wọn, sì fi àwọn àṣẹ ati òfin rẹ̀ hàn wọ́n.
O sọ fun mi pe ọmọ mi ti wa ni Mọ́ṣúárì Oríṣun àwòrán, Facebook/Nigeria Airforce Baba rẹ ṣe apejuwe rẹ gẹgẹ bi ọlọpọlọ pipe ati akikanju ọmọ, to si jẹ pe lati igba to wa ni èwe lo ti ni afojusun lati di ọmọ ogun oju ofurufu.
OLUWA sọ nípa àwọn eniyan náà pé,“Ó wù wọ́n láti máa ṣáko kiri,wọn kò ṣọ́ ìrìn ẹsẹ̀ wọn;nítorí náà wọn kì í ṣe ìtẹ́wọ́gbà lọ́dọ̀ OLUWA,nisinsinyii OLUWA yóo ranti àìdára wọn,yóo sì jẹ wọ́n níyà ẹ̀ṣẹ̀ wọn.
Expired goods in Nigeria: Jíjẹ tàbí lílo nkan tí ọjọ́ ti lọ lórí rẹ̀ le fa àìsàn tàbí ikú
" Nigba to wa n fesi, Ọba Ogunwusi ni iwọde yii jẹ ọna lati fi isẹ ransẹ sijọba pe awọn ọdọ naa lee se nnkan lọna to dara.
Ṣaaju eyi, Buhari lọ fun imọ ẹkọ Cadet ni ile iwe Mons Officer Cadet School, Aldertson ni ilẹ Gẹẹsi laarin ọdun 1962 si 1963.
    Ìgbà tí ilẹ̀ ọjọ́ kejì mọ́, ó gbé ìgo epo àlááfíà jáde, gbogbo wa fi ra ara, lẹ́yìn náà ó pín fìlà àìrí fún ni, a dée ẹnikẹ́ni ko sì lè rí wa mọ́ àfi òun.
Ìdìbò 2019: Fani-Kayode ní kí Buhari gbáradì fún ìfẹ̀yìntì
Jesu wí fún un pé, “Bí mo ti pẹ́ lọ́dọ̀ yín tó yìí, sibẹ ìwọ kò mọ̀ mí, Filipi?
Mo sọ fún àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ pé kí wọn lé ẹ̀mí náà jáde, ṣugbọn wọn kò lè ṣe é.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù 2019 Elections: Ìpínlẹ Akwa Ibom ti gbà kí Buhari lo pápá ìṣeré fún ìpolongo 24 Ọ̀pẹ̀̀ 2018 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 25 Ọ̀pẹ̀̀ 2018 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Awọn ididje ere bọọlu lorisirisi ni wọn ti gba ni aaye yi Lẹyin ti o kọ lati yọnda ki ẹgbẹ oṣelu All Progressives Congress (APC) lo papa iṣere Godswill Akpabio to wa ni ilu Uyo fun ipolongo ibo ni ipinlẹ Akwa Ibom, ijọba ipinlẹ naa ti fọwọ si pe ki ẹgbẹ naa tẹsiwaju lati lo papa isere ọhun.
 Iko igbmo ẹlẹnu meje nile ejo
Akonimoogba agba iko agbaboolu Chelsea, Antonio Conte ti gbosuba kare lai fun agbaboolu re omo bibi ati agbaboolu kan gbogi ninu iko Super Eagles Naijiria, Victor Moses.
Ọmọ Naijiria ọhun kẹkọọ gboye Ọmọwe ni Northeastern University, iyẹn ni ilu Boston.
Ijiya fun ẹni ti ko ba ni 'Speed Limiter' ninu ọkọ rẹ: Hyginius Omejie ni owo itanran to jẹ faini ẹgbẹrun mẹta naira ni awọn ti ko ba ni yoo ma a san, Koda, wọn yoo tun fi ẹwọn osu mẹta jura gẹgẹ bii ijiya fun awọn arufin yii.
Láti ọjọ́ ìkómọjáde náà ni ìyá rẹ̀ yóò ti máa gbé e káàkiri bí ó bá ti fẹ́.
Irú Fẹntílàtọ̀ yii ni wọn ń pè ní Non-invasive Ventilation nítorí pé wọn tí nkan kan bọ ẹni náà lọ́fun.
Iroyin naa ni Alhaji Aminu Magari lo se ipo keji pẹlu ibo mẹjọ, nigba ti Taiwo Ogunjọbi ni ibo meji, ti Chinedu Okoye ko si ni ibo kankan.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ sí: Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ọmọdé tó ń fi ọpọ́n àyò gba ipò Naomi Osaka: Obìnrin adúláwọ̀ Japan tó na Serena Àwọn wo ni alátakò Ambode fun àṣíá APC?
Àwọn ará Amori kọ̀, wọn kò jáde ní òkè Heresi, Aijaloni ati Ṣaalibimu, ṣugbọn àwọn ọmọ Josẹfu kò fi wọ́n lọ́rùn sílẹ̀ títí tí àwọn ọmọ Josẹfu fi bẹ̀rẹ̀ sí fi tipátipá kó wọn ṣiṣẹ́.
Neo: Oríṣun àwòrán, Instagram/Neo Neo Akpofure ni o ṣeeṣe ki o gba ipo to kẹyin ni BBNaija ti ọdun 2020 yii.
Àbẹ̀wò àwọn èèkàn APC kò tíì dáwọ́ dúró Ní ọ̀sán Ọjọ́rú ni akọ̀wé ìjọba àpapọ̀, Boss Mustapha náà bẹ Omisore wo nile rẹ lẹyin ikede rẹ pe APC ni oun n ba lọ.
Mo ti pinnu láti túṣu dé ìsàlẹ̀ ìkòkò lóríì ìdí tí kò sí ìdàgbàsókè ní Niger Delta - Buhari Ènìyàn 156 ló tún ṣẹ̀ṣẹ̀ lùgbàdì ààrùn Coronavirus ní ìpínlẹ̀ Eko A fura pé ejò lọ́wọ́ nínú ikú Tolu Arotile, ẹ ṣe ìwádìí ikú rẹ̀ - Afenifere, Gani Adams, Huriwa Ohun tí o kò mọ̀ nípa Ebila One Million Boys"" àti Ekugbemi, olórí ẹgbẹ́ òkùnkùn méjì tó da ìlú Ibadan rú Abajade ipinlẹ kọọkan ninu esi tuntun naa re e: Eko-156 Ondo-95 Rivers-53 Abia-43 Oyo-38 Enugu-29 Edo-24 FCT-23 Kaduna-20 Akwa Ibom-17 Anambra-17 Osun-17 Ogun-14 Kano-13 Imo-11 Delta-6 Ekiti-5 Gombe-4 Plateau-4 Cross River-2 Adamawa-1 Bauchi-1 Jigawa-1 Yobe-1 Àpapọ̀ àwọn tuntun to ṣẹṣẹ lugbadi ààrùn Coronavirus ní Nàìjíríà jẹ 643 ní 15/07/2020 Ninu ikede ti Ajọ NCDC fi sita ni Ọjọ Ìṣẹgun lo ti fojuhan pe , awọn to ti ni aarun naa ti pe 34,259 bayii."
Ipo kẹrin ni Chelsea wa lori tabili idije Premier League, nigba ti Man U wa ni ipo keje.
Ibasepo naa yoo tun je ki itesiwaju de ba eto okoowo ati oro aje orile ede mejeeji.
Iroyin to tẹ BBC Yoruba lọwọ ni pe wọn fi ẹsun kan Seigo ni pe o gbiyanju lati da eto ipolongo ibo ita gbangba ti ẹgbẹ oṣelu All Progressives Congress, APC ṣe nipinlẹ naa.
O ti ẹ ṣeeṣe ko jẹ oun lowo oṣu rẹ pọ ju.
Will Ross, to jẹ olootu ile-isẹ BBC World Service Africa, foju sunnukun wo ifarajọ to wa laarin isẹlẹ naa ati ti ijinigbe awọn ọmọ Chibok, losu Kẹrin, ọdun 2014 to sẹlẹ ni agbeegbe Chibok ti ko jina si Guusu- Ila oorun Dapchi.
Gbogbo awọn ti wọn n foju ba ile ẹjọ lori ọrọ naa titi kan Ọgbẹni Moro ati Ahmadu ni wọn sọ fun ile ẹjọ pe awọn ko jẹbi ẹsun naa.
Diezani Madueke: Díẹ̀ lára ohun ìni Diezani tí ilé ẹjọ́ gbẹ́sẹ̀ lé
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ó dára kí obìnrin níṣẹ́ lọ́wọ́ - Toyin Lawani 4.
Ẹni bá ń lọ si Bàrígà, tí ó bá gba Yáàbá wọlé, yóò gba Abúlé Ọjà kọjá .
Ọlọ́pàá kó àwọn ọmọ ẹgbẹ́ òkùnkùn Ẹiyẹ Confraternity ni Ikorodu Ó lé ní ẹ́gbẹ́ta àwọn ọmọ Naijiria tí wọ́n ti ṣetàn láti padà sílé!
Onisegun oyinbo Bukola Saraki to je aare ile ni ise yii ko gbodo yo ekun Kankan sile rara.
"Awọn ibudo yii ni wọn ti n da awọn agbẹ to n lọ si oko duro lati maa gba owo lọwọ wọn""."
Àwọn tí wọn bá ń fúnrúgbìn ire pẹlu alaafia yóo kórè alaafia.
Awọn dokita tiẹ sọ fun awọn obi mi pe ẹsẹ naa ko nii dagba ju ti ọmọ ọdun kan lọ, to jẹ ọjọ ori mi lasiko to mu mi.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Nigerian high commission in Ghana: Ọ̀rọ̀ n yanjú bọ̀, ìjọba Ghana ni yóò kọ́ ilé tí àwọn kan wó 21 Òkùdu 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 26 Òkùdu 2020 Oríṣun àwòrán, Dele Momodu/fred smith Ijọba orilẹ-ede Ghana sọ pe iwadii awọn ṣafihan lootọ ni ilẹ ti wọn kọ ileeṣẹ aṣoju Naijiria ni Ghana si ni awuyewuye lori.
Pupo ninu awon ile adayeba ni o je pe, o ju emi gan an alara lọ.
Aare tun so pe “A mo nipa awon daran-daran.
35 Àti pé àwa mọ̀ pé àwọn ohun wọ̀nyí jẹ́ òtítọ́ àti gẹ́gẹ́bí àwọn ìfihàn Johannù, láì ní àfikún, tàbí àyọkúrò nínú àsọ̀tẹ́lẹ̀ inú ìwé rẹ̀, àwọn ìwé mímọ́, tabí àwọn ìfihàn ti Ọlọ́run tí wọn yíò wá lẹ́hìnnáà nípa ẹ̀bùn àti agbára Ẹ̀mí Mímọ́, ohùn Ọlọ́run, tàbí iṣẹ́ ìránṣẹ́ àwọn angẹ́lì.
Wọn fi kun pe o ṣeeṣe ko jẹ pe awọn ọmọde to n ṣere nitosi igi naa lo fa wahala naa fun awọn.
Àrà ọ̀tọ̀ ni ìdíje eré bọ́ọ̀lù FIFA 2018 ń jásí lọ́tẹ̀ yìí.
Ogagun Daramola fikun oro re pe, ise akanse Operation Diran Mikiya, eyi to bere lojo kokanlelogbon osu keje odun ti a wayii, ni won se agbekale re lati maa doju ija ko awon omo-ogun olote, awon agbesunmomi to n dojuko awon eka ila oorun orile-ede Naijiria.
Èmi fúnra mi náà yóo jí ní òwúrọ̀ kutukutu,
Ṣugbọn bí kò bá fẹ́ ra ilẹ̀ náà pada, tabi ti ó bá ti ta ilẹ̀ náà fún ẹlòmíràn, kò ní ẹ̀tọ́ láti rà á pada mọ́.
Arabinrin naa ni awọn ọlọpaa ti pa awọn arakunrin oun, wọn si ti ju wọn si inu kọnga.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Wòlíì Kasali ní Dolapo Awosika kò lé ìyàwó òun jáde 'Alífábẹ́ẹ́tì Ohùn Oduduwa di ìtẹ́wọ́gbà ni Ajaṣẹ' Ṣẹ gbọ́ nípa Alájọ Ṣómólú, tó ta mọ́tò ra kẹ̀kẹ́?
Ogunlọ́gọ̀ eniyan péjọ ní Jerusalẹmu ní oṣù keji láti ṣe Àjọ Àìwúkàrà.
Ẹ̀rọ ayárabíàṣá oní Braille náà nbẹ!
" Ọ ̀ rọ ̀ "" èmi -ò-gbà ìwọ -ò -gbà "" yìí ló jẹ ́ kí àwọn alábàágbé Ẹ ̀ gbá maa pòwe mọ ́ wọn pe "" Ẹ ̀ gbá kò lólú , gbogbo wọn ló ń se bí ọba "" Ọba wá di púpọ ̀ ."
Koda ẹwọn ọdun marun un gbako ni wọn kan an lọdun naa.
Ní àkókò yìí àwọn ọmọ ogun Israẹli gbógun ti ìlú Gibetoni ní ilẹ̀ Filistia.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Michael Jordan: $560,000 ni wọn lu gbàǹjo bàtà ìlúmọ̀ọ́ká agbábọ́ọ́lùù àlápẹ̀rẹ̀ náà fún ẹ̀ṣọ́ ilé 22 Èbibi 2020 Oríṣun àwòrán, Sotheby's Bata ti ilumọọka agbabọọlu alapẹrẹ, Michael Jordan lo ni ọdun 1985, ni wọn ti lu gbanjo rẹ ni ẹgbẹrun lọna ọtalelẹẹdẹgbẹta dọla ($560,000).
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Igbó mímu lè ṣe kóríyá, kò lé fi kún orín ẹnu òṣèré - 9ice Ìtàn tó wà nídi òwe ‘Sebótimọ Ẹlẹ́wà Sàpọ́n’ Ọba Adesoji Aderemi, Ọọ̀ni Ifẹ̀ tó gba ipò ọba mọ́ tòṣèlú Kókó ọ̀rọ̀ tí Buhari sọ ní àyájọ́ June 12 Kufuor ati Obasanjo ni, bo tilẹ jẹ pe ọrọ idibo jẹ ohun ti tẹru-tọmọ yẹ ko pa, amọ ohun to n ṣẹlẹ ni Benin ko ri bẹẹ.
Oríṣun àwòrán, @MBuhari Mo wọ agbada ati fila, tii se asọ ibilẹ wa lọ sibi igbeyawo naa, nibẹ si ni mo ti lọ pade aarẹ Buhari ni papakọ ofurufu.
"Wọ́n ti rẹ ipò ọ̀gágun Olusegun Adeniyi sílẹ̀ lẹ́yìn tó jẹ̀bi títú àṣírí kùdiẹ-kudiẹ iléeṣẹ́ ológun lórí ayélujára 'Boko Haram ti gbilẹ̀ kan nílẹ̀ Hausa, wọ́n ti ń ní ""Check Point"" láti gba owó lọ́wọ́ àwọn àgbẹ̀' Èèyàn 281 ló kó covid-19 lọ́jọ́ Ìṣẹ́gun, 123 wá láti ìpínlẹ̀ Eko nìkan Inú mi dùn lẹ́yìn tí mo ní àrùn HIV ju kí n tó lárùn náà lọ - Christopher Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Ọkọ mi wa ọkọ̀ tẹ ""Poly Bag"" lásán, àfi gbùùàà!"
Gbolohun yìí dá àríyànjiyàn sílẹ̀ láàrin àwọn Juu.
O ṣeeṣe ki ilu tabi orilẹede ti o fẹ lọ ti ti ibode wọn, eleyii ti o le da irinajo rẹ ru.
Òní ló yẹ kí Ibidunni Ighodalo pé ogójì ọdún, Tope Alabi, Kenolly àtàwọn míì tí yóò kọrin níbẹ̀ rèé Olorì àgbà mẹ́rin tó jẹ́ igi lẹ́yìn ọgbà fún Aláàfin Adeyemi Joy Nunieh: Tani adarí àjọ NDDC tẹ́lẹ̀ to fẹ̀sùn jegúdújẹrá kan Godswill Akpabio?
Mo kórìíra àwọn oníyèméjì,ṣugbọn mo fẹ́ràn òfin rẹ.
Ó ní, “Ìhín ni ibi ìsinmi mi títí lae,níhìn-ín ni n óo máa gbé, nítorí pé ó wù mí.
Ṣé ẹ rántí àkọ́lé àwọn ìwé àkàgbádùn yìí?
Ó dà bí ẹni pé wọ́n fọ́ mi tútú.
Ní ọdún 1980, ó tún gba iṣẹ́ olùkọ́ sí ìbàdàn Boys High School, Ìbàdàn, Nàìjíríà.
Pásítọ̀ gún ìyàwó rẹ̀ lọ́bẹ nínú ṣọ́ọ̀ṣì, ló bá tì í bọ ara rẹ̀ náà níkùn Ènìyàn 241 tuntun ló ti lùgbàdì àrùn Coronavirus ní Ọjọ́ Ìṣẹ́gun ní Naijiria Adajọ Olusegun odusola kọ eti ikun ẹbẹ agbẹjọro Alfa Babatunde lati ṣi apo ifowopamọ rẹ marun un eleyi ti ajọ ọtẹlẹmuyẹ DSS tipa.
lati ṣiṣẹ wọn lori abadofin isuna-owo ilu naa.
Orilẹ-ede mẹta ni Afirika, Ethiopia, Sudan ati Egypt ti fẹnuko bayii lati bẹrẹ ijiroro.
Lawọn ọsẹ diẹ sẹyin ni iroyin jade si igboro pe nnkan ko dan mọran laarin gomina Ṣeyi Makinde ati igbakeji rẹ, Oloye Rẹmi Ọlaniyan.
O ti di ènìyàn Mẹrinlelógóji to ti ni ààrun Coronavirus ni Naijiria Èṣi àyẹ̀wò jáde, Gómìnà Bauchi ti ní aàrùn coronavirus báyìí Ilé ìgbìmọ̀ Aṣòfin Nàìjíríà kó igbá wọlé l'Abuja nítorí coronavirus Soyinka sọ fun BBC ninu ifọrọwerọ kan pe, to ba jẹ pe ijọba Naijiria ti ṣe ohun to tọ lasikọ to yẹ ni, arun naa kò ba ma ti tan kalẹ to bo ṣe ri yii.
“Nígbà tí Farao bá rí wọn, Tòun ti àwọn ọmọ ogun rẹ̀ tí a fi idà pa, yóo dá ara rẹ̀ lọ́kàn le, nítorí gbogbo àwọn ọmọ ogun rẹ̀.
Pẹlu àwọn tí wọ́n lọ sinu isà òkú.
Bí aláṣẹ bá ń bínú sí ọ,má ṣe torí rẹ̀ kúrò ní ìdí iṣẹ́ rẹ,ìtẹríba lè mú kí wọn dárí ẹ̀ṣẹ̀ tí ó bá tóbi jini.
Aworan Afrika to rẹwa ju laarin ọsẹ
” Angẹli tí ń bá mi sọ̀rọ̀ sì dáhùn pé, “N óo sọ ìtumọ̀ wọn fún ọ.
Ẹ óo pín ilẹ̀ fún àwọn náà.
Ó pada sí ibùdó Israẹli, ó ní, “Ẹ dìde, nítorí OLUWA ti fi àwọn ọmọ ogun Midiani le yín lọ́wọ́.
Gege bi ile-ise akoroyin se so lojo Aiku (Sunday), won ni, Carlo Ancelotti ti ko lati sise gege bi akonimoogba agba iko agbaboolu orile-ede Italy.
Awọn ọrọ kan to n kọ sori ayelujara rẹ lẹnu ọjọ mẹta yii n jọ ti ẹni to ti la oriṣiriṣi nkan ti ko dara kọja, to si n fi ọrọ tu ara rẹ ninu, ni ireti pe ọjọ ọla yoo dara.
Ilana agbekale ohun ni won gbagbo pe, yoo gba osu meji, eyi ti yoo bere ninu osu kerin si osu karun odun 2018, lara eyi ti a ti ri sise abewo e n le n beun si awon asofin nipinle Kaduna.
Ogbeni Oshiomole wa fi da asoju naa loju pe, oun yoo sa ipa oun lati ri I pe eto idibo gomina  ni ipinle Ekiti lo ni irowo-irose.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Binta Ayo Mogaji: Kìí ṣe iṣẹ́ tíátà làwọn òṣèré ti rí owó ra ọkọ̀ ńlá àti ilé àwòdamiẹnu 25 Ògún 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 10 Òkùdu 2020 Oríṣun àwòrán, Instagram/bintaayomogaji Osere tiata to ba ni ọkọ gidi nile, to bimọ, to si ni ẹbi rere ko ni de idi sinima, ko maa ṣi ara silẹ tabi se afihan ihooho bi Ọlọrun se daa.
Oludije fun ipo aarẹ naa ni, awọn ẹrọ kaadi idibo ni awọn agbegbe kan lorilẹede Naijiria, ti awọn alatilẹyin oun pọ si, lo ṣeeṣe ko ma ṣiṣẹ daradara.
Bi mo ṣe maa n bẹ wọn lati ran awọn ọmọ wọn lọ sileewe, naa ni mo maa n kilọ pe, maa fi ofin gbe awọn obi wọn to ba kọ lati fun awọn ọmọ wọn ni ẹkọ to dara.
Afihan idẹyẹsi ati ikorira ni aṣa jiju bata lu eniyan ni aṣa awọn larubawa.
Bí mo ti ń lọ tí mò ń bọ̀ ni mò ń fojú wo àwọn ohun tí ẹ̀ ń sìn.
“Nígbà tí ẹ bá lọ bá àwọn ọ̀tá yín jagun, tí OLUWA Ọlọrun yín bá fi wọ́n le yín lọ́wọ́, tí ẹ bá sì kó wọn lẹ́rú; 
Afolabi Olajide sọ pe o yẹ ki awọn eeyan maa bọwọ fun ọmọbinrin lawujọ, o ni o ṣe pataki lati ṣe itọju wọn daadaa.
Loju opo NCDC ni wọn ti ṣe alabapin iroyin yi eleyi ti wọn ni o wa lati ọwọ ijọba ipinlẹ Eko Coronavirus kò rí ju èèyàn 304 tó forí kó o lọ lọ́jọ́ àìkú O fẹ dabii pe iroyin ayọ ti n ṣẹlẹ lorilede Naijiria lẹnu ọjọ perete yii leyii ti iye awọn to n ko arun Coronavirus dinku si tatẹyinwa.
Ìdílé kọ̀ọ̀kan ní ọgbà àjàrà ati àwọn igi ọ̀pọ̀tọ́ tirẹ̀.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: 'O yẹ ki dokita ọpọlọ yẹ ọpọlọ mi wo' Ijiya Ọlọrun n'ijọba Buhari - Okurounmu 'Kí Bùhárí gbé àpótí ìbò wò, bóyá yóò borí' Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí kan sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
Lalẹ ọjọ Abamẹta ni ẹgbẹ agbabọọlu South Africa fi ami ayo kan sodo le Egypt kuro ninu idije to n lọ lọwọ ti orilẹ-ede Egypt n gbalejo ẹ.
Ogbeni Yakubu soro yii nigba ti awon adari ile igbimo asoju-sofin n se ipade po pelu ajo eleto idibo lorile ede Naijiria (Independent National Electoral Commission ,INEC) labe akoso ojogbon Mahmoud Yakubu.
 iranlose se atunse eyi ni 1993 .
Ogbeni Olukolu tun fi asiko naa ro akoroyin lati rii
N óo kọlù ú nígbà tí àárẹ̀ bá mú un; tí ọkàn rẹ̀ sì rẹ̀wẹ̀sì; ẹ̀rù yóo bà á, gbogbo àwọn eniyan rẹ̀ yóo sì sá lọ.
Páro-páro ni àwọn mọ́ṣálááṣí dá káàkiri Nàìjíríà lásìkò ìrun Jímọ̀ nítorí coronavirus Ìjọba àpapọ̀ fẹ́ f'òfin dé irina ọkọ̀ akero jakejado Nàìjíríà ‘Ọ̀pọ̀lọpọ̀ ni inú wọn kò dùn sí bí Hajj kò ṣe ní wáyé lọ́dún yii’ Ìbánújẹ́ gbọkàn àwọn èèyàn nílé abílékọ ọlọ́mọ mẹ́ta tí wọ́n ṣẹ̀ṣẹ̀ pa ní Ibadan Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
'Ó ku ọ̀la kí Isiaka ṣe 'Freedom' ní àṣìta ìbọn bà á ní Ogbomọshọ ' Kìí ṣe gbogbo ohun tí dókìtà ni kí n má jẹ torí àìsàn jẹjẹrẹ ni mo tẹ̀lé- Soyinka Wo àfiwé owó oṣù Ọlọ́pàá Nàìjíríà pẹ̀lú akẹgbẹ́ wọn lókè òkun Àwọn ọmọ Nàìjíríà fi èpè àti àdúrà ránṣẹ́ sí àwọn adarí pé: ó tó gẹ́!
‘Tèmi ni gbogbo fadaka ati wúrà rẹ, tèmi náà sì ni àwọn tí wọ́n dára jùlọ lára àwọn aya rẹ, ati àwọn ọmọ rẹ.
Obasanjo: Ìpasẹ̀ ìparun ni Nàíjíríà ń tọ̀ lábẹ́ Buhari
Èmi fẹ́ràn wọn; ṣugbọn ẹ̀sùn ni wọ́n fi ń kàn mí,sibẹ, adura ni mò ń gbà fún wọn.
Eyi lo yẹ ko jẹ ibeere ti yoo jẹ wa logun, ka si lọ se awari talẹnti wa gẹgẹ bi Duro Ladipọ ti se, kawa naa le wọ inu iwe itan manigbagbe.
Awuyewuye lori ẹni ti ipo ọba kan ni Ikire ti bẹrẹ lati ọdun 1993 nigba ti Ọba Falabi gori itẹ.
Nítorí ìfẹ́ Baba mi ni pé, kí ẹnikẹ́ni tí ó bá rí Ọmọ rẹ̀, tí ó bá gbà á gbọ́, lè ní ìyè ainipẹkun.
Nítorí ìwọ ni ó dá ohun gbogbo,ati pé nípa ìfẹ́ rẹ ni wọ́n ṣe wà,nípa rẹ ni a sì ṣe dá wọn.
Ẹni to bori: Benin Nigeria vs Guinea-Bissau.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Child Safety: Òkú Seyi ọmọ ọdún mẹ́ta tó kó ni wọ́n rí 16 Ìgbé 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 23 Ògún 2020 Oríṣun àwòrán, LASEMA Ọmọ ikoko kan ti iroyin sọ pe o ko sinu kanga ni agbegbe Ipaja niluu Eko ni ajọ to n ri si iṣẹlẹ pajawiri Eko, LASEMA ti doola.
CityNewcastle United v ​ArsenalManchester United v Chelsea.
Olùrànlọ́wọ́ fún ààrẹ lórí ọ̀rọ̀ ilé asòfin àgbà, Ita Enang, ló sísọ̀ lójú ọ̀rọ̀ yìí fún àwọn akọ̀ròyìn ní ilé ìjọba ní Àbújá.
iya agbebi ki won le nimo to yẹ ati  lati
Vice Presidential Debate: Osinbajo,Peter Obi ko yọju Lẹyìn tí mo figbe ta, INEC mú PVC mi wá bá mi nílé - Gani Adams Ademola Ogunbanjọ ní Inssuance o kìí ṣe ojuutu, ò ni ètò amuludun ló 'se pataki, kin àwọn oogun to wa nibẹ, àwọn osiṣẹ́ ǹkọ kíni àwọn ṣe mọ iṣẹ́ sí.
Nígbà tí wọ́n jáde kúrò lẹ́wọ̀n, wọ́n lọ sí ilé Lidia.
3 Níní gbogbo agbára ní ìkáwọ́, àní láti pa Sátánì àti awọn iṣẹ́ rẹ̀ run ní òpin ayé, àti ní ọjọ́ ìdájọ́ nlá tí ó kẹ́hìn, èyí tí èmi yíò ṣe ní orí àwọn olùgbé ibẹ̀, ní dídájọ́ olukúlùkù ènìyàn gẹ́gẹ́bí iṣẹ́ rẹ̀ àti awọn ohun èyí tí ó ti ṣe.
Operation Falcon: Omi tẹ̀yìn wọ̀gbín lẹ́nu fáwọn ọmọ Nàìjíríà mẹ́ta tó lu èèyàn 50,000 ní gbájúẹ̀ jákèjádò àgbáyé
Nítorí náà ọ̀nà wọn yóo dàbí ọ̀nà tí ń yọ̀ ninu òkùnkùn,a óo tì wọ́n sinu rẹ̀, wọn yóo sì ṣubú,nítorí n óo mú kí ibi bá wọn ní ọdún ìjìyà wọn.
Eto Idajọ ti wọn fi ikede rẹ sita ninu iwe ile ẹjọ naa ni awọn alatilẹyin awọn ti ọrọ naa kan fi sọwọ sawọn oniroyin yoo waye laago mẹsan owurọ.
Iroyin iku Precious ti da rogbodiyan silẹ, ti awọn ọdọ kan si yabo ileeṣẹ ọlọpaa Gomoa Buduburam ni Ghana.
" Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, World Press Day: Ọ̀pọ̀ ìgbà ni àwọn jàǹdùkú ká mi mọ́lé nítórí ìròyìn tí mo kà Marichka jẹwọ pe lootọ ni o yẹ ki oun ti ṣatunṣe eyin oun lati bi ọdun mẹwa, lẹyin ti ọmọ rẹ ṣeeṣi fi aago onirin kan gba a l'ẹnu.
Ni kete tawọn olorin South Africa pe olorin pataki ọmọ Naijiria to jẹ ọlọwọ aje si i, ṣe lo gbe ẹwa orin naa jade to si wa di orin gbogbo igba lẹnu awọn eeyan - awọn ede to jẹyọ ninu orin ọhun ni ede Yoruba, Gẹẹsi, Pidgin ti Naijiria, Isizulu ati Isixhosa.
Àwọn adigunjalè náà gun kẹ̀kẹ́ alupùpù bí wọ́n se pọ̀ tó wọ ìlú Kabaro, ilu Danmani Hausawa àti Danmani Dakarkari.
Eleyii ni yoo jẹ atọna fun yiyan aare
7 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Fídíò, Soyinka Cancer: Àṣe ara mi ni iso ti n run gbogbo bí mo ṣe n ṣèrànwọ́ lórí jẹjẹrẹ27 Bélú 2019 Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Ta ni Yusuf Satia ti iku mu lọ?
Oriṣiiriṣii ero ni awọn eniyan maa n ni nipa opó paapaa opó obinrin ni awujọ wa.
Gbogbo iṣẹ́ ibi, ọwọ́ wọn ló kun mọ
Labani fi Silipa ẹrubinrin rẹ̀ fún Lea pé kí ó máa ṣe iranṣẹ fún un.
Ó bá a sọ̀rọ̀ rere, ó sì fi sí ipò tí ó ga ju ti gbogbo àwọn ọba tí wọ́n wà pẹlu rẹ̀ ní Babiloni lọ.
O sọrọ yii lẹyin ọkan-o-jọkan iṣẹlẹ aburu lori awọn agunbanirọ lẹnu ọjọ mẹta yii Kazaure ni ko saye wẹjẹ-wẹmu tabi igbafẹ mọ fawọn agunbanirọ afeyi ti awon alaṣẹ ajọ naa ba fọwọsi.
Ní tèmi, pẹlu ayọ̀ ni ǹ bá fi náwó-nára patapata fún ire ọkàn yín.
Oríṣun àwòrán, others O ba ajọ naa ṣe dunadura lodun 2008 lati san lara owo to ko jẹ pada ki o si maa.
Lẹyin ọdun diẹ, o pari ẹkọ rẹ.
 Ó fẹ ́ rẹ ̀ tó ìdajì bílíọ ̀ nù ìwọ ̀ n oríṣi àjẹsára náà kan tí a tí fún àwọn ènìyàn .
rárà sísun báyìí pé oriṣi méjì tàbí mẹ ́ ta ni agbègbè ibi tí wọn ti ń suún .
won yii ni Mínísítà mẹ́tàlélógójì ti Ààrẹ Muhammadu Buhari ṣe ìbúra fún, ipo ati ojuse awon
ṣugbọn níkẹyìn ọ̀rọ̀ rẹ̀ á korò bí iwọ,ẹnu rẹ̀ á sì mú bí idà olójú meji.
“Àmì yóo yọ ní ojú oòrùn ati ní ojú òṣùpá ati lára àwọn ìràwọ̀.
Nibi ipade ajọ amuṣẹya ni awọn ipinlẹ naa ni wọn ti buwọlu abdofin naa, ti yoo wa lo si ile igbimo asofin ibilẹ nibi ti wọn yoo ti jiroro lori rẹ.
ipade to yẹ ki won se naa.
Máa gbádùn ayé pẹlu aya rẹ, olólùfẹ́ rẹ, ní gbogbo ọjọ́ asán tí Ọlọrun fún ọ nílé ayé.
Lẹ́yìn ọpọlọpọ ọjọ́, OLUWA sọ fún mi pé, “Dìde, lọ sí odò Yufurate kí o mú aṣọ tí mo ní kí o fi pamọ́ sibẹ wá.
Nigba ti wọn bii, Afaa Jamiu ni gbogbo owo ti oun gba lọwọ arakunrin naa, ẹbọ ati etutu ni oun fi ṣe fun un.
Àwọn àwòrán ìrántí tó ń sàmì ogójì ọdún tí Ọba Adesoji Aderemi jáde láyé Adesoji Aderemi, Ọọ̀ni Ifẹ̀ àti gómìnà Adúláwọ̀ àkọ́kọ́ láyé eèbó amúnisìn Kí ìjọ mi ní Sagamu le gbòòrò ni mo fi ń ṣiṣẹ́ ajínigbé pawó - Pásítọ̀ Orúkọ Aisha Yesufu náà wọ inú BBC 100 Women tí a fi ń sọri àwọn obìnrin tó pegedé ní 2020 Saaju ni Ooni ti ṣadehun pe oun yoo sọ ọmọ tuntun ti a bi lọjọ Kejidinlogun oṣu Kọkanla ọdun 2020 lorukọ ọkan lara awọn Ooni to jẹ saaju rẹ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù South Africa killings: Ìjọba àpapọ̀ ní kò sóun tó jọ ìbúgbàmù àdó olóró níléeṣẹ́ ìjọba South Africa tó wà nílùú Abuja 7 Owewe 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Iroyin kan gba ori itakun ayelujara pe awọn leṣebi-leṣeka ẹda kan ti ju ado oloro si olu ileeṣẹ ijọba orilẹede SouthAfrica to wa nilu Abuja.
Awọn arinrinajo Hajj orilẹede Naijiria yoo bẹrẹ si sanwo ori ni Saudi
Ayansike: SS3 ní mo wà báyìí, mo sì ti gba àmì ẹ̀yẹ̀ púpò nílé-lóko gẹ́gẹ́ bí onílù Oúnjẹ́ aṣaralóòre nìkan kò tó ò tí o bá n gbèèrò láti lóyún tàbí tí ó bá lóyún Èkúté tó sàwárí bọ́mbù ilẹ̀ gbàmi ẹ̀ye wúrà fúniṣẹ́ takuntakun Afẹ́fẹ́ gáàsì ṣe ìjàmba fún èèyàn 30, ilé 23,ọkọ 15 ní ìpínlẹ̀ Eko Bakan naa ni awọn ẹgbẹ SEC ni APC ni ipinlẹ Ekiti naa sọ wi pe ki alaga ẹgbẹ naa, Paul Omotosho lọ rọkun nile ati awọn ajọ amuṣẹya miran.
Benjamin Uwajumogu, sẹnẹtọ ẹkun ariwa Imo Sẹnẹtọ Benjamin Uwajumogu to n ṣoju ẹkun ariwa ipinlẹ Imo papoda lọjọ kejidinlogun oṣu kejila ọdun 2019.
(Peoples Democratic Party ) tako ibo to gbe aare Muhammadu Buhari wọle gẹgẹ bi
Ṣùgbọ́n àwọn obìnrin kan wà tí wọ́n máa ń ṣe ipa ẹni tí kò gba ìgbàkugbà nínú eré.
Oríṣun àwòrán, Ogun State Governor's office Àkọlé àwòrán, Awọn lọbalọba ilẹ Yoruba naa pejo si ibi adun ilu ti ọdun 2019.
Jesu bá sọ fún wọn pé, “Ọmọ-Eniyan ni Oluwa Ọjọ́ Ìsinmi.
Lẹ́yìn náà Jesu ní, “Ẹni tí ó bá ní etí láti fi gbọ́ràn, kí ó gbọ́!
Ère irin lásánlàsàn, tí eniyan ṣe, tí ń kọ́ni ní irọ́ pípa.
Ni soki, ohun ti Jamilu n sọ pe bi ohun ko ba foju ri oṣu,ohun kii dawọ awẹ gbigba duro.
Gẹgẹ bi a ti ṣe gbọ awọn ọdọ ti kọkọ ṣe iwọde lọ si aafin naa lati fẹhonu han lori iku Isiaq Jimoh ti wọn yinbọn pa nibi iwọde ENDSARS lọjọ Abamẹta.
25 Òkùdu 2019 Àkọlé àwòrán, Ohun ti agba fi tẹlẹ ikun ni oro yii gba lasiko yii Ọmọde gbọ́n, agba gbọ́n la fi da ilẹ̀ Ifẹ ni ọrọ eto aabo dukia awọn eniyan ipinlẹ Oyo, Ogun, Ondo, Oṣun, Ekiti ati Eko gba bayii.
 si awon iwa  ti Olubadan ati Iyawo re, Olori Rasheedat
Oríṣun àwòrán, Getty Images Eleyi tumọ si pe Gnassingbe si le jẹ aarẹ orilẹede naa di ọdun 2030 to ba wọle idibo gbogbogbo toni ati to ba tun ṣe saa kan sii.
Amọ Buhari ni eto abo ti yatọ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù AFCON2019: Idije òní á yàtọ̀ láàrin Super Eagles ati BafanaBafana Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ AFCON2019: Idije òní á yàtọ̀ láàrin Super Eagles ati BafanaBafana 10 Agẹmo 2019 A n gbe ife ẹyẹ AFCON bọ wa sile ni.
Ẹni tí ó sun mààlúù náà gbọdọ̀ wẹ̀ kí ó sì fọ aṣọ rẹ̀, òun náà yóo jẹ́ aláìmọ́ títí di ìrọ̀lẹ́ ọjọ́ náà.
Ó bí ọmọkunrin mẹta tí orúkọ wọn ń jẹ́ Ṣemu, Hamu, ati Jafẹti.
Ṣaaju lati fi to yin leti pe eeyan mọkanla miran tun ti ni arun Coronavirus lorilẹede Naijiria, eleyii ti apapọ awọn to ni arun naa fi da mọkanlelọgọrin.
Oshiomole: Asaajú, àtẹ̀lé yẹ kó fìmọ̀ sọ̀kan nínú APC
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Agolo gáásì kéeké tó ń jò bú gbàmù l‘Eko, ẹ̀mí kan bọ́, mẹ́ta fara pa Akeredolu yan ọmọ Ilajẹ gẹ́gẹ́ bíi igbákejì rẹ̀ tí wọ́n yóò jọ díje dupò ní Ondo Ìjọba àpapọ̀ ti gba 800 bílíọ̀nù padà lọ́wọ́ àwọn tó jí owó ìlú kó, àwọn 1,400 ti wà nínú ẹ̀wọ̀n -Lai Mohammed Toke Makinwa ti sọ̀rọ̀; Amcon náà dá a padà fún un pé.
o ni alaafia, ti ko si ni si ijaya kankan bi o se le wu ko mo.
mu awon ileri ti won se fun awon omo orile ede sẹ .
Jijawe olubori ohun, ran Coric lowo lati bo sipo kẹ́tàlá lagbaye.
Awon adari orile ede mejeeji naa yoo tun jo ma jiroro nipa  ile-ise ajinle , eto eko ,ise akanse nipa opa  afefe gaasi laarin awon orile ede Naijiria ati Morocco, awon kemika ti yoo tun maa ran awon afefe gaasi lowo ati atile yin fun ajinle  ati kemika pana-pana  ti orile ede Morocco.
  Atọ́ka yìí júwèé ilé kan lókèrè tí ìtura oúnjẹ àti nkan mímu onírúirú wà fún àràjẹ.
Pápà mímọ́ gbarata lóríi ìpànìyàn Benue Chibok Girls: ilé ejọ́ ju ajínigbe sẹ́wọ̀n Àwọn mọ̀lẹ́bí ajínigbé tó pàdánù ẹ̀mí l'Ondo kò tí ì yọjú Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 3 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 5 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Lẹ́yìn náà, Maria múra pẹlu ìwàǹwára, ó lọ sí ìlú Judia kan tí ó wà ní agbègbè orí òkè.
Maina dákú fún ọ̀pọ̀ ìṣẹ́jú, iléejọ́ sáré so ìjókòó rọ̀ Wo ìròyìn tó pọ̀ jùlọ táwọn èèyàn ń wá ní Google lọ́dún 2020 Obasanjo àti Gani Adams tẹ́ mi pẹ̀lú bí wọn ṣe tahùn síra wọn - Adebanjo Buhari le sọ ipò ààrẹ́ nù tí kò bá yọjú sáwọn aṣòfin - Amòfin Àlàyé rèé lórí ìdí tí mo fi lọ sílé Tinubu - Rashidi Ladoja Ẹgbẹ́ òṣèlú alátakò takú láti gba èsì ìbò ààrẹ ní Ghana Ilé ìgbọ̀nsẹ̀ kan ṣoṣo ni aṣòfin mẹ́rin ń pín lò!
Oríṣun àwòrán, FACEBOOK/KAYODE AJULO Àkọlé àwòrán, Labe ofin ko to ki eeyan sise lai ni iwe eri pe ko pari agunbaniro ''Bí oun gbogbo bá dúró ní ṣẹpẹ́, Ààrẹ yóò fí orúkọ ẹni náà ránṣẹ sí ilé aṣòfin àgbà.
Ní gbogbo agbègbè ati káàkiri ibi tí òfin ati àṣẹ ọba dé, ni àwọn Juu tí ń ṣọ̀fọ̀ tí wọn ń gbààwẹ̀ tẹkúntẹkún.
NFF lasiko ti wọn n ṣedaro agbabọọlu ọwọ ẹyin to doloogbe naa loju opo Twitter wọn, sọ wi pe ibanujẹ ni iroyin iku rẹ jẹ fun awọn.
Peteru wá bi Jesu pé, “Oluwa, àwa ni o pa òwe yìí fún tabi fún gbogbo eniyan?
Bí àwọn tí a tà lé'rú wọ̀nyí, yálà láti ìdílé kan náà tàbí ìlú kan náà bá pàdé, nwon kò ní mọ ara wọn rárá.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Mo ni baba isalẹ' Ọpọ ọmọ Naijiria lo ti bu ẹnu ẹtẹ lu ileesẹ ọlọpaa, nitori fidio naa.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Buns ni ọmọ mi jẹ tán ní ṣọ́ọ̀ṣì, ló bá di àwátì' Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Bí OLUWA kò bá kọ́ ilé,asán ni wahala àwọn tí ń kọ́ ọ.
Ta ni ninu yín tí ó lè páyà títí dé ibi pé yóo fi ẹsẹ̀ bàtà kan kún gíga rẹ̀?
Wọn daa silẹ pẹlu erongba pe ki awọn gomina le maa mojuto ohunkohun to n ṣẹlẹ ni Naijiria bẹrẹ lati ipinlẹ koowa wọn.
Ó ní òun óo jẹ Jerusalẹmu níyà bí òun ti jẹ Samaria níyà.
Ẹ sọkún tẹ̀dùntẹ̀dùn,ẹ̀yin tí ó ń gbé etí òkun.
Oríṣun àwòrán, @Mr Saleem Ninu nnkan ti pupọ ninu wọn sọ, wọn ni aawọ darandaran ati agbẹ kọja ọrọ mo fẹ dako, iwọ fẹ daran, bi kii ṣe pe ẹlẹyamẹya ti wọ.
Ojú afọ́jú yóo là nígbà náà,etí adití yóo sì ṣí;
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Ọ̀lọ́pàá shátà mi láti Mowe dé Magboro dé Shagamu, wọ́n ní ṣé mi ò mọ̀ pé ìjọ́ba ni mo ṣiṣẹ́ fún' Bákan náà ló tun rọ àwọn ìjọ tó ni onírúúrú ààyè nínu ilé ìjọsin wọ́n, pé ki wọ́n pin àwọn ènìyàn síbẹ̀ tàbi kí wọ́n pín ìsì wọ́n sí ọ̀nà ọ̀tọ̀ọ̀tọ, ki èrò má ba pọ nínú ìsìn.
“Ẹ kò gbọdọ̀ jẹ́ kí àjẹ́ wà láàyè.
Ẹsẹ ̀ àti ojú ní ó sábà maa ń ràn , bí ó tilẹ ̀ jẹ ́ wípé kò sí ibi tí kò loè ràn lára .
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù CCT: Adájọ́ fẹ̀yìntì ní àwọn asòfin àpapọ̀ yẹ kó fòǹtẹ̀ lu ìgbẹ́jọ́ adájọ́ àgbà 14 Sẹ́rẹ́ 2019 Àkọlé àwòrán, Gbogbo eto ti to ni CCT fun igbejo Adajo Onnoghen Adajọ fẹyinti Folarinwa Oloyede ti sọ pe gbigbe ti wọn gbe Adajọ agba orilẹede Naijiria, Walter Onnoghen lọ si waju ile ẹjọ to n gbo ẹsun aṣemaṣe awọn to di ipo ilu mu, CCT, ko tọna rara.
Orukọ baba rẹ ni Olumọsa lati Ẹgba Owu Ẹfunroye se igbeyawo pẹlu ọkunrin pupọ, o si bi ọkunrin meji fun ọkọ aarọ rẹ to fẹ lati ẹya Owu Nigba ti ọkọ rẹ akọkọ ku tan, lọdun 1833 lo tun fẹ Ọba Eko ti wọn le lori oye, Adele Ajosun, lasiko ti onitọun wa se abẹwo silu Abẹokuta, ti ẹwa Ẹfunroye si faa mọra Ẹfunroye tẹle Ọba Adele pada silu Badagry, nitori ilu yii ni Ọba naa fori pamọ si, agbara Adele si ni Ẹfunroye lo lati mu ki okoowo siga, iyọ ati owo ẹru to n se fẹju si Ọba Eko, Ọba Idewu jẹ ipe awọn baba rẹ, ti ọba Adele ti wọn le lori oye si pada lọ jọba ilu Eko, eyi to sọ Ẹfunroye di olori, bi o tilẹ jẹ pe ọba naa ko lo ju ọdun meji lọ to fi waja ni 1837 Oluwọle, tii se ọmọ ọba Adele gori itẹ, ti Ẹfunroye si fẹ Yesufu Bada Ọbadina.
Bẹ́ẹ̀ náà ẹ lè fìwé ránṣẹ́ sí mi ní
Yatọ si eleyi, o di ipo to pọ mu bi Dan Majen ilu Kano,ki o to bọ si ori apere gẹgẹ bi Emir tuntun.
 ní àwọn àgbegbè tí ibà pọ ́ njú-pọ ́ ntọ ̀ wọ ́ pọ ̀ si ti àjẹsára ó sì wọ ́ pọ ̀ , ìwádìí kíákíá tí àwọn ìṣẹlẹ ̀ àti abẹ ́ rẹ ́ àjẹsára tí ọ ̀ pọ ̀ lára àwọn ará ìlú ni ó ṣe pàtàkì láti dẹ ́ kun àjàkálẹ ̀ arùn .
Juda, Bẹnjamini ati Ṣemaaya, ati Jeremaya.
Ó kọjá ohun tí eniyan lè là kọjá.
Oríṣun àwòrán, Barcroft Media Àkọlé àwòrán, Ta ike rọba ki o di olowo Ta ló gé orí ọkùnrin mẹ́ta ní Lekki?
Àwọn kan ninu wọn fẹ́ mú un, ṣugbọn kò sí ẹni tí ó fi ọwọ́ kàn án.
Nítorí náà, a ní ìgboyà nígbà gbogbo.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ronke Ojo àti Toyin Lawani: Ó dára kí obìnrin níṣẹ́ lọ́wọ́ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Ronke Ojo àti Toyin Lawani: Ó dára kí obìnrin níṣẹ́ lọ́wọ́ 20 Òkùdu 2020 Ronke Ojo, ti ọpọ eeyan mọ si Ronke Oshodi Oke ati Toyin Lawani ba BBC sọrọ lori ipa to yẹ ki obinrin maa ko ninu ile.
Lọjọ iṣẹgun ni ọrọ yii jẹyọ nileegbimọ asofin orilẹede Naijiria lasiko ti awọn asofin agba fi n jiroro lori ikọlu ipaniyan to waye ni ipinlẹ Zamfara to wa ẹlkun iwọoorun ariwa orilẹede Naijiria.
 O ni: “A o sa gbogbo ipa wa lati ri i pe awọn aṣagbeyẹwo
Nítorí náà, OLUWA sọ nípa àwọn ará Anatoti, tí wọn ń wá ẹ̀mí Jeremaya, tí wọn sì ń sọ fún un pé, “O kò gbọdọ̀ sọ àsọtẹ́lẹ̀ mọ́ ní orúkọ OLUWA.
Eyi si maa n yọri si ki wọn o wu, ibasepọ wọn si maa n dinku.
Àkọlé àwòrán, Awọn mẹji ti wọn dajọ iku fun nitori pe wọn ji alufaa John Adeyi gbe Oṣu kẹfa, ọdun 2016 ni awọn ajinigbe naa ji alufaa Adeyi to jẹ alufaa agba fun diọsisi Otukpo ni Ipinlẹ Benue gbe.
Idajọ yii ko ṣẹyin bi awọn obinrin kan to fi mọ ayaworan ọmọ orileede Zahira Leeneke Maus ṣe fẹsun kan pe o fi ọna aitọ ba wọn laṣepọ.
Osisẹ Jamb: Ọga mi lo mi 36m, kii se ejo
Ofin daṣọ aṣiri bomi yi jẹ eyi to maa n daabo bo bi wọn ti ṣe n ṣe iṣakoso ijọ Aguda.
 nígbàtí iye àwọn tó gba àjẹsára náà láàárín àwùjọ kan bá ju 93 % lọ , àtànkálẹ ̀ àrùn ìta kìí sábà wáyé mọ ́ ; ṣùgbọ ́ n wọ ́ n ṣì tún lè wáyé bí ìwọ ̀ n àjẹsára gbígbà bá tún wálẹ ̀ síi .
Eleyi ti mu ki awọn eeyan kaakiri agbaye maa pe fun gbigbe ade ‘agbabọọlu to mọọ gba julọ lagbaye’ le Salah lori bayii.
Atiwipe gbogbo eroja ara obinrin lo ma n dinku ti agba ba ti n de fun obinrin.
Kí oore-ọ̀fẹ́ Oluwa wa Jesu Kristi kí ó wà pẹlu yín.
WHO yoo kapa aisan Lassa Fever 'Àwọn Dókítà fẹ́ kẹ́yin s'awọ̀n alárùn lassa' Ìgò ọtí méje àti sìgá ṣokùnfà ẹjọ́ ikú Kọmisọnna fun eto ilera naa wa parọwa fun awọn to n se garri lati ma a yan lori ina , ki o gbe daradara ko o to di wi pe wọn yoo ma a ta a fun awọn eniyan.
John Amanam: Ìfẹ́ tí mo ní sí àbúrò mi ló sọ mi dí ẹni tó ń ṣe 'Prosthetic' báyìí
Àwọn ará ìlú Ikarẹ Akoko ń ṣọ̀fọ̀ Ọba Adegbite, Ọwá Ale Ikarẹ tó wàjà Gbajúgbajà òṣèré “Blue film'' wọ gàù ẹ̀sùn fífipá bá obìrin 13 lòpọ̀ Ẹgbẹ́ wa ò dàrú o!
Gbogbo àwọn tí ń gbé ilẹ̀ náà ni yóo sin wọ́n, wọn óo sì gbayì ní ọjọ́ náà, nígbà tí mo bá fi ògo mi hàn.
N óo wá fi òpin sí orin kíkọ ninu rẹ; a kò sì ní gbọ́ ohùn dùùrù ninu rẹ mọ́.
Gege bi iroyin kan to jade pe titipa ni enu- ona abawole  ile iwosan Numan wa , bee si ni won ko je ki oko Kankan wole si ile – iwosan naa.
Ṣugbọn ní tiyín, ó ní kí ẹ yipada, kí ẹ sì máa lọ sinu aṣálẹ̀, ní apá ọ̀nà Òkun Pupa.
30 usd fún ìwọ ̀ n egbògi náà kanṣoṣo ní ọdún 2014 .
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Chris Ndukwe and Olamide Alli: Ọkùnrin kan gún àfẹ́sọ́nà rẹ pa, òun náà gbé ògùn jẹ 23 Òkùdu 2020 Oríṣun àwòrán, others Ileesẹ ọlọpaa ipinlẹ Eko ti fidi rẹ mulẹ pe, arakunrin kan ti wọn ni orukọ rẹ n jẹ Chris Ndukwe, ẹni ọdun mọkandinlogoji, ni wọn fura si pe o gun obinrin kan, to n jẹ Olamide Alli pa.
Tí a fiṣọwọ́ ní 12:52 29 Èbibi 201912:52 29 Èbibi 2019 Gomina Dave Umahi ti ìpínlẹ̀ Ebonyi búrawọlé BBCCopyright: BBC Gomina Dave UmahiImage caption: Gomina Dave Umahi Article share tools Facebook Twitter ṢàpínlòView more share options Share this post Copy this linkKà síwájú síi nípa àwọn ìtọ́kasí wọ̀nyí.
 Awon sinima miran lowo Marvel studio ni: Robert Downey to se Iron Man, Chris Evans’ to se Captain America, Scarlett Johansson’s Black Widow ati  Chadwick Bosemanto se Black Panther.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Asofin Mishau ni o to ilaji gbogbo ọlọpa orilẹede Naijiria ti wọn ko si nidi isẹ igbofinro mọ Laipẹ yii ni awọn janduku agbebọn kan kọlu agbegbe ijọba ibilẹ Zurmi ni ipinlẹ Zamfara leyi ti awọn eeyan kaakiri orilẹede Naijria ati lagbaye ti bu ẹnu atẹ lu.
Ìgbà tí ara olórí wọn yá tán, tí wọ́n bá ṣọdẹ lọ títí, ibẹ̀ ni wọ́n ń fàbọ̀ sí títí tí ó fi ń gbòrò sí i.
Àdó okoró búrẹ́kẹ' Ẹṣọ oju popo ti gba awọn eniyan nimọran lati gba ọna miran yatọ si opopona Ibadan si Eko.
Nítorí a ti fi Kristi ọ̀dọ́ aguntan Ìrékọjá wa rúbọ.
Ọ̀kọ̀ ojú omi dànù, ènìyàn méjì kù, ẹnìkan di àwátì Àṣírí tú!
Igba akọkọ ree ti awọn alakoso ere ile ẹlẹgbọn yoo gbe iru ofin yi kalẹ lati yọ awọn oludije kuro ninu ile ọhun.
Ìbànújẹ́ bá mi,nígbà tí mo rí ibi tí ó ṣẹlẹ̀sí àwọn ọmọbinrin ìlú mi.
Bí ó ti pàdé wọn ó wí pé, “Ẹ máa kálọ sí ọ̀dọ̀ Gedalaya ọmọ Ahikamu.
wa dun lopolopo lati je orile-ede ti ajere ori ati sagbateru idije FIFA U20
O jagun ni Awka, Abagana, Onitcha atawọn agbegbe miran lasiko ogun abẹle.
Lẹ́yìn ọjọ́ díẹ̀, Agiripa ọba ati Berenike wá kí Fẹstu ní Kesaria.
Iko agbaboolu Guingamp soro ohun di mimo lori ero ayelujara lojo Aje(Monday).
Ìròyìn sọ pé àwọn oníṣẹ́ ibi náà fọ òkúta mọ ọmọbinrin náà lórí ní idáji ọjọ karùn-ún, oṣù kẹfà bó tilẹ̀ jẹ́ pé, ikú tirẹ jẹ mọ ìfinirúbọ̀ ní gẹ́gẹ bi àwọn ọlọ́pàá ṣe sọ.
”A ni igbagbo pe olorun yoo ran wa lowo.
wọ́n wá sọ́dọ̀ Serubabeli, ati sọ́dọ̀ àwọn baálé baálé, wọ́n wí fún wọn pé, “Ẹ jẹ́ kí á jọ kọ́ ọ nítorí ọ̀kan náà ni wá, Ọlọrun yín ni àwa náà ń sìn, a sì ti ń rúbọ sí i láti ìgbà ayé Esaradoni, ọba Asiria, tí ó mú wa wá síhìn-ín.
Ẹni ire gbáà ni ikú mún lọ l'ọ́tẹ̀ yìí o.
Nibi iwọde naa to waye ni agbagbe Surulere/Ojuẹlẹgba ni eyi ti waye.
Nígbà tí ó bá mi sọ̀rọ̀ tán, mo dojúbolẹ̀, mo sì ya odi.
oselu alatako lati yan adari ile igbimọ asofin , ni eyi ti o tapa si ilana egbe
Bẹ́ẹ̀ ni yóo rí fún ìran burúkú yìí.
Gbogbo ayé ní ń sìn ọ́;wọ́n ń kọ orin ìyìn fún ọ,wọ́n ń kọ orin ìyìn sí orúkọ rẹ.
Kini ero awọn eniyan kan lori irinajo aarẹ Buhari?
Ronke Oshodi Oke: N kò ṣe mọ́na-mọ̀na púpọ̀ ni ìgbéyàwó mi ṣe tọ́jọ́
Gomina  Aminu Tambuwal ti ipinle Sokoto naa wa ki gbogbo awon omo egbe ati alatileyin won kaabo si ipinle Sokoto.
Ọ̀kan ninu àwọn iranṣẹ náà lọ sí oko láti já ewébẹ̀, ó rí àjàrà tí ó máa ń hù ninu igbó, ó sì ká ninu èso rẹ̀.
Iroyin kan tẹ sọ pe ọga ọlọpaa kan naa tẹri gbaṣọ nibi iṣẹlẹ ọhun ṣugbọn ile isẹ ọlọpaa ko tii fidii ọrọ naa mulẹ.
Kí ìjọ mi ní Sagamu le gbòòrò ni mo fi ń ṣiṣẹ́ ajínigbé pawó - Pásítọ̀ Àwa àti fijilanté pẹ̀lú ọdẹ́ ìbílẹ̀ ló dojú kọ adigunjalè ní First Bank Okeho - Iléeṣẹ́ ọlọ́pàá Ìtàn ọba Yorùbá tí wọn yẹgi fún torí ó jí ọmọ gbé ṣe ètùtù Ẹ káàbọ̀ sọ́jọ́ Arafat, tí Ọlọ́run yóò fi ààwẹ̀ Mùsùlùmí pa ẹ̀ṣẹ̀ wọn rẹ́ Boko Haram da ìbọn bo ọkọ̀ gómìnà Borno, ẹ̀ṣọ́ àláàbò rẹ̀ farapa Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí 3 sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 2:23 Fídíò, Water Generator: Ó leè ṣiṣẹ fún wákàtí mẹfà, kó tó sinmi, Duration 2,2310 Òkùdu 2020 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
Ọmọde yii lo ri ẹja Sadini gba nibi ajọdun ọlọdọọdun tawọn ẹja ti maa n sere wa si eti okun ni South Afrika Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ayẹyẹ nla ree o, eyi ko wa pọ ju.
''Núdùlù ẹmí gígùn'' èyí máa ń gùn jú núdùlù lọ, wọn máa ń dín-in tabí kí wọn bọ̀ọ́, wọn sì máa ń sábà fi ṣe ayẹyẹ ọdún túntún ní China ni.
Ogun yóo kó wọn, tọkọtaya,àtàwọn àgbàlagbà àtàwọn arúgbó kùjọ́kùjọ́.
À ó ṣe àtúngbéyẹ̀wò àsìkò ìwọ́le àwọn akẹ̀kọ̀ọ́-Ìjọba apapọ̀ Báwo ni #stingymenassociation ṣe gba ojú òpó twitter kan?
Láti Haṣimona wọ́n lọ sí Moserotu.
Ilé iṣẹ́ tó ń mójú to iye ènìyàn to wà nínú ìlú sàlàyé pé àwọn ilé-ìwé, ilé ìtajà, àti gbogbo ilé iṣk tó ti wà ní títì pa lásìkò Covid-19 náà ba ńkan jẹ́.
 Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Akomolede ati Aṣa lori BBC: Mọ̀ si nípa oríṣìí ẹ̀ka ìsọ̀rí ọ̀rọ̀ àti ìwúlò wọn Bakan naa lo pe oun yoo ṣe idaro Baba Legba nitori ipa ribiribi to n ko ninu fiimu nigba aye rẹ."
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Àwọn onímọ̀ ọpọlọ ní to bá gbé ìgbésẹ̀ yìí, aṣeyege dájú ní ìdánwò Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àwọn onímọ̀ ọpọlọ ní to bá gbé ìgbésẹ̀ yìí, aṣeyege dájú ní ìdánwò 13 Èbibi 2019 Iroyin ibanujẹ kan ni ọjọ Aje wipe ọmọkunri kan, Segun mu òògùn apakòkòrò tórí máàkì 167 nínú JAMB, idanwo si ile iwe giga ni Naijiria.
Ko gbogbo àwon àgbà pé níbo ni Adéláyò ti kó irú ogbón tí ó lò.
Bakannaa ni esi iwadi Oxfam tun tọka si bi ọrọ awọn to lowo julọ ni Afrika ṣe n pọ si, ti iṣẹ oun aini si n lọ si oke laarin awọn alaini.
tun beere  iranwọ lati ọdọ awon egbe
Ẹ yọ mí látìmọ́lé DSS, ó lòdì s'ẹ́tọ̀ọ́ mi- Ṣowore Togo sòfin aago ti olùfẹ̀hónú han lè jáde àtí àsìkò tí ó wọlé Sowore ṣèpàdé pẹ̀lú Nnamdi Kanu láti dojú ìjọba Nàíjíríà bolẹ̀ - Àjọ DSS Àṣìta ìbọn ló pa obìnrin nílùú Eko lọ́jọ́ Satide- Ọlọ́pàá Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Aláráǹbàraà!
Awọn aya ọba, ta n pe ni Olori abi Ayaba lo maa n ti igba ni aafin Ọyọ, eyi si jẹ ara ojuse pataki ti wọn gbọdọ ṣe gẹgẹ bi aya ọba.
ni “lọsẹ to n bọ, ni a o  bẹrẹ  si
DJ Cuppy gbóṣùbà ràbàndẹ̀ fún Anthony Joshua ṣáájú ìjà rẹ̀ pẹ̀lú Andy Ruiz Mo ṣetán láti kojú Andy Ruiz ni Saudi lọ́jọ́ Sátidé- Anthony Joshua Saheed Balogun sìnkú ìyá rẹ̀, Ogogo ní ẹgbẹ́ agbábọ́ọ̀lù!
O ni eeyan meji ninu awọn to ku naa ni wọn kọlu ninu sọọsi, ọkùnrin ati obinrin kan ti wọn fi ọbẹ ya ọrun wọn.
Dafidi ati àwọn eniyan rẹ̀ sì lọ bá àwọn ará Filistia jagun.
Ìwà ìtìjú, ọ̀rọ̀ òmùgọ̀, tabi àwàdà burúkú kò yẹ yín.
Àkọlé àwòrán, Baba Obasanjọ darapọ mọ ikọ ọmọogun Naijiria ni ẹka imọ ẹrọ ti o si jagun ni Congo, Britain, ati India titi to fi de ipo ọgaagun.
Funke Akindele fún mi lówó tí mo fi gba ilé, kò ra ilé fún mi o - Ajirebi Ìrọ̀rùn dé!
O fi kun un wipe awọn kan n rojọ kiri pe oun n ra ibo fun ọmọ oun ṣugbọn irọ ni wọn n pa.
    Kábíyèsí, kí ọlọ́run bùn yín lẹ́mìí, é ó pẹ́ láyé fún wa.
Lẹyin o rẹyin, ko sẹni to mọ ohun to sẹlẹ si Gbọnka mọ, ti oun naa si pada di ara ilẹ.
Bákan náà lo fi kun pé, láti ìgbà tí o ti de orí oyè ni wọn ti n lo àwọn afọbajẹ kógun tii.
Àwọn tí wọ́n ti oko ẹrú dé fi akọ mààlúù mejila rú ọrẹ ẹbọ sísun sí Ọlọrun Israẹli fún ẹ̀yà Israẹli mejila, pẹlu àgbò mẹrindinlọgọrun-un, ọ̀dọ́ aguntan mẹtadinlọgọrun-un, ati òbúkọ mejila fún ẹbọ ìmúkúrò ẹ̀ṣẹ̀.
"Àkọlé àwòrán, Alága ètò nàá, Ọ̀jọ̀gbọ́n Ayọ Bámgbóṣé Ó sọ pé ""ọ̀nà kínní ona tí èyí fi ń jẹyọ ni pé ọ̀pọ̀ òbí kìí sọ èdè Yorùbá sí àwọn ọmọ wọn, bíkò ṣe èdè Gẹ̀ẹ́sì."
Lẹyin to lo ọpọlọpọ ọsẹ ni ọdọ awọn ajọ EFCC ni ile ẹjọ gba oniduro rẹ.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Immanuel ni awọn arugbo lo pọ ju ninu awọn alaisan Coronavirus ti oun wosan, koda, awọn miran ni aisan atọgbẹ ati ikọ semisemi.
Imaamu naa yoo wọ kaa ilẹ sun gẹgẹ bi ilana ẹsin Musulumi.
Ó ṣe òbìrìkítí kan sórí omi,ó fi ṣe ààlà láàrin òkùnkùn ati ìmọ́lẹ̀.
Ó lè jẹ́ ìdí nìyí ti gómìnà fi rs àwọn ará ìlú láti maa sàmúlò ojú omi, nínú àtẹjáde kan ti àgbẹnusọ rẹ̀ Gboyega Akosile buwọlù lánà òdé yìí.
lasiko  ti won n koju ikọ agbabọọlu orile
Lẹ́yìn tí wọ́n ti parí gbogbo nǹkan wọnyi tán gẹ́gẹ́ bí òfin Oluwa, wọ́n pada lọ sí Nasarẹti ìlú wọn ní ilẹ̀ Galili.
Àkọlé àwòrán, Mexico ni Odò kékeré ti Germany fojú di, wọn ṣíná fún àwọn Germany to gba ife gbẹyin Sọ àsọtẹ́lẹ̀ nípa ikọ̀ tí yóò gba ife ẹ̀yẹ àgbáyé 2018 pẹ̀lú eré ìdárayá tuntun ti BBC Ilé yá!
“OLUWA gbọ́ ọ̀rọ̀ yín nígbà tí ẹ̀ ń bá mi sọ̀rọ̀, ó sì wí fún mi pé, ‘Mo gbọ́ ohun tí àwọn eniyan wọnyi bá ọ sọ; gbogbo ohun tí wọ́n sọ pátá ni ó dára.
Dubai (UAE) n reti ẹni to ba fẹ wọle si orilẹede wọn lati Ọjọ Keje, Oṣu Keje, lati ri pe wọn mu iwe to fihan pe, wọn ko ni arun Coronavirus dani wa.
Fun'ra awọn ọmọ ẹgbẹ naa si lo ma n yan awọn adari wọn amọ Gomina Makinde fi ofin de ẹgbẹ NURTW naa nitori rogbodiyan to n waye ni gbogbo igba nipa yiyan awọn adari rẹ.
O ni didẹwọ isede ati awọn ofin yii laarin oṣu kẹfa si oṣu keje jẹ ki iye awọn to lugbadi Covid 19 pọ sii nilẹ Adulawọ.
Ẹ kò ní rí ìjì tabi òjò, sibẹsibẹ àwọn odò gbígbẹ náà yóo kún fún omi, ti yóo fi jẹ́ pé ẹ̀yin ati àwọn mààlúù yín ati àwọn ẹran ọ̀sìn yín yóo rí ọpọlọpọ omi mu.
Oríṣun àwòrán, Twitter/NFF Ajọ ẹṣọ oju popo FRSC sọ pe awọn mẹtẹẹta lo ja laisi lojuna ti ijamba ọkọ naa ṣẹlẹ tan.
Ó fi àwọn aṣọ́nà sí ẹnu àwọn ọ̀nà ilé OLUWA kí ẹnikẹ́ni tí kò bá mọ́ má baà wọlé.
Mo lóbìnrin tó bímọ fún mi, ṣùgbọ́n ọ̀rọ̀ ìyàwó kò tíì yọ fún mi báyìí-Pasuma Ìdí mẹ́ẹ́rin tí sísùn ní ìhòhò lé gbà ṣe ara a rẹ l'óore O ni awọn opo afara naa to ti n rẹ sara laarin agbegbe Alaka si Costain titi wọ Apọngbọn ni wọn fẹ tun ṣe.
Ó ní ẹnikẹ́ni tí ó bá jẹ́ kí ẹnìkan lọ, pípa ni a óo pa á.
OLUWA sọ fún Mose ati Aaroni ní ilẹ̀ Ijipti pé, 
Ẹ̀yin ará, mo bẹ̀ yín pé kí ẹ máa fura sí àwọn tí ó ń dá ìyapa sílẹ̀ ati àwọn tí ń múni ṣìnà, tí wọn ń ṣe àwọn nǹkan tí ó lòdì sí ẹ̀kọ́ tí ẹ ti kọ́, ẹ yẹra fún irú àwọn eniyan bẹ́ẹ̀.
Kí a filẹ̀ mú ti èérí kúrò, ki ni kí a ti pe ti ilé wọn tí kò ní fèrèsé tàbí ilẹ̀ ilé tí ó tùtù nini, kí ló lè mú àìsàn wá tí ó kọja irú èyí!
Igba akọkọ kọ niyi ti iru eto yii ṣeleri èrè kiakia fun awọn oludokowo, ti ọpọ eniyan si n ṣe e bo tilẹ jẹ wi pe awọn alaṣẹ n kilọ fun wọn.
Aare ana  fun orile ede Naijiria , Olusegun Obasanjo si yan an gege bi  alaga fun ajo ICPC lodun 2000 titi di odun 2005.
O gbé oúnjẹ kalẹ̀ níwájú mi,níṣojú àwọn ọ̀tá mi;o da òróró sí mi lórí;o sì bu ife mi kún ní àkúnwọ́sílẹ̀.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Coronavirus: Ọ̀pọ̀ àwọn arìnrìnàjò wá sí Nàíjíríà ló kọjá àbẹ̀wò tó lágbára Awọn ileeṣẹ ọkọ ofurufu bi i Etihad Airways ti fi ọrọ yi sita loju opo wọn o to ọjọ mẹta.
Òun ni alákòso àti adarí ilé isẹ́ fíìmù Jaylex Aesthetic Production.
"Nkan ti orilẹ-ede America si le ṣe lati gbe erongba wọn lẹyin, ni lati wa awọn orilẹ-ede mii ti yoo darapọ mọ wọn lati tako o.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù BUSA 2019: Èrò yapa ní mọ́ṣáláṣí Jimọ̀h láti wá fójú lóúnjẹ lórí ìgbéyàwó Buhari 12 Ọ̀wàrà 2019 Kini o ṣẹlẹ ni Mọṣalaṣi Jimoh lanàá ti wọn royin ofege pe Buhari fẹ ṣe igbeyawo nibẹ?
Gbogbo àgbààgbà Ilẹ̀ Yorùbá ní kí n máa kì ọ
Eyi lo si faa ti ajọ INEC nipinlẹ Ọyọ fi ṣi oju opo kan silẹ fun pipe awọn oludibo lori ẹrọ ibanisọrọ lati wa gba kaadi idibo wọn ninu eto naa ti wọn bẹrẹ ni ọjọ Aje.
ipinle Kebbi ,so pe igbimo naa gbe iwe meji ti won fenuko le lori lọ siwaju
Ninu apo asunwọn owo mẹrinla ti iroyin naa sọ pe Obasa lo ni i ni banki Zenith, mẹfa pere lo jẹ tiẹ, meji pere si lo n lo ninu wọn."
Eléyìí tún mú kí èmi náà sọ̀rọ̀, mo ní, ‘Bí baba tí ó bí ọ tilẹ̀ ju baba ẹlòmíràn, ssíbẹ̀ tí ọ kò ju baba tí ó bí mi, nítorí náà jọ̀wọ́ jẹ́ kí n mọ baba tí ó tóbí náà tí ó jẹ́ baba tí ó bí ọ.
Gẹgẹ bo ṣe sọ, iye wakati ti awọn to wa ni isọri D fi n lo ina lojumọ jẹ nnkan bii wakati mẹjọ, nigba ti awọn to wa ni isọri E n lo ina ijọba fun nnkan bii wakati mẹrin din diẹ.
Nítorí pé OLUWA Ọlọrun ní, “Ẹ pe ogunlọ́gọ̀ eniyan lé wọn lórí kí wọ́n ṣẹ̀rù bà wọ́n, kí wọ́n sì kó wọn lẹ́rù; 
Mose gba ìdajì ninu ẹ̀jẹ̀ ẹran náà sinu àwo ńlá, ó sì da ìdajì yòókù sí ara pẹpẹ náà.
Agọ ọlọpaa Iganmu nilu Eko, Ọọjọ nilu Ibadan ati ti Plateau ni wọn jo kanlẹ, ti ẹmi awọn ọlọpaa kan si bọ lasiko isẹlẹ naa.
Ni Igba aye rẹ, Babajide Shorunmuti jẹ akọnimọọgba fun ẹgbẹ agbabọọlu Niajiria, Shooting Stars.
Ṣé lóòtọ́ ni Kayode Fayemi, gómìnà ìpínlẹ̀ Ekiti fẹ́ du ipò ààrẹ orílẹ̀èdè Nàìjíríà?
1 Ìgbé 2019 5:03 Fídíò, Òkè Ìdànrè: Òkè tó kéré jùlọ jẹ́ ẹsẹ̀ bàtà 3000, Duration 5,0312 Ọ̀pẹ̀̀ 2018 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Èré Ọṣun: Àtáója ní wọn kò jí ère Ọṣun, ó sì wà níbi tó wà Olukọ naa to jẹ ẹni ọdun mẹrinlelọgbọn ni wọn ni o n gbe ọrọ sayẹnsi larugẹ.
Ṣugbọn awọn eeyan ni toriipe o bu ẹnu atẹ lu iṣesi gomina ipinlẹ Kano, Abdullahi Ganduje ninu ọkan ninu awọn orin naa ti awọn olorin mii naa si bẹrẹ si ni ṣe ohun to ṣe.
ÈTÒ ÀÀBÒ Àkọlé àwòrán, Eto aabo ti ko fararọ ní ìpínlẹ̀ Ogun Rotimi Paseda Àkọlé àwòrán, #BBCOGUNDEBATE: Èrò àwọn oludije ṣe ọtọ̀ọ̀tọ lóri ètò ẹkọ Ofẹ Paseda ni ojutu ti oun ni lori abo ni pipada si ori ibi ti a ti bere.
Dino Melaye nánwó fún Ayefẹlẹ A ó gbé'gbésẹ̀ lẹ́yìn ìwádìí fídíò tí Dino ti ń náwó lójú agbo- Ọlọ́pàá Sẹ́nétọ̀ Dino Melaye kéde láti dupò gómìnà Kogi Ṣaaju, Ile iṣẹ ọlọpaa sọ pe awọn yoo ṣe iwadi fọnran naa to ṣafihan bi Sẹnẹtọ Dino Melaye ti n fi owo mọ olorin Yinka Ayefẹlẹ lori loju agbo.
osu keje odun 2019, gege bi alaga ajo eleto idibo fun ipinlẹ naa Perekeme
Ajọṣepọ laarin awọn onigbagbọ ati ijọba lo jẹ wa logun.
O ni “ijoba ni o le
Wọ́n mú akọ mààlúù tí wọ́n fún wọn, wọ́n pa á, wọ́n sì bẹ̀rẹ̀ sí ké pe oriṣa Baali láti àárọ̀ títí di ọ̀sán.
“Iwa odaran ni, fun eni ti o ta iwe irinna fun un yin, sugbon ti o kuna lati ko o yin pada wa sile, leyin ti o ti gba owo lati koo yin pada.
Yoruba bọ, wọn ni ọmọ ti yoo ba ti jẹ aṣamu, ati kekere ni yoo ti ma ṣẹnu ṣamu ṣamu.
Ó bá pàṣẹ fún àwọn ọmọ-ogun kí wọn wá fi agbára mú Paulu kúrò láàrin wọn, kí wọn mú un wọnú àgọ́ àwọn ọmọ-ogun lọ.
Àwọn ọmọ Iyabọ Ojo rí Bàbá lẹ́yìn ọdún mẹ́fà Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ogundiya: Àṣìṣe Dókítà ló sọ mi di aláàbọ̀ ara lórí kẹ̀kẹ́ Lati ilẹ yii titi de oke okun ni ariwo ti lori isẹlẹ yii - bi awọn kan ṣe n ti wọn lẹyin pe ko si ohun to buru ninu rẹ, ni ọgọọrọ miran ti n pariwo pe Ọlọrun ko roro to bẹẹ.
Ó bá rọ̀ mọ́ Bẹnjamini arakunrin rẹ̀ lọ́rùn, ó sì bú sẹ́kún, bí Bẹnjamini náà ti rọ̀ mọ́ ọn, ni òun náà bú sẹ́kún.
Kódà gbọingbọin la wà lẹ́yìn Akintoye gẹ́gẹ́ bíi adarí YWC nílé, lẹ́yìn odi Ìjọba ìpínlẹ̀ Kogi kéde ọjọ́ ìwọlé àwọn akẹ́kọ̀ọ́ Àṣírí tú!
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Oyenusi ló mú mi wọ ẹgbẹ́ adigunjalè kó tó di pé mo b'Ólúwa pàdé' Oríṣun àwòrán, Nigeria Army Oríṣun àwòrán, Screenshot Àwọn ọ̀dọ́ fi ọ̀nà àrífín pe Tinubu lórí aago àmọ́ ó ní òun kò mọwọ́-mẹsẹ̀ nípa ìpànìyàn Lekki Oríṣun àwòrán, @AsiwajuTinubu Asiwaju ẹgbẹ oselu APC nilẹ wa, tii tun se gomina tẹlẹ nipinlẹ Eko, Asiwaju Bola Ahmed Tinubu, tun ti sọrọ lori isẹlẹ isekupani to waye ni Lekki fun igba keji.
Oludamọran pataki fun Aarẹ Buhari, Mallam Garba Shehu nigba ti o n fesi si ọrọ naa sọ wi pe, ọro to buru jai ni adari ijọ naa sọ, ati wi pe ko si otitọ nibẹ.
Àwọn eniyan OLUWA sì yan jáde láti ẹnubodè ìlú wọn.
Bí wọ́n ti njẹ oúnjẹ àgbàdo yìí lèyìí.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Security: Ìpínlẹ̀ 9 yóò lo ẹ̀rọ ayàwòrán díróònù láti paná ìpèníjà ààbò 6 Ògún 2019 ẹ̀rọ ayàwòrán díróònù Oríṣun àwòrán, @CTAflash Awọn ipinlẹ kọọkan to wa ni ilẹ Yoruba yoo bẹrẹ si ni lo ẹrọ ofurufuru ayaworan igbalode, taa mọ si Drone, lati ma a fi sọ agbeegbe wọn lọna ati gbogun ti eto aabo to denukọlẹ lorilẹede Naijiria.
Ẹ wò wá ẹ wo iṣẹ́ ọwọ́ wa Yàtọ̀ sí eku gọ́tà tàbí èku inú ilé, kò sí eku téèyàn ò lè jẹ - Òǹtajà Eléwé ọmọ Àwọn ọba tó wà lábẹ́ mi ń talẹ̀ nítàkutà- Oluwo Ibà Lassa wọ ìpínlẹ̀ Èkó!
Àyẹwò Lassa Fever la n ṣé f'èèyàn 16 ní Kwara kìí ṣé tí Coronavirus- Coronavirus: Italy sọ àgádágodo sí ilé ẹ̀kọ́ alákọ̀ọ́bẹ̀rẹ̀ àti girama Àrùn Coronavirus ti tàn dé orílẹ̀-èdè míràn nílẹ̀ Afrika Onínúfùfù ni Saheed Oṣupa, ṣùgbọ́n èèyàn dáradára ni-Taye Currency Buhari ò, àwáwí rẹ ṣú wa, aáyan ìjọba rẹ̀ mẹ́hẹ lórí ètò ààbò - Ìjọ Aguda figbe ta Kọmiṣọna feto ilera ni ipinlẹ Eko, Ọjọgbọn Akin Abayọmi lo ṣi aṣọ loju igbesẹ ajọ WHO.
Nítorí náà, Ahabu ọba pe ọ̀kan ninu àwọn iranṣẹ rẹ̀ kí ó lọ pe Mikaya wá kíákíá.
Ọga Adamu sọ eyi lasiko to n kaakiri awọn ileeṣẹ ọlọpaa kaakiri olu ilu orilẹede Naijiria, Abuja.
Ṣugbọn n óo fi ìyàn pa àwọn ọmọ ilẹ̀ rẹ,a óo sì fi idà pa àwọn tó kù ní ilẹ̀ rẹ.
Ninu ọrọ to fi ransẹ si ileesẹ BBC Yoruba, Oba Abdulrasheed sapejuwe Ọlọfa gẹgẹ bi ọba to se fi yangan lawujọ awọn ọba ilẹ Yoruba.
Ọkàn wọn ti yigbì, ṣugbọn èmi láyọ̀ ninu òfin rẹ.
 nínú àbájádèe àwọn aláyẹ ̀ wò nípa iṣẹ ́ àgbẹ ̀ , wọ ́ n sọ pé , ó tó ìpín bi ọgọ ́ ọ ̀ rin ènìyàn tí wọ ́ n n ṣiṣẹ ni ọ ̀ nà kan tàsí òmíran nípa iṣẹ ́ àgbẹ ̀ .
Ipari ogun Agbekoya ati ipẹyinda rẹ: Lẹyin o rẹyin, ogun Agbekoya wa sopin ni kete ti wọn tu Oloye Obafemi Awolowo silẹ lọgba ẹwọn, to si pẹtu si awọn agbẹ lati bomi suuru mu.
O ni lẹyin ti eto ọhun ba ti to tan ni awọn oṣiṣẹ yoo lọ bẹrẹ iṣẹ lori afara naa.
Ṣugbọn Amasaya fi ìgboyà kó ogun rẹ̀ lọ sí Àfonífojì Iyọ̀, ó sì pa ẹgbaarun (10,000) ninu àwọn ọmọ ogun Seiri.
Àpáta ńlá tí ó wà ninu oko Joṣua ará Beti Ṣemeṣi, tí àwọn ọmọ Lefi gbé àpótí OLUWA náà lé wà níbẹ̀ gẹ́gẹ́ bí ẹ̀rí ohun tí ó ṣẹlẹ̀ títí di òní olónìí.
Ileẹjọ ti wa kede pe oun sun igbẹjọ naa siwaju di ọjọ Aje, ọjọ Kẹrindinlogun osu Kẹta ọdun 2020.
jẹ  26,446, nitori pe, ibo naa ni kọhun-kọhun
 Bringing back the element of boxing 🥊A post shared by  Anthony Joshua (@anthony_joshua) on Jan 24, 2019 at 5:13am PSTIroyin fi mule pe, Joshua n duro de aridaju pe boya ifigagbaga yoo si waye laarin re ati Miller ni gbagede Madison Square, ninu osu kefa odun yii.
Alaafin: Àwọn ọba Ekiti kò nílò alàgàta, bí wọ́n bá tilẹ̀ nílò rẹ̀, Ọọ̀ni nìkan ló láṣẹ bẹ́ẹ̀
OLUWA Ọlọrun yín tìkararẹ̀ ni ó ń tọ́jú rẹ̀, tí ó sì ń mójútó o láti ìbẹ̀rẹ̀ ọdún títí dé òpin.
O fikun wi pe gbogbo ilakaka rẹ lati jẹ aarẹ orilẹede Naijiria ni ọdun 2015, 2019 ati 2023 lo ti ja si pabo bayii.
Kò sí àwáwí kankan fún ọ, ìwọ tí ò ń dá ẹlòmíràn lẹ́jọ́, ẹnikẹ́ni tí ó wù kí ó jẹ́.
Ènìyàn kan kú, méje farapa nínú ìjàmbá afárá Otedola ní Eko 'Ìbọn dún láàfin Ọ̀ọ̀ni ilé ifẹ̀ lóòtọ́, ṣùgbọ́n kò séwù' Àwọn ìbejì Akeugbagold kò le rìn dáadáa mọ́ lẹ́yìn tí wọ́n dáwọn padà Àfi ìgbà tí mo bọ́ sọ́wọ́ ọ̀tá mí nínú ìrìnàjò ìfẹ́- Roshan Gẹgẹ bí adajọ ti se sọ, ni ṣiṣẹ n tẹle ni idajọ naa yóò tẹle ara wọn.
Champions league: Real Madrid jẹ wábiwọ́sí ìyà lọ́wọ́ PSG, Di Maria ló hun pàṣán ìyà wọn
Bí ó ti ń gbé e fún un, ni Amnoni gbá a mú, ó wí fún un pé, “Wá, mo fẹ́ bá ọ lòpọ̀.
fun ohun ọgbin ati ise agbe lorile ede Naijiria.
Igbesẹ pataki ni fifọ ọwọ loore-koore, paapa pẹlu omi ati ọṣẹ.
Iṣẹ́ ọpọlọ ló yẹ ká ṣe nínú tíátà, kìí ṣe àfihàn ara bíbó àbí ìhòòhò wa - Binta Mọgaji Níbo làwọn òṣèré apanilẹ́rìn ín wọ̀nyí tó pilẹ̀ sínima àgbéléwò Yorùbá wà?
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù 'Soapy', àwo orin tuntun Naira Marley tó ń milẹ̀ tìtì 28 Òkùdu 2019 Oríṣun àwòrán, INSTAGRAM@NAIRAMARLEY Àkọlé àwòrán, Naira Marley Afeez Fashola ti gbogbo eniyan mọ si Naira Marley ti gbe awo orin tuntun kan jade to n jọba oju opo ayelujara lọwọlọwọ.
Agbẹjọro agba ati Kọmisọna fun eto idajọ nipinlẹ Ondo, Adekola Olawoye naa ni yoo maa ṣoju ijọba ninu ẹjọ to pe tako olori ijọ Sọtitobirẹ.
Ko si si igba to wu ki wọn o si awọn ile itaja, ileesẹ ati ileewe, ibẹru ati ipaya ti Covid-19 mu wa ko le lọ kiakia,yoo to ọpọlọpọ oṣu.
Ṣugbọn bí ojú rẹ kò bá ríran tààrà, gbogbo ara rẹ ni yóo ṣókùnkùn.
Olukuluku kó àwọn eniyan rẹ̀ tí wọ́n ṣíwọ́ lẹ́nu iṣẹ́ ní ọjọ́ ìsinmi wá, wọ́n dúró pẹlu àwọn tí wọ́n fẹ́ gba ipò wọn, nítorí Jehoiada alufaa kò jẹ́ kí wọ́n túká.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, FFK: Buhari ló ń fún àwọn Fulani láàyè láti máa pa ènìyàn' Bii Babajide Sanwo-Olu ti ipinlẹ Eko, Dapọ Abiọdun lati ipinlẹ Ogun, Rotimi Akeredolu ipinlẹ Ondo, Gboyega Oyetọla lati ipinlẹ Ọṣun, Kayode Fayẹmi ipinlẹ Ekiti ati gomina Ṣeyi Makinde ipinlẹ Ọyọ ti o jẹ olugbalejo.
Wọ́n ti bá àwọn ọlọrun mìíràn lọ, wọ́n sì ń sìn wọ́n.
Láti ìsinsìnyìí lọ n kò ní lé èyíkéyìí, ninu àwọn orílẹ̀-èdè tí ó kù kí Joṣua tó kú, jáde fún wọn.
Lẹ́yìn náà, ẹ mú un jáde sẹ́yìn odi ìlú, kí ẹ sì sọ ọ́ lókùúta pa.
Lẹ́yìn ọ̀ rẹyìn, ilé ẹjọ́ gba oníduro Sowore pẹ̀lú ọgọ́rùn ún mílíọ̀nù náírà Ìjọba máa ní láti dá òsìsẹ́ dúró kí wọ́n tó lè san gbedéke owó osù tí ẹ fẹ́ - Ngige Mo sọkún bíi ọmọ́dé nígbà tí à ń gbé òkú àwọn èèyàn jáde - Imam tó gba àwọn Krìstẹ́nì là Bàbá ọlọ́mọ méjì kú sínú àgbàrà òjò Ẹ yéé purọ́ kiri!
Ní ọjọ́ kẹjọ, Mose pe Aaroni ati àwọn ọmọ rẹ̀ ati àwọn àgbààgbà Israẹli; 
Siwaju sí i, aadọjọ (150) àwọn Juu ati àwọn ìjòyè ni wọ́n ń jẹun lọ́dọ̀ mi, yàtọ̀ sí àwọn tíí máa wá láti àwọn orílẹ̀-èdè tí ó yí wa ká.
Ile igbimọ tun jẹ ko di mimọ pe bi riru ofin yii ba tẹsiwaju, ile yoo lo ilana to wa ninu ofi eyi tii ṣe yiyọni nipo.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Buhari: Àì lè ṣe dáradára tó mi wà lọ́wọ́ àwọn aṣòfin àpapọ̀ 10 Ìgbé 2018 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 3 Bélú 2018 Oríṣun àwòrán, TWITTER/BASHIR AHMAD Àkọlé àwòrán, Buhari ní ìṣèjọba òun yóò túbọ̀ gbájúmọ́ ètò àbò, gbígbógun ti ìwà ìjẹkújẹ Aarẹ Muhammadu Buhari ti di ẹbi bi awọn akanṣe iṣẹ lori ohun amayedẹrun lorilẹede naijiria ṣe n falẹ labẹ iṣejọba rẹ ru sunkẹrẹ-fakẹrẹ awọn aṣofin apapọ lori bibuwọ lu abadofin iṣuna eyi to ni o n ṣe ọpọ akoba.
Lẹyin ọrẹyin ni awọn alakoso ija naa ba panupọ pe Anthony Oluwafẹm Joshua lo bori Joseph Parker.
Ìjí idágbére ti wọ́ Elozonam àti Ike kúrò nílé ẹlẹ́gbọ̀n àgbà BBNaija Ọpẹ́ o!
Wunmi Toriola, Aisha Lawal, Sotayo àtàwọn ọmọge Yollywood mìí
O si da mi loju pe awọn ọmọ Naijiria gan mọ pe mo ti gbiyanju lati se ohun ti agbara mi ka lori wọn.
Wọ́n sin òkú rẹ̀ sinu ibojì tí ó wà ninu ọgbà Usa ní ààfin.
Ogbeni Mutiu Agboke lo fun Seyi Makinde ni iwe eri naa.
Ìkáwọ́ rẹ ni ipá ati agbára wà, ó wà ní ìkáwọ́ rẹ láti gbéni ga ati láti fún ni lágbára.
Wọ́n sọ̀rọ̀ Ọlọrun Jerusalẹmu gẹ́gẹ́ bí wọ́n ṣe ń sọ̀rọ̀ nípa àwọn oriṣa àtọwọ́dá tí àwọn orílẹ̀-èdè mìíràn ń bọ.
eleto aabo naa wa n ro awon eniyan lati maa duro si ibi ti opo eniyan ba wa.
Bo tilẹ jẹ pe Lai ni awọn ṣoja naa yinbọn, ṣugbọn o ni kii ṣe ọta to lagbara lati gbẹmi eeyan ni wọn yin, ati pe inu afẹrẹ lasan ni wọn yin ibọn naa si, wọn ko doju rẹ kọ ẹnikẹni.
Ọpẹlọpẹ ọdẹ alẹ kan ni Ileesẹ Gbadero, to wa lara awọn ẹlẹrii, to tan imọlẹ si idi ọrọ yii.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Fayoṣe figbe ta pé wọ́n fẹ́ gbẹ̀mí òun ‘Fayose ń lo owó osù òsìsẹ́ fún ara rẹ̀’ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, #EkitiDecides: Fayose sùn lórí ibùsùn aláìsàn Iwadii fihan wipe awọn to n se isẹ fayawọ naa maa n ko o pamọ si inu paali, ti wọn si n lo atẹjisẹ lori ẹrọ ikansiraẹni Whatsapp lati ba ara wọn sọrọ pẹlu orukọ bii 555, Tokapi ati Africa Demand.
ẹ mọ̀ dájú pé Ọlọrun ni ó dá mi lẹ́bi,tí ó sì fi àwọ̀n rẹ̀ yí mi ká.
Lẹ́yìn náà, Eliṣa pàṣẹ fún un pé kí ó ta ọfà náà.
Níbo ni àjàkálẹ̀ àrùn rẹ wà?
Bákan náà ni Brazil, Quatar Ilẹ Amerika àti Russia kò si nínú àwọn orílẹ̀-èdè tí yóò láànfàní láti wọ EU, títí di àsìkò yìí, ilẹ̀ gẹ́ẹ̀sì si ni ẹtọ́ kan náà gẹ́gẹ́ bi ara EU títí ti àdehuń Brexit yoo fi kẹ́sẹ jári lópin ọdún yìí.
Ìpọ́njú ti gba agbára mi;gbogbo egungun mi sì ti di hẹ́gẹhẹ̀gẹ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Police Brutality: Bí ọlọ́pàá ṣe bọ́ aṣọ mi tí wọ́n lù mi, wọ́n tún gba #260, 000 lọ́wọ́ mi- Olumide 16 Agẹmo 2020 Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Police Brutality: Bí ọlọ́pàá ṣe bọ́ aṣọ mi tí wọ́n lù mi, wọ́n tún gba #260, 000 lọ́wọ́ mi Lẹ́yìn ti ọmọkùnrin kan ké gbàjarè lórí àtéjíṣẹ́ twitter lówùrọ ọjọ Iṣẹ́gun ní ọ̀pọ̀ sì bẹ̀rẹ̀ sí ni bẹnu àtẹ́ lu ilé iṣẹ́ ọlọ́pàá orílẹ̀-èdè Nàìjíríà.
Opọ igba ni wọn maa n fẹsun kan ara wọn pé wọn n ji ẹran ọsin ara wọn ko.
Coronavirus: Àwọn ohun tí a kò tíì mọ̀ nípa àrùn Covid-19 Kí lo mọ̀ nípa fẹntilétọ̀, ohun èlò aṣèrànwọ́ èémí Ṣé òògùn Chloroquine lè dènà ààrùn Coronavirus bí?
 Àwọn àtúnbọ ̀ tán tó burú ju ìwọ ̀ nyí lọ kò wọ ́ pọ ̀ .
Tí a fiṣọwọ́ ní 18:20 10 Ọ̀pẹ̀ 202018:20 10 Ọ̀pẹ̀ 2020 Ooni Adeyeye ti Ile Ife fẹ sèrànwọ́ owó iléèwè fún akẹ́kọ̀ọ́ 5 mílíọ̀nù ní Nàìjíríà Ooni Ile Ife gbe akanṣẹ eto iranwọ owo ileewe fun akẹkọọ miliọnu marun un.
O wa rọ awọn ọkunrin wi pe ki wọn gbiyanju lati tọju iyawo wọn nitori awọn lo jẹ iya ati iyawo fun wọn.
" boko haram tún túmọ ̀ sí "" Ẹ ̀ ṣè ni ọ ̀ làjú "" and "" Ọlàjú kìí ṣe oun tó mọ ́ "" ."
Nígbà tí ó yá, ọba Ijipti pe àwọn obinrin Heberu tí wọ́n ń gbẹ̀bí, tí orúkọ wọn ń jẹ́ Ṣifira ati Pua, ó sọ fún wọn pé, 
Nígbà tí eniyan burúkú bá wà lórí oyè, ẹ̀ṣẹ̀ a máa pọ̀ síi,ṣugbọn lójú olódodo ni wọn yóo ti ṣubú.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Wasiu Ayinde: Ó pọn dandan fún Mayegun láti ri pé àláfíà jọba 13 Sẹ́rẹ́ 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 15 Sẹ́rẹ́ 2020 Oríṣun àwòrán, Instagram/K1 the ultimate Àkọlé àwòrán, Ó pọn dandan fún Mayegun láti ri pé àlaáfíà jọba Ile Ọba Alaafin ti ilu Oyo ti sọ ipa ti Mayegun ti ilẹ Yoruba, Wasiu Ayinde yoo ma a ko ni ilẹ Yoruba.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Òwú tí ìyá gbọ̀n, lọmọ ó ran ni ọ̀rọ̀ Saraki nínú òṣèlú 1 Ògún 2018 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 5 Ògún 2018 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ilé tóó lọ: Bukola Saraki padà sí ẹgbẹ́ òṣèlú PDP tó ti wá sí APC Aarẹ Ile Igbimọ Asofin Agba, Sẹnetọ Bukola Saraki ti di adari ẹgbẹ oṣelu PDP, lẹyin to kuro ni ẹgbẹ oṣelu APC lọ si ẹgbẹ oṣelu PDP.
Okoroafor salaye pe, ilana ile-ifowopamo CBN paala si nini anfaani si owo ile-okere lati ipin owo ori oja idokowo orile-ede Nigeria fun awon alagbata oja bi mokanlelogoji, ti se anfaani fun owo ipamo orile-ede Nigeria ohun.
4 ninu miliọnu ) ni orilẹ-ede amẹrika , iye iku 20 l ' ọdun ni orilẹ-ede gẹẹsi ( 0.
"Nigba ti Lateef n ṣafihan aworan igba ti awọn obi rẹ domije ayọ loju lori opo Instagram rẹ, o ni ""Iya mi, iya Lati, omije ayọ ni."
Oríṣun àwòrán, AFP Àkọlé àwòrán, Ile Igbimọ asofin yoo se'wadi Banki apapọ lori idiyele owo ti ko t'ọnọ Awọn asofin naa faramọ wipe ki wọn se ijiroro ita gbangba pẹlu awọn alakoso ile-isẹ ifowopamọ to wa lorilẹede Naijiria, to fi mọ Gomina banki apapọ, Gọdwin Emefiele.
Amosun salaye pe, niwọn igba to si jẹ pe ko lee si idagbasoke nibiti rudurudu ba wa, idi ree ti oun fi se agbekalẹ ajọ ẹdawo fun eto aabo nipinlẹ Ogun, Ogun State Security Trust Fund, STF.
Ayinla Ọmọwura, orin èébú àti oríyìn lo fi di ọ̀rẹ́ àwọ̀n obìnrin Wo àwọn nkan tí o le ṣe gẹ́gẹ́ bi aláboyún lásìkò àjàkálẹ̀ ààrùn Covid-19 Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, East Africa: Àwọn kokoro ti ba èrè oko jẹ nílẹ̀ Afirika Lori pe boya ijọba n fi ọrọ lọ wọn ko to o gbe igbesẹ, Duyile sọ pe ijọba kii ṣaba pe wọn, ṣugbọn awọn n ba wọn sọ ni idakọnkọ, ti wsn le tẹle tabi kọ imọran naa.
Gẹgẹ bi agbeyẹwo Ajọ Sub-National Salary Survey ti wọn gbe jade ni Oṣu Kẹsan, 2018 lati ọwọ Ajọ to n tọ pipin bi ijọba se n na owo, BudgIT, ipinlẹ 12 ninu 35 ni ko i tii san owo oṣu awọn olukọ ti wọn jẹ.
Lamido sọrọ yii nibi eto kan ti ijọ Convenant Christian Centre, ti pasitọ Poju Oyemade n dari pe ni ipinlẹ Eko.
ole jija lawujo yii , ni eyi ti eto alaafia yoo se jọba lorile ede Naijiria.
"Yomi fabiyi loju opo instagram ni ""lẹẹkan sii, mo rawọ ẹbẹ si Lizy Anjorin ati Toyin Abraham lati wa ọna fi tete yanju ohun to wa larin wọn."
Chidozie Awaziem (Nantes FC, France); William Ekong (Bursaspor FC, Turkey); Leon Balogun (FSV Mainz 05, Germany); Kenneth Omeruo (Kasimpasa FC, Turkey) and Stephen Eze (Lokomotiv Plovdiv, Bulgaria).
Ipinlẹ Ogun leeyan mọkanla nibẹ, eeyan kan ṣoṣo lo wa lati ipinlẹ Oṣun.
Ohun ni osu kini ọdun musulumi, tawọn musulumi si ma n yago fun ogun jija, itajẹsilẹ tabi itahun sira ẹni ninu oṣu yii.
" Onimọ nipa eto ọrọ aje, Temitọpẹ Kolawole ti salaye ohun ti igbesẹ ijọba tunmọ si fun awọn ọmọ Naijiria.
Ẹ̀yin ará mi olùfẹ́ ọ̀wọ́n, mo fẹ́ kí ẹ mọ nǹkankan: eniyan níláti tètè gbọ́ ọ̀rọ̀, ṣugbọn kí ó lọ́ra láti désì pada, kí ó sì lọ́ra láti bínú.
- Lizzy Anjorin Ẹgbẹ́ òṣèlú PDP, ẹ̀ka ìpínlẹ̀ Eko fún Fayose lọ́jọ́ méje láti bẹ àwọn adarí ẹgbẹ́ Làásìgbò òṣèlú wáyé nílùú Ondo, ọ̀pọ̀ èèyàn fara pa A ti ń bimọ ju ǹkan tí apá orílẹ̀èdè lè ká lọ, ẹ má bí ju méjì, mẹ́ta lọ mọ́ o!
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Deontay Wilder: Wilder ní òun sì ń gba ìtọ́jú lọ́wọ́ lẹ́yìn tí Fury fẹ̀ṣẹ́ já iṣan ọwọ́ rẹ̀ loṣù kejì 11 Ọ̀wàrà 2020 Oríṣun àwòrán, Reuters Iya ko to iya ni ọmọde maa sọ pe ko ni dara fun ẹni to lu oun.
Ọdun to tẹle ni mo ṣe Ija ọmọde.
Ọ̀nà ikú yóò gbà l’óṣe ọ̀tọ̀ọ̀tọ̀
Ọọ̀ni - BBC News Yorùbá BBC News, YorùbáFò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Cancer center: Ọdún 38 ni ìyá mí fi ṣiṣẹ́ ní UCH, màá kọ́ ibùdó ìtọ́jú àrùn jẹjẹrẹ ní ìrántí rẹ - Ọọ̀ni 12 Ẹrẹ̀nà 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 27 Èbibi 2020 Oríṣun àwòrán, Ooni Àkọlé àwòrán, Ọdún 38 ni ìyá mí fi ṣiṣẹ́ ní UCH, màá kọ́ ibùdó ìtọ́jú àrùn jẹjẹrẹ ní ìrántí rẹ - Ọọ̀ni Ọọni tilu Ile Ifẹ, ọba Enitan Adeyeye Ogunwusi, Ọjaja keji ti seleri lati kọ ibudo itọju awọn alarun jẹjẹrẹ sile iwosan nla UCH nilu Ibadan.
Awọn ajinigbe kọ, wọn ko tii kan si idile ọmọ naa lori ohun to ṣokunfa eyi ati ipo ti ọmọ naa wa bayii.
Ó jókòó ninu ọkọ̀ ẹlẹ́ṣin rẹ̀, ó ń ka ìwé wolii Aisaya.
Ki lo de to jẹ pe ẹnikan ti iṣẹlẹ naa soju rẹ lo tu asiri pe ọrẹ rẹ atijọ kan lo fi ọkọ kọlu ọmọbìnrin naa, amọ tile iṣẹ ologun ofurufu kan kede iku rẹ lasan, lai salaye ọna to gba ku fun araye."
Gígùn gbogbo ìyẹ́ kerubu mejeeji jẹ́ ogún igbọnwọ (mita 9).
" Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Hepatitis: A kò leè kóo nípa dídìmọ́ ara ẹni Alarina ọlọpaa fikun pe lara awọn ohun ti wọn gba lọwọ awọn adigunjale naa ni ibọn agbelẹrọ labẹle, aake, ọbẹ meji ati oniruuru oogun abẹnu gọngọ.
Ọ̀fọ̀ ṣẹ̀ Donald Trump, àbúrò rẹ̀ Robert, dèrò ọrun Ibùdó ìyàsọ́tọ̀ ni mo wà, ló fi pẹ́ kí ń tó sọ̀rọ̀ lórí tírélà tó já l‘Eko - Omotola Jalade Ekeinde Alaga ẹgbẹ Ilorin Emirate Youth Development Association naa, Alhaji Abdullahi Salahudeen Babatundesi lo n gbiyanju lati da si aawọ laarin lọkọlaya naa.
Ko gbudọ jẹun nita gbangba loju gbogbo eniyan.
Akume so pe “Olola julo, aare,”A mo ise takun-takun ti e n se lorile ede Naijiria, a mo ife ti e ni si orile ede Naijiria, awa naa si ti setan lati ku fun orile ede wa.
Lara wọn ati awọn ti o n se alamojuto fun eto ifilọlọlẹ wọn ni: Agbarijọpọ ẹgbẹ awọn ọmọ Naijiria (Coalition for Nigeria Movement) Aarẹ Olusegun Ọbasanjọ Ọlagunsoye Oyinlọla Donald Duke Ajọ idasi Isipopada Naijiria(Nigeria Intervention Movement): Olisa Agbakoba Charles Soludo Pat Utomi Yatọ sawọn ogulọgọ ọdọ to peju sibi awọn ifilọlẹ ẹgbẹ alajumọse wọnyi, awọn eekan ọmọ orilẹede yi miran ti n pe fun sise ifilọlẹ awọn ẹgbẹ oselu miran lati dopin aisedeede awọn ẹgbẹoselu APC ati PDP ti o ti wa ni ipo latẹyinwa.
23 Owewe 2020 Oríṣun àwòrán, Getty Images Bo ṣe ku nkan bii oṣu mẹta ki idibo orilẹede Ghana waye, awọn adari oṣiṣẹ alaabo nileeṣẹ ọlọpa ti n rọ awọn ọlọpaa lati ṣe adinku iye igba ti wọn n ni ibalopọ ki wọn lee ṣiṣẹ karakara lasiko idibo.
 Àwọn ìlú tó kù lábẹ ́ Ẹ ̀ gbá aké ni Ìjokò , Ìjẹùn , Ọ ̀ bà , Ìgbẹ ̀ Ìn , Ìjẹmọ ̀ , Ìtọ ̀ kú , imọ ̀ , emẹ ̀ rẹ ̀ , kéesì , kéǹta , Ìrò , erunwọ ̀ n , Ìtórí , Ìtẹsi , Ìkọpa , Ìpóró ati Ìjákọ .
- Yinka TNT Odesola ni : A faramọ titu ẹka ọlọpaa SARS ka, a si gba ẹka Special Weapons and Tactics, SWAT, ti wọn ṣẹṣẹ da silẹ."
Akeredolu ní ọlọ́pàá ń lẹ̀dí àpò pọ̀ pẹ̀láwọn tó ń kó Coronavirus wọ Ondo Ijọba ipinlẹ Ondo ti fẹsun kan awọn agbofinro pe awọn gan n pẹlu ọbọ jawura lori bi iye awọn to ni aarun Coronavirus ṣe n waye ni ipinlẹ naa.
Ṣugbọn ẹnikẹ́ni tí ó bá ń rìn lálẹ́ níí kọsẹ̀, nítorí kò sí ìmọ́lẹ̀ ninu rẹ̀.
"O tun sọ fun wa pe ka fi aṣọ pelebe nu ẹjẹ rẹ, ka si mu u wa fun oun.
 Àwọn àjẹsára tí a mú dára síwájú síi di ohun tó wà fún lílò ọ ̀ pọ ̀ lọpọ ̀ ènìyàn ní àwọn ọdún 1960 .
Jumada- Al Ula: Orukọ oṣu yi waye latari bi ọgbẹlẹ ṣe maa n waye .
Kíni àbájáde ìwádìí nípa báàjì àyà tí àwọn olóṣèlú kan ń wọ̀?
2 Nítorí lõtọ́ ni ohùn Olúwa nkọ sí gbogbo ènìyàn, kò sì sí ẹnikan tí yíò yọ; àti pé kì yíò sí ojú tí kì yíò rí, tàbí etí tí kì yíò gbọ́ tàbí ọkàn tí kì yíò wọnú rẹ̀.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Pẹ̀lú gbogbo bùkátà, Bàbá 80 gboyè Masters Gomina Sanwo-Olu ni oun ko le e sun, ki oun ji pẹlu ero wipe wahala sunkẹrẹ-fakẹẹrẹ ọkọ yoo ti dopin, bẹẹ si ni oun ko le e sun, ki oun ji pẹlu ireti wipe ọrọ sunkẹrẹ-fakẹẹrẹ Apapa yoo ti poora.
Orogun rẹ sare gbe e lọ silewosan lasiko ti wọn n duro de awakọ, amọ o ni ẹpa ko boro.
Iṣẹ́ amòfin tí mo kọ́ ni Fáṣítì kò mú owó wọlé fún mi bíi iṣẹ́ tíátà - Femi Adebayo Àjọ NCDC kéde ènìyàn 381 míràn tó ní ààrùn Covid-19 l'órílẹ̀-èdè Nàìjíríà Àwọn Dókítà fárígá ní ìpínlẹ̀ Ondo, wọ́n ní kí Gómìnà san owó oṣù mẹ́ta tó jẹ wọ́n!
O fikun pe ẹlẹyinju aanu kan, to pe orukọ rẹ ni Hon Obama Oludare Akande lo fun oun ni kẹkẹ tuntun naa fun oun lati orileede Amẹrika.
S National Academies of sciences, Engineering and Medicine) o yẹ ki obinrin maa mu omi lita meji ati kọbu meje, nigba ti ọkunrin gbudọ maa mu omi lita mẹta ati kọbu meje.
Coronavirus: Àjọ bọ́ọ̀lù ní France sún ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ PSG àti Strasbourg síwájú nítorí Coronavirus
Nítorí ẹni tí a bá fún ní nǹkan pupọ, nǹkan pupọ ni a óo retí láti ọ̀dọ̀ rẹ̀.
Má jẹ́ kí ẹnu rẹ mú ọ dẹ́ṣẹ̀, kí o má baà lọ máa yí ohùn pada lọ́dọ̀ iranṣẹ Ọlọrun pé, èèṣì ló ṣe.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Child Mortality in Nigeria: Ìyanṣẹ́lódì àwọn Nọ́ọ̀sì ṣé àkóbá, ìkókó mẹ́jọ kù níléèwòsàn lalẹ ọjọ́ kàn 29 Agẹmo 2020 Ibanujẹ ti dori awọn abiyamọ kan kodo ni orileede Zimbabwe lẹyin ti awọn ọmọ ikoko mẹjọ ku lalẹ ọjọ kan ni ile iwosan.
Ọna lati bọ lọwọ awọn to le mu u lẹru, lo mu ko sa kuro nilu Bida, wa silu Eko lai naani pe ọjọ ori rẹ kere jọjọ.
Nígbà tí ó di òwúrọ̀ ọjọ́ kejì tí a jẹun tán, Baba-onírùngbọ̀n rán mi létí nípa ti àwọn ọ̀rẹ́ rẹ̀ tí ó wí pé kí a lọ kí, ó sì dàmọ̀ràn pẹ̀lú pé ilé Ikú ni kí á kọ́kọ́ lọ, a sì múra a ń lọ.
Atẹjade naa ṣalaye pe ẹgbẹ NUPENG pinnu lati so iyanṣẹlodi naa rọ lẹyin ti ijọba ipinlẹ Eko ṣepade pẹlu wọn.
Leyin eyi ni wọn gba ile ẹjọ to n gbọ ọrọ idibo lọ, ti oriṣiriṣi idajọ si ti n jade.
Bí sánmọ̀ ṣe jìnà si ilẹ̀ tó ni Elétù Òdìbò ṣe jìnà sí Báálẹ̀.
Àwọn onwoye si n sọ pe yiyan ọmọ Afrika si ipo yi yoo mu idagbasoke ba karakata nilẹ naa eyi ti o daduro si ida meji si mẹta idokowo lagbaye.
N óo jẹ́ Ọlọrun wọn,wọn yóo sì jẹ́ eniyan mi.
Àwọn orin báwọ̀nyí, tí a kọ sí orí ìlú reggae àtijọ́ tí a fi àlùjó kún, ṣe kẹ̀rẹ̀kẹ̀rẹ̀ mi ìgboro:
Ijamba ina gbemi eniyan metala ni agbegbe Ho Chi Minh lojo Eti(Friday) ni Vietnamese.
Sugbọn Ọgbẹni Nkrumah sọ pe gbogbo nkan ti Lai Mohammed tọka si kii ṣe otitọ.
7 Kíyèsíi, bí wọn kò bá ní gba àwọn ọ̀rọ̀ mi gbọ́, wọn kì yíò gbà ọ́ gbọ́, ìránṣẹ mi Joseph, bí ó bá ṣeéṣe pé kí ìwọ fi gbogbo àwọn ohun wọnyí hàn wọ́n tí èmi ti fà lé ọ lọ́wọ́.
Bakan naa o ti ba wọn kopa ninu gbigbogun ti isẹlẹ pipa awọn adari orilẹede Naijiria.
Oluwo ti ilu Iwo ni ko si idi meji ti ọpọ awọn ọdọ fi n digba di agbsn wọn gba oke okun lọ bikoṣe iwa ajẹbanu to gogo laarin awsn to di ipo oslu ati iṣejọba mu lorilẹede Naijiria.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Yollywood: Àwọn ayé ló tú èmi àti Iyabo Ojo ká, wọ́n rò pé à ń fẹ́ ara wa ni- Muka Ray 13 Èbibi 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 30 Èbibi 2020 Oríṣun àwòrán, Instagram/Muka Ray Yoruba ni oju kii ri arẹwa ko ma kii, oju to ba sì rẹwa, o di dandan ko pawo wale.
Ọjọgbọn Edeko ni ajọ ASUU ko lẹtọ labẹ ofin lati di oun lọwọ nibi ti oun ba ti n kọ awọn akẹẹkọ, nitori oun kii ṣe ọmọ ẹgbẹ ajọ naa.
Ọwọ́ ibinu rẹ wúwo lára mi,ìgbì ìrúnú rẹ sì bò mí mọ́lẹ̀.
 gege bi isun kan se so , sankara ko so igbagbo re nu ninu esin katholiki botiwu ki ife re o je ninu isemarx .
Lẹyin ti ọpọ nkan ti n ṣẹlẹ lẹyin ti iwadii BBC yii jade ni fasiti Eko ni wọn ti ni ki Boniface lọ rọọkun nile naa titi awọn yoo fi pari iwadii wọn lori ọrọ yii.
Kò sí ẹni tí ó dàbí rẹ, OLUWA, kò sì sí Ọlọrun mìíràn lẹ́yìn rẹ, gẹ́gẹ́ bí ohun tí a ti fi etí wa gbọ́.
Àwọn erékùṣù yóo wárìrì ní ọjọ́ ìṣubú rẹ.
Losu kẹwa ọdún tó kọjá, awọn Dókítà orileede Naijiria, labẹ àsìá ẹgbẹ onimo isegun sapèjúwe ẹgbẹ àwọn oṣiṣẹ ilera Johesu gẹgẹ bii ajo ti ko bofinmu""."
si ile iwosan  Gwarimpa General Hospital
Aare Macron ti fi igbakan wa lorile-ede Naijiria lodun 2002, lasiko ti o wa lenu ikose ni Embassi ile Faranse ti o wa nipinle Eko.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ọmọ ogún ọdún tó fẹ́ràn kí obìnrin ní ìdí ni mí- Sophie 25 Ọ̀wàrà 2019 Oríṣun àwòrán, @Sof Àkọlé àwòrán, Ọpọ ọkunrin lo maa n fẹran ki obinrin ni idi to tobi ni eyi to n jẹ ki awọn obinrin gbe igbesẹ loriṣiiriṣi.
Ninu awọn ilu ti Google pẹka ẹrọ ajuweọna yii de lati ri Abuja, Benin, Enugu ati Ibadan.
amhariki Èdè sẹ ̀ mítíìkì ( semitic ) kan ni eléyìí tí nǹkan bú mílíọ ̀ nu márùndínlógún ń sọ gẹ ́ gẹ ́ bí èdè àkọ ́ kọ ́ ní ethopia ( ìtópíà ) .
Amọ, baba rẹ lasiko to n sọrọ ni agọ ọlọpa sọ wi pe ohun ti bẹrẹ si ni ko ile igbọnse naa, ati wi pe ohun ko le e pẹ kọ tan.
 ní àwọn agbègbè ibití àrùn náà kò ti wọ ́ pọ ̀ rárá , fífúnni ní àjẹsára náà bí a bá ti pé ọmọ oṣù méjìlá bá ọgbọ ́ n mú .
Ọba Ọwa Ale ilu Ikarẹ, Ọba Samuel Kolapo Adegbite-Adedoyin ti rebi agba n re.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Àtíkù: Ọbásanjọ́ kìí se Ọlọ́run tó leè ní kí ń má di ààrẹ 29 Ìgbé 2018 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ọjọ́ pẹ́ tí aáwọ̀ ti wà láàárín Ọbásanjọ́ àti Àtíkù Igbákejì aarẹ tẹ́lẹ̀ ní Nàíjíríà, Àtíkù Abubakar ti kéde pé dandan kọ́ ni kí òun lọ fomí balẹ̀ ní orílẹ̀èdè Amẹ́ríkà, kí òun tó leè di ààrẹ orílẹ̀èdè Nàíjíríà.
15 Èrèlè 2018 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Lẹyin ọpọlọpọ irinajo, Cyril Ramaphosa yoo di aarẹ̀ orilẹ̀ede South Lẹyin ọpọlọpọ awuyewuye, ọgbẹni Jacob Zuma fi ipo aarẹ orilẹede South Africa silẹ ni alẹ ọjọọbọ.
Ipade naa ti yoo waye ni aago mejila ọsan oni lori ẹrọ ayelujara ni Ajọ Iṣọkan Agbaye, (UN ) gbe kalẹ.
Ọba bi ayaba Ẹsita pé, “Ẹsita, kí ló dé?
 o ti ló iríniwó ọdún ṣẹ ́ yìn tie ̀ tò ìjọba náà ti bẹ ̀ rẹ .
Ikoro pari ọrọ rẹ pe, kọmiṣọna ọlọpaa ipinlẹ Ondo ti bẹrẹ ipade pẹlu awọn ẹlẹkajẹka lọna ati wa ojutu si rogbodiyan naa to n rugbo bọ.
    Kí a ma sà fà á gùn lọ títí, iwin inú fìlásayépọ̀ bá mi lọ sí ọ̀dọ̀ obìnrin náà, o lọ kíi fún mi.
 Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ohun tẹ́ẹ gbúdọ mọ nípa kókó orí ọyàn yín lásìkò fífọ́mọlọ́yàn Ṣugbọn eyi ko tumọ si pe gbogbo awa nọọsi ta n ṣíṣẹ kara lo yẹ ki wọn maa tabuku, bi wọn ba ṣe n bu awọn ti ko ṣe daadaa, lo yẹ ki wọn gboriyin fun awa ta n ṣe daadaa lẹ́nu iṣẹ.
O ni awọn ipinlẹ naa ni Ebonyi, Ekiti, Kaduna, Katsina, Eko, Ogun, Ondo ati Oyo.
Ìkọlù sáwọn àjèjì kò tíì tán ní South Africa, ètò ń lọ láti kó ọmọ Nàíjíríà wálé Omíyalé àgbàrà ti ya ṣọ́ọ̀bù ní Niger Wọ́n gbé Akọ̀ròyìn ní Morocco lọ sílé ẹjọ́ lórí ẹ̀sùn àgbèrè àti oyún ṣíṣẹ́ Ìdí rèé ti Nàìjíríà fí ń gbé inú òkùnkùn Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Wọn kò ní rí òkúta kan mú jáde ninu rẹ,tí eniyan lè fi ṣe òkúta igun ilé;tabi tí wọn lè fi ṣe ìpìlẹ̀ ilé,ń ṣe ni o óo wó lulẹ̀ títí ayé.
OLUWA àwọn ọmọ ogun wà pẹlu wa;Ọlọrun Jakọbu ni ààbò wa.
”O tenumo pe,“Oro-ilu nise pelu igbayegbadun ara-ilu, mimu igberu ba eto oro aje ati sise afihan lilo owo-ilu lai ni owo kolofin ninu .
Apejuwe to fẹẹ se rẹgi rẹ lori ọrọ to n sẹlẹ laarin ẹgbẹ osise orileede Naijiria ati Gomina ana fun ipinlẹ Ondo Olusegun Mimiko to ni oun fẹ du ipo Aarẹ Naijiria labẹ asia ẹgbẹ oselu osisẹ,LP.
Gege bi ile-ise eleto idibo se so pe, eto ipolongo ohun yoo waye laarin ojo kerin osu keji si ojo karun-un osu karun-un odun 2018, ti eto ipolongo ohun yoo wa sopin,  nigba ti o ku ojo meji si eto idibo naa.
Ṣugbọn ẹni tí ó bá sá di mí,ni yóo ni ilẹ̀ náà,òun ni yóo sì jogún òkè mímọ́ mi.
34 Fi apákan ohun ìní rẹ fún ni, bẹ́ẹ̀ni, àní apákan àwọn ilẹ̀ rẹ, àti gbogbo rẹ̀ bí kò ṣe ìtọ́jú àwọn ẹbí rẹ.
Atamatase iko agbaboolu Super Eagles, Alex Iwobi ti bowolu iwe ibasepo pelu ile-ise to n ri si ipese ero igbalode LG Electronics, lati je asoju ile-ise naa.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Yemen Water Child: Ọmọdé 44 ni Sọ́jà pa, tí 100 míì sì kú látọwọ́ ohun ìjà olóró Bẹẹ ni awọn eeyan kan n kun kiri pe ilu Eko ni olori Badra wa, to ti bẹrẹ igbe aye tuntun bayii, nitori iriri aye kii ti ni titi, ko ti ni pa, ọgbọn lo fi n kọ ni.
Aisha Buhari: Òlùrànlọ́wọ́ pàtàkì fi orúkọ mi gba owó
Wọ́n sọ ìjọba Juda di alágbára, wọ́n sì ṣe alátìlẹ́yìn fún Rehoboamu ọmọ Solomoni fún ọdún mẹta; wọ́n ń rìn ní ìlànà Dafidi ati ti Solomoni ní gbogbo ìgbà náà.
 Bakan naa lo fi ye won pe ijoba apapo labe aare Mohammadu Buhari ti paa lase fun oun lati gbe eyikeyi ninu osise oloopa to ba sise to laamilaaka ga laifi ti ipo se.
Ẹ̀mí OLUWA ti bà lé mi ní ìrọ̀lẹ́ ọjọ́ tí ó ṣáájú ọjọ́ tí ẹni tí ó sá àsálà náà dé, OLUWA sì ti là mí lóhùn kí ọkunrin náà tó dé ọ̀dọ̀ mi ní àárọ̀ ọjọ́ keji; n kò sì yadi mọ́.
Ó bá ń lu ara rẹ̀ láyà (bí àmì ìdárò), ó ní, ‘Ọlọrun ṣàánú mi, èmi ẹlẹ́ṣẹ̀.
Ọmọde yii bu sẹkun, ti ẹkun rẹ si gbalẹ.
Wọ́n lọ sọ́dọ̀ àwọn olórí alufaa ati àwọn àgbààgbà, wọ́n ní, “A ti jẹ́jẹ̀ẹ́, a sì ti búra pé a kò ní fẹnu kan nǹkankan títí a óo fi pa Paulu.
Oríṣun àwòrán, @Rebecca Àkọlé àwòrán, Iwe eto isinku Baba Okediji ti wọn lo nibi eto isinku naa ni Oyo.
Ọkan lara awọn manigbagbe amuludun nilẹ Yoruba, ti onirese wọn ko fin igba mọ, amọ to jẹ pe eyi ti wọn ti fin silẹ ko lee parun ni Waidi Ayinla Ọmọwura, ti gbogbo eeyan mọ si Eegun Mọgaji.
Oríṣun àwòrán, Image copyrightFLIGHRADAR24 Àkọlé àwòrán, Oju opo ayelujara Flightradar24 se afihan ọ̀na ti baalu naa gba Ẹni naa s'afikun wipe ọsisẹ baalu mẹfa lo wa ninu ọkọ-ofurufu naa.
igbakeji re Onimo ero Rauf Olaniyan nibi ti o oun naa ti seleri lati fowosowopo
Ìran Ibi Nípa Àwọn Ọkunrin Wolii Èké.
Gbaju-gbaja olori ẹsin Islam nilu Kano, Sheik Nazifi Inuwa sọ fun BBC pe iṣẹlẹ naa ko ba ẹsin Islam mu.
"Aarẹ ile asofin agba lorilẹede Naijiria, Bukọla Saraki, ti ransẹ ""ẹ ku isẹ takuntakun"" si awọn ọmọ orilẹede yii mẹta kan ti wọn ngbaradi lati kopa nibi idije olimpiiki ti yoo waye lọdun yin."
 Tí ẹ bá mọ ìbásepọ̀ tí ó wà láàrin àwòrán yìí ẹ sọ fún wa.
Lẹ́hìn tí ó wí báyìí tán, mmo kígbe ńlá, mo ni, ‘Dé ilé ta ni?
Oríṣun àwòrán, Twitter Awọn asofin to ba Gomina ipinlẹ Ondo, Oluwarotimi Akeredolu lọ si Abuja lati lọ gba sabuke lati dije dupo ninu idibo abẹlẹ saaju idibo sipo gomina ni ipinlẹ Ondo.
Ohun ti agbẹnusọ ọlọpaa Femi Joseph sọ nigba naa ni pe arakunrin kan Deji Adenuga lo sọ ina si ile ọrẹbinrin rẹ nitori ti o ni oun ko ṣe mọ.
Mose sì sọ gbogbo nǹkan tí OLUWA rán an fún Aaroni ati àwọn ọmọ rẹ̀, ati fún gbogbo àwọn eniyan Israẹli.
Ṣùgbọ́n ọ̀tọ̀ọ̀ lọmọ́ sorí nípa bí àwọn ènìyàn ṣe n ṣe ìbálòpọ̀ láti orílẹ̀èdè kan sí omíràn.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Chineme Martins: NFF ní àyẹ̀wò gbogbo irinṣẹ́ ètò ìlera ti di dandan báyìí ṣáájú eré bọ́ọ̀lù kankan 9 Ẹrẹ̀nà 2020 Ajọ to n ri si ere bọọlu ni Naijiriia, NFF ti sọ pe dandan ni ṣiṣayẹwo gbogbo irinṣẹ eto ilera awọn ẹgbẹ agbabọọlu bayi ki ifẹsẹwọnsẹ kankan to le bẹrẹ.
feto iroyin ati aṣa ati Minisita abele fun oro epo rọbi.
Nítorí Oluwa Ọlọrun ati Ọ̀dọ́ Aguntan ni Tẹmpili ibẹ̀.
Báyìí  ni Ìjàǹbáforítì sọ tí gbogbo wa dákẹ́ minimini, bí ó sì ti ń fẹ́ẹ́ bá ìddí lọ sí ilẹ̀, ó tún dìde ó kọjú síwa, ó ní Ẹ̀yin ènìyàn wa, à ń lọ lọ́la, ẹ tẹ̀lé mi, n ó ṣe aṣáájú yín ẹ máa di ẹrù, ẹ ṣe ọkàn yín gírí, a ní ènìyàn pàtàkì láàárin wa.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Omotola Jalade-Ekeinde: Olùrànlọ́wọ́ Ààrẹ Buhari fèsì sọ́rọ̀ Omotola 16 Ìgbé 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 17 Ìgbé 2019 Oríṣun àwòrán, Facebook/Omotola Ọgọrọ eeyan lori ayelujara lo ti n fesi sọrọ ti oṣere tiata Nollywood, Omotola Jalade-Ekeinde sọ nipa ijọba Aarẹ Muhammadu Buhari.
Wọ́n yí òkúta dí ẹnu ihò kinniun náà.
Ó yẹ kí á lè rí èsì mú pada fún àwọn tí wọ́n rán wa wá.
Ajọ naa ni oun to wa laarin ajọ naa ati ṣiṣe idanwo fawọn akẹkọọ oniwe mẹwaa lọdun yii ni ilana ti ijọba ba gbe kalẹ ati ṣiṣi awọn ileewe pada.
Odunsanya so pe, oun maa gba oju ona kara-kata orile-ede Ghana ati orile-ede ni gbogbo igba.
O ni Ọlọrun ti fi ẹni ti yoo bori idibo naa han oun ati pe ẹnikẹni to ba gbiyanju ati tọwọ bọ idibo naa lati eru yoo fori ko idajọ Ọlọrun.
"Atẹjade naa salaye pe ""Ijọba ipinlẹ Ọyọ lo n gbọ bukata lori awọn ọkọ ayọkẹlẹ ti ijọba Ajimọbi ra lati osu keji ọdun 2019, amọ ti awọn ọkọ naa ti di awati bayii, irufẹ awọn ọkọ tuntun yii si ni a ko lee sọ pe wọn ko se lo mọ."
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Atiku fẹ́ fa Lauretta Onochie, amúgbálẹ́gbẹ́ Buhari, lọ silé ẹjọ́ fún ọ̀rọ̀ orí Twitter, ó tún bèèrè fún N500m 19 Èbibi 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 20 Èbibi 2019 Oríṣun àwòrán, LAURETTE ONOCHIE Àkọlé àwòrán, Lauretta Onochie Oludije ẹgbẹ oṣelu PDP fun idibo aarẹ to kọja Atilu Abubakar ni oun yoo fa ọkan lara awọn amugbalẹgbẹ Aarẹ Muhammadu Buhari Lauretta Onochie lọ ile ẹjọ ti ko ba san owo itanran fun oun.
adie, eyin, eja abbl lati maa pese losoose.
Yóo ti pẹ́ tó kí àwọn ọmọ Israẹli tó di mímọ́?
 Àjẹsára náà wà gẹ ́ gẹ ́ bí àdàlù pẹ ̀ lú àwọn àjẹsára mìíràn nìkan .
Bi ko ba jẹ bẹẹ, bi wọn ba dagba tan, yoo nira ki wọn to le yi iwa pada'' Gẹgẹ bi ohun ti ọga ọgba naa sọ awọn yoo gbe ilana olopo mta kan kalẹ ti yoo mu ki awn eeyan ma ṣa idọti ati awọn nkan pantiri mi kuro nilẹ ninu ọgba naa.
Lẹ́yìn tí àwọn ọmọ ogun Kalidea ti kúrò ní Jerusalẹmu, nígbà tí wọ́n rí i pé àwọn ọmọ ogun Farao ń bọ̀, 
"Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Nike Davies-Okundaye: Àṣírí tó wà nídìí ìmúra mi Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Nike Davies-Okundaye: Àṣírí tó wà nídìí ìmúra mi 18 Agẹmo 2019 ""."
O pari ọrọ rẹ pe oun jẹ Oba to ni ifẹ ara ilu lọkan nitorinaa, oun ko ni gba ki ẹni kankan wa maa tẹ ẹtọ ara ilu mọlẹ.
Awon asoju ijoba apapo to wa ni be ni Oloye Lai Mohammed to je minista fun ifitonileti, asa ati irin ajo afe, minista fun oro abele, Gomina Ibrahim Geidam to je gomina ipinle Yobe, awon omo ile igbimo asofin ipinle Yobe, oga agba ile iwe naa ati igbakeji re pelu asoju gbogbo obi ati alagbato pelu awon osise eleto aabo atawon miran.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Amole festival in Akure: Deji pàṣẹ kí gbogbo ọjà àti ṣọ́ọ̀bù wà ní títì pa 30 Ògún 2019 Ọdun de, ka jọ maa ṣe amọdun laṣẹ Eledua ni adura awọn eniyan Akurẹ.
Ẹni tí ń rìn pẹlu òótọ́ inú yóo bẹ̀rù OLUWA,ṣugbọn ẹni tí ń rin ìrìn ségesège yóo kẹ́gàn rẹ̀.
 ọmọ ọdún márùn dín ní ọgọ ́ ta ni .
Eyi si lo tako igbagbọ awọn eeyan kan pe ikọ naa ko ni gba owo oṣu.
À ń hùwà ìkà ati ìlara.
Nígbà náà ni ọmọge tí ó ń ṣọ́nà sọ fún Peteru pé, “Ṣé kì í ṣe pé ọ̀kan ninu àwọn ọmọ-ẹ̀yìn ọkunrin yìí ni ọ́?
O sọ a ni lati pawọpọ dẹkun aarun coronavirus ni Naijiria.
Balaamu bá dìde, ó pada sí ilé rẹ̀; Balaki náà bá pada sí ilé rẹ̀.
Kábíyèsì fẹnu ara rẹ̀ tú àṣírí àwọn Fulani Daran daran tó ń ṣọṣẹ́ nílùú rẹ̀ Tacha tọrọ àforíjí, ó da gbogbo ẹ̀bi lé ara rẹ̀ lórí Bàbá ọlọ́mọ méjì kú sínú àgbàrà òjò Ẹ yéé purọ́ kiri!
Eyi dun mọ mi ninu, mo si fẹ ri pe mi o pada si ti tẹlẹ mọ'.
Yollywood: Ẹ wo àwọn ohun tí ẹ kò mọ̀ nípa Mama Rainbow tó pé 77 lóniìí
O jẹ́ ọ̀kan lara awọn olórí ni Afrika to n gba owó ju lọ Oríṣun àwòrán, NIC BOTHMA Àkọlé àwòrán, Abọ iwadi kan sọ pe ìlọpo igba le mọkandinlọgbọn owo oṣu ti oṣiṣẹ n gba ni Cameroon, ni owo oṣu Aarẹ Biya Aarẹ Biya wa lara awọn aarẹ to n gbowo ju lọ ni Afrika.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Wolii Arole Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
 Aare  Muhammadu Buhari tọwọbọ iwe adehun eto
Eleyi da ẹgbẹ agbabọọlu Chelsea pada si ipo kẹrin lori tabili Premier League.
Ṣemaaya bí ọmọ marun-un: Hatuṣi, Igali, Baraya, Nearaya ati Ṣafati.
Wọ́n bá gbé ẹni meji siwaju: Josẹfu tí à ń pè ní Basaba, tí ó tún ń jẹ́ Jusitu, ati Matiasi.
A tun ti ṣe ayẹwo fun ẹgbẹrun mẹrinla eeyan mii nipinlẹ Oyo lati oṣu kejila ọdun 2020 si akoko yii, eeyan mẹrindinlẹẹdẹgbẹrin(696) ni ayẹwo fihan pe wọn larun coronavirus, Makinde ṣalaye.
Ẹfunsetan Aniwura, obìnrin tó ju ọkùnrin lọ Ọ̀rọ̀ǹpọ̀tọ̀niyùn, Aláàfin obìnrin àkọ́kọ́ rèé, tó ní nǹkan ọkùnrin Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí kan sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
Gbogbo nǹkan yòókù tí Ṣalumu ṣe, ati ìwà ọ̀tẹ̀ tí ó hù ni a kọ sinu Ìwé Ìtàn Àwọn Ọba Israẹli.
Kan sí oju opo ajọ National Identity Management Commission [NIMC] tii ṣe www.
gbogbo àwọn ará ìlú ló ń bú wa .
'Tinubu 2023': 'Èmi kọ́ lò rán ẹgbẹ́ 'Asiwaju Reloaded Ambassadors' níṣẹ́ o'
ijoba ohun yoo sa ipa rẹ lati mu gbogbo awon onisẹ ibi, ọlọtẹ,awon onisumọmi
Minista so pe, o ti to igba marun un ti awon igbimo ti se ipade lori oro naa.
Lẹ́yìn náà, ẹ gbé òfìfo ìkòkò náà léná, kí ó gbóná, kí idẹ inú rẹ̀ lè yọ́; kí ìdọ̀tí tí ó wà ninu rẹ̀ lè jóná, kí ìpẹtà rẹ̀ sì lè jóná pẹlu.
Ó gbọ́dọ̀ gba wa ni akoko nítorí ìtàn kíkọ dá bí ipilẹ ilé ni.
Oun nikan ni aarẹ lagbaye ti yoo ka ọrọ apilẹkọ lasiko ayajọ iranti naa ni olu ile ise ICC ni Hague.
" Ṣùgbọ́n Olatunji ni, riro ni ti eniyan, àmọ́ sise ni ti Ọlọrun, torí nígbà tó di ọdún 2017, ní gbajumọ akọroyin orí ayélujára kan, Stella Dimoko-Korkus kesi òun pé, òun ni òun sọ fún Toyin pé kò pé òun, láti máa sisẹ Alarina fun-un, ó ni akoko yii gan an ni àìmọye abawọn si tí tá sì aṣọ ààlà Toyin Abraham.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Cameroon Atrocity, BBC Africa Eye: Ẹwọ́n ọdún méjìlá ni wọ́n fún àwọn sója mẹ́rin tó pa ìyá àti ọmọ méjì ní Cameroon 31 Ògún 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 21 Owewe 2020 Àwọn ọmọ ogun orilẹ̀-èdè Cameroon mẹ́rìn ni wọ́n ti dájọ ẹ̀wọ̀n ọdún méjìlá fún, wọ́n jẹ̀bi ìpànìyàn lásìkò ti wọ́n ń ja ìjà àwọn agbésùmọmí lórílẹ̀-èdè náà.
Ọba bá sọ fún Siba pé, “Gbogbo ohun tí ó jẹ́ ti Mẹfiboṣẹti di tìrẹ láti ìsinsìnyìí lọ.
Ṣé lóòtọ́ ni Afenifere fún àwọn èèyàn ẹ̀yà Igbo ní wákàtí 48 láti fi ilẹ̀ Yorùbá sílẹ̀?
Ilé Aṣòfin Àgbà fòǹtẹ̀ lu N30,000 owó oṣù òṣìṣẹ́ 'CAN kò rán ẹnikẹ́ni lọ ṣọ́ọ̀ṣì COZA, iṣẹ́ ara wọn ní wọ́n lọ jẹ́' Seyi Makinde figbe ta lórí bí Ajimobi ṣe ń ná owó ìlú Alaga ajọ to n mojuto agbekalẹ owo oṣu lorilẹ-ede Naijiria, Richard Egbule ṣalaye pé igbesẹ naa bẹrẹ lẹyẹ o sọko.
Adejare Adeboye: Àwọn kan ní ṣé ọ̀nà láti gba owó oṣù àkọ́kọ́ lọ́wọ́ ọmọ ìjọ kọ́ ní ìkéde ààwẹ̀ ọlọ́jọ́ 63
Bakan naa ni banki apapọ Naijiria naa ti fi ikilọ sita lori eto yii kan naa.
Jíjáde tí mo sì tún jáde pẹ̀lú, ilé Ìbínú-ẹkùn ni mo kọ orí sí.
“Mo ti sọ nǹkan wọnyi fun yín kí ayọ̀ mi lè wà ninu yín, kí ẹ lè ní ayọ̀ lẹ́kùn-únrẹ́rẹ́.
ẹ̀yin náà ti rí ohun tí OLUWA Ọlọrun yín ti ṣe sí gbogbo àwọn orílẹ̀-èdè wọnyi nítorí yín, ati pé OLUWA Ọlọrun yín ni ó jà fun yín.
Kí ló mú kí àwọn èèyàn máa jẹ ọ̀rọ̀ Adeboye lẹ́nu lórí Twitter Èyí ni ọ̀nà tí àwọn obìnrin n gbà kó ara wọn sí wàhálà nítorí ara bíbó Óya gbé bọ́dì ẹ!
Ẹ sá àsálà fún ẹ̀mí yín!
ko lati inu eda iwe to wa lowo awon asoju egbe oselu nitori awon janduku ti dana
'A ko ti i le sọ igba ti ẹgbẹ akẹkọọ (SUG) yoo pada bẹrẹ, nitori pe nkan to kọkọ jẹ wa logun ni eto ẹkọ wọn, kiiṣe ọrọ ẹgbẹ.
Oludari ajo naa so pe ,awon ipinle Kogi, Niger, Delta ati Anambra  ni isele naa pọju sii.
Bakan naa ni awọn miran ni Ọbasanjọ jẹ eniyan ti o máa n sọ wi pe, ade gun loni, ti a tun sọ wi pe ade ko gun mọ lọla.
Kí a má fa ọ̀rọ̀ gùn, òun ìyàwó sì ti yà ní ilé wa láti sọ fún bàbá mi pé ó fẹ́ si àbúrò rẹ̀, ó sì ti lọ sí ilé- oníwòsàn, ṣùgbọ́n òun kò bá wọn nílé.
Bi Fashọla ba lee daruks wọn, awọn sms orilẹede Naijiria yoo lee so wọn mu fun gbigbe owo ilu to yẹ fun akanṣe iṣẹ lori ipese ina manamana sa lọ."
Ida ọgbọn to ku wa lati Malawi, UK, Namibia, eSwatini, ti a mọ si Swaziland tẹlẹ, India atawọn ibo miran.
Ó bá dojúbolẹ̀ níwájú Jesu, ó dúpẹ́ lọ́wọ́ rẹ̀.
Bakan naa ni Abdulwasiu, ti ọpọ eeyan tun mọ si baba Kaosara tun dupẹ pupọ lọwọ ileesẹ iroyin BBC Yoruba fun atilẹyin wa lori ọrọ naa ati ibi taa ba de, eyi to ni apẹrẹ rere.
Òfin Tẹmpili nìyí, gbogbo agbègbè tí ó yí orí òkè ńlá tí ó wà ká gbọdọ̀ jẹ́ mímọ́ jùlọ.
Njẹ́ Alákọ̀wé ò ní wá ọ̀nà ra ọ̀kan báyìí?
"Oríṣun àwòrán, Toyin Abraham ""Lásìkò yìí, ọna bí ẹnì kọ̀ọ̀kan wá kò ṣe ní kú là ń ṣàn, bí a ṣe ye là ń wá, a kò lè owó mọ rárá àbí bá ti tà sinima wá, kódà, èmi àti ọkọ mi kan gbé mọto wa kalẹ ni, lai le lọ síbi kankan, ẹ rí pé èyí lágbára gan ni."
Oríṣun àwòrán, Fatima Muhammad Gẹgẹ bi Abraham Adepelumi, tii se onimọ̀ nipa ayika ni fasiti Obafemi Awolowo ti wi, wọn da adagun omi naa silẹ nitori ọna atijẹ.
‘Àwọn òlóṣèlú kò ní ìwà ọmọlúwàbí ló jẹ́ kí wọ́n má a lọ láti ẹgbẹ́ òṣèlú kan lọ sí òmìràn’ Ọwọ́ ọlọ́pàá ìpínlẹ̀ Kebbi tẹ bàbá àti ìyàwó rẹ̀ méjì fún pé wọn so ọmọ pọ̀ mọ́ ewúrẹ́ fún ọdún méjì Àwọn ǹkan tí ó yẹ kí o mọ̀ nípa 'Sharia Law' ní Nàìjíríà Àmọ̀tẹ́kùn gbéra!
5bn Wo ohun tuntun tó n ṣẹlẹ̀ lágboolé CAF Super Falcons gòkè odò bọ́ sípele ìkẹrìndínlógún ní France Mà á fún àwọn ọba alayé ní ojúṣe nínú ìjọba mi - Seyi Makinde Awọn eniyan APC ni ko ṣeeṣe fun ẹni to n sọ buruku nipa ẹgbẹ to n tukọ Naijiria lọwọ lati tun jẹ igbadun wọn.
Ore ni yoo tun maa ri awon adari orile ede Naijiria  lati ọjọ kọ́kàndínlọ́gbọ̀n osu kẹ́rin titi di ọjọ kẹ́rin
2 mílíọ́nù owó ìtanràn Oríṣun àwòrán, @WillieObiano Bakan naa lo kede ohun mẹta ti oun fẹ gbe ṣe lati ran awọn ọdọ ni ipinlẹ naa lọwọ ninu eyi to ni fifi James Nwafor jofin wa.
Ọmọ a yan eó meka run
Ohun ti pasitọ se yii, to waye lẹba ile ijọsin rẹ ti ko jinna silu Johannesburg, ni ọpọlọpọ ti bẹnu atẹ lu bi fidio naa ṣe tan kakakiri.
"Gẹ́gẹ́ bi o ṣe sọ ọ́ "" Ìwà ọ̀daràn ni ọ̀daràn ń jẹ́, ṣe a lé sọ pé ǹkan tó dára ni adigunjale ṣe, nítori pé ó tòsì tàbi kò lówó?"
Ile ẹjọ ni fun idi eyi, ko buru ti ijọba ba sọ ibudo iṣembaye naa di Mọṣalaṣi.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Uber Boat ṣẹsẹ já ọkọ ojú omi tuntun láti ṣàdínkù súnkẹrẹ fàkẹrẹ ọkọ̀ 11 Ọ̀wàrà 2019 Oríṣun àwòrán, Techcabal facebook Àkọlé àwòrán, Oko oju omi Uber Ile iṣẹ kan ti a mọ si Uber ti bẹrẹ si ni fi ọkọ oju omi ṣiṣẹ bayi ni ilu Eko.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ẹ wo adúrú ǹkan tí Softface ma ń tò pọ̀ láti sín àwọn òṣèré, gbajúgbajà jẹ Afurasi naa ni ẹmi awọn eeyan naa yoo lọ ba babalawo ti o sọ pe o n ran oun yii, ṣugbọn ti baba ko si sọ idi ti o fẹ fi mu ki oun maa pa awọn eeyan naa.
 Eyi ti won ko riru re ni o le ni ogorun un odun seyin.
O si fi idunnu re han pe iko ohun, Plateau United yoo bere si ni n.
Àwọn tí o fún ní ìmísí kò l'ónkà.
kan ṣe maa n kọ mọṣalaṣi si inu ile wọn dipo ki wọn kọ ọ fun ilu lati
Ijọba apapo ti pese owo fun eto ilera, bee ni ileegbimọ asofin agba naa ti buwọlu ofin SADC lati gbogunti ọwọja arun lorilẹede yii.
Ọmọ ogún ọdún tó fẹ́ràn kí obìnrin ní ìdí ni mí- Sophie
7 122685 Orilẹede Armenia 2445 82.
Ṣugbọn ó dáná sun ara ẹran akọ mààlúù náà, ati awọ rẹ̀, ati ìgbẹ́ rẹ̀ lẹ́yìn ibùdó náà, gẹ́gẹ́ bí OLUWA ti pàṣẹ fún un.
Ibi to koju si ẹnikan, ẹyin ma lo kọ si ẹlomiran.
Bákan náà, Jerusalẹmu, bí òpópó ṣe pọ̀ tó ní Jerusalẹmu, bẹ́ẹ̀ náà ni pẹpẹ tí wọ́n fi ń sun turari sí Baali, tí ó jẹ́ ohun ìtìjú, ṣe pọ̀ tó ninu rẹ̀.
”Egbe oselu APC wa gba awon omo Naijiria niyanju lati maa se je ki iwa ibajẹ joba, ki won si jo gbaruku gbogun ti iwa ibajẹ lorile-ede yii.
O tun ni ,“leyin ipade igbimo oloye egbe ULC lojo Isegun niluu Eko
Ninu àwọn ìwé wọnyi, àwọn ọ̀rọ̀ mìíràn le.
Àkọlé àwòrán, Páropáro ni ile olóògbé náà dá nígbàtí akọ̀ròyìn BBC Yorùbá de ilé rẹ̀ Páropáro ni ile olóògbé náà dá nígbàtí akọ̀ròyìn BBC Yorùbá de ilé rẹ̀ tó wà lágbègbè Agodi GRA nílùú Ìbàdàn.
Awijare tileesẹ ologun fisita lori isẹlẹ naa ni pe, awọn ro wi pe ajinigbe lawọn ọlọpaa ọhun, eyi lo jẹ ki awọn dabọn bo wọn.
"To ba wa jẹ pe maalu se iyebiye sawọn darandaran yii bi ọmọ, o yẹ kawọn naa ranti pe ire oko tawọn agbẹ gbin sinu oko wọn naa dabi ọmọ lara wọn.
Wo ohun mẹ́wàá tó yẹ kí o mọ̀ tí o bá fẹ́ lọ fún ìsinmi lẹ́yìn Covid 19 Wo bi wọ́n ṣe n ṣe àmójútó ilé ìjọsìn Prophet Israel Oladele, CCC Genesis Global Seyi Makinde fún olórin Fuji Taye Currency lẹ́bùn ọkọ̀ bọ̀kìnnì Toyota Prado 2020 Ìjọba àpapọ̀ pàṣẹ pé kí gbogbo ọkọ̀ agbépo kúrò ní márosẹ̀ Lagos-Ibadan Ó dájọ́ pé, gbogbo ìlẹ náà ti wọn fi ṣe gáràjì kẹ̀kẹ́ ni agbàgbè náà ti olupẹjọ ti gbé fún ilé iṣẹ́ Gitto Construzioni Generali Nig Limited, agbègbè abúlé Ikot Akpan lo wa ni Etoi ìjọba ìbílẹ̀ Uyo ní ìpínlẹ̀ Akwa Ibom lo wa.
Awon miiran tun ni asofin  Barau Jibrin, APC Kano North; Abdulfata
Lanlẹyin tun fikun pe, oun gẹgẹ bii ẹnikan ko ni nkan se pẹlu adehun ajumọse naa mọ, to ba si wu ẹgbẹ oselu oun, tii se ẹgbẹ ADC, o lee tẹsiwaju pẹlu adehun naa.
A ko yinbọn bẹ si ni ko si ẹni ti ibọn ba tabi to ku'' Fadeyi ṣalaye siwaju pe awọn oluwọde naa fẹ fipa bori awọn ọlọpaa ni ṣugbọn awọn ko gba fun wọn.
Nígbà tí ó di ìrọ̀lẹ́, wọ́n gbé ọpọlọpọ eniyan tí wọ́n ní ẹ̀mí èṣù wá sọ́dọ̀ rẹ̀.
Sugbọn bo ba se jẹ, a ko ni jẹ ki eti yin di nipa isẹlẹ naa.
À ń ṣe èyí kí ẹnikẹ́ni má baà rí nǹkan wí sí wa nípa ọ̀nà tí à ń gbà ṣe ètò ti ẹ̀bùn yìí.
Lẹ́yìn náà, Ṣelumieli, ọmọ Suriṣadai tún ko akọ mààlúù meji, àgbò marun-un, òbúkọ marun-un, ati akọ ọ̀dọ́ aguntan marun-un ọlọ́dún kọ̀ọ̀kan kalẹ̀ fún ẹbọ alaafia.
Bí bẹ́ẹ̀ kọ́, yóo fà ọ́ fún onídàájọ́.
Ẹni ti ọrọ naa ṣoju rẹ sọ pe, Kazeem fi kaadi idanimọ rẹ han awọn agbofinro naa gẹgẹ bi agbabọọlu, ṣugbọn wọn kọti ikun sii.
Bakan naa lo ni wọn ko lee di ohun elo fun sinsin tabi gba gbese pada fun awsn ileeṣẹ.
Ọkunrin náà bá mú mi wá sí ibi gbọ̀ngàn tí ó wà ní ìta, ó mú mi yíká gbogbo igun mẹrẹẹrin gbọ̀ngàn náà, gbọ̀ngàn kéékèèké kọ̀ọ̀kan sì wà ní igun kọ̀ọ̀kan.
Ẹja ati ẹran adiẹ Oríṣun àwòrán, Getty Images ''Jijẹ ẹja bi ẹja abori tabi ẹja crocker yoo ṣeranwọ lati maa sanra ju tabi yọkun,''Adanna lo sọ bẹẹ.
O si ti di ilu mọọka fawọn ipa ribiribi to ma nko ninu awọn ere rẹ.
Ènìyàn kan nínú ẹbí wọn tí kò fẹ́ ká a dárukọ rẹ, sọ pé àwọn kò fẹ́ sọ̀rọ̀ nítorí ọ̀rọ̀ tó kan mọ̀lẹ́bí ni.
Eyi ko si sẹyin aisan ara to ṣee laipẹ yii, to mu ki wọn gbee lọ soke okun fun itọju pẹlu atilẹyin awọn ẹlẹyinju aanu ọmọ Naijiria kan.
Àkọlé àwòrán, #BBCGOVDEBATE: Ẹṣẹ Mẹ́ta ni ètò ìjọba fi lélẹ̀ ní Ogun Ètò ti bẹ̀rẹ̀ ni pẹrẹwu báyìí ní ìpínlẹ̀ Ogun.
Lori boya awọn ajinigbe naa ti bere owo lati fi tu olori naa silẹ, Isah ni ohun ko le fesi si ibeere naa .
Ẹ máa kéde ìgbàlà rẹ̀ lojoojumọ.
Nítorí kò sí ẹnìkan tí ó kórìíra ara rẹ̀.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Àyà mi kọ́kọ́ máa ń já nígbà ti mo ṣẹ̀ṣẹ̀ bẹ̀rẹ̀ -Alaga iduro ọkùnrin Fun ijọba ibilẹ Ogu Bolo, AAC ni ibo 814 nigba ti PDP ni ibo 11855.
Eso Ironu ni awọn meje naa lọ ba awọn ara ilu wọ́n wa ninu igbo irunmole to kun fun iwin, ẹbọra, Olori Igbo, Abami ẹda, ati ọrọ igi.
Oríṣun àwòrán, LASEMA Ṣaaju ni iroyin to n tẹ wa lọwọ bayii n fiye ni pe ọpa afẹfẹ idana gaasi kan ti bẹ lagbegbe Magboro, nitosi ileeṣẹ iwe iroyin Punch lopopona marosẹ Eko si Ibadan.
, Duration 2,1522 Bélú 2020 Èyí tí a wò jùlọ 5:03 Fídíò, Omolola Arohunmolase Welder: Mo ti fí iṣẹ́ 'Welder' gbayì láwùjọ, tó mo fi tọ́ ọmọ yanjú, Duration 5,039 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 5:39 Fídíò, Akomolede ati Asa lori BBC: Olùkọ́ Kikelomo Ogunboye tan ìmọ́lẹ̀ sí ìwà olè ọ̀gá ọlọ́pàá Audu gẹ́gẹ́ bí àwòkọ́ṣe àsìkò yìí, Duration 5,398 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 4:11 Fídíò, Oba Adeyeye Ogunwusi: Ojú mi ti rí lọ́pọ̀ lọpọ̀, ọ̀pọ̀ èèyàn ni kò tilẹ̀ gbàgbọ́ pé mo lè jọba- Ooni, Duration 4,117 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 4:43 Fídíò, Promise Akinlade: ọmọ ọdún mọ́kànlá tó ń fi ìlù dárà bíi àgbàlagbà sọ̀rọ̀ nípa tálẹ́ǹtì rẹ̀, Duration 4,437 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 0:59 Gbọ́, Ìsẹ̀lẹ̀ jákèjádò orílẹ̀èdè àgbáyé láàárín ìṣẹ́jú kan, Duration 0,59wákàtí 5 sẹ́yìn 7:03 Fídíò, Olumuyiwa Bolade Adedeji Military Bruitality: Bí arákùnrin onípèníjà ara tí sọ́jà lù ṣe dé, Duration 7,035 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 4:45 Fídíò, Yoruba Films: Ẹ̀ẹ́ bẹ̀ mi kúrò láyé ni, mi ò lè kú - Fadeyi Oloro, Duration 4,4526 Èrèlè 2020 2:48 Fídíò, Esther Ajayi: Èmi náà ti borí ìṣòro rí ló ń mu mi ṣojú àánú, Duration 2,481 Ògún 2019 6:08 Fídíò, Adebola Ademilua: Àìrísẹ́ ṣè lẹ́yìn ìwé kíkà ló sọ mi dí ìyá onírú, mo dúpẹ́ tèmi, Duration 6,0827 Bélú 2020 5:55 Fídíò, Soyinka Cancer: Àṣe ara mi ni iso ti n run gbogbo bí mo ṣe n ṣèrànwọ́ lórí jẹjẹrẹ, Duration 5,5527 Bélú 2019 BBC News, Yorùbá Ìdí tí ẹ fi le è nígbàagbọ́ nínú ìròyìn BBC Ìlànà Lílò Nípa BBC Òfin Àṣírí Cookies Kàn sí.
Bakan naa ni lati mu igberu ba awon oludokowo oja ipin idokowo ohun Ronke Osundiya.
Lẹyin naa lo n ko koko, rọba, kọfi, ati eso ori lọ soke okun, to si n ko simenti pada wa sile lati ta Gbogbo awọn onibara rẹ lo ni igbẹkẹle nla ninu rẹ, to si tun ri owoya gba lati fi se amugbooro eto okoowo rẹ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Mama Arsenal: Màmá àgbà yìí máa ń lọ sí ìbùdó tí wọ́n ti ń wo bọ́ọ́lù láti wòran Nigba to di ọdun 1960, Henry ti di ọkan lara awọn ilumọọka olokoowo simẹnti eyi to n ko wọle lati orilẹ-ede Egypt ati Poland Ile ifowopamọ kan ni London si lo n fun un ni owoya lati mu ki okoowo naa rọrun, ko si fẹju sii.
Ajo eleto idibo lorile ede Naijiria (Independent National Electoral
Pẹ̀lú ìdásílẹ̀ àwọn akọ̀ròyìn-in Reuters, ẹ̀ṣẹ̀ ní òmìnira ọ̀rọ̀ sísọ ṣì jẹ́ ní Myanmar
Ninu ikede to fi sita lori ayelujara Twitter, Akọwe ikede fun Gomina Babajide Sanwo-Olu, Gboyega Akosile, sọ pe aago mẹjọ alẹ si mẹfa idaji ni isede yoo ma a wa bayii.
Woman who gave birth in Dubai: Nàìjíríà ní Suliyat Abdulkareem fẹ́ bímọ sí ṣùgbọ́n wọ́n há sí Dubai nítorí Coronavirus
Àwọn ọmọ ti Juda ni: Eri, Onani, Ṣela, Peresi, ati Sera, (ṣugbọn, Eri ati Onani ti kú ní ilẹ̀ Kenaani) àwọn ọmọ ti Peresi ni Hesironi ati Hamuli.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Akinyele: Ẹ wo àwọn ọ̀rọ̀ ìkẹyìn tí Alexander Akinyele ṣo kọ́lọ́jọ́ tó dé 15 Bélú 2019 Oríṣun àwòrán, facebook/Alex Akinyele Àkọlé àwòrán, Akinyele jẹ ẹni to fẹran lati ma sọrọ lori ẹrọ ayelujara Ole ko ni ja agba ko ma ṣe e loju firi.
Òun ni ó ṣàn yí gbogbo ilẹ̀ Hafila ká, níbi tí wúrà wà.
Àkọlé àwòrán, Losu keji odun 2018 pelu atunse Dokita Adan ni yoo jẹ idunnu nla fun oun ti ile iṣẹ Aamin ba n pese iranlọwọ ọkọ lasiko kaakiri gbogbo Somalia.
Ẹkún àti ìbànújẹ́ láwọn mọ̀lẹ́bí fi sìnkú ọmọ méje ní Kumba, Cameroon lónìí Ìdájọ́ ikú ló bá dé fáwọn méjì tó fipá bá ọmọ ọdún mẹ́rìnlá lò pọ̀ Afẹ́fẹ́ gáàsì sí gbiná ní Ijora ìpínlẹ̀ Eko, bó ṣe n ṣẹlẹ̀ rèé Awọn oṣiṣẹ ajọ to n ri si iṣẹlẹ pajawiri ni ipinlẹ Eko, LASEMA ti de ibi iṣẹlẹ ina naa ti wọn si n gbiyanju lati pa a.
Dogara sisọ loju ọrọ yii lasiko to n ba BBC sọrọ lati ipasẹ amugbalẹgbẹ rẹ feto iroyin, Turaki Hassan.
Atẹjade RRS kan ni ọwọ tẹ afẹsunkan naa Hassan Abubakar ẹni ọdun mejilelọgbọn nigba to n wa ọkọ akẹru kan to fi ko apo simẹnti mọkanlelogun ni bi aago marun aabọ aarọ nigba ti awọn n kaakiri adugbo naa.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Barister lo bi gbogbo oníṣẹ́ fújì -Oṣupa Sikiru Ayinde lọ si ile ẹkọ alakọbẹrẹ Muslim Mission School, ati Model School ni Mushin, nipinlẹ Eko.
Dafidi ọba bá ní kí wọ́n pe Batiṣeba pada wọlé.
OLUWA sin ín sí àfonífojì ilẹ̀ Moabu tí ó dojú kọ Betipeori, ṣugbọn ẹnikẹ́ni kò mọ ibojì rẹ̀ títí di òní olónìí.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Ighalo ti gba goolu marun un wọ le bayii lati igba ti idije AFCON 2019 ti bẹrẹ.
won se ise won pelu otito inu lati se akojopo eto bi isipo-ropo yoo se lo pelu
Kí á fi ìfaradà sá iré ìje tí ó wà níwájú wa.
 Èdè yìí jẹ ́ ọ ̀ kan lára àwọn èdè ìjọba mọ ́ kànlá ilẹ ̀ south africa .
Ibadan Chieftancy Tussle: 'Ọba Balogun ní Olubadan kò le è lé àwọn kúrò nílùú láéláe
Bí bẹ́ẹ̀ kọ́, kí alaafia tí ẹ ṣe kí ó pada sọ́dọ̀ yín.
Ayẹyẹ igbeyawo melo ni Aarẹ Buhari lọ latigba to ti gori oye?
Nítorí àwọn alágídí pọ̀, tí wọn ń sọ̀rọ̀ asán, àwọn ẹlẹ́tàn, pàápàá jùlọ lára àwọn ọ̀kọlà.
Obinrin ẹlẹwa yii mọ ounjẹ naa se debi pe awọn eeyan maa n pe biba sọdọ rẹ lati du ẹwa rẹ ra ni.
Bakan naa lo sọ pe Ọlọrun sọ fun oun pe awọn ipo ti oun ti de ṣaaju wa lati mu oun dide fun ipo aarẹ lọdun 2019, ohun ti o wa n fa ibeere bayii ni boya ohun Ọlọrun naa ti yipada?
Ẹni tí ó bá rí aya fẹ́ rí ohun rere, ó sì rí ojurere lọ́dọ̀ OLUWA.
“Bí mo ṣe mú gbogbo ibi ńlá yìí bá àwọn eniyan wọnyi, bẹ́ẹ̀ ni n óo ṣe mú kí gbogbo ohun rere tí mo ti ṣe ìlérí fún wọn dé bá wọn.
Ajọ JAMB fun osisẹ n'iwe lọ gbe'le ẹ JAMB f'ọjọ kun asiko iforukosilẹ Awọn nnkan miran wo ni o lero wipe ejo le jẹ?
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ìgbátí ìgbámú àná látọwọ́ sọ́jà obìnrin ti bá arákùnrin náà dé iléèwòsàn Oṣiṣẹ INEC meji sọnu nibi atundi ibo ile igbimọ aṣofin ipinlẹ Zamfara ti ko fẹnu ko Ajọ INEC ti kede pe atundi ibo ile igbimọ aṣofin ipinlẹ Zamfara ọjọ Satide ko fẹnu ko sibi kan.
Kí alufaa yẹ̀ ẹ́ wò, bí ibìkan bá wú ní ara rẹ̀, tí ó funfun, tí ó sì sọ irun ọ̀gangan ibẹ̀ di funfun, bí ibi tí ó wú yìí bá di egbò, 
Ẹ̀wẹ̀ ìjọba ti fi orilẹ̀-èdè Sweden àti Austgria si àra àwọn orilẹ̀-èdè ti wọ́n ti fi ofin de láti ma wọ Naijiria mọ.
Ki ni orukọ rẹ, nibo si ni onitọun wa lọwọ lọwọ?
Ti adajọ ko ba si ṣe iwadi daada ko n i mọ.
Ọmọ Bàbá Sala: Àwọn ènìyàn fẹ́ran Baba nìtorí apanilẹ́ẹ̀rín ni wọ́n
Àwọn tó ń sanwó orí ti rúgọ́gọ́ sí lábẹ́ ìjọba Buhari
Saulu ní, “Ẹ ṣẹ́ gègé láàrin èmi ati Jonatani, ọmọ mi.
gbogbo omo ile kaaro-oojiire lapapo fun iwa to tako asa ati ise ilu Ibadan.
Àwọn akẹ́kọ̀ọ́-bìnrin Naijiria fẹyin US ati China gbolẹ nidije ìmọ ẹrọ Àwọn ọ̀nà tí obìnrin fi le gbádùn ìbálòpọ̀ Serena fẹ ṣe idije tennis ni Afirika Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Oun idunu ni aseyọri yi jẹ fun Naomi Osaka Lẹyin pe a mọ wi pe o je ọmọ orileede Japan kini awọn nkan miran ti oi ye ki ẹ mọ nipa ọmọdebirin yi?
A ti yí ayé pada bí amọ̀ tí a fi òǹtẹ̀ tẹ̀,ati bí aṣọ tí a pa láró.
 'Okù 11 ni mo rí níbi tí iléeṣẹ́ ológun àti ẹgbẹ́ Shiite ti kọlu ara wọn' Aṣòfin ìpínlẹ̀ Èkìtì tí wọ́n yìnbọn fún ti dolóògbé Minimum wage: Kí ló fàá tí owó oṣù tuntun fi ṣòro?"
Ilé ẹ̀jọ́ tún pàṣẹ pé ẹnikẹ́ni tó bá nífẹ̀ẹ́ láti ra àwọn dúkìá náà gbọ́dọ̀ yọjú láàárín ọ̀sẹ̀ méjì péré
Agbẹnusọ ọlọ́paàá tún rọ ará ìlú láti ran ọlọ́pàá lọ́wọ́ láti jẹ́ ki àwọn mọ́ ti wọn ba kofìrí rẹ̀, ibi ti ó ń rìn sí kí gbogbo àṣírí tó wà nídìí ọ̀rọ̀ náà le ba tú.
Gbogbo wọn yoo fọwọsọwọpọ pẹlu àwọn oṣiṣẹ eleto aabo to ku lati pese eto aabo to ye fawon olugbe ipinle Oṣun lasiko yii.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: 'Àgbàrọ́ òjò wọ́ ọmọ méjì lọ ní Ketu l'Eko lálẹ́, a ṣì ń wá wọn di òní' Mo le búra pé kò sí ìbáṣepọ̀ láárin Olorì Badrat àti Wasiu Ayinde - Olori Folashade Nàíjíríà ti pín yẹlẹyẹlẹ láyé Buhari, ìjákulẹ̀ dé!
"O ni wiwa nibẹẹ awọn adari yii lee ṣeranwọ lati yanju ọrọ to wa nilẹ - ""boya ipo wọn gẹgẹ bii adari nilẹ Afirika lee mu ki wọn gbọrọ si wọn lẹnu ki alafia si jọba ni Mali."
olopaa niluu Abuja, ti bale sipinle Jalingo, ti n se olu-ilu ipinle Taraba, lati
Dabiri-Erewa, lo pe ipe yii lasiko apejẹ ti won se fun awon asoju omo egbe  APC to n gbe niluu okeere , ni eyi to waye
Ṣaaju ni igbimọ ẹgbẹ oṣelu APC to n ṣayẹwo awọn oludije nipinlẹ Edo ti wọn yọ ọ kuro lara awọn oludije fun ipo gomina ninu idibo abẹle to n bọ.
Wò ó, àwọn orílẹ̀-èdè dàbí ìkán omi kan ninu garawa omi, ati bí ẹyọ eruku kan lórí òṣùnwọ̀n.
Dárí ẹ̀ṣẹ̀ wa jì wágẹ́gẹ́ bí àwa náà ti dárí ji àwọn tí wọ́n ṣẹ̀ wá.
Pásítọ̀ gún ìyàwó rẹ̀ lọ́bẹ nínú ṣọ́ọ̀ṣì, ló bá tì í bọ ara rẹ̀ náà níkùn Ènìyàn 241 tuntun ló ti lùgbàdì àrùn Coronavirus ní Ọjọ́ Ìṣẹ́gun ní Naijiria Nǹkan oṣù obìnrin le jáde ní imú tàbí ìdodo yàtọ̀ sí ojú ara - Dókítà Ṣé lóòtọ́ ni òjòjò dá Abiola Ajimobi wólẹ̀?
Ìpínlẹ̀ Oyo àti Eko kò nífẹ̀ẹ́ láti gba 'Ruga Settlement' láyè Ọwọ́ tẹ awakọ̀ tó ń ra ọjà olè Biodun Fatoyinbo fi ipò sílẹ̀ lorí ẹ̀sùn ìfipábánilòpọ̀ Seyi Awolowo, ọmọ-ọmọ Awolowo, kí ló ń wà lórí ètò BB Naija?
Òkúta iyebíye oríṣìíríṣìí ni wọ́n fi ṣe ìpìlẹ̀ odi ìlú náà lọ́ṣọ̀ọ́.
Akogun nla nilu Ẹwẹ, lori ipo rẹ to kan lo ti ni orukọ to di gbajugbaja gẹgẹ bi olori ọmọ ogun oju ofurufu ilẹ Egypt ati minisita fun eto abo.
Pasitọ naa sọ pe kii ṣe ẹbi awọn ọdọ to n gunle iwọde End SARS nitori ohun ti oju wọn n ri lọwọ awọn ọlọpaa ko ṣee fẹnusọ.
Ẹ níláti máa rú ẹbọ àjọ ìrékọjá sí OLUWA Ọlọrun yín láti inú agbo mààlúù yín, tabi agbo aguntan yín, níbi tí ó bá yàn pé kí ẹ ti máa sin òun.
Ibẹ si lo wa ti ọkọ rẹ akọkọ tun fi n fa oju rẹ mọra.
Naijiria ti won ko mowo mese.
Ó kọ́ ọ bí wọ́n tí ń ṣe ọdẹ,ó sì ń pa eniyan jẹ.
Demilade nínú fídíò yìí sọ fún BBC Yorùbá pé gbogbo ìgbà tí òun bá ń fọn fèrè ni inú òun máa ń dùn.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ẹgbẹ́ awakọ̀ Ekiti fẹ́ pa ìjọba dà lẹ́yìn tí Fayẹmi di gómìnà 30 Ọ̀wàrà 2018 Oríṣun àwòrán, Lere Olayinka/Facebook Àkọlé àwòrán, 'Níṣe ni wọ́n fọ́n sí àárin ìlú, tí wọ́n sì bẹ̀rẹ̀ sí ni fi oríṣiríṣi nkan ìjà olóró bá ara wọn jà.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, O kọrin niwaju gbogbo alagbara Amerika nigba ti Obama di aarẹ.
Èmi kò fi ìròyìn ìrànlọ́wọ́ ìgbàlà rẹ pamọ́.
Kòbákùngbé ìfèsì ọ̀rọ̀ láti ẹnu àwọn akẹ́kọ̀ọ́ tí ó ń gbé ní òkè òkun gbùngbùn òkè-odò China.
E kú ìfé Èdè àti Àsà Yorùbá lára mi o.
Ṣugbọn Saulu ti mú Mikali, ọmọ rẹ̀ tí ó jẹ́ iyawo Dafidi, ó ti fún Paliti ọmọ Laiṣi tí ó wá láti Galimu pé kí ó fi ṣe aya.
Nígbà tí àwọn olórí alufaa ati àwọn amòfin gbọ́, wọ́n ń wá ọ̀nà tí wọn yóo fi pa á.
Owo ti wọn ni ijọba gbe jade yii ko ja mọ ohunkohun ninu ohun gan an ti a n beere.
Ó bá tún pe àwọn ọmọ-ẹ̀yìn mejila sí apá kan, ó bẹ̀rẹ̀ sí sọ àwọn ohun tí yóo ṣẹlẹ̀ sí òun fún wọn.
ní agbègbè congo ( zaire ) ni a tin í àwọn ẹ ̀ yàn woyo .
“Kò sí ẹni tí ó lè sin oluwa meji.
Algeria, adajọ lasẹ lati da awon eniyan ti won fẹsun kan silẹ tabi ki won wa ni
Owo ori ilẹ ati ọkọ ti wọn sọ wipe gbogbo awọn to ni ile yoo ma san lati mu igbayegbadun ba awọn ara ilu ati fun ipese ohun amayedẹrun.
Wo díẹ̀ lára àwọn ọ̀rọ̀ ìkẹyìn ti Alexander Akinyele fi léde kó tó papódà Tani Victor Boyle-Komolafe to fẹ gba Ami Ẹyẹ 2020 Africa Price?
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Lockdown the world: Awọn ọmọ Nàìjíríà káàkiri àgbáyé sọ ìrírí lábẹ́ àṣẹ kónílé-ó-gbélé Iku ọwọọwọ ni Kano n kọ ọpọ lominu.
Ẹ gbọ́ igbe àwọn eniyan mijákèjádò ilẹ̀ náà tí wọn ń bèèrè pé,“Ṣé OLUWA kò sí ní Sioni ni?
Saraki ni ifura wa pẹlu ọwọ́ wara-n-ṣeṣa ti wọn fi sare gbe ẹjọ naa kalẹ paapaa nigba ti ọpọ ẹjọ ti wọn ti pe fun ọpọlọpọ oṣu n bẹ nilẹ ti wọn ko fi ọwọ kan.
atejade kan ti won fi sowo si minisita ohun lati ile ise to n mojuto eto aabo
Adams Oshiomole ní ààrẹ Buhari pe òun sínú ẹgbẹ́ APC gẹ́gẹ́ bi alága láti ṣe àtúntò ẹgbẹ́ ní, àti pé ààrẹ Buhari kan náà ló lo oyé rẹ̀ láti gbárúkù ti bi wọn ṣe tú ìgbìmọ̀ amúṣẹ́ṣe náà ká.
OLUWA ní, “Ẹ wá sí Bẹtẹli, kí ẹ wá máa dẹ́ṣẹ̀ níbẹ̀, kí ẹ sì wá fi ẹ̀ṣẹ̀ kún ẹ̀ṣẹ̀ ní Giligali; ẹ máa mú ẹbọ yín wá ní àràárọ̀, ati ìdámẹ́wàá yín ní ọjọ́ kẹta kẹta.
Asán ni èyí, ìpọ́njú ńlá sì ni.
"O ni ""A ti ṣagbeyẹwo ofin to de kẹkẹ maruwa ati ọkada, agbofinro to ba wọ aṣọ iṣẹ to si n wa alupupu rẹ nikan la gba laaye lati lo lawọn ibi ti a fofin de."
Má hú ohun tí àwọn baba ńlá rẹ rì mọ́lẹ̀,tí wọ́n fi pa ààlà kúrò.
Ọlọ́pàá kó àwọn ọmọ ẹgbẹ́ òkùnkùn Ẹiyẹ Confraternity ni Ikorodu Akitiyan ìjọba láti mú kí àwọn ọmọ Nàìjíríà san owó orí Ó lé ní ẹ́gbẹ́ta àwọn ọmọ Naijiria tí wọ́n ti ṣetàn láti padà sílé!
Ẹni tí a bá bí ní bíbí ti Ẹ̀mí, ẹ̀mí ni.
Bayii, ọpọ awọn obinrin wọn lo ti n kawe sii ju ti tẹlẹ lọ ni eyi to ti n jẹ ki awọn obinrin yẹ awọn ofin igbeyawo ti ko fun wọn layọ wo.
Porn Sites 2019 in Retrospect: Njẹ́ ẹ mọ̀ pé orílẹ̀-èdè Nàìjíríà ló n wo 'Blue film' jù?
Ṣugbọn Jesu mọ èrò ibi tí ó wà lọ́kàn wọn.
 Oga agba ile ise oloopa ni ipinle Oyo, Shina Olukolu wa
O lo ọdun mẹjọ nile aṣoju-ṣofin, mẹjọ nile aṣofin agba, mẹjọ gẹgẹ bii igbakeji aarẹ.
"O jẹ ibanujẹ pe ijọba apapọ kuna lati dahun ibeere awọn oluwọde naa, eyi to mu ki iwọde alalaafia di itajẹ silẹ, didana sun dukia ati kiko sọọbu awọn eeyan.
Wayi o, egbe awon olootu naa tun menu ba eto aabo to mehe lorile-ede yii, ti o si ro awon toro kan ati ile-ise alaabo lorile-ede yii lati wa ojutu si oro naa lai pe.
Mo wa rọ awọn ololufẹ wa pe aikawe kii ṣe arun, ki wọn ye ma yẹyẹ wa tabi fa ila si asise wa ninu oyinbo.
awon ohun amayederun , ti o ti denukole , ti aare ti bere ti n se ise lori rẹ,
Farao, pẹlu ogunlọ́gọ̀ àwọn ọmọ ogun rẹ̀, ati ọpọlọpọ eniyan rẹ̀, kò ní lè ràn án lọ́wọ́ nígbà ogun; nígbà tí ogun bá dótì í, tí wọ́n sì mọ òkítì sí ara odi rẹ̀ láti pa ọpọlọpọ eniyan.
Baba agbẹ ẹni ọdun mọkanlelaadọrin naa ti wọn pe orukọ rẹ ni Eric Olowokande ni awọn ọlọpaa ṣalaye pe o fi ẹṣẹ lu iyawo rẹ, ti orukọ rẹ n jẹ Mojere.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Amọ ṣa, ẹgbẹ CAN ni ọrọ ọhun ku sọwọ awọn eeyan to ba n lọ sawọn ile ijọsin kọọkan.
Ronaldo ati Messi jọ dabira ninu idije La Liga nibi ti wọn ti jọ gba ami ẹyẹ loriṣiiriṣii fun ẹgbẹ agbabọọlu wọn, Real Madrid ati Barcelona ki Ronaldo to darapọ ikọ Juventus.
of the games he played for Nigeria at the tournament and told the handlers of
Nibayii, awọ̀n olufẹ̀honu han naa ti wa ni ọọfisi ọga agba ọlọpaa.
Awọn iroyin ti ẹ le nifẹ̀ si: Dòdò Ìkirè dúdú sùgbọ́n oyin ni Ipenija oju kii ṣe idena si atijẹ Yomi Lanso wipe ka jọ gbadun laye Ope Aiyeọla: Nkan to pa emi ati Baba Suwe pọ Irun gígẹ̀ kọjá orí fífá lásán Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí kan sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
0 632 Erekusu Faroe Island 0 0.
Kini ijọ Deeper Life sọ lori ẹsun yii?
Nibẹ ni Hajiya Halima naa ti kẹkọ imọ nipa Qur'an ati Hadith Awọn mọlẹbi rẹ ṣalaye fun BBC news pe lẹyin ọjọ mẹrin ti aisan ti daa wolẹ lo jade laye.
Igbesẹ Kẹfa: Lọ yẹ apo iwe atẹranṣẹ ori ayelujara rẹ ti a mọ si Email wo ki o si kọ number to ba firanṣẹ sibẹ ti oo lo lori ayelujara naa.
Ó ní tí a bá fi ọwọ́ ìtún bamọ wi, o di dandan ki a fi ọwọ́ òsì fàá mọ́ra nítori náà òun fẹ́ fún ni mílíọ̀nù kan náírà.
Ilu Ilorin nipinlẹ Kwara ni wọn ni Biodun Fatoyinbo ti da ẹsẹ naa ni nnkan bi ogun dun sẹyin amọ lọwọ bayi ilu Abuja lo fi ṣe ibujoko.
Nítorí náà, gbogbo eniyan bẹ̀rù rẹ̀,kò sì náání àwọn tí wọ́n gbọ́n lójú ara wọn.
Eyi ti mu ko jẹjẹ atilẹyin fun awọn ẹlẹsin to fibo wọn gbe e wọle.
Alhaji Yasin ni awọn yoo ṣepade pẹlu gomina Makinde laipẹ lati wa ojuutu si ọrọ naa.
 iceland je agbese lileru ati loro-ile .
Ninu ọrọ rẹ, Aarẹ Trump ni orilẹede to ba ni agbara lagbaye kii ja ogun ti ko nidi.
Ẹ fẹ́ràn OLUWA, gbogbo ẹ̀yin olódodo,OLUWA a máa ṣọ́ àwọn olóòótọ́,a sì máa san àlékún ẹ̀san fún àwọn agbéraga.
O ní ẹsẹ ti àwọn ile iṣẹ yii sẹ jẹ oríṣiriṣi, sùgbọn kò kéré sí àwọn ilé ìròyìn tó wọn jẹ ki wọn fi ilé iṣẹ́ wọn tẹ́ pẹpẹ èèbu àti sisọ àwọn ọ̀rọ̀ alufansa.
Bi nkan ṣe ri yii, o ṣeeṣe ki Nyame to jẹ ẹni ọdun mẹtalelọgọta bayii o pe ẹni ọdun mọkanlelssdọrun ko to ṣẹwọn tan.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Tẹ̀gbọ́n-tàbúrò gé orí ọmọ aládùúgbò torí ₦200,000 owó ìkómọ Ìgbà tí Aisha Buhari ti f'ọ̀rọ̀ da ìgboro rú lórí ìjọba ọkọ rẹ̀ Ẹ má bẹ̀rù àgbára ìjọba àpapọ̀, ànàbolẹ̀ ni PDP yoo nà APC - Saraki O ni aibọwọ fun ẹtọ araalu gan ni eku ẹda to da eyi silẹ lori wahala ipenija abo lorilẹede Naijiria ni lọwọlọwọ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù AFCON 2019 final: Kọ̀lọ̀kọ̀lọ̀ Algeria là kìnìún Senegal mọ́ lẹ̀ lẹ́ẹ̀kejì gba ife 19 Agẹmo 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Ikilọ kẹlẹgbẹ mẹgbẹ rẹ ni ẹgbẹ agbabọọlu Algeria fi ifẹsẹwọnsẹ aṣekagba idije AFCON 2019 ṣe fun ikọ Senegal lẹyin ti wọn rọ ojo iya le wọn lori lẹẹkeji ti wọn si gba ife ẹyẹ AFCON mọ wọn lọwọ.
nítorí pé Iṣimaeli ọmọ Netanaya ti pa Gedalaya, ọmọ Ahikamu, tí ọba Babiloni fi ṣe gomina ilẹ̀ náà.
Gbogbo àkọ́bí yín lọkunrin, ni ẹ gbọdọ̀ rà pada.
mo búra pé, a óo pa ilẹ̀ Moabu run bí ìlú Sodomu, a óo sì run ilẹ̀ Amoni bí ìlú Gomora, yóo di oko tí ó kún fún igbó ati ihò tí wọ́n ti ń wa iyọ̀, yóo di aṣálẹ̀ títí lae, àwọn eniyan mi tí ó kù yóo kó àwọn ohun ìní wọn tí ó kù.
Àsikò Epo-rọ̀bi ni ilú fi irẹsi òkèrè dipò oriṣiriṣi oúnjẹ ilẹ̀ wa.
A ti rán àwọn èèyan wa lọ́ sí àwọn ibi tí wọ́n kọlù.
Buhari ń fowó aráàlú gbàtọ́jú nílùú òyìnbó nígbà táwọn ilé ìwòsàn wa ti di mọ́ṣúárì - Falana Ojo ni ohun to ṣe ni laanu ni pe ọpọlọpọ ninu awọn obi naa ko mọ wi pe ohun ti wọn ṣe ko dara.
A sì tún mú owó mìíràn lọ́wọ́ pẹlu láti ra oúnjẹ.
WHO ṣe lara awọn eeyan ẹgbẹrundinlọgọta fi han pe: 6% ṣaisan naa gidi -ẹdọforo wọn kọṣẹ, ẹya ara wọn kan ko ṣẹṣẹ daadaa leyi to le yọri si iku.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, coronavirus prevention badge update: Wo òótọ́ àti irọ́ tó wà nínú báàjì àyà náà A máa ná N10.
Awọn ileesẹ ọlọpa ni lootọ ọwọ ti tẹ arakunrin afurasi ọdaran naa ti wọn si ti fi oju rẹ faraye ri nilu Abẹokuta, tii se olu ilu ipinlẹ naa l'Ọjọọbọ (Thursday).
Sani El-katuzu - Ọmọ ẹgbẹ́ 8.
Ṣugbọn bí wọn bá pa ẹnikẹ́ni ninu àwọn tí wọ́n wà ninu ilé pẹlu rẹ, ẹ̀jẹ̀ rẹ̀ yóo wà lórí wa.
Ominira yii lo ṣi oju awọn ọdọ agbegbe miran si ọna abayọ iṣoro to n koju koowa ni abule wọn to sọ wọn di ẹru labẹ awọn adari amunisin gbogbo.
Ṣugbọn bí àrùn ẹ̀yi yìí bá bẹ̀rẹ̀ sí i tàn káàkiri lẹ́yìn ìwẹ̀nùmọ́, 
Yàtọ̀ sí ikọ àgbábọọlu Nàìjíríà, Kanu ti gbá bọọ̀lù fún ikọ̀ mẹ́fà, Nwuanyanwu National, Ajax, Inter Milan, Arsenal, West Bromwich Albion àti Portsmouth, ó si gbá bọ́ọ́lù mẹ́jìdínláàdọ́fa sáwọ̀n.
Òrùka aṣọ ìgbàyà yìí ni wọ́n fi dè é mọ́ òrùka ara efodu pẹlu aṣọ aláwọ̀ aró tẹ́ẹ́rẹ́ kan, kí ó lè sùn lé àmùrè efodu náà tí wọ́n ṣe iṣẹ́ ọnà sí lára, kí ìgbàyà náà má baà tú kúrò lára efodu, gẹ́gẹ́ bí OLUWA ti pàṣẹ fún Mose.
iṣuna owo ọdun 2019 yii, a fi ohun ti awọn ara ilu n fẹ sọkan lati pese
Ọmọ Yorùbá mẹ́wàá tó jẹ́ àmúlùúdùn ní Amẹ́ríkà àti Yúróòpù Wo iye ìgbà tí wọ́n ti wọ́gilé ayẹyẹ ọdún ilẹya ní ìpínlẹ̀ Kano Àwọn alágbára ni mo bá díje ṣùgbọ́n mo ti gbà f'Olọrun- Agboola Ajayi O ti lé ní ènìyàn mẹ́wàá tí ina jó gúrúgúrú nínú ìjàmbá tó wáyé ní Delta O yẹ ki aarẹ orilẹede Ghana, Nana Akufo Addo ati ti orilẹede Côte d'Ivoire naa, Alassane Ouattara wa nibi ijiroro naa.
” Ó bá sọ ohun tí Jesu sọ fún un fún wọn.
Ipinlẹ Borno ni awọn ikọ agbebọn Boko Haram yii kan naa ti sọsẹ ni ọdun 2014 ti wọn ko awọn akẹkọbinrin to le ni igba nileewe kan ni ilu Chibok.
 Ìjìnlẹ ̀ èdè yorùbá ni ònkọ ̀ wé náà fi kọ ìwé náà , tí ó sì gbé ìtàn rẹ ̀ lé orí ìtàn gidi tí ó sì jẹ ́ ojúlówó ìtàn ilé yorùbá .
Dokita Daware soro yii lasiko to n ba awon akoroyin soro  lori pataki itoju oju de asiko ojo ogbo.
    Mo ò pé ẹ̀yin náà ó wá rí i, nípa gbogbo srs tá mo sọ yìí, irú ipò tí ẹ wà, lọ́kàn mi, mo sì bẹ̀ yín tọkàn tọkàn wí pé kí ẹ máṣe bínú láti gbọ́ ọ̀rọ̀ tí n ó ba a yín sọ nípa irú ipò tí mo wà yìí.
Kí o wí pé, ‘Ti Jakọbu iranṣẹ rẹ ni, wọ́n sì jẹ́ ẹ̀bùn tí ó fi ranṣẹ sí Esau oluwa rẹ̀, òun alára ń bọ̀ lẹ́yìn.
 Ọgbẹni Ọlọpade ṣalaye siwaju nibi idije naa pe ọpọlọpọ awọn eniyan to wa nibi ayẹyẹ iṣide ere idije yii ni Ile-iṣẹ Rite pese jijẹ mimu fun nibẹ, ti wọn si pese ọpọlọpọ ọti ẹlẹrindodo ati awọn ounjẹ ipanu oyinbo fun awọn ọmọde to wa nibi idije yii.
Agbegbe Iju Ishaga ni ipinlẹ Eko ni isẹlẹ naa ti waye ni nkan bii aago meje ku isẹju mẹẹdogun owurọ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Lagos-Ibadan Expressway: Ọ̀pá afẹ́fẹ́ gáàsì bẹ́ lópópónà márosẹ̀ Ibadan sí Eko 16 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Oríṣun àwòrán, LASEMA Iroyin ti jade bayii wipe ajọ to n ri si iṣẹlẹ pajawiri ni ipinlẹ Eko, LASEMA ti ri ọpa afẹfẹ gaasi to bẹ ni tosii ile iṣẹ iroyin Punch lagbegbe Magboro to wa ni opopona Eko si Ibadan.
Fuel price hike: Wo iye ìgbà tí ẹgbẹ́ òṣìṣẹ́ àtàwọn ọmọ Nàìjíríà ti ṣèwọ́de lórí àfikún owó epo bẹntírò
Bí wọn tí ń yọ́ fadaka ninu iná alágbẹ̀dẹ, bẹ́ẹ̀ ni n óo fi ibinu yọ yín, ẹ óo sì mọ̀ pé èmi OLUWA ni mo bínú si yín.
 osi ni ọmọ lúwà ; eginrin sì ni ọmọ alárẹ ̀ .
R Kelly sunkún lóri Tẹlifísàn nípa ẹ̀ṣùn ìbálòpọ̀ Ẹ̀sùn ìfipábánilòpọ̀: Orí Twitter ló ti bẹ̀rẹ̀, ikú ló já sí Kí ló mú àwọn obìririn meji yìí pa bàbá wọ́n?
 Ni ti Mallam Labbo Tanimu, ọmọ rẹ meji ati oṣiṣẹ mẹta lo ba iṣẹlẹ naa lọ, ninu oko irẹsi wọn."
Oríṣun àwòrán, Getty Images Ẹlẹsẹ ayo, Gabriel Martinelli gba goolu meji sawọn fun Arsenal laarin iṣẹji mẹwaa, ni ere bọọlu ba di ami mẹti sẹyọkan.
Ní ọjọ́ keji, ní àkókò ìrúbọ òwúrọ̀, omi ya wá láti apá Edomu, títí tí gbogbo ilẹ̀ fi kún fún omi.
Pasitọ David Oyedepo Lọpọ igba ni pasitọ David Oyedepo ti ma n sọrọ soke tako ijọba paapaa lori eto abo,ẹsin ẹlẹyamẹya ni Niajiria.
Nítorí ibinu ti dé sórí gbogbo wọn.
Gomina wá mi orí sí Paulu.
Ṣugbọn èmi wà láàrin yín bí ẹni tí ó ń ṣe iranṣẹ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Omidan jáde láyé lẹ́yìn tí ìlú lù ú, jáa sí ìhòhò lórí ẹ̀ṣẹ̀ tí kò ṣẹ̀ Egbẹ okunkun, oogun oloro ati owo eeyan ṣiṣe Iwa to wa lọwọ awọn ẹgbẹ okunkun mi kọja orileede bode orileede Naijiria.
Biotile je pe, ekun omiyale sakoba lopo-lopo, pupo awon eniyan ni won so pe, o ye ki ijoba ti wa woroko fi sada, saaju ki o to to akoko ojo ohun.
Banki Nàìjíríà, CBN ṣàlàyé nípa àwọn tó máa rí gbà nínú owó ìrànwọ́ N75b tíjọba gbé kalẹ̀ Afẹ́fẹ́ gáàsì tí gbiná ní Ijora ìpínlẹ̀ Eko, bó ṣe n ṣẹlẹ̀ rèé Oṣú mẹ́fà ni òṣìṣẹ́ ìjọba tó bá bímọ yóò máa lò nílé kó tó wọṣẹ́ padà- Seyi Makinde A ti gbé ìwádìí dìde lórí ìpànìyàn tó wáyé lásìkò ìwọ́de EndSARS- Ilé ẹjọ́ àgbáyé, ICC Oríṣun àwòrán, Twitter/Nigeria Police Force 'Àwọn ọlọ́pàá tó farapa nínú ìwọ́de EndSARS yóò gba ìgbéga, a ó ṣèrànwó f'ẹ́bí àwọn tó kú' Ileeṣẹ ọlọpaa ti ṣe koriya fun awọn ọlọpaa lorilẹede Naijiria, eyi wa lara ohun ṣuyọ lẹyin rogbodiyan to tẹle ifẹhonuhan #EndSARS.
ni ilu Ibadan to wa ni ibamu  ade ti won
Fireboy lo kọkọ forin da gbogob eeyan lara ya lori eto naa.
5 25730 Orilẹede Mauritania 210 4.
Ọgbà kan wà níbi tí wọ́n ti kan Jesu mọ́ agbelebu.
Ẹ múra gírí kí ẹ sì mú ninu èso ilẹ̀ náà bọ̀.
Àlọ́ náà dá lóríi òwìwí tí kò ríran ní ọ̀sán nítorí ó yan àgbọ̀nrín jẹ.
Awọn aawọ miran ni ko han pupọ sita nigba ti awọn miran di ranto mọ awọn ọmọ ẹgbẹ ti ọrọ kan lọwọ.
Ìyá mi sì fún wa ní gèlè dúdú láti wé.
Ta lo n lewaju ninu eto idibo orilẹede Ẹgbẹ oṣelu Democrats Biden 52% Ẹgbẹ oṣelu Republicans Trump 44% Wiwo bi nkan ṣe n lọ gangan nipa ibo ọlọdani nibudo idibo ibo enikọọkan Ṣafihan Ibo enikọọkan JFMAMJJUS3040506003 BélỌjọ idibo02 BélO N GBONA LORI AYELUJARA44%52% Erongba oludibo lori ibo ẹni kọọkan Fo ibi kọja Ọjọ Biden Trump Nov 02 52 44 Nov 02 52 44 Nov 02 52 44 Nov 02 52 44 Nov 01 52 44 Nov 01 52 44 Nov 01 52 44 Nov 01 52 44 Nov 01 52 44 Nov 01 52 44 Oct 31 52 44 Oct 31 52 44 Oct 31 52 44 Oct 31 52 44 Oct 31 52 44 Oct 30 52 43 Oct 30 52 43 Oct 29 52 43 Oct 29 52 43 Oct 29 52 43 Oct 29 52 43 Oct 28 52 43 Oct 28 52 43 Oct 28 52 43 Oct 28 52 43 Oct 28 52 43 Oct 27 51 42 Oct 27 51 42 Oct 27 51 42 Oct 27 51 42 Oct 27 51 42 Oct 27 51 42 Oct 26 51 43 Oct 26 51 43 Oct 26 51 43 Oct 26 51 43 Oct 26 51 43 Oct 25 51 42 Oct 25 51 42 Oct 25 51 42 Oct 24 51 43 Oct 24 51 43 Oct 24 51 43 Oct 24 51 43 Oct 23 51 42 Oct 23 51 42 Oct 22 51 43 Oct 22 51 43 Oct 21 51 43 Oct 21 51 43 Oct 20 51 43 Oct 20 51 43 Oct 20 51 43 Oct 20 51 43 Oct 20 51 43 Oct 19 52 42 Oct 19 52 42 Oct 19 52 42 Oct 19 52 42 Oct 18 52 42 Oct 18 52 42 Oct 18 52 42 Oct 18 52 42 Oct 17 52 42 Oct 17 52 42 Oct 17 52 42 Oct 16 52 42 Oct 16 52 42 Oct 15 52 42 Oct 15 52 42 Oct 15 52 42 Oct 14 52 42 Oct 14 52 42 Oct 13 53 42 Oct 13 53 42 Oct 13 53 42 Oct 13 53 42 Oct 13 53 42 Oct 13 53 42 Oct 13 53 42 Oct 12 52 42 Oct 12 52 42 Oct 12 52 42 Oct 12 52 42 Oct 11 53 42 Oct 11 53 42 Oct 10 52 42 Oct 10 52 42 Oct 09 52 42 Oct 09 52 42 Oct 08 52 42 Oct 07 52 42 Oct 06 52 42 Oct 06 52 42 Oct 06 52 42 Oct 06 52 42 Oct 06 52 42 Oct 06 52 42 Oct 05 51 42 Oct 04 51 42 Oct 04 51 42 Oct 04 51 42 Oct 04 51 42 Oct 03 51 43 Oct 03 51 43 Oct 02 51 42 Oct 01 51 43 Oct 01 51 43 Oct 01 51 43 Oct 01 51 43 Sep 30 51 43 Sep 30 51 43 Sep 30 51 43 Sep 29 51 43 Sep 29 51 43 Sep 29 51 43 Sep 28 50 43 Sep 27 50 43 Sep 27 50 43 Sep 26 50 43 Sep 25 50 43 Sep 25 50 43 Sep 24 50 43 Sep 24 50 43 Sep 24 50 43 Sep 23 51 43 Sep 23 51 43 Sep 22 51 43 Sep 22 51 43 Sep 22 51 43 Sep 22 51 43 Sep 21 51 43 Sep 21 51 43 Sep 21 51 43 Sep 20 51 43 Sep 20 51 43 Sep 19 51 43 Sep 19 51 43 Sep 19 51 43 Sep 18 50 43 Sep 17 51 43 Sep 16 51 43 Sep 16 51 43 Sep 16 51 43 Sep 15 50 43 Sep 15 50 43 Sep 15 50 43 Sep 15 50 43 Sep 14 51 43 Sep 14 51 43 Sep 13 51 43 Sep 12 51 43 Sep 12 51 43 Sep 11 51 43 Sep 10 51 43 Sep 10 51 43 Sep 09 51 43 Sep 08 51 43 Sep 08 51 43 Sep 08 51 43 Sep 08 51 43 Sep 08 51 43 Sep 08 51 43 Sep 07 50 42 Sep 06 50 42 Sep 06 50 42 Sep 05 51 43 Sep 04 51 42 Sep 04 51 42 Sep 03 51 42 Sep 02 51 43 Sep 02 51 43 Sep 01 50 42 Sep 01 50 42 Sep 01 50 42 Sep 01 50 42 Sep 01 50 42 Sep 01 50 42 Aug 31 50 42 Aug 31 50 42 Aug 31 50 42 Aug 31 50 42 Aug 31 50 42 Aug 30 50 41 Aug 30 50 41 Aug 29 51 42 Aug 28 51 43 Aug 28 51 43 Aug 27 51 43 Aug 26 50 43 Aug 25 50 42 Aug 25 50 42 Aug 25 50 42 Aug 24 50 42 Aug 23 50 42 Aug 22 50 42 Aug 21 50 42 Aug 20 50 42 Aug 19 50 42 Aug 18 50 42 Aug 18 50 42 Aug 18 50 42 Aug 17 50 42 Aug 16 50 42 Aug 15 50 42 Aug 15 50 42 Aug 14 50 42 Aug 14 50 42 Aug 13 50 41 Aug 12 50 42 Aug 12 50 42 Aug 11 50 42 Aug 11 50 42 Aug 11 50 42 Aug 11 50 42 Aug 10 50 41 Aug 09 49 41 Aug 08 49 41 Aug 07 49 41 Aug 06 50 41 Aug 05 50 42 Aug 04 50 42 Aug 04 50 42 Aug 03 50 42 Aug 02 50 42 Aug 01 50 42 Jul 31 50 42 Jul 30 50 42 Jul 29 49 41 Jul 28 49 41 Jul 28 49 41 Jul 28 49 41 Jul 27 50 42 Jul 26 51 41 Jul 25 51 41 Jul 24 51 41 Jul 23 51 41 Jul 22 50 41 Jul 21 50 41 Jul 21 50 41 Jul 20 50 41 Jul 19 51 41 Jul 18 51 41 Jul 17 50 41 Jul 16 50 41 Jul 15 50 41 Jul 15 50 41 Jul 14 50 40 Jul 14 50 40 Jul 13 51 40 Jul 12 51 40 Jul 12 51 40 Jul 11 49 40 Jul 10 49 40 Jul 09 49 40 Jul 08 49 40 Jul 07 50 41 Jul 07 50 41 Jul 06 49 41 Jul 05 49 40 Jul 04 49 40 Jul 03 49 40 Jul 02 49 40 Jul 01 50 41 Jun 30 50 41 Jun 30 50 41 Jun 30 50 41 Jun 29 50 41 Jun 28 49 41 Jun 27 50 40 Jun 26 50 40 Jun 25 50 41 Jun 24 50 41 Jun 23 50 40 Jun 23 50 40 Jun 22 50 41 Jun 22 50 41 Jun 21 50 41 Jun 20 50 41 Jun 19 50 41 Jun 18 51 41 Jun 17 50 41 Jun 16 50 41 Jun 16 50 41 Jun 15 49 41 Jun 14 50 42 Jun 13 49 41 Jun 12 49 41 Jun 11 49 42 Jun 10 49 42 Jun 09 49 42 Jun 08 49 42 Jun 07 49 42 Jun 06 49 42 Jun 05 49 42 Jun 04 49 42 Jun 03 49 42 Jun 03 49 42 Jun 03 49 42 Jun 02 48 41 Jun 02 48 41 Jun 01 48 42 Jun 01 48 42 May 31 48 42 May 30 48 43 May 29 48 43 May 28 48 43 May 27 48 42 May 26 48 42 May 25 48 42 May 24 48 42 May 23 48 43 May 22 48 43 May 21 48 43 May 20 48 43 May 19 48 43 May 19 48 43 May 18 49 44 May 17 49 44 May 16 49 44 May 15 49 44 May 14 49 43 May 14 49 43 May 13 48 43 May 12 47 43 May 11 48 43 May 10 48 43 May 09 47 42 May 08 48 42 May 07 48 42 May 06 48 42 May 05 48 42 May 04 48 42 May 03 47 42 May 02 48 42 May 01 48 42 Apr 30 48 42 Apr 29 48 42 Apr 28 48 42 Apr 28 48 42 Apr 27 49 42 Apr 26 49 42 Apr 25 49 42 Apr 24 48 42 Apr 23 48 42 Apr 22 48 42 Apr 21 48 42 Apr 20 48 43 Apr 19 49 43 Apr 18 49 43 Apr 17 49 42 Apr 16 49 42 Apr 15 48 42 Apr 14 48 42 Apr 13 48 42 Apr 12 48 42 Apr 11 48 42 Apr 10 48 42 Apr 09 48 42 Apr 08 48 42 Apr 07 48 42 Apr 07 48 42 Apr 07 48 42 Apr 06 49 42 Apr 06 49 42 Apr 06 49 42 Apr 05 48 43 Apr 04 48 43 Apr 03 48 43 Apr 02 48 43 Apr 01 49 44 Mar 31 49 45 Mar 30 49 45 Mar 29 49 45 Mar 28 49 45 Mar 27 49 45 Mar 26 49 45 Mar 25 49 44 Mar 24 49 43 Mar 24 49 43 Mar 23 50 44 Mar 22 50 44 Mar 21 52 42 Mar 20 52 43 Mar 19 52 43 Mar 18 52 42 Mar 17 52 42 Mar 16 52 43 Mar 15 52 43 Mar 14 52 43 Mar 13 52 43 Mar 12 52 43 Mar 11 51 43 Mar 10 50 43 Mar 09 51 42 Mar 08 51 42 Mar 07 50 43 Mar 06 49 45 Mar 05 49 45 Mar 04 49 45 Mar 03 49 45 Mar 02 49 45 Mar 01 50 45 Feb 29 50 45 Feb 28 50 45 Feb 27 50 44 Feb 26 50 45 Feb 25 50 45 Feb 24 50 45 Feb 23 50 45 Feb 22 50 45 Feb 21 50 44 Feb 20 50 44 Feb 19 50 44 Feb 18 50 44 Feb 17 51 44 Feb 17 51 44 Feb 16 50 44 Feb 15 50 43 Feb 14 50 43 Feb 13 50 43 Feb 12 50 46 Feb 11 50 44 Feb 10 50 44 Feb 09 50 44 Feb 08 49 44 Feb 07 49 44 Feb 06 49 44 Feb 05 50 46 Feb 04 50 45 Feb 03 50 45 Feb 02 50 45 Feb 01 50 44 Jan 31 50 44 Jan 30 50 44 Jan 29 50 44 Jan 28 50 44 Jan 27 50 45 Jan 26 50 45 Jan 25 50 45 Jan 24 50 46 Jan 23 50 46 Jan 23 50 46 Jan 22 50 44 Jan 21 51 45 Jan 20 51 45 Jan 19 51 45 Jan 18 48 46 Jan 17 48 46 Jan 16 48 46 Jan 15 48 46 Jan 14 48 46 Jan 13 48 46 Jan 12 48 46 Jan 11 48 46 30 days until Ọjọ idibo Eto ibo iwadii ti BBC yoo maa wo awọn idibo iwadii ni orilẹede kọọkan laarin ọjọ mẹrinla, eleyi ti yoo wa fi ṣe agbekalẹ odinwọn aarin gbogbo rẹ lapapọ Lọwọlọwọ, o ti le ni ọdun kan bayi ti Joe Biden ti n lewaju ninu akojọ ero awọn oludibo jakejado Amẹrika .
Nípa ìwà ìfẹ́kúfẹ̀ẹ́ ara ati ìwà ìbàjẹ́ wọn, wọ́n ń tan àwọn tí wọ́n ṣẹ̀ṣẹ̀ ń kúrò láàrin ìwà ìtànjẹ ti ẹgbẹ́ wọ́n àtijọ́ jẹ.
Àfonífojì Tí ó kún fún Egungun Gbígbẹ.
atunse ayika lati lowo ninu oju se yii.
Bo tilẹ jẹ baba kan naa lo bi awọn mejeji, iya ọtọtọ lo bi wọn.
Balaamu bá bẹ̀rẹ̀ sí fi òwe sọ̀rọ̀, ó ní:“Balaki, dìde, wá gbọ́,fetí sí mi, ọmọ Sipori;
Nítorí àkókò ìgbàlà wa súnmọ́ tòsí ju ìgbà tí a kọ́kọ́ gbàgbọ́ lọ.
Ẹ̀mí Ọlọrun ni ó dá mi,èémí Olodumare ni ó sì fún mi ní ìyè.
A o wa lati kan an ni abuku, nitori pe o n soju awọn  eniyan re.
Àkọlé àwòrán, Àwòrán àwọn olùkópa bí wọn ṣe n fi orukọ silẹ ni ibi eto, WAEC International Centre l'Eko.
Silva fikun ọrọ rẹ pe alaṣeju ni Messi, oun nikan lo fẹ fọn feere, o fẹ dari ere bọọlu naa, bakan naa lo n ṣe ariyanjiyan pẹlu rẹfiri.
Ahasaya ọba ṣubú láti orí òkè ilé rẹ̀ ní Samaria, ó sì farapa pupọ.
Ajo awon to m mojuto oro ere boolu alafesegba ni Naijiria, NFF fun Infantino ni ami eye o kare ni Naijiria.
Iroyin yii hande nigba ti fọnran kan bẹrẹ si ni tan kalẹ lori ayelujara bi awọn janduku kan ṣe n yabo awọn ile ti wọn n ko ẹru si jakejado orilẹede Naijiria.
Ẹwa ede to kọja afẹnusọ ni awọn agba onkọwe maraarun yii lo nipa kikọ awọn iwe itan arosọ maraarun ti a gbe yẹwo wọnyii Awọn agba onkọwe yii fi ọrọ dara pupọ, wọn fi ọrọ yaworan to fi dabi pe ẹni pe eeyan n woran sinima ni ti eeyan ba n ka awon iwe ko see ma ni ti kosi see ma ka naa.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: 'Ìnira nlá ní iyanṣẹlodi lẹka òfúrufú yóò dá sílẹ fún arinrinajo Nàìjíríà' 'Ootọ ní fídíò ọmọogun Nàìjíríà tí kò fẹ́ kojú Boko Haram ṣùgbọ́n.
 Ìmọ ̀ ẹrọ àtòhúnrìnwá tí mú àyè rọrùn fún tilétoko .
 Oludari ijoba orile ede naa Ali Hassan Khayre lo yan Gelle
Ẹwẹ, nigba ti BBC Yoruba kan si ile iṣẹ ọlọpaa, ohun ti awọn ọlọpaa fọ ni wi pe awọn n se iwadii kikun lati ri aridaju boya awọn ẹgbẹ okunkun lo ṣe iṣ laabi yii tabi bẹẹ kọ.
Ọlọrun wa yóo jà fún wa.
“Iranṣẹ rẹ ni wọ́n, eniyan rẹ sì ni wọ́n, àwọn tí o ti fi ipá ati agbára ọwọ́ rẹ rà pada.
    Báyìí ni mo sọ̀rọ̀ fún àwọn artá ìlú wa.
Gẹgẹ bi o ṣe sọ, ni igba ti awọn to ṣaaju n kọ orin tiwọn, gbogbo ohun to n lọ lawujọ ni wọn fi n kọrin lati ṣi araalu leti.
 lati ipinlẹ ̀ ṣẹ ̀ tíátà , ni ó ti ń mú orísiirísi àrà dání .
Obìnrin Kwara tí wọ́n tà sóko ẹrú ní Lebanon figbe ta, ọwọ́ tẹ èèbó kọ̀ráà tó ṣiṣẹ́ náà Díẹ̀ lára àwọn ìṣẹ̀lẹ̀ tí yóò mi ìgboro tìtì l'ọ́dún 2020 rèé Ǹjẹ́ ọmọ Buhari lásẹ láti wọ Ọkọ̀ òfúrufú Nigeria Air force lọ sí òde?
Lati aye ere ori itage wọ sinima onifọnran celulloid ni Aluwẹ ti n da bira.
Ninu ọrọ tirẹ agbẹnusọ fun Aarẹ Buhari, Garba Sheu sọ lalẹ ọjọ Aiku pe nitori ti Aarẹ Buhari ko fi ẹlẹ yọ Onnoghen lawọn eeyan Naijiria ti ṣe n binu.
Àmọṣá, ó ní àwọn ọlọpàá àti iléeṣẹ ọmọogun ti mú kí àlááfíà padà sí agbègbè náà.
"O ni ""Soffie Dossie, gbajugbaja to n lọ ara ni awokọṣe mi""."
olorejore meji leyin ti won pegede fun idije 2019 Africa Cup of Nations, eleyi
to si tun tẹsiwaju ninu oṣelu nigba ti o dije fun ipo sẹnẹtọ lati ṣoju aarin-gbungbun ipinlẹ Kwara.
Akpabio list: James Manager, Peter Nwaboachi, Samuel Anyanwu fèsì sí ẹ̀sùn ti Godswill Akpabio NDDC fi kàn wọ́n
Ẹni to bori: Nigeria Morocco vs Tanzania.
Wàhálà bẹ́ sílẹ̀ níbi ìpolongo ìbò APC l'Eko Dino Melaye ṣubú lulẹ̀, ó d'èrò ilé ìwòsàn MC Oluọmọ, àtàwọn èèkàn míràn sọ̀rọ̀ lórí ikú Fẹ́lẹ́ Bakan naa la gbọ wi pe nibi wahala to waye lasiko ipolongo ọhun ti oludije fun ipo gomina labẹ asia ẹgbẹ APC, Babajide Sanwo-Olu fi ṣide ipolongo ibo rẹ, ni ọkan lara awọn oloye ẹgbẹ awakọ eero nipinlẹ Eko, MC Oluọmọ naa fi ara pa.
Ẹgbẹta ó dín aadọta (550) ni àwọn lọ́gàálọ́gàá tí Solomoni fi ṣe alákòóso àwọn tí ó ń kó ṣiṣẹ́ tipátipá, níbi oríṣìíríṣìí iṣẹ́ ilé kíkọ́ rẹ̀.
Lara awọn nnkan to ni wọn ri nibẹ ni owo ti iye rẹ jẹ din din ni miliọnu mẹta, ₦2,722,750, aadọfa idi igbo, 110, pali oogun codein aadọta ati pali poogun Rephnol mejila.
Nigba ti a de ilu Ikare la gbọ pe wọn ṣe ikọlu si ọkọ wa.
ati láti waasu ọdún tí Oluwa yóo gba àwọn eniyan rẹ̀ là.
" Alufaa Fatoyinbo ni oun mọ pe igbesẹ naa yoo tubọ mu ki oun le jọwọ ara oun silẹ fun awọn aṣiwaju oun lati tan ina wo hulẹhulẹ ọrọ naa.
Alukoro fásitì náà, ọ̀gbẹ́ni Abíọ́dún Ọláńrewájú ṣàlàyé nínú ìfọ̀rọ̀wérọ̀ rẹ̀ pẹ̀lú BBC Yorùbá pé àwọn méjèèjì yìí ní wọn pè síwájú ìgbìmọ̀ ọ̀hún ṣùgbọ́n arábìnrin tọ́rọ̀ kàn nínú fọ́nràn náà ko farahàn.
Ọga agba ileeṣẹ VIO nipinlẹ Eko ọhun wa ke sawọn ọlọkọ, lati kun ijọba lọwọ lọna ati wagbo dẹkun si ọwọja ayederu iwe ọkọ lorilẹede Naijiria.
Wọ́n tẹ́ pẹpẹ náà sí ibi tí ó wà tẹ́lẹ̀, bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé wọ́n ń bẹ̀rù àwọn eniyan ibẹ̀; wọ́n sì ń rú ẹbọ sísun sí OLUWA lórí rẹ̀ ní àràárọ̀ ati ní alaalẹ́.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù AFCON 2019: Amuneke gbé Tanzania lọ ìdíje ilẹ̀ Afirika fún'gbà àkọ́kọ́ láti ọdun 1980 24 Ẹrẹ̀nà 2019 Oríṣun àwòrán, Twitter/Emmanuel Amuneke Àkọlé àwòrán, AFOCN 2019 Orukọ akọnimọọgba Emmanuel Amuneke ti wọ iwe itan lẹyin to ṣagbatẹru bi orilẹede Tanzania ti pegede fun idije ere bọọlu ilẹ Afirika-AFCON fun igba akọkọ ni nnkan bi ọdun mọkandinlogoji(39 years).
Ọmọ Naijiria mọ́kàndínláàdọ́jọ pada sile China, Nàìjíríà, kò s'áyè òwò mọ́ ní Ghana!
Lẹ́yìn náà, àwọn ará Juda wá sí Heburoni, wọ́n fi òróró yan Dafidi ní ọba wọn.
Àwọn nǹkan wọnyi ni kí o máa pa láṣẹ, kí o sì máa kọ́ àwọn eniyan.
O tẹsiwaju pe Ẹ fun wọn ni nọmba awọn ẹbi yin ti wọn lee pe lati wa gba yin nigba ti wahala ba ṣelẹ."
Amọ ṣa, iran kọ wiwo nigba ti aarẹ yoo fi pari agbekalẹ rẹ pẹlu bi o ṣe di sinima agbelewo ninu eyi ti awọn aṣofin kan ti n dẹyẹsi aarẹ ti awọn ti o ṣe tirẹ pẹlu si n yin in.
Kí wọ́n dàbí fùlùfúlù ninu afẹ́fẹ́,kí angẹli OLUWA máa lé wọn lọ!
Àwọn Farisi gbọ́ pé àwọn ọmọ-ẹ̀yìn Jesu ń pọ̀ ju àwọn ọmọ-ẹ̀yìn Johanu lọ; ati pé Jesu ń ṣe ìrìbọmi fún ọpọlọpọ eniyan ju Johanu lọ.
Awọn alatilẹyin ẹgbẹ agbabọọlu Manchester United yoo gbe lẹyin Manchester City ti awọn ti Liverpool yoo si ma gbadura ki Manchester United fẹnu Man City gbole.
Ṣugbọn nígbà tí mo gbé e mì, ó korò ní ikùn mi.
8 131963 Orilẹede Moldova 3228 79.
Nígbà tó yá, ifẹ́ àfẹ́jù tí ń bẹ láàrin ọmọ ènìyàn àti ṣúgà bá bímọ.
Won yii ni bi awon agbaboolu Tottenham se fi idunnu won han leyin ti won jawe olubori ninu ifigagbaga ifesewonse pelu iko agbaboolu Ajax pelu ami ayo meji si meta(2-3)🎵🎉 Dressing room delight!
Wo ohun tó ń ṣẹlẹ̀ níbi ayẹyẹ àyájọ́ ọdún òmìnira ní ìpínlẹ̀ Oyo Ẹ wo ìyá ẹni ọdún 81 tó sẹ̀sẹ̀ parì ilé iwé alákọ̀bẹ̀rẹ̀!
Bẹẹ naa ni awọn eeyan tun lee wo bo ba ṣe n lọ loju opo Facebook, Twitter, Instagram ati YouTube.
Àwọn ìmúra málegbàgbé Dino Melaye níle aṣòfin àgbà Iná ẹ̀lẹ́ńtíríkì pa ẹlẹ́wọ̀n márùn ún lọ́gbà ẹ̀wọ̀n l'Eko Wo bí kòkòrò ààrùn HIV se bẹ̀rẹ̀ lágbàyé!
“Èmi OLUWA àwọn ọmọ ogun ni mo ní kí o lọ bèèrè ìdáhùn lórí ọ̀rọ̀ yìí lọ́wọ́ àwọn alufaa.
Ajọ EFCC to fi isẹlẹ naa sita loju opo Twitter rẹ tun kede pe bakan naa tun ni oun ko awọn eeyan meji mii, Adigun Fatai Olusegun ati Olufemi Kolawole sahamọ.
Amọṣa kọmiṣọna feto ilera, Akin Abayọmi ni COVID-19 to ṣe gomina naa kii ṣe eyi tii da ni wolẹ nitori awsn afihan kekeke lo n fi han lara gomina naa.
Oríṣun àwòrán, @CAPT__Vincent Àkọlé àwòrán, Akure Ọgangan iwaju ọfisi gomina ipinlẹ ọhun, Rotimi Akeredolu ni wọn patẹ eto adura naa si, ti wọn si n ke pe Eledua pe ko da si ọrọ Naijiria.
Awon oko ologun n lo soke sodo laarin awon oju-popo, won ko I ti mo eniti o pe fun iyanselodi fidi kale naa.
Lẹ́yìn náà, àwọn baba ńlá yín kígbe pe OLUWA fún ìrànlọ́wọ́.
MKO Abiola, iṣẹ́ aṣẹ́gità ló fi bẹ̀rẹ̀ okoòwò Ẹ wo fídíò bí Ìyálóde Ìbàdàn se sùn tẹ̀yẹ-tẹ̀yẹ BBC Yorùba balẹ̀ bàgẹ̀ s'ílée MKO Abiola l'Eko Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí 2 sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 2:23 Fídíò, Water Generator: Ó leè ṣiṣẹ fún wákàtí mẹfà, kó tó sinmi, Duration 2,2310 Òkùdu 2020 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
Iranṣẹ náà bá ti ọwọ́ rẹ̀ bọ abẹ́ itan Abrahamu oluwa rẹ̀, ó sì búra láti ṣe ohun tí Abrahamu pa láṣẹ fún un.
O ni ko si bi eto abo to gboopsn ṣe lee wa ni orilẹede ti ko ba bọwọ fun ofin.
"Aawọ abẹnu wa lori ẹni ti yoo di ipo asaaju kọọkan mu lẹkun yii, ti Makinde si ni ki wọn yẹju awọn alasẹ ẹgbẹ lẹkun yii, kawọn igbimọ afunsọ si gba ipo wọn, eyi ti ẹgbẹ oselu naa tẹle.
Òun ni òbíi wa, òun ni ó ń gbà wá nímọ̀ràn.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Iyabo Ojo ṣílé, Toyin Abraham fẹ́ ṣílé iṣẹ́ f'ọmọ, àtàwọn nǹkan míràn lágbo òṣéré Wo fọ́tò àrà MC Oluomo, Pasuma àtàwọn òṣèré tíátà míì níbi ìṣílé Iyabo Ojo Wo àwọn òṣìṣẹ́ kólẹ̀-kódọ̀tí tó ń fi ẹ̀mí wọn wéwu kí Abuja leè mọ́ tónítóní Àwón Oníbúrẹ́dì ń gbé ìgbésẹ̀ láti fi kún owó Búrẹ̀dí ní Nàìjírià Wo ìyá ọlọ́mọ mẹ́ta tó ti pé ọdún 48 tó ń ṣe ìdánwò WAEC, kó le di nọ́ọ́sí Awọn oniruuru ẹlẹgbẹjẹgbẹ to jẹ ti ẹya kọọkan lawọn ẹkun gbogbo to wa ni Naijiria , bii Afenifere, Middle Belt, Agbaagba lẹkun ariwa, Ohanese Ndi Igbo ati Pan Niger Delta Forum.
Ìwé náà kún fún ọ̀rọ̀ alaafia ati òtítọ́, 
Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí EndSars Protest: A kò lọwọ́ sí ìwé ìpẹ̀jọ́ tó tako ìdásílẹ̀ ìgbìmò ìwádìí aṣemáṣe ikọ̀ SARS4 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Seyi Makinde: Gbogbo ìgbà ni ìyá mi máa ń sọ fún mi pé díẹ̀ ló kù kí àwa méjèjì kú lọ́jọ́ tó bí mi4 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Obasanjo: Mo lòdì sí ìgbé ayé tí Gani Adams ń gbé látẹ̀yìnwá, ṣùgbọ́n n kò bá a jà - Obasanjo3 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Fídíò, EndSARS: Olatunde Abolarinwa London Tailor ní òun á ṣe baba fún mi, kò tilẹ̀ dúró ṣe bàbá àwọn ọmọ tirẹ̀ tóríi ìwà Ọlọ́pàá Mopol5 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
 O wa rọ Ile naa lati fẹmi imoore han si arabinrin, agbọpa aṣẹ Ile, ẹni ti awọn janduku naa ṣe leṣe nibi ti o ti n gbiyanju lati du ọpa naa mọ wọn lọwọ.
Ẹ padà wá gbọ́ àbọ̀ ọ̀rọ̀.
Àwọn Kìrìstẹ́nì àti Júù wí pé ọmọ Ibrahim kejì Isaac ni Ọlọ́run ní kó fi rúbọ sí Òun.
Gẹgẹ bi o ṣe sọ, awọn igun mejeeji yii lo mọ bi wọn ṣe n pari aawọ ati dukuu aarin wọn.
Ọdun to lọ ni Ronke bi ọmọ rẹ akọbi, Fife.
Bakan naa ni Wooli Chukwuemeka Odumeje, ti ẹnu ti kun lori ayelujara nitori fidio kan to fihan bo ṣe n jijakadi pẹlu ọmọ ijọ rẹ kan to sọ pe o ni ẹmi okunkun ninu - naa ti gba oriyin lori Twitter fun bose fun awọn ti ebi le pa lasiko igbele ọsẹ meji.
Loju opo instagram rẹ lo ti fesi si awọn to n ṣe marimasọ lori igbeyawo rẹ, eyi to ni wọn ni nitori ati lee di olori lo fi lọ fẹ Alaafin.
O ni oun ko ni gbagbọ ti ẹnikan ba sọ fun oun pe Sholaye maa yipada lẹyin ti awọn ti mọ ara awọn fun ọdun mẹta ti awọn si jọ gbero lati fẹ ara awọn bi tọkọ taya.
Lẹyin ti iroyin jade pe Owolewa ti bori ninu idibo ọhun, ọpọ awọn ololufẹ rẹ kaakiri Naijiria ati loke okun lo ti bẹrẹ si n kii ku ori ire lori itakun agbaye.
Ó dára kí ìjọba ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́ ní àjọ tó ń gbógun ti ìwà ìbàjẹ́!
Àwa ní tiwa, a óo tẹra mọ́ adura gbígbà ati iṣẹ́ iwaasu ọ̀rọ̀ ìyìn rere.
Bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé àwọn ará Kalidea yí ìlú náà po, wọ́n lu odi ìlú náà, wọ́n gba ẹnu ọ̀nà tí ó wà láàrin odi mejeeji lẹ́gbẹ̀ẹ́ ọgbà ọba, wọ́n sì gba ọ̀nà tí ó lọ sí Araba.
Ogóje náírà (#140), péré ni wọ́n bá nígbà tí ó kú tán.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Mo fa àwọn tó wó ilé mi sí kóótù Ọlọ́run - Ayefẹlẹ Àwòrán ọ̀pọ ohun tó bàjẹ́ ní iléesẹ́ rédíò Yinka Ayefẹlẹ Àwọn obìnrin tí kò lọ́kọ ń kojú ìsòro ilé gbígbà Irú ẹ̀dá wo ni Kofi Annan jẹ́?
 “ Nigba ti orile-ede Gambia fi ajo naa sile ni odun 2013, awon olori ijoba fi edunokan won han bi orile-ede ohun se fi ajo molebi re sile, a n reti igba ti orile-ede Gambia yoo pada wa, inu wa dun lopolopo leyin ti aare Barrow jawe olubori ninu eto idibo ti o waye lodun to koja, ti aare adibo yan seleri ati pada ninu ajo naa, iwe akoranse ti orile-ede Gambia ko lati tun dara po mo ajo naa ni awon omo egbe mejilelaadota fowo si lai dena penu, ti won si ki arakunrin ati arabinrin won kaabo pada sinu ajo naa, lati tun le bere ojuse won lai kaare ninu ajo commonwealth ohun ni kikun”.
Lẹ́yìn náà, ṣe àgbàlá yí i ká, kí o sì ta aṣọ sí ẹnu ọ̀nà àgbàlá náà.
Oríṣun àwòrán, Ayodeji Abass Alesinloye Ko si idi meji fun eyi, ju iroyin kan to n lọ kaakiri pe ijọba ipinlẹ Ọyọ ti na ọwọ alaafia si ẹgbẹ awọn alaga kansu naa, ALGON.
Oríṣun àwòrán, Google Fẹrẹẹ, nigba to fi di ọdun 1957, o ti da ẹgbẹ́ Fatai Rolling Dollar & African Rhythm Band"" silẹ."
Tomato Oríṣun àwòrán, Getty Images Tomato naa n ko ipa ribiribi ninu awọn eroja ara paapaa ki atọ ọkunrin le dara si.
Orile ede Naijiria fi agba han akegbe won, ti iko orile ede Iceland pelu ami  ayo meji si odo(2-0), ti iko Iceland ko si lee ta putu.
Àwọn kan ń pe àwọn ẹlẹgbẹ́ wọn pé, ‘A lù fun yín, ẹ kò jó, A sun rárà òkú fun yín, ẹ kò sunkún.
Arsenal ati ikọ Burnley ni wọn jijọ gbe ina woju ara wọn.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ramadan 2018: Sultan rọ Mùsùlùmí láti gba àlààfía lááyè 17 Èbibi 2018 Àkọlé àwòrán, Àwẹ Ramandan; Àwọn ouńjẹ tí a fi ń já àwẹ̀ Sultan ti Sokoto, Alhaji Muhammad Sa'ad Abubakar, tí ó jẹ́ adarí àjọ tí ó ń ṣàkósó ọ̀rọ̀ àwọn Musulumi jákèjádò orilẹ́ èdè Naijiria (NSCIA), ti kéde pe, Ramadan bẹ̀rẹ̀ ní Ọjọ́bọ, lẹ̀yin tí wọn rí oṣù.
Laipẹ yii ni Liverpool lu Chelsea ni alubami, ko to di wi pe wọn gberasọ pada.
Oríṣun àwòrán, BBC Sport Abẹwo BBC si ile naa si fihan pe, wọn ko tii pari ile ọhun, asọ ati ọra ni wọn ta si awọn oju ferese ati ẹnu ọna ile, ti wọn ko si rẹ ara ile ọhun rara.
Ọmọ Yorùbá tó bá ti rú òfin, ẹ gbé e jàntò - Oluwo Mo ṣe tán láti kú tọmọ taya bí wọn kò bá fi El-Zakzaky sílẹ̀ - ọmọ ẹgbẹ́ Shiite Ṣé o mọ̀ pé ìwé ẹ̀rí ìgbéyàwó rẹ lè jẹ́ ayédèrú?
Pataki lara awọn to ti ki gomina naa ni Sẹnetọ Abiọla Ajimọbi to fi ipo naa silẹ lọdun 2019.
O tun so pe“A n duro de wọn  lorile ede Naijria, iru iwa ti ẹ hu yii, fihan pe ẹ jẹ ọmọluabi, pe ẹ tun ni ibọwọ fun ara yin ati orile ede yin.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Fake Pastors: Bunmi àti Rukayat ni agbódegbà àwọn afurasi pasitọ náà 4 Ọ̀pẹ̀̀ 2019 Oríṣun àwòrán, others Àkọlé àwòrán, Rukayat Folawewo ni òun ri iṣẹ́ ìyànu gba lọ́dọ̀ pasitọ Favour David lẹ́yìn ìjàmba ọkọ tó lágbara Awọn òṣìṣẹ́ ọ̀tẹlẹ́múyẹ́ to n rí si ìwádìí ọ̀dáran nípinlẹ̀ Eko ti mú àwọn mẹ́rin kan tọ fi mọ olùsọ́aguntan méji.
àwọn tí wọn ń yọ̀ ninu ìwà ibití wọ́n sì ní inú dídùn sí ìyapa ibi;
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Kílò fa èdè àìyedè láàrin ìjọba àti àwọn ọmọ lẹ́yìn El-Zakzaky?
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ohun mẹ́jọ tóo ní láti mọ̀ bí o bá fẹ́ lọ ilé ọdun Ti wọn ba ti dibo tan, wọn yoo da gbogbo awọn iwe pelebe naa pọ, wọn yoo ka a, wọn yoo si ṣi wọn.
Ó ta àwọn òkú ọ̀run jí láti kí ọ,àwọn tí wọ́n ṣe pataki ní àkókò wọn,Ó gbé gbogbo àwọn ọba orílẹ̀-èdè dìde lórí ìtẹ́ wọn.
Simoni Peteru bá sọ fún un pé, “Bí ó bá jẹ́ bẹ́ẹ̀, Oluwa, ẹsẹ̀ mi nìkan kọ́, ati ọwọ́ ati orí mi ni kí o fọ̀ pẹlu.
Àkójọpọ̀ àwòrán láti ìpàdé ìtagbangba pẹ̀lú àwọn olùdije ní Ọyọ Àwọn ohun mánigbàgbé níbi ìfọ̀rọ̀wérọ̀ BBC Yorùbá l'Ọyọ Èwo nínú ìlérí tí Buhari ṣe ní 2015 ló ti mú ṣẹ?
Kí wọ́n rán àgbékọ́ meji mọ́ etí rẹ̀ mejeeji, tí wọn yóo fi lè máa so ó pọ̀.
“Nígbà tí àlejò kan bá wọ̀ tì yín ninu ilẹ̀ yín, ẹ kò gbọdọ̀ ṣe é ní ibi.
Ṣugbọn OLUWA sọ fún Mose pé, “Na ọwọ́ rẹ, kí o mú un ní ìrù.
Ti ẹ ba wo daada, ẹ o ri wi pe awọn eeyan ko tuyaya jade paapa julọ nilu Eko lati dọwọ idunnu esi ibo'' Sowore tẹsiwaju pe, pupo eeyan ni ko ri bi dibo latari kọnukọhọ to wa ninu eto idibo naa.
Ìpéjọpọ̀ tí ó lọ́wọ̀ ni, nítorí náà, ẹ kò gbọdọ̀ ṣe iṣẹ́ líle kankan.
ni orile ede Zimbabwe ko tii ni owo ilẹ won 
Koda a gbo pe Gomina ipinlẹ Nassarawa ati ti Niger lawọn eeyan gba fọọmu fun.
Lati igba yii ni ayanmọ rẹ ti rọ mọ iṣẹ ere tiata ti ko si rẹwẹsi lori rẹ.
Bakan naa lo sọrọ lori bi o ṣe n ri lara oun ti ọkọ rẹ ba n ba obinrin mii ṣere ifẹ lori sinima.
Solomoni bá yọ Abiatari kúrò ninu iṣẹ́ alufaa OLUWA tí ó ń ṣe, ó sì jẹ́ kí ọ̀rọ̀ tí OLUWA sọ ní Ṣilo ṣẹ, nípa Eli alufaa ati arọmọdọmọ rẹ̀.
Ọjọ kẹsan an oṣu kinni lawọn gomina ilẹ Yoruba ṣe agbekalẹ Amọtẹkun ni olu ilu ipinlẹ Oyo, Ibadan.
ng Àkọlé àwòrán, Lẹyin ọdun mejilelogun, olukọni ikọ agbabọọlu Nàìjíríà tẹ́lẹ̀, Bonfere Jo, ṣẹṣẹ gba kọkọrọ ile ti wọ́n fun un Gbajugbaja agbabọọlu orilẹ-ede Naijiria nigbakan ri, Ṣẹgun Ọdẹgbami, ti sọ wi pe pupọ awọn elere idaraya ti ijọba pinnu ati fun ni awọn ẹbun ni wọn ti ń gba irufẹ awọn ẹbun bẹẹ.
Ó bá bèèrè pé, “Èwo ni ó ṣe pataki jùlọ ninu gbogbo òfin?
Koda, awọn ọlọja ko lee si sọọbu tabi patẹ ọja wọn lasiko ti iwọ̀de naa n waye, ti ohun gbogbo si dẹnu kọlẹ.
'Àìjáfáfá àwọn panápaná ló mú kí ọṣẹ́ iná Akure pọ̀' Wọ́n ti gbé òkú Ibidunni Ighodalo sílé ìgbókúpamọ́sí l'Eko Jimoh ni lati ọdun 2014 ni ẹgbẹ awọn dokita naa ti n bere awọn ẹtọ wọn lọwọ ijọba apapọ ṣugbọn ijọba ko kọbi ara si awọn ibere naa.
Mercy Aigbe ati Lauretta Sawyer Oríṣun àwòrán, Mercy Aigbe Àkọlé àwòrán, Mercy Aigbe Ẹni to ba oṣere Mercy Aigbe ni isọrọ n gbesi yii kii ṣe oṣere bi ko ṣe ni kan to fi ẹsun kan ni nkan bi ọdun to kọja lori ẹrọ ayelujara pe aṣọ igbeyawo oun ni Mercy Aigbe wọ fi ṣe ọjọ ibi.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Àwọn afọbajẹ wọ́ Oluwo relé ẹjọ́, ìjọba Osun kò tíì fọùn Ẹ gbà mí, Nàíjíríà gbá mi lórí àyẹ̀wò Covid-19 - Iyabo Ojo figbe ta A ti ja aráàlú kulẹ̀, ta bá pè wọ́n fún ìwọ́de, wọn kò ní jẹ́ wa mọ́ - NLC Eko Àlàyé rèé lórí ìdí tí ẹgbẹ́ òṣìṣẹ́ kò fi ní bẹ̀rẹ̀ ìyanṣẹ́lódì mọ́ lónìí Ẹgbẹ́ òkùnkùn yìnbọn lu ọmọ kan ní ikùn lásìkò ìdárò akẹẹgbẹ́ wọn Laycon ni ọmọ ológo tó jáwé olúborí ní ètò BBNaija season 5 'Lockdown' Kí ló wà láàrin Olorì Badra àti Bobrisky, tí ọ̀rọ̀ wọn fi wọ̀?
“Gba ọ̀pá mejila láti ọwọ́ àwọn ọmọ Israẹli, ọ̀pá kọ̀ọ̀kan láti ọwọ́ olórí ẹ̀yà kọ̀ọ̀kan, kí o sì kọ orúkọ olukuluku sí ara ọ̀pá tirẹ̀.
Gbogbo àpapọ̀ àwọn tó ti lùgbàdi ààrùn Coronavirus nni Nàìjíríà ti di ẹgbẹ̀rún méjìlélélọ́gọ́rin ọ le díẹ̀ (82,747) tí àwọn ẹgbẹ̀rún lọ́nà ààdọ́rín ó lé díẹ̀ (70239) sì ti rí ìtọ́jú gbà.
Awọn dokita ni ile iwosan nla ti fasiti ilu Eko, LUTH ti gunle iyanṣẹlodi.
Yatọ si alagba Saka, eekan oṣere miran, Kelvin Idkeduba pẹlu ṣe ọjọ Ibi rẹ lọsẹ yii.
Omowe Tedros je eni akoko ninu omo ile Afrika ti yoo di ipo oga agba ajo eleto ilera ninu ajo isokan orile ede agbaye mu leyin ti o jawe olubori ninu eto idibo pelu ibo mẹ́rìndínláàdọ́wàá ninu egbe.
80 Papakọ ofurufu ti ipinlẹ Kano, Port Harcourt, Owerri ati Maiduguri yoo si ni Ọjọ kọkanla, Osu Kẹjọ, Nigba ti awọn papakọ ofurufu to ku yoo ṣi ni Ọjọ Karundinlogun, Osu Kẹjọ.
Bunkunmi Oluwasina ṣe ìgbèyàwó, ẹ̀yin bẹ́lẹ́jayán ẹ lọ sẹ́mpẹ́ Ọpọ̀ ọkọ̀ bàjẹ́ nígbà tí alátìlẹ́yìn PDP àti APC kọlù àrà wọ́n l'Ondo Àwòrán òkú ọmọ mi ni mo kọ́kọ́ rí lójú òpó ayelujara - Bàbá ọmọ tí SARS lé dójú ikú Ọdún méjì, wàhálà méjì lójúbọ Osun Osogbo, Atẹjade kan ti Kehinde Aderemi, tii ṣe akọwe feto iroyin Gani Adams fisita L'ọjọru lo sísọ loju ọrọ yii.
Bo ba si jẹ awọn ounjẹ koya koya naa ni, ẹ o ba a nibẹ.
Bí mo bá sọ fún ẹrú mi pé, ‘Ṣe èyí!
je, trilionu mẹ́tàlélọ́gọ́rùn ún owo Naira(103
Ati wi pe nitori awọn idi naa ni ijọba paapa ko fi ṣe eto orin Keresimesi to maa n ṣe lọdọọdun nibẹ.
"Gambari ni oun ko tii lee sọ ibi ti oun yoo ti bẹrẹ si nii mu iṣẹṣe ṣugbọn ohun mọ daju pe, ""oun ko ni abọ kankan n jẹ fun ọmọ Naijiria bi ko ṣe Aarẹ Buhari""."
Ẹfunsetan Aniwura, obìnrin tó ju ọkùnrin lọ Lasiko ti ikọ iroyin BBC Yoruba sabẹwo lẹẹkansi si oke Olumọ lati mọ ohun to n waye labẹ apata naa ati ojuse awọn iya agba to wa nibẹ, ẹnu ko gba iroyin.
Ní ọjọ́ kan, bí a ti ń lọ sí ibi adura, a pàdé ọdọmọbinrin kan tí ó ní ẹ̀mí àfọ̀ṣẹ.
N óo ba yín ṣẹ́ gègé lórí wọn níhìn-ín, níwájú OLUWA Ọlọrun wa.
Wo iye owó tí ìjọba Amẹrika ń na sí ìdìbò Ààrẹ àti ibi tí owó náà ti ń wá Ǹkan tí a mọ̀ nípa kọ́lẹ̀jì olùdìbò tó ń fìdì ẹni ti yóò jẹ ààrẹ ilẹ̀ Amérika múlẹ̀ Wo àwọn Ṣọ́ọ̀ṣì Nàìjíríà àti l'Áfíríkà tó ń wólẹ̀ àdúrà kí Trump lè wọlé ìbò ààrẹ America US election 2020: Bi kò tilẹ̀ wọlé, ẹ wo ayípadà tí Ààrẹ Trump mú bá awọn orilẹede ní àgbáyé Lara ohun to lee sọ bi aṣeyọri Trump yoo ṣe ri ni awọn esi ti yoo wa lati Pennsylvania ati Florida.
Awọn ọmọ Naijiria n sọ ọrọ oriṣii nípa ọrọ Buhari ati Shagari
Èyí ni àwọn nkan tó yẹ́ kí o mọ̀ nípa Abba Kyari tí coronavirus pa Abba Kyari ti iku wọlede mu lọ lẹyin ikọlu ajakalẹ arun coronavirus to n gbẹbọ lọwọ gbogbo agbaye yii jẹ odu ti kii ṣe aimọ fun oloko.
Ẹ yára kí ẹ lè bá a, kí ó tó lọ sí orí òkè lọ jẹun; nítorí pé àwọn eniyan kò ní bẹ̀rẹ̀ sí jẹun títí tí yóo fi dé.
Siasia yanana oro yii latari awuyewuye mimu Obi lo kopa ninu idije 2016 Olympic, eyi ti o si gba ami-eye ipo keta silver wale.
Baba Kidwaya, Terry Waya to jẹ gbajugbaja gbajumọ lawujọ, n gbe ilu London ni Ilẹ Gẹẹsi ni ibi to ti n ṣe kara-kata.
Sùgbọ́n ní ti Olatayo Amokade, eyi kìí ṣe Sinimá rárá o bíkò ṣe ìṣẹ̀lẹ̀ ojú ayé.
Texas Shootings: Wọ́n ti pa ẹni to yìnbọn pa àwọn ará Texas márùn ún -ọlọ́pàá
"Nigba to wa n sọrọ lori ilana ti ijọba Naijiria n lo lati pin owo iranwọ fun igbele Coronavirus, eyi to ni ko de ọpọ ibi to yẹ ko de, agba Inaki ni ""ijọba ko pese ohun elo igbaye-gbadun fun araalu lati ibẹrẹ pẹpẹ, lo mu ko nira fun wọn lati lee ṣe awari araalu to nilo iranwọ."
049bn, fun ṣíṣe, ayẹwo ati ikojade ẹ̀rọ ti yoo ma a gbe reluwe to ba ni ijamba kuro loju ọna.
Ewe, pelu gbogbo idunadura ifigagbaga naa, Wilder ni igbagbo pe ifigagbaga ohun yoo si waye.
si, bakan naa, ni lila ona fun oko oju’rin lati ibudo naa de ilu Kano yoo se e
Alukoro ileeṣẹ ọlọpaa ni nigba tawọn de ibẹ lawọn ba oku ọlọpaa naa ati iyawo rẹ nilẹ.
Ilé iṣẹ́ olórúkọ ''Massi' ní Spain ló kọ́kọ́ ṣe lòdì sí ìyọ̀ǹda lílo orúkọ Messi tẹ́lẹ̀, pé, ó ṣeéṣe kí orúkọ máa dàpọ̀ lórí ohun eèlò.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Níbo ni owó Crowd 1 ti wá?
”Arabinrin Buhari wa gbosuba fun ilana ti egbe APC gunle lati fi emi isokan han laarin awon omo egbe , o wa ro awon obinrin lati  tele awon eto ilana naa, ki won si dena iwa aparo kan, ko ga ju okan lọ.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Lọsẹ to kọja lawọn ajinigbe gbe e salọ lẹyin iku eeyan márùndínlọ́gọ́ta ni Kasuwan Magani.
Ó dà bí ẹni tó fẹ́ bò awọ olóógbò ni.
Iroyin sọ pe agolo gaasi kan ti wọn fi n tun ẹ̀rọ amule tutu kan ṣe ninu ile alaja kan naa lo bu gbamu, nitori pe ó ń jò.
Ṣugbọn wọn kò tẹ̀lé àpẹẹrẹ rere baba wọn.
Ó kó wọn papọ̀ sinu àwọ̀n rẹ̀, Nítorí náà ó ń yọ̀, inú rẹ̀ sì dùn.
Nígbà náà ni wolii Aisaya lọ sí ọ̀dọ̀ Hesekaya, ó bèèrè lọ́wọ́ rẹ̀ pé, “Níbo ni àwọn ọkunrin wọnyi ti wá, kí ni wọ́n sì sọ fún ọ?
Wọn ni koko ko ni ara ọta le, ati pe Baba Lawuyi ṣi ba ninu wọn sọrọ ni aarọ ana ki ọlọjọ to kan ilẹkun ni ọjọ kọkanlelogun, osu kẹsan an.
Gómìnà Makinde, pe Sunday Igboho àti Auxilliary kóo parí ìjà wọn, àwọn ọmọ Nàìjíríà sọ̀rọ̀ jáde Atirobẹ́lẹ́ṣindọ́gba ni ọ̀pọ̀ ọ̀dọ́ ní ìsin yìí-Ọlọ́fàiná Ki ree?
Arakunrin Samuel Aruwan to jẹ oluranlọwọ agba fun gomina ipinlẹ Kaduna lori eto iroyin lo fi ọrọ naa lede ninu atẹjade ni ilu Kaduna.
O ni wọn ko nifẹ orilẹede Naijiria l'ọkan.
Gẹgẹ bii ọrọ rẹ, Aisha ninu fidio ti a n sọrọ rẹ yii, n lọgun too pe ki wọn si ilẹkun fun oun lati wọle, lẹyin ti Buhari ti paṣẹ pe ki wọn fi ile onigilaasi naa silẹ fun Yusuf ọmọ oun, amọ yẹyẹ ni Fatimah to jẹ ọmọ Daura n fi oun ṣe.
O ní ìjàmba ọkọ náà kan ènìyàn mẹ́rinla, ọkùnrin mẹtala, òbinrin kan ti ọkunrin mẹrin si kú, ọkunrin mẹrin farapa.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Chelsea: Sarri ní Eden Hazard lè lọ tó bá fẹ́ lọ 30 Sẹ́rẹ́ 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ọrọ lori ẹlẹsẹ ayo Eden Hazard Akọnimọọgba Chelsea Maurizio Sarri ti sọ fun ẹlẹsẹ ayo Eden Hazard pe o le fi ẹgbẹ agbabọọlu naa silẹ to ba wu u.
Mo fẹ́ kí ẹ mọ̀ dájúdájú pé oluwa rẹ̀ yóo fi ṣe ọ̀gá lórí gbogbo nǹkan tí ó ní.
Lizzy, ẹni to fi ikede naa sita loju opo Instagram rẹ tun kede pe lati igba ti Alaafin ti beere owo ori yii ni ọkọ oun ti n gbọn kiri.
Ile isẹ ọlọpaa ni ipinlẹ Eko lo fi eyi lede ninu atẹjade kan pe afurasi naa ti orukọ rẹ n jẹ Sunday Adefonou Anani jẹwọ lẹyin ti ẹrọ ayaworan ikọkọ(CCTV) fihan wi pe oun lo pa ọga rẹ.
Iṣẹ́ ọwọ́ rẹ tóbi pupọ, OLÚWA!
Alakoso ọja naa, Haruna Mai Yasin to fi idi iṣẹlẹ naa mulẹ fun ikọ iroyin BBC Yoruba ṣalaye pe, ṣadede ni wọn rii wi pe awọn Hausa kan to jẹ ontaja ninu ọja naa n ba ara wọn ja debi pe, awọn kan fi ara pa ninu iṣẹlẹ naa.
A sì ní ìdánilójú pé a ti rí ààyè dé ọ̀dọ̀ rẹ̀ nípa igbagbọ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Ṣíṣe àyẹ̀wò abẹ́lé fún ẹni to fẹ̀ gba gẹ́gẹ́bi òṣìsẹ́ ìnú ilé lè dóólà ẹ̀mí rẹ̀' Ko pẹ lẹyin ti Oniṣegun oyinbo Adan de lo ronu ọna lati mu igbe aye awọn eniyan rẹ rọrun sii ni oun fi bẹrẹ iṣẹ wiwa ọkọ igboku si.
Kì í ṣe àwọn ohun èèlò wúrà ati ti fadaka nìkan ni ó ń wà ninu ilé ńlá.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Kéré o!
Ó ní ọkùnrin ti wọ́n lọ gbé òun pẹ̀lú kìí ṣe àláàrùn Coronavirus, ó sì ti wà ní àkàtà ìjọba fún ìtọ́jú báyìí.
ofin nitori ofin to mu eni to gba owo abetele naa,lo mu eni to fun eniyan.
Àwọn ọmọ Ṣefataya jẹ́ ọrinlelọọdunrun ó dín mẹjọ (372).
Ijọba Oyo ko fi oju kekere mu ọrọ yii, ti wọn sì ti fohun silẹ pe awọn ko ni yẹ lori ipinu wiwọgile ijọsin aisun ọjọ ọdun.
Gege bi oro Udoma, akosile ile-ise ti o n ri isiro lorile-ede Ngeria NBS fihan pe, igberu ti o ba eto oro-aje ohun wa lati eto ogbin bi 4.
Ninu idahunn rẹ, Aṣofin Agunbiade ṣọ pe gbogbo akiyesi yii ni wọn yoo tun ṣagbeyẹwo rẹ ki Abadofin naa to di Ofin.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, A kò mọ́ pé wọ́n kẹ́ òògùn olóró sí àbúrò mi l'ọ́rùn Universal Music Group jẹ aṣaaju ninu oniruuru iṣẹ to rọ mọ orin kikọ.
O óo sì mú kí arọmọdọmọ mi wà níwájú rẹ títí laelae.
Àwọn ọmọ Lefi fi ọ̀pá gbé e lé èjìká wọn gẹ́gẹ́ bí Ọlọrun ti pàṣẹ fún Mose.
Obinrin náà yára pa ẹgbọ̀rọ̀ mààlúù tí ó ń sìn, ó sì ṣe burẹdi díẹ̀ láì fi ìwúkàrà sí i.
Tillerson ni: “Loni ni mo n kede owo iranwo to le ni eedegberun milionu owo dola ti a fe fi se iranwo lori ipese ohun jije ati awon ohun eelo miran to mu ifaseyin ikolu ni Somalia, South Sudan, Ethopia ati Lake Chad Basin.
Ilana TuntunPelu ilana tuntun ti ajo eleto idibo ( INEC)laa sile ni pe oludibo kankan ko gbodo mu ẹrọ- ipe alagbeeka lo si ibi ti won ti n dibo.
Bakan naa ni ileeṣẹ ọlọpaa ni ipinlẹ Ondo ti bẹrẹ si ni fimu finlẹ lori awọn afurasi kan naa kaakiri ipinlẹ ọhun, ọwọ si ti tẹ eeyan mẹwaa o kere tan.
Jẹ́ kí ojú ti gbogbo àwọn tí wọn fẹ́ gba ẹ̀mí mikí ìdàrúdàpọ̀ bá wọn;jẹ́ kí á lé àwọn tí ń wá ìpalára mi pada sẹ́yìn,kí wọn sì tẹ́.
Ṣugbọn àwọn Juu rú àwọn gbajúmọ̀ obinrin olùfọkànsìn sókè, ati àwọn eniyan pataki-pataki ní ìlú, ni wọ́n bá ń ṣe inúnibíni sí Paulu ati Banaba.
Gbọ́ adura mi, Ọlọrun;tẹ́tí sí ọ̀rọ̀ ẹnu mi.
Lẹ́yìn èyí, ó tún fi ilé kan han Adéforítì, a rí obìnrin àti ọkùnrin kan nínú ilé náà a sì rí ọmọ owú kan ní ilẹ̀.
Ẹwẹ, ọga patapata ileeṣẹ ọlọpaa Naijiria Mohammed Adamu ti dupẹ lọwọ awọn ọmọ orileede Naijiria fun atilẹyin wọn eyi to ja si bi wọn ti ṣe mu Sunday Shodipe.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ìdílé tó gba olùkọ́ èdè Yorùbá fún àwọn ọmọ nílẹ̀ Gẹ̀ẹ́sì Alakalẹ inu lẹta naa ni pe awn eto ori rẹdio naa yoo jẹ eyi to n kọ ni lẹkọ pọnbele ti wọn si ṣeto rẹ fun awọn arinrinajo bii apẹja, daran daran, ọdẹ, agbẹ ati bi iru rẹ.
Ó ní, “Àríyá yín ti dópin,ẹ̀yin ọmọ Sidoni tí à ń ni lára.
Sexual harassment bill: Àwọn aṣòfin buwọ́lu ẹ̀wọ̀n ọdún mẹ́rìnlá f'olùkọ́ tó bá fọwọ́ kan akẹ́kọ̀ọ́bìnrin lọ́nà àìtọ́
Òòró rẹ̀ jẹ́ aadọta igbọnwọ, (mita 25), ìbú rẹ̀ sì jẹ́ igbọnwọ mẹẹdọgbọn (mita 12½).
Ṣugbọn kò pa àwọn pẹpẹ oriṣa run, àwọn eniyan ṣì ń rúbọ; wọ́n sì ń sun turari níbẹ̀.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Howards Graduates: Barrack Obama gba àwọn akẹ́kọ̀ọ́jáde nímọ̀ràn láti fi àwọ̀ wọn yangàn 18 Òkùdu 2019 Oríṣun àwòrán, @ObamaFoundation Yoruba ni bi eegun ni ba jo re, ori a maa ya atọkun rẹ, bẹẹ si ni inu ẹni kii dun, ka pa mọra.
Ṣugbọn OLUWA gba Israẹli là,títí ayé sì ni ìgbàlà rẹ̀.
Ninu atẹjade kan ni ijọba Kano ti fẹsun kan Sanusi pe, ko bọwọ fun ofin ati awọn ilana kan, lo jẹ ki wọn fi ọwọ osi juwe ile fun un.
Wọ́n bá múra láti bá Samaria jagun.
Rehoboamu ṣe nǹkan burúkú, nítorí pé kò fi ọkàn sí ati máa rìn ní ìlànà OLUWA.
Saudi fẹ́ gbẹ̀mí 23 ọmọ Nàìjíríà tó gbé òògùn olóró Ìjọba, ẹ yé fi ọlọ́pàá àtàwọn ológun dúnkokò máwọn èèyàn- Ṣoyinka Irọ́ ló pa, a kò mọ̀ ọ́ rí tàbí fún ọ ní ₦13m - APC tako afurasí ajínigbé Ajeyẹmi wa gbadura fun gbogbo awọn obinrin rere fun ibukun Ọlọrun lori wọn, bakan naa lo gbadura pe wọn o jere iṣẹ ọwọ wọn.
Isẹju mẹfa ti ọkọ naa gbera kuro lati papakọ ofurufu Addis Ababa lọ si Nairobi ni orilẹede Kenya lo ja.
Maarun re ninu awọn iku wọn yi ti awọn akoroyin lagbegbe ti o ti ṣẹlẹ kọkọ gbe jade ti ikọ BBC to wa ni agbegbe naa si fidi wọn mulẹ fun wa.
Eeyan 35 miran ko aarun iba Lassa WHO yoo kapa aisan Lassa Fever Ẹgbẹ awọn dokita iṣegun oyinbo lorilẹede Naijiria ni lọwọ yii iye ti ijọba apapọ n ya sọtọ ni eto isuna rẹ fun eto ilera kere jọjọ, eyi si n se akoba fun idagbasoke ẹka yii, paapaa julọ eto ilera alabọde.
" Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 3 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 5 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
” Gbogbo ibo ti o yege  jẹ 2,199,535 ninu gbogbo ibo ti won si
Wọ́n ń fojú tẹmbẹlu àwọn aláṣẹ.
àìjíríà kéde èèyàn míràn pẹ̀lúu àrùn Coronavirus - BBC News Yorùbá BBC News, YorùbáFò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Yàjóyàjó - Nàìjíríà kéde èèyàn míràn pẹ̀lúu àrùn Coronavirus 9 Ẹrẹ̀nà 2020 Oríṣun àwòrán, Getty Images Ìròyìn tó ń tẹ̀ wa lọ́wọ́lọ́wọ́ ní wí pé ijọba apapọ orilẹede Naijiria ti kede eeyan keji to to ko aarun Corona virus lorilẹ̀ede Naijiria.
Àwọn iṣẹ́ náà nìwọ̀nyí: Òpó meji, ati àwọn ọpọ́n rìbìtì rìbìtì meji tí ó wà lórí àwọn òpó náà, ati iṣẹ́ ọnà tí ó ṣe sí ara àwo meji tí ó wà lórí ọpọ́n.
Ìkà, aninilára ni olórí tí kò ní òye,ṣugbọn ẹ̀mí ẹni tí ó bá kórìíra à ń jèrè lọ́nà èrú yóo gùn.
Lẹyin naa ni ileẹjọ giga ni ki wọn tun igbẹjọ naa bẹrẹ, amọ EFCC ti ni awọn n lọ si ileẹjọ giga lati yi idajọ naa pada.
Ìpínlẹ̀ Eko, Ọyọ ló lékè nínú àwọn tó ṣẹ̀ṣẹ̀ lùgbàdì àrùn Coronavirus ní Naijiria Apapọ awọn to ni arun Coronavirus ni Naijiria ti pe 65,457 bayii.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Nigeria 2019 Elections: Tinubu ní òun yóò sàjọyọ̀ ìsẹ́gun lọ́sẹ̀ tó ń bọ̀ 20 Èrèlè 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 21 Èrèlè 2019 Oríṣun àwòrán, @AsiwajuTinubu Eekan kan ninu ẹgbẹ oselu APC, Bola Ahmed Tinubu ti woye pe jinnijinni ti n ba awọn ọmọ ẹgbẹ oselu PDP, ti wọn si ti n sa kijokijo kiri.
Nítorí pé ó ti ṣẹ́ àjàgà tí ó wọ̀ wọ́n lọ́rùn,ati ọ̀pá tí wọn fí ń ru ẹrù sí èjìká,ati kùmọ̀ àwọn tí ń fìyà jẹ wọ́n.
 Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Gbajúgbajà òsèré tó tún mọ́ ọbẹ̀ sè Abajade ipade Obiano pelu awọn ọdọ: Lati gbe igbe aye idẹrun kalẹ ni ipinlẹ Anambra, Gomina Obano pinnu lati gbe igbimọ alakoyawọ kan kalẹ lati gbe awọn iwa kotọ to waye labẹ ikọ SARS ni ipinlẹ naa yewo."
Erongba orile-ede Israel lati da awon arinajo naa pada tabi ki won koju ewon ti sokunfa ibenu-ete lu latodo ajo ti o n ri si oro awon asatipo ninu ajo isokan orile-ede agbaye.
Wọ́n bá gbé Hamani kọ́ sí orí igi tí ó ti rì mọ́lẹ̀ fún Modekai, nígbà náà ni inú ọba tó rọ̀.
 Ósi yìí , bí a ti mọ ̀ ṣáájú jẹ ́ ọmọ lúwà .
Nigba ti iṣẹlẹ yi waye lọdun 1986, Naijiria si wa labẹ ijọba ologun labẹ akoso Ọgagun Ibrahim Babangida.
 Ìtàn lè xxxxxx pa wọ ́ n pọ ̀ nipa àjọjẹ ́ orúkọ , àjọṣe kankan lè máa sí láàárin wọn nígbà kan tí rí ju wí pé orúkọ yìí , tó wu ọ ̀ gbọ ́ ni kìíní Ọba Ìjẹ ̀ bú - jẹ ̀ ṣà nígbà tí ó bá àbúrò rẹ ̀ ajíbógun lọ bòkun , wọ ́ n gba ọ ̀ nà Ìjẹ ̀ bú - Òde lọ .
AMAA 2018- AYIAM OSIGWE FOUNDATION Ami eye fun fiimu NAijiria to pegede
Moi gba ilẹ naa to le ni aadọta ékà to jẹ ilẹ opo naa Susan Cheburet Chelugui, gẹgẹ bi adajọ ṣe sọ.
O mọ àwọn ohun tí ó dára jù nítorí a ti fi Òfin kọ́ ọ.
82% ọkùnrin ní kó mọ̀ pé òun ní àìsàn jẹjẹrẹ asẹtọ ní Naijiria Ìlànà ojúlówó márùn ún tó dènà àrùn Coronavirus Eyi sì ni yóò fi ọkàn wa balẹ pé, àkókò Coronavirus tá ń lá kọjá yìí náà yóò lọ.
Emi ati awọn ọrẹ mi ko gba, a gba ile ijo lọ, ti ọwọ si tẹ wa, eyi to mu ki wọn le wa kuro nile ẹkọ fasiti naa, lati fi wa jofin fawọn akẹkọọ yoku.
Àkọlé àwòrán, Bayii ni gbogbo igboro ti kun nibi isinku gomina Abiola Ajimobi Oríṣun àwòrán, Ajimobi Lives on Àkọlé àwòrán, Wọ́n ti sin Abiola Ajimobi!
A di ohun ẹ̀sín fún gbogbo ayé.
2bn Nigba ti Diamond Bank yoo san owo itanran N0.
Lójú opo ikan sira ẹni Twitter àti Facebook, onírúurú ọ̀nà ni awọn ọmọ Nàìjíríà ń gba daro olóògbé náà, bí àwọn kan se kárí bọnu pé ẹni re lọ, ní àwọn miran lọ ikú rẹ láti sọ oko ọ̀rọ̀ sáwọn oloselu Nàìjíríà.
Nígbà tí Jehu pada sí ọ̀dọ̀ àwọn ẹgbẹ́ rẹ̀, wọ́n bèèrè lọ́wọ́ rẹ̀ pé, “Ṣé kò sí nǹkan?
Oríṣun àwòrán, YouTube Àkọlé àwòrán, Fidio yii fihan bi wọn ti n ti oku eeyan sinu koto BBC Afaan Oromo gbe iroyin kan jade pe itankalẹ fidio naa ṣe okunfa ikọlu awọn ẹya Oromo ti wọn n gbe ni orilẹede Djibouti ati Somalia.
Wọ́n gbé àwọn òpó tí a fi òkúta ṣe ati àwọn ère Aṣerimu sí orí àwọn òkè ati sí abẹ́ àwọn igi tí wọ́n ní ìbòòji.
Wọ́n yan àwọn ọmọ Lefi tí wọ́n ti tó ọmọ ogún ọdún tabi jù bẹ́ẹ̀ lọ, láti máa bojútó iṣẹ́ ilé OLUWA.
 Kọmiṣọna naa ni ijọba ipinlẹ Eko ko ni yi ipinnu rẹ pada lori bo ṣe fofin de ọkada ati kẹkẹ maruwa ni ipinlẹ ọhun, ṣugbọn o sọ pe Titi Oṣu Kẹrin ọdun, ijọba yoo pese awọn ọkọ ti yoo rọpo ọkada ati kẹkẹ ẹlẹsẹ mẹta.
Ìwọ ni OLUWA, Ọlọrun, tí ó yan Abramu, tí o mú un jáde wá láti ìlú Uri tí ó wà ní ilẹ̀ Kalidea, tí o sì yí orúkọ rẹ̀ pada sí Abrahamu.
Nítorí rẹ̀ ni a ṣe bí mi, nítorí bẹ́ẹ̀ ni mo ṣe wá sáyé, kí n lè jẹ́rìí sí òtítọ́.
Ọlọ́pàá gbé àwọn tó yìnbọn lu olólùfẹ́ ní Ajegunle Ìgbà wo ni àjọ ọ́lọ́pàá yóò káwọ́ SARS?
Jesu dá wọn lóhùn pé, “Èmi gan-an ni oúnjẹ tí ń fún eniyan ní ìyè, ẹni tí ó bá wá sọ́dọ̀ mi, ebi kò ní pa á, ẹni tí ó bá sì gbà mí gbọ́, òùngbẹ kò ní gbẹ ẹ́ laelae.
“Nígbà tí àwọn talaka ati àwọn aláìní bá ń wá omi, tí omi kò sí,tí òùngbẹ ń gbẹ wọ́n, tí ọ̀nà ọ̀fun wọn gbẹ,èmi OLUWA yóo dá wọn lóhùn,èmi Ọlọrun Israẹli kò ní fi wọ́n sílẹ̀.
Kí n tó dé, tẹra mọ́ kíka ọ̀rọ̀ Ọlọrun, ati gbígba àwọn eniyan níyànjú, ati iṣẹ́ olùkọ́ni.
Nígbà tí Pilatu gbọ́ èyí, ó bèèrè bí ará Galili bá ni Jesu.
Ohùn kan wá láti inú ìkùukùu náà wí pé, “Àyànfẹ́ ọmọ mi nìyí, inú mi dùn sí i.
Ọjọ kẹrin, oṣu Kọkanla, ni nkan bi aago mẹjọ aabọ owurọ ni ikọlu tuntun yii waye, nigba ti awọn agbebọn wọ inu ileewe naa, ti wọn si pàṣẹ fun olukọ ati akẹkọọ láti bọ aṣọ wọn.
Akegbe re, Paul Kehinde gba ami-eye ipo keta ti n se, silver leyin ti o gbe ikun irin iwon ti o le okòólénígba-o dín kàn Kilo(219.
Ọgbẹni Olumẹkun ti o tẹnu mọ pataki pipese aabo fun awọn ondibo, rọ awọn alẹnulọrọ lati tubọ maa polongo pataki ṣiṣe eto idibo pẹlu alaafia ati idanilẹkọọ nipa eto idibo fun awọn ara ilu, bo ti lẹ ṣe pe wọn n gbiyanju lojuna eyi.
 gégẹ ́ bí a ṣe mọ ̀ pé àwọn yorùbá kìí ń sọ ̀ rọ ̀ lásán , wọn máa ń sọ ̀ rọ ̀ pẹ ̀ lú làákàyè àti ọgbọ ́ n .
Wọ́n ń bèèrè ìdájọ́ òdodo lọ́dọ̀ mi,wọ́n ní ìfẹ́ ati súnmọ́ Ọlọrun.
Àkọlé àwòrán, To ba ti kan ẹru kiko, ọwọ ara ẹni la fi n tun iwa ara ẹni ṣe Àkọlé àwòrán, Àwọn ẹṣọ pápákọ̀ òfurufú Abuja gan n fi pẹlẹ kutu ṣiṣẹ ni Àkọlé àwòrán, Diẹ diẹ lawọn ọkọ ofurufu to n rinrinajo.
5 million àwọn ọkùnrin ní united states .
 Ó tún maa ń jẹ ́ kí obìrin tí ó bá lóyún bímọ ̀ lọ ́ jọ ́ àìpé .
Ó sọ fún un pé, “Bí Ọmọ Ọlọrun bá ni ọ́ nítòótọ́, bẹ́ sílẹ̀.
Lẹ́yìn náà Jobu tún gbé ogoje (140) ọdún sí i láyé, ó rí àwọn ọmọ ati àwọn ọmọ-ọmọ rẹ̀ títí dé ìran kẹrin.
Àwọn ti ó nlọ si ibi iṣẹ́ agogo mẹjọ ni lati kúrò ni ilé ki agogo marun tó lù, wọn yio si wọlé ni agogo mẹwa lẹhin ti wọn bá pari iṣẹ́ ni agogo marun.
Nítorí ẹnu alágbèrè obinrin a máa dùn bí oyin,ọ̀rọ̀ rẹ̀ sì tuni lára ju òróró lọ,
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Ọ̀lọ́pàá shátà mi láti Mowe dé Magboro dé Shagamu, wọ́n ní ṣé mi ò mọ̀ pé ìjọ́ba ni mo ṣiṣẹ́ fún' Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Christmas: Ohun márùn ún tó yẹ kóo mọ̀ nípa ìtàn Kérésì25 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 2nd wave of Covid-19: Sanwo-Olu késí àwọn adarí ẹ̀sìn láti wọ́gilé ìsìn àṣálẹ́ àìsùn ọdún àti ìṣọ́ òòru25 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 3 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 5 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Ṣugbọn mò ń sọ ohun tí mo rò gẹ́gẹ́ bí ẹni tí Oluwa ti ṣàánú fún, tí eniyan sì lè gbẹ́kẹ̀lé.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'A ò tíì rí omi mu, ẹ ní ká máa fọwọ́ tóríi Coronavirus' Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Nigeria Debt: NBS ní Nàíjíríà jẹ gbèsè ₦32.
Ọlọrun àwọn eniyan yìí, eniyan Israẹli, yan àwọn baba wa.
"O ni ajakalẹ arun covid-19 si wa ni Naijiria, amọ ""sayẹnsi n sọ fun wa pe a le bori arun naa nipa ṣiṣọra."
egbe PDP Secondus naa ti pe lati yo alaga ajo eleto idibo lorile ede Naijiria
Ibeere re ti awọn ọmọ Naijiria n gba ni agba tungba loju opo Twitter niyii lẹyin ti Obasanjọ fori jin Atiku.
yoo waye ni ojo kerindinlogun osu keji odun yii’’.
Ìdáhùn àwọn òbí wa sí kíkí ọ̀kan-ò- jọ̀kan wọ̀nyí ni:
Àpanisáyé ni ẹ̀wà tí wọ́n n fí 'sniper' sí Ìtàn tó wà nídi òwe ‘Sebótimọ Ẹlẹ́wà Sàpọ́n’ Yetunde Barnabas ọkan ninu awọn arinrin oge naa ni ko si nkan to le ba oun ninu jẹ lori bi Aṣẹda ṣe da aawọ ara oun.
Liverpool kun Arsenal wẹ́lẹ́wẹ́lẹ́ bí ẹran àsun 'lójúbọ' Anfield Ọwọ́ ba Ole!
Omooba Wales, to tun je aremo si ipo oba ni orile ede Britain , Chales ati iyawo re Camilla ti de si ilu Abuja.
Ahasu-erusi ọba bi Ẹsita Ayaba pé, “Ta ni olúwarẹ̀, níbo ni ẹni náà wà, tí ń gbèrò láti dán irú nǹkan bẹ́ẹ̀ wò?
Ijọba ilẹ Gẹẹsi rọ awọn ẹgbẹ agbabọọlu ogun to wa ninu idije naa lati gba awọn ifẹsẹwọnsẹ to ku lawọn papa iṣere mii yatọ si ti wọn.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, CAN: Samson ni ọrọ awọn ajinigbe ti gba àpérò ní Naijiria Aarẹ Buhari Buhari ti gba ẹnu ẹgbẹ oṣelu APC ki alagba Fasoranti pe oun ba a kẹdun ipapoda ọmọ rẹ ti awọn ti Ọlọpaa ipinlẹ ṣapejuwe gẹgẹ bii janduku apaayan pa lọna Ondo si Ọrẹ.
Mo tún ṣe ìlérí pé, n kò ní í jẹ́ ẹelẹnu méjì bí i fèrè, kí n wí pé mò ń lọ sí odò, kí wọ́n bá mi ni oko, ki n pé ẹnìkan ní ará ilé mi, ki wọ́n báa pá kò bá mi tan.
Oríṣun àwòrán, @NGRSenate Àkọlé àwòrán, Pupọ awọn ti wọn ko lọ ni wọn ta si oko ẹru igbalode Asoju ajọ isọkan ilẹ Yuroopu, Eulorilẹede Naijiria, Ketil Karlsen ni tirẹ salaye siwaju sii wipe, Owo to to biliọnu mọkanlelogun Naira ni ajọ isọkan ilẹ Yuroopu, EU ti na lori gbigbogun ti iwa kiko awọn eeyan lọ silẹ okeere lọ sowo kotọ lorilẹede Naijiria.
Àwo kòtò tí wọ́n fi wúrà ṣe kan tí ìwọ̀n rẹ̀ jẹ́ ṣekeli mẹ́wàá, tí ó sì kún fún turari; 
Fayose to sọrọ naa loju opo Twitter rẹ sọ pe, ti ajọ EFCC ko ba le duro di igba naa pẹlu iwadi wọn, ki wọn wa si ọọfisi oun l'Ọjọbọ nilu Ado Ekiti.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Mother Language Day: Bàbá míì ní àìkọ́ ọmọ òun ní Yorùbá ló mú kò pàdánù iṣẹ́ olówó ńlá Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Lẹyin-o-rẹyin, wọn fi panpẹ ofin mu, o si gba lati tẹle wọn lọ si agọ wọn.
Mo bá lọ sí ẹ̀bá odò Yufurate; mo gbẹ́ ilẹ̀, mo yọ aṣọ funfun náà jáde kúrò ní ibi tí mo bò ó mọ́.
Bi o tile je pe, China ti ni oko oju-omi Soviet-era Liaoning nla kan tele, eyi ti won ra lowo ijoba orile-ede Ukraine lodun 1998, sugbon ni bayii, won ti n ko oko oju-omi nla miran ti won yoo se ifilole re lodun 2020.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Satguru Maharaj Ji: Lẹ́yìn tí wọ́n fi kakata hú gbogbo iṣú àti ẹ̀gẹ́ mí, wọ́n tún ṣá àwọn ọmọ mi ládàá 8 Agẹmo 2020 Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Satguru Maharaj Ji: Awọn ọmọ onílẹ̀ àti ọlọ́pàá jọ gbìmọ̀ pọ̀ láti gba ilẹ̀ mí Satguru Maharaji ti fẹ̀sùn kan pé àjọ ọlọ́pàá ní ìpińlẹ̀ Oyo pé wọn gbìmọ ọ̀tẹ pẹlú àwọn ọmọ onílẹ̀ láti gba ilẹ̀ òun.
    Nípa ọ̀rọ̀ tí ẹ bá mi sọ, mo bẹ̀ yín kí ẹ máṣe bínú èsì tí mo fẹ́ fún yín: ọ̀rọ̀ náà kò ní lè rí bẹ́ẹ̀ rárá.
Lọwọlọwọ, mi ko ni ololufẹ kankan.
Bẹẹ ba gbagbe, o ti to ọjọ mẹta bayii mẹta ti ikede ti n lọ pe Sunday Igboho yoo ko awọn eeyan kan sodi, lati se iwọde fun ominira ilẹ Yoruba.
Gbogbo wọn ni wọ́n faramọ́ ìmọ̀ràn yìí àfi Jonatani, ọmọ Asaheli ati Jahiseaya, ọmọ Tikifa.
Ará ìlú dájọ́ oró fún ọkùnrin to bẹ́ orí ẹ̀gbọ́n rẹ̀ ní Cross River Pẹ̀lú gbogbo bùkátà, Bàbá 80 gboyè Masters Kíni N11trn owó ìrànwọ́ epo tí ìjọba àpapọ̀ san fún àwọn agbépo lè rà?
O pari ọrọ rẹ pe ki awọn eeyan ṣora fun orilẹ-ede France ati ilẹ Gẹẹsi lasiko yii nitori awọn orilẹ-ede naa ni Covid-19 ti burẹkẹ ju ninu oṣu Kẹwaa ọdun 2020 yii.
Lẹyin idajọ naa ni ijọba ipinlẹ Osun gbiyanju lati yọ Ọba Falabi lori itẹ.
Àwọn ọmọ Besai jẹ́ ọọdunrun ó lé mẹrinlelogun (324).
Àwọn ará Beti Asimafeti jẹ́ mejilelogoji.
“O je ojuse wa lati ri I daju pe,  aabo ati eto ilera  to peye wa ni ibamu pelu ofin ati ilana ti won la sile laifi  ipenija to n doju ko  won se.
Yakubu  ni aare Buhari ni iye ibo to yẹ ko ni labẹ
Wọn á máa so èso títí di ọjọ́ ogbó wọn,wọn á máa lómi lára, ewé wọn á sì máa tutù nígbà gbogbo;
Bí ẹ bá ti ká èso àjàrà yín, ẹ kò gbọdọ̀ pada sẹ́yìn láti ká àwọn èso tí ẹ bá gbàgbé.
“Àwọn ẹṣin wọn yára ju àmọ̀tẹ́kùn lọ, wọ́n burú ju ìkookò tí ebi ń pa ní àṣáálẹ́ lọ.
Wo bí àwọn ọmọ yìí ti ń ṣe é Koda onimọ nipa ẹṣin Islam naa sisọ loju rẹ pe, afurasi ọhun lo sun mọ oun bii iṣan ọrun, to si n ṣe akoso awọn oju opo ayelujara ti oun ti maa n ṣe waasi aawẹ Ramadan.
Ó yẹ kí Buhari dá owó epo padà sí ₦97 tàbí kó kọ̀wé fipò sílẹ̀ - Àwọn akẹ́kọ̀ọ́ Ọmọ Ààrẹ lẹ́tọ̀ọ́ láti ṣe ìgbéyàwó yálà àwọn ará ìlú fẹ́ràn ìjọba bàbá rẹ̀ tàbí bẹ́ẹ̀ kọ́ - Aisha Buhari Owó lítà epo ní Nàíjíríà ló kéré jùlọ l‘Áfíríkà - Lai Muhammed Ìjà ẹgbẹ́ òṣèré TAMPAN àti ANTP ni kò jẹ́ kí wọ́n pe Baba Legba sínú eré mọ́, kó tó kú - Owolabi Ajasa Atẹjade NBS fihan pe ọrọ aje awọn olugbe ipinlẹ mẹrẹẹrin naa dẹnu kọ lẹ laarin oṣu kẹfa si ekeje.
Oríṣun àwòrán, YASUYOSHI CHIBA O ni ijọba aarẹ Buhari kuna lati mu igbayegbadun ba awọn eniyan lasiko rẹ nitori wi pe ohun gbogbo lo nira fun wọn, paapaa pẹlu bii ikọ ọlọpaa SARS ṣe n dẹmi awọn ọdọ legbodo, ti ijọba ko si bikita.
Bí wọ́n ti ń pada bọ̀ wálé, lẹ́yìn tí Dafidi ti pa Goliati, àwọn obinrin jáde láti gbogbo ìlú Israẹli, wọ́n lọ pàdé Saulu ọba, pẹlu orin ati ijó, wọ́n ń lu aro, wọ́n sì ń kọrin ayọ̀ pẹlu àwọn ohun èlò orin.
Mohammed Badaru Abubakar ti ipinle  Jigawa , Gboyega Oyetola ti ipinle Osun, Abubakar
Bí ọjọ́ ṣe ń lọ láì rí ẹ̀rí tí ó yanrantí dì mú, SNTP darapọ̀ tí ó bẹ̀rẹ̀ àbẹ̀wò sí olú ilé iṣẹ́ẹ Ọ̀tẹlẹ̀múyẹ́ :
Arakunrin kan to ti gbiyanju lati gbe iwe iroyin naa lọ ile ẹjọ tẹlẹ ri lo ṣe ikọlu naa.
‘Èpè ni Toyin Abraham sẹ́ fún mi nínú ìgbìyánjú mi lórí ìgbeyàwó rẹ̀ tó dàrú’ Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí kan sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
Òun ló sọ pé, àfi bí àwọn àṣẹ wọnyi bá yipada níwájú òun,ni àwọn ọmọ Israẹli kò fi ní máa jẹ́ orílẹ̀-èdè títí lae.
Baba olórìṣà Seusi bá mú mààlúù ati òdòdó jìngbìnnì, òun ati ọpọlọpọ èrò, wọ́n ń bọ̀ lẹ́nu odi ìlú níbi tí pẹpẹ Seusi wà, wọ́n fẹ́ wá bọ wọ́n.
Oríṣun àwòrán, @Ondo House of assembly Àkọlé àwòrán, Aṣòfin Iroju Ogundeji, Favour Tomowewo àti Williams Adewale ń lọ rọọkún nílé Olórí òṣìṣẹ́ ìjọba ìpínlẹ̀ Kwara, Adisa Logun ti dágbére fáyé lẹ́yìn tó lùgbàdì àrùn Covid-19 Fọwọ́ kan obìnrin lọ́nà àìtọ́, kí o rẹ́wọ̀n ọdún mẹ́rìnlá he- Àwọn aṣòfin yarí Bí àwọn adarí ìjọba ṣe ń kó Coronavirus, ń kọ wá lóminú - Ìjọba àpapọ̀ Àkójọ́pọ̀ àwòrán rèé lórí bí ìwọlé akẹ́kọ̀ọ́ ṣe lọ sí ní Oyo Ẹsun ti wọn fi kan awọn aṣofin mẹtẹẹta yii ni pe wọn n tapa si ofin ile igbimọ aṣofin.
Oríṣun àwòrán, Seyi Makinde Bakan naa ni gbajugbaja ajafẹtọ ẹni kan, Sunday Igboho naa sọ bẹ ẹ laipẹ yii, to si ni oun ati awọn oṣiṣẹ alaabo kan lo le awọn janduku naa kuro ninu igbo kan ni agbegbe Oke Ogun nipinlẹ Oyo.
Ebunoluwa lọ́ si fásitì Sussex láti kan Media Technology, lẹ́yìn náà ló tú lọ sí fásitì Oxford Brooks nibi tó ti ka Media Communication àti Culture.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù August Alsina: Ohun tó ṣẹlẹ̀ rèé láàrin wa àti àlè ìyàwó mi 11 Agẹmo 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 12 Agẹmo 2020 Oríṣun àwòrán, Red table talk Ilumọọka olorin August Alsina ti fesi si ọrọ ti ololufẹ tẹlẹ, Jada Pinketh Smith sọ pe oun atirẹ n ba ara wọn lajọṣepọ lasiko toun ati ọkọ rẹ fi pinya.
Idi ni yii to fi ronu pe ẹnikansoso to lee ge iyẹ apa Timi ni ọrẹ minu rẹ, Gbọnka Ebiri nitori ole nii mọ ẹsẹ ole tọ lori apata.
O wa tun wa ro awon eniyan
Wọ́n ń lu àwọn ohun èlò orin olókùn tí wọ́n ń pè ní hapu, ati lire; ati ìlù, ati ṣẹ̀kẹ̀rẹ̀ ati aro.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ìtàn ayé Henry Fajemirokun, olówó tó fi owó mọ Olúwa àti ènìyàn Iléesẹ́ rẹ́kọ́ọ̀dù tí mo ti bẹ̀bẹ̀ láti kọrin, padà di tèmi lónìí - Ebenezer Obey Ọ̀pá epo NNPC bú gbàmú ní Benin, òṣìṣẹ́ méje kàgbákò ikú òjijì Ọ̀fọ̀ ńlá ṣẹ̀ ní Ivory Coast, Olóòtú ìjọba, Amadou Gon Coulibaly jáde láye Tó o bá fẹ́ wọ bàálù lásìkò yìí, wo òfin tuntun tó tẹ̀lé Nigba ti BBC Yoruba kan sile oloogbe Adeyeri nilu Akure, a ri awọn olubanikẹdun ti wọn ti ya bo ile naa lati daro ẹni re to lọ.
Ọrẹ Tolu to sọ fun BBC Yoruba pe oun ko fẹ darukọ oun ṣalaye pe ọrẹ Tolu nileewe girama lo ri i loju titi, nibi ti ọrẹ rẹ ọun ti n rifaasi sẹyin pẹlu ọkọ lo ti kọlu Tolu.
Àwọn ọmọ ogun tí a kà ninu wọ́n jẹ́ ẹgbaa mẹtalelogun ó lé ẹẹdẹgbẹta (46,500).
Nebukadinesari, ọba Babiloni, gbógun tì í, ó sì fi ṣẹ́kẹ́ṣẹkẹ̀ dè é, ó fà á lọ sí Babiloni.
Oríṣun àwòrán, FACEBOOK Àkọlé àwòrán, Oludije si ipo gomina ni Ọṣun labẹ ẹgbẹ oselu SDP ni ọdun 2018 n jẹ agbado sisun lori ọkọ ayọkẹlẹ lasiko ipolongo.
- Ẹgbẹ́ àgbẹ̀ kìlọ̀ Ìséde ń bọ̀ káàkiri Nàìjíríà, àwọn gómìnà ìpínlẹ̀ fẹ́nukò Báwo lọ̀rọ̀ Tafsir, ìdanilẹ́kọ̀ọ́ lásìkò Ramadan yóò ṣe jẹ́ pẹ̀lúu Coronavirus tó gbòde yìí?
Aare Buhari ni pupo ninu awon
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù EndSARS Protest Update: Àwọn olórí orílẹ̀èdè yí nígbàkanrí sọ̀rọ̀ nípa ọ̀nà láti dẹ́kun ìwọ́de ọ̀dọ́ lọ́jọ́ iwájú 22 Ọ̀wàrà 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 25 Ọ̀wàrà 2020 Oríṣun àwòrán, Presidency nigeria Awọn olori orilẹede Naijiria nigbakan ri ti mu amọran wa lori bi orilẹede Naijiria ṣe le dena irufẹ iwọde to waye lori #EndSARS eleyii to fa rogbodiyan ti ko lẹgbẹ lawọn ipinlẹ kan lorilẹede Naijiria.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Elebuibon: Àwọn àṣà àtọ̀húnrìnwá ló fa títa ẹ̀jẹ̀ nítorí ògùn owo Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Nitori naa Niajiria yoo gbe igbesẹ to yẹ nigba ti asiko ba tọ lati ri wi pe iṣẹ dopin ni Naijiria.
Èmi OLUWA ni mo wí bẹ́ẹ̀.
Ọlọ́pàá ìpínlẹ̀ kọ́ ní ojútùú ìṣòro ìjínigbé ilẹ̀ Yoruba - Onímọ̀ ọ̀rọ̀ ààbò Amọṣa, agbẹjọro fun ijọba ni irọ funfun balau ni awijare naa nitori oun fidi rẹ mulẹ pe orukọ Amaju Pinnick tabi eyikeyi ninu awọn mẹrin toku ko si lara awọn ikọ ti ijọba apapọ ran lọ.
bi awon ile –eto idajo ati igbimo asoju ipinle yoo se da duro nipa eto inawo
Ile Igbimọ Aṣofin Ipinlẹ Eko ṣe ipade bonkẹlẹ ni
"Agbẹjọro SERAP Kolawole Oluwadare ati Opeyemi Owolabi to pe ẹjọ yii ni: ""Ṣiṣe iṣẹ tọ ilu tumọ sí pe kí eeyan fi awokọṣe daada le'lẹ to fi mọ ki awọn to di ipo mu gan mu adinku ba owo gọbọi ti wọn n gba, ko le wa ni ibamu pẹlu t'awọn ara ilu to pe wọn lẹjọ"" Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Blind Couples: Pẹ̀lú ìpèníjà ojú, tọkọtaya bímọ mẹ́ta, tí wọn sì tún ń ṣiṣẹ́ olùkọ́ Won tun ni ki ile ẹjọ f'asẹ sí pe owo t'awọn eekan ninu ijọba n gba, toun ti bi ilu ko ṣe rọgbọ, ko bofin mu."
"Oríṣun àwòrán, Other ""Ṣe o ni ida kan owo ti awọn olowo agbaye bii Jeff Bezos, Bill Gates ati Warren Buffet, ti kii san ida mẹwaa ni bi?"
Okoye ni iroyin ti de eti ajọ Inec lori bi wọn se n ji apoti idibo gbe ni agbegbe Akokotoro ati Bonny nipinlẹ Rivers, Eko ati ni Anambra.
Nitori naa a duro lori pe gbogbo ibo ti Atiku ni lasiko idibo, ofo lasan ni.
Àwọn akẹ́kọ̀ọ́ bẹ̀ ìjọba láti ṣ'íléèwé fún ìdánwò WAEC, ìpinnu ìjọba ilẹ̀ Yorùbá rèé Ìkéde ìjọba àpapọ̀ pé àkẹ́kọ̀ọ́ kò ní ṣe ìdánwò WAEC yàtọ̀ sí àdéhùn wa - ANCOPSS Èmi àti Sanyeri ti tọrọ oúnjẹ jẹ rí nílé oninawo torí ebi, ká tó di gbajumọ oṣere Ìjọba àpapọ̀ kéde ọjọ́ tí ìdánwò NECO, NABTEB àti BECE yóò bẹ̀rẹ̀ Gẹgẹ bi at alakalẹ naa ṣe ri eyi ti ileeṣẹ BBC Yoruba ri, bayii ni gbogbo eto idanwo naa yoo ṣe lọ: Oríṣun àwòrán, Waec Oríṣun àwòrán, Waec Oríṣun àwòrán, Waec Oríṣun àwòrán, Waec Oríṣun àwòrán, Waec Oríṣun àwòrán, Waec Ajọ WAEC wa gba awọn aṣedanwo nimọran pe ki wọn tẹle ofin ati alakalẹ fun idanwo naa nipa yiyọwọ kuro lawo magomago lasiko idanwo ati pe ki wọn tẹle gbogbo ofin to rọ mọ Covid-19 eyi ti awn ibudo idanwo wọn ti fi silẹ.
Kanran, ẹni to ke gbajare bẹẹ lori eto redio kan nilu Ibadan, lo n ṣe omije loju poroporo lasiko eto naa.
Sùgbọ́n nígbà ti òun débẹ̀ lọ́jọ́ náà ni wọ́n sàlàyé pé nítori ààrùn Covid-19, àwọn kò ní lé ṣe ètò náà mọ́.
Bakan naa ni ija lori ẹni ti yoo maa ṣakoso ipese epo-rọbi to wa ni agbegbe Niger Delta, naa ko ipa pataki.
Amọṣa o, ẹgbẹ oṣelu APC ti ni igbesẹ awọn aṣofin mẹta yii ko tu irun kan lara oun o.
Àwọn osisẹ yabo iléesé MTN ní Nàìjíríà Iroyin fikun wipe ikọwefiposilẹ rẹ waye nigba to ku ọgbọn isẹju ti olotu naa yoo se ipade pẹlu awọn asofin ni Ile Igbimo Asofin Orilẹede naa nipa afihan ero rẹ tuntun lori ati kuro ninu Ajo Isọkan Europe ( European Union) naa.
Fayoṣe ti gba ìtúsílẹ̀ kúrò l'ẹ́wọ̀n Ìwádìí ìwé ẹ̀rí àwọn olùdíje Ààrẹ lọ́dún 2019 PDP: Ayé sì wà fún Ambode to bá fẹ tíkẹ̀ẹ̀tì Gómìnà lọ́dọ̀ wà Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Adetoun Ogunṣẹyẹ: ìrìnàjò ẹ̀kọ́ mi títí dé òkè kò rọrùn rárá Ẹsun ti wọn fi kan Omisore ni pe ẹgbẹ Afenifere ye ki wọn mọ gbogbo igbesẹ to gbe lasiko idibo ni ipinlẹ Osun , ṣugbon Omisore kọ lati se bi o ti yẹ ki o se e.
    Bí á ti ṣe ètò yìí náà ni a tẹ̀lé e, ìgbà tí ọba dé ààrin ọjà, a gbọ́ ariwo ni ilé wa, àwa ọdẹ sì to ni ẹsẹẹsẹ a tẹ̀lé ara wa ọgbọn-ọn ran kan, à ń lọ, gbogbo wa jẹ́ àádọ́ta.
Kwara Politics: Ayo Adedoyin ti ẹgbẹ Accord Kwara sọ̀rọ̀ lórí níní bàbá ìsàlẹ̀
ni aadọta ati meje (15,357), nigba ti akẹgbẹ rẹ lati ẹgbẹ oṣelu PDP,
ọ̀dàlẹ̀, jàǹdùkú, àwọn tí ó jọ ara wọn lójú pupọ, àwọn tí wọ́n fẹ́ràn fàájì, dípò kí wọ́n fẹ́ràn Ọlọrun.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Dandan ni bàyíì fún àwọn màálù ni Uganda láti gba ìwé ọjọ́ ìbí 19 Agẹmo 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Gbogbo maalu l'orilẹede Uganda yoo bẹrẹ si ni gba iwe ọjọ ibi laipẹ, ko le baa rọrun lati tọ pinpin ibi ti wọn ti wa.
Bí ẹnìkan bá ń lò yín bí ẹrú, tí ó ń jẹ yín run, tí ó fi okùn mu yín, tí ó ń ṣe fùkẹ̀ láàrin yín, tí ó ń gba yín létí, ẹ ṣetán láti gba irú ẹni bẹ́ẹ̀.
Ní ọdún karun-un tí Joramu ọmọ Ahabu jọba ní Israẹli, ni Jehoramu ọmọ Jehoṣafati jọba ní ilẹ̀ Juda.
Nígbà náà ni Miriamu, wolii obinrin, tíí ṣe arabinrin Aaroni, gbé ìlù timbireli lọ́wọ́, gbogbo àwọn obinrin sì tẹ̀lé e, wọ́n ń lu timbireli, wọ́n sì ń jó.
Kí o wá kó àwọn ọmọ ogun mìíràn jọ, kí wọ́n pọ̀ bí i ti àkọ́kọ́, kí ẹṣin ati kẹ̀kẹ́ ogun pọ̀ bákan náà.
ẹri mo yege ni ọjọ kẹ́tàdínlọ́gbọ̀n
Mo sì tún dáhùn mo ní, Èni ọmọ ènìyàn ní ń pè ọ́ lórí igi, mo fẹ́ kí o ṣe ìrànlọ́wọ́ fún mi kí n lè tètè kúrò níbi tí mo lé téńté sí lórí igi.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ero ara ilu lori owo awọn sẹnatọ Naijiria Mallam Aaron ni nitootọ ni banki Naijiria kede pe ki awọn gba awọn owo atijọ pada wọle ni gbendeke asiko kan.
Harani ni baba Milika ati Isika.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Kano Chained Man: Ìdáǹdé dé fún bàbá táwọn ẹbí rẹ so mọlẹ fun ọgbọn ọdun 10 Ọ̀pẹ̀̀ 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 21 Ògún 2020 Oríṣun àwòrán, Human Rights Network Ni ilu Kano lẹẹkan si, itura ti de ba baba ẹni ọdun marundinlọgọta kan, ti wọn fi ẹwọn so mọlẹ fun ọgbọn ọdun.
 nígbà tí ilẹ ̀ austria-hungary ríbi tí ọ ̀ rọ ̀ yìí ń tọ , wọ ́ n tẹsẹ ̀ dúró fún ìjíròrò pẹ ̀ lú ilẹ ̀ russia .
Ogunlọ́gọ̀ ìlú kéékèèkéé ni a kàn lójú ọ̀nà, àǹfààní tí mo sì rí nínú ìlú wọn-ọnnì pọ̀ gidigidi.
Gẹgẹ bi akọsilẹ ajọ to n gbogun ti ajakalẹ arun ni Naijiria, NCDC, eeyan to din ọgọrin ni ẹgbẹrun mẹrun(3,820) lo ko arun coronavirus lapapọ ni Naijiria lọsẹ to kọja.
Agbábọ́ọ̀lù Super Falcons tẹ́lẹ̀, Chiejine jáde láyé Joseph Attah ni nitootọ ni sunkẹrẹ fakẹrẹ n wa lasiko yii ṣugbọn awọn ko figba kankan ti ẹnu bode naa pa.
Ọpẹ́ ni fún OLUWA,tí kò fi wá ṣe ẹran ìjẹ fún wọn.
O fi kun un pe oun yoo ran awọn ile alaini naa lọwọ.
Ṣugbọn ó sọ fún wọn pé, “Dandan ni fún mi láti waasu ìyìn rere ìjọba ọ̀run ní àwọn ìlú mìíràn, nítorí ohun tí Ọlọrun rán mi wá ṣe nìyí.
Nígbà àtijó, ogun àti ọ̀tẹ̀ pò ní orílè èdè Nàìjíríà.
Ṣùgbọ́n a dúpẹ́ lọ́wọ́ Ọlọ́run Ọba wí pé Igbó Irúnmọ́lẹ̀ dẹ ẹ̀dá náà lọ́rùn ju Igbó Olódùmarè lọ.
Shuvra Kar kọ sí oríi Facebook:
Pẹ̀lú èyí ni àwọn ọ̀rẹ́ méjéèjì jọ ń ṣòwò, tí wọ́n ń bóde pàdé tí wọ́n sì ń kó èrè wọn pọ̀ sójú kan náà.
Àwọn ọmọ ìlú tí wọ́n ń ṣàmúlò ayélujára ti bẹ̀rẹ̀ ìkọkúkọ sórí àwòrán ààrẹ Nkurunziza nínú ìfẹ̀hónúhàn pẹ̀lú àmì ìdámọ̀: Nkurunziza àti Burundi:
OLUWA sì dá angẹli tí ń bá mi sọ̀rọ̀ lóhùn pẹlu ọ̀rọ̀ ìtùnú.
Bakan naa ni wọn ko dakẹ lori bi Atiku Abubakar, tọ jẹ oludije fẹgbẹ oṣelu PDP ṣe kọ lati kopa ninu eto ijiroro naa, lẹyin to yọju sibudo ijiroro ọhun.
O da bii wipe awọn alaṣẹ ni ki awọn eeyan kan jokoo sile ṣugbn wọn kọ lati pin nkan iranwọ lati mu asiko naa dẹrun fun awọn ti ko rọwọ họri lawujọ, SERAP kọ eyi sinu ipẹjọ wọn.
Iroyin naa ni iwa ijinigbe ti wọpọ pupọ ni ọpọ agbegbe lorilẹede Naijiria, to fi mọ ipinlẹ Kaduna, tawọn ajinigbe yii si maa n foju sun awọn ọmọ Naijiria ati awọn ajeji lati ji wọn gbe gba owo.
Àwọn ará Ijipti lò wá ní ìlò ìkà, wọ́n pọ́n wa lójú, wọ́n sì mú wa sìn bí ẹrú.
Nigba to wa laye,o ko ipa ribiribi lagbo orin 'Rap' pẹlu bi o ti ṣe n fi ede abinibi rẹ,Yoruba da awọn eeyan lara ya.
O ti di ẹyìn tí a gbọ́dọ̀ dìmú pẹ̀lẹ́pẹ̀lẹ́ nítorí tí a bá jẹ́ kí o bọ́, tí o sì fọ́, kò ní ṣé kójọ mọ.
Bakan naa ni wọn wa parọwa si ijọba lati ri wi pe wọn ṣe agbekalẹ awọn ibudo ayẹwo ti awọn ọkunri to ba ti to ẹni ogoji ọdun ti le se ayẹwo ni kiakia.
Solomoni tún fi kún un pé, “Ó jẹ́ èrò ọkàn baba mi láti kọ́ ilé fún OLUWA Ọlọrun Israẹli.
Nítorí náà, ẹni tí ó bá gbọ́n yóo dákẹ́ jẹ́ẹ́ ní irú àkókò yìí, nítorí pé àkókò burúkú ni.
Awọn agogo yii a maa dun bi wọn ba ti n lu ilu naa, yatọ didun ilu agogo eti rẹ naa ni adun lọtọ.
Nítorí ninu gbogbo ẹ̀yà Israẹli, ẹ̀yà Lefi ati ti arọmọdọmọ wọn ni OLUWA Ọlọrun yín ti yàn láti máa ṣe iṣẹ́ alufaa fún un.
Wo ọ̀pọ̀ àṣeyọrí tí Aláàfin ṣe láti àádọ́ta ọdún tó ti jọba Yoruba ni ariṣe larika, arika si ni baba iregun.
Ẹni tí Ẹwadàpọ̀ rẹ́rìn-ín sí, olúwarẹ̀ ṣe àríyá, ẹni tí o kí olúwarẹ̀ pa màlúù mẹ́tà, ẹni tí ó mọ́ lójú olúwarẹ̀ ṣubú lulẹ̀ ó tàkìtì méje.
Donny Van de Beek lo gba bọọlu sawọn Tottenham , ti bogbo igbiyanju ikọ Tottenham lati da a pada si ja si pabo.
Gẹ́gẹ́ bí alákòóso Bangladesh Waqf Administratioń ṣe sọ, gbígba àṣẹ pọn dandan láti gbé iṣẹ́ sílẹ̀, tà tàbí ṣe àtúnṣe sí ohunkóhun tí ó bá jẹ́ ti Waqf.
 O ni: “A fe se Kulturefest kaakiri Naijiria ki awon ewe le tubo mo sii nipa odun ibile agbegbe won ki o ma baa parun lojiji nitori asa ati ise se Pataki nile Adulawo.
Gbogbo wọn si lo jingiri ninu iwa gbigba ọkọ ayọkẹlẹ loju ibọn, jija ile ifowopamọ lole, to fi mọ awọn ileesẹ nlanla ati ibudo itaja, bẹẹ si ni wọn n da ẹmi awọn alaisẹ ọmọ Naijiria legbodo lojoojumọ Oyenusi, lo sọ ara rẹ di Dokita ọsan gangan, tawọn eeyan si mọ si Dokita ajanilole pani, to si di Dokita ọsan gangan lai lọ sile iwe girama lasan debi ileẹkọ fasiti Oyenusi la gbọ pe o ni ifẹ pupọ, paapa si abo, to si jẹ pe o gunle iwa idigunjale rẹ nitori pe ọrẹbinrin rẹ nilo irinwo Naira pere, eyi ti agbara Oyenusi ko ka, to si tori eyi bẹrẹ si ni gbe ibọn Oyenusi lọ ja ọkọ kan gba, to si ta mọto naa ni irinwo naira, eyi tii se deede iye owo ti ọrẹbinrin rẹ nilo, to si ko fun.
Ẹgbẹ CAN ni irufẹ isọkan bayii ni ijọ kristọni nilo lati dide lori awọn ohun to wi pe o n sẹlẹ ti 'ko bojumu lorilẹede Naijiria bii aisi ipin oni dọgba-n-dọgba ni bi wọn se pin ipo' Lori boya idi ti ijọ aguda fi pada darapọ mọọ nii se pẹlu oselu, agbẹnusọ fun ẹgbẹ CAN ni ẹgbẹ naa kii se ẹgbẹ oloselu bi awọn kan se n lero ati wipe idapọ ijọ aguda pẹlu ẹgbẹ naa to ti kọ silẹ lọdun marun sẹyin ko si fun imurasilẹ idibo ọdun 2019.
Jẹ́ kí àwọn ènìyàn máa rẹ̀ ọ jẹ, mú sùúrù fún wọn, ṣé ìwọ mọ̀ nínú ara rẹ pé, wọ́n bẹ̀rẹ̀ ìṣubú ni eléyìínì.
Àwọn àmì aposteli hàn ninu iṣẹ́ mi láàrin yín nípa oríṣìíríṣìí ìfaradà, nípa iṣẹ́ abàmì, iṣẹ́ ìyanu, ati iṣẹ́ agbára.
Adewale Ayuba: Ogun ń ja àgbo Fújì, ni wọ́n ṣe ń jà
9 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 EndSars in Portharcourt: Ọjọ́ méjì sẹ́yìn ni aya awakọ̀ Márúwá tí ọlọ́pàá pa bímọ tuntun10 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 3 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 5 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Ọba dáhùn, ó ní, “Ẹ má pa ààyè ọmọ yìí rárá, ẹ gbé e fún obinrin àkọ́kọ́.
Torinaa o kilọ pe wọn gbudọ fara balẹ gidi gan bi wọn ba fẹ ṣe iru ipinu yii tori wọn kii ko agba ogun ja wa lati ita.
Oríṣun àwòrán, Adesoji Aderemi Family Àkọlé àwòrán, O jẹ ọkan lara awọn eeyan to kọkọ laju, o kọ ẹkọ iwe, o lowo, o lọla, o gbajumọ, o si jẹ asaaju ilu.
 Mo dupe fun ebun wiwa laaye.
'Nínúu kí a yọ oyún inú rẹ tórí iṣẹ́ abẹ tàbí kóo wà nínú ìrora' Oyenusi ló mú mi wọ ẹgbẹ́ adigunjalè kó tó di pé mo b'Ólúwa pàdé - Kayode Williams Tunde Idiagbon, ọ̀gágun kògbagbẹ̀rẹ́ tó ní ẹ̀ẹ̀kan lóṣù ló yẹ kí ológun máa rẹ́rìín Oluwo yí ìpinnu padà,Telu lóun yóò tẹlé àṣẹ lọ rọọ́kún nílé ṣùgbọ́n.
Ohun miiran ti ijọba tun le ṣe ni ki o ṣeto abẹrẹ ajẹsara fun gbogbo araalu.
Àwọn ọmọ Israẹli ati àwọn ọmọ Lefi yóo dá oúnjẹ, waini ati òróró jọ sinu àwọn gbọ̀ngàn, níbi tí àwọn ohun èlò tí a ti yà sí mímọ́ fún lílò ní ilé Ọlọrun wa, pẹlu àwọn alufaa tí wọ́n wà lẹ́nu iṣẹ́ ìsìn ati àwọn olùṣọ́ tẹmpili, ati àwọn akọrin.
Ile-ise olopaa lorile-ede Uganda ti bere igbese akotun ninu osu tuntun  nipa yiya ojo kan sota, lati sayeye ojo igbera-eni sita awon olopaa obinrin, lati duro si awon opopona ilu Kampala ti n se olu ilu orile-ede Uganda.
" Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Mother Language Day: Bàbá míì ní àìkọ́ ọmọ òun ní Yorùbá ló mú kò pàdánù iṣẹ́ olówó ńlá Elebuibọn pari ọrọ pe, iwa ọlaju maa n koba eeyan ni, ti ko si n jẹ ki eeyan ni ami idanimọ gẹgẹ bi ọmọ ilẹ Yoruba atata.
Ṣé ó tọ́ kí ilé asòfin buwọ́lù abàdòfin mẹ́fà tí Ààrẹ Buhari kọ̀ sílẹ̀?
Lẹ́yìn náà Abineri pe Joabu, ó ní, “Ṣé títí lae ni a óo máa ja ìjà yìí lọ ni?
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, afin pupa Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
9 Ìgbé 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 23 Ìgbé 2020 Oríṣun àwòrán, Getty Images Osu Kejila ọdun to kọja ni coronavirus sẹyọ sugbọn bayi gbogbo aye lo n farakasa ajakalẹ kokoro aifojuri rẹ ati arun to n fa iyẹn Covid-19.
Ọ̀gágun náà bá fà á lọ́wọ́, ó mú un lọ sí kọ̀rọ̀.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù NLC: Ìpàdé ọjọ́ Ajé ni yóò sọ bóyá á yansẹ́ lódì 5 Sẹ́rẹ́ 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Ẹja pọnbele ni ipade to waye laarin minisita fọ̀rọ̀ osisẹ́ ati ijọba apapọ lọjọ Ẹti, nitori igun mejeeji ko lee fi ẹnu ọrọ jona lori igbesẹ sisan ẹgbẹrun lọna ọgbọn naira gẹgẹ bii owo osu to kere julọ fun osisẹ kan ni orilẹede yii.
O ni o han gbangba pe awọn ọta Iwọ-oorun Gusu Naijiria, to jẹ ilẹ Yoruba, lo awọn iwọde alaafia to waye naa, lati doju ogun kọ ẹkùn naa""."
Saraki fi da a loju pe ise irinna oko-oju – irin yoo kari Naijiria.
Wo iye tí ìjọba yóò gbà lọ́wọ́ Laycon gẹ́gẹ́ bí owó orí ẹ̀bùn BBNaija tó jẹ Ẹ gbà mí, Nàíjíríà gbá mi lórí àyẹ̀wò Covid-19 - Iyabo Ojo figbe ta N kò mọ ẹni tó fẹ́ gba ìyàwó mi, àmọ́ wọn máa ń sọ pé ó rẹwà - Mike Bamiloye Sadiya Umar Farouq ti ní pé ọwọ òun mọ́ lórí N2.
Kọmisọna fun ọrọ ọdọ ati ere idaraya Monday Uko lo fọrọ naa lede.
 Ọ ̀ rẹ ́ orímóògùnjẹ ́ ni ajíṣefínní tí ó ń ta kòkó .
Fayoṣe lo fi ọrọ yii lede lori opo Twitter rẹ nibi ti o ti sọ pe ko sewu loko, afi giri aparo.
Ami-ayo kan soso ti Adnan Januzaj gba wole lo ran iko agbaboolu orile-ede Belgium lati jawe olubori ninu ifesewonse ti o keyin nipele keje(Group G), eyi ti iko ohun gba pelu iko agbaboolu orile-ede England lojobo(Thursday).
BBC ko lọwọ ninu ayipada kankan to ba waye.
Àwọn tí wọ́n ṣeé náà sì ni wọ́n fún-un lórúkọ l’édè Jamaní àti Gẹ̀ẹ́sì.
Ṣaaju ni ijọba ipinlẹ naa fi atẹjade kan sita lati ṣalaye idi ti ijọba ko ṣe fẹ ki Aarẹ Muhammadu Buhari ati ẹgbẹ APC lo papa iṣere naa, to le gba ọgbọ̀n ẹgbẹrun eeyan lati joko fun ipolongo.
Joshua Ajayi, tileesẹ BBC Yoruba se sabẹwo si abule atọkọse naa lati bawọn mẹkaniki naa sọrọ, sugbọn asiko yii ni awọn osisẹ ileesẹ ọrọ ayika ya bo ibẹ lati gbe ilẹkun ibẹ ti, ti wọn si fi tipa gba ẹrọ agbohunsilẹ akọroyin naa.
Bẹẹ si awọn ọmọ ẹgbẹ́ Shitte ti n se iwọde lọpọ igba láti bèérè fún ìtúsílẹ̀ olórí wọn, Ibrahim El-Zakzaky, tó ti wà ní àhámọ́ àwọn ológun láti bi i ọdún méjì.
Ọ̀kan ninu wọn tí ó jẹ́ amòfin, bi í ní ìbéèrè kan láti fi dẹ ẹ́, pé, 
Ṣugbọn Aroloye sọ pe lodi si iṣẹṣe ilu Idanre ki obinrin jẹ Adele Ọba.
Ọbabinrin náà pẹlu àwọn iranṣẹ rẹ̀ bá pada sí ilẹ̀ wọn.
Ipinlẹ Ondo ni ohun alumọni to le bọ awọn ara orilẹede Naijiria ti wọn ba lo awọn ohun alumọni yii fun imugboro ọrọ ajẹ lorilẹede Naijria.
Alaafin of Oyo: Kí ni àjọṣepọ̀ tó wà láàrín Aláàfin, àwọn olorì àti àṣà igbá títí lóde Ọ̀yọ̀?
’Kí àwọn ará Jerusalẹmu sì wí pé,‘Ẹ̀jẹ̀ wa ń bẹ lórí àwọn ará ilẹ̀ Kalidea.
Ṣugbọn ko kọbi ara si i, nitori pe ko mọ pe ejo ni.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Awọn ologun gbajọba ni Robert Mugabe Powell ati Thyne ifipagbajọba to ba ju ọjọ meje lọ gan an ni a le pe ni ifipagbajọba.
Nítorí àwọn Mesaya èké ati àwọn wolii èké yóo dìde.
Fun bi wakati meta ni awon olopaa ati awon afehonu-han fija peeta, ki awon adari ti won pe fun ifehonu-han naa to juwo sile.
2019 Election: Naijiria ní àlùmọ́ọ́nì, owó láti mú 'Next Level' Buhari sẹ Ero awọn eniyan se ọtọọtọ lori iwe ipolongo ti Aarẹ Buhari gbe jade saaju idibo sipo aarẹ lorilẹ-ede Naijiria ni idibo gbogboogbo ti 2019.
Awọn elo ti wọn fi n se egbo ni agbado, ẹwa, epo pupa, tomati, abubọsa, ata, ati bẹẹ bẹẹ lọ.
OLUWA, kí ni mo tún lè sọ, nígbà tí àwọn ọmọ Israẹli ti sá níwájú àwọn ọ̀tá wọn?
Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Fídíò, Genotype: Kí làwọn àǹfàni àti ewu tí ẹ̀yà jínótáìpù rẹ le mú bá ìgbé ayé rẹ̀?
Nigba mii, Akinyele a sọrọ lori awọn aṣẹyọri to ti gbele aye ṣe, nigba miran ẹwẹ, Akinyele a sọrọ lori ilera rẹ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù India: Ẹ wo bí àwọn ènìyàn ṣe dóòlà èmí erin tó jálulẹ̀ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ India: Ẹ wo bí àwọn ènìyàn ṣe dóòlà èmí erin tó jálulẹ̀ 6 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Ọpẹlọpẹ awọn oṣiṣẹ pajawiri ati awọn araalu Tamil, lorilẹede India ni wọn jade lati doola erin to ja si koto ni agbegbe naa.
"Bo ṣe n lo n pariwo pe, ""ẹ ba mi mu Ọmọyẹ, ko duro fi aṣọ sara, ẹru lasan ni mo da baa pẹlu eewọ naa, ẹ jọwọ, ẹ ma jẹ ki Ọmọyẹ rin ihooho wọ ọja."
Nígbà tí mo wò ó dáadáa tí mo mọ̀ pé òun ni tí òun náà wò mí dáadáa tí ó mọ̀ pé emi ni a kí ara wa tayọ̀tayọ̀, mo ní, Ìjàǹbáforítì baba erin, òun náà sì dá mi lóhùn, ó ní Èmi ọkùnrin ni.
ohun tójú oníròyìn ń rí' Emir Sanusi to jẹ gomina apapọ banki Naijiria tẹlẹ, ko i tii sọrọ nipa igbesẹ gomina yii.
yoo gbe waye ni ojo Abameta yii.
O ni bi o tilẹ jẹ pe awọn ọmọ ẹgbẹ okunkun naa kan gbe oku Ebila lọ, sibẹ awọn lee sọ pe ẹkọ ṣoju mimu nibi ikọlu naa nitori pe awọn ri ẹni ti wọn ji gbe naa gba pada, ti wọn si tun ṣọṣẹ si ẹgbẹ okunkun naa.
Awọn ara adugbo kan ni awọn lero wipe ikọlu awọn ọmọ ẹlẹgbẹ okunkun lo fa iku awọn oloogbe naa.
Ṣugbọn, mi o ki n jẹ ko pẹ ti mo ti maa n jẹ ki ẹni naa o mọ nkan ti mo n ba a finra.
A fún wọn ní àṣẹ láti fi idà ati ìyàn ati àjàkálẹ̀ àrùn ati ẹranko burúkú pa idamẹrin ayé.
wahala oselu to wa ni orile ede naa.
ilé-okógbà : Àdúgbò yìí gba orúko rè nípa sè baba kan tí ó fé ràn isé oko púpò.
Asán ninu asán, bí ọ̀jọ̀gbọ́n ti wí, asán ninu asán, gbogbo rẹ̀ asán ni.
Ọṣẹ ti awọn ọlọpaa ṣe laarin ilu naa gba odi, awọn ọdẹ, agbẹ ati araalu lapapọ fa ibinu yọ, wọn ba ọpọ dukia to wa ninu aafin jẹ, ti wọn si tun sọ ina saafin Ọba Layode naa.
Gomina Oyetọla si tun kede pe oun yoo san ẹgbẹrun lọna ogún Naira fun eniyan 15,289 to jẹ arugbo ati akanda ẹ̀dá.
Kí ló dé tí ò ń fi ọwọ́ ara rẹ fa ìjàngbọ̀n tí ó lè fa ìṣubú ìwọ ati àwọn eniyan rẹ?
 Èyí túmọ ̀ ṣi pé babaláwo tí kò ba fojú bodù kò tii dangajia .
Nígbà tí Hadadi kú, Samila ará Masireka, jọba tẹ̀lé e.
Gbajugbaja eto BB Naija fun 2018 g'ori afẹfẹ
"Oríṣun àwòrán, PoliceNG ""A ti gbe oku lọ sibudo igbokusi nile iwosan, awọn to sese lati se itọju fun wọn, ta si ti bẹrẹ iwadi wa, awọn ọlspa ati fijilante ti wa ninu igbo lati se awari awọn eeyan to huwa ibi yii."
Àwọn ọmọ ilé ìwé fi páálí bojú láti má se jí ìwé wò!
Oluwo of Iwo: Nàìjíríà, sọ́ra, ogun ń sọ ilé ọlá di ahoro!
O ni oun fi iwe han wọn, ti wọn si ni ki oun maa lọ.
ọgọrun ninu oṣu kọkanla ọdun, eleyii to ri bẹẹ latari adinku to ba owo
Adari ẹgbẹ yii ni iha Guusu-Iwọ Oorun wa ni bi o ba jẹ aridaju ni pe ijọba Naijiria ṣe eyi, iwa naa ko mọgbọn dani rara.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Kogi FMC: Àwọn Jàndùkú kó àwọn àkọsilẹ̀ ilé ìwòsàn, ẹ̀rọ kọ̀mpútà ati fóónù àwọn dókìtà lọ 1 Agẹmo 2020 Oríṣun àwòrán, others Ìròyìn sọ pé àwọn jàndùkú yabo ilé ìwòsàn ìjọba àpapọ̀ FMC to wa nílùú Lokoja, ìpínlẹ̀ Kogi, ti wọ́n sì kó gbogbo àwọn àkọsilẹ̀ ilé ìwòsàn, àwọn kọ̀mpútà ati fọ́ọ̀nù àwọn dókìtà lọ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù 'Àgba tóri ẹ bá pé ni Naijiria nílò lásìkò yìí' Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ 'Àgba tóri ẹ bá pé ni Naijiria nílò lásìkò yìí' 22 Sẹ́rẹ́ 2019 Baba 70 ti dàgbà jú fún Naijiria ni èrò àwọn mii.
Iya Joseph, naa salaye pe, gbogbo igba ni oun maa n la ala ri ọmọ to ti ku naa, to n rin kiri plu ẹkun kikoro Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí 2 sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
Ajọ ajafẹtọ ọmọniyan l'agbaye, Amnesty International, ti ṣapejuwe idajọ naa gẹgẹ bi nkan to yanilẹnu, to si bani lọkan jẹ.
Bi o ba wa da ọ loju pe o mọ owe Yoruba, tẹ ibi yii ki o dahun bi o ṣe yẹ.
Kí á tó dá mi tán ni o ti rí mi,o ti kọ iye ọjọ́ tí a pín fún misinu ìwé rẹ,kí ọjọ́ ayé mi tilẹ̀ tó bẹ̀rẹ̀ rárá.
Tinubu afikun pe eyi lewu pupọ, to si lee se orilẹede kan ni ijamba taa ba gba iwa imọtara ẹni nikan laaye lati dagba.
12) lati fi maa sami ayeye eto ijoba tiwa-n-tiwa lorile ede yii.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ọwọ́ ọ̀lọ́pàá tẹ́ àwọn afurasí ayédèrú apòógùn l'Eko 14 Ọ̀pẹ̀̀ 2018 Oríṣun àwòrán, Abba Kyari Àkọlé àwòrán, Ileeṣẹ ti wọn ti n ṣe oogun naa to wa ni adugbo Ikọtun-Egbe, nipinlẹ Eko, ni ileeṣẹ ọlọpa tu aṣiri rẹ lọjọru.
Bi wọn ṣe n ṣe, BBC news Yoruba naa wa nibẹ.
Ikọ agbabọọlu Egypt ati Zimbabwe ni wọn koju ara wọn ninu idije iṣide ni Cairo.
Ẹni tí ó bá ti rí mi ti rí Baba.
Fayọse ninu atẹjade to fi lede, ti o si buwọlu sọ wi pe irọ lasan ni ijoko ajọ naa, nitori wi pe wọn ti mọ tẹlẹ wi pe Fayemi ni wọn ma a sọ wi pe o jawe olubori nibẹ.
 a gbọ ́ dọ ̀ bẹ ̀ rẹ ̀ sí fúnni láti ìgbà tí ènìyàn bá ti tó ọmọ ọ ̀ sẹ ̀ mẹ ́ fà .
Lọdun 2014 ni Macron da Minisita fun eto ọrọ aje ati idokowo labẹ Aarẹ tẹlẹri Francois Hollande to gba ipo lọwọ rẹ.
Orílẹ̀èdè Ígílándì ni wọ́n ti wá àmọ́ irúfẹ́ ìlù tí wọ́n lù, Brasil ni àṣà ọ̀hún ti jẹyọ.
Iṣẹ́ tí A Rán sí Sedekaya.
Nollywood Round up: Lizzy Anjọnrin fẹ̀si fáwọn agbọ́yì-sọ̀yí lórí ìgbéyàwó rẹ̀, Madam Sajẹ dasójú ilé iṣẹ́ àti àwọn ǹkan míràn tó ṣẹlẹ̀ lágbo tíátà lọ́sẹ̀ yìí
Eyi ni ẹlẹẹkẹta ti ina yoo jo ọja yii laarin ọdun mẹta.
Ajọ FRSC sọ ọrọ yii nitori iṣẹlẹ to to ṣẹlẹ ni ọja naa kọ awọn lominu.
Àwọn aguntan yín yóo di ti àwọn ọ̀tá yín, kò sì ní sí ẹni tí yóo ràn yín lọ́wọ́.
Bí o bá ti ń bá ọba sọ̀rọ̀ ni n óo wọlé, n óo sì sọ pé òtítọ́ ni ọ̀rọ̀ rẹ.
 Augustine Tochukwu Ukwuoma, alaga egbe awon onigbagbo fun ijo  Pastoral Agents Catholic, ojogbon Amidu Sanni,
Orukọ awọn akọni meje naa niwọnyii: -Akara Oogun - Kako Oni kumọ ẹkun - Olohun Iyọ - Elegbeje Ado - Aramọnda Olotutu - Imọdoye -Efo Iye Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Àmì ohùn ṣe pàtàkí nínú èdè Yoruba púpọ̀ 3) Ọmọ Olokun Ẹṣin lati ọwọ oloogbe Adebayọ Faleti Iwe itan arosọ yii ni Adebayo Faleti kọ lọdun 1958 ṣaaju ominira Naijiria to pada wa si imuṣẹ ni ọjọ kinni, oṣu kẹwaa, ọdun 1960.
Omi òkun pada sí ipò rẹ̀, ó sì bo gbogbo kẹ̀kẹ́ ogun, ati àwọn ẹlẹ́ṣin, ati àwọn ọmọ ogun Farao tí wọ́n lépa àwọn ọmọ Israẹli wọ inú Òkun Pupa, ẹyọ kan kò sì yè ninu wọn.
O ti dáwọ́ ìfẹ́ ati àánú rẹ dúró lára wa ni?
Sowore: Ilé aṣòfin Amẹrika ní ìwà ìfìyàjẹni tíjọba Nàíjíríà hù ń kọ àwọn lóminú
Atun ṣẹṣẹ wọ inu oṣu ba-ba-ba ni ti a n lero pe a o tun maa pa ṣenji diẹdiẹ ni ijọba ba tun ni afikun owo ina ati epo lo kan, ṣe wọn fẹ pa wa ni?
7m kó sí páńpẹ́ EFCC Adìyẹ́ jẹ̀fun ara wọn!
”Bẹ́ẹ̀ ni wọ́n ṣe bẹ̀rẹ̀ sí jiyàn níwájú ọba.
Gbogbo arinrinajò to ba n bọ gbọdọ ti ṣe àyẹwò ààrùn Covid-19, ki o si ti mọ pé oun ko ni ààrun náà ko to wá Arìnrinàjo ti gbọdọ ṣe àyẹwò yiì'ó kéré tan ọjọ mẹ́rin ki o to rìnrìn àjò, sùgbọ́n èyí to dára jù ni wákàtí mejìléláàdọ́rin si ìgbà to fẹ́ rìnrìn àjò.
 a má a ń gbàá gẹ ́ gẹ ́ bí abẹ ́ rẹ ́ tí a gún sínú ẹran-ara ẹni .
Ki amojuto wa fun awọn ileeṣẹ nla-nla Oríṣun àwòrán, Getty Images Eefin ati afẹfẹ gaasi to n jade lati awọn ileeṣẹ jẹ ọ̀kan lara awọn nkan gboogi to n fa oju ọjọ ti ko dara ni Naijiria.
Lẹ́hìn àwọn òkúta yìí wọ́n gbin igi kékeré bá ojú ọ̀nà lọ, wọ́n tanná wọ́n sì lẹ́wà gidigidi.
" O sọ pe ijọba ti lọ si ile ti wọn de si, wọn si ti fin oogun apakokoro sibẹ.
O pe akori ayeye ajodun ohun ni:”Alaafia ati isejoba rere fun idagbasoke orile ede.
Regent female kings: Wo àwọn Adelé-Ọba aládé méje tó jẹ́ obìnrin nílẹ̀ Yorùbá
Ṣé o rántí itú tí Bright Omokharo fi Algeria pa ní MAROC '88?
BBC ni ileeṣẹ iroyin akọkọ ti o kọkọ ba Adeleke sọrọ, lẹyin ti ọrọ idibo rẹ ipinlẹ Ọṣun ri bo ṣe ri fun un.
Ṣébi wọn ni ibi gbogbo là ń dáná alẹ́ nitori naa, Kayefi ti oṣu yii kii ṣe lati tabuku ba ẹnikẹni, ẹgbẹ tabi ijọ kankan.
ṣapejuwe mọṣalaṣi gẹgẹ bi ile ijọsin fun Allah ati ibi igbadura si I.
Ogbeni Saab so pe pupo ninu awon to ku naa lo je  elewon, sugbon awon  obinrin meji ku, lasiko ti won wa fun ibewo.
Zurich (Switzerland), Geneva (Switzerland), Osaka (Japan) , Seoul (South Korea), Copenhagen (Denmark) ati New York lorilẹede Amẹrika wa ni ipo keje ti Tel Aviv (Israel) ati Los Angeles (amẹrika) pẹlu ko gbẹyin laaarin awọn ilu mẹwa akọkọ ti owo ati gbe ibẹ gaara pupọ julọ lagbaye.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Money ritual: Àwọn àṣà àtọ̀húnrìnwá ló fa títa ẹ̀jẹ̀ sílẹ̀ nítorí òògùn owo Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Money ritual: Àwọn àṣà àtọ̀húnrìnwá ló fa títa ẹ̀jẹ̀ sílẹ̀ nítorí òògùn owo 18 Ẹrẹ̀nà 2020 Oniruuru ọna ẹrọ lawọn eeyan fi n ṣe etutu ọla.
O tesiwaju wi pe awon omo orile-ede naa ti won fi orile-ede South Sudan se ibujoko ni lo lati kiyesara lori tita ati rira,ati bi won se n se ohun gbogbo lorile-ede naa.
(Ní àkókò yìí àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ ti lọ ra oúnjẹ ninu ìlú.
’ Ó sọ fún un pé, ‘Gba ìwé àkọsílẹ̀ rẹ, tètè jókòó, kọ aadọta.
,so pe awon wa si orile ede ede Niajiria lati mo ona ti awon yoo gba lati ran
Aare tun ki gbogbo osise ajo NFF ati apapo awon akonimoogba iko Super Falcons fun ifarada, ifarasin ati ise takun-takun won, eleyi ti o so eso rere fun orile-ede Naijiria nigbeyin.
O maa n din eefin agbegbe kù fun ilera pipe.
Awọn eekan ẹgbẹ oṣelu naa ni wọn ti n ke si Adams Oshiomhole pe ko kọwe fi ipo silẹ nitori pe igba rẹ ko fẹ ṣe bi ẹni san ẹgbẹ oṣelu naa.
O ni, “ko gbọdọ si oṣiṣẹ olutoju ile ti ọjọ ori rẹ kere si ọmọ odun mejidinlogun ati pe dipo ki wọn maa ko awọn to ba tapa si ofin yii lọ si ile ẹjọ ki wọn maa gbẹsun wọn ni ile-ẹjọ pataki to jẹ mọ idile tabi ẹbi”Ṣaaju eyi ni ni Aṣofin Adefunmilayọ Tẹjuosho, Alaga Igbimọ Teekoto fun eto Idajọ, Ẹtọ ọmọniyan, ọrọ Ifẹsunkan ate Idibo ni Ipinlẹ Eko ninu Ile Igbimọ Aṣofin Ipinlẹ Eko sọ pe abadofin naa ṣe pataki, eleyii ti yoo le daabo bo ati awọn onise ati awọn oṣiṣẹ wọn, ti ọkan awọn mejeeji yoo fi balẹ.
Àwọn ọmọ ọmọ Keni, àna Mose, bá àwọn ọmọ Juda lọ láti Jẹriko, ìlú ọlọ́pẹ, sí inú aṣálẹ̀ Juda tí ó wà ní apá ìhà gúsù lẹ́bàá Aradi; wọ́n sì jọ ń gbé pọ̀ níbẹ̀.
Èmi tí mo ní ìyàwó tí a kò í tí ì jọ gbé pọ̀ jú bẹ́ẹ̀ lọ rí, n kò ì tíì jọ gbé pọ̀ jù bẹ́ẹ̀ lọ rí, n kò ì tíì fẹ́ kí tèmi parí nínú ayé, bẹ́ẹ̀ ni èmi tí mo ṣẹ̀ṣẹ̀ gbọ́ pé mo bímọ tí n kò ì tí ì rí ọmọ náà, n kò ì tí ì fẹ́ kí témi sọnù, èmi tí ó sì ti ń jìyà káàkiri inú ayé, tí n kò ì tí ì gbádùn ayé náà rí, n kò ì tí ì fẹ́ẹ́ múra ọ̀run alákeji.
Eewọ ni wiwo fidio to ba ṣe afihan ibalopọ tabi ihoho ni awọn oju opo naa.
Obinrin yìí so mọ́ ọn lẹ́wù, ó ní, “Wá bá mi lòpọ̀.
‘Operation Wild Stroke’ yoo gbogun ti odaran
Lori awọn kudiẹ-kudiẹ yii, gbajugbaja elere idaraya commonwealth, to tun jẹ ọmọ Naijiria, Blessing Okagbare, ni nkan ko deede ri bẹẹ.
Awọn asofin lati ẹgbẹ APC to wa lori ijọba ati awọn akẹgbẹ wọn lati ẹgbẹ PDP ko fun ara wọn ni ọrọ sọ nigba ti Aarẹ Buhari n bawọn sọrọ.
O fi kun un pe awọn yoo rii pe awọn ọdọ n kọ iṣẹ ọwọ wọn si n kopa ninu ere idaraya bọọlu Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ẹ̀yin ọmọ Yorùba, kí ló le nínú fí fí àmì sí A-la-pa-n-dẹ-dẹ?
Timothy Weah yoo kuro ninu iko agbaboolu Paris St Germain (PSG), ti o n kopa fun lati lo darapo mo iko agbaboolu Celtic.
Isẹlẹ yii lo mu ki ogiri la ẹnu laarin baba ati ọmọ, sugbọn itakun to ni ki erin ma wọ odo ni iwa Bukọla ni agbo oselu, toun -terin ni yoo jọ lọ, eyi to fi idi rẹ mulẹ pe ko sẹni ti Biukọla ko le e gbéná woju lori ipo oselu to ba n fẹ ni akoko kan.
Ayẹyẹ ọjọ ibi mi niyii, mo si dupẹ pe emi, ẹbi mi, ati awọn ọrẹ mi wa ni ilera pipe."
Wọ́n jẹ́ ọrẹ Netaneli ọmọ Suari.
Wọn tun sọ pe, awọn ri ogoji miliọnu dọla le diẹ gba lọwọ wọn pẹlu ọkọ ayọkẹlẹ mẹtala, ti iye owo wọn le ni miliọnu mẹfa dọla.
O wa gbarata pe, ilẹ Yoruba yoo dide lati tako ikọlu awọn darandaran yii nitori pe ọrọ naa ti de ojuẹ.
" O fikun pe ohun to jẹ ko se ni laanu pe iran Yoruba tun padanu Adewole ree.
Ṣugbọn kì í ṣe gbogbo nǹkan ni ó ń ṣe eniyan ní anfaani.
Lara awon isẹ akanse ti aare
Àìmọye jàmbá la gbọ́ pé ó ṣelẹ̀ káàkiri àgbáyé lọ́dúnnìí.
Ìpínlẹ̀ Ogun, Eko ti gbáradì fún ẹ̀kún omi yalé Ìjọba Ondo kéde ìsimi ọ́sẹ̀ mẹ́ta fún àwọn ilé ìwé to lùgbàdì omíyalé!
Opin ọsẹ ni fidio kan jade nibiti awọn ọmọ ile iwe girama ti n sa asala fun ẹmi wọn lẹyin ti rogbodiyan bẹ silẹ ni ile iwe naa.
Oríṣun àwòrán, Facebook/Dapo Abiodun Ọlọ́pàá Ogun ti dá àwọn olùwọ́de #ENDSARS tí wọ́n mú lánàá sílẹ̀- Gómìnà Dapo Abiodun Ileeṣẹ ọlọpaa ipinlẹ Ogun ti mu awọn oluwọde #ENDSARS mẹtalelogun ni ilu Abeokuta tii ṣe olu ilu ipinlẹ naa.
Kò sí ẹnikẹ́ni ninu Saulu ati àwọn eniyan rẹ̀ tí ó mọ ohun tí ó ṣẹlẹ̀, tabi tí ó jí nítorí OLUWA kùn wọ́n ní oorun.
Eyi ni diẹ lara awọn baba isalẹ oloṣelu ti nnkan ko ṣẹnu 're fun ninu idibo gomina to waye ni Naijiria lọdun 2019.
Imoran yi jẹ atẹwọgba lọdọ ìjọba apapọ koda awọn ipinlẹ kookan nilẹ kaarọ o jiire bi Eko ti gbe igbimọ yi kalẹ.
Ademọla Adeleke ni yóò sojú PDP nínú ìbò gómìnà Ọ̀sun Ǹkan o rọgbọ níbi ìdìbò abẹ́lé PDP l'Osun ‘A ó rántí Ààrẹ Buhari fún ìtàjẹ̀sílẹ̀ lásìkò rẹ̀’ Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Awon osise eleto-abo ni awon ipago idibo naa so pe, awon eniyan ko jade lowo aaro lati dibo, pupo ni won fagbara mu lati rin lo si ibi ipago idibo ti o sunmo odo won, toripe,  won ti fofin de irina oko lojo-idibo, latari eto-abo.
mọ̀ pé kò sí ẹnikẹ́ni tí Ọlọrun yóo dá láre nípa iṣẹ́ òfin, àfi nípa igbagbọ ninu Jesu Kristi.
O ni iwadii n lọ lọwọ lori ọrọ naa ati pe o ti yaju lati sọ ni pato bi ọkunrin naa ti wọn ba ara rẹ ninu agba naa ṣe ku.
Wòólì Alfred kú lọ́dún 1964, ó tún padà wà sí ìlú Agelu f'ọ́jọ́ mẹ́rìnlá!
 Alukoro fun ile-isẹ  ọlọpaa , Jimoh Moshood  sọ pe  awọn   afurasi mejilelogun lo ti wa ni ahamọ  awọn  ọlọpaa  bayii, lẹyin ohun ti  awọn  afurasi naa  sọ ati pe  ọkan ninu ọkọ ti  awọn  ri gba lọwọ  awọn  adigunjale naa lo ni ni akọle kan to nii se pẹlu Saraki.
 omi tí ó maa ń jáde yìí maa ń funfun tàbí kí ó ní àwọ ̀ eérún .
Lọ́jọ́ tí ọwọ́ pálábá Dáúdà ségi, ẹnu rẹ̀ kọ ìroyìn.
Èmi Ọba tí wọ́n ń kó jẹ nígboro- Oluwo ti ilú Iwo Ta ni Yusuf Satia ti iku mu lọ?
Mose dáhùn pé, “Kí ló dé tí o fi ń jowú nítorí mi?
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Uganda Condom Case: Ilééṣẹ́ ìjọba àti aládáni wọ gàù nítórí Kọ́ńdọ̀mù tó fa HIV, gonorrhoea àti òyun 7 Ògún 2020 Oríṣun àwòrán, Getty Images Ọmọ orilẹ-ede Uganda mẹta ti gbe ajọ to n mojuto ipese oogun lorilẹ-ede naa, ati ajọ aladani kan, Marie Stoppes, lọ sile ẹjọ, nitori pe wọn fi wọn sinu ewu aarun ati oyun airotẹlẹ.
N kò sá jìnà jù bẹ́l lọ tí iwin náà fi fa kìnìhún ya tí ó tún n lé mi lọ.
Abadofin ilera fun iṣoro ọpọlọ - 2019.
Fún Naijiria, èyí yóò mu ki owó iṣúna wọ́n kí o tun rú gọ́gọ́ sí O fi ku pé àwọn orilẹ̀-èdè yìí yoo túbọ náwó láti gbé epo rọ̀ọ̀bi wọ àwọn orilẹ̀-èdè yìí Orílẹ̀-èdè bii Cameroon to maa n ta epò rọ̀ọ̀bi ní alábọde, wọ́n o na owó to pọ̀ ju iye ti wọ́n yóò pa lọ China àti Russia ni yóò jẹ mudùmúdùn jùlọ ti ogún bá bẹ́ silẹ̀ láàrin Iran àti US.
Ṣugbọn, awọn akọroyin n fi ẹhonu han pe ọgbọn lati di ọna mọ ominira awọn oniroyin ni igbesẹ naa.
Èṣù yóo gbé ẹlòmíràn ninu yín jù sinu ẹ̀wọ̀n láti fi dán yín wò.
Ọbasanjọ ṣalaye pe oun tako ohun ti awọn ileeṣẹ iroyin kan fi sita nipa ọrọ ti oun sọ nibi ipade awọn ọmọ bibi ilẹ Owu, to waye nilu Iwo nipinlẹ Ọṣun laipẹ yii.
 Bẹẹ si ni awon obi awọn akẹkọọ wọnyi ti kọkọ san owo-ori wọn tẹlẹ.
Bí ó ṣe farahàn wọ́n nìyí: 
” Ṣugbọn kò tilẹ̀ kọ ibi ara sí ohun tí wọ́n sọ, kò sì dá wọn lóhùn.
COZA: Mi ò fípá bá obìrin lò pọ̀ rí láyé mi - Pásítọ̀ Fatoyinbo Damasus, Omotola, Ezekwesili, Funmi Iyanda dá sí ẹ̀sùn ìfipábánilòpọ̀ Fatoyinbo CAN kò rán ẹnikẹ́ni lọ ṣọ́ọ̀ṣì COZA, iṣẹ́ ara wọn ní wọ́n lọ jẹ́ -Samson Ayokunle A ti wọ́gilé ìwọ́de lórí COZA tí a fẹ́ ṣe tẹ́lẹ́ nítorí.
Èṣù burú ju àwọn ẹ̀dá ìyókù lọ, nígbà tí òun sì ti gba ọkàn àwọn ènìyàn wọn-ọnnì, wọ́n ń wọ inú ẹ̀sẹ̀ bí ẹni ń wọ yàrá, wọ́n ń pòṣé sí Ọlọ́run  wọn, wọ́n ń wí pé ipòo tí ó fi àwọn sí kò tó, wọ́n sì ń sọ̀rọ̀ àìyẹ̀ sí Ẹlẹ́dàá wọn.
Oluwa yóo jẹ́ kí ìtumọ̀ rẹ̀ yé ọ lẹ́kùn-únrẹ́rẹ́.
Iṣẹlẹ yii waye niluu Ijedun, abule kan lẹbaa Ojoo, Ibadan nipinlẹ Oyo.
O fèsì si ọrọ ti Malami sọ pe idasilẹ ikọ Amọtẹkun ko ba ofin Naijiria mu.
Eniyan dàbí èémí,ọjọ́ ayé rẹ̀ sì dàbí òjìji tí ń kọjá lọ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Third mainland bridge: Afárá Third mainland gùn, ṣùgbọ́n afárá Hong Kong-Zhuhai tó gùn jùú lọ ti di ṣíṣí 23 Ọ̀wàrà 2018 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 24 Agẹmo 2020 Oríṣun àwòrán, Getty Images Ko si aniani pe afara Third mainland bridge ni afara ori omi to gun julọ ni ilẹ Olooru Afirika.
Itan sọ fun wa pe idile ọla ati ọmọwe ni Oyinkan ti wa, oun naa kawe, o si tun gbajumọ lobinrin amọ ko jẹ ki ipilẹ ọla to ni ko si oun lórí, lati maṣe naani obinrin ẹgbẹ rẹ.
Oríṣun àwòrán, Google Laipe yii ni gomina ipinlẹ Ondo, Oluwarotimi Akeredolu, Gomina ipinlẹ Ọyo, Seyi Makinde, Gomina ipinlẹ Osun,Adegboyega Oyetola, Gomina ipinlẹ Ekiti, Kayode Fayemi,Gomina ipinlẹ Eko, Babajide Sanwo-Olu ati Gomina ipinlẹ Ogun, dapo Abiodun parapọ se ipade ni Iwo-Oorun Naijiria lori ọna abayọ si ipenija eto aabo to mẹhẹ ni ilẹ Yoruba.
Awọn obi kii mọ iru ọmọ ti wọn bi, wiwo ẹsẹntaye ọmọ tabi difa lo ma n jẹ ki wọn o mọ.
Gẹgẹ bi iroyin ṣe sọ Federal Bureau of Prison (BOP), Ramon 'Hushpuppi' Abbas ko si ni ọgba ẹwọn Chicago ti wọn fi si tẹlẹ mọ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Working religious women: Ẹ̀lẹ́hàá kìí ṣe ọ̀lẹ- Aminat Adegoke Ma ṣe ge irun tabi fa eekanna rẹ Nkan akọkọ ni pe ti enikan ba n gbiyanju lati se aluwala, lati ọjọ akọkọ, oṣu Dhu al - Hijjah, ma se ge eekanna rẹ tabi ki o fa irun kankan lara.
28 Òkùdu 2020 Akojọpọ aworan isinku gomina ipinlẹ Oyo tẹlẹri, Abiola Ajimobi Àkọlé àwòrán, Àna olóògbé Abiola Ajimobi, tó tun jẹ́ gómínà ìpínlẹ̀ Kano, Abdullai Ganduje ni bi tó ti n buwọ́lu ìwé àkọlsilẹ̀ níle olóògbé.
 Wọn ko ṣeye meji ninu igbagbọ wọn si Ọlọrun.
”O wa rọ awọn ara ilu lati yago fun awọn iwa to le
Moghalu jẹ́ onímọ̀ nínú ìdókòwò àgbáyé àti òfin gbogbo ènìyàn ní ilé ìwé Òfin àti Ọgbọ́n Fletcher ní Ifásitì Tufts ní Massachusetts, USA.
Agbaboolu iko Leicester City ati CSKA Moscow tele ri ohun, tun gba egberun mewa owo ile Saudi (10,000 Saudi Riyal), eleyi t pasipaaro re sowo naira je ẹgbẹ̀rún lona ẹ̀ẹ́dẹ́gbẹ̀rún le die làádọ́rin (N970,045.
Nítorí Ọlọrun kò nílò láti yan àkókò kan fún ẹnikẹ́ni,láti wá siwaju rẹ̀ fún ìdájọ́.
Ní ìtọ́jú ẹbọra olójú kan, àgbègbè ilé Ikú,
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Olaitan Olamide: mò lè má nílò ìwé ẹ̀rí mi tí mo bá parí ní LASU Arabinrin kan ni ṣe ni ọkọ n fi iya jẹ iyawo rẹ to bi ọmọ mẹrin fun un to n ṣe e baṣu baṣu titi ti wọn fi pinya.
DFL: Ìdánilẹ́kọ̀ọ́ yìí tún ń kọ́ àwọn akẹ́kọ̀ọ́ girama ní iṣẹ́ Asoná, bàtà àti báágì ṣíṣe
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Sikiru Ayinde Barrister: Kwam 1 ní Agbajelola ló ṣe olùlànà fún àwọn olórin Fuji òde òní 19 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Oríṣun àwòrán, Fuji Opera Gbajugbaja olorin Fuji ati Mayegun ilẹ Yoruba, Wasiu Ayinde, ti ọpọ eeyan mọ si K1, ti kan sara si ẹni to da orin fuji silẹ, Sikiru Ayinde Barrister.
Alufaa yóo sì ṣe ètùtù fún un níwájú OLUWA.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ọgbà ẹ̀wọ̀n ni wọ́n ti já ìbálé Esra lábẹ́ àwáwí àyẹ̀wò wúndíá Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Ọgbà ẹ̀wọ̀n ni wọ́n ti já ìbálé Esra lábẹ́ àwáwí àyẹ̀wò wúndíá 13 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Ninu aworan yii, obinrin kan sọ iriri rẹ lori bi o ṣe la iwa ifipa ṣe ayẹwo funni lọgba ẹwọn labẹ awawi a n ṣe ayẹwo abale funni.
 admission to the hospital is rarely needed .
Igba to de yaara rẹ, o ni ọmọbinrin kan ti oun pade nibi ayẹyẹ naa pe e pe D'banj ri nibi ayẹyẹ, o si nifẹ lati wa pẹlu rẹ lalẹ ọjọ naa.
Oríṣun àwòrán, @ImamShams Àkọlé àwòrán, Ọ̀gọ̀rọ̀ àwọn èèyàn ló jáde wá pàdé Ààrẹ Buhari nígbà tó gúnlẹ̀ sí pápákọ̀ òfúrufú ní Dutse Nibayii, Aarẹ Buhari ti wa ni Auyo lati ṣi ibudo ipese omi to wa ni Hadejia.
Ẹni to bori: South Africa Namibia vs Egypt.
ọpọlọpọ ẹka imọ ẹrọ ati awọn ile iṣẹ epo bẹntiroo ati afẹfẹ gaasi lorile-ede
LASEMA ni ko si ẹni to ku ninu iṣẹlẹ naa ninu eyi ti wọn ti n dari awọn ọkọ ki wọn gba ọna Ọjọta tabi 7 Up lati din sunkẹrẹ-fakẹrẹ ọkọ ku.
Ọba Ijipti bá pe àwọn agbẹ̀bí náà, ó bi wọ́n pé, “Kí ló dé tí ẹ fi ń dá àwọn ọmọkunrin tí àwọn Heberu bí sí?
Yóo dá odi ìlú lu, yóo gba ibẹ̀ jáde.
Goliati Pe Àwọn Ọmọ Israẹli Níjà.
Bẹ́ẹ̀ náà ni àwọn ọmọ-ẹ̀yìn àwọn Farisi.
Eyi yoo fun awọn ololufẹ awọn ero iworan loore ọfẹ lati gbegba oroke ninu ile ẹlẹgbọn agba naa.
ni a bá rán Timoti si yín, ẹni tí ó jẹ́ arakunrin wa ati alábàáṣiṣẹ́pọ̀ pẹlu Ọlọrun ninu iṣẹ́ ìyìn rere ti Kristi, kí ó lè máa gbà yín níyànjú, kí igbagbọ yín lè dúró gbọnin-gbọnin.
Ní ti ìmọ̀, yóo di ohun tí kò wúlò mọ́.
Pẹpẹ yìí ni pẹpẹ kinni tí Saulu tẹ́ fún OLUWA.
Ohun to yan laayo bayii dabii pe aṣa diran ni tori gẹgẹ bi Yeye ṣe sọ fun BBC Yoruba, ati ile baba ati ile iya rẹ ni wọn.
Biotilẹpe ẹnikan ninu wọn ni, iwe ifẹyinti ni wọn pe iwe idaduro naa amọ wọn ko fi idi rẹ mulẹ boya ileesẹ mejeeji sọwedowo mọ iwe maa lọ sile rẹ naa.
Aarẹ rọ awọn eeyan nipinlẹ Rivers lati ṣiṣẹ pọ pẹlu awọn agbofinro ki wọn le dẹkun awọn ẹlẹgbẹ okunkun to n yọ ipinlẹ naa lẹnu.
Oríṣun àwòrán, @others Àkọlé àwòrán, Oni ni wọn n ṣe ẹyẹ ikẹyin fun akọni Ọpọ igba ni Pius Adesanmi maa n sọrọ nipa Naijiria tuntun nigba aye rẹ.
Wa a kú, to ba n ṣe e!
 odù Òwọ ́ nrínsẹ ̀ náà nìyí :.
Oríṣun àwòrán, @mamarainbowofficial Àkọlé àwòrán, Orukọ rẹ 'Iya Rainbow' jẹyọ lati ara orukọ ẹgbẹ oṣere ọkọ rẹ, Oṣumare Orukọ rẹ 'Iya Rainbow' jẹyọ lati ara orukọ ẹgbẹ oṣere ọkọ rẹ, Oṣumare, eyi to tumọ si 'Rainbow' ni ede oyinbo.
BBC Yoruba jade lọ ṣiṣẹ iwadii nipa ọrọ yii ni eyi ti o ti hande pe ko dun mọ awọn ọmọ ninu.
Ọkan lara awọn obinrin to ṣe e, Maha sọ fun BBC pe inira pupọ ni igbesẹ naa fa fun oun.
Ẹwẹ, Joe Biden ni iṣẹ ṣi ku ni ṣiṣe fawọn lorii ṣiṣeranwọ lati bẹrẹ iṣẹ atilẹyin fun eto ti wọn la kalẹ lorii Covid-19.
Ẹ̀ ń sọ pé: “Nígbà wo ni ìsinmi oṣù titun yóo parí, kí á lè rí ààyè ta ọkà wa?
Kàkà bẹ́ẹ̀, ọpẹ́ sí Ọlọrun ni ó yẹ yín.
Iwadii si n lo lori awọn to da wahala naa silẹ ni ile ẹkọ girama naa, ati wi pe Ọjọ Aje, Ọjọ Kẹtadinlọgbọn ni ọkunrin to fi tajutaju naa yoo pada si agọ ọlọpaa.
Iroyin ori ero ayelujara naa so pe, atunse ohun wa lara akitiyan lati je ki awon agbe ri eyawo ti ko lere lori gba.
Jesu wí fún wọn pé, “Ẹ tú aṣọ kúrò lára rẹ̀, kí ẹ jẹ́ kí ó máa lọ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Grace Oshiagwu: Gómìnà Makinde ké sáwọn ọlọ́pàá, àwọn lọ́balọ́ba lágbègbè Akinyele Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Grace Oshiagwu: Gómìnà Makinde ké sáwọn ọlọ́pàá, àwọn lọ́balọ́ba lágbègbè Akinyele 15 Òkùdu 2020 Kí ló ṣokùnfà afárá tó já tó pa ènìyàn kan ní Ilorin?
Ariwo Iya Osumare ni pe, yoo dara ki wọn maa se ẹyẹ fun awọn osere tiata lasiko ti wọn ba wa laaye, kii se lẹyin ti wọn ba ku tan.
Ìlú Kẹsibu ni ó wà nígbà tí ó bí ọmọ náà.
Ṣugbọn lọdun 2019, o darapọ mọ ileeṣẹ to n gbe orin jade, Fierce Nation.
Angẹli náà tí mo rí, tí ó gbé ẹsẹ̀ lé orí òkun, ati orí ilẹ̀, wá gbé ọwọ́ ọ̀tún rẹ̀ sí òkè ọ̀run, 
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ sí: Anfani de fun ọ lati lo internet lọfẹ Aworan ìṣẹlẹ òṣùpádeje káàkiri àgbáyé Lunar Eclipse: Ifá letùtù wa lẹyìn Òṣùpádẹ̀jẹ̀ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ikogosi-Ekiti: Ilu ti omi tutu ti dapọ mọ gbigbona Nínú àkọsílẹ̀ nípa Sẹ́nétọ̀ yìí tó wà lórí ìkànì ayélujára ilé ìgbìmọ̀ aṣòfin àgbà, Adeleke ní oyè Diploma nínú imọ̀ ẹ̀kọ́ nípa ọ̀daràn ó sì kẹ́kọ̀ọ́ jáde ní ọdún 1986.
Amọ, o ṣeni laanu pe eto yii ko pẹ rara ti o fi ta pau bi i guguru.
Ajọ EFCC fi ẹsun kan an pe o ko owo to le ni miliọnu mẹrinlelogun dọla ($24million) jẹ.
Gbòngán ni ó ń gbé ṣùgbọ́n gẹ́gẹ́ bíi fìlísíà, ó ní ilé sí Ibadan.
ní ọjọ́ ti à ń wí yìí, kùmọ̀ tí àwọn iwin na Kùmọ́dìran tó ẹgbẹ̀ta, Kùmọ́dìran kú.
Gẹgẹ bo ṣe sọ, o ni Naijiria ko ni ilọsiwaju kankan to lamilaaka lati ọgọta ọdun sẹyin.
Mo mọ̀ pé ẹ gbà wọ́n gbọ́.
ati obinrin tí ó ṣe nǹkan oṣù rẹ̀ tabi tí nǹkan oṣù di àìsàn sí lára; ẹnikẹ́ni tí nǹkan bá sá ti ń dà lára rẹ̀, kì báà jẹ́ ọkunrin tabi obinrin, ati ọkunrin tí ó bá bá obinrin tí ó jẹ́ aláìmọ́ lòpọ̀.
Nígbà tí ọkùnrin náà tún wí báyìí inú túbọ̀ bí mi, mo ní, Baba-onírùngbọ̀n n kò mà fẹ́ o.
Ẹru atu itankalẹ aarun yii kan naa lo ti mu ki ajọ UEFA so abala keji ifẹsẹwọnsẹ idije Champions League laarin Real Madrid ati Manchester City rọ bayii.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Olusegun Obasanjo: Ọmú ìyá mi ti mo fi ń mùkọ ni kekere ló jẹ ki ń lókun Ọpọlọpọ lo n gboṣuba fun Malema pé o sọ ohun to jẹ awokọṣẹ fun gbogbo olori orilẹ-ede agbaye pe: Wọ́n jí ọmọ yìí gbé láti máa fi tọrọ bárà l'Eko Ọwọ́ ọlọ́pàá tẹ ọmọ Britain tó ń ta kẹ́míkà gẹ́gẹ́ bi omi ìyanu Facebook yóò bẹ̀rẹ̀ ìnáwó orí ayélujára Theresa May bú sẹ́kún, ó ní òun kò ṣe olóòtú ìjọba UK mọ́ Oríṣun àwòrán, @ayisha Àkọlé àwòrán, Aisha, iwọ naa kọkọ lọ ba ọkọ rẹ sọrọ niyara kẹta!
O ni niṣe ni ọkọ oun n paarọ obinrin bi aṣọ.
Wọ́n kọ àkọlé kan sí ìyànà náà, nǹkan tí wọ́n sì kọ ni èyí:
Ọlọpaa ni o wa lara apaniyan ti ẹsun rẹ pọju ti ikọ IRT ti mu lati ọjọ ti wọn ti da ẹka ọlọpaa naa silẹ.
Èyí ló mú kí wọn di kòrí-kòsùn ara wọn láti kékeré wá, wọn kí í sì í yara wọn bí ó ti wú kí ó rí.
Nigba ti Amofin Mohammed Fawehinmi yoo kan lu agbami ọrọ, abuubu tan ni ọrọ ti ọmọ Oloye da walẹ.
Gbogbo òṣìṣẹ́ kọ́ ni #30,000 owó oṣù tuntun yóò kan"" Ọ̀rọ̀ǹpọ̀tọ̀niyùn, Aláàfin obìnrin àkọ́kọ́ rèé, tó ní nǹkan ọkùnrin Eyi lo fi gba gbogbo ẹni to ba n la oniruuru iriri kọja lati mu ara wọn lọkan le ki wọn le bori."
"Mi o ki n wo ibẹ.
Ọgbọ́n burúkú kó wọn Ìjàpá, ni ọjọ́ kan ó bẹ̀rẹ̀ si ṣe àdúrà lojiji pé “Àkóbá , àdábá, Ọlọrun ma jẹ ká ri”, Ọ̀bọ kò ṣe “Àmin àdúrà” nitori ó mọ̀ wi pé kò si ẹni ti ó lè ṣe àkóbá fún Ìjàpá, à fi ti ó bá ṣe àkóbá fún elòmiràn.
Oríṣun àwòrán, Facebook/NLC Àkọlé àwòrán, Ẹgbẹ́ òṣìṣẹ́ sèwọ́de Nibi ipade oniroyin kan to waye nilu Abuja ni awọn adari ẹgbẹ oṣiṣẹ ti fi ohun ṣọkan pe awọn naa ko le gba owo oṣu to ba din ni ọgbọ̀n ẹgbẹrun gẹgẹ bi owo oṣu to kere ju.
Ọpọ ọmọ Naijiria ni ko nigbagbọ ninu iye jala epo ti wọn n ko wọ orilẹede yii, asiko si ti wa to bayii lati mọọ."
Fún ẹbọ ohun jíjẹ, ẹ lo ìdámẹ́wàá mẹta ìyẹ̀fun òṣùnwọ̀n efa, tí a fi òróró pò fún akọ mààlúù kan ati idamẹrin ìyẹ̀fun òṣùnwọ̀n efa tí a fi òróró pò fún àgbò kan.
Ẹnu ya gbogbo àwọn tí wọn gbọ́ ọ̀rọ̀ rẹ̀ nítorí òye rẹ̀ ati nítorí bí ó ṣe ń dáhùn àwọn ìbéèrè tí wọn ń bi í.
DSS ti fi ẹ̀sọ́ àbò abẹnugan ilé ìgbìmọ̀ asofin tó pa fẹ́ndọ̀ l'Abuja sátìmọ́lé Wọ́n ti rí òkú Alága ẹgbẹ́ APC ní Nasarawa tí àwọn agbébọn jí gbé lọ́jọ́ Satide Mohammed gbìyànjú láti dóòlà, ọ̀rẹ́bìnrin rẹ̀, Rabi nínú iná náà tó sì gbe lọ si ilé ìwòsàn, nibi tó ti pada pàdánù ẹ̀mí rẹ̀ lọ́jọ́ sátide, ọjọ́kọkànlélógún, ọdún 2021.
Ṣaaju eyi naa ni ọpọlọpọ eekan oloṣelu ti kọwe si ile iṣẹ ọlọpaa ti awọn naa ko si jafinra lori iwadii ọrọ naa.
Wọ́n níláti máa gbé ojú àgbàrá,ninu ihò ilẹ̀, ati ihò àpáta.
1 Fetísílẹ̀, ìranṣẹ́ mi Jòhánnù, kí o sì tẹ́tísí àwọn ọ̀rọ̀ Jésu Krísti, Olúwa rẹ àti Olùràpadà rẹ.
Nítorí ilé Ọlọrun alààyè ni àwa jẹ́.
Ọpọ ninu wọn n bere wi pe njẹ awọn osisẹ Banki naa ko ni dii alainisẹ lẹyin ti wọn ba ti darapọ mọ Access Bank.
Ọlọ́pàá kó àwọn ọmọ ẹgbẹ́ òkùnkùn Ẹiyẹ Confraternity ni Ikorodu Òfin ṣì gbẹ́sẹ̀lé Ẹgbẹ́ awakọ̀ èrò NURTW ní ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́ Iye epo rọ̀bì tí wọ́n ń kó níbùdó ìpọnpo ti dínkù, ṣé ẹ fẹ́ mọ ìdí i rẹ̀?
Bí wọ́n ti tẹjú mọ́ òkè bí ó ti ń lọ, àwọn ọkunrin meji tí wọ́n wọ aṣọ funfun dúró tì wọ́n.
Laarin ọdun 1970 si 2008, obinrin to le ni irinwo ẹgbẹrun ni wọn ti fi ipa ba lo pọ ni Cameroon, gẹgẹ bi akọsilẹ ileeṣẹ German Technical Cooperation lasiko to ṣe ifilọlẹ ipolongo tako ifipabanilopọ.
Sẹnatọ Saraki ni ara ohun ti igbimọ apero naa yoo lee ṣiṣẹ le lori ni mimu ayipada baa bi awọn ọdọ ṣe n sa fi ilẹ baba wọn silẹ lọ soke okun ti wọn si n tipasẹ bẹẹ kagbako iku wọn.
 Ó ye kì á tètè so báyìí pé ohun tí ó wà nínú gbólógùn ju èyí lo .
Ninu iroyin ti ajọ FCCPC fi sita lọjọ Ẹti, wọn ni awọn fi ofin mu Dokita Anu, nitori pe ko tẹle awọn ilana ti ajọ naa la kalẹ fun iwadii ẹsun naa.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ikogosi-Ekiti: Ilu ti omi tutu ti dapọ mọ gbigbona Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Ikogosi-Ekiti: Ilu ti omi tutu ti dapọ mọ gbigbona 18 Agẹmo 2018 Ilu ikọgọsi Ekiti lo gbajugbaja, to si tun jẹ ibudo igbafẹ nitori omi odo kan to nmu omi gbigbona ati tutu jade.
Nítorí náà, ẹ̀yin àyànfẹ́ mi, ẹ sá fún ìbọ̀rìṣà.
Ojo ni: “Ninu ise iwadii ti a se ni a ti rii pe o to apero omo eriwo odiwon iye owo ti a n sonu lodoodun ni Naijiria.
Bayii olori awon iko omo ogun ogagun agba fun Naijiria, Sadique Abubakar ti ko lo si Yobe lojo Isegun lati lo maa wa awon omodebinrin naa.
ó sọ fún wọn pé, “Ẹ lọ sí abúlé tí ẹ̀ ń wò ní ọ̀kánkán yìí, bí ẹ bá ti wọ inú rẹ̀, ẹ óo rí ọmọ kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ kan tí ẹnikẹ́ni kò gùn rí, tí wọ́n so mọ́ èèkàn, ẹ tú u, kí ẹ fà á wá.
Nitori naa, ko jẹ iyalẹnu pe mo n bi awọn ọmọ to ni i.
igbakeji kọmiṣona ọlọpaa sọ siwaju si pe bi oloogbe naa ṣe dero ọrun ko ṣeyin oun.
Oríṣun àwòrán, @OfficialPDPNig Buhari, ìjọba rẹ ń jọ bí ègún f'órílẹ̀èdè Nàìjíríà-Oyedepo Àbádòfin láti ṣàmójútó ayélujára kò lè fẹsẹ̀ múlẹ̀ láéláé, Sowore fàáké kọ́rí Ìdí mẹ́ẹ́rin tí sísùn ní ìhòhò lé gbà ṣe ara a rẹ l'óore Ọmọ Nàìjíríà ni ẹnìkejì tó ní Coronavirus ní Washington 3.
O ni idibo ẹka ti wọn ni ajọ INEC yoo gba wọle fun idibo gangan.
Ó sì ti ṣe yín ní pípé ninu rẹ̀.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Nigeria Police: Ilé iṣẹ́ ọlọ́pàá fẹ́ gba ọ̀pọ̀ kọ́ńsítébù láti ranwọ́ lórí ètò ààbò 11 Èbibi 2019 Oríṣun àwòrán, Nigeria Police Force Àkọlé àwòrán, Eto aabo Naijiria Lara akitiyan rẹ lati ri wi pe eto aabo gbopọn si lorilẹede Naijiria, ile iṣẹ ọlọpaa ti ṣetan lati gba ọpọlọpọ kọnsitebu ti yoo maa ṣiṣẹ pẹlu awọn agbofinro lawujọ Alukoro fun ile iṣẹ ọlọpaa Frank Mba ṣalaye pe awọn kọnsitebu yii yoo maa ṣeranwọ fawọn ọlọpaa ṣugbọn wọn ko ni lanfani lati gbebọn.
E Ewart fi Ọba Seriki Abass Williams se olori oselu ilu Badagry lọdun 1895 Ọdun 1895 yii naa ni awujọ Musulumi fi jẹ Seriki ilẹ Yoruba, to si kọ Mọsalasi nla to wa ni Sango nilu Badagry lọdun 1896 Ọdun 1899 lo da ẹgbẹ Kila silẹ, to si ko awọn musulumi jọ lati kọwe ẹhonu si adele gomina Denton pe ko da ileẹkọ silẹ fawọn Musulumi nilu Badagry Ọba Seriki Abass Williams di aarẹ fun kootu ibilẹ nilu Ilaro, Addo, Idogo, Igbeda, Oke Odan, Eggua Ipokia, Leke ati bẹẹ bẹẹ lọ Ọba Seriki Abass Williams ni aarẹ fun gbogbo ẹkun Ilaro, to si maa n gbe ade le awọn Alase tilu Ilase ati Oniboro tilu Iboro lori Ọjọ Kọkanla osu Kẹfa ọdun 1919 ni Ọba Seriki Ifaremilekun Abass Williams Fagbemi waja nilu Badagry.
FRSC: Ajínigbé tó kọlu òṣìṣẹ́ wá, èèyàn méjì kú, mẹ́rin farapa, a kò mọ ibí tàwọn mẹ́wàá wà
billion dollars) lati fi mu ayipada otun de ba eto oro aje orile-ede naa, bere
Oṣu Kọkanla, ọdun 2014, ni wọn da ẹgbẹ naa silẹ, nigba ti ẹgbẹ ajijangbara Ansar Bayt al-Maqdis to ti wa nibẹ lati ọdun 2011, jẹjẹ atilẹyin rẹ fun IS.
Alukoro ileeṣẹ ọlọpaa, Frank Mba ti sọ pe, oṣiṣẹ to ba jade lati ṣe iwọde lọjọ yoo foju wina ofin.
" Ni gbogbo akoko ti ọgagun Idiagbon n ṣíṣẹ lọ yii, ko si ẹnikẹni to pade ẹrin lẹnu rẹ ri nita gbangba nitori kii rẹrin si ohunkohun.
Ọlọrun lọ́wọ́ sí ohun tí àwọn ará Juda ń ṣe, ó fi sí wọn ní ọkàn láti mú àṣẹ tí ọba ati àwọn olórí pa fún wọn ṣẹ, gẹ́gẹ́ bí àṣẹ OLUWA.
 Ó lajù afọ ́ jú , Ó jí okù dìde , Ó mú arọ ní ara dá .
Kí wọ́n má baà kọ yín ní ìkọ́kúkọ̀ọ́, kí ẹ má baà máa ṣe oríṣìíríṣìí àwọn ohun ìríra tí wọn ń ṣe nígbà tí wọ́n bá ń bọ àwọn oriṣa wọn, kí ẹ má baà dẹ́ṣẹ̀ sí OLUWA Ọlọrun yín.
Má dárí ìwà ibi wọn jì wọ́n,má sì pa ẹ̀ṣẹ̀ wọn rẹ́ níwájú rẹ.
Ṣíṣe tí ẹ ṣe bẹ́ẹ̀ fi yín hàn bí ẹlẹ́rìí pé ẹ lóhùn sí ìwà àwọn baba yín: wọ́n pa àwọn wolii, ẹ̀yin wá ṣe ibojì sí ojú-oórì wọn.
Ní ọdún 2015, àwọn ẹgbẹ́ òṣèlúu rẹ̀ tún gbé e sípò fún sáà kẹ́ta lórí oyè.
Alex Oxlade-Chamberlain fi ẹsẹ rọ́ Ohun naa si ni pe, Alex Oxlade-Chamberlain fi ẹsẹ ṣeṣe, ti wọn si gbee jade.
Ṣugbọn ẹ kò gbọdọ̀ mẹ́nuba ẹrù OLUWA mọ́.
Agbẹnusọ ijọba kan ti sọ fun ile isẹ́ BBC pe, awọn si wa lori dídúnàá dúrà pẹ̀lú ikọ̀ Boko Haram lori bi wọn yoo se tú awọn ọmọbirin méjìléláàádọ́fà ọun to wà ninu àhámọ́ wọn sílẹ̀, ati pé, awọn ò ní káàárẹ̀ lori ìgbìyànjú awọn.
Xenophobic Attack: Ìjọba rọ ọmọ Nàìjíríà pé kí wọ́n dẹ́kun kíkọlu iléeṣẹ́ South Africa
Àwọn tí wọn ń fi ìwà aiṣododo fa ẹ̀ṣẹ̀ bí ẹni tí ń fi okùn fa ẹṣin.
Ayinla Ọmọwura, orin èébú àti oríyìn lo fi di ọ̀rẹ́ àwọ̀n obìnrin ''Wàhálà Ikẹja ló sọ mí di oníṣẹ́ ọwọ́ àgbọn ní Badagry'' Ìtàn tó rọ̀ mọ́ òwe ‘aṣọ kò bá Ọ́mọ́yẹ mọ́.
Bakan naa lori ẹsun ti ajọ aṣọbode fi kan pe, bọọsi naa ko aṣọ ti ofin ko faaye gba ni awọn oṣiṣẹ awọn ṣe da a duro, Solomon sọ pe: Irọ ni, wọn kan n wa ọna lati bo iwa ti wọn hu mọlẹ ni, kiiṣe 'tori pe ọkọ bọọsi wa ko aṣọ ti ofin ko fọwọ si."
Àwọn tí wọn ń dá àbá tí ó yàtọ̀ sí tèmi,tí wọn ń kó ẹgbẹ́ jọ,ṣugbọn tí kìí ṣe nípa ẹ̀mí mi;kí wọ́n lè máa dá ẹ̀ṣẹ̀ kún ẹ̀ṣẹ̀.
“Gbogbo àwọn aya rẹ ati àwọn ọmọ rẹ ni wọn yóo kó lọ sọ́dọ̀ àwọn ará Kalidea, ìwọ gan-an kò sì ní bọ́ lọ́wọ́ wọn.
Awọn oloútú orin, (music producer) ni mi o ba tun ṣe.
Oríṣun àwòrán, @odunlade Àkọlé àwòrán, Ere itage, fiimu agbelewo, sinima ati awọn ọna idanilaraya miran ni Yoruba ma n ṣe ki wọn fi pa ironu mọ.
Ninu ìdílé Iṣari, Kenanaya ati àwọn ọmọ rẹ̀ ni wọ́n yàn ní alákòóso ati onídàájọ́ fún àwọn ọmọ Israẹli.
merin ti yoo lo ninu ewon yoo bere lojo ketala osu keji odun ti a wayii, ti n
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Boko Haram: ile ejọ dá ẹ̀wọn ọdún 20 fún Banzana Yusuf 13 Agẹmo 2018 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ile Ẹkọ Chibok níbi ti ìjínigbé ti wáyé ní ọdún 2014 Ilé ẹjọ́ tí dájọ́ ẹwọn ogún ọdún fún ọdaran míran tó kópa nínú ìjínigbé àwọn ọmọbinrin Chibok.
Nigba to n fidi isẹlẹ iku oloogbe naa mulẹ fun BBC Yoruba, gbajumọ osere tiata miran, Ebun Oloyede, ti ọpọ eeyan mọ si Olaiya Igwe ni lootọ ni baba naa ti lọ.
Òtítọ́ ni gbogbo ọ̀rọ̀ rẹ,gbogbo òfin òdodo rẹ ni yóo máa wà títí lae.
Arisekọla Alao: Ka ni Baba n bẹ laye.
Aworan yii lo si n fi ye wa pe oju ọrun to ẹyẹ fo lai fi apa kan ara wọn Oríṣun àwòrán, AFP Àkọlé àwòrán, Iya ati ọmọ lo tu jade ni Khartoum, lorilẹede Sudan lati se iwọde tako ijọba ologun.
Àwọn onigbagbọ ibẹ̀ ti gbọ́ ìròyìn wa.
OLUWA Ọlọrun, wọ́n ń sọ nípa mi pé, ‘Ǹjẹ́ òun fúnrarẹ̀ kọ́ ni ó ń ro òwe yìí, tí ó sì ń pa á mọ́ wa?
Ẹni ọdún mọkanlelogun ni Sedekaya nígbà tí ó jọba, ọdún mọkanla ni ó sì fi wà lórí oyè ní Jerusalẹmu.
ọmọ Elikana, ọmọ Jerohamu, ọmọ Elieli, ọmọ Toa, 
Ninu wọn la ti ri ilumọọka ọjọgbọn Litireṣọ, Wọle Soyinka t'oun ati awọn miran ni fasiti Ibadan da ẹgbẹ wọn silẹ Àkọlé àwòrán, Wole Soyinka Salaye abamọ ti wan ko leyin ti Pyrates bere Awọn akẹkọọ ta n sọ yi pe ẹgbẹ wọn ni National Association of Seadogs, or Pyrates, ti wọn si gbe kalẹ lati tako awọn to n fi ipo ọla yan awọn ara toku jẹ.
Minista naa soju abe niko lori ipinnu ijoba apapo tuntun lori oro ikorira ti o n gbale kan lasiko yii.
7 Àti pé, bí ìwọ bá pa àwọn òfin mi mọ́ tí o sì fi orí tìí dé òpin ìwọ yíò ní ìyè ayérayé, ẹ̀bùn èyí tí ó ga jùlọ nínú àwọn ẹ̀bùn Ọlọ́run.
O ṣiṣẹ gẹgẹ bi agbẹjọro agba orilẹede Ghana laarin ọdun 2001 si ọdun 2003.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìpàdé àwọn orílẹ̀èdè G7:Trump lòdì sí àbájáde ìpàdé 10 Òkùdu 2018 Àkọlé àwòrán, Ààrẹ Trump tàpá sí àbájáde ìpàdé G7 Sáájú, Ààrẹ Trump ti sáájú buwọ́lù àbájáde ìpàdé náà ṣùgbọ́n o yí ìpinu rẹ pàdà Ààrẹ orílẹ̀-èdè Amẹ́ríkà Donald Trump ti yí ọrọ pàdà lórí àbájáde ìpàdé àwọn orílè-èdè G7 ti o tí sáájú buwọ́lù.
Ojú mi rí nǹkan nínú Igbó Olódùmarè, ojú mi rí nǹkan.
Ẹni tí ó bá fẹ́ràn ọmọ rẹ̀ ọkunrin tabi obinrin jù mí lọ, kò yẹ ní tèmi.
Gbogbo àwọn tí o fi ìmọ̀ rẹ jínkìn-ín l'Áfíríkà ń ṣe lé dè lẹ́yìn rẹ
"A máa n ṣe àgbéyèwò ìròyìn kan, à ó yẹ gbogbo ẹ̀rí to níṣe jáde pẹlu àìní ẹni ti a ń ṣègbè fún lọ́kan"" A mọ pé ó n ira láti dá ìròyìn tó jẹ́ ojúlowó mọ̀ lári ẹ̀rọ ayélujára."
Bí ó bá jẹ́ ìbejì, ọjọ́ náà la ó tó kó wọn sí gbangba òde.
Bakanaa ni iroyin ti sọ siwaju wi pe gbogbo awọn olugbe agbegbe mẹta ti ọrọ naa kan ni wọn gba ikilọ latọdọ ikọ alakatakiti Al-Shabaab pe wọn ko gbọdọ maa tan ina iwaju ile wọn silẹ ni alẹ mọ nitori o seese ki awọn ikọ naa o maa fẹ ki lilọ-bibọ wọn lalẹ o maa di mimọ.
Irun orí rẹ̀ náà dàbí irun aguntan funfun,ìtẹ́ rẹ̀ ń jó bí ahọ́n iná,kẹ̀kẹ́ abẹ́ ìtẹ́ rẹ̀ sì dàbí iná.
Ṣaaju ni ijọba apapọ Naijiria naa ti kede pe ki awọn akẹkọọ ti yoo kọ idanwo aṣekagba jakejado Naijiria pada sile ẹkọ ni igbaradi de idanwo wọn.
Mana kò dà ní òwúrọ̀ ọjọ́ keji, àwọn ọmọ Israẹli kò rí i kó mọ́, lẹ́yìn tí wọ́n ti jẹ ninu èso ilẹ̀ náà.
Bí ọkùnrin náà ti ń fẹ́ parí ọ̀rọ̀ rẹ̀ ni imọ̀nàmọ́ná bù tí mo wo ibi ti ọ̀rọ̀ náà ti ń wá, mo rii, ó lóṣòó gọ́ú sí ẹ̀bá ogiri ilé mi; mo rii, ó wọ ẹ̀wù péńpé bí ẹ̀wù ọdẹ, ó gbé ìbọn kan tì sí ẹ̀gbẹ́ ogiri.
'Iléèṣẹ́ ọlọ́pàá ló gbégbà orókè nínú ìwà jẹgudujẹra ní Nàìjíríà' O ni ọrọ akọmọna ipolongo idibo ẹgbẹ oṣelu APC, Next level ko gbọdọ pari sibẹ o nitori naa gbogbo igbesẹ eto idagbasoke ọrọ aje to wa ninu akọmọna naa bii fifẹ oju eto ọrọ aje, mimu idagbasoke awọn obinrin ati ọdọ lọkunkundun sii lo yẹ ko jẹ ijọba logun bayii ki orilẹede Naijiria naa le janfani ayipada rere gbogbo to ba n waye lawujọ agbaye.
Aadọta miliọnu owo dọla ni owo ti yoo kọ fasiti naa tan gẹgẹ akọsilẹ ẹka ijọba to n ri si eto irinna ni Naijiria.
Onimọ kan lati fasiti Oxford, Ọjọgbọn Jeffery Almond sọ pe abẹrẹ yii ko le ṣayipada si DNA eeyan.
Onibaara naa ni oun yoo san ẹgbẹrun mewa naira fun aṣẹwo naa, ni o ba wọ inu ọkọ arakunrin naa.
Nítorí náà ni wọ́n ṣe sọ ọ́ ní Jakọbu.
Lori opo ikansiraẹni Twitter ni onkowe kan ti sọ itan Ken Saro-Wiwa, to si pe fun idajọ otitọ lori isekupani naa.
Toyin to ṣẹṣẹ bẹrẹ owo tita awọn ewe ati egboogi ibilẹ ni ilana igbalode ni oun n sọ itan b'oun ṣe di abiyamọ lati le jẹ ọna ibukun fun ọpọlọpọ.
paapaa ni aṣiko Agbẹnusọ to wa nipo bayii, Aṣofin
Nigba ti eeyan mẹfa ku ni o fofin de lilọ bibọ gbogbo ni ilẹ naa-nigba ti yoo fi di ogunjọ osu Kẹrin, eeyan mejila nikan lo ku nibẹ.
Davido gba ami-eye ohun lojo Aiku(Sunday), ojo kẹ́rìnlélógún osu kefa odun ti a wayii, ni gbagede Microsoft Theater nilu Los Angeles, California.
 Adari ijoba orile ede Britain ti lọ yika ilu Eko, o si ti setan lati tun fowosowopo pelu  wa ,lati tun je ki awon omo orile ede Britain tun da okoowo sile si i.
Oyè adelé alága APC kúrò ní gúúṣù Nàíjíríà, ó bọ́ sẹ́kùn àríwá Gomina ipinlẹ Yobe, Mai Mala Buni ti di Alaga ẹgbẹ oṣelu APC tuntun ni Naijiria.
Ati pé Elisabẹti, ìbátan rẹ náà ti lóyún ọmọkunrin kan ní ìgbà ogbó rẹ̀.
“Ọjọ́ meje ni ẹ óo fi jẹ burẹdi tí kò ní ìwúkàrà ninu.
O rọ ileẹjọ lati kede pe ijọba apapọ n ṣegbe lẹyin ẹnikan lẹyin to faye gba iru ẹṣọ alaabo bi Amọtẹkun lapa ariwa.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Wolii Arole Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Aseyọri ami ayo meje si ọkan ti Real Madrid se lọjọ aiku ti jẹ ki wọn gun oke si ipo kẹrin lori tabili La Liga.
Ó na nǹkankan tí ó dàbí ọwọ́, ó fi gbá ìdí irun orí mi mú, ẹ̀mí sì gbé mi sókè sí agbede meji ọ̀run ati ayé, ó gbé mi lọ sí Jerusalẹmu, ninu ìran Ọlọrun, ó gbé mi sí ẹnu ọ̀nà àgbàlá gbọ̀ngàn ti inú tí ó kọjú sí ìhà àríwá, níbi tí wọ́n gbé ère tí ń múni jowú sí.
Lára àwọn eré tó ti kópa ni Abami Eda, Ibeji Gbajumọ, Mama Iyawo Ika, Pregnancy Test, Owo ni koko àti bẹ́ẹ̀ bẹ́ẹ̀ lọ.
OLUWA má bínú pupọ jù,má máa ranti ẹ̀ṣẹ̀ wa títí lae.
Wọ́n fi igi olifi ṣe férémù ìlẹ̀kùn onígun mẹrin, wọ́n rì í mọ́ ẹnu ọ̀nà àbáwọ gbọ̀ngàn ńlá.
EFCC fikun wi pe awọn n ṣiṣẹ pẹlu Ajọ Otẹlẹmuyẹ ilẹ Amerika, FBI titi ọwọ palaba rẹ fi segi.
Ìkòkò inú ilé OLUWA, yóo sì máa dàbí àwọn àwo tí ó wà níwájú pẹpẹ.
“Akoko aawẹ Ramadan jẹ asiko ti a fi n ni arojinlẹ.
Oríṣun àwòrán, Facebook/Sanuel Ortom Àkọlé àwòrán, Atundi ibo Benue Ọga ajọ INEC, Sebastain Maimako to kede esi ibo naa ṣalaye pe Ortom ni ibo 434,473 nigba ti oludije ẹgbẹ APC to sun mọ julọ Ọgbẹni Emmanuel Jime ni 345,155.
aarẹ ni Abubakar Badaru( Jigawa) Abiola Ajimobi (Oyo) ati Yahaya Bello (Kogi) .
Bakan naa ni Igbakeji Gomina naa gboriyin fun Adajọ Agba ni ipinlẹ Ondo fun iduro sinsin rẹ, to si tẹle ofin orilẹede Naijiria ti ọdun 1999.
Tope Alabi: Mo ti tọrọ aṣọ àti yẹtí etí rí, kí n tó leè ṣe àwo orin
Omo bibi ipinlẹ Adamawa ni ọgagunfẹyinti Alex Badeh jẹ.
Iroyin ti a gbọ ni pe ọkọ ayọkẹlẹ ti wọn wa ninu rẹ lo lọ fori sọ ọkọ nla akẹru kan nibi ti o duro si .
Ṣaaju ni Ajọ to n mojuto eto idajọ ni Naijiria, NJC, rọ Aarẹ Buhari lati sọ Onidajọ Muhammad di Adajọ Agba Naijiria.
-ẹjọ ri i pe asofin Adeleke wọ ile-iwe girama lọdun 1976, sugbon ko si ẹri
14 Ògún 2020 Obadiah Mailafia: DSS ti fi igbákejì gómìnà CBN tó ní gómìnà kan ní Àríwá Naijiria ní Ọ̀gá Boko Haram sílẹ̀14 Ògún 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 3 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 5 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Amọ wọn ko ri iwe ẹri to fihan gbangban pe lootọ, lo ti ku amọ aburo baba naa ni oun buwolu iwe eri pe ẹgbọn oun ti ku.
Gẹ gẹ gẹ si ni awọn ayaba kekere maa n gbe olori agba yii nitori pataki ipo rẹ ninu aafin, ti iya naa si ti pe ẹni ọdun mẹtalelaadọrin loke eepẹ.
O wọ inu ipolongo ibo aarẹ lai ni anfaani to Trump, to ti lo gbogbo asiko to fi wa nipo aarẹ lati gbaradi fun ipolongo saa keji.
Ṣugbọn lẹyin ọpọ awuyewuye, wọn gba pe awọn ọmọbinrin aadọfa ni wọn n wa bayi lẹyin ikolu ọhun.
Ni  sise-n-tele, alekun ba awon oja idokowo ohun bi iko 8.
letoo si i,ni awon ko faramo.
 púpọ ̀ àbájáde ìwádìí àwọn onímọ ̀ -èdè tí ó wà ní àrọ ́ wọ ́ tó ni ó dálé ìpín-sí-ìsọ ̀ rí àwọn ẹ ̀ ka-èdè yorùbá .
Ṣé ojú ara ní mo fẹ́ fi bímọ ni tàbí iṣẹ́ abẹ, kí ni ìdí.
Ó ní àwọn akọ́ṣẹ́mọṣẹ́ ti wò ó fínífíní wọ́n sì rí i pé Cannabis jẹ́ ọ̀kan lára àwọn oògùn tó lè fa ààrùn ọpọlọ tó wọra fún ènìyàn.
" wọ ́ n ma ń fi igbá àti ṣe àmì Ọbàtálá àti odùduwà nígbà tí ọnọrí igbá ń rọ ́ pò Ọbàtálá tí ìyá igbá sì ń dúró fún odùduwà gẹ ́ gẹ ́ bíese "" Ọlọ ́ fin Ọ ̀ yẹ ́ tẹ "" tí ó túmọ ̀ sí ẹni tí gba igbá ìyè lọ ̀ dọ ̀ elédùmarè ."
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Genotype: Kí làwọn àǹfàni àti ewu tí ẹ̀yà jínótáìpù rẹ le mú bá ìgbé ayé rẹ̀ Ileesẹ ọlọpaa ni aayan ti n lọ lọwọ lati sawari awọn olubi ẹda naa.
OLUWA fi iṣẹ́ ibi wọn hàn mí, ó sì yé mi.
Ati pe ayọ ti o ba ri ọmọ rẹ ko wa laaye ati ni alaafia yoo jẹ ki o gbagbe awọn ounjẹ tabi nkan didun to wu ọ jẹ tẹlẹ ṣugbọn to le ṣe akoba fun oyun inu rẹ nigba naa.
lati tako ilana ati agbara ajo INEC , ni eyi ti yoo se lee gbe lẹyin awon kan
Alao akala ni gẹgẹ bii Ọlọpaa to ti feyinti oun mọ ọna abayọ si ipenija ọrọ abo.
Akin Ogungbe: Oríṣun àwòrán, Premium times Ọdun 1934 ni Akintola Ogungbe, ti ọpọ eeyan mọ si Baba Ibeji dele aye, oṣere, Onkọrin, onijo, Olootu ati oludari ere nii ṣe ko to jade laye ni ọdun 2012.
0 1 Please update your browser to see full interactive Show more This information is regularly updated but may not reflect the latest totals for each country.
" O ni o yẹ ki ọmọde maa kunlẹ, ki wọn si tu maa dọbalẹ fun agbalagba gẹgẹ bo ṣe wa ninu aṣa ati iṣe ilẹ Yoruba.
Wọn ti gbe ojuṣe le mi lọwọ lati jẹ awokọṣe fun ọpọlọpọ eniyan, mo ṣi ṣe ileri pe maa ṣe ojuṣe mi pẹlu ẹmi ifọkansin si Allah, bi Allah ba fẹ."
Òun nìkan ni kí ọ̀rọ̀ rẹ̀ máa pá ọ láyà.
Ọkùnrin kan báyìí bá wa bọ̀ tí orúkọ rẹ̀ ń jẹ kùmọ̀dìran, bẹ́ẹ̀ ni ènìyàn pàtàkì ni, ó jẹ ẹnìkan tí ìṣẹ̀da tirẹ̀ yàtọ̀ gbáà, bí ènìyàn kò bá lùú ní kùmọ̀ dáadáa lẹ́yìn ọrùn ara rẹ̀ kìí le.
Ogunlogo awon omo orile-ede Zimbabwe ni won peju si papa ti Robert Mugabe lati se isin iranti fun oloogbe Morgan Tsvangirai, ti o je olori ijoba orile-ede naa saaju eto isinku re ti yo waye loni  ogunjo  osu keji odun 2018 ni ilu re Buhera lorile-ede naa.
Àwọn ni wọ́n súnmọ́ ọn jù, tí ipò wọn sì ga jùlọ).
nígbà náà ni àwọn ẹ̀dá ọ̀run lọkunrin ṣe akiyesi pé àwọn ọmọbinrin tí eniyan ń bí lẹ́wà gidigidi, wọ́n sì bẹ̀rẹ̀ sí fẹ́ èyí tí ó wù wọ́n lára wọn.
Baraba ni kí o dá sílẹ̀ fún wa.
Nigbati Bàbá mba iṣẹ́ oselu kiri gbogbo àgbáyé, Iyá ló di ilé mú, ti ọkàn Olóògbé Olóyè Ọbáfẹ́mi Awólọ́wọ̀ fi balẹ̀ lati le fi ipò Olóri Òsèlú ṣe iṣẹ́ ribiribi ti ó ṣe.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù France 2019: orílẹ̀-èdè Adulawọ mẹ́ta ló n lọ ṣojú Afirika 7 Òkùdu 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Asisat Oshoala maa gba bọọlu fun Naijiria Orilẹ-ede France lo maa gbalejo awọn agbabọọlu obinrin ni gbogbo agbaye lọdun 2019.
Makinde fi asiko naa tenumo ileri to se lati na ida mẹ́wàá (10%) owo eto isuna
Ta ni OLUWA ti bá sọ̀rọ̀, kí ó kéde rẹ̀?
” Àwọn ẹ̀wọ̀n tí wọ́n fi de Peteru bá yọ bọ́ kúrò ní ọwọ́ rẹ̀, 
O sọ bi awọn ṣe maa n so asọ ara awọn papọ, ki iji lile ati ẹkun omi maa ba gbe awọn lọ.
Olόwό Ìbínú ló ní owó jùlọ jàkéjádò ìlú-u wọn ní àtijọ́.
Àwọn jàǹdùkú pa fadá ní Taraba-Iléeṣẹ́ ọlọ́pàá Ọwọ́ EFCC tẹ ọ̀kan lára àwọn ti FBI fi èsún jìbìtì kàn!
Ó dùn mọ́ mi nítorí yín pé n kò sí níbẹ̀, kí ẹ lè gbàgbọ́.
Nígbà náà ni Mahila, Noa, Hogila, Milika ati Tirisa, àwọn ọmọbinrin Selofehadi, ọmọ Heferi, ọmọ Gileadi, ọmọ Makiri, ọmọ Manase, ti ìdílé Manase, ọmọ Josẹfu, 
Fun idi eyi,awẹ yoo bẹrẹ lọjọ kini oṣu tuntun.
Nigeria Senate: Àwọn àbádòfin pàtàkì márùn ún áti ipa wọn nílùú láàrin ọdún kan tí wó̩n fi ṣiṣẹ́
Nítorí èyí, ọpọlọpọ ninu àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ pada lẹ́yìn rẹ̀, wọn kò tún bá a rìn mọ́.
Ó sì ń fa àmì ìfòyà.
Gẹgẹ bẹẹ se mọ pe alasẹ ekeji orisa ni awọn Ọ́ba alaye nilẹ Yoruba, awọn si ni araalu ri bi igbakeji orisa, ti wọn gbọkan wọn le.
Ó lọ sí Beeriṣeba, ní ilẹ̀ Juda.
Láti òní lọ, mo fi ilé ìyá mi sílẹ̀ , mo di ìyá sí ilé tèmi.
Chris Murphy to ti ekun ti isele buruku ti Sandy Hook to gbemi opo eniyan ni odun 2012 wa ni o dabi pe egbe NRA ni agbara tani-o-mu-mi ti won maa n lo lasiko tijiroro ba n waye nile igbimo asofin.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Awọn aṣofin f'ọwọsi Imam gẹgẹbi adajọ agba ile ẹjọ Sharia 8 Ẹrẹ̀nà 2018 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Wọn fi ẹniọwọ Rufai Imam jẹ adele adajọ agba ilẹjọ kotẹmilọrun Sharia ni osu kẹta ọdun 2017 Ile asofin agba lorilẹede Naijiria ti buwọlu orukọ Ẹniọwọ Rufai Imam gẹgẹbii adajọ agba fun il ẹjọ kotẹmilọrun Sharia ni lu Abuja.
Ṣugbọn nígbà tí àwọn ọmọ Israẹli di alágbára, wọ́n bẹ̀rẹ̀ sí fi tipátipá mú àwọn ará Kenaani sìn, wọn kò sì lé wọn jáde patapata.
Ẹgbe oselu African National Congress (ANC) to ja fun ominira awọn eniyan dudu lorilẹede naa lo ti wa lori aga iṣejọba orilẹede ohun lati ọdun 1994.
"Baba Mero, Ọga mi lo fun ni orukọ Aluwẹ ti mo n jẹ ninu ere, ṣugbọn agba olorin, Sunny Ade lo fi Papiluwẹ kun un.
Army Vs Police: Ẹ gbọdọ wẹ́ orúkọ ilé iṣẹ́ ọmọ ogun mọ́ kúrò nínú ọ̀rọ̀ yìí- Buratai
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Ó ṣojú mi kòró, ẹ wọ bí ìgbà ayé Bàbá Fagunwa ṣe rí' Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
A gbo pe awọn ẹka ileeṣẹ orileede Amerika nilu Eko ati nilu Abuja lọrọ yi kan.
Sunday Ayẹni: Damilọla, aya ọmọ mi fìgbónára sọ mi sókùnkùn alẹ́
Ìmọ́lẹ̀ rẹ̀ dàbí ti òkúta iyebíye.
“Kinniun bú ramúramù, ta ni ẹ̀rù kò ní bà?
Nkan ìgbàlódé ni SIM Card jẹ́.
Iroyin ti wa ko to kẹẹ wo fọnran naa funra yin.
ni ọjọ kẹ́tàlélógún  osu yii se n sunmọle
“Sọ fún gbogbo àwọn eniyan ilẹ̀ náà ati àwọn alufaa pé, nígbà tí ẹ̀ ń gbààwẹ̀, tí ẹ sì ń ṣọ̀fọ̀ ní oṣù karun-un ati oṣù keje fún odidi aadọrin ọdún, ṣé èmi ni ẹ̀ ń gbààwẹ̀ fún?
Bi nnkan ti ṣe ri bayi, Manchester City lo jọ bi pe wọn yoo gba ife naa.
Oríṣun àwòrán, @Segunmimiko Àkọlé àwòrán, Mimiko ni fun anfani ẹgbẹ oṣelu Zenith Labour Party ni igbesẹ ti oun gbe Ni bayii, oludije fun ipo sẹnetọ ni ẹkun idibo ile aṣofin apapọ Ondo Central tẹlẹ, Onimọ ẹrọ Gboye Adegbenro ni oun pẹlu ti yọ ọwọ kuro ninu idije fun ipo sẹnetọ lọdun 2019 lati fun gomina ana nipinlẹ Ondo, Dokita Oluṣẹgun Mimiko laaye lati dije.
Ìgbà tí wọ́n ronú nípa bí àwọn ìbá ti ṣe owó yìí, wọ́n pinnu láti kó o lọ nígbà tí ilẹ̀ bá ṣu, nítorí bí àwọn wà, ìgbà tí wọ́n ronú nípa bí àwọn ìbá ti ṣe owó yìí, wọ́n pinnu latí kó o lọ nígbà tí ilẹ̀ bá ṣu, nítorí bí àwọn bá kóo o ní ọ̀sán, wọ́n ó mú àwọn gẹ́gẹ́ bí olè.
Irú ẹ̀dá wo ni olówó yalumọ àkọ́kọ́ nílẹ̀ Yorùbá, Candido Da Rocha?
Iṣẹlẹ ọhun ni wọn ni o waye niwaju ile itura Wetland lagbegbe Ughelli ni ipinlẹ Delta.
Ẹ sọkún tẹ̀dùntẹ̀dùn, ẹ̀yin tí ẹ̀ ń gbé Mota, ní Jerusalẹmu; nítorí pé àwọn oníṣòwò ti lọ tán patapata; a ti pa àwọn tí ń wọn fadaka run.
Jesu wí fún wọn pé, “Òtítọ́ ni Aisaya sọ ní àtijọ́ nípa ẹ̀yin àgàbàgebè, tí ó sì kọ ọ́ báyìí pé,‘Ọlọrun wí pé: Ẹnu ni àwọn eniyan wọnyi fi ń yẹ́ mi sí,ṣugbọn ọkàn wọn jìnnà sí mi,
Super Eagles kò ní já àwọn ọmọ Nàìjíríà kulẹ̀- Musa Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Ife Farao wà ní ọwọ́ mi, mo bá mú èso àjàrà náà, mo bẹ̀rẹ̀ sí fún un sinu ife Farao, mo sì gbé ife náà lé Farao lọ́wọ́.
Fún ẹni tí ààrùn Coronavirus bá bá jà gidi, Fẹntíletọ̀ nìkan lọ́nà àbáyọ láti lè jẹ kí òní anfaani yíyè.
Bẹ́ẹ̀ náà ni ó sọ ní ibòmíràn pé,“Alufaa ni ọ́ títí laelaegẹ́gẹ́ bíi ti Mẹlikisẹdẹki.
Ọba Babiloni pa àwọn ọmọ Sedekaya ní Ribila níṣojú rẹ̀, ó sì pa gbogbo àwọn ìjòyè Juda pẹlu.
Mose sì ṣe bí OLUWA ti pàṣẹ fún un.
 ibi tí àwọn kan ti ń gbá owó ni àwọn kan ti ǹ gbá òsi .
Alaafin maa njẹ eso bii ọgẹdẹ, to si tun maa njo daada.
Wọn bẹrẹ si ni ṣe eyi ni iranti awọn to ja fitafita fun ijọba awaarawa ni Naijiria.
2 Àti pé ìwọ ti sọ ẹ̀bùn rẹ nù ní ìgbà kannáà, iyè rẹ sì ti ṣókùnkùn.
Isaaki tún àwọn kànga tí wọ́n ti gbẹ́ nígbà ayé Abrahamu baba rẹ̀ gbẹ́, nítorí pé, kò pẹ́ lẹ́yìn tí Abrahamu kú ni àwọn ará Filistia ti dí wọn.
Ninu ọkan lara ipe ipejọpọ bẹẹ ti wọn pee fun lasiko ipolongo ibo fun Goodluck Jonathan to fẹ dije fun ipo aarẹ lẹẹkeji lọdun 2015 ni Toyin ti sọ pe oun lee ku nitori ẹgbẹ oṣelu PDP.
Lassa Fever: Ṣe ẹ rí eku tí ẹ̀ ń pè yẹn, oúnjẹ tó dára ni - ìyá ẹgbẹ́ àwọn eléwé ọmọ̀ Lẹ́yìn ọdún mẹ́ta l'ẹ̀wọ̀n akọrin ẹ̀mi gbẹ̀mí ará rẹ̀ látìmọ́lé Iku Mọkaliki: Àgbáríjọ àwọn ajàfẹ́tọ̀ọ́ pè fún ìdádúró kọmísánà ọlọ́pàá Ìjọba Ọṣun ti dásí ìjà láàrin Oluwo àti Agbowu Otun ni ohun ti wọn ma n ṣe ni Ibadan ni wi pe, wọn ma n fi oye fun awọn ti wọn ba ni orukọ rere ni awujọ, bi wọn ko tilẹ ni owo lọwọ.
Wọn yóo jẹ àwọn nǹkan tí wọ́n fi ṣe ètùtù láti yà wọ́n sọ́tọ̀ ati láti yà wọ́n sí mímọ́, eniyan tí kì í bá ṣe alufaa kò gbọdọ̀ jẹ ninu rẹ̀, nítorí pé mímọ́ ni wọ́n.
29 Owewe 2020 Fídíò, Akomolede àti Asa lórí BBC Yorùbá: Mọ̀ síi nípa ẹ̀kún ìyàwó níbí3 Bélú 2020 Fídíò, Akomolede Yoruba: Ìtàn ọ̀rẹ́ tó fi ògùn gba ọkọ ọ̀rẹ́ rẹ̀ nílùú òyìnbó rèé15 Owewe 2020 Fídíò, Akinwumi Isola: Wo ohun tí Abeni fi ojú ọkọ rẹ rí tórí iṣẹ́ bọ́ lọ́wọ́ rẹ̀ nínú ìwé Nitori Owo""27 Ọ̀wàrà 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!"
Ibudo igbọnsẹ naa (The unko) maa n jẹ ki awọn eniyan ya aworan alarambara nipa igbọnsẹ.
Agbẹnusọ Ile Igbimọ Aṣofin Eko tun gba awọn musulumi niyanju pe ki wọn  ṣe ọdun naa  ni irọrun, ti ko ni fi si ọta tabi laasigbo lawujọ.
 O ṣapjuwe rẹ gẹgẹ bi oniwa pẹlẹ eniyan, to n fi gbogbo igba wa alaafia ilu ati gẹgẹ bi ẹni ti o n lakaka fun idagbasoke ipinlẹ rẹ igba aye rẹ.
Oríṣun àwòrán, Instagram/@therealremisurutu Awa naa wa n ba Remi Surutu yọ pe o ku oriire idana ọmọ rẹ, ọba oke yoo jẹ ka ri adun pupọ nibẹ Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
O fikun ọrọ rẹ pe nitori Naijiria jẹ ilẹ ọlọra to ni ohun alumọni ni Ilẹ Gẹẹsi fi n wa ibasepo to dan mọran pẹlu orilẹ-ede Naijiria lẹyin ti wọn ba kuro ninu Ajọ Isọkan Europe, European Union(EU).
O fikun pe ọjọ Ẹti to kọja ni wọn fun tọkọtaya naa ni kọkọrọ ile naa, nigba to ku ọla ti wọn yoo so yigi.
Ọba kò gbọdọ̀ gbà ninu ilẹ̀ àwọn ará ìlú láti ni wọ́n lára; ninu ilẹ̀ tirẹ̀ ni kí ó ti pín ogún fún àwọn ọmọ rẹ̀.
Ẹ̀yin òṣìṣẹ́, ẹ kọ ìyà tí wọ́n fi ń jẹ yín lórí owó oṣù tuntun - Oshiomole gbarata Ẹwẹ, ẹgbẹ oṣelu All Progressives Congress APC ti fesi si aṣẹ ile ẹjọ giga Abuja to ni ki alaga ẹgbẹ naa Adams Oshiomole lọ rọọkun nile.
 nínú ìlò ni àwon kan ti lè so pé òkan jé àtéwógbà , èkejì kò jé àtéwógbà .
 A wa lati ran ijoba lọwọ ati lati
Oríṣun àwòrán, others Awọn oludije mẹwaa ni yoo maa dije du aṣia ẹgbẹ oṣelu PDP loni fun idibo sipo gomina nipinlẹ Ondo ti yoo maa waye loṣu kẹwaa, ọdun 2020.
Awọn afurasi wo ni ọwọ ti tẹ nipa iṣẹlẹ naa, ati pe, nibo ni iwadi de duro lori iṣẹlẹ yii?
" Ọdun 2019 ni wọn pada bẹrẹ si ni ṣe amulo ofin ifipabanilopọ nipinlẹ Ekiti.
“Awon omo ologun orile ede yii, ti se gudu gudu meje yaya mefa nipa aseyori won lori awon iko olote, nitori naa, a ti setan lati se atileyin fun  awon omo ogun orile ede yii nipa pipese ohun irinse ati ironilagbara lati tubo lee se aseyori lori iko omo ogun olote.
Ìdí nìyí tí mo fi ń sa ipá mi kí ọkàn mi lè jẹ́ mi lẹ́rìí pé inú mi mọ́ sí Ọlọrun ati eniyan nígbà gbogbo.
Ni ọdun 1954, ajọ ontaja ẹkun iwọ oorun Naijiria, Western Region Marketing Board ni owo to to miliọnu mefa ati ẹgbẹrun lọna igba pọun (£6.
Atẹjade kan ti idile ọba Akinsemoyin fisita lori isẹlẹ naa, eyi ti Ọmọọba Salami-Abisako ati Ọmọọba Adeyemi Sarumi fọwọsi, wa fun awọn jandukan naa ni ọjọ kansoso pere lati da ọpa asẹ pada sinu aafin.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ayédèrú Afenifere ló bá Buhari ṣépàdé - Odumakin gbanájẹ Dapo Abiodun wà lára àwọn tó ta ohun ìjà olóró fún mi - Amoṣun 'A máa ń fí oògùn olóró 'ginger'ká tó ka ẹsẹ bíbélì ni ṣọ́ọ̀ṣì' Orin kíkọ kò dí ìwé mi lọ́wọ́ rárá -Hameen School Boy Ta lo wa ji oku ikoko?
Nígbà tí àwọn ẹyẹ tí wọ́n máa ń jẹ òkú ẹran rábàbà wá sí ibi tí Abramu to àwọn ẹran náà sí, ó lé wọn.
Wọ́n dá a lóhùn pé, “Bí o bá ṣe bí iranṣẹ fún àwọn eniyan wọnyi lónìí, tí o sì sìn wọ́n, tí o sì fún wọn ní èsì rere sí ìbéèrè tí wọ́n bèèrè lọ́wọ́ rẹ, ìwọ ni wọn óo máa sìn títí lae.
’’Ewe, awn eniyan jankan-jankan ti yoo maa wode leyin aare ni, gomina ipinle Enugu, Ifeanyi Ugwuanyi, ipinle Kogi, Yahaya Bello ati gomina ipinle Niger, Abubakar Bello.
Ẹ wo bí Hushpuppi ṣe farahàn nílé ẹjọ́ l'Amẹrika fún ìgbà àkọ́kọ́ láti jẹ́jọ́ Oríṣun àwòrán, HUSHPUPPI/INSTAGRAM Saaju la ti mu iroyin wa fun yin pe Raymond Abass, ti gbogbo eeyan mọ si Hushpuppi, ti farahan nile ẹjọ nilẹ Amẹrika.
Ẹ̀wọ̀n gbére ni fún ẹnikẹ́ni tó bá fipá bánilòpọ̀ ní ìpínlẹ̀ Ọ̀ṣun June 21 ni pápákọ̀ òfurufú márùn-ún yóò di ṣíṣí padà - Ìjọba àpapọ̀ Auxiliary korò ojú sí àwọn ọmọ ẹ̀yìn rẹ̀ tó ń dàlú rú Òṣìṣẹ́ ètò ìlera méjì ló wà nínú àwọn tó lùgbàdì àrùn coronavirus ní Ekiti Àkọlé àwòrán, Eyín ọ̀ọ́kán mi ni Barakat tí wọ́n pa lẹ́yìn tí wọ́n fipá bá a lòpọ̀- Ìyá Barakat Justice For Barakat: Nítòsí balùwẹ̀ ni wọ́n ti bá Barakat nínú àgbàrá ẹ̀jẹ̀, lẹ́yìn tí wọ́n fipá báa lòpọ̀- Ìyá Barakat Ati ẹbi ati awọn aladugbo lo pejupesẹ lati kẹdun arabirin Barakat Bello, ọmọ ọdun mejidinlogun ti awọn oniṣẹ ibi kan gba ẹmi rẹ lẹyin ti wọn fi ipa baa lopọ lọjọ Iṣẹgun.
Bù ninu rẹ̀, kí o gún un lúbúlúbú.
Lai Muhammed yóò fojú ba'lé ẹjọ́ - ICPC Ẹ̀yin tẹ́ẹ tako àgbékalẹ̀ àgọ́ Fulani, ìkórira ló ń yọ yín lẹ́nu - Ìjọba àpapọ̀ OPC: Bí a ṣe gbéná wojú awọn ọ̀daràn tó ń d'àlú Ikire rú rèé Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Kayefi BBC Yorùba: Bàbá ọmọ, Mọ́ṣúárì, Ọlọ́pàá kẹ́jọ́ rò nípa òkú ọmọ tó pòórá Joseph ni ile isẹ ọlopaa n ṣa gbogbo ipa awọn lati ri i wi pe wọn doola ẹmi dirẹba ti wọn ji gbe lọ.
Iya Muiz ni oun ni akọbi ni ile baba oun pẹlu ọmọ mejidinlogun ti ko si agbara rara.
Nígbà tí Huṣamu kú, Hadadi, ọmọ Bedadi, tí ó ṣẹgun àwọn ará Midiani ní ilẹ̀ Moabu, jọba tẹ̀lé e.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ebola Virus: ìdí tí Ebola fi ń tàn kálẹ̀ Bakan naa, oun lo kọkọ fi ọrọ Ebola ti oloogbe Sawyer gbe wọ Naijiria to ileeṣẹ eto ilera ijọba apapọ l'eti.
Amòye eniyan rí ewu, ó sì fi ara rẹ̀ pamọ́,ṣugbọn òpè kọjá lọ láàrin rẹ̀, ó sì jìyà rẹ̀.
O ro awon  akekoo ohun lati se ojuse won bi o se to ati bi o se ye lakoko eto idibo naa.
Gbogbo àwọn ìjòyè ìlú yín parapọ̀ wọ́n sálọ,láì ta ọfà ni ọ̀tá mú wọn.
 Nitori naa, ijoba orile ede Naijiria ba awon
Bill, National Research and Innovation Council Est.
“Ninu àwọn ẹ̀dá alààyè tí ń gbé inú omi, ẹ lè jẹ àwọn wọnyi: gbogbo ohun tí ó bá ní lẹbẹ ati ìpẹ́, kì báà jẹ́ èyí tí ó ń gbé inú òkun tabi inú odò, ẹ lè jẹ wọ́n.
Oríṣun àwòrán, FEMI FALANA FACEBOOK O ni o ti tapa si ofin ijọba orilẹede Naijiria ti ọdun 1999 eyi ti wọn si ti ṣe atunṣe rẹ ni ti ẹtọ ọmọniyan.
 Ó jẹ ́ ilé-iṣẹ ́ asońje tí ó tóbi jùlo ní àgbáyé bí a bá fi òṣùwòn owó pípa wolé àti awon òṣùẁòn mìíràn láti ọdún 2014 .
A ó ò dasẹ́ sílẹ̀ fún ojọ́ gbọọrọ tí ìjọba bá kọ̀ láti san owó oṣù mẹ́rin tó jẹ wa- Àwọn dokita ìpínlẹ̀ Ondo
“Nítorí èyí ni mo ṣe sọ fun yín pé kí ẹ má máa ṣe àníyàn nípa ẹ̀mí yín, pé kí ni ẹ óo jẹ tabi kí ni ẹ óo mu, tabi pé kí ni ẹ óo fi bora.
 ""Mo ro pe ọna to dara lati koju aisan ọmọ mi ni ki n lọ ya Tattoo, eyi si ti ran mi lọwọ."
NCDC lo kede bẹẹ loju opo Twitter rẹ ni Ọjọ́ọ̀rú.
Ni ọjọ Aiku ni ileeṣẹ ọlọpaa kede pe Sunday Shodipẹ ti wọn mu fun lilọwọ ninu iku Barakat Bello, Azeezat Shomuyiwa, atawọn eeyan miran lẹyin ti wọn mu u loṣu keje ọdun yii.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Aláboyún oṣù mẹ́jọ kú lẹ́yìn tí ejò bù ú jẹ nílé ìyàgbẹ́ ilé rẹ̀ 3 Sẹ́rẹ́ 2020 Oríṣun àwòrán, Usman Ahmad Nuraini Àkọlé àwòrán, Zainab Aliyu Balarabe padanu ẹmi rẹ lẹyin ti ejo bu u jẹ nile iyagbẹ to wa nile rẹ.
Eniyan meji lo wa ni ipinlẹ Ọyọ lara wọn, mẹta si wa lati ilu Abuja.
Lẹ́yìn ò rẹyìn, Seyi Makinde bori arun Coronavirus Iroyin ayọ fun gbogbo awọn eeyan ipinlẹ Ọyọ.
Àwọn òmùwẹ̀ ń wá èèyàn kan tó pòórá lẹ́yìn ìjàmbá ọkọ̀ ojú omi to dójúdé l'Eko
Ileri ti Buhari fẹ gbajumọ ni saa keji iṣejọba rẹ: Nitootọ Aarẹ Buhari ko soju abẹ niko ni pato lori ileri rẹ, ṣugbọn o ṣapejuwe awọn koko ti ijọba oun yoo gbajumọ lasiko yii bii: Aṣepari awọn iṣẹ akanṣe ti ijọba rẹ ti bẹrẹ tẹlẹ.
Ondo Crisis: Aṣòfin Iroju Ogundeji, Favour Tomowewo àti Williams Adewale ń lọ rọọkún nílé
Ṣugbọn a óo máa san gbogbo ẹ̀jẹ́ wa, a óo máa sun turari sí ọbabinrin ojú ọ̀run, oriṣa wa, a óo sì máa ta ohun mímu sílẹ̀, bí àwa ati àwọn baba ńlá wa, ati àwọn ọba wa ati àwọn olórí wa ti ṣe ní gbogbo ìlú Juda ati ní ìgboro Jerusalẹmu; nítorí pé nígbà náà à ń jẹ oúnjẹ ní àjẹyó, ó dára fún wa, ojú wa kò sì rí ibi.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Russia infanticide: 11,000 ọmọdé làwọn òbí ti pa láàrin ọdún 1976 sí 1997 18 Agẹmo 2019 Ọpọ ninu awọn obinrin lo maa n jẹjọ lori ẹsun pe, wọn ṣeku pa ọmọ ti wọn bi fun ra wọn.
Ìran tí Aisaya ọmọ Amosi rí sí Babiloni:
Ninu oṣu kẹrin, ọdun 2018, ni awọn oludari eto sogundogoji ọhun kede pe awọn n kogba wọle nigba ti baba'salẹ wọn to bẹrẹ rẹ, Sergie Mavrodi kuÀìsan ọkàn pa olùdásílẹ̀ sogúndogójì MMM.
Ọmọwe Busari Adebisi, tii se arole fun idile Sanusi Adebisi ni Idikan n‘Ibadan salaye, lasiko to n ba BBC Yoruba sọrọ pe, eeyan kii sunkun wọ ile Adebisi, ko ma ba ẹrin jade.
pe ki wọn ko gbogbo awon to farapa nibi isẹlẹ naa lọ sile iwosan .
 ) ( the engine isn ' t firing .
Nígbà tí ó mú mi dé ìlú náà, mo rí ọkunrin kan tí àwọ̀ rẹ̀ dàbí idẹ.
Democratic Party,(PDP) padanu idije dupo asofin fun ekun ila oorun ipinle Gombe, sowo akegbe re ti o wa lati egbe
Aṣiṣe meji lo ṣokunfa ifidirẹmi Chelsea ninu ifẹsẹwọnṣẹ naa.
Wakati mẹrinlelogun pere lẹyin ti akanṣe Ọ̀rọ̀ ń bọ́ lóríi fídíò Codeine iroyin ọtẹlẹmuyẹ BBC yii jade nipa bi ọja okunkun tita oogun ikọ olomi Codeine ṣe n gberu sii ni Naijiria ni ijọba gbera lati wa wọrọkọ fi ṣ'ada.
Wọn yóo fọ́nká lọ sí Asiria; Ijipti ni yóo gbá wọn jọ, Memfisi ni wọn yóo sin wọ́n sí, Ẹ̀gún ọ̀gàn ni yóo hù bo àwọn nǹkan èlò fadaka olówó iyebíye wọn, ẹ̀gún yóo sì hù ninu àgọ́ wọn.
lọ si orile ede Saudi Arabia ni awon  oluranlọwọ  rẹ,aare yoo maa gunle si orile ede Saudi
Èrè mi sì wà lọ́wọ́ mi, tí n óo fún ẹnìkọ̀ọ̀kan gẹ́gẹ́ bí iṣẹ́ rẹ̀ bá ti rí.
Ohun tí ó fa ìjà tí Ògúndélé àti Jinádù ń jà ni pé Ògúndélé tí ó jé alágbẹ̀dẹ rọ kọ́kọ́rọ́ kan fún jìnádù ní múrí mẹ́ta (#60), Jìnádù san Múrí kan (#20) níbẹ̀ ó ku múrí méjì (#40).
“Sọ fún wọn pé, èmi OLUWA ní bí wọn kò bá fetí sí ọ̀rọ̀ mi, kí wọn máa pa òfin tí mo gbé kalẹ̀ fún wọn mọ́, 
se ifilole awon ise akanse ti ijoba ipinle naa ti gbe se.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù DSTV Price Hike: Ọmọ Nàìjíríà faraya lórí èlé owó DSTV tó ń wáyé ní ẹ̀ẹ̀kan lóṣù mẹ́rin 25 Ògún 2020 Oríṣun àwòrán, others Ileesẹ Multichoice tun ti kede pe, oun yoo tun ṣe afikun owo tawọn ọmọ Naijiria n san fun oju opo iworan DSTV ati GOTV.
Gẹgẹ bo se jẹyọ ni oju opo ikansiraaẹni ẹgbẹ ajafẹtọ ẹni kan, @justempower, jei, ẹgbẹ naa ni ọna ipa ti ijọba apapọ n gba le ogunlọgọ ero kuro ninu ile wọn lai bọwọ fun ofin to yẹ.
Ìdílé Barrister àti K1 Wasiu Ayinde sọ àsọyépọ̀ nílé Obey Commander - BBC News Yorùbá BBC News, YorùbáFò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Barrister - K1 rift: Ìjà parí!
Osu Kejila, ọdun to kọja ni ọmọ ọdun mẹrindinlaadọta naa pada wa si Man United lati gba isẹ lọwọ Jose Mourinho gẹgẹ bi akọnimọọgba.
"Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ayinla Ọmọwura, orin èébú àti oríyìn lo fi di ọ̀rẹ́ àwọ̀n obìnrin Ẹ wo ojú àwọn afurasí tí yóò rojọ́ ẹ̀ṣùn àjẹbánu lọ́dún 2021 Bí Nàíjíríà bá fẹ́ kí ọdún 2021 dára, ohun tí yóò ṣe rèé - Obasanjo Ẹgbẹ́ ọ̀dọ́ méjì fìjà pẹẹ́ta, ẹ̀mí kan bọ́, ọ̀pọ̀ farapa ""Àhámọ́ ajínigbé ni ń bá wà lónìí, ọ̀pẹ́ awakọ̀ mi"" Ẹ wo nkan tí Deeper Life High School tún sọ lórí Don Davis, akọ́kọ̀ọ́ JS1 tí wọ́n fi ipá bálòpọ̀ Àjọ NIMC ti gbé ìlànà tuntun jáde fún gbígba NIN lọ́nà ìrọ̀rùn Wo ọ̀pọ̀ mílíọ̀nù fóónù tí Whatsapp kò ní bá ṣiṣẹ́ mọ́ lọ́dún 2021 Ibodè àgbáyé ní Saki, ìbẹ̀ ni agbébọn ń gbà wọ ilẹ̀ Káàrọ̀ Oòjíire - Makinde gbarata Oniluola jẹ ipe Ọlọrun lẹyin osu kan ti wọn se ayẹyẹ ọjọ ibi rẹ eyi tawọn eeyan jankanjankan peju si."
"Awọn agbẹ yii bẹrẹ si ṣe iwọde yika aba kọọkan, ti wọn si n kọrin ""Ọ̀kẹ́ mẹfa la o san"", eyi tii ṣe ọgbọn ṣílè."
Ajafẹtọ Ọmọniyan, Femi Falana ti bu ẹnu atẹ lu isejọba Aarẹ Buhari lori eto aabo to mẹhẹ lorilẹede Naijiria.
Àkọ́bí talaka yóo rí oúnjẹ jẹ,aláìní yóo sì dùbúlẹ̀ láì léwu.
Nítorí èyí, ẹ fi aṣọ ọ̀fọ̀ bora,ẹ sọkún kí ẹ máa ké tẹ̀dùntẹ̀dùn,nítorí ìrúnú gbígbóná OLUWAkò tíì yipada kúrò lọ́dọ̀ wa.
Ìwọ tí o lẹ́wà jùlọ láàrin àwọn obinrin,bí o kò bá mọ ibẹ̀,ṣá máa tẹ̀lé ipa agbo ẹran.
Gẹgẹ bi ohun ti a ri ka loju opo Twitter niṣe ni Gbajugbaja olorin takasufe ni, Kcee leri si Dike Chidozie@mrchidozie pe oun yoo fun ni miliọnu naira kna ti Liverpool ba fi le na Barcelona.
Wọ́n wá kún fún oríṣìíríṣìí ìwà burúkú: ojúkòkòrò, ìkà, owú jíjẹ, ìpànìyàn, ìrúkèrúdò, ẹ̀tàn, inú burúkú.
Nítorí pé ní ọjọ́ tí ó bá kú,kò ní mú ohunkohun lọ́wọ́ lọ;dúkìá rẹ̀ kò sì ní bá a wọ ibojì.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Samuel Umtiti lo fi ori kan bọọlu wọ awọn Belgium eleyi to fun France lanfani ipele aṣekagba Ifẹsẹwọnsẹ ọhun jẹwọ ara rẹ gẹgẹ bii ifigagbaga laarin awọn ikọ akọni agbabọọlu meji ni ibamu pẹlu ireti awọn onwoye ati ololufẹ ere bọọlu jakejado agbaye.
Ni igbà àtijọ́, ẹranko ti wọn pè ni Ẹkùn jẹ alágbára ẹranko, bẹni Kìnìún si jẹ́ alágbára ẹranko.
Njẹ́ ó yẹ́ kí ọmọ ènìyàn máa gbé irú ìlú báyìí?
Lẹsẹkẹsẹ Jesu bá fà á lọ́wọ́, ó sọ fún un pé, “Ìwọ onigbagbọ kékeré yìí!
Kí wá ni ìdí rè tí a fi ń ko ilà?
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Iná Ibadan: Àwọn olùgbé inú ilé ń rawọ́ ẹ̀bẹ̀ fún ìrànwọ́ 18 Òkùdu 2019 Ijamba nla ṣẹ ni adugbo oke Ado nilu Ibadan lowurọ ọjọ isẹgun nigba ti ile alaja kan gbina.
Ko wọpọ rara lasiko tirẹ ki odidi ọba ilu nla bii ilu Ile Ifẹ, tun maa se akoso ẹkun rẹ, tii se ipo oselu.
Sugbọn o ni ti eyi ko ba ri bẹẹ, awọn ko ni bọwọ fun ofin yii, ijọba Eko gbọdọ wọgile ofin yii, kawọn lee wulo fun ara awọn ati orilẹede wa.
Ẹnikẹ́ni wà láàrin yín tí ó gbọ́n, tí ó tún mòye?
Ó ti wá hàn sí gbogbo àwọn tí ó wà ní ààfin ati gbogbo àwọn eniyan yòókù pé nítorí ti Kristi ni mo ṣe wà ninu ẹ̀wọ̀n.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Alaafin: Àwọn ọba Ekiti kò nílò alàgàta, bí wọ́n bá tilẹ̀ nílò rẹ̀, Ọọ̀ni nìkan ló láṣẹ bẹ́ẹ̀ 16 Ẹrẹ̀nà 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 17 Ẹrẹ̀nà 2020 Oríṣun àwòrán, @others Agba oṣere tiata, Peter Fatomilọla ni ikọja aye gbaa ni igbesẹ Alaafin lati yọju si ohun to n lọ laarin awọn lọbalọba ni ipinlẹ Ekiti.
Ilẹ̀ náà yóo so ọpọlọpọ èso, ẹ óo jẹ àjẹyó, ẹ óo sì máa gbé inú rẹ̀ láìséwu.
Àwọn ọmọ Nàìjíríà 320 yóò padà wálé láti South Africa lọ́jọ́rú - Adama Àgbáríjọpọ ẹgbẹ OPC, fijiláńté VGC, Agbẹkọyà ti bẹrẹ ètò aàbò ní ilẹ Yorùbá Ọlọ́pàá kò rí ǹkankan lábẹ́ pẹpẹ ilé ìjọsìn mi - Olùṣọ́àgùntàn Akure Oríṣun àwòrán, CLUB PORTAL Àkọlé àwòrán, Frankurt FC Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 3 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 5 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Bí Zakzaky yóò bá lọ gba ìtọ́jú ní India, ó gbọdọ̀ ṣe àwọn nǹkan wọ̀nyìí Gbígba onídùròó Zakzaky ṣàfihàn àṣeyọrí ìfaradà wa lásìkò ìfìyajẹni - Shiite Fulani kò leè dúró, táa bá lo ohun ta jogún lọ́dọ̀ àwọn bàbá wa - Sunday Igboho Ọjà Àgbáláta ní Badagry rèé, níbití ẹran ejò ti dùn ju ẹran adìẹ lọ Kọmisana feto iroyin ni Ekiti, nigba taa bi pe se ijọba ipinlẹ Ekiti yoo sugba ọmọ bibi ipinlẹ naa to jẹ ọlọpaa nilẹ Gẹẹsi, to seese ko padanu isẹ rẹ nilẹ Gẹẹsi, Olomilua ni Khafi ko fi igbesẹ rẹ naa to ijọba ipinlẹ Ekiti leti lasiko ti eto BB Naija fẹ bẹrẹ.
Lara awọn ohun manigbagbe naa, eleyii to waye lasiko ti wọn pade ni ipele to kangun si aṣekagba yii kan naa ni tọdun 1988 ni a mu wa fun un yin yii.
Èmi Paulu, tí Ọlọrun pè láti jẹ́ òjíṣẹ́ Kristi Jesu, ati Sositene arakunrin wa ni à ń kọ ìwé yìí–
Utin ti won yoo jo darapo mo iko Super Eagles nipago won fun igbaradi ifesewonse
Folukẹ Daramọla ko awọn agba ọjẹ ere tiata Yoruba lẹnujọ Oríṣun àwòrán, foluke daramola/instagram Ọpọ igba ni iroyin ailera, atọpọ ipenija to n koju awọn agba oṣere tiata maa n jade sita ti o si maa n ba awọn ololufẹ wọn ninu jẹ lọpọlọpọ.
Ìyá 73 rọ ọmọ ní oúnjẹ dèrò ẹ̀wọ̀n l'Ámẹ́ríkà Ramadan 2018: Wákàtí àwẹ̀ káàkiri àgbáyé Koko iroyin: Ọwọ tẹ awọn ọlọ́ṣà Ọfa, Ọmọ Naijiria ń ta ara wọn nilu òyìnbó Eyí túmọ si pé àwọn orilẹ̀-èdè míràn, bii Norway yóò maa gbààwẹ fún odidi ogun wákàti lójoojumọ ninu ọdun yìí.
Kí ẹni tí ó jẹ lówó gba gbogbo ohun ìní rẹ̀,kí ẹni ẹlẹ́ni sì kó èrè iṣẹ́ rẹ̀.
Nígbà náà ni Balaki sọ fún Balaamu pé, “Kí ni ò ń ṣe sí mi yìí?
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Olutoye: Ọmọ ọdọ̀ àgbà ni mí, kò sì y kí èdè Yorùbá parun Ko si owo kankan ti wọn maa n san fawọn ọmọ to n sisẹ sin wọnyi Kini Ohun ti ẹsin Islam sọ nipa imọtoto: Idaji ẹsin ni imọtoto jẹ Ki o to jẹun tabi ti o ba jẹun tan, o gbọdọ fọwọ rẹ Bi o ba se igbọnsẹ, o di dandan ko fọwọ Ọwọ fifọ, oju ati ẹsẹ gbodo waye ki eeyan to ki irun lẹẹmarun un lojumọ Iwẹ di ọranyan ki eeyan to ki irun akojọpọ Jimọ ni gbogbo ọjọ Eti Bi eeyan ba salaisi, wọn gbọdọ wẹ oku, awọn onimọ ẹsin kan ni ko se dandan ti ko ba si anfaani lati se bẹẹ Kini ero ijọba bayii?
 Àpápè oyè yìí ni ó di awùjalẹ ̀ dòní yìí .
Sugbọn awọn ọlọpa ilẹ wa ni n se lawọn agbebọn naa n yinbọn soke laibikitalasiko ti wọn gbẹmi awọn eeyan mejeeji ọhun.
” bi Omo-oba birin Gloria Akobundu se so.
Black yii nikan lo ba BBC sọrọ, bo tilẹ jẹ pe wọn dokita ati nọọsi miran ba BBC sọrọ, ṣugbọn wọn ni ki a ma fi orukọ wọn lede nitori ibẹru pe iṣẹ lee bọ lọwọ wọn.
Nibi itẹ gangan, eeyan perete pẹlu iyawo oloogbe, Oloye Florence Ajimobi atawọn ẹbi gangan lo wa nibẹ.
Awọn ọlọpa lagbegbe naa ni awọn ara ilu ti ṣeku pa Laban.
buruku bayii si awọn ọmọ orilẹ-ede Naijiria pẹlu ipa ti a sa lati gbeja
Eleruwa: Ilé ẹjọ lé Ọba Èrúwà kúrò lórí Àpèrè lẹ́yìn ọdun 21
Ìtàn tí ó gbà pé odùduwà ni ó bí àwọn ọmọ méje tó tẹ ilẹ ̀ yorùbá dó sọ pé olówu ni àkọ ́ bí odùduwà .
Wò ó, bákan náà ni èmi pẹlu rẹ rí lójú Ọlọrun,amọ̀ ni a fi mọ èmi náà.
Ó ti ṣe ohun tí ó lè ṣe: ó fi òróró kun ara mi ní ìpalẹ̀mọ́ ìsìnkú mi.
NECO: Ààrẹ Buhari ti fi ọwọ́ òsì júwe ilé fún Ọ̀gá Àjọ NECO àti àwọn mẹ́rin míràn lórí ẹ̀sùn ṣíṣe owó báṣubàṣu
Minisita soro  yii lasiko idanilẹkọọ lori ‘ibasepo
O ni ewu kiko coronavirus wa ninu bi ọpọ eeyan ṣe n to si ibudo iforukọsilẹ kaadi kaakiri Naijiria.
- Lopopona Maroṣẹ yatọ si ibi ti wọn ti ay sọtọ lẹgbẹ ẹ titi.
N óo dójú lé olúwarẹ̀, n óo fi ṣe ẹni àríkọ́gbọ́n ati àmúpòwe.
Oríṣun àwòrán, @dinomelaye Ni apakan, Melaye kọrin ni ede Yorùbá pe: Kilo tun ku ti o sọ?
Aawọ laarin Abba Kyari ati aya aarẹ, Aisha Buhari Iyawo aarẹ Buhari, Aisha Buhari ni a lee sọ pe o jẹ eeyan akọkọ lara awọn to sun mọ aarẹ Buhari to kọkọ pariwo sita pe lootọ ni awọn igbimọ alagbara yii wa.
O si bẹrẹ si ni lọ si ijọ Living Faith Chapel, ti a tun mọ si Winners Chapel.
Akọnimọọgba ẹgbẹ agbabọọlu Portugal Fernando Santos ko tilẹ fi orukọ Ronaldo s'ara awọn agbabọọlu ti yoo soju orilẹede naa ninu ifẹsẹwọnsẹ wọn to n bọ pẹlu Scotland ati Poland nitori ẹsun kan naa.
“O salaye pe, “ nigba isoro, o satileyin fun orile-ede re lati ri daju pe, alaafia joba lorile-ede naa ati ojo iwaju eto ijoba tiwa-n-tiwa, ni eyi ti o ti lana alaafia sile fun eniti o n bo leyin”.
Oríṣun àwòrán, @BarackObama Nigba to n sọrọ nibi ayẹyẹ ikẹkọjade naa gẹgẹ bii alejo pataki, aarẹ tẹlẹ ni orilẹede Amẹrika, Barrack Obama, ti oun naa jẹ adulawọ, lo sọrọ nipa ẹlẹyamẹya, to si rọ awọn akẹkọjade ileẹkọ naa lati maa fi awọ wọn yangan, ki wọn si nifẹ bi Ọlọrun se da wọn.
Olùdarí ifẹsẹwọnsẹ orí pápá bákan náà to je ọmọ orílèèdè Turkey ti ri ìbínú awọn ololufẹ Super Eagles.
Ọkan lara awọn ti iṣẹlẹ naa ṣoju rẹ sọ pe, ni ṣe ni awọn adigunjale ọhun ṣọ arakunrin naa lati lori alupupu, ki wọn to ṣakọlu si i.
Bakan naa ni Pasitọ Sam Adeyemi rọ Aarẹ Buhari lati gbọ ohun ti awọn araalu sọ, ki o wọ ibi ti bata ti n ta wọn lẹsẹ, ki o si ṣe atunṣe.
Awon ti won jo n lo fun irinajo naa ni: Minista fun eto aabo Naijiria, Ogagun feyinti agba Mansur Dan-Ali, minista fun oro ile okeere, Ogbeni Geoffery Onyeama ati Oloye Lai Moghammed to je minista fun ifitonileti gbogbo.
Laipẹ yii ni Igbakeji gomina ipinlẹ Kogi, Simon Achuba pariwo fun aye gbọ lasiko to ba awọn oniroyin sọrọ pe aarin oun ati ọga oun ko gun eyi to jẹ koko ninu gbun-gbun-gbun to ti n waye laarin awọn mejeeji lati igba diẹ sẹyin.
Deji Adenuga tó jó èèyàn mẹ́sàn-án mọ́lé bọ́ sọ́wọ́ Ọlọ́pàá Tani Deji Adenuga to dáná sun ènìyàn mẹ́jọ?
Nítorí náà, OLUWA kò láyọ̀ lórí àwọn ọdọmọkunrin wọn,àánú àwọn aláìníbaba ati àwọn opó wọn kò sì ṣe énítorí pé aṣebi ni gbogbo wọn, wọn kò sì mọ Ọlọrun,ọ̀rọ̀ burúkú ni wọ́n sì ń fi ẹnu wọn sọ.
Wọ́n ń bá àwọn Asiria dá majẹmu, wọ́n sì ń ru òróró lọ sí ilẹ̀ Ijipti.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Nigeria vs Seychelles: Ikọ Super Eagles bori Seychelles pẹ̀lú 3-1 nínú ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ AFCON 22 Ẹrẹ̀nà 2019 Oríṣun àwòrán, @thenff Àkọlé àwòrán, Orilẹ̀ede Nigeria ati Seychelles yoo waako ni agogo mẹrin ọjọ ẹti Orilẹede Naijiria jawe olubori ninu ifẹsẹwọnsẹ wọn Seycheles loni ọjọ Ẹti ninu idije ife ẹyẹ AFCON ti ọdun 2019.
Abbo, to ni ọmọ kii mọ ẹkọ jẹ ko ma ra lọwọ, tun tọrọ aforijin lọwọ ijọ Ọlọrun lagbaye lori iwa aidaa ti oun hu yii, nitori o ni gẹgẹ bii asoju Kristi, iru iwa yii ko tọ si oun.
Ninu oṣu kejila dun to kọja olorin Chris Martin yan an lati jọ kọrin pọ pẹlu gbajugbaja olorin Beyonce, Ed Sheeran ati Jay Z ni ilu Johannesburgh, South Africa niwaju ero to to miliọnu lọna aadọrin nigba ti wọn ṣe ayẹyẹ iranti ọjọ ibi oloogbe Nelson Mandella Champions league: A jurawa lọ, Liverpool kó àjọ ìyà lọ́wọ́ọ Barcelona Ọlọ́pàá tó n gba rìbá sọ pé 'Ọlọ́run gan fara mọ́ olè jíjà' Ṣé N30,000 le mú ìyàtọ̀ gorí N18,000 owó oṣù òṣìṣẹ́?
Ọjọgbọn Gambari ṣalaye eyi lasiko to fi n ba awọn akọroyin sọrọ lẹyin ti wọn kede rẹ lọjsbọ ni ileeṣẹ aarẹ, nilu Abuja.
Too, a mu ẹnu ro nigba naa, gbogbo aye si ba ko lee daa bọ.
wọn jẹun tan wọn si fẹ ti ìl\\lkun mọ àwọn tó kú.
Obinrin naa to jẹ ẹni bii ọgbọn ọdun jẹwọ fun ọlọpaa pe, aarẹ ọpọlọ ṣe oun nigba ti oun pa ọkunrin naa ni.
Ìpín ti OLUWA ninu rẹ̀ jẹ́ ẹẹdẹgbẹrin ó dín mẹẹdọgbọn (675).
To ba jẹ pe mo feti si ti wọn ni, mi o ba ti maa ro pe otitọ ni nkan ti wọn n sọ.
gegi dina awọn iwa ọdaran lawujọ.
”Rutu bá sọ gbogbo ohun tí ọkunrin náà ṣe fún un.
Ìròyìn ti sọ ṣááju pe ni ìjọba ipinlẹ Bauchi, o dín díẹ̀ ni eniyan ẹgbẹ̀run méjìlélógójì tó wà lóri iwé owó osù ìjọba lai ni BVN.
Orile-ede naa ti eto oro aje won da lori eto ogbin ati irin-ajo afe gberu  ni aleku iko merin le mejo 5.
Èmi OLUWA Ọlọrun yín ni mo sọ bẹ́ẹ̀.
Lọpọ igba lo ti ba ijọba lẹlẹkajẹka wọ ṣokoto kanna lori orisirisi ọrọ to ni ṣe pẹlu iṣejọba.
O woye pe eleyi lo n ṣe okunfa ki awọn ara ita maa fipa ba awọn ọmọ kekeeke tage tabi ni ibalopọ pẹlu ipá.
O fi kun un pe wọn ti paṣẹ fun gbogbo awọn ọlọpaa ẹkun naa lati lọ ya ara wọn sọts ni ile titi di igba ti esi ayẹwo wọn yoo fi jade.
Lọdun 2018 ni iṣẹlẹ idigunjale kan waye nilu Ọffa, ni ipinlẹ Kwara.
Ọjọ kọkanlelogun, ọdun 1994 ni awọn iku ajijagbara fun idagbasoke ilẹ Ogoni, MOSOP pa oloye mẹrin to wa lẹyin ijọba.
Iwaju ile wọn si ni ile ijọsin naa wa.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Sotitobire àti àwọn wòlíì ọmọ Nàìjíríà míràn tó ti lọ sẹ́wọ̀n nítorí ẹ̀sùn ìwà ọ̀daràn 7 Ọ̀wàrà 2020 Kìí ṣe ìròyìn tuntun mọ́ pé, wọ́n ti dájọ ẹ̀wọ̀n gbéré fún Alfa Babatunde ti ìjọ Sotitobire ni ìlú Akure tíí ṣe olúùlú ìpínlẹ̀ Ondo lórí ẹsùn ìjímọgbé.
Awọn ni Van Persie dantọ ju Ole lọ nigba to fi ṣoju ẹgbẹ agbabọọlu Man bo tilẹ jẹ pe akoko to lo ko to ti Ole.
Àwọn kan ti wí fún mi tẹ́lẹ̀ náà pé àràmàndà ni ilé ọ̀hún jẹ́.
Awọn ti yoo ba di ọlọpaa SWAT yoo lọ fun ayẹwo ilera ọpọlọ ati ilera ara wọn, lati le mọ bi wọn ṣe pojuowo si fun isẹ tuntun naa.
Oríṣun àwòrán, Screenshot Ki ni Sunday Igboho sọ lori gbedeke ọlọjọ meje naa?
Alami naa ṣalaye fun wa pe mẹta ninu awọn ọmọlẹyin Ebila ji eeyan kan gbe ni ikọ operation Burst ba ko sẹnu i'sẹ lọgan nitori awa pẹlu ti mọ pe awọn ọmọ ẹgbẹ okunkun One million boys ti sọ ara wọn ikan ti n jẹle lagbegbe naa.
Níbẹ̀ ni ó ti ṣẹ́ ọfà ọ̀tá tí ń rọ̀jò,ati apata, ati idà, ati àwọn ohun ìjà ogun.
Lọwọ lọwọ ni Naijiria iṣoro nla ni ṣise ayẹwo arun Covid-19 jẹ.
N óo sì máa kọ yín ní ohun tí ó dára láti máa ṣe ati ọ̀nà tí ó tọ́ fun yín láti máa rìn.
Kí o lè mọ ohun tí yóo ṣẹlẹ̀ sí àwọn eniyan rẹ lẹ́yìn ọ̀la ni mo ṣe wá, nítorí ìran ohun tí yóo ṣẹlẹ̀ ní ọjọ́ iwájú ni ìran tí o rí.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Covid-19 60seconds: Ṣé ìjìnà síra-ẹni ṣe paàtàkì lẹ́yìn lílo ìbòmú?
Ileẹjọ giga to kalẹ si Jabi nilu Abuja ti pasẹ pe ki awọn ọlọpa lorilẹede Naijiria ati ajọ ọtẹlẹmuyẹ lagbaye lọ gbe awọn afurasi ti wọn fi ẹsun kan lori ẹsun ajẹbanu to nii se pẹlu ọrọ epo Malabu ti wọn ta nijooni.
Ṣugbọn títí di òní yìí, OLUWA kò tíì jẹ́ kí òye ye yín, ojú yín kò ríran, bẹ́ẹ̀ ni etí yín kò gbọ́ràn.
2 Nítorí kíyèsíi, èmi sọ̀rọ̀ sí ọ pẹ̀lú ohùn mímú àti pẹ̀lú agbára, nítorí apá mi wà lórí gbogbo ilẹ̀ ayé.
Boko Haram: Awọn ọmọogun ò sọnu, enikan péré ló farapa Ilé iṣẹ́ ọmọogun orílẹ̀ tí kédé pé ìròyìn tó gbòde kan pé àwọn ọmọogun orílẹ̀-èdè Nàìjíríà pòórá ní ìjọba ìbìlẹ̀ Bama ní ìpínlẹ̀ Borno.
 A nilo lat ṣe awọn eto ironilagbara yii fun wọn lati mu inu wọn dun.
" O ni ko si ohun to buru nibẹ ti awọn eeyan ba gbọ gomina ni agbọye nitori idagabsoke ede ati aṣa ṣe pataki lasiko yii.
Nigba to maa fi de Cinema Complex lo ko oni tiẹ nigba ti ọlọpaa miran gbebọn fun un.
Ilé ẹjọ́ dájọ́ ikú fún èèyàn mẹ́ta nítorí ikú akẹ́kọ̀ọ́ fásitì UNIOSUN Ìṣẹ̀lẹ̀ Bakana: àwọn tórí kó yọ fẹ́ bẹ̀rẹ̀ ètò ìrànlọ́wọ́ ‘Buhari kò bú àwọn ọdọ’ Buhari ṣ'eleri iṣẹ f'awọn ọdọ Diẹ lara awọn agbabọọlu ti wọn ti ko sọwọ ti wọn ba BBC sọrọ ni Micheal Ọbumneme, Emmanuel Clement, Idowu Oluwole Julius atawọn mii.
Delta Building Colapse: Ilé wó lu ọ̀gọ̀ọ̀rọ̀ èèyàn ní Abraka
Èso olódodo ni igi ìyè,ṣugbọn ìwà aibikita fún òfin a máa paniyan.
Ó ní, “Ẹ ká lọ, ẹ óo sì rí i.
 Ọwọ́ ọlọ́pàá tẹ afurasí ajínigbé 93, àti ìbọn 'AK47' márùndínlógójì Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, N1 mílíọ́nù leè mú kí, orílẹ̀èdè Nàìjíríà, Pẹ̀lúmi Akínṣọlá ó pàdánú àmì ẹ̀yẹ Olympiad Ni ọjọ kẹwa oṣu karun ọdun 2019 ni Bukọla Adewale tun pe mi pe ki n pade oun nilu Oṣogbo ti mo si jẹ ẹ ni hoo."
Ẹ̀wẹ́, Abike Dabiri ti tún kọ sórí àtẹjíṣẹ́ twitter rẹ̀ pé, kìí ṣe òun ni òun kọ àkọlé pé àwọn ọmọ náà ti gba ìtúsílẹ̀ àti pé, ó ṣeeṣe kó jẹ́ àwọn ènìyàn tó ló àtẹ̀jísẹ́ òfégè ni orúkọ òun ló kọ̀ọ́.
O ni lati ayebaye lawọn Yoruba ti maa n le laali sara fun oge ṣiṣe, ''laye ode oni ni wọn kan n pe ni ''tattoo.
OLUWA àwọn ọmọ ogun yóo dáàbò bo àwọn eniyan rẹ̀.
Ile-ise iroyin ohun so pe, Abol Fotouh pelu oruko awon marundogun miiran ni won fi kun awon adunkoko-moni naa, leyin iwadii ile-ise eleto abo pe, won darapo mo egbe ti ijoba fofin de, pelu erongba ati maa da laasigbo sile lorile-ede naa.
Trump ló wọlé, gẹ́gẹ́ bi wọn ti nṣe é, àwọn Olóri ilú àgbáyé ló kọ iwé tàbi pè lati ki ku ori ire.
Ṣugbọn ní tèmi ati ilé mi, OLUWA ni àwa óo máa sìn.
A n satielyin yii lai jere kobo kan biko se ona lati da pada si awujo kookan lati fihan pe MTN ri ara re gege bi okan lara awon agbegbe naa ni.
Nítorí pe Dafidi ní, “Tẹmpili tí a óo kọ́ fún OLUWA gbọdọ̀ dára tóbẹ́ẹ̀ tí òkìkí rẹ̀ yóo kàn ká gbogbo ayé; bẹ́ẹ̀ sì ni Solomoni, ọmọ mi, tí yóo kọ́ ilé náà kéré, kò sì tíì ní ìrírí pupọ.
Ninu alaye rẹ, Arinze Orogwe ni lootọ ni ijọba sefilọlẹ iwe iforukọsilẹ orukọ awọn eeyan to jẹbi ẹsun ifibanilopọ, amọ o wa n beere pe se yoo rọrun lati ri ọpọ orukọ awọn eeyan to jẹbi ẹsun naa tile ẹjọ ti se idajọ wọn.
Ẹẹmẹta ni ó ṣẹlẹ̀ bẹ́ẹ̀, ni nǹkankan bá tún fa gbogbo wọn pada sí ọ̀run.
Gege bi ogbeni Buba; “Ile-ise Voice of Nigeria je ile-ise akoroyin ti o n jabo iroyin nipa orile-ede Naijria fun awon eniyan lagbaye.
Ìwọ́ ọ̀rẹ́ mi, bí o bá ń bẹ̀rù ọ̀tá;
Wọ́n kọ́ pẹpẹ Tofeti ní àfonífojì Hinomu, wọ́n ń sun àwọn ọmọkunrin ati àwọn ọmọbinrin wọn níná níbẹ̀.
orile ede Naijiria yoo tun nifẹẹ si idagbasoke ni awon ile-ise yooku.
Nenadi Usman nàá darapọ̀ mọ́ wọn Mínísítà fún ètò ìnáwó nígbàkan rí, Abílékọ Nenadi Usman, tí wọ́n jọ fi ẹ̀sùn kan òun àti Fẹmi Fani-Kayọde, lọ̀jọ́ karùn ún, oṣù Kejìlá, 2017 nàá bẹ ilé ẹjọ́ gíga tìjọba àpapọ̀ tó wà ní ìlú Èkó láti fún un láàyè kó lọ sí ilẹ̀ Amẹrika fún ètò ìlera rẹ̀.
Sotitobire: Ìgbẹ́jọ́ kò le è wáyé mọ́ l‘Ọ́jọ́rùú, wọ́n ṣun síwájú di Ọjọ́bọ̀
Ọpọlọpọ awọn ọmọ orilẹede Naijiria ni wọn fi ojusọna fun ohun ti aarẹ yoo sọ ninu ọrọ rẹ, ti o si ṣe okunfa bi ọpọ ọmọ Naijiria nile ati loko ṣe sun ti awọn ohun elo gbogbo ti wọn lee fi ṣe alabapade aarẹ lori ohun to fẹ ka.
Lẹyin iṣẹju marun un pere ti wọn bẹrẹ ere bọọlu ọhun ni agbabọọlu Man City Kevin DE Bruyne gbayo wọle Cardiff ti City si bẹrẹ si leke.
Awọn ami ẹyẹ bi i Honoris Causa of Music at Saint John University Bakerfield California USA in 1989.
Ogunlọ́gọ̀ àwọn aláìbìkítà ẹ̀dá bẹ̀rẹ̀ sí pariwo lọ́dọ̀ yín, àwọn ọkunrin ọ̀mùtí lásánlàsàn kan sì wá láti inú aṣálẹ̀, wọ́n kó ẹ̀gbà sí àwọn obinrin lọ́wọ́, wọ́n fi adé tí ó lẹ́wà dé wọn lórí.
Ṣugbọn dokita sọ pe ayipada le wa ti iru obinrin bẹ ẹ ba n ṣe ere idaraya Kegel.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Idije AFCON ọdun 2010 Lẹyin ti wọn da Keshi duro gẹgẹ bi akọnimọọgba ikọ agbabọọlu Mali lo di akọnimọọgba fun ikọ Super Eagles ti orilẹede Naijiria.
pẹlu òbúkọ kan fún ẹbọ ìmúkúrò ẹ̀ṣẹ̀.
Ṣùgbọ́n kí ènìyàn tó dé ibib dídára yìí, Olúwarẹ̀ yóò kọjá ọ̀nà burúku kan, mo sì rí àwọn ẹranko búburú gbogbo tí wọ́n dúró sí etí ọ̀nà búburú náà, tí wọ́n ń sọ́ ọ.
Ní ọdún kẹrin ìjọba Jehoiakimu ọmọ Josaya ọba Juda, OLUWA sọ fún Jeremaya pé, 
Joramu ọba bá gbéra ní Samaria, ó sì kó gbogbo àwọn ọmọ ogun rẹ̀ jọ.
Bàbà ọmọ ọdún 75 kó HIV ran ọmọ ọdún 14 lẹ́yìn tó fi ipá báa lò Gbogbo ọjà di títì pa nílùú Akure, ṣugbọ́n nítorí kí ni?
com Ilé ẹjọ́ giga kan ni Ipinlẹ Ondo ti da ẹjọ iku fun ọmọkunrin kan, Chukwudi Onweniwe, ti wọn fẹsun kan pe o pa ololufẹ rẹ, Nifemi Adeyeoye.
Apero naa waye lọjọ Iṣẹgun ninu gbọngan nla Theophilus Ogunlesi, to n bẹ ladojukọ ile iwosan ẹkọṣẹ iṣegun oyinbo, UCH nilẹ Ibadan.
Nígbà tí Hẹrọdu ń ṣe ọjọ́ ìbí rẹ̀, ọdọmọbinrin Hẹrọdiasi bẹ̀rẹ̀ sí jó lójú agbo.
ó sọ ilẹ̀ eléso di aṣálẹ̀ oníyọ̀,nítorí ìwà burúkú àwọn tí ń gbé inú rẹ̀.
Maidawa ní bi wọ́n ṣe fi ẹsùn kan, ilé iṣẹ́ ọmọ ogun yóò ṣe ìwádìí tó péye láti fi ìdí òdodo múlẹ̀ tí ìdájọ òdodo yóò si tẹ̀lé ìwádìí náà.
6 % ojude aye ( 36.
Eyín akọ̀ròyìn fò yọ lásìkò tó n ka ìròyìn lọ́wọ́ lórí tẹlifísàn Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Black women live matters: Ọdún 2015 ní àwọn ọlọ́pàá pa India Kager láìní ìdí- Gina Best Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Aṣekagba Champions League to waye ni ọdun 2008 ni igba akọkọ ti ikọ Ilẹ Gẹẹsi meji yoo figa gbaga ninu aṣekagba idije Champions League.
'Ọpọ owo ori lo wa f'awọn eeyan lati san l'Eko ‘Ẹ maa kọrin orilẹede wa l’ede Yoruba’ Nibayii, ijọba ipinlẹ Eko yoo din ida ọgọrun kuro lara owo ori ilẹ to yẹ ki awọn to nfi ilẹ wọn se okoowo san, eleyi to tunmọ si wipe, ẹni to yẹ ko san ẹgbẹrun mọkanlelaadọrun ati igba naira (N91,200) tẹlẹ, yoo wa san ẹgbẹrun marundinlaadọta ati ẹgbẹta naira (N45,600) lọdun bayi.
Yatọ si eyi, iye ibo ti awọn ọdọ di lori BBNaija ati iye owo ti irufẹ awọn ibo yii pa wọle si apo awọn eeyan to se agbatẹru eto naa gan, tun n kọ awọn ọmọ́ Naijiria kan lominu.
Fún àtúnṣe, ó ṣe pàtàki ki gbogbo ará ilú parapọ̀ lati tún ohun ti ó ti bàjẹ́ ṣe nipa gbi gbé ogun ti iwà ìbàjẹ́ àti àbẹ̀tẹ́lẹ̀ gbi gbà.
Agbẹnusọ ẹgbẹ́ PDP ni ìpínlẹ̀ Eko Taofik Gani sọ nínú àtẹjáde kan to fisíta pé Fayose sọ ọ̀rọ̀ àbùkù lásìkò ti Fayose ni òun n gba àwọn ọdọ ẹgbẹ́ níyànjú tó le mú kí àwọn ọdọ ẹgbẹ́ kọjú ìjà sí àwọn àgbà ẹgbẹ́ ní ìpínlẹ̀ Eko.
lo  ni igbagbo ninu wa, ni eyi ti a ko si
Mo bá súnmọ́ ọ̀kan ninu àwọn tí wọ́n dúró níbẹ̀, mo bèèrè ìtumọ̀ ohun tí mo rí, ó sì sọ ìtumọ̀ rẹ̀ fún mi, ó ní, 
Wọn sọrọ lori pataki nini ifẹ awọn ara ilu ti kaluku n dari.
2019 Guber election: Mi ò fara mọ èsi ìdìbò Ọyọ́ ‘Kò tọ́sí Adeleke láti díje dupò gomina Ọṣun’ Ààrẹ Abdulaziz Bouteflika ti kowe fipo silẹ Magu,'estimated billing' àti àwọn ohun míràn tí ilé aṣòfin Nàìjíríà kò rí yanjú Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
"Adajọ Maureen Onyetenu, tún kéde pé bí ijọba àpapọ̀, láti ipasẹ àwọn Ọlọpaa ṣe da ìwọde náà ru ""kò bófin mú, ìwà ìjẹgàba ni, kò bá ìlànà ìjọba alagbada mú, tó sì tún tako àmúlò òfin ilẹ wa""."
Àjọ NJC fún Onnoghen àti Mohammed ní gbèdéke ọjọ́ méje Aṣòfin ọmọ Naijiria ní Ilẹ̀ Gẹ̀ẹ́sì rẹ́wọ̀n oṣù mẹ́ta he Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Day 17: Àwọn olórí tó wà ní Kwara ń ṣe fún ara wọn nìkan ni #BBCNigeria2019 Ẹwẹ awọn onimọ nipa oju ọjọ ni ipinlẹ Iowa ti kilọ fun awọn ara ilu naa pe ki wọn ṣọra fun mimi kanlẹ ki wọn si din ọrọ sisọ ku bi wọn ba wa ni ita.
Wọ́n bẹ̀rẹ̀ sí sọ láàrin ara wọn pé, “Irú ọ̀rọ̀ wo ni èyí?
Irufẹ Magun yii lo saba n fara han lori ayelujara lode oni.
Ọgbẹni Alimi tun gbadura loju opo Instagram pe, oun ati ọkọ oun yoo ṣe ọpọlọpọ ọdun laye.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Díẹ̀ lára àwon oúnjẹ ìbílẹ̀ wa tó tin ń di àwátì báyìí 16 Ọ̀wàrà 2019 Ọpọlọpọ awọn ounjẹ abalaye orilẹede wa lo ti n di awati bayii, paapaa ju lọ nilẹ Yoruba .
Wọ́n bá ń ṣe àríyá lórí ohun tí wọ́n fi ọwọ́ wọn ṣe.
Awọn kan tiẹ gbagbọ pe ti ijọba ba tun ṣe ofin konile o gbele, ọrọ aje yoo dẹnukọlẹ.
ní ìbẹ ̀ rẹ ̀ , ní ipele èkíní nínú àrùn náà , ibà , orí-fífọ ́ , ara-yíyún , àti ìrora oríìké-ara a má a wáyé .
 O ro awon osise ijoba lati tubo sise bi o ti ye ki awon ase okowo naa le so eso rere ti a n reti lorile-ede yii.
Sọ fún mi, ìwọ ẹni tí ọkàn mi fẹ́:níbo ni ò ó máa ń da àwọn ẹran rẹ lọ jẹko?
Nígbà tí Dafidi gbọ́, òun náà múra láti lọ gbógun tì wọ́n.
Ikọlu Daradaran: Ibẹru mu awọn eniyan n'ipinlẹ Ogun
Ni se ni Jose n tọ soke sodo, ti inu re si n dun de di.
ti Temitope yoo bere oselu re, o koo je Kansilọ ni ijọba ibilẹ Ọdẹda, o tun je amugbalẹgbẹ
Di etí rẹ sí àwọn ọ̀rọ̀ játijàti tí kò ṣeni ní anfaani ati àwọn ọ̀rọ̀ tí àwọn kan ń ṣì pè ní ọ̀rọ̀ ọgbọ́n.
winston leonard spencer-churchill , kg , om , ch , td , pc , frs ( 30 november 1874 - 24 january 1965 ) je oloselu ara britani ti o gbajumo fun isolori re fun orílẹ ̀ -èdè isodokan ile-oba ni asiko ogun agbaye keji .
Ojú òpó Twitter ilé iṣẹ ìjọba Naijirià ní wọn fí ìkéde náà sì lọ́jọ́rú ọ̀sẹ̀.
Thai Deer: Pátá awọtẹlẹ, rọba àti ìdọ̀tí kilo méje ṣekú pa Ìgalà
ijoba apapo lati lee ri i  pe wọn se
Laipẹ yii si ni ile asofin naa gbindanwo lati yọ igbakeji gomina, ti omi alaafia ibẹ ko si toro nitori awọn asofin mẹsan to tako igbesẹ naa.
9 15548135 Orilẹ́ede Brazil 179765 85.
Daurama fẹ ẹ fun iwa akikanju rẹ.
Ọdun 2011 ni gomina tẹlẹri naa jade laye ni ẹni ọdun mẹtadinlọgọrin.
Lara awọn to ba aarẹ orilẹede Naijiria peju si ibi ayẹyẹ naa ni ikọ agbabọọlu Naijiria to se ipo keji nibi idije ife ẹyẹ bọọlu fun awọn agbabọọlu to n gbabọọlu jẹun nilẹ Afirika pẹlu ikọ akọkọ lati ilẹ Afirika ti yoo kopa nibi idije olimpiiki orii yinyin to pari lorilẹede South Korea laipẹ yii.
“Ẹnikẹ́ni tí ó bá jẹ́ alufaa àgbà láàrin àwọn arakunrin rẹ̀, tí wọ́n ti ta òróró sí lórí láti yà á sọ́tọ̀, kí ó lè máa wọ àwọn aṣọ mímọ́, kò gbọdọ̀ jẹ́ kí irun orí rẹ̀ rí játijàti; kò sì gbọdọ̀ fa aṣọ rẹ̀ ya, láti fi hàn pé ó ń ṣọ̀fọ̀.
Kò tún sí ọ̀rọ̀ pé ẹnìkan ni Juu, ẹnìkan ni Giriki mọ́, tabi pé ẹnìkan jẹ́ ẹrú tabi òmìnira, ọkunrin tabi obinrin.
" Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Africa Eye: Ọwọ́ tẹ ayédèrú dókítà Abdallah tó ń tà oògùn Coronavirus Awọn ọlọpaa sọ pe awọn ti gbe ọmọbìnrin naa lọ si ileewosan Mirabel, fún ayẹwo.
Lodun 2013, Odugbemi ko ere nipa oloogbe DO Fagunwa ti o se si fiimu to de tun dari e lati fi saponle onkowe Yoruba to dagba oje ninu idagbasoke iwe itan Yoruba to ko iwe bii: ‘ÒgbójúỌdẹnínúIgbóIrúnmalẹ̀’.
Olódùmarè mọ ohun tí òun ń ṣe: kò jẹ́ sọ wúrà Rẹ̀ sí iwájú ajá, bẹ́ẹ̀ ni kò jẹ́ gbé òkúta olówó iyebíye rẹ̀ síwájú ẹlẹ́dẹ̀, ẹni tí ó bá mọ àǹfààní lò ni Ọlọ́run Ọba ń fi àǹfààní fún.
Ṣùgbọ́n ẹ̀yìn ni wọ́n ń yín àgbàdo sí lọ́dọ̀ Dáúdà.
Fadeyi ni òun kò le fìdí ọ̀rọ̀ náà múlẹ̀ afi ti ìwádìí ba pari ṣùgbọ́n ni òótọ́ ni àwọn bá ìgbẹ́ lọ́wọ́ rẹ̀ ti àwọn si ti kó wọ́n lọ fun àwọn àyẹwò to yẹ́.
Oríṣun àwòrán, Lagos State Government Sugbọn ẹni kan to pe ara rẹ ni aburo oloogbe naa, Daniel Obi-Enadhuze, ti wa kede loju opo Twitter pe awọn janduku lo wọle wa pa ẹgbọn oun, kii se asita ibọn rara.
Awọn ẹgbẹ agbabọọlu to wa ni isọri kẹfa Guinea Bissau, Benin, Ghana, ati Cameroon Ẹwẹ, akọnimọọgba Super Eagles Gernot Rohr sọ pe oun fẹ lati gba ife ẹyẹ AFCON lọtẹ yii lẹyin to ti gbe Niger ati Gabon lọ si idije naa ri.
Owo Ijiya yi pẹlu pe yoo sisẹ sin ilu ni adajọ Julius Ajibare ni ko maa jẹ ijiya ati ẹkọ fun Ikechukwu Vincent to tapa si ofin to pọn ni dandan ki awọn eeyan wọ ibomu ti wọn ba jade sita nipinlẹ Ekiti.
Eyi lee mu ki aisan naa ti rin jina ni titankale mọ awọn mii ti wọn ko le tọpasẹ rẹ tabi ko ti kọja afẹnusọ lara wọn.
Nígbà tí Jesu rí ọ̀pọ̀ eniyan tí wọ́n yí i ká, ó pàṣẹ fún àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ pé kí wọn kọjá sí òdìkejì òkun.
 O fidunnu re si ipinnu ijoba apapo yii nitori pe nkan ko rorun fun gbogbo awon toro kan.
Wọ́n tún mú òbúkọ mejila wá fún ẹbọ ìmúkúrò ẹ̀ṣẹ̀.
 o di alakoso ijoba apapo fun eto irinna ni july 26 , 2007 .
Àwọn ọmọ ogun Dafidi bá pada lẹ́yìn àwọn ọmọ ogun Israẹli.
Ọgbẹni Isreal Ajayi ẹni to gboriyin fun atunṣe si ofin yii sọ pe awọn eto
Ni bayii, iko agbaboolu obinrin naa yoo maa kopa ninu idije ohun, leyin ti opo beere fun.
”Wọ́n dá a lóhùn pé, “Mejila.
a máa fi àṣìṣe wọn hàn wọ́n,ati ẹ̀ṣẹ̀ ìgbéraga wọn.
Awọn idunkooko ọmọbinrin naa lo mu ki BBC Yoruba kan si Cute Abiola, ti ọpọ eeyan tun mọ si Lawyer Kunle lati gbọ tẹnu rẹ, ka si wadi ododo daju nipa awọn ẹsun ti ọmọge yii fi kan.
Ọ̀gọ̀rọ̀ l’ó ń d'orí kọ ẹ̀rọ-alátagbà lọ láti gba ẹ̀jẹ̀ fún àwọn aláìsàn.
Nínú iyààrá kan lọ́tọ̀ ni àwọn èèrà wà, níbẹ̀ ni wọ́n ti ń jẹun, ìgbà tí mo lọ kí àwọn èèrà, mo gbádùn wọn, wọ́n sọ̀rọ̀ dáadáa ohùn wọn rọra ń dún bí fèrè olòhùn goor, wọn kò bu ni jẹ mọ́, èyí tí o ni oró ti fi oró pamọ́ sílé, ìgbà tí àwọn ejò sì wá síbẹ̀ wá kí wọn, wọ́n jọ gbádùn ara wọn lọ́pọ̀lọpọ̀ nítorí ìgbà tí mo rí ejò òjòlá kan lẹ́yìn èyí, ó ròyìn bí àwọn àti èèrà ti gbádùn tó, bẹ́ẹ̀ ni àkókò yìí, ọ̀pọ̀lọ́ àti ejò jọ ń fi ọwọ́ kọ́ ọwọ́ rìn kiri ni, A!
Tí ènìyàn ba wá sín lẹ́ẹ̀kan ṣoṣo kòkòrò ẹgbẹ̀rún lọ́nà ọgbọ̀n ni yóò jáde tó sì kéré jọjọ, èyí leè rìn kìlómítà tó lé ní ọ̀ọ́dúrún láàrin wákàtí kan, bí Bromage ṣe sọ.
Nítorí náà ni ó ṣe wí pé òun yóo pa wọ́n run,bí kì í bá ṣe ti Mose, àyànfẹ́ rẹ̀,tí ó dúró níwájú rẹ̀, tí ó sì ṣìpẹ̀,láti yí ibinu OLUWA pada, kí ó má baà pa wọ́n run.
Wọ́n fi ojúlówó wúrà ṣe ẹ̀wọ̀n tí a lọ́pọ̀ gẹ́gẹ́ bí okùn fún ìgbàyà náà.
Lẹ́yìn tí ó bí Mahalaleli, ó gbé ẹgbẹrin ọdún ó lé ogoji (840) láyé, ó sì bí àwọn ọmọ mìíràn lọkunrin ati lobinrin.
O ni ko si si ohun to jọ ọ pe oun tun n yi orukọ NURTW pada si PMS.
Ẹ ṣe gírí, bí bẹ́ẹ̀ kọ́, yóo bá wa, yóo ṣẹgun wa, yóo sì pa ìlú yìí run.
Jẹ́ kí ògo rẹ yìí tẹ́ ọ lọ́rùn, kí ló dé tí o fi fẹ́ dá ìjàngbọ̀n sílẹ̀ sí ìparun ara rẹ ati ti Juda?
''Ní ọ̀pọ̀ ìgbà ilé ẹkọ ni àwọn agbésumọmi Boko Haram máa ń doju kọ ti wọn si mú ìfàẹ̀yin ba àwọn ọmọ ilé ẹkọ'' Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Oluwakaponeski ní iṣẹ́ ọmọogun ilẹ̀ Amẹ́ríkà ni òun tẹ́lẹ̀ kí òun tó di aláwàdà O ní ètò ìrànwọ náà yóò mójúto ètò ẹkọ ni kíákía, bákan náà ni yóò ṣetò ààbò fáwọn ọmọde àti àwọn ọdọ ọkunrin àti obinrin ti ìgbésumọmi dà láàmú.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Beyonce New Album: Ìyá àgbà láti Nàíjíríà ní inú òun dùn láti kọrin pẹlú Beyonce nílẹ̀ Amerika 15 Ògún 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 18 Ògún 2020 Oríṣun àwòrán, Others Àkọlé àwòrán, Iya agba Mojisola Odegbami ti bọ si inu ọla bayii lẹyin to kopa ninu awo orin olorin takasufe ilẹ Amerika, Beyonce.
OLUWA wà pẹlu àwọn ọmọ Juda, ọwọ́ wọn tẹ àwọn ìlú olókè, ṣugbọn apá wọn kò ká àwọn tí ó ń gbé pẹ̀tẹ́lẹ̀, nítorí pé irin ni wọ́n fi ṣe kẹ̀kẹ́ ogun wọn.
Return (Dida oludije pada) : Eyi ma n waye ti
Ko pẹ lẹyin rẹ ni a tun ri arabinrin naa to farahan niwaju ijọ lati ni oun pa irọ mọ adari ijọ naa ni.
Ìjọba ìpínlẹ̀ Èkó kéde ìyè èèyàn tókú ní ilé alájà tó wó l'Eko
Ọjọ nla si ni ọjọ Kẹrinla osu Kinni ọdun 1971 ti atọbatẹlẹ ko to jọba, Lamidi Atanda Olayiwola Adeyemi gori itẹ awọn baba nla rẹ.
Oloselu naa to fi orukọ Adolf Uunona dije ko ida marundinlaadorin ninu ida ọgọrun ibo to waye loṣu to kọja ni Ompundja ilu kekere kan to wa ni Ariwa orileede naa.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Unicycle School: Olùdarí ibùdó ìkẹ́kọ̀ kẹ̀kẹ́ alájọwà ń fẹ́ ìrànwọ́ ìjọba Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Gbajugbaja olorin reggae lorilẹede Naijiria ti gbogbo eniyan mọ siDaddyshokey ti ni oun ko fayegba iwa ibajẹ lawujọ ati wi pe oun ko le lọwọ si.
Wọ́n kó gbogbo ẹran ọ̀sìn wọn ati gbogbo agbo ẹran wọn ati gbogbo ohun ìní wọn.
O ni ki n gbaa ni imoran ko o lọ ge irugbọn rẹ o, ki wọn ma baa ṣìí mu fún ẹsẹ ti ko mọ'di rẹ.
Igba ti awọn akẹkọọ naa si se abẹwo si ọdọ rẹ lọgba Secretariat ,lati fi ẹhonu han lori akude to ba eto ẹkọ wọn, ni wọn ba ibinu Ajimọbi pade tori wọn baa sọrọ lọna aitọ.
Ajọ to n mojuto ajakalẹ aarun l'orilẹ-ede Naijiria, NCDC, kede pe eniyan igba ati marundinlaadọrin ni ayẹwo fihan pe o tun ni aarun coronavirus ni Naijiria.
Nígbà tí ó ń bá wọn jẹun, ó mú burẹdi, ó súre sí i, ó bù ú, ó bá fi fún wọn.
Ọdun 2002 ni idije naa bẹrẹ.
Ọkan lara awọn ẹsọ eti okun yii ma n wa ni ibi isẹ laarin ọsẹ, nigbati mẹta si n sisẹ ni opin ọsẹ ti awọn eniyan ma n pọ ni eti okun.
Iwa-ipa Fulani darandaran: ọlọpa fi panpẹ ọba mu eniyan meji
Nítorínáà, a kò ní orúkọ Yorùbá pọnbélé kankan fún-un.
Thomas John: Kí ló yẹ kóo mọ̀ nípa adelé alága NNPC tuntun?
Nigba ti o jẹ olukọ ni fasiti ilu Eko,Awojọbi pa ọkọ rẹ ti wọn wa pẹlu ọwọ ọtun pada si eleyi ti wọn wa lati apa osi.
Awọn eto idibo lagbegbe to gbona janajan Sun atẹ wa silẹ tabi oke lati ri ẹkunrẹrẹ akọsilẹ Tẹ ibi yii ki o le ṣe tabili lati isalẹ si oke tabi lati oke si isalẹ ninu atẹ naa Ipinle Biden Trump Ta lo bori nilẹ naa lọdun 2016?
’ rèé Afọnja, ẹni tó finú wénú ní Ilọrin, àmọ́ tó jẹ iwọ Ẹfunsetan Aniwura, obìnrin tó ju ọkùnrin lọ Ọ̀rọ̀ǹpọ̀tọ̀niyùn, Aláàfin obìnrin àkọ́kọ́ rèé, tó ní nǹkan ọkùnrin Èyí tí a wò jùlọ 5:03 Fídíò, Omolola Arohunmolase Welder: Mo ti fí iṣẹ́ 'Welder' gbayì láwùjọ, tó mo fi tọ́ ọmọ yanjú, Duration 5,039 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 5:39 Fídíò, Akomolede ati Asa lori BBC: Olùkọ́ Kikelomo Ogunboye tan ìmọ́lẹ̀ sí ìwà olè ọ̀gá ọlọ́pàá Audu gẹ́gẹ́ bí àwòkọ́ṣe àsìkò yìí, Duration 5,398 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 4:11 Fídíò, Oba Adeyeye Ogunwusi: Ojú mi ti rí lọ́pọ̀ lọpọ̀, ọ̀pọ̀ èèyàn ni kò tilẹ̀ gbàgbọ́ pé mo lè jọba- Ooni, Duration 4,117 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 4:43 Fídíò, Promise Akinlade: ọmọ ọdún mọ́kànlá tó ń fi ìlù dárà bíi àgbàlagbà sọ̀rọ̀ nípa tálẹ́ǹtì rẹ̀, Duration 4,437 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 0:59 Gbọ́, Ìsẹ̀lẹ̀ jákèjádò orílẹ̀èdè àgbáyé láàárín ìṣẹ́jú kan, Duration 0,59wákàtí 5 sẹ́yìn 7:03 Fídíò, Olumuyiwa Bolade Adedeji Military Bruitality: Bí arákùnrin onípèníjà ara tí sọ́jà lù ṣe dé, Duration 7,035 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 4:45 Fídíò, Yoruba Films: Ẹ̀ẹ́ bẹ̀ mi kúrò láyé ni, mi ò lè kú - Fadeyi Oloro, Duration 4,4526 Èrèlè 2020 2:48 Fídíò, Esther Ajayi: Èmi náà ti borí ìṣòro rí ló ń mu mi ṣojú àánú, Duration 2,481 Ògún 2019 6:08 Fídíò, Adebola Ademilua: Àìrísẹ́ ṣè lẹ́yìn ìwé kíkà ló sọ mi dí ìyá onírú, mo dúpẹ́ tèmi, Duration 6,0827 Bélú 2020 5:55 Fídíò, Soyinka Cancer: Àṣe ara mi ni iso ti n run gbogbo bí mo ṣe n ṣèrànwọ́ lórí jẹjẹrẹ, Duration 5,5527 Bélú 2019 BBC News, Yorùbá Ìdí tí ẹ fi le è nígbàagbọ́ nínú ìròyìn BBC Ìlànà Lílò Nípa BBC Òfin Àṣírí Cookies Kàn sí.
 Àwọn èdè náà ni fáàsì ( farsi ) tí àwọn tí ó ń sọ ó ẹgbẹ ̀ rún méjìdínláàádọ ́ ta ( 48 , 000 ) ; Úúdù ( urdu ) tí àwọn tí ó ń sọ ọ ́ tó ẹgbẹ ̀ rún lọ ́ nà ogún ( 20,000 ) àti àwọn èdè fílípíìnì ( phillipine ) mìíràn tí àwọn tí ó ń sọ wọ ́ n tó ẹgbẹ ̀ rún lọ ́ nà ogún ( 20,000 ) .
Eemeji ọtọọtọ lo sọ bọọlu sáwọn ẹgbẹ agbabọọlu Rotherham nigba ti Leicester City pade wọn lọjọ Abamẹta.
Nígbà tí àwọn oníṣẹ́ Johanu pada lọ, Jesu bẹ̀rẹ̀ sí sọ fún àwọn eniyan nípa Johanu pé, “Kí ni ẹ jáde lọ wò ní aṣálẹ̀?
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù EFCC 2019 in Retrospect: Gomina mẹ́ta wà láàrín ènìyàn 1,245 tó kó sí panpẹ wa ni 2019 8 Sẹ́rẹ́ 2020 Oríṣun àwòrán, EFCC Àkọlé àwòrán, Àjọ tó ń gbógun ti ìwá ìbàjẹ́ ní Naijiria, EFCC ní gbogbo ètò wọ̀n láti gbógun ti ìwà ìbàjẹ́ ló so èso rere.
Irufẹ igbesẹ bẹẹ lo fẹ waye ni Ọjọ Kẹfa, Osu Kọkanla, Ọdun 2018, tawọn osisẹ si fẹ faraya pẹlu ijọba lati beere fun ẹkunwo sugbọn Wabba sọ fun awọn osisẹ to n mura lati da isẹ silẹ naa pe, eyi ko lee ri bẹẹ mọ.
 lẹ ́ yìn tí ó lo ọdún mẹ ́ ẹ ́ san pẹ ̀ lú oyin adéjọbí , ó darapọ ̀ mọ ́ egbé tíátà yunifásitì ilé ifẹ ̀ níbi tí ó tí bá olóyè olá rótìmí , tí ó jẹ ́ òṣèré àti olùkọ ́ ṣisẹ ́ .
Ṣugbọn Dafidi sọ fún Abiṣai pé, “O kò gbọdọ̀ ṣe é ní ibi kan, nítorí ẹni tí ó bá pa ẹni àmì òróró OLUWA yóo jẹ̀bi.
Ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ náà ló jẹ́ àgbákẹ́yìn fún Wenger nílé Man U k'ótó fipò rẹ̀ sílẹ̀ ní Arsenal lópin sáà yìí.
 Ọ ̀ pọ ̀ àwọn ìsẹlẹ ̀ titun wáyé ní orílẹ ̀ -èdè 16 , tí Índíánì sí jẹ ̀ bíi ìdajì .
Ikọlu yii waye lẹyin ọjọ kan ti ikọlu kan waye nileewe P S Kumbo.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ọkúnrin kan gún àfẹ́sọ́nà rẹ̀ pa tán ló bá tún pa ara rẹ̀ náà Ohun tí a mọ̀ nìyí nípa àwọn tí yóò láǹfàní àti lọ sí Hajj lọ́dún yìí Àìmọ̀kan ló ń ṣe ìjọba Oyo tó fẹ́ ṣí iléèwé, gbogbo ìpínlẹ̀ ló ní àrùn COVID 19- Ijọba àpapọ̀ Lórí bóyá igbákejì gómìnà Ondo yóò fipò sílẹ̀ tàbí rárá, ohun tó lu sí wa lọ́wọ́ nìyí Ènìyàn 675 ni èsì àyẹ̀wò sọ pé ó tún ṣẹ̀ṣẹ̀ ní Covid-19 ní Nàìjíríà Iroyin naa ni wọn kò fààyè gba àwọn ọmọ ìgbìmọ̀ amúṣẹ́ṣe fún ẹgbẹ́ náà láti wọlé sùgbọ́n wọ́n gba àwọn òṣìṣẹ́ àti awọn akọ̀ròyìn láti wọlẹ́ láì gbé mótò wọ́n wọlé.
Bi ọrọ yi ba ri bẹ, ajẹ wi pe ẹgbẹ meje to fi mọ APC ni PDP yoo ma ba wọ iya ija lọjọ idibo.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ẹrọ alágbèéká Ọfiisi JAMB to ba wa ni ipinlẹ̀ yin naa, ibudo CBT ni""."
Awọn iroyin ti ẹ lee nifẹẹ si: Ọwọ tẹ alufa lori ẹsun ijọmọgbe l'Ọsun Ijọba taari ọga ọlọpa si Yobe 'Aibikita ileeṣẹ ijọba nkoba eto iṣuna 2018' Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Ọlọrun fúnrarẹ̀ ni ó rán mi ṣáájú yín láti gba ẹ̀mí là.
34 Ṣùgbọ́n kíyèsíi, ọgbọ́n nìyí, àti nítorí tí mo fi ọgbọ́n hàn ọ́, tí mo sì fún ọ ní àwọn òfin nípa àwọn nkan wọ̀nyí, ohun tí ìwọ yíò ṣe, má ṣe fi hàn sí ayé títí tí ìwọ yíò fi ṣe àṣeyọrí iṣẹ́ ìtumọ̀ náà.
Lara iwa ẹlẹyamẹya to ka ni bi awọn ọlọọpa ṣe ya wọ ile okan lara awọn agba ilẹ Niger Delta, oloye Edwin Clark, ati iponju ti adajo agba Naijiria tẹlẹri, adajọ Walter Onnoghen n la kọja.
Nítorí pé OLUWA yóo pa àwọn ará Filistia run,àwọn tí wọ́n kù ní etí òkun ní Kafitori.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Àwọn agbébọn tó ń gba ojúgbó wọlé máa ń tó 1000 lẹ́ẹ̀kan náà - Amotekun Wo ìṣẹ̀lẹ̀ márùn-ún míì tí kò bá ti sọ Nàíjíríà sínú ogun abẹ́lé kejì Ọlọ́pàá kò fẹ́ yìnbọn, kó má ba à ba aráàlú, l‘àwọn afurasí olóògùn olóró ba sá mọ́ wọn lọ́wọ́ Ẹ má ṣùn àṣùnpiyè o!
Barakat ṣèlérí tó pọ̀ fún mí, sùgbọ́n àwọn ẹni ibi kò jẹ́ Ọwọ́ ọlọ́pàá tún tẹ afurasí tó fipá bá odi àti adití lòpọ̀ nílùú Ibadan Bó bá jẹ́ òrìṣà kan ni wọ́n ń fi ẹ̀jẹ̀ bọ l' Akinyele, ẹ wáa jáde- Seyi Makinde Àṣírí tú, è wọ àwọn dókítà tó ń ta ayédèrú oògùn Coronavirus Kọmiṣọnna ọlọpaa ni ipinlẹ Ekiti, Amba Asuquo kilọ fun awọn obi lati mojuto awọn ọmọ wọn obinrin to n kiri ọja.
Kí ó gé e sí wẹ́wẹ́, ati orí rẹ̀, ati ọ̀rá rẹ̀, kí alufaa to gbogbo rẹ̀ sórí igi tí ó wà ninu iná lórí pẹpẹ.
Ọpọlọpọ ọmọ Naijiria lo koro oju si ihuwasi sẹnetọ naa.
Ogunṣola ni Awọn ẹgbẹ olukọ ati awọn ti kii ṣe ti olukọ ti kọwe atilẹyin pe iṣẹ Ogundipọ tẹ awọn lọrun ranṣẹ si oke bi o ṣe yẹ lẹyin ọpọlọpọ ipade lati ana.
Bakan naa ni olori ikọ ogun amuṣẹya ro dẹdẹ ni imura ologun ki aabo lee daju nibi eto iburawọle.
Àní ohun tí ó lógo tẹ́lẹ̀ kò tún lógo mọ́ nítorí ohun mìíràn tí ògo tirẹ̀ ta á yọ.
Nítorí OLUWA, OLUWA, àwọn ọmọ ogun yóo ṣe iṣẹ́ rẹ̀ ní àṣeparí láàrin gbogbo ayé gẹ́gẹ́ bí ó ti ṣe é lófin.
9th Assembly: Àwọn ohùn tó yẹ kí ẹ mọ nípa Femi Gbajabiamila tó di Olórí Ilé Asojú-sòfin Nàìjíríà tuntun
Inú Saulu kò dùn sí orin tí wọ́n ń kọ, inú sì bí i gidigidi.
Awọn meji yii ni wọn fi ṣe paṣipaarọ ọga agba ọmọ ogun ọlọtẹ Taliban mẹta.
CP Egbetokun Kayode - CP Kwara Command lv.
Ina naa bẹrẹ ni nkan bii ago mẹfa aabo irọle ni Paris to si ba gbogbo orule ile ijọsin naa jẹ ki ọwọ awọn panapana to kaa.
Nígbà náà ni Jakọbu tẹríba lórí ibùsùn rẹ̀.
Wọn ní o se pàtàkì fún àwọn eleto ààbò láti mójú tó àwọn tó wà leyin gbogbo ìwà ìpànìyàn tó ń lọ jákèjádò orile-ede Naijiria.
Èso Mandirake ń tú òórùn dídùn jáde,ẹnu ọ̀nà wa kún fún oríṣìíríṣìí èso tí ó wuni,tí mo ti pèsè wọn dè ọ́, olùfẹ́ mi,ati tuntun ati èyí tó ti pẹ́ nílé.
Oríṣun àwòrán, Twitter/ senator adebayo osinowo Bayo Osinowo: Ọmọ Ìjẹ̀bú tó wọlé sílé aṣòfin ìpínlẹ̀ Eko nígbà mẹ́rin ọ̀tọ̀ọ̀tọ̀ Osinowo, ti wọn ko tii mọ iku to pa a, ni wọn yoo sin lọjọ Ìṣẹgun oni nile rẹ to wa nilu Ijẹbu Ode, nipinlẹ Ogun.
 Ìpín kẹ ̣ ́ rin jẹ ́ àwọn òrìṣà tí ó jẹ mọ ́ ẹ ̀ yà ara wa bíi : orí , ẹsẹ ̀ , okó , òbò , ìdí , ẹnu , àti bẹ ́ ẹ ̀ bẹ ́ ẹ ̀ lọ .
Olu ileeṣẹ ilẹ Amẹrika sọ loju opo Twitter wọn pe iṣinilọna gbaa ni iroyin naa to jade.
Odò-Ẹsẹ̀ wà ní ìlú jèèjì yí bẹ́ẹ̀ náà ni Ẹrẹ́jà pẹ́lù.
O ni labẹ ofin Naijiria, orisirisi igbeyawo meta ti o wa ni igbeyawo ti wọn lọ si ileejọ lati lọ ṣe igbeyawo wọn, eleyii ti ẹsin musulumi fi aye gba ati igbeyawo ti ẹsin abalaye ẹkun si ẹkun fi aye gba.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ọlọ́pàá mẹ́rin d‘òkú lásìkò tí wọn wọ̀yá ìjà pẹ̀lú agbébọn Kí lo mọ̀ nípa Olùṣirò owó Àgbà àkọ́kọ́ ní Afrika?
OLUWA bukun Hana: ọmọkunrin mẹta, ati ọmọbinrin meji ni ó tún bí lẹ́yìn Samuẹli.
"Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Àwọn kókó ohun tó wà nínú lẹ́tà tí Aláàfin kọ sí Fayemi rèé AMVCA7Award: Yewande Famakin lo gba àmì ẹ̀yẹ sinima èdè ibílẹ̀ Ronke Oshodi Oke ṣe àwo orin jáde fún MC Oluomo fún ọjọ́ ìbí rẹ̀ ""Inú ìbẹ̀rù bojo làwa ọmọ Nàíjíríà wà ní Italy, a kò leè jáde tàbí ra ọjà"" Ẹ wo ìdí tí El Rufai kò fi leè fi Sanusi sílẹ̀ ""N kò kọ̀ kí ń kú, ìfẹ́ tí mo ní sí Buhari ni mo ṣe sáré dì mọ"" Ẹ wo fidio naa fun ẹkunrẹrẹ alaye nipa igbadun ibalopọ nilana Tantra."
Ọlọpaa ni Sẹneto Adeleke ati awọn mẹta ti wọn fi ofin mu lori ẹsun naa ni awọn ti ṣetan lati gbe lọ si iwaju adajọ ni Ile Ejọ Giga ti ilu Abuja ni ọjọ kọkanlelogun oṣu kẹsan, ọdun 2018.
Aarẹ Trump ni oun idunnu ni yoo jẹ fun oun, ti awọn ba lee maa ta ohun ọgbin ilẹ Amẹrika fun Naijira lati mu ibugbooro ba ọrọ aje orilẹede Naijiria.
Ohun ti a gbọ nipe Sẹnẹtọ Uwajumogu yọ ṣubu nibi ti o ti n wẹ, lati ibẹ ni wọn ti gbe digbadigba lọ si ile iwosan ni Apo nibi ti ẹlẹmi ti gba a.
Ewe, agbaboolu owo iwaju fun iko Watford, Isaac Success ti bale siluu Eko, ireti si wa pe, yoo ti teko baluu leti lo siluu Uyo, ti n se olu ilu ipinle Akwa ibom.
Iyalẹnu to wa nibẹ ni pe, ti ọpọ ba n ronu nipa 'masturbation', ọkunrin ni wọn ma n ro o si.
Embassy: À kò ni dási ọ̀rọ̀ ìdìbò Nàìjíríà
Wọ́n sùn káàkiri yí pẹpẹ inú ilé Ọlọrun wọn ká, lórí aṣọ tí wọ́n gbà lọ́wọ́ àwọn onígbèsè wọn; wọ́n ń mu ọtí tí àwọn kan fi san owó ìtanràn.
Nígbà tí wọ́n kàn án mọ́ agbelebu tán, wọ́n pín aṣọ rẹ̀ mọ́ ara wọn lọ́wọ́, wọ́n ṣẹ́ gègé láti mọ èyí tí yóo kan ẹnìkọ̀ọ̀kan wọn.
oṣiṣẹ ijọba lorile-ede Naijiria n ṣe faaji pẹlu isinmi ọlọjọ kan saaju idibo ti
Ọmọ moreye mamaroko, morokotan ẹyẹ mátìlo
Nígbà náà ni n óo máa kọ́ àwọn ẹlẹ́ṣẹ̀ ní ọ̀nà rẹ,àwọn ẹlẹ́ṣẹ̀ yóo sì máa yipada sí ọ.
Idije ife ẹyẹ UEFA Ikọ agbabọọlu Arsenal ti ilẹ Gẹẹsi yoo maa fi ìwo lu ìwo pẹlu Athletico Madrid ti orilẹede Spain.
Awon eniyan to wa ni ekun naa ko ju milionu meta aabo lo.
Ṣaaju ni kọmisanna fun eto ẹkọ, Muhamaad Sanusi Kiru ti paṣẹ pe ki awọn ile ẹkọ aladani ati ti ijọba o wa ni titi pa.
Access Bank: Ilé ìfowópamọ́ Access ti gbà láti dá owó àwọn oníbàráà wọ́n padà
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù DR Congo Ebola: Òṣìṣẹ́ ìlera méje kú torí ibínú àwọn èèyàn nípa Ebola 1 Ògún 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Nitori ikọlu, awọn oṣiṣẹ eto ilera maa n bẹru lati wọ aṣọ iṣẹ́ ni gbangba.
Ẹ ma a se ere idaraya pẹlu igbe aye to ni itumọ.
Diana já kúrò nínú ìdíje BBnaija Ọwọ́ tẹ babaláwo àti adigunjalè márùń ni Imo - Olọpàá Ile ẹjọ dajọ ẹwọn ọdun kan fun afẹsọna rẹ ti dokita to wa nile iwosan naa si fẹwọn ọdun meji jura.
O wa ro awon eniyan lati fowosowopo pelu ajo eleto idibo, ki won le gbokun ti iwa ibajẹ yii.
Nítori àwọn àtúgbẹ́yẹ̀wò, o níra láti ṣe àkójọpọ fún àwọn ọkọ́ naa Orisun: Johns Hopkins University atawọn ajọ eto ilera ilu Iye akọsilẹ to waye gbẹyin 15 Oṣù Ṣẹ́rẹ́ 2021 20:44 WAT+3 Èèyàn 91 míràn tún ti ní àrùn Coronavirus ní Nàíjírìa Eeyan mọkanlelaadọrun miran ni ayẹwo tun ti fihan pe o ni arun Coronavirus bayii lorilẹede Naijiria.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Wọ́n rò pé mo ya wèrè ni Saudi lẹ́yìn ikú ọkọ mi Iwe iroyin Punch jabọ pe ẹni to n rojọ tako Sunday, J.
O ni ohun to n ṣẹlẹ yii n bu omi tutu si ọkan awọn olukọ to n ṣiṣẹ ni ẹkun naa ti kii sii fẹ jẹ ki ọpọ olukọ o faramọ ki iṣẹ gbe wọn lọ sibẹ pẹlu.
Ó da Ẹ̀mí yìí lé wa lórí lọpọlọpọ láti ọwọ́ Jesu Kristi Olùgbàlà wa.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ààrẹ Gani Adams: Olùdíje tó bá ṣetán lórí àtúntò ìlànà ìṣèjọba ni Yorùbá yóò dìbò fún 3 Èrèlè 2019 Àkọlé àwòrán, Gani Adams ní pẹ̀lú bí nǹkan ṣe rí báyìí àtúntò ìlànà ìṣèjọba ti di pàtàkì fún ìlọsíwájú Nàìjíríà Aarẹ Ọna kakanfi ilẹ Yoruba, Iba Gani Adams ti ṣalaye wi pe irufẹ aarẹ ti ilẹ Yoruba yoo dibo fun ni eyikeyi ninu awọn oludije fun ipo aarẹ to ba ṣetan lati mu atunto ilana iṣejọba (Restructuring) lọkunkundun.
Ẹ̀ṣẹ̀ tó ṣẹ̀ ló ń kéèésú rẹ̀.
 bótilẹ ̀ jẹ ́ pẹ ́ èyí kìí ṣe ẹ ̀ bùn nobel gangan , ìkéde àti ìfifún ré ̀ ń sélẹ ̀ nígbà kan náà mọ ́ àwọn ẹ ̀ bùn yókù .
Nígbà náà ni gbogbo wọn kígbe pé, “Kàn án mọ́ agbelebu!
Gomina Makinde wa lara awọn gomina to farahan nibi ipade igbimọ naa, gẹgẹ bi atẹjade ọhun ṣe sọ.
"Igba kẹta ree laarin oṣu mẹta.
Ọpọ lo bu ẹnu atẹ lu awọn ilumọọka naa, ati awọn oloṣelu, to ba Hushpuppi ya fọto ri, pe o ṣeese ki wọn o mọ pe iṣẹ jibiti"" ti wọn fi ẹsun rẹ kan an, lo n ṣe."
Ibidun Ighodalo: Ǹkan ti amọ̀ nípa ilúmọ̀ọ́ká arẹwà obìnrin nígbà kan rí tó d'olóògbé Oríṣun àwòrán, Others Ọpọlọpọ awuye lo n lọ lori iku to pa Ibidun Ighodalo to jẹ́ ọbinrin tó rẹ̀wà jùlọ nígbàkan rí, tó sì tún jẹ́ ìyàwó adarí àti olùdásílẹ̀ ìjọ Trinity House.
Bakan naa lo sọ fun Aarẹ Buhari pe, oun ti paṣẹ pe ki iwadii to muna doko ko bẹrẹ lori iṣẹlẹ naa.
2 53 Ọkọ oju omi Zaandam 2 9 Orilẹede Bhutan 1 0.
Mo pa àwọn kan ninu yín run bí mo ti pa Sodomu ati Gomora run, ẹ dàbí àjókù igi tí a yọ ninu iná; sibẹsibẹ, ẹ kò pada sọ́dọ̀ mi.
Alaafin ti Oyo to yan Wasiu Akande amyegun gẹgẹ bi Maiyegun ti ilẹ Yoruba naa lo sọ fun un pe oye ẹni to n gbe asa Yoruba ga, Bakan naa ni wọn tun fikun pe oye Maiyegun ti Kayode Ajulo gba lọwọ aarẹ ọna kakanfo ni lati fi ṣisé.
Lẹ́yìn ìkún omi, àwọn mẹtẹẹta bí ọmọ tiwọn.
com Àkọlé àwòrán, Lalong ni iyawo oun yan kiniun meji ti oun naa si mu erin kan.
Pupọ ninu awọn agba ọjẹ ninu awọn oṣere ẹgbẹ rẹ atawọn amuludun miran lo n kii ni mẹsan an mẹwaa.
pé kí o mú gbogbo àṣẹ tí o ti gbà ṣẹ láìsí àléébù ati láìsí ẹ̀gàn títí Oluwa wa Jesu Kristi yóo fi farahàn.
Eleyi lo jẹ ko ṣatilẹyin fun Akinlade, ṣugbọn pabo ni gbogbo igbiyanju rẹ ja si lẹyin ti Dapo Abiodun fẹyin Akinlade gbo lẹ.
Awọn elere idaraya: Ọkan lara awọn oluwọde naa gbe alupupu Power bike rẹ wa sojuko ọhun lati da awọn eeyan laraya.
Oluwatoyin Olanipekun: Wo àwọn òyìnbó tó ń kẹ́kọ̀ọ́ èdè Yorùbá ní Michigan, America
Coronavirus Ghana: Ààrẹ Nana Akufo-Addo ti wọ́lé ìyàsọ́tọ̀ ọlọ́jọ́ mẹ́rìnlá
Irun 'Miss Congo' gbaná lẹ́yìn tó gbadé 'Miss Africa 2018 Ìdájọ́ ikú ń dínkù, àmọ́ orílẹ̀-èdè mélòó ló sì ń pa ẹlẹ́sẹ̀?
Ni ile iwe girama ti ọlọdun mẹta ti ipele akọkọ, ipinlẹ mẹsan lo ni eto yii, nigbati ile iwe girama ti awọn akẹẹkọjade ko ju ipinlẹ mẹta.
OLUWA kò sì bá mi sọ nǹkankan nípa rẹ̀.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Jerusalema Remix: Wo orin l'édè Yoruba àti Zulu tí Burna Boy fi fa ayélujára ya 20 Òkùdu 2020 Oríṣun àwòrán, @MasterKGsa Gbajugbaja olorin ọmọ Naijiria, Burna Boy wa lara awọn orukọ to n falẹ ya loju opo Twitter latari awo orin tuntun, Jerusalema eyi to pawọpọ ṣe pẹlu ọmọ orilẹede South Africa kan, Master KG.
Ninu ọrọ kan to ba awọn oniroyin sọ ni ile rẹ ni Onimọẹrọ Ọlaniyan ti sọrọ yii.
Rabi-Al Awwal: Oṣu Kẹta ree, ohun si ni igba ti irugbin maa n ṣu yọ, to si ṣe deede pẹlu asiko ti irugbin maa n gberi lọdọ wa nibi.
"Oríṣun àwòrán, Twitter/seyi makinde ""Ko si aawọ laarin emi ati gomina."
 lára àwọn amì àkọ ́ kọ ́ rí ni ibà àti ara rínrìn ní àwọn ibi tó hàn síta .
 Ọ ̀ jọgbọ ́ n edger pada si kémíbirììji ní ọdun 1919 , ni igba ti o di ọdun 1925 .
”“A ni asole meta ti o dara, sugbon ni bayii, a ni lati fun Francis Uzoho lanfaani lati ni iriri awon ifigagbaga ti o lagbara saaju idije nla naa.
Oríṣun àwòrán, Baba wande Bákan náà lo ṣàlàyé nipa ìròyìn kan tó já nilẹ pé òun fẹ́ gbé Tunde Kelani lọ sílè ẹjọ́, gbajumọ osere náà ni ìròyìn eke ni ìròyìn náà, òun kò sọ bẹẹ, òun kò sì leè gbé Kelani lọ sílè ẹjọ́ láéláé.
Ti EFCC ba ti ile-onile, ki ẹni to nile naa jada, tabi ko gbe ọrọ naa lọ ile ẹjọ.
Canadian Kidnap: Ghana ti mu àwọn afurasí ajínigbé ọmọ Naijiria
Pataki igba titi ni aafin Oyo: Oríṣun àwòrán, Alaafin oyo Igba titi jẹ ara ọna ti wọn n gba ṣe afẹ ninu aafin, paapaa lasiko ayẹyẹ kan, ọdun ibilẹ tabi ti Alaafin ba gba alejo pataki ti wọn fẹ fi ere da laraya.
Ayọ̀ ń bẹ fún àwọn tí ìgbé ayé wọn kò lábàwọ́n,àní àwọn tí ń rìn gẹ́gẹ́ bí òfin OLUWA.
ibile silẹ lorile ede yii, ki won si tun yi oruko SARS pada si iko to n gbogun
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ẹlẹ́wọ̀n: Ẹ̀sùn ìbálòpọ̀ ọmọdé ló gbé dé mi dé ẹ̀wọ̀n Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Ẹlẹ́wọ̀n: Ẹ̀sùn ìbálòpọ̀ ọmọdé ló gbé dé mi dé ẹ̀wọ̀n 18 Ìgbé 2018 Ẹlẹ́wọ̀n kan gba máákì 248 nínú ìdánwò Jamb ní ọgbà ẹ̀wọ̀n Ìkòyí ní ìlú Èkó.
"Kìí ṣe coronavirus ló paá, sùgbọ́n à ó ṣe ìwádìí ǹkan to n fa ikú tó ń ṣẹlẹ̀.
Jẹ ẹni tí ó bá ṣẹ̀ níyà bí ó ti tọ́ gẹ́gẹ́ bí ẹ̀ṣẹ̀ rẹ̀, kí o dá ẹni tí kò ṣẹ̀ láre gẹ́gẹ́ bí òdodo rẹ̀.
Sinimá àwòdamiẹnu, Ẹ̀fáńjẹ́líìsì jìyà àjẹmumi nílé aṣẹ́wó l'Ejigbo ní ìlú Eko Ọkùnrin kan da ṣọ́ọ̀ṣì rú lásìkò ìgbéyàwó, Ó ní òun lọkọ àárọ̀ ìyàwó tuntun Èèmọ̀!
Kì í ṣe ohun tí ó kàn wá lórí àwọn ajàfúnẹ̀tọ́ obìnrin, kì í sì í ṣe ọ̀rọ̀ àgbélẹ̀rọ tàbí ọ̀rọ̀ òfìfo, LÓÒÓTỌ́ NI!
9 Oríṣun àwòrán, Twitter/@AyindeBarrister Àkọlé àwòrán, Sikiru Ayinde Barrister ṣiṣẹ ologun, ko to o di olorin Fuji patapata.
Ṣẹ́ eniyan burúkú ati aṣebi lápá,tú àṣírí gbogbo ìwà burúkú rẹ̀,má sì jẹ́ kí ọ̀kan ninu wọn farasin.
Ó le ṣí ìwé náà ó sì le tú èdìdì meje tí a fi dì í.
Ọba Asiria kó àwọn ọmọ Israẹli ní ìgbèkùn lọ sí Asiria, ó sì kó wọn sí ìlú Hala ati Habori tí ó wà ní agbègbè odò Gosani ati sí àwọn ìlú àwọn ará Media.
Ó pe àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ mejila, ó rán wọn lọ ní meji-meji, ó fi àṣẹ fún wọn lórí àwọn ẹ̀mí èṣù.
Olutunde Boroffice to jẹ Ọga agba ileeṣẹ Chanja Datti Ltd ati alakoso Waste Africa ṣalaye pe o ṣoro fun ijọba lati kan si awọn eeyan yii nitori pupọ wọn ni ko forukọ silẹ pẹlu ijọba.
Sadoku alufaa, ati Natani wolii, ati Bẹnaya, pẹlu àwọn ará Kereti ati àwọn ará Peleti tí wọn ń ṣọ́ ọba, bá gbé Solomoni gun kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ Dafidi ọba, wọ́n sì mú un lọ sí odò Gihoni.
Ẹgbẹrun mẹtalelọgọta ati ọrinlelugba ati meji (63,282) lawọn ti ara wọn ti ya nigbati aarun naa si ti gbẹmi awọn ẹgbẹrun kan ati mejilelaadọjọ (1173) eeyan.
Àwọn ọba ayé, àwọn ọlọ́lá, àwọn ọ̀gágun, àwọn olówó, àwọn alágbára, ati gbogbo eniyan: ẹrú ati òmìnira, gbogbo wọn lọ sápamọ́ sinu ihò òkúta ati abẹ́ àpáta lára àwọn òkè.
Adajọ Michael tilẹ sọ wi pe ofin ti tẹlẹ ti ko fi aaye gba a n gbe lẹyin apa kan ni.
Adeleke jẹ aburo Baba gbajugbaja olorin takasufe, ti gbogbo aye mọ si Davido sugbọn se ẹ mọ wi pe, awọn ọmọ rẹ okunrin meji naa a ma kọ orin takasufe?
Ará, bí ẹ bá ká ẹ̀ṣẹ̀ mọ́ ẹnìkan lọ́wọ́, kí ẹ̀yin tí ẹ̀mí ń darí ìgbé-ayé yín mú irú ẹni bẹ́ẹ̀ bọ̀ sípò pẹlu ẹ̀mí ìrẹ̀lẹ̀.
Nígbà tí Esau jẹ, tí ó mu tán, ó bá tirẹ̀ lọ.
Iṣimaeli kó wọn lẹ́rú ó sì fẹ́ kó wọn kọjá sí ọ̀dọ̀ àwọn ará Amoni.
 Ẹni yii lo jẹwọ ibi ti awọn to ku rẹ wa."
O tun kẹkọgboye ninu ede Yoruba ni Ile-iwe giga fasiti ti Eko ni ọdun 1978 ṣaaju ki o to bẹrẹ iṣẹ ijinlẹ gẹgẹbi olukọni ni ile ẹkọ giga fasiti ti Obafemi Awolowo.
”O tun wa faramọ ipinnu lati seto oko oju-irin , nitori pe yoo mu idagbasoke ba eto ọrọ aje.
tolohun, eyi lo difa fun awọn Yahoo boys nigba ti ọwọ palanba won segi , ti won
“Ọjọ́ ń bọ̀, tí ọkà yóo so jìnwìnnì,tóbẹ́ẹ̀ tí wọn kò ní lè kórè rẹ̀ tánkí àkókò gbígbin ọkà mìíràn tó dé.
Mo rí yàrá meji ninu gbọ̀ngàn yìí: ọ̀kan wà lẹ́gbẹ̀ẹ́ ẹnu ọ̀nà ìhà àríwá, ó dojú kọ ìhà gúsù, ekeji wà lẹ́gbẹ̀ẹ́ ìhà gúsù, ó dojú kọ ìhà àríwá.
Ọkunrin náà dáhùn pé, “Olùkọ́ni, láti ìgbà tí mo ti wà ní ọdọmọkunrin ni mo ti ń pa gbogbo nǹkan wọnyi mọ́.
Kilo de to fi di agbẹnusọ fun wọn.
O ni won fopin si ofin orile
Ọgbẹni Okhiria ṣalaye pe awọn ọkọ reluwee naa yoo maa na Eko si Ibadan ni igba mẹrindinlogun lojoojumọ.
Jehoiakimu jẹ́ ẹni ọdún mẹẹdọgbọn nígbà tí ó jọba, ó sì jọba ní Jerusalẹmu fún ọdún mọkanla.
Wọn yóo jẹ́ ìtùnú fún ọ nígbà tí o bá rí ìwà ati ìṣe wọn, O óo sì mọ̀ pé bí kò bá nídìí, n kò ní ṣe gbogbo ohun tí mo ṣe sí wọn.
Lẹ́yìn náà, Joṣua sọ fún wọn pé, “Bí ó bá rí bẹ́ẹ̀, ẹ kó àwọn oriṣa àjèjì tí ó wà láàrin yín dànù, kí ẹ sì fi ọkàn sọ́dọ̀ OLUWA Ọlọrun Israẹli.
Tí ẹ bá fẹ́ jẹ ẹ́ ní ẹyọ-ẹyọ, ẹ lè rà á bẹ́ẹ̀.
Ohun ìkọsẹ̀ ni iwaasu wa yìí jẹ́ lójú àwọn Juu, ọ̀rọ̀ òmùgọ̀ sì ni lójú àwọn orílẹ̀-èdè yòókù; 
Gbajabiamila  sọrọ yii lasiko to n ba awon akoroyin ile
Ọdun 2016 ni wọn fi panpẹ si lọwọ, amọ to si sọ wi pe oun ko jẹbi ẹsun ti wọn fi kan oun.
OLUWA ní, “Nisinsinyii, ẹ kíyèsí ohun tí yóo máa ṣẹlẹ̀ láti àkókò yìí lọ.
  Orin ‘Manya’ lo ko fi dara nibe fi ra iyi.
Ẹ Máa Ran Ara Yín Lọ́wọ́.
IkeazorIla Gusu: Senator Godswill AkpabioOludari etoOludari , igbimo
Ileeṣẹ ọlọpaa ti kọkọ ṣalaye wi pe awọn ko mọ ohunkohun nipa ahamọ ti wọn fi alaga ajọ EFCC ti arẹ Buhari yọ nipo naa.
Eeyan mẹtadinlọgojọ lo padanu ẹmi wọn ninu iṣẹlẹ naa.
Sise atileyin fun egbe oselu SLPP ati APC da lori eleyameya .
Àwọn ẹ̀dá alààyè náà ń já lọ sókè sódò bí ìgbà tí manamana bá ń kọ.
Iyaafin Dabiri so pe“Inu mi baje lati fi to yin leti nipa iku omo orile ede Naijiria kan ogbeni Abraham Badru,omo odun merindinlogbon,ti won fi ibon pa si opopona Ferncliff ni London ni agogo mokanla ale ninu osu keta ,ojo karundinlogbon”.
Awọn ọmọlẹ́yìn El-Zakzaky: Ọlọ́pàá ló ń fa rúkèrúdò lásìkò ìwọ́de wọn
Ohunkohun ti aarẹ ilẹ Amerika ba ṣe, gbogbo agbaye ni yoo mọ ọ ni ara.
Akọnimọọgba tẹlẹri fun ikọ agbabọọlu Chelsea ati Manchester United ti bu ọwọ lu iwe adehun ọlọdun marun un 2022 si 2023.
A kò sì ṣe ohunkohun láti gbà á pada lọ́wọ́ ọba Siria.
Beti Makabotu, Hasasusimu, Betibiri, ati Ṣaaraimu.
Messi ò lè dúró mọ́, aṣojú Manchester City ti balẹ̀ sí Barcelona láti dú ìná dúrà Ronald Koeman di akọ́nimọ̀ọ́gbá Barcelona tuntun lẹ́yìn ìjàmbá Champions League Orileede Portugal yoo koju Sweden ninu ifẹsẹwọnṣe idije Nations League lỌjọru.
Ó ti dí ènìyàn ẹgbẹ̀rúnlọ́nà mẹ́tàléláàdọ́ta àtí makàlelógún to ti lùgbàdì ààrùn náà ni Nàìjíríà Ènìyàn mẹ́ta tún ti jẹ́ Ọlọ́run nípè, ó sì ti dí ẹgbẹ̀rún kan àti ènìyàn mẹ́wàá to ti bá ìṣẹ̀lẹ̀ náà rìn báyìí.
 A n tun ipinnu apapo fun ipinle mesan naa yewo ki a le gbe awon igbese to ye lasiko”O ni opolopo ise lo wa lowo ajo naa gege bi won se sagbekale re fun idagbasoke ekun epo robi ohun.
Lẹyin ti ọlọpaa fi panpẹ mu tan ni wọn tu gbogbo agbegbe naa yẹbẹ yẹbẹ, ti ọwọ si tẹ awọn yoo ku.
Bí igi kan ò ṣe lè dágbó ṣe, bẹ́ẹ̀ náà ni ẹnìkan ò lè dálùúgbé.
”Kazeem fikun oro re pe, “Awon osise alaabo oju popo de sibi isele naa ni wakati marun ti isele ohun waye, ti o fi mo awon osise oloopa, ajo to n ri si isele pajawiri eka ipinle Eko ati awon osise ajo to n ri si didari oko loju popo.
Bi awọn ọlọpaa sẹ wọle ni awọn eniyan to wa nibẹ bẹrẹ si ni salọ.
Gbogbo ẹyẹ ojú ọ̀run, pa ìtẹ́ sára àwọn ẹ̀ka rẹ̀.
Láti ọjọ́ náà, ìdajì àwọn òṣìṣẹ́ mi ní ń bá iṣẹ́ odi mímọ lọ, ìdajì yòókù sì dira pẹlu ọ̀kọ̀, àṣíborí, ọrun ati aṣọ ogun.
"Mo lọ fun idanilekọọ iṣẹ ologun fun oṣu mẹfa, ti n ko si fi fidio awada kankan sori ayelujara lasiko naa.
Kì í sìí ṣe ti dídé tí ó dé nìkan ni, ṣugbọn ó ròyìn fún wa, gbogbo bí ẹ ti dá a lọ́kàn le ati gbogbo akitiyan yín lórí wa, bí ọkàn yín ti bàjẹ́ tó fún ohun tí ó ti ṣẹlẹ̀, ati bí ẹ ti ní ìtara tó fún mi.
Ẹ dúró níhìn-ín kí ẹ máa ṣọ́nà.
Nígbà tí Enọṣi di ẹni aadọrun-un ọdún, ó bí Kenani.
Awọn eeyan kan bi i gbajugbaja onimọ ẹrọ, Elon Musk, ṣe gba pe igbesẹ to dara ni, ti wọn si jẹjẹ atilẹyin fun.
Ta ni ó tó bá a jà?
olubori ninu eto iselu to n bọ ati pe alafo ti egbe APC yoo fi na awon egbe
O fikun pe, igbe aye ‘taa ni yoo mu mi’ ti awọn ẹlẹsin Hakika n hu lo n se iwuri fawọn ọdọ lati tete dara pọ mọ wọn.
Ẹyin odi ni owo ko ti si ti eleyi si mu ki ijọba orileede Naijiria kede pe ohun yoo kogba awọn ọfisi kan to n soju rẹ nilẹ okere wọle.
Èèyàn 204 míràn tún ti ní àrùn Coronavirus ní Nàíjírìa Eeyan mẹrinlenigba miran ni ayẹwo tun ti fihan pe o laarun Coronavirus lorilẹede Naijiria bayii.
Ẹ̀dá ò láròpin, Super Eagles ṣẹ́só ìyá fún Cameroon
Onímọ̀ nípa ìhùwàsí: ibi a gbé dàgbà níi ṣe pẹ̀lú ìhùwàsì
Ṣaaju ni ọkunrin ọhun to wa si Naijiria lati ilu Milan lọjọ kẹrinlelogun, Oṣu Keji ọdun yii ti n gba itọju nile iwosan ijọba to wa ni yaba, nilu Eko.
Omoyele Sowore rèé Omoyele Sowore, kìí ṣe màjesìn, ó si ti pẹ nínú ìjìjagbàra, láti June 12 1993 ní ó ti máá ń gbarùkù ti ọ̀rọ̀ orílẹ̀-èdè Nàìjíría O jẹ́ ọmọ bíbí ilẹ̀ Ilaje ni ìpínlẹ̀ Ondo.
Mo gbadun ilu Abuja ati Eko, inu mi si dun bi eto oro aje se n se aseyọri nibẹ.
Nigba to n sọrọ, olori awọn ọdẹ ni ilu naa, ọgbẹni Adebayọ Ọdẹyẹmi salaye wipe awọn ọlọdẹ ti bẹrẹ igbesẹ ati gbogun ti awọn darandaran Fulani lagbegbe naa.
Ogbeni Ayo Adams to jẹ alakoso irinajo afẹ́ nibẹ ṣalaye fun BBC Yoruba ni kikun lori odo adagun naa.
Yóo ṣẹgun wọn, yóo sì pa wọ́n.
Sex For Grades: Four Square Church tí ní kí olùkọ́ fásitì Pasitọ̀ Boniface lọ fìdímọ́lé
Àwọn ọ̀rẹ́ rẹ̀ a sì maá bá a ṣeré.
Koju o ma ribi 'Koro'lo fi ọrọ ṣe Oríṣun àwòrán, others Àkọlé àwòrán, Kini ka tun ti pe ibomu-bẹnu yii o?
Aare Buhari wa pase fun awon ajo kookan to n mojuto isele pajawiri jake-jado orile-ede yii ti o wa labe isakoso ijoba Naijiria lati lo awon osise ati ohun elo ise won lojuna lati ran awon ipinle ti o n koju isoro ohun lowo.
Ẹ máa bu ọlá fún ọba.
Wọn yoo si gba gbogbo ifẹsẹwọnsẹ naa lai si eero iworan.
Eniyan mẹta ni wọn jigbe nibi ikọlu naa.
Kí lo mọ̀ nípa fẹntilétọ̀, ohun èlò aṣèrànwọ́ èémí Nitorinaa, o pe e lati maa fi owo gọbọi ra wọn ki wọn ṣi le wa laaye.
Lílọ bibọ Kiise lílọ bibọ lati lati ilu kan si òmíràn nikan ni o kan, irinajo laarin awọn ilu nla kaakiri agbaye ti dawọ duro.
Ó sì jọba fún ọdún mejila.
”Obinrin náà dáhùn pé, “Kabiyesi, bí o ti bèèrè ìbéèrè yìí kò jẹ́ kí n mọ̀ bí mo ti lè yí ẹnu pada rárá.
Aare Muhhamadu Buhari ti se apejuwe iku oloogbe Winnie Mandela gege-bi adanu nla fun ile Afirika.
Oríṣun àwòrán, @HQNigerianArmy Sugbọn lẹyin igba ti gomina ipinlẹ Eko, Babajide Sanwo-Olu se abẹwo yika awọn ile iwosan ilu Eko loru mọju ọjọ ti isẹlẹ naa waye, o fidi rẹ mulẹ pe ẹmi kan soso lo ku nile iwosan ti wọn gbe awọn oluwọde to fara gbọgbẹ lọ.
Àwọn ìtàkùn àgbáyé bi i Snopes tàbí factcheck.
Gbogbo àwọn tí ń rékọjá lọń pàtẹ́wọ́ lé ọ lórí,wọ́n ń pòṣé,wọ́n sì ń mi orí wọn sí ọ, Jerusalẹmu.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Osun Election Results 2018: Adeleke sọ pé PDP yóò gba ipò gómìnà rẹ̀ padà nílé ẹjọ́ Ki ni òfin èto idibo Naijiria sọ?
Ikọ́ ẹ̀ẹ̀kan lè gbé àwọn kòkòrò ẹgbẹ̀rún mẹ́ta síta tó sì le rìn ìwọ̀ Mítà ọgọ́rin láàrín wákàtí kan gẹ́gẹ́ bí Bromage ṣe sọ, ọ̀pọ̀ àwọn kòkòrò yìí si ló tóbi to fi je pé ilẹ̀ ni yóò jábọ́ sí, ṣùgbọ́n àwọn mìíràn fúyẹ́ tí won sì le dúró nínú afẹ́fẹ́ tàbí kí wọn fò wọ yàrá.
N óo fi àjàkálẹ̀ àrùn ńlá kọlu àwọn ará ìlú yìí, ati eniyan ati ẹranko ni yóo sì kú.
Kì í ṣe bí eniyan ṣe rú òfin tó ni Ọlọrun fi ń wọn ìfẹ́ ati àánú rẹ̀.
Ọpọ ikunsinu lo n waye laarin awọn agbẹ yii atawọn asoju ijọba to n yẹ koko wo nitori ayẹwo ati osunwọn eke pẹlu eru ti wọn n ṣe nidi koko.
Tinubu dibo ni deede aago mọ̀kànlá  kọja iseju mọ́kànlélógún (11:21 am)ni
Kódà, àwọn tí kò lérò wí pé ìgbẹ́sẹ̀ tí àwọn òṣìṣẹ́ yìí gbè leè pa àwọn lára, ṣe ni wọ́n ń dì ẹrù wọn padà sílé.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Akọ́mọlédè àti Àṣà lórí BBC Yorùbá: Kọ̀ síi nípa iṣẹ́ tí oúnjẹ ń ṣe lára níbí Ninu idajọ rẹ, Adajọ ile ẹjọ naa, Onidajọ Odunade Ademola sọ pe ile ẹjọ naa ko ni i ma woran, titi wahala yoo fi ṣẹlẹ ki oun to gbe igbesẹ to yẹ.
Naijiria ti wọn n fi ẹhonu han, paapaa awọn ti wọn n ba nnkan ini awọn
Nigba tẹẹ ba ri ọmọ ọdun mẹtalelogun to kan dede joko, ko ṣiṣẹ, ko sabọ, ko lọ ileewe, ẹ o ti mọ pe nkan ti yiwọ""."
Eeyan kan loju opo twitter, @TeeBaibie lo fi fidio naa sita nibi ti awọn oṣiṣẹ kansu naa ti n gbiyanju ati jo taya ọkọ arabinrin naa lọjọ Satide lagbegbe Ojodu Abiọdun.
O dọgbọn wọ aṣọ bi ologun.
Oríṣun àwòrán, Reuters Àkọlé àwòrán, Jesse Lingard ló bá Manchester United gbá bọ́ọ̀lù sí àwọ̀n Liverpool Ṣugbọn akọnimọọgba Liverpool ni gudugudu awọn agbabọọlu oun naa ko fi gba kan tura silẹ.
Bi wọn ti gbe ọmọbinri yii de ile iwosan naa lo tun ti n bi ti wọn fi sare gbe e lọ ṣe iṣẹ abẹ fun un.
Ṣugbọn ile itura Glee ti sọ pe irọ ni pe akọrin naa fi ipa ba ẹnikan lopọ ni ọdọ wọn.
Adari eto irinna ni ilẹ Ghana naa wa parọwa si awọn ara ile Ghana lati ma a wu iwa daradara si awọn ọmọ Naijiria.
Ninu ifẹsẹwọnsẹ naa Liverpool ja ireti Barcelona kulẹ pẹlu ami ayo mẹrin si mẹta.
Leyin idibo ni wahala be sile ti awon alatako si so pe àádọ́ta eniyan lo ti ku nibi isele naa,sugbon iroyin lati odo ijoba so pe eniyan mẹ́ta lo ku.
Bákan náà ni gbogbo àwọn aládùúgbò wọn láti ọ̀nà jíjìn bí ẹ̀yà Isakari ati ti Sebuluni ati Nafutali di oúnjẹ ru kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́, ati ràkúnmí, ati ìbakasíẹ, ati akọ mààlúù wá fún wọn.
Gege bi akowe ajo to n sakoso olokan-o-jokan isele nipinle Rajasthan, Hemant Gera,  “ikolu yii je ohun iyalenu fun mi pupo, o je ikolu akoko irure ti yoo waye loju mi lati ogun odun ti mo ti n sise pelu ajo yii,”“Bakan naa, irufe ikolu iji lile yii waye lojo kokanla osu kerin in, ti o si gbemi eniyan mokandinlogun – sugbon iji eleyi bere ni asale, leyi ti ko fun awon olugbe lanfani lati jade kuro ninu ile won, kii iji lile ohun o to wo ile mo awon miiran lori.
O  tun wa  fikun ọrọ rẹ pe ijoba oun ko ni kọ ile iwosan
Nígbà tí Jobabu kú, Huṣamu ti ilẹ̀ Temani, gorí oyè.
Eyi kii ṣe igba akọkọ ti ileeṣẹ aarẹ labẹ ijọba Buhari yoo maa tako ọrọ aarẹ ana Obasanjo .
Air Canada: Obìnrin to jí nínú òkùnkùn nínú ọkọ̀ òfurufú
Nítorí náà, àwa náà ń dúpẹ́ lọ́wọ́ Ọlọrun nígbà gbogbo, nítorí nígbà tí ẹ gba ọ̀rọ̀ Ọlọrun tí ẹ gbọ́ lẹ́nu wa, ẹ gbà á bí ó ti rí gan-an ni.
Vietnam: Ọkan ejo Sèbé ni awọn eniyan ma fi n se ounjẹ jẹ.
Wayi o, atẹjade kan ti Adeoti fi ransẹ si wọọdu idibo rẹ, tii se Wọọdu kejila, nijọba ibilẹ Iwo, fihan pe o ti fi ẹgbẹ oselu APC silẹ.
Ẹwẹ, DSP Oyeyemi tun ṣalaye pe ileeṣẹ ọlọpa si n wa ọkọ oju omi agbera pa wọn tawọn ajinigbe gbe lọ nigba ti wọn fi doola ọmọ Imaamu atawọn meji ti wọn gbe lọwọ wọn.
‘Se ẹ̀yin ènìyàn dúdú ò fẹ́ se oríire nípa òsèlú ni?
Awọn agbofinro mawọn ọkunrin naa lẹyin tawọn ara adugbo lọ fẹjọ sun ileeṣẹ ọlọpaa pe ariwo awọn ọkunrin pọ lati ile ijo ti wọn wa lẹkun tawọn ololufẹ akọ sakọ pọ si ni rue des Pierres.
idibo INEC ati ile-ise agbofinro fun eto aabo to peye ni  Ipinlẹ Ọyọ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Coronavirus: Gbogbo ilé ẹ̀kọ́ alákọ̀ọ́bẹ̀rẹ̀ àti girama yóò wá ní titipá ní Italy 4 Ẹrẹ̀nà 2020 Oríṣun àwòrán, Reuters Orileede Italy lawọn n gbero lati ti gbogbo ile ẹkọ ati fasiti lorileede naa pa nitori ajakalẹ aisan Coronavirus.
Ninu ọrọ to kọ si ori ayelujara Instagram, arakunrin naa, Loveday, sọ pe o ṣeni laanu pe arẹwa obinrin naa kagbako iku lasiko yii.
Ninu atẹjade kan, Ile-isẹ Olotu Ijọba IlẹGẹẹsi (No 10 ) , dupẹ lọwọ Arakunrin Johnson fun isẹ ribiribi to se nigba to wa ni ipo, atiwipe wọn ko ni pẹ kede ẹni ti yoo gba ipo rẹ.
" Bi o tilẹ jẹ pe ahesọ ọrọ n lọ kaakiri pe mo fẹ fi ẹgbẹ silẹ, irọ ni.
Ibi kanna ni Òkín Oba Eye@St_michaelalter sun, ti o kọ ori si ibi kanna.
Nítorí bí ìfẹ́ obìnrrin bá wọ ọkùnrin tọ́kàn tán tí wọ́n kò sì rí àyè fẹ́ ara wọn, ìdàrúdàpọ̀ a gba ìsàlẹ̀ odò ikùn, ìbànújẹ́ a da orí àgbà kọ odò, òkèlè kò nì lọ ní ọ̀nà ọ̀fun, ìrora olúwwarẹ̀ a ju ti onísòbìyà, ìrònú á dé bá olúwarẹ̀ bí onígbèsè, ọkàn olúwarẹ̀ á bàjẹ́ bii ti ẹlẹ́wọ̀n, ìrìn ẹsẹ̀ olúwarẹ̀ a dàbí ti olókùnrùn, ètè olúwarẹ̀ a gbé bi ti aboyun, itọ́ ẹnu olúwarẹ̀ a yi tikẹ́ bí ti ẹni ti ń sáré ìje, ìsọ̀rọ̀ olúwarẹ̀ a dàbí ti ará oko, ojú olúwarẹ̀ á dàbí tí ẹlẹenga, ara olúwarẹ̀ á gbóná bí ara alákọ̀wé tí ó ṣẹ̀ṣẹ̀ gbọ́ pé òun re ẹ̀yìn nínú ìdánwò, olúwarẹ̀ a sì máa kọsẹ̀ nibi ti kò sí gbòngbò ttàbí òkúta.
Lẹ́yìn èyí ni ó lọ ilé ìfowópamọ́ First Inland Bank, èyí tí a mọ̀ sí First City Monument Bank báyìí.
N óo na àwọ̀n mi lé e lórí, yóo sì kó sinu tàkúté tí mo dẹ sílẹ̀.
Kí wọn wá fá orí wọn.
 fun ti eroungba ise laye , pelu okan pataki lara imu idagbasoke ba eso fun eyan ni ile naijiria .
john burdon sanderson haldane frs ( 5 november 1892 - 1 december 1964 ) , to gbajumo bi jack ( sugbon o lo ' j.
Kí ló dé tí Aàrẹ Buhari kìí fí í dá sí aáwò àwọn ọmọ ẹgbé APC?
 O ni, nibayii eto ti to sile lati ri daju peorile-ede Naijiria ko woju enikeni ki o to je.
A kò dàbí Mose tí ó fi aṣọ bojú rẹ̀, kí àwọn ọmọ Israẹli má baà rí ògo ojú rẹ̀.
Ni bayii, aare Muhammadu Buhari sapejuwe iku oloogbe adajọ Kutigi gege bi ohun ti o bani ninu je pupo, leyin gbogbo ise takun-takun re ti o ti n gbese ni eka eto idajo lorile-ede Naijiria.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Mr Macaroni sọ nípa eré tí Fraky freaky, Sugar Daddy, You are doing well, freaky spicy fẹ́ Eyi la gbọ pe o bi awọn ọdọ adugbo ninu, ti wọn si bẹrẹ si ni ṣe iwọde.
Ẹgbẹrun lọna ogoji lemi san nitori mo sọ fun wọn pe mi o fẹ bata tapa sẹgun yii."
Ekọ nipa ere itage ni Gabriel ka ni fasiti ibadan.
Gẹ́gẹ́ bí o ti fún un ní àṣẹ lórí ẹ̀dá gbogbo, pé kí ó lè fi ìyè ainipẹkun fún gbogbo ẹni tí o ti fún un.
Oba Folagbade Olateru-Olagbegi wàjà lẹ́ni ọdún 77
Awọn Dogon fẹsun kan awọn Fulanis pẹ wọn n padi apo pọ pẹlu awọn alakatakiti Jihadi ti awọn Fulani naa si n sọ pe ile iṣẹ ologun Mali n se iranwọ nnkan ija fun awọn ọlọdẹ Dogon.
Atẹjade naa ṣalaye pe ijọba ko ni ṣe ohun kan to tako ipinlẹ naa gẹgẹ bi ipinlẹ to wa fun gbogbo araalu lai fi ti ẹsin kankan ṣe.
Nígbà tí Dafidi gbọ́ ohun tí ó ṣẹlẹ̀ sí wọn, ó ranṣẹ sí wọn pé kí wọ́n dúró sí Jẹriko títí tí irùngbọ̀n wọn yóo fi hù, lẹ́yìn náà kí wọ́n máa pada bọ̀ wá sílé.
6 6152 Orilẹede Cyprus 163 13.
Yóo na ọwọ́ ìjì líle sí orí odò Pirati,yóo sì pín in sí ọ̀nà meje,kí àwọn eniyan lè máa ríbi là á kọjá.
Mo fi ọ́ wé igi kedari Lẹbanoni,àwọn ẹ̀ka rẹ̀ lẹ́wà,wọ́n sì ní ìbòòji ó ga fíofío,orí rẹ̀ sì kan ìkùukùu lójú ọ̀run.
OLUWA, mo fẹ́ràn ilé rẹ, tí ò ń gbé,ati ibi tí ògo rẹ wà.
Dúkìá àti ọkọ̀ jóná, ọlọ́pàá mẹ́sàn-án fara gbọta lásìkò ìwọ́de Shiite Gba owó lọ́wọ́ àkẹ́kọ̀ọ́ ìjọba, ko rugi oyin - Seyi Makinde Iṣu ló wà nínú mọ́tò mi, kìí ṣe èèyàn ni mo sọ di iṣu - Afurasí Ajínigbé figbe ta Ìlú tí ọ̀daràn bá tí dẹ́ṣẹ̀ ló yẹ kí wọn tí gbẹjọ́ rẹ̀ -Agbẹjọ́rò Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Lara awon eniyan ti won fi oye ọmọwe da lọla ni Fafiti ọhun ni ,minisita
Ṣugbọn níbi èrè aiṣododo nìkan ni ojú ati ọkàn yín ń wà,níbi kí ẹ máa pa aláìṣẹ̀, kí ẹ máa ni eniyan lára,kí ẹ sì máa hùwà ìkà.
 ede ati asa awon meji yato gidi .
Nítorí náà, nígbà tí ó jẹ́ pé a níláti fi ẹbọ sọ ẹ̀dà àwọn nǹkan ti ọ̀run di mímọ́, a rí i pé àwọn nǹkan ti ọ̀run fúnra wọn nílò ẹbọ tí ó dára ju èyí tí ẹ̀dà wọn gbà lọ.
Ìdáhún àtàwọn ìbéèrè míì Ṣé òògùn Chloroquine lè dènà ààrùn Coronavirus bí?
Oke Arafah ni Ojisẹ Allah, Mohammed se ẹsiin ati iwaasu ikẹyin to fi ki wọn pe o digba kan naa.
Tarrant tó yìnbọn pa èèyàn 51 ní mọ́ṣálááṣí méjì gbà'dájọ́ ẹ̀wọ̀n gbére Wo ojú àwọn afurasí tó fipá bá Uwaila, akẹ́kọ̀ọ́ Uniben sùn tí wọ́n tún pa á sínúu ṣọ́ọ̀ṣì Ìtàn ayé Ọba Seriki Abass ti Badagry, tó ní aya 128, ọmọ 144 Tunde Idiagbon, ọ̀gágun kògbagbẹ̀rẹ́ tó ní ẹ̀ẹ̀kan lóṣù ló yẹ kí ológun máa rẹ́rìín Ajọ naa sọ pe lẹyin ti aṣẹ aarẹ ba bẹrẹ iṣẹ, awọn onibaara yoo ni agbara lori iye ti ileeṣẹ amunawa n gba lọwọ wọn - eyi yoo si mu ki o ka ileeṣẹ DisCos naa lara lati tete pin mita fun gbogbo eeyan.
Pẹlu ifọwọsowọpọ awọn ọba ati alaga ijọba ibilẹ awọn gomina.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Aminat Abiodun: Òun ni Iyalode kẹtàlá, tó sì ń gun àkàsọ̀ láti ọdun 1971 8 Ọ̀pẹ̀̀ 2018 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 9 Ọ̀pẹ̀̀ 2018 Oríṣun àwòrán, Kola Carew Oloye Aminat Abiọdun ti wa saye, to si ti di ero ọrun bayii, amọ o yẹ ka mọ iru eeyan ti obinrin takun-takun yii jẹ nigba aye rẹ.
’’ “ẹnikẹta ni o ba ile kan jẹ, sugbon ti oun naa pa ara rẹ.
Ọkan lara awọn ọna naa ni eyi to sọ laipẹ lori awọn oniṣegun oyinbo ti wọn sa kuro ni Naijiria lasiko yii.
Èmi ni ọkùnrin náà tí orúkọ rẹ̀ ń jẹ́ Ìrìnkèrindò tí ń gbá ilé Alárìnkiri.
Ẹ yọ mí látìmọ́lé DSS, ó lòdì s'ẹ́tọ̀ọ́ mi- Ṣowore Ẹgbẹ́ òṣèlú AAC fi ọwọ́ òsì júwe ilé fún Ṣowore!
OLUWA Ọlọrun àwọn ọmọ ogun,yóo ti pẹ́ tó, tí o óo máa bínú sí aduraàwọn eniyan rẹ?
Alhaji Rají Mohammed tó jẹ alákoso ètò ẹ̀kọ́ àti kọmisọnà fún ètò ẹkọ́ tẹ́lẹ̀rí ní ìpínlẹ̀ Kwara ṣe àtúpalẹ̀ àwọn ohun tó n kóbá ètò ẹ̀kọ́ Nàìjíríà.
ẹni tí ó dá wa sí tí a fi wà láàyè,tí kò sì jẹ́ kí ẹsẹ̀ wa yẹ̀.
Naijiria lati lo anfaani to wa nikawọ won lorile ede yii, ni eyi ti yoo se mu
"Irọ nla ni pe awọn ọkunrin maa n ra dukia fun mi.
Ọlọ́paà Ọ̀ṣun: Ààbò wà fún ẹ̀mí àti dúkìá aráàlú
Alukoro ajọ EFCC, ọgbẹni Samin Amadin sọ fun BBC Yoruba pe Babachir Lawal ti dahun awọn ibeere ti o jọ mọ iwa ibajẹ nigbati o wa nipo ijọba.
Ará ilé ẹni ni ọ̀tá ẹni.
Àwon wònyí a máa mú onírúurú ohunèlò Ogun bí ìbon,òkò, àdá, idà, òbe abbl dání lo sí oko olè láti dáàbòbo ara won nítorí ìdágirì bí onílé bá jí àti láti le wón ìlèkùn.
Oríṣun àwòrán, others Àkọlé àwòrán, ọpọ ọja lo ṣofo si iṣẹlẹ yii Ileeṣẹ ọlọpaa fidi rẹ mu lẹ pe ko sẹni to ku ninu iṣẹlẹ naa, bakan naa awọn mẹrin ti wọn ṣeṣe ti n gba itọju nile iwosan.
pa kọ ́ lọ ́ , pa kọ ́ lọ ́ kọ ́ lọ ́ , v.
Zlatan sọ ninu orin naa pe Tacha ko ni pa'yan pẹlu oorun ara rẹ""."
Ọlọ́lá jù lọ Terry Waya ni Bàbá Terseer Kiddwaya tó ń kópa nínú BBNaija 2020 Wo ohun tí Adájọ́ sọ nípa ìgbẹ́jọ́ Wòlíì Sotitobire l'Ondo Ìgbésẹ̀ wo ní aláboyún lé gbé láti dẹ́kun ìjẹkújẹ nínú oyún?
Ninu ọrọ tiẹ, Mogaji ilu Ibadan, Alhaji Moshood Atẹrẹ sọ wi pe, enikeni ko ti i le sọ pato ibi ti ọrọ naa nlọ.
Meles tun tesiwaju pe  ọkọ  oju ofurufu ti Ethiopian ko ni pẹ maa gbe awọn  eniyan to din ni ẹ̀ẹ́dẹ́gbẹ̀ta lọ si olu-ilu Eritrean ti Asmara lọjọ kejidinlogun osu kéje    .
Lẹyìn tí gíwá fásitì yìí sì ti yẹ ọ̀rọ̀ náà wò tó sì fìdí rẹ̀ múlẹ̀ pé ó jẹ̀bi, ó ti pàṣẹ kí ọ̀jọ̀gbọ́n Akíndélé ó lọ rọọ́kún nílé dìgbà tí wọ́n yóò parí ẹ̀kúnrẹ́rẹ́ ìwádìí.
Wọ́n ti yíjú kúrò lọ́dọ̀ mi, wọ́n sì kẹ̀yìn sí mi.
 Àwọn wọ ̀ nyìí ni ojúlówó Ìjẹ ̀ bú-rẹ ́ mọ ní ìpìlẹ ̀.
Ọdún 1940 ni wọ́n ti ń sin ọ̀ọ̀nì ilé Delesolu ní Ìbàdàn
Ọna lati fẹhonu wọn han si isin igbeyawo kayeefi ọhun, lo mu kawọn ọdọ ilu Agba, to ri igbeyawo naa gẹgẹ bi eewọ dana sun ile ijọsin ti isin igbeyawo naa ti waye.
"Mo n pada lọ ni oṣu to n bọ, maa si pada wa ni oṣu Kẹta fun ayẹyẹ igbeyawo wa, ki emi ati ọkọ mi to maa lọ si America.
Ọba Ijipti kò lè jáde kúrò ní ilẹ̀ rẹ̀ mọ́, nítorí pé ọba Babiloni ti gba gbogbo ilẹ̀ ọba Ijipti láti odò Ijipti títí dé odò Yufurate.
Mo fẹ́ di obinrin to dára júlọ lágbàyé-Bobrisky Mo bu ọlọ́pàá jẹ nígbà tó fẹ́ yí mi lọ́rùn ní Mushin- Àáfà Fatai A ṣetán láti fìyà jẹ ọmọ ogun ti adé ìwà ìbàjẹ́ fídíò náà bá ṣímọ́ lórí- Iléeṣẹ́ ọmọ ogun Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Lagos King: Mátikú ọba tó lo lo ọdun mẹta lórí oyé latari rogbodiyan Eko Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 3 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 5 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Ìdí rèé tí BBC Yorùbá se fẹ́ mọ èrò àwọn aráàlú nípa ìmọ̀ràn yìí àti ipa tí yóò ní lóríi ìlera àwọn ọmọ̀ orílẹ̀èdè Nàíjíríà lápapọ̀.
Eeyan 54,905 ni apapọ ni wọn ti fara ko aarun Coronavirus, ti awọn 42,922 si ti ri iwosan gba lọwọ ajakalẹ arun ọhun.
lowo Olorun ati ijoba orile-ede Naijiria fun  atileyin won, eleyi ti o sokunfa idi ti mo fi
Ko ti i si ẹni to mọ orukọ awọn oloogbe naa tabi ibi ti wọn ti wa.
Ìgbà tí a bá ti ṣe ìwọ̀nyí tán èyí tí ó kù kò ní ju kí á dá ọjọ́ lílọ wa kẹ́ ẹ gbó kẹ́ẹ tọ́ o.
Cairo: Ilé oúnjẹ fáwọn Yorùbá ní Cairo, Egypt
Ni gbogbo agbaye ni ifẹhọnu han iku George Floyd ti waye, ti awọn eniyan si n pe fun atunto lori ajọ ọlọpaa lorilẹede Amerika.
Eeyan to le ni eeyan ọọdunrun ti Dokita Stella ti sọ pe oun tọju pẹlu Hydroxychloroquine ti ara wọn si ti ya.
Ile asofin binu s'awọn ologun Cameroun Awọn asofin Naijiria jiroro lori iba ọrẹrẹ Nigba to n gbe lori akiyesi naa, aarẹ ile asofin agba orilẹede Naijiria ni Ọrọ se pataki pupọ bẹẹni gbogbo kudiẹ-kudiẹ to n waye lori awọn ofin ati igbesẹ ijọba gbogbo wọnyii nilo amojuto."
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ìgbátí ìgbámú àná látọwọ́ sọ́jà obìnrin ti bá arákùnrin náà dé iléèwòsàn Oloye Harry Akande jẹ gbajumọ oniṣowo nile ati lẹyin odi Naijiria.
Awọn ọmọ ẹgbẹ naa wa lara awọn metalelogun t'awọn agbofinro ilẹ Spain mu l'agbegbe Catalonia lọdun 2015 pe wọn n se owo fifi eeyan s'owo ẹru ti wọn a sì tún ma ta oogun oloro to fi mọ ṣíṣe ayederu iwe irina fawọn eeyan.
Eyi je igba akoko ti egbe oselu alatako n gbegba oroke latigba ti ajo eleto idibo ti gbe esi akoko jade.
Irú ẹ̀mí burúkú báyìí kò lè jáde àfi nípa adura ati ààwẹ̀.
Ṣugbọn ẹ̀ṣẹ̀ yín ni ó fa ìyapa láàrin ẹ̀yin ati Ọlọrun yín,àìdára yín ni ó mú kí ó fojú pamọ́ fun yín,tí kò fi gbọ́ ẹ̀bẹ̀ yín.
Awọn yoku to jẹ ọmọ igbimọ naa niyi.
O fikun pe, baba ma n ran oun lọwọ nile idana.
Àwọn ẹ̀yà ara kọ̀ọ̀kan wà nínú ara wa tí iṣẹ́ wọn jẹ́ pípèsè àti dídarí àwọn ọmọ-ogun ara náà.
Ninu ọrọ rẹ, Oludari ile-isẹ naa,Umaru
Wo ọ̀nà láti gbógun ti àìsàn Ibà lásìkò yìí Ẹ wo àwọn gbajúmọ̀ òṣèré tíátà tó jogún eré ṣíṣe lọ́dọ̀ òbí wọn Coronavirus: Kíni àwọn àmì tuntun tó n fihàn?
Họnarebu Wasiu Olatunbosun ni kọmiṣọna fun eto iroyin.
Bẹẹ lo tun sọ pe, awọn ọmọ ogun ko gbe oku ẹnikankan kuro nibi iṣẹlẹ naa.
L'Ọjọbọ ọjọ kẹẹdọgbọn oṣu kẹfa ni Ajimọbi jade laye lẹni aadọrin ọdun.
Ko yẹ ki o pọju,wọn tun wọn si lo yẹ ki o jẹ.
 Ọmọ náà bẹ ̀ rẹ ̀ sí í ké , ó sì ń fa mọ ́ adé orí bàbá ìyá rẹ ̀ .
eto abo ti ẹkun naa n koju bayii.
ajo eleto aabo lati yago fun iwa aparo kan ga ju okan lọ ninu eto idibo to n
Gẹgẹ bi ọgbẹni Ibrahim Farinloye to jẹ agbẹnusọ ajọ to n risi iṣẹlẹ pajawiri ni Naijiria, NEMA lẹka iwọ oorun Guusu Naijiria ti ṣe sọ fun BBC .
Ogagun James Myam ninu atẹjade kan ti o fi sita loju opo Twitter, Iléeṣẹ́ ológun Nàìjíríà so pe ikọlu naa waye nigba ti awọn ọmọ ẹgbẹ ẹlẹsin naa gbegi dina awọn ọmọ ogun ti wọn n gbe ọta ati ohun ija lati Abuja lo si Kaduna.
"Ẹkọ yii na mi lowo gan, mi o si jere kankan nibẹ, mi o ba ma ti ṣe laalaa to bẹẹ lori rẹ.
Ọmọ ọdún mejila ni Manase nígbà tí ó jọba, ó sì wà lórí oyè ní Jerusalẹmu fún ọdún marundinlọgọta.
Nítorí pé n kò jẹ̀bi níwájú rẹ̀, bẹ́ẹ̀ ni n kò sì ṣe nǹkan burúkú sí ìwọ ọba.
Nígbà tí mo wo dígí náà dáadáa, bàbá mi bi mi ohun tí mo rí, mo sì sọ fún un.
Ọlọ́pàá: Ọmọ ìyá méjì gé orí ọmọ ọdún mẹ́wàá nítorí N200,000
  a-kéré-finú-sogbón "" ni oríkì ifá ."
Ẹgbẹ olukọni ya si meji ni fasiti Awolọwọ Akẹkọ kan ku,ileẹkọ jona ninu ija akẹkọ fasiti Modibbo Alukoro fásitì Ọbafẹ́mi Awólọ́wọ̀ ní Ìlú Ilé ifẹ̀, OAU, Ọ̀gbẹ́ni Abíọ́dún Ọláńrewájú n,i fásitì náà ti bẹ̀rẹ̀ ìwádìí lórí rẹ̀ tí wọ́n sì ti gbé ìgbìmọ̀ kan kalẹ̀ láti tú'ṣu dé ìsàlẹ̀ ìkòkò ọ̀rọ̀ náà.
Ó tún yípo lọ ní apá ìwọ̀ oòrùn, sí apá ìhà gúsù lọ sí ara àwọn òkè tí ó wà ní apá ìhà gúsù tí ó dojú kọ Beti Horoni, ó sì pin sí Kiriati Baali (tí wọ́n tún ń pè ní Kiriati Jearimu), ọ̀kan ninu àwọn ìlú ẹ̀yà Juda.
2bn) fun saa eto ẹkọ kan fawọn akẹkọ girama.
O kò gbọdọ̀ bá aya aládùúgbò rẹ lòpọ̀, kí o sì sọ ara rẹ di aláìmọ́ pẹlu rẹ̀.
Ninu ọrọ to ba BBC news Yoruba sọ lori ẹrs ibanisọrọ, Seriki awọn Fulani ni ipinlẹ Ọsun Alhaji Oluwatoyin Sulaeman ṣalaye pe ko si otitọ ninu iroyin naa.
Àkọlé àwòrán, Aarẹ Trump lọ ṣe abẹwo ẹ kare sawọn ọmọ ogun ilẹ Amrica ni Afghanistan.
YCE Crisis: Kunle Olajide ní áwọn tó déte yíyọ òun ní ákọ̀wé YCE kò lẹ́nu ńbẹ̀
Nínú àwọn lẹ́tà ọ̀hun ní àwọn míràn tún ni kí ààrẹ kọju ija si iṣẹ òhun òṣì nítori pé iṣẹ́ àti òsì ló n bí ìwà ìbájẹ àti àjẹbanu to àwọn ọmọ Naijiria.
Iṣẹ nọọsi, iyẹn olutọju alaisan ni ẹlẹṣọ n ṣe ki o to di elere itage.
Port Harcourt: Afurasí wà ní àhámọ́ ọlọ́pàá
OLUWA ní,“Ẹ lọ dúró ní oríta kí ẹ wo òréré,ẹ bèèrè àwọn ọ̀nà àtijọ́,níbi tí ọ̀nà dáradára wà, kí ẹ sì máa tọ̀ ọ́.
Báwo ní Barack Obama, Bill Gates, Elon Musk, Jeff Bezos ṣe lùgbádì àwọn gbájúẹ̀ orí ayélujára?
 Gomina ipinle Ogun Ibikunle Amosun lo soro yii lasiko ipolongo ibo aare  egbe All Progressives Congress APC to waye ni
Ọmọ-Eniyan dé, ó ń jẹ, ó ń mu.
Lo difa fun gbajugbaja oṣere tiata Yoruba, Eniola Badmus to ke gbajare si awọn eeyan to maa n bu ẹnu atẹ lu lori ayelujara pe o ti sanra ju.
Ko ti si aridaju boya wọn sanwo idoola lati fi gba awọn ọmọ yi pada.
OLUWA fi wọ́n lé àwọn ọmọ Juda lọ́wọ́, wọ́n sì ṣẹgun ẹgbaarun (10,000) ninu wọn ní Beseki.
Nígbà náà ni gbogbo àwọn wundia náà tají, wọ́n tún iná àtùpà wọn ṣe.
Lọwọlọwọ, Aarẹ orilẹede Naijiria, Muhammadu Buhari ni alaga ajọ Ecowas.
Bi ọpọlọpọ obi ṣe n pariwo pe bawo lọbọ ṣe ṣori ti inaki o ṣe to fi jẹ wi pe awọn akẹkọọ ileewe aladani ni yoo maa sanwo ayẹwo COVID-19 ki wọn to wọle pada sileewe.
Bí ẹ bá ti fẹ́ kí eniyan máa ṣe si yín, bẹ́ẹ̀ gan-an ni kí ẹ máa ṣe sí wọn.
Bẹẹ minista ti wọn ni Buhari fẹ fẹ wa ni Geneva nilẹ okeere lasiko yii.
Pilatu bá dá wọn lóhùn pé, “Ṣebí ẹ ní olùṣọ́.
Bó tilẹ̀ jẹ́ pé nínu ìtàn to gbé ìjọba Emir kalẹ̀ ní Kano láti ọ̀ọ̀rùndún kẹẹ̀dógún sẹ́yìn ní ó ni ọwọ́ ìja Jìhádìì àti jàgídíjàgan àwọn onirúuru jagunjagun nínú láti ọdun 1903, ìjọba Emir ní Kano ti rídi joko dáada láti ẹyin wá.
Funke Adesiyan: Gbajúgbajà òṣèré Yollywood di olùrànlọ́wọ́ aya ààrẹ, Aisha Buhari
Idà ni yóo pa Asiria, ṣugbọn kì í ṣe láti ọwọ́ eniyan;idà tí kò ní ọwọ́ eniyan ninu ni yóo pa á run.
 Mo nsọ nipa nkan ti mo ti foju ri titi di akoko yi, o si wu mi ko lọ fun saa mii gẹgẹ bii gomina, ti kii ba se ofin ti ko lee faaye gbaa.
Ti a ko ba gbagbe, ijọba apapọ ti gba lati bẹrẹ si ni san ẹgbẹrun lọna ọgbọn (30,000) gẹgẹ bi gbedeke owo osu tuntun fawọn osisẹ Naijiria.
Oríṣun àwòrán, Twitter/Emmanuel Amuneke Àkọlé àwòrán, Emmanuel Amuneke fakọyọ nilẹ okere Ikọ Taifa Stars orilẹede Tanzania ti agbabọọlu Naijiria tẹlẹ, Amuneke jẹ akọnimọọgba wọn pegede lati kopa ninu idije AFCON 2019 ti yoo waye lorilẹede Egypt lẹyin ti wọn pokọ iya fun Uganda pẹlu ami ayo mẹta sodo lọjọ Aiku.
Gege bi agbenusoro awon agbofinro Memphis lorile-ede Amerika, Louis Brownlee se so, arabinrin alaboyun kan ti awon agbesunmomi agbebon yinbon mo ninu oko ayokele Chevrolet Impala ti bimo pelu apa ibon lara omo naa si ile-iwosan Tennessee lopin ose yii.
Ṣugbọn Aṣipenasi sọ fún Daniẹli, pé, ẹ̀rù ń ba òun, kí ọba tí ó ṣètò jíjẹ ati mímu Daniẹli ati àwọn ẹlẹgbẹ́ rẹ̀ má baà lọ ṣe akiyesi pé Daniẹli rù ju àwọn ẹlẹgbẹ́ rẹ̀ lọ, kí òun má baà fi ẹ̀mí òun wéwu lọ́dọ̀ ọba.
Awon gomina ipinle ti fenuko pe awon ko lagbara lati san ju ogun  egberun naira lọ ti ijoba apapo si ni egberun merinlelogun ni awon lagbara lati san fun osise won.
Àkọlé àwòrán, Aare Buhari yoo ni anfani lati dije lẹẹkansii gégé bii aarẹ Naijiria Buhari ni yoo dije dupò pẹlu ẹnikẹni ti ẹgbẹ oṣelu PDP bá fa kalẹ atawọn ẹgbẹ oṣelu to ba kù ninu ẹgbe mokanlelọgọrun ti ajọ eleto idibo INEC kede.
"Alaga tẹlẹ fun ajọ INEC naa ni ""o dabi ẹni pe a ko mu ipe wa gẹgẹ bii ẹni to ni imọ ati ẹkọ to yẹ ni ọkunkundun, emi ko si mọ boya awọn eeyan to ti yipada ni mo n ba sọrọ abi mo kan n sọ isọkusọ ni"" Jega wa fikun pe orilẹede Naijiria ko ni bọ lọwọ awọn isoro ọrọ aje, aifararọ eto aabo ati aisi idagbasoke to yẹ, ti a ko ba sa ipa wa bo ti yẹ lati yan asaaju to kaato si ipo lati maa dari wa."
lati gba egbe PDP laaye lati se ayẹwo atẹ ayelujara ti ajo INEC lo lasiko eto
Pupọ ninu awon asofin naa lo ti faramo pe ki atunse waye nipa ofin naa saaju
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 2019: Wo fídíò bí wọ́n ṣe sọ nǹkan lu àwọn adarí APC l'Abẹokuta Tori ti awọn ẹgbẹ oṣelu ko fẹ ki ibo awọn sofo, pupọ ninu wọn ti n fi ipolongo sita loju opo Twitter ati ni aye ipolongo ibo fun awọn ọmọ ẹgbẹ wọn nipa ika to yẹ lati fi dibo.
Ṣé ìwọ mọ Bukọla Saraki dáadáa?
"Ooni Ife fohùn ránṣẹ́ sí Boris Johnson, ó ní, ""bóo bá joun gbé, má johùn gbé"" Israel Adebajo: Ìlúmọ̀ọ́ká oníṣòwò tó fi òkò Stationery Stores pa ẹyẹ púpọ̀ Ìjọba ti bẹ̀rẹ̀ sí báwọn tó gbé òṣìṣẹ́ aláàánú mẹ́fà sọ̀rọ̀- Garba Shehu Ẹni orí yọ, ó dilé!"
ṣugbọn ọ̀rọ̀ Oluwa yóo wà títí lae.
nirowo-rose ti o han kedere, ti ko si ni ni kolofin ninu lodun yii.
Wọn wa a fun ọpọ igba pẹlu igbagbọ pe wọn yoo ri lọjọ kan nitori ẹni to ku ati ẹni to nu a pade lọjọ kan, amọ nigba to ṣe diẹ, wọn gba fun Ọlọrun.
Bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé mo ti jẹ ẹ̀yin ọmọ Juda níyà tẹ́lẹ̀, n kò ní jẹ yín níyà mọ́.
Wo orúkọ àwọn ẹ̀yà ara rẹ̀ ní èdé Yorùbá Andrew Haruna: So-bàtà tó di ọ̀jọ̀gbọ́n fásitì tó tún jẹ́ ọ̀gá àgbà pátá (V.
" O wa gbadura pe ki Alaafin tubọ pẹ laye ninu ilera to peye.
Gómìnà Obaseki ní pásítọ̀ Adeboye sọ àsọtẹ́lẹ̀ pé òun yóò wọlé ìbò gómìnà Edo lẹ́ẹ̀kejì Oríṣun àwòrán, Facebook/Godwin Obaseki Gomina ipinlẹ Edo, Godwin Obaseki ti ṣalaye pe, oludari ijọ Redeemed Christian Church of God, Enoch Adeboye gbadura foun, o si tun sọ asọtẹlẹ pe oun yoo wọle ibo gomina ipinlẹ Edo fun saa keji.
O ni lowurọ ọjọ Aiku ti wọn wa ba awọn loko, awọn ọdaran yii gbe ọrẹ oun ati awọn eeyan miran to n ṣiṣẹ loko lọjọ naa.
Gómìnà ní sáájú àsìkò yìí ní gbogbo ọmọ ìgbìmọ̀ aláṣẹ ti ṣe àyẹ̀wò ààrùn coronavirus súgbọ̀n mẹta nínú wọ́n ni ayẹwò fi idí rẹ̀ múlẹ̀ pé ó ti ni ààrùn náà nígbà tí àyẹ̀wò àwọn méjì kò sì dájú bóyá wọ́n ni tàbi wọ́n kò ni ààrùn.
Ọpọlọpọ eeyan to ri bi i temi lo sọ pe awọn ko fi bẹ ẹ ni ipaya lasiko ajakalẹ aarun yii.
”Wọ́n dáná sun gbogbo ilé ìsìn Ọlọrun tí ó wà ní ilẹ̀ náà.
 Ọ ̀ pọ ̀ àwọn lámèyítọ ́ ló sọ wípé Àbẹ ̀ ní sọ ̀ rọ ̀ rẹ ̀ pẹ ̀ lú  Àìmọkan "" ."
akọkọ fun orilẹede mejeeji ohun .
O han kedere pe awon eniyan
Nítorí náà, máa pa gbogbo wọn mọ́ tọkàntọkàn.
Ninu ọrọ rẹ, Olukọlu fikun pe awọn akẹkọ naa ti jẹwọ pe ọmọ ẹgbẹ okunkun Ẹyẹ ni awọn, tawọn si ti n foju awọn eeyan akẹkọ ẹlẹgbẹ awọn ati araalu danrin.
O ni ohun to ba mu ki wọn ko SARS nlẹ, ijọba gbọdọ fopin si ajọ to n gbogun ti iwa ibajẹ, EFCC naa.
Ajọ to n ri si ètò ẹkọ ló sọ èyí pé àṣà kí à máa fi Nkan gbigbiona pọn àyà ọmọ obinrin to ṣẹ̀ṣẹ̀ ń gúnmú láti maa yọri àti kí ó maa ba wu ọkunrin kii ṣe ohun to dára.
Kò ní sí ayẹyẹ ọdún Ojúde Oba lọ́dún yìí- Awujale ilẹ̀ Ijebu Mi ò tíì gba ìwé ìfitónilétí pé wọ́n fẹ́ yọ mí nípò igbákejì gómìnà ìpínlẹ̀ Ondo- Agboola Ajayi Fọwọ́ kan obìnrin lọ́nà àìtọ́, kí o rẹ́wọ̀n ọe- Àwọn aṣòfin yarí Ilé aṣofin Ondo fọwọ́ òsì júwe ilé fún aṣòfin mẹ́ta pé wọ́n tàpá sí òfin ilé Ipa IS dinku lorilẹ-ede naa lẹyin oṣu Kejila, ọdun 2016, ti agbara bọ mọ lowo niluu Sirte.
Bó bá rí bẹ́ẹ̀, ẹ̀yin náà ẹ múra, kí ẹ parí ohun tí àwọn baba yín ṣe kù!
Awọn iroyin ti ẹ le nifẹ si Lẹ́yìn ọdún mẹ́ta l'ẹ̀wọ̀n akọrin ẹ̀mi gbẹ̀mí ará rẹ̀ látìmọ́lé Ìjọba Ọṣun ti dásí ìjà láàrin Oluwo àti Agbowu 'Mi ò fẹ́ gbé àrùn Coronavirus lọ sí Áfíríkà' Ilé ìgbìmọ̀ aṣofin ti bẹ̀rẹ̀ òfin tí yóò máa mú àwọn olùkọ́ fásitì tó ń bèrè fún ìbálòpọ̀ Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Bakan naa, ni ogagun  Otiki tun dupe lowo awon egbe oju-ni-
Abadofin naa n wa ki abojuto gbogbo orisun omi yala loke eepẹ ni tabi labẹ ilẹ ko wa labẹ akoso ijọba apapọ.
Bí nǹkan oṣù rẹ bá dáwọ́ dúró, àwọn ohun tí yóò ṣẹlẹ̀ sí ọ rèé Adájọ́ Dogo tí wọ́n jí gbé ti gba ìtúsílẹ̀ Ẹlẹ́wọ̀n tẹ́lẹ̀ gboyè ìmọ̀ ìjìnlẹ̀ méjì lọ́gbà ẹ̀wọ̀n Kíni ìdí ti àwọn ọmọ ogun fi n ṣọ́ àwọn Imaam ni Mecca?
Aare Buhari wa salaye pe oun fojusona lati tun mu ibasepo ti o
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Yemi Osinbajo: Ènìyàn 108 lò kú ní ìsẹ̀lẹ̀ omíyalé ní Kogi 17 Owewe 2018 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 25 Owewe 2018 Ijọba apaapọ orilẹede Naijiria ni wọn yoo se iranwọ fun awọn agbegbe ti omiyale ti ṣọsẹ ni ipinlẹ Kogi to wa ni apa aarin gbungun ariwa orilẹede Naijiria.
Ipade yii ni ẹlẹẹkẹta iru rẹ fun ipele kẹrindinlogun ninu idije Champions League laarin Chelsea ati Barcelona Ẹgbẹ agbabọọlu Chelsea ti ni ilọsiwaju ninu idije yii kọja ipele akọkọ komẹsẹ o yọ fun saa marun to kọja, ti wọn si f'idirẹmi lẹẹmeji ni ipele yii.
Àwọn olóṣèlú Nàìjíríà márùn ùn tó sọ̀rọ̀ tí ará ìlú fà ìbínú yọ Gómìnà Sanwo-Olu dẹ okùn ìséde l'Eko, ó gbé ìlànà tuntun jáde Ọmọ ọdún mọ́kànlá tó bá wọn fọ́ àgọ́ ọlọ́pàá, wọ gàù ọlọ́pàá ní Edo Eyitayo Jegede gbé Akeredolu lọ síwájú ìgbìmọ̀ tó n gbọ́ ẹ̀sùn ìdìbò Ni ti iyatọ to wa ninu idiyele atijọ ati tuntun yii, Ofulue sọ pe awọn eeyan yoo maa san owo ina gẹgẹ bi wọn ṣe n lo ina si.
Kò sí ohunkohun tí a kọ si yín tí ẹ kò lè kà kí ó ye yín.
"Ni temi, mi o ro pe mo le forijin awọn ọmọ ikọ Boko haram fun nkan ti wọn foju mi ri"" Ètò ìsìnkú arẹwà Ibidunni Ighodalo ń lọ lọ́wọ́ Kí ló dé tí Aàrẹ Buhari kìí fí í dá sí aáwò àwọn ọmọ ẹgbé APC?"
Kó igi kedari, sipirẹsi ati aligumu ranṣẹ sí mi láti Lẹbanoni.
Tó fi mú Adébọ́lá Àkànjí mi lọ
Arun Ẹ̀yi yii ni ajọ UN kede pe o maa n ran ẹlomiran, eyi to si lee se akoba fun ilera agọ ara, ti yoo si nipa lori ọpọlọ ati ọna ọfun.
Ọ̀rọ̀ náà wá di eniyan, ó ń gbé ààrin wa, a rí ògo rẹ̀, ògo bíi ti Ọmọ bíbí kan ṣoṣo tí ó ti ọ̀dọ̀ Baba wá, tí ó kún fún oore-ọ̀fẹ́ ati òtítọ́.
Asa jáde láyé, wọ́n sì sin ín sí ibojì àwọn ọba ní ìlú Dafidi.
Ìlú àwọn ọmọ Kohati yòókù jẹ́ mẹ́wàá pẹlu àwọn pápá ìdaran tí ó wà ní àyíká wọn.
Àlàyé rèé lórí ìdí tí mo fi lọ sílé Tinubu - Rashidi Ladoja ‘Sim Card’ títà àti ìforúkọsílẹ̀ rẹ̀ dèèwọ̀ ní Nàíjíríà - NCC Ẹ̀yin tí ẹ máa ń bú àwon tó sanra ni ẹ ń jẹ́ kí wọ́n ronú pa ara wọn - Eniola Badmus Ṣé lóòtọ́ ni tírélà ti gba ààrín Ronke Odusanya àti bàbá ọmọ rẹ̀, Jago?
 Ó kú ní 1946 níbi ti ó ti n se kànpéè .
Kaini, Gibea, ati Timna, gbogbo ìlú ati ìletò wọn jẹ́ mẹ́wàá.
Isele yii waye ni asale ojo Abameta si owurọ ojo Aiku ,nigba ti iroyin kan iko omo oogun ofurufu pe iko olote ti wo ilu Gashigar lati kolu won.
Lagos-Ibadan Train: Iléeṣẹ́ Rélùwéè ní ìgbà 16 ní àwọn ọkọ̀ ojú irin náà yóò máa rìn lójúmọ́
Amọ Ọga agba ileeṣẹ ọlọpaa Lahore sọ ni ọjọ keji ti iṣẹlẹ naa waye obinrin naa ni ẹbi lori iṣẹlẹ naa.
Bakan naa ni ajọ NDDC ni awọn gbagbọ wi pe iwadii ti wọn n ṣe naa yoo mu igba ọtun de ba ọjọ iwaju ajọ NDDC.
O ni Ronke beere fun ọpọlọpọ miliọnu Naira lọwọ Jago, lati ṣe ayẹyẹ ọjọ ibi ọdun kan ọmọ wọn.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Edo State House of Assembly: Obaseki ní Oshiomole fẹ́ fipá gbàjọba lọ́wọ́ òun 13 Bélú 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 6 Ògún 2020 Gẹgẹ bi ara igbesẹ ki ẹnikẹni ma joko ṣe ohunkohun ni ile aṣofin ipinlẹ Edo, gomina ipinlẹ naa, Godwin Obaseki ti paṣẹ ki wọn lọ yọ awọn orule ile naa igbimọ aṣofin naa lẹyin ti gomina ọhun atawọn agbofinro to fẹ fi tipa gbe ilẹkun ile nla naa ti pa ti gbe'na woju ara wọn.
Iléeṣẹ́ epo rọ̀bì ná ₦116m lórí báírò, ìwé ìkọ̀wé, àwọn aṣòfin fìka hánu Wo oríṣìí àrùn márùn ún tí ìgbéyàwó láàrin ìbátan si ìbátan máa ń fà Sanwo-Olu, El-Rufai fara pamọ́ torí COVID-19 lẹ́ẹ̀kejì Ìdí rèé tí mo fi yan ikọ̀ PMS rọ́pò NURTW nípìnlẹ̀ Oyo - Seyi Makinde Ileeṣẹ ọlọpaa ni ọpọ awọn akẹkọọ lo sa asala fun ẹmi wọn nigba tawọn kọlọnbiti ẹda ọhun de ọgba ileewe wọn.
pẹlu ọkàn kan ati pẹlu òdodoníwájú rẹ̀ ní gbogbo ọjọ́ ayé wa.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Surrogate: Ibi táwọn kan ti fẹ́ yọ oyún, ni Judith ti bẹ̀ wọ́n fún pàsípàrọ̀ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Surrogate: Ibi táwọn kan ti fẹ́ yọ oyún, ni Judith ti bẹ̀ wọ́n fún pàsípàrọ̀ 14 Agẹmo 2020 Ẹ̀ẹ̀mẹ́jọ ní oyún walẹ̀ lárá Akinwumi Judith kó tó di ìyá ìbejì, àmọ́ ohun toju rẹ ri ko to dohun, o kọja ohun to yẹ kẹni ọjọ ori rẹ ri.
Àṣeyọrí alailẹgbẹ yìí ló ṣe iwuri fáwọn òbí rẹ láti jẹ ko tẹsiwaju lẹ́nu ẹ̀kọ́ rẹ lọ sókè òkun lọ́dún 1951, láti lọ kọ ẹ̀kọ́ ìmọ̀ òfin nílùú Ọba United Kingdom (UK), to sì yege ni ọdun 1955.
Nígbà tí obinrin náà gbọ́ nípa Jesu, ó gba ààrin àwọn eniyan dé ẹ̀yìn rẹ̀, ó bá fi ọwọ́ kan aṣọ rẹ̀, 
"Oríṣun àwòrán, Getty Images Gẹgẹ bi awọn mejeeji ti wi,"" Bi o tilẹ jẹ pe lọpọ igba ni Ọbasanjọ maa n tako Atiku, sugbọn ko si ohun to buru to ba pinnu lati yi ero rẹ pada nipa Atiku, a sa n pa ọna oko da, anbọsin ọna ẹnu."
Oríṣun àwòrán, Adejare Taofeek Àkọlé àwòrán, 'Ọṣun kọ idajọ ti wọn fi owo ra.
Ìkìlọ̀: ìròyìn yìí ní àwọn àwòrán tí ó ń ṣe àfihàn ikú àti  ipá.
Jọ̀wọ́ yẹ̀ wọ́n wò, kí o mọ ẹni tí ó ni èdìdì yìí pẹlu okùn rẹ̀, ati ọ̀pá yìí.
Ṣaaju ni ileeṣẹ ọlọpaa ipinlẹ Oyo sọ fun BBC pe awọn ko yin ibọn lu awọn oluwọde ati wi pe afẹfẹ gaasi tajutaju lasan ni awọn yin lu awọn to yabo agọ ọlọpaa .
O kuro ninu iṣẹ ologun, lo fi di olorin Fuji patapata, to si da ẹgbẹ akọrin rẹ 'Supreme Fuji Commanders' silẹ.
Jakọbu bá ń tọ́jú agbo ẹran Labani tí ó kù.
Mo fẹ́ kí a máa bá ìtàn náà lọ.
Iroyin sọ pe, ẹni ti wọn fi ẹsun ifipabanilopọ kan, deede wọ yaara Juanita laarin oru.
Awọn agbofinro orilẹ-ede India ni awọn ko tii le kede pe ọlọwọ idan yii ti ku laijẹ pe wọn ri oku rẹ yọ ninu odo to wọ lọ.
Ó wá mú baba ati ìyá ọmọ náà pẹlu àwọn ọmọ-ẹ̀yìn tí ó wà pẹlu rẹ̀, ó wọ yàrá tí ọmọde náà wà lọ.
Aisi ina ọba sokunfa bi ọpọ ẹniyan ti se'n na ọwọ to po lori rira ẹpo si ẹrọ amunawa lọpo igba.
Wọn parọwa si ijọba ati awọn agbofinro lati fi oju ṣebi han.
Wọ́n fẹ́ ọkọ láàrin ẹ̀yà Manase ọmọ Josẹfu, ilẹ̀-ìní wọn sì dúró ninu ẹ̀yà baba wọn.
Tí ìjọba kó bá dẹ́kun ìpànìyàn ní Gúúṣù Kaduna, aráàlú yóò jà fúnra wọn - CAN CAN ní àwọn ènìyàn yóò jà fún ara wọn tí ìjọba kó bá paná ìṣekúpani ní Gúúṣù Kaduna Ẹgbẹ ọmọlẹyin Kristi lorilẹede Naijiria, CAN ti fesi si iṣekupani ojoojumọ to n waye ni Guusu ipinlẹ Kaduna, ti agbegbe ti awọn ọmọlẹyin Kristi pọ si julọ.
Mo ní, “Èwo ninu wọn ló wà ninu ìgbìmọ̀ OLUWA tí ó ti ṣe akiyesi tí ó sì gbọ́ ọ̀rọ̀ rẹ̀?
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ondo: Gómìnà Akeredolu fa ìjọba lé igbákejì rẹ̀ lọ́wọ́ 19 Ògún 2019 Oríṣun àwòrán, @RotimiAkeredolu Ijọba ipinlẹ Ondo ti ni gomina tuntun.
Bí Ọgbọ́n kan kò bá parí iṣẹ́, Ọgbọ́n mìíràn yóó gbè é lẹ́yìn.
Funke Akindele ti di ìyábejì Ajọ LASEMA sọ̀rọ̀ lórí okùnfà iná to jó l'Abule Ẹgba.
"Oríṣun àwòrán, Eti-Inyene Godwin @sirinyenephotography Àkọlé àwòrán, Ẹgbẹ MOSOP ko si ootọ ninu ọrọ si Aarẹ Buhari to sọ laipẹ yii pe isẹ afọmọ agbegbe Ogoni ""nlọ ni sẹpẹsẹpẹ."
How to make bread Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Orílẹ̀-èdè tí kò bá ní ìfihàn láti ọ̀run, yóo dàrú,ṣugbọn ayọ̀ ń bẹ fún ẹni tí ń pa òfin mọ́.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù PDP: Ọjọ́rú la máa mọ̀ bóyá Jonathan ṣelòdì sí PDP ní ìdìbò Bayelsa 19 Bélú 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 20 Bélú 2019 Oríṣun àwòrán, Alamy Àkọlé àwòrán, Àwọn adarí ẹgbẹ́ òsèlú APC se àbẹ̀wò sí Ààrẹ tẹ́lẹ̀rí, Goodluck Jonathan ní ìdìbò sípò gómìnà ní Bayelsa.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Sotitobire church news: Ilé ẹjọ́ sún ìgbẹ́jọ́ pásítọ̀ ìjọ Sotitobire sí ọjọ kẹrinla, oṣu Kẹsàn án 29 Òkùdu 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 22 Agẹmo 2020 Ile ẹjọ giga to kalẹ si ilu Akure ti sun igbẹjọ pasitọ ijọ Sotitobire Miracle Centre, Alfa Babatunde Sotitobire si ọjọ kẹrinla, oṣu Kẹsan an ọdun 2020.
Ọmọ ogún ọdún kan tún di àwátì nílùú Akurẹ nípìnlẹ́ Ondo- PPRO Bayìí ni àwọn ọlọpàá Akure ṣe ko àwọn ará ìlú ti o ji ẹrù ni sọọsi Sotitobirẹ Tápà sí ìlànà tuntun CBN kí o fí owó ìtanràn ₦2m gbára Wo ọ̀rọ̀ ìkíni kú ọdún Keresi tí Sowore fi ránṣẹ́ lẹ́yìn ìtúsílẹ̀ rẹ̀ Fayemi to fi ikede naa sita lati ọwọ Akọwe ikede Agba fun un, Yinka Oyebode, O rọ awọn ọmọ Naijiria lati fi ifẹ ba ara wọn gbe lai fi ti ẹ̀sìn ṣe.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Lílo òógùn apakòkòrò fún oúnjẹ l'éwu Ṣaaju ni ajọ to n mojuto ipese ounjẹ ati oogun lilo ni Naijiria, NAFDAC, kilọ fun awọn ọmọ Naijiria lati yago fun awọn ounjẹ ti wọn ba fi kẹmika 'sniper' ṣe lọ́jọ̀.
O ni awọn ilana yii di dandan ki ile iwe to ku le di ṣiṣi fun awọn akẹkọọ to ku lati bẹrẹ kilaasi wọn pada.
Tabi Ki o jẹ pe awọn aṣiri ọrọ miran ti tu sita, ti o si nilo ki wọn wọgile ẹjọ akọkọ lati pe ẹjọ tuntun lodi si Woodberry.
Obinrin mẹtalelọgọrin ni Abikẹ Dabiri ni o wa ninu wọn.
Ṣùgbọ́n bí ó ti pàṣẹ náà tán ni ọkùnrin yìí tọrọ gáfárà lọ́wọ́ àwọn ẹranko wọn-ọnnì wí pé wọ́n fún òun láyè kí òun sọ ti ẹnu òun, wọ́n sì gbà bẹ́ẹ̀ fún un.
Ninu ọrọ tirẹ, Odinga pe fun ẹyọnu awọn eniyan lati se aforiji fun ara wọn, ki wọn si jẹ ki alaafia o jọba laarin awọn ọmọ ile naa, gẹgẹbi o se pe aarẹ Kenyatta ni ibatan oun.
Gẹgẹ bi a ṣe gbọ, agogo marun irọlẹ ọjọbọ ni iroyin naa gbe pe yoo gbera kuro ni orilẹede India.
Àwọn nǹkan tí obìnrin lè ṣe pẹ̀lú olólùfẹ́ oníwà ipá lásìkò ìgbélé Coronavirus yìí Ìtàn tó rọ̀ mọ́ òwe ‘aṣọ kò bá Ọ́mọ́yẹ mọ́.
Àwa náà rí i pé, títí di òní olónìí, gbogbo ẹ̀dá ayé ni wọ́n ń jẹ̀rora, tí wọ́n sì ń rọbí bí aboyún.
#Queen Dihya: Obinrin tó gbógun tàwọn agbésùnmọ̀mí ni Algeria Ṣé ìjọba Naijiria lè jọ̀wọ́ ìdajì ipò mínísítà fàwọn obìnrin?
" Lẹyin naa lo ni ki awọn eeyan ma ṣe kọbi ara si fidio ọhun.
Ó bá wí fún OLUWA pé, “Ohun tí mo ṣe yìí burú gan-an, ẹ̀ṣẹ̀ ńlá gbáà ni.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù International Champions Cup: Kane fi góòlù àràmọ̀ndà kọ ojú Ronaldo s'óòrùn alẹ́ 21 Agẹmo 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Ẹlẹsẹ ayo ẹgbẹ agbabọọlu Tottenham, Harry Kane gba goolu aramọnda sawọn Juventus ninu idije International Champions Cup ti wọn fi n gbaradi fun saa bọọlu to n bọ lorilẹede Singapore lọjọ Aiku.
idà ni kí ẹ fi pa àwọn tí wọn ń gbé ìlú náà.
Hajj 2020: Yàtọ̀ sí covid-19, wo ìgbà mẹ́wàá míì táwọn mùsùlùmí kò lè ṣiṣẹ́ Hajj ní Mecca
A fẹ́ yọ ààrẹ ẹgbẹ́ Yorùbá YCE nípò torí àwọn ìwà tí kò bójúmu"" Erica gungi rékọjá ewé pẹ̀lú ìwà tó hù lálẹ́ ọjọ Satide - Ọmọ Nàíjíríà faraya Wo àànfàní ‘Masturbation’, fífún ara rẹ̀ ní adùn ìbálòpọ̀ Iroyin ni apa ibi to ti farapa wa lori rẹ, bakan naa ni oju ibi ti wọn ṣa a ladaa ṣi wa lara rẹ lẹyin ti wọn wu oku rẹ tan."
”Jehu dáhùn, ó ní, “Bí ó bá rí bẹ́ẹ̀, fún mi ní ọwọ́ rẹ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ikọlu Daradaran: Ibẹru mu awọn eniyan n'ipinlẹ Ogun 29 Sẹ́rẹ́ 2018 Oríṣun àwòrán, AFP Àkọlé àwòrán, Naijiria ti n koju ipaniyan ati ipafara awọn afurasi Fulani darandaran fun igba die Awọn ọlọpa ipinlẹ Ogun n rọ awọn olugbe ipinlẹ naa lati dẹkun ibẹru-boju ati ipalara pẹlu ireti ikọlu awọn Fulani darandaran gẹgẹbi iroyin naa se ruyọ lopin ọsẹ ti o kọja nilu Abẹokuta.
Awa ko mo nipa ohun ton sele Agbẹnuso fẹ́gbẹ́ APC nipinle Ekiti, Ogbeni Taiwo Olatunbosun ninu iforowanilenuwo pẹlu ile ise BBC so pe, awọn ko lowo si ohun to sele.
Mo fi OLUWA alààyè tí ó fún Israẹli ní ìṣẹ́gun búra pé, pípa ni a óo pa ẹni tí ó bá jẹ̀bi ọ̀rọ̀ yìí, kì báà jẹ́ Jonatani ọmọ mi.
Mohammed Bello Adoke ni Minisita feto idajọ labẹ ijọba Goodluck Jonathan laarin ọdun 2010 si 2015.
Gígùn rẹ̀ jẹ́ ogún igbọnwọ, pákó kedari ni wọn fi gé e láti òkè dé ilẹ̀.
Alukoro ẹgbẹ ọmọ bibi ilu Offa, Maruf Olalekan Ajenifuja to fidi ọrọ yi mulẹ fun BBC ni awọn ko san owo itanran kankan fun awọn ajinigbe ki wọn to tu wọn silẹ.
Bakan naa ni wọn ni awọn fẹ ri ẹrọ akaworan silẹ CCTV lati ọdọ ileeṣẹ naa, eleyi ti yoo tọka si bi arakunrin naa ti ṣe ṣagbako iku lọjọ Aje.
EU kan sáárá sí ájọ INEC lórí ìdìbò Ọ̀sun Sunny Ade ń se ọjọ́ ìbí, Obey kí i kú oríire Ilé ìfowópamọ́ Skye wọ gàù, CBN gbẹ́sẹ̀ le Ra ibo l‘Ọ́sun, ko ru'gi oyin - INEC Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Osun Election 2018: Aráàlú ní àwọn kò fẹ́ ìjọba elébi mọ́ Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Nítorí náà ni OLUWA ṣe rán wolii Hagai sí wọn ó ní, 
Diẹ lara awọn to ta julọ ni a ṣakojọpọ rẹ yii lai nii fi ṣe pe bayii ni wọn ṣe dùn tó.
Àkásílẹ̀ àjọsọ ọ̀rọ̀ láàárín akẹ́kọ́bìnrin ọ̀hún àti ọ̀jọ̀gbọ́n Richard Akindele pẹ̀lú ẹ̀rọ ìbánisọ̀rọ̀ lori bí ọ̀jọ̀gbọ́n náà ṣe ń bèèrè fún ìbálòpọ̀ lọ́wọ́ akẹ́kọ́bìnrin náà ti di èròyà wá wòó lóríi ìkànnì ayélujára.
Standby): Theophilus Afelokhai (Enyimba FC); Bryan Idowu (Lokomotiv Moscow,
Amosi ní:“OLUWA bú ramúramù lórí Òkè Sioni,ó fọhùn ní Jerusalẹmu;àwọn pápá tútù rọ,ewéko tútù orí òkè Kamẹli sì rẹ̀.
Lara awọn idi ti igbẹkẹle awọn eeyan fi n lọ silẹ ni bi ọwọja aisan bẹẹ ba ti lọlẹ; ọpọ eeyan ni kii ri idi kan pato ti wọn fi lee gba a.
Ilu Abeokuta ni ipinlẹ Ogun lo maa n gbalejo awọn aṣoju ati akopa lati orilẹede bii mẹtalelogun kaakiri ilẹ Afirika.
pe, mo ni okun lati lọ si gbogbo ipinlẹ ati Ilu Abuja lorile ede yii, ni eyi ti
Nígbà tí ọ̀gá rẹ̀ gbọ́ ọ̀rọ̀ tí iyawo rẹ̀ sọ fún un pé, “Bí ẹrú rẹ ti ṣe sí mi nìyí” inú bí i gidigidi, 
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Àsìkò Amojúẹ̀rọ Seyi ni ló fi wọlé l'Oyo, kìí ṣe àsìkò èmi Omobolanle' Ọpọlọpọ eniyan lo ri idibo naa gẹgẹ bi ẹni yii ti ko si ẹni to le sọ bi esi idibo naa se ma a ri.
Yatọ si ọrọ oúnje, ijọba ipinlẹ Eko tun seto ẹ̀kọ́ kikọ lori redio ati tẹlifiṣan fun awọn akẹ́kọ̀ọ́ lasiko igbele naa.
Ajọ to n ri si ere bọọlu ni Naijiria naa sọrọ loju opo Twitter wọn pe Super Falcons yoo jẹwọ orukọ wọn fun South Korea lọsan oni.
Coronavirus: Àìsàn yíì ti ràn dé Amẹrika, Thialand àti South Korea
 ilẹ ̀ rẹ ̀ ní bodè mọ ́ benin ní apá ìwọ ̀ òrùn , nijẹr ní apá àríwá , tshad àti kamẹróòn ní apá ìlàòrùn àti Òkun atlantiki ni apá gúúsù .
Wọ́n sì kó àwọn abọ́ kéékèèké, àwọn àwo ìfọnná, ati àwọn àwokòtò; àwọn ìkòkò, àwọn ọ̀pá fìtílà, ati àwọn àwo turari, ati àwọn abọ́ tí wọ́n fi ń ta ohun mímu sílẹ̀.
Awọn ọmọ ẹgbẹ Taliban tẹlẹ lo wa ninu ẹgbẹ Wilayat Khorasan.
Ninu atẹjade kan, adari ile isẹ BBC to n bojuto eto iroyin kaakiri agbaye, BBC World Service, Jamie Angus sọ wipe, Shah jẹ akọroyin ti awọn eniyan buyi fun, nitori o gbajugbaja, o si mọ isẹ rẹ ni isẹ Ọga agba ile isẹ naa ati awon osisẹ kẹdun pẹlu ẹbi, ara ati ọrẹ akọroyin to papoda naa, wọn si sọ wipe awọn yoo sa ipa wọn lati gbaruku ti awọn idile akọroyin naa lasiko yii.
Eyín ọ̀ọ́kán mi ni Barakat tí wọ́n pa lẹ́yìn tí wọ́n fipá bá a lòpọ̀- Ìyá Barakat Ní Ọjọ́ọ̀rú nìkan, ènìyàn 348 ló lùgbàdì àrùn Coronavirus ní Naijiria IGP ti jọ̀wọ́ Hamisu Wadume fún aádájọ́ àgbà Nàìjíríà O ni bio tilẹ jẹpe awọn oṣiṣẹ eto ilẹra ko fi ami kankan han pe wọn ni arun Coronavirus, o pọn dandan ki wọn si ma a gba itọju.
Salah ko beṣu bẹgba, niṣe lo gba pẹnariti naa wọ le, eleyi to mu Liverpool siwaju pẹlu ami ayo meji sodo.
Super Falcons fagbahan akegbe won lati orile-ede Cameroon pelu boolu agbesile gba(Penalty shoot-out), ifesewonse ti o pari ami ayo merin si meji(4-2).
Ó rí agbowó-odè kan tí ó ń jẹ́ Lefi tí ó jókòó níbi tí ó ti ń gba owó-odè.
Wọ́n wá láti ọ̀dọ̀ àwọn olórí alufaa ati àwọn amòfin ati àwọn àgbà.
Ẹ níláti jẹ gbogbo rẹ̀ tán ní ọjọ́ kan náà, kò gbọdọ̀ kù di òwúrọ̀ ọjọ́ keji.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù UN gbé mílíọ́nù méjì dọ́là kalẹ̀ fún ìtọ́jú onígbáméjì 25 Èbibi 2018 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 26 Èbibi 2018 Oríṣun àwòrán, @UN_Nigeria Àkọlé àwòrán, Àjàkálẹ̀ ààrùn onígbáméjì ti di kálé n káko láwọn ìpínlẹ̀ bíi Borno, Yobe àti Adamawa Ajọ iṣọkan agbaye ti ya miliọnu meji dọla owo ilẹ Amẹrika sọtọ lati ṣe agbatẹru igbesẹ lati koju arun onigbameji to bẹ silẹ lagbegbe ila oorun ariwa orilẹede Naijiria.
Iná ń jó lọ níwájú rẹ̀,ó sì ń jó àwọn ọ̀tá rẹ̀ lọ́tùn-ún lósì.
Ko ni dara ki ina eesi tun jo wa lẹẹkeji.
WhatsApp sàlàyé pé ìgbésẹ̀ yìí pọn dandan láti le jẹ́ ki ààbò wà fún àwọn tó kù tó nlo ápùù náà.
Ijọba Naijiria ṣeto idanilẹkọ nibi apero ọlọjọ meji to waye ni ọjọ Aje ati ọjọ Iṣẹgun ọsẹ yii, ṣaaju ibura toni n ilu Abuja.
Bí wolii yìí ti ń sọ̀rọ̀ lọ́wọ́ ni ọba dá a lóhùn pé, “Panumọ́, ṣé wọ́n fi ọ́ ṣe olùdámọ̀ràn ọba ni?
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Lagos rain: Ilé méjì, ọ̀pọ̀ igi àti òpó iná wó lẹ́yìn òjò tó rọ̀ nílùú Eko 20 Èbibi 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 21 Èbibi 2019 Oríṣun àwòrán, @lasemasocial Àkọlé àwòrán, Ajọ LASSEMA ni ọpọ ọṣẹ ni o ba ojo naa kọwọrin, awọ̀n ko si tii le sọ iye ọṣẹ to ṣe ni pato Ojo to rọ lọjọ aje ni ilu Eko ti da ṣugbọn ọwọja rẹ ati ipa ti o fi silẹ ṣi n ja ranyinranyin.
Àwọn olùgbé Tarkwa Bay ń fọ́ ọ̀pá epo, jí epo ta, la ṣe lé wọn - Iléeṣẹ́ Ológun Àkíyèsí nípa àìsàn ‘Coronavirus’ tó ń ṣàkóbá fún ba ṣe ń mí Ìbẹ̀rù nípa Amotekun ló ń mú káwọn èèyàn kan máa wí ìwíkùwí - Soyinka Wo àwọn àdúgbò tí ìpínlẹ̀ Eko ti fòfin de ọ̀kadà àti Marwa Àwa ò ri lẹ́ta kankan gbà láti ọ̀dọ̀ Malami lóri ọ̀rọ̀ àwọn alága Kansu - Makinde Àwọn nkan tó yẹ kí o mọ̀ nípa ìgbẹ́jọ Trump tí yóò blrẹ̀ l'ọ́dọ̀ àwọn Sẹ́nétọ̀ Mí ò le nífẹ̀ẹ́ obìnrin Nàìjíríà kankan mọ lẹ́yìn ti mo ti tọ́ obìnrin òyìnbó wò- Issa Ko sai tun sọ ero rẹ nipa awọn eeyan to n se atilẹyin fun agbekalẹ eto Amotekun, to si salaye pe ọpọ wọn ni ko ni oye pupọ nipa eto naa, gẹgẹ bi awọn eeyan to jẹ alatako eto naa ko se ni oye nipa rẹ pẹlu.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Sextuplet: Àdúrà Ìbùkún ló kú lẹ́yìn ọmọ mẹ́fà yìí- Ifeoma Thelma àti Onyemaechi Chiaka Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Sextuplet: Àdúrà Ìbùkún ló kú lẹ́yìn ọmọ mẹ́fà yìí- Ifeoma Thelma àti Onyemaechi Chiaka 12 Ògún 2020 Kini Oluwa ko le ṣe?
Orile ede Naijiria tun ti fowo si iwe adehun  labe ofin lati r ii  pe ko si ibi ti awon jegudu-jera yii lee sa a si lorile ede.
Èyí ni ó mú u fura pé ìkoni síta bíi ọmọ ọjọ́ mẹ́jọ yìí kò sẹ́yìn àwọn aláṣẹ China.
“Ẹni tí ó bá gbọ́ tiyín, ó gbọ́ tèmi.
Aṣọ kò gbó mọ yín lára, bẹ́ẹ̀ ni bàtà kò gbó mọ yín lẹ́sẹ̀.
Wọ́n jẹ́ ọ̀kẹ́ marundinlọgọta (1,100,000) ninu àwọn ẹ̀yà Israẹli, ati ọ̀kẹ́ mẹtalelogun ó lé ẹgbaarun (470,000) ninu àwọn ẹ̀yà Juda.
Eyi si jẹ gẹgẹ bi owo iranwọ lasiko Covid-19.
Awọn osisẹ to to ẹgbẹrun mẹta lo n sisẹ ni ibujoko ajọ isọkan orilẹede agbaye naa to wa nilu New York to si seese ki wọn fi wọn si abẹ ayẹwo pẹlu.
Abiọla ti jẹ́ olùdárí iwe ìròyìn Trumpeter rí ti Obasanjọ sì jẹ́ igbákejì rẹ̀
World Menopause Day: Ǹkan osù tó ń se ségesège jẹ́ àmì
ati gbogbo ohun tí ó ṣe sí àwọn ọba Amori mejeeji tí wọ́n wà ní òdìkejì odò Jọdani, Sihoni ọba àwọn ará Heṣiboni ati Ogu ọba àwọn ará Baṣani tí ń gbé Aṣitarotu.
Ẹ mọ̀ pé nígbẹ̀yìn, nígbà tí ó fẹ́ gba ìre tí ó tọ́ sí àrólé, baba rẹ̀ ta á nù.
BB Naija: ọ̀fọ̀ ṣẹ̀ lágboólé Olanrewaju Malcolm, olólùfẹ́ Bisọla rí
 lẹ ́ yìn tí orúkọ rẹ ̀ ti tàn kálé-káko nneka ri àǹfàní àti kà àwo rẹ ̀ àkọ ́ kọ ́ sílẹ ̀ .
Ipese owo iranwo yii yoo mu irorun ba igbe aye awon eniyan.
Ní ayé àtíjọ́, kò sí báńkì bíi tayé òde òni, bẹ́ẹ̀ ni àjọ tàbí èsúsú dídá kò fi bẹ́ẹ̀ wọ́ pọ̀ rárá.
Ọjọ́ Ẹti lo farahan niwaju ile ẹjọ naa, ti wọ́n si ka awọn ẹsun rẹ sii.
Dokita fikun ọrọ rẹ pe, awọn arun ajogunba kan tiẹ wa ti igbeyawo laarin ibatan maa n fa, eleyi tawọn ẹbi gan an kii ṣaba mọ.
Isinku rẹ waye nilu Ibadan ni ibamu pẹlu ilana ẹsin musulumi.
Oríṣun àwòrán, odunlade adekola Àkọlé àwòrán, Ẹwà àwọn òṣèré ọkùnrin wọ̀nyí leè mú kí obìnrin maa pariwo 'bi eleyi o jẹ ọkọ ẹni ko saa ti jẹ ale ẹni' Lara awọn oṣere yii ni a ti ri awọn ọkunrin oloṣere ti wọn jẹ ọdọ, ti aye n fẹ, ṣugbọn ju gbogbo rẹ lọ, ti ẹwa wọn lee sọ obinrin maa pariwo 'bi eleyi o jẹ ọkọ ẹni ko saa ti jẹ ale ẹni'.
Wọ́n mú wọn wá siwaju àwọn adájọ́.
Oríṣun àwòrán, Others Lẹyin atotonu agbẹjọro fun ijọba ati igun olujẹjọ, ni adajọ kede pe Maryam jẹbi ẹsun ipaniyan ti wọn fi kan, to si ni ki wọn lọ yẹgi fun titi ti ẹmi yoo fi bọ ni ẹnu rẹ.
 Lara awon ti o wa nibi ipolongo naa ni igbakeji aare orile ede Naijiria Yemi
Laarin ọdun to le ni adọta, osere naa kopa ninu fiimu to le ni 150.
Látàrí ìlérí tí gómìnà ìpínlẹ̀ Ọyọ, Abiọla Ajimọbi ti ṣe láti wá ǹkan ṣe sí ilé iṣẹ́ rẹ́díoò Yinka Ayefẹlẹ tí wọ́n wó, ó ti ṣèpàdé pẹ̀lú olórin náà.
Ètò ti tò ki àjọ INEC bẹ̀rẹ̀ ìkéde èsì ìdìbò gómìnà rivers INEC-Àwọn jándùkú àti ọmọ ilé ìṣẹ́ ológun lo dá ètò ìdìbò Gómìnà Rivers rú Ilé ẹjọ kò pàṣẹ dá kíkà èsì ìbò ìpínlẹ̀ Rivers dúró-INEC Wike fẹ́ lò wá láti da ìdìbò rú pẹ̀lú rìbá - Iléeṣẹ́ ológun INEC yóò kéde àtúndì ìbò láwọn agbègbè kan torí rògbòdìyàn Lọwọlọwọ ni àwọn agbofinro kun ibudo ikabo naa ti wọn si di opopona mejeeji to jade si olu ileeṣe ajọ INEC nilu Pọta ni opopona PortHarcourt si Aba.
ile aare soro niluu Abuja,Masari so pe awon wa ri aare Muhammadu Buhari  nipa abajade ipade ọlọjọ mewaa ti won se niluu
Nibi ti ọrọ naa buru de, ọgọọrọ ọlọpaa ati ọmọ ologun ti wọn fi ransẹ silu Ogbomoso ko lee dẹkun laasigbo naa, tori ọpọ dukia lo bajẹ sinu iṣẹlẹ naa, ti ọpọlọpọ oku si sùn pẹlu.
Tunde Bakare: Ṣé lóòtọ́ ni àṣírí Pásítọ̀ wà lọ́wọ́ Femi Fani -Kayode?
igba ti orile ede naa ti fopin si ijoba ologun, ti won si ti bere eto ijoba
Gbé mi lé oókan àyà rẹ bí èdìdì ìfẹ́,bí èdìdì, ní apá rẹ;nítorí ìfẹ́ lágbára bí ikú.
Ambode: Àwọn aṣòfin Eko kò le è wádìí mi, àwọn ló fòǹtẹ̀ lu owó tí mo ná
" Ile Ajimobi to wa ni GRA lagbegbe Ring-Road, nilu Ibadan, ni wọn padà sin in si.
Ọbasanjọ ni ọmọ òrùkàn tó di olóri orílẹ̀èdè lẹ́ẹ̀mẹ́ta ọ̀tọ̀ọ̀tọ̀ Seyi Makinde làwa ń bá lọ lọ́jọ́ Satide - Ladọja Àgbère ẹgbẹ́ ló wà nídìí ọ̀rọ̀ Amosun àti APC - Jiti Ogunye Ni ọpọ igba, Aarẹ tẹlẹri lorilẹede Naijiria, Olusegun Obasanjo ti ma n bu ẹnu atẹ lu isejọba Aarẹ Muhammadu Buhari.
Ogoji iṣẹju ni Harry Kane, balogun ikọ Tottenham ba tun gba ọkan si.
Irú àwọn ọ̀rọ̀ àbáláyé báyìí a máa súyọ nínú orin, ewì àti ìtàn àwọn baba wa.
 láti nǹkan bí ọmọ ọdún mẹ ́ ta ni ó ti ní etí inú fún orin .
Fídíò náà, tó bẹ̀rẹ̀ láti ìlú Kano dé Ìlọrin tú àsírí tó wà nínú títà àti títa Òògùn ikọ́ olómi Codeine ní Nàíjíríà.
Lọjọ Ẹti ni ọrọ yii jẹyọ lati ọdọ Rafiu Ajakaiye, tii se agbẹnusọ fun Gomina Abdulrahaman Abdulrazaq.
Àkọlé àwòrán, Ó lé ní mílíọ́nù ènìyàn tí wọ́n kó kúrò lágbèègbè Orissa Ti a ko ba gbagbe, orilẹede India si n se idibo gbogboogbo lọwọ, eyi to bẹrẹ ni osu to kọja, ti yoo si wa sopin ni ipari osu yii.
O tẹsiwaju wi pe, ipinlẹ Ọyọ tun ti gba oye tuntun gẹgẹ bii ipinlẹ ti agbekalẹ eto aabo ẹlẹkunjẹkun akọkọ iru ẹ ti gbinaya.
Bakan naa, Ọmọwe Ndimi to jẹ ọkan lara awọn biliọniaa to lowo ju ni Naijiria jẹ ana si aarẹ Muhammadu Buhari lọwọlọ ati ana minisita tẹlẹri lasiko ijọba Abacha, Bashir Dalhatu.
Rochas Okorocha: Fayose rọ Rochas Okorocha, Ibikunle Amosun láti jọ̀wọ́ ara wọn fún EFCC
Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Yoruba Film: Wo àwọn òṣèré tíátà Yorùbá mẹ́fà tó bẹ̀rẹ̀ eré ṣíṣe láti kékéré29 Bélú 2020 Ginimbi Genius Kadungure: Ẹ wo àwọn ọkọ̀ bọ̀gìnì tí ọ̀dọ́mọdé olówó kó jọ lẹ́ni ọdún 3614 Bélú 2020 Rape: ‘Uncle àti Granpa’ mi máa ń fi owó àti ẹ̀bùn fa ojú mi mọ́ra3 Agẹmo 2019 Rape: Ọmọ tí wọn ń fipá bá lòpọ̀ yóò máa ní ìrora ọkàn nígbà gbogbo26 Ẹrẹ̀nà 2019 Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Ní ìta gbangba ibi wọ́n to àga sí fún àwa oníbàárà wọn ni mo fìkàlẹ̀ lé o.
wọn yóo pa á; a óo sì jí i dìde ní ọjọ́ kẹta.
O ni pẹlu ọwọ lile latọdọ awọn agbofinro, eyi yoo jẹ ki wọn gba iye owo ori ti wọn ni ki wọn san tipatipa.
Ẹ jẹ́ kí wọ́n lọ pe ara wọn lẹ́jọ́ níbẹ̀.
Egbe oselu APC ni apapo ibo mẹ́rìnlélọ́gbọ̀n le ẹgbẹ̀ta
Ati wi pe, ti irufẹ awọn ọmọ bẹẹ ba wa de ileewe giga tan lai tii pe ọdun mejidinlogun ti wọn yoo wa maa ba ipenija loriṣiriṣi pade nibẹ.
Kò sì pé tí a rí i tá wọ́n yẹgi mọ́ àwọn mẹ́tẹ́ẹ̀ta.
1988 (Semi - final) Rabat Nigeria 1-1 (9-8 kọju si goli ko o gbaa sile) Algeria 02.
Ẹ̀yin tẹ́ẹ tako àgbékalẹ̀ àgọ́ Fulani, ìkórira ló ń yọ yín lẹ́nu - Ìjọba àpapọ̀ Òṣìṣẹ́ OSCOTECH gb'òmìnira lọ́wọ́ ajínigbé darandaran Fulani Fulani darandaran lo iwa ipa ni guusu Akurẹ Ọmọogun pa darandaran mẹwa ni Adamawa Ileeṣẹ ọlọpaa bẹrẹ igbesẹ tuntun yii lẹyin ti awọn ti ọlọpaa pe ni agbebọn pa ọmọ olori Afẹnifẹre, Funke Olakunrin ni opopona Kajola si Orẹ.
Idẹ ni kí o fi ṣe gbogbo àwọn ohun èlò inú àgọ́ náà ati gbogbo èèkàn rẹ̀, ati gbogbo èèkàn àgbàlá náà.
39 Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
N kò sùn mọ́jú ọjọ́ kejì, ẹ̀ẹ̀kan ṣoṣo tí mo si pa ojú dé, àlá burúkú ni mo lá, ṣe ni mo rí ẹbọra burúkú kan lójú àlá tí ó bẹ̀rẹ̀ sí lé mì kiri, ibi tí ẹbọra náà ti ń lé mi lọ ni mo ti pàdé ejò kan lójú ọ̀nà eyín rẹ̀ dàbí kìnnìún, ìgbà tí mo sì tún ní kí ń sa fún eléyìínì mo pàdé ẹranko tí kò sanra, tí ó dàbí olókùnrùn ti èékan rẹ̀ gùn ṣọ̀bọ̀lọ̀, eléyìínì tún ń fẹ ojú mọ́ mi.
Coronavirus in Africa: Wo ìdí tí coronavirus kò fi ṣọṣẹ́ púpọ̀ jù nílẹ̀ Africa bí i tàwọn tó kù
OLUWA, n óo máa kọrin ìfẹ́ rẹ tí kì í yẹ̀ títí lae;n óo máa fi ẹnu mi kéde òtítọ́ rẹ láti ìran dé ìran.
Ijọba yoo tun se ohun amoriya fun ajo to n mojuto bi  awọn  eniyan se n wole –jade lorilẹ ede  Naijiria lona ti won yoo fi lee maa gbokun ti bi  awọn  janduku ati odaran se n wole sorilẹ ede  Naijiria.
Lẹ́yìn náà, gbogbo eniyan, ati àwọn mẹ̀kúnnù ati àwọn eniyan ńláńlá ati ọlọ́rọ̀ ati talaka, ati ẹrú ati òmìnira ni ẹranko yìí mú kí wọ́n ṣe àmì sí ọwọ́ ọ̀tún tabi iwájú wọn.
Nígbà tí Aaroni wo Miriamu ó ri wí pé ó ti di adẹ́tẹ̀.
Kí ẹ mọ̀ pé àwọn onigbagbọ ẹgbẹ́ yín ń jẹ irú ìyà kan náà níwọ̀n ìgbà tí wọ́n wà ninu ayé.
Wo ọ̀nà tí àwọn ‘ẹ̀lẹ̀ Daddy’ gbà dé ààfin Ọyọ Èyí ni àwọn arẹwà ‘ẹ̀lẹ̀ Daddy’, àfẹ́fẹ́ tí Aláàfin fi ń mí Alaafin bi ibeji l‘ẹẹmeji lọsẹ kansoso Àwọn kókó ohun tó wà nínú lẹ́tà tí Aláàfin kọ sí Fayemi rèé Oríṣun àwòrán, Olori Abibat Adeyemi Igba ti Ọba Adeyemi ko si ti ni owo tabi lọla ni olori Abibat ti fẹ, awọn mejeeji si dijọ pilẹ ọla ni gẹgẹ bii tọkọtaya.
OLUWA bá tún sọ fún mi pé, “Mose ati Samuẹli ìbáà wá dúró níwájú mi, ọkàn mi kò lè yọ́ sí àwọn eniyan wọnyi.
'Ọkùnrin tí kò bá sanwó iléèwé ọmọ, kó lọ wẹrí' Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Ma Long enikaji re lati orile-ede kan-naa jawa le lati ipo keji sipo kefa.
Iléẹjọ gíga jùlọ da ẹjọ́ SDP àti PDP nù, wọ́n ní Yahaya Bello ló wọlé ìbò gómìnà Kogi Ààrẹ Buhari buwọ́lu gbígbé ìṣàkoso nọ́mbà ìdánimọ̀ (NIMC) lọ sí ẹ̀ka ìjọba tó ń rí sí ìbáraẹnisọ̀rọ̀ Wọ́n ti sún ìdájọ́ àwọn sójà tó pa ìyá àti ọmọ ní ọdun 2018 sí oṣù tó m bọ̀ Ọba ni mí, mi ò le b'ọ̀rìṣà, Olorì tuntun tó ń bọ̀ já gbogbo ''scale''- Oluwo ti Iwo O wa fi awọn alakalẹ wọnyii silẹ pe o ṣe koko ki wọn tẹle e: Ati akẹkọọ, ati olukọ, wọn gbọdọ tẹle awọn ofin Covid-19.
Ṣé ẹni tí ń ṣé irú èyí lè bọ́?
''Ẹni to ba fẹ ra ounjẹ tabi oun ọgbin lati ilẹ okeere gbọdọ ṣetan lati san owo rẹ'' Onimọ nipa eto idokowo ni Naijiria, Temitope Kolawole ti sọ wi pe yoo lẹra fun awọn eniyan to n ra ounjẹ ati nkan ọgbin lati oke okun nigba ti ijọba ti kọ lati ta owo ilẹ okeere fun wọn mọ ni owo pọọku mọ yii.
Mo ti rù láàrin ọ̀sẹ̀ kan, iṣẹ́ Eko kò dẹ́rùn - Sanwo-Olu Ẹ yé irọ́ pa, mí o fún Super Eagles ní ẹbùn owó kánkan -Sanwo Olu Awọn orúkọ naa ti Akoṣile ni Sanwo Olu fi iriri wọn yan sipo naa ni wọnyii: Wo àwòrán ńkan tó ń ṣẹlẹ̀ ní ìpádé ìran Yorùbá ní Ibadan báyìí ''Òsìsẹ́ Custom tó déédé sọ ara rẹ̀ di Ọ̀gá Àgbà CG ní ìdàmú ọpọlọ'' Wo àwọn ìlérí tàwọn Gómìnà tuntun ṣe nínú ìbúra wọn A kò lè gba àwọn jandùkú Fulani láàyé nílẹ̀ Yoruba -Awọn gómínà Ipinlẹ Eko kò sí lóko ẹ̀rú ẹnì kankan - Sanwo-Olu Awọn ti orukọ wọn tun jade lẹyin ti wọn ti sin ipinlẹ Eko tẹlẹ ni Tunji Bello to ti ṣe akọwe ijọba tẹlẹ, Wale Ahmed to ti ṣe kọmiṣọnna tẹlẹ ati Abilekọ Uzamat Akinbile-Yusuf atawọn miran.
Bakan naa mi Umar lewaju ninu bi ajọ EFCC ti ṣe n tọ pinpin aarẹ ile aṣofin agba Naijiria tẹlẹ Bukola Saraki.
Asiko idakẹrọrọ Awọn aṣofin ni awọn yoo ṣe asiko idakẹrọrọ iṣẹju kan fun awọn ologun awọn yoo si funpe si ijọba apapọ lati ṣe kia kia pese awọn nkan ijagun fawọn ologun.
O wa pe fun idasilẹ igbimọ oluwadi kan ti yoo ṣe ọfin toto ọwọja wahala awọn darandaran ati agbẹ olohun ọgbin ki wọn le e san owo ofo to ṣẹ koowa fun un.
Nígbàgbogbo, àwọn obìnrin tí kò lárá tí ó tálákà ní í máa ń fi ara kááṣá.
Ẹ gbó òhun tí àwọn olùdíjé sípò gómìnà nípínlẹ̀ Ondo sọ nípa bàbá ìsàlẹ̀.
“Ni bayii, ko si iyato ninu pe mo wa nile, leyin ti mo ti lo n kopa fun orisirisi iko agbaboolu ki n to wa darapo
Senator Elisha Abbo: Ilé aṣòfin àgbà gbé ìgbìmọ̀ kalẹ̀ lórí Sẹ́nétọ̀ tó lu obìnrin l'Abuja
Ààrẹ Muhammadu Buhari buwọ́lu owó ìṣúná ọdún 2019 Bóò ṣe lè yẹra fún ikú nígbà òjò - Onímọ̀ Ehi Iden Kò sí àyè fún fíìmù eré ìfẹ ṣíṣe ni Kannywood mọ́ Kí ló ṣe ikú pa Adediwura Lateefat Bello lẹ́yìn ọ̀sẹ̀ méjì tí wọ́n ń wá a?
Day 26: Atiku ní oun ṣì ní okun, agbára àti ìlera láti dupò aàrẹ Naijiria #BBCNigeria2019 Irú kan náà ni Atiku àti Buhari, kò s'íyàtọ̀ nínú wọn - Tunde Bakare Gbàjarè!
Mateo Kovacic dayo kan pada fun Chelsea, amọ Calvert-Lewin gbayo kẹta wọle fun Everton, ni okote ba bo niru fun Chelsea.
Ilé iṣẹ́ tó ń móju tó ìṣẹ̀lẹ̀ pàjáwírì nípinlẹ̀ Eko (LASEMA) ní ọkọ̀ akẹ́run Dangote tó kún fún simẹnti, ní ìjánu rẹ̀ dédé já, tí o si lọ kọlu ọkọ èrò BRT to kó èrò ọgọta lópóna Ikorodu.
Ilé aṣòfin ti buwọ́lu Tanko Muhammad gẹ́gẹ́ bi adájọ́ àgbà Nàìjíríà CAN kò rán ẹnikẹ́ni lọ ṣọ́ọ̀ṣì COZA, iṣẹ́ ara wọn ní wọ́n lọ jẹ́ -Samson Ayokunle Yinka Ayefele di bàbá ìbẹta Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Àwọn afẹ̀hónúhàn bọ́ra sí ìhòhò lórí pápá lòdì sí sísọ eré bọ́ọ̀lù di jẹunjẹun Wo ìyàtọ̀ ńlá tó wà láàrin Oṣó, Àjẹ́ àti Emèrè Akẹ́kọ̀ọ́ ṣe ìdánwò àṣekágbá WAEC ní ibùdó ìtọ́jú aláàrún ní Gombe Ilé ẹjọ́ ní kí ''Yahoo boy'' lọ darí ọkọ̀ f'óṣù mẹ́ta pẹ̀lú N50,000 owó ìtanràn DPO ọlọ́pàá fi ọmọ odó lu èèyàn méjì pa, ó ṣe ẹnìkan lééṣe lágọ̀ọ́ ọlọ́pàá Jegede lo kede Ikengboju loju opo Twitter rẹ lọjọ Aje.
Nigba to n fesi si ọrọ ti awọn alatako rẹ lori ipo tuntun naa, Ajimobi sọ pe ẹgbẹ APC mọ iru atunṣe rere ti oun lee mu ba ẹgbẹ naa ni guusu Naijiria ati ni orilẹ-ede yii lapapọ.
Ẹ máa wo àwọn aláìsàn sàn.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Babcock Sex Video: Ọ̀pọ̀ èèyàn ní kò yẹ kí wọn lé akẹ́kọ̀ọ́bìnrin ọ̀hún torí kìí ṣe ọmọdé 21 Bélú 2019 Oríṣun àwòrán, Babcock University Ọpọ ọmọ Naijiria lo ti n tako igbesẹ fasiti Babcock lori bo se juwe ọna ile fun akẹkọbinrin kan ti wọn n ba lopọ ninu fidio kan to lu ori ayelujara pa.
Wọ́n fi ipá mú àwọn ọdọmọkunrin pé kí wọn máa lọ ọlọ,àwọn ọmọde ru igi títí àárẹ̀ mú wọn!
Ajo NFF sun ibasisepo won pelu Rohr siwaju lati ma a tuko Super Eagles di odun 2020.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Mo máa n forin mi kìlọ̀ ìwà ìbàjẹ́ láwùjọ ni -Hameen O ni, ki i ṣe igba akọkọ ree ti awọn baalu ileeṣẹ naa yoo rin iru irin naa.
Owo rẹpẹtẹ, iṣoro diẹ Ni ibẹrẹ ọdun yii, owo ti fẹ ẹ tan ni apo ikọ ipolongo Biden.
Nítorí OLUWA ti pè ọ́,bí iyawo tí ọkọ rẹ̀ kọ̀ sílẹ̀, tí ọkàn rẹ̀ bàjẹ́,àní, bí iyawo àárọ̀ ẹni, tí a kọ̀ sílẹ̀;OLUWA ló sọ bẹ́ẹ̀.
Òùngbẹ títẹ̀lé òfin rẹ ń gbẹ ọkàn mi, nígbà gbogbo.
Joshua Iginla Oríṣun àwòrán, Champions Royal Assembly Adari ijọ Champions Royal Assembly to wa ni Kubwa, Abuja yii tẹ pẹpẹ ọrọ ninu isin ọjọ Aiku nigba to jẹwọ niwaju ijọ rẹ wipe oun jẹbi ẹsun agbere kan ti iyawo oun fi kan oun ati wipe nitori naa, oun ati iyawo oun ti ṣetan lati kọ ara silẹ.
Page 1 nínú 50 rewind previous Navigate to the next page nextNavigate to the last page forward Padà sí òkè ÀkọléÀkọlé abala Àkọlé abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Rìn káàkiri BBC News Sport Weather Radio Arts Ìlànà Lílò Nípa BBC Òfin Àṣírí Cookies Ìrànlọ́wọ́ Ìwọlé Ìtọ́ni Òbí Kàn sí BBC Get Personalised NewslettersCopyright  2020 BBC.
Liverpool kun Arsenal wẹ́lẹ́wẹ́lẹ́ bí ẹran àsun 'lójúbọ' Anfield Rẹ́rẹ́ run!
Lójijì yóo wá sí àwọn ibi tí ó ní ọrọ̀ jùlọ ní agbègbè náà, yóo máa ṣe ohun tí àwọn baba ńlá rẹ̀ kò ṣe rí.
O maa n ri lọ si isalẹ inu awo igbọnsẹ ni.
Ààrẹ Buhari ti lọ sí ìlú Daura fún ọdún Sallah Àlàyé rèé lóríi ìdí tí wọ́n fi ń pe aya ní ìyàwó Àwọn ọmọ Nàìjíríà kan ń dá ẹ̀bi, òmíràn ń dárò, lórí bí ológun ṣe pa ọlọ́pàá mẹ́ta Ọ̀la ni Arafat, wo iṣẹ́ tó ṣe kókó láti ṣe ní Hajj lásìkò Àràfá àti lẹ́yìn rẹ̀ Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
A lè sọ pé ìyàndá ṣubú
Amọṣa fun awọn olugbe ipinlẹ Eko, ohun ti oju wọn ri, paapaajulọ awọn osiṣẹ to n lọ si ẹnu iẹ oojọ wọn, kọja sisọ.
Klopp ni ikọ Liverpool ṣetan lati rii wi pe ẹgbẹ agbabọọlu tun pegede fun aṣekagba idije Champions League lẹẹkan sii.
Atẹjade kan to jade lati aafin Ọọni Adeyẹye Ogunwusi fi idi iṣẹlẹ ijamba ina naa mulẹ.
Kelly ní wọn padà sórí ẹsùn ti ó wáyé lọ́jọ́sí láti jẹ ki gbogbo ǹkan to ṣẹ̀lẹ̀ lásìkò yìí dàbi tòòtọ́ lóju àwọn ènìyàn."
Ile ise aare ti so pe aare Muhammadu Buhari ko ni tako oro ti  aare ana, Olusegun Obasanjo  so  pe, ijoba aare Buhari ti kuna nibi  isejoba re.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Seyi Makinde: Àwọn iléẹkọ́ àdáni le è lọ fún ìsinmi ìdajì táámù 11 Òkùdu 2019 Oríṣun àwòrán, Google Àkọlé àwòrán, Ìjọba ní ìdí tí àwọn fi gbé ìgbẹ́sẹ̀ náà ni pé àwọn akẹ́ẹ̀kọ́ ti dúró nílé nítorí ìyansẹ́lódì ọlọ́jọ́ gbọọrọ.
Ni bayi ti o ku ọjọ diẹ ki wọn pari saa wọn, a fẹ ṣe ayẹwo awọn nnkan ti wọn dawọle kọọkan ti ko daju pe wọn yoo ribi pari wọn ati iru ipa ti eleyi yoo ni lara iṣejọba ati igbayegbadun awọn ara ilu.
APC ati si awon to dupo ninu egbe naa lasiko eto idibo to koja ohun.
Alaga ẹgbẹ awọn lọgalọga lẹnu iṣẹ ọba ẹka ti ipinlẹ Ọyọ, Comrade Emmanuel Ogundiran lo tẹpẹlẹ mọ ọrọ yii nigba to n ba BBC Yoruba sọrọ.
” Ara ọdọmọbinrin rẹ̀ bá dá láti àkókò náà.
Ọ̀pọ̀ èèyàn tí kò yin Ajimobi lojú ayé, tó ń yìn-ín lẹ́yìn ikú, yóò jẹ ìyà - Oníwáàsí Ọ̀pọ̀ ìgbà ní Hushpuppi àtàwọn èèkàn PDP ti ya fọ́tò ní Dubai, EFCC ẹ wádìí wọn - APC ń lọgun Àwòrán rèé nípa àwọn gbajúmọ̀ tó ti bá Hushpuppi ṣe Mo ti bá ọmọ ọwọ́ mẹ́ta lòpọ̀ sẹ́yìn, ọmọ oṣù mẹ́ta ló ṣìkẹrin - Afurasí jẹ́wọ́ Lọdun yii, iroyin to n jade lati ọdọ ileeṣẹ to n risi bi oju ọjọ ti se ri sọ pe ojo yoo rọ gan, ti yoo si mu ki ipinlẹ Ogun ati awọn ipinlẹ to yika foju ba omiyale.
O ni oun o ra ọkọ̀ àjàgbé kan, oun o si lọ fun isinmi.
 alákùnrẹ ́ wá já ọwọ ́ rẹ ̀ nínú irọ ́ kẹ ̀ kẹ ̀ àti akitiyan láti jẹ ́ ọba fún ìlú Àkúrẹ ́ bí ó tilẹ ̀ jẹ ́ pé òun gan-an ni ẹni kìíní tí ó kọ ́ kọ ́ tẹ ìlú Àkúrẹ ́ dó .
"Meji ninu wọn sa sinu orule ṣugbọn oloogun wọn ko lee gbera tori ẹsẹ rẹ kan yọnu.
Ẹ̀yin òjíṣẹ́ Ọlọrun mi, ẹ wọlé,kí ẹ sì fi aṣọ ọ̀fọ̀ bora sùn,nítorí a ti dáwọ́ ẹbọ ohun jíjẹ ati ẹbọ ohun mímu dúró ní ilé Ọlọrun yín.
Àwọn ọmọ yín ọkunrin ati àwọn ọmọ yín obinrin óo di ti ẹni ẹlẹ́ni.
Thailand jẹ mẹ́tàlá lọ́wọ́ Amẹ́ríkà ní ìdíje FIFAWWC Ẹrù ìyà ni Norway dì lé Super Falcons lórí ní 2019 Women's World Cup Rohr já Iheanacho àti Semi jùú lẹ̀ lọ Egypt fún AFCON 2019 Agbára wo ni June 12 fún MKO Abiola tó ṣì ń fọhùn lẹ́yìn ikú rẹ̀?
Awọn ọmọ Naijiria naa dasi ni ori ẹrọ ayelujara Bakan naa ni awọn ọmọ Naijiria kan to n sọrọ lori ẹrọ ayelujara naa n sọ wi pe ohun ti Obasanjo sọ dara.
Minisita to n mojuto isise si oko ofurufu, ogbeni Hadi Sirika pe fun atileyin aare Muhammadu Buhari ninu eto idibo gbogbogbo to n bo lọdun 2019.
Eyi mu ki awọn eeyan lorileede maa bẹnu atẹ lu wi pe o yẹ ki o fodinwọn si oge siṣe.
 Òun ni ó ń bá jìnádù jà .
Ongbontarigi olorin raggae ni, Majẹkodunmi Fasheke ti ọpọ mọ si 'Majek Fashek' ti re iwalẹ asa nibi ere tii so'kan.
Àwọn ọmọdé méjì náà pinnu àti kúrò ní ilé ní alẹ̀, ní àkókò òṣìpá, wọ́n sì fi àdéhùn sí i pé kì àwọn pàdé ara àwọn léti odò kan, ẹni tí ó bá kọ́ dé ọ̀hún kí ó dúró de ẹni kejì, igbà tí àwọn méjèèjì bá pé sí etí odò náà kí àwọn máa sálọ, kí àwọn sì ti ipa bẹ́ẹ̀ bi ẹni tí ń gbé pọ̀ kí àwọn máa fi ìfẹ́ jẹ iyán, kí àwọn máa ffi ìfẹ́ jẹ ọkà, kí àwọn sì máa fi ìfẹ́ jẹ àkàṣù baba ẹ̀kọ.
Sotitobire: Adájọ́ dá Pásítọ̀ Alfa Babatunde padà s'ẹ́wọ̀n fún ọjọ́ mọ́kàndílógún Bí ọ̀rọ̀ ṣe ṣẹlẹ̀ Arabinrin Olawole to jẹ́ iyá Gold Kolawole lo gbe ọmọ rẹ̀ lọ si sọọsi awọn ọmọde nile ijọsin wọn lẹ́yin ọ̀pọ̀lọpọ ọ̀rọ̀ latọdọ àwọn olukọ ọmọde ninu ijọ náà pe ki iya Gold maa gbé ọmọ rẹ̀ wá si ilé ijọsin ọmọ wẹwẹ.
 ní báyìí , orílẹ ́ -èdè nàìjíríà àti hamburg ni ó fi ṣe ibùgbé .
Nítorí náà, máa rìn ní ọ̀nà àwọn eniyan rere,sì máa bá àwọn olódodo rìn.
Jesu wà ní ẹ̀yìn ọkọ̀, ó fi ìrọ̀rí kan rọrí, ó bá sùn lọ.
Alwan Hassan - Ọmọ ẹgbẹ́ 4.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Olayemi Oluwabamigbe Samson: Àwọn pàntí ọ̀rá omi yìí ṣì wúlò Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Olayemi Oluwabamigbe Samson: Àwọn pàntí ọ̀rá omi yìí ṣì wúlò 2 Òkùdu 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 3 Òkùdu 2019 Oniṣẹ ọwọ ni Olayemi Oluwabamigbe Samson jẹ ti ori rẹ si maa n ya si ki awọn eniyan gbe ni adugbo to mọ.
Fun idi eyi, maa jẹ eso loriṣiiriṣii daadaa.
O ni oun se akiyesi pe ọpọ ọmọ Yoruba to wa nilẹ okeere, ni kii fẹ fi Yoruba da esi pada, ti eeyan ba n ba wọn sọrọ ni ede abinibi wa.
Ṣugbọn ọba Asiria kò pa irú ète yìí,kò sì ní irú èrò yìí lọ́kàn;gbogbo èrò ọkàn rẹ̀ ni láti pa ọpọlọpọ orílẹ̀-èdè run
 bí àpẹẹrẹ : a , e , ẹ , i , o , ọ , u , an , ẹn , in , ọn , un .
Awọn ọmọde wọnyii maa n di ọmọ lile nipa bi wọn ṣe n ri ti awọn ọrẹ wọn n ku."
Hagia Sophia: Tayọ̀tayọ̀ làwọn Musulumi fi kí Jimọ níbẹ̀
Báwo ni a óo ṣe kọ orin OLUWA ní ilẹ̀ àjèjì?
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù EndSars Protest: Ǹkan mẹ́ta ti Gómìnà Babajide Sanwo-Olu pinu fún àwọn ọlọ́pàá ìpińlẹ̀ Eko 29 Ọ̀wàrà 2020 Gómìnà ìpińlẹ̀ Eko, Babajide Sanwo-Olu ti pàsẹ fáwọn ilé tó ń ṣètò ẹ̀kọ́ ọ̀fẹ́ ní ìpińlẹ̀ Eko láti fún ọmọ àwọn ọlọ́pàá tó bá ìṣẹ̀lẹ̀ abájádè ìfẹ́hónú ọ̀rọ̀ EndSars rìn.
Ko si ani ani pe akọkọ lo jẹ loju ewe awọn apanilẹrin to dantọ ju fun awọn kan.
Ẹni tí à ń waasu rẹ̀ ni Jesu Kristi pé òun ni Oluwa.
Oríṣun àwòrán, Facebook/Seyi Makinde Ile asofin ni kii se pe awọn de idi fun aba isuna naa, tabi fi owo kun, eyi ti yoo bọ sapo awọn.
Nítorí Baba fẹ́ràn Ọmọ rẹ̀, ó sì fi ohun gbogbo tí ó ń ṣe hàn án.
Onyenso so pe, akori ipade ti odun 2018 ti a wa yii safihan ipa ti ile-eko naa n ko lori oro idagbasoke orile-ede Nigeria.
Ẹ máa ní èrò yìí ninu ara yín, irú èyí tí ó wà ninu Kristi Jesu, 
'Àwa ọmọ Nàìjíríà tó farapa fẹ́ wálé láti Lebanon, ìjọba kó wa pamọ́' Ogun Àgbẹ́kọ̀yà, ìjà òmìnira fáwọn àgbẹ̀ ni tàbí ìfẹ́míṣòfò?
“Ilana naa yoo tun je ki awọn ohun amayedẹrun bi i eto irinna, omi mimu, ina mona-mona, ile -igbọnse ati awọn  ohun amayederun to ye ko wa ni aarin ilu.
Ta ni yóò gba Premier League?
Gbogbo àwọn olórí àwọn agbègbè, àwọn baálẹ̀, àwọn gomina ati àwọn aláṣẹ ọba ran àwọn Juu lọ́wọ́, nítorí pé ẹ̀rù Modekai ń bà wọ́n.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Amotekun: Miyetti Allah ní òun yóò péjú síbi ìpàdé ìta gbangba lọ́jọ́ Ajé láti sọ tẹnu òun 22 Èrèlè 2020 Bi wọn ba n ke gbe gbe gbe, ti a ko ba bawọn gbe, afaimọ ki wọn ma gbe si ẹyinkule wa.
Ọlọrun, ìwọ ṣá ni ọba wa láti ìbẹ̀rẹ̀ wá;ìwọ ni o máa ń gbà wá là láàrin gbogbo orílẹ̀-èdè.
Wo ohun tó yẹ kí o mọ̀ nípa àwọn obìnrin méje ti Buhari forúkọ wọn ránṣẹ Abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò dágbére fáyé lẹ́yìn ìjà rẹ Àgùnbánirọ̀ akọ̀ròyìn Channels náà ti dágbére fáyé látààrí ìkọlù Shiite l'Abuja Ipa tí ìyànsípò Olóòtú ìjọba Gẹ̀ẹ́sì tuntun yóò mú bá ‘Brexit’ Èèmọ̀!
" Ni ti Fury ni tirẹ, o sọ fun awọn oniroyin lẹyin ija naa pe Ọba ti pada bọ sori itẹ,"" lẹyin naa lo gboriyin fun Wilder pe iṣe lo ṣe."
Oluwo ti Iwo: O yẹ́ ká rán àwọn Fulani lọ ìlú òyìnbó láti kẹ́kọ̀ọ́
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Fire Eater: Azonto ní àfojúṣùn òun ni láti lọ fi idán iná yìí pa owó lókè òkun 22 Èrèlè 2020 Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Fire Eater: Azonto ní àfojúṣùn òun ni láti lọ fi idán iná yìí pa owó lókè òkun Ara ko ni tan nile alara ni Yoruba n sọ, airin jinna si ni airi abuke ọkẹrẹ.
Omotola Jalade ní Nàìjíríà dàbí ọ̀run àpáàdì lábẹ́ ìjọba Buhari Ibrahim Chatta fesi sí ẹ̀sùn pé òun na iyawo rẹ̀!
bíi iye àwọn ọmọdé tó tó 85 % káàkiri àgbáyé ni ó ti gba àjẹsára yìí ní bí ọdún 2013 .
Ile ise Cadbury Nigeria Plc ti won n pese ohun lila elerindodo TomTom pelu ajo NFF ti towobo iwe ibasepo olodun meta ni ona lati gbe iko agbaboolu Super Eagles laruge si.
Fìlà rẹ̀ sí bọ́ sílẹ̀ nínú mọ́tò tí ó wọ̀.
ti ko dun mo awon kan ninu nitori ipinnu oun lati mu ilosiwaju ba gbogbo eniyan
" Ko tan sibẹ, atẹjade asaaju ẹgbẹ APC naa ni, awọn eeyan to tun n kesi ijọba apapọ lati jẹ gaba, tabi sọ ẹkun guusu Naijiria di akurẹtẹ, lo ti sọnu lai mọ ibi ti wọn n lọ, ti ẹmi ibẹru si ti di oju inu wọn, bẹẹ ni agbara oselu ti kun ọpọlọ wọn ni oorun.
Ọlọrun ni ó yọ wá ninu ewu ńlá náà, òun ni yóo sì máa yọ wá.
Ikede yii wa lati awon afojusun ti awon olori orile ede fenuko le lori nibi ipade apero to waye ni Malabo ni orile ede Equitorial Guinea losu kefa odun 2014 pelu ipinnu lati se pari titi odun 2025.
Àwọn ọmọ tí ó bí fún un nìwọ̀nyí: Nadabu, Abihu, Eleasari, ati Itamari.
Ilu Abeokuta to je olu ilu ipinle Ogun ni guusu Naijiria ti gbaradi lati gbalejo Odun ilu ile Adulawo todun 2018 bere lati ojo kokandinlogun si ojo kokanlelogun osu kerin odun 2018.
Nígbà tó ń sọ̀rọ̀ lórí eto iranwọ to ṣe lásìkò igbele Coronavirus yìí, Toyin Abraham ni òun ti pín owó àti èròjà oúnjẹ fún àwọn olólùfẹ́ òun ti oun mọ káàkiri ìlú Èkó, ibadan, Ogbomoso, Ilorin, Kano àti ní Ìpínlẹ̀ Ogun, ní ìwọ̀nba tí agbára òun ka.
Peteru bá tẹnu bọ̀rọ̀, ó ro gbogbo ohun tí ó ṣẹlẹ̀ fún wọn lẹ́sẹẹsẹ.
Angẹli náà sọ fún àwọn obinrin náà pé, “Ẹ má bẹ̀rù.
Egbeyemi sọ pe awọn eeyan naa jẹwọ fun oun pe airiṣẹ ṣe lo mu ki awọn o darapọ mọ ẹgbẹ okunkun, ati pe awọn yoo di ẹda tuntun ti awọn ba n ri iṣẹ aje ṣe.
Sugbọn oluranlọwọ Ọọni lori ọrọ iroyin, Comrade Moses Ọlafare sọ wipe ko tilẹ si ohun to jọ mọ isẹlẹ yẹn to waye ni ilu PortHarcourt.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: 'Mímu ọyàn àyà ìyàwó rẹ̀ ní àǹfàní tó pọ̀' Kò sáyè ìgbafẹ́ mọ́ fáwọn àgùnbánirọ̀ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Sunday Ayẹni: Damilọla, aya ọmọ mi fìgbónára sọ mi sókùnkùn alẹ́ Olorin takasufe naa tun jẹ ko di mimọ ninu ọrọ pelebe to kọ sori ikanni Instagram rẹ pe,  A o jumọ la gbogbo idanwo ti a ba n koju kọja ni."
Ó bá ki Ẹranko Ewèlè náà mọ́lẹ̀, ejò àtijọ́ náà tíí ṣe Èṣù tabi Satani, ó fi ẹ̀wọ̀n dè é fún ẹgbẹrun ọdún.
O ti to igba diẹ bayii ti owo epo lagbaye ti n kuta nitori ajakalẹ arun coronavirus.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Pákáleke lórí ìdìbò àti ọrọ̀ ajé Nàíjíríà ń já wa láyà - UN Sáà kan péré ni mo tọrọ lọ́dún 2019 - Atiku 'Ẹ yéé t'ọwọ́ òṣèlú b'ọ̀rọ̀ ológun Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ìyá Darasimi: Ọlọ́run fi ìbejì rẹ̀ mí lẹ́kún, lẹ́yìn ikú Darasimi tó mu sódà O ní àtúnpín àwọn ọmọogun yìí ṣe pàtàkì látàrí àbájáde ìwádìí ètò ààbò ní Maiduguri, sùgbọn o ṣe ni láànú pé, àwọn ọmọogun kan ṣi ọ̀rọ̀ náà gbọ́ ti wọn si bọ́ síta láti fẹ̀hónú hàn nípa yinyin ìbọn ní pápákọ̀ òfurufu nítorí wọn si ọ̀rọ̀ náà gbọ́.
Koda, ohun ti owo ori yii wa ko tii ye oun.
"Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Obateru Akinruntan: Wíwá ohun tá jẹ títí láé ló gbé wa kúrò nílé Ife Akintoye ni: ""Mi o fi igba kankan sọrọ lori ayajọ ọjọ ominira Naijiria, October 1, ju pe ki awọn to ba sọ pe dandan ni ki awọn ṣe iwọde ṣe e pẹlu alaafia ati ọwọ."
Ẹfunsetan Aniwura, obìnrin tó ju ọkùnrin lọ Ọ̀rọ̀ǹpọ̀tọ̀niyùn, Aláàfin obìnrin àkọ́kọ́ rèé, tó ní nǹkan ọkùnrin Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Èmi ni afunfèrè àkọ́kọ́ lágbo eré KWAM 1 ní 1983' Eyi waye lẹyin atẹjade ti igbimọ alaṣẹ ile iwe naa fi sita pe awọn fi ikede ranṣẹ si gbogbo ọmọ ile iwe lati kuro ninu ile iwe ko to di agogo mẹta ọsan oni.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Ko pẹ lẹyin rẹ ni Frank Lampard da a pada pẹlu ami ayo kan fun pẹlu ami ayo kan fun ikọ rẹ Chelsea.
Lanko Adeọla Ṣorẹmi: Ọlọrun nìkan ló ń bá wa to ilé wa
"Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Eeyan 35 miran ko aarun iba Lassa WHO yoo kapa aisan Lassa Fever 'Awọn ipinlẹ ni iṣẹ lati ṣe lori iba lassa' Aarẹ ẹgbẹ awọn dokita iṣegun lorilẹede Naijiria, Dokita Mike ogirima ni ""Ko si bi awọn dokita ko ṣe ni kọ ipakọ si awọn alaisan to ba wa fun itọju aisan iba lassa ni ileewosan gbogbo, nitori ijọba ko tii ṣe ohun to kun oju oṣuwọn lori aisan naa."
" Jàǹdùkú pà ọlọ́pàá méjì, jó àgọ́ wọn mẹ́wàá, báńkì mẹ́ta, jí ọ̀pọ̀ owó l'Eko - Iléeṣẹ́ ọlọ́pàá Oríṣun àwòrán, @Odolz_ Ileeṣẹ ọlọpaa ti ke sita lori bi awọn janduku to fi iwọde End SARS boju, ṣe n kọlu awọn ọọfisi atawọn oṣiṣẹ wọn ni ipinlẹ Eko.
Oríṣun àwòrán, EPA Àkọlé àwòrán, ogun eeyan ṣagbako iku ojiji lọwọ agbebọn Awọn oniroyin ilẹ Amerika kan ti sọ pe Patrick Crusius lorukọ rẹ.
Àwọn bíi mẹ́rin mǐran tẹ̀lẹ́ wọn.
Ileeṣẹ to n ri si pinpin ina ọba jakejado Naijiria, TCN ti rawọ ẹbẹ sawọn ọmọ Naijiria fun itakun ina to ja kaakiri orilẹede Naijiria lọjọ Aiku eyi to sọ gbogbo ọmọ Naijiria sinu okunkun birimu.
Igbesẹ yi gẹgẹ bi wọn ṣe sọ jẹ ọna kan gbogi lati koju aisan Coronavirus to n ja rain nilẹ naa.
 ibẹ ̀ ló ti mú orúkọ yìí bọ ̀ tí ó sì fi sọ ilú tí òun náà tẹ ̀ dó .
Ọ̀rọ̀ tí ó tuni lára dàbí afárá oyin,a máa mú inú ẹni dùn, a sì máa mú ara ẹni yá.
Nollywood: Gbajugbaja òṣèré ''Toromagbe'' nínú fíìmù ''Arelu'' ti jáde láyé
Nígbà tí wọ́n pada dé ọ̀dọ̀ Reueli, baba wọn, ó bi wọ́n pé, “Ó ṣe ya yín tó báyìí lónìí?
Eyi si lo mu ki ẹgbẹ osisẹ nilẹ wa fi igbe ta fawọn gomina lawọn ipinlẹ pe ki wọn mase san iru asọ bẹẹ soro nitori wọn le ru igi oyin.
Ki eniyan too ṣe minisita labẹ isejọba awọn amofin, awọn eniyan gbọdọ dibo yan ẹni naa ni ẹkun rẹ, amọ aarẹ le yan ẹni to wu u si ipo minisita.
Mo mọ̀ pé nígbà gbogbo ni ò ń gbọ́ tèmi, ṣugbọn nítorí ti àwọn eniyan tí ó dúró yíká ni mo ṣe sọ èyí kí wọ́n lè gbàgbọ́ pé ìwọ ni o rán mi níṣẹ́.
Wọ́n máa ń lo òfin Sharia láti sàmójútó ọ̀rọ̀ ìgbéyàwó àti ogún pínpín láàrín àwọn Musulumi.
Nítorí ó wà ní àkọsílẹ̀ pé, “Máa yọ̀, ìwọ àgàn tí kò bímọ rí.
Tí n óo bá sọ̀rọ̀ bí ẹni tí orí rẹ̀ kò pé, mo jù wọ́n lọ gẹ́gẹ́ bí iranṣẹ Kristi.
Akoroyin kan lati ile asoju orile-ede America so pe, Tillerson ni ireti wa pe yoo sepade pelu Aare Mohammadu Buhari lojo-Isegun “Ti o ba wa sorile-ede Nigeria, Tillerson yoo je osise agba ninu isakoso Aare Trump ti o sabewo sorile-ede Nigeria”.
Ni ipari, ẹgbẹ mejeeji parọwa fun awọn ara ilu lati murasilẹ lati maa ra burẹdi ni owo to le diẹ si ti atẹyinwa ni eyi ti kii ṣe ẹbi awọn oniburẹdi rara.
Àkọlé àwòrán, Ṣọ́ọ̀bù àti ọkọ lóríṣiríṣi ni wọ́n bàjẹ́ lásìkò tí àwọn agbébọn naa kọlu àdúgbò náà Nigba ti akọroyin BBC News Yoruba yoo fi de adugbo naa ni ọjọbọ nṣe ni gbogbo adugbo naa pa lọọlọ.
Ẹ máa ṣe ẹ̀tọ́ ati òdodo, kí ẹ máa gba ẹni tí wọn ń jà lólè lọ́wọ́ àwọn aninilára.
Àwọn igi bá tún lọ sọ́dọ̀ igi àjàrà, wọ́n wí fún un pé kí ó wá jọba lórí àwọn.
Oju opo ikanni BBC Yoruba yi yoo tun se agbekalẹ itumọ to yanranti fun igbe aye, asa, ise,ajọdun ibilẹ, owe ati bẹẹ bẹẹ lọ, laarin awọn iran Yoruba.
Ẹnikẹni to ba wa lati idile yii ko le e de ipo adari ni awujọ wọn, bakan naa ni ko le e dije -dupo , nitori ko si ẹni ti yoo dibo fun ẹni to wa lati idile ẹru.
Gẹgẹ bi atẹjade naa ṣe sọ awọn eeyan kan lo sin igbimọ to n ṣe kokaari eto igbogun ti ajakalẹ arun coronavirus ni ipinlẹ naa ni gbẹrẹ ipakọ.
Oríṣun àwòrán, @NLCHQ_ABUJA Lẹyin ijiroro fun ọpọlọpọ wakati, ni ijọba paṣẹ ki iye owo ti awọn eniyan n san lori owo ina ọba pada si bo ṣe wa tẹlẹ fun ọsẹ meji.
Awọn ọmọ ilé igbimọ asofin náà yọju sibi ti ọ̀rẹ yiì, Dino Melaye, Enyinaaya Abaribe, Ike Ekweremadu, awọn adẹrinpòsónú bi Basket Mouth, Funny Bone.
Bayii, ajọ eleto idibo ti ka awọn ibo ti wọn gbe wa ni eyi ti ọpọlọpọ Link ti ṣe iṣiro le lori.
O ni lópin igba ti awon alasẹ ko ba ka ààbò èmí ara ilu lapapọ kún, iru ìṣẹlẹ bayi ko ni ye máa wá yẹ.
Ilé ìwòsàn l'Àbuja ti ya àwọn ìbejì tí wọ́n sọpọ̀ láyà lọ́fẹ̀ẹ́ Gómìnà mẹ́ta àtí ènìyàn 1,242 ló kó sí panpẹ EFCC ni ọdún 2019 Wọ́n tẹ àádọ́ta olùdárò pa níbi ìsìnkú Qasem Soleimani tí kò wáyé mọ́ Díẹ̀ lára àwọn ìṣẹ̀lẹ̀ tí yóò mi ìgboro tìtì l'ọ́dún 2020 rèé Gẹgẹ bi ohun ti ileeṣẹ ijọba to n mojuto ọrọ aabo lorilẹ-ede Amẹrika sọ, ọpọ ado oloro ni wọn ju sinu ibudo awọn ọmọ ogun naa to wa ni orilẹ-ede Iraq.
“Dájúdájú ilẹ̀ rẹ tí ó ti di aṣálẹ̀,ati àwọn tí ó ti di ahoro,yóo kéré fún àwọn tí yóo máa gbé inú rẹ̀ tí ó bá yá,a óo sì lé àwọn tí ó pa ọ́ run jìnnà sí ọ.
Àkọlé àwòrán, PDP ni ifisẹ silẹ Akintayọ nii se pẹlu owo kan, eyi to le ni biliọnu mẹrindinlogun naira Sugbọn ẹgbẹ alatako kan nipinlẹ Ọsun, eyiun ẹgbẹ oselu PDP ti n ke tantan pe, ifisẹ silẹ Akintayọ nii se pẹlu owo kan, eyi to le ni biliọnu mẹrindinlogun naira tijọba apapọ yọgbe jade fun ipinlẹ Ọsun gẹgẹ bii owo idapada gbese.
Bí a kò bá ṣe bẹ́ẹ̀, àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ lè wá jí òkú rẹ̀ lọ, wọn yóo wá wí fún àwọn eniyan pé, ‘Ó ti jinde kúrò ninu òkú.
Nígbà tí ẹnìkan rí i, ó bò ó mọ́lẹ̀, ó lọ tayọ̀tayọ̀, ó ta ohun gbogbo tí ó ní, ó bá ra ilẹ̀ náà.
O ni awọn kan wa laye to jẹ pe tẹẹ ba rọra fọwọ kan wọn lasan, aye ẹ maa dara gidi gan.
Ilẹ̀ tí Abrahamu rà lọ́wọ́ àwọn ará Hiti ni wọ́n sin ín sí pẹlu Sara aya rẹ̀, 
Lẹyin iṣẹlẹ naa ni ijọba sọ pe oun kò kó ounjẹ naa pamọ ṣugbọn oun n duro ki iwọde EndSARS tan nilẹ ki oun to pin ni.
Ẹni to bori: Namibia Burundi vs Cameroon.
Zidane: Ọjọ́ ọ̀la mi kò nìí se pẹ̀lú ife ẹ̀yẹ UCL
Iwájú ìtẹ́ náà dàbí òkun dígí, ó rí bíi yìnyín, ó mọ́ gaara.
lenu ise ijoba laini wahala tabi isoro.
Awọn iroyin ti ẹ lee nifẹẹ si: Soyinka: Buhari ti wọnu ẹmi lọ Tinubu s'abẹwo si iwọ orun ariwa Naijiria lati yanju aawọ APC O ni iwe ẹsun naa, ti wọn kọ lọjọ kẹrindinlogun osu keji ọdun 2016, paa lasẹ fun Magu lati f'esi si ẹsun naa, ko si fi ransẹ si minista feto idajọ ko to di ogunjọ osu keji ọdun 2018.
Eeyan le dero ẹwọn ti wọn ba ri wọn nibi ti wọn ti n fẹnu ko ara wọn lẹnu, koda ki wọn jẹ tọkọ taya.
Nitori naa, alamojuto whatsapp ti ni ki gbogbo ẹni to n lo whatssap lọ ṣe eto ayipada ti wọn pese pẹlu 'update'.
Ile ẹjọ naa wọgile idibo to gbe Gboluga ti ẹgbẹ oselu PDP wọle nitori Wọn fi ẹsun kan pé o jẹ ọmọ orilẹede meji(Uk ati Naijiria).
Gogu Gẹ́gẹ́ Bí Ohun Èlò Ọlọrun.
Naomi bá gba ọmọ náà, ó tẹ́ ẹ sí àyà rẹ̀, ó sì di olùtọ́jú rẹ̀.
Bí o bá fi ìyà jẹ àwọn ọmọbinrin mi, tabi o tún fẹ́ obinrin mìíràn kún àwọn ọmọbinrin mi, bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé kò sí ẹnìkan pẹlu wa, ranti o, Ọlọrun ni ẹlẹ́rìí láàrin àwa mejeeji.
Kudirat Abiola: Akọni obìnrin tó jẹ́ igilẹ́yìn ọgbà fún ọkọ rẹ̀
Wọ́n ní, “Ọkunrin yìí ń kọ́ àwọn eniyan láti sin Ọlọrun ní ọ̀nà tí ó lòdì sí òfin.
Àbí wọn a máa gé lára rẹ̀ kí wọn fi gbẹ́ èèkàn tí wọ́n fi ń so nǹkan mọ́lẹ̀?
24 Eka eto irinna n dagbasoke si, ti o si n la awon atunto ati atunse koja, lati faye gba eto abo to peye layika wa.
Nasir El-Rufai ni gomina kẹta to laarun covid-19 lorilẹede Naijiria.
Ṣugbọn ti o ba se pe o n se ẹyin ni kayeefi, ẹkọ nla kan re fun yin lati kọ - oloselu ko ni ọrẹ titi lailai.
Jakọbu bá sin Labani fún ọdún meje nítorí Rakẹli, ó sì dàbí ọjọ́ mélòó kan lójú rẹ̀ nítorí ìfẹ́ tí ó ní sí Rakẹli.
Kọmisana ọlọpa naa ni lọjọ Kẹtala osu Kẹrin ọdun 2019 ni awọn ọtẹlẹmuyẹ ileesẹ ọlọpa naa, lẹyin isẹ iwadi wọn to jinlẹ, gba awọn afurasi afọmọ sowo naa mu, to fi mọ iya ọmọ tuntun naa ati Nọọsi to gbẹbi fun.
Ó sì ti rán Sadoku alufaa, ati Natani wolii, ati Bẹnaya ati àwọn tí wọn ń ṣọ́ ọba pé kí wọ́n tẹ̀lé Solomoni, wọ́n sì ti gbé e gun orí ìbaaka ọba.
orúkọ ọmọ sáábà máa ń wá láti ọ ̀ dọ àwọn òbí méjéèjì ìyá àti bàbá ọmọ àti àwọn obí tó bí òbí méjéèjì yí wọ ́ n bí ọmọ tí wọ ́ n fẹ ́ sọ lórúkọ.
Yoruba Nollywood: Jide Kosoko ní Mr Latin ò lè dá a ṣe gẹ́gẹ́ bí ààrẹ TAMPAN
Jehoṣafati bá dìde dúró láàrin àwọn tí wọ́n ti Juda ati Jerusalẹmu wá sinu tẹmpili, níbi tí wọ́n péjọ sí níwájú gbọ̀ngàn tuntun, 
O kere tan, ẹgbẹrun mẹta awọn ọmọ ẹgbẹ oṣelu APC lati ẹkun idibo mẹtalenigba kaakiri ipinlẹ Ondo lop n kopa ninu idibo abẹle naa lati yan ẹni ti yoo gbe apoti ibo sipo gomina ni ipinlẹ Ondo.
Bẹ̀rẹ̀ pẹ̀lú àtẹ̀jáde ti Ọdún 1835, àwọn ẹ̀kọ́ méje tẹ̀lé-n-tẹ̀lé nípa ìmọ̀ ẹ̀sìn wà nínú rẹ̀ bákannáà; ìwọ̀nyí ni a fún ní àkòrí Lectures on Faith (Ìdánilẹ́kọ̃ lórí Ìgbàgbọ́).
  Ọlọrun si pase pe ki imole jade lati inu okunkun.
Ta ni o tilẹ̀ ń fi ara rẹ pè?
aṣọ aláwọ̀ aró, ti aláwọ̀ elése àlùkò, ati aṣọ pupa, aṣọ funfun onílà tẹ́ẹ́rẹ́tẹ́ẹ́rẹ́, ati irun ewúrẹ́; 
Bibọwọ fun awọn ọmọ Naijiria le mẹhẹ diẹ nigba ti ko ba ti si ẹni ti wọn yoo sa lọ ba gẹgẹ bi aṣoju ilẹ wọn lẹyin odi.
Ni ipari ni Aare ranse ibanikedun sijoba ipinle Bauchi lori iku awon akekoo mokanlelogun atawon oluko won to sele ninu ijamba oko to sele nigab ti won n rirnrinajo afe lo si Kano.
Ninu ọrọ ikini rẹ to fi ranṣẹ, o ki Aarẹ ile aṣofin agba tuntun, Ahmed Lawan ati igbakeji rẹ, Ovie Omo-Agege, Adari ile aṣoju-ṣofin tuntun, Femi Gbajabiamila ati igbakeji rẹ, Idris Wase gẹgẹ bi wọn ṣe bẹrẹ irinajo wọn nile igbimọ aṣofin ikẹsan.
Buhari ṣalaye fun awọn aṣofin agba pe gbese owo awọn akanṣe iṣẹ to jẹ ti ijọba apapọ, eleyii ti ijọba ipinlẹ Kogi na owo le lori ni oun fẹ fi owo naa san.
Kikọ 20,000 ile ẹdinwo fawọn eeyan ni 260 ilu nla atawọn ilu kereje laarin ọdun mẹrin.
Nigeria international flight resumption: Àwọn ìlànà tuntun ti o gbọdọ tẹlèé rèé ki ó to le wọkọ̀ òfurufú lọ sókè òkun
Oríṣun àwòrán, @Akinyemi Ileewosan to ṣe ayẹwo naa wa lara awọn ileeṣe ayẹwo fun arun Coronavirus to gba ontẹ ijọba ati ajọ to n risi ọrọ ajakalẹ arun ni Naijiria, NCDC.
Ibrahim Magu: Ọ̀gá àgbà báńkì tẹ́lẹ̀ rojọ́ tako alága EFCC tẹ́lẹ̀, ó fẹ̀ṣùn ìbàjẹ́ kàn-án
Adesanya ti wọn n pe ni Last Stylebender"" lo gba Ami Ẹyẹ naa lẹyin to la Robert Whittaker mọlẹ, ni asekagba Idije UFC Middleweight Champion to waye ni Australia."
 Èèwọ ́ Ọbàtálá ni pe kò rú ẹbọ kí ó tó máa bọ ̀ .
O ni eyi ko ṣẹyin iye nkan ti awọn janduku to ja iwọde ENDSARS gba, bajẹ.
Bẹẹ gẹgẹ lọrọ Kofi Kingston ri o.
O ni: “Eto yii wa fun ilaniloye fawon oludibo Kristienin lori eto oselu Naijiria.
Akeredolu kópa nínú ìdíje eré sísá ni Ondo ‘70% ọ̀dọ́ àti obìnrin ní yóò bàmi ṣisẹ́’ Boko Haram pa ọmọ ogun Nàìjíríà 53 Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ọba Olutayọ: ìgbésẹ̀ Ọọni àti Alaafin ti ń mú ìṣọ̀kàn dé sáàrin àwọn Ọba Yorùbá Ohun alumọni to wa ni ipinlẹ Ondo Okun to jin julo nilẹ Afirika Bitumen- ekeji to tobi julọ lagbaye Cocoa - 240 tonnes ni wọn n gbe lọ si oke okun Ilọ ọlọra ati oju ọjọ to sunwọn Ohun ere oko bii agbado,ọgẹdẹ lorisirisi, ẹgẹ, eso, ẹfọ, irẹsi, obi, epo pupa, rọba, isu, ẹran ọsin, Ki lo sẹlẹ si awọn ohun alumọni ipinlẹ Ondo?
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Nigeria Looting: Àwọn jàǹdùkú dárà, ẹ wo àwòrán àwòdamiẹnu nǹkan tí wọ́n jí gbé 27 Ọ̀wàrà 2020 Awodamiẹnu ni aworan awọn janduku to yabo awọn ipinlẹ Naijiria ti wọn si ji nkan orisirisi gbe.
Aláàfin ìlú Oyo, Ikú Bàbá Yèyé tún bímọ tuntun làǹtì lanti Ìpínlẹ̀ Oyo, Ogun, Ondo buwọ́lu àbádòfin Àmọ̀tẹ́kùn Akẹ́kọ̀ọ́ wọlé padà, ìjọba Oyo kò pèsè ìbòmú lòdì sí ìlérí rẹ̀ Ilé aṣòfin Oyo àti Ogun buwọ́lu àbádòfin ikọ̀ aláàbò Amotekun Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Awon Alufaa mewaa naa so pe, asiko ko ti to bayii lati se ijiroro tabi fenuko lori sise atunse si iwe abadofin.
Ikede yii jẹyo gẹgẹ bi ile iṣẹ naa ṣe fi awọn ilu mẹrin miran kun eleyi to ti wa nilẹ nibi ti awọn eeyan yoo ti ma lo ẹrọ ajuwe ọna.
Alukoro fun ileeṣẹ ọlọpaa ni afurasi ọhun gbiyanju lati pa obinrin naa ninu iyara ti wọn jọ wa lẹyin to gun un lọbẹ ni ikun.
Lasiko naa, ara ko rọ okun, bẹẹ ni ko rọ adiẹ pẹlu, tawọn osisẹ gunle iyansẹlodi, awọn osisẹ elepo rọbi ko sisẹ, ohun gbogbo dẹnu kọlẹ, ti ẹya Yoruba si n dunkooko lati ya kuro nilẹ Naijiria ti wọn ko ba kede oloye Abiola bii aarẹ Naijiria.
Òun ni orí fún ara, tíí ṣe ìjọ.
Bí a ti ṣe ṣe ètò gbogbo nǹkan wọnyi nìyí.
Òní ni ọjọ́ tí OLUWA dá,ẹ jẹ́ kí á máa yọ̀, kí inú wa sì máa dùn.
Lẹ́yìn náà, ó fara han Jakọbu, ó sì tún fara han gbogbo àwọn aposteli.
Nítorí tí kò bá ṣe ẹ̀yin, ta tún ni ìrètí wa, ayọ̀ wa, ati adé tí a óo máa fi ṣògo níwájú Oluwa wa Jesu nígbà tí ó bá farahàn?
Ìtàn ti akọkọ yìí ló sọ bí olódùmarè ṣe ran àwọn oriṣa láti wá dá ayé .
 ara mi ń sú gàn-in gàn-ìn .
Ninu ọrọ ti wọn sọ lọjọ Aje, wọn ni wọn fẹ gbe akoso ileeṣẹ naa le ọmọ Naijiria lọwọ ni.
OLUWA, Olùràpadà rẹ, Ẹni Mímọ́ Israẹli, ní,“Èmi ni OLUWA Ọlọrun rẹ,tí ń kọ́ ọ ní ohun tí yóo ṣe ọ́ ní anfaani,tí ń darí rẹ, sí ọ̀nà tí ó yẹ kí o gbà.
O ni banki CBN gbe ero kan kalẹ lati ṣatunṣe si iye owo ti ijọba n na lapapọ ni igboro.
Àwọn ọmọ àwọn tí ń ni ọ́ lára yóo wá, wọn óo tẹríba fún ọ;gbogbo àwọn tí ń kẹ́gàn rẹ,yóo wá tẹríba lẹ́bàá ẹsẹ̀ rẹ;wọn óo pè ọ́ ní ìlú OLÚWA,Sioni ti Ẹni Mímọ́ Israẹli.
 Aye Henshaw wa gbosuba fun ile-eko
Eyi ni mo fi wa mọ pe wọn fẹran mi.
ó sì fà mí yọ lọ́wọ́ àwọn ọ̀tá mi.
Ẹ mú kí iṣẹ́ wọn jẹ́ ayọ̀ fún wọn, ẹ má jẹ́ kí ó jẹ́ ìrora.
O rọ awọn ara ilu lati ṣe ọdun naa laisi wahala kankan ki wọn si lo asiko naa lati fifẹ han si ọmọnikeji wọn.
Amaraya, olórí alufaa ni alabojuto yín ninu gbogbo nǹkan tí ó bá jẹ mọ́ OLUWA.
tabi bí ẹnìkan bá ń jowú tí ó sì rò pé ọkunrin kan ń bá iyawo òun lòpọ̀, bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé ọ̀rọ̀ kò rí bẹ́ẹ̀, 
Bayii ti wọn ti ni ki Umar Abba maa dari eto ajọ naa, ibeere tawọn eeyan n beere ni pe ta ni Umar Abba jẹ?
29 Agẹmo 2019 Ministerial Screening: Aregbesola, Fashola àti Gbemi Saraki wí tẹnu wọn29 Agẹmo 2019 Food Festival: Ìbọn pa èèyàn mẹ́ta níbí ayẹyẹ Oúnjẹ ní Carlifornia29 Agẹmo 2019 Fídíò, Joke Silva: Olu, ó tó gẹ́ pẹ̀lú obìnrin yìí níkan tó ń ba ẹ ṣeré ìfẹ́ nínú sinimá!
 irinsẹ ́ àwọn ọ ̀ mọ ̀ lé , ahunsọ , àwọn alágbẹ ̀ dẹ ni yóò rọ ̀ ọ ́ jáde .
" Akojọpọ awọn nkan meje to se koko nipa Weah ni yii: Oríṣun àwòrán, Reuters Wọn bii ni ọjọ kinni, osu kẹwa, ọdun 1966 O dagba ni agbegbe kan ti awọn ti ko rọwọ họri n gbe ni olu ilu Liberia Okiki rẹ kan lasiko to gba bọọlu fun Monaco fun saa maarun lati ọdun 1987 Ohun nikan ni ọmọ Afirika to gba ami ẹyẹ FIFA gẹgẹ bi agbabọọlu to dara julọ lagbaye, to fi mọ Ballon d'Or O fẹyinti gẹgẹbi agbabọọlu lọdun 2002 Ọdun 2005 lo kọkọ dije du ipo aarẹ Wọn d'ibo yan an gẹgẹ bi aarẹ ninu osu kejila, ọdun 2017.
Wa orilẹ-ede Wa orilẹ-ede Awọn eniyan n dahun bi wọn ṣe fi ara mọ gbolohun yii to tabi bẹẹkọ Yan gbolohun kan lati mọ esi 1.
“Ayọ̀ ń bẹ fún ẹni tí ó bá gbẹ́kẹ̀lé OLUWA,tí ó fi OLUWA ṣe àgbẹ́kẹ̀lé rẹ̀.
Malcolm to jẹ alakoso oṣere nigba aye rẹ niroyin to n tẹ wa lọwọ sọ pe o ku laarọ oni, ọjọ Abamẹta si ile iwosan kan ni agbegbe Surulere, nilu Eko.
Oríṣun àwòrán, @ASK_des Ọkan lara awọn to fesi si ọrọ Trump sọ pe, o dara bẹẹ, iwọ lo faa Iwọ nikan ṣoṣo lo yẹ ko daa duro, o yẹ ki o doola ọpọ ẹmi."
Amọ, iroyin ti o kọkọ jade ni pe eniyan ọgbọn lo ku ninu iṣẹlẹ naa lẹyin ti ikọ Boko Haram ṣekọlu si wọn.
Àwọn alátakò ní, àwọn físà yìí wà fún àwọn ilé ìṣẹ́ Silicon Valley láti gbé iṣẹ́ àwọn ọmọ ilẹ̀ amẹrika fáwọ́n míràn láti ilẹ òkèrè kí wọ́n ó le san owó péréte fún wọn pẹ̀lú.
“Ẹ̀yin ni ẹ dúró tì mí ní gbogbo àkókò ìdánwò mi.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Oyo SUBEB: Ayédèrú ní ìròyìn tó ní à ń gba ènìyàn sísẹ́ 6 Ògún 2019 Oríṣun àwòrán, Ministry of information, Oyo Ajọ to n risi eto ẹkọ ni ipinlẹ Ọyo, Oyo SUBEB ti n se iwadii lori awọn to gbe iroyin ayederu jade pe ijọba ipinlẹ Ọyọ n gba awọn olukọ sisẹ.
Yorùbá ma nlo Aso-Oke fún Igbéyàwó, Ìkómọ, Òkú ṣi ṣe, Oyè ji jẹ, àti ayẹyẹ ìbílẹ̀ yoku.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Kwara yóò gbàlejò BBC Yoruba Ti a ko ba gbagbe, Ọjọ Isinmi ni iroyin gbe jade wi pe, awọn ọmọogun Naijiria ṣigun bo ile iṣẹ Daily Trust.
Àwọn Ọba alayé ní Naijiria ṣàbẹ̀wò sí Ọba Eko, Gómìnà Eko àti Bola Tinubu lẹyin ìwọ́de EndSARS Lẹyin naa lo sọ pe oun ni ifẹ arakunrin naa gidigidi.
"Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Apple iPhone 12 pro Max:Mọ̀ nípa iPhone 12, fóònù ológo 5G tí kìí lo ""Charger” tó ṣẹ̀ṣẹ̀ jáde 15 Ọ̀wàrà 2020 Oríṣun àwòrán, APple Àkọlé àwòrán, Foonu iphone 12 to jẹ alawọ buluu, niwaju ati lẹyin lleeṣẹ Apple Corps ti fọwọ sii pe iPhone 12 tuntun to jade ni iru rẹ akọkọ ti yoo lo itakun ayelujara 5G."
Awọn eeyan to gba lati maa woran nigba ti irawọ orilẹ-ede yii fẹ maa wọmi loju wọn.
Ni bayii apapọ iye eeyan to ti ni arun naa ni Naijiria ti wọ 102,601.
tun tesiwaju pe wọn mọ eredi ti awon eniyan se fi ẹhonu han latari iwa buruku
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Nkechi Blessing: Blessing ní ìkébé òun tóbí ju ohun tí òun lè dọwọ́ bò lọ, gbogbo èèyàn ló mọ̀ 26 Owewe 2020 Oríṣun àwòrán, Instagram/NkechiBlessingSunday Yoruba bọ, wọn ni ọla abata lo n mu odo ṣan an, ọla baba ọmọ ni mu ọmọ yan.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù FBI List: A tí mú obinrin kan lára àwọn gbájuẹ̀ ti FBI ń wá- EFCC 2 Owewe 2019 Oríṣun àwòrán, FBI Àkọlé àwòrán, EFCC gba ọkọ ayọkẹlẹ 30, òògùn ìbilẹ àti ọ̀pọ̀ fóònù lọ́wọ́ àwọn gbájúẹ̀ Àjọ tó ń gbogun ti ìwà jẹgudu jẹra ni orílẹ̀-èdè Nàijíríà ( EFCC) ní ọwọ́ sìkún oun ti tẹ̀ obinrin kan lára àwọn ti FBI ń wa.
0 2,933 Channel Islands 76 44.
 Ààfin ọba ni ilé ẹjọ ́ tó ga jù .
Igbesẹ yii ko sẹyin bi awọn jaguda kan se pa aadọta eniyan ni agbegbe naa lopin ọsẹ.
Nígbà tí Josaya ọba rí ibojì wolii tí ó sọ àsọtẹ́lẹ̀ náà, 
Ìjẹ̀ṣà kò kọ̀ láti kọ ọmọ wọn lọ́mọ tí ó bá jalè tàbí tí kò níṣẹ́ kan pàtàkì lọ́wọ́.
World Toilet Day: Onímọ̀ kan ní ìpèsè ilé ìgbọ̀nsẹ̀ nìkan kò lè tàn ipenija yí
Ninu atẹjade kan to fi sita loju opo twitter rẹ,Amnesty International ni ibanujẹ nla lo jẹ pe irufẹ iṣẹlẹ tun lee maa waye ni kopẹkopẹ si asiko ti ọwọ awọn ọlọpaa ṣẹ tẹ awọn ọkunrin mọkanla kan fun fifi ipa ba ọmọ ọdun mejila kan lajọṣepọ ni Limawa ni ilu Dutse ni ipinlẹ Jigawa.
 d ) ní ìmọ eré ìtàgé .
Nítorí náà, ilẹ̀ náà ń ṣọ̀fọ̀, gbogbo àwọn tí wọn ń gbé ibẹ̀ ń jìyà, àwọn ẹranko, àwọn ẹyẹ, ati àwọn ẹja sì ń ṣègbé.
kí ó tó já Àwọn olùgbé Fiditi pé fún ìrànlọ́wọ́ lórí àwọn òrùlé tí atẹ́gùn ojó ṣí lọ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Okùnrin SARS náà sọ pé òun máa pa èèyàn síbi ni- Aladugbo Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
'Imọran mi si awọn to n pariwo pe awọn eniyan to wa laye ti pọju, ati pe ohun lo n fa aito ounjẹ ni awọn ibi kan, ni pe irọ patapata ni.
Bakannaa, Kylian Mbappe to jẹ ọmọ ọdun mọkandinlogun lo gba ami ẹyẹ ọdọmọde agbabọọlu to pegede julọ ninu idije ife ẹyẹ agbaye ni Russia.
O ni ijamba ina ti o sẹlẹ yii, ti ko ba igbe aye awọn eniyan naa, nitori naa, eto iranwo lati odo ijọba , ibilẹ ati ipinlẹ yoo din ipenija to de ba awọn eniyan naa ku.
"O ni ""ẹyin ti ẹ n fun mi lọrun lori ọrọ ara sisan yii, ẹ jọwọ ẹ fi mi lọrun silẹ ki n ṣaye mi bo ṣe wu mi."
Wọ́n mú ọmọ náà lọ sílé láàyè.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ìbejì Oníbẹ̀mbẹ́ Òru tí kò yara wọn lẹ́yìn ọgọ́ta ọdún Ohùn ìjálá lásán ni mo fi ń pa ẹran nínú igbó - Ọdẹ Oníjàálá Mo fẹ́ ọkọ mi torí bó se ń kọrin, kìí se torí owó - Ìyàwó Aràrá Mo fẹ́ kí àyẹyẹ ìgbeyàwó mi dùn ni mo se bú sẹ́kún - Ọkọ ìyàwó ẹlẹ́kún Samuel Ladoke Akintọla jẹ́ Agbẹjọ́rò àti Akọ̀ròyìn tí ọ̀rọ̀ dá lẹ́nu rẹ̀ Hubert Ogunde rèé, baba àwọn òsèré tíátà Ìyàtọ̀ wà nínú ìlépa àwọn òṣèré tíátà ayé àtijọ́ àti ìsisìnyí-Papalolo O fi kun pe ọkan ninu awọn ọmọ iya meji naa bimọ, to si n wa owo ikomọ tii se ẹgbẹrun lọna igba naira, ni eeyan kan to n wa ori eeyan ba bẹẹ nis pe to ba lee gbe ori wa, yoo gba owo naa.
Kini o de ti o fi n ti lẹkun?
Ooni Ile ife, Ààrẹ Gani Adams fárígá lórí ikú ọmọ Fasoranti Ta ni Ọgágun àgbà Lamidi Adeosun tó ṣẹṣẹ gba ìgbéga?
Nígbà tí ó bá yà n óo mú kí o kọlu ilẹ̀ mi, kí àwọn orílẹ̀-èdè mìíràn lè mọ̀ mí nígbà tí mo bá ti ipasẹ̀ ìwọ Gogu fi bí ìwà mímọ́ mi ti rí hàn níṣojú wọn.
Wọ́n sì ń fún un ní burẹdi kan lojumọ láti òpópónà àwọn oníburẹdi títí tí gbogbo burẹdi fi tán ní ìlú.
Amọ o ni wọn se ipinnu ọhun lẹyin iwadi wọn nipa isesi Oluwo si awọn ọba alaye yoku nilẹ Yoruba.
Oríṣun àwòrán, INSTAGRAM/HUSHPUPPI Amọ aarẹ ana fun ile asofin agba ilẹ wa, Senatọ Bukola Saraki ti foju lai wo ikede ẹgbẹ oselu APC naa.
OLUWA ní, “Nígbà tí ó bá yá,n óo já àjàgà kúrò lọ́rùn wọn.
" O fi kun ọrọ rẹ pe awọn obi oun tun sọ pe oun o ti i ju ọmọ ọdun marun un nigba naa.
 Ìtọ ́ jú àwọn ènìyàn tó ní taeniasis ṣe pàtàkì ní dídènà ìtànkálẹ ̀ rẹ ̀ .
Wọ́n bá ń fi ṣe yẹ̀yẹ́, ó bá lé gbogbo wọn jáde.
Abiodun ni awọn ọlọpaa to pa ọmọ naa kii ṣe ọlọpaa ipinlẹ Ogun lati ọdọ adari zone ni wọn ti wa.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Eégun àti orò, bí wọ́n ṣe jọ bí Ẹ̀ṣà Egúngún nílẹ̀ Yorùba rèé Awọn onibara to wa ni adugbo naa sọ pe awọn ko fẹ ki Omotara mọ ibi tọmọ naa wa nitori awọn ko fẹ ki nkankan ṣẹlẹ sii.
Ṣe ni wan ń yọ bii ọjọ ti awn ankara wọn rẹwa jọjọ, ati Yoruba ati oyinbo lo yọ bi ọj ninu aṣọ ibilẹ Yoruba.
Nítorí Sẹ́nétọ̀ Adeleke, ìyá àti ọmọ gbé iléeṣẹ́ ọlọ́pàá lọ sílé ẹjọ́ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ìbejì Àyànbìnrin tó ti ń di gbajúgbajà Lójú òpó Twitter, ọ̀pọ́ ènìyàn ló n ṣeléde lẹ́yìn akọni Gẹ́gẹ́ bi ìtàn ṣe sọ ọjọrú jẹ ọ̀kan pàtàkì láye olóògbé, a bíi ni ọjọrú, ọgbọ̀n ọjọ, oṣù kẹsàn ọdún 1959, ó bẹ̀rẹ̀ ilé ìwé ní ọjọrú, ìrìnajò akọkọ rẹ̀ lọ si ilẹ̀ Amẹrika jẹ ọjọrú, ètò orí rẹdiò àkọkọ wáyé lọjọrú bákan náà ló kú lọjọrú, ọgbọ̀n ọjọ oṣù kẹ́rin ọdun 2003, ti wọn sín-ín ní ójórú, ọjọ́ kẹrìnlá, oṣù kaàrún ọdún 2003.
Ajo eso onibode lorile ede Naijiria (The Nigerian Customs Service) ti mu oko-epo robi J5 ati oko to n se fayawo iresi lati Kaduna si Zaria.
N óo yí ìtìjú wọn pada sí ògogbogbo aráyé ni yóo máa bu ọlá fún wọn.
Ìjìyà ń bẹ fún àwọn ti adé ọ̀rọ̀ náà bá ṣí mọ́ lóri -Ọga àgbà FRSC Ambode ní kò sí gìrì, eré ọwọ́ lásán ni EFCC ń ṣe Ta ni Seun Fakorede, ọmọ ọdún 27 tó fẹ́ di kọmiṣọna?
Opopona marosẹ Akurẹ si Ileṣa ni wọn ti ri ọjs Ọgbẹni Agbeyangi.
Gbogbo àwọn tí wọ́n mọ̀ ọ́ láàrin àwọn eniyan láyé ni ó yà lẹ́nu nígbà tí wọ́n rí ọ.
Ta ni ó lè máa gbé orí òkè mímọ́ rẹ?
Opopona Marosẹ Eti-Osa Lekki Epe Expressway8.
Oṣere tiata Mercy Aigbe ati sọrọsọrọ Toke Makinwa naa wa lara awọn to ba dunnu fun iroyin ayọ yii.
Ọgbẹni Agada sọ pe lati asiko diẹ sẹyin, ọpọlọpọ onijibiti eniyan lo ti wọ ile aṣofin wa, ti wọn si n pe ara wọn ni akọroyin.
Ẹfunsetan Aniwura, obìnrin tó ju ọkùnrin lọ Ọ̀rọ̀ǹpọ̀tọ̀niyùn, Aláàfin obìnrin àkọ́kọ́ rèé, tó ní nǹkan ọkùnrin Àkọlé àwòrán, Ibodè Lekki Ipinlẹ Eko ni ibudo kata kara to fẹ ju lorilẹede Naijiria bẹẹ naa si ni bii baraku ni sunkẹrẹ fakrẹ ọkọ jẹ ni ilu naa to bẹẹ to fi n ṣakoba fun ati oṣiṣẹ ọba to fi mọ awọn oniṣẹ aladani lojoojumọ.
Adele Aarẹ Osinbajo yọ Daura nipo lẹyin to ran ọtẹlẹmuyẹ DSS lati dina mọ awọn aṣofin agba ti wọn fẹ wọle l'Abuja.
Ojú Shagbada Erigga rèé lẹ́yìn tó pa ọ̀rẹ́bìnrin rẹ̀ l'Akinyele ní Ibadan Ọwọ́ ọlọ́pàá ìpínlẹ̀ Oyo tẹ àwọn afurasí lórí ìpànìyàn tó wáyé ní Akinyele Lẹyin naa ni awọn ọlọpaa lati ẹka ileeṣẹ ọlọpaa to wa ni Moniya ri oku rẹ ninu igbo naa.
O ní agogo ẹ̀gbẹ̀ẹ̀gbẹ́ náà Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ara 'ọmọ ènìyàn máa ń gbìnyànjú láti dúró dédé ni gbogbo ìgbà.
Kò sí ẹni tí ó lè kọ́ ilé fún un, nítorí pé ọ̀run, àní ọ̀run tí ó ga jùlọ, kò le è gbà á.
OLUWA sán ààrá láti ọ̀run,Ọ̀gá Ògo fọhùn, òjò dídì ati ẹ̀yinná sì fọ́n jáde.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù EndSars Protest: A kò lọwọ́ sí ìwé ìpẹ̀jọ́ tó tako ìdásílẹ̀ ìgbìmò ìwádìí aṣemáṣe ikọ̀ SARS 4 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Oríṣun àwòrán, NPF Ileesẹ ọlọpaa lorileede Naijiria ti koro oju si iwe ipẹjọ kan to tako idasilẹ igbimọ iwadii lawọn ipinlẹ Naijiria eyi to n tọpinpin aṣemaṣe ìkọ ọlọpaa SARS.
Báyìí ni Baba onírùngbọ̀n yẹ́úkẹ́ parí ọ̀rọ̀ rẹ̀, lẹ́hìn èyí a díde kúrò ní orí ilé rẹ̀, a wá sí ìsàlẹ̀ pẹ̀tẹ́ẹ̀sì náà á ń gbádùn ara wa.
Ọmọ orílẹ̀èdè Ṣáínà ni onítọ̀hún ń ṣe.
Igi pomegiranate, igi ọ̀pẹ ati igi ápù, ati gbogbo àwọn igi eléso ti gbẹ,inú ọmọ eniyan kò sì dùn mọ́.
Ìtẹ́ ògo tí a tẹ́ sí ibi gíga láti ìbẹ̀rẹ̀ ni ibi mímọ́ wa.
Naira mọ́kàndínlọ́gọ́fà ní àwọn ilé epo míràn ń tà á ní ìpínlẹ̀ Porthacourt, sùgbọ́n láìpẹ́ nǹkan ti olúkúlùkù bá rà, ni wọ́n ó tà, ẹni tó bá sì rà ọjà ọ̀wọ́n, náà ni yóò wá bí yóò ṣe tà á.
Ilẹ Gẹẹsi ti fi atilẹyin wọn han fun ikọ ọmọogun Naijiria to n gbogun ti Boko Haram ni agbeegbe Ariwa orilẹede Naijiria.
Awọn wọnyii maa n rin kaakiri lai wọ asọ, wọn maa n jẹ ẹran ara eniyan ti wọn a si ma a fi agbari eniyan ṣe igba imumi ati ti ounjẹ, ati pe oogun oloro marijuana ki n wọ́n lọwọ wọn lasiko naa.
Manase ṣe nǹkan tí ó burú lójú OLUWA nítorí pé ó tẹ̀lé ìwà ìríra àwọn eniyan ilẹ̀ náà, tí OLUWA lé jáde kúrò níwájú àwọn ọmọ Israẹli.
Oríṣun àwòrán, Fatima Muhammad Koda, arun Coronavirus to n ja kiri yii tun mu ki awọn ọdọ nifẹ lati lọ se abẹwo si ibi ti ẹwa ayika pin si naa.
Oríṣun àwòrán, others A pe awọn Emir ati ijoye jọ lati ẹkún guusu ati ariwa Naijiria pẹlu awọn eekan ilu, awọn eeyan to wa ninu ijọba ati awọn ti ko si nibẹ, A ṣe ipade naa ni ibudo igbafẹ awọn ologun Camp Bassey, ta si pinnu lori agbekalẹ ofin idunkooko mọ Naijiria, ta si fi ẹnu ko lori awọn igbesẹ kan."
Ohun ti a ti jabọ saaju nipa iroyin yi Loni ni iwọde ni iranti iku Imam Hussein to jẹ ọmọ ọmọ anọbi n waye lọdọ awọn ẹlẹsin Shiite lagbaye Lẹyin ti iroyin gba oju ayelujara pe awọn agbofinro ti pa mẹta ninu awọn ọmọ ẹyin Shiite ni Kaduna, BBC kan si abẹnugan awọn Shiite.
Bí ènìyàn bá tọ̀ mí wá fún ìrànlọ́wọ́, mo máa dúró tì wọ́n gbágbágbá,” ó sọ nínúu ìfọ̀rọ̀wánilẹ́nuwò orí ẹ̀ro-ìbánisọ̀rọ̀ kan.
Idí niyii ti mo ṣe gbọ́dọ̀ fi ipò mi silẹ̀ ni NIMC.
Àwòrán aràmbarà nípa ìdìbò 2015 #BBCNigeria2019 Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí kan sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
Ẹ kìlọ̀ fún àwọn orílẹ̀-èdè pé ó ń bọ̀,kéde fún Jerusalẹmu pé,àwọn ológun tí ń dó ti ìlú ń bọ̀, láti ilẹ̀ òkèèrè.
le die ni Milioni Kan Naira; Apo iresi to
Ṣùgbọ́n ó dùn mí láti sọ fún ọ pé pẹ̀lú ìjà ni wọ́n fi túká ni ibi àsè náà, nítorí ọ̀tọ̀ ni wọ́n kó àwọn ẹranko sí tí wọ́n sì tẹ́ teburu fún wọn.
Orumọju ni wọn pari abala kinni, ni ibi ti wọn ti fi ẹsun kan an pe, o ṣi ipo rẹ lo gẹgẹ bi aarẹ ti wọn si fi ọwọ osi juwe ile fun un.
Bi o ba n wakọ, ma ṣe mu ọti, ti o ba n mu ọti, ma ṣe wakọ.
Nibayii, gbogbo eto lo di doju ọgbagade ninu ẹgbẹ oselu PDP bayii fun eto idibo abẹnu naa to n waye loni ọjọ Isẹgun.
Ni tõtọ, owó ni enia ma fi lọ ra èlò ọbẹ̀ lọ́jà, ṣùgbọ́n fún ẹni ti ó mọ ọbẹ̀ se, ìwọ̀nba owó ti ó bá mú lọ si ọjà, ó lè fi ra èlò ọbẹ̀ gẹ́gẹ́ bi owó rẹ ti mọ, ki ó si se ọbẹ̀ na kó dùn.
Bẹ́ẹ̀ náà ni oúnjẹ tí mo fún ọ.
"Lara awọn to kopa ninu eto idunadura naa ni olugbaninimọran mi, awọn lọga-lọga lẹnu isẹ ologun, ọlọpaa ati ikọ Miyetti Allah.
Ọlọrun ti sọ̀rọ̀ níbìkan,mo sì ti gbọ́ ọ bí ìgbà mélòó kan pé,Ọlọrun ló ni agbára;
Ní Bẹtani tí ó wà ní apá ìlà oòrùn odò Jọdani ni nǹkan wọnyi ti ṣẹlẹ̀, níbi tí Johanu ti ń ṣe ìrìbọmi.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Walter Onnoghen: Ṣé lòótọ́ ní pé adájọ àgbà Nàìjíríà tí wọ́n ní kó lọ rọ́ọ́kún nílé tí kọwe fiṣẹ sílẹ?
Ati pe awọn yoo kede ilana tuntun fun irinajo silẹ okeere.
Obasanjo: Ilé ni bàbá wà, kò wọkọ̀ òfurufu kankan
lati koju ipenija airisẹ, ati eto idajọ lorile ede Naijiria’ eleyii wa lara
Mo ké pe OLUWA,mo gbé ohùn ẹ̀bẹ̀ sókè sí i.
Ẹ̀yin amòfin ati ẹ̀yin Farisi, ẹ̀yin aláṣehàn.
 O ni, awon igbese yii ni ijoba apapo gbe lati koju awon omo ogun olote, laasigbo laarin awon agbe ati daran-daran, ati awon idojuko miiran: Kiko apapo awon omo ogun alaabo kaakiri, eyi ti o je apapo awon omo ogun ori ile, omo ogun oju ofurufu, omo ogun oju omi, ile-ise olopaa, ati awon ajo eleto aabo miiran lorile-ede Naijiria.
Nítorí náà, ẹ̀yin ará, ẹ wá ẹni meje láàrin yín, tí wọ́n ní orúkọ rere, tí wọ́n kún fún Ẹ̀mí Mímọ́ ati ọgbọ́n, kí á yàn wọ́n láti mójútó ètò yìí.
Nínú ọ̀rọ̀ rẹ agbẹnusọ ẹgbẹ́ náà Yinka Odumakin nínú ìfọ̀rọ̀wánilẹ́nuwo rẹ̀ pẹlu ilé iṣẹ́ ìròyìn Punch ni kì ba sàn ki Tinubu pa ẹnu rẹ mọ kìí ṣe àsìkò yìí lo yẹ ki eniyan maa fi orí ahọ́n sọ̀rọ̀ kíní ìdí?"
Afurasi kan to ni oko igbo, Clement Akor ti rọ ajọ to n gbogun ti ilokulo egboogi oloro ni Naijiria (NDLEA) pe ki wọn pa oun san ju ki wọn ba oko eeka mẹwaa ti oun fi gbin igbo jẹ lọ.
 Àfojúdi gbáà ni yóò jẹ ́ .
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ibadan Accident: Èèyàn méjì kú, ẹnìkan wà nílé ìwòsàn Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Ibadan Accident: Èèyàn méjì kú, ẹnìkan wà nílé ìwòsàn 23 Agẹmo 2019 Ariwo nla gbalẹ kan lọsan ọjọ Aje ni adugbo Ologunẹru nilu Ibadan nigba ti erupẹ wo lu eeyan mẹta mọlẹ, ti meji si jẹ Ọlọrun nipe loju ẹsẹ.
Awon olopaa ko so oruko awon ti won n fesun kan Weinstein sugbon won paa mo kuro ninu ariwo awon akoroyin nigba ti won n muu lo ile ejo Manhattan nibi ti adajo yoo ti gba oniduro re.
Ṣabetai ati Josabadi, láàrin àwọn olórí ọmọ Lefi, ni wọ́n ń bojútó àwọn iṣẹ́ òde ilé Ọlọrun.
Gẹgẹ bi nkan ti ẹni to yọ̀ ejo naa jade kuro ninu iho ile igbọnṣẹ naa, Helen Richards to jẹ ẹni ọdun mọkandinlọgọta ti ejo bujẹ fẹ ẹ lo ile igbọnsẹ to wa nile ibatan rẹ kan ni ejo naa yọ ori rẹ sita, to si bu ni idi jẹ.
Yọ mí kúrò ninu ìhámọ́,kí n lè yin orúkọ rẹ lógo.
Láti ọjọ́ tí àwọn baba ńlá yín ti jáde ní ilẹ̀ Ijipti títí di òní, lojoojumọ ni mò ń rán àwọn wolii iranṣẹ mi sí wọn léraléra.
Àkókò tó láti gbẹ̀san lára ẹ̀fọ̀n mùjẹ̀mùjẹ̀
Dangote ni agbajọwọ bayi laa fi sọya ati pe, o ṣe pataki lati pese ọna iṣẹ fawọn ọdọ gẹgẹ bi ọna kan lati dẹkun iwa janduku to n peleke lawujọ wa.
Titi di afẹmọjumọ ọjọ Aje, ọpọ awọn ọlọja to ni ṣọọbu lagbegbe naa ni ko tii mọ bi ina aje ṣe jo wọn to ninu ijamba ina naa nitori ofin konile o gbele eyi ti ijọba ipinlẹ naa gbe kalẹ.
Nígbà tí ó oẹ́díẹ̀ ọ̀kan nínú àwọn igi gíga wọn-ọnnì forìbalẹ̀ lẹ́bàá ọ̀dọ̀ mi mo yára jókòó sí orí rẹ̀ kì ó tóó dìde, ìgbà tì atẹ́gùn sì tún fẹ́ tí ó dìde tán tèmi ti igi náà ni a dìde.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ifọrọwanilẹnuwo pẹlu Adeniyi Akintola lori Arisekola Alao Arisekola wulo pupo fun ilu Se asọ to ba kangun si eegun ni wọn npe ni Jẹpẹ, Asofin Adeniyi Akintola, tii se agba amofin (SAN) je ọkan lara awọn to sunmọ Arisekola Alao nigba to wa laye.
Baba obinrin náà rọ̀ ọ́ títí ó fi wà pẹlu wọn fún ọjọ́ mẹta; wọ́n ń jẹ, wọ́n ń mu, wọ́n sì wà níbẹ̀.
aadọta odun ati ikẹkọọ -gboye awon to pari ni Fafiti naa.
Ogbeni Rotimi Amaechi to je minista fun oro igbokegbodo oko lo so eyi di mimo leyin ti won pari ipade awon igbimo amusese nile ijoba l’Abuja, eyi ti Aare Buhari dari.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù SERAP: Ọ̀rọ̀ àwọn alájẹbánu ti kúrò lọ́rọ̀ yàrá, ó ti di ọ̀rọ̀ gbangba 26 Ògún 2019 Oríṣun àwòrán, @SERAPNigeria Gbogbo aye lo mọ pe ọrọ iwa ijẹkujẹ jẹ ohun kan to ti ba orukọ Naijiria jẹ nile ati loke okun fun ọpọlọpọ ọdun sẹyin.
Nítorí náà ní ìtara, kí o sì ronupiwada.
“Bí ọwọ́ bá tẹ ọkunrin kan ní ibi tí ó ti ń bá iyawo oníyàwó lòpọ̀, pípa ni ẹ gbọdọ̀ pa àwọn mejeeji; ati ọkunrin ati obinrin náà.
Eyi lohun to ṣẹlẹ lọdun 2016 to fi jẹ pe pẹlu bi Hillary Clinton ṣe ni ibo araalu to pọ julọ, ọwọ rẹ ko tẹ ipo aarẹ Amẹrika.
"Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Bawo ni aje yoo se ri fun ni South Africa ""Nibẹ ijijagbara fun ominira lo bi awọn ẹgbẹ oselu, ko si si bi oloselu se lee pe ara rẹ ni nkan lai lọwọ ẹgbẹ oselu ninu."
O je onijo to tun n korin lorisiirisii si awo bii Mejemerya Fikri ati Abashawel.
Ọjọ kẹtala oṣu kini ọdun 2011 ni wọn kede Jonathan gẹgẹ bi ẹni to jawe olubori ti Namadi Sambo si di igbakeji rẹ́.
Ọlọrun ni ó ń ṣe ìdájọ́ àwọn alaigbagbọ.
Atoun ati ile iṣẹ rẹ, Destra Investment ni ẹjọ yii kan eyi to nii ṣe pẹlu ẹsun meje ọtọtọ lori yiyi owo ti o gba lọwọ olugbaninimọran lori ọrọ abo tẹlẹ ri, Ogagun Sambo Dasuki si tirẹ.
Fayose, lasiko to se abẹwo pẹlu awọn alaga ẹgbẹ PDP nipinlẹ Osun, Ekiti ati Eko lọ silu Abeokuta lọjọru, lo fewe ọmọ mọ Makinde leti bẹẹ.
Ẹni tí ó bá sì wá kọ̀ mí, ó kọ ẹni tí ó fi iṣẹ́ rán mi.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Èmi ò kí ń lu ìyàwó mi' Bakan naa lo fikun un pe, osu kẹfa si Ikeje yii naa ni oun bi ọmọ oun ni ilu Jos lai si ibalẹ ọkan rara tabi ri ifẹ yatọ si lati ọdọ iya ọkọ oun, to si n dupẹ lọwọ mama Ijẹbu, eyiun iya rẹ.
Wọn kò fi ìyàtọ̀ sáàrin àwọn nǹkan mímọ́ ati nǹkan àìmọ́; wọn kò sì kọ́ àwọn eniyan ní ìyàtọ̀ tí ó wà láàrin nǹkan mímọ́ ati àìmọ́.
"Ko ye awọn eeyan nigba ti mo n sọ ọrọ yii, wọn a ni mo n gbiyanju lati bu ẹnu atẹ lu awọn ologun Naijiria ṣugbọn ọpọ ibatọmọlakeji eeyan jẹ wa ninu ijọba yii!
Bakan naa ni jijo igi ni igbo n ṣe akoba fun ọna ọfun, eleyii ti aisan yii ma n kọlu.
Ibídùn fí ọkọ àti ìbejì rẹ̀ silẹ̀ sáyé lọ Ọjọ́ kọkàdínlógún Oṣù tó ń bọ̀ ló pinu láti ṣe ayẹyẹ ọjọ́ ìbí ojójì ọdún rẹ̀.
Ibẹ lo ti ya sinima Ayanmọ ati Aropin n teniyan, ibudo naa si wulo fun awọn osere tiata lode oni.
Nígbà tí ó bá ń wá a, ẹ níláti dá a pada fún un.
 Vice President Yemi Osinbajo takes oath of office #Inauguration2019 pic.
lati maa ko idoti n soro, o je ki o di mimo pe ko si anfaani fun enikeni lati
Wọ́n mú kí baba wọn mu ọtí waini ní alẹ́ ọjọ́ náà pẹlu, èyí àbúrò lọ sùn tì í, baba wọn kò mọ ìgbà tí ó sùn ti òun, bẹ́ẹ̀ ni kò mọ ìgbà tí ó dìde.
Wọn kò pa wọ́n run, ṣugbọn wọ́n pa àwọn ohun tí kò níláárí run.
Orilẹede Cameroon lo yẹ ko gba alejo idije AFCON 2019, ṣugbọn wọn gba a kuro lọwọ wọn l'oṣu Kọkanla, ọdun 2018, nitori pe wọn ko jara mọ imurasilẹ ati eto aabo to mẹhẹ l'orilẹede naa.
Ṣugbọn Samuẹli dúró sí Ṣilo, ó ń ṣiṣẹ́ iranṣẹ sin OLUWA, lábẹ́ alufaa Eli.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Àwọn wo ni ọ̀rẹ́ Atiku tó fẹ́ sọ di olówó?
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ọ̀pọ̀ àwọn alase lo maa n gba ẹkọ fun ọpọọdun ki wan to lasẹ láti se ẹja náà 3.
Amọṣa, adajọ to n gbọ ẹjọ ijinigbe ti wọn fi kan Alfa Babatunde atawọn eeyan mẹfa miran, iyẹn Onidajọ Oluṣẹgun Oduṣọla ko faye gba ki wọn gba oniduro rẹ.
Ìfipábánilòpọ̀: Ọlọ́pàá ní ọkùnrin tó fipá bá ọmọ ilé ìwé UNILAG lò, tún jí pátá rẹ̀
Koda omi ati ọti ẹlẹrindodo kii ṣee ka, ibikibi lẹ ti le ri wọn ra.
Mí ò ṣe ǹkankana láì da bákan náà ní mí ò ti gbà lẹ́tà kankan láti ọ̀dọ̀ FIFA lóri ọ̀rọ̀ yìí Collin Udoh fi kún pé ó fi dá òun lójú pé oun yóò jà fiktafita lati wẹ orúkọ oun mọ."
”Ẹ̀san mi ń bẹ lọ́dọ̀ Ọlọrun mi, yóo san án fún mi.
Fi aṣọ ọ̀gbọ̀ dá ṣòkòtò fún wọn; láti máa fi bo ìhòòhò wọn, láti ìbàdí títí dé itan.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Awọn ọmọogun Naijiria ati ikọ Boko Haram ti n gbena wo ju ara wọn ti pẹ Kete ti iroyin iṣẹlẹ naa lu si ẹrọ ayelujara ni awọn eeyan bẹrẹ si ni ko iriwisi orisirisi, lẹyin naa ni fọnran fidio kan lati ọdọ awọn ọmọ ikọ Boko Haram naa runa si ọrọ naa.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ejo abami to n mu owo ni ajọ Jambu Bakan naa ni wọn ko ri oyun oṣu mẹjọ to wa ninu rẹ doola.
Ohun mẹ́fà tí kò yẹ́ kí o gbàgbé nípa Gómìnà Ambode Duro Ladipọ, ìlúmọ̀ọ́ká òṣèré tíátà àti ọmọ àlúfà tí kò gbàgbé àṣà ìbílẹ̀ Awọn kan ri oye yii gẹgẹ bi ohun to n tọka si ipa ti orileede China ni kaakiri ilẹ Afrika, ti awọn kan si n bẹru pe laipẹ China yoo gba akoso ọpọlọpọ ẹka mọ awọn eeyan Afrika lọwọ.
Margret Ngozi Igwe - Ọmọ ẹgbẹ́ Àtẹ̀jáde ọ̀hún náà tún dárúkọ àwọn ọmọ ìgbìmọ̀ tí yóò pẹ̀tù sááwọ̀ to bá súyọ lẹ́yìn ìdìbò abẹ́lé 1.
”Adeosun so pe awon iko yii ti de ilu Eko ki won to wa si Abuja , won yoo si tun maa foju gan an ni awon gimona  to wa ni ipinle ila oorun.
Nigba to n sọrọ lori bi gomina tuntun naa se wọgile ẹgbẹrun mẹta naira owo iranwọ eto ẹkọ tawọn akẹkọ ileẹkọ girama n san, Alaga ẹgb osisẹ nipinlẹ Ọyọ, Bayọ Titilọla Sodo kan saara si Makinde pe o mu ileri to se, lati wọgile owo naa sẹ.
Àkókò ìjìyà ati ẹ̀san ti dé, Israẹli yóo sì mọ̀.
ede Amerika ti fi idunnu han bi won se fọwọsowọpọ ati  lati satileyin fun orile ede Naijiria nipa
Bí a ti ń rìn súnmọ́ ni a túbọ̀ ń rí àwọn ọgbà ọ̀pọ̀lọ́ wọ̀nyí tí àwọn ejò ń sìn bí ewúrẹ́.
dola owo ilẹ okeere lati fi mu eto idagbasoke ba ina mona-mona.
Eniyan 10,152 lo ti ri iwosan gba lọwọ arun Coronavirus ni Niajiria.
Nitootọ ni ìdìbò míràn á wáyé ní Kogi, mo máa di gómínà ni -Dino Kíni ẹ mọ̀ nípa Tolani Alli, ayàwòrán tí igbákejì ààre Osinbajọ ṣẹ́ṣẹ́ yàn?
Oríṣun àwòrán, Others Oyedepo ni ara ojuse iyawo ni ko tẹriba fun ọkọ patapata, gbogbo ohun to ba si dawọle yoo yọri si rere.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Fulani Kidnapping: Owó púpọ̀ la san kí wọ́n tó fi mi sílẹ̀ Lẹyin ifẹsẹwọnsẹ ikọ agbabọọlu Super Eagles Naijiria ti wọn ti gbewuro soju Cameroon lati tẹsiwaju ninu idije Afcon 2019 ni iroyin naa bẹrẹ si nija pe Sanwoolu fun wọn lowo.
Jesu dá a lóhùn pé, “A ti sọ pé, ‘Ìwọ kò gbọdọ̀ dán Oluwa Ọlọrun rẹ wò.
Gomina ipinlẹ Ọyọ naa wa parọwa fun wọn lati dawo gbogbo ise yii ku, ki ipinlẹ Ọyọ le tẹsiwaju.
Igbesẹ yii ni wọn n pe ni infibulation.
Ijoba ipinle Gombe so pe, oun yoo gbin egbon-owu ti o to ẹgberùn lona mewaa ile(Hectres) kaakiri agbegbe mokanla nipinle naa ninu odun ti a wa yii.
“NIRSAL ti gba lati pese owo fun wa lati bere ise akanse naa, besini a ti fi oruko awon agbe ti yoo ba wa sise kale, ti ijoba Gombe yoo si se ikore ohun ogbin naa.
tele igbakeji aare lati dari awon eniyan naa .
Dà wọ́n mọ́ àwọn tí o gé wẹ́wẹ́ ati orí rẹ̀, 
Gege bi oro re, bi ise-akanse ohun ba pari tan, yoo pese anfaani ise ti o to egberun lona adosan  170,000 ninu eto oro-aje.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ayẹyẹ ifilọlẹ ileeṣẹ BBC Yoruba nipinlẹ Eko 21 Ẹrẹ̀nà 2018 Ifilọlẹ BBC Yoruba, Igbo ati Pidgin ni ẹkun iwọ oorun Africa waye nipinlẹ Eko.
Adájọ́ fi amòfin tó pá ọkọ rẹ̀ satìmọ́lé títí yoo fi gbàmọ̀ràn
Ẹ máa pa ọjọ́ ìsinmi mi mọ́, kí ẹ sì máa bọ̀wọ̀ fún ibi mímọ́ mi.
Bu yẹ̀ẹ̀pẹ̀ sí i lẹ́gbẹ̀ẹ́ kí ọ̀nà dé ibẹ̀.
Ọ̀kan ninu àwọn ọdọmọkunrin Nabali sọ fún Abigaili, iyawo Nabali pé, “Dafidi rán àwọn iranṣẹ láti aṣálẹ̀ wá sọ́dọ̀ oluwa wa, ṣugbọn ó kanra mọ́ wọn.
Àwọn ọmọ-ẹ̀yìn Jesu ní Kesaria bá wa lọ.
Ẹ̀rù ba àwọn eniyan tí wọn ń wo ohun tí ó ṣẹlẹ̀.
Ṣugbọn dípò kí ẹ ṣe bẹ́ẹ̀, ẹ̀ ń yọ̀, inú yín ń dùn.
"Alukoro ajọ Peace Corps ni owo asọ isẹ ati ẹkọsẹ ni owo ti wọn gba.
Òfin Ẹ̀tọ́ Ààbò Abódiakọ-akọ́diabo Ènìyàn ọdún 2018 tí a bu ọwọ́ lù nínú ilé ìgbìmọ̀ aṣòfin fi àṣẹ fún ọmọ ẹgbẹ́ náà láti gba ìwé àṣẹ ọkọ̀ wíwà, ìwé ìrìnnà, ní ẹ̀tọ́ láti pààrọ ìṣẹ̀dá ẹni nínú àkọsílẹ̀ ìlú àti Àjọ Ìforúkọsílẹ̀ (NADRA), ìfòpinsí ìjìyà, àyè láti kàwé, iṣẹ́ nínú káràkátà àti ètò ìlera láì sí ìyàsọ́tọ̀.
Lati aarọ ọjọ Isẹgun ni rogbodiyan ti gbode kan lawọn ipinlẹ kan bii Eko, Oyo, Osun, Ekiti, Ondo, Plateau ati Kano.
Ṣebí ìwọ ni o gé Rahabu wẹ́lẹwẹ̀lẹ,tí o fi idà gún diragoni?
Nisinsinyii wá rán àwọn kan lọ sí Jọpa, kí wọn lọ pe ẹnìkan tí ń jẹ́ Simoni, tí àpèlé rẹ̀ ń jẹ́ Peteru, kí ó wá.
Bi mo ti ṣe ri iroyin baalu to ja lulẹ lori ẹrọ amounmaworan,,niṣe ni o rẹmi sara'' Ọkọ òfurufú bàálù Lion Air to já ohùn gbé èèyàn mọ́kàndínláàdọ́wàá.
Àwọn ni wọ́n ni ìdá ọgọ́ta gbogbo àwọn àlárùn tuntun ni òpin oṣù June.
Shittu fi kún pé, èyí yóò túbọ ràn ìlànà ètò ìdìbò Nàìjíríà lọ́wọ́ síí ni.
Àwọn ọmọ Jakọbu sin òkú rẹ̀ gẹ́gẹ́ bí ó ti pa á láṣẹ fún wọn.
Iyaafin Dabiri –Erewa  pe ipe yii ninu iwe  to  fi ransi si ile –ise asoju orile ede Britain to wa niluu Abuja.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ìtàn rèé nípa bí Ogbomoso ṣe pa ọba, yọ nǹkan ọkùnrin rẹ jó kiri ìlú Ènìyàn mẹ́ta pàdánù ẹ̀mí wọ́n lọ́wọ́ àrùn Coronavirus ní Nàìjíríà ní Ọjọ́ọ̀rú Bí nǹkan ọkùnrin bá há sójú ara obìnrin, kìí ṣe Mágùn, ẹ má páyà Bàbálọ́jà márùn ún la ó ò ní l'Oyo tí Makinde bá lè buwọ́lu ìyànsípò YK Abass Ìjọba, e yé dẹ́yẹ sí wa mọ́, àwọn ẹlẹ́sìn ìbílẹ̀ ṣèwọ́de n'Ibadan Auxiliary gbé èèyàn mẹ́fà tó ń jáwèé ayédèrú fáwọn awakọ̀ lọ sí ilèẹjọ́ ní Ibadan Fayose ni ibi ti wọn ba fi Ẹlẹmọsọ gomina Makinde sọ, ni ko yaa sọ, oun ko si gbọdọ ri ẹsẹ rẹ nipinlẹ toun, tii se Ekiti.
Alaga igbimọ naa ni ki a tun pada wa fun ipade miran lori ọrọ ọhun ni ọjọ Eti to kọja, sugbọn o ṣeni laanu pe, awọn ọmọ ile igbimọ asofin ko yọju."
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Lọdun 1983 nijọba Shehu Shagari pasẹ pe ki miliọnu kan awọn eeyan ẹkun iwọ oorun Afirika, ti ọpọ wọn jẹ ọmọ orilẹede Ghana maa lọ silu wọn nitori ọrọ aje Naijiria to dagun.
Àkọlé àwòrán, Awọn afẹhonuhan naa taku si inu ọgba ile asofin agba l'Abuja.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ìjẹ̀bú: Àgbàlàgbà ni mo máa ń ṣe nínú eré tẹ́lẹ̀ Osere tiata naa wa sọ fun awọn ololufẹ rẹ naa pe ko le ye wọn idi ti oun fi n fo fayọ lori isẹ toun gba latọdọ Funke Akindele, oloye ni ọrọ naa yoo ye.
Àfi Olọ́run Ọ̀gá Ògo nìkan ló lè parí ìjà tí ó wà láàárin wa: olórró ejò, ọ̀tá ènìyàn, aláìlóró ejò, ọ̀tá ènìyàn, bí ènìyàn rí ejò ní gbangba ènìyàn á pa á; bí ènìyàn rí ejò ní ìkọ̀kọ̀ ènìyàn á pa á; kò sí ọ̀tá tí ó dà bí ọ̀tá tí ó wá láàárin ejò pẹ̀lú ènìyàn àfi ọ̀ta tí ó wà láàárin ọmọ èṣù àti ọmọ Ọlọ́run Ọba.
Ọ̀rọ̀ rẹ yóo sì di ìyanu ati ẹ̀rù ní gbogbo orílẹ̀-èdè ayé.
Awọn iroyin ti ẹ lee nifẹẹ si: Ta lo ni igbo?
Eyi ni ki eeyan wukọ ṣugbọn ki o ma ba omi tabi kẹlẹbẹ jade.
Nígbà tí ó ṣe díẹ̀ síi àwọn tí ó dúró sọ fún Peteru pé, “Dájúdájú, o wà ninu wọn nítorí ará Galili ni ọ́.
Ẹ ṣọ́ra kí Hesekaya má baà fi ọ̀rọ̀ rẹ̀ ṣì yín lọ́nà, kí ó máa sọ pé, ‘OLUWA yóo gbà wá.
Ó ní, “Àwọn ará Kalidea ń gbógun bọ̀, wọn yóo da òkú àwọn eniyan tí n óo fi ibinu ati ìrúnú pa kún àwọn ilé tí ó wà ní ìlú yìí, nítorí mo ti fi ara pamọ́ fún ìlú yìí nítorí gbogbo ìwà burúkú wọn.
Ó kàn jẹ́ pé ó fẹ́ gbówó lérí díẹ̀.
Wọn ni nigbati ọrọ kan eti onile ni onile kọwe ranṣẹ si ọdọ awọn ti wọn si bẹrẹ si ni gbe igbesẹ.
Agogo ara Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Àsìkò oúńjẹ àárọ̀, ní ìlànà ẹranko esi (bear) Ní àsìkò tí alẹ́ ń gùn sií ti àsìkò orun sì ń gùn sií, ọpọlọ máa ń gbẹ́ èròjà melatonin jáde- èròjà tó máa ń mójútọ́ orun àtí títají.
ati awon ọlọtẹ lati ekun Darfur ni won n lo awon kan lati da wahala sile lorile
Àwọn ọmọ Nàìjíríà ṣe ìwọ́de l'Osogbo lórí àfikún owó epo bẹntiróò Wo ohun tí ilé ẹjọ́ ní kí wọ́n ṣe fún Sunday Shodipe, afurasí ìṣekúpani l'Akinyele Owo ounjẹ ni Dupe lọ ọ gba, oyun ọmọ karun-un lo gbe pada sile.
OLUWA ní, “Àkókò ń bọ̀ tí n óo jẹ́ Ọlọrun gbogbo ìdílé Israẹli,tí àwọn náà yóo sì jẹ́ eniyan mi.
“Ìwọ OLUWA àwọn ọmọ-ogun, Ọlọrun Israẹli, ìwọ tí ìtẹ́ rẹ wà lórí àwọn Kerubu, ìwọ nìkan ni Ọlọrun gbogbo ìjọba ayé, ìwọ ni ó sì dá ọ̀run ati ayé.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Corona virus update in Nigeria: Ó lé ní N213 bílíọ̀nù tó wọlé fún ìjọba nípasẹ̀ COVID-19 14 Agẹmo 2020 Oríṣun àwòrán, Babajide sanwo-olu Ajọ kan to n wadi iṣuna ati inawo ijọba lorilẹede Naijiria ti kede rẹ pe owo to le ni igba o le mẹtala biliọnu naira lawọn ijọba apapọ ati ipinlẹ mẹrẹrindinlọgbọn to wa lorilẹede Naijiria ti tẹwọ gba lori ajakalẹ arun coronavirus lati fi koju arun naa.
O wa pe ajo INEC  lati tete wa ojutuu si isoro yii.
Nigeria Police Recruitment 2020: Àwọn ohun tí ẹ nílò fún àyẹ̀wò ìgbanisíṣẹ́ ọlọ́pàá tí yóò bẹ̀rẹ̀ ní Mon, Aug 24 Ọkùnrin tó dàgbà jù lágbàyé jáde láyé lẹ́ni ọdún 116 Orí àkìtàn ni wọ́n ti rí ọkùnrin tó ń fi ìgbẹ́ jẹ Búrẹ́dì -Iléeṣẹ́ ọlọ́pàá Oyo Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ǹjẹ́ o leè fẹ́ ẹni tó bá ń jẹ ẹran Ajá?
O jẹ ọkan pataki ninu ala wọn.
Ẹni to bori: South Africa Kenya vs Egypt.
10 Èyítí a fún ni nípa ìmísí, àti tí a fi ìdí rẹ̀ múlẹ̀ sí àwọn míràn nípa ìṣẹ́ ìránṣẹ́ ti àwọn ángẹ́lì, tí a sì kéde rẹ̀ sí ayé nípa wọn—
O tun sọ pe bi wọn ṣe fẹ maa gbe arabinrin naa lọ ni aburo baba sẹnetọ Abbo jade sita to si pariwo lẹyin to ri awọn agbebọn naa.
Bakan naa, AVM Kingsley Lar, leni ti o je oga agba fun eka tee-ko to, ni bayii, O di oga agba eka isakoso.
Nigba to n bawọn akọroyin sọrọ lọjọ Abamẹta nipa isẹlẹ naa, oludari ikọ Amotekun nipinlẹ Ekiti, Ajagunfẹyinti Joe Komolafẹ ni pẹlu ibọn ni awọn agbegbọn fi da ọkọ awọn eeyan naa duro.
"Ìyàwó Ọ̀ọ̀ni Ogunwusi kò bímọ tuntun Ọlọ́jọ́ Festival 2020:Ọ̀ọ̀ni ti Ilé Ifẹ̀ tí wọ ìléèdí ọlọjọ méje tí kò ní rí ẹnikẹ́ni sójú Iku gbajumọ Ginimbi mu ki Davido pahun da,o ni asan nile aye jẹ Wo ìbéèrè tí Femi Otedola bi ọmọ rẹ̀, Temi nípa ìgbéyàwó Ọọni fi si oju opo opo Instagram rẹ pe ""gbogbo ọpẹ ni fun Ọlọrun fun ore nla to ti ṣe."
Àwọn ẹranko ìgbẹ́ pàápàá ń kígbe sí ọ, Ọlọrun,nítorí gbogbo àwọn odò ti gbẹ tán,àwọn pápá oko sì ti jóná.
Gbogbo ọdún tí Kenani gbé láyé jẹ́ ẹẹdẹgbẹrun ọdún ó lé mẹ́wàá (910) kí ó tó kú.
Awọn sẹnẹtọ to n ṣoju apa ila oorun guusu (South East) ati awọn to ṣoju apa aarin gbungbun guusu ( South South) yari, wọn ni ko si ẹnikan lati agbegbe awọn ninu awọn ti aarẹ yan sipo.
Nígbà tí ó sọ báyìí, ìyapa bẹ́ sílẹ̀ láàrin àwọn Farisi ati àwọn Sadusi, ìgbìmọ̀ bá pín sí meji.
alimo ni a bi ni agbegbe mushin ti ilu eko si awọn obi raski ipadeola balogun alimi ( ọlọpa ilu nigeria ) ati idiatu alake alimi ( akọwe ile-ẹkọ giga ) .
Ìgbádùn déé Lọ́jọ́ àbámẹ́ta náà lọ́hun nílé, ó ṣí ǹkan ìṣeré ìbálòpọ̀ rẹ̀ tuntun ló bá bẹ̀rl iṣẹ́.
A lè se àkànpọ̀ kí á ri ọ̀rọ̀ bí&nbsp abẹ, baba, adé, alẹ́ abbl.
Jesu ní, “Ṣebí wakati mejila ni ó wà ninu ọjọ́ kan?
Lẹ́sẹ̀ kan náà wọ́n bá fi àwọ̀n wọn sílẹ̀, wọ́n ń tẹ̀lé e.
Bawumia so pe, “A ti bere ijiroro lori igbese lati ri daju pe, gbogbo goolu ti won ba n gbe kuro nile-ise ni o kuju osuwon, bakan naa,ki won si mo ibi ti o n lo”.
Oyo TUC: A ṣì fa ìjọ̀ba léti ni pẹ̀lú ìyanṣẹ́lódì
Nítorí náà, OLUWA ní: òun óo mú ọ kúrò lórí ilẹ̀ ayé.
Ibi tí èmi àti Ìjàǹbáforítì tí ń ṣiré báyìí ni mo ti rí ènìyàn mi kan, orúkọ ẹni tí ń jẹ́ n Ènìyàn-ṣe-pẹ̀lẹ́ tí ó jẹ́ àná mi ní ilé, nítorí òun ni ó fẹ́ ọmọ ẹ̀gbọ́n mi tí ó jẹ́ iyèkan ìyá mi.
24 Àti pé Ó gòkè re ọ̀run, láti jókòó lọ́wọ́ ọ̀tún ti Bàbá, láti jọba pẹ̀lú agbára títóbi-jùlọ gẹ́gẹ́bí ìfẹ́ inú Bàbá;
Gbogbo awọn to kopa lo ti wa ni iyasọtọ bayii.
Ó mú kí àwọn nǹkan wọnyi ṣẹlẹ̀,bóyá fún àtúnṣe ni, tabi nítorí ilẹ̀ rẹ̀,tabi láti fi ìfẹ́ rẹ̀ hàn.
Ni bayii, Theophilus Afelokhai yoo ropo Uzoho lati kopa ninu ifesewonse ipegede fun idije boolu ile Afrika(Africa Cup of Nations qualifier), ti iko naa yoo gba pelu iko agbaboolu South Africa, bee si ni yoo tun kopa fun ifesewonse olorejore pelu iko agbaboolu orile-ede Uganda ninu osu yii.
"Lẹyin naa ni wọn fẹ ẹ kọju ija si awọn ẹgbẹ alatako wọn.
Toyin Abraham Awọn ololufẹ oṣere Toyin Abraham ati ọkọ rẹ Kola Ajeyemi fi oriṣiiriṣii fọto awọn mejeeji pẹlu ọmọ wọn, Ire, soju opo Instagram, nibi ti wọn ti di kaka di kuuku niluu London.
ó lọ dúró lẹ́yìn lẹ́bàá ẹsẹ̀ Jesu, ó ń sunkún, omijé rẹ̀ ń dà sí ẹsẹ̀ Jesu, ó bẹ̀rẹ̀ sí fi irun rẹ̀ nù ún, ó ń fi ẹnu kan ẹsẹ̀ Jesu, ó tún ń fi òróró kùn ún lẹ́sẹ̀.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù MKO Abiola: Ọmọ 23 ni bàbá MKO Abiọla bí saájú rẹ̀, àmọ́ òun ni àkọ́bí 12 Òkùdu 2019 Oríṣun àwòrán, @mko_abiola Ti a ba n sọrọ awọn ọlọla, olowo, ọlọrọ, oloselu, ẹlẹyinju aanu ati onisowo pataki lorilẹede Naijiria, o loju ẹni to lee bọ sita pe oun siwaju Moshood Kashimawo Ọlawale Abiọla, ti gbogbo eeyan mọ si MKO Abiọla.
Erongba ijọba ni lati yanju iṣẹ to le ni ẹgbẹrun lọna ẹẹdẹgbẹta laarin ọdun 2020 si ọdun 2023.
Ẹni to bori: Côte d'Ivoire Guinea vs Kenya.
''Olóde'' ni Yorùbá ń pe coronavirus, iléeṣẹ́ Yemkem ti rí òògùn rẹ̀ báyìí- Olùdásílẹ̀ Yemkem Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Coronavirus tips: Kìí ṣe gbogbo ìbòmù ló ń dá coronavirus dúró Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Nítorí OLUWA níí fún ni ní ọgbọ́n, ẹnu rẹ̀ sì ni òye ati ìmọ̀ ti ń wá.
AFCON 2019: Níbo ni ọ̀rọ̀ owó ajẹmọnu ikọ Super Eagles dé dúró?
Wón ń kó Codeine wọlé láti ilẹ̀ òkèèrè ni ṣùgbọ́n àwọn iléeṣẹ́ tó ń se òògùn ikọ́ olómi tó ní èròjà codeine síta lé ní ogún ni Nàìjíríà, Àjọ tó ń gbógun ti àṣìlò oògùn olóró ní Nàìjíríà (NDLEA) ń gbógun ti àṣìlò rẹ̀.
Wahala yóo dé bá àwọn ará Etiopia ní ọjọ́ ìparun Ijipti.
Àwọn òmìrán tíí ṣe ìran Anakimu ni wọ́n.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Female Driver: Sokunbi ni obìnrin àwakọ̀ Dáńfó l‘Eko, tó ń lọ̀ láti ìpínlẹ̀ kan sí òmíì Agbeyẹwo tijọba n se yoo mu ilọsiwaju ba awọn awakọ, ti ijọba yoo si nawo fun atunse awọn gareji ọkọ wa, ti iyatọ yoo si ba wọn laarin ọdun kan, yatọ si bi awọn eeyan kan se maa n da owo gareji si apo ara wọn."
Bí Hushpuppi ṣe tiraka rèé l‘Eko, kí ọlà ‘òjijì’ tó dé Akẹ́kọ̀ọ́ wọlé padà, ìjọba Oyo kò pèsè ìbòmú lòdì sí ìlérí rẹ̀ Ẹ wo bí ọ̀rọ̀ òṣèlú, ẹ̀sìn àti ẹ̀yà ṣe fa ogun abẹ́lé Biafra Kàkà k‘éwé àgbọn dẹ̀ lágbo òṣèlú l‘Ondo, akọ̀wé ìjọba tún kọ̀wé fipò sílẹ̀ Ẹ wo bí ọ̀rọ̀ òṣèlú, ẹ̀sìn àti ẹ̀yà ṣe fa ogun abẹ́lé Biafra Ti temi ni pe ki n duro sinu ẹgbẹ APC, ki n si maa tọpinpin awọn ti yoo dije ninu awọn oludije ẹgbẹ wa.
"Soyinka sọ ohun to difa fun akọle yii pe ""igba ti awọn daran daran fẹ wa jọba le wa lori ninu ile ti mo kọ ni mo kọ akle naa mo si sọ fun baalẹ ati ọlọpaa agbegbe yii""."
fun ipinlẹ Niger ti fihan pe egbe , All Progressives Congress (APC) lo tun jawe
Ààrẹ Trump kọ̀wé lọ gbélé rẹ fún Agbẹjọ́rọ̀ Àgbà Ikú Ope Bademosi la ṣe fagilé ọdún Ekimogun 2018 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
"Ní ìta gbangba àwọn èròjà míràn wa tí kò ni jẹ́ kí ààrùn naa ràn, ènìyàn máa n mi gúle-gúle sínú àti síta lásìkò eré ìdárayá, àsìkò yìí kéré jọjọ fún kòkòrò yii láti bọ́ sí ọ̀dọ̀ ẹlòmíràn gẹ́gẹ́ bo se sọ fun BBC.
Ìpayà yóo bá wọn, ojú yóo sì ti gbogbo wọn papọ̀.
Àwọn ọmọ rẹ yóo pada wá láti ilẹ̀ ọ̀tá wọn.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Harry Akande: Makinde, Dele Momodu ń ṣèdárò Àgbà Oyè Ilẹ̀ Ibadan, Harry Akande tó jáde láyé 5 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 6 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Oríṣun àwòrán, AFriTVOnline Awọn eekan ilu ti bẹrẹ si ni ṣe idaro gbajugbaja olokoowo ati Agba Oye ilẹ Ibadan to di oloogbe, Oloye Harry Akande.
A ní láti ṣe iṣẹ́ ìpìlẹ̀ fún ìtako èyí.
Iyawo rẹ , Aisha,naa ko gbeyin
Bí ó ti ń fúnrúgbìn, irúgbìn díẹ̀ bọ̀ sí ẹ̀bá ọ̀nà, àwọn ẹyẹ bá wá, wọ́n ṣà á jẹ.
Gege bi wọn ti ṣe sọ,wọn ni ko le di awọn lọwọ lati ma se iwọde.
Atunto naa waye lataari asẹ tile-ise aare pa fun oga agba ile-ise olopaa ohun, Ibrahim Idris  lojoBo(Thursday) pe, ki o se atunse si eka ile-ise olopaa to n mojuto iwa odaran SARS ni kia-kia.
Olùbádamọràn pàtàki ààrẹ lóri ọ̀rọ̀ owó amúludùn Maryam Uwais kéde lọ́jọ́bọ̀ ọjọ kẹtàlélógun osù karun ọdun 2019 pé ìjọba ti ṣe àgbéjade owó láti pèsè gbogbo ètò rẹ̀ lóri mímú ti àwọn alaini gbọ láwujọ, èyí to pín si ẹ̀ka mẹ́rin, N-Power, pínpín owó fún àwọn to toṣi jùlọ, fífún àwọn ilé ìwé alákọbẹ̀rẹ̀ lóúnjẹ ẹ̀ẹ̀kan lójúmọ àti rírọkun sápá àwọn olókoowò kékèké (GEEP).
Ọọni gba pe, oriṣa ti a ko ba fidi ẹ han ọmọde kii pẹ parun, o yẹ kawọn ọmọ yii mọ pataki iran wọn.
8 508 Erekusu Bermuda 9 14.
lowo ninu jibiti ori ero ayelujara ati awon iwa gbaju-ẹ mi-in to fara pẹ ẹ, yen
nitori pe wọn ko ni agbọye ẹsin daada.
Oríṣun àwòrán, @essienudom Awọn to pe e ni ajinigbe ṣalaye pe, Saheed pọn ọmọlangidi ti ọpọ mọ si 'bebi' si ẹyin, eleyii to maa fi n tan awọn ọmọde lagbegbe naa.
lati so riri ipa pataki ti orile-ede Naijiria n ko lagbaye, bakan naa si ni mo
Sibẹ pẹlu gbogbo eleyii, awọn obinrin to n yan Garri ta yii ni owo ti wọn n na lati ṣe e gan pọ ṣugbọn ere to wa lori ni wọn fi n gbe ọpọlọpọ nkan ṣe ninu ile.
Kò tún sí Ọlọrun mìíràn lẹ́yìn mi.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Nǹkan wọ̀lú!
26 Bélú 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Garba ni awọn ajọ eleto aabo Naijiria fi n da wọn loju pe Leah ṣi wa laaye ati pe irọ ni pe o ti kú.
Nígbà tí Enọku di ẹni ọdún marundinlaadọrin ó bí Metusela.
Oluwo: Àwọn baálẹ̀ tí a sọ dì ọba ló fẹ́ fí ọ̀pá fọ́ mi lójú Oyè Ibadan kò sí fún títà - Otun Olubadan, Lekan Balogun Yàtọ̀ sí eku gọ́tà tàbí èku inú ilé, kò sí eku téèyàn ò lè jẹ - Òǹtajà Eléwé ọmọ Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Wo ohun tó ń fa àfikún epo lóòrèkóòrè ní Nàìjíríà Gbajabiamila balẹ̀ sí Ghana láti pẹ̀tù sááwọ̀ láàrin Nàìjíríà àti Ghana Isiaka Busari, Mighty Joe tó jẹ́ adigunjalè tó rọ́pò Ọyenusi lẹ́yìn tí wọ́n pa á E wo ọmọ Yorùbá àkọ́kọ́ tó jà fún ẹ̀tọ́ àwọn aláwọ̀dúdú ní America!
Lẹsẹkẹsẹ ó dìde lójú gbogbo wọn, ó gbé ibùsùn rẹ̀, ó lọ sí ilé rẹ̀, ó ń yin Ọlọrun lógo.
- Yinka TNT Gẹgẹ bi a ṣe gbọ, oloogbe naa kan ṣagbako iku nigba to wa lẹnu iṣẹ rẹ lọjọ buruku eṣu gbomi mu ọhun.
Àbúrò mi kan báyìí tí ó lọ sí ìdálẹ̀ tí kò fẹ́ wa sílé mọ́ ni bàbá mi ni ki n lọ mú wá.
”Nibayii, erongba mi ni lati fowosowopo pelu awon agbaboolu, besini awon oluranlowo akonimoogba yooku lati jo sise po fun idagbasoke iko agbaboolu yii.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fọ́nrán ohùn, Àdéhùn ètò ọrọ̀ ajé ilẹ̀ Afirika le lẹ́yìn Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ekiti Election: Ará Èkìtì ń fẹ́ gómìnà tí yòò tù wọ́n lára Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Stella Akinsọ: Àwọn Ìwé Mímọ́ fi àsẹ sí ìfètòsọ́mọbíbí Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ede Poly Rector suspension: Wọ́n ní kí ọ̀gá àgbà Pólì Ede lọ rọ́kún ńlé lórí ẹ̀sùn pé 'ó kan bẹ́ẹ̀dì sí ọ́fíìsì' 15 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Oríṣun àwòrán, Facebook/John Adekolawole Igbimọ alaṣẹ ile iwe giga Poli Ede ni ipinlẹ Osun ti ni ki ọga agba ileewe naa, John Adekolawole lọ rọkunle.
Akinwumi Isola: Wo ohun tí Abeni fi ojú ọkọ rẹ rí tórí iṣẹ́ bọ́ lọ́wọ́ rẹ̀ nínú ìwé \Nitori Owo\"""
Takọ-tabo ni ó dá wọn, ó súre fún wọn, ó sì sọ wọ́n ní eniyan.
Èyí mú kí ọ̀rọ̀ wolii Aisaya ṣẹ nígbà tí ó sọ pé,“Oluwa, ta ni ó gba ìròyìn wa gbọ́?
Òfò ni ọ̀nà ti ó bàjẹ́ mú bá ara ilú nipa ijàmbá ọkọ̀ fún onilé àti àlejò.
Muyiwa Ademola (Muyi Authentic): Osere tiata, Olootu ati Oludari ere ni Muyiwa Ademola, ti ọpọ eeyan mọ si Muyi Authentic, ti iyawo rẹ, Omolara si bi ibeji fun.
Ìlú Ìkirè sì ni wọ́n ti máa ń se Dòdò Ìkirè.
Mẹta ní ìhà ìlà oòrùn odò Jọdani ati mẹta ní ilẹ̀ Kenaani.
“Ìwọ̀fà ń yọ̀ séji tó gbojúmọ́, ó hàn pákànpọ̀ gan-an niṣẹ́ rẹ̀ bó dọ̀la”.
Kùtùkùtù òwúrò ọjọ́rú làwọn òṣìṣẹ́ ikọ̀ amúṣẹ́yá láti àjọ olówó-orí ípínlẹ̀ Ọ̀ṣun, OIRS, gúnlẹ̀ sí ọgbà fásitì náà, tí wọ́n sì ti gbàgede ìgbìmò alákòóso tó ga jùlọ níléèwé náà ati ọ́fíísì ìṣàkóso níbẹ̀.
- Lizzy Anjorin Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Wo Adigun ọmọ ọdún mẹ́rin tí òwe Yorùbá àti ìtúmọ̀ gbó lẹ́nu rẹ̀ ju tìrẹ̀ lọ Agbẹnusọ ẹgbẹ́ òṣèlú PDP rọ Fayose láti ma jẹ́ àwòkọ́ṣe òdì fún àwọn ọdọ́ nínú ẹgbẹ́.
’’“mo ro awon ijoba ati ajo ti oro yii kan lati tete pese eto iranwo fun awon ti ajalu buruku yii kolu.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù FIFA Women World Cup 2019: Orúkọ agbábọ́ọ̀lù Super Falcons 23 tí yóò lọ sí France ti ṣarajọ 25 Èbibi 2019 Oríṣun àwòrán, Nff Àkọlé àwòrán, Super Falcons yoo si koju Norway, Korea ati France ni ipele akọkọ.
Ni ọjọ yii, wọn a maa ṣe agbeyẹwo ipa ti awọn to wa ni ilẹ okere le ko lati mu idagbasoke ba Naijiria.
" irú wọn ló máa ń pe ọ ̀ sẹ ̀ tí wọ ́ n bá ti ilé lọ ́ dọ ̀ àwọn òbí wọn dé ní "" Ọṣẹ ìgbéraga ' Èyí kò yẹ ọmọlúàbí pàápàá ."
Diego Maradona ṣiṣẹ́ abẹ lórí ẹ̀jẹ̀ tó dì sí i lọ́pọlọ lẹ́yìn ọjọ́ ìbí ọgọ́ta ọdún Àlàyé rèé lóríi ìdí tí wọ́n fi ń pe aya ní ìyàwó Ẹ wo ẹyẹ ayékòótọ́ tó kó olówó rẹ̀ yọ lọ́wọ́ ikú gbígbóná Ọ̀rọ̀ ìjókòó ìgbìmọ̀ ìwádìí #EndSARS náà dé ìpínlẹ̀ Ogun Àwọn agbébọn kọlu iléèwé, wọn bọ́ olùkọ́ àti akẹ́kọ̀ọ́ sí ìhòhò Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Orlando Owoh: Èmí àti Oladipupo Owomoyela jọ lọ ẹ̀wọ̀n Alágbọn- Caroline Owoh, aya Orlando Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Ibadan Tailor: Ilé-ẹjọ́ dá ẹjọ́ lòdì sí ìwà ọ̀gá ọlọ́pàá sí télọ̀ rẹ̀18 Bélú 2020 Fídíò, Soyinka Cancer: Àṣe ara mi ni iso ti n run gbogbo bí mo ṣe n ṣèrànwọ́ lórí jẹjẹrẹ27 Bélú 2019 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 3 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 5 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Bi ó ti ẹ jẹ wi pé, Ali ti wà lóri àisàn fún bi ọgbọ̀n ọdún, inú ọmọdé àti àgbà ni àgbáyé ṣe ìdárò nigbati wọn gbọ ìròyìn ikú rẹ.
Lori fọran aworan to gbe soju opo instagram rẹ, Brown sọ wipe ayọ oun kun pẹlu bi oun ti se darapo mọ egbẹ agbabọọlu naa.
” Àwọn iranṣẹ wá ń gbá a létí bí wọn ti ń mú un lọ sí àtìmọ́lé.
Agbẹnusọ fun ileeṣẹ ọlọpaa ti Ipinlẹ Ondo, Ọgbẹni Femi Joseph ṣalaye fun BBC Yoruba pe: Ileesẹ ọlọpa fi ẹsun idigunjale ati ijinigbe kan an.
Bakanna lo ni, ko si bi o ti lee wu ko ri, ijọba yoo ni faaye gba ohunkohun ti yoo sọ orilẹede Naijiria di akitan, ti tọtun-tosi yoo maa wa da awọn ohun eelo si, eleyi to ni o seese ko sakoba fun awọn ileesẹ to sẹsẹ n gberu labẹle.
Awọn Iroyin mii ti ẹ le nifẹ sii Israel Adebajo: Ìlúmọ̀ọ́ká oníṣòwò tó fi òkò Stationery Stores pa ẹyẹ púpọ̀ Barrister ló sọ mí di èèyàn ńlá - Ayinla Kollington Ìtàn tó wà nídi òwe ‘Sebótimọ Ẹlẹ́wà Sàpọ́n’ Ìtàn tó rọ̀ mọ́ òwe ‘aṣọ kò bá Ọ́mọ́yẹ mọ́.
Oríṣun àwòrán, Reuters Aarẹ ilẹ naa, Recep Tayyip Erdogan lo kede bẹẹ lẹyin ti ile ẹjọ kan fọwọ si pe ile naa ko yẹ ni aye ile iṣẹmbaye mọ.
Ṣugbọn mo kọ́kọ́ waasu fún àwọn tó wà ní Damasku, lẹ́yìn náà mo waasu fún àwọn tó wà ní Jerusalẹmu, ati ní gbogbo ilẹ̀ Judia, ati fún àwọn tí kì í ṣe Juu.
Ọlọ́pàá tí tẹ Hamisu Wadume Oríṣun àwòrán, Nigeria Police Force Ṣe wọn ni ẹgbẹrun Saamu ko lee sa mọ Ọlọrun lọwọ.
“Nítorí tayọ̀tayọ̀ ni ẹ óo fi máa jáde ní Babiloni,alaafia ni wọ́n óo fi máa sìn yín sọ́nà,òkè ńlá ati kéékèèké yóo máa kọrin níwájú yín.
Coronavirus: Ọmọ ilẹ̀ Amẹrika kú sí Ekiti Ìjọ kò ní tilẹ̀kùn ilé ìjọsìn nítorí àrùn Coronavirus - Ondo PFN Wo àwọn irọ́ tí wọ́n ń pa fún ọ nípa àrùn Coronavirus Eyii ti mu ki apapọ awọn eeyan to ni arun naa ni Naijiria pe mejila bayii.
Oloogbe naa je omo bibi ogbontarigi olorin ni, Victor Olaiya.
Yoruba Stars in Hollywood / Europe: Sade Adu, Chamillionaire, Sikiru Adepoju wà lára ọmọ Oodua tó jẹ́ àmúlùúdùn níbẹ̀
Koda iroyin ti a tun n gbọ ni pe Kabiyesi Ọlọwọ ti ilu ọwọ ti fun Arẹmọ tuntun yii lorukọ.
Nígbà tí ó bá gbà kí ẹ lọ, òun fúnra rẹ̀ ni yóo tì yín jáde patapata.
Ìdí tí mo ṣe fẹ́ yọ ayédèrú ìdí ńlá tí mo ní- Sophie Okunrin ọhun ti orukọ rẹ n jẹ Adegboyega Adenekan, lo ri ẹwọn ọgọta ọdun he, lẹyin ti iwadii fihan pe o jẹbi ẹsun fifi ipa ba ọmọ naa lopọ.
Ní ọjọ́ keji, a gbéra, a lọ sí Kesaria.
“Ó yá tí n óo bínú si yín, tí inú mi óo ru si yín gidi.
Ninu ọrọ rẹ, Vincent ni ijiya ti ile ẹjọ gbe kalẹ yi jẹ ohun to kan oun laya.
Jordan Geller, to da ibudo iṣe nkan iṣẹnbaye lọjọ si silẹ nilu Las Vegas, lo ta bata ti Michael Jordan lo pati lọdun 1985 naa.
Nígbà tí Balaki ọmọ Sipori, ọba Moabu rí gbogbo ohun tí àwọn ọmọ Israẹli ṣe sí àwọn ará Amori, 
12 Owewe 2018 Àkọlé àwòrán, Ali Ahmad,BolajjiAbdullahi,Zakari Mohammed ati Aliyu Ahman Pategi wa lara awọn oludije fun ipo Gomina labẹ ẹgbẹ PDP Ọrọ oselu ipinlẹ Kwara n polukuu musu ni lọọlọ yii paapa julọ nipa ẹni ti yoo jawe olubori lati soju ẹgbẹ PDP ninu idibo Gomina ni ipinlẹ naa.
Ẹni to bori: Madagascar Egypt vs Angola.
Douye Diri: Ìgbìmọ̀ olùgbẹ́jọ́ ẹ̀hónú ìbò yẹ àga mọ́ Gómìnà Bayelsa nídìí
Nígbà tí wọ́n lọ ra epo, ọkọ iyawo dé, àwọn tí wọ́n ti múra sílẹ̀ bá wọ ilé ibi igbeyawo pẹlu rẹ̀, wọ́n sì ti ìlẹ̀kùn.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Oba Adeyeye Ogunwusi: Ojú mi ti rí lọ́pọ̀ lọpọ̀, ọ̀pọ̀ èèyàn ni kò tilẹ̀ gbàgbọ́ pé mo lè jọba- Ooni Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Oba Adeyeye Ogunwusi: Ojú mi ti rí lọ́pọ̀ lọpọ̀, ọ̀pọ̀ èèyàn ni kò tilẹ̀ gbàgbọ́ pé mo lè jọba- Ooni 7 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Irin ajo mi kun fun oriṣiiriṣii iṣẹlẹ nla ṣugbọn mo dupẹ lọwọ Ọlọrun O ka mi yẹ.
Ẹnikẹ́ni tí ó bá sì fi ọwọ́ kan ohunkohun, ninu ohun tí ó fi jókòó di aláìmọ́ títí di ìrọ̀lẹ́.
Bi wọn ko ba riran nipa ajalu ti yoo ṣẹlẹ, wọn a si ma fun ara ilu ni iro nipa awọn ti yoo padanu ẹmi wọn tabi ti yoo jẹ ipo kan tabi omiran ninu ijọba.
Bíi fìtílà ẹni ibi ni gbígbé ojú gangan ati ìgbéraga,ẹ̀ṣẹ̀ sì ni wọ́n.
Ará, ǹjẹ́ bí mo bá wá sọ́dọ̀ yín, tí mò ń fi èdè àjèjì sọ̀rọ̀, anfaani wo ni mo ṣe fun yín?
"Adekunle Gold ni ọdun marun sẹyin ni oun ti mọ Simisọla Bọlatito Ogunlẹyẹ ti ọpọ mọ si ""Simi"" Oríṣun àwòrán, @adekunleGOLD Àkọlé àwòrán, ""Ọdún márùn ún ni mo fi mọ Simi ká tó ṣègbéyàwó"" O ni idi ti awọn fi ṣe igbeyawo awọn ni bonkẹlẹ ni wi pe, kii pẹ ti afẹfẹ ilumọọka maa fi n gbe eniyan lọ, nitori naa ni awọn fi fẹ jẹ ki igbeyawo ati igbe aye awọn o wa ni bonkẹlẹ."
Níbẹ̀ ni ó ń gbé pẹlu àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Say no to rape: Àwọn òṣèré tíátà Yorùbá pariwo síta lórí wàhálà ìfipábánilòpọ̀ O dupe lọwọ Olorun fun aṣeyọri esi ayẹwọ naa, o si gbadura fun awọn to ti ni arun naa pe ki Olorun fun wọn ni iwosan pipe.
Aarẹ Buhari ni oun ko ṣai mọ ipenija araalu lori iwa kotọ awọn ọlọpaa ikọ SARS naa.
Ìyẹn ni pé kí ojúmọ́ àti ilẹ̀ṣú jẹ́ dọ́gba-dọ́gba.
Awọn eeyan to n gbe lagbegbe omi ni yoo kọkọ jẹ anfani yii.
Ó wípé àwọn jàgùdà pọ̀ láàrin yẹn tí wọ́n wá nkan tí wọ́n máa jígbé.
Wọn ni lo ba wọle lọ gbe ibọn ni o si dabọn bolẹ ti ọrọ naa di pẹntuka ni Kano.
Ihekweazu ni awọn yoo ṣe iṣẹ pupọ lati wadii sampu tuntun ti wọn gba lati mọ boya eleyii lee fa aranka kiakia lorilẹede Naijiria.
Ko jẹ tuntun mọ pe ijọba n mu awọn olori alatako lorileede Zambia ti awọn eeyan si ti n bẹnu atẹ lu bi ko ti ṣe si igbalaye fun titako ijọba.
Ó jẹ́ aláìmọ́; òun nìkan ni yóo sì máa dá gbé lẹ́yìn ibùdó.
" Oríṣun àwòrán, Instagram/mo_bimpe Oṣere naa, to tun n ta aṣọ ati eroja aṣaraloge sọ pe, iṣẹ igbohunsafẹfẹ ni oun i ba tun ṣe, ka ni oun ko di oṣere.
Àwọn ti ọrọ naa ṣe oju wọn ni ojo arọọrọda lo fa bi afara naa ṣe ja ni alẹ́ Ọjọ Abamẹta.
O ni oun n fẹ ki wọn gbẹsẹle iwa ti ko ba aṣa ilẹ Yoruba mu bii wiwọ aṣọ ti ko bo aya.
kinni-  Baba Kura Abba JatoIgbakeji oludari
Ṣugbọn ọdún keje yóo jẹ́ ọdún ìsinmi tí ó ní ọ̀wọ̀ fún ilẹ̀ náà, ilẹ̀ náà yóo sinmi fún OLUWA, ẹ kò gbọdọ̀ gbin ohunkohun sinu oko yín, ẹ kò sì gbọdọ̀ tọ́jú àjàrà yín.
Nitori naa nigba ti Aarẹ tẹlẹ, Oluṣẹgun Ọbasanjọ sọ pe  eto abo ti dẹnu kọlẹ pẹlu ijinigbe ni ibi gbogbo"" oots ọrs lo sọ nitori pe ijigbe tun ti burẹkẹ sii, ni pataki julọ pẹlu bi wọn ṣe ji awọn akẹkọbinrin to le ni ọgọrun gbe ni Dapchi ni ọdun 2018."
Àsìkò ààwẹ jẹ àsikò ti ó dára jùlọ ni àyíká yìí a si fẹ ki àwọn ènìyàn sín ọlọrun kíkó irú àwọn ènìyàn báyìí kúro ilẹ yóò mú ki àwọn ara ilú le pa ọkan wọn pọ si ojú kan láti lé ṣe iṣẹ́ ẹsin fún Ọlọrun.
Gideoni rán àwọn oníṣẹ́ jákèjádò agbègbè olókè Efuraimu, ó ní, “Ẹ máa bọ̀ wá bá àwọn ará Midiani jagun, kí ẹ sì gba ojú odò lọ́wọ́ wọn títí dé Bẹtibara ati odò Jọdani.
 Ajoku so pe Quadri jebi esun ti ajo EFCC  fi kan, wipe o n pe ara re ni oruko ti ko je lati fi lu awon eniyan ni jibiti, ti o si leto lati foju wina ofin, Fun idi eyi idajo mi re,”Iwo  Adebimpe Babajide Quadri, yoo fi ewon osu merin gbara pelu ise asekara.
Bí àwọn ará ìgbèríko náà ti wí bẹ́ẹ̀ náà ló rí.
Eléyì jẹ́ díẹ̀ lára ìdí tí àwọn òṣìṣẹ fi ń jà fún fífi owó kún owó oṣù.
O tun so pe “Gege bi agbofinro, a gbodo se ojuse wa lati dekun ohun to baa lee  je ki mu hila-hilo wa  .
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé Ninu atẹjade to fi sita, Ajani sọ pe''Ki lo de tawọn eeyan fi n ti irọ ẹlẹyamẹya mọ Amọtẹkun pẹlu bi wọn se koju awọn ọdaran?
Ganduje máa bá iṣẹ́ rẹ lọ- ilé ẹjọ́ gíga jùlọ Orí ló kó mi yọ níbi ìṣẹ̀lẹ̀ ọ̀pá epo tó gbaná ni Abule Ẹgba- Oluwatoyin Ojo Ninu atẹjade ti Atiku fi sita lati ọwọ oludamọran rẹ lori ọrọ iroyin, Paul Ibe, igbakeji aarẹ orilẹ-ede Naijiria tẹlẹ ni bi eto aabo ṣe ri ni nnkan bi ọdun mẹwaa sẹyin fihan pe ọrọ eto aabo nilo atunṣe ni Naijiria.
Nipataki julọ ọgbẹni Gate ni eto ilera alabọde si ku diẹ kaato eleyi to ni o n ṣokunfa iku ọwọọwọ laarin awọn ewe lorilẹede Naijiria.
Awon osise orile-ede Kenya n gbe igbese lati se agbekale ilana eyawo olodun mewaa si ogbon odun , eyi ti iye re je bilioni kan abo owo dollars of $1.
Ẹbọ ohun jíjẹ tí yóo máa pèsè pẹlu rẹ̀ láràárọ̀ ni: ìdámẹ́fà eefa ìyẹ̀fun ati ìdámẹ́ta hini òróró tí wọn yóo fi máa po ìyẹ̀fun náà fún ẹbọ ohun jíjẹ fún OLUWA.
Àwọn tó lọ inú òṣùpá , ti wọ ́ n wà nínú mọ ́ to yìí.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ìgbátí ìgbámú àná látọwọ́ sọ́jà obìnrin ti bá arákùnrin náà dé iléèwòsàn Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
O ni ẹẹkan lọsẹ lee fa aisan ọlọjọ pipẹ.
"Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: ""Lẹ́yìn ọdún méjìlá, mo gun òkè fún ọjọ́ márùn-ún kí ń tó rí ìyá mi"" Kíni ìwọ mọ̀ nípa Funmilayọ Ransome-Kuti?"
Ọjọ̀gbọ́n Akintoye ni, ìlànà ti àwọn mẹ́rin náà fẹ́ ki òun tọ́ kìí ṣe ǹka ti òun lè ṣe gẹ́gẹ́ bi àdari.
Mompha: Oríṣun àwòrán, Instagram/hushpuppi Ọrẹ timọtimọ ni awọn eeyan maa n pe awọn mejeeji yii.
Wón yoo si maa gbọ nipa iroyin agbaye, ohun to n lọ nigboro, ere idaraya, imọ ẹrọ ati iroyin amuludun nibẹ.
Ó sọ fún un pé, “Má sunkún mọ́.
14 ni àwọn akẹ́kọ̀ọ́ yóò padà sí iléèwé ní Kogi Ijọba ipinlẹ Kogi ti kede pe awọn akẹkọọ yoo wọle pada ni Ọjọ Kẹrinla, Oṣu Kẹsan an, ọdun 2020 lai yọ ileẹkọ alakọbẹrẹ, girama ati awọn ileewe giga ipìnlẹ naa.
ẹ fi èyí tí ó bá jẹ́ akọni jùlọ lára àwọn ọmọ ọba sí orí oyè, ẹ sì múra láti jà fún ilẹ̀ oluwa yín.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Lizzy Anjorin: Àsìkò 'Honeymoon' ni mo dédé rí Aláàfin àti olorì méjì tó wá súre fún wa 11 Agẹmo 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 3 Ògún 2020 Oríṣun àwòrán, @lizzyanjorin/alaafin_oyo Ilumọọka osere tiata lobinrin to ṣẹṣẹ ṣe igbeyawo, Lizzy Anjorin ti kede pe, baalu kekere taa mọ si Private Jet ni baba oun, Alaafin fẹ gba bii owo ori lọdọ ọkọ oun.
Bí ẹ tilẹ̀ fi eérú fọ ara yín,tí ẹ sì fi ọpọlọpọ ọṣẹ wẹ̀,sibẹ, àbààwọ́n ẹ̀bi yín wà níwájú mi.
Iran:: Ẹ má fi taratara dúró níbì kan nítorí àwọn tó fẹ́ gbẹ̀san ikú Soleimani
Gbogbo eleyii ko si sẹyin eto aabo to mẹhẹ lawujọ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù CAN: Ìjọ tó bá bá àwọn èèyàn láramu ni kí wọ́n lọ̀ 10 Ògún 2018 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, CAN ni ọrọ ọhun ku sọwọ awọn eeyan to ba n lọ sawọn ile ijọsin kọọkan Ni ẹnu lọọ-lọọ yii, ariwo gee ti gba ori ikanni ayelujara lori bi awọn iranṣẹ Ọlọrun kan ṣe n pe fun 'eso owo' lati ọdọ awọn ọmọ ijọ wọn.
Àwọn òmùgọ̀ a máa fi ọ̀rọ̀ ẹ̀ṣẹ̀ ṣe àwàdà,ṣugbọn àwọn olódodo a máa rí ojurere.
" Wọ́n ti wọ́gilé ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ Arsenal àti Brighton lẹ́yìn tí Mikel Arteta lùgbàdì àrùn Coronavirus Ighalo d'àràbà!
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù AFCON 2019: Àwọn olólùfẹ́ Super Eagles fẹ́ kí Rohr tún wọn tò Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ AFCON 2019: Àwọn olólùfẹ́ Super Eagles fẹ́ kí Rohr tún wọn tò 30 Òkùdu 2019 Awọn ololufẹ ẹgbẹ agbabọọlu Super Eagles faraya lori idije to waye pẹluu Madagascar.
O Obadare lasiko to wa waasu nibẹ.
Ọọni ni Mo ti dán àwọn òògùn ìbílẹ̀ náà wò, mo ti lo fún alárùn Coronavirus kan, tí wọn sì ni ajẹbiidan ni òògùn ìbílẹ̀ náà."
Mountain of Fire: Bẹẹ naa ni oludasilẹ ijọ Mountain of Fire and Miracles Ministry, sọ pe ijọsin awọn yoo waye laarin ago mẹsan si mọkanla.
- Ìjọba àpapọ̀ Donald Trump ti gbà pé Coronavirus yóò burú jáì kí ǹkan tó dára fún Amẹ́ríkà Wo bí ètò ìsìnkú Tolulope Arotile ṣe lọ nílùú Abuja Nǹkan mẹ́sàn án tí Mùsùlùmí gbọdọ̀ ṣe nínú oṣù Dhual- Hijjah Hushpuppi Ramoni Abass gangan n wa n kọ?
O ni kii ṣe idaamu, tabi aisan lo gbe oun de inu ijọ alaṣọ funfun.
Mercy Aigbe ṣá ọmọ rẹ̀ sínúu fíìmù tuntun, wo itú tí ọmọ ọdún mẹ́wàá náà pa Ariwo ló ń mú owó wọlé fún mi, kò wù mí láti gbé ayé tó dákẹ́ rọ́rọ́ - Lizzy Anjorin Aláàfin fẹ́ gba bàálù kékeré bíi owó orí mi, ọkọ mi ń gbọn kiri - Lizzy Anjorin Ọ̀nà kan ò wọjà fáwọn òṣèré tíátà, bí wọn ṣe ń ta ìpara ìbóra ni wọ́n ń ta aṣọ ẹbí Ìjà Toyin àti Lizzy kìí ṣe àkọ́kọ́, àwọn òṣèré t'ọ́rọ̀ ìjà kàn rí rèé Toyin Abraham kìí bá èmi náà yọ̀, ni kò jẹ́ kí ń gbé e lárugẹ fún ayọ̀ ọmọ - Lizzy Anjorin Gbẹgẹdẹ gbiná!
Ẹni to bori: Senegal Ìpele to ṣaaju eyi to kangun si aṣekagba Kenya vs South Africa.
Alaga egbe  oselu APC so pe ile-ise olopaa ti fi awon olopaa egberun lona ogbon ranse si ipinle Ekiti fun eto idibo naa.
Eyi si lo mu kawọn osere tiata kan fajuro lori ohun tawọn akẹẹgbẹ wọn n kọ nipa iku ọkunrin naa, ti wọn si n gbena woju ara wọn.
O wa rọ awọn araalu, paapaa julọ awọn omidan lati kiyesara lori awọn ti n lo orukọ kabiyesi fi ja wọn lole ara.
Nítorí ti àwọn ará ati àwọn ẹlẹgbẹ́ mi,n óo wí pé, “Kí alaafia ó wà ninu rẹ.
Kidnapping: Kò sẹ́ni tó mọ̀ bóyá àwọn ajínigbé gba owó ìtúsílẹ̀
Wọn ni awọn ọlọpaa naa sọ pe awọn nilo iranwọ si lati le koju awọn ajinigbe naa.
Lisa Li jẹ olokiki ni orilẹ ede China lori ẹrọ ayelujara bii iṣana ẹlẹta, ti aworan rẹ si rẹwa lọpọlọpọ.
Dokita jẹ ko di mimọ pe ẹya ẹjẹ kan ṣoṣo ti ẹni to jẹ SS le fẹ ni AA.
Nígbà tí Josẹfu dé ọ̀dọ̀ baba rẹ̀, ó rọ̀ mọ́ ọn lọ́rùn, ó sì sọkún fún ìgbà pípẹ́.
Saaju asiko yii, aarẹ Muhammadu Buhari ti kọkọ darapọ mọ awọn akẹgbẹ rẹ lọjọ ẹti to kọja fun eto ifarakinra saaju iside ipade naa.
Shehu ni ojowu, opurọ ati odalẹ ni Aarẹ tẹlẹri naa, ati wi pe oun jọwu Aarẹ Buhari ni.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Kaduna killings: Afurasí mẹ́jọ ti wọ gbaga agbófinró nítorí ìpànìyàn Gúúsù Kaduna 26 Èrèlè 2018 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 11 Ògún 2020 Oríṣun àwòrán, @simonfmudu Ikọ alaabo to n jẹ Security forces of Operation Safe Haven ti mu eeyan mẹjọ gẹgẹ bii afurasi to wa nidii ipaniyan to n waye ni lemọ lemọ ni iha Guusu Kaduna.
Adari ikọ ọmọogun oju omi orilẹede Naijiria, Ọgagun Ibot-ete Ibas lo sọ bẹẹ fun awọn akọroyin, ni ile aarẹ ni Abuja, lẹyin ti Aarẹ Buhari se ipade pọ pẹlu awọn adari ile isẹ ọmọogun Naijiria.
Ẹkẹjọ mú Jeṣaya, òun ati àwọn ọmọ rẹ̀ ọkunrin, ati àwọn arakunrin rẹ̀ jẹ́ mejila.
“Èmi OLUWA Ọlọrun Israẹli bá àwọn baba ńlá yín dá majẹmu nígbà tí mo kó wọn jáde kúrò lóko ẹrú ní ilẹ̀ Ijipti, mo ní, 
“Ẹ kọ́ ẹ̀kọ́ lára igi ọ̀pọ̀tọ́.
Manoa bá mú ọmọ ewúrẹ́ náà, pẹlu ẹbọ ohun jíjẹ, ó fi wọ́n rúbọ lórí òkúta kan sí OLUWA tí ń ṣe iṣẹ́ ìyanu.
Segalinks sọ pe, kaka ki aarẹ mu ileri rẹ to ṣe pe oun yoo ta ninu awọn baalu to wa ni arọwọto rẹ, nnkan miran lo n gbaju mọ.
"Iroyin naa n fẹsun ka oludije fun ipo Aarẹ ẹgbẹ alatako lorilẹede Senegal, Ousmane Sonko pe o gba abẹtẹlẹ gọbọi lọwọ ileeṣẹ epo ilẹ Yuropu wọn si gbe e jade pe ""Michelle Damsen"" lo kọ ọ"", lẹta meji pere lorukọ yii fi yatọ si temi - Michelle Madsen."
Orile-ede Iran ti sepinnu lati mu ileri re se lojuna lati satileyin fun atunse orile-ede Syria nipase pipese eto isuna, oselu ti o fese mule ati atileyin iko omo ogun.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Chelsea wa ni ipo kẹrin pẹlu ami àádọ́ta Ọmọ ikọ Bournemouth, Callum Wilson lo kọkọ gba bọọlu s'inu awọn ni gẹrẹ ti wọn bẹrẹ ifẹsẹwọnsẹ naa ni papa isere Standford Bridge, ki o too di wipe wọn bori Chelsea ninu ifẹsẹwọnsẹ naa pẹlu ami ayo mẹta si odo.
orile ede Naijiria ti so pe awon ti se aseyori lati gbogun ti iko omo ogun
 Àwọn tí ó ń sọ azerbaijani tó mílíọ ̀ nù mẹ ́ rìnlá ní azerbaijan ní ibi tí wọ ́ n ti ń lò ó gẹ ́ gẹ ́ bí èdè ìṣe ìjọbi .
Reno Omokri to jẹ agbẹnuọ fun aarẹ Goodluck Jonathan bu ẹnu atẹ lu Buhari lapa kan, o si tun bu ẹnu atẹ lu Ezekwesili lapa keji.
A kò ni bọ́jọ́ ọlọ́jọ́ lọ
Nítorí pé mo ti jẹ́jẹ̀ẹ́ níwájú OLUWA n kò sì gbọdọ̀ má mú un ṣẹ.
Orilẹede wa jẹ eyi o n gbogun ti ara ilu rẹ, agbẹnusọ fun ẹgbẹ alatako Movement for Democratic Change (MDC), to wa nibi igbẹjọ naa lọjọ aje to si bi wọn ṣe doju ti awọn obinrin yii wa lara ọgbọn oṣelu ati ko ibẹru sọkan awọn araalu.
Lọjọ iṣẹgun yi ni igbẹjọ yii yoo waye.
Oríṣun àwòrán, FURG Àkọlé àwòrán, Eroja ti wọn fi se burẹdi yii lo ni iyẹfun eroja asaraloore latinu awọn kokoro Ninu ọrọ ti wọn, Ajọ Isọkan Agbaye ni, kokoro n sara loore, ti ko si wọn lati ri gẹgẹbi wọn ti n se lawọn apa agbeegbe kan ni Guusu-Ila oorun Asia.
Bẹ́ẹ̀ ni Ọlọrun dá gbogbo wọn, ó wò wọ́n, ó sì rí i pé wọ́n dára.
Awọn elede Gẹẹsi si maa n pe wọn ni witches and wizards.
 Àwọn iníṣègùn kìí dífá yanbọ fúni rárá , àmọ ́ eọ ́ n ma ń gbowọ ́ ọ ̀ yà lẹ ́ yìnbtí eọ ́ n bá ṣe ìtọ ́ jú aláàrẹ ̀ tán gẹ ́ gẹ ̀ bí èrè iṣẹ ́ wọn .
Ọkàn mi dààmú, jìnnìjìnnì dà bò mí;wọ́n ti sọ àfẹ̀mọ́júmọ́ tí mò ń retí di ìbẹ̀rù mọ́ mi lọ́wọ́.
Kọmiṣọna feto ilera fi kun un pe, ileewosan ile ẹkọ naa to lọ lati ṣalaye pe iba n ṣe oun lo fi di ẹ mulẹ pe, nigba ti ko san lẹyin gbogbo itọju aisan iba gbogbo ti wọn fun un, ni wọn yẹ wo fun arun Lassa.
Igbesẹ yii waye lẹyin ti iroyin gba ori ayelujara kan wipe, ile ounjẹ China kan to wa ni Ikeja nilu Eko, Shi Shi Chinese Restaurant kọ, lati jẹ ki awọn ọmọ Naijiria wa ra ounjẹ ninu ileeṣẹ wọn.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Mo ni baba isalẹ' Oríṣun àwòrán, @Toyin Abraham/Facebook Àkọlé àwòrán, Òsèré Tíátà Toyin Abraham Toyin Abraham Toyin Aimaku ló ń jẹ́ tẹ́lẹ̀.
Kò sí ẹni tí ó lè ká a lọ́wọ́ kò,tabi tí ó lè yẹ̀ ẹ́ lọ́wọ́ wò.
Yóo jẹ́ ọjọ́ òkùnkùn ati ìbànújẹ́,ọjọ́ ìkùukùu ati òkùnkùn biribiri.
Ọ̀dọ̀ Ọlọrun ni ẹni tí ó bá ń ṣe rere ti wá.
" Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ǹjẹ́ o mọ pàtàkì igi tó wà ní àyíká rẹ bí?
Ka ni ko si ofin konile o gbele ni, awa mejeeji o ba ti jaye ori wa daada kaakiri igboro loni Iyawo mi tootọ, ayẹyẹ ọjọ ibi rẹ yoo larinrin bi iwọ pẹlu ti ṣe mu ọpọlọpọ ayọ wọ inu aye mi.
”O ni awon onisegun akosemose naa yoo ni anfaani lati lo sisei ni eyikeyi ile iwosan to ba wu won to faaye gab won nigberiko paapaa ninu itoju awon alaboyun ati awon to n tomo lowo pelu awon omode.
Ààrẹ ilẹ̀ Amẹrika Donald Trump di ààrẹ àkọkọ lóri àléfà ti yóò wọ ilẹ̀ North Korea lẹ́yìn ìpàdé pẹ̀lú Kim Jung-un ní ojú ààla to pí prílẹ̀-èdè Korea méjèèjì tí wan ń pe Demilitariksed Zone (DMZ).
Ìtìjú ńlá dé bá wa,a níláti kó jáde nílé,nítorí pé àwọn ọ̀tá ti wó ilé wa.
isoro to n dojuko orile ede yii.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Adebola Ademilua: Àìrísẹ́ ṣè lẹ́yìn ìwé kíkà ló sọ mi dí ìyá onírú, mo dúpẹ́ tèmi Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Oluwo: Oluwo ṣàlàyé ohun tó ń mú káwọn èèyàn máa gba tirẹ̀ láwùjọ28 Bélú 2020 EndSARS, Daniel Chibuike Ikeaguchi: ọlọ́pàá yìbọn pa Sleek ní Port Harcourt niléẹjọ́ bá bú N50 mílíọ̀nù, owó gbà má bínú28 Bélú 2020 Latest ASUU strike update: Ẹgbẹ́ òṣìṣẹ́ ASUU tí gbà láti fòpin sí ìyanṣẹ́lódí lẹ́yìn tí ìjọba gbà látí sàn N70bn28 Bélú 2020 Ọkùnrin kan lu ìyàwó rẹ̀ pa"" ní ìpínlẹ̀ Ogun nítorí ó lọ síbi ayẹyẹ ìsọmọlórúkọ28 Bélú 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!"
 Ọba ìlú náà ní ipa pàtàkì tirẹ ̀ làti kó .
Akitiyan ìjọba láti mú kí àwọn ọmọ Nàìjíríà san owó orí Kò tíì sí ìrànlọwọ owó f'àwọn ọmọ Nàìjíríà tí ń bọ láti South Africa -Abike Dabiri Ó lé ní ẹ́gbẹ́ta àwọn ọmọ Naijiria tí wọ́n ti ṣetàn láti padà sílé!
Ọláṣùpọ ̀ sháṣore , agbejoro agba ni orile-ede naijiria ( ọjọ ́ ìbí - ọjọ ́ kejì-lé-lógún oṣù kíní ọdún 1964 ) jẹ ́ onimo nipa ofin .
Bí ọwọ́ ọlọ́pàá Kano ṣe tẹ ọkùnrin tó fẹ́ yọ́ wọ ilé ibùsùn obìnrin
Oniruuru ọna l'awọn ọmọ Naijiria ti gba ko ipa ninu idagbasoke agbaye.
O salaye pe, mimu eto idanilekoo ohun wa si orile-ede Nigeria yoo seranlowo fun ijoba apapo lati le se aseyori ninu erongba ti yoo mu idagbasoke ba eto oro-aje ati didi ona ti owo n gba jade lapo ijoba lona aito.
Ǹjẹ́ kò yẹ kí ẹ máa fi ìbẹ̀rù rìn ní ọ̀nà Ọlọrun, kí àwọn orílẹ̀-èdè tí wọ́n jẹ́ ọ̀tá wa má baà máa kẹ́gàn wa?
Ijọba fikun wi pe, wọn yoo pese ọkọ ti yoo ma gbe awọn eniyan kaakiri ni awọn ilu nla ni orilẹede Naijiria, to fi mọ igberiko, ki ọdun 2021 to pari.
Omo Fakorede naa tun ni alaga igbimọ to n mojuto ile iṣẹ Reasone Innovations.
Oríṣun àwòrán, Facebook/Barrister Fans page Àkọlé àwòrán, ọjọ kan nina a dilẹ leyin gbogbo asunsu je laye Aisha Buhari figbe ta,o ní pé Garba Sheu tí gbàbọde Ọ̀jọ̀gbọ́n fásitì OAU pàdánù ẹ̀mí rẹ̀ lópoópónà Benin sí Auchi.
Wọ́n bá a jẹ, wọ́n mu, wọ́n sì bá a ṣe àríyá.
ICC pari iwadi lori pipa Shiites, IPOB Àwọn ọmọ àwùjọ Shia ní orílẹ̀èdè Nàìjíríà máa ń sábà bọ́ sí gbangba ígboro láti bèèrè pé kí wọ́n tú Sheikh Zakzaky, olórí ẹgbẹ́ mùsùlùmí lórílẹ́èdè Nàìjíríà sílẹ̀.
Àkọlé àwòrán, Ẹ ń lẹ́ ń bẹun o!
N kò ní ìjà pẹ̀lú Fayemi, ipò mi bíi aláàbò àṣà Yorùbá ní mó ṣe kọ lẹ́tà sí gómìnà Ekiti - Aláàfin Oríṣun àwòrán, Alaafin Oba Adeyemi III Saaju la ti sọ fun yin pe Alaafin tilu Ọyọ, Aba Lamidi Ọlayiwọla Adeyemi Kẹta ti salaye pe agba kii wa lọja, ki ori ọmọ tuntun wọ, ni oun se fi imọran sọwọ si gomina ipinlẹ Ekiti, Kayode Fayemi lori aawọ awọn lọbalọba.
CAF Awards: Mo Salah gbà àmì ẹ̀yẹ agbábọ́ọ̀lù Áfíríkà fún ìgbà kejì
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, SS3 ní mo wà báyìí, mo sì ti gba àmì ẹ̀yẹ̀ púpò nílé-lóko gẹ́gẹ́ bí onílù - Ayansike Kò sí iléẹjọ́ tó le dá wa dúró, ìyanṣẹ́lódì yóò bẹ̀rẹ̀ ní Ọjọ́ Ajé - NLC Ẹgbẹ oṣiṣẹ lorilẹede Naijiria, NLC ti ni dandan awọn yoo tẹsiwaju ninu iyanṣẹlodi ti awọn fẹ gunle bẹrẹ lati Ọjọ Aje, ọsẹ to n bọ.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, A tun bori ni 2019 - Naijiria O ni inu oun dun pupọ pe idije bọọlu alapẹrẹ ti ni idagbasoke to yẹ laisko yii.
Tolulope Arotile: Ẹ wo ọgbọ́n tí wọ́n tò pọ̀ láti túfọ̀ ikú Tolu fún bàbá àti ìyá rẹ̀ Ta ni Yusuf Satia ti iku mu lọ?
Ṣòwòrẹ́, káàbọ̀ ságbo àwa tí wọ́n ti fẹ̀sùn kàn rí -Soyinka Ètò ọmọ wa ni ẹ jẹ́ kó ṣe é ló ń dá ìdàgbàsókè Nàìjíríà dúró -Osinbajo Mi ò fẹ́ dá sí ìjà Toyin ati Lizzy!
" Oríṣun àwòrán, Ayaba folashade/instagram Ko tan sibẹ o, Olori Folashade tun ni, ni kete ti Ẹlẹda yọnda awọn ọmọ naa fun oun, ni oun ti di obinrin ti kii sọ ireti nu.
 Oṣere ni ti a bi ni Rio de Janeiro to ti n ṣere lori ẹrọ amohunmaworan lati kekere.
Bí kò bá sí, alaafia yín yóo pada sọ́dọ̀ yín.
Olukuluku ń sọ̀rọ̀ alaafia jáde lẹ́nu fún aládùúgbò rẹ̀,ṣugbọn ète ikú ni ó ń pa sí i ninu ọkàn rẹ̀.
Bí a ti ń gba èébú, bẹ́ẹ̀ ni à ń gba ìyìn.
Amọ ile ẹjọ ko ri aridaju lori nọọsi naa, ti ko si si ẹri pe eniyan kan n jẹ orukọ naa.
Jesu bá pa òwe kan fún wọn.
Bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé ẹ̀gún ọ̀gàn ati ẹ̀wọ̀n agogo yí ọ ká, tí o sì jókòó láàrin àwọn àkeekèé, má ṣe bẹ̀rù ohunkohun tí wọn bá wí.
Bakan naa ni iwadii fihan pe iyatọ wa laarin eroja ajẹsara abawaye awọn obinrin ati ti ọkunrin ati ọna ti awọn eroja ajẹsara yii maa fi n gbera sọ nigbakugba ti aisan tabi arun kan ba fẹ dide.
Ìgbà tí Àkàrà-oògùn ti fi eléyìí hàn mí tán ni ó jókòó rẹ̀gẹ̀jì lórí àga, ó ní kí n ka òun sí bí ẹni pé Olówó-yé mi òun, ó sì fi ara rẹ̀ si ipò bàbá rẹ̀ o ń ka ìwé náà fún mi, èmi náà mú ohun ìkọ̀wé mi, mo jókòó bí ó ti yẹ kí ẹni tí ń kọ̀wé jókòó, mo ń ba iṣẹ́ lọ.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Awọn ọmọde n wa ọna abayọ si omi to n ya wọnu ile obi wọn Orọ omiyale agbara ya ṣọọbu yii ko yọ awọn ọdọmọde silẹ ni Naimey.
Ẹbi Arabinrin Tolulope Arotile ti ni wọn gbọdọ ṣe iwadii iku to pa ọmọbinrin akọkọ ti yoo wa ọkọ ẹlikọpta awọn ọmọogun ofurufu ni Naijiria.
Níkẹhìn inú bí ọkọ ìyàwó ó sì lé gbogbo wọn lọ.
Mo ti paṣẹ ayẹwo ojule si ojule fun awọn ikọ eleto aabo lati lo ma a wa awọn ohun ini ti awọn eniyan jigbe lọ yii pada''.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Akọ́mọlédè àti Àṣà lórí BBC Yorùbá: Kọ̀ síi nípa iṣẹ́ tí oúnjẹ ń ṣe lára níbí Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Fídíò, Rape cases in Nigeria: Ọmọ ọdun 5 àti 14 ni Kalu wà nígbà tí obìnrin fipá ba lòpọ̀21 Ògún 2020 Fídíò, Rape: Oríṣí ìjìyà ní àwọn bíi Gómìnà El Rufai àti Fayemi ń bèèrè f'àwọn afipábánilòpọ̀2 Agẹmo 2020 Lagos Rape: Ẹnikẹ́ni tó bá á ní ìbálòpọ̀ pẹ̀lú ọmọ kékeré jẹ́ alárùn ọpọlọ- Onímọ̀25 Ọ̀wàrà 2019 Fatai Rolling Dollar: Baba 70 jayé kọjá 70 kó tó dágbére fáyé pé ó dìgbóṣe!
Wọ́n bá tún bi í pé, “Kí ló dé tí Mose fi pàṣẹ pé kí ọkọ fún aya ní ìwé ìkọ̀sílẹ̀, kí ó sì kọ̀ ọ́ sílẹ̀?
Awọn ẹkọ kika ri wọn n kọ ni fasiti yii ko pọ bẹẹ si ni awọn ẹka ẹkọ naa ko pọ.
com/VEC9eLyPM4Ewe, bi a ko ba gbagbe wipe iko Flying Eagles
Estonia pàdánù owó gọbọi látàri Eku tó gba ìjọba ní Estonia
Ọjà àìmọye mílíọ̀nù naira ni wọ́n kó nílé ìtajà mi torí ìgbẹ̀san ìkọlù South Africa"" Ọrọ ikọlu to n waye sawọn adulawọ ati awọn ọmọ Naijiria lorilẹede South Africa ti bẹyin yọ lọjọ Isẹgun nitori iwa igbẹsan ti awọn eeyan kan nilu Eko gunle."
O gba l'adura pe ajo INEC yoo so layo lori idibo yii ti APC yoo si jawe olubori.
Nígbà gbogbo ni ogun máa ń wà láàrin Rehoboamu ati Jeroboamu.
Ninu ọrọ tiẹ, Aarẹ Lungu ṣe ayalo ọrọ ti ajaja ominira ilẹ India, Mahatma Gandhi sọ pe ilọsiwaju ati igoke agba orile-ede kankan da lori iha to kọ si awọn ẹranko rẹ.
Wọle Soyinka sọ fun BBC pe ere lawọn kan n se pẹlu ẹgbẹ t'awọn da silẹ yi.
"O ni ""Ko ro wipe oun lee di gomina ninu ẹgbẹ APC lo jẹ ko lọ darapọ ẹgbẹ PDP."
ojú mi ti di bàìbàì nítorí ìbànújẹ́.
Àṣà àti ìgbàgbọ́ Yorùbá ni pé òbí wọn máa ń padà wá sáyé
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: 'Mo fẹ́ kí agbábọ́ọ̀lù tíò fakọyọ bínú' Ààrẹ George Weah padà sórí pápá EFCC f'orúkọ Fayose sórí ìwé afurasí Ronaldo to kuna lati gbayo kankan wọle ninu ifẹsẹwọnsẹ mẹta akọkọ to gba ninu idije liigi Serie A gbayo akọkọ wọle ni iṣẹju aadọta gerege.
 fúndí èyí , kálukú wọn ló lẹ ́ tọ ̀ ọ ́ sí jíjoyè nínú ẹgbẹ ́ awo .
Ohun ti aare Buhari ba awon eniyan so ni 
Kò wọ́pọ̀ ki èniyàn kúrò ni ilé lati lọ gbé ilú miran.
Wo bí àwọn ọmọ yìí ti ń ṣe é Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí kan sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
Àwọn ọba wa, ati àwọn ìjòyè wa, àwọn alufaa wa ati àwọn baba wa kọ̀, wọn kò pa òfin rẹ mọ́, bẹ́ẹ̀ ni wọn kò tẹ̀lé ìlànà rẹ, wọn kò sì gbọ́ ìkìlọ̀ rẹ.
Kidnapping in Nigeria: Ara sọ́ọ́bù oníṣòwò ni wọn ti rí nọ́ńbà ìpè rẹ̀, tí wọn sì tàn-án jáde lásìkò ìsìn
Inú káàdì ìránti tí mo rí he ní mó tí rí fọ́tò ìhòhò Salawa, mó kàn fẹ́ gbà owó díẹ̀ ni- Afurasí Olorì Anu Adeyemi ń ṣe ọjọ ìbí, ẹ gbọ́ ǹkan tò sọ sí Kábíyésì Jesu Oyingbo rèé, pásítọ̀ tó láṣẹ ìbálòpọ̀ lóri ọmọ ìjọ obìnrin Mo fẹ̀ lọ gba owó oúnjẹ lọ́wọ́ bàbá mí ni mo bá wọn tí wọ́n ti pokùnso- Ọmọ Oloogbe Ìnàkí bímọ lẹ́yìn tí ìfẹ̀tòsọ́mọbíbí pòfo!
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù 10,000 Police constables: Ilé ẹjọ́ wọ́gilé ètò ìgbanisíṣẹ́ tí ọgá ọlọ́pàá ṣé lọdun 2019 1 Ọ̀wàrà 2020 Oríṣun àwòrán, @PoliceNG Ọrọ ti di maa kẹru rẹ pada sile fawọn ọlọpaa ẹgbẹrun mẹwa, ti ọga agba ọlọpaa Naijiria ṣeto igbanisiṣẹ fun lọdun 2019.
Rashidi Ladoja: Nígbà tí Ajimobi fìdí rẹmi ló ṣẹ̀ṣẹ̀ yan àwọn akọ̀wé
Ukraine President: Zelensky jẹ ààrẹ, ọ̀pọ̀ adẹ́ẹ̀rínpòṣónú Nàìjíríà kún ojú òṣùwọ́n jú àwọn adarí wa lọ
O sọ fún mi pé ènìyàn ni ìyá òun ṣùgbọ́n ẹbọra lo bí òun fún àti pé ẹbọra náà ni ọba àgbègbè ibi tí a wà àti pé ààfin bàbá òun kò jìnà sí etí omi tí òun ti rí mi, ó rọ̀ mi pé ki ń wá lọ mọ ilé òun kí n kí bàbá òun ṣùgbọ́n mo kọ̀ mo wí fun un pé mo sa n fẹ́ kí ọkan mi túbọ̀ balẹ̀ díẹ̀ sii ni ni n wẹ̀ padà sí òdí kejì odò ki n wá àwọn tí a jọ ń bọ̀ lọ.
Ìwádìí ICPC fi hàn pé ènìyàn 721 fi ayédèrú ìwé ẹ̀rí gba iṣẹ́ ìjọba àpapọ̀
Kìlọ̀ fún wọn níwájú Ọlọrun pé kí wọn má máa jiyàn lórí oríṣìíríṣìí ọ̀rọ̀ tí kò wúlò, tíí sìí máa da àwọn tí ó bá gbọ́ lọ́kàn rú.
Imọran Aisha Raheem fun awọn ọdọ ni wi pe ki wọn ṣe iṣẹ wọn bi iṣẹ, ki wọn si gbajumọ nkan ti wọn ba fẹ ṣe.
Pẹlu ayọ̀ ati inú dídùn ni a fi ń mú wọn lọ,bí wọ́n ṣe ń wọ ààfin ọba.
Oludari ajo eso naa ti Zone B to n mojuto ekun ipinle Kaduna, Usman Dakingari lo so fun awon akoroyin pe won mu awon oko naa.
Lẹ́yìn náà, àwọn ọmọ Israẹli yóo pada tọ OLUWA Ọlọrun wọn, ati Dafidi, ọba wọn lọ.
wipe, orile-ede Naijiria ni o sokunfa bi orile-ede Zimbabwe ko se le tesiwaju
Ṣugbọn lọgan ni awọn minisita ijọba kan fẹsun kan wọn pe wọn yi irọ ninu itan ni lati tabuku ba ijọba ati lati yi oju ijọba kuro lara ikopa awọn obinrin yii ninu ifẹhonuhan to lodi si ofin.
    Èmi ni mo kọ́ bọ́ sí orí afá odò Ẹ̀jẹ̀.
Ṣugbọn Sẹnẹtọ Abudulahi ni ọrọ ikorira ti ṣokunfa iku fun ọpọ eeyan, o ni ohun lo n fa irẹwẹsi ọkan fun ọpọ to si tun ti mu ọpọ gbẹmi ara wọn.
Opin ọsẹ to kọja ni ileesẹ NIPOST fi ikede naa sita.
Wo ohun tó yẹ ko mọ̀ nípa olùdarí àjọ EFCC tuntun Ìdùnnú ṣubú layọ̀!
Èèyàn abìdí yàn- án yà- án
Gomina Ganduje ati awọn alatilẹyin rẹ tilẹ fi ẹsun kan Emir Sanusi pe ẹgbẹ oṣelu PDP lo ṣatilẹyin fun ninu eto idibo gomina to kọja.
Wọn gbe e lọ si kanse ileẹjọ alagbeka tijọba gbe kalẹ fun iwa ọdaran to wa ni adugbo Oshodi nilu Eko, ni awọn ọlọpaa gbe Naira Marley yọju si.
Ṣaaju ni Gomina Benue ti sọrọ pe.
Àsìkò tó láti fi ìwọ́de gba ara wa sílẹ̀ lọ́wọ́ ebi àti oko ẹrú - Sowore Wo mi ki n gba siọ ti wọn n pe ni pẹnariti ni wọn yanju rẹ.
 o je oguna gbongbo onkowe itan aroso , bakanaa o tun je oluko ede yoruba .
Fun awọn kan bi Queen Ola Ifeolamitide, ọrọ lori bi awọn adigunjale ṣe n da awọn agbegbe kan laamu niipinlẹ Eko ati Ogun lo fẹ ki aarẹ o sọrọ le lori.
Ṣugbọn ẹni tí ó bá fẹ́ fọ́nnu,ohun tí ó lè máa fi fọ́nnu ni pé òun ní òyeati pé òun mọ̀ pé, èmi OLUWA ni OLUWA tí ń ṣe ẹ̀tọ́,tí sì ń fi ìfẹ́ tí kì í yẹ̀ ati òdodo hàn lórí ilẹ̀ ayé;nítorí pé àwọn nǹkan bẹ́ẹ̀ ni mo ní inú dídùn sí.
Nígbà tí a bá wọ ilẹ̀ yìí, mú okùn pupa yìí, kí o so ó mọ́ ibi fèrèsé tí o ti sọ̀ wá kalẹ̀.
“A niloo lati ni awon oludokowo ti yoo kowo lori oja idokowo, a ko le gbokanle owo ori epo-robi tuntun nikan”.
Wakajaye Egbeda to wa ni ekun Gusu ni ipinle Oyo , aago mẹ́sán án  owuro yii ni eto idibo to bẹrẹ nibẹ.
Bí wọ́n sì ti ń sá lọ fún àwọn ọmọ Israẹli, tí wọ́n sì ń sọ̀kalẹ̀ ní ibi gẹ̀rẹ́gẹ̀rẹ́ Beti Horoni, OLUWA mú kí àwọn òkúta ńláńlá máa bọ́ lù wọ́n láti ojú ọ̀run, títí tí wọ́n fi dé Aseka, wọ́n sì kú.
Mo ki Seun Adigun, Ngozi Onwumere, Akuoma Omeoga ati Simidele Adeagbo ku oriire pẹlu bi wọn se n fi orukọ wọn ati orukọ Naijiria lelẹ ninu iwe itan.
Modekai sọ gbogbo ohun tí ó ṣẹlẹ̀ fún un, títí kan iye owó tí Hamani ti pinnu láti gbé kalẹ̀ sí ilé ìṣúra ọba kí wọ́n fi pa àwọn Juu run.
Kábíyèsì fẹnu ara rẹ̀ tú àṣírí àwọn Fulani Daran daran tó ń ṣọṣẹ́ nílùú rẹ̀ Àjẹ́ àti Aṣẹ́wó ní ìyá Rainbow - Òjòpagogo Fábàdà!
Wọ́n kúrò ní Refidimu lọ sí aṣálẹ̀ Sinai.
Wọ́n sì sin ín sí ibojì àwọn baba rẹ̀ ní ìlú Dafidi.
Aare Buhari soro ohun di mimo lasiko ifilole olu ile-ise ajo to n mojuto gbigbogun ti iwa ibaje lorile-ede yii, (Economic and Financial Crimes Commission EFCC), ti o waye lojo isegun(Tuesday).
Àkókò tó fún ìdájọ́ ayé yìí.
25 Agẹmo 2020 BBNaija: Terry Waya sọ oun tó fojú Kiddwaya rí nílé nígbà tó ń bẹ̀bẹ̀ láti lọ BBNaija28 Ògún 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Stolen phone: Fóònù mi ni mo lọ́ tún ṣe lọlọ́pàá bá he mí pé mo jí fóònù Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
"Awọ ara mi to dudu ati Ọlọrun lo sọ mi di nkan ti mo di lonii.
tí ó ní, “N kò ní wọ inú ilé mi,bẹ́ẹ̀ ni n kò ní bọ́ sí orí ibùsùn mi;
Àwọn Farisi ati àwọn amòfin wá ń kùn; wọ́n ń sọ pé, “Eléyìí ń kó àwọn ẹlẹ́ṣẹ̀ mọ́ra, ó tún ń bá wọn jẹun.
 Àwọn okùnfà lè jẹ ́ lílo irinṣẹ ́ tí wọ ́ n fi ńgbomisára gbomisára , kí obìrin maa bá ọkùnrin tó pọ ̀ lòpọ ̀ , lílo egbògi , lílo ohun tí wọ ́ n ń pè ní intrauterine device lára àwọn nkan míràn .
” Jakọbu dáhùn pé “OLUWA Ọlọrun rẹ ni ó ṣe ọ̀nà mi ní rere.
Àwọn ọ̀dọ́ wa yóò màa ríṣẹ́ láì san owó orí Araale kan bere pe ki ni Eyitayo Jegede yoo ṣe nipa ọrọ aje ipinlẹ Ondo.
Ikede rẹ yi ti mu ki iriwisi ọtọọtọ wa .
Ẹ máa ṣe gbogbo nǹkan tìfẹ́tìfẹ́.
Bẹẹ lo ni oun ṣe idaro baba oun nitori to ba wa laye, igbe aye oun yoo dara sii ju bi o ti wa lo.
Gomina Ipinle Oyo, asofin Abiola Ajimobi ti gba  awon osise ni Ipinle Oyo niyanju je omoluabi
Banki Nàìjíríà, CBN ṣàlàyé nípa àwọn tó máa rí gbà nínú owó ìrànwọ́ N75b tíjọba gbé kalẹ̀ Ẹ dẹ̀kun lílo Sniper àti Dichlorvos fún ìtọ́jú oúnjẹ- NAFDAC kìlọ̀ Wo ọ̀nà àbáyọ fún àwọn akẹ́kọ̀ọ́ tí àjọ WAEC gbẹ́sẹ̀ lé èsì ìdánwò wọn ''Àjọ NERC ti fún Disco láṣẹ láti padà sí owó tàríìfù tuntun iná mọ̀nàmọ́ná'' EFCC bẹ̀rẹ̀ ìwádìí lórí ẹ̀sùn ìwà jẹgúdújẹrá tí wọ́n fi kan Fowler tó jẹ́ Alága iléeṣẹ́ FIRS tẹ́lẹ̀ Gẹgẹ bi Sangodoyin se sọ, igbesẹ igbimọ alasẹ ijoba lori ọrọ yii wa ni ibamu pẹlu ajọ isokan agbaye lori ọrọ ilera WHO nitori pe o pọn ni dandan lati fun ọmọ lọyan fun odidi osu mẹfa lai si amulumala.
Olórí ilé asòfin l‘Ọ́sun pàdánù N38m sọ́wọ́ gbájúẹ̀ 137 obìnrin ni ikú ń pa lójúmọ́ lágbàáyé Boko Haram tó pa òsìsẹ́ Red Cross mú omi lójú Ezekwesili Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Sunday Ayẹni: Damilọla, aya ọmọ mi fìgbónára sọ mi sókùnkùn alẹ́ Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
ati gbogbo ilé-ìṣọ́ gígaati gbogbo odi tí ó lágbára,
A ti dáwọ́ ẹbọ ohun jíjẹ ati ti ohun mímu dúró ní ilé OLUWA,àwọn alufaa tíí ṣe iranṣẹ OLUWA ń ṣọ̀fọ̀.
Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Fídíò, Soyinka Cancer: Àṣe ara mi ni iso ti n run gbogbo bí mo ṣe n ṣèrànwọ́ lórí jẹjẹrẹ27 Bélú 2019 Fídíò, Akinwumi Isola: Wo ohun tí Abeni fi ojú ọkọ rẹ rí tórí iṣẹ́ bọ́ lọ́wọ́ rẹ̀ nínú ìwé Nitori Owo""27 Ọ̀wàrà 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!"
O se alabapade ọmọkunrin ti iya rẹ bi lẹyin rẹ, ti wọn si di ẹbi Afẹfẹ orilẹede naa ba lara mu, ko mu oogun oloro mọ, o ri isẹ gidi, ti Sara si pada di ọmọluabi lawujọ.
Àwọn ọmọ Hamu ni: Kuṣi, Ijipti, Puti ati Kenaani.
Liverpool to ti pegede fun aṣekagba idije UEFA Champions League ko tii ri ife ẹyẹ Premier League fun ọgun mọkakandinlọgbọn bayii.
All Progressive  Congressm APC to n soju
Lẹyin igbeyawo to gba ori opo ayelujara kan ni BBC Yoruba lo wadii ijinlẹ ohun to sọ ọgbẹni yii di afọju ọsan gangan.
Ó wá rí talaka opó kan, tí ó fi kọbọ meji sibẹ.
"Toyin Abraham bí ọmọkùnrin jòjòló ""Lati oni lọ, ijọba ti gbẹsẹ le sisọ ede oyibo lawọn eto to ba jẹ ti aṣa."
Isreal Adesanya fàgbàhàn Kelvin Gastelum ni Atlanta
" Ifẹ orilẹede tabi ipinlẹ ti o fẹ yan an: O ni ohun keji ti awọn aṣofin maa n wo ni ṣe ẹni ti wọn fi orukọ rẹ ranṣẹ ni ifẹ ilẹ rẹ denudenu.
”Titele eto IlanaGomina Yari  ni ijọba aare Muhammadu Buhari n tele eto ilana, ni eyi ti o mu ki adele aare ojogbon Yemi Osinbajo gba isẹ lọwọ adari ajo eleto aabo DSS fun iwa ibajẹ  ati aibofinmu ti won hu lati  ti ile igbimo asofin pa, fihan pe ijọba n tele ofin orile ede Naijiria.
Nígbà tí Peteru rí i, ó bi Jesu pé, “Oluwa, eléyìí ńkọ́?
Kí ló ń fa 'tsunami' tó pa 220 ènìyàn ní Indonesia?
Awọn ọba to ba tọ si bi i Ẹlẹkọle ti Ikọle, Ajero ti Ijero, Alara ti Ilara, Ewi ti Ado ati awọn miran nikan lo lẹtọ si igbimọ naa lati lọ si ipade."
Kassim ni ki awọn oniroyin ma baa ṣi awọn eniyan lọkan, oun ni lati fi ọrọ sita lati bu nu atẹ lu iroyin ofege yii pe irọ gbaa ni ohun ti wn n gbe kiri tori Babangida ko tii ku.
Àwọn eniyan Ọlọrun tí ó bá ní ìpín ninu ajinde kinni ṣe oríire.
Apapọ isiro owo yii yoo si ku si biliọnu kan ati miliọnu lọna igba naira (₦1.
Oluwo ni lẹyin naa loun pe ile ifowopamọ Access lati ṣalaye ohun to ṣẹlẹ, ṣugbọn o ni wọn ko tii ṣe ohun kan lori rẹ.
‘Kí OLUWA bukun yín,kí ó sì pa yín mọ́.
Eyi ko ni fi aaye silẹ fun oṣiṣẹ kankan lati kuro ninu baalu to ba ya loju ọna.
“Mo ṣebí kọbọ meji ni wọ́n ń ta ológoṣẹ́ marun-un.
O gba ami ẹyẹ, to si n fọnrere pe ki awọn onijo maa wọ sokoto fẹlẹfẹlẹ to fun mọra, to si ba awọ ara ẹni to n jo mu.
 Òun kan náà ni bàbá arẹwà àti òbùrẹ ́ wà .
 Nigba ti wọn bi pe ko fi idi ọrọ yii mulẹ, o fikun pe: Tiku-tiye.
" Fọto rẹ ati ọkọ ayọkẹlẹ pupa naa si lo gbe soju opo Instagram rẹ ọhun, ti ọpọ awọn ololufẹ ati akẹẹgbẹ rẹ ninu iṣẹ tiata si n ki ku oriire ọkọ ayọkẹlẹ tuntun naa.
Igbakeji aare ana fun orile ede Sierra Leone , Victor Foh ati minisita fun ohun alumooni ile ana, Minkailu Mansaray  ni won  ti mu fun iwa ibaje.
 ""Ṣe ki n ma parọ, ẹmi mi kọkọ lọ, nitori pe irora kekere kọ ni mo n jẹ lati ọjọ ijamba naa."
Adeleke Vs Oyetola: Òní ni ilé ẹjọ́ tó ga jù lọ yóò kéde ìdájọ́ lórí èsì ìdìbò gómìnà ìpínlẹ̀ Ọṣun
”Wọn yóo dá a lóhùn pé, “Rárá.
N óo fi ogun ko yín, tí yóo gbẹ̀san nítorí majẹmu mi.
"INEC: Kò sí ìká tí o kò lè fí dìbò, ṣáà tí tẹ̀ ẹ́ sójú ẹ dáadáa ""Gbogbo òṣìṣẹ́ kọ́ ni #30,000 owó oṣù tuntun yóò kan"" O ni ọtọ ni ẹgbẹ ti ohun fẹ dibo yan ati pe apọju awọn ami idanimọ ẹgbẹ oṣelu lo ko iporuru ọkan ba oun."
Nígbà tí Jesu parí ọ̀rọ̀ tí ó ń bá àwọn eniyan sọ, ó wọ inú ìlú Kapanaumu lọ.
Lóòótọ́ ó lu òkúta tí omi fi tú jáde,tí odò sì bẹ̀rẹ̀ sí ṣàn.
Real Madrid lo ṣi wọn lọwọ ninu awo ikẹfa ti wọn fẹ gba lọdun 2018.
OLUWA sọ fún Mose pé, “Gun orí òkè Abarimu yìí lọ, kí o sì wo ilẹ̀ tí n óo fún àwọn ọmọ Israẹli.
Omowe Onu wa fi da ile-eko naa loju , pe ajo  ti oun sakoso le lori  yoo satileyin fun ile-eko naa lori iwadii lati lee ko awon ile to se e gbe ati awon oju-ona ti ko won pupo lorile ede Naijiria.
Nigba ti awọn akọroyin de ibẹ lati ṣewadii ohun to ṣẹlẹ, awọn oṣiṣẹ alaabo ko jẹ ki wọn wọle, wọn ni latoke wa ni aṣẹ ọhun ti wa.
Ajo Isokan Agbaye, United Nations, ti tepele mo ikede re pe agbaye se lodi si didabe fun omobinrin lainii fise iran, eya tabi esin awon omo naa.
 Ti egbe oselu ANC ba mo pea won si few ole leekan sii, won ko gbodo fise awon osise sere rara lasiko yii nitori lati 1994 ni awon osise ti n dibo gbe ANC wole”.
Macbeth nigba ti o ti mu ọti yo tan ni: ọti lile n mu ibalopọ wu ni ṣugbọn kii jẹ ki eeyan le ta pútú dáadáa.
Ẹsẹ̀ rẹ̀ ń dà gẹ̀rẹ́gẹ̀rẹ́ lọ sinu ikú,ìgbésẹ̀ rẹ̀ sì lọ tààrà sinu ibojì.
Ó sì tún fún mi ní àsìkò láti ronú jinlẹ̀ dáadáa.
Olú ileesẹ ọmọ ogun to fi ikede naa sita lori ayelujara Twitter rẹ, sọ pe l'oju ẹsẹ ni iforukọ silẹ yoo bẹrẹ lori ayelujara.
Àbí ta ni yóo dá wọn lẹ́bi?
Nígbà tí wọ́n tu ọkọ̀ dé èbúté, wọ́n fi ohun gbogbo sílẹ̀, wọ́n ń tẹ̀lé e.
" Mo lọ si agbègbè náà láti lọ bá aṣerunlóge mi lọ́jọ́ ti ọ̀rọ̀ náà ṣẹlẹ̀ nítori mo fẹ́ kún irun mi padà si dúdú, sùgbọ́n kò pẹ́ sí ìgbà ti mo dé ọ̀dọ̀ rẹ̀, mó ri ọ̀pọ̀ ènìyàn ti wọ́n ń sáré sí ibi ilé ìtàja ọ̀hún, mó tún gbọ́ ǹkan to jọ ìró ìbọ̀n, sùgbọ́n ko dámi lójú, gbogbo wa ni ẹru ba ti olúkálùkù sì sá àsálà fún ẹmi rẹ ni àyíka ilé ìtajà náà.
Ọjọ ti pẹ ti Femi Gbajabiamila ti n wa ipo olori ile aṣoju-ṣofin orileede Naijiria, ala naa si ti wa di ohun bayi.
Àwọn aguntan mi túká, wọ́n ń káàkiri lórí gbogbo òkè ńlá ati gbogbo òkè kéékèèké.
Tí ó dáhùn tí ó wí pé, Mo jẹ ọ́ ní gbèsè ni?
Nígbà tí Jakọbu, Peteru ati Johanu, tí àwọn eniyan ń wò bí òpó ninu ìjọ, rí oore-ọ̀fẹ́ tí Ọlọrun ti fi fún mi, wọ́n bọ èmi ati Banaba lọ́wọ́ gẹ́gẹ́ bí àmì ìdàpọ̀, wọ́n ní kí àwa lọ sáàrin àwọn tí kì í ṣe Juu bí àwọn náà ti ń lọ sáàrin àwọn tí ó kọlà.
Ninu àwọn tí mo rán si yín, èwo ni mo lò láti fi rẹ yín jẹ?
Ọjọ meji lẹyin ti dokita naa pari ẹkọ rẹ ni awọn agbebọn naa gbẹmii rẹ.
Ẹwẹ, ọkan lara awọn oludije gomina labẹ ẹgbẹ oselu APC nipinlẹ Eko tẹlẹ, Ọbafẹmi Hamzat ti yẹba fun Babajide Sanwo-Olu, saaju idibo naa.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Dele Momodu : Lẹ́yìn Buhari àti Atiku, èrò ọjà làwọn olùdíje yóòkù ní ìdìbò 2019 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Oríṣun àwòrán, @FAYOSE/TWITTER Nínú èsì ìwádìí ayẹ̀wé owó wò fún ti ọdún 2017, ó hàn gbangba pé ,TUC gba mílíọ̀nù kàn Naira lósoosù tí NLC sì ń gbà mílíọ̀nù márùn-ún náírà lábẹ́ ìjọba Fayose.
Oríṣun àwòrán, BBNaija Àkọlé àwòrán, Bayii ni awọn eeyan ṣe dibo to mu ki Laycon jawe olubori.
Ọrọ yi ni ọwọ oṣelu ninu, a si mọ wipe kọmiṣọna fun eto iroyin ati aṣa nipinlẹ Ọyọ, Toye Arulogun lo wa nidi ẹ nitori lọpọlọpọ igba lo ti pe wa wipe ki a paarọ awọn eto wa kan nitori wọn n tako ijọba.
00) ni ó gbà ní owó kòkó náà.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: ‘Buhari ti gbàbọ̀dè fún Nàìjíríà’ 'Ọ̀tá ìjọba alágbádá ni ọ̀gá ọlọ́pàá’ Àìsàn ibà Lassa tún pa ènìyàn ní Ondo Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí kan sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
nibi ipade ti igbimo ijoba apapo se, ni eyi ti aare Muhammadu Buhari dari rẹ.
Ileri yi jẹ ọkan gboogi ninu awọn eto ti o la kalẹ ninu iwe ilana iṣejọba to gbe jade lọjọ Aiku.
Coronavirus: Báwo ní gbogbo àgbáyé ṣe lè gba abẹ́rẹ́ ajẹ́sara àrún Coronavirus?
ASUU Strike: Àwọn akẹ́kọ̀ọ́ kan dunnú, àwọn míràn fajúro Àkọlé àwòrán, ko si si olukọ kankan ninu awọn yara ikẹkọ lati sisẹ ni ọgba fasiti Ibadan Ẹgbẹ awọn olukọ ilẹ ẹkọ giga fasiti ijọba lorilẹede Naijiria (ASUU), ẹka ti fasiti Ibadan (UI), naa darapọ mọ awọn akẹgbẹ wọn jakejado orilẹede yii ninu iyanṣẹlodi alainigbedeke to bẹrẹ lọjọ aje.
Jẹ́ kí àwọn ikọ̀ wá láti Ijipti,kí àwọn ará Kuṣi tẹ́wọ́ adura sí Ọlọrun.
Ọwọ́ ọlọ́pàá tún tẹ afurasí tó fipá bá odi àti adití lòpọ̀ nílùú Ibadan Àṣírí ẹgbẹ̀rún kan ayédèrú òṣìṣẹ́ SUPEB tú ní Kwara -EFCC Omijé ń p'omijé rán níṣẹ́ níbi ìsìnkú dípiò ọlọ́pàá táwọn ọlọ́ṣà pa ní Kogi Ẹ̀wọ̀n gbére leè jẹ́ ìjìyà fún afipábánilòpọ̀ bí àwọn gómìnà ṣe dìde si"" Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!"
Ní ọjọ́ náà, ẹnu rẹ óo yà, o óo sì le sọ̀rọ̀; o kò ní ya odi mọ́.
Ni ọj kẹrinlelogun oṣu kinni ọdun 2019, igbimọ awọn oriade Yewa pe fun idajọ lori sun pe awọn ẹṣọ aṣọbode pa eniyan marun ni Owode-Yewa nigba ti wọn ya wọ awọn ile kan ati ṣọọ̀bu ti wọn ni ẹru ole lo wa nibẹ.
Eeyan mẹjọ ni awọn afurasi ti ọlọpaa mu, ti ọjọ ori wọn si wa laarin ogun ọdun si mejilelọgbọn, ọkunrin si ni gbogbo wọn.
Wọ́n fi òwú funfun ati òwú àlàárì ṣe okùn, wọ́n fi so wọ́n mọ́ òrùka fadaka, wọ́n gbé wọn kọ́ sára òpó òkúta mabu.
" Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Se lootọ ni pe eniyan le ko Coronavirus lara ẹni to ti kú?
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Òjò àrọ̀rọ̀dá: Àrá sán pa màálù mẹ́tàlélógùn ní Ekiti 3 Ọ̀wàrà 2018 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Àrá abàmì kan ṣe ikú pa màálù tó lé lógún Kayefi, nkan ṣẹlẹ ni duniyan.
Mide Martins Mustapha Sholagbade Oríṣun àwòrán, Mustapha Sholagbade Tí iye iná tí ẹ rí gbà bá kéré ju owó tí ẹ rà á lọ, ẹ ti jẹ gbèsè tẹ́lẹ̀ ni - Iléeṣẹ́ apínnáká Mo pinu láti dá Iphone tì mo mú padà kí ọlọ́pàá tó mú mi Ojúmọ́ kan, ìdàmú kan ni mo fi lo ogún ọdún àkọ́kọ́ lórí oyè - Alaafin Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Kété tí wọ́n bá ti báa yín sùn tàn torí pé ẹ tóbi, ẹ gbà pé ìfẹ́ yẹn ti parí - Auntie Remi Ọlọ́yàn ńlá Idowu Phillips (Mama Rainbow) Oríṣun àwòrán, Idowu Phillips Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Gbajugbaja oṣere tiata, Motilọla Adekunle ló fi aya gbangba rẹ han lori èto ṣé o láyà.
Ọpọlọpọ mọto, ọja ati nkan amuludun lo jona ninu iṣẹlẹ ohun.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ruga Settlement: Ìpínlẹ̀ Oyo àti Eko kò ní èròǹgbà láti kópa nínú ètò Ruga Settlement 1 Agẹmo 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Ninu ọrọ ti wọn ba BBC Yoruba sọ, awọn akọwe agba fun ọrọ to kan araalu fun gomina ipinlẹ Ọyọ ati Eko, Taiwo Adisa ati Gboyega Akọsile sọ pe ijọba ipinlẹ awọn ko nifẹ si eto Ruga Settlement ti ijọba apapọ n gbeero rẹ.
O lo ọdun mejidinlogoji lẹnu iṣẹ ologun ko to fẹyinti ninu iṣẹ ologun ni oṣu keje, ọdun 2015.
Eliṣa sọ fún un pé, “Níwòyí àmọ́dún, o óo fi ọwọ́ rẹ gbé ọmọkunrin.
Aarẹ Trump jẹ ẹni ti ko ka ọrọ Covid-19 si ti o si tun fi alatako rẹ Biden ṣe yẹyẹ pe o wọ ibomu lasiko itakurọsọ to waye laipẹ yi.
Àsìkò tó tí a óo gbé mi ga.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Bisi Alimi: Ìyà mi rò pé n kò leè ṣe ni àmọ́ n kò ní ìfẹ́ abo ni mo ṣe fẹ́ akọ Ajọ naa wa fikun wi pe awọn yoo bẹrẹ si ni da awọn eniyan pada si gbogbo ibudoko ti wọn yoo ti lo tun iforukọsilẹ naa se.
Loni ni ko ni dọla ti agbaye yoo mọ ẹgbẹ agbabọọlu ti yoo pegede, fi gbọọrọ jẹ ka ninu idije UEFA champions league ti ọdun 2019.
Lara awon ti o wa pade aare ni
Alábòyun ṣe iṣẹ́ abẹ pẹ̀lú abẹfẹ́lẹ́, ó gbé ọmọ jádé nínú ara a rẹ̀ Ará ìlú dájọ́ oró fún ọkùnrin to bẹ́ orí ẹ̀gbọ́n rẹ̀ ní Cross River Ẹgbẹ agbabọọlu Extremadura ni Reyes wa ki o to di oloogbe.
Ẹ ̀ yà yorùbá kan náà ni gbogbo àwọn ènìyàn ìlú Ọ ̀ ra-Ìgbómìnà àti Òkèwù .
Aarẹ Buhari yanju ọrọ yii nigba to ṣalaye pe oun ko figba kankan fọwọsi ilana ọlọpaa agbegbe o.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Kurt sweater: Wo aṣọ òjò tó wọ́n jùlọ ní àgbáyé!
Ọ̀rẹ́ rẹ̀, Modu Mustapha ni kò mọ ohun tó ń se mọ́, tí orí rl sì ń mì dirọ̀-dirọ̀ ní ààrin èjìká rẹ̀ tó jk kìkì eegun.
O ni oun ki Adeleke ati awọn ara Osun fun aduroti wọn, bẹẹ si ni ẹgbẹ oṣelu PDP ni Ipinlẹ Osun naa ni awọn gba idajọ naa wọle Supreme Court : Oyetola fẹ̀yìn Adeleke janlẹ̀ nílé ẹjọ́ tó ga jù lọ!
Hana bá dá a lóhùn pé, “Jẹ́ kí èmi, iranṣẹbinrin rẹ, bá ojurere rẹ pàdé.
Kókó mẹ́jọ tó jẹyọ nínú ọ̀rọ̀ Ààrẹ Buhari fáwọn ọmọ Nàìjíríà Àwọn òṣìṣẹ́ ìjọba ìpínlẹ̀ Oyo láti ipele kẹtàlá ti padà sí ẹnu iṣẹ́ lọ́jọ́ ajé Gbogbo ìgbésẹ́ to yẹ ni a gbé nígbà ti àwọn ọ̀daràn dé ọgbà wa- Agbẹnusọ ọgbà ẹ̀wọ̀n Adari ẹgbẹ oṣelu APC, Asiwaju Bola Ahmed Tinubu ni awọn gbe igbese lati se ayẹwo naa kete ti ayẹwo fi lede pe arun Coronavirus lo pa Alhaji Raheem.
“Nígbà tí mo gbọ́, ọkàn mi wárìrì,ó sì fò sókè ní ipò rẹ̀.
Ó lágbára ju ariwo omi òkun lọ,ó lágbára ju ìgbì omi òkun lọ.
Orílẹ̀ -èdè Amẹrika fidi ọ̀rọ̀ yìí múlẹ̀ nínú àtẹ̀jáde kan tí olú ilé iṣẹ́ Amẹríkà ní Nàìjíríà fi síta lọ́nìí, pé gẹ́gẹ́ bi ọ̀rẹ́ Nàìjíríà àwọn ṣetàn láti gbáruku ti ǹkan ti àwọn ènìyàn ń fẹ ti wọn si fọ òhun ìsskan nínú ìdìbò wọn.
SARS fi ìyà jẹ àwọn akẹ́ẹ̀kọ́ fásitì Akungba Kọmiṣọna naa ni ofin ti de awọn ọlọpaa kogberegbe lasiko yii nitori pe wọn kò gbọdọ kọja aala wọn mọ.
Oríṣun àwòrán, BBNaija/ Instagram Ó jọ́ bi ẹni pé nǹkan o ṣẹnu ire fún Erica nínú ilé BB Naija láti alẹ ọjọ́ Sátidé.
Igbele wọn ọgọ́ta tumọ si pe irinajo yoo gba ìdá ọgọ́ta ju ti oju ọna ba da paroparo.
Awọn nkan wọnyii ni yoo si sọ boya awọn ṣọọṣi ati mọṣalaaṣi naa yoo ṣi pada.
Tí a fiṣọwọ́ ní 12:0012:00 Wo ìdí tí Oluwo fi ń wọ ìbòmú lẹ́yìn tó ní covid-19 ò lè wọ ìlú Iwo láéláé Oba AbdulRasheed Akanbi ni oun n wọ ibomu lati jẹ awokọṣe rere fawọn ọmọ Naijiria nitori ifẹ ti oun ni si wọn.
”Aare Buhari tun ri leta miiran gba lati odo asoju orile ede Congo si orile ede Naijiria ogbeni Jacques Obindza, so pe orile ede Niajiria fe  ibasepo to dan monran pelu orile ede Congo paapaa julo nipa eto oro aje.
Kí ni èrè tí ẹ rí nígbà tí ẹ lọ sí Ijipti,tí ẹ lọ mu omi odò Naili,àbí kí ni èrè tí ẹ gbà bọ̀ nígbà tí ẹ lọ sí Asiria,tí ẹ lọ mu omi odò Yufurate.
  Ní àsìkò tí mo lọ tún wá bọ́ sí ìgbà ìkórè.
Nínú ọ̀rọ̀ọ rẹ̀ ní TEDxLahore ní ọdún 2017, Jannat Ali ṣe àlàyé ìrìnàjòo rẹ̀ gẹ́gẹ́ bí abódiakọ-akọ́diabo ní Pakistan lẹ́yìn ìgbà tí ó fi irú ènìyàn tí òun ń jẹ́ han ẹbí àti àwọn ènìyàn.
Ewe, bi a ko ba gbagbe pe, ni aipe yii ni iko Eagles fagba han orile-ede Libya pelu ami-ayo merin sodo(4-0), meta si meji(3-2) ninu ifigagbaga ipegede fun idije boolu afesegba ile Afrika.
Kò sáyè ìgbafẹ́ mọ́ fáwọn àgùnbánirọ̀ DBanj gbé àwo tuntun jáde lẹ́yìn ikú ọmọ rẹ̀ Alárùn ọpọlọ lu àwọn nọ́ọ̀sì àti dókítà agba níléèwòsàn ní àlùdákú Awọn ọmọ ìjọ sàtánì ń bínú sí Nàìjíríà Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ọ̀ṣọ́ Aṣọ Òkè ti kọjá lílo ìlẹ̀kẹ̀ níkan Díẹ̀ lára àwọn okòwò tí ó ṣeéṣe lásìkò yi pẹlu N10,000 Iwadii BBC fihan pe eniyan le maa ta aṣọ àlòkù oyinbo ti àwọn kan n pe ni òkìrìkà ni ẹyọ.
Georgina Ehuriah to jẹ akọwe agba ajọ naa lo kede isinmi yii lorukọ ijọba apapọ.
Ó dé àṣíborí bàbà, ó wọ ẹ̀wù tí wọ́n fi bàbà pẹlẹbẹ-pẹlẹbẹ ṣe, tí ìwọ̀n rẹ̀ jẹ́ ẹẹdẹgbaata (5,000) ṣekeli.
Ìwọ̀n ṣekeli ibi mímọ́ ni kí wọ́n fi wọn owó náà.
Wọn óo máa kọ ọ́ nípa Ijipti ati ogunlọ́gọ̀ àwọn eniyan rẹ̀.
Olukuluku ń rìn lọ siwaju tààrà.
Ile- isẹ Asobode orilẹ ede Naijiria( Nigerian Customs)
Ọba Oluwo wa gba awọn ọmọ Naijiria ni iyanju lati ma a wọ asọ àwọn ẹya miiran lati le bu ẹwa kun orilẹede Naijiria.
Ibi ni wọn yóo jèrè lórí ibi tí wọn ń ṣe.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù El Rufai: Òfin má wàásù ìpínlẹ̀ Kaduna ti ń gba àpérò 10 Òkùdu 2019 Oríṣun àwòrán, @El Rufai Àkọlé àwòrán, Ọrọ ariwo iwaasu ni Kaduna n gba ero tuntun Ipinlẹ Kaduna gbe ofin kalẹ to n mojuto bi awọn olori ẹlẹsin gbogbo ṣe lee waasu.
níbi tí Jesu aṣiwaju wa ti wọ̀ lọ, tí ó di olórí alufaa títí lae gẹ́gẹ́ bíi Mẹlikisẹdẹki.
awon osise naa lati se isẹ won bi isẹ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Akomolede ati Aṣa lori BBC: Mọ̀ si nípa oríṣìí ẹ̀ka ìsọ̀rí ọ̀rọ̀ àti ìwúlò wọn Daddy Freeze ni, ìdúkokò ikú mọ́ni jẹ́ ẹṣẹ̀ si ẹ̀tọ́ ìgbé ayé ọmọnikeji, ti òfin orílẹ̀-èdè Nàìjíríà si takòó gidigidi.
@Mayor_fx sọ ni tirẹ pe bi wọn ti gbọn nile ọkọ naa ni wọn gbọn nile ale.
yoo fi ransẹ si aarẹ Muhammadun Buhari lati bọwọ luu.
Lasiko to n fi idi ọrọ naa mulẹ, alukoro ileeṣẹ ọlọpaa nipinlẹ Ọyọ, Wo ohun mẹ́wàá tó yẹ kí o mọ̀ tí o bá fẹ́ lọ fún ìsinmi lẹ́yìn Covid 19 Wo bí o ṣe lè ṣe eré ìdárayá tí yóò fún ọ ní adùn àti okun fún ìbálòpọ̀ Iṣu ata yáan yàan!
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìwé kíkà ló pín ọmọ tálákà yìí àti àwọn òbí rẹ̀ níyà Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Ìwé kíkà ló pín ọmọ tálákà yìí àti àwọn òbí rẹ̀ níyà 15 Owewe 2019 Airin jinna ni airi abuke ọkẹrẹ, bii eeyan ba rin jinna, yoo kuku ri ibiti wọn ti n fi odo ibulẹ jẹun.
Lẹ́yìn náà, wọ́n dojú ìjà kọ ara wọn, wọ́n sì pa ara wọn run.
Ìṣẹ́ kọ̀ndọ́ ní Fẹ́lẹ́ fí bẹ̀rẹ̀ iṣẹ́ níbẹ̀rẹ̀ ayé rẹ̀ Alága àwọn awakọ̀ ní ìhà gúúsù-ìwọ̀-oòrùn (NURTW) Alhaji Taofeek Oyerinde tí gbogbo ènìyàn mọ̀ sí Fẹ́lẹ́ tún jẹ́ alága ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́.
Ni nkan bi oṣu melo sẹyin ni awọn olori mejeeji ntako ọrọ sira wọn.
Life is not about how long you spend but how well you live to serve humanity, Amb.
Iye awọn eeyan to ṣẹṣẹ ko arun naa ni ipinlẹ kọọkan ree: Eko -345 Rivers-51 Ogun-48 Gombe-47 Oyo-36 Imo-31 Delta-28 Kano-23 Bauchi-18 Edo-12 Katsina-12 Kaduna-9 Anambra-7 Jigawa-5 Kebbi-4 Ondo-4 Nasarawa-1 Èèyàn 409 míì ti lùgbàdì àrùn Coronavirus ní Naijiria Oríṣun àwòrán, Twitter/todayng Ayẹwo ti fi han pe eeyan 409 mii tun ti ni aarun Coronavirus ni Naijiria.
Mose ṣe gẹ́gẹ́ bí àṣẹ OLUWA, gbogbo wọn sì gòkè Hori lọ níwájú gbogbo àwọn ọmọ Israẹli.
Ẹ̀wẹ̀, T Cell"" le wa ni àyíka ara fun ọ̀pọ̀ ọdún ní agbegbe ti ẹ̀jẹ̀ wa, láti ma a ṣọ́ ààrùn tàbi eroja àjòjì kan tó bá fẹ́ wọ inú ara."
Ó sàn kí ẹ pa mí ju kí ẹ ba oko tí mo gbin igbó sí jẹ́ lọ- Afurasi Clement sí NDLEA A kú oríire!
Lẹyin ọ̀pọ̀lọpọ̀ ohun to waye nile ẹjọ, adajọ ni ki wọn sọ Pasitọ naa si ẹwọn ọjọ mọkanlelogun gbako titi wọn yoo fi pari iwadii.
Bakan naa ni arẹwa obinrin, Oyebade Adebimpe naa pe ọdun miran loke eepẹ.
Ṣugbọn àwọn eniyan tí ó kù gbọdọ̀ pa àṣẹ OLUWA mọ́.
Oríṣun àwòrán, Others Oṣu Keje ọdun 1997 ni Muyiwa bi awọn ibeji ọkùnrin meji naa,lasiko ti okiki rẹ ko tii tan ninu isẹ tiata, ti awọn ibeji ọhun si ti pe ọdún mẹtalelogun ni ọdun 2020.
Ni bayii, iko agbaboolu orile-ede Croatia yoo teko leti losi orile-ede England lati tesiwaju ninu ifigagbaga idije UEFA Nation League.
30 Owewe 2019 Oríṣun àwòrán, Twitter/Premier League Àkọlé àwòrán, Manchester United vs Arsenal: Ta ni yóò borí nínú ìjà arọ méjì yìí?
A óo wọ́ òkú wọn jùnù,òkú wọn yóo máa rùn;ẹ̀jẹ̀ wọn yóo sì máa ṣàn lórí àwọn òkè.
Lọpọ igba ti eto idibo ba si n bọ, ni ariwo yoo gba ilẹ kan, ti ibẹru bojo yoo si wa pe se orilẹede Naijiria ko ni pin si yẹlẹyẹlẹ bayii.
Bí ebi bá ń pa ẹnikẹ́ni, kí ó jẹun kí ó tó kúrò ní ilé, kí ìpéjọpọ̀ yín má baà jẹ́ ìdálẹ́bi fun yín.
oro jona pe o se pataki ki ibasepo to danmoran wa laarin ile -ise oloopa ati
O wa sọ pe ti Sẹnẹtọ Ajimobi ba fẹ maa ba Ọlọrun ja lori idajọ naa ''ki o mura sii, a o wo ẹni ti yoo pegede.
Elija bá bá a lọ sọ́dọ̀ ọba.
Ó ni bí oun ṣe ń sọrọ̀ yìí, àwọn oṣìṣẹ́ mẹ́wàá lo ti wà ní agọ́ ọlọ́pàá.
Nítorí náà, báyìí ni kí ẹ̀yin máa gbadura: ‘Baba wa tí ń bẹ ní ọ̀run:Kí á bọ̀wọ̀ fún orúkọ mímọ́ rẹ,
Ààye wà fún àgunbanirọ láti wọ sòkòtò labúlabú- Ọ̀gá àgbà Toyin Abraham ní 'gbogbo wa loníbárà', Ijebu ta sí Odunlade Ọjọ kejila oṣu kẹsan an ọdun 2019 ni akọlu naa waye, ti awọn adigunjale ọhun yinbọn fun un, leyii to mu ki ọta ibọn wọ oju rẹ.
Aarẹ ana Obasanjo fikun ọrọ rẹ pe ọkan oun bajẹ nitori Aarẹ Buhari ti fi awọn ọmọ Naijiria silẹ sọwọ awọn ọdaran afurasi Fulani darandaran ti wọn dabi awọn agbesumọmi Boko Haram.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Olùkọ́ fásitì gba ìdájọ́ iku 'torí pé ó sọ̀rọ̀ òdì sí Ànọ́bí lórí ayélujára 21 Ọ̀pẹ̀̀ 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Olukọ fasiti kan ni Pakistan ti gba idajọ iku fun ẹsun ọrọ odi sisọ.
Ó di ẹni ìgbàgbé lórílẹ̀ ayé,bẹ́ẹ̀ ni a kò gbórúkọ rẹ̀ mọ́ ní ìgboro.
 talenti ramanujan je siso , latowo eni pataki olusemathimatiki ara ilegeesi g.
Ọkunrin tí àwọ̀ rẹ̀ tutù jùlọ, tí ó sì jẹ́ afínjú jùlọ ninu àwọn ọkunrin yín, yóo di ahun sí arakunrin rẹ̀, ati sí iyawo rẹ̀ tí ó fẹ́ràn jùlọ, ati sí ọmọ rẹ̀ tí ó kù ú kù, 
Yatọ si Ka'abah, awọn alalaji ko tun ni fọwọ kan okuta dudu ti a mọ si Hajar Aswad, ti wọn si tun gbọdọ fi aye ijina sira ẹni iwọn mita kan ati aabọ si ara wọn silẹ, lasiko ti wọn ba n ṣe ijọsin .
Ni kete ti a ba ti ni iroyin miran nipa iṣẹlẹ yi ni a o fi too yin leti.
Soleimani Killing: Ẹgbẹ́ Shiites wọ́de l'Abuja, wọ́n jó Àsìá Amẹ́ríkà Soleimani ń gbìmọ̀ràn láti kọ lù wá l'Amerika la ṣe kọ́kọ́ yára mú u balẹ̀ - Trump Wọ́n tẹ àádọ́ta olùdárò pa níbi ìsìnkú Qasem Soleimani tí kò wáyé mọ́ Ṣugbọn Interpol ti sọ pe ohun ko ni siju wo iwe ti Iran kọ.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Awọn ọdọ to n fa wahala lẹyin eto idibo ọdun 2011 ni Naijiria Iwọde naa pada yọri si rogbodiyan ni ẹkùn naa, ti ọpọlọpọ ile, ile ijọsin, ile itaja ati awọn dukia mi si ti di bibajẹ tabi jijo ni ina.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ìtàn tó wà nídi òwe ‘Sebótimọ Ẹlẹ́wà Sàpọ́n’ Ọba Adesoji Aderemi, Ọọ̀ni Ifẹ̀ tó gba ipò ọba mọ́ tòṣèlú MKO Abiola, iṣẹ́ aṣẹ́gità ló fi bẹ̀rẹ̀ okoòwò Iṣọla Oyenusi rèé, ẹnití ìfẹ́ obìnrin ṣun dé ìwà ìdigunjalè Lasiko ti ikọ iroyin BBC Yoruba se abẹwo si ile to jona naa, a ri pe rẹrẹ run nibẹ, ti ọpọ dukia si sofo, bi o tilẹ jẹ pe ko si ẹmi kankan to sofo lasiko isẹlẹ naa.
Eyi fihan pe gbogbo agbara koṣeemu ti Fayoṣe ni lori aleefa gẹge bii gomina ipinlẹ Ekiti labẹ ofin Naijiria a too pari.
Ile-ise panapana so pe, o niira lati lo si oke ile naa latari ina ti o gbaale kan, beesini awon ona miran lati gba de bi isele ohun ni ina ti  baje patapata.
Wo àwọn ayédèrú ìròyìn tó gbà'gboro kan lásìkò ìwọ́de #EndSARS 'Ọlọ́pàá kò yìnbọn pa olùwọ́de EndSARS kankan' MC Oluọmọ gbé ara rẹ̀ ṣépè nítorí ìwọ́de #ENDSARS Kíní ìtumọ̀ ''Sọ̀rọ̀ Sókè'' tí àwọn afẹ̀họ́núhàn EndSars ń lò káàkiri Ọlọ́pàá mẹ́fà, àgọ́ ọlọ́pàá márùn-ún ló bá wàhálà ìwọ́de #ENDSARS lọ nípìnlẹ̀ Oyo - Kọ́mísánnà Oni wọn yoo fa a lọ si ọgba ẹwọn awọn majesin tọjọ orí wọn ko ju ọdun mejidinlogun lọ gẹgẹ bi ilana ofin ṣe laa kalẹ.
Coronavirus lè tara òkú Abba Kyari ran àwọn tó péjú síbi ìsìnkú rẹ̀- Ààrẹ ẹgbẹ́ dókítà ní Nàìjíríà Ìyàn ń bọ̀ ní Nàìjíríà lẹ́yìn coronavirus àyàfi.
Osun: Àwọn ọ̀daràn tó ń d'àlú Ikire rú wọ gàù Ọlọ́pàá
Ni bayii, eeyan mẹrinlelaadọsan an (174) lo ti lugbadi arun naa ni Naijria, awọn mẹsan an ti gbawosan, ti eeyan meji lara wọn si ti jẹ Ọlọrun nipe.
Àti lọ s'Amẹrika ti yàtọ̀ báàyí Àǹfàní wà láti fí ìwé ìrìnnà ránṣẹ́ ṣùgbọ́n àwọn èèyàn kò lòó ni -NIS Wo bí o ṣe le è gba páálí ìrìnnà àti bí ò ṣelè di ọmọ orílẹ́èdè Malta Ṣé Coronavirus leè tẹ̀lé ọjà Chinco wọ Nàìjíríà?
Agbegbe Asia náà ni ajakalẹ àrùn onigbameji ọhun tí wáyé, tó sì na ọwọja rẹ dé àwùjọ àgbáyé tó fi mọ ilẹ̀ Áfíríkà pẹlu.
Ọ̀pọlọpọ̀ eniyan lo n tẹle awọn okunrin ti wọn ba oku lọpọ yii, ti wọn si n jẹ ẹran ara eniyan.
2 miliọnu lori owo iranwọ ounjẹ fun awọn ti Covid-19 ṣakoba fun.
Sáájú ní Gómìnà ìpínlẹ̀ Ogun, dapo Abiodun ti ṣàbẹ̀wò si ilú Ijebu-Igbo to jẹ́ ìlú olóògbèé.
"Ṣugbọn ẹ jẹ ki n tun sọ fun yin pe gbogbo awọn oniṣẹ ibi to ṣe iṣẹ yii ni ọwọ yoo tẹ, bẹẹni a n sa gbogbo ipa wa lati daabo bo ẹmi awọn ọmọ orilẹede Naijiria""."
Oríṣun àwòrán, Others Hadi ni Ọjọ Kẹjọ, Osu Keje ni papakọ ofurufu ti ilu Eko ati Abuja yoo ṣi pada.
OLUWA, Ọlọrun àwọn ọmọ ogun,òun ló fọwọ́ kan ilẹ̀,tí ilẹ̀ sì yọ́,tí gbogbo àwọn tí ń gbé inú rẹ̀ ń ṣọ̀fọ̀,tí gbogbo nǹkan ru sókè bí odò Naili,tí ó sì lọ sílẹ̀ bí odò Naili ti Ijipti;
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: ‘Lootọ ni nkan pa emi ati Baba Suwe pọ’ Mercy Aigbe: Èmi ni ìyá onílé tuntun Ẹni bá láyà: Ṣé ìwọ mọ àmì Yorùbá dáadàa?
Ṣugbọn Jesu wí fún wọn pé, “Ẹ fi í sílẹ̀, kí ni ẹ̀ ń yọ ọ́ lẹ́nu sí?
Ajọ NCDC naa fi lede loju opo ikansiraẹni Twitter wọn ni alẹ Ọjọ Iṣẹgun.
’’Oba naa wa fi idunnu re han
"Makinde fi ọrọ naa lede l'Ọjọbọ nibi isin idagbere to waye fun iya rẹ ni gbagede ""Arcade"" ile ijọba ipinlẹ Ọyọ gẹgẹ bi o ṣe n fi kun ọrọ rẹ wi pe iku iya oun ṣi jẹ ọgbẹ ọkan nla."
 oyèbámijí ( awy ) ( 1990 : 4 ) ni.
 Alaga naa wa kilo fun egbe APC lati maa yi ibo ti awon eniyan
Bongani Zungu lo fi ori kan bọọlu sawọn Naijiria.
Olófìn-íntótó, ọmọ olusínà kọ̀wé sí Túndé Atọ̀pinpìn.
Ọmọkunrin ẹni ọdun mẹrindinlọgbọn, Issa Sulaimon Panshekara to fẹ ẹ fẹ obinrin oyinbo ọmọ ilẹ America kan, ẹni ọdun mẹrindinlaadọta, Janine Sanchez la fọrọ wa lẹnu wo.
Igbakeji Aare Yemi Osinbajo ti ro awon onile-ise nla-nla lati dale-ise sile si orile-ede Nigeria, bi o se n se ifilole ile-ise Nestle ti yoo maa pese  ohun mimu Milo, ti iye owo re to bilionu merinNaira sile nilu Agbara, ti o wa nipinle Ogun.
Koda wọọ wọọ lero maa n wọ lati wa jẹ ounjẹ Yoruba ni kete ti wọn ba ti ṣilẹkun titi di aago mejila oru.
Kí lẹ rò pé ó şẹlẹ̀ gan?
Ìran tí gbogbo wá fẹ́ wò náà nìyẹn, nítorí láti ibẹ̀ ènìyàn á máa wo ilẹ̀ lókèrè.
Bí àwọn alufaa ti jáde láti inú Ibi-Mímọ́ náà, ìkùukùu kún inú rẹ̀, 
Eyi ri bẹẹ nitori bi adajọ to n gbọ ẹsun naa yọ ọwọ kuro ninu ẹjọ ọhun nitori o da bi ẹni pe o ṣeeṣe ko ṣe ègbè.
Ohun ni ẹgbẹ́ agbabọọlu naa wọ lọdun 1970 ti wọn gba ife idije agbaye.
Olórí Alufaa bá fa ẹ̀wù rẹ̀ ya, ó ní, “Ẹlẹ́rìí wo ni a tún ń wá?
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ann Grace Aguti: Obìnrin kan to fẹ́ ọkọ mẹ́ta lẹ́ẹkàn ṣoṣo 28 Ọ̀wàrà 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 20 Òkùdu 2020 Oríṣun àwòrán, AFP Àkọlé àwòrán, Ann Grace Aguti: Obìnrin kan to fẹ́ ọkọ mẹ́ta lẹkàn soso Ọ̀rọ̀ òbìnrin kan tí bẹ̀rẹ si ni jà rànyìn-ranyin lórí ẹ̀rọ ayélujára lóri ìgbésẹ̀ rẹ̀ láti fẹ́ ọkọ mẹ́ta lẹẹ́kan ṣoṣo.
Bí ọmọdé yìí ṣe ní kí òun náwo mú bàntẹ́ ni ó gbọ́ tí bàntẹ́ bẹ̀rẹ̀ sí kọrin báyìí pé: 
Iko omo-ogun eleto-abo ni ilu Abidjan lorile-ede Cote D”Ivoire dekun ipinnu ifehonu-han apapo awon omo-egbe oselu alatakoGege bi okan lara awon agbenuso apapo awon omo egbe oselu alatako naa pe, “apapo fun ijoba tiwa-n-tiwa ati isejoba ara-eni”.
Kí á má tilẹ̀ sọ ti ìwọ Jobu, tí o sọ péo kò rí i,ati pé ẹjọ́ rẹ wà níwájú rẹ̀,o sì ń dúró dè é!
O ni o yani lẹnu iru iroyin ti awọn ileeṣẹ iroyin Naijiria maa n gbe kiri.
Àwọn aṣòfin Democrats ilẹ America kúnlẹ fún ìṣẹjú mẹsàn án nínú aṣọ Kèǹte ilẹ Ghana fi yẹ Flyod sí Lẹ́yìn tó ṣá Monisola aya rẹ̀ ládá, Oniya ní iṣẹ́ èṣù ni ₦80m la fi rán ogún ìyàwó asòfin lọ Dubai - Obasa A ti bẹ̀rẹ̀ ìwádìí kíkún nípa àwọn tó lọ́wọ́ nínú ikú Barakat Bello - Iléeṣẹ́ ọlapàá Wọn ni ni ọjọ Aje ni aarẹ Nkurunziza jade laye.
N kò jẹ oúnjẹ aládùn, n kò jẹran, n kò mu ọtí, n kò sì fi òróró para ní odidi ọ̀sẹ̀ mẹtẹẹta náà.
Nígbà tí àwọn ọ̀gágun bá parí ọ̀rọ̀ tí wọn ń bá àwọn eniyan náà sọ, wọn óo yan àwọn kan tí wọn óo máa ṣe aṣaaju ìsọ̀rí-ìsọ̀rí àwọn jagunjagun.
iforukosile  awon oludibo fun awon egbe
Ọrọ ko ri bẹẹ fun ọkunrin ti wọn fẹsun iwa kan kan lẹyin to yaso ninu ọkọ Uber.
O ṣalaye pe wọn kan fẹ fi ohun ti wọn kọ jade bo otitọ mọlẹ ni.
Àwọn obìnrin ilé ìgbìmọ̀ aṣòfin Amẹrika fọnmú sí ọ̀rọ̀ Trump Wakati mẹwaa gbako ni ijiroro lori ọna ti ilana iyọnipo naa yoo gba fi waye laarin awọn aṣofin naa gba ni Amerika.
O san láti ma ni ǹkan ṣe pẹlu ẹnikẹni to ba ni ọ̀fìnkìn tàbi to ni ikọ́, eyi ni ọ̀na láti daabo bo ara ẹni lọ́wọ́ COVID19 Ati àwọn onimọ sayensi ni Naijiria ati gbogbo àgbáye ni wan ti jọ n gbimọ pọ lati mọ idi aisan náà ati lati wa ọ̀na abayọ Oríṣun àwòrán, Kevin Frayer Àkọlé àwòrán, Awon alase ni aisan na le ran lati ara eniyan si eniyan miran Kini awon apẹrẹ aisan Coronavirus Awọn apẹrẹ gbòògi ni: Imi to nira tabi ki èèmi ma ja geere Iba Ikọ ati Kata Awon ẹya ara le da iṣẹ silẹ Otutu aya Ati iku Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Coronavirus Symptoms: Full explanation of Covid-19 outbreak, everitin you need to know30 Èbibi 2020 Coronavirus: Nigeria goment promise N36m for scientist wey find cure for di disease and lassa fever14 Èrèlè 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
 jẹ ́ ọ ̀ kọrin hip hop ọmọ orílẹ ̀ èdè amẹ ́ ríkà .
Àwọn eniyan ṣù bo Filipi kí wọ́n lè gbọ́ ọ̀rọ̀ tí ó ń sọ, wọ́n sì ń rí iṣẹ́ abàmì tí ó ń ṣe.
Nítorí náà inú ọba ru, ó sì bínú gidigidi, ó bá pàṣẹ pé kí wọ́n pa gbogbo àwọn ọlọ́gbọ́n Babiloni run.
- Ayodele Fayose / Oṣu kẹwaa, 2018 A o ka ẹsẹ eto yi nilẹ pẹlu Gomina Ekiti ana, Ayodele Fayose lẹẹkansi.
Kọniliu dáhùn pé, “Ní ijẹrin, ní déédé àkókò yìí, mo ń gbadura ninu ilé mi ní agogo mẹta ọ̀sán.
Sanwo- Olu sọ pe igbesẹ yi jẹ ọna kan gboogi lati fi ẹmi imoore han lasiko ọdun Keresimesi.
Bakan naa ni ajs ajafẹts lagbaye, Amnesty Internation pẹlu ti bu ẹnu atẹ lu iṣẹlẹ naa.
Afuye wi pe, ile igbimọ asofin Ekiti ko tii fiwe pe gomina ana oun, sugbọn o kọ pinnu lati wa bẹ ile igbimọ aṣofin naa wo lai ro tẹlẹ ni.
Àwọn orílẹ̀-èdè yóo wá sinu ìmọ́lẹ̀ rẹ,àwọn ọba yóo sì wá sinu ìmọ́lẹ̀ rẹ tí ń tàn.
OLUWA Ọlọrun mi, fi etí sí adura èmi iranṣẹ rẹ, kí o sì gbọ́ ẹ̀bẹ̀ tí mò ń bẹ̀ níwájú rẹ lónìí.
Ṣaaju ni minisita olu ilu naa ti sọ fun awọn olugbe agbegbe bi Nyanya lati joko sile wọn, ṣugbọn ọpọ ninu awọn eeyan ọhun sọ pe wọn ni lati jade si igboro nitori atijẹ.
Bello ni: “Kii se ohun tuntun ,ti eniyan ba padanu lati jawe
" O ni akoko ti to, to jẹ pe asọtẹlẹ latinu ijọ Ọlọrun yoo maa sẹ, ẹniti wọn ba ni ko ku, yoo ku, ẹni ti wọn ba si ni ko ye, yoo ye.
Awon ile-ise iwakusa lorile-ede Ghana ni a ti ri Newmont Mining Corporation, Gold Fields, Anglogold Ashanti ati Asanko Gold.
Wọ́n fi awọ àgbò tí wọ́n ṣe ní pupa ati awọ ewúrẹ́ ṣe ìbòrí àgọ́ náà.
Wọ́n ti ṣí ilé oúńjẹ oní ọgbọ̀n náírà (N30) ní Kano Ilé ẹjọ́ rán àwọn mérìndínlógún lẹ́wọ̀n gbére fún dídáná-sun Nusrat Ọwọ ṣìkún òfin ti tẹ Maina, alága àná fún ọrọ owó ìfèyìntì - DSS Ìdí tí mo ṣe fẹ́ yọ ayédèrú ìdí ńlá tí mo ní- Sophie O ṣójú mí kóró bí wọ́n ṣé fí àdó olóró pa Dele Giwa lọdún 1986- Soyinka Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ogun flood: ọ̀ps àwọn olùgbé agbegbe yii ti fi iṣẹ́ sílẹ̀ nítorí wọn kò lè jáde Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Wo oríṣìí oúnjẹ márùn ún tó lè dẹ́kun ikùn yíyọ àti ara àsanjù Góòlù pọ̀ ní ìlú Madaka ṣùgbọ́n wọn kò ní ọ̀nà fún ọgọ́rùn ún ọdún Ìbínú ẹlẹ́wọ̀n!
Kọmiṣọnna fun ọrọ iroyin ni ipinlẹ Borno, Babakura Jatau lo sọ eyi, lasiko ifọrọwanilẹnuwo kan.
Àwọn kerubu yìí dúró, wọ́n kọjú sí gbọ̀ngàn ilé náà; gígùn gbogbo ìyẹ́ wọn jẹ́ ogún igbọnwọ (mita 9).
Àwọn ọmọ Israẹli sì ṣẹgun àwọn ará Amoni.
Ọlọrun fihan àwọn wolii wọnyi pé ohun tí wọn ń sọ kì í ṣe fún àkókò tiwọn bíkòṣe fún àkókò tiyín.
Minisita ere-idaraya, Solomon Dalung ni adari agba to n ri si siseto oniruuru ninu ajo naa, iya-afin Hauwa Kulu-Akinyemi lo soju re, eyi ti komisona to n ri si oro ifitoniileti nipinle Akwa-Ibom, ogbeni Charles Udoh gba ami-eye naa fun ijoba ipinle Akwa Ibom.
Ijọba apapọ lo paṣẹ fawọn ileeṣẹ ẹrọ ibaraẹnisọrọ lati ja awọn onibara wọn ti ko ba ni kaadi idanimọ NIN kuro loju opo wọn.
Gbogbo ohun tí ó yẹ kí ẹ ṣe nígbà náà ni mo pa láṣẹ fun yín.
Adari Eto Iroyin Ajọ EFCC, Tony Orilade ninu atẹjade to fi lede sọ wi pe ajọ naa n ṣewadii gbogbo owo to gba gẹgẹ bi owo osu lasiko to jẹ gomina ni ipinlẹ Kwara ati eyi to gba lasiko to jẹ aarẹ Ile Igbimọ Asofin.
Akori ayeye ayajo todun yii ni,”iko omo-ogun Naijiria ati oro aabo ilu: ohun kan gbogi ti yoo mu igberu ba oro aje orile-ede Naijiria” Tobi Sangotola.
- Agbẹnusọ Kassim Àìsàn tó ń ṣe mí kìí ṣojú lásán!
Kí olukuluku máa gbé ìgbé-ayé rẹ̀ bí Oluwa ti yàn án fún un, kí ó sì wà ní ipò tí ó wà nígbà tí Ọlọrun fi pè é láti di onigbagbọ.
Aarẹ Buhari ni isejọba oun n sisẹ kikankikan lati dẹkun dukuu to n waye laarin awọn agbẹ ati Fulani lawọn ipinlẹ kan lorilẹede Naijiria atipe ijọba ko ni faaye gba ipaniyan labẹ idi yoowu to lee jẹ.
Ti ọrọ ba si ti n di ti pe owo to kere ju ti osisẹ n gba ko ba lee ra lita epo kan, wahala wa niyen o.
Jeremy Corbyn to jẹ olori ẹgbẹ Labour naa ni ko si aaye rara fun Boris lati so ijokoo ile rọ lasiko yii.
Eyi lo ki awọn ẹlẹyẹ pinnu le wọn lori, lati pa wọn ni ẹyọ kọọkan, orukọ wọn si ni Kutannle, Oleegba, ati Tẹtẹrẹgun.
Lojo-Aje (Monday) Aare teleri lorile-ede Liberia,  Ellen Johnson-Sirleaf di obinrin akoko ti yoo gbami eye Mo Ibrahim fun aseyori re gege bi asiwaju nile Africa, latari akitiyan ati mu igberu ba orile-ede re, ti o koju  laasigbo ogun abele fun igba meji ototo.
akede Niajiria, Voice of Nigeria , niluu Abuja.
Nígbà tí Farao gbọ́, ó ń wá ọ̀nà àtipa Mose.
Imaamu ni ẹni akọkọ ninu ẹṣin islam, oun si ni yoo maa tọ ero ẹyin sọna, eeyan kii si beere lati jẹ Imaamu, wọn maa n fi eeyan jẹ ní.
Umar to jẹ ọmọ ọdun mejilelogun yi ni alukoro ọlọpaa Frank Mba ṣafihan rẹ, pẹlu awọn afurasi miran nilu Abuja lọjọru.
Iṣoro ati idamu ti awọn ileeṣẹ la kọja lọdun 2016 si 2017 ti di ohun igbagbe bayii.
Sibẹ, mo ti fi ìgboyà tẹnumọ́ àwọn kókó ọ̀rọ̀ mélòó kan ninu ìwé yìí, láti ran yín létí nípa wọn.
9 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 3 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 5 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù OAU: Ọ̀jọ̀gbọ́n jẹ̀bi ìbèèrè ìbálòpọ̀ fún máákì 20 Òkùdu 2018 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 21 Òkùdu 2018 Oríṣun àwòrán, OAU Àkọlé àwòrán, Ọ̀gá àgbà ilé-ìwé Ọbafẹ́mi Awolọ́wọ́ sọ pé àwọn ń sapá láti fopin sí gbogbo ìwà ìdúkòò-mọ́ni fún ìbálòpọ̀ nílẹ̀ ẹ̀kọ́ náà Fásitì Obafemi Awolowo Ilé-Ifẹ̀, ti gba isẹ́ lọ́wọ́ Ọ̀jọ̀gbọ́n Richard Akindele fún bíbèrè ìbálòpọ̀ lọ́wọ́ akẹ́kọ̀ọ́ kan, Monica Osagie, láti fún ní máàkì.
Nípa ìjọba ìpínlẹ̀ náà tó ti ìjọba ìbílẹ̀ Kabba Bunnu pa ní ǹkan bi ọsẹ díẹ̀, ó ni gómínà ṣe èyí láti lé jẹ kí àwọn eletò ìlera ṣe ìwádìí ni, nígbà ti ba abájade ìwádìí náà ba sì jáde àtéjáde tabi ìpàdé oníròyìn yóò wáyé.
Ní àkókò náà Jesu ń la oko ọkà kan kọjá ní Ọjọ́ Ìsinmi àwọn Juu.
síwájú sí i , àwọn oníṣòwò gbọ ́ dọ ̀ máa sètò to jíire lórí ìnáwó wọn .
Ó bi í pé,“Ta ni ẹni tí ń bu ẹnu àtẹ́ lu ìmọ̀ràn,tí ń sọ̀rọ̀ tí kò ní ìmọ̀?
Samson Siasia fèsì lórí FIFA tó fòfin dèé Ọlọ́pàá Bayelsa ní àwọn ti kán lugbó láti wá ìyá Siasia Siasia kọ̀wè fún ipò akọ́nimọ̀ọ́gbá Cameroon Ilé-ẹjọ́ fi Sẹ́nétọ̀ sátìmọ́lé #Russia2018: Super Eagles ti koju Argentina rí Ofin ayeraye ni ajọ FIFA fi de akọnimọọgba SIasia ti iya rẹ ṣi wa ni akata awọn ajinigbe bayii.
Ikú ṣe wa padà mú ọ láìròtẹ́lẹ̀?
Àwọn ọmọ tí ẹrú náà bá sì bí ninu ilé alufaa náà lè jẹ ninu oúnjẹ náà pẹlu.
Nígbà tí Adamu di ẹni aadoje (130) ọdún, ó bí ọmọkunrin kan.
8 163972 Orilẹede Myanmar 2926 5.
Alaga egbe naa Ogbeni John Oyegun so pe awon igbimo naa ti pari ise won , won yoo si gbe e wa siwaju awon igbimo amusese fun ijiroro.
Nibayii, eeyan 1,057 lo ti ba ajakalẹ arun naa lọ ni Naijiria.
Ní ìgbà wọ̀nyí, àwẹ̀ gbígbà a máa dàbí àdánwò àti ìpèníjà fún àwọn mùsùlùmí tí wọ́n gba àwẹ̀ fún wákàtí pípẹ́.
Ofin tuntun fun awọn arinrinajo lati South Africa, UK 1.
Àwọn ìjì nlá-nlá tún jà káàkiri àgbáyé, tí wọ́n sì kó ọ̀pọ̀ ẹ̀mí àti dúkìá lọ́.
Géńdé agbébọn jí adájọ́ gbé lọ ní ìpínlẹ̀ Ondo Wàhálà ejọ́ yìí bẹ̀rẹ̀ lásìkò tí àjọ ọlọpàá fẹ̀sùn kan ilé iṣẹ́ ọlọpàá pé wọ́n já ètò igbànisísẹ́ náà gbà mọ àwọn lọ́wọ́.
Ṣugbọn OLUWA yóo fi irú ìyà àwọn aṣebi jẹàwọn tí ó yà sí ọ̀nà àìtọ́.
 Ó jẹ ́ ẹ ́ límẹ ̀ ntì olójú-ìsopọ ̀ mẹ ́ jì tó ṣe é rí nínú ìdàpọ ̀ mọ ́ àwọn ẹ ́ límẹ ̀ ntì míràn nìkan nínú àwọn àlúmọ ́ nì .
Kódà, bí èèyàn bá fẹ́ ra páálí ẹgbẹ̀rún kan, a kò ní fún wọn ní rìsítì""."
Okan lara awon eto akanse ti won n gbero lati fi fa oju awon ara ile okeere si owo Ankara ni sise odun Ankara nipinle Eko ti won pe ni LAAFEST.
Bẹ́ẹ̀ ni ti àwọn tí wọ́n ń fi ipá kó ọrọ̀ jọ rí,ọrọ̀ tí wọn fi ipá kójọ níí gba ẹ̀mí wọn.
kookan jake-jado orile-ede yii, lati ron awon ara ilu leti awon ileri wa ti a
“Kò sí ẹni tíí fi ìrépé aṣọ titun tí kò ì tíì wọ omi rí lẹ ògbólógbòó ẹ̀wù, Bí bẹ́ẹ̀ kọ́, ìrépé aṣọ titun náà yóo súnkì lára ògbólógbòó ẹ̀wù náà, yíya rẹ̀ yóo wá burú ju ti àkọ́kọ́ lọ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Pottery: Àwọn onímọ̀ nípa amọ̀ wúlò púpọ̀ ju ike àbí irin lọ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Pottery: Àwọn onímọ̀ nípa amọ̀ wúlò púpọ̀ ju ike àbí irin lọ 16 Owewe 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 20 Owewe 2019 Lara awọn isẹ isẹnbaye wa nilẹ Yoruba ni amọ mimọ jẹ eyi to n mu owo wa fun ọpọ eeyan.
com Ọkan lara awọn afunrasi mẹta ti ọwọ ọlọpaa ba fun ipaniyan ọwọọwọ to n waye lagbegbe Akinyẹle nilu Ibadan, ni ipinlẹ Oyo ti sọrọ sita.
Eniyan mẹjọlenigba ninu awọn to ni arun ọhun ni Naijiria ti ri iwosan gba, ṣugbọn mejilelọgbọn ti filẹ ṣaṣọ bora.
Ọjọ Kẹrinla, oṣu Kọkanla, ọdun 1942 ni Samuel ati Abigail Ajike Ogunsola bi akọni oṣere tiata naa sile aye, to si jẹ ọmọ agboole Baala Dasaolu lẹyin mọsalasi Ita Igbẹyin ladugbo Oke Itoku.
ate lu isekupani eniyan mẹ́tàdínlógójì, eleyi ti awon alakatakiti
Ìgbéyawó yìí lárinrin Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Theresa May: A ó fún Nàìjíríà ní £70-million láti pèsè isẹ́ 28 Ògún 2018 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 30 Ògún 2018 Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'O yé kí ìbáṣepọ̀ Nàìjíríà àti UK dán mọ́rán síi lẹ́yìn àbẹ̀wò May' Ijọba Ilẹ Gẹẹsi ti kede pe awọn yoo fun orilẹ-ede Naijiria ni aadọrin miliọnu owo ilẹ okeere Euros lati fi pese ọkẹ marun isẹ fun awọn ọdọ Naijiria.
Coronavirus: Wale Akintade ní ìjọba ń sanwó oṣù fáwọn àmọ́ nǹkan kò rọgbọ
Ileeṣẹ ọlọpaa gbagbọ pe awọn oniṣowo naa ''mọọmọ kọ ẹyẹ ayekootọ naa ni ofofo ṣiṣe ni,'' nitori lọgan ti awọn ọlọpaa ba ti sun mọ ile ti awọn oloogun oloro naa wa, ni yoo bẹrẹ si ni i pariwo.
 wọn kò gba alátakò kankan láyè .
 Orilé ede mejilelọgbọn lo kopa ninu idije ife ẹyẹ agbaye tọdun 2018.
Makinde salaye pe iya oun ko fẹ ki oun lọwọ ninu eto oṣelu orilẹ-ede Naijiria rara, nitori igbagbọ awọn eniyan pe awọn oloṣelu kii ṣẹni ire.
Gege bi atejade ajo FIFA ti o jade ninu ero ayelujara won lojo-Bo(Thursday) se so, Iko agbaboolu Super Eagles ti o wa ni ipo mokanleladota lagbaye pelu ami egbeta-lemokanleladota ninu osu-kinni odun yii.
ẹni tí ó ń fún wa ní ìwúrí ninu gbogbo ìpọ́njú tí à ń rí, kí àwa náà lè fi ìwúrí fún àwọn tí ó wà ninu oríṣìíríṣìí ìpọ́njú nípa ìwúrí tí àwa fúnra wa ti níláti ọ̀dọ̀ Ọlọrun.
Ohun tí ó bá ṣẹ́kù ninu ohun jíjẹ náà di ti Aaroni ati àwọn ọmọ rẹ̀.
Eyi tumọ si pe bi ijọba ti yoo gba iṣẹ lọwọ Ambode ba ni aato kan naa bii tirẹ ti yoo mu alafia ati ilera wa fun gbogbo eniyan, yoo tẹsiwaju bi ko ba si gbagbọ ninu tirẹ, aato tiwọn naa yoo wulo fun awọn ara ilu.
Fún ayẹyẹ ọdún, kò si iyàtọ̀ laarin Ìgbàgbọ́ àti Mùsùlùmi ni ilẹ̀ Yorùbá nitori Yorùbá gbà wi pé “Ẹni ọdún bá láyé, ó yẹ kó dúpẹ́”.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Bitcoin: Wo àwọn nkan tí ó yẹ kí o mọ̀ nípa Bitcoin, kí o tó ó dáwọ́ le e 16 Agẹmo 2020 Oríṣun àwòrán, Reuters Owó Bitcoin ati awọn owó orí ayelujara miran jẹ owó airi.
‏ Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 3 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 5 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Kódà, gbajumọ osere tíátà míì, Razak Olayiwola, tí wọn tún ń pè ní Ojopagogo, lo fẹ́ Mojisola ọmọ Adeyemi Afolayan ni ìyàwó, tí àwọn méjèèjì sì tún dijọ ń ṣe iṣẹ́ tíátà papọ.
”Wọ́n dáhùn pé, “Lọ gbógun tì í, Ọlọrun yóo fún ọ ní ìṣẹ́gun.
"Aṣini lọna kan lo fi agidi mu wọn.
Ṣugbọn ni ọdun 2016 ni awọn kan lara wọn yapa, ti wọn si darapọ asia ẹgbẹ Islamic State ti agbegbe iwọ oorun Afrika.
Olówó-ayé, Olówó-ayé, mú ẹbọra lápa, mú ẹbọra lẹ́sẹ̀, gbé ẹbọra kúrò ní ilẹ̀ tán pátápátá.
Nigba to n sọ ero rẹ lori iwa ifipa bani lopọ to n gogo nilẹ wa lẹnu lọ lọọ yii, Sola ni ẹni ti ori rẹ ko pe lo n fi tipa ba obìnrin lopọ, tori wọn ni agbara lati kọ ẹnu si obìnrin to ba wu wọn.
Ajimọbi ni ileri oun lati rii pe awọn to pa 'ṣugar' foju ba ina ofin, ileri naa ko si tii yẹ rara.
Aidan Dumuje - BBC News Yorùbá BBC News, YorùbáFò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Olympics ni ọkàn mi wà gẹ́gẹ́ bí òmùwẹ̀ - Aidan Dumuje Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Olympics ni ọkàn mi wà gẹ́gẹ́ bí òmùwẹ̀ - Aidan Dumuje 12 Bélú 2019 Ọlọrun lo mọ ọdun gan ti Aidan Dumuje Abulu bẹrẹ si ni luwẹ to fi jẹ wi pe ni ọmọ ọdun mẹjọ afi bii ẹja ni wiwẹ rẹ.
Nítorí ìwọ kì í ṣe Ọlọrun tí inú rẹ̀ dùn sí ìwà burúkú;àwọn ẹni ibi kò sì lè bá ọ gbé.
Bakan naa lo fi kun pe, awọn ti gbe igbesẹ lati ya ara awọn sọtọ, ti awọn yóò si ri iwosan gba.
Gbogbo àwọn ọmọ Israẹli yóo wá gbà pé o ti kẹ̀yìn sí baba rẹ, ọkàn gbogbo àwọn tí wọ́n wà lẹ́yìn rẹ yóo sì balẹ̀.
'MC Oluọmọ kò kú o, kò sí ikú lójù rẹ̀' ‘Ènìyan 12 pàdánù ẹ̀mí wọn nínú ìjàmbá ọkọ̀ Ekiti’ ‘Yorùbá, ẹ dìbò fún Buhari láti bu ọlá fún M.
O ni ki ẹ si maa wa wo o, awọn o jẹ nile oro jẹ nile eegun oloṣelu ni wọn wa nidi ọrọ yii ati pe awọn ọta ẹya Fulani naa wa nidi ẹ; ṣe ẹ si mọ pe eeyan kii wa laye ki o ma ni ọta tirẹ naa.
Nítorí náà, ẹ̀yin ará, ẹ dúró ṣinṣin, kí ẹ di àwọn ẹ̀kọ́ tí a fi le yín lọ́wọ́ mú, kì báà ṣe àwọn tí a kọ yín nípa ọ̀rọ̀ ẹnu tabi nípa ìwé tí à ń kọ si yín.
ohun tun gbosuba kare lai fun aare orile-ede Ghana, Nana Akuffo-Addo, aare
Ẹ̀rù bà á, ó ń gbọ̀n, ó bá wá kúnlẹ̀ níwájú Jesu, ó sọ gbogbo òtítọ́ ọ̀rọ̀ náà fún un.
Iwaadi naa ṣe afihan iroyin nipa awọn obinrin mẹtadinlaadọta ti wọn ṣeku pa lọjọ kini oṣu kẹwa ọdun 2018.
Ni itẹsiwaju bakan naa atẹjade ipade yi daba ṣiṣe ayẹwo ọpọlọ fawọn oṣiṣẹ SARS ti wọn ba da silẹ to fi mọ idanilẹkọ ṣaaju ki wọn to pin wọn si ẹka ọlọpaa mii.
Iroyin bọ si gboro ni ọjọ aje pe awọn ọlọpaa ti mu Sẹnetọ Ademọla Adeleke si ahamọ lori ẹsun to niiṣe pẹlu ẹsun pe o lo ayederu iwe ẹri girama.
Iwadii ti ajọ WHO ati UNICEF ṣe fihan pe orilẹede Afirika mẹfa pere lo ti ṣi gbogbo ileewe wọn pada lẹyin ti wọn ti gbe tipa nitori ajakalẹ aarun covid-19.
o beere fun aaye lati maa yan fanda fanda kaakiri bo ṣe wu u, to si ni ki wọn si fi oun wọ si ile itura olowo nla kan dipo ile iwosan to yẹ ko wa eleyi ti awọn alaṣẹ orilẹede India tako nitori pe irinajo lati gba itọju lawọn gbọ pe wọn fun un laṣẹ fun, kii ṣe ti irinajo afẹ."
Bakan naa, awon oga agba mewaa miiran nile-ise ijoba ti o wa labe ajo to n mojuto oro abele tun je anfaani igbega lenu ise, eleyi  ti aare Buhari fi da won lola lataari ise takun-takun won.
Nengi si ti gba ẹbun owo to le ni miliọnu marun-un, N5,328,000 tẹlẹ lori eto.
Bukunmi kọ soju opo ayelujara rẹ naa pe gbju-gbaja osere tiata kan, Funke Akindele ti ransẹ si oun , eyi to mu ki inu oun dun kọja aala.
Ẹ̀wẹ̀ ìjọba ìpínlẹ̀ Kwara náà ti ni ki gbogbo oṣiṣẹ tirẹ maa siṣẹ́ láti ilé.
Nitori ati yẹra fun ikọlu awọn janduku naa, nṣe ni gbogbo wọn n bọ aṣọ ti wọn wọ gbogbo to ni ami idanimọ Dapọ Abiọdun lara Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 3 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 5 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Ọba Adesoji Aderemi, Ọọ̀ni Ifẹ̀ tó gba ipò ọba mọ́ tòṣèlú Ìtàn tó wà nídi òwe ‘Sebótimọ Ẹlẹ́wà Sàpọ́n’ Àìle è ka kéú ló sọ mí di Krìstíẹ̀nì - Adewale Ayuba Lẹ́yìn-ọ̀-rẹyìn, bàbá ọgọ́rùn-ún ọdún gba ìdáǹdè l‘ẹ́wọ̀n Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Òpó mẹẹdogun mẹẹdogun wà ní ìlà kọ̀ọ̀kan.
Gbogbo àwọn alufaa tí wọ́n bá ṣiṣẹ́ ninu ilé OLUWA a sì máa kó owó tí àwọn eniyan bá mú wá sinu rẹ̀.
"Ni meni meji,awọn ti a le ranti ni wọn yi: ""Ìgbìmọ ẹlẹ́ni méji ló ń dari ọkọ mi"" Oríṣun àwòrán, Mamman Daura Àkọlé àwòrán, Mamman Daura Ní ibi ìpàdé àpérò kan nilu Abuja ní Aisha ti pe awọn ọmọ Naijíríà nija láti kọju ìjà si àwọn ìgbìmọ̀ ẹlẹ́ni méji si mẹ́ta tó n dari ìjọba Muhammadu Buhari ni lòdì si àwọn ènìyàn Nàìjíríà."
Pẹlu owo osu rẹ, yoo gba ọ ni odun 260 lati gba iye owo ti sẹnatọ kan n gba lọdọọdun.
Bakan naa, o seese ki iko agbaboolu Arsenal tun fise akonimoogba lo Ancelotti, leyin ti akonimoogba iko ohun Arsene Wenger  ti pinnu lati fi iko naa sile bi saa yii ba pari.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Mo fẹ́ gbé ògo ìdílé ìyá àti bàbá mi ga pẹ̀lú iṣẹ́ Mọkálìíkì' Ninu igbiyanju lati lẹ imu naa pada lo ti ṣalabapade dokita Zalmai Khan Ahmadzai, to jẹ onimọ ijinlẹ nipa titun ẹya ara to ti bajẹ ṣe.
Ni abala eto ẹko, ofin odun 2018 to n risi ẹka naa yo se atiwaye isakoso eto ẹko pẹlu ifojusun ti o dan maran.
o fi kun pe awọn ọlọpaa ti wọn yoo gba fun amojuto agbegbe kọskan yoo jẹ awọn ti a bi ni irufẹ agbegbe bẹẹ ki wọn lee daabo bo wọn bi o ti tọ.
Ninu ọrọ to ba BBC News Yoruba sọ, aarẹ ẹgbẹ awọn dokita ni ileewosan nla fasiti ilu Eko, LUTH, Dokita Ọlawale Ọba ni ọrọ lori owo oṣu awọn dokita ti awọn alaṣẹ kuna lati san lo ṣokunfa iyanṣẹlodi naa.
'Àwa ọmọ Nàìjíríà tó farapa fẹ́ wálé láti Lebanon, ìjọba kó wa pamọ́' Oríṣun àwòrán, others Awọn alaṣẹ ijọba Lebanon ti da ọmọ Naijiria marun un pada ki wọn ma lee ririnajo jade pẹlu ọkọ ofurufu ti ijọba Naijiria pese pe ko lọ gbe wọn ni ọjọ kejila, oṣu kẹj,ọ ọdun 2020.
Ni nnkan bi oṣẹ meji sẹyin ni wọn mu wọn lori ẹsun pe wọn kopa ninu idigunjale bankii naa nibi ti eeyan meje ti padanu ẹmi wọn.
Tinubu gbaleji Abiru toun ti awọn ọmọ ẹgbẹ oṣelu APC nile rẹ rẹ nibi ti wọn ti n yọ ayọ iṣẹgun ẹgbẹ oṣelu naa ninu ibo ọjọ Abamẹta.
A ko ni lati duro de ijọba, ki olukuluku ṣe ipa tirẹ lo tọ.
Ikọ ijọba apapo ti minista fun ọrọ awọn oṣiṣẹ, Chris Ngige n ṣaaju ni yoo ba wọn ṣe ipade.
Dípò ìtìjú ìpín tiyín yóo jẹ́ meji,dípò àbùkù ẹ óo láyọ̀ ninu ìpín tí ó kàn yín.
Òun ni ó dá gbogbo orílẹ̀-èdè láti inú ẹnìkan ṣoṣo láti máa gbé gbogbo ilẹ̀ ayé.
àwọn ọmọ Bakibuki, àwọn ọmọ Hakufa, ati àwọn ọmọ Harihuri, 
Nibi idajọ Onyeri ni ile ẹjọ ijọba apapọ kan ni ilu Austin, Ipinlẹ Texax, adajọ Lee Yeakel ni arakunrin naa yoo lo iyoku aye rẹ ni ẹwọn.
Ẹni tí ó bá fẹ́ràn aya rẹ̀, òun tìkararẹ̀ ni ó fẹ́ràn.
Kọmisọnna salaye pe ile lilọ ni aago meji fun awọn ọlọmọ wẹwẹ ko ni waye mọ ti wọn ba ti wọ iṣẹ pada lẹyin osu mẹfa.
Ẹrù ìyà ni Norway dì lé Super Falcons lórí ní 2019 Women's World Cup Gómìnà ìpínlẹ̀ Osun wọ́gilé ìrìnàjò àwọn alága sí Dubai Rohr já Iheanacho àti Semi jùú lẹ̀ lọ Egypt fún AFCON 2019 Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Iba Gani Adams: Bẹ́ẹ gbé màláíkà kan lọ sí Aso Rock, kò lè ṣàṣeyọrí Ifẹsẹwọnsẹ ọhun ni akọkọ fun orilẹ€de Thailand ninu idije ife ẹyẹ agbaye.
Àwọn arọmọdọmọ Efuraimu nìwọ̀nyí: Ṣutela ni baba Beredi, baba Tahati, baba Eleada, baba Tahati, 
Alága àjọ INEC, Ọ̀jọ̀gbọ́n Mahmood Yakubu, ló sọ èyí di mímọ̀ lásìkò tó ń bá àwọn alẹ́nulọ́rọ̀ sọ̀rọ̀ lórí ìdìbò sípò Gómìnà ìpínlẹ̀ náà, tí yóò wáyé lóṣù keje.
    Ìgbà tí a ṣe eléyìí tán, inú iwin náà dùn púpọ̀, ṣùgbọ́n ó ku bí a o ti ṣe ahọ́n ìyàwó rẹ̀ gígùn gbọ̀ọ̀rọ̀.
Lara wọn ni Banki, NEPA, Ileewosan ati bẹẹ bẹẹ lọ eyi to si maa n wulo gidi gan lasiko ipade adura ọlọdọọdun.
Àwọn Ìlú tí A Fún Àwọn Ọmọ Lefi.
Iroyin ni arakunrin naa bẹrẹ si ni sọ kantan kantan wi pe Aarẹ Muhammadu Buhari lo pa asẹ fun oun lati wa gba isẹ lọwọ Ọga Agba Ajọ Custom patapata, CG, Hameed Ali.
Wa kuro bi o ba ti jina.
Wọ́n gba ìhà gúsù gòkè lọ sí Heburoni, níbi tí àwọn ẹ̀yà Ahimani, ati ti Ṣeṣai ati ti Talimai, àwọn òmìrán ọmọ Anaki ń gbé.
Wọ́n fi ẹ̀sùn kàn wọ́n pé wọ́n lọ́wọ́ nínúu ìjínigbé àti ìṣekúpa Stompie Moeketsi, tó jẹ́ ọmọ ọdún mẹ́rìnlá.
Ọ̀ràn-an ìṣọdẹ-àjẹ́ ti wà l’ákọsílẹ̀ ní Chattisgarh, Odisha, Gujarat, West Bengal Assam, Bihar, Maharashtra àti Rajasthan pẹ̀lú.
Covid-19 ti pa akọni afúnfèèrè Sax ilẹ̀ Africa Solomon Oladimeji soro ni kikun lori ipa ti ofin yii le ni lori ọrọ aje ati igbe aye awọn eniyan lasiko ibẹru coronavirus yii.
Ní oókan-àyà rẹ̀ ni wọ́n kọ àkọlé yìí sí: ‘Ọkàn olódodo balẹ̀ bí ọkàn ẹni tí kò hùwà ìbàjẹ́ sí ọmọ nìkejì, tí kò sì ṣe ohun ìkọ̀kọ̀ pamọ́ sí ọwọ́ ẹni ẹlẹ́ni, ọkan olódodo funfun gbòò, ara rẹ tutù bí ara ewéko etí omi, olódodo dúró gbọnin bí òkè ńlá.
O fikun un pe ohun to wu gomina naa lo n se nipinlẹ naa, amọ ko da eto ẹgbẹ oṣelu PDP to jawe olubori ninu idibo to kọja ru nitori ẹka osisẹ yato si eto oselu lorilẹ-ede Naijiria.
Lẹyin orẹyin, arakunrin Patrick Sawyer to gbe aarun naa wọ Naijiria ku ti osisẹ ilera mẹfa si padanu ẹmi wọn bakanna.
Ọgbà ẹ̀wọ̀n ni Naira Marley yóò ti wo ìbúra Buhari ní May 29 Ẹfunsetan Aniwura, obìnrin tó ju ọkùnrin lọ Abiodun Koya ti gbe orin olohun gooro rẹ de ile ijọba ilẹ Amẹrika (White House).
Njẹ agbo naa dara fun ara?
Oríṣun àwòrán, Getty Images Apapọ awọn to ti ni arun naa kaaakiri orilẹ-ede Naijiria ti wa di 23,298 bayii.
Oríṣun àwòrán, @yahaya Àkọlé àwòrán, A maa fiya to tọ jẹ àwọn ti wọn ko nkan ìní ijọba jẹ Gomina tuntun fun ipinlẹ Gombe ni oun ko ni tẹlẹ awọn awuyewuye to ti n waye lati oṣu kẹta ni Gombe rara.
LASEMA ni kete ti wọn de ibi iṣẹlẹ naa ni wọn rii pe ile alaja meji ọhun lo ti wo de ilaji to si wo lu awọn ọmọ mẹrin ninu rẹ.
Okiki Osinowo kan lẹyin to fidi Gbenga Ashafa janlẹ ninu idibo abẹnu sipo ṣenetọ to wa ye ninu ẹgbẹ oṣẹlu APC ni ẹkun idibo ila-oorun ipinlẹ Eko lọdun 2019.
Lẹ́yìn náà, se irú oúnjẹ aládùn tí mo fẹ́ràn fún mi, kí n jẹ ẹ́, kí ọkàn mi lè súre fún ọ kí n tó kú.
 Ìwa ti Ààbò wù yìí mu kí àwọn àlejò mẹ ́ ẹ ́ tẹ ̀ ta wọ ̀ nyí fì ifá sílẹ ̀ laipa .
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù World Event: Wo ohun tó ṣelẹ̀ ní àgbáyé lọ́sẹ̀ tó kọjá 22 Owewe 2019 Kíni Donald Trump, Mohammadu Buhari, Awọn olóró Isẹyin àtàwọn míì ṣe lagbaye láàrin ọ̀sẹ̀ tó kọja?
Baba Obasanjo ni orilẹede Naijiria ni ohun alumọni to jẹ wi pe ko yẹ ki iya ati iṣẹ ma a jẹ ẹnikẹni.
7 Nítorínáà, bí a ṣe ti rì ọ́ bọmi láti ọwọ́ ìránṣẹ́ mi Joseph Smith, Kekeré, gẹgẹbí èyíinì tí mo paláṣẹ fún un, òun ti ṣe ohun tí mo pa láṣẹ fún un.
Irọlẹ Ọjọru ni ayẹyẹ Iftar naa pẹlu awọn Alfa ati Imaamu waye ni Ile Ijọba Ipinlẹ naa.
Lọ wádìí kí o rí i pé wolii kankan kò lè ti Galili wá!
pupo lowo awon olugbe ilu FCT fun abewo won, bee si ni o tun lo
Àwọn wọnyi ni àwọn olórí ìdílé ati olórí ẹgbẹẹgbẹrun ọmọ ogun ati olórí ọgọọgọrun-un ọmọ ogun, ati àwọn olórí tí wọ́n jẹ́ aṣojú ọba ní gbogbo ìpínlẹ̀ ní oṣooṣù, títí ọdún yóo fi yípo ni wọn máa ń yan ọ̀kẹ́ kan ó lé ẹgbaaji (24,000) eniyan, tí wọn ń pààrọ̀ ara wọn.
Kí ló ṣe ọ́, Israẹli, tí o fi ń sọ pé,“OLUWA kò mọ ohun tí ń ṣe mí,Ọlọrun kò sì bìkítà nípa ẹ̀tọ́ mi.
Ẹ̀yin ọmọ eniyan, yóo ti pẹ́ tó, tí ẹ óo máa fi ojú ọlá mi gbolẹ̀,tí ẹ óo máa fẹ́ràn ọ̀rọ̀ asán, tí ẹ óo sì máa wá irọ́ kiri?
Alaga egbe awon akoroyin nipinle Benue Saater Undu so fun oga agba ajo NCPC naa pe, abewo re ohun ni lati safihan awon ojuse egbe naa,ati lati ri daju pe, isokan ati idagbasoke ipinle naa je won logun.
24 Kíyèsíi, èmi ni Ọlọ́run, mo sì ti sọ ọ́; àwọn òfin wọ̀nyi jẹ́ tèmi, a sì fi wọn fún àwọn ìránṣẹ́ mi nínú àìlágbára wọn, ní irú èdè wọn, kí wọn ó lè ní òye.
Akinwunmi Ambode naa ti ki aare 
Ọọni ile Ifẹ sọ eyi lasiko to gbalejo aṣoju ijọba ilẹ Gẹẹsi, Catriona Laing, ni aafin rẹ, Ile Oodua nilu ile Ifẹ.
Àwọn àjẹsára àkọ ́ kọ ́ tí a lò láti kojú àrùn onígbáméjì ni a ṣe àgbéjáde wọn ní ìparí àwọn ọdún 1800 .
Rárá o, ojú kì í tì wọ́n; nítorí pé wọn kò lójútì.
Ẹwẹ,ijọba ti fofin de awọn ẹgbẹ ọlọdẹ ti wọn ni wọn wa nidi ikọlu naa to mu ẹmi eeyan aadoje le mẹrin lọ .
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Àabo ilẹ̀ Yoruba: Ọlọ́pàá ìpínlẹ̀ dára ṣùgbọ̀n ọ̀ràn lè tibẹ̀ jáde 26 Òkùdu 2019 Oríṣun àwòrán, Getty/LUIS TATO Orọ eto aabo ipinlẹ Yoruba méféefa ti gba apero awọn gomina ati ori ade bayii.
majebi Àkọlé àwòrán, Awo igbọnsẹ naa ko ribi bọ lọwọ awọn janduku.
Amramu fẹ́ Jokebedi, arabinrin baba rẹ̀.
 ilé Ọ ̀ rúntọ ́ ti wà ní ifẹ ̀ kí lámurúdu tó dé.
Oríṣun àwòrán, Other A kò tíì lè sọ ti ìfipabánilòpọ̀ àmọ́ òkúta ni wọ́n fi fọ́ orí Azeezat - Ọlọ́pàá Oyo Mẹwaa n ṣẹlẹ ni duniyan, kayefi nla mii tun ṣẹlẹ.
Ilẹ̀ Yorùbá ni ohun ọrọ̀ ajé àti oúnjẹ ni oriṣiriṣi tẹ́lẹ̀, ṣùgbọ́n lati igbà ti Ìjọba àpapọ̀ ti da gbogbo ẹ̀yà orilẹ̀ èdè Nigeria pọ̀ ti wọn si bẹ̀rẹ̀ si pin owó epo rọ̀bì ni ìfẹ́ oúnjẹ àti ọjà òkèèrè/òkè-òkun ti sọ ọ̀pọ̀lọpọ̀ di ọ̀lẹ àti ẹni ti kò ni ìrònú.
gbe igbese lati ri wi pe, aabo to muna doko wa nile.
Ẹ̀gbọ́n ni ó jẹ́ fún Ilésanmí.
Ọgbọn ọjọ, oṣu Kẹta, ọdun 2020 ni aarẹ kọkọ kede isede ni ipinlẹ Eko, Ogun ati ilu Abuja, nibi ti coronavirus ti kọkọ n gbilẹ.
'Yan Daudu' lorukọ tawọn eeyan ma n pe iru awọn ọkunrin bẹẹ ni ilẹ ariwa.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Oladejo Okediji, gbajúgbajà òǹkọ̀wé Yorùbá papòdà lẹ́ni ọdún 89 11 Ìgbé 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 26 Ọ̀wàrà 2019 Oríṣun àwòrán, Oladejo Okediji/Facebook Àkọlé àwòrán, Erin wo!
Awọn iroyin ti ẹ lee nifẹ si: Agbebọn pa ọmọ ogun mejila ‘Atunse ofin lo le dẹkun jẹgudujẹra’ Nigba wo ni isuna 2018 yoo dohun?
Kí ni ogún mi lọ́dọ̀ Olodumare?
Amọṣa gbigba rẹ lo di wahala nla sawọn ọmọ orilẹede Naijiria lọrun paapaa julọ ilana ati gba a.
Ọjọ kẹtadinlọgbọn, Osu kọkanla, ọdun 1967 ni wọn bi Pasuma ni agbeegbe Mushin, ni Ipinlẹ Eko, ti o si dagba si ipinlẹ Kwara, lorilẹede Naijiria.
OLUWA Ọlọrun ní:“Èmi fúnra mi ni n óo mú ọ̀kan ninu ẹ̀ka kan ní ṣóńṣó igi Kedari gíga,n óo ṣẹ́ ẹ̀ka kan láti orí rẹ̀,n óo gbìn ín sí orí òkè gíga fíofío.
Ekejii, iṣẹ ti bọ lọwọ James Nwafor to jẹ olori iko SARS tẹlẹ ni Anambra, yoo si jẹjọ; Ẹkẹta, Nrii daju pe.
Araale: Njẹ Seyi n pinu lati dara pọ mọ oṣelu?
" Wo ọkùnrin tó dáná sun ọ̀rẹ́bìnrin rẹ̀ torípé kó gbà látí jẹ́ aya rẹ̀ Ààrẹ ti kọ̀wé fipò sílẹ̀ torí èèyàn méjì t'ọ́lọ́pàá pa níbi ìfẹ̀hónúhàn lòdì sí ìjọba Ìpínlẹ̀ Eko ní èèyàn 136 nínú èèyàn 152 lápapọ̀ tó lùgbàdì àrùn Coronavirus ní Nàìjíríà Awọn ọlọ́pàá gbòde kan ní Ajah, ọwọ́ tẹ àwọn afurasi tó ń jalè Oluwo ṣalaye pe aafin oun ní ilu Iwo ni aafin Ọlọrun nile aye ko sì sí Ọba miran mọ nitori Ọba kii pe meji laafin.
Awọn to wa ninu ikọ to ṣe iṣẹ abẹ naa ni awọn dokita oniṣẹ abẹ atawọn onimọ ilera mii ti wọn lo wakati mẹta lati doola awọn ọmọ mejeeji lọjọ kẹwaa oṣu kẹjọ ọdun 2020 ti wọn bi wọn pẹlu ẹdọ ati eegun aya kan naa ti wọn jọ mu wa latọrun.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ki ni o mọ to n jẹ owo iranwọ epo?
Ẹnikẹni to ba kọ lati tun ayẹwo ṣe yoo fi ẹwọn oṣu mẹfa jura ijọba yoo si gba iwe irina wọn kalẹ.
pọ ́ n-na inú àwọn àṣàyàn ìwé yorùbá kan ni kókó ohun tí iṣẹ ́ yìí dá lé lórí .
Musa wa lara awọn agbabọọlu to kopa fun Naijiria ninu idije ere bọọlu agbaye ni Russai lọdun 2018 ti o si jẹ goolu meji nibẹ.
Lẹ́yìn náà, ó ṣiwaju mi lọ sí ìhà àríwá; ó wọn ìbú ati òòró ẹnu ọ̀nà kan tí ó wà níbẹ̀ tí ó kọjú sí ìhà àríwá, tí ó sì ṣí sí àgbàlá òde.
Ẹ máa kọ́ wọn láti kíyèsí gbogbo nǹkan tí mo pa láṣẹ fun yín.
Idi ni pe gomina ana nipinlẹ Ekiti, Ayodele Fayose ti fa aala sibi ti gomina ipinlẹ Oyo, Seyi Makinde gbọdọ rin de, paapaa nipinlẹ Ekiti.
Àjọ elétò ìlera lágbáyé ń lọgun pé èèyàn lée kó àrùn coronavirus nípasẹ̀ níná owó bébà Aarun Coronavirus ti di ẹrujẹjẹ to n dẹru bonile ati alejo kaakiri agbaye bayii, bẹẹni ajọ eleto ilera lagbaye ti jẹ ko di mimọ bayii pe, beba owo naa lee ṣe agbodegba fun itakalẹ arun yii.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Nigeria 2019 Elections: Àwọn ẹbí rẹ̀ ní àwọn agbébọn tó ya wọ àgọ́ ìdìbò ló ta á níbọn Ki araalu keti ikun si iroyin ẹlẹjẹ tawọn ẹgbẹ PDP n gbe kaakiri ori ikanni ibanisọrs Whatsapp."
orile ede Naijiria, Stuart Symington lo soro yii lasiko ti o n sinu pelu awon
Jẹ́ kí ẹ̀bẹ̀ mi dé iwájú rẹ,kí o sì gbà mí là gẹ́gẹ́ bí ìlérí rẹ.
Gbogbo àwọn àgbààgbà Israẹli bá kó ara wọn jọ, wọ́n lọ sí ọ̀dọ̀ Samuẹli ní Rama; 
Oríṣun àwòrán, Others Iléẹjọ gíga jùlọ da ẹjọ́ SDP àti PDP nù, wọ́n ní Yahaya Bello ló wọlé ìbò gómìnà Kogi Ààrẹ Buhari buwọ́lu gbígbé ìṣàkoso nọ́mbà ìdánimọ̀ (NIMC) lọ sí ẹ̀ka ìjọba tó ń rí sí ìbáraẹnisọ̀rọ̀ Ìjà d'ópin, fún ìgbà àkọ́kọ́, bàálù gbéra láti Israel lọ sí UAE Yàtọ̀ sí Eko, wo ohun t'áwọn ìpínlẹ̀ meje míràn ń sọ nípa ìwọlé àwọn akẹ́kọ̀ọ́ Ọba ni mí, mi ò le b'ọ̀rìṣà, Olorì tuntun tó ń bọ̀ já gbogbo ''scale''- Oluwo ti Iwo Alaga NUJ ni ipinlẹ Oyo, Demola Babalola naa fidi ẹ mulẹ pe awọn pinnu lati ma bu ọla fun iwe ipe ti FFK ti kọkọ fi ranṣẹ si ẹgbẹ wọn Eyi ko ṣẹyin bi awọn alaṣẹ ẹgbẹ akọroyin ti ṣe paṣẹ fawọn akọroyin pe ko si ẹnikẹni ninu wọn to gbọdọ de ibi idibo naa.
Àwọn Ìpínlẹ̀ tí coronavirus kò tíì dé ní Nàìjíríà, àti ìgbésẹ̀ tí wọ́n ń gbé láti dènà rẹ̀ Bí Coronavirus kò bá pa wá, ẹ má fi aisun pa wá torí ìbẹ̀rù olè - Àwọn olùgbé Ibadan figbe ta Ìlànà ojúlówó márùn ún tó dènà àrùn Coronavirus Kí lo mọ̀ nípa fẹntilétọ̀, ohun èlò aṣèrànwọ́ èémí Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí 3 sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
Wọn ṣi n wa awọn ọmọ meji kan ti iroyin sọ pe agbara ojo gbe lọ lalẹ ọjọ Abamẹta ni agbegbe Ketu ni ipinlẹ Eko.
Ó bẹ̀ wá pé kí á jọ̀wọ́ kí á fún òun ní ààyè láti máa ṣa ọkà tí àwọn tí wọn ń kórè ọkà bá gbàgbé sílẹ̀.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Báwo ni èèyàn ṣe le mọ pé òun ti ní àrùn Coronavirus?
Ojú òpó Instagram Dorathy Bachor gbaná lẹ́yìn tí ètò àgbéléwò BBNaija bẹ̀rẹ̀ Eto agbelewo ori amohunmaworan ti a mọ si BBNaija ti gbinaya bayii awọn ọmọ Naijiria si ti n fi ero wọn han lori awọn olukopa kọọkan.
Sugbọn Ọlọrun se Tanitoluwa, ti gbogbo eeyan mọ si Tani logo, nigba to ta awọn akẹ ẹgbẹ rẹ to jẹ alawọ funfun yọ, to si di ẹni to gbe igba oroke ninu idije New York state Chess Championship Gẹgẹ bi iwadi ikọ Newsday to wa labẹ ileesẹ iroyin BBC ti wi, Itajẹsilẹ ikọ adunkoko mọni Boko Haram lo le awọn obi Tani, eyiun Kayọde ati Oluwatoyin kuro ni Naijiria, ti wọn si lọ sorilẹede Amẹrika lati lọ se atipo.
Lẹyin ọpọlọpọ iṣẹlẹ alatamọ to ti rọ mọ eyi, Pasitọ ijọ naa ṣaa ti wa latimọle titi di dun to mbọ bayii.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Akomolede ati Aṣa lori BBC:Wo ìrúfẹ́ ìgbeyàwó méje tó wà nílẹ̀ Yorùbá àti ojúṣe Alárinà Lati le mu adinku ba itankalẹ rẹ, Olootu ijọba orilẹ-ede Germany, Angela Merkel, tun kede isede miran, bẹrẹ lati ọjọ Aje titi di ipari oṣu Kọkanla.
Gboyega Oyetola: A ṣetán láti pèsè ọkọ̀ oun ìjà fún ilẹ Yorùbá
Ninu oro ti oluranlowo pataki si aare lori oro ifitonileti ati igbodegba, ogbeni Laolu Akande gbejade lojo aje(Monday), O ni,  Igbakeji aare Yemi Osinbajo pelu ijọba lapapo kẹdun pelu ebi, obi, ara ati awon ore awon agunbaniro ti o doloogbe naa, “Ojogbon Osinbajo banuje so pe, orile-ede yii ti padanu lara awon odo ti o kun fun ogbon ati oye lakoko yii,”“Isele buruku yii fopin si aye awon odo okunrin ati obinrin yii lakoko ti won si n orile-ede won.
Yóo wá rán angẹli rẹ̀ pẹlu fèrè ńlá, wọn yóo kó àwọn àyànfẹ́ rẹ̀ jọ láti igun mẹrẹẹrin ayé; àní láti ìkangun ọ̀run kan dé ìkangun keji.
Makinde ni àwọn ǹkan ìrànwọ ti ìjọba pèsè fún ará ìlú ti wà ni ṣẹpẹ báyìí ti wan si ti yan ìdílé ẹgbẹ̀run 'lọ́nà ààdọ́rùn sọtọ̀ láti jẹ àǹfàní ètò náà Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Ẹbi ọkọ yio kó ẹrù ti ẹbi iyàwó ma ngbà fún wọn, lẹhin eyi, ẹbi iyàwó yio pèsè oúnjẹ fún onilé àti àlejò.
Oríṣun àwòrán, Pinterest Pa Akojede ku ni bi ago mẹta oru ọjọ Ẹti, lẹyin naa ni aya rẹ papoda nigba to gbọ iku ọkọ rẹ lẹyin wakati diẹ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Nigeria 2019 Elections: Amòfin, àwọn òṣèré Tíàtà jà f'ẹ́tọ̀ọ́ àwọn olùdìbò àti òṣìṣẹ́ pàjáwìrì 17 Èrèlè 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 18 Èrèlè 2019 Oríṣun àwòrán, Kayode Ajulo, Funke Akindele, Omotola Jalade Àkọlé àwòrán, Funke Akindele, Omotola Jalade Ekeinde, Kayode Ajulo Awọn kan lorilẹede Naijiria ti n polongo pe ki ijọba ṣe moriya fun awọn mọ Naijiria to padanu ohun kan tabi omiran nitori idibo ti ajọ INEC sun siwaju.
Amọ, Funke Akindele ti rawọ ẹbẹ sawọn eeyan wi pe ki wọn jeburẹ, o ni oun gba pe ohun t'oun ṣe ku diẹ kaato.
Ilana lati forukọ silẹ fun idanwo JAMB Loju itakun agbaye wọn, ajọ JAMB ti ṣe alakalẹ awọn ilana ti eniyan le ṣe lati forukọ silẹ lori ẹrọ alagbeka wọn (iyẹn fun Airtel ati MTN nikan).
Ìgbà tí wọ́n dé ìdí igi náà, wọn kò rí ẹnikẹ́ni, ṣùgbọ́n dípò èyí wwọ́n bá àpò owó méjìlá, owo ṣílè gbáà ni.
- Iya Rainbow Kemi Olunloyo ń làjà láàrin Toyin àti Lizzy lọ́wọ́ Lizzy Anjorin: Mi ò bẹ Toyin o!
ninu won ni ọdọ ati obinrin.
Se ni asọ maa n pe asọ ransẹ lasiko ayẹyẹ naa, ti awọn ọkunrin yoo si ko si oniruuru sitaili agbada, tawọn obinrin naa yoo si lo asọ lọ bii rẹrẹ, asọ oke yoo maa pe asọ oke ransẹ ni, to fi mọ adirẹ ati bẹẹ bẹẹ lọ.
 akitiyan wọn nínú ẹ ̀ sìn yìí láti tàn-án ka ló mú ọ ̀ pọ ̀ lọpọ ̀ àwọn ará wum dí ẹlẹ ́ sìn mùsùlùmí .
Àwọn tafàtafà gbógun tì í kíkankíkan,wọ́n ń ta á lọ́fà, wọ́n sì ń dà á láàmú gidigidi,
Lọ́wọ́ ìbànújẹ́ owó, lọ́wọ́ ìbànújẹ́ ọmọ, lọ́wọ́ ìbànújẹ́ ibi iṣẹ́, lọ́wọ́ ìbànújẹ́ ọ̀tá ilé, lọ́wọ́ ìbànújẹ́ ọ̀tá òde, lọ́wọ́ ìbànújẹ́ ààrin iyèkan, Ìwọ Ọlọ́run yìí nìkan ni Aláfẹ́hìntì ẹni.
Wọ́n ta ẹ̀jẹ̀ àwọn eniyan rẹ ati àwọn wolii rẹ sílẹ̀, nítorí náà o fún wọn ní ẹ̀jẹ̀ mu.
Ẹ ̀ gbá gbágùrá ni orísìí kẹta .
Ó kígbe lóhùn rara, ó ní: “Gbọ́ mi, ìwọ Jeroboamu ati gbogbo ẹ̀yin eniyan Israẹli, 
O tan kakiri agbaye lori bi ijọba to wa lode lorilẹede Naijiria lasiko naa ṣe kuna lati daabo bo awọn akẹkọ naa.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, '500 level'' ni mo wà nígbà tí mo di adélé Ọba' Mọlẹbi rẹ kan ni lẹyin ti Baalẹ gba ipe latọdọ awọn kan ti wọn ni awọn n bọ wa saafin rẹ to si lọ pade wọn ni ko ti pada saafin lati igba naa.
Amọ, awọn eniyan to n gbe ni agbegbe ti awọn eranko yii pọ si n ran ẹsọ alaabo lọwọ lati le sawari ẹkun naa, ki wọn le fi ni alaafia lagbegbe naa.
O óo máa gbé ilé rẹ ní àìséwu.
"Ninu ifọrọwerọ pẹlu ileesẹ akoroyinjọ ilẹ Russia, TASS saaju ipade apero to waye lọsẹ yii, aarẹ Putin ni ""Ibasepọ laarin Russia ati awọn orilẹede Afirika naa wa loke tente, to si tun sọrọ nipa fifun wọn ni awọn anfaani yii: Atilẹyin lẹka ọrọ oselu ati ibasepọ laarin orilẹede Eto aabo ati iranwọ lori aabo Iranwọ lẹka ọrọ aje Imọran nipa akoso aisan Ipese eto iranwọ fun ọmọniyan Idanilẹkọ fun isẹ ọwọ ati eto ẹkọ Oríṣun àwòrán, Getty Images Orilẹede Russia ti n se amugbooro ẹka agbara rẹ nidi eto iselu lẹkun Afirika, tawọn olori orilẹede lẹkun naa mejila si n se abẹwo si Russia lati ọdun 2015, mẹfa ninu wọn si tun ls si Russia ni 2018 nikan."
Wàyí ò, OLUWA, kí ló kù tí mo gbójú lé?
Bo tilẹ jẹ pe mi ko safihan apẹrẹ arun ọhun, mo maa fi ara mi si igbele.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Rivers court and Anti Piracy 2019 law: Ilé ẹjọ́ ju olè orí omi mẹ́ta sí ẹ̀wọ̀n, ó tún ní kí wọ́n san 60 miliọ̀nù 14 Ògún 2020 Oríṣun àwòrán, others Onidajọ I.
Tabi tí ó bà bèèrè ẹja, tí ó jẹ́ fún un ní ejò?
Fun apẹrẹ ki ni ojuṣe awọn ẹṣọ aṣọbode?
lati gbogun ti awọn iwa ọdaran nipa wiwa ni ojufo ni gbogbo igba lati maa sọra.
O salaye pe, ogunlogo awon agbe onirese ni won ti janfaani eto yii ni ijoba ibible Mani, nipa gbigba ajile ati awon ogun ajeni-ru ti o le ba ire oko won je, ero-omi ti won yoo fi maa won-oko won.
Ẹ sọ fún Joabu kí ó wá gbọ́!
Don Davis Iniobong Archibong, jẹ ọmọ ọdun mọkanla, to si wa ni ipele eto ẹkọ kinni JSS 1 nile ẹkọ Deeper Life High School, nipinlẹ Akwa Ibom.
Transfer Window: Èrò olólùfẹ́ eré bọ́ọ̀lù ṣọ̀ọ̀tọ̀tọ̀ lórí Iwobi, Lukaku àti Luiz
"Oríṣun àwòrán, Nba O fi kun un wipe ""ofin Sharia lee jẹ ojulowo ninu ilana ẹsin Islam tabi ni orilẹede ti ofin wọn fi aaye gba iru nkan bẹẹ amọ o ni ilu to lofin ijọba awarawa ni Naijiria eyi si ni ofin to ba lori ohun gbogbo."
Àwọn wolii ń sọ àsọtẹ́lẹ̀ èké,àwọn alufaa ń sọ ọ̀rọ̀ èké àwọn wolii di òfin,àwọn eniyan mi sì fẹ́ ẹ bẹ́ẹ̀.
Yóo bá dì mọ́ ọmọkunrin tí kò gbọ́n náà, yóo fi ẹnu kò ó lẹ́nu,yóo wí pẹlu ainitiju pé,
Igbagbọ awọn eniyan Ilaramọkin ni pe ẹgba naa kìí pẹ́ pa ojú dé nitori omi ẹ̀rọ̀ ti wọn n wọn sí ojú ọgbẹ́ naa.
Àdéhùn owó fadaka kan ni mo bá ọ ṣe.
Irú nǹkan burúkú yìí kọ́ ni àwọn baba yín pàápàá ṣe tí Ọlọrun fi mú kí ibi bá àwa ati ìlú yìí?
O ti fi ọ̀nà ìyè hàn mí,O óo sì fi ayọ̀ kún ọkàn mi níwájú rẹ.
”Saaju eyi,, iyaafin  Osinbajo  dupe lowo Olorun fun aabo rẹ lori aare Buhari  lasiko,eto ipolongo  ni eyi ti aare se kaakiri gbogbo ipinle mẹ́rìndínlógójì to wa lorile ede Naijiria ati
Àwọn ọmọ ogun rẹ dàbí obinrin!
Ẹ̀rù OLUWA ba ìjọba gbogbo àwọn orílẹ̀-èdè nígbà tí wọ́n gbọ́ pé OLUWA bá àwọn ọ̀tá àwọn ọmọ Israẹli jagun.
EndSARS Protest Update: Iléèṣẹ́ ọlapàá sọ pé Ọlọ́pàá mẹ́fà ni jàndùkú pa, wọ́n tún kọlù àgọ́ ọlọ́pàá márùn-ún lásìkò ìwọ́de
 Ìwé yìí yóò wúlò púpọ ̀ fún àwọn akẹ ́ ẹ ̀ kọ ́ ilé-ẹ ̀ kọ ́ gíga ti wọ ́ n ń kọ ́ nípa àwọn ẹ ̀ ka-èdè yorùbá .
Adari ikọ Amotẹkun ti Agency 2'C, Comrade Kazeem Babalola lo fi lede wi pe awọn mẹfa ti awọn gbamu lo jẹwọ wi pe awọn kii ṣe oṣiṣẹ ikọ Amọtẹkun, ati wi pe ayederu aṣọ ni awọn wọ.
Amọ iwadi iwadii ijinlẹ kan ree, eyi to salaye bi ọmọ ale se le wọnu idile lai jẹ pe iyawo ile se asemase pẹlu ọkunrin miran nita.
“Ọ̀rọ̀ yín dára lójú mi, mo sì yan ọkunrin mejila láàrin yín, ọkunrin kọ̀ọ̀kan láàrin ẹ̀yà kọ̀ọ̀kan.
Bakan naa ni ile ẹjọ pasẹ ki iwe iroyin ti orilẹede Naijiria fi lede pe ki Maina jọwọ gbogbo awọn dukia naa fun ijọba.
Bi ogbeni Sani se so,“Ojuse wa gege bi igbimo kan gbogi ni lati ri pe a pese iwuri, idagbasoke yala fun ile-ise tabi fun awon eniyan, bee si ni lati mu awon eto won lokunkundun jake-jado agbaye.
Ọjọ kẹẹdogun, oṣu Kẹwaa ni awọn mejeeji yoo tun fojurinju ni Miami, Florida.
"Mo ni mi o fi bẹẹ mọ nkan to n ṣẹlẹ nipa rẹ, ṣugbọn to ba jẹ pé ki n jẹ pe ki n kan sọrọ ni, maa sọ, mo rọ wọn pe ki wọn fun ijọba laye ki wọn wa ojuutu si ọrọ naa ati awọn ọdọ ati ijọba ki wọn gba fun ara wọn.
Iyabo, lo wọ aṣọ bii ọmọ ìsọta, to si kẹ ohun rẹ, o n sọrọ bii janduku, to si n fa siga.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Baba Obasanjo: Àwọn ọ̀rẹ̀ sàpèjúwe Baba Obasanjọ ní ọjọ́ ìbí 83 wọn 5 Ẹrẹ̀nà 2020 Oríṣun àwòrán, Getty Images Ẹgbẹ awọn agbaagba nilẹ Yoruba ti sapejuwa aarẹ tẹlẹri lorilẹede Naijiria gẹgẹ bi ẹbùn rere ni Baba Obasanjọ jẹ fun Naijiria.
Babaláwo rèé pẹ̀lú afurasí adigunjalè mẹ́rin láhàmọ́ọ́ ọlọ́pàá Báwo ni ọkùnrin tí ọlọ́pàá bá òkú rẹ̀ nínú àgbá ní Oyingbo ṣe kú?
Ìran rẹ kò ní parun, arọmọdọmọ rẹ ni yóo sì máa jọba títí ayé, ìjọba rẹ̀ yóo sì wà títí lae.
Mo ṣèlérí láti rí sí ìrẹ́pọ̀ àti ìwòsàn Amẹ́ríkà - Joe Biden Jíjáwé oluborí Joe Biden jẹ ìborí ìmọ́lẹ̀ lórí òkùnkùn-Obasanjo Ta ni Kamala Harris obìnrin àkọ́kọ́ tí yóò jẹ igbá-kejì ààrẹ orílẹ̀èdè Amẹrika?
A óo tọ́ ibi tí ó bá ṣe kọ́rọ-kọ̀rọ,a óo sì sọ ọ̀nà tí kò bá dán tẹ́lẹ̀ di dídán
Aṣọ funfun lá fi ṣe ìwọ́de lórí wíwọ Hijab lẹ́yìn Jumat - MURIC Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Àwa táa jẹ́ alágbàtọ̀ gan, èèyàn ni wá, ẹ ye ṣe wa bí ẹranko' Sẹnetọ Abbo ṣalaye siwaju sii pe ni kete tawọn agbebọn naa gunlẹ si agbegbe ọhun, 'taarata ni wọn gba ile awọn lọ nibẹ ni wọn si ti fi ipa ji iyawo baba mi to ṣẹṣẹ bims ni ọjs mọkanla sẹyin gbe lọ tawọn ti ibọn AK 47 lọwọ.
Poopu sọ pe awọn ko ni i fi aṣiri gbogbo akọsilẹ ti wọn ba gbọ nipa ifipabanilopọ naa, ti wọn yoo si gbe igbesẹ otitọ, ati aabo fun awọn ti wọn ba balopọ.
Ní òde kí á tó wọ odi ìlú ni tẹmpili Seusi wà.
Oríṣun àwòrán, Reuters Àkọlé àwòrán, Oni fọto yii s'akiyesi awọn awọ alarambara ni abule Dapchi, ilu kan to n ṣe eema ijinigbe awọn akẹkọbirin.
Ijọba ipinlẹ Oyo ni gbogbo eto lo ti to lati rii pe awọn olukọ atawọn akẹkọọ n tele ilana ti ijọba la kalẹ lati dena itankalẹ aarun covid-1 Àìmọ̀kan ló ń ṣe ìjọba Oyo tó fẹ́ ṣí iléèwé, gbogbo ìpínlẹ̀ ló ní àrùn COVID 19- Ijọba àpapọ̀ Ajọ NCDC ti ni ko si ipinlẹ kankan ni Naijiria to dantọ lọwọ arun Coronavirus.
Jesu dá wọn lóhùn pé, “Gbogbo igi tí Baba mi tí ń bẹ lọ́run kò bá gbìn ni a óo hú dànù.
Asiri ibẹ gẹgẹ bi awọn onimọ ti se sọ ni pe awọn orileede to ba n se ayẹwo ni iye awọn eeyan tuntun to n ko arun naa ma n dinku lẹyin wa.
31 Ẹrẹ̀nà 2019 Oríṣun àwòrán, EFCCofficial Àkọlé àwòrán, Ajọ EFCC nmi to awon yoo se iwadii finifini Kẹ̀rẹ̀ kẹ̀rẹ̀ bi àwọn aláṣẹ ijọba tuntun ti wọn dibò yàn yoo ṣe fẹ gba ijọba, àjọ to ri sí ìwà jẹudujẹra (EFCC) ti pari ètò láti bẹ̀rl ìwádìí àwọn gomínà ti wọn fẹsun kan pe wọn ṣe owo ilú maku-maku.
Mose bá kọ òfin yìí sílẹ̀, ó fún àwọn alufaa, àwọn ọmọ Lefi tí wọ́n ru àpótí majẹmu OLUWA ati gbogbo àwọn àgbààgbà Israẹli.
Nítorí nígbà tí ó bá rí àwọn ọmọ rẹ̀,tíí ṣe iṣẹ́ ọwọ́ mi láàrin wọn,wọn óo fi ọ̀wọ̀ fún orúkọ mi.
láti máa jọba lórí ọ̀sán ati òru, ati láti fi ààlà sí ààrin ìmọ́lẹ̀ ati òkùnkùn.
- Aráàlú ń bèèrè Ẹ fura, làásìgbò le wáyé ní ìjọba ìbílẹ̀ mẹ́fà yìí lásìkò ìbò gómìnà Ondo - YIAGA Wo ìṣẹ̀lẹ̀ márùn-ún tí kò bá pín Nàíjíríà sí yẹ́lẹ-yẹ̀lẹ Bọ́ síta láti ṣe ìwọ́de mọ́ ìjọba Nàìjíríà lónìí, ko rugi oyin - Iléeṣẹ́ ọlọ́pàá Ẹ̀yin ọlọ́pàá 10,000 tí ọ̀gá ọlọ́pàá gbà ṣíṣẹ́ ní 2019, ẹ padà sílé - Iléẹjọ́ pàṣẹ Amọ abọ iwadi wa ni pe ofuutu fẹẹtẹ, aasa ti ko ni ọmọ ninu gbaa ni iroyin naa, nitori Olori Naomi ko bi ọmọ tuntun.
Ìtàn Gbọnka àti Timi, akọni méjì tó borí Aláàfin Ṣango Ọkọ̀ òfúrufú gbiná nítorí obìnrin tó ń fa Shisha!
O fikun-un pe,“Awon agbaboolu mi ti fi ara won han pe awon to gbangba sun loye.
Nítorí náà, mo sọ fun yín pé ẹ kò ní fojú kàn mí mọ́ títí di àkókò tí ẹ óo wí pé, ‘Olùbùkún ni ẹni tí ń bọ̀ wá ní orúkọ Oluwa!
A kò gbo̩dò̩ s̩e ìgbeyàwó kan láìjé̩ pé àwo̩n tí ó fé̩ fé̩ ara wo̩n ní òmìnira àto̩kànwá tó péye láti yàn fúnra wo̩n.
Alufaa yóo sun wọ́n lórí pẹpẹ gẹ́gẹ́ bí ẹbọ sísun fún OLUWA, ó jẹ́ ẹbọ ìmúkúrò ẹ̀bi.
Ẹka UNGA lo wa fun ijiroro lori igbesẹ ti ajọ UN ba fẹ gbe.
 o budo si inu okun atlantiki ni ariwa kuba ati hispaniola ( dominiki olominira ati haiti ) , ariwaiwoorun awon erekusu turks ati caicos , ati guusuilaorun orile-ede awon ipinle aparapo ile amerika ( nitosi ipinle florida ) .
Ninu ọrọ ti wọn fi lede, ijọba ipinlẹ Cross River ni awọn fẹ fi ọsẹ meji naa se ayẹwo gbogbo awn ileewe naa lati le gbaradi fun iwọlẹ awọn akẹkọ naa.
gọfa ọdun ni n o lo laye.
Ọmọ ọdun mẹ́tàléláàdọ́rùn ún ni Robert Mugabe nigba ti o fi fi ipo silẹ.
finni-finni nipa rẹ  gege bi ilana ofin
Àbí ìwà òdodo rẹ kò fún ọ ní ìrètí?
Wọn yoo kan sọ pe ki ẹni naa buwọlu iwe tabi fi iwe idanimọ rẹ silẹ.
Ọga ọlọpaa Orlando ni fọnran ori kamẹra fihan bi Ofori ti yinbọn pa iyawo rẹ nigba ti o fẹ wọ ile itaja nla naa.
Tún ara mú gidigidi, kí o sì gba ìlú náà.
Wo àwọn Ṣọ́ọ̀ṣì Nàìjíríà àti l'Áfíríkà tó ń wólẹ̀ àdúrà kí Trump lè wọlé ìbò ààrẹ America Wo àwọn tó kàgbákò Covid-19 ní White House lẹ́yin Ààrẹ Trump Trump kò yẹ láti jẹ́ ààrẹ lásìkò yìí, èèyàn kò le fi mọ̀kàrúrù ṣe ààrẹ - Michelle Obama Ṣé Biden lè fẹ̀yìn Trump kó di ààrẹ America tó kàn?
–iworan Mandarari to wa ni ijoba ibile Konduga ni ipinle  Borno kẹdun.
Láti èèyàn ogúnléndé aláìníbùgbé sí olórí ìgbìmọ̀ akẹ́kọ̀ọ́
achmatowicz reaction jẹ ́ ìṣètò organic èyí tí furan ma a ń yípadà sí dihydropyran .
Wọ́n fi ọ̀pá sí ọwọ́ ọ̀tún rẹ̀.
Eeyan mẹta ni ayẹwo ṣi fihan pe o ni arun yii ni ipinlẹ Ondo, ṣugbọn ijsba ipinlẹ naa n ṣalaye pe awọn to wọ ilu lẹyin igba ti wọn ti iloro ẹnubodu ipinlẹ naa gbogbo lawọn eeyan naa wọle.
Bí igbó ṣe ń dínkù látàrí ìgbẹ́ pípa àti igi gẹdú gígé jákèjádò orílẹ̀ èdè náà, igbó tí wọ́n fi ṣe ilé ti di ti nǹkan mìíràn.
Ọpọlọpọ awọn ọmọ Naijiria lo bu ẹnu atẹ lu aworan naa lẹyin ti o jade lori ẹrọ ayelujara, pẹlu asisẹ aato ọrọ kikọ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ibadan Murder: Oyún oṣù méje ló ń bẹ nínú Azeezat, kí wọ́n tó f'òkúta fọ́ ọ lórí Alukoro Ajọ FRSC, Bisi Kazeem ninu atẹjade ti wọn fi lede ni awọn kii ba wọn jẹ eera ti ko lọmọ ninu, nitori naa kii se ọdọ awọn ni asemase naa ti wa.
O pọn dandan ki eniyan mọ iru ẹya aja ti a lee sin ninu ile lati le daabo bo awọn to wa ni agbegbe naa.
Eberi bí ọmọkunrin meji: Ekinni ń jẹ́ Pelegi, (nítorí pé ní àkókò tirẹ̀ ni àwọn eniyan ayé pín sí meji); ọmọ Eberi keji sì ń jẹ́ Jokitani, 
Sẹnetọ Ali Ndume ti gba Ahmed Lawan lọga pẹlu abajade esi idibo ile igbimọ aṣofin agba gẹgẹ bi o ṣe ki Lawan ku oriire ni iṣẹju perete ki wn to kede rẹ gẹgẹ bi aarẹ.
Bayii lawọn mejeeji ṣe fija pẹta, bẹẹ lawọn ẹya wọn da si ija naa lo ba di nla ti awọn ọmọ ita kan ṣi da si ija naa.
Ní ọjọ́ náà,OLUWA yóo pa ẹ̀yin eniyan Israẹli bí ẹni pa ọkà,láti odò Yufurate títí dé odò Ijipti,yóo sì ko yín jọ lọ́kọ̀ọ̀kan.
Bí ẹnìkan ti ń wí pé.
sira wọn, ki wọn si gbadura fun awọn olori wọn ninu ọdun Ileya.
Ẹ sọ ìwé kíkà di dandan fún ẹ̀yà Fulani - Oluwo rọ ìjọba àpapọ̀ Buhari gbà wá, àwọn àjèjì ti gbàkóso ilẹ̀ Yorùbá - Ọọ̀ni figbeta Èyí tí mo ṣe tó!
Ile ẹjọ paṣẹ ki Aku da owo naa pada fun ile ijọsin naa ati gbogbo ohun ini ti o ba to iye owo ti o ji naa.
Ìrìnà ọkọ̀ akérò àti ọkọ̀ òfurufú bẹ̀rẹ̀ padà jákèjádò Nàìjíríà!
Alara ti Ilara-mọkin to jẹ Agbekọrun II sọrọ lori awọn ayipada to ti de ba ọna ṣiṣe ọdun Òbèrèmóyè.
Ẹ̀ṣẹ̀ ni ète òmùgọ̀,ẹni ìríra sì ni pẹ̀gànpẹ̀gàn.
Wọn ni owo naa ti di ti ijọba apapọ Naijiria.
Ẹẹmelo lo yẹ ki n ṣe igbọnsẹ loojọ?
“Fi aṣọ aláwọ̀ aró ati elése àlùkò, ati aṣọ pupa ati aṣọ ọ̀gbọ̀ funfun, tí wọ́n ṣe iṣẹ́ ọnà sí létí ṣe aṣọ títa kan fún ẹnu ọ̀nà àgọ́ náà.
Oríṣun àwòrán, NPF Osu Keji, ọdun 2020 Lẹyin ti ọlọpaa pa ọkan lara awọn ọmọ ẹgbẹ agbabọọlu Remo Stars, Tiamiyu Kazeem ni ilu Sagamu, nipinlẹ Ogun ni IGP Mohammed Asamu sọ wi pe ki wọn ti gbogbo ileese ikọ SARS kaakiri orilẹede Niajiria.
Àkọlé àwòrán, O yẹ ka maa se agbelarugẹ awọn ọlọpọlọ pipe ọmọ Kaarọ Oojire to ti kọja lọ, ko si yẹ ka jẹ ki dukia wọn segbe pẹlu wọn Àkọlé àwòrán, Ọmọ Yoruba, ẹ dide lati maa seranti awọn akọni wa to ti lọ bii Fagunwa.
Ipinlẹ Eko lo ni eniyan to poju pẹlu eniyan 142 ni Ojo Iṣẹgun nikan soso.
Nítorí àwa gan-an ni ọ̀kọlà, àwa tí à ń sin Ọlọrun nípa Ẹ̀mí, tí à ń ṣògo ninu Kristi Jesu, tí a kò gbára lé nǹkan ti ara, 
”Hamani rò ó ninu ara rẹ̀ pé, ta ni ọba ìbá tún dá lọ́lá bíkòṣe òun.
Ṣugbọn ẹ ṣọ́ra kí òmìnira yín má di ohun tí yóo gbé àwọn aláìlera ṣubú.
Fasanmi jẹ senetọ ri to si tun se asojusofin ri nigba aye rẹ.
Ṣ’ẹ ri àwọn àgbà ọlọ́jọ́ orí
Sibẹsibẹ OLUWA Ọlọrun Israẹli yàn mí ninu ilé baba mi láti jọba lórí Israẹli títí lae; nítorí pé ó yan ẹ̀yà Juda láti ṣe aṣaaju Israẹli.
Afurasí méjì fi áńbúláǹsì kó Tramadol N60m wọlé l'Apapa Ẹgbẹ́ àwọn òṣìṣẹ́ TUC fárígá sí ìjọba Naijiria lórí owó oṣù tuntun Olólùfẹ́ méjì jábọ́ láti àjà kẹsàn án lásìkò tí wọ́n n ṣe kerewà Mercy Aigbe bu èpè jó àwọn tó ní gómìnà kan ló ra ilé fún-un Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Ìwọ á gbà pé àti ṣàkì o, àti ọ̀rá o, ẹran abọ́dìí ni ọba gbogbo wọn”
Lowurọ ọjọru ni wọn yoo bẹrẹ ayewo fawọn minisita ti Aarẹ Buhari fi orukọ wọ́n ranṣe si ile aṣofin agba Naijiria.
Nkan tí a mọ̀ nìyíì Àṣeyọrí Anthony Joshua fi hàn pé owó tí à ń ná lórí eré ìdarayá kò lọ lásán - Dapo Abiodun Lóòtọ́ ni mo yìnbọn níbi yánpọnyánrin tó wáyé ládúgbò mi-Seun Kuti Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Awọn agbaagba mejeeji naa ni Oloye Olusegun Obasanjo ati Ọọni tilu Ile Ife, Ọba Adeyeye Enitan Ogunwusi, ti wọn sọrọ lori iwọde naa.
Oríṣun àwòrán, Nurphoto Àkọlé àwòrán, Ọjọ keje oṣu kinni ni ọjọ ajọdun keresimesi wọn Ṣaaju ajọdun keresimesi yii, ọjọ mẹtalelogoji ni wọn fi n gba awẹ lati pese ara wọn silẹ fun gbigba Kristi.
Ò máa gba àwọn onírẹ̀lẹ̀,o dójú lé àwọn agbéraga, láti rẹ̀ wọ́n sílẹ̀.
Ògo kì í ṣe fún wa, OLUWA, Kì í ṣe fún wa,orúkọ rẹ nìkan ṣoṣo ni kí á yìn lógo,nítorí ìfẹ́ rẹ tí kì í yẹ̀, ati nítorí òtítọ́ rẹ.
Titi ti wọn ti awọn ibode ọhun pa ti da ọpọlọpọ ipalara silẹ to si ti fa wahala laarin Naijria atawọn orilẹede agbegbe rẹ ti wọn si n kigbe pe ofin ijọba yii n pa ọrọ aje awọn lara.
Nigba ti awọn miran sọ wi pe ariwo lasan ni Kanu n pa, ati wi pe ọrọ rẹ kii se oun ti awọn ọmọ Naijiria ye ki wọn fesi si.
Akinjide Isola: Ara fu mí ní ọdún márùń sẹ́yìn pé bàbá fẹ́ pa’pòdà
Ni ọdun 1492 lo ri pe awọn ara ilu ti o di Cuba, Haiti ati Bahamas lonii n fi ikoko fa taba naa.
Ọ̀dọ̀ fásitì jànkàn Oxford ló ti jáde Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Biu tun wa gbosuba fun gomina  Kashim Shettima fun atileyin rẹ fun  ile-isẹ omo ogun naa,.
Wọ́n fún un ní ìwé wolii Aisaya.
Lasiko ti Olatunji wa ni ileese Morehouse, ọpọlọpọ nkan to buru jai lo waye nigba naa ti awọn alawọfunfun ṣe si awọn alawodudu nitori ofin ẹlẹyamẹya.
Sùgbọn agbẹnusọ fún àjọ ọmọogun sọ pé irọ́ pátápátá ni ọrọ náà pé àwọn ń fi tipátipá báwọn aṣatipo lájọṣepọ̀ ni ipagọ.
Nítorí gbogbo yín jẹ́ ọmọ Ọlọrun nípa igbagbọ ninu Kristi Jesu.
Awon akekoo meta miiran wa nile-iwosan, nigba ti awon yoku ti pada sile won.
2) Ṣọra fun yiya fọto tabi fidio ni igba gbogbo lojoojumọ.
Nígbà tí wọ́n mú un dé, 
Olugbaninimran fun sẹnetọ Adeleke ba BBC Yoruba sọrọ.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ẹfunsetan Aniwura, obìnrin tó ju ọkùnrin lọ Hubert Ogunde rèé, baba àwọn òsèré tíátà Kíni ìwọ mọ̀ nípa Funmilayọ Ransome-Kuti?
Wo ìdí tí Risikat Moromoke Azeez n'Ilorin fi ní Blue Eyes"" - Dókítà NCDC kéde èèyàn 423 míràn tó ṣẹ̀ṣẹ̀ lùgbàdì Covid-19 ní Nàìjíríà, 263 gbàwòsàn Àmọ̀tẹ́kùn gbéra!"
Ibudo ìwa iyanrin ni ilu Ibadan ni ipinlẹ Oyo ni iṣẹlẹ laabi ọhun ti waye.
Agbẹnusọ fun Ile-iṣẹ Ọlọpaa fi kun ọrọ pe awọn ọlọpaa ko le sọ boya otitọ ni pe aafa naa fi asọ nun oju-ara ọmọbinrin naa lẹyin ti o ba lopọ gẹgẹ bi awọn ẹbi rẹ ṣe sọ ati pe wundia ni ọmọ awọn.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìsẹ̀lẹ̀ iná Venezuela: Ẹ̀mí 68 bọ́ ní àgọ́ ọlọ́pàá Valencia 29 Ẹrẹ̀nà 2018 Oríṣun àwòrán, Reuters Àkọlé àwòrán, Awọn molebi faraya nitori isẹlẹ naa ni iwaju agọ ọlọpaa Awọn alasẹ ni ilu Valencia nipinlẹ Carabobo, lorilẹẹde Venezuela so pe ifẹhonu han ati ijamba ina ni agọ ọlọpaa kan ti sokunfa ki ẹmi mejidinlaadọrin bọ.
Ẹ̀ṣẹ̀ ti ọkunrin ni pé, ó ba àfẹ́sọ́nà arakunrin rẹ̀ jẹ́.
Ìjàmbá tó ń bá ètò ọ̀rọ̀ aje to dẹnukọlẹ̀ rìn kò rí bákan náà fún gbogbo ènìyàn.
Ẹni tí ó bá rí mi, ó rí ẹni tí ó rán mi.
Lowurọ ni wọn kọkọ gba arabinrin kan ṣoṣo ti o wa laarin wọn silẹ pe awọn si n ṣe iṣẹ lati gba awọn to ku naa silẹ.
 kòpẹ ́ kòjìnàn tí ó padà sí nàìjíríà tí ó sì bẹ ̀ rẹ ̀ iṣẹ ́ olùkọ ́ .
Oríṣun àwòrán, Getty Images Lagos-157 Edo-59 Ondo-56 Oyo-31 Akwa Ibom-22 Borno-21 Plateau-19 Kaduna-18 Katsina-18 Bayelsa-17 FCT-17 Delta-14 Kano-11 Rivers-10 Enugu-8 Ogun-6 Kwara-4 Imo-3 Nasarawa-2 Osun-2 Abia-1 Ekiti-1 Niger-1 Yobe-1 Apapọ iye eniyan to ti ni aarun naa ni ipinlẹ kọọkan l'orilẹ-ede Naijiria niyii: Oríṣun àwòrán, Ncdc Àpapọ̀ àwọn tó ní ààrùn Coronavirus ní Nàìjíríà tayọ 30,000 ní 08/07/2020 Ọtalenirinwo eeyan ni aarun coronavirus tun ṣẹṣẹ ran mọ l'orilẹ-ede Naijiria.
Amọṣa nigba to n ba BBC News Yoruba sọrọ lori oku ti wọn lọ wu ninu saree naa, alukoro ileeṣẹ ọlọpaa ni ipinlẹ Ondo, DSP Teo-Leo Ikoro ni ọrs ko ri bẹẹ rara.
Wàyí o, bi aibọwọ fún òfin ìtakété síra ẹni ṣe ń wáyé n'ilu Eko, naa lo ṣe ri ni Abuja, nítorí báwọn èrò àti ọlọkada ṣe tó fún ayẹwo ọlọ́pàá, lòdì sí òfin ìtakété síra ẹni, ṣe ni wọn to si ẹyin ara wọn lai fi ààyè kankan silẹ.
Ẹ mọ̀ nípa Jesu ará Nasarẹti, bí Ọlọrun ti ṣe yàn án, tí ó fún un ní Ẹ̀mí Mímọ́ ati agbára; bí ó ti ṣe ń lọ káàkiri tí ó ń ṣe rere, tí ó ń wo gbogbo àwọn tí Satani ti ń dá lóró sàn, nítorí Ọlọrun wà pẹlu rẹ̀.
Ṣùgbọ́n nígbà tí ó pẹ́ dípò ayọ̀ ẹkún ló yẹ kí n máa sun.
ibo ẹgbẹrun mejila-le-mejidinlọgorun (12,098) nigba ti akẹgbẹ rẹ,
O ni ọjọ yii yoo duro ninu itan gẹgẹ bii ọjọ ti awọn eeyan kan jẹ eewọ nitori aidọgba ironu lori oṣelu.
" Àwọn olùkọ ̀ wé míràn rò wípé ọ ̀ pọ ̀ lọpọ ̀ tí wọ ́ n maa ń rí ní santiago , santa cruz , àti santa fe ( tí ó wà pẹ ̀ pú àwọn erékùṣù kékèké ) yàtọ sí àwọn ẹ ̀ yà ( "" m."
Ẹwẹ, Aarẹ Buhari ti ṣeleri lati fi panpẹ ofin mu awọn apaniyan naa.
Nígbà tí mo wò yíkà mo rí i pé orí òkúta ni ilé náà wà àti pé gbogbo ẹ̀gbẹ́ ògiri rẹ̀ jẹ́ kìkì òkúta.
Ojú ni o óo fi rí i, nítorí pé, o kò ní kọjá odò Jọdani yìí sí òdìkejì.
Nígbà tí ó yá, obinrin náà bí ọmọkunrin kan, ó sì sọ ọ́ ní Samsoni.
A gba afurasi naa laaye lati pe awọn mọlẹbi rẹ, ki wọn lee wa gba oniduro rẹ, nitori ẹsẹ to ṣẹ́, ṣe e gba oniduro rẹ.
O jẹ ajagunfẹyinti nileeṣe ologun ofurufu, eyi to jẹ adari agba fun ni 2012 si 2014 Oun ni o jẹ olori ikọ ọlogun apapọ to n daabo bo Naijiria lọdun 2014 si 2015.
Máa bọ̀, olùfẹ́ mi,jẹ́ kí á jáde lọ sinu pápá,kí á lọ sùn ní ìletò kan.
Iṣẹlẹ to jọ mọ pe o n ka otutu yii ṣẹlẹ nibi ayẹyẹ kan to waye nilu Berlin tii ṣe olu ilu orileede Germany.
Lisabi di ilumọọka ni aarin ọdun 1775 si 1780 nigba to ja fita fita lati gba ilu Abẹokuta silẹ loko ẹru Ọlọyọ ti ilu Ọyọ nigba naa, ẹni to n gba isakọlẹ lọwọ awọn ọmọ Ẹgba lasiko naa.
Ooni Ogunwusi: Ìròyìn òfégè ló ń lọ kiri pé ìyàwó mí bimọ tuntun
Ile ẹjọ to n gbọ ẹhonu idibo naa bẹrẹ iṣẹ ni pẹrẹwu bi o tilẹ jẹ pe ọpọ awuyewuye lo kọkọ waye lori rẹ, ki o to di pe o gbe ijoko rẹ lọ si olu ilu ilẹ Naijiria, Abuja.
Nígbà tí wọ́n rí Jobu ní ọ̀ọ́kán, wọn kò mọ̀ ọ́n mọ́.
Ẹyin naa ẹ wo fọnran fidio naa: Ati awọn iriwisi to tele Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Tàbí tí mo bá ń wa'kọ̀ lọ sí ibi tí n kò dé rí.
 a sábà maa ń ṣàwarí ibà nípa àyẹ ̀ wò ẹ ̀ jẹ ̀ nípa lílo ohun elò awo kòkòrò fíìmù ẹ ̀ jẹ ̀ , tàbí pẹ ̀ lú ìdálórí ántígínì- àyẹ ̀ wò ìṣawarí kíákíá .
”Ewe, Ademola Adepoju ti o je adari imo ero labe eka Yoruba naa tun so pe bi eka ede Yoruba se bere igbohun safefe lati ilu Abuja je ohun ti yoo tun je ki awon olugbo ile akede Naijiria lati ilẹ okeere tun maa gbọ won yeke-yeke.
" O wa nrọ ijọba apapọ lati tete kan si arabinrin Aisha Wakili, ti gbogbo eeyan mọ si Mama Boko Haram, ẹni to ti gburo ibiti awọn akẹkọ naa wa, ki wọn si dunadurapẹlu rẹ, lori bi wọn yoo se gba idande awọn akẹkọbinrin yii.
Nisinsinyii, ẹ̀yin alufaa, ẹ mú irú ọrẹ bẹ́ẹ̀ lọ́wọ́, ẹ̀ ń gbadura sí Ọlọrun, pé kí ó lè fi ojurere wò yín; Ṣé ẹ rò pé OLUWA yóo fi ojurere wo ẹnikẹ́ni ninu yín?
Àwọn ìjòyè náà fún àwọn eniyan ní ẹgbẹrun (1,000) akọ mààlúù, ati ẹgbaarun (10,000) aguntan.
Mose wí fún wọn pé, “Ẹ gbọ́ bí OLUWA Ọlọrun Israẹli ti wí, ó ní, ‘Gbogbo ẹ̀yin ọkunrin, ẹ sán idà yín mọ́ ẹ̀gbẹ́ yín kí ẹ sì máa lọ láti ẹnu ọ̀nà dé ẹnu ọ̀nà, jákèjádò ibùdó, kí olukuluku máa pa arakunrin rẹ̀ ati ẹlẹgbẹ́ rẹ̀, ati aládùúgbò rẹ̀.
Awọn oṣiṣẹ pajawiri ni eeyan mọkandilogun miiran lo farapa ti awọn si ti gbe wọn lọ si ile iwosan.
Fọran fidio kan to jade si ori ayelujara fi awọn alaga kansu kan han nibi ti wọn ti pade lati fi atilẹyin wọn han fun Jide Sanyaolu Sanwonolu ti wọn n ṣọọ kikankikan ninu fidio naa pe oun ni oloye Tinubu n fẹ gẹgẹ bii gomina ipinlẹ Eko.
O sọ pe aarẹ orilẹ ede Naijria ti sọ pe ki wọn je ki  gbogbo awọn ti ọrọ naa kan lọwọ ninu eto naa, ki ọrọ naa ma baa da wahala tabi ede ayede silẹ , ni eyi ti o lee fa akoba si eto ọrọ aje orilẹ ede yii.
Ileẹṣẹ ologun lo kede bẹẹ ninu atẹjade kan to fi lede, eyi ti alukoro rẹ, Sagir Musa fọwọ si.
Ní ọjọ́ keji ó gbéra lọ sí Dabe pẹlu Banaba.
 Ni Kwara, ileeṣẹ ọlọpaa ti fi oju afurasi 144 lede ni Ilorin lori awọn ẹru ti wọn ji ko."
“Ẹnikẹ́ni kò lè wo ìmọ́lẹ̀ ojú ọ̀runnígbà tí ó bá ń tàn ní awọsanma,nígbà tí afẹ́fẹ́ bá fẹ́ tí ó sì gbá wọn lọ.
Eto idanileko naa eyi ti won se fun awon to ku die ka to fun lawujo ati awon obirin ni awon igberiko ,ninu  oniruru ise owo bi fifi ileke se ohun eso ara ati ile, akara oyinbo sise,ose sise , irun gige,sise oju loge ati beebelo.
Kódà, ònu ni ọ̀pọ̀lọpọ̀ fi ń yẹ Ayélujára wò gẹ́gẹ́ bí ẹ̀rọ ayárabíàṣá wọn.
" Dandan kọ́ ni kí Buhari ó bá ayín sọ̀rọ̀ lórí coronavirus, ó ti ṣe gbogbo nkan tó yẹ kó ṣe - Iléèṣẹ́ ààrẹ Iléyá!
''Jẹ alakoyawọ ki o si dawọ le awọn akanṣe iṣẹ eleyti ti yoo mu inu ara ilu dun'' Oríṣun àwòrán, @seyiamakinde Àkọlé àwòrán, Makinde ati Falae O sọfun pe o gbọdọ fun ara ilu ni nnkan to da yatọ si ''eleyi ti aburo mi a ma pe ni oṣelu sọ sapo.
O gboriyin fun Gomina Ortom fun akitiyan re to n sa, lati ri pe oun pana ikolu ohun patapata nipinle naa.
Njẹ́ o mọ pé N3000 ló o sàn láti gbà kaadi ìdánimọ̀ míì bí tí tẹ́lẹ̀ bá sọnù?
Obin n sukun, ijọba ko mọ ibi tawọn akẹkọbirin Dapchi wa
Idi-Ape - Bashorun Akobo Road ti di Abiola Ajimobi way.
Pẹlu ìrànlọ́wọ́ rẹ̀, mo lè run ọ̀wọ́ àwọn ọmọ ogun,àní, pẹlu àtìlẹ́yìn Ọlọrun mi, mo lè fo odi ìlú.
Ọjọ́ ńlá lọjọ́ náà yóo jẹ́,kò sí ọjọ́ tí yóo dàbí rẹ̀,àkókò ìpọ́njú ni yóo jẹ́ fún ilé Jakọbu;ṣugbọn wọn yóo bọ́ ninu rẹ̀.
 Oríṣun àwòrán, facebook/godwin obaseki Ni tirẹ, Kọla Ologbondiyan to jẹ agbẹnusọ fun ẹgbẹ oṣelu PDP lapapọ ṣalaye fun BBC pe ""ki gomina Obaseki to lee di ọmọ ẹgbẹ oṣelu PDP ni ṣan an, igbesẹ naa yoo bẹrẹ pẹlu ẹka ẹgbẹ oṣelu naa ni ipinlẹ Edo ki o to kan apapọ ẹgbẹ oṣelu ọhun."
Àwọn ọmọ Aaroni nìwọ̀nyí: Eleasari baba Finehasi, baba Abiṣua; 
Níkọ̀kọ̀ ni a sọ̀rọ̀ kí gbogbo iré-ìje tí mò ń sá ati èyí tí mo ti sá má baà jẹ́ lásán.
Bí Filistini náà ṣe ń bọ̀ láti pàdé Dafidi, Dafidi sáré sí ààlà ogun láti pàdé rẹ̀.
Lati ọjọ Abamẹta lawọn eeyan ti n sọrọ lori fọnran ọkunrin naa to n fi shishan ṣagbeji ara nibi to joko si.
Gbogbo ẹni tí ó bá bá ọ rojọ́ nílé ẹjọ́,ni o óo jàre wọn.
Àgbékalẹ̀ Amotekun dára torí agbára òògùn àwọn baba wa kò dínkù tàbí parẹ́ - Peter Fatomilola Owó ìjọba ìbílẹ̀ ló wọ àwọn alága káńṣù APC lójú l‘Ọyọ - Seyi Makinde Ọ̀rọ̀ owó lo da emi àti Saheed Balogun pọ ti mo fi ke gbajare lori Instagram-Sotayogaga Ko si ǹkan to jọ Corona Virus ni Ivory Coast.
Ileeṣẹ ọlọpaa lorilẹede Naijiria da ikọ naa silẹ lati le koju ole jija ati iwa ọdaran lawujọ.
nígbà náà ni o óo wí pé,“Kí ló dé tí mo kórìíra ìtọ́ni,tí ọkàn mi sì kẹ́gàn ìbáwí!
Àwọn eniyan bá bẹ̀rẹ̀ sí sá kúrò lẹ́yìn Saulu.
A tún fún un ní àṣẹ lórí gbogbo ẹ̀yà ati orílẹ̀-èdè ati oríṣìíríṣìí èdè ati gbogbo eniyan.
Ninu awọn ẹlẹrii mẹtẹẹta naa, ẹlẹri akọkọ ti yoo kọkọ sọrọ ni iyawo Woli Sọtitobirẹ, Ajihinrere Busola Alfa.
, Duration 3,2117 Bélú 2020 Oluwo: Èmi ni adarí àti aláṣẹ lórí gbogbo òrìṣà ilẹ̀ Yoruba àti káàkiri àgbàyé16 Bélú 2020 Èyí tí a wò jùlọ 5:03 Fídíò, Omolola Arohunmolase Welder: Mo ti fí iṣẹ́ 'Welder' gbayì láwùjọ, tó mo fi tọ́ ọmọ yanjú, Duration 5,039 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 5:39 Fídíò, Akomolede ati Asa lori BBC: Olùkọ́ Kikelomo Ogunboye tan ìmọ́lẹ̀ sí ìwà olè ọ̀gá ọlọ́pàá Audu gẹ́gẹ́ bí àwòkọ́ṣe àsìkò yìí, Duration 5,398 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 4:11 Fídíò, Oba Adeyeye Ogunwusi: Ojú mi ti rí lọ́pọ̀ lọpọ̀, ọ̀pọ̀ èèyàn ni kò tilẹ̀ gbàgbọ́ pé mo lè jọba- Ooni, Duration 4,117 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 4:43 Fídíò, Promise Akinlade: ọmọ ọdún mọ́kànlá tó ń fi ìlù dárà bíi àgbàlagbà sọ̀rọ̀ nípa tálẹ́ǹtì rẹ̀, Duration 4,437 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 0:59 Gbọ́, Ìsẹ̀lẹ̀ jákèjádò orílẹ̀èdè àgbáyé láàárín ìṣẹ́jú kan, Duration 0,59wákàtí 5 sẹ́yìn 7:03 Fídíò, Olumuyiwa Bolade Adedeji Military Bruitality: Bí arákùnrin onípèníjà ara tí sọ́jà lù ṣe dé, Duration 7,035 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 4:45 Fídíò, Yoruba Films: Ẹ̀ẹ́ bẹ̀ mi kúrò láyé ni, mi ò lè kú - Fadeyi Oloro, Duration 4,4526 Èrèlè 2020 2:48 Fídíò, Esther Ajayi: Èmi náà ti borí ìṣòro rí ló ń mu mi ṣojú àánú, Duration 2,481 Ògún 2019 6:08 Fídíò, Adebola Ademilua: Àìrísẹ́ ṣè lẹ́yìn ìwé kíkà ló sọ mi dí ìyá onírú, mo dúpẹ́ tèmi, Duration 6,0827 Bélú 2020 2:36 Fídíò, Sotitobire: Ìdájọ́ òdòdò ló fẹsẹ̀ múlẹ̀ lórí ọ̀rọ̀ Pásítọ̀ Sotitobire - Agbẹjọ́rò fún ìjọba, Duration 2,367 Ọ̀wàrà 2020 BBC News, Yorùbá Ìdí tí ẹ fi le è nígbàagbọ́ nínú ìròyìn BBC Ìlànà Lílò Nípa BBC Òfin Àṣírí Cookies Kàn sí.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ko si aṣegbe laye, aṣepamọ niakn lo wa.
Pásítọ̀ ọmọ Nàìjíríà, Omotoso, tí wọ́n fi ẹ̀sùn ìfipábánilòpọ̀ kàn pàdánù ìwé ìgbélùú ní South Africa Ẹ̀yin òṣìṣẹ́, ẹ kọ ìyà tí wọ́n fi ń jẹ yín lórí owó oṣù tuntun - Oshiomole gbarata Àwọn Pásítọ́ ijọ Redeem márùn ún bọ́ sọ́wọ́ ajínigbé ní Ijebu Ode Bakan naa lo tun sọ fun kọmisana ọlọpa nipinlẹ Enugu lati da awọn ọlọpa sita, ki wọn lee tete mọ awọn eeyan to sisẹ ibi naa.
Koda, aarẹ Naijiria tẹlẹ, Goodluck Jonathan gbagbọ ni tiẹ̀ pe alafo ti iku Rolling Dollar ṣi silẹ yoo nira fun ẹnikẹni lati dí.
Òbí àwọn ọmọ tó j'óná mọ́lé n'Ibadan leè dáràn ìjọba o!
Ile-ise Ologun oju ofurufu ti ise akanse “Operation LAFIYA DOLE ti
lati fi ifẹ han si ọmọlakeji wa, ki a si fi asiko yii ṣafihan ifẹ ati
Ọpọlọpọ nkan ni awọn ọmọ Naijiria ti n sọ lori ọrọ naa lori ayelujara lati igba to ti ṣẹlẹ.
Dapọ Abiọdun ree, ẹni tó dépò gómìnà ní àyájọ́ ọjọ́ ìbí rẹ̀ Buhari mórí lé Saudi lẹ́yìn ìbúrawọlé fún sáà kejì Wo àwọn ìlérí tàwọn Gómìnà tuntun ṣe nínú ìbúra wọn Ọ̀tá Nàíjíríà ni Saraki àti Dogara - Buhari Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Bí ìrẹsì tèmi Ayinde bá ń pàkùta, kò tọ́ sẹ́nu aláàrù Barrymaade' Onidajọ Oweibo wa sun igbẹjọ si ọjọ kejilelogun, ọjọ kẹtalelogun ati kẹrinlelogun, oṣu kẹwaa, ọdun 2019.
Agbẹnusọ fun ile isẹ ọlọpaa ni ipinlẹ Ondo, Femi Joseph to fi idi ọrọ naa mulẹ fun BBC Yoruba sọ wi pe iwadii n lọ lọwọ lori isẹlẹ to waye ni agbeegbe Ọda, Akure ni ipinlẹ Ondo.
 Iroyin so pe awon  eniyan merin lo ti pdadanu emi won .
OLUWA ni ìpín wọn gẹ́gẹ́ bí OLUWA Ọlọrun yín ti wí fún wọn.
Kí o dá wọn lóhùn pé, nítorí pé àwọn baba wọn ti kọ̀ mí sílẹ̀, wọ́n ń tẹ̀lé àwọn ọlọrun mìíràn, wọ́n ń sìn wọ́n, wọ́n sì ń bọ wọ́n.
Ẹnikẹni to n sin iru awọn ọlọrun bẹ ẹ, ẹni to da a ni wọn n sin.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ogedengbe Agbógun Gbórò, Akọni tó ń dẹ́rù ba ikú.
Wọn óo bojú wo ilẹ̀, kìkì ìdààmú ati òkùnkùn ati ìṣúdudu ati ìnira ni wọn óo rí.
Akoroyìn BBC John MaManus to wà nibi ìṣẹ̀lẹ̀ náà sàlàyé pé òun ri àwọn agbárijọ ọkunrin kan lori afára náà ti wọ́n n jà.
Baba rẹ̀ yóo kú ní tirẹ̀, nítorí pé ó ń fi ipá gbowó, ó ń ja arakunrin rẹ̀ lólè, ó sì ń ṣe ohun tí kò dára sí àwọn eniyan rẹ̀; nítorí ẹ̀ṣẹ̀ tirẹ̀ ni yóo ṣe kú.
1990 (Aṣekagba) Algiers Algeria 1-0 Nigeria 21.
Ìbẹ̀rù OLUWA ni ìpilẹ̀ṣẹ̀ ọgbọ́n, ìmọ̀ Ẹni Mímọ́ sì ni làákàyè.
Bẹ́ẹ̀ náà sì ni Kọ̀lọ̀kọ̀lọ̀ bẹ̀rẹ̀ sí hu ìwà àgbàbàgebè pẹ̀lú, òun a tọrọ àyè lọ́wọ́ kìnnìún ti ó jẹ́ alága, a wá sí ọ̀dọ̀ àwọn ẹyẹ a bẹ̀rẹ̀ sí wo ojú àwọn adìẹ̀ – ìwà burúkú gbáà ni.
 Ẹjọ ́ tí ọba bá dá ni òpin .
Coronavirus yii lo n ba gbogbo agbaye finra leyi to ti mu ki ọpọ orilẹede gbe ofin konile-o-gbele kalẹ.
Ẹ fún OLUWA ní ògo tí ó yẹ orúkọ rẹ̀,ẹ máa sin OLUWA ninu ẹwà mímọ́ rẹ̀.
Wọ́n mú ọjọ́ ìgbẹ́jọ́ agbésúnmọ́mí 9/11 tó ṣẹlẹ̀ l'Amẹrika Kí ni ó gbé ọlọ́pàá dé ibi àjọ̀dún ọjọ́ ìbí i Bobrisky?
awon akoroyin soro niluu Abuja, ni ile igbalejo International Conference Centre
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Awọn elomiran a tun ma a da idoti si oju omi ati panti si odu odo, eyi ti o fa ki odo o ma dagun ati ẹkun omi.
Nígbà tí wọ́n wọlé, wọ́n bá a níbi tí ó sùn sí lórí ibùsùn ninu yàrá rẹ̀, wọ́n lù ú pa, wọ́n sì gé orí rẹ̀.
OLUWA gbé gbogbo àwọn tí ń ṣubú lọ dìde,ó sì gbé gbogbo àwọn tí a tẹrí wọn ba nàró.
Koda, igbakeji aarẹ tẹlẹ Atiku Abubakar pẹlu gbajugbaja agbabọọlu ni Neymar ko lee duro lẹgbẹ rẹ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Kemi Dairo: Iṣẹ́ abẹ nínú ọpọlọ àti ẹ̀rọ ni mo fi ń gbọ́ ọ̀rọ̀ báyìí Ìjọba Ondo, inú fìfo la fi ń ṣiṣẹ́, ẹ ṣan ọ̀pọ̀ owó oṣù tẹ jẹ wa - Àwọn dókítà fárígá Awọn dokita ile iwosan ẹkọsẹ isegun to n yansẹ lodi ti n fẹhonu han ninu ọgba ile iwosan naa to wa nilu Akure, tii se olu ilu ipinlẹ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Jiti Ogunye: Ìjọba àkóbá lológun gbé kalẹ̀ ni 1999 Ọrọ lori awọn minisita Lori ọrọ awọn minisita ti Aarẹ Buhari yoo yan fun saa keji ijọba rẹ, o ni oun ko tii sọ fun ẹnikan nipa wọn.
“Bẹnjamini dàbí ìkookò tí ebi ń pa,a máa pa ohun ọdẹ rẹ̀ ní òwúrọ̀,ati ní àṣáálẹ́ a máa pín ìkógun rẹ̀.
Wọn yóo wá máa gbadura fun yín, ọkàn wọn yóo fà sọ́dọ̀ yín nítorí ọ̀pọ̀ oore-ọ̀fẹ́ Ọlọrun lórí yín.
Crystal Palace naa gbena woju Bournemouth pelu ami ayo meji si eyokan.
 “ko derun fun awon ile-ise to n pese ina mona-mona nitori pe ida ogoji ninu ogorun un ni awon to n sanwo ina mona-mona, to si je pe opolopo awon onibara won ni won n gbona eberu lati ja won lole , laisan owo ina mona-mona”.
Nígbà tí mo bá sé ojú ọ̀run, tí òjò kò bá rọ̀, tabi tí mo pàṣẹ fún eṣú láti ba oko jẹ́, tabi tí mo rán àjàkálẹ̀ àrùn sí ààrin àwọn eniyan mi, 
 lẹ ́ yìn tí ó parí nílé-ẹ ̀ kọ ́ yí , bàba rẹ ̀ mu lọ sí ilé-ẹ ̀ kọ ́ markazu ta ' liimil ' arabi al-islami , ilé-ẹ ̀ kọ ́ tí ó jẹ ́ àgbọ ́ n-ọgbẹ ilé ìmọ ̀ ẹ ̀ sìn mùsùlùmí ní ìlú agége lábẹ ́ àkóso afáà àgbà sheik adam abdullah al-ilory fún ìtẹ ̀ síwájú ẹ ̀ kọ ́ .
Ó pé ọdún mẹ́rìnlélàádọ̀ta tí Akintola kú, ìdí abájọ ìja rẹ̀ pẹ̀lú Awolowo rè é Ìtàn Gbọnka àti Timi, akọni méjì tó borí Aláàfin Ṣango Nigba to n sọrọ lori idi ti ile ẹkọ Poly Ibadan fi se agbekalẹ awọn ẹrọ mejeeji naa, Alhaji Soladoye Adewole, tii se osisẹ alukoro agba fun ile ẹkọ naa ni ọna lati se ohun ti yoo seranwọ nidi itọju arun Coronavirus lo sokunfa rẹ.
Awọn owo yii jẹ owo beba ilẹ okeere, ti ẹjẹ si kun ara owo naa, wọn n lo gele obìnrin kan lati nu ẹjẹ kuro lara owo naa.
Obasanjo ni idibo si ipo gomina ni ipinlẹ Osun ko nilo atundi idibo to waye lawọn agbeegbe kan, amọ O ni nitori ijọba to wa lode ni Ajọ INEC fi gbe igbesẹ naa, eyi ti o mu ki APC o wọle sipo gomina ni ipinlẹ naa.
Àmọ́, ‘ilọsiwájú’ yi kò tó nkankan lára ogún ti Olóògbé Olóyè Awólọ́wọ̀ ṣe silẹ̀.
Àkọlé àwòrán, Wọn si ti sun igbẹjọ si ọjọ kọkandinlogun, oṣu Kọkanla, ọdun 2018 Lẹ́yìn tí ilé ẹjọ́ ti gba onídùúró gómìnà ìpínlẹ̀ Ekiti tẹ́lẹ̀ rí, Ayodele fayoṣe lórí ẹ̀sùn tí wọ́n fi kàn an, wọ́n ti gbé e lọ sí ọgbà ẹ̀wọ̀n tó wà ní Ikoyi, ìpínlẹ̀ Eko.
“Bí ọkunrin kan bá bá arabinrin rẹ̀ lòpọ̀, kì báà jẹ́ ọmọ baba rẹ̀ tabi ọmọ ìyá rẹ̀, tí wọ́n sì rí ìhòòhò ara wọn, ohun ìtìjú ni; lílé ni kí wọ́n lé wọn jáde kúrò ní àdúgbò, kí wọ́n sì yọ wọ́n kúrò láàrin àwọn eniyan wọn, nítorí pé ó ti bá arabinrin rẹ̀ lòpọ̀.
Jotamu di alágbára nítorí ó rìn ní ọ̀nà ẹ̀tọ́ níwájú OLUWA Ọlọrun rẹ̀.
àwọn ọmọ Kerosi, àwọn ọmọ Sia, ati àwọn ọmọ Padoni, 
naa ni ; eni ọwọ, Rev.
“Ẹ gbọ́, ẹ̀yin eniyan mi, n óo sọ̀rọ̀,Israẹli, n óo takò yín.
Nigeria 2019 Elections: Jonathan, Buhari, Obasanjọ sọ̀kò ọ̀rọ̀ lórí làáṣìgbò ìbò
Kò sí ẹni tí ó rí Ọlọrun rí nígbà kan.
Awọn dokita iṣegun Naijiria n kerora lori ẹka ilera
Ko tan sibẹ, o tun ni ki wọn ko ike iwe, ago imumi, ṣibi, abọ ounjẹ ati igbalẹ lọwọ.
Dariusi ọba bá kọ ìwé sí gbogbo eniyan ní gbogbo orílẹ̀-èdè ati gbogbo ẹ̀yà tí ó wà ní orí ilẹ̀ ayé ó ní, “Kí alaafia wà pẹlu yín, 
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Risikat Moromoke Azeez: Inú èmí àti Òbí mi dùn nígbà ti Risi bí ọmọ olójú búlù- Wasiu Bi Shina Rambo ṣe bẹrẹ aye rẹ de idi ole jija: Ọdun 1958 ni wọn bi Shina sile aye, ọmọ bibi ilu Abeokuta nipinlẹ Ogun ni baba rẹ nigba ti iya rẹ jẹ ọmọ ilu Sabongida-Ora nipinlẹ Edo.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Risikat Azeez: Kaosarat àti Hassanat gba ẹ̀bùn ẹ̀kọ́ ọ̀fẹ́ ₦1.
“Ṣé ìwọ ni o fún ẹṣin lágbára,tí o sì fi agbára ṣe gọ̀gọ̀ sí i lọ́rùn?
Ṣugbọn Abramu dá a lóhùn ó ní: “Mo ti búra fún OLUWA Ọlọrun Ọ̀gá Ògo, ẹni tí ó dá ọ̀run ati ayé, 
Ó tún gbé ọdún mẹtalenirinwo (403) sí i láyé lẹ́yìn tí ó bí Eberi tán, ó sì bí àwọn ọmọ mìíràn lọkunrin ati lobinrin.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Akita Aja Boxer: Ohun naa jẹ aja ti kii ja kikankikan, amọ ọpọlọ rẹ pe, nitori naa wọn ki n tete tẹle ohun ti olowo wọn ba sọ fun wọn.
Maria Magidaleni ati Maria keji wà níbẹ̀, wọ́n jókòó ní iwájú ibojì náà.
Nítori àwọn àtúgbẹ́yẹ̀wò, o níra láti ṣe àkójọpọ fún àwọn ọkọ́ naa Orisun: Johns Hopkins University atawọn ajọ eto ilera ilu Iye akọsilẹ to waye gbẹyin 15 Oṣù Ṣẹ́rẹ́ 2021 20:44 WAT+3 Gbenga Adeboye: Ó tẹ́ bàbá mi lọ́rùn pé ká mu gàárì nílé ju kí ebi pa ará ìta lọ - Ọmọ Gbenga Adeboye Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Gbenga Adeboye: Ó tẹ́ bàbá mi lọ́rùn pé ká mu gàárì nílé ju kí ebi pa ará ìta lọ - Oluwadamilola Adeboye, tíì ṣe ọmọbìnrin gbajugbaja adẹrinposonu nnì, Gbenga Adeboye, tí sọ àwọn ìrírí tó sì rántí nípa bàbá rẹ̀ tó ti di olóògbé.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Mí ò ya wèrè, mí ò burú, ọ̀nà àtijẹ là ń wá' Olubunmi Ajiboye ati Okanlawọn Olugbenga naa tun sọrọ pe: Oríṣun àwòrán, Tweet Àkọlé àwòrán, Ẹ̀kọ́ ọ̀fẹ́, ètò iléra ọ̀fẹ́ àti iná ọba lo jé wá lo jẹwa lógu Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Òṣìṣẹ́ Bánkì ni mí l'Amẹ́ríkà kí n tó bẹ̀rẹ̀ Tíátà' Awọn bii Ainu Lateef gbadura fun aarẹ Buhari ni nigba ti awọn bii Jacobson Adeniji, Toheeb Olawale, ati Oluseye Funmiso gba pe ko si ohun tuntun to le jade lọwọ Aarẹ Buhari.
Ipinlẹ Plateau lo tun lewaju iye awọn to laarun naa lojumọ lọjọ Aiku.
“Nígbà tí ẹ bá fẹ́ kó kúrò ní ibùdó kan, Aaroni ati àwọn ọmọ rẹ̀ yóo wá láti ṣí aṣọ ìbòjú tí ó wà níwájú Àpótí majẹmu, wọn yóo sì fi bo Àpótí náà.
Ọmọdebinrin ọhun ti wọn fi orukọ bo laṣiri ṣalaye ara rẹ nibi ijiroro lori fifi awọn eeyan sowo ẹru, ti awọn aṣofin agba orilẹede Naijiria ṣe ni ilu Benin, lẹkun aringbungbun gusu orilẹede Naijiria.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù AfCFTA: Orilẹẹde 44 t'ọwọ bọ'we ilana okoowo tuntun fun Afrika 21 Ẹrẹ̀nà 2018 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Orilẹẹde metadinlogbon lo fowo si karakata lai si idiwo laarin awọn orilẹẹde Orilẹẹde mẹrinlelogoji loti tọwọ bọwe manigbagbe adehun ilana okoowo tuntun fun Afrika eyi ti yoo mu irọrun ba karakata nilẹ Afrika.
Eyín akọ̀ròyìn fò yọ lásìkò tó n ka ìròyìn lọ́wọ́ lórí tẹlifísàn Ènìyàn 653 míràn tún kún iye àwọn tó ní COVID-19 ní Nàìjíríà Wo àwọn olorì àgbà mẹ́rin tí Aláàfin ń wárí fún Ààrẹ Buhari fi ọ́fíìsì reluwé tó wà ní ìlú Agbor sọríi ààrẹ àná, Goodluck Jonathan Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Orísun: Unicef Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Sugbon, pipadanu asekagba idije Halle sowo Borna Coric koto, leyin ti o tun padanu ipo kinni-in re sowo Nadal peli ami àádọ́ta, ti idije Wimbledon tun se n sun metile.
Kí wá ni ìdí ìgbéraga yín bí ẹni pé ẹ̀yin ni ẹ dá a ní?
Oríṣun àwòrán, Twitter/MMMDProvost2 Umaru Dikko gẹgẹ bi ọrọ naa ti ṣe lọ ṣa lọ si ilẹ Gẹẹsi ṣugbọn ijọba ran awọn ọtẹlẹmuyẹ lati lọ ji gbe pada wa sile.
Ọjọ́ abámì sì ni ọjọ́ òní, tí ọkùnrin pàdé ọkùnrin, tí mo ṣe alábàápàdé rẹ; ìwọ ọ̀gbẹ́ni àgbàlagbà, Baba-onírùngbọ̀n-yẹ́úkẹ́, ẹni tí ń gbé ibi gegele òkúta.
Nígbà tí ọjọ́ kẹjọ pé láti kọ ọmọ náà ní ilà-abẹ́, wọ́n sọ orúkọ rẹ̀ ní Jesu, gẹ́gẹ́ bí angẹli ti wí, kí ìyá rẹ̀ tó lóyún rẹ̀.
Gbogbo ale ojo Abameta ni won fi sile igbafe The Attieke Republic Restaurant sile fawon ero lati fi gbadun asa ati ede Faranse nilu Abuja.
Iṣẹ́ ni àwọn dókítà ṣe o kí àwọn ọmọ naa to ni iwosan pipe.
 O wa fi asiko naa tubo bebe fun atileyin won.
Ife East Ọjọ Abamẹta, 29/08/2020 13.
2 bílíọnù fi tún wáyà iná àti inú ilé Aso Rock ṣe- Buhari Wo ìdí tí Tẹni, ọ̀dọ́mọdé olórin obìnrin kìí fi ń ṣí ìhòhò rẹ silẹ̀ Wo ìgbà mẹ́rin tí ìjọba ti tú ikọ̀ ọlọ́pàá SARS ká sẹ̀yín ṣùgbọ́n.
com Àkọlé àwòrán, Awọn gaari ti wọn n da silẹ lo n fa eku to ni aisan lassa lati tọ si ori garri yii, eleyi ti yoo fa aarun Lassa fun gbogbo ẹni to ba jẹ garri naa Ijọba ipinlẹ Ondo tun ti kesi awọn araalu ati awọn to n se garri, lati sọra fun aṣa sisa gaari sita ni ilẹ lasan.
Ṣugbọn ẹ kọ̀, ẹ kò gbọ́, òun nìyí nisinsinyii, ẹ̀san ni ó dé yìí.
Ìjọba kò tú Dasuki àti Sowore sílẹ̀ látàri akitiyan ilẹ̀ Amẹrika- Dasuki Bayìí ni àwọn ọlọpàá Akure ṣe ko àwọn ará ìlú ti o ji ẹrù ni sọọsi Sotitobirẹ Olè yabo báńkì,fọ́n owó ká fáwọn èrò lẹ́yìn tó pariwo 'Merry Christmas' Èyí ni bí wọ́n ṣe n dìbò yan Póópù tuntun nínú ìjọ Àgùdà Ninu awọn ẹlẹwọn to gba idande lati ri Bestman Dennar; Wasiu Jimoh; Augustine Opara; Folakemi Osin; Rebecca Danladi ati Njoku Ogechi.
Nítorí pé ní ìkáwọ́ rẹ̀ ni ìfẹ́ tí kì í yẹ̀ wà,ní ìkáwọ́ rẹ̀ sì ni ìràpadà kíkún wà.
Gbogbo iwa akinkanju yii lo sọ Ogedengbe di akọni niluu rẹ to si fi di ọkan lara awọn ọkunrin to pataki ju lọ ni ilẹ Yoruba, orilẹ-ede Naijiria ati ilẹ Afirika.
Òun jẹ alágàbàgebè obìnrin, àwọn ẹ̀dá ọ̀run sì bẹ̀rẹ̀ sí kọ ẹ̀hìn sí ara wọn.
Ìrìnkèrindò ni ìwé ìtàn-àròsọ yìí dá lé lórí .
Gbogbo àwọn ìjòyè, àwọn alágbára, ati gbogbo àwọn ọmọ Dafidi ọba ni wọ́n jẹ́jẹ̀ẹ́ láti máa gbọ́ ti Solomoni.
Ní bayìí wọn ti bura wọlé fún gbogbo wọn.
Awọn olukopa mẹrin lorukọ wọn wa lori iwe ile ya fun ọsẹ kẹrin.
Koda o ni orukọ inagijẹ rẹ''Ọwọ'' to n jẹ ''emi ni mo fun un.
 kó yà ni apá ọ ̀ tún ní òpópó ìjìyà ẹ ̀ sẹ ̀ .
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Ìgbà tí mo máa fi lajú sáyé padà, ọ̀fọ̀ ikú mi ní wọ́n ń kígbe' Nigba wo ni DisCos le fi kun owo ina?
" Ọdun méjìlá ni ìyàwó mi fi wá ọmọ.
Eyi to fihan pe l'Ọjọbọ ati Ẹti, ipinlẹ Plateau lo moke pẹlu iye awọn to laarun naa lorilẹede Naijiria.
Wọn fi kun un pe àwọn bi ẹgbẹrun mẹrinla to ku ti ko ri owo gba tumọ si pe orukọ wọn pada ni, nitori pe orukọ wọn ti jẹyọ nile iṣẹ ijọba apapọ miran eyi si lodi si ofin N-Power.
Wo orúkọ àwọn ẹ̀yà ara rẹ̀ ní èdé Yorùbá Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Igbagbọ awọn mii nipe àtẹlẹwọ́ ẹni kìí tan ni jẹ.
Kí OLUWA ran àwa mejeeji lọ́wọ́ ati àwọn ọmọ wa, kí á lè pa majẹmu tí ó wà láàrin wa mọ́ laelae.
 Sisọ ẹka ipese ina ọba di ti aladani (Privatisation) Oríṣun àwòrán, @batcolloquium Àkọlé àwòrán, Tinubu tun pe fun imugboro ipese ina ọba ni ida aadọta ninu ọgọrun (50%) laaarin ọdun mẹrin si asiko yii Tinubu ni asiko to fun Buhari lati gbe igbimọ ọlọpọlọ pipe kalẹ fun tita ẹka ipese ina ọba di aladani."
isoro ti oko oju omi naa ni, lo faa ti  a
Akeugbagold ni abamọ ni yoo gbẹyin iru awọn ọkunrin to ba lowo lọwọ ṣugbọn ti wọn n ṣe ahun si obinrin.
O ni ohun ko foju apẹrẹ arun naa han ṣugbọn ohun ti bẹrẹ iyasọtọ ati itọju.
Kinniun ni yóo pa àwọn ará Moabu tí ó bá ń sá lọati àwọn eniyan tí ó bá kù ní ilẹ̀ náà.
 Ó jẹ ́ oníṣòwò , olóṣèlú àti ọlọ ́ rẹ àtinúwá Ọmọ orílẹ ̀ -èdè nàìjíríà .
 kò wọ ́ pọ ̀ kí wọ ́ n gba ẹni tí ó ti lọ ́ kọ lati ṣisẹ ́ ìtọ ́ jú aláìsàn ní àkókò yẹn .
Mo rán oníṣẹ́ mi ṣiwaju rẹòun ni yóo palẹ̀ mọ́ dè ọ́.
Ajínigbé kọlu òṣìṣẹ́ FRSC, èèyàn méjì kú, mẹ́rin farapa, mẹ́wàá di àwátì Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Aràrá bíi tèmi, kó má rò pé kò sì ǹkan tó lè ṣe láyé ju iṣẹ́ agbe lọ' Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Gbogbo awọn to yi irinṣẹ ilu ati ipinlẹ wọn di ogun wọn 9.
Obi ti ko ba lagbara lati kọ ọmọ rẹ ni ẹkọ iwe, yẹ ko fi si ẹnu ẹkọsẹ abi okoowo nitori ọwọ to ba dilẹ ni esu n bẹ lọwẹ.
Wọ́n jó ilé OLUWA, wọ́n wó odi Jerusalẹmu, wọ́n jó ààfin ọba, wọ́n sì ba gbogbo nǹkan olówó iyebíye ibẹ̀ jẹ́.
Ìròyìn tó tẹ BBC lọ́wọ́ sọ pé, Fagoriola jẹ́ alága ijọba ibilẹ Akure North láàrín ọdun 2004 si 2007, lábẹ́ Gómiànà Olusẹ́gun Agagu, sùgbọn wọn jíi gbé nínú oko rẹ̀ tó wà ní ààlà Ondo àti Ekiti láàrin Akure si Ikẹ̀rẹ́ lópòónà Ekiti.
Aṣẹ yii wa lati lee mọ ọjọ ti awẹ yoo pari ti awọn Musulumi yoo ṣi tunu.
Àwọn ọ̀pá náà wà níbẹ̀ títí di òní yìí.
    Èṣù kò rí àwa, ṣùgbọ́n àwa ríi dáadáa.
Ìyanṣẹ́lódì ọlọ̀jọ̀ mẹta bẹ̀rẹ̀ l'Ọsun Ipinlẹ Ọ́yọ̀: Ile-iwe wa ni titi pa nitori iyansẹ̀lodi 'Ẹnu lásán kò lè sàn owó oṣu oṣiṣẹ l'Ekiti' Oríṣun àwòrán, Labour Party Facebook Àkọlé àwòrán, Ẹgbe oselu awon osisẹ Naijiria ni Labour Party Ayuba Waba to jẹ Aarẹ ẹgbẹ osise lo sọ fun BBC Yoruba ninu ifọrọwanilẹnuwo kan pe adisọkan Mimiko ati tawọn ko papọ fun idi eyi,awọn ko le gba gẹgẹ bi oludije Aarẹ awọn.
Ìdí tí o kò fi gbọdọ̀ pa oríṣi inú rírun márùn-ún yii mọ́ra
Ipade naa bere ni ofiisi ile aare , ni kete ti May de si ile –aare ni deede aago mejiLa osan.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Làá hàn mí: Ètò yìí ló ń kìlọ̀ fún wa láti mú ìmọ́tótó ní pàtàkì láti dènà Coronavirus Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Wọ́n jọ ń ṣe àríyá, wọ́n jọ lọ sí ilé oriṣa wọn, wọ́n ń jẹ, wọ́n ń mu, wọ́n bẹ̀rẹ̀ sí fi Abimeleki ṣe ẹlẹ́yà.
Asiko yii ni Sara lanfaani lati kọwe si iya to bi, ti onitọun si fesi pe oun yoo dahun awọn ibeere to ba fẹ bi oun amọ ko wu oun lati ni ajọsepọ kankan bi tii wu ko mọ pẹlu ọmọ naa rara, koda, ko kari bọnu lati sọrọ yii.
"Òṣìṣẹ́ ètò ìlera méjì ló wà nínú àwọn tó lùgbàdì àrùn coronavirus ní Ekiti Eyín ọ̀ọ́kán mi ni Barakat tí wọ́n pa lẹ́yìn tí wọ́n fipá bá a lòpọ̀- Ìyá Barakat Ní Ọjọ́ọ̀rú nìkan, ènìyàn 348 ló lùgbàdì àrùn Coronavirus ní Naijiria Mimiko sọ siwaju pe "" igba ti mo ṣíṣẹ labẹ wọn lọdun 1992 gẹgẹ bii kọmisana, wọn kọ wa bi wọn ṣe n fi ara ati ọkan sin ilu, oselu tiwọn kii si ṣe oselu jẹgudu-jẹra, ki la le ri ko, oselu ti wọn fi sin Ọlọrun ati eniyan ni."
Iṣẹlẹ naa waye lasiko ti awọn oṣiṣẹ naa n pada si ilu Port Harcourt lati irinajo ẹni iṣẹ ti wọn rin lọ si ipinlẹ Bayelsa.
Mo ti fi ọ̀rọ̀ mi sí ọ lẹ́nu,mo ti pa ọ́ mọ́ lábẹ́ òjìji ọwọ́ mi.
Seyi Makinde, bàtà tí Ajimobi bọ́ sílẹ̀ ni ko tẹsẹ̀ bọ̀ fún àṣeyọrí Ọyọ - APC Ọrọ̀ ajé Nàíjíríà yóò forí ṣánpọ́n tá a bá san ₦30,000 fún òṣìṣẹ - Ìjọba Kò sí ìfoyà, mò ṣetán láti sàn jù ₦30,000 fáwọn òṣìṣẹ́ l‘Eko - Sanwo-Olu 'Kìí ṣe ojúṣe mi láti sọ bóyá òótọ́ ni Buhari fẹ́ gbéyàwó tàbí irọ́' Ta ni Mamman Daura?
Ọmọ Otedola bú sẹ́kún lẹ́yìn tí Brighton tún d'ẹrù ìyà lé Arsenal lórí Wo àwọn oníròyìn méje tó kú láàrin ọjọ́ méje ní Nàìjíríà Wo àwọn àsọtẹ́lẹ̀ ìgbà tó yẹ kí ayé parẹ́ àtàwọn tó sọ àsọtẹ́lẹ̀ náà Báwó ni òògùn dexamethasone ṣe ń ṣiṣẹ́ lára Ó di gbéré!
Naijriia n ko lati koju iwa ibaje iwa jegudu jera to gbode kan lawujo;Lilo obinrin
Ǹjẹ́ ẹ mọ ohun tí igbákejì ààrẹ Yemi Osinbajo sọ nílé bàbá Fasoranti Akosile ni awọn orukọ yii ni ti ipele akọkọ nitori pe iṣẹ ṣi n lọ lọwọ lati yan awọn to ku ti wọn yoo ba Sanwo Olu ṣiṣẹ fun ilọsiwaju ipinlẹ Eko.
Ọba Siria ti pa gbogbo wọn run, ó lọ̀ wọ́n mọ́lẹ̀ bíi erùpẹ̀.
Nígbà tí Abineri dé ọ̀dọ̀ Dafidi ní Heburoni pẹlu ogún ọkunrin tí ń bá a lọ, Dafidi se àsè ńlá fún wọn.
Ó bá pàṣẹ pé kí wọn máa pa gbogbo àwọn ọmọ-ọwọ́ lọkunrin ní Bẹtilẹhẹmu ati ní gbogbo agbègbè ibẹ̀ láti ọmọ ọdún meji wálẹ̀ títí di ọmọ tí wọ́n ṣẹ̀ṣẹ̀ bí, gẹ́gẹ́ bí àkókò tí ó fọgbọ́n wádìí lọ́wọ́ àwọn amòye.
À ń lo àwọn kan fún nǹkan pataki; à ń lo àwọn mìíràn fún ohun tí kò ṣe pataki tóbẹ́ẹ̀.
Bí Abrahamu ti gba Ọlọrun gbọ́, tí Ọlọrun wá gbà á gẹ́gẹ́ bí olódodo, 
Joshua àti Ruiz gbà láti jàjà mííràn lóṣù kọkànlá Anthony Joshua darapọ̀ mọ́ Mohammed Alli, Lenox Lewis ati Holyfield Ẹẹmẹrin ọtọọtọ ni Ruiz fi ẹsẹ kan Joshua mọlẹ lai le dide.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ètò ìsìnkú Abba Kyari tako ìlànà ìjìnàsíraẹni lórí ààrùn covid-19- Àwọn ọmọ Nàìjíríà yarí Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Ọdọmọkunrin náà wá dáhùn pé, “Àwọn Juu ti fohùn ṣọ̀kan láti bẹ̀ yín pé kí ẹ mú Paulu wá siwaju ìgbìmọ̀ lọ́la kí àwọn le wádìí ọ̀rọ̀ rẹ̀ ní fínnífínní.
Eliṣa sọ fún un pé “Máa lọ ní alaafia.
O tun sọ ninu fidio naa wi pe awọn ọlọpaa ko le mu ohun nitori wi pe awọn mejeeji yoo jọ lọ ''pade Ọlọrun pọ ni'' Lẹyin igba naa lo p'okun so ninu iyara ibusun wọn.
Bẹ́ẹ̀ ni wọ́n ṣe fi àwọn ọmọ ogun wọn sí ipò, àwọn tí wọn yóo gbógun ti ìlú gan-an wà ní apá ìhà àríwá ìlú, àwọn tí wọn yóo wà lẹ́yìn wà ní apá ìwọ̀ oòrùn, ṣugbọn Joṣua alára wà ní àfonífojì ní gbogbo òru ọjọ́ náà.
    Kí Ayédèrú-ẹ̀dá tó parí ọ̀rọ̀ rẹ̀ tán ni púpọ̀ nínú wa tí a ti jókòó le orí ogiri kekere tí o yí ilé Òmùgọ̀diméjì po ti n fẹ́ sọ̀rọ̀.
Koda, aarẹ ilẹ Ivory Coast, Alassane Quattara ati Davido gan an wa ni papa iṣere Félix Houphouet Boigny Stadium ti wọn ti ṣe ẹyẹ ikẹyin fun Arafat.
Ò sì ní agogo nínú gbogbo sẹ́ẹ́lì rẹ Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Gbogbo sẹ́ẹ́lì lọ́ mọ̀ àsìkò Gbogbo sẹ́ẹ́lì ni ara rẹ ní agbára àti máa jí à ti máa jí l'àáàrín wákàtí 24.
Lẹ́yìn náà ó lọ bá Dafidi ní Heburoni láti sọ ohun tí àwọn ará Bẹnjamini ati gbogbo ọmọ Israẹli ti gbà láti ṣe fún Dafidi.
àwọn ọmọ Nesaya, ati àwọn ọmọ Hatifa.
 Ó lọ ilé-Ìwé alákọ ̀ ọ ́ bẹ ̀ rẹ ̀ ti muslim mission àti ilé-Ìwé model ti mushin tó wà nílù Èkó .
Gomina Ipinlẹ Ogun, Dapo Abiodun naa kesi awọn ọmọ Niajiria lati ni igbagbọ pe arun Coronavirus yii yoo dopin.
Ọgbẹni Ugbe ṣalaye pe, milọnu lọna ẹẹdẹgbẹrun ni awọn eeyan di lapapọ fun awọn olukopa lori eto naa.
Diẹ lara iṣẹ ijinigbe ti wọn ti se ni jiji awọn ọmọbinrin Chibok gbe lọdun 2014 ati ti Dapchi lọdun 2018.
‘Ọ̀rọ Baba Ọbasanjọ kò jọ wá lójú mọ́’ Atiku ti buwọ́lu ìwé àdéhùn àláàfíà Ohun tó yẹ ko mọ̀ nípa àdéhùn àláàfíà táwọn olùdíje ààrẹ fọwọ́sí O fikun wi pe iwe ofin ipinlẹ Eko to nii se pẹlu iwa aito lawujọ sọ wi pe ẹni to ba wu iru iwa bẹẹ lawujọ yoo fi ẹwọn ọdun meji si mẹta jura gẹgẹbi iwe ofin to niise pẹlu iwuwasi lawujọ to wa ni Section 134 (a) ati section 136 ti iwe ofin ipinlẹ Eko.
“Àwọn òfin ati ìlànà, ati ìdájọ́ tí OLUWA Ọlọrun yín pa láṣẹ fún mi láti fi kọ yín nìwọ̀nyí; kí ẹ lè máa tẹ̀lé wọn ní ilẹ̀ tí ẹ̀ ń lọ gbà; 
OPC: Bí a ṣe gbéná wojú awọn ọ̀daràn tó ń d'àlú Ikire rú rèé Ìròyìn èké lásán ni pé wọ́n yọ mí nínú ẹgbẹ́ YCE - Kunle Olajide Kí ló ń mú olóòtú ìjọba Merkel máa gbọ̀n pẹ̀pẹ̀ lóde?
Òfin eniyan, tí wọn kọ́ sórí lásán, ni ìbẹ̀rù mi sì jẹ́ fún wọn.
Koda, wọn ko lu u nikan, niṣe ni wọn tun fa a le ọlọpaa lọwọ gẹgẹ bi arufin.
 “Laifi ojo pe Aina , a lee sọ pe ipa ti awon osise
Lẹyin ti wọn pa eniyan to le ni ọgọrun un lasiko naa ni awọn kan tun ni irọ nipe Shekau ku lara wọn.
O ti yo fidio naa kuro ni kete ti awon eniyan ti n soro ti awon alase Tanzania ni o se lodi si asa ile naa.
Fọlọrunṣọ Alakija: Obinrin nilo imọ 'Dokita ilé ìwòsàn ló gba ẹsẹ̀ lọ́wọ́ mi' 'Ọṣinbajo jọmí lójú pẹ̀lú ìwà akin tó hù' Fatimah: Kò sí ẹni ti kò le yi agbègbè rẹ padà Àrà tuntun tí aṣọ òkè ń gbé jáde Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí 2 sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 2:23 Fídíò, Water Generator: Ó leè ṣiṣẹ fún wákàtí mẹfà, kó tó sinmi, Duration 2,2310 Òkùdu 2020 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
Ẹkẹtadinlogun mú Joṣibekaṣa, òun ati àwọn ọmọ rẹ̀ ọkunrin, ati àwọn arakunrin rẹ̀ jẹ́ mejila.
Nitori pe awọn to ti dide bi i Aluwẹ, Ọga Bello la ba lẹnu iṣẹ.
Idi ree ti ori gomina ipinlẹ Ọyọ, Onimọ ẹrọ Seyi Makinde fi n fo fun ayọ, to si ni ori oun wu pupọ lati awọn agba ijoye ilẹ Ibadan ti wọn kọwọ rin pẹlu Olubadan ilẹ ibadan, Ọba Saliu Akanmu Adetunji, Aje Ogungunnisọ Kinni.
Oríṣun àwòrán, @NLCtoday O tẹsiwaju pe, lọwọlọwọ ọgba ẹwọn naa ko ti ṣe gbe pada, tori naa, wọn ti gbe awọn ẹlẹwọn ibẹ lọ si ibomiran titi ti omi yoo fi gbẹ nibẹ.
Alaafin Adeyemi: Lára àwọn òrékelẹ́wà ayaba náà ló dẹnu ìfẹ́ kọ Ọba Adeyemi fúnra wọn
com/9LBUWIhK5kEsi ifesewonse naa je ohun Iyalẹnu pupo fun awon ololufe iko
O parọwa si awọn ara ilu lati ran ileeṣẹ ọlọpaa lọwọ nipa ṣiṣe amojuto ayika wọn ni gbogbo asiko ki wọn si maa yara fi ọrọ to awọn agbofinro leti ti wọn ba kẹẹfin ohunkohun ti ko bojumu layika wọn.
Dafidi sì tún ṣẹgun Hadadeseri, ọmọ Rehobu, ọba Soba, bí ó tí ń lọ láti fi ìdí ìjọba rẹ̀ múlẹ̀ ní ilẹ̀ tí ó wà ní agbègbè odò Yufurate.
Ayọ̀ ń bẹ fún ẹni tí ó bá kó àwọn ọmọ wẹ́wẹ́ rẹ,tí ó ṣán wọn mọ́ àpáta.
Ta ló wà láyé tí kò ní kú?
"Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Èyí ni àwọn ìdí tí INEC fi sún ìdìbò aarẹ síwájú Ẹnikẹ́ni tó bá ṣáájú láti jì àpótí ìbò, ẹ̀mí rẹ̀ ló fi ń ṣeré - Buhari Ihalẹ Buhari: PDP na ìká àbuku sí Buhari lẹyìn ìpàdé wọn O ṣeéṣe ki iṣẹ́ bọ́ lọ́wọ́ ọlọ́pàá inú àwòrán 4+4 APC, PDP, CUPP kọ etí ikún sí òfin INEC INEC kéde pé àwọn ẹgbẹ́ òṣèlú lé tẹ̀síwájú pẹ̀lú ìpolongo ìbò ""To ba jẹ pe olori orilẹede yii ati alasẹ patapata fun ilẹ Naijiria lo pa asẹ fun wa pe, ka mu ẹyin ẹnikẹni to ba ji ibo balẹ, ẹ jẹ ko da yin loju pe, a mu asẹ naa sẹ laisi tabi sugbọn kankan nipa rẹ."
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Oshoala ti Nigeria ati Thembi ti South Africa naa yoo kopa Papa iṣere Parc Des Princes to jẹ ile fun Paris St-Gwermain ni wọn yoo ti gba idije ibẹrẹ ti wọn yoo fi ṣide ni France.
Wọn ni o ma n sisẹ fun aisan ikọfe e ati aisan ẹdọ.
Ileeṣẹ WhatsApp ni ati ṣe ipinu yii le gan ṣugbọn igbesẹ to tọ ti yoo jẹ kawọn eeyan le maa kan si ara wọn.
Oluwoye kan, Dan Ives ni o fẹrẹ to ida ogoji ninu awọn to fẹẹ to ọgọrun miliọnu to n lo iPhone ni ko tii ṣe foonu wọn ko gbera siwaju fun o kere tan ọdun mẹta abọ eyi to si lee fun wọn ni anfani pupọ bi wọn ba ṣe e.
Nítorí náà, aré tí èmi ń sá kì í ṣe ìsákúsàá láìní ète.
Àìgbẹ̀kọ́, ètò ìlera tí ò pójú òṣùwọ̀n àti kòlàkòṣagbe tí ó ń gb’àgbègbè tí ìwà pálapalà wọ̀nyí ti gbalẹ̀ bí i ìtàkùn ni ó fi wọ́pọ̀.
Ìpàdé oníròyìn ni a fi bẹ̀rẹ̀ ètò ní Ilé Ẹgbẹ́ Akọ̀ròyìn ní Lahore níbi tí wọ́n ti fi ẹ̀dùn ọkàn-an wọn hàn; lẹ́yìn náà ni wọ́n yide kiri dé Ilé Àṣà Al Hamra níbi tí wọ́n ti jó, kọrin lọ́nà, kí wọn ó tó fọ́nká lẹ́yìn tí wọ́n jẹun tán.
O ni isẹlẹ naa to waye ladugbo Alagbaka jẹ ajoji si ipinlẹ Ondo.
Lara awọn odo to gbajumọ ti awọn ara ilu Mamu-Ijẹbu ti n pọnmi ni Odo Idi-Arika, odo Apata, odo Iyemoja, odo Iya onirobo,odo Ẹpa, odo Ogbirigbiri, abbl pẹlu awọn kanga diẹ
''A ni awọn ọmọ Almajiri yi ni adugbo Sabo ati ni Oke Ogun.
Wairagala Wakabi, àgbà ọ̀jẹ̀ ajàfẹ́tọ̀ọ́ ẹ̀rọ ayárabíàṣá tí ó wá láti Uganda, di ẹni àtìmọ́lé ní Pápákọ̀ òfuurufú Julius Nyerere International Airport ní Dar es Salaam, Tanzania lọ́jọ́ 25 oṣù Igbe.
1 585857 Orilẹede Chech 9341 87.
Ọlọ́pàá Ondo: Ìyá ọmọ tó kú yóò fojú balé ẹjọ́
Iná ń ṣàn jáde bí odò níwájú rẹ̀.
Ilé wọn kún fún ìwà ọ̀dàlẹ̀,bíi kùùkú tí ó kún fún ẹyẹ.
Ijamba ti ko dun mọ wa ninu ni.
Eeyan 59,748 lo ti ri iwosan ninu awọn 63,508 ti ayẹwo fihan pe wọn larun coronavirus ni Naijiria.
Èmi nìkan ṣoṣo ni mo ṣẹ́kù, wọ́n sì fẹ́ gba ẹ̀mí èmi náà.
Ilé ẹjọ́ tí ṣọ́ọ̀ṣì pa nítorí ariwo tó ń pa sétí aráàlú Èrò yapa ní mọ́ṣáláṣí Jimọ̀h láti wá fójú lóúnjẹ lórí ìgbéyàwó òfegè Buhari.
Bàbá akẹ́kọ̀ọ́ LASU tí ọ̀rẹ́kùnrin rẹ̀ àti pásítọ̀ fi ṣ'oògùn owó ń bèèrè fún ìdájọ́ òdodo Ọlọ́pàá hú òkú akẹ́kọ̀ọ́ fásítì LASU tí ọ̀rẹ́kùnrin rẹ̀ àti pásítọ̀ ṣekúpa Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, LASU Ritual: Àwọn akẹẹgbẹ́ akẹ́kọ̀ọ́ LASU tí wọn fi ṣowó sọ̀rọ̀ lórí ìgbé ayé olóògbé Favour, ni iroyin sọ pe o kuro nile l'ọjọ kẹjọ, oṣu Kejila, ọdun 2019, to si di awati.
Lẹyin iwadii, Ile ẹjọ ti wa paṣẹ bayii lati da ibo naa sọnu ki wọn si ṣe atundi ibo laarin aadọrun un ọjọ.
Nǹkan tí Jeremaya gbọ́ nípa gbogbo àwọn Juu tí wọn ń gbé Migidoli ati Tapanhesi, ati Memfisi ati ilẹ̀ Patirosi ní ilẹ̀ Ijipti nìyí.
Makinde lati lati ẹkun idibo Ifakọ-Ijaye keji labẹ ẹgbẹ oṣelu APC ni
 Festus Okoye Esq   alaga to n mojuto ajo INEC ni ipinle Rivers, Igbimo  to n ri si eto ilanilọyẹAdemola Adepoju.
Àwọn bàbá ìsàlẹ̀ òṣèlú tó bá ìtìjú bọ̀ nínú ìbò Gómìnà rèé Ọ̀rọ̀ Aisha Buhari sí Ramaphosa wú ọ̀rọ̀ síta lẹ́nu àwọn ọmọ Nàìjíríà Aisha Buhari bá ìyàwó ààrẹ Gambia ṣàjọyọ̀ ọjọ́ ìbí Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ìdílé tó gba olùkọ́ èdè Yorùbá fún àwọn ọmọ nílẹ̀ Gẹ̀ẹ́sì O ní owó ti wọn ni wọn fi rà àwọ̀n apẹ̀fọn kìí ṣe èyi to ṣee gbọ́ séti rárá.
Ìwọ tí o dàbí ìkún omi tí ń bì síwá sẹ́yìn,o kò ní jẹ́ olórí, nítorí pé o ti bá obinrin mi lòpọ̀,o sì ti sọ ibùsùn èmi baba rẹ di aláìmọ́.
"Ninu fidio ti a fi sori ẹrọ Instagramu yi, Melaye sọ pe oun la ala kan nibi ti oun ti ri Ogbẹni Bello ninu ""asọ ẹwọn pẹlu ẹṣọ pataki""."
Asofin 2,964 lo f'ọwọ si atunṣe naa, nigba, ti mẹji tako ti mẹta si kọ lati dibo.
Ninu atẹjade ti wọn fi sita, wọn ni eyi wa lati bọwọ fun ilana tawọn ijọba apapọ ati ipinlẹ gbe jade nitori itankalẹ Covid-19.
" Mó máá ń fi bí o ṣe kúrú ṣe yẹ̀yẹ́, ní àìpẹ́ yìí ti a fi àtẹ̀jíṣẹ́ rànṣẹ́ si ara wa, mo ṣì fí ṣe yẹ̀yẹ́ pé ṣe o ti ga síi, o fi fèsì pé dúró di ìgbà ti o bá rí mi.
Àwọn awuyewuye tó jẹyọ̀ lórí Lawal Daura kí wọ́n tó yọ ọ́ níṣẹ́ Iyansipo Lawal Daura gẹgẹ bi ọga agba ajọ ọtẹlẹmuyẹ DSS lọdun 2015, mu awuyewuye dani.
Lójijì, iná ṣẹ́ láti ọ̀dọ̀ OLUWA wá, ó jó ẹbọ sísun náà, ati ọ̀rá tí ó wà lórí pẹpẹ.
Pinnick: Àwọn ọ̀tá mi ló fẹ́ b'orúkọ mi jẹ́
Xenophobia Idẹyẹ si awọn ọmọ Naijiria lati ọwọ awọn eeyan South Afrika kan ko jẹ tuntun mọ.
òkun àwòyó ni ń bẹ ní gúsù.
O ni kete ti awọn ba ti pari iwadi lawọn yoo wọ ọ lọ si iwaju ile ẹjọ lori ẹsun yii.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Kogi Prison: Kò sí ẹ̀mí kankan tó nù, a sì tí rí lára àwọn tó fẹsẹ̀ fẹ́ ẹ 29 Ọ̀wàrà 2019 Oríṣun àwòrán, Others Awọn alaṣẹ ọgba ẹwọn agbegbe Koton-karfe ni ipinlẹ Kogi ti ẹkun omi ti ṣọṣẹ ni awọn ti ri lara awọn ẹlẹwọn to sa lọ pada ko si si ẹmi kankan to nu.
Ẹ̀yin Ọba Yorùbá, ẹ jáwọ́ nínú ẹgbẹ́ òkùnkùn!
Má rò pé ọ̀kan ninu àwọn oníranù obinrin ni mí.
Ó ní, “Ògo Ọlọrun ti fi Israẹli sílẹ̀, nítorí pé wọ́n ti gbé àpótí Ọlọrun lọ.
nítorí oúnjẹ Ọlọrun ni ẹni tí ó ń ti ọ̀run sọ̀kalẹ̀ wá, tí ó ń fi ìyè fún aráyé.
Bẹẹ ni ọrọ ri pẹlu obinrin kan, Kemi Remi Dairo tii se abani se kokari ayẹyẹ, ti eti rẹ sadede di lẹyin to ti ibi inawo kan de.
Ọlọ́pàá tún ọ̀daràn mú lẹ́yìn ọjọ́ karún tó kurò lẹ́wọ̀n Awọn obinrin naa ni awọn afẹsun kan ọhun lọ ba awọn obinrin yii ninu ọkọ ti wọn wa ti wọn si bẹ wọn ki wọn fun awọn ni owo ti wọn le fi jẹun.
Mo ti ya fọto ara (scan) lẹẹmẹrin, wọn ko si ri ọpa to n gbe ẹyin lọ sile ọmọ, pe boya wọn le ri ẹyin ọmọ lati lo ilana igbalode IVF, fun mi ki n le di ọlọmọ,ṣugbọn ko ṣe e ṣe.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Mr Macaroni sọ nípa eré tí Fraky freaky, Sugar Daddy, You are doing well, freaky spicy fẹ́ Adajọ Oyinloye tun paṣẹ pe ki wọn gba ẹrọ ibanisọrọ ati ẹrọ kọmputa ti ọmọkunrin naa n lo lati lu awọn eeyan ni jibiti lori ayelujara, ki wọn si ko fun ijọba apapọ.
Ẹ dìde, ẹ jẹ́ kí á lọ.
Ṣaaju asiko yii, Amaechi ti wọ Obuah lọ ile ẹjọ lori ẹsun pe o n ba oun lorukọ jẹ ti o si ni ki o san owo itanran ọ́ọ̀dúnrún biliọnu naira nigba naa.
Ààrẹ Buhari kí Akeredolu kú orííré bí ó ṣe jáwé olúborí nínú ìdìbò sípò gómínà Gomina Kano tí ní kí olùrànlọ́wọ́ rẹ̀ lọ rọ́kún nílé nítori o bu Ààrẹ Buhari lórí #EndSars Ọjọ Kẹrin, Oṣu kẹwaa, ọdun 2020 Ọga agba ọlọpaa lorilẹ-ede Naijiria, Mohammed Asamu paṣẹ ki ikọ FSARS ye e kaakiri lati ma a wo ọkọ ati dukia awọn eniyan mọ loju popo, tabi ki wọn ma a gbe ọkọ kaakiri lati fi ṣe ọṣẹ.
Ó wá sọ fún wọn pé, “Ṣugbọn ní àkókò yìí, ẹni tí ó bá ní àpò owó kí ó mú un lọ́wọ́; ẹni tí ó bá ní igbá báárà, kí òun náà gbé e lọ́wọ́.
Ẹ fura o, wọ́n ti ń fi orúkọ Adeboye àti Olukọya lu jìbìtì ní Facebook 'Kọ́kọ́ kànsí àlúfà lórí ọ̀rọ̀ ìgbéyàwó' Kí la tún gbọ́ nípa ìdámẹ́wàá?
Ninu gbogbo ẹbọ mímọ́ tí a kò sun lórí pẹpẹ, ẹbọ ọrẹ, ẹbọ ohun jíjẹ, ẹbọ ìmúkúrò ẹ̀ṣẹ̀, ati ẹbọ ìmúkúrò ẹ̀bi, tí wọn ń rú sí mi yóo jẹ́ mímọ́ jùlọ fún ìwọ ati àwọn ọmọ rẹ.
Lọjọ Isẹgun ni ọwọ tẹ Muhammad lẹyin to wọ inu ile kan lati lọ fipa ba awọn ọmọde kan lo pọ nibẹ ki ọkan ninu awọn ọmọde naa to kigbe sita.
Ninu ọrọ rẹ ẹgbẹ agba ni ilẹ Yoruba ni Obasanjọ kii se ẹlẹyamẹya, bẹẹ ni kii fun eniyan ni iṣẹ tabi fi ẹni si ipo nitori wọn jẹ ẹya kan naa, eleyii to tako iwa wobiliti wọbia to wọpọ bayii ni awujọ wa.
Ondo Kidnapping: Egbìnrìn ọ̀tẹ̀ ni ọ̀rọ̀ àwọn ajínigbé ní ìpínlẹ̀ Ondo
OLUWA àwọn ọmọ ogun ní bí eléyìí bá jẹ́ ohun ìyanu lójú àwọn eniyan yòókù, ǹjẹ́ ó yẹ kí ó jẹ́ ohun ìyanu lójú òun náà?
Pupo ninu awon omo ogun orile ede yii lo padanu emi won laarin ose yii ni ileto Metele to wa ni ipinle Borno, nigba ti iko olote Boko Haram kolu won.
 O jẹ itabuku ba ẹka aṣofin orilẹ-ede yii.
Gẹgẹ bi ileeṣẹ ologun ṣe fi atẹjade kan sita, , o kopa pataki ninu kikoju awọn adigunjale ni iha aarin gbungbun orilẹede Naijiria labẹ akoso ikọ Operation Gama Aiki"" ni Minna, ipinlẹ Niger."
Oríṣun àwòrán, Twitter Garba/Durotoye/Sowore Àkọlé àwòrán, Awọn ọdọ ni asiko to lati gba ijọba lọdọ awọn agba oloseelu Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Buhari, Obasanjo ṣe'pade nilu Abuja Babangida si Buhari: bọọlẹ k'awọn ewe bọ sipo Ẹ̀mí márùń bá ìjà àwọn jàǹdùkú lọ ní Ìjẹ̀bu A kò fẹ́ bàbá àgbà mọ́ nípò ààrẹ - Fayose Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Saraki kẹkọọ gboye ni Fasiti ilu London nibi ti o ti gba iwe ẹri gẹgẹ bii oniṣegun oyinbo lọdun 1982 si 1987.
awon ọdọ :sadiq to je oludari  awon odo
NYSC: ìdí tí a fí gba Davido láàyè láti jade
Nítorí náà OLUWA, OLUWA àwọn ọmọ ogun ní, “Ẹ̀yin eniyan mi tí ń gbé Sioni, Ẹ má bẹ̀rù àwọn ará Asiria bí wọn bá fi ọ̀gọ lù yín, tabi tí wọn gbé ọ̀pá sókè si yín bí àwọn ará Ijipti ti ṣe si yín.
Wọn tẹsiwaju pe ọna eru ni Saraki fi gba ilẹ naa fun Baba rẹ lasiko to wa lori alefa nitori ọtọ ni nkan ti ijọba fẹ fi ilẹ naa ṣe.
Bó tilẹ̀ jẹ́ pé, gbogbo àwọn òṣìṣẹ́ to yẹ ki o mú ọ̀rọ̀ náà lójúùtú lo ti wà ni ẹnu iṣẹ́.
Wọn óo gbógun tì ọ́ ní gbogbo ọ̀nà pẹlu apata, asà ati àkẹtẹ̀ ogun.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù How to get your National Identification Number: Àwọn ọ̀nà tí o le gbà rí fọ́ọ̀mù ìforúkọsílẹ̀ fún NIN rẹ gbà àti àwọn ibùdó ìforúkọsílẹ̀ lágbáyé nìyí 16 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 22 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Oríṣun àwòrán, NIMC Ọrọ iforukọsilẹ fun nọmba idanimọ apapọ orilẹede Naijiria ti fi ọpọlọpọ sinu hilahilo, pẹlu bi ijsba apaps ti ṣe kede pe awọn nọmba ibanisọrọ ti ko ba ni asopọ pẹlu nọmba idanimọ ẹni to nii yoo di titi pa.
" Hospital Wedding: Oṣù kan péré ni Tash fi ṣe ìgbéyàwó pẹ̀lú Simon kó tó kú Èèyàn 11 kú, èèyàn 438 míràn tún kó COVID-19 ní Nàìjíríà l'Ọ́jọ́ Àbámẹ́ta Lizzy Anjọnrin fẹ̀si fáwọn agbọ́yì-sọ̀yí lórí ìgbéyàwó rẹ̀, Madam Sajẹ dasójú ilé iṣẹ́, àti àwọn ǹkan míràn tó ṣẹlẹ̀ lágbo tíátà lọ́sẹ̀ yìí Ọba Ogunwusi ni wọn kan nipa fun awọn lati se adinku ọdun naa, tii se ọdun pataki nilu Ile Ife.
(Àwọn eniyan Israẹli rìn láti Beeroti Benejaakani lọ sí Mosera, ibẹ̀ ni Aaroni kú sí, tí wọ́n sì sin ín sí.
Ṣugbọn OLUWA gbé ìjì kan dìde lójú omi òkun, afẹ́fẹ́ náà le tóbẹ́ẹ̀ tí ọkọ̀ ojú omi fẹ́rẹ̀ ya.
“Eleyii n jẹ ki okan wa ru soke si Ọlọrun, o n jẹ ki a le sin Ọlọrun, o jẹ ki a mọ Ọlọrun, o n fa wa sun mọ Olọrun, o n jẹ ki ọkan wa ṣipaya si awọn ohun tii ṣe ti Ọlọrun paapaa ni igba iporuuru ọkan”Ikọ Ẹgbẹ Akọrin Ijọ Eleto, ẹka ti Ipinlẹ Eko lapapọ (Lagos Diocese of Methodist Musical Society) tun ti ṣaṣeyọri ninu Ajọdun Orin Iyin ati Orin Imisi Ẹmi ti ọdun 2018 (2018 Festival of Hymns and Canticles), pẹlu awọn ẹgbẹ akọrin mejidinlogun ti wọn ṣoju awọn ile-ijọsin Methodist kaakiri Ipinlẹ Eko lọjọ isinmi yii ni Ile Ijọsin Eleto City Mission Circuit ni Surulere ni Ipinlẹ Eko.
Ọjọ Kẹrindinlọgbọn, Osu kẹfa ọdun 1941 ni won bi Ọlọwọ ti ilu Ọwọ to doloogbe gẹgẹ bi akọbi Sir Olateru Olagbegi (1910-1998).
Ọgbọ́n ati ìmọ̀ rẹ mú ọ ṣìnà,ò ń sọ ní ọkàn rẹ pé, ‘Èmi nìkan ní mo wà.
I came back and was arrested and imprisoned by Abacha.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: N kò fẹ́ kí ojú ti ọkọ mi, ni mo ṣe gbe oyún wá láti ìta - Abilékọ Wo ọ̀pọ̀ àsọtẹlẹ̀ àwọn òjíṣẹ́ Ọlọ́run tí kó ṣẹ́ lọ́dún 2020 APC àti PDP ń dìtẹ̀ láti yọ Seyi Makinde ní 2023, ẹ gbàdúra fun kó gúnlẹ̀ ayọ̀"" EFCC gba ọ̀pọ̀ owó àti dúkìá, ó tún fọwọ́ òfin mú afurasí 865 lọ́dún 2020 Ìwọ́de ńlá míì ń bọ̀ ní March, tí December 2021 yóò sì gbóná fáwọn ọ̀jẹ̀lú olóṣelú - Alfa sọ àsọtẹ́lẹ̀ Njẹ́ ẹ ti gbọ́ nípa àríyá oníhòhò àti ìbálòpọ̀ tó fẹ́ wáyé ní Kaduna lásìkò ọdún?"
Àwọn ọmọbinrin rẹ̀ bá fẹ́ àwọn ọmọ Kiṣi, àbúrò baba wọn.
A ti ṣe iwaasu fun wọn ti a si ti parọwa si wọn lati maa kirun.
Ṣugbọn oorun ti ń kun Peteru ati àwọn tí ó wà pẹlu rẹ̀.
Àkọlé àwòrán, Iléeṣẹ́ Bioraj, Emzor àti Peace Standard ni ìwádìí fihàn pé wọn jẹ́bi bí òògùn codeine ṣe tàn kálẹ̀ Àbọ̀ ìwádìí àjọ NAFDAC, tó ṣe lẹ́yìn fídíò ìṣẹ́ ìwádìí BBC tú àṣírí ìlòkulò òògùn nàá, fihàn pé lóòtọ́ ni iléeṣẹ́ Bioraj jẹ́bi Àì ṣàmójútó àwọn alágbàtà rẹ̀ Pé ọ̀nà tó n gbà kó àwọn òògùn rẹ̀ pamọ́ kò bójú mu Ìlànà tó fi n pèsè àwọn òògùn rẹ̀ kò dára rárá Àti pé òṣìṣẹ́ rẹ̀ kan lẹ̀dí àpò mọ́ ọ́kan tí wọ́n ti lé kúrò lẹ́nu iṣẹ́ láti maa ta èròjà codeine tí wọ́n jí kó ní iléeṣẹ́ nàá lọ́nà tí kò bófin mu.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Lekki Toll gate: Àwọn awakọ̀ Lekki sọ èrò wọn nípa ìrìnà ọ̀fẹ́ ní ibodè Lekki Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Lekki Toll gate: Àwọn awakọ̀ Lekki sọ èrò wọn nípa ìrìnà ọ̀fẹ́ ní ibodè Lekki 11 Agẹmo 2019 Àwọn awakọ̀ to n rin loju ọ̀na marosẹ Lekki si Ajah nilu Eko ti kan saara si gomina Babajide Sanwo-Olu lori bo se si ẹnu bode ọna naa silẹ ni Ọjọbọ.
 mùsùlùmí ni ọ ̀ pọ ̀ lọpọ ̀ àwọnm ará wolof .
Ṣugbọn ariyanjiyan bẹ silẹ, ti awọn sẹnẹtọ kan si dide si ara wọn.
''N ko tilẹ mọ ohun ọkunrin yii ṣe fun mi nigba naa, ṣugbọn ohun ti mo le ranti ni pe o fi ọwọ rẹ to dọti bọ oju ara mi.
Òun níí fi ọgbọ́n fún ọlọ́gbọ́ntíí sì í fi ìmọ̀ fún àwọn ọ̀mọ̀ràn.
Ní báyìí ó ti yẹ kó yẹ wá pé kò yẹ ká kò aya sókè nítorí ajakalẹ àrùn Coronavirus nítorí pé ọwọja àwọn àrùn tá mẹ́nubà lókè yìí gan lè ju ti Covid-19 lọ.
A kò fòfin de owó naira tó ti pẹ́ ní Naijiria -CBN Ẹ yé gba owó orí níbi ìdána ìyàwó mọ́, sísọmọbìnrin s'óko ẹrú ni- Daddy Freeze Ọwọ́ ọlọ́pàá ti tẹ ọkùnrin kan tó pa ọ̀rẹ́ rẹ̀ nítorí N40 ní Kano APC ní yóò jáwe olúbori ni Bayelsa ati Kogi- Tinubu Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí kan sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
 Omotayo Alasuadura – Ondo, Minisita abẹle fun ọrọ oṣiṣẹ ati igbanisiṣẹ( Labour), State mẹ́rìndínlógójì  ) Rauf Aregbesola – Osun, Minisita fun ọrọ abẹle(Interior) mẹ́tàdínlógójì  ) Sunday Dare – Oyo, Minisita fun ọrọ ọdọ ati ere idaraya(Youth and Sports) méjídínlógójì ) Dame Pauline Tallen – Plateau,  Minisita fun ọrọ awọn obinrin(Women Affairs) mọ́kàndínlógójì ) Rotimi Amaechi – Rivers, Minisita fun igbokegbodo ọkọ(Transportation) ogójì ) Mohammed Maigari Dangyadi – Sokoto, Minisita fun ọrọ ọlọpaa(Police Affairs) mọ́kànlélógójì) Engr.
Ṣugbọn Jesu ń wò yíká láti rí ẹni tí ó fọwọ́ kan aṣọ rẹ̀.
Wo ohun tí Fashola rí níbi ìṣẹ̀lẹ̀ Lekki Tollgate tó ń fa ariwo lórí ayélujara Igbagbọ awọn eeyan dopin ninu Desmond Elliot nitori ọrọ to sọ Jẹjẹ lawọn eeyan joko si oju opo ayelujara ki Desmond Elliot aṣoju ile aṣofin ipinlẹ Eko to fa okete niru.
Minisita to n mojuto oro abele, ogagun Abdulrahman Dambazau lo se ikede ohun fun ijọba apapo.
Mílíọ́nù kan Naira ni wọ́n fún wa láti pa Uwaila sínú ṣọ́ọ́ṣì ní Benin - Afurasí Ìrọ̀rùn dé!
O tun sọ pe ajọ ajafẹtọ oun ti kọ iwe ẹhonu bayii.
Aribisala tẹnu mọ ọ pe awọn olori ijọ miiran kan n lo ipo wọn lati ṣe agbere lasan ni.
O si jẹ ọkan pataki lara ofin to wa ninu iwe ofin ajọ iṣọkan agbaye, ṣugbọn iha ati ilana ti orilẹ-ede kọọkan n ṣamulo yatọ lori orilẹ-ede ti ọmọ naa yoo maa jẹ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, APC: òfin NYSC ti APC fi mú mi ni wọ́n kò lò fi mú Ajimọbi tí a kò jọ sìnrú ìlú Lara awọn eekan to wa kirun pẹlu aarẹ Buhari lana ni Abdulaziz Yari to jẹ gomina ipinlẹ Zamfara tẹlẹ atawon minista mii.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Àlàyé rèé lórí bo ṣe le è dá Emèrè mọ̀ tàbí dara pọ̀ mọ́ ẹgbẹ́ wọn Àṣírí ńlá tó ń bẹ láàrín Alaafin àtàwọn onílù rẹ̀ rèé Wo oríṣìí ìlù Yorùbá, ìwúlò wọn àti ba ṣe ń lò wọ́n Oyedepo àti ìjọba ń tahùn síra lórí bí ìjọba ṣe ń gba àkóso àwọn ilé ìjọsìn EFCC tún gbé Mompha lórí ẹ̀ṣùn lílu jìbìtì lórí ayélujára Ọlọ́pàá méjì wọ gàù lóri bí afurasí apanìyàn l‘Akinyele ṣe sá lọ Iroyin ti a gbọ sọ pe, ijamba ọkada kan to waye lọjọ Aiku lo sọ Kumbalee di ero ọrun.
Awọn igbesẹ yii nii o ni lati gbe lati fi orukọ silẹ: Lọ si oju opo yii: https://recruitment.
Lati ọwọ Ann Hardman ni Radcliffe, Manchester Iroyin BBC Ikọ eleto ilera Awọn ijọba orilẹ-ede agbaye n ṣatunṣe si ofin wiwọ iboju loorekoore ṣugbọn ajọ WHO gba imọran lati maa wọ iboju nigba gbogbo, yala o ni ami ara gbigbona tabi ikọ tabi pe o n ṣe itọju fun ẹni to ni coronavirus tabi afurasi to ni coronavirus O ṣeeṣe ki iboju daabo bo ẹ lọwọ ajakalẹ arun yii, ti o ba loo daadaa pẹlu awọn igbesẹ miran bii fifọ ọwọ rẹ nigbagbogbo ki o si gbe ile lai jade sita pupọ Idi oriṣii ni awọn ijọba kọọkan ṣe n yi ofin lilo iboju wọn pada bii pe ki iboju ma lọ tan ni agbegbe wọn de ibi pe awọn oṣiṣẹ eleto ilera ko ni ri lo mọ.
"Àṣírí ilé ìmúni nígbèkùn míràn tú síta ni Katsina ""A ti ra rọba idaabobo ọgbọn miliọnu."
Saulu sọ fún un pé, “Kí OLUWA kí ó bukun ọ, Samuẹli, mo ti pa òfin OLUWA mọ́.
Awon osise ajo eleto idibo orile-ede Sierra Leone ati awon ohun elo idibo ti wa kaakiri awon ipago idibo.
Kò sí ìfoyà, mò ṣetán láti sàn jù ₦30,000 fáwọn òṣìṣẹ́ l‘Eko - Sanwo-Olu 'Kìí ṣe ojúṣe mi láti sọ bóyá òótọ́ ni Buhari fẹ́ gbéyàwó tàbí irọ́' Ta ni Mamman Daura?
'Èkúté jẹ oògùn olóró níbi tí wọn fi pamọ sí ní àgọ ọlọpàá' El-Rufai sọ̀kò ọ̀rọ̀ sí igbákejì ààrẹ, Yemi Osinbajo, Ó ní òun ni alága àwọn èèyàn kúkurú Ìgbéyàwó èmi àti Aláàfin kò pé, ṣùgbọ́n.
Ni bayii, adajo so pe, osu
Ọmọ Naijiria hú ẹ̀sùn ìfipá bánilòpọ̀ tí wọ́n fi kan Fatoyinbo síta lẹ́yìn tó lọ sí Shiloh Ìwọ́de ńlá yóò bẹ́rẹ̀ lọ́jọ́ táwọn gómìnà bá yá ₦17trn nínú owó ìfẹ̀yìntì òṣìṣẹ́ - NLC Kunlere sọ pe ọpa aṣẹ ni ami aṣẹ ninu ile igbimọ aṣofin.
Aare tun so pe “Ẹ gbọdọ lee se ayipada rere lori eto ijoba, ki eto oro aje si tele.
, nitori pe awon gbọ pe awon kan n gbero lati yi ibo ti awon eniyan di.
Ninu oṣu yi lawọn larubawa maa n fọnka lori lẹ lati wa omi ati ounjẹ fun nnkan ọsin wọn.
Gomina Simon Lalong tẹgbẹ oṣelu APC ati Jeremiah Useni ni yoo jọ ja du ipo naa.
NGA VS GUI: Super Eagles fi Guinea ṣe ẹṣin lọ sí ìpele 'Round of 16' Ola Aina, àwọn akẹgbẹ́ rẹ̀ bá BBC sọ̀rọ̀ lórí owó àjẹmọ́nú wọn Lori ohun to fa a ti Super Eagles ko fi bẹẹ ṣe daada lati igba ti idije naa ti bẹrẹ, Musa ni eyi ko ṣẹyin bi oorun to n mu ni ilu Alexandria ṣe ti l'agbara ju, ti ko si tii mọ awọn lara.
Dafidi kọ́ ọpọlọpọ ilé fún ara rẹ̀ ní ìlú Dafidi.
Nígbà tí wọ́n dé Jerusalẹmu wọ́n dúró sí ibi ọ̀nà tí àwọn tí wọn ń hun aṣọ tí ń ṣiṣẹ́, lẹ́bàá kòtò omi tí ń ṣàn wá láti adágún omi tí ó wà ninu ìlú lápá òkè.
Sibẹsibẹ inú OLUWA kò rọ̀,bẹ́ẹ̀ ni kò dáwọ́ ìjà rẹ̀ dúró.
Wọ́n fi ẹ̀sùn kan wọ́n pé wọ́n mu ọ̀daran jáde pé awọ́n fẹ́ lọ ṣe ìwádìí, sùgbọ́n kàkà bẹ́ẹ̀ wọ́n mú ọdaran náà lọ si ilé ìfówópamọ́ Zenith lopópónà Unity nílùú ilorin lati lọ gba owó to lé ni mílíọ́nù kan Náírà.
Ki o to gba iwe iyansise, ogbeni Bala ti figba kan je asoju sile England ri.
Ṣugbọn ṣa, Ọga Agba Ọlọpaa lorilẹede Naijiria, Muhammed Adamu paapa ti fi aṣẹ tuntun sita nipa ofin konile o-gbele kaakiri orilẹede Naijiria.
ikede naa ni kete ti won se ifilole, ti won si bura fun awon minisita ohun
Nítorí náà, OLUWA bínú sí Jerusalẹmu ati Juda; ó sì lé wọn kúrò níwájú rẹ̀.
 iye owó rẹ ̀ lójú pálí jẹ ́ bíi 3.
Nítorí ẹnikẹ́ni tí ó bá fun yín ní omi mu nítorí tèmi, nítorí pé ẹ jẹ́ ti Kristi, mo fẹ́ kí ẹ mọ̀ dájúdájú pé yóo rí èrè rẹ̀ gbà.
Wọ́n fa aṣọ wọn ya láti fi ìbànújẹ́ wọn hàn, olukuluku wọn bá di ẹrù rẹ̀ ru kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ rẹ̀, wọ́n pada lọ sí ààrin ìlú.
Mo kìlọ̀ fun yín, ẹ̀yin ọmọbinrin Jerusalẹmu,ní orúkọ egbin, ati ti àgbọ̀nrín pé,ẹ kò gbọdọ̀ jí ìfẹ́ títí yóo fi wù ú láti jí.
Awon ti o tun kopa ninu ipade ohun ni, alaga ipolongo fun ipo gomina nipinle Osun, ti o fi mo gomina ipinle Kano, Abdullahi Ganduje.
Amọ, Makinde sọ pe iwadii ati ayẹwo ti ipinlẹ Oyo ṣe lori bi coronavirus ṣe n ran nipinlẹ naa fihan pe, ko buru ju ti at'ẹyin wa lọ.
Dafidi jíròrò pẹlu àwọn ọ̀gágun ẹgbẹẹgbẹrun ọmọ ogun ati àwọn ti ọgọọgọrun-un, ati gbogbo àwọn olórí.
Awọn orilẹede ti ọrọ kan naa ni orilẹede China, Italy, Iran, South Korea, Spain, Japan, Faranse, Germany, Amẹrika, Norway, ilẹ Gẹẹsi, Netherlands ati orilẹede Switzerland.
“Mú ọ̀rá àgbò náà ati ìrù rẹ̀ tòun tọ̀rá rẹ̀, ati gbogbo ọ̀rá tí ó bo ìfun ati èyí tí ó bo ẹ̀dọ̀; ati kíndìnrín rẹ̀ mejeeji, pẹlu ọ̀rá tí ó bò wọ́n ati itan rẹ̀ ọ̀tún, nítorí àgbò ìyàsímímọ́ ni.
Ọlọrun Yóo Jẹ Àwọn Ọ̀tá Rẹ̀ níyà.
Lasiko to n fidi isẹlẹ naa mulẹ fun awọn akọroyin nilu Eko, Jerry Oche, tii se ọga agba fun ẹka to n risi ibasepọ pẹlu ara ilu, salaye pe ọkọ oju irin to n lọ lati agbegbe Ijoko si Iddo lo tẹ alagbe naa pa lẹba tesan reluwe to wa ni Mushin.
gbogbo omo orile ede Naijiria yoo se  lee
Nureni Adeniran ni lọwọ bayi, awọn eto miran wa nilẹ fawọn ọmọ ti ko si ni ile ẹkọ ti ipinlẹ Oyo ni lọkan lati ṣe.
awon osise naa, ni eyi ti o ti ye ki won gbe lo siwaju ile igbimo asofin.
Apapo iko méjídínlọ́gbọ̀n ni kikun:DR Congo Squad;Joël Kiassumbua (FC Lugano/ Suisse), Anthony Mossi Ngawi (Chiasso / Suisse), Auguy Kalambay (SM Sanga Balende/ RD Congo), Djo Issama Mpeko (TP Mazembe/RD Congo), Wilfried Moke (Koniaspor/ Turquie), Kevin Mandeko (TPM Mazembe/ RD Congo), Chancel Mbemba Mangulu (New Castel/ Grande Bretagne), Christian Luyindama Nekadio (Standard de Liège/ Belgique), Yannick Bangala Litombo (AS V.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Àwọn ọlọ́pàá, ọdẹ asọ́lé dènà adígunjalè láti fọ́ báǹkì l'Ọsun Ìgbẹ́ yiyá síta gbángba n fún Nàìjíríà lórúkọ tí kò dá Ǹjẹ́ ó seése kí Buhari se àtúnse ilé-ìwé 10,000 lọ́dọọdún?
pabo ni eyi ja si, nitori pe awon omo egbe Gnassingbé,lo poju nile igbimo
Ninu atẹjade ti ẹgbẹ ọhun fi sita ni wọn ti fikun pe awọn ọlọpaa tilẹ n ti wọn mọle ni aini idi.
Kí gbogbo àwọn tí ń wá ọ máa yọ̀ nítorí rẹ,kí inú wọn sì máa dùn,kí àwọn tí ó fẹ́ràn ìgbàlà rẹ máa wí nígbà gbogbo pé,“Ọlọrun tóbi!
Àwọn Asòfin Naijiria yarí lórí ètò ìsúná 2019 Buhari nìkan kọ́ ni aṣíwájú táwọn èèyàn dẹ́yẹsí Ètò àbò, ètò ẹ̀kọ́, gbégbá orókè nínú àbádòfin 2019 Àwọn olùgbé Fiditi pé fún ìrànlọ́wọ́ lórí àwọn òrùlé tí atẹ́gùn ojó ṣí lọ Lara ojuṣe ti iwe ofin la kalẹ fun ẹka aṣofin ni ki wọn sagbatẹru awọn ofin eleyi ti yoo mu idagbasoke ati alafia ba awọn ara ilu.
Bí o bá dákẹ́ ní irú àkókò yìí, ìrànlọ́wọ́, ati ìgbàlà yóo ti ibòmíràn wá fún àwọn Juu, ṣugbọn a óo pa ìwọ ati àwọn ará ilé baba rẹ run.
Kò ní sí ẹni tí yóo ṣẹ́kù nítorí pé òun óo mú kí ibi dé bá àwọn ará Anatoti, nígbà tí àkókò bá tó tí òun óo jẹ wọ́n níyà.
Ọdún 2012 ni awọn akẹ́ẹ̀kọ́ ilé ìwé ìmọ̀ òfin tó wà láti ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́ ti gba N100,000 kẹ́hìn gẹ́gẹ́ bí owó ìrànwọ́.
oojọ  lojo kan ni igba marunun lose,tabi
Awọn olubi ẹda naa si tun da ẹmi awọn obinrin marun un mii legbodo ni ijọba ibilẹ kan naa niluu Ibadan, laarin oṣu kan ti Barakat di oloogbe.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Àṣà wa l'Ekiti ló dára jú lórílẹ̀èdè Nàìjíríà' Oṣu Keji ọdun 2017 ni adajọ Oluremi Oguntoyinbo ni ki wọn gba oniduro Egbegbe pẹlu miliọnu marun un naira, ṣugbọn o ni ko wa lọgba lọgba ẹwọn titi ti yoo fi ri owo itanran ọhun.
3 trillion ni CBN gbé jáde fún ọdun 2020 21 Bélú 2019 Oríṣun àwòrán, OTHERS Àkọlé àwòrán, Ilé ìgbìmọ̀ asòfin lé àwọn àkòròyìn jáde lásìkò ti asojú bánkì àpàpọ̀ ń sọfún ilé asòfìn nípà iye owó ètò ìsúná wọn.
 Àwọn irúfẹ ́ méjì yíì yàtọ ̀ nípa iye àwọn ohun ayí àwọ ̀ padà tí kò dára , àwọn bálabála àwọn ara , pẹ ̀ lú tí o ní márùn tàbí díẹ ̀ àti multibacillary tí o ní ju márùn .
Ó ti wá di ẹni àmúsìn.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Osun Supreme: Àwọn èèyàn Ọṣun rọ Oyetọla láti jẹ́ kí àsìkò rẹ̀ tú aráàlú lára Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
"Bí mo ṣe ń dàgbà ni ǹkan ọmọkùnrin mi ń tóbi síi àmọ́ obìnrin ni mi' ""Ọkùnrin kọ́ ló ra jeep fún Iyabo Ojo, òógùn ojú mi ni mo fi rà á fun"" Àwọn ọ̀dọ́ l‘Eko yarí, ìwọ́de tó tako ọlọ́pàá SARS gbòde Ohun méjì yìí ní Buhari gbọ́dọ̀ ṣe ká tó wọlé padà - ASUU Adìyẹ́ jẹ̀fun ara wọn!"
Nasreen ni ko si igbeyawo laarin oun ati Muhammed niwọn igba ti ko ti lọwọ ofin ninu, saaju si ni aawọ ti wa laarin tọkọtaya naa, eyi to mu ki wọn maa gbe lọtọọtọ lati ọdun 2016.
Ẹ yé irọ́ pa, mí o fún Super Eagles ní ẹbùn owó kánkan -Sanwo Olu Gẹgẹ bi Enelamah ṣe sọ ọ, o jẹ igbesẹ ti yoo ko ipa pataki ti yoo si ṣe atunto nilẹ Afirika fun odidi ọgọrun ọdun si isisiyii tabi ko tilẹ ju bẹẹ lọ.
Aare Muhammadu Buhari ti se idaaro oludari ile-ise  to n mojuto idagbasoke ekun Niger Delta ana, Pastor Power Aginighan,  ti o ku ninu ijamba ọkọ .
Ọ̀tá tí wọn kò kanlẹ̀ ṣílẹ̀kùn fún gan-an, díẹ̀ díẹ̀ ni imú ẹlẹ́dẹ̀ nwọ’gbà.
Oun lo n mojuto idari awọn ọmọ ogun lori eto aabo ẹmi ati dukia awọn eniyan Ethiopia.
Ìkébé mi tóbí ju ohun tí mo lè dọwọ́ bò lọ, n kìí fí ṣakọ- Nkechi Blessing Ẹ̀yin òṣìṣẹ́, ẹ má ṣáì lọ síbi iṣẹ́ lọ́jọ́ Ajé, olórí àwọn òṣìṣẹ́ ní Nàìjíríà tako ìyanṣẹ́lódì Kii si ṣe awọn ọlọmọge nikan laa n wi, awọn to ti ṣe igbeyawo to sanpọn ati awọn mii ti ko ri ọkọ gan ko gbẹyin ninu awọn to n wa ọkọ lori ayelujara.
”Alukoro fun ile-ise olopaa, Moshood so pe” Kọmiṣọna ọlọpàá tuntun  kan ni yoo si  maa dari ajọ FSARS naa .
 owu tita lo je 40 % gdp ati bi 80 % ipawo oja okere iseoba .
Àwọn ọmọ Adonikamu jẹ́ ọtalelẹgbẹta ati meje (667).
Ìròyìn Yàjóyàjó -Gómìnà ìpínlẹ̀ Edo Godwin Obaseki tí darapọ̀ mọ́ ẹgbẹ́ òṣèlú PDP Ohun tí a rí nílé Ajimobi rèé lẹ́yìn ìròyìn òfégè pé ó jáde láyé Ìjọba Amẹrika fi ojú àwọn ọmọ Yahoo mẹ́fà léde, wọ́n gbẹ́sẹ̀ lé dúkìá wọn Kí ló mú ọlọ́pàá wú òkú géńdé nínú sàréè l'Ondo Awọn eeyan jankanjankan lo wa nibi isinku naa, ninu wọn ni Gomina Rotimi Akeredolu ipinlẹ ONdo.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Nigeria Police: Ọ̀gá àgbà dín wákàtí iṣẹ́ ọlọ́pàá kù 'torí wàhálà 26 Ìgbé 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Ọga agba ileeṣẹ ọlọpaa Naijiria, Mohammed Adamu ti paṣẹ pe ki adinku de ba iye wakati ti awọn ọlọpaa fi n ṣiṣẹ l'ojoojumọ.
Zainab Habib:Zainab Habib tí ilẹ̀ Saudi Arabia pa irọ́ mọ́ pé o gbé cocaine tí gba sabuké NYSC!
Ní òjijì ni ẹnìkan bá dìde láàrin wọn.
Fun iwuri gbogbo awọn to gbọ Hridoy Sarkar ṣe aṣeyọri ninu idanwo naa si idunnu iya rẹ.
Ayé á bínú olówó gbèrò sọ́ ọ di tálákà
Bẹẹ naa lo rọ awọn obi lati kọ awọn ọmọ wọn lati kekere, lati ma ṣora ṣe lẹgbẹ awọn okunrin ti wọn ko ba mọ daadaa.
Nítorí ìwọ ni o mú kí àtùpà mi máa tàn,OLUWA, Ọlọrun mi ni ó tan ìmọ́lẹ̀ sí òkùnkùn mi.
Eto isin itusilẹ ijọ MFM Eto itusilẹ yii ni ijọ Mountain of fire and miracles, MFM lero ati gbe ṣe ni opin ọsẹ yii tẹlẹ.
Oríṣun àwòrán, @Govsia Àkọlé àwòrán, Gomina ipinlẹ Ogun, Ibikunle Amosun, ati ti Imo, Rochas Okorocha, naa ti pe awọn yoo ṣiṣẹ tako ẹgbẹ́ APC.
NCDC lo kede bẹẹ loju opo Twitter rẹ loru ọjọ Ẹti, ipinlẹ Eko si ni iye eeyan to pọ ju to ṣẹṣẹ ni arun ọhun ti wa.
Fi mi silẹ, ko lọ maa ṣaye rẹ.
"A gbadura ki ara rẹ ya kia kia""."
Akeredolu to jẹ oludije labẹ ẹgbẹ oṣelu APC la oludije ẹgbẹ oṣelu PDP, Eyitayo Jegede to sun mọ ọ julọ ninu eto idibo naa mọlẹ.
Ṣugbọn ti Mose, iranṣẹ mi yàtọ̀.
Ṣaaju, ileesẹ Ọlọpaa ipinlẹ Ogun ti kede pe ọwọ sinkun oun ti ba afurasi apaayan, ọmọ ẹgbẹ okunkun ati amu oogun oloro ti wọn n wa.
O ni gbigba ẹkọ lori oogun ibilẹ yoo dẹkun ọpọ awọn eeyan ti ko yẹ ki wọn wa nibi iṣegun ibilẹ ti wọn wa nibẹ lọwọ yii.
Ile to wo yii ti pe ọdun mẹẹdọgbọn, o wa ni nọmba 95, agbegbe Cemetry Street, lopopona Eko si Abeokuta ni Ebute Metta.
dabi pe ki wọn pese igbe aye irọrun fun awọn ara ilu.
Ọ̀pọ̀ àwọn ọ̀rẹ́ Ifeanyi ló sàlàyé pé kìí ṣe ìgbà àkọ́kọ́ rèé ti Abdullahi ti maa n yìnbọn ni gbogbo ìgbà ti abẹnugan ba ti n kọjá.
 rẹ ̀ nínú ìmọ ̀ biological chemistry lati california institute of technology .
PFN: Fatoyinbo kọ̀ láti yọjú ni ìwádìí wa kò ṣe parí Iṣẹ́ bọ́ lọ́wọ́ ọlọpàá mẹ́rìn to pa afurasí, wọ́n tún dèrò ẹ̀wọ̀n Fayemi fojú Alufa to fipa bá ọmọde lòpọ̀ síta l'Ekiti Nǹkan kò ṣẹnuure fáwọn obìnrin nínú ìgbìmọ̀ ìṣèjọba Buhari Àwọn ọmọ Yorùbá wo ni mínísítà ní ìjọba Buhari?
Ìjọba Ghana ṣí iléeṣẹ́ àwọn ọmọ Nàìjíríà padà.
Bí Josaya ti yí ojú pada, ó rí àwọn ibojì kan lórí òkè.
Stefanu yìí jẹ́ onigbagbọ tọkàntọkàn, tí ó kún fún Ẹ̀mí Mímọ́.
Bi ẹ ko ba ni gbagbe iroyin bọ̀ sita lowurọ Ọjọru ni kabiyesi, Ọọni ti Ife, Ọba Enitan Adeyeye Ogunwusi kede pe iyawo oun, olori Naomi ti bimọ.
Mẹfa ninu àwọn arakunrin bá mi lọ.
ezra weston loomis pound ( 30 october 1885 - 1 november 1972 ) je akoewi ati alayewo ara amerika okere , ati eni pataki ni ibere irinkankan aseodeoni ninu ewikiko .
Presidency: Buhari kò leè ṣàtìlẹyìn fún olùdíje Amosun l'Ogun
Ninu atẹjade to fi si oju opo rẹ lori ayelujara Twitter ati Facebook,Osinbajo ni oun ṣetan lati ofin aṣemaṣebawi ti ofin faye gba oun silẹ lori ọrọ naa.
orilẹ-ede yii lati tubọ maa gbadura fun awọn olori wọn lati le ṣe
Buhari ti sapejuwe aare ana fun orile ede Najiria Olusegun obasanjo gege bi eni
Nítorí ikú ti dé ojú fèrèsé wa,ó ti wọ ààfin wa.
" Eyi ni esi ti Agbẹnusọ fun Sọun Ogbomọṣọ, Ọgbẹni Toyin Ajamu lasiko to n ba BBC Yoruba sọrọ lori rogbodiyan to wa ye ni aafin naa lọjọ Aiku.
Hesironi bí Ramu, Ramu bí Aminadabu; 
Awọn kan figba kan n ri Satia lẹyin KWAM 1 agba ọjẹ onifuju n ni lọpọ ọdun sẹyin.
Ẹ wa nkan fidi le lati wo ẹkunrẹrẹ fidio naa, amọ o seese ki ara ta yin gẹgẹ bii abiamọ abi akẹkọ.
’ rèé Ìgbín ní èmi àti ìyá mi máa ń he kiri, ká tó lee jẹun - Lizzy Anjọrin Akọsile ṣapejuwe awọn eeyan yii pe ọrọ wọn yoo ye ara wọn fun itẹsiwaju nitori pe awọn ọdọ ti ko tii pé ọmọ ogoji ọdun wa ninu wọn laiyọ obinrin silẹ.
Àwọn èèrò ìwòran ní kóótù gbalé ẹjọ́ dọ́gbà ẹ̀wọ́n l'Ọṣun Wo àwọn ọmọbìnrin tó mu ìtọ̀ ara wọn nítorí òùngbẹ aṣálẹ̀ Sahara 'Dokita ilé ìwòsàn ló gba ẹsẹ̀ lọ́wọ́ mi' Ǹjẹ́ òògùn vitamin C lè pa coronavirus?
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Shehu Sani: Irandiran àwọn ọmọ Naijiria ni yóò má a san gbèsè owo tí Buhari bá yá 29 Bélú 2019 Oríṣun àwòrán, BUHARI SALAD Àkọlé àwòrán, Ogún bílíọ́nù Naira ni Naijiria jẹ sílẹ̀, àmọ́ tí o si fẹ́ yá ọgbọ̀n miliọnu dọla míràn láti se àwọn isẹ́ àkànse ní Naijiria.
Jesu bá dá a lóhùn pé, “Lónìí yìí ni ìgbàlà wọ inú ilé yìí, nítorí ọmọ Abrahamu ni Sakiu náà.
Nígbà tí wọ́n tú Àgọ́ Àjọ palẹ̀, àwọn ọmọ Geriṣoni ati àwọn ọmọ Merari tí ó ru Àgọ́ Àjọ náà ṣí tẹ̀lé àwọn tí wọ́n wà lábẹ́ ọ̀págun Juda.
Eyi ni ero ọkan ọpọ ọmọ Naijiria loju opo Twitter lori iwa idojule ti awọn ọmọ South Afrika n hu si awọn ọmọ Naijiria nilẹ wọn.
Nígbà tí mo wí fún un kí ó fún wa ní ìmọ̀ọ̀ràn ọ̀nà tí a lè gbà ó wí fún wa wí pé ìmọ̀ràn tí òun lè fún wa ni wí pé kí á jókòó sí ọ̀dọ̀ òun kí á máa ṣiṣẹ́ kí á sì máa jẹun láraiṣẹ́ wa.
Àkọlé àwòrán, E ko le wonu ijo wa ni COZA Abuja Ìjọ Satani dá MI lóhùn lórí ọ̀rọ̀ Fatoyinbo Ò ti pé ọdún 27 tí Shah Rukh Khan ti ń se fíìmù India Buhari fi àmì ẹ̀yẹ dá olóògbé Adadevoh tó dènà Ebola l'ọ́lá Modele Fatoyinbo to jẹ iyawo Pasitọ Biodun Fatoyinbo ti wọn fẹsun kan lori ifipabanilopo ti sọrọ.
Nígbà tí gbogbo àwọn tí wọ́n ń gbé ilé ìṣọ́ tí ó wà ní Ṣekemu gbọ́, wọ́n sá lọ sí ibi ààbò tí ó wà ní ilé Eli-beriti.
Obaseki: Ilé ẹjọ́ gíga àpapọ̀ fa ìwé ẹjọ́ tí wọ́n pè tako ìdíje Obaseki lẹ́gbẹ́ PDP Oríṣun àwòrán, other Ile ẹjọ giga apapọ ilẹẹwa to wa ni ilu Portharcourt ti fa iwe ẹjọ ti wọn pe tako iduro gomina Godwin Obaseki gẹgẹ bi oludije ni idibo abẹle fun ipo gomina lẹgbẹ oṣelu PDP ni ipinlẹ Edo.
Àwọn mẹ́fà lára àwọn ẹgbẹ́ náà tí ó ti gba òmìnira báyìí ṣe ìtàkùrọ̀sọ àgbáyé àkọ́kọ́ ní ìlú Ghana ní àsìkò àpérò FIFA: Atnaf Berhane, Befeqadu Hailu Techane, Zelalem Kibret, Natnael Feleke Aberra, àti Abel Wabella náà wá sí àpérò.
Gen Joe Komolafe ti kede pe awọn to ti forukọ silẹ fun eṣọ naa pe wọn yoo bẹrẹ igbaradi lọjọ Aiku ọjọ kẹtadinlọgbọn oṣu kẹsan an ọdun 2020.
Lojo Ru ni isele buruku yii sele nile iwe girama Marjory Stoneman Douglas High School to je nkan bii irin wakati kan si Miami ni nkan bii aago meji osan asiko won.
Mo kọ̀ láti yí ọ̀rọ̀ mi padà lórí ètò ẹ̀kọ́ ọ̀fẹ́ - Gómìnà Dapo Abiọdun Ilẹ ẹjọ fagilé ìbò ọmọ ẹgbẹ́ APC nípinlẹ̀ Ogun pè kí àtúndì ìbò wà Ronaldo, Messi ẹ yàgò lọnà fagbábọ́ọ̀lù Nàìjíríà tó n gbowò julọ!
Èmi ni mo yàn yín, tí mo ran yín pé kí ẹ lọ máa so èso tí kò ní bàjẹ́, kí Baba lè fun yín ní ohunkohun tí ẹ bá bèèrè ní orúkọ mi.
 Oluwo ni ""Awa ti a ni ẹri ọkan yoo wa awọn asa yii jade nitori a ko lee pẹlu ọbọ jẹ oko, lara awọn asa kan gboogi ti ọjọ ti lọ lori wọn ni ila kikọ, asa Yoruba si gbọdọ maa ba igba mu."
Ọlọ́pàá DSS fi pańpẹ́ ọba mú Ọmọyele Sowore Òṣèré tíátà, Kemi Afolabi fi ohùn ìdúpẹ́ ránṣẹ́ láti Meccah fún àdúrà ọmọ Nàíjíríà A kò ní fi adé wa sílẹ̀ nítorí Olubadan - Àwọn Ọba 27 Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Imperial Majesty ni Olubadadan, Royal Majesty làwa, òfin sì tẹ̀lé e - Ọtun Olubadan Awọn alaṣẹ fasiti AAUA naa ti fesi si eyi pe lootọ iwadii ti n lọ lọwọ lori ẹsun naa.
Owó ìfẹ̀yìntì àwọn Gómìnà ní ìpínlẹ̀ Zamfara dì àlọrámirámi Àṣírí tú!
ti Kabiyesi, ti wọn tun jẹ alaga ayẹyẹ naa n kan saara si akitiyan awọn
O tesiwaju pe  “iwadii yii fihan pe orilẹ ede  Naijiria maa n fi orilẹ ede  wọn  yangan, pelu  awọn  orisirisi asa ati ise to gbounjẹ fẹgbe gbawo bọ, ati pe wọn  je alakinkanju eniyan to nigbagbo ninu isọkan orilẹ ede  yii.
O fi ọrọ yii sita lẹyin ti oju opo Twitter gbọn ọmọ rẹ agba lọkunrin kuro lori opo wọn nitori pe o ṣe alabapin fidio ti Dokita Stella ti sọ pe ki awọn eeyan ma lo Hydroxychloroquine (HCQ).
Davido: Àpètàn orukọ̀ ọmọ tuntun náà ní David Adedeji Ifeanyi Adeleke
Buhari lo kede bẹẹ nigba to n bawọn ọmọ Naijiria sọrọ laarọ ọjọ kinni, oṣu Kẹwaa, ọdun 2020, fun ajọyọ ọgọta ọdun ti Naijiria gba ominira lọwọ oyinbo alawọ funfun.
Ó ya Beseri sọ́tọ̀ fún ẹ̀yà Reubẹni ninu aṣálẹ̀ láàrin ilẹ̀ tí ó tẹ́jú.
O ti jẹ́ kí n rí ọpọlọpọ ìpọ́njú ńlá,ṣugbọn óo tún mú ìgbé ayé mi pada bọ̀ sípò;óo tún ti gbé mi dìde láti inú isà òkú.
Ninu ọrọ atẹjiṣẹ ti agbẹnusọ Oshiomole Simon Egbegbulem fi ranṣẹ si akọroyin wa, o ni awọn ti kọwe kotẹmilọrun lati tako idajọ naa.
Ati lati gbe awọn agbabọọlu obinrin ni England de ipo pataki ninu iṣẹ wọn.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Àwọn adarí APC pín sí méjì lórí ìdìbò abẹ́lé l'Eko Wo àwọn tí yóò díje fún ipò gómìnà lábẹ́ ẹgbẹ́ PDP ní 2019 Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Mí ò ya wèrè, mí ò burú, ọ̀nà àtijẹ là ń wá' Ọgbẹni Kadiri sọ pe eyi nigba akọkọ ti irufẹ iṣẹlẹ yii yoo ṣẹlẹ s'oun lati igba ti oun ti n ṣe ọsin maalu fun ọdun marundinlogoji.
" ni april 2009 , korea ariwa tun ofin igbsgbepo re se lati tokasi jong-il bi "" "" olori gigajulo "" "" ."
júpítérì ni plánẹ ̀ tì karun lati odo orun ati planeti totobijulo ninu sistemu orun .
Kò gbọdọ̀ sí ọlọrun àjèjì kan kan láàrin yín;ẹ kò gbọdọ̀ foríbalẹ̀ fún oriṣa-koriṣa kan.
Saulu bá bèèrè lọ́wọ́ Ọlọrun pé, “Ṣé kí n lọ kọlu àwọn ará Filistia?
Ojo kejila, oṣu kẹsan an si ọjọ kẹrinla, oṣu ni wọn fi jọ n ja ijajangbara naa.
Ninu ere Ti Oluwa Ni Ile ni irawọ Baba Wande ti yọ to si ti n tan lati igba naa pẹlu awọn awada a-wo-ma-le-e-lọ rẹ.
Mo ṣebí ẹ̀yin sàn ju àwọn ẹyẹ lọ!
Nígbà yìí ni Isaaki kò tó ṣọ̀fọ̀ ìyá rẹ̀ mọ́.
Bákan náà ni, iṣẹ́ rere a máa hàn sí gbogbo eniyan.
Ọ̀rọ̀ ẹnu rẹ̀ dùn, àfi bí oyin,ó wuni lọpọlọpọ.
Àtẹ̀jáde kan fi yéni pé, ó kéré tàn àgọ́ ọlọ́pàá mọ́kàndílọ́gbọ̀n ní wọ́n sùn níná, ti àwọn ibùdó ọlọ́pàá kéékèké mẹ́tàdínlógún sì lọ síi pẹ̀lú.
Iṣẹ pọ lọrun ikọ ọlọpa FSARS, lati koju iwa idigunjale, ijinigbe, jiji ẹran ọsin gbe atawọn iwa ipa gbogbo Ko si ẹni to ran awọn ọlọpa ikọ naa lati maa da ọkọ duro tabi ṣe ayẹwo ọkọ Gẹgẹ bii ọga ọlọpa naa tun ṣe tẹẹ si oju ikanni Twitter, o ni ''ko si ilana iṣẹ awọn ọlọpa ikọ FSARS to fun wọn lagbara tabi aṣẹ lati mu alaiṣẹ''.
Fọ́ọ̀mù ìgbanisíṣẹ́ ikọ̀ Amotekun ti jáde - Ìjọba ìpínlẹ̀ Ondo Wo àwọn ohun tó yẹ kí o mọ̀ nípa Pierre Nkurunziza, ààrẹ orílẹ̀-èdè Burundi tó dolóògbé Àwọn 'ẹ̀bùn' tí ikú George Floyd fún àgbáyé Olu Jacobs: Ipò wo ni gbajúmọ̀ òṣèré tíátà yìí wà?
Idahun awọn ọjọgbọn ni pe 'rara'ṣugbọn awọn akọṣẹmọṣẹ kan ti n sọ ọ wi pe o ṣeeṣe o ki ọrọ maa ri bẹẹ Oriṣiriṣi nnkan ni oyun nini maa n ṣe fun ara, lara rẹ si ni dindin agbara awọn eroja ajẹsara ara ku.
Ọpọ eeyan lo ro pe o n se aisan lo se wa nile iwosan lai mọ pe ere sinima lasan ni.
Aare Buhari gbosuba fun ise takuntakun ati ilana ti oloogbe naa ti la sile fun awon odo to n bo leyin ninu eto idanilaraya ati ni papaajulo ipa ti o ko lati mu igberu ba igberu ba egbe osere Nollywood ni Naijiria.
Bi o tilẹ jẹ wi pe ọpọ awọn onworan lo fẹhonu han pe ija naa ko dun bi awọn ṣe lero, sibẹ gbogbo awọn onidajs mẹtẹẹta to wa nikalẹ fun ija naa ni wọn gbe idajs kalẹ pe ọwọ Adesanya lo dun Romero julọ lasiko ija naa.
Bí ẹnikẹ́ni tí nǹkan dà lára rẹ̀ bá tutọ́ sí ara ẹni tí ó mọ́, kí ẹni náà fọ aṣọ rẹ̀, kí ó sì wẹ̀, yóo jẹ́ aláìmọ́ títí di ìrọ̀lẹ́.
Ijoba orile-ede Zimbabwe   yoo gbalejo awon orile-ede ti won to metadinlaadota ninu eyi ti orile-ede China wa lara won lati se itopinpin eto-idibo  gbogbogbo ti yoo waye orile-ede naa laarin odun ti a wa yi.
 adágbà fi àwon ìbàràpá tí ogun lé dé ori olúmo yìí sí ìdi igi ìto kan .
Aarẹ ẹgbẹ Miyetti Allah, Bello Abdullahi Bodejo lo sọ bẹẹ lasiko to fi n yannana ọrọ ni ilu Bauchi.
tí ẹnu wọn kún fún irọ́,tí ọwọ́ ọ̀tún wọn sì kún fún èké.
Bakan naa ni oriade ọhun fikun pe awọn osisẹ ọba ni ipinlẹ Ọsun ti pọ lapọju, atunse nla si gbọdọ ba ẹka isẹ ọba nipa gbigbe awọn osisẹ ti ko ba ri isẹ se lọ sawọn ẹka ti isẹ wa fun wọn.
Aṣíwájú ilẹ̀ Yorùbá tuntun sí ọmọ Yorùbá-Tọwọ́ tẹsẹ̀ ni mo fi gba ipò yìí
Jesu bá lọ sí Kapanaumu, ìlú kan ní ilẹ̀ Galili.
Anti social media bill: Ilé aṣòfin ní ìjíròrò ìtagbangba ló kù lórí àbá láti mójútó ayélujára
Àwọn ọba maraarun sá, wọ́n sì fi ara pamọ́ sinu ihò tí ó wà ní Makeda.
"Ọlọ́pàá wú òkú obìrin tó ń múra ìgbéyàwó lọ́wọ́ tí 'gate-man' rẹ̀ ṣekúpa ""A fẹ́ yọ ààrẹ ẹgbẹ́ Yorùbá YCE nípò torí àwọn ìwà tí kò bójúmu"" Wo àànfàní ‘Masturbation’, fífún ara rẹ̀ ní adùn ìbálòpọ̀ Ẹ fura o, Boko Haram ti pàgọ́ sí Abuja, yóò ṣe ìkọlù láìpẹ́ - Iléèṣẹ́ Aṣọ́bodè lọgun Idi ni pe dokita obinrin kan to yẹ ko sare lọ sile iwosan lati sisẹ abẹ fun alaboyun naa lasiko isede nitori Coronavirus, lo bọ sọwọ awọn ọlọpaa to da duro ladugbo Ikeja nilu Eko."
Àkọlé àwòrán, Bí àwọn ọmọ Nàíjíríà se kúndùn òògùn lílò ti di ìràwọ̀ ọ̀sán, tó ń ba àgbà lẹ́rùn báyìí - àjọ ìsọ̀kan àgbáyé sì fẹ́ se ìwádìí lópin ọdún yìí Àwọn olórí àtàwọn ológun ni wọ́n se Tramadol fún, àmọ́ bí àwọn àdúnkookò-mọ́ni se wá kúndùn rẹ̀ láti máa gbẹ̀mí ẹni, wá di àpérò àwọn ọmọ eríwo báyìí, èyi tí wọn ló ń dákún bí ọwọ́jà wọn se ń le koko síi.
Ní àkókò yìí, ọkunrin ọlọ́rọ̀ kan wà ninu ìdílé Elimeleki, ẹbí kan náà ni ọkunrin yìí ati ọkọ Naomi.
Ní àkókò kan, ìyàn mú gidigidi ní ilẹ̀ Kenaani.
Bẹ́ẹ̀ ni àwọn tí ẹ jọ ń ṣiṣẹ́ pọ̀ rí sí ọ, àwọn tí ẹ ti jọ ń ṣòwò pọ̀ láti ìgbà èwe rẹ.
eto idibo, ki i se nipa ijoba ati awon eniyan nikan, sugbon ibasepo laarin enikan
Awọn gomina naa ni ko dabi ẹni pe aarẹ Buhari ni ọ̀wọ̀ fawọn eeyan agbegbe Niger Delta, eto iṣejọba tiwantiwa ati ẹka iṣedajọ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù WhatsApp: Àwọn fóònù wọ̀nyìí kò ni lè ṣe WhatsApp láti ọdún 2020 31 Ọ̀pẹ̀̀ 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Tete maa yẹ foonu rẹ wo boo ṣe n ka iroyin yii boya ori yọ ọ.
Oríṣun àwòrán, Tunji Oladejo Àkọlé àwòrán, Ori lo yọ awọn olugbe ile to ku lọwọ ewu ina naa BBC Yoruba wadi lọwọ alukoro fasiti naa boya oloogbe ohun ni ipenija ti o le mu gba ẹmi ara rẹ ti o si dahun pe ohun kan mọ pe arakunrin naa ati iyawo rẹ ni ede aiyede eleyi ti o mu ki wọn pinya.
Oríṣun àwòrán, @SZakzakyOffice Àkọlé àwòrán, Ẹgbẹ Shiite O fidiẹ mulẹ pe ootọ ni pe awọn ọmọ ẹgbẹ Shiite kora wọn jọ fun iwọde ṣugbọn wọn ti tuka bayii nibi eto Ashura ti wọn n ṣe.
"Ọmọkùnrin tó pa ọmọ igbákejì Gómìnà Ondo gba ìdàjọ́ ikú ""Ẹ sinmi ariwo Saraki, ẹnikẹ́ni ló le è di ààrẹ aṣòfin àgbà"" Adajọ to gbọ ẹjọ naa, Onidajọ Binta Nyako ni eredi aṣẹ yii ko ṣẹyin bi Nnamdi Kanu ti ṣe ti kuna lati fara han niwaju ile ẹjọ naa lati igba ti wọn ti gba oniduro rẹ ni oṣu kẹrin ọdun 2017."
Ẹ̀rí ni wọ́n fi ṣe láàrin àwa pẹlu yín.
Akọsilẹ wa pe o ti pegede nigba mẹrindinlọgbọn labala komẹsẹoyo idije Europa.
" Iṣẹ alagbaṣẹ ni Blom fi pupọ ninu igbesi aye rẹ ṣe ko to fẹyinti lẹyin to le ni ọgọrin ọdun.
Ìwé òfin ìlú Pakistan sọ wípé “A kò gbọdọ̀ fi ẹ̀tọ́ ìgbé ayé tàbí òmìnira du ẹnikẹ́ni ní ìbámu òfin,” tí ó wà lábẹ́ Àwọn Ẹ̀tọ́ ọmọ ìlú.
Sẹnetọ Ita Enang, to jẹ olubadamọran fun aarẹ Buhari lori ọrọ ile aṣofin apapọ, lo fi ẹ̀bẹ̀ naa sita.
Oríṣun àwòrán, @GboyegaOyetolaileriOluwa Eto aabo Gomina Gboyega Oyetọla ni ijọba ti ṣiṣẹ takuntakun lati rii wi pe ipinlẹ Oṣun ṣi wa lara awọn ipinlẹ ti eto aabo wọn muna doko.
Ọjọgbọn Akinwunmi Ishola pa'poda lẹyin ọdun mọkandinlọgọrin
 awon amioro leta meji 136 ni won je fiforukosile .
Akomolede ati Aṣa lori BBC:Wo ìrúfẹ́ ìgbeyàwó méje tó wà nílẹ̀ Yorùbá àti ojúṣe Alárinà
Idi ni pe Senator to n soju ẹkun idibo Ariwa Adamawa, Elisha Ishaku Abbo ti kede pe oun fẹ se apejẹ ati ayẹyẹ idawọ idunnu pẹlu Leycon to jawe olubori naa.
Ninu fọnran to gba ori ayelujara kan ni sọja kan ti n sọ pe o ti su awọn lati maa sin orilẹede wọn.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fọ́nrán ohùn, Ọrọ Sound Sultan lori Wenger to fẹ fipo silẹ Bẹẹ gẹgẹ pẹlu lo fẹẹ̀ jẹ wi pe ero awọn ololufẹ ikọ naa kaakiri agbaye ko yatọ si ipa meji yii.
Gbogbo akitiyan lati kan si ijọba ipinlẹ Ọyọ nipasẹ kọmiṣọnna fun eto katakara lo ja si pabo .
 A gbọdọ tẹle ilana to yẹ, ao si ri i pe a tẹle nitori ki otitọ le jọba."
" Ọba Ogunwusi wa rawọ ẹbẹ sawọn ọdọ naa lati jeburẹ, ki wọn si duro de ohun ti ijọba fẹ se lori ibeere wọn.
Ohun tí a rí nílé Ajimobi rèé lẹ́yìn òfégè ìròyìn pé ó jáde láyé Ìjọba Amẹrika fi ojú àwọn ọmọ Yahoo mẹ́fà léde, wọ́n gbẹ́sẹ̀ lé dúkìá wọn Ìwadìí ti bẹ̀rẹ̀ lórí àrá tó sán pa òṣìṣẹ́ FRSC mẹ́ta nípínlẹ̀ Ogun- Ọ̀gá àjọ FRSC Invictus Obi, Hushpuppi, àwọn ọ̀dọ́ Nàìjíríà méjì tí ẹ̀sùn gbájúẹ̀ wà lọ́rùn wọn Gẹgẹ bi iroyin agbegbe naa ṣe sọ, eeyan kan ku ti eeyan kan si fi ara ṣeṣe lasiko itakangọn awọn ẹlẹgbẹ okunkun naa.
Gbogbo wọn yóo wà nílẹ̀,wọn yóo di ìjẹ fún àwọn ẹyẹ orí òkè,ati àwọn ẹranko inú ìgbẹ́.
Gbogbo àwọn tí wọ́n bá ṣẹ́kù ní Juda, tí wọ́n lọ sí Ijipti yóo wá mọ ọ̀rọ̀ ẹni tí yóo ṣẹ, bóyá tèmi ni, tabi tiwọn.
Òun ni asà mi, ìwo ìgbàlà mi ati ibi ìsásí mi.
Kí o sì sọ fún wọn pé èmi OLUWA ní, ní ọjọ́ tí mo yan Israẹli, mo búra fún àwọn ọmọ Jakọbu, mo fi ara mi hàn fún wọn ní ilẹ̀ Ijipti, mo sì búra fún wọn pé èmi ni OLUWA Ọlọrun wọn.
O ni o ti pẹ ti ijọba ti ṣeleri igbega lẹnu iṣẹ fun awọn lati nkan bi oṣu keje ọdun 2018 to si jẹ wi pe awọn kan ti n jẹ mudun-mudun rẹ lẹka eto ilera.
Ọwọ́ Jehoaṣi tẹ Amasaya, lẹ́yìn náà, ó lọ sí Jerusalẹmu, ó wó odi Jerusalẹmu lulẹ̀ láti Ẹnubodè Efuraimu títí dé Ẹnubodè Igun, gbogbo rẹ̀ jẹ́ irinwo igbọnwọ (400 mita).
Bashir lọ si ile iwe alakọbẹrẹ Maksha Nursery and Primary School lọdun 1999 si 2005.
níbo ni ìrètí mi wá wà?
Ní báyìí tó sì ti dé sí Ado, ó gbọ́dọ̀ ṣe ayẹwo àrùn Coronavirus ni, kò to dára pọ mọ wa.
A bá kúnlẹ̀ lórí iyanrìn ní èbúté, a gbadura.
Ipade ọhun tun sọ pe awọn faramọ agbekalẹ igbimọ iwadii yii laarin ọsẹ kan ti wọn yoo si pe fun iwe ẹhonu lati ọdọ ara ilu ti SARS ti tẹ oju ẹtọ wọn mọlẹ.
Ilé ẹ́jọ́ tó ń gb'ẹ́sùn ìdìbò wọ́gilé ẹjọ́ tí Ajimọbi pè tako Kọla Balogun
Awọn agbebọn ti ẹnikẹni ko damọ lo ji Adajọ naa gbe ti wọn ni wọn n beere fun aadọta milionu owo itanran.
Ẹ pọn omi sílẹ̀ de àkókò tí ogun yóo dótì yín, ẹ ṣe ibi ààbò yín kí ó lágbára; ẹ lọ sí ibi ilẹ̀ alámọ̀, ẹ gún amọ̀, kí ẹ fi ṣe bíríkì!
Adele ọga agba naa wa kede agbekalẹ ikọ oluwadi kan feto idibo, ti yoo wa fun iwadi ati igbẹjọ awọn to ba sẹ si ofin eto idibo.
Nítorí náà, mo ti bẹ̀rẹ̀ sí pa yín run n óo sọ ìlú yín di ahoro nítorí ẹ̀ṣẹ̀ yín.
Maaka yìí kan náà ni ó bí Ṣaafu, baba Madimana, tí ó tẹ ìlú Madimana dó, ati Ṣefa, baba Makibena ati Gibea, àwọn ni wọ́n tẹ ìlú Makibena ati ìlú Gibea dó.
Ẹ kò gbọdọ̀ fi àjẹkù kankan sílẹ̀ di ọjọ́ keji, ẹ kò sì gbọdọ̀ fọ́ ọ̀kankan ninu egungun ẹran tí ẹ bá fi rú ẹbọ náà.
Agbẹnusọ fun ijọba orilẹede Tanzania sọrọ lori opo Twitter pe Aarẹ ko sọ ohun to jọ bẹ rara.
aare fun saa keji gege bi aare orile ede Naijiria.
ṣugbọn, ẹ bẹ̀rù idà,nítorí pé ìrúnú níí fa kí á fi idà pa eniyan,kí ẹ lè mọ̀ dájú pé ìdájọ́ ń bẹ.
Ọwọ́ gbogbo wọ́n yóo rọ; orúnkún wọn kò ní lágbára.
Wo àwọn orílẹ̀-èdè márùn ún tó fún àwọn obìnrin làńfàní tuntun sí ẹ̀tọ́ wọn Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, U.
Atẹjade naa fikun pe, akọsẹmọsẹ apoogun to dantọ ni Adeọsun, to si gba oye imọ ijinlẹ akọkọ nile ẹkọ fasiti Benin lọdun 1990, nigba to gba oye imọ ijinlẹ keji nile ẹkọ fasiti yii kanna lọdun 1997.
Ṣugbọn ò ń kọ ìbẹ̀rù Ọlọrun sílẹ̀,o sì ń dènà adura níwájú rẹ̀.
section 177 ti odun 1999, ni eyi ti o sọ pe oludije fun ipo gomina gbọdọ
Ọ ṣòro fún mi láti foríjin ìbátan mi tó jé ọmọ ikò Boko Haram tó fipá bámi lòpò Wo odò tí wọ́n ti rí Aishat tí àgbárá òjò gbé lọ ní Eko Wo bí ìpinu Amẹ́ríkà lórí gbígba físà ṣe kan ọ́ Ọkùnrin kan bá ọmọ oṣù mẹ́ta lòpọ̀, ìfun ọmọ tú jáde!
Tayo Odukoya ni wọn le nitori oun naa ṣẹ magomago to tako ofin ajọ naa, nigba ti wọn si le agbẹjọrọ Babatunde Aina nitori o yi akọsilẹ pade, ti o si ṣe magomago nipa tita ile igbe ajọ naa.
Emi ni mo ṣi n ṣejọba, ko si ile ẹjọ kan to yọ mi nipo"" ni ọrọ to tẹnu Gomina Oyetọla jade."
Ki eledua fi oore si igbiyanju gbogbo ni to n wa atijẹ ati mu '' Lara awọn aworan to fi safihan ipalara yi lo wa ni isalẹ yi: Oríṣun àwòrán, mydemartins Oríṣun àwòrán, mydemartins Okiki Bakare@kikibakare ti wọn jijọ n ṣe ere naa ti ko ti jade kan sara si Mide Martins bi o ti ṣe fi inira ori to la mọlẹ mọra .
Ṣugbọn wọ́n kọ̀, wọn kò gbọ́.
Ṣugbọn inu BBC Yoruba dun lati ṣawari Adewumi Waliu Mufutau ti o jẹ ọmọ bibi ilu Ṣaki ni ipinlẹ Oyo ṣugbọn to fi orilẹ-ede Finland ṣe ibujoko rẹ to si n kọ awọn ọmọ rẹ ni ede Yoruba.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Europa league: Ìjàmbà tún ṣe Ole àtàwọn ọmọ rẹ níwájú AZ Alkmaar, ọ̀mì ni wọ́n ta 3 Ọ̀wàrà 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Kikankikan ni olukọ atawọn agbabọọlu ẹbẹ agbabọọlu Manchester n pariwo lori papa iṣire ti wọn ti gba ifẹsẹwọnsẹ wọn pẹlu AZ Alkmaar ninu ifẹsẹwọnsẹ idije Europa.
Cameroon wa ìyà mu bíi gaàrí lọ́wọ́ England, 3-0 ló bá dé
Awon Agbaboolu owo-arin(Midfielders): Mikel John Obi (Tianjin Teda, China); Ogenyi Onazi (Trabzonspor FC, Turkey); Wilfred Ndidi (Leicester City, England); Oghenekaro Etebo (Las Palmas, Spain); John Ogu (Hapoel Be’er Sheva, Israel); Uche Agbo (Standard Liege, Belgium) ati Joel Obi (Torino FC, Italy).
Gbọ́, ọmọ mi, gba ẹ̀kọ́ mi,kí ẹ̀mí rẹ lè gùn.
Nítorí bí omi òkun ni ìparun rẹ gbòòrò;ta ló lè mú ọ pada bọ̀ sípò?
Adari ajọ SERAP Adetokunbọ Mumuni sọ fun BBC Yoruba wipe kii ṣe awọn aṣofin tuntun yii nikan ni yoo gba owo yanturu bi saa iṣejọba Aarẹ Muhammadu Buhari ti 2015 si 2019 yii ṣe n pari.
"Ohun to wa nidii ọrọ yii gangan ni pe awọn ologun wa n gbiyanju daadaa, kii ṣe kekere.
Ilé Aṣòfin Àgbà fòǹtẹ̀ lu N30,000 owó oṣù òṣìṣẹ́ Ìjì líle mú ẹ̀mí èèyàn 1000 lọ, odidi ìlú kan bàjẹ́ Ẹlẹ́rìí 400 ni yóò tako Buhari lórí èsì ìbò - Atiku Ọ̀gá iléèwé dèrò ilé torí fídíò akẹ́kọ̀ọ́ tó lé torí owó iléèwé Egbirìn ọ̀tẹ̀ lọ̀rọ̀ Boko Haram, ọ̀pọ̀ ẹ̀mi tún ṣùn nílùú Michika, Seyi Makinde figbe ta lórí bí Ajimobi ṣe ń ná owó ìlú Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fọ́nrán ohùn, Akẹ́kọ̀ọ́ dókítà: Fásitì Ìbàdàn gbọdọ̀ dín owó iléẹ̀kọ́ wa Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Kasonde fikun ọrọ rẹ pe iwadii si n lọ lọwọ lori ohun to ṣekupa ẹja akorede ọhún.
Lọ kúrò lọ́dọ̀ mi, lọ kúrò lọ́dọ̀ mi, ìwọ ni ọ̀tá ogunlọ́gọ̀ ohun ẹlẹ́mìí tí Olódùmarè sọ lọ́jọ̀ sí orí ilẹ̀ ayé.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Àhámọ́ ajínigbé ni ń bá wà lónìí, ọ̀pẹ́ awakọ̀ mi"" Ìdájọ́ ọwọ́ tó di lemọ́-lemọ́ n‘Ibadan, ohun tó fà á rèé Bodè àgbáyé ní Saki, ìbẹ̀ ni agbégbọn ń gbà wọ ilẹ̀ Káàrọ̀ Oòjíire - Makinde gbarata Saheed tí wọ́n dáná sun ní OkeAdo, Ibadan, ajínigbé ni àbí àrìnfẹsẹ̀sí?"
O bẹrẹ orin kikọ ninu ẹgbẹ akọrin ijọ New Bethel Baptist ni ilu rẹ, Detroit.
Ó tilẹ̀ máà fẹ̀ ẹ́ sí orin tó gbajúmọ̀ tó orin yìí lásìkò nàá.
Tí a fiṣọwọ́ ní 12:31 29 Èbibi 201912:31 29 Èbibi 2019 Dapo Abiodun gbàjọba lọ́wọ́ Amosun Video content Video caption: Nigeria swearing-in: Ètò ìbúrawọlé Dapo Abiodun ní OgunNigeria swearing-in: Ètò ìbúrawọlé Dapo Abiodun ní Ogun Article share tools Facebook Twitter ṢàpínlòView more share options Share this post Copy this linkKà síwájú síi nípa àwọn ìtọ́kasí wọ̀nyí.
Ẹ jẹ́ àjèjì sí àwọn ọmọ-ìbílẹ̀ Israẹli.
Awọn ololufẹ meji maa n ṣe ere ifẹ daadaa ti akọrin naa si ni oun gba aye lọwọ ọkọ Jada ki oun to maa ba a ṣe ere ifẹ to wọra to bẹyẹn.
Nítorí náà, wá sọ́dọ̀ wa nígbà tí o bá fẹ́, a óo sì fà á lé ọ lọ́wọ́.
Ọpọlọpọ iroyin lo bẹrẹ si ni tan an kalẹ lonii wi pe IBB ti dagbere faye lowurọ oni ko da titi dori oju opo aṣewadi iroyin lagbaaye Wikipedia gan.
Udoma salaye , “igberu ti ba awon eka miiran nbi: eka irinaajo, eka amuna wa ati afefe gaasi, irin-tutu, ati eka ipese nnkan, ni paapaa julo awon akosileni eka kara-kata”.
Igbẹjọ bẹrẹ, awọn ẹlẹri bii orisi mẹta jade lati abule Alimoso, ti wọn si jẹri pe gbangba ni awọn ri Gbadero lọjọ naa ni abule wọn pẹlu ọkọ Pijo 504 rẹ.
Ìyanṣẹ́lódì ẹgbẹ́ òṣìṣẹ́ kò le fa ọ̀wọ́n epo - NNPC Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, NNPC sọ pe awọn to n lo ọkọ ati awọn to tun n lo eporọbi fun awọn nkan mi ko ni ohunkohun lati bẹru Ileeṣẹ to n mojuto ipese epo rọbi ni Naijiria, National Petroleum Corporation, NNPC ti ni, ko si nkan to jọ pe epo bẹtiro yoo di ọwọn gogo ni orilẹede Naijiria.
Jafileti bí ọmọ mẹta: Pasaki, Bimihali, ati Aṣifatu.
ṣalaye pe pẹlu bi orilẹ-ede Naijiria ṣe n sapa lati goke agba bayii, o ṣe
 nítorí ìdí èyí ifá rọ àwọn ọkùnrin láti gbọ ́ n nínú gbọ ́ n lode tí ọ ̀ rọ ̀ ba ti di ọ ̀ rọ ̀ obìnrin .
 Bo tile je pe, a ni àádọ̀rún  oselu to n kopa ninu eto idibo lorile
#FIFAWWC: Amẹ́ríkà to pàṣán má r'ágbà fín sí ìdí Thailand
Àwọn ọmọ ogun Ai pa tó mẹrindinlogoji (36) ninu wọn, wọ́n sì lé gbogbo wọn kúrò ní ẹnubodè wọn títí dé Ṣebarimu.
Ẹ kí Pasisi, arabinrin àyànfẹ́ tí ó ti ṣiṣẹ́ pupọ ninu Oluwa.
Bẹ́ẹ̀ ni Josẹfu ṣe sọ ọ́ di òfin ní ilẹ̀ Ijipti, tí ó sì wà títí di òní olónìí pé ìdámárùn-ún gbogbo ìkórè oko jẹ́ ti Farao, ati pé ilẹ̀ àwọn babalóòṣà nìkan ni kì í ṣe ti Farao.
”Awon akoroyin tun bere wipe, ki ni aare ri so si oludije alatako re ti o wa lati egbe oselu PDP, Alhaji Atiku, ti o n gbero lati pe abajade esi idibo aare lejo?
Ààbò tó péye wà fún àwọn okòwò ará South Africa ni Eko -Sanwo Olu Àwọn èèyàn to n fẹ̀hónú hàn dáná ṣun iléeṣẹ́ MTN n‘Ibadan ShopRite Ibadan gbé ìlẹ̀kùn tìpa torí ìkọlù àwọn tó ń fẹ̀hónú hàn Xenophobic Attack: Àwọn ọmọ Nàìjírìá bínú kọlu Shoprite l'Eko Bakan naa lo mẹnuba ipese owo okowo lati Bank of Industry Naijiria fawọn to fẹ bẹrẹ òwò nile ati iṣẹ ọwọ́.
Lọjọ aiku ni onimọ ilera kan salaisi nipinlẹ Edo nigba ti o ko aisan naa lara ọmọ kan.
Aṣofin Babatunde Ọlatunji to jẹ ọmọ ileegbimọ aṣofin ni ipinlẹ Ọṣun, to si tun jẹ alaga igbimọ to n mojuto karakata nile aṣofin naa ṣalaye pe ohun marun lo ṣe koko.
Olusegun Obasanjọ Olusegun Obasanjo to ti fi igba kan jẹ adari orilẹede Naijiria ma n sọrọ soke lati igba de igba, ti yoo si tọka si awọn ohun ti ko tọ ti ijọba to wa lode n ṣe ati ọna abayọ si iṣoro to n koju orilẹede Naijiria.
Buhari fi ranse si Obasanjo lati fi sami ayẹyẹ ọdun méjílélọ́gọ́rin ti o pe, aare Buhari
Ẹfunsetan Aniwura, obìnrin tó ju ọkùnrin lọ Ọ̀rọ̀ǹpọ̀tọ̀niyùn, Aláàfin obìnrin àkọ́kọ́ rèé, tó ní nǹkan ọkùnrin Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Kayefi BBC Yorùba: Bàbá ọmọ, Mọ́ṣúárì, Ọlọ́pàá kẹ́jọ́ rò nípa òkú ọmọ tó pòórá Ninu fọnrán fídíò náà ti Marley fi sita loju opo Instagram rẹ, o jo iru ijo kan ti o mu ọwọ lọ si apa ibi nkan ọmọ kunrin rẹ eyi to fi n ṣapejuwe ọrọ inu orin rẹ.
Ile ẹjọ giga ni ile asofin agba jare Magu Nibayii, agbẹnusọ fun ile igbimọ asofin agba, Sẹnatọ Aliyu Sabi Abdullahi ni idajọ ile ẹjọ naa dun mọ awọn asofin ninu.
Gẹgẹ bi ajọ to n gbodun ti ajakalẹ aarun, NCDC, ṣe sọ ninu ikede to fi sita lalẹ ọjọ Aje, ipinlẹ mẹsan an, ati ilu Abuja ni awọn esi ayẹwo naa ti wa.
44 fún lítà kan Koda, o fi ẹsun kan Alaafin pe o n lepa ẹmi oun, to si fẹ ẹ ji oun gbe nitori pe oun kuro ninu igbeyawo naa.
"O ni: "" A ti kàn si awọn ijọba UK lori ọrọ yii, ohun ti mo ro ni pe ipade naa jẹ ti awọn aṣofin UK ni kii ṣe agbẹnusọ ti ijọba."
Building Collapse: Ìdí tí ilé fi ń wó nìyí'
 iye àwọn ènìyàn tó tó 99 % ni ó má a ń ní agbára àti kojú àrùn náà láàárín oṣù kan lẹ ́ yìn tí wọ ́ n bá ti gba àjẹsára náà , èyí sì dàbí ẹni pé yóò wà títí ayé wọn .
Nigba miran, awọn eniyan kii ka awọn ofin to rọmọ lilo awọn oju opo wọnyii ni igba de igba, lati mọ ohun ti wọn le ṣe, to le mu ki wọn gbegile oju opo ikansiraẹni wọn.
A túwíìtì àwòrán ìkọkúkọ wa ní ìbánikẹ́dùn ìṣẹ̀lẹ̀ náà.
Bíbéèrè fún ìbálòpọ̀ gbogbo ìgbà sọ ìyàwó ilé dèrò ilé ìwòsàn Ìjọba ti bẹ̀rẹ̀ sí báwọn tó gbé òṣìṣẹ́ aláàánú mẹ́fà sọ̀rọ̀- Garba Shehu Ẹni orí yọ, ó dilé!
Ninu ipade apero  to waye ni ẹkun Gusu iwo oorun orile ede yii
Àwọn tí wọ́n sọ fún mi kò tilẹ̀ sọ ìdajì ohun tí mo rí.
Eyi lo sun ipo ẹgbẹ rẹ siwaju sii lori àtẹ bayii.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ron Jeremy: Òṣèré tó ti ṣe ''Blue film'' fún ọdún 40 ti wọ gàù pẹ̀lú ẹ̀sùn ìfipábánilòpọ̀ 1 Owewe 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 2 Owewe 2020 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Gbajugbaja ni arakunrin Ron Jeremy ni agbo oṣere ''Blue film'' to si ti kopa ninu fiimu to ju 1700 lọ.
Kí àwọn tí ó bá wà ninu ìlú sá kúrò níbẹ̀.
” Ṣugbọn Dafidi ṣẹgun ibi ààbò Sioni, tí à ń pè ní ìlú Dafidi.
25 Àti lẹ́ẹ̀kansíi, èmi pàṣẹ fún ọ pé ìwọ kò gbọdọ̀ ṣe ojúkòkòrò sí aya ẹnìkéjì rẹ; tàbí kí o lépa ẹ̀mí ẹnìkéjì rẹ.
Europa league: Ìjàmbà tún ṣe Ole àtàwọn ọmọ rẹ níwájú AZ Alkmaar, ọ̀mì ni wọ́n ta
Asa ṣe ohun tí ó dára lójú OLUWA gẹ́gẹ́ bíi Dafidi baba ńlá rẹ̀.
O Fágúnwà máa ń sùn sí ibojì, aginjù tàbí ti ara rẹ̀ mọ́lé láti kọ̀wé
Nisinsinyii mo ti kọ́ ilé kan tí ó lọ́lá fún ọ,níbi tí o óo máa gbé títí lae.
O pasẹ fun awọn ọkunrin naa lati gba awọn ẹrọ ibaraẹnisọrọ ati ẹrọ ayaworan wa.
Ahabu ọba ranṣẹ pada, ó ní, “Jagunjagun kan kì í fọ́nnu kí ó tó lọ sójú ogun, ó di ìgbà tí ó bá lọ sógun tí ó bá bọ̀.
Idahun ranpẹ: Wọn ko tii ka a ni ipele kika akọkọ.
Won fẹ pami ni mo fi sa nilu'' Nnamdi Kanu dupe lọwọ awọn alatilẹyin rẹ to duro ti lasiko ti o fi sa nilu.
Oloye Lai Mohammed to je minista fun asa, eto iroyin ati irin ajo afe ni Naijiria atawon eekan ninu oselu kedun pelu gbajugba onkorin DBanj ati ebi re lori iku omokunrin won, Daniel Oyebanjo.
Nigba to n salaye lori idunkooko pe awọn asaaju ọlọkọ naa yoo pasẹ fawọn awakọ lati dasẹ silẹ, ijọba Ọyọ ni ala ti ko lee sẹ ni idunkooko naa, ko si si awakọ kankan nipinlẹ Ọyọ ti yoo tẹle asẹ awọn adari ẹgbẹ NURTW naa.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Lagos Explosion: Àwọn akẹ́kọ̀ọ́ iléẹ̀kọ́ Bethlehem ń gbàdúrà òwúrọ̀ lọ́wọ́ ní ìbúgbàmù wáyé 16 Ẹrẹ̀nà 2020 Oríṣun àwòrán, others Àkọlé àwòrán, Bi awọn dukia kan ṣe wo kanlẹ, ni wọn tun jona Ẹnikan ti isẹlẹ ile to dawo ladugbo Festac nilu Eko, ti iṣẹlẹ naa ṣoju rẹ sọ fun BBC pe, o ṣoju oun koro nigba ti wọn gbe ọkan lara awọn sista ileewe Bethlehem Girls College jade, lẹyin ti ile iwe ọhun wọ le wọn lori.
Agbẹnusọ fún àwọn ọmọ ilé ìgbìmọ̀ asofin Lamidi Olatunji pé àwọnti fi ìmọ sọkan láti lọ mú èróngbà wọn ṣẹ ní nínú ẹgbk òṣèlú APM.
Germany si duro loke tente tabili ipo ate lagbaye, ti Brazil si tele won, Belgium bo si ipo keta lati ipo karun-un ti won wa tele.
5m ẹnì kọ̀ọ̀kan lọ́dún19 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Oríṣun àwòrán, Facebook/Abiola Ajimobi Abiola Ajimobi jáde láyé!
 apapo iye aala ile re je 13,939 km ( 5,382 sq.
“O kò gbọdọ̀ pọ́n àlejò lójú, ẹ mọ̀ bí ọkàn àlejò ti rí, nítorí ẹ̀yin pàápàá jẹ́ àlejò rí ní ilẹ̀ Ijipti.
Ọgọfa ileewe ni yoo wa ni titi pa lawọn agbegbe ti ajakalẹ aisan yi ti peleke.
Oríṣun àwòrán, @officialEFCC Malami ni ile iṣẹ oun ko mọ iye ile, owo tabi nkan ini ti won gba lọwọ awọn alajẹbanu oloṣelu, bakan naa ni o rọ Aarẹ pe o ti to ki Magu lọ rọkun nile.
Ni kia mọṣa si ni wọn ti yan adele alaga, Leonard Nzewanu ti wn si ti bura wọle fun un.
Àwọn àgbààgbà mẹrinlelogun sì jókòó lórí ìtẹ́ mẹrinlelogun náà.
Bẹẹ ni eto ayẹwo to l'agbara wa ni papakọ ofurufu ati ibudokọ ori omi to wọ Naijiria.
"Super Eagles ti mbọ̀ wálé Chelsea lu West Brom lalubomi Ninu atẹjade to Moses fi kede ifẹyinti rẹ, o ni, ""Mo ti fẹnu ba awọn igba to dara ju laye mi nigba ti mo wọ aṣọ iko Super Eagles, mi o le gbagbe awọn akoko naa fun igba pipẹ."
Nígbà tí ilẹ̀ mọ́ ṣe ni ó dàbí ẹni pé bí èmi ti sùn lọ nì ọkàn mi kò sùn, ó ń ronú lórí àgbàdo yìí, nítorí bẹ́ẹ̀ ni ọ̀pọ̀lopọ̀ nǹkan tí ènìyàn bá ń ronú rẹ̀ máa ń déédéé dẹ olúwaarẹ̀ lọ́rùn àti ṣe bí olúwaarẹ̀ bá sun oorun díẹ̀ tí ọkàn simi.
Atiku ni o fihan pe 'lootọ, ẹka idajọ ni ireti araalu ati olugbeja iṣejọba tiwantiwa.
Lizzy Anjori ṣèyàwó, àwọn òṣèré púpọ̀ ṣọjọ́ ìbí f'ọ́mọ lọ́sẹ̀ yìí Joy Nunieh: Tani adarí àjọ NDDC tẹ́lẹ̀ to fẹ̀sùn jegúdújẹrá kan Godswill Akpabio?
Àmọ́ ọ̀rọ̀ ọjọ́ mìíì nìyẹn jẹ́.
Ile igbimo asoju- sofin ti ilu Abuja ti ro aare Muhammadu Buhari lati maa lo ase ofin ti o towobo lose to koja, ni eyi ti yoo tun tepele mo gbigbokun ti iwa ibajẹ  lorile ede yii.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, EndSars, EndSwat: Ọlọ́pàá ti fi ìbọn lù mí láyà rí torí mó ní 'extra tyre' méjì- afẹ́hònúh Islam, ẹsin ti mo yan laayo lo paṣẹ fun gbogbo obinrin lati maa bo ihoho wọn nibikibi ti wọn ba n lọ.
Ogbeni Gidado wa dupe lowo gomina ati awon omo ipinle naa fun anfaani lati sin won gege bi igbakeji gomina fun ipinle naa.
Oríṣun àwòrán, Others Amọ ẹmi awọn obinrin meji lo ba isẹlẹ naa rin, ta si ti gbe oku wọn lọ si ile igbokusi.
Ẹ má ṣe fara wé wọn, nítorí Baba yín ti mọ ohun tí ẹ nílò kí ẹ tó bèèrè lọ́wọ́ rẹ̀.
Nítorí èmi ni mo ni gbogbo ẹran inú igbó,tèmi sì ni gbogbo mààlúù tó wà lórí ẹgbẹrun òkè.
22 Àti pé iye àwọn tí wọ́n bá ronúpìwàdà tí a sì rìbọmi ní orúkọ mi, èyí tíí ṣe Jésu Krísti, àti ti wọ́n forítì í dé òpin, àwọn kannáà ni a ó gbàlà.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Iléesẹ̀ ọlọ́pàá: NHRC fẹ́ mọ bàwọn afurasí se dé túbú 13 Òkùdu 2018 Oríṣun àwòrán, RCCG Àkọlé àwòrán, Bí wọ́n ṣe ń ti àwọn ènìyàn mọ'lé ní Naijiria jẹ kókó ọ̀rọ̀ Àjọ tí ó ń rí sí ẹ̀tọ́ ọmọ ènìyàn (NHRC) yóò ṣe àyẹ̀wò gbogbo túbú àwọn ọlọ́pàá tó wà ní orílẹ̀èdè Naijiríà.
Eyi ni awon ifesewonse ti yoo waye ninu idije boolu ile-okere lolokan-o-jokan lojo abameta(Saturday) ati Aiku(Sunday):English Premier League: February 10Tottenham Hotspur ?
Ẹ̀yin òmùgọ̀, nígbà wo ni ẹ óo gbọ́n?
Ṣugbọn o si tun n ni ireti pe awọn obi baba oun yoo le ran oun lọwọ.
Inú dídùn a máa múni dárayá,ṣugbọn ìbànújẹ́ a máa mú kí ojú eniyan rẹ̀wẹ̀sì.
Ní ìrọ̀lẹ́ ọjọ́ náà Jesu wí fún àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ pé, “Ẹ jẹ́ kí á lọ sí èbúté ní òdìkejì òkun.
Ẹ̀wẹ̀, bi ilé ẹjọ India ba fààyé gba El-Zakzaky lati dúró nítori ààbo ẹmi rẹ̀ lórílẹ̀-èdè India, èyí yóò r-tako ìdájọ ilé ẹjọ ti Nàìjíríà to fún láàyè láti lọ tọ́ju àrà rẹ ni India ki o si pàdà wálé, èyí bákan náà yóò fún ni àfàní láti sọ ẹgbẹ́ IMN di ti gbogbo aye.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Yaba Left: Awon àṣírí ìkọkọ to jẹyọ nínú ìwádii 23 Sẹ́rẹ́ 2020 Oríṣun àwòrán, Cable Àkọlé àwòrán, YabaLeft: #7000 si #10000 ni bẹẹdi ní ilé àwọn aláìsàn ọpọlọ Fisayo Soyombo, tún ti ṣe àbẹwò si ajọ ijọba míràn láti wádiìí àwọn kudiẹ̀kudíẹ̀ to n ṣẹ̀lẹ̀ níbẹ̀.
Gẹgẹ bi o se sọ, o ni  ogójì egberun awon eniyan lo n se atipo bayii  lasiko ti wahala ti o sele naa  sọ won di alainile lori ni , o ni ibugbe mejo si ni awon ko won si bayii.
Ajo ajafẹtọ ọmọniyan lagbaye sọ wi pe, awọn ọna ti wọn n gba pa eniyan ni ki wọn bẹ ori wọn, ki wọn so okun mọ wọn lọrun titi ẹmi yoo fi bọ lara wọn, ati fifun eniyan ni abẹrẹ iku, pẹlu yi yin wọn ni ibọn.
Gbogbo ọ̀gbun ni yóo jẹ́ dídígbogbo òkè gíga ati òkè kéékèèkéni yóo jẹ́ rírẹ̀ sílẹ̀.
Ní oṣù keje tí àwọn ọmọ Israẹli ti pada sí ìlú wọn, gbogbo wọn péjọ sí Jerusalẹmu.
Ètò ìdìbò abẹ́lé sípò gómìnà APC ni ipinlẹ Ondo ti bẹ̀rẹ̀ ní pẹrẹwu Eto idibo abẹle lati mọ ẹni ti yoo gbe apoti ibo sipo gomina ninu ẹgbẹ oṣelu APC ni ipinlẹ Ondo bẹrẹ ni pẹrẹwu.
Oyeyẹmi fi kun un wi pe, kọmisọna fun ajọ ọlọpa ni ipinlẹ naa, Ahmed Iliyasu wa parọwa si awọn ara ilu, ile-iwosan tijọba ati tibilẹ lati tete fi to awọn ọlọpaa leti, ti wọn ba ri ẹnikẹni to yọju sile iwosan pẹlu ọgbẹ ọta ibọn.
Ewe, asofin Sanai Agunbiade to je olori egbe to poju lo
Bí ìyá ṣe ń bí ọmọ, tí bàbá ń wo ọmọ àti bí ọ̀rẹ́ àti ojúlùmọ̀ ṣe ń báni gbé, bẹ́ẹ̀ ni ìbá gbépọ̀ ẹ̀dá n gbòòrò si.
Murphy, lasiko to n ba BBC Yoruba sọrọ ni, afojusun oun ni lati jẹ ẹniti egungun rẹ yoo rọ julọ lagbaye, lati maa ka a bo se wu.
Oríṣun àwòrán, twitter/babajide Sanwoolu O ni, bẹẹ, ijọba ipinlẹ Eko lo ti n ṣa gbogbo ipa lati yanju iṣoro to wa nilẹ nipa gbigbaruku ti awọn ọdọ ninu akitiyan lati wa alaafia Naijiria.
Iroyin sọ pe, kete ti Ọgbẹni Atanda ba ti rowo gba lọwọ awọn eeyan ni yoo pa oju opo Facebook wọn rẹ, ki wọn ma ba le mọ ibi to wa.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ẹmi mẹrin ṣ'ofo, mẹrindinlogun f'arapa ninu ijamba ọkọ ni Lekki 11 Ẹrẹ̀nà 2018 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 12 Ẹrẹ̀nà 2018 Oríṣun àwòrán, LASEMA Àkọlé àwòrán, Ọkọ danfo yii ati ọkọ jiipu kan ni wọn kọlu arawọn Ileeṣẹ ti o n risi iṣẹlẹ pajawiri ni ipinlẹ Eko (Lasema) ti fidirẹ mulẹ wipe eniyan mẹrin ni o padanu ẹmi wọn ti awọn bi mẹrindinlogun miran si f'arapa yanayana nilu ijamba ọkọ ti o ṣẹlẹ ni opopona marosẹ Lekki/Epe lọjọ aiku.
ludwig van beethoven ( ( u.
ti ko si ni yọ ẹya kankan silẹ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Á rọ̀ wá lọ́rún tí wọ́n bá lè ṣí ibodè Lekki lọ̀fẹ̀ẹ́ láàrọ̀' Olori Hisbah ni Kano, Abaa Sufi sọ fun BBC pe oun ti gba ẹbẹ awọn ọkunrin naa, oun si ti kilọ fun wọn ki wọn o ma ṣe bẹ ẹ mọ.
Lati igba naa wa ni Shina Rambo ti n waasu ihinrere Ọlọrun, to si dagbere fun iwa idigunjale.
Ó dára kí á máa wá ara ẹni ninu ohun rere nígbà gbogbo, kì í ṣe nígbà tí mo bá wà pẹlu yín nìkan.
Ẹ pe àpèjẹ mímọ́ ní ọjọ́ náà; ẹ kò sì gbọdọ̀ ṣe iṣẹ́ líle kankan ní ọjọ́ náà.
O ti di ènìyàn Mẹrinlelógóji to ti ni ààrun Coronavirus ni Naijiria Èṣi àyẹ̀wò jáde, Gómìnà Bauchi ti ní aàrùn coronavirus báyìí Wo bí àwọn ará Ibadan ṣe ń ṣe lásìkò Coronavirus yìí Ilé ìgbìmọ̀ Aṣòfin Nàìjíríà kó igbá wọlé l'Abuja nítorí coronavirus O ní ki olukuluku dáwọ ipejọpọ duro, yala ìkómọ ni tabi igbeyawo, eyi ni yóò ran ijọba lọ́wa láti tete de ọdọ àwọn to nilo iranlọ́wọ́.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ìjọba pàṣán ni ìjọba Buhari yóò jẹ́ fún Nàìjíríà ní sáà kejì- Ṣoworẹ Ọjọ́ Àbámẹ́ta la ó mọ ẹni tí yóò lékè láàrín bàbá ìsàlẹ̀ àti àwọn mẹ̀kúnnù nipinlẹ̀ Ọyọ.
Wọ́n tó àádọ́ta wọn kò sì pa ju ẹsẹ̀ bàtà mẹta mẹ́ta lọ, wọ́n fi ẹfun òun osùn sá ojú, wọ́n so ìyẹ́ mọ́ orí, wọ́n dudu mọ́namọ̀na.
Awọn bii: @akeula_trendy Jù gbogbo rẹ lọ, àwọn oloselu Naijiria ni wọn ń kesi julọ lórí ikú olórí òṣìṣẹ́ fún Ààrẹ Buhari, láti fi ikú rẹ ṣe arikọgbọn.
Lara awọn ọmọ Naijiria to jẹ alatilẹyin fun Nnamdi Kanu fesi si ọrọ naa lọri oju opo ikansiraẹni Twitter, ti wọn si gboriyin fun ipa ti Nnamdi Kanu nko lati mu iyipada ba aye awọn alatilẹyin rẹ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Coronavirus: Ìpínlẹ̀ méjìlá tó wà ní ìṣọ̀rí àkọ́kọ́ ní yóò gba owó ìrànwọ́ lọ́sẹ̀ yìí 20 Ọ̀wàrà 2020 Oríṣun àwòrán, @Fredick_Leonard Lati ibẹrẹ ọsẹ yii lọ, ijọba apapọ yoo bẹrẹ si san owo iranwọ pẹ pẹ pẹ fawọn olokoowo ke ke ke ati alabọde.
Olórí àwọn tí wọn ń ṣọ́ ọba Babiloni mú Seraaya, olórí alufaa ati Sefanaya tí ó jẹ́ igbákejì rẹ̀ ati àwọn aṣọ́nà mẹtẹẹta.
OLUWA sọ pé, “Kò sí alaafia fún àwọn eniyan burúkú.
Ẹlẹ́wọ̀n 68 kẹ́kọ̀gboyè iṣẹ́ ọwọ́ Ọwọ́ tẹ ayédèrú agbẹjọ́rò ní Eko EFCC: Èèyàn 647 la ti rán lọ sẹ́wọ̀n Idi ti ọgba ẹwọn fi nkun akunfaya ni Naijiria Bi o tilẹ jẹ pe ọgbẹni Adeniyi kọ ni ẹlẹwọn akọkọ ti yoo kẹkọ gba oye ijinlẹ lọgba ẹwọn ṣugbọn ko fẹẹ si eyi to tii gba meji nibẹ ṣaaju rẹ.
Èyí ni ìgbà karùndínlọ́gbọ̀n tí ikò Barcelona yóò gba ife ẹ̀ye La liga.
Nígbà tí ó wí báyìí tàn ẹ̀rù bà mí, mo ní, mo sún mo kan ògiri ná wàyí, mo gbé ẹbọ kọjá mọ́ṣáláṣí, mo fi ẹlẹ́dẹ̀ jẹ sàrì, mo sun ọ̀gẹ̀dẹ̀ dúdú fún Òyìnbó jẹ, mo ní kí Haúsá kọ górò sílẹ̀, mo wí pé Yorùbá kò gbọdọ̀ jẹ ẹ̀kọ - Ọ̀rọ̀ yìí bí mi nínú tóbẹ́ẹ̀ tí n kò fi sọ̀rọ̀ sí Baba-onírùngbọ̀n-yẹ̀úkẹ́ títí a fi dé ilé.
" Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Africa Eye: Ìrírí àwọn ọ̀dọ́bìnrin tó dágbà sójú pópó àti ìrètí wọn fún ọjọ́ ọ̀la Oladele wa rọ awọn ero lati maa rinrinajo pẹlu ọkọ ti wọn se fun ẹru kiko nikan nitori awọn ijoko wọn ko wa fun ijoko.
Pelu edun okan ni awon egbe oselu Movement Democratic Change  (MDC) ohun wa, awon alatileyin egbe naa ko faramo awon adari meji ti won ni, eyi ti o sokunfa yiyan adele Aare tuntun Nelson Chamisa.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Fulani Kidnapping: Owó púpọ̀ la san kí wọ́n tó fi mi sílẹ̀ Nkan ti ileeṣẹ ọlọpaa le sọ ni pe agbebọn ni awọn to ṣe ikọlu naa, nitori pe a ko ti i ni aridaju pe ẹya kan, Fulani darandaran tabi adigunjale ni wọn."
Ọkọ̀ òfurufú náà gba àṣẹ láti gbé adájọ́ àgbà ilé ẹjọ́ gíga kan nílú Eko Justice Adefowope Aokojie Sirika sọ èyí lásìkò ijábọ̀ ojoojúmọ́ ti àwọn ìgbìmọ̀ amúṣẹ́ṣe ti ààrẹ Buhari yàn lori Coronavirus ma ń ṣe fún ará ìlú nílùú Abuja sàlàyé pé àṣẹ ilé iṣẹ́ ọkọ̀ òfurufú ni wọ́n fọ́wọ́si pé kó rìn ni ọjọ́ kẹrinla oṣù láti gbé adájọ́ náà nítorí iṣẹ́ pàtàkì ló ń lọ fún.
AFCON 2019: Orílẹ̀èdè wo ló tún leè mókè lẹ́ka míràn l‘Afirika
"Ọ̀pọ̀ ìwádìí lo ti fi ìfdí rẹ̀ múlẹ̀ báyìí pé, àwọn tó ti ni ààrun covid-19, ti wọ́n si ruu la le ni èròjà T Cell, ti yoo si máa foju sọ́nà fún ààrun covid-19 tó bá tún jẹyọ, yála ẹni náà fàmì hàn nígbà àkọ́kọ́ tàbi kò fàmìhàn, Oríṣun àwòrán, Getty Images Ìmọ̀ tún ti fi hàn pé, ìgbà míràn àyẹ̀wò lé fi hàn pé, ẹ̀lòmìràn le maa ni èròjà tó le gbògun ti ààrun covid-19, eyiun ""Antibodies', sùgbọn tí yóò ni ""T Cell""."
Ẹ má jẹ́ kí èyí yà yín lẹ́nu pé a pẹ́ tó bẹ́ẹ̀ bí ìlú kan tí a kò lọ sí ibi tí wọ́n rán wa.
Nítorí mímọ́ ni Tẹmpili Ọlọrun, ẹ̀yin náà sì ni Tẹmpili Ọlọrun.
osisẹ ajọ eleto idibo INEC mẹ́ta lasiko eto idibo naa.
Ọkùnrin kan da ṣọ́ọ̀ṣì rú lásìkò ìgbéyàwó, Ó ní òun lọkọ àárọ̀ ìyàwó tuntun Ìwọ tó ń ṣí ara sílẹ̀ lọ ṣọ́ọ̀ṣì, ṣé apàyàn kọ́ ni ẹ́ báyìí?
Nígbà tí ó tún ṣe, ejò kejì tún bẹ̀rẹ̀ sí gun Ìjànbáforítì lára eléyìí náà sì tún tọ ara rẹ̀ títí ó fi de èjìká rẹ̀; nígbà tí àwọn ejò, méjèèjì yìí sí rí ara wọn, wọ́n bẹ̀rẹ̀ sí ṣiré ní ọ̀run ọkùnrin náà.
Àwọn ọmọ Merari nìwọ̀nyí: Mahili ni baba Libini, Libini bí Ṣimei, 
Ọpọ awọn ọmọ Naijiria lo ni iṣẹ takuntakun ni awọn obinrin n ṣe ninu ogo ere idaraya Naijiria lasiko yii.
Oríṣun àwòrán, @BashirAhmaad Ilé Aṣòfin yóò pe Godswill Akpabio l'ẹ́jọ́ fún ìbanilórúkọ jẹ́ Ta ni Yusuf Satia ti iku mu lọ?
Awon ti won yapa ohun, ti won pera won ni orile-ede Ambazonia n tiraka lati yapa kuro lorile-ede Cameroon, eyi ti ijoba ko faramo igbese naa, leyin ti won da ifehonu-han ti o waye ninu osu  kewaa odun to koja ru, eyi ti won fi sami erongba lati kede ominira won.
iṣuna owo ilu Ile Igbimo Asọfin Ipinlẹ Eko ti gbaradi
Ọjọru, ọjọ kẹtadinlọgbọn, oṣu Karùn-ún, ọdun 2020 ni àwọn kan fipá bá ọmọbìnrin ẹni ọdún 22 yii lopọ̀ nínú sọ́ọ́sì.
 WizkidAdako Rege to dun ju Holy Holy – 2BabaEyi ti won ya daradara julo lodunJoromi – SimiTakasufe to je itewogba juReekado BanksEyi to maa dun siiMayorkunOrin miran to dun juFun mi lo wo mi – Aramide feat.
Agbaboolu owo iwaju fun orile-ede Portugal, Cristiano Ronaldo ti yanana idi ti oun fi darapo mo iko agbaboolu Juventus pe, oun fe ran iko naa lowo lati gba ife-eye idije lolokan-o-jokan nile Europe, papaajulo ife-eye UEFA champions league.
Ẹfunroye Tinubu - Ògbóǹtagí oníṣòwò, olówò ẹrú àti afọbajẹ Samuel Ajayi Crowther, òjíṣẹ́ Ọlọ́run tó gbé èdè Yoruba lárugẹ Mọrèmi Àjàṣorò, akọni obìnrin tó gba Ilé Ifẹ̀ sílẹ̀ lóko ẹrú Bakan naa lo fi ye wa pe isẹ́ abẹ́ ko sẹsẹ bẹrẹ, o ti wa lati atetekọse, ti awn eeyan kan si gba pe Aláàfin Ọ̀rọ̀ǹpọ̀tọ̀niyùn ni ẹda akọkọ to jẹobinrin, amọ to yipada si ọkunrin, gẹgẹ bawọn eeyan kan se n se lode oni.
Ohun to daju ni pe, nkan pataki ni ọ̀pá àṣẹ jẹ fun ọba nilẹ Yoruba, eyi si lo mu ki BBC Yoruba ba awọn onimọ nipa àṣà ati ìṣe ilẹ Yoruba sọrọ.
ni “owo to le ni ọgọ́rùn
68,879 ti gba iwosan nigba ti awọn 1,231 ti ba arun naa lọ.
Nítorí pé ìyè ni wọ́n jẹ́ fún àwọn tí ó rí wọn,ati ìwòsàn fún gbogbo ẹran ara wọn.
Koda, Iraq ti ibode rẹ pẹlu Syria nitori bẹ ẹ.
“Báyìí tún ni ìjọba ọ̀run rí.
Láti ayébáyé ni a ti yàn mí,láti ìbẹ̀rẹ̀, kí á tó dá ayé rárá.
O ṣalaye pe owurọ ọjọ Ẹti ni wọn gba ominira wọn ti wọn si ti darapọ mọ awọn ẹbi wọn.
Wọn yóò máa da omi tútù sórí òrùlé bí ìyá ìkókó ṣe ń gbé omọ rẹ̀ bọ̀.
O fikun pe wọn yoo gbe osisẹ ọlọpaa naa lọ sile ẹjọ laarin ọjọ meji si asiko yii.
Ìjàmbá ṣe wá ní Barcelona, aṣọ ò bá Ọmọ́ye wa mọ́- Gerard Pique Mama Arsenal ṣeé débi èrè, ẹgbẹ́ kan ti fún màmá l'ẹ̀bùn owó Mi ò tí ì mọ obìnrin rí; kódà, mí ò ní 'Girlfriend'- Mr Macaroni Agbára Oṣó àti Àjẹ́ yóò mú àgbéga bá ìmọ̀ ẹ̀rọ Nàíjíríà - Elebuibon Ìdẹra dé fún Nàíjíríà!
Àjọ ajàfẹ́tọ̀ọ́: Ènìyàn 2000 ti kú nínú ìṣẹ̀lẹ̀ darandaran
Awon eniyan meji ti padanu-emi won nigba ti awon meje si farapa, ninu laasigbo ti o waye laarin awon olopaa ati awon ara-ilu nilu Harare ti n se olu ilu orile-ede Zimbabwe.
Ó ní ààbò tó dájú wà ni ìpińlẹ̀ Kebbi ko sì sí ìdí kan ti àwọn yóò fi ti ilé ìwé pa lásìkò yìí.
Ẹ kò gbọdọ̀ fi ohunkohun tí ó bá ní àbààwọ́n rúbọ, nítorí pé, OLUWA kò ní tẹ́wọ́gbà á lọ́wọ́ yín.
niluu Ibadan, ti so omokunrin kan ti oruko re n je Adebimpe Babajide Quadri, si
O tun jẹ ọga agba ikọ ọlọpaa kogberegbe, Mopol 5 to wa ni ilu Benin.
Baba Suwe: Àwọn ǹkan tí ọ̀pọ̀ kò mọ̀ nípa Baba Suwe
N óo mú wọn jáde kúrò láàrin àwọn orílẹ̀-èdè yòókù, n óo kó wọn jọ láti gbogbo ilẹ̀ ayé, n óo sì kó wọn wá sí ilẹ̀ tiwọn.
Bẹ́ẹ̀ ni èmí àti ọ̀rẹ́ mi kúrò nínú ilé ẹ̀mí burúkú náà tí a bá ilé tiwa lọ, nígbà tí a sì ń bọ̀ lọ́nà tí mo béèrè ìdí rẹ̀ tí Baba-onírùngbọ̀n fi ń ṣẹ́jú sími wípé kí n má bọ Ikú lọ́wọ́, kí n má sì ṣe dọ̀bálẹ̀ fún ẹbọra náà, àti wí pé n sọ́ra lórí àkete rẹ̀, ó dá mi lóhùn, ó wí pé: Ẹni tí ó bá bọ Ikú lọ́wọ́ tí olúwaarẹ̀ parí, ẹni tí ó dọ̀bálẹ̀ fùn un ti olúwaarẹ̀ sọnù, bẹ́ẹ̀ ni ẹni tí ó bá jókòó lórí akéte rẹ̀ ti olúwaarẹ̀ di ọ̀run alákeji.
Nitori eyi, àṣà àti èdè Yorùbá kò ṣe fi ọwọ́ rọ sẹhin.
Ẹsẹ́ púpọ̀ fún àti leyin yín pẹ̀lú  ÈDÈ YORÙBÁ REWÀ láti ọdún tí a ti bẹ̀rẹ̀, ọdún 2019 a tún fún yàtò.
Abẹwo Buhari si Taraba Faari Buhari Àwọn àwòrán mánigbàgbé nípa Ààrẹ Muhammadu Buhari Iroyin nipa awọn ti Buhari ti fi orukọ wọn ranṣẹ: Mamora, Lai Mohammed, Gbemi Saraki wà lára minista Buhari tuntun.
Bi won yoo se maa se ise Oga olopaa ti se atunto bi awon eka FSARS’ naa yoo se maa se ise won.
Wọ́n ń ta gbọ̀n-ọ́n-gbọ̀n-ọ́n káàkiri bí ọ̀mùtí,gbogbo ọgbọ́n sì parẹ́ mọ́ wọn ninu.
Nigba ti awọn ọlọpaa mu Akinola, o jẹwọ wipe ọmọ ẹgbẹ okunkun Aiye ni oun.
Awọn oṣiṣẹ maa n ṣe aṣiṣe Nigba miran ti oniṣẹ ba tiẹ ra ohun elo ikọle to jẹ ojulowo, awọn oṣiṣẹ le maa po gbogbo rẹ pọ daradara.
Ẹ̀mí mi rọ̀ mọ́ ọ;ọwọ́ ọ̀tun rẹ ni ó gbé mi ró.
Ẹfunsetan Aniwura, obìnrin tó ju ọkùnrin lọ Ọ̀rọ̀ǹpọ̀tọ̀niyùn, Aláàfin obìnrin àkọ́kọ́ rèé, tó ní nǹkan ọkùnrin Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Olusegun Obasanjo: Ọmú ìyá mi ti mo fi ń mùkọ ni kekere ló jẹ ki ń lókun Ṣugbọn iwadi ẹka ajọ EU naa fi han pe awọn kudiẹ kudiẹ ṣi wa ninu ilana eto idibo naa.
Eyi mu ki ara mi gbọn jinnijinni, ti mi o si mọ nkan ti mo n ṣe mọ.
Má lọ́wọ́ ninu ọ̀rọ̀ ìsọkúsọ,sì jìnnà sí ọ̀rọ̀ àgàbàgebè.
Ó bá gbogbo àwọn eniyan pataki pataki Asiria ṣe àgbèrè, ó sì fi oriṣa gbogbo àwọn tí ó ń ṣẹ́jú sí ba ara rẹ̀ jẹ́.
Ó bẹ̀rẹ̀ ìrìn àjò rẹ̀ láti Babiloni ní ọjọ́ kinni oṣù kinni, ó sì dé Jerusalẹmu ní ọjọ́ kinni oṣù karun-un nítorí pé ó rí ojurere Ọlọrun.
' 'Àti kékeré ni mo ti ń tẹ̀lé bàbáa mi lọ ibi iṣẹ́ tórí mo fẹ́ mọ iṣẹ́ Mọkálìíkì' Idẹyẹsi ọhun pọ latọdọ ọ̀kọ, mọlẹbi ọkọ koda ladugbo to bẹẹ to fi pada dero ile baba rẹ.
Ọjọ́ kejìdílọ́gbọ̀n oṣù kejìlá ọdun 2018 ni àwọn alásẹ Saudi ti mú Zainab sẹ́wọn nígbà ti []oun , màmá àti ẹgbọ̀n rẹ̀ jọ lọ fún Umrah, ni Saudi Arabia, ti wọn si ni wọn ká òògunolóró mọ inú ẹrẹ̀ rẹ̀.
Ṣugbọn Jesu pè wọ́n sọ́dọ̀, ó ní, “Ẹ mọ̀ pé àwọn aláṣẹ láàrin àwọn alaigbagbọ a máa jẹ ọlá lórí wọn, àwọn eniyan ńláńlá láàrin wọn a sì máa lo agbára lórí wọn.
Iko agbaboolu Super Eagles ti sun soke ninu ipo ate ajo FIFA ti inu osu kewa ti o sese jade.
Ní ọ̀sẹ̀ mẹ́ta lẹ́hìn tí  wọ́n parí Ìdíje London 2012, abala kejì tí wọ́n npè ní Paralimpics á bẹ̀rẹ̀.
Gbajugbaja onkorin omo ile Mali ni, Kassé Mady Diabaté, ti dagbere faye pe o digbose.
Èyí ni àwọn arẹwà ‘ẹ̀lẹ̀ Daddy’, àfẹ́fẹ́ tí Aláàfin fi ń mí Mọ̀ síi nípa Victor Giadom tó já ipò adelé alága ẹgbẹ́ APC gbà mọ́ Ajimobi lọ́wọ́ Gbogbo ọmọ ìgbìmọ́ aláṣẹ ìjọba ìpínlẹ̀ Oyo ló ṣe àyẹwò ààrùn Covid-19 Sùgbọ́n.
Awọn iroyin miran ti ẹ le nifẹ si: Ọwọn epo petiroo n tẹ siwaju Lẹta Ọbasanjọ si Buhari Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Yoruba Films: Femi Adebayo sọ ẹran àgbò rẹ̀ lórúkọ tuntun, Bukky Wright ṣ'ọjọ ìbí 3 Ìgbé 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 5 Ìgbé 2020 Oríṣun àwòrán, others Ajakalẹ aarun coronavirus le wa nita ni tootọọ, amọ aarun naa ko ni kawọn oṣere tiata Yoruba ma ṣe ti wọn.
Sibẹ ọpọlọpọ ninu àwọn aṣaaju gbà á gbọ́; ṣugbọn wọn kò jẹ́wọ́ nítorí wọ́n bẹ̀rù àwọn Farisi, kí wọn má baà yọ wọ́n kúrò ninu àwùjọ; 
Abilekọ Babalọla ni ọmọ oun jẹ ọmọ to ma n mu inu oun dun nigba gbogbo nitori o ma n pa oun lẹrin pẹlu iṣesi rẹ.
Maya Jammal, omo odun meta pere to gbadura ilera pipe fun mi lori ero ayelujara to kari aye jomiloju pupo, omo odun mewaa Aisha Aliyu Gebbi naa fi leta ranse si mi pe inu oun n dun si mi, bakan naa ni Nicole Benson to je omo odun mejila fi egberun marun ati eedegberin nair o le kobo marundinlaadorun (N5,700.
Ni deede aago mejo koja iseju marun un aaro yii ni oludije fun ipo gomina labe asia egbe Peoples Democratic Party, PDP, ogbeni  Ademola Adeleke, jade lati wa dibo re ni  Ward 2 Unit 9 Saka Abogunde .
Ẹ wo àwọn ọdọmọkunrin Sioni,àwọn ọmọ tí wọn níye lórí bí ojúlówó wúrà,tí a wá ń ṣe bí ìkòkò amọ̀;àní, bí ìkòkò amọ̀ lásánlàsàn.
 “Nigba ti mo to se ise abe si ifarapa ti mo ni lowo mi, ni mo to mo ohun ti Juan Martin la koja.
“Ẹ kò gbọdọ̀ gbin ohunkohun sáàrin àwọn àjàrà tí ẹ bá gbìn sinu ọgbà àjàrà yín, bí bẹ́ẹ̀ kọ́, àjàrà náà, ati ohun tí ẹ gbìn sáàrin rẹ̀ yóo di ti ibi mímọ́.
Adajọ Shusaidah ko sọrọ nipa iṣẹlẹ yi amọ o ni nina eeyan lẹgba labẹ Sharia a ma jẹ ẹkọ fun ẹ́lẹṣẹ́ lati dẹkun hihu iru iwa bẹẹ mọ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Onigbinde àti Owolabi: Ààrẹ NFF tuntun gbọdọ̀ sàwárí ọ̀jẹ̀ wẹ́wẹ́ agbábọ́ọ́lù Iṣorọ mii tawọn eniyan ko tun fi gba ti ẹ ni bii ti eyi ti ajọ elere sisa Naijiria ko tii rẹnu ṣalaye ohun ti wọn fi ẹgbẹrun lọna aadoje owo dọla ilẹ okeere ti ajọ elere sisa agabye ṣeṣi san sinu asunwọn banki wọn.
Iwáju ilé gagara ti wọ́n n pè ni Opic lágbàgè Iṣẹri ni ìṣẹ̀lẹ̀ náà ti wáye,ọ̀ps àwọ̀n ènìyàn lo n fi ẹsẹ̀ rin nláàrin igboro nítori ko si bí wan yóò ṣe ri mọ́tò.
Oríṣun àwòrán, @BashirAhmaad Ṣugbọn fun ipinlẹ Kano, isede tọsan-toru ni yoo ṣi wa nibẹ.
Gomina Ìpínlẹ̀ Osun, Adegboyega Oyetola bá àwọn èèyàn Ìpínlẹ̀ náà sọ̀rọ̀ ni irọlẹ Ọjọ́bọ.
Ó da ìsọ̀ àwọn tí wọn ń ta ẹyẹlé rú.
Awọn ibi ti aarẹ Trump a ṣabẹwo si ni Westminister Abbey ati ọdọ Omọba Charles ati aya rẹ.
"O ni ""nkan ti mo sọ ni pato lọjọ yẹn ni pe aarun yẹn maa dawọ duro nibi to ti bẹrẹ."
“OLUWA sán ààrá láti ọ̀run wá,ayé sì gbọ́ ohùn ọ̀gá ògo.
O so pe “Ni bayii, awon eniyan bi I mọ́kànlélọ́gọ́rùn ún ni won ti so emi won nu, ti awon eniyan bi i ọ́ọ̀dúnrún ti di alainile lori, ipinle kogi ni iye awon eniyan to farapa nibi isele naa poju si i.
Ẹ̀yin òkè ńlá, kí ló dé tí ẹ fi fò bí àgbò?
Oluwo fikùn pé òun wà nínú ogún Liberia lọ́dún 1989, tí òun sì ti dé ẹnu ikú ni igba mẹ́jọ, bẹ́ẹ̀ si ni àkókò ogun aifojuri là wá yìí, to jọ tí ogun ìbọn.
Ẹ mù Olówó-ayé, ẹni tí ó gba Igbó Olódùmarè lọ́wọ́ Àǹjànnú-ìbẹ̀rù, ẹ wẹ̀ ẹ́, \w wọ̀ ọ́ ni ṣòkòtò, ẹ ṣe é lọ́ṣọ̀ọ́ tí ó ju ìwọ̀nyí lọ.
Ẹwẹ, ajọ ajafẹtọ ọmọniyan, Amnesty Int.
Bẹẹ ni irufẹ obinrin bẹẹ ko gbọdọ ja ewe ati egbo tabi fi ọwọ kan wọn, titi ti nnkan oṣu rẹ yoo fi pari.
Koda ọrọ ibomu lasan gan ti di ọrọ oṣelu, pẹlu bi wan ṣe maa n ri Biden ni gbogbo igba to n lo ibomu nigba ti Trump ni tirẹ mu ọna ida keji gba lori eyi.
Àwọn ọba alágbára ti jẹ ní Jerusalẹmu, wọ́n ti jọba lórí gbogbo agbègbè òdìkejì odò, wọ́n sì gba owó ìṣákọ́lẹ̀, owó bodè lọ́wọ́ àwọn eniyan.
"Lẹyin iṣẹlẹ yii ni ileeṣẹ iroyin Daily Trust gbe iroyin kan jade ti wọn pe akọle rẹ ni ""FFK, The Drug Addled Thug In Designer Wears"" lati jẹ ki awọn eniyan mọ iru eniyan ti Femi Fani Kayode jẹ."
Opin ọsẹ ni awọn ibi ti o ti wa silẹ julọ.
    Ìgbà tí ètè Ayédèrúẹ̀dá dákẹ́ ọ̀rọ̀ i sọ, ojú tìí púpọ̀, nǹkan tí ó burú níbẹ̀ ni pé ẹnikẹ́ni kò lágbára lórí ètè rẹ̀, ètè ń tìkararẹ̀ sọ̀rọ̀ ni, ìbá ṣe pé ènìyàn lè kìlọ̀ díẹ̀ fún ètè ni, ayédèrú-ẹ̀dá ìbá ti kilọ́ fún tirẹ̀.
Niṣe ni Motara n fi ọmọ naa ṣe yẹyẹ bo ti ṣe n tọrọ ọti ẹlẹrindodo to si n sare tẹle ọkọ.
Bakan naa ni wọn tun fi ẹsun kan an pe o dari owo ti ajọ naa pa lara tita awọn dukia ti ijọba gba lọwọ Ọga Agba ọlọpaa nigba kan, Tafa Balogun, ati gomina ipinlẹ Bayelsa, Alamieyesiegha.
"Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: PDP: A ò fẹ́ ẹ̀jẹ̀ Buhari gẹ́gẹ́ bí alábojútó ìbò kíkà ASUU: A kò ṣetán láti fòpin sí ìyanṣẹ́lódì Ènìyàn márùn-ún kú nínú bàlúù ogun tó já ni Damasak Ilé ẹjọ́ fagilé ìpè Dino láti wá kó Ọlọ́pàá kúrò nílé rẹ̀ Ọ̀sẹ̀ méjì péré la fẹ́ kí iṣẹ́ reluwe Eko sí Ibadan parí - Amaechi Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ìgunnukó: Àwọn Tápà gbà pé ẹni tó bá ń sin Ìgunnukó kò ní ráùn ohun rere ""Eeyan okoolelọọdunrun o din mẹjọ (312) pere la ni ko lọ naju ni ọgba ẹwọn lọdun 2018, am ni 2019 ta wa yii, ajọ EFCC yoo ri daju pe a sọ iye awọn taa ju sẹwọn di okoolelẹgbẹta ati mẹrin (624)."
''₦30000 ní mo fí bẹrẹ iṣẹ yí.
Awon oludibo lorile-ede Sierra Leone tu yaayaa jade lojo-Ru lati dibo yan Aare tuntun, leyin ti Aare Ernest Koroma ti o wa lori alefa n kogba wole.
fun ekun Gusu –  Jasper AzuatalamOludari
Kí ló dé tí o fi dàbí ẹni tí ìdààmú bá;bí alágbára tí kò lè gbani là?
Kàkà bẹ́ẹ̀, ó jíròrò pẹlu àwọn ọdọmọkunrin, ẹlẹgbẹ́ rẹ̀, tí wọ́n jọ dàgbà pọ̀, tí wọ́n wà ní ààfin pẹlu rẹ̀.
Yorùbá dùn lédè, ẹ máa sọọ́ Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Yoruba culture: Adelé Olúbọ̀rọ̀pa ní ọmọ ọdún 16 ni òun jẹ́ Adelé, kó tó lọ sí Fáṣítì
Ènìyàn 452 ni èsì àyẹ̀wò sọ pé ó tún ṣẹ̀ṣẹ̀ ní Covid-19 ní Nàìjíríà Ìhòhò ọmọlúàbí ni mo má a ń bá àwọn ọmọkùnrin mi wí - Elesho Makinde kéde àyípadà lórí ọjọ́ táwọn akẹ́kọ̀ọ́ yóò wọlé padà l'Oyo Ohun tí ọlọ́pàá ń ṣe rèé láti sàwárí àwọn ‘mùjẹ̀-mùjẹ̀’ ní Akinyele Ileesẹ ijọba Ghana to n dari ọrọ ilẹ ni awọn ko ni akọsilẹ to fi han pe ileesẹ ijọba Naijiria san owo kankan lori ilẹ naa.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Akomolede ati Asa: Mọ̀ si nípa àwọn ọ̀nà tí Yorùbá ń gbà ran ara wọn lọ́wọ́ Tinubu ni awọn oluwọde ni lati fun ijọba Buhari laaye, ko le ṣe amuṣẹ awọn ileri to fẹ ṣe nipa ọrọ to wa nilẹ yii, paapa atunto ileeṣẹ ọlọpaa.
Àwọn eniyan ṣá tún ń mú ọrẹ àtinúwá yìí tọ Mose lọ ní àràárọ̀.
Ọlọ́pàá Germany ń wádìí àfurasí mẹ́rin nínú àwọn tó kọlu Ekweremadu ni Germany
Awọn onisowo kan n fapajanu lori bi wọn ti ṣe fẹ fi oye iyalaje ati babalaje lọlẹ ni ọja naa.
This was confirmed by the Nigeria Supreme Council for Islamic Affairs which announced the sighting of the crescent moon marking the start of the Islamic month.
má fi ojú pamọ́ fún mi!
Ninu idibo ọdun 2019, ti saa keji isejọba Abiola Ajimobi n tẹnu bọ odo lọ, o tun gbinyanju lati dije fun ipo Ṣẹnetọ sile asofin agba, Àwọn àdúgbò Ibadan gborúkọ tuntun látẹnu Ajimobi Ko si ẹrí to dájú láti dá Ajimobi láre gẹgẹ bí olúborí - Ilé Ẹjọ́ Ọmọ atàpátadìde ni mí, télọ̀ ni bàbá mi- Abiola Ajimobi Seyi Makinde, yé é sọ̀rọ̀ mi láìdà - Gomina Ajimobi Amọ ṣe lo fidi rẹmi ninu idije naa, ti Ṣẹnetọ Kola Balogun si jawe olubori.
Gbogbo ìdílé Kora ni alabojuto iṣẹ́ ìsìn ninu tẹmpili ati olùṣọ́ ẹnu ọ̀nà àbáwọlé àgọ́, gẹ́gẹ́ bí baba wọn ti jẹ́ alabojuto Àgọ́ OLUWA ati olùṣọ́ ẹnu ọ̀nà àbáwọlé rẹ̀.
Fadaka ati wúrà tí ọba kójọ, pọ̀ bíi òkúta ní Jerusalẹmu, igi kedari sì pọ̀ bí igi sikamore tí ó wà ní Ṣefela, ní ẹsẹ̀ òkè Juda.
Ọlọ́pàá Kogi - BBC News Yorùbá BBC News, YorùbáFò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Kogi àti Bayelsa: Irọ́ ni pé wọ́n sèkọlù sí Gómìnà Seyi Makinde - Ọlọ́pàá Kogi 15 Bélú 2019 Oríṣun àwòrán, SeyiMakinde/Facebook Àkọlé àwòrán, Seyi Makinde ni Alága ẹgbẹ́ òsèlú PDP fún ètò ìdìbò sípò gómìnà tí yóò wáyé ní Ọjọ Kẹrindinlogun, Osu Kọkanla, odun 2019.
Ọba Ọlagbegi II kúrù ní ǹǹkan yẹpẹrẹ, àfi bí a bá máa tan ara ẹni jẹ.
Ta ló ń lọ sílé lónìí nílé ẹlẹ́gbọ̀n ọ́n àgbà BB Naija?
“Iranṣẹ náà bá pada lọ jíṣẹ́ fún oluwa rẹ̀.
Obìnrin kan dèrò ilé ẹjọ́ lórí ẹ̀sùn pé ó fi ọ̀bẹ rẹ́ ọmọ rẹ̀ lọ́rùn Adamu Adamu, Minista ètò ẹ̀kọ́ ti fi òfin àátẹ̀lẹ́ síta kí àwọn ilé ìwé lè wọlé Makinde ti sọ̀rọ̀ lẹ́yìn tí asekúpani Akinyele sálo mọ́ àwọn ọlọ́pàá lọ́wọ́ ní àhámọ́ Olólùfẹ́ mi ṣèèsì fi ọkọ́ gbá mi sí gọ́tà, mo rò pé ọlọ́jọ́ dé ni - Iya Osogbo Bẹẹ ba gbagbe, asaaju ijọ Living Spring, David Oyedepo ti kọkọ koro oju si ofin CAMA naa, ti ijọba si fesi pada fun pe o gbọdọ tẹle ofin Naijiria dandan ni.
Ọrọ Oṣelu Awọn alatilẹyin gomina ipinlẹ Kano ti ṣaba maa n fi aidunnu wọn han si ipa ti Emir n ko lori eto oṣelu ipinlẹ naa.
Ó ní àwọn padà tẹ̀lé wọn wọnú igbó lọ níbi tí wọ́n ti bẹ̀rẹ̀ sí ko wọn ní pápámọ́ra.
odaran meji to lowo si gbigba keke alupupu ti a mo si okada lowo awon to ji won
Amoni ọmọ rẹ̀, sì jọba lẹ́yìn rẹ̀.
Nítorí Jeroboamu ṣe ohun tí ó bí OLUWA Ọlọrun Israẹli ninu: ó dẹ́ṣẹ̀, ó sì mú kí Israẹli náà dẹ́ṣẹ̀.
Lara awọn to tun wa nibi abẹwo naa ni minisita fun ọrọ abẹle, Rauf Aregbesola, ati minisita keji fun eto ilera, Olorunninbe Mamora, to fi mọ minisita fun okoowo ati ọrọ awọn ileeṣẹ, Niyi Adebayo.
Ní inú ìwé tí a kọ sí àwọn àlejò tí ó wá sí RightsCon, àpérò tó dá lórí ẹ̀tọ́ irinṣẹ́ ẹ̀rọ-ayárabíaṣá tí ó wáyé ní Toronto nínú oṣù Èbìbì ọdún 2018, Alaa rọ àwọn alátìlẹ́yìn láti “ṣe àtúnṣe sí ìjọba àwa-arawa ti wọn”.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Eégun àti orò, bí wọ́n ṣe jọ bí Ẹ̀ṣà Egúngún nílẹ̀ Yorùba rèé Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Fídíò, Erelu Elemure: Ìyá mi rò pé mi ò lè tibi kíkọrin bíi bàbá mi là21 Bélú 2020 Akomolede Eko round up: Àwọn Olùkọ́ ìpínlẹ̀ Eko dárà lórí Akọ́mọlédè àti Àṣà lórí BBC7 Bélú 2020 4:26 Fídíò, Akomolede Yoruba: Kí ni ìdí tí aṣọ fi máa ń pọ̀ lára Egúngún ju Orò lọ́?
Modekai tíí ṣe Juu ni igbákejì sí Ahasu-erusi ọba.
Tí ó bá wá ń dá òfin lẹ́jọ́, ó sọ ara rẹ̀ di onídàájọ́ òfin dípò olùṣe ohun tí òfin wí.
Oríṣun àwòrán, @IsiakaAdeleke1 Àkọlé àwòrán, Awọn amoye kan ni orukọ ẹgbọn Ademola, Isiaka Adeleke ko ipa ribibi bi o ti se di Sẹnẹtọ Idile Oloselu ni Ademọla ti wa Ti a ba so wi pe oselu jẹ nkan ti o n tọ iran Sẹnẹtọ Adeleke lẹyin, a ko j'ayopa.
Oloye Ladoja ni gẹgẹ bii gomina to n kogba wọle lọ, o yẹ ki Ajimobi fi gbogbo iṣẹ pataki to n ṣe han Seyi Makinde ni.
Kì í ṣe irú majẹmu tí mo bá àwọn baba ńlá wọn dá, ní ìgbà tí mo fà wọ́n lọ́wọ́ jáde ní ilẹ̀ Ijipti, àní majẹmu mi tí wọn dà, bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé èmi ni ọkọ wọn.
Mo ṣetán láti mú kí àwọn tí kò bèèrè mi máa wá mi, ati láti fi ara mi han àwọn tí kò wá mi.
Ó ń retí kí wọn máa ṣe ẹ̀tọ́,ṣugbọn kàkà bẹ́ẹ̀ wọ́n ń paniyan;ó ń retí ìwà òdodo,ṣugbọn kàkà bẹ́ẹ̀, àwọn tí wọn ń ni lára ni wọ́n ń kígbe.
Wọ́n gbàgbé iṣẹ́ rẹ̀,ati iṣẹ́ ìyanu tí ó ṣe hàn wọ́n.
OLUWA mú kí ìpayà bá àwọn ará Amori, nígbà tí wọ́n rí àwọn ọmọ Israẹli, àwọn ọmọ Israẹli bá bẹ̀rẹ̀ sí pa wọ́n ní ìpakúpa ní Gibeoni.
Nítorí Ọlọrun yóo dájọ́ fún àwọn oníṣekúṣe ati àwọn àgbèrè.
Abala kejì ija wọn lo waye ni alẹ ọjọ ti a n sọ yii.
 fàtáì di ìlú mọ ̀ ọ ́ ká pẹ ̀ lú ìṣọwọ ́ ta jìtá rẹ ̀ lọ ́ nà àrà .
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Sheffield United vs Arsenal: Evra ní Arsenal sì wà lọ́mọ ìkókó lẹ́yìn ọdún mẹ́wàá 22 Ọ̀wàrà 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Ko si iyatọ kankan ninu ẹgbẹ agbabọọlu Arsenal lati bii ọdun mẹwaa sẹyin, bakan naa ni si wa.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: ‘Gbajúgbajà òsèèré míràn tún jáde láyé’ Ǹjẹ́ o mọ̀ pé Baba Sala ló kọ́ Sunny Ade nísẹ́?
Buhari n gbogun ti , lati igba ti o ti di aare lorile ede Naijiria.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Nnamdi Kanu kò sí ní orílẹ̀èdè wa rárá o- Ìjọba Orílẹ̀èdè Israel 19 Èrèlè 2018 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 23 Ọ̀wàrà 2018 Oríṣun àwòrán, Elliot Ugochukwu-Ukoh Orilẹede Israel ti ṣalaye pe aṣiwaju ẹgbẹ IPOB, Nnamdi Kanu ko si ni orilẹede naa.
Inú ìyàrá ni ìyá ìkókó gbọ́dọ̀ wà pẹ̀lú ìkókó náà láti ọjọ́ tí ó bá ti bímọ títí di ọjọ́ ìkomọjáde.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Se lootọ ni pe eniyan le ko Coronavirus lara ẹni to ti kú?
Yàtọ̀ sí mímu, àǹfàní tó wà lára igbó pọ̀ jaburata- Akeredolu Kò tíì sí ẹni tó lè sọ ìgbà táwọn akẹ́kọ̀ọ́ yóò wọlé padà ní Nàìjíríà-Mínísítà fétò Ẹ̀kọ̀ọ́ Òṣìṣẹ́ ààfin mi tí kò bá lo ìbòmú yóò pàdánù isẹ́ rẹ̀-Oluwo Gómìnà Ṣèyí Mákindé ṣàlàyé ìdí tí òun kò fi leè ti ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́ pa nítorí COVID-19 Wọn ní ṣe akọtun ìbéèrè fún owoya yìí, èyí tí yóò mú kí gbèsè tí ilẹ wa jẹ́ láwùjọ agbaye fò fẹrẹ sì biliọnu mẹtadinlọgọrun dọla ($97bn), kò ní ṣe àkóbá ńlá fún igbaye-gbadun àti ọjọ́ ọ̀la àwọn ọmọ orílẹ̀ èdè yìí?
Ó ní, kò yẹ ènìyàn tó jẹ́ Sẹ́nétọ̀ hùwà bẹ́ẹ̀, bí ó ti lẹ̀ jẹ́ pé òun kórira bí Aare Muhammadu Buhari ṣe ń ṣe sí àwọn tí ó gbe sórí oyè.
Àpèjúwe ìpín tí ó kan ẹ̀yà Juda lára ilẹ̀ tí àwọn ọmọ Israẹli gbà, tí a pín fún wọn gẹ́gẹ́ bí iye ìdílé wọn nìyí:Ilẹ̀ náà lọ títí dé apá ìhà gúsù, ní ààlà ilẹ̀ Edomu, títí dé aṣálẹ̀ Sini.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ìgbà àkọ́kọ́ kọ́ nìyíì tí omíyalé yòó ṣọṣẹ́ ní Nàìjíríà Awọn eniyan ṣi pọ babi ni ile iwe alakọbẹrẹ ilu Jibiya, ti wọn lo gẹgẹ bi ibudo ifiniwọ si, sugbọn awọn eniyan naa n kun pe awọn ko ri ounjẹ ati awọn nkan amaye dẹrun mi i gba.
1 Èbibi 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 17 Ọ̀wàrà 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Awọn obinrin niYoruba gba pe wọn jẹ alamojuto ọja ti wọn a si ma yan Iyalọja laarin wọn Bi eeyan ba n gbe ni ilẹ Yoruba, ko jẹ kayeefi ti wọn bá darukọ Iyalọja tabi Iyalaje Lati ijọ ti alaye ti daye ni ilẹ Yoruba ni wọn ti n yan awọn obinrin to kaju osunwọn lati di ipo náà mu.
Ó ti fi ẹnu ba iṣẹ́ oníṣẹ́ jẹ́, ó ti fi àpáàdì ńlá bo iṣẹ́ rere ẹlòmíràn mọlẹ̀, kí aráyé má baà rì iṣẹ́ rere wọn, bẹ́ẹ̀ ni a máa wá ibi kọ́lọ́fin kiri láti mú ọmọnìkejjì, rẹ̀, a sì máa sọ àṣìẹ kékeré wọn di títtóbi lójú àwọn ọmọ aráyé.
Amọ itọ jẹ eroja kan pataki ti yoo tete pe akiyesi wa si aisan to ba wọle si agọ ara wa.
Kí á máa ranti àwọn ọ̀rọ̀ Oluwa Jesu, nítorí òun fúnra rẹ̀ sọ pé, ‘Ayọ̀ pọ̀ ninu kí a máa fúnni ní nǹkan ju kí á máa gbà lọ.
Nígbà tí ó di òwúrọ̀ kutukutu, OLUWA bojú wo ogun Ijipti láti òkè wá, ninu ọ̀wọ̀n iná, ati ọ̀wọ̀n ìkùukùu, ó sì dẹ́rùbà wọ́n.
Ewe, bi o tile je pe, iko agbaboolu PSG lo koo-gba ami-ayo akoko wole, sugbon iko Real Madrid pada jawe olubori pelu ami-ayo meta sookan(3-1) ni papa isere Santiago Bernabeu.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Boko Haram, ISWAP in Borno: Islamic State West Africa Province ni àwọn mọ̀ọ́mọ̀ pa ṣọ́jà méje náà ni 19 Ògún 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 20 Ògún 2020 Oríṣun àwòrán, OTHERS Àwọn alákatakítí Islamic State West Africa Province kéde pé wọ́n tún ti pa àwọn ṣọ́jà ní Kukawa ni ipinlẹ̀ Borno to sunmọ orilẹ-ede Lake Chad ISWAP sọ pe oun ti ṣeku pa ọmọ ogun meje ni ila oorun ariwa Naijiria nilu ti wọn n pe ni Kukawa.
Lẹnu lọwọlọwọ yii, oju gbajugbaja adẹrinpoṣonu yii ko fi bẹẹ han mọ ninu sinima.
Ijọba fidi rẹ mulẹ ninu atẹjade kan ti akọwe agba nileeṣẹ eto iroyin ati aṣa, Grace Gekpe fi sita pe iyawo El-Zakzaky tako awọn oṣiṣẹ eleto aabo India ati Naijiria.
Teachers‘ new salary in Nigeria: Wike ní owó oṣù tuntun fáwọn olùkọ́ tí Buhari kéde yóò dá aáwọ̀ sílẹ̀
pẹlu òbúkọ kan fún ẹbọ ìmúkúrò ẹ̀ṣẹ̀ láti ṣe ètùtù fun yín.
Kí akọ tí ó bá ń wá amá wulẹ̀ ṣe ara rẹ̀ ní wahala,nítorí yóo yọjú nígbà tí àkókò gígùn rẹ̀ bá tó.
Nígbà tí baba rẹ bá wá bẹ̀ ọ́ wò, wí fún un pé, kí ó jọ̀wọ́ kí ó jẹ́ kí Tamari arabinrin rẹ wá fún ọ ní oúnjẹ.
Ọrọ lori alaga ẹgbẹ oṣelu APC Adams Oshiomole lo jẹ @KabirAbdulazee6 logun ni tirẹ, o ni wọn yan an sipo wipe ko sẹni to dipo fun gẹgẹ alaga ẹgbẹ APC.
Ọkọ agbepo naa, ni atẹjade lati ọwọ ọga agba ajọ LASEMA, Olufemi Ọsanyintolu, sọ pe o gbe jala ẹgbẹrun mẹtalelọgbọn epo diisu, ṣugbọn to ṣubu lulẹ lasiko ti ọkan lara awọn taya rẹ fọ, ni adugbo Ozumba Mbadiwe.
Bakan naa lo jẹ ọkan lara awọn ọmọ ẹgbẹ to bẹrẹ ile ẹkọṣẹ awọn oluṣiro owo agba, Institute of Chartered Accountants of Nigeria, ICAN, ohun naa ni Aarẹ akọkọ fun ile ẹkọ naa.
Fani Kayode wa fi eyi kan si iran Yoruba lati gbe igbesẹ ni waransesa lati da abo bo awọn eeyan wọn.
Nigba ti eyi ko pa baba, wọn fi irọri boo loju ko ma baa le mi.
A máa pa ẹni tí ó bá fẹ́, a sì máa dá ẹni tí ó fẹ́ sí.
Ijọba wa fidi rẹ mulẹ pe awọn akẹkọọ naa yoo de ọdọ awọn obi wọn ki ilẹ ọjọ Ẹti oni to su.
“Ẹni tí ó bá ní etí, kí ó gbọ́ ohun tí Ẹ̀mí ń sọ fún àwọn ìjọ.
Shiite: Ẹgbẹ́ Shiite fẹ́ wọ́de ní ìrántì àwọn ọmọ ẹgbẹ́ wọn ti iléèṣẹ́ ológun Nàìjíríà pa
Bakan naa ni Muraina kede pe, gbogbo awọn ileesẹ to ba kopa ninu ajọdun tuntun yii ni yoo ni anfaani fun afihan awọn ọja ati isẹ ọwọ wọn.
Telọ naa ni Alhaji Idris Bawa kan ti oun ti mọ fun ọun mẹwaa lo mu oun mọ DPO ọhun.
Ọwọ́ pálábá ségi fún gbajúgbajà olè méjì tó ń ṣọṣẹ́ lọ́wọ́ l‘Eko Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ohun ti Seyi Makinde sọ lẹyin ipade awọn ẹgbẹ alatako Kọmiṣọna fun eto iroyin ati aṣa nipinlẹ Ọyọ, Toye Arulogun to gbẹnusọ gomina sọrọ ni, Ajimobi ko le ka ọwọ gbera, maa wo ilu niran titi ti ọjọ ti yoo kuro nipo yoo fi pe.
Ati pe idije ti Algeria gba kẹyin gbo wọn pupọ nitori wọn gba bọọlu pẹlu afikun asiko ki wọn to gba kọju si goli koo gba a si àwọn lọjọbọ to kọja.
" Lizzy fikun pe ibẹrẹ igbe aye oun nira diẹ, ẹni to ba si n se oriire ni awujọ, ko le e jẹ ọrẹ awọn ti ko se daadaa.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, '500 level'' ni mo wà nígbà tí mo di adélé Ọba' Gbigbe eto iṣuna ile sita Lẹyin ọpọ atotonu awọn ọmọ orilẹ-ede Naijiria, ile igbimọ aṣofin fi eto iṣuna ile sita lọdun 2017.
Lẹ́yìn náà, wọ́n sọ fún ara wọn pé, “Ohun tí à ń ṣe yìí kò dára, ọjọ́ ìròyìn ayọ̀ ni ọjọ́ òní.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Mama Rainbow: iṣẹ́ tíátà kò ta sánsán mọ́ bíi ti ayé àtijọ́ Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí End SARS protest: Lára àwọn ìlú tí ìwọ́de ti wáyé ní Ibadan, Ado Ekiti, Osogbo, Ado Ekiti ati Eko19 Ọ̀wàrà 2020 Fídíò, Soyinka Cancer: Àṣe ara mi ni iso ti n run gbogbo bí mo ṣe n ṣèrànwọ́ lórí jẹjẹrẹ27 Bélú 2019 Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Ẹwẹ, Babandede ni iforukọsilẹ yóò tẹsiwaju lati lee fun awọn arinrinajo lanfani ati forukọ silẹ ki wọn si le gbe ilu wọn.
 Ọjọ ́ Ẹ ̀ tẹ ̀ Àgbayé bẹ ̀ rẹ ̀ ní 1954 láti mú mímọ ̀ nípa wá fún àwọn tí o ní ẹ ̀ tẹ ̀ .
Kí ẹ kọ èyí sílẹ̀ fún ìran tí ń bọ̀,kí àwọn ọmọ tí a kò tíì bí lè máa yin OLUWA,
Nítorí nígbà tí ebi ń pa mí, ẹ kò fún mi ní oúnjẹ jẹ.
Mama Ire, ẹni to n gbarata lori ohun ti yoo sẹlẹ si ọmọ ọwọ ti Maryam Sanda gbe dani lasiko ti wọn dajọ iku fun, wa n rawọ ẹbẹ si ọba oke pe ko siju aanu wo obinrin naa.
Odion Ighalo ti iko Super Eagles lo gba bọọlu kan ṣoṣo ọhun wọle
 Momoodu tún woye pe ìlànà wiwo ọ̀rọ̀ ẹṣin, ẹ̀yà àti owó láti fà oludije kalẹ ni Naijiria kò bójú mú nítorí ẹni tí kò bá ní owó láti pin tàbí jẹ́ ẹlẹ́ṣin tó kàn láti díje, wọn kò ní ṣe atileyin gùn onitohun."
Ọpẹ́ fún Ọlọrun nítorí Ìdájọ́ Òdodo Rẹ̀.
Ṣugbọn ilé ìṣọ́ kan tí ó lágbára wà ninu ìlú náà, gbogbo àwọn ará ìlú sá lọ sinu rẹ̀, atọkunrin, atobinrin.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ìrìnna ọkọ́ òfúrufú s'ílẹ̀ òkèèrè bẹ̀rẹ̀ padà ní Nàìjíríà Jegede (PDP) ti yan Aṣojúṣòfin Ikengboju gẹ́gẹ́ bí ìgbákejì rẹ̀ tí wọ́n yóò jọ díje dupò DPO ọlọ́pàá fi ọmọ odó lu èèyàn méjì pa, ó ṣe ẹnìkan lééṣe lágọ̀ọ́ ọlọ́pàá Àwọn afẹ̀hónúhàn bọ́ra sí ìhòhò lórí pápá lòdì sí sísọ eré bọ́ọ̀lù di jẹunjẹun Wo ìyàtọ̀ ńlá tó wà láàrin Oṣó, Àjẹ́ àti Emèrè Ẹwẹ, Kọmisọna ọlọpaa ni ipinlẹ Oyo, Joe Enwonwu lo pada salaye pe, awọn ọlọpaa meji ti aje ọrọ naa ṣi mọ lori, ni awọn n ṣe ifọrọwanilẹnuwo fun lọwọ.
Ajọ to n gbogun ti ajakalẹ arun lorilẹ-ede Naijiria, NCDC lo fi eyi sita loju opo Twitter rẹ.
Bẹẹ naa lo fi kun pe iroyin ofege naa tọka pe Abike Dabiri kọ orukọ oludije sipo Sẹnẹtọ Tokunbo Abiru si ara awọn nnkan iranwọ Covid yii.
Balaki ṣe ohun tí Balaamu sọ, ó sì fi akọ mààlúù kọ̀ọ̀kan ati àgbò kọ̀ọ̀kan rúbọ lórí pẹpẹ kọ̀ọ̀kan.
Bojúwo ilẹ̀ láti ibùgbé mímọ́ rẹ lọ́run, kí o sì bukun Israẹli, àwọn eniyan rẹ, ati ilẹ̀ tí o ti fi fún wa gẹ́gẹ́ bí o ti ṣèlérí fún àwọn baba wa, ilẹ̀ tí ó kún fún wàrà ati oyin.
Kí ẹni tí ó bá fẹ́ darapọ̀ mọ́ ìpolongo “100 ọjọ́ fún Alaa” ó fi “àròkọ, àwòrán tàbí ìṣe ìlọ́wọ́sí ìpolongo” ṣọwọ́ tí a lè tún tẹ̀ jáde sórí ibùdó-ìtàkùn-àgbáyé ìpolongo náà:
Inú Ọlọrun kò dùn sí ọ̀rọ̀ náà, nítorí náà ó jẹ àwọn ọmọ Israẹli níyà.
Lẹ́yìn tí meji ninu àwọn ọmọ Aaroni kú, nígbà tí wọ́n fi iná tí kò mọ́ rúbọ sí OLUWA, OLUWA bá sọ fún Mose pé, 
Fayose so pe awon awako ko ni se ise titi di aago merin , nigba ti egbe oselu APC yoo pari ipolongo won.
Níbẹ̀ ni àwọn èrò ti tò láti gun àkàsọ̀ afẹ̀rọfà tí ń gbéni lọ sókè nítorí ilé ọ̀hún ga tó bẹ́ẹ̀ gẹ́, kò ṣé fẹsẹ̀ lásán gùn dé òkè.
"Olori fikun un pe ""Mo tun dupẹ lọwọ ọkọ mi fun ipa to ko lati jẹ ki n bi awọn ọmọ daradara ti Ọlọrun fun mi, mo mọ pe n ko pe, sugbọn wọn duro ti mi digbi lasiko ipenija"" Olori Alaafin tun tọkasi pe loootọ ni igbeyawo oun ati ọba naa kii ṣe eyi to pe julọ, amọ awọn tiraka lati jẹ ko jẹ igbeyawo alayọ, ọkọ oun si ni nkan to dara julọ, ti yoo sẹlẹ si oun, ti oun si n reti lati lo ọpọ ọdun laye pẹlu rẹ."
1) Eto pipese ounjẹ fun ọmọ ileewe: Fun awọn obi ti o ni ọmọ nileewe alakọbẹrẹ nipinlẹ Osun, yoo ṣoro diẹ ki wọn to le gbagbe Aregbesola fun eto ipese ounjẹ lọfẹ fun awọn akẹẹkọ ileẹkọ alakọbẹrẹ to wa ni ipele kilaasi kinni si ikẹrin, ti oloyinbo n pe ni basic 1-4 Oríṣun àwòrán, @raufaregbesola Bi o tilẹ jẹpe awọn eeyan kan ko fara mọ iru igbesẹ yii, ti wọn si ni owo to n tako ipese ounjẹ yii pọ ju, paapa lasiko ti ọrọ aje Naijiria ko fara rọ, sibẹ awọn akẹkọ to n jẹun ko ni gbagbe Arẹgbẹsọla.
Eyi ko ṣẹyin fidio kan ti awọn ololufẹ eto naa fi sita loru oni mọju, to si ṣafihan awọn 'ololufẹ' mejeeji nibi ti wọn ti n 'fun ara wọn ni eso ifẹ jẹ'.
Ní ibi tí Akin ti dá mọ́lò dúró nígbà tí o fẹ́ ẹran ìgbẹ́ ni bàbá alágbẹ̀dẹ kan ti sọ fún ọmọ kan pé kí ó wò ọkọ̀ náà.
Àwọn ọmọ Israẹli lọ ra ọkà pẹlu àwọn mìíràn tí wọ́n wá ra ọkà, nítorí kò sí ibi tí ìyàn náà kò dé ní ilẹ̀ Kenaani.
Bàbá-à mi ni ό sì fi ìtàn náà tó mi létí kí n tó ní ìyàwó.
Baba Obasanjọ kò ní àrùn Coronavirus- NCDC NCDC kéde èèyàn 437 míràn tó ṣẹ̀ṣẹ̀ lùgbàdì Covid-19 ní Nàìjíríà, 142 gbàwòsàn Iná jó àwọn ènìyàn 10 tó ń gbà ìwòsàn arùn Coronavirus níbùdó ìtọ́jú Eric ati Tochi ni wọ́n lé kúrò nílé ẹlẹ́gbọ̀n àgbà BBNaija lọ́sẹ̀ yìí Iya agba, ẹni ọdun mọkandinlọgọrin, Mojisọla Odegbami ni ''iya Moji'' ni awọn oṣiṣẹ Beyonce ma n pe oun, ti iya FJ si fi orukọ oun silẹ pẹlu awọn ileeṣẹ to ma n wa awọn to ni ẹbun.
Akẹgbẹ rẹ, Sẹnẹtọ Rochas Okorocha to n ṣoju ẹkun guusu ipinlẹ naa lo kede iku rẹ fawọn akọroyin.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Eégun àti orò, bí wọ́n ṣe jọ bí Ẹ̀ṣà Egúngún nílẹ̀ Yorùba rèé Tuntun tó tún wáyé nínú ọ̀ṣẹ́ yìí ni ọlọ́pàá kan tó tún lọ yìnbọn pa ọ̀dọ́mọkunrin kan Olaoye Abayomi àti àwọn ọ̀rẹ́ rẹ̀ Idris Adebayo tó n muti nílé ìtura kan nílùú Ado Ekiti.
Kíni ẹ̀yin náà rí sí ọ̀rọ̀ yìí.
" Adisa ṣalaye pe awọn to wa ni ipele kẹfa ile iwe alakọbẹrẹ, awọn to wa ni ipele kẹta akọkọ ati ipele kẹta keji ni ile iwe girama nikan ni ijọba lero pe yoo pada sẹnu ẹkọ wọn.
”Ó sọ fún ẹni tí kò lọ́gbọ́n pé,
Ṣùgbọ́n, iléèṣẹ́ ológun kò sọ ẹ̀kúnrẹ́rẹ́ bí ìjà nàá ṣe wáyé.
Oṣu Kẹta, ọdun 2020, ni ijọba ti ti gbogbo ileewe pa.
Wọn gba pe o ṣeeṣẹ ki orisun ina naa nii ṣe pẹlu iṣẹ atunṣe nla to n lọ lọwọ.
Wọn óo sì wà níbẹ̀ bí ìjọba tí kò lágbára.
Ẹ jẹ́ kí ó ye yín,ẹ̀yin tí ẹ ya òpè jùlọ láàrin àwọn eniyan!
N óo fi idà pa àwọn ọdọmọkunrin Oni ati ti Pibeseti; a óo sì kó àwọn obinrin wọn lọ sí ìgbèkùn.
Odion Ighalo, Henry Onyekuru ati Moses Simon lo gba ayo mẹtẹẹta wọle.
  Ótó bíi ọgọ́rùún wọ́n níbẹ̀ tí ènìà ní láti rìn kọjá lẹ́gbẹ̀ẹ́ wọn.
Oga agba Daramola salaye pe,  “Erongba sise ifilole ise akanse eka iko omo ogun yii ni lati dojuko awon omo ogun olote ti won ba kofiri won ni agbegbe Lake Chad ati igbo agijun Sambisa tabi awon ibudo won ti o ba wa nipinle Borno.
Toyin Abraham bí ọmọkùnrin jòjòló Àjẹ́ àti Aṣẹ́wó ní ìyá Rainbow - Òjòpagogo Ọdẹ ìbílẹ̀, OPC àti agbófinró ń pèèlò tí yóò se ọbẹ̀ ààbò jinná nílẹ̀ Yorùbá El-Zakzaky fẹ́ jayé ọlọ́ba ní India, kò sígbà tí kò ní padà wálé - Ìjọba àpapọ̀ Bí Khafi ṣe ní ìbálòpọ̀ ojútáyé tako àṣà Yorùbá - Ìjọba Ekiti Ileeṣẹ ọlọpaa ṣalaye fun BBC pe, agbegbe Aguda nipinlẹ Eko ni iṣẹlẹ ọhun ti ṣẹlẹ.
Yorùbá jẹ èrè àwọn ohun gidi, amáyé-dẹrùn bi ilé-iwé ọ̀fẹ́, ilé-ìwòsàn ọ̀fẹ́, ilé iṣẹ́ amóhùn-máwòrán àkọ́kọ́, ilé àwọn àgbẹ̀ (olókè mẹrin-lé-lógún – ilé giga àkọ́kọ́), ọ̀nà ọlọ́dà, omi, iná mọ̀nà-mọ́ná àti bẹ́ẹ̀bẹ́ẹ̀ lọ.
O ṣalaye pe ''iyẹn o ni wi pe mọ yi ohun pada lori iwa buruku ti Aarẹ ana, Olusegun Obasanjo wu nigba ti o wa ni ipo.
Bi apẹẹrẹ ninu idije tọdun 2011, o gba ẹrọ gbohungbohun lori papa ni kete to gba bọọlu sáwọ̀n Columbia ki wọn to koju Japan nibi to ti kọrin nipa ibi rẹ ni Amerika.
Ó tún mú àwọn Giriki wọ inú Tẹmpili; ó wá sọ ibi mímọ́ yìí di àìmọ́.
Àwọn akẹ́kọ̀ọ́ fásitì Adekunle Ajasin, Akungba-Akoko fẹ̀hónú hàn ní ìpínlẹ̀ Èkó
Joaṣi ọmọ Ahasaya nìkan ni kò pa nítorí pé Jehoṣeba ọmọbinrin Joramu ọba, arabinrin Ahasaya, gbé e sá lọ; ó sì fi òun ati alágbàtọ́ rẹ̀ pamọ́ sí yàrá kan ninu ilé OLUWA, kí Atalaya má baà pa á.
Lẹ́hìn èyí a tún padà gun orí òkè ilé náà lo, nígbà tí a sì dé ọ̀hùn tí a jókòó tán, tí mo jókòó díẹ̀ tí a kò sọ̀rọ̀, mo dìde mo fi ọwọ́ bọ inú àpò ṣòkòtò mi bí ìgbà tí àwọn alákọ̀wé bá ń ṣe fáàrí, nígbà tí mo sì yan sókè tí mo yan sódò tán, mo tún bá ìdí lọ sí orí àga, mo gbé ẹsẹ̀ ọ̀tún mi lé ẹsẹ̀ òsì, mo fi ọwọ́ mi méjèéjì di orúnkún mú, mo fi ẹ̀hìn mi ti dáadáa lórí aga, mo sì wí fún Baba-onírùngbọ̀n wí pé, mo tún ń fẹ́ẹ́ gbọ́ ọ̀rọ̀ díẹ̀ sí i lẹ́nu rẹ̀.
Títọ́ ni kí ẹ máa tọ́ wọn ninu ẹ̀kọ́ ati ìlànà ti onigbagbọ.
Bí ẹ ti rí níwájú OLUWA, bẹ́ẹ̀ náà ni àjèjì tí ó wà láàrin yín rí.
Ko si nkan ati ṣiṣẹ ni awọn ileewosan wa, a kawe o, a pari agboye o, ṣugbọn ko si nkan ati ṣiṣẹ lawọn ileewosan wa ati pe owo ti ijọba n san kere jọjọtaa ba fi wo gbogbo ọdun ti dokita lo nileewe, lo jẹ ki awn eeyan maa sọ pe ti awọn ba ri ibi to daa, wọn a lọ""."
Lẹyin ọsẹ mẹta ti Yusuf ṣiṣẹ laabi yii tan lọwọ awọn agbofinro too tẹẹ lẹyin to ti sa lọ siluu Ilorin nipinlẹ Kwara.
Tani ẹni to le gba ẹmi ara rẹ?
 nítorí náà , ó dára kí ìṣọ ̀ kan jọba ni àwujọ-ẹ ̀ dá .
Lẹ́yìn náà ó mú mi jáde, ó mú mi wọ inú gbọ̀ngàn ti inú lápá ìhà àríwá, ó sì mú mi wọ inú àwọn yàrá tí ó wà níwájú àgbàlá Tẹmpili, ati níwájú ilé tí ó wà ní ìhà àríwá.
Ẹ gbé Etete, Adoke àtàwọn míràn lórí ọ̀rọ̀ epo Malabu - Iléẹjọ́ Nàìjírìa pàdánù $6bn owó epo lórí ìwà àjẹbánu Àti ilé àti ilẹ̀, mi ò ní ǹkankan ní ilẹ̀ òkèrè-Goodluck Jonathan Ile ẹjọ giga ijọba apapọ to wa nilu Abuja lo fun ajọ to n gbogun ti iwa ibajẹ ni Naijiria, EFCC, ni aṣẹ lati fi Agbẹjọro -Agba Naijiria, to tun jẹ Minisita fun eto idajọ, Mohammed Adoke si ihamọ fun ọjọ mẹrinla.
Bí ara láìsí ẹ̀mí ti jẹ́ òkú, bẹ́ẹ̀ ni igbagbọ láìsí iṣẹ́.
O menuba igbese ijoba ti yoo jade laipe.
Bí ilé-aiyé ṣe tóbi tó, àti bí àwa ọmọ ènìà ṣe kéré síi to, ló fi dà bẹ́ẹ̀ lójú tiwa.
Máa lépa òdodo ati ìṣòtítọ́, ìfẹ́, ati alaafia, pẹlu àwọn tí ó ń képe Oluwa pẹlu ọkàn mímọ́.
Leprosy Day: Ìgbé ayé arákùnrin tó di alábàágbé pẹ̀lú àwọn adẹ́tẹ̀ 137
39 Àti pé nígbàtí ẹ̀yin bá ti rí wọn ẹ̀yin yíò fi àwọn nkan wọ̀nyí hàn sí wọn.
Irú kan náà ni Atiku àti Buhari, kò s'íyàtọ̀ nínú wọn - Tunde Bakare Ọmọ Nàíjíríà faraya lórí àìkópa Buhari àti Atiku nínú ìjíròrò Lẹ́yìn osù méjì, kò sọ́nà àbáyọ sí ìyanṣẹ́lódì ASUU Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ezekwesili: Àfojúsùn mi ni láti mú ààbò ẹ̀mí ọmọ Nàíjíríà ní ọ̀kúnkúndùn Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Atiku ní òun kò dènà kí ọ̀dọ́ kankan dupò ààrẹ ní Nàìjíríà Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Kí ló tún wá kù tí mo lè ṣe fún ọ, ọmọ mi?
Lẹ́yìn náà ó lọ sí Penueli, ó wó ilé ìṣọ́ wọn, ó sì pa àwọn ọkunrin ìlú náà.
O kan n gbiyanju ni, paapaa nipa idasilẹ ajọ Amọtẹkun.
Síbẹ̀síbẹ̀, títí di oní  olónìí, àwọn àgbàlagbà kì í yéé sọ̀rọ̀ ìjà ibodè Igbó Olódùmarè yìí, nítorí ibẹ̀ ni àwọn oníjà gbé di ọká, tíwọ́n di erè, ti wọ́n sì di àjànàkú bàbá ẹranko.
Lẹnu lọọlọ yi, ijọba Naijiria ti n gbe awọn ọmọ ilẹ naa ti wọn ṣatipo lọ si ilẹ Libya pada wa sile.
Ọ̀nà títẹ́jú ni ọ̀nà àwọn olódodoó mú kí ọ̀nà àwọn olódodo máa dán.
Nítorí ẹni tí ó bá ní, a óo tún fi fún un sí i; ẹni tí kò bá sì ní, a óo gba ìba díẹ̀ tí ó ní lọ́wọ́ rẹ̀.
Nisinsinyii, kabiyesi, ẹ fi ọwọ́ sí òfin yìí, kí ó lè fi ìdí múlẹ̀, gẹ́gẹ́ bí òfin Mede ati Pasia tí kò gbọdọ̀ yipada.
Ògbóǹtarìgì oloṣelu yii jẹ ọmọ ile igbimọ aṣofin ati kọmiṣọna fun irinna laarin ọdun 1979 si 1983.
" O ṣalaye pe ibanujẹ nla ni pe ko si iyatọ laarin awọn adijale to kọlu ile ifowopamọsi naa atawọn ara ilu to tun ji owo ọhun gba lọwọ wọn.
Wọ́n ti mu aṣojú ọmọ Britikó ní orílẹ̀-èdè Iran Eid el-Fitri : ---- Eyi ni ayẹyẹ ọdun pe awọn musulumi pari aawẹ Ramadan fun ọdun 2020.
Olumuyiwa Adejobi to jẹ alukoro ọlọpaa ni arabinrin Precious Chukwu ẹni ọdun mejilelogun ati Ujunwa Offiah jijọ lẹdi apo pọ pẹlu Ifesinachi Blessed lati parọ pe awọn ji Ujunwa gbẹ.
OLUWA yóo dáríjì í nítorí pé ọkọ rẹ̀ ni kò gbà á láàyè láti san ẹ̀jẹ́ rẹ̀.
Bakan naa ni apapọ ẹgbẹ CUPP latẹnu agbẹnusọ rẹ, Imo Ugochinyere ni ki awọn eeyan rẹ ni ohun ti Yakubu n sọ ko ba ofin mu.
Èmi náà kọ́, àṣìṣe ló mú kí ń gún ọkọ mi pa láàrin ọjọ́ 51 taa fẹ́ ara wa"" Lateef Adedimeji rèé tó mú omi lójú àwon òbí rẹ̀ lọ́jọ́ ẹ̀yẹ Naijiria ati Ilẹ Amerika buwọ́lu ìwé àdéhùn lórí owó ìlú tí Abacha lù ní póńpó Ileasanmi wa fọwọ gbaya pe ""lọjọbọ ni olujẹjọ naa, Alfa Babatunde yoo yọju sile ẹjọ lati tẹsiwaju nidi igbẹjọ rẹ, gbogbo awọn agbẹjọro si ni yoo yọju sile ẹjọ giga naa lọjọbọ naa."
Ṣugbọn àwọn eniyan Juda kò lè lé àwọn Jebusi tí wọn ń gbé inú ilẹ̀ Jerusalẹmu jáde.
Aarẹ Trump ni awọn obinrin naa wa lati orilẹ-ede ti ko lojutuu ati pe ki wọn pada sile.
Ọba ní kí ẹ má ṣe jẹ́ kí Hesekaya tàn yín jẹ, nítorí kò ní le gbà yín là.
EFCC sọ pe Soewu to wa ni ahamọ lọdọ awọn pin owo naa fawọn oloṣelu ati awọn Ọba alade kan.
EFCC p'oṣiṣẹ banki l'ẹjọ Wọn fi ẹsun abẹtẹlẹ kan Danladi Umar Òfin lè má mọ oògùn ṣùgbọ́n èmí gbàgbọ́ pé ǹkan wà nídìí bí wọ́n ṣe pa ọmọ mi- Baba Favour Ọlabisi Ajala rèé, ó gun ọ̀kadà yíká àgbáyé, tó sì dé orílẹ̀èdè 87 Ninu idajọ tuntun naa, adajọ ile ẹjo kotẹmilorun, adajo Abdul Aboki, ni ki Yusuf lo fi ẹwon ọdun mẹfa gbara, ko si da owo biliọnu mejilelogun pada.
àfi ilẹ̀ àwọn ọmọ Amoni nìkan ni ẹ kò súnmọ́, àwọn ilẹ̀ tí ó wà ní etí odò Jaboku, ati àwọn ìlú ńláńlá tí ó wà ní agbègbè olókè, ati gbogbo ibi tí OLUWA Ọlọrun wa ti paláṣẹ pé a kò gbọdọ̀ dé.
ile-ifowopamo ti ijoba apapo lorile ede Naijiria, Godwin Emefiele so nibi ayeye ajodun  egbe awon osise ile ifowopamo ti odun yii: “Ounje
ibinu mi yóo sì ru sí yín, n óo fi idà pa yín, àwọn aya yín yóo di opó, àwọn ọmọ yín yóo sì di aláìníbaba.
Ọ̀rẹ́bìnrin míì dáná sí ọ̀rẹ́kùnrin rẹ̀ lára lẹ́yìn tó kọ̀ láti fẹ́ ẹ gẹ́gẹ́ bí aya Wo ìgbà tí Ààrẹ Buhari yóò ṣí 'bọ́dà' padà Èyí ni ìtàn Ọkùnrin tó rí ẹ̀wọ̀n he nítorí àkùkọ aládúgbò rẹ̀ tó pa Lóòtọ́ ni ọkọ mi lù mí bí àṣọ òfì, àmọ́ gómìnà ti bá wa parí ẹ̀, ẹ máa gbàdúrà fún ìdílé mi- Dokita Ifeyinwa Mi ò kí n ṣe afẹfẹ-yẹ̀yẹ̀ lórí ayélujára nítorí pé mí ò ní dúkìá tí mó le fihàn- Ronke Oshodi-Oke Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Ẹni to bori: Nigeria Cameroon vs Angola.
 iye àwọn ọ ̀ rọ ̀ gbọ ́ dọ ̀ jẹ ́ adópin .
Alshinloye ni ẹni tó gbé lọ yìí kii se ara NURTW, ọmọ Auxiliary ni, kò sì sí òun tó kàn àwọn nibẹ torí àwọn Auxiliary kii se Ọlọkọ mọ, Alakoso gareji ni wọn.
Ẹ gbọ́ ohun tí Desmond Elliot sọ lórí ayélujára tó bí àwọn ọmọ Nàìjíríà nínú Bọ́ọ̀sì ìrìnà 106 tuntun yóò máa ná Ibadan sí Eko àtàwọn ìpínlẹ̀ míì - Seyi Makinde Wo àwọn Ṣọ́ọ̀ṣì Nàìjíríà àti l'Áfíríkà tó ń wólẹ̀ àdúrà kí Trump lè wọlé ìbò ààrẹ America Ṣé Biden lè fẹ̀yìn Trump kó di ààrẹ America tó kàn?
Diẹ lara awọn to ti ba irufẹ itiju ati ariwo idẹyẹsi bayii pade niwọnyii: Donald Trump: Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ọrọ kii si n lẹyin Aarẹ Donald Trump ti Amẹrika; Bi o ṣe n dẹyẹsi awọn ọmọ orileede rẹ lawọn naa n da pada fun un Aarẹ orilẹede Amẹrika, Donald Trump kii ṣe ajeji si idẹyẹsi; paapaa lati igba ti o ti di aarẹ orilẹede Amẹrika ni ọdun 2016.
Bakan naa ,ni ajo agbaye to n ri si iwa ọdaran, to wa ni Hague tun fi ẹsun iwa ipaniyan lasiko ogun kan Bahir , ni eyi ti o hu lasiko rẹ.
Osun elections: Adeleke gba iléẹjọ́ tó ga jùlọ ní Nàìjíríà lọ pẹ̀lú agbẹjọ́rò àgbà mẹ́fà, òdú amòfin mẹ́tàdínlógún míràn
” Wọ́n tẹríba, wọ́n bu ọlá fún un.
 A fi n dayin loju pe a o se atileyin ti o to fun yin.
Nigba to ṣàìsàn láwọn ọdun yii, isẹ ti kuro ninu ọrọ rẹ to bẹẹ to fi n rìnrìn àjò lọ orílẹ̀èdè Amẹrika fun itọju.
Ó p'ọ́dún méjì tí Keshi kú Ààrẹ ẹgbẹ́ agbábọ́ọ̀lù Nàìjíríà, Pinnick yóò fojú ba ilé ẹjọ́ D'Tigress tún ti fakọyọ nínú ìdíje àgbáyé Adebayo Shittu: Minista fun ibanisọrọ Oriṣiiriṣii ẹsun ni wọn fi kan minista yii ni kete to ti gbe igba ibo lati dije dupo gomina ipinlẹ Oyo ninu saa yii.
Darandaran náà kò gbọdọ̀ bèèrè bóyá ó dára tabi kò dára, bẹ́ẹ̀ ni kò sì gbọdọ̀ pààrọ̀ rẹ̀.
Mo ṣetán láti sin Ààrẹ Buhari pẹ̀lú gbogbo agbára mi- Ibrahim Gambari Ìdí táwọn apòògùn Nàìjíríà fi tako oògùn Coronavirus láti Madagascar Aláàfin gbé àṣẹ kalẹ̀ láti dènà àtúnṣẹ̀ ìṣẹ̀lẹ̀ 'Soka'nílùú Ọ̀yọ̀ Lagos Lockdown: Ìgbésẹ̀ ìjọba lórí Twitter tì mí lójú tì- Jimi Disu NCDC ní, ìpínlẹ̀ Eko ní ènìyàn mọ́kànléláàdọ́ọ́ta, mẹ́tàlélógun ni Jigawa, Kastsina àti Bauchi ni mẹ́rìndílógún nigbàti Kano ni mẹ́rìnlá.
Idahun: Wọn ko tii ka a ni ipele kika akọkọ.
Gẹ́gẹ́ bí ó ti túmọ̀ àlá wa, bẹ́ẹ̀ gan-an ni ó sì rí.
O jẹ ajijagbara fun ẹ̀tọ́ àwón obinrin lẹkun ìwọ̀ oorun ilẹ Adulawọ nigba naa.
O ni Naijiria o ṣẹsẹ ma ṣe iwadii lori ọrọ yi,tori naa ki wọn ma wulẹ dawọ le iwadii ti wọn o ni tele abajade rẹ.
Lara rẹ ni wi pe ibatan aarẹ Muhammadu Buhari lo jẹ ko si boju mu ko wa nidi ibo kika ninu idibo kan naa ti mọlẹbi rẹ ti jẹ oludije.
 Alaaja Oluwo fi kun ọrọ rẹ bayii.
Nítorí pé OLUWA ti yan Jakọbu fún ara rẹ̀,ó ti yan Israẹli gẹ́gẹ́ bí ìní rẹ̀.
" Oríṣun àwòrán, PastorEAAdeboye Àkọlé àwòrán, RUGA: Adeboye ní àsìkò tó láti wá nǹkan ṣe sí ọ̀rọ̀ ètò pápá ìjẹko RUGA pátápátá Ninu ọrọ tirẹ nibi apero naa, aarẹ ẹgbẹ ọmọlẹyin Kristi lorilẹ-ede Naijiria, Ọmọwe Ṣupọ Ayọkunle ni bi eto aabo ṣe di eyi to n ko tẹru-tọmọ laya soke ni Naijiria yii ti di itiju nla gbaa fun awọn ọmọ Naijiria.
Èèwọ̀ ni láti pa ẹja nínú odò Sogidi ni Aáwẹ́ nipinlẹ Oyo Àròsọ àti ìgbàgbọ́ àwọn ènìyàn lórí gbígba ẹ̀jẹ̀ Ayinla Ọmọwura, orin èébú àti oríyìn lo fi di ọ̀rẹ́ àwọ̀n obìnrin Sanwo-Olu kò lè tori ìjà Ọjọta fòfin de NURTW ní Eko - Agbẹnusọ gómínà Arakunrin Patrick Sawyer to jẹ ọmọ orilẹ-ede Liberia lo kó ebola wọ Naijiria.
Èmi a máa ṣe bẹ́ẹ̀ kí n lè jèrè àwọn tí kò gba ètò ti Òfin Mose.
OLUWA tún bi Satani pé, “Níbo ni o ti ń bọ̀?
Mó fẹ́ kí ọmọ tí ó bá rí i pé òun ń hu ìwà tí ó ń bí àwọn òbí nínú,m tí ó ń ba àwọn olúkọ́ lẹ́rù, tí ó sì ń fún iyèkan ní ìbànújẹ́ ṣe ìpinnu àti fi ìwà bẹ́ẹ̀ sílẹ̀ ní ọjọ́ tí ó bá rí ìwé yìí, nítorí ẹ̀hìn ọ̀la.
''Èmí ni mo se atona abadofin ti o faaye gbà àwọn ọdọ láti du ipò tí o bá wù wọ́n èyí tí ààrẹ buwọ́lù.
O ni ki obi dẹkun fifi agidi mu ọmọ lọ lo isinmi nibi ti ko fẹ tabi lọ ki ẹnikẹni nile ti ọmọ naa kò fẹ Idi ti ọgba ẹwọn fi nkun akunfaya ni Naijiria Àjọ NEMA fèsì ẹ̀sùn táwọn aṣòfin fi kan Ọṣinbajo 'Oshiomọle, APC ti sọ owó di Ọlọ́run ni Kwara' Wọn ta Tutu ni miliọnu pọun nilẹ Gẹẹsi Ọpọlọpọ iṣẹlẹ lo ti han de lori bi àwọn ẹ̀bí atawọn aladugbo ṣe n ṣe awọn ọmọde niṣekuṣe lasiko yii ni eyi to tó àpérò ọmọ eríwo.
Ó ní kí wọ́n tún da mẹrin mìíràn, wọ́n tún ṣe bẹ́ẹ̀.
Ẹ má tẹ̀lé àwọn oriṣa; ohun asán tí kò lérè, tí kò sì lè gbani ni wọ́n.
Kò sí àníàní, Coronavirus ló mú ẹ̀mí Ajimobi lọ - Ìjọba Eko Wo bí o ṣe lè di aṣojú tó ṣe pàtàkì nínú àjọ ìṣọ̀kan àgbáyé 'UN Goodwill Ambassador' A kò ní fara mọ́ fífi àkókò ṣòfò lórí ẹjọ́ Sotitobire - Ìjọba Ondo Ìpínlẹ̀ Oyo sọ àsìá Nàìjíríà kalẹ̀ láti dárò Abiola Ajimobi Ojogo sọ pe Ọwo awọn eeyab lo ku si lati yanju iṣoro Covid-19 ni ipinlẹ Ondo nitori ọpọ ninu wọn ko gbagbọ pe aisan naa wa lode."
Olugbe agbegbe naa kan la gbọ pe o pariwo sita nigba to ni oun ri Saheed to n tan ọmọ ọdun mẹrin kan pẹlu erongba lati ji gbe.
"Ẹ wá dánrawò níbí pẹ̀lú Àpólà Ọ̀rọ̀ Orúkọ, ""Noun Phrase"" Ẹ̀yin tí ẹ kò gbọ́ Yorùbá, ẹ ṣúnmọ́ bí láti kọ́ lítíréṣọ̀ èdè Yorùbá lórí BBC Ẹ ṣúnmọ́ bí láti kọ́ ẹ̀kọ́ nípa ìsọ̀rí ọ̀rọ̀ nínú gbólóhùn Yorùbá Iwe ti ajọ eleto idanwo aṣekagba WAEC yan fun awọn akẹkọ aṣedanwo ni Akomolede Yoruba gbe yẹwo lonii ti Akọle rẹ jẹ ""Ọ̀rẹ́ mi""."
Asiko yii si ni awọn agbẹ lọ duro de wọn ni Olorunda, ti wọn ko si ṣe ohunkohun sáwọn ọlọpaa naa nitori wọn n duro de asaaju wọn, Tafa Adeoye, ko de gẹgẹ bii adehun wọn.
Bí apá tabi ẹsẹ̀ mààlúù tabi àgbò kan bá gùn ju ekeji lọ, ẹ lè mú un wá fún OLUWA gẹ́gẹ́ bí ọrẹ ẹbọ àtinúwá, ṣugbọn OLUWA kò ní tẹ́wọ́gbà wọ́n gẹ́gẹ́ bí ẹran ìrúbọ láti fi san ẹ̀jẹ́.
Ẹ̀ka rẹ̀ nà sọ́dọ̀ idì yìí lókè, ṣugbọn gbòǹgbò rẹ̀ kò kúrò níbi tí ó wà.
Ni a bá fún obinrin náà ní ìyẹ́ idì ńláńlá meji, kí ó lè fò lọ sí aṣálẹ̀ níbi tí wọ́n ti ń tọ́jú rẹ̀ fún ọdún mẹta ati oṣù mẹfa, tí ó fi bọ́ lọ́wọ́ ejò náà.
Tinubu parí aáwọ̀ Ambode àtàwọn aṣòfin ìpínlẹ̀ Eko #BBCNigeria2019 Ọ̀rọ̀ LAUTECH gba àpérò f'áwọn Olúdíje Ọṣun Bààlú Sala tó pòórá ti di àwárí nínú òkun Àkójọpọ̀ àwòrán láti ìpàdé ìtagbangba pẹ̀lú àwọn olùdije ní Ọyọ Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Àmúwá Ọlọ́run lásán ní ìṣẹ̀lẹ̀ tó wáyé ní Iba-Eburu Iba Oba Okunoye Ajọ 'Say Her Name' to jẹ aladani ti kii 'se tijọba to n ran awọn ara ilu lọwọ naa n pariwo pe ki ẹmi ṣe pataki.
Ọ̀rẹ́bìnrin míì dáná sí ọ̀rẹ́kùnrin rẹ̀ lára lẹ́yìn tó kọ̀ láti fẹ́ ẹ gẹ́gẹ́ bí aya Wo ìgbà tí Ààrẹ Buhari yóò ṣí 'bọ́dà' padà Èyí ni ìtàn Ọkùnrin tó rí ẹ̀wọ̀n he nítorí àkùkọ aládúgbò rẹ̀ tó pa Lóòtọ́ ni ọkọ mi lù mí bí àṣọ òfì, àmọ́ gómìnà ti bá wa parí ẹ̀, ẹ máa gbàdúrà fún ìdílé mi- Dokita Ifeyinwa Mi ò kí n ṣe afẹfẹ-yẹ̀yẹ̀ lórí ayélujára nítorí pé mí ò ní dúkìá tí mó le fihàn- Ronke Oshodi-Oke Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Ni kete ti ayẹyẹ naa wa sopin ti igbakeji aarẹ si wọ baalu alawọ tinu ẹyin (YELLOW) ati olomi aro (BLUE) naa, to si gbera, ni ko lee fo kọja awọn igi to wa nile ẹkọ̀ naa, to si tun n yọ eefin.
Edo Election 2020: Ààrẹ Buhari, Atiku àti àwọn èèkàn ìlú míràn ti n kí Obáseki ku oriire
IGP ti jọ̀wọ́ Hamisu Wadume fún aádájọ́ àgbà Nàìjíríà Háà Ibadan!
 Ile igbimo asofin tun rọ ijọba apapọ lati
Omọ ijọba ibilẹ Maiha nipinlẹ Adamawa ni Bashir.
Agbẹjọro to kawe gboye ni o si tun ni iwe ẹri imọ ijinlẹ keji ninu imọ ofin ajọṣepọ ilẹ okeeere, (Masters in International Law) Ọjọ kọkandinlogun, oṣu karun ọdun 1964, ni wọn bi Sam Okwaraji ni ilu Orlu ni ipinlẹ Imo, o si gba bọọlu jẹun lawọn ẹgbẹ agbabọọẹu to lorukọ ni ilẹ Yuroopu bi AS Roma (1984-1985), NK Dinamo Zagreb (1985-1986), Austria Klagenfurt (1986-1987), VfB Stuttgart (1987-1989) ati SSV Ulm 1846 (loan) (1987-1988) Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Agbẹjọ́rò àgbà mẹ́fà, òdú amòfin mẹ́tàdínlógún míràn yóò ṣojú Sẹ́nétọ̀ Adeleke níléẹjọ́ tó ga jùlọ Awọn àgbà ọ̀jẹ̀ agbábọ̀ọ̀lù ní Afíríkà yẹ́ Gomina Ambode si Ẹ dá owó wa padà kíá!
Èròńgbà wa tí a fi tẹ̀lé ìròyìn náà ó ju láti fa àkíyèsí àwọn tí yóò tán ìṣòro sí ìjìyà àwọn ènìyàn.
Ó kígbe lóhùn rara sí àwọn angẹli mẹrẹẹrin tí a fún ní agbára láti ṣe ayé ní jamba.
Ibo ni 'Ìgẹ̀' wà ní ààgọ̀ ara?
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Lagos Okada ban: Àwọn àkàndá ẹ̀dá ní àwìn làwọn gba kẹ̀kẹ́ táwọn fi ń jẹun 7 Èrèlè 2020 Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Awọn akanda ti fẹhọnu han tako ijọba Eko lori fifi ofin de maruwa ati ọkada.
Naijiria, ojogbon Yemi Osinbajo soro ohun di mimo lasiko ti o gba alejo
iṣẹ miliọnu mẹẹdogun Pọun pẹlu ikọ agbaboolu Bluebirds.
Ìgbà tí o sì dé ọ̀dọ̀ ìyàwó rẹ̀, ìyàwó bu omi sùúrù fún un mu ó wí fún un kí ó máṣe bínú níwájú bàbá rẹ̀ mọ́.
Fun ọjọ kẹta ni ṣisẹ n tẹle, ipinlẹ Plateau lo tun gbegba oroke bayii laarin awọn ipinlẹ ti ọwọja aarun naa n pọ si lọwọlọwọ lorilẹede Naijiria.
" Femi Adebayo wá kadi ọ̀rọ̀ rẹ nilẹ pé, ẹgbẹ́ àwọn osere tíátà tí ń gbé ìgbésẹ láti kan sì àwọn onileesẹ ibaraenisọrọ láti máa fún àwọn nínú owó tí àwọn èèyàn fi ń rà káàdì gùn ìlò ojú òpó ayélujára, taa mọ sì data, èyí tí wọn fi ń wo fíìmù lórí ayélujára.
OLUWA Ọlọrun yín ti sọ yín di pupọ, lónìí ẹ pọ̀ bí ìràwọ̀ ojú ọ̀run.
Ijọba apapọ Naijiria fẹ fi ofin de gbigbe irẹsi wole lati ilẹ okere ninu ọdun 2018 nitori ati ran awọn agbẹ Naijiria l'ọwọ .
Ẹ̀yin tí ẹ wo àwọn àwòrán wọ̀nyí, ojú yín ò ní fọ́.
Nítorí náà, mo wí fun yín pé ẹ óo kú sinu ẹ̀ṣẹ̀ yín.
Agbẹnusọ ile iṣẹ Aarẹ Garba Shehu fi ẹkunrẹrẹ alaye ohun ti Aarẹ Buhari sọ nibi to ti tẹwọgba aba naa lede loju opo Twitter rẹ.
Alukoro ẹgbẹ oṣelu PDP, Kola Ologbondiyan lo sọrọ yii ninu ifọrọwerọ pẹlu lori ago pẹlu BBC Yoruba.
Pẹlu bi ile jọ giga ṣe dajọ, Zakzaky di ẹni ti wọn o ri mu liriṣiriṣi ọna.
Oríṣun àwòrán, Omo obabinrin Cambridge Ṣe ọmọbinrin abi ọmọkunrin ni?
Agbègbè Ìkóríta Ọ̀tẹ́dọla ní opópónà márosẹ̀ Ìbàdàn sí ìlú Èkó ni ìsẹ̀lẹ̀ náà ti wáyé.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Fídíò mánigbàgbé nípa ìgbà ayé Bàbá Sala Hubert Ogunde rèé, baba àwọn òsèré tíátà Gbajúgbajà òṣèré tíátà, Ijẹwuru"" ti jáde láyé Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Alápinni: Kò sí ẹni to fẹ́ kọ́kọ́ kọ́ iṣẹ́ òṣèré bíi ti àtẹ̀yìnwá Igbeyawo Oríṣun àwòrán, funkejennifaakindele Oríṣun àwòrán, funkejennifaakindele Funke Akindele pẹlu ọkọ aarọ rẹ, Adeola Kehinde Oloyede pinya lọdun 2013 latari ohun ti wọn pe ni aibaramu iwa."
Ọpọ lo n gbenu ile ti ijọba ti ṣami wiwo si Lọpọ igba ni ijọba ti ṣami si awọn ile kan lati wo ṣugbọn ti wọn ko tii wo.
Lara awọn abẹre ajẹsara ti wọn ṣẹṣẹ gbe jade ni eyii ti ilẹ UK ti fọwọ si lati ileeṣẹ apoogun Pfizer/BioNTech.
Nigba aye rẹ, Jimoh Aliu ṣe gudugudu meje ati yaya mẹfa lati mu iyatọ ba iṣẹ tiata lori mohunworan.
Ìyàwó mi ló ṣì ń dáná, bu oúnjẹ mi, gé èékáná fún mi - Pásítọ̀ Adeboye Ọkùnrin kan fipá bámi lòpọ̀ lọ́mọ ọdún mọ́kàndínlógún- Funke Oshonaike Ọlọ́pàá kọ́ lo pa olórí àwọn ''One Million Boys'' Ebila n'Ibadan- Ọ̀gá ọlọ́pàá Oyo Kí ló fa ìjà láàrin Wunmi Toriola àti Seyi Edun?
Ó ń bọ̀ ninu awọsanma, gbogbo eniyan ni yóo sì rí i.
Ọpọlọpọ eniyan lo n sọ pe Buhari ko joko sẹ idanwo naa.
Titi di akoko ti a fi n ko iroyin yii jọ, awọn agbegbe kan lorilẹede Naijiria ko tii ri ina gba pada.
Nomba  Oko ofurufu naa lo ni Sikorsky CH-53E.
Akọrin-olóhùn-òkè ni arábìnrin Tasić Knežević ní Gbọ̀ngan Eré-ìtàgé ti orílẹ̀-èdè Serbia tí ó wà ní Novi Sad, ìlú kejì tí ó tóbi jù lọ ní orílẹ̀-èdè náà.
Adájọ́ kọ̀ láti gba oniduro Dino Melaye Adájọ́ fún Dino Melaye ni beeli N100,000 Ọlọ́pàá mú Sẹnetọ Dino Melaye A ó gbé'gbésẹ̀ lẹ́yìn ìwádìí fídíò tí Dino ti ń náwó lójú agbo- Ọlọ́pàá Lazarus Ogbe - Ebonyi Ile ẹjọ to n ṣegbẹjọ ẹsun idibo ni Abakaliki ti ni ki ọgbẹni Lazarus Ogbe, ọmọ ẹgbẹ PDP to n soju ẹkun guusu Ezza kẹru rẹ kuro nile aṣoju l'Abuja pada sile.
Ọjọ̀gbọ́n Banji Akintoye: Oríṣun àwòrán, Others Nínú ọ̀rọ̀ rẹ̀ Akintoye sọ pé, Yoruba Organization lo se ìpàde ni ọjọ́ kejìlélógun, oṣù kẹjọ, ọdún 2019, tí wọ́n sì ní àwọn fẹ́ yan òun sípò ààrẹ ẹgbẹ́.
Ọkàn lára àwọn ará àdúgbò náà, Ogbeni Ogundamisi, ṣàlàyé pé, òwúrò ọjọ eti(Friday) ni àwọn àjọ Olopaa ṣẹ̀ṣẹ̀ wá gbé òkú arábìnrin náà tí òjò sì tún paa mọ́lẹ̀.
Won n pese aabo fun eranko yii bo ṣe n wa ibi to maa ye ẹyin si lọjọ Eti to kọja.
Èèyàn ní láti da ìdọ̀tí inú ẹ̀ nù lẹ́ẹ̀kọ̀ọ̀kan tó bá ti kún.
Nígbà náà ni ó wí pé, “Jẹ́ kí n lọ nítorí ilẹ̀ ti ń mọ́” Ṣugbọn Jakọbu kọ̀, ó ní, “N kò ní jẹ́ kí o lọ, àfi bí o bá súre fún mi.
Ẹni tí bá ń ṣẹ́jú sí ni láti sọ̀rọ̀ èké, a máa dá ìjàngbọ̀n sílẹ̀,ṣugbọn ẹni tí bá ń báni wí ní gbangba, ń wá alaafia.
Everton vs Liverpool: VAR gba Everton sílẹ̀ lọ́wọ́ ogun ẹ̀yìn Liverpool, ọ̀mì ayò 2-2 ní wọ́n gbá ní Merseyside
Ó ṣe wá sọ pé, láti ọ̀run ni òun ti sọ̀kalẹ̀ wá?
Awọn eniyan wa ti ko mọ nipa MRKH, mo fẹ ẹ polongo faraye.
O ni abala ofin karun un ti Tribunal of Inquiry law lo fun wọn lagbara lati gbe abajade iwadii wọn sita pẹlu irufẹ idajọ iya to tọ si ẹni ti ade iwa ibajẹ ba ṣimọ lori.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ọọ̀ni: Ìpèníjà ààbò di ìràwọ̀ ọ̀sán tó ń ba àwa àgbà lẹ́rù 18 Agẹmo 2019 Oríṣun àwòrán, Oba Adeyeye Ogunwusi Ọọni tilu Ile Ifẹ, Ọba Ẹnitan Adeyẹye Ogunwusi, Ọjaja keji, ti keboosi too fun aarẹ Muhammadu Buhari lori ipenija eto aabo to n ba ilẹ Yoruba finra.
Sugar tun gba iwe ẹri olukọni onipo kini ni ile-iwe ikọṣẹ
 Adari eka ede Yoruba ni ilu Abuja Abiodun Popoola so fun awon eniyan pe, opolopo eto ni awon ti ya sọtọ fun igbadun awon ololufe jake-jado agbaye.
Wọn fi ẹsun kan arabinrin naa, Ifeoma King pe o kan iṣo mọ ọmọ ọdun mẹwaa ọhun, Nenoma Ndadi lori.
”Igbimo Pyongyang tenumo pe, igberu ti o ba ibasepo larin orile-ede Korea mejeeji, ati larin North Korea ati Amerika ye ko wa ni ifenuko tabi ifowosowopo ti o yekooro.
Oríṣun àwòrán, Twitter/AmDanky Ibi taa ti n ṣe iwọde, imọtoto naa ṣe pataki Akojọpọ awọn eeyan maa n mu ki awọn eeyan da panti silẹ boya lẹyin ti wọn jẹun tan tabi ti wọn ba mu ohun mimu tan.
Mose kà wọ́n ní ọ̀kọ̀ọ̀kan ninu aṣálẹ̀ Sinai gẹ́gẹ́ bí OLUWA ti pàṣẹ fún un.
WASSCE: Ìpínlẹ̀ Delta fòfin de olùkọ́ 41 tó ṣe màgòmágó nínú ìdánwò
Ipade ti yoo waye ni  Berlin lati ojo keta si ikerin lo je pe awon orile ede meta ati ajo gbaye (UN) lo se onigbonwo rẹ,ipade ohun ni eyi ti o lagbara julo lọdun 2018 fun ekun  Lake Chad.
Ó sọ fún Peteru pé, “Èyí ni pé ẹ kò lè bá mi ṣọ́nà fún wakati kan?
Iranṣẹ ẹlẹgbẹ́ rẹ ni èmi náà ati ti àwọn wolii, arakunrin rẹ, ati ti àwọn tí wọ́n ti pa àwọn ọ̀rọ̀ ìwé yìí mọ́.
Àwọn olórí náà nìwọ̀nyí: láti inú ẹ̀yà Juda, a yan Kalebu ọmọ Jefune.
Nínú ìfọ̀rọ̀wánilẹ́nuwò tó ṣe láìpẹ́ yìí ló sàlaàyé bi ó ṣe rin ìrìnàjò ayé rẹ̀ gẹ́gẹ́ bi ìyàwò Prof Peller.
O si dabi ẹni pe ede aiyede to n waye lori ọrọ lọbalọba nipinlẹ Ekiti, eyi to ti n mu ọpọ awuyewuye dani, ko ni pẹ rodo, lọ ree mumi bayii, ta ba wo isẹlẹ to n waye ni aafin Ọyọ lọsan ọjọ Aiku.
Ó jẹ́ onínúrere, ó sì máa ń bá àwa ọmọdé ṣeré púpọ̀.
O fi kun pe, “didaabobo awon eniyan lati nawo ti ko ye nile-iwosan sadinku ewu, ise ati osi, laarin awon eniyan.
CCC Genesis Global: Ǹkan mẹ́wàá tí ẹ ò gbọ́ rí nípa Israel Oladele, Woli ìjọ Genesis Global Ìpànìyàn orí ayélujára lásán lẹ̀ ń pariwo, ìbọn òfifo làwọn sọ́jà yìn sínú afẹ́fẹ́ - Lai Muhammed Adájọ́ ní Seun Egbegbe ṣì lẹ́jọ́ láti jẹ́ lórí ẹ̀sùn gbájúẹ̀ Ìtàn ayé Abiola Peller, ọlọ́wọ́ idán tó fi ọ̀bẹ gé ìyàwó rẹ̀ sí méjì Kà nípa ibi tí wọ́n bí Àrẹ̀mọ tuntun Ọọ̀ni Ife sí, àti orúkọ tó ń jẹ́ Lẹyin naa ni wọn gbe e lọ si olu ileeṣẹ ọlọpaa Naijiria niluu Abuja fun ifọrọwanilẹnuwo niwaju igbimọ oluwadii FCID.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ẹ̀mí sọnu nínú ìkọlù ìpínlẹ̀ Adamawa Afẹ́nifére: Àwọn Ọba kò lè júwe ìdìbò 2019 Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Fídíò òògùn ikọ́ Codeine: Ó dùn lóòtọ́ àmọ́ ewu ni Bo tilẹ je pe ẹgbẹ agbesunmọmi kankan ko ti farahan wi pe awọn la wọn se ikọlu naa, awọn eniyan gbagbọ wi pe ikọ Boko Haram lo seese ki wọn se ikọlu naa ni Adamawa.
Yorùbá ni “Oníyàwó kan kò mọ ẹjọ́ oníyàwó  púpọ̀ da a”.
Ẹni tí ó fi ọgbọ́n dá ọ̀run,nítorí pé ìfẹ́ rẹ̀ tí kì í yẹ̀ wà títí lae; 
Ó dé ibi ihò àpáta kan, ó sì sùn níbẹ̀ mọ́jú ọjọ́ keji.
Ajọ Eleto Idibo lorilẹ-ede Naijiiria, INEC ti gbogbo eto lo ti to lati ri i wi pe ko si kudiẹ-kudiẹ ninu atundi idibo sipo sẹnetọ to n soju ẹkùn Ìwọ̀-Òòrùn Kogi.
Ṣugbọn nípa oore-ọ̀fẹ́ Ọlọrun ni mo jẹ́ ohun tí mo jẹ́.
“Afojusun wa ni lati mu ife awon babanla wa sẹ lati ni orile ede ti yoo je ti gbogbo wa, orile ede ti yoo lee je ki awon onisowo lee lowo ninu eto oro aje orile ede yii.
Wọ́n ti mú ọlọ̀pàá náà ni ọjọ́ ẹtì ó sì ti wà ní àtìmọ̀lé ọlọ́pàá láà fààyè gbà kí ẹbí kankan fojú kàn an gẹ́gẹ́ bí àwọ́n ẹbí rẹ̀ ṣe sọ.
Nigeria, Niger, Benin, Sierra Leone ati Guinea Bissau lo fi idirẹmi pẹlu maaki to kere julọ nipa nina owo ara ilu, owo ori ati kara-kata oja lorilẹede wọn.
Lojoojumọ, láti ọjọ́ kinni títí di ọjọ́ tí àsè náà parí, ni wọ́n ń kà ninu ìwé òfin.
0 15 Erekusu Marshall islands 0 0.
Esi ifẹsẹwọnsẹ yii ko jẹ iyalẹnu fun ọpọ onwoye ere bọọẹu lagbaye, paapaa idije liigi Premiership.
Adajọ yì ìgbẹ́jọ rẹ̀ padà lóri àtúndi ìbò Adamawa Wo ọjọ́ tí àfikún ìdìbò gómìnà yóò wáyé nìpínlẹ̀ mẹ́fà - INEC Atundi ibo naa waye lẹyin ti ile ẹjọ giga kan fagile ofin to n dena ki ajọ eleto idibo ṣe atundi ibo ni awọn ibudo idibo mẹrinlelogoji nipinlẹ naa.
"A kọ́ mi láti máa dìde jà fún òtítọ́, nítorí náà ni mo fi se bẹ́ẹ̀"" Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Sé aráàlú mọ àdínkù owó ọjà lára?"
Ọgbẹni Reno Omokri to figbakan ri jẹ amugbalẹgbẹ fun aarẹ ana, Goodluck Jonathan ninu ọrọ tirẹ ni irọ nla ni minisita lai Mohammed pa.
"Wo ojú àwọn òṣèré yìí láì lo ""Make-up"" orí ìtàgé bó ṣe rí gẹ́lẹ́ Èèyàn 162 ló kó àrùn Coronavirus ní Nàìjíríà lọ́jọ́ Àbámẹ́tà England kéde ìséde ọ̀sẹ́ mẹ́rin míràn láti dẹ́kun ìtànkálẹ̀ Covid 19 Ènìyàn méjì pàdánù ẹ̀mí wọn nínú ìjàmbá ọkọ̀ tó wáyé ní Abúlé Ẹ̀gbá, ní ìpínlẹ̀ Eko Olapade Agoro lọ sile iwe alakọbẹrẹ ti girama ati Enfield Training Centre, College of Technology ni Willesden London ati Gateshead Co Durham."
Bó tilẹ̀ jẹ pé ó kọ̀ láti yọju sí ilé ẹjọ, síbẹ, wọ́n wọn ẹ̀wọ̀n ọdún mẹ́jì fun ní ilé ẹjọ kan ni France.
" léhìn rè ni alárè kúrò ní ilè wàdáì ; tí ó gba asálè núbíà dé ilé-ifè , tí ó sì se "" e-nlé-ń bèun o "" fún odùdùwà ."
South Africa gbọ́dọ̀ dá owó ìtanràn padà kí wọ́n si fìyà jẹ àwọn ti ọ̀rọ̀ kàn -Sen Basiru Láìpẹ́, ará ìlú rẹ ni ọlọ́pàá tí yóò máa ṣọ́ ìlú rẹ Òfin ṣì gbẹ́sẹ̀lé Ẹgbẹ́ awakọ̀ èrò NURTW ní ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́ Agbejọ́rò Dakolo:Mílíọ́nù mẹ́wàá náírà tí a béèrè kì í ṣe owó gbà má-bínú Amọṣa ni ilu Abuja, awọn ọmọlẹyin Shiite naa ko lo to ọgbọn iṣẹju fun irin wọn naa ti wọn fi ṣẹri pada sile.
Ni dede aago mẹsan an ku iṣẹju mẹwaa owurọ ọjọ Aje ni wọn gbe pasitọ naa atawọn mẹfa mii de lati ọgba ẹwọn Olokuta to wa ni ilu Akure.
Bí ẹ bá ṣe bẹ́ẹ̀, n óo mú ẹ̀jẹ́ tí mo jẹ́ fún àwọn baba ńlá yín ṣẹ, pé n óo fún wọn ní ilẹ̀ tí ó kún fún wàrà ati oyin,’ bí ó ti rí ní òní.
Lẹ́yìn náà Mose pa á, ó tọ́ ninu ẹ̀jẹ̀ rẹ̀, ó fi kan etí ọ̀tún Aaroni, ati àtàǹpàkò ọwọ́ ọ̀tún rẹ̀, ati àtàǹpàkò ẹsẹ̀ ọ̀tún rẹ̀.
Ọrọ di ija, debi pe lasiko ija naa ni Adekunle fi ọ̀bẹ gun Stanley, ni eyi to si ja si iku fun un.
Alágbẹ̀dẹ a mú irin, a fi sinu iná, a máa fi ọmọ owú lù ú, a sì fi agbára rẹ̀ rọ ọ́ bí ó ti fẹ́ kí ó rí.
Idanwo naa, UTME ti ọpọ maa n pe ni JAMB ni idanwo ti awọn ti awọn to ba fẹ wọ ile iwe giga lorilẹede Naijiria.
Oríṣun àwòrán, @vera Àkọlé àwòrán, Àwọn obinrin yoo ri anfaani to pọ jẹ - Vera Songwe Dapọ Abiọdun ree, ẹni tó dépò gómìnà ní àyájọ́ ọjọ́ ìbí rẹ̀ Ilé ẹjọ́ gba onídúró Naira Marley pẹ̀lú mílíọ́nù méjì náírà Ohun tó yẹ kí o mọ̀ nípa OIC rèé Wo àwọn ìlérí tàwọn Gómìnà tuntun ṣe nínú ìbúra wọn Akọṣẹmọṣẹ Vera Songwe to jẹ akọwe ajọ iṣokan agbaye UN lori eto ọrọ aje nilẹ Afrika sọrọ kikun lori anfaani fawọn oloko owo obinrin.
Oríṣun àwòrán, TWITTER Àkọlé àwòrán, Nibi ipade kan to waye ni ile Aarẹ ni Abuja ni Aare Muhammadu Buhari ti tu Igbimọ Amuṣẹya ẹgbẹ oselu APC ka.
Sibẹsibẹ, mo rí i pé ọgbọ́n ju agbára lọ, bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé wọn kò ka ọgbọ́n ọkunrin yìí kún, tí kò sì sí ẹni tí ó fetí sí ọ̀rọ̀ rẹ̀.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Buhari, Saraki, Dangote, abẹ́ mi ni wọ́n wà' Lizzy salaye pe, ko si bi awọn se lee sọra to, ori ẹsẹ awọn ni oun ati iya oun yoo sun lori iduro lasiko ti ẹkun omi ba de, tawọn yoo si maa ju ọpọ ohun ti awọn gba lawin danu nitori ilẹ to n yọ lasiko ojo.
Ọjọ́ meje ni wọ́n fi fi tayọ̀tayọ̀ ṣe ayẹyẹ Àjọ Àìwúkàrà, nítorí pé Ọlọrun ti fún wọn ní ayọ̀ nítorí inú ọba Asiria tí ó yọ́ sí wọn, tí ó sì ràn wọ́n lọ́wọ́ láti tún ilé Ọlọrun Israẹli kọ́.
Ìkà rẹ̀ pada sórí ara rẹ̀,àní ìwà ipá rẹ̀ sì já lù ú ní àtàrí.
Yewand ti ṣe fiimu bi maarun láti igba to ti bẹ̀rẹ̀ ere tiata.
Àwọn ìlú tí wọ́n fún àwọn ọmọ Aaroni, alufaa, jẹ́ mẹtala pẹlu àwọn pápá ìdaran tí ó wà ní àyíká wọn.
 Àwọn àwòkọ wọ ̀ nyí ṣe é tà , sùgbọ ́ n eni tó tà gbọdọ ̀ mọ ̀ pé elòmíràn náà lè ṣe àtúnṣe síi láì gbàṣẹ lọ ́ wọ ́ rẹ ̀ .
Kilode ti awọn ipaniyan wọnyi ṣe pataki?
Ọkan lara awọn eeyan to n kọja lasiko ti iṣẹlẹ naa waye, Ọgbẹni Ademọla fi idi isẹlẹ naa mulẹ pe lasiko ti ohun lọ si ẹnu iṣẹ ni alẹ ana ni ina dede sọ ni ọọfisi MTN ọhun.
Ẹ ní kí wọn máa ṣílẹ̀kùn ọjà gbogbo fún wákàtí mẹ́fà, kí wá lo dé tí ẹ kò fi silẹkun sọọsi fún wákàtí méjì, mo ní ìgbàgbọ́ pé iditẹ mọ ìdàgbàsókè àwọn sọọsi ni Nàìjíríà ni èyí.
Ọpọ eeyan ni Isho Pepper kọ ni iṣẹ tiata, lara wọn ni Samson Eluwole (Jinadu Ewele), oloogbe Adeniyi Orofo (Ewejoko) ati oloogbe Gbolagade Adedeji (Aro onifila gogoro).
Igbagbọ rẹ̀ kò yẹ̀ bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé ó ro ti ara rẹ̀ tí ó ti di òkú tán, (nítorí ó ti tó ẹni ọgọrun-un ọdún) ó tún ro ti Sara tí ó yàgàn.
N kò ba yín wí nítorí ẹbọ rírú;nígbà gbogbo ni ẹ̀ ń rú ẹbọ sísun sí mi.
Kò yẹ kí ìjọba máa ní àwọn mẹ̀kúnú lára lásìkò Coronavirus yìí- Rewane Akitiyan ìjọba láti mú kí àwọn ọmọ Nàìjíríà san owó orí Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
ewuro iya aayo marun un sodo(5-0) soju iko agbaboolu Dynamo Kiev.
Bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé àwọn ọ̀jọ̀gbọ́n ń sọ pé àwọn mọ iṣẹ́ OLUWA, sibẹsibẹ wọn kò lè rí ìdí rẹ̀.
Lara àwọn ǹkan ti Gbenga Adeboye gbá ayé ṣe Oríṣun àwòrán, Itubaba ita Àkọlé àwòrán, Ǹjẹ ẹ si ránti Fúnwọntán, Alhaji pásítọ̀, Olúwo Gbenga Adeboye Gbénga Adeboye tí fi ọ̀wọ̀ kàn ayé ọ̀pọ̀ ti a sì n rí lónìí, lára wọn ni Yinka Ayefele, Fathia Balogun, Ereke ni Sọọbu, Bashiru Adisa ti gbogbo ènìyàn mọ si Baba Gbọin Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Lẹyin ti ijọba apapọ kede pe awọn ileewe girama rẹ ko ni le kopa ninu idanwo aṣejade iwe mẹwaa, WAEC eyi ti yoo bẹrẹ ninu oṣu kẹjọ, ọdun 2020 nitori coronavirus, awọn ipinlẹ Yoruba naa ti sọ ero wọn lori igbesẹ ijọba apapọ.
Amọ, ijọba ipinlẹ Eko ninu atẹjade ti ko si ẹni to buwọlu sọ wi pe, ile ikohunsi to jẹ ọkan lara ti ijọba ni awọn janduku lo ṣe ikọlu si naa, Ati wi pe awọn ohun eelo naa wa fun awọn ti nkan ko lo deede fun ni awujọ.
Ṣugbọn ojuṣe mi ni lati rii pe orilẹ-ede yii jẹ ọkan ṣoṣo, ati pe o ni itẹsiwaju.
Dada ṣalaye fawọn akọroyin pe awọn iwa kan ti Risikat n hu ti ko tẹ oun lọrun lo fa ija laarin awọn mejeeji ti ipinya fi de bawọn.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Katsina kidnap: Ìyá àti ọmọ ọdún mẹ́ta gba òmìnira lọ́wọ́ ajínigbé lẹ́yìn tí wọ́n san ₦1.
Jesu bá gba ọ̀rọ̀ mọ́ ọn lẹ́nu, ó ní, “Mo fẹ́ kí o mọ̀ dájúdájú pé, ẹnikẹ́ni tí a kò bá tún bí láti ọ̀run kò lè rí ìjọba Ọlọrun.
Kí ó má baà sọ àwọn ọmọ rẹ̀ di aláìmọ́ láàrin àwọn eniyan rẹ̀; nítorí pé èmi ni OLUWA, tí mo sọ ọ́ di mímọ́.
Agba olorin takasufe, Innocent Idibia ti gbogbo eniyan mọ sí 2Baba lo gba ami ẹyẹ orin takasufe to gbayi julọ ni ilẹ Afirika.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Wo bí Sunday Orimola ṣe gba ikú ẹranko kú ní Ifon ni Ondo lórí ọ̀nà àtijẹ Ṣe ọmọ ilẹ̀ Afirika ni Boseman Chadwick?
" Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, coronavirus prevention badge update: Wo òótọ́ àti irọ́ tó wà nínú báàjì àyà náà Wọn ni miliọnu marun un ati igba naira ni wọn yoo fi yanju ọrọ atunse jẹnẹratọ amunawa ti wọn yoo si fi miliọnu marundinlaadọta N45m ra epo jẹnẹratọ.
Eyi ni ohun ti agbẹjọro rẹ Femi Falana sọ fun BBC ni irọlẹ oni ninu ifọrọwanilẹnuwo lori ẹrọ alagbeka.
Mi o gbọdọ fi oju ri ẹni to wọ aṣọ SARS; Oku meji a ba Olorun nile ni- Iya Agbabọọlu tiamiyu Kazzim Kaka Inu mi maa n bajẹ ni ti mo ba ti ri SARS- Baba Kaka Tiamiyu Kazim Ènìyàn méjì pàdánù ẹ̀mí wọn nínú ìjàmbá ọkọ̀ tó wáyé ní Abúlé Ẹ̀gbá, ní ìpínlẹ̀ Eko Ẹ̀gbọ́n mi tán ìṣòro mi nípasẹ̀ ṣíṣe ẹ̀ya ara àtọwọ́dá fún mi- Ubokobong Sunday England kéde ìséde ọ̀sẹ́ mẹ́rin míràn láti dẹ́kun ìtànkálẹ̀ Covid 19 Akinwumi Isola dárà nínú ìwé Nítorí Owó"" lórí Akomolede Yoruba Sanwo Olu àti Okowa dẹwọ́ ìséde ní Eko àti Delta pẹ̀lú àlàyé tuntun Fasasi Tiamiyu to jẹ baba rẹ naa sọrọ ilẹ kun pe o wu oun lati foju kan Niyi Ogunsoro ti ọpọ n pe ni O yatọ to jẹ ọlọpaa SARS ti awọn alafojuri ni o pa ọmọ wọn."
Ẹ jẹ́ kí á kó ara wa jọ,kí á sá lọ sí àwọn ìlú olódi,kí á sì parun sibẹ;nítorí OLUWA Ọlọrun wa ti fi wá lé ìparun lọ́wọ́,ó ti fún wa ní omi tí ó ní májèlé mu,nítorí pé a ti ṣẹ̀ ẹ́.
Nibi osẹ meji sẹyin ni aarẹ Buhari fi adajọ Ibrahim Tanko Muhammad rọpo Onnoghen.
Àwọn ajàfẹ́tọ̀ọ́-ènìyàn tí a fọ̀rọ̀ wá lẹ́nu wò lórí ìṣẹ̀lẹ̀ yìí jẹ́ kí á mọ̀ wípé àbùkù ìrànwọ́ ìjọba àti àwọn onímọ̀ ni kò mú ìwà àìbójúmu náà ṣíra kásẹ̀ ńlẹ̀.
Lai pẹ yi ni awuyewuye waye lori bi o ti ṣe juwe olori ẹgbẹ ẹsin Shia Zakzakky gẹgẹ bi ẹrankọ ninu ifọrọwerọ kan lori ẹrọ amohunmaworan Ninu awọn to ti n faraya lori ọrọ naa lati ri Femi Fani Kayode,Aisha Yesufu ati Sẹnẹtọ Ben Murray Bruce to fi mọ ẹgbẹ oselu PDP ti wọn bu ẹnu atẹ lu ihalẹ El Rufai yi.
sẹsẹ gbọ nipa Awon omo egbe ,All Progressives Congress (APC) to padanu emi won
Lọjọ Satide ọhun ni ijọba paṣẹ fun awọn oṣiṣẹ ileeṣẹ naa ki gbogbo wọn dawọ iṣẹ duro ki wọn si ma lọ sibi iṣẹ mọ.
Túbọ̀ máa fi ìfẹ́ rẹ tí kì í yẹ̀han àwọn tí ó mọ̀ ọ́,sì máa fi òdodo rẹ han àwọn ọlọ́kàn mímọ́.
Ibẹrẹ ọsẹ yii ni awọn alaṣẹ ileeṣẹ ologun ofurufu fi orukọ ẹni to fi ọkọ gba Tolulope sita.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Itan Ilu gangan Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Ko ti daju boya wọn yoo fi ibo tẹnikọọkan ba di han ṣugbọn eyi keyi to ba jẹ,bi oludije kan ba ti le ni ibo to pọju tẹni keji rẹ, oun ni yoo di aarẹ.
 ilé ẹ ̀ kọ ́ gíga ilé ọgbọ ́ n , ilé ẹ ̀ kọ ́ gíga ilé òmìnira .
Ìṣẹ́ ló jẹ́ kí n sọ ọmọ nù sórí ààtàn- Dupẹ, Ìyá Muiz A kú oríire!
Gbiyanju òwe yii nípa fifi èyí to jẹ idahun ipari rẹ̀ kan ara wọn Fi igun ibẹrẹ òwe naa kan igun ipari òwe naa papọ Wo iye máákì mi Ṣe afihan esi rẹ Adé orí ọ̀kín kò lè ṣe déédé orí ẹyẹkẹ́yẹ Àgbàdo inú ìgò, ó di àwòmọ́jú fún adìyẹ Pẹ́pẹ́yẹ ńlérí lásán ni, kò ní kọ A kì í dàgbà jù fún ohun tí a kò bá mọ̀ Kíkéré l'abẹ́rẹ́ kéré, kì í ṣe mímì fún adìyẹ Ó di ìgbà tí òjò bá dá kí alágborùn tó mọ̀ pé ẹrù lòún gbé Dídákẹ́ lerín dákẹ́ àjànàkú ló lẹgàn Adẹ́tẹ̀ ò lè fún wàrà ṣùgbọ́n ó lè da wàrà nù Àdánìkànrìn ejò ló ńjẹ ọmọ ejò níyà Tí ẹja bá sùn ẹja á fi ẹja jẹ.
Nítorí náà, mo pinnu pé n kò tún fẹ́ kí wíwá tí mo bá wá sọ́dọ̀ yín jẹ́ ti ìbànújẹ́ mọ́.
Àkọlé àwòrán, Àmì ìdánimọ̀ àti oge ṣíṣe ni ilà jẹ́ nílẹ̀ Yorùbá Arabinrin Sekinat Adekoge ni 'ohun amuyangan ni ila oju oun jẹ fun oun, lai fi ti eebu ti awọn eniyan maa n bu oun ṣe.
Atejade ohun so pe, “ni asiko yii, ko si awon ara-ilu ti o padanu-emi re ninu ikolu naa”.
Ni àwọn eniyan náà bá bẹ̀rẹ̀ sí kùn sí Mose, wọ́n ní, “Kí ni a óo mu?
Ai ni ìtẹ́lọ́rùn ló fa ki àgbàlagbà jowú ọmọdé nitori ọmọ àná ti ó rò pé kò lè da nkankan ti da nkan, tàbi ki ọ̀gá ilé-iṣẹ́ ma jowú ọmọ iṣẹ́.
Sugbọn ohun ara meeriri ti Djxgee se, ko to ki aye pe o digbose ni pe, o lọ si oju opo ikansira ẹni rẹ loju opo Instagram, to si kọ sibẹ pe, asọ funfun ni ohun fẹ kawọn eeyan wọ fi se ọfọ oun, tori oun ko nifẹ asọ dudu rara, o ni o duro fun asọ ọfọ.
Eto abo to jọju wa lawọn ileewe kan ni ipinlẹ yii sugbọn ijọba ti n gbe igbesẹ lati se atunto ilana eto abo lawọn ileewe gbogbo nipinlẹ yii.
Oríṣun àwòrán, Olu Alebiosu Àkọlé àwòrán, Ọdọọdun ninu oṣu kẹjọ ni ọdun Ọṣun Oṣogbo maa n waye Kaakiri agbaye ni awọn eeyan ti maa n wa lati ṣe ọdun Ọṣun Oṣogbo.
 gbogbo ìró fáwẹ ̀ lì èdè yorùbá ló jẹ ìró akùnyùn .
Kó má a lọ bẹ̀ ẹ́ ní ìséde coronavirus fún ọ̀sẹ̀ méjì míràn - Ìjọba Nàìjíríà Ijọba orilẹ-ede Naijiria ti kede pe isede yoo tẹsiwaju fun ọsẹ meji miran.
Ileeṣẹ naa si ti fesi pe oun yoo ṣe gẹgẹ bi ijọba ti pa laṣẹ fun un.
Arìnrìn àjò tó bá ṣẹ̀ṣẹ̀ dé gbé, ábẹ́ ààbò ọjọ́ mẹ́rìnlá ni wọn yóò wà torí Covid19 - Uganda Gómìnà ìpínlẹ̀ Kaduna, El-Rufai fi ipò míì dá Sanusi lọ́lá Ganduje fún Aminu Ado Bayero ní ìwé ìyannisípò gẹ́gẹ́ bí Emir ìlú Kano Coronavirus ti di àjàkálẹ̀ àrùn káàkiri àgbáyé- WHO Ṣugbọn lẹyin iṣẹ takuntakun ti ijọba ilu Eko gunle, pẹlu iranlọwọ lati ọdọ ijọba apapọ, wọn ṣawari awọn eeyan naa.
O ṣeeṣe ko jẹ aarẹ lasan ni, o le maa jẹ arun Coronavirus.
Olori awọn oṣiṣẹ nipinlẹ Eko, Hakeem Muri-Okunola lo kede ọrọ yii ninu atẹjade kan to fi sita, to si tun fi ṣọwọ sawọn olori ẹka ijọba gbogbo l'Ọjọru Ọgbẹni Muri-Okunola ni nitori iṣẹ to n lọ lori ẹkunwo owo oṣu oṣiṣẹ tuntun yii ni ko jẹki awọn oṣiṣẹ gba owo oṣu kọkanla yii lọjọ kẹtalelogun ti wọn maa n gba tẹlẹ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Oba Adedokun Abolarin ti Oke Ila: Ó ya ọ̀pọ̀ tó súnmọ́ mi lẹ́nu bí mo ṣe ń kọ́ Adejobi fi kún pé, kọ́mìsọ́nà ọlọ́pàá nípìnlẹ̀ Eko, Hakeem Odumosu ti páá lásẹ̀ pé ki wan gbé ẹja náà lọ sí Panti fún ìwádìí tó dájú Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Eégun àti orò, bí wọ́n ṣe jọ bí Ẹ̀ṣà Egúngún nílẹ̀ Yorùba rèé Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Ondo Election 2020: Ẹ wo àwọn olùdíje sípò gómìnà nípínlẹ̀ Ondo tó takò bàbá ìsàlẹ̀26 Owewe 2020 Fídíò, Akọ́mọlédè àti Àṣà lórí BBC Yorùbá: Kọ́ síi nípa iṣẹ́ tí oúnjẹ ń ṣe lára níbí24 Bélú 2020 9ice Marriage: Ẹ ba mi bẹ ìyàwó mi, òun ni igi lẹ́yìn ọgbà mi22 Bélú 2020 Fídíò, The New Pandemic: Kíni àwọn onímọ̀ sáyẹ́ńsì ń sọ nípa rẹ̀?
Ariyanjiyan si ti n waye lori boya Buhari yoo lọ ọ tabi ko ni i lọ, paapa lẹyin ti Agbẹjọro Agba Naijiria, to tun jẹ Minisita fun eto idajọ, Abubakar Malami sọ l'Ọjọru pe, awọn aṣofin ko ni ẹtọ labẹ ofin lati ranṣẹ pe Buhari.
Lẹyin ti gbogbo ọmọ Naijira bẹnu atẹ lu bi awọn ọlọpaa ṣe lu arakunrin naa, ni wọn ṣe ayẹwo oku rẹ.
 Ati pe lootọ ni ofin kò gba ki wọn sin oku si adugbo ti ijọba ya sọtọ, ìyẹn GRA.
Lẹnu ọjọ mẹta yi, Gomina ipinlẹ Oyo Seyi Makinde ati Ayodele Fayose jijọ n tahun sí ara wọn lori didari ẹgbẹ oṣelu PDP.
Igbimo to n ri si isele pajawiri(NEMA)Ewe, ile igbimo ohun tun benu ate lu gbigbogun ti igbimo to n mojuto ise ajo NEMA, lati igba ti igbimo naa ti jabo lori ajo ohun lose ti o koja.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 2020: Ọdun 2020 yii ko nìí nira fún àwọn tó bá bẹ̀rù Olorun Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Ayé kò lè kórìíra yín, èmi ni wọ́n kórìíra, nítorí ẹ̀rí mi lòdì sí wọn nítorí pé iṣẹ́ wọn burú.
Oríṣun àwòrán, @gidabless Ǹjẹ́ ewu wà nínú lílò ẹ̀rọ FaceApp?
Chelsea vs Manchester United: Àwọn agbábọ́ọ̀lù Ole lé Chelsea kúrò ní ìdíje Carabao Cup
ṣugbọn ati àwọn tí wọn kò sí níhìn-ín lónìí, ati ẹ̀yin alára tí ẹ dúró níwájú OLUWA Ọlọrun yín lónìí, ni majẹmu náà wà fún.
Onimo ero Seyi Makinde fi idunnu re han to si dupe lowo gbogbo omo bibi ati olugbe Ipinle Oyo bi won se fi ibo won gbe oun wole gege bi gomina tuntun  ni Ipinle Oyo.
Sarri: Ìbéérè márùn ùn yìí ni Chelsea ní láti dáhùn
Koda iṣẹlẹ ọrọ riba yii ni Kwesi ba kuro nipo gẹgẹ bii aarẹ ajọ to n mojuto ọrọ ere bọọlu ni Ghana.
Ẹ̀wẹ̀, ìgbésẹ̀ yìí ti fa ọ̀pọ̀lọpọ̀ awuyewuye káàkiri yálà láti gbè lẹ́yin ohun tí gómìnà Ajimọbi ṣe tàbí ta kò ó.
"Ipinlẹ kọọkan ni yoo gba awọn osisẹ Amotekun tiẹ si ẹnu isẹ lati ẹsẹkuku to wa lagbegbe koowa wọn, iyẹn awọn eeyan to kaato ninu ilana ibilẹ lati gbe eto aabo larugẹ pẹlu awọn ileesẹ agbofinro, laipẹ yii si ni ilana isọwọsisẹ Amotekun yoo bẹrẹ, lẹyin ta ba yọrọ rẹ tan, ti ikọ Amotekun yoo si bẹrẹ isẹ ni pẹrẹu.
Ǹjẹ́ ìran èké kọ́ ni wọ́n ń rí, tí wọ́n sì ń woṣẹ́ irọ́, nígbàkúùgbà tí wọn bá wí pé, ‘OLUWA wí báyìí’, bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé n kò sọ̀rọ̀?
Ọmọ isaac Adewọle gba ìdáǹdè lọ́wọ́ ajínigbé Ayinla Ọmọwura, orin èébú àti oríyìn lo fi di ọ̀rẹ́ àwọ̀n obìnrin A kò fẹ́ Festus Adedayo ní ìjọba Buhari - Àwọn olólùfẹ́ APC yarí Gbìyànjú àwọn òwé Yòrúbà yìí wò Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Ọlọrun ti dí ọ̀nà mọ́ mi, kí n má baà kọjá,ó mú ọ̀nà mi ṣókùnkùn.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Bi ọrọ orogun adedigba ni ifẹsẹwọnsẹ laarin Arsenal ati Tottenham maa n jẹ nitori ifigagbaga awọn mejeeji lori mimọ tani alagbara ẹkun ariwa ilu London, eyi ti a ms si North London.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ẹgbẹ ajijagbara Niger Delta Avengers Bẹẹ ba si gbagbe, osu kọkọnla ọdun to kọja, lẹgbẹ ajijagbara naa kede pe awọn ti jebure, bẹẹ si ni lọdun 2016 yi kanaa, ẹgbẹ Niger Delta Avenger kọlu opo eroja ipese epo to wa labẹ omi ni Forcados, eyi ti awọn omuwẹ abẹ omi se.
Amọṣa, ẹdinwo tuntun yii ko kan epo disu.
Ko da iroyin sọ pe o ti ba ọkọ toun naa jẹ oṣere Toyin Abraham sọ ọrọ pupọ, bẹẹ si ni Kolawole Ojeyemi Ọkọ Toyin Abraham pẹ́ ọ̀rọ̀ sọ lórí aáwọ̀ láàrin ìyàwó rẹ̀ àti Lizzy Anjorin nigba to fi ọrọ bi afiwe sita loju opo instagram tirẹ naa lai gbe lẹyin ẹnikan ṣugbọn to n fi apẹrẹ bo ṣe yẹ ki ọrọ maa rin laarin awn oṣere han.
Bẹ́ẹ̀ ni wọn kò bi òun náà pé kí ló dé tí ó fi ń bá obinrin sọ̀rọ̀?
Sibẹ àwọn eniyan ń lọ sọ́dọ̀ rẹ̀ láti ibi gbogbo.
O ni o yẹ ki awọn awakọ yii mọ riri ijọab to n pese iranwlọwọ fun wọn ni kii ṣe pe ki wọn tun maa fi iṣẹ oojọ ti wọn ni awọn ara ilu miran lara nipa fifa sunkẹrẹ-fakẹrẹ ọkọ.
BBC Yoruba kan si gomina tẹlẹ nipinlẹ Oyo, Otunba Adebayo Alao Akala lati mọ bi iku Ajimọbi se ri lara rẹ.
Gomina ipinle, Carabobo Rafael Lacava ba awon eniyan re kedun, o tun so pe”iwadii gidigidi n lo lowo nipa isele naa ati nipa awon eniyan to lowo nibi isele buruku naa.
O fikun ọrọ rẹ pe, awọn Ọba mọkalelogun gan an lo lagbara lati yọ Olubadan nipo, Olubadan ko lagbara lati yọ awọn Ọba ilu Ibadan.
Ṣe ko kuku si obinrin ti yoo gbọ ọrọ ọmọ ti ko ni ta kiji, eyi lo si gbe BBC News Yoruba de Igboọra lati mọ aṣiri ibi ibeji nibẹ.
Wọ́n pa ẹgbẹẹdogun (3,000) eniyan, wọ́n sì kó ọpọlọpọ ìkógun.
Ọmọ ilu Agbamu nipinlẹ Kwara ni awọn Afọlayan.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Children's Day: Àwọn ọmọdé tó ń ṣe bẹbẹ láwùjọ Afíríkà 27 Èbibi 2019 Àkọlé àwòrán, Òun ní ẹni tó kr jùlọ tó sì gba àmì ẹ̀yẹ ní òrílẹ̀-èdè GhanaChildren's Day: Àwọn ọmọde tó ti bẹ́bẹ́ láwùjọ Afíríkà Òní ni àyájọ ọjọ́ àwọn èwé lórílẹ̀-èdè Nàìjíríà, gẹ́gẹ́ bí àjọ tó ń ri sí ẹ̀tọ́ ọmọ wẹ́wẹ́ lágbàyé (UNICEF) ṣe là á kalẹ̀.
'Ilé làbọ̀ ìsinmi oko fọ́mọ Yorùbá lórí Brexit' Olootu ijọba UK yóò ṣèpàdé láti dóòlà ‘Brexit’ Olootu ijọba UK yóò ṣèpàdé láti dóòlà ‘Brexit’ Ni adugbo Downing street ni May ti ṣe ikede yii pe ó tó gẹ́, O digba ti wọn ba yan adari miran sipo ki Theresa May to kogba wọle patapata.
Naomi ati àwọn opó àwọn ọmọ rẹ̀ mejeeji jáde kúrò ní ilẹ̀ Moabu, wọ́n ń pada lọ sí ilẹ̀ Juda, nítorí ó gbọ́ pé OLUWA ti ṣàánú fún àwọn eniyan rẹ̀ ní ilẹ̀ Juda, ati pé wọ́n ti ń rí oúnjẹ jẹ.
Agbẹnusọ fun ileeṣẹ ọlọpaa ṣalaye pe, ko si ẹni to ba iṣẹlẹ naa lọ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Fashola: Omi ń bẹ lámù nídìí ìpèsè ina ọba 17 Ìgbé 2018 Oríṣun àwòrán, Reuters Àkọlé àwòrán, Inà mọ̀nàmọ̀nà ti wà déédé láti ǹkan bíi osù méjì sẹ́yìn Ibùdọ Amúnáwá ní Nàìjíríà tún ti kọsẹ́ lẹ́ẹ̀mejì láàrín ọjọ́ márùn ùn, bẹ́ẹ̀ iná ọ́ba ti ń se déédéé láti bíi osù méjì sẹ́yìn ní orílẹ̀èdè Nàìjíríà.
Ó ṣètò ìràpadà fún àwọn eniyan rẹ̀,ó fi ìdí majẹmu rẹ̀ múlẹ̀ títí lae,mímọ́ ni orúkọ rẹ̀, ó sì lọ́wọ̀.
Niwọn igba to jẹ pe ika to ba tọ simu, laa fi nre imu, ileesẹ BBC gba awọn osisẹ ti musemuse wọn da musemuse sẹnu isẹ.
Oṣu Kẹjọ, ọdun 2020 yii ni Sean Connery ṣe ayẹyẹ ọjọ ibi ẹni aadọrun ọdun lori ilẹ aye ko to di wi pe o di oloogbe.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Oyo: Ọkùnrin mẹ́tàlá, obìnrin kan ni Makinde fi orúkọ wọn sílẹ̀ 25 Agẹmo 2019 Oríṣun àwòrán, Seyi makinde/instagram Gomina ipinlẹ Ọyọ, Seyi Makinde ti kede ti o si fi orukọ awọn to fẹ yan si ipo kọmisana ipinlẹ naa ranṣẹ sile aṣofin.
Laarin ọsẹ meji pere ni awọn onibaara naa gbọdọ fi nọmba NIN wọn ranṣẹ, bẹrẹ lati ọjọ kẹrindinlogun, oṣu Kejila si ọgbọnjọ, oṣu Kejila, ọdun 2020.
Olówó ọmọ orílẹ̀èdè Tanzania náaà sọ ọ́ di mímọ̀ lójú òpó Twitter rẹ̀ fún ra rẹ̀ wí pé òun ti padà sílé lálàáfíà.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù FBI List: Ìwádìí EFCC àti FBI ti ń so èso rere 28 Ògún 2019 Oríṣun àwòrán, @ChikeEjiofor Àkọlé àwòrán, Awọn afurasi ọgọrin, ti ọpọlọpọ wọn jẹ ọmọ Naijiria ni ajọ FBI ti fi ẹsunn kan wi pe, wọn lu gbajuẹ nilẹ Amẹrika Alaga fidihẹ fun ajọ EFCC, Ibrahim Magu, ti sọ wi pe, ajọ naa ti bẹrẹ si nii ṣe akojọpọ iwadii awọn ọmọ Naijiria ti ajọ ọtẹlẹmuye Amẹrika, FBI, fi ẹsun kan lori iwa jibiti.
Ó sọ fún wọn pé, “Àwọn nǹkan tí ó tó kórè pọ̀ ninu oko, ṣugbọn àwọn òṣìṣẹ́ kò pọ̀ tó.
O ni ibẹrẹ oun ọtun ree ninu aye oun, Ogo si ni fun Ọlọrun.
Ẹ wá lọ mú mààlúù tí ó sanra wá, kí ẹ pa á, kí ẹ jẹ́ kí á máa ṣe àríyá.
Nígbà náà ni n kò tó ni bínú sí àwọn eniyan náà mọ́.
Awon alase lorile-ede ti fowo sinkun mu eniyan mejo ninu iwadii won, latari ikolu omo –ogun orile-ede Faranse.
Pigeon: Wo ìdí tí wọ́n fi ta ẹyẹlé kan ṣoṣo ní ₦893,000,000
 Àbúrò orímóògùnjẹ ́ ni ilésanmí tí òun àti olófìn-íntótó jọ wá ṣe ìwádìí ní ilé-ifè .
Kí Ọlọrun má kà á sí wọn lọ́rùn.
Wọ́n gbé ìkòkò omi wọn pada lófìfo,ojú tì wọ́n, ìdààmú dé bá wọn,wọ́n káwọ́ lérí.
Ó lọ ilé ìwé Girama ní ìlú Eko, ilé ẹ̀kọ́ gbogbo nìṣe ti Ibadan ní ìpínlẹ̀ Ọyọ níbi tó ti kẹ́kọ̀ọ́ nípa ètò ìsúná.
Bakan naa, igba keji ree ti ẹgbẹ agbabọọlu Senegal yoo gba ipo keji(fadaka) ninu idije AFCON lẹyin ti wọn kọkọ gbaa lọdun 2002 nigba ti wọn gbalejo idije naa.
Wòlíì Kasali ní Dolapo Awosika kò lé ìyàwó òun jáde Awọn ohun to se koko to yẹ ko mọ nipa Alajọ Somolu ree: Ọjọ Kẹrindinlogun osu Kẹjọ ọdun 1915 ni wọn bi baba Alajọ Somolu Ẹ̀ta òkò ni Alphaeus Taiwo Olunaike, tí gbogbo èèyàn mọ̀ sí alájọ Sómólú, ìbẹta ni wọ́n bíi Ilu Isọnyin Ijẹbu nipinlẹ Ogun ni iya rẹ, Grace Okuromiko Olunaike ti bii ni ibẹta, ti wọn si fi ọkan rubọ ninu wọn gẹgẹ bii asa igba naa Ile ẹkọ alakọbẹrẹ Emmanuel nilu Ijẹbu Isọnyin ni alajọ Somolu lọ Ọmọ ọdun mẹta lo wa to fi padanu baba rẹ, ti aburo baba rẹ si mu lọ silu Eko Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, The Polytechnic Ibadan: Ẹ̀rọ abẹ́lé tó ń fọ ọwọ́ àti ‘Ventilator’ ló ṣẹ̀ṣẹ̀ gbé jáde Olunaike kọ isẹ aransọ, taa mọ si Taylor, to si fi se isẹ se, amọ owo perete to n ri nibẹ ko to na rara Nigba ti aburo baba rẹ́ yii n lọ fun okoowo ni orilẹede Cameroon ni Taiwo ba tẹle lati wa isẹ kun isẹ rẹ Ilu Cameroon lo ti kọ isẹ ajọ gbigba, to si bẹrẹ isẹ tiẹ ni kete to pada de si ilu Eko lọdun 1954, to si pe orukọ ajọ rẹ ni ‘Alajọ Somolu’ Alajọ̀ Somolu ta mọto rẹ lati fi ra kẹkẹ nigba ti isẹ ajọ rẹ buyari, eyi tawọn eeyan fi maa n pa aṣamọ pe ‘ori rẹ pe bii Alajọ Somolu, to ta mọto, fi ra kẹkẹ O kọ ile akọkọ lati idi ajọ̀ to n gba si ojule kẹwa, opopona Odunukan, Ijẹsatẹdo, amọ to ta ile naa fun ijọ kan lẹyin o rẹyin Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Risikat Moromoke Azeez: Inú èmí àti Òbí mi dùn nígbà ti Risi bí ọmọ olójú búlù- Wasiu Ile keji ti Alajọ Somolu kọ lo wa ni ojule kẹwa, Ọlọrunkẹmi Owotutu, Bariga nilu Eko Baba Olunaike jẹ akapo fun ijọ Anglika to n lọ ni adugbo Ṣomolu, to tun jẹ akabibeli lasiko isin, taa mọ si ‘Lay-reader’ Odu ni alajọ Ṣomolu nigba aye rẹ nidi ajọ gbigba, kii si se aimọ fun oloko lawọn adugbo bii ọja Awolọwọ, Ṣomolu,Ọlalẹyẹ, Oyingbo ati bẹẹ bẹẹ lọ Ẹni ọdun marundinlọgọrun, 95, ni baba Olunaike fẹyinti ninu isẹ ajọ gbigba, lọdun 2010, lẹyin to ti sisẹ takuntakun ninu isẹ ajọ gbigba Alphaeus Taiwo Olunaike jẹ Ọlọrun nipe lọjọ kọkanla, osu kẹjọ ọdun 2012, to si ki aye pe o digbose.
Àwọn aláṣẹ orílẹ̀-èdè Ghana ti ní Nyantakyi àti àwọn mìíràn tí wọn gba rìbá naa ni yóò wọ wàhálà.
Àwọn Farisi wá sọ́dọ̀ rẹ̀, wọ́n ń dán an wò; wọ́n bi í pé, “Ǹjẹ́ ó tọ̀nà pé kí ọkunrin kọ iyawo rẹ̀ sílẹ̀ fún ìdí kankan?
Nítorí náà, ẹ̀yin àyànfẹ́ mi, a ti kìlọ̀ fun yín tẹ́lẹ̀.
Ní ọjọ́ náà, OLUWA Ọlọrun wọn yóo gbà wọ́n,bí ìgbà tí olùṣọ́-aguntan bá gba àwọn aguntan rẹ̀.
O kò gbọdọ̀ bá eniyan burúkú pa ìmọ̀ pọ̀ láti jẹ́rìí èké.
Lẹyin ipade gbogbogbo ti wọn ṣe lọgba ile ẹkọ giga gbogboun'se ipinlẹ Ọṣun ni ilu Iree, agbẹnusọ fun ẹgbẹ awọn olukọni ile ẹkọ giga gbogboun'se lorilẹede naijiria, ASUP lawọn ileewe naa, Ọmọwe Jacob Adegbite ni igbesẹ awọn olukọni ọhunda lori ẹhonu wọn.
Bó ti rí gẹ́lẹ́ ní ilẹ̀ Yoòbá nìyẹn láìsí ìjà, láìsí rògbòdìyàn.
Ìwòyí Ìjẹ ̀ bú , mo ti tàná dé .
OLUWA sọ fún Jehu pé, “Níwọ̀n ìgbà tí o ti ṣe èyí tí ó dára lójú mi, o ti ṣe ohun tí mo fẹ́ ṣe sí ilé Ahabu, tí o ṣe ohun tí ó wà lọ́kàn mi, àwọn ọmọ rẹ, títí dé ìran kẹrin, yóo máa jọba ní Israẹli.
Ẹlòmíràn ni kí o jẹ́ kí ó yìn ọ́, má yin ara rẹ,jẹ́ kí ó ti ẹnu ẹlòmíràn jáde,kí ó má jẹ́ láti ẹnu ìwọ alára.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Kwara Kidnap: Ọlọ́pàá láwọn yóò wá àwọn ọmọ ilẹ̀ Turkey mẹ́rin tí wọ́n jígbé rí láàyè 21 Agẹmo 2019 Oríṣun àwòrán, Facebook/Kayode Egbetokun Ile ọlọpaa ipinlẹ Kwara ti wọ igbo lọ lati doola ẹmi awọn ọmọ orilẹede Turkey mẹrin tawọn agbẹbọn mẹfa kan jigbe lalẹ ọjọ Abamẹta nibi ti wọn ti gbafẹ ni igberiko kan ti wọn ni Gbale.
Ewe, bi ayeye ohun se n lo lowo, ni oko baluu oju ofurufu ti won kun lawo funfun ati awo eweko n se afihan asia orile-ede Naijiria kaakiri gbogbo ayika ati awon agbegbe gbagede ohun.
Kini Yoruba n pe ni 'pen'?
Nítorí náà mo fẹ́ kí gbogbo eniyan máa gbadura ninu gbogbo ìsìn, kí wọn máa gbé ọwọ́ adura sókè pẹlu ọkàn kan, láìsí èrò ibinu tabi ọkàn àríyànjiyàn.
Bí a bá sì mọ̀ pé ó ń gbọ́ tiwa nípa ohunkohun tí a bá bèèrè, a mọ̀ pé à ń rí gbogbo ohun tí a bèèrè lọ́wọ́ rẹ̀ gbà.
Lara ohun to n fa iru iku yi la gbọ pe ailera wa, ailemidaada tabi awọn ipenija ara miran.
Ọpọ ọmọ Naijirià lo ti n jaran àjínde ọkọ òfurufú ti orílẹ̀èdè Naijiria.
O ni gbogbo awọn ọrẹ oun wa n pe oun pe nkan to fẹ ṣe niyẹn ṣugbọn ti emi o fẹ ki ẹnikẹni ba mi sọrọ nipa rẹ.
Ìnú ń bí Boko Haram pé wọ́n ń fi ẹsùn ìfípabánilò kàn wọ́n Àwọn ọmọbinrin ti wọ́n fi ọ̀rọ̀ wá lẹ̀nu wò, sàlàyé pé wọ́n ó fi ipá bá àwọn lò tàbí fẹ́ àwọn ni túlàsì, sùgbọ́n nígbà míràn wọn máa n ba àwọn sọ ọ̀rọ ìgbéyàwó Àkọlé àwòrán, àwọn ọmọbinrin náà fi ìwé náà pamọ Nínú àkọsilẹ̀ wọ́n, wọn ni Boko Haram ń binu lori ìròyin pé àwọn ń fipa ba àwọn náà lajọṣepọ̀, Bakan naa ni wọn máà ń wa wàásù sí àwọn ni alaalẹ́ ki awọn le kọ nipa Jihad ati ẹsin Islam sii.
Naira Marley kii sii jina si ibi ti awuyewuye ba ti n ṣẹlẹ.
Wọn yóo sọkún ninu gbogbo ọgbà àjàrà yín, nítorí pé n óo gba ààrin yín kọjá.
Èyí tún mú kí gbogbo èrò kígbe kí wọ́n sì pàtẹ́wọ́.
Gbogbo orilẹede agbye lo fẹẹ tan de tan.
Tí a fiṣọwọ́ ní 14:48 10 Ọ̀pẹ̀ 202014:48 10 Ọ̀pẹ̀ 2020 Háà!
“Èmi ni OLUWA, bẹ́ẹ̀ ni orúkọ mi;n kò ní fi ògo mi fún ẹlòmíràn,n kò sì ní fi ìyìn mi fún ère.
Ọrọ ẹni ti yoo jẹ Balogun ikọ Ghana jẹ eleyi ti o ti n mu wahala wa tipẹ.
Idibo awọn mejeji si igbimọ aṣofin ikẹsan waye lai si alatako kankan.
    Ṣùgbọ́n n kò fẹ́ kí ẹ ni èrò pé bẹ́ẹ̀ ni gbogbo obìnrin rí sí mi rárá-ó tì 0- kìí ṣe bẹ́ẹ̀.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Fayoṣe: Mo rọ àwọn asòfin Ekiti láti súgbá Fayẹmi 15 Agẹmo 2018 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 12 Ọ̀wàrà 2018 Oríṣun àwòrán, EFCC/Fayose/Twitter Àkọlé àwòrán, Ẹ̀nu kun EFCC lórí ìkéde tó fi síta nípa Fayose níkété tí wọ́n kéde èsì ìbò gómìnà Ekiti Gómìnà Ipínlẹ̀ Ekiti, Peter Ayodele Fayoṣe sọ pe, oun ko ni le lọ sibi ifilọlẹ ijọba Kayọde Fayemi gẹgẹ bi gomina tuntun lọjọ Iṣẹgun.
Dákúdájí Chelsea bínú já òrùlé Stamford Bridge lé Crystal Palace lórí Ronaldo ati Messi yoo kojú ní Champions League tọdun yii €10,000, ara owó tí wọn fi ra Ighalo pòórá, Ilé aṣòfin Osun bẹ̀rẹ̀ ìwádìí Nínú akànṣẹ́ mẹ́ta ọmọ Nàìjíríà tó dáńtọ́ lágbàáyé, Yorùbá méjì wà nínu wọn Owó wọgbó!
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Wo Adigun ọmọ ọdún mẹ́rin tí òwe Yorùbá àti ìtúmọ̀ gbó lẹ́nu rẹ̀ ju tìrẹ̀ lọ O ti ṣe diẹ ti ipinlẹ Aarẹ Buhari, iyẹn Katsina ati awọn ipinlẹ mii ni iwọ oorun ariwa Naijiria, ti n koju ipenija aabo lọwọ awọn ajinigbepawo.
Iroyin naa ni igbesẹ lile awọn eeyan to wa ni agbegbe Badagry keji pẹlu awọn agbegbe miran to wa ni adugbo Ajegunlẹ lo kọkọ saaju, ti wọn si fi ọba le pẹlu lile awọn olugbe adugbo mẹrinlelogun miran to wa ni erekusu Eko.
Afọnja, ẹni tó finú wénú ní Ilọrin, àmọ́ tó jẹ iwọ A fẹ́ lo ẹ̀jẹ̀ àwọn èèyàn tó ye àrùn Coronavirus láti fi ṣe ìwòsàn fún àwọn tó wà lórí àárẹ- UK Coronavirus: Kíni àwọn àmì tuntun tó n fihàn?
 ikú ọmọ ọba yìí ló sokùnfà ogun àgbáyé nígbà tí orílẹ ̀ -èdè astria-hungary gbaná jẹ .
“Nígbà tí ẹ bá ń kórè ọkà ninu oko yín, tí ẹ bá gbàgbé ìdì ọkà kan sinu oko, ẹ kò gbọdọ̀ pada lọ gbé e.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ibeji to lepo ni Bauchi: Ọkan ninu re ye ninu isẹ abẹ 13 Èrèlè 2018 Àkọlé àwòrán, Ọpọ ibeji to lẹpọ ni wọn ti sisẹ abẹ fun jakejado to si yọri si rere Ọmọdebinrin kan to jẹ ibeji ti ye isẹ abẹ ti wọn se fun oun ati ikeji rẹ eyi to yọri si rere lẹkun ariwa ipinlẹ Bauchi.
 A ṣeyi sọpọ rẹ laye o.
Kii ṣe orilẹ-ede Naijiria nikan lo ti ṣe olukọni fasiti, o kọ ni ni fasiti Cornell University, United States ninu imọ nipa ilẹ Afirika ati imọ Tiata, bakan naa ni Emery university nibi to tun ti gba oye Ọjọgbọn Robert W.
Bí ọ̀nà eniyan bá tẹ́ OLUWA lọ́rùn,a máa mú kí àwọn ọ̀tá rẹ̀ pàápàá bá a gbé pẹlu alaafia.
Ọmọkùnrin tó ya 'Blue film' nínú igbó Osun Osogbo ti bayé ara rẹ̀ jẹ́ - Yemi Elebuibon Ó yẹ kí Sotitobire gbọ́ ìdájọ́ lónìí ṣùgbọ́n ẹ wo bí ilé ẹjọ́ ṣe tún ṣe é Ìbẹ̀rù-bojo dé l'Ado Ekiti!
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù NLC: Àwọn òsìsẹ́ Naijiria ló ń gba owó osù tó kéré jù!
Adari ile-ise aare, Alhaji Abba Kyari, tuko awon eniyan jankan-jankan  pelu apapo awon osise ajo NFF lati gba iko Super Falcons wo ilu Abuja nirole ojo Aiku(Sunday).
3 528469 Orilẹede Egypt 8421 8.
Ohun méje pàtàkì nípa Commonwealth Ọbabìnrin fẹ́ k’àrẹ̀mọ gbasẹ Commonwealth Òfo ni ìrìnàjò Bùhárí sí Commonwealth - PDP Ẹ jẹ ki a se agbeyẹwo diẹ lara anfani to mu wa fun orileede Naijiria.
Senegal lu Naijiria bi aṣọ ofi pẹlu ami ayo mẹta sodo ninu ifẹsẹwọnsẹ ipele ẹlẹni mẹrindinlogun(Round of 16).
fi maa fẹsun kan Ile Igbimọ Aṣofin Ipinlẹ Eko lori pe wọn ko tete
“Nígbà tí àwọn arọmọdọmọ yín tí wọn kò tíì bí, ati àwọn àlejò tí wọ́n bá wá láti ilẹ̀ òkèèrè bá rí ìpọ́njú, ati àrùn tí OLUWA yóo dà bo ilẹ̀ náà, 
Ẹ̀wẹ̀, ìgbìmọ aláṣẹ ìjọba ìpínlẹ̀ Kaduna ti n wá ojúùtú si rògbòdìyàn tó mú ẹ̀mí ènìyàn márùnléláàdọ́ta lọ lọ́jọ́ àìkú.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Cannabis: Akeredolu, Ọgá NDLEA lọ kọ nípa gbíngbin igbo ní Thailand 14 Èbibi 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Akeredolu gbàgbọ́ pé ànfàní ńlá ni ṣíṣe ọ̀gbìn igbó yóò jẹ́ fún orílẹ̀èdè Nàìjíríà.
Kílò fa èdè àìyedè láàrin ìjọba àti àwọn ọmọ lẹ́yìn El-Zakzaky?
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Omiyalé Àkútè: N50 si N100 làwọn èèyàn fi ń kọjá lórí ẹ̀kún omi l‘Ákútè Agbára ju agbára lọ: Wo bàbá Godwin to pe òjò Kíni ọ̀nà àbáyọ si ọ̀rọ omíyale ni Naijiria?
Nigba to n sọrọ lori aisi ipese awọn ohun eelo fun aabo lọwọ ikọlu, tawọn osisẹ ile-wosan naa n fẹhonu han le lori, Oloniyọ fi kun pe, diẹ-diẹ ni ijọba yoo maa pese awọn ohun eelo aabo nile iwosan nitori ilu Romu ko se kọ ni ọjọ kan soso.
A óo tú ọ sí ìhòòhò,a óo sì rí ìtìjú rẹ.
Ọ̀kan ninu àwọn olórí ogun náà dá ọba lóhùn pé, “Ṣebí àwọn eniyan náà yóo kú ni gẹ́gẹ́ bí àwọn tí wọ́n ti kú.
Awọn kan tiẹ n binu tẹlẹ pe BBNaija ko ri fọnran ohun to ṣẹlẹ laarin Ozo ati Nengi wo.
OLUWA a máa gbẹ̀san, a sì máa bínú.
Ìgbéraga-ìbànújẹ́ dùbúlẹ̀, bí ogójì ènìyàn bẹ̀rẹ̀ síi ṣiṣẹ́ sí ara ẹ̀wù rẹ tí a ge ẹ̀wù náà wẹ́lẹwẹ̀lẹ tí a fi bọ́ ọ kúrò lára rẹ̀ tán po.
Lọwọlọwọ bayii, Ile iṣẹ ọlọpaa ipinlẹ Oṣun ti hu oku akẹkọọbinrin fasiti ipinlẹ Eko LASU, ti awọn afurasi naa si ti wa ni gbaga ile iṣẹ ọlọpaa lori ẹsun pe wọn jọ gbimọ pọ pa ọmọbinrin naa ni Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Dambe fight: ìdíje ìjà láàrin àwọn akóni tó n ja ẹ̀ṣẹ̀ Bi eto isinku naa ba se n lọ, la maa mu wa fun yin.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Banky W: ojoojúmọ́ ayé mi ni mo ti fi lá àlá kó lè wá sí ìmúṣẹ 11 Bélú 2018 Oríṣun àwòrán, @bankyw Àkọlé àwòrán, Mo mọ pe àwọn eniyan n fẹ aṣoju ọkan wọn Olorin Takasufe Bankọle Wellington ti kéde loju opo twitter rẹ pe òun ti fẹ mu ìran oṣelu ṣẹ laye oun ni 2019.
Ìjọba kò mẹ́nuba ọ̀rọ̀ àwọn ará ìlú tó kú tàbi farapa lásìkò ìfẹ́hónúhàn #EndSars, èyí tó mú wọ́n ṣe àgbékalẹ̀ ìgbìmọ̀ tó n gbẹ́jọ ìwà àìtọ́ tí àwọn ọlọ́pàá ti hù.
Wọn ni ki wọn pada sile pẹlu awọn agbo ẹran wọn nitori ibẹru fun aabo ẹmi awọn ati ẹran wọn.
DiBella ṣalaye ninu atẹjade kan to fi sita pe, oloogbe Day ko tiẹ nilo lati ja ẹṣẹ nitori o kawe, bẹẹ lo si ti ile ire jade, ati pe, o ni awọn ohun amuyẹ to le mu ṣe iṣẹ miiran yatọ si ẹṣẹ kikan.
Ṣugbọn àwọn Farisi ati àwọn amòfin kọ ìlànà Ọlọrun fún wọn, wọn kò ṣe ìrìbọmi ti Johanu.
Ọba ati àwọn ìjòyè rẹ̀ sì fi òǹtẹ̀ òrùka wọn tẹ ọ̀dà tí wọ́n yọ́ lé e, kí ẹnikẹ́ni má lè gba Daniẹli sílẹ̀.
Oniruuru awọn eeyan ati ẹlẹgbẹjẹgbẹ lorilẹede Naijiria lo ti sọrọ lori ọrọ yii, ti wọn si ti fi iha ti wọn kọ si bi nnkan ṣe n lọ laarin mọlẹbi akọkọ lorilẹede Naijiria han.
O tun kede pe oun yoo pese nkan amayedẹrun fun awọn araalu.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ọlọ́pàá mu afẹ̀sùnkan ti wọn pè ni ọgá awọn ajínigbé 14 Èbibi 2018 Oríṣun àwòrán, NIGERIA POLICE Àkọlé àwòrán, Àwọn ọlọpàá gba ibọn méjì ati ọta mọ́kànlélàádọ́ta lọ́wọ́ Barau Ọwọ́ àwọn ọlọpàá ti tẹ ọ̀gbẹ́ni kan Barau Ibrahim, tí wọn f'ẹ́sùn kan pé o jẹ́ ògbójú ajínigbé àti apàniyàn ti oun da Birnin Gwari ni Ipinlẹ̀ Kaduna, òpópónà Abuja si Kano àti Ìpìnlẹ̀ Zamfara rú.
Jọ̀wọ́ gba ẹ̀bùn tí mo mú wá fún ọ nítorí pé Ọlọrun ti ṣe oore fún mi lọpọlọpọ ati pé mo ní ànító.
Àwọn Ará Gibeoni Tan Joṣua Jẹ.
Mo n ro pe ṣe mi o ti da wahala silẹ fun aye ati ile awọn kan bayii?
Ina nla kan tun sọ lagbegbe Ọba nla ni ilu Akurẹ eleyii to run ọpọlọpọ dukia olowo iyebiye, ọọbu ati ileegbe.
 Titi di bi a ṣe n sọrọ yii, ẹgbẹrun mọkanlelogoji eeyan o le ọọdunrun ati mẹrinla (41314) ni iye awọn to ti gba iwosan lọwọ aarun naa ti ẹgbẹrun kan o le mọkanla si ti jade laye."
Fani Kayọde ni igbagbọ ohun ninu iṣọkan orilẹede Naijiria ko yẹsẹ rara bi o tilẹ jẹ wi pe oun ati olori ẹgbẹ naa sun mọ ara wọn pẹkipẹki.
Ẹ ṣe ọkàn yín gírí, nítorí Oluwa fẹ́rẹ̀ dé.
Bí ó bá wa tí à ń ta òkòtó, yóò bá wa ta á; bí à ń ṣe bojúbojú, á bá wa ṣe é; à ní bí ó ṣe taní-wà- nínú ọgbà náa ni à ń ṣe, yóò bọ́ sínú ọgbs̀ bí ẹni wí pé ẹgbẹ́ ni wá.
Pátákò ẹsẹ̀ ẹṣin wọn le bí òkúta akọ;ẹsẹ̀ kẹ̀kẹ́ ogun wọn dàbí ìjì líle.
" Akẹkòó Obìnrin Chibok 57 tí lọkọ ní Cameroon Gbáko!
Olori Aishat Folasade Adeyemi: Oríṣun àwòrán, Ayaba Folashade Adeyemi Ayaba Folasade lo tẹle Olori Abiodun, ti oun naa si wa lara awọn ẹlẹ ẹlẹjẹ tutu, ti Alaafin fi n se afẹfẹ gbẹmiro ni Aafin Ọyọ.
Wọ́n ní ẹlẹ́yàmẹ̀yà ni ìjọba UK fi ṣe.
Ohùn Ọlọrun dún bí ààrá tìyanu-tìyanu,a kò lè rí ìdí iṣẹ́ ìyanu rẹ̀.
Ọrọ naa jade lẹnu gomina ambọde nigba to n ba àwọn ọmọ ẹgbẹ osẹlu APC sọrọ lasiko eto idibo lati yan awsn aṣoju ti yoo ls fun idibo abẹle lati yan oludije fun ipo aarẹ labẹ asia ẹgbẹ naa, ati ipade gbogboogbo ẹgbẹ.
Hassan Sale, Hussaina Sale ati Muhusin Sale lorukọ awọn ibẹta ti o padanu ẹmi wọn ninu isẹlẹ naa ti orukọ ọmọ iya wọn ọkunrin naa njẹ Aliyu Sale.
”Jakọbu dáhùn, ó ní, “Àwọn ọmọ tí Ọlọrun fi ta èmi iranṣẹ rẹ lọ́rẹ ni.
Ó fi ọwọ́ ọ̀tún mú Efuraimu, ó fà á súnmọ́ ẹ̀gbẹ́ ọwọ́ òsì baba rẹ̀, ó fi ọwọ́ òsì mú Manase, ó fà á súnmọ́ ẹ̀gbẹ́ ọwọ́ ọ̀tún baba rẹ̀.
Òfin ìjọba de ọdún eégún ìlú Ibadan,eégún Olóòlù kò ni kọ́ja agboolé rẹ̀!
Igbẹjọ naa yoo waye lọjọ kọkandinlogun oṣu kẹta ọdun yii niluu Lausanne, lorilẹede Switzerland.
Ọjọ́bọ̀ jẹ ọjọ́ ti wọn ńṣe àisùn-òkú; ọjọ́ Ẹti ni isinkú, ọjọ́ Àbámẹ́ta ni ti ayẹyẹ igbéyàwó nigbati ọjọ́ Àikú wà fún idúpẹ́ pàtàki ni ilé ijọsin onigbàgbọ́.
Jehoiada bá mú Joaṣi jáde, ó gbé adé lé e lórí, ó fún un ní ìwé òfin.
orúkọ àdúgbò tí wọ ́ n ń pè é ni itajikan .
A ka àwọn ọmọ Mose, iranṣẹ Ọlọrun, pọ̀ mọ́ àwọn ẹ̀yà Lefi.
Ṣugbọn a níláti kọ́kọ́ waasu ìyìn rere fún orílẹ̀-èdè gbogbo ná.
Ẹgbẹ oṣiṣẹ NLC ni awọn tẹlẹ gbogbo igbesẹ to yẹ lati ri wi pe ijọba yi ipinnu wọn pada ko to di asiko yii.
Gẹ́gẹ́ bi Oluwo, Ọmọ Oodua tààrà ni mi"", Iya mi ni wọ́n n pe ni ""Luwo Gbagida, baba to bi Luwo Gbagida Ọọni Ogun ló jáde níbẹ, Baba to bi iya mi ni Ọta-aata, Owodo bi Ọta-aata, nígbà ti Owodo jẹ ọmọ Alade ju òògun lọ ti wọ́n ń pè ni Ladejogun, ni ọmọ-ọmọ Lajamisan ti lajamisan fi jẹ ọmọ-Ọmọ Oranmiyan titi to fi kan Oodua."
Iwaju igbimọ olubaniwi yii ni awọn ọmọ ẹgbẹ naa ti ni anfani lati wa sọ iha ti wọn lori ohun to ṣẹlẹ.
Èkúté tó sàwárí bọ́mbù ilẹ̀ gbàmi ẹ̀ye wúrà fún iṣẹ́ takuntakun Ẹ gbọ́ òhun tí àwọn olùdíjé sípò gómìnà nípínlẹ̀ Ondo sọ nípa Bàbá ìsàlẹ̀.
Àwọn ọmọ Israẹli gba gbogbo ìlú àwọn ará Amori, Heṣiboni ati àwọn ìlú tí ó wà ní agbègbè rẹ̀, wọ́n sì ń gbé inú wọn.
Ẹni to bori: Morocco South Africa vs Mauritania.
Esabod, ẹni to bẹrẹ lilo ori ayelujara lati ọdun 2012, táwọn eeyan si ni o maa n si pata silẹ lori Facebook tun kede pe, oun ko kabamọ awọn iwa ti oun n hu loju opo Facebook.
Bolanle Sarumi-Aliyu - NIP Àkọlé àwòrán, ìpàdé ìfọ̀rọ̀wérọ̀ BBC Yorùbá Bolanle Sarumi ni gbogbo awon ọmọ wẹwẹ ti ọjọ ori wọn ko ju marun lọ yoo gba eto ilera ofe.
Ninu ọrọ tirẹ, Aṣofin Yinka Ogundimu ṣapejuwe Ọba Akiolu gẹgẹ bi Oba ti o ti kopa ribribi ninu idagbasoke orilẹ-ede Naijiria, paapaa Ipinlẹ Eko nipa ṣiṣe atilẹyin to nitumọ fun ijọba rere lati ṣe aṣeyọri ninu iṣẹ ilu wọn.
Kallon so pe “o le ni milionu mewaa awon eniyan to wa ni ipinle meta lorile ede Naijiria to wa ni ekun Ila -oorun Ariwa ti won nilo eto iranwo.
” Ẹlòmíràn sì ń wí pé, “Ẹ̀yìn Kristi ni èmi wà.
Queen Salawa, to ni iwe mẹfa l'oun ka tun sọ pe, aadọta kọbọ lawọn eeyan maa fi n pe oun sode nigba t'oun bẹrẹ iṣẹ orin kikọ.
Àjọ to n gbógun ti àjàkálẹ̀ ààrùn lórílẹ̀-èdè Naijiria NCDC ti kéde ènìyàn ogún àwọn ènìyàn míràn to ti ni ààrun Corornavirus lórílẹ̀-èdè Naijiria.
*Kaakiri agbaye ni wọn ti bu ẹnu atẹ lu ijọba apapọ fun didoju kọ ijọ ẹsin Musulumi naa, titi kan iṣẹlẹ to waye lọdun 2015 nibi ti ologun ti pa ọpọlọpọ awọn ọmọ ijọ naa.
Eyi ko sẹyin bi awọn kan ṣe bu ẹnu atẹ lu lẹyin ti fidio jade nibi ti o ti n jo pẹlu oyinbo ni ilẹ okeere to ti gba beeli pe oun fẹ lọ gba iwosan fun ara oun.
Ó lọ bá Eliṣa ní orí òkè Kamẹli.
Baṣọ̀run Gáà, tó yan ọba mẹ́rin, pa ọba mẹ́rin àmọ́ ọba karùn-ún ló pa á Àràmọ̀ǹdà!
Ẹnikẹ́ni tí ó bá ṣe oríkunkun sí ẹni tí ó jẹ́ onídàájọ́ nígbà náà, tabi alufaa tí ó wà lẹ́nu iṣẹ́ ní àkókò náà, pípa ni kí ẹ pa á; bẹ́ẹ̀ ni ẹ óo ṣe yọ ohun burúkú náà kúrò láàrin Israẹli.
Lóòótọ́ ni ìjìyà àwọn obìnrin, ó wà lóòótọ́.
Bakan naa ni wọn kede pe mẹta wa ni ilu Edo, mẹta ni Oyo, mẹta ni Rivers, mẹji ni Osun, ẹyọkan ni Akwa Ibom, ẹyọkan ni Bayelsa, ẹyọkan ni Ebonyi, ẹyọkan ni Kebbi.
Igbimo alase naa so pe ijoba apapo ti seleri lati fi  egbe naa si ara awon ti yoo je anfaani bilionu márùn ún naa.
Rabuṣake ní, “Ẹ sọ fún Hesekaya pé, ọba ńlá, ọba ilẹ̀ Asiria ní kí ni ó gbẹ́kẹ̀lé?
Gẹ́gẹ́ bi àjọ náà ṣe sọ ènìyàn tó kú ti n peléke sí, bá ààrùn náà ti mú ẹmi èèyàn mẹ́tàdínlógún lọ lóòjọ́ tí àwọn tó kú sì ti di ọgọ́rùn lé mẹ́tàlélógójì nígbà ti àwọn ọgọ̀rún méje àti mẹ́jìdínlọ́gọ́rin ti gba ìwòsàn lọ́wọ́ ààrùn náà.
Ṣugbọn ẹni tí ó ń waasu ń mú ìjọ dàgbà.
Kọmisọnà ọlọ́pàá ni àwọn yóò tú iṣu dé ìṣàlẹ̀ ìkòkò lóri ọ̀rọ̀ náà
It was an extremely close fight that could have gone either way had it gone the distance, as both men met in the middle of the Octagon and traded blows from start to finish, eschewing their world-class wrestling abilities in favour of an all-out brawl.
 ile aare  niluu Abuja ,lojo Isegun lati fi sami eto awẹ
Nígbà ìkọ́ṣẹ́, bí ọmọ Mauritania aláwọ̀ funfun kan kò bá ṣe dáadáa, wọn á ṣì borí aláwọ̀ dúdú mìíràn.
 O tun kopa fun iko Real Madrid ati Barcelona.
án koja iseju méjílélọ́gbọ̀n, ko to di pe Ayi, iya re naa dibo pelu.
Nígbà tí ó di kùtùkùtù ọjọ́ kan mo lọ sí ibojì bàbá mi, mo sọkún sii, mo ké lóhùn arò, mo ni ‘Ayé mi nìyí, bàbá mi, mo fi ọ́ sílẹ̀ ní ènìyàn, mo bá ọ ni ilẹ̀pa!
Isà òkú yí mi ká,tàkúté ikú sì dojú kọ mí.
Arẹwa oṣere ninu ọrọ kan to kọ si oju ewe ayelujara Instagram rẹ pẹlu awọn aworan to jẹ oju ni gbese sọ pe ijọ ẹsin Islam, Hizbullahi International Prayer Outreach Ministry, lo fi oun jẹ oye naa l'ọjọ Aiku, ọjọ kẹjọ, oṣu Kẹta, ọdun 2020.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ààrẹ Buhari- Boko haram kò f'ẹsẹ rinlẹ l'ágbègbè kánkan ní Nàìjíríà 6 Ìgbé 2019 Oríṣun àwòrán, @NGRPresident Bi o ba jẹ ti ọrọ ikọ Boko Haram ni, wọn ko ni agbegbe Naijiria kankan ti wọn dimu.
ti bẹrẹ iṣejọba awarawa lọdun 1999, mi o mọ ipinlẹ kankan ti wọn ti jẹ gbese owo oṣu fun ọdun mẹta gbako yatọ si ti ipinlẹ Ọṣun.
Ṣugbọn ẹ ti sọ ẹ̀tọ́ di májèlé, ẹ sì ti sọ èso òdodo di ohun kíkorò.
Ṣugbọn ko pẹ ti atilẹyin awọn ọmọ ẹgbẹ Democrat fi poora amọ awọn ti Republican ko jawe ninu atilẹyin wọn fun un.
Ẹ jẹ́ kí n gbọ́ èsì yín o.
Bí ó ti ń lọ sí ẹnu ọ̀nà, iranṣẹbinrin mìíràn tún rí i, ó bá sọ fún àwọn tí ó wà níbẹ̀ pé, “Ọkunrin yìí wà pẹlu Jesu ará Nasarẹti.
Àwọn ọmọ wẹ́wẹ́, àwọn ẹran ọ̀sìn wọn ati àwọn ẹrù wọn ń lọ níwájú wọn.
A kò fòfin de owó naira tó ti pẹ́ ní Naijiria- CBN
Èmi ni mo ṣẹ̀dá rẹ, iranṣẹ mi ni ọ́,n kò jẹ́ gbàgbé rẹ, Israẹli.
Ijọba apapọ nipasẹ ileeṣẹ epo rọbi lorilẹ-ede Naijiria, NNPC ti kede afikun owo epo ni Naijiria leyi to gbe owo ori epo bẹntiro soke sii.
Ile ẹjọ CCT onijoko mẹta ti adajọ Danladi Umar se adari fun sọ eyi lẹyin ti Onnoghen pe ẹjọ wi pe oun o lẹjọ iwa ibajẹ kankan.
Ọpọlọpọ awọn to fesi si ọrọ to n lọ naa lori ẹrọ ayelujare ni wọn bu ẹnu atẹ lu lẹta Baba Ọbasanjo, ti awọn miran si wa lẹyin Baba Ọbasanjo.
naira ti awon fenuko le lori.
Mose bá dá Farao lóhùn pé, “Bí mo bá ti jáde kúrò ninu ìlú n óo gbadura sí OLUWA, ààrá kò ní sán mọ́, bẹ́ẹ̀ ni yìnyín kò ní bọ́ mọ́, kí o lè mọ̀ pé, ti OLUWA ni ilẹ̀.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Amoṣun: Mo gba àṣẹ lọ́wọ́ Jonathan láti dá iléeṣẹ́ aláàbò sílẹ̀ àti ríra ohun ìjà olóró 26 Òkùdu 2019 Oríṣun àwòrán, @SIAmosun Gomina ana nipinlẹ Ogun, Sẹnetọ Ibikunle Amosun, ti fesi lori iroyin kan to n ja rainrain nilẹ.
Mo ba tun pe ọga wọn lẹnu iṣẹ.
Ẹsẹ ti ha o si ti kan sinu Kẹkẹ Maruwa to run jegejege.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ado Ekiti Blind Couple: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú Awọn ọba ilu miiran naa to ba lẹmi iru rẹ le paṣẹ bẹẹ niluu ti wọn naa,'' Oluwo lo sọ bẹẹ.
Dáhún ìbéèrè yìí kí o wo àkókò tí yóò ná ọ̀ Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí 2 sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 2:23 Fídíò, Water Generator: Ó leè ṣiṣẹ fún wákàtí mẹfà, kó tó sinmi, Duration 2,2310 Òkùdu 2020 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
Ààrẹ Buhari ti lọ sí ìlú Daura fún ọdún Sallah Ìbànújẹ́ ni ọdún Orò ma ń jẹ́ fún àwọn obìnrin ní ìlú Ikorodu Ẹgbẹ́ òṣèlú AAC fi ọwọ́ òsì júwe ilé fún Ṣowore!
Lẹ́yìn tí ó ti sọ báyìí tán, ó sọ fún wọn pé, “Lasaru ọ̀rẹ́ wa ti sùn, mò ń lọ jí i.
Àkọlé àwòrán, #BBCOGUNDEBATE: O ṣe pataki láti yan àwọn akanda ẹda si ipò kọmisọna.
,paapaa julọ ijoba apapo ati awon asoju ni ẹlẹkunjẹkun lorile ede yii.
Oludije keta ni Comfort Babatunde, ti o jade nipele kinni ifigagbaga naa.
Bákan náà ni àwọn mẹrẹẹrin rí.
" Ileesẹ aarẹ wa rọ awọn akọroyin lati dẹkun dida awuyewuye silẹ, ki wọn ma si faaye gba sise itumọ ofin lọna odi lori ọrọ naa.
Ajimobi ni kii ṣe pe oun bẹbẹ fun ipo ọhun, ṣugbọn awọn alakoso APC ri oun gẹgẹ bi ẹni to ṣe e fọkan tan ni wọn ṣe fi oun si ipo naa ni iha guusu Naijiria.
'' Oloṣelu ko le e duro si ojukan naa.
Lọdun 2001, awọn orilẹede to jẹ ọmọ ajọ AU ṣeleri lati maa ya idamẹẹdogun owo eto iṣuna sọtọ lọdọọdun fun ẹka eto ilera.
5 12327 Orilẹede Jamaica 323 11.
Nibi ipade finukonu ti wọn ṣe pẹlu aarẹ Muhammadu Buhari lori wahala to ṣẹyi lasiko ati lẹyin iwọde naa lawọn olori orilẹede Naijiria nigba kan ri naa ti jẹ ko di mimọ pe omi nii poro ina, ojo ni poro ọgbẹlẹ, ohun to lee pa oro irufẹ wahala bẹẹ ni ipese iṣẹ fun awọn ọdọ, mimu ọrọ aje gbooro sii ati ṣiṣeto ọna fun awọn oludokoowo lati ilẹ okeere lati wọle wa.
jade pe aare so pe “Awon odaran ohun ko ni lọ laijẹ iya labẹ ofin.
Bakan naa ni ẹgbẹ oselu PDP ti gbogbogbo fi àtẹ̀jáde síta pé APC ṣe màgòmágó nínú ìdìbò Ekiti.
Nígbà tí ó dé ọ̀dọ̀ Elija òun náà tún sọ fún un pé, “Ìwọ eniyan Ọlọrun, ọba sọ pé kí o sọ̀kalẹ̀ wá kíákíá.
O kere tan eniyan merindinlogbon lo ba isele ibugbamu ado-oloro lo, eyi ti arakunrin kan de mo ara re lara lati dun ni Kabul lojoBo(Wednesday), tin se olu-ilu orile-ede Afghan.
Jẹ́ kí àwọn àkànpọ̀ igi mejeeji tí wọ́n wà ní igun àgọ́ wà ní ọ̀tọ̀ọ̀tọ̀ ní ìsàlẹ̀, ṣugbọn kí o so wọ́n pọ̀ ní òkè ní ibi ìtẹ̀bọ̀ àkọ́kọ́.
“Tún lọ sọ́dọ̀ Serubabeli ọmọ Ṣealitieli, gomina ilẹ̀ Juda, ati Joṣua ọmọ Jehosadaki, olórí alufaa ati gbogbo àwọn eniyan tí wọ́n ṣẹ́kù, kí o bèèrè pé, 
Centre,ti  ile eko giga Fasiti Ibadan,ni
Bí ó ti jáde kúrò ninu ọkọ̀, ọkunrin wèrè kan wá pàdé rẹ̀ láti inú ibojì pàlàpálá àpáta.
Oríṣun àwòrán, @PulseNigeria247 Ṣaaju ni awọn oṣiṣẹ ileeṣẹ ọlọpaa pẹlu ifọwọsowọpọ awọn ọmọ ẹgbe Vigilante Group of Nigeria ti n wa inu igbo ti wọn fura si pe awọn ajigbe ọhun ti n ṣọṣẹ.
Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Conjoined twins: Ilé ìwòsàn l'Àbuja ti ya àwọn ìbejì tí wọ́n sọpọ̀ láyà8 Sẹ́rẹ́ 2020 Iran ti jáwọ nínú ìlù ogun tó n lù -Trump8 Sẹ́rẹ́ 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Èso ilẹ̀ náà yóo sì di ohun ògo ati àmúyangàn fún àwọn ọmọ Israẹli tí wọ́n bá kù.
Naijiria fi ìgbájú mẹ́ta lé Cameroon kúrò ní AFCON Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, CAN: Samson ni ọrọ awọn ajinigbe ti gba àpérò ní Naijiria Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
ina to waye, ni eyi ti opolopo emi ati dukia sofo nibẹ.
Oyo traders crisis: Ẹgbẹ́ oníṣòwò ṣèwọ́de lórí ìyànsípò YK Abass gẹ́gẹ́ bí bàbálọ́jà tuntun
Eyi waye ninu atejade kan ti agbenuso fun ile-ise ijoba ti o n ri si oro ile-okere, Tiwatope Adeleye Elias-Fatile fowo si.
Awọn obinrin Yoruba maa n jo tarugbo tomidan.
Won tun pase fun adari iko omo ogun lati gbe olu –ile- ise won ti o je 8 Division kuro ni Sokoto lo si Gusau ni ipinle  Zamfara lati lee mojuto iko omo ogun SHARAN DAJI.
Ó gbà wá sílé fún ọjọ́ mẹta, ó sì ṣe wá lálejò.
O wa ba awon molebi ti isele burku yii  sele ,kedun , o tun wa gbadura pe ki Olorun dun won ninu.
Ní ọjọ́ keje, ẹ níláti fọ aṣọ yín, kí ẹ sì di mímọ́, lẹ́yìn náà, ẹ óo pada wá sí ibùdó.
Ewe, eyi waye lataari ẹsun ti
 A ti wọ́gilé ìwọ́de lórí COZA tí a fẹ́ ṣe tẹ́lẹ́ nítorí."
Wọ́n ń rìn ní ọ̀nà Kaini.
Israel Adesanya fẹ́ gbéná wojú Romero Ẹ̀ṣẹ́ ju ẹ̀ṣẹ́ lọ!
Deji Adeyanju àtàwọn mìí tí mú ìwé ẹ̀sùn dé iléèṣẹ́ ọlọ́pàá lórí ọ̀rọ̀ Elisha Abbo Oríṣun àwòrán, Elisha Ishaku abbo Ajafẹtọ ọmọniyan kan l'orilẹede Naijiria, Comrade Deji Adeyanju kede lọjọ Iṣẹgun pe oun yoo ko awọn eniyan jọ lori ọrọ yii.
Atẹjade naa tun fi kun un pe, Mallam Mele Kyari to jẹ akọṣẹmọṣẹ imọ nipa epo rọbi wiwa yoo maa ti Minisita kekere fun epo rọbi, Ibe Kachukwu lẹyin ninu iṣẹ rẹ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Oba Adedokun Abolarin ti Oke Ila: Ó ya ọ̀pọ̀ tó súnmọ́ mi lẹ́nu bí mo ṣe ń kọ́ Nibayii awọn oṣiṣẹ ọlọpaa ati ileeṣẹ ologun ti duro wamuwamu si gbogbo agbegbe naa titi ti o fi de agbegbe Total Garden.
Katsina si ni wọn ti wa'' Pasitọ to n lewaju awọn ajinigbe pawo naa ko si panpẹ ọlọpaa: Ẹwẹ, Frank Mba ṣe afihan Paitọ ẹni ọdun mejilelaadọta kan, Adetokumbo Adenopo to jẹ baba isalẹ fawọn ajinigbe kan.
Ewe, leyin ifigagbaga idije CAF U17 Africa Cup of Nations ohun, Samson Tijani gba ami-eye agbaboolu ti o niye lori julo, Olakunle Olusegun gba ami-eye agbaboolu ti o gba boolu sagbon julo pelu ami-ayo merin in.
Ọ̀fẹ́ ni ìforúkọsílẹ̀ fún iṣẹ́ ọmọogun òfurufú yìí àti àwọn míràn lórí ayélujara, olùforukọsilẹ̀ kò si ni san owó kankan láti ìbẹ̀rẹ̀ titi de òpin.
Joṣua dìde ní òwúrọ̀ kutukutu, àwọn alufaa gbé Àpótí Majẹmu OLUWA.
Nígbà tí wọ́n gba yín mú, dídá ni ẹ dá mọ́ wọn lọ́wọ́, tí ẹ ya wọ́n léjìká pẹ́rẹpẹ̀rẹ.
kí wọ́n mú ọ̀dọ́ akọ mààlúù náà lọ sí àfonífojì tí ó ní odò tí ń ṣàn, tí ẹnikẹ́ni kò gbin ohunkohun sí rí, kí wọ́n sì lọ́ ọ̀dọ́ mààlúù náà lọ́rùn pa níbẹ̀.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù AFRIMA: Davido, Falz, Ambọde gba àmì ẹ̀yẹ olórin Afíríkà 25 Bélú 2018 Oríṣun àwòrán, Davido Àkọlé àwòrán, Agba olorin takasufe, 2Baba lo gba ami ẹyẹ orin takasufe to gbayi julọ ni ilẹ Afirika Awọn gbajugbaja akọrin smọ orilẹede Naijiria Fakọyọ nibi eto ami ẹyẹ fawọn olorin nilẹ Afirika, AFRIMA to waye ni ilu Accra, orilẹede Ghana.
Kii ṣe wipe wọn yoo gbe ẹku 1960 wa, to ti dọti, to n run-un.
Máa jẹ, máa mu, máa gbádùn!
Òfin OLUWA pé, a máa sọ ọkàn jí;àṣẹ OLUWA dájú, ó ń sọ òpè di ọlọ́gbọ́n.
Ogu, ọba Baṣani, ati àwọn eniyan rẹ̀ bá ṣígun wá pàdé wa ní Edirei.
Bi anfaani ba si wa fun lati yanju nkan to n wa lọ si ilẹ okere, ki o yara yanju rẹ nile lai lọ si ita.
Luiz kọwọ bọwe adehunọlọdun meji pẹlu Arsenal lẹyin ti Arsenal san miliọnu mẹjọ owo pọun.
”) Wọ́n bá dá a pada lọ sí Sikilagi.
"Bi awọn ọlọpaa ṣe rii pe wọn n bọ ni wọn bẹrẹ si ni da ibọn bolẹ kaakiri.
Ó nií ti àwọn olùdíje tó kù yóò ba gbọ́ ti toun kí gbogbo wọn gbárùkù tí Buhari ní yóò ṣe wọn láǹfàní.
”Òjò àdàpọ̀ mọ́ yìnyín yóo gbá ibi ààbò irọ́ dànù,omi yóo sì bo ibi tí wọ́n sápamọ́ sí.
Lọdun 2007, o gba ami ẹyẹ Africa Movie Academy Awards.
Ojú kò ní tì wọ́n nígbà tí àjálù bá dé;bí ìyàn tilẹ̀ mú, wọn óo jẹ, wọn óo yó.
Bẹẹ, Ka pilẹ nnkan ko si tumọ si pe ẹni naa ni yoo pari rẹ.
Lẹ́yìn náà àwọn ọmọ Lefi bẹ̀rẹ̀ sí ṣiṣẹ́ ninu Àgọ́ Àjọ, wọ́n ń ṣe iranṣẹ fún Aaroni ati àwọn ọmọ rẹ̀.
 lára àwọn ogún èdè yìí ni àwọn èdẹ ̀ tí wọ ́ n ń pè ní Àmẹ ́ rídíánà ( ameridian languages ) wà .
Ó ń dún bí ejò tí ó ń sálọ;nítorí pé àwọn ọ̀tá rẹ̀ ń bọ̀ tagbára tagbára,wọ́n ń kó àáké bọ̀ wá bá a,bí àwọn tí wọn ń gé igi.
Amọṣa, ọwọ tẹ ọkan ninu wọn, lọgan si ni Ẹlẹha n pariwo, 'ẹ ba mi mu, ẹ maa jẹ ko salọ o!
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ẹ wo àrà tí ẹ le fi gèlè dá láàrín ìṣẹ́jú mẹ́ta Ọdun awọn ibeji yoo fun wa ni anfani lati ṣe afihan ilu Igbo-Ọra gẹgẹ bi ilu ti o tayọ ninu onka ibeji ati ọmọ to ju mẹji lọ lagbaye."
Awọn agbabọọlu orilẹ-ede Germany ni ikeji to dara julọ ni gbogbo agbaye.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Electricity tariff hike: SERAP ní aráàlú kò lè máa jìyà, káwọn tó dipò òṣèlú mú máa gbádùn 6 Sẹ́rẹ́ 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 19 Ọ̀wàrà 2020 Ajọ ajafeto-ọmọniyan kan ni Naijiria, SERAP ati awọn eeyan mejilelọọdunrun mii, ti pe aarẹ Buhari ati ile aṣofin lẹjọ lori afikun owo epo bentiroo ati owó ina ọba.
Wọ́n ní, níwọ̀n ìgbà tó jẹ́ pé Tinubu jẹ́ ọ̀kan gbòógì, lára àwọn tó dá ẹgbẹ́ òṣèlú APC tó gbé Buhari wọlé sí ipò ààrẹ sílẹ̀, ó yẹ kó le bá a sọ̀rọ̀ nípa Zakzaky.
Oríṣun àwòrán, AFP Àkọlé àwòrán, Awon eeyan orilẹede Libya naa ko gbẹyin ninu sise iranti ọjọ pataki kan, Ọjọ kẹtadinlogun osu keji ni iranti ọdun keje ti wọn yẹ aga mọ Ọgagun Muammar Gaddafi nidi Oríṣun àwòrán, AFP Àkọlé àwòrán, Lẹyin odi, orilẹede Egypt n se igbaradi fun idibo,bẹẹ ni awọn olupolongo n lẹ aworan aarẹ orilẹede naa kaakiri Oríṣun àwòrán, AFP Àkọlé àwòrán, Orilẹede South-Africa ko tii se idibo, sugbọn o ti ni aarẹ tuntun.
Nigba ti Ọrunmila de ilu rẹ, inu awọn ara ilu rẹ dun lati ri pe Wuraọla papa ja mọ Ọrunmila lọwọ, ti wọn si n beere pe nibo ni aya rẹ naa wa, awọn fẹ rii.
Ọba Siria yóo wá dóti ìlú olódi kan, yóo sì gbà á.
Oríṣun àwòrán, others Lọdun 2015 ni ẹgbẹ rẹ tun fa a kalẹ lati dije fun ipo aarẹ fun saa kẹta eleyi ti ọpọ awọn ẹgbẹ alatako koro oju si.
Omole ni ọla Ọjọru ni wọn yoo mọ bi ohun gbogbo yoo se lọ lori ọrọ iyọnipo naa.
Lẹ́yìn náà ó bọ́ ojú rẹ̀, ó jáde, ó gbìyànjú, ó dárayá, ó ní, “Ẹ gbé oúnjẹ wá.
Ètò yìí sì ti mú kí ilé iṣẹ́ ọlọ́pàá fí àwọn òṣìṣẹ́ tó dín díẹ̀ ni ẹgbẹ̀rún méjì sí àwọn bùdó ìdìbò tí ìdìbò yóò ti wáyé Àwọn òṣìṣẹ́ tó pọ̀ndandan fún láti lọ ṣíṣẹ́ nìkàn ló pọ̀dandan fún láti jáde.
Kete ti ikede naa jade loju opo Twitter lawọn ọmọ Naijiria kan ti n sọ ero ọkan wọn nipa rẹ: Oríṣun àwòrán, @BashirAhmad Oríṣun àwòrán, Twitter Kò gbọdọ̀ sí ìfẹ̀họ́núhàn EndSARS ní ìpínlẹ̀ Rivers - Gomina Wike Gomina ipinlẹ Rivers, Nyesom Wike ti fofin de gbogbo ifẹhọnuhan nipinlẹ naa.
” Dafidi dáhùn pé, “Kò sí idà tí ó dàbí rẹ̀, mú un fún mi.
Ó fẹ́rẹ̀ tó àkókò tí a óo fi Ọmọ-Eniyan lé àwọn eniyan lọ́wọ́.
Ó bá sọ fún mi pé, Ọlọrun àwọn baba wa ni ó yàn mí tẹ́lẹ̀ pé kí n mọ ìfẹ́ rẹ̀, kí n fojú rí iranṣẹ Olódodo rẹ̀, kí n sì gbọ́ ohùn òun pàápàá; 
Ọkunrin náà bẹ̀rẹ̀ ọ̀rọ̀ rẹ̀, ó ní, “Iranṣẹ Abrahamu ni mí, 
O sọ pe majele ni wọn yoo fun ẹnikẹni to ba gba lati ba ọkọ ọga rẹ lopọ jẹ.
lorile ede Naijiria, Yakubu Dogara,ti ni osu kefa odun yii, ni ile igbimo asoju-sofin
Lọdun 2019 Harris ṣe ifilọlẹ ipolongo rẹ lati di oludije ipo aarẹ Amẹrika labẹ asia ẹgbẹ Democrats ṣugbọn o fidi rẹmi lọwọ Joe Biden.
Muyiwa Ademola: A ó jọ rọ́ọ̀kì ọdún 2021 papọ̀ ni lágbára Ọlọ́run
9 3404 Orilẹede Taiwan 7 0.
'' A ko gbọdọ dakẹ lori ọrọ yii mọ nitori awọn kan joko si Eko, wọn si n gba owo oṣu ni Ekiti lai nidi'' Bakan naa ni gomina Fayemi naa wa fikun wi pe awọn yoo fi ohun gbogbo sipo ti iru awọn iwa buruku yii ko ni waye mọ.
Koda, awọn fọto igba ewe wọn yii si lo jẹ kí araye mọ pe ọmọ dudu ni wọn amọ ti ọpọ wọn ti di oyinbo bayii.
MaguEFCC: Omale ni orúkọ tí Magu ń lò.
Bakan naa ni wọn yóò fi orukọ awọn to ba yege sinu àwọn iwe iroyin lorilẹ-ede Naijiria.
ekunwo owo osu awon osise lorile ede Naijiria.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ojora ń mú mi lọ́wọ́ lórí ìkọlù tó wáyé, ara mi kò tíì balẹ̀ - Toyosi Adesanya Bí Amẹrika bá dínà mọ́ Nàíjíríà láti wá sílẹ̀ wọn, ewu ń bẹ fún wa - Lai Muhammed Tìpá-tìkúúkùù, àwọn Alága Káńṣù l‘Ọyọ, tí Makinde fòfin dè yọjú síjọba ìbílẹ̀ wọn Àgádágodo ní wọ́n fi ti ẹnú ọ̀nà káńṣù l‘Ọyọ, ọlọ́pàá gbàródan síbẹ̀ Okada Ban: ọjọ kini oṣù keji ni òfin tuńtun yóò bẹ̀rẹ̀ Toyin Abraham, loju opo Instagram rẹ lo n wa ẹkun mu poroporo, to si ni oun ko tii sunkun to bayi ri laye oun, ti idajọ naa si ba oun lọkan jẹ.
O si gbọdọ ni nọ́mbà idanimọ gbogboogbo, National Identity Number (NIN).
Àwọn tó bá ikọ ìròyìn BBC sọ̀rọ̀ láti ìlú Èkó, Ibadan àti Oshogbo sàlàyé ìdojúkọ wọn.
Ọmọ atàpátadìde ni mí, télọ̀ ni bàbá mi- Abiola Ajimobi Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ekiti: Ìjọba ti iléeṣẹ́ rẹ́díò Fayose pa nipinlẹ Ekiti 14 Èrèlè 2019 Àkọlé àwòrán, Iléeṣẹ́ ààtò ìlú ní iléeṣẹ́ rẹ́díò náà kò gba ìwé àṣẹ ìkọ́lé.
Laipẹyii ni awọn olukọni labẹ isakoso ẹgbẹ awọn olukọni fasiti lorilẹede Naijiria, ASUU se ifilọlẹ awọn ọmọ igbimọ isakoso rẹ tuntun ninu eyi ti Ọmọwe O.
Ẹ jẹ ki a gbé èdè àti àṣà Yorùbá Lárugẹ
Lọjọbọ ẹwẹ, ṣaadede ni igbẹjọ olorin naa wa sopin gẹgẹ bi iroyin ṣe ni aigbọraẹniye dede suyọ laarin awọn agbẹjọro lori aaye atijoko ninu ile ẹjọ kekere naa.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Lagos King: Mátikú ọba tó lo lo ọdun mẹta lórí oyé latari rogbodiyan Eko Bi wọn se ju Gbọnka sinu ina lo jona di eeru patapata, ti Alaafin si n fo fayọ pe oun ri ẹyin ọta oun mejeeji, amọ oju ẹsẹ ni Gbọnka jade pe oun ko ku, to si pasẹ pe Alaafin Sango pe ko se bi ọkunrin.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Yaa Asantewaa: Ti ẹyin ọkunrin Ashanti kò bá tẹsiwaju, awa obinrin yóò lọ Igbes'ẹ ọkọ iyawo yii ni ọpọ awọn ọkunrin ro pe ko dara rara pe o tako aṣa akọ.
Ìkòkò tí ó ń fi amọ̀ mọ bàjẹ́ lọ́wọ́ rẹ̀, ó bá fi amọ̀ náà mọ ìkòkò mìíràn, tí ó wù ú.
Ọba sọ fún ọmọbinrin náà pé, “Bèèrè ohun tí o bá fẹ́, n óo fi í fún ọ.
Modric wa ni ipo kinni, Cristiano Ronaldo ni ipo keji, Antoine Griezmann ni ipo kẹta, ti Kylian Mbapeé si wa ni ipo kẹrin.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Mayowa Omoniyi: Kò sí orin Obey, Sunny Ade abí tàkasúfèé tí ń kò le ta gìtá sí Nigba to n bawọn akọroyin sọrọ, Alaga ikọ Amotekun nipinlẹ Oyo, Ajagunfẹyinti Kunle Togun, sisọ loju rẹ pe awọn yoo finmu finlẹ lati mọ boya awọn eeyan yii ni akọsilẹ iwa ọdaran ri.
Amosa, ẹ maa laagun jina o, Aishaa Yesufu funrarẹ ti ṣalaye idi abajọ.
mahafali Àwọn ènìyàn yìí lé ní mílíọ ̀ nù kan àti ààbọ ̀ , wọ ́ n ń gbé ní apá gúúsù ìwọ ̀ oòrùn madagascar .
Ninu idile iya ati baba tirẹ ko si ẹnikẹni to ni iru oju yii o.
Gbogbo rẹ̀ ni wọ́n fọ́ tí wọn rún wómúwómú; wọ́n sì kó gbogbo bàbà tí ó wà ninu ilé OLUWA lọ sí Babiloni.
Paulu Kí Ọpọlọpọ Eniyan ninu Ìjọ Romu.
 Ìtọjú yíì maa ńpa ìdin ṣùgbọ ́ n kòle pa àwọn ìdin tí ó ti dàgbà .
Irọ́ ní pé bàbá wa, Soun Ogbomoso paradà di ọmọ tuntun, báyìí ni àwọn ọ̀rẹ́ ṣe dalẹ̀ rẹ̀ tí wọ́n pa á Remilekun Fatolu bú sẹ́kún fún ohun tó ti pàdánù láyé torí ọyàn ńla rẹ̀.
Nítorí náà, láti ọjọ́ tí a ti gbọ́ ìròyìn yín, àwa náà kò sinmi láti máa gbadura fun yín.
''Kiiṣe ẹẹkan tabi ẹẹmeji ni iroyin ti gbe e pe mo ku.
 Ìwọ ̀ n egbògi náà méjì tàbí mẹ ́ ẹ ̀ ta ni a gbọ ́ dọ ̀ fún ènìyàn kí ó tó pé ọmọ oṣù mẹ ́ ẹ ́ fà .
Gbogbo àwọn eniyan bá lọ kọ orúkọ wọn sílẹ̀, ẹnìkọ̀ọ̀kan lọ sí ìlú ara rẹ̀.
"Bẹẹ ba gbagbe, ọpọ igba ni ariwo ti sọ nigboro ilu Ibadan nipa bi awọn ọmọlẹyin Auxiliary ṣe n hu iwa ipa ni awọn ibudokọ ti wọn ti n ṣíṣẹ.
Ile ẹkọ Isabatudeen Girls Grammar School ni Baṣọrun ni olukọ wa ti n ṣiṣẹ bayii.
Nisinsinyii, bí ẹ bá ti gbọ́ ìró ipè, fèrè, dùùrù, ìlù, hapu, ati oniruuru orin, tí ẹ bá wólẹ̀, tí ẹ sì sin ère tí mo ti yá, ó dára, ṣugbọn bí ẹ bá kọ̀, tí ẹ kò wólẹ̀, wọn óo gbe yín sọ sinu adágún iná ìléru.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Coronavirus: Togo di orílẹ̀èdè kẹsàn án tí àrùn Coronavirus dé ní Afíríkà 7 Ẹrẹ̀nà 2020 Oríṣun àwòrán, Getty Images Bi aarun Coronavirus ṣe n ran kaakiri bii ina inu ẹrun lagbaye bayii, Orilẹede Togo naa ti darapọ mọ awọn orilẹede ti arun naa ti tan de lagbaye.
O ni afojusun ohun ni lati mu igbe aye irọrun ba awọn eeyan ipinlẹ Ọyọ, ati la ọna to tọ ninu oṣelu lorilẹede Naijiria .
tí ẹ kò bá fi ìyà jẹ àwọn àlejò, ati àwọn aláìníbaba, tabi àwọn opó, tabi kí ẹ máa ta ẹ̀jẹ̀ aláìṣẹ̀ sílẹ̀ ní ibí yìí, tí ẹ kò sì máa bọ oriṣa káàkiri, kí ẹ fi kó bá ara yín, 
Ile-ise olopaa so pe, meji ninu awon afurasi naa mu oti amupara lasiko ikolu naa.
Absalomu dáhùn pé, “Nítorí pé mo ranṣẹ pè ọ́, pé kí o wá, kí n lè rán ọ lọ bèèrè lọ́wọ́ ọba pé, ‘Kí ni mo kúrò ní Geṣuri tí mo sì wá síhìn-ín fún?
Fún ọpọlọpọ ọjọ́ ni ó fi ara hàn fún àwọn tí wọ́n bá a wá sí Jerusalẹmu láti Galili.
Ìgboyà tí a ní níwájú Ọlọrun nìyí, pé bí a bá bèèrè ohunkohun ní ọ̀nà tí ó fẹ́, yóo gbọ́ tiwa.
 Láti inu fídíò tó wà lókè yìí lẹ ó ti gbọ́ ọ̀pọ̀lọ̀pọ̀ ọ̀rọ̀ àgbọ́ ya ẹnu sílẹ̀ lẹ́nu àwọn tí kò léè ju ìgbàgbọ́ wọn nínú ohun tí wọ́n ti ń ṣe tàbí jẹ látayé dáyé nù kí wọ́n wá gba ti òyìnbó tàbí ònímọ̀ ìlera wọlé - Fáàbàdà."
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Àwọn olóṣèlú ló fẹ́ sọ darandaran Fulani lórúkọ burúkú, àwa kìí gbébọn-Miyetti allah 22 Agẹmo 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Miyetti Allah ni aikọbiara si ipenija awọn gomina lẹkun oke ọya orilẹede NAijiria lo fa awuyewuye lori RUGA Ẹgbẹ agbajọpọ awọn darandaran Fulani lorilẹede Naijiria, Miyetti Allah, ti wa jade lati pariwo ẹ ma sọ wa ni suna buruku, ko si ọmọ ẹgbẹ wa to n gbe ibsn fi daran igi ni wọn nlo.
Àkọlé àwòrán, Ayẹyẹ ikẹyin fun Baba Sala Àkọlé àwòrán, Ayẹyẹ ikẹyin fun Baba Sala Lẹhin isin idagbere ni wọn yoo gbe baba Salah wọ kaa ilẹ lọni ilẹ rẹ to n bẹ ni agbegbe Abiọla Avenue nilu Ileṣa.
Ibo ẹ̀gbẹ̀rún mejila ni ajo INEC fagile lataari bi apapo ibo ohun se poju bi won se lero lo.
Wo àwọn tó ń jí owó Covid-19 tí Ìjọba ní wọ́n yóò káwọ́ pọ̀nyìn rojọ́ Agbẹjọrọ naa ni ti ileeṣẹ iroyin Daily Trust ko ba ṣe ifẹ awọn, awọn yoo gbe wọn lọ si ileẹjọ.
Ọwọ́ epo ni aráyé ń ba ni la, wọn kì í bá ni la ọwọ́ ẹ̀jẹ̀, ò ṣì ní ń jẹ ‘Ta ni mọ̀ ọ́’, owo ni ń jẹ́ ‘Mo bá ọ tan’.
Ààrin àwọn ẹranko ni ó wà, ṣugbọn àwọn angẹli ń ṣe iranṣẹ fún un.
Báyìí ni PDP ṣe kí APC kú oríiré títú àwọn adárí ẹ́gbẹ́ wọn ká Kí làwọn nǹkan tó lè rán ọkùnrin sí ọ̀run alákeji lásìkò ìbálòpọ̀ pẹ̀lú obìnrin?
Joabu bá lọ sí ọ̀dọ̀ ọba, ó bèèrè pé, “Irú kí ni o ṣe yìí, Abineri wá sí ọ̀dọ̀ rẹ, o sì jẹ́ kí ó lọ bẹ́ẹ̀?
Wọ́n wípé ó ti ṣòro jù látì kà nítorí ihò méjìlá ti pọ̀jù láti fi ìka ènìyàn kàn lẹ́ẹ̀kannáà.
Kèǹgbè lílù ní Ilọrin rèé, orin ìgbéyàwó, àwàdà àti ẹ̀ẹ̀kẹ́ èébú Abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Patrick Day dèrò ọ̀run lẹ́yìn tó gba ẹ̀ṣẹ́ s'órí!
Ẹ fi òdodo bo àyà yín bí apata.
Yóo tún fi àwọn iṣẹ́ tí ó tóbi jù wọnyi lọ hàn án, kí ẹnu lè yà yín.
Amọ, ẹpa o boro mọ ni pẹlu iru iya ti Usman fi jẹ Masvidal lati di Ami Ẹyẹ rẹ mu gẹgẹ bi Alami Ẹyẹ UFC Welterweight Champion.
Mẹlikisẹdẹki jẹ́ alufaa Ọlọrun Ọ̀gá Ògo.
" Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Joke Silva: Olu, ó tó gẹ́ pẹ̀lú obìnrin yìí níkan tó ń ba ẹ ṣeré ìfẹ́ nínú sinimá Imọran Esher Abọdẹrin fun awọn ọdọ Naijiria ni pe: Iya ewe, to ti le ni ọgbọn ọdun to ti wa loke okun, wa gba awọn ọdọ to n lakaka lati wa iṣẹ aje lọ soke okun nimọran pe, ki wọn ni suuru nitori nnkan ko fi bẹẹ dara mọ lọhun.
Atẹjade kan ti akọwe feto iroyin fun gomina ipinlẹ Ọyọ, Taiwo Adisa fisita lọjọ Ẹti salaye pe akọsẹmọsẹ nileesẹ elepo Shell ni Adeọsun, eyi ti gomina Makinde ni yoo seranwọ lati kopa ninu minu ayipada rere ba ipinlẹ Ọyọ.
Nígbà tí mo bá ráyè n óo tún ranṣẹ pè ọ́.
jo sise po fun anfaani awon omo orile-ede Naijiria.
Nígbà tí wọn ń sá bọ̀ wálé, àwọn kan wá sọ fún Dafidi pé, “Absalomu ti pa gbogbo àwọn ọmọ rẹ, ati pé kò ṣẹ́ku ẹyọ ẹnìkan.
Gẹgẹ bi BBC News Yoruba ṣe gbọ, ọrọ naa bẹrẹ ni owurọ ọjọ ẹti nigba ti awọn aṣofin mejidinlogun ninu mẹrindinlọgbọn to wa ni ile naa dibo yọ ni ile olori ile aṣofin ipinlẹ Ondo, Bamidele Oloyelogun ati igbakeji rẹ, Iroju Ogundeji kuro nipo.
Aarẹ Muhammadu Buhari to n ṣoju apa ariwa yoo ti lo ọdun ,mẹji lori laeefa to ba pari saa keji rẹ lọdun 2023.
Iya ọmọ tuntun naa ṣalaye fun BBC pe oriṣiiriṣii aisan lo ṣe ẹ̀dọ̀, kidinrin àti ọ̀fun oun yatọ si oyún ìju, ṣugbọn oun bori gbogbo rẹ nigbẹyin ti wọn a si maa fi orukọ ọmọ pe oun naa bayii.
Nítorí pé ó ti tà wá, ó sì ti ná owó tí ó gbà lórí wa tán.
Ó wá tún sọ fún wọn pé, “Bẹ́ẹ̀ ni ó wà ní àkọsílẹ̀ pé Mesaya gbọdọ̀ jìyà, kí ó sì jí dìde kúrò ninu òkú ní ọjọ́ kẹta.
Edward Akudo-Addo den Adeline ni baba rẹ.
Ẹ gbọ́ ẹ̀yin ará, ati àpéjọ gbogbo ìlú; ohun tí ó ti dára ni pé kí eniyan bẹ̀rù OLUWA; 
Shangula ni omi inu n kan oun pe awọn kọlọrọsi kan le e gba owo lọwọ awọn eeyan fun awọn oogun tabi iwosan ti ko ṣiṣẹ.
Òkú àwọn tí a fi idà pa ni yóo kúnbẹ̀.
Ní ọdún 2014, ogunlọ́gọ̀ ìbílẹ̀ ní Mekong bẹ̀rẹ̀ sí ní í ṣe àkọsílẹ̀ àwọn àlọ́ àti ìtàn àtọwọ́dọ́wọ́ọ wọn pẹ̀lú ìrànlọ́wọ́ ẹgbẹ́ aṣèwádìí kan tí ó ń ṣe àyẹ̀wò fínnífínní sí bí ìtàn wọ̀nyí ṣe lè ṣe ìrànwọ́ tí yóò tú àṣìírí ìmúdìbàjẹ́ àyíká tí àwọn iṣẹ́ ńláǹlà ń fà ní agbègbè náà.
ly/2rHOXzO eyi ti BBC Yoruba ti pese.
 ""To ba jẹ iwọ ni adura yii wa fun, ko yara tete wa ọ ri ni kiamọsa."
Iwe iroyin ẹgbẹ oselu kan lorilẹede Cuba fi lede wipe, eniyan mẹta lo bo ninu ijamba naa, ti wọn si wa ni ile iwosan, nibi ti wọn ti n gba itọju pajawiri.
Láti ǹkan bi ọdún mẹ́ta sẹ́yìn ló ti wà ni ilé ẹjọ́ tó n dúró de ìgbéjọ lórí ẹsùn tó lé ni mẹ́tàdíláàdọ́rùn tó fi mọ́, fífíni ṣòwò ẹrú, ifipabá awọn obinrin lò pọ̀ nínú ìjọ rẹ̀.
Iye ibo ti wọn di jẹ – 553,
Baba Leah Sharibu ti fohun sita pe oun o gbagbọ rara ninu awuyewuye ti awọn kan n gbe kiri pe ọmọ oun ti ku.
Koda, awọn ẹni ibi tun n ta awọn ohun eelo itọju alaisan Covid 19 nibẹ.
Owó ọ̀yà èké ni eniyan burúkú óo gbà,ṣugbọn ẹni tí ó bá hùwà òdodo yóo gba èrè òtítọ́.
"O ni Ọọni ile ifẹ nikan lo laṣẹ labẹ itan Yoruba lati da si ọrọ lọbalọba kaakiri nitori gẹgẹbi ọrọ rẹ, ""Ọọni ni olori ọba lagbaye"" O ni awọn to lee ba gomina Fayẹmi wi bo ba taṣẹ agẹrẹ wa nipinlẹ Ekiti ti ko si si idi fun Alaafin lati maa da si ọrọ laarin wọn."
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ẹgbẹlẹgbẹ owo ni ipinlẹ Eko ya sọtọ fun ipese ohun amayedẹrun Ambọde tun buwọlu awọn abadofin meji.
Ẹ wo àwòrán àti pipè èlò ọbẹ ni abala ojú iwé yi.
Ile-ise agbaye to n se ayewo inawo ,salaye pe ọgbọ̀n milionu dola ni owo ilu orile ede  naa , ti awon osise ijoba , osise aladaani, onikoowo  ati awon oloselu ji ko lo .
Alaga ajọ eleto idibo ipinlẹ Kano, Siec, Ọjọgbọn Garba Sheka ni lọjọ Aje ti igbimọ ba n gunlẹ si ipinlẹ Kano ni wọn yoo de ọdọ oun.
- MC Oluomo Sanwo-Olu fi ẹ̀gbin dá àrà tuntun l'Eko Ààbò tó péye wà fún àwọn okòwò ará South Africa ni Eko -Sanwo Olu Bianca júwe ilé fún Serena Williams nínú ìdíje l'America Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
NCDC lo kede bẹẹ loju opo Twitter rẹ loru ọjọ Abameta, ipinlẹ Eko si ni iye eeyan to pọ ju to ṣẹṣẹ ni arun ọhun ti wa.
Ni irọlẹ ọjọ aiku ni ajọ EFCC gbe Fayoṣe lọ silu Eko lati lọ jẹjọ lori ẹsun mọkanla ti wọn fi kan an eleyi to nii ṣe pẹlu ṣiṣe owo ilu baṣubaṣu.
Ẹni ti o di Emir ikẹẹdogun ni Kano bayi ti agbara si tiwa ni ikapa rẹ ni Aminu Ado Bayero.
Akọroyin wa to kan si agbegbe naa jabọ pe nnkan bi ago mẹta ọsan ọjọ Ẹti ni ijamba ọkọ naa ṣe Eeyan 18 ku ni marosẹ Ibadan si Eko Eeyan mẹjọ jona ninu ijamba ọkọ agbepo Eeyan mẹrin ku ninu ijamba ọkọ l'Eko Oríṣun àwòrán, Yemi Akintunde Àkọlé àwòrán, Awọran ọkọ to kọlu awọn eeyan ni ọja toi wa ni iwaju Oke Mapo ni Ibadan Bakanna lo ni awọn ọlọja to wa nibẹ sọ pe awọn ọlọpaa ti wa gbe oku awọn to padanu ẹmi wọn lọ si ile igbokupamọsi ti wọn si ti wọ ọkọ akero naa lọ.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ṣé ẹ̀yin lè ṣe jú àwọn tó f'àmì sí Awọlumatẹ?
" BBC ko ti i fidi awọn ẹsun yii mulẹ.
Àdó okoró búrẹ́kẹ' Nigba ti awọn oniroyin kan si alukoro ọlọpaa ipinlẹ naa, Irene Ugbo ni bi emi naa ṣe gbọ iroyin naa ree mo si n mura ati jade kuro nile lati lọ fidi ọrọ naa mulẹ ni ọfiisi rẹ""."
Ó fi ìdí wọn múlẹ̀ títí laelae;ó sì pààlà fún wọn tí wọn kò gbọdọ̀ ré kọjá.
 Oríṣun àwòrán, Agencies Alabi fikun pe Inu n bi gbogbo wa, a fẹ foju kan awọn eeyan wa to se alaisi ninu isẹlẹ naa, ka se ẹyẹ ikẹyin fun wọn, ki wọn si lọ tẹ wọn si iboji, sugbọn awọn ọlọpa fẹ pari iwadi wọn ki wọn to gbe awọn oku naa fawọn mọlẹbi wọn.
Ivory Coast tẹle pẹlu gbigba ami ẹyẹ naa lẹẹmẹjọ, Ghana lẹẹmẹfa, ti Naijiria si gba ni igba maarun.
Ninu ọrọ tiẹ, Sẹnetọ Abdulfatai Buhari ni gbogbo nnkan patapata ni Ọlọrun fun oloogbe, Ṣẹnetọ Abiọla Ajimọbi ni igbesi aye rẹ.
Ogun Àgbẹ́kọ̀yà, ìjà òmìnira fáwọn àgbẹ̀ ni tàbí ìfẹ́míṣòfò?
Olóòótọ́ yóo ní ibukun lọpọlọpọ,ṣugbọn ẹni tí ń kánjú àtilówó, kò ní lọ láìjìyà.
“Èmi OLUWA bínú sí àwọn baba ńlá yín.
Ṣugbọn mo sọ èyí fun yín kí ẹ lè ní ìgbàlà.
Kí oore-ọ̀fẹ́ ati alaafia láti ọ̀dọ̀ Ọlọrun Baba wa ati Oluwa Jesu Kristi, kí ó wà pẹlu yín.
Ó dàbí ẹni pé ẹ wí fún mi pé àbúrò yín kan lọ sí ìdálẹ̀ ní ọjọ́sí, o ti dé bí?
'Ti a ba ni aarẹ ati olootu ijọba ni Niajiria, agbara aarẹ a dinku, ti wọn a si pin ohun ini kari ni Niajiria.
Mo bẹ Olódùmarè kí ó jẹ́ kí n mọ ipò mi láàrin àwọn ọdẹ wọ̀n-ọnnì ki n lè máa ṣe sí Olúkúlùkù bí mo ti fẹ́ kí o ṣe sí mi.
Bakan naa ni iwe aṣe igbelu tabi iwe aṣẹ wiwọ ilu tabi orilẹ-ede kọọkan [visa] jẹ ohun ti o gba oogun lọpọlọpọ lati ri gba fun irin ajo naa.
Ọmọ ọdun marun kan, Aisha Ibrahim, ni ori ti ko yọ lọwọ awọn ajinigbe to gbe pamọ, to si pade alawore ọlọpaa kan, Bukan-Kwatu nilu Lafia nipinlẹ Adamawa, to gba a silẹ.
Yìnyín ńláńlá tí ó tóbi tó ọlọ ata wá bẹ̀rẹ̀ sí bọ́ lu eniyan láti ojú ọ̀run.
Sugbọn o seese ki aburu ti o de ba ara kọja afarada ti awọn ẹya ara ko si ni lagbara lati sisẹ mọ.
Àwa ọba Ekiti kìí ṣe Ajẹ́lẹ̀ rẹ̀, máṣe yọnu sí ohun tí kò kàn ọ́ ní Ekiti - Aláwẹ̀ fèsì fún Aláàfin Lẹta ti Alaafin tilu Ọyọ, Ọba Lamidi Ọlayiwọla Adeyẹmi Kẹta kọ si gomina ipinlẹ Ekiti, Dokita Kayọde Fayemi, ti n bi Ige ati Adubi bayii.
Ọ̀kan nínú wọn pupa, ó tóbi, ó síngbọnlẹ̀, ó sí da bi ẹni tí ó ti wọ ilé ọkọ, ṣùgbọ́n èyí ekejì kò sanra púpọ̀ bẹ́ẹ̀ ni kò ga, ènìyàn dúdú ni, eyín rẹ̀ sì funfun bi àgbàdo àṣẹ̀ṣẹ̀yọ.
O ni kii ṣe arun Coronavirus nikan ni Naijiria n koju lọwọlọwọ, awọn aisan bii Lassa Fever, ikọ fere ati arun ti ko gboogun, HIV naa ṣi n ba awọn ọmọ Naijiria finra ju arun Coronavirus lọ.
Sọ fún un pé, o fẹ́ kí ó wá se oúnjẹ náà lọ́dọ̀ rẹ níbi tí o ti lè máa rí i, kí ó sì fi ọwọ́ ara rẹ̀ gbé e fún ọ.
Oró agbọ́n leè wo àìsàn jẹjẹrẹ ọmú sàn, wo ohun tí wàá lò pọ̀ mọ́ra wọn Wo bí àwọn obìnrin kan ṣe n sọ ara wọn di 'fágìn' lẹ́ẹ̀kejì Wo bí o ṣe lè mọ orúkọ àwọn afípabánilòpọ̀ ní Nàìjíríà Ìdí rèé tí mo fi ṣẹ̀ṣẹ̀ sọ̀rọ̀ lẹ́yìn tí wọ́n fipá bámi lopọ̀ lọ́mọ ọdún méje lọ́gọ́ta ọdún sẹ́yìn-Eli Arabinrin Dupe ṣalaye pe ija ati idaamu lo mu oun kuro nile ọkọ oun akọkọ.
Orilẹ ede yii ni igun ibi omi mẹrin ti o si ti ni idagbasoke pẹlu yẹpẹ funfun.
Ojú rẹ tutù bíi ti àdàbà.
Mose ati Aaroni ati gbogbo àwọn ọmọ Israẹli sì ya àwọn ọmọ Lefi sọ́tọ̀ gẹ́gẹ́ bí OLUWA ti pàṣẹ fún Mose pé kí wọ́n ṣe.
Ó fẹ́ràn ọmọ rẹ̀ tí ń jẹ́ Abija ju gbogbo àwọn ọmọ rẹ̀ yòókù lọ.
Bakan naa, ni won ko fayegba awon oniroyin ati awon osise miiran lati wole.
O ku osu meji pere ki Baba pe eni ọdun marundinlọgọ́run un lo dagbere faye pe o digbose.
Kò gbàgbọ́ pé òun lè jáde kúrò ninu òkùnkùn;ati pé dájú, ikú idà ni yóo pa òun.
Ojo naa ni won fi seranti eto idibo odun 1972, eleyi ti awon ara-ilu pawopo lati dibo yan ijoba oloogun.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Waste to Wealth: Ẹ̀gbin tìrẹ ni èròjà táwọn èèyàn míràn fi n ṣiṣẹ́ ajé, okoòwò ńlá ni Lọwọ lowọ bayii, ipese ina ọba lorilẹede Naijiria lo n se segesege, ti awọn ọmọ Naijiria si n gbara le ipese ina ọba lati ara awọn ẹrọ amunawa, eyi ti wọn n na owo gege le lori lati fi ra epo sinu wọn.
Bí bẹ́ẹ̀ kọ́, bí ó bá ké pè mí, n óo dá a lóhùn, nítorí pé aláàánú ni mí.
Ibaṣepọ to dara pẹlu ololufẹ rẹ Kris Ero sọ pe, ti ara iwọ ati ololufẹ rẹ ba n kan ara wọn nigba ti ẹ ba sun si ẹgbẹ ara yin, yoo ran yin lọwọ lati maa wu ara yin.
1 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 3:49 Fídíò, Boko Haram: Oluwatobi Adeigba, Ọkọ mi ń lọ siṣẹ́ fún àjọ INEC ló kàgbákò ikú - Opó Adeigba, Duration 3,492 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Aare Muhammadu Buhari darapo mo gbogbo omo leyin Kristi lagbaye paapaa awon omo ijo Irapada Onigbagbo iyen, The Redeemed Christian Church of God (RCCG), lati fohun sokan ki Olusoagutan Enoch Adejare Adeboye ku ayeye ojo ibi odun kerindinlogorin lori oke eepe loni.
Ikede yi lo waye lati ẹnu ileeṣẹ ọlọpaa apapọ lorile-ede Ethiopia ti o kọkọ sọ pe ẹṣọ to ṣekupa olori ọmọ ọgun ilẹ naa Ọgagun, Seare Mekonnen, ti yinbọn pa ara rẹ.
Kàyééfì Promo: Ìyá, ọmọ tuntun àti olubi ló wà níbùdó ìgbókùsí, àmọ́ òkú ọmọ di àwátì
Oríṣun àwòrán, Instagram/toyin abraham Toyin ṣe igbeyawo lẹẹkeji.
Ninu fọnran fidio 'Fox Hunt 2' ni wọn ti ṣafihan rẹ.
Prostate Cancer: 82% ọkùnrin ní kó mọ̀ pé òun ní àìsàn jẹjẹrẹ asẹtọ ní Naijiria
O ni ki wọn o si darapọ mọ awọn to ni erongba lati tun Naijiria ṣe.
Ẹ tẹ́tí ẹ gbọ́, nítorí pé ọ̀rọ̀ pataki ni mo fẹ́ sọ.
Fún wákàtí mélòó kan lẹ́hìn tí Elizabeth wọlé lọ tán, àwọn akọrin tí wọ́n lókìkí tí wọ́n sì gbajúmọ̀ gorí ìtàgé nlá tí wọ́n kọ́ síwájú àfìn ọba, wọ́n sì nfi orin aládùn dá àwọn erò tó péjọ l’árayá.
Fabiyi salaye bẹẹ lasiko to n kopa lori eto kan ni ikanni BBC Yoruba pẹlu afikun pe, iya n jẹ ọpọ elere tiata lasiko yii.
Laipẹ ni ileeṣẹ to n gbogun tiwa ibajẹ ni America gbe orukọ awọn ọmọ Naijiria sita lori iwa jibiti Ọwọ́ òfin ti tẹ ọ̀pọ̀ ọmọ Nàìjíríà lórí ẹ̀sùn jìbìtì l'Amẹrika- FBI Ọjọgbọn kan ti ni, bi ajọ ọtẹlemuyẹ Amẹrika, FBI, ṣe fi orukọ awọn ọmọ Naijiria lede gẹgẹ bi afurasi oni jibiti, kii ṣe ohun ti o buyi fun wa.
Wọ́n sùn pẹlu àwọn aláìkọlà, pẹlu àwọn tí wọ́n ti lọ sí ipò òkú.
Ajọ UN ṣalaye fun BBC pé awọn eniyan wọn naa wa ninu iṣẹlẹ ibi naa to dùn wón gidigidi.
Nígbà tí wọn ń tú kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ náà, àwọn oluwa rẹ̀ bi wọ́n pé, “Kí ló dé tí ẹ fi ń tú kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́?
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ó dára kí obìnrin níṣẹ́ lọ́wọ́ - Toyin Lawani Apẹrẹ ti a ri lati fi kin ọrọ yi lẹyin ni bi Gomina Godwin Obaseki ko ti se jẹ ki ọjọ pẹ rara ki o to sare lọ darapọ mọ ẹgbẹ oselu PDP lẹyin ti APC lawọn ko fun ni tikẹẹti ẹgbẹ.
Bakan naa lo le fi ẹjọ sun lori ayelujara Twitter, Facebook tabi imeeli.
Àmọ́ ṣá, bí ó ti fẹ́ẹ́ jáde nínú igbó náà, ọ̀nà dí mọ́n ọn ní ojú, kò sì mọ ọ̀nà mọ́.
" Oniwaasu kan nilẹ Naijiria n wo arun Coronavirus san: Oniwaasu kan to ni oun lee wo arun Coronavirus san naa tun ara awọn iroyin ti ko fidi mulẹ.
Bí o bá mọ ìgbà náà, sọ fún mi.
 Gómìnà ìpínlẹ̀ Kaduna, El-Rufai fi ipò míì dá Sanusi lọ́lá Ganduje fún Aminu Ado Bayero ní ìwé ìyannisípò gẹ́gẹ́ bí Emir ìlú Kano Coronavirus ti di àjàkálẹ̀ àrùn káàkiri àgbáyé- WHO Ẹ wo ọ̀nà márùn ùn tí ọkùnrin ṣì fi ń jẹ gàba lé obìnrin lórí Nigba ti Sanusi de ilu naa, ile oni yara meji kan, ti wọn ni o jẹ ti ọkan lara awọn eeyan ijọba ibilẹ ilu naa lo sun mọju."
Davido fi orúkọ bàbá rẹ̀, Adedeji, sọ ọmọ tuntun tó bí MTN Dáapadà, máa danwò- Isa Pantami Mínísítà fún ìbárẹnisọ̀rọ̀ Health Talk: Onímọ̀ ìṣègùn ní àìsàn tó o ṣe l'óru yóò tètè sàn ju èyí tó o ṣe lọ́sàn-án lọ Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 3 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 5 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: ‘Ó kò lé gba ìwé ìgbéèlú U.
Muntasir Mamun ti kọ àìmọye ìwé lóríi ìtàn-ìṣẹ̀lẹ̀-àtẹ̀yìnwá àti àjogúnbá ìlúu Dhaka.
Ẹ̀yin tí ẹ̀ ń gbé etí òkun, orílẹ̀-èdè Kereti!
Ipa 'oloye Ọtun' ti o ta ilẹ oriṣa ninu sinima naa, si ni baba Wande se.
Osise ile-ejo kan so lojo-Ru (Wednesday) ile-ejo kan lorile-ede Egypt  se idaduro ewon odun kookan  fun awon eniyan merindilogun sewon odun kan, latari ikolu ile-ijosin kan to waye ninu osu kejila, ni abule kan ti o wa ni apa gusu ilu Cairo lorile-ede Egypt.
Òkúta tí wọ́n sì yí dí ẹnu kànga náà tóbi pupọ.
Spirit - Kwesta ati Wale Orin yii da lori ibọwọ fun ohun ti ẹmi.
Mo wá ewé wẹẹrẹ mo kó o jọ mo sì kó ọ̀pọ̀lọpọ̀ ewé títóbí mo fi bo ogunlọ́gọ̀ ewé wọn-ọnnì, mo fi eléyìí ṣe ìrẹ̀rí sí ibùsùn mi.
" Ọgagun Buratai ti wa seleri pe ileesẹ ologun yoo mu ayipada rere ba igbo Sambisa, ti wọn yoo si sọ igbẹ rẹ digboro.
Gẹgẹ bi Modinat ti wi, ọkọ oun ko awọn ọmọ mejeeji naa wa sile pẹlu alaye pe, ọrẹ oun kan ati iyawo rẹ lo ja, ti wọn ko si fẹnuko lori ẹni ti yoo ko awọn ọmọ wọn sọdọ, idi si ree ti ọkọ oun ṣe gba lati ko awọn ọmọ naa wale.
Àtakò Sí Títún Ilé Ọlọrun Kọ́.
 Ọjọ ́ ìbí rẹ ̀ ni ọjọ ́ kẹta oṣù kẹrin ọdún 1942 .
Oluwatobi Adeigba, Ọkọ mi ń lọ siṣẹ́ fún àjọ INEC ló kàgbákò ikú - Opó Adeigba Ìdí tí a fi pa àwọn àgbẹ̀ onírẹ̀sì ní Borno, Boko Haram ṣàlàyé nínú fídíò tuntun Èèyàn 281 ló kó covid-19 lọ́jọ́ Ìṣẹ́gun, 123 wá láti ìpínlẹ̀ Eko nìkan Wọ́n ti rẹ ipò ọ̀gágun Olusegun Adeniyi sílẹ̀ lẹ́yìn tó jẹ̀bi títú àṣírí kùdiẹ-kudiẹ iléeṣẹ́ ológun lórí ayélujára Kọmisọnna fun eto iroyin, Abdulwaheed Odusile sọ wi pe ijọba ti bẹrẹ iwadii lori iṣẹlẹ naa, nitori awọn ti fi to ọlọpaa leti.
Ẹwẹ, nipinlẹ Kaduna, Gomina El-Rufai naa ti wọ yara iyasọtọ lọ bayii pẹlu bi o ṣe ni awọn kan ninu mọlẹbi, alabaṣiṣẹ ati amugbalẹgbẹ oun, ti ko arun naa.
Ó bá ń bá wọn gbé ní Jerusalẹmu, ó ń wọlé, ó ń jáde, ó ń fi ìgboyà waasu lórúkọ Oluwa, 
Kò sí iye tó lè tẹ́ ẹni tí ó bá ní ìfẹ́ owó lọ́rùn; bákan náà ni ẹni tí ó bá fẹ́ràn ọrọ̀, kò sí iye tí ó lè jẹ lérè tí yóo tẹ́ ẹ lọ́rùn.
gomina ipinle  lorile ede Naijiria  ni yoo wa nibi ipade ohun , ipade naa yoo bẹrẹ
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Kọmisọnà ọlọ́pàá ni àwọn yóò tú iṣu dé ìṣàlẹ̀ ìkòkò lóri ọ̀rọ̀ náà Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Kọmisọnà ọlọ́pàá ni àwọn yóò tú iṣu dé ìṣàlẹ̀ ìkòkò lóri ọ̀rọ̀ náà 2 Ìgbé 2019 Ilé iṣẹ́ ọlọ́pàá ìpínlẹ̀ Eko ti sàfihan àwọn ti wọn fẹ̀sun kan pé wọn yìbọn pa Kolade Johnson laja ìsìnmi tó kọja.
 Aare Buhari ati awon adari ile-ise ijoba apapo ni won wa pade May naa.
Lẹ́nu ọ̀nà Àgọ́ Àjọ ni kí ẹ wà tọ̀sán-tòru fún ọjọ́ meje, kí ẹ máa ṣe àwọn ohun tí OLUWA pa láṣẹ fun yín, kí ẹ má baà kú; nítorí pé bẹ́ẹ̀ ni ó pa á láṣẹ fún mi.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Baba Suwe bọ́ lọ́wọ́ àìsàn, ó bẹ̀rẹ̀ tíátà padà Jàndùkú yabo ilé ìwòsàn ìjọba sáájú ìpàdé akọ̀ròyìn táwọn dókítà pè Ojú Shagbada Erigga rèé lẹ́yìn tó pa ọ̀rẹ́bìnrin rẹ̀ l'Akinyele ní Ibadan Ìdí tí lílọ Yúrópùù fi di èèwọ̀ fún Nàìjíríà àti àwọn orílẹ̀-èdè adúláwọ̀ míì Arúfin ni Seyi Makinde pẹ̀lú bó ṣe gbà kí wọ́n sin Ajimobi sí GRA - Amòfin Ko tan sibẹ, alaga ẹgbẹ awakọ ero nipinlẹ Oyo tijọba Oyo ti fofin de, Abideen Olajide, ti ọpọ eeyan mọ si Ejiogbe naa wa lara awọn ọmọ igbimọ agbanisisẹ naa.
ti lọ si ile-iwosan ti wọn ko awon to farapa nibi isẹlẹ naa lọ/ O ni ijoba ni
OLUWA wí pé ohun tí o óo fi mọ̀ pé òun ni OLUWA nìyí: n óo fi ọ̀pá tí ó wà ní ọwọ́ mi yìí lu odò Naili, omi odò náà yóo sì di ẹ̀jẹ̀.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Aisha Buhari: Ẹni tí wọ́n ní ọkọ mi fẹ́ fẹ́ kò mọ̀ pé ìgbéyàwó kò ní wáyé 13 Ọ̀wàrà 2019 Oríṣun àwòrán, @aishambuhari Iyawo aarẹ orilẹ-ede Naijiria, Aisha Buhari ti sọ pe, oun ko ni ọrọ lati sọ lori iroyin kan to tan ka laipẹ yii pe, aarẹ Muhammadu Buhari fẹ gbe iyawo miran.
BBC Africa Eye: ìwádìí ìkọ̀kọ̀ BBC fihàn pé àwọn kan ń jí ohun eèlò ìdáàbòbò ìjọba tà nígboro
Bí Kunle Ọlasọpe, ìlúmọ̀ọ́ká agbóhùnsáfẹ́fẹ́ ṣe lo ìgbésí ayé rẹ̀ rèé Awaye ku ko si, ọrun ma kanju, gbogbo wa la n bọ.
Ọwọ́ ọlọ́pàá ti tẹ ọkùnrin kan tó pa ọ̀rẹ́ rẹ̀ nítorí N40 ní Kano Ìfẹ̀hónúhàn l'Abuja lórí ìdájọ́ ilẹ̀ Gẹ̀ẹ́sì tó gbẹ́sẹ̀ lé $9.
Pẹsẹ́ ní Ọlọ́pàá Nàìjíríà wà látàrí ìṣekúpani Ọ̀gágun Iran- Ọ̀gá Ọlọ́pàá Ẹ wo àwòrán bí ọjà Akẹsan ṣe jóná ràùràù ní ìlú Oyo!
Èyí wáyé lẹ́yìn tí wọ́n fẹ̀sùn pípa ọ̀dọ́kùnrin kan ní ìlú Iwo kan àwọn ọlọ́pàá kògbéregbè SARS ní ọjọ́rú ọ̀sẹ̀.
O ni ijoba orile ede Korea yoo fowosowopo pelu ijoba orile
Ó wá ṣe bí ẹni pé èmi gan-an ni ògbójú ọdẹ nínú igbó Maravia.
Abdullahi, to ti gba bọọlu ri ni ilẹ Kuwait ati Portugal, yoo darapọ mọ awọn akẹgbe rẹ William Troost-Ekong, Mikel Agu ati Paschal Okoli ni Bursaspor labẹ akọni Paul Le Guen to ti dari ikọ agbabọọlu ilẹ Cameroon ni igba kan ri.
'Inú mi dùn pé wọ́n dájọ́ sísọ̀kò pa bàbá arúgbó tó fipá b'ọ́mọ lòpọ̀' Nigeria Sharia law: Àwọn òbí ní Kano dunú sí ìdájọ́ ikú fún bàbá ẹni ọdún 61 À ń dúró de ìgbẹ́jọ́ mìí tó tún n bọ̀ láti pinu bí ẹjọ́ náà yòó ṣe yọrí."
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Mama Rainbow: Toyin Adegbola àti Razak Olayiwola ní ìyá rere àti àwòkọ́ṣe gidi ní Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Mama Rainbow: Toyin Adegbola àti Razak Olayiwola ní ìyá rere àti àwòkọ́ṣe gidi ní 16 Ọ̀wàrà 2019 Arise ni arika, arika si ni baba iregun, ohun taa ba si se loni, yoo di itan to ba di ọla.
N kò mọ bí wọ́n ṣe n bá obìnrin sọ̀rọ̀ ìfẹ́ - Aláàfin Olorì Anu Adeyemi ń ṣe ọjọ ìbí, ẹ gbọ́ ǹkan tò sọ sí Kábíyésì Kí ló wà ní ìdí igbá tí àwọn olorì Aláàfin máa ń tí lóde Ọ̀yọ̀ Alaafin bi ibeji l‘ẹẹmeji lọsẹ kansoso Bawo ni alaafin ṣe n dẹnu ifẹ kọ awọn ọdọmọde arẹwa wọnyii?
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Femi Falana: Ìjọba Buhari kò lé è dá ààbò bo àwọn ará ìlú 17 Ìgbé 2019 Oríṣun àwòrán, Google Àkọlé àwòrán, Gbajúgbajà Agbẹjọ́rọ̀ Femi Falana ti ní àwọn olósèlú ló wá ní ìdí ìsekúpani àti ìjínigbé lórílẹ̀èdè Nàíjíríà.
eto idibo to ma n waye kaakiri awọn ipinlẹ to wa lorilẹ-ede lati yan awọn
Mustapha ni óṣeéṣe kí àwọn ilé ìjọsìn ṣí bótilẹ̀ jẹ́ pé kò ni sí ìpíjọpọ̀ to ju ogún èèyàn lọ níbikíbi to ba yàtọ̀ si ibi iṣk àti ilé ìjọsìn.
Bawo ni awọn ikọ ọmọogun ilẹ Cameroon ṣe pa obinrin kan ati awọn ọmọ rẹ?
Ọ̀pọ̀ ọmọ bibi ìlú Ọwọ lo jẹ olólùfẹ́ Awolowo àti Adekunle Ajasin, bí ológun si se gba ìjọba tún ṣe iwuri fún làásìgbò láti fọn iná sójú n'ilu Ọwọ, Won si gbógun ńlá ti Ọba James Titus Olateru-Olagbegi kejì, èyí sì lo mú kí ìjọba ológun, lábẹ́ Adekunle Fajuyi, tó ń darí ìjọba ẹkùn ìwọ oòrùn Naijiria nígbà náà, yọ ọba Olateru-Olagbegi kejì lórí ìtẹ́ ni oṣù kẹfà, ọdún 1966.
Ọugbọn iya naa ti fi ibẹ silẹ lati bi osu mẹjọ saaju, to si jẹ wipe oun lo n gbs bukaata ara rẹ.
Ẹgbẹ alagbelebu pupa, Red Cross, toun naa ko gbẹyin nibi isẹlẹ ina yii, salaye pe, o ti to eeyan mẹẹdogun ti awọn ti doola ẹmi wọn lọwọ ijamba nileẹks naa, ti wọn si ti gbe wọn lọ sile iwosan.
Nítorí náà, bí wọn tíí kó èpò jọ tí wọn ń sun ún ninu iná, bẹ́ẹ̀ ni yóo rí ní ìgbẹ̀yìn ayé.
" Wọn ti gbe Emir ilu Kano tẹlẹ, Sanusi Lamido Sanusi kuro ni ilu Loko, nipinlẹ Nasarawa.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ààrẹ Muhammadu Buhari Aarẹ gbegba oroke pẹlu ifarajin lati koju iwa ajẹbanu, airiṣẹ ati iṣoro aabo.
 a ma ń rí àwọn ẹ ̀ yà kan ní gbogbo àárín àtí ìwọ oòrùn àwọn erékuỳṣù tí ó ní ìbáṣepọ ̀ pẹ ̀ lú àkókó òkun lọlẹ ̀ díẹ ̀ , tí ó sì jẹ ́ pé a maa ń rí àwọn ẹ ̀ yà mẹ ́ fà kan ní eteetí àwọn erékùṣù .
Wọ́n késí ìjọba àpapọ̀ láti wá ojútùú sí ọ̀rọ̀ owó oṣù òṣìṣẹ́ tí ó kéré jù.
Walter Carrington ràn mí lọ́wọ́ kí ń lè sá àsálà lásìkò tí Abacha ń wá mí kiri- Obasanjo BBC Africa Eye: ìwádìí ìkọ̀kọ̀ BBC fihàn pé àwọn kan ń jí ohun eèlò ìdáàbòbò ìjọba tà nígboro Àwọn èèyàn ìlú Okeho ló kó gbogbo owó tí wọn rí gbà lọ́wọ́ àwọn adigunjalè tí wọ́n mú"" Olùrànlọ́wọ́ pàtàkì fún ọ̀rọ̀ ibojì òkú, àti àwọn ipò òṣèlú mìíràn tó jẹ́ kàyééfì ní Nàìjíríà Buruji Kashamu jẹ́ ènìyàn tó nífẹ̀ aráàlú- Gómínà Dapo Abiodun Beyonce ni awo orin naa fihan gbangba pe awọn alawọ dudu jẹ ẹya eniyan to wunilori, ti itan wọn si bu iyi kun ọmọniyan."
Ijọba Naijiria, pẹlu ajọ alamojuto fun eto ilera agbaye (WHO) pẹlu ajọ UNICEF, ti ṣe ipinnu lati gbe ipolongo naa ni ọdun yi, eyi ti yoo idẹda ajesara ti o tobi julọ ti orilẹ-ede yi ti se.
" Ìjọba Nàìjíríà tí kéde orúkọ tuntun fún ọkọ̀ òfurufú orílèèdè náà tí wọ́n fẹ́ ṣe àjínde rẹ̀.
Àwọn ará Amori tí wọn ń gbé agbègbè olókè náà bá jáde sí yín, wọ́n le yín bí oyin tíí lé ni, wọ́n sì pa yín ní ìpakúpa láti Seiri títí dé Horima.
Wọn kọkọ fiya jẹ ẹ ki wọn to fi agidi ni wọn fi gba kamẹra mọ lọwọ rẹ.
Igbeyawo wọn ni èso ọmọ mẹta.
 Ó lẹ ́ ni tẹ ́ bá ri i , ẹ ṣá maa pè ní baba  ."
Èmi kò ní kí Shiite má ṣe ẹ̀sìn won o -Muhammadu Buhari Kí ló mú ọlọ́pàá ilẹ̀ Gẹ̀ẹ́sì san owó gbà má bínú £2500 fún pásítọ̀ yí?
Bí àwọn kan ṣe ń sọ pé, ọrọ ọmọ ni bàbá Kiddwaya ń ṣe, ni àwọn míràn sọ pé, ọgban àti lu àwọn ọmọ Nàìjíríà ni jìbìtì ni.
Ẹ ranti bí ó ti rí fun yín kí ẹ tó fi ìpìlẹ̀ tẹmpili yìí lélẹ̀.
Dafidi gbé orí ati ihamọra Goliati; ó gbé orí rẹ̀ lọ sí Jerusalẹmu, ṣugbọn ó kó ihamọra rẹ̀ sinu àgọ́ tirẹ̀.
Nítorí pé láìpẹ́, ibinu mi si yín yóo kásẹ̀ nílẹ̀, n óo sì dojú ibinu mi kọ wọ́n láti pa wọ́n run.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Kíni Condom nse níbi ìdíje Olympic?
Jesu wá kìlọ̀ fún wọn gidigidi, ó ní “Ẹ má jẹ́ kí ẹnikẹ́ni mọ̀.
A fún wọn ní agbára ninu ìrù wọn láti ṣe eniyan léṣe fún oṣù marun-un.
” Bíríkì ni wọ́n lò dípò òkúta, wọ́n sì lo ọ̀dà ilẹ̀ dípò ọ̀rọ̀.
Robert kii ṣe aburo mi lasan, ọrẹ kori o sun mi ni,'' Aarẹ Trump lo sọ bẹẹ.
Kanu sọ ọrọ yii lati kilọ fun ijọba apapọ lati ma ṣe ohunkohun ti yoo mu inu bi oun nitori oun le jẹ ki orilẹ-ede Naijiria gbona.
Nítorí èso ìmọ́lẹ̀ ni oríṣìíríṣìí iṣẹ́ rere, òdodo ati òtítọ́.
pe “Ohun ti o fa irinajo won lo si orile ede naa ni, isele to waye
“Nígbà tí ọkunrin tabi obinrin kan bá ṣe ìlérí láti di Nasiri, tí ó sì ya ara rẹ̀ sọ́tọ̀ fún OLUWA, 
"Ninu atẹjade naa ti ọga ileeṣẹ naa Amoako Baah fọwọ si,wọn ni ""Iṣẹlẹ naa kọja agbara wa ṣugbọn kete ti a ba ti yanju rẹ nia o da ina pada si awọn agbegbe ti ọrọ naa kan."
Àwọn Ọmọ Israẹli Ṣẹgun Àwọn Ará Midiani ní Àṣẹ́tán.
Kò sí irú rẹ̀ rí ní ìjọba kankan.
Ẹ má bínú pé mo kọ́kọ́ ní akẹ́kọ̀ọ́ mẹ́wàá péré ni wọn kó nílé ìwé Kankara - Garba Shehu Wo àwọn nǹkan to tún nílò NIN fún yàtọ̀ fún ìforúkọsílẹ̀ síìmù Ilé aṣòfin àgbà yọ gómìnà nípò, ẹni tó fi owó ìlú rán ọmọ lọ sí Amẹ́ríkà Amẹ́ríkà yarí pé àwọn agbégbọn tó jí akẹ́kọ̀ọ́ 344 gbọ́dọ̀ fojú winá òfin Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Lọdun 1935 ni wọn bi Ọba Adegbite Adedoyin ti asiko ibi rẹ si ṣe deede ọdun meji si igba ti wọn bi Moses Orimolade oludasilẹ ijọ mimọ Kristẹni Cherubim and Seraphim Church.
O fikun pe, mẹta ninu awọn eeyan naa lo gbẹmi mi loju ẹsẹ nigba ti awọn mẹrin yoku dagbere faye nile iwosan ti wọn gbe wọn lọ.
Aṣofin Brahimoh wa gbadura fun Ọba bayii, “mo ki Ọba ku oriire, ki ade pẹ lori, ki bata pẹ lẹsẹ, igba ọdun, ọdun kan.
Lẹ́yìn náà, kí ẹ fọn fèrè, kí ẹ sì hó pé, ‘Kí ẹ̀mí Solomoni, ọba, kí ó gùn!
Minisita fun eto isuna lorile-ede Kenya so pe, o seese ki igberu iko marun o le 5.
Kí ògiri jẹ́ ìlè igi kan lórí ìlè òkúta mẹta.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Awọn eroja yii pe oriṣiriṣi; ọṣẹ, ipara, ororo, tabilẹti oogun ati abẹrẹ.
lasiko abewo ohun, gege bi Dr Bello, ogagun Dambazau tun kan si ipago awon
”Asofin Ahmed Lawal,okan lara adari ile igbimo asoju-sofin niluu Abuja naa tun so pe , lara ohun ti awon jiroro nibi ipade naa ni bi won yoo se yanju aawọ to wa laarin awon omo egbe won.
Ta ni ò ń sọ̀rọ̀ aṣa sí, tí ò ń fí ń ṣe ẹlẹ́yà?
Ó gbé ọ̀pá fìtílà náà sinu àgọ́ àjọ níwájú tabili ní apá ìhà gúsù àgọ́ náà.
 O parowa fawon eniyan Naijiria lati ma gba owo tabi ebun fi mu won so ibo won nu to ba di 2019.
I can proudly say he was a true friend and brother.
Má ṣe bẹ̀rù, má sì jẹ́ kí àyà fò ọ́.
Shekau so wipe, ikọ oun lo ja ọkọ orufufu awon ọmogun Naijiria bọ, ati wipe ogun sẹsẹ bẹrẹ pẹlu ijọba apapọ lorilẹede Naijiria ati agbegbe Lake Chad ni.
Niṣe ni wọn maa n diye le ìbálé ọmọbinrin.
Ẹni tí ó bá ń pa wọ́n mọ́ yóo wà láàyè.
Ọ̀rọ̀ OLUWA sí ilẹ̀ Damasku nìyí: “Damasku kò ní jẹ́ ìlú mọ́òkítì àlàpà ni yóo dà.
Ẹ jẹ́ ká gbafẹ́ pẹ̀lú àwọn àwòdamiẹnu àwòrán nípa ìgbé ayé rẹ 25 Bélú 2020 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Diego Maradona gbe ife ẹyẹ lọwọ ni 1986, o tun se igbaradi, oun ati iyawo rẹ tẹlẹ ri Claudia ati awọn ọmọbinrin rẹ Dalma ati Gianina Ka fi ẹgan si koda ka tun yọ kuro, agbabọọlu Maradona sọwọn lagbo ere bọọlu lagbaye.
n fẹ nipa pe ijoba yii nifẹẹ si otitọ , iru ajo bayii si ni yoo jẹ ki won mọ
Akoko ọdun Ọṣun Oṣogbo yii jẹ asiko yatayoto nilu Osogbo, ti wọn si tun maa n lo akoko naa lati se etutu fun ilu tabi fọ ilu mọ ni ilana ti ibilẹ.
Salah to jẹ ọmọ orilẹede Egypt to si n gba bọọlu fun ikọ Liverpool nilẹ Gẹeṣi naa lo gba ami ẹyẹ ọhun lọdun to lọ.
Wo àwọn tó ti dákú bíi Maina níwájú ìjẹ́jọ́ O fi kun un pe, ayẹwo miran yoo waye fun gomina naa lọjọ Abamẹta lati mọ boya o ti ko arun naa abi bẹẹkọ.
Kìlómítà márùn là ń rìn ká tó rí omi mu’ Ẹwẹ, ni Naijiria ajọ kan ti ko rọgbọku le ijọba ti n kilọ pe lai si omi to mọ gaara, orilẹede Naijiria ko lee borii Coronavirus.
COZA: Lẹ́yìn ìwadìí PFN ni CAN tó leè sọ̀rọ̀ lórí ẹ̀sùn tí wọ́n fi kan Fatoyinbo
Lojo marun un seyin, iko omo ogun Naijiria ko orisirisi ohun elo ija ogun wole lati Czech Republic, ni erongba lati fopin si ikolu awon omo ogun olote.
Adajọ Olusegun Odusola ni Babatunde jẹbi ẹsun igbimọ pọ lati ji Kolawole Gold, ọmọ ọdun kan to di awati nile ijọsin naa niluu Akure lọdun 2019.
yoo jẹ ki orile ede yii ni itẹsiwaju.
Awọn apata to ku fun okuta girafu ni wọn ti gbẹ wọlẹ amọ awọn eyi ti wọn ko tii gbẹ, lo ga fiofio wọ oju ọrun eyi to mu ko rẹwa pupọ.
Awọn ilu Yoruba ilẹ Yoruba: Gangan/Dundu Iya ilu Bata Omele akọ Gbẹdu/Ogido Ashiko Saworoidẹ Gangan/Dundun: Oríṣun àwòrán, Others Gangan lo wọpọ julọ ti Yoruba maa n lo fun ayẹyẹ ọlọkan o jọkan nilẹ Yoruba.
Ibinu jẹ mihuwasi to lagbara pupọ eyi to maa n kesi eeyan lati kọbi ara sii amọ ibeere to yẹ ka bi ara wa ni pe bawo ni a se lee se akoso ibinu wa si?
Kì ṣe èyí nìkan: Rúbà ìdáàbò, òògun oníkóró, oyún ṣíṣí, jẹ́ ọ̀kan tí kò jẹ́ kí àìsan ìbálòpọ̀ wọ́pọ̀.
Ẹ máa fara da ìṣòro, kí ẹ sì tẹra mọ́ adura.
Marimba je akojopo igi di ilu ti won n firin lu fi gbe orin dundun jade fi ko orin loniruuru ni eyi ti o ti n di tigbalode bayii.
Bẹẹ naa si ni ọrọ ri ni ipari awẹ.
Láti ìgbà náà wá, ó kọ́ nípa èdè, àṣà àti ìṣẹ̀ṣe Buddha ti Tibet, ó sì di àjà-fún-ẹ̀tọ́ ọmọ ènìyàn.
Àwọn kọmisana ajọ INEC meji to ba àwọn to sẹ iwọde ọhun sọrọ, May Agbamuche-Mbu ati Mohammed Haruna, sọ pe ajọ INEC ti pinnu lati ṣe eto idibo ti ko ni i ni ikunsinu ninu l'ọdun 2019.
Ènìyàn 675 ni èsì àyẹ̀wò sọ pé ó tún ṣẹ̀ṣẹ̀ ní Covid-19 ní Nàìjíríà Ize-Iyamu borí ìbò abẹ́nú fún idíje gómìnà l'Edo Gbọ́yì-sọ̀yí àti ìròyìn èké láti ọ̀dọ̀ àwọn olólùfẹ́ wa ló ṣáábà ma ń da ìgbéyàwó àwọn òṣèré rú- Ọpẹ Ayeola Wo bí nǹkan ṣe ń lọ sí níbi ìpàdé ìta gbangba láti gba igbákejì gómìnà Ondo wọ PDP Gẹgẹ bi a ṣe gbọ, igbọnsẹ lo sọ fun awọn ẹgbọn rẹ pe oun fẹ lọ ṣe ti wọn si ṣilẹkun to jade si ẹyinkule ile naa fun pe ko lọ gbọnsẹ .
Bbí ẹnìkan bá fẹ́ kí òun yípadà sí ọ̀bọ, bí o ba ṣa ti lè wí báyìí pe, ‘Emi ọbọ’ yóò di ọbọ wéréwéré, bí ó bá wí pe, ‘Emi òjòlá’, wéréwéré ni yóò di ejò ti yóò máa wọ́ kiri.
Kanye West ṣèrànwọ́ $2m fún ẹbí George Floyd, yóò tún rán ọmọ rẹ̀ nílé ìwé Níbo ni Sẹ́nétọ̀ Abiola Ajimobi, gómìnà àná ní ìpínlẹ̀ Oyo wà?
Ẹẹmẹẹdọgbọn lo yẹ ko fara han ṣugbọn ko pada ri anfani kankan lati sọ fawẹli A lasan ninu ere naa.
Ẹ̀yin tí ẹ ti ipasẹ̀ rẹ̀ gba Ọlọrun tí ó jí i dìde kúrò ninu òkú gbọ́, tí ó ṣe é lógo, kí igbagbọ ati ìrètí yín lè wà ninu Ọlọrun.
Ta ni ìmọ́lẹ̀ rẹ̀ kò tàn sí?
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ìtàn ọba Yorùbá tí wọn yẹgi fún torí ó jí ọmọ gbé ṣe ètùtù Ọdẹ ìbílẹ̀ ní Okeho pa adigunjalè mẹ́rin tó fọ́ báńkì, aráàlú dáná ṣun wọ́n Akẹ́kọ̀ọ́ Babcock tí wọn bá lòpọ̀ nínú fídíò rí ẹ̀kọ́ ọ̀fẹ́ ní fásitì òkè òkun Aláwàdà ni ọmọ mi láti kékeré, kò ṣẹ̀ṣẹ̀ máa gbé mi mọ́ra- ìyá ‘Mummy calm down’ (Toluige Olokoobi Babalola) Wo ìyàtọ̀ tó wà láàrin Bíbélì Yorùbá tí Kumuyi kọ sí èyí tó wà ńlẹ̀ Ìkúnlẹ̀ abiyamọ, ìkókó mẹ́jọ kú nílé ìwòsàn lálẹ́ ọjọ́ kàn Dayo Amusa gbarata lórí bí agbófinró ṣe ń pa ọ̀dọ́ láì nídìí Láti ìgbà tí ìrun àílà bá ti to, titi di ìgbà tí òòrùn bá wọ, ni wọn yoo maa gun oke Arafa, láti ṣe ọkan lára àwọn koko iṣẹ hajj naa.
Wọn fi idi ọrọ mulẹ wi pe lẹhin wakati diẹ ni Ajanaku pada si ile rẹ ni agbegbe naa.
Fun apẹẹrẹ, lọdun 2011, gbogbo oṣiṣẹ ijọba to n gba ju ẹgbẹrun mejidinlogun Naira lọ gba ẹkunwo ẹẹdẹgbẹrun Naira pere.
Abiṣai, arakunrin Joabu, ni olórí àwọn ọgbọ̀n ọ̀gágun.
Olootu agba iwe iroyin Newswatch jẹ ọkan lara awọn oniroyin ti o dantọ ni Naijiria ki ọlọjọ to de.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Cancer: Àṣe ara mi ni iso ti n run gbogbo bí mo ṣe n ṣèrànwọ́ lórí jẹjẹrẹ O ni lasiko ibalopọ, ibalopọ dabi ere idaraya ti yoo mu ki ara eeyan ji pepe.
Ọjọ kinni oṣu kẹsan an ọdun 2020 yii ni ijọba orilẹede Vanuata n gbero lati ṣi ibode rẹ pada.
OLUWA ní,“Nítorí pé àwọn obinrin Jerusalẹmu jẹ́ onigbeeraga,bí wọn bá ń rìn, wọn á gbé ọrùn sókè gangan;wọn á máa ṣẹ́jú bí wọn tí ń yan lọ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Coronavirus: Fífi nkan bó ìmu nìkan kò le dènà kíkó coronavirus Ni bayii, eeyan mọkanlelaadọta lo ti lugbadi arun covid-19 ni Naijiria ninu eyi ti ẹnikan ti di oloogbe, ti awọn meji si ti kuro nile iwosan lẹyin ti wọn ri iwosan.
Lẹ́yìn náà, ní ìsàlẹ̀, láti Janoa, lọ sí Atarotu ati Naara.
À kò gba owó kankan lọ́wọ́ àwọn ẹgbẹ́ agbésùmọ̀mí ISWAP- MURIC Ẹlẹ́wọ̀n 44 kú sọ́gbà ẹ̀wọ̀n nítorí ooru tó mú púpọ̀ Àwọn ǹkan tí ó yẹ kí o mọ̀ nípa 'Sharia Law' ní Nàìjíríà Joe Biden kéde Kamala Harris, obìnrin aláwọ̀ dúdú gẹ́gẹ́ bí igbákejì rẹ̀ nínú ìdíje sípò Ààrẹ Amẹrika Àmọ̀tẹ́kùn gbéra!
Sugbọn asa Kengbe lilu yii lo wọpọ nilu Ilọrin lasiko igbeyawo, idaraya fun ọba ati nibi orisirisi ayẹyẹ miran.
 johnson je riranti daada fun ikowe re to je iwe itan-aeoko , ewi , ikojopo awon itan ibile .
Amọ awọn miran tako ọrọ rẹ to sọ nipa yiyan akowe obinrin Awọn ẹlomiran tilẹ mu amọran tiwọn to yatọ si ti Pasito Adeboye wa lọna ati dẹkun ifẹkufẹ oju Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Eto yii lo n se akojọpọ awọn oniruuru ade isẹmbaye ti awọn ọba ilu Oṣogbo, taa mọ si Ataoja, ti lo kọja, ti wọn yoo si lo wọn fun iwure lati gba ibukun.
"Nkan tí a mọ̀ nìyíì Mo ti kúrò ní ààfin Oyo, kí ìròyìn tó ò jáde pé èmi àti Wasiu Ayinde n fẹ́ ara wa - Olori Badirat ""Bi mo ṣe sọ tẹlẹ, ọpọlọpọ nkan to n ṣẹlẹ ko jẹ kii eeyan o gbagbọ pe ẹnikẹni wa ni iṣakoso."
 Ẹ le fun wa ni imọran miiran ti a le fi
Abadofin ọhun tilẹ pe fun ki wọn da ajọ kan silẹ lati maa mojuto o.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Falz: Èmi kò ní sàtúnse fídíò tó sọ àsìse Nàíjíríà náà Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Falz: Èmi kò ní sàtúnse fídíò tó sọ àsìse Nàíjíríà náà 6 Òkùdu 2018 Adarí àjọ ti ó ń rí sí ẹ̀tọ́ àwọn Musulumi (MURIC), Ọ̀jọ̀gbọn Ishaq Akintola, ti ṣalayé yéké-yéké nípa ohun tí ó fa gbèdéke ọjọ́ méje, ti àjọ́ náà fun olórin taka-sufe ọmọ Naijiria ni, Folarin Falana, tí gbogbo èèyàn mọ̀ sí Falz, lórí fìdíò rẹ̀, ‘This is Nigeria’, tí gbogbó ọmọ Naijíria ń sọ̀rọ̀ nipa.
Ẹ máa yọ̀ ninu OLUWA, ẹ̀yin olódodo,kí ẹ sì máa yin orúkọ mímọ́ rẹ̀.
O sọ eyi nigba to n ba awọn akọroyin s'ọrọ ni ipinlẹ Plateau lori eto lati kuro ni ọnọ igbohunsafẹfẹ ti atijọ wa si ti igbalode (DSO).
Irúgbìn díbàjẹ́ sinu ebè,àwọn ilé ìṣúra ti di ahoro,àwọn àká ti wó lulẹ̀,nítorí kò sí ọkà láti kó sinu wọn mọ́.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìpínlẹ̀ Kaduna tún ti dá olùkọ́ 4,562 tuntun dúró 19 Ìgbé 2018 Oríṣun àwòrán, Twitter Àkọlé àwòrán, Gómínà Nasir El-Rufai dá ogunlọ́gọ́ àwọn olùkọ́ ìpínlẹ̀ náà dúro l'ọdún tó kọjá Ìjọba Ìpínlẹ̀ Kaduna tún ti dá àwọn olùkọ́ ẹgbẹ̀rún mẹ́rin àti ọ̀tàlélẹ́ẹ̀dẹ́gbẹ̀ta lé méjì (4,562) dúró nínú àwọn ti wọ́n ṣẹ̀ṣẹ̀ gbà lẹ́hìn tí wọ́n ní kí olùkọ́ ẹgbẹ̀rún méjìlẹ́lógún (22,000) lọ rọ́kún nílé ní bíi oṣù márùń sẹ́hìn.
" Oríṣun àwòrán, Alaafin Oba Adeyemi III Alawẹ ni se ni Alaafin kan n feti si gbọyisọyi kiri lai wadi otitọ ko to maa naka aleebu si gomina Fayemi, to si tun kọ lati darukọ awọn ọba to to ni o kere ni ipo, o si n beere pe awọn ọba wo lo n baa wi gan?
Ẹ má ṣe hùwà bí ẹni tí kò gbọ́n, ṣugbọn ẹ hùwà bí ọlọ́gbọ́n.
Jesu ní, “Ọkunrin kan ní ọmọ meji.
'Kíni OPC ń fi POS ṣe ní ilé òòṣà?
Bí a ti dé ọ̀hún ni a tún rán oníṣẹ́ kan wọ ààfin lọ.
Ipade ilu naa, ti wọn pe akọle ti saa yii ni “Nigbaradi fun Eto Idibo ti yoo waye ni irọwọ Irosẹ, ti yoo si jẹ Ojulowo” ti ẹkun idibo Koṣofẹ keji yii ni ọpọ awọn alẹnulọrọ ati awọn oleṣelu lẹkun naa peju pesẹ si.
Ọwọ ọlọpaa orilẹ-ede Uganda tẹ Sam Little, ati ọmọ orilẹ-ede Uganda meji: Sauel Albert, ati Samula Tadeop ni Ọjọbọ niluu Fort Portal lorilẹ-ede naa.
O si jẹ ọkan lara awọn adẹrinpoṣonu ninu ọpọlọpọ ere.
Saraki: Ilé ẹjọ́ ní yóò yanjú ọ̀rọ̀ lórí ilé mí tí Ìjọba gbẹ̀sẹ̀ lé
K Odukoya 'ń gun orí òkè àdúrà nítorí COVID-19'-Wò báwọn èèyàn fi wò wọ́n Iléeṣẹ́ aṣọ́bodè yarí, kò gba ìrẹsì tó bàjẹ́ padà lọ́wọ́ Ṣeyi Makinde Ọwọ́ tẹ̀ èèyàn 65 tó tàpá sí òfin gbéléẹ níbi ayaẹyẹ ọjọ́ ìbí Èèyàn 196 míràn tún ti ní àrùn Coronavirus ní Nàíjírìa Mo ki obinrin to lagbara kulọ lara awọn ti mo mọ ku ọjọ ibi.
 wọ ́ n dúró súú sùù súú káàkiri .
Ìjọba Èkó yóò ṣètò ààbò àti àtúnṣe Abúlé Ẹgba tí iná jó - Igbákejì gómìnà Oríṣun àwòrán, Twitter/drobafemihamzat Igbakeji Gomina ipinlẹ Eko, Obafemi Hamzat ti ṣe abẹwo sawọn adugbo ti o farakasa iṣẹlẹ ijamba ina lagbegbe'Abule Egba ,nilu Eko.
Wọ́n pẹ̀rẹ̀sì í tọ́júu rẹ̀ ìgbà tí wọ́n ṣe àkíyèsí wí pé ọgbẹ́ náà san díẹ̀, wọ́n tún gbéra, wọ́n mù ọ̀nà-àjò wọn pọ̀n Igbà tí wọ́n dé ibi tí a ń pè ní Ìjẹ̀bú-Jẹ̀ṣà lónìí yìí ni ẹ̀jẹ̀ bá tún bẹ̀rẹ̀sí í sàn jáde láti ojú ọgbẹ́ ọkùnrin náà.
INEC: Ẹgbẹ̀rún márùn ún náírà ni ìbò Òǹdó,Edo àti Anambra
Ẹwẹ, kọmiṣọnna eto ilera fun ra rẹ sọ loju opo Twitter rẹ pe o da oun loju pe oun yoo jajabọ lọwọ coronavirus laipẹ.
Àwọn ọmọ ilẹ̀ wa á máa mú ìwúrí báni.
“Ni ekun kookan lorile-ede Uganda, ni won ni aye ti won fi sile fun awon obinrin nile-igbimo asofin”.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ronke Oṣodi: òótọ́ ọ̀rọ̀ máa ń korò gan ni f'áwa èèyàn Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Naira Marley: Ohun tó yẹ kóo mọ̀ nípa rẹ̀ Oríṣun àwòrán, Instagram/@nairamarley Àkọlé àwòrán, Naira Marley Azeez Fashola ti inagijẹ rẹ lori itage n jẹ Naira Marley jẹ olorin Naijiria to ṣẹṣẹ n goke.
Ramaphosa gbe jade , o ni “A ba
  Dokita Maikanti Baru, salaye pe bi o tile
L'Eko awọn eeyan fero wọn han lori ile-isẹ kolekodọti tuntun
Amí ni ó rán wọn wá ṣe, kí wọ́n lè wo gbogbo ìlú wò, kí ó baà lè ṣẹgun wa.
A ti sún ìgbẹ́jọ́ Ganduje, Tambuwal àti Ihedioha sí ọ̀la Wo àwọn ibùdó ìtàn Mánigbàgbé ni Ìbàràpá méjèèje Ìpàdé náà kò sẹ̀yìn bí Ọmọbakùnrin Harry àti ìyàwó rẹ̀, Meghan Markle se ní àwọn fẹ́ fi ipò sílẹ̀ gẹ́gẹ́ bí òkan gbòógì nínú ìdílé ọba.
Ó dá wọn lóhùn pé, “Ẹni tí ó bá ní dàńṣíkí meji, kí ó fún ẹni tí kò ní lọ́kan.
Nítorí náà bí ẹ tilẹ̀ gbin igi dáradára tí ẹ̀ ń bọ ọ́,tí ẹ sì gbin òdòdó àjèjì tí ẹ̀ ń sìn ín;
Ó ṣáná sí àwọn ìtùfù náà, ó sì tú àwọn kọ̀lọ̀kọ̀lọ̀ náà sílẹ̀ ninu oko ọkà àwọn ará Filistia.
Ọrọ ko lee dun lẹnu wa bii ọlọrọ bi wọn ṣe sọ ọ ninu fidio to wa loke yii.
 Iroyi lẹkununrẹrẹ  n bọ laipẹ…Ademola Adepoju.
Nítorí náà nígbà tí a bá ti nà án tán, n óo dá a sílẹ̀.
Niṣe ni awọn eeyan kan n fi ọwọ kan awọn obinrin lọna aitọ nibi iwọde nitori naa ni wọn fi fun wọn ni feere pe ki wọn fi pariwo sita.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ìtàn rèé nípa bí Ogbomoso ṣe pa ọba, yọ nǹkan ọkùnrin rẹ jó kiri ìlú Wo àwọn obìnrin abúlé kan tó dáwó ra ọkọ̀ láti máa gbé aláboyún lọ ilé ìwòsàn Alámì ẹ̀yẹ Scrabble Paul Sodje àti ọ̀rẹ́ rẹ́ kú lásìkò tó fẹ́ lọ́ sanwó ìdóòlà ẹ̀mí àbúrò rẹ̀, tí afurasí darandaran jí gbé Ìjàmbá iná míràn tún wáyé ní pápákọ̀ ojú omi Beirut Ẹ fi dókítà àgùnbánirọ̀ rọ́pò àwọn dókítà tó ń yanṣẹ́ lódì - Ìjọba àpapọ̀ pàṣẹ Afenifere fara ya lórí bí Tinubu ṣe jókòó kí Ooni Háà ilẹ̀ wẹ!
din logun yii Aṣofin Rotimi Abiru ti o n soju fun agbegbe Ṣomolu keji ni jẹ alaga rẹ.
Ṣimei bí Mika, Mika bí Reaaya, Reaaya bí Baali; 
Wo ohun tí ìwọ́de ENDSARS ṣé fáwọn akẹ́kọ̀ọ́ tó fẹ́ ṣèdánwò NECO Oríṣun àwòrán, The guardian nigeria Ajọ idanwo aṣekagba ẹkọ girama lorilẹede Naijiria, NECO ti sun idanwo, rẹ siwaju nitori iwọde awọn ọdọ kaakiri orilẹede Naijiria to n lọ lọwọ.
Manchester United tún wẹ̀wù ìyà fún Chelsea lẹ́ẹ̀kan síi Èèdì rèé o!
Ko si ani ani pe eguna to n joni lọwọ ni iṣoro abo ni lọọlọ yii o si n ru ibinu awọn ara iha ariwa orilẹede yii soke.
 Àwọn ló ń pàsẹ ìlú .
Eliakimu, ọmọ Hilikaya tí ó jẹ́ alákòóso ààfin ati Ṣebina, akọ̀wé ilé ẹjọ́, ati Joa, ọmọ Asafu, akọ̀wé ààfin wá sọ́dọ̀ Hesekaya pẹlu àwọn ti aṣọ wọn tí wọ́n ti fàya láti fi ìbànújẹ́ wọn hàn, wọ́n sì sọ ohun tí Rabuṣake wí fún un.
Oluṣiro agba ni fasiti Oxford, Jason Oke sọ pe ida 99.
dindin owo oko ku, yala oko ofurufu tabi oko oju popo.
Oríṣun àwòrán, @NGRPresident Àkọlé àwòrán, Bill Gates ni ọdun mẹtalelaadọta ni ọpọ ọmọ Naijiria nku Abajade naa ni nitori orilẹede Naijiria ko kọbi ara si idagbasoke ọmọ eniyan ni yoo fa ti iṣẹ yoo fi pọ ni orilẹede naa.
 Ṣùgbọ ́ n ẹ ̀ ka-èdè tí ẹ ̀ yà kọ ̀ ọ ̀ kan ń sọ yàtọ ̀ láti ilú kan sí èkeji .
Ọ̀tẹ́gbẹ̀yẹ: Ọmọ tí a bí lẹ́yìn ọ̀tẹ̀ ìlú.
 Lilo ni oun ko ni ya oun lẹnu ti Eric ba bẹrẹ ere ifẹ pẹlu ẹlomiran lẹyin ti oun kuro lori eto BBNaija 2020, ṣugbọn yoo dun oun."
Dafidi pa gbogbo wọn, lọkunrin ati lobinrin, ó sì kó àwọn aguntan, mààlúù, kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ ati ràkúnmí wọn, ati aṣọ wọn, ó sì pada lọ bá Akiṣi.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Àgbà ni Obasanjo, oun tó ń sọ yé e, ìjọba ni kó tají - Wale oke O fi kun ọrọ rẹ pe, bii ẹgbẹrun lọna irinwo akẹkọọ ni ko lanfani lati tẹsiwaju lẹnu ẹkọ wọn nipinlẹ Ọyọ, nitori ipenija owo.
Ninu kí ẹ tọ́jú igi, kí ó dára, kí èso rẹ̀ sì dára, tabi kí ẹ ba igi jẹ́, kí èso rẹ̀ náà sì bàjẹ́.
Alẹ Ọjọ Ẹti ni ijọba ti afara naa ni ọna mẹjeeji amọ ti wọn si fi alakalẹ lede lori igba ati akoko ti awọn eniyan yoo fi le ma a raaye kọja nibẹ ni ojoojumọ.
Ìjínigbé Kaduna: Àwọn agbébọn jí ènìyàn tó lé ní ọgọ́rin
Ọjọ kejidinlogun, oṣu Kẹwaa, ọdun 2020, ni Chisom dagbere faye.
Aisha Buhari sàtìlẹyìn fáwọn ọ̀dọ́ tó fọnmú lórí ìyànsípò àwọn alátakò sínú ìjọba APC Mà á fún àwọn ọba alayé ní ojúṣe nínú ìjọba mi - Seyi Makinde Buhari yan Kyari ní olùdarí tuntun fún àjọ NNPC Èmi kò mọ obìrin tí DSS mú rí —Aisha Buhari Igba gbogbo ni Festus Adedayo maa n sọrọ lori ayelujara ni eyi ti awọn ololufẹ APC sọ pe o fi n ṣe lodi si ijọba Buhari ni.
“O kò gbọdọ̀ yí ìdájọ́ òdodo tí ó tọ́ sí talaka po nígbà tí ó bá ní ẹjọ́.
Nítorí Ẹlẹ́dàá rẹ ni ọkọ rẹ,OLUWA àwọn ọmọ ogun ni orúkọ rẹ̀.
Yan ẹnìkan, gẹ́gẹ́ bí ọba fún wa, tí yóo máa ṣe alákòóso wa bí àwọn orílẹ̀-èdè yòókù.
Bii ti ẹni to gba eku ida lọwọ rẹ, Pierre Nkurunziza lọdun 1995, Ọgbẹni Ndayishimiye mori bọ lọwọ iku ti wọn o ba pa a nigba ti wọn n pa awọn akẹkọ ẹya Hutu nileewe rẹ ni olu ilu orilẹede naa, Bujumbura.
Nítorí títí di àkókò Johanu gbogbo àwọn wolii ati òfin sọ ohun tí yóo ṣẹlẹ̀.
Bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé mo ti kọ́ kábàámọ̀ pé ìwé náà bà yín lọ́kàn jẹ́ fún ìgbà díẹ̀, 
Awuyewuye ọrọ aṣẹ lọ́rọkunle ti ijọba Naijiria pa fun afdajọ agba Walter Onnoghen ati bi wọn ti ṣe yan adajọ miran dipo rẹ jẹ ọrọ to gbode ni Naijiria toun ti bi idibo ọdun 2019 ti ṣe n sunmọ le.
Ìlú Abúlé Ọjà kìí ṣe ìlú kékére rárá, gbogbo ohun tí ó ń tọ́ka sí ìlú ńlá lówà ní Abúlé Ọjà bí óti lẹ̀ jẹ́ pé Abúle tí ó wà nínu orúkọ yìí lè ṣi èèyàn lọ́nà láti rò pé Abúlé ni ìlú náà yóò jẹ́.
Aarẹ Buhari tun sọ pe ijọba oun yoo gbiyanju lati yọ ọpọ ọmọ Naijiria kuro ninu iṣẹ ati oṣi to n ba ọpọ eeyan finra.
" Àwọn yorùbá tó wà ni "" cuba ' ni wọ ́ n ń pé ní "" lucumi ' ."
Ambode m'òfo nílé ẹjọ́ lóríi pé k'áwọn aṣòfin yéé tojú bọ ọ̀rọ̀ ọkọ̀ bọ́ọ̀sì 820 tó rà Wo bí o ṣe lè se ọbẹ̀ ẹ̀fọ́ yìí àti àwọn oúnjẹ Yorùbá aládùn míràn Ìjọba fi páńpẹ́ ọba mú àwọn àkàndá tó fẹ̀họ́nú hàn ní Eko ''Kazeem ṣèlérí pé oun máa mú mi lọ ìlú òyìnbó k'àwọn SARS tó pá á'' Amọ ko i ti si ẹni to lugbadi aarun naa lorilẹede Naijiria,awọn mọkanla ti wọn ṣe ayẹwo fun ni wọn ri wi pe ko ni aarun naa lara.
Ibrahim Lawal Esq ṣapejuwe ipade itagbangba PDP bi igbesẹ omugọ ti ko mu ọgbọn wa rara.
Alaga ajọ eleto aabo Amọtẹkun nipinlẹ Ọyọ, Ajagunfẹhinti Kunle Togun lo ti kọkọ ti ke gbajare saaju l‘Ọjọbọ pe, awọn Fulani daran-daran ti kii ṣe ọmọ Naijiria, to si dihamọra ogun n wọle si ipinlẹ naa.
Ẹ̀yin olólùfẹ́ mi àti ẹbí ni mo bẹ̀ Toyin Abraham rèé, ọmọ ìpínlẹ̀ Edo tó di àràbà nínú tíátà Yorùbá Kemi Olunloyo dá sí ìjà Toyin Abraham àti Lizzy Anjorin Àwọn olólùfẹ̀ Toyin Abraham ati Liz Anjorin ti gbé ọ̀rọ̀ wọn rù sórí, ẹ wo òjò òkò ọ̀rọ̀ Koda, sinima yii ti di wiwo lawọn ile sinima yika orilẹede yii, ti ọpọ eeyan si ti n woo fun ọgbọn ati idanilaraya.
 Òtọ ̀ ọ ̀ tọ ̀ ni wọ ́ n ṣe iṣẹ ́ tí wọ ́ n gba ògo rẹ ̀ yìí .
EndSars Protest: TB Joshua, Indaboski àtàwọn Wòlíì méjì míràn ti kéde wàhálà ìwọ́de sáájú
Ilé ẹjọ́ kàn-án nípá fún Wòlíì Sọtítóbirẹ̀ kó tó wọ ilé ẹjọ́ Ninu awọn mẹta miran to n baa jẹjọ la ti ri minisita fọrọ abẹle tẹlẹ, Abba Moro ti wọn js n jẹjọ liluni ni jibiti ati titẹ ofin kọngila ọja rira fun ijọba loju mọlẹ.
Ogun abẹle Sri Lanka ni ololufẹ mejeeji ti jọ jagun lodi sira wọn fun ọdun mẹwaa.
Gèlè oriṣiriṣi ló wà̀, a lè lo gèlè aṣọ ìbílẹ̀ bi: aṣọ òfi/òkè, àdìrẹ, tàbi ki á yọ gèlè lára aṣọ.
Kanye West ṣèrànwọ́ $2m fún ẹbí George Floyd, yóò tún rán ọmọ rẹ̀ nílé ìwé Oríṣun àwòrán, others Olorin naa ti ko sọ ohunkohun lori ayelujara lẹyin iwọde to tẹle iku ologbe ọhun tun ṣagbekalẹ owo ile iwe fun Gianna Floyd, to jẹ ọmọ ọdun mẹfa ti Floyd fi saye lọ.
O tesiwaju pe yiyan Gbajabiamila  gege bi abenugan yoo tun je ki eto ijoba
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Mọrèmi: Ọọ̀ni ní láìsi Mọrèmi, kò leè sí ilẹ̀ Yorùbá Bolarinwa ní, yàtọ sí ẹgbọ́n oun, gbogbo àwọn olùgbé ilé náà ni wọn ti ti mọ ìtá, wọn fi ṣẹ́kẹ́sẹkẹ̀ sí ọwọ ẹni tó ń sọ ẹnu ọ̀nà ilé náà, àti pé, ìyá àwọn to jẹ́ aláìlera pẹ̀lú kò ri ọ̀nà wọlé.
Gbogbo nǹkan tí mo pàṣẹ fun yín ni kí ẹ ṣe.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù FEC: Ìgbìmọ tuntun dìde láti sàtúntò ọlọ̀pàá 15 Ògún 2018 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 16 Ògún 2018 Oríṣun àwòrán, Federal Govt/twitter Àkọlé àwòrán, Ìjọba bẹ̀rẹ̀ ìgbésẹ̀ àtúntò ọlọ̀pàá Ìgbmọ tó ń moju to ètò ọrọ̀ ajé ti sàgbé dìde ìgìmọ tẹ̀ẹ́kótó lati mu ojuṣe ilé iṣẹ́ ọlọpàá pín sí ipele.
Ṣugbọn ọpọ ileeṣẹ ifiweranṣe ni ko tii bẹrẹ iṣẹ ni kikun nitori ajakalẹ arun naa.
lorile ede Naijiria yoo kogba wọle, nitori ọpọlọpọ isẹ lo wa niwaju won lati se.
Arsene Wenger ni akọnimọọgba ikọ Arsenal nigba naa.
Àkọlé àwòrán, Awọn kan sọ pe nitori pe Akpabio ti fi ẹgbẹ PDP silẹ Saraki ṣe huwa bẹ si Laipẹ yii ni Godswill Akpabio kuro ninu ẹgbẹ oṣelu Peoples Democratic Party, PDP, to si lọ darapọ mọ ẹgbẹ oṣelu All Progressives Congress, APC.
B Joshua-Angel Gomes Agbẹjọ́rò ni n kò bá jẹ́, tí n kò bá bá bàbá mi ṣe tíátà - Sola Kosoko Toyin pòórá lẹ́yìn tó figbe ta nípa ìfipábálòpọ̀ lójú òpó Twitter - Àwọn ǹkan ti BBC mọ nípa rẹ̀ rèé Ẹ̀kọ́ mẹ́jọ tó yẹ kí ilẹ̀ Afirika kọ́ lára àjàkálẹ̀ aàrùn coronavirus Alaṣẹ ile iṣẹ Executive Jet, Sam Iwuajoku ṣalaye pe Adajọ kan ni wọn ti kọkọ ṣeto irinajo naa fun lọjọ Aiku ki ohun gbogbo to yipada.
Akẹẹkọ obinrin naa fikun fun awọn ọlọpaa wi pe igba akọkọ kọ ni yii ti olukọ naa ti ba oun lọpọ, ati wi pe SS1 ni olukọ naa ti kọkọ ba oun ni ajọsepọ, ti o si tun bere fun ibalopọ ki oun fi le tẹsiwaju lo si ipele miran.
Ẹwẹ, Bulama Bukarti to jẹ akọṣẹmọṣẹ nipa ọrọ abo ilẹ Afirika ni bi wọn ba ko awọn ologun ilẹ okere wọ Naijiria, ko difa fun opin iṣoro abo.
Mo pinu láti dá Iphone tì mo mú padà kí ọlọ́pàá tó mú mi Ẹ gbọ́ Ohun tí Desmond Elliot àti Mojisola Alli-Macaulay sọ lórí ayélujára táwọn ọmọ Nàìjíríà fi ìbínú Àwọn olóṣèlú Nàìjíríà márùn ùn tó sọ̀rọ̀ tí ará ìlú fà ìbínú yọ Gómìnà Sanwo-Olu dẹ okùn ìséde l'Eko, ó gbé ìlànà tuntun jáde Araalu da awọn ohun ini ijọba ti wọn jigbe pada lasiko ifẹhọnuhan EndSars Rogbodiyan bẹ silẹ kaakiri orilẹede Naijiria lẹyin ti awọn ologun pa awọn afẹhọnuhan ni Lekki tollgate ti wọn pẹ fun opin si ikọ ọlọpaa Sars lorilẹede Naijiria.
Awọn alaṣẹ ṣalaye pe ọmọ orilẹ-ede Italy kan to gunlẹ sorilẹede Naijiria lọjọ mẹta sẹyin ti ko aarun naa.
“Ẹ gbọdọ̀ ní ibìkan lẹ́yìn àgọ́ tí ẹ óo máa yàgbẹ́ sí.
 Ìlú yìí wà láàárín Ìkàrẹ ́ àti Ìrùn tó jẹ ́ ààlà àríwá Àkókó àti Èkìtì .
Mo jókòó bẹ́ẹ̀ títí di àkókò ẹbọ àṣáálẹ́.
"Ohun to ṣe pataki fun ijọba ni lati wa awọn ọna gbogbo to ba yẹ, lati fi rii daju pe irora iyanṣẹlodi naa ko pọ lapọju fun araalu.
Bakan naa, minisita oun tunbo fi oye anfaani ti o wa ninu lilo ero igbalode yii ye awon eniyan nipa ilaniloye loore-koore.
Aya Aarẹ, ti olubadamọran agba fun Aarẹ lori ọrọ awọn obinrin, Hajo Sani, ṣoju fun sọ pe, Covid-19 ti da rogbodiyan silẹ kaakiri agbaye eyi to n ṣokunfa oriṣiriṣi ifẹhonuhan ati iwa ipa lawujọ, paapa si awọn obinrin.
“Nkan ti ko le yi pada lorile-ede Naijiria ni ife ere boolu afesegba.
Àwọn ni àwọn tí Mose ati Aaroni kà pẹlu ìrànlọ́wọ́ àwọn olórí mejila tí a yàn láti inú àwọn ẹ̀yà Israẹli.
Nígbà tí àwọn iranṣẹ Saulu dé láti mú Dafidi, Mikali sọ fún wọn pé, “Ara rẹ̀ kò yá.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Babajide Sanwo-Olu: Ìjọba ní Gómìnà Eko kò ní ṣ'àyẹ̀wò covid-19 míì 22 Agẹmo 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 25 Ògún 2020 Oríṣun àwòrán, Twitter/Babajide Sanwo-Olu Kọmiṣọnna eto iroyin nipinlẹ Eko, Gbenga Omotosho ti sọ pe iti ọgẹdẹ ti ko to ohun ti aa yọ ada si ni ọrọ kọmiṣọnna eto ilera, Ọjọgbọn Akin Abayomi to lugbadi coronavirus jẹ fun Gomina Babajide Sanwo-Olu.
Ẹ pada sí ilé yín, ẹ̀yin ọmọ Israẹli.
Ileeṣẹ ọlọpaa Ekiti rọ awọn araalu Iyin-Ekiti pe, ki wọn fi to awọn ọlọpaa leti ti wọn ba kẹfin ẹnikan to ṣeeṣe ko wa lara awọn adigunjale naa.
Ti mejeeji si sọ pe awọn alaga ijọba ibilẹ ti awọn ara ilu dibo yan ni ẹtọ lati pari saa iṣakoso wọn.
Kí o wá na ọwọ́ rẹ kí o ṣe ìwòsàn, ṣe iṣẹ́ abàmì, ati iṣẹ́ ìyanu nípa orúkọ Jesu ọmọ mímọ́ rẹ.
Kastina ni èèyàn mọkanlelọ́gbọ̀n, Abuja ní Ogun, Borno mẹ́tadinlogun, Bauchi mẹẹdódogún, Nasarawa mẹ́rìnlá, Ogun mẹ́tàlá àti Plateau pẹlú èèyàn mẹ́wàá.
Ní ọjọ́ kẹrin, a gbéra, a lọ sí ilé Ọlọrun, a wọn fadaka, wúrà ati àwọn ohun èlò, a sì kó wọn lé Meremoti, alufaa, ọmọ Uraya lọ́wọ́.
5 4965 Orilẹede Benin 44 0.
Mo bá wí fún un pé, ‘Jọ̀wọ́ fún mi lómi mu.
Nigba to n lewaju aba lori rẹ, sẹnatọ Benjamin Uwajumogu ni o se pataki ki ile tete mojuto ọrọ naa ki o to di eyi ti yoo tun ran pupọ ọmọ ilẹ Naijria lọ si oko gbese bii ti awọn to saaju rẹ.
“Nítorí náà, gbogbo wa wà ní Kadeṣi fún ìgbà pípẹ́.
Mummy calm down video: Oreoluwa fẹ́ di 'Ambassador' Oríṣun àwòrán, Oreoluwa Lawal-Babalola Gbajugbaja akọrin ẹmi nni, Yinka Ayefele ti ke gbajare lori ayelujara pe ki awọn eeyan ba oun wa nọmba ipe Oreoluwa.
Ati pe o tun diidi gbera lọ silu Abuja lati lọ jiṣẹ awọn ọdọ fun aarẹ to si gba esi bọ fun wọn.
Bákan nàá nínú ọ̀rọ̀ rẹ̀, ó jọ bi ẹni pé, Lizzy ti n fẹ́ ọkùnrin náà láti bíi ọdún mẹ́rìnlá sẹ́yìn, ṣùgbọ́n wọ́n ṣẹ̀ṣẹ̀ ṣe ètò tó tọ́ àti èyí tó yẹ̀ ni lóri ìrìnàjò ìfẹ́ wọ́n.
Jesu wá mú burẹdi náà, ó dúpẹ́ lọ́wọ́ Ọlọrun, ó bá pín in fún àwọn eniyan tí ó jókòó.
Lorilẹede South Sudan, ida mọkanlelọgọta awọn olugbe ibẹ lo foju wina ebi ti ko lẹgbẹ lọdun to kọja gẹgẹ bi abajade iwadii naa ṣe fi kalẹ.
Ọgbẹni Adamu sọ pe lootọ ni iwọde jẹ ọna ti awọn ara ilu le gba fi ẹhonu han si ijọba, amọ o yẹ ki wọn o ma a ṣe pẹlu iwa ọmọluabi.
O jẹ ohun didan gbiinrinn ti a ṣe latara kẹmika silikọọnu.
ó ní, “Ẹ wo bí Babiloni ti tóbi tó, ìlú tí mo fi ipá ati agbára mi kọ́, tí mo sọ di olú-ìlú fún ògo ati ọlá ńlá mi.
00) Ní ọjà, Olófìn-íntótó bá obìnrin kan pàdé.
Lodun 2007 ni iko South Korea lo ki Pyongyang keyin, eni to je pe ko fi bee gbalejo lati ile okeere lati odun 2011 to ti de ori aleefa.
Koda, aimọye awọn isẹlẹ adaluru lo ti waye, ti ko ba tun pada di ogun abẹle miran, amọ ti Ọba oke ba wa dẹkun rẹ.
Ẹgbẹ amunisin ọhun la gbọ wi pe wọn pẹka de orilẹ-ede Italy, Germany ati Denmark.
 Mo tun fẹ dupẹ lọwọ alaga egbe
OLUWA bi Israẹli pé,“Báwo ni mo ṣe lè dárí ẹ̀ṣẹ̀ jìn ọ́?
Nítorí gbogbo nǹkan tí ìmọ́lẹ̀ bá tàn sí níí máa hàn kedere.
Community Shield: Man City fọ́ Liverpool lẹ́nu bẹ̀rẹ̀ sáà bọ́ọ̀lù tuntun ní Wembley
”Ni bayii, Djokovic ti jawe olubori igba kẹ́tàlélọ́gbọ̀n ninu  ifigagbaga  márùndínlógójì ti o ti gba lapapo lọdun yii.
Àìsan N30,000 owó oṣu f'óṣìṣẹ́ kò ní rọgbọ o- NLC Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ireti Yusuf: Ìsòro àti fẹjọ́ sùn ló ń mú kí ìwà ìfipábánilòpọ̀ gbilẹ̀ si Agbẹnusọ ileeṣẹ NNPC ọhun sọ pe, ikede naa di dandan fun wọn lati ṣe nitori awuyewuye to n lọ kaakiri ilu pe, o sẹeṣe ki awọn eniyan ma ri epo ra jakejado Naijiria, nitori iyanṣẹlodi ti ẹgbẹ oṣiṣẹ fẹ ẹ gun le.
Ṣugbọn ẹni tí ó ń waasu ń bá eniyan sọ̀rọ̀ fún ìdàgbà ti ẹ̀mí, fún ìtùnú, ati ìwúrí.
Bi wọn ṣe ji awọn akẹkọọ naa gbe nipinlẹ Katsina, ti mu ki ọpọ eyan ma a beere ibeere nipa bi Boko Haram ṣe l'agbara to ni Iwọ oorun Ariwa Naijiria, ati boya awọn ọmọ ogun orilẹ-ede naa le bori wọn.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Kolade Johnson: Adájọ́ pàṣẹ kí wọ́n fi ọlọ́pàá tó lọ́wọ́ nínú ikú Kolade Johnson sí àhámọ́ 5 Ìgbé 2019 Inspẹkitọ ọlọpaa ti wọn yọ niṣẹ lori ọrọ arakunrin Kolade Johnson ti wọn yinbọn pa nilu Eko ti foju ba ile ẹjọ.
Ó fún ẹsẹ̀ mi lókun láti sáré bí àgbọ̀nrín,ó sì mú kí n wà ní àìléwu lórí àwọn òkè.
Èmi ni OLUWA Ọlọrun rẹ, tí ó mú ọ jáde wá láti ilẹ̀ Ijipti, láti fi ilẹ̀ Kenaani fún ọ ati láti jẹ́ Ọlọrun rẹ.
Ọlọrun Olodumare yóo bukun ọ, yóo fún ọ ní ọmọ pupọ, yóo sì sọ ọ́ di orílẹ̀-èdè ńlá.
Oga agba ile-ise ipate idokowo agbaye ti o je ti omo orile-ede Germany kan, Martin Marz ti fi igbagbo re han pe, orile-ede Naijiria ni ebun ati di orile-ede kan gboogi lagbaye, ti yoo maa ko ounje lo si ile okere.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù NIN: Ohùn mẹ́ta pàtàkì tó yẹ kí o mọ nípa nọ́mbà ìdánimọ̀ Nàìjíríà 16 Ọ̀wàrà 2019 Oríṣun àwòrán, Google Lẹnu lọọlọ yii, oju opo Twitter ti n sọ putuputu lori ọrọ owo sisan lati gba kaadi idanimọ mi ti ti tẹlẹ ba sọnu tabi ti ọjọ ba pe lori ti tẹlẹ.
Awon omo orile-ede Sierra Leone yoo dibo yan Aare, awon omo ile-igbimo asofin ati awon alaga ijoba ibile lojo-Ru.
Àmọ́ ẹ ríi pé ẹ dáàbò bo ẹ̀mí yín - Ọ̀gá àgbà ọlọ́pàá Wo ojú àwọn òṣèré yìí láì lo Make-up"" orí ìtàgé bó ṣe rí gẹ́lẹ́ Ọpọlọpọ ọdun lo ti fi kopa ninu awọn fiimu to lamilaaka, to si ti gba ami ẹyẹ Oscar, ami ẹyẹ Bafta lẹẹmeji ati Ami ẹyẹ Golden Globe ni ẹẹmẹta."
Ninu ọrọ to sọ, Neo sọ pe oun ti ṣetan lati jaramọ eyikeyi iṣẹ aje to ba yọju.
yàtọ ̀ sí ọba aláké tí a to orúkọ wọn sókè yìí , ọba mẹ ́ rin míìrán tún sì wà ní abẹ ́ òkúta tí wọn ń se olórí ìlú wọn .
Wọ́n sì ti kó oriṣa ìríra wọn kún ilẹ̀ mi.
Alaga PFN, Alufaa Felix Omobude ni ọrọ ẹsun ifipabanilopọ naa ba ni ninujẹ pupọ.
Lẹ́yìn èyí, ó tẹ̀síwájú lọ sí Fásitì ti ìlú Ìbàdàn tó ti kẹ́kọ̀ọ́ gboyè nínú ìmọ̀ ẹ̀kọ́ Tíátà ó sì tún gba oyè gíga Msc.
30 Àti pé ìwọ yíò ṣe é pẹ̀lú gbogbo ìwà ìrẹ̀lẹ̀, níní ìgbẹ́kẹ̀lé nínú mi, láì pẹ̀gàn àwọn apẹ̀gàn.
Ojú alágbe ni wọ́n fi ń wo alága ìdúró- Ayo Oladokun Ọpọ ibi ti mo nifẹ si lati maa lọ, ni n ko lee lọ mọ nitori ko rọrun fun mi lati maa fun ọmọ lọyan nita gbangba tabi loju awsn eeyan miran.
Nkan miran to tun n fa omiyale ni isoro awọn adagun odo dáàmù pẹlu bi ojo arọọrọda se n jẹki awọn adagun odo to n mu ina ijọba wa fun awọn eniyan bii Kainji, Jebba ati Shiroro ru soke.
Bi a ti ṣe jogun ba lọdọ awọn babanla wa, bi ọkunrin ba ri obinrin to wu lọkan, yoo lọ nipasẹ alarina lati kan si awọn obi obinrin naa.
Lisabi Agbongbo Akala rèé, ẹni tó fi ìfẹ́, ìṣọ̀kan àti ìrẹ́pọ̀ gba ilẹ̀ Ẹ̀gbá lọ́wọ́ ìmúnisìn Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 3 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 5 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Ile-ise aare ti so pe aheso oro lasan ni iroyin to n tan kale pe awon ajo agbaye ti n lo ipa won lati so fun aare Muhammadu Buhari  lati yi iipinnu re pada lati dije fun ipo aare lọdun 2019.
Saulu dá a lóhùn pé, “Àwọn eniyan mi ni wọ́n kó wọn lọ́dọ̀ àwọn ará Amaleki.
1984 (Ipele ẹlẹgbẹjẹgbẹ) Bouake Algeria 0-0 Nigeria 23.
kò ní jẹ́ kí n mí,ìbànújẹ́ ni ó fi kún ọkàn mi.
“Nípa èmi nìkan ni àwọn eniyan yóo máa pé,‘Ninu OLUWA ni òdodo ati agbára wà.
Nígbà tí ó sì di òwúrọ̀ ọjọ́ kejì tí a máa kúrò ní ilé náà mo fẹ́rẹ̀ sọkùn nítorí n kò rí nǹkan kan tí ǹ bá fún àwọn ọmọ ilé náà.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ọ̀rọ̀ǹpọ̀tọ̀niyùn, Aláàfin obìnrin àkọ́kọ́ rèé, tó ní nǹkan ọkùnrin Baṣọ̀run Gáà, tó yan ọba mẹ́rin, pa ọba mẹ́rin àmọ́ ọba karùn-ún ló pa á Ọbasanjọ sọ àsírí sàgbàdèwe rẹ̀ Jesu Oyingbo rèé, pásítọ̀ tó láṣẹ ìbálòpọ̀ lóri ọmọ ìjọ obìnrin Igbó mímu lè ṣe kóríyá, kò lé fi kún orín ẹnu òṣèré - 9ice Ìtàn tó wà nídi òwe ‘Sebótimọ Ẹlẹ́wà Sàpọ́n’ Ọba Adesoji Aderemi, Ọọ̀ni Ifẹ̀ tó gba ipò ọba mọ́ tòṣèlú Bi o tilẹ jẹ pe Isho Pepper ati meji ninu awọn iyawo marun-un to n ba ṣe ere tiata ti jade laye, sibẹ o yẹ ki awọn ọdọ iwoyi mọ nípa igbe aye ati iku akọni oṣere tiata naa, to fi mọ ipa to ko si idagbasoke iṣẹ tiata nigba aye rẹ.
Oríṣun àwòrán, Olasunkanmi Ogunmuko Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Lere Ọlayinka: Ayo Fayose sí wà ní gbaga àwọn EFCC Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Iléẹ́jọ́ gbégi lé owó Ayodele Fayose Ninu ijọba Buhari lawọn ole wa — Fayose Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Ta ló dà bíi Ọlọ́run Fayoṣe' lorin tó ń jáde nílé ẹjọ́ Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Oríṣun àwòrán, JAMB/FACEBOOK Àkọlé àwòrán, Ẹdinwo fọọmu idanwo Idanwo NECO ti wọn n gba fọọmu rẹ tẹlẹ ni ẹgbẹrun mẹwaa aadọta din ni irinwo naira(11,350) yoo di ẹgbẹrun mẹwaa din aadọjọ naira(9,850).
Lootọọ Tinubu ko tii fi ero rẹ han lori ikọ Amọtẹkun ti awọn gomina mẹfẹẹfa ilẹ Yoruba ṣe ifilọlẹ rẹ lọjọ kẹsan oṣu yii niluu Ibadan.
22 Bélú 2020 Fídíò, Akomolede ati Aṣa lori BBC:Wo ìrúfẹ́ ìgbeyàwó méje tó wà nílẹ̀ Yorùbá àti ojúṣe Alárinà10 Bélú 2020 Fídíò, Erelu Elemure: Ìyá mi rò pé mi ò lè tibi kíkọrin bíi bàbá mi là21 Bélú 2020 Fídíò, Akomolede Yoruba: Kí ni ìdí tí aṣọ fi máa ń pọ̀ lára Egúngún ju Orò lọ́?
Ìbọn, àfẹ́fẹ́ atajú àti katakata ní àwọn ológun fi lé àwọn olùgbé Tarkwa Bay ní erékùṣù Eko Oríṣun àwòrán, @justempower Iroyin kan to gba ori ayelujara kan salaye pe awọn ọmọ ologun ti n fi tipa le awọn eeyan to n gbe ni adugbo Tarkwa Bay nilu Eko.
"Ẹ wá dánrawò níbí pẹ̀lú Àpólà Ọ̀rọ̀ Orúkọ, ""Noun Phrase"" Ẹ̀yin tí ẹ kò gbọ́ Yorùbá, ẹ ṣúnmọ́ bí láti kọ́ lítíréṣọ̀ èdè Yorùbá lórí BBC Olukọ wa salaye lori ilana sise Ajọ, Aaro ati Ọwẹ lati fi ran ara wa lọwọ ati iyatọ to wa laarin wọn."
Ajinde, akoko ti awon onigbagbo n sami iku ati ajinde Jesu, duro fun isegun lori, iku ati iwa ese gbogbo.
Ó sọ fún mi pé, “Ọmọ eniyan, dìde dúró, mo fẹ́ bá ọ sọ̀rọ̀.
Fatai Akinbade ninu iwe to kọ lati fi ẹgbẹ oṣelu PDP silẹ ṣalaye pe abajade esi idibo abẹnu naa ninu eyi ti o ti ni ibo mejilelaadọta lo fa oun si irin lati fi ẹgbẹ oṣelu naa silẹ.
Ohun ayọ ati idunnu lo maa n jẹ ti idile kan ba bi ibeji, ti gbogbo ẹbi yoo si maa du wọn gbe lọtun losi.
Nipa oludari Ileeṣẹ Foyungbowo yii Arabinrin Funmi sọ fun BBC Yoruba wipe ninu oṣu keji ọdun 2020 ni awọn ti gbọ finrin pe ileeṣẹ foyungbowo kan wa nipinlẹ Ogun ti Ọlọpaa si lọ.
"O fi fọnran awọn arinrinajo to n sa kuro nibi ọkọ to n jona sita to si kọ akọle pe ""ẹyin ara, alafia ni mo wa o ati ara pipe""."
Ọmọ onílẹ̀ wọ gàù, ó kó sí gbaga ọlọ́pàá Olùdíje ààrẹ bíi ọgọ́ta tako Atiku lórí ọ̀rọ̀ INEC Wo àwòrán ńkan tó ń ṣẹlẹ̀ ní ìpádé ìran Yorùbá ní Ibadan báyìí Àǹfàní wà láti fí ìwé ìrìnnà ránṣẹ́ ṣùgbọ́n àwọn èèyàn kò lòó ni -NIS Amọ, lẹyin igba to ri ara rẹ lori fonran to n sọ adugbo, lo wa jẹwọ wi pe lootọ ni oun gun ọga oun pa, lẹyin ti oun ji owo rẹ.
àwọn oriṣa yóo sì pòórá patapata.
Oríṣun àwòrán, LASEMA Ìbúgbàmù gbogbo ìgbà nílù ú Èkó, kí ló ń ṣokùnfà rẹ̀?
Nigba ti ajo to n ri si oko oju omi nla (Nigeria
Iroyin yi n jade lẹyin ti agbẹnusọ ọlọpaa ni Naijiria, Frank Mba ni ko si oun kankan to ṣe Ogah ati wi pe, ṣe ni o funra rẹ wa ọkọ rẹ wa si agọ ọlọpaa Nyanya ki o to gbẹmi mi.
Rárá o, yóo gbọ́ ọ̀rọ̀ ẹnu mi.
Gbogbo ibukun wọnyi ni yóo mọ́ ọ lórí, tí yóo sì ṣẹ sí ọ lára, bí o bá gbọ́ ti OLUWA Ọlọrun rẹ.
 Ti o si fi idi alatako re Samura Kamara re mi ninu eto idibo naa.
Ki awon to ba si tapa si ofin yii maa san ẹ̀gbẹ̀rún márùndínlọ́gọ́rin
’ Wọn yóo dá ọ lóhùn pé, ‘Ṣé a kò mọ̀ pé gbogbo ìkòkò ni a óo rọ ọtí waini kún ni?
Adultery/Adeboye: Agbẹjọró ní ìjìyà wà lábẹ́ òfin Naijiria fún pànságà nínú ìgbéyàwó
Dìbò fún un níbí Napoli Vs Arsenal: Àwọn olólùfẹ́ Arsenal ń gara pẹ̀lú àṣeyọrí Europa Ni ti Iheanacho, o ti kopa ninu idije mejidinlọgbọn ni saa yii fun Leicester, o si gba bọọlu sinu awọn lẹẹkan ṣoṣo.
O ni iyawo Gomina Kwara to ti kọ́kọ́ ṣe adehun iranlọwọ fun oun ti mu ileri naa ṣe bayii.
Amọ kaka kewe agbọn dẹ lori isẹlẹ naa, n se lo tun n le koko sii, nitori bi ilẹ ọjọ Ẹti se mọ, lawọn ọdọ ya bo oju popo nigba ti ọkan lara wọn ni oun da sọja kan, to wa lẹnu iloro awọn ologun mọ, gẹgẹ bii ọkan lara awọn to wa se ikọlu ni oru mọju.
Maaka ọmọ Absalomu ni ìyá rẹ̀.
Ẹwẹ, oṣu kejila ọdun 2019 ni Makinde yan Taye Currency gẹgẹ bi oludamọran rẹ lori ọrọ aṣa ati irinajo igbafẹ nipinlẹ Oyo.
Agbẹjọro agba yii fi igba kan jẹ minisita feto ẹkọ ni saa iṣejọba alagbada akọkọ, ti o si tun jẹ Minisita feto idajọ ni saa iṣejọba ẹlẹẹkeji ni Naijiria.
Ẹ̀yin oríadé, tẹ bá fẹ́ mọ ìtàn Yorùbá, ẹ lọ kọ́ lọ́dọ̀ Alaafin - Oluwo Èèrà kò gbọdọ̀ rin Mattew Kukah ní Sokoto, ẹ má halẹ̀ mọ - Ìjọba àpapọ̀ Covid-19 pa Ọlọ́lá Akin Olugbade, ẹ wo dúkìá jaburata tó fisílẹ̀ Ọ̀dọ́ Bauchi ṣe àríyá ìbálòpọ lẹ́yìn tí àpèjẹ oníhòòhò forí ṣánpọn ní Kano Wọn ni gbogbo wọn fi ọwọ si wi pe ki awọn ileewe ṣi pada kaakiri Naijiria.
" 'Coronavirus ló mú mi fẹ́ ọkọ mi tí a sì ṣèyàwó lóríi ‘Zoom’ Nínúu kẹ́ẹ kọ̀wé fipò sílẹ̀ tàbí kí ẹ gba ìdádúró, ẹ mú ọ̀kan - Ilé aṣòfin sí àwọn ọ̀gá àgbà ológun Wo bí ètò ìsìnkú Isa Funtua ṣe wáyé ní ìlú Abuja Alaafin Oyo kò dàgbà jù fún mi, ohun tó wù mí ní mo ṣe pẹ̀lú ayé mi- Olori Aanu Gomina ọhun ṣalaye pe ifọwọsowọpọ nikan lo lee mu itẹsiwaju ba ẹgbẹ oṣelu APC ati ipinlẹ Ondo, nitori naa ni o ṣe gbe igbesẹ ọhun, ki alaafia lee jọba.
Wo òtítọ́ nípa oúnjẹ Nódùùlù táwọn ọmọde ma ń jẹ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fọ́nrán ohùn, Alaafin Ọyọ: Asiri agbara bibi ibeji lọpọ igba Gẹgẹ bii ọrọ kan ti Oludari eto iroyin ati ipolongo ni Ile Oodua tii ṣe aafin Ọọni ti Ilẹ ifẹ, sọ 'awọn alagbeda ni wọn ti lu omidan naa ni jibiti pẹlu orukọ Kabiyesi' ati pe 'ẹsun ti ko lẹsẹ n lẹ ni eyi jẹ.
Ikede irinajo ọfẹ lori reluwe ni Naijiria lẹnu igba ti ijọba n gbiyanju lati sọ ka irina yi ji pada kii 'se tuntun.
Ojo to ṣọṣẹ si awọn ile to le ni aadọta naa lo tún ṣekú pa ọmọbìnrin kan ti ko si ẹni ti o le sọ ibi tí ọmọbìnrin náà ń lọ tàbí ibi tí ó ti ń bọ̀.
Bí Bádérù kìí bá ṣe olè, ó yẹ ní ẹni tí à bá máa pè ní “ẹni ayé yẹ”.
Wí fún àwọn tí wọn ń kun odi náà ní ọ̀dà pé, òjò ńlá ń bọ̀, yìnyín ńlá yóo bọ́, ìjì líle yóo jà.
Naijiria gbe ile-ẹkọ giga okeere lọ ile-ẹjọ Ọ̀gá ọlọ́pàá Adamu Pàṣẹ́ iṣẹ́ àkànṣe nílẹ̀ Yorùbá Ijọba Eko din owo-ori ilẹ ati ile ku Ebí àwọn òkú ya bo ile ìwòsan lati wá òkú wọn Akoroyin BBC ni ọpọlọpọ wakati ni awọn oṣiṣẹ ajọ to n mojuto iṣẹlẹ pajawiri àti awọn ara ilu fi ṣiṣẹ lati doola ẹmi awọn to ri sinu ile to da wo naa.
”Batiṣeba bá bi í pé, “Kí ni nǹkan náà?
Ile ẹjọ naa da ẹjo ọhun lasiko ti wọn n fi ọwọ osi da ẹjọ ti sẹnetọ Rashidi Ladoja pe lati sọ wi pe gomina Ajimobi ko lasẹ lati yan ọba ni ipinlẹ Ọyọ, nu.
O Ọshin gba ki ẹni ti wọn fi ẹsun kan an wa ni ọgba ẹwọn fun bi oṣu kan, lati le faaye gba iwadi to munadoko.
O kú ni ẹni ọdun méjidinlọgbọ̀n, lọdun 2009.
Gomina Sanwo-Olu tun rọ araalu ta kete sáwọn iroyin eke to le da omi alaafia ipinlẹ naa ru.
Ikede yii waye leyin ipade alati-lekun –mori ti awon adari orile ede se, ni Lome, lorile ede Togo.
Iṣẹlẹ na waye leyin ikọlu ti ileeṣẹ ọmọ ogun ṣe si awọn oluwọde EndSARS ni Lekki Toll Gate.
Ninu atẹjade kan ti ileeṣẹ ọrs abẹle fi sita, ijọba ipinlẹ Ọṣun rọ awọn ẹlẹsin iṣẹṣe lati ṣe ọdun wọn naa ni pẹlẹ-putu ki wọn si ṣe iwure fun ijọba ki ohun gbogbo lee lọ nirọwọ rọsẹ, ki eku lee ke bi eku, ki ẹyẹ si maa ke bi ẹyẹ.
Eyi yoo fihan pe ọwọ rẹ mọ.
'Àwa ọmọ Nàìjíríà tó farapa fẹ́ wálé láti Lebanon, ìjọba kó wa pamọ́' Ọlọ́run nìkan ló mọ bí ìrìnàjò ìfẹ́ ẹ̀dá á ṣe rí láyé, ọ̀dọ́ Aláàfin ní orí gbémí yà sí, ó sì tẹ́milọ́rùn- Olorì Aanu Èèyàn 334 ló gbàwòsàn lọ́wọ́ Covid-19 l'Ọjọru, 453 míì tún lùgbàdì rẹ̀- NCDC David ni tirẹ n jẹjọ ẹsun aibikitita to fa ijamba si ohun ini ati eniyan.
Ọdun marundinlọgọta ni aarẹ Nkurunziza ko to jade laye.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Abiola Ajimobi: Iku Ajimọbi jẹ́ ǹkan ìjayà nítori kò só sí ẹnìkan tó ń reti irúẹ̀ lásìkò yii 25 Òkùdu 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 28 Òkùdu 2020 Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Abiola Ajimobi: Àwọn aṣòfin Naijiria ṣọ̀rọ̀ ìwúrí nípa Ajimobi Ṣẹnetọ to ṣoju aringbungbun Ọyọ, Oyo Central Senatorial District"", Teslim Folarin lo ko awọn akẹgbẹ rẹ marun un mii ṣodi lati lọ ba wọn kẹdun nile gomina tẹlẹri nipinlẹ Ọyọ, Ṣẹnetọ Abiọla Ajimọbi to di oloogbe."
Lagos Building Collapse: Ìjọba ìpínlẹ̀ Eko gbé ìgbìmọ̀ olùwádìí kalẹ̀ Kínni ó ń fa ilé wíwó?
, ni ọkọ ayọkẹlẹ pa awon omo egbe Boys Brigade
Iwe aṣẹ irina ọmọ ileewe ni mo gba.
 gẹ ́ gẹ ́ bí olùwá-Ìbẹ ̀ rù àti abọrẹ ̀ obìnein Òjòwú pẹ ̀ lú olóyè ràsákì oṣímodi , gbogbo wọn lápapọ ̀ gba ilé-ifẹ ̀ kọjá láti forí balẹ ̀ fún odùduwà , ṣìwájú kí wòn tó kúrò nílé-ifẹ ̀ , olú-Ìwà fi ọ ̀ kan lára àwọn ọmọ rẹ ̀ gborowo fún odùduwà gẹ ́ gẹ ́ bì ìyàwó tí ó sì bí ọmọ mẹ ́ ta fun .
Kí Ọlọrun alaafia kí ó wà pẹlu gbogbo yín.
Oòrùn kò ní pa wọ́n mọ́, ooru kankan kò sì ní mú wọn mọ́.
Ṣugbọn à ń sọ̀rọ̀ ọgbọ́n Ọlọrun, ohun àṣírí tí ó ti wà ní ìpamọ́, tí Ọlọrun ti ṣe ètò sílẹ̀ láti ìṣẹ̀dálẹ̀ ayé fún ògo wa.
Yatọ si pe ọpọ obinrin ni o n jẹ iya lilu lọwọ ọkọ, iwa ipa ninu idile kọja ki ọkọ o gbe ọwọ soke lu iyawo rẹ.
Ninu idahun rẹ, Ọgbẹni Biden ṣeleri lati maa fi eyi sọkan ninu iṣesi rẹ sawọn eniyan.
A ni ọpọlọpọ eeyan lati fi orukọ wọn silẹ, nitori naa, fun gbogbo ẹyin ti ẹ n gbọ, o san ki ẹ tete kara bọ ọ ko to pẹ.
” Jakọbu náà bá búra ní orúkọ Ọlọrun tí Isaaki baba rẹ̀ ń sìn tìbẹ̀rùtìbẹ̀rù.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ibadan Accident: Èèyàn méjì kú, ẹnìkan wà nílé ìwòsàn Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Itaniji: Oluwo sọ ìtàn bí Orunmila ṣe jìyà nílùú Iwo àti ayọ̀ tó gbẹ̀yìn rẹ̀ torí sùúrù Sugbọn laarin awọn obinrin, wahala yii maa n tọ ara wọn ja ni, ti yoo si wọ wọn de ori ẹsẹ wọn.
Wọ́n tún kó ọgọta eniyan ninu àwọn ará ìlú tí wọn rí láàrin ìgboro.
Ó dá wọn lóhùn pé, “Kí ló dé tí ẹ fi ń wá mi kiri?
Àwọn ará Mikimaṣi jẹ́ mejilelọgọfa (122).
Ẹ̀kán omi tútù yóò kán sára ìkókó.
Ile ẹjọ naa ni awọn ajijangbara to n ja fun ominira agbegbe to n sọ ede Gẹẹsi nilẹ Cameroon, ko tẹlẹ ofin ilẹ naa.
Okùn onípọn mẹta kò lè ṣe é já bọ̀rọ̀.
Shittu ni ko si dandan ninu agunbanirọ ki eeyan to wulo fun awujọ.
Ijinigbe lawọn oju popo Naijiria ti wa peleke si lẹnu ọjọ mẹta yi ti ọpọ si ti padanu ẹmi wọn lọwọ awọn alaburu ẹda ajinigbepawo Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Laipẹ yi ni Gomina ipinlẹ Ebonyi, David Umahi da họwuhọwu silẹ pẹlu bo ti ṣe fi ẹgbẹ PDP silẹ lati lọ darapọ mọ ẹgbẹ oṣelu APC to wa lori oye.
Lati nkan bi ọmọ ọdun mẹrin lẹyin ti baba rẹ ku ni iya Buhari ti n tọ ọ titi ti o fi dagba.
Kọmisọnna fun eto ilera nipinlẹ Eko, Ọjọgbọn Akin Abayomi lo sọ ọrọ yii lasiko to n ba awọn akọroyin sọrọ nipinlẹ Eko.
Igbeṣẹ yii lo waye lẹyin ti pasitọ ọhun sọ pe nẹtiwọọki 5G lo ṣokunfa ajakalẹ arun Coronavirus.
Ìgbà tó yá ó kúkú wá dákẹ́ pátápátá.
Oore-ọ̀fẹ́ ni a fi gbà yín là.
Benue ní ìjọba ṣẹ̀ṣẹ̀ gbé ìgbésẹ̀ tó yẹ ni Ogbẹ́ni Tever Akase, tó jẹ́ agbẹnusọ ìpínlẹ̀ Benue, ba BBC Yoruba sọ̀rọ̀ pé ohun tó kù ni kí ìjọba àpapọ̀ pàṣẹ fún àwọn òṣìṣẹ́ elétò ààbò pé kí wọ́n fi òfin náà múlẹ̀ bí ó ti yẹ káàkiri.
pe  “Awọn oludije fun ipo gomina  jẹ mẹ́rìndínlọ́gbọ̀n .
 olukotan ni dan fogelman , ti adari si je chris koch .
Níbẹ̀, a fi tipátipá so ọkọ̀ kékeré tí ó wà lára ọkọ̀ ńlá wa, kí ó má baà fọ́.
"O ni ""irọ lati ọrun apaadi ni ẹsun naa""."
Ọkọ̀ agbépo tó da epo nù fa súnkẹrẹ-fàkẹrẹ lòpópónà márosẹ̀ Eko sí Ibadan Ẹ ronúpìwàdà lásíkò ọdún, àti àwọn ìkíni mìrán tó jẹ yọ fún Kérésì Èyí ni ìdí tí Bàbá Kérésì fi máa n wọ aṣọ pupa àti funfun nígbà gbogbo Funke Akindele, Toyin Abraham, Bimbo Oshin ṣe Kérésìmesì lọ́nà àrà Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Mo n wa'yawo - Falz Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Saaju asiko yii, ohun oyinbo lo ma n juwe ọna fawọn ọmọ Naijiria lori ẹrọ naa ti a si maa mu inira ba awọn ti ko ba gbo ohun ti oyinbo n sọ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ondo: Dejí sun ọmọ méje àtagbalagba meji mọ́lé nítorí pé ó ń bínú Lati bi ọgbọn ọdun bayii ni wọn ti ri i pe siga mimu ko dara run ilera.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Tramadol tó ń polówó ikú tantan-tan NDLEA gbéṣèlé tọ́ọ̀nù mẹ́rìn oogun Tramadol Ijọba àpapọ̀ fòfin de oògùn ikọ́ olómi codeine Ṣugbọn, bawo ni iṣẹlẹ naa gan an ṣe waye?
Eniyan meji padanu emi won ninu ikolu ti o waye ni mosalasi lasiko adura lorile-ede South Africa.
Àríyànjiyàn kan nbẹ nínú ìyàtọ̀ tó wà nínú ìtàn yìí.
Bákan náà ni àwọn ẹlòmíràn dàbí irúgbìn tí a fún sórí òkúta, nígbà tí wọn bá gbọ́ ọ̀rọ̀ náà, wọn á fi inú dídùn gbà á.
Sanusi wa dupe lọwọ ijọba lori bi wọn se yọwọ iranwọ kuro lori epo, o ni nkan to tọ lati ṣe ni, nitori pe, o ti pẹ to yẹ ki ijọba ti ṣe tori bi eto ọrọ aje ṣe ri.
Iròyìn tó tó wa léti ni pé, gbájúgbajà òṣèré náà ń pinu láti tún gbé atunṣe eré míràn jáde lára ọ̀kan lárá èyí to ṣe tẹ́lẹ to fi di ìlúmọ̀ọ́ká.
Ọpọ eniyan lo si ti n tẹle ofin naa, ṣugbọn ti ọna ti wọn n gba lo ibomu naa kii ṣe ọna to tọ.
Akpabio ni ida ọgọta iṣẹ akanṣe ajọ NDDC ni o jẹ pe awọn ọmọ ile igbimọ aṣofin ni wọn gbe e fun.
Ọrẹ awakọ ofurufu jagun to padanu ẹmi rẹ ninu ijamba niluu Kaduna lo sọ bẹẹ nipa ọmọ ọdun mẹrinlelogun to di oloogbe.
Kíyè sí púpọ̀ nínú àwọn olówó, kìí ṣe gbogbo wọn, ṣùgbọ́n nígbà tí púpọ̀ nínú wọn bá ti di olówó tán àtijẹun sí ẹnu ara wọn  a di nǹkan, wọn a bẹ̀rẹ̀ sí hùwà bí ẹni tí ènìyyàn ṣẹ́ èpè fún, wọn a máa wa gaàrí mu lọ́sàn-án, wọn a máa wa gaàrí mu lóru, títí ẹ̀rẹ̀kẹ́ wọn á fi di pẹlẹbẹ tí gbogbo ara wọn á sì gbẹ pátápátá bí ẹran tí ìyàwó mi sè ní ọbẹ̀ lálẹ̀ àná tí egungun rẹ̀ ń dún kérekéré lẹ́nu mi.
Bamiloye ni ''o n wọ aṣọ to ṣi ara silẹ lọ si ṣọọṣi, o tumọ si pe o ti pinnu lati di apayan ni ṣọọṣi.
Ayajọ ọjọ ominiran awọn oniroyin Ayajọ ọjọ ominiran awọn oniroyin ni ajọ Iṣọkan Agbaye da silẹ ni ọdun 1993 ti wọn si maa n ṣe ayẹyẹ rẹ ni ọjọ kẹta oṣu karun un ni ọdọọdun.
Nítorí pé OLUWA kò ní fi ìgbà gbogbo gbàgbé àwọn aláìní,bẹ́ẹ̀ ni ìrètí àwọn talaka kò ní já sí òfo títí lae.
Labẹ ẹgbẹ oṣelu National Party, lo si ti n dije.
Awon asofin agba, ti kan saara si aare fun igbese akin to gbe yii,sugbon won wa pe ajo eleto idibo (the Independent National Electoral Commission,INEC ) lati kede esi ibo aare to waye ni osu kejila, odun 1993.
ó ní, “OLUWA, dákun, mo bẹ̀ ọ́ ni, ranti bí mo ti ṣe fi tọkàntọkàn rìn níwájú rẹ pẹlu òtítọ́ inú, tí mo sì ṣe ohun tí ó tọ́ lójú rẹ.
Gege bi a se mo pe opo iko
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ogbologbo ijapa l'aafin Sọun Wo itan Ilu gangan Òkè Ìyámàpó ní ìlú Ìgbẹ́tì Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí kan sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
ki wọn tẹsiwaju lọ si abala ti o kan ninu idije Europa League ti ọdun yii.
Moṣétán lọ si oko ohun na a pa Igun, ó gbe wá si ilé, ṣùgbọ́n kò jẹ́.
Shittu fi ẹsun kan gomina ipinlẹ Ọyọ, Abiọla Ajimọbi, ati alaga gbogboogbo fun ẹgbẹ APC, Adams Oshiomole pe awọn lo wa nidi bi oun ko ṣe ri tikẹẹti gba.
Coronavirus ló lé mi kúrò níléèwòsàn UCH n'Íbàdàn- Ogun Majek Auxiliary lo ń jà káàkiri ìlú Ibadan lọ́jọ́ Aje, ẹgbẹ́ ọlọkọ èrò NURTW kọ - Ejiogbe Ìyàwó mi ṣẹ̀ṣẹ̀ bímọ tuntun, kò si oúnjẹ fún wa torí ìgbélé Coronavirus- Yakubu Kíni àwọn ojúṣe olórí àwọn òṣìṣẹ́ ààrẹ̀ Nàìjíríà?
Nítorí náà, nígbà tí mo bá dé, n óo ranti àwọn iṣẹ́ rẹ̀ tí ó ń ṣe, tí ó ń sọ ìsọkúsọ nípa mi.
Bakan naa, awon asofin naa tun sepade lati yan igbimo ti yoo kun fun eniyan marun un ati akowe kan lati joko satunse si ofin ati ilana ti o ro mo ile igbimo ohun.
Ṣugbọn Jesu sọ fún un pé, “Ìwọ tẹ̀lé mi, jẹ́ kí àwọn òkú máa sin òkú ara wọn.
” Ọmọbinrin náà bá yára lọ pe ìyá ọmọ náà.
Asa bá kó àwọn eniyan jọ jákèjádò Juda, wọ́n lọ kó òkúta ati pákó tí Baaṣa fi ń kọ́ Rama, wọ́n lọ fi kọ́ Geba ati Misipa.
Ó sọ omi odò wọn di ẹ̀jẹ̀,tí wọn kò fi lè mu omi wọn.
Gẹgẹ bi ipe ti wọn pe e, oun ni yoo jẹ alejo pataki nibi eto naa nibi ti ohun gbogbo ti yipada ti wọn si n sọ ẹyin adiẹ mọ ọ.
kí ó lè yọ ọkàn eniyan kúrò ninu ọ̀fìn ìparun,kí ó má baà kú ikú idà.
Eyi ti fa ijiroro ati igbẹjọ gbogbo di iwaju awọn aṣofin agba lorilẹ-ede naa lati mọ boya lootọ, Trump yoo fi ipo silẹ.
awn agbagba ẹgbẹ oṣelu naa ni wọn tẹw gbaa sinu ẹgbẹ nibi akanṣe ipade itagbangba kan ti wọn ṣe ni ilu Akurẹ.
Amọ awọn akanda eeyan to n ṣe iwọde ṣalaye pe awọn ti ijọba mu ninu awọn ti kere ju.
Coronavirus: Ọmọ Nàìjíríà faraya lórí bí Naira Marley ṣe kọrin l'Abuja níwájú ọ̀pọ̀ èrò Diẹ lara ohun ti ẹ le ma mọ nipa olorin to tun ti n di gbaju gbaja latari ẹsun ti wọn fi kan an niyii.
Oloogbe naa, Ajibola Olaoye padanu ẹmi rẹ nibẹ naa nigbati awọn mẹrin mii fara gba iṣẹlẹ ọhun ti wọn fara pa gidi amọ wọn ti sare gbe wọn lọ sileewosan kan to wa ni tosi.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Cancer: Àṣe ara mi ni iso ti n run gbogbo bí mo ṣe n ṣèrànwọ́ lórí jẹjẹrẹ Shina Rambo ni iyawo ati ọmọ mẹta sugbọn gbogbo rẹ lo padanu ni ọjọ kan naa lasiko tàwọn ọlọpaa bẹ ile rẹ wo nigba to ti jade lọ ṣíṣẹ idigunjale, ṣe atakoro wọ inú Ado, ko le mu ọmọ rẹ wọ ọ.
Ènìyàn mélòó ló n kú ní Afíríkà?
Lara awọn orilẹ-ede naa la ti ri - Cameroon, Gambia, Ghana, Malawi, Namibia, Nigeria, Sieraa Leone, South Africa, Tanzania, Zambia, ati awọn orilẹede mi i to wa ni Afrika tawọn naa jẹ ọmọ ẹgbẹ́ Commonwealth.
Ogun COVID-19 test: Ìjọba kéde ìlànà tuntun fún ìwọlé àwọn akẹ́kọ̀ọ́ tó fẹ́ ṣe ìdánwò àṣejáde
Onimọ nipa eto ilera, Dokita Ikubese Wilson ṣe atupalẹ bi eeya ti le ko aarun coronavirus nipasẹ ṣiṣe ere idaraya.
Ajagun-wakọ Tolulope Arotile jẹ apọn, ko tii fẹ ọkọ ko to di ọj to ku lọjọ iṣẹgun ọjọ kẹrinla oṣu keje ọdun 2020.
"Ọkan lara wọn ba tun dahun pe, ""bẹẹni o, isin ko waye lori ayelujara naa""."
Ọdun 1991 lo gba kọkọ ami ẹyẹ Grammy, to si tun gba ami ẹyẹ naa ni ẹẹkeji lọdun 2009.
Olusegun Obasanjo: Ìjọba Ààrẹ Buhari kò yàtọ̀ sí ti Abacha
Ofin tun de ipejọpọ eniyan to le ni aadọta ti wọn tun pada dinku si ogún, eyi to kan awọn ile ijọsin ati òde àríyá.
Stephen Mamza sọ pe aarẹ orilẹede Naijiria da bi ologun to n sun loju ogun.
Ẹnu yà wọ́n sí ẹ̀kọ́ rẹ̀, nítorí pẹlu àṣẹ ni ó fi ń sọ̀rọ̀.
Wón gbà fun béè, wón sì fun ní ojó méje péré.
, Duration 5,4413 Ògún 2020 Chad prisoners death: Ẹlẹ́wọ̀n 44 kú lagbà ẹ̀wọ̀n ní Chad látàárí ooru tó mú púpọ̀12 Ògún 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
" Ọ ̀ wọ ́ kẹta ni wọ ́ n ń pè ní "" comedy films "" ( àwàdà ) ."
Lẹ́yìn tí Saulu ti di ọba Israẹli tán, ó bẹ̀rẹ̀ sí bá àwọn ọ̀tá tí wọ́n yí i ká jagun; àwọn bíi: Moabu, Amoni, ati Edomu, ọba ilẹ̀ Soba, ati ti ilẹ̀ Filistini.
sọrọ ninu ipade itagbangba lori Abadofin Ṣiṣe Atunṣe si  Ofin Agbeyẹwo Iṣuna Owo ti Ipinlẹ Eko, ni
“mo pe yin nija , ki  e sayewo finni-finni lati Europe,Amerika ati Asia laarin odun 1999 si 2014, iye epo robi ti orile ede Naijiria maa n pese, le ni  agba milionu meji ti won si n ta agba kan epo robi  ni ogorun un dola, nigba to ya, won tun bere si n taa ni márùndínláàdọ́jọ dola.
Ó bá súre fún Josẹfu, ó ní,“Kí Ọlọrun tí Abrahamu ati Isaaki, baba mi, ń sìn bukun àwọn ọmọ wọnyi,kí Ọlọrun náà tí ó ti ń tọ́ mi ní gbogbo ọjọ́ ayé mi títí di òní yìí bukun wọn,
Amọṣa Ọọni ni ko si giri lori ina to jo naa nitori pe gbogbo nnkan ṣi wa ni sẹpẹ ati pe ko si ẹmi to ba iṣẹlẹ ijamba ina naa lọ.
Mimu atunto ba eto oselu ati oro-ajeIwode ifehonu-han koko waye ni odun 2015, eyi ti won fi n pe fun atunto eto isejoba ati oro-aje, bakan naa ki won si fopin si bi iwa ibaje se gbinle bi olu oran lorile-ede naa.
Wọn kò bẹ̀rù Ọlọrun, ṣugbọn wọ́n gbógun tì yín lójú ọ̀nà nígbà tí ó ti rẹ̀ yín, wọ́n sì pa gbogbo àwọn tí wọn ń bọ̀ lẹ́yìn.
Ṣugbọn Marley pada sọ pe aburo oun lo n jẹ orukọ kan naa pẹlu minisita.
orile ede Naijiria , Seyi Makinde ti jawe olubori ninu eto idibo gomina to sẹsẹ
Awon olopaa to  sare lo  yo awon eniyan nibi isele naa , ni ko tun  ni irinse ti won yoo lo.
43 Àti láti fi ìdí ìjọ múlẹ̀ nípa gbígbé ọwọ́ léni lórí, àti fífúnni ní Ẹ̀mí Mímọ́;
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Facebook yóò bẹ̀rẹ̀ ìnáwó orí ayélujára 'GlobalCoin' lọ́dún 2020 24 Èbibi 2019 Oríṣun àwòrán, AFP Àkọlé àwòrán, Ileeṣẹ ayelujara nla naa yóò bẹ̀rẹ̀ ìnáwó orí ayélujára to jẹ ti ara rẹ Facebook ti n gbero lati gbe eto iṣuna ori ayelujara, Crypto-currency jade ni ọdun to n bọ.
Eyi rọrun nitori pe adugbo kan naa l'oun ati obinrin yii n gbe.
Nígbà tí obìnrin náà padà dé tí ó gbé òkú náà dé ààfin tí mo wò ó, o di ọkùnrin tí mo rí pllú ìyàwó mi ni ọ̀gànjọ́ òru tí wọ́n ń fi ẹnu ko ara wọn lẹ́nu – kí Olódùmarè gba ni lọ́wọ́ àwọn ayédèrú ènìyàn tí àwọn ọmọ ayé ìwòyí ń fi hàn bí ẹ̀gbọ́n, tí wọ́n ń gbé ga gẹ́gẹ́ bí àbúrò, tí wọ́n ń yẹ́ sí gẹ́gẹ́ bí ìbátan wọn.
Tanko Abdullateef pa ọga rẹ ni VGC Omiran tun ni ti obinrin oniṣowo kan, Mabel Okafor, ti aṣọgba rẹ pa ni adugbo VGC l'Eko.
Aarẹ ni gbogbo kudiẹ kudiẹ to ṣẹlẹ lalẹ ọjọ eto idibo ṣẹlẹ ki ẹgbẹ Democrat le jale ibo ni.
Nítorí wọ́n ti yapa kúrò lójú ọ̀nà wọn;wọ́n ti gbàgbé OLUWA Ọlọrun wọn.
nígbà tí a sin yín ninu omi ìrìbọmi, tí ẹ tún jinde nípa igbagbọ pẹlu agbára Ọlọrun tí ó jí Kristi dìde ninu òkú.
O tẹsiwaju pe awon tun ji awon
Ninu atẹjade kan ti agbẹnusọ fún gomina Fayose, Lere Olayinka, fi sita loju opo ayelujara,o ni wakati méjíléláàdọ́rin ni oun fun ajọ EFCC lati se atunse bi bẹẹ kọ, awọn agbejọro yoo pe wọn lẹjọ.
Ohun tí a rí nílé Ajimobi rèé lẹ́yìn ìròyìn òfégè pé ó jáde láyé Ninu igbiyanju wa lati fi idi otitọ mulẹ lori awuyewuye to n lọ ni igboro, ikọ BBC Yoruba ṣe abẹwo si ile gomina tẹlẹri nipinlẹ Ọyọ, Abiọla Ajimọbi.
Ṣugbọn kì í ṣe ohun tí mo fẹ́ ni ṣíṣe, bíkòṣe ohun tí ìwọ fẹ́.
A ti wá ojurere rẹ̀, ó sì fún wa ní alaafia ní gbogbo ọ̀nà.
" O ni titi di asiko ti oun fi n ba BBC sọrọ, awọn ajinigbe naa ko tii kan si ẹbi tabi ileewe naa lori ohun ti wọn fẹ ki wọn to lee da Ọjọgbọn naa pada.
Nígbà tí mo kà wọ́n, wọ́n jẹ́ mẹ́rinlélógún.
Ni ọsẹ meji sẹyin ni aarẹ ba awọn ọmọ orilẹede Naijiria sọ irufẹ ọrọ bayii kẹyin nigba to kede afikun iye ọjọ igbele lati dena arun Coronavirus ni ipinlẹ Ogun, Eko ati Abuja tii ṣe olu ilu orilẹede Naijiria.
Onimo nigba iwe ofin, Agbẹjọro Jiti Ogunye lo salaye yii lasiko to n ba BBC sọrọ lori yanpọn-yanrin to bẹ silẹ laaarin awọn oloselu lori ẹni ti yoo soju ẹgbẹ oselu lati dije Aarẹ Ile Asofin Apapọ.
Ṣé Sanwo-Olu, gómìnà Eko yóò farahàn níwájí ìgbìmọ̀ olùwádìí ìṣẹ̀lẹ̀ Lekki Tollgate?
Noa na ọwọ́ jáde láti inú ọkọ̀, ó sì mú un wọlé.
Ọjọ́ ayé ọmọ eniyan dàbí ti koríko,eniyan a sì máa gbilẹ̀ bí òdòdó inú igbó;
Ile ẹjọ giga l'Abuja ni wọn gbe obinrin naa lọ pẹlu awọn meji miiran, ti wọn si fi ẹsun onikoko mẹjọ kan wọn.
Ọwọ́ wọn ni mo ti gba ìwé lọ sí ọ̀dọ̀ àwọn arakunrin wa ní Damasku.
Ipo kẹrin ni Germany gbe lọdun 1991 ati 2015.
Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Tinubu 2023: Àwọn èèkàn ilẹ̀ Yorùbá ń ṣèpàdé ṣáájú dídìbò fún Tinubu ní 202315 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Tinubu kọ lẹta si Odigie pe o'n gbegi di'na iṣẹ oun23 Èrèlè 2018 Nigeria 2019 Elections: Tinubu ní òun yóò sàjọyọ̀ ìsẹ́gun lọ́sẹ̀ tó ń bọ̀21 Èrèlè 2019 Fídíò, Bọla Tinubu: Ìpínlẹ̀ Ọ̀ṣun kò ní owó mi lọ́wọ́9 Owewe 2018 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Ègbé ni fún àwọn tí wọ́n jí ní òwúrọ̀ kutukutu,láti máa wá ọtí líle kiri,tí wọ́n ń mu ún títí di ìrọ̀lẹ́,títí tí ọtí yóo fi máa pa wọ́n!
Ọwọ́ ikọ̀ aláàbò STF tẹ afurasí mẹ́jọ tó lọ́wọ́ nínú ìpànìyàn lemọ́-lemọ́ọ Gúúsù Kaduna Diezani gan an ní Hushmummy tó ń bú àwọn Yahoo boys- Àwọn Ọmọ Naijiria lórí Twitter Olùrànlọ́wọ́ pàtàkì fún ọ̀rọ̀ ibojì òkú, àti àwọn ipò òṣèlú mìíràn tó jẹ́ kàyééfì ní Nàìjíríà Asojú ìjọba orílẹ̀-èdè Lebanon ti kọ̀wé fipò silẹ̀ nítorí ìbágbàmù tó gbẹ̀mi ènìyàn 200 Dẹ́rẹ́bà kẹ̀kẹ́ Maruwa rí ẹ̀wọ̀n gbére he lẹ̀yìn tó fi ipá bá ọmọ ọdún mẹ́rìnlá lòpọ̀ Awọn oluranlọwọ ti dide fun iya ọmọ oloju buulu: Ìyàwó Bukola Saraki fún tìyá-tọmọ olójú búlúù ní N250, 000!
O ṣapejuwe iwọde naa gẹgẹ bi ija a gbogbo agbaye."
Eré bọ́ọ̀lù, ìpàdé ìta gbangba àtàwọn nǹkan míì tó di àpatì torí Coronavirus Lati igba ti arun Coronavirus ti bẹ silẹ ni ilu Wuhan, lorilẹ-ede China lọdun 2019, ọpọloọpọ awọn eeyan lo ti lugbadi arun naa kaakiri agbaye.
Wọn yọ abẹnugan naa ni owurọ ọjọ Aje.
Wọ́n bá ń waasu ìyìn rere níbẹ̀.
Ni awọn ẹya kan lorilẹede Naijiria, wọn ma n pe ni Ukpo Oka, Sapala, Oka Ekusu tabi Ekoki, awọn miiran tun ma n pe nigba Ngwu Oka.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ìjọba Nàìjíríà ti ránsẹ pé àsoju ijọba ni South Africa láti dari wálé Ọlọ́pàá fi afẹ́fẹ́ tajú-tajú àti omi tú àwọn tó fẹ́ ṣun ilé ìtajà ShopRite l‘Abuja ká Àwọn òṣèré tíátà takò ìkọlù South Africa àti ìgbẹ̀san ọmọ Nàíjíríà Kaakiri awọn ilu bi Eko, Ibadan, Uyo ati Abuja ni awọn ọmọ Naijiria ti n fi ẹhonu han lori iṣẹlẹ ikọlu ọhun, ti awọn kan si n ba ileeṣẹ ti wọn fura si pe o jẹ ti awọn ọmọ South Africa jẹ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Temitope Akinnusi: Ọ̀pọ̀ iléeṣẹ́ ló takú láti gbà mí síṣẹ́ torí mo ní ojú kan Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Temitope Akinnusi: Ọ̀pọ̀ iléeṣẹ́ ló takú láti gbà mí síṣẹ́ torí mo ní ojú kan 7 Owewe 2020 Ọmọ ọdun mẹwa ati akẹkọọ kilaasi kẹta nile iwe alakọbẹrẹ ni Temitope Akinnusi nigba ti isẹlẹ kan waye eyi to mu oju osi rẹ lọ lọdun 2003.
"Dino, èyí o ṣe yìí kù díẹ̀ káàtó"" ASUU: Àrúmọjẹ lásán ni N208 bílíọ́nù tí Buhari buwọ́lù Ṣẹ gbọ́ nípa Alájọ Ṣómólú, tó ta mọ́tò ra kẹ̀kẹ́?"
Inú èyí ni mo wà tí òjò bẹ̀rẹ̀ sí rọ̀, òjò náà sì pa mí títí mo fi ń pa eyín keke.
Bayi ti ọdun lọ si opin ti awọn eeyan si n palẹmọ lati ririn ajo ọdun Keresimesi, o tọ ki a la ara wa lọyẹ nipa awọn ofin to yẹ ni mimọ loju popo.
"Ilu Oniluola ati ajọsepọ rẹ pẹlu Omowura lo jẹ ki Ayinla di ilumọọka, ti awọn mejeeji fi jọ ni okiki papọ.
“Mo dupe lowo Olorun fun anfani yii, papaajulo lati tun pada sori papa.
N ṣe ni wọn sẹ pẹpẹ obinrin to wa ni ihoho, pẹlu orin ikọkukọ.
Ọba Saudi Arabia yọ ọmọ rẹ̀ àti àbúrò rẹ̀ kúrò nípò nítorí ìwà àjẹbánu lórí owó tó yẹ fún ààbò ìlú Ààrẹ Buhari pọ́n ọ̀dọ́ Nàíjíríà lé, ó ya Nov 1st sọ́tọ̀ fún àyájọ́ ọ̀dọ́ Bi ọrọ ṣe n lọ bayii, o ṣeeṣe ko jẹ pe naira mejilelọgọta ni wọn yoo pada naa taa nitori ohun ti alaga awọn agbepo lẹkun iwọ oorun guusu Naijiria, Dele Tajudeen sọ fawọn akọroyin kan ni wi pe iye ti awọn yoo maa ta epo niyen niori pe ijọba pẹlu ti gbe owo sisan ni ibdu igbepo gbogbo ti di naira mọkanlelaadọta, (N151.
 Ẹgbẹ BMO tun ni oun fẹ ran Ọjọgbọn Soyinka atawọn eeyan rẹ yoku leti pe awọn agbofinro kii sadede gbe ẹnikẹni lọna aitọ, ayafi ti ẹri to daju ba wa nilẹ pe irufẹ awọn eeyan bẹẹlatipasẹ iwa, ise ati ọrọ ẹnu wọn, jẹ ewu nla fun eto aabo, irẹpọ ati isọkan orilẹede yii."
Tọkọtaya méjì, ọmọ ìyá mẹ́rin bá ìjàmbá ọkọ̀ ayọ́kẹ́lẹ́ lọ l'Amerika
" ni pato , ni "" oke gdp "" ."
Omiran tun ni pe ki o fi aya sun, ki o si gbe iku rẹ soke, pẹlu ọwọ rẹ ko di ẹọẹ rẹ mejeeji mu lati ẹyin.
Ọpọlọpọ lo bu ẹnu ẹtẹ lu Daura nigba naa pe bawo ni ipinlẹ Katsina, to jẹ ipinlẹ rẹ yoo ṣe ni to bẹ ju awọn ipinlẹ yooku lọ.
"Wo àbọ̀ tí ọmọba kan, obìnrin àkọ́kọ́ tó ṣe ìwádìí nípa rẹ̀ gbé jáde Ọlọ́pàá Funso ló fi ààyè sílẹ̀ fún mi láti sá kúrò ní àgọ́ ọlọ́pàá tó wà ní Mokola - Sunday Shodipe Aráyé ẹ gbà mí, nǹkan ń ṣe mí, èyí tó ju àìsàn lọ - Kanran Àwọn òṣèré Nollywood tí wọn ò sí lóri amóhùmáwòrán mọ́ O ni ""Mo sọ pe ki o ma binu nitori bi awọn akẹẹgbẹ mi kan ti a jọ wa nibi ipade oniroyin naa ṣe n ba mi wi loju ẹsẹ pe n ko ba ma ti beere ibeere naa."
Ti wọn si tun ṣẹ ọgọrun milionu Naira sì Dọla, fun lilo Ọgbẹni Ahmadu ati ileesẹ naa.
Sanwo-olu gbé ìwé ẹ̀dùn ọkàn olùwọ́de ENDSARS lé Buhari lọ́wọ́ Ni eyi to bi awọn iwọde ninu ojo ati ninu oorun yii.
Ebi dé sí i, ó wá ń wá nǹkan tí yóo jẹ.
Ọjọ kẹta oṣu Kẹta ọdun 2020 ni o pe ẹni ọdun kẹtalelọgọta.
Idahun ranpẹ: Ile igbimọ aṣofin ko tii gba aba naa wọle, wọn kan ti fọrọjomitoro ọrọ lori rẹ ni ni ipele kika meji.
awon to n fi ehonuhan ti  n di oju popo
Ẹ yàgò fún ibi, rere ni kí ẹ máa ṣe;ẹ máa wá alaafia, kí ẹ sì máa lépa rẹ̀.
Oludari eka eto iroyin nile-ise akowe agba fun ijoba orile ede Naijiria, Ogbeni Lawrence lo jabo oro ohun lojoBo(Thursday) niluu Abuja.
A ti gba àwọn òṣìṣẹ́ 15,000 làti ṣètò ìdìbò gómìnà ní ìpínlẹ Ondo lóṣù kẹwàá - INEC Àìsí iṣẹ́ nígboro lọ̀pọ̀ ọ̀dọ́ fi fẹ́ gba iṣẹ́ Amotekun - Toogun Wo iye àwọn tó ti gbẹ̀mí ara wọn ní Nàìjíríà láàrin ọdún mẹ́rin ìjọba Buhari Gbèsè Nàìjíríà ti lé ní 18 tírílíọ́ọ́nù lábẹ́ ìṣèjọba Ààrẹ Buhari- DMO Wo bí iṣẹ́ abẹ wákàtí mẹ́fà, tí wọ́n fi dóòlà ẹ̀mí ìjàpá tí ọkọ̀ tẹ̀, ṣe lọ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Mayowa Omoniyi: Kò sí orin Obey, Sunny Ade abí tàkasúfèé tí ń kò le ta gìtá sí Ki lo ti ṣẹlẹ sẹyin?
Ọba ba mu tọ́rọ́ tí ó gbà lórí àwọn ìyàwó rẹ̀, ó kó o fún un, owó wá ku kọ́bọ̀ kan láti san, ojú mi báyìí ni ọba ṣe ń wa owó yá tí kò rí ẹni yá a ní kọ̀bọ̀ kan, ojú mi báyìí náà sì tún ni ẹni tí o ni owó yìí ṣe lọ sí ọ̀dọ̀ akọ̀we Ìgbìmọ̀ tí ó ní kí ó fún òun ni ìwe ẹjọ́ kí òun fi bá ọba ṣe ẹjọ́ náà.
Kí ló ṣe wá di ohun tí ẹnikẹ́ni ninu yín kò lè gbàgbọ́ pé Ọlọrun a máa jí òkú dìde?
Phillipe Coutinho fi ọba le fun Barcelona lẹyin to gba goolu aramọnda wọ le eleyi to jẹ goolu kẹta ti Barca gba sawọn.
Nítorí náà, ilẹ̀ náà wà ní alaafia fún ogoji ọdún, lẹ́yìn náà, Otinieli ọmọ Kenasi ṣaláìsí.
Ṣugbọn nígbà tí ó tó àkókò tí ó yẹ kí Saulu fi Merabu fún Dafidi, Adirieli ará Mehola ni ó fún.
Minimum Wage: Buhari ló kù tí yóò fẹnu ọ̀rọ̀ jóná lóri owó oṣù tuntun
O Fagunwa: Ó kó ipa sí àgbéga Yorùbá àmọ́ dúkìá rẹ̀ kò tó nkàn 7 Bélú 2018 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 8 Bélú 2018 BBC Yoruba sabẹwo si ile ati yara ti gbaju-gbaja onkọwe ni, D.
Èdè-àìyedè nílé aṣòfin lórí ìyànsípò ìgbìmọ̀ olùdarí EFCC 'EFCC gbẹ́sẹ̀ lé owó Davido, Adeleke' ‘Patience Jonathan yoo yọju sileẹjọ’ Ajọ EFCC ni ki Saraki ranti pe awọn ni asẹ labẹ ofin ati ibura lati ri wi pe awọn fi opin si iwa ibajẹ lorilẹede Naijiria.
"Awujọ maa n yara lati pe awọn eniyan ni ẹni buruku tabi ẹni rere.
CP Bola Longe - CP Nasarawa Command xxxii.
Nigba ti akọroyin BBC News Yoruba de agbegbe ile rẹ ni Oluyọle Estate gbogbo ọna abawọle mejeeji to wọ adugbo Agbaoye ibadan naa lo da paroparo ti wọn si ti abawọle ile rẹ gba-gba-gba.
O rí i pé ó ṣe olóòótọ́ sí ọ, O sì bá a dá majẹmu láti fún àwọn ìran rẹ̀ ní ilẹ̀ àwọn ará Kenaani ati ti àwọn ará Hiti, ti àwọn ará Amori, ti àwọn ará Perisi, ti àwọn ará Jebusi ati ti àwọn ará Girigaṣi, o sì ti mú ìlérí náà ṣẹ nítorí pé olódodo ni ọ́.
2 mílíọ́nù owó ìtanràn Ìjọba Nàìjíríà ti gbà láti san N30b owó àjẹmọ́nú fún ASUU Àjẹ́ àti Aṣẹ́wó ní ìyá Rainbow - Òjòpagogo Cardi B ṣàlàyé ohun tó gbé fọ́tò ìhòhò rẹ̀ d'órí ayélujára Instagram Ìdí táwọn olùwọ́de EndSARS fi kọ oúnjẹ àti ọtí ẹlẹ́rìndòdò tí MC Oluomo gbé wá rèé Wo ìgbésẹ̀ mẹ́ta tí Gómìnà Obiano gbé lórí ọ̀rọ̀ SARS ní Anambra Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Gbajúgbajà òsèré tó tún mọ́ ọbẹ̀ sè Saaju laarọ oni ọjọ Satide: Ọkọ̀ agbépo méjì gbiná ní orí afárá Otedola ní ìpínlẹ̀ Eko!
Nígbà tí ó si ṣe tí a yọ sí òpópó kan báyìí ni à ń wo ọlọ́pàá àwọn ejò wọn-ọnnì lọ́kàn-ánkán tí wọ́n dúró tí wọ́n ń wo apá ọ̀dọ̀ wa.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Wo àwọn ọ̀nà to fi leè ní owó lọ́wọ́ láti ipasẹ̀ iṣẹ́ amọ̀ Wòlíì Kasali ní Dolapo Awosika kò lé ìyàwó òun jáde Dòkítà tó ṣe iṣẹ́ abẹ fún oyún inú l‘Amẹrika ló ń sọ Yorùbá yìí, bíi ẹní la oyin 'Alífábẹ́ẹ́tì Ohùn Oduduwa di ìtẹ́wọ́gbà ni Ajaṣẹ' Gẹgẹ bi a se rii ka loju opo itakun agbaye, olokiki ati gbajumọ nla ni ọkunrin yii, ti okiki rẹ si tan kale, ka oko ati nilẹ okeere.
''Wọn lọ si ile rẹ lati wa bo ya ọmọ naa wa nibẹ, koda wọn wo pata obinrin ti wọn nile rẹ, ṣugbọn wọn ko ri nkankan, idajọ yii kudiẹ kaato,'' ọmọ ijọ Sotitobire kan lo sọ bẹẹ.
N óo sì fi òkú wọn ṣe oúnjẹ fún àwọn ẹyẹ ati àwọn ẹranko.
Ni afikun, won ti pe David Olowookere ati Abu Joy fun idije oje wewe lagbaye.
Oríṣun àwòrán, @Kitchnbutterfly O ni bẹẹ awọn oniburẹdi san ida mẹẹdogun ti ijọba n beere fun owo idagbasoke ki ijọba to le mu idagbasoke ba awọn oniburẹdi.
O si tumọ si pe iye ina ti iru awọn eeyan bẹ ẹ ba lo nikan ni wọn o san owo rẹ.
O sẹ alaye wi pe, arọ ipinlẹ naa fẹ jo,sugbọn ẹsẹ ni ko ni, latari aisi owo lati fẹ ayẹyẹ naa loju.
Gbogbo awọn asofin mọ́kàndínláàdọ́fà ni yoo dibo yan ẹni tọkan wọn fẹ.
Gbogbo odò wọn yóo máa rùn,gbogbo àwọn odò tí ó ṣàn wọ odò Naili ní Ijipti,ni yóo fà, tí yóo sì gbẹ:Gbogbo koríko odò yóo rà.
Ẹ wo ọwọ́ mi ati ẹsẹ̀ mi, kí ẹ rí i pé èmi gan-an ni.
Ko tii daju awọn ọrọ ti yoo mẹnu ba ninu ọrọ rẹ akọkọ gẹgẹ bi aarẹ.
Báwo ni wọ́n ṣe ṣàwári abẹ́rẹ́ àjẹsára?
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù #EndSARS: Ìbọn ba Kolade Johnson níbi tó tí ń wo bọ́ọ̀lù 1 Ìgbé 2019 Oríṣun àwòrán, PoliceEN_PCRRU/Twitter Ariwo ẹ fopin si ọlọpaa SARS lo gba oju ayelujara kan lori ẹsun ti wọn fi awọn ọlọpaa ọhun pe wọn yinbọn pa ọmọkunrin kan ti orukọ rẹ jẹ Kolade Johnson lagbegbe Onipẹtẹsi niluu Eko lọjọ Aiku.
Nígbà tí wọ́n bẹ̀rẹ̀ sí tẹ èso ninu rẹ̀, ẹ̀jẹ̀ ni ó bẹ̀rẹ̀ sí yọ jáde láti inú ìfúntí náà.
 kárbọ ̀ nù ni ìkan nínú àwọn ẹ ́ límẹ ̀ ntì díẹ ̀ tí wọ ́ n ti jẹ ́ dídámọ ̀ láti ìgbà àtijọ ́ .
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Mọ̀ nípa DJ Switch, akíkanjú obìrin sàfihàn fídíò ìpànìyàn Lekki bó ṣe ń wáyé Buhari, máṣe gbá ìpànìyàn Lekki sórí ààtàn, kò yẹ́ kí ológun yin ọ̀dọ́ níbọn - Bode George Ọ̀kan lára olùwọ́de tó fara gbọgbẹ́ ní Lekki jáde láyé - Sanwo-Olu Kò sí olùwọ́de tó kú ní Lekki - Sanwo-Olu N kò lọ́wọ́ nínú ìpànìyàn, kò dáa bí wọn ṣe lo ọta ìbọn ní Lekki - Tinubu Ọjọ́ Ìsẹ́gun di ọjọ́ ìbànújẹ́ fún ọ̀pọ̀ ìdílé ní Nàíjíríà torí òkú tó ṣùn Ọ̀dọ́ 30 ń gba ìtọ́jú lọ́wọ́ nílé ìwòsàn torí ọ̀gbẹ́ ìbọn ní Lekki - Sanwo-Olu ṣàlàyé Àwọn ṣọ́jà ṣíná ìbọn bolẹ̀ ni Lekki Tollgate O ni ajọ agbaye ti ṣe tan lati ṣe iranlọwọ fun lori igbesẹ wiwa atunse."
omo orile ede Naijiria, nitori ise gudugudu meje yaya mefa ti ijoba re ti  gbese lorile ede yii.
O kéré tán ìpínlẹ̀ méjìlá ni yóò gba gómina túntún ní ọjọ kọkandinlọgbọ̀n oṣù karun ti sáà tó n bẹ lóde yìí ba wá sópin.
Ṣugbọn nǹkankan ni mo fẹ́ kí o ṣe, o kò ní fi ojú kàn mí, àfi bí o bá mú Mikali ọmọbinrin Saulu lọ́wọ́ nígbà tí o bá ń bọ̀ wá rí mi.
A má a fún wọn ní èsì ní kíkún.
Oríṣun àwòrán, Policeng Àkọlé àwòrán, Army Vs Police: Ẹ ṣe àwárí ọdànran tó bọ mọ́yin lọ́wọ́ - Turkur Buratai Ọlọ́pàá mẹ́ta ló bá ìṣẹ̀lẹ̀ náà rìn Mark Ediale, Usman Danzuni àti Dahiru Musa.
Tọmaasi alaigbagbọ ni oye awọn miran lori ayelujara, wọn ko gbagbọ pe aya aarẹ funra rẹ gan an lo fi fidio naa sori ayelujara Aisha Buhari bá ìyàwó ààrẹ Gambia ṣàjọyọ̀ ọjọ́ ìbí Èmi kò mọ obìrin tí DSS mú rí —Aisha Buhari 82% ọkùnrin ní kó mọ̀ pé òun ní àìsàn jẹjẹrẹ asẹtọ ní Naijiria Ọlọ́pàá Adamawa ni #30,000 ni wọ́n fi bọ́ igún látìmọ́lé Ohun kan ṣoṣo to hande ni pe, ọlọgbọn lo n jo ìlù agidigbo, ọmọran lo si n mọọ, asiko ti to fun awọn olori kaakiri agbaye lati dẹkun fifi awọn opurọ alatẹnujẹ yi ara wọn ka ki wọn gbe igbesẹ lati maa mọ okodoro ohun ti ara ilu to jade ninu ojo ati ninu oorun wa dibo yan awọn sipo n fẹ ni tootọ ki idagbasoke to yẹ le wa ni alaafia.
Ṣugbọn ranti pé, Ọlọrun yóo ṣe ìdájọ́ gbogbo ohun tí o bá ṣe.
Ìgbà tí wọ́n tún bẹ̀rẹ̀ lẹ́ẹ̀kejì, kùkùté wá ọ̀nà ó so mọ́ ẹbọra náà ní ìdí, ibi tí o sì n tìí ká, ó tìí sínù kòtò kan báyìí, ẹbọra jìn si i, ó bá ṣubú, Oníbodè pàtẹ́wọ́ pé kùkùté ṣẹ́gun.
bí o tilẹ̀ fún mi ní ààfin rẹ, tí ó sì kún fún fadaka ati wúrà, sibẹsibẹ, n kò ní agbára láti ṣe ohunkohun ju ohun tí OLUWA bá sọ lọ.
ara nla kan to san lẹyin ojo arọrọda ni Abule Okeowa Eluju nipinlẹ Ekiti lo ti pa maalu mẹtalelogun ni Gaa wọn.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Shiite: Suhaila El-Zakzaky ní ẹgbẹ́ àwọn kọ́ ló kéde àti dáwọ́ ìwọ́de dúró 1 Ògún 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Awọn ọmọ ẹgbẹ́ Shiite n fẹ̀hónú hàn fún ìtúsílẹ̀ olori wọn Sheikh Ibrahim Zakzaky.
Aarẹ ni o ba oun lọkan jẹ bi awọn janduku ti n pawọn alaiṣẹ ati bi wọn ti n sọ ọpọ di alaabọ ara ti wọn si n tun n jawọn lole.
Gbogbo awọn ajọ ti o nii ṣe pelu ọrọ yii ni a ti rọ lati foju sìta lori Codeine,Tramadol ati awọn oogun bẹẹbẹe.
Ṣegun Dawodu, Arabinrin Fọlaṣade Adefisayọ, Arabinrin Ponle Ajibọla, Ọmọwe
ipade apero awon omo-ogun ile Afrika ni akole re yoo je “Isokan je agbara, gbigbogun ti idojuko to n koju eto-abo.
Ẹẹdẹgbẹrin (700) ni àwọn obinrin ati ọmọ ọba tí Solomoni gbé níyàwó, ó sì tún ní ọọdunrun (300) obinrin mìíràn.
Bakan naa lo fi kun un pe eeyan mẹta larun naa tun ti ran lọ sọrun, eyi si ti mu iye awn to ti ko arun naa di ẹgbẹfa, 1200.
Ninu adura wa sí Ọlọrun Baba wa, à ń ranti bí igbagbọ yín ti ń mú kí ẹ ṣiṣẹ́, tí ìfẹ́ yín ń jẹ́ kí ẹ ṣe akitiyan, tí ìrètí tí ẹ ní ninu Oluwa wa Jesu Kristi sì ń mú kí ẹ ní ìfaradà.
Ramu bí Aminadabu, Aminadabu bi Naṣoni, olórí pataki ninu ẹ̀yà Juda, 
Bakan naa, osise ajo isokan agbaye kan, ti won foruko bo lasiri so pe, arabinrin oloogbe naa n gbe ni agbegbe Baidoa, ilu ti ko jina si Mogadishu.
Àlàfo tí ó wà láàrin àwọn yàrá ẹ̀gbẹ́ náà jẹ́ igbọnwọ marun-un (mita 2½).
Ẹyin ọmọ Naijiria maa n pa eeyan lẹrin sa.
OLUWA bá rán Balaamu pada sí Balaki, ó sọ ohun tí yóo sọ fún un.
Lootọ gbajugbaja ni Majek Fashek kaakiri agbaye ṣugbọn awọn ohun mẹfa wọnyii ni awọn eeyan ko mọ nipa rẹ.
Ìjàmbá ọkọ̀ tó ṣẹlẹ̀ sí Adams Oshiomole kìí ṣe ojú lásan, àwọn kan ló fẹ́ pa á- APC Ọba Saudi Arabia yọ ọmọ rẹ̀ àti àbúrò rẹ̀ kúrò nípò nítorí ìwà àjẹbánu lórí owó tó yẹ fún ààbò ìlú Èèyàn 239 míràn ṣẹ̀ṣẹ̀ kó COVID-19 ní Nàìjíríà Ọkùnrin kan di èrò ọ̀run nítorí pé o fi ẹ̀sùn kan alájọgbélé rẹ̀ pé o n yan ìyàwó ẹnìkan lálè Victoria Rubadir ọmọ Kenya ló gba àmì ẹ̀yẹ Komla Dumor BBC World News Oríṣun àwòrán, Lasema/Facebook Wọn ni awọn doola ẹmi eniyan meje, agbalagba mẹfa ati ọmọde kan, ti wọn si farapa Amọ, awọn obinrin agbalagba meji sọ ẹmi wọn nu ninu ijamba ọkọ naa.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ikọgosi Ekiti: Itan nipa omi gbigbona ati omi tutu Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Ikọgosi Ekiti: Itan nipa omi gbigbona ati omi tutu 27 Èrèlè 2018 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 10 Èbibi 2020 Ilu ikọgọsi Ekiti lo gbajugbaja, to si tun jẹ ibudo igbafẹ nitori omi odo kan to nmu omi gbigbona ati tutu jade.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Bi iṣẹ perfume tita ti ṣe yí ìgbésí ayé Adéwálé Aladejana padà Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Bi iṣẹ perfume tita ti ṣe yí ìgbésí ayé Adéwálé Aladejana padà 8 Owewe 2018 Gbogbo igba ti Adéwálé Aladejana ba n rántí bí o tí ṣé bẹrẹ iṣẹ perfume tita,n'isẹ ní inú rẹ má n dùn.
Ó sàn láti máa gbé kọ̀rọ̀ kan lókè àjà, ju pé kí eniyan máa bá oníjàngbọ̀n obinrin gbé ilé lọ.
Ariwo sì ti gba gbogbo ìlú.
Russia 2018: Àwọn tó ń lọ sípele kejì ìdíje 'Ọdaràn yóò pọ̀ tí a bá kó ọlọ́pàá SARS ń lẹ̀'' 'Ọjọ́ Burúkú: Àwọn ọlọ́pàá mú ẹ̀mí ìyàwó mi lọ' 'Wọ́n jí bàbá mi gbé ká tó kojú Argentina' Àwòrán ìwọ́de ẹ̀lẹ́gbẹ́-jẹgbẹ́ lórí ìpànìyàn Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí 2 sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 2:23 Fídíò, Water Generator: Ó leè ṣiṣẹ fún wákàtí mẹfà, kó tó sinmi, Duration 2,2310 Òkùdu 2020 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
“Alàgbà, ọmọ-ọ̀dọ̀ mi kan wà ninu ilé tí àrùn ẹ̀gbà ń dà láàmú, ó sì ń joró gidigidi.
Ní ọjọ́ iwájú bí àwọn ọmọkunrin yín bá bèèrè ìtumọ̀ ohun tí ẹ̀ ń ṣe lọ́wọ́ yín, ohun tí ẹ óo wí fún wọn ni pé, ‘Pẹlu ipá ni OLUWA fi mú wa jáde kúrò ní ilẹ̀ Ijipti, níbi tí a ti wà ní ìgbèkùn rí.
Independent National Electoral Commission(INEC) jẹ ayederu , ni eyi ti o yatọ
S nítorí wọ́n bí ọ síbẹ̀ mọ́’ Àwọn ọmọ ẹ́gbẹ́ NURTW kọjú ìjà síra wọn nítorí ipò l'Ekiti Ẹgbẹ́ òṣìṣẹ́ ṣe ìwọ́de lọ́jọ́ Ìṣégun káàkiri orílẹ́èdè Nàìjírìa pe awọn ko ni gba din ni ọgbọn ẹgbẹrun náírà gẹ́gẹ́ bí owó oṣù òṣìṣẹ́ tó kéré jùlọ.
Ẹ̀yin tí ẹ kò gbọ́ Yorùbá, ẹ ṣúnmọ́ bí láti kọ́ lítíréṣọ̀ èdè Yorùbá lórí BBC Ẹ ṣúnmọ́ bí láti kọ́ ẹ̀kọ́ nípa ìsọ̀rí ọ̀rọ̀ nínú gbólóhùn Yorùbá Mọ sii nipa akoonu ẹkun iyawo.
Owó ìsìnkú kò lè mú òkú padà di alààyè, bí a bá ti ṣe ti ọmọlúwàbí ó ti tó, owó ànájù ń sọ wa di gọ̀ǹgọ̀sú ènìyàn ó si ń fi wá  si ipò ìlábùrù, baba ọ̀bọ.
Pẹlu iye awọn eeyan tuntun yii, o ti pe 79,789 eeyan to ti ni arun naa l'orilẹede Naijiria bayii.
 Abadofin mẹsan-an ni a ti sọ di ofin, ti a si ti fẹnu ko lori ipinnu Ile marun-undinlaadọta.
Ile Igbimọ Aṣofin Ipinlẹ Eko wa rọ Ijoba Apapọ
Oniwaasi agbaye naa wa gba aya Ajimobi niyanju lati tẹle ohun ti iwe Alukurani sọ nipa opo sise, eyi to ni o jẹ osu mẹrin ati ọjọ mẹwa, eyiun aadoje ọjọ, ti yoo si jade opo ni ọjọ keji osu Kọkanla ọdun 2020.
Gbajúgbajà sọ̀rọ̀sọ̀rọ̀ orí rédíò Dan Foster ti dágbére fáyé A kò tíì fi ìdí ẹ̀ múlẹ̀ pé ògùn Dexamethsaone ń ṣiṣẹ́ fún àrùn coronavirus- WHO Ǹkan mẹ́jọ tó máa kọ́kọ́ ṣẹlẹ̀ kí olólùfẹ́ méjì tó pa ara wọn Ilé ẹjọ́ kòtẹ́mílọ́rùn yọ alága ẹgbẹ́ òṣèlú APC Adams Oshiomhole nípò Ajafẹtọmọniyan lawọn obinrin mẹta ọhun lẹgbẹ oṣelu MDC ti wọn si n foju wina ofin lori ẹsun pe wọn parọ pe wọn ji awọn gbe wọn si fipa ba wọn lopọ loṣu to kọja.
Ṣaaju ni agbẹnusọ fun ajọ ṣe akoso awọn papakọ ofurufu ni Naijiria, Henrietta Yakubu sọ fun BBC pe awọn arinrinajo gbọdọ maa de papakọ ọkọ ofurufu o keretan, wakati mẹta ṣaaju asiko ti baalu wọn yoo gbera.
Nibayii, ibeere to gba ẹnu ọpọ eeyan ni pe, bi ọrọ ṣe wa ri yii, bi El-Zakzaky ba pada de nibo ni yoo wa?
 Èrò ọkàn rẹ ̀ ni pé , bí òun bá tilẹ ̀ débẹ ̀ , bóyá òún á jẹ ́ bá ohun tó jọ bí ọsàn pàdé .
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ajàfẹ́tọ: Awàkọ̀ mi sùn ẹ̀wọ̀n ọjọ́ márùń t'orí aṣẹ́wó 6 Èbibi 2018 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Asẹwo di olùpẹ́jọ́ ti wọn fi fa Darlington de agọ ọlọpaa to wa ni Utako, Abuja Ajafẹtọ ọmọ ènìyàn, Bukky Shonibare, tió ń gbé Abuja ti ṣ'alaye iṣẹlẹ kayefi kan ti o gbe awakọ rẹ ti o n jẹ Darlington lọ ẹwọn ọjọ marun fun ẹṣẹ ti ko m'ọwọ ti ko m'ẹsẹ.
N kò rú èyíkéyìí ninu àwọn òfin rẹ, bẹ́ẹ̀ ni n kò sì gbàgbé wọn.
Ìpẹ́ ikùn rẹ̀ dàbí àpáàdì tí ó mú,wọn ń fa ilẹ̀ tútù ya bí ọkọ́.
OLUWA, OLUWA àwọn ọmọ ogun yóo múgbogbo àwọn tí àwọn eniyan gbójúlé kúrò,ati àwọn nǹkan tí wọ́n gbẹ́kẹ̀lé ní Jerusalẹmu ati Juda.
A wá ṣe ìdájọ́ ẹnìkọ̀ọ̀kan wọn gẹ́gẹ́ bí iṣẹ́ rẹ̀.
Ikú alaga PDP: Niyi Aborisade ni alága PDP ní ìjọba ìbílẹ̀ Apápá
O wa ro awon omo orile ede Naijiria lati maa fi oselu bo awon isele buruku bayii, o ni ebi kan  naa ni iko omo ogun orile ede Naijiria, ti won si ti setan latu tubo maa daabo bo awon omo orile ede Naijiria.
da idoti si ibi to ba wu won yato, si ibi ti ijoba fowosi fun agbasese lati ko
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù LASK vs Manchester United: Ighalo fi góòlù àrámọ̀ndà góòlù àrámọ̀ndà ló fi gbẹyẹ lọ́wọ́ LASK fún Manchester United 12 Ẹrẹ̀nà 2020 Oríṣun àwòrán, Getty Images Bi ọmọ ẹni dara, ẹ jẹki a wi.
Eleyi yatọ si miliọnu mẹẹdọgbọn naira ti wọn ma fi n parọ ọkọ fun wọn ati ẹgbẹrun mẹta milọnu ti wọn fi n kọ ile fawọn Gomina ana silu Abuja.
Ṣugbọn tí o bá rú Òfin, bí àìkọlà ni ìkọlà rẹ rí.
Ile-ise asoju orile-ede America lorile-ede Ethiopia fi erongba re han lojo-Aiku tako ipinnu ijoba nipa kikede ilu-o-fara ro lorile-ede naa, ni iyanju ati je ki alaafia joba leyin ti olori ijoba kowe fi ipo re sile.
kí wọ́n lè bọ́ kúrò ninu tàkúté Satani, tí ó ti fi mú wọn láti máa ṣe ìfẹ́ rẹ̀.
Ọ̀rọ̀ Yorùbá ti ó sọ pé “Iwájú lèrò mbá èrò” ṣe gba ẹni ti kò bá ni ìtẹ́lọ́rùn ni ìmọ̀ràn.
Ohun tí ojú wa ń rí nìyí níbi ìbò abẹ́nú fún olùdíje gómìnà lẹ́gbẹ́ òṣèlú APC ní Edo Àwọn tó ní Covid-19 ní Nàìjíríà ti tayọ ẹgbẹrun lọ́nà ogún Wọ́n ti pàṣẹ lọ rọọ́kún nílé fún òṣìṣẹ́ káńsù tó lú obìnrin kan ní ìpínlẹ̀ Ogun Àjọ Lasema rí òkú èèyàn nínú èèrù iná àwọn ọkọ̀ agbépo tó jóná ní afárá Kara Fayoṣe ni niwọn igba ti ko ti si ofin kan to laa kalẹ pe ọlọpaa ko lee fun igbkeji gomina laaye lati lo ọkọ ọfiisi rẹ mọ nitoripe o rekọja si ẹgbẹ oṣelu miran.
Nígbà tí ó yá, Josẹfu kú, gbogbo àwọn arakunrin rẹ̀ náà kú ní ọ̀kọ̀ọ̀kan títí tí gbogbo ìran náà fi kú tán.
sabaa maa n fa wahala naa ni ija ile ati oju ojo .
Amuneke to tun ti jẹ agbabọọlu fun Barcelona ni igbakeji akọnimọọgba Naijiria nigba ti Naijiria jawe olubori ni ife ẹyẹ agbaye FIFA U- 17 fun igba kẹẹrin i UAE lọdun 2013.
"Koda, bi oṣere tiata kan ba gba owo lati kopa ninu ere lasiko yii, ti ko si si ọna lati rinrin ajo lọ kopa ninu ere ọhun nipinlẹ ti wọn ti fẹ ya iṣẹ, iru iṣẹlẹ bẹẹ tun le da ede aiyede silẹ, eyi to le da ẹgbẹ ru.
Ogoji eniyan lo ti ku lorilẹede Naijiria lati igba ti arun Coronavirus naa ti bẹrẹ si ni ja rain ni Naijiria.
Oríṣun àwòrán, BBC Zarka ṣalaye pe lẹyin ọdun kan ti oun fẹ arakunrin naa lo ni oun fẹ gbe iyawo tuntun miran, ṣugbọn o maa n fi ikanra airi owo ori iyawo tuntun naa san mọ oun.
láti inú ìdílé Usieli, ọkunrin mejilelaadọfa (112), Aminadabu ni olórí wọn.
O rò pé o lè fi owó ra ẹ̀bùn Ọlọrun.
Babalawo kan to fi ilu Ibadan ṣe ibugbe, Oluwo Jọgbọdọ Orunmila ti sọ fun ile ifowopamọ naa pe, ti ko ba ẹgbẹrun lọna igba le mẹfa (₦206,000) owo mama oun to yọ pada, titi aago mẹrin irọle ọjọ Ẹti ọjọ kọkanlelogun oṣu kẹjọ yii, oun yoo ti ọwọ Ifa bọ ọ.
Ati pe ti awọn mẹrindinlọgọta to ku ko si ni iwe yi.
Ènìyàn òjìlélúgbà àti méjìlá ni àwọn to tun ṣẹ̀ṣẹ̀ ní ààrùn náà báyìí.
won, awon eniyan to le ni ọ́ọ̀dúnrún ni o
Bí ó ti rí i, ó fa aṣọ rẹ̀ ya ó ní, “Ha!
Oludari agba ajọ LASEMA, Olufẹmi Oke- Ọsanyintolu ṣalaye pe ipenija nla ni ọrọ ilekanle, orule-kan-orule n mu ba ilakaka ati koju ijamba ina ni ipinlẹ Eko.
Nígbà tí Josẹfu ti gba òkú náà, ó fi aṣọ funfun tí ó mọ́ wé e.
wọ́n mú Uraya jáde ní ilẹ̀ Ijipti, wọ́n mú un tọ ọba Jehoiakimu wá.
 Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ọmọ Nàíjíríà tako Nafdac lórí ọ̀rọ̀ Codine NAFDAC ti parí ìwádìí lórí codeine Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Fídíò òògùn ikọ́ Codeine: Ó dùn lóòtọ́ àmọ́ ewu ni Ojú Kolo dúdú, tó sì pọ́n bíi ẹ̀yẹ iná, ohùn rẹ̀ ń lọ́ pọ̀, tí kò sì já gaaraga bó se ń sọ̀rọ̀."
"Eto ọrọ aje ti n pada bọ sipo, owo wa si ti i burẹkẹ sii lojoojumọ; nnkan yoo tubọ maa se rẹgi lorilẹ-ede yii.
“Ẹ̀rí ẹyọ ẹnìkan ṣoṣo péré kò tó láti fi dá ẹnikẹ́ni lẹ́bi lórí ẹ̀sùnkẹ́sùn tí wọ́n bá fi kàn án, tabi ẹ̀ṣẹ̀kẹ́ṣẹ̀ tí ó bá ṣẹ̀.
Ilé-ìwé Gamalieli ni mo lọ, ó sì kọ́ mi dáradára nípa Òfin ìbílẹ̀ wa.
Ori mi wu pẹlu isẹ takuntakun Seun Adigun, Ngozi Onwumere ati Akuoma Omeoga."
Baluu ẹya Boeing 744 naa ti nọmba idanimọ rẹ jẹ 5N/DBK la gbọ pe idaamu de ba ọkan lara awọn ẹnjini rẹ bi o ṣe n sunmọ papakọ ofurufu naa.
Dalung, Audu Ogbe, Shittu Adebayo àti Isaac Adewole kò wọlé Ṣé irúfẹ́ oúnjẹ tí ò ń jẹ́ lè jẹ́ kí o gbádùn ìbálòpọ̀ rẹ síi?
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Farms to You: Irú ajílẹ̀ wo ló yẹ fún lílò lásìkò yìí- Aisha Wo awọn ibi ti ọkada ati ko ni le de mọ bayii ni ipinlẹ Eko Awọn opopona Marosẹ:1.
Ó bá Shina Peters dọ́rẹ wan si bímọ kan fun ara wọn ti wan pe orukọ rẹ̀ ni Clearence Abiodun Peters Yàtọ sí eré Sinima, Clarion ń ṣe eto iṣẹ́ ẹyinju àámú ni Nàìjíríà, Cameoon àti Tanzania bákan náà ni wọ́n n ta asọ Saliu Babatunde Abiola (Baba Agba) ní ọkọ rẹ̀ tó jẹ́ Aburo MKO Abiola kìí ṣe Abiola gan ló fẹ́ Ajíhìnrere ni Clarion Chukwura, èyí ló sì mú kí ó ma ṣètò ìrànwọ́ fún obínrin ti wọ́n bá ń tọ́mọ́.
Day 25: Àwọn àkànlò èdè lásìkò ìdìbò #BBCNigeria2019 Lẹ́yìn òkò ọ̀rọ̀, Buhari àti Ọbasanjọ fẹ̀rín pàdé ara wọn l‘Abuja Exclusive: Atiku dára ju Buhari ní ìlọ́po méjì - Obasanjo #BBCNigeria2019 Tani Ọjọgbọn Mahmood Yakubu ti yóò ṣètò ìdìbò 2019?
Oríṣun àwòrán, Dagrin Fimilejo O ba awọn akọrin bi i 9ice, Y.
Lẹ́yìn náà OLUWA ti ẹnu wolii Jehu ọmọ Hanani bá Baaṣa ati ìdílé rẹ̀ wí nítorí gbogbo ibi tí ó ṣe lójú OLUWA, tí ó fi iṣẹ́ ọwọ́ rẹ̀ mú OLUWA bínú nítorí pé ó dẹ́ṣẹ̀ bíi Jeroboamu, ati pé òun ló tún pa ìdílé Jeroboamu run.
Femi Adesina tun so pe “Oun nikan ni aare ti wọn pe fun ayẹyẹ ajọdun ogun odun ati pe awọn oga agba ile-ise lorile ede Naijiria  ri pipe yii gege bi ona lati  fi dupe lori atileyin ti orile ede Naijiria n se fun ajo naa.
O fikun pe ara oun dun oun, amọ orilẹede naa yoo bori aarun naa gbogbo.
 Nitori naa, irinajo aare wa si ile-ejo agbaye je ona lati fi ife han si atileyin rẹ.
Ẹnikẹ́ni tí ó bá sọ̀rọ̀ òdì sí orúkọ OLUWA, pípa ni wọn yóo pa á.
, ati pe ijọba yoo mojuto igbẹjọ wọn.
Lati inu oṣu kẹrin ni aarẹ dawọ le ijabọ ojoojumọ, lasiko naa lo ni oun yoo maa fun awon eniyan ni bẹrẹ ti o le wo aarun Coronavirus Wo àwọn ọ̀nà míràn tí o leè gbà lẹ́yìn tí wọ́n bá ti afára Third Mainland Kí ló pa Bobrisky àti Olorì Aláàfin Oyo pọ̀?
“Ati ẹni tí ó pa mààlúù rúbọ,ati ẹni tí ó pa eniyan;kò sí ìyàtọ̀.
Igbimọ naa, ti Adajọ-fẹyinti Ayo Salami ko sodi lo ransẹ pe Magu lati gbọ tẹnu rẹ lori awọn ọrọ kan to nii se pẹlu awọn alasẹ ajọ EFCC.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: ‘Mí ò lọ́rọ̀ bá ilé aṣòfin sọ’ FBI: Àwọn kan rò pé orí wa kò pé 'Ọ̀tá ìjọba alágbádá ni ọ̀gá ọlọ́pàá’ Ọ̀tẹ̀ tó pa wọ́n pọ̀ náà ló ń tu wọ́n ka Wàyí ò, ẹgbẹ́ òsèlú PDP, tó jẹ́ ẹgbẹ́ òsèlú alátakò gbòógì ní ilẹ̀ Nàíjíríà, ti fèsì lórí ìsẹ̀lẹ̀ yìí.
Mo mọ̀ pé ẹ̀rọ ayárabíàṣá lorúkọ tí computer njẹ́ ní èdè Yorùbá.
Ẹnikẹ́ni tí kò bá gbààwẹ̀ ní ọjọ́ náà, a óo yọ ọ́ kúrò lára àwọn eniyan rẹ̀.
’Ṣé ó lè ṣe ìdájọ́ láti inú òkùnkùn biribiri?
Mejidinlọ̀gọ̀rin lara awọn eeyan naa lo wa lati ipinlẹ Eko, mẹrila si wa lati ilu Abuja.
Ki lo mu ki eleyi ṣẹlẹ gan?
Bí òkúta yìí bá bọ́ lu eniyan, yóo rẹ́ olúwarẹ̀ pẹ́tẹ́pẹ́tẹ́.
- Olukoya ti ìjọ MFM Ẹ̀kọ́ ọ̀fẹ́, ètò ilera ọ̀fẹ́ àti iná ọba ló jẹ wá lógún- ọmọ Nàìjíríà Nàìjíríà bí ìkókó 26, 039 lónìí ọjọ́ kíní, oṣù kínií, ọdún 2020- UNICEF Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 2020: Oloye Awurela Ifaleke ti wúré ọdún ìgbéga fún kóówá Amo Fayose ni ayẹwọ ara ni oun lo se e, oun ko dubulẹ aisan, nitori naa oun laṣẹ lati jo ati y ninu ọdun tuntun naa.
àgbàrá ìbá ti gbá wa lọ,ìṣàn omi ìbá ti bò wá mọ́lẹ̀;
Àwọn alufaa, ọmọ Aaroni ni yóo máa fọn fèrè náà.
Amosi bá dáhùn, ó ní: “Èmi kì í ṣe wolii tabi ọmọ wolii, darandaran ni mí, èmi a sì tún máa tọ́jú igi ọ̀pọ̀tọ́.
Wọn ti ri ninu awọn ọmọdebinrin naa ṣugbọn wọn ko tii pé.
awon eniyan ni opolo todagba daada , to le e ni ironu afoyemo , ede , ifinuwo , ati isojutu isoro .
Bákan náà ló tún ìlérí náà ṣe lọ́dún 2019, sùgbọ́n lẹ́yìn gbogbo èyí, ètò ààbò kò níyanjú, pàápàá jùlọ ní aríwá orílẹ̀-èdè yìí.
Ìkejì ni ọ̀gbẹ́ni Mitt Romney tí í ṣe gómìnà ìpínlẹ̀ Massachusetts.
UNICEF: O fẹ́rẹ tó 900 ọmọdé tó gba ìtúsílẹ̀ lọ́wọ́ àwọn ọlọ́de CJTF
Ó sọ fún wa bí òun ti ṣe rí angẹli tí ó dúró ninu ilé òun tí ó sọ pé, ‘Ranṣẹ lọ sí Jọpa, kí o pe Simoni tí àpèlé rẹ̀ ń jẹ́ Peteru wá.
A kó àdá jọ a sì lọ̀ wọ́n, wọ́n mú bí abẹ.
Awon agbofinro ni ki oko ofurufu awon akoroyin fun won laaye lati le gbo igbe awon to ba n pe fun iranlowo ninu ijamba naa.
Ọdún 2008 ni àwọn ènìyàn bẹ̀rẹ̀ síí mọ̀ ọ̀ lẹ́yìn tó fara hàn nínú eré Jenifa.
Lọ bá àwọn eniyan rẹ tí wọ́n wà ní ìgbèkùn, kí o sọ ohun tí OLUWA Ọlọrun sọ fún wọn; wọn ìbáà gbọ́, wọn ìbáà má sì gbọ́.
”Losu kejo odun to koja ni won bere igbero kiko afara naa nigba ti akekoobinrin omo odun mejidinlogun kan lati San Diego ku sijamba opopona nigba ti o fe soda sodi keji.
Oniruuru irun didi, asọ ibilẹ, ounjẹ ilẹ Ijẹbu tii se Ifọkọrẹ ati ijo ibilẹ ko si ni gbẹyin.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Hakeem: Mo lè sọ arúgbó dí ọmọge nígbà tó bá wù mí Dokita Adan ṣalaye pe oun ti ba Kọmiṣọna ọlọpaa sọrọ lẹyin ti oun gbọ iroyin naa.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Onitsha market fire: Ilé tó lé ni 100 ló bá ìṣẹ̀lẹ̀ ìjàmbá iná lọ ní Onitsha 17 Ọ̀wàrà 2019 Àkọlé àwòrán, Ọja to ṣofo nibi ijamba ina ọhun le ni ẹgbẹgbẹrun miliọnu naira Inu ibanujẹ ati ọfọ ni ọpọlọpọ awọn olugbe ilu Onitsha wa bayii, lẹyin ina to ṣẹyọ ni igba ti ọkọ elepo kan la'na ni ilu ọhun.
    Kí ni iwn gbọ́ bẹ́ẹ̀ ṣe, ó ni, Mo mọ tiyín bẹ́ẹ̀ ẹ̀yin ọmọ ènìyàn, ẹ̀yin onisọ́kúsọ, oníròkurò, onírrìnkurìn, oníwàkuwà, oníjẹkújẹ, onímukúmu, oníṣekúṣe, ọlọ́kẹ̀,ọlọ́ṣà, olè, aláìmọ̀kan, aláìmèrò, aláìlágbára, ẹ̀yin kò mọ̀ pé àwa kì í ṣe ẹgbẹ́ yín?
Oga ọlọpaa naa ni ṣe ni afurasi naa n pariwo Allahu Akbar kíkankíkan.
 Àjẹsára náà tún lè dènà àrùn náà bí a bá fúnni láàárín ọjọ ́ díẹ ̀ lẹ ́ yìn tí ènìyàn bá ti wà ní àyíká ibití àrùn náà gbé wáyé .
Ọpọ lo gbagbọ pe ko yẹ ki Gomian Makinde le pe iru ipade nla bẹ lasiko ti arun coronavirus n rin kaakiri ilu.
Gẹgẹ bi ajọ to n gbogun ti ajakalẹ arun lorilẹede Naijiria, NCDC ṣe fi sita, eeyan mẹrindinlọgbọn lo tun ko arun naa ni ipinlẹ Eko, mẹtalelogun fara kaasa rẹ ni olu ilu orilẹede yii, ogun eeyan lati ipinlẹ Kaduna ti mọkanla si wa lati ipinlẹ Katsina.
Ọwọ́ àlejò yín ni ẹ óo ti máa tọrọ nǹkan, àwọn kò sì ní tọrọ ohunkohun lọ́wọ́ yín.
Àwọn ọmọ Israẹli sin OLUWA ní gbogbo àkókò tí Joṣua fi wà láàyè, ati ní àkókò àwọn àgbààgbà tí wọ́n ṣẹ́kù lẹ́yìn Joṣua, tí wọ́n mọ gbogbo ohun tí OLUWA ṣe fún Israẹli.
Lẹ́hìn ìgbà tí a gba gbogbo oògùn wa tán a múra ogun-jíjà,àwọn ejò náà sí bá wá fi ìjà pa ẹẹ́ta.
Kí ló tún kù tí ó yẹ kí n ṣe sí ọgbà àjàrà mi tí n kò ṣe?
Osun Festival: Ooni ní àwọn ọlọ́ṣun kìí ṣe abọ̀rìṣà Ni ọjọ Satide ni ọdun Ọsun waye nilu Ile Ife lai naani ariwo ati ofin to de iwa itakete ati ijinna sira ẹni.
Gẹgẹ bi alaye ti Interpol fi sita ninu atẹjade, wọn ni ''niṣe lawọn afurasi wọn yi fọna ẹburu lu awọn eeyan ni gbajuẹ nipa fifi imeeli ayederu ransẹ'' Wọn tẹsiwaju pe wọn lo awọn ''virus'' buruku ti wọn fi ranṣẹ yi wọ inu akoto owo ileeṣẹ ijọba ati awọn ileeṣẹ ọlọdani to le ni aadọjọ kaakiri agbaye.
OLUWA yóo fi àrùn jẹ̀dọ̀jẹ̀dọ̀ ṣe ọ́, ati ibà, ìgbóná ati ooru; yóo sì rán ọ̀gbẹlẹ̀, ọ̀dá, ati ìrẹ̀dànù sí ohun ọ̀gbìn rẹ, títí tí o óo fi parun.
2 % , other protestanti 2.
Yoruba ni agba kii wa lọja, ki ori ọmọ tuntun wọ, bẹẹ si ni aye ko gbọdọ toju awọn agba bajẹ.
Yoruba ni ajeje ọwọ kan ko gbe ẹru dori, nitori naa lo fi se pataki lati maa ran ara wa lọwọ.
"Governorship Election Results: Àgbùnbánirọ̀ tó bá INEC ṣiṣẹ́ kú nínú ìjàmbà ọkọ̀ ojú omi l'Ondo Link Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, APC jáwé olúborí nípínlẹ̀ Ekiti ""Eyi si n ṣe ọpọ akoba fun idagbasoke eto ọrọ aje ni ẹkun naa."
"A ti gbọ́ ẹdùn ọkàn yín a sì ti ṣetan láti dá awọn owó náà padà Oríṣun àwòrán, AccessBank Sáájú ni ilé ìfowópamọ́ náà ti fi àtẹjáde kan sọ́wọ́ pé àwọn kò yọ ""Stamp Duty"" lórí kátàkárà tó wáyé láàrín ọjọ́ kini oṣù keji àti ọgbọ̀n ọjọ́, oṣù kẹrin ọdun yìí tẹ́lẹ̀."
Àwọn agbo ẹran yóo dùbúlẹ̀ láàrin rẹ̀, ati àwọn ẹranko ìgbẹ́, àwọn ẹyẹ igún ati òòrẹ̀ yóo sì máa gbé inú olú-ìlú rẹ̀.
Kì í ṣe ọ̀ranyàn ni pé kí á kọ Titu tí ó wà pẹlu mi nílà nítorí pé ọmọ ẹ̀yà Giriki ni.
Mu iṣọri igun kan Mu iṣọri igun kan Bi intanẹt rẹ se yara si Bi wọn se njẹ irẹsi si Ọrọ aje Gbese ti wọn jẹ silẹ okeere Bi ẹmi eeyan se n gun si Iye eniyan to wa ni orilẹede kan Bi ilẹ orilẹede se tẹju si Bi iwa ajẹbanu se gogo si lorilẹede kan Idunnu Awọn obinrin to wa nile asofin Ami ẹyẹ ere idaraya Olimpiki Ibudo ajogunba agbaye ti Unesco Orilẹede wo lo ni intanẹti to yara ju?
"Gbìyànjú àwọn òwé Yòrúbà yìí wò Pàtàkì June 12 fún Nàíjíríà Iṣẹ́ Kudirat Abiọla ṣì ń fọhùn síbẹ̀, lẹ́yìn ọdún 23 tó papòdà Ọ̀nà márún-ún láti mú àdínkù bá dátà (Data) lílò rẹ ""Bí Ajimobi bá dẹ pánpẹ́ sílẹ̀ fún Seyi Makinde, ṣe o fẹ ko maa ba a lọ bẹẹ ko ko si i?"
Àkọlé àwòrán, Shiite ní ó yẹ kí Tinubu lee bá Buhari sọ̀rọ̀ nípa Zakzaky.
Aare Fayez al-Sarraj yoo koko lo se ipade pelu awon adari ijoba
Fayose fi ku ọrọ rẹ pe, o lodi sofin fun ajọ EFCC lati ṣe iwadi oun nigbati saa oun si gẹgẹ gomina nipinle Ekiti ko ti tan.
Yóo sàn fún Tire ati fún Sidoni ní ọjọ́ ìdájọ́ jù fún yín lọ.
 Ọ ̀ pọ ̀ lọpọ ̀ ìwé tí ó wuyì ni ó ń jáde tí a fi àwọn èdè àdúgbò kọ , bí àpẹẹrẹ , uzbek .
Mnisita ba sọ fun wọn pe ki wọn lo owo naa fun awọn nkan ti wọn ko tii ri yanju niwọn igba ti kii ṣe owo wọn ṣugbọn wọn o s iru nkan ti wọn fi owo naa ṣe.
Sẹnẹtọ Bukola Saraki ni sisọ fun ile ẹjọ pe ko gbẹsẹ le dukia oun ni Ilorin tumọ si idunkooko mọni ati lilo agbara nilo kulo.
"Oṣere ọmọ Ilorin yii ti baba rẹ ati aburo rẹ naa jẹ akẹgbẹ fun un ninu iṣẹ fiimu ti n fi oriṣiriṣi aworan sinima ara ọtọ meji kan sita - ""Ẹsin Agbere"" eyi to ṣe lati fi tu aṣiri awọn aafaa to n ṣe lodi si bi o ṣe yẹ ki wọn maa ṣe ẹsin ati ""Sisi""."
    Ìgbà tí ó di ọjọ̀ kejì, Wèrédìran wá bẹ̀ mi wò gẹ́gẹ́ bí ó ti sọ, èmi náà sì wí fún un pé n ó dé ilé rẹ̀ lọ́jọ́ kẹta èyí nì.
Bí ọ̀rọ̀ orin kan ti sọ, pé,“Dìde, ìwọ tí ò ń sùn;jí dìde kúrò ninu òkú,Kristi yóo tan ìmọ́lẹ̀ sí ọ lára.
Ko tan sibẹ, ẹgbẹ Feminisit Coalition tun pẹlu alaafia ni awọn oluwọde EndSARS fi n se iwọde wọn yika Naijiria, ti wọn si safihan iwa ọlọgbọn.
Igbimọ yii ni Sanwo Olu gbekalẹ lẹyin ti ijọba Naijiria tu ikọ awọn olọpaa kogberegbe ka kaakiri Naijiria.
sibẹ ìró wọn la gbogbo ayé já,ọ̀rọ̀ wọn sì dé òpin ayé.
Èyí ni àwọn tí òfin kónílé-ó-gbélé tí ààrẹ Buhari pa l'áṣẹ kò kàn ní Eko, Ogun àti Abuja Ó ṣe é ṣe kí o ti ní coronavirus kí ó má mọ̀ nítorí pé ó kò rí àpẹẹrẹ Máfọ́ya, mo wà pẹ̀lú ẹ, Ajimọbi kàn sí Makinde lóri Coronavirus to ni Èèyàn mẹ́wàá míì tún ti ní àrùn Coronavirus ní Naijiria, àpapọ̀ jẹ́ 184 Ki wá ní è àwọn ewu bí òjò orí bá ṣe ń gòkè sì?
Lara awọn ti aarẹ Buhari ko ni ba ṣisẹ ni saa yi ni Audu Ogbeh, minista fun eto ọgbin.
OLUWA bá dá Mose lóhùn pé, “Wò ó, mo ti sọ ọ́ di ọlọrun fún Farao, Aaroni, arakunrin rẹ ni yóo sì jẹ́ wolii rẹ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Wasiu Ayinde: Èmi àti Aláàfin sọ fún Gani Adams nípa oyè Mayegun, a kò jà rárá Gbajugbaja oniṣegun ibilẹ ni Alhaji Fatai Ọkọoloyun ti o jẹ ilu mọọka pẹlu awọn ọkan-o-jọkan ogun ibilẹ rẹ eleyi ti o gbajugbja.
Ìwádìí bẹ̀rẹ̀ lórí iná tó sọ nileeṣẹ EFCC
Eyo sọ eyi ninu ọrọ kan to ba BBC sọ pe ni kete ti iṣẹlẹ naa waye ni oun ti gba fun Ọlọrun.
Samuẹli pa ọmọ aguntan kan tí ó ṣì ń mu ọmú, ó sun ún lódidi, ó fi rúbọ sí OLUWA.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Mansa Musa: Ó lówó, ó ní dúkìá rẹpẹtẹ àmọ́ kò pẹ́ láyé 20 Ẹrẹ̀nà 2019 Oríṣun àwòrán, @ItsMansaMusa Oludasilẹ ile iṣẹ Amazon, Jeff Bezos lo lowo julọ lagbaye bayii gẹgẹ bi atẹjade ti iwe iroyin Forbes gbe fi lede, pẹlu owo to le ni biliọnu lọna aadoje owo dọla ($131bn) Ṣugbọn iwadii fihan pe, ọmọ ilẹ Afririka lo lowo julọ lagbaye ninu itan ni Mansa Musa.
Ohun ni ijọba to buruju, koda bii egun lo ri.
Ijọba funrare kọ lati tele asẹ ile ẹjọ to ni ki o si awọn ile ise iroyin to tipa pada.
Bá mi kí àwọn ará ilé rẹ,
Coronavirus lè tara òkú Abba Kyari ran àwọn tó péjú síbi ìsìnkú rẹ̀- Ààrẹ ẹgbẹ́ dókítà ní Nàìjíríà Sultan, ẹni tí akọ̀wé ẹgbẹ́ àpapọ̀ musulumi, Ọmọwe Khalid Abubakar-Aliyu gba ẹnu rẹ sọ̀rọ̀ nílu Kaduna, tun rọ àwọn musulumi lati mase lọ fún Haji kékeré taa mọ si Umurah nílẹ̀ Saudi Arabia nítorí àrùn Coronavirus.
Ọmọ eniyan jẹ lára oúnjẹ àwọn angẹli;Ọlọrun fún wọn ní oúnjẹ àjẹtẹ́rùn.
Pẹlu ibọn lọwọ ni awọn ajinigbe wọnyii ko awọn obinrin naa ni agbegbe Kumasi niwaju Dema Private Hostel.
Bayii, ìjóba Naijiria ti fi ofin de lilo Coedine ati Tramadol ninu òògùn ikọ́ pípò.
Oshiomhole se so lasiko to n ba awon akoroyin soro, o fi oro re mule wipe, egbe
Orile-ede Naijiria ko tun gbodo foju wina isele awon akekoo Chibok ti o waye ni nnkan bi odun merin seyin, fun idi eyi, ile-igbimo asofin ti pinnu nipa sise agbekale igbimo oluwadii kan,lati bere iwadii lori isele ohun ni kiakia.
Ẹ pe àwọn àgbààgbà jọ,ẹ kó àwọn ọmọde ati àwọn ọmọ ọwọ́ jọ.
Ọ̀pọ̀ olólùfẹ́ Iya Jogbo banújẹ́ lórí ìròyìn ikú rẹ̀ Wo àwọn nkan tó yẹ kí o mọ̀ nípa Abdulganiyu Abdulrasaq, bàbá gómìnà Kwara tó kú Ọ̀gá tíṣà rí ẹ̀wọ̀n ọdún mẹ́wàá he nílùú Eko fún ẹ̀sùn lílú jìbìtì Ò kéré tán N1million là ń ná lórí alárùn Coronavirus kọ̀ọ̀kan; àlàyé rèé- Ìjọba Eko 'Kìí ṣe pé ìjánu Ọkọ̀ tó pa Tolulope Arotile já tàbí kò já, ìwádìí wà lọ́wọ́ ọlọ́pàá' Ayoola Faleti to jẹ akọbi Adebayo Faleti sọ nipa gbogbo ipa baba rẹ lati fi tọ wọn ni ilana ẹkọ to yẹ nigba to wa laye gẹgẹ bii obi rere si ọmọ.
Election Update 2019: Amúgbálẹgbẹ̀ẹ́ Saraki ní ọ̀gá òun kò kí olùdíje APC kú oríire
Adonija yìí ni wọ́n bí tẹ̀lé Absalomu, ó jẹ́ arẹwà ọkunrin; baba rẹ̀ kò sì fi ìgbà kan dojú kọ ọ́ kí ó bá a wí nítorí ohunkohun rí.
Eyi jẹ́ ki wọn sọ ilé di ọ̀wọ́n, nitori owó ti wọn má a ri gbà lọ́wọ́ Onilé àti Agbalésanwó lai ro inira Agbalésanwó.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Sim Card Regulation: Amòfin kan ní iye ‘Sim Card’ ta bá ní, kò ní ǹǹkan ṣe pẹ̀lu ìwà ọ̀daràn 6 Èrèlè 2020 Oríṣun àwòrán, Getty Images Awọn ọmọ Naijiria kan ti sọ pe, ọrọ iye Kaadi ibaraẹnisọrọ, Sim Card ti eeyan n lo kọ lo yẹ ko jẹ ijọba logun bayii, bikoṣe bi o ṣe maa ṣakoso awọn ileeṣẹ ibanisọrọ.
Laarin bii ọjọ kẹta, wọn ti wa fi katakata hu gbogbo igbo yẹn.
Wọ́n sì jagun títí dé Mareṣa.
Igbe àyé Ọbáfẹ́mi Awólọ̀wọ́ nigba aye rẹ̀ Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí kan sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
Iléèṣẹ́ Ààrẹ bẹ àwọn aṣòfin láti bẹ̀rẹ̀ ìjókò padà Ṣaaju ki Saraki to pe ipade pajawiri naa ni ileeṣẹ aarẹ bẹ àwọn aṣofin pe ki wọ́n bẹrẹ ijoko ilé ìgbìmọ̀ padà laipẹ nitori ọ̀rọ̀ Nàìjíríà.
Sibẹsibẹ, ninu àìsàn náà kàkà kí ó ké pe OLUWA fún ìwòsàn, ọ̀dọ̀ àwọn oníṣègùn ni ó lọ.
Awọn ọmọ orilẹede Naijiria n fẹ ẹkunrẹrẹ iroyin nipa rẹ, kii se ariwo gee ni wọn n fẹ, nitori pupọ awọn dukia yii ni wọn ti ta, ti wọn si tun ti tun ta.
"Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: ""Mo fẹ́ pa ara mi torí ojú àbùkù tí wọn ń fi wò mí pé mo fi iṣẹ́ abẹ bímọ"" Fulani kò leè dúró, táa bá lo ohun ta jogún lọ́dọ̀ àwọn bàbá wa - Sunday Igboho Ọjà Àgbáláta ní Badagry rèé, níbití ẹran ejò ti dùn ju ẹran adìẹ lọ Ọlọ́run yóò ṣe ìdájọ́ nkan tó wà láàrin èmi àti Ireti Ajanaku - Tope Alabi A kò jáde ṣe ìwọ́de ìtagbangba mọ́, inú ọkàn wa lá ti máa ṣe ìfẹ̀hónú hàn - Revolution Now Arabinrin Dakolo sọ pe ọsẹ bi i meji sẹyin ni oun ṣe ifọrọwanilẹnuwo naa pẹlu UK Guardian."
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Odumakin sọrọ lori Fulani darandaran Adamu fi da Oloye Reuben Fasoranti loju pe oun a rii pe agbara ofin mu awọn oniṣẹ ibi ti awọn ọlọpaa pe ni agbebọn.
Ọkunrin gbọ̀ngbọ̀nràn kan wà níbẹ̀, ìka mẹfa ni ó ní ní ọwọ́ kọ̀ọ̀kan ati ní ẹsẹ̀ kọ̀ọ̀kan.
Child Education: Mílíọ̀nù mẹ́rìndínlógún ọmọdé ni kò sí níléèwé lórílẹ̀èdè Nàìjíríà
Lara awon to wa nibe ni, adari
Egungun rẹ̀ dàbí ọ̀pá idẹ,ọwọ́ ati ẹsẹ̀ rẹ̀ rí bí irin.
Wọ́n bá dìde lẹsẹkẹsẹ, wọ́n pada lọ sí Jerusalẹmu.
ile-igbimo asofin, ti wa loju ona bayii pada siluu Abuja.
Wọ́n bá pada sí Sifi ṣáájú Saulu.
Oríṣun àwòrán, @NGF Àkọlé àwòrán, Adamu ṣalaye pataki radio Fulfulde pe kawọn darandaran le ni ẹkọ to peye ni Nibi ipade asegbẹyin awọn minista yii ni Adamu ti ni inu oun ko dun to nitori oun ko ri awọn ọmọ ko pe lọ sile iwe de idaji.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Bakare Mubarak: ọ̀pọ̀ èèyàn ló máa ń fẹ́ dúró sí ẹgbẹ́ mí tójú si máa n tì mí Akitiyan lati kan si alukoro ileewe giga naa lati mọ iha awọn alaṣẹ ileewe naa lo ṣi ja si pabo.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Olufon ti Ifon Murder: Àwọn agbébọn tó pá Olufon ti Ifon ti ṣe ohun èèwọ̀ ní ilẹ̀ Yoruba 27 Bélú 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 1 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Oríṣun àwòrán, flashinfoNg12/twitter Awọn lọbalọba nipinlẹ Ondo ti ni ohun eewọ ni awọn agbebọn to ba Olufọn ti Ifọn, Oba Isreal Adeusi ṣe lẹyin ti yinbọn pa.
Ilé wó lu ọ̀gọ̀ọ̀rọ̀ èèyàn ní Abraka Kò sí ẹni tó léè dí àlàfo tí Funke fi sílẹ̀ - Ọkọ rẹ̀, Olakunrin lahùn fún ìgbà àkọ́kọ́ Barrister ló sọ mí di èèyàn ńlá - Ayinla Kollington O ni awọn ọba mejeeji naa ti fun oun ni imọran lori ọna ti awọn le gba, lati mu ki eto aabo gbooro si kaakiri awọn agbegbe to wa lorilẹede Naijiria.
 kò gbọ ́ iṣẹ ́ olúwòó , bẹ ́ ẹ ̀ ni kò rí ikọ ̀ tìmì .
Mo yìnbọn títí ẹ̀tù fi tán ni àpò mi ṣùgbọ́n àwọn ẹran tí mo rí pa ní  àkókò tí ẹ̀tù wwà ṣe mí lóoore gan-an ni.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Sọ́ra fún gbájúẹ̀, BBC kò ṣètò owó ẹ̀kọ́ ọ̀fẹ́ Kí lo fẹ́ mọ̀ nípa D.
'Orúkọ pásítọ̀ ni Magu fi ra ilé N573 mílíọ̀nù sì Dubai - PCARA Ẹ wo Daniel tí wọ́n fẹ́ yẹgi fún lẹ́yìn tí US kò ṣe irú ẹ̀ fún odidi ọdún 17 Nínú ọ̀rọ̀ rẹ ọkan lára àwọn tó ń bá alábàráà sọ̀rọ̀ fún ilé iṣẹ́ náà Nonye sàlàyé pé ọkọ̀ òfurufú (Helicopter) náà yóò má gbé ènìyàn mẹ́jọ ni ìrìn ẹ̀ẹ̀kan.
Ọmọ mi, bí o bá gbọ́n,inú mi yóo dùn.
Lọjọ Kẹsan an, oṣu Kẹjọ ni gbedeke fifi iwe ranṣẹ loju opo N-power wa sopin lẹyin ti wọn ti gba iwe awọn to n wa iṣẹ to le ni miliọnu marun un lọ.
Idẹyẹsi awọn ọmọ ilẹ Afrika lati ọwọ awọn ọmọ South Afrika ko ṣẹṣẹ ma waye.
Àbí, kí ló pa èmi ati ìwọ pọ̀?
Loju opo Twitter,niṣe ni awọn eeyan n daro iku Richard.
Mose bá pàṣẹ fún àwọn ọmọ Israẹli, gẹ́gẹ́ bí OLUWA ti wí fún un, pé, “Ohun tí ẹ̀yà Manase sọ dára, 
Lẹ́yìn èyí ní àwọn ènìyàn ọkánléláadọ́rin dìbò yan Akintoye nígbà ti ènìyàn mẹ́ta yan Asiwaju Ahmed Tinubu.
Ọgbẹni Zulum fi aridaju ọrọ sita pe awọn Boko Haram yabo oko kan ni Koshebe nibi ti wọn ti kọkọ waasu fun awọn agbẹ to wa nibẹ lẹyin naa ni wn ko wọn sinu ile kan ti wọn ti bẹrẹ si ni mu wọn jade lọkọọkan lati dumbu wọn.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ikọ̀ Super Falcons ṣetán láti kojú Equatorial Guinea Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Ǹ bá dá a dúró, kó máa wà lọ́dọ̀ mi, kí ó lè máa ṣe ìrànlọ́wọ́ fún mi dípò rẹ lákòókò tí mo wà ninu ẹ̀wọ̀n nítorí iṣẹ́ ìyìn rere.
Òfin ṣì gbẹ́sẹ̀lé Ẹgbẹ́ awakọ̀ èrò NURTW ní ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́ Nítoríi fóònù ìbánisọ̀rọ̀, géńdé méjì kú sínú u kọ̀ǹga l'Ékìtì Ni ipari Shittu mẹnuba bi gbogbo agba ẹgbẹ APC ṣe kilọ fun Ajimọbi ṣugbọn ti ko gbọ ki APC to padanu ipinlẹ Oyo ninu idibo gomina to kọja.
Pẹlu bi nnkan ṣe ri yii, ẹgbẹrun mẹtadinlaadọrin o le ọọdunrun ati ọgbọn (67,330) eeyan lo ti ko aarun naa lorilẹede Naijiria lati igba ti wọn ti kẹẹfin ẹni akọkọ to laarun naa ni Naijiria ni ibẹrẹ ọdun 2020.
Nnkan bii ọgọjọ miliọnu awọn ọmọ Naijiria ti ko fẹ padanu ila ipe wọn lo bẹrẹ si n ṣu bo awọn ẹka ileeṣẹ NIMC ọhun kaakiri Naijiria, eyii ti NCDC sọ pe o lagbara ran itankalẹ arun Coronavirus lọwọ.
 ( 30 december , 1958 ) .
Wọn kede pe ko ni si iṣẹ ni ọjọ Iṣẹgun, ọjọ kẹrin, oṣu yii ati ni ọjọ karun un, Ọjọru ọsẹ yii.
Awọn kan tilẹ n sọ pe, boya ile iwosan ijọba ti Garki ti wọn gbe oloogbe naa lọ si ni ko ṣe iṣẹ wọn to, sugbọn ọgbẹni Awosanya ni ko ri bẹẹ.
Ondo election 2020: Àwọn ara ìpínlẹ̀ Ondo ránṣẹ́ sí Akeredolu ohun ti wọ́n ń retí ní báyìí Tani Akeredolu tó wọlé láti tukọ̀ ìṣàkóso ípìnlẹ̀ Ondo lẹ́ẹ̀kejì yìí?
Àwọn obi ọmọ Obìnrin Chibok ni wọn tí lọkọ ní Cameroon
Abiola Ajimobi: Tinubu ní àwọn ìpínlẹ̀ ló yẹ kó máa gba owó orí ọjà
Oríṣun àwòrán, XXX Àkọlé àwòrán, Rauf Aregbesola yoo fi ipọ gomina si le leyin ọdun mẹjọ labẹ ẹgbẹ oselu APC Abdul'aziz Abubakar Yari sọ wi pe idibo abẹlẹ naa se afihan bi idibo gbogboogbo yoo ti se lọ ni ọdun 2019.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ibugbamu afẹfẹ gaasi meji pa ọpọ eniyan nipinlẹ Eko Ààyè sí sílẹ̀ fún ọmọ Nàíjíríà láti di ológun nílẹ̀ Gẹẹsì Ohun márùn ún to se kókó fún ọ lásìkò ìyanṣẹ́lódì òṣìṣẹ́ Ààyè sí sílẹ̀ fún ọmọ Nàíjíríà láti di ológun nílẹ̀ Gẹẹsì Kí lo fẹ́ mọ̀ nípa ‘Ajala Travels’?
Àwọn sinimá tó pegedé ni 2018 lágbàyé Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ṣọla Allyson: Obìnrin tí kò bá rẹwà ni yóò máa ṣí ara sílẹ̀ Ijiroro n waye lati dena iyanṣẹlodi Iroyin ta gbo sọ wi pe awọn ti ọrọ kan lẹka yi ti n gbe igbese lati ri wi pe wọn dena iyanṣẹlodi yi ti o le mu inira ba awọn arinrinajo ofurufu ni Naijiria.
Mo dìde mo lọ sílé Ìbínú-ẹkùn láti yíì lọ́kàn padà kúrò nínú èrò yìí, ṣùgbọ́n pẹ́lú kùmọ̀ ni o fi lé mi jáde.
"A o maa gbadura fun ajinde ara ni kiakia fun ọ.
A ti fẹnu kò lórí ọ̀rọ̀ Brexit- Boris Johnson Funke Adesiyan, òṣèré Yollywood tó di olùrànlọ́wọ́ aya ààrẹ, Aisha Buhari Ibẹẹta ati ọmọ iya wọn jona ni jigawa Bakan naa lo ṣalaye pe awọn olugbe Onitsha ti n bere idi ti ileeṣẹ panapana ipinlẹ ọhun ko ṣe da wọn lohun lasiko ti wọn ke si wọn, ni kete ti ina naa bẹrẹ.
si igbe ati ẹdun ọkan awon eniyan , ni eyi ti won yoo fi lee maa gba ijoba
Nàìjíríà kó 354 nínú ẹ̀ lọ́jọ́bọ̀ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ìdílé tí ọkọ da ọmọ síta tóríi ojú Búlùú tí wọ́n ní bá BBC sọ̀rọ̀ Buka/ile ounjẹ igbalode/omi/ọti ẹlẹrindodo Bẹẹ ba fẹ we ọwọ ounjẹ okele, jantirẹrẹ lawọn ile ounjẹ wa ni aaye ti wọn ya sọtọ fun itaja.
Idi ti mo fi lọ fun imọ ẹkọ yii ni wi pe awuyewuye wa pe orilẹede wa nilo ọpọlọpọ amojuẹrọ."
Kabiyesi Ọba Ajibade ṣalaye pe ibi Arẹmọ naa tun tubọ fi idi ajọṣepọ lati iṣọkan ati ipilẹ to wa laarin Ifẹ ati Ọwọ mulẹ ni.
Ẹ kò lè mu ninu ife Oluwa tán kí ẹ tún lọ mu ninu ife ti ẹ̀mí burúkú.
N óo ṣa àwọn ọlọ̀tẹ̀ ati àwọn tí ń ṣe oríkunkun sí mi kúrò láàrin yín.
Ileẹjọ ni idunkoko mọ fun awakọ Uber naa, Aleksander Bonchev ti to gẹẹ nitori awọn ero mii naa ti ṣe ikọlu fun un lẹyin wa.
Nígbà tí àkókò bá tó, ojú yóo ti olukuluku wolii fún ìran tí ó rí nígbà tí ó bá ń sọ àsọtẹ́lẹ̀, kò sì ní wọ aṣọ onírun mọ́ láti fi tan eniyan jẹ.
A fẹ́ràn rẹ̀ nítorí pé Ọlọrun ni ó kọ́ fẹ́ràn wa.
Fún ọ̀sẹ̀ mẹta ni ó fi ń bá wọn fi ọ̀rọ̀ wé ọ̀rọ̀ láti inú Ìwé Mímọ́.
Ẹni tí ó bá ni talaka lára àbùkù Ẹlẹ́dàá rẹ̀ ni ó ń ta,ṣugbọn ẹni tí ó ṣàánú fún àwọn aláìní ń bu ọlá fún Ẹlẹ́dàá rẹ̀.
A máa gbà wọ́n lọ́wọ́ àwọn aninilára ati oníwà ipá,ẹ̀mí wọn sì ṣe iyebíye ní ojú rẹ̀.
Amọ o se ni laanu pe meje ninu awọn ọmọ wọn yii lo ku lalẹ ọjọ kan ṣoṣo.
Àwọn ará ìlú náà bá wí fún Joaṣi pé, “Mú ọmọ rẹ jáde kí á pa á, nítorí pé ó ti wó pẹpẹ oriṣa Baali, ó sì ti gé ère oriṣa Aṣera tí ó wà ní ẹ̀gbẹ́ rẹ̀.
Ipade naa lawọn fọwọ si ki Comrade Sam Agbetuyi di ipo akọwe ẹgbẹ mu gẹgẹ bi fidihẹ.
idibo abẹle lo ti fidi re’mi.
Alukoro ile iṣẹ́ ọlọ́pàá, Bala Elkana sọ pe Blessing Bayo ati Smart Alfred lorukọ awọn afurasi ọun.
Afirika ni iṣẹlẹ ifipagbajọba ti pọju lagbaaye.
Apapa Gridlock: Ààrẹ Buhari ti pàṣẹ kí wọ́n ó kó àwọn ọkọ̀ kúrò láàrin ọjọ́ díẹ̀
Mò ń tọ̀ s'ára ni mo fi gba ara à mi l'óko ẹrú ní Oman 'Ojú mi rí tóó, àwọn ìyàwó kìí ṣiṣẹ́, ọkọ àtàwa ọmọ-ọ̀dọ̀ laláṣekú lórílẹ̀èdè Oman' 'Iṣẹ aṣẹwo ni wọn fi mi ṣe ni Moscow' Òwò ẹrú pé irinwó ọdún tó bẹ̀rẹ̀, àwọn Amẹrika tó jẹ́ dúdú wá sí Afirika láti bẹ ilé wò Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí 3 sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 2:23 Fídíò, Water Generator: Ó leè ṣiṣẹ fún wákàtí mẹfà, kó tó sinmi, Duration 2,2310 Òkùdu 2020 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
Gbogbo ijọba ibilẹ mẹtalelogun to wa nipinlẹ Oyo ni igbimọ PMS wa.
Nígbà tí ó parí àkókò tí yóo fi ṣiṣẹ́ alufaa ninu Tẹmpili, ó pada lọ sí ilé rẹ̀.
Onimọ kan nipa imọ ori ayelujara, Shola Akinlade salaye fun BBC nipa igbesẹ marun ti oludokowo lori ayelujara kan gbọdọ gbe, ko to le lu aluyọ.
Mo bá pe àwọn ènìyàn mi, mo ní kí olúkúlùkù mú abẹ nínú àpò rẹ̀ kí á gé ẹ̀wù náà wẹ́lẹwẹ̀lẹ kúrò lara iwin náà.
N85mílíọnù àtàwọn ẹ̀bùn míràn ni olúborí BBNaija yóò gbà lọ́dún yìí Eto agbelewo ile ẹlẹgbọn agba ti a mọ si Bbnaijia ti ọdun 2020 yoo bẹrẹ ni ọjọ Aje to n bọ yii, iyẹn ọjọ kọkandinlogun oṣu keje.
Ọpọlọpọ awọn obi ni ilẹ adulawọ ni ko loye nipa iru nkan ti eniyan le ṣe lati ba ọmọ wi lai fi iya jẹ ọmọde naa.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Mo máa n forin mi kìlọ̀ ìwà ìbàjẹ́ láwùjọ ni -Hameen Yara igbalejọ Theophilus Ogunlesi Multipurpose Hall ni ipade naa yoo ti waye.
Òtítọ́ ọ̀rọ̀ ọ̀rẹ́ ẹni lè dunni bí ọgbẹ́;ṣugbọn ẹ̀tàn ni ìfẹnukonu ọ̀tá.
Àwọn tí wọn yóo kú ikú ìyàn,kí ìyàn pa wọ́n;àwọn tí wọn yóo lọ sí ìgbèkùn,kí ogun kó wọn lọ.
Ìjọba gbé ilé ijó oníhòhò tì pa lórí ẹ̀sùn títàpá sí ìlànà àti dẹ́kun coronavirus Coronavirus: ''Ìjọba kò tíì pàṣẹ ìlànà ìtakété-síra-ẹni padà nínú BRT la ò ṣe máa tẹ̀le'' Àwọn tó jí àwọn akẹ́kọ̀ọ́ GSSS gbé ní Kankara ti kàn sí wa - Masari Wọ́n ti fi Omah Lay sínú ọgbà ẹ̀wọ̀n ní Uganda Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Akomolede ati Aṣa: Mọ̀ síi nípa ìró afárànma àti agbárànmọ́ fáwẹ́ẹ̀lì Yorùbá Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
O gbagbọ pe awọn iriri naa lo sọ ọ di oloju aanu, ti kii fi oju kere ẹni to ba nilo iranlọwọ tabi jẹ onibara.
Ìyá dú ọmọ rẹ̀, o yíi láta, ó sì tún jòkó jẹ ẹ́ Adigunjalè fọ́ báńkì ní Oye Ekiti, wọ́n tún ṣun ọkọ̀ ọlọ́pàá níná Gbogbo ohun tó bá gbà lá máa fún un láti wa àwọn agbébọn náà- Ọlọ́pàá Andrew Haruna: So-bàtà tó di ọ̀jọ̀gbọ́n fásitì tó tún jẹ́ ọ̀gá àgbà pátá (V.
Ohun to ba wu kaluku ni ko fi ẹnu rẹ sọ lori ayelujara.
Bo tilẹ jẹ pe iya rẹ bi ọmọ naa saye, o gba ibẹ lọ.
fọwọsowọpọ wa iyanju patapata si ipenija eto aabo ti a n koju yii.
Bakan naa lo sọ pe iyalẹnu lo jẹ fun oun, nigba ti EFCC mu oun de ọfiisi won, ti ajọ naa sọ pe, miliọnu marunlelọgọta Dọla ni oun gba, dipo mẹẹdogun.
Opọlọpọ ọdun sẹyin ni wọn ti gbiyanju lati ta gita Cobain yii ni Rock and Roll Hal;l of Fame ki won to wa rii ta lọjọ Abamẹta yii.
O kò gbọdọ̀ gba àbẹ̀tẹ́lẹ̀, nítorí pé àbẹ̀tẹ́lẹ̀ a máa fọ́ àwọn aláṣẹ lójú, kì í jẹ́ kí wọn rí ẹ̀tọ́, a sì máa mú kí wọn sọ ẹjọ́ aláre di ẹ̀bi.
Mose ati Aaroni kúrò níwájú àwọn eniyan náà, wọ́n lọ dúró ní ẹnu ọ̀nà Àgọ́ Àjọ, wọ́n dojúbolẹ̀, ògo OLUWA sì farahàn.
Adari ikọ naa, Captain Usolo lo kede rẹ lọjọ Aje lẹyin ti o tọrọ aforijin lọwọ awọn eeyan ti wọn yanjẹ.
Idí tí àwọn dókítà ọpọlọ kò fi faramọ́ lílo igbó fún ìtọ́jú àìsàn Canada sọ igbó mímu àti títà rẹ̀ di ìrọ̀rùn Idí tí àwọn dókítà ọpọlọ kò fi faramọ́ lílo igbó fún ìtọ́jú àìsàn Akeredolu, Ọgá NDLEA lọ kọ nípa gbíngbin igbó ní Thailand Sé Nàìjíríà yóò gba lílo igbó láàyè?
Ẹni tó bá ń bínú kàn ń bínú lásán ni- Oyedepo Lóòtọ́ ni mo yìnbọn níbi yánpọnyánrin tó wáyé ládúgbò mi-Seun Kuti ''Buhari àti Tinubu ṣ'àdéhùn pé Yorùbá ni yóò jẹ́ olùdíje ipò ààrẹ APC lọ́dún 2023'' Ọwọ si ti pada tẹ ọlọpaa mẹta, fun pe wọn pa imọ pọ pẹlu awọn to ṣeto ariya naa, lati pese aabo nibẹ.
Àwọn ọmọ Israẹli kó àwọn obinrin ati àwọn ọmọ Midiani lẹ́rú.
Ninu esi rẹ, Agbẹnusọ Ile Igbimọ Aṣofin Ipinlẹ Eko, Aṣofin Mudashiru Ọbasa fi kun oṛọ awọn aṣofin yooku lati bẹnu atẹ lu iwa naa.
Sanyeri ni oun maa n kabamọ pe oun ko kawe nitori ti oun ba kawe, oun ko ba ti ju bayii lọ.
APC Yemi Osinbajo, Peoples Democratic Party,PDP)  Petr Obi ati Young Progressive Party YPP) Umma
Àwọn ọmọ ogun ilẹ̀ Nàìjíríà dóòlà ẹ̀mí ẹni méjì ní Owena ní Ondo Wo àwọn nkan tó yẹ kí o mọ̀ nípa Abdulganiyu Abdulrasaq, bàbá gómìnà Kwara tó kú Ọ̀gá tíṣà rí ẹ̀wọ̀n ọdún mẹ́wàá he nílùú Eko fún ẹ̀sùn lílú jìbìtì Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ìjọba ilẹ̀ Turkey yí ilé Ìṣẹ̀mbáyé tó ti lo ọdún 1,500 padà sí Mọ́ṣáláṣí Ki lo ti ṣẹlẹ sẹyin?
Bi a ti se n sọrọ yi, awọn ile ẹkọ wọnyi ti di ahoro ti awọn akẹkọọ si ti tuka pada soju titi nibi ti wọn ti n tọrọ bara.
Máa sáré lọ, sáré bọ̀ ní àwọn òpópónà Jerusalẹmu,wò yíká, kí o sì ṣàkíyèsí rẹ̀!
Oríṣun àwòrán, DesmondOElliot Desmond Elliot ko sọ ju pe ki awọn gbajumọ lawujọ ati awọn oloṣere ye sọrọ kobakungbe lori ayelujara mọ-o tun pe awọn oluwọde ni ''ọmọde'' Hmm.
 arábìnrìn kongo la gbọ ́ pó dá ilú woyo kejì silẹ ̀ .
Dafidi ń ṣe àṣeyọrí ninu àwọn iṣẹ́ tí Saulu ń rán an.
Ewe, ijoba ilu Mogadishu binu lopolopo si erongba awon Emirati lati ko iko omo ogun wa si ipago igbaradi ti o gunle si orile-ede Somalia, won wa fi mule pe, awon ko nilo iranwo ijoba UAE mo bi o ti le wu ko mo.
Pẹlu owo osu rẹ, yoo gba ọ ni odun 130 lati gba iye owo ti sẹnatọ kan n gba lọdọọdun.
Ati pe ki awọn olori to ba ni i, ko gba ilu oyinbo ti wọn maa n lọ tẹlẹ lọ lati gba itọju.
Òyìnbó ẹni ọdún 46 wá ṣe mọ̀'mí n mọ̀ ọ́ ní Kano pẹ̀lú Isah olólùfẹ́ rẹ̀ Àwọn ọjọ́ ìsìnmi tó máa wà nínú ọdún 2020 ní Nàìjíríà Nibayii lẹnu wakati melo lọjọ kan naa, Davido ati aya rẹ Chioma tun ti bẹrẹ si ni tẹle ara wọn gẹgẹ bii ọrẹ lori oju opo ayelujara awọn mejeeji.
Ajọ naa sọ pe ọna ti wọn n gba ṣe iwọde ọhun tako ilana ati dena itankalẹ aarun coronavirus bii itakete si ara ẹni.
Solomoni mú iyawo náà wá sí ìlú Dafidi títí tí ó fi parí ààfin rẹ̀ ati ilé OLUWA tí ó ń kọ́, ati odi Jerusalẹmu tí ó ń mọ lọ́wọ́.
Bi o tilẹ jẹ pe emi ko tii foju kan-an lati ọ̀dun mẹfa sẹyin, n se lo dabi ẹni pe ọsẹ diẹ sẹyin ni mo ti ri gbẹyin, nigba ti a foju kanra loni.
Bakan naa lo sọ pe ibugbe idokowo nla l'Eko jẹ fawọn gbajugbaja oniṣowo papaa julọ pẹlu ọpọ eeyan to n gbe niluu Eko.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Natalia Mufuta ìyá Yakub, Kamil àti Adam sọ̀rọ̀ lórí bí wọ́n ń sọ èdè mẹ́rin pàpọ Lootọ, ni ọjọ Ẹti ni iroyin kan jade pe Olubadan ti ilẹ Ibadan, Ọba Adetunji ti fi Alhaji Yekeen Abass ti ọpọ mọ si YK Abass, baba alaṣọ ni Gbagi ni ilu Ibadan jẹ ni aafin olubadan.
Agbenusọ fun ajo ọlọpa ni ipinlẹ Ogun, Abimbọla Oyeyẹmi nigba to n sọrọ lori isẹlẹ naa, wipe awọn ẹgbẹ ajinigbe naa ti ji ọkunrin kan, Saani Nasarawa gbe, ti wọn so o mọ igi fun ọjọ meje, nigba ti wọn duro de awọn ẹbi rẹ lati san owo idasilẹ Oyeyẹmi wi pe ọkunrin ti wọn jigbe naa tu ara rẹ silẹ, ti o si na papa bo'ra nigba ti awọn ti o jii gbe n sun.
Ẹni to bori: Côte d'Ivoire Cameroon vs Mali.
Kí òkun ó hó, ati gbogbo ohun tí ó wà ninu rẹ̀,kí ayé hó, ati àwọn tí ń gbé inú rẹ̀.
Àkọlé àwòrán, Aworan afikun iroyin nipa ajakalẹ arun coronavirus ni Naijiria Atupalẹ onka iye awọn to ti ni aarun naa, iye awọn to n gba itọju lọwọ, iye awọn to ti ri iwosan ati awn ti arun naa ti ran lọ si ọrun niyi ninu atẹ tabili yii.
Bakan naa lo ṣalaye pe, ko si eeyan to kọja ofin irinna lorilẹede Naijiria.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Sheffield vs Chelsea: Ayé le!
Wo ohun tí ilé ẹjọ́ ní kí wọ́n ṣe fún Sunday Shodipe, afurasí ìṣekúpani l'Akinyele Èèmọ̀!
Ohun ti wọn n ṣe ninu ẹgbẹ naa ni lati ma a kọ ara wọn ni ẹkọ lati jẹ ọkunrin gidi, gẹgẹ bi ọkọ, baba, oṣiṣẹ inu ijọ ati adari.
 tí èni tó eà níbẹ ̀ lásìkò yí jẹ ́ director-general ìyẹn ọ ̀ gágun brig.
Aawọ ṣẹlẹ laarin awọn mejeeji lẹyin ti ọga ọlọpaa ni Adeniyi ti ba aṣọ oun jẹ.
Èyí ni pé òfin jẹ́ olùtọ́ wa títí Kristi fi dé, kí á lè dá wa láre nípa igbagbọ.
Commonwealth: Eléré ìdárayá Cameroon mẹ́jọ di àwátì
Àwọn kókó ìtakùrọsọ ọ̀hún dá lórí  ìjàkú akátá pẹ̀lú Armenia lóríi Nargono- Karabakh, iṣẹ́ ìlú, àtúnṣe sí ètò ọrọ̀ Ajé, àti ìbáṣepọ̀ pẹ̀lú Ẹgbẹ́ Aláṣẹpọ̀ Eurasian àti Ẹgbẹ́ Aláṣẹpọ̀ Europe.
"Oríṣun àwòrán, MEDIAMAFIA Ọ̀gá ""pension"" tẹ́lẹ̀, Abdulrasheed Maina tó sákúrò ní Nàíjíríà tí fojú ba ilé ẹjọ́ Ọga agba ẹka owo ifẹhinti lorilẹede Naijiria tẹlẹ, Abdulrasheed Maina ti wa ni ile ẹjọ bayii lori ẹsun iwa ajẹnu."
Gbọingbọin ni awọn ololufẹ pasitọn naa wa nile ẹjọ titi di igba ti ẹjọ ọhun pari.
Ọna wo ni wọn n gba ri oṣu?
O lọ sile iwe tijọba Government College ni Apata ni ilu Ibadan.
Awọn to maa n bu eeyan, ẹ ri pe awọn talaka ti ko ba nkankan mu ni, awọn ọta Ọlọrun ni wọn nitori awọn ti Ọlọrun ba se daada fun, ọta Ọlọrun nii maa tẹ wọn tabi ba wọn jẹ.
Aisha lo sọ ọrọ yii nigba to n ba akọroyin BBC sọrọ ni kete to gunlẹ si Naijiria lati orilẹ-ede Gẹẹsi.
Ó ṣe ohun tí ó dára lójú OLUWA, ṣugbọn kò fi tọkàntọkàn sìn ín.
To ba n pẹ jẹun alẹ́, o le ni jẹjẹrẹ ọyan àti asétọ̀ Ìgbẹ́ ọmọdé ń dènà ààrun jẹjẹrẹ, àìsàn ìtọ̀ súgà Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, ẹ̀fọ́ rírò jẹ́ alábárìn iyán, fùfú, ẹ̀bà, àmàlà àti ìrẹsi funfun Lati bi ọdun meji ni wọn ti ṣe odiwọn iyọ to dipọ to iwọn kilomita mẹwa ninu iho Malham Cave naa, to doju kọ okun Dead Sea.
"Agbẹnusọ àjọ ọlọ́pàá ìpínlẹ̀ Ondo Tee-Leo Ikoro ní kóda inú ìròyìn ní òun ti n gbọ gbogbo ǹkan tó ń ṣẹlẹ̀ sùgbọ́n oun kò kófìrí rẹ láyìká Mo ṣetán láti ta ilé tí mo ń gbé, kí n le rí àwọn ìbejì mi padà - Akeugbagold Ìjọba àpapọ̀ mọ̀ sí bí wàhálà àjàkálẹ̀ àrùn Coronavirus ṣe ń búrẹ́kẹ́ síi ní ìpínlẹ̀ Kano-Ganduje Èèyàn 91 míràn tún ti ní àrùn Coronavirus ní Nàíjírìa Ààrẹ Buhari yóò bá àwọn ọmọ Nàìjíríà sọ̀rọ̀ lónìí ""Mo kàá nínú ìwé ìwé ìròyìn ni, kò sí ìwé kankan tó fìdí rẹ̀ múlẹ̀ ni ọfíísì mi"" Bákan náà ni agbẹnusọ ọlọ́pàá náà tún ni, "" bi wọ́n ṣe mú, àti ibi ti wọ́n ti mú wọn òn kò mọ̀, bóya àgbẹnusọ ọlọpàá àpapọ̀ lé sàlàyé lórí rẹ̀ nítori àwọn ni wọ́n kéde bí wọ́n ríi àwọn ọdaran náà mú"" Ikoro ní ilé iṣẹ́ ọlọ́pàá ìpínlẹ̀ Ondo n ṣe gbogbo ǹkan to lè ṣe láti tẹ̀lé ìlànà àti òfin ti ìjọba là sílẹ̀."
"O mu gbogbo akẹkọọ bi ọmọ rẹ, oloju aanu si ni""."
Wọn wa ke si ijọba apapọ lati tete wa wọrọkọ fi ṣada lori amojuto igbayegbadun awọn oṣiṣẹ, alekun owo oṣu, ati ilana iṣẹ to tọna fun awọn oṣiṣẹ nibẹ.
Ṣugbọn nígbà tí Hẹrọdu gbọ́, ó ní, “Johanu tí mo ti bẹ́ lórí ni ó jí dìde.
Ilẹ̀ náà ati ihò tí ó wà ninu rẹ̀ ni àwọn ará Hiti fi fún Abrahamu láti máa lò bí itẹ́ òkú.
“Mo ti sọ àjàgà náà kalẹ̀ lọ́rùn rẹ;mo ti gba agbọ̀n ẹrù kúrò lọ́wọ́ rẹ.
Kí ló ma n fa Àkúfà nílẹ̀ Yorùbá, àti ọ̀nà àbáyọ?
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù EFCC: Akala se magomago biliọnu mọkanla at‘aabọ naira 5 Ẹrẹ̀nà 2018 Oríṣun àwòrán, @AkalaAdebayo Àkọlé àwòrán, Oniruuru ẹsun to nii se pẹlu kiko dukia jọ lọna aitọ ni ajọ EFCC fi kan Adebayọ Akala Ajọ to n gbogun ti iwa ijẹkujẹ lorilẹede yii, EFCC, tun ti gbe gomina nipinlẹ Ọyọ nigbakan ri, Adebayọ Alao Akala atawọn meji mii yọju sile ẹjọ giga ipinlẹ Ọyọ, to kalẹ silu Ibadan.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Àrùn Coronavirus àti ìbálòpọ̀ akọ àt'abo: Wo àwọn ohun tó yẹ kí o mọ̀ nípa 31 Ẹrẹ̀nà 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 14 Ìgbé 2020 Oríṣun àwòrán, Getty Images Tí Mo ba ní ìbálòpọ̀ njẹ mo lè kó aarun Koronafairọs?
“Ṣugbọn bí ó bá jẹ́ pé rírà ni ó ra ilẹ̀ tí ó yà sọ́tọ̀ fún OLUWA, tí kì í ṣe apá kan ninu ilẹ̀ àjogúnbá tirẹ̀, 
"Bakan naa, awọn ọmọ ẹgbẹ rẹ, Revolution Now ni idi tawọn fi n wọde ni pe ""a nilo iyipada adari ni Naijiria, ki awn to ni ifẹ araalu lọkan bọ sibẹ kawọn oloṣelu oni janduku ko ra wọn danu""."
soro lati ni eyi sugbon kii se ohun ti ko le se e se.
Nítorí Jerusalẹmu ti kọsẹ̀,Juda sì ti ṣubú.
Ní ọdún kẹtadinlogoji lẹ́yìn tí a ti mú Jehoiakini, ọba Juda lọ sí ìgbèkùn, ní ọjọ́ kẹẹdọgbọn oṣù kejila ọdún náà Efilimerodaki, ọba Babiloni yẹ ọ̀rọ̀ Jehoiakini wò ní ọdún tí ó gorí oyè, ó sì pàṣẹ pé kí á tú u sílẹ̀ kúrò ní àtìmọ́lé.
Ẹni tí a bá fẹ́ pọ́nlé nìkan la lè dàpè tí a kò ní pẹ̀ é lórúkọ rẹ̀ pàtó.
Olori ile aṣofin ipinlẹ Ọṣun ni lẹyin ti wọn ba ṣe ofin naa, yoo wa ọwọ bi awọn ọmọ ti ko ti ja lẹnu ọmu ṣe n jade ileewe girama ni Naijiria.
Oríṣun àwòrán, @Akinogunbiyi48 Àkọlé àwòrán, Ogunbiyi ni bi wọ́n se se ayẹwo orukọ awọn asoju to dibo, eto idibo ati kika esi ibo ni wọn se lati gbe lẹyin alatako oun, Senatọ Ademọla Adeleke.
ọ̀dọ́ 47,000 fẹ́ di Amotekun, agbófinró yẹ̀ wọ́n wò yẹ́bẹ́yẹ́bẹ́ Aáwọ̀ oyè PDP gbé Fayose àti Seyi Makinde kọlu ara wọn, ìjà ń bọ̀ Bàbálọ́jà márùn ún la ó ò ní l'Oyo tí Makinde bá lè buwọ́lu ìyànsípò YK Abass Auxiliary gbé èèyàn mẹ́fà tó ń jáwèé ayédèrú fáwọn awakọ̀ lọ sí ilèẹjọ́ ní Ibadan Ijamba ina ọhun lo tun waye ni ibudo yii kannaa, ti ẹmi to to mọkanlelaadọwa ti bọ losu to kọja nigba ti ibugbamu kan waye ni ibudokọ oju omi naa.
Mo bá rí ìtẹ́ kan ní ọ̀run.
Oun ni aarẹ to dagba julọ lagbaye.
DJ Avicil onijo ti gbogbo aye n fẹ dẹni ilẹ loṣu kẹrin ọdun.
BBCCopyright: BBC Ile igbimọ aṣofinImage caption: Ile igbimọ aṣofin Article share tools Facebook Twitter ṢàpínlòView more share options Share this post Copy this linkKà síwájú síi nípa àwọn ìtọ́kasí wọ̀nyí.
OLUWA ní, ‘N óo sọ ọ́ di ìpayà fún ara rẹ ati fún gbogbo àwọn tí wọ́n fẹ́ràn rẹ.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àwọn àmì mẹ́fà tó ń sàfihàn ìwà ipá lára ọkùnrin Sọra fun ọkunrin ti o ba soro fun lati jẹ ki ọrẹbinrin rẹ da nkankan se Sọra fun ọkunrin ti ko ba ti ni ero rere nipa obinrin, tabi ti ko mọ apọnle obinrin Sọra fun ọkunrin to ba fẹran lati ma a pasẹ, amọ ti ko fẹ ki obinrin ni ero tirẹ.
Àmọ́ nkan tó jẹ́ ìyanu nlá fún wa ni pé ní àkọ́kọ́ ilé náà dàbí eni pé ó léfò lórí afẹ́fẹ́ ni!
Ó kéré tán ọmọ ilé ìgbìmọ̀ aṣòfin mẹ́rìndínlọ́gbọ̀n nínu ẹgbẹ́ òṣèlú All Progressives Congress (APC) ló ti kúrò lọ sí ẹgbẹ́ òṣèlú Allied Peoples Movement APM Jíjá ẹgbẹ́ òṣèlú APC sílẹ̀ yìí wáyé lẹ́yìn òṣẹ̀ kan tí eni àmì òróró Gominà Ibikunle Amosun fún ipò gómìnà ní ìpínlẹ̀ Ogun lọ sí inú ẹgbẹ́ APM.
Ṣugbọn a kò lo anfaani tí a ní yìí.
Oṣere yii kii ṣe ọkan lara awọn oṣere ti wọn maa n saaba gbe nkan jade lori ayelujara nipa ara wọn tabi nipa iṣẹ wọn.
Ṣugbọn o ni ninu iwe kootu kan to tẹ awọn akọroyin lọwọ, ni wọn ti fiwe pe Gomina Makinde, kọmiṣọna fun ọrọ ilẹ ati ilegbe, to fi mọ adajọ agba ipinlẹ Oyo, lati wa sọ tẹnu wọn lori bi ọrọ ọhun ṣe jẹ.
Igbagbọ ijọba ni pe owo oṣu awọn kọmisanna ati awọn amugbalẹgbẹ to ku yoo tun mu ki gbese ti ijọba o pọ si.
Wọ́n mú Jesu lọ sí ọ̀dọ̀ Olórí Alufaa, gbogbo àwọn olórí alufaa ati àwọn àgbà ati àwọn amòfin wá péjọ sibẹ.
Nibayii, Arsenal ti wọ ipele aṣekagba ife ẹyẹ FA cup bayii, eyi si ni igba ikọkanlelogun iru ẹ ti wọn yoo maa ṣe bẹẹ.
Oríṣun àwòrán, @Gov_Wike Oun paapa si jẹwọ pe awọn oluranlọwọ Gomina Wike lo fun oun ni owo naa pẹlu ileri ile to jọju fun, lasiko ti yoo fi wa ni ipinlẹ naa.
Mide Martins, tóun náà jẹ́ òsèré tíátà míì, ní ojú òpó twitter rẹ̀@mydemartins ní, inú òun dùn pé Mercy gbé ohun rere se, tó sì ń bèèrè pé ìgbà wo ni àwọn yóò sí ilé náà.
Bakan naa ni wọn fẹsun kan wọn pe wọn n fun wọn ni aáyán jẹ nítorí wọn kò bá afojusun ìdíyelé ọjà títà.
Gomina ipinlẹ Ekiti, Kayode Fayemi ni o ṣeeṣe ki a ma ko firi iwalaaye ẹgbẹ oṣelu All Progressives Congress nigba ti saa aarẹ Buhari yoo fi pari.
Isaaki bá pe Jakọbu, ó súre fún un, ó sì pàṣẹ fún un pé kò gbọdọ̀ fẹ́ ninu àwọn ọmọbinrin ará Kenaani.
O la ọ̀nà tí ó gbòòrò fún mi,n kò sì fi ẹsẹ̀ rọ́.
Follow next Article share tools Facebook Twitter ṢàpínlòView more share options Share this post Copy this linkKà síwájú síi nípa àwọn ìtọ́kasí wọ̀nyí.
Kí àwọn wolii tí wọn lá àlá máa rọ́ àlá wọn, ṣugbọn ẹni tí ó bá gbọ́ ọ̀rọ̀ mi, kí ó sọ ọ́ pẹlu òtítọ́.
Mo fẹ́ kí o mọ̀ dájúdájú pé, à ń sọ ohun tí a mọ̀, a sì ń jẹ́rìí ohun tí a rí, ṣugbọn ẹ̀yin kò gba ẹ̀rí wa.
Saka ń wá ọ̀rẹ́ rẹ̀ kan nítorí aṣọ kóòtù ọdún 34 sẹ́yìn DSS ṣèlérí iwadìí tí kò rújú lórí bí òṣìṣẹ́ rẹ̀ kan ṣe yìnbọn pa fẹ́ńdọ̀ lẹ̀yìn Gbajabiamila CCC Genesis Global: Ǹkan mẹ́wàá tí ẹ ò gbọ́ rí nípa Israel Oladele, Woli ìjọ Genesis Global Bàbá mi, ẹ yé fi mí gba ìràwọ̀, ọmọbìnrin Charly Boy, Dewy Oputa fárígá fún bàbá rẹ̀ Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí #EndSars Lagos Judicial Panel: Iléeṣẹ́ ológun ní òtítọ́ làwọn sọ́jà gbé ìbọn tó lọ́ta gidi nínú lọ sí Lekki Toll Gate22 Bélú 2020 Lady Peller: Ọjọ́ ni ọjọ́ tí idán yíwọ́ fún ọkọ mi lẹ́yìn tó gé mi sí méjì, mo kú tán15 Bélú 2020 Emmanuella: Ohun mẹ́wàá tó yẹ kóo mọ̀ nípá Emmanuella tó kọ́ ilé ńlá fún ìyá rẹ̀15 Bélú 2020 Prophet Israel Oladele: Kilo gbe e de ijọ Celestial?
Joabu bá sọ fún ọ̀kan ninu àwọn ará Kuṣi pé, “Lọ sọ ohun tí o rí fún ọba.
" Alága ìjọba ìbílẹ̀ Iganna, Jacod Adeleke ti gba òmìnira lọ́wọ́ àwọn ajínígbé - Ọlọ́pàá ìpínlẹ̀ Oyo Ọlọ́pàááá!
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Nigeria Yahoo Boys: Ìjọba Amẹrika fi ojú àwọn ọmọ Yahoo mẹ́fà léde, wọ́n gbẹ́sẹ̀ lé dúkìá wọn 19 Òkùdu 2020 Oríṣun àwòrán, Other Ijọba ilẹ Amẹrika ti gbe igbesẹ lati fi iya jẹ awọn ọmọ Naijiria mẹfa ti wọn fẹsun kan pe wọn lu awọn ọmọ ilẹ naa ni jibiti owo to le ni miliọnu mẹfa dọla.
Ilé ẹjọ́ yẹ àga mọ́ Ọba Ìkirè nìdí lẹ́yìn ọdún 27 lórí ìtẹ́ Wọ́n rí òkú ọmọ ọdún mẹ́fà tí wọ́n fipá bálopọ̀ nínú mọ́ṣálàáṣí ní Kaduna Bí òṣìṣẹ́ tó ń ta epo nílé epo ṣe di onímọ̀ ìṣẹ́gun òyìnbó, kàyéèfì ńlá!
Èyí ni ‘kíkó- ọmọ- jáde’ ní ọjọ́ ìsọmọlórúkọ.
Oríṣun àwòrán, @jidesanwoolu Kò sí Ààrẹ tàbí Gómìnà tó lè dá ìfẹ̀họ́núhàn àwọn Nàìjíríà lórí #EndSARS dúró- Monday Ubani Agbẹjọro Agba lorilẹede Naijiria, Monday Ubani ti bu ẹnu atẹ lu igbesẹ gomina ipinlẹ Rivers, Nyesom Wike to ni ki awọn eniyan ma fi ẹhọnuhan ni ipinlẹ naa.
Amọ ṣa, awọn kan to wa nilu Kano n binu pe ileeṣẹ ọlọpaa ipinlẹ naa fi atẹjade sita pe ko ni i si lilọ bibọ lati aago mẹfa idaji si mẹfa irọlẹ ọjọ Abamẹta.
Lẹ́yìn tí obinrin náà ti lọ sí ààrin ìlú, àwọn ọmọ-ẹ̀yìn Jesu ń bẹ̀ ẹ́ pé, “Rabi, jẹun.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Titi Oyinsan:Tosyn Bucknor kun fun ayo, okun ati agbara Eyi jẹ iṣẹ àkànṣe ti kò lówó ijọba ninu rara Adan ni 'Aamin' ninu ede Somalia tumọ si 'ootọ inu' ni eyi ti ọpọlọpọ ninu awọn ara ilu gba pe oun ni Adan fi n ṣiṣẹ yii.
Àṣeyọrí míì tún dé lórí ìwòsàn Coronavirus Ìkéde ìjọba àpapọ̀ pé àkẹ́kọ̀ọ́ kò ní ṣe ìdánwò WAEC yàtọ̀ sí àdéhùn wa - ANCOPSS Ìtàn ayé Henry Fajemirokun, olówó tó fi owó mọ Olúwa àti ènìyàn Kini ara ilu n sọ lori igbesẹ Aarẹ Turkey yii?
America: Àìsàn jẹ̀jẹ̀rẹ̀ pa Sẹ́nétọ̀ John McCain l'ọmọ ọdún 81
Gẹgẹ bi akọroyin BBC to wa ni papakọ ofurufu Nnamdi Azikwe nilu Abuja ti wi, deede aago mejila ku ogun isẹju lọsan ọjọ Ẹti ni baalu Ethiopia E9-11 to gbe tọkọ-taya naa balẹ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Fuel price hike: Wo iye ìgbà tí ẹgbẹ́ òṣìṣẹ́ àtàwọn ọmọ Nàìjíríà ti ṣèwọ́de lórí àfikún owó epo bẹntírò 23 Owewe 2020 Oríṣun àwòrán, Twitter/@ayemojubar Ẹgbẹ apapọ awọn oṣiṣẹ ni Naijiria, Nigeria Labour Congress(NLC) ti kede pe ohun yoo gunle iwọde lọjọ Aje ọjọ kejidinlọgbọn, oṣu kẹsan an lati fi ẹhonu han lori afikun owo epo bẹntiro ati ina ọba.
Bí ọ̀rọ̀ ti rí gan-an ni mo sọ fún kabiyesi yìí, Ọlọrun ti fi ohun tí ó fẹ́ ṣe han kabiyesi.
Aarẹ Trump ni, ọwọ oun mọ, ati pe wọn fẹ fi iwadi naa dunkoko mọ oun ni; Sugbọn ọkan lara awọn eekan ẹgbẹ Democrat, Nancy Pelosi ni o di dandan ki aarẹ Trump wa wi tẹnu rẹ Kini o mu ki iwaadi yi ṣe pataki?
Àyọrísí gbogbo èyí ni pé, láti ìgbà yìí lọ, àwa kò tún ní wo ẹnikẹ́ni ní ìwò ti ẹ̀dá mọ́.
o óo sì lọ gbé e fún baba yín, kí ó jẹ ẹ́, kí ó baà lè súre fún ọ, kí ó tó kú.
ẹni tí ó fẹ́ kí gbogbo eniyan rí ìgbàlà, tí ó sì fẹ́ kí wọn ní ìmọ̀ òtítọ́.
Ati gbogbo dúkìá wọn, àwọn ọmọ wọn ati àwọn aya wọn, gbogbo wọn ni wọ́n kó lẹ́rú, wọ́n sì kó gbogbo ohun tí ó wà ninu ilé wọn pẹlu.
Ṣé ẹni tí ń jẹ àwọn orílẹ̀-èdè níyà,ni kò ní jẹ yín níyà?
Ẹ kò gbọdọ̀ kórè èso tí ó bá so ninu ọgbà àjàrà yín tí ẹ kò tọ́jú.
Elédùmarè ló rán mi sí gbogbo Ọba Yorùbá - Oluwo A ó fimú gbogbo ẹni tó lọ́wọ́ nínú ikú Tiamiyu Kazeem dánrin - Ìjọba ìpínlẹ̀ Ogun Yàtọ̀ sí eku gọ́tà tàbí èku inú ilé, kò sí eku téèyàn ò lè jẹ - Òǹtajà Eléwé ọmọ Iṣẹ́ ìgbóhùnsáfẹ́fẹ́ lórí rédíò máa ń mú ẹ̀wà àti àpọ́nlé ba ni àmọ́ kò lówó lórí"" Ṣugbọn ẹni ti ọrọ ọhun ṣoju rẹ sọ pe, awọn SARS mu Kazeem lẹyin ti wọn fẹsun jibiti ori ayelujara kan an, to si sọ fun wọn pe iṣẹ bọọlu gbigba ni oun n ṣe, ṣugbọn awọn ọlọpaa kọti ikun si aroye rẹ."
Omowe Nkwachukwu Orji to adari ajo eleto idibo ni ipinle Anambra lo soro yii lasiko iforowanilenuwo , pe yoo soro se fun enikankan lati mo eni ti  oludibo dibo fun un.
kí ohun tí OLUWA ti sọ láti ẹnu wolii Jeremaya lè ṣẹ, pé, “Ilẹ̀ náà yóo di ahoro fún aadọrin ọdún kí ó lè ní gbogbo ìsinmi tí ó yẹ kí ó ti ní, ṣugbọn tí kò ní.
Gomina ipinlẹ Katsina, Aminu Bello Masari sọ fun awọn akọroyin pe, akẹkọọ 333, ni awọn ko ti i ri pada.
Bẹẹ lo sọ pe awọn eeyan ni wọn yoo fidi nọmba ẹrọ kọmputa to sọ pe ajọ INEC fihan oun nibi to ni oun ti rii pe PDP lo jawe olubori ninu ibo aarẹ to lọ.
Ó pé ọdún mọ́kànlélọ́gbọ̀n tí Samuel Okwaraji ṣubú lójú ìjà Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
 látàrí èyí , ó pinnu láti fi ìlú sílẹ ̀ fún àbúrò rẹ ̀ .
Ìdábòbò àti ìmọ ̀ ọ ́ ṣe àjẹsára lódì sí àrùn pọ ́ njú-pọ ́ ntọ ̀ wà , àwọn orílẹ ̀ -èdè kan sì nílò àwọn àjẹsára fún àwọn arinrìn-ajò .
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, EkitiRapeCastration: ìgbésẹ̀ míì lè dẹ́kun ìwà ìfipábánilòpọ̀ O tẹsiwaju pe fifi ipa ba ọmọde lopọ lee ṣe ijamba nla fun aye wọn, bii ki iru ọmọ bẹ le jẹ ẹni ti yoo fẹran ibalopọ pupọ ju lọjọ iwaju.
Wọ́n fura sí arákùnrin yìí pé ó wà lára ẹgbẹ́ adúnkokò mọ́ni, Boko Haram tó ń pànìyàn lorílẹ̀ède Nàìjíríà lákòókò àwọn ìkọlù to ń waye ní àwọn ilé ìwe àti ìlú.
Wọ́n fi irú aṣọ kan náà ṣe àmùrè dáradára kan.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Lockdown the world: Awọn ọmọ Nàìjíríà káàkiri àgbáyé sọ ìrírí lábẹ́ àṣẹ kónílé-ó-gbélé Musatpha sọ pe kọkọrọ kan to ba eyin aja jẹ ni awọn ti ko tẹle ilana ijọba fun aarun Covid-19.
Iroyin yi wa lẹyin ti iwọde leralera waye eleyi ti awọn eeyan ilẹ naa fi n kesi i wi pe 'o to gẹ' , ki o kọwe fiṣẹlẹ.
Ṣugbọn ó sọ fún wọn pé, “Kì í ṣe gbogbo eniyan ni ó lè gba nǹkan yìí, àfi àwọn tí Ọlọrun bá fi fún láti gbà á.
0 15893 Orilẹede Bahrain 356 22.
Tanzania: Lẹ́yìn ọjọ́ mẹ́wàá, ajínigbé dá Dewji olówó sílẹ̀
Ojú rẹ yóo rí nǹkan àjèjì,ọkàn rẹ á máa ro èròkerò.
Ọwọ tilẹ tẹ awọn kan ti wọn si fi wọn jofin toju tiyẹ lawọn eniyan ṣi fi n ṣọ ori lai fina sori orule sun.
Ṣugbọn kí ni mo lè ṣe lónìí sí àwọn ọmọbinrin mi wọnyi ati sí àwọn ọmọ tí wọ́n bí?
Ẹ̀kọ́ ọ̀fẹ́, ètò ilera ọ̀fẹ́ àti iná ọba ló jẹ wá lógún- ọmọ Nàìjíríà Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ọbẹ Ẹgusi sise ati jijẹ Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
COZA: Mi ò fípá bá obìrin lò pọ̀ rí láyé mi - Pásítọ̀ Fatoyinbo Ara san pa eeyan 16 ninu ṣọọṣi ni Rwanda Pásítọ̀ bẹ́'rí ọmọ ìjọ ní ìpínlẹ̀ Ògùn Ṣé o mọ̀ pé ìwé ẹ̀rí ìgbéyàwó rẹ lè jẹ́ ayédèrú?
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Wòlíì Kasali sọrọ nípa awuyewuye pé o lè ìyàwó rẹ̀ jáde nílé Oríṣun àwòrán, Femi Adebayo Àkọlé àwòrán, Fẹmi Adebayọ Fẹmi Adebayọ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù ECOWAS: Orílẹ̀èdè 15 tó wà nínú àjọ ECOWAS yóò bẹ̀rẹ̀ sí níì ná owó kan nàá l'ọ́dún 2020 29 Òkùdu 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Aarẹ Buhari yoo gbe iṣakoso fun alaga ajọ ECOWAS tuntun Awọn olori orilẹede to wa ninu ajọ Iwọ oorun Afrika, ṣe ipade nilu Abuja fun ipade karundinlọgọta lati dibo yan alaga tuntun, ti wọn si tun sọrọ lori bi ẹkùn naa yoo ṣe maa na owo kan naa.
Ìlé-ìwé alákọ̀ọ́bẹ̀rẹ̀ tí njẹ́ Sandy Hook ni ọkùrin aṣebi yìí ti da ìbọn bo àwọn ọmọdé kékèké tí ọjọ́-orí wọn jẹ́ mẹ́fà àti méje.
Ileeṣẹ ibaraẹnisọrọ ọhun to wa lati orilẹ-ede United Arab Emirate lọdun 2008nde ipo kẹrin lara awọn ojugba rẹ ni Naijiria.
Kàkà bẹ́ẹ̀, mo fi ara mi lọ́kàn balẹ̀, mo dákẹ́ jẹ́ẹ́,bí ọmọ ọwọ́ tíí dákẹ́ jẹ́ẹ́ láyà ìyá rẹ̀.
Wo àwọn Gómìnà Naijiria tí àrùn Covid-19 ti bá fínra Kí ló dé tí ìjọba ìpínlẹ̀ Oyo kéde fífagilé Sáà ètò ẹ̀kọ́ kẹta fún àwọn akẹ́kọ̀ọ́?
Awọn oṣiṣẹ mejeeji yii da awọn apo yii pada ni ibudo ti wọn ti ri wọn he.
Ẹwẹ, ohun to tun mu eto yii dantọ ni pe bi ohunkohun ba ṣẹlẹ ni bii agbegbe aala tabi ibode ipinlẹ Yoruba meji ti iṣẹlẹ kan si waye, ikọ Amọtẹkun ipinlẹ mejeeji lee re sọdọ ara wọn lati jọ ṣiṣẹ papọ tori aala pa wọn pọ.
Ẹ̀yin olólùfẹ́ mi àti ẹbí ni mo bẹ̀ Kí ló pa Bobrisky àti Olorì Aláàfin Oyo pọ̀?
Bàbà ọmọ ọdún 75 kó HIV ran ọmọ ọdún 14 lẹ́yìn tó fi ipá báa lò Kìí ṣe gbájúẹ̀ nìkan lọmọ Nàìjá ń ṣe lókè òkun!
Ǹjẹ́ kò ní tètè dá wọn lóhùn?
Eyi ko sẹyin lẹta to jade lori ẹrọ ayelujara nibi ti Alaafin Ọyọ, Ọba Lamidi Olayiwola Adeyemi Kẹta ti kilọ fun gomina ipinlẹ Ekiti lati sọra ṣe, ki o si tẹlẹ jẹjẹ.
nítorí iná ajónirun ni Ọlọrun wa.
Aruwan so pe awon eniyan le maa rin bayii titi di agogo márùn ún, o tun ni alaafia to ti n joba bayii ni ipinle naa lo je ki ijoba tun ero rẹ pa pe ki awon eniyan maa rin bayii lati aago mefa owurọ di aago márùn ún             irole.
idibo ni ipinle naa, Alhaji Umar Ibrahim se
" Oríṣun àwòrán, other Bakan naa ni Salawatu Abẹni wa gba awọn olorin ode oni niyanju, lati maa kọ ọrin to ni itumọ seti araye.
Ẹyọ ewé kan kò kù lórí igi, tabi koríko, tabi ohun ọ̀gbìn kan ninu oko, jákèjádò ilẹ̀ Ijipti.
Super Falcons: Iṣẹ́ ẹmí ẹtan ló bàlemi lasiko tí mọ so aṣọtẹlẹ̀ pé wọn ó wọ ipele aṣekágbá.
Àwọn ajàfúnẹ̀tọ́ ọmọnìyàn àti àjọ òmìnira ọ̀rọ̀ sísọ náà darapọ̀ mọ ìpolongo yìí pẹ̀lú DondeEstaLuisCarlos (Níbo ni Luis Carlos wà?
Bákan náà ló sàlàyé pé owó èrò kọ̀ọ̀kan yóò máa jẹ́ ẹ̀ẹ́gbẹ́tà dọ́là (#200, 000), ìyẹn ẹ́gbẹ̀rún lọ́nà ìgbá Naira.
Bí Gehasi ti ń sọ fún ọba bí Eliṣa ṣe jí òkú dìde, ni obinrin tí Eliṣa jí òkú ọmọ rẹ̀ dìde wá sọ ẹ̀dùn ọkàn rẹ̀ fún ọba.
Ilẹ Gẹẹsi:Ounjẹ aarọ to peleke ni ki eniyan o fi ẹjẹ ẹlẹdẹ ti wọn ti sè, kun ounjẹ to fẹ jẹ lojumọ.
Nigeria 2019 Election: 'Àwa yóò ṣì polongo ìbò di Ọjọ́bọ̀'
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Da ẹran jẹ̀ nígboro, ko fẹ̀wọ̀n oṣù méje jura tàbí san ₦200,000 - Ilé aṣòfin Ọyọ dábàá Kí ni Oluwo lọ ṣe ní Aso Rock lẹ́yìn lẹ́tà rẹ̀ sí ààrẹ Buhari?
“Ṣíṣọ́ ni kí o ṣọ́ owó yìí ná: fi ra akọ mààlúù, àgbò, ati ọ̀dọ́ aguntan ati èròjà ẹbọ ohun jíjẹ ati ohun mímu, kí o fi wọ́n rúbọ lórí pẹpẹ Tẹmpili Ọlọrun rẹ tí ó wà ní Jerusalẹmu.
Bí Peteru ti ń sọ̀rọ̀ báyìí lọ́wọ́, kò tíì dákẹ́ ọ̀rọ̀ tí ń sọ, bẹ́ẹ̀ ni Ẹ̀mí Mímọ́ bá bà lé gbogbo àwọn tí ó ń gbọ́ ọ̀rọ̀ náà.
Ninu gbogbo ẹran tí ó bá jẹ́ mímọ́, mú wọn ní takọ-tabo, meje meje, ṣugbọn ninu gbogbo ẹran tí kò bá jẹ́ mímọ́, mú akọ kan ati abo kan.
Nigba ti wọn yọ jade nitori pe ofara pa, nise ni Ronaldo ya ẹrọ ibanisọrọ dokita rẹ lati fi yẹ oju rẹ wo ninu digi.
naa omowe, Frankland Briyailo soro yii lasiko to n ba akoroyin ile
Iyansipo awọn Ọba yii ko dun mọ awọn afọbajẹ ninu, ti wọn si gba agbẹjọro lati tako iyansipo awọn ọba wọn yii nile ẹjọ.
O ni: Ẹ ma duro de ijọba Naijiria ki o to dawọle nkan lati maa ṣe.
oluranlowo aare lori iroyin ati ikede, Garba Shehu gbe jade  lojo Isegun , o so pe:“Aarẹ Muhammadu Buhari
Gbogbo eniyan ni wọ́n mọ ìwé yìí, tí wọ́n sì ń kà á.
Pupọ ninu ounjẹ ti awọn baba nla wa n jẹ laye atijọ ni awọn ọmọ aye ode oni ko mọ, awọn miiran gan ko tilẹ gbọ orukọ irufẹ awọn ounjẹ bẹẹ ri.
 wọ ́ n fi yábàá colleg lọ ́ lẹ ̀ ní january 1934.
O ni nigba ti wọn gbiyanju lati sa tẹlẹ obinrin naa nitori ọna ifura to gba sa jade sita ni wọn rii pe ẹsẹ rẹ ya ti o si fẹsẹ fẹẹ.
Gbani, OLUWA; nítorí àwọn olódodo kò sí mọ́;àwọn olóòótọ́ ti pòórá láàrin àwọn ọmọ eniyan.
#RevolutionNow: Àwọn olùwọ́de ń fẹ́ kí ìjọba wọ́nà àbáyọ sí ààbò tó mẹ́hẹ
Ṣugbọn Ìwé Mímọ́ sọ nípa Mẹlikisẹdẹki pé ó wà láàyè.
Brian ni orilẹede kekere ni Palau, awọn eeyan orilẹede naa kii fẹ gba ile itura Palau.
Ṣé òótọ́ ni àwọn ará Amẹ́ríkà máa ń hán an lọ́wọ́ kan tí wọ́n bá gbọ́ ọ̀rọ̀ ìbálòpọ̀?
Wọn yóo máa ṣubú lórí ara wọn bí ẹni tí ogun ń lé lọ, bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé kò sí ẹnikẹ́ni tí ń lé wọn.
Gómínà ìpínlẹ̀ Eko Babajide Sanwo-Olu ti kede pé pé kí gbogbo òṣìṣẹ́ ìjọba láti ipile kejila si isàlẹ̀ jòkó silé wọn fún ọsẹ̀ méji.
 Ìtọ ́ jú , bí ènìyàn bá ti kó àrùn náà , jẹ ́ nípasẹ ̀ àwọn egbògi agbógun ti àkóràn , gẹ ́ gẹ ́ bíi : doxycycline , penicillin , tàbí ceftriaxone .
Yóo di ibi-mímọ́ ati òkúta ìdìgbòlù, ati àpáta tí ó ń mú kí eniyan kọsẹ̀, fún ilẹ̀ Israẹli mejeeji.
Ninu àwọn ìkógun tí wọ́n kó lójú ogun, wọ́n ya àwọn ẹ̀bùn kan sọ́tọ̀ fún ìtọ́jú ilé OLUWA.
O sọ pe O ku ki a maa woye pe boya aarun Covid-19 yoo dinku bi ayipada ba ṣe n deba oju ọjọ bi i ooru ati otutu."
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Afrika: Awọn aworan awodamiẹnu lọsẹ yi 23 Èrèlè 2018 Akojọpọ awọn aworan to jẹ agbayanu nilẹ Afrika ati tawọn ọmọ adulawọ lọsẹ yii.
OLUWA ní: “Bẹ́ẹ̀ ni àwọn ọmọ Israẹli yóo ṣe máa jẹ oúnjẹ wọn ní àìmọ́, láàrin àwọn orílẹ̀-èdè tí òun óo lé wọn sí.
Olúbàdàn, ẹ bá wa bẹ́ Seyi Makinde kó tú wa sílẹ̀ - Oyo NURTW Àpò 65 là fi gbé owó N1.
ati Anderu, Filipi, Batolomiu, Matiu, ati Tomasi, Jakọbu ọmọ Alfeu, Tadiu, ati Simoni, ọmọ ẹgbẹ́ ìbílẹ̀ Kenaani, 
Ni afikun Aare pase fawon ile ise ijoba apapo gbogbo lekaleka pe ki won bere igbese erongba lilo awon akosemose to je eniyan Naijiria ninu gbogbo ise akanse won gbogbo laiyo ti eto aabo sile pelu ase pe nigba ti ko ba si akosenose lati Naijiria nikan ni ki won to lo eniyan ile okeere.
Nítorí náà, ẹ gbọ́, ẹ̀yin olùṣọ́-aguntan: 
Bẹ́ẹ̀ gan-an ni igbagbọ tí kò bá ní iṣẹ́: òkú ni.
"Newcastle run Manchester United mọ́lẹ̀ jégéjégé Ìjọba, ẹ yé fi ẹ̀tọ́ ọmọnìyàn dun ọmọ Nàìjíríà mọ́- SERAP ""Afihan iwa idojuti ati ailaju gbaa ni titẹ ẹtọ afurasi mọlẹ, eyi to n fa ọwọ aago idagbasoke orilẹede Niaijira sẹyin, to si tun n dena iwa alaafia pẹlu."
"Ọsẹ mẹta lo ti wa ni ileewosan Zenith Kidney hospital nibi ti o ti n gba itọju.
akoroyin niluu Daura, sleyin ti o dibo tan nile idibo re to wa ni Niyam ni
 O ni oun ati ọrẹ oun jọ dawo ra danfo ti wọn fi bẹrẹ ere tiata, laye igba naa lọhun."
Bi o tile je pe, Joshua ni awon ololufe ere ija ohun foju si lara pe yoo yege, sugbon Parker ti fowo-soya pe, oun yoo fagba-han ninu ifigagbaga naa.
Yóo jẹ́ ẹ̀mí ìdájọ́ ẹ̀tọ́fún adájọ́ tí ó jókòó lórí ìtẹ́ ìdájọ́,yóo jẹ́ agbára fún àwọn tí ó ń lé ogun sẹ́yìn lẹ́nu ibodè.
Gomina Akeredolu, ẹni to kede pe ile ẹkọ fasiti to wa nilu naa n gba obitibiti owo lapo ijọba.
Ìfẹ̀hónúhàn àwọn èèyàn láti tako èròńgbà fa ìkọlura, ọgọọgọ̀rún àwọn èèyàn sì sá lọ sí àwọn orílẹ̀-èdè ìtòsí láti fi oríi wọn pamọ.
Orisun: Akọsilẹ iwa ajẹbanu fọdun 2018 ti ajọ Transparency International se Orilede wo ni inu awọn eeyan rẹ dun julọ?
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ìtàn tó wà nídi òwe ‘Sebótimọ Ẹlẹ́wà Sàpọ́n’ Ọba Adesoji Aderemi, Ọọ̀ni Ifẹ̀ tó gba ipò ọba mọ́ tòṣèlú MKO Abiola, iṣẹ́ aṣẹ́gità ló fi bẹ̀rẹ̀ okoòwò Iṣọla Oyenusi rèé, ẹnití ìfẹ́ obìnrin ṣun dé ìwà ìdigunjalè Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí 2 sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 2:23 Fídíò, Water Generator: Ó leè ṣiṣẹ fún wákàtí mẹfà, kó tó sinmi, Duration 2,2310 Òkùdu 2020 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
Ṣobali baba Kiriati Jearimu ni baba gbogbo àwọn ará Haroe, ati ìdajì àwọn tí ń gbé Menuhotu, 
 Àwọn ará ìlú wá gbé Àjàpadá ga ju alákùnrẹ ́ tí o kọ ́ kọ ́ dé ìlú Àkúrẹ ́ lọ .
alakoso eto aabo sipo lorile ede yii.
Ìdílé Natani náà yóo ṣọ̀fọ̀ tiwọn lọ́tọ̀, bẹ́ẹ̀ náà sì ni àwọn iyawo wọn, àwọn náà óo ṣọ̀fọ̀ tiwọn lọ́tọ̀.
yoo si wa nibẹ titi laelae.
Ipinlẹ Plateau to wa ni ipo keji nibi ti ọta le lugba eeyan o le mẹtala(273) ti karun naa.
Jọ̀wọ́ sọ bí eniyan ṣe le dè ọ́ lókùn fún mi.
Ọba Adetunji ni bi kii baa se ilana ofin to lee sediwọ eyi to fofin de awọn gomina lati mase se kọja saa meji, Gomina Ajimọbi yẹ ko see saa kẹta ni.
Oríṣun àwòrán, Jaye Kuti/Instagram Àkọlé àwòrán, Òsèré Tíátà Jaye Kuti Jaye Kuti A bí i ní ìlú Ilaro, ìpínlẹ̀ Ogun ní ọjọ́ kẹ́wàá, osù keje.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù 'Àwa la pa ọ̀dọ́mọdé olówó OOU àti olólùfẹ́ rẹ̀' 23 Òkùdu 2018 Oríṣun àwòrán, Nigeria Police Àkọlé àwòrán, Muritala Babatunde àti Taiwo Rasak ní wọ́n jọ pa àwọn olólùfẹ́ nàá ni Olólùfẹ́ méjì jọ gba ọ̀run lọ lọjọ kan náà nílé ìwé OOU.
Iléẹjọ́ wọ́gilé ìgbeyàwó nílànà ẹ̀sìn Islam pé kò bófin mu Adeboye, ìmọ̀ràn rẹ láti dènà panṣágà tako àwọn obìnrin - Ọmọ Nàíjíríà Díẹ̀ lára àwọn òṣèré Nollywood ti wọ́n ti ṣe ìgbéyàwó lẹ́ẹ̀kejì Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, No reception wedding: Adewale ni àpèjẹ kò ṣe pàtàkì sí òun A ko fibẹ mọ nkan to pada ṣẹlẹ, ṣugbọn ileeṣẹ ọlọpaa ti wọn kesi lati wa yanju ọrọ sọ fun BBC pe mọlẹbi iyawo tuntun naa yabo Asif, wọn ya aṣọ rẹ, wọn si tun lu u bi aṣọ ofi.
Sowore kopa ninu idibo lootọ ṣugbọn ko jawe olubori ninu idibo, koda orukọ rẹ ko si lara awọn mẹta to lewaju ninu ibo aarẹ.
da gbogbo omo orile ede Naijiria loju pe  ile igbimo asoju kesan an  yii yoo ri pe idagbasoke de ba orile ede
Nítorí náà, n kò ní lé wọn jáde fun yín mọ́; ṣugbọn wọn yóo di ọ̀tá yín, àwọn oriṣa wọn yóo sì di tàkúté fún yín.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù 'Oriṣiriṣi ọkunrin ni mo ba sun lọna ati jẹ ni Russia' 26 Èrèlè 2018 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ipo kẹtalelogun ni orilẹede Naijiria wa ninu awọn orilẹede to owo ẹru igbalode wọpọ si julọ lagbaye Ọkan lara awọn ọmọbinrin ti wọn ko lọ ṣowo kotọ loke okun ti wi tẹnu rẹ lori ohun oju ri loke okun.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ìpàdé ìtagbangba BBC Yorùbá ti ìpínlẹ̀ Ọyọ Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
''Ki lo de ti ẹya yi yoo dide pe awọn ko fẹ Iyalọja.
Apetan orukọ rẹ ni Candido Da Rocha, ti orukọ baba rẹ si n jẹ Joao Ẹsan Da Rocha Baba rẹ yii jẹ ọmọ ilu Ileṣa, ti wọn ko lẹru lọ si orilẹede Brazil lọdun 1840 nigba to wa lọmọ ọdun mẹwa Ẹsan gba ominira, to si se igbeyawo ni Brazil, o si bi Candido Da Rocha nibẹ lọdun 1860 Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Toyin Atoyebi mechanic: Ẹ wo Toyin, ọmọbinrin ọdún 16 tó ń tún skadà àti gẹnẹrátọ̀ ṣe ní Candido Da Rocha lọ sile ẹkọ alakọbẹrẹ ni Brazil ko to pada sile lẹyin ti baba rẹ, Ẹsan, tọpasẹ orisun rẹ́ wa silẹ Yoruba, ile ẹkọ girama CMS nilu Eko si ni Da Rocha lọ, nibi to ti jẹ olori awọn akẹkọ, Head Boy Iroyin ni Da Rocha di olowo lati ipasẹ oyinbo kan to maa n ta goolu, to fẹ pada sile nilẹ Gẹẹsi, to si fẹ ta awọn goolu to ti wa kusa wọn lọdun 1894, eyi to mu ko tọ Da Rocha lọ Ẹgbẹrun mẹfa owo Pọun ni oyinbo naa fẹ ta goolu rẹ, eyi kọja agbara rẹ, to si lọ gba owoya ni banki lati ra awọn goolu naa Goolu yii ni Da Rocha ta, to si ri ere gọbọi lori rẹ, eyi to sọọ di olowo jaburata ati Miliọnia akọkọ nilu Eko Owo yii ni Da Rocha fi da ile ifowopamọ silẹ lọdun 1907, to si di alawọ dudu akọkọ ti yoo da banki silẹ nilẹ Afirika Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Sogidi Lake: Kòṣẹja-kòṣèèyàn lá bá nínú adágún odò náà -Ojedele O dokoowo papọ pẹlu ọmọ Yoruba meji miran, Doherty ati Sedu Williams lati sagbekalẹ ile ifowopamọ ọhun, to si tun si ile ounjẹ ati okoowo kiko ẹja yinyin wọle Korikosun ni Da Rocha ati gbajumọ elere tiata nni, Herbert Adedeji Ogunde nigba aye awọn mejeeji Ilu oyinbo ni Da Rocha maa n fi awọn aṣọ rẹ to ba dọti ranṣẹ si lati fọ, kii si fọ aṣọ rẹ ni ilu Eko Ojule kẹrin, opopona Tinubu ati opopona Kakawa ni ile Da Rocha wa, to si tun kọ irufẹ ẹya ile naa si orilẹede Brazil Da Rocha nikan lo da pese omi ẹrọ lati Iju si aarin gbungbun Eko, Yaba, Ebute-Mẹtta atawọn adugbo mii ti wọn ti n poungbẹ omi ẹrọ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Cancer: Àṣe ara mi ni iso ti n run gbogbo bí mo ṣe n ṣèrànwọ́ lórí jẹjẹrẹ Ile Da Rocha nikan lo ni kangadẹrọ ati omi ẹrọ omi niwaju ile rẹ, to si maa n ta omi fawọn araalu niwaju ile rẹ Da Rocha da gbe nigbẹyin aye rẹ ni, tori ko se igbeyawo pẹlu obinrin kankan, ti iroyin si ni o jẹ eeyan kan to le pupọ lati ba gbe inu ile A gbọ pe lasiko kan, o ba awọn obinrin mẹta kan gbe ile lasiko ọtọọtọ, ti wọn si bimọ fun, to si bi ọmọkunrin kan ati obinrin mẹta Lara awọn ọmọ rẹ ni Alexander Candido Da Rocha, Ẹnitan Salakọ, Louissa Ẹbun Turton ati Angelica Fọlasade Thomas Kẹkẹ ẹlẹṣin ti wọn n gun laye atijọ ni Da Rocha fi se ẹsẹ rin nigba aye rẹ, ti ko si lo awọn ọkọ bọginni rara.
Nígbà tí ó di ọjọ́ keji, ó dìde, ó bá wọn lọ.
Nítorí a kò ní pè ọ́ ní ayaba àwọn orílẹ̀-èdè mọ́.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Offa Robbery: Àwọn aráàlú ṣì n gbé nínú ìpaya lẹ́yìn ọdún kan Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Offa Robbery: Àwọn aráàlú ṣì n gbé nínú ìpaya lẹ́yìn ọdún kan 5 Ìgbé 2019 Ọjọ naa re e bi ana ti ariwo sọ niluu Ọffa, nipinlẹ Kwara, nitori iṣẹ awọn adigunjale to yabo ilu naa lọsan gan-gan.
Gẹgẹ bi ijọba, ako ni sare gbagbe ohun to ṣẹlẹ lẹnu ọjọ diẹ sẹyin yii to ja si iku Isiaka Jimoh, Ganiyu Moshood ati Adeoye Taiwo.
” Obinrin náà dáhùn pé, “Háà!
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Oba Abd-Ganiyu Adekunle Salaueen Oloogunebi Ajinese 1 ti kéde pẹ orò ló kù láti lé àwọn ajínigbé 17 Owewe 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 21 Owewe 2020 Oríṣun àwòrán, Oro Festival A fẹ́ gbé orò láti lé àwọn ajínigbé kùrò ní ìpínlẹ̀ Oyo- Asẹyin Aseyin ti ilu Iseyin, Oba Abd-Ganiy Adekunle Salaueen Oloogunebi Ajinese 1 ti sọ idi pataki ti ọdun oro yoo fi waye ni ilu Isẹyin ni asiko yii.
Ghana 2020 election: Jean Adukwei Mensa,Tani akíkanjú obìnrin tí yóò kéde èsì ìbò aàrẹ Ghana?
Ọna wo ni eeyan fi n di ajẹ?
Wọ́n wá gbogbo agbègbè olókè Efuraimu káàkiri, ati gbogbo agbègbè Ṣaliṣa, ṣugbọn wọn kò rí àwọn kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ náà.
 gege bi iyawo aare bill clinton , ohun lo je iyaafin akoko amerika lati 1993 de 2001 .
Angẹli kẹfa da ohun tí ó wà ninu àwo rẹ̀ sórí odò ńlá tí wọn ń pè ní Yufurate, ni omi rẹ̀ bá gbẹ láti fi ọ̀nà sílẹ̀ fún àwọn ọba tí ń bọ̀ láti ìhà ìlà oòrùn.
Ọjọ́ pẹ́ tí mo ti ń wá ọ kiri, k[po sí ibi ti mo saláì wá ọ dé ni òde ayé yìí, nítorí kí bàbá mi to ṣe aláìsí ó ti wí fún mi pé kí n wá ọ̀nàkọnà láti rí ọ ki ń tó kúrò lórí ilẹ̀ ayé, ki ń sọ nǹkan tí ojú mì ti rí sẹ́yìn fún ọ, nítorí kí ìwọ bà kéde rẹ̀ fùn àwọn olùgbé inú aye, eléyìí nì lè mú àǹfàní bá àwọn ọmọ ènìyàn kí wọn fi ọgbọ́n kun ọgbọ́n inú wọn.
Lekki Toll Gate: CNN vs Lai Mohamamed rèé o!
6bn padà 5 Òkùdu 2019 Oríṣun àwòrán, Ekiti@official Àkọlé àwòrán, Ilé aṣòfin Ekitini awọn alaga na owo ilu ni inakuna Ile Igbimọ Aṣofin Ekiti ti ni ki awọn alaga ijọba ibilẹ ti wọn ni ko lọ rọkun nile ni ọdun 2018 da biliọnu mẹta aabọ o le diẹ ti wọn fẹsun kan wọn pe wọn na ni inakuna pada.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ẹ̀bùn ọ́kọ N303m: Fún ààbò ẹ̀mí ni àbí àbẹ̀tẹ́lẹ̀?
Kí ìkùukùu ṣíji bò ó,kí òkùnkùn sì dẹ́rù bà á.
Aago meje aabọ (GMT) ni ọkọ ofururu naa yẹ ko balẹ si papa'kọ ofurufu Jomo Kenyatta to wa ni Kenya.
Ta ló tó bi í pé, ‘Kí ni ò ń ṣe?
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Asia ẹgbẹ agbabọọlu Chelsea Ninu ifẹsẹwọnṣẹ akọkọ ti wọn gba ni Stamford Bridge,ami ayo mẹta si odo ni wọn fi sagba Dynamo.
4m Wo ohun tí yóò ṣẹlẹ́ tí wọ́n bá jí ọpa àṣẹ gbé nílé àṣòfin Ìlú méjì kọjú ìjà síra wọn l‘Ondo torí aáwọ̀ ilẹ̀, ọba kan wà ní ‘Coma’, èkejì fo ògiri jáde Ọmọ Naijiria hú ẹ̀sùn ìfipá bánilòpọ̀ tí wọ́n fi kan Fatoyinbo síta lẹ́yìn tó lọ sí Shiloh Wo diẹ lara awọn eeyan to ti daku bii Maina, tabi to dede dubulẹ aisan lẹyin ti wọn fẹsun ikowojẹ kan wọn.
 O ni eleyiii jẹ ara aṣeyọri nlanla ti oun ṣe lati ọdun
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù EFCC ju akọwe ijọba Babachir silẹ 24 Sẹ́rẹ́ 2018 Oríṣun àwòrán, @GarShehu Àkọlé àwòrán, Akọwe ijọba ilẹ Naijiria nigbakanri, ọgbẹni Babachir Lawal n dahun ibeere lori ẹsun iwa ibajẹ ti wọn fi kan-an.
Agbọ́tí bá rọ́ àlá tirẹ̀ fún Josẹfu, ó ní, “Mo rí ìtàkùn àjàrà kan lójú àlá.
ati lórí àwọn òkè ninu pápá.
Onwoye ohun to n lọ lawujọ kan to n fi ilu Kano ṣebugbe, Sani Musa sọ fun BBC pe, ni ṣe lo yẹ ki idile Aarẹ sun ọjọ igbeyawo naa siwaju nitori bi ọrọ aje Naijiria ṣe ri lasiko yii.
Awọn apẹẹrẹ naa le jẹ ara gbigbona, ori fifọ, egbo ọna ọfun, ki ara o ma ji pepe, ikọ, eebi, igbẹ gbuuru, ki iṣan ara o maa ro ni, aya didun.
Buhari ti fi idunnu re han lori bi awon omo-orile ede Naijiria ti se
Ọjọ́ kẹrinlelogun, oṣù kẹfa, ọdún keji ìjọba Dariusi, ni wọ́n bẹ̀rẹ̀ sí kọ́ ilé náà.
Amọṣa, ileeṣẹ ọlọpaa ti ni awọn ti bẹrẹ iwadii lori iku wọọkilu mọ naa, lati mọ boya lootọ ni arakunrin naa gbẹmi ara rẹ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Van Persie vs Solskjaer: Ole bínú tán, ó lóun ò mọ Van Persie rí, bẹ́l kò lẹ́tọ̀ọ́ láti sọ̀rọ̀ s'óun 4 Sẹ́rẹ́ 2020 Oríṣun àwòrán, Other Bi oju akata ba lewo, ẹnu adiẹ kọ la o ti gbọ.
56 bn Ileeṣẹ ijọba to n risi eto ilẹra - N380.
Ó mú burẹdi dídùn kan tí kò ní ìwúkàrà ninu, ninu agbọ̀n burẹdi tí ó wà níwájú OLUWA, ati burẹdi olóròóró kan tí kò ní ìwúkàrà ninu ati burẹdi fẹ́lẹ́fẹ́lẹ́ kan, ó kó wọn lé orí ọ̀rá náà ati itan ọ̀tún àgbò náà.
"Dr Maynunah Kadiri, tó jẹ́ olùdásílẹ̀ Pinnacle Medical Services, tó má a ń yan amójútó àwọn ìpénija tó ni nnkan ṣe pẹ̀lú ọpọlọ láàyò salaye pe, "" Ọ̀pọ̀ àwọn tó má n gbèrò láti pa ara wọn, tí o bá rí wọ́n, yóò dàbí ẹni pé wọ́n ń ṣe àwàdà ní, sùgban ti o bá tẹtí láti gbọ́ ìtàn wọn , òyé yóò ye ènìyàn láti mọ́ pé, wọ́n le pa ara wọn,"" Ó ní ọ̀pọ̀ tilẹ̀ máá n fi ìwé sílẹ̀ fún àwọn tó sún mọ́ wọ́n, láti sọ ìdí ti wọ́n fi gbé ìgbẹ́sẹ̀ náà, wọ́n le kọ̀ ọ́ pé, asán ni aye yìí, tí wọn yoo si ti fi iwé yìí sílẹ̀."
OLUWA, Ọlọrun wa, tìrẹ ni gbogbo ohun tí a mú wá, láti fi kọ́ ilé fún orúkọ mímọ́ rẹ, ọ̀dọ̀ rẹ ni wọ́n sì ti wá.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Eegunjobi Omotanbaje Ajobiewe- Èébú ní wọ́n kọ́kọ́ ń bù mí nígbà tí mo bẹ̀rẹ̀ ẹ̀ṣà pípé ní Iwọde tako ẹka ọlọpaa SARS lorilẹ-ede Naijiria ṣi n tẹ siwaju lainaani ikede ti ọga ọlọpaa patapata lorilẹ-ede Naijiria, Mohammed Adamu ṣe ni ọjọ Abamẹta pe wọn ti wọgile ẹka SARS.
Gbogbo nǹkan wọnyi kò yé àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ ní àkókò yìí, ṣugbọn nígbà tí a ti ṣe Jesu lógo, wọ́n ranti pé a ti kọ gbogbo nǹkan wọnyi nípa rẹ̀ ati pé wọ́n ti ṣe gbogbo nǹkan wọnyi sí i.
Samuel Ajayi Crowther, òjíṣẹ́ Ọlọ́run tó gbé èdè Yoruba lárugẹ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Ẹ dá owó padà f’áwọn ẹbí MKO Abiọla' A bí Kudirat Abiola ni ọdún 1951 ní ilú Zaria, òun ni ìyàwó keji ti Abiola fẹ́, tó si bi ọmọ mẹ́fa.
Òrí ló yan iṣẹ́ olùkọ́ fún mi ni ń kò ṣe jẹ́ kí Ọba ti mo jẹ́ dí mi lọ́wọ́- Kabiesi Abolarin Oke Ila Kabiesi ṣalaye idi ti o fi da ileewe Abolarin silẹ ni Oke Ila fun awọn ọmọ alaini lawujọ.
 awon ibarasepo awujo larin awon eniyan ti sedasile orisirisi opo iyi , ise awujo , ati awon igbese , ti lapapo won da ipilese awujo eniyan .
Mercy Aigbe Oríṣun àwòrán, @mercyaigbe Mercy Aigbe kii ṣe ọmọ Yoruba.
Ọpọ ọmọ orilẹede Naijiria lo n ṣedaro aarẹ ana.
Nígbà tí ó di ọjọ́ kẹjọ, wọ́n wá láti kọ́ ọmọ náà ní ilà-abẹ́.
Ladugbo Iwo road, Challenge, Ọjọọ, Bẹẹrẹ, Mọlete, Ọja ọba, Gate ati Sango, ko si ẹni to kofiri pe iwọde kankan n waye nibẹ bi o tilẹ jẹ pe awọn agbofinro ti gbarodan sawọn agbegbe yii, ti oju wọn ko si srẹrin rara.
Gbogbo àwọn wọ̀nyí náà ló parapọ̀ di àwùjọ-ẹ̀dá.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Èmi gan máa ń béèrè lọ́wọ́ ara mi pé ta ni Wole Soyinka gangan' Soyinka ni bi nkan ṣe ri bayii ni Naijiria, awọn ọmọ Naijiria ko mọ ibi ti wọn n lọ, tabi ibi ti irinajo wọn yoo pari si.
”Leyin ijiroro ni awon ile –ise aladaani,ile-ise  ijoba ati awon ti ọrọ kan  fẹnuko lori ipinnu wọnyii, pe:  Ademola Adepoju.
Ọjọ Aje lo ku to si fi ọmọ mẹfa silẹ saye lọ.
 A nilati ji giri sipenija yii ni Naijiria bayii ki awon eniyan le maa fura.
Àkọlé àwòrán, Ọ̀jọ̀gbọ́n Wọlé Soyinka ní ẹlẹ́nu méjì ni Muhammadu Buhari Àkọlé àwòrán, Bi a ba ku laa dere, eeyan kii sunwọn laaye.
Láìṣe àní-àní, ẹni tí ó bá tóbi ju eniyan lọ níí súre fún un.
Lẹyin eyi, Wole Soyinka tun ti di ọpọlọpọ ipo nla mu ni ẹka imọ ede Gẹẹsi ni fasiti ti ilu Eko.
nítorí ibi tí wọ́n ṣe, wọ́n mú mi bínú nítorí pé wọ́n sun turari sí àwọn oriṣa tí àwọn tabi àwọn baba wọn kò mọ̀ rí, wọ́n sì ń sìn wọ́n.
OLUWA óo yọ láti ibùgbé rẹ̀,láti fi ìyà jẹ àwọn tí ń gbé inú ayé, nítorí ẹ̀ṣẹ̀ wọn,ilẹ̀ yóo tú ẹ̀jẹ̀ àwọn tí wọ́n pa sórí rẹ̀ jáde,kò sì ní bo àwọn tí a pa mọ́lẹ̀ mọ́.
    Lọ́gán, obinrin yìí kígbe ǹlá pe ọ̀gbọ́n rẹ̀ náà láti ọ̀nà jíjìn réré, pnítọ̀hún náà sì dáhùn bí ìgbà tí jàgídíjàgan obìnrin bá da orogún rẹ̀ ní ohùn líle.
Wọ́n ta gìrì, ẹ̀rù bà wọ́n; wọ́n ṣebí iwin ni.
Àmọ́ tí wọ́n bá wípé “Ìròhìn ò tó àmójúbà” bẹ́ẹ̀ gẹ́lẹ́ lọ̀rọ̀ yìí rí.
    Ṣùgbọ́n ó yà mi lẹ́nu púpọ̀ bí Aláyélúwà ọba Ọmùgọ́dimẹ́ta ṣe hùwà lẹ́yìn èyí.
Ẹsẹ̀ yín yá sí ọ̀nà ibi,ẹ sì yára sí àtipa aláìṣẹ̀.
Rwanda: Orilẹ ede yii jẹ eyi ti o ni imọ toto julọ ti ọpọ awọn oludokowo ati awọn arinrin ajo afẹ si fi ṣe ibi ojukkọ ogun ni ọdun 1994,ni iyatọ ti wa.
Dafidi ati àwọn ẹgbẹta (600) ọmọlẹ́yìn rẹ̀, bá lọ, nígbà tí wọ́n dé odò Besori, apá kan ninu wọn dúró ní etí odò náà.
Àwọn ọmọ ilẹ Indonesia ṣe ìwọ́de lóri fífòfin de ìbalòpọ ṣáájú ìgbéyàwó Inú mí dùn bí ìpínlẹ̀ Ọyọ se setán láti bẹ̀rẹ̀ ilé-ìwé tí àwọn akẹkọ̀ọ́ ń gbé- Òbí Ilé ẹjọ́ kọ̀ láti tú Omoyele Soworẹ sílẹ̀ Àwọn mẹ́rin t'íjọba Buhari k'etí ikún s'àṣẹ òmìnira iléẹjọ́ lórí wọn rèé Kunle Afolayan, òṣìṣẹ́ báńkì tẹ́lẹ̀ kó tó di gbajúgbajà òṣèré Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Intersextuality: Dokita ni ká mu èyì tó wù wá nínú jíjẹ́ akọ tàbí abo Gomina ipinlẹ Ọyọ, Ṣeyi Makinde ṣalaye pe nọmba naa ni nọmba fun idaabobo araalu ti wọn yoo ma lo nibẹ.
Ṣugbọn ileeṣẹ ologun Naijiria kede wipe oun ti gba awọn ọmọ ile-iwe naa la.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, #JusticeforTina: Àwọn obi Tina Ezekwe ń bèrè fún ìdájọ́ òdodo pẹ̀lú omijé lójú Okezie Ikpeazu, Abia Afẹmọju ọjọ Kẹjọ, oṣu kẹfa ọdun 2020 ni iroyin kan jade pe gomina ipinlẹ Abia, Okezie Ikpeazu naa ti fara kasa arun Covid-19.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ṣo mọ̀ pé J.
Ẹ óo lé àwọn ọ̀tá yín jáde, ẹ óo sì máa fi idà pa wọ́n.
Omi òkun, ẹ pàtẹ́wọ́;kí ẹ̀yin òkè sì fi ayọ̀ kọrin pọ̀
Ipade awọn oloselu mejeeji yii waye lasiko abẹwo Minisita fun ọrọ ilẹ okeere lorilẹede Amẹrika, Rex Tillerson gunlẹ si orilẹede naa fun abẹwo ọlọjọ mẹrin.
Abrahamu gbé ilẹ̀ àwọn ará Filistia fún ìgbà pípẹ́.
Nítorí ẹ̀ṣẹ̀ rẹ ni ó ń fa irú ọ̀rọ̀ tí ń ti ẹnu rẹ jáde,ètè rẹ sì kún fún àrékérekè.
Gbogbo àwọn ẹran wọnyi jẹ́ ẹbọ sísun fún Ọlọrun.
O ti di eeyan 63,173 ti ayẹwo ti fihan pe wọn ni coronavirus lapapọ ni Naijiria bayii.
isà òkú ati inú àgàn,ilẹ̀ tí ń pòùngbẹ omi ati iná,wọn kì í sọ pé, “Ó tó.
- Ilé ẹjọ́ ìpínlẹ̀ Ondo Ilé ìwòsàn kan rèé tó ń fi àtùpà gbẹ̀bí aláboyún Ninu awọn aworan to fi kin iroyin naa lẹyin, a ri ti awọn eeyan kan joko si inu gbagede kan ti o si jọ pe wọn se idanilẹkọ fun wọn.
Ìpín yìí jẹ́ ọ̀rọ̀ ìsaájú ìwé Olúwa sí àwọn ẹ̀kọ́, àwọn májẹ̀mú, àti àwọn òfin tí a fi fúnni ní ìgbà yí.
Nígbà tí ó yá OLUWA sọ fún Noa pé, “Wọ inú ọkọ̀ lọ, ìwọ ati àwọn ará ilé rẹ, nítorí pé ìwọ nìkan ni o jẹ́ olódodo sí mi ní gbogbo ayé.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ko si ika ti o ko le tẹ, ṣaa tẹẹ daadaa ni Lara ohun ti wọn n sọ ni pe ika aarin a ma jẹ ki ọda itẹwe ti Inec pese fun ontẹ duro daada si aarin oju aye ẹgbẹ ti oludibo fẹ dibo fun.
Eliṣa dáhùn pé, “Ṣé o kò mọ̀ pé mo wà pẹlu rẹ ninu ẹ̀mí, nígbà tí Naamani sọ̀kalẹ̀ ninu kẹ̀kẹ́-ogun, tí ó gùn, tí ó wá láti pàdé rẹ?
Ninu alaye rẹ Alhaji Bashir Dan Malam to jẹ alaga IPMAN ni Kano sọ pe iye yi di dandan ki awọn baa le ri owo tawọn naa yọ lẹyin gbogbo isiro to ba iye owo epo de.
Eze tun so pe “WANEP, ECOWAS/AU ti ni awon yoo gbe awon ise akanse kan jide lori ero ayelujara , ni eyi ti yoo maa jabọ, ti yoo si tun maa topinpin bi eto idibo se n lo si.
 Òkè àtẹ yìí ni orí tí ìsàlẹ ̀ ọpọ ́ n náà jẹ ́ , ẹsẹ ̀ tí ó súnmọ ́ oníyẹ ̀ míwò jùlọ .
”(Gbogbo ilẹ̀ Baṣani ni wọ́n ń pè ní ilẹ̀ àwọn Refaimu.
Pato idi ti wọn fi ji ọgbẹni Dewji gbe ko ti jẹyọ.
Laipẹ yii ni awọn eniyan bẹrẹ si ni fẹhọnu han lori awọn eniyan ti wọn n ṣekupa nipa wiwọ aṣọ pupa lati fi ibanujẹ wọn han.
Nítorí ti ilé OLUWA, Ọlọrun wa,èmi óo máa wá ire rẹ.
"Esi to si saaba maa n fọ jade fun wọn, lati rọ wọn ki mase ra ẹwa lawin ni pe ""Ṣe bo ti mọ"", eyi to tumọ si pe mase ra kọja iye owo too ni lapo bayii."
Makinde sọ pe gbogbo igba ti iya oun ba fẹ gba ohun kohun lọwọ oun ni iya naa maa n ran oun leti pe diẹ lo ku ki awọn mejeji ku lọjọ to n rọbi.
Ṣé ẹ ranti pé àwọn ni wọ́n tẹ̀lé ìmọ̀ràn Balaamu tí wọ́n sì mú àwọn ọmọ Israẹli ṣẹ̀ sí OLUWA ní Peori, nítorí ẹ̀ṣẹ̀ yìí ni àjàkálẹ̀ àrùn ṣe bẹ́ sílẹ̀ láàrin àwọn ọmọ Israẹli?
9 75203 North Macedonia 2051 98.
Ti a ko ba gbagbe, o ti to ọdun kan tawọn ajọ eleto aabo lorilẹede Naijiria ti gba ọgọọrọ awọn ọmọ ati iya, lọwọ awọn ọdaran ti wọn n ta awọn ọmọ kekeke lati fi sowo.
Ni ọdun 2005 ni wọn yan an gẹgẹbi Chancelor ile iwe giga fasiti ti ilu Abuja.
 agbara asofin wa lowo ijoba ati iléaṣòfin ilẹ ̀ bòtswánà .
Mo bá rí àwọn angẹli meje tí wọn máa ń dúró níwájú Ọlọrun, a fún wọn ní kàkàkí meje.
Lasiko to n dahun ibeere lori bi awọn ọmọ ẹgbẹ PDP ṣe n yalọ si ẹgbẹ oṣelu APC lasiko yii, Bode George ni ẹgbẹ mejeeji yatọ sira wọn.
Odidi ogoji ọjọ́ ni Goliati fi pe àwọn ọmọ ogun Israẹli níjà ní àràárọ̀ ati ìrọ̀lẹ́ ìrọ̀lẹ́.
Bí wundia náà bá sì lọ́kọ, kò dẹ́ṣẹ̀.
Ọmọ Mike Bamiloye tó ṣe fíìmù Ayamatanga fẹ́ ṣègbéyàwó, kà síi nípa ọkọ rẹ̀ Oríṣun àwòrán, Darasimi/Lawrence Oyor Instagram O ṣe diẹ ti iroyin igbeyawo olorin Kristeni da oju opo ayelujara ru bi ti iroyin eleyi ta mu tọ yin wa.
Gbogbo àpéjọ àwọn tí wọ́n pada dé láti oko ẹrú pa àgọ́, wọ́n sì ń gbé inú àgọ́ wọn.
Àwọn ohun ọ̀sìn tí wọ́n pè láti ilé kò lè wá wọ́n sì yan àwọn àgbébọ̀ adiẹ̀ mẹ́fà gẹ́gẹ́ bí aṣojú wọn.
Awọn obinrin naa wa gba awọn oloro yii niyanju lati maa se oro wọn lọganjọ oru dipo ọsan gangan, eyi ti ko ni di awọn lọwọ lati lọ sẹnu isẹ abi okoowo awọn.
Nígbà tí àwọn iwin ń bọ̀ wá sí ibi àsè yìí, ẹ̀rù ba ènìyàn gidigidi: nítorí kí ni ńkọ́, nítorí dúkìá ọwọ́ wọn ni: òmíràn a wọ ẹ̀wù ìlẹ̀kẹ̀, òmíràn a dé adé owó, òmíràn a máa fi ọ̀pá góòlù ti ilẹ̀, òmíràn a máa fi ṣíbí dáyámọ́ǹdì òkúta olówó iyebíye jẹun.
Ninu ọrọ rẹ, oluranlọwọ fun Ọọni lori ọrọ iroyin, Moses Olafare sọ wi pe irọ patapata gbaa ni Oluwo pa mọ Ọọni ati wipe ogunlọgọ awọn oniroyin ati awọn ayaworan to wa nibi ipade naa yoo ti fi fọnran naa han gbangba to ba jẹ wipe iru isẹlẹ bẹẹ waye.
Nítorí èyí, ó yẹ kí obinrin ní àmì àṣẹ ní orí nítorí àwọn angẹli.
" Lẹyin naa lo ni iba dara ki ijọba ipinlẹ Eko tun ero rẹ pa lori igbesẹ ọhun.
 india ni ileasofin oniyewumeji to n sise bi sistemu onileasofin iru westminster .
degree ninu imọ ẹrọ, Electrical Engineering.
Luku, àyànfẹ́ oníṣègùn ati Demasi ki yín.
Kí ló kàn fún Godwin Obaseki lẹ́yìn tó kúrò lẹ́gbẹ́ òṣèlú APC?
 Àgbẹ , ọde , ̣ apẹja àti ọ ̀ ṣìn ẹran ni ìṣe wọn .
Ọtí líle ń ti alufaa ati wolii,ọtí waini kò jẹ́ kí wọ́n mọ ohun tí wọ́n ń ṣe mọ́.
 ní ọ ̀ pọ ̀ lọpọ ̀ ìgbà , ojú ibi abẹ ́ rẹ ́ náà a má a pupa yòò , a má a wú , a sì má a dun ni .
 Aarẹ yoo maa pada wa si orile ede Naijiria ni osu kárùn ún, ọjọ kárùn ún,odun 2019”.
Bakan naa ni iranṣẹ Ọlọrun naa tun ranṣẹ ibanikẹdun sawọn ẹbi pẹlu adura pe ki Ọlọrun tu wọn ninu.
Amọ iwadii ikọ iroyin BBC ni orilẹede Naijiria fihan pe ọpọ awọn araalu naa ni ko gbagbọ pe arun kankan wa, to n jẹ Coronavirus.
l’áràárọ̀ ni èrò máa ntò síwájú àwọn ilé oúnjẹ wọ́nyìí tí wọ́n sì njẹ àjẹrìn dé ibiṣẹ́.
Ko din ni Aadọjọ awọn eniyan ti o ti rin iru irin ajo bẹẹ sugbọn ti o jẹ pe Oyinbo alawọ funfun ni ọpọ wọn Ilé aṣọ̀fin Nàìjíríà ń gbèrò ẹ̀wọ̀n f'áwọn olùkọ̀ tó bá dẹnu ìfẹ́ kọ akẹ́kọ̀bìnrin.
 Wòlíì Kasali ní Dolapo Awosika kò lé ìyàwó òun jáde 'Alífábẹ́ẹ́tì Ohùn Oduduwa di ìtẹ́wọ́gbà ni Ajaṣẹ' Ṣẹ gbọ́ nípa Alájọ Ṣómólú, tó ta mọ́tò ra kẹ̀kẹ́?"
Azman Airline: Ọkọ̀ òfúrufú gbiná nítorí obìnrin tó ń fa Shisha!
Aba, okan gbogi ninu awon ilu ti o wa nipinle Abia, ipinle ti o kogun si gusuu
ni ijoba ibile meta otooto ti o di ekun kan soso, ni o figagbaga pelu ogbeni Dogara.
Ṣaaraimu, Aditaimu, Gedera, Gederotaimu; gbogbo ìlú ati ìletò wọn jẹ́ mẹrinla.
95bn sórí reluwé làti Kano sí Niger Republic- PDP Osanyintolu ṣalaye pe awọn ti lo irinsẹ agbe ọkọ lati fi gbe ajoku ọkọ naa kuro ti lilọ bibọ ọkọ si ti n lọ geere.
 dírẹ ́ bà ọkọ ̀ yìí kò mọ ọkọ ̀ wà dáadáa .
Ọbẹ̀ kìí gbé inú àgbà mì
Lẹ́yìn náà wọ́n mú Jesu kúrò níwájú Kayafa lọ sí ààfin.
Ọ̀fọ̀ mejeeji ni yóo ṣe ọ́ lójijì, lọ́jọ́ kan náà: o óo ṣòfò ọmọ, o óo sì di opó,ibi yìí yóo dé bá ọ lẹ́kùn-únrẹ́rẹ́.
Ó di ìgbà tí kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ bá bí ọmọ rẹ̀ ní eniyan,kí òmùgọ̀ eniyan tó gbọ́n.
Kì í ṣe pé mò ń fi èyí ba yín wí.
28 Àti nísisìyí, kíyèsíi, èmi fi fún ọ, àti bákannáà fún ìránṣẹ́ mi Joseph, àwọn kọ́kọ́rọ́ ẹ̀bùn yìí, èyí tí yíò mú iṣẹ́ ìranṣẹ́ yìí wá sí ìmọ́lẹ̀; àti pé ní ẹnu ẹlẹ́rìí méjì tàbí mẹ́ta ni a ó fi ìdí gbogbo ọ̀rọ̀ múlẹ̀.
Kódà, ó kúkú ti sọ ẹrọ̀ asọ̀rọ̀mágbèì di asọ̀rọ̀gbèsì nítorípé ó fún àwọn òlùgbọ́ ètò ní ànfàní àti dásí ètò kí wọ́n sì fèsì sọ́rọ̀.
Ó kúnlẹ̀, ó ń gbadura, ó sì ń yin Ọlọrun, nígbà mẹta lojoojumọ.
kede  abajade esi idibo to waye ni ojo
Sugbọn Olubadan ko dẹkun ipe rẹ pe gbogbo awọn agba oye naa lo gbọdọ gbe ade wọn silẹ nitori ọba meji kii wa ni aafin.
Ṣugbọn ẹni tí yóo fi í lé àwọn ọ̀tá lọ́wọ́ gbé!
Nígbà tí àwọn tí a rán kúrò, wọ́n dé Antioku, wọ́n pe gbogbo ìjọ, wọ́n fún wọn ní ìwé náà.
Bode George ṣepade oniroyin ni ile rẹ to wa ni Ikoyi ipinlẹ eko nibi to ti sọ fun BBC Yoruba pe Asiwaju Bola Tinubu to jẹ agba ninu ẹgbẹ oṣelu APC kan n dibọn lasan ni ati pe ọrọ to sọ pe oun o gba nkankan nidii ibode Lekki ko ri bẹẹ.
Òun ni ó fi ohun tí yóo ṣẹlẹ̀ lẹ́yìn ọ̀la han Nebukadinesari ọba.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Okunrounmu: Ijọba Buhari jẹ ijiya Ọlọrun fun Naijiria 5) Zainab Ahmed: Odu ni ninu iṣẹ minista kii ṣe aimọ fun oloko.
Ọmọ náà ń dàgbà, ó ń lágbára, ó kún fún ọgbọ́n, ojurere Ọlọrun sì wà pẹlu rẹ̀.
 Ìṣesí , ìhùwàsí , àṣà àti ẹ ̀ sìn wọn kò yàtọ ̀ .
5 70883 Orilẹede Slovenia 1949 93.
Ọba Babiloni pa àwọn ọmọ Sedekaya lójú rẹ̀, ó sì pa àwọn ìjòyè Juda ní Ribila.
Ileewosan to ti n tọju àwọn ọmọ rẹ ọkùnrin to ye ninu ijamba naa, ni wọn ti bura fun un.
Christmas: Ẹ ronúpìwàdà lásíkò ọdún, àti àwọn ìkíni mìrán tó jẹ yọ fún Kérésì
Oríṣun àwòrán, @IsiakaAdeleke1 Àkọlé àwòrán, Ọmọ igbimọ ile asofin agba lori ọrọ idasẹsilẹ ati isẹ ilu ni Sẹnẹtọ Adeleke Adeleke gbe igba oroke, ti o si jẹ asofin agba to n soju ni ile asofin agba labuja lọwọ-lọwọ yii.
" Alukoro ileesẹ ologun oriilẹ lorilẹede Naijiria ni awọn ọmọogun yoo ri daju wi pe gbogbo awọn kọlọransi ti wọn baa kẹẹfin ni wọn fi panpẹ ofin gbe.
Ṣebí a ní àwọn baba tí wọ́n bí wa, tí wọn ń tọ́ wa sọ́nà, tí a sì ń bu ọlá fún wọn.
Àwọn kan ninu àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ bẹ̀rẹ̀ sí sọ láàrin ara wọn pé, “Kí ni ìtumọ̀ ohun tí ó wí fún wa yìí, ‘Láìpẹ́ ẹ kò ní rí mi mọ́.
Alufaa yóo sì sun gbogbo rẹ̀ lórí pẹpẹ náà gẹ́gẹ́ bí ẹbọ ohun jíjẹ tí a fi iná sun sí OLUWA.
Ẹ óo wá mọ̀ pé èmi OLUWA ni mo wí bẹ́ẹ̀, tí mo sì ṣe bẹ́ẹ̀.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Lizzy Anjorin vs Toyin Abraham: Madam Saje, Antar Laniyan, àtàwọn míì wí tẹnu wọn 21 Owewe 2019 Oríṣun àwòrán, @madamsaje Ni ti Toyin Abraham lori ija to wa nilẹ yii, ọna ka maa kọ iwe ranṣẹ si alatako lo n yan lati maa dahun bẹẹ si ni ni ti Lizzy, ṣiṣe fọnran jade sori ẹrọ ayelujara lati fesi loun yan.
Awọn akẹkọ naa ni wọn yabo agbegbe Bariga nilu Eko, pẹlu paali ti wọn kọ ẹhọnu wọn si lọwọ wọn, ti wọn si n sọ wipe ọpọlọpọ awọn ni ko tii forukọ silẹ fun idanwo naa.
Àwọn ọmọ Merari ni: Mahili ati Muṣi.
Mi ò gbọ́ pé Akeredolu ti yọ mí nípò gẹ́gẹ́ bíi Olùbádámọraǹ rẹ̀ - Pelemo Ta ni Sadiya Umar Farouq tí ìròyìn ẹlẹ́jẹ̀ ń gbé pé òun ló fẹ́ dí ìyàwó tuntun Buhari?
Nígbà tí wọn fún ọba ní ìwé ìpẹ̀jọ́, ọba dọ̀bálẹ̀ láàin ìgbìmọ̀, ó bẹ ọkùnrin náà.
Kí a yé kó gbogbo owó wa wá sí òkè òkun níbi tí wọ́n ti ń yàn wá jẹ káàkiri, tí wọ́n tún ń fi ẹ̀gbin lọ̀ wá.
Lẹyin naa lo lọ kawe sii ni fasiti ijọba ipinlẹ Ekiti, to wa ni ilu Ado Ekiti, to si kẹkọọ nipa Psychology gẹgẹ bi Ọba alade.
“Ẹ tẹ́tí sílẹ̀ kí ẹ súnmọ́ ọ̀dọ̀ mi, ẹ gbọ́ ohun tí mò ń wí kí ẹ lè yè.
Won fenuko pe ki aown omo igbimo naa gbe igbese to ye lori ipese owo wewe nita ki aown onisowo le rowo se pasipaaro bi o ti ye.
Ajo isokan orile-ede agbaye ati orile-ede Faranse ti gbe iru igbese ohun tako awon arakunrin meteeta naa.
 Ninu ọrọ rẹ  nibi ipade apero eto okoowo ti ọdun yii  ( Annual Investment Meeting(AIM) to waye ni Dubai
Kàkà ki ará ilú para-pọ̀ lati wo ẹ̀tẹ̀ san, nipa gbi gbé ogun ti iwà-ibàjẹ́ ni ilé-iṣẹ́ mọ̀nàmọ́ná, onikálùkù bẹ̀rẹ̀ si ṣètò fún ará wọn nipa ri ra ẹ̀rọ́ iná mọ̀nàmọ́ná ti àwọn Òyinbó ngbe dani nigbati wọn bá fẹ lọ pàgọ́.
Ọkan lara ọmọ ogun ilẹ to kopa ninu ogun nigba naa , Baba Gabriel Aladejẹbi ba BBC rin irinajo ohun ti oju rẹ ri lasiko ogun Biafra.
Ẹ yìn ín, gbogbo ẹ̀yin angẹli rẹ̀;ẹ yìn ín, gbogbo ẹ̀yin ọmọ ogun rẹ̀.
“ni oni yii, O ti le ni ọgọ́ta awon eniyan ti won ti gba iwe idije fun awon ipo to si sile ninu egbe APC fun eto idibo to n bo, won si n ta  iwe idije lowo ,a o ri i pe a tele awon eto ti a ti la sile, kikuro mi ninu ipo egbe ko ni pa egbe lara.
Àkọlé àwòrán, Erekuṣu Lambok ni Indonesia Kílódé tíleeṣẹ ààrẹ ń fẹ́ káwọn aṣòfin pada sile?
Ó dámi lójú pé wọ́n ti sọkún púpọ̀, agara sì ti dá wọn.
Ero Sẹnatọ Ladọja yi lo se afihan bi ireti awọn ọmọ ilẹ Kaarọ oo jiire se jinlẹ si nipa agbekalẹ oju opo BBC Yoruba, se tiwa n tiwa, akisa ni ti aatan.
ITakasufe igboro to dun juPenalty – Small DoctorAdako poopu to dara juIF – DavidoR ati B aladako to dun juSmile for Me – SimiAlagbe orin to je itewogba juloYou Rappers Should Fix up your Lives – M.
Àkọlé àwòrán, Àṣegbé ni ohunkóhun tí òṣìṣẹ́ aláàbò náà bá ṣe lẹ́nu iṣẹ́ Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Wọ́n yìnbọn pa àwọn tó fipá bá ọmọ ọdún 12 lòpọ̀ ní gbangba lẹyin ìdájọ́ Ajínigbé méjì kàgbákò lásìkò tí wọ́n fẹ́ ẹ́ já ọmọ gbà lọ́wọ́ ìyá rẹ̀ l'Ondo Àwọn ǹkan ti ọ̀pọ̀ ko mọ nípa Baba Suwe China ṣe àgbéjáde App"" tí ẹ lè fi mọ̀ bóyá ẹ súnmọ́ aláàrùn Coronavirus Obìnrin tó rè kọjá lójú pópó ló fà ìjàmbá ọkọ́ Osun Eyi ni ni ọkàn lára ẹsẹ ofin to wà ninu àbádofin to de isọwọ sisẹ ikọ Amotekun nipinlẹ Ekiti, (Ekiti State Security Agency Bill) ti ọdun 2020, èyi to ti wà niwaju ile igbimọ aṣòfin bayii."
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Blind DJ: Etu Omotayo kò ríran àmọ́ ó le to irinṣẹ́ eléré pọ̀ láti kọrin láì sí ìrànwọ́ Ki lo ti kókó sele seyin?
ẹ ti gbà pé ẹni bẹ́ẹ̀ kò ní ohunkohun í ṣe fún baba tabi ìyá rẹ̀ mọ́.
O fikun un pe o kere tan awọn n na N100,000 to jẹ ẹgbẹrun lọna ọgọrun un naira lori awọn ti arun naa ko ba peleke ni ara wọn, amọ ti wọn ṣi n gba itọju.
Jẹ́ kí ojú wọn ṣú,kí wọn má lè ríran;kí gbogbo ara wọn sì máa gbọ̀n rìrì.
 Inu mi dun pe ohun gbogbo ti n pada bo sipo bayii.
Angẹli karun-un da ohun tí ó wà ninu àwo rẹ̀ sórí ìtẹ́ ẹranko náà, ó bá sọ ìjọba rẹ̀ di òkùnkùn.
Itan Iṣẹlẹ COVID 19 ní Naijiria: Ọjọ kẹtadinlọgbọn, oṣu Keji, ni Naijiria kọkọ ni akọsilẹ aarun naa, lẹyin ti ọmọ orilẹ-ede Italy kan ni i.
O ni bi o tilẹ jẹ wi pe awọn eeyan kan n reti ki oun gbe lẹyin Oṣupa nitori awọn jọ jẹ ọmọ ilu kan naa, sibẹ, wọn tun gbọdọ roo pe oun ati Paso ni awọn jumọ jọ wa lati aye alalumọlẹ.
Wọ́n Rí Àkọsílẹ̀ Àṣẹ tí Kirusi Ọba Pa.
Oríṣun àwòrán, @wumitoriola Àkọlé àwòrán, Wunmi Toriola Wunmi Toriola Wunmi Toriọla jẹ́ òṣèré Tíátà ọmọ Nàìjíríà tó ń yára dìde nínú iṣẹ́ tó yàn láàyò.
25m ni wọn ta akọ ẹyẹle ti owo rẹ wọn julọ lagbaaye tẹlẹ.
 Èyí tó jásí wípé Ṣadé lẹ ́ wà ( sade is beautiful ) yàtọ ̀ sí Ṣadé lẹ ́ wà ( sade has beans ) tàbí sade ni ẹ ́ wà ( sade is the beauty ) .
2019 Election: Tinubu ní Atiku lè ṣèpàdé nínú igbó tó bá wù ú Ẹgbẹ́ oṣèlú PDP ti ṣeé níkìlọ̀ fún adarí àgbà ẹgbẹ́ oṣèlú All Progressive Congress (APC), Aṣíwájú Bola Ahmed Tinubu lórí pé ó ní ẹ̀rù ò bodò kódà bí Atiku bá lọ ṣèpàdé ní Dubai tàbí nínú igbó.
Opọ eyan lo gboriyin fun Isreal ti a bi ni Naijiria lori awọn ọna ifakayọ rẹ.
" Ẹgbẹtokun sọ pe Ọjọbọ ni ọwọ ti kọkọ tẹ ọkan lara awọn ajinigbe naa pẹlu ibọn AK-47 lọwọ rẹ, ti ọwọ si tun tẹ awọn meji mi lọjọ Ẹti.
Ọsẹ meji ni won fun igbimo naa
PDP Kogi Primaries: Tá ní àwọn ọmọ ẹgbẹ́ yóò gbé áṣíà gómìnà ìpínlẹ̀ Kogi lè lọ́wọ́?
Koda, ijọba ti ṣeto ilana aatẹlẹ fun awọn Olukọ lasiko yii ki ọsan le so didun fun awọn akẹkọọ ipinlẹ Oyo Alaafin Oyo kò dàgbà jù fún mi, ohun tó wù mí ní mo ṣe pẹ̀lú ayé mi- Olori Aanu Mo ti bẹ̀rẹ̀ sí ń bá àwọn tí a jọ díje nínú ìdìbó abẹ́lé sọ̀rọ̀ kí àláàfíà léè jọba - Akeredolu Kanye West ti bẹ̀rẹ̀ ìpolongo àti díje dupò aàrẹ ilẹ̀ Amẹrika Wo àwọn nkan tó yẹ́ kí o mọ̀ nípa 'Awawa Boys', ọ̀kan lára ẹgbẹ́ òkùnkùn tó n dá Eko rú Adarí àjọ NDDC, Pondei ṣetán láti sọ ohun tó mọ̀ nípa ìwàdíì tó bá ti gbádùn- NDDC Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Funmi Adewara: Tele Medicine' ní a fi ń ṣàyẹ̀wò èèyàn ìdá ọgọtá láti dènà ìtànkálẹ̀ Covid Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Fídíò, End SARS, End SWAT: Ó pé mi bí SARS kò ṣe sọ mí dolówọ́- Fulani Kwajafa17 Ọ̀wàrà 2020 Fídíò, Soyinka Cancer: Àṣe ara mi ni iso ti n run gbogbo bí mo ṣe n ṣèrànwọ́ lórí jẹjẹrẹ27 Bélú 2019 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
51 Iranti awsn oloogbe - N5,247,153.
Ààrẹ Buhari ni, Bí ó ṣe wá ń ṣe ayẹyẹ ọjọ́ ìbì ọdún méjìlélọ́gọ́rin, mo gbàdura fún àlékun àláfíà, ọgbọ́n àti ìmọ̀ nínú sínsin Ọlọrun àti ènìyàn"" Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!"
Sowand ni ASUU o ni yẹba kuro lori ipinu rẹ titi yoo fi gba gbogbo nkan to to fun atunto awọn ile ẹkọ ijọba apapọ jakejado Naijiria.
Oríṣun àwòrán, Twitter/Gboyega Akosile Eniyan mẹtẹẹta to wa ninu ọkọ baluu naa lo ti ku bayii, amọ eniyan meji lo kọkọ ku lẹsẹkẹsẹ ti iṣẹlẹ naa waye.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Alaafin: Oluwo àti Sunday Dare sọ irú ẹ̀dá ti Aláàfin jẹ́ 14 Sẹ́rẹ́ 2021 Oríṣun àwòrán, Instagram/Oluwo/Alaafin Oluwo ti Iwo, Ọba Abdulrasheed Akanbi ti ki Alaafin ilu Ọyọ, Ọba Lamidi Ọlayiwọla ku oriire lilo aadọta ọdun loke eepẹ.
Lọsẹ to kọja ni iroyin kan kaakiri ori ayelujara pe Aarẹ Muhammadu Buhari fẹ ṣe igbeyawo keji ti awọn eniyan si fẹ mọ nipa Ta ni Sadiya Umar Farouq tí ìròyìn ẹlẹ́jẹ̀ ń gbé pé òun ló fẹ́ dí ìyàwó tuntun Buhari?
Àákú ayé ò bá o, ilẹ̀ ló tún tẹ̀yin ṣe
“Ọlọrun lágbára, kì í kẹ́gàn ẹnikẹ́ni,agbára ati òye rẹ̀ pọ̀ gan-an.
Àṣà Yorùbá: Èèwọ̀ ni kí obìnrin wọ igbó orò
Ìgbà wo ni o sì fẹ́ pada?
‘Kò tọ́sí Adeleke láti díje dupò gomina Ọṣun’ Ilé ẹjọ́ kòtẹ́milọ́rùn yá lórí ọ̀rọ̀ Adeleke- PDP Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Adeleke fọhùn, 'èmi ni gómìnà tí wọ́n dìbò yàn' Gẹgẹ bii iroyin to tẹ wa lọwọ ṣe sọ, agogo mẹsan owurọ ọjọ aje ni Adeleke farahan ni olu ileeṣẹ ọlọpaa orilẹede Naijiria nilu Abuja.
Nítorí rẹ mo pa odidi ìlkú rẹ, nítorí rẹ mo mú ènìyàn kúrò lórí oyè, ọ̀rẹ́ mi ayé, ọ̀rẹ́ mi ọ̀run, ọjọ́ wo ni ìwọ ń bọ̀ wáá bá mi?
Sugbọn nigba ti ina wọn jo de ori koko, akude nla lo mu wọ isọkan ati irẹpọ Naijiria, ọpẹ Ọlọrun ti ko si fẹ ki okun irẹpọ ati isọkan ja ni orilẹede yii.
Ìdààmú ńlá ńbọ̀ fún Nàíjíríà lábẹ́ ìjọba Buhari - Ọbasanjọ A ò dójúlé Saraki pé kó dá nọ́mbà ọkọ̀ tó lò padà- FRSC Kókó ọ̀rọ̀ tí Buhari sọ ní àyájọ́ June 12 Ọba Adesoji Aderemi, Ọọ̀ni Ifẹ̀ tó gba ipò ọba mọ́ tòṣèlú O ṣalaye pe ofin eto idibo lorilẹ-ede Naijiria ko sọ pe ki ajọ INEC ko esi idibo aarẹ sinu ''server'' kọmputa INEC.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Alaafin Oyo: Níbo ni Olorí Anu àti Dami wà?
Oríṣun àwòrán, @officialEFCC Àkọlé àwòrán, Magu ni olú iléeṣẹ́ tuntun nàá kò le gba àwọn òṣìṣẹ́ tó wà ní ìlú Abuja.
Ó kúnlẹ̀, ó gbé ọwọ́ rẹ̀ sókè sí Ọlọrun; 
Nígbà tí ó pẹ́ tí wọn kò lọ, inú bi Ìjàǹbáforítì: ó mú ṣòkòtò rẹ̀ ó fún un le, ó mú ìbọn rẹ̀ ó tún un ṣe, ó sì kọjù sí wa ó wò wá bí alágbára tí í wo ènìyàn ó bú sí ẹ̀rín, ó ní ‘Ẹni máa kú pàdé ẹni máa pa á, èmi Ìjànbáforítì ọkùnrin, mo gba gbogbo nǹkan, ṣùgbọ́n n kò gba ìwọsí, ènìyàn kì i kú lẹ́ẹ̀mejì, bí ikú bá mú mi n ó maa bá ikú lọ.
Wo àwọn ohun márùn ún tó yẹ kí o mọ̀ nípa Sanusi Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 3 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 5 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Gbogbo àwọn onigbagbọ wà ní ibìkan náà.
Nígbà tí o bá rí wọn,inú rẹ yóo dùn,ara rẹ óo yá gágá.
” Wọ́n kẹ́gàn rẹ̀, wọn kò sì mú ẹ̀bùn wá fún un, ṣugbọn Saulu kò sọ̀rọ̀.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Kemi Afolabi di màmá olóyè nínú ẹ̀sìn, oyè ìmọ́lẹ̀ Àdínnì ni wọ́n fi jẹ 9 Ẹrẹ̀nà 2020 Oríṣun àwòrán, Instagram/Kemi Afolabi Gbaju-gbaja oṣerebinrin Yoruba, Kemi Afolabi Adesipe ti di ọkan lara awọn oloye ẹsin Islam.
Àwọn ọmọ Nàìjíríà la ohùn Olùdásílẹ̀ Twitter bá wọn jó 'Soapy' ní Nàìjíríà , ó fi òǹtẹ̀ jan Tacha Titi di igba ti a nko iroyin yii jọ, igbiyanju lati ba olori ijọ ti ọmọ naa ti sọnu, ijọ Sọ titobi rẹ, sọrọ lo ja si pabo, ti ko si gbe ẹrọ ibanisọrọ rẹ.
Mose bá dáhùn pé, “Wò ó, ń óo jáde kúrò ní iwájú rẹ nisinsinyii, n óo sì lọ gbadura sí OLUWA, kí ọ̀wọ́ eṣinṣin wọnyi lè lọ kúrò lọ́dọ̀ rẹ ní ọ̀la, kí wọ́n sì kúrò lọ́dọ̀ àwọn ẹmẹ̀wà rẹ ati àwọn eniyan rẹ pẹlu ṣugbọn kí Farao má tún dalẹ̀, kí ó má wí pé àwọn eniyan Israẹli kò gbọdọ̀ lọ rúbọ sí OLUWA.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Odumakin sọrọ lori Fulani darandaran Ijọba apapọ Naijiria ti fi ikede sita pe ko si dandan ninu fifi ilẹ rẹ silẹ rara.
Igbe náà sì tún fi hàn pé ara ọmọ náà dápé.
"Bello tẹsiwaju pe ""Bo tilẹ jẹ pe arun yii ti n peleke si ni Naijiria, ileeṣẹ eto ilera ipinlẹ wa n ṣiṣẹ takuntakun lati ri pe arun naa ko si ni ipinlẹ Oyo."
Iṣoro inu ọpọlọ lo pada pa Beau lọdun 2015 lẹni ọdun mẹrindinlaadọta.
Ẹ wo irú ìfẹ́ tí Baba fẹ́ wa tí a fi ń pè wá ní ọmọ Ọlọrun!
Ẹ wo Olufemi Lanlehin ti ADC tó ń dupò gómìnà ní Ọyọ!
A wọ ilé Filipi, ajíyìnrere, ọ̀kan ninu àwọn meje tí àwọn ìjọ Jerusalẹmu yàn ní ijọ́sí.
Joṣua bá bá wọn ṣẹ́ gègé ní Ṣilo, níwájú OLUWA, bẹ́ẹ̀ ni Joṣua ṣe pín ilẹ̀ fún àwọn ọmọ Israẹli.
Wọ́n ti yìnbọn pa ọkùnrin ẹni ọgbọ̀n ọdún tó ń jà sí ogún ilẹ̀ bàbá rẹ̀ Ẹgbẹ́ NULGE Oyo dìbò yan olóyè ẹgbẹ́ tuntun èyí tó tako àṣẹ iléẹjọ́ Ilé iṣẹ́ ọmọogun òfurufú sọ orúkọTolulope Arotiba di málegbàgbé lórílẹ̀-èdè Nàìjíríà Ìdùnnú subú layọ̀ nípìnlẹ̀ Ọyọ́, àwọn tó dé láti Lebanon sọ ọmọ wọn ní Seyi Wo ọ̀nà tí o fi lè dáàbò bo ọmọ rẹ lọ́wọ́ COVID-19 níléèwé Ẹ yé parọ́ kiri!
Nígbà náà ni ẹnìkan tí ó sá àsálà lójú ogun náà wá ròyìn fún Abramu, tí ó jẹ́ Heberu, tí ń gbé lẹ́bàá igi Oaku, ní igbó Mamure, ará Amori.
Àwọn ọmọ rẹ̀ nìkan ni wọ́n lè jogún ilẹ̀ rẹ̀ títí lae.
A fún un ní agbára láti gbógun ti àwọn eniyan Ọlọrun ati láti ṣẹgun wọn.
Lara awọn ti ijọba tun yan ni Oloye ẹgbẹ oṣelu APC, Alhaji Mutiu Are, ati ọmọ asiwaju ẹgbẹ naa, Folasade Tinubu-Ojo, to fi mọ alaga ẹgbẹ ọmọ lẹyin Kristi nipinlẹ Oyo, Benjamin Akanmu.
óyá dára wò pẹ̀lú àwọn òwe Yorùbá
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Dele, ọmọdé tó ń fi iná ẹ̀rọ ATM ṣe iṣẹ́ àmurelé sọ ìdí tó fi kára mọ́ ẹ̀kọ́ rẹ̀ fún BBC Yorùbá Elédùmarè ló rán mi sí gbogbo Ọba Yorùbá - Oluwo 'Ẹ jọ̀ọ́, a ò fẹ́ gbọ́ òfófó ìròyìn mọ́ pé àbúrò mi gún bàbá àti ìyá mi pa, ó ti tó gẹ́!
Ní ọdun 1796 Jenner sé ìwádìí kan tó si lo James Phipps ọmọ ọdun mẹ́jọ nígbà tó fí àìsàn máàlú si oju egbò láìpẹ́ ọmọ náà bẹ̀rẹ̀ si ni fi ami àìsàn náà han.
Ẹ lọ pe gbogbo àwọn ẹranko igbó jọ,ẹ kó wọn wá jẹun.
Àwọn kan wá sọ fún Jehoṣafati pé ogun ńlá kan ń bọ̀ wá jà á láti Edomu ní òdìkejì òkun.
Juda bá pe Onani, ó ní, “Ṣú iyawo arakunrin rẹ lópó kí o sì bá a lòpọ̀, kí ó lè bímọ fún arakunrin rẹ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Sexual harassment bill: Àwọn aṣòfin buwọ́lu ẹ̀wọ̀n ọdún mẹ́rìnlá f'olùkọ́ tó bá fọwọ́ kan akẹ́kọ̀ọ́bìnrin lọ́nà àìtọ́ 18 Èrèlè 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 7 Agẹmo 2020 Oríṣun àwòrán, Gettty Ile igbimọ aṣofin agba l'Abuja ti buwọlu ofin to tako fifọwọ kan obinrin lọna aitọ laarin awọn olukọ si akẹkọọ ni Naijiria.
"Ipo ọrọ aje tijọba mi jogun nsọ fun wa pe isẹ pọ lati se, taa si tun gbọdọ gbe ọpọ ipinnu kalẹ pẹlu.
Ṣugbọn ẹni tí ó bá sọ̀rọ̀ àfojúdi sí Ẹ̀mí Mímọ́, a kò ní dáríjì í.
O ni: “Ijoba wa mo pe a ko le da ise idagbasoke se laifi t’awon aladani se rara paapaa lori igbanisise ati ipese ipin idokowo.
Omotara pàdánù isẹ́ olówó ńlá nítorí ó fi ọtí ẹlẹ́rìndòdò sódà lá ọmọ alágbe lójú Mí o fẹ́ kí wọ́n tún jí mi gbé léèkejì- Falae ké gbàjarè!
Nígbà tí ilẹ̀ bá sì mọ́, wọn á ṣe ibi tí wọn ń gbèrò.
Mikel lo soju Naijiria ninu idije boolu agbaye tawon odo tojo ori won koju ogun odun lo, FIFA U-20 World, ti O si gba ami eye agbaboolu keta ti o kopa julo ninu idije naa tele Lionel Messi, besini o bere si ni kopa fun Super Eagles lojo ketadinlogun osu kejo odun 2005.
Gẹgẹ bi aarẹ ṣe sọ, igbesẹ naa ṣe pataki lati ri i daju pe eto idibo to fẹ ẹ waye ni Guinea Bissau yoo mu nkan pada bọ sipo l'orilẹede naa.
Ranyin ranyin lorukọ rẹ n ja lori awọn iroyin Naijiria ati ilẹ Afirika bayii to bẹẹ́ to jẹ wi pe orukọ rẹ gba ori ẹrọ ayelujara kan.
Tyson Fury d'ẹ̀ṣẹ́ bo Deontay Wilder lórí, ó gbadé WBC mọ́ ọ lọ́wọ́ Boko Haram tún ṣọṣẹ́ ní Adamawa, ọ̀pọ̀ òkú ṣùn, àìmọye dúkìá jóná Otedola Bridge: Àwọn ẹ̀ṣọ́ ojú pópó ti gbé Ọkọ̀ agbépo tó dànù kúrò lọ̀ná Ninu atẹjade kan lati ọwọ agbẹnusọ rẹ, Kunle Somorin, Abidoun sọ pe ẹnikẹni lara awọn agbofinro ti aje ọrọ ọhun ba ṣi mọ lori yoo jẹ iyan rẹ niṣu.
Eyìn o rẹyin, Abiola ti léwáju ninu ìdìbò náà ní ìpínlẹ̀ Mọ́kandínlógun nígbà ti Tofa bori ibo ní ìpínlẹ̀ mọkanla, Sùgbọ́n ààrẹ ológun nigbà náà, Ọ̀gágun Ibrahim Babangida wọgile ìdìbò náà, kí wọn to ka èsì ìdìbò naa tan.
Ibeere yi ni Lahiri fi ẹrin dahun pe: Ti mo ba ṣe é to ba di odindin, o di idán ni yẹn; ṣugbọn ti ko ba jọ ara wọn, a jẹ pe aṣiṣe ni ni yẹn to dẹ le mu ewu dani.
O bẹrẹ sini gbadun ibalopọ Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Bo tilẹ jẹ pe ọmọọba ni, eyi ko ṣe idiwọ fun un lati ṣewadii ibalopọ fun awọn obinrin Lẹyin to bi ọmọ meji fun ọkọ rẹ - ti wọn jọ gbe papọ fun aadọta ọdun - lo to o mọ pe ọnku rẹ, Ọmọọba Valdemar ti Denmark, ni ọkọ rẹ nifẹ si.
Balaamu dá a lóhùn pé, “Ǹjẹ́ n kò tí sọ fún ọ pé ohun tí OLUWA bá sọ fún mi ni mo gbọdọ̀ sọ?
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ohun tawọn eeyan Kogi n sọ saaju idibo Gomina Bello naa gboriyin fawọn eniyan ipinlẹ Kogi pẹlu ileri tuntun lati ṣeto ijọba to dara lasiko yii.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù World environment day: MOSOP ní Ààrẹ Buhari kò sòótọ́ lórí àfọ̀mọ́ Ogoni 5 Òkùdu 2018 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, MOSOP ní nńkan ò rọgbọ fún àwọn èèyàn ẹkùn Niger Delta, paapaajulọ agbègbè Ogoni Ẹgbẹ kan to n ja fun igbayegbadun awọn eeyan agbegbe ogoni lẹkun Niger Delta, MOSOP, ti ke si ijọba apapọ ati awọn ileeṣẹ awapo rọbi tọrọ kan lati tubọ kona mọ eto afọmọ agbegbe Ogoni ni ibamu pẹlu abajade iwadi ajs to n mojuto atunṣẹ idibajẹ to waye nipasẹ epo rọbi, HYPREP.
Lara wọn ni sọja obinrin koda wọn fa irin to fi n gbiyanju lati rin gẹgẹ bii onipenija ara.
Wọ́n ń gbé Gati pẹlu àwọn ará ilé wọn.
 Obasanjo fikun pe nigba ti Bajọwa de, to si beere pe oun fẹ sọ ọmọ tuntun naa ni orukọ oun, o ni oun fun aṣẹ lati lo orukọ oun."
1 1491 Orilẹede Burundi 2 0.
fi se ise ọgbin  kuro nibẹ, ni eyi ti o
” Jesu sọ èyí nítorí láti ìbẹ̀rẹ̀ ni ó ti mọ àwọn tí kò gbàgbọ́ ati ẹni tí yóo fi òun lé àwọn ọ̀tá lọ́wọ́.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, EndSARS protest in Nigeria: Mr Macaroni, Falz, Wizkid, Tiwa Savage àtàwọn míì ṣe ìwọde Dokita Faduyile sọ pe awọn oluwọde yii wa lati oriṣiiriṣii ile to yatọ eleyi to le mu ki aarun covid-19 tete tan kalẹ laarin wọn.
kí ọ̀rẹ́ náà wá ti inú ilé dáhùn pé, ‘Má yọ mí lẹ́nu.
When @VictorMoses lets fly…💥 #BURCHE pic.
Nisinsinyii a ti dé Kadeṣi, ìlú kan tí ó wà lẹ́yìn odi agbègbè rẹ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Nigeria Diaspora Day: Ìjọba ní láti ronú jinlẹ̀ nípa òun tó n sọ ọmọ Nàìjíríà d'ero ilẹ ókéèré 25 Agẹmo 2019 Oríṣun àwòrán, AFP Idagbasoke orileede Naijiria kii ṣe iṣẹ ijọba nikan bi kii ṣe ki awa ti a wa nilu okere naa ṣa ipa ti wa.
Coronavirus tún ti ṣe ọṣẹ́ lórí iṣẹ́ líla ojú ọ̀nà relùwe láti Eko sí Ibadan - Ìjọba àpapọ̀ Ijọba orilẹede Naijiria ti sọ wi pe, ajakalẹ arun Coronavirus lo mu ki wọn dawọ iṣẹ ti wọn n ṣe, loju ọna reluwe Eko si Ibadan.
O ni ṣiṣe eto ikọni fawọn oṣiṣẹ eleto ilera ati ririsi eto ipolongo Every Child Alive naa a tun din iku awọn ikoko yii ku.
Pẹlú bandeji lọrùn rẹ, ni Gómìnà Fayoṣe fi n bẹnu àtẹ lù bí àwọn òṣìṣẹ́ alaabó ṣe gẹgun tii lọrun nilé ìjọba, ti wọn sì yín afẹfẹ tajutaju lù u.
"Niṣe ni wọn n fi ipa ṣe akoba fun awọn dukiya ijọba jakejado ipinlẹ Ọyọ""."
Aare orile-ede Russia, Vladimir Putin ti se ikilo fun awon gomina kookan lorile-ede naa, lati mase so awon ipago igbaboolu tabi ayika papa isere ti won yoo lo fun idije boolu agbaye di ile itaja.
Labani bá bi í léèrè pé, “Kí ni kí n máa fún ọ?
Awọn dokita naa wa n rawọ ẹbẹ sijọba ipinlẹ Ondo labẹ gomina Rotimi Akeredolu, to fi ms gbogbo ọmọ Naijiria lati bawọn kesi awọn alasẹ ile iwosan naa pe ki wọn jẹ owo ti wọn jẹ wọn.
 ilè cameroon ni wọ ́ n ti ń sọ ọ ́ .
Oríṣun àwòrán, Others Ọkùnrin meji ni awọn ibeji akọkọ ti Taiwo kọkọ bi, oṣu keje ọdun 2013 si lo bi awọn ìbejì naa fun ọkọ rẹ, Olayemi Abimbola, bi o tilẹ jẹ pe igbeyawo laarin tọkọtaya ọhun ti tuka.
Oríṣun àwòrán, @ekitistategov Gbalaja ni Fayemi fi idọbalẹ bẹ fun Alaafin, eyi to n fihan pe ko si aawọ ma.
Bakan naa, ni a o tun lo sabewo si ipago awon ara-ilu ti awon agbesunmomi yii ti sekolu si.
Gẹ́gẹ́ bí àkọsílẹ̀ ìran wọn ní ìdílé ìdílé, àwọn jagunjagun tí wọ́n ní tó ẹgbaa mejidinlogun (36,000) kún ara wọn, ní ìsọ̀rí ìsọ̀rí; nítorí wọ́n ní ọpọlọpọ iyawo ati ọmọ.
O ni wọn n ta ilẹ Iwo, oun si ni oun fi awọn ọba abẹ oun sipo, koda awọn ọba to wa laarin oun ati Agbowu lọjọ naa to mẹrin, ti wọn ko si jẹ ki ọwọ oun to o.
OLUWA àwọn ọmọ ogun,ayọ̀ ń bẹ fún ẹni tí ó bá gbẹ́kẹ̀lé ọ.
Apó ọfà wọn dàbí isà òkú tó yanu sílẹ̀,alágbára jagunjagun ni gbogbo wọn.
Àkọlé àwòrán, Iyara akẹkọọ kan ni Block G ni nibugbe awọn akẹkọkunrin ni Fasiti Bayero ni Kano Awọn to ti kawe nilẹ okeere ni àwọn ile ti awọn akẹkọọ Naijiria n gbé kò bọ sii rara.
Àjogúnbá , ìtàn-ìṣẹ̀lẹ̀-àtẹ̀yìnwá, àṣá jẹ́ ọ̀rọ̀ tí kò já mọ́ nǹkan ní orílẹ̀-èdè yìí!
Fi idẹ ṣe ìkòkò láti máa kó eérú orí pẹpẹ sí, fi idẹ ṣe ọkọ́, àwo kòtò, ọ̀kọ̀ tí wọ́n fi ń gún ẹran ẹbọ ati àwo ìfọnná, idẹ ni kí o fi ṣe gbogbo àwọn ohun èlò pẹpẹ náà.
Amosa, awon to n fi ehonuhan 
Afọnja fikun pe ojuse awọn alakoso ibudokọ naa ni lati maa gba owo ita ati sise akoso awọn akọsẹmọsẹ lorukọ ijọba, wọn yoo maa gba igba naira lojumọ lọwọ awọn ọlọkada Oríṣun àwòrán, Seyi Makinde O wa mẹniba pe ahesọ lasan ni iroyin kan to n ja nilẹ pe ijọba ipinlẹ Ọyọ yan alaga tẹlẹ fẹgbẹ awakọ ero, Mukaila Lamidi, ti gbogbo eeyan mọ si Auxiliary, gẹgẹ bii ọkan lara awọn alakoso ibudokọ.
Osinbajo Crisis: Ìbéèrè mẹ́rin ti Laolu Akande ń bèèrè lọ́wọ́ Festus Adedayo
Oríṣun àwòrán, @Aminu Bello Masari Àwọn tó jí àwọn akẹ́kọ̀ọ́ GSSS gbé ní Kankara ti kàn sí wa - Masari Gomina ipinlẹ Katsina, Bello Masari ti sọ fun Aarẹ Muhammadu Buhari pe awọn to ji awọn akẹkọọ ile iwe girama to wa ni Kankara, ni ipinlẹ naa ti kan si awọn.
Paulu bá kígbe pè é, ó ní, “Má ṣe ara rẹ léṣe, nítorí gbogbo wa wà níhìn-ín.
Ajo to n mojuto eto ilera lagbaye World Health Organisation (WHO), ti pe fun ipade pajawiri lati jiroro nipa ona ti won yoo gba fi dena bi arun Ebola to gbode kan lorile-ede Democratic Republic of the Congo ko se ni tan kakaakiri.
Coronavirus: Ọmọ Nàìjíríà tó darí láti France wá labẹ àyẹwò lórí Coronavirus
O ni ki wọn fopin si ifiyajẹni ti ko ba ofin mu.
Eleyii to tun hande ninu ipade apero naa ni bi awọn alẹnulọrọ ati awọn ẹlẹgbẹjẹgbe ṣe tun fọwọ si pe ki Aṣofin Tunde Braimoh tun gbe apoti ibo lẹẹkan lati ṣoju wọn ni ẹkun idibo Koṣọfẹ keji, gẹgẹ bi ẹni to ti fi akitiyan rẹ mu idagbasoke nla ba agbegbe Agboyi-Ketu ati pe inu awọn yoo dun lati jẹ ki o tẹ siwaju.
Gbogbo nǹkan yòókù tí Amoni ṣe ni a kọ sinu Ìwé Ìtàn Àwọn Ọba Juda.
Oríṣun àwòrán, Frankieleon Àkọlé àwòrán, Àṣìlò codeine wọ́pọ̀ láàrin àwọn ọ̀dọ́ Ẹ̀wẹ̀, wọ́n ní kò ní i sí ààyè láti kọ̀wé tuntun bèérè fún àṣẹ láti kó codeine wọ́lé láti ilẹ̀ òkèérè gẹ́gẹ́ bi èròjà gbòógì fún ṣíṣe òògùn ikọ́ olómi, tàbí sọ èyì tó ti wà nílẹ̀ tẹ́lẹ̀ dọ̀tun.
gomina ana ni Ipinle Ekiti, Ayodele Fayose; Omooba Olagunsoye Oyinlola; Oloye
Idi ti idibo to n bo
Wọn fẹ̀sùn kàn pé o ń fí owó ra ìbò àwọn ará ìlú.
James Akinjobi ni: “Ipinnu ijoba apapo ni lati fopin si aawo yii ki inu onikaluku to padanu ile dun nipa titun awon ile ti ikolu naa baje ko ki awon eniyan le pada sile won ni alaafia laipe ojo rara.
Emir of Kano: Oríṣiríṣi ẹ̀sùn ni ìjọba ìpínlẹ̀ Kano kà sí Sanusi l'ẹ́sẹ̀
Ìpàdé ìjọba ati ASUU forí sánpọ́n Ó seése kí ASUU fòpin sí ìyansẹ́lódì rẹ̀ lọ́jọ́ Ajé Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, ASUU Strike: Bí àwọn kan se dunnú, làwọn kan fajúro Awọn olukọni ile ẹkọ fasiti Naijiria ti dẹgun le iyansẹlodi ọlọjọgbọrọ lati ọjọ kẹrin osu kakanla ọdun yi yi.
Ilé ẹjọ́ sún ẹjọ́ Sẹ́nétọ̀ Abbo síwájú pẹ̀lú béèlì mílíọ̀nù márùn-ún Amuneke fipò sílẹ̀ gẹ́gẹ́ bí akọ́nimọ̀ọ́gbá Tanzania Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Orangun: Èdè àti àṣà Yorùba ní láti jọ wá lójú Awọn eekan mejeeji ni ọrọ ki awọn kan maa ro pe ìbí ju ìbí lọ ko yẹ ko ṣẹlẹ rara ni Naijiria.
Ile aṣofin naa daru lẹyin ti Sẹnetọ Bassey Akpan to n ṣoju ẹgbẹ oṣelu PDP, lati ipinlẹ Akwa Ibom, tọka si awọn kudiẹ-kudiẹ kan to waye nibi eto idibo abẹle ẹgbẹ APC to waye ni ipinlẹ Akwa Ibom.
Gẹgẹ bi itan ti sọ fun wa, olowo, ọlọrọ ati ẹlẹyinju aanu ni Adebisi nigba aye rẹ eyi to to ọgọrun un ọdun sẹyin.
Sadoku, alufaa, wà láàrin wọn, àwọn ọmọ Lefi sì wà pẹlu rẹ̀, wọ́n gbé àpótí ẹ̀rí lọ́wọ́.
CBN Policy: Buhari pàṣẹ fún báńkì àpapọ́ láti dẹ́kun owó ìrànwọ́ fáwọn tó ń gbé oúnjẹ wọ Nàìjíríà
Asa ọba fi ìyà jẹ àwọn kan ninu àwọn ará ìlú ní àkókò náà.
Ọmọ meji ni a gbọ pe wọn ti bi fun ara wọn.
Marlians, Grandpa Marlians ṣugbọn oun kọ lati jẹ Naira Marley nitori pe oun bẹru awọn ajọ EFCC to n gbogun ti iwqa ajẹbanu ni Naijiria pupọ Àwọn àádọ́ta ọ̀dọ́ wọ gàù nítorí ilé ijó ní Ilorin Báwó ni òògùn dexamethasone ṣe ń ṣiṣẹ́ lára Ẹ̀bi ta ni pé àwọn ọ̀dọ́bìnrin Nàìjíríà ń há sí Oman?
Onnoghen: Nítorí EFCC, ìgbìmọ̀ ìṣèdájọ́ tó ga jùlọ, NJC kọ̀wé ìfisùn tuntun ránṣẹ́ sí Onnoghen
Imohimi ti ni ki wọn gbe ọrọ naa lọ ẹka ileeṣẹ ọlọpaa ọtẹlẹmuyẹ to wa ni Panti, Yaba.
    Ẹni kaàrún ni ọkùnrin kan báyìí tí orúkọ rẹ̀ ń jẹ́ Olójú-Májèlé tí i ma gbé eyín erin kiri.
Dino Melaye: Mi o du ipo aarẹ ni 2019
(Iwe alakalẹ APC 2018) Agbeyẹwo Ọrọ Eto ilana ẹkọ ti ọdun 1999 ni ki ijọba pese eto ẹkọ ọfẹ fun awọn akẹẹkọ ni ile iwe alakọbẹrẹ.
ipinle naa  fun igbesẹ akin to gbe lasiko
Loju opo Twitter kaakiri lawọn eeyan ti n sọ nipa iyipada tawọn n reti lati ọdọ Mourinho amọ wọn ko ye sọ nipa bo ti ṣe ṣaaju sọ pe oun ko ni gba iṣẹ akọnimọọgba ẹgbẹ naa.
Mo ti ní ìyàwó àfẹ́sọ́nà, ayẹyẹ ìgbeyàwó mi ń bọ̀ láìpẹ́ - Lateef Adedimeji Ẹlẹ́tàn ni ọkùnrin, tó bá rí nkan tó n wa lára obìnrin, yóò yí ìwà padà - Bimpe Oyebade Irú ẹ̀dá wo ni Lamidi Adeyemi?
Ẹsun ti wọn fi kan an ni pe ko sọ ibi ti o ti ri iroyin kan to kọ ṣugbọn o kọ lati sọ ọ fun wọn.
O ni bi awọn eeyan ti sun mọ ara wọn nibi isinku Abba Kyari le ṣakoba fun awọn ọmọ Naijiria.
Aare yoo pada si orile ede
àwọn Juu péjọ ninu àwọn ìlú wọn ní àwọn ìgbèríko ilẹ̀ Ahasu-erusi ọba, wọ́n múra láti bá àwọn tí wọ́n fẹ́ pa wọ́n run jà.
Nínú ìlànà òfin àti ọ̀rọ̀ Ajé, iye òmìnira ọ̀rọ̀ ń dìde kárí Ilẹ̀-Adúláwọ̀.
 gẹ ́ gbẹ ́ bí oníṣòwò , ó jẹ ́ obìnrin àkọ ́ kọ ́ tí ó máa jẹ ́ alábápin ọjà fún nigerian tobacco company ( ntc ) ní ọdún 1957 .
Nígbà tí wọ́n bá wí fun yín pé kí ẹ lọ wádìí ọ̀rọ̀ lọ́dọ̀ àwọn àjẹ́ ati àwọn abókùúsọ̀rọ̀ tí wọn ń jẹ ẹnu wúyẹ́-wúyẹ́.
"Ifedayo ni ""Jẹ́ ki o wà nínú àkọsílẹ̀ pé tí òhunkóhun bá ṣẹ̀lẹ̀ sí mi lónìí, ẹ ti mọ̀ ẹni ti ó wà nídi rẹ̀."
" Alabi wa n beere pe ki wọn si mọsalasi ọhun pada, pẹlu ipese eto aabo to peye, o si se afikun pe, oun ko lero laelae pe irufẹ isẹlẹ bayi lee waye ni orilẹede New Zealand, nitori pe o jẹ orilẹede to ni alaafia gidigidi.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù NFF àtàwọn olólùfẹ̀ eré bọ́ọ̀lù ń ṣe ìdárò Big Boss: Keshi 7 Òkùdu 2018 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 9 Òkùdu 2018 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Olóògbe Stephen Keshi fìgbà kan jẹ́ akọ́nimọ̀ọ́gbá ẹgbẹ́ agbábọ́ọ̀lù orílẹ́lèdè Togo O pé ọdun meji ti akọnimọọgba ikọ Super Eagles, Stephen Keshi, jade laye lẹyin iku aya rẹ̀.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ọdún Orò ń sọ àwa obìnrin sí ìgbèkùn, ẹ̀wọ̀n, tó sì ń tẹ ẹ̀tọ́ wa lójú - Àwọn obìnrin Ikorodu faraya Èèyàn mẹ́rìnlá tí ọpọlọ wọ́n pé la buwọ́lù bíi kọmísọ́nà l‘Oyo - Olórí ilé aṣòfin kan sáárá Èmi àti Saheed kìí ṣe ọmọdé, a ti jọ ṣe Sinimá papọ̀, èyí túmọ̀ sí pé ìjà ti parí - Fathia Balogun Mo fẹ́ pa ara mi torí ojú àbùkù tí wọn ń fi wò mí pé mo fi iṣẹ́ abẹ bímọ"" Fulani kò leè dúró, táa bá lo ohun ta jogún lọ́dọ̀ àwọn bàbá wa - Sunday Igboho Soyinka, ẹni to mu igbe yii bọnu lasiko to n bawọn akọroyin sọrọ nilu Akurẹ nibi ayẹyẹ kan, tun salaye pe o n bọ, o n bọ, awọn laa dẹ de, amọ laye ode oni, oju ni wọn n mu to, nitori eto aabo ti mẹhẹ nilẹ Kaarọ Oojire kọja sisọ, o si yẹ ko wa nkan se nipa rẹ."
Tabi báwo ni o ṣe lè wí fún arakunrin rẹ pé, ‘Jẹ́ kí ń bá ọ yọ ẹ̀ẹ́rún igi tí ó wà lójú rẹ,’ nígbà tí ó jẹ́ pé ìtì igi wà ní ojú tìrẹ alára?
O ni oun pe aarẹ Buhari lori isẹlẹ ipaniyan naa laarọ ana, amọ wọn n bun mi gbọ pe ko tii de si ọọfisi.
Nítorí náà, dìde ní òwúrọ̀, ìwọ ati àwọn iranṣẹ oluwa rẹ, tí wọ́n bá ọ wá, kí ẹ sì máa lọ ní kété tí ilẹ̀ bá ti mọ́.
"Amọ ootọ ọrọ to wa nilẹ ni pe a lee yago fun awọn nkan kan nitori ojoojumọ ni ọpọ iroyin n wa nipa awọn ọkunrin to n pa iyawo wọn ati awọn obinrin to n pa ọkọ wọn, tawọn afẹsọna lọkunrin-lobinrin naa si n gbẹmi ara wọn nitori ẹsun sise oju meji.
Lori oju to fi wo ipo ti awada ṣiṣe ninu ere tiata de duro lode oni, adẹrinposonu naa tun woye pe, ọpọ awọn eeyan to n ṣe awada lasiko yii ni wọn n ṣe gudugudu meje ati ya ya mẹfa nitori ko rọrun lati pa awọn eeyan ni ẹrin.
Ìwà òmùgọ̀ ni o hù yìí.
Haram bi  ọsẹ se n soju.
Àwọn ìyàwó tó jẹ́ igi lẹ́yìn ọgbà fún Isola Ogunsola Mojisola Ogunsola Oloogbe Mojisola Ogunsola ti awọn eeyan mọ si Iya Alakara nigba aye rẹ, ni iyale patapata ninu awọn iyawo Isho Pepper, to si maa n tẹle ọkọ rẹ lọ ṣe ere tiata kaakiri.
(Wọn kò ì tíì ju Johanu sẹ́wọ̀n ní àkókò yìí.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Coronavirus: Agbábọ́ọ̀lù Man U tẹ́lẹ̀, Marouane Fellaini, Paulo Dybala àti ọ̀rẹ́bìnrin rẹ̀ lùgbàdì covid-19 22 Ẹrẹ̀nà 2020 Oríṣun àwòrán, Getty Images Agbabọọlu ikọ Manchester United tẹlẹ, Marouane Fellaini ti ko arun coronavirus.
N óo máa jẹ́ kí òjò máa rọ̀ lásìkò wọn, òjò ibukun ni yóo sì máa jẹ́.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù AFCON 2021: Orílẹ̀-èdè Cameroon tí yóò gbàlejò ìdíje nàá yí ọjọ́ padà 15 Sẹ́rẹ́ 2020 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Oṣu Kẹfa ati Ikeje loyẹ ki idije naa waye, ṣugbọn Fecafoot sọ pe ayipada waye nitori bi oju ọjọ ṣe maa n ri ni akoko naa.
Aṣọ wọn jẹ́ aláwọ̀ pupaati ti elése àlùkò,iṣẹ́ ọwọ́ àwọn oníṣọ̀nà ni gbogbo wọn.
“Ṣé ọ̀nà àtijọ́ ni ìwọ óo máa tẹ̀lé;ọ̀nà tí àwọn ẹni ibi rìn?
naa , ni odun 2020 ti won lero pe won yoo bẹrẹ  si maa se amulo rẹ .
Ogo rẹ bá bẹ̀rẹ̀ si nii tán, o bẹ̀rẹ̀ si ni ṣeré orin lori itage fún iléese Nigeria Broadcasting Corporation.
Gbogbo ẹnubodè rẹ wà ní ṣíṣí sílẹ̀ fún àwọn ọ̀tá rẹ; iná sì ti jó gbogbo ọ̀pá ìdábùú ìlẹ̀kùn bodè rẹ.
O fi kun ọrọ rẹ pe ẹnikẹni to ba tapa sofin irina yoo ṣe ọdun Keresi ati ọdun tuntun rẹ lọgba ẹwọn.
Fífẹ́ ju ìyàwó kan lọ ló mú ìṣẹ́ àti ìfàsẹ́yìn ba àpá àríwá Nàìjíríà- Lamido Sanusi Ṣé Burna boy yóò leè dá igbó Grammy Awards lu fún Nàìjíríà lọ́dún yìí?
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, ìgbà ayé ọbabìnrin Victoria tí àwọn dókítà ṣe àgbéjáde rẹ̀ fún ìrànwọ́ àwọn obìnrin tí kò lè mára dúró Ẹ̀rọ̀ fún fífẹ́ ìbálòpọ̀ ní gbogbo ìgbà Ní ìgbà tí wọ́n rò wí pé béèyàn bá dé ìpele gbígbádùn ìbálòpọ̀ léè wò àìlèmáradúró.
Báwo ni ẹ kò ti ṣe ní gba ìdájọ́ ọ̀run àpáàdì?
O lọ fun eto ilera ara rẹ ni.
 Ó gba ìwé ẹ ̀ rí hnd ( higher national diploma ) ní ilé-ẹ ̀ kọ ́ gbogbo-nìṣe ìlú Ìbàdàn ìyẹn ( ibadan polytechnic ) , lásìkọ ́ yí , ó jẹ ́ akẹgbẹ ́ pẹ ̀ lú dibie , c.
Aarẹ ẹgbẹ ọhun, Ọjọgbọn Biodun Ogunyemi lo sọ be fun ileeṣẹ iroyin abẹle Punch lọjọ Aiku.
“Mo bẹ̀ ọ́, lọ wádìí nípa ìgbà àtijọ́,kí o ṣe akiyesi ìrírí àwọn baba wa.
Ó kọ̀wé sí Efuraimu ati Manase pẹlu, pé kí gbogbo wọ́n wá sí ilé OLUWA ní Jerusalẹmu láti wá ṣe Àjọ Ìrékọjá ní orúkọ OLUWA Ọlọrun Israẹli.
 báyìí ni ogun yìí di ogun àgbéyé , tí ó di ìjà àjàràn .
Ti o ba fẹ gba itura ju ẹẹkan lọ, sinmi fun bi iṣẹju kan tabi meji ki o to pada gba ikeji.
bí mo bá ń yọ̀ nítorí pé mo ní ọrọ̀ pupọ,tabi nítorí pé ọwọ́ mi ti ba ọpọlọpọ ohun ìní.
Hubert Ogunde rèé, baba àwọn òsèré tíátà Kí lo fẹ́ mọ̀ nípa ‘Ajala Travels’?
Ṣe o lẹtọ ki wọn maa gbe ibọn ati ki wọn maa deede yin lati fi dẹru ba alafia awọn eniyan?
 Èèyàn mẹ́rin míì tún ni Coronavirus nípìnlẹ́ Oyo, ó di èèyàn 97 tó níi ní Nàìjíríà Ààrẹ Buhari tí ẹ n béèrè tí fojú hàn sí àwọn èèyàn Náíjíríà Fíímù ṣíṣe dáwọ́ dúró, Joke Muyiwa di 'grandma', Lizzy Anjorin sọ pé coronavirus ko gbọdọ̀ díwọ́ ọjà títà Ìjọba ìpínlẹ̀ Eko bẹ̀rẹ̀ oúnjẹ pínpín fún àwọn èèyàn lásìkò ìgbélé Coronavirus Abiodun tẹsiwaju pe ki awọn eeyan ipinlẹ naa fọwọsowọpọ pẹlu ijọba oun lati gbogun ti ajakalẹ arun naa to n ba gbogbo agbaye finra."
tun bowolu iwe ibasepo ninu iko naa.
Ink_Hart ni ọrọ yii ko yọ ẹni kankan silẹ lara ọmọ Naijiria.
Ikomọjade, iṣile, ifinjoye, isinku agba abbl ni awọn inawo ti gbogbo ẹbi, ara, ọrẹ jọ maa n dawọ idunnu si.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù 9ice: Ǹjẹ́ olórin tàkasúfèé yìí ń mu igbó bí àwọn òṣèré mìíràn?
36 Ti o ba yege ninu eto iforukọsilẹ lori ayelujara, ileesẹ ọlọpaa yoo ránṣẹ pe ọ lati farahan fun ayẹwo ojukoroju ti yoo waye ni awọn ileesẹ ọlọpaa kaakiri Naijiria, laarin ọjọ kẹrinlelogun, oṣu Kẹjọ, si ọgbọnjọ, oṣu Kẹjọ, ọdun 2020.
Nítorí pé èrò máa n pọ lọjọ yí, àwọn aláṣẹ ti gbe atibaba tí wọn ti ga kalẹ pẹlú ẹrọ amuletutu (AC) sínú rẹ.
Àmúwá Ọlọ́run lásán ní ìṣẹ̀lẹ̀ tó wáyé ní Iba-Eburu Iba Oba Okunoye Wo àwọn olorì àgbà mẹ́rin tí Aláàfin ń wárí fún Ǹjẹ́ o mọ iye ẹ̀bùn owó tí olúborí BBNaija yóò gbà lọ́dún yìí?
Fatai Owoseni: O dìgbà tí mo bá bẹ̀rẹ̀ iṣẹ́ kí ń tó sọ ìpinnu mi
Oríṣun àwòrán, others Igbeyawo rẹ akọkọ foriṣanpọn Ni ọdun 2013 ni Toyin kọkọ ṣe igbeyawo.
Ẹni to bori: South Africa Senegal vs Cameroon.
Idi si ree ti Ọmọtọsọ fi pe ẹjọ kotẹmilọrun lati tako aṣẹ naa.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìtàn Mánigbàgbé: Samuel Ladoke Akintọla jẹ́ olóṣèlú pàtàkì tó tako Awolọwọ 28 Bélú 2018 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 29 Bélú 2018 Oríṣun àwòrán, @abati1990 Samuel Ladoke Akintọla jẹ ojulowo ọmọ Yoruba to ko ipa manigbagbe ni saa isejọba alagbada akọkọ ni orilẹede Naijiria.
Pàápàá jùlọ àwọn adúláwọ̀ àti àwọn obìnrin nítorí pé ọ̀pọ̀lọpọ̀ ẹ̀mí ló ṣòfò, ọ̀pọ̀lọpọ̀ ẹ̀jẹ̀ ló ti dà sílẹ̀ kí ẹ̀tọ́ ìdìbò tó sún kan àwọn obìnrin àti àwọn adúláwọ̀ ní Orílẹ̀èdè Amẹrika.
Bẹ́ẹ̀ kọ́, àmọ́ bẹ́ẹ̀ náà ni, ìlù orin náà ba orin náà mú gẹ́gẹ́ bí àwọn olólùfẹ́ẹ Ijó ìta-gbangba tí ó máa ń gbádùn un Ijó ìta-gbangba ṣe máa ń fẹ́ ẹ.
Mo ti fún un ní ilẹ̀ Ijipti gẹ́gẹ́ bí èrè gbogbo wahala rẹ̀, nítorí pé èmi ni ó ṣiṣẹ́ fún.
Wọ́n lé wọn títí dé Sidoni ati Misirefoti Maimu, ati apá ìlà oòrùn títí dé àfonífojì Misipa, wọ́n pa wọ́n títí tí kò fi ku ẹyọ ẹnìkan.
Ijamba ọkọ-ofurufu ologun pa 'yan mẹjọ
N kò gbà fún obinrin láti jẹ́ olùkọ́ni tabi láti ní àṣẹ lórí ọkunrin.
N kò ní ìjà pẹ̀lú Fayemi, ipò mi bíi aláàbò àṣà Yorùbá ní mó ṣe kọ lẹ́tà sí gómìnà Ekiti - Aláàfin Wò ó ọ̀nà láti mú ara rẹ dé ibi tó ga jùlọ nínú ìbálòpọ̀ pẹ̀lú ìlànà Tantra Ọ̀sẹ̀ yìí laá gbàwọn ẹ̀sọ́ Amotekun sísẹ́, ìparí oṣù kẹta ni iṣẹ́ yóò bẹ̀rẹ̀ - Akeredolu Ìpele tuntun ló kàn nínú ìrìnàjò ayé mi, ń kò pe ẹjọ́ lóri ìrọ̀lóyé - Sanusi Lasema ni oun ti de ibi isẹlẹ naa, ti ọwọ awọn osisẹ ajọ naa si ti n ka ina yii.
Ọba yóo bá wọn wọlé nígbà tí wọ́n bá wọlé, nígbà tí wọ́n bá sì jáde, yóo bá wọn jáde.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Funmi Adewara: Tele Medicine' ní a fi ń ṣàyẹ̀wò èèyàn ìdá ọgọtá láti dènà ìtànkálẹ̀ Covid Ọmọ Oodua mẹwaa to n ṣe bẹbẹ ni ẹka amuludun loke okun: 1) Sade Adu: Ilu Ibadan ni wọn bi Helen Folasade Adu si ni ọjọ kẹrindilogun, oṣu kinni, ọdun 1959, tii ṣe ọdun mọkanlelọgọta ṣẹyin.
kurt gödel ( ; april 28 , 1906 , brno , moravia - january 14 , 1978 , princeton , new jersey , usa ) je onimomathematiki , onimo-oye ati onimo-ogbon omo ile austria .
Iru ẹni bẹ le maa ni ipaya ju bose yẹ lọ nipa kokoro aifojuri, eyi to le mu ki wọn o maa ṣe imọtoto ju bose yẹ lọ.
    Bí wọ́an ti ṣe ètò ilé Òmùgọ̀diméjì yàtọ̀ púpọ̀ sí tí ilé àwọn ọba tí mo mọ̀.
Mo ti rù láàrin ọ̀sẹ̀ kan, iṣẹ́ Eko kò dẹ́rùn - Sanwo-Olu Baṣọ̀run Gáà, tó yan ọba mẹ́rin, pa ọba mẹ́rin àmọ́ ọba karùn-ún ló pa á Ọbasanjọ sọ àsírí sàgbàdèwe rẹ̀ Ọdẹyẹmi ni lootọ ni kii se gbogbo igba lo yẹ ki awọn asofin maa tako ifẹ inu aarẹ ati ẹgbẹ oselu rẹ.
Dídá ni kí ẹ dá àwọn ẹṣin wọn lẹ́sẹ̀, kí ẹ sì sun gbogbo kẹ̀kẹ́ ogun wọn.
awẹ Ramadan yii, pe a se nnkan to ni itumọ.
'Ẹ má ṣi Fayemi túmọ̀ lórí àṣẹ tó pa nípa sísọ èdè Yorùbá' Kòsí àṣà tó faramọ́ fífi èmí ènìyàn ṣe ìrúbọ - Olúwó Ajínigbé ń bèèrè fún epo, iṣu àti ọ̀tí Schinap gẹ́gẹ́ bí owó ìtanràn Wo ohun tó yẹ kí o mọ̀ nípa àwọn obìnrin méje ti Buhari fẹ́ yàn sípò minista Oga agba FRSC yii ni gbogbo owo naa ni ajọ FRSC ti da pada fun awọn ẹbi awọn ẹni naa lẹyin iwadii ti o yẹ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ìdílé tí ọkọ da ọmọ síta tóríi ojú Búlùú tí wọ́n ní bá BBC sọ̀rọ̀ Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
, Duration 0,5926 Ẹrẹ̀nà 2020 1:09 Fídíò, Coronavirus: Njẹ́ jíjẹ́ aláwọ̀ dúdú le gbà ọ́ sílẹ̀ lọ́wọ́ ààrùn Coronavirus?
ÌFÉWÓ; èyí ni kí ènì kí ènìyàn ó rí nnkan tí ó pò nílè, kí ó sì yo níbè.
Àbí ẹ̀yin náà fẹ́ di ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ ni?
Lẹyin nkan bi iṣẹju meji ara rẹ da, ti o si pada wa bọwọ pẹlu Minisita tuntun feto idajọ lorileede naa, Christine Lambrecht.
Ọba aláde o gbọdọ kọ aya rẹ̀ sílẹ̀ Yemisi Oyedepo Broadcast Journalist 16 Ọ̀pẹ̀̀ 2019 Oríṣun àwòrán, Oluwo Àkọlé àwòrán, Olúwòó ilú Iwo: Èèwọ!
sugbọn o tẹsiwaju lọ ilẹ Amẹrika nibi to ti kọ imọ nipa ọkọ ofurufu.
Akọ̀wé mi, o kú iṣẹ́ o, jẹ́ kí n máa bá ìtàn Olówó-ayé lọ, nítorí eléyìínì ni ọ̀rọ̀ pàtàkì tí à ń sọ lọ́wọ́ kí ó tóó di pé mo dà ọ̀rọ̀ ti oníbodè tí ó dípò Àǹjànnú-ìbẹ̀rù sílẹ̀.
Ni ọjọ kẹrindinlọgbọn oṣu kẹwa ọdun 2015 ni awọn afọbajẹ ni Ilẹ Ifẹ kede orukọ Adeyẹye Ẹnitan Ogunwusi gẹgẹ bii Ọmọ oye ti yoo jẹ Ọọni.
Wọn tun fẹsun kan ile iṣẹ ọlọpaa ọtẹlẹmuyẹ pe wọn fun un awọn mejeeji ni mọjele jẹ latimọle, ti oju olori awọn kan si ti fọ nigba ti iyawo rẹ ko lee da rin funra rẹ mọ lai lo kẹkẹ ti wọn fi n tii kiri.
"Mo ni igbagbọ pe, eyi yoo rọ ọpọ to ti n binu nitori nkan to ṣẹlẹ naa, lọkan.
Lagos Building Collapse: Èèyàn méjì tó há sábẹ́ ilé tó wó ní Ebute Meta ti ń gba ìtọ́jú, LASEMA ń ṣàyẹ̀wò ilé náà ló̩wọ́
Gẹgẹ bi BBC se se awari rẹ, ilu Nairobi lorilẹede Kenya ni idan orita naa ti n waye, nibiti wọn ti haya ibudo kan to wa fun ile ijo, ti orin si n dun lakọlakọ nibẹ, sugbọn kinni kan to ba Ajao jẹ, ti apa rẹ fi gun ju itan lọ ni pe kikida awọn obinrin lo wa lagbo ijo naa, to n jo pẹlu ara wọn.
Ọpọ ninu lo bẹrẹ si ni fi orukọ rẹ kọrin, kete ti wọn gbọ pe iṣẹ abẹ naa ti pari.
Oríṣun àwòrán, Facebook/Famuyantan Razak Olawale Àkọlé àwòrán, Aworan iwe ikede Iyansẹlodi ọlọjọ mẹta losun Ni igba to ń ba ile isẹ BBC Yoruba sọrọ, Komiṣọna fun eto iroyin, Adelani Baderinwa, ni ijọba Gomina Aregbẹsọla n gbiyanju lati yanju aawọ to rọmọ iyanṣelodi naa.
Síbẹ̀ mo náwó lórí ọ̀rọ̀ náà kí n tóó lè yọ.
omo ogun  212 tun gbena wo iko Boko Haram
Wọn kò pé kí á dá wọn sílẹ̀, nítorí kí wọ́n lè gba ajinde tí ó dára jùlọ.
Iléeṣẹ́ ọlọ́pàá sọ afurasí ọlọ́pàá tó yìnbọn fún ọ̀dọ́kùnrin tó fún èèyàn lóyún lẹ́sẹ̀ s'átìmọ́lé Oniruuru awọn ikọlu bayii lo ti waye lati igba ti One million boys ti bẹrẹ iwa ika wọn, ti ọpọ ẹmi si ti bọ laarin ẹgbẹ naa ati awọn orogun wọn bii Indomie.
Ooni ti ile Ife, Oba Adeyeye Ogunwusi, Ojaja II ni iṣẹ gbogbo wa ni lati mu idagbasoke ba awọn eniyan, paapaa ọdọ lorilẹ-ede Naijiria.
Bakan naa lo ṣalaye pe aago mẹjọ lawọn oṣiṣẹ yoo maa wọṣẹ, nigba ti wọn yoo ṣiwọ laago mẹrin irọlẹ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Shiite: Tinúbú, bá Buhari sọ̀rọ̀ kó tú ZakZaky sílẹ̀ kó tó pẹ́ jù Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Shiite: Tinúbú, bá Buhari sọ̀rọ̀ kó tú ZakZaky sílẹ̀ kó tó pẹ́ jù 10 Èbibi 2018 Àwọn ọmọ ẹgbẹ́ ẹlẹ́sìn Shiite ti fọnmú, tí wọn sì sèwọ́de lọ sọ́dọ̀ asaájú ẹgbẹ́ òsèlú APC, Bọ́lá Ahmed Tinubu ní ìlú Èkó.
“Ṣé ìwọ lo kọ́ àwòdì bí a ti í fò,tí ó fi na ìyẹ́ rẹ̀ sí ìhà gúsù?
Èdè arméníà je ikan lara èdè indo-european ( indo-Ùrópóàànù ) kan ni eléyìí .
Mọ sii nipa ẹka isọri ọrọ Yoruba.
Nítorí àjàgà mi tuni lára, ẹrù mi sì fúyẹ́.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, BIAFRA at 50: Ìhàlẹ̀ ológun ni Gowon ni ká kọ́kọ́ fi bẹ̀rẹ̀- Aladejẹbi A bi Akintola lọjọ kefa, oṣu keje, ọdun 1910 si idile Akintola Akinbola and Akanke niluu Ogbomoṣo to wa labẹ ipinlẹ Oyo bayii.
Bí ó bá ṣe ti pé kí á dán agbára wò ni,agbára rẹ̀ pọ̀ tayọ!
À ń ròyìn ìfaradà ati igbagbọ yín ninu gbogbo inúnibíni ati ìpọ́njú tí ẹ̀ ń faradà.
Diẹ niyii lara awọn oṣere tiata Yoruba atawọn ilumọọka ọmọ Yoruba miiran ti iyawo wọn bimọ silẹ Amẹrika.
Atẹ́gùn àlàáfíà kan náà bẹ̀rẹ̀ sí í fẹ́.
Iye owo ilẹ Naijiria si iye owo orilẹede Amẹrika lọjọ 20, Osu Keta,2018 ni 1USD=359.
Àwọn ará Kalidea sì ń pada bọ̀ wá gbé ogun ti ìlú yìí; wọn yóo gbà á, wọn yóo sì dáná sun ún.
Yóo kó wọn ní ìgbèkùn lọ sí Babiloni, yóo sì fi idà pa wọ́n.
Ṣugbọn o ni o ṣe pataki lati maa fi ọrọ oṣelu bọ ọrọ naa.
Mohammed Shaba Lafiaji O ti figba kan jẹ gomina ipinlẹ Kwara lọdun 1992 labẹ asia ẹgbẹ oselu SDP.
K Odukoya 'ń gun orí òkè àdúrà nítorí COVID-19'-Wò báwọn èèyàn fi wò wọ́n 30 Ìgbé 2020 Oríṣun àwòrán, Twitter Awọn ọmọ Naijiria ṣi n sọrọ nipa awọn iranṣẹ Ọlọrun kan ti wọn ni awọn yoo gba adura ati aawẹ lati fi ṣẹgun arun Coronavirus.
Ìjàpá  pẹ̀lú Ọ̀bọ di ọ̀rẹ́ nitori wọn jọ ngbé àdúgbò.
Aisha Buhari se ikede naa loju opo Facebook rẹ, lẹyin ti awọn ọdọ yika Naijiria fariga pe, ifiyajẹni ati iṣekupani lọwọ awọn ọlọpaa gbọdọ dopin ni Naijiria.
Eyi lo mu BBC News Yoruba ba Amofin Sadiku Ibitayọ sọrọ lori awọn nkan to rọ mọ ṣiṣe oniduro fun ẹni to n j'ẹjọ.
Siga tita d‘eewọ lẹba ile ẹkọ Kẹmi Adeosun ni anfaani meji to wa ninu igbesẹ naa ni pe, yoo se aleekun owo to n wọle sapo ijọba, ati pe, yoo tun mu adinku ba bi awọn eniyan se n mu oti ati siga lọna to lee sakoba fun eto ilera wọn.
Orilẹede Finland lo ṣi wa ni ipo kinni gẹgẹ bi orilẹede ti idunnu pọ si ju lọ laye.
Wọ́n fún obìnrin kan lọrùn pa, awuyewuye ti ń wáyé Wo iye owó tó wọlé fún ìjọba lórí COVID-19 àti bí wọ́n ṣe ná an Háà, àṣé Pastor Adeboye kò léè dá èékánná ara rẹ̀ gé, àwọn ọmọ Nàìjíríà kan pariwo Àwọn àádọ́ta ọ̀dọ́ wọ gàù nítorí ilé ijó ní Ilorin Báwó ni òògùn dexamethasone ṣe ń ṣiṣẹ́ lára Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Ninu ìdílé Pahati Moabu: Adina, Kelali, ati Benaaya; Maaseaya, Matanaya, ati Besaleli; Binui, ati Manase.
 Èyí tó jásí pé ó máa ń sa ìgbá mu otí .
OLUWA yóo fìyà jẹ àwọn ará Ijipti ṣugbọn yóo wò wọ́n sàn, wọn yóo pada sọ́dọ̀ OLUWA, yóo gbọ́ adura wọn, yóo sì wò wọ́n sàn.
Awon omo igbimo yii pinnu lati sabewo si Ninte, Ungwan Ajo, Golkofa, Godogodo, Dogon Fili, Gadabiyu, Anton, Pasakori, Kario, Dalle, Asso, Goska, ati Dangoma ni ijoba ibile  Jema’a.
Bi awọn kan ṣe n sọ pe niṣe ni Kidd n ki ika si oju ara Erica, ni awọn kan sọ pe ibalopọ taara ni wọn n ni.
Ìpalẹ́numọ́ iléeṣẹ́ akọ̀ròyìn aládàádúró  nípasẹ̀ àwọn àdàlù ìṣíwèé fún ilé iṣẹ́ akọ̀ròyìn àti ìrókẹ́kẹ́ mọ́ oníṣẹ́-ìròyìn ti di ìdẹ́rùbà, ìkóra-ẹni-ní-ìjánu àti ìbẹ̀rù láti sọ èrò ọkàn ẹni nípa àwọn olórí orílẹ̀ èdè náà.
Ogagun Buratai gboriyin fun ise akinkanju iko naa ni gbagede ija pelu awon omo ogun olote naa.
Ènìyàn 170 tún ti ní ààrùn Covid-19 l'órílẹ̀-èdè Nàìjíríà Ajọ to n gbogun ti ajakalẹ aarun ni Naijiria ti kede pe esi ayẹwo ti fihan pe aadọsan eeyan lo tun ti ni aarun Covid-19 l'orilẹ-ede Naijiria.
tí wọ́n bá ronupiwada tọkàntọkàn ninu ìgbèkùn níbi tí a kó wọn lẹ́rú lọ, tí wọ́n gbadura sí ìhà ilẹ̀ tí o fún àwọn baba wọn, ati sí ìlú tí o ti yàn, ati sí ilé tí mo kọ́ fún ìjọ́sìn ní orúkọ rẹ, 
Ọba ilú Ayégbẹgẹ́ kede pé èèwọ̀ ni lati jẹ ẹiyẹ Igún ni ilú wọn.
Ó bá lọ sí ọ̀dọ̀ rẹ̀, ó fà á lọ́wọ́ dìde.
À ó ṣe àtúngbéyẹ̀wò àsìkò ìwọ́le àwọn akẹ̀kọ̀ọ́-Ìjọba apapọ̀ Ìgbákejì ààrẹ, tètè yọ Trump nípò, bí bẹ́ẹ̀ kọ́.
Ìdí nìyí tí ó fi lè gba àwọn tí wọ́n bá súnmọ́ Ọlọrun nípasẹ̀ rẹ̀ là, lọ́nà gbogbo títí lae nítorí pé ó wà láàyè títí láti máa bẹ̀bẹ̀ fún wọn.
omoniyan, ipese eto iwosan to peye, eto ogbin ti o fimo eto eko abbl fun awon
Die ninu akọle naa ni eyi ti wọn kọ ọ si pe Ẹ dẹkun idẹyẹsi awọn ẹlẹsin ibilẹ, gbogbo wa ni ipinlẹ Oyo wa fun."
" N ko ro pe ẹnikẹni wa ni ile ijọba Aso Rock to n dari Naijiria, mo ti n woye bi nnkan ṣe n lọ lati ọdun kan aabọ, mo si gbagbọ pe aarẹ yii kọ lo n ṣe akoso Naijiria ni gbogbo ọna.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Lafup: Kò sí ẹni kankan tó ń ṣe ẹ̀fẹ̀ ní Ibadan nígbà táwa bẹ̀rẹ̀ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Lafup: Kò sí ẹni kankan tó ń ṣe ẹ̀fẹ̀ ní Ibadan nígbà táwa bẹ̀rẹ̀ 19 Agẹmo 2019 Adẹrinpoṣonu ti ko ṣee fọwọ rọ sẹyin ni Oluwasegun Ogundipe ti gbogbo eniyan mọ si Lafup jẹ ni ilu Ibadan.
lataari isele iji lile ti o waye lojo Eti(Friday).
Kí ìròyìn náà ó ba hó ye létí àwọn ènìyàn, ajàfúnẹ̀tọ́ọ nì àti akẹ́kọ̀ọ́ Ifáfitì, David Mendes, kọ, ní ọjọ́ ìwọ́de náà, iṣẹ́-ìjẹ́ fún ààre orílẹ̀-èdè Angola João Lourenço:
Ọkàn mi balẹ̀ lórí ọ̀rọ̀ yín.
Adebayo, ẹni ọdun mẹrindinlọgbọn la gbọ pe o n ba akẹkọọ rẹ, to jẹ ọmọbinrin ọdun mẹẹdogun ni ibalopọ lọna aitọ.
Mo fẹ rọ ọjọgbọn Yẹmi Ọṣinbajo ati ikọ rẹ lati da igbesẹ yoowu ti wọn ba n gbe lori afikun owo ori ọja, VAT duro, mo bẹ yin."
Jesu dáhùn pé, “Bí mo bá bu ọlá fún ara mi, òfo ni ọlá mi.
Ẹsita kò sọ inú ẹ̀yà tí òun ti wá, tabi ìdílé rẹ̀, fún ẹnikẹ́ni nítorí pé Modekai ti kìlọ̀ fún un pé kí ó má ṣe sọ nǹkankan nípa rẹ̀.
Níbi tí èmi alára bá wà, níbẹ̀ ni iranṣẹ mi yóo wà.
Ṣé wọ́n gba Samaria lọ́wọ́ mi?
Bí ìgbà tí eniyan bá sun pàǹtí, tí ó sì jóná ráúráú ni n óo pa gbogbo ìdílé rẹ run.
Ninu ifọrọwero naa ti pupọ awọn ololufẹ rẹ ti darapọ mọ wa Yemi My Lover tu kẹkẹ ọrọ silẹ nipa awọn nkankan.
Èwo ninu àwọn oriṣa ilẹ̀ wọnyi ni ó gba ilẹ̀ rẹ̀ kalẹ̀ lọ́wọ́ mi, tí ẹ fi rò pé OLUWA yóo gba Jerusalẹmu kalẹ̀ lọ́wọ́ mi?
Iṣẹ́ iranṣẹ tí ó ṣe ní Efesu kò ṣe àjèjì sí ìwọ alára.
His involvement in the many causes in Africa cannot be over-emphasised.
"To ba jẹ pe agbebọn naa wọnu mọsalasi ni, gbogbo wa ni ko ba ti jẹ Ọlọrun nipe, ti awọn eeyan to wa ninu mọsalasi naa si ti n lakaka lati dara pọ mọ ẹbi wọn.
Wọn ba BBC Yoruba sọrọ lori igbe aye wọn ati ipenija ti oju wọn n ri nitori ibi ti ori da wọn si ti wọn n gbe yii.
Mose bá kọ orin yìí ní ọjọ́ náà-gan an, ó sì kọ́ àwọn ọmọ Israẹli.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Akọ́mọlédè àti Àṣà lórí BBC Yorùbá: Kọ́ síi nípa iṣẹ́ tí oúnjẹ ń ṣe lára níbí Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Akọ́mọlédè àti Àṣà lórí BBC Yorùbá: Kọ́ síi nípa iṣẹ́ tí oúnjẹ ń ṣe lára níbí 24 Bélú 2020 Iyan lounjẹ, ọka loogun, airi rara la n jẹ ẹkọ.
Àwọn obinrin gba àwọn eniyan wọn tí wọ́n ti kú pada lẹ́yìn tí a ti jí wọn dìde kúrò ninu òkú.
Oríṣun àwòrán, Kola Bankole Àkọlé àwòrán, Àwọn olóṣèlú a má ṣé ìlérí tí wọn kò ní lè mú ṣẹ fún ará ìlú lọpọ ìgbà Ọgbẹni Kola ní lootọ ni pé Fáyẹmí tí je Gómìnà nígbà kan rí ṣugbọn bí nnkan ti ṣe n ló lẹnu ọjọ mẹta yí tí owó tó yẹ kí ìjọba àpapọ pin fun àwọn ìjọba ìpínlẹ̀ kò ti ni iyanju, yóò ṣòro kí Fáyẹmí le mú irú ìlérí bẹẹ ṣé.
ng Ojú òpó ti ó ti lè fórúkọ sílẹ̀ fún ìgbànisíṣẹ̀ ọlọ́pàá sí wa ní ṣíṣí títí di àsìkò yìí àti pé ọmọ Naijiria to bá sì nífẹ̀ sii le forúkọ fun ètò ìgbànisíṣẹ́ ọlọ́pàá ọdun 2020.
Nígbà tí wọ́n gbọ́ gbolohun yìí, wọ́n bẹ̀rẹ̀ sí kígbe pé, “Ẹ pa irú ẹni bẹ́ẹ̀ rẹ́ kúrò láyé!
Ohun tí wọn ń wá ni kí wọ́n lè fi yín sinu àhámọ́, kí ẹ lè máa wá wọn.
Awọn agbabọọlu mii yoo dije fun ami ẹyẹ 'Young Player of the Season' ni Demarai Gray, Harvey Barnes, Youri Tielemans, Ben Chilwell, James Maddison, Filip Benković, Çağlar Söyüncü ati Hamza Choudhury.
lo anfaani naa mu ibasepo ti yoo so eso rere fun ijoba orile-ede Naijriia, ti o
Wọn gba gbogbo ohun elo idibo wọn si sun nina, sùgbọ́n kò si ọmọ eleto idibo kankna to farapa, ó ní òun ti pàṣé fun àwọn ọmọ olgun láti ko gbogbo òṣìṣẹ́ àjọ INEC kúrò ní agbégbé náà.
Èmi nìkan ṣoṣo, ni mo ṣẹ́kù, wọ́n sì fẹ́ gba ẹ̀mí èmi náà.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù NLC: A ó gbé ìpínlẹ̀ tí kò bá san ₦30,000 owó osù tuntun lọ sílé ẹjọ́ 23 Ọ̀wàrà 2019 Oríṣun àwòrán, TWITTER Àkọlé àwòrán, Àjọ Òsìsẹ́ lórílẹ̀èdé Naijiria, NLC ti ní àwọn yóò gbé ìjọba ìpínlẹ̀ tó bá kọ̀ láti san 30,000 gbèdéke owó osù òsìsẹ́.
Ninu oṣu Kọkanla tabi Ikejila ọdun 2019, ni Joshua ati Ruiz yoo tun ija naa ja nilẹ Gẹeṣi.
Wọ́n jẹ àsè ní ilé rẹ̀, wọ́n káàánú rẹ̀, wọ́n sì tù ú ninu, nítorí ohun burúkú tí OLUWA ti mú wá sórí rẹ̀, olukuluku wọn fún un ní owó ati òrùka wúrà kọ̀ọ̀kan.
Ẹbí Buhari lásán ni Mamman Daura kò nípò òṣèlú kankan Kò sí ìdí fún àjọyọ̀ lórí ọdún kan ìṣèjọba Fayemi - Ekiti PDP Kíni ẹ mọ̀ nípa Mama Rainbow tó jẹ́ àgbà òṣẹ̀ré tíátà Yoruba?
Bode Akindele jẹ ẹni ti eledua fi ọrọ ta lọrẹ, to si maa n na owo rẹ lati fi ran awọn eeyan lọwọ.
Èmi ni mo dúró fún ọmọdekunrin náà lọ́dọ̀ baba wa, mo wí fún un pé, ‘Bí n kò bá mú ọmọ yìí pada, ẹ̀bi rẹ̀ yóo wà lórí mi ní gbogbo ọjọ́ ayé mi.
Nígbà tí àwọn iranṣẹ náà dé, wọ́n bá ère ní orí ibùsùn pẹlu ìrọ̀rí onírun ewúrẹ́ ní ìgbèrí rẹ̀.
Nígbà tí odi náà bá wó, ǹjẹ́ àwọn eniyan kò ní bi yín pé, ‘Ọ̀dà funfun tí ẹ fi ń kun ara rẹ̀ ńkọ́?
Bi ibajẹ kankan ba si waye laarin wọn, wọn yoo yanju rẹ laarin ara wọn laisi wahala kankan.
Ìbánújẹ́ gbọkàn àwọn èèyàn nílé abílékọ ọlọ́mọ mẹ́ta tí wọ́n ṣẹ̀ṣẹ̀ pa ní Ibadan Osinowo ti figba kan jẹ ọmọ ile igbimọ aṣofin ipinlẹ Eko fun saa mẹrin ọtọtọ, nibi to ti ṣoju ẹkun idibo Kosofe.
Ẹni tí ó bá fúnrúgbìn pupọ, pupọ ni yóo kórè.
Gbogbo àwọn ọlọ́gbọ́n ati aláfọ̀ṣẹ wá siwaju mi, wọ́n gbìyànjú láti ka àkọsílẹ̀ yìí, kí wọ́n sì sọ ìtumọ̀ rẹ̀ fún mi, ṣugbọn kò sí ẹni tí ó lè ṣe é.
OLUWA wá sọ fún mi pé, “Ní ibí yìí ni àwọn alufaa yóo ti máa se ẹran ẹbọ ìmúkúrò ẹ̀bi ati ẹbọ ẹ̀ṣẹ̀.
Ó bá dá wọn lóhùn pé, “Ṣé ẹ rò pé ẹ̀yin ati ọba nìkan ni ọba Asiria rán mi sí ni?
Adeleke: Àwọn ará Ẹdẹ bẹ síta pẹ̀lú ìdùnnú lórí ìdájọ́ èsì ìdìbò gómínà Ọṣun
Lẹ́yìn èyí, Jehu ati Jehonadabu lọ sinu ilé ìsìn náà, ó ní, “Ẹ rí i dájú pé àwọn olùsìn Baali nìkan ni wọ́n wà níhìn-ín, ati pé kò sí ẹnikẹ́ni tí ń sin OLUWA níbí.
Fún ọdún márùn ún ni kò fi sí Baálẹ̀ lórí àtẹ́ ní ilú Abúlé Ọjà.
Google ati awọn ọmọ Naijiria ṣe ìrántí ọjọ ibi Dokita Stella Adadevoh pẹlu àwòrán
Ṣugbọn ìwọ OLUWA ni ààbò mi,ògo mi, ati ẹni tí ó fún mi ní ìgboyà.
À bá lè gbé ọ̀rọ̀ Jobu yẹ̀wò títí dé òpin,nítorí pé ó ń sọ̀rọ̀ bí eniyan burúkú.
Kabiyesi, ìwọ ọba àwọn ọba ni Ọlọrun ọ̀run fún ní ìjọba, agbára, ipá ati ògo.
Tabili mẹrin wà ninu, mẹrin sì wà ní ìta, lẹ́gbẹ̀ẹ́ ẹnu ọ̀nà; gbogbo rẹ̀ jẹ́ tabili mẹjọ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Jiti Ogunye: Ìjọba àkóbá lológun gbé kalẹ̀ ni 1999 Wọ́n jí ọmọ yìí gbé láti máa fi tọrọ bárà l'Eko Theresa May bú sẹ́kún, ó ní òun kò ṣe olóòtú ìjọba UK mọ́ Ọwọ́ ọlọ́pàá tẹ ọmọ Britain tó ń ta kẹ́míkà gẹ́gẹ́ bi omi ìyanu ‘Bi Gomina Ajimobi se yan adarí òsìsẹ́ tuntun ní Oyo kò dí wa lọ́wọ́’ Ọpọ ojo lo ti rọ tilẹ ti fi mu ni iṣẹ awọn minista ti wọn ba Buhari ṣe ijọba lọdun mẹrin to n kogba wọle yii.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Nikesuliat: Ọ̀dọ́mọdébìnrin akéwì tó n fi ẹ̀ṣà kìlọ̀ ìwá lásìkò yìí Abba Kyari lùgbàdì aàrùn coronavirus- Reuters Coronavirus in Nigeria: Èèyàn mẹ́rin míì kó coronavirus ní Nàìjíríà, ogójì ló ti di níi báyìí Iroyin ti Reuters fi lede ni Ogbẹni Abba Kyari to jẹ awọn oṣiṣẹ nile ijọba apapọ ni Aso Rock nilu Abuja ti lugbadi aarun coronavirus.
Bi iye awọn to ni ni awọn ipinlẹ to ku ṣe lọ ni yii; Eko-142 Oyo-15 FCT-13 Kano-12 Edo-11 Delta-10 Kaduna -9 Rivers-9 Borno-8 Jigawa-4 Gombe-3 Plateau-3 Osun-1 Bauchi-1 Ènìyàn 416 ló ti lùgbàdì àrùn Coronavirus ní Ọjọ́ Ajé ní Naijiria Ajọ NCDC ti kede eniyan 416 gẹgẹ bi apapọ eniyan to ni arun Coronavirus lorilẹede Naijiria ni Ọjọ Aje lorilẹede Naijiria.
Mo rẹ́rìn-ín sí wọn nígbà tí wọn ń ṣiyèméjì,wọn kò sì lè kó ìrẹ̀wẹ̀sì bá mi.
Iroyin sọ pe l'Ọjọbọ ni iṣẹlẹ naa waye nigba ti ijiroro nlọ lọwọ , eyi to mu ki onikaluku awọn aṣofin ọhun o sa asala fun ẹmi wọn.
tun ti mu adinku ba iye awon omo to kuro nile -iwe.
Oríṣun àwòrán, Facebook/Nigeria Airforce Amọ, ko i tii pe ọdun kan ti o gba Ami ẹyẹ akọkọ gẹgẹ bi Ajagun obinrin akọkọ ti ikọ ọmọgun Naijiria, ti o fi fi aye silẹ.
Awọn to mọ Mohammed Yusuf ni o jẹ ẹni kan ti ọrọ da lẹnu rẹ ti pupọ awọn eeyan a si ma tuyaya lati gbọ waasi rẹ.
Jesu ní, “Ẹ tún gbọ́ òwe mìíràn.
Nibi ayẹyẹ yii ni wọn ti maa n ṣe afihan ọkan o jọkan ilu iṣẹmbaye ati aṣa ilẹ Yoruba ati gbogbo Afirika.
    Ìgbà tí a máa lọ sí ibi ìgbéyàwó gan-an, àwọn iwin wọ̀n-ọnnì wa sínú ilé ńlá tí mò ń gbá tí bàbá ìyàwó mi fún mi, wọ́n mú èmi àti àwọn ẹnìkejì mi lọ sí ibi kan báyìí tí ó tẹ́jú pẹrẹsẹ, aṣọ tí wọn fi fàdákà ṣe ni wọ́n tẹ́ láti ile mi lọ sí ibi tí à ń sọ̀rọ̀ yìí, wọ́n gbé mi gun ẹṣin tí wọ́n fi díámọ́ǹdì ṣe ọ̀ṣọ́ sí lara jìngbìnnì kanlẹ̀, wọ́n sì to àwọn arẹwà ọkùnrin àti obìnrin sí etí ọ̀nà lọ ní apá ọ̀tún àti apá òsì.
Awọn eeyan to le ni miliọnu kan ati igba (1.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Justice for Jubril: Ọwọ́ ọlọ́pàá ìpínlẹ̀ Kebbi tẹ bàbá àti ìyàwó rẹ̀ méjì fún pé wọn so ọmọ pọ̀ mọ́ ewúrẹ́ fún ọdún méjì 11 Ògún 2020 Oríṣun àwòrán, KBSTGOV Àkọlé àwòrán, Aye le!
Wọn maa n sọ ọmọkunrin to ba gbe ibi kọrun wa sile aye ni Ojo.
Àwọn ọmọ-ẹ̀yìn náà lọ, wọ́n ṣe bí Jesu ti pàṣẹ fún wọn.
ṣugbọn tí wọn yóo máa wí pé, ‘Ní orúkọ OLUWA tí ó kó àwọn ọmọ ilé Israẹli jáde kúrò ní ilẹ̀ àríwá, ati gbogbo ilẹ̀ tí wọn kó wọn lẹ́rú lọ, tí ó sì mú wọn pada sí ilẹ̀ wọn.
Mo rí kinní kan lókè awọsanma tí ó wà lórí wọn, ó dàbí ìtẹ́ tí a fi òkúta safire ṣe; mo sì rí kinní kan tí ó dàbí eniyan, ó jókòó lórí nǹkankan bí ìtẹ́ náà.
ekunwo osu naa wa siwaju won, sugbon ko tẹ igbimo to n soju osise ijoba apapo
 Ninu oro re lasiko ipade igbami-eye eyi ti o waye nilu Eko, aare ohun so pe, orile-ede Russia ti setan lati sagbateru idije boolu agbaye to n bo lona, bi o ti le je pe iroyin so pe awon papa isere miran ti won yoo lo ninu idije naa koi ti pari.
Nígbà tí Elifasi ará Temani, Bilidadi ará Ṣuha ati Sofari ará Naama, àwọn ọ̀rẹ́ Jobu mẹta, gbọ́ nípa ìyọnu tí ó dé bá Jobu, wọ́n wá láti kí i, ati láti tù ú ninu.
Oríṣun àwòrán, Twitter/ FMPRng Àkọlé àwòrán, Ipade laarin Aarẹ Buhari ati Bernadus Van Buerden mu anfaani idokowo to to milionu mẹẹdogun dolla Nibi ipade naa, ile iṣẹ Royal Dutch Shell ati aarẹ Buhari se ipade eleyii to bi ikede idokowo biliọnu mẹẹdogun dollar ni Naijiria.
Àmúwá Ọlọ́run lásán ní ìṣẹ̀lẹ̀ tó wáyé ní Iba-Eburu Iba Oba Okunoye Ènìyàn 27 lo ti bá iṣẹ̀lẹ̀ ọkọ̀ ofúrufú tó já rìnrìn ajò O ni iṣẹ ni wọn mu u wa kọ lọdọ oun ti oun si ti kọkọ kọ ọ silẹ fun awọn iya rẹ to mu u wa ki oun to tun da ọrọ naa ro lati gba a si ẹkọṣẹ ifa ni ọdọ oun lọdun 2016.
Oṣu kinni, 2018 ni ọjọ omi naa ti pe.
26 Bélú 2020 10:17 Fídíò, Oba Adedokun Abolarin ti Oke Ila: Ó ya ọ̀pọ̀ tó súnmọ́ mi lẹ́nu bí mo ṣe ń kọ́ àwọn akẹ́kọ̀ọ́ pẹ̀lú ipò Ọba, Duration 10,1723 Bélú 2020 Amos Dauda, Iphone: Ilé ẹjọ́ dájọ́ ẹgba mẹ́ẹ̀dóògún fún ọ̀daràn tó jí Iphone ní Kaduna25 Bélú 2020 4:48 Fídíò, Akọ́mọlédè àti Àṣà lórí BBC Yorùbá: Kọ́ síi nípa iṣẹ́ tí oúnjẹ ń ṣe lára níbí, Duration 4,4824 Bélú 2020 Èyí tí a wò jùlọ 5:03 Fídíò, Omolola Arohunmolase Welder: Mo ti fí iṣẹ́ 'Welder' gbayì láwùjọ, tó mo fi tọ́ ọmọ yanjú, Duration 5,039 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 5:39 Fídíò, Akomolede ati Asa lori BBC: Olùkọ́ Kikelomo Ogunboye tan ìmọ́lẹ̀ sí ìwà olè ọ̀gá ọlọ́pàá Audu gẹ́gẹ́ bí àwòkọ́ṣe àsìkò yìí, Duration 5,398 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 4:11 Fídíò, Oba Adeyeye Ogunwusi: Ojú mi ti rí lọ́pọ̀ lọpọ̀, ọ̀pọ̀ èèyàn ni kò tilẹ̀ gbàgbọ́ pé mo lè jọba- Ooni, Duration 4,117 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 4:43 Fídíò, Promise Akinlade: ọmọ ọdún mọ́kànlá tó ń fi ìlù dárà bíi àgbàlagbà sọ̀rọ̀ nípa tálẹ́ǹtì rẹ̀, Duration 4,437 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 0:59 Gbọ́, Ìsẹ̀lẹ̀ jákèjádò orílẹ̀èdè àgbáyé láàárín ìṣẹ́jú kan, Duration 0,59wákàtí 5 sẹ́yìn 7:03 Fídíò, Olumuyiwa Bolade Adedeji Military Bruitality: Bí arákùnrin onípèníjà ara tí sọ́jà lù ṣe dé, Duration 7,035 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 4:45 Fídíò, Yoruba Films: Ẹ̀ẹ́ bẹ̀ mi kúrò láyé ni, mi ò lè kú - Fadeyi Oloro, Duration 4,4526 Èrèlè 2020 2:48 Fídíò, Esther Ajayi: Èmi náà ti borí ìṣòro rí ló ń mu mi ṣojú àánú, Duration 2,481 Ògún 2019 6:08 Fídíò, Adebola Ademilua: Àìrísẹ́ ṣè lẹ́yìn ìwé kíkà ló sọ mi dí ìyá onírú, mo dúpẹ́ tèmi, Duration 6,0827 Bélú 2020 5:55 Fídíò, Soyinka Cancer: Àṣe ara mi ni iso ti n run gbogbo bí mo ṣe n ṣèrànwọ́ lórí jẹjẹrẹ, Duration 5,5527 Bélú 2019 BBC News, Yorùbá Ìdí tí ẹ fi le è nígbàagbọ́ nínú ìròyìn BBC Ìlànà Lílò Nípa BBC Òfin Àṣírí Cookies Kàn sí.
Blessing Oborududu ti o ni osuwon kilogramu méjídínláàdọ́rin(68kg), ti bale silu New York lati darapo mo awon akegbe re yooku fun idije ifigagbaga “Beat The Streets Invitational Wrestling Tournament’’ ti yoo waye lojo ketadinlogun osu karun un odun ti a wa yii.
Yoruba Film: Baba Ijesha sọ bí ọ̀tá ṣe sún un bá iré gẹ́gẹ́ bíi aláwàdà òṣèré Yorùbá
Amọṣa ki a to wi ki a to fọ, nibi ti awọn oṣiṣẹ ikọ naa ti n gbee lọ ni awọn ọmọ ogun kan ti ṣina ibọn bolẹ ti wọn si pa ọlọpaa mẹta ati araalu meji.
25 usd fún ìwọ ̀ n egbògi náà kanṣoṣo ní ọdún 2014 .
Stars nipinle Eko, ti safihan akonimoogba agba tuntun, ogbeni Felix Nwosu, ti
ati ti oríṣìíríṣìí egbò, ati oówo, ati ti ara wúwú, tabi ti aṣọ tabi ilé tí àrùn ẹ̀tẹ̀ bò, 
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Seyi Makinde: Gbogbo ìgbà ni ìyá mi máa ń sọ fún mi pé díẹ̀ ló kù kí àwa méjèjì kú lọ́jọ́ tó bí mi 4 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Oríṣun àwòrán, Seyi Makinde Gomina ipinlẹ Oyo, amujuẹrọ Seyi Makinde ti sọrọ lori awọn ohun ti yoo saaro nipa iya rẹ lẹyin to jade laye tan.
Lẹ́yin ìwádìí iléesẹ́ BBC pẹ̀lú àjọṣepọ̀ Anas Arameyaw Anas, akọ̀ròyìn ọmọ Ghana kan, nijọba Ghana ṣe ìkéde tuntun yìí Eyi tumọ si pe yoo pa idije Liigi Abẹ́lé àti ti àwọn agbbọọlu agba lára.
Ní àkókò yìí, OLUWA ya àwọn ẹ̀yà Lefi sọ́tọ̀ láti máa gbé Àpótí Majẹmu OLUWA, ati láti máa dúró níwájú OLUWA láti ṣe iṣẹ́ ìsìn, ati láti máa yin orúkọ rẹ̀, títí di òní olónìí.
Ni ọdun 1976, ni iranṣẹ Ọlọrun Musa Asake bẹrẹ iṣẹ iranṣẹ rẹ ni ijọ ECWA to wa ni ilu rẹ ni Unguwar Rimi, Bajju nijọba ibilẹ Zangon Kataf, nipinlẹ Kaduna.
Sáájú àsìkò yìí ni gbogbo ìhà Iwọ-òòrun -Guusu Nàíjíríà ti rí June 12 gẹ́gẹ́ bíì ayájọ ọjọ ìjọba àwa arawa, tí wọn si n ṣe ajọyọ rẹ̀.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù NLC: Ìgbà kẹta rèé tẹ́gbẹ́ òsìsẹ́ yóò wàákò pẹ̀lú ìjọba lábẹ́ Wabba 1 Èbibi 2018 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 6 Bélú 2018 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Awọn gomina lawọn o le san ọgbọn ẹgbẹrun Naira f'oṣiṣẹ Ọjọ Kẹrinla, Osu Kẹrin,ọdun 2018 ni ẹgbẹ awọn osisẹ lorilẹede Naijiria yan Comrade Ayuba Wabba gẹgẹbi aarẹ ẹgbẹ naa.
Ijọba si ti gbe igbesẹ lati fi opin si itankalẹ rẹ ku, nipa titi awọn ileewe ati fasiti, ti wọn si n fi aaye gba awọn idije ere idaraya lai si awọn oluworan nibẹ.
O yẹ ki ibaraẹnisọrọ to loorin o wa gẹgẹ bii ara eroja eto iṣejọba tiwa-n-tiwa.
Nítorí náà, ẹ máa pa àwọn ìlànà ati òfin rẹ̀ tí mo fun yín lónìí mọ́, kí ó lè dára fun yín, ati fún àwọn ọmọ yín; kí ẹ lè pẹ́ lórí ilẹ̀ tí OLUWA Ọlọrun yín fun yín, títí lae.
Toyin Abraham bí ọmọkùnrin jòjòló El-Zakzaky fẹ́ jayé ọlọ́ba ní India, kò sígbà tí kò ní padà wálé - Ìjọba àpapọ̀ Ìjọba Ọyọ gbọdọ̀ tanná wádìí ìṣèjọba Abiola Ajimọ̀bi - PDP Ọ́kọ̀ mẹ́wàá tó kún fún àwọn agbófinró gba ìbùdó ìwọ́de kan ní Abuja Akinpẹlu ni ọrọ ajọṣepọ naa ko mọ lori ọlọpaa nikan, gbogbo awọn ẹka iṣẹ alaabo ni yoo kopa ninu igbesẹ naa gẹgẹ bi awọn agba majẹobajẹ kan ni ilẹ Yoruba ti ṣe n peelo rẹ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Coronavirus cases: Àjọ WHO ní ọ̀rọ̀ àrùn coronavirus ti di èyí tí yóò máa bá ọmọnìyàn gbé láéláé 15 Èbibi 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 9 Òkùdu 2020 Oríṣun àwòrán, Who Onikaluku orilẹ ede lo n sa kijo-kijo kiri lati wa iwosan fun ajakalẹ arun Coronavirus, eyi to n mu ẹmi ọpọ eeyan lọ.
Jẹ́ kí á lọ sí ọ̀dọ̀ rẹ̀, bóyá ó lè sọ ibi tí a óo ti rí àwọn kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ náà fún wa.
Ilu yii si ni orisa Sango yan laayo julọ laarin awọn ilu nilẹ Yoruba.
 Èyí jẹ ́ kí àwọn hóró dna gígùn ó le wọ inú kóróonú àhámọ ́ .
Kì í rọrùn bí a bá ń ṣe ìtọ́júu wọn, nítorí náà a máa sọ sùúrù nù.
Mike Zhang dì ọmọ China akọkọ tí wọ́n f'oye dá lọla ní ìpínlẹ̀ Kano
 O ni, “bi ẹ ba ri, ẹyin ara mi lati igba ti Kabiyesi ti gori aleefa ni idagbasoke alailẹgbẹ ti n ba ipinlẹ yii pẹlu atilẹyin wọn fun ijọba.
Orile ede Saudi Arabia lo ta epo  robi julo laarin gbogbo awon orile ede to wa lagbaaye, amosa lati odun 2017 ni ajo OPEC ti n sa  ipa won lati ri i pe adinku ba iwon epo robi ti awon orile ede kan n ta a si orile ede miiran.
Ní ìparí, ẹ̀yin ará, gbogbo nǹkan tí ó bá ń ṣe òtítọ́, gbogbo nǹkan tí ó bá lọ́lá, gbogbo nǹkan tí ó bá tọ́, gbogbo nǹkan tí ó bá jẹ́ mímọ́, gbogbo nǹkan tí ó bá fa eniyan mọ́ra, gbogbo nǹkan tí ó bá ní ìròyìn rere, àwọn ni kí ẹ máa kó lé ọkàn.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Onigbọwọ Day, Lou DiBella lo kede iku rẹ nigba ti o wa pẹlu awọn ẹbi ati ọrẹ rẹ.
 Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, RevolutionNow: Ẹ̀rù ò bàwá, a ṣetan láti wà ní àtì mọ́lé- olùfẹ̀hónúhàn Bakan naa ni Ọgbẹni Ozo-Eson tun sọ pe, bi awọn oṣiṣẹ ajọ alaabo DSS ṣe fi oludasilẹ iwọde Revolution Now, Omoyele Sowore si ahamọ, ko ba oju mu to, nitori pe igbesẹ Sowore ko fi ibi kankan dunkooko mọ iṣọkan tabi ijọba Naijiria."
Àwọn olùpolongo ìdìbò Aketi àti Jegede ń forígbárí l'Ondo, bí wọ́n ṣe n yìnbọn ni wọn n sun táyà Adìyẹ́ jẹ̀fun ara wọn!
"Okina ni, ""Awọn eniyan a maa ni wipe ọmọ lile l'awọn ọmọ t'ohun gbe lojupopona, ṣugbọn mo mo mọ wipe wọn kii ṣe ọmọ lile."
Ohun to ko iwaju si eni kan ni oro naa nitori minister otelemuye fun Isreal, Isreal Katz yombo igbese ijoba Trump yii pe ajo UNRWA lo n safikun si isoro awon asatipo Palestine.
Ajo eleto idibo lorile ede Naijiria ti sun eto idibo aarẹ to
Osere naa, ti awọn eeyan mọ si Sridevi, lọ si ọdọ awọn ẹbi rẹ ni Dubai nitori igbeyawo ọkan lara wọn.
Wọ́n gba ìlú náà, wọ́n mú ọba ibẹ̀.
OLUWA bá dá Mose lóhùn, ó ní, “Tọ àwọn eniyan náà lọ kí o sì yà wọ́n sí mímọ́ lónìí ati lọ́la.
Hela bí ọmọ mẹta fún un: Sereti, Iṣari, ati Etinani.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Diego Maradona: Ọlọ́pàá 200 ni yóò máa ṣọ́ ibojì Maradona torí àwọn olè 2 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Oríṣun àwòrán, Casa Rosada Yoruba bọ wọn ni ohun ti a ba fi silẹ, ni ewurẹ n gbe.
NCDC lo kede bẹẹ loju opo Twitter rẹ ni Ọjọ Aje.
    Nígbà tí àwọn ọdẹ wọn-ọnni dúró sí apá kan, inú ọmọ ènìyàn dùn.
Amọ, Pryke ṣalaye pe ti wọn ṣi ibode gan an bayii, awọn ọmọ orilẹede Australia ati New Zealand to n maa ṣabẹwo sawọn orilẹede Pacific ko le wa bayii nitori awọn naa ti ti ibode wọn.
Wọn kede rẹ gẹ́gẹ́ bi ajawe olubori fun ipo aarẹ lọj kọkanlelogun oṣu kẹrin ọdun 2007 ti wọn si bura wọle fun un ni ọjọ kọkandinlọgbọn oṣu karun dun kan naa.
Olorì Anu Adeyemi ń ṣe ọjọ ìbí, ẹ gbọ́ ǹkan tò sọ sí Kábíyésì Baṣọ̀run Gáà: Ó yan ọba mẹ́rin, tó sì pa ọba mẹ́rẹ̀ẹ̀rin àmọ́ ọba karùn-ún ló pa á Wo ipa tí Mayegun yóò ma kó ní ilẹ̀ Yoruba!
Bi wọn ṣe fi ọwọ si remdesivir tumọ si pe wọn le maa lo oogun naa fun itọju awọn ti coronavirus ti de mọlẹ sileewosan.
Gomina naa fi da awọn eniyan loju wi pe eto aabo fun awọn eniyan ipinlẹ naa lo jẹ oun logun.
Bẹ́ẹ̀ ni Rakẹli ṣe kú, wọ́n sì sin ín sí ẹ̀bá ọ̀nà Efurati, èyí nnì ni Bẹtilẹhẹmu.
Ìjọba amúnisìn sì ni wọ́n jẹ́ nígbànáà fún àwọn ẹ̀yà tó yí ilẹ̀ Yorùbá po.
O ni inú oyún oṣùmeji ni oun wa nigba ti ọkọ oun kú ni ọdun tokoja lásìkò ti àwọn ọdaran gun pa.
Awọn kan ti lẹ sọ pe ko si eleyii to kan awọn, nkan to ba wu aarẹ Buhari nitori awọn ko ni igbagbọ ninu rẹ mọ.
Wọn ti sin obinrin naa ni ilana ẹsin Islam ni ana.
A mọ wipe ikọ awọn ọmọ agbebọn, to seese ki wọn jẹ ọmọ ẹgbẹ Boko Haram yabo ilu Dapchi lọwọ irọle ọjọ Aje l'ọjọ kọkandinlogun osu keji.
Bẹ́ẹ̀ ni Ọlọrun ṣe dá ọ̀run ati ayé.
Ẹ óo tún fi aro lu ìlù ayọ̀, ẹ óo sì jó ijó ìdùnnú.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Torí ₦300, awakọ̀ ojú omi ṣokùnfà ikú èèyàn méjìlá l‘Eko - Ọlọ́pàá Láì san owó oṣù tẹ jẹ wá, kò sọ́rọ̀ kankan - ASUU sọ fún ìjọba Ìjọ́ mí ní Italy ni mo fi ń ṣèrànwọ́ fáwọn aṣẹ́wó ọmọ Nàíjíríà tó há - Taribo West Ààrẹ orílẹ̀èdè Mali, Boubacar Keita kọ̀wé fipò sílẹ̀ Àwọn òṣèré tíátà Yorùbá kọjú ìjà síra wọn lórí ìdárò akẹẹgbẹ́ wọn tó kú Ìpàkọ́ kò gbọ́ sùtì ní ọ̀rọ̀ ẹ̀yin tí ẹ̀ ń bú mi- Oyedepo Mo kọ̀ láti pín ọkọ mi pẹ̀lú ẹnikẹ́ni, nítorí náà ẹ tú wa ká- Abílékọ Idowu faraya ní kóòtù kọkọ-kọkọ Ibudo naa, ti wọn pe ni Crushed Rock, ti itumọ rẹ n jẹ apata ti wọn run wẹlẹwẹlẹ lo wa ni agbegbe Mpape nitori ilu Abuja.
Nigba ti wọn n sọrọ nileewosan lẹyin ohun ti wọn ni awọn la kọja, awọn obinrin ọhun ni awọn ẹṣọ orilẹede kan lo fiya jẹ awọn.
 Èdè pànyán-àn ni èdè tí wọ ́ n fi ń ṣe ìjọba ní ibẹ ̀ .
Ọlọpaa to yinbọn wọ atimọlẹ Ọgbẹni Segun Awosanya to jẹ ajafẹtọ ọmọniyan to de ile iwosan naa laipẹ ti iṣẹlẹ naa ṣẹlẹ ni nkan bii agogo mẹta oru ni wọn kuro nibi ajọyọ wọn lati dari sile.
Soyinka bu ẹnu ẹtẹ lu bawọn ọlọpaa ọtẹlẹmuyẹ ṣe mu ajefẹtọ ọmọniyan, Omoyele Sowore nile rẹ.
PDP ni ki Buhari dẹkun ẹkun alabosi lori ijinigbe Yobe
Champions League: Ajax f'imú Tottenham fọn fèrè Bakan-meji lọrọ ri fun ilẹ Gẹẹsi ninu idije bọọlu ilẹ Yuroopu.
 fáàrí àti yànǹga rẹ ̀ kúkú tó bẹ ́ ẹ ̀ ní tòótọ ́ .
"Mi ò ní ìyàwó nílé, àmọ́ mo ní ọmọ tó pọ̀-Saheed Oṣupa Shuaib ní wọ́n pa irọ́ mọ́ òun láti tako Sẹ́nétọ̀ Adeleke ní ilé ẹjọ́ Facebook gbégilé àwọn ojú òpó ayédèrú Ẹ wo Pelumi tó fẹ́ lọ ṣojú Naijiria ni orílẹ̀èdè Hungary lọ́dún yìí ASUU ń lérí ìyanṣẹ́lódì lórí ọwọ́jà ìjínigbé lórílẹ̀èdè Nàìjíríà Ọwọ́ ọlọ́pàá tẹ afurasí ajínigbé 93, àti ìbọn 'AK47' márùndínlógójì 60,000 àwakọ ló ń lo iwé ìrinà ọ̀kọ̀ tí kò k'oju oṣùwọn ní ìpínlẹ̀ Eko - FRSC Kí ló dé tí ìjọba Èkìtì ń fí àwọn òṣìṣẹ́ ṣé ''helo-helo testing""?"
Ọgbẹni Oguntona gba pe lootọọ ni awọn ko tẹle ilana itakete sira ẹni mọ ninu awọn ọkọ ero BRT nitori ijọba ipinlẹ Eko ko tii paṣẹ pe ki awọn maa ṣe bẹẹ ni.
Rakẹli ni ó kó àwọn ère oriṣa náà, ó dì wọ́n sinu àpò gàárì ràkúnmí, ó sì jókòó lé e mọ́lẹ̀.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù BBC World: Iléeṣẹ́ BBC fi ètò tuntun lọ́lẹ̀ fún àwọn àkàndá 3 Ọ̀wàrà 2019 Àkọlé àwòrán, Eto naa yoo ṣe awọn akanda ẹda lanfani Tony Hall to jẹ ọga agba patapata fun ileeṣẹ BBC ni gbogbo agbaye ti kede eto tuntun kan ti yoo ṣe awọn akanda ẹda ni anfani.
Atẹjade kan ti agbẹnusọ fun Aarẹ Muhammadu Buhari, Garba Shehu fi sita loju opo Twitter rẹ lorukọ aarẹ orilẹ-ede yii lo sisọ loju ọrọ naa.
Oríṣun àwòrán, Others Àkọlé àwòrán, Ilé ẹjọ́ wọ́gilé ìbò tó gbé Ikengboju Gboluga tó ń sojú ẹkùn ìdìbò Okitipupa/Irele nítorí ó jẹ́ ọmọ orílẹ̀èdè méjì.
  Farida ti ko iwe mefa bayii.
se beru, ki e ma si foya, aabo to peye wa fun yin lakooko ti e ba n se ojuse
Àwọn iròyin tì ẹ leè nífẹ̀ síí: Aláwàdà ni Buhari - Fáyóṣé Ìṣẹ̀lẹ̀ Èkó: Aáwọ̀ Ọbàkan sọ ilé di áláwọ̀ méjì Ìfẹ̀hónúhàn àwọn aláboyún ní ìpínlẹ̀ Òǹdó Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí kan sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
" Gẹ́gẹ́ bi Kolawole Oluwadarfe ṣe sọ, ó ní kàkà kí wọn gbé àbádòfin ti yóò ṣe àwọn ọmọ láǹfàní ni ti ètò ẹkọ́ to yantranti ni Bayelsa, àwọn ọmọ ilé aṣofin ló ìpò náà fúb ànfani àrà wọn láti maa gba owó gọbọi léyin ti wọn ba kúrò nipò.
Ó sọ fún BBC pé ìjọba pẹ̀lú ìfọwọ́sowọ́pọ̀ àwọn olórí agbègbè, gbọdọ̀ maa mójútó bí àwọ̀n ènìyàn ṣe n gbẹ́ kànga ní ìbámu pẹ̀lú àwọn ìlànà ètò ààbò.
Ní ìgbà karun-un, Sanbalati rán iranṣẹ rẹ̀ kan sí mi, ó kọ lẹta ṣugbọn kò fi òǹtẹ̀ lu lẹta náà.
ogbeni Rotimi Akeredolu, gomina ipinle Ekiti, Kayode Fayemi,gomina ipinle  Oyo , ogbeni Seyi Makinde ati gomina ipinle
O ni o ṣe e ṣe ko jẹ pe awọn ẹlẹyẹ lo ti leri lati ma a pa wọn.
kiini ninu ọrọ tirẹ rọ awọn ọdọ ọmọ orilẹ-ede Naijiria lati tẹ ẹ jẹjẹ
Pẹlu igi ni ẹsẹ ni Oluwatobi rin irin ajo rẹ lasiko to wa ninu oyun, titi to fi bimọ pẹlu iṣẹ abẹ.
Ọ̀pọ̀ lọpọ̀ ènìà ni wọ́n máa nwá sí ibi òkúta yìí láti ìtòsí àbí ọ̀nà-jíjìn.
Nítorí ọjọ́ ńlá ibinu wọn dé; kò sì sí ẹni tí ó lè dúró.
Ẹjẹ bẹrẹ si ni tu jade lara rẹ lẹyin ti abẹ bẹ ẹ lẹsẹ.
ara ilu sese dibo yan, meji yooku si je awon ti o ti je omo ile igbimo asofin
26 Bélú 2020 Grammy awards 2021 - Burna Boy, Beyoncé, àti Dua Lipa, wà lára àwọn ti wọ́n fi orúkọ wọn sílẹ̀25 Bélú 2020 Amos Dauda, Iphone: Ilé ẹjọ́ dájọ́ ẹgba mẹ́ẹ̀dóògún fún ọ̀daràn tó jí Iphone ní Kaduna25 Bélú 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 3 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 5 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Akomolede ati Aṣa lori BBC: Kí ní ìtúmọ̀ Sílébù àti àmi ohun tó ń fún ni?
UFC245: Kamaru Usman, f'ẹ̀ṣẹ́ borí ààyò Trump, Colby Covington ní ìjà UFC
Ikolu naa waye ni ojo Abameta ni awon agbegbe meta  to wa ni ijoba ibile Rabah ni ipinle Sokoto.
Ni ipinlẹ Kano, gomina Abdullahi Ganduje ti se agbekalẹ igbimọ ẹlẹni mẹrindinlogun ti yoo sawari awọn agbegbe ti wọn yoo tẹ abule Ruga naa si.
ti o mu ki o jawe olubori fun saa keji.
Bí ènìyàn bá jẹ́ méjì ni wọ́n le lo ‘ìwọ’ fún ara wọn tí ẹni a lò ó fún yóò fi mọ̀ pé òun ni à ń bá wí.
fun oludibo, lẹyin ti ẹlomiran ti lo orukọ rẹ lati fi dibo.
Wọn ni awọn ko deede gbe igbese yii bikoṣe lati pese eto aabo to peye fawọn Imaam naa ni.
Debora dáhùn pé, “Láìṣe àní àní, n óo bá ọ lọ.
Agbára mi ti lọ, ó ti ṣàn dànù bí omi,gbogbo egungun mi ti yẹ̀ lóríkèéríkèé;ọkàn mi dàbí ìda, ó ti yọ́.
Wọ́n ti pada sí ẹ̀ṣẹ̀ àwọn baba ńlá wọn, tí wọ́n kọ̀, tí wọn kò gbọ́ ọ̀rọ̀ mi.
Àwọn ẹ̀yà Reubẹni ati ẹ̀yà Gadi bá pe pẹpẹ tí wọ́n tẹ́ ní, “Ẹ̀rí” nítorí wọ́n ní, “Pẹpẹ náà ni ẹ̀rí láàrin wa pé, OLUWA ni Ọlọrun.
Ọkunrin kan wà ninu ẹ̀yà Efuraimu tí orúkọ rẹ̀ ń jẹ́ Elikana, ará Ramataimu-sofimu, ní agbègbè olókè Efuraimu.
“Bí ọ̀kankan ninu àwọn ẹran tí ẹ lè jẹ bá kú, ẹnikẹ́ni tí ó bá fara kan òkú rẹ̀ di aláìmọ́ títí di ìrọ̀lẹ́.
“Ogun pelu iko olote boko haram je, ogun ti o tonka, eleyi ti e
Yollywood: Sinimá Ajé Ọjà tún so Fathia àti Saheed Balogun pọ̀
Èyí ọkùnrin dé fìlà kan tí o fi ara jọ adé tí o ń kọ mọ̀nàmọ̀nà bí òkúta díámọ́ǹdì, ẹ̀wù rẹ̀ jẹ́ agbádá wọ́n sì gé onírúurú òkúta olówó iyebíye pẹlẹbẹ pẹlẹbẹ wọ́n fi ṣe ọnà sí i lára, gbogbo ìwọ́nyí ń dán gbinringbinrin bí ìgbà tí alágbẹ̀dẹ pàtàkì bá ṣe ohun ọ̀ṣọ́ dídára fún gbajúmọ̀ obìnrin.
Nisinsinyii baba rẹ kò dààmú nítorí ti kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ mọ́, ṣugbọn ó ń jáyà nítorí rẹ, ó ń wí pé, “Kí ni n óo ṣe nípa ọmọ mi.
Nígbà tí ó bá di ìrọ̀lẹ́ ọjọ́ náà, gbogbo ìjọ eniyan Israẹli yóo pa ẹran wọn.
Idije naa yoo pakasọ ti awọn onwoye si ti ni ko ti le si ẹnikan to le fọwọ sọya pe oun ni igba naa yoo ja mọ lọwọ.
N óo sì kọ tẹmpili yìí, tí mo ti yà sí mímọ́ fún ìjọ́sìn ní orúkọ mi sílẹ̀, nítorí pé yóo di ohun ẹ̀gàn ati àmúpòwe láàrin gbogbo eniyan.
Toyin Abraham fẹ́ wọ́ Lizzy Anjọrin lọ sílé ẹjọ́ Lizzy ni oju oun ti n ri mabo gẹgẹ bi iyawo Ibadan nitori dipo ki ọkọ oun, Alhaji Lawal maa beere fun burẹdi ati tii gbigbona gẹgẹ bi ounjẹ aarọ, awọn ounjẹ ibilẹ bii Ekuru ati ata ti wọn fi ọwọ lọ, irẹsi ọfada ati ata ṣiṣa ati bẹẹbẹẹ lọ, lo n beere.
Yorùbá dùn lédè, ẹ máa sọọ́ 'Mo máa ń parọ́ díẹ̀díẹ̀ ṣùgbọ́n kò pọ̀' Irú ẹ̀dá wo ni olówó yalumọ àkọ́kọ́ nílẹ̀ Yorùbá, Candido Da Rocha?
Ó bí ọmọkunrin mejidinlọgbọn ati ọgọta ọmọbinrin.
Igbakeji Aarẹ sọ ọ di mimọ, pe ij̣ọba ti n sa gbogbo ipa lati ṣe idasilẹ awọn okoowo alabọde fun awọn to ku diẹ kaa to fun lati fi mu wọn kuro ninu ipele iṣẹ ti wọn wa.
ìta ati òpópónà yóo sì kún fún àwọn ọmọkunrin ati ọmọbinrin tí wọn ń ṣeré.
Nínú fídíò náà tí wọn pè ní Number 12, tí wọ́n ṣe àfihàn rẹ̀ ní Ọjọ́bọ, ni a ti gbọ́ pé, ogunlọ́gọ̀ àwọn adarí eré bọ́ọ̀lù ni àwọn akọ̀róyin fún ní owó, láti ṣe màgòmágó ṣùgbọ́n wọ́n ya àwòrán wón laí mọ̀.
Oorun dídùn ni oorun alágbàṣe, kì báà yó, kì báà má yó; ṣugbọn ìrònú ọrọ̀ kì í jẹ́ kí ọlọ́rọ̀ sùn lóru.
Ọjọru ni wọn ṣi afara naa fun lilọ-bibọ ọkọ.
Nígbà tí olódodo bá di eniyan pataki,àwọn eniyan a máa yọ̀,ṣugbọn nígbà tí eniyan burúkú bá wà lórí oyè,àwọn eniyan a máa kérora.
ng Àjọ NIMC ti fún MTN, Glo, 9mobile àti Airtel ní àṣẹ láti bẹ̀rẹ̀ ìforúkọsílẹ̀ fún NIN Oríṣun àwòrán, other Iroyin tuntun to jade lati ọdọ ajọ to n risi idanimọ lorilẹ-ede Naijiria, NIMC, fi sita ni pe, awọn ileeṣẹ ibaraẹnisọrọ ti ni aṣẹ lati fi orukọ awọn eeyan silẹ fun nọmba NIN.
Ọpọ ọmọ Naijiria papaajulọ awọn ololufẹ ere bọọlu afẹsẹgba lo n ṣe iranti ẹni 're to lọ lori ayelujara.
Ṣaaju ni ẹgbẹ oṣelu PDP fi ikede kan sita pe, ajọ naa lọ tu ile awọn ọmọ Atiku wo, lati mọ boya wọn ko owo ilẹ okeere pamọ sile.
Ọna meji ni a le gba ṣalaye abajade iwadii naa lori eyii.
Gbogbo àwọn ará Bikiri bá péjọ, wọ́n sì tẹ̀lé e wọnú ìlú náà.
Awọn leekan-leekan to wa nibi ipolongo ibo naa ni Gomina ipinlẹ Ogun, Ibikunle Amosun, Gomina Ipinlẹ Ọyọ, Abiola Ajimobi, Gomina ipinlẹ Osun, Rauf Aregbesola, Gomina ipinlẹ Ondo, Rotimi Akeredolu ati Yahaya Bello ti ipinlẹ Kogi.
5 náà lọ láti arẹwà àti gúúsù Yau Ma Tei, àti ìrìnàjò dé ibi tí a ti pa ènìyàn 12 ní àárín-in wákàtí méjì.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Demilade Adepegba: Mo má a ń gbàgbé fèrè ni, tí mo bá wà nílé ìwé Ṣugbọn iru awọn eeyan yi ti wọn fẹ ta ibo wọn maa n ni ibi ti wọn ti maa n pade l'awọn adugbo kọkan, nitori ki ọwọ awọn agbofinro ma ba wọn nigba ti wọn fẹ ta ibo wọn.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Hajj 2020: Yàtọ̀ sí covid-19, wo ìgbà mẹ́wàá míì táwọn mùsùlùmí kò lè ṣiṣẹ́ Hajj ní Mecca 27 Òkùdu 2020 Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Muslims from around the world perform Hajj every year in Mecca, Saudi Arabia.
O sọ fun mi pe ki ṣe nkan to le.
Wọ́n ń fi àkàrà ìfihàn sórí tabili wúrà.
OLUWA ní, ‘Ẹ kò gbọdọ̀ lọ bá àwọn arakunrin yín jà.
Oṣu kini ọdun 2018 ni Ejelonu sọ fun ile ẹjọ wipe, Otema lu ọmọbinrin naa ni alubole, o fun-un lọrun, o tun ge jẹ nigba to fipa ba ọmọbinrin naa lo pọ ninu ọgba fasiti naa.
Awọn orilẹede mii nilẹ Adulawọ ṣi ileewe pada fawọn akẹkọọ to wa ni ipele aṣekagba nikan ki wọn le lanfaani lati ṣe idanwo aṣejade wọn.
    Nígbà tí mo kúrò nínú ilé tí mo ti lọ̀ ra nǹkan yìí, èmi àti àwọn enìkejì mi yí ìlú náà lọ.
 Àwọn ẹ ̀ yà ajá tí ó maa ń sábà ní ectropion ni cocker spaniel , saint bernard , bloodhound , the clumber spaniel , àti basset hound .
Àwọn ará Kalidea tí wọn gbógun ti ìlú yìí, yóo wọ inú rẹ̀, wọn yóo sì dáná sun ún pẹlu àwọn ilẹ̀ tí wọ́n tí ń sun turari sí oriṣa Baali lórí wọn, tí wọ́n sì tí ń rú ẹbọ ohun mímu sí àwọn oriṣa tí wọn ń mú mi bínú.
, tileesẹ ọlọpa si tun ti n sa ipa rẹ lati ri awọn eeyan miran, ti wọn ka pe o lọwọ ninu isẹlẹ yii, mu.
lati ile iwosan Ipensa ni wọn ti gbe Maradona lọ si ile iwosan Olivos Clinic to wa ni La Plata nibi to ti ṣiṣẹ abẹ naa.
Ó ní, “Ìwọ ọmọ eniyan, gbé ohùn sókè kí o kọ orin arò nípa Farao, ọba Ijipti.
Aare wa ro awon omo orile ede Naijiria lati je olooto ati olufokansin fun orile ede won, ni gbogbo ohun ti won ba n se.
Orin náà dún dáadáa ní etí àti pé ó mú èèyàn gbàgbé ara rẹ̀, ní ọ̀nà tí ó ń mú kí àwọn ayírapadà ó máa gbé ẹsẹ̀ ní ọ̀kọ̀ọ̀kan bí wọ́n ṣe ń rìn/jó ní ojú ọ̀nà.
O ni oun roun pe, ki ni ọna ti oun lee gba se iranwọ fawọn eeyan to n se asọ oke, ti ebi ko fi ni pa wọn, ti ko ba si igbeyawo tabi oku sise, ni oun se bẹrẹ isẹ yii.
Ohun tí àwọn eniyan yòókù fi sílẹ̀ ni ọ̀kẹ́ kan (20,000) ìwọ̀n diramu wúrà ati ẹgbaa (2,000) ìwọ̀n mina fadaka ati aṣọ àwọn alufaa mẹtadinlaadọrin.
OLUWA, n óo máa fi ọpẹ́ fún ọ láàrin àwọn eniyan;n óo sì máa kọrin ìyìn sí ọ láàrin àwọn orílẹ̀-èdè.
4m) ti gomina ko le fun Super Eagles lati apo ara a rẹ, lai mu owo ijọba?
Oríṣun àwòrán, Instagram/olori_omoh_one Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Àwọn ọmọ Raama ni: Ṣeba ati Dedani.
0 656 Erekusu Faroe Island 0 0.
Gbogbo àwọn ọmọ Israẹli ni yóo ṣọ̀fọ̀ rẹ̀, wọn yóo sì sin ín, nítorí òun nìkan ni wọ́n óo sin ninu ìdílé Jeroboamu, nítorí òun nìkan ni inú OLUWA Ọlọrun Israẹli dùn sí.
Oríṣun àwòrán, @Bauchi Bẹẹni, oju yin ko kuku tan yin jẹ.
Awọn ọdọ naa ṣeleri wi pe, ifẹhọnuhan naa yoo tẹsiwaju fun ọjọ meji kaakiri ipinlẹ Eko.
Saudi ṣàtúnṣe lílẹ òkò mọ́ Asitani láti dẹ́kun títẹra-ẹni-pa Ẹ fọkàn balẹ̀!
Wo awọn nkan itanjẹ ti awọn eniyan ti se ni Ọjọ April Fool.
Chelsea dìgbájú ru Watford bí olè tó jí ike owó Bournemouth fi àáké da Tottenham lágbo nù ní eré ìje fún Champions league Ajimobi figbe ta, ó ní 'èmi kọ́ ló pa Ṣugar o!
Ọ̀gágun Adékúnlé Fájuyi gba Olóri-ogun Aguiyi Ironsi ni àlejò ni ibùgbé Ìjọba ni Ìbàdàn nigbati àwọn Ológun dé lati fi ibọn gba Ìjọba ni igbà keji.
Àfi ẹni tí ó bá gbàgbọ́ pé Ọmọ Ọlọrun ni Jesu.
Awọn ọmọ ile igbimọ aṣofin nipinlẹ Kaduna lo ṣagbekalẹ ofin naa lati ọdun 1984 ni eyi ti ijọba Gomina El Rufai n ṣe atunṣe si ọna ti yoo gba fi mulẹ sii.
Babagan Zulum  tun so pe igbesẹ ti orile
Bawo ni a ṣe mọ pe ayederu iroyin ni?
Àwọn eniyan ń kígbe lé wọn lórí pé;“Ẹ máa lọ!
Irufẹ awọn ẹya ẹja yii mii ni eja Shark atawọn to tun n fi ẹja Penis yii ṣe ounjẹ wọn.
Eyi ti sun iye awọn to ti lugbadi arun naa siwaju di ẹtalelọgọtadinlẹgbẹfa Aworan atọnisọna Iye awọn to ti ni arun naa lagbaye Sunmọ aworan Àgbáyé Orilẹede Afrika Ariwa Amẹrika Apa Latin Amẹrika ati Caribbean Ilẹ Asia Ilẹ Yuroopu Agbegbe Middle East Erekusu Oceania Fihan 93418283 iye iṣẹlẹ arun naa 2000905 Iye awọn to ku Group 4 Jọwọ ṣe atunṣe ilana ikansi ayelujara rẹ lati ri ẹkunrẹrẹ rẹ Aworan n ṣafihan awọn ti ayẹwo ti fi han lorilẹede kọọkan Orisun: Johns Hopkins University atawọn ajọ eto ilera ilu Igba ti wọn kede iṣiro awọn to nii kẹyin 15 Oṣù Ṣẹ́rẹ́ 2021 20:44 WAT+3 Eniyan marundindinlọgọtalenigba ninu awọn to ni arun ọhun ni Naijiria ti ri iwosan gba, ṣugbọn ogoji eniyan ti filẹ ṣaṣọ bora.
Ó tú kẹ́kọ̀ọ́ jáde ní ilé ìwé girama Ẹdẹ Muslim Grammar School lỌ́ṣun pẹ̀lú ìwé ẹ̀rí Ordinary Level Certificate.
Your Poo and You: Ṣé o mọ̀ pé ìgbẹ́ rẹ leè sọ nípa ìlera rẹ?
Lọkan ninu awọn to fọrọ raṣẹ ba ni  ẹsun iwa ibajẹ kan n mi orilẹede mi titi, wọn si ti darukọ rẹ""."
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Chelsea: Chelsea dun DJ Cuppy nínú lẹ̀yìn tí Arsenal gba omijé lójú rẹ̀ 21 Òkùdu 2020 Oríṣun àwòrán, Getty Images Akọda oro koda bi bi ada gbẹyin ni Yoruba maa n wi.
Oríṣun àwòrán, @DAURA Àkọlé àwòrán, Ibrahim Issa to n figbadun ṣayọ 1.
Ajọ IAAF sọ pe awọn san aadoje ẹgbẹrun owo dọla ($130,000) le nigba ti awọn fowo iranwọ ranṣẹ si ajọ to n ri si ọrọ ere-ije ni Naijiria (AFN) lọdun 2017.
 wọ ́ n ṣeé lò láìséwu bí ènìyàn bá ní oyún , bẹ ́ ẹ ̀ sì ni àwọn tí agbára àti kojú àìsàn wọn kò múnádóko náà tún lè lò ó .
Awọn ọdọ atawọn araalu naa ya bo ile nla naa ni nnkan bii agogo mejila ku ogun i'sẹju lowurọ ọjọ Ẹti ti wọn si ko awọn ounjẹ bii noodles, irẹsi, ṣuga, garri atawọn ounjẹ miran ti wọn gbe pamọ fun irọrun COVID-19 ni ipinlẹ naa.
Ninu ọrọ ti wọn, wọn ni olori ko le ṣadede gbe igbesẹ to gbe, bi kii ṣe pe ẹmi rẹ wa ninu ewu lootọ.
Awọ pupa ni asọ naa ti wọn yoo si fi leesi alawọ wura tabi ayinrin (Gold&Silver) gba leti.
Lati oṣu kẹta naa ni ijọba ti sọ pe loṣooṣu ni ajọ PPPRA yoo maa ṣe ayẹwo owo epo bẹntiro ni Naijiria.
O le ni ebun milionu meta Randi ti o gba lo sile ni eyi to poju lati odun ti idije yii ti bere.
Iye ibo to wa laarin  Lalong ti 
DSS tu akọroyin ti wọn mu silẹ Ẹ̀sun olè ají-ìwé-àkọsílẹ̀ ní a fi kan Akoroyin Samuel Atiku ni yatọ si owo itanran yii, ki Onochie tọrọ aforiji lọwọ oun ninu iwe iroyin mẹfa laarin ọjọ meji.
Nàíjíríà tún ń wọnú ọrọ̀ ajé tó dagun lọ lẹ́ẹ̀kejì - Ìjọba àpapọ̀ laago ìkìlọ̀ Ǹ jẹ́ o mọ̀ pé oṣù ojú ọ̀run táwọn Mùsùlùmí ń lò ti wà saájú Ànọ́bì?
Awon torokan gbangban nilu Kashmir sapejuwe isele n la ibi ohun, gege bi adanu n la fun ilu naa, leyin ti opolopo eniyan padanu emi won.
Ẹ pa oko tabi koriko ti o ba wa ni agbeegbe, ki ayika naa le wa ni mimo ni gbogbo igba.
Ẹní bá ṣe àbẹ̀wò dé UK, kí enítọ̀hún yáa gbìyàjú dé ìlú Bath.
Ko si aniani pe arẹwa ni olori Anu ti n gbe ọla baba, Alaafin yọ.
Ọmọ tuntun kò ní kú ní Jerusalẹmu mọ́,àwọn àgbààgbà kò sì ní kú láìjẹ́ pé wọ́n darúgbó kùjọ́kùjọ́.
Fifi ipa da wọn pada ni wọn sọ pe o lodi si ofin to de orilẹede kan lati da abo bo awọn to ba wa se tabi bẹbẹ lati se atipo ni orilẹede naa lati orilẹede mii.
yanju wahala naa , ni eyi ti e o alaafia  yoo se jọba ni awon agbegbe yii.
Awọn koko ohun to wa ninu lẹta Alaafin naa ree: Koko ohun to wa ninu lẹta ti Alaafin kọ si Fayemi: Alaafin ni lẹta oun da lori agbekalẹ igbimọ lọbalọba nipinlẹ Ekiti, to si yẹ ki Fayemi ranti pe a kii fi ọwọ rọ baa se dagba ju ara wa lọ sẹyin nilẹ Yoruba, to si maa n fara han ninu ipo ta ba dimu.
Ẹ̀rí mi gan-an ni wọ́n sì ń jẹ́.
Amọ, awọn eleto aabo gomina ati ara agbeegbe naa da ikọlu naa duro, ti gomina si wa ni alaafia.
Ọlọ́pàá Adamawa ni #30,000 ni wọ́n fi bọ́ igún látìmọ́lé Ẹgbẹ́ òṣìṣẹ́ ìpínlẹ̀ Ọyọ bẹ̀rẹ̀ ìyanṣẹ́lódì aláìní gbèdéke Theresa May bú sẹ́kún, ó ní òun kò ṣe olóòtú ìjọba UK mọ́ Àáyá bẹ sílẹ o bẹ sáré,wábiwọ́sí ìyá ni Flying Eagles fi bẹrẹ fún Qatar Amọ wọn fikun wi pe sisẹ ayẹwo fun ọkunrin to ba ti pe ẹni ogoji ọdun yoo dẹkun ọpọlọpọ awọn eniyan to n ku latari aisan naa.
”O so pe:  “ijọba gbodo na owo, paapaa julo ni ipinle Benue ti won ti ni isoro eto aabo.
Mo gbọ́ tí ó ń sọ pé, ‘Ọmọ Òrónnà, Ọmọ Ìyáàlà, Ọmọ kí á fi ọ̀pá wá, k’á fi òjé, kí á fi ògèdègédé ọwọ wa dé Sẹri mọ́lẹ̀… Hee Hee Hee.
Wí fún un pé, mo ní, tí kò bá jẹ́ kí wọ́n lọ n óo da eṣinṣin bo òun ati àwọn ẹmẹ̀wà rẹ̀ ati àwọn eniyan rẹ̀, àwọn ará ilé rẹ̀ ati ti àwọn ará Ijipti, orí ilẹ̀ tí wọ́n dúró lé yóo sì kún fún ọ̀wọ́ eṣinṣin.
Àdùnní yìí tí kú ní ọdún mẹ́ta ṣáájú bàbá rẹ̀.
 fun apere itelentele 1 , 1.
Ìwọ ọmọ mi, bí àwọn ẹlẹ́ṣẹ̀ bá ń tàn ọ́,o ò gbọdọ̀ gbà.
Kí ògo OLUWA máa wà títí lae,kí OLUWA máa yọ̀ ninu iṣẹ́ rẹ̀.
 O ni “Idi ti awon eniyan ko se fẹ jade ni bi awon iko ologun se n mu awon eniyan si atimọle  lẹyin ti won pari eto idibo aarẹ  tan.
Ǹjẹ́ ó yẹ kí n mu ẹ̀jẹ̀ àwọn ọkunrin wọnyi?
- Ẹnu ọna abawọle ọja, ile iwe ati ile ti ẹlomii n gbe.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ikoyi Prison: Wáyà iná já lu ẹlẹ́wọ̀n márùn ún lọ́gbà ẹ̀wọ̀n l'Eko, ọ̀pọ̀ w'à níléèwòsàn 2 Ọ̀pẹ̀̀ 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 3 Ọ̀pẹ̀̀ 2019 Àkọlé àwòrán, Wáyà iná já lu ẹlẹ́wọ̀n mẹ́ta lọ́gbà ẹ̀wọ̀n l'Eko, ọ̀pọ̀ w'à níléèwòsàn O kere tan ẹlẹwọn márùn ún ni o ti di ero ọrun bayii lẹyin ti ina ẹlẹntiriki gbe wọn lọgba ẹwọn Ikoyi ni owurọ ọjọ Aje.
Tottenham ko fi ojuure wo Arsenal ninu ifẹsẹwọnsẹ naa pẹlu bi wọn ṣe side iya fun Arsenal ni iṣẹju kẹwa ifẹsẹwọnsẹ naa lati ẹsẹ Eriksen.
Ṣe ni wọn kede rẹ pe, ijọba n wa Dikko lori ẹsun pe o ji biliọnu kan dọla owo Naijiria, ti wọn si gbindanwo lati jí gbe pada wale, amọ ko seese tori ijọba Gẹẹsi doju igbesẹ naa bolẹ.
  O ni “awon eniyan ti won ko wa lati
Iku Maradona ti mu ki gbogbo eeyan lagbaaye papaa julọ awọn ololufẹ ere bọọlu ṣe idaro ẹni 're to lọ papaa julọ nilẹ abinibi rẹ, Argentina.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Xenophobia: Ezekwesili ní bá ṣe yanjú ìkọlù South Africa ló fa sábàbí 5 Owewe 2019 Oríṣun àwòrán, @obyezeks Àkọlé àwòrán, Obby Ezekwesili a ma bẹnu atẹ lu awọn igbesẹ ijọba Naijiria lori ọrọ iṣejọba ati aabo ara ilu Minisita tẹlẹ ri lorilẹ́ede Naijiria,Obby Ezekwesili ti mu alaye bẹnu lori oun to mu lọ kopa ninu ijiroro agbaye lori ọrọ aje to n waye ni South Africa.
Gẹgẹ bi wọn ṣe sọ, ko ju ọọdunrun iru inaki bẹẹ pere to wa ninu aginju ti wọn ti ri wọn, to n tumọ si pe ẹmi awọn ẹranko ọhun wa ninu ewu.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Parental Guidance: Ọdún méjì ni kí ẹ ti bẹ̀rẹ̀ kíkọ́ ọmọ nípa ìbálòpọ̀ Níwájú àwọn akọroyin lágbayé, ni Didier Drogba ti sọrọ ti o si parowa sí àwọn tó n já pe ki won dẹkun ija wọn.
Mose bá sọ̀kalẹ̀ lọ bá àwọn eniyan náà, ó sì jíṣẹ́ fún wọn.
" Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Gbogbo ènìyàn ló wọ agbádá ikú, ẹni tó kàn lẹnìkan kò mọ̀ Buhari ní Nàìjíríà ti bẹ̀rẹ̀ ìgbẹ́sẹ̀ ìmúṣẹ àdéhùn Paris 2020 Ọ̀pọ̀ ló ṣì n ṣelédè lẹ́yìn Barrywonder!
O ṣe apejuwe iṣẹlẹ naa bii iṣe ọwọ awọn ti ko fẹ ki Ethiopa ṣ'ọkan.
Alaafin Aole ri iwa Afonja lati tapa si asẹ oun bii igberaga ati ọyaju, Ọrọ naa si di isu ata yan-yan laarin awọn mejeeji, ija nla to gbona gidi dIde lati ibẹ ni eyi ti awọn Akọni mejeeji si gba lati doju ogun kọ ara wọn tabi fija pẹẹta.
Lati igba ti Al-Bashir ti gori alefa ni odun 1989 nile-ejo to n ri si iwa odaran lagbaye  ti a mo si Internatinal Criminal Court  (ICC) ni won ti n wa fun esun iwa siseku pa awon omode, tite eto omo eniyan loju mole ati awon iwa odaran miiran to sele nilu Darfur lorile-ede naa.
Láti inú ẹ̀yà Simeoni, a yan Ṣemueli ọmọ Amihudu.
Aare ki ogagun Onoja fun ise takuntakun re ti o n ti n gbese lateyin wa ati akinkanju re bakan naa, leni ti o dipo ti o gba ogbon mu nile-ise iko omo-ogun, ti o si tun je gomina ipinle otooto meji teleri.
”Lẹ́yìn náà ó tẹrí ba, ó bá dákẹ́.
Eyi to mu ki wọn o gbe e lọ sileewosan kan lorilẹ-ede South Africa.
Oludari ekun Oyo ati Ogun ohun tun salaye siwaju pe, eto
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Àgbò Man City tó tàdí mẹ́yìn fi ìkanra na Watford bolẹ̀ 21 Owewe 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Eléyìí ni àsìkò àkọ́kọ́ tí Bernardo Silva yóò gbá góòlù mẹ́ta s'áwọ̀n nínú ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ kan látigbà tó ti darapọ̀ mọ́ Manchester City L'áàrin ìṣẹ́jú méjìdílógún àkọ́kọ́ ni Manchester City gba bọ́ọ̀lù márùn un wọ àwọ̀n Watford tí Watford ò sì le tapútú.
Jiti Ogunye wa kesi awọn ara ilu lati wa wọrọkọ fi se ada nitori wọn ko le gbẹkẹle awọn oloselu to n kaakiri naa nitori wọn kii se eniyan gidi""."
” Obinrin náà dáhùn, ó ní, “Obinrin yìí sọ fún mi pé kí n mú ọmọ mi wá kí á pa á jẹ, bí ó bá di ọjọ́ keji a óo pa ọmọ tirẹ̀ jẹ, 
” Ó jáde lọ, ó pàdé rẹ̀ ní òkè Ọlọrun, ó sì fi ẹnu kò ó lẹ́nu.
O ni igbesẹ ijọba yii fihan wi pe ko ye wọn ohun ti awọn ọmọ Naijiria n la kọja kaakiri orilẹede Niajiria.
Ó kọ́ pẹpẹ ìrúbọ fún àwọn ìràwọ̀ ninu àwọn àgbàlá mejeeji tí wọ́n wà ninu ilé OLUWA.
Oríṣun àwòrán, EPA Pẹlu abajade ija ẹṣẹ kikan naa, Anthony Joshua ṣi ni agba ọjọ akanṣẹ to di bẹliti ẹyẹ WBO, WBA ati IBF mu bayii.
com/jumokeodetola/ Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Ooni ile Ife: Iná sọ láàfín Ọọ̀ni Ilé Ifẹ̀, Ọọ̀ni ilé ifẹ̀ ní kò sí ẹ̀mí tó báa lọ19 Ògún 2020 5:58 Fídíò, Akomolede ati asa Yoruba: Ẹ wá kọ́ nípa àpòtí ìṣura èdè wa lórí BBC Yorùbá, Duration 5,5820 Ògún 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Gbogbo àwọn ìjòyè tọ Jeremaya lọ, wọ́n bí í, ó sì fún wọn lésì gẹ́gẹ́ bí ọba tí pàṣẹ fún un.
Ajirotutu ni wọn n tun ile naa ṣe ki wọn baa le tete ta a ni.
N85m ni olubori eto agbelewo naa yoo ko lọ sile lọdun 2020 yii pẹlu awọn nkan wọnyii.
30 Agẹmo 2019 Oríṣun àwòrán, Twitter/Local blog Lẹyin oṣu mẹrindinlọgbọn ti ede aiyede ti waye laarin Olubadan ilẹ Ibadan, Ọba Saliu Akanmu Adetunji, Aje Ogungunnisọ Kinni, ati awọn ijoye rẹ ti gomina tẹlẹ nipinlẹ Oyo, Abiọla Ajimọbi gbe ade le lori, ija ti pari.
Àwọn mejeeji ni wọ́n sì ti di arúgbó.
Heburoni ni wọ́n ti bí àwọn ọmọ náà fún Dafidi.
Ta ni Babajide Sanwo Olu, gomina tuntun l‘Eko?
Idi ni pe ti wọn ba ri wa pẹlu Hijab, wọn yoo ya ẹnu pe ki la wa se nibẹ.
Ìgbìmọ̀ aláṣẹ fásítì UNILAG yọ gíwá iléèwé náà Ọ̀jọ̀gbọ́n Olawatoyin Ogundipe nípò Ó takò òfin kí àwọn obí jẹ̀yà ti ọmọ ba darapọ̀ mọ́ ẹgbẹ́ òkùnkùn- Ajàfẹ́tọ̀ọ́mónìyàn Ẹlẹ́wọ̀n 44 kú sọ́gbà ẹ̀wọ̀n nítorí ooru tó mú púpọ̀ Ilé ẹjọ́ ju ọmọ ìjọ tó fi ìpá bá ọmọ pásítọ̀ rẹ̀ sùn ní ìpínlẹ̀ Ondo sí ẹ̀wọ̀n gbére Oríṣun àwòrán, Others Àwọn ọmọ Nàìjíríà kò sinmi láti ànà lẹ́yìn tí ilé ẹjọ́ Sharia kan ní ìpínlẹ̀ Kano dá ẹjọ́ ikú fún ọdọ́mọkùnrin ẹni ọdún méjìlélógún kan lórí ẹ̀sùn pé ó sọ̀rọ̀ ódì sí ẹ̀sìn Islam.
Ṣaaju ki reluwe laarin ilu Abuja tii ṣe olu ilu Naijiria si Kaduna gbera sọ,ijọba kede irinajo ọfẹ oloṣumẹta.
Bẹẹ ba gbagbe, minisita fọrọ osisẹ, Chris Ngige lo ti sọ saaju pe awọn dokita ti pọ ju lorilẹede Naijiria, eyi to ba si wu ninu wọn lee kọri si oke okun lati wa isẹ aje lọ.
Adelabu to ti figba kan jẹ igbakeji gomina banki apapọ Nigeria, CBN, gbegba oroke nibi eto idibo abẹle ẹgbẹ APC nipinlẹ Ọyọ to waye l'ọjọ Aiku, ni papa iṣere Adamasingba, niluu Ibadan.
 Laisi fi imọ kun imọ awọn oṣisẹ, eyi le mu ifasẹyin ba idagbasoke awujọ”.
N óo tì ọ́ kúrò ní ààyè rẹ, n óo fà ọ́ lulẹ̀ kúrò ní ipò rẹ.
Ibi tí ọkùnrin yìí rò pé ayé ti ti ibẹ̀ sílẹ̀, nígbà tí Aṣojú-Olódùamrè dé tí ọkùnrin náà jáde wá sí ààrin àwọn ènìyàn, ó ti re ẹ̀hin pàtàpàtà, ojú bẹ̀rẹ̀ sí tì í ìrìn ẹsẹ̀ rẹ̀ kò dà bí ìrìn ẹsẹ̀ ọmọ ènìyàn, ó dàbí ẹranko tí ó gbé àwọ̀ ènìyàn bora.
Ipinlẹ Eko lo wa loke tente, eeyan mẹtalelogun lo gbẹmi ara wọn lọdun mẹrin ṣẹyin nibẹ.
Aare so pe  “Gege bi ipo mi bi alaga ajo ECOWAS fun gbogbo
Igbesẹ yii, bi o tilẹ jẹ wi pe amọ ni, ṣugbọn fifi aake kọri ti aarẹ Donald Trump faake kọri lori gbigbe ijọba silẹ ṣe pataki.
Peju ni ọjọ ibi oun jẹ ọjọ kan to ṣe pataki julọ ninu igbesi aye oun.
Ọjọgbọn Ọṣinbajo wa fi mulẹ pe bo tilẹ ṣe pe oun fara mọ ijọba ẹlẹkunjẹkun ati fifun ijọba ipinlẹ ni agbara kikun, sibẹ laisi ijọba ẹlẹkunjẹkun, wọn si le fun awọn ipinlẹ ni agbara kikun laisi pe wọn ṣe ayipada rẹpẹtẹ si ofin.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: 'Ẹwọn ọdun mẹẹdọgbọn ko pọ ju fun afipabanilopọ' Ẹ̀sùn ìfipábánilòpọ̀: Orí Twitter ló ti bẹ̀rẹ̀, ikú ló já sí Wọn dajọ iku mẹrin f'ẹni f'ipa b'ọmọde lo Ìbò 1.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Olubadan: Aáwọ̀ ń parí láàrín ìgbìmọ̀ lọ́ba-lọ́ba nílẹ̀ Ibadan 27 Ògún 2019 Dukuu to n jẹyọ laarin Olubadan atawọn agba oye ti ijọba ana ni ipinlẹ Ọyọ gbe ade le lori, n ṣebi eyi ti n jẹ rodo lọ momi bayii.
A mojuto bi awọn akoroyin ti ṣe gbe iroyin to ni ṣe pẹlu awọn obinrin ti ẹlomiran pa lọjọ kini oṣu kẹwa ọdun yi kaakiri agbaye.
Ìjọba ìpínlẹ̀ Zamfara ti pàṣẹ kí wọ́n gbé iléèwé mẹ́wàá tìpa lẹ́yìn ìkọlù Katsina Oríṣun àwòrán, TWITTER/@BELLOMATAWALLE1 Ijọba ipinlẹ Zamfara ti fofin sita ni kiakia pe ki wọn gbe awọn ileewe ti awọn akẹkọọ ti n gbe ninu ọgba ileewe atawọn ileewe alalọde kan tipa ni ipinlẹ naa.
lọjọ Aje, aare ni eto ilana gbodo wa nipa eyi ti yoo maa daabo bo  imọ
Awọn agbebọn ya bo Seyi Makinde ní Lokoja!
Ọrọ ti ẹni naa sọ farajọ fidio kan to tan kalẹ loju opo Facebook, eyi to ṣafihan ọkọ akoyọyọ to wa lẹba ibi ti gaasi naa ti fọn jade.
’’O tun tesiwaju lati so nipa
Atiku ni kò tíì dópin fún Adeleke, PDP ni àwọn gba idájọ́ wọlé Àlàyé rèé lórí ìdí tí ìyá mi fi sọ fáráyé pé mo ti kú Àbàwọ́n funfun ló sún Temilola di arìnrìnoge Vitiligo O ni koda lọdun 2016 ti wọn tun ni oun ni arun jẹjẹrẹ ni oun tun fi ṣe ohun gbogbo to yẹ ṣugbọn oun bori gbogbo rẹ.
0 1 Jọwọ ṣe atunṣe ilana ikansi ayelujara rẹ lati ri ẹkunrẹrẹ rẹ Ṣe afihan omiran si Akọsile imọ yii, da lori akojọpọ iṣẹ iwadi ni Fasisti Johns Hopkins, o si le ma ṣe afihan awọn akọsilẹ iroyin to ba igba mu lati orilẹede kankan.
Olólùfẹ́ méjì jábọ́ láti àjà kẹsàn án lásìkò tí wọ́n n ṣe kerewà
Ó sàn fun yín pé kí n lọ.
Aṣofin Desmond Oluṣola Eliot ni esi ibo ẹgbẹrun mẹẹdogun-le-ọọdurun le
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Akọ́mọlédè àti Àṣà lórí BBC Yorùbá: Kọ̀ síi nípa iṣẹ́ tí oúnjẹ ń ṣe lára níbí Ma ro ara rẹ pin ni koko iroyin yii, nitori pe ko si owo lọwọ rẹ lonii ko sọ pe o ko ni di ọlọrọ lọla.
Kabiyesi, ìdí tí mo fi kó ọ̀rọ̀ mi tọ̀ ọ́ wá ni pé, àwọn eniyan ń dẹ́rùbà mí, èyí ni ó mú kí n rò ninu ara mi pé, n óo wá bá ọ sọ̀rọ̀, mo sì ní ìrètí pé, kabiyesi yóo ṣe ohun tí mo wá bẹ̀bẹ̀ pé kí ó bá mi ṣe.
Ohun ti ile aṣofin sọ ni pe aba yii ni yoo dena iroyin ofege lori ayelujara atawọn nnkan mii to lodi sofin tawọn eeyan n ṣe lori ayelujara.
Kí ni ìtumọ̀ Pelúpelú, ìlànà àkàsọ̀ ọba tó fa wàhálà l'ọ́balọ́ba l'Ekiti Nílé ijó Fẹla Anikulapo, àrùn Coronavirus dá fàájì dúró Ayédèrú aláwo ló ń gb'ẹ̀mí èèyàn láti ṣòògùn owó-Ẹlẹ́búìbọn Coronavirus: Wo ohun tí o ní láti ṣe láti dáàbò bo ara rẹ Àwọn ọnà ti ènìyàn lé gbà láti ṣe àmojuto foóǹu lo wà nínú fọ́nran òkè yìí.
Gege bi iroyin ohun pe, nigba ti agbenuso kan fun egbe naa, Jean-Gervais Tcheide n ba awon oniroyin soro pe, o kere tan, pupo  eniyan ni won fi owo sinkun mu.
Nígbà tí ó di ọjọ́ kẹta, Josẹfu wí fún wọn pé, “Mo bẹ̀rù Ọlọrun, nítorí náà, bí ẹ bá ṣe ohun tí n óo sọ fun yín yìí, n óo dá ẹ̀mí yín sí.
” Ọkunrin náà bá yára wá sọ ohun tí ó ṣẹlẹ̀ fún Eli.
O ni, ikọ ọmọogun Naijiria ko ikogun to pọ nibuba Boko haram.
Kì í ṣe nítorí pé ó bìkítà fún àwọn talaka ni ó ṣe sọ bẹ́ẹ̀; nítorí pé ó jẹ́ olè ni.
Aare so pe “Tunde je akinkanju, olooto ati olufokansin eniyan lati mu ayipada rere wa si orile ede Naijiria, ni eyi ti ijoba to wa lasiko igba naa fẹ se.
"Nigba ti wọn bii pe ki lo fa idi eyi, ohun ti Toyin Abraham sọ ni pe 'ipinnu gbogbo ẹbi oun ni eyi, nitorina Toyin Abraham loun fẹ ki wọn maa pe oun"" lati igba naa lọ."
Gbogbo eyi lo ni iṣejọba oun yoo ṣe bi wọn ba dibo fun oun.
Fún ọdún mẹta lẹ́yìn èyí, kò sí ogun rárá láàrin ilẹ̀ Israẹli ati ilẹ̀ Siria.
Wò ó, OLUWA n kò pa ẹnu mi mọ́,gẹ́gẹ́ bí o ti mọ̀.
Gbogbo ẹni tí a bí láti ọ̀dọ̀ Ọlọrun kò ní máa dẹ́ṣẹ̀ nítorí irú-ọmọ Ọlọrun yóo máa gbé inú olúwarẹ̀, nítorí náà, kò ní máa dẹ́ṣẹ̀ nítorí a bí i láti ọ̀dọ̀ Ọlọrun.
Ó yẹ kí a mọ ọ̀rọ̀ í dá sí.
Kí ẹ sì máa yọ̀ níwájú OLUWA Ọlọrun yín ninu ohun gbogbo tí ẹ bá ń ṣe.
 Ọba Ìjẹ ̀ bú - jẹ ̀ ṣà ni ẹ ̀ gbọ ́ n tí Ọwá sì jẹ ́ àbúrò .
Wọn a máa fi àwọn ọmọkunrin ati àwọn ọmọbinrin wọn rúbọ sí oriṣa wọn.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Fulani kò leè dúró, táa bá lo ohun ta jogún lọ́dọ̀ àwọn bàbá wa - Sunday Igboho Dangote, jọ̀ọ́ nawọ́ ìrànwọ́ láti dá iléeṣé sílẹ̀ fún wa ní Ọyọ - Aláàfin rawọ́ ẹ̀bẹ̀ Láti orí 'Our Mumu don do' sí 'Revolution Now' Bí ọdún Ọ̀ṣun Oṣogbo ṣe bẹ̀rẹ̀ rèé àti pàtàkì rẹ̀ fún Nàíjíríà Saudi ṣàtúnṣe lílẹ òkò mọ́ Asitani láti dẹ́kun títẹra-ẹni-pa Sugbọn iyalẹnu lo jẹ fun wa nigba ti ikọ iroyin wa de adugbo Ọjọta, amọ ti eegun awọn oluwọde Revolution Now ko sẹ nibẹ, bi o tilẹ jẹ pe awọn ọlọpaa ati ọmọ ogun ti duro wa wa wa si agbegbe naa, lati wa pade awọn oluwọde ọhun.
Nigba ti South Africa fofin de ọti mimu lasiko isede ti wọn paṣẹ, ọpọ lo ri i bi eyi to le ṣugbọn wọn gba a mọra gẹgẹ bi ọna to tọ lati dinwọ iwa ipa ninu ile ku.
Ọlọrun ni ó rán mi ṣáájú yín láti dá yín sí, ati láti gba ọpọlọpọ ẹ̀mí là ninu ìran yín.
Bi o tilẹ jẹ pe Isho Pepper ati meji ninu awọn iyawo marun-un to n ba ṣe ere tiata ti jade laye, sibẹ o yẹ ki awọn ọdọ iwoyi mọ nípa igbe aye ati iku akọni oṣere tiata naa, to fi mọ ipa to ko si idagbasoke iṣẹ tiata nigba aye rẹ.
Ni idahun si oro naa, adari nile igbimo ohun, ogbeni Femi Gbajabiamila so pe asofin Udoma pe oun lati tako esun naa.
Ọmọ mi kuro nile lọ si ile iwe, nigba to wa ni kilaasi, ṣe wọn moju to o?
Amọṣa, aarẹ ile aṣofin agba ti sọ pe awọn yoo mu gẹgẹ bi iṣẹ lati rii pe awọn ọmọ wọnyii pada sileewe lẹyẹ-o-ṣọka.
Lootọọ ni Pochettino gbe Tottenham de ipele aṣekagba Champions League lọdun 2019 ṣugbọn wọn fidi rẹmi, Liverpool lo lu wọn gba ife naa.
”Wolii náà bá gbadura sí OLUWA, apá Jeroboamu ọba sì sàn, ó pada sí bí ó ti wà tẹ́lẹ̀.
Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí kan sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
Ní ọjọ́ náà Hẹrọdu ati Pilatu di ọ̀rẹ́ ara wọn; nítorí tẹ́lẹ̀ rí ọ̀tá ni wọ́n ń bá ara wọn ṣe.
Ati pe fun awọn to ba jẹ awọ oju Abimọ ni bii ti Risika ati awọn ọmọ rẹ, ko nilo atunṣe rara.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ṣe lilo Methtoletom lé koju aarun Corornavirus?
- Ilé ẹjọ́ ìpínlẹ̀ Ondo Ilé ìwòsàn kan rèé tó ń fi àtùpà gbẹ̀bí aláboyún Àwọn ìjọba ìbílẹ̀ méjìdínlógún yìí kò tíì lè bọ́ lọ́wọ́ ìséde - Ìjọba àpapọ̀ Ìrìnà ọkọ̀ akérò àti ọkọ̀ òfurufú bẹ̀rẹ̀ padà jákèjádò Nàìjíríà!
Lara won ti yoo tun lo si orile ede Russia ni adari awon osise fun abenugan ile igbimo asofin ,Hakeem Baba Ahmed, oluranlowo abenugan igbimo asofin fun  ile-ise aladaani ti ki I se ti ijoba ,ogbeni Innocent Onah ati oluranlowo abenugan ile igbimo asofin fun akanse ise omidan Eniola Shitta.
Kò sí ẹni tí ó mọ ọ̀ràn ní àmọ̀tán, bẹ́ẹ̀ ni kò sí wolii tí ó ríran, ní àrítán.
Gowon;akowe agba lorile ede Naijria,Boss Mustapha ati awon adari ile-ise ati
Wọ́n tu Bilasitu tíí ṣe ìjòyè ọba tí ó ń mójútó ààfin lójú, wọ́n ń bẹ̀bẹ̀ pé kí ọba má bínú sí àwọn nítorí láti ilé ọba ni wọ́n ti ń rí oúnjẹ jẹ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ondo Regent: Ó dùn mí pé mi ò lè wọ aṣọ obìnrin mọ́ gẹ́gẹ́ bí adelé ọba Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Ondo Regent: Ó dùn mí pé mi ò lè wọ aṣọ obìnrin mọ́ gẹ́gẹ́ bí adelé ọba 29 Ìgbé 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 30 Ìgbé 2019 Adele Ọba ti ìlú Aaye, ìjọba ibilẹ Ifẹdọrẹ ní ìpínlẹ̀ Ondo, Ọmọbabinrin Taiwo Oyebola Agbona jẹ lẹyin ti baba rẹ papoda ni ọdun kan o le sẹyin.
Ẹ má ṣe wọ́n níbi, ẹ má sì ta ẹ̀jẹ̀ aláìṣẹ̀ sílẹ̀ ní ibi mímọ́ yìí.
Ẹ máa fẹ́ iyawo fún àwọn ọmọ yín, kí ẹ sì fi àwọn ọmọ yín fún ọkọ, kí wọn lè máa bímọ lọkunrin ati lobinrin.
Ina ti eeyan ba lo lo yẹ ki wọn mu owo rẹ wa fun un ni sisan.
Agbẹ́nusọ ọlọpàá ní, pípa ti wọn pa àwọn ẹranko tó ku náà ṣe pàtàkì láti le kọja sọ́dọ̀ ẹni ti kìnìún pa.
Praise ati Ka3na lo kọkọ jẹ jẹ eso ifẹ.
Nígbà tí Josẹfu gbọ́ pé Akelau ni ó jọba ní Judia ní ipò Hẹrọdu baba rẹ̀, ẹ̀rù bà á láti lọ sibẹ.
Wọ́n fogun kó àwọn ilé ìṣọ́ rẹ̀, wọ́n sì sọ ọ́ di ahoro.
” Ó fún Ṣafani ní ìwé náà, 
Iya Roshan ko faramọ ajọṣepọ naa rara, bakan naa ni ẹgbọn Gauri to jẹ ọmọ ogun Tamil Tiger tẹlẹ naa fariga.
 Nibẹ la ti rí Ajala Jalingo to wa ninu ẹgbẹ osere miran ni Mushin, to si ni oun setan lati gba wa sinu ẹgbẹ amọ o gba wa to oṣu meji ka to ri ẹgbẹrun kan Naira owó iforukọsilẹ ti wọn beere san, tawọn sì lo ọdún mẹta nibẹ, ki awọn to kuro kuro ni ọdun 1998.
Ninu awọn wọnyi, o le ni ẹgbẹrun mẹta ti arun yii ti ran lọ sọrun lorilẹede China nikan.
Ṣe Laolu Akande n parọ ni?
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ogundiya: Àṣìṣe Dókítà ló sọ mi di aláàbọ̀ ara lórí kẹ̀kẹ́ Oṣu Kinni ọdun ni wọn ṣe iṣẹ abẹ fún gbajugbaja agbabọọlu naa.
nítorí ọrọ̀ kì í pẹ́ lọ títí,kí adé pẹ́ lórí kì í ṣe láti ìrandíran.
Ohun teyi tunmọ si ni pe wọn ko tete ṣafihan biu aarẹ Trump ṣe mu oke laarin awọn ti ko kawe pupọ titi ti ọjọ fi lọ mọ awọn alatako rẹ lọwọ.
Láti ibẹ̀ ni wọ́n ti rán oníṣẹ́ sí ọba Edomu, wọ́n ní, ‘Ẹ jọ̀wọ́, ẹ jẹ́ kí á gba ilẹ̀ yín kọjá.
Wọn ni wọn ti ná mílíọ̀nú mẹ́rìndílógun dọ́là láti ra àwọ̀n apẹ̀fọn.
Nígbà náà ni Jesu dá wọn lóhùn pé, “Mo fẹ́ kí ẹ mọ̀ dájúdájú pé, Ọmọ kò lè dá nǹkankan ṣe yàtọ̀ sí ohun tí ó bá rí tí Baba ń ṣe.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Kíló burú nínú kí Sanwo-Olu fún Super Eagles lówó?
Awọn ọkunrin naa ati awọn mẹrin miran ni wọn n koju iwadii to niṣe pẹlu owo laarin wọn ati ile iṣẹ eto aabo ilu naa.
Ó ṣe ni laanu pé Micah Johnson ọkùnrin Aláwọ̀-dúdú, jagunjagun fun orile ede Àméríkà, ló pa Ọlọpa marun, ó si ṣe ọ̀pọ̀lọpọ̀ léṣe nipa gbi gbé òfin si ọwọ́ ara rẹ pẹ̀lú ibinu.
Lọjọ ajinde to kọja ni Crystal Palace fagba han Arsenal pẹlu ami ayo 3-2 ni Emirate.
"Ohun to jẹ Faparusi logun ni lati jẹ ""ohùn rere"" fun gbogbo ọmọ Naijiria ati ilẹ Africa, to ba fẹ ẹ dije fun ipo oṣelu lorilẹ-ede naa."
Ọ̀jọ̀gbọ́n Olugbenga Mokuolu to jẹ́ onimo nipa aisan iba ati ọ̀nà láti kojú rẹ̀ wípé májèlé ni ẹ̀jẹ̀ ènìyàn tó bá ti lo ògùn Ivermectin yóò jẹ́ fáwọn yàmùyámú.
Jesu bá pè é lórúkọ, ó ní, “Maria!
Mr Latin sọ ninu fidio naa pe ati ẹgbẹ TAMPAN ati ẹgbẹ awọn alagbata sinima fi ẹnu ko nibi ipade kan ti wọn ṣe lọjọ lọsẹ yii pe osere kankan ko gbọdọ ya sinima kankan lati ọjọ kẹtadinlọgbọn, oṣu Kẹta titi di ọjọ kẹtadinlogun, oṣu Kẹrin ọdun 2020.
Ìrú ìṣẹ̀lẹ̀ abaní nínú jẹ yìí lo wáye lána nígbà ti ọmọ agbábọọlu pẹlu Nasarawa United dédé súbú lulẹ to si gba ibẹ lọ si ọrun alákeji.
Mercy Aigbe bu èpè jó àwọn tó ní gómìnà kan ló ra ilé fún-un Mercy Aigbe: Àwọn olólùfẹ́ rẹ̀ kẹ̀yìn sí í pé ó ní káwọn ọmọge gbọ́n àpò baálé ilé tí wọ́n ń fẹ́ gbẹ 'Àgbàrá òjò wọ́ ọmọ méjì lọ ní Ketu l'Eko lálẹ́, a ṣì ń wá wọn di òní' Daddy Freeze túbá!
Samuẹli sì ń dàgbà, OLUWA wà pẹlu rẹ̀, ó sì ń mú kí gbogbo ọ̀rọ̀ rẹ̀ máa ṣẹ.
A yi orukọ rẹ pada lati daabo bo.
Ṣugbọn Hesekaya gbadura fún wọn pé: “Kí OLUWA rere dáríjì gbogbo àwọn 
Làálàá ọ̀lẹ ń kó àárẹ̀ bá a,tóbẹ́ẹ̀ tí kò mọ ọ̀nà ìlú mọ́.
Ṣugbọn Peteru fà á dìde, ó ní, “Dìde!
ibilẹ ogún to wa ni ipinle naa.
kí wọn mú Jeremaya, kí wọn tọ́jú rẹ̀ dáradára, kí wọn má pa á lára, ṣugbọn kí wọn ṣe ohunkohun tí ó bá ń fẹ́ fún un.
 láti séńtúrì kefà ni wón ti ń fi Árámáìkì àtijó ( classical aramaic ) ko nnkan sílè ní Ààrin gbingbein ìlà-oòrùn àgbáyé ( middle east ) .
Ọlọ́run ló ní kí Abacha kú, àwọn àgbà Yorùbá púpò kò bá ṣòfò- Dele Momodu Toyin pòórá lẹ́yìn tó figbe ta nípa ìfipábálòpọ̀ lójú òpó Twitter - Àwọn ǹkan ti BBC mọ nípa rẹ̀ rèé Ìdí tí mo fi ṣàbẹ̀wò sí ilé ìjọ́sìn T.
N óo kó wọn lọ, kò sì ní sí ẹni tí yóo lè gbà wọ́n sílẹ̀.
Àwọn ọdọmọkunrin náà bá pada lọ sọ gbogbo ohun tí Nabali sọ fún wọn fún Dafidi.
Wayii o, ninu idahun si gbogbo
Lóòtọ́ lò n lo ìbomú-bẹnu, ṣùgbọ́n ṣe bóṣeyẹ kí o wọ̀ ọ́ ló ṣe n ṣe?
Gomina ipinlẹ Ekiti, Kayode Fayemi naa ti ki awọn eniyan ipinlẹ rẹ ku oriire ọdun Keresi.
Ọgbẹni Grisham ṣalaye pe igbesẹ yii ṣe pataki lati mu eto aabo ba irinrinajo si ilẹ Amẹrika gbopọn sii.
Abayomi ni o ti lẹ ni ẹgbẹrun mẹrinla eniyan to ti lugbadi arun Coronavirus ni ipinlẹ Eko nikan.
Kọmisana ọlọpaa ipinlẹ Oyo, Nwachukwu Enwonwu ni awọn eniyan naa wa kọju ija si awọn ọlọpaa lasiko yii.
Ikọ BBC Yoruba rin kaakiri awọn adugbo bii Ring Road, Mọkọla, Eleyẹle, Iwo Road, Mọnatan ati Iyana Church lati mọ bi imọtoto aarin ilu Ibadan se ri.
 a kọ ó ní ọdún 1949 , Òun sì ni ìwé-ìtàn àròsọ kejì òǹkọ ̀ wé náà , daniel o.
iwe merindinlogun ti aare ana  Olusegun
"1986 Abilekọ Madikizela-Mandela sọ ọrọ apilẹkọ kan to da wahala silẹ, ni bi to ti fi ontẹ lu ""ẹgba ọrun"", fifi taya kọ awọn ti wọn furasi pe wọn lọwọ ninu iṣejọba asiko naa lọrun, ti wọn si tun n dana sun wọn."
Àwọ́n ọmọ ẹgbẹ́ Shi'ite kò jú mílíọnù mẹ́rin lọ ti àwọn musulumi Sunni si fẹ́ẹ̀ tó ọgọ́run kan mílíọnu ni orílẹ̀-èdè Nàìjíríà.
Adajọ naa dajọ pe wọn jẹbi, o si dajọ ẹwọn oṣu mẹfa fun wọn tabi ki wọn o san ẹgbẹrun maarun Naira owo itanran.
Awon Omo ile igbimo asofin naa labe egbe oselu House of People’s Representatives (HPR) ati egbe oselu House of Federation (HoF) tewogba iwe ifisesile Aare orile-ede naa teleri Teshome Mulatu, ki won to yan Sahle-Work Zewde lati gba ipo re.
Nigba ti wọn sunmọ ibi ti awọn ọmọ naa wa, ikọ ọmọ ogun doju kọ atako loriṣiriṣi eyi ti wn mu kuro ti wọn si tẹra mọ wiwọ inu aginju lọ.
Alaga eto idanilekoo naa, Taju Olarewaju, ti o je oga agba ile-ise ti o n ri si oro eni-ibode lorile-ede Naijiria teleri so pe, awon osise ile-ise ijoba ko ran won lowo lori oro naa.
Koda, ni akọsilẹ ere bọọlu lorile-ede Naijiria, oun ni akọkọ agbabọọlu ti wọn yoo san owo tabua fun ni ilu rẹ.
Zimbabwe: Ìjọba fẹ̀sùn kan obìrin mẹ́ta lẹ́gbẹ́ alátakò, wọ́n d'éléẹjọ́ bọ̀
O tun ti de si orilẹ-ede DR Congo ati Uganda pada.
Oríṣun àwòrán, Nigeria Presidency O ni kudiẹkudiẹ nileeṣẹ ọlọpaa ati awọn ologun lati igba ti oun ti fiṣẹ ologun silẹ lo ṣe okunfa eto aabo ti ko mọyan lori ni Naijiria.
Ẹni ọdún mẹẹdọgbọn ni nígbà tí ó jọba, ó sì jọba ní Jerusalẹmu fún ọdún mọkandinlọgbọn.
Aarẹ Ibrahim Boubacar Keita wa ni ile rẹ ni agbegbe Sebenikoro, Bamko nigba ti awọn ologun kan de lati wa mu u ni nnkan bi agogo mẹrin irọlẹ.
Nítorí ìdí èyí, yẹ àdírẹ́sì (URL) nàá wò.
"Oniduro ti ileeṣẹ ọlọpa maa waye lasiko ti awọn ọlọpa ko ti i pari iwadi wọn lati mu ki ẹni naa duro fun afurasi ọdaran.
Eleso ni wọn mọ ọ si, Adewale Adeoye gangan ni orukọ rẹ.
Aarẹ Pierre Nkurunza ti n ṣe 'jọba orilẹede naa lati ọdun 2005 ti ogun abẹlẹ ti pari n'ilẹ naa.
 Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Jude Chukwuka: Wọ́n yóò fi ojú ọlọgbọ́n wo akúrí tó bá sọ ojúlówó èdè Yorùbá Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 3 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 5 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!"
Ó bá mú Balaamu lọ sórí òkè Peori tí ó kọjú sí aṣálẹ̀.
Lẹ́yìn náà, kó àwọn aṣọ náà, wọ Aaroni lẹ́wù àwọ̀tẹ́lẹ̀, ati ẹ̀wù àwọ̀kanlẹ̀ efodu, ati efodu náà, ati ìgbàyà.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Akomolede ati Asa: Mọ̀ si nípa àwọn ọ̀nà tí Yorùbá ń gbà ran ara wọn lọ́wọ́ O fikun pe ileeṣẹ iroyin LTV, Eko FM, Traffic Radio, ati Radio Lagos ni wọn ti tipa bayii lati dẹkun biba awọn ohun ini awon eniyan jẹ ati ti ijọba.
Aare egbe awon osise (Nigeria Labour Congress,NLC) ogbeni Ayuba Wabba, ni o gbe atejade yii sita  pelu awon akegbe re ogbeni Bobbio Kaigama alaga egbe awon osise Trade Union Congress (TUC)  ati ogbeni Joe Ajaero, ti oun naa je alaga egbe United Labour Congress (ULC) ni won jo fenuko lori igbese yii.
Kí àwọn ẹlẹ́ṣẹ̀ parẹ́ lórí ilẹ̀ ayé,kí àwọn eniyan burúkú má sí mọ́.
Ninu ilẹ̀ ìdajì ẹ̀yà Manase tí ó wà ní apá ìwọ̀ oòrùn, wọ́n fún ìdílé àwọn ọmọ Kohati tí ó kù ní Aneri ati Bileamu, pẹlu àwọn pápá oko tí ó yí wọn ká.
ti o tona , ti o si dara pelu.
17 Wo iye obìnrin tó bá Ginimbi ọ̀dọ́mọdé olówó kú àti obìnrin to ṣeéṣe kó jogún rẹ̀ Àǹfàní tó wà nínú Ẹmu mímu Nítorí ìwádìí yìí, a kàn sí onímọ nípa oúnjẹ àti oun mímu tí ó ṣara láànfàní Harrison Omonhinmin àti Collins Akano láti spalpayé àǹfàní ẹmu ni àga ara.
Mo fẹ́ kí gbogbo ènìyàn fi í sí ọkàn pé kò dí ẹni tí kò ní Igbó Olódùmarè tirẹ̀ láti lọ nínú ayé, Igbó Olódùmarè ti ẹni kan yàtọ̀ sí ti ẹni kejì, kí Olódùmarè jẹ́ kí olúkúlùkù ti Igbó Olódùmarè tirẹ̀ dé láìní ìpalára.
Kristi ti rà wá pada kúrò lábẹ́ ègún òfin, ó ti di ẹni ègún nítorí tiwa, nítorí ó wà ní àkọsílẹ̀ pé, “Ègbé ni fún gbogbo ẹni tí wọ́n bá gbé kọ́ sórí igi.
OLUWA mú ọkàn Farao, ọba Ijipti le, ó sì bẹ̀rẹ̀ sí lépa àwọn ọmọ Israẹli bí wọ́n ti ń lọ tìgboyà-tìgboyà.
Àkọlé àwòrán, Ọwọ ẹrọ ni ibura gomina mu dani ni Eko, Ojo wẹliwẹli rọ le gomina Sanwo-Olu lori Àkọlé àwòrán, Sokoto penpe ọlọpaa, a fi bii igba ti Naijiria ko i tii gba ominira Àkọlé àwòrán, Olori eto ẹsọ alaabo ni ipinlẹ Eko di ihamọ ogun wọ.
Ni bayii, Arabinrin sọ pe ile awọn obi oun ni oun pada si lati ma a gbe lati igba ti ọkọ ti le e jade tọmọtọmọ.
OLUWA rí i pé ìpọ́njú àwọn ọmọ Israẹli pọ̀, kò sì sí ẹni tí ìpọ́njú náà kò kàn, ati ẹrú ati ọmọ, bẹ́ẹ̀ ni kò sí ẹni tí ó lè ràn wọ́n lọ́wọ́.
O fi Olorun ati Anobi Muhomo be gbogbo olorin fuji ti won je kikida musulumi pe ki won dupe ti won.
Níbo lọ̀rọ̀ dé dúró nípa iṣẹ́ àwọn tó n wa iṣẹ́ N-Power?
Sanusi fi ọrọ yi sita ninu fọnran fidio kan to ṣe ki o to fi afin rẹ nilu Kano silẹ lọjọ Aje.
ko tẹ ika si iwaju ẹni ti wọn fẹ dibo fun bi o ti yẹ, nitori naa, awọn eleto
“Wo ẹni tí ó kọ̀, tí kò fi Ọlọrun ṣe ààbò rẹ̀,ṣugbọn ó gbẹ́kẹ̀lé ọrọ̀ rẹ̀ tí ó pọ̀,ati jamba tí ó ń ta fún ẹlòmíràn.
Janine Van Wyk: Lẹ́yìn ọdun mẹ́rìnlá ti mó ti gbà bọ́ọ̀lù, mó ń lọ fún ife ẹ̀yẹ àgbáye
”Abineri sì dáhùn pé, “Ìwọ ta ni ń pariwo!
Píparun ni ẹ óo pa gbogbo àwọn eniyan tí OLUWA Ọlọrun yín yóo fi lé yín lọ́wọ́ run, ẹ kò gbọdọ̀ ṣàánú wọn, bẹ́ẹ̀ sì ni ẹ kò gbọdọ̀ bọ àwọn oriṣa wọn, nítorí ohun ìkọsẹ̀ ni wọn yóo jẹ́ fun yín.
Fi ojú sí ìwé rẹ títí di àkókò tí ìwọ yóò fi rí ọkùnrin tí ó wù ọ́, tí ẹ ó sì ṣe ètò àti gbéyàwó l’ọ́jọ́ iwájú.
"Lootọ sisọ ọrọ yii sita maa n mu iranti aburu wa fun mi ṣugbọn bi yoo ba ti ṣeranwọ fun igbesẹ fifopin si iwa awọn agbofiro SARS yii, ẹ jẹ ka tẹsiwaju""."
Iroyin ni wọn ti pa o le ni ẹgbẹrun ọgọrun un eniyan ki ogun naa to pari lọdun 2009.
"Dokita Wale ni oun gbagbọ pe eeyan le ṣe oriire lorilẹede rẹ ṣugbọn kii ṣe keeyan kan lọ ibiṣẹ laarọ ko pada sile ni iṣoro ṣugbọn ki inu eeyan tun dun si iṣẹ teeyan nṣe ati agbegbe iṣẹ naa""."
Àbà ètò ìṣúná 2020 tó kéré yóò mú kí ètò ààbò mẹ́hẹ síi ní Nàìjíríà-Onwoye Èrò yapa ní mọ́ṣáláṣí Jimọ̀h láti wá fójú lóúnjẹ lórí ìgbéyàwó òfegè Buhari.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Sunday Igboho: Ẹ fi Ògún búra fún wa láti jà fún ilẹ̀ Yorùbá láì gbé Amotekun sábẹ́ ìjọba Wayii o, gomina ipinlẹ Oyo, Seyi Makinde ti wa paṣẹ fun ileeṣẹ ọlọpaa lati wa ọdaran naa ri pẹlu gbogbo ọna ti wọn ba lee gba.
Inú odò ni wọ́n ti rí òkú ọmọ ọdún méjì tó sọnù l'ọ́jọ́ ọdún Eid nílùú Ibadan Itan Omi Erin Itan omi gbigbona ati tutu ni Ikọgosi Ekiti Ǹjẹ́ fífi omi àti iyọ̀ yọnu leè dènà àrùn Coronavirus?
" Ṣé lóòtọ́ ní agbára àti ipá àwọn ọmọ ogun Iran tó ó kojú tí America?
 Bí Ọlọ́pàá SARS bá dá ènìyàn dúró kó gbọ́ sùgbọ́n."
Oríṣun àwòrán, @justempower Ẹgbẹ kan to pe ara rẹ ni Nigerian Slum/Informal Settlement Federation, ninu atẹjade kan to fisita lọjọ Isẹgun oni, koro oju si igbesẹ ijọba lati le ẹgbẹrun mẹwa eeyan to n gbe ni erekusu ọhun pẹlu ipa.
Àwọn Kerubu náà bá gbéra nílẹ̀, àwọn ni ẹ̀dá alààyè tí mo rí ní etí odò Kebari.
Ọkẹ, ninu ọrọ to sọ fun BBC Yoruba nigba ti a kan si i lori ọrọ ti Shittu sọ yii sọ pe ''o jẹ ọkan lara awọn to janfaani eto idibo to kọja.
Oríṣun àwòrán, others Ninu atẹjade kan ti wọn fi sita lori awọn opopona tawọn awakọ lee maa gba lasiko ti iṣẹ atunṣe yii yoo fi maa waye, ijọba ipinlẹ Eko latẹnu olubadamọran fun gomina ipinlẹ Eko lori ọrọ ohun amayedẹrun ṣalaye pe ijọba ko ṣe eyi lati mu inira ba araalu bikoṣe lati mu abo to peye waye lori awọn ohun amayedẹrun ti wọn n lo.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Erelu Elemure: Ìyá mi rò pé mi ò lè tibi kíkọrin bíi bàbá mi là Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Erelu Elemure: Ìyá mi rò pé mi ò lè tibi kíkọrin bíi bàbá mi là 21 Bélú 2020 Yoruba ni bi baba ba ku, baba nii kù.
2 Kíyèsíi, èmi ni Ọlọ́run; tẹ́tí sí ọ̀rọ̀ mi, èyí tí ó jẹ́ alààyè ati alágbára, ó mú ju idà olójú méjì lọ, sí pípín lọ́tọ̀ọ̀tọ̀ ti oríkèé àti mùndùnmúndùn; nítorínáà tẹ́tí sí ọ̀rọ̀ mi.
Wọ́n pa àwọn òfin rẹ tì sí apákan, wọ́n pa àwọn wolii rẹ tí wọ́n ti ń kìlọ̀ fún wọn pé kí wọ́n yipada sí ọ, wọ́n sì ń hùwà àbùkù sí ọ.
"Yomi fi kun un pe ""mo fẹran awọn akẹgbẹ mi mi o si ko iyan wọn kere yala lori ayelujara tabi lẹyin ayelujara."
Ará, ìròyìn yìí fún wa ní ìwúrí nípa yín, nítorí igbagbọ yín, a lè gba gbogbo ìṣòro ati inúnibíni tí à ń rí.
 nípasẹ ̀ ìtàn yìí , a lè sọ pé ilé-ifẹ ̀ ní àwọn yorùbá ti ṣẹ ̀ , àti pàápàá gbogbo ènìyàn àgbáyé .
Yóo wà lẹ́gbẹ̀ẹ́ ilẹ̀ mímọ́ náà.
Bakan naa lo ni, asẹ ti ọba Adetunji pa pe ki awọn si ade ori awọn ko dara, gbolohun naa si n yẹpẹrẹ ofin to ti agbeyẹwo ilana oye jijẹ nilẹ Ibadan nidi.
Aare Muhammadu Buhari ti panupo pelu ebi, ara, ore ati awon afenifere ti o fi mo apapo omo egbe oselu APC lati kii Minisita to n mojuto oro awon osise teleri, dokita Emeka Wogu ku oriire ayeye odun mẹ́rìnlélógójì nilee eepe.
Èrò yapa ní mọ́ṣáláṣí Jimọ̀h láti wá fójú lóúnjẹ lórí ìgbéyàwó òfegè Buhari.
lati tete se isẹ won, ki o to di osu kerin, ti ipade akọkọigbimo asofin  naa yoo waye.
Enikeji to dangajia ninu ere idaraya boolu afibaati gba julo lagbaye, Novak Djokovic, ti kede Andre Agassi gege bi akonimoogba tuntun.
Kì í ṣe ọwọ́ eniyan ni mo ti gbà á, bẹ́ẹ̀ ni kì í ṣe eniyan ni ó kọ́ mi.
O ni iṣẹ wa lọwọ ijọba lati ṣatunṣe si ọrọ eto ọrọ aje Naijiria ki awọn ero dinku ti wọn n wa jijẹ mimu lọ silẹ okeere.
Nipa bi ipinlẹ Ondo ṣe n gbaradi de arun Covid-19, o ni ijọba Ondo n sa ipa rẹ lati gbogun ti arun naa.
Bi o tilẹ jẹ pe Agboola si di ipo rẹ mu bii igbakeji gomina, sibẹ iroyin fi ye ni pe, awọn ọgọọrọ oloselu kan ti n ya lọ ba ninu ẹgbẹ oselu alatako naa.
 bí ọ ̀ pọ ̀ lọpọ ̀ àwọn Òkèwù tó rí ààyè kólé sí ṣe ń ránṣẹ ́ sí àwọn ọmọ ìyá wọn tó wà ní ẹkùn Òrò àti agbọndà nìyẹn .
Akọ̀wé ìpolongo gbogbogbò fún ẹgbẹ́ PDP, Kola Ologbondiyan nínú àtẹjade to fi síta, salaye pé ìwà ki ààrẹ maa fún ará ìlú ni orúkọ ti ko dára kìí ṣe ohun tó bojumu.
” Iranṣẹ alufaa náà á wí pé, “Rárá!
Oluwo ti Iwo: N kò ni nkan kan sọ lórí fídíò to gba ayélujára kan pé mo ń we igbó, ẹ mú ẹnu kúrò nibẹ
< Omoyele Sowore Owo nina ọlọdani lori ilera to ida mẹ́rìnléláàdọ́rin ninu ida ọgọrun ti awọn eeyan n na ti eleyi a si ma ṣe akoba fun ọpọlọpọ mọlẹbi lorileede Naijiria.
Eyi lo fa iyanṣẹlodi pẹlu iwọde kaakiri orilẹede Naijiria lọdun 2007.
Ǹjẹ́ mo lè gbàgbé ìṣúra aiṣododo tí ó wà ninu ilé àwọn eniyan burúkú, ati òṣùnwọ̀n èké ó jẹ́ ohun ìfibú?
Idije yii ni yoo jẹ ki ikọ agbabọọlu
Wọ́n sọ ọ́ di nnkan ìnira làti ya ara kódà, igbín àti ìkarahun ni wọ́n jẹ́ sí ara wọn.
Dogara wa ni awon osise letoo si owo ti yoo mu igbaye-gbadun ba won, ki i se
Amofin naa ni: ‘Ki ijọba to le e gbe iru igbesẹ bẹẹ, wọn gbọdọ wo ihuwasi awọn eniyan ati bi ilu ṣe rọrun si, ki wọn to le gbe iru igbesẹ bẹẹ'' Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Sextuplet: Àdúrà Ìbùkún ló kú lẹ́yìn ọmọ mẹ́fà yìí- Ifeoma Thelma àti Onyemaechi Chiaka Agbẹjọrọ Monday Ubani wa rọ ijọba orilẹ-ede Naijiria lati ma a ṣe idanilẹkọ loore-koore fun awọn oṣiṣẹ eleto aabo lati koju eto aabo to dẹnukọlẹ ni Naijiria.
Loju ẹsẹ lo pàṣẹ pe ki wọn o sọ asia orilẹ-ede Naijiria kalẹ, lati bu ọlá fun.
Oríṣun àwòrán, adesola_ogunwusi Laipẹ yii ni wọn gbe Arẹmọ Tadenikawo wọ inu aafin Ile Ife fun igba akọkọ ti wọn si fi oju rẹ han faraye fun igba akọkọ.
'Kò tọ̀nà láti yọ orúkọ Omisore àti Obanikoro' Oluwo gba Aláàfin nímọ̀ràn pé kí olorì máa dé adé Ja'afar sọ pe ''ẹ̀rù ile ẹjọ́ ti ijọba ipinlẹ naa ni oun yoo gbe mi lọ ko ba mi, nitori mo mọ pe otitọ ni iroyin ti mo gbe jade.
Ọ̀dọ̀ ẹni tí a rán an sí ni opó kan ní Sarefati ní agbègbè Sidoni.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ẹ wo fídíò Kìnìhún tí wọ́n mú l'Eko ní ibùgbé rẹ̀ tuntun, Bogije, Lekki Wo bí àwọn adigunjalè ṣe sọ Tomi Waziri onítaasín di afọ́jú lójijì!
Awọn obinrin naa maa n wọ aṣọ, ṣokoto ati fila gẹgẹ bi okunrin lasiko ti wọn ba wa lori itẹ gẹgẹ bi ọba tabi adele.
"O ni ""Ti ọlọpaa ba mu ẹnikẹni pẹlu aṣọ ologun, wọn ko laṣẹ lati fi iya jẹ iru ẹni bẹẹ tabi ki wọn lu."
Ati pe awon ileewe ti gbogbo ọmọ ba n lọ ni awọn akanda naa yoo maa lo Àkọlé àwòrán, Awọn oludije dupẹ fun awon eeyan ti won jade wa.
O tẹsiwaju wi pe ẹgbẹrun mẹrin din diẹ owo naira ti awọn obi n san ti di ohun itan ni ipinle naa.
Oríṣun àwòrán, Instagran/kingwasiuayindemarshal 'Nítori ààbò ẹmí MC Murphy ló fi gbá #100,000 lọ́wọ́ K1 lọ́jọ́ ìṣẹ̀lẹ̀' Àwọn ọmọ ẹgbẹ́ FIBAN ti fi ààké kọrí lórí ìṣẹ̀lẹ̀ to wáyé láàrin MC Murphy tó jẹ́ ọmọ ẹgbẹ́ wọ́n ní ìpińlẹ̀ Ogun àti gbájúgbaja olórín fújì, King Wasiu Ayinde Mashall.
E̩nì kò̩ò̩kan ló ní àwo̩n ojús̩e kan sí àwùjo̩, nípasè̩ èyí tí ó fi lè s̩eé s̩e fún e̩ni náà láti ní ìdàgbàsókè kíkún gé̩gé̩ bí è̩dá ènìyàn.
EndSars Protest in Edo: Iléeṣẹ́ alákòsóo ọ̀gbà ẹ̀wọ̀n bẹ aráàlú láti báwọn wá ẹlẹ́wọ̀n tó sálọ Ileesẹ to n ṣakoso awọn ẹlẹwọn ni Naijiria ti kesi ara ilu lati ran awọn lọwọ, nipa mimu awọn ẹlẹwọn to sa lọgba ẹwọn ilu Benin lọjọ Aje pada wa.
won gun ori orule , ki o to di pe orule naa ya 
Njẹ eeyan le ko aarun coronavirus nipa ṣiṣe ere idaraya?
Bauchi State: Okú 596 ló ṣì ń gba owó oṣù Kí ni Buhari sọ nípa ààrẹ tó kàn lọ́dún 2023?
Amọṣa lori epo pupa, ọtalelẹgbẹta o din mẹta dọla, iyẹn ẹgbẹrun lọna igba o le mẹtadinlogun naira.
"Lizzy Anjori ṣèyàwó, àwọn òṣèré púpọ̀ ṣọjọ́ ìbí f'ọ́mọ lọ́sẹ̀ yìí Messi sọ̀rọ̀ àbùkù sí Barcelona lẹ́yìn tó jẹ àjẹkún ìyà lọ́wọ́ Osasuna Ohun tí o kò mọ̀ nípa Ebila ""One Million Boys"" àti Ekugbemi, olórí ẹgbẹ́ òkùnkùn méjì tó da ìlú Ibadan rú A fura pé ejò lọ́wọ́ nínú ikú Tolu Arotile, ẹ ṣe ìwádìí ikú rẹ̀ - Afenifere, Gani Adams, Huriwa O ṣalaye pe kii ṣe tori owo nikan lawn dokita fi n sa lọ soke okun ṣugbn ai si irinṣ lawọn ileewosan ijọba gan n da ni lagara tori eyi awn alaisan a kan maa ku iku ti ko yẹ ki wọn ku ni""."
 antonio meucci , johann philipp reis , elisha gray , alexander graham bell àti thomas edison , nínú àwọn omìíran , gbogbo wọ ́ n tí gbá iyin pẹ ̀ lú iṣẹ ́ aṣájú lóri Ẹ ̀ rọ ìbánisọ ̀ rọ ̀ .
"Energy Drink: Ìjọba fi òfin de èyí tó ń mú ǹkan ọmọkùnrin le Ní Kano, wàhálà àwọ̀n jàǹdùkù, àìtètèdé òṣìṣẹ́ ìdìbò ń dá àtúndì ìbò dúró Ìdí tí Adeleke kò fi tíì lè kó lọ ilé ìjọba ìpínlẹ̀ Ọṣun ""Ńkan tó ṣẹlẹ̀ ní Kano kìí ṣe ìdìbò rárá sùgbọ́n jàndùkú àti ìpánle ti gbogbo ayé sì ń wo."
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù African in Greenland: Kí ló sún ilẹ̀ Afirika dénú gbígbé inú yìnyín?
 Ọ ̀ rọ ̀ nípa ìdàgbàsókè tó wọ inú ìlú lásìkò ọba kọ ̀ ọ ̀ kan .
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Witches Conference: Àjọ PFN kéde àdúrà ọjọ́ méjì láti tako àpérò àwọn àjẹ́ 25 Bélú 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Ajọ awọn kristẹni, PFN ti tako apero agbarijọpọ awọn ajẹ ti yoo waye lọsẹ yii ni fasiti ijọba apapọ to wa niluu Nsukka nipinlẹ Enugu.
Eronja ara ọkọ aloku Toyota Corolla ati eronja seeni ọkọ alupupu Honda kan ni wọn fi se fẹntilatọ wọn.
" O ni iru asiko yii lo yẹ ki gbogbo oṣiṣẹ lẹka eto ilera parapọ, wa koju ọta ọmọniyan yii, nitori naa, ohun to ku diẹ ka a to ni idaṣẹsilẹ naa.
Ẹ̀jẹ̀ wọn bá dà sí mi láṣọ:ó ti di àbààwọ́n sára gbogbo aṣọ mi.
Osinbajo so pe“Iwa ẹlẹya-mẹya kii se isoro orile ede yii lati maa
Atẹjade kan to gbori ayelujara lati ri pe ẹgbẹ naa ti ni ki oludamọran aarẹ Buhari Sẹnẹtọ Babafemi Ojudu ati ana Asiwaju ẹgbẹ APC Bola Tinubu, iyẹn Oyetunde Ojo lọ rọọkun nile.
Igbakeji minisita fun ọrọ ilera lorilẹede Iran, Iraj Harirchi ti lugbadi aarun Coronavirus to ti pa eniyan mẹẹdọgbọn ni orilẹede naa.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ekiti Election: Àwòrán bí ètò ìdìbò gómìnà ṣe lọ ní Ekiti 15 Agẹmo 2018 Ẹ wo akojọpọ aworan bi eto idibo gomina ṣe lọ ni ipinlẹ Ekiti.
Àkọlé àwòrán, Wọ́n fa ayaba Naomi lé Ọọ̀ni'rìsà lọ́wọ́ Ọọni Ogunwusi ṣe ọjọ́ọ̀bí; Àwọn ohun tó yẹ kí o mọ̀ nípa rẹ̀ nìyí Ọọ̀ni ilé Ifẹ̀, Ọba Adeyeye Ẹnitan Ogunwusi, Ọ̀jájá Kejì ń ṣe ayẹyẹ ọjọ́ ìbi ọdún Kẹrinlelogoji.
Ohun tí o sọ pé o óo ṣe sí àwa ati àwọn ọba wa náà ni o ṣe sí wa, tí àjálù ńlá fi dé bá wa.
A ṣe bi wọn ṣe ji Samuel gbe nilu Kano, ilu Eko ni wọn gbe e wa.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Eid-el-Kabir: ''A ò rí èèyàn ra ẹran àgbò lọ́dún yìí bíi ọdún Iléyá tó lọ'' Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Eid-el-Kabir: ''A ò rí èèyàn ra ẹran àgbò lọ́dún yìí bíi ọdún Iléyá tó lọ'' 10 Ògún 2019 Ileya ti de, Ileya ti de o, Barka De Sallah ẹ ku ọdun.
ro ijoba apapo lasiko iwasu  ayeye odun
    ‘Ìbẹ̀ǹbẹ́-olókùnrùn o kú iṣẹ́ o’- kò tilẹ̀ wo apá ọ̀dọ̀ mi, ounjẹ ti wọ̀ ọ́ lára ṣe ni ó tẹ orí mọ́ oúnjẹ koko, èmi náà sì mú sùúrù díẹ̀ sí i.
82% ọkùnrin ní kó mọ̀ pé òun ní àìsàn jẹjẹrẹ asẹtọ ní Naijiria Ènìyàn 26,000 ni àìsàn jẹjẹrẹ ń pa lóòjọ́ Kí ni àyájọ́ ‘Má wọ kọ́mú’ wà fún?
Awọn eeyan ṣi n pejọpọ ni ipejọpọ ọlọpọ ero Ni ọjọ akọkọ ti wsn dẹkun yii, fọfọfọ lawọn ero kun awọn banki atawọn ile itaja gbogbo kaakiri ilu Abuja ati Eko.
Ìgbà tí ó sì parí ọ̀rọ̀ rẹ́, ó ní, ‘Bí ẹ bá tí ń rí àmì wọ̀nyyí, ẹ múra ẹ máa sálọ.
Bakan naa ni wọn tun n lo àwọn ami idanimọ ara ọkọ ayokẹlẹ fi da ogidi ọmọ ijọ mọ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Coronavirus:: Òògùn ìtura dé fún Covid-19!
Yóo wẹ̀ ní ibi mímọ́, yóo kó àwọn aṣọ tirẹ̀ wọ̀, yóo sì jáde.
Àsọtẹ́lẹ̀ nípa Ijipti nìyí:OLUWA gun ìkùukùu lẹ́ṣin, ó ń yára bọ̀ wá sí Ijipti.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Lamidi Adedibu: Èyí ní àlàyé bí akọni olóṣèlú nílẹ̀ Ibadan ṣe sẹ̀ wá 17 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 19 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Oríṣun àwòrán, Getty Images Wọ́n ti sàpèjúwé Lamidi Adedibu gẹ́gẹ́ bi ojúlówó ọmọ Iba Oluyole, ọ̀kan pàtàkì lára àwọn tó jàjà òmìnira nílẹ̀ Ibadan.
Ibéèrè ti ó ń wáye fún Unai Emery ni pé níbo ni Arsenal ń lọ niniúdíje Champions League yìí Ẹ̀ẹ̀mèji ọ̀tọ̀ọ̀tọ̀ ni Jamie Vardy Gbá bọ́ọ̀l sáwọn láti gbọn búrẹdi Arsenal jábọ kúrò nínú àwọn ti yóò kopa nínú ìdíje Champions League.
Nítorí pé kì í ṣe idà wọn ni wọ́n fi gba ilẹ̀ náà,kì í ṣe agbára wọn ni wọ́n fi ṣẹgun;agbára rẹ ni; àní, agbára ọwọ́ ọ̀tún rẹ,ati ojurere rẹ;nítorí pé inú rẹ dùn sí wọn.
yii, ni ona ti eto idagbasoke yoo se de ba eto oro aje ati igba ọtun ni lorile
Ìwọ yóò máa gbọ́ nípa ìtàn eléyìínì níwájú.
AFCON 2019: Ṣìṣeṣìṣe Troost-Ekong ṣokùnfà ìyà àjẹsùn fún Nàìjíríà lọ́wọ́ Algeria
Rutu bá ń bá àwọn ọmọbinrin Boasi lọ láti ṣa ọkà títí wọ́n fi parí ìkórè ọkà Baali, ó sì ń gbé ọ̀dọ̀ ìyá ọkọ rẹ̀.
Gẹgẹ bi ọkọ ṣe sọ, o ni “Nigba ti mo wa ni kekere, mo maa n jẹ ororo pupọ, ṣugbọn ni bayii, mo maa n jẹ epo pupa.
bákan náà ni láti Betigiligali ati láti ẹkùn Geba, ati Asimafeti, nítorí pé àwọn akọrin kọ́ ìletò fún ara wọn ní agbègbè Jerusalẹmu.
Wọ́n tò láti ìhà gúsù ilé náà títí dé ìhà àríwá, ati ní àyíká pẹpẹ ati ti ilé náà.
 Ọkọ ̀ ojú omi ni ọjà yìí máa ń bá dé .
Ẹ má mú ẹbọ asán wá fún mi mọ́;ohun ìríra ni turari jẹ́ fún mi.
ni igbakeji re, Mahadi Aliyu-Gusau, oludari iko agbofinro ni agbegbe Lilo ni
Mose Rọ Àwọn Ọmọ Israẹli Pé kí Wọn Máa Gbọ́ràn.
Ẹni tí à ń báwí tí ó ń ṣoríkunkun,yóo parun lójijì láìsí àtúnṣe.
Ẹ óo ní ìpọ́njú ninu ayé, ṣugbọn ẹ ṣe ara gírí, mo ti ṣẹgun ayé.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ẹ̀mí sùn níbi ìkọlù Shiite àti ọlọ́pàá Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Ẹ̀mí sùn níbi ìkọlù Shiite àti ọlọ́pàá 22 Agẹmo 2019 Ẹgbẹ shiitee sọ pe ọmọ ẹgbẹ awọn mọkanla lo gbẹmi mi ti ọpọ eeyan si farapa nibi ikọlu to waye laarin ẹgbẹ naa atawọn ọlọpaa lọjọ Aje loluulu orilẹede Naijiria, Abuja.
Minisita fun oro ile-ise, kara-kata ati eto idokowo lorile-ede Naijiria, omowe Okechukwu Enelamah, so fun awon akoroyin ile-igbimo asofin pe, eyi je ara awon ohun ti won fenuko le lori nibi ipade igbimo amusese ijoba apapo lojo-Ru, eyi ti igbakeji Aare Yemi Osinbajo dari re.
A gbìn ín ní àìlọ́lá; a jí i dìde pẹlu ògo.
Ileeṣẹ ti wọn ti n ṣe oogun naa to wa ni adugbo Ikọtun-Egbe, nipinlẹ Eko, ni ileeṣẹ ọlọpa tu aṣiri rẹ lọjọru.
Omi odò yìí mọ́ tóní-tóní bí enipé ó ṣeé mu ni.
Nígbà tí ó dé Jọpa, ó lọ sí iyàrá lókè.
Kí Olódùmarè má ṣe jẹ́ kí irú eléyìí dé sàkání wa.
Ìsìnkú Ọba Sijúwadé bẹ̀rẹ̀ ni ọjọ́ Ẹti, ọjọ́ kẹrinla, oṣù Kẹjọ, ọdún Ẹgbãlemẹ̃dógún.
Àwọn ọ̀tá ń yọ̀ yín, wọ́n ń sọ pé, àwọn òkè àtijọ́ ti di ogún àwọn.
Yóo kígbe mọ́ gbogbo aráyé bí igbe àwọn tí ń tẹ àjàrà.
Maryam Sanda pe ẹjọ́ kòtẹ́milọ́rùn lóri ìdàjọ́ ikú Bàbá àti ìyá mi kò fẹ́ kí n ṣe eré tíátà - Wale Akorede Okunnu Bàbà ìyàwó ló yẹ kí ọkùnrin dọ̀bálẹ̀ fún, kìí ṣe ìyàwò tó fẹ́ fẹ́ - Yemi Elebuibon Sunday Igboho gba àwọn èèyàn Soka n‘Ibadan sílẹ̀ lọ́wọ́ àwọn ọmọ onílẹ̀ tó wá ṣọṣẹ́ Àwọn olùkọ́ èdé Yorùbá l‘Eko dábírà ní àyájọ́ èdè abíníbí Ìhàlẹ̀ lásán ní NURTW ń ṣe torí pé a dínà owó tí wọn ń kó sápò - Ìjọba Ọyọ Olùkọ́ tó fi tipá gba ìbálé akẹ́kọ̀ọ́ tó fẹ́ wọ fásitì rí ẹ̀wọ̀n ọdún 21 he Wọn ni ifẹ awọn si Toyin ati Kola ko le tan laelae, nitori ọmọluabi ni wọn.
Lasiko iwadi wọn lori isẹlẹ yii ni ọwọ sinkun awọn ọlọpa ba afurasi meji kan, ti wọn si doola ẹmi ọmọdebinrin naa lọwọ wọn.
Má jẹ́ kí ó dàbí ọmọ tí ó ti kú kí á tó bí i, tí apákan ara rẹ̀ sì ti jẹrà.
Ohun ti gomina ipinlẹ Ekiti sọ lori isẹlẹ naa Ninu ọrọ rẹ, gomina ipinlẹ Ekiti, Ayọdele Fayose ni ọwọ yoo ba eniyan yoo wu to pa rakunrin Ọlayẹmi, yoo si fi oju wina ofin.
Mo gba ẹ̀kọ́ rẹ, mo sì ń tẹ̀lé ìlànà rẹ;gbogbo ìṣe mi ni ò ń rí.
Ìgbéyàwó àjùmọ̀ṣe 'Shao' ní Kwara, ìyàwó 25 lọ sílé ọkọ lọ́jọ kan Ìgbéyàwó Harry àti Markle: Ohun tí ó yẹ kí o mọ̀ Ọpọlọpọ iku lo ṣẹlẹ laarin lọkọ laya Lọdun 2018 ni Naijiria ti awọn ololufẹ gun ara wọn pa sinu ilé ni eyi ti ofin ṣi le ya wọn sọtọ ki wọn ṣi wa laye.
Oluwa rẹ̀ wí fún un pé, ‘O ṣeun, ọmọ-ọ̀dọ̀ rere.
Digbara ni ọga awọn ọmọ ẹgbẹ okunkun Greenlander ni ipinlẹ Rivers.
  Lati kooju ayipada oju ojo ,lati gba igi gbingbin laye ati Pataki julo pipese ise fun awon omo ipinle naa ati awon anfaani miran.
Ni ipari, idije ohun yoo waye nilu merin lorile-ede France: Vannes, Concarneau, Dinan-Lehon ati Saint-Malo, bere lati ojo karun-un osu kejo di ojo kerinlelogun odun ti a wayii.
”Biṣọọbu Ijọ Methodist’ fun Apa Iwọ-oorun Ipinlẹ Eko (Lagos West), Ẹni-ọwọ Agba Sunday Ogunlere ninu ọrọ tiwọn nibi ayẹyẹ ajọdun orin kikọ naa, fi mulẹ pe erongba ajọdun orin kikọ ọlọdọọdun yii ni lati polongo pataki orin kikọ ninu ijọ Eleto orilẹ-ede Naijiria (Methodist Church Nigeria) siwaju.
Ọkọ mí kò wúlò, emi si ni mo ń ṣeto jijẹ mimu.
Àwọn sinimá tó pegedé ni 2018 lágbàyé Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ṣọla Allyson: Obìnrin tí kò bá rẹwà ni yóò máa ṣí ara sílẹ̀ Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Oríṣun àwòrán, Instagram/@mo_bimpe Lori iroyin to wọpọ pe awọn oṣerebinrin ma n ni ibalopọ pẹlu awọn alaṣẹ ati oludari ere, ki wọn o to o goke, Adebimpe sọ pe, iṣẹ ọwọ onikaluku lo n polongo rẹ, kii ṣe dandan ni lati ni ibalopọ pẹlu ẹnikẹni.
Eto naa jẹ ajọṣepọ ẹgbẹ awọn Onimọ Yoruba, iyẹn Yoruba Studies Association of Nigeria àti apapọ ẹgbẹ Akomolede Naijiria.
Agbekalẹ awọn to laarun naa lati ipinlẹ de ipinlẹ niyii: Èèyàn 562 tuntun ló tún ti lùgbàdì COVID-19 ní Nàìjíríà ní àná Olu ilu orilẹ-ede Naijiria, Abuja lo lewaju lori atẹ awọn ti ayẹwo fihan gẹgẹ bi ara awọn to kun iye arun coronavirus lọjọ Aje.
Aare ba awọn ijoba orile ede
Ọmọ Yahoo fẹ́ pa ìyá rẹ̀ ṣ'owó l'Eko Lẹ́yìn ọdun mẹ́ta tó kú, ilé ẹjọ́ dájọ́ ikú fún alásè tó pa Temidayo Adeleke Yewande, to jẹ agbẹjọro ni wọn fi ẹsun kan pe o pa ọkọ rẹ, oloogbe Lowo Oyediran lọjọ keji, oṣu Keje, ọdun 2016 ni agbegbe Akobo, nilu Ibadan.
Èyí kò rí bẹ́ẹ̀ ti ẹni náà kìí bá ti ṣe oṣisẹ ilera tabi awakọ, kóda lilo ìbọwọ́ tun le ṣe akóba fún ọ láti ma huwa aibikita níto ri pé o fi ibọwọ si ọwọ.
Akinwumi Isola dárà nínú ìwé Nítorí Owó"" lórí Akomolede Yoruba Ìtàn ọ̀rẹ́ tó fi òògùn gba ọkọ ọ̀rẹ́ rẹ̀ ni Akomolede BBC Yorùbá fẹ́ kọ́ wa lònìí Àwọn oúnjẹ ilẹ̀ Yorùbá ní à ń kọ nínú Akọ́mọlédè àti Àṣà lónìí ""Asiko ọjọ́ iwaju"" ni awọn atọka ati wurẹn ti a le fi da wọn mọ ṣugbọn ni ti ""asiko afanamoni eyi ti ẹ mọ si ""Past tense""."
A mọ̀ pé òfin jẹ́ ohun tí ó dára bí a bá lò ó bí ó ti tọ́.
“Èmi OLUWA Ọlọrun fi ara mi búra pé, Sodomu arabinrin rẹ ati àwọn ọmọ rẹ̀ obinrin kò tíì ṣe tó ohun tí ìwọ ati àwọn ọmọbinrin rẹ ṣe.
Ile isẹ ilu London ti ni agbesunmọmi ni arakunri to sekọlu si awọn ara London ni Ọjọ Eti ti awọn yinbọn pa.
Èmi ati gbogbo arakunrin tí ó wà lọ́dọ̀ mi ni à ń kọ ìwé yìí sí àwọn ìjọ Galatia.
Ijoba Ipinle Eko ni guusu iwo oorun Naijiria ti fi da awon eniyan re loju pe oun ti setan lati mu igberu ba irinajo-afe nipinle naa ki eto oro-aje re le tubo bureke sii.
Kó gbogbo ẹ̀dá alààyè tí ó wà pẹlu rẹ jáde, àwọn ẹyẹ, ẹranko ati àwọn ohun tí ń fàyà fà lórí ilẹ̀, kí wọ́n lè máa bímọ lémọ, kí wọ́n sì pọ̀ sí i lórí ilẹ̀ ayé.
 Eleyii lo fi ṣe pataki ki a maa lara wa lọyẹ ni gbogbo igba paapaa nipa ewu to wa ninu awọn idọti onike yii sawujọ wa.
Idi ree ti Alaafin Sango fi n wa ọna lati ya ọrẹ korikosun mejeeji naa, to si ni ki wọn ran Timi Agbale to buru julọ laarin awọn mejeeji nisẹ iku ti ko ni lee pada de mọ.
Lagbegbe kan ti wọn n pe ni Danko saaju ki a to de Sagamu ni o ti waye.
Awọn apẹẹrẹ ibà Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ara gbigbona, otutu, ati ori fifọ̀ ni awọn apẹẹrẹ ti ibà kọkọ maa n fihan Awọn apẹẹrẹ ibà - ara gbigbona, ori fifọ, ati otutu - eyi to maa n fi ara han laarin ọjọ mẹwaa si mẹẹdogun ti ẹ̀fọn to n pin ibà ba jẹ ni Awọn apẹẹrẹ naa le ma han pupọ, ṣugbọn ti ko ba si itọju laarin wakati mẹrinlelogun, ibà ti kokoro aifojuri 'P.
Gẹ́gẹ́ bí ìlérí rẹ̀, à ń dúró de àwọn ọ̀run titun ati ayé titun níbi tí òdodo yóo máa wà.
Mo wá rí ẹranko náà ati àwọn ọba ilé ayé ati àwọn ọmọ-ogun wọn.
O ní àwọn kan láàrin ìjọ tí wọ́n gba ẹ̀kọ́ Balaamu, ẹni tí ó kọ́ Balaki láti fi ohun ìkọsẹ̀ siwaju àwọn ọmọ Israẹli, tí wọ́n fi ń jẹ oúnjẹ ìbọ̀rìṣà, tí wọ́n tún ń ṣe àgbèrè.
Ọba oke fi ohun to gbooro, to si dun un gbọ leti jinki Ayinla Ọmọwura pẹlu awọn agberin ti ọpọlọ wọn ji pepe kẹẹ.
Ẹ̀kọ́ ọ̀fẹ́ déé fáwọn ọmọ Ọlọ́pàá tó kú lásìkò EndSARS, Gómìnà Sanwo-Olu kéde Wo bi o ṣe le fi orúkọ̀ sílẹ̀ fún ẹ̀kọ́ ọ̀fẹ́ ìjọba Nàìjíríà fún ọdún 2021/2022 Ṣé o mọ̀ pé o leè forúkọ̀ iléeṣẹ́ rẹ̀ sílẹ̀ lọ́fẹ̀ẹ́?
Nígbà tí ó yọ sí ibẹ̀, abàmì ẹ̀dá náà ṣubú lulẹ̀ sí ààrin àwọn ẹranko wọ̀nyí ọkùnrin náà sì dúró pẹ̀lú ìbẹ̀rù láàárin wọn.
Ẹ gbọ́ ọ̀rọ̀ OLUWA,ẹ̀yin tí ẹ̀ ń wárìrì nítorí ọ̀rọ̀ rẹ̀:“Àwọn arakunrin yín tí wọn kórìíra yín,wọ́n tì yín síta nítorí orúkọ mi;wọ́n ní, ‘Jẹ́ kí OLUWA fi ògo rẹ̀ hàn,kí á lè rí ayọ̀ yín.
ati Araba, títí dé òkun Ṣinerotu ní apá ìlà oòrùn, ní ọ̀nà ìlú Beti Jeṣimotu, títí dé òkun Araba, (tí wọ́n tún ń pè ní Òkun Iyọ̀), títí lọ sí apá ìhà gúsù, títí dé ẹsẹ̀ òkè Pisiga.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, JusticeforBarakat: O lé lọ́mọ ọdún mọ́kànla kí n tó rí abúrò rẹ̀ bí lée O wa rọ ijọba lati ti gbe igbeṣe to dantọ lọna lati fopin si iwa ifipabanilopọ lorilẹ-ede yii.
"Nigba to n dahun ibeere latọdọ awọn akọroyin lori ohun ti yoo sọ fun Buhari tawọn mejeeji ba foju se mẹrin ara wọn, Soyinka ni, ""Maa sọ pe, Ọgbẹni Aarẹ, o dabi ẹnipe o ti wọnu ẹmi lọ."
Ikọlu ọjọ Ajinde naa wa lara eyi to buru ju to ṣẹlẹ ni Sri Lanka ri lati igba ti ogun abẹle orilẹede naa ti pari ni 2009.
Wọn óo parẹ́ ṣugbọn ìwọ óo wà títí.
Òní ló yẹ kí Ibidunni Ighodalo pé ogójì ọdún, Tope Alabi, Kenolly àtàwọn míì tí yóò kọrin níbẹ̀ rèé Ṣé ojúlówó ni Oogùn apakòkòrò 'Sanitizer' tó ń lò?
O fi kun un pe ilana gbogbo to tọ labẹ ofin ni wọn tẹle.
Ẹni tí ó tẹ̀lé e ninu àwọn ọ̀gágun olókìkí mẹta náà ni Eleasari ọmọ Dodo ará Aho.
Ṣugbọn bí kò bá tilẹ̀ gbà wá, a fẹ́ kí ọba mọ̀ pé a kò ní fi orí balẹ̀, kí á sin ère wúrà tí ó gbé kalẹ̀.
” Sisera bá yà sinu àgọ́ rẹ̀, ó sì fi aṣọ tí ó nípọn bò ó.
kan naa n gbiyanju lati sa kuro lati ilẹ okeere wa si orile ede Naijiria.
Ẹni to ba ri anfaani ẹkọ ọfẹ yii gba yoo ni anfaani lati kẹkọọ gba iwe ẹri akọkọ ni Russia, Morocco, Algeria, Hungary, Egypt, Tunisia, ati Romania.
Nígbà tí ó dé ibìkan tí ó rí i pé ilẹ̀ ti ń ṣú, ó gbé ọ̀kan ninu àwọn òkúta tí ó wà níbẹ̀, ó fi ṣe ìrọ̀rí, ó sì sùn.
Ọkùnrin náà ní egbòogi púpọ̀, gbogbo ènìyàn ló sì mọ̀ ọ́n jákèjádì ìlú wa.
Pe wọn ni ile iwosan naa silẹ, ki wọn lee ti gbaradi de ọ.
Ṣugbọn èmi óo máa yọ̀ títí lae,n óo kọ orin ìyìn sí Ọlọrun Jakọbu.
Awọn ọmọ Naijiria ṣe akiyesi bi Buhari ti ṣe na ẹni naa ni pasan ọju ti wọn si fi iriwisi ọtọọtọ sita lori nnkan to fa.
Adari awọn oniṣegun oyinbo naa ni pe ẹni ti wọn kọkọ fun ni kindinrin tuntun naa nilo kindinrin ṣugbọn ko si lara awọn torukọ wọn wa loke pe asiko ko pọ fun mọ.
Oloye Lai Mohammed to je minista fun ifitonileti, asa ati irinajo afe fun orile ede Naijiria lo so iye nomba yii di mimo leyin ti awon asoju ijoba apapo to lo si Dapchi lati lo se ipade pelu awon ti oro kan lohun lojo Aiku.
Mahmoud Trezeguet lo gba ami ayo kan ṣoṣo naa si awọn ikọ Zimbabwe.
Èyí yóo jẹ́ ilẹ̀ fún ibi mímọ́ mi, níbẹ̀ sì ni ìpín ti àwọn alufaa yóo wà, yóo jẹ́ ọ̀kẹ́ kan ati ẹẹdẹgbaata (25,000) igbọnwọ (kilomita 12½), ní ìhà àríwá, ní ìwọ̀ oòrùn, ìbú rẹ̀ yóo jẹ́ ẹgbaarun (10,000) igbọnwọ (kilomita 5), ní ìlà oòrùn, ìbú rẹ̀ yóo jẹ́ ẹgbaarun (10,000) igbọnwọ (kilomita 5), òòró rẹ̀ ní ìhà gúsù yóo sì jẹ́ ọ̀kẹ́ kan ati ẹẹdẹgbaata (25,000) igbọnwọ (kilomita 12½).
Amọ ninu ọrọ to ba ileeṣẹ BBC news Yoruba sọ, agbẹnusọ fun gomina ipinlẹ Ọyọ, Ọgbẹni Taiwo Adisa ni, gẹgẹ bii ijọba ti ko fẹ wahala, to si fi oju woo pe ati tọtun, ati tosi, ọmọ ipinlẹ Ọyọ ni gbogbo wọn, lo mu ki ijọba gbe aba alaafia naa kalẹ.
Oṣu Kẹfa ọdun 2020 ni Aarẹ ilẹ naa fun ọmọde ọhun ni ami ẹyẹ fun iṣẹ ọpọlọ to ṣe.
yii, ni  awon omo egbe APC lati gbogbo
E̩nì kò̩ò̩kan ló ní è̩tó̩ láti kó̩ è̩kó̩.
Ọọni Adeyeye ni oun ki gbogbo ara ile Oduduwa ati Olori Silekunola to ṣẹṣẹ bi Arole ọmọ fun itẹẹ Oduduwa.
Ẹwẹ, ọpọ araalu Iwu lo fọn sita lati fi ẹhonu han lori igbesẹ awọn oloye to fẹ yọ Oluwa ni ipo.
Láìpẹ́ lẹ́yìn èyí, Jesu lọ sí ìlú kan tí ń jẹ́ Naini.
Kọ̀mpútà yín ò ní gbiná nígbà kankan.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Adebayo Alao-Akala: 'Mo ti dàgbà ọ̀jẹ̀, n kò ní díje fún ipò gómìnà ìpínlẹ̀ Oyo mọ́' 29 Ògún 2020 Oríṣun àwòrán, Facebook/Otunba Adebayo Alao-Akala Gomina ana ipinlẹ Oyo, Otunba Christopher Adebayo Alao-Akala ti kede pe oun ko ni dije fun ipo gomina ipinlẹ naa mọ nibi ti oun ba a de bayii.
Àyìndé bí o rágbà o f’àgbà mọ́dọ ọọọọ
Digbí ni mo wà lẹ́yìn Amotekun, máà ṣèrànwọ́ mílíọ̀nú èèyàn fun - Nnamdi Kanu Fulani kò leè dúró, táa bá lo ohun ta jogún lọ́dọ̀ àwọn bàbá wa - Sunday Igboho Ọwọ́ ọlọ́pàá tẹ afurasí tó ní òun ló jí ọmọ gbé láti parọ́ mọ́ pásítọ̀ ìjọ Sotitobire 'Ẹ yé pè wá ní NEPA mọ́ tí ẹ bá fẹ́ ká fún yín ní iná, DisCos ni wá' Imam tó fẹ́ ọkùnrin míì níyàwó forí kó ìjìyà òfin Ṣo mọ̀ pé J.
A pín iṣẹ́ fún àwọn náà gẹ́gẹ́ bí a ti pín iṣẹ́ fún àwọn arakunrin wọn yòókù tí wọ́n ń ṣiṣẹ́ ninu ilé OLUWA.
Bala Shagari, ọkan lara awọn ọmọ Alhaji Shehu Shagari to tukọ orilẹ-ede Naijiria titi di 1983 sọ fawọn oniroyin pe baba oun padà forijin Buhari ko to dẹni ilẹ̀.
"Lati ọjọ kinni ti gbogbo wa si ti foju kan ara wa, lati di ""bi igbin ba fa, ikarahun a tẹle"", taa si fọwọ sowọpọ lati sisẹ papọ."
''Ko dara ki awọn eniyan ma a na ọja loju popo nitori ijamba ọkọ'' ''Ti ijamba ọkọ ba ṣẹlẹ ni oju popo, o ma n mu ọpọ ẹmi lọ nitori awọn eniyan ma n su jọ si oju popo lati ta ọja wọn''.
Akinwumi Adesina bọ́ lọ́wọ́ ẹ̀ṣùn jẹgúdújẹrá tí wọ́n fi kan - AFDB Ṣé lóòótọ́ ni Amcon gba ilé Toke Makinwa ti wọn ní bàbá olówó rà á fun?
Odunlade, Toyin, Ijebu dásí ìwọ́de #EndSARS, Mercy Aigbe gbébọn Ọkọ̀ akẹ́rù tí ìjánu rẹ̀ já ló kọlù ọkọ̀ agbépo tó fa ìjàmbá iná ní Otedola- LASEMA Ẹ foríjìn wá ọmọ Nàìjíríà, mó mọ̀ pé ẹ̀ ń bínú tórí a kò tètè gbé ìgbésẹ̀ lórí ọ̀rọ̀ EndSARS- Osinbajo Àwọn olùwọ́de ṣetán láti bá mínísítà FCT Abuja wọ̀ ṣòkòtò kan lórí àṣẹ má ṣe ìwọ̀de Ayẹwo siwaju si fihan pe awọn ọgọsan miran pẹlu rẹ ti lugbadi arun naa ni ileewe ọhun.
Ọlọrun fún Paulu lágbára láti ṣe iṣẹ́ ìyanu tóbẹ́ẹ̀ 
Ṣaaju ni iwe iroyin UK Guardian fi iroyin sita pe awọn fi ọrọ wa Busola lẹnu wo, o si sọ fun awọn pe awọn ọlọpaa to di ihamọra nkan ijagun fi ipa mu oun tibọn-tibọn lati fi ọwọ si iwe kan ti wọn kọ oriṣiriṣi nkan to le jẹ ẹri pe irọ ni gbogbo ẹsun to fi kan Fatoyinbo si.
“Erongba ohun se awari awon agbegbe meta gboogi ti o le mu igberu ba eto idokowo ati ipese ise.
“Bí àlejò tí ó wà láàrin yín bá di ọlọ́rọ̀ tí arakunrin rẹ̀ tí ó jẹ́ aládùúgbò rẹ̀ sì di aláìní, tí ó sì ta ara rẹ̀ fún àlejò náà, tabi fún ọ̀kan ninu ìdílé àlejò yín, 
“Oku yii tun ti gba ami eye lati odo awon olopaa fun iwa akoni lati gba awon eniyan kan ti won fe sagbako awon odaran to fe fipa ba won lo po sile, ti awon odaran yii si je iya ese won.
Heṣiboni ati Eleale ń kígbe lóhùn rara,àwọn ará Jahasi gbọ́ ariwo wọn;nítorí náà àwọn ọmọ ogun Moabu sọkún,ọkàn rẹ̀ sì wárìrì.
Àwọn agbébọn pa ènìyàn tó lé ní àádọ́ta ní abúle kan lágbègbè kan náà lọ́sẹ̀ tó kọjá.
Ajọ naa ni bẹrẹ lati ọjọ kini oṣu kẹfa ọdun 2019, banki yoowu ti o ba tun pẹlu ọbọ jawura lori ọrọ naa yoo fi ẹnu fẹra bi abẹbẹ.
Gomina Abdulfatah Ahmed lo ti tukọ ipinlẹ Kwara fun ọdun mẹjọ gbako labẹ asia ẹgbẹ oṣelu People's Democratic Party (PDP) naa wa lara awọn to n kogba wọle.
*O yọju rẹ sita pe iṣekupa ọgọrọ awọn ọmọ ijọ ẹlẹsin Musulumi Shiite to n doju ko ijọba ti ile ẹjọ si fofin de wọn.
O ni ọpọlọpọ agba ẹgbẹ ni ko ṣe ti oun nitori oun kọ̀ lati maa pin owó.
Ìlú mẹtala ati pápá ìdaran tí ó wà ní àyíká wọn ni ilẹ̀ tí ó jẹ́ ti àwọn ọmọ Geriṣoni, gẹ́gẹ́ bi iye ìdílé wọn.
Àwọn òṣìsẹ́ ètò ìlera tó n kojú ewu ikú láti gba ẹ̀mí là Ọ̀nà àbáyọ mẹ́rin rèé, tó bá nira fún ọ láti fún ọmọ lọ́yàn Òwò ẹrú pé irinwó ọdún tó bẹ̀rẹ̀, àwọn Amẹrika tó jẹ́ dúdú wá sí Afirika láti bẹ ilé wò Lẹnu lọlọ yii, iwọde ẹgbẹ naa ti n lagbara ti awọn eeyan kan si ti padanu ẹmi wọn nitori rẹ.
Wọ́n bá lọ mú ninu àwọn tí wọ́n ń fẹsẹ̀ wọ́lẹ̀ kiri, àwọn jàgídíjàgan, wọ́n kó wọn jọ.
Awọn iroyin kan tilẹ sọ pe búrẹ́dì ni awọn janduku naa rẹ ni epo bẹtiro, ti wọn si n ju sinu sọọbu, ki wọn o to sọ ina si i.
Ẹni tí ó ti ń wé gèlè rí, di ẹni tí kò lè wé gèlè mọ́, ẹni tí ó ti ń sọ̀rọ̀ ní àwùjọ, di ẹni tí kò lè sọ̀rọ̀ ní àwújọ; bẹ́ẹ̀ ni nínú ọlá tí Ọlọ́run Ọba fi fún mi mo ti pa àwọn ọmọ aráyé lẹ́kún, mo ti sọ wọ́n di ẹni tí ń gbé ara ṣánlẹ̀, mo ti sọ wọ́n di ẹni tí ń doríkodò, tí ń pòṣé, tí ń sọkún, tí ń sì ń mí ìmí ẹ̀dùn kanlẹ̀, emi náà, ẹbọra pàtàkì ńlá nì, Ikú ẹni tí ilé rẹ́ ń bẹ lágbedemejì ayé òun ọ̀run.
O salaye pe, “Orile-ede Nigeria ti fowo si orisirisi iwe ibasepo pelu awon orile-ede lagbaaye”.
“Ẹ gbọdọ̀ san ìdámẹ́wàá gbogbo ìkórè oko yín ní ọdọọdún.
Border Closure: Ilé aṣòfin àpapọ̀ pàṣẹ fáwọn àṣọbodè láti fààyè gba èpo lẹ́nu bodè
Gbogbo àwọn eniyan ṣe akiyesi ohun tí ọba ṣe yìí, ó sì dùn mọ́ wọn.
Ẹ fi tọkàntọkàn jẹ́ olóòótọ́ sí OLUWA Ọlọrun wa, kí ẹ tẹ̀lé ìlànà rẹ̀, kí ẹ sì máa pa àwọn òfin rẹ̀ mọ́ bí ẹ ti ń ṣe lónìí.
Ó mú kí ìgbì dáwọ́ dúró,ó sì mú kí ríru omi òkun rọlẹ̀ wọ̀ọ̀.
Ọjọgbọn Wole Ṣoyinka tẹnu mọ ọ pe iroyin ofege ti di bii kokoro ajẹnirun to n jẹ Naijiria run.
Lọdun 1959 si 1960, Shagari jẹ Minisita fun idagbasoke eto ọrọ aje.
elesin musulumi , ikọ ologun gba ijọba lowo re lodun 2013, leyin opolopo ifehonuhan
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Regent female kings: Wo àwọn Adelé-Ọba aládé méje tó jẹ́ obìnrin nílẹ̀ Yorùbá 14 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 15 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Oríṣun àwòrán, others Wo àwọn ọ̀dọ́bìrin tó tún jẹ́ Ọba aládé ní ilẹ̀ Yoruba Ni Naijiria, ọkunrin lo maa n ṣaba n jẹ ọba, paapaa nilẹ Yoruba.
Oríṣun àwòrán, Reuters Awọn orilẹede Afirika kan to ṣi ileewe wọn gbe tipa pada lẹyin ti awọn to n ko aarun coronavirus tun n pọ si.
Apejọpọ Hawan Daushe ti Emir maa n bẹ gomina wo nile ìjọba l'agbegbe Shettima House laarin awọn ayẹyẹ to ku ko ni waye.
Ẹ má ṣe bí àwọn baba ńlá yín, tí àwọn wolii mi rọ̀ títí pé kí wọ́n jáwọ́ ninu ìgbé-ayé burúkú, kí wọ́n jáwọ́ ninu iṣẹ́ ibi, ṣugbọn tí wọ́n kọ̀, tí wọn kò gbọ́.
Ọlọrun ní: “Wo ààrin àwọn orílẹ̀-èdè yíká, O óo rí ohun ìjọjú yóo sì yà ọ́ lẹ́nu.
O ni ajọ CAC yoo forukọ ileeṣẹ ẹgbẹrun mẹfa le ni ẹgbẹta lawọn ipinlẹ mẹrinlelọgbọn ni Naijiria.
Akinwumi Adesina bọ́ lọ́wọ́ ẹ̀ṣùn jẹgúdújẹrá tí wọ́n fi kan - AFDB Ṣaaju ni fidio kan ti jade lori ayelujara, ninu eyii ti dokita naa ti sọ pe oun lo awọn oogun naa lati fi tọju aadọtalelọọdunrun eeyan to ni arun Coronavirus, ti gbogbo wọn si ri iwosan.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Àjẹ́, eégún, kí ni wọn ò pè mí tán tórí Vitiligo lára mi' Ipara ti wọn fun un ko si lara awọn eroja iṣaraloge ti wọn fi ọwọ si ni Sri Lanka.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ireti wa wipe igbesẹ lati se ayipada amojuto igbokegbodo ọkọ nipinle Eko yoo tẹsiwaju lọdun 2018 Ofin naa n se odiwọn ipese igbokegbodo ti owo rẹ ko ga ju ara lọ.
Mo fẹ́ kí ẹ mọ̀ dájúdájú pé, yóo di ara rẹ̀ ní àmùrè, yóo fi wọ́n jókòó lórí tabili, yóo wá gbé oúnjẹ ka iwájú wọn.
Àwọn kan wọ ọkọ̀ ojú omi,wọ́n ń ṣòwò lórí agbami òkun,
Ko tii daju boya yoo jade labẹ aṣia APC lọdun 2019.
‘Ọ̀rẹ́ mi ní kí n fi ‘acid’ sí oúnjẹ ọmọ mi’ 'Ojú mi gún régé nítòótọ́ ṣùgbọ́n ọ̀pọ̀ máa ń sá fún mi ni' 'Mo gba kádàrá lórí àìlera mi láìnáání yẹ̀yẹ́' 'Kò sí ǹkan tí o kò lè ṣe tóo bá ní àfojúsùn' 'Pẹ̀lú ìpèníjà ara mi, mo kọ̀ láti ṣagbe' Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí 2 sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 2:23 Fídíò, Water Generator: Ó leè ṣiṣẹ fún wákàtí mẹfà, kó tó sinmi, Duration 2,2310 Òkùdu 2020 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
 oríṣi kan ni àwọn èyí tí obìnrin-ilé máa ń sun.
Mo fún wọn ní òfin mi, mo sì fi ìlànà mi hàn wọ́n, èyí tí ẹnikẹ́ni tí ó bá tẹ̀lé yóo yè.
O óo gbin ọgbà àjàrà, o kò sì ní jẹ ninu èso rẹ̀.
Bẹẹ si ni ọmọ sori ni aafin Ọyọ, nibi ti Ọba Lamidi Olayiwola Adeyemi Kẹta ti ni ayaba to pọ lọọdẹ.
Ṣíṣe àgbéyẹ̀wò ewu to wá níbi tí a n lọ.
Ilẹkẹ ọrun wọn gan n da ni lọrun Àkọlé àwòrán, Ọdun ibeji yii ko yọ awọn agba ibeji silẹ, a kii saa dagba ‘Malabẹ, eegun ẹran la le fọ’ BBC News, Yorùbá Ìdí tí ẹ fi le è nígbàagbọ́ nínú ìròyìn BBC Ìlànà Lílò Nípa BBC Òfin Àṣírí Cookies Kàn sí.
O di ọmọ ọdun mẹrindinlogun ni osu kọkanla ọdun 2017,eyi to mu ko jẹ ọkan lara awọn oludije ti ọjọ ori rẹ kere julọ nibi idije naa.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù World Toilet Day: Onímọ̀ kan ní ìpèsè ilé ìgbọ̀nsẹ̀ nìkan kò lè tàn ipenija yí 19 Bélú 2018 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 20 Bélú 2018 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Orisisrisi aisan lawọn eeyan ma n ko latara yiyagbe sita Ati oṣisẹ ilera ati ara ilu, ko si ẹni to ko fẹ ẹ mọ ipalara ti ṣiṣe igbọnse si ita gbangba n ṣe lawujọ.
Tí ènìyàn bá fẹ́ láti máa dáwà, kí o maa sá fún ọ̀rẹ́ tàbi àéjọ àwọn ènìyàn, èyí jẹ́ ọ̀kan gbòógí pé ìrónú tó n dàmú ọpọlọ ti ṣẹlẹ, tí ènìyàn kò bá tètè fúra, ó lè jásí kí ó gba ẹ̀mi ara rẹ̀.
Yari to jẹ Gomina ipinlẹ Zamfara sọ eyi lẹyin ipade apero ọlọjọ meji ti ile igbimọ asofin agba gbe kalẹ lori eto aabo ni orilẹede Naijiria.
A dúro bí iké lẹ́yìn ìròyìn táa gbé jáde nípa Lekki Tollgate; CNN tako Lai Mohammed Ìjọba Naijiria faraya nínú lẹ́tà tó kọ sí CNN lórí ìwádìí rẹ̀ nípa ìṣẹ̀lẹ̀ Lekki Toll Gate Wo àwọn ayédèrú ìròyìn tó gbà'gboro kan lásìkò ìwọ́de #EndSARS Báyìí ni olùwọ́de EndSARS, Eremosele Adene ṣe gba òmìnira lọ́wọ́ ọlọ́pàá Nàìjíríà Pásítọ̀ Sam Adeyemi, Taaooma, Falz àti gbogbo àwọn tí ilé ẹjọ́ fẹ́ rí nìyìí Oríṣun àwòrán, @Falz Ijọba Naijiria ko ti i fi igba kan sọ pe lootọ ni awọn eleto aabo yinbọn mọ awọn oluwọde naa.
 Bayii, pelu oju ojo to dara, inu mi dun lati so pe Naijiria yoo too maa pese ohun jije re fun ra re laipe.
Fúnra ìlẹ̀kùn yìí ni ó ṣí sílẹ̀ fún wọn.
Bí o bá ti ń hùwà òmùgọ̀, tí ò ń gbé ara rẹ ga,tabi tí o tí ń gbèrò ibi,fi òpin sí i, kí o sì ronú.
Akinwumi Ambode: Ilé aṣòfin Eko ṣèpàdé pàjáwìrì 'tórí Ambode
Òun ni ọmọ Naijiria kejì ti wín yoo pa ni London laarin ọ̀sẹ̀ kan.
Kò sí èèyàn ṣe lè ní òun gbọ́n tinú tẹ̀yìn tí kò níí bá ẹnìkan tó gbọ́n jù ú lọ níwájú.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Iléẹjọ́ fún Seyi Makinde láṣẹ láti yan adelé alága ìbílẹ̀ ní ìpínlẹ̀ Oyo Olóòtú ìjọba Gẹ̀ẹ́sì yan ọmọ Yorùbá ní Mínísítà Òṣèré tíátà, Kemi Afolabi dùbúlẹ̀ àìsàn ní ìlú Mecca Àṣírí mẹ́wàá tí mo mọ̀ nípa Boko Haram-Naomi Adamu Ṣaaju asiko yii ni Olubadan ti paṣẹ pe, eyikeyi awọn ijoye naa ko gbọdọ wa si aafin oun fun ipade pẹlu ade ọba lori.
Àìrísẹ́se àwọn ọ̀dọ́ leè fa wàhálà lẹ́sẹ̀ Lọ́sẹ̀ tó kọjá, asojú ilẹ̀ Britain sí orílẹ̀èdè Nàìjíríá, Paul Arlwright fi irú ìjẹlọ́kàn yìí kan náà hàn níbi ìpàdé àpérò kan nílu Abuja.
Abewo ajo ti o n ri si imo ijinle lori awon ohun iseto ohun ija oloro silu Douma ti jasi pabo bayii, latari ikolu awon omo ogun olote si agbegbe ohun, eleyi ti won furasi pe won se ikolu mejele inu afefe si agbegbe naa lojo Isegun(UNTuesday).
BBC 100 Women 2019: Wo ọmọ Nàíjíríà kan tó wà nínú wọn Seyi Makinde, bàtà tí Ajimobi bọ́ sílẹ̀ ni ko tẹsẹ̀ bọ̀ fún àṣeyọrí Ọyọ - APC Ṣe ẹnu ibodè tí Buhari tì, ló ń mú kí èròjà oúnjẹ gbówó lórí?
Amọ, oludamọran fun Tinubu lori eto iroyin, Tunde Rahman sọ ninu atẹjade kan to fi sita lọjọ Ẹti pe ayederu iroyin lawọn kan n gbe kiri.
Ilé ẹjọ́ dajọ ikú fun ọkunrin tó pa olólùfẹ́ rẹ̀ Ta ni Naira Marley jẹ́ gan?
” Aare wa rọ awon alatileyin
Aarẹ Buhari fi eyi lede gba ọwọ oluranlọwọ pataki ninu eto iroyin igbalode, Bahir Ahmad, eleyii to fi si oju opo Twitter.
Diẹ ninu awọn olujọsin lo lo ibomu ti o sí je pe ati omode ati agbalagba lo wa se ijọsin.
" "" mọnigbùwà gbà láti ṣe bẹ ́ ẹ ̀ ."
Kí á di ìjẹ́wọ́ ìrètí wa mú ṣinṣin láì ṣiyèméjì nítorí ẹni tí ó tó ó gbẹ́kẹ̀lé ni ẹni tí ó ṣe ìlérí.
Ọba dáhùn, ó ní: “Dájúdájú, òfin Mede ati Pasia ni, tí a kò lè yipada.
Wọn ti wà lórí àpáta tipẹ ti wọn ń ya foto nígbà ti ìjì bẹ̀rẹ̀.
Bààlú to gbé Zainab dé láti Jeddah, Saudi Arabia balẹ̀ si pápákọ̀ Aminu Kano ní ǹkan bíí ààgo mẹ́wàá ààrọ̀ òní ọjọ́ ajé, ti asoju orilẹ̀-èdè Nàìjíríà ni Jeddah Garba Satomi Grema sì tèlée ọmọ náà wálé.
Oríṣun àwòrán, @efcc Bobrisky dárò pé EFCC gbé Mompha, ọ̀dọ́mọdé olówó tó ń lo aago ₦20m Àwọn òrin tó ń k'ókìkí àwọn ọmọ Yahoo Àwọn Ìyá àwọn ọmọ Yahoo ti ń kórajọ láti dá ẹgbẹ́ sílẹ̀ - EFCC Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ọmọ Yahoo tú àṣírí ara rẹ̀ fún, bí wọ́n ṣe ń ṣe é BBC Yorùbá Ẹwẹ, lonii ọjọ aje, ajọ EFCC wọ ọ lọ si ile ẹjọ giga to wa ni Ikoyi, ilu Eko.
Ẹ fọn fèrè ní òkè Sioni,ẹ kéde ààwẹ̀ kí ẹ sì pe àpéjọ.
Ninu oro tirẹ, akẹkọọ kan Yinusa Mutiat, to jẹ akẹkọọ ile ẹkọ De Ayo International college Ibadan, ni ki ijọba ṣe aanu fawọn, ki wọn ba le ṣe idanwo asejade lasiko.
pé nígbà tí ẹ bá gbọ́ ìró fèrè, dùùrù, ìlù, hapu, ati oniruuru orin, kí ẹ dojúbolẹ̀ kí ẹ sin ère wúrà tí ọba Nebukadinesari gbé kalẹ̀.
Oshiomole: Ilé ẹjọ́ kòtẹ́milọ́rùn wọ́gilé ìyọnípò Oshiomole gẹ́gẹ́ bíi alága ẹgbẹ́ òṣèlú APC
Ambode ní kò sí gìrì, eré ọwọ́ lásán ni EFCC ń ṣe Ọlọ́ọ̀pá ti mú afurasí ajínigbé Hamisu Wadume Òyìnbó sísọ di èèwọ̀ ní ìpínlẹ̀ Ekiti Ìpínlẹ̀ Ọ̀ṣun kéde ìsinmi lẹ́nú iṣẹ́ nítorí ọdún Ìṣẹ̀ṣe ''Àwọn ọmọ wa ma ń wọ ọkọ̀ ojú omi láìsí ẹ̀wù ìdàábòbò nítorí àti kàwé'' Ile aṣofin ipinlẹ naa ti ke si adajọ agba ipinlẹ naa, Onidajọ Nasir Ajanah lati gbe igbimọ ẹlẹni meje kan kalẹ lati se iwadii awọn ẹsun aṣemaṣe ti wọn fi kan igbakeji gomina naa.
Nítorí ó sàn fún wọn kí wọn má mọ ọ̀nà òdodo ju pé kí wọn wá mọ̀ ọ́n tán kí wọn wá yipada kúrò ninu òfin mímọ́ tí a ti fi kọ́ wọn.
Nítorí nisinsinyii, à ń ríran bàìbàì ninu dígí.
Nibayii, o n sọ itan igbe aye rẹ fun awọn ọdọmọbinrin to ba koju ifipabanilopọ lati mọ pe, kii ṣe awọn nikan ni ọrọ naa kan.
Beckham, àgbábọ́ọ́lù tẹ́lẹ̀ rèé tó ń sọ èdè Yorùbá UEFA Champions League: Barca yọ Man U dànù bí ẹni yọ jìgá!
Dokita Fintin Ekochim to je komisona fun eto ilera nipinle Enugu lo so eyi di mimo lasiko to n ba awon oniroyin soro ni Enugu pe ijoba yoo gbe dokita mejidinlogbon lapapo lo si igberiko gbogbo ki won le lo mojuto eto ilera awon ti won ko ni oore ofe lati wa si igboro.
Kìí ṣe gbájúẹ̀ nìkan lọmọ Nàìjá ń ṣe lókè òkun, Yoruba ń mókè, wọ́n ń gbéṣẹ́ ńlá ṣe
Koda, awọn ipade ati iwọde kan waye ni ilu Eko ti ọpọlọpọ eeyan si lọdi wọn mọ adape ọrọ yii to ti gbẹnu awọn kan ni ipinlẹ Eko.
Alufaa yóo mú ninu ìwọ̀n ìgò òróró náà, yóo dà á sí àtẹ́lẹwọ́ òsì rẹ̀.
John McCain jẹ oloṣelu to ni igboya lati ja fun ohunkohun to ba gbagbọ ninu rẹ de opin.
Ibasepọ Russia pẹlu awọn orilẹede Afirika lẹka ologun Orilẹede Russia jẹ alabasepọ aabo fawọn orilẹede kan ni Afirika, to si jẹ ogbontagi laarin awọn to n pese ohun ija oloro fun wọn, sugbọn taa ba wo yika agbaye, ilẹ Aifika kọ lo tobi ju ti wọn n ta awọn ohun ijagun rẹ si, ẹkun Asia ni.
Awọn iroyin ti ẹ lee nifẹẹ si: Ọwọ awọn ologun tẹ afunrasi to pa ṣọja Awọn ọmọogun Indonesia n mu ẹjẹ ejo Agbẹnusọ fún iléeṣẹ́ àbò-ara-ẹni-làbò-ìlú, Civil defence ńìpínlẹ̀ Kwara, ọ̀gbẹ́ni Ayọ̀délé Bello tó fìdí ọ̀rọ̀ náà múlẹ̀ f'áwọn oníròyìn fi àwọn aráàlú lọ́kàn balẹ̀ pẹ̀lúu àfikún wí pé áwọn agbóòfiró ǹ ṣiṣẹ́ lóríi ọ̀rọ̀ náà láti ríi wí pé gbogbo àwọn tí aje ọ̀rọ̀ náà bá ṣí mọ́ lórí ni wọn fi pańpẹ́ òfin gbé.
Oyo physically challenged protest: Ìdí rèé táwọn àkàndá ẹ̀dá fi dí iwájú iléeṣẹ́ ìjọba ìpínlẹ̀ Oyo pa l'Agodi n'Ibadan
Lọwọlọwọ, apapọ awọn to ti ni aarun naa ni Naijiria bayii ti pe 77,013, eeyan 67,484 ti ri iwosan, nigab ti awọn 1,212 ti dagbere faye.
Lẹ́yìn náà Johanani ọmọ Karea, ati gbogbo àwọn olórí ogun tí wọ́n wà pẹlu rẹ̀, kó gbogbo àwọn tí Iṣimaeli ọmọ Netanaya kó lẹ́rú ní Misipa, lẹ́yìn tí ó pa Gedalaya ọmọ Ahikamu tán, ó bá kó ati àwọn ọmọ ogun, ati àwọn obinrin, ati àwọn ọmọde, ati àwọn ìwẹ̀fà, pada wá láti Gibeoni.
Ẹlẹsẹ ayo naa ni ikọ Man United n yalo lati ikọ rẹ tẹlẹ, Shanghai Greenland Shenhua to wa lorilẹ-ede China.
Kàkà bẹ́ẹ̀, Johanani, ọmọ Karea, ati gbogbo àwọn olórí ogun kó gbogbo àwọn ará Juda tí wọ́n ṣẹ́kù, tí wọ́n pada wá sí ilẹ̀ Juda láti oríṣìíríṣìí orílẹ̀-èdè tí wọ́n ti sálọ: 
Òfin ọ̀dájú ni àṣọ́bodè ṣe pé epo kò gbọdọ̀ dé ẹnu bodè Nàíjíríà - Ilé aṣojú-ṣòfin Ìjọba Ọyọ yàtọ̀ sí ti Ọṣun àbí Ekiti tí APC leè fi àṣẹ iléẹjọ́ lé dànù - Seyi Makinde Toun ti bi awọn agbagba ẹgbẹ naa ti ṣe gbiyanju lati dẹkun aigbọraẹniye laarin wọn,iṣẹlẹ to ṣẹlẹ yi n ṣafihan pe nnkan ko rọgbọ ni ipinlẹ naa falaga ẹgbẹ APC.
Nitori eyi, nṣe lawọn ileeṣẹ apọnpo gbogbo bẹrẹ si ni ya agba ikeposi kaakiri lati ko awọn apọju epo naa si, eyi lo si fa bi owo epo rọbi ilẹ Gẹẹsi ṣe dẹnukọlẹ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Brazil: Àwọn ọlọ́pàá tí f'òfin mú ẹyẹ tó n tú àṣírí fún àwọn ọ̀daràn 27 Ìgbé 2019 Ẹyẹ ayekootọ kan l'orilẹede Brazil ti wa ni ahamọ ọlọpaa nitori ẹsun pe o maa n ṣe ofofo fun awọn oniṣowo oogun oloro ti awọn ọlọpaa ba ti fẹ wa mu wọn.
Oluwo: Ọọni ran awọn eniyan lati yọmilẹnu
Gege bi amugbalegbe pataki sile-ise aare lori oro ile-igbimo asofin, asofin Ita Enang, o salaye pe ipele keyin ni o ku fun igbimo naa lati sakojo iwa isuna odun 2019 ohun, eleyi ti won yoo lo sagbakale re fun ile-igbimo asofin ti o ba pari.
Eyi ni iroyin ti orilẹede Amẹrika fi sita bi minisita f'ọrọ ilẹ okeere nibẹ, ọgbẹni Rex Tillerson se n gbaradi lati se abẹwo akọkọ rẹ si ilẹ Afirika.
Ninu ifẹsẹwọnsẹ naa to waye lọjọru, ni Atletico ti fakọyọ pẹlu ami ayo mẹta si meji, ti ireti ikọ Liverpool lati raga bo ipo asaaju rẹ ninu idije awọn akọni agbaabọọlu nilẹ Yuroopu, si fori sanpọn.
Oríṣun àwòrán, NDLEA To si tun bẹbẹ fun agbekalẹ awọn eto ilanilọye fawọn ọdọ lati dena mimu oogun oloro ati gbigbe rẹ.
5 owó naira ni ọọfiisi àjọ INEC ni Zamfara
 – Captain @mikel_john_obi #SoarSuperEagles #WorldCup #NGA #NGAISL #Team9jaStrong pic.
Chelsea tún ṣubú dàánù sọ́wọ́ Liverpool Wàhálà bẹ́ sílẹ̀ láàrín àwọn ọ̀dọ́ ní Oke Odo ní ìpínlẹ̀ Eko Mo dáríjì àwọn IPOB tó nà mí ní Germany nítorí wọn o m'ohun tí wọ́n ń ṣe- Ekweremadu Ohun si tun ni akọkọ fun oluksni wọn tuntun, Frank Lampard ni Stamford bridge to jẹ ibuba ikọ Chelsea.
Bakan naa lo fikun pe miliọnu lọna mejidinlọgọfa naira ni oun na fun ile iwosan UCH ninu owo yii.
Kì í ṣe òní, nítorí pé ọmọ ọba ni ó kú.
Àwọn ará Filistia bá àwọn ọmọ Israẹli jagun ní orí òkè Giliboa.
A wí pé, ‘Ṣe é mi, ṣe é mi wàyí ṣá!
Ilé ẹjọ́ fún Elzakzaky àti ìyàwó ní ẹ̀tọ́ sí ètò ìwòsàn Lẹ́yìn òkò ọ̀rọ̀, Buhari àti Ọbasanjọ fẹ̀rín pàdé ara wọn l‘Abuja Day 25: Àwọn àkànlò èdè lásìkò ìdìbò #BBCNigeria2019 Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Obasanjo: Atiku kìí se Áńgẹ́lì, àmọ́ yóò se dáadáa ní ìlọ́po méjì ju Buhari lọ Bayii, ti iroyin yii, jade, A ko tii mọ igbesẹ ti ẹgbẹ oṣiṣẹ fẹ gbe, boya wọn maa gba àbá ijọb apapọ wọle tabi bẹẹ kọ.
N óo fi yín ṣe oúnjẹ fún oniruuru àwọn ẹyẹ ati àwọn ẹranko burúkú.
Ọlọ́pàá Eko ní kí olùkọ́ UNILAG Boniface wá sọ tẹnu rẹ̀ lórí ẹ̀sùn ìfipábánilòpọ̀ Háà, ó ṣe!
O bu ẹnu atẹ lu nkan ti ọpọ eniyan n ro ti wọn si n sọ nipa rẹ.
Ó ní, “Ẹnìkan gbin igi ọ̀pọ̀tọ́ sinu ọgbà rẹ̀.
6 2337966 Orilẹede Iran 51496 63.
Awọn eeyan yii ni wọn ti yege lati kopa ninu eto iranwọ arun Coronavirus ti apapọ owo rẹ to biliọnu marundinlọgọrin naira.
Wọ́n sì sọ fún un wí pé, wọ́n wà ní Naioti ti Rama.
Ni Abuja ẹgbẹrun mẹsan o le ni mẹrinlelọgọrin,9,084 nigba ti Kano yoo si ni aaye fun ẹgbẹrun mẹjọ le ni irinwo eeyan (8400).
Ọpọlọpọ kò tilẹ̀ mọ ìdí rẹ̀ tí wọ́n fi péjọ!
‘Buhari kò bú àwọn ọdọ’ ‘Irọ́ ni pé Ọmọ ọdọ̀ Ọpẹ Bademosi kú’ Sowore: olùdíje Ààrẹ tó fẹ gbà Nàìjíríà padà fún àwọn ọdọ 'Peace Corps, ẹ funmi lowo mi pada' O jẹ aarẹ ajọ CDS ni ilu Eko lọdun 2018 nigba ti o n sinru ilu (NYSC) Oun naa lo jẹ aṣoju ikọ Platoon ẹ lọdun 2017 nigba ti o wa ni ipagọ fun sinsin ilẹ baba rẹ.
2bn fún Obanikoro Apo nla marunlelọgọta la fi gbe owo wa fun Obanikoro nigba naa.
ti ko tona ati anfaani to wa ninu ki a ma gbe ni agbegbe to mọ, o je ko di mimo
Oríkì Amúṣan Amúṣan ògogó, O r'íbà ọrọ̀!
Nitori naa ni Amadi se mu ọkan le wipe ọna abayọ kan ni lati jẹ ki awọn akọsẹmọsẹ obinrin pọ lara awọn to nsakoso awọn ikọ elere ori papa bii ti adari ikọ agbabọọlu obinrin ilu Port Harcourt to jẹ obinrin to si nja fun ẹtọ awọn agbabọọlu rẹ.
Ó kúnlẹ̀ níwájú Jesu, ó bá sọ ìdí tí òun ṣe fọwọ́ kàn án lójú gbogbo eniyan ati bí òun ṣe rí ìwòsàn lẹsẹkẹsẹ.
Ó dá wọn lóhùn pé, ‘Ọ̀tá ni ó ṣe èyí.
Latẹyin wa ni awọn ọmọ Naijiria ti maa n rojọ lori bi aarẹ ṣe maa n rinrinajo kaakiri.
Ìwọ ìlú Temani,ìbẹ̀rùbojo yóo dé bá àwọn akọni rẹ,gbogbo àwọn ọkunrin tí wọ́n wà ní òkè Esau ni a óo sì fi idà pa.
Awọn ọjọgbọn fasiti, ọmọwe ileewe giga gbogbo, awọn onimọ ẹsin islam atawọn oṣiṣẹ ni wọn ti ba ajalu yii lọ.
Olùrànlọ́wọ́ pàtàkì fún ọ̀rọ̀ ibojì òkú, àti àwọn ipò òṣèlú mìíràn tó jẹ́ kàyééfì ní Nàìjíríà Diezani gan an ní Hushmummy tó ń bú àwọn Yahoo boys- Àwọn Ọmọ Naijiria lórí Twitter Nítorí pé mo gba ẹ̀há kò ní kí ń ṣọlẹ̀ tàbí ṣagbe- Ẹ̀lẹ́hàá Amina Èdè Yorùbá dùn lẹ́nu àwọn ọmọ òyìnbó yìí ní Michigan!
"Olórí Ọ̀dọ́ l'Ondo ní oníkálùkù yóò bẹ̀rẹ̀ sí ní jà fúnra wọn Kògbérèégbè mẹ́ta nínú òṣèré Yorùbá Àṣìta ìbọn pa èèyàn kan lásìkò tí SARS ń kojú adigunjalè l'Eko 'Kò sí ǹkan tó jọ tòmátò tó ní májèlé ní Nàìjíríà' "" Òòyà á yà á o"" ni idahun ti ẹni to n ṣe irun maa fi dahun ti wọn ba ki i tan."
Oludari ilé iṣẹ́ tó ń gbógun ti àjàkálẹ̀ ààrùn ní America, Anthony Fauci sọ pé iye ènìyàn tí coronavirus ti pa níbẹ̀ jẹ́ nkan tó n bánilọ́kàn jẹ́, tó sì jẹ́ àwọn àgbàlagbà tó ti ní àìsàn tí wọ́n ń tọ́jú tẹ́lẹ̀.
Bi ko ba ma tako ọkọ rẹ to jẹ aarẹ yoo ma bẹnu atẹ lu awọn amugbalegbe kan to ni wọn ko jẹ ki aarẹ Buhari ṣe ijọba rẹ bo ti ṣe yẹ.
Agbegbe naa ti a ko jẹ ki awọn eniyan gba kọja, ti fa sunkẹrẹ fakẹrẹ ọkọ ni oju ọna naa.
Ṣiṣaki ọba Ijipti gbógun ti Jerusalẹmu pẹlu ẹgbẹfa (1,200) kẹ̀kẹ́ ogun, 
Akọsilẹ to wa lọwọlọwọ bayii fi han pe o ti le lẹgbẹrun lọna ogun eeyan to ti lugbadi arun naa ti o si ti le ni ẹẹdẹgbẹta to ti gba ibẹ ku ni Naijiria.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, SARS ti bẹ̀rẹ̀ ìgbésẹ̀ láti yọ àwọn ọ̀bàyéjẹ́ kúro Orilẹede Naijira ti fofin de didun kooko mọni lori ayelujara ni ọdun 2015 nigba ti aarẹ Buhari buwọ lu abadofin naa.
Bakan naa ni gomina Babajide Sanwo-Olu ti ipinlẹ Eko, Dapọ Abiọdun lati ipinlẹ Ogun, Gboyega Oyetọla ipinlẹ Ọṣun ati Ṣeyi Makinde to jẹ olugbalejo awọn akẹgbẹ rẹ naa sọrọ.
Ni ọjọ Kejila osu Kẹfa ọdun 1993 ti ibo naa waye, ilana gbangba laṣa n ta yii jẹ ki eto ibo naa lọ geerege, ti awọn eeyan si dibo fun oludije to wọn lai fi ti ẹya, ẹsin ati ede ṣe.
Nígbà tí o bá ń gbọ́ ìró ẹsẹ̀ lórí àwọn igi balisamu ni kí o kọlù wọ́n, nítorí pé n óo ṣáájú rẹ lọ láti kọlu ogun Filistini.
O óo máa bá a sọ̀rọ̀, o óo sì fi ọ̀rọ̀ sí i lẹ́nu.
"Ileesẹ ọlọpaa ti n se iwadii nipa oun to fa isẹlẹ naa, ti a ko si lee se alaye awọn ẹgbẹ oselu ti aje ọrọ naa si mọ lori nitori o ti di ija igboro.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Idaamu darandaran: Ganduje pe awọn darandaran si Kano 5 Èrèlè 2018 Oríṣun àwòrán, AFP Àkọlé àwòrán, Ọpọlọpọ awọn olugbe ipinlẹ Kano jẹ Fulani darandaran Gomina Abdullahi Umar Ganduje ti Ipinlẹ Kano sọ pe oun ni ọnọ abayọ fun orilẹede Naijiria ninu idaamu ati ijamba ti o n waye nitori ija laarin awọn darandaran fulani ati awọn agbẹ afoko-sọrọ jadejado orilẹede yi.
, Ọmọ ọdún mẹ́rìnlá kàwé gboye jáde ni fasiti Oxford Ọmọ náà ti kopa nínú àwọn oníruuru ìpáde ti àwọn agbaagba àti ọjọgbọn máa ń peju si.
'Kìí ṣe gbogbo ohun tí dókìtà ni kí n má jẹ torí àìsàn jẹjẹrẹ ni mo tẹ̀lé' Rògbòdìyàn tó bẹ́ sílẹ̀ lórí afárá London jọ ìgbésùnmọ̀mí Ilé ẹjọ lé Ọba Èrúwà kúrò lórí Àpèrè lẹ́yìn ọdun 21 Aàrẹ Trump kọ̀ láti jẹ Tòlótòló ìsìn ìdúpẹ́ 2019 nílé, ó gba Afghanista lọ!
Kii janpata lati ta jita rẹ bo ba n kọrin lọwọ.
Ní ọdún kẹjọ tí ọba Babiloni jọba ni Jehoiakini ọba Juda jọ̀wọ́ ara rẹ̀ sílẹ̀ fún ọba Babiloni, ó sì jọ̀wọ́ ìyá rẹ̀, àwọn iranṣẹ rẹ̀, àwọn ìjòyè rẹ̀ ati àwọn òṣìṣẹ́ ààfin rẹ̀ pẹlu, ọba Babiloni bá kó wọn ní ìgbèkùn.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Iba Gani Adams: Bẹ́ẹ gbé màláíkà kan lọ sí Aso Rock, kò lè ṣàṣeyọrí Ajọ ipese alaafia ninu ajọ Iṣọkan Agbaye, United Nations ti kede pe oun ti gbe igbeṣẹ lati dẹkun iwa ibi yii.
Iṣẹju marun din ni aadọrun ninu ifẹsẹwọnsẹ naa ni Thembinkosi Lorch, agbabọọlu South Africa gba bọọlu sawọn Egypt.
6 - Orísun àkọsílẹ̀ Ri i dájú pé o mọ ibi tí wọ́n ti rí àwọn ònkà tí wọ́n fi sínú ìròyìn nàá.
O lọ tọ ọjọ meji ninu igbọ ko to ri ọna ẹsẹ kan tọ gba lọ sabule kan ti wọn pe nii Bashu nipinlẹ Cross River to wa ni Naijiria, ni ibi to ti ba awọn ẹbi re laarin ọpọ atipo.
Nítorí pé ohun tí ọba bá sọ ni abẹ gé.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 2020: Ọdun 2020 yii ko nìí nira fún àwọn tó bá bẹ̀rù Olorun Bakan náà ni moto ti wọ́n fi ṣe àṣemaṣe naa ti wa ni àhámọ ọlọpàá, Elkana fi kun un pé àwọn yóò gbé àwọn ọdaran náà lọ si ilé ẹjọ laipẹ.
Awọn ọmọbinrin ti wọn n ku iku aitọjọ yii si lo jẹ akẹkọọ, ti ọjọ ọla rere wa fun, to si ṣee ṣe ki wọn gbe ogo Naijiria ga lọjọ ọla.
 ní àtijọ ́ ọdún Ògún ni eré àpíìrì wà fún , ṣùgbọ ́ n níwọ ̀ n ìgbà tí ó jẹ ́ pé yíyí ni ayé ń yi , àwọn òṣèré náà wá ń báyé yí nípa pé kí wọn ṣẹ ̀ dá orin àpíìrì fún onírúurú àṣeyẹ tí a ó mẹ ́ nu bà níwáju .
Neymar ni lati dawọ igbaradi durọ lọjọ aje nigba to fi orokun ṣeṣe bi o tilẹ jẹ pe ko pọ pupọ.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Minista awọn eniyan to wa ṣatipo, ọro omi ati itọju ayika, Lindwe Sisulu Egbẹ oṣelu alatako ni South Africa, Democratic Alliance loṣu kẹwaa, ọdun 2018 di ẹbi iṣẹlẹ yii ru ijọba to n tukọ South Africa nigba naa.
 Ọwọ́ tẹ babaláwo àti adigunjalè márùń ni Imo - Olọpàá Kí ni pàtàkì nọ́mbà 615 láàrín àwọn èèyàn ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ̀ Àwọn mẹ́rin t'íjọba Buhari k'etí ikún s'àṣẹ òmìnira iléẹjọ́ lórí wọn rèé Ilé ẹjọ́ kọ̀ láti tú Omoyele Soworẹ sílẹ̀ Atiku ṣalaye siwaju sii pe ""Awọn oniroyin ko lee sọrọ bo ti tọ ati boti yẹ lai bẹru pe awọn alagbara kan yoo fiya jẹwọn."
Oríṣun àwòrán, Ayaba folashade/instagram Koda, ninu oṣu Kẹsan-an, ọdun 2020, ni wọn kọ ọ ṣori ayelujara Instagram Alaafin fun'ra rẹ pe lẹyin ti iṣẹda yọnda ibẹta fun un gẹgẹ bi akọbi ọmọ, o ti di ọkan lara awọn ayaba ti ẹsẹ wọn mulẹ patapata ninu aafin.
Àwọn òṣìṣẹ́ tẹmpili ati àwọn ọmọ àwọn iranṣẹ Solomoni jẹ́ irinwo ó dín mẹjọ (392).
com/APC Àkọlé àwòrán, APC kò tíì sàlàyé oun to sẹlẹ̀ Arakunrin kan, Justin Sun ni o ti gbàsàkóso ìkànì Twitter ẹgbẹ oselu APC lọ́jọ́ ìsinmi.
Àwọn ọmọ rẹ̀ a máa mu ẹ̀jẹ̀,ibi tí òkú bá sì wà ni idì máa ń wà.
Gbọ́, ìwọ ọmọbinrin, ronú kí o sì tẹ́tí sílẹ̀,gbàgbé àwọn eniyan rẹ ati ilé baba rẹ;
"Oríṣun àwòrán, @Realshisha ""Nnkan akọkọ to yẹ ka mojuto ni pe, a gbọdọ gbagbe ero pe nigba ti eniyan ba wa nijọba, lo n jẹ asoju ẹya abi ẹsin rẹ, ko yẹ ki o ri bẹẹ""."
" Lẹyin naa lo kede pe oun ti yan adari fasiti ẹkọṣẹ iṣẹgun to wa ni ilu Ibadan, Temitope Alonge lati tukọ igbimọ amuṣẹya to n ri si ọrọ arun naa ni ipinlẹ Oyo.
Ó wá jẹ pé òun ni alága lálẹ́ ọjọ́ náà.
odun yii, iyen, CEO Leadership Caegory- Gold, , nipa ise ribi-ribi  ti o se fun idagbasoke  ile-isẹ ati ayipada rere  ti o mu ba ajo to n mojuto oro owo ifeyinti
Agbẹnusọ ileeṣẹ ọlọpaa, Frank Mba lo fi ọrọ yii lede ninu atẹjade wọn pe iṣẹ ti bẹrẹ lori iṣẹlẹ naa.
Nigba to n tako iroyin kan to ni o n gba owo lọwọ awọn oloselu, Oyedepo ni oun ko gba kọbọ ri lọwọ oludije kankan ko to de ipo, ti oun ko si setan lati gba owo lọwọ oloselu kankan.
Oluranlọwọ fun Buhari lori ọrọ ayelujara, Bashir Ahmad lo fi ikede naa sita.
Bẹẹ lawọn eeyan mii naa n sọ pe ko si ẹnikẹni to lẹtọọ lati sọrọ odi si Anọbi.
Boris Johnson ti seleri lati mu UK kuro ninu ajọ isọkan ilẹ Yuroopu nipari osu Kẹwa ọdun yii ni tiku-tiye."
EFCC: Ọwọ́ pálábá àwọn ọmọ China méjì tó fẹ́ fún ọ̀gá EFCC ní àbẹ̀tẹ́lẹ̀ N100m ségi
Ìwo mẹrin wà lára rẹ̀, wọ́n gùn ní igbọnwọ kọ̀ọ̀kan (ìdajì mita kan).
 iye ìṣẹlẹ ̀ líle ti dínkù láti 5.
Nígbà tí ó tó àkókò fún àwọn òbí rẹ̀ láti ṣe àṣà ìwẹ̀mọ́ gẹ́gẹ́ bí òfin Mose, wọ́n gbé ọmọ náà lọ sí Jerusalẹmu láti fi í fún Oluwa.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Community Policing: ìjọba ìbílẹ kọọkan yóò gbà ààdọta òsìsẹ 31 Agẹmo 2019 Oríṣun àwòrán, Policeng Àkọlé àwòrán, Community Policing: ìjọba ìbílẹ kọọkan yóò gbà ààdọta òsìsẹ Gbogbo ijoba ibile merinleniaadorino le ni eedegbeje ni eto naa yoo ti waye.
 Àwọn orílẹ ̀ -èdè míràn ìtòsí rẹ ̀ náà tún ni singapore , philippines , australia , àti ilẹ ̀ agbègbè Índíà andaman and nicobar islands .
Niṣe ni wọn n ju okuta si agọ ọlọpaa.
gẹgẹ bi eyi ti yoo fi ẹmi iṣọkan mulẹ siwaju lorilẹ-ede yii.
" Oladoye salaye siwaju si pe awọn araalu ti oun ba sọrọ gan fidi isẹlẹ naa mulẹ pe lemọ-lemọ ni isẹlẹ ijinigbe maa n waye lagbegbe naa.
Oun funra rẹ naa faragbọgbẹ lasiko iṣẹlẹ nla ibi yii.
Ile ẹjọ naa ni ofin orilẹ-ede Naijiria sọ pe ẹnikẹni to ba fẹ dije sipo Aarẹ gbọdọ kawe, o kere ju, ko lọ sile iwe girama.
O gboriyin fun Gomina Zulum, fun gbogbo akitiyan rẹ lati ri pe awọn ti ogun sọ di alainilelori, pada si ilu abinibi ati isẹ oojọ wọn.
Coronavirus ti mú kí Rábí elépo pupa ó lówó ju Rábí elépo rọ̀bì lọ́ Kí làwọn ìdàmú tí Coronavirus n mú bá àgọ́ ara?
Eyi si lo mu gomina Akeredolu kesi awọn agbofinro lati gbe akọwe ijọba ana naa, ki wọn lee fi ọrọ wa lẹnu wo lati seranwọ ninu iwadi ẹsun mago mago naa.
Ko ti si aridaju boya ẹsọ naa n gba itọju fun ọgbẹ ti o fi ọwọ ara rẹ da tabi eleyi ti wọn da si lara.
Wọ́n wá gbé adití kan tí ń kólòlò wá sí ọ̀dọ̀ rẹ̀, wọ́n bẹ̀ ẹ́ kí ó fi ọwọ́ lé e.
Ojọgbọn Steve Lindsay ti fasiti Durham ni ilẹ̀ United Kingdom, lo ṣe agabtẹru iwadii naa nibi ti wọn ti lo ìbọ̀sẹ̀ àwọn ọmọde mẹta lati orilẹ-ede Gambia.
Èmi ni n óo tọ̀ ọ́ lọ, kò tún lè pada tọ̀ mí wá mọ́.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Iná Ibadan: Gbogbo dúkìá tó wà lókè ilé alájà kan náà ló jóná tán Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Iná Ibadan: Gbogbo dúkìá tó wà lókè ilé alájà kan náà ló jóná tán 18 Òkùdu 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 19 Òkùdu 2019 Lasiko ti wọn n ba BBC Yoruba sọrọ, awọn olugbe inu ile naa rawọ ẹbẹ si awọn ẹlẹyinju aanu ọmọ ilẹ yii lati se iranwọ fun wọn, lori awọn dukia wọn to jona mọle.
Bi awọn ipinlẹ to ni Coronavirus ṣe lọ ree: Eko-82 Plateau-82 Oyo-19 FCT-18 Edo-16 Kaduna-15 Enugu-9 Ogun-9 Kano-8 Kwara-8 Cross River-5 Ondo-5 Rivers-5 Ekiti-4 Imo-3 Borno-2 NCDC kéde èèyàn 437 míràn tó ṣẹ̀ṣẹ̀ lùgbàdì Covid-19 ní Nàìjíríà Ajọ to n gbogun ti ajakalẹ arun lorilẹede Naijiria, NCDC ti kede pe eeyan irinwo le ni mẹtadinlogoji miran ti lugbadi arun Covid-19 ni Naijiria.
Wòlíì náà ti fi ìlọ́ra fi ààyè sílẹ̀ kí àwọn ojú ewé ìwé náà kúrò ní ìpamọ́ rẹ̀ bọ́ sí ọ̀dọ̀ Martin Harris, ẹnití ó ti ṣiṣẹ́ fún ìgbà díẹ̀ bíi akọ̀wé nínú iṣẹ́ ìtumọ̀ Ìwé ti Mọ́mọ́nì.
Ọlọrun pàṣẹ pé kí àwọn ìmọ́lẹ̀ wà ní ojú ọ̀run, láti fi ààlà sí ààrin ọ̀sán ati òru, kí wọ́n wà láti jẹ́ àmì, ati láti máa fi àkókò àjọ̀dún, ọjọ́, ati ọdún hàn, 
nile igbimo asofin , niluu Abuja  lati mu
ìṣẹ ọwọ awọn baba nla wa bii ẹmu dida, irun didi, apẹja, ọdẹ ṣiṣe, irin rirọ ati bẹẹ bẹẹ lọ ni wọn fi n ri owo Oríṣun àwòrán, @Jeromi Àkọlé àwòrán, Iyan lounjẹ, ọka loogun, airi rara la n jẹkọ, ki ẹnu ma dilẹ ni ti guguru ni igbagbọ awọn Yoruba.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Shiite: Ẹ̀mí àti ara wa kọ ohun tí ìjọba ń ṣe sìwa láti 2015 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Lionel Messi: ''Kò sí ohun to lè mú Messi dúró sí Barcelona mọ́'' 26 Ògún 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 1 Owewe 2020 Oríṣun àwòrán, Getty Images Bi gbogbo nnkan ti n lọ yii, afaimọ ki agbaọjẹ agbabọọlu Barcelona, Lionel Messi ma fi ikọ agbabọọlu naa silẹ ni kopẹ kopẹ.
Gbà mí lọ́wọ́ ìnilára àwọn eniyan,kí n lè máa tẹ̀lé ìlànà rẹ.
Má wulẹ̀ yọ olùkọ́ni lẹ́nu mọ́.
com/yoruba/46176740 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Bí ó bá jẹ́ ẹran tí kò mọ́, kí ó san owó rẹ̀ pada gẹ́gẹ́ bí iye tí ẹ bá dá lé e, kí ó sì fi ìdámárùn-ún owó náà lé e.
Ajọ FA pe Guardiola lẹjọ lori mimu oṣelu wọ bọọlu Roberto Carlos ẹlẹsẹ idan Mourinho sọ wipe: O n kọ bi yoo se gba bọọlu pẹlu wa, awa naa si n gbiyanju lati ri anfani to tọ lati ara rẹ."
O pọ to bẹẹ ti wọn fi ni lati gbe ọkọ oju omi si aarin adugbo lati maa gbe awọn ara ilu kakakiri.
Ko si kankan ninu wọn ti wọn ri aga yẹ nidi rẹ kuro nipo.
Nigba ti BBC Yoruba kan si ile iwe naa, ọga agba ile iwe to gbe ẹrọ ibanisọrọ kọ lati fọhun lori ọrọ naa ṣugbọn olukọ mii ti ko darukọ rẹ fidi rẹ mulẹ pe iṣẹlẹ naa ṣẹ ṣugbọn kii ṣe ile iwe awọn ni Favour ti dakẹ.
’’Lori oro eto aabo, minisita wa ro  awọn  gomina lati mojuto eto ijọba rere , ki won si  dekun lati maa fesun kan ijọba apapo tabi ajo eleto aabo.
Nígbà tí bàbá mi dé ọ̀dọ̀ obìnrin náà ó kí ii, àláàfáì kọ́ ni ilée wà bi, ara kò le bí, ṣe kò sí ǹkan?
Nígbà tí ẹ bá mú ẹran tí ó fọ́jú, tabi ẹran tí ó múkùn-ún, tabi ẹran tí ń ṣàìsàn wá rúbọ sí mi, ǹjẹ́ kò burú?
Elizabeth Ọmọwunmi Tekovi Da-Silva ni apetan orukọ rẹ, amọ ilu Eko ti wọn bi si lo ṣe iranlọwọ fun lati maa fi ede Yoruba jẹun.
Ko ye mi ọna ti maa gbe gba, to si n ka mi lara pe n ko lee mu irora kuro lara ọmọ mi.
Ó da ẹ̀jẹ̀ yòókù sídìí pẹpẹ fún ètùtù, bẹ́ẹ̀ ni ó ṣe yà wọ́n sí mímọ́.
Olórí ẹ̀sìn náà kò yọjú sí ilé ẹjọ July 31, 2019 Àwwọn IMN so àdàgbá ìwóde wọn rọ̀ láti wọ́ ojútu míràn sí ẹ̀dùn ọkan wọ́n àti láti gbé ìjọba àpapọ lọ sí ilé ẹjọ́ fún pípè wọ́n ni ẹgbẹ́ agbésùmọmí.
Ojo kẹfa, oṣu kẹsan an, ọdun 2019 ni Robert Mugabe gbẹmi mi lẹni ọdun marundinlọgọrun un.
Nítorí náà àwọn náà óo ṣubúnígbà tí àwọn yòókù bá ṣubú,a óo bì wọ́n ṣubúnígbà tí mo bá ń jẹ wọ́n níyà,OLUWA ló sọ bẹ́ẹ̀.
Awọn ti ilana tuntun naa kan ni ṣọọṣi, mọṣalaaṣi, gbọngan ayẹyẹ, ile itaja igbalode nla, gbọngan sinima, ati awọn ibi igbafẹ.
O ni lọwọ bayi, alafiaa ti pada si ilu Ogbomosho.
Nígbà tí ìyá mi lọ tán tí mo gbé àkàrà mi tí mo jáde kúrò ní ìpàlàpálá òkúta nì, bí mo ti jáde tán ni mo rí ọkùnrin tí ó wọ aṣọ funfun tí mo kọ́ ri kí n tóó’wọ inú òkúta lọ.
Ọpọ lo ti tako awọn aṣofin laarin ọdun to kọ ja ti wọn ti n ṣofin ni olu ilu Naijiria, Abuja.
Lọdọ awọn akẹgbẹ rẹ akẹkọọ lo ti ri alajẹ orukọ to n jẹ, nigba naa lọhun o ṣi jẹ bii ọmọ ọdun mẹsan an pere.
Okeowo fidi rẹ mulẹ fun BBC Yoruba wi pe lọjọ Aiku ni igbakeji Gomina Ondo kọwe fipo silẹ gẹgẹ ọmọ ẹgbẹ osẹlu APC.
Lọti bá gbójú sókè, ó wo gbogbo agbègbè odò Jọdani títí dé Soari, ó rí i pé gbogbo koríko ibẹ̀ ni wọ́n tutù dáradára tí ó dàbí ọgbà OLUWA ati bí ilẹ̀ Ijipti.
Ahmed sọ pe awọn ẹlẹwọn okoolenigba ati mẹjọ lo wa ni ọgba naa nigba ti ẹkun omi naa ya wọ ibẹ.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Aregbesola: mí ò gba owó oṣù gómìnà rí Ọ̀gbìn ìrẹsì dìrọ̀rùn, ìjọba àpapọ̀ yóò yá àgbẹ lówó Àmàlà ṣekúpa ènìyàn mẹ́rin ní Ilorin Ayefẹlẹ bá BBC sọ̀rọ̀ lórí ilé orin rẹ̀ tí Ajimọbí ń tún kọ́ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ìfipábánilòpọ̀: Abiamọ bú sẹ́kún nígbà tí ọkùnrin kan fi tipá bá ọmọ méjì lòpọ̀ O ni, bi oun se moke ninu atundi ibo naa jẹ aseyori to n bọ lọpọ fawọn eeyan ipinlẹ naa.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ìrìnna ọkọ́ òfúrufú s'ílẹ̀ òkèèrè bẹ̀rẹ̀ padà ní Nàìjíríà Jegede (PDP) ti yan Aṣojúṣòfin Ikengboju gẹ́gẹ́ bí ìgbákejì rẹ̀ tí wọ́n yóò jọ díje dupò DPO ọlọ́pàá fi ọmọ odó lu èèyàn méjì pa, ó ṣe ẹnìkan lééṣe lágọ̀ọ́ ọlọ́pàá Àwọn afẹ̀hónúhàn bọ́ra sí ìhòhò lórí pápá lòdì sí sísọ eré bọ́ọ̀lù di jẹunjẹun Wo ìyàtọ̀ ńlá tó wà láàrin Oṣó, Àjẹ́ àti Emèrè Ofin naa sọ pe, awọn ile ijọsin lẹyin iforukọ silẹ pẹlu CAC ati ile isẹ to wa fun amojuto rẹ, ni ijọba maa ṣe akoso wọn.
Bakan naa ni ìjọba Nàìjíríà ti kéde ìsinmi lọ́jọ́ Ìṣẹ́gun àti Ọjọ́rú ọjọ karun oṣu kẹfa gẹgẹ bii ọjọ isinmi lẹnu iṣẹ lati ṣajọyọ itunu awẹ Ramadan lorilẹede Naijiria.
O si pari rẹ si Ondo Boys High School laarin ọdun 1942 si 1944 Lẹyin eyi lo dara pọ mọ ileesẹ ologun RWAFF lẹni ọdun mejidinlogun, to si bawọn ja ogun agbaye keji Bakan naa lo sisẹ bii akọwe nileesẹ ifiweransẹ Post Office lẹyin ogun agbaye keji, to si tun di aarẹ fun ẹgbẹ awọn ajagunfẹyinti lọdun 1948 Oun yii naa si tun ni aarẹ ẹgbẹ awọn akọwe nile ifiweransẹ lọdun 1952.
Ìwọ tí mo mú wá láti òpin ayé,tí mo pè láti ìkangun ayé tí ó jìnnà jùlọ,mo wí fún ọ pé, ‘Iranṣẹ mi ni ọ́,mo ti yàn ọ́, n kò ní ta ọ́ nù.
Mo dàbí odi,mo sì fi ìgbà gbogbo dákú.
Anatomy Book: Ọjọgbọn nílé ìwòsàn UCH àti UI gbé ìwé orúkọ ẹ̀yà ara lédè Yorùbá jáde
Oríṣun àwòrán, @DailyPostNGR Ekiti Ni ti ipinlẹ Ekiti, iṣẹ igbimọ naa ni lati gbọ ẹdun ọkan awọn eeyan ilu lori iwa ipa awọn ọlọpaa si awọn ara ilu.
Wo ìjìyà tó wà fún àwọn ọmọ Naijiria tí kò bá fi nọ́mbà NIN kún ìforúkọsílẹ̀ Siimu wọn láàrin ọ̀sẹ̀ méjì Ìjọba ìpínlẹ̀ Kano pàṣẹ pé kí gbogbo ilé ẹ̀kọ́ ètò ìlera di títì pa Mínísítà dèrò àgọ́ ọlọ́pàá nítorí ẹ̀sùn kíkó owó ìrànwọ́ Covid-19 sápò Ṣé lóòtọ́ ni pé Aisha Buhari ti kó lọ sí Dubai?
won,ni eyi ti o waye niluu Abuja, o fi kun  oro re pe igbimo gomina yoo se ise papo pelu
 Èyí tí ó wà láàyè si wá ́ n sunkún ṣá .
8 wọlé lójúmọ́ lẹ́yìn tíjọba ti ẹnu bodè -Ali Ìjọba ní ọmọ Naijiria yóò padà sí ní san owó ‘tollgate' Ọmọkùnrin kan sin Baba rẹ̀ láàyè torì pé ó gbàgbọ́ pé oṣó ni!
Eyi mu jẹ ọkan lara awọn obinrin aṣofin tọjọ ori wọn kere julọ.
Ikọlu darandaran: Fayọṣe ṣe abẹwo si Ortom ni Benue
" Ibùdó ìyàsọ́tọ̀ ni mo wà, ló fi pẹ́ kí ń tó sọ̀rọ̀ lórí tírélà tó já l‘Eko - Omotola Jalade Ekeinde Agbára Oṣó àti Àjẹ́ yóò mú àgbéga bá ìmọ̀ ẹ̀rọ Nàíjíríà - Elebuibon Ìdẹra dé fún Nàíjíríà!
Ṣugbọn à ń ṣe jẹ́jẹ́ láàrin yín, àní gẹ́gẹ́ bí obinrin alágbàtọ́ tíí ṣe ìtọ́jú àwọn ọmọ tí ó ń tọ́jú.
 wọ ́ n ṣe àfihàn cupid níbi tí ó ti ń gbìyànjú lati má jẹ ́ kí ajá yìí dẹgbó nítorí pé venus ti sàsọtẹ ́ lẹ ̀ wípé adonis ma ́ a kú ní àkókò ọdẹ .
Lakọkọ, lọjọ Ẹti la gbọ pe wọn ti ni ki gomina Ekiti, Kayode Fayemi lọ rọọkun nile.
Àwọn ọmọ ogun Israẹli pàgọ́ sí Ebeneseri, àwọn ọmọ ogun Filistini sì pa tiwọn sí Afeki.
Mo wá sọ fún àwọn agbo ẹran náà pé, “N kò ní ṣe olùṣọ́ yín mọ́.
Nítorí ẹ óo níláti jáde kúrò ninu ayé tí ẹ kò bá bá irú àwọn wọnyi lò.
Oríṣun àwòrán, Twitter/seyi makinde Alaga ajọ alaabo nipinlẹ Ọyọ, Oyo State Security Network ti ọpọ mọ si Amọtẹkun, Ọgagunfẹyinti, Ajibọla Toogun ti alaye awọn ohun ti awọn oṣiṣẹ amọtẹkun ko ni ṣe .
Gbajugbaja agbabọọlu Barcelona to jẹ ọmọ Argentina lo sọ fun akọnimọọgba Brazil, Tite pe ko yee sọrọ mọ ninu ifẹsẹwọnsẹ ọlọrẹẹsọrẹẹ to waye laarin orilẹ-ede mejeeji lorilẹ-ede Saudi Arabia lọjọ Ẹti.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Àjọ̀dún ìlù bẹ̀rẹ̀ nílú Abẹ́òkúta Ọbabìnrin fẹ́ k’àrẹ̀mọ gbasẹ Commonwealth Ọ̀nà àbáyọ dé fún àìsàn ibà Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
ayewo iye awon omo ti o kuro nile-iwe, a o ri i pe adinku ti de ba won.
O ya ẹ fi ami ohun ọrọ si ori 'aifagbafẹnikan' Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: 'Ìjà fún ìdájọ́ òdodo lórí ìyá mi tí wọ́n ṣekú pa' Irọ́ ni ò,ọwọ́ wà kò tí tẹ afurasí to jí olórí ìlú Buhari gbé Thai king: Ọ̀nà wo ní ẹ̀ṣọ́ ọba gbà di olorì láàfin?
O ni awọn oniṣẹ ibi kan n ja ṣọọbu ile itaja awọn eniyan ti wọn si n ji ọja wọn ko lọ ti wọn si n jo awọn ile itaja miran ni ina.
Iroyin sọ pe lasiko ti ọba naa nn pada si ilu rẹ, lẹyin ipade awọn lọba-lsba to lọ fun nilu Akure, ni awọn ajinigbe naa kọlu.
Bẹ́ẹ̀ ni o wà láàrin wa, OLUWA,a sì ń fi orúkọ rẹ pè wá,má fi wá sílẹ̀.
“Ṣebí ìkógun ni wọ́n ń wá, tí wọ́n sì ń pín?
Lẹyin o rẹyin, ẹlẹha ri ẹgbẹrun lọna ọgbọn naira gba pada ninu owo rẹ lọwọ arabinrin ọhun ki wọn to fi silẹ ko maa lọ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Alao Akala:Èmi àti Ajimọbi kò ṣe ìlérí kankan fún ara wa Ijọba ti pasẹ ki wọn si Daily Trust Lẹyin awuye wuye to ṣẹlẹ lori bi ileeṣe Ologun Naijiria ṣe ti ile iṣẹ iwe iroyin Daily Trust pa ni ìjọba Naijiria paṣẹ fawọn ọmọ ogun lati ṣi Daily Trust padà.
Orile ede Ethiopia ti ko  tele lati maa gba ipe alaafia ti Eritrea  koko pe, paapaa julo nipa awon ibi ti ede ayede ti maa n waye ni Badme, ti Ethiopia n se akoso re.
Ìròyìn dé etí ìjọ tí ó wà ní Jerusalẹmu nípa wọn.
Ọdún tí Abrahamu gbé láyé jẹ́ aadọsan-an ọdún ó lé marun-un (175), 
Ṣugbọn di ẹni tí o fúnra rẹ yàn mú,àní, ọmọ eniyan, tí o fúnra rẹ sọ di alágbára.
Bí eniyan ti wù kí ó ní owó tó, kò gbọdọ̀ san ju ìdajì ṣekeli kan lọ; bí ó sì ti wù kí eniyan tòṣì tó, kò gbọdọ̀ san dín ní ìdajì ṣekeli kan, nígbà tí ẹ bá ń san ọrẹ OLUWA fún ìràpadà ẹ̀mí yín.
Jesu bá sọ fún wọn pé, “Ẹ mú idà ati kùmọ̀ lọ́wọ́ láti wá mú mi bí ẹni pé ẹ̀ ń bọ̀ wá mú ọlọ́ṣà?
ebenezer obey jẹ ́ olórin jùjú láti orílẹ ̀ -èdè nàìjíríà .
Bode George sọ̀rọ̀ sókè lórí àwọn tó faragbọta lásìkò ìwọ́de EndSARS ní Lekki
E lé yìí ni ìyàtọ̀ láàárín àsikò tí ara wọn fẹ́ jí àti àsìkò tí agogo ara wọn sùn.
Ajọ WHO naa wa rọ awọn obi lati ma a fun awọn ọmọ wọn ni abẹrẹ ajẹsara ti o ba yẹ nigba kugba, ki o ba le dena aarun ati iku ọmọde lorilẹ-ede Naijiria.
OLUWA ní, “Ẹ yipada sí mi tọkàntọkàn nisinsinyii,pẹlu ààwẹ̀, ẹkún ati ìkẹ́dùn,
Ninu ọrọ tiẹ, Minisita fọrọ osisẹ, Dokita Chris Ngige salaye pe, oun to mumu julọ laya aarẹ Muhammadu Buhari bayii ni sisan owo osu tuntun fawọn osisẹ ilẹ yii.
Odọmọde adẹrin pa òṣónú lori ayelujara Instagram ni BBC Yoruba gbalejo ẹ.
Ọlọrun gba ìsìn wọn, ó sì fún wọn ní alaafia ní gbogbo ọ̀nà.
”Gege bi igbimo to n ri si esin musulumi lorile-ede South Africa se so,“O je ohun iyalenu fun wa pupo, awon eniyan meji ti o padanu emi won ohun ni won gbadura I’tikaaf lowo ki won o to je olorun nipe.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Ìdí miran tun ni bọọlu gbigba l'agbaye ati bi eniyan ṣe pọ to laye.
Amọṣa ọrọ ba ibomiran yọ nigba ti arabinrin naa gbiyanju lati beere ibi ti ileeṣẹ ijọba ibilẹ naa wa lọwọ arakunrin kan ti o pada wa mọ oruks rẹ si Ọgbẹni Peter.
Ti Lisa ba wole sipo aṣofin to n du lọwọ, yoo jẹ igba kẹrin ti o ṣoju awọn eeyan rẹ lati ọdun 2007 to ti bẹrẹ.
2 mílíọ́nù owó ìtanràn Àjẹ́ àti Aṣẹ́wó ní ìyá Rainbow - Òjòpagogo Tola Oyediran ọmọ Obafemi Awolowo ti jáde láyé ''Ọpọ lo ro pe a ti dakẹ ju lọri ọrọ to wa nilẹ wi pe igbesẹ ijọba kudiẹ kaato.
Ogun si wà láàrin Abijah ati Jeroboamu.
Ijọba ti kọ kede pe wọn yoo san owo ajẹmọnu awọn oṣiṣẹ fẹhinti naa ninu ọdun yii, amọ ti wọn ko ti i ri i gba titi di asiko yii Ṣaaju ni ijọba Naijiria ṣe ikojade ileeṣẹ ọkọ ofurufu tuntun l'Ọjsru l'orilẹede England, lati fi rọpo meji to ti wa nigba kan ri, Nigeria Airways ati Air Nigeria .
Awọn ìlú ilẹ̀ Yoruba kun fun itan ati ẹkọ loriṣiirisi.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Seyi Makinde: Àwọn jàǹdùkú Mali ń gba Saki wọlé àmọ́ Amotekun kápá wọn 29 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Oríṣun àwòrán, Abdulmumin Rabiu Gomina Seyi Makinde, ti ipinlẹ Oyo ti kede pe awọn agbesunmọmi ti n gba agbegbe Oke Ogun nipinlẹ naa wọ ẹkun Iwọ Oorun Guusu Naijiria.
Ojú yóo tì wọ́n lọpọlọpọ nítorí wọn kò ní lè borí mi.
Wọn ni lasiko ti awọn ara Yuroopu rirnirnajo wa si America wa bẹrẹ igbe aye ọtun 1621.
""owó ríbi ríbi sí ni mo n san láti fi èpo sínú wọn Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!"
Lagos-Ibadan Rail: Amaechi ní ojú irin Ìjú Àgbàdo gbọdọ̀ se rìn láìpẹ́
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Buns ni ọmọ mi jẹ tán ní ṣọ́ọ̀ṣì, ló bá di àwátì' Gbogbo bo ṣe ṣẹlẹ yii lawọn ti o ṣoju wọn koro ko iroyin ro fun awọn akọroyin nipa ohun to ti n ṣẹlẹ ninu ile pasitọ yii ati iyawo rẹ.
Nígbà tí Simoni Peteru tí ó tẹ̀lé e dé, ó wọ inú ibojì lọ tààrà.
 Ọna kan ṣoṣo ti ẹ fi le ni ilọsiwaju ni aye ni lati jẹ aṣoju rere fun orilẹ-ede pẹlu iwa rere yin”Agbẹnusọ naa sọ siwaju pe o ṣe pataki ki awọn obi mojuto awọn ọmọ, ki wọn le tete ṣakiyesi awọn iwakiwa ti wọn ba fẹ hu, ki wọn si le tete gba a lọwọ wọn, ‘nitori ati kekere ni wọn ti n pẹka iroko, bo ba dagba tan, ẹbọ nii gba.
Láti 462 sí 386, àwọn tó ní àrùn Covid-19 já wálẹ̀ ní Nàìjíríà lọ́jọ́ Àbámẹ́ta Dúkìá àti ọjà jóná ráúráú lásìkò tí iná sọ ní ọjà Mushin ní Eko Kí ló mú Olorì Badrat Ajoke kúrò ní ààfin Oyo lọ́jọ́ Iléyá?
Ìjàmbá bàálù gba ọ̀pọ̀ ẹ̀mi ní Cuba 'Awakọ̀ bàálù Ethiopia Airline tó já kò jẹ̀bi' Ìdí tí ilé fi wó lu ènìyàn méjì ní Oshodi -LASEMA Èyí ẹ ṣe tó, England àti VAR júwe ilé fún Cameroon Tiffani sọrọ lori iriri rẹ to ba ni lẹru pe niṣe ni aya oun ja bi oun ṣe ji ti gbogbo ẹ dudu.
Oríṣun àwòrán, @MBuhari Sugbọn niwọn igba to se pe isọrọ ni igbesi, idi ree ti olugbanimọran fun aarẹ lori eto iroyin, Femi Adesina fi bọ sita lati sọrọ nipa iroyin to n ja rainrain nilẹ naa.
Nisinsinyii, jọ̀wọ́ Ọlọrun Israẹli, mú ọ̀rọ̀ rẹ tí o sọ fún Dafidi, iranṣẹ rẹ ṣẹ.
Aṣòfin Nàìjíríà tó jẹ́ ọmọ orílẹ̀èdè méjì jáwé olúborí nílé ẹjọ́ Òtítọ́ inú òfin ilẹ̀ Nàìjíríà nípa asòfin tó bá jẹ́ ọmọ orílẹ̀èdè méjì?
wọ́n lo owó náà fún ilẹ̀ amọ̀kòkò, gẹ́gẹ́ bí Oluwa ti pàṣẹ fún mi.
O fi kúun pe oun ko ni ero kankan lori ìfẹ̀yìntì oun ki o to di ìgbà náà.
aba iṣuna owo yii niwaju Ile Igbimọ Aṣofin yii, ko ti i si eto iṣuna-owo kankan
Nítorí pé kì í kàn déédé ni eniyan láratabi kí ó mú ìbànújẹ́ dé bá eniyan láìní ìdí.
Ẹ óo ké pè mí nígbà náà,n óo sì da yín lóhùn.
Ni ìjọ eniyan bá ranṣẹ sí àwọn ará Bẹnjamini tí wọ́n wà níbi àpáta Rimoni, pé ìjà ti parí, alaafia sì ti dé.
" Ìyàwó mi ló ṣì ń dáná, bu oúnjẹ mi, gé èékáná fún mi - Pásítọ̀ Adeboye Pasitọ ijọ Redeem tun ti m'oke patapata lara awọn ti wọn n ka atẹjade wọn ju lori ayelujara.
Ẹ wo àgbẹ̀ tí ó ń retí èso tí ó dára ninu oko, ó níláti mú sùúrù fún òjò àkọ́rọ̀ ati òjò àrọ̀kẹ́yìn.
Building Collapse: Iléèwé míràn tún dàwó ní ìpínlẹ̀ Eko Yatọ̀ sí pé ó ṣe sọ́jà, tó tún jẹ́ ọkọ Oriṣabunmi, wo àwọn nkan tí o kò mọ̀ nípa Jimoh Aliu Lẹ́yìn olóògbé Barrister àti Kollington, èmi làgbà kàn nínú iṣẹ́ orin Fuji- Obesere yarí Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Ọ̀nà àtijẹ kan ṣoṣo táa ní ni Màálù àwọn Fúlàní ti bàjẹ́' Ní kété ti eyí balẹ̀ ló tún ju fọ́nran ibi ti òun pẹ̀lú ìyàwó ọlẹ̀lẹ̀ ti ń fẹsẹ rajo.
Oríṣun àwòrán, @followlasema Àkọlé àwòrán, O ni iṣẹlẹ omiyale to n waye lawọn agbegbe kan nilu Eko ko ṣẹyin bi awọn eeyan ṣe ma n da idọti sinu gọta Bello tun sọ pe ki awọn eeyan ma mura silẹ fun ṣiṣi daamu ọhun, nibi ti wọn yoo ti ṣi omi silẹ ni Oṣu Keje, Oṣu Kẹjọ, Oṣu Kẹsan an ati Oṣu Kẹwaa, ọdun 2020.
A seto idanilekoo yii lai fi rogunsawon obinrin lapa ati lati satileyin fun erongba Aare Buhari fun idagbasoke awujo ki ise le dinku laarin awon obinrin wa”.
Idi ni wipe agbẹjọro Sotitobi rẹ ke pe adajọ pe ko sun igbẹjọ naa siwaju eyi to ti waye lọpọlọpọ igba tawọn eeyan si ti n reti idajọ ikẹyin' Ni adajọ ba ni lai lai, oun ko ni sun ẹjọ siwaju mọ.
    Nígbà tí mo dé ilé tií a wọ̀ si ni ìlú náà mo ròyìn fún àwọn ọ̀rẹ́ mi.
O fẹrẹẹ to eeyan ẹgbẹrun mọkanlelogun to ti ku bayii ti awọn aadọrinlelẹgbẹta si ti ti ri iwosan gba.
ti o n ṣagbeyẹwo abadofin naa, Aṣofin Agunbiade, so pe abala mọkanlelọgbọn
Gbogbo ẹbọ tí ọmọ aráyé n rú sí Èṣù ní ìkoríta wọ̀n-ọnnì, èyí tí wọ́n ba rú lójóojúmọ́ a wà ní etí ọ̀nà ilé Èṣù lọ, ìgbà tí Èṣù àti àwọn ọmọ ogun rẹ̀ bá sì fi máa jẹ ti ọjọ́ kan tán, ọmọ aráyé á ti pèsè ti ọjọ́ kejì sílẹ̀, nítorí èyí, àpáàdì pẹ̀lú egungun ẹran a dàbi okiti ọ̀gán sí apá ọtun àti apá òsì ọ̀nà lọ, nítorí ọjọ ti pẹ́ tí àwọn ọmọ aráyé ti ń ṣe wọ̀nyí àpáàdì pọ̀ tó bẹ́ẹ̀ tí ó jẹ́ pé nígbà mìíràn tí ènìyàn bá wo tó apá ọ̀tún a rí egungun àti àpáàdì lọ ni ogunlọ́gọ̀ mẹ́ẹ̀lì, bí ó tún wo òsì a ri i bákan náà lọ.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Oluwo gba Aláàfin nímọ̀ràn pé kí olorì máa dé adé Ọọni kọ́lé fàwọn ọmọ òrukàn ní Ibadan Gẹ́gẹ́ bí àṣà Yorùbá, àti bí olùgbani nímọ̀ràn Ọba lórí ìròyìn ṣe sọ ọ́, gbogbo ètò tó yẹ sáàjú mímú olórì tuntun wọ ààfin ni wọ́n ti ṣe.
Ẹni to bori: Morocco Nigeria vs Egypt.
Bákan náà ni ó ṣe sí ọpọ́n orí òpó keji.
Ero ọkan mi ni pe ti wọn ba gbe, wọn o ni le mọ pe emi ni mo ju ọmọ sibẹ.
Awọn alatako Trump ni, niṣe lo n dun mọhurumọhuru mọ ileeṣẹ aarẹ Ukraine ki wọn ba le ba ṣe akoba alatako rẹ ninu ẹgbẹ Democrat, Joe Biden Oríṣun àwòrán, Teresa Kroeger/Getty Images Àkọlé àwòrán, Hunter Biden n wo Baba rẹ Joe Biden, nibi to ti n ba awọn eeyan sọrọ layẹyẹ kan lọdun 2016 Ẹwẹ, ọgbẹni Trump ati awọn alatilẹyin rẹ naa n naka abuku si Biden to figba kan jẹ igbakeji aarẹ, pe o lo ipo rẹ lọna aitọ ki Ukraine ma ba ṣe iwaadi to le tu asiri pe ọmọ rẹ Hunter, ṣe aṣemaṣe.
Bẹẹ ba gbagbe, lati oṣù kẹta ọdun 2020 nijọba apapọ ti ti afara Eko pa lati ṣe atunse rẹ ko to dẹnu kọlẹ.
Kọmisọna ọlọpàá ìpínlẹ̀ Eko Zubairu Muazu náà ṣe àbẹwo si ilé ọlọogbe to si fi dáwọn lóju pé ẹlẹ́sẹ̀ kan ò ni lọ láìjìyà.
Awọn to ba BBC Yoruba sọrọ ṣe afihan dukia ati ohun ini wọn to ṣofo ni ọdun 2019 lasiko ti wọn ṣi daamu naa.
Ní ayé àtijọ́ kí ẹ̀sin Kìrìstẹ́nì tó dé’lẹ̀ yìí, àwọn náà ní ẹ̀sìn ìbílẹ̀ tiwọn.
Má bẹ̀rù nítorí ojú kò ní tì ọ́,má sì dààmú, nítorí a kì yóo dójú tì ọ́,nítorí o óo gbàgbé ìtìjú ìgbà èwe rẹ,o kò sì ní ranti ẹ̀sín ìgbà tí o jẹ́ opó mọ́.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Brazil Yoruba: A n gbé àwọn ère Yorùbá káàkiri- Ọọni ti Ilé Ifẹ Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Pásítọ̀ pe Naira Marley ní ẹlẹ́mìí èṣù, Marley fèsì padà pé kí pásítọ̀ gan tẹ èṣù mọ́lẹ̀ Ẹ́ gba fóónù, ẹ pe ẹbí yín pé a fẹ́ dáná ṣun yín - Aráàlú sọ fún adigunjalè méji N kìí gbádùn ara mi tí ń kò bá jà lọ́jọ́ kan- Ango Argungun Díẹ̀ lára àwọn ìṣẹ̀lẹ̀ tí yóò mi ìgboro tìtì l'ọ́dún 2020 rèé Ó ti di ogójì èèyàn tí wọ́n tẹ̀ pa níbi ìsìnkú Qasem Soleimani tí kò wáyé mọ́ Amọ Naijiria ti ori rẹ ba pe, to ba si ti ba aarẹ Muhammadu Buhari sisẹ ri yoo mọ pe kii se ẹni to lee ti ọwọ bọ ofin ilẹ wa Naijiria.
Nígbà tí Jobabu kú, Huṣamu, ará ìlú kan ní agbègbè Temani, jọba tẹ̀lé e.
Ọṣun; Àwọn aláìsàn ojú ké sí ìjọba láti ràn wọ́n lọ́wọ́
Ṣùgbọ́n àwọn ẹja kò lè wá, nítorí omi jìnnà sí ojú ìjà náà, bẹ́ẹ̀ ni ẹja tí ó bá kúrò nínú odò, eléyìínì múra ọ̀run alákejì.
Ikọ Chelsea fẹ ki Hazard bọwọ lu iwe adehun tuntun ki o to di pe adehun to wa laarin wọn yii yoo tan lọdun to n bọ.
Oríṣun àwòrán, others ''Ki a ṣe apero ju bẹẹ lọ, ko le dẹkun awọn aiṣedeede to wa ninu iwe ofin Naijiria.
Olódodo mọ ohun tí ó dára láti sọ,ṣugbọn ti eniyan burúkú kò ju ọ̀rọ̀ ẹ̀tàn lọ.
Ó kú, wọ́n sì sin ín sinu ibojì àwọn ọba ní ìlú Dafidi, Jotamu, ọmọ rẹ̀, sì jọba lẹ́yìn rẹ̀.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ọlọ́pàá Ondo: A ti da ọtẹlẹ̀múyẹ́ síta láti ṣe àwári Fagoriola.
Rita Chikwelu ló gbá góòlù ìkanyìn sí àwọ̀n Equatorial Guinea ní ìṣẹ́jú mẹ́tàlélọ́gọ́ta sí ìgbà tí wọ́n bẹ̀rẹ̀ eré.
Àkọlé àwòrán, Wọ́n sọ ilé oújẹ náà ní Sabo Nanono, orúkọ mínísítà ètò ọ̀gbìn, wọ́n sì ''n ta oújẹ ọgbọ̀ náírà níbẹ̀ Àkọlé àwòrán, Àwọn tí wọ́n dá ilé oúńjẹ náà sílẹ̀ sọ àwọn ti ń jẹ èrè lẹ́yìn tí àwọn dá ilé oúńjẹ náà sílẹ̀ Àkọlé àwòrán, Èèyàn méjì ló dá ilé oúńjẹ náà sílẹ̀ ni eyi to ṣafihan pe ọrọ minista Mohammed Sabo Nanono pe ounjẹ ọgbọn naira wa ni Kano Àkọlé àwòrán, Wọ́n kọọ́ sí iwájú ilé oúńjẹ náà pé wọ́n ń ta oújẹ ọgbọ̀ náírà níbẹ̀ Àkọlé àwòrán, Nanono ni orúkọ tí wọ́n fún ilé oújẹ náà Àkọlé àwòrán, Àwọn kan nínú àwọn tí wọ́n jẹ oúńjẹ náà sọ pe àwọn yó, ṣùgbọ́n àwọn kan sọ pe wọn kò yó Àkọlé àwòrán, Àwọn kan sọ pé oúńjẹ náà ò dùn lénu.
Ni orile-ede Rwanda, fun apere, ati ti seto ifenuko pelu ile-ise omo ile Africa kan lati maa samojuto ile-iwosan wa to tobi julo, awon ohun ti o n sele nibe fihan pe, igberu ba ile-iwosan naa”.
Bẹ́ẹ̀ ni ètò ìrìn àjò àwọn ọmọ Israẹli rí nígbà tí wọ́n ṣí kúrò ní ibùdó wọn.
Amọ ṣa, ikilọ naa kìí wọ wọn leti.
Ojú kò sì ti ọba níggbà tí mo wí bẹ́ẹ̀, ó dáhùn ó ni, òhun tí àwọn ń pè ní ẹṣin ní ìlú awọn ni èyí nì.
Àkọ́bí ẹni tí ó bá fi ìpìlẹ̀ rẹ̀ lélẹ̀ yóo kú,àbíkẹ́yìn rẹ̀ yóo kú nígbà tí ó bá gbé ìlẹ̀kùn ibodè rẹ̀ ró.
O jẹ akọṣẹmọṣẹ ninu imọ ẹrọ.
Nibayii, eeyan 936 lo ti ṣe alaisi nipasẹ ajakalẹ arun naa ni Naijiria.
Leah Sharibu ṣì wà láàyè - Iléeṣẹ́ Aarẹ Buhari Wo àwọn àwòràn tó làmìlaaka nílẹ̀ Adúláwọ̀ lọ́sẹ̀ yìí BBC Yoruba yoo maa mu gbogbo nkan to n ṣẹlẹ nibẹ wa si etigbọ yin: Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Nitori naa, awọn ọba ni wọn lo.
Oríṣun àwòrán, @Lagostalks913 A fẹ se agbekalẹ awọn ilana ofin ti ẹka eto idajọ yoo gbajumọ."
Bi igbakeji aare se n bo sile lati inu oko ofurufu ni ijoba ibile ado-Odo
gba ni  ibọn  atamatase,ọkọ ogun  oju omi meji  , awon ija ogun,ero ibanisoro mẹ́rìndínlógún  redio agbohunsafẹfẹ
Ifẹsẹwọnsẹ naa ni akọkọ ti Chelsea yoo maa gba niwaju awọn alatilẹyin wọn ni saa liigi 2019/2020.
World Aids Day: Wo bí kòkòrò ààrùn HIV se bẹ̀rẹ̀ lágbàyé!
N óo rán àwọn tí ó yè lára wọn sí àwọn orílẹ̀-èdè; àwọn bíi: Taṣiṣi, Puti, ati Ludi, ilẹ̀ àwọn tafàtafà, ati Tubali ati Jafani, ati àwọn erékùṣù tí ó jìnnà réré; àwọn tí kò tíì gbọ́ òkìkí mi, tí wọn kò sì tíì rí ògo mi rí.
Nígbà tí mo rí yín ni ijọ́sí, aṣọ tí ẹ ró dàbí ẹni pé wọn bí yín mọ́ ọ ni, èwù tí ẹ wọ̀, dàbí ẹ̀wù ọba pàtàkì, gèlè tí e wé dàbí òkúta olówó iyebíye, bẹ́ẹ̀ ni odidi ọjọ́ mẹ́fà ni mo fi la àlá rí ìborùn yín.
”Ifowosowopo ati ibasepo laarin awon orile ede to wa ni lake Chad ati awon ti yoo pese eto iranwo se pataki pupo.
Bí a ti rí náà nìyẹn o.
Ó ṣe abọ́ ńlá mẹ́wàá, ó gbé marun-un ka ẹ̀gbẹ́ gúsù, ó sì gbé marun-un yòókù ka ẹ̀gbẹ́ àríwá.
Mo di ẹni ìríra lọ́dọ̀ iyawo mi,mo sì ń rùn sí àwọn ọmọ ìyá mi.
 Àmì àti àpẹẹrẹ tí a fì lè mọ ̀ pé àkóràn yìí ti wọ ara ní pípọ ́ n ròdòrodo ara tí ó sì maa ń fẹ ̀ lẹ ́ yìn ọjọ ́ díẹ ̀ .
Arakunrin yii ni afurasi ti o sa mọ ileeṣẹ ọlọpaa ilu Ibadan lọwọ ṣugbọn ti wọn ti ri mu pada ni Bodija lọjọ Aiku.
Awọn kan ni oun to tọ ni gomina Ambode ṣe nigba ti awọn miiran n beere wi pe bawo ni yoo ti ṣe e yanju pẹlu bi o ṣe ku perete oṣu mẹta fun un lori alefa.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Arsenal lu Fulham bolẹ̀ 'Buhari máa múra sílẹ̀ láti fẹ̀yìntì' Baba Sala dágbére fáyé Ṣugbọn Ronaldo ti fesi pe oun ko jẹbi ẹsun ti obinrin naa fi kan oun.
Orile-ede Russia lo mu aba wa nibi ipade naa ni eyi ti won jiroro le lori ni Kuwait ati Sweden.
    Lẹ́yìn tí a kí ìyá rẹ̀ tán, ó mú wa lọ sí ibi tí a máa gbé, ó ní kí á dá ara wa sí ọ̀nà mẹ́rin, a sì ṣe bẹ́ẹ̀, ṣùgbọ́n bákan náà ni gbogbo iyààrá ńlá ńlá náà rí.
Ní Ọjọ́ Ìsinmi àwọn Juu, Jesu lọ sí ilé ìpàdé, ó bá bẹ̀rẹ̀ sí kọ́ àwọn eniyan.
Abiola Ajimobi: Ẹ wo àwòrán bí ìsìnkú Abiola Ajimobi ṣe lọ!
“A n fojusona lati safihan re lojo isegun(Tuesday) niluu New York.
Rukiya ni afojusun oun ni lati gbe nibi ti yoo fi oun lọkan balẹ ti yoo si dabi ile fun oun.
“Ẹ jẹ́ kí á lọ sí ibùgbé rẹ̀;ẹ jẹ́ kí á lọ wólẹ̀ níbi àpótí ìtìsẹ̀ rẹ̀.
Ninu gbogbo ifesewonse olorejore iko ohun, ni awon ololufe iko naa ti n bu enu ate lu, Ozil ati Gundogan ti won je agbaboolu orile-ede Germany sugbon ti won tan mo orile-ede Turkey fun pipade aare ile Turkey RecepTayyip Erdogan.
Àjọ tó ń rí sí ètò ìdìbò lórílẹ̀-èdè Nàìjíríà (INEC) ka èsì ìbò pé Oní ìmọ̀ ẹrọ Segun Oni ló jáwe olúbori, tí Ọ̀mọ̀wé Kayode Fayemi sì fáriga pé òun ló jáwé olúbori, èyí ló fàá ti ọ̀rọ̀ fí di ti ilé ẹjọ́ sùgbọ́n tó fìdí rẹmi bọ̀ níbẹ̀.
Awọn adẹrinpoṣonu bii Ushbebe to jẹ adẹrinpoṣonu, ati Ayọdele Makun to jẹ adẹrinpoṣonu naa.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Boko Haram: Ọlọ́pàá ní aràrá wà láàárín àwọn afurasí 18 Agẹmo 2018 Oríṣun àwòrán, AUDU MARTE Ilé iṣé ọlọ́pàá Nàìjíríà ti ṣe àfihàn àwọn afurasi méjo ọmọ ẹgbẹ Boko Haram to jí àwọn akẹkọ Chibok gbé.
" Oríṣun àwòrán, @victoryomogiate Victory fikun pe oun ati adẹrinposonu naa bẹrẹ si ni ajọsepọ, ọjọ kan si wa to dabi ẹni pe oun tabuku ara oun nipa gbigbe nnkan ọkunrin rẹ sẹnu lasiko ti awọn n sere ifẹ, bẹẹ lo tu omi nnkan ọkunrin si oun lẹnu.
bill, National Agricultural Seed Council Bill, Agriculture Credit Guarantee
Wọn salaye pe, awọn gbiyanju lati sare ko awọn ohun elo to n bẹ ninu ile naa jade lasiko ti eefin bẹrẹ sini ru.
Ọba Ilorin ló pàṣẹ pé kí ń padà sọ́dọ̀ ọkọ mi - Risikat olójú búlúù Ilé wa ni mo ṣì wà, èmi kò tíì padà sọ́dọ̀ Bàbá Kaosara Arabinrin Risikat Azeez ti ọpọ eeyan mọ si oloju buluu, naa ti fesi lori awọn ohun ti ọkọ rẹ ba BBC Yoruba sọ l‘Ọ́jọbọ.
Nitori naa, ilokulo oogun Chloroquine le ṣakoba fun ọ, koda, o le ṣeku pa ọ.
Ki n tun to ba Yọmi Ogunmọla ati Antar Laniyan ṣiṣẹ.
 Ètò ní í mú kóhun gbogbo rí rẹ ́ mú .
 Ìlú ijẹ ̀ bú - jẹ ̀ ṣà sì tó nǹkan bí ibùsọ ̀ mẹ ́ fà sí iléṣà ní apá àríwá ilẹ ̀ Ìjẹ ̀ ṣà .
rọ ile-isẹ agbofinro ati ile-isẹ ọtẹlẹmuyẹ lati se iwadii, ki won si fọrọ wa
”Asofin Ita Enang tun tako oro pe ile-ise aare n da iwa isuna odun 2019 duro, o salaye pe, iwe isuna odun 2018 si ni osu meje nile ko to koja akoko.
Wọn rọ ijọba wi pe ki bẹẹ ni wọn ko maa jẹ bẹ nitori awọn ni awọn ara ilu n wo fi ṣe awokọṣe.
Gẹgẹ bi ohun ti awọn onimọ naa sọ, o ṣeeṣe ki iho naa gun si bi òjò ba ṣe n rọ si.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, October 1 Celebrant: Atinuke Oladeru ni kẹ yé ṣépè fún Nàíjíríà mọ́, ẹ pa ohùn dà Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Gbogbo bí ò ó tíí ṣe tí à ń gbọ́;tún wá ṣe bẹ́ẹ̀ nígbà tiwa;sì ranti àánú ní àkókò ibinu rẹ.
Adari orile ede yii tun so pe eto idibo to n bọ yoo lọ ni irowo-irosẹAare
Ó wá dàbí ẹni pé mò ń fi ọkàn èmi pàápàá ranṣẹ sí ọ.
Òun ni ó sì ń pín àwọn ẹ̀bùn tí a yà sọ́tọ̀ fún OLUWA ati àwọn ọrẹ mímọ́ jùlọ.
Ninu oro agbeleko re, eyi ti amugbalegbe pataki si minisita ohun ni eka iroyin ati oro ifitonileti se so, ogbeni Nneka Ikem-Anibeze, O ni, minisita gba won niyanju lati lo soju orile-ede Naijiria daradara.
O ni ijọba gbọdọ jẹ ki awọn to n ṣayẹwo fun pọ si ju bo ṣe n ṣe lọwọlọwọ.
Ẹ sọ ìwé kíkà di dandan fún ẹ̀yà Fulani - Oluwo rọ ìjọba àpapọ̀ EFCC ya bo ìlé Akinwumi Ambode N kò fẹ́ eégún onídọ̀tí ní ààfin mi - Oluwo Ninu atẹjade kan lati ọwọ akọwe rẹ̀, Alli Ibraheem, Oluwo pe fun ofin ti o lagbara lodi si awọn agbenipa ati awọn oniwa ibajẹ, lona lati daabo bo emi awọn ara ilu.
Tomi Waziri: Kí n tó gbé fóònù lé wọn lọ́wọ́, wọ́n ti fi ìbọn fọ́ mi lójú
Abajade: ko si ẹni lee sọ ni pato idi ti awọn alaṣẹ nigba naa ko fi fi Azikwe jofin.
Gbogbo akitiyan ijọba ipinlẹ Kogi atawọn oṣiṣẹ alaabo gbogbo kaakiri Naijiria to fi mọ awọn figilante ibilẹ lo n ṣeranwọ fun ẹka aabo yii lati ṣawari awọn ti wọn ko tii ri.
Kìí ṣe ààrùn Covid-19 ló pa adájọ́ àgba ìpínlẹ̀ Kogi-Kọmísọ́nà ìlera Eeyan 566 tuntun mii lo ṣẹṣẹ lugbadi arun Coronavirus ni Naijiria.
S - Oworonshoki Mile 2 - Addax/Falomo Mile 2 - Marina/C.
O jẹ ọkan lara awọn ọmọ ẹgbẹ Faira ni Tijjaniya, o si maa n gbadura nigba marun un lojumọ.
Mose ati Aaroni bá dojúbolẹ̀ níwájú àwọn eniyan náà.
Ninu ifọrọwerọ pẹlu BBC Yoruba, Abegunde ni irọ gedegbe ni ọrọ naa, oun ko si fi igba kankan kede pe magomago abi ayederu ni ibo to gbe gomina Akeredolu wọle lọdun 2016.
 Ó Ṣeéṣe kó jẹ ́ wípé ìran kan ní gbogbo àwọn ẹ ̀ yà wọ ̀ nyí ti wá .
- Mike Bamiloye Ọkùnrin kan da ṣọ́ọ̀ṣì rú lásìkò ìgbéyàwó, Ó ní òun lọkọ àárọ̀ ìyàwó tuntun Mi ò fẹ́ ìrànwọ́ ẹgbẹ́ òṣèré, àwọn kọ́ ló kóbá mi- Chief Kanran Ohun tí a mọ̀ nìyí nípa gbọ́nmi síi omi ò tó lórí ọ̀rọ̀ oyè Babaloja-General ní ìpínlẹ̀ Oyo YWC yọ Ààrẹ Banji Akintoye nípò àbi Akintoye tú ìgbìmọ̀ aláṣẹ YWC ká?
Kùrù-kẹrẹ Coronavirus ṣeéṣe kó dópin láàrín ọdún méjì - WHO Ọkọ̀ rélùwéè 16 yóò ná Eko sí Ibadan láti oṣù tó ń bọ̀ lọ - Iléeṣẹ́ Rélùwéè kéde Gẹgẹ bi ohun ti awọn oṣoju mi koro sọ, awakọ epo naa ati ẹnikeji rẹ gbẹmi mi nigba ti awakọ ẹja ti wọn fori sọra moribọ.
Baba rẹ jẹ oṣiṣẹ ologun taa mọ si Sọja, to si ni iyawo to le ni mejidinlogun nitori ọpọ ibi ti iṣẹ gbe lọ, lo ti n fun obinrin loyun.
Nítorí pé, báwo ni àwọn eniyan yóo ṣe mọ̀ pé, inú rẹ dùn sí èmi ati àwọn eniyan rẹ?
Opo awọn ololufẹ rẹ lo bọ sita ṣe iwọde E tu Sowore silẹ lọsẹ to kọja.
A sì leè ni ọba alaye náà jogún bá ọlá nílé ni nítorí bàbá rẹ̀ gan an, ọba Atanneye Olateru-Olagbegi Kínní, tó jẹ Ọlọwọ tilu Ọwọ láàárín ọdún 1913 sí 1933, náà ni ọpọlọpọ ọmọ àti ìyàwó bíi ọọdunrun, tí marun un nínú awọn aya rẹ náà, kò sì tíì mọ ọkùnrin nígbà tí ọba ọhun jáde láyé.
Lọdun 1972, ile ẹkọ naa kọwe si pe, awọn ko fẹ ja pẹtẹ ẹsẹ rẹ nileewe awọn mọ.
Wọ́n ti ṣẹ́ gègé lórí àwọn eniyan mi,wọ́n ti ta àwọn ọmọkunrin wọn,wọ́n fi owó wọn san owó aṣẹ́wó,wọ́n sì ta àwọn ọmọbinrin wọn,wọ́n fi owó wọn ra ọtí waini.
won, nitori naa ki ajo INEC gba oruko awon oludije naa wole.
Ọ̀nà tí a fi mọ ìfẹ́ nìyí: kì í ṣe pé àwa ni a fẹ́ràn Ọlọrun ṣugbọn òun ni ó fẹ́ràn wa, tí ó rán ọmọ rẹ̀ wá sáyé láti jẹ́ ọ̀nà ìwẹ̀mọ́ ẹ̀ṣẹ̀ wa.
Gbogbo àkọ́bí ẹran ọ̀sìn yín tí ó bá jẹ́ akọ, ti OLUWA ni.
” Ó tún sọ fún mi pé, “Òdodo ọ̀rọ̀ Ọlọrun ni ọ̀rọ̀ wọnyi.
Igi oaku láti Baṣani ni wọ́n fi ṣe ajẹ̀ rẹ̀Igi sipirẹsi láti erékùṣù Kipru ni wọ́n fi ṣe ilé rẹ.
O ni o di dandan ki banki tẹwọ gba awọn owo to ti ya tabi to ti dọti pa yii wọle ki wọn si fi owo tuntun sanwo fawọn onibara wọn sita.
Àbọ̀ ìpàdé bòńkẹ́lẹ́ láàrin Tinubu àti Buhari rèé Pásítọ̀ pe Naira Marley ní ẹlẹ́mìí èṣù, Marley fèsì padà pé kí pásítọ̀ gan tẹ èṣù mọ́lẹ̀ Díẹ̀ lára àwọn ìṣẹ̀lẹ̀ tí yóò mi ìgboro tìtì l'ọ́dún 2020 rèé Ọmọdé tó ń ṣeré pẹ̀lú àdò olóró ló fa ìbúgbàmu Borno- Cameroon Ọ̀pọ̀ ìbejì tí wọ́n sopọ̀ ní ìsàlẹ̀ ikùn bii mọkanla ni wọ́n ti ṣisẹ́ abẹ fún láti tú wọn ká, àmọ́ ìgbà àkọ́kọ́ nì yíì tí àwọn dokìta náà yóò ya ìbejì tí wọ́n sopọ̀ láyà.
Oṣojumikoro fi idi ọrọ naa mulẹ fun awọn akọroyin wi pe abọ́ ni arabinrin naa n fọ ni iwaju ile ni idaji ọjọ naa ki awọn olubi ẹda to ṣe ikọlu sii.
Nollywood: Àwọn òsèré tíátà Nàìjíríà tó jẹ́ ọmọ Yorùbá
Ó ká mi lára nípé iṣẹ́ẹ wa kò yé ikọ̀ ajagun yékéyéké.
Àwọn ọmọ ogun náà sọ ọ̀rọ̀ tí Dafidi sọ níwájú Saulu, Saulu bá ranṣẹ pè é.
Awọn ologun ṣalaye pe koda awn janduku ọhun tun gbiyanju lati yabo ile ijọba ipinlẹ Eko ṣugbọn wọn bẹgi dina wọn.
Fifariga àwọn ẹ́ka ijọ Celestial mii pe o gbe olorin aye wa sinu ijọ mimọ Wasiu Ayinde K1 De Ultimate Oríṣun àwòrán, Genesis Global Alhaji Wasiu Ayinde K1 De Ultimate naa lara awọn ilumọọka to ti ṣabẹwo si ijọ Celestial CCC (GENESIS) labẹ akoso pasitọ Ogundipe.
Yala wọn lọ kawe ni tabi lati lọ ṣowo, ileeṣẹ orileede wọn ni ilẹ ti wọn lọ a ma ṣe awọn iṣẹ kan ti yoo mu igbayegbadun rọrun fun wọn nibẹ.
Aàrẹ Buhari buwọlu yíyí orùkó àwọn ibùdókọ ọkọ ojú ìrìn bíi ti Apapa padà fi sọrí àwọn èèkàn ìlú Nàìjíríà ṣí àwọn ilé ìwé padà; Ìdánwò WAEC á bẹrẹ lẹyìn ọdún Iléyá!
Ìgbáyé-gbádùn ọmọ Nàìjíríà ní South Afrika ló jẹwá lógún- Buhari Khadijah, obìnrin àkọ́kọ́ tó dẹnu ìfẹ́ kọ àyànfẹ́ rẹ̀ South Africa: Báwo ni ìkọlù sáwọn àjèjì ṣe wọ́pọ̀ tó?
Olori ile, Bamidele Oleyelogun lo pasẹ bẹẹ lasiko ijoko ile to waye lọsan ọjọ Isẹgun.
Dapo Abiodun - MFR Lara awọn to wa ninu igbimọ naa ni ajafẹtọ ọmọniyan, awọn to ti fẹyinti nidii iṣẹ ọlọpaa, aṣoju awọn akẹkọọ, ati bẹẹ bẹẹ lọ.
Tunde Idiagbon: Ṣé ìlàkàkà rẹ̀ láti paná ìwà ìbàjẹ́ ní Nàìjíríà sèso rere bí?
Ahmed fikun pe loore koore ni awọn asọbode yoo maa paraaro awsn ẹnu bode ilẹ wa lati ri daju pe awọn eroja kotọ naa ko ri ọna wọle sorilẹede yii.
Wọ́n Pa Àwọn Ọmọ Ọmọ Saulu.
Aisha Buhari vs Police : Ọgá Ọlọ́pàá kọ̀ láti tú àwọn ẹ̀ṣọ́ ìyàwó Ààrẹ sílẹ̀ Oríṣun àwòrán, @Aishambuhari Àkọlé àwòrán, Ọ̀gá àgbà Ọlọ́pàá wọ́ ọ̀rọ̀ Aisha Buhari tì sẹ́gbẹ̀ẹ́ kan Ọga agba awọn ọlọpaa Naijiria ti kọ lati da iyawo aarẹ Naijiria, Aisha Buhari lohun lati igba to ti fun pe si i lọjọ ẹti pe ko tu awọn ẹṣọ rẹ silẹ lahamọ ọlọpaa.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Barcelona to yan Ramon Planes gẹgẹ bi oludarieto kata-kara agbọọlu eleyi ti Eric Abidal di mu tẹlẹ ki wọn to ni ko maa lọ lọjọ Iṣẹgun.
Ninu atẹjade kan ti ileeṣẹ naa fi sita, eleyii ti agbẹnusọ rẹ, Ọgbẹni Rasheed fi ṣọwọ si BBC News Yoruba, o ni gbogbo ẹsun ti awọn ọlọpaa fi n kan an ni ile ẹjọ ti n joko le tabi gbe idajọ kalẹ le lori.
” Ati pé, “Oluwa ni yóo ṣe ìdájọ́ àwọn eniyan rẹ̀.
Ayade  fi idunnu re han lori bi eto idibo se n lọ irọwọ
Ọgagun Komolafe sọ pe lẹyin igbaradi ni wọn yoo gbe awọn to ti forukọ silẹ kaakiri ipinlẹ Ekiti lati ṣiṣẹ pọ pẹlu awọn oṣiṣẹ eto alaabo mii.
Wọ́n ti gbẹ́ kòtò jíjìn ní ìlú Ṣitimu; ṣugbọn n óo jẹ wọ́n níyà.
Laarin ọjọ kẹtala Oṣu kọkanla ọdun 2017 si ọjọ kẹfa oṣu kini ọdun 2018, awọn ajinigbe ti jin awọn obinrin ijọ aguda mẹfa gbe.
Nígbà tí ó di Ọjọ́ Ìsinmi mìíràn, Jesu wọ inú ilé ìpàdé lọ, ó ń kọ́ àwọn eniyan.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Dino: Ohun tó mú mi fò bọ́ sílẹ̀ nínú mọ́tò ọlọ́pàá Ìjọba ìbílẹ̀ márùn nínú òkùnkùn birimù Ààrẹ Buhari fẹ́ yọjú sí Dókítà ní London Àwọn àbòdé láti orílẹ̀èdè Libya yìí ni yóò jẹ́ kó di ẹgbẹ̀rún mẹ́jọ àti mọ́kàndínláàádoje àwọn ọmọ orílẹ̀èdè Nàíjíríà, tí wọ́n ti kó padà dé láti orílẹ̀èdè Libya báyìí, láti ìgbà tí òkìkí ìwà ìmúnilẹ́rú lórílẹ̀èdè náà ti kárí ayé.
Àní mo dé àríwá ayé níbi yìnyín gbé rọ̀ dàálẹ̀ bí òjò.
Ó gbé àwọn òpó náà kalẹ̀ níwájú tẹmpili, ọ̀kan ní ìhà àríwá, wọ́n ń pè é ní Jakini, ekeji ní ìhà gúsù, wọ́n ń pè é ní Boasi.
Ọ̀nà ọlọ́gbọ́n lọ tààrà sinu ìyè,kí ó má baà bọ́ sinu isà òkú.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Mo sun ẹkún kíkorò nígbà tí a kí ara wa kẹ́yìn' Ọbasanjọ sọ ninu lẹta rẹ pe, iṣeku pa arabinrin Olakunrin ba ni ninu jẹ paapaa lasiko yii ti ọpọ awọn aṣiwaju orilẹede Naijiria n pe fun iṣọkan, ikonimọra ninu eto oṣelu orilẹede Naijiria.
'Àìsàn baba Ogun Majek le pupọ, tó sì jẹ ara àwọn àìsàn tó maa n gbẹmi ẹni ní."
Suicide Prevention Day: Wo àmì márùn-un tí o fi le mọ ẹni tó fẹ́ gbẹ̀mí ara rẹ̀
60 Àti pé èmi yíò fi hàn àwọn ènìyàn yìí pé mo ní àwọn àgùntàn míràn, wọ́n sì jẹ́ ẹ̀ka ti ilé Jakọbù;
Agbẹnusọ fun ileese ọlọpa nipinle Ọyọ, Adekunle Ajisebutu, sọ wipe awọn adigunjale ni wọn pa ọga ọlọpa SARS naa.
Ní ilé ọlọ́gbọ́n ni à á tí ń bá nǹkan olówó iyebíye,ṣugbọn òmùgọ̀ a máa ba tirẹ̀ jẹ́.
Orukọ awọn onisegun ọhun ni Daniel Ojo, Enoch Falayi ati Gabriel Olabinrinjo, Falayi si lo jẹ babalawo si Alaaye tilu Efon naa.
Ní ọjọ́ kan, èyí ẹ̀gbọ́n wí fún àbúrò, ó ní, “Baba wa ń darúgbó lọ, kò sì sí ọkunrin kan tí yóo fẹ́ wa gẹ́gẹ́ bí ìṣe àwọn eniyan.
O ni 'Lati ṣiṣẹ isin gẹgẹ bi igbakeji aarẹ ninu idari ere bọọlu gbigba ni Afrika jẹ anfaani nla fun mi.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ogun Cholera: Ọdọọdún ni àrùn onígbá-méjì máa n ṣọṣẹ́ ní Nàìjíríà-NCDC Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Ewe, ireti yoo wa pe Ronald Koeman yoo ran iko naa lowo lati pegede fun idije Euro 2020, bakan naa idije agbaye odun 2022 lorile-ede Qatar.
Koda ilumọọka ni nigba to fi wa nile iwe girama nitori Eleduwa fun ni ẹbun bọọlu gbigba.
"Bakan naa ni Dokita Ehanire sọ pe ""ti awọn eniyan ba mu ilo ibomu-bẹnu, yiyago fun'ra ẹni lawujọ, ni koko, yoo fun wa ni esi ti a n fẹ""."
Nigba to n mẹnuba ọjọ manigbagbe fun lasiko to wa lori eto BB Naija, Olamilekan ni ayajọ Johnny Walker ati Guinness stars, ti oun, Vee ati Nengi wa ni isọri kannaa, ni oun ko le gbagbe laelae.
Nígbà tí àkókò Elisabẹti tó tí yóo bí, ó bí ọmọkunrin kan.
 owun ni eni akọkọ ti okọkọ ṣẹ ́ iru nkan bayi .
Ó pàṣẹ fún afẹ́fẹ́ ati ìgbì omi, wọ́n sì ń gbọ́ràn sí i lẹ́nu!
Wo ipa tí ìlànà tuntun tí ìjọba Eko gbé jáde lórí Covid-19 yóò nìí ní ìgbésí ayé rẹ Ìtàn ìgbé ayé Bode Thomas rèé, ó kọ́ wa láti máa kó ẹnu wa ní ìjánu Àwọn ọba Yorùbá kan rèé tí wọ́n rọ̀ lóyè, tí ọba míràn jẹ lójú ayé wọn Ṣé kí òfin kónílé -ó-gbélé kásẹ̀ nílẹ̀ ni tàbí kó tẹ̀síwájú?
"Nigba ti wọn bere igba ti arabinrin naa ti wa lẹwọn, awọn oṣiṣẹ ọgba ẹwọn naa ko sọ nitori wọn ni ""iroyin aṣiri ni awọn ko si le fesi""."
Àwọn eniyan kẹ́gàn rẹ̀,wọ́n sì kọ̀ ọ́ sílẹ̀;ẹni tí inú rẹ̀ bàjẹ́ tí ó sì mọ ìkáàánú ni.
" Ọpọlọpọ awọn oṣiṣẹ eto ilera lo ti ku nitori pe wọn n tọju tabi polongo igbogun ti aarun Ebola ni orilẹede Democratic Republic of Congo.
Iko agbaboolu Naijiria yoo koju orile-ede South Africa niluu Johannesburg lojo ketadinlogun osu yii, leyin re ni won yoo koju Uganda lojo keta si ifesewonse kinni niluu Asaba.
À ṣé olóòrùn ni ayálégbé mi tó ń fojóojúmọ́ ṣakọ lórí ayélujára- Onílé Lisa Li Wo ohun tó ń ṣẹlẹ̀ níbi ayẹyẹ àyájọ́ ọdún òmìnira ní ìpínlẹ̀ Oyo Ẹ wo ìyá ẹni ọdún 81 tó sẹ̀sẹ̀ parì ilé iwé alákọ̀bẹ̀rẹ̀!
Iru igbẹ yii saaba maa n di pọ ku ku ku pẹlu ifarahan awọn ounjẹ ti ko sẹrẹ lara.
 Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ọba Ilorin ló pàṣẹ pé kí ń padà sọ́dọ̀ ọkọ mi - Risikat olójú búlúù Làásìgbò òṣèlú wáyé nílùú Ondo, ọ̀pọ̀ èèyàn fara pa Ǹ jẹ́ o mọ̀ pé oṣù ojú ọ̀run táwọn Mùsùlùmí ń lò ti wà saájú Ànọ́bì?"
Koda, emi ni Igbakeji Aarẹ ẹgbẹ Mandela Washington Fellow ni Naijiria, eyi to jẹ pe ileeṣẹ aṣoju America lo n gbọ bukaata wa.
Nígbà tí Paulu bẹ̀rẹ̀ sí sọ tirẹ̀ nípa ìwà rere, ìkóra-ẹni-níjàánu, ati ìdájọ́ tí ń bọ̀, ẹ̀rù ba Fẹliksi.
Nítorí náà, inú bí OLUWA sí wọn, ó sì fi wọ́n lé Kuṣani Riṣataimu ọba Mesopotamia lọ́wọ́; wọn sì sìn ín fún ọdún mẹjọ.
Ṣé o mọ òfin wọnyi: ‘Ìwọ kò gbọdọ̀ ṣe àgbèrè; ìwọ kò gbọdọ̀ paniyan; ìwọ kò gbọdọ̀ jalè; ìwọ kò gbọdọ̀ jẹ́rìí èké; bọ̀wọ̀ fún baba ati ìyá rẹ.
Ní olú ìlú ilẹ wá, Abuja, ẹwẹ, àwọn òṣìṣẹ́ nibẹ ya bo ojú pópó láti lọ síbi isẹ koowa wọn lọ́jọ́ Aje.
A óo fi idà run àwọn ìlú wọn, irin ìdábùú ìlẹ̀kùn bodè wọn yóo ṣẹ́, a óo sì pa wọ́n run ninu ibi ààbò wọn.
Ni erongba lati fopin si idojuko iko omo-ogun olote tabi awon janduku ti o n se ikolu sipinle Zamfara, ipinle ti o kogun si ila oorun orile-ede Naijiria ati awon ipinle miiran ti o tun fara ti ipinle ohun, oga agba yanyan fun ile-ise olopaa, Ibrahim Idris ti sagbekale igbimo alaabo tuntun ti o kun fun iko omo ogun Naijiria Army, awon olopaa ati awon ile-ise alaabo miiran fun ise akanse naa.
Balogun ni lati ogoji ọdun sẹyin ti oun ti jẹ ọkan gboogi fun idile ọba ni ko ti si ẹni to n ta oye ni ilu Ibadan.
Àwọn ẹ̀ka rẹ̀ yóo bọ́ sílẹ̀ lórí àwọn òkè ati ní àwọn àfonífojì, igi rẹ̀ yóo sì wà nílẹ̀ káàkiri ní gbogbo ipadò ilẹ̀ náà.
Eli ti di ẹni ọdún mejidinlọgọrun-un ní àkókò yìí, ojú rẹ̀ sì fẹ́rẹ̀ má ríran mọ́ rárá.
Ohunkohun tí eniyan bá gbìn ni yóo ká.
Iyabo Ojo: Wọ́n gba N51,950 lọ́wọ́ mi ní pápákọ̀ òfurufú láì ṣe àyẹ̀wò Coronavirus fún mi
Iná ọ̀tẹ̀ wọn ń jò bí iná ojú ààrò, inú wọn ń ru, ó ń jó bí iná ní gbogbo òru; ní òwúrọ̀, ó ń jó lálá bí ahọ́n iná.
INEC: Kò sí ìká tí o kò lè fí dìbò, ṣáà tí tẹ̀ ẹ́ sójú ẹ dáadáa Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, APC jáwé olúborí nípínlẹ̀ Ekiti Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
"Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Abuja Nightclub: Àwọn ọmọge wọ gàù nítorí asọ péńpé 30 Ìgbé 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 1 Èbibi 2019 Oríṣun àwòrán, PIUS UTOMI EKPEI Àkọlé àwòrán, Diẹ lara awọn ọmọbinrin ti ikọ̀ amuṣẹya naa mu lo fi ẹsun kan wọn pe ""wọn fi ipa ba diẹ lara wọn lopọ."
Nítorí kì í ṣe òkè Sinai ni ẹ wá, níbi tí iná ti ń jó, tí ó ṣú dẹ̀dẹ̀ tí ó ṣókùnkùn tí afẹ́fẹ́ líle sì ń fẹ́, 
awon ohun amayedẹrun ni eyi ti yoo mu igbe aye irorun ba awon omo orile ede
Ní ìlú yìí ni a gbé tọ́ mi dàgbà.
Lati igba naa ni okiki Abiola Ebila ti kan ni Ibadan, ó si di ọrẹ imulẹ pẹlu awọn agba oselu.
Ẹ̀yin ọmọde, ẹ má ṣe jẹ́ kí ẹnikẹ́ni tàn yín jẹ.
Awon ti won ro pe won ni orile ede miiran , lee maa lo sibe.
Lẹyin oniruru aba ati ijiroro, awọn asofin agba orilẹede Naijiria ti wa dari igbimọ to nse amojuto banki atawọn ile ifowopamọ lati mu aba wa lori wiwa ojuutu si isoro naa.
Ó tó nǹkan agogo mejila ọ̀sán.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù US election 2020: Ibú-owó Bloomberg fẹ́ wàákò pẹ̀lú Trump nínú ìbò ààrẹ Amẹrika 9 Bélú 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, US election 2020: Ibú-owó Bloomberg fẹ́ wàákò pẹ̀lú Trump nínú ìbò ààrẹ Amẹrika Ọlọrọ Michael Bloomberg to ti figba kan jẹ Méyọ̀ to dari ilu New York ti fi erongba rẹ han lati dije dupọ aarẹ ilẹ Amẹrika ninu ibo aarẹ ọdun 2020.
2019 elections: Ganduje ní òun yóò gba èsì yóòwù tó bá jáde ní ìdìbò gómìnà Kano
Oríṣun àwòrán, others Àkọlé àwòrán, Bi eeyan ba ri ọlọrọ rẹ .
2 22396 Orilẹede Cameroon 451 1.
Ìgbà tí òògùn ẹ̀jẹ̀ ríru lè ṣiṣẹ́ jù rèé- Onímọ̀ Ìlú kò mọ ohunkóhun nípa iṣẹlẹ màálù tó kú nilu Ikarẹ- Oba Olukarẹ Bẹẹ, ti onirese ko ba fingba mọ, eyi to ti fin tẹlẹ ko ni bajẹ layelaye.
 Mo mọ pe ti o ba ni ibasepo to dan monran pelu awọn ti ẹ jo mu ala papo owo ti waa na lori eto aabo ati ọrọ aje yoo dinku jọjọ,”Aare wa ni bi awọn fayawọ se n ko awọn ohun ija oloro wọ orile ede Naijiria n ko ba eto aabo ati ọrọ aje orile ede yii.
Àwọn kan wá sọ fún Joṣua pé wọ́n ti rí àwọn ọba maraarun ní ibi tí wọ́n fi ara pamọ́ sí ní Makeda.
Oríṣun àwòrán, Facebook/Ignatius Longjan Sẹnẹtọ Longjan to tun ti fi igba kan ri jẹ igbakeji gomina ipinlẹ Plateau papoda lẹyin to ti ṣ'aisan fun ọjọ pipẹ.
Bakan naa ni wọn fi lede pe awọn yoo ma fito awọn araalu leti bi o ba ṣe n lọ.
"Wo bóo ṣe lè mọ̀ ayédèrú Àwọn ọ̀dọ́ ilẹ̀ Yoruba kò gbọdọ̀ gbàgbé àṣà ati ohun àdàyébá wọn - Ooni Ile Ife ""Orukọ ti yoo maa jẹ bayii ni Goodluck Jonathan Railway Station & Complex."
Ọlọ́pàá gbọ́dọ̀ wá àwọn tó gbàbọ̀dè láàrín wọn nítorí ẹ̀mí wa ò dè ní Akinyele Ẹ ṣetò ìbò gómìnà míràn ní Bayelsa kó tó di Nov - Adájọ́ pàṣẹ Kí ló wá nínú àbádòfin pínpín omi àti àwọn ǹkan inú omi tó ń mú awuyewuye wa?
Elija bá lọ, ó ṣe bí OLUWA ti wí, ó sì ń gbé ẹ̀bá odò Keriti, ní ìhà ìlà oòrùn odò Jọdani.
Olisa Metuh: Oríṣun àwòrán, Twitter Ajọ EFCC fi ẹsun kan Metuh pe o ji owo to to irinwo miliọnu Naira ni ileeṣẹ oludamọran lori eto aabo, labẹ isakoso Sambo Dasuki.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ẹ̀kún omi India: Ìsẹ̀lẹ̀ náà ló tíì burú julọ́ làti ọgọ́rùn-ún ọdún sẹ́yìn 18 Ògún 2018 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Awọn eniyan ni Cochin n lo gbogbo ọkọ ti wọn le ri lati sa kuro nibi ti omiyale wa Eniyan to ju ọọdurun lọ ti padanu ẹmi wọn ninu isẹlẹ́ ẹkun omi to fa ilẹ riri ni ipinlẹ Kerala to wa ẹkun Guusu India.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Nikesuliat: Ọ̀dọ́mọdébìnrin akéwì tó n fi ẹ̀ṣà kìlọ̀ ìwá lásìkò yìí Atẹjade naa tun sọ pe Hushpuppi lẹdi apo pọ mọ awọn kan lati ko $14.
Onínúfùfù a máa rú ìjà sókè,ṣugbọn onínútútù a máa pẹ̀tù sí ibinu.
The NHS sọ ìtumọ̀ vaginismus gẹ́gẹ́ bí ìdáhùn àgọ́ ara kánmọ́ kánmọ́ sí ìbẹ̀rù ohunkúhun tàbí ohun gbogbo tó fẹ́ wọ ojú ara obìnrin.
A níláti lọ sinu aṣálẹ̀ ní ìrìn ọjọ́ mẹta kí á sì rúbọ sí OLUWA Ọlọrun wa gẹ́gẹ́ bí ó ti pa á láṣẹ fún wa.
Oun fúnra rẹ ti ṣe ifọrọwanilẹnuwo pẹlu akọroyin Will Rose ti BBC ni Naijiria, ilé isẹ iroyin AFP.
Ṣugbọn a ti dá ẹni tí kò bá gbà á gbọ́ lẹ́bi ná, nítorí kò gba orúkọ Ọmọ bíbí Ọlọrun kanṣoṣo gbọ́.
Bí o bá sìn mí tọkàntọkàn pẹlu òtítọ́ inú, gẹ́gẹ́ bí Dafidi, baba rẹ, ti ṣe, bí o bá ṣe gbogbo ohun tí mo pa láṣẹ fún ọ, tí o sì pa òfin ati ìlànà mi mọ́, 
"Nígbà tó ń ṣẹ lórí ahesọ ọ̀rọ̀ kan tó ní owó kotọ ni wọn ń gbà lọ́wọ́ àwọn ọlọkada, Auxiliary ṣàlàyé pé ìjọba ló yan àwọn sípò, ìjọba náà sì ni àwọn n pawo fún, kò sì sí owó kankan tí àwọn gba, tí ìjọba kò mọ sí.
Láti àkókò yìí, Ọmọ-Eniyan yóo jókòó lọ́wọ́ ọ̀tún Ọlọrun Olodumare.
Bákannáà ló ní àwọn oṣiṣẹ aláàbò n dun koko mọ awọn ọmọ ẹgbẹ PDP nipinlẹ naa.
Bakan naa ni wọn si le e gbe igbesẹ lati ri wi pe awọn ijọba ipinlẹ kọọkan gbe igbesẹ fun ara wọn.
SERAP ni awọn owo nla ti awọn aṣofin ati ileeṣẹ aarẹ n bu fun ara wọn jẹ oun abuku fun Naijiria.
Àwón nkan ti o ṣeeṣe koo ma mọ nipa Victor Moses Njẹ ẹ mọ pe ibanujẹ ni Victor Moses fi di ọmọ Ilẹ Gẹẹsi?
Ó wí fún wọn pé, “Nítorí OLUWA Ọlọrun àwọn baba yín bínú sí àwọn ará Juda ni ó fi jẹ́ kí ẹ ṣẹgun wọn, ṣugbọn ẹ pa wọ́n ní ìpakúpa tóbẹ́ẹ̀ tí Ọlọrun pàápàá ṣàkíyèsí rẹ̀.
Apapa - Iganmu Bridge Ijọba ibilẹ Surulere Ọọ̀ni obìnrin, Lúwòó Gbàgídà rèé, akọni tó ń gun ọkùnrin ní ẹṣin rìn Ẹ̀yin ẹ máà wò ó, ó ṣeéṣe kí APC túká lẹ́yìn ìṣèjọ́ba Buhari!
Láì jáfara ó bẹ̀rẹ̀ sí waasu ninu ilé ìpàdé àwọn Juu pé Jesu ni Ọmọ Ọlọrun.
Kí àwọn tí ń yọ̀ máa ṣe bí ẹni pé wọn kò yọ̀.
''Sisọ otitọ fun ara rẹ ati awọn ọmọ rẹ nipa oun to n sẹlẹ se pataki'' Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Sport Betting: Idí rèé tí àwọn ọ̀dọ́ kan fi n ta tẹ́tẹ́.
Àwọn tafàtafà rẹ̀ yí mi ká,ó la kíndìnrín mi láìṣàánú mi,ó sì tú òróòro mi jáde.
Eyín oníròyìn fò yọ lásìkò tó n ka ìròyìn lọ́wọ́ lórí tẹlifísàn Ṣé ojúlówó ni Oogùn apakòkòrò 'Sanitizer' tó ń lò?
“Gege bi  Bartomeu se so, o ni adupe lopolopo fun ise takuntakun ti akonimogba  Luis Enrique se fun iko agba-boolu naa, ati wipe akonimogba oun  lo  finu fedo  fe fi iko agba-boolu naa sile.
Oríṣun àwòrán, @PastorEAAdeboye Ẹwẹ, awọn kan naa n beere pe ṣe kii ṣe ara ọna ati maa gba owo osu akọkọ lọwọ awọn ọmọ ijọ ni wọn se kede aawẹ naa, gẹgẹ bi awọn ijọ kan ti maa nṣe.
Ati pe, o ṣi n da awọn eniyan lara ya lori itage leyin to si ti le lọgọrin ọdun nigba naa.
johnson gbà pé Ọ ̀ yọ ́ ni àwọn Ẹ ̀ gbá ti wá .
Ọrọ yii di ọrọ ajọsọ kaakiri orilẹede Naijiria paapaa julọ lasiko ti ara aarẹ Buhari ko fi ya to fi lọ gba itọju ni ilu Lọndọn.
Aare ni:“Mo dupe lọwọ rẹ nipa iwe ti o fun mi,
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Court of Appeal: Ilé ẹjọ́ ní òfin kò mọ Omo-Agege, Waive gẹ́gẹ́ bíi olùdíje APC ní ìpínlẹ̀ Delta 29 Ẹrẹ̀nà 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 30 Ẹrẹ̀nà 2019 Oríṣun àwòrán, @OvieOmoAgege Àkọlé àwòrán, Wahala ipinya laaarin awọn igun to wa ni ẹgbẹ oṣelu APC ni ipinlẹ Delta lo ṣokunfa ọrọ igbẹjọ ọhun Ileẹjọ kotẹmilọrun to fikalẹ si ilu Benin ni ipinlẹ Edo ti wọgile ẹjọ kotẹmilọrun kan ti Sẹnetọ Ovie Omo-Agege ati Ẹniọwọ Francis Waive pe niwaju rẹ lati doju idajọ ile ẹjọ giga apapọ ilu Asaba to wọgile ibo rẹ bolẹ.
Láti ìgbà laelae ni o ti fi ìpìlẹ̀ ayé sọlẹ̀,iṣẹ́ ọwọ́ rẹ sì ni ọ̀run.
Se ni wọn ran nọọsi mejila lọ sile ki wọn lọ ya ara wọn sọtọ.
Eniola Ajao Oríṣun àwòrán, Eniola Ajao Ijọba ibilẹ Epe lEko ni wọn ti bi Eniola lọjọ kọkanlelogun, oṣu kinni.
26 Bélú 2020 Amos Dauda, Iphone: Ilé ẹjọ́ dájọ́ ẹgba mẹ́ẹ̀dóògún fún ọ̀daràn tó jí Iphone ní Kaduna25 Bélú 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 3 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 5 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Ezekwesili lati je aare orile ede yii, nitori oye ati ogbon re.
Ẹranko náà tí mo rí dàbí àmọ̀tẹ́kùn.
 wọ ́ n pèé sí àwùjọ amòfin gẹ ́ gẹ ́ bí agbẹjọ ́ rò ní ọdún 1978 tí ó si di senior advocate of nigeria ( san ) ní ọdún 2004 .
’ ‘Mi o le gbagbọ pe ẹni ti mo gbe lọ ni wakati kan ṣẹyin ti ku.
Yọ ọ́ lára ìkógun wọn kí o sì kó wọn fún Eleasari alufaa gẹ́gẹ́ bí ọrẹ ẹbọ sí OLUWA.
Amọ, awọn onimọ nipa eto iroyin ati awọn to n lo ẹrọ ayelujara ti fi ero wọn han lori ofin tuntun ti ijọba gbe kalẹ naa.
Nitori naa ni BBC Yoruba ṣe ṣe akojọpọ ẹbun ti awọn olukopa lori eto naa ti jẹ.
Kinni a mọ nipa ọmọ ọba tuntun Ilẹ Gẹeṣi to n bọ yii?
Wúrà ati fadaka ni wọ́n fi ṣe àwọn àga tí ó wà ninu ọgbà.
Bí o bá fẹ́ pada, pada lọ bá Gedalaya ọmọ Ahikamu, ọmọ Ṣafani, ẹni tí ọba Babiloni fi ṣe gomina àwọn ìlú Juda, kí o máa bá a gbé láàrin àwọn eniyan náà.
Kò sí ìgbádùn kan tí n kò fi tẹ́ ara mi lọ́rùn, nítorí mo jẹ ìgbádùn gbogbo ohun tí mo ṣe.
Ẹni tawọn agbofinro ba ri pe o mu ọti lasiko tabi ṣaaju ki o to wa ọkọ yoo jẹ iyan rẹ niṣu.
Ọwọ ileeṣẹ ọlọpaa ipinlẹ Eko ti tẹ igara ọmọ onilẹ kan, to tun jẹ agbanipa nipinlẹ naa.
Netanyahu ni: “Leyin ijiroro lori oro yii, ohunkohun tijo mimo yi ati awon asoju ijoba ba jo fi enuko le lori ni a maa gba wole ki a le ri aridaju pe awon arinrinajo lati agbaye to feran Jerusalem n ri aaye wo oun ti won fe ri gege bii Kristiani laisi wahala kankan fun esin meteeta pelu isokan.
Bí ẹ̀mí bá wà, ìrètí ń bẹ Òkò tí a bá bínú jù, kì í pa ẹyẹ Bí a kò bá rí ẹni bá là ọ̀là kì í yá.
O kọwe fipo silẹ funra rẹ lọdun 1992 lẹyin eyi to ṣe adari fun igbimọ ọpọlọpọ ile iṣẹ, lara wọn ni ile ifowopamọ UBA.
Alukoro ileeṣẹ ọlọpaa ni ipinlẹ Ondo, DSP Tee Leo-Ikoro ṣalaye fun BBC pe iṣẹlẹ naa ko dun mọ kọmiṣọna ọlọpaa ni ipinlẹ Ondo to bẹẹ gẹ to fi pe awọn eekan ẹgbẹ oṣelu gbogbo ni ipinlẹ naa fun ijiroro lori rẹ l'Ọjọbọ.
gomina fun saa keji ni ipinle Kano state.
Sugbọn sa, ijọba sọ lati ẹnu kọmiṣọnna fun ìdẹ̀rùn ara ilu, Hafsat Muhammad Baba, pe igbesẹ naa jẹ dandan nitori pe awọn onibara naa ko tẹle asẹ ati ilana ti ijọba la kalẹ.
2020: Oloye Awurela Ifaleke ti wúré ọdún ìgbéga fún kóówá Ẹ gbàdúrà kí ogun má bẹ́ sílẹ̀ ní 2020- Primate Ayodele Ajeponula: Òṣíkí kọja ọbẹ̀ lásán, kìí dá rìn láì mu òkèlè dání Ẹ̀kọ́ ọ̀fẹ́, ètò ilera ọ̀fẹ́ àti iná ọba ló jẹ wá lógún- ọmọ Nàìjíríà O fikun un wi pe ẹni to ba tapa si ofin Olorun yoo ru igi oyin ti adura itusilẹ ko ni le e gba a silẹ.
Ṣugbọn, ìwọ ní tìrẹ, fi ara balẹ̀ ninu ohun gbogbo.
Ẹ gbọ́ ọ̀rọ̀ OLUWA, ẹ̀yin ọmọ Israẹli; OLUWA fi ẹ̀sùn kan gbogbo àwọn tí wọn ń gbé ilẹ̀ Israẹli pé, “Kò sí òtítọ́, tabi àánú, bẹ́ẹ̀ ni kò sí ìmọ̀ Ọlọrun ní ilẹ̀ náà, 
Ní ọjọ́ kinni, oṣù kinni, ọdún kẹtadinlọgbọn, OLUWA bá mi sọ̀rọ̀, ó ní, 
 ní àtẹ ̀ jáde osman achmatowicz jr.
com/aLz05l4TgxOpe pataki lowo ami ayo kan soso ti Harry Keane gba wole sagbon, eleyi ti oran iko re lowo lati jawe olubori.
Ṣugbọn ẹni tí ó bá ní ìdàpọ̀ pẹlu Oluwa di ọ̀kan pẹlu rẹ̀ ninu ẹ̀mí.
Ìwọ́de EndSARS kìí ṣe ọ̀rọ̀ ẹlẹ́yàmẹ̀yà, ara ti kan àwọn èèyàn ni - Afenifere Grandson to pe ara rẹ ni aarẹ ẹgbẹ awọn ọdọ Yoruba to n pe fun ominira, Young Yorubas for Freedom (YYF), ni awọn ọlọpaa nilẹ Gẹẹsi ti kọkọ mu ni oṣu Kẹjọ, ọdun 2019, nilu London , fun pe o n dunkooko mọ awọn ẹya Igbo ati Fulani lori ayelujara.
Bakan naa ni igbimọ ọhun yoo dabaa iye owo itanran to yẹ ki ijọba ṣan fun ẹnikẹni ti ẹri rẹ ba dantọ.
Ilu naa lo wo lulẹ l'ọsan oni lasiko ti awọn oṣiṣẹ abanikọle n ṣiṣẹ lọwọ.
O ni awọn ti wọn n gb aitọju wa ni ile iwosan Victory to wa nilu Ogere Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Wo Bullet, ọmọ ọdun mẹjọ tó fẹ́ lùwẹ̀ wọ Olympics Bakan naa lo tun ran awọn awakọ leti lati tẹlẹ aṣẹ ere sisa oni kilomita aadọta loju opopona ti wọn n tunṣe naa titi wọn yoo fi pari iṣẹ nibẹ.
Ki ni aarẹ Trump sọ lẹyin ikede yi?
Lasiko ti a fi n ko iroyin yii jọ, wọn ti gbe oku rẹ lọ si ile igbokupamọ si.
Mo rò ó wípé àwọn obìrin tí ó ronú láti ṣe iṣẹ́ tí ọkùnrin máa ń ṣe, gbọdọ̀ gbéraga.
Awọn agbejọro rẹ sọ pe ko si igba kankan ti ajọ EFCC tabi awọn alasẹ miran ni Naijiria tabi ibomiran sọ pe awọn n wa a.
Nípa igbagbọ ni odi ìlú Jẹriko fi wó lulẹ̀ lẹ́yìn tí àwọn ọmọ Israẹli ti yí i ká fún ọjọ́ meje.
A wá mú ìyìn rere wá fun yín pé ìlérí tí Ọlọrun ṣe fún àwọn baba wa ti ṣẹ, fún àwọn ọmọ wa, nígbà tí ó jí Jesu dìde, gẹ́gẹ́ bí ó ti wà ní àkọsílẹ̀ ninu Orin Dafidi keji pé,‘Ọmọ mi ni ọ́, lónìí yìí ni mo bí ọ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Sotitobire latest news: Adájọ́ ṣí àṣùwọ̀n ìfowópamọ́sí Wòlíì Sotitobire, ṣùgbọ́n kò fàyè béèlì sílẹ̀ fún un 19 Ẹrẹ̀nà 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 8 Ògún 2020 Ile ẹjọ giga kan ni ilu Akurẹ ti gbẹsẹ kuro lori aṣuwọn ifowopamọsi pasitọ ijọ Sọtitobirẹ Praising Chapel ni ilu Akurẹ, Wolii Alfa Babatunde.
Ìjàpá ni àṣiri ni pé Ọ̀bọ ma nṣu di dùn, lára igbẹ́ rẹ ni òhun bù wá fún Ẹkùn.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Super touch: Roller Blader ni mí láti ọdún mẹ́jọ sẹ́yìn Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Super touch: Roller Blader ni mí láti ọdún mẹ́jọ sẹ́yìn 19 Sẹ́rẹ́ 2020 Ọpọ igba ni mo ti ṣubu sẹyin- Omotosho Samson Samson Omotosho ti ọpọ maa n pe ni Super Touch Roller Blader ṣalaye fun BBC pe iṣubu oun maa n kọ oun lẹkọọ sii nipa ere idaraya ti oun yan laayo ni.
Bí àwọn ọmọ rẹ̀ bá ń pọ̀ sí i,kí ogun baà lè pa wọ́n ni,oúnjẹ kò sì ní ká wọn lẹ́nu.
Ohun ti o mu gbogbo atotonu yi wa ko ju awuyewuye to nlọ lọwọ lori jijẹ oye iyalọja ati babalọja nilu Ibadan ni ipinlẹ Oyo lasiko yii.
Ko si yẹ ko jẹ pe awọn dokita bẹẹ lo wa n da iṣẹ silẹ niru asiko bayii ti Naijiria n ba ajakalẹ arun finra.
Oríṣun àwòrán, Alaafin Oba Adeyemi III Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
 Kikopa asoju lati Trinidad ati Tobago lodun yii je ki a tun ri ajosepo to jora ati awon igbese to yato ninu asa iran mejeeji yii”.
Se ẹ ranti ọrọ Risikat ati Wasiu ọkọ rẹ nitori oju bulu aya ati ọmọ rẹ meji?
Ilé tuntun ọ̀hún, ni alága àjọ nàá, tó n gbógun ti ìwà ìbàjẹ́ àti ìjẹkújẹ l'órílẹ̀èdè Nàìjíríà, Ibrahim Magu ní '' ó yẹ kí àwọn ọmọ Nàìjíríà yin òun ni fún lílo bílíọ́nù mẹ́rìnlélógún Naira fi kọ́ ilé tó yẹ kí àwọn kọ́ pẹ̀lú ọgọ́rùn bílíọ́nù Naira.
Bichi ti ṣiṣẹ́ gẹ́gẹ́ bi Olùdarí àjọ DSS ní ìpínlẹ̀ Jigawa, Niger, Sokoto àti Abia.
awọn olori ni Baghdada ba Egypt jagun.
Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí 'A ti pa Boko Haram run patapata' - Ọmọogun Ikọ̀ ọmọ ogun ilẹ Naijiria sọ nini ifilọlẹ apapọ ọmọ ogun orilẹede Naijiria ati Cameroon pe awọn ti sẹgun Boko Haram ni àsẹ́wọlẹ̀4 Èrèlè 2018 Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Ati àwọn ìlú wọnyi pẹlu àwọn pápá ìdaran tí ó wà ní àyíká wọn: Jatiri, Eṣitemoa, 
Samuẹli bá sọ fún àwọn ọmọ Israẹli pé, “Bí ẹ bá fẹ́ pada sọ́dọ̀ OLUWA tọkàntọkàn, ẹ gbọdọ̀ kó gbogbo oriṣa ati gbogbo ère oriṣa Aṣitarotu, tí ó wà lọ́dọ̀ yín dànù; ẹ palẹ̀ ọkàn yín mọ́ fún OLUWA, kí ẹ sì máa sin òun nìkan ṣoṣo; yóo sì gbà yín lọ́wọ́ àwọn ará Filistia.
Ekiti Assembly: Ilé ìgbìmọ̀ aṣòfin júwe ilé fáwọn alága ìjọba ìbílẹ̀
Ileeṣe aarẹ ti fesi ní àná pe ki Ọbasanjọ lọ sile iwosan fun ayẹwo to yẹ nitori pe o nilo oniṣegun to mọ iṣẹ daadaa.
Nǹkan tí ẹ bá jẹ kù, kí ẹ máa fi tiwa ránṣẹ́ sí wa o.
nítorí o ti ní ọkọ marun-un rí, ẹni tí o wà lọ́dọ̀ rẹ̀ nisinsinyii kì í sì í ṣe ọkọ rẹ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'IBB da Abiola lẹ́yìn tó búra pẹ̀lú Quran' Ọpọlọpọ anfaani lo wa fun Naijiria ninu adehun naa; ọpọ eniyan ni yoo maa ni anfaani si awọn nkan to ba n ṣe jade kaakiri ilẹ Afrika.
Wọ́n bi í pé, “Ta ni ẹni náà tí ó sọ fún ọ pé kí o ru ẹni, kí o máa rìn?
Ni bayii ti orilẹede Austria ati Sweden ti kun un, a jẹ wi pe iye orilẹede ti Naijiria ti se ilẹkun rẹ mọ bayii ti di marundinlogun.
Nítorí náà, gẹ́gẹ́ bí ẹ ti gba Kristi Jesu bí Oluwa, bẹ́ẹ̀ ni kí ẹ máa gbé ìgbé-ayé yín ni ìrẹ́pọ̀ pẹlu rẹ̀.
Ohun mẹ́fà tí àgbáyé kò mọ̀ nípa Majek Fashek tó d'olóògbé nìyí Ni ọjọ Aje, ọjọ kini, oṣu kẹfa, ọdun 2020 ni gbajugbaja akọrin Raggae ni, Majek Fashek jade laye lẹyin to lo ọdun mẹtadinlọgọta lorilẹ-ede aye.
Oludije keji, Hope Uzodinm, a to jẹ ọmọ wọọdu kan naa pẹlu Nwodu lo gba gbogbo ibo aadọrun naa.
Oríṣun àwòrán, @horpizzle Àkọlé àwòrán, Bi awọn kan ṣe n sọ ina sinu ile ijọsin naa ni awọn mii n jo ọkọ̀ Ṣugbọn ọpọ ero to wa nibẹ ko jẹ ki awọn ọlọpaa ṣe iṣẹ wọn, eyii lo mu ki wọn yin tajutaju si awọn eeyan ọhun.
Zainab Balogun paapaa gba yiyan fun ami ẹyẹ ELOY lataari ipa to kó ninu fiimu naa.
Oríṣun àwòrán, Others Lara awọn akanse isẹ to tun se koko ti wọn daba pe a le lo ẹrọ amunawa fun ni ẹrọ to n gbe ni lọ soke, wa si isalẹ taa mọ si ẹlifetọ, awọn ileesẹ iwadi ati awọn ipese isẹ miran to n waye nisẹ-isẹju lai dawọ duro.
Nibi ifọrọwerọ yii ni ko ba ti l'anfaani lati ṣalaye ọna to fẹ ẹ gbe gba.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ibadan Refuse: E wo àwòrán bí ìlú Ibadan se di ààtàn nítorí ìdòtí 13 Bélú 2019 Akojọpọ aworan lori ọ̀pọ̀ ẹ̀gbin bí òkè tó sọ Ibadan tii se olu ilu ipinlẹ Oyo di ààtàn: Àkọlé àwòrán, Oriṣiriṣi awọn panti ati ilẹ ti awọn eeyan n da si aarin igboro ilu Ibadan.
Eric Lamela lo kọkọ gbayo wọ le fun ikọ Tottenham ninu ifẹsẹwọnsẹ ọhun ki Gonzalo Higuain to d'ayo naa pada.
O ni aare Buhari ti je ki iwa ikora-eni-nijanu nipa lilo awon oro  orile ede yii ati idagbasoke lori eto aabo  wa lokan awon eniyan.
* O ṣe pàtàkì láti mọ àwọn ibi ìtọjú to wà ni àyíka ní ìpińlẹ̀ tàbí ni agbègbè wọ́n * Àwọn elétò ìlera ti gbọdọ̀ kọ́kọ́ lọ fún ìdánilẹ́kọ̀ọ́ bi a ṣe n tọ́jú àjàkálẹ̀ ààrùn ti wọ́n pè ni (Infection, Prevention, And Control IPC).
Lẹ́yìn tí Jesu Oluwa ti bá wọn sọ̀rọ̀ tán, a gbé e lọ sí òkè ọ̀run, ó wá jókòó ní ọwọ́ ọ̀tún Ọlọrun.
Oluwa mi, a yá àáké yìí ni!
ni lati bebe fun ifowosowopo won, ki o lee rorun fun ile ise ọlọpaa lati koju
Joṣua bá fi akọ òkúta ṣe abẹ, ó fi kọ ilà abẹ́ fún gbogbo ọkunrin Israẹli ní Gibeati Haaraloti.
Isaaki bá tọ Abimeleki ọba àwọn ará Filistini lọ ní Gerari.
Lọdun 2019, Miracle gba iwe ẹri gẹgẹ awakọ ofurufu.
Fiimu Africa Magic n ṣe igbelaruge asa ati iṣe idẹyẹsini ni ilẹ Igbo'Arabinrin Maduagwu fikun wi pe o buru de ibi pe awọn eniyan ma n fi ẹya wọn pamọ nitori idẹyẹsi yii.
Isẹlẹ naa lo mu ki ibinu awọn ọdọ tubọ ru soke, ti awọn janduku kan si ya si igboro lọjọ keji yika Naijiria, wọn n jo ile, mọto, ileesẹ ijọba, agọ ọlọpaa, bẹẹ ni ọpọ ẹmi ba rogbodiyan naa rin.
Wọn ni abala akọkọ atunsẹ afara ọhun yoo waye fun oṣu mẹta, nigba ti abala atunṣẹ keji yoo waye fun oṣu mẹta miran.
Orí kó Ààrẹ yọ lọ́wọ́ àdó olóró Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Sunday Ayẹni: Damilọla, aya ọmọ mi fìgbónára sọ mi sókùnkùn alẹ́ Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Àṣà iyàwó púpọ̀ ṣi pọ̀, ni àwọn ilú kékeré tàbi Abúlé laarin àwọn àgbẹ̀ àti àwọn ti kò kàwé.
Burkina Faso jẹ orilẹ ede ti awọn ọmọ Naijiria fẹran lati maa lọ ti o si ni Wura ati Fadaka lọpọ yanturu.
Ọ̀rọ̀ ìfẹ́ ti wọn fi ń lọ̀ mí lágbo àmúlùúdùn ni ìṣòro kan tí mo ní - Lizzy Jay ọmọ Ibadan Coronavirus Cases in Africa:Ẹ wo ọ̀nà tí àwọn èniyàn ń gbà rí oúnjẹ̀ jẹ lásìkò àrùn Coronavirus Coronavirus: Opó afọ́jú kan sọ̀rọ̀ lórí ìnira tó ń kojú pẹ̀lúu coronavirus Bi a ko ba gbagbe ni nkan bi ọsẹ meji sẹyin ni iroyin gbode pe o ti ko arun Covid-19.
O so pe: “Aare Muhamamadu Buhari ti buwolu ekunwo owo osu osise sinu iwe ofin ati ilana Act 2019.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Opo eniyan ku ninu ikolu fulani darandaran nipinle Benue Wọn fikun wipe awọn ọlọsa naa tun kopa ninu isẹlẹ naa, nipa kiko ohun ini awọn eniyan ti ọfọ ba see.
Bákan náà ni ìwọ̀n àwọn yàrá mẹtẹẹta rí.
Ọ̀nà wo lowó osù tuntun yóò tọ̀, kó tó dé àpò òsìsẹ́?
Fun ipinle Ogun ni apa iwo- oorun guusu orile-ede Naijiria , ile-ise Faranse  Francaise de Development (AFD) pelu ifowosowopo ile ise alamojuto eto ondokowo lorile-ede Naijiria ti a mo si Nigeria Sovereign Investment Authority yo ko awon ondokowo wole ati yo si fun million lona igba owo dola lati fun awon eniyan ti won ba gba ile won ni owo  pada fun anfaani gbingbin igi ni ipinle naa.
Ṣugbọn bí wọ́n bá ní kí á máa bọ̀ lọ́dọ̀ àwọn, a óo tọ̀ wọ́n lọ.
 kí ó tó di alàkóso yunifásítì ìlú Ìbàdàn , Ó jẹ ́ alàkóso ilé Ìwòsan ti yunifásítì ìlú Ìbàdàn , ilé Ìwòsan yunifásítì tí ó tóbi jù lo in orílẹ ̀ - èdè nàìjíríà .
 orúkọ tí a ń pe ajé tàbí agbè wọ ̀ nyí ní Ìwọ ̀ oòrùn Èkìtì ni , Èyé ajé tàbí Èyé ùlù , kugú , ọ ̀ pẹẹẹrẹ àti agogo .
Wọ́n gbójú sókè sí OLUWA, wọ́n láyọ̀; ojú kò sì tì wọ́n.
bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé n kò ṣe ibi,adura mi sì mọ́.
Wọ́n sì ń rú ẹbọ sísun ní ilé OLUWA lojoojumọ, ní gbogbo àkókò Jehoiada.
Nítorí náà, OLUWA sọ nípa Jehoiakimu, ọba Juda, ọmọ Josaya pé, wọn kò ní dárò rẹ̀, pé,“Ó ṣe, arakunrin mi!
Ṣugbọn èmi wá ń sọ fún yín pé, ẹni tí ó bá bínú sí arakunrin rẹ̀ yóo bọ́ sinu ẹjọ́.
Gẹ́gẹ́ bí òwe ìgbà àtijọ́ ti wí, àwọn eniyan burúkú a máa hùwà burúkú, ṣugbọn n kò ní ṣe ọ́ ní ibi kan.
Pamela Okoroigwe tó jẹ́ agbẹjọ́rò fún ètò ìrànwọ́ Legal Defence and Assistance Project (LEDAP) sọ pé ''ó wọ́pọ́ láti bá ẹni tó ti gba ìdájọ́ ikú láti bi ọgbọ̀n ọdún.
A ṣì ń ṣèwádìí lọ́wọ́ lórí àwọn t'ọ́ta ìbọn pa lọ́jọ́ ọdún Eid n'Ibadan - Ọlọ́pàá 'Ọ̀fọ̀ ọkọ ló mú ìyàwó Ajimobi ṣe ohun tó ṣe sí mi, ṣùgbọ́n n kò bínú síi' O ni omi ẹkun n gba oju oun kan nigbagbogbo nitori pe oun a maa ṣe afẹri awọn nnkan to pọ nigba ọkọ oun.
Lọjọ Kẹwa oṣu Kẹfa ọdun 2020, eeyan mẹwa lawọn agbebọn pa ni Faskari ti wọn si tun pa eeyan mẹẹdogun loṣu to tẹle.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Gómìnà Makinde fẹ́ dá àjọ tó ń gbógun ti ìwà ìbàjẹ́ sílẹ̀ l'Oyo 10 Òkùdu 2019 Oríṣun àwòrán, WIKIPEDIA Àkọlé àwòrán, Ipinlẹ Kano wa lara awọn ipinlẹ to wa lara awọn ipinlẹ to ni ajọ to n gbogun ti iwa ibajẹ ni ipinlẹ naa.
O fikun pe laipẹ ni wọn yoo gbe awọn afurasi naa lọ sile ẹjọ.
 Àwọn ìtàn wọ ̀ yí fi múlẹ ̀ wípé odùduwà ni elédùmarè rán wá sáyé láti wádá ayé sorí ẹ ̀ kún omi .
Oríṣun àwòrán, Twitter Ọgbọnjọ, Oṣu Kẹfa ni Gomina ipinlẹ Ondo kede pe oun ti ko arun Coronavirus, ti oun si ti ya ara oun sọtọ.
Owó, ọmọ, àlááfíà àti àìkú á bá gbogbo wa gbé ni 2020- Oloye Ifaleke Ògo tuntun yóò sọ ní ọdún 2020!
Ajimobi: Orúkọ èmi, Akala, Ladoja, Adebayo Faleti àtàwọn míì
Àbí ẹ kò mọ̀ pé àwa onigbagbọ ni yóo ṣe ìdájọ́ àwọn angẹli!
Òṣìṣẹ́ ẹka arinrinajo ọkọ̀ òfúrufú Nàìjíríà fagilé ìyanṣẹ́lódì Saraki gbé N16.
Oríṣun àwòrán, Instagram/Seyi Awolowo Bẹẹ ba gbagbe, awọn oludije mẹrindinlọgbọn lo bẹrẹ eto BB Naija fun tọdun yii, ti wọn pe akọle rẹ ni 'Pepper Dem', ti oludije mọkanlelogun si ti ja kulẹ lasikokan tabi omiran.
110 ni ìyè àwọn àgbẹ̀ tí Boko haram dúmbú ní Borno tí dì báyìí-UN Bí mo bá leè rí ọmọ alágbe t'áyé fẹnu sí pé mo fi ẹlẹ́rìndòdò lá lójú, máa kúnlẹ bẹ ẹ - Motara Wo ohun tó ṣẹlẹ̀ sí àwọn ọba tó kọ ifá sílẹ̀ gbé Bíbélì àti Kùránì Èèyàn 82 tún ti ní COVID-19 ní Nàìjíríà Ẹka ti Ikeja ni ipinlẹ eko jẹ ko di mimọ fawọn araalu loju opo Twitter pe ina ti ko si waye latari irinṣẹ awọn to dẹnukọlẹ.
Marcus ṣalaye pe ọkan oun balẹ nitori ko si ẹni to n gbiyan lati yin oun nibọn nitori pe oun jẹ alawọ dudu.
Títẹ̀lé ìṣe wọn nìkan kò tẹ́ ọ lọ́rùn, bẹ́ẹ̀ ni ṣíṣe ohun ìríra bíi tiwọn kò tó ọ.
Mummy Calm Down di aṣojú iléeṣẹ́ ńlá kan l'Abuja A dúpẹ lọ́wọ́ ará ìlú fún àtìlẹ́yìn wọ́n nígbà táa n wa Sunday Shodipe-iléèṣẹ́ ọlọ́pàá Loju opo Twitter niṣe lawọn eeyan kan n gboṣuba kare fun Vee bo ti ṣe da Ebuka lohun tawọn miran si n sọ pe ki awọn eeyan sọra fun Ebuka.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ọdún kan lẹ́yìn ogun musulumi Rohingya, ìbànújẹ̀ dorí àgbà kodò Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Mi o fẹẹkan ni mo fẹ dupo aarẹ' Olùdíje fún ipò aàrẹ (Republican) lọdun 2008 jáde láyé Ẹ̀wẹ̀, akọ̀ròyìn wa tó ṣe abẹwo kaakiri erekusu ilu Eko jabọ pe wámúwámú ni àwon òṣìṣẹ́ agbófinró dúró láti mójútó ìgbòkègbodò ọkọ̀ nigba ti afara naa wa ni titi pa.
O ni eredi ree ti ijọba Eko ṣe gbe ọna abayọ owo tuntun naa kalẹ lati lee ri owo to yẹ gba lọwọ awọn ileeṣẹ ọhun.
orile ede kan si omiran (International Organisation for Migration IOM)ati ajo
Ẹ̀rù ńlá ba gbogbo ìjọ ati gbogbo àwọn tí ó gbọ́ nípa ìṣẹ̀lẹ̀ wọnyi.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ìwà ipá nínú ìdílé máa ń bí ìgè àti àdùbí ni tó lè já sí ikú Ninu alaye rẹ, alaga FIDA, Deborah Collins sọ pe ijọba ṣe nkan ti ofin fun un ni agbara lati ṣe ni.
Ìgbìmọ̀ aláṣẹ APC jáwe lọ gbéle rẹ fún ìgbákejì alága: Hilliard Eta!
Ìrẹ́pọ̀ yìí ni a ní pẹlu Baba ati pẹlu Ọmọ rẹ̀ Jesu Kristi.
tiwa-n-tiwa yoo maa waye lorile ede yii.
Nigeria Senate Decides: Ta ni àṣẹ ilé aṣòfin àgbà Nàìjíríà yóò já mọ́ lọ́wọ́?
 Ati lati jẹ ki awọn ara ilu mọ iṣẹ ribribi ti ijọba n ṣe si ẹkun yii, eyi ti yoo jẹ ki ijọba Eko tun tẹ siwaju.
Àkíyèsí mi sí àwùjo fi hàn wí pé púpò nínú àwa ènìyàn àwùjo ni a máa n fún jíja olè àti ìdigunjalè ní Ìtumò kannáà ní èyí tí wón sì yàtò gédégbé sí ara won.
Ọkàn Hẹrọdu a máa dàrú gidigidi nígbàkúùgbà tí ó bá gbọ́ ọ̀rọ̀ Johanu, sibẹ a máa fẹ́ gbọ́ ọ̀rọ̀ rẹ̀.
Ẹ múra ogun,ẹ rú àwọn akọni sókè.
Idi si ree ti ọpọ ọmọ Naijiria fi ń beere pe ki lo ṣe agba oṣere Ibrahim Chatta, to fi dùbúlẹ̀ lóri ìbùsùn nilé ìwòsàn.
Iroyin tilẹ fi kun un pe afurasi naa tun fi irin gba ọmọdebinrin naa to jẹ akẹkọọ ileewe girama ijọba naa lori eyi to da ọgbẹ nla si agbari rẹ.
Bakan naa ni oju opo yii maa ṣagbejade mẹwaa loke tente lara awọn orin, ere idaraya, awọn oṣere ati fiimu wọn gangan to fi mọ ifọrọwanilẹnuwo to fakọyọ.
Àwọn Ẹ̀ṣẹ̀ Tí Ó Nílò Ẹbọ Ìmúkúrò Ẹ̀ṣẹ̀.
Musiliu Ayorinde Akinsanya ti gbogbo eniyan mọ si MC Oluọmọ jẹ alaga fun ẹka ẹgbẹ naa tẹlẹ ni agbegbe Oshodi ki o to di Alaga fidihẹ bayii.
Itọju oloyun, jijẹ ounjẹ aṣaraloore lai ṣe wahala tabi hílàhílo maa n jẹ ki eso inu aboyun dara.
Ile-ise to n mojjuto eto ilera
Wọ́n ń pe afẹ́fẹ́ náà ní èyí tí ó wá láti àríwá ìlà oòrùn.
Oun oun naa gboṣuba fun AJ fun awọn aṣeyọri rẹ lagbo ẹṣẹ kikan, amọ oun mọ awọn ibi ti Joshua ku si ninu ẹṣẹ kikan.
Èmi OLUWA ní mo sọ bẹ́ẹ̀.
Bi ẹnikẹni ko ba wa yiwa pada, awọn alaṣẹ yoo gbe igbesẹ lati ṣe ijiya to ba tọ.
Ìyà mi ti fi apá ọmọdé jẹ̀ àkàṣù ẹ̀kọ, òun ti fi ẹesẹ̀ àgbàlagbà jẹ ìrẹsì, òun si ti fi párì ẹ̀rẹ̀kẹ́ géńdé wa gàrí mu.
kíndìnrín rẹ̀ mejeeji, ati ọ̀rá tí ó bò wọ́n níbi ìbàdí ati gbogbo ẹ̀dọ̀ rẹ̀.
Awọn wọọ kilu mọ lagbo afẹ lorilẹ-ede Naijiria ti n pe fun fifi ofin gbe sẹnetọ to n ṣoju ẹkun Adamawa North nile aṣofin agba Naijiria naa.
Kosi eegun kan ti yoo wọ aafin mi to gbọdọ dọti."
"Oríṣun àwòrán, PIUS UTOMI EKPEI 'Buhari ti kuna' Ajafẹtọ ọmọniyan kan, comrade Kabiru Dakata ni oun ni toun lero pe asiko ti to fun aarẹ Naijiria lati gbe igbesẹ idajọ O ni ""idajọ akọkọ ta n reti latọdọ aarẹ Buhari ni pe ko fipo aarẹ silẹ, nitoripe ootọ́ ni pe o ti kuna ni ẹka abo, eyi to jẹ ibi to yẹ ko ti ko ipa pataki""."
Nítorí wọ́n rò pé nípa ọ̀rọ̀ pupọ ni adura wọn yóo ṣe gbà.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Risikat Moromoke Azeez: Inú èmí àti Òbí mi dùn nígbà ti Risi bí ọmọ olójú búlù- Wasiu Orukọ awọn ọmọdebinrin oloju buluu naa ni Kaosara ati Hassanat Abdulwasiu.
 Èkejì ní Àsà àti ìṣe yorùbá lórí ìsìnkú nílẹ ̀ yorùbá .
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Àlàyé rèé lórí ìdí tí Gbenga Daniel fi kowe fi PDP sílẹ̀ Kò sí èèyàn kánkan tó kù nílé tó wó ní Ibadan- NEMA Offa Bank Robbery: Àwọn ọlọ́pàá fí ìyà jẹ wá láti sọ nkan ti wọn fẹ ká sọ ni Àlàyé rèé lórí ìdí tí Gbenga Daniel fi kowe fi PDP sílẹ̀ Tẹlẹ ri, ohun ti iwadii n sọ ni pe, eeyan to le diẹ ni miliọnu mẹta lo ni kokoro arun naa,.
Ṣùgbọ́n bí mo ti n ti ibi tí àkísà ẹ̀wù náà wà bọ̀, mo yà sí ọ̀dọ̀ Ahọ́ndíwúrà, mo fi ọwọ́ kan ahọ́n rẹ̀ gígùn, bí omi tí ń bẹ lọ́wọ́ mi sì ti kan ahọ́n náà ni mo ri i ti o n ká wọ inú bí ẹ̀wọ̀n agogo.
Aare soro idupe yii ni asalẹ ana lojo Isegun nile ipolongo egbe
Gomina Makinde kẹdun pẹlu ileeṣẹ ọlọpaa lori ọlọpaa marun un to ba iṣẹlẹ naa lọ ati ọlọpaa mejila to farapa nipinlẹ Oyo.
Lionel Messi, lati orilẹede Argentina ati ẹgbẹ agbabọọlu barcelona pẹlu Cristiano Ronaldo ti orilẹede Portugal ati ẹgbẹ agbabọọlu Real Madrid tẹlẹ ki o to darapọ mọ Juventus ni ọdun 2018 ni wọn n pin ami ẹyẹ yii mọ ara wọn lọwọ lati nnkan bii ọdun mẹwa sẹyin.
Mò ń fi ọwọ́ yín sọ̀yà.
Wo oríṣìí oúnjẹ márùn ún tó lè dẹ́kun ikùn yíyọ àti ara àsanjù Kí làwọn nǹkan tó lè rán ọkùnrin sí ọ̀run alákeji lásìkò ìbálòpọ̀ pẹ̀lú obìnrin?
Odidi talẹnti wúrà marundinlaadọrin ni ó lò lórí ọ̀pá fìtílà yìí ati àwọn ohun èlò tí wọ́n jẹ mọ́ ti ọ̀pá fìtílà.
Èyí ni ìyà tí yóo jẹ ilẹ̀ Ijipti ati gbogbo orílẹ̀-èdè tí kò bá wá síbi Àjọ Àgọ́.
 Seere Ẹ̀rẹ̀lẹ́  Ẹrẹ́nà Igbe Ẹ̀bìbí Okúdù Agemọ Ògún Ọ̀wéwè Ọ̀wàrà Béelú Ọ̀pẹ.
Amọ, ko buru, ẹlẹran ara ni mi, mi o wà lai ni abuku.
A ni lati ge eto ode kuru ki a si koju mọ riro awọn ọdọ lagbara.
Nítorí náà, ẹni tí ń tọ́jú wọn bẹ̀rẹ̀ sí fún wọn ní ẹ̀wà, dípò oúnjẹ aládùn tí wọn ìbá máa jẹ ati ọtí tí wọn ìbá máa mu.
 Ìtàn yìí tẹ ̀ síwájú pé ọkùnrin yìí ní aáwọ ̀ ni ààfin , èyí ló mú kí odùduwà ṣe fún aláayè ní ilẹ ̀ sí ìráyè tí a mọ ̀ sì modákẹ ́ kẹ ́ lónìí .
Inú Titu dùn si yín lọpọlọpọ nígbà tí ó ranti bí gbogbo yín ti múra láti ṣe ohun tí ó sọ fun yín ati bí ẹ ti gbà á pẹlu ìbẹ̀rù ati ìwárìrì.
“Nígbà náà, àwọn òkè ńlá yóo kún fún èso àjàrà,agbo mààlúù yóo sì pọ̀ lórí àwọn òkè kéékèèké.
Orile ede merinla lati ile Afrika ni yoo kopa pelu egbe osere idanilaraya metadinlogun lati ile okeere pelu awon egbe osere lati ipinle ogbon ni Naijiria ni yoo kopa ninu todun 2018.
Irú ohun tí baba yín ṣe ni ẹ̀ ń ṣe.
Kí àjèjì tí ó faramọ́ OLUWA má sọ pé,“Dájúdájú OLUWA yóo yà mí kúrò láàrin àwọn eniyan rẹ̀.
obinrin wa si odo aare , iyaafin Sani so pe a ni awon obinrin to je pe won yege
Yatọ si gbogbo ipenija wọn yi, awọn kan ti sawari pe sise isẹ lati ile lasiko ajakalẹ yi si le jẹ ọna isẹ to sanfaani pupọ paapaa ti eeyan ba ni awọn isesi to daa ati ibalẹ ọkan ti yoo mu ki isẹ lọ deede.
 Adamu ni o le ni egberun meta awon oluko ti o ti padanu
nítorí pé ẹ̀kọ́ tí wọn bá kọ́ ọ yóo dàbí adé tí ó lẹ́wà lórí rẹ,ati bí ohun ọ̀ṣọ́ ní ọrùn rẹ.
9 Bẹ́ẹ̀ni, lõtọ́, lati fi èdídí dì wọn títí di ọjọ́ náà nígbàtí ìbínú Ọlọ́run yíò di títú jade sí orí àwọn ènìyàn búburú láì ní òṣùnwọ̀n—
Ọkunrin kan wà níwájú rẹ̀ níbẹ̀ tí gbogbo ara rẹ̀ wú bòmù-bòmù.
Bákan náà lo tún fi ogun rẹ gbà rí pé ayédèrú àti magomago ibo kò ní wáyé rárá lásìkò ijoba tòun.
Akitiyan OIC lori awọn to ṣatipo Ẹgbẹ OIC ti gbalejo awọn atipo bi miliọnu mejidinlogun lati igba ti ẹgbẹ ọhun ti wa titi di ọdun 2010 Awọn orilẹede to jọ ọmọ ẹgbẹ OIC ti n gbalejo awọn atipo lati awọn orilẹede ti rukerudo ti n ṣẹlẹ lati ọdun 2010 Oríṣun àwòrán, Wilkipedia Àkọlé àwòrán, Kinni o mọ nipa OIC?
Asofin Ekweremadu lo n fi oro yii to awon igbimo asofin leti nipa isele naa, pe ijoba apapo ti yo ise akanse to ye ki won se lati fi se atunse lori irinna oju irin to ye ki won se ni ila oorun kuro.
Oríṣun àwòrán, Ronke Ojo Anthony Ninu awo naa si lo tun ti n salaye pe igi gbongbo to n so eso fun ẹni ti ebi n pa ni Oluọmọ jẹ, to si ni ni ori gbogbo ti ọlọjọ ibi naa ti da lọla, yoo jẹ ko maa lọ siwaju si, ti Ọlọrun yoo si jẹ ko se ọpọlọpọ ọdun laye.
2019 Election: Ọbasanjọ ní ìrètí wà pé Nàíjíríà kò ní pẹ́ ní ààrẹ tuntun
Arakunrin to doloogbe naa, Muhammed Jamiu to jẹ atunnaṣe (electrician) to si ni ọmọ kan, ni wọn ba ninu yara rẹ to pokunso ni agbegbe Yakubu Habibu, Agura, Sabo, Sagamu.
Ṣugbọn awọn dokita meji tawọn ẹni ẹbi rẹ gba lati ṣe ayẹwo ohun to ṣokunfa iku rẹ, esi ayẹwo naa si fihan pe wọn fun un lọrun pa ni.
Wọn ni nigba ti wọn fọrọ wa lẹnu wọ, o ni ọdun 1961 ni wọn bi oun, eyi to yatọ si 1959 to wa ninu iwe fasiti rẹ.
Ina naa ti jo gbogbo ohun ini wa lọ.
Èyí ni ọrẹ Eliabu ọmọ Heloni.
 wọ ́ n a ní :.
N óo fìyà jẹ ayé nítorí iṣẹ́ ibi rẹ̀,n óo sì jẹ àwọn ìkà níyà nítorí ẹ̀ṣẹ̀ wọn.
 kilómítà mẹ ́ tàlá ni Ọ ̀ ra-Ìgbómìnà sí Ìlá-Ọ ̀ ràngún tó wá ní ìpínlẹ ̀ Ọ ̀ yọ ́ , kílómítà mẹ ́ ta péré ni Ọ ̀ ra sí Àránọ ̀ rin tó wà ní ìpínlẹ ́ kwara , ó sì jẹ ́ kìlómítà kan péré sí Ọ ̀ sàn Èkìtì tó wà ní ìpínlẹ ̀ oǹdó .
"NDDC kò gbé iṣẹ́ kankan jáde si ìta debi ti mo fẹ́ ri kọngila gba.
Awọn mẹfa ni wọn jọ dupo olori ile, TrikyTee nikan ni ko dije nitori oun ni o wa nipo olori ki Nengi to jawe olubori.
Òṣiṣẹ́ Emzor tó ta Codeine fun BBC ti bọ́ sọ́wọ́ ọlọ́pàá
Àìle è ka kéú ló sọ mí di Krìstíẹ̀nì - Adewale Ayuba FRSC: Èèyàn mẹ́jọ ló kù nínú ìjàmbá ọkọ̀ nípìnlẹ̀ Ògùn Ìdààmú ńlá ńbọ̀ fún Nàíjíríà lábẹ́ ìjọba Buhari - Ọbasanjọ Lara awọn ere ti Dagunro ti se nigba aye rẹ ni Ija Abija, Dagunro, Jagunmolu, Ibinu Ọmọ Eleye, Abẹni Agbọn, Kakaki 'leku, Ikilọ agba ati Inu bibi.
Ó wù mí bíi pé kí n wà lọ́dọ̀ yín nisinsinyii, kí n yí ohùn mi pada, nítorí ọ̀rọ̀ yín rú mi lójú.
Eyi lo si fa itahunsira laarin oun ati Naira Marley.
Ewerikumo Siasia to jẹ ẹbi Siasia lo fidi ọrọ yii mulẹ fun BBC wi pe iya agbabọọlu Naijiria nigba kan ri, Beauty Siasia kuro lakata awọn ajinigbe lalẹ ọjọ Abamẹta.
Wo àwọn gbàgede rẹ̀, bóyá o óo rí ẹnìkan,tí ó ń ṣe ìdájọ́ òdodo,tí ó sì ń fẹ́ òtítọ́,tí mo fi lè torí rẹ̀ dáríjì Jerusalẹmu.
Ẹ fi iṣẹ́ kún iṣẹ́ wọn.
Awọn nọmba ibanisọrọ naa ni 08023169485, 08033565529 ati 08052817243 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
,’’Bakan naa, inu mi dun pupo lati darapo mo iko agbaboolu yii.
Àwọn olùgbọ ́ kó ipa pàtàkì nínú eré àpíìrì tí ó jẹ ́ ọ ̀ kan nínú lítíréṣọ ̀ aláfohùnpè .
O tun maa n fi ọkọ rẹ gbe awọn oloyun to n rọbi lọ sile iwosan laigba kọbọ lọwọ wọn.
oun yoo yan lọsẹ  to n bọ.
Ẹnìkan ló fi ikú ìbọn rán àwọn ọmọdé kékeré lọ sọ́run òjijì ní Amẹrika ni ìjọ́sí.
A mọ pe awọn igbes yi yoo gba ka ṣe ifarada kekeeke ati awọn mi ti yoo ga'' ''Ṣugbọn o di dandan, a ni lati gba akoso itọju ara wa'' Oríṣun àwòrán, EPA Àkọlé àwòrán, Wọn n fin awọnile ijọsin ni Naples lọna ti koju Coronavirus Yatọ si awọn to wa ni ariwa agbegbe Lombardy, awọn to wa ni Modena, Parma, Piacenza, Reggio Emilia, Rimini, Pesaro ati Urbino, Alessandria, Asti, Novara, Verbano Cusio Ossola, Vercelli, Padua, Treviso ati Venice lọrọ yi kan.
Awọn aṣofin f'ọwọsi Imam gẹgẹbi adajọ agba ile ẹjọ Sharia
Coronavirus: Àjọ elétò ìlera lágbàyé tí pe Coronavirus ní àjàkálẹ̀ àrùn káàkiri àgbáyé
Ẹwẹ, ajọ yii kan naa tun ti kede pe eeyan 1,479 miran ti lugbadi arun naa ni Naijiria.
Àkọlé àwòrán, Tẹrin tọyaya tagbara n rin ko odo lọna lawọn ewe rin pade Oba Alayeluwa loni Ààrẹ Muhammadu Buhari buwọ́lu owó ìṣúná ọdún 2019 Kò sí àyè fún fíìmù eré ìfẹ ṣíṣe ni Kannywood mọ́ Ọ̀gọ̀rọ̀ èèyàn lórí ayélujára bú Dalung lórí owó IAAF Aisha Buhari ké gbàjare pé ètò ìjọba Buhari kò ṣànfàní f'óbìrin Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Bode George: òòtọ́ ni ìkìlọ̀ Obasanjọ ati Soyinka Ọpọlọpọ idije Tan-mọọ lo waye nibi eto akanṣe fawọn ewe naa bii ti idije ìṣirò, ijo ibilẹ ati afihan aṣa Yoruba loriṣiiriṣii.
Ẹran ọ̀sìn àwọn mejeeji pọ̀ tóbẹ́ẹ̀ tí ilẹ̀ náà kò fi láàyè tó mọ́ fún wọn láti jọ máa gbé pọ̀.
Oniruru ẹsun bii ipaniyan nwọn ti fi kan an saaju asiko yii sugbọn ileejọ ni ko jẹbi ẹsun yii bi o ti l ẹ jẹ wipe olori ẹgbẹ oselu Economic Freedom Fighters, Julius Malema ni oun ri Ramaphosa gẹgẹbi ẹni ti yoo maa ta awọn eeyan rẹ lọpọ fun awọn onisowo lati ilẹ okeere atawọn atọhunrinwa.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Small Doctor: Mo kórira igbó, ọtí àti sìgá nítorí màmá mi lòdì si Asuquo ọmọ bibi ìpínlẹ̀ Akwa Ibom bẹ ẹni to ni sọ̀ọ́bù ti o já pé ki wọ́n fi orí jin òun ni èyi to sàlàyé pé ó mu ẹbi to n pa oun dinku.
Láti Mitika wọ́n lọ sí Haṣimona.
Ọkunrin náà bá bèèrè lọ́wọ́ rẹ̀ pé, “Kí ni orúkọ rẹ?
Laipẹ yii ni Blessing tun sọ fawọn akọroyin pe ikebe ti Eleduwa fi jinki oun tobi ju ohun ti oun le dọwọ bo lọ.
 igbà tí olórí yà papòdà ni awọṅ láíubáwó amúnilérú àti àwọn òyìbó anúnisìn sọ ìjọba ńlá wọn di yẹpẹrẹ .
Diẹ lara awọn aworan ibi ayẹyẹ ti Google ti ṣe ifilọlẹ yii ree ladugbo Lekki nilu Eko.
Ìjọ Satani dá MI loùn lórí ọ̀rọ̀ Fatoyinbo Ò ti pé ọdún 27 tí Shah Rukh Khan ti ń se fíìmù India Àrùn Ẹ̀yi di ilọ́po mẹ́ta jákèjádò àgbáyé lọ́dún 2019 - UN Ìjọba Germany mú afurasi ọmọ Boko Haram Ọpọ awọn ti wọn fọrọ wa lẹnuwo gba pe lootọ lawọn n gbe ni ilẹ Larubawa ṣugbọn igbagbọ wọn ninu ẹsin n dinku sii ni.
Funke Akindele O ṣeeṣe ki Funke gunle irinajo pọn lọ si ile Dubai laipẹ yii o.
Dòdò Ìkirè: Ó dúdú lára sùgbọ́n oyin ni lẹ́nu
“Oluwa ni ó ṣe èyí fún mi.
OLUWA yóo gbà mí là,a óo fi àwọn ohun èlò orin olókùn kọrin ninu ilé OLUWA,ní gbogbo ọjọ́ ayé wa.
Mò ń sọ fun yín pé bí ẹ kò bá ronupiwada, gbogbo yín ni ẹ óo ṣègbé bákan náà.
Àwọn ìpèníjà òṣèlú tí ó ń kojú wọn ní Hong Kong lẹ́yìn Àkójọpọ̀ Ẹgbẹ́ Alábùradà; 2014 Umbrella Movement kò ṣe àjòjì sí Chemi Lhamo, ṣùgbọ́n ó bá àwọn ará Hong Kong kẹ́dùn, ó pẹ̀tù sí wọn lọ́kàn pé kò kí wọ́n máà ṣe juwọ́ sílẹ̀:
O ni alaga apapọ fun ẹgbẹ oselu PDP, Uche Secondus lo ko igbimọ ẹlẹni mọkanlelogun sodi, lati se abẹwo ikinni si ọdọ Ọbasanjọ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Àwọn gómínà ilẹ̀ Yoruba ní àwọn yòò dojú ijà kọ jàndùku Fulani 8 Òkùdu 2019 Oríṣun àwòrán, Osun State Government Àkọlé àwòrán, A kò lè gba àwọn jandùkú Fulani láàyé nílẹ̀ Yoruba -Awọn gómínà Ailaṣọ-lọrun pakàá, ti n gba apero ọmọ eríwo bayii ni ipinlẹ Yoruba.
Niṣe lo rọra mu eyin akonisita bi ọmọ ọjọ mẹjọ naa dani, to si rọra n ba iṣẹ rẹ lọ.
Amasa kò fura rárá pé idà wà ní ọwọ́ Joabu.
Oju opo ayelujara 'Porn Hub' sọ pe eyi jẹ abajade akiyesi wọn nipa awọn to wo fidio ibalopọ loju opo wọn l'ọdun 2019.
Kí alufaa jó aṣọ náà, ibi yòówù tí àrùn náà lè wà lára rẹ̀, kì báà jẹ́ aṣọ onírun tabi olówùú, tabi ohunkohun tí wọ́n fi awọ ṣe; nítorí pé irú àrùn tí ó máa ń ràn káàkiri ara ni; jíjó ni kí wọ́n jó o níná.
Won te oku Tsvangirai si ibi isimi ikeyin leba iyawo re akoko Susan.
Teach your children Yoruba: Wo àwọn òyìnbó tó ń kẹ́kọ̀ọ́ èdè Yorùbá ní Michigan, America Obasanjọ dúró lórí ọ̀rọ̀ tó sọ lẹ́yìn ikú Kashamu- Kehinde Akinyemi Àwọn akẹ́kọ̀ọ́ da ìdánwò WAEC rú, wọn gún infijilátọ̀ ní 'compass' Irinwó lé méje èèyàn ló gbàwòsàn lọ́wọ́ Covid-19 lọ́jọ́ Àbámẹ́ta, 453 míì tún lùgbàdì rẹ̀ Oríṣun àwòrán, Getty Images Aarẹ orilẹ-ede America, Donald Trump ti ṣeleri lati darapọ mọ ipade naa.
 Ìtàn sọ pé àtọmọdọ ́ mo sẹ ̀ pẹ ̀ lúwà tí ó jẹ ́ awùjalẹ ̀ ìkejìdínlógún ti ilẹ ̀ Ìjẹ ̀ bú ni olúbákin jẹ ́ .
Africa Events: Ilẹ̀ Afrika lọ́sẹ̀ yìí nínú àwòrán!
Wo ìdí tí wọ́n ṣe lé Erica dànù kúrò nílé BBNaija l'ọ́sẹ̀ yìí Kí ló ṣe Ibrahim Chatta tó fi dèrò ilé ìwòsàn?
 Wọ́n jí ọmọ yìí gbé láti máa fi tọrọ bárà l'Eko Kí ló ṣe ikú pa Adediwura Lateefat Bello lẹ́yìn ọ̀sẹ̀ méjì tí wọ́n ń wá a?"
 a lee maa le se bi ijoba se n se ti won maa n ran awon eniyan bi irinwo lo sile -mimo , bi igba ti mo je gomina ipinle Kwara.
Olúwa yó máa fúnwa ní alékún okun àti agbára o.
Orúkọ ìyá rẹ̀ ni Abija, ọmọ Sakaraya.
O ni ko si ofin kankan to ṣe atilẹyin fun lilo awọn ọmọ ogun nigba idibo.
Iranṣẹ náà dá Saulu lóhùn, ó ní, “Mo ní idamẹrin owó ṣekeli fadaka kan lọ́wọ́, n óo fún un, yóo sì sọ ibi tí a óo ti rí wọn fún wa.
Sugbọn ni agbo oselu Naijiria nilẹ toni to mọ yi, awọn oloselu ko fi tẹgbẹ se.
NCDC fikun pe awọn ipinlẹ ti ọrọ naa kan ni ipinlẹ Eko,Ogun, Plateau, Edo,Kaduna,Oyo,Abuja, Adamawa,Jigawa, Ebonyi, Borno, Nasarawa, Bauchi, Gombe, Enugu ati Bayelsa.
“A nilo lati gbaa oja kan ba yii, eyi ti o je ohun aridaju lagbaye.
agogo mẹjọ owurọ ni eto idibo yoo bẹrẹ pẹlu ṣiṣe ayẹwo orukọ awọn oludibo
Ó fọ́ wọn bí afẹ́fẹ́ ìlà oòrùn tií fọ́ ọkọ̀ Taṣiṣi.
Awọn ajọ to wa fọrọ awọn atipo ki wọn kaabọ.
Igbakeji gomina ipinle ohun, ogbeni Silas Agara, soro lasiko abewo sibi isele ohun.
Iwaadi ti ajọ eleto ilera agabye.
 Ó fún wáìnì náà pèlú otí lílè .
Igbesẹ Ijọba Ipinlẹ Ondo Oríṣun àwòrán, @RotimiAkeredolu Gomina ipinlẹ Ondo naa, Rotimi Akeredolu ti kede isede laarin aago meje irọlẹ si meje àárọ̀ nitori aarun coronavirus.
Iṣẹlẹ naa to waye lalẹ ọjọ Abameta ko mu ẹmi kankan lọ ṣugbọn o ṣe idiwọ fun lilọ bibọ ọkọ lori afara naa.
awon ile idibo ni ijọba ibilẹ méjìdínlógún  (18) to wa ni
Labẹ pe awọn oloselu ko bikita fun erongba tabi ilana yi naa la ti ri pe awọn ọmọ ẹgbẹ oselu PDP naa gba tọwọ tẹsẹ, ti wọn si tun fi aaye awọn nkankan gba a, ki o ba le jẹ ẹni ti ẹgbẹ fẹ gbe asia le lọwọ lati du ipo.
Simoni Peteru bá ṣẹ́jú sí i pé kí ó bèèrè pé ta ni ọ̀rọ̀ náà ń bá wí.
ni lati gbogun ti iwa ibaje  nile-ise
 bíṣọ ́ bù náà ṣe ìdánilẹ ́ kọ ̀ ọ ́ ìtagbangba ní ọ ̀ jọ ́ oṣù kejìlá ọdún 1956 nígbà tí queen elizabeth ii ṣe àbẹ ̀ wọò sí ilẹ ̀ nàìjíríà , ní st.
to n ri si ikolekodoti ni Ipinle Oyo (West Africa Energy) wa si agbegbe Ayeye
"Bákanáà ló ní Monica Usetobe Osagie ni orúkọ akẹ́kọ́́bìnrin tí ohùn rẹ̀ hàn nínú ìtàkùrọ̀sọ tó wáyé nínú ohùn tí wọ́n ká sílẹ̀ náà.
Oṣu kẹjọ, Ọdun 2019 lo di Minisita fun Abojuto lori ọrọ Ijamba ati Igbayegbadun ọmọniyan lorilẹ-ede yii Wo ohun tó yẹ kí o mọ̀ nípa àwọn obìnrin méje ti Buhari fẹ́ yàn sípò minista.
Ojogbon Osinbanjo yoo tun maa sepade po pelu awon adari
Ẹ̀tọ́ ni fún mi láti ní irú èrò yìí nípa gbogbo yín, nítorí mo kó ọ̀rọ̀ yín lékàn.
Gẹ́gẹ́ bí wolii Aisaya ti kọ ọ́ tẹ́lẹ̀ ni ó rí: “Ọlọrun ní,‘Wò ó!
Azikiwe International airport niluu Abuja, lojo Aiku(Sunday).
Ọkàn mi dúró ṣinṣin, Ọlọrunọkàn mi dúró ṣinṣin.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Coronavirus: Àwọn ìpèníjà márùn ún tó wà lórí pínpín abẹ́rẹ́ ajẹ́sara àrún Coronavirus Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Coronavirus: Àwọn ìpèníjà márùn ún tó wà lórí pínpín abẹ́rẹ́ ajẹ́sara àrún Coronavirus 3 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Lati igba ti arun Coronavirus ti bu jade ni nnkan bi ọdun kasẹyin niluu Wuhan, lorilẹ-ede China ni awọn onimọ kaakiri agbaye ti n wa ọna ababyọ si arun naa.
Àwọm ìròyìn mìíràn tí ẹ lè nífẹ̀ẹ́ sí: A kò lè gba àwọn jandùkú Fulani láàyé nílẹ̀ Yoruba -Awọn gómínà Àwọn òṣèré, olórin Yorùbá gbàdúrà fún MC Oluomo Àwa ọba alayé ń wọ́nà láti ṣẹ́ eegun ẹ̀yin ọ̀daràn Fulani - Ọọ̀ni Oloselu lo sokunfa bi ọlọpa ko se to ni Naijiria 'Ọkọ̀ la rí, a ò tíì rí adárí Ilé iṣẹ́ pána-panà Eko àtàwọn mẹ́fà' - Ọlọ́pàá Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Adesewa ni ọlọpaa gan ko tilẹ gba aṣẹ lọwọ ẹbi ki wọn to bẹrẹ ayẹwo, ṣugbọn awọn ṣaa dakẹ.
Oríṣun àwòrán, Others Àkọlé àwòrán, Ohun tí ó wọ́pọ̀ ni orilẹ̀-èdè Naijiria ni kí àwọn olórí Ilé Ijọsìn kọ̀ọ̀kan sọ àsọtẹ́lẹ̀ nípa ọdún tuntun ní ìbẹ̀rẹ̀ ọdún.
Ọmọ kekere naa, Gold Kolawole yẹ ko ṣe ayẹyẹ ọdun meji lọjọ Abamẹta to kọja.
Ẹnu ya gbogbo wọn, wọ́n sì ń yin Ọlọrun, wọ́n ní, “A kò rí èyí rí.
Ẹlẹfẹ ori itage ti gbogbo eniyan mọ si Tattafo ni pẹlu ohun rẹ hẹrẹ hẹrẹ to bẹẹ ti a da bii pe ọmọde lo ń sọrọ.
Oyè Ibadan kò sí fún títà - Otun Olubadan, Lekan Balogun Lẹ́yìn ọdún mẹ́ta l'ẹ̀wọ̀n akọrin ẹ̀mi gbẹ̀mí ará rẹ̀ látìmọ́lé Yàtọ̀ sí eku gọ́tà tàbí èku inú ilé, kò sí eku téèyàn ò lè jẹ - Òǹtajà Eléwé ọmọ Ilé ìgbìmọ̀ aṣofin ti bẹ̀rẹ̀ òfin tí yóò máa mú àwọn olùkọ́ fásitì tó ń bèrè fún ìbálòpọ̀ Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Bíó tilẹ̀ jẹ́ wí pé a gbà pè àsìkò rẹ̀ ló tó gẹ́gẹ́ bíi musulumi, ṣùgbọ́n ìrú èyí kò bá má ṣẹlẹ̀ kání a ní omi ẹ̀rọ̀ nínú ilé wa tàbí nítòsí."
Dípò kí n fún àwọn arakunrin rẹ ní Ṣekemu, tí ó wà ní ẹ̀gbẹ́ òkè, níbi tí mo jagun gbà lọ́wọ́ àwọn ará Amori, ìwọ ni mo fún.
Lọdun 2018, awọn oṣisẹ ẹka ọkọ ofurufu gun le iyanṣelodi kan ti ikọ BBC Yoruba si ba awọn arinrinajo sọrọ ni papakọ ofurufu Murtala Muhammed l'Eko.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù INEC: Àwọn ẹgbẹ́ òṣèlú yóò dìbò àbẹ́lé lóṣù Kẹjọ 9 Ìgbé 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 10 Ìgbé 2019 Ajọ eleto idibo ilẹ wa ti kede pe ọjọ́ Kejì, oṣù Kọkànla, ọdún 2019 ni ìbò gómìnà nipinlẹ́ Kogi àti Bayelsa yóò wáyé.
Bákan náà ni ẹnu ọ̀nà wọn rí, ati ìlẹ̀kùn wọn.
Oríṣun àwòrán, @TheVyralTrendz O rọ àwọn obìnrin tí wọn ba ti n gbero lati fi Ibalopọ de ọkunrin mọlẹ pe ki wọn tun ero wọn pa, ki wọn si ṣe ipilẹ tuntun fun Irinajo ifẹ wọn.
Wọn yóo fi agbára wọn ati àṣẹ wọn fún ẹranko náà.
Ẹ jọ̀ọ́, ẹ má jẹ́ kí ikú ọmọ mi lọ lásán - Ìyá Tiamiyu tí ọlọ́páà pa Ààrẹ Buhari ṣí ilé iṣẹ́ àti afára ní ìpínlẹ̀ Ondo Ẹ̀wọ̀n ọdún méje gbáko ni Olisa Metuh yóò fi ṣara ridin!
O ti fẹẹ to ọdun marun-un bayii ti Magu ti jẹ adele alaga ajọ EFCC.
Ninu osu kejila odun 2017, awon omo ile-igbimo asofin orile-ede ohun  panupo fimo-sokan  lori ipinnu orile-ede ohun lati pada sinu ajo Commonwealth naa.
Gbajugbaja ni ijọ yii jẹ ninu ka gba adura to ni ina ninu .
Iroyin sọ pe, awọn ọmọ ogun naa tẹle ọkọ agboworin kan to gbe owo naa lati ilu Sokoto si Kaduna, lati pese aabo fun.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Arúfin ni Seyi Makinde pẹ̀lú bó ṣe gbà kí wọ́n sin Ajimobi sí GRA - Amòfin Ọjọ́bọ̀ la ó mọ̀ bóyá a ní Coronavirus - Aṣòfin Ondo Baba Suwe bọ́ lọ́wọ́ àìsàn, ó bẹ̀rẹ̀ tíátà padà Àjọ NCDC kéde ènìyàn 561 tó tún ṣẹ̀ṣẹ̀ ní Coronavirus ní Nàìjíríà Egúngún kan rèé tí kò bìkíáfù, ó kọjú ìjà sí ọlọ́pàá pẹ̀lú ohun ìjà olóró Ọ̀kan lára òṣìṣẹ́ ilé ìwòsàn náà to ba BBC Yoruba sọrọ labẹ asọ ni ariwo àwọn oṣiṣẹ́ ni òun gbọ́, lásìkò ti òún pè láti báwọn sọ̀rọ̀ lórí ìpàdé ti ó yẹ kó wáye lówùrọ̀ òní.
Nínú àbá ìṣúná 2020, ìjọba Ọyọ fẹ́ gba 500 òṣìṣẹ́ ìlera pẹ̀lú ọ̀pọ̀ olùkọ́ Makinde sàbẹ̀wò sí LAUTECH, ó gbé owó ₦500m kalẹ̀ láti tán ìyanṣẹ́lódì àwọn olùkọ́ Akẹ́kọ̀ọ́ mẹ́fà tó lu akẹẹgbẹ́ wọn ní fásitì FUTA dèrò ilé 'Ẹ gbà mí o lọ́wọ́ ṣọ́ọ̀ṣì wa, mi ò lènìyàn, ẹ bá mi wá ọmọ mi rí'!
UK ṣetán láti dá Adìyẹ 'Àkùkọ' Nàíjìrìa ti wọ́n gbé padà Ohùn tó yẹ ní mímọ nípa òfin ojú pópó Wòólì Ajayi kú ní ìlú Àgelú, òkú rẹ pòórá, ìjọ sin pósí lásán!
Bí ó bá tilẹ̀ jẹ́ pé lótìítọ́ ni mo ṣẹ̀,ṣebí ara mi ni àṣìṣe mi wà?
Ipinlẹ Eko ati Kaduna lo wa ni ipo kinni, ati ikeji, ninu esi ayẹwo ti ajọ NCDC fi lede nipa awọn to ṣẹṣẹ ni coronavirus.
Wọ́n gbé àpótí ẹ̀rí jáde kúrò ní ilé Abinadabu tí ó wà lórí òkè, wọ́n sì gbé e ka orí kẹ̀kẹ́ tuntun kan.
BBC Yoruba ṣe alaye lẹkunrẹrẹ lori itakun ayelujara 5G.
Ẹ má jẹ́ kí ẹnikẹ́ni ninu wọn sá lọ.
Eyi lo si mu ko ranṣẹ pe Akpan ati awọn yooku rẹ lati gbe wọn lọ ọ pa sinu igbo.
Bakan naa lo sisẹ gẹgẹ bi ọmọ ẹkose ni ile iwe Price Water Company, PWC ni oṣu kẹfa, ọdun 2011 si oṣu kẹjọ, ọdun 2011.
Ilé ẹjọ́ kan náà ni Ọ̀jọ́ tí wọn ti mú arákùnrín náà ni awọn ọlọ́pàá gbé e lọ láti lọ jẹ́jọ́.
Ó ti rẹ Sisera tóbẹ́ẹ̀ gẹ́ẹ́ tí ó fi sùn lọ fọnfọn.
Oyebọde sọ pe gomina Fayẹmi ro o wi pe ki oun duro lati pawo wọle diẹ, ko to o yan wọn.
Alága àjọ tí ń rí sí owó oṣù, àti ipòwòwọlé, Olóyè Richard Egbule, lo sọ ọrọ yìí ni Abuja nígbà tí ó ń fi ọ̀rọ̀ j'omi toro oro pelu àwọn akọ ròyìn lọ́jọ́ ajé.
Ikú ni èrè ẹ̀ṣẹ̀, ṣugbọn ẹ̀bùn Ọlọrun ni ìyè ainipẹkun pẹlu Jesu Kristi Oluwa wa.
Aisha Buhari: Aya ààrẹ tọrọ àforíjìn lórí fídìo tó ti fi ìbínú sọ̀rọ̀
Iyẹni, sinima eeyan ti iya jẹ titi titi ko to je eeyan laye ti ọrọ̀ rẹ tun wa poora to yi i sinu isẹ ki Ẹlẹda to faaye gba a padà nítorí fun bii ọdun mẹẹdọgbọn ni ko fi si ninu isẹ orin to bẹẹ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ara: Láti kékeré ni mo ti ń lu ìlú pẹ̀lú ayọ̀ Kini o ti ṣẹlẹ ni Ghana nipa Coronavirus?
Labẹ gomina ana ni ipinlẹ Ọyọ, oloogbe Abiọla Ajimọbi ni wọn ti yan awọn alaga kansu naa ki Gomina Makinde to tu wọn ka ni wakati diẹ lẹyin to gori oye.
fún BBC Yorùbá fún ayẹyẹ ọdún méjí - Mike Ifabunmi láti Brazil Coronavirus: Ó dá mi lójú pé ìwá ìbàjẹ́ ló fa àrùn yìí - Ọ̀gá àgbá EFCC Ibà Lassa wọ ìpínlẹ̀ Èkó!
-Olugbo Obateru Akinruntan Ṣe lóòtọ́ ní ọmọ Nàíjíríà mílíọ́nù 25 yóò má ló ìná Solar látí Dec 1, 2020?
Angẹli náà bá mú àwo turari yìí, ó bu iná láti orí pẹpẹ ìrúbọ kún inú rẹ̀, ó bá jù ú sí orí ilẹ̀ ayé.
Ẹ gbọ́ ohun tí Ọlọrun sọ: Ẹ dìde, kí ẹ ro ẹjọ́ yín níwájú àwọn òkè ńlá, kí ẹ sì jẹ́ kí àwọn òkè kéékèèké gbọ́ ohùn yín.
ti wọn yoo fi yọ arabinrin Zainab kuro ninu igbekun , ti won yoo si muu wa pada
"Ìpínlẹ̀ Oṣun kò nílò Gómìnà oníjó - Oshiomole Ọ̀rọ̀ LAUTECH gba àpérò f'áwọn Olúdíje Ọṣun Ẹgbẹ́ òṣìṣẹ́, ìjọba ṣèpàdé lórí owó oṣù sísan l'Ọ́ṣun Moshood sọ ninu atẹjade kan ni ọjọ Ọjọru pe, ""Adeleke forukọ sile lati ṣe idanwo NECO ni ọdun 2017, ṣugbọn ko yọju lati kọ idanwo naa botilẹ jẹ pe o gba iwe ẹri idanwo naa."
pupa ati bẹẹ bẹẹ l wa.
osu kárùn ún  (May 29),  lati  fi
Ozil ṣapejuwe ohun to n waye ni Naijiria gẹgẹ bi eyi to buru jai, to si yẹ ki o jẹ koko ọrọ nibi gbogbo.
George Weah, agbabọọlu ọmọ orilẹede Liberia to ti di aarẹ bayii ni agbabọọlu akọkọ ti yoo gba ami ẹyẹ naa lai kii ṣe ọmọ ilẹ Yuroopu.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Tinubu: Nítorí Tinubu, àwọn ọmọge Sanwo-Olu da ìlù bolẹ̀ Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Bayi,Son ti di agbabọọlu akọkọ ti wọn yoo fun ni kaadi pupa lẹẹmẹta ni saa bọọlu yi.
Ètò kóníléógbélé alágo méjila oru si mẹ́rin ìdájú ti ìjọba àpapọ̀ gbé silẹ̀ kò ti kásẹ̀ nílẹ̀, bákan naa ni lílo ìbòmú ṣe pàtàkì láàrín èrò, nílé iṣẹ́, àti inú ọjà.
Ti pé àwọn iggi sì wà lẹ́yìn wọn ràn wọ́n lọ́wọ́ púpọ̀, nítorí pé nígbà tí ìjà kọ́ bẹ̀rẹ̀ tí a wọnu Igbó Elégbèje tán àṣé inú àwọn igi tí ó wá lẹ́yìn wa ni àwọn wọ̀nyí lo máa ń kọrin nígbà tí wọ́n ba ń Ọlọ́run lógo, wwọn kò sì jagun.
N óo gbẹ̀san lára wọn lọpọlọpọ; n óo fi ìrúnú fi ìyà ńlá jẹ wọ́n.
Lẹyin naa lo lo èdè buta tí Hausa n pe age to si sọ pe Buta n bẹ, buta (voter) si n bẹ.
Géńdé agbébọn jí adájọ́ gbé lọ ní ìpínlẹ̀ Ondo Kí ni àwọn olórí Áfíríkà ń wá lọ sí Russia?
Bakan naa la gbọ pe ọwọn gogo epo mu awọn awakọ to lawọn ile epo ni Seme ''border'' nipinlẹ Eko lọjọ Aje.
Fun anfani awọn to sanra tabi ti ko fẹ sanra pupọ.
Oríṣun àwòrán, TWITTER O ni '' Akeredolu ku orire iyansipo gẹgẹbi gomina fun ọdun mẹrin miran lati tukọ ipinlẹ Ondo''.
Àwọn ojú oge Yollywood t'ọ́jà wọ́n ṣì ń tà wàràwàrà Ọ̀nà ọ̀fun, ọ̀nà ọ̀run!
Wọ́n fi ìwé rán wọn, pé:“Àwa aposteli ati àwa alàgbà kí ẹ̀yin tí kì í ṣe Juu ní Antioku, Siria ati Silisia; a kí yín bí arakunrin sí arakunrin.
ni ipinle Zamfara so pe ,egbe APC ti se eto idibo abẹle lati yan awon oludije
Ọwọ́ ti tẹ ọ̀gbẹ́ni tó wà lẹ́yìn ìdigunjalẹ̀ Báńkì l'Abuja Ìjọba Gomina Raman Razak padà wólé arúgbó ní Ilọrin!
5 kilo ohun ogbin egbogi  Cannabis ni won gba lowo awon afurasi naa.
Bí inú rẹ̀ bá yọ́ sí ọ n óo ranṣẹ sí ọ.
"Nínú ìṣèjọba yìí, Èmi àti Ààrẹ Buhari lọlọ́rọ̀, kìí ṣe ọmọ Nàìjíríà-Ibrahim Gambari, olórí òṣìṣẹ́ lọ́fíìsì ààrẹ Mo kábàámọ̀ pé n kò kàwé, kí n tó bẹ̀rẹ̀ iṣẹ́ tíátà - Sanyeri "" Aarẹ ẹgbẹ wa, Bolaji Amusan, taa mọ si Mr Latin n saayan lati to ẹgbẹ naa, ọmọ ẹgbẹ ti ko ba si ṣe ojuse rẹ ninu ẹgbẹ, yoo da ran isoro to ba baa ni."
Ṣugbọn bí ẹnìkan bá mọ̀ọ́nmọ̀ bá ẹlòmíràn jà, tí ó sì fi ọgbọ́n àrékérekè pa á, bí irú ẹni bẹ́ẹ̀ bá sálọ sí ibi pẹpẹ mi, fífà ni kí ẹ fà á kúrò níbi pẹpẹ náà kí ẹ sì pa á.
“Ọlọrun kò ní dáwọ́ ibinu rẹ̀ dúró,yóo fi ẹsẹ̀ tẹ àwọn olùrànlọ́wọ́ Rahabu mọ́lẹ̀.
Abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò dágbére fáyé lẹ́yìn ìjà rẹ Boko Haram gbọ̀nà àrà yọ, kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ ló so àdó olóró mọ̀ láti kọlu Gómìnà Borno Ohun marun t'ejo n jẹ Akukọ to ba le fi abẹ ti wọn so mọ ọ lẹsẹ yi bẹ ikeji rẹ lo jawe olubori ninu idije yi.
 Won ti ro ebi ati ara to ba n wa enikeni lati kan si ile ise olopaa nipa lilo awon nomba ti won kede.
Amọṣa, yatọ sawọn asiwaju ijọba wọnyiajọ EFCC ti wọn gbe kalẹ lasiko isejọba Olusẹgun Obasanjọ ti se ọpọ iṣẹ ti wọn si ti gbe ọpọ awọn eekan ati oloselu ju si gbaga fun ẹsun ikowojẹ.
 ilé elékuru : Ìwádìí fi yé mi pé olùpilèsè ilé yìí féràn láti máa bo Èsù .
6 Lépa láti mú jade wá àti láti ṣe àgbékalẹ̀ Síónì mi.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ebola: Ènìyàn méji ló ti kú lórí àìsàn Ebola lórílẹ̀èdè DRC 1 Ògún 2019 Oríṣun àwòrán, Reuters Àkọlé àwòrán, Ní òwúrọ̀ ọjọ́run ni ọkunrin awa kùsà kan kú ní Goma níbi ti ènìyàn tó le ni miliọnù meji.
Ṣugbọn àwọn tí a kà yẹ fún ayé tí ó ń bọ̀, nígbà tí àwọn òkú bá jinde, kò ní máa gbeyawo, bẹ́ẹ̀ ni wọn kò ní máa fọmọ fọ́kọ.
    Èyí àtẹ̀lé nínú àwọn ọmọ ọba yìí tí kò mọ òpin ọfà ti òun, kò dákẹ́, ó rọra dìde ó ń wá ọfà rẹ kiri, ó rìn títí kò tètè rí i ṣùgbọ́n nígbà tí ó ṣe, ó ri i, bí o sì ti ń fẹ́ mú u, ni ó rí ìlẹ̀kùn kékeré kan tí ó bá ihò ilẹ̀ lọ.
Awon oludibo iko merinlelogorin 84%ninu ida ogorun tu yaya lati dibo ninu eto-idibo gbogbogbo ti o waye ni ojo keje osu keta odun ti a wa yii.
O ti pe ọdun mẹrindinlogun bayii ti ẹgbẹ agbabọọlu Arsenal gba ife ẹyẹ Premier League lai fidi rẹmi ninu ifẹsẹwọnsẹ kankan ni saa bọọlu ọdun 2003/2004.
Agbe ló laró, ki ráhùn aró,
Ó tẹ́ pẹpẹ sinu gbọ̀ngàn meji tí ó wà ninu tẹmpili, wọ́n sì ń bọ àwọn ìràwọ̀ ati gbogbo ohun tí ó wà lójú ọ̀run níbẹ̀.
L'Ọjọru ọsẹ yii ni gomina Ganduje buwọlu aba ti yoo jẹki Sanusi lagbara lori ijọba ibilẹ mẹwaa pere ninu mẹrinlelogoji to wa nipinlẹ Kano.
tesiwaju lati se ju bi o se n se lo lati ateyinwa nipa mimu igbe aye iderun ba
"Ìjọba ìpińlẹ̀ Eko ti kédé ìwọlé àwọn akẹ́kọ̀ọ́ ní gbogbo iléèwé aládàni àti ìjọba ""Tí a ko ba ti lé foriji ẹnii to gbé ìbọ̀n lọ jalè nítorí kò lọ́wọ́, bẹ́ẹ̀ náà ni a ò le fọwọ́ ra awọn to já sọ́ọ̀bù lóri."
kinní kan ni mo fẹ́ bá ọ sọ.
Ó ṣalayé pé, wón ní kí ọmọ ìjọ kọọkan fi oróró sí iwájú orí ẹni tí ó wà ní sàkání rẹ̀ ní.
"Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ọkùnrin tó fẹ́ fipábámilòpọ̀ fín ǹkan sí mi lójú ló ṣe rọ́nà wọlé sí mi lára ""Ọba ti a lee pe ni Ọba, ti aṣa Yoruba wa lori rẹ, ti awọn eewọ Yoruba si wa lori rẹ ni awọn ọba to jẹ wi pe bi awọn baba nla wa ṣe nfi ọba jẹ ni wọn ṣe fi wọn jẹ,"" O ni ọba ti yoo ba pe ara rẹ ni ọba ni ilẹ Yoruba gbọdọ jẹ ọba ti wọn ṣe iwadii rẹ lati inu ifa, to si de ipebi to si lo iye ọjọ to yẹ ko lo ni ipebi; to si jẹ gbogbo nnkan to yẹ ko jẹ, to si yẹ ko mu mu."
"Oríṣun àwòrán, NATIONAL IDENTITY MANAGEMENT COMMISSION Àkọlé àwòrán, Káàdì ìdánimọ̀ ""Ni ibamu pẹlu aṣẹ ijọba apapọ'' wọn ni awọn gbe igbesẹ wọn yi: ""Afikun ọsẹ mta fawọn to ni NIN bẹrẹ lati ọgbọnjọ Oṣu Kejila 2020- ọjọ Kọkandinlogun Oṣu Kini 2021'' ati ""Ọsẹ mẹfa fawọn ti ko ni NIN tẹlẹ lọgbọnjọ Oṣu Kejila 2020- Ọjọ Kẹsan oṣu Keji ọdun 2021."
O óo gbàgbé àwọn ìyọnu rẹ,nígbà tí o bá sì ranti rẹ̀,yóo dàbí ìkún omi tí ó ti wọ́ lọ.
(Ó ń retí àkókò ìjọba Ọlọrun), ó bá fi ìgboyà tọ Pilatu lọ láti bèèrè òkú Jesu.
Ṣugbọn ẹ kò gbọdọ̀ súnmọ́ Àpótí Majẹmu náà jù, ẹ gbọdọ̀ fi àlàfo tí ó tó nǹkan bí ẹgbaa (2,000) igbọnwọ sílẹ̀ láàrin ẹ̀yin ati Àpótí Majẹmu náà.
N kò mọ̀ pé ojú mi ṣì lè là mọ́ lọ́wọ́ ìgbájú- Boluwatifẹ FUTA Wòólì Ajayi kú ní ìlú Àgelú, òkú rẹ pòórá, ìjọ sin pósí lásán!
Oríṣun àwòrán, kimbbby1 Ẹ má gbìyànjú láti bo àṣírí ìpànìyàn tó wáyé ní Lekki, á ní ẹ̀rí tó dájú - Amnesty International Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Kété tí wọ́n bá ti báa yín sùn tàn torí pé ẹ tóbi, ẹ gbà pé ìfẹ́ yẹn ti parí - Auntie Remi Ọlọ́yàn ńlá Bo tilẹ jẹ wipe a ko le sọ boya lootọ lọrọ dun wọn ti wọn fi bu sẹkun, awọn araalu ko foju rere wo iwa yi.
Adébọ́lá Pius Adésànmí gbé lé ayé ṣe rere
Ó mú ìyìn rere ayérayé lọ́wọ́ láti kéde rẹ̀ fún àwọn tí wọ́n wà ninu ayé, ninu gbogbo ẹ̀yà ati gbogbo orílẹ̀-èdè.
”Níṣojú wa, gbẹ̀san ẹ̀jẹ̀ àwọn iranṣẹ rẹ tí a palára àwọn orílẹ̀-èdè!
Elihu tún tẹ̀síwájú ninu ọ̀rọ̀ rẹ̀, ó ní,
Belarus: Ààrẹ orílẹ̀èdè Lukashenko tún wọlé lẹ́yìn ọdún 25 lórí oyè!
O fikun ọrọ pe o le maa si olorin Fuji bi Barrister mọ laye.
Ẹ ̀ dá ìtàn méjì ní a gbọ ́ tí ó rọ ̀ mọ ́ bí eré sákárà ṣe bẹ ̀ rẹ ̀ .
Oluranlọwọ aarẹ lori ọrọ ile igbimọ aṣofin agba l'Abuja lo fọrọ naa lede.
Wọ́n bá pada sí Listira ati Ikoniomu ati Antioku ní Pisidia.
OLUWA kìlọ̀ fún Manase ati gbogbo àwọn eniyan rẹ̀, ṣugbọn wọ́n kọ̀, wọn kò gbọ́.
Wọn sin in ni ọjọ kẹtàlá, oṣù kẹfà, ọdun 2013 nile rẹ to wa ni Ikorodu, Eko.
Ọpọlọpọ ri i gẹgẹ bi adari to lee yanju aawọ awọn araalu eyi to bẹ silẹ lẹyin ti awn ologun da si i lati dena ki ẹgbẹ ẹlẹsin Islam kan bori ninu idibo gbogbo gbo ti ọdun 1992.
Eyi lo mu ki o gba ọkan lara awọn ìsọ ti ijọ naa maa n fun awọn ọmọ ijọ lati fi ta ọja lasiko ti ipagọ ba n lọ lọwọ.
Mo bá tún gbọ́ tí gbogbo ẹ̀dá tí ó wà lọ́run ati ní orílẹ̀ ayé, ati nísàlẹ̀ ilẹ̀, ati lórí òkun, ati ohun gbogbo tí ń bẹ ninu òkun, ń wí pé,“Ìyìn, ọlá, ògo, ati agbára ni ti ẹnití ó jókòó lórí ìtẹ́ ati Ọ̀dọ́ Aguntan lae ati laelae.
#BBCOGUNDEBATE: Ìjọba mi yóo dé gbogbo ẹsẹ̀kùkú àti ìgbèríko -Akinlade
forikori pelu awon gomina ipinle ,awon abenugan ile igbimo asoju to wa ni ipinle,
" Mo tun n sọ ọ lẹẹkan si pe, ki ijọba apapọ dẹ́kun titan awọn oluwọde to n fi ẹ̀mí wọn wewu lati beere fun igbe aye idẹrun.
Oríṣun àwòrán, Others Aisan to rọmọ ọjọ ogbo lo ṣe Baba legba to fi papoda, amọ, ede aiyede to ṣẹlẹ laarin ẹgbẹ TAMPAN ati ANTP, lo mu ka maṣe pe oloogbe naa si iṣẹ pẹlu aisan to ṣe wọn.
Gẹgẹ bi ohun ti ọmọ rẹ ṣe lalaye fun BBC News Yoruba lori ẹrọ ibanisọrọ, ẹni ọgọrin ọdun ni Ajihinrere Bamidele Olumilua ki ọlọjọ to de.
Trump picture: ọjọ́ tí Trump kí mi kú iṣẹ́ lórí 'twitter' ní inú mi dùn jù- Oyedele Ọkọ̀ òfurufú Boeing 737 jábọ́ ni kété tó gbéra ní pápákọ̀ òfurufú ni orílẹ̀-èdè Iran Gómìnà mẹ́ta àtí ènìyàn 1,242 ló kó sí panpẹ EFCC ni ọdún 2019 Ẹ́ gba fóónù, ẹ pe ẹbí yín pé a fẹ́ dáná ṣun yín - Aráàlú sọ fún adigunjalè méji Tunwẹ, Ọdun 2018 ni Alaga Ajọ Ere Idaraya, Deji Tinubu naa fọ sanlẹ ku lasiko to n ṣe ere idaraya bọọlu alafẹsẹgba ni agbeegbe Epe ni Ilu Eko.
Ó yára gun kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ rẹ̀, òun pẹlu àwọn iranṣẹbinrin rẹ̀ marun-un, wọ́n sì tẹ̀lé àwọn iranṣẹ Dafidi lọ, Abigaili sì di aya Dafidi.
Idi si ni yi ti BBC News Yoruba fi tọọ lọ fun iṣiniye lori awọn igbesẹ to n lọ lọwọ nipa idagbasoke ẹya Yoruba, orilẹ-ede Naijiria ati ajakalẹ arun coronavirus to n fẹju koko kaakiri agbaye bayii.
Samsoni bá ké pe OLUWA, ó ní, “OLUWA Ọlọrun, jọ̀wọ́, ranti mi, kí o sì fún mi lágbára lẹ́ẹ̀kan péré sí i, jọ̀wọ́ Ọlọrun mi, kí n lè gbẹ̀san lára àwọn Filistini fún ọ̀kan ninu ojú mi mejeeji.
Nigba ti wọn da ọjọ idanwo, ogunlọgọ eniyan lo kú lasiko ti wọn tẹ ara a wọn pa nitori ọpọ eero to wa ni papa isere ilu Abuja, nibi ti idanwo naa ti ileesẹ ìjọba fun ọrọ abẹle seto.
Kii si se gomina nikan lo da bori ibo yii, idi si niyi ti ko fi yẹ ki oun, iyawo ati awọn ọmọ rẹ maa danikan maa se ijọba, bikose gbogbo awa taa sisẹ to fi moke, lo jẹ ka dijọ se ohun to wa nilẹ yii.
Nítorí níbi tí ìṣúra yín bá wà, níbẹ̀ ni ọkàn yín náà yóo wà.
Ajo eleto idibo lorile-ede Sierra Leone so pe, awon oludije dupo mefa ni won n dije fun ipo Aare naa, lara eyi ti a ti ri awon obinrin meji ati okunrin merin.
Ó ní ère ìbejì níwájú rẹ̀.
Awọn ọmọ ologun ni agbeegbe Iwọ-oorun ilẹ Afirika naa ni awọn gbe igbese naa lati da eto oselu tiwantiwa pada si orilẹede naa.
Oríṣun àwòrán, Others Àkọlé àwòrán, Gbajugbaja osere Nollywood, Uche Odoputa ni wọn ka oogun oloro mọ lọwọ ni ọdun 2007, ti o si lo osu mẹjọ ni ọgba ẹwọn.
Bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé gbogbo àwọn tí wọ́n jáde láti ilẹ̀ Ijipti ni wọ́n kọ ilà abẹ́, ṣugbọn gbogbo àwọn tí wọ́n bí lójú ọ̀nà ninu aṣálẹ̀ lẹ́yìn tí wọ́n jáde ní ilẹ̀ Ijipti kò kọ ilà.
Gẹ́gẹ́ bi àwọn oníròyìn abẹ́lé ṣe sọ Akpabio ni Anyanwu gba kọngila mọ́kandílógún.
Ẹrú tí ò kú, á sin olówó rẹ̀ kú
Crytsal Palace fagbahan Manchester City pẹlú àmì ayò mẹ́ta sí méjì ninu
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé Ki ni awọn ọlọpaa sọ sii?
Wọ́n rò pé nítorí èrè ni eniyan fi ń ṣe ẹ̀sìn.
Dokita ọmọ Naijiria jàjàbọ́ nílẹ̀ Ọba Tọkọtaya lu ọmọ ni gbanjo fun 400k Wọn fẹbi ẹ̀sùn ìpàniyan kan an ní inú oṣù keji ọdún pe ó fi tipatipa fún ọmọ oṣù mẹ́jọ̀, Enitan Salubi ni mílììkì mú ní tulàsì lágbegbe Glenarden ní inu oṣù kẹwàá ọdún 2016 ti ọmọ náà si gba ibẹ̀ lọ.
Ẹnikẹ́ni tí kò bá sí orúkọ rẹ̀ ninu ìwé ìyè, a óo sọ ọ́ sinu adágún iná.
Ọwọ́ ọ̀lẹ kò lè tẹ ohun tí ó ń lé,ṣugbọn ẹni tí ń fi tọkàntọkàn ṣiṣẹ́ yóo ní ọpọlọpọ ọrọ̀.
Lẹ́yìn náà, a gbọ́ ìró ohùn rẹ̀,ó sọ̀rọ̀ ninu ọlá ńlá rẹ̀,bí ìgbà tí ààrá bá sán,sibẹsibẹ kò dá mànàmáná dúróbí àwọn eniyan ti ń gbóhùn rẹ̀.
N kò sì gbọdọ̀ jẹ ohunkohun tí ó jẹ́ aláìmọ́; nítorí pé, Nasiri Ọlọrun ni ọmọ náà yóo jẹ́ láti ọjọ́ ìbí rẹ̀ títí yóo fi jáde láyé.
OLUWA fìyà jẹ àwọn eniyan rẹ̀,ó kó wọn lọ sí ìgbèkùn;ó lé wọn jáde ní ìlú,bí ìgbà tí ẹ̀fúùfù líle bá ń fẹ́ láti ìlà oòrùn.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ondo election 2020: Àwọn ara ìpínlẹ̀ Ondo ránṣẹ́ sí Akeredolu ohun ti wọ́n ń retí ní báyìí Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Ondo election 2020: Àwọn ara ìpínlẹ̀ Ondo ránṣẹ́ sí Akeredolu ohun ti wọ́n ń retí ní báyìí 12 Ọ̀wàrà 2020 Inu wa ko dun ṣugbọn.
Nígbà tí ó súnmọ́ ẹ̀bá Bẹtifage ati Bẹtani, ní apá òkè tí à ń pè ní Òkè Olifi, ó rán meji ninu àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀.
“Mo fẹ fi da yin loju pe ijọba ẹgbẹ oṣelu All Progressives Congress (APC) ni gbogbo ipele n sa gbogbo ipa wọn lati mu igberu ba igbe-aye irọrun awọn ara ilu”.
Nítorí náà kọ àwọn ohun tí o rí sílẹ̀, ati àwọn ohun tí ó wà nisinsinyii ati àwọn ohun tí yóo ṣẹlẹ̀ lẹ́yìn ọ̀la.
Gedalaya bá búra fún àwọn ati àwọn eniyan wọn pé, “Ẹ má bẹ̀rù ati sin àwọn ará Kalidea.
Atẹjade ọhun tẹsiwaju pe, ààfin ọba náà wà lára àwọn ibi tí wọn ṣe ikọlu sí nígbà rogbodiyan ifẹhonuhan EndSARS, nítorí náà ló ṣe ṣe pàtàkì kí àwọn Ọba lọwọ nínú ìgbìmọ̀ oluwadii ti ijọba gbe kalẹ."
Àkànṣe eto naa si lọ dá lórí igbele àrùn Covid-19 àti akoso Ìpínlẹ̀ Osun.
“O da mi loju pe, didawole ohun osin miiran yoo rorun pupo fun awon osise wa ati awon ebi won lapapo.
Lẹ́yìn náà wọ́n pa àwọn àgbò, wọ́n sì da ẹ̀jẹ̀ wọn sára pẹpẹ.
 Asa ati ise awon ile ola ni ki omobabinrin Danish di obabinrin ni kete ti oko re ba ti gori ite oba sugbon okunrin ko le saa deede di oba lataari pe o fe obabinrin.
Awọn miran gan an a ni ohun ti eti ko gbọri ni bi iyawo ṣe ko ero sẹyin wa sile ọkọ fun eto igbeyawo funra rẹ.
Ẹ sọra fun sisanra lasan ju Ẹ ma mu oti la muju.
Ọpọ awuyewuye lo ti wa lori ẹni ti o bẹrẹ orin Fuji ni Naijira laarin oloogbe Sikiru Ayinde barrister ati Alhaji Kollington, Kebe n Kwara.
Ni idahun si ibeere lori igbagbọ ninu agbara baba isalẹ ninu oselu Naijiria o ni awọn oloseelu to saaju ni wọn ni igbagbọ ninu baba isalẹ.
Saaju, adele komisona naa, Amy Galigan so pe orisirisi ibasepo ni o le jeyo laarin orile-ede Naijiria ati Canada ti yoo si se anfaani lopolopo fun orile-ede mejeeji, papaa julo ni eka imo-ero oju ofurufu.
Adajọ niigbẹjọ ọrọ yi yoo waye lọjọ keje ati ikẹjọ oṣu Kẹrin ọdun 2020.
Oga agba fun ile-ise alaabo irinna oko loju opopona nipinle ohun, Federal Road Safety Corps (FRSC), iya afin Faustina Alegbe, lo jabo iku eniyan meji, ti eniyan mẹ́tàdínlógójì miiran si farapa.
a Baba Wande, Kayode Odumosu a.
O dúpẹ lọ́wọ ọmọ Naijira bákan náà lo gbadura pé àsìkò yìí yóò ré kọja ti a ba tèlé àwọn alasill ìjọba Coronavirus: Ọmọ ilẹ̀ Amẹrika kú sí Ekiti Oríṣun àwòrán, Ekiti state government Pẹlu bi arun Coronavirus ṣe fẹ sọ ara rẹ di tọrọ fọnkale bayii lorilẹede Naijiria, ipinlẹ Ekiti naa ti ni ipin ninu rẹ bayii.
Ewe, eleyi yoo sanfaani fun Rohr lati mo agbaboolu ti o kaju osuwon, ti o leto lati wa lori papa abbl.
Alaga igbimọ ile asofin fun ere idaraya, Adegbile salaye pe, igbimọ naa ko ti pari iwadii wọn lori ọrọ naa.
 o jọ wipe anafilasisi ti ounjẹ ṣe okunfa rẹ npọ sii.
Osinbajo lasiko to n ba awọn oniroyin sọrọ ni ipinlẹ Kano, sọ wi pe o lodi si igbelarugẹ ẹto ọmọniyan ti awọn adari ilẹ South Africa ja fun ni igba aye wọn.
Lẹnu ọjọ mẹta yii ti idibo Aarẹ sunmọ, awọn ọmọ Naijiria ko fi bẹẹ gbohun rẹ amọ ni bayii ti ayederu ''Dino Melaye'' ti fi ikede miliọnu mẹwaa Naira sita, awọn eeyan ti n fun un lesi loju opo Twitter.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Gómìnà rè sodò nì Kenya nígbà tó ń ya fọ́tò ara rẹ̀ 18 Èbibi 2018 Oríṣun àwòrán, @BarakaFmKe Àkọlé àwòrán, Gómìnà Mutua, igbakeji rẹ àti àwọn akoroyin lára àwọn tó já sodo nígbà tí afárá náà já Ọrọ burúkú tòun ẹrín.
Iṣẹ agbẹ ati imọ ẹrọ lafojusun ọjọ iwaju Dangote parọwa si awọn ọdọ Afrika lati ma ṣe jẹ ki ọrọ wọn dabiowe Yoruba to niowo ti ọmọde ba kọkọ ri,akara nii fi jẹ O ni ki wọn ni adisọkan to rinlẹ ki wọn si ma na inakuna Oríṣun àwòrán, ERIC PIERMONT Àkọlé àwòrán, Pupọ ninu owo Dangote wa lati idi ọja Dangote Cement rẹ ''Lọpọ igba, ati oju owo ati ere,gbogbo rẹ ni a ma n na.
Amọ o fikun pe ti asẹ naa yoo ba mulẹ, awọn gbedeke kan wa ti oun yoo gbe kalẹ, eyi ti olori ijọ Shiite naa ati iyawo rẹ ti wọn dijọ n jẹjọ lọwọ, gbọdọ tẹle ki ọna to si silẹ fun wọn.
“Ẹ gbọdọ̀ máa dá ẹjọ́ ẹ̀tọ́, kí ẹ sì fi àánú ati ìyọ́nú hàn sí ara yín.
Ọ̀pọ̀ àwọn tó ń ṣiṣẹ́ yìí ni yóò pàdánù iṣẹ́ wọn ti àwọn ènìyàn kò bá ra ọjà tó nílò láti fi ránṣẹ́ si ibò míràn.
 Mo ti setan lati gba iwe ifise sile re … Bee si ni lataari ikowe fise sile naa, mo ti pinnu lati yan Tito Mboweni gege bi minisita tuntun fun eto isuna.
O ṣe wá sọ pé kí n lọ sọ fún oluwa mi pé o wà níhìn-ín?
7 117283 Orilẹede Venezuela 919 3.
Ko tan sibẹ o, o tun ni oun dupẹ lọwọ Ọlọ́run pe gbogbo àwọn obinrin ti oun kọkọ dẹnu ifẹ kọ ko gba lati fẹ oun.
Àwọn ẹ̀yà Reubẹni, àwọn ẹ̀yà Gadi, ati ìdajì ẹ̀yà Manase, ní ẹgbaa mejilelogun ati ẹẹdẹgbẹrin ó lé ọgọta (44,760) akọni ọmọ ogun tí wọ́n ń lo asà, idà, ọfà ati ọrun lójú ogun, tí wọ́n gbáradì fún ogun.
Ẹ dúpẹ́ lọ́wọ́ Ọlọrun tí ó ju gbogbo àwọn oriṣa lọ,nítorí pé ìfẹ́ rẹ̀ tí kì í yẹ̀ wà títí lae.
"Asa yii tumọ si awọn asiko ti aaye wa fun obinrin lati jẹ awọn nkan ti o yẹ ko maa saa fun bi Hormes se sọ.
María Fernanda Espinosa Garcés ni gẹrẹ ti oun ba n kuro ni ipo ni wọn yoo maa bura wọle fun Bande.
Bí ọ̀gangan ibẹ̀ bá wú, tí ó funfun tabi tí ó pọ́n, kí olúwarẹ̀ lọ fihan alufaa.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Oludije ipò Gómìnà labẹ asia PDP ní Oyo sọrọ nípa Ladoja Ni ọdun 1985, o wọ ile iwe giga fasiti ilu Eko, nibi to ti gba oye Bachelor's degree ninu imọ ẹrọ, Electrical Engineering.
Christmas: Ìdí tí Bàbá Kérésì fi máà n wọ aṣọ pupa àti funfun nígbà gbogbo
ifọrọwanilẹnuwo  ti a se pelu awon
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Àwọn agbófinró Nàíjíríà yóò rojọ́ níwájú iléẹjọ́ àgbáyé ICC Wo ìgbéyàwó olówó iyebíye tí awakọ̀ Kabúkabú ti jẹ̀bùn ọkọ N3.
Eeyan 6,581 lo ti ri iwosan gba, nigba ti awọn 487 ti dero ọrun nitori arun ọhun.
Yahaya Bello lẹ́ẹ̀kan síi ni APC ṣe ní ìdìbò abẹ́lé ní Kogi 'Òṣòkòmọlẹ̀' ní ẹjọ́ láti jẹ́ lórí owó Káńsù l'Ekiti Awọn ẹgbẹ agbabolu mejeeji ni wọn jọ figa gbaga lati jawe olubori ko to di wi pe ẹkọ ko soju mimu fun ikọ ti Cameroon.
Isoro to lee pagidina amulo iwe iforukọsilẹ orukọ awọn afipabanilopọ: O seese ki amulo iwe iforukọsilẹ naa koju isoro pupọ nitori pe awọn ọmọ Naijiria kii fẹ jade sita lati wa fi ẹjọ awọn eeyan to ba bawọn lopọ sun tabi ọmọ wọn.
Obinrin kan tí ọdọmọbinrin rẹ̀ ní ẹ̀mí èṣù gbọ́ nípa rẹ̀.
Awọn ọlọpaa n wadii Sẹnetọ Ademọla Adeleke, oludije fun ipo gomina ipinlẹ Ọṣun ninu idibo gomina ọdun to kọja lori ẹsun ayederu iwe ẹri girama lọwọlọwọ.
Lasiko to n ba ile ișẹ BBCYoruba sọrọ, alukoro ile ișẹ ọlọpaa ipinlẹ Oyo, Fadeyi Olugbenga salaye pe, gbogbo nkan to jẹ ile ișẹ wọn logun julọ ni bi wọn yoo se gba afurasi naa mu.
Kí oore-ọ̀fẹ́ ati alaafia láti ọ̀dọ̀ Ọlọrun Baba wa ati Oluwa wa Jesu Kristi kí ó wà pẹlu yín.
Lasiko ogun abẹle Naijiria Barrister ṣiṣẹ takuntakun, o tun jẹ amuludun fun awọn ọmọ ogun to ku nigba naa.
Ile isẹ Iroyin News Agency of Nigeria fi lede wi pe alẹ ọjọ Isinmi ni awọn agbebọn naa wa ṣe ọsẹ́, ti ọpọlọpọ si ku, ti awọn miran si farapa.
 Bakan naa ni o rọ Ile Igbimọ Aṣofin yii lati fọwọsowọpọ pẹlu ile-iṣẹ to n ri si irin ajo lọ si ilẹ okeere (Immigration Service) lati le maa yẹ awọn awọn to n fi awọn ọmọde ṣe iṣẹ ti ko tọ ni ilẹ okeere lọwọ wo, eyi ti wọn maa n ko awọn oṣiṣẹ bayii wa.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Líìgì ilẹ Gẹẹsì: Salah ni agbábọọlù tó pegedé jùlọ 23 Ìgbé 2018 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Salah gbẹyẹ mọ agbábọọlù márùn ún lọ́wọ́ Wọn ti kéde agbábọọlù Liverpool àti ọmọ orílẹèdè Egypt, Mohammed Salah, gẹgẹ bíi agbábọọlù tó pegede jùlọ, ní sáà ìdíje líìgì premiership ilẹ Gẹẹsì fún ọdún 2017 si 2018.
Coronavirus guidelines: Kí ló ń mú àwọn adarí obìnrin lágbáyé rọwọmú nípa kíkojú covid 19?
Ẹṣin kún ilẹ̀ wọn,kẹ̀kẹ́ ogun wọn kò sì lóǹkà.
Adele naa fi kun un pe awọn janduku ọhun fi agidi gbe oun lọ si afin Aroloye nibi ti wọn ti fi ija jẹ oun niwaju rẹ.
26 Ìgbé 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 6 Èbibi 2020 Oríṣun àwòrán, others Ilé asofin táwọn aṣojú nilẹ wa ká àbá òfin tí yóò máa ṣe àkóso ajakalẹ-arun fún ìgbà kejì ni ọṣẹ tó kọjá àmọ́ igbesẹ náà tí ń mú awuyewuye lọwọ láàrin àwọn ọmọ Nàìjíríà.
Ìjọba Èkó figbé ìkìlọ̀ ta Duro Ladipọ, ìlúmọ̀ọ́ká òṣèré tíátà àti ọmọ àlúfà tí kò gbàgbé àṣà ìbílẹ̀ Ẹwẹ, ijọba Naijiria ti tẹnu bọ ọrọ naa bayii.
Eyi kii ṣe ohun to bo rara.
Ọdẹ́gbàmí: Púpọ eléré ìdárayá ló ti gba ẹ̀bùn wọn lọ́wọ́ ìjọba
Ṣugbọn ó jẹ́ ẹni tí a ti dán wò ní gbogbo ọ̀nà bíi wa, ṣugbọn òun kò dẹ́ṣẹ̀.
Gbìyànjú àwọn òwé Yòrúbà yìí wò Pàtàkì June 12 fún Nàíjíríà Iṣẹ́ Kudirat Abiọla ṣì ń fọhùn síbẹ̀, lẹ́yìn ọdún 23 tó papòdà Ọ̀nà márún-ún láti mú àdínkù bá dátà (Data) lílò rẹ Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí 2 sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 2:23 Fídíò, Water Generator: Ó leè ṣiṣẹ fún wákàtí mẹfà, kó tó sinmi, Duration 2,2310 Òkùdu 2020 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
Moabu ni ìkòkò ìwẹsẹ̀ mi,lórí Edomu ni n óo bọ́ bàtà mi lé,n óo sì hó ìhó ìṣẹ́gun lórí Filistia.
Kunle Afolayan ba BBC Yoruba sọrọ lori iriri rẹ ati igbiyanju rẹ.
 orúko àwon ìyàwó rè láti orí ìyàwó àkókó ni múìbátù orímipé , folásadé Àkísan , mopélólá Ìsòlá , deborah akérédolú ati ìyábò ańjoórìn .
A ní ìrètí pé bí a bá gbé e wọ̀, a kò ní bá ara wa níhòòhò.
Hesekaya bá sọ fún wọn pé: “Nisinsinyii tí ẹ ti ya ara yín sọ́tọ̀ fún OLUWA, ẹ wá, kí ẹ sì mú ọrẹ ati ẹbọ ọpẹ́ wá sí ilé OLUWA.
A ri kà lójú òpó itakun àgbáyé pé, kòkòrò aifojuri kan ló ń ṣokùnfà àrùn òtútù náà, èyí tí ọwọja rẹ tán káàkiri àgbáyé, bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé ìwádìí kò fìdí rẹ múlẹ̀ nípa ibi tó ti ṣẹ wá.
Nígbà tí Serugi di ẹni ọgbọ̀n ọdún ni ó bí Nahori.
Igboho Ultimatum to Fulani: Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní gbèdéke ọjọ́ méje láti fi Ibarapa sílẹ̀, àwọn Fulani ní ìwà màdàrú ló ń bá kiri
Dokita Michael Adeyeri, to jẹ oludari ile iwosan Shekinah Hospital ladugbo Alagbaka nilu Akure, la gbọ pe o padanu ẹmi rẹ lọwọ arun yii .
OLUWA ti jẹ ẹ́ níyà ní ìlọ́po meji nítorí ẹ̀ṣẹ̀ rẹ̀.
Ẹni tí kò lè kó ara rẹ̀ níjàánu,dàbí ìlú tí ọ̀tá wọ̀,tí wọ́n sì wó odi rẹ̀ lulẹ̀.
Minimum wage: Àwọn gómìnà PDP láwọn yóò san #30,000 owó oṣù fáwọn òṣìṣẹ́
 Oríṣun àwòrán, Instagram/@officialpasuma ""O to asiko kan to jẹ pe, owo diẹ bayii lo ku ki owo tan ni asunwọn mi ni banki, nitori bi mo ṣe n ṣe yafun-yafun fun awọn ti mo ranlọwọ."
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Inter-family marriage: Wo oríṣìí àrùn márùn ún tí ìgbéyàwó láàrin ìbátan máa ń fà 12 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 17 Sẹ́rẹ́ 2021 Oríṣun àwòrán, others Igbeyawo laarin ibatan si ibatan wọpọ laarin ẹya Hausa ati Fulani ju bi ọpọ ṣe ro lọ.
Nígbà tí bàbá mi yọ sí Àjànnú-ìbẹ̀rù ti í ṣe oníbodè Igbó Olódùmarè òun náà mọ̀ pé òun dé ọ̀dọ̀ ẹbọra pàtàkì kan.
Ẹwẹ, olori awọn oṣisẹ lorilẹede Naijiria, Ọmọwe Folasade Yemi-Esan tẹlẹ ti rọ awọn oṣiṣẹ jake jado Naijiria pe ki wọn ma ṣalai lọ sibi iṣẹ lọjọ Aje.
Kì í ṣe sí wa gẹ́gẹ́ bí ẹ̀ṣẹ̀ wa,bẹ́ẹ̀ ni kì í san án fún wa bí àìdára wa.
''Mo fẹ ki ọrọ aje Naijiria pada gbeeru si, kawọn eeyan si wa lalaafia kaakiri orilẹede Naijiria,'' Oluwo lo sọ bẹẹ.
OLUWA rán Mose ati Aaroni pé 
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ọbasanjọ figbe ta pé Buhari fẹ́ gbé òuń ‘Kò sí ìsinmi June 12 lọ́jọ́ ìsẹ́gun’ Àwọn orílẹ̀èdè tó gba ife ẹ̀yẹ àgbáyé kọjá Ọ̀kan nínú àwọn òfin ọ̀hún tún ni fífún àjọ eletò ìdìbò (INEC) ní àsìkò tó péye láti se àtúndì ìbò.
“Gbogbo ohun tí mo pa láṣẹ fun yín ni kí ẹ fọkàn sí, kí ẹ sì ṣe é, ẹ kò gbọdọ̀ fi kún un, ẹ kò sì gbọdọ̀ mú kúrò ninu rẹ̀.
Awọn panapana kan ni wọn ya aworan awodamiẹnu ina to n jo ni papa yii.
Gomeri tún lóyún, ó sì bí ọmọbinrin kan.
Àlàyé rèé lórí ikú tó pa Ogun Majek Iroyin to n tẹ wa lọwọ ni yajoyajo ti salaye pe, ilumọọka osere tiata Gbolagade Akinpelu, ti ọpọ eeyan mọ si Ogun Majek ti jade laye.
Bí a óo bá san ẹ̀san fún olódodo láyé, mélòó-mélòó ni ti eniyan burúkú ati ẹlẹ́ṣẹ̀.
Trump ń lérí láti ti ojú òpó ìkànsíraẹni ayélujára pa nílẹ̀ Amẹrika Oloselu lo sokunfa bi ọlọpa ko se to ni Naijiria Àwọn Minisita agbègbè Lake Chad se ìpàdé Kókó ọ̀rọ̀ tí Buhari sọ ní àyájọ́ June 12 Mo ń bá ọ́kùnrin 15 sùn lọ́ọ̀jọ́ láti sàn owó ọ̀gá mi- Ngozi Iran ti jáwọ nínú ìlù ogun tó n lù -Trump Wo diẹ lara awọn Aarẹ ilẹ Adulawọ to ti táa tán sori oye nitori pe wọn di 'Field Marshal': Ta ni Idi Amin Dada tó jẹ 'Field Marshal' ni Uganda?
O ye ki Zuma fi alefa sile, leyin ti o ti wa lori alefa fun saa meji ototo, leyin ti o gori alefa ninu eto idibo ti o waye ni odun 2009.
Wo àwọn èèyàn jáńkán tí yóò ṣe ọdún tuntun ní ọgbà ẹ̀wọ̀n Àwọn fóònù wọ̀nyìí kò ní lè ṣe WhatsApp láti ọdún 2020 Àwọn orílẹ̀-èdè tó ti ṣáájú Nàìjíríà wọ ọdún 2020 Loju Ogbeni Olatunbosun Abolarinwa ati Akinkunmi Akinpelu Kure Jnr ni ti wọn, iṣẹ aabo ilu, ọrọ pipalẹ awọn SARS mo ati pe ti arẹ ko baa rii ṣe mọ, o le pada sile.
Awọn iroyin miran ti ẹ le nifẹ si: Njẹ ọrọ awọn akẹkọbirin Dapchi jọ ti Chibok ?
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Sex for marks: Ilé aṣọ̀fin àgbà ń gbèrò ẹ̀wọ̀n ọdún mẹ́rìnlá fún olùkọ̀ tó bá dẹnu ìfẹ́ kọ akẹ́kọ́ 9 Ọ̀wàrà 2019 Ile aṣofin agba orillẹede Naijiria ti gunle aba kan ti yoo dẹkun bi awọn olukọ Fasiti ṣe n dẹnu ifẹ kọ awọn akẹkọbinrin.
Nígbà tí wọ́n ṣírò iye owó àwọn ìwé ọ̀hún, wọ́n rí i pé ó tó ọ̀kẹ́ meji ààbọ̀ (50,000) owó fadaka.
"O salaye pe ""Mo ṣẹṣẹ kuro ni Ile igbimọ aṣofin ipinlẹ Ekiti ni, nibi ti moti ṣe ipade pelu agbẹnusọ ati awọn jankan jankan ile aṣofin naa."
Eji Gbadero, ọmọ Ibadan àti jayé-jayé ọmọ ónílẹ̀ ti wọn yẹgi fun l'Eko Ọọ̀ni obìnrin, Lúwòó Gbàgídà rèé, akọni tó ń gun ọkùnrin ní ẹṣin rìn Èyí ni àwọn arẹwà ‘ẹ̀lẹ̀ Daddy’, àfẹ́fẹ́ tí Aláàfin fi ń mí Ṣaaju ki wọn o to kede rẹ gẹgẹ bi adele alaga ẹgbẹ APC, Giadom ni igbakeji Akọwe Apapọ ẹgbẹ naa.
Bàbá ẹni ọgọ́ta ọdún dèrò ilé ẹjọ́ nítorí ó wọ inú oko Obasanjo láì gba àṣẹ Mi ò fẹ́ ìrànwọ́ ẹgbẹ́ òṣèré, àwọn kọ́ ló kóbá mi- Chief Kanran E wo ọmọ Yorùbá àkọ́kọ́ tó jà fún ẹ̀tọ́ àwọn aláwọ̀dúdú ní America!
Mo ti gbọ́ nípa rẹ pé o lè túmọ̀ ohun ìjìnlẹ̀, o sì lè yanjú ọ̀rọ̀ tí ó bá díjú; nisinsinyii, bí o bá lè ka àkọsílẹ̀ yìí, kí o sì sọ ìtumọ̀ rẹ̀ fún mi, wọn óo wọ̀ ọ́ ní aṣọ elése àlùkò, wọn óo sì fi ẹ̀gbà wúrà sí ọ lọ́rùn, o óo sì wà ní ipò kẹta sí ọba ní ìjọba mi.
Nígbà tí òùgnbẹ bá ń gbẹ ọ́, lọ sí ìdí àmù, kí o sì mu ninu omi tí àwọn ọdọmọkunrin wọnyi bá pọn.
Idi ni wi pe eni naa le fẹ gbagbe iya to jẹ ẹ nipa pipada si awọn iṣesi ti o maa n ṣe ni kekere.
Fidio naa ree: Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Africa Eye: Ìrírí àwọn ọ̀dọ́bìnrin tó dágbà sójú pópó àti ìrètí wọn fún ọjọ́ ọ̀la Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
 Ìgbà tí bàbá àti Ìyá rẹ ̀ fẹ ́ ẹ ́ kúró nílé ni jìjì pàápàá ti ń múra lọ ́ wọ ́ .
Gbogbo agbaye si lo n kan saara si oloogbe naa pe oun lo fopin si isejọba ologun fun ọpọlọpọ ọdun ni Mali.
Awọn afurasi marun un ti wọn farahan niwaju ile ọjọ loni ni Ayoade Akinnibosun, Ibikunle Ogunleye, Adeola Abraham, Salaudeen Azeez ati Niyi Ogundiran.
Aare Muhammadu Buhari ti pe fun  ifowosowopo awon orile ede Afirika   lati je ki  eto aabo to monyan lori wa ni kaakiri orile ede Afirika ati awon agbegbe re, ki eto aabo to peye lee wa fun emi ati dukia awon eniyan , ni eyi ti yoo dekun idukooko moni ati iwa janduku  to maa n waye.
Àwọn ohun tó yẹ́ kí o mọ̀ nípa Ọ̀gá DSS tuntun Àwọn àwòrán mánigbàgbé nípa Ààrẹ Muhammadu Buhari 'Kọ ọkọ rẹ sílẹ̀ kí o lọ fẹ́ Buhari' #Elections2019 Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'A máa ń bẹ́ orí ẹni tó bá gbé imọlẹ̀ ọdún ìjẹṣu tó bá ṣubú ni' 2.
Nígbà tí ẹ dé ibí yìí, Sihoni, ọba Heṣiboni ati Ogu, ọba Baṣani gbógun tì wá, ṣugbọn a ṣẹgun wọn.
Ọdun 2019 ni Makinde gbe igbimọ oluṣakoso kan kalẹ, to pe ni Park Management System (PMS).
Ninu atẹjade kan ti adari eto iroyin fun aya Aarẹ Naijiria, Ọgbẹni Suleiman Haruna fi sita lorukọ Aisha lo ti bẹbẹ fun idarijin.
Oríṣun àwòrán, EPA Àkọlé àwòrán, Akojọpọ esi ayẹwo aarun Covid-19 ni orilẹ-ede Naijiria gẹgẹ bi ajọ NCDC ṣe n kede rẹ.
Ẹbá ọ̀nà kékeré kan ní àdúgbò kọ́lọ́fín kan láàrìn gbùgbùn ilú Lọndọn ni ilé-oúnjẹ náà sápamọ́ sí.
'Ẹ má ṣi Fayemi túmọ̀ lórí àṣẹ tó pa nípa sísọ èdè Yorùbá' Kòsí àṣà tó faramọ́ fífi èmí ènìyàn ṣe ìrúbọ - Olúwó Ajínigbé ń bèèrè fún epo, iṣu àti ọ̀tí Schinap gẹ́gẹ́ bí owó ìtanràn Kòsí àṣà tó faramọ́ fífi èmí ènìyàn ṣe ìrúbọ - Olúwó Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Kùrù-kẹrẹ Coronavirus ṣeéṣe kó dópin láàrín ọdún méjì - WHO Géńdé agbébọn yabo àgọ́ ọlọ́pàá n‘Ibadan, ẹ̀mí ọlọ́pàá kan bọ́ Ọba Ilorin ló pàṣẹ pé kí ń padà sọ́dọ̀ ọkọ mi - Risikat olójú búlúù NCDC kéde èèyàn 340 míràn tó ṣẹ̀ṣẹ̀ lùgbàdì Covid-19 ní Nàìjíríà A fí ara mọ́ ìdájọ́ ikú Sharia tó tọ́ sí Olórin Yahaya- ẹgbẹ́ Amòfin Mùsùlùmí ẹ̀ka ìpínlẹ̀ Kano O ni ohun kii kọkọ tọ ẹnikẹni amọ ẹni to ba tọ oun rugi oyin, bẹẹ si ni oun ko gbagbe ipilẹ oun, ti oun si maa n ranti akoko toun kiri ọja.
‘Ẹni mẹ́rin àti Àlága ADC nípìnlẹ̀ Ondo ni wọ́n jígbé lọ’ Ǹjẹ́ o mọ Olorì Moremi tó jà fún òmìnira àwọn ẹrú nílẹ̀ Ifẹ̀?
OLUWA bínú sí èmi pàápàá nítorí tiyín, ó ní èmi náà kò ní dé ibẹ̀.
Lati ọdun 2015 lawọn ọmọ ẹgbẹ ti n ṣe iwọde eyi ti wọn fi n beere pe ki ijọba da olori wọn, Sheikh Ibrahim El-Zakzaky, ati iyawo rẹ, Zeenat silẹ.
Abiola Ajimobi Wọn bi gomina ana ni ipinlẹ Oyo, Abiola Ajimobi lọjọ karundinlọgbọn, oṣu kẹfa, ọdun 1949 si idile Ajimobi ni Oja-Iba ni ilu Ibadan.
Igba titi ma n mu irẹpọ ati ibọwọ funra ẹni wa si aarin awọn ayaba.
n ri sise owo ilu kumokumo ( Oyo State Economics and Financial Crimes
Ni ijọba ibilẹ Gokana nipinlẹ Rivers ni iṣẹlẹ ọhun ti ṣẹlẹ.
Oríṣun àwòrán, @YeleSowore Amọ ẹgbẹ Amofin Amẹrika ni iti ọgẹdẹ ni awọn ẹsun ti wọn fi n kan Sowore ọhun, ko si to ohun to yẹ ki ijọba apapọ yọ ada si.
Ṣugbọn ibi tí OLUWA yín bá yàn láàrin ẹ̀yà yín, ni kí ẹ ti máa rú ẹbọ sísun yín, kí ẹ sì máa ṣe gbogbo ohun tí mo pa láṣẹ fun yín níbẹ̀.
Ẹbọ fún Ẹ̀ṣẹ̀ Tí Eniyan Bá Ṣèèṣì Dá.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Odion Ighalo: Ole Gunnar Solskjaer gbóṣùbà káre fún Ighalo lẹ́yìn tó sọ góòlò méjì sáwọ̀n Derby County 6 Ẹrẹ̀nà 2020 Oríṣun àwòrán, @AfricaFactsZone Àkọlé àwòrán, Ohun ti ẹnikẹni ba sọ ko kan oun, bi ko ṣe ki oun gbaju mọ iṣẹ Atamatase ikọ Manchester United, Odion Ighalo ti ni, ọrọ ti awọn kan n sọ kiri lori igbeṣẹ oun lati darapọ mọ Manchester United ko tu irun kankan lara oun.
Inú wọn dùn pupọ pupọ bí wọ́n ti rí i.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Oluwo: Oluwo sọ̀rọ̀ nípa ẹwà rẹ̀ gẹ́gẹ́ bí Ọba alayé tó rẹwà gidigidi 23 Agẹmo 2020 Oríṣun àwòrán, Temperor telu1 Lara awọn gbajugbaja Ọba ti ko ṣee fi ọwọ rọ sẹyin ni ilẹ Yoruba ni Oluwo ti ilu Iwo nibi ti Kabiyesi Adewale Akanbi ti n jọba lọwọlọwọ.
Isu: Ọpọ eeyan ni ko mọ pe ewebẹ ni eroja isu, ounjẹ lasan la mọ si.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Buhari gbọ́dọ̀ bẹ̀rẹ̀ ìwádìí Ganduje láàrín ọjọ́ mẹ́rìnlá-SERAP NUPENG ti ìyanṣẹ́lódì NLC lẹ́yìn Ninu oju opo twitter rẹ ni Fayoṣe ti beere ibeere mẹrin kan lọwọ Buhari.
O ni ṣe ni ohun n ranti bi iya ti oun ṣe ku lasiko to n rọbi lati bimọ.
Omo odun mokanlelogbon ohun ni koi ti kopa ninu idije naa lati igba ti o ti ran Spain lowo lati gba ife-eye ohun nigba marun-un otooto, eyi ti o gba keyin lodun 2016 lorile-ede India.
OLUWA Ọlọrun àwọn ọmọ ogun, OLUWA ni orúkọ rẹ̀: 
Naijiria bẹrẹ ifẹsẹwọnsẹ naa pẹlu agbara bi Alex Iwobi ṣe jẹ tẹtẹ ayo kan ni iṣẹju karun-un, ṣugbọn Ahmed Musa to yẹ ko ran an lọwọ ko jẹ ki ayo naa wọle.
Yóo ti pẹ́ tó, Ọlọrun, tí ọ̀tá yóo máa fi ọ́ ṣẹ̀fẹ̀?
Àwọn tí ń ṣojúkòkòrò èrè àìtọ́ ń kó ìyọnu bá ilé wọn,ṣugbọn àwọn tí wọn kórìíra àbẹ̀tẹ́lẹ̀ yóo yè.
Laarin agbo ere tiata ni oun ati iyawo rẹ, Peju, to jẹ ọkan lara awọn ọmọ agba oṣere to ti fi ilẹ bora, Oloye Ogunmọla.
àwọn aguntan, ati àwọn mààlúù, ati gbogbo ẹranko ninu igbó;
Ààrẹ ẹgbẹ́ ọdẹ Soludẹrọ nílùú Ibadan Nureeni Ajijolaananbi sàlàye fún BBC Yoruba pé, ní àkọ́kọ́ ti ọlọ́pàá mú Sunday Shodipe náà, iṣẹ́ ọwọ́ àwọn ọdẹ Soludẹrọ ni.
O ṣalaye pe iyalẹnu lo jẹ fun oun lati ri i ninu iwe iroyin kan pe oun sọ pe Aarẹ Buhari ni yoo jẹ aarẹ to kẹyin ni Naijiria, tabi pe ọjọ kinni, oṣu Kẹwaa, ni ẹya Yoruba yoo tun ero rẹ pa.
Láti inú ẹ̀yà Efuraimu, ọ̀kẹ́ kan ó lé ẹgbẹrin (20,800) akikanju ati alágbára, tí wọ́n jẹ́ olókìkí ninu ìdílé wọn ni wọ́n wá.
Oríṣun àwòrán, @Oyinkan Oyinkan tun ṣiṣẹ bii Kanselọ to n soju awọn obinrin ni ijọba ibilẹ Eko fun odindi ọdun meje gbako, to si lọ soju fun ẹtọ awọn obinrin nile asofin lẹkun Iwọ oorun Naijiria.
 Leyin eyi, a o bere ipolongo wa lati awon ekun oselu
Awọn ni awọn dokita kan eyi ti ileeṣẹ to n sọ iwọlewọde si orile-ede Naijiria, (NIS) dena mọ ni papakọ ofurufu ilu Eko.
"Ilé aṣòfin Oyo àti Ogun buwọ́lu àbádòfin ikọ̀ aláàbò Amotekun Obìnrin tó ń ṣiṣẹ́ ẹrú ní Oman tó bá fẹ́ òmìnira, yóò bá ọ̀gá rẹ̀ ṣùn - obìnrin méjì tó ti oko ẹrú dé ""Inú mi kìí dùn torí ẹ̀ẹ̀kan lọ́dún mẹ́rin ni ọjọ́ ìbí mi máa ń wáyé"" Kàyééfì ńla!"
Ikọ Taifa Stars orilẹede Tanzania ti agbabọọlu Naijiria tẹlẹ, Amuneke jẹ akọnimọọgba wọn pegede lati kopa ninu idije AFCON 2019 lẹyin ti wọn pokọ iya fun Uganda pẹlu ami ayo mẹta sodo lọjọ Aiku.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Silas Robotic Engineer: Kò sí ǹkan rere tí ọmọ Nàìjíríà kò lè ṣe Bakare ní kò sí irú nkan ti o lé ṣẹlẹ̀ ti Ọba fi le kọ ìyàwó silẹ kóda ko ni àjẹ tabi kó tilẹ̀ ma ri ọmọ bi, Ọba ko ni ẹtọ láti kọ̀ọ́ silẹ̀.
Ẹ mọ pe mo nifẹ awọn ololufẹ mi, amọ ẹ le ba mi wi pẹlu ifẹ, lai ṣepe fun emi ati idile mi.
A ko faaye gba ki o ma le gbọ bukata ẹnikankan ninu wọn.
Rélùwéè Èkó sí Ìbàdàn: tíkẹ́ẹ̀tì ọ̀fẹ́ lẹ ó lò fún oṣù mẹ́rin gbáko- Amaechi
O ni Naijria ti ba anfaani lati tun ọrukọ orilẹede yii ṣe nipa ere idaraya jẹ.
"Ẹ̀ẹ̀kan láàrin ọjọ́ méjì là ń jẹun ní ìgbèkùn, ìyà jẹ wá - Akẹ́kọ̀ọ́ Kankara ṣàlàyé Ọkan lara awọn akẹkọọ ti wn sẹsẹ tu silẹ ti salaye fawọn akọroyin pe ""ẹẹkan laarin ọjọ meji ni awọn n jẹun ni igbekun ajinigbe""."
Opo eeyan lo ti n pin fidio ti iya onile Lisa Li fi sita lati ṣafihan iwa ọbun rẹ lori ayelujara pe ki awọn ọdọ iwoyi yee ṣoge lasan ṣugbọn ki wọn fi imọtoto kun iwa wọn.
 o wa bi guusu halifax , nova scotia , kanada , ati ariwailaorun miami , florida .
Obinrin Kenaani kan tí ó ń gbé ibẹ̀ bá jáde, ó ń kígbe pé, “Ṣàánú mi, Oluwa, ọmọ Dafidi.
Àwọn onímọ̀ ṣàwárí 'ihò ìyọ̀ tó gùn jù láyé' nítòsí ìbì tí ìyàwó Lọti inú Bíbélì ti di iyọ̀
Òun ati Aaroni kó gbogbo àwọn eniyan náà jọ siwaju àpáta náà.
Ogun yii, (ti ami rẹ jẹ re re) si tun tumọ si rogbodiyan, pakaleke ati aisi alaafia to peye.
Akoroyin tawọn agbofin fi si ahamọ lorilẹede Naijiria gba itusilẹ
nítorí yóo dára tí o bá pa wọ́n mọ́ lọ́kàn rẹ,tí o sì ń fi wọ́n ṣe ọ̀rọ̀ sọ jáde.
OLUWA, Ẹni Mímọ́ Israẹli, Olùràpadà yín, ní,“N óo ranṣẹ sí Babiloni nítorí yín,n óo dá gbogbo ọ̀pá ìlẹ̀kùn ibodè,ariwo ẹ̀rín àwọn ará Kalidea yóo sì di ẹkún.
Ta ni yóo wá ẹ̀ṣẹ̀ wa rí?
UnitedBurnley v SouthamptonCrystal Palace v EvertonLeicester City v WolverhamptonWatford v BrightonTottenham Hotspur v Aston
Oríṣun àwòrán, @ekitistategov Dangote, Fayemi pari ìjà láàrin Ganduje àti Emir Sanusi Sababi lo kuku gbe wọn rina ko ra wọn lọjọ keje, oṣu keje, ọdun yii nigba ti gomina Kayode Fayemi lọ ba awọn ọmọ ile iwe alakọbẹrẹ jẹun ọsan pọ.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Mo fẹ́ gbé ògo ìdílé ìyá àti bàbá mi ga pẹ̀lú iṣẹ́ Mọkálìíkì' Ìjọba fòfin de kátà-kárà ọtí líle lásìkò igbele covid-19, àwọn èèyàn ń fi ọ̀gbìn oyinbo àti ọkà bàbà ṣe ọtí lílé labẹle Òfin tí ìjọba fi dé oko-owo ọtí líle lásìkò igbele Coronavirus ni orílẹ̀ èdè South Africa tí mú kí ọ̀pọ̀ ibùsùn làwọn ilé ìwòsàn ṣófo, mú kí àìmọye oko-owo dojú de, tí làásìgbò oselu sì ń peléke si, èyí tó mú kí àwọn ènìyàn nifẹ báyìí sí ọgbin òyìnbó tá mọ si Pineapple.
Ìgbàmíràn èyàn tún le rí 6 fún àwọn ẹlẹ́sẹ̀ kékeré, tàbí 13 (tàbí jù bẹ́ẹ̀ lọ) fún àwọn ẹlẹ́sẹ̀ gòdògbà.
kejila odun yii, niluu Uyo, olu ilu ipinle Akwa Ibom.
 Ọ ̀ nà oǹdó ni àjèji yíí gbà wọ ìlú .
Ìwọ ni o óo jẹ́ àmì fún wọn; wọn óo wá mọ̀ pé èmi ni OLUWA.
Ṣugbọn ojú kò ní ti ẹni tí ó bá gbà á gbọ́.
Ajọ naa tun salaye apẹẹrẹ kan ninu eyi to gba ileesẹ ENI ni ojilenirinwo o din mẹwa ọjọ lati gbe igbesẹ dipo wakati mẹrinlelogun ti ofin orilẹede Naijiria la kalẹ.
Papaajulo bi iko ohun tun se padanu ifesewonse akoko sowo orile-ede Croatia pelu ami-ayo meji sodo(2-0).
Ṣugbọn Isaaki dáhùn pé, “Àbúrò rẹ ti wá pẹlu ẹ̀tàn, ó sì ti gba ìre rẹ lọ.
Ajọ iṣọkan agbaye UN ni awọn ya ọjọ Kọkandinlogun oṣu Kẹfa ọdọọdún sọtọ lati mu opin ba ifipabanilopo fawọn to wa ninu wahala ati laasigbo bi ti arabinrin yi.
Goolu to gba wọle fun ikọ rẹ, Liverpool ninu ifẹsẹwọnsẹ wọn pẹlu Bournemouth lọjọ abamẹta lo gbee lọ si tente oke pẹlu ọgbọn goolu.
Gẹ́gẹ́ bí ìròyìn ṣe jáde pé apá kan òpópónà márosẹ̀ Lagos-Ibadan yóò di títì pá kí ọdún kérésìmesì, ọ̀pọ̀ ènìyàn tó ń ṣe àmúlò ọ̀nà náà ló si ti ń ke gbàjare pe súnkẹrẹ fakẹrẹ ojú pópó náà kò ṣe fẹnu sọ.
Ó ṣe àwọn nǹkankan bí ẹ̀wọ̀n, ó fi wọ́n sórí àwọn òpó náà.
Agbẹnusọ ọlópàa Hisbah Adamu Yahaya sọ fún ilé iṣẹ́ BBC pe àwọn ti àwọn gbámu ni àwọn mùsùlùmí ti wọn o gbà ààwẹ̀ lásiko Ramadan.
orile ede Naijiria ni imọran nipa ohun ti AFDB ti se ati ohun ti o fẹ se.
Eliṣa rí i tí ó ń bọ̀ lókèèrè, ó bá sọ fún Gehasi, iranṣẹ rẹ̀, pé, “Wò ó!
A kì í gba igbó lọ́wọ́ onígbó
Ninu ọrọ rẹ aarẹ ileegbimọ aṣofin agba lorilẹede Naijria, Sẹnatọ Bukọla Saraki ni abajade iwadi igbimọ ile naa ti fihan wipe orilẹede Naijiria ko ṣe aṣeyọri kankan ninu igbesẹ gbigbogun ti iwa ibajẹ.
Sugbọn nigba ti ẹ ba fi ma da ọrọ baalu silẹ letigbọ rẹ, se ni ohun rẹ yoo yatọ.
Coronavirus: Gbogbo igbá ti ṣófo láwọn ilé ìtajà káàkiri London
Oríṣun àwòrán, Getty Images Iwadii fihan pe, laarin osu mẹta, ipaniyan ti peleke si lagbeegbe Zamfara, Kaduna, Kastsina ati ipinlẹ Niger.
Ni mo bá rú ẹbọ sísun.
"Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Abike Dabiri-Erewa: Ìròyìn òfégè ní pé mò kò ""Palliatives""pamọ́ sí ilé mí 6 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Oríṣun àwòrán, Willy Ibimina Jim-george Alaga ajọ to n risi ọrọ awọn ọmọ Naijiria lẹyin odi, Abike Dabiri Erewa ti ke gbajare lori iroyin to gbode pe o ko awọn nkan iranwọ Covid-19 pamọ sile rẹ."
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Alaafin: Ọ̀pọ̀ èèyàn ń bèèrè pé kí ló dé tí Olorì Badra kò fi sí nínú fọ́tò ọdún Ileya 1 Ògún 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 8 Ògún 2020 Oríṣun àwòrán, Instagram/olori_omoh_one Ọjọ Ẹti ni ọdun Ileya waye fọdun yii jakejado agbaye ti gbogbo idile si joko sile lati se ayẹyẹ ọdun naa papọ.
Iroyin kan tiẹ sọ pe, olori ẹgbẹ Republican nile, Kevin McCarth to jẹ ọkan lára ọwọ ọtun Trump ti ni oun ko ni sọ fawọn ọmọ ẹgbẹ Republican to ba fẹ dibo yọ Trump nipo, pe kí wọn maa ṣe bẹẹ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Akomolede ati Aṣa: Mọ̀ síi nípa ìró afárànma àti agbárànmọ́ fáwẹ́ẹ̀lì Yorùbá Suga pupo a máa kọ di ọpọlọ lati le gba ounjẹ protein sara ati awọn eronja miiran.
Àwọn ọ̀jọ̀gbọ́n Yorùbá foríkorí gbé ìwé tó lè sọ ẹ̀yà ara yín lédè Yorùbá.
Ile ise to n ri si oro irin ajo ni Naijiria The Nigerian Immigration Service (NIS) ti fowo sinkun mu asofin Dino Melaye ni papako ofurufu Nnamdi Azikiwe lojo Aje(Monday) nilu  Abuja.
O wa fọwọ gbaya pe agbara melo ni awọn Fulani ni, ti wọn fi n da Yoruba laamu, amọ ti oun ati awọn eeyan miran ba ri atilẹyin awọn oriade nilẹ Yoruba, ti awọn si lo awọn ohun ajogunba lati ọdọ awọn baba nla wa, awọn Fulani yii ko lee duro de awọn.
Sirleaf lo ipo naa fun ọdun mejila.
Ṣugbọn bí ẹ bá jìyà gẹ́gẹ́ bí onigbagbọ ẹ má jẹ́ kí ó tì yín lójú, kàkà bẹ́ẹ̀, ẹ máa yin Ọlọrun lógo fún orúkọ tí ẹ̀ ń jẹ́.
Joe okei-Odumakin ni lootọ eto abo jẹ ọkan gboogi lara eroja fun idbo to munadoko, ṣugbọn ko yẹ ko di eyi ti yoo maa mu ikayasoke ba araalu ṣẹlẹ.
Ǹjẹ́ o mọ̀ pé ètò ìdìbò kan wà tí erin àti òkúta Dáyámọ́ǹdì leè yí èsì rẹ̀ padà Ẹfunsetan Aniwura, ọmọ Ẹ̀gbá tó di akíkanjú obìnrin nílẹ̀ Ibadan Iroyin kan ti ko fidi mulẹ si ti n tan kaakiri pe awọn ajinigbe naa ti n beere aadọta miliọnu naira ki wọn to fi silẹ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Lagos train accident: Ọkọ̀ ojú irin pa ènìyàn mẹ́rin ní Eko 30 Ìgbé 2019 Oríṣun àwòrán, Google Àkọlé àwòrán, Àwọn tí ọ̀rọ̀ náà sojú ní wí pé kẹ̀kẹ́ márúwá náà ń tiraka láti gba ojú irin, eléyìí tó jásí pàpo.
Ìtàn ọ̀rẹ́ tó fi òògùn gba ọkọ ọ̀rẹ́ rẹ̀ ni Akomolede BBC Yorùbá fẹ́ kọ́ wa lònìí Ṣé ẹ̀yin ti rí ọkùnrin tó ń sún ẹ̀kún ìyàwó rí?
Ìtàn kan ni ó jẹ sí mi lọ́kàn lónìí yìí.
N kò fẹ́ kí ẹ ní ìdàpọ̀ pẹlu àwọn ẹ̀mí burúkú.
Wọ́n ò mọ̀ pé ilé náà ti di ẹgẹrẹmìtì, ó sì lè wò lulẹ̀ kí ó wó lù wọ́ntí í ṣe àpẹẹrẹ àìmọ̀kanmọ̀kàn àwọn ènìyàn sí ìpamọ́ ohun àjogúnbá àti àtìlẹ́yìn fún àtúnṣe sí ilé àtijọ́ tí ó wà ní Bangladesh.
Ní àràárọ̀ ati ní alaalẹ́ ni wọ́n ń rú ẹbọ sísun, tí wọ́n sì ń sun turari.
Bi awọn ipinlẹ to ni Coronavirus ṣe lọ ni yii: Eko -180 Plateau-148 FCT- 44 Ondo- 42 Kwara-38 Rivers-32 Oyo-29 Kaduna-21 Osun-20 Edo-17 Ogun-17 Ekiti-11 Kano-9 Benue-9 Delta-9 Abia-9 Niger-7 Gombe-3 Borno-1 Bauchi-1 Imo-1 Èèyàn 555 míràn tún kó COVID-19 ní Nàìjíríà l'Ọ́jọ́ Aiku Eeyan 555 ni wọn tun kede pe ayẹwo tun ti fihan pe o laarun COVID-19 lorilẹede Naijiria bayii.
Níbẹ̀ ni ó wà tí ó ń retí ìgbà tí gbogbo àwọn ọ̀tá rẹ̀ yóo di àpótí-ìtìsẹ̀ rẹ̀.
Bí wọn ti gbìyánjú tó pé kí àwa ọmọdé- ilé mọ nkan kan, ń ṣe ni a mọ̀ pé ayọ̀ sí nínú ilé wa ní ọ̀sẹ̀ náà.
Bester, tíì ṣe ọga agba fún ileesẹ ibaraenisọrọ MTN ni ẹkun àríwá orílẹ̀ èdè Zambia, lo ń pariwo pe ẹgbẹ̀rún lọ́nà mọ́kànlélógún dọla ($21,000), tíì ṣe mílíọ̀nù mẹ́jọ náírà (N8m) ni oun san bíi owó ilé ẹ̀kọ́ ọmọ náà àmọ́ tó lọ gba odo wale.
Ọmọyẹle Ṣoworẹ ni lara awọn ohun to kọ oun lominu nipa eto idibo sipo aarẹ lorilẹ-ede Naijiria ni iha kokan mi ti awọn oludije kọ si idibo naa.
Ati pe awọn eeyan ile naa kan wa ti wọn n sọ ede Germany.
Abrahamu bá súnmọ́ OLUWA, ó wí pé, “O ha gbọdọ̀ pa àwọn olódodo run pẹlu àwọn eniyan burúkú bí?
Ẹ óo kérora nígbà tí ara bá ń ni yín,tí ara ń ni yín bíi ti obinrin tí ń rọbí ọmọ!
Irọ́ yóo ti pẹ́ tó lọ́kàn àwọn wolii èké tí wọn ń sọ àsọtẹ́lẹ̀ ẹ̀tàn.
Alukoro ile-isẹ ọlọpaa ni ipinlẹ naa, David Misal ṣalaye wi pe ,awọn jaguda lo se iṣẹ ibi naa ti wọn si dana sun Fada naa ninu ọkọ re.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ṣajẹ tó mókè, àwọn ènìyàn gbé e gbà lọ́wọ́ ara wọn Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Ṣajẹ tó mókè, àwọn ènìyàn gbé e gbà lọ́wọ́ ara wọn 8 Agẹmo 2018 Ọ̀tọ̀ọ̀tọ̀ ni èròńgbà àwọn ènìyàn nípa onírúurú ṣajẹ tó wà lóde àti bí ó ṣe wọ́pọ̀ tó.
Ó wó gbogbo ibi tí àwọn tí wọ́n máa ń ṣe panṣaga fún ìsìn Aṣera ń gbé létí ilé OLUWA lulẹ̀, níbi tí àwọn obinrin ti máa ń hun aṣọ fún ìsìn Aṣera.
Lasiko to n ba BBC Yoruba sọrọ, akọwe feto iroyin fun gomina, Taiwo Adisa, to gbẹnu Seyi Makinde sọrọ salaye pe, awọn awakọ nipinlẹ Ọyọ nikan lo lasẹ lati sọrọ lori igbesẹ tijọba gbe lati yan awọn awọn adari ọkọ sawọn gareji gbogbo nipinlẹ naa.
Ẹ̀mí mẹ́ta ṣòfò nínú ìjàǹbá ọkọ̀ nípìnlẹ̀ Èkó Eeyan mẹrin ku ninu ijamba ọkọ l'Eko Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ijamba ọkọ le m'ẹmi lọ Ninu awọn awakọ naa la ti ri arakunrin kan ati ọmọ rẹ mẹta ti wọn jijọ wa ninu ọkọ naa.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Amotekun: Àwọn ọdẹ nìkan kọ́ ni àmọ̀tẹ́kùn wà fún, a gba àwọn ọ̀dọ́ tó sán eegun pẹ̀lú 13 Agẹmo 2020 Oríṣun àwòrán, others Oludari fun ikọ Amotekun nipinlẹ Oyo, Ajagunfẹyinti Olayinka Olayanju tun ti fi idi rẹ mulẹ pe o di dandan kawọn eeyan to ba fẹ dara pọ mọ ikọ Amotekun fi orukọ silẹ lori ayelujara.
24 Bélú 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 25 Bélú 2020 Oríṣun àwòrán, @LagosSarsPanel O fẹ jọ ere sinima agbelewo lasiko ti olujẹri kan niwaju igbimọ to n gbẹjọ lori iwa ipa awọn ikọ ọlọpaa SARS ṣadede kọju si ọlọpaa kan to si ni o gba oun leti lẹmẹẹrin.
Nítorí àwọn eniyan yóo wà tí ó jẹ́ pé ara wọn ati owó nìkan ni wọn óo fẹ́ràn.
Babangida fọrọ yii lede lasiko tawọn alaṣẹ ẹgbẹ oṣelu PDP kan sii nile rẹ niluu Minna, ni ipinlẹ Niger.
Jeremaya bá pe Baruku ọmọ Neraya, ó sọ àwọn ọ̀rọ̀ tí OLUWA bá a sọ fún un, Baruku bá kọ wọ́n sinu ìwé kíká kan.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Amadou Toumani Toure: Ọdún 72 ló lò lókè èèpẹ̀, kó tó jáde láyé 10 Bélú 2020 Oríṣun àwòrán, Getty Images Aarẹ tẹlẹ fun orilẹede Mali, Amadou Toumani Toure ti jade laye.
Ṣebí bí o bá wà pẹlu wa bí a ti ń lọ ni a óo fi lè dá èmi ati àwọn eniyan rẹ mọ̀ yàtọ̀ sí gbogbo aráyé yòókù.
Wọn ni Richard nikan soso ni ọkunrin tawọn bi, iku rẹ si ti mu ki orukọ idile parun.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Insecurity: Agbẹkọya ní òògùn abẹnugọ̀ǹgọ̀ ní ọ̀nà àbáyọ fún ìjínigbé!
Kini otitiọ kini irọ́ nínú gbogbo ìṣẹ̀lẹ̀ náà Gẹ́gẹ́ bí ìyá ọmọ náà ṣe sọ, nígba ti ọmọ sọnú, o ni oludásìlẹ̀ ijọ náà Alufa Babatunde rọ àwọn láti lọ simi silé ki wọn si ma fi ọ̀rọ̀ náà lọ ọlọpàá.
N ò mọ̀ bóyá ojú ń tì í ni tàbí ẹ̀rí ọkàn ń jẹ́ ẹ.
E jẹ ki a jijọ maa fọkan ba ọrọ yi bọ.
Ọga agba patapata awọn lọpaa si ti fa awọn ọlọpaa leti pẹlu ọpọ ofin ati ikilọ pe awọn yoo maa mu awọn ọga agọ ọlọpaa fun ipaniyan lọna aitọ.
“Bí ẹ bá dé ìlú tabi ìletò kan, ẹ fẹ̀sọ̀ wádìí bí ẹni tí ó yẹ kan bá wà níbẹ̀; lọ́dọ̀ rẹ̀ ni kí ẹ máa gbé títí ẹ óo fi kúrò níbẹ̀.
Awon ìbejì to jẹ obinrin, ti wọn jẹ ọmọ oṣù mẹ́sàn àti ẹgbọn wọn, to jẹ ọmọ ọdún méjì, pàdánù ẹmí wọn ní ilé ìwòsan ologun to wa ni ìlú Accra, ní orílẹ-èdè Ghana ni kété ti wọn gbé wọn dé ibè.
Bí àwọn baba yín ti rí, bẹ́ẹ̀ ni ẹ̀yin náà rí.
Gbé àwọn ẹ̀wù náà wọ Aaroni arakunrin rẹ, ati àwọn ọmọ rẹ̀, kí o sì ta òróró sí wọn lórí láti yà wọ́n sọ́tọ̀ ati láti yà wọ́n sí mímọ́, kí wọ́n lè máa ṣe iṣẹ́ alufaa fún mi.
Wo ǹkan mẹ́jọ tó yẹ kóo mọ̀ nípa Alex Badeh táwọn agbébọn pa ‘Awakọ̀ Ọ̀gágun Alex Badeh tí wọ́n pa kò kú’ Nínú àwọn mẹ́ta tó wà nínú mótò náà, Badeh nìkan ní wọn pa, èyí ló mú kí àwọn ènìyàn máa ròò pé bóyá àwọn agbénipa ló ṣiṣẹ́ náà Awọn ọ̀daràn náà gbé ọ̀rẹ́ Badeh ti wọn jọ wà nínú mótò sùgban wọn fi sílẹ̀ lẹ́yìn ti àwọn ẹbi rẹ̀ sàn owó kí wọn to túu sílẹ̀ Ẹ̀wẹ̀ àwọn ọmọ ogun mẹ́rin tó ń sọ́ọ ní wọn ni wọn wà ní kìlómità diẹ̀ sí ibi tó wà, àwọn náà ti wà ní atìmọlé báyìí Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 3 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 5 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Ṣé kí àwa ati àwọn ẹran ọ̀sìn wa lè kú ni?
“Nítorí náà, a óo wó ọ mọ́lẹ̀, o óo sì sùn láàrin àwọn aláìkọlà pẹlu àwọn tí wọ́n kú lójú ogun.
Ilé Jakọbu yóo dàbí iná,ilé Josẹfu yóo dàbí ọ̀wọ́ iná,ilé Esau yóo sì dàbí àgékù koríko.
" Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Widows Day 2019: Mo máa ń sá kiri wá owó ilé ni -Opó Jonathan ni RUGA ti ijọba Buhari gbe kalẹ kii ṣe ẹyawo bikoṣe eto ijọba lati na owo ilu lati fi gbe okoowo aladani larugẹ pẹlu gbigba ilẹ ilu fun awọn okoowo adani bẹẹ.
Àwọn òbí rẹ̀ ni Michel Akínlàdé àti Elizabeth Akínlàdé.
Ta a ba si n sọrọ nipa eto ijọba alagbada lorilẹede Naijria, a ko lee kọ iyan eto iselu naa, ka ma fi ewe bo ayajọ June 12 nitori ọpọ isẹlẹ kayeefi to waye lasiko naa ati ẹkọ to kọ orilẹede Naijiria.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ọmọ ọdún méjìlá ni mo ti ń ṣe bàálù, ọkọ̀, ilé àti ọkọ̀ ojú omi - Ọdọ́mọdé ‘Engineer’ Ìkọlù sáwọn àjèjì kò tíì tán ní South Africa, ètò ń lọ láti kó ọmọ Nàíjíríà wálé Ajé ò!
Ẹ kó ara yín jọ ní ìdílé ìdílé ati ní ọ̀wọ̀ọ̀wọ́ gẹ́gẹ́ bí ìlànà Dafidi, ọba Israẹli ati ti Solomoni ọmọ rẹ̀.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ìgbà wo ni Buhari yóò simi àwáwí?
Jesu mọ ohun tí wọn ń rò lọ́kàn.
 Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Fire Eater: Azonto ní àfojúṣùn òun ni láti lọ fi idán iná yìí pa owó lókè òkun ""Igba ta wa wo ọrọ yii si ọtun ati osi, a ri pe ta ba fun Oluwo ni ewe dẹkun, o le e ma siwọ ohun to n se yii, ijoko wa ko si fun wa lasẹ lati yọ ọba kankan, awa ko tiẹ fẹ ki wọn yọ ọba, tori idile to ti wa ati ati abuku to maa jẹ fun ori ade kaakiri nilẹ Yoruba."
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ojúlówó Shina Rambo yọjú sígboro lọ́jọ́ Àìkú, ó fi ìka hánu lórí ìpànìyàn tó ti ṣe Ọmọ Nàìjíríà mẹ́fa tó n fi owó ránṣẹ́ sí Boko Haram rẹ́wọ̀n he ní Dubai Mọ̀ síi nípa Shina Rambo tó pàdé Jesu lọ́gbà ẹ̀wọn lẹ́yìn tó ti jalè Wàhálà míì dé!
"Lati igba ti mo ti wa ninu ipebi ni igbaradi fun ati joye, ni awọn Ọyọmesi ti jẹ ko di mimọ fun mi pe, mo gbọdọ yan oloye si igbimọ mi.
Àtàwọn eniyan pataki pataki, ati mẹ̀kúnnù, ni yóo kú ní ilẹ̀ yìí, wọn kò ní rí ẹni sin òkú wọn, kò ní sí ẹni tí yóo sọkún wọn; ẹnìkan kò ní fi abẹ ya ara, tabi kí ẹnìkan fá orí nítorí wọn.
Orin Fuji ti Sikiri Ayinde Barrister kọ nigba aye rẹ jẹ akojọpọ Apala, Sakara, Awurebe ati awọn mii.
Babcock Sex Video: Láti ìgbà tí fásitì ti lé àkẹ́kọ̀ọ́ náà ló ti dùbúlẹ̀ àìsàn amọ́ ara rẹ́ ti dá
Oluranlọwọ Agba fun Aarẹ Muhammadu Buhari, Garba Shehu lo fi iroyin naa sita.
O wa salaye pe ijọba ipinlẹ Ondo ati ọgba ẹwọn ti ṣe nkan to tọ, sùgbọ́n igbesẹ ọna ilera ti n lọ lọwọ botilẹ jẹ pe eyi ko ṣee sọ nitori irú ẹsẹ ti wọn ṣe, o si lewu lati sísọ loju eegun ibi ti wọn wa bayii, sugbọn itọju ti n lọ.
Nítorí náà, alẹ́ yín yóo lẹ́ ṣugbọn àwọn aríran yín kò ní rí nǹkankan, òkùnkùn yóo kùn, àwọn woṣẹ́woṣẹ́ yín kò ní rí iṣẹ́ wò.
Ṣé àwọn oriṣa orílẹ̀-èdè tí àwọn baba ńlá mi parun gbà wọ́n sílẹ̀, àwọn orílẹ̀-èdè bíi Gosani ati Harani, Resefu ati àwọn ará Edẹni tí ń gbé Telasari?
O kọkọ wọle si ipo asofin agba nigba ti o jawe olubori gẹgẹ bi asofin to'n soju ẹẹkun ariwa Kwara lọdun 2011.
Ọjọ́ mẹfa ni kí ẹ fi ṣiṣẹ́, ṣugbọn ọjọ́ keje jẹ́ ọjọ́ ìsinmi tí ó lọ́wọ̀, ati ọjọ́ ìpéjọ mímọ́.
Fi ọ̀nà rẹ lé OLUWA lọ́wọ́;gbẹ́kẹ̀lé e, yóo sì ṣe ohun tí ó yẹ.
Àwọn ọmọ Israẹli ṣe ohun tí ó burú lójú OLUWA, wọ́n ń bọ oriṣa Baali.
ati rogbodiyan lotun losi to n koju orile-ede yii, gbodo tenu bo le.
Èmi náà ni, Èwo la ó ṣe?
Bakan naa ni awọn ọlọpaa to wa ni iwaju banki apapọ Naijiria naa wa nibẹ ni pẹsẹpẹsẹ lati koju awọn oluwọde naa.
Paroparo ni awọn ojupopo dá lọdun yìí - to si ṣe e ṣe ki wọn o tun ribẹ ni ọjọ Ajinde lopin ọsẹ yii.
Ẹ̀yin tí ẹ kì í ṣe eniyan nígbà kan, ṣugbọn nisinsinyii ẹ di eniyan Ọlọrun.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Irinwo ati ọgbọn awọn ẹlẹwọn ti wọn kẹkọgboye imọ ijinlẹ nileẹkọ giga fasiti agbele-gboye National Open University.
Fadeyi sàlàyé pé, alábaṣiṣẹ́ pọ̀ lóyẹ ki ikọ̀ Àmọ̀tẹ́kùn àti ọlọ́pàá jẹ́, nítorí náà, kò sí ìdí tí ọlọ́pàá yóò fi ṣe ẹsun ti wọ́n fi kan wọ́n.
Ojú rẹ̀ ti rí oríṣìíríṣìí lọ́dọ̀ àwọn oníṣègùn.
Buhari sọ ọrọ naa lasiko ti oun ati awọn olori ile aṣofin naa, Bukọka Saraki ati Yakubu Dogara ṣinu aawẹ pẹlu rẹ nile ijọba l'Abuja.
Aretha Franklin ni arun jẹjẹrẹ lati ọdun 2010.
1 Èmi ni Álfà àti Òmégà, Krístì Olúwa; bẹ́ẹ̀ni, àní èmi ni, ìbẹ̀rẹ̀ àti òpin, Olùràpadà aráyé.
Gbogbo ènìyàn bẹ̀ ẹ́ títí kò fẹ́ gbọ́.
Máa wọ aṣọ àríyá nígbà gbogbo, sì máa fi òróró pa irun rẹ dáradára.
Kusugu Nigba ti Bayajidda de si ilu Daura, o de si ile obirin arugbo kan, Ayyana.
Bakana naa, ni orile ede  South Africa fi orile ede  Egypt nakan-nakan bii igba ti eniyan ba  ta rọba lu ẹyẹ  lati fidii won rẹmi  pelu ami kan si odo (1-0 )lasiko ti idije
Lẹyin ti ọwọ tẹ wọn tan, ni a fi lilu bi i bara da wọn lọla nigba ti a ka ori obinrin kan ati awọn ori eeyan miran mọ wọn lọwọ."
Amin Aisan jẹjẹrẹ asẹtọ Ọkunrin Ki itọ o ma joni nidi ti Ọ̀mọkunrin ba fe tọ Isoro lati le tọ tabi lati da itọ duro nigba ti Ọ̀mọkunrin ba nsẹyọ Ki Ọ̀mọkunrin ma tọ nigbakugba loru Ailemu itọ duro Ki itọ o se tabi ki o ma jade daradara Ki Ọ̀mọkunrin o ma tọ itọ ẹjẹ Ki ẹsẹ ati ibi Ọ̀mọkunrin o ma wu Irọra ni ibadi, ẹsẹ ati ika ẹsẹ Irọra ninu egungun to le jasi ki eegun o run Aisan jẹjẹrẹ asẹtọ ọkunrin n paniyan ju aisan jẹjẹrẹ ọyan lọ Fun igba akọkọ nile Gẹẹsi, iyẹ awọn Ọkunrin to ku nipa aisan jẹjẹrẹ asẹtọ ọkunrin ti bori iyẹ awọn ọbinrin to n ku nipasẹ aisan jẹjẹrẹ ọyan, atọka ti fihan bẹẹ.
Wọn yóo fa obinrin náà lọ sí ẹnu ọ̀nà ilé baba rẹ̀, àwọn ọkunrin ìlú yóo sì sọ ọ́ ní òkúta pa, nítorí pé ó ti hu ìwà òmùgọ̀ ní Israẹli níti pé ó ṣe àgbèrè ní ilé baba rẹ̀.
Afọnja ni eyi yatọ si ohun to maa n waye latẹyinwa, ijọba si ro pe o yẹ ki awọn eeyan kan wa ti yoo lewaju ninu pipa owo wọle fun ijọba, gbogbo awọn alakoso gareji ọkọ ati ti ibudo iwakusa ni yoo maa sanwo fun ijọba.
odun meji seyin lo ti ye ki ogbeni Kabila ti kuro lori ipo.
Ẹ̀kọ́ mẹ́jọ tó yẹ kí ilẹ̀ Afirika kọ́ lára àjàkálẹ̀ aàrùn coronavirus Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Oríṣí ìjìyà ní àwọn bíi Gómìnà El Rufai àti Fayemi ń bèèrè f'àwọn afipábánilòpọ̀ Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Gomina Makinde:Osù tó ń bọ̀ la ó gbé ètò ààbò ilẹ̀ Yoruba jáde!
Bakan naa ni òtòṣì lè ni àròkàn nitori à i lówó lọ́wọ́ tàbi aini, àisàn, ọ̀fọ̀, ìrẹ́jẹ lati ọ̀dọ̀ ẹni ti ó ju ni lọ, ìrètí pi pẹ́ àti àwọn idi miran.
Ikoyi / Obalende Bridge Ijọba ibilẹ Ikeja Eti-Osa.
Oríṣun àwòrán, Others Awọn mejeeji ko lee sọ ibi ti ori n ba ẹsẹ wọn re, sugbọn pẹlu ifẹ nla to wa laarin wọn, wọn gba pe ọla yoo dara.
Ìgbà ọtun ti dé fún àwọn oníṣẹ́ ọwọ́ Nàìjíríà David Mark fìfẹ́ hàn láti dupò ààrẹ Gbèsè Nàìjíríà ti di N23 Trillion Ilé[-iṣẹ́ agunbanirọ sàlàyé péọdun lati sìnrú ilú baba ẹni ṣe pàtàki àti pé ọdun kan gbáko ló wà fún lójúnààti mú ìrẹ́pọ̀ wà láàrín gbogbo ẹku orílẹ̀-èdè yìí.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Àwọn obìnrin Ekiti fi tọ̀yàyà tọ̀yàyà kí Fayẹmi Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àwọn obìnrin Ekiti fi tọ̀yàyà tọ̀yàyà kí Fayẹmi 16 Agẹmo 2018 Láti ìgbà tí èsì ìdìbò ìpínlẹ̀ Ekiti ti jáde ní ọjọ́ àìkú, àwọn ará ìpínlẹ̀ náà ti bẹ̀rẹ̀ àjọyọ̀ fún àṣeyọrí Kayode Fayemi.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ṣé ẹ̀yin lè ṣe jú àwọn tó f'àmì sí Awọlumatẹ?
Nígbà tí ó bá di òwúrọ̀ ọ̀la, ẹ óo rí ògo OLUWA, nítorí ó ti gbọ́ kíkùn tí ẹ̀ ń kùn sí i.
Gusu, ipinle Oyo ni ile igbimo asofin Abuja  lorilede Naijiria, ni o ti ba iku ojiji pade
Yóo fi èyí tí ó kù gbẹ́ ère oriṣa rẹ̀, yóo máa foríbalẹ̀ fún un, yóo máa bọ ọ́, yóo máa gbadura sí i pé, “Gbà mí, nítorí ìwọ ni Ọlọrun mi.
Olamide ba wa l'orukọ jẹ ni, o si ta epo si aṣọ ala iṣẹ wa.
Ìwọ̀fà tí ò rọ̀run, á sin olówó rẹ̀ kú
Ara gbogbo àwọn tí kò kú ninu wọn kún fún kókó ọlọ́yún.
Wọn ni o ṣeeṣe ki arakunrin naa o ma ri apẹrẹ arun naa lara rẹ titi di igba to fi ẹmi silẹ; amọṣa o fara han ninu ayẹwo naa.
Aare tun so pe  “Akinkanju eniyan , bi I Akanbi ko nifee si iwa ibaje nitori pe iwa ibaje gbode kan tabi to gbile  laarin awon eniyan”.
O kere tan, eeyan to fara kaasa aarun naa le ni irinwo laarin wakati mẹrinlelogun, leyi to ti mu ki iye awọn to n ba arun ọhun finra naa le ni ẹgbẹrun meji bayii.
Pololikashvili sọrọ yii nibi abẹwo oni minista mẹjọ ti wọn n ṣe kaakiri orile-ede mẹrinlelogoji to wa nilẹ Adulawọ.
Láti ayé àwọn baba wa títí di ìsinsìnyìí, ni àwa eniyan rẹ ti ń dẹ́ṣẹ̀ lọpọlọpọ.
Kò ì tìí tó àsìkò tí yóò kǔ.
bákan náà ni ó tún jẹ ́ àbúrò bàbá fún constantine ( dino ) leventis ( 1938-2002 ) , olùṣòwò tí ó jẹ ànfàní lọ ́ pọọ ̀ nínú àwòrán hellenic art ní ( metropolitan museum of art in new york ) àti àwọn ilé ìṣura ohun àbáláyé káàkiri àgbáyé .
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Risikat Azeez: Ìyá àti bàbá ọmọ olójú búlù tí parí ìjà- wọ́n fẹ́ tún yìgì so Nibi ayẹyẹ fifunni lẹbun ẹkọ ọfẹ naa si ni Kọmisana feto ẹkọ nipinlẹ Kwara, Hajia Fatimah Ahmed bawọn peju si.
Iwadii ajọ to n mojuto ilo oogun ni Uganda, iyẹn Uganda National Drug authority fihan pe iho diẹdiẹ wa lara awọn rọba idaabobo ti ileeṣẹ Life Guard ti India ba wọn ṣe.
ikose yoo din iwa adigunjale ati ogun airise ku laarin awon ọdọ.
iranṣẹ kan wá sọ́dọ̀ Jobu, ó ròyìn fún un pé, “Àwọn akọ mààlúù ń fi àjàgà wọn kọlẹ̀, àwọn kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ sì ń jẹko nítòsí wọn; 
Ltd ló wákàti mẹ́tàdílógún láti kaa kò 10.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Elebuibon: Àwọn àṣà àtọ̀húnrìnwá ló fa títa ẹ̀jẹ̀ nítorí ògùn owo O jẹ akori ọrọ ti wọn n lo l'abẹle fun ipade awọn ọba.
Ifooya ati wahala ojoojumọ ni wọn fi jọ lo ọdun mọkanla ti wọn jọ gbe papọ ki ọlọjọ to de fun Bose.
Opin ọsẹ to kọja ni Gomina Ipinlẹ Kano, Abdullahi Ganduje fi iwe asẹ fun awọn Emir tuntun mẹrin lati bẹrẹ isẹ.
Àsìkò tó láti fi ìwọ́de gba ara wa sílẹ̀ lọ́wọ́ ebi àti oko ẹrú - Sowore Ọ̀gá àgbá ọlọ́pàá pàṣẹ pé kí wọn ṣàwárí àwọn pásítọ̀ tí wọn jí gbé Èmi kò gbé pọ̀ pẹ̀lú Kollington Ayinla àmọ́ ọjà t'ọ́mọ ti wọ̀ lọ̀rọ̀ àwa méjééjì - Salawa Abẹni Òṣèré tíátà, Kemi Afolabi fi ohùn ìdúpẹ́ ránṣẹ́ láti Meccah fún àdúrà ọmọ Nàíjíríà Pásítọ̀ ọmọ Nàìjíríà, Omotoso, tí wọ́n fi ẹ̀sùn ìfipábánilòpọ̀ kàn pàdánù ìwé ìgbélùú ní South Africa Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
O sọ pe okoowo oun ni oun yoo gbajumọ lẹyin eto BBNaija.
Àwọn ọmọ Hamu nìwọ̀nyí ní ìdílé ìdílé wọn, olukuluku ní agbègbè tirẹ̀, oríṣìíríṣìí orílẹ̀-èdè ni wọ́n, wọ́n sì ń sọ oríṣìíríṣìí èdè.
Mo ti fi ọ́ ṣe majẹmu fún aráyé,mo sì fi ọ́ ṣe ìmọ́lẹ̀ àwọn orílẹ̀-èdè;
Ẹnu ya àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ pupọ.
Àjẹ́ àti Aṣẹ́wó ní ìyá Rainbow - Òjòpagogo Ọdẹ ìbílẹ̀, OPC àti agbófinró ń pèèlò tí yóò se ọbẹ̀ ààbò jinná nílẹ̀ Yorùbá El-Zakzaky: Arúfin ni ijọba Muhammadu Buhari gan-an - Ladoja Buhari o, pèsè ohun tó yẹ sí ọgbà ẹ̀wọ̀n, kí àyípadà orúkọ wọn léè pegedé Wọn wa kadi ọrọ wọn nilẹ pe lasiko ti igun olujẹjọ gan n kadi ọrọ rẹ nilẹ, ko tako ẹri ti ọkan lara awọn ẹlẹri ti wọn ko wa siwaju igbimọ naa, tii se akọsẹmọsẹ olusiro gbe kalẹ, eyi to n tọkasi pe asise wa ninu esi ibo ti ajọ INEC kede.
Iná sọ lóòtọ́ láàfin mi, ṣùgbọ́n kò sí gìrí- Ooni Ile Ife Ìjọ́ mí ní Italy ni mo fi ń ṣèrànwọ́ fáwọn aṣẹ́wó ọmọ Nàíjíríà tó há - Taribo West Makinde ti sọ̀rọ̀ lẹ́yìn tí asekúpani Akinyele sálo mọ́ àwọn ọlọ́pàá lọ́wọ́ ní àhámọ́ Risikat, ìyá àwọn ọmọ olójú búlù tí bẹ̀rẹ̀ sí ní kọ́sẹ́ aṣojú lóge Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí 5:58 Fídíò, Akomolede ati asa Yoruba: Ẹ wá kọ́ nípa àpòtí ìṣura èdè wa lórí BBC Yorùbá, Duration 5,5820 Ògún 2020 Ooni ile Ife: Iná sọ láàfín Ọọ̀ni Ilé Ifẹ̀, Ọọ̀ni ilé ifẹ̀ ní kò sí ẹ̀mí tó báa lọ19 Ògún 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Oríṣun àwòrán, others Ọkan ninu awọn akopa ninu idijẹ Big Brother tọdun 2020 to n lọ lọwọ̀, Aisha Umaru thi gbogbo eniyan mọ si Kaisha lo fọ sẹkun lasiko ifọrọwerọ pẹ ẹlẹgbọn agba ninu yara.
Ẹwẹ, Makinde o mikan, o tẹra mọ ipinu rẹ o si kuro ni ẹgbẹ oṣelu PDP lọ si ẹgbẹ oṣelu Social Democratic Party, SDP nibi tó ti dije gẹgẹ bii gomina ipinle Oyo lodun 2015 ṣugbọn nigbẹyin, ko bọ sii fun un.
Báwo ni àwọn ọmọ Jakọbu yóo ṣe là, nítorí pé wọ́n kéré níye?
Oríṣun àwòrán, Twitter Wo awọn ohun marun un to yẹ ki o mọ nipa gbajugbaja olorin takasufe naa: Kanye West ti fẹ Alexis Phifer ri: Ko to di pe West gbe Kim Kardashian niyawo, o ti figba kan kọ ẹnu ifẹ si Alexis Phifer, to si sọ pe oun yoo gbe niyawo.
OLUWA ti dá mi dúró láti má ṣe ọ́ ní ibi.
''Ati ẹni tó gba wákàtí meji ati ẹ́ni to gba wákàtí méjìlelogun kò sí eyi tó rọrùn láti gbà.
Ireti wa pe, iko Super Eagles yoo gbaradi ni owuro oni fun ifigagbaga olorejore miiran ti yoo waye laarin iko ohun ati iko agbaboolu Atlético de Madrid, ti o n kopa ninu idije La Liga lorile-ede Spain, ni papa isere  Godswill Akpabio laago mefa irole oni.
World Water Day; Àwọn ara Ezeukwu ma ń rin ìrìn wakati méjì torí omi mímu
Pẹlu atilẹyin ọga rẹ, William Abass kọ ibudo nla kan silu Badagry ti wọn pe ni Brazillian Barracoon eyi ti wọn kọkọ fi ọparun kọ lọdun 1840.
Ọjà Àgbáláta ní Badagry rèé, níbití ẹran ejò ti dùn ju ẹran adìẹ lọ Láti orí 'Our Mumu don do' sí 'Revolution Now' Bí ọdún Ọ̀ṣun Oṣogbo ṣe bẹ̀rẹ̀ rèé àti pàtàkì rẹ̀ fún Nàíjíríà Saudi ṣàtúnṣe lílẹ òkò mọ́ Asitani láti dẹ́kun títẹra-ẹni-pa Ẹgbẹ́ Akọ́mọlédè àti Àṣà Yorùbá Nàìjíríà pé àádọ́ta ọdún Amọ iwadii naa fikun wi pe, ohun to n fa ifasẹyin diẹ nipa lilo ẹrọ diroonu ni iwadii finnifinni lati ọdọ ijọba apapọ, lori iwulo ohun elo naa ni awọn agbegbe to beere fun ‘drone’.
O si ṣalaye pe ede mẹrin ni awọn Adam, Kamil ati Yakub ẹgbọn wón le sọ daadaa, iyẹn Yoruba, ede Oyinbo, Polish ati Finish to jẹ ede Finland ti wón n gbe.
Bí kùkùté igi ṣe lọ́ mọ́ ọ̀rẹ́, ló bu igbe ta pé “yéè, ẹ gbà-mí- o, òkú ti dì mí láṣọ mú o, ará igbó, èrò ọ̀nà, ẹ wá yọ mí nínú ọ̀fìn yí o”.
Báyìí ni bàbá mi máa ń sọ nígbà tí ó bá sọ ìtàn náà fún wa, gbogbo wa á sì máa rẹ́rìn-ín, gbogbo wa á máa tàkìtì, gbogbo wa á máa yí ní ilẹ̀ kiri.
Kí Ọlọrun fi ojurere wò ọ́, ọmọ mi.
O si ti kopa ninu idije mẹrinlelọgbọn ni saa Premier League to n lọ lọwọ, to si gba bọọlu sinu awọn lẹẹmeji.
Kí ló mú kí àwọn èèyàn máa jẹ ọ̀rọ̀ Adeboye lẹ́nu lórí Twitter Wo àwọn ẹ̀ṣọ́ ara tó tó $40m Diezani Madueke tí ilé ẹjọ́ gbẹ́sẹ̀ lé Óya gbé bọ́dì ẹ!
Wọn a gba wọn bi ẹni gba ni ṣiṣẹ́, wọn a si ko wọn lọ maa ṣe iṣẹ nọbi.
9th Assembly: Gbajabiamila fi èróńgbà rẹ̀ láti jẹ adarí ilé aṣojú ṣòfin hàn
Kikọ ile fun ajọ to n gbogun ti ajakalẹ arun ni Ghana Kikọ ile iwosan arun ọpọlọ meji atawọn to wa tẹlẹ Ohun amayedẹrun Ṣiṣe eto ẹyawo ti ko gara fawọn eeyan, ṣiṣẹ pọ pẹlu awọn olokowo aladani lati ṣeto ẹyawo fawọn ọmọ orilẹede Ghana.
Igbimo to n mojuto eto oro aje lorile-ede Naijiria ti sagbekale igbimo tuntun ti yoo maa mojuto eto abo ati ilana ti yoo pese isuna lopo yanturu fun awon olopaa.
Ẹ̀mí rẹ̀ bá pada sinu rẹ̀, ni ó bá dìde lẹsẹkẹsẹ.
Awon merin naa ni ibode Seme ni ẹkun Guusu Iwọ-Oorun, Illela ni ipinlẹ Sokoto, Maigatgari ni iha Ila Oorun-Ariwa ati Mfun ni ẹkun Guusu-Guusu.
00 lọdun kan,fun awọn alaboyun ti iye wọn jẹ 7,445,100 iye owo $305,249,100.
Ọlọrun ní àwọn ọmọ yín kéékèèké, tí kò tíì mọ ire yàtọ̀ sí ibi, àwọn tí ẹ sọ pé wọn yóo bọ́ sọ́wọ́ àwọn ọ̀tá yín, àwọn ni wọn yóo dé ilẹ̀ náà, àwọn ni òun óo sì fi fún, ilẹ̀ náà yóo sì di ìní wọn.
Ní ìgbà náà, wọ́n ń ra owó dola ní naira 155, sùgbọ́n ní bá yì dola kan ti di naira 363.
Gomina Makinde:Osù tó ń bọ̀ la ó gbé ètò ààbò ilẹ̀ Yoruba jáde!
Awọn miran le nilo itọju ni ileewosan pajawiri ti wọn ko ba le mi dada.
Ninu awọn ti yoo ṣe ọdun tuntun ninu ẹwọn lati ri awọn eeyan jankan bii oloṣelu, pasitọ, oṣere tiata, ati bẹbẹ lọ.
Àwọn àgbààgbà bá wí fún wọn pé, “Ẹ má pa wọ́n.
Òun ni ó jẹ́ olókìkí jùlọ ninu “Àwọn Ọgbọ̀n Akọni,” ó sì di aṣiwaju wọn, ṣugbọn kò lókìkí tó “Àwọn Akọni Mẹta” àkọ́kọ́.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Promise Akinlade: ọmọ ọdún mọ́kànlá tó ń fi ìlù dárà bíi àgbàlagbà sọ̀rọ̀ nípa tálẹ́ǹtì rẹ̀ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Promise Akinlade: ọmọ ọdún mọ́kànlá tó ń fi ìlù dárà bíi àgbàlagbà sọ̀rọ̀ nípa tálẹ́ǹtì rẹ̀ 7 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Ilu lilu maa n mu inu mi dun ni- Promise Akinlade Omọ ọdun mọkanla ni Promise Akinlade to n fi ilu da ara to wu u.
Beraya bí ọmọkunrin meji: Heberi ati Malikieli, baba Birisaiti.
Lẹyin ọdun marun, adajọ gba ẹbẹ agbẹjọro naa, to si dajọ pe: Ki ile iwosan fun ọmọ Catherine to ti pe ọdun marun ni iwe ọjọ ibi Ki agbẹjọro agba lorilẹ-ede Kenya se agbekalẹ igbimọ amusẹya kan ti yoo daba awọn ọna tawọn ọmọ to ni oju ara meji yoo fi maa gbe aye gbadun bii awọn eeyan yoku laisi idẹyẹ si kankan Àlàyé rèé lóríi ìdí tí wọ́n fi ń pe aya ní ìyàwó Lóòtọ́ lò n lo ìbomú-bẹnu, ṣùgbọ́n ṣe bóṣeyẹ kí o wọ̀ ọ́ ló ṣe n ṣe?
 lẹ ́ yìn tí ó rúbọ náà tán , yemọja finú ṣoyún ó sì fẹ ̀ yìn súnmọ sókè .
Ohun ti igbesẹ Sani,Yushau,Jamilu ati awọn miiran bi ti wọn n ṣe ni pe lọjọ ti awọn musulumi yoku ba n dawọ idunu itunu awẹ awọn ko ni ti dawọ awẹ gbigba duro.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Sanwó Olú búra fún ìgbìmọ̀ ìṣàkóso rè níbi tó ti yan àwọn 38 sípò 21 Ògún 2019 Oríṣun àwòrán, @Sanwo Olu Àkọlé àwòrán, Sanwo Olu bura fun awọn kọmiṣọna tuntun ni Eko Ni ọjọ Isegun ọ̀sẹ̀ yìí ni gomina ìpínlè Èkó, Ogbeni Babajide Sanwó Olú ṣe ifilole igbimo ìjọba rẹ ni ọ́fíìsì ijoba ni Alausa Ikeja.
Buhari: Obasanjo ló mú ìgbéga bá òṣèlú Nàìjíríà, ó yẹ ká yìn-ín
Grace Oshiagwu: Afurasí ní abọ́ oúnjẹ kan, ẹ̀ẹ́dẹ́gbẹ̀ta náíra lòun ń gbà lóri àwọn tó pa l'Akinyele
Onínúfùfù yóo jìyà inúfùfù rẹ̀,bí o bá gbà á sílẹ̀ lónìí, o níláti tún gbà á sílẹ̀ lọ́la.
Serubabeli bí Abihudi, Abihudi bí Eliakimu, Eliakimu bí Asori.
Oman ń ṣelédè lẹ́yìn Sultan Qaboos bin Said
Kò sí ẹni tí ó lè sùn mọ́.
Wọ́n ti pa ẹni to yìnbọn pa ará Texas márùn ún -ọlọ́pàá Àwọn orílẹ̀èdè tó ń ṣe bẹbẹ nínú ìdíje AFCON 2019 tó ń lọ ní Egypt Òní nilé ẹjọ́ tó ga jùlọ yóò gbẹ́jọ́ ẹ̀sùn ayédèrú sabuké tí wọ́n fi kan Buhari Dino, Wada àti àwọn olùdíje 11 míràn n dù àsíá PDP fún gómìnà ìpínlẹ̀ Kogi Minista ere idaraya gboriyin fun awọn akọni yii fun gbigbe ogo Naijiria ga ni Morocco.
Bakan naa ni agbẹnuso Ile Aṣofin naa rọ awọn ọmọ orilẹ-ede Naijiria lapapọ lati jẹ ki alaafia jọba, ki wọn si yago fun awọn ọrọ ati iwa ti o le ṣokunfa aisi iṣọkan laarin wọn.
Jafani ni baba ńlá àwọn ọmọ Eliṣa, Taṣiṣi, ati àwọn ará Kitimu, ati Rodọni.
Sugbọn lati igba ti o ti bẹrẹ niṣe ni o n jọ mi loju.
 ikú àwon omo yìí dùún gidigidi .
3 bílíọ̀nù sọ́tọ̀ fún ètò ẹ̀kọ́ nínú àbá ètò ìṣúná ọdún 2021 Òmùwẹ̀ kó s'ọ́wọ́ ẹja Sháàkì nínú odò, ikú ló padà já sí Wo ìjìyà tí ilé aṣòfin orílẹ̀-èdè UK kéde fún Naijiria nítórí ẹ̀sùn nípa ENDSARS Motara si jẹ ki ọmọ yii sare le ọkọ rẹ tori ko kan le re kekere mu lara ọti ẹlẹrindodo naa.
Dafidi ọba ya àwọn ẹ̀bùn náà sí mímọ́ fún ìlò ninu ilé OLUWA, pẹlu gbogbo fadaka ati wúrà tí ó rí kó láti gbogbo orílẹ̀-èdè tí ó ti ṣẹgun; 
Oríṣun àwòrán, VCG Ṣugbọn ọpọ ni kii mu omi deede yala nitori pe ko si aaye tabi ni ọpọ igba ko si aaye igbọnsẹ iṣẹju-iṣẹju layika wọn, ẹwẹ ẹlomiran ko tilẹ mọ pe omi ti oun n mu ko kun oju osuwọn to.
Ọrọ Fayose jade nigba to sọrọ lori Twitter nipa igbesẹ Buhari lati yọ Adajọ Agba Walter Onnoghen nipo.
Sheffield United vs Arsenal: Evra ní Arsenal sì wà lọ́mọ ìkókó lẹ́yìn ọdún mẹ́wàá
Nígbà tí mo rí ìwé yìí, àfí bí ẹni pé wọ́n fi mi jọba ni.
Wọn yóo máa jẹ́ eniyan mi, Èmi náà óo sì máa jẹ́ Ọlọrun wọn.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìbúgbàmù àdó olóró pa èèyàn kan ni Mubi 11 Òkùdu 2018 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ìjọba náà ní kìí ṣe ìkọlù àwọn agbébọn niṣẹlẹ naa Ibugbamu ado oloro ti pa ọdọmọde kan ti awọn meji miiran si farapa nilu Mubi, ipinlẹ Adamawa.
"Èyí ni ohun tí Ọọ̀ni sọ nípa Àrẹ̀mọ rẹ àti ètùtù tó ń ṣe lọ́wọ́ Àwọn ohun tó yẹ kí o mọ̀ nípa Ọ̀ọ̀ni Ilẹ̀ ifẹ̀ Àwọn ọbá aláye ilẹ̀ Yorùbá márùn-ún pẹ̀lú ọ̀pá àṣẹ wọn ""Àsìkò yí ló yẹ kí Yorùbá fi ìmọ̀ ṣọ̀kan"" Ilé ẹjọ́ dájọ́ ẹgba mẹ́ẹ̀dóògún fún ọ̀daràn tó jí Iphone ní Kaduna Ki wa ni igbesẹ ti Ọba fi le ri ọmọ tuntun nilẹ Yoruba?"
"O ni ""a o ni kọkọ le ẹni ti ayẹwo ba mu, dipo bẹẹ, a o ko wọn jọ fun ikọni."
Ṣugbọn ìwọ, OLUWA, ni Ọlọrun aláàánú ati olóore;o kì í tètè bínú, o sì kún fún ìfẹ́ tí kì í yẹ̀, ati òtítọ́.
Sugbọn Nasreen morile ileẹjọ Kotẹmilọrun lori ọrọ yii, amọ ti ileẹjọ naa da ẹjọ ọhun nu lọdun 2018, to si kede pe igbeyawo to waye laarin Mohammed ati Nasreen ko bofin mu.
Kayode Ajulo: Ò dára kí Ilé Ìgbìmọ̀ Asòfin buwọ́lù àwọn àbádòfin tí Buhari kọ̀sílẹ̀
Akẹkọ fasiti purọ mọ ọlọpa lẹyin to fowo ileewe ta MMM
Bẹ̀rẹ̀ láti orí àkọ́bí Farao, tí ó jókòó lórí ìtẹ́, títí kan àkọ́bí iranṣẹbinrin tí ń lọ ọkà, ati àkọ́bí gbogbo ẹran ọ̀sìn.
“Kí ni ẹni tí ó ni ọgbà náà yóo wá ṣe?
Coronavirus: Ọ̀gá iléèṣẹ́ tó n ṣe kọ́ńdọ́mù Durex sọ pé ìbálòpọ̀ dínkù lásìkò ìgbélé yìí
"Madikizela-Mandela ti ""jagun ti awọn ẹda alawọ kan, iṣiro ile-iwe ati ipalara awọn ọkunrin""."
Mímọ́ ni wọ́n jẹ́ fún alufaa náà, pẹlu àyà tí a fì ati itan tí wọ́n fi rúbọ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ondo judgment: Pásítọ̀ Kolawole ṣá Olaniyi pa lóko kọ̀ǹkọ̀, adájọ́ bá ní kí wọ́n yẹgi fún un 27 Èbibi 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 29 Èbibi 2020 Oríṣun àwòrán, others Ile ẹjọ giga kan ni ilu Akurẹ ti dajọ iku fun pasitọ kan ti orukẹ rẹ n jẹ Kọlawọle Samson fun jijẹ ẹsun ipaniyan.
Sunday Igboho ṣalaye pe, oun atawọn eeyan kan ti setan lati lọ koju awọn Fulani, ṣugbọn awọn ọba alaye atawọn agbaagba ilẹ Yoruba gbọdọ fọwọ si pe, awọn lo ran awọn niṣẹ, ki omi maa ba tẹyin wọgbin lẹnu.
Nígbà tí mo parí ọ̀rọ̀ mi tán, èkúté mú ọ̀nà rẹ̀ pọ̀n, ó ń wá óunjẹ òòjọ́ rẹ̀ lọ, ó sì wáá ku èmi, mo lé téńté s’orí igi.
Orí yéye ní mògún, t’àìṣẹ̀ ló pọ̀.
 ”Salami menuba ise ti egbe SHEGOFAN ti se nipa siseto idanilekoo fagbe to le ni egberun lona aadota lodun 2017 kaakiri Naijiria paapaa lori idanilekoo lori ona eran osin tonigbalode.
Nítorí pé inú OLUWA dùn sí àwọn eniyan rẹ̀,a sì máa fi ìṣẹ́gun dé àwọn onírẹ̀lẹ̀ ládé.
Ni àwọn ẹ̀yà Reubẹni, ẹ̀yà Gadi ati ìdajì ẹ̀yà Manase bá dá àwọn olórí ẹ̀yà Israẹli lóhùn pé, 
Tí a fiṣọwọ́ ní 19:56 10 Ọ̀pẹ̀ 202019:56 10 Ọ̀pẹ̀ 2020 Ọkùnrin kan rí ẹ̀wọn he lẹ́yìn tó lu obìnrin ní jìbitì ìfẹ́ tí iye rẹ̀ tó $15,000 lórí ayélujára Ọkunrin kan ti dero ẹwọn lẹyin to lu jibiti ori ayelujara.
Ohun tó ṣẹlẹ̀ láàrin Ozo àti Nengi olórí àti igbákejì nílé BBNaija rèé Awọn ololufẹ eto ile ẹlẹgbọn agba, BBNaija tun sọrọ lori ohun to ṣẹlẹ laarin olori ile, Ozo ati igbakeji rẹ, Nengi lalẹ Ọjọru mọju Ọjọbọ kan.
Dafidi ati àwọn ọmọ Israẹli lọ gbógun ti ìlú Jerusalẹmu, (Jebusi ni orúkọ Jerusalẹmu nígbà náà, ibẹ̀ ni àwọn ará Jebusi ń gbé.
Pupo esin awujo ile Africa, won ka awon obinrin si iyawo ile lasan, eyi ti ko leto si nnkan bi awon okunrin.
Lẹyin to bẹrẹ ni China, arun naa ti tan de South Korea, Italy, Iran atawọn ilẹ mii lagabye.
Masazo Nonaka láti ilẹ̀ Japan ni ẹni tuntun tó dàgbà jù lọ lágbàyé
Bí Ọlọrun bá wọ koríko ìgbẹ́ láṣọ báyìí, koríko tí yóo wà lónìí, tí a óo fi dáná lọ́la, mélòó-mélòó ni yóo fi aṣọ wọ̀ yín, ẹ̀yin onigbagbọ kékeré yìí!
Lati kúrò ni ilú ẹni lọ ṣe iyàwó tàbi ayẹyẹ ni ilú miran, wọn ni lati ṣẹ́ Naira si owó ilu ibi ti wọn ti fẹ́ lọ ṣe ayẹyẹ, lẹhin ìnáwó iwé irinna àti ọkọ̀ òfúrufú.
Afikun iroyin lati ọwọ Linnete Baahati ti ẹka BBC Monitoring ati Yẹmisi Adegoke ti BBC Africa.
Ìtàn ayé Henry Fajemirokun, olówó tó fi owó mọ Olúwa àti ènìyàn Orílẹ̀-èdè mẹ́wàá tí ẹgbẹ́ alákatakítí Islamic State n fínna mọ́ ní àgbáyé Ó ṣeéṣe kí ènìyàn 12,000 máa kú lójoojúmọ́ lẹ́yìn Covid-19 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Kí olukuluku yín ní ọ̀pá kan, tí yóo máa dì mọ́ ara ohun ìjà rẹ̀, tí ó lè fi gbẹ́lẹ̀ nígbà tí ó bá fẹ́ yàgbẹ́; nígbà tí ó bá sì yàgbẹ́ tán, ọ̀pá yìí ni yóo fi wa erùpẹ̀ bò ó mọ́lẹ̀.
Baba Adeboye, gẹgẹ bi ọpọ eeyan lagbaye ṣe maa n pee ni ki ni ka ti pe tawọn ibudokọ gbogbo, ati awọn ọja nibi ti ero n pọ si.
O ni àwọn ìgbìmọ amúṣẹ sẹ ijọba lori COVID-19 ni yóò kede igbésẹ ti àwọn yóò gbe nitori alaye ọlọdani ni oun ṣe fun àwọn oniroyin.
O ni irọbi jẹ laarin aye ati ọrun ni eyi ti ko yẹ ki oṣiṣẹ eleto ilera tun maa na wọn tabi pariwo mọ wọn lasiko irọbi rara.
"Ootọ ni nkan ti gomina Akeredolu sọ, ṣugbọn ibeere to yẹ ka bi Akeredolu ni pe, so ti da ileeṣẹ ti wọn yoo ti maa lo igbo silẹ, abi ti wọn ba bẹrẹ si ni i gbin, ta a lo fẹ lo?
Abẹ akoso Ọba Gẹẹsi, King George IV la wa, ti ko si si ẹni to ga ju ofin lọ nigba naa, Lloyd Crow si lo n soju awọn eebo fun igbẹjọ.
Lábàlúyẹ̀gẹ̀ t’orí ẹ̀gbin, ó fàkìtàn ṣe yẹ̀wù.
Wo àdúgbò tó ń jẹ́ orúkọ èèbó amúnisìn tí yóò pa orúkọ dà l’Eko Ṣé lóòótọ́ ní pé ìyàwó Gómìnà Ìpínlẹ̀ Ondo tí lugbadi Covid-19?
Bí wọn tí ń gun òkè Luhiti, bẹ́ẹ̀ ni wọ́n ń sọkún,nítorí pé nígbà tí wọn tí ń lọ níbi ẹsẹ̀ òkè Horonaimu,ni wọ́n tí ń gbọ́ igbe ìparun; pé,
Bakan naa lo kọminu lori ọda awọn irawọ tuntun lagbo fuji.
Kí àwọn eniyan máa sìn ọ́, kí àwọn orílẹ̀-èdè sì máa tẹríba fún ọ.
 } ( èyun gbogbo nọ ́ mbà tí kí se tí òdì ) .
eto ijoba tiwa-n-tiwa lorile ede yii .
'Ológun kò ṣe àyọjúràn sí ìdìbò 2019' Kò sí ìwé ẹ̀rí fun olùdíje tí tó ba wóle lábẹ hílàhílo Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, BBC Yorùbá: Àwọn akọ̀ròyìn wa ti lọ káàkiri láti jábọ̀ ìròyìn ìbò Awọn meje miran ti ori yọ ninu iṣẹlẹ ọhun n gba itọju nile iwosan bayi.
Wọn a máa fi aro, ìlù, ati fèrè kọrin,wọn a sì máa yọ̀ sí ohùn dùùrù.
Mó sọ pé rárá, rárá, rárá, kò si ọkan ninu àwọn ọmọ mi ti yóò la ǹkan ti mo lakọja kọja nítori pe ràbàràba rẹ̀ kò ti kúrò lára mi.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Kíni ẹ mọ̀ nípa àwọn gbajúgbaja Yollywood?
tabi ijoba orile-ede ya owo, niwon igba ti won  ba fi owo ohun s’owo tabi pese ise ti yoo pa
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Woli Kasali: Angẹli mi ni orékelẹ́wà Dọlapo Awoṣika Ẹwẹ, ọj meje ni ẹgbẹ TUC ipinlẹ kọkọ fun ijọba gẹgẹ bii gbedeke ki wọn to yi ọkan pada nigba ti wọn ri i pe ọrọ ori ahọn lasan ni gbogbo ileri ti ijọba n ṣe fun awọn.
Wọ́n bá dá Jesu lóhùn pé, “Àwa kò mọ̀.
Iyanṣẹlodi naa bẹrẹ lowurọ Ọjọ Aje lẹyin ti awọn aṣoju ẹgbẹ naa sọ agadagodo si ẹnu ọna abawọle fasiti ilu Ibadan.
ati afiwe rẹ̀ pẹlu awn orilede to ku.
Aare ajọ agbabọọlu Ghana (GFA), Nyantakyi Kwasi ti kọwe fipo rẹ silẹ.
Ninu ohun ta ri gbọ lẹnu Baba Kaosara bakan naa o sọ pe, iyawo Gomina lo ba awọn pari ija naa ,ti o si tun ṣatọkun bi wọn ti ṣe jijọ ya aworan papọ.
(19,489) tayọ akẹgbẹ rẹ lati ẹgbẹ oṣelu PDP, ti o ni ẹgbẹrun
N óo tún odi rẹ̀ mọ, n óo tún un kọ́ yóo sì rí bí ó ti wà tẹ́lẹ̀ rí.
Party primary (Idibo abẹle) : idibo yii ma n waye ninu
Ọkunrin náà dáhùn pé, “Israẹli sá níwájú àwọn ará Filistia.
 Idagbasoke ati igbelaruge awon ohun-eelo inu eto ogbin yoo tubo je ki ise naa rorun fagba ati ewe.
wa nilee fun awon osise alaabo lati gbese.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ijamba ọkọ tirela to sẹlẹ lori afara Kara ni ilu Eko gbẹmi mẹrin 31 Sẹ́rẹ́ 2018 Oríṣun àwòrán, Bella Naija Àkọlé àwòrán, Iya kan ati ọmọdekunrin rẹ kagbako ijamba lori afara Kara Ọmọdekunrin,ọmọ ọdun marun kan atawọn eeyan mẹta min lo ti jalaisi ninu isẹlẹ ijamba kan to waye laarọ oni lori afara Kara to wa ni opopona marosẹ Ibadan silu Eko.
 síṣẹ ́ nípa lílo aṣọ náà to .
Loṣu Kẹfa ọdun to lọ, o le ni ọgọsan ẹlẹwọn ti awọn agbebọn tu silẹ ni ọgba ẹwọn Koton Karfe yii kanna.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, CAN: Samson ni ọrọ awọn ajinigbe ti gba àpérò ní Naijiria O ṣalaye pe ọrọ ipenija aabo to mẹhẹ ko mọ si ẹkun kan lorilẹ-ede Naijiria, kaakiri orilẹ-ede yii lo ti n waye.
Wọ́n ja ìjà yìí títí ilẹ̀ fi mọ́.
Lọdun 2016, agbenusọ ajọ EFCC nigba naa, Wilson Uwajaren, sọ fun iwe iroyin The Nation pe: O seese ki a kọwe pe ọlọpaa ilẹ okeere ati awọn ajọ miran lati tọ pinpin Mahmood Ahmadu."
5m ni owo ajẹmọnu osoosu awọn sẹnatọ!
Eyi ni alaye ti Vincent to jẹ ọmọ ilu naa ṣe lori bi o ṣe ṣẹlẹ.
Ìpàdé ìtagbangba BBC Yorùbá: Gbọ̀ngàn Mapo ṣeé mú yangàn ní Ibadan
Ikọ ọmoogun orilede Amẹrika ti doola ẹmi ọmọ orilede wọn ti wọn jigbe ni iha ẹkun ariwa orilẹede Naijiria.
Bee si ni, won yoo safihan ife-eye ohun pelu irufe ife-eye Jules Rimet, eleyi ti o je ife-eye akoko ti won sagbekale re nigba ti idije ohun koko bere lọdun 1930 seyin.
Ẹ má ṣe é bí ẹni tí ó fẹ́ jẹ́ aláṣẹ lórí àwọn tí ó wà lábẹ́ yín ṣugbọn ẹ ṣe é bí àpẹẹrẹ fún ìjọ.
Irú àwọn ẹni bẹ́ẹ̀ kò ní lè dúró láàrin àwọn èrò iwájú, ààrin èrò ẹ̀yìn ni wọ́n ó máa wà láéláé.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Bolanle Sarumi Aliyu: Nígbà tó bá di àsìkò tèmi, èmi náà á dé 'bẹ̀ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Bolanle Sarumi Aliyu: Nígbà tó bá di àsìkò tèmi, èmi náà á dé 'bẹ̀ 27 Èbibi 2019 Àwọn 'agent' mi ló fọ́mbù lọ́jọ ìbò nitori owó -Sarumi Arabinrin Omobolanle Sarumi Aliyu ni obinrin akọkọ to jade lati dije dupo gomina ipinlẹ Ọyọ.
 o je didaloruko sipo yi latowo aare islam karimov ni ojo 12 osu kejila 2003 , beeni ileasofin usbeki si faramo .
Oríṣun àwòrán, Facebook/Femi Adesina Àkọlé àwòrán, Aarẹ Muhammadu Buhari n lọ fun ipade OIC Aarẹ n lọ fun apero ẹgbẹ Organisation of Islamic Cooperation ti ọpọ mọ si OIC ti yoo waye lọjọ Ẹti niluu Makkah.
Ile ẹjọ giga ni Kaduna ti pasẹ ki ijọba ipinlẹ Kaduna fun adari ẹgbẹ Shia lorilẹ-ede Naijiria, Ibrahim Elzakzaky ati iyawo rẹ, Zinat ni eto iwosan to peye.
Ni Bayajidda ba gba gooro ipọnmi kan lọwọ rẹ, o si lọ si ibi ti kanga naa wa.
Ẹsun naa gba gbogbo ori ayelujara kan, ṣugbọn Fatoyinbo ni oun ko fipa ba obinrin kankan lo pọ ri.
Oríṣun àwòrán, oTHERS Àkọlé àwòrán, Ọ̀kan lára àwọn fóto àwòtúnwo tó fisíta rèé fun ayẹyẹ ọjọ́ ìbí rẹ̀.
Àkọlé àwòrán, Ojulowo ọmọ Yoruba naa ni awa Àkọlé àwòrán, Aṣa Yoruba rẹwa Àkọlé àwòrán, 'ÀbÍ a ò rẹwà báyìí?
Ní ọjọ́ kan, Samsoni lọ sí ìlú Gasa, ó rí obinrin aṣẹ́wó kan níbẹ̀, ó bá wọlé tọ̀ ọ́ lọ.
Àwọn àádọ́ta ọ̀dọ́ wọ gàù nítorí ilé ijó ní Ilorin Lati ojule de ojule ni wọn n lọ lati rii pe imọtoto wa bi o tilẹ jẹ pe eyi naa ri bakan.
Agbaje ni awon osise aje eleto
Eyi lo sọ ọ di aarẹ ikẹrinla orilẹede Naijiria.
Ìdáhún àtàwọn ìbéèrè míì Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Kí lo tíì rí nípa Amotekun?
Alagabagebe: Ẹ fi àmì ohùn Yorùbá sí orí rẹ̀
Bí ó tilẹ̀ ń ru sókè, kò lágbára kan,kí ìgbì rẹ̀ máa hó yaya, kò lè kọjá ààlà náà.
Aarẹ Kenyetta bori ninu atundi idibo to waye losu kẹwa, sugbọn ọgbẹni odinga ko kopa ninu idibo naa.
Ṣugbọn alágbára ni Olùràpadà wọn, OLUWA àwọn ọmọ ogun ni orúkọ rẹ̀.
Ọba dá Daniẹli lọ́lá, ó kó oríṣìíríṣìí ẹ̀bùn ńláńlá fún un, ó sì fi ṣe olórí gbogbo agbègbè Babiloni, ati olórí àwọn ọ̀jọ̀gbọ́n ní Babiloni.
dibo, sugbon ohun to n komi lominu ni bi awon osise eleto idibo yoo mojuto awon
Bẹ́ẹ̀ ni bí nǹkan bá ti ń tóbi tó ni iṣoro rẹ ń tóbi tó ṣùgbọ́n, Gwynne-Jones borí ìṣoro tírẹ̀ patapata.
Eto ọrọ aje Souh Africa ti n lọ silẹ sii.
Ogagun John Enenche to jẹ agbẹnusọ fun ileṣẹ ologun sọ pe awọn ọmọ ogun pa Boko haram mẹjọ nigba ti ọpọ salọ pẹlu ọgbẹ to pọ.
Oríṣun àwòrán, Genesis global Ẹgbẹ awọn aladura Awọn wọnyii lo ma n fi adura jagun fun awọn ọmọ ijọ naa, ati ẹnikẹni to ba fi ẹbẹ adura ranṣẹ sinu ijọ naa.
Àwọn nǹkan tí ẹ̀ ń rù kiri wá di ẹrù, tí àwọn ẹranko tí ó ti rẹ̀ ń rù.
Alhaji Olajide ni awọn si n rawọ ẹbẹ si ijọba Gomina Makinde lati gbẹsẹ kuro lori ẹgbẹ NURTW nipinlẹ Oyo.
"Awọn Ọba to n s'atilẹhin fun Buhari ko fi ohun ti awọn ọmọ ilẹ Yoruba fẹ han.
La ba wa nibi apejẹ kan o.
Ìyá rẹ lè lówó lọ́wọ́, Bàbá si lè lẹ́ṣin leekan
Ile iwosan First Cardiology to wa ni Ikoyi niluu Eko ni Ajimobi dakẹ si nibi ti o ti n gba itọju nile iwosan.
Bi èniyàn bá lówó tàbi wa ni ipò agbára kò ni ki ó má ro àròkàn nitori ìbẹ̀rù ki ohun ini wọn ma
Farao bá pe gbogbo àwọn ọlọ́gbọ́n, ati àwọn oṣó, ati àwọn pidánpidán tí wọ́n wà ní ilẹ̀ Ijipti, àwọn náà pa idán, wọ́n ṣe bí Aaroni ti ṣe.
O ni ibanujẹ lo jẹ fun ajọ naa pe awọn agunbanirọ mẹsan tun ku nipinlẹ Taraba.
Ijọba orilẹede DR Congo n di ẹbi awọn ikọlu naa ru awọn oriṣiriṣi ikọ ajijagbara to wa ni orilẹede naa.
Bẹẹ si ni ọpọ awọn eeyan lo n sa asala fun ẹmi wọn lasiko rogbodiyan awọn ọmọ ẹgbẹ okunkun naa.
Àṣẹ yìí ni ẹ̀ṣẹ̀ rí dìrọ̀ mọ́ láti fi ṣiṣẹ́.
 (15), eleyii lo fẹ jẹ eyi ti o pọju to
Boko Haram titu awọn olukọni mẹta Unifasiti Maiduguri silẹ
Ìdì abájọ mẹ́ta táwọn arẹwà fi ń gba ti Aláàfin 'Èkúté jẹ oògùn olóró níbi tí wọn fi pamọ sí ní àgọ ọlọpàá' El-Rufai sọ̀kò ọ̀rọ̀ sí igbákejì ààrẹ, Yemi Osinbajo, Ó ní òun ni alága àwọn èèyàn kúkurú Ìgbéyàwó èmi àti Aláàfin kò pé, ṣùgbọ́n.
Lati bi ọdun kan ni Christina ti n fi owo pamọ, lati le fi orúkọ silẹ fun idanwo, lai wo bukaata awọn ọmọ rẹ mẹtẹẹta.
Farao bá ranṣẹ pe Mose ati Aaroni, ó sọ fún wọn pé, “Mo ti dẹ́ṣẹ̀ nisinsinyii; OLUWA jàre, èmi ati àwọn eniyan mi ni a jẹ̀bi.
ní 2013 ìṣẹlẹ ̀ 148 àrùn náà ni a jábọ ̀ rẹ ̀ .
 Àkókò láárin ìgbà kíkó àrùn yíi àti ìgbà tí àmì jẹyọ jẹ ́ láàrín oṣù kan sí mẹ ́ ta .
Nígbà tí àwọn ọmọ Israẹli gbọ́ pé àwọn ẹ̀yà Reubẹni, ẹ̀yà Gadi ati ìdajì ẹ̀yà Manase ti tẹ́ pẹpẹ kan sí ìhà ibi tí ó jẹ́ ti àwọn ọmọ Israẹli, ní agbègbè odò Jọdani, ní àtiwọ ilẹ̀ Kenaani, 
Njẹ́ ó mọ àwọn àìsàn aṣeku pani to rọ mọ ooru?
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Eégún Iwobi jóo re, orí ya Liverpool 30 Ọ̀pẹ̀̀ 2018 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ori n ya atọkun Iwobi Unai Emery ti gboriyin fun Alex iwobi ati Maitland-Niles.
lati foju lamẹẹtọ wo abajade akosile ti ile-ise to n mojuto eto omoniyan lorile
Coronavirus Cases in Africa: Àwọn àràmọ̀ndà ìbomú-bẹnu tó gbòde lásìkò Coronavirus yìí
Kì í ṣe pípọ̀ tí àwọn ọmọ ogun pọ̀ ní ń gba ọba là;kì í sì í ṣe ọ̀pọ̀ agbára níí gba jagunjagun là.
Alẹ ọjọru ni awọn eniyan ọtalenigba din mẹẹrin (256) naa de pada si Naijiria.
Kinniun yìí kò jẹ òkú rẹ̀ rárá bẹ́ẹ̀ ni kò sì ṣe kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ ní ohunkohun.
ÀmínOúnjẹ wo ni àwọn ènìyàn mo ìlú tie mó?
 Olori Anu ni oun n lo anfaani ikede naa lati tọrọ aforijin lọwọ ẹnikẹni ti oun ba ti ja kulẹ tabi to n binu si oun nitori ikede naa."
"Wo àwọn ojúṣe àti èèwọ̀ fún ikọ̀ ọlọ́pàá SWAT tó gba iṣẹ́ lọ́wọ́ SARS Ọlọ́pàá mú afurasí 31 tó ń dúnkokò máwọn ọmọdé lórí ayélujára Pásítọ̀ Enoch Adeboye darapọ̀ mọ̀ #ENDSARS, ó fún ìjọba Nàìjíríà ní ìmọ̀ràn ọ̀nà àbáyọ Mọ̀ nípa iPhone 12, fóònù ológo 5G tí kìí lo ""Charger” tó ṣẹ̀ṣẹ̀ jáde Àṣé àṣírí wà nínú Hijabu tí Aisha Yesufu ń wọ̀ lọ ìwọ́de Ẹ wo èrò bìbà níbi ìwọ́de #EndSARS ní ìlú Ibadan Kaka ki ewe agbọn agbọn dẹ, niṣe lo n le koko si."
Àwọn ará Ijipti ń lé wọn lọ, pẹlu gbogbo ẹṣin ati kẹ̀kẹ́ ogun Farao, ati gbogbo àwọn ẹlẹ́ṣin rẹ̀, ati gbogbo àwọn jagunjagun rẹ̀, wọ́n bá wọn níbi tí wọ́n pàgọ́ sí lẹ́bàá òkun, lẹ́bàá Pi Hahirotu ni òdìkejì Baali Sefoni.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Bode George sọ̀rọ̀ sókè lórí àwọn tó faragbọta lásìkò ìwọ́de EndSARS ní Lekki Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Bode George sọ̀rọ̀ sókè lórí àwọn tó faragbọta lásìkò ìwọ́de EndSARS ní Lekki 27 Ọ̀wàrà 2020 Ọkan lara awọn eekan ati agba ninu ẹgbẹ oṣelu Peoples Democratic Party, Oloye Bode George naa ti mẹnu ba ọrọ iṣẹlẹ to waye ni Lekki lasiko iwọde EndSARS ni ipinlẹ Eko.
Oke Imesi ni a ti bii ni ìpińlẹ̀ Ekiti O ti kópa ninu awọn ere bii Fopomoyo Yanpan yanrin Ajalu Arelu Igbo Eleje Irinkirindo Rukerudo Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Tunde Kelani; Èmi ò jẹ́ Baba Wande ní owó lórí fíímù Tolúwanilẹ̀ Oríṣun àwòrán, Others Ẹni ọdún makànlélọ́gọ́rin ni báyìí, o si le jẹ ntori agba to de ni baba ṣe fi ere agbelewo silẹ.
Ko da, ajọ naa ni, ti a ba ko ẹgbẹrun lọna ọgọrun ọmọ Naijiria jọ, aadọjọ ninu wọn ni atẹgun ti ko dara yoo gbẹmi rẹ.
Orí mi wú, Joke Silva kọ ewì ìfẹ́ lọ́jọ́ ìbí Olu Jacobs Nibẹ ni ogbontarigi oṣere naa ti sọrọ lori ẹsun ifipabanilopọ ti Busola Dakolo fi kan Biodun Fatoyinbo to n dari ijọ COZA.
Oríṣun àwòrán, Facebook/Barrister Fans page Àkọlé àwòrán, Ko sẹni ti ko ni ku ni Yoruba n wi 'Tìbínú-tìbínú ni Liverpool fẹ́ fi kojú Man U' Ìsèjọba ìgbìmọ̀ asòfin dára ju ìsèjọba ààrẹ lọ -Femi Okunronmu Ààrẹ Ethiopia tẹ́lẹ̀ Giorgis papòdà lẹ́ni ọdún 94 Àwọn agbébọn ṣekúpa akẹ́kọ̀ọ́ tó wà nípele àṣekágbá ní fásítì Kogi Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Silas Robotic Engineer: Kò sí ǹkan rere tí ọmọ Nàìjíríà kò lè ṣe Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Ìgbà tí obìnrin náà gbọ́ ọ̀rọ̀ yìí ó sáré ó lọ ṣe oògùn rẹ̀, wéré àyípadà dé, adágún omi di ìlú, àwọn ẹja sì di ènìyàn wọ́n ń ta ọjà wọ́n sì ń ra ọjà, wọ́n ń wọlé wọ́n sì ń jáde.
Ṣùgbọ́n ní èdè Gẹ̀ẹ́sì, gbólóhùn pàtàkì gbáà ni.
Ọba pàṣẹ pé kí ọ̀sanyìn ẹlẹ́sẹ̀ mẹ́wàá ó lọ mú bàntẹ́.
Wọ́n rí ọdọmọbinrin arẹwà kan ní ìlú Ṣunemu, tí orúkọ rẹ̀ ń jẹ́ Abiṣagi, wọ́n sì mú un tọ Dafidi wá.
Aijaloni ati Gati Rimoni, gbogbo wọn jẹ́ ìlú mẹrin.
Bakan naa, ojogbon Olusola tun so pe egbe oselu PDP  tun  le gbe igbese lati mu esun awọn agbofinro  lọ sile ẹjọ pelu awọn esun miiran bi i :fifipa mu awọn agba egbe oselu ati asoju wọn, ifiya jẹ awọn oludibo lona aitọ, siseto iranwo fun awọn odaran ati dida aabo bo awọn asoju egbe APC to n fowo ra ibo lasiko eto ibo.
"Ninu iwe to kọ, igbakeji alaga APC fun ẹkun ariwa Sẹnetọ Lawal Shu'aibu ni ""ipinlẹ mẹtalelogun ni a ni lọdun 2015, ṣugbọn nigba to di ọdun 2019 a padanu meje""."
Sugbọn ohun ti awa sakiyesi ni pe, Olori naa ko fi bẹẹ gbe aworan oun ati ọkọ rẹ, Alaafin soju opo ayelujara rẹ, gẹgẹ bo se maa n se.
OLUWA Ọlọrun ń bọ̀ pẹlu agbára ipá rẹ̀ ni yóo fi máa ṣe àkóso.
Ẹ óo jẹ́ eniyan mi, n óo sì jẹ́ Ọlọrun yín.
Tí ó bá jẹ́ rere ni mo sọ, kí ló dé tí o fi lù mí?
Ẹsira ṣí ìwé náà lójú gbogbo eniyan, nítorí pé ó ga ju gbogbo wọn lọ, bí ó ti ṣí ìwé náà gbogbo wọn dìde.
Oko tí ó lọ jẹ́ ti Boasi, ìbátan Elimeleki.
69 Àti Nísisìyí, kíyèsíi, ẹnikẹ́ni tí ó bá jẹ́ ti ìjọ mi, ati tí ó fi ara da ìjọ mi títí dé òpin, òun ni èmi yíò gbé kalẹ̀ lórí àpáta mi, ọ̀run àpádì kì yíò sì lè dáa dúró.
Tọkan tọkan, mo tọrọ aforiji fun gbogbo iwa ti mo ti wu to fi ri bayii mo si gba a lẹbi.
Adegbenro ni awọn to n sa gaari silẹ n fayegba eku to ni aisan lassa lati tọ si ori garri yii, eleyi ti yoo fa aarun Lassa fun gbogbo ẹni to ba jẹ garri naa.
Nígbà tí ó rí ohun tí ó ṣẹlẹ̀, ó lọ sí ilé Maria ìyá Johanu tí àdàpè rẹ̀ ń jẹ́ Maku.
Gẹ̀ẹ́sì gbẹ́sẹ̀ lé ₦82bn owó Abacha Bakan naa, lo ni lara ohun ti awọn to dide ogun si ile aṣofin apapọ ṣe ni ti awọn agbofinro to ṣingun wọ gbagede ile aṣofin apapọ ni oṣu kẹjọ, ọdun 2018.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Toma Unu: Ọmọbìnrin tó ń fi ẹsẹ̀ rẹ̀ ya àwọran nítori pe ó ni ìpènija ọpọlọ Ajọ INEC sọ pe sisun ti wọn sun eto idibo naa siwaju ko ṣẹyin bi ijọba ipinlẹ Bayelsa, ati awọn ẹlẹgbẹ-jẹgbẹ, to fi mọ awọn olori ẹsin, ṣe kọwe ẹbẹ si ajọ naa lati sun un siwaju nitori pe ọjọ ti wọn kọkọ da fun idibo jẹ ọjọ kan naa pẹlu eto idupẹ ọdọọdun ti wọn maa n ṣe ni ipinlẹ Bayelsa.
Wọ́n ní eléyìí wáyé lẹ́yìn ìfọ̀rọ̀jomitoro ọ̀rọ̀ pẹ̀lú ẹ̀ka ìgbìmọ̀ tí Sẹ́nétọ̀ Chris Ngige funra rẹ̀ darí tí wọ́n sì gbé ọ̀rọ̀ mẹ́rin yẹ̀wò.
Ó ti gba agbára mi ní àìpé ọjọ́,ó ti gé ọjọ́ ayé mi kúrú.
BBC Yoruba kan si akọwe aafin Soun Ogbomoso, Arakunrin Totin to si jẹ ko di mimọ pe ẹni ori yọ o dile ni tori awọn n sa asala fun ẹmi awọn.
Ọkunrin náà bá mú mi gba ọ̀nà tí ó wà ní ẹ̀gbẹ́ ìlẹ̀kùn, ó bá mú mi lọ sí ibi àwọn yàrá tí ó wà ní apá àríwá ibi mímọ́ náà, tí ó jẹ́ ti àwọn alufaa, mo sì rí ibìkan níbẹ̀ tí ó wà ní ìpẹ̀kun ní apá ìwọ̀ oòrùn.
15 Sẹ́rẹ́ 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 16 Sẹ́rẹ́ 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Aṣa Yoruba dùn pupọ Eyi ni akojọpọ diẹ lara awọn òwe ti BBC Yorùbá ti lò sẹyin.
Ijoba orile ede Naijiria ti kede ojo Isegun ,ojo kinni ose karun un fun ojo isinmi lati fi se ajodun awon osise ti odun 2018 yii.
Oríṣun àwòrán, @AsoRock Àkọlé àwòrán, Kìí ṣe ààrẹ Buhari ní yóò kó orúkọ àwọn tí yóò ṣiṣẹ́ jọ, àwọn òsìsẹ́ ni, ẹnikẹ́ni kò sì lée gba ẹ̀rí wọn jẹ.
Prophet Israel Oladele: Kilo gbe e de ijọ Celestial?
O ni ki wọn ṣọra fun iwa abuku ati iwa idọti 'Operation Rewire' EFCC / FBI sèso owó tó lè ní mílíọ̀nù N153 Ẹ wo àwòrán ìkọlù sí aya Fayemi ní Ọyẹ-Ekiti!
Ènìyàn kán kú, méjé farapa nínú ìjàmbá afárá Otedola ní Eko Àwọn ìbejì mi kò le rìn dáadáa nítorí ọgbẹ́ tí wọ́n dá sí wọn lára ní ìgbèkùn - Akeugbagold Ènìyàn 284 ló ní àrùn Coronavirus ní Ọjọ́òrú ní Nàíjíríà Journey to Europe: Ọ̀pọ̀lọpọ̀ ìnira lojú àwọn ọ̀dọ́ ilẹ̀ Áfíríkà tó ń wá ìgbé ayé rere lọ sí Yúróòpù ń rí Ọkọ Golf naa wa lara awọn ọkọ to lugbadi ijamba ọkọ naa, amọ ajọ LASTMA ni ko si ẹni to farapa ninu ọkọ naa.
Oríṣun àwòrán, Sean Gallup Àkọlé àwòrán, Ẹni tawọn agbofinro ba ri pe o mu ọti lasiko tabi ṣaaju ki o to wa ọkọ yoo jẹ iyan rẹ niṣu.
Bi a ko ba gbagbe, ijọba ipinlẹ Eko ya ọjọ ọjọ́ kọkàndínlọ́gbọ̀n, Osù Kẹẹ̀ta ọdun to kọja gẹ́gẹ́bí ọjọ́ Ìsinmi fún àwọn òsísẹ́ ní ìpínlẹ̀ náà lasiko ti Aarẹ Buhari ṣe abẹwo sipinlẹ naa lati ṣe ifilọlẹawọn akanṣe iṣẹ kan.
Ko si si bi wọn yoo sẹ fi to igbimọ l'eti, ti ko ni i mọ si.
  Á kọ́kọ́ jọ ilé nlá kan.
Orile ede Naijiria, Germany, Norway, ati ajo gbaye (United Nations)ti pade ni Berlin, lojo Aje lati “sepade lori ikọ ọlọtẹ boko haram”.
Ọjọ kẹrinla, oṣu Kejila ni wn yoo ṣe idajọ wọn.
End SARS Protest: Babangida ní ejò lọ́wọ́ nínú lórí ìsẹ̀lẹ̀ rògbòdìyàn tó ń wáyé káàkiri Nàìjíríà
Àwọn tí ń pe ibi ní ire gbé;tí wọn ń pe ire ní ibi!
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Dangerous Animal: Ẹ wo àwọn ajá mẹ́wà tó máa ń hùwà ipá tí ẹ kò gbọdọ̀ sìn nílé 20 Bélú 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 21 Bélú 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Akita Aja yẹ ko jẹ ọrẹ fun awọn to fẹran rẹ, amọ awọn aja kan wa to le se ipalara fun awọn eniyan to ba n sin wọn.
kí olukuluku yín yipada kúrò ní ọ̀nà burúkú rẹ̀ ati iṣẹ́ ibi tí ó ń ṣe, kí ẹ lè máa gbé ilẹ̀ tí OLUWA fún ẹ̀yin ati àwọn baba ńlá yín títí lae, láti ìgbà àtijọ́.
Bi a ba fi ibi ti wọn bi si tọọ, ojulowo ọmọ Ibadan ni Hugo Weaving gbọdọ jẹ.
"Mo le fi ògún rẹ gbari pe, Olori Badirat ati King Wasiu Ayinde ko ni ajọṣepọ.
eto ilera ofe naa dupe lopolopo fun eto naa.
Lẹyin orẹyin, ala d'ohun Ẹ fi ẹ̀dùn ọkàn yín ránsẹ́ si BBC Yoruba Àwọn olùkọ́ èdé Yorùbá l‘Eko dábírà ní àyájọ́ èdè abíníbí Ẹgbẹ Akọmọlede naa fi ami ẹyẹ da BBC Yoruba lọla lasiko ayẹyẹ aadọta ọdun ti wọn da silẹ, eyi ti wọn fi sọri ayajọ agbelarugẹ ede abinibi to waye lọjọ Ẹti.
Oríṣun àwòrán, Youtube/Onyx Food Hill ọjọjọ dabi akara loju, paapaa ti eeyan ba n wo o lati okere.
Ó kó àwọn pẹpẹ àjèjì ati àwọn pẹpẹ ìrúbọ wọn kúrò, ó wó àwọn òpó oriṣa wọn lulẹ̀, ó sì fọ́ ère Aṣera.
Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí 6:30 Fídíò, Akomolede ati Aṣa lori BBC: Mọ̀ si nípa oríṣìí ẹ̀ka ìsọ̀rí ọ̀rọ̀ àti ìwúlò wọn, Duration 6,308 Owewe 2020 Fídíò, Akomolede: Bolaji Faleke ni Olùkọ́ tó ń kọ́ wa ní àṣà oge ṣiṣe lórí BBC Yorùbá1 Owewe 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Eyi ni igba keji ti ikọ ijọba maa ṣe ipade pẹlu egbẹ ASUU ṣugbon to n fori ṣọnpọn.
Wo Sultan Qaboos bin Said, ẹni tó gbàkóso ìgbé ayé òṣèlú Oman fún àádọta ọdún Ẹ kò nílò nọ́mbà ìdánimọ̀ NIN fún ìdánwò àṣewọlé ọdún 2020 - JAMB Pósí tí wọn ń tà lẹ́nu ọ̀nà ilé ìwòsàn àpàpọ̀ ló ń tètè pa wá - Aláìsàn figbeta Ṣo mọ̀ pé J.
Koda o tun tẹsiwaju, O ni o san fun oun lati jẹ onijo ki oun si fi ays inu oun han ju ki oun maa po ẹkọ ibinujẹ ati wahala faraalu nipa lilu aṣuwọn owo ilu ni ponpo."
Jide Kosokọ gbe Karimat ati Henriatta ni iyawo.
Mailafia fikun pe awọn oṣiṣẹ ajọ DSS wuwa ọmọluwabi si oun, ti wọn ko si fi iya jẹ oun lasiko ifọrọwanilẹnuwo naa.
Abadofin naa ti wọn ka nile igbimọ aṣofin n pe fun ẹwọn ọdun marun un si mẹrinla fun olukọ ti ọwọ ba tẹ pe o n ni ibalopọ pẹlu awọn akẹkọọ.
Bakan naa ni ijọba ipinlẹ Ọyọ tun paṣẹ fun awọn oṣiṣẹ ijọba ipinlẹ naa lati ọjọ Aje to n bọ.
Àkọlé àwòrán, Alhaji Gboyega Oyetọla n lọ bura gẹgẹ bii gomina tuntun ipinlẹ Ọsun.
O ni tako iroyin ti awọn eeyan n sọ kiri, gbọyi-sọyi lati ọdọ awọn to korira oun ni iroyin naa.
  Bẹ́ẹ̀ wọn a máa fi èpo ẹyìn gbígbẹ ko iná ààrò kó lè baà jò dáadáa.
Nítorí pé OLUWA yóo dìde bí ó ti ṣe ní òkè Firasi,yóo bínú bí ó ti bínú ní àfonífojì Gibeoni.
Àfonífojì kan sì wà láàrin wọn.
Agbẹnusọ fun aarẹ Buhari, Femi Adesina lo kede iku rẹ lojo opo twitter ni oru ọjọ Abamẹta.
“Àwọn ati àwọn baba wa hùwà ìgbéraga, wọn ṣe orí kunkun, wọn kò sì pa òfin náà mọ́.
Oríṣun àwòrán, Oluwo/facebook Àkọlé àwòrán, Ọba Gbadamọsi: Olúwòó, ọ̀pọ̀ ọmọ Naijiria fi ìkíni ránṣẹ́ si Ọlọ́fà fún ayẹyẹ ọdún mẹwàá lórí oyè Sugbọn pẹlu bi arun Coronavirus ti se gbode kan bayi,apejọ ko ni le waye bi yoo ti se wu Ọlọfa tabi awọn ara ilu naa.
Orúkọ àwọn ọmọ náà nìyí, bẹ̀rẹ̀ láti orí àkọ́bí: Ṣemaaya, Jehosabadi, ati Joa; Sakari, ati Netaneli; 
O ni iwadi oun fi han pe, ọpọ wọn lo gbagbọ pe ti awọn ba n sọ ede Yoruba, eyi lee ba ede Gẹẹsi ti awọn n sọ jẹ.
Ènìyàn 26,000 ni àìsàn jẹjẹrẹ ń pa lóòjọ́ Máṣe tijú láti gé ọmú rẹ to bá ṣàkíyèsí kóró nínú ọyàn, ilèra ló ṣe kókó - Ẹni tó ye àìsàn jẹjẹrẹ ọyàn 82% ọkùnrin ní kó mọ̀ pé òun ní àìsàn jẹjẹrẹ asẹtọ ní Naijiria Ìgbẹ́ ọmọdé ń dènà ààrun jẹjẹrẹ, àìsàn ìtọ̀ súgà Awọn nkan to ma n fa jẹjẹrẹ colon cancer Gẹgẹ bi ileeṣẹ eto ilera ilẹ UK ṣe sọ, ko si ẹni to mọ nkan to n fa jẹjẹrẹ yii ni pato, ṣugbọn awọn nkankan wa to le fi eniyan sinu ewu rẹ bii: Ọjọ ori - eeyan bi i mẹsan ninu mẹwaa to ni aisan yii lo ti pe tabi le ni ọgọta ọdun Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, jkkkkk Ounjẹ - jijẹ ounjẹ to kun fun ẹran bi ti maalu, ewurẹ, agutan tabi ẹran ẹlẹdẹ le ṣokunfa jẹjẹrẹ yii Ko yọ awọn ẹran inu agolo naa silẹ.
Eyi ri bẹẹ ki wọn o le maa tẹle ilana lati ọdọ ajọ ilẹ Yuroopu.
Orile-ede Ghana ti je orile-ede akoko ti yoo pegede ni abala asepari ti idije AFCON fun iko awon egbe agbaboolu ti ojo-ori won ko ju odun metadinlogun lo to n lo lowo ni Gabon.
Mike Ifabunmi: Ifá fìdí ẹ̀ múlẹ̀ pé kò sí ohun ti Ọlọrun kò lè ṣe Bakan naa ni BBC News tun gbe iroyin Mike Ifabunmi, ọmọ ilẹ Brazil, ti o di ẹlẹsin ifa pẹlu Yoruba to dan mọran lẹnu rẹ.
leyin ipade ni won yoo mo boya ekun ile Afirika ti setan lati maa na owo kan
Amọṣa lọwọ yii iroyin ayọ ti wọle tọ gomina tẹlẹ fun banki apapọ orilẹede Naijiria ọhun pẹlu ọkan lara awọn iyawo rẹ, Saadatu to bi ọmọ tuntun bayii.
iṣẹ, kiko awọn oṣiṣẹ nijanu, gbigbe awọn oṣiṣẹ ga lẹnu iṣẹ.
"Nínú ìwé ti wọ́n pe àkọle rẹ̀ ni ""Adedibu the Strongman and Generalissimo of Nigeria Politics"" èyí ti Hazeem Gbolarunmi àti olóyè Lekan Saka jìjọ kọ, ni ọ̀rọ̀ yìí ti jẹyọ."
Bakan naa nilu Akurẹ, awọn eeyan to se iwọde nibẹ kede pe ikọ alajumọse Amotekun kọja ọrọ ẹsin nitori awọn ọdẹ ati awọn Agbẹkọya lo wa nibẹ.
Nigbati àwọn Ajagun dé lati gbé Olóri Ogun Aguiyi Ironsi lọ, gẹ́gẹ́ bi àṣà Yorùbá, Ọ̀gágun Adékúnlé Fájuyi bẹ̀bẹ̀ ki wọn fi àlejò òhun silẹ̀, ṣùgbọ́n wọn kọ.
Nítorí ọkọ tí kì í ṣe onigbagbọ di ẹni Ọlọrun nípa aya rẹ̀, aya tí kì í ṣe onigbagbọ di ẹni Ọlọrun nípa ọkọ rẹ̀.
O fesi yi ni idahun si ibeere ti eeyan kan fi sọwọ si lori itakurọsọ BBC Yoruba.
Ní ọjọ́ kẹwaa kẹwaa ni wọ́n máa ń tọ́jú ọpọlọpọ waini sinu awọ fún mi.
Bakan naa ni oreilẹede Israel ṣalaye pe o ṣeeṣe ki fọnran aworan ti awọn kan n fihan pe Kanu n gbadura ni orilẹede Israel jẹ eyi ti o ti pẹ.
Awọn naa ni Walid Bin Attash; Ramzi Bin Al-Shibh; Ammar Al-Baluchi ati Mustapha Al-Hawsawi.
 “A ti sa gbogbo ipa lati ba ijọba sọrọ lati tubo mu idagbasoke ba ilu yii, paapaa lori ipese omi nitori ọpọ awọn ọna ipese omi ti ijọba ṣe bii kanga dẹrọ, ẹrọ ni ko pese omi mọ, eleyii ti o mu ọpọ eniyan maa lo omi odo”
Àwọn arakunrin tí ó wà lọ́dọ̀ mi ki yín.
Ó seni láànu láti máa pàdé àwọn ara ilé nílu òyìnbó kí wọ́n máa fara pamọ́ ki a máà ba pè wọ́n ní ọmọ Yorùbá.
Oríṣun àwòrán, AFP Àkọlé àwòrán, Ọ̀gágun Tukur Buratai ní kí àwọn ènìyàn apá ìlà oòrùn àríwá padà sí ilé wọn Burutai rọ àwọn ará ìlú tí ogun lé kúrò nílé láti padà nítorí pé àláfíà ti jọba lagbeegbe naa.
Nígbà tí Uraya dé, Dafidi bèèrè alaafia Joabu ati ti gbogbo àwọn ọmọ ogun rẹ̀.
Akọni ni láàrin “Àwọn Ọgbọ̀n Akọni”, ṣugbọn kò lókìkí tó “Àwọn Akọni Mẹta” ti àkọ́kọ́, òun ni Dafidi sì fi ṣe olórí àwọn ẹ̀ṣọ́ rẹ̀.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Working religious women: Ẹ̀lẹ́hàá kìí ṣe ọ̀lẹ- Aminat Adegoke Ẹgbẹ awọn akanda ẹ̀dá láwùjọ sọ pe igbesẹ naa tako ileri tí wọn ṣe fun awọn lasiko ìpolongo ibo.
Lára àwọn òṣèré tó kópa níbi ayẹyẹ nàá ni Seyi Edun.
lo anfaani lati wo awon aseyege wa, ki a si tun tesiwaju nipa awon aseyori yii.
Sola Kosoko: Ẹ tẹ ọkùnrin tó bá fipá bá obìnrin lòpọ̀ ní ọ̀dá, ìwà ìkà ni
“Mo dáwọ́ ibinu mi dúró ná, nítorí orúkọ mi,nítorí ìyìn mi ni mo ṣe dá a dúró fun yín,kí n má baà pa yín run.
Awọn ènìyàn bi George Weah to jẹ ààrẹ orilẹ̀-èdè Liberia, Eto'o, Toure lo yẹ ko peju sibi ayẹyẹ ohun.
1m sanwo lilo ayelujara (Internet) Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Abayọmi Aranmọlatẹ, Dr Laser: Vagino Plasty àti iṣẹ́ abẹ ẹwà Obìnrin ló jẹ mí lógún Wo owó tí Buhari bù fún ẹ̀ka kọ̀ọ̀kan nínú ìṣúná ọdún 2021 Aarẹ Muhammadu Buhari gbe aba kalẹ lọjọbọ siwaju ile asofin apapọ ilẹ wa eyi ti apapọ rẹ totriliọnu mẹtala naira (₦13.
"Wọn ò gbà àwọn ènìyàn láàyẹ lati sùn ní ẹnu iṣẹ́ pàápàá jùlọ ni àwọn ilé iṣẹ́ ìjọba àyàfi tí ẹni náà ba gba àṣẹ, èyí wà nínú àtẹjáde ti ìjọba fi síta nínú oṣù yìí.
Bo tilẹ jẹ pe ikọ tuntun naa tun ti fa awuyewuye laarin awọn ọmọ Naijiria, diẹ re e lara eto ti yoo waye ki wọn o to o le gba ẹnikẹni si iṣẹ ninu ikọ ọlọpaa SWAT: 1.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Salawa Abeni: Ìpolówó ọjà ni àwòrán tí èmi àti Kolington ti dì mọ́ra, ìfẹ́ kọ́ 22 Èrèlè 2020 Oríṣun àwòrán, other Kii ṣe pe emi ati Alhaji Kollinghton Ayinla ti pada di tọkọtaya o!
Lára ẹ̀jẹ̀ tí ó kù, yóo fi sára àwọn ìwo pẹpẹ turari olóòórùn dídùn tí ó wà níwájú OLUWA, ninu Àgọ́ Àjọ.
ede yii lati lee fowosowopo pelu awon ajo eleto aabo  miiran lorile ede Naijiria.
 fíìmù yorùbá tí ó jáde ní àkókò yìí lé ní igba ( 200 ) .
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Coffin Ghana: Òkú yóò lọ sílé ìkẹyìn pẹ̀lú afẹ́ tó kẹjẹgbẹ 26 Bélú 2018 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 7 Èbibi 2020 Oniruuru aramọnda posi lo wa bayii, eyi to n sọ nipa igbe aye oku, ala to ni, itara rẹ fun nkan ati ipo to wa nigba to wa laye.
: Bakan naa ni wolii naa wa n rọ asaaju ẹgbẹ oselu APC, Bola Ahmed Tinubu lati jami lori afojusun rẹ lati dije fun aarẹ orilẹede yii."
"Iléẹjọ́ dá Adeleke sílẹ̀ lórí ẹ̀sùn màgòmágó ìdánwò tí wọn fi kàn án Ẹ gbà mí o, ọ̀rẹ́ lù mí ní jìbìtì owó mọ́tò, ẹsẹ̀ ni mò ń rìn kiri - Portable Ẹ wo díẹ̀ lára àṣeyọrí tí ìṣèjọba Ààrẹ̀ Buhari sọ pé òun ti ṣe láàrin ọdún márùn-ún Ìdí tí a ṣe fikún owó okọ̀ BRT l'Eko rèé - Fola Tinubu Fanwo ni ""O yẹ ki ajọ NCDC dẹkun ati maa tan awọn eeyan orilẹ-ede yii jẹ pẹlu Coronavirus nitori mi o gbagbọ pe NCDC n ṣe iranlọwọ kankan fun orilẹede yii."
Bí ẹnikẹ́ni bá níláti lọ sí ìgbèkùn, yóo lọ sí ìgbèkùn.
Ọdun mẹrin sẹyin ni awọn dokita sọ fun un pe o ni jẹjẹrẹ inu ifun, to si ti wọ ipele kẹta nigba naa.
Wọ́n dá a lóhùn pé ẹnikẹ́ni kò ṣe nǹkankan fún un.
Ọgbẹni Ironside gba awọn alaboyun nimọran lati maa lọ si ileewosan gidi fun itọju to peye.
kíni wọn yóò máa ṣe ní ìpínlẹ̀ - DAWN Commission Ni kete ti ileeṣẹ iroyin ilẹ Iran, Tasnim kede pe wọn ti mu aṣoju ilẹ̀ Gẹẹsi naa ni ile iṣẹ iwe iroyin Etemad na fi fọto aṣoju naa si ori ikanni twitter rẹ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Eduardo: Mo ń jí mọ́tò pẹ̀lú àwọn ọ̀rẹ́ mi nítorí pé mo fẹ́ di 'Big boy' Akọwe agba fun ileeṣẹ ilẹ Gẹṣi to n ri si ajọṣepọ lagbaye, Dominic Raab ti fi atẹjade sita.
Lọdọọdun níí máa ń lọ yípo Bẹtẹli, Giligali, ati Misipa, láti ṣe ìdájọ́.
Wọn ni ẹṣọ Amọtẹkun ti n ṣe ohun tí ìjọba ko ran wọn.
Ambode soro yii nibi ipade elekeji iru re ti Bola Tinubu fun awon odo, eyi to waye ni ipinle Eko.
Awon akoroyin jabo oro naa pe, igbakeji minisita ohun ko lati dahun si ipe ile igbimo asofin lati wa salaye bi oro naa se je ni pato.
Gbogbo àwọn arakunrin talaka ni wọ́n kórìíra rẹ̀,kí á má ṣẹ̀ṣẹ̀ sọ ti àwọn ọ̀rẹ́ rẹ̀ tí wọ́n jìnnà sí i!
Isejoba oun yoo si lo awon agunbaniro atawon akeko to ni imo isegun lati maa sise lawon ile iwosan alabode Gboyega Isiaka ní ti rẹ sàlaàyé pe àwọn ile iwosan alabọde ko dara to ní ti Health Insurance ǹkan to se pataki ni Awọn ómọde gbọdọ ni ànfani si ètò ilera ọfẹ pàápàá jùlọ àwọn obinrin, àti àgbpalagbà.
 Ìpìlẹ ̀ núkléù pirimidínì karùún , urasílì ( kíkékúrú sí u ) , ló úndípò timínì nínú rna , ó sì yàtọ ̀ sí timínì nkpa pé kò ní àdìpọ ̀ mẹ ́ tílì nínú òrùka rẹ ̀ .
Mo mọ̀ pé òun lè sọ̀rọ̀ dáradára; ó ń bọ̀ wá pàdé rẹ, nígbà tí ó bá rí ọ, inú rẹ̀ yóo dùn gidigidi.
Mo gbọ́ èébú tí o bú mi,mo sì mọ irú èsì tí ó yẹ kí n fọ̀.
"Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù EndSars Protest;Oluwapọ̀nmile sọ ìrírí rẹ̀ lọ́wọ́ àwọn sójà tó fìyàjẹ́ ní Ibadan Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ EndSars Protest;Oluwapọ̀nmile sọ ìrírí rẹ̀ lọ́wọ́ àwọn sójà tó fìyàjẹ́ ní Ibadan 3 Bélú 2020 Arakunrin Ẹmiọla David Oluwapọnmile ṣe alabapade ikọ ologun ""Operation Burst"" ni agbegbe Bẹẹrẹ nilu Ibadan ti wọn si fi abẹ ṣekele fa irun ori rẹ."
Ireti wa wipe Aarẹ Akufo Addo yoo fesi si ọrọ ọhun lasiko ti yoo ba gbogbo awọn ọmọ orilẹede naa sọrọ ni ọjọọbọ.
Ṣugbọn, Palmatah ti fihan pe oun yatọ si awọn to kù, pẹlu bo 'se ṣaṣeyọri ninu idanwo aṣewọle sileewe giga nilẹ okeere.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Mo n wa'yawo - Falz Ọjọ wo ni ọjọ' Boxing Day'?
Bakan naa lo fi ewe ọmọ mọ awọn osisẹ fasiti LAUTECH leti pe ki wọn dẹkun dida ija silẹ pẹlu ijọba ipinlẹ Ọsun, to si tun seleri pe ko si osisẹ fasiti naa ti wọn yoo le lẹnu isẹ lai naani ipinlẹ ti wọn ti wa.
Ilẹ̀ wọn bẹ̀rẹ̀ láti Aroeri tí ó wà ní etí àfonífojì Arinoni, ati ìlú tí ó wà ní ààrin gbùngbùn àfonífojì náà, ati gbogbo ilẹ̀ tí ó tẹ́jú ní Medeba.
Oríṣun àwòrán, Facebook/Prophet Jeremiah Omoto Fufeyin Lọjọ Kejilelogun osu Kefa ọdun 2020 si lo ti sọ saaju pe orilẹede Naijiria, lati ipasẹ awọn ipinlẹ kan yoo mi titi, ti gbogbo agbaye yoo si gburo rẹ.
Gbogbo àwọn eniyan Juda ati ti Jerusalẹmu ṣe ẹ̀yẹ fún un.
Ugba, ni ijọba orile ede yii ko ni je ki awon  odaran naa lo ni alaafia , o wa ro  awọn  olulufe ere idaraya to je omo orile ede Naijiria lati fi iwe akosile wọn  ranse si ile-ise wọn, lati le je ki ijọba mu  awọn  odaran naa.
Ó tún gbé igba ọdún ó lé mẹsan-an (209) sí i láyé lẹ́yìn tí ó bí Reu, ó sì bí àwọn ọmọ mìíràn lọkunrin ati lobinrin.
Oríṣun àwòrán, Forest department Àkọlé àwòrán, Orílẹ̀-èdè India tó ní ẹranko igbó tó pọ̀jù lágbàáyé ń kojú ìsòrò òhún tó yẹ kí wọ́n se láti kojú àwọn ẹranko igbó to n pa àwọn ènìyàn.
Kíkìlọ̀ ni ó máa ń kìlọ̀ fún wọn gan-an kí wọn má ṣe fi òun hàn.
"Oríṣun àwòrán, Chiagozie Nwonwu Inu rirun ninu oyun: ""Ko yẹ ki aboyun ni irora kankan, ayaafi ti nkan ko ba ri bo ṣe yẹ."
Awon afehonu han ohun ti won fi ila oorun ilu Kitwe se ibugbe, nigbagbo pe ijoba orile-ede Zambia ti ta ile-ise(Zambia Forestry and Forest Industries Corporation Limited, Zaffico) fun awon olokoowo lati ile China.
Ọmọbìnrin ti ọ̀rẹ́kùnrín ọmọ Yahoo yahoo rẹ́ dáná sún l'Èkó tí dì èrò ọrùn Èèwọ̀!
Áwọn alákósó ẹgbẹ́ òṣìṣẹ́ náà ṣe àlàyé pé àwọn yóò gùnlé ìyanṣẹ́lódì aláìnígbèdéke láti ọjọ́ kẹfà, oṣù kọkànlá, odún yìí, bí ìjọba bá kọ̀ láti ṣe ohun ti wọ́n fẹ́.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, June 12:Àwọn tó wà ní ìjọba Baba mi ní kò lu owó ìlú ní póńpó- Ọmọ Abacha Oríṣun àwòrán, Twitter/Aisha Buhari Ileesẹ ọlọpaa Naijiria naa ko ti fesi boya lootọ lawọn ẹsọ iyawo aarẹ wọn wa lahamọ.
Ẹnikan ninu awọn to wọ ọkọ danfo naa sọ wipe lati Ikate l'oun ti wọ ọkọ naa.
Gbogbo wọn ni wọ́n ń wá láti gbọ́ ọ̀rọ̀ ọgbọ́n tí Ọlọrun fún un.
Lọwọlọwọ, orilẹ-ede mẹrindinlọgbọn lo ti ni aarun naa l'agbaye.
”Joramu sì dáhùn pé, “Ọ̀nà aṣálẹ̀ Edomu ni.
Amọṣa, ko si ẹri to gbe ọrọ yii nidi.
Ẹ̀yin obìnrin tẹ́ẹ fẹ́ wá bímọ ní America, ọ̀nà ti tì pa látònì!
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Koffi Olomide: Ilé ẹjọ́ kan nílẹ̀ Faranse ló sọ́ sẹ́wọ̀n ọdún méjì 19 Ẹrẹ̀nà 2019 Oríṣun àwòrán, KoffiOlomide_MM Koffi Olomidé, ọkan nínu àwọn gbajúgbàjajà olórin takansufe nìlẹ̀ Afíríkà, ní wọn ló jẹbi ẹ̀sùn pé ó fipá bá ọ̀kan lára àwọn ọmọ tó ń ba jó lopọ, nìgbà tí ò wà ní ọmọ ọdún mẹ́ẹ̀dógún.
Amosun lẹ́tọ̀ọ́ láti gbè lẹ́yìn oludíje tó bá wù ú - APC Gómìnà Amosun f'ohùn sílẹ̀ láti kúrò ní APC Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Claudiah: ìrẹ̀wẹ̀sì ọkàn bá mi fínra fún ọpọlọpọ ọdún Oríṣun àwòrán, @Mr Khaleed Àkọlé àwòrán, Ohun ti Aarẹ Buhari sọ nipa Adekunle ko ti jẹyọ si awọn eeyan Aworan yi ati awọn miiran ti wọn ya nibi ipade naa ti n da awuyewuye loju opo Twitter ti awọn ọmọ ẹgbẹ APC kan si ti ni iru iwa bayi fidi rẹ mule pe Aarẹ Muhammadu Buhari lo n fi ọwọ ararẹ sakoba fun irẹpọ ninu ẹgbẹ.
Siasia kọ̀wè fún ipò akọ́nimọ̀ọ́gbá Cameroon #Russia2018: Super Eagles ti koju Argentina rí Ọlọ́pàá Bayelsa ní àwọn ti kán lugbó láti wá ìyá Siasia Ọmọ Yorùbá míràn tún dé ipò gíga l‘Amẹrika Khafi wọ gàu lẹ́nu iṣẹ́ lórí ẹ̀sùn ìbálòpọ̀ ní BB Naija Eyi to waye leyin iwadi ti ajọ naa se lori bii Ọgbeni Wilson Raj se gbiyanju lati yi esi idije kan pada lati fi ta tẹtẹ.
Àwọn ọmọ wolii tí wọn ń gbé Bẹtẹli tọ Eliṣa wá, wọ́n bi í pé, “Ǹjẹ́ o mọ̀ pé OLUWA yóo mú ọ̀gá rẹ lọ lónìí?
O ni, gbogbo wọn lo jẹbi ẹsun iwa ọdaran ni ijọba ṣe mu wọn.
(Jesu sọ èyí bí àkàwé irú ikú tí Peteru yóo fi yin Ọlọrun lógo.
Emi ati awọn ti a jọ wa ninu rẹ wa ni alaafia, a si n tẹsiwaju ninu eto 'Next level' wa ati ipinnu wa fun ipinlẹ Kogi.
lo ya ọjọ naa sọtọ lọdun 2012 lati jẹki awọn eeyan mọ awọn ipenija ti awọn ọmọbinrin n koju ninu eto ẹkọ, ounjẹ jijẹ, ati fifi ọmọdebinrin lọkọ.
Ayẹwo fun awọn to forukọ silẹ nilu Ibadan yoo waye laarin ọjọ kẹẹsan si ọjọ kẹrinla oṣu kẹẹsan ọdun yii, nigbati awọn ayẹwo to ku jakejado ipinlẹ Ọyọ yoo waye laarin ọjọ kẹẹdogun si ọjọ kọkanlelogun oṣu yii.
Ni bayii, itakurọsọ awọn ọkunrin mejeji ti da gbas gbos silẹ loju opo Twitter ti ọpọ eeyan sit i n da si ọrọ na gẹgẹ bi iwoye wọn.
awọn eniyan wa ni, a si gbọdọ ṣe ojuṣe wa pẹlu eyi.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Báyìí ni ẹgbẹ́ ajàfẹ́tọmọnìyàn ṣe pè fún ìdájọ́ ikú fún àwọn afipábánilòpọ̀ Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
“Nisinsinyii OLUWA ti mú ìlérí rẹ̀ ṣẹ: mo ti gorí oyè lẹ́yìn Dafidi, baba mi, mo ti jọba ní ilẹ̀ Israẹli bí OLUWA ti ṣèlérí; mo sì ti kọ́ ilé fún OLUWA Ọlọrun Israẹli.
"Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ọṣun; Àwọn aláìsàn ojú ké sí ìjọba láti ràn wọ́n lọ́wọ́ 21 Ògún 2018 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 30 Ògún 2018 Àkọlé àwòrán, ""Ohun to tọna bayii ni ki awọn ti Ọlọrun ṣẹgi ọla fun lawujọ o dide fun ipese owo lati seto itọju fun awọn ti oju n dun lawujọ"" ""Lootọ ni oju n dunmi; ṣugbọn airi itọju ni o koba oju mi."
Olukuluku dira pẹlu idà ní ẹ̀gbẹ́ rẹ̀, nítorí ìdágìrì ọ̀gànjọ́.
Ó ń fi inú burúkú pète ibi, ó sì ń fi ojoojumọ dá ìjà sílẹ̀,
“Bí mo sọ̀rọ̀, ọ̀rọ̀ kò mú kí ara tù mí,bí mo bá sì dákẹ́, ṣé dídákẹ́ lè tán ìrora mi?
Yatọ si wọn, gomina tun da igbimọ meji silẹ, ti yoo ma a pari aigbọra ẹni ye to ṣe e ṣe ko waye laarin ijọba ati awọn ọmọ ikọ PMS.
Wọn n ṣe eyi gẹgẹ bi igbaradi lati mu ala asiko oṣelu tuntun ni ilẹ Yoruba ṣẹ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Coronavirus: Ọ̀gá iléèṣẹ́ tó n ṣe kọ́ńdọ́mù Durex sọ pé ìbálòpọ̀ dínkù lásìkò ìgbélé yìí 17 Ọ̀wàrà 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 3 Èbibi 2020 Laisi ani-ani, ibalopọ ti dinku lasiko konle-o-gbele nitori aarun coronavirus to wa lode.
Kí á yin Oluwa Ọlọrun Israẹlinítorí ó ti mú ìrànlọ́wọ́ wá fún àwọn eniyan rẹ̀,ó sì ti dá wọn nídè.
Ní ọdún 2006, a fi ọwọ́ọ ṣìgún òfin mú u fún ipa tí ó kó nínú ìyíde kiri ìfẹ̀hànnúhàn tí kò fa ìdíwọ́ fún ẹnikẹ́ni.
Ní alẹ́ yìí, ìbà lọ́wọ́ Ajíbọ́lá
Nígbà tí ààrá meje yìí ń sán, mo fẹ́ máa kọ ohun tí wọn ń sọ sílẹ̀, ṣugbọn mo gbọ́ ohùn kan láti ọ̀run, tí ó sọ pé, “Àṣírí ni ohun tí àwọn ààrá meje yìí ń sọ, má kọ wọ́n sílẹ̀.
Ta ni Naira Marley jẹ́ gan?
Kaakiri agbaye, paapaajulọ lawọn orilẹede Mexico, Canada, Brazil, Australia, New Zealand titi kan awọn orilẹede kan nilẹ Afirika.
Adamu bí Seti, Seti bí Enọṣi.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Mama Arsenal: Màmá àgbà yìí máa ń lọ sí ìbùdó tí wọ́n ti ń wo bọ́ọ́lù láti wòran Bakan naa lo tun ṣakoso ẹgbẹ agbabọọlu Paris Saint Germain lorilẹede France.
Àwọn ológun gba ìjọba ilẹ̀ Gabon Ohun ti o ru ọpọ loju lori ọrọ naa ni bi aarẹ yoo ṣe ṣatilẹyin fun oludije meji lati ẹgbẹ oṣelu meji ọtọọtọ ni ipinlẹ kan naa.
Atamatase agbaboolu iko Super Eagles, Ahmed Musa ti gba ami-eye agbaboolu ti o darajulo ninu idije boolu afesegba orile-ede Saudi Arabia tose ti o koja lo yii.
Ọpọ eniyan si ni ko ba lara mu, nitori pe ọmọ ṣiṣẹ́-ṣiṣẹ́ ni wọn, tabi ẹni ti igbeaye oju kan ko mọ lara.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Irú Kọ́mú wo lò ń lò?
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù 2018: Badeh, Alkali bẹ̀rẹ̀ ọdún 2018 ṣùgbọ́n wọn kò là á já 27 Ọ̀pẹ̀̀ 2018 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ọ̀gọ̀ọ̀rọ̀ ẹ̀mí làwọn apànìyàn rán lọ s'ọ́run àpàpàǹdodo lọ́dún 2018 Ọpọ ipaniyan lo waye lọdun 2018 lorilẹede Naijiria.
darajulo  – Lionel Messi (Barcelona ati Argentina)Agbaboolu Obinrin ti o
Wọ́n sábà máa n lo òògùn tuntun yìí fún àwọn tí wọ́n bá wà nílé ìwòsàn tí wọ́n sì ń lo ẹ̀rọ aṣèranwọ́n èèmí, èyí túmọ̀ sípé àwọn tó wa ní ipò tó léwu.
egbin ati idoti di awati loju popo ati oju agbara, ile ise to n ri si oro
Bakan naa ni 2018, o bori pẹlu ibo ìdá mọkanlelaadọrin, botilẹ jẹ pe eniyan miliọnu meji ataabọ pere lo dibo ninu miliọnu mejilelogun to yẹ ko dibo.
Ninu atẹjade kan ti Oludari Apapọ fun eto ofin ati ikede fun CAN, Ajihinrere Kwamkur Samuel Vondip fi sita lọjọ Aje lo ti ni ọrọ ko ri bẹẹ.
Lori iroyin kan to n lọ pe awọn to wo ile naa sọ pe ilẹ ti Naijiria kọ ọfiisi naa si kii ṣe ti ẹ, Garba Sheu sọ pe ko ṣe e ṣe ki orilẹ-ede kan deede kọ ile si orilẹ-ede miran, lai gba aṣẹ lọwọ ijọba ibẹ.
Oríṣun àwòrán, @drummer Àkọlé àwòrán, Ilu ṣe pataki nilẹ Yoruba, a fi n ṣe ikede, a fi n yin awọn oriṣa ati Adẹdaa, oriṣa kọọkan lo ni ilu tirẹ bii Ṣango to ni bata.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Amotekun: Fayemi ni ikọ̀ àláàbò yìí ni yóò máa ṣe àkóso ìpínlẹ̀ kọ̀ọ̀kan 9 Sẹ́rẹ́ 2020 Gomina Kayọde Fayẹmi ti ipinlẹ Ekiti, to tun jẹ alaga agbarijọpọ awọn gomina orilẹede Naijiria ṣe alaye wi pe, lojoojumọ ni a n koju ipenija wahala awọn adigunjale, darandaran ati bẹẹbẹẹ lọ ni ẹkun iwọ oorun Naijiria.
Èrò wọn ni láti dènà dè é, kí wọ́n baà lè pa á.
Owó ilé-ìwé le wọ́n síi Nítolrí ìdí èyí, ọ̀ps àwọn tó ti kàwé gboyè le ri pé yóò nira fún wọ́n ki wọ́n tó rí iṣẹ́ àkọkọ́ wọ́n.
Gbogbo àwọn tí wọ́n wà ninu ilé ìṣọ́ Ṣekemu sì kú patapata.
Ọkunrin yìí fọn fèrè, ó ní,“Kò sí ohun tí ó kàn wá pẹlu Dafidi,a kò sì ní ìpín nílé ọmọ Jese.
N óo fún Farao, ọba Ijipti mu, ati àwọn iranṣẹ rẹ̀ ati àwọn ìjòyè rẹ̀, ati gbogbo àwọn eniyan rẹ̀ 
fi ife han si ara won.
Gege bi Ogunyemi se so:“A ti bere ijiroro lori oro yii, bi o ti le je pe, a ti soro jina, sugbon lati panupo mu ojo miiran ti a se ipade fun idunadura.
MURIC pè fún ìwọ́de lẹ́yìn Jumat láti tako ìgbésẹ̀ ISI lórí Hijab wíwọ̀
 Ó jẹ okan lara awon oludasile ati alabaṣepọ ninu ile-iṣẹ ofin ti alp ( ofin ilu afirika ) .
Bakan naa lo tún fi atejise ranse sì Oga Olopaa kan naa pe, lai si owo, ọmọ náà kò ní jáde.
Lion Air Crash: Arákùnrin kàn tórí kó yọ nínú ìjàmbá ọkọ̀ òfurufú rèé
"Oríṣun àwòrán, JEKESAI NJIKIZANA/GETTY IMAGES Ó ní ""àwọn ilé isẹ́ náà ti kó wa lọ́rọ̀ lọ, àpò ìsúná kàn ti ri owó díẹ̀ ǹka bíi bílíọ̀nù mẹ̀ẹ́dógún dollar tí wọ́n ti ní Kò tíì hàn yékéyéké bóyá Robert Mugabe ẹni ọdún mẹ́rinléláàdọ́rùún náà yóò fara hàn níwájú ilé asòfin Zimbabwe Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Àwòrán ayẹyẹ ajọ̀dún ìlù nílú Abẹ́òkúta Wo ikọ̀ ọlọ́pàá tí àwọn ọ̀daràn ń sá fún PDP: A fẹ́ dara pọ̀ mọ́ àwọ́n ẹgbẹ́ míì Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!"
O ni ẹni to ba fẹ wu iwa ọdaran lee huwa ọdaran, bo ba n lo kaadi ipe kan tabi ju bẹẹ lọ.
Awọn ìkànni ìbáraẹni sọ̀rọ̀ tuntun ti ẹgbẹ́ ọ̀ún fi síta nìyí: Website: www.
kí ó sọ fún àwọn ọmọ Israẹli pé, “Bí aya ẹnìkan bá ṣìṣe, tí ó hu ìwà àìtọ́ sí i; 
Gbogbo eyi da bii iji lile fun awọn oniṣẹ iroyin to si waye laarin ọjọ diẹ.
Akonimoogba iko egbe agba-boolu ABS FC, Henry Makinwa, dupe lowo Olorun ti o si fi idunnu re han fun esi ifesewonse ohun, o sapejuwe ami ayo ti  Anaekwe gba wole gege bi eyi ti o dara julo lati ibere idije saa todun yiiAkonimoogba iko egbe agba-boolu El-kanemi Warriors, Ladan Bosso, ti benu ate lu ami keji ti iko egbe ABS FC gba wole, wi pe oun o tewo gba lataari ai-pa okan po awon agba boolu re lasiko ti won gba ami naa wole.
 Óhun ni ó tóbi jù ní ààrin gùngùn Áílándì tí ó ní ilé iṣẹ ́ bíi : epo rọ ̀ bì àti ' súgà , ilé ìpọtín , síméntì , apo ògùn òyì ́ nbó , ilé isé irin , aṣo àti tábà .
"A si tun n sọ pe ao mu ki iwadii ati abajade rẹ han si gbogbo ara ilu.
Disability: Àwọn òbí mi gbìyànjú títí ní kékeré mi ṣùgbọ́n .
kí o sì wí fún wọn pé OLUWA àwọn ọmọ ogun, Ọlọrun Israẹli ní òun óo lọ mú Nebukadinesari ọba Babiloni, iranṣẹ òun wá, yóo sì gbé ìtẹ́ rẹ̀ ka orí àwọn òkúta tí òun rì mọ́lẹ̀ yìí, Nebukadinesari yóo sì tẹ́ ìtẹ́ ọlá rẹ̀ sórí wọn.
Ọwọ́ ọlọ́pàá tẹ afurasí tó ní òun ló jí ọmọ gbé láti parọ́ mọ́ pásítọ̀ ìjọ Sotitobire Ìgbéyàwó ọkùnrin s'ọ́kùnrin, obìnrin s'óbìnrin ti di òfin ní Northern Ireland Àǹfààní wo ló wà nínú Brexit fún Nàìjíríà àtàwọn orílẹ́-èdè Afíríkà?
orísìírìsìí isé ajé ni àwọn Ẹ ̀ gbá n mú se nínú ìlú .
Ṣe ni Pedro rọrọ pẹ 'omi Jordan' silẹ, to si gba bọọlu sinu awọn.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Wọn ni afaimọ kọwọ maa bọ sori ti ileẹjọ ko ba fun wọn ni beeli lọjọ Aje.
Kódà ìṣàmúlò Twitter Aliyev dà gẹ́gẹ́ bí wèrè aládàásọ̀rọ̀ ju ìgbìyànjú ìbá ará ìlú sọ̀rọ̀ lọ.
Loju opo Twitter ẹgbẹ oṣelu APC,awọn naa ti ki Gomina Oyetola ku orire aṣeyọri rẹ nile ẹjọ Paro paro ni ile Adeleke da ni Ẹdẹ Akọroyin wa to ṣe abẹwo si ilu Ẹdẹ la ti mọ bi awọn ara ilu naa ti ṣe gba iroyin ohun jabọ pe paroparo ni ita ile Ademola Adeleke da.
Ogun yóo pa àwọn ọmọkunrin ati àwọn ọmọbinrin yín tí ẹ fi sílẹ̀.
O to ọkọ panapana marun to ti wa nikalẹ lati pa ina ọhun.
Usa ati Ahio ọmọ Abinadabu sì ń ti kẹ̀kẹ́ náà; 
John Blake: Wo ohun tó yẹ kí o mọ̀ nípa ọmọ ọdún 17 tí wọ́n ní ó pa èèyàn méjì níbi ìwọ́de Black Lives Matter ní Kenosha
Nígbà tí wọ́n dé ibẹ̀, òògùn ni Ọ̀sanyìnnínbí wá ṣe.
Gbigba iwosan niiṣe pẹlu bi eniyan ba ṣe ṣe aisan si nitori arun Coronavirus le ma lagbara lori awọn eniyan kan, amọ ko si ṣọṣẹ lara awọn eniyan miran.
Nítorí àwọn ìjọ Masedonia ati ti Akaya ti fi inú dídùn ṣe ọrẹ fún àwọn aláìní ninu àwọn onigbagbọ tí ó wà ní Jerusalẹmu.
Njẹ o ti ẹ mọ iye awọn ọmọ Naijiria to ti gbẹmi ara wọn nitori bi ilu ti ri ni nkan bi ọdun mẹrin ṣẹyin?
Bakan naa ni Minisita fun eto ilera ni Maharashtra, Eknath Shinde, fidirẹmulẹ pe awọn obinrin to to ẹgbẹrun mẹrin le ẹgbẹta ati marun un, 4,605, lo ti yọ ile ọmọ wọn kuro.
Yóo gbé ara rẹ̀ ga ju èyíkéyìí ninu àwọn oriṣa lọ; yóo tilẹ̀ lọ jókòó ninu Tẹmpili Ọlọrun, yóo sì fi ara hàn pé òun ni Ọlọrun.
7 16598 Orilẹede Mozambique 139 0.
Ọlọ́pàá Ondo: A ó ṣe àfihàn ọ̀rẹ́kùnrin Khadijat l'Ọjọ́rú
ni aduru iwe ti baba Fagunwa kọ, ko yẹ ka gbagbe awọn ohun to fi silẹ.
“Gbogbo ìwọ̀nyí ni ojú mi ti rí rí,tí etí mi ti gbọ́, tí ó sì yé mi.
O ni toun ti bi gbogbo igbeṣẹ ti ṣe n lọ ni iwaju ile ẹjọ kotẹmilọrun, Adams Oshiomole ṣi ni alaga ẹgbẹ naa.
Nítorí náà, Jehoaṣi, ọba Israẹli, gòkè lọ, òun ati Amasaya ọba Juda sì kojú ara wọn lójú ogun ní Beti Ṣemeṣi ní ilẹ̀ Juda.
Mutallab: Bàbá rẹ̀ ní ọmọ òun ti kábàmọ́ọ̀ ìwà tó wù, kí wọn ṣàánú rẹ̀
Jesu bá bá a wí, ó ní, “Pa ẹnu mọ́, kí o jáde kúrò ninu ọkunrin yìí!
nipa eto aabo lorile ede Naijiria lojo Isegun .
Wọn a rú ẹbọ ìríra, wọn a mú kí òórùn dídùn ẹbọ wọn bo gbogbo ibẹ̀, wọ́n a sì bẹ̀rẹ̀ sí ta ohun mímu sílẹ̀.
Ṣé ó ṣeéṣe kí ará Kuṣi yí àwọ̀ ara rẹ̀ pada?
Congo, Sierra Leone, Ghana, Cameroon, Zambia, Burundi, South Africa, Zimbabwe, Malawi, Tunisia, Tanzania, Botswana, Angola, Uganda, Somalia, Algeria, Togo, South Sudan, Kenya, Gambia, Namibia, Rwanda, Mozambique, Morocco ati Nigeria.
Nígbà tí ó tú èdìdì kẹrin, mo gbọ́ tí ẹ̀dá alààyè kẹrin ní, “Wá!
Kí ó máa gúnwà níwájú Ọlọrun títí lae;máa fi ìfẹ́ rẹ tí kì í yẹ̀, ati òtítọ́ rẹ ṣọ́ ọ.
Eka Intelligence Response Team to n risi ọrọ ijinigbe ni Naijiria ti ṣe awọn aritọkasi aṣeyọri kọọkan lati doola awọn ti wọn jigbe.
Ajọ naa fidi rẹ mulẹ pe, ileẹjọ ICC ti ṣalaye tẹlẹ pe iwa ọdaran ni ki awọn ọmọde maa lanfani si ile ẹkọ.
ni Osaka ti n la koja lati igba ti o ti bo si oke tente tabili ipo ate ATP,
Ẹni tó bá ń bínú kàn ń bínú lásán ni- Oyedepo Matt ni awon ti fi to ajọ ilera agbaye leti ati pe ilese ayẹwo ilera ile naa Porton Down ti n se Iwadii nipa rẹ.
Olubadamọran pataki fun aarẹ Muhammadu Buhari lori iroyin igbalode, Tolu Ogunlesi, lo fi ọrọ naa lede loju opo Twitter rẹ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Akanṣe awọn aworan aṣa ati iṣe awọn ọmọ Yoruba 19 Èrèlè 2018 Awọn ọmọ Yoruba fẹran wiwọ Asọ oke fun ayẹyẹ, bẹẹsi ni ọja alẹ wọpọ lawọn agbegbe ti wọn ti n sọ ede Yoruba: Oríṣun àwòrán, AFP Àkọlé àwòrán, Ọdọọdun ni wọn ma n sọdun Eyo ni ipinle Eko Oríṣun àwòrán, AFP Àkọlé àwòrán, Ọdun Ọsun-Osogbo jẹ gbajugbaja ni ipinlẹ Ọsun, to ma n waye losu kẹjo ọdun Oríṣun àwòrán, AFP Àkọlé àwòrán, Ọgọọrọ eniyan lo ma n wa si ojubọ naa lati bere ẹdun ọkan wọn lọwọ yeye Ọsun Àkọlé àwòrán, Lorilẹede Naijiria, Ilu isẹyin loni Aso-Oke.
Nígbà tí ìyọnu tabi inúnibíni bá dé nítorí ọ̀rọ̀ náà lẹsẹkẹsẹ wọn á kùnà.
Gẹ́gẹ́ bó ṣe sọ, àwọn ìdojúkọ ètò ààbò yìí ní gbogbo ilé iṣẹ́ elétò ààbò ń ṣe àtòpọ̀ rẹ̀, o fi kún pé àwọn ìgbìmọ míràn yòó tún dìde láti máa ṣe àbẹwò láti rẹyin gbpogbo ìdojukọ lori ààbo Ìdìbò 2019: INEC fẹ́ ná N6bn lórí ounjẹ fún àwọn ọlọ́pàá Àjọ́ eleto idibo INEC ni awọn yoo na N6bn sori ounjẹ ti awọn ọlọpàá ti yoo kopa ninu eto idibo gbogboogbo 2019 a jẹ.
Ni afikun, wọn ni ko mojuto ọrọ atungba idije bọọlu aṣekagba ti wọn sun si 2019, 2021 ati 2023.
 Lara ohun ti won tun maa n pese ni –Afẹfẹ gaasi, eedu, epo rọbi,  – ina lati ibi oorun (solar),ina mona-mona lati ibi  Afẹfẹ (wind) ati  ina mona-mona lati ara omi (hydro).
Paradà, wá ràn mí lọ́wọ́, kí o sì rí i fúnra rẹ.
Njẹ ẹ mọ ohun to sọ fun un ki o to wọle?
1 249224 Orilẹede Ireland 2117 43.
Àwọn atukọ̀ ń wá bí wọn yóo ti ṣe sálọ kúrò ninu ọkọ̀.
Babajide Sanwo-Olu, Gboyega Oyetola, Kayode Fayemi, Seyi Makinde ati Rotimi Akeredolu ti leri wi pe awọn yoo sa gbogbo ipa wọn lati doju ija kọ awọn janduku darandaran to n ṣoṣẹ ni agbegbe naa.
Ẹ̀kùnrẹ́rẹ́ ohun tó ń ṣẹlẹ̀ lọ́wọ́ rèé lórí aláwọ̀ dúdú t'ọ́lọ́páá tún dàbọn bò l'Amẹrika Oríṣun àwòrán, Others Ọgbẹni John Blake, ọkunrin alawọ dudu tawọn ọlọpaa yinbọn fun ni Kenosha nipinlẹ Wisconsin wa ni wọọdu ICU nibi ti o ti n gba itọju lọwọ Ileeṣẹ ọlọpaa ko tii fi darukọ awọn ọlọpaa ti ọrọ naa kan sita, amọ awọn ọlọpaa naa ti bẹrẹ isinmi lẹnu iṣẹ ni kiakia.
Àwọn tó fẹ́ gba ẹ̀mí mi dẹ tàkúté sílẹ̀ dè mí,àwọn tí ń wá ìpalára mi ń sọ̀rọ̀ ìparun mi,wọ́n sì ń pète àrékérekè tọ̀sán-tòru.
Jẹ́ kí àbá Ẹni Mímọ́ Israẹli di òtítọ́kí ó ṣẹlẹ̀, kí á lè mọ̀ ọ́n!
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Segalink:ìkùnsínú pọ̀ láàrin àwọn agbófinró bẹ́ẹ̀ wọn kò ni agbẹnusọ Ife ẹyẹ yii ni ikarun un iru rẹ ti yoo gba.
Olori Ganiyat Gloria Mojisola Adeyemi: Oríṣun àwòrán, queenmoji_gloo Instagram Mojisola naa wa lara awọn ẹlẹ daddy, atupa palọ ati 'oxygen' ti Alaafin fi n mi lode Ọyọ.
Ọjọ́ méjì péré ni Orisabunmi lò níléèwòsàn kó tó jáde láyé"" Nígbà wo ni ìsìnkú Orisabunmi yóò wáyé?"
Ninu ọrọ to sọ lasiko yii, Akosile sọ pe bi igba ti awọn to n bu gomina lori igbesẹ naa kan n fi oju keere gomina ni.
Àkọlé àwòrán, Iṣẹ n lọ lọwọ ni opopona Maryland Ijọba ipinlẹ Eko ti rọ awọn to n gba ori afara naa lati ma foya, nitori abala kan yoo wa fun lilo lori afara ọhun.
Ojọgbọn Simon Mallam ni adari ajọ Nigeria Atomic Energy Commission to n mojuto ọrọ ado oloro ni Naijiria.
Ọmọbìnrin ọdún 25 gún ọ̀rẹ́kùnrin rẹ̀ pa nítorí ó ní ko lọ ṣẹ́ oyún Wo ohun tó ṣẹlẹ̀ sí Saka, Sunkanmi Omobolanle àtàwọn òṣèré sinimá míràn lọ́sẹ̀ yìí Iku tun to wọ agbo awọn oṣere tiata nilẹ yii naa, nigba ti yoo si fi jade, ọkan lara awọn aṣaraloge (Makeup Artist) lẹka ere tiata Yoruba, lo mu lọ.
Oniruuru orin to jẹ mọ oriki Alaafin to wa lori aleefa ni awọn ayaba yii yoo maa kọ, bi wọn ṣe n tigba yii, ti wọn yoo si tun maa ki ọba naa mọ awọn baba nla rẹ, tii ṣe Alaafin to ti kọja lọ.
Oyinbo sọrọ o fi Saikọlọji sinu rẹ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Akomolede ati Aṣa lori BBC: Mọ̀ si nípa oríṣìí ẹ̀ka ìsọ̀rí ọ̀rọ̀ àti ìwúlò wọn Tí mo bá kú lónìí, Pásítọ̀ Ibiyeomie ló pa mi - Daddy Freeze kébòòsí Àwọn afurasí lórí ẹ̀ṣùn jíjí ìbejì Akeugbagold gbé yọnú sílé ẹjọ́ láì ní agbẹjọ́rò Tí òṣèré tíátà yóò fi kú, eré ni wọn yóò ló ń ṣe - Ibrahim Chatta Aṣòfin méje yarí mọ́ Akeredolu lọ́wọ́ torí ọkọ̀ ayọ́kẹ́lẹ́ tí kò pín fún wọn Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 3 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 5 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Taara ta ilu rẹ ni Ṣagamu lo mori le, nibẹ lo si ti ṣe baba kẹẹ pẹ sawọn ọbalaye ati oriade gbogbo to wa nilu naa.
Bẹ́ẹ̀ ìlú kìí wà kí ó mà ní olórí tàbí ibi tí ó ti ṣẹ̀ wa nígbà ìwáṣẹ̀, odò á ní orísun dandan.
Gomina ipinlẹ Kaduna, Nasir El-Rufai to bu ẹnu ẹtẹ lu bi awọn agbebọn se ṣe ikọlu naa, sọ pe gbogbo awọn to lọwọ ninu iṣẹ ibi naa ni ọwọ ofin yoo te laipe.
Oríṣun àwòrán, Twitter Àkọlé àwòrán, Obafẹmi Hamzat ti ni oun yoo gbe'na woju Ambode Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
''Irun arun jẹjẹrẹ oju yii ti maa n mu ọmọ ti wọn tiẹ to bi sile aye nitori arun ajogunba ni,'' Dokita Hassan lo sọ bẹẹ.
 “Mo fi da gbogbo eniyan loju pe, ijoba  ati egbe yoo se ojuse re lati daabobo awon
Ta ni yóo fẹ́ kí á gbé òun mì?
Diẹ ree ninu akojọpọ awọn awọran manigbagbe lati ilẹ Áfríkà lose to kọja fun igbadun yin.
Bí ẹ bá ní ẹ̀sùn nípa nǹkan ti ayé, kí ló dé ti ẹ fi ń pe àwọn alaigbagbọ tí kò lẹ́nu ninu ìjọ láti máa jókòó lórí ọ̀rọ̀ yín?
Awọn ọtọkulu bi Ọjọgbọn Wole Soyinka, eekan ẹgbẹ Afenifere, Oloye Ayo Debanjo; agbẹjọro agba ati ajafẹtọ, Femi Falana, Oloye Olu Falae, ati Aarẹ Ọnakakanfo, Iba Gani Adams atawọn mii ni wọn ti sọrọ lati gbaruku ti eto Amọtẹkun.
Nígbà tí mo gun orí òkè lọ, láti gba tabili òkúta, tíí ṣe majẹmu tí OLUWA ba yín dá, mo wà ní orí òkè náà fún ogoji ọjọ́, láìjẹ, láìmu.
Ninu àwọn ọmọ Asigadi, Johanani, ọmọ Hakatani, ni olórí;orúkọ aadọfa (110) eniyan ni wọ́n kọ sílẹ̀ pẹlu rẹ̀.
Lẹyin eyi lo rii pe ko si bi oun ṣe fẹ fo silẹ ni iwọn ẹsẹ bata aadọta.
Ìjọba àpapọ̀ pàṣẹ pé kí alága EFCC, Ibrahim Magu lọ rọọ́kún nílé Ijọba apapọ orilẹ-ede yii ti pasẹ pe Ibrahim Magu lọ rọọkun nile na gẹgẹ bii alaga ajọ EFCC.
O ni nitori pe Ezekwesili ko sọrọ nigba ti Buhari kọkọ bẹrẹ si ni gbogun ti awọn adajọ ni.
Ni opin ọsẹ yii ni kọmiṣọnna fun eto ẹkọ sọ ipinnu ijoba Oyo yii di mimọ lasiko ti wọn n ṣi iṣẹ akanṣe ti awọn akẹkọọ jade ile iwe Ibadan City Academy ṣe ni Ibadan.
 Omowe Nwani tun fi kun  oro re pe ko si ohun to buru ninu ki enikan
ẹgbẹ si ti n gbe igbese lati wa ojutu si awọn ipenija to n sele ninu ẹgbẹ  wọn.
Ajọ SEC ṣe ikede yii lẹyin iwadii ti wọn ṣe lori gbogbo kudiẹ-kudiẹ to ṣẹlẹ ninu awọn akọsilẹ ile iṣẹ naa.
Ọmọ ọdun mẹfa ni Oshodi wa, tí ogun abẹle fi ja nilu rẹ, eyi to mu ẹmi awọn obi rẹ lọ.
Ó dá oòrùn láti máa ṣe àkóso ọ̀sán,nítorí pé ìfẹ́ rẹ̀ tí kì í yẹ̀ wà títí lae.
Bákan náà, kí àwọn obinrin wọ aṣọ bí ó ti yẹ, aṣọ tí kò ní ti eniyan lójú, kí wọ́n ṣe ara wọn lọ́ṣọ̀ọ́ níwọ̀ntúnwọ̀nsì.
Ọ̀mọ̀wé Philip Seargeant ti fásitì Open University l'órílẹ̀-èdè Amẹrika pèsè àwọn ọ̀nà àbáyọ kan.
End bad government: Wọn rò pé a maa jà tàbí ba ǹkan jẹ́ ni ṣùgban ọmọlúwàbí ni wa-Afẹ̀hónúhàn
Yóo yọ mí láìfarapa,ninu ogun tí mò ń jà,nítorí ọ̀pọ̀ ni àwọn tí wọ́n dojú kọ mí,tí wọn ń bá mi jà.
Ìfẹ̀hónúhàn tí ó wáyé ní gbàgede ìlú wà lára ìkéde gbogboògbò saveLGBTinRussia tí wọ́n fi ń polongo ìyà tí ó rorò tí wọ́n fi ń jẹ àwọn ènìyàn aṣe-ìbálòpọ̀-akọ-àti-akọ ní orílẹ̀ Chechnya.
" Àwọn òṣèrè bíi jídé kòsọ ́ kọ ́ àti Ṣọlá fósùdó ṣe fíìmù kan tí wọ ́ n pè ní "" Ọkọ Ìyàwó "" ."
Àwọn agbébọn pa ọ̀gá àjọ tó ń rí sí ọ̀rọ̀ ìjọba ìbílẹ̀ Lai Mohammed, Ayo Fayose, Afẹnifẹre, Ndigbo, Arewa dá sí ọ̀rọ̀ Buhari àti Obasanjo Erin lo nigbo!
Bawo wa lo ṣe ṣeeṣe ki wọn o yọ eeyan nipo, ko si tun máa ṣakoso?
Bakan naa ni won parowa fawon ara ile Amerika ti o n gbe ni Turkey ki won sora ibi ti won n rin si ati lilo sibudo iworan tero po si lasiko yii.
Àwọn eniyan wa níláti kọ́ láti ṣe iṣẹ́ rere kí wọ́n lè gbọ́ bùkátà wọn; wọn kò gbọdọ̀ jókòó tẹtẹrẹ láìṣe nǹkankan.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Working religious women: Ẹ̀lẹ́hàá kìí ṣe ọ̀lẹ- Aminat Adegoke Gomina ipinlẹ Kebbi, Abubakar Bagudu ti pàṣẹ pe ki iwadii ijinlẹ waye lori ọrọ Jubril.
Eid el Kabir: Àwọn ohun mẹ́sàn án tí Mùsùlùmí gbọdọ̀ ṣe nínú oṣù Dhual rèé
Ṣé yóo san ẹ̀san fún ọ lọ́nà tí ó tẹ́ ọ lọ́rùn,nítorí pé o kọ̀ ọ́?
Iroyin taa gbọ ni pe awọn ọmọ igbimọ amuṣẹya ti aarẹ gbe kalẹ lori kikoju arun coronavirus, PTF lo wa kan si ọga ọlọpaa lorilẹede Naijiria ki o to paṣẹ ki wọn tu wọn silẹ lẹyin ti wọn ti lo bii wakati meji lagọ ọlọpaa.
 mà kàn dúró síbè sá ; ìwò òmùgò yìí .
Ó ti ṣẹ́ gègé, tí wọn ń pè ní Purimu, láti mọ ọjọ́ tí yóo pa àwọn Juu run patapata.
Nítorí náà, ẹ yan ìyè kí ẹ̀yin ati àwọn ọmọ yín lè wà láàyè.
 O ni “A nigbagbo pe aare yoo tele ipinnu
Mercy rọ gbogbo eeyan lati lo asiko yii ki wọn fi gboriyin fawọn oṣiṣẹ eleto ilera to n tọju awọn to lugbadi aarun corona virus.
OLUWA sọ fún Jehoiakini ọba, ọmọ Jehoiakimu, ọba Juda, pé, “Mo fi ara mi búra, èmi OLUWA ni mo sọ bẹ́ẹ̀.
Ọjọ nla ni Ọjọ yii jẹ ninu irinajo awọn musulumi lọ si ilu Mecca, ilẹ mimọ, to si jẹ ọkan ninu awọn ọjọ to se pataki si wọn.
''Abdulrasheed Maina yóò wà ní ọ̀gbà ẹ̀wọ̀n Kuje kó má ba tún sálọ'' Ẹ wo ìpínlẹ̀ táwọn gómìnà tẹ́lẹ̀ àti igbákejì wọn ń gba dúkìá ìfẹ̀yìntì tabua Kò yé káwọn Gómìnà fẹ̀yìntì máa gbowó gọbọi mọ́- Èrò ọmọ Nàìjíríà Ó tó gẹ́!
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Cancer: Àṣe ara mi ni iso ti n run gbogbo bí mo ṣe n ṣèrànwọ́ lórí jẹjẹrẹ Ṣugbọn si iyalẹnu gbogbo eniyan, eto okowo ti awọn eniyan ko ri bajẹ ni eku ti yi pada ni Estonia.
 bi jeografi , awon bahama wa ni asopo erekusu kanna bi kuba , hispaniola ( dominiki olominira ati haiti ) ati awon erekusu turks ati caicos .
Lọwọlọwọ bayii, ikọlu awọn darandaran naa ko tii ni ojutu, eyi to n dunkooko gidi mọ irẹpọ Naijiria nibayii to n sami ajọdun ominira ọgọta ọdun rẹ.
Kazaure ti o je asoju orile ede fun orile ede Australia to je okan lara  ajo commonwealth , naa tun ni asoju fun New Zealand, Fiji Island, Independent State of Papua, New Guinea ati orile ede Vanuatu.
Ninu fọnran fidio naa ni ọgbẹni Ilesanmi to jẹ ọmọ ọdun mẹrinlelọgọta ti n sọ fun awọn ọlọpaa naa pe ''Jesu nikan ni ọna iye'' Ọlọpaa to mu u ninu fidio naa si n sọ pe ''Mi o ba ọ jiyan amọ ko si ẹni to fẹ gbọ ohun to n sọ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Estimated Billing: Wo ọ̀nà tí àṣẹ tuntun tí Ààrẹ Buhari pa nípa owó iná gbà kàn ọ 27 Ògún 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 28 Ògún 2020 Oríṣun àwòrán, TWITTER/@BASHIRAHMAD Aarẹ Muhammadu Buhari ti pe fun fifi opin si bi ilana ti awọn ileeṣẹ amunawa n gba bu owo fun awọn onibaara jakejado Naijiria.
AFDAC kígbe síta lórí ẹja aṣekúpani tó wà nígboro - BBC News Yorùbá BBC News, YorùbáFò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Pufferfish - NAFDAC kígbe síta lórí ẹja aṣekúpani tó wà nígboro 3 Èbibi 2018 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 3 Bélú 2018 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Gẹgẹ bii ajọ NAFDAC ṣe sọ ninu awọn ẹya ara ẹja naa bii ẹdọ, ifun ati awọ ara rẹ ni awọn majele fara sinko si Bi o ba ri ẹja kan lọja eleyi ti wọn n pe orukọ rẹ ni 'Pufferfish' tete yara sa asala fun ẹmi rẹ.
UNGA: Tijjani Bande jẹ́ àgbà ọ̀jẹ̀ nípa ìbásepọ̀ àwọn orílẹ̀èdè
Angẹli Oluwa kan bá yọ dé, ìmọ́lẹ̀ sì tàn ninu ilé náà.
Elisafani ọmọ Usieli ni yóo jẹ́ olórí wọn.
Ṣugbọn ẹnikẹ́ni kò lè rí wọn láti ìta.
Aare nigbese ibukun ni fun onilaja yii ko seyin mimu ilosiwaju ba egbe oselu APC to n tuko Naijiria lowo lasiko yii.
OLUWA pàṣẹ fún angẹli náà pé kí ó ti idà rẹ̀ bọ inú àkọ̀, ó sì ṣe bẹ́ẹ̀.
Òye mi ju ti àwọn olùkọ́ mi lọ,nítorí pé ìlànà rẹ ni mo fi ń ṣe àṣàrò.
wọn le jẹ ọlọ́dani tàbi ki wọ́n jẹ́ ẹgbẹ́.
A rìn díẹ̀ nínú igbó náà níbà tí a já sí inú ọgbà ńlá tí ó lẹ́wà gidigidi, nígbà tí ọkùnrin náà sì ṣí ìlẹ̀kùn ọgbà yìí tí a wọlé tán mo rí ọ̀nà títóbi kan tí ó lọ síwájú gbọrangandan tí ó sì bá inú ilé ńlá kan lọ.
Man Utd Vs Man City: Kò ṣèlẹ́rí!
"Ko si nnkan kan laarin wa.
O gba awon omo Naijiria niyanju pe“E ma se je oloselu loni tipa-tikuu-ku… ohun ti  apa mi o to ma fi gongo fa, Iru won ma n gbe igbese ti o ye ki won gbe ni,”Asofin Nnamani tenumo:“Mo lero pe isoro wa ninu oselu orile-ede yii ni pe, bi a ba n le ipo kan bi a ba ri gba, a wa ma wa ibi ti o sona lati wo, leyi ti o si je igbese ti o buru jai.
Iroyin kan tilẹ sọ pe awọn eeyan naa di oju ọna to bẹẹ ti gomina Abdulrahman Abdulrazaq fi gbe alupupu lọ ile rẹ.
A máa gba àwọn aláìṣẹ̀,yóo sì gbà ọ́ là,nípa ìwà mímọ́ rẹ.
’ rèé MKO Abiola, iṣẹ́ aṣẹ́gità ló fi bẹ̀rẹ̀ okoòwò Iṣọla Oyenusi rèé, ẹnití ìfẹ́ obìnrin ṣun dé ìwà ìdigunjalè Taiwo Akinkunmi, ọmọ Ibadan tó ya àsìá Naijiria Ayinla Ọmọwura, orin èébú àti oríyìn lo fi di ọ̀rẹ́ àwọ̀n obìnrin Boya lasiko ti ayẹyẹ ọjọ ibi wọn ba ko tabi tawọn ọmọ wọn, eyi to n kọ ọpọ onwoye lominu.
Ijọ aguda Adoration Ministry Ko sẹni ti ko mọ alufaa Mbaka ti ijọ Aguda, Adoration Ministry, to wa ni ilu Enugu lẹkun ila oorun Naijiria.
Josẹfu, ọmọ ìdílé Lefi ará Kipru ẹni tí àwọn aposteli ń pè ní Banaba, (èyí ni “Ọmọ ìtùnú,”) 
 Ìpín ọgọ ́ rún àwọn tí àkóràn yìí ń kóbá ní ìgbàkugbà yàtọ ̀ láàrín 5 % àti 70 % .
Alágbára yóo dàbí ògùṣọ̀,iṣẹ́ ọwọ́ rẹ̀ bí ìṣáná.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, O leè má mọ̀ bóyá o ní àrùn HIV/AIDS o!
Wo àwárí akọ́ṣẹ́mọṣẹ́ yìí Lori pe boya wọn ti jọ sun si inu 'yara kan naa lati igba to ti de si Kano ni ọjọ mẹfa sẹyin; A o jọ sun si 'yara kan naa o."
Mo ti kọ́ ọ ní ọgbọ́n,mo sì ti fẹsẹ̀ rẹ lé ọ̀nà òtítọ́.
Ṣugbọn n kò ní gba gbogbo ìjọba náà kúrò lọ́wọ́ rẹ̀, n óo ṣẹ́ ẹ̀yà kan kù sí ọmọ rẹ lọ́wọ́, nítorí ti Dafidi iranṣẹ mi ati ìlú Jerusalẹmu tí mo ti yàn.
"Iṣẹ́ fẹ́ bọ́ lọ́wọ́ ọlọ́pàá tó gba N100k lọ́wọ́ awakọ̀ tó gba""One way"" l'Eko Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Akọ́mọlédè àti Àṣà lórí BBC Yorùbá: Kọ̀ síi nípa iṣẹ́ tí oúnjẹ ń ṣe lára níbí Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Fídíò, The New Pandemic: Kíni àwọn onímọ̀ sáyẹ́ńsì ń sọ nípa rẹ̀?"
" Ìjọba Amẹrika fi ojú àwọn ọmọ Yahoo mẹ́fà léde, wọ́n gbẹ́sẹ̀ lé dúkìá wọn Invictus Obi, Hushpuppi, àwọn ọ̀dọ́ Nàìjíríà méjì tí ẹ̀sùn gbájúẹ̀ wà lọ́rùn wọn Ohun tí a rí nílé Ajimobi rèé lẹ́yìn ìròyìn òfégè pé ó jáde láyé Yẹ̀kínì kan kò lè yẹ ipinnu wa láti ṣí iléèwé pàda lóṣù yí - ìjọba ìpínlẹ̀ Oyo Arabinrin ti a n wi yi sọ pe oun ati awọn ọmọbìnrin mii ribi sa mọ wọn lọwọ nibi ti awọn oniṣẹ ibi yii ko wọn pamọ si lasiko ti wọn n sun ni nkan bi aago kan oru.
Idile Ohu ati Osu ni idile ẹru ni Ile Igbo Awọn to wa lati idile ẹru yii pin si ọna meji- awọn kan wa ti wọn n jẹ Ohu ati Osu.
Igbimọ ẹlẹni meje, ti adajọ agba ni Naijiria, Tanko Mohammed ko sodi, tun wọgile ẹjọ Kotẹmilọrun ti oludije fun ipo aarẹ labẹ asia ẹgbẹ oselu PDP, Atiku Abubakar pe, eyi to fi n tako eto idibo ọdun aarẹ 2019.
Ó ní, “Kí ló dé tí àwọn kẹ̀kẹ́ ogun rẹ̀ fi pẹ́ tóbẹ́ẹ̀ kí wọ́n tó dé?
Ẹ̀yin ará Mareṣa, n óo tún jẹ́ kí àwọn ọ̀tá borí yín; ògo Israẹli yóo sì lọ sí ọ̀dọ̀ Adulamu.
Lizzy Anjorin: Ibadan ní ọkọ mi, ata wíwẹ́ lo fẹ́ràn
Wọ́n bá pada lọ ròyìn fún àwọn ìyókù.
Ọ̀nà kan wà tí ó tọ́ lójú eniyan, ṣugbọn òpin rẹ̀, ikú ni.
 Gomina ipinle Kaduna,  Nasiru  El-Rufai  wa rọ awon eniyan lati dojuti awon arijẹ
Iroyin sọ pé Ani to n Kẹmika ni ọjà ọhun ń ṣètò ìgbéyàwó pẹ̀lú obinrin mìíràn ní ọjọ kẹrin oṣù kíní ọdun 2020, lẹ́yìn ti ìná òun àti Ogboke o wọ̀ mọ́ botilẹ̀ jẹ́ pé ìbásepọ náà mu ọmọkunrin ọdun kan abọ dáni.
O ṣalaye pe ile itura ni awọn ọmọ naa yoo kọkọ duro si, nibi ti wọn o ti wẹ, jẹun, sinmi, ki dokita to ṣe ayẹwo ara wọn.
o ti je ki orile ede yii ti ni owo ti iye re je bilionu mejilelogun owo dola
Brad naa ti gba lati sise bi o ti ye fun aseyori Trump.
Lẹ́yìn náà, yóo mú ẹ̀yinná láti orí pẹpẹ tí ó wà níwájú OLUWA sinu àwo turari, yóo sì bu turari olóòórùn dídùn tí wọ́n gún, ẹ̀kúnwọ́ meji, yóo sì gbé e lọ sinu ibi tí aṣọ ìbòjú wà.
Oríṣun àwòrán, @jide2816 Lootọ ni awọn asa ati ise yii pọ lọ jantirẹrẹ, bo si se wa fawọn obinrin, naa ni tawọn ọkunrin wa, ti gbogbo awujọ ilẹ Yoruba si ni awọn eewọ to n dari wọn, nitori idalu ni iselu.
Ipinlẹ Osun: Lara iṣẹlẹ to lamilaaka ninu iwọde End SARS ni eyii to waye ni ilu Osogbo lẹyin ti gomina ipoinlẹ naa, Gboyega Oyetola yọju si awọn oluwọde naa, ṣugbọn ti awọn janduku kan ṣekọlu sii.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Nàìjíríà ló wà nípò kẹfà nínú ewu ikú àìtọ́jọ́ l'ágbàáyé nítorí nkan mímú tó ní ṣúgà 5 Ìgbé 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Iwadi tuntun kan ti fihan pe awọn nkan minu ẹlẹrindodo to ni ṣuga ninu n mu ki iku aitọjọ o pọ si Iwadii tuntun kan ti fihan pe awọn nkan minu ẹlẹrindodo to ni ṣuga ninu n mu ki iku aitọjọ o pọ si nipasẹ awọn aisan bi i aarun ọkàn ati awọn aisan jẹjẹrẹ kan.
Àtúnse keji ti àjọyọ yoo jẹ osu keta ojo meji-le-logun di arundinlogbon ojo ni 2019 ni ilu tunis .
 Inu si dun pupo lati darapo mo iko yii.
Àsẹ̀yìnwá àsẹ̀yìnbọ̀, Èsù kà á sí ẹni burúkú, ó lé e jáde, ìgbà tí òun náà ń bọ̀, Ó pàdé ọ̀kan nínú àwọn ẹ̀mí ọ̀dọ̀ Olódùmarè lọ́nà, ìgbà tí ó sì kó tí ó rò fún un, inú ẹ̀mí náà dùn ó sì fi filà kan ta á lọ́rẹ, ohunkohun tí ó bá n fẹ́ ni fìlà náà lè ṣe fún un, nítorí iwin ń bẹ nínú filà náà, bí ó bá sì ti sọ̀rọ̀ sí fìlà kẹ́lẹ́kẹ́lẹ́, iwin á jáde, ohunkóhun tí ó bá ní kí o ṣe ni yóò ṣe.
Ìròyìn sọ pe àwọn ọkọ to n bọ wá si ilú Eko lati ilú Ibadan ko le wọlẹ pàápàá jùlọ lati ori afára Kara, bákan náà ni àwọn to n lọ si ìlú Ibadan náà ko ni ànfani láti tẹ̀síwájú.
N óo fún ọ ní gbogbo ilẹ̀ Kenaani, ilẹ̀ náà tí o ti jẹ́ àlejò yìí yóo di ìní rẹ títí ayérayé ati ti atọmọdọmọ rẹ, n óo sì máa jẹ́ Ọlọrun wọn!
ede Naijiria loju nipa ojuse wa.
ó sì pa ìlú náà run ati gbogbo àfonífojì náà.
Arsenal ti wa ni ipo kẹẹdogun bayii lori tabili idije Premier League.
A ó bẹ̀rẹ̀ si kọ oríkì oriṣiriṣi ìdílé Yorùbá.
Eyi naa kun idi ti awon omo Naijiria fi n kominu lori ohun to mu Senato Akpan gba ọkọ ayokele lati fi daabo bo ẹmi re Ọgbẹni Adetokunbo Mumuni wa lara awọn to faraya: ''A ní ki wọn wà jẹun ní ṣùgbọ́n n'isẹ ni wọn mú wà lọwọ sí lẹ.
Atẹjade naa tun wa loju opo Twitter agbẹnusọ aarẹ Buhari, Bashir Ahmad.
Ọ̀rọ̀ Aisha Buhari sí Ramaphosa wú ọ̀rọ̀ síta lẹ́nu àwọn ọmọ Nàìjíríà Kí ló ṣe ikú pa Adewura Latifat Bello lẹ́yìn ọ̀sẹ̀ méjì tí wọ́n ń wá a?
 ibẹ ̀ ló gi mú orúkọ yìí bọ ̀ tí ó sì fi sọ ilú tí òun náà tẹ ̀ dó .
Alukoro ileeṣẹ ọlọpaa, Chibuzor fidirẹ mulẹ fawọn ileeṣẹ iroyin abẹle kan pe lootọ lọmọ naa wa lara awon to kọlu ileesẹ ọlọpaa naa sugbọn  a muu ninu aṣọ iṣẹ ọlọpaa sajẹnti naa."
Irú ìyà kan náà ni n óo fi jẹ wolii alára ati ẹni tí ó lọ wádìí ọ̀rọ̀ lọ́wọ́ rẹ̀.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Teach your children Yoruba: Wo àwọn òyìnbó tó ń kẹ́kọ̀ọ́ èdè Yorùbá ní Michigan, America Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
O fẹrẹẹ to ọdun mẹwaa to ti jẹ aarẹ orilẹede Burundi.
Nigba ti o di ojo keji, adajọ́ fi iwe asẹ sita pe ki wọ́n tunbo je ki o rookun latimọ́le.
Iwadii fihan pe eniyan miliọnu marundinlọgọrin lo ti ni aarun kokoro naa.
Adehun okoowo naa, AfCFTA ba idiwọ pade lọdun to kọja nigba ti Naijiria yọ ọwọ kuro ninu rẹ ṣaaju ọjọ to yẹ ko buwọlu u.
Bí ìyìn rere Jesu Kristi Ọmọ Ọlọrun ṣe bẹ̀rẹ̀ nìyí: 
"O ni, ""Mimu ayipada de ba bi a ṣe n ṣe oṣelu ni Naijiria kii ṣe oun ti ẹnikan ṣoṣo le ṣe."
Ijọba ilẹ Biafra fi ẹsun kan pe Naijiria n lo ebi ati pipa awọn eniyan wọn nipakupa lati fi bori ogun naa, wọn si beere fun iranlọwọ lati ilẹ okeere.
Premier league: Arsenal kọrin 'kọ́stọ́mà daada ni' fún Burnley pẹ̀lú àmì ayò méjì sí ẹyọkan
Dájúdájú, ọ̀nà jíjìn ni àwọn ẹlẹ́ṣin wọn ti ń wá; wọn a fò, bí idì tí ń sáré sí oúnjẹ.
Eleyi ti sọ iye awọn eeyan to ko aarun naa di mẹjọ.
Wọ́n dá a lóhùn pé, “Kò ṣeéṣe, àfi bí gbogbo àwọn olùṣọ́-aguntan bá dé tán, tí a bá yí òkúta kúrò lórí kànga, nígbà náà ni a tó lè fún àwọn aguntan ní omi mu.
Ninu ọrọ rẹ, Giwa to jẹ iya ọmọ kan ke si ileẹjọ lati tu igbeyawọ oun ka nitori ọdun mẹrin ni ọkọ oun fi fi oun silẹ lai wẹyin wo.
Nígbà wo ni ọ̀kan ninu àwọn ọlọrun orílẹ̀-èdè wọnyi gba orílẹ̀-èdè wọn lọ́wọ́ ọba Asiria rí, tí OLUWA yóo fi gba Jerusalẹmu lọ́wọ́ mi?
Bakan naa ni Minisita fun igboke-gbodo ọkọ ofurufu, Femi Fani-Kayode naa sọ pe Akinjide jẹ olori ilu ti ko ṣe fọwọ rọ sẹyin.
Amọ oṣiṣẹ alarina ọlọpaa nipinlẹ Oyo naa ni ọwọ ọlọpaa ko tii tẹ afurasi kankan lori iku Barakat Bello ti wọn fi tipa ba lopọ, ki wọn to pa ninu baluwẹ lagbegbe Akinyele.
Àwọn mẹrin kan ń gbé arọ kan bọ̀ wá sí ọ̀dọ̀ rẹ̀.
Yóo fi pátákò ẹsẹ̀ àwọn ẹṣin rẹ̀ tú gbogbo ilẹ̀ ìgboro rẹ, yóo fi idà pa àwọn eniyan rẹ; yóo sì wó àwọn òpó ńláńlá rẹ lulẹ̀.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù AAUA; Ọ̀pọ̀ ìgbà ni SARS ma ń lu àwọn akẹ́kọ̀ọ́ fásitì wa 19 Òkùdu 2018 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 20 Òkùdu 2018 Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, AAUA; Ọ̀pọ̀ ìgbà ni SARS ma ń lu àwọn akẹ́kọ̀ọ́ fásitì wa Awọn akẹẹkọ fasiti Adekunle Ajasin, AAUA ti fi ẹsun kan awọn ọlọpa SARS wi pe wọn ja wọ ile ibusun wọn, ti wọn si lu awọn akẹẹkọ bi ẹni lu bara.
Ayé ti fọ́, ayé ti fàya,ayé sì mì tìtì.
Gbajugbaja agbabọọlu Juventus, Cristiano Ronaldo fọba lee pẹlu goolu keji fun Juventus nigba ti ere bọọlu ọhun pe wakati kan geere.
Pupọ awọn orilẹede Afirika lo ni ajọṣepọ okoowo ati ọrọ aje pẹlu orilẹede China.
Ninu ikọ ogun ilu Ibadan, Ogedengbe ja fitafita titi to fi di Ọgagun o si wa pada lati lọ dari ikọ ogun ti ilu Ijeṣa.
NIS ní àwọn kò ṣèṣẹ̀ máa fí ìwé irinnà ránṣẹ sí àwọn tó bá fẹ
Ènìyàn 27 lo ti bá iṣẹ̀lẹ̀ ọkọ̀ ofúrufú tó já rìnrìn ajò Pasuma kìí ṣe ọkọ mi o!
Nigba ti BBC News Yoruba kan si alukoro ẹgẹ oṣelu APC, Ọgbẹni Issa Onilu, o ni ẹgbẹ oṣelu APC yoo fi ero rẹ han lori ọrọ ọhun ni ọsan ọjọ aje.
Nítorí bí ó bá jẹ́ pé ara wa ni wọ́n, wọn ìbá dúró lọ́dọ̀ wa.
Bakan naa ni Emerald fikun ọrọ rẹ pe ọmọkunrin mi ni Mercy maa n pee.
Ninu fidio taa n wi yi, niṣe lawọn ekute n da igba ru ninu lẹda kan ti wọn gbe kalẹ lẹgbẹ ibusun alaisan.
awon adari egbe oselu kookan lojuna ati fopin gbogbo ruke-rudo naa.
Ipinlẹ Abia lo ṣe ipo keji nibi ti eeyan mọkanlelogun ti lugbadi aarun ọhun.
Iyawo Bamidele lo sọ eyi fun BBC Yoruba.
 Ọgbẹni Olumẹkun lo sọ ọrọ yii.
àwọn ará Hifi, àwọn ará Ariki ati àwọn ará Sini; 
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Awakọ kan d'oloogbe ninu ikọlu afurasi darandaran nipinlẹ Ondo 30 Sẹ́rẹ́ 2018 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Iroyin sọ pe awakọ ọmọ ọdun mẹrinlelọgbọn k'agbako nipinlẹ Ondo Iroyin sọ wipe afurasi Fulani darandaran kan ti pa ọkunrin awakọ kan ti orukọ rẹ njẹ Victor Ajisafe nitori aigbora-ẹniye ni ilu Akure, nipinlẹ Ondo.
Fawọn ti kii baa ṣe igbaradi tabi ere idaraya loore koore eyi le mu ki wọn maa kaju oṣunwọn to.
Àbí wọ́n lè pín Lefiatani láàrin ara wọn?
Ọpọ eeyan lo si n beere pe, se Naijiria yoo se ajọdun ọgọrun ọdun gẹgẹ bii orilẹede kan soso bi?
Lásìkò ìkéde yìí alága INEC kéde Bello Muhammad Mutawalle to jẹ olùdíje PDP fun gomina gẹ́gẹ́ bi ẹni to jáwe olúbori ní Zamfara.
Akọ̀wé yi kọ ìṣirò ki ó tó bẹ̀rẹ̀ ilé-ìwé lọdọ ìyá rẹ̀ àgbà.
Ọlọrun Alágbára, Ọlọrun ni OLUWA, ó mọ ìdí tí a fi ṣe ohun tí a ṣe, a sì fẹ́ kí ẹ̀yin ọmọ Israẹli náà mọ̀ pẹlu.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Itaniji: Oluwo sọ ìtàn bí Orunmila ṣe jìyà nílùú Iwo àti ayọ̀ tó gbẹ̀yìn rẹ̀ torí sùúrù Bakan naa lo ṣalaye pe aisan ẹjẹ ruru naa tun wọ pọ ninu igbeyawo laarin ẹbi.
Akẹkọ ko le se ounjẹ tabi ẹran jẹ Sise irufẹ ounjẹ ninu yara awọn akẹkọ ko mu u rara o.
pataki isejoba tiwa-n-tiwa gege bi ona kan ti o dara ju lati yan awon oludari
Nígbàtí Alákàn dé ọ́dọ̀ onígbèsè , tí ìrèlè ìwà pẹ̀lú ìtẹríba tí a mọ sí Ìwà ọmọlúwàbí ni Alákàn fi jísé fún onígbèsè.
Ṣugbọn nisinsinyii mò ń ba yín wí,mo sì ń fi ẹ̀sùn kàn yín.
Eyi ko sẹyin bi Ajo Eleto Idibo lorilẹede Naijiria, INEC se sọ wi pe, Smart Adeyemi ti ẹgbẹ oṣelu APC lo wọle ninu eto atundi idibo to waye ni ẹkun idibo iwọ-ooorun ipinlẹ Kogi.
Ṣugbọn gbogbo anfani yii ni yoo dopin gbara ti Ilẹ Gẹẹsi ba ti fi ajọ EU silẹ.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ohun to ṣe pataki julọ ni ki olori sẹ ohun to yẹ fara ilu Gbogbo igbiyanju BBC lati bá Hafsat sọrọ lori iṣẹlẹ yii ja si pabo nitori wọn ni o n gba itọju.
 Pẹ̀lú ìwòye tèmi Yorùbá ló maa ń tọju obìnrin 
Àwọn ayaba ati àwọn obinrin mìíràn ní ààfin sì ń yìn ín.
Ọkọọkan ninu awọn oludije yoo lanfaani lati yan awọn akẹgbẹ wọn mẹrin ti o ni ibo to kere julọ ninu iyara ifọrọwanilẹnuwo,'Diary Room'.
Wọn óo dàbí àsíá ati àmì lórí òkè.
mo sì wá sí Jerusalẹmu, ìgbà náà ni mo wá rí nǹkan burúkú tí Eliaṣibu ṣe nítorí Tobaya, tí ó yọ yàrá fún ninu àgbàlá ilé Ọlọrun.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Lockdown updates: Naira Marley gbóríyìn fún Jude Chukwuka pẹ̀lú #1 míliọnù Iyẹn ni pe ko saye ipe lori foonu tabi wiwo mohunmaworan.
Ó tún Eloti kọ́, ó gbà á pada fún Juda lẹ́yìn ikú Amasaya, baba rẹ̀.
A ti se ipade po pelu ajo to n ri si eto inawo , a tun ti se ipade po pelu ajo to n ri si eto isuna ati ilana .
Ọmọwe David Mathews ni fasiti Bristol naa ni wọn lo awọn cẹẹli atọwọda nigba ti wọn n po abẹrẹ ajẹsara naa pọ, ṣugbọn kii ṣe ti oyun ti wọn ṣẹ.
OLUWA àwọn ọmọ ogun ní, ‘N óo rán ogun, ìyàn ati àjàkálẹ̀ àrùn sí wọn, n óo sì ṣe wọ́n bí èso ọ̀pọ̀tọ́ tí ó bàjẹ́ tóbẹ́ẹ̀ tí ẹnikẹ́ni kò lè jẹ ẹ́.
A ti sọ fun wọn lati dawọ ijọsin wọn duro titi ti wọn o fi koju osuwọn.
iwa odaran ni ipinle Oyo ati lati dupe lowo won fun atileyin won lati igba ti
Bí etí bá sọ pé, “Èmi kì í ṣe ojú, nítorí náà èmi kò sí ninu ara,” kò wí pé kí ó má ṣe ẹ̀yà ara mọ́.
O ṣalaye pe ki awọn eeyan ma ṣe foya nitori ileeṣẹ oun ko gbe ẹrọ kọmputa ti awọn kan n sọ nipa rẹ jade.
Agbẹjọ́rò àgbà mẹ́fà, òdú amòfin mẹ́tàdínlógún míràn yóò ṣojú Sẹ́nétọ̀ Adeleke níléẹjọ́ tó ga jùlọ Níbo làwọn òṣèré apanilẹ́rìn ín wọ̀nyí tó pilẹ̀ sínima àgbéléwò Yorùbá wà?
Uganda kó rọ́bà ìdáàbòbò mílíọ̀nù kan kúrò ní ìlú Ganduje fi ọwọ́ òsì da ìdájọ́ ilé ẹjọ̀ nù lórí Emir tuntun mẹ́rin!
Láìpẹ́, lẹ́yìn tí Rehoboamu fi ìdí ìjọba rẹ̀ múlẹ̀ tí ó di alágbára, òun ati àwọn eniyan rẹ̀ kọ òfin OLUWA sílẹ̀.
OLUWA ń ṣọ́ àwọn tí ó bẹ̀rù rẹ̀,àní àwọn tí ó gbẹ́kẹ̀lé ìfẹ́ rẹ̀ tí kì í yẹ̀,
Ẹ dẹ̀kun lílo Sniper àti Dichlorvos fún ìtọ́jú oúnjẹ- NAFDAC kìlọ̀ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, EndSars, EndSwat Protest: Òbí agbábọ̀ọ̀lù Gbenga Tiamiyu Kaka àtàwọn míì tí ọlapàá pa sọ̀r Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Fídíò, Akomolede àti Asa lórí BBC Yorùbá: Mọ̀ síi nípa ẹ̀kún ìyàwó níbí3 Bélú 2020 Fídíò, Soyinka Cancer: Àṣe ara mi ni iso ti n run gbogbo bí mo ṣe n ṣèrànwọ́ lórí jẹjẹrẹ27 Bélú 2019 Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
" Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ọlọpàá ti bẹ̀rẹ̀ ìwaàdí lórí ikú Bademọsi Atiku yan Peter Obi gẹ́gẹ́ bi ìgbákejì rẹ̀ fún ìbò aarẹ 2019 Taa ni Jọkẹ Silva, òsèré tíátà tó ń se ọjọ́ ìbí ?
Àwọn ni wọ́n ń mu ẹmu tàkìtì kiri ìlú
Ta ni Naira Marley jẹ́ gan an?
Nítorí pé kí ọmọ náà tó mọ bí a ti í kọ nǹkan burúkú tí a sì í yan nǹkan rere, ilẹ̀ àwọn ọba mejeeji tí wọn ń bà ọ́ lẹ́rù yìí yóo ti di ìkọ̀sílẹ̀.
Ife tí ó fi ń bu ọtí fún eniyan nikí o fi bu ọtí tí ó le ní ìlọ́po meji fún òun alára.
Lakotan, oludije PDP Obaseki ni ibo 307,955 nigba ti Ize-Iyamu si ni ibo 223,619 ninu ibo naa.
Ikọ̀ Àmọ̀tẹ́kùn ṣèsì yìnbọn pa akẹ́kọ̀ọ́ nílùú Ibadan Ibi ti o ti le ṣe iforukọlẹ lati kopa ninu ipade naa ree.
OLUWA fi àwọn orílẹ̀-èdè wọnyi sílẹ̀ láti fi dán Israẹli wò, pàápàá jùlọ, gbogbo àwọn ọmọ Israẹli tí wọn kò tíì ní ìrírí ogun jíjà ní ilẹ̀ Kenaani.
Risikat Azeez: Ìyàwó Gómìnà ìpínlẹ̀ Kwara mú ìlérí rẹ̀ ṣẹ, Risikat tí bẹ̀rẹ̀ sí ní kọ́sẹ́ aṣojú lóge
Ó bẹ ̀ ẹ ̀ rẹ ̀ eré ṣíṣe ní odún 1964 lẹ ́ yìn tí ó darapọ ̀ mọ ́ ẹgbẹ ́ òṣèré oyin adéjọbí .
Ìdáhùn mi nìyí fún àwọn tí wọn ń rí wí sí mi.
Orilẹede Australia lo n lewaju atẹ igbelewọn naa pẹlu ọgọrin goolu, ilẹ Gẹẹsi tẹlee pẹlu goolu marundinlaadọta ti India si ṣe ipo kẹta pẹlu goolu mẹrindinlọgbọn.
Akiolu Staff of Office: Àwọn ológun láwọn ló dóòlà Ọba Eko àti ìdílé rẹ̀ ṣáájú ìwọ́de EndSARS
Ìdí ẹ̀ ni pé àwọn igi abẹwélórí wọ̀nyí ò tíì di arúgbó igi.
O darapọ mọ ẹgbẹ oṣere Naijiria ni ọdun 2008.
Òpè eniyan kò lè mọ̀,kò sì le yé òmùgọ̀: 
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Kini Yoruba n pe ni 'pen'?
Ṣugbọn OLUWA Ọlọrun yín ni kí ẹ súnmọ́ gẹ́gẹ́ bí ẹ ti ṣe títí di òní.
Àkọsílẹ̀ ìran wọn nìyí: Nebaiotu ni àkọ́bí Iṣimaeli, lẹ́yìn náà ni ó bí Kedari, Adibeeli, ati Mibisamu; 
O ni, a o fẹ muu lerefe ki a bẹrẹ sini polongo awọn ogun ibilẹ naa lai ṣe ayẹwo ti o tọ pẹlu imọ sayẹnsi."
O si fori le Ilẹ Gẹẹsi lọjọ keji to kọwe fipo silẹ gẹgẹ bii minisita fun eto inanwo lorilẹ-ede Naijiria.
Wọn a máa sọ gbogbo nǹkan dáradára tí ó ń ṣe lójú mi, bẹ́ẹ̀ sì ni wọn a máa sọ ọ̀rọ̀ témi náà bá sọ fún un.
Wọn ni bẹẹ naa lo tun n pariwo orukọ iyawo rẹ, ṣugbọn ninu agbara ẹjẹ ni wọn ti ba iyawo naa.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ibadan: Òkìtì iyanrìn wó pa Wale àti Adeyemi lágbègbè Ologuneru 23 Agẹmo 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Awọn miran pẹlu fi ara ṣeṣe ninu iṣẹlẹ naa.
O ní bí a bá ṣe bẹ́ẹ̀ a kò ní pẹ́ ṣẹ́gun.
Wo ohun márùn-ún tó ń fa ìjàmbá iná nínú ilé 'Kò sí ìyàtọ̀ nínú ọ̀kùnrin olóòtọ́ àti èyí tí kò sòótọ́ mọ́' Ọmọ Nàíjíríà faraya lórí àìkópa Buhari àti Atiku nínú ìjíròrò Gbàjarè!
achamán wà ni ọlọrun ti ọrun si atijọ olugbe ti awọn erekusu ti tenerife ( Àwọn erékùṣù kánárì ) , awọn guanches npe ni .
Bí wọ́n pé ọgbọ̀n kú, n ò ní sí nínú wọn
Bí ẹ bá tún ṣe bẹ́ẹ̀ n óo jẹ yín níyà.
” Dafidi bá lọ gbé àpótí ẹ̀rí náà kúrò ní ilé rẹ̀ wá sí Jerusalẹmu, pẹlu àjọyọ̀ ńlá.
Abike Dabiri vs Pantami: Èrò ọmọ Nàìjíríà sọ̀tọ̀tọ̀ lórí fàákájáa láàrin Abike Dabiri-Erewa àti mínísítà ètò ìbárẹ̀nisọrọ̀
A gbọ pe aigbọraẹniye yii waye tori ile ẹjọ kii fibẹẹ tobi.
Ìtàn wọ̀nyí lè di ìdánimọ̀ọ wọn gẹ́gẹ́ bí ọmọ ìlú àti ìbáṣepọ̀ t'ó dán mánrán pẹ̀lú àyíká.
Kò tọ́ sí Ọlọ́pàá láti ti ọmọ mi mọ́lé tórí ore tó ṣe lásìkò ìwọ́de EndSARS - Iya Eremosele Èmi ni mò ń jóko sórí ìtẹ́ Ọlọrun alààyè nílé ayé - Oluwo Wo ìdí tí wọ́n fi ta ẹyẹlé kan ṣoṣo ní ₦724,000,000 'Banji Akintoye kìí ṣe adarí àwọn ọmọ Yorùbá mọ́, a ti ní ẹgbẹ́ tuntun' Ọpẹ́ o!
Apá keta ti bà bí àdàbà o.
Paulu gé irun rẹ̀ ní ìlú Kẹnkiria nítorí pé ó ti jẹ́ ẹ̀jẹ́ kan.
Lara awọn to fi ero wọn lede ohun sọ pe iya ati iṣẹ ti poju lawujọ lasiko arun Coronavirus yii, nitori naa ki ijọba fi wọn silẹ lati wa ounjẹ ojo wọn.
Nwodo soro yii nilu Enugu pe lilo kemikaa ni anfani pupo ju papa jijona lo.
Obìnrin méje, ìjàngbọ̀n méje; a’ti bẹ́ẹ̀ bẹ́ẹ̀ lọ,
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Àwa táa jẹ́ alágbàtọ̀ gan, èèyàn ni wá, ẹ ye ṣe wa bí ẹranko' 'Ayọ lo maa n jẹ fun mi pe mo bi to ọmọ mẹtadinlogun.
Awọn olupẹjọ, Kalu Kalu, Labaran Ismail ati Hassy Kyari El-Keris tọ ile ẹjọ lọ pe ko fagile Buhari gẹgẹ bi oludije nitori iwe ẹri ileewe to lọ.
Ó kẹkoọ jáde nípa eto oro àyíká ni Fáṣítì ìjọba apapo tí ìlú Èkó.
pé kí ó pàṣẹ fún àwọn ọmọ Israẹli kí wọn máa mú ọrẹ wá fún ohun ìrúbọ sí òun OLUWA ní àkókò rẹ̀, ati àwọn nǹkan tí wọn yóo máa fi rú ẹbọ sísun olóòórùn dídùn.
Wọn óo kọlu àwọn ará Filistini ní ìhà ìwọ̀ oòrùn,wọn yóo jọ ṣẹgun àwọn ará ìlà oòrùn.
Àarẹ̀ Yoweri Museveni ti orílẹ̀èdè Uganda ló se agbátẹrù òfin náà pẹ̀lú àwíjàre pé àwọn ojú òpó ìkànsíraẹ́ni náà máa ń se kóríyá fún ìwà gbéborùn àbí ọ̀rọ̀ ẹ̀yìn.
Igbakeji minisita fun eto ilera, Dokita Faustine Ndugulile ni awọn rọba idaabobo naa ti wa nikalẹ bayii fun lilo.
O fi kun pe, nkan ayọ ni ede Yoruba jẹ́, o si yẹ ka maa gbe e larugẹ ni, gẹgẹ bawọn ara India, China ati Germany ti n gbe ede wọn larugẹ.
Ati pe lati ọna oke ọya ni oun gbọ́ pé wọn ti n ko iṣu naa bọ wa si Eko.
Ìwọ ni mo gbára lé láti inú oyún;ìwọ ni o mú mi jáde láti inú ìyá mi.
"Akeugbagold tún gbarata pé, ibanujẹ ni kí òbí má rí ọmọ rẹ, ibanujẹ tó ga ní, tí òun si ń rántí bí àwọn ọmọ náà ṣe máa ń dá oúnjẹ òun ru lásìkò isinu.
Nítorí mo ní eniyan pupọ ninu ìlú yìí.
Ko saye ati lo o fi da eeyan lohun Ẹ ko ni lee lo ohun ti o ba ka silẹ pẹlu eroja naa lati fi da eeyan lohun tabi taare atẹjiṣẹ eeyan kan si ẹlomiran.
Ẹ lọ ka itan yii ni: https://www.
Ẹ ní etí lásán ni, ẹ kò fi gbọ́ràn?
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Akeredolu: Kìí ṣe Buhari ló wà nídìí rẹ̀, ẹ jẹ́ ká gbà pé àmúwá Ọlọ́hun ni Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!"
Saulu ranṣẹ sí Jese, ó ní, “Jẹ́ kí Dafidi máa bá mi ṣiṣẹ́ nítorí ó ti bá ojurere mi pàdé.
gbagbe, ojọ abamẹta(Satide) ose to koja, ti n se ọjọ kẹrindinlogun oṣu keji odun
Awọn to nii awọ ewe lo dara ju ti alawọ yẹlo ko si buru to awọn to ni awọ pupa.
Ekinni bá dé, ó ní, ‘Alàgbà, mo ti fi owó wúrà kan tí o fún mi pa owó wúrà mẹ́wàá.
A ti gbé kọ́kọ́rọ́ sẹ́nu ibodè Nàìjíríà kí ọrọ̀ ajé wa leè gbé pẹ́lí- ìjọba àpapọ̀ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ti o bá dá ara ẹ lójú, ki ẹni tó n ṣe irun kí n gbọ́?
Ẹni tí ń ṣiṣẹ́ oko dáradára, yóo ní oúnjẹ pupọ,ṣugbọn ẹni tí ń fi àkókò rẹ̀ ṣòfò yóo di talaka.
Alaafin ni Wasiu ko to bẹẹ lati nawọ si iru awọn ọba nla bayii ti wọn ba pade lode.
Moriam Seun Adigun Ọjọ ori: Mọkanlelọgbọn Orilẹẹde: Nigeria Ere idaraya: Kẹkẹ ori yiyin ‘Bobsleigh’ Seun Adigun loludasilẹ ikọ kẹkẹ ori yiyin ‘Bobsleigh team’ akọkọ fun orilẹẹde Nigeria.
egbe oselu APC, asiwaju Bola Tinubu abbl.
Sony MDREX50LPW tí mo rà níjọ̀ọ́sí ló mà ti bàjẹ́ o.
Ninu abajade naa ni wọn ti fẹsun kan an pé, igbe aye ti ọga ajọ EFCC naa n gbe ju iye owo osu to n gba lọ.
ile ise asobode lati se ise won bo se tọ ati bo se yẹ.
Iṣẹ ìjọsìn ni Hajj, kí ṣé afẹfẹ yẹyẹ rara.
Wọ́n bi Baruku pé, “Sọ fún wa, báwo ni o ṣe kọ gbogbo ọ̀rọ̀ wọnyi sílẹ̀?
Obí ta ọmọ tuntun tí kò ju wákàtí mẹ́fà lọ ní ₦850,000 .
Ninu ọrọ rẹ lẹyin ibo naa, May ni oun yoo maa ṣiṣẹ lati ri pe oun mu gbogbo ireti wọn lori ibo itagbagba, ninu eyi ti wọn ti fi han wipe awọn fẹ fi EU sile, wa si imuṣẹ.
Sunday Igboho yarí, ó fohùn ránsẹ́ sáwọn èèyàn tó ń pẹ̀gàn rẹ̀ Alaga ajọ to n mojuto iṣẹlẹ pajawiri nipinlẹ Eko, Olufemi Oke-Osanyintolu, to fidi iṣẹlẹ naa mulẹ, sọ pe wọn ti ko gbogbo eeyan to n gbe ninu ile naa kuro.
Ọọni, Aláàfin, Ojisẹ Ọlọ́run àti oniṣẹ ìwádìí fi Ògún gbari pé òògùn ìbílẹ̀ le wo Covid-19 Ijọba ipinlẹ Ọyọ ti bẹ awọn oniṣegun ibilẹ lọwẹ lori aarun Coronavirus Iṣẹ́ amòfin tí mo kọ́ ni Fáṣítì kò mú owó wọlé fún mi bíi iṣẹ́ tíátà - Femi Adebayo Coronavirus: Kíni àwọn àmì tuntun tó n fihàn?
Àwọn arakunrin ati arabinrin Jobu ati àwọn ojúlùmọ̀ rẹ̀ tẹ́lẹ̀ pada wá bẹ̀ ẹ́ wò.
Oríṣun àwòrán, @Ransome Kuti Àkọlé àwòrán, Agbara obinrin pọ̀ Ẹgbẹ́ Iṣọ̀kan àwọn obinrin Ẹ̀gbá Funmilayọ Ransome-Kuti ati àbúrò ọkọ rẹ̀, Ẹniọla Ṣoyinka ( Iya Wọle Ṣoyinka), ni wọn jọ dá ẹgbẹ iṣọkan yii silẹ lati fi ja ija ominira awọn abo kuro lọwọ awọn Ajẹlẹ.
OLUWA Ọlọrun yín tí ń ṣáájú yín ni yóo jà fun yín, gẹ́gẹ́ bí ó ti jà fun yín ní ilẹ̀ Ijipti, tí ẹ̀yin náà sì fi ojú ara yín rí i.
Babiloni ṣubú lójijì, ó sì fọ́;ẹ sun ẹkún arò nítorí rẹ̀!
"O ni ""A n ya fidio awo orin lọwọ ni diẹ lara awọn ọkọ ayọkẹlẹ ti a n lo bajẹ, a si nilo ọkọ lati ko awọn eniyan lọ si ibomiran ti a ti fẹ lọ ṣiṣẹ, lo jẹ ka lo ọkọ to ni apoti oni gilaasi naa."
Abia Warriors 16:00Ifeanyi Ubah United ?
Mi ò sọ fáwọn ẹ̀ṣọ́ pé kí wọ́n ti géètì mọ́ igbákejì mi- Akeredolu Gomina ipinlẹ Ondo Rotimi Akeredolu ti fesi si fidio kan to lu ori ayelujara pa ninu eyi ti awọn ẹṣọ kan ti dina mọ igbakeji gomina Ondo, Agboola Ajayi lati jade kuro nile ijọba.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, #Queen Dihya: Obinrin tó gbógun tàwọn agbésùnmọ̀mí ni Algeria O ni oun nii lọkan lati pada si abule ti ṣọja Salikawa n gbe nigba naa lati da seri aiya fun un nitori pe o yẹyẹ olori abule oun.
"Oríṣun àwòrán, Instagram O fikun pe ""awọn obi mi ko tako awada ti mo n ṣe lori ayelujara, koda wọn n gbaruku ti mi ni, gbogbo ohun ti mo ba fẹ, si ni wọn maa n ba mi fẹ."
"Ìyàwò lárìnlọọ̀dù mi pè mí ní akálòlò ni mo ṣe paa - Afurasí ""Ambode, wá jẹ́jọ́ lórí ọkọ̀ BRT 5000 to ló fi ₦45b rà, àmọ́ 820 péré ló kó wá"" O tẹsiwaju pe, awọn Ọlọọpa yoo ko ipa pataki lati ṣe atilẹyin fun idasilẹ ẹgbẹ alaabo tuntun naa ni ilẹ Yoruba, eyi ti yoo mu ki iwa ọdaran dinku lawujọ wa."
Ṣugbọn ní àkókò yìí, ó pàṣẹ fún gbogbo eniyan ní ibi gbogbo láti ronupiwada.
Sááju nínú osù yìí àjọ EFCC ti mú àwọn kọmisọnà mẹ́fà àti àti àwọn aláṣẹ ijọba ní ìpínlẹ̀ Kwara nítori wọn dari owo to to bílíọ̀nu kan náírà sí ọ̀nà ìbòmiran ńgbà ti ók u ọsẹ̀ kan ti ìdìbò ààrẹ àti ti ilé ìgbìmsọ̀ asofin àgbà yóò wáye Ní ti Amosun, ìwádìí tirl kò ṣẹ̀yìn ìwé ẹsun ti àwọn ẹgbẹ́ kan ti a mọ si Committee for the protection of Peopl's Mandate kọ ránṣẹ́ lóri bi Amosun ṣe ṣe bílíọ̀nu mẹ́rìn naira owo àwọn àgbe ní ìpínlẹ̀ Ogun mọ́ku-mọ̀ku Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Midcharki Midfieldki n lọ kuro ni awọn agbalagba ilẹ Afirika Wydad Casablanca, lakoko ti El Yamiq ti wa lori awọn iwe ti Raja.
S Embassy O ni o wu gbogbo banki lati ṣatunṣe si bi awọn eniyan ṣe n ṣe owo naira Naijiria jakujaku.
Eyi ko sẹyin ija oṣelu to ti waye ri laarin oun ati gomina ipinlẹ Ogun nigba naa, Olabisi Onabanjo.
11 Nítorí, kíyèsíi, Olúwa Olùràpadà rẹ jìyà ikú nínú ẹran ara; nítorínáà òun jìyà fún ìrora gbogbo ènìyàn, kí gbogbo ènìyàn lè ronúpìwàdà kí wọ́n sì wá sí ọ̀dọ̀ rẹ̀.
 ( 11 ) nìkan ni a lé rì nínú ( 9 ) ;.
’’O tun salaye pe ijọba naa n se ojuse rẹ lori eto agbẹ nipa pipese ida ogun ninu ọgọrun un lọdun ati  ida mẹwaa ninu ọgọrun un, to wa nibi owo epo rọbi.
Ṣé Pochettino lè gba ife ẹ̀yẹ UEFA Champions League tí PSG ń wá fún wọn?
Ìdáhùn rẹ̀ yà wọ́n lẹ́nu, wọ́n bá dákẹ́.
Nígbà tí bàbá mi àti ẹbọra náà simi tán, tí wọ́n jẹun ìyàwó wọn tán, wọ́n tún bẹ̀rẹ̀ sí ìjà wọn.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Hepatitis: A kò leè kóo nípa dídìmọ́ ara ẹni Bawo ni igbẹbi Arẹmọ Ọọni Ile Ifẹ ṣe wa ṣẹlẹ?
Mò ń ranti nígbà gbogbo,ọkàn mi sì ń rẹ̀wẹ̀sì.
to n waye lorile ede naa nipa bi o se n se ijoba re.
Sedekaya wolii, ọmọ Kenaana bá súnmọ́ Mikaaya, ó gbá a létí, ó ní, “Ọ̀nà wo ni Ẹ̀mí OLUWA gbà fi mí sílẹ̀, tí ó sì ń bá ìwọ sọ̀rọ̀.
Paulu ati Banaba wá fi ìgboyà sọ pé, “Ẹ̀yin ni a níláti kọ́ sọ ọ̀rọ̀ Ọlọrun fún.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ondo: Iya lu ọmọ pa nítori ẹgbẹ̀rún mọkànlélógun Naira Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Ondo: Iya lu ọmọ pa nítori ẹgbẹ̀rún mọkànlélógun Naira 29 Sẹ́rẹ́ 2019 Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí kan sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
Ẹ̀yin òṣèrè tíátà, ẹ ní ṣùúrù de àsìkò Ọlọ́run, ẹ máṣe kánjú kọjá kádàrá - Madam Ṣajẹ Ọdọọdún làwọn ọmọ ònilẹ̀ ń dà wá láàmú ní Soka, kí Sunday Igboho tó gbà wá sílẹ̀ - Àwọn olùgbé Soka Bode George ni abosi lo wa n bẹ ti ipinlẹ Eko ko ba ṣe Amọtẹkun lẹyin ti gbogbo awọn gomina ipinlẹ Yoruba yoku ti fọwọ si agbekalẹ eto naa.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ojojúmọ ní mọ ń kẹ́kọ̀ọ́ lára ọmọ mi to jẹ akanda Ilé ìgbìmọ àṣofin ti lọ fun ìsinmi ránpẹ lati pada ni ọjọ kẹsan oṣú kẹrin láti ráye moju to àwọn iṣẹ́ ìgbìmọ tẹ̀ẹ́kóto tóń móju to ìsúna owó.
Lẹ́tà náà tọ́ka sí ti àríyànjiyàn Abala 66(d) tí ó sọ nípa òfin ìbánilórúkọjẹ́ tí àwọn aláṣẹ ń lò láti to fi ẹ̀sùn ìtakò, ìjìjàgbara, àti akọ̀ròyìn.
Kí ló mú Gómìnà lè àwọn alága lọ sílé Lọ́jọ́ ìṣẹgun ní Gómìnà ìpínlẹ̀ Kwara,Abdulrahman Abdulrazaq fún gbogbo àwọn alága ijọba ìbílẹ̀ Mẹ́rẹ̀rìndínlógun àti àwọn ìgbimọ míràn, ni ìwé lọ gbé ile rẹ̀ gẹ́gẹ́ bi abá ti àwọn ọmọ ile ìgbìmọ aṣofin dá.
Saaju ikede agbabọọlu to ku oju iwọn julọ lagbaye ni wọn ti kede olukọni ẹgbẹ agbabọọlu Liverpool, Jurgen Klopp ni wọn yan gẹgẹ bii olukọni to pegede julọ.
Àṣírí ayédèrú ibùdó atúnwàṣe tú n'Ilorin, èèyàn 108 bọ́ yọ!
Ileefowopamọ ọhun nikan lo wa ni ilu Iso-Ani.
Orile-ede Cameroon sajoyo ayeye odun mẹ́rìndínláàdọ́ta igbominira lojo Aiku(Sunday), laarin gbogbo rogbodiym ti orile-ede ohun n koju ni eka ila oorun ati iwo oorun Orile-ede naa.
Lẹ́yìn èyí, Jesu fúnrarẹ̀ rán wọn lọ jákèjádò ayé láti kéde ìyìn rere ìgbàlà ayérayé, ìyìn rere tí ó ní ọ̀wọ̀, tí kò sì lè díbàjẹ́ lae.
” Wọ́n bá rán àwọn aadọta ọkunrin lọ, wọ́n wá Elija ní àwọn orí òkè ati àwọn àfonífojì fún ọjọ́ mẹta, ṣugbọn wọn kò rí i.
Ṣugbọn lode oni, awọn ọmọ ẹgbẹ yi lawọn fasiti ti yi ipinu pada.
Koda wọn pe fun titi fun titi oriko ajọ naa jakejado Naijiria.
RUGA: Gómìnà ìpínlẹ̀ Kano ní gbogbo Fulani lè máà bọ̀ lọ́dọ̀ àwọn
O ni eyi ni yoo fawọn ọmọ awọn to yoo maa ṣiṣẹ nibẹ lanfaani lati fi ọmọ wọn sile iwe.
Eto lati yọ mi nipo ti wọn n ṣe yii n fa ibinu, nnkan to buru jai ni wọn n ṣe, Trump lo sọ bẹẹ.
Nígbà náà ni Ọlọrun fi sí mi lọ́kàn láti ranṣẹ pe àwọn ọlọ́lá jọ, ati àwọn olórí, ati àwọn eniyan yòókù, láti wá ṣe àkọsílẹ̀ orúkọ wọn ní ìdílé ìdílé.
Oun ti rí omijé rẹ̀, òun óo sì fi ọdún mẹẹdogun kún ọjọ́ ayé rẹ̀.
O ti rí i, OLUWA, má dákẹ́.
"Oríṣun àwòrán, @Naija_PR Salami ṣalaye fun awọn oniroyin pe ""o kọkọ sọ fun baba rẹ pe awọn gbọmọ-gbọmọ lo ji aburo rẹ ọhun gbe ko to jẹwọ pe ọmọ naa wa ninu kanga."
“Ẹ ṣe akiyesi pé mò ń ran yín lọ bí aguntan sáàrin ìkookò.
Lai Mohamed so pe, ijoba le se aseyori ninu eyi, nipa mimu eto ipolowo oja ori ero amohun-maworan wa ni ibamu pelu sise amulo ilana to dara awon orile-ede yoku lagbaye.
Ọgbẹni Shamsutdinov pa oṣiṣẹ meji pẹlu awọn akẹgbẹ rẹ ti wọn jọ jẹ ọmọ ogun mẹfa.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Muhammadu Buhari: Amòfin Adebayo wá kábàámọ̀ pé ọ̀pọ̀ nǹkan ni wọ́n ń tọwọ́ òṣèlú bọ 9 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 10 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Oríṣun àwòrán, @NGRPresident Oni Ọjọbọ lo yẹ ki Aarẹ Muhammadu Buhari farahan niwaju ijoko ile asofin apapọ fun ilẹ Naijiria.
” Ìdí nìyí tí wọ́n fi ń pe ilẹ̀ náà ní Kabulu títí di òní olónìí.
Sugbọn ọpọ oju oro ati osibata to n gba oju awọn odo to wa nilu Eko kan, to fi mọ awọn odo to wa lawọn agbegbe eti okun ti di irawọ ọsan to n ba awọn agba lẹru bayii, to si n di awọn apẹja ati igboke-gbodo ọkọ lọwọ lorilẹede Naijiria Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, N jẹ ẹmọ pe odo nla lo wa ni abẹ afara yii tẹlẹ, ti wọn n pe ni odo Merille, lorilẹede Kenya, sugbọn ẹẹrun lo mu ki odo naa gbẹ, ti ọkunrin kan si n mu Rakunmi rẹ rin kọja lori odo to ti gbẹ naa.
Ẹsun oniga-mẹrinla ti wọn fi kan an naa ni pe o gba owo ẹburu to le ni ọọdunrun miliọnu naira, N300milion.
O le ni miliọnu eniyan ti wọn ti fesi si ọrọ naa lati igba ti aṣiri rẹ tu pe ọbun paraku ni lati ọwọ iya onile rẹ, Madam Chen, Ẹ wo àwọn ìlúmọ̀ọ́ká olórin, òsèré tó ti sẹ̀wọ̀n rí!
'Kò sí ohun tó burú nínú bí Ajimobi ṣe dá Yewande tó pa ọkọ rẹ̀ sílẹ̀' Facebook yóò bẹ̀rẹ̀ ìnáwó orí ayélujára Àti lọ s'Amẹrika ti yàtọ̀ báàyí Kí ló kan AS Roma àti ìrẹsì jọ̀lọ́fù?
Ọga Agba Ajọ EFCC, Ibrahim Magu sọ wi pe igba akọkọ ni yii ti awọn yoo fi awọn asebajẹ jofin, eleyii ti gomina mẹta si wa ninu wọn.
Oríṣun àwòrán, @lasemasocial Àkọlé àwòrán, Ọ̀pọ̀ ẹ̀mí sọnù sínú Ọkọ̀ ojú omi to dànù l'Eko Ọkọ̀ ojú omi dànù ní Kwara, ọmọ́dé 9 ba rìn Ìṣẹ̀lẹ̀ Bakana: àwọn tórí kó yọ fẹ́ bẹ̀rẹ̀ ètò ìrànlọ́wọ́ Ọ̀pọ̀ ẹ̀mí sọnù sínú ilẹ̀ rírì Indonesia A kò fipá mú ẹnikẹ́ni láti dá Ruga, aàgọ́ Fulani sílẹ̀ -Iléeṣẹ́ aàrẹ Eeyan mẹrin ni wọn ribi dooola amọ oku mẹta ni o ti foju han pe o ba iṣẹlẹ naa lọ.
Beeriṣeba ni wọ́n ti ń ṣe adájọ́.
Oríṣun àwòrán, Twitter Àkọlé àwòrán, Awọn ọdọmọde meji yii se bẹbẹ ninu ere asayipo ọun Nigba ti o n sọ̀rọ̀ nibi ayẹyẹ ọun, Gomina ipinlẹ̀ Eko, ọ̀gbẹ́ni Akinwumi Ambode sọ pe, awọn o gbiyanju lati rii pe akopa ọmọ orilẹede Naijiria lo gbegba oroke ninu ididje ti ọdun to n bọ̀.
OLUWA bá sọ fún Mose pé, “Mú Joṣua ọmọ Nuni, ẹni tí Ẹ̀mí èmi OLUWA wà ninu rẹ̀, gbé ọwọ́ rẹ lé e lórí, 
OLUWA tí ó la ọ̀nà sí ojú òkun,tí ó la ọ̀nà lórí agbami ńlá;
Ope pataki fun ami-ayo ti awon atamatase iko ohun Akinkunmi Amoo ati  Olakunle Oluwasegun gba wole, eleyi ti o ran iko naa lowo lati pegede sinu asekagba idije naa ti yoo waye lojo abameta(Saturday) pelu orile-ede Ghana, leyin ti Ghana gbo ewuro si iko agbaboolu Ivory Coast loju pelu ami-ayo meji sookan(2-1).
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ijinigbe Dapchi: Awọn olori ileesẹ aabo tẹdo si Dapchi 2 Ẹrẹ̀nà 2018 Oríṣun àwòrán, @NigAirForce Àkọlé àwòrán, Aarẹ Buhari ti seleri wi pe gbogbo ọna nijọba yoo gba lati sawari awọn akẹkọ Dapchi Ijọba apapọ orilẹede Naijiria ti ko gbogbo awọn olori ileesẹ ologun lorilẹede Naijiria lọ si ẹkun ila oorun ariwa orilẹede yii lati tẹsiwaju nidi wiwa awọn ọmọ ileewe girama ilu Dapchi nipinlẹ Yobe tawọn agbebọn Boko haram ji gbe.
Ohun tí ẹnìkọ̀ọ̀kan tí o bá kà yóo san ni: ìdajì ṣekeli, tí a fi ìwọ̀n ilé OLUWA wọ̀n, (tí ó jẹ́ ogún ìwọ̀n gera fún ìwọ̀n ṣekeli kan), ìdajì ṣekeli náà yóo sì jẹ́ ti OLUWA.
“Ẹ ka iye àwọn ọmọ Israẹli, àwọn tí wọ́n tó ẹni ogún ọdún tabi jù bẹ́ẹ̀ lọ, tí wọ́n tó lọ sójú ogun, gẹ́gẹ́ bí àkọsílẹ̀ wọn ní ìdílé-ìdílé.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Premier League: Ta ni yóò gba Premier League láàrin Man City àti Liverpool?
Ṣugbọn nisinsinyii iṣẹ́ ìsìn ti Olórí Alufaa wa dára pupọ ju ti àwọn ọmọ Lefi lọ, nítorí pé majẹmu tí ó jẹ́ alárinà fún dára ju ti àtijọ́ lọ, ìdí ni pé ìlérí tí ó dára ju ti àtijọ́ lọ ni majẹmu yìí dúró lé lórí.
O si tẹ iwe tuntun kan jade lọdun 1950, to pe akọle rẹ ni 'Female Bonaparte', nibi to ti fagile gbogbo nkan to kọ nipa iwadii rẹ tẹlẹ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Divorce: Ilé ẹjọ́ tú ìgbéyàwó ọdún mọ́kànlá ká nítórí pé ìyàwó fí ìbálòpọ̀ dun ọkọ rẹ̀ 12 Bélú 2020 Oríṣun àwòrán, Getty Images Ìléẹjọ́ tú ìgbéyàwo'ọdún 11 ká nítórí ìyàwó fí ìbálòpọ̀ dun ọkọ rẹ̀ Ileejọ magisreti ni ilu Ibadan ti tu igbeyawo ọdun mọkanla ka laarin Nurudeen Mabinuori ati Zainab lori ẹsun pe iyawo n fi ibalopọ dun ọkọ rẹ.
Èèyàn 82 tún ti ní COVID-19 ní Nàìjíríà lọ́jọ́ Ajé Esi ayẹwo coronavirus lati ipinlẹ mọkanla ti ajọ NCDC fi sita ni ọjọ Aiku.
Aṣofin Ṣẹgun Olulade, Alaga Igbimọ Tẹẹkoto fun ọrọ Ilera ninu Ile Igbimọ Aṣofin naa, ti o ṣaaju ijiroro lori abadofin naa sọ pe erongba abadofin naa ni lati daabo bo ẹtọ awọn alarun ọpọlọ.
Ilu Iwo ló yẹ kó kọ́kọ́ jẹ́ Sultan àkọ́kọ́ ní Nàìjíríà - Oluwo WAEC gbé èsì ìdánwò WASSCE jáde Etí ìjọba Buhari di sí ìmọ̀ràn àwọn ará ìlú -Jiti Ogunye Transfer Window: Pogba, Maguire, Bale, Neyman, báwo ni nkan ṣe ń lọ?
Oluwo tẹsiwaju wipe, eleyi yoo mu ki o rọrun fun tọmọde tagba lati sun mọ awọn egungun naa, dipo sisa fun wọn gẹgẹ bi nnkan ibẹru.
O dije fun ipo asoju labe asia ẹgbẹ oselu PDP, lẹyin to kuro ninu ẹgbẹ APC.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Obasanjo: Buhari ní àìlera lẹ́mìí, lára, àti lọ́kàn.
Aare ajo FIFA ni apero to waye nilu Eko yii yoo mu atunse ba odiwon gbendeke ojo ori awon olukopa ninu ididje.
Agbẹnusọ ileeṣẹ ọlọpaa ni Eko, Bala Elkana ni awọn ọlọpaa naa ti n jẹjọ bayii bi kọmiṣọna ọlọpaa Zubairu Muazu si ṣe pàṣẹ pe ki wọn wa ọkan lara wọn, Insipekitọ Dania Ojo, to fẹsẹ fẹ lẹyin ti iṣẹlẹ naa ṣẹlẹ.
Dalung so oro naa di mimo lasiko to n  ba awon akoroyin soro, leyin ayeye isiso loju eegun idije ere idaraya abele ti yoo waye nilu Abuja lojo Aje (Monday).
“Nisinsinyii, OLUWA Ọlọrun wa, ìwọ tí o kó àwọn eniyan rẹ jáde ní ilẹ̀ Ijipti pẹlu agbára ńlá, nítorí orúkọ rẹ tí à ń ranti títí di òní, a ti ṣẹ̀, a sì ti ṣe nǹkan burúkú.
Bí àwọn tí ń kórè èso àjàrà bá bẹ̀rẹ̀ sí kórè,ṣebí wọn a máa fi èso díẹ̀ díẹ̀ sílẹ̀?
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Kathleen Thomas wẹ la agbami Bristol ja Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Kathleen Thomas wẹ la agbami Bristol ja 8 Ẹrẹ̀nà 2018 Kathleen Thomas wẹ la agbami Bristol ja nilẹ Gẹẹsi.
Olùrànlọ́wọ́ pàtàkì fún ọ̀rọ̀ ibojì òkú, àti àwọn ipò òṣèlú mìíràn tó jẹ́ kàyééfì ní Nàìjíríà NCDC kéde èèyàn 437 míràn tó ṣẹ̀ṣẹ̀ lùgbàdì Covid-19 ní Nàìjíríà, 142 gbàwòsàn Wo ohun tí Adájọ́ ṣe sí àṣùwọ̀n ìfowópamọ́sí Wòlíì Sotitobire Buruji Kashamu jẹ́ ènìyàn tó nífẹ̀ aráàlú- Gómínà Dapo Abiodun Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Teach your children Yoruba: Wo àwọn òyìnbó tó ń kẹ́kọ̀ọ́ èdè Yorùbá ní Michigan, America Ki lo ti ṣẹlẹ sẹyin?
Ẹsa awọn aworan to rẹwaju kaakiri Arfika l'ọsẹ yii
Ile-ise ti o n ri si isiro lorile-ede Naijiria, National Bureau of Statistics (NBS), ti so bayi pe, ile-ise amuna wa lorile-ede Naijiria ti pese megawasi egberun lona marundinlogorun 94,627 (MWh) ni kota kerin  odun 2017.
"Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Coronavirus in Nigeria: Ẹ wo bí ẹ ṣe lè ṣe ""hand sanitizer"" nínú ilé yín Nibayii, o ti di eeyan mẹtadinlọgọrun un (97) to ti ni aarun naa lorilẹede Naijiria."
Nítorí pé ó ti sọ bẹ́ẹ̀,ó ti rò ó dáradára, kò tíì jáwọ́ ninu rẹ̀,bẹ́ẹ̀ ni kò ní yipada.
48 Bẹ́ẹ̀ni, èyí sì ni ìgbàgbọ́ wọn—pé ìhìnrere mi, èyí tí mo fi fún wọn pé kí wọn lè máa wàásù rẹ̀ ní ọjọ́ ayé wọn, lè wá sí ọ̀dọ̀ àwọn arákùnrin wọn àwọn ará Lámánì, àti bákannáà gbogbo àwọn tí wọn ti di ara Lámánì nípa ìyapa wọn.
Kí ló dé tí àwọn tí ń bọ Milikomu ṣe gba ilẹ̀ ẹ̀yà Gadi,tí wọ́n sì fi àwọn ìlú Gadi ṣe ibùjókòó?
Abimeleki bá pe Abrahamu, ó bi í pé, “Kí ló dé tí o fi ṣe wá báyìí?
Ṣugbọn, awọn orilẹede wo lo wa ninu ewu ju awọn to ku lọ?
“O ti rí ìpọ́njú àwọn baba wa ní ilẹ̀ Ijipti o sì gbọ́ igbe wọn ní etí Òkun Pupa, 
Mo ti fòpin sí òṣé ati ìjìyà tí Babiloni kó bá gbogbo eniyan.
ni awon adari eto oselu, awon ajo ti ki i se ti ijoba ati egbe awon ọdọ.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Orílẹ̀-èdè Zimbabwe léti bèbè dídàwó lẹ́ẹ̀kan si Nigba ti wọn n sọrọ nileewosan lẹyin ohun ti wọn ni awọn la kọja, awọn obinrin ọhun ni awọn ẹṣọ orilẹede kan lo fiya jẹ awọn.
Wíwó ni kí o wó àwọn ilé oriṣa wọn lulẹ̀, kí o sì fọ́ gbogbo àwọn òpó wọn túútúú.
Bẹẹ, ọmọde gbọn, agba gbọn la fi da Ilẹ Ifẹ ni ọrọ naa, ohun ti ọkunrin ko le ri ṣe, o ṣeeṣe ti a ba fun obinrin laaye ko ṣe e ju ohun ti a lero lọ.
Gbogbo àwọn nǹkan yòókù tí Abijamu ṣe wà ninu Ìwé Ìtàn Àwọn Ọba Juda.
Wo ọ̀nà láti gbógun ti àìsàn Ibà lásìkò yìí Àgbáríjọpọ ẹgbẹ OPC, fijiláńté VGC, Agbẹkọyà ti bẹrẹ ètò aàbò ní ilẹ Yorùbá Nàìjíríà ní ìgboyà láti kojú ilẹ̀ South Africa - Foluṣọ Philips Ilééṣẹ́ Facebook leè mọ ìgbà tí àwọn tó wà lójú òpó wọn ń ní ìbálòpọ̀ Ojọgbọn Osagie fidiẹ mulẹ pe awọn eniyan marundinlọgọta o ba arinrinajo ara Italy naa rin ni wọn ti n ṣe ayẹwo fun laisko yii.
Awọn olowo nọbi naa labẹ aṣia ẹgbẹ kan ti wọn pe ni Self Made Women SMW, ṣalaye lati ẹnu alaga wọn ni ipinlẹ Anambra, arabinrin Uto Nwanyi fi ẹsun kan ijọba apapọ pe ko nifẹ araalu rara ati pe inira ẹkunwo naa yoo ba awọn finra pupọ nitori pe yoo pa iye awọn to n na ohun ti wọn n ta wo.
Saaju igba naa lo ti ba ile ise Quicksilver Courier Company lorileede America sisẹ gẹgẹ bi osisẹ́ fun igba ranpẹ.
"Ọmọ bíbí ìlú Oyo ni mí, bi mo ṣe jáde kúrò nílé ẹ̀kọ́ alakọbẹrẹ, ní mo darapọ mọ ère tíátà ni ọdọ ọga mi n'ilu Oyo, ibẹ sì ni mo ti pàdé Afonja Olaniyi, tá mọ sì Sanyeri.
Nínú àtẹ̀jáde nàá tó tẹ ìwé ìròyìn Punch lọ́wọ́, wọ́n ni ọjọ́ nàá yó le fún àwọn aráàlú ní ànfàání láti ṣe àjọyọ̀ ọjọ́ ìṣèjọba àwaarawa.
Wọ́n pada wá, wọ́n wọ inú àgọ́ mìíràn, wọ́n tún ṣe bákan náà.
Báyìí náà ni ó fi ògo ńlá rẹ̀ hàn pẹlu fún àwọn tí ó ṣàánú fún, àní fún àwa tí ó ti pèsè ọlá sílẹ̀ fún.
Joe Biden lo bori ni Wisconsin pẹlu ibo to lẹ ni 20,000 ju ti aarẹ Trump lọ.
Ẹwẹ , ijọba apapọ Naijiria ti sun gbedeke ti igbimọ to n mojuto pipalẹmọ oju ọna Apapa mọ gbe kalẹ siwaju si .
Àjọ Ìlera Àgbáyé ( who ) gbani nímọ ̀ ràn pé kí a fún gbogbo àwọn ọmọdé tí n gbé ní àwọn agbègbè ibi tí àrùn náà ti wọ ́ pọ ̀ ní àjẹsára náà .
Àbí ó ha fẹ́ lọ sí ààrin àwọn ará wa tí ó fọ́nká sí ààrin àwọn Giriki ni?
Ẹ̀yin tí ẹ̀ ń yọ̀ nisinsinyii, ẹ gbé,nítorí ọ̀fọ̀ óo ṣẹ̀ yín, ẹ óo sì sunkún.
Láti Babiloni ni Ẹsira tí à ń wí yìí ti dé.
Ìfojú iyì àwọn obìnrin àti ìtasẹ̀ àgẹ̀rẹ̀ sí òfin ẹ̀tọ́ sí ayé iyì fún gbogbo ọmọ ènìyàn.
Gbogbo apẹẹrẹ lo si fihan pe Niyi fẹ ẹ fi oun ṣe oogun owo ni.
Aarẹ tẹlẹri Olusegun Obasanjo, ti rọ osisẹ Ajọ INEC Amina zakari lati kọwe fi ipo rẹ silẹ gẹgẹbi kọmisọnna gbogboogbo fun Ajọ INEC ninu idibo 2019.
Ní òwúrọ̀ ọjọ́ keji, nígbà tí Paṣuri tú Jeremaya sílẹ̀ ninu ààbà, Jeremaya wí fún un pé, “Kì í ṣe Paṣuri ni OLUWA pe orúkọ rẹ, ìpayà lọ́tùn-ún ati lósì ni OLUWA pè ọ́.
Orí ọmọ yìí ni wọn fi ransẹ si Kurunmi, láti pa asamọ fún pé ó ti fidi rẹmi nínú ogun náà, ibanujẹ si ni èyí jẹ fun Kurunmi torí ọmọ rẹ maraarun lo bá ogun náà lọ.
 Awon iko yii fun Pyongyang nil eta lati owo Aare Moon Jae-in to ti fi pe Pyongyangfun ijiroro miran.
Man U fi bọọlu kilọ fun Man City ni ẹẹmelo kan, ki wọn o to fi titete ronu gba bọọlu kan si awọn Man City.
 o ti je alakoso eto ibanisoro labe ijoba aare jerry rawlings .
OLUWA ṣí iranṣẹ náà lójú, ó sì rí i pé gbogbo orí òkè náà kún fún ẹṣin ati kẹ̀kẹ́ ogun, iná sí yí Eliṣa ká.
Lara awọn aṣeyọri rẹ ni bo ṣe ba ajọ UEFA Federation ṣiṣẹ nilẹ Yuroopu.
Ọjọ kẹfa oṣu kọkanla nile ẹjọ ti paṣẹ pe ki ajọ DSS fi Ṣowore ati Bakare silẹ lahamọ, ṣugbọn DSS kọ eti ikun si aṣẹ ile ẹjọ.
ṣugbọn Israẹli tí ó ń lépa òfin tí yóo mú wọn rí ìdáláre gbà níwájú Ọlọrun kò rí irú òfin bẹ́ẹ̀.
Wọn gbe ọkọ bọgini Hyundai Tuscon fun un, pẹlu sọwedowo miliọnu marunlelogun Naira, eroja amule ṣeringindin to to miliọnu mẹta fun un.
Ẹ sọ pé ẹṣin tí ó lè sáré ni ẹ óo gùn.
Ǹ jẹ́ o mọ̀ pé ìdọ̀tí rẹ le è sọ ẹ́ di olówó?
Oríṣun àwòrán, @joeshooar Ikoro lọ sọ ọrọ naa ninu ifọrọwerọ pẹlu BBC Yoruba.
Ó wí pé, “Ọlọrun ti mú ẹ̀gàn mi kúrò,” ó sọ ọmọ náà ní Josẹfu; ó ní, “Kí OLUWA má ṣàì fún mi ní ọmọkunrin mìíràn.
Kò ku ẹyọ ọmọ kan àfi èyí àbíkẹ́yìn tí ń jẹ́ Ahasaya.
Wo díẹ lára ẹkọ tí àwọn Mùsùlùmí leè kọ lásìkò Ramadan tó ń wáyé nínú àrùn Coronavirus Bí ilumọọka agbabọọlu Drogba ṣe dáwọ ogun dúró ní Ivory Coast Coronavirus: Kíni àwọn àmì tuntun tó n fihàn?
Ṣugbọn nígbà tí Ẹ̀mí òtítọ́ tí mo wí bá dé, yóo tọ yín sí ọ̀nà òtítọ́ gbogbo.
Njẹ́ mo ti wí ní ìgbàkan rí pé iPhone ni èmi gan-an alára ń lò.
Àwọn ọmọkunrin meji ni Eberi bí, orúkọ ekinni ni Pelegi, nítorí pé ní ìgbà tirẹ̀ ni ayé pínyà, orúkọ ekeji ni Jokitani.
Wọ́n yí orúkọ wọn po kí àwọn ènìyàn má baà máa rò pé ìbátan àwọn ọlọ́ṣà náà ni wọ́n.
Shehu ni oun nigbagbọ pe awọn oṣiṣẹ mẹfa naa yoo gba ominira laipẹ lọwọ awọn ajinigbe.
Àkọlé àwòrán, Ó nú rúgbó bọ̀!
E̩nì kò̩ò̩kan ló ní è̩tó̩ láti kúrò lórílè̩‐èdè yòówù kó jé̩, tó fi mó̩ orílè̩‐èdè tirè̩, kí ó sì tún padà sí orílè̩‐èdè tirè̩ nígbà tó bá wù ú.
Kii ṣe bii tawọn adari mii lẹkun naa, isejọba tirẹ ggẹ bi aarẹ bori ifẹhonu han awọn ara Arab lodi si ijọba.
Ẹ múra nígbà gbogbo láti dáhùn bí ẹnikẹ́ni bá bi yín ní ìbéèrè nípa ìrètí tí ẹ ní.
ìlú Eko kọ́ ló léwu jùlọ láti gbé lágbàáyé- Ìjọba Eko Kí ni pàtàkì nọ́mbà 615 láàrín àwọn èèyàn ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ̀ Gẹgẹ bi asọfin, o ja fun ẹtọ awọn ọmọ Naijiria to wa lati oke ọya ni ifọwọsowọpọ pẹlu ẹnikeji rẹ, Alhaji Ahmadu Bello.
Mẹ́rìn nínú àwọn tro ń jó fún gbájugbajà olórin náà ló jẹ́rìí nilé ẹjọ pe ó fi ipá ba àwọn lòpọ̀ láàrín ọdun 2002 si 2006.
Ninu awọn ilana ti wọn gbe kalẹ leleyi to nii ṣe pẹlu ṣiṣe ayẹwo boya eeyan larun Covid-19.
Asọ ẹgbẹjọda si ni awọn mejeeji maa n wọ lasiko kan, eyi ti ko yọ awọn ayaba yoku silẹ nigba miran.
Wọn sọ eyi nitori pe a ti ri apẹrẹ ninu ẹgbẹ APC nibi ti awọn to kan si Aarẹ lati ba wọn wa wọrọkọ fi ṣada si ọrọ wọn ko mu ababọ daadaa pada wa sile.
Eyi ti yoo si maa fi rinlẹ lọkan wọn pe ki wọn dibo fun ẹgbẹ oṣelu tiwọn.
Seun Egbegbe lo ọdún méjì àti oṣù méje lẹ́wọ̀n láì tìí san béèlì rẹ̀ Àwọn ojú oge Yollywood t'ọ́jà wọ́n ṣì ń tà wàràwàrà Ìjọba ìpínlẹ̀ Oyo kò mọ̀ si Ìyá àti Bàbálọ́jà tí wọ́n yàn- Kọmíṣọ́nnà Okòwò Irú ọjà wo ni wọ́n kò ti lè yan Ìyálọ́jà?
’ Èyí èkínní sì tún dáhùn, ó ní, Bẹ́ẹ̀ ni, ìgbà tí ọ̀gá tóó sùn tán lánàá ni obìnrin náà tó jáde lọ, àkùkọ sì kọ kí ó tóó dé ní òwúrọ̀ yìí.
Pagieli ọmọ Okirani, kó akọ mààlúù meji ati àgbò marun-un kalẹ̀, pẹlu òbúkọ marun-un, ati ọ̀dọ́ àgbò marun-un, ọlọ́dún kọ̀ọ̀kan, fún ẹbọ alaafia.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Irun gígẹ̀ kọjá orí fífá lásán Bandile, ọmọbinrin orileede South Africa yii ni , Nigbakugba ti mo ba ti yọ irun ti mo lẹ mọ ori mi, ṣe ni maa ni ki wọn ba mi fi ọṣẹ fọọ."
Iyabo Ojo gé okùn àjọṣepọ̀ rẹ̀ pẹ̀lú olóṣèlú nínú ẹgbẹ́ APC ati PDP Mo ti tọrọ aṣọ àti yẹtí etí rí, kí n tó leè ṣe àwo orin - Tope Alabi 'Bí ìgbà èèyàn bọ́ aṣọ lára àgbàdo lọ̀rọ̀ àwa apálórí' Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí US presidential election 2020: Kíni Kọ́lẹ̀jì ìdìbò, àwọn ìpińlẹ̀ tó le gbé olùdíje wọlé àti àwọn ǹkan ti o yé kí o mọ̀ nípa ìdìbò ilẹ̀ Amerika.
Ilana ele lori owooya lorilẹede Naijiria lo fẹrẹ le kenka julọ ni ilẹ Afrika.
Mo ti buwọ́lu àdínkù owó orí nítorí ìrọ̀rùn àwọn èèyàn ìpínlẹ̀ Ogun lásìkò Covid 19- Dapo Abiodun Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, BBC Africa Eye: ìwádìí ìkọ̀ks BBC fihàn pé àwọn kan ń jí ohun èèlò ìdáàbòbò ìjọba tà nígbo Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Nítorí Olórí Alufaa tí a ní kì í ṣe ẹni tí kò lè bá wa kẹ́dùn ninu àwọn àìlera wa.
Ileeṣẹ ICPC sọ nibi apejọ ilaniloye kan ninu osu kejila ọdun 2018 pe ibo riria jẹ ijamba fun ilana democrasy.
Awon a-ji-ja-gbara  so pe eniyan ogójì lo ti padanu ẹmi wọn nibi isẹlẹ  naa.
a fúnni ní ìwé-àṣẹ àkọ ́ kọ ́ fún àjẹsára ṣegede ní ọdún 1948 ; ṣùgbọ ́ n èyí kò ṣiṣẹ ́ fún ìgbà pípẹ ́ .
rọrun lati maa san fun awon osise.
Wọ́n gbé òkú wọn lọ sí Ṣekemu, wọ́n sin wọ́n sinu ibojì tí Abrahamu fowó rà lọ́wọ́ àwọn ọmọ Hamori ní Ṣekemu.
O ni oun kọ lati fọwọ lẹran lori ọrọ yii ati p\\w ohun ti ẹgbẹ n fẹ ni ki ajọ NBC tete yi ipinnu rẹ pada.
Ọlọrun kó Naijiria yọ lọwọ ijamba ojiji ti ko bà fa ọ̀fọ̀ l'Ọjọbọ Ijamba ojiji kan ni Ọlọrun koore rẹ ni orilẹ-ede Naijiria nigba ti baalu kekere to gbe igbakeji aarẹ, Ọjọgbọn Yẹmi Ọsinbajo, deede bà silẹ pada ni kete to gbera tan.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù #Adewura Latifa Bello: Àwọn ará àdúgbò sọ nípa ihò yìí 28 Èbibi 2019 Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'A sọ fún ọlọ́kadà pé omi kún, omi kún, ṣùgbọ́n ó kọ etí ikún' Agbegbe Gowon Estate ni Iyana Ipaja ni iroyin sọ pe olóògbé Adediwura Lateefat Bello ti kagbako iṣẹlẹ yii.
Ọ̀nà wọn tọ́ ju tìrẹ lọ, nítorí náà, ó yẹ kí ojú tì ọ́, nítorí o ti mú kí àwọn arabinrin rẹ dàbí olódodo lẹ́gbẹ̀ẹ́ rẹ.
Àwọn tí ó ti ṣe rere yóo jí dìde sí ìyè, àwọn tí ó ti ṣe ibi yóo jí dìde sí ìdálẹ́bi.
Bí mo bá rú òfin, tabi bí mo bá ṣe ohun tí ó yẹ kí á dá mi lẹ́bi ikú, n kò bẹ̀bẹ̀ pé kí ẹ má pa mí.
’’Ile-ise to n ri si isakoso eru ati pasipaaro nipinle naa (Commodity Depot and Exchange Centre), ni  Gomina Ibrahim Dankwambo  sagbekale lasiko saa re lodun 2011.
Ewe, inu Costa dun pupo lati pada sinu iko Spain, leyin ti ko kopa fun iko naa lasiko awon ifesewonse ipegede fun idije agbaye naa latari wahala ti o koju lasiko re ninu iko agbaboolu Chelsea.
 Bakan naa lo ni ipinnu Akeredolu lati mase jẹ ki isejọba tẹsiwaju lasiko to wa ni iyasọtọ yii nitori arun Coronavirus fihan pe, ẹnu lasan lo fi n gbogun ti arun Covid-19 to n ja rain nilẹ.
Mo bẹ̀ yín pé kí ẹ jẹ́ kí ó mọ̀ pé ẹ fẹ́ràn òun.
Àwọn ọmọ Lefi meji: Meṣulamu ati Ṣabetai náà faramọ́ àwọn tí wọ́n lòdì sí i.
Oríṣun àwòrán, Twitter Àkọlé àwòrán, Àjọ to n risi eto aabo, DSS lo gbe Sowore lọ si ile ẹjọ lori ẹsun pe ile ẹjọ kò lásẹ láti da sílẹ̀.
Muhammed ni ajo  agbaye to n ri si bi awon eniyan se n lọ lati
Ọmọyẹni lo jẹ aburo fun Ọmọlufa, agba naa kii si se agba kan to pẹ lọ titi, tori ọdun meji pere ni wọn gba lọwọ ara wọn.
Dokita to n sise lori itoju kindinrin, Michael Adelaja, pelu ile iwosan Garki nilu Abuja to je olu ilu Naijiria ti parowa fun ijoba apapo lati fi itoju kindinrin kun eto adojotofo eto ilera NHIS tijoba apapo gbe kale ki owo ti awon alaisan n na le dinku.
Wo àdúgbò tó ń jẹ́ orúkọ èèbó amúnisìn tí yóò pa orúkọ dà l’Eko Kò yẹ kí ìjọba máa ní àwọn mẹ̀kúnú lára lásìkò Coronavirus yìí- Rewane Jean-Bédel Bokassa, Emperror ti orilẹ-ede Central African Republic: Wọn bi Bokassa loṣu keji, ọdun 1921, o si kawe ni Brazzaville.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Zambia Rats Video: Fọ́nrán fídíò èkúté ní ilé ìwòsan jẹ́ ìdójútì fún ìjọba -Mínísítà ìlera 24 Ògún 2020 Oríṣun àwòrán, Matthieu Aubry Fọnran fidio kan to lu sita lori ayelujara ti mu ki awọn alakoso ile iwosan kan ni Zambia wọ gau.
Oṣiṣẹ ilu naa to jẹ ọdọ pade Nelson Mandela, to jẹ amofin ati gbajugbaja alatako iṣejọba awọn alawọ funfun.
Lara awọn to ṣoju wọn ti BBC ba sọrọ ṣalaye pe ina naa ti ran de ọja Ochanja ati Relief Market ni Onitsha.
ede Naijiria, aare Muhammadu Buhari ko ni da si atundi eto idibo ti yoo waye ni
Lẹ́yìn tí Jesu ti sọ ọ̀rọ̀ wọnyi tán, ó gbé ojú sókè ọ̀run, ó ní, “Baba, àkókò náà dé!
Naijiria, ni eyi ti o ju iyatọ ti o wa laarin wọn lọ.
A ní ìrètí pé bí igbagbọ yín ti ń dàgbà, bẹ́ẹ̀ ni ipò wa pẹlu yín yóo máa ga sí i, gẹ́gẹ́ bí ààyè wa.
Wọ́n sọdá sí òdìkejì odòwọ́n sùn ní Geba di ọjọ́ keji.
Ó kọjú sí ìyàwó mi, o ní kí o tún maa wí àwọn ọ̀rọ̀ wọ̀nyí tẹ̀lé òun;
Oríṣun àwòrán, Facebook/Hrm Oba Rilwan Akiolu Ayangburen wa koro oju si hihu iwa eewọ lori ọpa asẹ naa ati si ipo ọba alaye nipinlẹ naa, ti igbimọ awọn lọbalọba lapapọ si foju laifi wo isẹlẹ naa.
Nítorí pé OLUWA sọ fún mi péòun óo fi pẹ̀lẹ́pẹ̀lẹ́ wolẹ̀ láti ibi ibùgbé òunbí ìmọ́lẹ̀ ní ọ̀sán gangan,ati bí ìkùukùu ninu ooru ìgbà ìkórè.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Àwòrán mánigbàgbé BBC news Yorùbá fún ọ̀sẹ̀ yìí 10 Èbibi 2019 Èyí ni àkójọpọ̀ àwọn oun tí ojú wa rí ní ìgboro ní ọ̀sẹ̀ yí Àkọlé àwòrán, Iṣẹ́ loógùn ìṣẹ́ Àkọlé àwòrán, B'ọ̀sàn bá dùn, máà mu igba Àkọlé àwòrán, Ẹran ọbẹ̀ ní gbangba òde.
Nitootọ ni ìdìbò míràn á wáyé ní Kogi, mo máa di gómínà ni -Dino A kò tí ẹnu Bodè pa rárá- iléeṣẹ́ Aṣọ́bodè Ẹgbẹ́ Ilẹ̀ Yorubà gba Aṣíwájú tuntun!
Aṣoju awọn akẹkọọ naa ni ohun to yẹ ki ijọba ṣe ni ko ṣafikun iye owo to la kalẹ fun eto ẹkọ ni ida marundinlogoji ati iye owo to la kalẹ fun eto ilera, ko maa san owo ajẹmọnu ẹgbẹrun lọgọrun un nairan fun awọn akẹkọọ atawọn nnka miran.
Bo tilẹ jẹ pe ogbontarigi adilemu fun Senegal, kalidou koulibaly ko lanfani lati kopa ninu ifẹsẹwọnsẹ ọhun nitori o ti gba kaadi olomi ọsan(yellow card) meji ninu ifẹsẹwọnsẹ mẹta, ikọ Senegal ṣi ja fitafita isbẹsibẹ.
21 Kí ìgbàgbọ́ pẹ̀lú lè gbilẹ̀ nínú ilẹ̀ ayé.
00 Isẹ ilu gbogbo - 108,005,447,953.
Inu aare dun pupo fun iwa akin, isokan ati isera-eni ti iko naa fihan , aare wa tun ro iko agbaboolu Super Eagles lati tesiwaju nipa jijawe olubori  pelu akegbe won ti orile ede Argentina,nibi ifese-wonse ti yoo waye lose to n bo.
O kò ní kan àwọn òkúta ninu oko rẹ,àwọn ẹranko igbó yóo wà ní alaafia pẹlu rẹ.
Eeyan kan sọ si oju opo Facebook pe''Bi ba lọ si ọgba yi,ti ẹ si ju idọti silẹ, ẹ ri wi pe ẹ ṣa nigba ti ba n kuro nibẹ.
Oríṣun àwòrán, Others Àkọlé àwòrán, Ọpọlọpọ awuyewuye lo n lọ lori iye eniyan to ti kọ arun Coronavirus ni ipinlẹ naa ati ọna ti ijọba n gba lati dojukọ itankalẹ arun naa.
omo ipinle Rivers lati  “dibo fun Atiku, ki isokan lee pada si
Nínú ìwée rẹ̀, “Ọ̀run-àpáàdì ní Inal“, tí a tẹ̀ jáde ní ọdún 2000, ó ṣàpèjúwe ìjìyà-oró tí ó jẹ, nígbà tí àwọn apàṣẹ ológun dì í lójú, so ó mọ́lẹ̀, tí wọ́n sì jù ú sínú omi ìdọ̀tí rírùn.
Usman ti orukọ inagijẹ rẹ n jẹ Nigerian Nightmare lu ọmọ Amẹrika to jẹ alatako rẹ bi bara ninu ija ọhun niluu Las Vegas.
Àwọn ìhà méèjèjì ná ló si n sọ pé àwọn làwọn jàre bọ̀ láti ilé ẹjọ́, kọ́da àwọn ìhà ti Musulumi ná[gbé àwọn ìwé kan jáde ti wọ́n fi ti ọ̀rọ̀ wọ́n lẹ́yìn pé àwọn jàre ẹjọ́ náà.
Oríṣun àwòrán, Khaled Desouki William Troost Ekong lo de goolu lade fun Naijiria ni iṣẹju kọkandinlaadọrun.
Orilẹede wa ni ipo keji bayi laarin awọn orilẹede to n ṣe igbọnsẹ sita gbangba lagbaye nitori ida marundinlọgbọn ninu ọgọrun lo n ṣe igbọnsẹ si ita gbangba lorilẹede yii.
gba gba lo yiyọ Ben Bella loye ti wọn fi Houari Boumedienne sibẹ.
Lẹ́yìn tí Peteru ati Johanu ti gbé ọwọ́ lé wọn, wọ́n bá gba Ẹ̀mí Mímọ́.
Eleyii fa ọpọlọpọ awuyewuye ati ariwo nigba naa.
Ṣugbọn ẹ kò wo ojú ẹni tí ó ṣe ohun tí ń ṣẹlẹ̀, bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò bìkítà fún ẹni tí ó ṣètò rẹ̀ láti ìgbà pípẹ́ wá.
Ó ṣa ẹgbẹta (600) kẹ̀kẹ́ ogun tí ó dára, ati àwọn kẹ̀kẹ́ ogun ilẹ̀ Ijipti yòókù, ó sì yan àwọn olórí ogun tí yóo máa ṣe àkóso wọn.
Oríṣun àwòrán, Facebook Àkọlé àwòrán, Eniola Aluko ni wọn kọkọ pa ni ọsẹ yii Ni ọdun to kọja ọmọ Naijiria miiran ti orukọ rẹ n jẹ Harry Uzoka ku ninu ikọlu kan lẹyin ti wọn gun pa ni London kan naa.
aseyege wa, ki a tun wa ona lati tun tesiwaju nipa awon aseyori naa, sugbon ni
Saheed Osupa dá sí ọ̀rọ̀ Barrymade àti K1 Èèmọ̀ rèé!
Amọ iru adura yii gan ni Chelsea nilo lasiko yii ninu idije Premier League lẹyin ti ẹgbẹ agbabọọlu Manchester City ṣe wọn bi ọṣẹ ṣe maa n ṣe oju lọjọ Aiku.
won ba dibo fun un gege bi aare orile ede yii.
Wo ipò tí Buhari fún Faṣọla, Lai Mohammed, Saraki àti bẹ́ẹ̀ bẹ́ẹ̀ lọ Kíni àwọn ọ̀dọ́ Naijiria ń fẹ́ lọ́wọ́ àwọn mínísta tuntun?
Omohtee Twitter: Ìrora púpọ̀ ni mo là kọjá lẹ́yìn iṣẹ́ abẹ tí mo ṣe láti jẹ́ kí ìdí mi tóbi sii
Ti apẹẹrẹ ami arun Coronavirus ba le ju nkọ?
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Bolaji Faleke ni Olùkọ́ tó ń kọ́ wa ní àṣà oge ṣiṣe lórí BBC Yorùbá O wa ke s'awọn dokita ti n woṣẹ niran naa lati pada si ẹnu iṣẹ wọn, ki wọn lee tẹnpẹlẹ mọ ijiroro wọn to n lọ lọwọ pẹlu ijọba apapọ, lori awọn ibeere wọn naa.
Ijọba fọn awọn ọlọpaa da sita lati ṣẹ eegun awọn agbẹ naa, bẹẹ si ni gbogbo ẹbẹ tawọn agbẹ ṣe sijọba lati ipasẹ awọn eekan ilu, lo ja si pabo.
Isẹ ọna naa, to jẹ aworan Ọmọọba Adetutu Ademiluyi lati Ile Ife, eyi ti Ben Enwonwu ya ni odun 1974 di ami isokan orilẹẹde Naijiria leyin ogun abele Biafra.
Naijiria wa ni ipo keji lori akasọ awọn orileede ti iye owo ina lori itọju ilera ti ga ju lọ.
Troicki ti oun naa jẹ ọmọ orilẹede Serbia ni Djokovic kọkọ koju ki o to koju Dimitrov ati Borna Coric.
ẹ̀rù ibi gíga yóo máa bani, ìbẹ̀rù yóo sì wà ní ojú ọ̀nà; tí igi alimọndi yóo tanná, tí tata yóo rọra máa wọ́ ẹsẹ̀ lọ, tí ìfẹ́ ọkàn kò ní sí mọ́, nítorí pé ọkunrin ń lọ sí ilé rẹ̀ ayérayé, àwọn eniyan yóo sì máa ṣọ̀fọ̀ kiri láàrin ìgboro; 
Ni ọpọ awọn ilu okeere naa, awọn ọkunrin ko dẹyin lati maa wa beere ọwọ Wuraọla llati fi se aya.
Wọ́n ní ara nkan tí ó nfa èrò wá sí ìlú àwọn nìyẹn.
tun n yo bilionu naira sile lori eto ilera.
Amosun lẹ́tọ̀ọ́ láti gbè lẹ́yìn oludíje tó bá wù ú - APC Gómìnà Amosun f'ohùn sílẹ̀ láti kúrò ní APC Olùdíje fún ipò gómìnà 24 ló pegedé ní APC Minisita naa nikan kọ ni ọmọ ẹgbẹ APC to ti dun kooko lati ṣiṣẹ tako oludije ẹgbẹ naa fun ipo gomina lasiko eto idibo gbogboogbo ti yoo waye l'ọdun 2019.
Ẹ jẹ́ kí á ṣe àkíyèsí àwọn nnkan wọ̀nyí tí wọ́n mẹ́nu bà ní orí yìí.
”Ninu irufe idije ohun ti o waye sikeyin, eleyi ti balogun iko naa teleri, Joseph Yobo ati Vincent Enyeama tuko re, iko ohun de ipele keji ninu idije naa kii iko agbaboolu France ko to ja won kuro.
Àpẹẹrẹ ni èyí fún gbogbo wa.
Nígbà tí ó dé ọ̀dọ̀ Solomoni, ó sọ gbogbo ohun tí ó wà lọ́kàn rẹ̀ fún un.
”O tun so pe , “Bi okunkun se wa lori ilẹ, bẹẹ ni ẹmi
“Àjèjì kankan kò gbọdọ̀ jẹ ninu àwọn ohun mímọ́, bẹ́ẹ̀ ni àlejò tabi alágbàṣe tí ń gbé ilé alufaa kò gbọdọ̀ jẹ ninu wọn.
Ṣugbọn ní ìgbẹ̀yìn a máa so èso alaafia ti ìgbé-ayé òdodo fún àwọn tí a bá ti tọ́ sọ́nà.
@mrtsmilez lero tiẹ ni orilẹede Naijiria ree, nibi ti gbogbo wa ti jẹ ọdaran, ti aarẹ ẹgbẹ akẹkọ si ti gba owo.
"Obi awọn akẹkọ Dapchi nbeere ọmọ wọn Bode George s'ọrọ lori abadofin tuntun ipinlẹ Eko Wenger sọ wipe: ""Aṣeyọri to ṣe pataki ni nitori wipe ọsẹ to kọja buru fun wa pupọ."
Lẹ́yìn náà, OLUWA fi Joṣua olórí alufaa hàn mí; ó dúró níwájú angẹli OLUWA, Satani sì dúró lọ́wọ́ ọ̀tún rẹ̀ láti fi ẹ̀sùn kàn án.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ata jijẹ maa n jẹ ki ara ji pipe ni Endorphins yii wa lara awọn nkan to maa n mu inu eniyan dun ti ọkan yoo si gbe soke.
Nígbà tí Mose gbọ́ ọ̀rọ̀ yìí, ó sálọ.
Olusegun Obasanjo Àkọlé àwòrán, Oloye Olusegun Obasanjo Olusegun Mathew Okikiola Aremu ni aarẹ ikarun ati ikejila to jẹ lorilede Naijiria.
Nítorí pé lọ́tẹ̀ yìí, òun óo da gbogbo àjàkálẹ̀ àrùn òun bo Farao gan-an, ati àwọn ẹmẹ̀wà rẹ̀, ati àwọn eniyan rẹ̀, kí ó lè mọ̀ pé kò sí ẹni tí ó dàbí òun OLUWA ní gbogbo ayé.
Wọn yóo mú ẹwà ati ọlá àwọn orílẹ̀-èdè wá sí inú rẹ̀.
Bí iṣẹ́ ẹnikẹ́ni bá jóná, olúwarẹ̀ yóo pòfo, ṣugbọn òun alára yóo lá, bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé bí ẹni tí a fà yọ ninu iná ni.
O sọ eyi lasiko ti BBC Yoruba kan si lori ilana ti owo oṣu tuntun naa yoo gba, ko to o di sisan.
16 Èbibi 2019 Elon Musk, Ọ̀gá àgbà iléeṣẹ́ SpaceX, Tesla CEO ń bá Bill Gates du ipò ẹni tó lówó jùlọ ṣèkejì lágbayé26 Bélú 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Ibi ṣíṣe a máa dùn mọ́ òmùgọ̀,ṣugbọn ìwà ọgbọ́n ni ayọ̀ fún ẹni tí ó mòye.
OLUWA ní, “Ẹ gbọ́ ọ̀rọ̀ èmi OLUWA, ẹ̀yin orílẹ̀-èdè,kí ẹ sì kéde rẹ̀ ní èbúté lókèèrè réré;ẹ sọ pé, ‘Ẹni tí ó fọ́n Israẹli ká ni yóo kó wọn jọ,yóo sì máa tọ́jú wọn, bí olùṣọ́-aguntan tíí tọ́jú agbo aguntan rẹ̀.
 o di ọ ̀ tá pẹ ̀ lú oluṣọlá Ọláòṣebìkan fun gbigbemi olóyè Ọbafẹ ́ mi awólọ ́ wọ ̀ .
1 11081 Orilẹede Latvia 304 15.
láti rọ òjò sí orí ilẹ̀ níbi tí kò sí eniyan,ati ní aṣálẹ̀, níbi tí kò sí ẹnikẹ́ni?
Sùgbọ́n ìjọ̀ba kọ̀ tíì pinnu lórí iye tí wọn yóò fi kún owó àwọn òṣìṣẹ́.
Ìjọba ìpínlẹ̀ Oyo kò mọ̀ si Ìyá àti Bàbálọ́jà tí wọ́n yàn- Kọmíṣọ́nnà Okòwò 'O ṣójú mí kóró bí wọ́n ṣé fí àdó olóró pa Dele Giwa lọdún 1986' Wayi o, awọn ọmọ Naijiria ti n se jaginni yodo pẹlu ọba orin naa fun ayọ ọmọkunrin jojolo to baa lalejo naa, bi o tilẹ jẹ pe obinrin meji ọtọọtọ ti bi ọmọbinrin meji fun tẹlẹ.
coronavirus: Ìdí tí obìnrin fi leè rù ú là ju ọkùnrin lọ
Báwo ni ìlù gángan se bẹ̀rẹ̀?
Mekong Watch tẹ àwọn ìtàn wọ̀nyí jáde sórí ìwé ìròyìn pélébé àti sórí ẹ̀rọ ayárabíàṣá, wọ́n sì tún lò ó ní ìdánilẹ́kọ̀ọ́ nípa àyíká ní àwọn ìlú náà.
O ni awọn ilu nlanla bii Minna, Bida, Suleja, Kotongora atawọn ilu miran.
Ó ti tàpá sí òfin mi ju àwọn orílẹ̀-èdè yòókù lọ, ó sì ti kọ ìlànà mi sílẹ̀ ju àwọn agbègbè tí ó yí i ká lọ.
Awọn iroyin ti ẹ le nifẹ̀ si: Charles Okah gba'dajọ ẹwọn gbere 'Naijiria ko laṣeyọri lori gbigbogun t'iwa ijẹkujẹ' Rufai Imam di adajọ agba ile ẹjọ Sharia ‘A ko mọ ibi ti Nnamdi Kanu wa’ Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Àtúntò FSARS: Àwọn ọmọ Nàìjíríà bẹ̀nu ẹ̀tẹ́ lu àtúntò FSARS
Kò sí irúfẹ́ gbólóhùn yí tó jẹ́ mímọ̀ pàtó ní èdè Yorùbá tẹ́lẹ̀ ṣùgbọ́n ní ọ̀sẹ̀ tó kọjá gbólóhùn ọ̀hún ti balẹ̀.
Ò báà dìde kí o lọ sí Kipru,ara kò ní rọ̀ ọ́ níbẹ̀.
Elija bá sọ fún àwọn wolii Baali pé, “Ẹ̀yin ni ẹ pọ̀, ẹ̀yin ẹ kọ́kọ́ mú akọ mààlúù kan, kí ẹ tọ́jú rẹ̀.
 fún àpẹrẹ , mo tọka sí àwọn àdúgbò tí wọn ti mọ ̀ nípa Òrìṣà Ògún dáadáa nínú àwòrán .
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Oti lile le jẹ ki ara rẹ gbe Ọti mimu a maa ṣafikun si adun ibalopọ nitori pe o maa n mu itiju kuro loju ololufẹ ni.
"Mo rò pé gbogbo ǹkan sì ńlọ bí mo ṣe rò ni àfi ti mó gbọ nínú ìròyìn lọ́ja keji pé ẹnikàn ń gbìyànjú láti bá òun lórúkọ jẹ́, ẹgbọ́ ìyá mi ni mo wà nígbà ti ìròyìn náà n lọ lorí Rẹdíò ti ìyá mi náà sì n ṣépè lé ẹni tó fẹ́ ba Salawa lórúkọ jẹ́ láì mọ̀ pé, ẹmi gàn ni mo wà nídìí ọ̀rọ̀ náà "" Mo rọra yọ jáde, mo sì lọ ba káàdì ìpè mi àti káàdì ìràntí náà jẹ́ tí mò sì júù sọnu ti fóònù si inú omi kan ni Magboro, kò sì si ẹni to sọ ǹkankan nípa ọ̀rọ̀ náà tabi pé Alhaja Salawa lori ọ̀rọ̀ náà mọ"" Oríṣun àwòrán, Instagram Àkọlé àwòrán, Ọwọ́ ọlọ́pàá ti tẹ ẹni tó fẹ́ ba Queen Waka lórúkọjẹ́ lọ́jọ́sí Ẹ̀wẹ̀ gbájúgbàja olórin náà Salawa Abeni ti dúpẹ́ lọ́wọ́ gbogbo àwọn olólùfẹ́ rẹ̀ ní Nàìjíríà àti lókè òkun fún àdúrótì, bákan náà lo dúpe lọ́wọ́ àjọ ọlọ́pàá pàápàá jùlọ ẹka RRS fún iṣẹ́ ribiribi tí wọ́n ṣe láti wá ọmọkunbrin náà jáde."
Ìdí rèé tí mo fi gbàdúrà ìyàwó bí Chanel Chin fáwọn tó d'ẹ̀bi ìkọ̀sílẹ̀ rẹ̀ rù mí- Oluwo 'Nínúu kí a yọ oyún inú rẹ tórí iṣẹ́ abẹ tàbí kóo wà nínú ìrora' Oyenusi ló mú mi wọ ẹgbẹ́ adigunjalè kó tó di pé mo b'Ólúwa pàdé - Kayode Williams Tunde Idiagbon, ọ̀gágun kògbagbẹ̀rẹ́ tó ní ẹ̀ẹ̀kan lóṣù ló yẹ kí ológun máa rẹ́rìín Oral Sex: Bóo bá ń gba ẹnu ní ìbálòpọ̀, wo àìsàn tóo lè kó lójú ara rẹ Bayo Osinowo, sẹnẹtọ ẹkun ila oorun Eko Ọjọ Aje, ọjọ kẹẹdogun oṣu kẹfa ọdun 2020 ni Sẹnẹtọ Bayo Osinonowo ti ọpọ mọ si Pepperito jade laye.
 Ẹlomiran to tun ba BBC sọrọ ni Ọgbẹni Adetokunbọ Mumuni ti ajọ to n tọpinpin ọrọ aje ati idagbasoke ilu, SERAP to ni ireti ohun ni wipe ijọba apapọ orilẹede Naijiria ti gbe atunbọtan igbesẹ rẹ naa yẹwo lati mọ boya ko ni pa ọjọ iwaju awọn ọmọ orilẹede Naijiria lara.
Obasanjọ ni nigba ti ogun iditẹgbajọba Dimka waye ni ọdun 1976, ọpẹlọpẹ ipa ti Bajọwa ko lọjọ naa lọhun, lo ko oun yọ.
Won fontẹ lu owo iranwo naa lọjọBọ
Missing Child: Òbí àti asọ́nà ṣọ́ọ̀ṣì 14, lọ́ búra nì'dí imọlẹ̀ l'Akure Ẹ̀wọ̀n oṣù mẹ́ta àti #3,000 ni awakọ̀ tí kò bá ní ‘speed limiter’ yóò fi jura- FRSC Owó ìfẹ̀yìntì àwọn Gómìnà ní ìpínlẹ̀ Zamfara dì àlọrámirámi O ni nigba ti isejọba Aarẹ Muhammadu Buhari bẹrẹ ni ọdun 2015, Naijiria jẹ gbese to to biliọnu mẹwaa naira.
Wúndía àti Ọba nìkan ló lè dé Orí Òkè Ọwá ní Ìjàrẹ Ondo- Àgbà Oloye Akẹ́kọ́ọ̀ mẹ́tàdínlọ́gọ́ta ni wọ́n ti ko lọ sílé ìwòsàn Kenya Ilé Ìfowópamọ́ Unity ilú Ekó jóná Gẹgẹ bi ẹni ti o jẹ alakoso ile itura naa Williams Ekwzie, ti ṣalaye, o ni, lootọ ni awọn mejeeji sanwo lati wọ inu yara ti wọn si wọle.
Oríṣun àwòrán, Getty Images/LOIC VENANCE Àkọlé àwòrán, Aarẹ Buhari ni iwuri nla ni Seun Adigun, Ngozi Onwumere, Akuoma Omeoga ati Simidele Adeagbo jẹ fun awọn ọdọ Naijiria Aarẹ Buhari gbosuba fawọn ikọ Naijiria ti wọn n kopa ninu idije kẹkẹ ori yinyin 'bobsleigh'paapaa julọ bi wọn se di ikọ akọkọ lati ilẹ Afirika ti yoo maa kopa ninu idije ere idaraya ori yinyin lagbaye, Winter Olympics.
“Bẹ́ẹ̀ ni o óo ṣe ya àwọn eniyan Israẹli kúrò lára àìmọ́ wọn, kí wọ́n má baà sọ ibi mímọ́ tí ó wà láàrin wọn di aláìmọ́, kí wọ́n sì kú.
Iná jó dórí kókó, Buhari pe Lawan, Gbajabiamila sí ìpàdé lórí ìwọ́de àwọn ọ̀dọ́ Aisha Buhari polongo àwo orin tó ní Nàíjíríà ń ṣun ẹ̀jẹ̀ lásìkò ìwọ́de Lizzy Anjorin ń kiri àgọ́ ọlọ́pàá láti gba ọ̀dọ́ afẹ̀hónúhàn, tó wà láhàámọ́ sílẹ̀ 2015 ni mo ti ń kígbe pé gudugbẹ̀ máa já ní Nàíjíríà - Oyedepo O fi kun un pe wọn ti sun idanwo ẹkọ nipa kọmputer to yẹ ko waye ni ọjọ Aje ọjọ kọkandinlogun oṣu kẹwa si ọjọ kẹrindinlogun oṣu kọkanla.
Ẹyẹ Spiny Babbler, tí a lè rí ní Nepal nìkan, ti fa àwọn onímọ̀-nípa-ẹyẹ àti olólùfẹ́ ẹyẹ káríayé mọ́ra.
Awọn imọran to le mu ki ẹ gbadun sise isẹ lati ile lasiko idejumọle to n lọ lọwọ lasiko konile-o-gbele yii Wo diẹ lara awọn aba ati ọna ti yoo jẹ ki ṣiṣe isẹ lati ile rọrun sii lasiko konile-o-gbele coronavirus yii: Sarah M, to n sisẹ nilu London ni oun ti wa ri wi pe didanikanwa jẹ nkan to maa n mu irẹwẹsi ba ọkan.
 ara àwọn oyè tí wọn ń jẹ ni jagùnà ( ajagun lójú ọ ̀ nà ) olúkọ ̀ tún ( olú tí Í ko ogun òtún lójú ) , akíngbógun , Òsíẹ ̀ lẹ ̀ àti akílẹ ́ gun .
Orí meje tí ẹranko náà ní jẹ́ òkè meje tí obinrin náà jókòó lé lórí.
    Nǹkan kín-ín-ní tí o lè kọ́ yà ẹnikẹ́ni lẹ́nu nígbà tí ó bá dé ọ̀run Àpáàdì ni àti sí èyò rárá fún ohunkóhun.
Nítorí náà, OLUWA Ọlọrun ní, “Bí ẹ̀ka àjàrà tí mo sọ di igi ìdáná láàrin àwọn igi, bẹ́ẹ̀ ni n óo ṣe àwọn tí ń gbé Jerusalẹmu.
Wọ́n bá sin ín sórí ilẹ̀ rẹ̀ ní Timnati Sera, tí ó wà ní agbègbè olókè Efuraimu, ní apá ìhà àríwá Gaaṣi.
Bakan naa ni wọn ko i tii beere owo itusilẹ ni ọwọ awọn ẹbi.
Ijoba apapo ti fi oruko  egbe  awon to n wa ekusa lorile ede Naijiria si ara awon ti yoo je anfaani bilionu  márùn ún ti won ya sọtọ lati fi ran awon onise –owo ati onisowo keekeeke lọwọ ni jake –jado orile ede yii.
Bẹẹ ni ọrọ ri fun awọn ololufẹ meji to pa ara wọn ninu Oṣu Kẹsan an yii lẹyin ti awọn obi wọn kọ fun wọn lati fẹ ara wọn nitori ọkan ninu wọn wa lati idile ẹru ni ipinlẹ Anambra.
Ọlọrun, n óo kọ orin titun sí ọ,n óo fi hapu olókùn mẹ́wàá kọrin sí ọ.
Gomina ipinlẹ Ọyo ni tire wa rọ awọn ọmọ Naijiria lati gbe igbe aye mimọ, ifẹ, ododo, ibẹru Ọlorun ati ise ore, gẹgẹ bi awọn ohun amuyanga ti eniyan le ko ninu igbe aye Ojisẹ Ibrahim nigba aye rẹ.
Ṣé o fẹ́ pa mí bí o ti ṣe pa ará Ijipti lánàá ni?
Èyí tí ó dùn mi jùlọ rékọjá gbogbo rẹ̀ ni pé n kò lo àǹfààní tí mo ni tó nígbà tí a jọ rí ara wa, àkókò tí ìfẹ́ tẹ̀ sì ń gùn mi bí ẹni gun ẹsin yìi’, n kò ríi mọ.
Akintola to jẹ alakoso ijọba apa iwọ oorun Naijiria nigba naa wa lara awọn gbajugbaja oloṣelu tawọn ologun ti wọn ditẹ gbajọba awarawa lọdun 1966.
“Bí ó bá jẹ́ pé ẹran ni eniyan jẹ́jẹ̀ẹ́ láti mú wá, gẹ́gẹ́ bí ọrẹ ẹbọ sí OLUWA, gbogbo irú nǹkan bẹ́ẹ̀ tí eniyan bá fún OLUWA jẹ́ mímọ́.
Nígbà tí Mẹfiboṣẹti, ọmọ Jonatani, tíí ṣe ọmọ ọmọ Saulu dé, ó wólẹ̀ níwájú Dafidi, ó sì kí i tọ̀wọ̀tọ̀wọ̀.
Nítorí ta ni a lè fi wé ọ ní ọ̀run, OLUWA?
Ko si enikeni to farapa nibi isele ohun.
" Bakan lo kesi awọn ọba, baalẹ ati awọn olori ẹṣin musulumi, Kristẹni ati ẹṣin ibilẹ lati fi ọwọ sowọpọ pẹlu ijọba, ki opin le ba rogbodiyan to n waye nipinlẹ Eko.
Ojọ kejilelogun, oṣu keje, ọdun 2019 ni wọn yoo kéde ẹni ti yoo wọ bata ti Theresa May bọ silẹ yii.
 Àléjò pàtàkì tí ó sọ ̀ rọ ̀ níbẹ ̀ ní Ọ ̀ jọ ̀ gbọ ́ n professor nathaniel oyerinde , tí ó jẹ ́ olùkọ ́ ní ilé ẹ ̀ kọ ́ ìjìnlẹ ̀ baptista , ogbomoso , tí ó sì jẹ ́ Ọ ̀ jọ ̀ gbọ ́ n baptist àkọ ́ kọ ́ ti orílẹ ̀ èdè nàìjíríà .
Asofin agba, omowe Ahmad Lawan ti ba egbe akoroyin ipinle Yobe kedun, lori iku okan lara omo egbe won , ogbeni Jonathan Gopep, lojo Aje.
Ṣugbọn Jesu tún wí fún wọn pé, “Ẹ̀yin ọmọde, yóo ṣòro pupọ láti wọ ìjọba Ọlọrun!
Ilẹ China ń sàmì àádọrin ọdun tí wọn gbòmìnira pẹ̀lú ìfẹ̀hònúhàn Ọwọ́ tẹ babaláwo àti adigunjalè márùń ni Imo - Olọpàá Ọwọ ṣìkún òfin ti tẹ alága àná fún ọrọ owó ìfèyìntì, Maina - DSS Bakan naa ni Ọlọpaa ti wa kesi gbogbo awọn ti o ni ile iwe aladani lati sowọpọ pelu wọn lojuna ati dẹkun iru iṣẹlẹ bẹẹ.
Nítorí náà, àwọn ẹ̀bùn ni ó kọ́ lọ ṣáájú rẹ̀, òun pàápàá sì dúró ninu àgọ́ ní alẹ́ ọjọ́ náà.
Obafẹ́mi ni ''Ọrọ yi mu abuku ba ẹni ti a n soju fun paapa julọ pe o tilẹ jẹ Gomina ti ofin daabo bo.
 Èka yìí ní ó se pèlú àrògún .
Iwadii naa to ni oun ṣe lori lori bi awọn eleto aabo Naijiria ṣe dana ibọn mọ awọn oluwọde ti ko dihamọra ogun ni Lekki Toll Gate nipinlẹ Eko, lasiko iwọde #ENDSARS, ko ba igbelewọn iṣẹ iroyin mu.
Báyìí ni àsọtẹ́lẹ̀ Aisaya ṣe ṣẹ sí wọn lára, nígbà tí ó sọ pé.
Lẹyin ipade yii ni awon mejeejidi ọrẹ ti wọn si maa n so fawon eniyan to ba beere lowo won pe se ibeji ni won pe awon ko mo, amo boya ni aye miran ibeji ni awọn.
Mo bá tún mú ìpanu aláta kan tí mo múdání, mo sọ ọ́ sẹ́nu kàló, mo rún un lẹ́nu wómú-wómú.
Bí o bá fẹ́ ohunkohun sí i fún lílò ninu Tẹmpili Ọlọrun rẹ, gbà á ninu ilé ìṣúra ọba.
Ile-ise iwe iroyin The SUN fi ami-eye Sports Personality of the Year da aare ajo NFF, Amaju Melvin Pinnick lola, fun igbakeji lodun meji seyin, lojo Aiku(Sunday).
Ọgaagun Roger Nicholas, to dari ikọ to n koju Boko Haram lagbegbe iwọ-oorun ariwa orilẹede Naijria sọ wipe awọn ti bori ikọ Boko Haram ni osu Kini, ọdun yii.
Oríṣun àwòrán, Other Ìgbìmọ̀ aláṣẹ UNILAG yọ gíwá iléewé náà nípò Igbimọ alaṣẹ fasiti ijọba apapọ to wa niluu Eko, UNILAG ti da giwa fasiti naa, Ọjọgbọn Olawatoyin Ogundipe duro lẹnu iṣẹ.
Kó dáju mọ báyìí bọ́ya Arsenal yóò kógojá fún Champions League.
Aare  Buhari wa ro awon odo lati lowo ninu ise agbe
Bẹẹ ni ọrọ ri nigba ti oju opo ikansiraẹni Instagram ati Twitter bẹrẹ si ni gbona jainjain, lẹyin ti awọn alaṣẹ ikanni Instagram gbegile oju opo Tunde Ednut nigba ti o ni awọn alatilẹyin bii miliọnu kan laarin ọjọ meji.
Wọ́n wá gbọ́ ọ̀rọ̀ rẹ̀ ati pé kí ó lè wò wọ́n sàn kúrò ninu àìsàn wọn.
Lasiko ti ọja rira agbabọọlu ṣi silẹ ninu oṣu kinni ọdun 2020 ni Ighalo darapọ mọ Manchester United lati ikọ agbabọọlu China, Shanghai Shenhua.
Oríṣun àwòrán, @BashirAhmaad Àkọlé àwòrán, Aarẹ Buhari ni ko si adehun to se koko ju abo ati igbelewọn eto ọrọ aje orilẹede Naijiria lọ Aarẹ Buhari ni isejọba orilẹede Naijiria ko ni faramọ ohunkohun ti yoo ba mu eebu ẹyin idagbasoke awọn oludaleesẹ silẹ atawọn olokoowo gbogbo labẹle.
26 Bélú 2020 Iléèṣẹ́ ọlọ́pàá mú ọkùnrin ẹni ọdún 55 tó gé ẹ̀yà ara èèyàn nílẹ̀ ìsìnkú ṣọ́ọ̀ṣì l'Ogun25 Bélú 2020 Covid 19 vacine updates: America kan sárá si Dókítà Ogbuagbu, ọmọ Nàìjíríà tó ṣàwárí abẹ́rẹ́ àjẹsára COVID-19 àkọ́kọ́25 Bélú 2020 Burna Boy Twice as Tall: Ǹkan tí ó yẹ ki o mọ̀ nípa Damini Ebunoluwa Ogulu Rex (Burna Boy) ti orin rẹ̀ lu ìgboro pa báyìí25 Bélú 2020 Amos Dauda, Iphone: Ilé ẹjọ́ dájọ́ ẹgba mẹ́ẹ̀dóògún fún ọ̀daràn tó jí Iphone ní Kaduna25 Bélú 2020 Grammy awards 2021 - Burna Boy, Beyoncé, àti Dua Lipa, wà lára àwọn ti wọ́n fi orúkọ wọn sílẹ̀25 Bélú 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Odion Ighalo di ọmọ Naijria àkọ́kọ́ tí yóò gbá bọ́ọ̀lù fún ikọ̀ Manchester United 1 Èrèlè 2020 Oríṣun àwòrán, Getty Images Ẹgbẹ agbabọọlu Manchester United ti fi ọrọ lede pe Odion Ighalo ti darapọ mọ ikọ ọhun.
 Nipa iwe eto alaafia ti awon oludije towobo , o je ki won lee dena wahala ti ko ba sele ki eto idibo to waye,tabi lasiko eto idibo ati leyin eto idibo.
Gómìnà ìpínlẹ̀ Kano, Abdullahi Ganduje tí fún Emir Kano, Muhammadu Lamido Sanusi keji ní ìwé wá wi tẹnu rẹ lọ́nìí ọjọ́bọ̀, lóri ẹ̀sùn pé ó ṣe owó mọ́kumọ̀ku.
Bàbà ọmọ ọdún 75 kó HIV ran ọmọ ọdún 14 lẹ́yìn tó fi ipá báa lò Jamilu Sani to jẹ oju mi too nibi iṣẹlẹ naa ni Kano sọ fun akọroyin BBC, Mansur, pé gbogbo awọn joko sibi igbafẹ ti awọn si jọ n ṣere ni.
Buhari fún Ẹ̀ka ìdájọ́, ilé àsòfin ìpínlẹ̀ l'òmìnira owóòná
Wọn yóo mú mààlúù ati aguntan wá, láti fi wá ojurere OLUWA, ṣugbọn wọn kò ní rí i; nítorí pé, ó ti fi ara pamọ́ fún wọn.
Gbogbo àwọn tí wọ́n jẹ́ akọni ọmọ ogun náà jẹ́ mẹtadinlogoji.
Ẹ dúpẹ́ lọ́wọ́ OLUWA, nítorí pé ó ṣeun,nítorí pé ìfẹ́ rẹ̀ tí kì í yẹ̀ wà títí lae.
” Bẹ́ẹ̀ ni Jobu máa ń ṣe ní gbogbo ìgbà.
Abuja lorile ede Naijiria ti gbe igbse lori iwe abadofin naa sugbon ti won n
A wa nibi loni nitori awọn ipenija to n ba ibagbepọ alaafia ati eto abo orilẹede Naijiria finra."
Ọpọ awọn ilumọọka agbẹjọro atawọn ajafẹtọ omoniyan lo ti ṣatilẹyin fun eto Amọtẹkun lẹyin ti tako agbekalẹ eto naa.
Forúkọ sílẹ̀ nínú ìròyìn yìí Ọba Ilorin ló pàṣẹ pé kí ń padà sọ́dọ̀ ọkọ mi - Risikat olójú búlúù Wo àmúyẹ kí o tó lè di ọmọ ogun ilẹ̀ Nàìjíríà pẹ̀lú fọ́ọ́mù tó jáde yìí Adeeko ni pupọ ninu awọn opo ọhun ni ko rọwọ họri tẹlẹ, ṣugbọn oun ti gba lati yi igbe aye wọn pada.
Márosẹ̀ Eko sí Ibadan àti Ibadan sí Eko dí pa fún ṣúnkẹrẹ́-fàkẹrẹ ọkọ̀ Èyí ni bí ogun abẹ́lé Biafra ṣe bẹ̀rẹ̀ ní Nàìjíríà Àwọn omidan Naijiria ni wọ́n fi ń ṣerú ní Lebanon- Ọmọlọla Lori ọrọ ikọ Amotekun to ti di ariwo lẹyin ti ijọba apapọ ni ko ba ofin mu, o sọ pe ko sẹni to mọ ọmọ pọn bi ọlọmọ, fun idi naa, ko si eewọ ninu ka ṣọra ẹni, ṣugbọn ki ijọba fi oju ṣunukun wo ọrọ ọhun.
Àkọlé àwòrán, Fowler kò sí lábẹ́ ìwádìí kankan-Garba Sheu Garba fi kún un pe àpẹẹrẹ òhun ọtun ni ọ̀rọ ti ààrẹ só lásìkò ìpàgọ àwọn mínísítà túntún àti àwọn akọwé ilé iṣẹ́ ìjọba.
Abiru ṣ'àbẹ̀wò sí Tinubu lẹ́yìn tó wọlé àtúndi ìbò Sẹnẹtọ ìlà oòrùn ìpínlẹ̀ Eko Ọdun 2012, 2016 àti 2020 ni John Mahama àti Nana Akufo-Addo ti jọ ń figagbága dupò aàrẹ Ghana Idi ti Odili fi gba ibi ìbálòpọ̀ lọ sí ọ̀run alákeji nílùú Port Harcourt Gbọ́yì-sọ̀yí àti ìròyìn èké láti ọ̀dọ̀ àwọn olólùfẹ́ wa ló ṣáábà ma ń da ìgbéyàwó àwọn òṣèré rú- Ọpẹ Ayeola Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí D.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Wedding nights: Kí ni aṣọ ìbálé túmọ̀ si lálẹ́ ọjọ́ ìgbeyàwó ?
akoroyin ile-ise aare lasiko ipade alatilekun-mori ti o se pelu aare Muhammadu
Nítorí pé ẹ ti gbàgbé Ọlọrun olùgbàlà yín,ẹ kò ranti Àpáta tí ó jẹ́ ààbò yín.
    Jíjáde tí mo jáde ṣe ni mo rí onílù tí o ń rékọjá lọ mo bá ní kí ó máa lu ìlú tẹ̀lé mi.
”Joramu dáhùn pé, “Rárá, OLUWA ni ó ti pe àwa ọba mẹtẹẹta yìí jọ láti fi wá lé ọba Moabu lọ́wọ́.
Ilé ẹjọ́ tó ga jùlọ nílúu Abuja ti dá
Oloye Fulani kan ni baba rẹ jẹ ti orukọ iya rẹ si n jẹ Zulaihat.
" Oju kokoro ati ẹtan owo, ifẹ ori ayelujara ati ifẹ afẹju si ọkùnrin wa lara idi ti awọn obinrin fi n fi ara da iya lati ọwọ ọkùnrin.
Paapaa lorilẹ-ede South Africa, eyi to fidi rẹ mulẹ pe bo ti n se fun alejo, naa lo n se fun onile Lasiko ogun abẹle ni Naijiria, ipa nla lo ko lati se atilẹyin fun ẹgbẹ alaanu Red Cross.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù IS Global: Oúnjẹ alẹ́ lẹ́yìn aago mẹsan leè fa jẹjẹrẹ 20 Agẹmo 2018 Oríṣun àwòrán, @matsecooks Àkọlé àwòrán, Igbagbọ awọn onimọ ni pe pipẹ ẹ jẹun lalẹ maa n mu ki ara ko wu.
13 Ògún 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 14 Ògún 2020 Oríṣun àwòrán, Getty Images Onimọ nipa eto aabo lorilẹ-ede Naijiria, Slyvester Emiantor ti sọ awọn ọna miran ti awọn ọmọ Naijiria le gba lati daabo bọ ara wọn lọwọ ijamba lasiko ti eto aabo mẹhẹ ni Naijiria yii.
Ọwọ́ tẹ́ àwọn ọkùnrin Fulani mẹ́ta tí wọ́n jí Màálù méjì kó ní Ogbomọṣọ- Àjọ NSCDC Ọmọ́ Yorùbá korò ojú sí Buhari bí kò ṣe fi orúkọ Obasanjo sọ ibùdókọ̀ ojú'rin Ọ̀nà tó fi le è mọ gbájúẹ̀ babaláwo - Ẹlẹ́buìbọn Iṣẹlẹ naa la gbọ pe o waye nileewe girama Ekeugwu Azuinyaba, nijọba ibilẹ Ishielu, nipinlẹ Ebonyi, lọjọ kẹwàá, oṣu Keje.
Oríṣun àwòrán, Rotimi Akeredolu Aketi Bẹẹ ba gbagbe, ede aiyede bẹ silẹ nile ijọba Akure lẹyin ti igbakeji Gomina ipinlẹ Ondo yapa kuro ninu ẹgbẹ oṣelu APC, to si darapọ mọ ẹgbẹ oṣelu PDP.
tí kò ní rí ìlọ́po-ìlọ́po gbà ní ayé yìí, yóo sì ní ìyè ainipẹkun ní ayé tí ń bọ̀.
minisita fun oro to je mọ ile okeere fun orile ede  Angola , Manuel  Augusto, lọjọRu niluu Abuja.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Wo bí o ṣe leè ṣe ìjìnàsíraẹni ní ibiṣẹ́ lásìkò Coronavirus yìí Wo àwọn bẹbẹ tí Umar Musa Yar'adua ṣe lórí àlééfà Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Awọn ọmọ Naijiria n ṣeranti aarẹ ana Ọjọ́ ńlá, ọjọ́ manigbagbe ni ọjọ́ karùn-ún oṣù karùn-ún ọdún 2010, tí aarẹ tẹ́lẹ̀ ni Nàìjíríà, Umaru Musa Yar'adua jáde láyé, èyí tó pé ọdún mẹ́wàá gbáko lónìí ọjọ́ Isegun.
Ìgbà tó kọ̀dí sí òòrùn ni ìgbà òtútù ní ìhà àríwá ilé-aiyé.
Ó ranṣẹ pe Baraki, ọmọ Abinoamu, ní Kedeṣi, tí ó wà ní Nafutali, ó wí fún un pé, “OLUWA Ọlọrun Israẹli ń pàṣẹ fún ọ pé kí o lọ kó àwọn eniyan rẹ̀ jọ ní òkè Tabori.
Ninu atẹjade ori ayelujara naa, Mike ni ọwọ kekere ti mo ni fun ẹ ti parẹ."
Ki ni ka ti wi ni ti iṣẹlẹ to ṣẹ leyi ti awọn adigunjale ti lọ ja agọ ọlọpaa lole.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Òwe: Kí ni ìtumọ̀ òwe ikú tó ń pa ojúgbà ẹni?
Ile riri to to odiwon kilomita ota leleedegberun ti sele ni ariwa Port Moresby to je olu ilu Paupau New Guinea lojo Aiku ni aago merin ku iseju meedogun asiko ile naa.
Ọjọ kinni, oṣu kewaa, ọdun 1960 ni orilẹ-ede gba ominira lọwọ ilẹ Gẹeṣi to koo lẹru.
Sugbọn eyi to se ni laanu ni awọn ẹmi to bọ sọwọ awọn agbofinro lasiko ti wọn n se isẹ wọn lati ri daju pe awọn eeyan tẹle ofin fidimọle.
Bi eeyan ko ba si se iwadi bo se yẹ, tabi ko ka ojulowo iroyin lati awọn ileesẹ iroyin bii BBC Yoruba, to maa n tọpinpin iroyin bo se yẹ, afaimọ ki eeyan ma sẹ dẹsẹ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ikọ̀lù Darandaran: ìwọ́de pẹ̀lẹ́ kùtù wáyé nípìnlẹ̀ mẹ́ta 29 Ìgbé 2018 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 30 Ìgbé 2018 Oríṣun àwòrán, TITTER/ANTHONY BERNARD Àkọlé àwòrán, Ààrẹ CAN ni ìwọde náà wa fun pipe àkíyèsí ìjọba sí ipaniyan jákèjádò Naijiria ìwọde òní pẹ̀lẹ́ kùtù ń lọ lọ́wọ́ nípìnlẹ̀ Òndó, Osun àti Èkìtì.
Ipinlẹ Kaduna jẹ ọkan lara awọn ipinlẹ Naijiria ti ija ẹsin ati ija ẹlẹyamẹya ti wọpọ julọ.
Ohun tí ó jẹ ìyanu jùlọ pátápátá ni àkókò yìí ni àláàfíà tí o wà láàrin àwọn ẹ̀dá alà[[e, ìrẹ́pọ̀ irú èyí t;i ẹnikẹ́ni kò pìtàn rí.
Bakan naa ni adari ile tun safihan aworan iru ile igbimọ aṣofin tuntun ti awọn aṣofin ṣe fun gomina.
Ìdènà àrùn tó níí ṣe pẹ ̀ lú àpò omi nínú ara jẹ ́ nípasẹ ̀ ìtọ ́ jú àwọn ajá tó lè ti ní àrùn náà lára àti nípasẹ ̀ fífún àwọn àgùtàn ní abẹ ́ rẹ ́ àjẹsára .
Sé o ti rí ère MKO Abiola tuntun?
Kọ́ mi ní ọ̀nà rẹ, OLUWA,kí o sì tọ́ mi sí ọ̀nà títẹ́jú rẹ,nítorí àwọn ọ̀tá mi.
ati ọ̀dọ̀ Jesu, alárinà majẹmu titun, ati sí ibi ẹ̀jẹ̀ tí a fi wọ́n ohun èèlò ìrúbọ tí ó ní ìlérí tí ó dára ju ti Abeli lọ.
 onípapapa náà ò sì ní í dáwọ ́ dúró .
Òrìsà jẹ́ ń dàbí onílé yí
Agba Inaki to ni oun ko tii ṣe igbeyawo tun sọ pe, Kristẹni pọnbele ni oun amọ oun kan maa n fi ẹsẹ ifa ṣe ẹfẹ ni.
Borno mu ala pelu awon orile ede bii – Niger, Cameroon ati Chad.
 Ipinle, fun ọrọ to jẹ mọ  Niger Delta .
Kí alaafia láti ọ̀dọ̀ Kristi máa ṣe alákòóso ọkàn yín; nítorí Ọlọrun pè yín láti jẹ́ ara kan nítorí alaafia yìí, ẹ sì máa ṣọpẹ́.
'Àwa la pa ọ̀dọ́mọdé olówó OOU àti olólùfẹ́ rẹ̀'
Ibi ti ọrọ naa yoo kangun si ko ti yewa, ṣugbọn eyi to daju ni pe ijọba Naijiria ni, South Africa ti ba doju ẹ ati pe, awọn ko ni mu ni kekere pẹlu wọn.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Ipaya to n ba ọpọ oṣiṣẹ bayii bi pupọ ninu wọn ṣe n pada sẹnu iṣẹ ni pipadanu iṣẹ.
Awọn to fẹ kọ ẹkọ nipa bi wọn ṣe n kọ awọn nnka bi ile, bi wọn ṣe n tu ọkọ sẹ, ati bẹbẹ lọ ni N-Power build wa fun.
Ṣaaju, aarẹ Muhammadu Buhari ti paṣẹ lọ gbele ẹ na fun adajọ agba orilẹede Naijiria Walter Samuel Nkanu Onnoghen.
Bi ọrọ ti ṣe lọ Senetọ Ajimọbi ni oun ni oun jawe olubori ninu eto idibo to kọja nipinlẹ Oyo.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ẹni to ni ile iwe sare lati doola awọn akẹkọ ni ile wolu Ko si ẹni to mọ iye awọn eniyan to ṣi ku sinu àwótì ile alaja mẹta naa ni eyi ti iṣẹ tun ti bẹrẹ ni aarọ kutu oni.
Yàrá tí mo já sí jọ èyí tí mo tí ń bọ̀, àmọ́ ó kéré jù ú lọ.
Ara ọrẹ rẹ̀ tún ni àwo kòtò kan tí wọ́n fi wúrà ṣe, tí ìwọ̀n rẹ̀ jẹ́ ṣekeli mẹ́wàá, tí ó sì kún fún turari.
Bákan náà, àwọn ará Memfisi ati Tapanhesi ti fọ́ adé orí rẹ̀.
William Abass n sisẹ owo ẹru lọ pẹlu ọga rẹ ni Brazil, to si n fi ọpọ ẹrun ransẹ si onitọun, ti oun naa si n ni owo ati ọrọ lati ipasẹ okoowo ẹru naa.
Ẹgbẹlẹgbẹ owo ti oloogbe Abacha ko pamọ silẹ okeere nigba to wa lori oye ni ijọba Naijiria ti gba.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Paystack Shola Akinlade: Ìgbésẹ̀ 5 yìí ni mo gbé tíléeṣẹ́ Stripe fi dókòwò $200m pẹ̀lú mi Iwa mimọọmọ paarọ ọmọ mọ iya ikoko lọwọ: Eyi maa n waye nifọwọ kọwọ pẹlu awọn osisẹ eleto ilera nile iwosan, to ti gba owo lati paarọ ọmọ laarin iyalọmọ kan si ekeji.
" Wabba tun wa lu aago ikilọ seti awọn gomina naa pe, ni ọjọkọjọ toun ba gbọ pe wọn ti ya owo ifẹyinti ọhun ni iwọde alagbara yoo bẹrẹ, ti gbogbo osisẹ yoo si da soju popo.
Miyetti Allah ní kí wọn wọ́gilé Amotekun, Sunday Igboho yarí Sunday Igboho yarí, ó fohùn ránsẹ́ sáwọn èèyàn tó ń pẹ̀gàn rẹ̀ Miyetti Allah ní kí wọn wọ́gilé Amotekun, Sunday Igboho yarí Àwọn ọmọ onílẹ̀ lọ ṣe àmúṣẹ àṣẹ iléẹjọ́ ní Soka, làwọn ‘Jàǹdùkú’ fi dá wọn lọ̀nà - Iléeṣẹ́ ọlọ́pàá Ọyọ Ọpọ eeyan ni awọn adunkooko mọ ni yii ti pa nilu Kishi to wa nijọba ibilẹ Irepo nipinlẹ Oyo, ti wọn si ti sọ awọn miran di alaabọ ara.
Amotekun: Fayemi ni ikọ̀ àláàbò yìí ni yóò máa ṣe àkóso ìpínlẹ̀ kọ̀ọ̀kan
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Nigeria Pensioners: Wàhálà àyẹ̀wò iwé ìfẹyinti yì ti pọ̀jù Akọsilẹ Ile Ẹjọ lori IMN labẹ El Zakzakky: Akọsilẹ ile ẹjọ fihan pe Adajọ Tionye Maha ni ko si idi kankan fun ẹnikẹni lati da ilu ru mọ lorukọ ẹgbẹ kankan.
Àṣírí ilé tí wọ́n ti ń fipá bá àwọn ọmọdékùnrin lò tú síta Ajọ ọ̀tẹlẹ̀múyẹ́ Benue wú òkú èèyàn mẹ́wàá jáde ní ibojì àwọn ajínigbé Ìbẹ̀rẹ̀pẹ̀pẹ̀ Ibẹrẹ awọn mejeji ko fibẹẹ dan mọran.
Yèyé Tóyìn Adégbọ, tí gbogbo èèyàn tún mọ̀ sí Asẹ́wó tó re Mecca, lásìkò tó ń bá BBC Yorùbá sọ̀rọ̀ ní ipa kan tó kó nínú eré ni wọ́n se ń pèé ní Asẹ́wó tó re Mecca àmọ́ ní báyìí, òun ti yíi padà sí Asẹ́wó tó re London.
World Cup 2018: Ṣé àwọn tó kù ní Moscow ló tó gbangba sùn?
Lẹ́yìn náà, ọkàn Dafidi bẹ̀rẹ̀ sí dá a lẹ́bi nítorí pé ó gé etí aṣọ Saulu.
Yoruba Culture: Ọjọ́ méje ni wọ́n fí n rẹ ẹ̀kú Danafojura kó tó jáde
Abenugan ile-igbimo asofin, dokita Bukola Saraki ti teko leti lo si orile-ede Amerika bayii lati lo kopa nibi ifilole ilana  eto aare ile Amerika, Donald Trump  fun ile Afrika, eleyi ti won yoo kede re lojoBo(Thursday), ojo ketala osu kejila odun ti a wayii.
Àwọn Ará Ijipti Fipá Kó Àwọn Ọmọ Israẹli Ṣiṣẹ́.
Àgọ́ mi ti wó, gbogbo okùn rẹ̀ sì ti já.
Bákan náà ló fi kun pé, gbogbo ǹkan ti pada bọ̀ sípò níbẹ̀ báyìí.
17 Wo ọ̀pọ̀ ìgbà tí Ginimbi ọ̀dọ́mọdé olówó ti ṣe àríyá aláṣọ funfun kó tó kú Ta ni olóògbé Jerry Rawlings, tí wọ́n fún ní àlàjẹ́ 'Junior Jesus' ''Aláàfin kìí ṣe ọkùnrin tí wàá jẹ lásán, tó sì wá sálọ - Aráàlú fèsì fún Olorì Anu Iléeṣẹ́ ológun sọ ikọ̀ ọdẹ́ ìbílẹ̀ JTF di ológun ní Borno, ẹ̀yà yókù ní Nàíjíríà fọnmú ''Gomina ti tẹti si ohun tara ilu sọ eyi ti o tako sisan owo ifẹyinti fawọn Gomina ati Igbakeji wọn'' Oríṣun àwòrán, facebookpage adbulrahman ''Ni ibamu pẹlu adehun ipolongo rẹ, Gomina yoo fi aba yii ṣọwọ si awọn aṣofin fun agbeyẹwo lọsẹ to n bọ'' Bẹẹ naa ni Ajakaiye sọ ninu atẹjade naa pe, Gomina ni ''yoo da ki awọn aṣofin pe ipade apero araalu lati sọ erongba wọn lori ọrọ yii'' O fi kun pe, Gomina Abdulrahman ro pe asiko ti to bayi ki wọn wọgile ofin naa, ki wọn baa le lo owo ọhun fun idagbasoke ipinlẹ Kwara.
ohun ti ajo  EFCC naa ri gba lowo awon
Wúrà ń bẹ, òkúta olówó iyebíye sì wà lọpọlọpọ,ṣugbọn ọ̀rọ̀ ìmọ̀ ni ohun ọ̀ṣọ́ olówó iyebíye.
Wọ́n dá Mose lóhùn pé, “A óo kọ́ ilé fún àwọn ẹran ọ̀sìn wa níhìn-ín ati ìlú olódi fún àwọn ọmọ wa.
Àkọlé àwòrán, Aláàfin Àjàgbó lo kọkọ fi aarẹ ọna kakanfo jẹ Oniruru ogun ni wọn ja lasiko Latoosa sugbọn eyi to gbajugbaja ni bẹ ju ni ogun kiriji ti wọn ja fun ọdun mẹrin.
”Ọkàn mi dá ọ lóhùn pé, “Ojú rẹ ni n óo máa wá, OLUWA,
Ṣugbọn ohun to mumu julọ laya rẹ ni orileede ti yoo ba awujọ agbaye pe ati igbe aye idẹrun fun mutumuwa.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Pásítọ̀ ọmọ Nàìjíríà, Omotoso, tí wọ́n fi ẹ̀sùn ìfipábánilòpọ̀ kàn pàdánù ìwé ìgbélùú ní South Africa Ẹ̀yin òṣìṣẹ́, ẹ kọ ìyà tí wọ́n fi ń jẹ yín lórí owó oṣù tuntun - Oshiomole gbarata Àwọn Pásítọ́ ijọ Redeem márùn ún bọ́ sọ́wọ́ ajínigbé ní Ijebu Ode Ó tó gẹ́ẹ́!
Lara awọn sọrọ to sọ ni pe '''awọn ọlọla ni orilẹede Naijiria yoo wọ wahala ti wọn ko ba tọju awọn alaini ati awọn mẹkunu to wa ni awujọ.
Ìgbà tí Èṣù dé ibẹ̀ ó ní, “Ẹ bẹ̀rẹ̀ kẹ” bí ó ti wí báyìí tán, ṣe ni ọkùnrin ki ọmọ owú mólẹ̀ tí ó bẹ̀rẹ̀ si í fẹ́ ọ mọ obìnrin lórí, lẹ́yìn èyí, Èṣù ní, Wòó bí ọkùnrin náà ti ń fọ irin mọ́ obìnrin lórí, bẹ́ẹ̀ ni tọkọtaya ni wọ́n?
Asọ yìí bákan náà gbòde kan láti inú osù kẹsan ọdún 2018.
Iye owo ti awon oludije yoo maa fi gba  iwe idije niwonyi; alaga egbe- ẹ̀gbẹ̀rún lẹ̀ẹ́dẹ́gbẹ̀ta naira( N500,000), awon ipo to tun powo le ti alaga egbe yoo maa san  – ẹ̀gbẹ̀rún lòjìlénígbalémewaa naira( N250,000), awon yoo ku yoo maa gbawe idije yii pelu – ẹ̀gbẹ̀rún lonaọgọ́rùn ún naira –(N100,000).
Ire ni kí ẹ máa wá, kì í ṣe ibi kí ẹ lè wà láàyè; nígbà náà ni OLUWA Ọlọrun àwọn ọmọ ogun yóo wà pẹlu yín, bí ẹ ti jẹ́wọ́ rẹ̀.
Òṣìṣẹ́ OSCOTECH gb'òmìnira lọ́wọ́ ajínigbé darandaran Fulani Fulani darandaran lo iwa ipa ni guusu Akurẹ 'Iha kokanmi Buhari lewu fun Nigeria' Gani Adams kilọ f'awọn darandaran Ọyọ yoo da papa ijẹko silẹ Ibẹru ipalara awọn darandaran mu'pinlẹ Ogun Àkọlé àwòrán, O to gẹẹ lori ọrọ ikọlu nilẹ Yoruba Gbogbo iṣoro ti ko fi àwọn eniyan Yoruba lọkan balẹ yii naa ni wọn ro papọ.
Ogbeni Nur Sherrif naa soro lori ogbe okan re lati igba ti awon onise ibi boko haram ti kolu ibudo Rann nibi ti omo ogun mejo ati awon osise aranilowo marun un ti gbemi mi ni awon toro kan ti kuro nibe.
IlorinDurbar: Emir Sulu-Gambari léwájú àwọn èèkàn ẹlẹ́ṣin níbi àjọ̀dún Dubar nílú Ilọrin
    Ní àkókò tí Òmùgọ́dimẹ́ta fi ń ṣe tí oyè yìí mo bẹ ààfin wo tó ìgbà mẹ́ta, nítorí kò sí ìgbà tí mò ń dé òhún tí ìyá rẹ̀, Ìlábùrù ko ń kí mi dáadáa.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Sextuplet: Àdúrà Ìbùkún ló kú lẹ́yìn ọmọ mẹ́fà yìí- Ifeoma Thelma àti Onyemaechi Chiaka Ọjọgbọn Feyi mẹnuba oriṣii awọ oju ti eeyan le ni boya rẹsurẹsu ni tabi dudu, tabi awọ ayinrin tabi olomi aro.
fenuko le lori nibi ipade Abidjan to waye lọdun 2017 ati awon nnkan miiran, won
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Dókítà Trump: Trump ló kọ èsì ìlera rẹ̀ lásìkò ìbò 2 Èbibi 2018 Oríṣun àwòrán, EPA Àkọlé àwòrán, Ọdun 2015 ni wọn se ayẹwo oni wakati mẹta fun Aarẹ Donald Trump Dokita Aarẹ Donald Trump ti ilẹ Amerika ti sọ wi pe, oun kọ loun kọ lẹta to juwe ilera ara Trump lọdun 2015, gẹgẹbi ilera to peye ti ko ni abuku.
Buhari gba ife ẹyẹ agbaye Ta ló máa gba iṣẹ́ lọ́wọ́ Theresa May?
4 291285 Orilẹede Croatia 4550 109.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé Ṣugbọn ọrọ naa dojuru lẹyin ti awọn oṣiṣẹ NIMC daṣẹ silẹ nitori ibẹru pe arun ọhun le de wọn lalejo bi ọpọ ero ṣe n ya bo ileeṣẹ wọn.
Nkechi Blessing: Àgbo tí yóò mú mi tíírín ti jẹ́ kí ìbàdí mi lọ sílẹ̀
Bẹ́ẹ̀ ni ó máa ń sọ sí wa nígbà tí inú wa bá dùn tí a bá ń fi í ṣe yẹ̀yẹ́.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Abule Ado explosion: Irọ́ ńlá ní NNPC pa lórí ìbúghbàmù Abule Ado níbí tí ẹ̀mí èèyàn 23 Awọn eeyan marundinlọgbọn lo farapa ninu ijamba ọhun.
Nígbà tí ilẹ̀ bẹ̀rẹ̀ sí ṣú ní àwọn Ẹnubodè Jerusalẹmu kí ó tó di ọjọ́ ìsinmi, mo pàṣẹ pé kí wọ́n ti gbogbo ìlẹ̀kùn, ati pé wọn kò gbọdọ̀ ṣí i sílẹ̀ títí tí ọjọ́ ìsinmi yóo fi rékọjá.
Bi ere bi ere ni ifẹsẹwọnsẹ wọn pẹlu Wolves bẹrẹ amọ nigba ti wọn yoo fi de ipari abala kini,Arsenal ti lọ mu bọọlu ninu awọn nigba ẹmẹta.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Èrò àwọn ènìyàn nípa ikú Khadijat Olubọyọ Minisita fọ́rọ̀ ilẹ̀ òkèèrè kọ̀wẹ́ fipò sílẹ̀ NYSC: Kí ni òfin sọ nípa ìwé ẹ̀rí fún àyẹwò iyansipo?
Ẹni tí ó bá ru òkú ẹran náà gbọdọ̀ fọ aṣọ rẹ̀, yóo sì jẹ́ aláìmọ́ títí di ìrọ̀lẹ́ ọjọ́ náà.
Ajọ EFCC ṣalaye loju opo Facebook rẹ lọjọ Aje wi pe, lootọọ ni Magu lọ farahan niwaju igbimọ ijọba to ṣayẹwo iṣẹ EFCC lọjọ Aje niluu Abuja.
Lori orukọ rẹ, ti ọpọ ti maa n wadii ohun to tumọ si, nitori pe kii ṣe orukọ to wọpọ nilẹ Yoruba, Kunle Afod sọ pe: Orukọ mi, Afod kii ṣe inagijẹ"" ."
kí ó tó já Bakan naa ni awọn kan sọ wi pe lati inu iwe ti Geoffrey Chaucer kọ to pe orukọ rẹ ni Canterbuty Tales ni ayajọ ọjọ itaja naa bẹrẹ.
Ṣugbọn bí ẹ kò bá dáríjì àwọn eniyan, Baba yín kò ní dárí àwọn ẹ̀ṣẹ̀ yín jì yín.
Bẹẹ ba gbagbe, ọjọ Aje ni Ileesẹ Ọlọpaa ipinlẹ Oyo ṣe afihan oju awọn afurasi to ji ibeji Akeugbagold gbe lọ, ki wọn to ri wọn pada, ti Opeyemi si wa lara awọn afurasi naa.
Ni bayii na, ijọba ipinlẹ Plateau ti kede pe ki onile o gbele lawọn adugbo ti rogbodiyan naa ti waye.
Ẹ̀rù mi kò tilẹ̀ bà yín?
O sa kuro ni ọgba ẹwọn ni ọdun 2011 lẹyin ti adajọ pasẹ fun pe ki wọn yẹ igi fun.
“Nígbà tí ẹ bá kọjá odò Jọdani sí òdìkejì, àwọn ẹ̀yà Simeoni, ẹ̀yà Lefi, ti Juda, ti Isakari, ti Josẹfu ati ti Bẹnjamini yóo dúró lórí òkè Gerisimu láti súre.
Oyinkan Abayomi: Ajàfẹ́tọ̀ọ́ ẹni tó dá ẹgbẹ́ òṣèlú obìnrin àkọ́kọ́ sílẹ̀, tó tún jà fún ètò ẹ̀kọ́, ìṣèlú àti òmìnira obìnrin
Bẹẹ ba gbagbe, lọdun to kọja ni iroyin gba ilẹ kan nilu Akure pe ọmọ ọdun kan, Gold Babatunde di awati lasiko to wa ni ijọ awọn ọmọde inu ijọ Sotitobire nilu Akure.
"Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ileesẹ aarẹ ni ariwo ati atako lati ọdọ awọn ẹgbẹ osisẹ, ẹka idokoowo lo sokunfa bii aarẹ se jawọ ninu adehun AfCFTA "" Ohun ti o yẹ fun orilẹede yii ni pe ko si bi o se lee kopa to jọju ninu eto idokoowo agbaye pẹlu bi nkan se ri pẹlu ẹka osisẹ rẹ ati gbogbo ẹka ọrọ aje rẹ."
Aarẹ Buhari koju ipenija ninu ibaṣepọ rẹ pẹlu ile igbimọ aṣofin lori ọrọ iyanni sipo ati ilana aba eto isuna, ati bẹẹ lọ.
Ọlọrun tún bi í pé, “Ǹjẹ́ o ṣàkíyèsí Jobu, iranṣẹ mi, pé kò sí olóòótọ́ ati eniyan rere bíi rẹ̀ ní gbogbo ayé.
Ní ọdún 1998, Sani Abacha, tí ó jẹ́ ológun apàṣẹwàá ní ìgbà náà, pè fún ìbò gbogboògbò ṣùgbọ́n tí ó hàn ketekete pé Abacha kò ṣetán láti gbé ìjọba sílẹ̀ fún alágbádá.
Iwe “Purple Hibiscus” Adichie lo gba ami ẹyẹ ‘Commonwealth Writers’ tọdun 2003.
Gẹgẹ bi a ṣe gbọ ajọṣepọ laarin iks amọtẹkun atawọn ọmọ ikọ alaabo alajọṣe JTF ni ipinlẹ naa lo ṣokunfa mimu ti wọn mu awọn ajikusa wa naa pẹlu ajọṣepọ araalu.
Agbábọ́ọ̀lù Super Falcons tẹ́lẹ̀, Chiejine jáde láyé lẹ́ni ọdún 36 PFN: Fatoyinbo kọ̀ láti yọjú ni ìwádìí wa kò ṣe parí Ilé iṣẹ́ márùn ún tí wọ́n dárukọ kìí ṣe túntun- Garba Shehu FRSC dá N443,180 padà fún ẹbí ẹni to ní ìjàmbá mọ́tò Ọlọ́pàá Germany ń wádìí àfurasí mẹ́rin nínú àwọn tó kọlu Ekweremadu ni Germany Iṣẹ́ bọ́ lọ́wọ́ ọlọpàá mẹ́rìn to pa afurasí, wọ́n tún dèrò ẹ̀wọ̀n Adetuberu ṣalaye ninu atẹjade ọhun pe lootọ ni pasitọ Akinola Akinwale pe Fatoyinbo lori aago pe ko wa farahan niwaju igbimọ PFN, ṣugbọn COZA sọ fun un pe ko le wa nitori iwadii si n lọ lọwọ lori ẹsun ti Busola fi kan an.
Attah ni ọrọ osisẹ naa ko ba ara wọn mu ni awọn se pe dokita lati wa se ayẹwo fun ọkunrin naa, ti o si ti wa ni ile iwosan lọwọlọwọ.
Ọjọ ́ ewì ayaba ti pẹ ́ láwùjọ yorùbá .
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ajínigbé: Afurasi Ajínigbé jí ọmọkùnrin kan gbé ní Ibadan, ọwọ́ tẹ̀ẹ́ ní Eko 9 Agẹmo 2019 Ẹnu ko gba iroyin ni deede aago meje alẹ ọjọ Isẹgun ni adugbo Ikoyi nilu Eko, nigba ti ọwọ palaba ọkunrin afurasi kan, ti a ko mọ orukọ rẹ, segi.
Ìbálé ìyàwó: Àwọn onímọ̀ sọ ìdí tí àwọn obìnrin kan kìí ṣe sẹ̀jẹ̀ lẹ́yìn ìbálòpọ̀ àkọ́kọ́
Lẹyin iṣẹju meji pere si igba naa ni ẹlẹsẹ ayo Olivier Giroud fi ọba le fun Chelsea eyi ti o mu Chelsea siwaju pẹlu ayo meji sodo.
Máa kọrin sókè, ìwọ tí kò rọbí rí.
Atiku gba ilé ejọ́ tó ga jùlọ, ó ní òun ló jáwé olúborí nínú ìbò ààrẹ Ìbọ̀wọ̀ fófin ni bí wọ́n se fi Sowore sílẹ̀ Ẹ̀kọ́ ńlá ni ọ̀nà tí Ghana fi paná ìdìtẹ̀gbàjọba tó yẹ kó wáyé níbẹ̀ Ninu atẹjade kan ti ajọ NYSC fi lede, mẹta ninu awọn agunbanirọ ọhun sọ pe wọn kẹkọjade ni Fasiti Istop, to wa ni Cotonou, sugbọn eyi to jẹ irọ funfun balau.
Nigba ti gomina Ajimobi gboriyin fun Makinde latari iwa
 Awon eniyan meji lo ti padanu emi won , ti awon eniyan méjílélọ́gọ́ta si ti farapa yana-yana.
 kókó inú ìwé ìtàn eré oníṣe yìí ni wípé kí a má ṣe ìkà .
Labẹ iṣejọba rẹ, orilede Egypt ko ipa adari lati ri i pe ibadowo pọ wa laarin orilede Israel ati Palestine.
Vibrator -Ǹkan ìṣeré ìbálòpọ̀ mi ńpaná iṣẹ́ mọ́ mi lára'
Sanwo-Olu ni didari Ipinlẹ Eko kii ṣe ere ọmọde nitori atari ajanaku ni, kii ṣe ẹru ọmọde.
Ogbomosho shooting, End Sars, End SWAT: Isiaka Jimoh fi ọmọbìnrin kan àti ìyàwó tó lóyún sínú sílẹ̀ ló- Òbí Isiaka
Idí rèé ti Oyetola ṣi maa ṣe gomina Osun lọ titi ti ile ẹjọ kotẹmilọrun ba to ṣe idajọ tirẹ.
Àwòrán ìhòhò: Salawa Abeni ti sọ̀rọ̀, ẹgbọ́ ohun tó wí Àwọn ojú oge Yollywood t'ọ́jà wọ́n ṣì ń tà wàràwàrà Ẹ̀mí mi yi gan, Coronavirus kéré sí nọ́mbà mi- Ṣeyi Makinde Wo àwọn ohun tó yẹ kí o mọ̀ nípa àrùn Coronavirus àti ìbálòpọ̀ akọ àt'abo Èèyàn 23 míì tún ti ní àrùn Coronavirus ní Naijiria Eyi lo difa fun Ọọni ile Ifẹ, Ọba Adeyẹye Ogunwusi ti ke sawọn alalẹ ilẹ yii lati le arun Coronavirus to gbode kan bayii wọgbo.
Ọjọ kọkandinlogun oṣu kinni ọdun 2021 ni ijọba apapọ Naijiria ti sun gbedeke ṣiṣeto asopọ nọmba idanimọ apapọ ilẹ Naijiria, NIN ati nọmab ibanisọrọ awọn ọmọ orilẹede Naijiria kọọkan mọ si bayii.
Bakan naa, o fi kun oro re pe, igbese ile-ifowopamo ohun ni lati mojuto oja owo ori ile-okeere, gege bi o se han nipa sise adinku owo ori oja ti won n ra wole.
Fun idi eyi o ti ni ọmọ tuntun naa yoo ma jẹ orukọ pẹlu Ooni Tadenikawo Adesoji Aderemi to jẹ Ooni ṣaaju.
Ṣugbọn ó sọ fún Daniẹli pé, “Ọlọrun rẹ tí ò ń sìn láìsinmi yóo gbà ọ́.
Eyi ni awọn ohun to ṣẹlẹ lagbo awọn oṣere tiata lọsẹ yii.
State Police: Buhari pariwo síta, ó ní èmi kò buwọ́lu ètò ọlọ́pàá agbègbè o!
Ọmọ Italy kan lo kọkọ gbe e wọle.
Ǹjẹ́ ìnira kò ní ba yín, bí ìrora obinrin tí ń rọbí?
Òkùnkùn biribiri ni ìjìyà ẹ̀ṣẹ̀ ìjọba ìbílẹ̀ mẹ́fà nílẹ̀ Ìjẹ̀ṣà tó na òṣìṣẹ́ àjọ amúnáwá Ọmọ Nàíjíríà tó jẹ́ Ìmáàmù mọ́ṣálásí tí wọn kọlù ní New Zealand ṣàlàyé ìṣẹ̀lẹ̀ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Collapsed Building: Ayálégbé ló dára bí ìjọba ṣe wólé àmọ́ wọ́n fẹ́ ìrànwọ́ ilé míràn Koda posi ti ko si oku ninu rẹ ni wọn bo mọ lẹ ni olu ilu Ethiopia tii ṣe Addis Ababa lati le maa ṣe iranti awọn to ku ninu iṣẹlẹ ọhun.
Agbébọn pa ènìyàn 14, ọmọọ̀gun Naijiria sígun ni Kaduna Kíni yóò sẹlẹ̀ sí àwọn òsìsẹ́ Diamond Bank?
Òkìtì kìínì kìíní kún fún egungun ènìyàn, èkejì kún fún egungun ẹranko, ẹ̀kẹta jẹ́ ti ejò, ẹ̀kẹrin jẹ́ ti ẹja, ẹ̀karùn-ún jẹ́ tí ẹyẹ, ẹ̀kẹfà jẹ́ ti àwọn kòkòrò, bẹ́ẹ̀ ni èkeje jẹ́ ti àwọn eṣinṣin, ṣùgbọ́n òkìtì keje yìí kò kúkú ní egungun bí i tí àwọn ìṣáájú, ó ní iṣan tẹ́ẹ́rẹ́tẹ́ẹ́rẹ́ báyìí, àwọn wọn-ọnnì ni ó  dúró gẹ́gẹ́ bí egungun.
Ọ̀nà tí a fi mọ Ẹ̀mí òtítọ́ ati ẹ̀mí ìtànjẹ yàtọ̀ nìyí.
Lamidi Adeyemi Jọba lẹ̀yìn Gbadegesin Ladugbolu lọdún 1970 lásìkò gomínà Robert Adeyinka Adebayo lẹ́yìn ogun abẹlé Nàìjíríà, bakan naa ní ààrẹ ológun Muritala Ramat Mohammed náà yàn láti kọ́wọ̀ rìn pẹ̀lú rẹ̀ lọ sí Hajj.
Awon ebi awon oloogbe nibi isele naa ni egbe ile enikookan kedun awon eni won to lo nigba ti awon miran binu sawon alase lori isele naa pe won ko pese iranwo to ye lasiko.
 orúkọ ̀ bàbá rẹ ̀ ni ìyàngèdè .
ó fi ẹni tí ó wà láàyè lae ati títí laelae búra, ẹni tí ó dá ọ̀run ati ohun tí ó wà ninu rẹ̀, tí ó dá ayé ati ohun tí ó wà ninu rẹ̀, tí ó dá òkun ati ohun tí ó wà ninu rẹ̀.
Bẹẹ ni ọrọ yoo ri fun gbajugbaja agbabọọlu nni, Cristriano Ronaldo ti o ba koju ẹgbẹ agbabọọlu Manchester United lalẹ ọjọ isẹgun ninu idije Champions League pẹlu awọn akẹgbẹ rẹ lati ẹgbẹ Juventus.
5 milionu naira' Owo oṣu rẹ melo ni wọn ma yọ ninu owo oṣu aṣofin kan lorilẹede Naijiria?
Sugbọn ti omi mimu ko ba to o ma njẹ ki awọ ara ṣe rakọrakọ ti o si yi bi ara agiliti.
“Sọ fún àwọn ọmọ Israẹli pé kí wọ́n yan àwọn ìlú ààbò tí mo bá Mose sọ nípa rẹ̀, pé kí ó sọ fun yín.
Sebadaya, ọmọ Iṣimaeli, tí ó jẹ́ gomina ní Juda ni alabojuto lórí ọ̀rọ̀ ìlú, àwọn ọmọ Lefi yóo sì máa ṣe òjíṣẹ́ yín.
5 22499 Orilẹede Mauritania 188 4.
Baba oloselu kan wa, to gbajumọ lorilẹ-ede Naijiria, oun si la ba maa pe ni afọbajẹ, oun gan ni baba isalẹ oselu.
Nítorí alabojuto ìjọ níláti jẹ́ ẹni tí kò lẹ́gàn gẹ́gẹ́ bí ìríjú Ọlọrun.
Òfin tuntun ọ̀hún ti yóò bẹ̀rẹ̀ ní ọjọ́ keji, oṣù kẹwàá, ọdun 2018 sàlàyé lóri ìgbésẹ tó ṣe pàtàkì láàrin ilé ìfowópamọ àti àwọn oníbara wọn lásìkò ti wọn bá ń fi owó ranṣe sí ènìyàn MTN, Banki mẹ́rin wọ gàù CBN ‘Báwo ni iléesẹ́ òfúrufú se ná 462 mílíọ́nu dọ́là?
Wọn ni awakọ naa papa sa kuro nile iwosan ti wọn yaa sọtọ si, to si n dunkoko lati tan arun naa kalẹ ayafi ti awọn mọlẹbi ọkunrin naa ba san milinu lọna ọgọrun naira.
Kogi FMC: Àwọn Jàndùkú kó àwọn àkọsilẹ̀ ilé ìwòsàn, ẹ̀rọ kọ̀mpútà ati fóónù àwọn dókìtà lọ
Iroyin sọ pe Oluomo ti sọ ọ̀rọ̀ yii lati ọdun to kọja lasiko ti gomina n gbe aba eto isuna ti ọdun yii siwaju ile ẹjọ.
Nígbà tí ejò kan bẹ̀rẹ̀ sí lọ́ mọ́ Ìjàǹbáforítì lára kiri ara Ìjàǹbáforítì kọ ìyà yìí nítorí ejò náà bẹ̀rẹ̀ láti ẹsẹ̀ rẹ̀ ó sì tọ̀ ọ́ títí dé èjìká.
Kí ẹ máa fi ìfẹ́ bá ara yín lò nípa ìfaradà.
Àwọn eniyan láti inú gbogbo ẹ̀yà, ati gbogbo orílẹ̀-èdè yóo máa wo òkú wọn fún ọjọ́ mẹta ati ààbọ̀.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ààrẹ Buhari, Ezekwesili, àti àwọn olùdíje míràn tọ́wọ́bọ̀wé àjùmọṣe àláfìà Buruji Kashamu ni Awolọwọ àsìkò yìí - Igun PDP Ṣẹ̀ s’ófin ìrìnà l‘Eko, ko fi ẹ̀wọ̀n ọdún mẹ́ta jura - Ìjọba Eko Kíni ìdí tí àwọn obìnrin tó wà nípò kò fi lágbára?
Oríṣun àwòrán, Others Ere Tinko Tinko: Awọn obinrin lo fẹran ere yii julọ nitori pe awọn meji ni yoo koju ara wọn, ti wọn yoo si ma a kọrin bii ere naa ṣe n lọ.
Baba rẹ, tí ó rí ohun tí ó wà ní ìkọ̀kọ̀, yóo san ẹ̀san rẹ fún ọ.
Wọ́n bá dá ìrúkèrúdò sílẹ̀ ninu ìlú.
Kiiṣe nkan to dara rara ti eyi ba n ṣẹlẹ nitootọ.
Ipinlẹ Eko: Àkọlé àwòrán, Gomina sanwo-olu ti ipinlẹ Eko ati ẹbi rẹ.
Aláìṣeégbẹ́kẹ̀lé ni wọ́n, aláìnífẹ̀ẹ́, ati aláìláàánú.
5 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Lagos Senatorial Elections: Abiru ṣ'àbẹ̀wò sí Tinubu lẹ́yìn tó wọlé àtúndi ìbò Sẹnẹtọ ìlà oòrùn ìpínlẹ̀ Eko7 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 11:29 Fídíò, EndSARS: Olatunde Abolarinwa London Tailor ní òun á ṣe baba fún mi, kò tilẹ̀ dúró ṣe bàbá àwọn ọmọ tirẹ̀ tóríi ìwà Ọlọ́pàá Mopol, Duration 11,295 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Èyí tí a wò jùlọ 5:03 Fídíò, Omolola Arohunmolase Welder: Mo ti fí iṣẹ́ 'Welder' gbayì láwùjọ, tó mo fi tọ́ ọmọ yanjú, Duration 5,039 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 5:39 Fídíò, Akomolede ati Asa lori BBC: Olùkọ́ Kikelomo Ogunboye tan ìmọ́lẹ̀ sí ìwà olè ọ̀gá ọlọ́pàá Audu gẹ́gẹ́ bí àwòkọ́ṣe àsìkò yìí, Duration 5,398 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 4:11 Fídíò, Oba Adeyeye Ogunwusi: Ojú mi ti rí lọ́pọ̀ lọpọ̀, ọ̀pọ̀ èèyàn ni kò tilẹ̀ gbàgbọ́ pé mo lè jọba- Ooni, Duration 4,117 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 4:43 Fídíò, Promise Akinlade: ọmọ ọdún mọ́kànlá tó ń fi ìlù dárà bíi àgbàlagbà sọ̀rọ̀ nípa tálẹ́ǹtì rẹ̀, Duration 4,437 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 0:59 Gbọ́, Ìsẹ̀lẹ̀ jákèjádò orílẹ̀èdè àgbáyé láàárín ìṣẹ́jú kan, Duration 0,59wákàtí 5 sẹ́yìn 7:03 Fídíò, Olumuyiwa Bolade Adedeji Military Bruitality: Bí arákùnrin onípèníjà ara tí sọ́jà lù ṣe dé, Duration 7,035 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 4:45 Fídíò, Yoruba Films: Ẹ̀ẹ́ bẹ̀ mi kúrò láyé ni, mi ò lè kú - Fadeyi Oloro, Duration 4,4526 Èrèlè 2020 2:48 Fídíò, Esther Ajayi: Èmi náà ti borí ìṣòro rí ló ń mu mi ṣojú àánú, Duration 2,481 Ògún 2019 6:08 Fídíò, Adebola Ademilua: Àìrísẹ́ ṣè lẹ́yìn ìwé kíkà ló sọ mi dí ìyá onírú, mo dúpẹ́ tèmi, Duration 6,0827 Bélú 2020 5:55 Fídíò, Soyinka Cancer: Àṣe ara mi ni iso ti n run gbogbo bí mo ṣe n ṣèrànwọ́ lórí jẹjẹrẹ, Duration 5,5527 Bélú 2019 BBC News, Yorùbá Ìdí tí ẹ fi le è nígbàagbọ́ nínú ìròyìn BBC Ìlànà Lílò Nípa BBC Òfin Àṣírí Cookies Kàn sí.
Aare Buhari fikun un oro re pe, okan ohun wa pelu awon eniyan ti isele ohun sele si lakoko inira won.
Irinna oko oju irin lati ipinle Eko si Kano bere nipa gbigbe awon egberun eniyan.
Koda iroyin naa fidi rẹ mulẹ pe awọn janduku naa tun ya aṣọ mọ olori ile naa tẹlẹ, Jumọkẹ Akindele lọrun lasiko ti gbogbo rukerudo yii fi waye.
Iya awọn ibeji naa sọ wi pe inu oun dun de bi wi pe oun ko mọ oun ti oun le sọ, ti o si dupẹ lọwọ awọn oṣiṣẹ ile iwosan naa fun bi wọn ṣe saanu fun wọn.
Ìwọ̀n tí wọ́n ń lò ní ibi mímọ́ ni wọ́n fi wọ̀n ọ́n.
Koda awọn onimọ to n fi oku kọṣẹ iṣegun maa n lo taba lati pa oorun oku.
Ni afikun, wọn rọ ijọba lati sọ fawọn ile ijọsin ati ẹka idajọ lati maa lo esi ayẹwo ẹjẹ gẹgẹ ọkan lara amuyẹ fun igbeyawo.
Ẹrí rè é, Sanwo-Olu ṣèlérí lóòtó lórí súnkẹrẹ-fàkẹrẹ Apapa Gani Adams: Iléèṣẹ́ ọlọ́pàá ti kàn sí OPC lórí ètò ààbò Ayinla Ọmọwura, orin èébú àti oríyìn lo fi di ọ̀rẹ́ àwọ̀n obìnrin A kò fẹ́ Festus Adedayo ní ìjọba Buhari - Àwọn olólùfẹ́ APC yarí Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
O ni ọna mẹta ni ijọba yoo gba mu awọn ti yoo janfani eto naa.
A kò ní fara mọ́ fífi àkókò ṣòfò lórí ẹjọ́ Sotitobire - Ìjọba Ondo Wo bí ọwọ́ orílẹ̀-èdè Dubai ṣe tẹ Ramoni Igbalode tí gbogbo ayé ń pè ní Hushpuppi Ìtàn ìgbésí àyé olóògbé Isiaka Abiola Ajimobi Omijé bọ́ níbi ìsìnkú Ogun Majek Tun orukọ ẹgbẹ naa ṣe l'oju awọn ọmọ Naijiria Lati bi ọdun melo kan, ni awọn ọmọ Naijiria lo da bi ẹni pe orukọ ẹgbẹ naa ati awọn olori ẹgbẹ APC, ti n dibajẹ lọkan awọn ọmọ Naijiria.
Awọn mẹtẹẹta naa ni Aminu Usman to jẹ ọmọ ọdún mẹẹdọgbọn, Ibrahim Iliyasu to jẹ ọgbọ̀n ọdun àti Abdulrahman Umar to jẹ́ ọdún mẹẹdọgbọn.
Idi niyi ti won ṣe rọ musulumi lati tiraka lati ṣe gbogno nkan wọnyi ninu oṣu mimọ yii.
Nígbà tí Ṣekemu ọmọ Hamori, ará Hifi, tíí ṣe ọmọ ọba ìlú náà rí i, ó fi ipá mú un, ó sì bá a lòpọ̀ tipátipá.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Njẹ o le dọrẹ pẹlu awọn eleyii?
Ó sì dáná sun ẹran ati awọ mààlúù náà lẹ́yìn ibùdó.
N óo pa àwọn eniyan rere ati àwọn eniyan burúkú tí ó wà ninu rẹ run, nítorí náà, n óo yọ idà mi ninu àkọ̀ rẹ̀, n óo sì bẹ̀rẹ̀ sí pa gbogbo eniyan láti ìhà gúsù títí dé ìhà àríwá.
Lara ẹṣẹ ti ọpọ tun sọ pe Ribadu ṣẹ ni pe, ko sọ otitọ nipa iye dukia rẹ to kede.
A tún ń fi àwọn ìṣòro wa ṣe ọlá, nítorí a mọ̀ pé àyọrísí ìṣòro ni ìfaradà; 
Ẹwẹ, aarẹ orilẹede naa kede laipẹ yii pe irin-ajo ọkọ ofurufu yoo bẹrẹ pada lọjọ kinni oṣu kẹsan.
Síbẹ̀síbẹ̀, mo ti jìyà nítorí ìwà pálapàla yìí.
Ọdun 2013 lo kọkọ salọ kuro lorilẹede Naijiria, amọ to yọ pada wale ni ọdun 2017, ti ọwọ palaba rẹ si sege.
Bí ọkunrin kan bá bá obinrin lòpọ̀ ní àkókò tí obinrin yìí ń ṣe nǹkan oṣù rẹ̀, lílé ni kí wọ́n lé àwọn mejeeji kúrò ní àdúgbò, kí wọ́n sì yọ wọ́n kúrò láàrin àwọn eniyan wọn.
“Gbọ́ bí mo ti ń kérora,kò sí ẹnìkan tí yóo tù mí ninu.
” Bush je obinrin ilumoka jakekado pelu irun un funfun ori re, pelu aabo ti ko legbe ti o da bo ebi re.
Kano-Niger rail line: PDP ní àìmèyí tó kàn n'ìgbèsẹ̀ ìjọba láti ná $1.
Aare egbe awon osise lorile ede
Wọ́n pa ogun wọn pọ̀ ní àfonífojì Sidimu.
Ẹ má wo ojú eniyan ṣe ìdájọ́, ṣugbọn ẹ máa ṣe ìdájọ́ ẹ̀tọ́.
Buhari ṣabẹwo si Kaduna Aarẹ Muhammadu Buhari sọ pe ijọba apapọ orilẹede Naijiria ti ṣetan lati ṣe iwadii, ti yoo ṣi aṣọ l'oju eegun awọn aṣekupani ọhun.
Adájọ́ Ibrahim Sarki Yola ni bàbá náà jẹ̀bi ẹ̀sùn fífi ipá bá ọmọ ọdún mejila kan lò pọ̀.
Ijọba Naijira ko tii sọ ohunkohun lori fọran ọhun, bẹẹ naa ni ẹgbẹ Islamic State ti Iwọ oorun Afrika ko ti sọrọ kankan nipa rẹ.
’ Ààrẹ Buhari ti lọ sí ìlú Daura fún ọdún Sallah Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, ''Ọjà ẹran àgbò kò yá bí ti ọdún tó lọ'' Bakan naa ni Gomina ipinlẹ Ogun, Dapo Abiodun, Gomina ipinlẹ Ọyo, Seyi Makinde naa pe fun ki awọn ọmọ Naijiria ati awọn ẹlẹsin musulumi lo asiko Sallah yii lati fi kọ ẹkọ pataki lara ojisẹ Allah, Ibrahim to ni ibẹru Ọlọrun, to si pa ofin rẹ mọ titi ọjọ aye rẹ ninu ifẹ.
ṣadinkun iwa odaran ni ipinlẹ yii Amofin Femi Falana, to jẹ agbẹjọro agba lorilẹ-ede Naijiria (SAN) pe ipe yii nibiIpade Ita-gbangba awọn alenulọrọ fun atunṣe Ofin ti wọn fi ṣagbekalẹIkọ Ẹṣọ Alaabo ilu labẹle ni Ipinlẹ Eko, ti a mọ si Lagos StateNeighbourhood Safety Corps (LNSC) yii.
omo omo bishop samuel ajayi crowther ni .
Ṣugbọn bí wọ́n bá kọ̀, tí àwọn náà dìde ogun si yín, ẹ dó ti ìlú náà.
Idije ti 2018 n waye laarin ọjọ karun un si ọjọ kẹrinlelogun, oṣu Kẹjọ.
" Agba Inaki ni ko rọrun rara nigba ti oun kọkọ de South Africa sugbọn oun dupẹ pe oun ri ọna abayọ bayii.
Kò yẹ kí ìjọba máa ní àwọn mẹ̀kúnú lára lásìkò Coronavirus yìí- Rewane Akitiyan ìjọba láti mú kí àwọn ọmọ Nàìjíríà san owó orí Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 3 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 5 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Coronavirus in Nigeria: Àwọn ọmọ Nàìjíríà bu ẹnu àtẹ́ lu ètò ìsìnkú Abba Kyari, wọ́n ní ó tako ìlànà ìjìnàsíraẹni
Ẹ lè lo ọ̀rá ẹran tí ó kú fúnra rẹ̀ ati ọ̀rá èyí tí ẹranko burúkú pa, fún ohun mìíràn, ṣugbọn ẹ kò gbọdọ̀ jẹ ẹ́.
mo si ti ṣiṣẹ fún ọpọlọpọ aarẹ Naijiria mii."
Ọdún kẹta kẹta ni wọ́n máa ń pada dé, wọn á sì máa kó ọpọlọpọ wúrà, ati fadaka, eyín erin, ìnàkí, ati ẹyẹ ọ̀kín bọ̀.
Ni ipari, ifigagbaga ipele keta si asekagba idije Davis Cup ohun yoo waye lojo kefa si ojo kejo inu osu kerin-in odun ti a wa yii.
“Ṣugbọn ọlọ́gbà àjàrà náà dá ọ̀kan ninu wọn lóhùn pé, ‘Arakunrin, n kò rẹ́ ọ jẹ.
Ẹ̀wọ̀n gbére ni fún ẹnikẹ́ni tó bá fipá bánilòpọ̀ ní ìpínlẹ̀ Ọ̀ṣun Wákàtí márùn ún márùn ún ní wọ́n ń fipá bá obìnrin kàn lò pọ̀ ní Nàìjíríà- Ọga Ọlọpaa Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, JusticeforUwa:Awọn àkẹkọ̀ọ́ Uniben wọ́de ìfẹ̀hónú hàn nítórí Uwa tí wọ́n fipa bálòpọ̀ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Justice for Uwa: Bàbá Uwa, akẹ́kọ̀ọ́ fásitì tí wọ́n fipábálòpọ̀ ní Benin bá BBC sọ̀rọ̀ Uwaila jẹ akẹkọọ ipele ikini ninu imọ ẹkọ Microbiology ni fasiti Uniben ti awọn obi rẹ si ni ọmọ to da yatọ ni laarin gbogbo ọmọ ti Ọlọrun fun wọn.
Nọọsi agba nileewosan University Hospital Coventry lo fun ni abẹrẹ naa.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Odumakin sọrọ lori Fulani darandaran Ọ̀rọ̀ ètọ ààbò ilẹ̀ Yorùbá ti gba àpérò ọmọ eríwo, àwọn orí adé àti gómínà pé ìpàdé pàjáwìrì lórí ọ̀rọ̀ ìjínigbé.
Lẹyin naa lo jẹ Ọlọrun nipe ni ọjọ kẹtala, oṣu kẹrin, ọdun 1978 kan naa.
Ibas ni, inu aarẹ Buhari dun si igbesẹ awọn ẹsọ eleto aabo lorilẹede Naijiria pẹlu akitiyan wọn lati bori ikọ agbesunmomi ati eto aabo to mẹhẹ kaakiri ẹkun to wa lorilẹede naa.
Oludamọran fun Gomina ipinlẹ Kano, Fatima Abdullahi Dala, to ba BBC sọrọ ṣalaye pe Du Merci ti wa fun bi ọdun mẹẹdọgbọn lai niwe ofin.
Usman vs Masvidal: Àlùbami ní Kamuru na Jorge Masvidal láti dí Àmí Ẹ̀yẹ rẹ mú!
Àwọn t'Ojuẹlẹgba l'Eko sọ̀rọ̀ nípa iṣẹ́ oògùn olóró lára
Ẹ gbọ́ orin ti àwọn ọmọ ilé iwé ńkọ ni àsikò eré-ìbílẹ̀ ni ojú iwé yi.
Àwọn aṣòfin ìpínlẹ̀ Ogun pariwo sí Gómìnà wọn Ohun tó yẹ kẹ́ẹ mọ nípà olùdíje mèjì tó lágbára nínú ìdìbò Ghana rèé Amọṣa, gẹgẹ bi ọpọ ṣe mọ pe eniyan ọtọ ni awọn Ọba alaye, gbogbo ohun ti tẹrutọmọ ba n ṣe ni gbẹfẹ ni kii rọrun fun awọn ọba lati ṣe; paapaa julọ, Ọọni ile Ifẹ ti iran Yoruba gba gẹgẹ bi Olori aye.
Gbogbo nǹkan ló ní àkókò ati ìgbà tirẹ̀, bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé wahala wọ ẹ̀dá lọ́rùn.
Kí ló dé tí ẹ fi níláti gbẹ́yìn ninu ètò àtidá ọba pada sí ààfin rẹ̀.
ati Aṣani ati Beti Ṣemeṣi pẹlu pápá oko tí ó yí wọn ká.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, olounjẹ ni oloogun ebi Imọran àwọn oniṣowo mii ni pe ki wọn maa ta àwọtẹlẹ obinrin bii kọ́mú àti pátá àti tọkunrin naa ni èrè lórí ti ko si nilo owó okowo to pọ ju.
inu mi tun dun pe, e mo riri ohun ti orile ede Naijiria n se fun orile ede yin.
O fikun pe iye eeyan to ti ba arun Coronavirus lọ ti to ọrinlelaadọfa o le mẹrin, 1,184 dipo ọtalelaadọfa ati meje to wa lọsẹ meji sẹyin.
" Sola Kosoko wa kadi ọrọ rẹ nilẹ pe, ko si ẹṣin ti oun ko le ṣin nitori ẹlẹṣin.
 “Mugabe ki Mutinhiri ku ori-ire lori igbese ako re, nieyi ti o so pe, awon omo orile-ede Zimbabwe niloo akikanju lokunrin ati lobinrin, ti yoo ja fita-fita lati daabobo ominira awon ara-ilu”.
OLUWA ń bẹ ninu tẹmpili mímọ́ rẹ̀,ìtẹ́ rẹ̀ wà lọ́run;OLUWA ń kíyèsí àwọn ọmọ eniyan,ó sì ń yẹ̀ wọ́n wò.
Àwọn kọ̀lọ̀kọ̀lọ̀ yìí bá tan iná ran gbogbo ìtí ọkà ati àwọn ọkà tí ó wà ní òòró ati gbogbo ọgbà olifi wọn; gbogbo wọn sì jóná ráúráú.
Ajo eleto idibo ( Independent National Electoral Commission ,INEC)ti kede egbe oselu , mẹ́tàlélógún tuntun, ni eyi ti yoo je ki egbe oselu to wa tele lorile ede Naijiria jẹ mọ́kànléláàdọ́rùn ún, ti yoo dije ninu eto idibo odun 2019 to n bọ.
Ẹ gbójú sókè kí ẹ wo ojú ọ̀run, ta ni ó dá àwọn nǹkan tí ẹ rí wọnyi?
Iroyin ti a gbọ ni pe ọdọbinrin naa gbe igbesẹ yii lẹyin ti ololufẹ rẹ lati ṣe igbeyawo pẹlu rẹ.
Sani Abacha tún gbé owó míì dé láti Ireland Ire ṣ'ọjọ́-ìbí, Mide àti ọkọ rẹ̀ lẹ̀pọ̀, Iyabo Ojo f'aṣọ ilẹ̀ Afirika dárà O tẹsiwaju pe A fẹ fi akoko yii bẹ Ọba Ataoja ki wọn gba fun wa lọdun yii, ṣugbọn a fi da wọn loju pe, ti ọdun to n bọ yoo dun ju bayii lọ, a o si faye gba ọpọ ero lati peju sibi ọdun naa."
Nígbà tí Rutu dìde, láti tún máa ṣa ọkà, Boasi pàṣẹ fún àwọn ọdọmọkunrin rẹ̀, ó ní, “Ẹ jẹ́ kí ó máa ṣa ọkà láàrin àwọn ìtí ọkà tí ẹ dì jọ, ẹnikẹ́ni kò gbọdọ̀ yọ ọ́ lẹ́nu.
Ó lé àwọn orílẹ̀-èdè jáde kí wọn ó tó dé ibẹ̀;ó pín ilẹ̀ àwọn orílẹ̀-èdè fún wọn bí ohun ìní;ó sì fi àwọn ọmọ Israẹli jókòó ninu àgọ́ wọn.
Ohun to ṣeni laanu ni wi pe Sẹnẹtọ Dino Melaye to jẹ ojulowo gangan kọ ni ka awọn esi yi .
Wọn fi kun pé, ohun ti Nàìjíríà sọnu nípa ẹni to ku yìí kii ṣe ńkan to ṣe fẹnu sọ tan.
Wọ́n pa wọ́n láti Nohahi títí dé iwájú ìlà oòrùn Gibea.
Ilu Houston to ti dagba ni wọn yoo sin oku George Floyd si.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù N11trn subsidy: Ǹjẹ́ ẹ mọ̀ pé owó ìrànwọ́ epo lè kọ Second Niger Bridge méjìléláàdọ́ta?
'Ìpòrúuru bá ìyàwó mi bó ṣe gbọ ohun ọmọ wa' L'Ekiti, ẹgbẹ́ òṣìṣẹ́ fòfinde adarí òṣìṣẹ́ méjì Kíni iyatọ tó wà láàrin FSARS àti SARS?
ìjọba Eko - BBC News Yorùbá BBC News, YorùbáFò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Coronavirus: Ẹ tilẹ̀kùn ṣọ́ọ̀ṣì àti mọ́ṣáláṣí yín tí èrò bá ju 50 lọ láti dẹ́kun Coronavirus - ìjọba Eko 18 Ẹrẹ̀nà 2020 Oríṣun àwòrán, Getty Images Ijọba ipinlẹ Eko ti gba awọn olori ẹlẹsin lamọran lati gbẹsẹ le apejọpọ ita gbangba ti awọn eeyan rẹ ba le ni aadọta lawọn ile ijọsin wọn.
Alubami ni Chelsea lu ẹgbẹ agbabọọlu Watford lọjọ Aiku eleyi to fun wọn lanfaani lati wa nipo kẹta bayii lori tabili Premier League.
ṣugbọn Rehoboamu jọba lórí àwọn ọmọ Israẹli tí wọn ń gbé Juda.
Ọjọ́ yìí ni ni mo tó fojú rinju pẹ̀lú àwọn olorì, nígbà míràn tí mo tún rí wọn, wọn máa ń wà pẹ̀lú Aláàfin, Oríṣun àwòrán, Wasiu Ayinde Ìkórira pé mo jẹ Mayegun lo fa wàhálà àti ahesọ ọrọ yìí, tí mo si tún gbọ laipẹ yìí pé, àwọn kan ni òye náà kò tọ́ si mi.
Israẹli ní, “Irú ọ̀ràn ńlá wo ni ẹ tún dá sí mi lọ́rùn yìí, tí ẹ lọ sọ fún ọkunrin náà pé ẹ ní arakunrin mìíràn?
2) Alagba Niyi Osunlolu ni olukọ miran to tun kọ wa nipa Silebu Ede Yoruba.
Ṣugbọn Yemi-Esan ti sọ pe lati igbayi lọ, awọn oṣiṣẹ yoo maa lọ sibi iṣẹ lati ọjọ Aje si ọjọ Ẹti.
Ọdún meje péré ni ó ṣe ní ilé ọkọ, tí ọkọ rẹ̀ fi kú.
Àjọ JAMB kéde ìlànà ìgbà ni wọlé tuntun fún àwọn ilé ẹ̀kọ́ gíga Ifẹ̀họ̀núhàn ń lọ lọ́wọ́ ní Belarus lẹ́yìn tí ìdìbò tùn gbé Ààrẹ̀ Lukashenko tó ti wà nípò fún ọdún 26 wọlé Ẹgbẹ́ òṣèlú ZLP gbàmí tọwọ́tẹsẹ̀ láti díbò gómínà ní Ondo- Agboola Ajayi Orílẹ̀-èdè Chad pé ọgọ́ta ọdún, àwọn ara ìlú ń pariwo lábẹ́ Aàrẹ Deby tó gba 'Field Marshal' Mínísíta fún ọ̀rọ̀ àwọn ọ̀dọ́ àti eré ìdáraya ní Naijiria Sunday Dare ti kéde pé àwọn ṣetán láti rán àwọn ọmọ olójú búlúù ti bàbá wọ́n lé àwọn àti ìyá wọ́n síta lọ si ilé iwé.
Gbọ̀ngàn tí ó wà níwájú Ibi-Mímọ́-Jùlọ yìí gùn ní ogoji igbọnwọ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, #Queen Dihya: Obinrin tó gbógun tàwọn agbésùnmọ̀mí ni Algeria Aṣa ati iṣe ninu igbeyawo ti Khadiza yipada: Ninu aṣa igbeyawo Bangladesh, ọkọ iyawo ati ẹbi rẹ maa lọ si agboole iyawo nibi ti wọn yoo ti ṣeto igbeyawo.
’ rèé Olè wọ ilégbèé obìnrin ní fásitì Ibadan, àkẹ́kọ̀ọ́ méjì farapa Orí mi wú, Joke Silva kọ ewì ìfẹ́ lọ́jọ́ ìbí Olu Jacobs Ọkùnrin mẹrin wọ gàù torí ìgbéyàwó orí Facebook Ìgbín ní èmi àti ìyá mi máa ń he kiri, ká tó lee jẹun - Lizzy Anjọrin Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Adewunmi ni, awọn akọroyin gbọdọ rọra lori eto aabo ilu, ki wọn si ṣọra lati ma a kọ awọn iroyin ti yoo fi han awọn ikọ Boko Haram wi pe, awọn ọmọogun n bọ wa ṣigun bo wọn.
O ni wọn yoo lo owo yii lati fi se aayan eto isuna naa, nigbati ijọba yoo ya owo kun un lati rii pe erongba rẹ fun ọdun 2018 jọ Bakana ni gomina ọhun tun sọ awọn aba meji ọtọọtọ di ofin.
Ninu atẹjade kan ti agbẹnusọ rẹ, Kunle Somorin fi lede, Abiodun ni Johsua gbe ogo ipinlẹ Ogun ga.
"Atẹjade kan ti ẹgbẹ Amnesty naa fi soju opo rẹ lori Twitter, lo pe akọle rẹ ""Ẹ se iwadii bawọn ologun se pa awọn oluwọde EndSARS""."
Amnoni bá dùbúlẹ̀, ó ṣe bí ẹni tí ó ń ṣàìsàn.
Amọ aarẹ wa fi aidunnu rẹ han lori isesi awọn asaaju ikọ alaabo wa, o ni o yẹ ki wọn se aseyọri ju bayii lọ.
Mo sì ti fún gbogbo àwọn oníṣẹ́ ọnà ní ọgbọ́n, kí wọ́n lè ṣe gbogbo ohun tí mo pa láṣẹ fún ọ.
Money transfer: Òdíwọn iye owó tí èèyàn n fi rànṣẹ́ sílé ń dínkù púpọ̀ jù
Àwọn Ọba alayé ní Naijiria ṣàbẹ̀wò sí Ọba Eko, Gómìnà Eko àti Bola Tinubu lẹyin ìwọ́de EndSARS Mi ò to iṣẹ́ Regina Daniels rárá kí n tó fẹ́ ẹ láàrin ọ̀sẹ̀ mẹ́ta, mo sì tún le fẹ́ ìyàwó míì - Ned Nwoko Àyà mi já nígbà tí Ganduje rọ Sanusi lóyè Emir Kano tó fi Bayero síi, ṣùgbọ́n.
Akori ti gomina Ajimobi  se idanilekoo le lori ni  “Alaafia ati eto aabo, opakutele fun
Àwọn ará Juda jẹ́ alaiṣootọ sí OLUWA, àwọn eniyan ti ṣe ohun ìríra ní Israẹli ati ní Jerusalẹmu.
"Lara awọn oju tuntun naa ni: Ozoemena ""Ozo"" Chukwu Ọmọ ọdun mẹtadinlọgbọn ni Ozo lati ipinlẹ Imo."
Olόwό-Ìbínú ní Ìdààmú-Ayé nìkan lό wu òun lóbìnrin.
Orúkọ odò keji ni Gihoni, òun ni ó ṣàn yí gbogbo ilẹ̀ Kuṣi ká.
Igboho, lasiko to n ba BBC Yoruba sọrọ ni ohun ti awọn daba rẹ kọ ni ijọba n se, ko si tọ bi wọn se gbe Amotekun sabẹ ijọba rara.
Irú ẹ̀rí títóbi wo ni o tún lè ní jù láti ọ̀dọ̀ Ọlọ́run lọ?
Nígbà tí wọ́n mọ̀ pé Juu ni, wọ́n figbe ta, wọ́n ń pariwo fún ìwọ̀n wakati meji.
 láti nǹkan bí ọdún 1840 ni karl marx fúnra rẹ ̀ ti ṣe ẹ ̀ kúnrẹ ́ rẹ ́ àlàyé lórí awujọ ati àṣà , ṣùgbọ ́ n ní nǹkan bí sẹ ́ ńtúrì ogún ni tíọ ́ rì náà búrẹ ́ kẹ láwùjọ àwọn akadá .
Ọlọ́gbọ́n ní ọmọ tí ó kórè ní àkókò ìkórè,ṣugbọn ọmọ tí ó bá ń sùn lákòókò ìkórèa máa kó ìtìjú báni.
Atẹjade kan to fi sita ni Osinbajo kede pe oun ti fa ọrọ yii le awọn agbofinro lọwọ fun iwadi ati igbẹjọ to yẹ.
" Ohun ti ileesẹ ọlọpa sọ?
Iran ajọ ECOWAS di ọdun 2050 to gbọdọ wa si imuṣẹ.
Nígbà tí ẹni tí ó jẹ́ olùdarí ìsìnkú bá kó eegun òkú jáde, tí ó bá bi àwọn eniyan tí ó kù ninu ilé pé, “Ǹjẹ́ ó ku ẹnikẹ́ni mọ́?
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Karakata Agbabọọlu: Bi o se nlọ 30 Sẹ́rẹ́ 2018 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Karakata Agbaboolu n waye kaakiri bayii Nigbati eto karakata awọn ọmọ ẹgbẹ agbaboolu yoo wa sopin n'ilẹ Yuroopu l'ọjọru, awọn iduna-dura ti n lọ lọwọ laarin awọn ọmọ ẹgbẹ agbabọọlu jadejado ilẹ Yuroopu lati kopa to yan ati lati se ẹkun fun ikọ wan lati dupo, duje fun awọn ife ẹyẹ.
Láti inú ẹ̀yà Sebuluni, ọ̀kẹ́ meji ó lé ẹgbaarun (50,000) àwọn ọmọ ogun, tí wọ́n gbóyà, tí wọ́n mọ̀ nípa ogun jíjà, tí wọ́n sì ní gbogbo ihamọra ogun ni wọ́n wá láti ran Dafidi lọ́wọ́ pẹlu ọkàn kan.
Oníṣkúṣ ń fi ikú ṣiré, onínàákúnáà ń fi ikú ṣiré, onírìnkurìn ń fi ikú ṣire, onígbèéraga ń fi ikú ṣiré, onírìkíṣí ń fi ikú ṣiré.
“Ranti ọjọ́ ìsinmi kí o sì yà á sí mímọ́.
Ní ọjọ́ tí a fi òróró yàn wọ́n, ni OLUWA ti pàṣẹ fún àwọn eniyan Israẹli láti máa fún wọn, ó jẹ́ ìpín tiwọn láti ìrandíran.
 Ọwọ ́ wákàtí fún déédé wákàtí méjìlá aago àfọwọ ́ ṣe ń yípo 360 ° ní àwọn wákàtí méjìlá ( ìṣẹ ́ jú 720 ) tàbí 0.
N o sì kóèyí tí ó ba kù lára rẹ pamọ́ sínú ilé mi, nínú òkìtì ọ̀gán – Háá!
Ṣugbọn nigba ti wọn tun jọ pada ja ninu oṣu Kejila, Anthony Joshua gba igbanu ogo rẹ pada lẹyin to bori Andy Ruiz ninu idije ẹṣẹ kikan to waye ni lu Riyadh ni Saudi Arabi.
N óo bèèrè lọ́wọ́ Baba, yóo wá fun yín ní Alátìlẹ́yìn mìíràn tí yóo wà pẹlu yín títí lae.
Keke Alupupu Ọna pataki kan lati rinrinajo kaakiri inu ipagọ ijọ Redeem ni kẹkẹ ẹlẹsẹ mẹta tabi awọn ọkọ kuukuku.
Agbárí àwọn tí ó jù ọ́ lọ ń bẹ nínú ìṣaasùn mi, eegungun ẹ̀hìn wọn ń bẹ ni kọ̀rọ̀ oyàrá, gẹ̀ǹgẹ̀ àyà àwọn ọmọ aláìgbọràn ni èmi sì fi ń jókòó nínú ilé mi.
Ọ̀rọ̀ rẹ dùn mọ́ mi pupọ,ó dùn ju oyin lọ.
Ìdájọ́ ẹ̀wòn gbére kò ní kí Wòlíì Sotitobire má lọ sí ilèẹjọ́ kòtẹ́milọ́rùn - Agbẹjọ́rò Pásítọ̀ Alfa Babatunde Afurasí darandaran jí èèyàn mẹ́rìnlá gbé ní Ọ̀ṣun Àwọn mẹ́wàá tí wọ́n jígbé ní Ọ̀ṣun gba ìtúsílẹ̀ Oríṣun àwòrán, TWITTER Awọn ọdọ gbe iwe akọle lorisirisi dani bii opin gbọdọ de si iwa ifiyajẹni lọna aitọ Say no to brutal injustice"", irun ori to ta koko kii ṣe ẹsẹ, ""Dreadlocks are no crimes"", ọlọpaa yẹ ko ma a ṣọ wa ni, kii ṣe ki wọn ma a gba owo ọwọ wa, ""Protect not exploit' ati eleyii ti wọn kọ pe ki ọlọpaa Naijiria ye pa wọn, ""Nigeria police stop killing us'."
Bakan naa la fẹ mọ awọn eto to wa nilẹ ti ẹgbẹ awọn osere tiata n se lati ri daju pe awọn ọmọ ẹgbẹ wọn ko maa laagun, ki wọn to ri itọju lasiko ti ilera wọn ba yinjẹ?
Toyosi Adesanya, ẹni to ni alaafia ni oun wa, seleri pe ni kete ti ara oun ba ti bọ sipo lati sọrọ nipa bi isẹlẹ naa se waye, ni oun yoo dahuin ibeere latọdọ BBC Yoruba.
com Àkọlé àwòrán, Àdéhùn ọdún mẹ́ta ni Lampard tọwọ́bọ̀ pẹ́lúu Chelsea Ẹgbẹ agbabọọlu Chelsea ti kede Frank Lampard gẹgẹ bii olukọni tuntun fun ikọ naa.
Nígbà tí àwọn ọmọ Jakọbu pada dé sílé, tí wọ́n gbọ́ ọ̀rọ̀ náà, inú bí wọn gidigidi nítorí bíbá tí Ṣekemu bá Dina lòpọ̀ pẹlu ipá yìí jẹ́ ìwà àbùkù gbáà ní Israẹli, irú ìwà bẹ́ẹ̀ kò tọ́ sí ẹnikẹ́ni láti hù.
Lasiko itankalẹ aarun Covid-19 , Aisha lọ si ilu Dubai fun itọju, to si jẹ pe igba to n pada bọ si Naijiria ni baalu ijọba to wa ninu rẹ ni ijamba.
Saaju ni ọpọ ọmọ Naijiria ti n poungbẹ lori asiko ti fọọmu ati gba ni siṣẹ ọmọ ogun ilẹ yoo jade ki awọn le darapọmọ wọn maa fọ orilẹ-ede yii mọ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ọmọogun mu darandaran fulani mẹfa, wọn pa mẹwa ni Adamawa 28 Èrèlè 2018 Oríṣun àwòrán, @HQNigerianArmy Àkọlé àwòrán, Nigba ti ina jo dori koko lori ikọlu awọn darandaran fulani ni ijọba apapọ gbe ikọ ologun dide labẹ akanse eto abo 'Ayem Akpatuma' Ọwọ awọn ọmọogun ti tẹ awọn kọlọransi darandaran mẹfa kan ti wọn kọlu ileto Gwanbar ni ipinlẹ Adamawa.
Bi awọn kan ṣe n sọ pe ohun ti Nkechi ṣe dara pupọ, lawọn mii n bere pe ki gan ni ẹṣẹ ti Nkechi ṣe Toyin to fi n sọ pe ki Toyin jeburẹ.
Ó sọ fún oníṣẹ́ tí ó rán pé, “Bí o bá ti sọ ohun tí ó ṣẹlẹ̀ lójú ogun fún ọba tán, 
Nígbà tí ó bá yá, wọn yóo ké pe OLUWA, ṣugbọn kò ní dá wọn lóhùn; yóo fi ojú pamọ́ fún wọn, nítorí nǹkan burúkú tí wọ́n ṣe.
O ni lati igba ti alaye ti daye, bi awọn ọba se ga ju ara wọn lọ wa laarin awọn ọba mẹrindinlogun laisi ija abi ariyanjiyan laarin wọn lori eyi, eyi tawọn agbegbe miran nilẹ Yoruba maa fi n se awokọse rere.
Ayẹwò kò dáwọ́ dúro botílẹ̀ jẹ́ pé èròjà ayẹwò (Reagents) kò si mọ́ Ìjọba àpapọ̀, ẹ so ifilọlẹ ẹ̀rọ alatagba 5G rọ na - ilé asofin àgbà Mo ti tọrọ aṣọ àti yẹtí etí rí, kí n tó leè ṣe àwo orin - Tope Alabi Ẹ bá mi dúpẹ́ lọ́wọ́ Sunday Igboho, Ajimobi, Seyi Makinde àti àwọn ọlọ́pàá fún iranwọ wọn láti rí ìbejì gbà padà Orílẹ̀ èdè Áfíríkà bíi Madagascar Cameroon àti Nàìjíríà sì ti ń fi ogun rẹ gbari pé, àwọn òògùn ìbílẹ̀ kan leè wo àrùn Coronavirus, tí Madagascar sì ti ń lo òògùn ìbílẹ̀ tiẹ̀ fún ìwòsàn àrùn náà.
Fáfitì Èkó àti apákan Bàrígà ló rọ̀ ká a ní ìhà gúsu, Bájùláyé àti Abúlé Ìjẹṣà ló gbè é ní ìwọ̀ òrùn nígbà tí Yábàá yíì ká ni ìhà àríwá.
Nígbà tí àwọn ọmọ-ẹ̀yìn meji náà gbọ́, wọ́n tẹ̀lé Jesu.
Ó dá mi lójú pé ” Ìyá àgbà” yìí yóò ṣòro tí ó wúni lórí ju Ilham Aliyev lọ.
"Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Toríi ""Coro"", ẹ wo bí ètò ìsìn ìgbéyàwó orí ayélujára Zoom ṣe lọ Iha wo lawọn eeyan Naijiria kọ si iṣẹlẹ yi?"
Ẹ̀gbẹ́ alájòótà yìí ti tasẹ̀ àgẹ̀rẹ̀ sí òfin abala 505(a) tí ó ní wípé ọ̀daràn ni ẹni tí ó bá polongo ọ̀rọ̀, àyesọ, tàbí jábọ̀ irúu rẹ̀ pẹ̀lú èrò láti mú kí ikọ̀ ajagun ó máà ka ojúṣe rẹ̀ kún tàbí kùnà láti ṣe ojúṣee rẹ̀.
olóyè sunday adéníyì adégeyè ( mfr ) , tí a mò pèlú isé won gégé bíi king sunny ade je eni tí a bí ní ojó kejìlélógún , osù september , odún ( 1946 ) jé olórin àti akorin pèlú onímò orísirísi ohun èlò orin ìlú nàìjíríà nínú àsà orin ti apá ìwò oòrùn ilè adúláwò tí a mò sí jùjú .
Fìtílà meje wà lórí ọ̀pá náà, fìtílà kọ̀ọ̀kan sì ní òwú fìtílà meje.
Ni Jesu bá kígbe sókè bí ó ti ń kọ́ àwọn eniyan ninu Tẹmpili.
Aláàfin ń se ọgọ́rin ọdún, àwọn àwòrán mánigbàgbé Ọjọ kọkanlelogun, oṣu kinni, ọdun 1920 ni wọn bi i ni Imobi, Epe, nilu Eko.
AIT ati Sun juwe ile fun 300 osisẹ Ìdí tí a fi ṣe òfin tuntun fún àwọn akọ̀ròyìn tí yóò ṣiṣẹ́ nílé aṣòfin - NASS Àwọn òṣìṣẹ́ NAN ya bo Abuja fún ẹ̀tọ́ wọn Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fọ́nrán ohùn, NUJ: A fẹ mọ ẹsẹ awọn akọroyin tẹ da duro Omowe Modibo Kawu to jẹ adari ajọ NBC ti ṣalaye pe ileeṣẹ amohunmaworan AIT kii san owo idiyele ominira lati ṣiṣẹ wọn lasiko.
Ọrọ naa ṣi wa nile ẹjọ bayii nilu Abuja.
Ni oṣu kẹta ọdun 2019 ni oloogbe Chadwick Boseman kọkọ sọrọ ni pa ọrọ ifẹ oun ati Ledward ni ibi eto ami ẹyẹ 50th NAACP Image Awards.
Bí ilẹ̀ bá mọ, bàbá á dọ̀bálẹ̀ fún àwọn ọmọ rẹ̀ káàkiri ilé, ìyá a tún kúnlẹ̀ fún wọn.
Ọpọ awọn olorin, onijo ati alafẹ si lo ti n ya lọ sibudo naa lati da ara wọn lara ya.
Oríṣun àwòrán, @abikedabiri Àkọlé àwòrán, Ọmọ Naijiria mejilelaadoje pada sile lati Libya loṣu kinni ọdun Ogunlọgọ awọn atipo ọmọ orilẹede Naijiria ni wọn ti npada wale lati orilẹede Libya lẹyin awuyewuye lori ọrọ ifeniyan dokoowo ati ifiyajẹni ni orilẹede naa.
 O si kere tan, o n gba ẹẹdẹgbẹrun ọdun ki idoti onike to jẹra.
Ìyàwó Ọ̀ọ̀ni Ogunwusi kò bímọ tuntun Ooni Ile Ife pàdánù Màmá àgbá Ganiyat tó fi irin gbígbóná àti àdá ya ara ọmọ àbúrò ọkọ rẹ ti dèrò àgọ́ ọlọ́pàá l' Ogun Alaafin ni awọn kan si Ifa nipasẹ Araba Agbaye olori awọn onifa lagbaye ki awọn to sọ orukọ yi di mimọ faraye.
" Gaddafi ló l‘ẹ̀bi ìkọlù darandaran - Bùhárí Ninu ijọba Buhari lawọn ole wa — Fayose Ààrẹ Bùhárí sọ, nínú ìfọ̀rọ̀wérọ̀ rẹ̀ pẹ̀lu Bíṣọ́ọ̀bù àgbà ìjọ Anglican ní Canterbury, Ẹniọ̀wọ̀ Justin Welby ní ìlú London, pé ààrẹ orílẹ̀èdè Libya, Moumah Ghadafi tó kú ní ọdún méje sẹ́yìn ló kó ohun ìjà olóró fún àwọn ọmọlẹyìn rẹ̀ tí wọ́n ti wá ṣàn wọ orílẹ̀èdè Nàìjíríà.
Ilẹ gbigba,Orukọ ti wọn sọ ati ọrọ Aje lo wa nidi aawọ naa Loju opo Twitter ati lawọn aaye miran, awọn eeyan n tapa si Ruga nitori awọn idi lorisirisi.
Mo le fọwọ sọya fun yin bayi bayi pe afurasi ọdaran to sa lọ, Sunday Shodipe ti wa lahamọ Ọlọpaa ipinlẹ Oyo""."
satileyin fun un nitori awon ohun ti o ti gbe se.
Man United bọ́ si ìpele àsekágbá ninu ìdíje FA
NNPC: Kyari ṣàlàyé ohun tó fa ẹ̀dínkù iye epo rọ̀bì tí wọ́n ń kó níbùdó ìpọnpo ní Nàìjíríà
8% Jọwọ ṣe atunṣe ilana ikansi ayelujara rẹ lati ri ẹkunrẹrẹ rẹ Orisun: US Census Iye akọsilẹ to waye gbẹyin 03/11 Lọdun 2016, Trump fi 1% ja Clinton lawọn ipinlẹ wọn yi.
Bí Hushpuppi ṣe tiraka rèé l‘Eko, kí ọlà ‘òjijì’ tó dé Èèyàn 7 kú, 21 di àwátì lásìkò tí ọkọ̀ ojú omi dojúdé ní Eko àti Benue Ìjọba àpapọ̀ yóò ti afárá Third Mainland pa fún oṣù mẹ́fà láti ṣe àtúnṣe Akẹ́kọ̀ọ́ wọlé padà, ìjọba Oyo kò pèsè ìbòmú lòdì sí ìlérí rẹ̀ Ẹ wo bí ọ̀rọ̀ òṣèlú, ẹ̀sìn àti ẹ̀yà ṣe fa ogun abẹ́lé Biafra Kàkà k‘éwé àgbọn dẹ̀ lágbo òṣèlú l‘Ondo, akọ̀wé ìjọba tún kọ̀wé fipò sílẹ̀ EFCC ni ajọ DSS ko fi panpẹ ofin mu Magu, bẹẹ si ni igbimọ ijọba to lọ farahan niwaju rẹ ko fi tipa mu un pe ki o wa farahan.
Iṣẹ́ rẹ ti ìkẹyìn tilẹ̀ dára ju ti àkọ́kọ́ lọ.
Ìlé iṣẹ ọlọpàá ní àwọn yóò gba òsìṣẹ kọọkan láti àgbègbè tí wọn bá n gbé, ó kéré tán ẹnìyàn ààdọtá láti ìjọba ìbìlẹ kọọkàn jákejádò orílẹ-èdè Nàìjíríà Jesu orí ayélujára kan rèé tó wa fun isoji ni Afirika Arẹ́májà kò sí, Olubadan fi tìlù-tìfọn kí àwọn ìjòyè káàbọ̀ lẹ́yìn ọdún méjì Àṣírí mẹ́wàá tí mo mọ̀ nípa Boko Haram-Naomi Adamu Ọkùnrin méjì, obìnrin mẹ́ta jáde láyé ní Mecca lásìkò Hajj 2019 - NAHCON Èèkànlú ní ìpínlẹ̀ Ogun lọ kí Buhari l‘Abuja torí ẹ̀yẹ tó fi dá Abiọla lọ́lá Bákan náà ni wọn fí kún un pé ènìyàn ọọdúnrún lé ni ẹgbẹrún ní àwọn ní yóò gbà sísẹ nínu àwọn akọṣẹmọṣẹ àti àwọn ẹgbẹ ọdọ ní Nàìjíríà.
N óo sọ àwọn ìlú yín di ahoro, àwọn ilé ìsìn yín yóo sì ṣófo, n kò ní gba ẹbọ yín mọ́.
Idájọ ti wọn da túmọ si pe Semenya yóò maa lo oogun ti yóò maa mú àdínku bá okún náà nígbà ti wọn ba fẹ sá eréje to kéré si àwọn eyi ti wọn là sílẹ.
Ọkùnrin náà sọ fún wa pẹ̀lú pé ẹnikẹ́ni tí ó bá máa bu omi náà ní òde ọ̀run kò gbọdọ̀ kọ ojú sí i nígbà tí ó bá ń bù ú, kàkà bẹ́ẹ̀ ó níláti kọ ẹ̀hìn síi; ìdí rẹ̀ ni pée ẹnikẹ́ni kò gbọdọ̀ wo inú omi náà nítorí ẹni tí ó bà wò ó gbangba ni olúwaarẹ̀ yóó maa wo ìtẹ́ Ọlọ́run Ọ̀gá Ògo àti àwọn alágbára ẹ̀mí tí wọ́n dúró yí ìtẹ́ Olódùmarè ká tí wọ́n ń yin Ẹni tí Ó dá wọn, tí Ó dá ẹlòmíràn, yí Ó dá gbogbo wa.
"Baṣọ̀run Gáà, tó yan ọba mẹ́rin, pa ọba mẹ́rin àmọ́ ọba karùn-ún ló pa á Ọ̀rọ̀ǹpọ̀tọ̀niyùn, Aláàfin obìnrin àkọ́kọ́ rèé, tó ní nǹkan ọkùnrin Àwọn onímọ̀ Islam àti Oluwo takora lórí oyè Wàzírì Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Osinbajo: Ikẹnnẹ yẹ kó jẹ́ Mẹ́kà òṣèlú ni Aarẹ ṣapejuwe awọn olugbe ilu Abuja gẹgẹ bii ""awọn eeyan buburu ti ko ṣee ma ni""."
Ki aarẹ to yan an sipo, Ọgbẹni Adamu jẹ igbakeji ọga ọlọpaa, to si n ṣiṣẹ nile iwe ọlọpaa to wa ni ilu Kuru, nipinlẹ Plateau.
"Ǹkan ti a mọ ni pe àwọn ènìyàn máa n sápamọ lọ jeun, ""sùgbọn ti ẹ ba mọ ile ounjẹ tabi ile itura ti àwọn ènìyàn ti ń jẹun, ẹ jẹ ki a mọ láti gbe igbesẹ̀ to yẹ""."
N óo bukun wọn, n óo jẹ́ kí wọn pọ̀ sí i, n óo sì gbé ilé mímọ́ mi kalẹ̀ sí ààrin wọn títí lae.
"Soweto Baby - DJ Maphoriza pẹlu Wizkid ati DJ Bucks (2015) Yoruba maa n ni ""ati ranmu gangan ko sẹyin eekana."
Gbogbo eeyan n beere iranlọwọ iṣẹ fun Ojo Adebayọ lasiko yii.
Bakan naa tun ni One million boys maa n fi iwe ransẹ si adugbo ti wọn ba ti fẹ lọ jale.
O ni oun kọkọ ra ọkọ bọọsi akero kekere, eyi ti oun tun ṣe ki o le rọrun lati fi maa gbe awọn alaisan to ba wa lori kẹkẹ nitori ailerin.
Buhari ati oludari ijoba niluu London ,Theresa May, tọwọbọ iwe adehun lasiko  Ipade apero lori idagbasoke eto  oro aje laarin orile ede Naijiria ati orile
Commission ,INEC)ti gbe ami idanimọ bi iwe idibo ati apoti idibo aarẹ ati ile
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù African Drum Festival: Ìbejì Àyànbìnrin tó ti ń di gbajúgbajà Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ African Drum Festival: Ìbejì Àyànbìnrin tó ti ń di gbajúgbajà 30 Ìgbé 2019 Bẹẹ ba ti ri ogidi ọmọ ile onilu to mọ iṣẹ idile rẹ, wọn o ṣoro da mọ tori orukọ a maa ro wọn.
Wọ́n ní kí ọjọ́ náà tó dé, àwọn ti n ṣọ ìrìn Adebísí.
 mo ni olórí fún àpólà orúko olùwà ní ( 7d ) , arópò-orúko sì ni mo yìí .
Bee si ni aare yoo tun lo anfaani eto ohun, lati fi salaye bi orile-ede Naijriia se setan lati sise po pelu ile okere lojuna ati jo koju idojuko iyipada oju ojo nile Africa ati lagbaye.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ẹkún sọ ní ìsìnkú Aisha Abimbọla ní Toronto Ko sí ifoya Ebola lọ́rọ̀ ìdíje Nigeria àti Congo Afara tuntun já, Gómìnà rè sodò nì Kenya Sé o leè yẹ ara Ọlọ́pàá wò, kó tó yẹ̀ ọ́ wò ?
Ẹni tí ó bá ṣe bẹ́ẹ̀, kabiyesi, kí wọ́n jù ú sinu ihò kinniun.
Ọdọmọkunrin náà sọ fún Jesu pé, “Gbogbo òfin wọnyi ni mo ti pamọ́.
Nítorí ó wà ní àkọsílẹ̀ pé, Ọlọrun ní, “Ẹ jẹ́ mímọ́, nítorí èmi náà jẹ́ mímọ́.
Nitori eyi ni ọpọlọpọ ijọ ṣe maa n fi eyi ṣe iranti ọjọ ọjọbọ mimọ naa.
Kí oore-ọ̀fẹ́ ati alaafia láti ọ̀dọ̀ Ọlọrun Baba, ati Kristi Jesu Olùgbàlà wa, wà pẹlu rẹ̀.
Ẹ̀ṣọ́ Amotekun ní láti ṣiṣẹ́ pọ̀ pẹ̀lú ọlọ́pàá agbègbè- Ọ̀gá ọlọ́pàá Naijiria Gbọingbọin lọmọ Nàìjíríà wà lẹ́yìn iléẹjọ́ gíga jùlọ lórí ìdájọ́ ìbò Bayelsa- Atiku Àwọn ọmọ onílẹ̀ lọ ṣe àmúṣẹ àṣẹ iléẹjọ́ ní Soka, làwọn ‘Jàǹdùkú’ fi dá wọn lọ̀nà - Iléeṣẹ́ ọlọ́pàá Ọyọ Bàbá àti ìyá mi kò fẹ́ kí n ṣe eré tíátà - Wale Akorede Okunnu Ẹ̀yin òṣèrè tíátà, ẹ ní ṣùúrù de àsìkò Ọlọ́run, ẹ máṣe kánjú kọjá kádàrá - Madam Ṣajẹ Ọjọ kẹwa oṣu keji ọdun 2020 ni aṣẹ jade pe, ki wọn gbẹsẹ le awọn ilẹ ọhun nitori pe lilo rẹ lodi si anfani awọn ara ilu ati ijọba.
Oríṣun àwòrán, @imnig_org Àkọlé àwòrán, Shiite tún fẹ́ fi ẹ̀hónú hàn lórí 'ọ̀pọ̀' ọmọ ẹgbẹ́ wọn ti iléèṣẹ́ ológun Nàìjíríà pa.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Dangote ni ìdàgbàsókè ẹ̀ka ọ̀gbìn ti mú àwọn agbẹ gòkè àgbà 1 Òkùdu 2018 Oríṣun àwòrán, @NGRPresident Àkọlé àwòrán, Bí Nàìjíríà bá tẹra mọ́ ìdàgbàsókè ẹ̀ka ọ̀gbìn, yóò leè bọ́ ẹkùn ìwọ̀ oòrùn Áfíríkà lapapọ Olokoowo to lowo ju ni Afirika, Aliko Dangote, ti fi ọrọ ẹri lelẹ pe nnkan ti n sẹnuure fawọn agbẹ lorilẹ-ede naijiria.
Saraki fi kun ọrọ rẹ wipe, inira ati awọn ipenija to n ba awọn eeyan ipinlẹ Ọṣun finra ko lẹgbẹ lorilẹede Naijiria, pẹlu alaye wipe ko si ipinlẹ to jẹ awọn oṣiṣẹ lowo to ipinlẹ Ọṣun lati igba ti iṣejọba awarawa ti bẹrẹ lọdun 1999.
Eleyii lo mu ki oun fi ara rẹ jin fun isẹ sisọ ẹti okun.
Oríṣun àwòrán, @others Àkọlé àwòrán, Ìná ẹgbẹ́ òṣìṣẹ́ NLC ati ìjọba kò wọ̀ níbi ìpadé Ngige ni ipade naa yoo tẹsiwaju ki wọn le jọ fẹnuko lori iye owo naa laisi aṣiṣe kankan.
Ìjọba àpapọ̀ kò leè ṣùn torí ìyanṣẹ́lódì òṣìṣẹ́ tó ń bọ̀ FRSC dá N443,180 padà fún ẹbí ẹni to ní ìjàmbá mọ́tò Ìdùnnú ni yóò jẹ fún wa ti wọn bá ṣe àwọn ọnà tí kò dára wọnyíì-Bosun Aguda Awakọ̀ bàálù ológun òfurufú obìnrin àkọ́kọ́ ní Nàìjíríà rè e Ọkọ Ajagbe naa lo kọlu ọkọ ayọkẹlẹ meji ti awọn ti o wa ninu ọkọ naa si fara pa ṣugbọn ti o da ẹmi arabinrin naa legbodo.
Ikilọ awọn ikọ naa ni pe, wọn ko gbọdọ kofiri eyikeyi awọn akẹkọ naa mọ nileewe, lo ku ti n da omi tutu si awọn eeyan lọkan bayii lori ọrọ naa.
Ọlọrun yín, tí ó ko yín jáde wá láti ilẹ̀ Ijipti nìyí.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Chloroquine: Àwọn oníṣègùn òyìnbò ní China sọ pé Coronavirus o le duro wo tan 20 Èrèlè 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 19 Ẹrẹ̀nà 2020 Oríṣun àwòrán, Other Ọrọ yii da bi ọrọ iwe mimọ to sọ pe ''okuta tawọn ọmọle kọ silẹ, lo di pataki igun ile.
Paulu bá sọ pé, “Ìrìbọmi pé a ronupiwada ni Johanu ṣe.
Wọ́n ní, “Alàgbà, a ranti pé ẹlẹ́tàn nì sọ nígbà tí ó wà láàyè pé lẹ́yìn ọjọ́ mẹta òun óo jí dìde.
Lọ́sàn àná ni ìròyìn gbòde pé wọ́n ti ri ọ̀dọ́mọde náà mú tí ó sì ti wà ní àhámọ́ ọlọ́pàá gẹ́gẹ́ bi agbẹnusọ ọlọ́pàá ìpínlẹ̀ Oyo Olugbenga Fadeyi ṣe sọ fun ilé iṣẹ́ BBC Ìbéérè tó tún tèlé e ni pé Báwo ni wọ́n ṣe rii mú gan-an Ìdí èyí ni ilé iṣẹ BBC fí ṣe ìfòrọ̀wánilẹ́nu wò fún àwọn tó lọ́wọ́ nínú ọ̀nà ti wọ́n fi mú ọmọkùnrin náà.
Domestic Violence: Ǹkan mẹ́jọ tó máa kọ́kọ́ ṣẹlẹ̀ kí olólùfẹ́ méjì tó pa ara wọn
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Al-Shabaab gbẹsẹ le bọọlu gbigba lorilẹede Somalia 8 Ẹrẹ̀nà 2018 Oríṣun àwòrán, Reuters Àkọlé àwòrán, Awọn olugbe ilu Mogadishu naa n bẹru awọn ikilọ ikọ Al-Shabaab Iroyin n fidi rẹ mulẹ wi pe ẹgbẹ alakatakiti ẹsin ni, Al-shabaab ti ṣe ikilọ f'awọn eeyan orilẹede naa lati yago fun ere idaraya bọọlu gbigba o lawọn agbegbe kan ni olu ilu orilẹede naa, Mogadishu.
Ó bá já sinu ìdámẹ́ta àwọn odò ati ìsun omi.
Oshodi Tapa: ìgbésí ayé Oshodi, ọmọ Tápà léǹpe tó di akọni ní ìlú Eko rèé
Ìdúnàdúrà ṣì n lọ láti dóòlà ọmọ Ọffa mẹ́fà lọ́wọ́ ajínigbé- ODU Irọ funfun báláwú ni, Boko Haram kò dawa lọnà rárá -Ọmọ ogun Naijiria Agbejọ́rò Dakolo:Mílíọ́nù mẹ́wàá náírà tí a béèrè kì í ṣe owó gbà má-bínú Ó lé ní ẹ́gbẹ́ta àwọn ọmọ Naijiria tí wọ́n ti ṣetàn láti padà sílé!
Asepati marosẹ Ibadan si Eko lewu - Fasọla Ọpa epo gbana nipinlẹ Eko Oríṣun àwòrán, Agege TV Ileeṣẹ to n ṣe iranwọ pajawiri ni ipinlẹ Eko wa ninu awọn ti wọn lọ ran awọn ti iṣẹlẹ naa kan l'ọwọ.
"#Nkalagu: Lẹ́yìn tó fẹnu kọ lórí Twitter, ọlọ́pàá sọ Yomi Shogunle bí òkò sí Nkalagu Nítorí Sẹ́nétọ̀ Adeleke, ìyá àti ọmọ gbé iléeṣẹ́ ọlọ́pàá lọ sílé ẹjọ́ Olùkọ́ 600 kú sínú ìkọlù agbébọn lẹ́kùn ìlà oòrùn àríwá Nàìjíríà Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Nollywood: Bẹbẹ ń lọ ní ibùdó yíya sinimá Àgbésọrísùn Bakan náà ni àwọn afẹhonu han náà kó akole orisirisi lọ́wọ́ ti wọn kọ ọ̀rọ̀ bíi ""obinrin ni mi, bó ba ṣe wumi ni mo ṣe le múrà"" Ọ̀pọ̀ àwọn ọmọbinrin ti àwọn ọlọpàá mú náà sàlàyé pe wọn fi ipá ba àwọn lòpọ̀ nígbà ti àwọn wà ni ahamọ."
Lootọ gbogbo aye lo mọ pe gbogbo nnkan ti aṣa ati iṣe Yoruba to jẹ temi duro fun ni mo n gbe ga.
Gbogbo àwọn ọmọ Israẹli yóo ṣẹgun,wọn yóo sì ṣògo ninu OLUWA.
O sọ mí sókè ninu afẹ́fẹ́,ò ń bì mí síhìn-ín sọ́hùn-únláàrin ariwo ìjì líle.
Bakan naa ni India, Australia, Kenya, Fiji, ati Sri Lanka, ni anfaani lati darapọ mọ ileeṣẹ ologun, koda ti wọn ko ba ti i gbe ni ilẹ Gẹẹsi ri.
Bakan naa ni ijọba ti paṣẹ pe ki awọn ọmọ ogun ori omi ati awọn ọmọ ologun mi i to n dari ọkọ̀ nibẹ dawọ iṣẹ duro, ki wọn o si ko awọn ibudo ti wọn ti n da ọkọ̀ duro fun ayẹwo kuro.
Bakan naa , ni egbe naa yoo tun gbe ise akanse miiran jide ti yoo ran  awon ti oro kan lowo lati lee gbogun ti ijamba to ba lee waye lasiko eto idibo , awon bi I ajo eleto idibo, ile-ise olopaa,ajo to n mojuto oro to je mo ilu,egbe onigbagbo ( kristeni) egbe awon musulumi ati ajo to n pese alaafia.
iwe ifehonuhanDabiri-Erewa  so pe lati ose to koja ni oun ti kowe ifehonuhan si ile-ise asoju orile ede Britain to wa niluu Abuja lati beere fun idajo ati iwadii lori awon isele buruku yii.
Iwa asise nidi pipaarọ ọmọ tuntun sira wọn: Ti wọn ba sẹsẹ bi ọmọ tuntun nile iwosan ijọba, wọn yoo so orukọ baba ọmọ naa mọ ọmọ ọhun lọwọ lati tete daa mọ laarin ọpọ ọmọ tuntun ti wọn bi wọn si akoko kan naa.
Àwọn ni àwọn ìran tó ṣẹ̀ lọ́dọ̀ Ketura.
N kò sọ fún ìyá mi kí ń tó lọ sílé BB Naija - Laycon Ọ̀rẹ́ wa ni Lawrence jẹ́, àmọ́ ó gbẹ̀yìn dẹ́nu ìfẹ́ kọ abúrò wa - Joshua àti Damilola Bamiloye Gbajugbaja oṣere ọhun to awọn eeyan ko mọ ẹnikan ni pato gẹgẹ bi ọrẹkunrin ṣalaye pe ko si ohun to buru ninu ki eeyan maa ti lọ sile ọkọ ni wọn igba to ba ti layọ.
Eyi ni akoko iru re nile Adulawo nitori pe oko naa kun fun ohun eelo ayewo ati itoju pelu ileri pe laipe la maa ni ibudo alagbeka arun jejere kaakiri Eko.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Aviation Strike: Ẹ̀gbẹ́ àwọn òṣìṣẹ́ pápákọ̀ òfurufú bẹ̀rẹ̀ ìyanṣẹ́lódì 22 Èbibi 2019 Oríṣun àwòrán, OTHER Àkọlé àwòrán, Ọkọ baalu Awọn oṣiṣẹ papakọ ofurufu yoo gun le iyanṣẹlodi lonii ọjọru ọjọ kejilelogun oṣu karun.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ondo: Dejí sun ọmọ méje àtagbalagba meji mọ́lé nítorí pé ó ń bínú Pẹlu ibanujẹ ni Gauri wa ẹgbọn rẹ kiri ki ọwọ awọn ọmọ ogun ọlọtẹ too tẹẹ.
Asán ni àwọ̀n tí eniyan dẹ sílẹ̀,nígbà tí ẹyẹ tí a dẹ ẹ́ fún ń woni,
’ Ó bá sọ fún mi pé, ‘Èmi ni Jesu ará Nasarẹti, ẹni tí ò ń ṣe inúnibíni sí.
Bákan náà lo fi àmì ẹ̀yẹ da a lọla to sì tún fún un ní iṣẹ gẹgẹ bí panapana.
Obìnrin kan tilẹ̀ sọkún tó bẹ́ẹ̀ gẹ́ẹ́, tí kò tilẹ̀ mọ̀ pé èmi ni mo jókǒ ní kọ̀rọ̀ kan ní ẹ̀yìnkùlé.
" Wọn ni awọn nigbagbo wipe, baalu naa jẹ irufẹ baalu ATR 72-500 to ti lo to ogun ọdun.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ọ̀rọ̀ ẹkún omi Eti Ọsa ló jẹwa lógun - Àwọn olùdíje aṣojú-sòfin Ilé ẹjọ́ dájọ́ ikú fún èèyàn mẹ́ta nítorí ikú akẹ́kọ̀ọ́ fásitì UNIOSUN Tinubu parí aáwọ̀ Ambode àtàwọn aṣòfin ìpínlẹ̀ Eko #BBCNigeria2019 Agbẹjọro fun Fayoṣe fi ọrọ wa Ọbanikoro lẹnu wo fun nnkan bii wakati meji, ki Onidajọ Mojisọla Olatoregun to kede isinmi ranpẹ ọlọgbọn iṣẹju lati gbọ ẹjọ miran.
Ènìyàn 653 míràn tún kún iye àwọn tó ní COVID-19 ní Nàìjíríà Wo bí Dorathy Bachor ṣe di gbajúmọ̀ lóríi Instagram lẹ́yìn tí ètò àgbéléwò BBNaija bẹ̀rẹ̀ Àwọn àádọ́ta ọ̀dọ́ wọ gàù nítorí ilé ijó ní Ilorin Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Black women live matters: Ọdún 2015 ní àwọn ọlọ́pàá pa India Kager láìní ìdí- Gina Best Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí US election 2020: Ibú-owó Bloomberg fẹ́ wàákò pẹ̀lú Trump nínú ìbò ààrẹ Amẹrika9 Bélú 2019 Trump impeachment: Àṣírí tùú, àkọsílẹ fihàn bí Trump ṣé béèrè iranwọ lọ́wọ́ ààrẹ Ukraine25 Owewe 2019 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Njoku salaye pe, awọn oluwọde labẹ asia ENDSARS kan lo ṣe ikọlu si ọgba ẹwọn to wa nilu Benin-City ati Oko, ti wọn si tu awọn ẹlẹwọn ti ileẹjọ ni ki wọn wa latimọle silẹ.
Jijo foonu awọn akẹkọ yii ni ina jẹ ọna kan ti o mu iriwisi ọtọọtọ wa paapa julọ ti a ba ro iye owo ti wọn fi ra awọn foonu wọn yii.
Olè ati ọlọ́ṣà ni gbogbo àwọn tí wọ́n ti wá ṣiwaju mi.
Coronavirus ti di ara wa, kò le è kúrò mọ láéláé - WHO Ìdí rèé tí ilẹ̀ Afirika fi gbọdọ̀ kópa nínú dídán abẹ́rẹ́ coronavirus wò Coronavirus cases in Africa- Atọ́nà bí nkàn ṣe ń lọ ní Afirika Ènìyàn 350 ló ní àrùn Coronavirus ní Naijiria ní Ọjọ́bọ̀ Eeyan 3696 lo ti ri iwosan gba, nigba ti awọn 333 ti papoda nitori arun ọhun.
Ohun tí gómìnà Seyi Makinde fẹ́ ṣe lórí ìwọ́dé EndSARS lẹ́yìn ìpàdé rẹ̀ pẹ̀ láwọn tọ́rọ̀ọ kàn Iyabo Ojo gé okùn àjọṣepọ̀ rẹ̀ pẹ̀lú olóṣèlú nínú ẹgbẹ́ APC ati PDP Àṣírí tó ń bẹ láàrín Oluwo àtàwọn ọ̀dọ́ Iwo tí wọ́n fi fi ẹ̀mí wọn lélẹ̀ dáàbò bo ààfin rẹ̀ Iléèṣẹ́ tẹlifísàn AIT, Arise TV àti Channels wọ gàù àjọ NBC nítorí ìpànìyàn Lekki Igba akọkọ ree ti Gomina Sanwo-Olu sọ ni pato pe lootọ lawọn ọmọ ogun yinbọn lu awọn oluwọde.
Ó sọ fún wọn pé, “Ẹ lọ sí abúlé tí ó wà ní ọ̀kánkán yìí.
Oríṣun àwòrán, others O fikun pe awọn abuda rere naa ni wọn yoo lo fun idagbasoke awujọ wa ati orilẹede Naijiria lapapọ.
O fi kun un pe pipana rogbodiyan tabi wahala to lee fẹ ṣuyọ lawọn ọlọpaa wa fun, wọn si ti n gbe igbesẹ gbogbo lati rii pe ko si ohunkohun tabi ẹnikẹni to da omi alaafia ilu ru.
Nibayii, o ti pe aadọrin eniyan (70) to ti ni aarun naa ni Naijiria.
Chelsea kọ́wọ̀ọ́ rìn pẹ̀lú Arsenal lọ àṣekágbá Europa O burú jai!
 A ti ko awon to le ni oodunrun eniyan laarin odun to koja si odun yii nipa ona gbigbe ise won sita lona igbalode.
Press freedom: Ohun tó ń fa ojúkòkòrò fún àwọn oníròyìn nìyìí
Border Closure reoppening: Àarẹ Buhari ní àti dẹ́kun fàyàwọ́ ogun ati ìbọn ló fa títi ẹnubodè pa, ṣùgbọ́n yóò di ṣíṣí padà láìpẹ́
Ati ẹlẹ́dẹ̀ nítorí pé pátákò ẹsẹ̀ rẹ̀ yà, ẹsẹ̀ rẹ̀ sì yà, ṣugbọn kì í jẹ àpọ̀jẹ, ó jẹ́ ohun àìmọ́ fun yín.
Ewe, leyin ti iko ohun jawale ninu atejade ipo ate FIFA losu ti o koja latari didin ami iko naa ti won fi pegede fun idije boolu agbaye, opo ninu awon ololufe iko Super-Eagles lo fokan si pe, ipo ate miran yoo wa soke, sugbon ti ko ri be.
Má kọ̀wé fipò sílẹ̀, àwọn àgbààgbà Yorùbá sọ fún Osinbajo Àwọn ọkùnrin tó wà nínú ayé wa gbúdọ̀ bọ̀wọ̀ fún wa - Olùdásílẹ̀ FIN Wo ìlú tí wọ́n tí ń ta ọmọ ọ̀dọ̀ kan fún #1.
OLUWA, ṣé àwọn odò ni inú rẹ ń ru sí ni,àbí àwọn ìṣàn omi ni ò ń bínú sí,tabi òkun ni ò ń bá bínú,nígbà tí o bá gun àwọn ẹṣin rẹ,tí o wà ninu kẹ̀kẹ́ ogun rẹ?
Dolapo Osinbajo nìkan ní ẹní ọkàn ìgbákejì Ààrẹ Osinbajo yan láàyò.
Fun apere owo naa le san owo ipin osoosu ti ipinlẹ Osun n ri gba ninu akoto owo ijọba apapọ lati osu yi titi di ipari ọdun 2018.
Ni dede aago meji kọja iṣẹju diẹ lọsan ni iṣele naa ṣẹlẹ, eyi taa gbọ pe o mu ẹmi eeyan meji lọ, awọn eeyan mejeeji yii, ti wọn jẹ ọkunrin ati obinrin si lo jona ku egungun ninu ijamba naa.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Mí ò mọ nípa ilé Bukola Saraki ti wọn ti pa- agbẹnúsọ EFCC 13 Èbibi 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 14 Èbibi 2019 Oríṣun àwòrán, @bukolasaraki Àkọlé àwòrán, Mí ò mọ nípa ilé Bukola Sara ki ti wọn ti pa- agbẹnúsọ EFCC Ajọ tó ń gbógun ti ìwà jẹgúdujẹrá lórilẹ̀-èdè Nàìjíríà (EFCC) ní àwọn ò mọ nípa ilé ààrẹ ilé igbìmọ aṣòfin Bukola Saraki ti wọn ti pa oo Adele agbẹnusọ fún iìròyìn àti ìgbóhùn sáfẹ́fẹ́ ọgbẹ́ni Tony Orilade ló sọ èyí di mímọ fún àwọn oníròyìn nílu Abuja.
Oríṣun àwòrán, @Planet_Bee Saaju asiko yii, aṣọ ekisa ni awọn eeyan naa ma n dana sun lati le awọn kokoro ọhun.
Awọn oṣiṣẹ ọgba ẹranko Khao Yai National Park lorilẹ-ede Thailand ṣalaye pe ọmọ erin kan lo yọ ṣubu nibi ida omi tawọn erin mi ṣi fẹ doola ẹmi rẹ.
Ohun to ṣe okunfa bi Kpomassie ti di ero Greenland ni pe, o jabọ lori igi lẹyin to ri ejo kan, eleyi to jẹ ko farapa yanayana.
Oun lo kọkọ sọ wi pe iṣejọba oun yoo san N30,000 owo oṣu ti àwọn òṣìṣẹ́ n ja fun.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, #Sweetsweetcodeine: Ẹ wo bí ìròyìn BBC nípa oògùn ikọ́ Codeine ṣe ń tún ayé tó ti bàjẹ́ ṣe Ijọba ipinlẹ Kaduna ni awọn ṣagbekalẹ ilana ofin naa kii ṣe lati fi da rugudu silẹ ni Kaduna rara bikoṣe lati yonbo alaafia laarin awọn olugbe ipinlẹ ọhun.
  N kò rí ẹ̀kọ-mímu lọ́jọ́ náà.
Ajọ NCDC kede eniyan 452 ti ayẹwo fihan pe o ni Covid-19 ni 23/06/2020 jọ to n mojuto ajakalẹ aarun ni Naijiria, NCDC, ti kede eeyan 452 miran to ni aarun coronavirus ni Naijiria.
Bakan naa ni kọmiṣọna fun eto ilera ni ipinlẹ Eko tun ke sawọn eeyan ipinlẹ Eko lati karamasiki ilera wọn ki wọn si yago fun ekute.
Kò sí orílẹ̀-èdè mìíràn ní gbogbo ayé, tí ó dàbí Israẹli, tí o yọ kúrò ní oko ẹrú láti fi wọ́n ṣe eniyan rẹ.
Ko tii pe iṣẹju kan, Joshua tun ṣubu yakata lai le dide.
Gígùn aṣọ kọ̀ọ̀kan jẹ́ ọgbọ̀n igbọnwọ, fífẹ̀ rẹ̀ sì jẹ́ igbọnwọ mẹrin; bákan náà ni òòró ati ìbú àwọn aṣọ mọkọọkanla.
11 Ẹrẹ̀nà 2020 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Láti Osù Kẹwá, ọdún 2017 ni ọ̀pọ̀lọpọ̀ àwọn obìrin ti fi ẹ̀sùn ìfipábánilòpò kan gbajúgbajù òsèré,Harvey Weinstein.
Ọ̀pọ̀ eniyan wá sọ́dọ̀ rẹ̀, wọ́n gbé àwọn arọ wá, ati àwọn afọ́jú, àwọn amúkùn-ún ati àwọn odi, ati ọ̀pọ̀ àwọn aláìsàn mìíràn.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, EndSARS protest in Nigeria: Mr Macaroni, Falz, Wizkid, Tiwa Savage àtàwọn míì ṣe ìwọde ''Agbẹjọro Shittu ni awọn ọdọ ni aṣẹ lati gba aṣẹ ni ileẹjọ tako ọrọ gomina Wike.
O ki awon eniyan ipinle Zamfara ku ara fe ara ku pelu adura pe ki Olorun te oloogbe si afefe rere.
Bakan naa lo kede pe ọjọ Kinni, osu Kejila ni eto ipolongo ibo fawọn oludije sipo gomina ati ile asofin lawọn ipinlẹ yoo bẹrẹ.
”Wọn kò ní ké pé,“Ó ṣe, oluwa mi!
Lẹ́yìn náà OLUWA sọ fún Mose pé, “Farao kò ní gba ọ̀rọ̀ rẹ, kí iṣẹ́ ìyanu mi baà lè di pupọ ní ilẹ̀ Ijipti.
Ìwádìí fi hàn pé orlando fé ni ibùjókòó ní ilú òyìnbó àti láti dá ilé-èkósé eré sílè bí olórun bá yònda ( akínmúwàgún 2001 : 1-3 ) .
O jẹ onkowe ati ontẹwe, alaga ile itẹwe ISOLAD.
lo mu wa lati wa ri aare ,pe a nilo igbese pajawiri lati lee dojuko awon wahala
Afurasi tó fa ìpayà nílé ìwé Port Harcourt ti wọ gàù Ọ̀rọ̀ Aisha Buhari sí Ramaphosa wú ọ̀rọ̀ síta lẹ́nu àwọn ọmọ Nàìjíríà Kí ló ṣe ikú pa Adewura Latifat Bello lẹ́yìn ọ̀sẹ̀ méjì tí wọ́n ń wá a?
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fọ́nrán ohùn, Oluwo fe fi oye Waziri lọle nilẹ Yoruba Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fọ́nrán ohùn, Oluwo Ìwo ṣ'àlàye lori oyé oba oni lawàni Ọba naa to ti maa n sọ lọpọ igba wi pe ifọwọsọwọpọ ni ọna abayọ si ọpọlọpọ isoro to n koju orilẹede Naijiria, ni wiwọ asọ awọn Igbo fihan wi pe oun fẹran ifọwọsọwọpọ.
 fún ìdí èyí , ó pinnu láti dín owó tó wà lode pàápàá èyí tí wón n ná le isé ìjoba lórí ku .
A o maa fi toyin leti bi eto idibo gomina ni ipinle Osun se n lọ bayii.
ibura fun aare Muhammadu Buhari ti saa keji yii, ti  yoo waye ni ojo kọ́kàndínlọ́gbọ̀n ,osu karun un, odun 2019
Ó kọ́ ilé ìṣúra tí ó kó fadaka, ati wúrà, ati òkúta olówó iyebíye, ati turari sí, ati apata ati gbogbo nǹkan olówó iyebíye.
A lérò wi pé Ijọba Òṣèlú ti àwọn ará ilú yàn fún “àyipadà” kúrò ninú iwà ibàjẹ́ tó gba orilẹ̀ èdè kan fún igbà pi pẹ́, yio wa àtúnṣe fún Èkó.
Ẹni ọdun mẹrindilọgbọn lo jẹ nigba ti wọn gun pa ni agbegbe Hackney ni ọdun 1994.
tí kì í jẹ ẹbọ lórí àwọn òkè, tí kò bọ àwọn oriṣa ilé Israẹli, tí kò bá aya aládùúgbò rẹ̀ lòpọ̀, 
Ninu wọn ni Banaba ati Simeoni tí wọn ń pè ní Adúláwọ̀ wà, ati Lukiusi ará Kirene, ati Manaeni tí wọ́n jọ tọ́ dàgbà pẹlu Hẹrọdu baálẹ̀, ati Saulu.
Aawẹ yii maa n waye fun ogoji ọjọ gẹgẹ bi Jesu Kristi ti gba a ninu bibeli.
Ìdí mẹ́rin tí wọ́n fi sọ Gbáná mímu di ìrọ̀rùn ní Canada Olootu ijọba orilẹede naa, Justin Trudeau to tun jẹ olori ẹgbẹ oṣelu Liberal to wa lori aga iṣakoso, ṣeleri pe, oun yoo sọ igbo mimu ati tita di ofin ti wọn ba fi dibo fun oun lasiko to n polongo ibo l'ọdun 2015.
ati ti àrùn ẹ̀tẹ̀ lára aṣọ tabi lára ilé, 
Ìfihàn tí a fifún Wòlíì Joseph Smith àti Oliver Cowdery, ni Harmony, Pennsylvania, oṣù kẹrin ọdún 1829, nígbàtí wọn bèerè nípasẹ̀ Urímù àti Tummimù bóyá Johannu, àyànfẹ́ ọmọ ẹhìn, sì wà nínú ẹran ara tàbí o ti kú.
'Àgbàrọ́ òjò wọ́ ọmọ méjì lọ ní Ketu l'Eko lálẹ́, a ṣì ń wá wọn di òní' Ilé ẹjọ́ yá lórí òfin CAMA tó fẹ́ gba àkóso ilé ìjọsìn, tẹ ẹ̀tọ́ aráàlú mọ́lẹ̀ - SERAP Wọn tí fòfin de iléeṣẹ́ ìròyìn Chris Oyakhilome nítorí ó sọ pé 5G ló ṣokùnfà àrùn Coronavirus N kò gba owó rí lọ́wọ́ olùdíje kó tó dé ipò - Oyedepo Háà, àṣé Pastor Adeboye kò léè dá èékánná ara rẹ̀ gé, àwọn ọmọ Nàìjíríà kan pariwo Ẹ fura o, wọ́n ti ń fi orúkọ Adeboye àti Olukọya lu jìbìtì ní Facebook Ọjọ ti pẹ ti ẹnu ti ma n kun Freeze nitori awọn ọrọ atako to ma n sọ nipa ẹsin Kristiẹni, paapa nipa idamẹwa ati ọrẹ.
Ojoojumọ ni n óo máa pa àwọn eniyan burúkú run ní ilẹ̀ náà,n óo lé gbogbo àwọn aṣebi kúrò ninu ìlú OLUWA.
Ẹbi Usman fi Naijiria silẹ lọ si orilẹede Amẹrika nigba ti o wa ni ọmọ ọdun mẹjọ.
Lasiko to n si lọwọ ilẹkun sọọbu naa lọwọ, to kọ ẹyin si ita, lawọn ajinigbe naa ba wọ lojiji lọ sinu mọto wọn, ti wọn si n fi tipa ji gbe lọ.
ó wí fún Aaroni pé, “Mú ọ̀dọ́ akọ mààlúù kan fún ẹbọ ìmúkúrò ẹ̀ṣẹ̀, ati àgbò kan fún ẹbọ sísun kí o sì fi wọ́n rúbọ níwájú OLUWA.
Dafidi ọba bá ranṣẹ lọ mú un lati ilé Makiri ọmọ Amieli, ní Lodebari.
O ni oun tun ri oku eeyan meji nilẹ, ti agbegbọ̀n naa si n sọ oniruuru ọrọ ti ko wu eti gbọ.
Mo rí i pé oríṣìíríṣìí oúnjẹ Farao ni ó wà ninu agbọ̀n tí ó wà ní òkè patapata, mo bá tún rí i tí àwọn ẹyẹ bẹ̀rẹ̀ sí jẹ àwọn oúnjẹ yìí ní orí mi.
Sọ pé, ‘Ẹ̀yin òkè Israẹli, ẹ gbọ́ ohun tí OLUWA Ọlọrun wí.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Kayefi BBC Yorùba: Bàbá ọmọ, Mọ́ṣúárì, Ọlọ́pàá kẹ́jọ́ rò nípa òkú ọmọ tó pòórá Kí ló mú bàbá àti ọmọ rẹ̀ méjì rẹ́wọ̀n oṣù mẹ́fà he ?
Ní ọjọ́ kẹrindinlogun, oṣù kejì, ọdún 1968, wọn gbé ọba Olagbegi lọ sílè igbalejo kan n'ilu Òkìtìpupa, níbi tó ti lo ọdún kan àti oṣù kan, tó sì kúrò n'ilu Òkìtìpupa lọ́jọ́ kejìdínlógún, oṣù kẹta ọdún 1969.
ana lorile ede Naijiria Obasanjo ni yoo maa dari adura ibẹrẹ.
Ṣugbọn mo fi OLUWA ṣe ẹlẹ́rìí mi, bí o kò bá yára láti pàdé mi ni, gbogbo àwọn ọkunrin ilé Nabali ni ìbá kú kí ilẹ̀ ọ̀la tó mọ́.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ọbasanjọ lo fa Ya'Adua àti Jonathan Kalẹ, o yan Buhari pẹlú Abajade ipade naa ko ti tọka boya wọn fẹ se ti Buhari tabi ti Atiku sugbọn ipade naa tubọ fi ifarajin ẹgbẹ afẹnifẹre lori ọrọ aato isejọba ti ọpọ mọ si ''Restructuring.
‘Ẹ fi páńpẹ́ ọba mú òsìsẹ́ SARS tó pa ènìyàn ní Iwo’ ‘Ọdún Ojúde Ọba kìí se gbàgede olósèlú’ Ikú mú Olanrewaju tó jẹ́ bàbá ọmọ Bisola lọ Ademola adeleke lo n dije du ipo labẹ ẹgbẹ oselu PDP nigba ti Adegboyega Isiaka Oyetola yoo dije labẹ ẹgbẹ oselu All Progressives Congress (APC).
Ni bayii, awọn obinrin ni Saudi ti n wa ọkọ funra wọn, wọn si lee jade lọ si ibikibi lai si pe ọkọ wọn tele wọn lẹyin.
Oríṣun àwòrán, acebook/Alaafin Oba Adeyemi III '' Ijọba yẹ ko lo akoko yii lati fi gbọ ohun ti awọn ọdọ nii sọ, ki iru iṣẹlẹ to waye lasiko ifẹhọnuhan EndSars ma ba tun waye.
Xenophobic Attack:Àwọn ọmọ Naijiria sọ fun South Africa pé \Ó tó gẹ́\"""
Ọkọ Toyota Avalon ati Villager minivan ni awọn ọkọ mejeeji ọhun.
Gbajugbaja ounjẹ, ari ma lee lọ ni irẹsi jọlọọfu ni ẹkun iwọ oorun Afirika eyi ti wọn maa n fi irẹsi, tomato atawọn eroja miran ṣe.
Bí ẹnikẹ́ni bá wá sọ́dọ̀ yín tí kò mú ẹ̀kọ́ yìí wá, ẹ má gbà á sílé.
Àkọlé àwòrán, Awọn ẹni atẹẹka to ti dogbo, ta ri ni yara Fagunwa ree.
Ileeṣẹ naa ṣapejuwe iku Richard gẹgẹ bi eyi ti wọn kabamọ rẹ gidi gan wn si ti ṣabẹwo si ẹbi oloogbe leyii ti wọn kọwọrin pẹlu ikọ aṣoju awọn akẹkọọ ileewẹ rẹ lọ sile wọn.
Ati pe, ṣe lootọ ni epe naa n ja ẹya Yoruba, eyi to mu ki ifẹ, isọkan ati igbọraẹniye sọnu laarin ọmọ Oodua.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, BBC Africa Eye: ìwádìí ìkọ̀ks BBC fihàn pé àwọn kan ń jí ohun èèlò ìdáàbòbò ìjọba tà nígbo Okonkwo tun jẹ ko di mimọ pe wọn pa ọkan lara awọn to kopa ninu ikọlu laipẹ yii lagbegbe naa.
Nígbà náà ni àwọn ará Bẹnjamini tó pada wá, àwọn ọmọ Israẹli sì fún wọn ní àwọn obinrin tí wọ́n mú láàyè ninu àwọn obinrin Jabeṣi Gileadi, ṣugbọn àwọn obinrin náà kò kárí wọn.
Nítorí pé Kristi ni mo wà láàyè fún ní tèmi, bí mo bá sì kú, èrè ni ó jẹ́.
 irú àwọn báyìí ni sódẹkẹ ́ , lísàbí , Ẹfúnróyè , tinúubú ati Ògúndìpẹ ̀ alátise .
Lataari ikede ajo INEC, eleyi ti egbe oselu alatako Peoples Democratic Party, PDP n gbe igba oroke lowo pelu ibo ọ̀ọ́dúrún le metaleladọta, ti  fesun kan ajo INEC pe won se ojusaaju ni erongba lati ran egbe oselu APC lowo ni.
Mi ò màmà ríhun tó pọ̀ tí ò ní tán
 kò sí ọmọ Ẹ ̀ gbá kan tí kò ní abúlé .
" Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: 'Ẹ ṣọ ìrìn yín lágbègbè Pen Cinema' Ìkéde Buhari: Ta ni yóò kojú u rẹ̀?
Iroyin naa fikun pe, gomina Seyi Makinde lo pinnu lati gbe ẹjọ fanfa laarin Olubadan ati awọn ọba alade yoku naa kuro nile ẹjọ, ki wọn lee yanju ọrọ naa nitubi n nubi, ki alaafia si pada jọba laarin Olubadan ati awọn ijoye rẹ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù UK Prime Minister: Boris Johnson, Olóòtú ìjọba Gẹ̀ẹ́sì tuntun sọ̀rọ̀ àkọ́kọ́ 23 Agẹmo 2019 Àkọlé àwòrán, Jeremy Hunt ti ki Boris Johnson ku oriire Boris Johnson ati Jeremy Hunt ni wọn jọ dije igbẹyin ninu eto idibo ọhun.
Ṣaaju ni awọn ẹgbẹ obinrin ni ipinlẹ Ondo ti ṣe iwọde pe ki Gomina Akeredolu gbe igbesẹ to yẹ lori ọrọ yii Àwọn abiyamọ figbe ta lórí ọmọ ọdún kan ti wọn wá nílé ìjọsìn l'Akure Bi awọn kan ti n bu ẹnu ẹ̀tẹ́ lu awọn ọdọ agbegbe to dana sun ile ijọsin pe ko yẹ ki wọn gbe igbesẹ yii ni awọn miran ni awọn agb pe ijọba yoo ṣe ohun to kan bayii.
Lẹ́yìn aadọjọ (150) ọjọ́, omi náà fà tán.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Brexit: Ilé làbọ̀ ìsinmi oko fọ́mọ Yorùbá nílẹ̀ Gẹ̀ẹ́sì 13 Ọ̀pẹ̀̀ 2018 Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ọ̀rọ̀ lórí Brexit Ọgọọrọ eeyan lo ti n sọrọ lori bi Olootu ijọba Ilẹ Gẹẹsi, Theresa May ṣe mori bọ l'Ọjọru nigba ti ile aṣofin fẹ yọọ nipo lori ọrọ Brexit.
71, fun iṣẹ agbaṣe oju ọna ọkọ reluwe ti yoo so orilẹ-ede Naijiria pọ mọ Niger Republic.
 Busari lo salaye oro yii ,lasiko ti o n ba akoroyin
Akojọ ero awọn oludibo(poll) n tọka si pe ni ipinlẹ bi Michigan, Pennsylvania ati Wisconsin, oun lo n lewaju.
Iṣẹ́ Ọlọrun àwámárídìí ni káàkiri àgbáyé Kìí ṣe òni ní a ti máa ń gbọ nípa àwọn alagbara ayé l'ókùnrin àti l'obinrin, àwọn aláwo ti wọn máa ń ṣe oníruuru òògùn, ti omíran a sì máa sọ pé oun le ti òjò tàbi yí oju ọja padà.
 Okeowo pari ọrọ rẹ pe igbakeji gomina ọhun ko ji ẹru ijọba ipinlẹ Ondo ko bi awọn kan ṣe lero, Ati pe iṣẹ ti awọn agbofinro ṣe lati dena rẹ nigba to fẹ jade ninu ile ijọba to wa ni ilu Akure ko ba ofin mu."
ÌTÀKÙRỌ̀SỌ LÁÀRÍN- ÍN ÈMI ÀTI ÌYÁ ONÍWÓRÓBO
 Ọmọ bibi ilu Ijẹfẹ ni mi tori wi pe Ile Ifẹ ni mama mi, Ijesha ni Baba mi.
ilu bi won se jẹ ki eto idibo aare lo ni irowo ati irose, bo tile je pe wahala
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Bolu Akin Olugbade: Ọkọ̀ olówó iyebíye Roll Royce Limousine mẹ́wàá nìkan ni ọlọ́lá yìí gùn nígbà ayé rẹ̀ 14 Sẹ́rẹ́ 2021 Oríṣun àwòrán, Bolu Akin-Olugbade Ọpọlọpọ ọlọla ati eniyan jankan lo ti n ṣedaro oniṣowo Bolu Akin- Olugbade to ki aye pe o digba o ṣe, nigba ti arun Coronavirus gba ẹmi rẹ.
Lára wọn ni Ajá to ń Lépa Ẹkùn, Ọ̣wọ̣̣́ Tẹ Amòokùnṣìkà, Àgbákò nílé Tẹ́tẹ́, Baṣọ̀run Olúyọ̀lé, Ajayi, the Bishop, Chaka, the Zulu, Esther, the Queen, Abraham, The….
Ìyá Sisera ń yọjú láti ojú fèrèsé,ó bẹ̀rẹ̀ sí wo ọ̀nà láti ibi ihò fèrèsé.
“Bí ó bá jẹ́ pé láti inú agbo aguntan tabi agbo ewúrẹ́ ni ó ti mú ẹran fún ẹbọ sísun rẹ̀, akọ tí kò ní àbààwọ́n ni kí ó mú.
Lootọ nigba ti ijọba apapọ atawọn ijọba ipinlẹ si ipinlẹ lorilẹede Naijiria kede didẹwọ lori eto igbele, oniruuru eto ni wọn gbe kalẹ lati rii pe lasiko ti wọn dẹwọ igbele naa ajakalẹ naa ko gbẹnu soke.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ọjọ́ burúkú, èṣù gbomi mu ní Ṣagamu nígbà tí agbábọ́ọ́lù kan dèrò ọ̀run Oluwo kò gbọdọ̀ kọrin òwe tàbí bá àkọ̀ròyìn sọ̀rọ̀, kó má baà ba ẹjọ́ ara rẹ̀ jẹ́ - Ọ̀ràngún ṣàlàyé BBC Yorùbá gba àmì ẹ̀yẹ akọni nídìí àgbéga àṣà àti èdè abínibí Ẹ má sọ Amotekun di ẹgbẹ́ OPC, ẹ fi wá sínú ẹ̀ṣọ́ aláàbò - Miyetti Allah Buhari, kí ló dé tó fẹ́ dá $100m owó Abacha padà fún gómìnà Kebbi?
Coronavirus and OCD: 'Mo fi ogún ọdún gbáradì fún àjàkálẹ̀ ààrùn yìí' Kí lo mọ̀ nípa fẹntilétọ̀, ohun eèlò aṣèrànwọ́ èémí Ṣé ìnàkí tún gbé owó tó lé ní mílíọ̀nu mẹ̀fà Náírà mì ni?
Ẹ óo rú ẹbọ yìí pẹlu ẹbọ ohun jíjẹ ati ẹbọ ohun mímu rẹ̀, gẹ́gẹ́ bí ìlànà ti ọjọ́ kinni, 
”Ṣugbọn àwọn ọmọ Eli kò gbọ́ ti baba wọn, nítorí pé OLUWA ti pinnu láti pa wọ́n.
Wọn yóo dáàbò bo ọba pẹlu idà ní ọwọ́ wọn, wọn yóo sì máa bá a lọ sí ibikíbi tí ó bá ń lọ.
Laipẹ yii ni iroyin sọ pe wọn dana sun awọn ọti lile.
nítorí ìwọ ni olùrànlọ́wọ́ mi,lábẹ́ òjìji ìyẹ́ rẹ ni mò ń fi ayọ̀ kọrin.
Àwọn ejò lọ́ mọ́ Ìjànbáforítì lára tó bẹ́ẹ̀ tí a kò fi rí ara rẹ̀ lóde mọ́.
Ṣugbọn wọn kò ní ọmọ, nítorí pé Elisabẹti yàgàn.
Ọ̀dọ́mọkùnrin náà tó sọ pé òun ti túbá, tí òun kò sì bá ẹgbẹ́ náà ṣiṣẹ́ mọ́, tún fikun pé àìsí iṣẹ́ ló fàá tóun fi darapọ̀ mọ́ ẹgbẹ́ náà.
Ninu iwe ti agbẹjọro Atiku, amofin agba Mike Ozekhome kọ si Onochie, eyi to fi ṣowo si awọn oniroyin, Atiku ni Onochie pa irọ mọ oun wipe awọn agbofinro n wa oun fun awọn ẹsun kan ni orilẹede UAE.
Daura Ruler: Ọlọ́pàá ti gba àna ẹ̀ṣọ́ ẹ̀yin Buhari silẹ̀ lọ́wọ́ ajínigbé
Oríṣun àwòrán, Twitter O fikun pe awọn eniyan n wo oju ijọba ti wọn dibo yan fun aabo to peye, amọ wọn kọ lati dide si wọn.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù WAFU: Falcons gbera lo si Abidjan 12 Èrèlè 2018 Oríṣun àwòrán, NFF Àkọlé àwòrán, Odu ni iko agbabọọlu obirin orilẹẹde Naijiria, Super Falcons, nibi idije bọọlu nile Afrika Ikọ agbabọọlu obirin Super falcons torilẹede Naijiria ti gbera lo si Cote'divoire lati kopa ninu idije fun ife ẹyẹ WAFU ti yoo bẹrẹ lojọru.
Ọjọ kinni, oṣu kẹwaa, ọdun 1060 ni Naijiria gba ominira kuro lọwọ ilẹ Gẹẹṣi to ko wọn lẹru.
Ni ibeere to ṣeese ko gba ẹnu awọn eeyan pupọ nitori Harry ni wọn mọ orukọ ọkọ iyawo ọjọ abamẹta si.
Ìwà òmùgọ̀ ni, ìtìjú sì ni, kí eniyan fèsì sí ọ̀rọ̀ kí ó tó gbọ́ ìdí rẹ̀.
Bakanna ni ibudo igbafẹ yii npa owo ribiribi wọle fun ijọba ipinlẹ Ekiti Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Mercy Aigbe: Èmi ni ìyá onílé tuntun 'Mo kan sara sawọn ayasọlo' 'Ẹ dá owó padà f’áwọn ẹbí MKO Abiọla' ‘Isẹ́ tíátà pé mi láì mú nkàn míì mọ’ Wo agbẹdẹ 'akọkọ ní Ìbàdàn Báwo ni ìlù gángan se bẹ̀rẹ̀ ?
Lanre Kuti ni mo fẹ́ - Jaiye Kuti Ènìyàn 27 lo ti bá iṣẹ̀lẹ̀ ọkọ̀ ofúrufú tó já rìnrìn ajò Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Kogi 2019: Àwọn ará ìlú sọ̀rọ̀ lórí ìrètí wọn lọ́wọ́ Yahaya Bello Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Amojúẹ̀rọ tó ń nu bàtà fi wá oúnjẹ òòjọ́ 6 Sẹ́rẹ́ 2020 Chekole Menberu to ti di ẹni ọdun mẹtadinlọgbọn bayii ni ọpọlọpọ ireti giga nigba ti kawe ja pẹlu oye fasiti onipele kinni ninu imọ chemical Engineering lọdun meji sẹyin ni orilẹede Ethiopia.
Mo fẹ foju kan aarẹ Trump Lara awọn ti ọrọ Dokita Stella yoo dun mọ ninu ni aarẹ orileede Amẹrika Donald Trump ati awọn alatilẹyin rẹ.
Àwọn ẹlòmíràn kà wá sí ẹlẹ́tàn, bẹ́ẹ̀ sì ni olóòótọ́ ni wá.
Bakan naa ni olorin gbajugbaja naa sọ wi pe ọlọ́pọlọ pípé kò leè ṣe òṣèlú lórílẹ̀èdè Nàìjíríà, nitori iwa ẹgbin bii jẹgudujẹra ti o wọpọ ninu oselu orilẹede Naijiria.
Eléyìí ni bàbá mi rí mọ - kò sì rí obìnrin náà mọ́.
O kuro ninu iko agbaboolu Chelsea lati darapo mo iko agbaboolu Shanghai Shenhua ninu idije orile-ede China lodun 2012, leyin osu mefa o tun darapo mo iko agbaboolu Galatasaray lorile-ede Turkey, ki o tun to darapo mo Chelsea pada lodun 2014.
Bobrisky lori Instagram ni oun ko gba ẹsun ti wọn fi kan Mompha gbọ, nitori oninure ni ọdọmọde olowo Instagram naa.
Fulani nìkan kọ́ ló ń pa ènìyàn ní Naijiria -Tinubu Ọmọogun pa darandaran mẹwa ni Adamawa Àwa ò mọ ẹgbẹ́ kankan tó ń jẹ́ fijilanté fulani l'Ondo- Ìjọba ìpínẹ̀ Ondo Ilé ẹjọ́ sún ìgbẹ́jọ́ Sẹ́nétọ̀ Elisha Abbo tó lu obìrin Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
 ní 2010 , àrùn ẹ ̀ dọ ̀ líle a fa ikú 102,000 .
Omo ogun olote Al Shabaab ohun, lo n se ikolu lorisirisi si olu ilu orile-ede naa ti n se Mogadishu ni gbogbo igba, ti o fi mo awon ibi miran ni Somalia.
Àwọn ọmọ-ẹ̀yìn júbà rẹ̀, wọ́n bá fi ọpọlọpọ ayọ̀ pada lọ sí Jerusalẹmu.
Òsèré Tíátà, onísòwò àti olóòtú eré ni.
Mercy Aigbe kò mọ ọ̀dá owó, ọkọ̀ ayọ́kẹ́lẹ́ tuntun ló fà yọ lásìkò Coronavirus Ǹjẹ́ o mọ àwọn òṣèré bí Oyin Adejọbi, Funmi Martins àtàwọn míì tó ti dágbére fáyé?
Nígbà tí ara tíí bàjẹ́ bá ti gbé ara tí kì í bàjẹ́ wọ̀ tán, tí ara tí yóo kú bá sì ti gbé ara tí kì í kú wọ̀, nígbà náà ni ọ̀rọ̀ tí a ti kọ sílẹ̀ yóo wá ṣẹ pé,“A ti gbé ikú mì,a sì ti ṣẹgun.
Idije yii yoo waye ni papa iṣere Etihad laarin Manchester City ati ẹgbẹ agbabọọlu Chelsea nirọlẹ ọjọ Satide oni.
Ẹ̀dá alàyè náà lósì fún ẹni tí a dá tẹ̀le e ní orúkọ.
Nyantekyi ní wọn kámọ́ nínú fọnrán kan tó tí ń ṣe ìpàdé ìdákankọ́ olówó ńlá kan lórúkọ ààrẹ orílẹ̀-èdè Ghana, Nana Akufo-Addo, àti igbákejì rẹ̀.
Ìtumọ̀ àbàdòfin lórí omi tí ìjọba tẹramọ́ tó n bí àwọn ọmọ Nàìjíríà nínú rèé Ìjọba Naijiria faraya nínú lẹ́tà tó kọ sí CNN lórí ìwádìí rẹ̀ nípa ìṣẹ̀lẹ̀ Lekki Toll Gate Iṣu ata yáan yàan!
Atẹjade kan ti agbẹnusọ fun gomina Makinde, Taiwo Adisa fi sita ṣalaye pe nibi ipade igbimọ ọrs aje lorilẹede Naijiria, NEC ni Makinde ti fẹrẹ ko arun ọhun.
BBC ti gbọ lẹnu agbẹ́joro to n soju awọn obi Neha ati awọn mọlẹbikunrin rẹ wi pe wọn yoo sọ fun adajọ wi pe awọn ko jẹbi ẹsun naa ni.
Ti a ba wó iye gbogbo rẹ̀ lápapọ, Afíríkà ló ni iye ènìyàn tó kéré jùlọ lágbayé, sùgbọ́n bi aàrùn náà ṣe ń tàn ka ni afíríkà jẹ́ ǹkan ti ó ń kọ àwọn elétò ìlera lóminu ni ìhà Afirika.
Lara ohun ti won jiroro le lori ni, oro to niise nipa eti okun, eto abo lori ero alatagba,ati eto idokowo laarin awon orile-ede ti won je omo-egbe.
Aba eto iṣuna naa fihan pe owo ajẹmọnu ati owo oṣu awọn agbofinro atawọn ọmọ ogun lo fẹẹ gba gbogbo owo tan ninu eto iṣuna ọhunWo gbèsè tí Nàìjíríà ti jẹ láàrin ọdún 2015 sí 2019 .
Sugbọn, o sọ pe ilana ti aarẹ yoo gbe e gba yoo yatọ, ko si ni ṣe e ni ilana bo ba o pa, bo o ba ko bu u lẹsẹ.
Ajọ CDC naa lo ni sanitaisa gbudọ wa lawọn ibudo idibo lati rii pe abo to daju wa fawọn oludibo ṣugbọn wọn rọ awọn oṣiṣẹ eto idibo atawọn oludibo lati rii pe ọwọ wọn gbẹ daadaa ki wọn to fọwọ kan iwe itẹka.
Awọn yoku ni Ile Oluji/Okeigbo, Owo, Idanre ati Ondo East.
Buhari sọ eyi nibi asekagba ipolongo ibo to waye ni ọjọ isẹgun ni ilu Ado Ekiti fun Dokita Kayode Fayemi, to n dije dupo gomina ninu idibo ti yoo waye ni Ọjọ Satide, ọsẹ yii.
Gideoni bá lọ sí odò Jọdani, ó sì kọjá odò náà sí òdìkejì rẹ̀, òun ati àwọn ọọdunrun (300) ọkunrin tí wọ́n tẹ̀lé e.
Fun igba diẹ bayii, ni awọn ọdọ ti bẹrẹ si ni ṣe ifẹhọnuhan kaakiri orilẹede Niajiria, lati tako iṣekupani ojoojumọ lati ọwọ awọn ọlọpaa Niajiria paapaa ikọ SARS.
” Davido sọ̀kò ọ̀rọ̀ sí Oyetola lẹ́yìn tí 'èèyàn méjì pádánù ẹ̀mí wọn' níbi ìwọ́de End SARS Osogbo Òkú tó jí lọ́jọ́ kejì ní mọ́ṣúárì padà kú síléèwòsàn Ṣé lóòtọ́ ni àjọ ọlọ́pàá dá Abayomi Shogunle àti Dolapo Badmus dúró?
Igbó sambisa kò ní pe di ibi ìgbàfẹ́ Só lè jẹ búrẹ́dì tí wọ́n fi Aáyán se?
Ṣugbọn bí wọn bá fi mí ṣe ààbò,kí wọn wá kí á parí ìjà láàrin ara wa;kí wọn wá kí á parí ìjà láàrin ara wa.
 Ó kàn jẹ ́ pé àwọn ọnà-èdè wọ ̀ nyí ṣodo sínú orin-ifá ju àwọn ohùn ẹnu yorùbá yòókù lọ .
Ó tún lóyún, ó bí ọmọkunrin keji, ó sọ ọ́ ní Onani.
Eyi waye lẹyin ọjọ mẹrin ti awọn ọdọ ti n fi ẹhonu han, ti wọn si n ṣe iwọde kaakiri Naijiria.
EFCC ń wádìí iléeṣẹ́ 'Bola Tinubu,' Alpha Beta Consulting Ltd' Àwọn agbébọn jí ìyàwó bàbá Sẹ́nétọ̀ Abbo tó lu obìnrin nílùú Abuja gbé Ooni Ile ife, Ààrẹ Gani Adams fárígá lórí ikú ọmọ Fasoranti Kí ni Obasanjo sọ lórí ikú ọmọ aṣíwájú Afenifere, Rueben Fasoranti?
Oríṣun àwòrán, TKelani Àkọlé àwòrán, Tunde Kelani Tunde Kelani ba BBC sọrọ wi pe oun ko yan Baba Wande jẹ, ati wi pe ẹtọ rẹ lohun fun un lẹyin ti won gbe fiimu naa jade.
Oríṣun àwòrán, Instagram/@queenola2 Amọ nigba to n sọrọ lori ọjọ ibi rẹ naa, to waye lọjọ Kẹta osu Kọkanla ọdun 2020, Olori Badra ni oju oun ti ri nnkan lọdun 2020 ta wa yii.
  Ǹjẹ́ ẹ jẹ́rìí Alákọ̀wé yín bí?
“Àwọn tí kò mọ Ọlọrun fẹ́ràn ibinu,wọn kì í kígbe fún ìrànlọ́wọ́,nígbà tí ó bá fi wọ́n sinu ìdè.
Ewe, iko agbaboolu PSG ti jawe
Nibẹ si ni awọn orilẹ-ede ti le yanju aawọ to ba waye laarin wọn nitori okoowo.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ìyàwó mi fẹ́ràn ìrìnàjò òfurufú ni mo ṣe kọ́ ilé Bàálù yìí fún un Omi ìṣẹ̀ńbáyé tó ń dà ní Ówù rèé, èyí tó ga jùlọ ní Afirika 'Ǹkan tó jẹ́ kí iṣẹ́ ọ̀nà tèmi yàtọ̀ lágbàáyé ni ǹkan tí mò ń lò' Mo ti sọ ìran nípa ọkọ aképo tó gbiná ní Onitsha kó tó ṣẹlẹ̀ - Primate Ayodele Àlá àwọn òjíṣẹ́ Olúwa tó fẹ́ jẹ ààrẹ Nàíjíríà leè má ṣẹ lógún ọdún - Abiara Ìbẹ̀rẹ̀ mi kò rọrùn rárá, omi máa ń bọ́ lójú mi tí mo bá rántí àkókò náà - Small Doctor Akori ẹkọ wa fun toni ni Ẹya Litireṣọ ede Yoruba, olukọ wa si ni ọgbẹni Lawanson Olumuyiwa.
O ni bi wọn ṣe n sọ oko ni wọn n fọ ilẹkun ati gilaasi ninu aafin naa.
  Ẹ sì kú ọdún tuntun 2014!
Ta ni Olatoye Temitope 'Sugar' tó di olóògbé?
Oluranlọwọ aare lori ọrọ  to jẹ mọ ti ile igbimo asofin agba, Ita
Nítorí pé ilẹ̀ tí ó kún fún ère ni,wọ́n sì kúndùn ìbọ̀rìṣà.
Nígbà tí wọ́n ṣí i, tí wọ́n rí i, ẹnu yà wọ́n.
Àwọn aposteli tí ó wà ní Jerusalẹmu gbọ́ bí àwọn ará Samaria ti gba ọ̀rọ̀ Ọlọrun.
"Apple iPhone 12 pro Max:Mọ̀ nípa iPhone 12, fóònù ológo 5G tí kìí lo \""Charger” tó ṣẹ̀ṣẹ̀ jáde"
 Ajagunfeyinti Abdulrahman Dambazau,  wa ki awon osise fun iwa akin ati ifarajin
Lẹ́yìn náà, ó ní kí olukuluku máa lọ sí ilé rẹ̀.
Gbogbo àwọn tí wọn ń gba ibẹ̀ kọjá ń pòṣé, wọ́n sì ń mi orí wọn.
Àwọn ará Ijipti sì ṣọ̀fọ̀ rẹ̀ fún aadọrin ọjọ́.
Bi wọn ṣe n duro ki ẹni to n ta Shawarma da wọn lohun, a gbọ pe ede aiyede bẹ silẹ laarin Okikiola ati onibara miran ti oun naa fẹ ra Sharwama.
Àwọn ọmọ Lotani ni Hori, ati Hemani, Timna ni arabinrin Lotani.
aarin awon omo orile ede Naijiria”o ni ijoba to n sakoso lowo ti da orile ede yii pada seyin.
Ẹni tí ń tọ́ oníyẹ̀yẹ́ eniyan sọ́nà fẹ́ kan àbùkù,ẹni tí ń bá ìkà eniyan wí ń wá ìfarapa fún ara rẹ̀.
Ní àkókò yìí ni ọmọ ń sọnù lairo tẹ́lẹ̀.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Nigeria vs Madagascar: Super Eagles ń gbáradì fún ọjọ́ àìkù Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Nigeria vs Madagascar: Super Eagles ń gbáradì fún ọjọ́ àìkù 29 Òkùdu 2019 Awọn ọmọ ikọ agbabọọlu Naijiria ti n gbaradi kikan kikan lati gbena woju ikọ agbabọọlu Madagascar.
Saulu bá wí fún gbogbo Israẹli pé, “Gbogbo yín, ẹ dúró ní apá kan, èmi ati Jonatani, ọmọ mi, yóo dúró ní apá keji.
“Ẹ ṣọ́ra nígbà tí ẹ bá ń ṣe iṣẹ́ ẹ̀sìn yín, ẹ má máa hùwà ṣe-á-rí-mi, kí àwọn eniyan baà lè rí ohun tí ẹ̀ ń ṣe.
àríwá-gúúsù a6 , máìlí ọgọrin ( 130km ) gúúsù paris ní agogo mẹjọ àárọ ̀ , táyà rẹ ̀ sì fòyọ nígbà tí ó ń sáré rin máìlì méjìdínlọ ́ gọrin ní wákàtí kan ( 126km / h ) , ogún máìlì fún wákàtí kan ( 32km / h ) bju eré ọkọ ́ sísá tí òfin fàyé gbà ní ìgbìyànju lati ṣe ìfipáju àkókò tó ti ṣòfò .
Nigba to wa lori oye gẹgẹ bi Aarẹ ile aṣofin Naijiria,ajọ to n risi igbogun ti awọn to n lu owo ilu ni ponpo ati gbigbogun ti iwa ibajẹ ICPC naa pe lẹjọ.
Ọjọ kẹrindinlọgbọn, osu Keje, ọdun 1926 ni a bii, Ile Oluji nipinlẹ Ondo si ni wọn ti wa.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Ṣé ẹ lè kí Liverpool kú oríire báyìí?
CAF: Wo ohun tuntun tó n ṣẹlẹ̀ lágboolé CAF
Kyari ku si ile iwosan kan ni ilu Eko lẹni ọdun mẹtadinlaadọrin lẹyin to lugbadi arun Coronavirus.
Mi o ṣe bẹẹ ri Bisọla nitoripe mo mọ pe ko si ẹda kan ti kii ṣẹ Ọlọrun lọba alaforiji.
O ni ti ajaga ba ti wuwo ju bose yẹ lọ, ti ko si se fara da mọ, awọn eeyan yoo ja lati bọ ninu rẹ, pẹlu afikun pe, igbe aye awọn ọdọ Naijiria ko wu ni lori rara.
Àwọn ni baba ńlá àwọn ọmọ Lefi.
Gómìnà Akinwunmi Àmbọ̀dé ni lati wá àtúnṣe si iyà ti ojú ará ilú nri nipa gbi gbé ọkàn lé ọkọ̀ ilẹ́ fún ohun irinna nikan, nipa pi pari iṣẹ́ ọkọ̀ ojú irin àti ibùdókọ̀ ojú omi ti Ijọba Gómìnà Babátúndé Raji Fáṣọlá bẹ̀rẹ̀, ki wọn si ṣe kun nipa ipèsè ibùdókọ òfúrufú àti ohun amáyédẹrùn yoku.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ọwọ́ tẹ ọkùnrin kan ní pápákọ̀ òfurufú l‘Eko tó ń kó ike ATM 2,886 lọ si Dubai Lẹ́yìn ọ̀pọ̀ ọdún, ìjọba Kwara fẹ́ sọ orúkọ Rashidi Yẹkini di mánigbàgbé Ọ̀kẹ àìmọye ẹ̀rọ àyẹ̀wò káàdì olùdìbò jóná mọ́lé l' Ondo Wo iye àwọn tó ti gbẹ̀mí ara wọn ní Nàìjíríà láàrin ọdún mẹ́rin ìjọba Buhari Nigba to n salaye bi ọba oke se mu se alabapade aya rẹ lati igba ewe loju opo Twitter rẹ, ọkunrin kan to n jẹ King Millie ni iyalẹnu lọrọ awọn.
 INEC ti setan fun eto idibo fun gomina ati ile igbimo
Ẹwẹ, Aṣofin Ọbasa wa rọ gbogbo awọn oṣiṣẹ lati ma ṣe fa sẹyin ninu awọn ojuṣe wọn gbogbo lati fi ṣe atilẹyin fun ijọba, “a nilo ifọwọsowọpọ, agbọye, atilẹyin ati adura yin ni gbogbo igba, awa  naa ko si ni ṣai maa beere fun awọn nnkan wọyin lati ọdọ yin”.
Mi o si ni ṣe bẹẹ mọ pẹlu ogo Ọlọrun'' Ìjà ìgboro rèé o, ṣe bí ọkùnrin ni Bobrisky ṣe bá ọkùnrin ẹgbẹ́ rẹ̀ jà ní?
Fasiti Ahmadu Bello to wa ni Zaria ni wọn fi pe orukọ rẹ lati yẹ ẹ si.
Wo àwọn fọ́ran to jẹyọ nibi ayẹyẹ náà Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 3 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 5 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
O gbọdọ ṣọra ṣe lori rẹ.
Tí n óo máa ké pé, “Wo ìwà ipá!
Alaga egbe LMC, ti o tun igbakeji aare ajo NFF teleri, Shehu Dikko ni ajo FIFA ti yan bayii sara igbimo awon torokan gbangban ninu ajo ohun, leyin ti o kopa ninu ipade apero akoko igbimo ohun ti o waye ni Zurich, lorile-ede Switzerland ti n se olu-ilu ajo FIFA lojo-Ru(Wednesday),Aare ajo FIFA, Gianni Infantino ati igbakeji re, Victor Montagliani leni ti o tun je aare ajo CONCACAF ni won pawopo lati sefilole igbimo tuntun naa.
” Ó sì mú wọn lọ sí Samaria.
 Àlá àkọ ́ kọ ́ ni mo rí tí mò ń wí , gbankọgbì nit i ìkejì tí n ó ròyin rẹ ̀ fún yín yìí .
Ṣugbọn akọsilẹ ti BBC ri arigbamu rẹ lori itakun agbaye ajọ ọgba ẹwọn nilẹ America, fihan pe Hushpuppi ko si ni ọgba ẹwọn ilu Chicago mọ, koda ogunjọ, oṣu Keje, ni wọn ti tu u silẹ.
Àrùn Coronavirus àti ìbálòpọ̀ akọ àt'abo: Wo àwọn ohun tó yẹ kí o mọ̀ nípa
AMAA 2018 Ami eye fun osere to saaju julo
SERAP - BBC News Yorùbá BBC News, YorùbáFò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù ₦22.
Eyi ni awọn nkan to yẹ ko mọ nipa Ọjọgbọn Femi Odekunle: Ọjọgbọn Femi Odekunle lọ si ileewe alakọbẹrẹ ni Otapete Methodist School ni ọdun 1955 ati ileewe girama ni Ilesha Grammar School ni ọdun 1962 Odekunle lọ si ile iwe giga fasiti ti Ibadan ni ọdun 1965 si 1968, ki o to lọ kawe ni ọke okun ni fasiti Ivy League's University of Pennsylvania, Philadelphia, USA (1969-1974), to si kẹkọ imọ oye nipa iwa ọdakan ati ihuwasi ọmọ eniyan Lẹyin ti wọn ti ṣiṣẹ olukọ fasiti fun ọdun meji ni orilẹede Amerika ni fasiti, Lincoln, lo wa pada wa si Naijiria ni ọdun 1974 nibi to ti ṣiṣẹ olukọ ni Fasiti Ahmadu Bello University Ọgbọn ọdun ni Odekunle fi ṣiṣẹ gẹgẹ bi ọjọgbọn to si ṣiṣẹ karakara ni awọn ipo to dimu Gẹgẹ bi onimọ nipa iwa ọdaran,, o ti kọ iwe lorisirisi lori ọna ati mu adinku ba iwa ọdaran lawujọ ati bi itẹsiwaju ṣe le ba awọn eniyan lawujọ Lasiko ijọba ologun Sani Abacha ni ọdun 1993- 1998 ni Odekunle di olubadamọran pataki fun ọgagun ọhun, to si ṣiṣẹ ni ọfiisi igbakeji Abacha, iyẹn Ọgagun Diya Nitori naa lasiko ti idukoko iditẹgbajọba gbode kan laarin Abacha ati Diya, Femi Odekunle di ero ẹwọn pẹlu ọpọlọpọ ifiyajẹni Oṣu Kejila, ọdun 1997 ni wọn gbe e lọ si ẹwọn, ti ko si jade kuro nibẹ titi di ọjọ Karundinlogun, Osu Keje, ọdun 1998, lẹyin ti Abacha jade laye.
Nahiṣoni ni baba Salima; Salima ni ó bí Boasi, 
Gẹgẹ bi ọpọlọpọ awọn ẹsọ ẹti ọkun, ibi ti wọn ti ma n ri owo ni awọn ti wọn ma n fun wọn lọwọ lẹyin ti wọn ba gba wọn la lọwọ iku.
Gomina fi ẹgbẹrun (1,000) ìwọ̀n diramu wúrà sí ilé ìṣúra ati aadọta àwo kòtò, ati ẹẹdẹgbẹta ó lé ọgbọ̀n (530) ẹ̀wù alufaa sí i.
O wa sekilọ pe o seese ko jẹ pe ibo ọdun 2023 naa ni yoo fopin si orilẹede ti wọn n pe ni Naijiria , eyiun tawọn alasẹ ba fi kuna lati se atunto orilẹede yii.
Àṣírí ilé ìmúni nígbèkùn míràn tú síta ni Katsina Patoranking,Teni,Burna Boy: tá ní yóò gbà àmì ẹ̀yẹ̀ Headies?
Nítorí èyí, àṣírí ọkùnrin náà kò le bò, àwọn ẹlòmírán ń bẹ láàrin ìlú tí wọ́n ju ìjoye lọ, yálà ni ipa ọgbọ́n, yálà ni ipa ìmọ̀, yálà nípa owó, yálà nipa aáṣíkì.
Lorilẹede Naijiria ti awọn obinrin jẹ ida mọkandinlaadọta iye awọn eniyan to wa lorilẹede Naijiria, amọ wọn kọ lati faramọ pipe fun idọgba laarin ọkunrin ati obinrin.
Àyìndé má j’obì lọ́gànjọ́ mọ́ ọọọ
#RevolutionNow: Ṣowore ké pe ilééjọ́ láti yọọ́ látìmọ́lé DSS nítorí ó lòdì s'ẹ́tọ̀ọ́ rẹ̀
Kenyan Dance Party: Òde ijó yìí kò sí fáwọn abo tó ń fẹ́ ara wọn pẹ̀lú
Ni ọjọ Kejidinlọ́gbọ̀n, oṣù Keje, ọdún Ẹgbãlemẹ͂dógún, iroyin jade ninú àwọn iwé-iroyin àti ori ayélujára pé Ọba Okunade Sijuwade, Olúbùṣe Keji, pa ipò da ni Ilú Ọba.
Ayọ̀ ń bẹ fún àwọn tí ń ṣọ̀fọ̀,nítorí Ọlọrun yóo tù wọ́n ninu.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Kí ló ń fa ìdádúró nípa ìfilọ́lẹ̀ ‘Amotekun’ tó yẹ kò wáyé lónìí?
Ẹ o pe ki wa ni?
Ileeṣẹ to n ri si pinpin ina ọba jakejado Naijiria, TCN rawọ ẹbẹ sawọn ọmọ Naijiria fun itakun ina to ja kaakiri orilẹede Naijiria lọjọ Aiku eyi to sọ gbogbo ọmọ Naijiria sinu okunkun birimu.
Awọn kan sọ pe bo ṣe yẹ ki nkan o ri niyẹn, ṣugbọn awọn kan ṣapejuwe rẹ gẹgẹ bi nkan ti oloyinbo n pe ni 'smoke and mirrors'.
Oríṣun àwòrán, Red table talk O fikun pe ọrọ ikọkọ ninu ile awọn lo ti wa bọ si gbangba yii, idi si niyi ti oun fi tete da si, bakan naa lo si dupẹ lọwọ ọkọ rẹ pe o n fara da fun oun.
Bi mo ba mọ pe iru nkan ti yoo ṣẹlẹ re e, mi o ba ma yọju.
Nítorí pé tọ̀sán-tòru ni mò ń rí ìyọnu;láràárọ̀ ni à ń jẹ mí níyà.
Bi BBC News Yoruba ṣe fọrọ wa Daddy Freeze, to n lewaju igun to ni pe idamẹwa ko lẹtọ, lasiko naa ni o tun ba Pasitọ Bakare sọrọ pẹlu nigba naa.
Filipi wá rí Nataniẹli, ó wí fún un pé, “Àwa ti rí ẹni tí Mose kọ nípa rẹ̀ ninu Ìwé Òfin, tí àwọn wolii tún kọ nípa rẹ̀, Jesu ọmọ Josẹfu ará Nasarẹti.
Oloye Harry Ayoade Akande gbe aye rẹ laarin ọjọ kẹta oṣu kẹta ọdun 1943 si ọjọ karun oṣu kejila ọdun 2020.
ijọba ibilẹ pese iṣẹ fun awọn ọdọ ati obinrin, ki olukuluku le ni nnkan
Àwọn ọmọ-ogun náà ń fi ṣe yẹ̀yẹ́.
Nítorí náà, OLUWA Ọlọrun ní, “Nítorí pé o ti gbàgbé mi, o sì ti kọ̀ mí sílẹ̀, o óo jìyà ìṣekúṣe ati àgbèrè rẹ.
Mo rí ọ̀run tí ó ṣí sílẹ̀.
Nígbà tí ó wọlé mi ní ọjọ́ kejì ó mú ìwé tí bàbá rẹ̀ fi ọwọ́ ara rẹ̀ kọ hàn mí; nínú ìwé yìi’, bàbá rẹ̀ sọ ìtàn ara rẹ̀ láti ìgbà tí ó ti wà ni ọ̀dọ̀ ọba Igbó Olódùmarè ó sì dọ ọ́ títí dé ibi tí ó ti padà wá sí ilé.
O ni ṣiṣe nkan mii yatọ si adehun ọdun 2014 ko ni ṣenu 're fun ẹgbẹ APC.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Abẹnugan ile to jẹ ọmọ ẹgbẹ Democrat, Nancy Pelosi lo lewaju iwaadi to fẹ daba ki wọn yọ aarẹ Trump Njẹ aarẹ ṣe ohun ti ko tọ?
Awọn olori Labour labẹ iṣakoso Jeremy Corbyn fẹ Brexit, ṣugbọn awọn ọmọ ẹgbẹ fẹ ki Ilẹ Gẹẹsi ṣe dibo itagbangba (referendum) ẹẹkeji lati jẹ ki orilẹ-ede naa duro sinu EU.
Ighalo ni aṣẹyọri oun ni Manchester United ti fi han pe, oun kun oju oṣuwọn lati darapọ mọ ẹgbẹ agbabọọlu naa.
Iroyin nipa Davies Kingleo Elijah, ti ijọ Glorious Mount of Possibility lo bẹrẹ si tan kalẹ lori afẹfẹ lẹyin fidio kan to ni oun yoo lọ tẹdo si Ghana lati pa arun Coronavirus run, eyi to gba oju opo YouTube atawọn oju opo ikansira ẹni miran kan.
Niṣe ni gbogbo ọkọ naa n kun fọfọ lai si aga ijoko kan to ṣofo.
Ninu àwọn mejeeji, èwo ni ó ṣe ìfẹ́ baba rẹ̀?
”Ipade yii tun fun awon alase orile ede yii lati jiroro pelu awon omo orile ede Naijiria to n gbe ni Poland, eleyii ni yoo je akoko iru re ti aare yoo wa si ipade awon igbimo to wa lara ajo agbaye ti won n ri si bi oju ojo se n yi pada (COP24 of Climate Change (UNFCCC), ni eyi ti yoo waye ni ojo keji si ojo kerin ,osu kejila odun yii.
O le ni miliọnu mẹta eeyan to ti ni Coronavirus lagbaye gẹgẹ bi iroyin to n jade lọdọ ileeṣẹ to n pese iroyin nipa Coronavirus ti fasiti John Hopkins l'Amẹrika.
Wole Soyinka: ìyàtọ̀ gedegbe wà láàrin ẹgbẹ́ Pirate Confraternity táwa dá sílẹ̀ lọ́dún 1952 àti ǹkan áwọn ọmọ ayé òde òní ń ṣe.
Amọ, awọn eniyan 276 lo ri iwosan gba lọwọ arun naa ni Ọjọ́ọ̀rú ohun.
O wa ro awon ara ilu lati tubo
Ileesẹ akoroyinjọ ilẹ wa, NAN lo kede pe oju opo iroyin kan lori ayelujara lo kede pe wọn ti sawari apo asunwọn owo ni banki mẹrinlelọgọta to so mọ nọmba idamọ BVN Obasa.
Komisọna ọlọpa fi kun ọrọ rẹ pe amojuto to pe ye yoo wa lori ayunlọ ati ayunbọ awọn ohun elo fun eto idibo naa.
Ṣugbọn ni bayii oun funra rẹ lo tu iroyin ayọ yii fun awọn oṣiṣẹ ileeṣẹ redio rẹ pe Yinka Ayefele di bàbá ìbẹta.
 lẹ ́ hìn èyí , àwọn Òjẹ ̀ yókù àti àwọn ènìyàn yóò máa lu ìlù eégún ní ibi tí wọn ti pa pẹrẹu lẹ ́ bàá igbó ìgbàlẹ ̀ náà .
Obìnrin tó rè kọjá lójú pópó ló fà ìjàmbá ọkọ́ Osun Ọwọ́ tẹ Sọ́jà tó fẹ́sẹ̀ fẹ́ẹ lẹyin tó gbọ́ ìdájọ lori ikú to pa àkẹgbẹ̀ wọ́n l'ọ́jọ́si BBC tún gbé e dé!
82% ọkùnrin ní kó mọ̀ pé òun ní àìsàn jẹjẹrẹ asẹtọ ní Naijiria Ọlọ́pàá Adamawa ni #30,000 ni wọ́n fi bọ́ igún látìmọ́lé Facebook yóò bẹ̀rẹ̀ ìnáwó orí ayélujára Theresa May bú sẹ́kún, ó ní òun kò ṣe olóòtú ìjọba UK mọ́ Ọpẹlọpẹ Aarẹ Ghana Nana Akufo-Addo to da si ọrọ naa lo mu ki Gyan yi ipinnu rẹ pada.
Wọ́n lọ sí ilé ìpàdé àwọn Juu ní Ọjọ́ Ìsinmi, wọ́n bá jókòó.
Ilé ìjọsìn, mọ́sálásí àti ọkọ òfurufú ṣí, Ẹ wo àwọn ìlànà tuntun tí ìjọba là sílẹ̀ Ènìyàn 416 ló ti lùgbàdì àrùn Coronavirus ní Ọjọ́ Ajé ní Naijiria A ó wá àwọn tó ṣekúpa Omozuwa láwàrí - Ọ̀pá Ọlọ́pàá Naijiria Ọwọ́ bàtá Auxiliary tó ń ró ní àrójù, leè ya láìpẹ́ - Ìjọba Oyo dúnkookò Ni ilu Benin city ni wọn bi Majek Fashek si.
Bí ó bá jẹ́ pé àwọn ọmọ rẹ dẹ́ṣẹ̀ ni,ó ti jẹ wọ́n níyà ẹ̀ṣẹ̀ wọn.
 ko si darukọ eyikeyi ninu awọn wọnyi ninu john .
Bí Khafi ṣe ní ìbálòpọ̀ ojútáyé tako àṣà Yorùbá - Ìjọba Ekiti Músò!
Mo ti la opolopo nnkan koja, mo ti je gomina ri, mo ti je alakoso fun ile-ise epo robi fun odun meta ri,mo tun ti je aare orile ede yii lasiko ijoba ologun , mo si ti de ijoba ibile mẹ́rìnléláàdọ́rin le ni ẹ̀ẹ́dẹ̀gbẹ̀rin(774) to wa jake jado orile ede yii.
Idi si ree to fi n ki ara rẹ ni 'Ajiun, a rí òbò sẹgun ọtẹ' Kiakia ni wọn dọbalẹ fun, ti wọn si n se ni Kabiesi.
Oluwo ni oun si gbagbọ pe ẹnikẹni to ba gbe ailera wọ ilu Iwo, aṣẹ naa loun maa pa ti Ọlọrun yoo si fun wọn lalaafia.
Nígbà tí Akisa dé ọ̀dọ̀ ọkọ rẹ̀, ó rọ ọkọ rẹ̀ pé kí ó tọrọ ilẹ̀ kan lọ́wọ́ baba òun.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Oyin sínsìn lérè lórí ṣùgbọ́n ó tún gbé ikú karí' Onimọ nipa eto isuna naa fi kun un wi pe aisi isẹ lorilẹede Naijiria si jẹ oun to n fa ifasẹyin fun awọn eniyan lorilẹede Naijiria, amọ ireti wa wi pe igbe aye awọn eniyan yoo gbe pẹẹli soke sii.
O ni bo tilẹ jẹ pe igba ti oun bẹrẹ ọja tita ni eebu maa n dun oun, amọ nibayii, o ti mọra, tori ara ipolowo ọja ni.
Ẹmi mejila ṣofo ninu ijamba ọkọ l'Ondo Oríṣun àwòrán, SOLA ILESANMI/ORANGE FM Àkọlé àwòrán, Iru ijamba bayi wọpọ loju ọnọ marosẹ Ojo buruku esu gb'omimu ni, nipinlẹ Ondo, nigbati ijamba ọkọ meji ọtọọtọ pa eniyan mẹwa ni agbegbe Akungba Akoko ati oju-ọnọ Ajibamidele ni popona marose Benin-Ọrẹ-si Eko nipinlẹ Ondo.
Manchester City: De Bruyne gba àmì ẹ̀yẹ Premier League mọ́ Henderson lọ́wọ́ lẹ́yìn tí Lyon fi City ṣ'ẹ̀sín
Atẹjade kan lati ọwọ agbẹnusọ Gomina Makinde, Taiwo Adisa ṣalaye pe, gomina kan tẹlẹ nipinlẹ ọhun lo ra ilẹ naa, ti gomina to ṣaaju rẹ si gbẹsẹ le e, to si fi ilẹ naa fun oniṣowo kan ni Ibadan.
Ipade apero COP24 maa n waye ni gbagede MCK, niluu Katowice kilomita ogorun un siluu Krakow.
Timi Agbale ati ọrẹ rẹ, Gbọnka Ebiri jẹ alagbara nla ni Ọyọ ile, to si de akoko kan ti agbara Alaafin Sango ko fẹ ka wọn mọ, ti ẹru si n ba a pe awọn mejeeji le pa oun tabi le oun kuro lori itẹ.
Ghana Floods: Omiyalé ní Ghana, èèyàn 28 dolóògbé!
Ọgbẹni Fapohunda koro oju si bi iwa ipa si awọn obinrin, paapaa, ifipabanilopọ, ṣe n pọ si nipinlẹ naa.
Ìwọ̀de kò lè wáyé sáájú aago mọ́kanla àárọ̀ tàbí kọja ààgo mẹ́fa ní ìrọ̀lẹ́, gẹ́gẹ́ bó ti ń ṣẹlẹ̀ sáájú àsíkò yìí, ìjọba Togo lé fòfinde wọ́n pátápátá nítori àwọn ìdí yìí.
Bi eyi ba si sẹlẹ, yoo nipa lori ọpọlọ, ọkan,awọ ara, egungunisan, bi ara ti n gbona si, ti yoo si tun fa aile ri oorun sun pẹlu.
Agbenuso fún ilé asofin àgbà ní bakan naa ni ọmọ sórí làwọn orile-ede míràn lagbaye, àmọ́ ó wà daba pé, ó yẹ kí ilẹ wa ṣe ìpèsè eto ìlera tó mọyàn lórí ni.
Ijọba ko fẹ ki ohun to ṣẹlẹ lọdun 1987 nigba ti awọn janduku ji ohun mere mere ko ninu ibojì Aarẹ Argentina tẹlẹ ri, Juan Peron lọ.
 lẹ ́ yìn èyí , àwọn díè nínú àwọn tí ń ṣe eré ìbílẹ ̀ káàkiri bẹ ̀ rẹ ̀ sí ní kópa nínú òwò fíìmù .
Tí a fiṣọwọ́ ní 9:529:52 Àwọn ìṣẹ̀lẹ̀ ńlà lọ́sẹ̀ tó kọjá tó fi mọ́ bí Covid-19 ṣe gbẹ̀mí èèyàn 23 lọ́jọ́ kan ṣoṣo Lara awọn iṣẹlẹ ọhun ni ijinigbe awọn oniṣowo ohun ti wọ́n jigbe lọ́nà ajò wọn si ilu Aba nipinlẹ Abia.
Ẹ̀yin ọ̀rẹ́ mi, ẹ jẹ, kí ẹ sì mu,ẹ mu àmutẹ́rùn, ẹ̀yin olùfẹ́.
Gbogbo ohun to ka silẹ yii dara ṣugbọn aini igbagbọ ninu ijọba lo jẹ pato idi to dakun wahala to wa nilẹ yii, to fi jẹ ki awọn eeyan mase ri dada kankan ninu igbesẹ yii.
Ayọ̀ ń bẹ fún ẹni tí ń bọ̀ wá ní orúkọ OLUWA,láti inú ilé rẹ ni a ti ń yìn ọ́, OLUWA.
Dòdò Ìkirè dúdú lójú sùgbọ́n oyin ni lẹ́nu.
se lu won ni jibiti je ohun ti o buru jai, ti o si n tabuku ba ile-ise aare.
O kó àwọn eniyan rẹ jáde bí agbo ẹran,o fi Mose ati Aaroni ṣe olórí wọn.
yan asofin Bamidele Oleyelogun ati igba keji re asofin Ogundeji Iroju  gege bi adari ile igbimo asoju naa yoo tun je
Oríṣun àwòrán, Getty Images Wọ́n ń pinnu láti máa pín àwọn ìledìí yìí, bi wọ́n ṣe máá n pín kọndọọmu fáwọn ọkùnrin nílé iwé gírámà àti ni fásitì, ilé ìwòsàn ti wọ́n bá ti ṣíṣẹ́ abẹ, àti ni àwọn ibi ti wọ́n ti n ta oogun, yálà ki wọn lọ bèrè fún tàbi ki wọ́n kọọ síwèé.
Báwo ni ó ti ṣe là ọ́ lójú?
Bakan naa ni wọn yabo aafin ọba ilu Eko to wa ni agbegbe Iga Idugaran, ni agbegbe Lagos Island, nibi ti wọn ti n ba awọn ọkọ ati dukia jẹ.
Ṣugbọn wọ́n kígbe pé, “Kàn án mọ́ agbelebu!
OLUWA súnmọ́ gbogbo àwọn tí ń pè é,àní, àwọn tí ń pè é tọkàntọkàn.
Ija laarin awọn ọmọ ẹgbẹ oṣelu APC nipinlẹ Ekiti ko ṣẹyin bi ẹgbẹ naa ṣẹ pin si meji ti awọn kan tẹle gomina ipinlẹ Ekiti, Kayode Fayemi, ti awọn miran si tẹle Sẹnetọ Ojudu.
Obasanjọ sọrọ ninu lẹta to fi sita lati ọwọ oluranlọwọ pataki lori eto iroyin rẹ, Kehinde Akinyemi pe dugbẹ dugbẹ to n mi loke lori eto aabo, afai-mọ-ko-ma-ja o.
Awọn obi naa, lasiko ti wọn n ba BBC Yoruba sọrọ ni, ki lo de tawọn akẹkọọ alakọbẹrẹ ati girama fi wọle pada sile iwe, nigba tawọn ẹgbọn wọn to wa ni fasiti ati Poly si wa nile.
80 Èyíkéyìí ọmọ ìjọ ti Krístì tí ó bá nṣe ìrékọjá, tàbí tí a bá mú nínú ìṣubú kan, ni a ó ṣe sí gẹ́gẹ́bí àwọn ìwé mímọ́ ṣe darí.
orile ede  Guinea Bissau lati yanju
Nítorí náà, OLUWA Ọlọrun Israẹli, mú ìlérí tí o ṣe fún iranṣẹ rẹ, Dafidi, baba mi ṣẹ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Toyin Ibietan: Àlòkù táyà ọkọ̀ ló mú mi rí nǹkan ṣe lásìkò ìgbélé COVID-19 Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Àti àwọn ìbéèrè míràn Bi awọn kan ṣe ni kalamu ni, ni awọn miran ni bíìrò ni, lawọn miran ni gege ikọwe ni ti awọn miran ni takada ni Awọn iroyin ti ẹ lee nifẹẹ si: Soyinka ni awọn ọdọ lokan lati ṣe'jọba Aworan aṣa ati iṣe awọn ọmọ Yoruba Awọn eni ilumọọka lu wa lontẹ Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí kan sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
Ọpọ ileeṣẹ iroyin n kede pe ọkan lara awọn adajọ ile ẹjọ to ga julọ ni Naijiria, Onidajọ Ibrahim Saulawa lo fi ikede naa sita, nibi ayẹyẹ ikojade olu ile ẹgbẹ awọn agbẹjọro to jẹ Musulumi, to waye nilu Abuja lọjọ Iṣẹgun.
"Ọ̀nà kan ò wọjà fáwọn òṣèré tíátà, bí wọn ṣe ń ta ìpara ìbóra ni wọ́n ń ta aṣọ ẹbí Ibrahim Chatta, to maa n se ere adẹrinposonu nigba miran, lo kọ akọle kan sabẹ aworan naa, to ni ""Stay Safe""."
Àwọn olè tún lè wá a kàn kí wọ́n jí i lọ.
Lójú wọn, o dàbí olóhùn iyọ̀ tí ń kọrin ìfẹ́, tí ó sì mọ ohun èlò orin lò dáradára.
Àwọn tí ń gbé etí òkun ilẹ̀ yìí yóo wí ní ọjọ́ náà pé, ‘Ẹ wo ohun tí ó ṣẹlẹ̀ sí àwọn tí a gbójú lé, àwọn tí à ń sá tọ̀ lọ pé kí wọ́n ràn wá lọ́wọ́, kí wọ́n gbà wá lọ́wọ́ ọba Asiria.
OLUWA wí fún Aaroni pé, “Jáde lọ sinu aṣálẹ̀, kí o lọ pàdé Mose.
Koda, oun ni Aarẹ Ile Aṣofin Agba orilẹ-ede Naijiria lọdun 1979 si 1983.
Bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé a ti fi ìlú yìí lé àwọn ará Kalidea lọ́wọ́, sibẹsibẹ, ìwọ OLUWA Ọlọrun ni o sọ fún mi pé kí n ra ilẹ̀, kí n sì ní àwọn ẹlẹ́rìí.
DJ Cuppy binu fi Arsenal silẹ, o gba Man U lọ laimọ pe, ohun to n bẹ lẹyin ẹfa.
 onírúurú ìjọ onìgbàgbọ ́ ló ní orísìírísìí ìtumọ ̀ fún bibeli torí ìdí eyi onírúrú ìlànà èsìn ni ìjọ kọ ̀ ọ ̀ kan ní .
“Lati tun fi ododo oro mule, ijoba yii tun sagbekale BVN lọdun 2014 lati tun ri daju pe apo ifowopamo kookan ni aworan, iteka idanimo eleyi ti yoo safihan eni ti o ni apo naa.
Ó da gbogbo wọn sẹ́yìn odi ìlú.
Òótọ́ – inú yóó maa mú ọ látti ìgbéga dé ìgbéga, yóó máa gbé ọ láti ipò ńlá dé ipò ńlá, yóó maa fi owó kún owó fún ọ, yóó máa fi ọmọ kún ọmọ, yóó máa fi ènìyàn kún ènìyàn, yóó sì ṣe ọ́ ní pàtàkì láàárin àwọn ọmọ aráyé gbogbo.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Church Wall Collapse: Ògiri ṣọ́ọ̀ṣì wó pa àwọn olùjọ́sìn 13 nílé ìjọsìn South Afrika 19 Ìgbé 2019 Oríṣun àwòrán, AFP Awọn olujọsin ẹlẹsin Kristẹni mẹtala kan ti padanu ẹmi wọn ni South Afrika.
Ṣebí díẹ̀ ṣínún ló kùtí a óo sọ Lẹbanoni di ọgbà igi elésoa óo sì máa pe ọgbà igi eléso náà ní igbó.
Wo ìdí tí Tẹni, ọ̀dọ́mọdé olórin obìnrin kìí fi ń ṣí ìhòhò rẹ silẹ̀ Ilé alájà mẹ́ta wó pa èèyan méje, èèyàn 20 farapa ní Obalende, Eko Awọn ara ilu naa ba BBC sọrọ, wọn ṣalaye ohun to wu wọn ati ohun ti wọn n reti lọdọ Akẹti to jẹ gomina tuntun to wọle bayii.
Ṣugbọn ẹ máa ṣí i ní ọjọ́ ìsinmi ati ọjọ́ oṣù tuntun.
Àwọn Ìpínlẹ̀ tí coronavirus kò tíì dé ní Nàìjíríà, àti ìgbésẹ̀ tí wọ́n ń gbé láti dènà rẹ̀ Ìtàn Manigbagbe: Àwọn àjakalẹ-àrun to ti wáyé rí ṣáájú Coronavirus Yewande bí'mọ tuntun jòjòló, Mercy Aigbe pàdánù èèyàn rẹ̀, Toyin Abraham fèsì lórí aṣoju NCDC Kí ló ń ṣẹlẹ̀ láàfin Ọ̀yọ́?
 ní apá ibìkan ní < nowiki > Áfíríkà < / nowiki > níbí tí áàńfàní púpọ ̀ lati kó meningitis , ìyànjú ń lọ lọ ́ wó lati ri wípé wọ ́ n gba abẹ ́ rẹ ́ àjésára fún àwọn ènìyàn tí ọjọ ́ orí wọn bẹ ̀ ẹ ̀ rẹ ̀ lati ọdún kan sí ọgbọ ̀ n ọdún .
Ìdajì ẹ̀yà Manase ń gbé Baṣani, wọ́n pọ̀ pupọ; wọ́n tàn ká títí dé Baali Herimoni, Seniri, ati òkè Herimoni.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Wòlíì Kasali sọrọ nípa awuyewuye pé o lè ìyàwó rẹ̀ jáde nílé Alaafin ilu Ọyọ ni ko si aniani pe digbi ni oun wa lẹyin Aarẹ Buhari ati iṣejọba rẹ ṣugbọn ominu n kọ oun lẹnu ọjọ mẹta yii lori ipenija ọrọ abo jakejado orilẹede Naijiria, paapaa julọ ilẹ Yoruba titi kan ipinlẹ Kwara, Kogi ati Edo.
Oloogbe ọhun si ti wọ kaa ilẹ sun ni iboji Gudu ni ilu naa.
ó ní, “Gbọ́ ọ̀rọ̀ majẹmu yìí, kí o sì sọ ọ́ fún àwọn ọmọ Juda, ati àwọn tí ń gbé Jerusalẹmu.
Nitorinaa, ni Ọga ọlọpaa ni ipinlẹ Ekiti se kede pe, ileeṣẹ ọlọpaa yoo ṣe aṣepọ pẹlu awọn ẹgbẹ ibilẹ to nii ṣe pẹlu ọrọ aabo ni ilẹ Yoruba bii OPC atawọn ẹgbẹ ọdẹ ibilẹ gbogbo.
Àwọn adigunjalè yabo ṣọ́ọ̀ṣì, fipá bá obìnrin kan lòpọ̀, yìnbọn fún òmííràn Gbajugbaja oṣere naa ni o jẹ iyalẹnu fun oun pe awọn kan n sọ kaakiri wi pe oun maa n ju idi oun fun ṣe ki a ri mi ṣugbọn o sọ pe ọrọ ko ri bẹẹ rara.
Gbogbo wọn ni wọn óo parun láti orí àwọn mẹ̀kúnnù dé orí àwọn eniyan pataki pataki; ogun ati ìyàn ni yóo pa wọ́n.
Nọọsi to ba wa sọrọ nibẹ sọ pe iṣẹ ọfẹ ni awọn n ṣe lati ọdun 2014, ijọba ko gba osisẹ eleto ilera sisẹ, wọn ko si san owo oṣu fun awọn.
Ati ehoro, nítorí pé ó ń jẹ àpọ̀jẹ, ṣugbọn pátákò ẹsẹ̀ rẹ̀ kò yà, ó jẹ́ ohun àìmọ́ fun yín.
Ohun tí ó kọ sinu lẹta náà ni pé:“A fi ẹ̀sùn kàn ọ́ láàrin àwọn orílẹ̀-èdè, Geṣemu náà sì jẹ́rìí sí i pé, ìwọ ati àwọn Juu ń pète láti dìtẹ̀, nítorí náà ni ẹ fi ń mọ odi yín.
Ó jẹ́ adarí àgbà ní iléeṣẹ́ Pacific Holdings Limited láti 2001 sí 2006 àti Quicksilver Courier Company ní Atlanta, Georgia láti 1985 sí 1989 Ademola Adeleke bẹ̀rẹ̀ òṣèlú ní ọdún 2007, ó sì dí sẹ́nétọ̀ tó ń sojú ẹkùn ìwọ̀-oòrùn Oṣun lẹ̀yìn ikú ẹgbọn rẹ̀ sẹ́nétọ̀ Isiaka Adeleke tó jẹ́ Gomìnà alágbádá àkọ́kọ́ ní ìpínlẹ̀ náà Senator Iyiola Omisore Social Democratic Party (SDP) < Padà lọ sí ọ̀dọ̀ Olùdíje Kíni ọjọ́ ìbí yin?
Hanlon ni awọn onifayawọ naa n gbe oogun oloro lati Afghanistan lọ si guusu-iwọ oorun Pakistan, lati ibẹ lọ si ariwa Mozambigue nibi ti wọn ti n gba ọna ẹburu gbe wọ ilẹ Europe.
A tun gbọ pe awọn ibale kan wa to ki pupọ, ti ko si lee tete ja, afi ti ọmọ ba fẹ gba oju ara obinrin jade nikan ni yoo to ja.
"Oríṣun àwòrán, Universal Music Group Àkọlé àwòrán, Tiwa Savage Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Oluwo: Mo lè jẹ Ọba ní Ile Ife Tiwa ni ""afojusun mi to ga ju ni lati fi ilẹ Afirika yangan, nitori naa, inu mi dun gidi gan si ajọṣepọ yii mo si dupẹ lọwọ ẹbi tuntun ti mo wọ yii, UMG."
Nígbà tí àwọn Farisi tí wọ́n fẹ́ràn owó gbọ́ gbogbo ọ̀rọ̀ yìí, ńṣe ni wọ́n ń yínmú sí i.
Atiku ni oun ti fitafita fawọn ọmọ Naijiria gẹgẹ bi ẹni to gbagbọ ninu eto ijọba awarawa, o ni oun yoo si tẹsiwaju lati maa ja fun Naijiria, fun ijọba awarawa ati fun ododo.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù How to wear facemask: Wo bí o ṣe le wọ ìbomú-bẹnu láti dènà Covid-19 5 Èbibi 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 9 Èbibi 2020 Oríṣun àwòrán, Getty Images O ti di ẹṣẹ bayii fun ẹnikẹni ti ko ba wọ ibomu-bẹnu laarin ilu l'orilẹ-ede Naijiria, nitori ofin ti ijọba ṣe lati fi dena itankalẹ aarun Covid-19.
Eniyan mímọ́ ni a óo máa pe àwọn tí wọ́n bá kù ní Sioni, àní, àwọn tí wọ́n ṣẹ́kù ní Jerusalẹmu; gbogbo àwọn tí a bá kọ orúkọ wọn sílẹ̀ pé wọ́n wà láàyè ní Jerusalẹmu.
Àjọ SERAP tí gba gómìnà ìpínlẹ̀ Bayelsa Seriake Dickson ní ìmọràn láti máa buwọlu àbádofin gbigba owó ìfẹ̀yìnti láíláí ti àwọn ilé ìgbìmọ asòfin ìpínlẹ̀ náà gbé si ìwáju rẹ̀.
Ọḳ iyawo naa fikun pe lẹyin wakati kan abo ti ibugbamu naa waye ni iyawo rẹ, Emmanuelle bi ọmọ tuntun, George.
Nkan bíì ọgọ́rùn-ún ọpọ́n àti ọkọ̀-ojú-omi ní wọ́n dárà lórí odò Thames fún ọjọ́ méjì.
Dokita agba Oluyinka Olutoye jẹ ọkan lara awọn ogo orilẹ-ede Naijiria ti itanṣan wọn n tan ka gbogbo agbaye fun ipa rere ti wọn n ko kaakiri.
Lasiko ti o fi ṣepade pẹlu awọn ọmọ ẹgbẹ oṣelu naa ni ọjọbọ ni Dokita Mimiko kede ọrọ yii.
Wo bí ọwọ́ orílẹ̀-èdè Dubai ṣe tẹ Ramoni Igbalode tí gbogbo ayé ń pè ní Hushpuppi Ọ̀pọ̀ ìgbà ní Hushpuppi àtàwọn èèkàn PDP ti ya fọ́tò ní Dubai, EFCC ẹ wádìí wọn - APC ń lọgun Diẹ lara awọn aworan naa ni a ṣe akojọpọ rẹ yii.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Àjọ NLC Naijiria : MTN kọ̀ jẹ́ kí òsìsẹ́ wọn darapọ̀ mọ́ àjọ òsìsẹ́ 9 Agẹmo 2018 Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Àjọ NLC Naijiria : MTN kọ̀ jẹ́ kí òsìsẹ́ wọn darapọ̀ mọ́ àjọ òsìsẹ́ Ajọ osisẹ lorilẹede Naijiria, NLC ti pasẹ fun awn akẹgbe rẹ lati se ifẹhọnu han niwaju ile isẹ ẹrọ ibaraẹnisọr, MTN kaakiri orilẹede Naijiria.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Kwara yóò gbàlejò BBC Yoruba Kini awọn eeyan n sọ lori igbesẹ yii?
Saaju ni gomina ti pasẹ fun gbogbo awọn eeyan to dipo oselu mu ninu ijọba rẹ ati awọn oludari agba nileesẹ́ ijọba kọọkan lati bọ sigboro ilu Ibadan, ki wọ̀n si ko gbogbo awọn idọti to wa laarin oju popo kuro, ki ayika lee dun wo.
O sì ń fún wọn ni omi mu nígbà tí òùngbẹ bá ń gbẹ wọ́n.
Oyintiloye soro yii pelu akoroyin ile Akede Naijiria, Voice of Nigeria, nilu Osogbo to je olu ilu ipinle Osun.
Ileeṣẹ igbokegbodo ọkọ lorileede Ethiopia ti fi esi abajade awọn iwadi ti wọn kọkọ ṣe nipa ọkọ baalu Ethiopia Airline 302 to ja loṣu to kọja.
N óo gbin igi sipirẹsi sinu aṣálẹ̀,n óo gbin igi firi ati pine papọ̀.
Oríṣun àwòrán, Others Mama Adenekan ni iya Bola Obasanjo to jẹ ọkan lara iyawo Baba Obasanjo.
com/WJLz3PGq9J— The NFF 🇳🇬 (@thenff) June 12, 2018.
Nilu Abuja, idanilẹkọ yoo waye eleyi ti Pasitọ Tunde bakare yoo ṣe.
Ìyá mi ní kí n pe àwọn ọ̀rẹ́ mi wá láti ilé-ìwé wa.
EFCC: Ẹlẹ́rìí ṣàlàyé bí wọ́n ti ṣé gbé N1.
Ẹni kejì tí ó tún wá sí ọ̀dọ̀ Aṣojú-Olódùmarè bẹ̀rẹ̀ ọ̀rọ̀ tirẹ̀ báyìí, ó ní ‘Ìwọ ìranńṣẹ́ Ẹlẹ́dàá ayé, ìwọ ìranńṣẹ́ Ẹlẹ́dàá ọ̀run, bá mi wí fún Ọlọ́run Ọba kó Ó gba ọ̀rọ̀ mi yìí yẹ̀wọ̀, ẹni tí ó jẹ́ ọ̀gá fún mí ní ibi iṣẹ́ burú bí ejò olóró, ó ní ìkà bí ẹni pé òun pàápàá kì í ṣe ènìyàn, ó le bí òkúta.
Coronavirus Update: WHO tí kéde pé Ó ṣeéṣe kí àrùn Coronavirus tànkálẹ̀ gba inú afẹ́fẹ
Amọ Tinubu ko sai daba pe ki ipade igbọraẹniye wa laarin awọn gomina ẹkun iwọ oorun guusu orilẹede yii ati agbẹjọro agba ni Naijiria, Abubakar Malami lori agbekalẹ eto Amotekun.
iwe ẹri ti asofin Adeleke fi silẹ pe oun pari ile- ẹkọ  girama (secondary school certificate).
11 Èrèlè 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 15 Èrèlè 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Oṣiṣẹ Inec n salaye bi awọn oludibo yoo ti ṣe tẹ ika soju iwe idibo Yoruba bọ wọn ni ika to ba tọ si imu laa fi n remu.
ogbeni Yakubu Dogara oludije labe asia egbe oselu PDP, gege bi eni ti o jawe
"Ninu atẹjade ijọba, akọwe iroyin fun Gomina Akeredolu sọ pe ""kii dena mọ ẹtọ ẹnikẹni lẹnu iṣẹ ṣugbọn ijọba yoo koro oju si igbimọpọ lati gbẹsẹ le nkan ijọba nipa lilo ominira tabi anfaani ti wọn ni si iru dukia bẹ ẹ""."
Agbẹnusọ fun ile iṣẹ ọlọpaa Ipinlẹ Kwara, Ajayi Okasanmi to ba BBC Yoruba sọrọ, ni awọn agbofinro yoo wa awọn ọmọ ilẹ Turkey naa ri laaye.
Bi a ko ba gbagbe, lọjọ Iṣẹgun to kọja ni iroyin gbode ladugbo Igbodigo nilu Okitipupa nibi ti awọn mọlẹbi kan ti padanu ẹmi wọn nigba ti eeyan kan sọ ina si ile wọn.
O kò lè ṣe bí bàbá rẹ ńdan?
 “Pupo ninu awon ti ogun le kuro nibi ibugbe won, ni won si n gbe nibi ti
Mí ò mọ ǹkan ti wọn ń lépa mi fun.
àwọn ọmọ ogun tí wọn ń wọ aṣọ àlàárì, àwọn gomina ati àwọn ọ̀gágun, ati àwọn ẹlẹ́ṣin, ọdọmọkunrin ni gbogbo wọn, ojú wọn sì fanimọ́ra.
Kò si ilú, ẹ̀yà tàbi àwọ̀ ti kò ni ẹni burúkú tàbi ẹni rere.
Nígbà tí ọjọ́ ọ̀fọ̀ rẹ̀ parí, Josẹfu sọ fún àwọn ará ilé Farao pé, “Ẹ jọ̀wọ́, bí inú yín bá dùn sí mi, ẹ bá mi sọ fún Farao pé, 
Gẹgẹ bi akọsilẹ to wa ni ori ayelujara ifayemisielebuibon.
Diẹ lara awọn aya igba ọdọ Alaafin ree, ti kii kọ iyan wọn kere rara: Olori Abibat Nihinlola Adeyemi ( Iya Adodo) : Oríṣun àwòrán, Oba Lamidi Olayiwola Adeyemi kẹta Olori Abibat Nihinlola ni iyawo akọfẹ Ọba Adeyemi, ti Ọlọrun si fun awọn mejeeji ni ẹmi gigun, alaafia ati ọmọ rere lati ba ara wọn kalẹ.
Akeredolu, Ọgá NDLEA lọ kọ nípa gbíngbin igbó ní Thailand Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 9ice: Ǹjẹ́ olórin tàkasúfèé yìí ń mu igbó bí àwọn òṣèré mìíràn?
Ìgbà tí o sì máa dá ẹjọ́, o ni nǹkan tí òun rò pé ó yẹ kí wọ́n ṣe ni pé kí wọ́n yìnbọn lu èmi náà.
Bi a bá ṣe akiyesi, ki àṣiri tó tú ni àsikò Ìjọba tuntun (Buhari/Òṣinbàjò), àwọn ti ilé-iṣẹ́ Agbógun ti ìwà ìbàjẹ́ tọka tàbi mú pé ó kó owó ilú jẹ jù̀, kò wọ aṣọ Òkè-Òkun.
Ajọ iwadi ijinlẹ nipa ọrọ aje lagbaye, Economist Intelligence Unit lo sọ bẹẹ ninu abajade iwadii ijinlẹ kan ti wọn ṣe kaakiri orilẹede agbaye.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Herbal Medicine: Gbígboyè fásítì nínú iṣẹ́ ìṣègùn ìbílẹ̀ dára, àrídájú gbọdọ̀ wà lórí rẹ̀ 31 Ògún 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Herbal Medicine: Gbígboyè fásítì nínú iṣẹ́ ìṣègùn ìbílẹ̀ dára, àrídájú gbọdọ̀ wà lórí rẹ̀ Kikọ sii nipa iṣegun ibilẹ yoo mu idagbasoke ba eto ilera -Ọjọgbọn Faduyile (NMA) Ẹgbẹ awọn oniṣegun oyinbo ni Naijiria, (Nigeria Medical Association) ohun to dara ni tawọn ileewe giga fasiti lorilẹ-ede Naijiria ba bẹrẹ si ni fawọn akẹkọọ loye ninu ẹkọ imọ iṣegun ibilẹ.
Ṣugbọn o óo gba owó ìràpadà dípò àkọ́bí eniyan ati ti ẹranko tí ó bá jẹ́ aláìmọ́.
"Bẹẹni baba mi kii jẹun kiri ni ode"" Ẹ gbọ Ọmọọbabinrin Olubunmi Labiyi siwaju si: Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fọ́nrán ohùn, Alaafin Ọyọ: Asiri agbara bibi ibeji lọpọ igba Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 3 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 5 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!"
Nibayii, ajọ NAFDAC ti pariwo sita lori ẹja yii ati ọṣẹ ti o n ṣe lagọ ara ti wọn si ti kilọ f'awọn onile ounjẹ gbogbo ati oniṣowo ẹja lati maṣe ta ẹja yii fun ẹnikẹni nitori ọta ilera ni.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Akure-Owo Accident: Ẹ̀mí 18 ṣòfò ní òpópónà ti ọ̀pọ̀ ti ń kú ní ìpínlẹ̀ Ondo 8 Òkùdu 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 9 Òkùdu 2019 Oríṣun àwòrán, Dominic Edem Iroyin ibanujẹ kan ni ọjọ Abamẹta wipe awọn eniyan mejidinlogun ti ṣegbe sinu ijamba ọkọ kan ni popona Akure-Owo, Oba Ile ni Ipinlẹ Ondo.
Wọ́n bá wí fún Samuẹli pé, “Gbadura sí OLUWA Ọlọrun rẹ fún wa, kí á má baà kú.
OLUWA sọ fún Aaroni pé, “O kò gbọdọ̀ gba ohun ìní kan tí eniyan lè jogún tabi ilẹ̀ ní Israẹli.
5% Gbigba bọọlu si oju ile 4 3 Gba bọọlu 16 12 kọna 6 7 Ṣẹ sofin 17 14 Awọn agbabọọlu ti wọn yan Awọn ti wọn o kọkọ bẹrẹ Nigeria 16 Akpeyi 2 Ola Aina 20 Awaziem 5 Troost-Ekong 22 Omeruo 7 Musa 4 Wilfred Ndidi 15 Simon 18 Iwobi 8 Peter Etebo 9 Ighalo Cameroon 1 Onana 4 Banana 2 Fai 6 Oyongo 5 Ngadeu-Ngadjui 7 N'Jie 13 Choupo-Moting 14 Mandjeck 11 Bassogog 15 Kunde 9 Bahoken Awọn iyipada 60 Simon                                                                  down Chukwueze                                                              up 85 Ighalo                                                                  down Paul Onuachu                                                              up 91 Iwobi                                                                  down Balogun                                                              up 62 Mandjeck                                                                  down Zambo Anguissa                                                              up 70 N'Jie                                                                  down Toko Ekambi                                                              up 87 Kunde                                                                  down Zoua                                                              up Awọn ti wọn paarọ 1 Ezenwa 12 Shehu 13 Chukwueze 19 Ogu 14 Paul Onuachu 11 Onyekuru 21 Osimhen 23 Uzoho 3 Collins 17 Kalu 6 Balogun 21 Kaptoum 17 Toko Ekambi 20 Boumal 12 Dawa 16 Ondoa 10 Sutchuin Djoum 23 Kameni 19 Zoua 22 Kana-Biyik 8 Zambo Anguissa 3 Bong Ẹni ba jawe olubori ni yoo tẹsiwaju lati pade Egypt tabi South Africa ni abala to kan ninu idije Afcon 2019.
Iranṣẹbinrin Lea bí ọmọkunrin kan fún Jakọbu.
National Electoral Commission ni ipinle  Cross River ti ni awon ti setan fun eto idibo
Ọlọrun kan ni ó wà, tíí ṣe Baba gbogbo eniyan, òun ni olórí ohun gbogbo, tí ó ń ṣiṣẹ́ ninu ohun gbogbo, tí ó sì wà ninu ohun gbogbo.
Òun gan-an ni mo sì ti dàníyàn láti máa ṣe.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Jeremiah Addo: Ọmọ ọdún méjì tó ṣeeṣe kò mọ̀wé jù l'ágbàáyé Ọkan o jọkan awọn alamojuto ati olotu ẹka iṣakoso gbogbo lorilẹede Naijiria ni wọn farahan nibi apero naa.
Xiavier Ndayongmong Ko tan sibẹ o, akọroyin nipa iwa ọdaran nile ise iroyin Daily Independent naa dagbere faye lọjọ jimọ, ọjọ kọkandinlogun, oṣu yii.
O ni Hushpuppi ni awọn ero to le ni miliọnu to pọ to n tẹle lori ayleujara ni eyi to n pa owo wọle fun un.
Ṣugbọn ẹnikẹ́ni ninu wọn kò bi obinrin náà pé kí ni ó ń wá?
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Champions league: Chelsea gbélé fọrùn rọ́ ní Stamford Bridge, àwìn ni Valencia fi ṣẹ Lampard lọ́wọ́ 18 Owewe 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Ẹgbẹ agbabọọlu Chelsea joye gbele forunrọ lalẹ ọjọ iṣẹgun nigba ti wọn gbalejo ẹgbẹ agbabọọlu Valencia ni idije Champions league.
Akọroyin BBC Yoruba to wa ni ibi ifẹhọnuhan naa fi lede pe, gbogbo ọna to wa ni agbegbe Challenge, New Garage ati Tipper Garage ni awọn ọdọ to n sewọde, ti tipa patapata.
“Ṣugbọn Ọlọrun kìí yipada,kò sí ẹni tí ó lè yí i lọ́kàn pada.
Osun Election 2018: Wọ́n ṣe ìbúra fún Oyetọla gẹ́gẹ́ bí gómìnà tuntun
igbimo asofin egbe APC to wa nipo bayiiGbogbo awon
Wò ó bí Alaafin àti aya àkọ́fẹ́ rẹ̀, Olorì Abibat ṣe pàdé ní èwe Ìjà ẹgbẹ́ òṣèré TAMPAN àti ANTP ni kò jẹ́ kí wọ́n pe Baba Legba sínú eré mọ́, kó tó kú - Owolabi Ajasa Tí mo bá kú lónìí, Pásítọ̀ Ibiyeomie ló pa mi - Daddy Freeze kébòòsí Àwọn afurasí lórí ẹ̀ṣùn jíjí ìbejì Akeugbagold gbé yọnú sílé ẹjọ́ láì ní agbẹjọ́rò Nigba to n ba awọn akọroyin sọro, agbẹnusọ awọn akẹkọọ ọhun, Kazeem Israel, sọ pe ele naa jẹ ọna lati mọọmọ ni awọn ara ilu lara.
Ọjọgbọn Ibrahim Ayagi Ni ọjọ Satide, ọjọ karundinlọgbọn oṣu kẹrin ọdun 2020 ni Ọjọgbọn Ayagi, jade laye.
Oríṣun àwòrán, fuji opera Ọjọ kẹsan an, oṣu Keji, ọdun 1948 ni wọn bi Sikiru Ayinde Barrister si idile Salawu Balogun ni ilu Ibadan.
O fikun ọrọ rẹ pe Banki Access tun sọ fun mama oun pe ki o buwọ luwe pe oun lo gba owo naa, bo tilẹ jẹ ko mọ bi eeyan ṣe le gba owo lori aapu to wa lori foonu.
Yakubu Dogara: Gómìnà Bauchi da ₦4bn owóyàá ìlú sápò iléeṣẹ́ àdáni kan
Àwọn àkànpọ̀ igi tí wọ́n wà ní igun kinni-keji jẹ́ mẹjọ pẹlu ìtẹ́lẹ̀ fadaka mẹrindinlogun, ìtẹ́lẹ̀ meji meji wà lábẹ́ àkànpọ̀ igi kọ̀ọ̀kan.
Òṣèré tíátà míì ń ṣàìsàn láti bí ọdún mẹ́ta, ọkan rèé tó ń bẹ̀bẹ̀ f'ówó ₦80m la fi rán ogún ìyàwó asòfin lọ Dubai - Obasa Wo ọ̀nà tí orin gbígbọ́ fi ń ṣèrànwọ́ f'ọpọlọ ọmọ ìkókó Ìdájọ́ ikú ni a fẹ́ fún àwọn afipábánilòpọ̀ - Ẹgbẹ́ ajàfẹ́tọmọnìyàn Báyìí ni ẹgbẹ́ ajàfẹ́tọmọnìyàn ṣe pè fún ìdájọ́ ikú fún àwọn afipábánilòpọ̀ Oluwo bẹ Ìjọba àpapọ̀ láti ṣe òfin tí yóò mú àdínkù ba ìwà ìfipá báni lòpọ Obìnrin Nàìjíríà tí wọ́n lù aago gbà njo lé lórí ní Lebanon sọ pé òun kò wá sílé mọ́ A ti bẹ̀rẹ̀ ìwádìí kíkún nípa àwọn tó lọ́wọ́ nínú ikú Barakat Bello - Iléeṣẹ́ ọlapàá #JusticeforTina: Àwọn obi Tina Ezekwe ń bèrè fún ìdájọ́ òdodo pẹ̀lú omijé lójú Níbo ni Sẹ́nétọ̀ Abiola Ajimobi, gómìnà àná ní ìpínlẹ̀ Oyo wà?
Oríṣun àwòrán, Facebook/Atinde Soaga Pupọ awọn akọroyin ni o wa ninu ewu arun yi ni Naijiria nipasẹ lilọ bibọ lati le se akojọpọ iroyin faraye gbọ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Òṣìṣẹ́ Bánkì ni mí l'Amẹ́ríkà kí n tó bẹ̀rẹ̀ Tíátà' Ninu ọrọ ibanikẹdun tirẹ, Sẹnẹtọ to n ṣoju ẹkun aringbungbun Kaduna, Uba Sani tọrọ aforiji fawọn to ba iṣẹlẹ naa lọ.
O ni, omo Yoruba ni won yọ, ti won si fi omo guusu ila oorun ti awọn iṣẹ to ti ṣe sẹyin to jẹ aridimu ko wu ni lori to.
Oríṣun àwòrán, AFP Àkọlé àwòrán, Eyi ni awọn eniyan to n fo nilu Abidjan, Ivory Coast lasiko ti wọn se ere idaraya akọkọ ti Circus Festival.
Mose bá pe Besaleli ati Oholiabu, ati olukuluku àwọn tí OLUWA ti fún ní ìmọ̀ ati òye ati gbogbo àwọn tí wọ́n ní ìfẹ́ sí iṣẹ́ náà láti wá bẹ̀rẹ̀ rẹ̀.
Òṣùká kékeré kò rẹrùn àgbà, orílẹ́èdè Nàìjíríà ṣòro púpọ̀ láti darí - Ibrahim Babangida Sowore ṣèpàdé pẹ̀lú Nnamdi Kanu láti dojú ìjọba Nàíjíríà bolẹ̀ - Àjọ DSS Àwọn obinrin wa lè máa rìrìnàjò lọ orilẹ̀èdè míì báyìí - Ìjọba Saudi ‘A ó ran àwọn tó lùgbàdì omíyalé ìpínlẹ̀ Kogi lọ́wọ́’ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Kayeefi: Facebook ni Wolii Arole Jesu fi tàn an wọ agbo, orí rẹ̀ ni wọ́n fi s'owó Nítorí ìdí èyí ni BBC Yorùbá ṣe sàlàyé àwọn ọ̀nà ti e lè gbà láti dènà ìṣòro omíyale àgbàrá ya sọọbu.
Ẹ̀yà Efuraimu ń fi tipátipá mú wọn ṣiṣẹ́ bí ẹrú.
Ni Bauchi, Bala Muhammad tii se gomina ibẹ naa ti salaye pe, gbogbo ara ni oun fi n ti agbekalẹ abule Ruga lẹyin nitori ida aadọrin ninu ọgọrun awọn olugbe ipinlẹ Bauchi lo jẹ Fulani darandaran.
”) Ọkunrin náà lọ, ó bọ́jú, ó bá ríran.
"Lara awọn iwe ti oloogbe naa ko ni ""Ẹfunṣetan Aniwura"", ""Madam Tinubu"" ati ogbufọ fun awọn iwe ti ọjọgbọn Wole Soyinka kọ si ede Yoruba."
Òun ni ó súnmọ́ Jesu pẹ́kípẹ́kí nígbà tí wọn ń jẹun, tí ó bi Jesu pé, “Oluwa, ta ni yóo fi ọ́ lé àwọn ọ̀tá lọ́wọ́ rí?
Ọba bá pàṣẹ fún Doegi pé, “Ìwọ, lọ pa wọ́n.
" Abajọ ti nkan fi n dara fun mi; abajọ ti mo fi ni iru awọn ọmọ to dara ti o bi fun mi; abajọ to fi dabi ẹni pe mo n lo àjídèwe, nitori pe o ko lo mi ni alobajẹ.
Ní àkókò náà gan-an ni ó dé, ó ń fi ìyìn fún Ọlọrun, ó ń sọ nípa ọmọ yìí fún gbogbo àwọn tí wọn ń retí àkókò ìdásílẹ̀ Jerusalẹmu.
Wole Soyinka rèé láti kékeré A kò ṣẹ̀ṣẹ̀ jọ máa pàdé ara wa!
 Oríṣun àwòrán, @NewsOvert ""Mo n lọ sibi ipade kan lọjọ naa ni, ṣugbọn mo tete tẹkọ leti lọ si agọ awọn ọlọpaa ọhun, ti mo si ri pe ohun ti wọn mu iyawo mi fun ko lẹsẹ nilẹ titi di oni yii."
Yóo kọ́ ilé kan fún mi, n óo jẹ́ kí atọmọdọmọ rẹ̀ wà lórí ìtẹ́ títí lae.
ilẹ Afirika ba si fẹ ni aṣeyọri, orilẹ-ede Naijiria gbọdọ ni aṣeyọri’.
Wọ́n sanwó ọ̀yà fún alágbẹ̀dẹ wúrà, ó bá wọn fi dá oriṣa.
Ẹrù ìyà ni Norway dì lé Super Falcons lórí ní 2019 Women's World Cup Ṣugbọn ẹgbẹ agbabọọlu Naijiria jẹwọ orukọ wọn gẹgẹ bi aṣaaju ikọ agbabọọlu obinrin lati ilẹ adulawọ lẹyin ti fagba han South Korea pẹlu ami ayo meji ninu ifẹsẹwọnsẹ keji ti wọn gba.
Taa ni Ebila One Million Boys àti Ekugbemi, olórí ẹgbẹ́ òkùnkùn míì tó da ìlú Ibadan rú?
Yekini Ajileye: Oríṣun àwòrán, others Ọmọ bibi ilu Osogbo ni Alhaji Yekini Ajileye, ti ọpọ ere rẹ si maa n da lori ihuwasi awọn ajẹ, ati iṣẹ ibi ti wọn n ṣe.
Third Mainland Closure: Wo ǹkan ti ojú àwọn ènìyàn ń rí lórí àfára 3rd Mainland Àkọlé àwòrán, Sunkẹrẹ fakẹrẹ Lorumọju oni ọjọ Abamẹta ni ijọba apapọ ti ori afara Third Mainland gẹgẹ bi wọn ṣe kede ṣaaju.
tí ó ń rìn ninu ìlànà mi, tí ó sì ń fi tọkàntọkàn pa òfin mi mọ́, olódodo ni irú ẹni bẹ́ẹ̀, yóo sì yè.
Wọ́n dá a lóhùn pé, “Kò sí oúnjẹ níhìn-ín, àfi burẹdi marun-un ati ẹja meji.
Ambode sanwo ènìyàn 50 tó há sí Russia Èsì PDP lórí bíborí Fayẹmi l'Ekiti Atọmọde ati agba jade fun idibo ni Ekiti PDP ní ìbò Ekiti kò tó dá ẹgbẹ́ àwọn rú!
Diẹ lara awọn igba ti awọn janduku oloṣelu da wahala silẹ ni Naijiria Eto idibo ọdun 2011 yọri si wahala ni ẹkùn Ariwa Naijiria.
abadofin ti wọn ti fọwọ si naa ṣọwọ si Gomina Akinwunmi Ambọde ti Ipinlẹ
Àmọ̀tẹ́kùn bẹ̀rẹ̀ iṣẹ́ pẹrẹu l'Ọ́ṣun Kí ló wà ní ìdí igbá tí àwọn olorì Aláàfin máa ń tí lóde Ọ̀yọ̀ ''Olóde'' ni Yorùbá ń pe coronavirus, iléeṣẹ́ Yemkem ti rí òògùn rẹ̀ báyìí- Olùdásílẹ̀ Yemkem Wo bí o ṣe lè jẹ́ kí bátììrì fóònù rẹ pẹ́ síi Aarẹ Andry Rajoelina ti Madagascar lo kede ni ọsẹ melo kan sẹyin pe orilẹ-ede oun ti fi ewe Artemisia ati awọn ewe ibilẹ miran ṣe agbo to le wo coronavirus san.
Ni ọjọ kan, ni awọn mejeeji ba jọ ya fọto àdáyà papọ, ti awọn obi Cassidy si bẹrẹ si ni beere lọwọ Miche boya Ọgbọn ọjọ, Osu Kẹrin, ọdun 1997 ni wọn bi?
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ojude Oba 2019: Ọba Adetọna ní bí òun bá papòdà, ẹni tó bá dáńtọ́ ni kí wọ́n fi jẹ Awùjalẹ̀ 14 Ògún 2019 Ṣe awọn agba bọ wọn ni, bi ẹyin agba yoo ṣe ri, oju rẹ laa tii mọ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ìya Emma oní POS ṣẹ̀ṣẹ̀ rékọjá lọ síbí ilé yẹn ni àtọmọdé, ó sì wó pa wọ́n - Láńlọọ̀dù Obalende O sọ pe anfani iwọde to n waye yii yoo di ohun atipe oun yoo tẹsiwaju ninu iṣẹ lati daabo bo ẹtọ gbogbo awọn ara ipinlẹ Eko nigba kuugba ati lọjọkọjọ.
Mose ati Aaroni pe gbogbo àwọn ọmọ Israẹli jọ ní ọjọ́ kinni oṣù keji, 
Bí mo bá ṣe èyí ní Burundi , ó ṣe é ṣe kí a fi mí sí àtìmọ́lé
Tí a fiṣọwọ́ ní 13:50 4 Ọ̀pẹ̀ 202013:50 4 Ọ̀pẹ̀ 2020 Irọ́ ni, abẹ́rẹ́ àjẹsára Covid-19 kò lè ṣàyípadà DNA rẹ A ṣagbeyẹwo awọn iroyin ofege mẹrin ti awọn eeyan n gbe kiri nipa abẹrẹ ajẹsara Covid-19.
Ọ̀rọ̀ yìí jẹ́ ohun ẹ̀dùn púpọ̀ fún mi, Kábíyèsí - ẹni tí n kò ì tí ì fi ojú kàn láti ọdún mẹ́ta!
Atẹjade kan ti adele oludari ẹka alarina nileesẹ ologun, ọgagun Sagir Musa fisita lọjọ Satide lo sísọ loju ọrọ yii.
0 5482 Erekusu Saint Martin ( Agbegbe ti France) 26 69.
Iyanṣẹlodi naa ko pe wakati mejila ti wọn fi kede pe awọn ti fagile.
Bẹ́ẹ̀ ni pupọ ninu àwọn ará Kọrinti; nígbà tí wọ́n gbọ́ ọ̀rọ̀ Oluwa, wọ́n gbàgbọ́, wọ́n bá ṣe ìrìbọmi.
Maharai, ará Netofa, ati Helodi, ọmọ Baana, ará Netofa; 
Ṣùgbọ́n ìgbà náà ni mo tó mọ̀ pé àwọn ọ̀dọ́ Tibet kan ò fẹ́ sọ èdè wọn bí ẹni pé wọn kàn-án nípa fún wọn láti sọ èdè elédè.
Nigba to n gbe idajọ kalẹ lori ẹjọ kan ti ẹgbẹ ọmọlẹyin kristi (CAN), ati awujọ awọn musulumi ni ilu Ipokia pe lati tako ọdun oro, onidajọ Sikiru Owodunni sọ fun awọn oloro pe wọn ko ni ẹtọ kankan labẹ ofin lati paṣẹ konileogbele fun awọn olugbe Ipokia, Idi-Iroko, Ihunbo, Ifonyintedo, Ogosa, Koko, Ilaṣhe, Ibatefin, Agosasa, Oniru ati Mede.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Arúfin ni Seyi Makinde pẹ̀lú bó ṣe gbà kí wọ́n sin Ajimobi sí GRA - Amòfin Ṣé ó leè jẹ́ ilẹ̀ tí Makinde kò jẹ́ kí Florence Ajimobi gbà ló ń bi nínú?
Lori Facebook yii kan naa ni ọkan lara awọn ọrẹ ọkunrin naa lori Facebook ti ṣe bi baba to fi iyawo fun ọkọ, awọn ọrẹ wọn meji to ku si ṣe 'ẹlẹri' igbeyawo naa.
Àwọn ẹ̀mí èṣù pàápàá gbàgbọ́ bẹ́ẹ̀, ìbẹ̀rùbojo sì mú wọn.
Ariwo ìyẹ́ àwọn Kerubu náà dé àgbàlá òde.
Ẹ níláti ya aguntan kọ̀ọ̀kan sọ́tọ̀ ninu agbo ẹran kọ̀ọ̀kan tí ó tó igba ẹran, ninu àwọn agbo ẹran ìdílé Israẹli.
aje to waye ni Dubai, United Arab Emirates.
Oríṣun àwòrán, Oyinkan Amọ itan miran sọ pe, Kofoworola John ni orúkọ ọkọ kejì to fẹ Oyinkan.
À ń kéde orúkọ rẹ,a sì ń ròyìn iṣẹ́ ribiribi tí o ṣe.
Bi o tilẹ jẹ pe ọtọọtọ ni ipilẹ orin kikọ lawọn ilu mejeji yii to si jẹ pe iṣọwọ kọrin wọn yatọ ṣugbọn awọn olorin gangan ti wa ọna ti ajọṣepọ wọn fi n ṣiṣẹ to ti n pọ owo gidi.
Lasiko igbẹjọ rẹ naa lo tun salọ kuro ni Naijiria lọ si Niger Republic ni ọdun 2020 yii, amọ ti Ajọ EFCC si tun ragba lasiko to n salọ.
Kìí ṣe àkọ́kọ́ rèé ni Nàaìjíríà o.
N óo pàṣẹ fún òjòkí ó má rọ̀ sórí rẹ̀ mọ́.
Amọ, o ni wi pe iwadii fihan wi pe baba to tọ oun dagba ko mọ nkankan nipa bi wọn se ji oun gbe rara, ti awọn ọlọpaa si fi i silẹ pe ko maa lọ ni alaafia.
Ó fi eyín erin ṣe ìtẹ́ ńlá kan, ó sì yọ́ wúrà dáradára bò ó.
Ms Palmer-Hughes ni o le ni idaji awọn onibara oun ti wọn ti ṣe iṣẹ abẹ ikebe nla yii ni orilẹ-ede bii Turkey, Hungary, Belgium ati Spain.
jẹ́ ọ̀kẹ́ meji ó lé ẹẹdẹgbẹta (40,500).
O kawe ni Fasiti Dakar ni Senegal to ti kọ nipa ede Faranse ko to lọ Fasiti Ibadan.
Láàrin ọjọ́ péréte tó ṣíwájú ìpòóráa rẹ̀, ètò ìkàn-sára- ẹni ti ìjọba Con el Mazo Dando ṣàfihàn fídíò tí Díaz sọ̀rọ̀ nínúu rẹ̀.
Ilé wa sì ni wọ́n ní wọn yóò tẹ́ òkú sí nítorí bàbá mi ni ó dúró bíi bàbá fún un, ilé onílé ni ó ń gbé.
Ilẹ̀ kẹrin tí wọ́n ṣẹ́ gègé lé lórí bọ́ sí ọwọ́ ẹ̀yà Isakari.
Lasiko ti BBC Yoruba fẹsẹ kan de si ibi ti wọn ti n ya sinima naa, a ri tọkọ-tiyawo naa ti wọn dijọ n sọrọ, abala kan tiẹ wa ninu sinima naa, ti Fathia gbe ori le Saheed lẹsẹ.
Coronavirus tún ti ṣe ọṣẹ́ lórí iṣẹ́ líla ojú ọ̀nà relùwe láti Eko sí Ibadan - Ìjọba àpapọ̀ Àrùn Coronavirus fa'lẹ̀ya láwọn ìletò aláwọ̀dúdú ní Amẹ́ríkà NCDC covid 19 updates (Breakout): Ìjọba àpapọ̀ ní kò tíì sí ọjọ́ fún ìwọlé àwọn akẹ́kọ̀ọ́ Oríṣun àwòrán, Unilag A o le sọ igba ti awọn ileeẹkọ yoo wọle pada ni Naijiria-Ijọba A ko ti le sọ igba tawọn ileeẹkọ yoo wọle.
''Kabiyesi Ọọni ni Arole Oduduwa ti gbogbo wa mọ, Ile Ife si ni gbogbo wa ti san wa, kii ṣe Oyo, bẹẹ si ni Ọọ ni ko lee kọ iru lẹta buruku ti Alaafin kọ yii si gomina Fayemi laelae, arifin gbaa ni oun ti Alaafin se naa'' Kabiyesi Alawe lo sọ bẹẹ.
Church Wall Collapse: Ògiri ṣọ́ọ̀ṣì wó pa àwọn olùjọ́sìn 13 nílé ìjọsìn South Afrika
Asoju Naijiria si orile-ede Sao Tome, arewa Worlu di oloogbe.
Oludamọran pataki fun aarẹ lori ọrọ iroyin, Femi Adesina lo sọ fawọn ọmọ Naijiria nile ati nilẹ okere pe iroyin ofege lawọn kan n gbe kiri.
Àwọn ọba Yorùbá kan rèé tí wọ́n rọ̀ lóyè, tí ọba míràn jẹ lójú ayé wọn Bí Fayemi bá tasẹ̀ àgẹ̀rẹ̀, àwọn oníbáwí rẹ̀ wà l'Ekiti-Peter Fatomilọla Coronavirus: Wo ohun tí o ní láti ṣe láti dáàbò bo ara rẹ Wọ́n gbé òkú ọgá iléẹ̀kọ́ àti òṣìṣẹ́ méjì míì tó kú nínú ìbúgbàmù lọ sílé ìgbókùsí ológun ojú omi l‘Eko Oríṣun àwòrán, Getty Images Nipa pe ọna ti ajakalẹ arun fi n tan kalẹ ni kikorajọ ọpọ eeyan, o ni ẹmi eṣu ko le raye laarin awọn ọmọ Ọlọrun.
Ẹwẹ, awọn kan tilẹ gbagbọ pe o ṣeeṣe ko jẹ oogun ti awọn kan ran si abule naa lo fa a.
Ajọ CAN to bu ẹnu atẹ lu atimọle awọn ọmọ Naijiria lọna aitọ, tun ke gbajari si ijọba apapọ lati wa ọna lati gba itusilẹ Leah Sharibu to ti wa ni panpẹ ikọ Boko Haram lati Osu Keji, ọdun to kọja.
 Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Akeredolu: Kìí ṣe Buhari ló wà nídìí rẹ̀, ẹ jẹ́ ká gbà pé àmúwá Ọlọ́hun ni Oun to n ja fun ni pe ki ijọba ṣaa ni ki awọn ara ilu gba nkankan gẹgẹ bii ma binu yatọ si ki wọn fi ẹnu sọ ọ.
Alaafia onibaraa mi lo jẹmilogun ju bayii.
Coronavirus in Nigeria: Àwọn ìpéjọpọ̀ ṣọ́ọ́ṣì àti ayẹyẹ nlá tí kò ní wáyé nítorí coronavirus
Abajade iwadii ajọṣe kan laarin ajọ ilera agbaye, WHO ati ajọ idagbasoke eto ẹkọ awọn ewe lagbaye, UNICEF (JMP) gbe kalẹ lọdun 2015 fi idi eleyi mulẹ, ṣugbọn eyi yatọ si ohun ti Buhari n sọ.
        Mo dúpẹ́ púpọ̀ fún ìwé rẹ tí mo rí gbà mo sì ka ìwé náà dáadáa.
Oríṣun àwòrán, @jidesanwoolu Iwọde End SARS bẹyin yọ ni ilu Eko lọjọ Iṣẹgun lẹyin ti Sanwo-Olu kede ofin konile-o-gbele oni wakati mẹrinlelogun bẹrẹ lati aago mẹrin irọle.
Mo bá pariwo, mo ní, “Mo gbé!
Amọ Aarẹ Buhari ni oun nilo lati ya owo naa ki awọn le e pari gbogbo iṣẹ akansẹ ti oun ti dawọ le ni saa yii.
Wọ́n ti yìnbọn pa olórí ẹgbẹ́ jàndùkú ''One Million Boys'' ní Ibadan’ Kí ló ṣẹlẹ̀ tí àwọn ọmọogun Nàìjíríà tó lé ní 350 fẹ́ kọ̀we fi iṣẹ́ sílẹ̀?
- Aregbesola Ẹgbẹ́ òṣèlú PDP, ẹ̀ka ìpínlẹ̀ Eko fún Fayose lọ́jọ́ méje láti bẹ àwọn adarí ẹgbẹ́ Adamu ni Buhari gbe igbesẹ naa lati se iwuri fawọn olukọ jakejado Naijiria, ki wsn lee sa ipa wọn lati sisẹ kara siwaju si, ki wsn si tun lee dantọọ lẹnu isẹ.
awon oniwa ibi, odaran ati apaniyan ti dinku lorile ede yii, nitori pe ijoba
Oríṣun àwòrán, Getty Images Kini awọn adari orilede lagbaye sọ nipa abẹrẹ ajẹsara naa?
Ó wá bi wọ́n pé, “Ẹ̀yin ńkọ́, ta ni ẹ̀yin ń pè mí?
" Coronavirus: Bàyíì ní àwọn ọmọbìnrin Afghanistan ṣe fi èròjà ara ọkọ ṣe fẹntilátọ Arákùnrin tó jí Ese Oruru gbé ti rí ẹ̀wọ̀n ọdún 26 he Àwọn ìbejì Akeugbagold kò le rìn dáadáa mọ́ lẹ́yìn tí wọ́n dáwọn padà Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, What causes coronavirus: Akeugbagold sọ àṣírí ohun ti àrùn coronavirus ń dá lárá f Baba awọn ibeji naa wa kan saara sawọn ọlọpaa fun iṣẹ takuntakun ti wọn n ṣe lati kapa iwa ọdaran lawujọ wa, to si rọ ijọba lati ṣanwo gidi fawọn ọlọpaa pẹlu irinsẹ igbalode lati ṣíṣẹ wọn.
”Bankole, leni ti o tun igbakeji komisona awon olopaa, wa ro awon omo orile-ede Naijiria ti o fi orile-ede China se ibugbe lati tu yaya sita lati wa ye awon oludije naa si.
Wọn kò ní ti àwọn ìlẹ̀kùn ìlú náà ní gbogbo ọ̀sán; òru kò sì ní sí níbẹ̀.
Nígbà tí ó gúnlẹ̀ ní Kesaria, ó lọ kí ìjọ ní Jerusalẹmu.
Kò sí ẹ̀rí tí ó fi ẹsẹ̀ rinlẹ̀.
Ojo kokanlelogun ,osu kewaa odun 1979 ,lo je igba akoko .
Èmi pàápàá ni oúnjẹ tí ó ń fún eniyan ní ìyè.
I don’t have a TV Licence.
Faicke ni ‘oun ti a ri ju gbogbo ile aye ati ọrun ti a le ri soju, ti o si tobi ju oorun lọna to le ni biliọnu mẹfa.
Omowe Olapade Agoro je okan lara awọn oju ti ọpọ n wo ninu iṣelu Naijiria gẹgẹ bi agba to moye.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Kìnìún pa okùnrin ọmọ aadọrin ọdún kan lorilẹ-èdè South Africa 22 Ògún 2019 Oríṣun àwòrán, @others Àkọlé àwòrán, Kinihun oloola iju kuro lẹran aa sin ninu ile Ọkunrin naa ti gbogbo eeyan mọ si The Lion Man"" ni Pretoria fẹ tun ile kiniun rẹ ṣe lo ba gba ekuru jẹ lọwọ ẹbọra."
Ninu ihò òkúta ni ibojì náà wà, òkúta sì wà ní ẹnu ọ̀nà rẹ̀.
Àkọlé àwòrán, Coronaviru: Àsìkò ti tó láti tilẹ̀kun mọ àwọn alejo to ń wọ Naijiria- Ilé Asofin Àwọn ọmọ ilé gba àbá ti Ibrahim Oloriẹgbẹ́ to jẹ́ alága ìgbìmọ lori ètò ìlera mu wá wọ́ lásikò ìjókó ilé.
Awọn to le ni ọgọrun un lo ṣi wa ni panpẹ awọn ikọ Boko Haram lẹyin ti wọn ji wọn gbe ninu ile iwe wọn lọdun 2014.
Dandan ni kí o pa wọ́n lẹ́nu mọ́, nítorí pé wọ́n ń da odidi agbo-ilé rú, wọ́n sì ń kọ́ àwọn eniyan lẹ́kọ̀ọ́ tí kò tọ́ nítorí èrè tí kò yẹ.
“Gbogbo àwọn ẹbọ mímọ́ tí àwọn ọmọ Israẹli bá mú wá fún mi ni mo fún ìwọ ati àwọn ọmọ rẹ, lọkunrin ati lobinrin, gẹ́gẹ́ bí ìpín wọn títí lae.
Oyo Politics: Ilé aṣòfin ìpínlẹ̀ Oyo jáwée lọ sinmi nílé fún alága ìgbìmọ̀ mẹ́tàlá káàkiri ìjọba ìpínlẹ̀
Ninu ikede ti ajọ to n gbogun ti ajakalẹ arun lorilẹede Naijiria, NCDC fi sita lọjọru, mẹtadinlaadọrun ninu wọn lo wa lati ipinlẹ Eko, mẹrinlelogun wa lati ipinlẹ Kano, Gombe ni mejidinlogun, Kaduna mẹtadinlogun bẹẹni olu ilu orilẹede Naijiria, Abuja naani mẹrindinlogun.
Wọ́n óo pa ibùdó wọn yí Àgọ́ náà ká.
Brexit: Ilé làbọ̀ ìsinmi oko fọ́mọ Yorùbá nílẹ̀ Gẹ̀ẹ́sì
Ní àkókò kan náà ni ìlú Libina ṣọ̀tẹ̀ sí Juda.
Bakan naa lo ni ijọba oun ti n mu iṣẹ ṣe lati satunse awọn opopona to ti dẹnu kọlẹ nilu naa.
Ejò jẹ́ alárèékérekè ju gbogbo ẹranko tí OLUWA Ọlọrun dá lọ.
Ó wá ku Jerusalẹmu bí àtíbàbà ninu ọgbà àjàrà,ati bí ahéré ninu oko ẹ̀gúsí;ó wá dàbí ìlú tí ogun dótì.
Bí ó bá ṣeéṣe, á jẹ́ wí pé ẹ̀yin náà lè hùwà rere;ẹ̀yin tí ibi ṣíṣe ti mọ́ lára.
Gbogbo eti to si gbọ̀ iroyin naa lo n fo fayọ, ti wọn si n ki ọba alaye naa pe wọn ku oriire ayọ ọmọ tuntun.
Oríṣun àwòrán, @Davido Àkọlé àwòrán, ọrọ ifẹ lagbara Davido fi mọ́tò N45M dá Chioma lọ́lá Davido, Wizkid, Falz kogoja gẹgẹbi ọ̀dọ́ tó pegedé l'Áfíríkà Simí, Davido gba àmì ẹ̀yẹ 'Headies' Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Davido fi ọkọ̀ Porsche ṣe ayẹyẹ ọjọ́ ìbí fún Chioma Avril 3) Star Boy to gbé Terri, Spotless, Ceeza Milli ati Wizkid sita - Soco Awọn Wizkid naa ni wọn gbe orin yii jade.
Ṣugbọn n óo fi ìyà ẹ̀ṣẹ̀ jẹ àwọn tí ọkàn wọn ń fà sí àwọn ohun ẹ̀gbin ati ìríra.
Ìjìyà ń bẹ fún àwọn ti adé ọ̀rọ̀ náà bá ṣí mọ́ lóri -Ọga àgbà FRSC Wo àwọn eléré ìdárayá mẹ́ta tí àjọ FIFA ti fòfin dè títí ayé Òkú sunkún òkú ní ìpínlẹ̀ Benue Àwọn òṣìṣẹ́ fásitì yóò fi ìyanṣẹ́lódì ṣẹ Nàìjíríà lọ́wọ́ lọ́jọ́ Ajé Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Ó bi wọ́n pé, “Níbo ni ẹ tẹ́ ẹ sí?
Nigba to n gba ero awọn asofin lori Ẹniọwọ Rufai Imam wọle, Aarẹ awọn asofin agba lorilẹede Naijiria, Sẹnatọ Bukọla Saraki ki Ẹniọwọ Rufai Imam ku oriire iyansipo rẹ pẹlu ikilọ wipe ko ṣe ohun to ba tọ pẹlu ipo rẹ lẹka iṣedajọ' Okah ati Nwabueze gba idajọ ẹwọn gbere Lush beauties: Ara sisan kii n ṣe arun Ni oṣu kejila ọdun 2017 ni aarẹ orilẹede Naijiria, Muhammadu Buhari fi orukọ Ẹniọwọ Rufai Imam ṣọwọ si ile asofin agba fun ifọwọsi wọn gẹgẹbii adajọ agba ileẹjọ Sharia ni olu ilu orilẹede Naijiria, Abuja.
“Nítorí náà, ẹ má ṣe àníyàn pé kí ni ẹ óo jẹ?
Òtítọ́ yóo rú jáde láti inú ilẹ̀;òdodo yóo sì bojú wolẹ̀ láti ojú ọ̀run.
Iná náà jó ibú omi, ráúráú ó sì bẹ̀rẹ̀ sí jó ilẹ̀ pàápàá.
OLUWA ni ó dá oòrùn, láti máa ràn ní ọ̀sán,tí ó fún òṣùpá ati ìràwọ̀ láṣẹ, láti tan ìmọ́lẹ̀ lálẹ́,tí ó rú omi òkun sókè, tí ìgbì rẹ̀ ń hó yaya,òun ni orúkọ rẹ̀ ń jẹ́ OLUWA àwọn ọmọ ogun.
" Akọwe ọja naa, ọgbẹni Gbenga Fayemi sọ pe awọn oludari ọja naa ti ṣe ipese awsn ohun idaabo bo awọn ọja nibẹ lati igba ti iṣẹlẹ ina ti waye nigbakan ri.
    N kò ni lè ròyìn ìjà tèmi àti ti Ìnàkí-ìbẹ̀rù jù bẹ́ẹ̀ náà lọ pẹ̀lú.
Minisita fun oro ile  okeere  lorile ede Naijiria, ogbeni Geoffrey Onyeama lo soro yii lasiko iforowero , pelu awon akoroyin lati fi se ayeye ifeyinti lenu ise  fun Olukunle Bamgbose, to  je akowe agba fun ajo to n mojuto oro to je mo ile okeere .
Naijiria le ọmọ Cameroon mejila Siasia kọ̀wè fún ipò akọ́nimọ̀ọ́gbá Cameroon Eléré ìdárayá Cameroon mẹ́jọ di àwátì Àkọlé àwòrán, Ariwa-Iwọ oorun ati Guusu-Iwọ oorun ẹkun naa ni agbegbe meji ti wọn ti n sọ ede Gẹẹsi lorilẹ-ede naa Ninu awọn ajijangbara ti wọn n ja fun ominira agbegbe Anglophone nilẹ Camaroon, naa ni olori wọn to tun jẹ akọroyin ni agbegbe Mancho Bibixy.
Mo wa fẹ fi asiko yii pe gomina tuntun naa lati jẹ ki a fọwọsowọpọ  lona ti isipopada naa yoo se waye ni irọrun.
Awọn ara adugbo ni iṣẹlẹ naa ya awọn lẹnu nitori orẹkunrin naa kii ṣe oni jagidijagan, amọ ṣaadede lo wa si ile ọrẹbinrin naa pẹlu galọọnu bẹntiroo, ti awọn si ro wipe wọn fẹ lo o fun ẹrọ alupupu wọn ni.
Wò ó bí a ti sọ ọ́ di ẹni ilẹ̀,ìwọ tí o ti pa ọ̀pọ̀ orílẹ̀-èdè run rí.
Fetí sílẹ̀ kí o gbọ́ ìtàn wọn, kí o gbọ́ ohun tí ó jẹ́ kí wọ́n fi ayé sílẹ̀ tì wọ́n sì fi di èrò ọ̀run:
Afenifere: Àsìkò tó tá tako ìkọlù darandaran nílẹ̀ Yorùbá
Oríṣun àwòrán, Twitter/Pastor Tunde Bakare Pasitọ Bakare ni ijọ Latter Rain gan an ti jọwọ gọngan meji to jẹ ti ṣọọṣi naa fun ijọba ipinlẹ Eko lati lo fun ibudo iyasọtọ awọn to ti lugbadi coronavirus.
O ni oloye Obasanjo ni wọ̀n ti fi orukọ rẹ sọri ọpọ nnkan tẹlẹ, to fi mọ ọpọ opopona ni Kano.
 lára wọn ni sheikh abubakr sidiq agbarigidoma , sheikh muhammad tukur bn amiinullah .
Lẹ́yìn náà ni ẹ̀yà Nafutali; Ahira, ọmọ Enani ni yóo jẹ́ olórí wọn.
LASEMA: Àwa àti panápaná ń ṣiṣẹ́ kára láti dènà ìjàmbá iná
Mugabe fi ìgboyà dáábò bo ilẹ̀ Áfíríkà lọ́wọ́ ìmúnisìn"" Àwọn ọ̀rọ̀ apanílẹ̀rín tí Mugabe sọ tó jẹ́ mánigbàgbé Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?"
Ile ẹkọ igbalode naa ti o di kikọ nipasẹ ajọṣepọ laarin ijọba apapọ ati ẹka eto ẹkọ nipinlẹ Ọyọ lo n bẹ ni ibudo idako Agbopa-Akufo ni ijọba ibilẹ Ido.
Aarẹ Buhari nìkan ni wọn fà kalẹ̀ pé kò ṣoju wọn ninu ẹgbẹ APC.
" O ni bayii ti wọn ti bẹrẹ si n pa awọn ọdọ ni ipakupa, wọn lẹtọọ lati sọ pe o to gẹ.
Ẹwẹ, lọkunrin lobinrin lawọn ololufẹ Inter Milan tu jade lati ki Lukaku kaabọ si ikọ agbabọọlu wọn l'Ọjọbọ.
#Russia 2018: Ta ni yóò gba ''golden boot'' ní Russia?
Ó yẹ kí a sì tètè lọ pẹ̀lú nítorí ọ̀pọ̀lọpọ̀ àwọn ọdẹ ni wọn tì bá Àkàrà-oògùn lọ.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ìtàn ayé Henry Fajemirokun, olówó tó fi owó mọ Olúwa àti ènìyàn Ìtàn ayé Taiwo Oredein rèé, àgbà òṣèlú tó parí ayé rẹ̀ sọ́gbà ẹ̀wọ̀n Ìtàn ìgbé ayé Bode Thomas rèé, ó kọ́ wa láti máa kó ẹnu wa ní ìjánu Ṣo mọ̀ pé J.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Wo bí o ṣe leè ṣe ìjìnàsíraẹni ní ibiṣẹ́ lásìkò Coronavirus yìí Kò tíì sí àrùn Coronavirus ní ìpínlẹ̀ Oyo - Ijọba Oyo Oríṣun àwòrán, @seyiamakinde Ijọba ipinlẹ Oyo ti sọ pe ko si ẹni kankan to tii ni arun Coronavirus nipinlẹ naa, ati pe oun ti bẹrẹ igbesẹ lati ṣawari awọn eeyan to ṣalabapade ẹni ti wọn fura si pe o ṣeṣe ko ti ko arun naa wọ ipinlẹ ọhun.
Pyotr gbagbọ pe, iṣẹlẹ naa ko ba ti ṣẹlẹ ti awọn ba mọ nipa aisan to n se abiyamọ lẹyin ibimọ.
Ó fi mí sinu òkùnkùnbí òkú tí ó ti kú láti ọjọ́ pípẹ́.
Kí oore-ọ̀fẹ́ Oluwa wa Jesu Kristi kí ó wà pẹlu gbogbo yín.
Òní niléẹjọ́ tó ga jùlọ yóò gbẹ́jọ́ ẹ̀sùn ayédèrú sabuké tí wọ́n fi kan Buhari APC ní yóò jáwe olúbori ni Bayelsa ati Kogi- Tinubu Wike kìí ṣe dọ́là tí Ganduje leè kó sápò- Agbẹ́nuso ìjọba ìpínlẹ Rivers Fábàdà!
Àjàkálẹ̀ àrùn ati ikú yóo bẹ́ sílẹ̀ láàrin yín, n óo sì jẹ́ kí ogun pa yín.
Ẹlẹsẹ ayo, Ahmed Musa ni awọn ko ni ja awọn ololufẹ awọn ọmọ Naijiria kulẹ nigba tawọn ba n koju Bafana Bafana.
Ìtura ihò ilé ìgbẹ́ (Anal Orgasm) Ọpọlọpọ obinrin le gba itura ti wọn ba ni ibalopọ lati iho ile ìgbẹ́, bi o tilẹ jẹ pe ko wọ́pọ̀.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Sotitotbire: Ilé ẹjọ́ dá Alfa Babatunde padà sí áhàmọ́ọ́ bẹ́ẹ̀ni ó tún sún ìgbẹ́jọ́ si Ọjọ́-Bo̩ 16 Ẹrẹ̀nà 2020 Ile ẹjo ti sun igbẹjo si ọjọ Ọjọbo.
16 Ọ̀wàrà 2020 10:43 Fídíò, Wole Soyinka sọ ìdí tó fi ni òun a fi màálù Fulani ṣe súyà fáwọn èèyàn abúlé, Duration 10,4323 Owewe 2020 Èyí tí a wò jùlọ 5:03 Fídíò, Omolola Arohunmolase Welder: Mo ti fí iṣẹ́ 'Welder' gbayì láwùjọ, tó mo fi tọ́ ọmọ yanjú, Duration 5,039 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 5:39 Fídíò, Akomolede ati Asa lori BBC: Olùkọ́ Kikelomo Ogunboye tan ìmọ́lẹ̀ sí ìwà olè ọ̀gá ọlọ́pàá Audu gẹ́gẹ́ bí àwòkọ́ṣe àsìkò yìí, Duration 5,398 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 4:11 Fídíò, Oba Adeyeye Ogunwusi: Ojú mi ti rí lọ́pọ̀ lọpọ̀, ọ̀pọ̀ èèyàn ni kò tilẹ̀ gbàgbọ́ pé mo lè jọba- Ooni, Duration 4,117 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 4:43 Fídíò, Promise Akinlade: ọmọ ọdún mọ́kànlá tó ń fi ìlù dárà bíi àgbàlagbà sọ̀rọ̀ nípa tálẹ́ǹtì rẹ̀, Duration 4,437 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 0:59 Gbọ́, Ìsẹ̀lẹ̀ jákèjádò orílẹ̀èdè àgbáyé láàárín ìṣẹ́jú kan, Duration 0,59wákàtí 5 sẹ́yìn 7:03 Fídíò, Olumuyiwa Bolade Adedeji Military Bruitality: Bí arákùnrin onípèníjà ara tí sọ́jà lù ṣe dé, Duration 7,035 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 4:45 Fídíò, Yoruba Films: Ẹ̀ẹ́ bẹ̀ mi kúrò láyé ni, mi ò lè kú - Fadeyi Oloro, Duration 4,4526 Èrèlè 2020 2:48 Fídíò, Esther Ajayi: Èmi náà ti borí ìṣòro rí ló ń mu mi ṣojú àánú, Duration 2,481 Ògún 2019 6:08 Fídíò, Adebola Ademilua: Àìrísẹ́ ṣè lẹ́yìn ìwé kíkà ló sọ mi dí ìyá onírú, mo dúpẹ́ tèmi, Duration 6,0827 Bélú 2020 5:55 Fídíò, Soyinka Cancer: Àṣe ara mi ni iso ti n run gbogbo bí mo ṣe n ṣèrànwọ́ lórí jẹjẹrẹ, Duration 5,5527 Bélú 2019 BBC News, Yorùbá Ìdí tí ẹ fi le è nígbàagbọ́ nínú ìròyìn BBC Ìlànà Lílò Nípa BBC Òfin Àṣírí Cookies Kàn sí.
Àwọn ìròhìn ayọ̀ oníkanòjọ̀kan náà la gbọ́ káàkiri àgbáyé.
Àní sẹ́, àwa fúnra wa, tí a ti rí Ẹ̀mí Ọlọrun gbà gẹ́gẹ́ bí ẹ̀bùn rẹ̀ àkọ́kọ́, à ń jẹ̀rora lọ́kàn wa, bí a ti ń retí àkókò tí Ọlọrun yóo pè wá lọ́mọ rẹ̀, tí yóo sì dá gbogbo ara wa nídè.
Igbakeji olori ile, Sẹgilọla Abdulkadir lo daba wipe ki wọn gba abọ igbimọ naa wọle, ti gbogbo awọn asofin naa si fọwọsii.
Daniel Prude: Ìbòjú tí àwọn ọlọ́pàá New York fi bo ọkunrin ọhun ló ṣe ikú pà á Mo ṣetán láti fi ẹ̀ṣẹ́ dín dòdò ìyà fún Anthony Joshua- Efe Ajagba A kú oríire!
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Collapse Building: Àjọ LASEMA ti gbe ọkùnrin náà lọ sílé ìwòsàn 17 Sẹ́rẹ́ 2020 Oríṣun àwòrán, LASEMA Ọkunrin kan to ha si abẹ awoku ile to dawo laarọ ọjọ Ẹti ni ori ti ko yọ lọwọ iku ojiji.
A kò lè s̩àdédé gba ohun ìní e̩nì kan ló̩wó̩ rè̩ láìnídìí.
Jẹ́ kí n kú ikú olódodo,kí ìgbẹ̀yìn mi sì dàbí tirẹ̀.
Inú àwọn ọmọ bàbá rẹ wọnyi kò dùn si wi pé wọn ti di atọrọjẹ àti alágbàṣe fún àbúrò wọn ninú ilé ara wọn.
“Ọba Siria yóo múra láti wá pẹlu gbogbo agbára ìjọba rẹ̀, yóo bá ọba Ijipti dá majẹmu alaafia, yóo sì mú majẹmu náà ṣẹ.
ipinle naa (state’s Peace Commission) lati pẹtu si gomina ipinle Kaduna Nasiru
Kí àwọn amí meji náà tó sùn, Rahabu gun òrùlé lọ bá wọn, ó ní, 
’ Ẹ gbọ́, ẹ̀yin ọmọ Israẹli: ọ̀nà tèmi ni kò tọ́ ni, àbí ọ̀nà tiyín?
bawo lo si se lee lo talẹnti naa fun agbega iran rẹ, ti orukọ rẹ ko si ni di igbagbe?
Ẹ sì ń yin àwọn oriṣa fadaka, ti wúrà, ti idẹ, ti irin, ti igi ati ti òkúta.
Mọjumọ Abamẹta ni wọn lawọn mu ni adugbo Korokoro nibi to sapamọ si pẹlu awọn akẹgbẹ rẹ.
n mojuto eto ilana bo se tọ ati bo se yẹ lorile ede Naijiria (Code of Conduct
Ó pa gbogbo àwọn alufaa ibi ìrúbọ lórí pẹpẹ ìrúbọ wọn, ó sì jó egungun eniyan lórí gbogbo àwọn pẹpẹ ìrúbọ náà.
O wa ro awon akoroyin nibi idanilekoo naa, lati maa se ojusaaju tabi figbakan-bokan ninu iroyin won.
Igbakeji aarẹ ni aṣoju Naijiria si ilẹ Amerika, Adajọ-fẹyinti Sylvanus Nsofor ti gba ni kete to gunlẹ ni papakọ ofurufu J.
Aarẹ Muhammadu Buhari ni ìsẹlẹ omiyale to waye ni Katsina yii ba oun lọkan jẹ pupọ.
Elipaali bí ọmọkunrin mẹta: Eberi, Miṣamu ati Ṣemedi.
Wọn yóo sọ fún ọ pé, ‘Wọ́n ti rí àwọn kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ tí ẹ̀ ń wá.
Lasiko to n sọrọ lori eto ileeṣẹ BBC kan, Hard Talk, Soyinka ṣalaye wipe, afojusun ati ala ti iran oun ni fun orilẹede yii ko ti i wa si imuṣẹ.
“Ìwọ olórí Israẹli, aláìmọ́ ati ẹni ibi, ọjọ́ rẹ pé; àkókò ìjìyà ìkẹyìn rẹ sì ti tó.
Popoola sọ pe eto ti n lọ lọwọ lati wa ojutu si sunkẹrẹ-fakẹrẹ ti yoo waye lẹyin ti iṣẹ naa ba bẹrẹ.
Sugbọn eyi to se laanu ninu gbogbo rẹ ni ti obinrin alaboyun kan ati ọmọ inu re to dero ọrun lasiko to n rọbi lọwọ lọjọ to kẹyin osu kẹjọ ọdun 2020.
Nkechi Blessing Sunday, toun naa jẹ osere tiata Yoruba naa n rawọ ẹbẹ sawọn ọmọ Naijiria pe iwa ka jo ile itaja, ka ba dukia jẹ kọ ni ọna wiwa ojutu si ikọlu to n waye ni South Africa nitori ara wa la n pa.
Nígbà tí wọ́n sọ fún Dafidi pé Uraya kò lọ sí ilé rẹ̀, ó bèèrè lọ́wọ́ rẹ̀ pé, “O ṣẹ̀ṣẹ̀ ti ìrìn àjò dé ni, kí ló dé tí o kò lọ sí ilé rẹ?
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Cedric Bakambu l'agbabọọlu to wọn ju l'Afirika 2 Ẹrẹ̀nà 2018 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Cedric Bakambu ni agbabọọlu Afrika to wọn ju lọ Gbajugbaja agbabọọlu orilẹede DRC, Cedric Bakambu, ti di agbabọọlu ti o wọn ju l'Afirika lẹyin igba to darapọ mọ ẹgbẹ agbabọọlu Beijin Guoan, to wa ni China.
Akoko to fun Buhari lati lọ - Pasitọ Tunde Bakare Kin lo faa ti Daddy Freeze fi n tako idamẹwa?
Jallow sọ pe, ẹyin eyi ni amugbalẹgbẹ naa sọ pe, dandan ni fun oun lati kopa nibi eto isin kan nile ijọba l'oṣu Kẹfa, ọdun 2015, gẹgẹ bi ọmọbinrin to rẹwa ju l'orilẹede naa.
Ajọ naa tun sọ pe iba Lassa jẹ aisan gboogi to n ba Iwọ-oorun ilẹ Africa finra, ati wi pe Naiiria lo ti maa n pọ ju.
Ahmed Musa lo gba ayo meji wọle fun orilẹede Naijiria ni iṣẹju kẹrin ati ikẹtadinlaadọta.
Kí ẹni tí ń bá Ọlọrun jiyàn dáhùn.
alawọ funfun  ni ona ati ba won lajosepo
Wọn ni kii ṣe ikoko, ati pe ko yẹ ki awọn akẹgbẹ rẹ laaye lati maa sọrọ buruku sii.
Ninu oṣu kẹrin Trump ni lootọ ni ajọ to n mojuto ajakalẹ arun sọ pe eniyan maa lo ibomu gẹgẹ bí ọna lati dẹkun aarun naa Ni ọjọ kẹfà osu keje aarẹ Trump sọ pe iku to n waye lori China virus"" bi o se maa n pe, ko ju ida mọkandinlogoji lọ."
Isẹlẹ arigbarimu lori owo to poora waye ni Burundi Burundi da eto idibo bi ọgbọn Lẹyin o rẹyin ni wọn sọ pe, alakoso ẹgbẹ agbabọọlu Kiremba Cyriaque Nkezabahiz ati igbakeji rẹ Michel Mutama ni wọn gbe awọn atipo ọun wa, niwọn ba fi ẹsun igbimọ pọ lọna aitọ kan awọn mejeeji ọun.
Ajo naa so pe won yoo si ile-itoju
Gbogbo àwo̩n o̩mo̩dé yóò máa je̩ àwo̩n àn fàní ààbò kan náà nínú àwùjo̩ yálà àwo̩n òbí wo̩n fé̩ ara wo̩n ni tàbí wo̩n kò fé̩ ara wo̩n.
Ó kọ́ gbọ̀ngàn ìtẹ́ kan, níbi tí yóo ti máa dájọ́; igi kedari ni wọ́n fi ṣe ara ògiri rẹ̀ láti òkè délẹ̀.
Ọjọ kẹtadinlogun, oṣu Karun ni anfaani jijade yẹ ko pari.
Kí ló ń sọ ọmọ Nàìjíríà d'èrò ilẹ̀ òkèèrè tí ìjọba kò ronú sí?
Ìṣesí àwọn ará Ìrè-Èkìtì kò yàtọ ̀ sí tí àwọn ìlú yorùbá yòókù , yálà nípa aṣọ wíwọ ̀ tàbí àṣà mìíràn .
Wọ́n Ṣẹgun Absalomu, Wọ́n sì Pa Á.
O sọ pe agbẹjọro oun ti n ṣiṣẹ lori ọrọ naa, ati pe idajọ ni oun n fẹ ko fẹsẹ mulẹ.
Ṣugbọn nisinsinyii, a ti bọ́ kúrò lábẹ́ Òfin.
Oniruuru ere itage to n kọni lọgbọn, pani lẹrin, to si tun n kọ ni lẹkọ ni Ogunde ti ṣe jade nigba aye rẹ, bẹẹ si ni awọn awo orin rẹ lo maa n gbe jade lati fi kilọ fun iwa ibajẹ lawujọ wa, paapa laye awọn oyinbo amunisin.
À fọwọ́ fà ni gbogbo eyi.
Akọkọ ni pe ohun to ṣẹlẹ paapa ni Eko kọja afẹnusọ.
Bi wọn ṣe ma n se Egbo ni pe, wọn ma se agbado gbigbe titi ti yoo fi rọ, bakan naa ni wọn ma se ẹwa lọtọ.
"Nigba ti BBC Yoruba beere pe se o ri irisi awọn eeyan to n sisẹ ibi naa, akọroyin naa ni "" A ko ri wọn lọ titi, amọ iwadii mi mi lọdọ awsn to ri wọn fihan pe awọn Fulani ni wọn, ti isẹlẹ naa si tun lọwọ awọn araalu ninu."
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Neha Sharma: obìnrin tó ń múra bíi ọkùnrin láti leè ṣiṣẹ́ gẹrígẹrí Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Neha Sharma: obìnrin tó ń múra bíi ọkùnrin láti leè ṣiṣẹ́ gẹrígẹrí 31 Ẹrẹ̀nà 2019 Idẹyẹsi jẹ ohun ti awọn obinrin awujọ lorilẹede India n ba finra gẹgẹ bii awọn obinrin lọpọlọpọ orilẹede agbaye.
28 Kíyèsíi, èmi ni Jésu Krísti, Ọmọ Ọlọ́run.
Amọ, Sunday Igboho bu ẹnu atẹ lu bi ikọ ọmọogun Naijiria ṣe yinbọn lu awọn afẹhọnuhan ni Lekki Toll-Gate nipinlẹ Eko.
Adeola Oloko salaye pe  ahesọ ati ọrọ ti
O ni alaanu eeyan kan to n kọja lọ lo to gbe oun lọ sileewosan.
Ijoba apapo Naijiria ti seleri lati satileyin ninu ise iwadii lori ewe ati egbo ki ajosepo le wa laarin awon Babalawo to je onisegun ibile atawon onimo igbalode ninu eto ilera jo dan monran sii ki idagbasoke le wa fun oogun ni Naijiria.
Ahabu bá wí fún Jehoṣafati pé, “Ṣebí mo ti sọ fún ọ pé kì í sọ àsọtẹ́lẹ̀ rere nípa mi, àfi burúkú?
Oríṣun àwòrán, Facebook Nígbà tó ń fi idi ìṣẹ̀lẹ̀ náà múlẹ̀ fún BBC Yoruba, àbúrò Akeugbagold to bá wà sọ̀rọ̀ ni, lóòótọ́ ni wọn jì àwọn ọmọ náà lọ àmọ́ Sheikh kò tíì leè sọ̀rọ̀ lórí iṣẹlẹ náà báyìí Àmọ́ ìkéde kan tí Akeugbagold fi soju òpó Facebook rẹ ṣàlàyé pé, kò ju ìṣẹ́jú mẹwa lọ tí òun kúrò nínú ilé, láti lọ ṣe igbohunsilẹ waasi aawẹ, tí àwọn agbebọn fi wọlé, kò òun ni ọmọ méjì lọ.
Bí o bá jẹ́ kí arakunrin wa bá wa lọ, a óo lọ ra oúnjẹ wá fún ọ, 
EFCC: Akinwumi Sorinmade ni orúkọ tí Aroke ń lo ni ilé ìfowópamọ
Hesekaya ranṣẹ sí gbogbo Juda ati Israẹli.
"Njẹ o mọ oju yi ni ""Yollywood""?"
Facebook: Atunto tuntun se idinku awọn alamulo
Bẹ́ẹ̀náàni fún gbogbo èdè káàkiri àgbáíyé!
Ileeṣẹ iroyin BBC News Yoruba ti ṣe ọpọlọpọ iroyin nitori awọn obinrin-imuṣẹ alaa wọn, idagbasoke ati ilepa wọn lawujọ.
Mose bá tọ àwọn eniyan náà lọ, ó sọ gbogbo ohun tí OLUWA sọ fún un fún wọn, ati gbogbo ìlànà tí ó là sílẹ̀, gbogbo àwọn eniyan náà sì fi ẹnu kò, wọ́n dáhùn pé, “Gbogbo ohun tí OLUWA wí ni a óo ṣe.
Falconets gbo ewuro soju orilẹ ede Cameroon nínú ìdije eré ti ilẹ Afrika
16 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Làásìgbò Boko Haram àti ọwọ́jà ẹlẹẹ̀kèjì àrùn coronavirus ti n fí ojú àwọn ènìyàn ri màbo ni ìhà àríwá orílẹ̀-èdè Nàìjíríà lọ́wọ́lọ́wọ́.
Ṣugbọn, wọn ti so okun aabo le lawọn agbegbe ti ọrọ kan, ti awọn ọlọpa digboluja ati awọn ọmọ ologun si wa ni ṣẹpẹ lati pa ina wahala to ba ṣeeṣe ko ṣuyọ.
awon adari ile igbimo asofin kẹ́sán
Alukoro ileeṣẹ ọlọpaa ipinlẹ Anambra, Haruna Mohammed, to fidi ọrọ naa mulẹ ṣalaye pe kọmiṣọnna ọlọpaa nipinlẹ naa ti ni ki ẹka ileeṣẹ ọlọpaa to n ri si ọrọ ọdaran bẹrẹ iwadii kikun lọri iṣẹlẹ naa.
Ọgọsan aṣoju ṣofin lo wa nibi ti Gbajabiamila ti kede erongba rẹ niluu Abuja.
    Èmi náà mú àdá, ó di ọ̀nà ìyààrá rẹ̀.
Ẹ wo bí ọlọ́gbọ́n ti í kú bí òmùgọ̀.
Mikaaya bá dá a lóhùn pé, “O óo rí i nígbà tí ó bá di ọjọ́ náà, tí o bá sá wọ yàrá inú patapata lọ, láti fi ara pamọ́.
"A le sun asun f'orile osuka bayii.
Ó sì gé mi kúrò bí aṣọ tí wọ́n gé kúrò lórí òfì.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Aisha Buhari: Ìyawó ààrẹ padà délé láyọ̀ láti Dubai 11 Òkùdu 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 23 Ògún 2020 Oríṣun àwòrán, @AishaBuhari Ọkọ̀ Bàálù mi rí ìdámú nínú afẹ́fẹ́ ṣùgbọ́n.
NaijaTV gbe sita wi pe, igba meji ọtọọtọ ni pasitọ naa fipa ba oun lo pọ.
 ""Nitori akitiyan ati ifarajin yin ni mo ṣe di ọmọ Naijiria akọkọ ti yoo di asojuṣofin nilẹ Amẹrika."
Awọn obinrin ti ofin naa ti dẹyẹ si sọ wi pe ofin orilẹede Naijiria n fi wọn ṣe ẹru lorilẹede wọn.
Ogbeni victor Olabintan to jẹ aṣoju ẹgbẹ APC to gbegba oroke ni tirẹ sọ pe inu gbogbo ọmọ ẹgbẹ APC dun pupọ si abajade esi idibo naa.
le ni egberun meta ti owo ori won din die ni adota Milioni Naira; Gallon ororo ti owo ori re din die ni
Joy Nunei dá awuyewuye silẹ̀, Buhari pinnu láti túṣu dé ìsàlẹ̀ ìkòkò lórí ìdàgbàsókè Niger Delta
Wọn ko jẹ ki awọn akẹkọọ to pọ jeun papaọ mọ Denmark Awọn naa dẹwọ ilana isede wọn ni aarin osu Kẹrin bi awọn ile ẹkọ ti se bẹrẹ isẹ pada tohun ti bi awọn obi kan se n bẹru pe ajakalẹ naa le tun jẹyọ lẹẹkeeji.
Blasphemy against Mohammed: Olórin Kano Yahaya Shariff-Aminu tí wọ́n dájọ́ ikú fún ti pe ẹjọ́ kòtẹ́milọ́rùn
Ahmed ti fi lede bayii pe oun ti jawọ ninu ero bẹẹ, nitori o ti han gbangba pe iru ero bẹẹ ko dara rara, ati wi pe ko fihan pe oun fẹran Hanan.
Báwo ni o ti túmọ̀ rẹ̀?
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Akojọpọ esi ayẹwo aarun Covid-19 ni orilẹ-ede Naijiria gẹgẹ bi ajọ NCDC ṣe n kede rẹ.
Naijiria ń ṣe ìrántí àwọn ọmọ ógun tó ṣubú lójú ìjà Wo òfín tuntun tí INEC ṣe fún ìdìbò 2019 Wo àwọn tó dipò ìlú mú tí wọ́n jẹ́jọ́ lórí dúkìa Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Oduduwa Alphabet: òmìnira èdè ti dé fún Port Novo báyìí Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Ọwọ ologun tẹ Bashir to pa ṣọja l'Okenne nipinlẹ Kogi Eko: Awọn Babalọmọ yoo maa gba isinmi ọsẹ meji Ọlayẹmi ni bi oun se padanu owo ileewe oun si inu eto sogundogoji igbalode MMM lo faa ti oun fi n sa kaakiri lai ri ọna abayọ.
Awọn onimọ ni oorun ni oogun to jẹ ọfẹ julọ, eyi to lee fun ara rẹ ni ilera to peye julọ, lẹyin iwadi imọ ijinlẹ to le ni aadọta ọdun, wọn ko lee beere mọ nipa awọn ohun ti oorun sisun lee mu wa fun wa, bikose pe ka beere pe, n jẹ nkankan wa ti oorun sisun ko lee se fun wa?
Ko dabi ti eleyi ti Biden ja Trump kalẹ daada.
Oríṣun àwòrán, Twitter/Aisha Buhari Sugbọn o jọ gate ko jọ gate, awọn ileesẹ iroyin Naijiria kan sọ pe ọrọ yii ko sẹyin bi ọkan lara awọn amugbalẹgbẹ aarẹ Buhari kan ti se dari si Aso Rock lati irinajo si ipinlẹ miran ni Naijiria.
“Ṣugbọn OLUWA bínú sí mi nítorí yín, kò sì gbọ́ ẹ̀bẹ̀ mi.
" Aláàfin gbé àṣẹ kalẹ̀ láti dènà àtúnṣẹ̀ ìṣẹ̀lẹ̀ 'Soka'nílùú Ọ̀yọ̀ Aṣa Igba Titi yii, ti wọn tun maa n pe ni Yúgbá, lo saba maa n waye ni aafin ọba Ọyọ tabi ni aafin awọn ọba alaye miran, to fẹran aṣa ati iṣẹṣe wa.
Gbé ìwé rẹ wá, bí ó bá wù mí èmi á búra, bi kò sì wù mí èmi kò ní í búra.
Adeniji fikun pe, ẹni ti ọkọ naa lọ gbe ni ẹjẹ ruru ni ẹru ba ba awakọ rẹ.
Ọlọ́pàá ní Kasali ko jẹ́ ki Sherifat lọ gba ìtọ́jú lẹ́yin ìjà náà.
O yẹ kawọn mejeeji tun jọ koju ara wọn lẹẹkan si lọjọ kẹẹdọgbọn oṣu keje ṣugbọn iṣede ajakalẹ aarun coronavirus ko jẹ ki ija naa waye.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Christmas: Jesu ni ọjọ́ ọ̀la àti ibi ìyanu mi- Jaga Koda, awọn dokita ati awọn oṣiṣẹ to ku gbọdọ bura pe ọrọ kankan nipa idibo naa ko ni i ti ẹnu awọn jade, tabi lo ẹrọ ayaworan ati gbohun-gbohun.
PDP Oludije fun igbakeji aare fun egbe oselu PDP Peter
Mo sọ fún wọn pé, n kò ní fọwọ́ mi kàn ọ́, nítorí pé ẹni àmì òróró OLUWA ni ọ́.
Ajíbogun dúró níbi tí a ń pè ní Iléṣa lónìí yìí, òun sì ni Ọwá Iléṣà kìíní.
Ọsẹ to kọja ni ijọba Madagascar ko agbo naa ránṣẹ si awọn orilẹ-ede ilẹ Afrika yooku.
Bode Thomas Ọmọ Yoruba to ba n gbe ilu Eko yoo ti gbọ orukọ Bode Thomas ri.
Diezani gan an ní Hushmummy tó ń bú àwọn Yahoo boys- Àwọn Ọmọ Naijiria lórí Twitter Iná jó àwọn ènìyàn 10 tó ń gbà ìwòsàn arùn Coronavirus níbùdó ìtọ́jú Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, BBC Africa Eye: ìwádìí ìkọ̀ks BBC fihàn pé àwọn kan ń jí ohun èèlò ìdáàbòbò ìjọba tà nígbo Baba rẹ, Muhammadu Indimi jẹ oniṣowo ọmọ Naijiria.
Sunny Ade ń se ọjọ́ ìbí, Obey kí i kú oríire Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ọdunlade Adekọla gbóṣùbà fáwọn ọkùnrin tó ń ran ìyàwó wọn lọ́wọ́ Joke Silva bẹ̀rẹ̀ iṣẹ́ eré ìtàgé rẹ̀ lati ọdún 1990, ọdún 1998 ló ṣe fíìmù tó gbée síta, to si gba àmì ẹyẹ oṣèrè tíàtà tó dara julọ.
'Mo lè fi ẹsẹ̀ mi jẹun, fọṣọ, mó tún lè fi gbá ẹni tó bá ṣẹ̀ mí létí' Mo fẹ́ máa kọ Classical"" lédé Ijebu, Hausa, Igbo Pidgin - Abiodun Koya 'Olódo ni mí nílé ìwé kí n tó ṣàwárí ẹ̀bùn mi' Mo fẹ́ 'rebrand' àwọn area boys ìpínlẹ̀ Ọyọ ni - Bolanle Sarumi Aguntaṣọọlo Afeez gba awọn obi nimọran lati ma gbe ọmọ wọn lọ fun ayẹwo nile iwosan ti wọn ba ti kẹ́fín ohunkohun ti ko ri bo ṣe yẹ lara rẹ."
Gba ẹbọ ìyìn àtọkànwá mi, OLUWA,kí o sì kọ́ mi ní ìlànà rẹ.
Akọwe Agba Ilẹ Gẹẹsi, Jeremy Hunt lo sọ eyi lasiko to n se abẹwo si ikọ omoogun to wa ni Maiduguri lati fi atilẹyin wọn han.
 Won ti fi erongba won han lati pada sile won, ati pe, Aare oun ba won kedun ipo ti won wa naa, ni eyi ti o fi dami loju pe, ijoba yoo gbe igbese ni kankan , lati ri daju, won tu ile awon  asafogun naa se.
''Mo n gbiyanju aje bayii, ko sẹni to ri mi, amọ nigba to ba ya, ti mo gbe aworan ọpọ ile mi sori ayelujara, wọ̀n yoo la ẹnu ẹlẹya wọn pe ‘gomina kan‘ abi ‘aarẹ kan’ lo ra ile awosifila, ọpọ ọkọ ayọkẹlẹ ati awọn ilegbe fun mi.
O péye ninu gbogbo ọ̀nà rẹ, láti ọjọ́ tí wọ́n ti dá ọ títí di ìgbà tí a rí ẹ̀ṣẹ̀ lọ́wọ́ rẹ.
Ó ṣe aiṣootọ sí OLUWA Ọlọrun rẹ̀.
Má sọ èdè Heberu mọ́, nítorí pé àwọn tí wọ́n wà lórí odi ń gbọ́ ohun tí ò ń sọ.
Ẹwẹ, ọrọ ati gba kaadi idanimọ ẹgbẹ awọn ọkunrin ahun lo jẹ awọn kan logun ni tiwọn.
Ní ọjọ́ náà, gbòǹgbò Jese yóo dúró bí àsíá fún àwọn orílẹ̀-èdè, òun ni àwọn orílẹ̀-èdè yóo máa wá.
O doloogbe ni ọjọ kọkanlelogun, oṣu keje, ọdun 2020.
Arsenal ti gba adehun pẹlu Dortmund ati ọmọ ẹgbẹ agbabọọlu orilẹede Gabon, Aubameyang ti o jẹ ọmọ ọdun mejidinlọgbọn.
Somaliland kede ominira fun orile ede tire lodun 1991 sugbon ti ajo isokan agbaye ko ti I gba a wole.
Ẹ̀yin fúnra yín jẹ́rìí mi pé mo sọ pé, ‘Èmi kì í ṣe Kristi náà, ṣugbọn èmi ni a rán ṣiwaju rẹ̀.
“Ṣugbọn bí o kò bá gbọ́ ti OLUWA Ọlọrun rẹ, tí o kò sì pa àwọn òfin ati ìlànà rẹ̀ mọ́, bí mo ti fi lélẹ̀ fún ọ lónìí, gbogbo àwọn ègún wọnyi ni yóo ṣẹ sí orí rẹ tí yóo sì mọ́ ọ.
Gẹgẹ bi orilẹ-ede South Africa ṣe ń lewaju loriṣiriṣi ọna nilẹ Afirika bẹẹ si ni lọwọlọwọ, wọn tun ti ṣe tan lati dari Afirika lọ si ipele to lewu lasiko Coronavirus yii ọna igbogunti Covid 19 ti wọn gunle.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, #Queen Dihya: Obinrin tó gbógun tàwọn agbésùnmọ̀mí ni Algeria Gauri jagun fun igba diẹ ki olori ikọ ogun rẹ to tuu silẹ lataari ilera ara rẹ ti ko pé.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ẹ̀mí kan náà ló n darí ìrìnàjò wa táa fi jọ kọ́lé papọ̀- Ìbejì Ẹgbẹ awọn ọdọ ati ọmọ Yoruba ati Igbo bii Ohanaeze pẹlu ẹgbẹ awọn ọdọ naa ti kilọ fun ile aṣofin pe ko jawọ lori aba ọhun.
’’Egbe naa wa pe fun suuru lati yanju isele naa “Nigba ti a n ba awon to ku ati awon ti won padanu ebi ati ore  won nibi isele yii kedun , a tun wa n ro awon  elesin ati adari ilu lati fi iwa adari han ,paapaa julo lasiko ipenija yii, ki won si  rọ awon ti oro  naa kan , pe ki won maa dajo lati owo ara won, bakan naa, ni ki won sora fun awon oro ati ihuwasi ti o le mu ki iru isele yii tun sele.
Tabi tí ó bá fi ohun ìjà olóró lu arakunrin rẹ̀ tí ẹni náà sì kú, apànìyàn ni, pípa ni wọn yóo pa òun náà.
Ẹgbẹ́ òṣìṣẹ́ nàá wá n bèérè fún sísọ owó oṣù wọn di ẹgbẹ̀rún mẹ́rìndínlọ́gọ́ta Naira.
Ko pẹ sira, ni oṣu to tẹle e ni gomina Seyi Makinde fi ikede sita pe oun ko ni i mọ, oun ti bọ to si dupẹ lọwọ awọn eeyan atawọn igbimọ to n moju to iṣẹlẹ Covid-19 ti wọn n gbadura fun un.
" Wahala to wa nibi jijẹ ki agbabọọlu tun tun ko kọkọ mọ ọwọ ikọ tuntun lo faa ti Mourinho ko fi nifẹsi ọja kara-kata agbabọọlu tosu kinni.
Wọ́n ti fòfin ọdún márùn ún de Aàrẹ̀ CAF, Ahmad Ahmad Iwulo ere idaraya Kegel fun awọn ọkunrin Oriṣiriṣi nkan lo ma n din agbara ẹya ara 'pelvis' ku.
Ajọ ti o ṣe iwadi lati gbe abajade naa sita, ti Bill Gates ati iyawo rẹ Melinda da silẹ lo ti n ṣe afihan ọrọ iṣẹ ati iya ni agbaye lati ọdun 2000.
Eyi ni ero agbẹjọro kan, Mohammed Ghali Alaaya ti o ba ile iṣẹ BBC Yoruba sọrọ lori ọrọ yi.
Wọn kò gbọdọ̀ mú oúnjẹ, tabi igbá báárà lọ́wọ́, tabi kí wọn fi owó sinu àpò wọn.
Lára àwọn àkànṣe isẹ ti ijọba si lo ṣe koko náà, tí wọn fẹ gbọ bùkátà wọn nínú owóya ọhun, lo wa ni ẹka eto ìpèsè ohun amusagbara, iwakusa, eto ọgbin, eto ìlera, ìpèsè omi tó ṣeé mú àti eto ẹ̀kọ́.
Wọn á gbàgbé wọn láàrin ìlú,ẹnikẹ́ni kì í ranti orúkọ wọn mọ́,bẹ́ẹ̀ ni ẹni ibi ṣe é wó lulẹ̀ bí ìtì igi.
Itaporogan laarin gomina Makinde atawọn alaga kansu labẹ aṣia ALGON ni ipinlẹ Ọyọ bẹrẹ ni kete lẹyin ti wọn bura wọle sipo fun Makinde gẹgẹ bii gomina ipinlẹ Ọyọ.
Orúkọ mejila ti àwọn aposteli mejila ti Ọ̀dọ́ Aguntan wà lára wọn.
Ọjọ kejila, oṣu Kọkanla, ọdun 2020, ni ijọba orilẹ-ede United Kingdom, ti fesi si iwe ẹsun ti awọn ọmọ Naijiria kọ si.
Bí àwọn kan sẹ gbàgbọ́ pé ọgbọ́n arékérekè ni Fayose n dá, ni àwọn kan ni ìfìyà jẹ ni ìṣẹ̀lẹ̀ nàá.
Ọkọ̀ òfurufú Boeing 737 jábọ́ ni kété tó gbéra ní pápákọ̀ òfurufú ni orílẹ̀-èdè Iran Okọ ofurufu to gbera ni Tehran ọhun jẹ ti orilẹ-ede Ukraine International Airlines lo ti jabo ni kopẹ kopẹ to gbera kuro ni Iran.
Ifipagbajọba ti ṣẹlẹ lọpọ igba nilẹ Afirika, ṣugbọn ọna lati fipa gbajọba iru eleyi ko wọ pẹ mọ.
Fasiti University of Ghana lo ti kẹkọ gboye imọ ofin lọdun 1993.
Oyún ṣíṣẹ́: Wíwá òògun ìsẹ́yún lórí àyélujára peléke síi
 tíátà ayé ìsinsìnyí ni ó tún kún fún òtítọ bí ó tilẹ ́ jẹ ́ pé ó pín sí oríṣiiríṣi ọ ̀ nà .
Ìtàn àwọn ọmọ rẹ̀, ati ọpọlọpọ àsọtẹ́lẹ̀ tí a sọ nípa rẹ̀, ati bí ó ti tún ilé Ọlọrun ṣe wà, tí a kọ ọ́ sinu ìwé Ìtàn Àwọn Ọba.
Àwọn alátakò olórín náà ni pé, ó fi Anọ́bi wọlẹ̀ ni nítori pé ó gbé orúkọ Imamu kan ga jú orúkọ Ànọ́bì Muhammed lọ` Baba Obasanjọ kò ní àrùn Coronavirus- NCDC Ìdí rèé tí igbákejì Gómìnà Ondo Agboola Ajayi tún ṣe fi ẹgbẹ́ òṣèlú PDP sílẹ̀ Ìyàwó Bukola Saraki fún tìyá-tọmọ olójú búlúù ní N250, 000!
Egypt to ṣi ni ibẹrẹ Oṣu Keje sọ pe awọn eniyan gbọdọ ni iwe eto ilẹra ti wọn yoo fihan awọn oṣiṣẹ ajọ aṣọbọde ni papakọ ofurufu.
Kete ti aworan wọn yii jade sita lawọn kan ti n sọ pe o ṣe afihan pe awọn to n pariwo ija laarin awọn oloṣelu ni lati lọ yẹ ara wọn wo.
Ẹ̀kọ́ ńlá: Ìtàn Gbọnka àti Timi, akọni méjì tó borí Aláàfin Ṣango Ajọ FRSC ṣèlérí láti fọwọ́ òfín mu eegun tó bá tasẹ̀ àgẹ̀rẹ̀ lásìkò ọdún Keresi Ìyàwó mi kórira kí Odunlade Adekola máa bú mi nínú eré tíátà - Ijebu Ibú-owó Bloomberg fẹ́ ta kànùngbọ̀n pẹ̀lú Trump nínú ìbò ààrẹ Amẹrika Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Illegal Rehab Centre: A le ni ogójì tí wan n kó 'sinú ìyará kékeré kan níle Ọlọrẹ Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Wọn ni awọn fun ajọ NBC ni wakati mẹrinlelogun pere ki wọn fi gbesẹ kuro lori ọrọ ileeṣẹ igbohunsafẹfẹ AIT ati Ray Power.
Ka to ni ka maa sinmi lori eto idibo ti ko ni kọnu nkọhọ ninu la gbọ pe ọwọ awọn ọlọpaa tẹ ọkunrin kan to dibo nigba mọkandinlaadọrun ni Kumba to wa ni ẹkun Guusu Iwọ Oorun Cameroon.
Oríṣun àwòrán, Others Iya naa ni bi ọrọ ṣe ṣẹlẹ ni wi pe oun ni oun ma n gbe ọmọde olorin naa lọ si ibi to ti n kọ ẹkọ orin kikọ nitori ọmọde olorin naa n kopa ninu awo orin tuntun.
yii wa fun awọn ti o ni aisan oju ti ko si le riran daradara, ki wọn baa le
olopaa lorile ede yii lati lee gbogun ti iwa igbesunmọmi,  ipaniyan ati awon iwa odaran miiran to sẹlẹ  ni awon apa ibikan lorile ede yii ,paapaa julọ
Ní kete ti ija ọhun bẹrẹ bayii, ẹgbẹgbẹrun obinrin lo sọ ara wọn di agabatẹru iwa ipa pẹlu awọn obinrin.
Àwọn ajínigbé jí adarí ìlú Daura gbé Agbébọn tún ya bo abule Moriki ní ìpínlẹ̀ Zamfara Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí kan sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
Ó sì gbọ́ ohùn kan láti ọ̀run tí ó wí pé, “Ìwọ ni àyànfẹ́ ọmọ mi, inú mi dùn sí ọ gidigidi.
Ijọba orilẹede Madagascar ti sọ tẹlẹ pe agbo naa n dena coronavirus, bakan naa lo n wo aisan naa.
Oríṣun àwòrán, Daily trust Nigba to n fidi iṣẹlẹ yii mulẹ fun BBC Yoruba, agbenusọ fun Ileesẹ ọlọpaa ipinlẹ Osun, Yemisi Opalola ni ọpẹlọpẹ awọn araalu kan to raga bo ọba ọhun, ti ko jẹ káwọn ọdọ ji gbe lọ.
Eyi yoo mu ki iye ti ijọba n na lori eeyan kọọkan lekun si ẹgbẹrun meje naira 7,000.
Èmi ni mo dá ìmọ́lẹ̀ ati òkùnkùn,èmi ni mo dá alaafia ati àjálù:Èmi ni OLUWA tí mo ṣe gbogbo nǹkan wọnyi.
Adeboye ninu iwaasu rẹ to pe ni ''Ki Olorun dide'' ni o ti sọ wi pe awọn alagbatẹru wọn naa ko ni kadun.
Gbaju-gbaja ni kaakiri apa Ariwa Naijiria.
N óo kéde ohun tí OLUWA pa láṣẹ ní ti èmi ọba;Ó wí fún mi pé, “Ìwọ ni ọmọ mi,lónìí ni mo bí ọ.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ọ̀dọ́ 30 ń gba ìtọ́jú lọ́wọ́ nílé ìwòsàn torí ọ̀gbẹ́ ìbọn ní Lekki - Sanwo-Olu ṣàlàyé Àwọn ṣọ́jà ṣíná ìbọn bolẹ̀ ni Lekki Tollgate Àwọn ọlọ́dẹ darapọ̀ mọ́ ìwọ́de #EndSARS l'Osogbo, wọ́n ní kò sáyè fún jàǹdùkú mọ́ Kíní ìtumọ̀ ''Sọ̀rọ̀ Sókè'' tí àwọn afẹ̀họ́núhàn EndSars ń lò káàkiri Ìpínlẹ̀ Ogun náà ti ilé ìwé títí dí ọjọ́ Ajé tó m bọ̀, kò ní sí lílọ bíbọ̀ ọ̀kádà fún wákàtí 24 Nilu Eko, Ibadan ati Plateau, awọn janduku to ja iwọde gba mọ awọn oluwọde EndSARS lọwọ dana sun awọn agọ ọlọpaa kan.
Wọ àwòrán àwọn ẹbí òṣèré Nollywood yii!
 Eyi ni ipe awọn opo nipinlẹ Ọṣun lasiko ti awọn aadọjọ opo kan n tẹwọ gba ohun elo amayedẹrun nipinlẹ Ọṣun."
Ó ní ìwo meji bíi ti Ọ̀dọ́ Aguntan.
"tsẹ ́ kì olómìnira ( tsẹ ́ kíà ; ; , , short form "" Česko "" ) je orile-ede ni arin europe ."
Bakan naa ni awọn eniyan ke irọra pẹlu sunkẹrẹ-fakẹrẹ ọkọ ti awọn ọlọkọ ajagbe da silẹ ni ọpọpọna afara Eko Bridge ni ibi to tun yẹ ki awọn eniyan ma a gba kọja.
Ẹmi mi se pataki si mi.
Local Government Autonomy: Ìgbésẹ̀ àjọ NFUI kò bá òfin mu rárá
Wọ́n ní, “Ṣebí ará Galili ni gbogbo àwọn tí ó ń sọ̀rọ̀ wọnyi?
Ikọlu ti iran ṣe si ibudó Irbil àti Al Assa wáye ni ààrọ kùtùkùtù ọjọrú.
Ẹ ranti OLUWA Ọlọrun yín nítorí òun ni ó fun yín ní agbára láti di ọlọ́rọ̀, kí ó lè fìdí majẹmu tí ó fi ìbúra bá àwọn baba yín dá múlẹ̀, bí ó ti rí lónìí.
ọba sọ fún Hasaeli, ọ̀kan ninu àwọn iranṣẹ rẹ̀ pé, “Mú ẹ̀bùn lọ́wọ́, kí o sì lọ bá wolii náà, kí o sọ fún un pé kí ó bá mi bèèrè lọ́wọ́ OLUWA bóyá n óo yè ninu àìsàn yìí.
Ilẹ̀ tí òkúta rẹ̀ jẹ́ irin, tí ẹ óo sì máa wa idẹ lára àwọn òkè rẹ̀.
Balaamu tún sọ fún Balaki pé, “Èmi ń lọ sí ilé mi, ṣugbọn jẹ́ kí n kìlọ̀ fún ọ nípa ohun tí àwọn eniyan wọnyi yóo ṣe sí àwọn eniyan rẹ ní ẹ̀yìn ọ̀la.
"- Ọọ̀ni Ife Botilẹjẹ wi pe agbẹjọro rẹ bayii, Asad Jamal sọ fun ileeṣẹ iroyin AFP pe awọn yoo pe ẹjọ kotẹmilọrun, niṣe ni awọn agbẹjọro to rojọ tako Hafeez n pin nkan ipanu fun awọn akẹgbẹ wọn, to n pariwo ""Allahu Akbar"" ati ""iku ni fun awọn to ba sọrọ odi""."
 iṣẹ ́ ọkọ ̀ ojú omi ( navigation ) ni ó ń ṣe .
(Ní ogoji ọdún tí Dafidi dé orí oyè, wọ́n ṣe ìwádìí nípa ìran Heburoni, wọ́n sì rí àwọn ọkunrin tí wọ́n lágbára ninu ìran wọn ní Jaseri ní agbègbè Gileadi).
Ki Ọlọrun ki o bawa lọọra ẹmi wọn ki wọn tubọ pẹ fun wa.
 irúfẹ ́ àwọn orin náà fara pẹ ́ òrìṣà kan pàtó .
Àkọlé àwòrán, Igbakeji gomina tuntun ni ipinlẹ Eko ati mọlẹbi rẹ.
Mose yan àwọn ọkunrin tí wọ́n lè ṣe alákòóso ninu àwọn eniyan Israẹli, ó fi wọ́n ṣe olórí àwọn eniyan náà, àwọn kan jẹ́ alákòóso fún ẹgbẹẹgbẹrun eniyan, àwọn mìíràn, fún ọgọọgọrun-un eniyan, àwọn mìíràn, fún araadọta, àwọn mìíràn fún eniyan mẹ́wàá mẹ́wàá.
Nítorí náà, àwọn iranṣẹ rẹ̀ wí fún un pé, “Kabiyesi, jẹ́ kí á wá ọdọmọbinrin kan fún ọ, tí yóo máa wà pẹlu rẹ, tí yóo sì máa tọ́jú rẹ.
Awọn onimọ sayẹnsi ni fasiti Oxford naa ni ọkan awọn balẹ nitori aṣeyọri nla lo jẹ fun awọn, ti arun Coronavirus naa ko si ni pẹ lọ si okun igbagbe.
Oríṣun àwòrán, Nigeria Presidency Owo isuna ọdun to n bọ naa ni wọn gbe le pasipaarọ owo naira ilẹ wa si Dọla tilẹ Amẹrika, eyi tii se naira ọrinlelọọdunrun o din kan (₦379) si dọla kan.
 won gbe lo si eto alumoni ati idagbasoke irin ni 2008 , nigba to si di april 2010 o je yiyansipo bi alakoso eto petroliom .
Àyipadà Òṣèlú kúrò ninú iwà burúkú ni ó lè mú ki owó ilú (Naira) kògè.
Ìdí tí ó fi kẹ̀yìn sí Solomoni nìyí:Nígbà tí Solomoni fi ń kún ilẹ̀ tí ó wà ní apá ìlà oòrùn Jerusalẹmu, tí ó sì ń tún odi ìlú náà kọ́, 
ṣugbọn bí ó bá ṣẹ́kù di ọjọ́ kẹta, sísun ni kí ó sun ún.
Bí ibi tí olówó ẹran ọ̀sìn yìí ń gbé bá jìnnà jù, tabi tí ẹ kò bá mọ ẹni náà, ẹ níláti fa ẹran ọ̀sìn náà wálé, kí ó sì wà lọ́dọ̀ yín títí tí olówó rẹ̀ yóo fi máa wá a kiri.
"Lẹ́yìn gbogbo làásìgbò tó wáyé lọ́sẹ̀ tó kọjá.
Akinwumi Isola tun kọ́ ọ́pọ́ iwe miran fun igbadun awọ́n ololufẹ́ ede Yoruba ki ọlọ́jọ́ to mu agba ajẹ̀ naa re ibi agba n re!
 Agbenuso ile-ise ologun oun tun salaye pe, “ijewo re yii lo sokunfa bi a se fi owo sinkun mu odaran miiran, Irambariye Mamman, eni ti o so pe, oun ni adari awon odo, ti o tun je adari egbe naa.
Ìjọ ni ara Kristi, Kristi ni ẹ̀kúnrẹ́rẹ́ ohun gbogbo.
hu , ti ireti wa pe yoo di ṣiṣi silẹ laarin oṣu Kẹwaa si oṣu Kọkanla ọdun 2020, lati fi orukọ silẹ.
fun awon agbẹjọro rẹ to wa ni orile ede Saudi Arabia  lati fọwọsowọpọ pẹlu orile ede Naijiria lona
Wọn le lo ọna mẹrin yii lati kopa ninu idibo naa: Fifi atẹjiṣẹ ranṣẹ lati ori ẹrọ foonu alagbeka.
Moshood Kashimawo Abiola jáde láti di ààrẹ orilẹ̀-èdè Naijírìa, ti Bahir Tofa náà si ta ko o latinu ẹgbẹ oselu miran, Abiola ri ìbò tó pọ láti ìhà Arewa, bákan náà ní wọn dibo fun ni iha Iwọ-òòrun Guusu nítori pe ó jẹ Yoruba.
Gbogbo ìjọ àwọn ọmọ Israẹli wà níbẹ̀, ọba bá yíjú pada sí wọn, ó sì gbadura fún wọn.
Nigba to n ba igbimọ eto abo lajọ iṣọkan agbaye sọrọ, Ọgbẹni Beasley ṣalaye pe gbogbo agbaye gbọdọ ṣe giri pẹlu igbesẹ to yẹ lori ọrọ yii.
 apá ìtàn kan sọ wípé olú-Ìwà , tí ó tẹ ilẹ ̀ Ìjéú fó ni ó mú agèmọ wó ilẹ ̀ Ìjẹ ̀ bú ní ǹkan bí ọdún 900 a.
Alaafin bi ibeji l‘ẹẹmeji lọsẹ kansoso Kí ló ń ṣẹlẹ̀ láàfin Oyo táwọn èèyàn fi ń ki Alaafin ní mẹ́sàn án mẹ́wàá?
Lati jẹ ki wọn ri itọju to peye, ki ofin si tun wa ti yoo gbe e lẹyin ati didaabo bo wọn lọwọ idẹyẹsi, ati ki awọn agbanisiṣẹ maṣe fọwọ rọ wọn sẹyin bi wọn ba yege fun iṣẹ naa.
Àṣírí tó ń bẹ láàrín èmi àtàwọn ọ̀dọ́ Iwo tí wọ́n fi fi ẹ̀mí wọn lélẹ̀ dáàbò bo ààfin mi rèé Ni ọjọ Satide ni iroyin kan pe awọn eeyan kan ti kọlu olu ileeṣẹ ijọba ibilẹ Iwo ti wọn si ba a jẹ kanlẹ.
Osun cow death: Iṣẹ̀lẹ̀ tó wáyé kò ni dá wàhálà sílẹ̀ láàrin àwa àti àwọn Fulani.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ruga settlement: YCE ní ìjọba àpapọ̀ kò tó bẹ̀ẹ́ láti kọ́ àgọ́ Fulani sílẹ̀ Yoruba Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Ruga settlement: YCE ní ìjọba àpapọ̀ kò tó bẹ̀ẹ́ láti kọ́ àgọ́ Fulani sílẹ̀ Yoruba 27 Òkùdu 2019 Lẹ́yìn awuyewuye tó ń ṣẹ̀lẹ̀ lórí ìgbésẹ̀ ìjọba àpapọ̀ láti bẹ̀rẹ̀ sí ní kọ àgọ́ Fulani ti wọ́n pè ní 'Ruga settlement' ní Ipinlẹ Benue, Ìgbìmọ̀ àwọn àgbààgbà Yorùbá ti fèsì.
Akojọpọ awọn ọmọ Kaarọ Oojire to ba ọdun 2020 lọ: Abiola Ajimobi: Oríṣun àwòrán, twitter/Ajimobi Àkọlé àwòrán, Abiola Ajimobi ninu aṣọ ibilẹ nibi eto kan ni ilu Ibadan Iku doro, iku ṣeka ni ariwo ti ọpọlọpọ ara ipinlẹ Oyo atawọn ọmọ Naijiria lapapọ mu bọnu nigba ti gomina ipinlẹ Oyo tẹlẹri, Abiola Ajimobi jade laye.
Ó bá tún kúrò, ó la agbègbè Galatia ati ti Firigia já, ó ń mú gbogbo àwọn ọmọ-ẹ̀yìn Jesu lọ́kàn le.
Sharapova fikun-un pe,“Isise po olodun merin ati orisirisi idojuko lati jo la koja lati odun merin-in seyin.
tí à ń fi orúkọ rẹ̀ pe gbogbo ìdílé lọ́run ati láyé.
‘Kàkà kín bá Saraki ṣẹgbẹ́ PDP má yà padà sí APC ’ ‘Bùhárí kùnà láti gbógun tìwà ìjẹkujẹ’ 'Èrò ọ̀dọ́ Kwara ṣọ̀tọ̀ọ̀tọ̀ lórí ọ̀rọ̀ Saraki' Sugbọn bi Aarẹ ile asofin Bukola Saraki ti se kede wi pe oun ti kuro ninu ẹgbẹ apc lọ si PDP, nise ni gbogbo awọn asoju to fi mọ Funke Adedoyin to salaisi naa sun tele.
Jehoṣafati fi ṣugbọn kan kún ọ̀rọ̀ rẹ̀ pé, “Jẹ́ kí a kọ́kọ́ wádìí lọ́wọ́ OLUWA ná.
 wọ ́ n fi ayé ni í lára .
Ajimobi: A gùnlé ìdájó ilé Ẹjọ́ àkọkọ lórí ẹjọ Ajimobi
Òfin kan náà tí ó de àlejò, ni ó gbọdọ̀ de onílé, nítorí pé èmi ni OLUWA Ọlọrun yín.
O si le di iya Ọba ni ọjọ kan."
Kinni idi abajọ ti ẹyẹle ṣe wọn to bẹẹ?
Ikú Djxgee: DJsosogee ní olóògbé fẹ́ràn ẹbí àti ọmọ
Ọpọlọpọ eniyan ni wọn si ti pa lori ẹsun pe wọn n ba awọn ohun to nii se pẹlu oyinbo tabi ijọba orilẹede naa ti wọn n sọ wi pe o n ba oyinbo se pọ.
”Nisinsinyii, OLUWA, Ọlọrun, ati Ẹ̀mí rẹ̀ ti rán mi.
Ẹnikẹ́ni kò ní máa kọ́ aládùúgbò rẹ̀ tabi arakunrin rẹ̀ bí a ti í mọ èmi OLUWA mọ́, gbogbo wọn ni wọn yóo mọ̀ mí ati àwọn mẹ̀kúnnù ati àwọn eniyan pataki pataki.
"O tun fa oju awọn ọdọ ilu gan mọra, o ni ""mo fẹ́ sọ àwọn Area Boys di ọmọ mi"" o ni ki awọn ọdọ ma jẹ ki oloṣelu kankan lo wọn nilokulo mọ ti ""wọn ko si fun un yin niṣẹ tabi ki ẹ tilẹ̀ le fẹ ọmọ wọn ṣugbọn tọrọ kọbọ ni wọn fi n gun yin lọwọ bi ẹ ba ti dibo tan wọn a tun rọọ yin sẹyin""."
a rí àwọn olóyè bí ìwàrèfà , ní òyọ ́ ni a ti ń pè wọ ́ n ní Ọ ̀ yọ ́ -mèsì .
Má ṣe kọ̀ fún ẹni tí ó bá fẹ́ yá nǹkan lọ́wọ́ rẹ.
Isọwọ pa ni lẹrin rẹ kọja afẹnusọ.
Balogun tí ó wà fún oṣù kẹjọ ni Sibekai, ará Huṣa, láti inú ìran Serahi; iye àwọn tí wọ́n wà ninu ìpín rẹ̀ jẹ́ ọ̀kẹ́ kan ó lé ẹgbaaji (24,000).
Ọkàn wọn kò dúró ṣinṣin lọ́dọ̀ rẹ̀;wọn kò sì pa majẹmu rẹ̀ mọ́.
BBC Yoruba kan si ẹka ibi iṣẹ fun ede Yoruba, Yoruba Language Centre ni ọgba ẹlẹranko Fasiti ni Ibadan lati mọ bi eto ẹkọ ede Yoruba naa ṣe n lọ si.
Ni kete ti aisan naa bẹrẹ lo si lọ si ileewosan nibi to dakẹ si.
Iforukọsilẹ fun gbogbo isọri tẹsiwaju titi di ọjọbọ ọjọ kẹẹdogun oṣu kẹwaa ọdun 2020 ko to pari.
Bakan naa, gomina Sanwoolu ṣepade pẹlu ọga agba awọn ọlọpaa to si ni oun gbagbọ pe ipada de oun lati Abuja yoo so eso rere latu fopin si iwa ipa awọn ọlọpaa.
Lẹ́yìn náà ó ni ki filásayépọ̀ pe iwin inú fila rẹ̀ fun òun, onítọ̀ún sì ṣe bẹ́ẹ̀.
Awọn Boko Haram maa ń wo ìròyìn púpọ̀ Àwọn Boko haram maa ń gbọ iroyin gbogbo nkan to n ṣẹlẹ ni agbaye.
Olúwa dáhùn sí ẹbẹ̀ ọkàn rẹ̀ nípa fífúnni ní ìfihàn yìí.
Bí a ti gbé àwòrán ti ẹni erùpẹ̀ wọ̀, bẹ́ẹ̀ gan-an ni a óo gbé àwòrán ti ẹni ọ̀run wọ̀.
Ṣaaju ija ọhun, gbajugbaja, abẹṣẹ ku bi ojo, Joshua ti sọ pe oun ti gbaradi fun ija ọjọ Abamẹta.
Olùfẹ́ mi ló ni mí,èmi ni ọkàn rẹ̀ sì fẹ́.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fọ́nrán ohùn, Lẹ́yìn ọ̀pọ̀lọ́pọ̀ oṣù tí òjò kò rọ̀ ní orílẹ̀èdè Cuba, Ọba ilẹ̀ Yorùbá ló Ṣugbọn lẹyinorẹyin, ọkan lara awọn to daba pe ki wọn pe Aarẹ, Ahmed Jaha ni o ti di ọranyan ki Aarẹ yọju sile naa, ti awọn aṣoju miran si ṣegbe lẹyin rẹ ki gbogbo ile to gba aba ọhun wọle.
Ìran Etani títí lọ kan Lefi nìyí: ọmọ Kiṣi ni Etani, ọmọ Abidi, ọmọ Maluki; 
"O le ma kari gbogbo eniyan ṣugbọn yoo ṣi rin jina""."
Kini ìdí ti Italy fi Fariga: Mínísítà Italy fún ọ̀rọ̀ abẹ́lé, Matteo Salvini, ni orílẹ̀-èdè Italy sọ pe, apá ibi tí wọ́n ti kó àwọn arinrìnàjò ọ̀hún súnmọ́ orílẹ̀-èdè Malta ju Italy lọ.
6 13368 Orilẹede Andorra 78 101.
Osibogun ni ìjà láàrin ọ̀rẹ́ ni, kìí ṣe láàrin ẹgbẹ́ YWC, nítori naa ọ̀rọ̀ tó ṣẹ́lẹ̀ kò lè da ẹgbẹ́ ru nítori kò sí ǹkan ti kò le dìjà láàrin ọ̀rẹ.
" Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Blind Couples: Pẹ̀lú ìpèníjà ojú, tọkọtaya bímọ mẹ́ta, tí wọn sì tún ń ṣiṣẹ́ olùkọ́ Nigba ti awọn akọrọyin kan si agbẹnusọ ileeṣẹ LLC, Veronica Jacob, o ni oun ko ni ọrọ kankan lati sọ nipa awọn iloro naa lọwọ yii.
Katsina  Bello Masari n ba awon akoroyin
Àwọn yòókù yóo pada, àwọn yòókù Jakọbu yóo pada sọ́dọ̀ Ọlọrun alágbára.
Ẹ sá pamọ́ fún ọjọ́ mẹta, títí tí wọn óo fi pada dé.
Òun ni yóo pọn ọtí ibinu ati ti ẹ̀san Ọlọrun Olodumare.
” O fikun un oro re pe,“Mo n sekilo gege bi mo se ma n se
Bí irun ọ̀gangan ibẹ̀ bá di funfun, tí àrùn náà bá jẹ wọ inú ara ẹni náà lọ, tí ó jìn ju awọ ara rẹ̀ lọ, àrùn ẹ̀tẹ̀ ni.
mo yára, bẹ́ẹ̀ ni n kò lọ́ra láti pa òfin rẹ mọ́.
Ẹkunrẹrẹ wa ninu ohun ti a ka silẹ loke yii.
“Nítorí ọpọlọpọ ni a pè, ṣugbọn àwọn díẹ̀ ni a yàn.
O ni kikọlu awọn dukia ati araalu yoo tubọ mu ki ipinya wa laarin wọn ni, eleyii to si lee da omi iṣọkan aarin wọn ru.
Ọ̀rọ̀ ti Olówó-ayé kọ sí inú ìwé ti ọmọ rẹ̀ kà fún mi ni yóò jẹ́ apá kejì ìwé yìí, ọ̀rọ̀ rẹ̀ náà ni ìwọ̀nyí:
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ó ní ìdí tí mo fi ń padà sí PDP"" Ikọ̀ ẹlẹ́sìn Hàkíkà rèé, níbití wọn ti ń pààrọ̀ ìyàwó láàrín ara wọn Atagitá Fẹ́mi Aníkúlápó-Kútì bá obìnrin lọ l‘Amẹ́rika Pásítọ̀ àti Ìmàámù yóò gba owó osù lọ́wọ́ ìjọba Àwọn ọmọ Iyabọ Ojo rí Bàbá lẹ́yìn ọdún mẹ́fà Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ìbaàrún pe ọdún kan O wa jẹjẹ lati sisẹ tọkan-tara pẹlu awọn olori orilẹ-ede yoku fun ipese eto aabo to duro re, alaafia , isejọba rere ati igbaye-gbadun araalu pẹlu eto ọrọ aje to mu yan-yan, ki ẹkun iwọ oorun Afrika lee ni idagbasoke to yẹ."
ó kan ààbà mọ́ ọ lẹ́sẹ̀,ó sì ń ṣọ́ ìrìn rẹ.
Nibayii, ijọba ipinlẹ Edo ti paṣẹ ofin konile-o gbele ọlọjọyipo kaakiri ipinlẹ naa.
Àkọlé àwòrán, Aarẹ Buhari tako iwa ajẹbanu, iwa ibajẹ ati asa sise atipo laarin awọn adulawọ Buhari rọ awọn asaaju Afrika lati yee fi owo fa oju awọn agbebọn mọra Ninu ọrọ rẹ nibi eto ifarakinra ọhun, Aare Buhari gba awọn olori orilẹede nilẹ Afrika nimọran lati ma se ba awọn janduku ati agbesunmọmi to jẹ pe isẹ wọn ni lati maa domi alaafia ilu ru dunadura, tabi ki wọn maa fi owo fa oju wọn mọra.
Hasaeli di ogoji ẹrù ràkúnmí tí ó kún fún oniruuru ohun rere tí ó wà ní Damasku, ó lọ bá Eliṣa.
Kí ni kí á wí nígbà náà?
Nítorí Kristi kú lẹ́ẹ̀kan ṣoṣo fún ẹ̀ṣẹ̀ wa; olódodo ni, ó kú fún alaiṣododo, kí ó lè mú wa wá sọ́dọ̀ Ọlọrun.
Embassy: À kò ni dási ọ̀rọ̀ ìdìbò Nàìjíríà 21 Ẹrẹ̀nà 2019 Oríṣun àwòrán, US Embassy Àkọlé àwòrán, A ń wo Nàìjíríà gẹ́gẹ́ bíi àdarí gbogbo ilẹ̀ Afirika tó kù, nítori náà ó ṣe pàtàkí láti jk àwokóṣe rere.
ti won tun kun won lowo loju ogun.
Nisinsinyii, oluwa mi, níwọ̀n ìgbà tí OLUWA wà láàyè, gbogbo àwọn ọ̀tá rẹ ati àwọn tí wọn ń ro ibi sí ọ yóo dàbí Nabali.
Bakanaa ni ẹsẹ iya ọmọkunrin to jalaisi ọhun tun ha sinu ile ẹru kan, toto ẹsẹ bata ogun, ti wọn so pọ mọ ọkọ akẹru to jabọ lori afara Kara bọ sinu odo ogun to wa labẹ afara naa.
Kò gba ẹnu Buhari láti tàbùkù ará Abuja - PDP Buhari, fí mí jẹ olùrànlọ́wọ́ pàtàkì fépo rọ̀bì- Guru Maharaji Air pollution: Nàìjíríà ni orílẹ̀ède kẹrin tí atẹ́gùn búburú ti ń pa ènìyàn jù làgbáyéé Ilé aṣòfin Ekiti ní kí àwọn alága ìjọba ìbílẹ̀ dá N3.
Bẹ́ẹ̀ ni OLUWA ṣe fọ́n wọn káàkiri sí gbogbo orílẹ̀ ayé, wọ́n pa ìlú náà tí wọn ń tẹ̀dó tì.
OLUWA yóo mú kí orí àwọn obinrin Jerusalẹmu pá;yóo ṣí aṣọ lórí wọn.
Ta ni yóò wá jẹ́ alámọ̀dájú náà?
Ní àkókò yìí, ohun tí ó jẹ́ àṣà àwọn ọmọ Israẹli nígbà tí wọ́n bá ń ṣe ètò ìràpada ati pàṣípààrọ̀ ohun ìní ni pé ẹni tí yóo bá ta nǹkan yóo bọ́ bàtà ẹsẹ̀ rẹ̀, yóo sì kó o fún ẹni tí yóo rà á.
Àwọn obinrin náà sọ ohun gbogbo tí a rán wọn fún Peteru ati àwọn ẹlẹgbẹ́ rẹ̀ ní ṣókí.
O pa àwọn àjèjì lẹ́nu mọ́;bí òjìji ìkùukùu tií sé ooru mọ́,bẹ́ẹ̀ ni o ṣe dá orin mọ́ àwọn oníjàgídíjàgan lẹ́nu.
Ṣugbọn gbogbo wọn bẹ̀rẹ̀ sí pariwo pé, “Mú eléyìí lọ!
Gẹ́gẹ́ bí baba ti rán mi níṣẹ́, bẹ́ẹ̀ ni mo rán yín.
Ò kìlọ̀ ffún wa dáadáa nítorí tí ó wí pé nígbà tí a bá dé ìlú wọn ṣe ni a ó máa rí onírúurú ejò tí wọ́n á máa siré kiri tí wọn ó máa ta ọjà tí wọn ó sí máa ra ọjà lójú wa.
Ẹkú ayájọ́ òmìnira orílẹ wa o.
Ṣé ẹ̀ ń gbẹ̀san nǹkankan lára mi ni?
Lilo àti Eric náà o gbẹ́yìn, kódà ìfẹnukẹnu ti wọ́n ni ọ̀pọ̀ àwọn olólùfẹ́ wọ́n ń rojọ́ le lórí jùlọ lálẹ́ ọjọ́ sátide, èyí kò ṣẹ̀yìn bi àwọn méjèèjì yìí ṣe ti bẹ̀rẹ̀ eré ìfẹ́ wọ́n ni kété ti wọ́n ti wọ ilé ẹlẹ́gbọ̀n àgbá lọ́sẹ̀ tó kọ́já Lẹ́yìn àríyá alẹ́ ọjọ́ sátida àwọn ọmọ ilé elẹ́gbọ̀n àgbà ko pari fàájì wọ́n síbẹ̀, sùgbọ́n alẹ́ ọjọ́ Aiku ní a o mọ ẹni àkọ́kọ́ ti yóò fi ilé ẹlẹ́gbọ́n àgbà sílẹ̀.
Ọwọ́ ọlọ́pàá Ogun tẹ afurasí apaàyàn tó ń ṣọṣẹ́ ní Ogere ati Iperu 'Orísúnmibáre ni àìsàn 'Polio' tó kọlù mí ní kékeré' Kayode ni oun o kabamọ rara pe oun da akọroyin naa lohun bi oun ṣe sọrọ.
Nigba ti oun naa n salaye ohun to gbe de ile ọmọ alaigbọran naa, Tọpẹ Collins Owonifaari salaye pe awọn eeyan kan ti oun ko mọ lo gbe nilu Eko, ti oun si ba ara oun nibudo to dọti naa, nibiti wọn ko awọn papọ si bii ẹran.
 lákọkọ ́ kòsí àwọn aamì .
Wọ́n fẹ̀sùn kan igbákejì gómìnà ìpínlẹ̀ Ondo lórí ayédèrú ìwé ìdìbò níbi ìdìbò abẹ́lé PDP tó ń lọ lọ́wọ́ Ikú ti yọ́wọ́ òṣèré Nollywood Yorùbá, Yusuf Satia l'áwo Òru òní ní ìjọba á ti afárá 'Third Mainland' ní Eko; Wo àwọn ọ̀nà míràn tí o leè gbà lẹ́yìn tí wọ́n bá tìí Wo àwọn ọ̀nà míràn tí o leè gbà lẹ́yìn òru òní tí àtúnṣe afára Third Mainland á bẹ̀rẹ̀ Ọpọ eeyan lo n kọminu boya ijọba Naijiria ati ti ipinlẹ eko le kaju iṣoro to le tẹlẹ titi afara nla yii pa lasiko yii.
Ṣé mo lè fún ọmọ mi lọ́yàn, tí ẹ kò bá gbà kíni ìdí?
Nígbà tí wọ́n dé aṣálẹ̀ yìí, wọ́n pàgọ́ wọn siwaju òkè Sinai.
Oríṣun àwòrán, Olaniyi Afonja/Facebook Àkọlé àwòrán, Olaniyi Mikail Afonja gan an ni Orukọ ti baba ati iya sọ ẹni ti ẹ mọ si Sanyẹri ninu ere Yoruba.
Mo gbéra, mo sọ̀kalẹ̀ láti orí òkè wá, mo sì kó àwọn tabili náà sinu àpótí tí mo kàn, wọ́n sì wà níbẹ̀ bí OLUWA ti pàṣẹ fún mi.
Awọn ẹsun naa, to jẹ onikoko mẹrin naa lo ni nkan ṣe pẹlu iwa ajẹbanu ati jẹgudu-jẹra, eyi to n fa awuyewuye lori ayelujara.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Omiyale Ile Ife: Dukia sọfọ, awọn eniyan si tun farapa Ajọ to n woye ayipada oju ọjọ ni orilẹ-ede Ghana ti sọ pe ọpọ ojo lo ṣi maa rọ sii lọdun yii ni Ghana.
Biya ti pe ẹni ọdun marundinlaadọrun.
Awon omo egbe to kere julọ
Gbajúmò òṣèré tíátà, Ogun Majek ń ṣàìsàn líle, ó sì nílò ìrànwọ́ owó yín- Foluke Daramola Àwọn Ìpínlẹ̀ tí coronavirus kò tíì dé ní Nàìjíríà, àti ìgbésẹ̀ tí wọ́n ń gbé láti dènà rẹ̀ Olori awọn oṣiṣẹ ni ileeṣẹ Aarẹ lorilẹede Naijiria, Abba Kyari ju awa silẹ, o dagbere faye lalẹ ọjọ Ẹti lẹyin to ba arun COVID-19 wọ iyaaja ṣugbọn ti ko lee bori.
Nígbà tí Jehu dé Jesireeli, Jesebẹli gbọ́; ó lé tìróò, ó di irun rẹ̀, ó sì ń yọjú wo ìta láti ojú fèrèsé ní òkè.
Ope pataki lowo awon ami ayo ti o waye lati owo agbaboolu
@JasmineEsset naa n gbarata pe se a tun maa sanwo ori fun lilo ẹrọ ibaraẹnisọrọ lati fi owo ransẹ ni?
”Aare Vaz ni inu oun dun fun imoran ti aare Buhari gba oun, o wa dupe lowo ijoba ati omo orile ede Naijiria fun bi won se gba oun towo-tase.
Yoruba Films: Iṣẹ́ amòfin tí mo kọ́ ni Fáṣítì kò mú owó wọlé fún mi bíi iṣẹ́ tíátà
Olusola Ayandele, PhD - O yege5.
gba oṣiṣẹ onipele Keje (GL 07) tabi ju bẹẹ lọ sẹnu iṣẹ ijọba ibilẹIgbimọ naa yoo ni agbara lati
Oríṣun àwòrán, Fellipe Abreu Àkọlé àwòrán, Posi ọkọ ofurufu ree, oku ọmọde ni wọn maa fi n sin ni Ghana.
Ó pada wọlé tọ Eliṣa lọ, ó sì kígbe pé, “Yéè, oluwa mi, kí ni a óo ṣe?
Muhammadu Buhari: Ààrẹ Buhari tìrìn àjò dé lẹ́yìn àbẹ̀wò sílẹ̀ Gẹẹsi
Ìpínlẹ̀ Oyo àti Osun sàlàyé ìdí tí wọn kò fi tí ṣè ifilolẹ ìgbìmò igbẹjọ aṣemáṣe SARS Buhari, jáde bá ọmọ Nàíjíríà sọ̀rọ̀, orí àgbá ẹ̀tù la dúró lé - NUJ pariwo N kò ní buwọ́ lu ìṣúná tí kò pèsè owó fún ẹ̀bí àwọn tó kú nínú ìwọ́de EndSARS - Gbajabiamila Kò sáyè iwọ́de mọ́ l'Eko ẹ lọ tọwọ́ yín bọṣọ - Ọlọ́pàá Awọn eniyan gboogi wo lo ti ''Sọrọ Soke'' ni Ilẹ Yoruba?
Ó fi ọkà tí ó rí han ìyá ọkọ rẹ̀, ó sì fún un ní oúnjẹ tí ó jẹ kù.
ó sì sọ àwọn eniyan náà di ẹrú rẹ̀ jákèjádò ilẹ̀ Ijipti.
Ẹ gbọdọ̀ máa pa gbogbo ìlànà mi mọ́, kí ẹ sì máa tẹ̀lé gbogbo òfin mi.
ijamba to waye ni Damasak ni ipinle Borno lojo keji osu kinni odun 2019 ,
Àwọn akópa tó ti jáwé olúborí ní BBNaija sẹ́yìn àti ibi tí wọ́n wà báyìí O tó gẹ́; A kò fẹ́ ìwòkuwò mọ́ ní Nàijíríà- Runsewe (NCAC) Músò!
Nibi ipolongo idibo ọhun to waye ni gbagede Skypower field ni Ikeja nilu Eko ni wahala ti bẹ silẹ ni nnkan bii agogo kan abọ ọsan lasiko ti gomina Akinwumi Ambọde fi wa lori pepele nibi ti o ti n sọ ọrọ rẹ.
tí OLUWA ti ran àwọn ọmọ Israẹli lọ́wọ́ láti gbà jẹ́ ilẹ̀ tí ó dára fún ẹran ọ̀sìn, àwa iranṣẹ yín sì ní ẹran ọ̀sìn pupọ.
Ní oṣù keje ni Iṣimaeli, ọmọ Netanaya ọmọ Eliṣama dé, ìdílé ọba ni ó ti wá, ó sì jẹ́ ọ̀kan lára àwọn ìjòyè ọba.
Ó sàn kí ẹ pa mí ju kí ẹ ba oko tí mo gbin igbó sí jẹ́ lọ- Afurasi Clement sí NDLEA ìkà ni àwọn Ọlọ́pàá Nàìjíríà, wọ́n fìyà ẹ̀ṣẹ̀ àìmọ̀dí jẹ́ mi fún ọdún 17- Adebayo Ojo Mo ṣetán láti fi ẹ̀ṣẹ́ dín dòdò ìyà fún Anthony Joshua- Efe Ajagba Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí MKO Abiola: Ọwọ́ ọlọ́pàá tẹ àwọn olè tó kó góòlù àti ẹgbẹ̀lẹ́gbẹ̀ mílíọ̀nù lọ nílé Abiola l'Eko4 Owewe 2020 6:18 Fídíò, Akomolede: Bolaji Faleke ni Olùkọ́ tó ń kọ́ wa ní àṣà oge ṣiṣe lórí BBC Yorùbá, Duration 6,181 Owewe 2020 Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí kan sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
Ejo lo gb'owo mi ni Naijiria, anabọ lo kowo lọ ni Burundi
“Sibẹsibẹ mo fojú àánú wò wọ́n, n kò pa wọ́n run sinu aṣálẹ̀.
 bí àwọn agbè wọ ̀ nyí ṣe tóbi sí ni a ṣe fún wọn lórúkọ .
Dafidi dá a lóhùn pé, “Ijó ni mò ń jó, níwájú OLUWA tí ó yàn mí dípò baba rẹ ati gbogbo ìdílé rẹ̀, láti fi mí ṣe alákòóso Israẹli, àwọn eniyan OLUWA.
Eeyan 3826 lo ti ri iwosan gba, nigba ti awọn 342 ti papoda nitori arun ọhun.
Wọn tun fi sita loju opo twitter wọn yatọ si pe wọn sọ fun BBC lori ẹrọ ibanisọrọ.
Ẹnikẹ́ni kò sì gbọdọ̀ máa wo iṣẹ́ kiri tabi kí ó di aláfọ̀ṣẹ tabi oṣó; 
''Bi ẹ ba kaakiri ilu, ẹ ko ni gbọ ariwo lori bi wọn ti ṣe yọ wọn niṣẹ nitori awọn naa mọ pe ojoro ni iṣẹ ti wọn fun wọn.
(Nigeria Association of Women Journalists, NAWOJ) se abewo si ile ise omo ogun
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Iriwisi Tunde,oludokowo lori MMM Sugbọn fun arabirin Lydia, ọrọ ko ri bee.
Mo pàṣẹ pé kí wọ́n ṣe ìwádìí, a sì rí i pé láti ayébáyé ni ìlú yìí tí ń ṣọ̀tẹ̀ sí àwọn ọba wọn.
Ìlànà kan náà ni yóo wà fún gbogbo ìjọ eniyan Israẹli ati àwọn àjèjì tí wọ́n wà láàrin yín.
Àwọn tó wà nínú ìjàmbá ọkọ̀ órí afára Otedola ń lọ ìpínlẹ̀ míì láti Eko ni - LASTMA 'Ìbọn dún láàfin Ọ̀ọ̀ni ilé ifẹ̀ lóòtọ́, ṣùgbọ́n kò séwù' Àwọn ìbejì Akeugbagold kò le rìn dáadáa mọ́ lẹ́yìn tí wọ́n dáwọn padà NCDC fikun pe awọn ipinlẹ ti ọrọ naa kan ni ipinlẹ Eko, Kano, Oyo, Edo, Katsina, Kaduna, Jigawa, Yobe, Plateau, Abuja, Gombe, Ogun, Bauchi, Nasarawa, Delta, Ondo, Rivers ati Adamawa.
 inú-rírun tàbí ìgbẹ ́ -yíyà tí kò fi bẹ ́ ẹ ̀ ní ipá lè wáyé .
"Ọkan lara awọn to kọ iwe naa, Ellen Fragaszy ni UCL sọ pe ""o se e ṣe ki a ri itura díẹ̀ lasiko ooru""."
com/yPeELwS2kq— The NFF 🇳🇬 (@thenff) June 28, 2018.
Lọsẹ yii, aya Adeyemo ni yoo maa kọ wa lẹkọọ nipa Isọri ọrọ ninu gbolohun Yoruba ati itumọ rẹ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Awakọ̀ àti ọmọ mẹta mọribọ nínú ìjàmbá ọkọ l'Eko 31 Ọ̀pẹ̀̀ 2018 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 1 Sẹ́rẹ́ 2019 Ijamba ọkọ kan ti waye loju ọna marose Eko si Ibadan lagbegbe Iyana Oworo.
“Ìwọ ni òòlù ati ohun ìjà mi:ìwọ ni mo fi wó àwọn orílẹ̀-èdè wómúwómú,ìwọ ni mo sì fi pa àwọn ìjọba run.
Amọ ọna lati wadi ohun gbogbo daju nipa ohun ti eto ilera sọ lori aawẹ gbigba lo mu ki BBC Yoruba kan si dokita oyinsegun oyinbo kan lati salaye boya o dara fun ara lati gba aawẹ ọlọjọ gbọọrọ bii eyi.
N óo gbẹ̀san ẹ̀jẹ̀ àwọn tí ẹ pa, n kò sì ní dá ẹlẹ́bi sí,nítorí èmi OLUWA ni mò ń gbé Sioni.
Nígbà tí Absalomu ń rúbọ lọ́wọ́, ó ranṣẹ sí ìlú Gilo láti lọ pe Ahitofeli ará Gilo, ọ̀kan ninu àwọn olùdámọ̀ràn Dafidi ọba.
Ní ẹẹkeji ni àwọn arakunrin rẹ̀ tó mọ ẹni tí Josẹfu jẹ́.
Ẹfunsetan Aniwura, obìnrin tó ju ọkùnrin lọ Baṣọ̀run Gáà, tó yan ọba mẹ́rin, pa ọba mẹ́rin àmọ́ ọba karùn-ún ló pa á Ọjọ kejila Osu kẹta ọdun 1937 ni wọn bi Ayodele Awojobi ladugbo Oshodi nipinlẹ Eko.
Wo àwọn ẹranko tí wọ́n máa figagbaga ni Egypt Kò dùn mí pé mo sọ̀rọ̀ tako Buhari -Adedayo Festus Wo ohun tuntun tó n ṣẹlẹ̀ lágboolé CAF Super Falcons gòkè odò bọ́ sípele ìkẹrìndínlógún ní France Wọn ni arun ebola wa lara awọn ẹran igbẹ bii igala, inaki, ọbọ lagido ati adan.
Ajo UNESCO pin akori ayajo naa sona meta ni eyi ti won pe okan ni sisoro lori orisii ona ikoroyin nipa ere idaraya, ona ikoroyin nipa isegbe fabo pe ibi ko ju ibi lo ati ipolongo alaafia ati idagbasoke ninu ere idararya.
" Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ọba Ilorin ló pàṣẹ pé kí ń padà sọ́dọ̀ ọkọ mi - Risikat olójú búlúù Ǹ jẹ́ o mọ̀ pé oṣù ojú ọ̀run táwọn Mùsùlùmí ń lò ti wà saájú Ànọ́bì?
Yéwándé: Ọ̀kan nínú àwọn ìyàwó Àkàngbé ni òun náà.
Ọba bá ní kí ó dúró ní ẹ̀gbẹ́ kan ná, ó bá dúró.
Èyí sì tẹ́ àwọn olórí yòókù lọ́rùn.
Bi o tilẹ jẹ pe afojusun to ga ju laye ti mo fẹ ni lati fi aworan tattoo bo gbogbo ara mi, amọ aisan ọmọ mi lo jẹ ko ya kiakia lati se bẹẹ.
Premier League: Arsenal àti Liverpool gbéná wojú ara wọn
Nítorí irú ènìyàn tí Buhari ń ṣe àti èrò wípé yóò gbógun ti ìjẹgúdújẹrá àti ìgbáwọlẹ̀ ẹgbẹ́ afẹ̀míṣòfò Boko Haram ni àwọn ará ìlú fi gbé e sórí àlééfà.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ó parí ni ohùn tó gbẹnu ọ̀pọ̀ ọmọ Nàíjíríà lẹ́yìn ọ̀rọ̀ Buhari Ìwọ́de EndSARS kìí ṣe ọ̀rọ̀ ẹlẹ́yàmẹ̀yà, ara ti kan àwọn èèyàn ni - Afenifere Buhari kọ́ ni ìṣòro wa, bó ṣe wà láti láéláé rèé - Fr Mbaka Àwọn ọ̀dọ́ fi ọ̀nà àrífín pe Tinubu lórí aago àmọ́ ó ní òun kò mọwọ́-mẹsẹ̀ nípa ìpànìyàn Lekki Á ràgà bo CCTV Lekki bí i ẹ̀rí tó dájú fún ìwádìí ìpànìyàn - Sanwo-Olu SERAP gbé ìjọba àpapọ̀ lọ ilé ẹjọ́ àgbáyé ICC lọrí ẹ̀sùn ìpànìyàn Jàǹdùkú gún ẹ̀gbọ́n mi lọ́rùn, jó ilé àti mọ́tò wa méjì, kòròfò la wà"" Olùwọ́de 12 kú ni Lekki, 38 lapapọ kú lọ́jọ́ Isẹ́gun, 56 ni àròpọ̀ àwọn tó bá ìwọ́de lọ - Amnesty International Gẹgẹ bi atẹjade naa ti wi, awọn gomina naa forikori, ti wọn si jiroro pupọ nipa eto aabo orilẹede yii, paapaa iwọde EndSARS to mu ọpọ ẹmi ati dukia lọ."
Nígbà tí ó pada dé ó bá Balaki ati àwọn àgbààgbà Moabu, wọ́n dúró ti ẹbọ sísun náà, Balaki sì bèèrè ohun tí OLUWA sọ lọ́wọ́ rẹ̀.
ni eyi ti yoo tan isoro orile ede yii.
Ní kété ti Eric àti Tochi jáde ni wọ́n ti n dúpẹ lọ́wọ́ àwọn ọmọ Naijria pé wọ́n kú àdúrótì lásìkò ti wọ́n wà nílé ẹlẹ́gbọ̀n àgbà.
"Orilẹede Amẹrika ni ko si orilẹede kan lagbaye"" "" to gbọdọ lanfani ati maa gbogun ti awọn eeyan rẹ nitori ẹsin ti wọn gba."
 oùn rẹ ̀ máa n rìnlẹ dòdò .
Awọn omiran ni ofin to nii ṣe pẹlu fifun ijọba ibilẹ lagbara ati eyi to mu
Nígbà tí Paulu di ìdì igi kan, tí ó dà á sinu iná, bẹ́ẹ̀ ni paramọ́lẹ̀ kan yọ nígbà tí iná rà á, ló bá so mọ́ Paulu lọ́wọ́.
Nínú gbogbo àwọn olóyè abìlà funfun t’Èkó, Elétùú Òdìbò ni olórí wọn.
Nebukadinesari kó gbogbo àwọn tí wọ́n kù tí wọn kò pa lẹ́rú, ati àwọn ọmọ wọn.
Ibẹ̀ ló gi mú orúkọ yìí bọ̀ tí ó sì fi sọ ilú tí òun náà tẹ̀dó.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Lockdown updates: Naira Marley gbóríyìn fún Jude Chukwuka pẹ̀lú míliọnù kan Náírà Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Lockdown updates: Naira Marley gbóríyìn fún Jude Chukwuka pẹ̀lú míliọnù kan Náírà 20 Agẹmo 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 21 Agẹmo 2020 'Lockdown' to jẹ isede lasiko ajakalẹ arun Covid 19 n bi eso rere nipa iṣẹ ati ayanmọ awọn eeyan bii Baba awon Marlians.
Tinubu gbéra lọ odidi Mecca láti lọ ṣàbòsí - PDP Ìdí tí a fi ṣe òfin tuntun fún àwọn akọ̀ròyìn tí yóò ṣiṣẹ́ nílé aṣòfin - NASS Igbesẹ yii ṣeeṣe ko fa idiwọ fun irina oju ofurufu tori ko ni si oṣiṣẹ ti yoo maa mojuto bo ṣe yẹ ki ohun gbogbo lọ ni papakọ ofurufu.
Alukoro fun ẹgbẹ oṣelu APC, Yekini Nabena, lo fi ọrọ naa lede nibi idibo abẹle ẹgbẹ ọhun lọjọ Aiku.
Ohun tawọn to mọ nipa iṣẹlẹ naa sọ ni pe ọdọbinrin yii sọna si ile ololufẹ rẹ lẹyin ọkunrin naa ti orukọ rẹ n jẹ Jude atawọn ti sun tan.
Díẹ̀ níhìn-ín, díẹ̀ lọ́hùn-ún,kí wọ́n baà lè lọ ṣubú sẹ́yìnkí wọ́n sì fọ́ wẹ́wẹ́;kí á lè dẹ tàkúté sílẹ̀ fún wọn,kí ọwọ́ lè tẹ̀ wọ́n.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ọ̀rọ̀ǹpọ̀tọ̀niyùn, Aláàfin obìnrin àkọ́kọ́ rèé, tó ní nǹkan ọkùnrin Baṣọ̀run Gáà, tó yan ọba mẹ́rin, pa ọba mẹ́rin àmọ́ ọba karùn-ún ló pa á Mọrèmi Àjàṣorò, akọni obìnrin tó gba Ilé Ifẹ̀ sílẹ̀ lóko ẹrú Wo oríṣi inú rírun márùn-ún tí o kò gbọdọ̀ pa mọ́ra Gẹgẹ ba se ka lori itakun agbaye Wikipedia, itan manigbagbe gbaa ni itan igbe aye oloogbe Duro Ladipọ, eyi to yẹ ki awọn ode iwoyi fi se awokọse ati arikọgbọn gidi.
da ijoba ati awon omo ipinle Rivers , paapaa julo awon molebi ti won padanu ebi
Ajo to n mojuto eto idibo lorile-ede Naijiria, (Independent National Electoral Commission) INEC ti kede ojoBo(Thursday), ojo ketadinlogbon osu kesan, odun ti a wayii gege bi ojo atundi ibo gomina ipinle Osun.
Wọ́n gbẹ́ àwòrán agbè ati òdòdó, wọ́n fi ṣe ọ̀ṣọ́ sára igi kedari tí wọ́n fi bo ògiri gbọ̀ngàn náà, òkúta tí wọ́n fi mọ ògiri ilé náà kò sì hàn síta rárá.
Nígbà tí fèrè dún, ó kọ, ‘Hàáà!
" Oríṣun àwòrán, @iKingMillie Alaye ọkunrin yii lo mu ki ọpọ eeyan maa ki ku oriire pe, o ba obinrin bii ọkan rẹ pade.
Kiyesara ti o ba n rinrinajo ninu ọkọ baalu Oríṣun àwòrán, others Awọn ti wọn ba n rin irinajo pẹlu ọkọ baalu gbọdọ kiyesi ara nitori ọpọlọpọ papako ni o ma n kun fọfọ, ti wọn kii si tẹle ofin ijinasiraẹni tabi lilo ibọmu.
”Ìbẹ̀rù OLUWA mú àwọn ọmọ Israẹli, gbogbo wọn patapata jáde láì ku ẹnìkan.
gbogbo ruke-rudo to n gba emi, ti o si tun ba ohun ini awon ara ilu je nipinle
Ọmọwe Adebisi ni ohun amuyangan ni Ọsun Osogbo jẹ, o si yẹ ka wa ọna lati jẹ ki ọwọ okiki ati anfaani okoowo to n mu wa maa tẹsiwaju fun ipinlẹ Ọsun ni, gẹgẹ bii ipinlẹ to n dokoowo ninu asa ibilẹ wa.
lati da si eto oko ile-ise ofurufu.
Olayinka ni Fayemi ti kọ orukọ rẹ sinu iwe itan gẹgẹ bi ẹni to n mu inira ba awọn eeyan ipinlẹ naa Ohun ti o tọ ni Fayemi ṣe,igbaniṣiṣẹ makaruru ni Fayose ṣe Arakunrin miiran to ba ikọ BBC sọrọ ti ohun naa ni ki wọn ma darukọ tirẹ naa ni ''gbogbo nnkan lo leto amọ bi ijọba ba fi oṣelu wọ gbigbani siṣẹ ko le labọ ti yoo da'' O tẹsiwaju pe ijọba Fayose ko to ri awọn eeyan ṣeto igbanisiṣẹ ati pe awọn to fun ni iṣẹ naa ko fi taratara ni igbagbọ si iṣẹ naa.
Kalebu lé àwọn ìran Anaki mẹtẹẹta jáde níbẹ̀, àwọn ni ìran Ṣeṣai, ìran Ahimani, ati ìran Talimai.
” Ọba dáhùn pé, “Elija ará Tiṣibe ni.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ọ̀rọ̀ ajé dẹnu kọ̀lẹ̀ yíká Nàíjíríà, àkẹ́kọ̀ọ́, olókoòwò àti òṣìṣẹ́ ọba jókòó sílé Ẹlẹ́wọ̀n 200 sálọ lọ́gbà ẹ̀wọ̀n Benin lásìkò ìwọ́de EndSars Ìjọba da ológun sí Abuja láti dẹ́kun ìwọ́de Mo fura pé ẹ fẹ́ da Nàíjíríà rú, ń kò ṣe ìwọ́de mọ́ - Segalink, agbátẹrù ìwọ́de yọwọ́ Ìwọ́de EndSARS gboró n‘Ibadan, kò sẹ́ni tó le wọlé tàbí jáde Buhari, ìwọ́de yóò yíwọ́, tó gbá jẹ́ káwọn ológun bá bẹ̀rẹ̀ ‘Operation Crocodile Smile’ "" Ìjọba Eko pàdánù ₦234m láàrín ọ̀sẹ̀ kan torí ìwọ́de End SARS Bí o bá fẹ́ darapọ̀ mọ́ ikọ̀ ọlọ́pàá SWAT tí yóò rọ́pò SARS, wo àmúyẹ tí o gbọ́dọ̀ ní Ẹbẹ ni ki ẹ ba wa bẹ ijọba: Olukọ ati oludari ile ẹkọ girama kan nilu Ibadan, ti BBC Yoruba ba sọrọ lori iṣẹlẹ yii, Ọmọwe Ayoyinka Babatunde ni awọn ko le da awọn oluwọde lẹbi."
Moabu yóo parun, kò ní jẹ́ orílẹ̀-èdè mọ́,nítorí pé ó ṣe ìgbéraga sí OLÚWA.
Akọwe ijọba, Wole Oyebamiji lo fi ọrọ naa lede nilu Osogbo pe igbeṣẹ naa yoo bẹrẹ lati ọjọ Abamẹta, ọjọ kejidinlọgbọn, oṣu kẹta ọdun 2020.
pe fun ajo to n mojuto eto idibo INEC, lati mu eto idibo naa waye nirowo-rose.
Gbogbo àwọn àmì tí Samuẹli sọ fún un patapata ni ó sì ṣẹlẹ̀ ní ọjọ́ náà.
CHRD sọ wípé fún wákàtí kan gbáko, àwọn ọlọ́pàá padà láti yẹ ilée Deng wò, wọ́n sì kó àwọn ẹ̀rọ lóríṣiríṣi:
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Báyìí ni Aguero ṣe gbá góòlù keji wọ àwọ̀n Watford.
ṣugbọn nisinsinyii, ẹ sá àsálà lọ sí Sioni, ẹ̀yin tí ẹ̀ ń gbé Babiloni.
Nígbà tí ó rí ọ̀pọ̀ eniyan náà, àánú wọn ṣe é nítorí wọ́n dàbí aguntan tí kò ní olùṣọ́, tí ọkàn wọn dààmú, tí ó sì rẹ̀wẹ̀sì.
Won fi esun kan Aare  Gurib-Fakim pe, o lo kaadi owo ajo kan ti kii se ti ijoba ti a mo si Planet Earth Institute, ra oja ti o le ni ogbon owo dollars $30,767,fun ohun elo ara re.
Oníṣẹ́ kan wá ròyìn fún Dafidi pé, “Ọkàn gbogbo àwọn ọmọ Israẹli ti ṣí sí ọ̀dọ̀ Absalomu.
Orilẹ ede naa ni a mọ si eyi ti o ni ojuko ibi omi ti o dara fun igbafẹ ati pẹpẹ atijọ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Àwọn ọ̀dọ́ Naijiria ti sọ̀rọ̀ síta lórí ohun ti wọ́n ń retí lọ́dọ̀ minista tuntun Ta ni Akintoye ninu oṣelu Naijiria?
Zainab so pe,” awon fojusona lati kopa ninu idije boolu afigigba ti o gbayi julo torile-ede Naijiria lodun 2019.
Èkó ṣe àjọ̀dún lóri agbami – Lagos celebrate on the Ocean
ajo INEC fun gudugudu meje, yaya mefa ti  won n se ni ipinle naa .
O ti lé ní ènìyàn mẹ́wàá tí ina jó gúrúgúrú nínú ìjàmbá tó wáyé ní Delta Ṣé lóòtọ́ ni pé Hushpuppi ti kúrò ní ọgbà ẹ̀wọ̀n l'America?
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Painter: Samuel ni ìdàgbàsókè Nàìjíríà ló jẹ òun lógún!
Ko si fun ikansiraẹni Bi o ba n gbọ ohun ti a ka silẹ ohun ti yoo kọkọ wa si ọ lọkan ni oju opo ikansiraẹni Whatsapp nibi tawọn eeyan ti maa n lo ohun ti wọn ka silẹ fi ba ara wọn sọrọ.
O jẹ ọmọ orilẹede France, o si tun dun un wo l'ọkunrin.
Awon osise iko ohun, ti o fimo awon akonimoogba won gbogbo, pelu agbaboolu mefa ni o side ipago ohun lojo Aje(Monday), kii awon yooku o to wa darapo mo won,Ni bayii, awon agbaboolu ti o ti wa ni kale ni: Francis Uzoho, Kenneth Omeruo, Elderson Echiejile, Stephen Eze, Abdullahi Shehu, Chidozie Awaziem, midfielders Joel Obi, John Ogu, Ogenyi Onazi, Uche Agbo, Wilfred Ndidi, Ahmed Musa, Moses Simon, Odion Ighalo, Kelechi Iheanacho ati Victor Moses.
ijoba apapo lorile ede Naijiria, Godwin Emefiele.
O si wu mi ki n kawe di dokita onisegun oyinbo, amọ bi eyi ko ba ṣee se, mo fẹ kawe gba oye ọmọwe PhD, ki n si di ọmọwe dokita.
Gbogbo agbo ẹlẹ́dẹ̀ bá dorí kọ gẹ̀rẹ́gẹ̀rẹ́ òkè náà, wọ́n sáré lọ, wọ́n sì rì sómi.
''Bi wọn ṣe debẹ lawọn ọdọ ilu doju kọ awọn ọlọpaa pẹlu ọbẹ.
7%) awọn obirin to ko arun naa lo jade laye.
Akọ́bi ilé náà tí ńjẹ́ Àdánwò ló sì fẹ́.
Lẹ́yìn èyí, Samsoni rí obinrin kan tí ó wù ú ní àfonífojì Soreki, ó sì fẹ́ ẹ.
"Oríṣun àwòrán, Instagram/officialoluboropa_of_iboropa Lori ọrọ ifẹ pẹlu ọkunrin, Adele Olúbọ̀rọ̀pa ni ""lootọ ni awọn ọkunrin n wa mi wa amọ n ko gbọdọ ba ara mi jẹ nipa nini ibalopọ gẹgẹ bii Adelé nitori eewọ nla ni, asa wa ko gba ki n lo ifẹ ikọkọ tabi sun mọ ọkùnrin."
Eyi jẹ jade ninu ọrọ ti oluranlọwọ pataki fun aarẹ, Garba Shehu fi sita eyi to sọ ọjọ́ ti aarẹ yoo lọ ati ọjọ ti yoo pada sile.
Ọdọọdun ni sapo n ruwe o, yoo maa wa bi ẹwa ni.
Desmond Eliot ni ki awọn gbajumọ lawujọ ati awọn oloṣere ki wọn ye sọrọ kubakugbe lori ayelujara mọ, amọ ki wọn lọ gba kaadi idibo wọn, ki wọn dibo fun ẹni ti wọn fẹ ninu eto idibo to n bọ,a bi ki awọn furawọn dije dupo.
Nígbà tí Samila kú, Ṣaulu ará Rehoboti lẹ́bàá odò Yufurate gorí oyè.
" chabas gba ẹbùn prix national ní ọdún 1899 ní paris salon pẹ ̀ lú "" joyeux Ébats "" rẹ ̀ ."
"O ni pe ""O ba ni lọkan jẹ pe ijọba apapọ ko kọbi ara si iwa ipanijaye ti o gbode kan lorilẹ-ede wa."
Buhari ni yoo maa je alaga fun ipade igbimo ipinle ti yoo waye ni ile-ise aare
Ó gba Solomoni ní ogún ọdún láti kọ́ tẹmpili OLUWA ati ààfin tirẹ̀.
Nítorí pé mo jẹ́rìí rẹ̀ pé ó ti ṣiṣẹ́ pupọ fun yín ati fún àwọn tí ó wà ní Laodikia ati ní Hierapoli.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Mama Arsenal: Màmá àgbà yìí máa ń lọ sí ìbùdó tí wọ́n ti ń wo bọ́ọ́lù láti wòran Ijọba ni ayẹwo fihan bayii pe, aarẹ naa ko ni arun Coronavirus, amọ o pọn dandan lati wa ni iyasọtọ ni asiko yii.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ìwádìí bẹ̀rẹ̀ l'órí ikú agbẹjọ́rò Ajah ‘Ibi a gbé dàgbà níi se pẹ̀lú ìhùwàsì wa’ Ọmọ Amẹrika mẹ́ta gba ìdáǹdè ní North Korea Ọdún méta ni àwọn agbẹjọro mejeeji fi jọ gbé ni lọ́kọláya ti wọn kò si bímọ fún ara wọn ki Otike tó doloogbe nile wón ni Daimond Estate ni Ajah nipinẹ Eko.
 Ó maa ń ṣawo kiri ní .
 ó tún ní àwọn ìwé méjì tí ó wà lọ ́ dọ ̀ rẹ ̀ tí yóò jáde ní àìpẹ ́ .
O fikun oro re pe, ede geesi ati ede faranse n figagbaga laarin ara won jake-jado agbalaaye.
Oun naa tun ni obirin akọkọ ti yoo ṣíṣẹ ni ile ifowopamọ ni orilẹ-ede Naijiria.
Ìyìn ni fún OLUWA, Ọlọrun Israẹli,lae ati laelae.
Ka àwọn ọ̀ràn ìsàlẹ̀ yìí síwájú:
Ahabu bá ranṣẹ pé gbogbo àwọn ọmọ Israẹli, ati àwọn wolii oriṣa Baali, pé kí wọ́n pàdé òun ní orí òkè Kamẹli.
 nigba tí ó ń sọ bí gbenga ṣe fun òun ní ọkọ ayọ ́ kẹ ́ lẹ ́ àkọ ́ kọ ́ tí òun kọ ́ kọ ́ ní láyé òun .
Àwọn eniyankeniyan meji tí wọ́n ya aṣa yìí jókòó níwájú rẹ̀, wọ́n sì purọ́ mọ́ ọn lójú gbogbo eniyan pé ó bú Ọlọrun ati ọba.
Ó dótì mí,ó fi ìbànújẹ́ ati ìṣẹ́ yí mi káàkiri.
Ní ọjọ́ kẹta tí Òmùgọ́dimẹ́ta joyè ni àwa náà múra tí a lọ̀ kí i gẹ́gẹ́ bí àlejò ní àgbègbè ibẹ̀.
, E:-:-:-e, Ẹlẹ́gbára ń bọ̀ lọ́nà o, ọ̀gọ lẹ́yìn aṣiwèrè, kùmọ̀ lẹ́yìn aláìgbọràn, ìjàngbọ̀n lẹ́yìn olórí kunkun, E:-:-:-e!
Mose yára tẹ orí ba, ó dojú bolẹ̀, ó sì sin OLUWA.
Wo àwárí akọ́ṣẹ́mọṣẹ́ yìí Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Awon omo ogun olote Islaamu ni awon ni won wa nidi ikolu awon jihad to n sele ni Turkey.
Mú takọ-tabo meje meje ninu àwọn ẹyẹ, kí irú wọn lè wà láàyè lórí ilẹ̀ ayé.
Everton to gbẹyẹ lọwọ Man U ti bọ si ipo keje bayii lẹyin ti wọn gbo ewuro soju Manchester United.
Igbimo Olubadan tun je ki o di mimo pe awon di oba alade
Ẹgbẹ naa ni ti awọn gomina ilẹ Kaarọ Oojire ko ba san sokoto wọn ko le lati se ohun to tọ nidi didaabo bo araalu, awọn araalu le pinnu lati maa se ohun to ba wu wọn lati daabo bo ẹmi ati dukia wọn.
Iyabo Ojo Iyabo Ojo naa fi fidio lede loju opo Instagram rẹ lati ki awọn ololufẹ rẹ ku ọdun Keresimesi.
Ìbàjẹ́ ọkàn ní ìwòsàn, a sì lè dènà ìpànìyàn.
Ṣugbọn igi àjàrà dá wọn lóhùn pé, ‘Ṣé kí ń pa ọtí mi, tí ń mú inú àwọn oriṣa ati àwọn eniyan dùn tì, kí n wá jọba lórí ẹ̀yin igi?
OLUWA tí ó yan Jerusalẹmu óo bá ọ wí!
Atẹjade naa ni titẹle awọn ilana to n dena Coronavirus nikan ni ọna lati dẹkun itankalẹ ati ọwọja arun naa.
F Odunjo jẹ aṣòfin àti mínísítà nílẹ̀ yìí, yàtọ̀ sí pé ó jẹ́ òǹkọ̀wé?
Hesekaya bá kọjú sí ògiri, ó sì gbadura sí OLUWA, ó ní, 
Immaculate Okochu: Arẹwà orí ìpolówóo Cold Stone Creamery ṣàgbàkò ikú nínú ìjámbá ọkọ̀ nígbèéyàwó ku díẹ̀
 ( his wages are ten naira per week .
Mo ti fi Sihoni, ọba Heṣiboni, ní ilẹ̀ àwọn ará Amori, le yín lọ́wọ́, àtòun ati ilẹ̀ rẹ̀.
Awọn onimọ nipa ilera si ti sọ pe inu rirun tabi didun le jẹ atọ́ka si aisan to lagbara, to si le ju bose yẹ lọ ti ko ba tete si amojuto ni ibẹrẹ pẹpẹ.
 bákannáà , àwọn àhámọ ́ tún le ní ju irú kan krómósómù lọ ; fún àpẹre , mitokọ ́ ndríà nínú ọ ̀ pọ ̀ àwọn eukarioti àti adáláwọ ̀ nínú àwọn ọ ̀ gbìn ní àwọn krómósómù kékeré ti wọn .
Àkọlé àwòrán, ẸNi ti ko ba lo ibomu yoo pada sile rẹ tabi ko jẹ bulala Nigeria lockdown: Báyìí ni àwọn ẹ̀ṣọ́ aláàbò ṣe dá ìrìnkèrindò ọkọ̀ dúró l'Abuja Iroyin lati Abuja, to jẹ Olu ilu orilẹede Naijiria ti fi han pe sunkẹrẹ fakẹrẹ ọkọ to waye nibẹ ko ṣẹyin iṣẹ takuntakun awọn agbofinro lati ri pe awọn eeyan tẹlẹ ilana ti ijọba gbe kalẹ lasiko yi.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Kogi Loan: Owó àkànṣe ìṣẹ́ ìjọba àpapọ̀ tíjọ́ba Kogi ṣe la fẹ́ dá padà 15 Ọ̀wàrà 2019 Oríṣun àwòrán, @A_Oshiomhole Aarẹ Buhari ti kọ lẹta si ile aṣofin agba lati beere owo to le ni biliọnu mẹwa naira fun ipinlẹ Kogi.
Láàárín ọ̀sẹ̀ kan náà, ìròyìn ikú obìnrin kan ni ó jáde láti ilé-iṣẹ́ Amóhùn-máwòrán Gbogboògbò orílẹ̀-èdè Angola tí ó ní wípé ọ̀rẹ́kùnrin ìgbà-kan-rí obìnrin náà ni ó gún un pa.
Oni, ọjọ kọkanlelọgbọn, oṣu karun un ọdun ni gbogbo agbaye ti tẹwọgba gẹgẹ bii ọjọ ayajọ pipa taba to ti jẹ oogun to dara fun ilera nigba kan ri rẹ.
Ṣugbọn nígbà tí wọ́n jáde, ńṣe ni wọ́n ń pòkìkí rẹ̀ káàkiri gbogbo agbègbè náà.
Ti eeyan ba si dakẹ, tara rẹ yoo ba dakẹ ni, mo si fẹ ki gbogbo ọmọ Naijiria gba mi lori iya to fi jẹ mi.
Pẹlu iye awọn eeyan tuntun yii, o ti pe 56,604 eeyan to ti ni arun naa l'orilẹede Naijiria bayii.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Grandma Maruwa: Ó yẹ kí obìnrin sisẹ́ láì wojú ọkọ kó tó jẹun Ko si ohun ti awọn kẹẹkẹ wọn yi fi yatọ si eyi ti awọn eeyan ma n wọ ni Naijiria, bi ko ṣe pe awọ ewe ni wọn kun awọn ọkọ naa.
Ìwọ ọkàn mi, kí ló dé tí o fi rẹ̀wẹ̀sì?
Bákan náà ni ó rí ní àkókò ti Lọti.
Nígbà tí wọ́n dé ọ̀dọ̀ Jesu wọ́n ń bẹ̀ ẹ́ pé kí ó tètè.
Lọdun 2013, o le ni biliọnu kan naira ti wọn fi tun apa kan Wo ohun tí Adájọ́ sọ nípa ìgbẹ́jọ́ Wòlíì Sotitobire l'Ondo Afárá Third mainland gba ẹ̀gbọ́n Ìgbésẹ̀ wo ní aláboyún lé gbé láti dẹ́kun ìjẹkújẹ nínú oyún?
Ìgbátí ìgbámú àná látọwọ́ sọ́jà obìnrin ti bá arákùnrin náà dé iléèwòsàn Ìjọba ìpínlẹ̀ Eko fún ẹbí àwọn ọlọ́pàá tó pàdánù ẹ̀mí lásìkò ìwọ́de EnSARS l'ẹ́bún owó 10 mílíọ̀nù Àrún ibà pónjú-pọ́ntọ̀ bẹ́ sílẹ̀!
Ìmọ̀ràn tèmi ni pé kí o kó gbogbo àwọn ọmọ ogun jọ jákèjádò ilẹ̀ Israẹli láti Dani títí dé Beeriṣeba, kí wọ́n pọ̀ bíi yanrìn etí òkun.
Ti ọrọ ba kan ẹsẹ ti wọn a fi yọ aarẹ nipo, orisirisi ni awọn ẹṣẹ naa, ti o si jẹ pe ohun ti ile ba panupọ pe o jẹ ẹsẹ aṣemaṣe naa ni wọn yoo fi yọ aarẹ nipo.
Oloogbe Pius Adesanmi ni ogbontarigi olukọ ati onkọwe ọmọ Naijiria to fi Canada ṣe ibujoke to dollogbe nibi ijamba ọkọ ofurufu Ethiopia to waye loṣu kẹta ọdun yii.
Níbo ni àwọn oriṣa Sefafaimu wà?
tifọn ni ayẹyẹ ìdána ọmọbìnrin rẹ fi wáyé - BBC News Yorùbá BBC News, YorùbáFò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Remi Surutu: Tilu - tifọn ni ayẹyẹ ìdána ọmọbìnrin rẹ fi wáyé 4 Sẹ́rẹ́ 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 4 Ògún 2020 Oríṣun àwòrán, Instagram/@therealremisurutu Àkọlé àwòrán, Bii ọdun melo kan ṣẹyin ni osere tiata, Remi Surutu padanu ọmọ kan Yoruba bọ wọn ni bi ẹkun pẹ titi di alẹ kan, ayọ n bọ lowurọ.
Ẹ fori ji mi'' Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Báyìí ni ayẹyẹ wíwé láwàní fún ọmọ China, olóyè Zhang ṣe lọ DSP Abdullahi Haruna to jẹ alukoro ọlọpaa ni Kano sọ fun BBC pe ni nnkan bi ago mẹwa alẹ ni awọn mu Ali lẹyin ti ọwọ awọn ẹṣọ ile ẹkọ naa tẹ ẹ.
irinajo lo silẹ mimọ HAJJ (The National Hajj Commission of Nigeria ,NAHCON) ti
Ajafẹtọ ọmọniyan, Jiti Ogunye ti ni awọn oloselu ti wọn n kuro ni ẹgbẹ oselu kan lọ̀ si ẹgbẹ oselu miran ko fẹran awọn ọmọ Naijiria, ati wi pe ikun wọn ni wọn n ja fun.
ni yoo maa san owo eto ilera awọn eniyan ti o
Ìbẹ̀rù-bojo yóo mú àwọn ará Asirianígbà tí wọ́n bá gbóhùn OLUWA,nígbà tí ó bá fi kùmọ̀ rẹ̀ lù wọ́n.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù 'Òpín yóò débá ìwà jàgídíjàgan ní Ekiti' Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ 'Òpín yóò débá ìwà jàgídíjàgan ní Ekiti' 15 Agẹmo 2018 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 16 Agẹmo 2018 Gomina ti wọn sẹsẹ dibo yan ni ipinlẹ Ekiti, Kayode Fayemi, ti so pe awọn eniyan dibo yan oun nitori ìyà àti ìṣẹ́.
Nigba to n fesi lori ọrọ ti aarẹ Buhari sọ yii, alaga ẹgbẹ oselu PDP, Uche Secondus ni o ti foju han bayii pe gbogbo ọna ni Buhari n san lati wa nipo, pẹlu asẹ to pa fun awọn osisẹ ologun ati ọlọpaa naa, eyi ti yoo awọn asaaju APC maa fija jẹ awọn oludibo.
Oríṣun àwòrán, Ekiti state government Awọn oyinbo naa pe awọn ọba diẹ ti wọn raaye kesi ni Ekiti, ọba mẹrindinlogun.
tun salaye nipa ohun ti ile ifowopamo AFDB yoo se lojo iwaju .
Lẹyin eyi ni wọn tu wọn silẹ ‘Bí ẹ se gba Zainab sílẹ̀, ẹ gba Leah Sharibu lọ́wọ́ Boko Haram’ ki boko haram to mu Leah silẹ pẹlu iroyin pe o kọ̀ lati gab ẹsin Islam ni tipatipa.
Sex for grade: Òkìkí olùkọ́ fásitì OAU míràn tún ti kàn lóríi pé ó fẹ́ bá akẹ́kọ̀ọ́ rẹ̀ lò pọ̀ fún máàkì
 O ro awon omo igbimo naa lati fowosopo pelu awon oloye ki won le saseyori ninu ise ti won gbe le won lowo yii leyin to ti dupe lowo awon to yan an sipo ohun.
o wa ni agbegbe Mokola niluu Ibadan ni ipinle Oyo, ekun Gusu orile ede Naijiria.
Apapo egbe oselu alatako ti a mo si Houphouetists for Democracy and Peace (RHDP), ko ijokoo adota 50 ninu awon olujide merindinladorin 66, gege bi  akosile egbe oselu AFP, eyi ti o wa ni ibamu pelu akojopo abajade esi idibo ti ajo eleto idibo kede re.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Jesse Duplantis ni òun kó fẹ lo bàálù naa fún ará òun bi kíì ṣe fún anfààní ọmọ ìjọ Ọrọ náà ti mú iriwisi wa láti ọdọ àwọn èèyàn, tí àwọn kan sì n ka ẹsẹ bíbélì tó pé àkíyèsí sí àwon woli èké.
Ondo APC: Àṣà ojú-àwo-làwo fi ń gbọbẹ̀ kò lè wáyé l'Ondo
Nigba to n gbe idajọ oniwakati marun ati abọ rẹ kalẹ, lori ẹsun ijọmọgbe onikoko mẹfa, adajọ Odusola ni ijọ Sotitobire ko kọbi ara si isẹlẹ bi ọmọ naa, se di awati lasiko ijọsin.
Akikanju ọkunrin kan, tí orúkọ rẹ̀ ń jẹ́ Goliati, ará ìlú Gati, jáde wá láti ààrin àwọn Filistini.
A tún rán arakunrin wa tí a ti dánwò ní oríṣìíríṣìí ọ̀nà ní ti ìtara rẹ̀ pé kí ó bá wọn wá.
Ta ní Ṣe Pataki Jùlọ ní Ìjọba Ọ̀run?
Oludije fun ipo arẹ lẹgbẹ oṣelu PDP, Atiku Abubakar ti ki Adeleke ku oriire idajọ to ṣẹṣẹ gba ni ile ẹjọ.
Ṣugbọn àwọn Juu kígbe pé, “Mú un kúrò!
Ilaji ọlọpa Naijiria lo n se dongari fun oloselu
Àwọn ọmọ-ẹ̀yìn mejilelaadọrin pada dé pẹlu ayọ̀.
Won gbe oku Olori ijoba naa wa si ilu re lati orile-ede South Africa nibi ti o ti lo gba iwosan .
Oludije mejidinlaadota lo dije du ipo gomina ipinlẹ Ọṣun lọdun 2018.
Wọn á máa sọ pé: “Ẹ wá, ẹ jẹ́ kí á mu waini,ẹ jẹ́ kí á mu ọtí líle ní àmuyó,bí òní ṣe rí ni ọ̀la yóo rí, yóo dùn tayọ.
nipa itanilolobo lati odo awon eniyan  pe
 Àwọn ìlú tó kù lábẹ ́ Ẹ ̀ gbá òkè -ọnà ni ejígbo , Ìkìjà , Ìjẹjà , odo , Ìkèrèkú , Ẹ ̀ runbẹ ̀ , Ìfọ ́ tẹ ̀ , erinjà , ilogbo àti Ìkànna .
Mo rí ìlẹ̀kùn kan tí ó ṣí sílẹ̀ ní ọ̀run.
Bí ẹni náà bá tó ẹni ọgọta ọdún tabi jù bẹ́ẹ̀ lọ, bí ó bá jẹ́ ọkunrin, kí ó san ṣekeli mẹẹdogun, ṣugbọn bí ó bá jẹ́ obinrin, kí ó san Ṣekeli mẹ́wàá.
Wọn ni ero ti pọ ju ti ko jẹ ki iṣẹ ayẹwo naa ya ti o fi n ga wọn lara.
Cyril si ni gbagede ifinijoye ohun ni papa isere Loftus Versfeld.
Ni apapọ ẹniyan mẹrinlenigba lo ti ni arun Coronavirus ni Naijiria, ti ẹniyan mẹẹdọgbọn ri si ti gba iwosan, amọ ti ẹniyan mẹrin si ti ku.
Afikun owo'bode Lẹkki fa ibinu araalu A ó gbé'gbésẹ̀ lẹ́yìn ìwádìí fídíò tí Dino ti ń náwó lójú agbo- Ọlọ́pàá Iléeṣẹ́ ọlọ́pàá Èkó ní àwọn kò mọ ohunkohun nípa ìwadìí ẹjọ́ Dakolo àti pásítọ̀ COZA mọ́ Ìlú ò rẹ́rìn ín rárá, Alaafin Adeyemi III fárígá fún Buhari nínú lẹ́tà tuntun Eyi kii ṣe igba akọkọ ti iru iwa akin bayii maa ṣẹlẹ ni Naijiria.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Coronavirus in Nigeria: Ẹ wo àǹfààní tó wà nínú àrùn Coronavirus Eyi n tumọ si pe ko ni si aye lati wọle tabi jade kuro ni ipinlẹ naa lasiko yii.
Láì lo Kakulétọ̀, mo ní ọpọlọ ìṣirò, tábìlì ìṣirò wà lórí mi - Human Calculator Ronke Oshodi Oke ṣe àwo orin jáde fún MC Oluomo fún ọjọ́ ìbí rẹ̀ Músò!
 Ọlọ́pà èwo ni tèpè,amúni ń jẹ́ amúni.
Bí ẹ bá ṣe bẹ́ẹ̀, olukuluku yín ni yóo máa jẹ èso àjàrà ati èso ọ̀pọ̀tọ́ rẹ̀, olukuluku yín yóo sì máa mu omi ninu kànga rẹ̀; 
Sugbọn tawọn to n fẹhọnu han naa sọ wipe, awọn fẹ ki wọn sun siwaju di osu Karun.
Lara awọn ilana to de Bitcoin ni pe miliọnu mọkanlelogun Bitcoin ni wọn le ṣẹ̀dá - o si ti fẹ ẹ pé bayii.
Nítorí náà èmi bẹ̀ ọ́, bá mi wí fún Ọlọ́run Ọba wí pé kí Ó wá ọ̀gá mìíràn fùn mi, bí bẹ́ẹ̀ bá sì kọ́, kí Ó yí àwọn ọ̀gá mi wọ̀nyí lọ́kàn padà, kí wọn máa wo ti ìyàwó mi, kí wọ́n ṣàánú àwọn ọmọdé, kí wọ́n sì ronú nípa àwọn ojúlùmọ̀, kí wọ́n yéé gbé mi kiri.
Ninu ifọrọwerọ rẹ pẹlu BBC News Yoruba ni Ba wasi ti sọ ọrọ yii.
Ayẹyẹ ọdún ìbejì dùn, ó lárinrin nílùú Igbó-ọrà Nigba ti Ọlọrun ṣaami si adura wọn to gba ọwọ awọn Dokita ṣiṣẹ tan, ayọ gbogbo wọn ko lonka.
''Mi o ni lati nawo kankan, awọn ilu gan an lo ṣe inawo ibẹ,'' Kabiyesi Uba lo ṣalaye bẹẹ.
Ní Èbúté Mẹ́ta,  àwọn agbẹ́gità, àwọn oníṣòwò pákó àti àwọn ìran apẹja ni iná nlá kan tó jó lánàá ṣe ní jàmbá.
Ko tan sibẹ o, o tun jẹ ẹbun foonu, ọda, eroja fun inu ile, ounjẹ ọfẹ, aṣoju ileeṣẹ, ati ẹẹdẹgbẹta Dọla owo Bitcoin.
Ilẹ̀ ṣú, ilẹ̀ sì tún mọ́, ó di ọjọ́ kẹfa.
labẹ ofin lati ṣe agbekalẹ ikọ alaabo, ki wọn si ro o lagbara, ki ojuṣe
N óo ṣe é tí wọn yóo fi wá sọ́dọ̀ rẹ, wọn yóo foríbalẹ̀ fún ọ, wọn yóo sì mọ̀ pé mo fẹ́ràn rẹ.
Bi Aarẹ Buhari ba fẹ mu ileri rẹ sẹ, o gbọdọ fi kun owo isuna eto ẹkọ si bii 1.
awon tun ti n ta ajẹlẹ fun awon agbe ni owo tasẹrẹ.
Jesu wá rán angẹli rẹ̀ sí Johanu, iranṣẹ rẹ̀, pé kí ó fi àwọn ìṣẹ̀lẹ̀ náà hàn án.
Hasaeli bèèrè pé, “Kí ló dé tí o fi ń sunkún, oluwa mi?
Họnọrebu Agunbiade kẹnu bọ ọrọ ninu ifọrọwanilẹnuwo pẹlu BBC Yoruba lati ṣalaye oun to ni awọn eeyan gba sodi nipa oun.
Ọsẹ meji ni wọn maa fi n ṣe ọdun ọṣun Oṣogbo.
Dino Melaye Marriage Proposal: Se lóòtó ni sẹ́nátọ̀ Dino Melaye fẹ́ gbé ìyàwò tuntun
Ọgbẹni Adejobi ni awọn ọlọpaa ti lọ ṣabẹwo si obinrin naa nile iwosan to wa fun Iwadii lori iṣẹlẹ naa.
O ni Oloye Akande ni alawolodu bi iyere ọmọ ilu Ibadan keji ti yoo jẹ ọlọrun ni pe lọdun 2020 yii lẹyin ti Parakoyi, Oloye Bode Akindele ti kọkọ ku.
Ẹ̀sùn Tí Wọ́n fi Kan Paulu.
 “Pelu ajosepo , a le e se aseyori lori awon ipenija ti a n dojuko nile ise wa.
 yorùbá gbàgbọ ́ pé , ọkọ ló máa ń sáájú aya rẹ ̀ kú , kí ìyàwó máa bójú tó àwọn ọmọ .
2015,ti orile ede yii lati pase fun Walter Onnoghen ki o wa salaye ara rẹ niwaju
Biggie tun fẹsun kan Erica pe o ru ofin miran lẹyin to kọ lati gba igbakeji olori ile naa, Prince, laaye lati sun si ibi to yẹ ki olori ile ọhun sun si.
Ẹlẹ́dẹ̀ náà jẹ méjìdínlọ́gbọ̀n nínú èso náà, ó sì fi mẹ́rin sílẹ̀ nínú èyí tí orílẹ̀èdè Naijria wà lára wọn.
Awọn iroyin ti ẹ lee nifẹẹ si: Wo àwọn tí wòlíì ríran sí pé COVID-19 yóò pa ní ìpínlẹ̀ Edo l'óṣù kẹsàn án Alága àjọ EFCC Ibrahim Magu yóò tún bẹ ìgbìmọ̀ olùwádìí Aàrẹ wò lónìí Wo ohun tí Adájọ́ sọ nípa ìgbẹ́jọ́ Wòlíì Sotitobire l'Ondo Ọmọ Yorùbá mẹ́wàá tó jẹ́ àmúlùúdùn ní Amẹ́ríkà àti Yúróòpù Nǹkan mẹ́sàn án tí Mùsùlùmí gbọdọ̀ ṣe nínú oṣù Dhual- Hijjah Ẹgbẹ́ Boko Haram pa àwọn òṣìṣẹ́ UN márùn ún tó wá ṣiṣẹ́ ìrànwọ́ ní Nàìjíríà Èèyàn 20 ni coronavirus pa l'Ọ́jọ́bọ nìkan Ogbẹni Rahman Wahab ṣalaye pe atọna ni ilu jẹ fun tẹru tọmọ, o tun jẹ akilọ iwa to si tun n ta ni lolobo.
Amọ iwadii imọ ijinlẹ lode oni ti tako igbagbọ naa, to si ni ko si ewu kankan ninu ki obìnrin ni ibalopọ pẹlu ọkunrin lasiko to ba n ṣe eela lọwọ, o kan nilo ko wẹ mọ tonitoni ko to wọle tọ ọkunrin ni.
Nítorí náà, kó àwọn eniyan mi lẹ́yìn kí o sì máa lépa rẹ̀ lọ.
AMVCA7 2020: Funke Akindele, Toyin Abraham áti Yewande Famakin gba àmí ẹ̀yẹ
Ìrìn ẹsẹ̀ rẹ ati ìwà rẹni ó mú kí àwọn nǹkan wọnyi dé bá ọ.
Wo òfín tuntun tí INEC ṣe fún ìdìbò 2019 Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Lọsan ọjọ ẹti, aarẹ ti bura wọle fun ọgbẹni Ibrahim Tanko Muhammed gẹgẹ bi adele adajọ agba tuntun.
Oríṣun àwòrán, BIG BROTHER NAIJA Wọn ti foju ọna ile han Kaisha nibi eto agbelewo ẹlẹgbọn agba Big Brother Naija to n lọ lọwọ.
Nígbà tí àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ gbọ́, ẹnu yà wọ́n pupọ.
O ni orin naa jẹ koriya fawọn eeyan to n la iṣoro kan tabi omiran kọja .
Bakan naa, awọn mejeeji sun mọ ara wọn pẹkipẹki lori tabili Premier League lẹyin tu Man City n fi ami ayo marun le laadọrun siwaju ti Liverpool si wa ni ipo keji pẹlu ami ayo mẹrinlelaadọrun.
 “O da mi loju pe, iko yii ko ni isoro asole bi o ti le wu ko mo,  mo ni igboya lori awon meteeta lopolopo.
 ó tún tẹ ̀ síwájú síi pé ọmọ àlè tàbí ẹrú ni Ẹ ̀ gbá tí kò bá ní orírun láti Ọ ̀ yọ ́ .
Hosni Mubarak: Ààrẹ́ Egypt tẹ́lẹ̀ jáde láyé
Àṣeyọrí míì tún dé lórí ìwòsàn Coronavirus Àlàyé rèé lórí bí agbẹjọ́rò tó ń ṣojú Hushpuppi nílé ẹjọ́ ṣe pegedé sí Ìtàn ayé Henry Fajemirokun, olówó tó fi owó mọ Olúwa àti ènìyàn Báwo ni Coronavirus ṣe n tànkálẹ̀ l'Afrika?
O dabi igba ti eeyan n wa ojutu si isoro mẹta amọ ti onitọun gbajumọ ẹyọ kanṣoṣo, to si fi awọn isoro yoku silẹ.
Iléẹjọ́ fún Seyi Makinde láṣẹ láti yan adelé alága ìbílẹ̀ ní ìpínlẹ̀ Oyo Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Joke Silva: Olu, ó tó gẹ́ pẹ̀lú obìnrin yìí níkan tó ń ba ẹ ṣeré ìfẹ́ nínú sinimá Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Kí á mú àbúrò wa patapata wá fún òun, nígbà náà ni òun yóo tó mọ̀ pé a kì í ṣe amí, ati pé olóòótọ́ eniyan ni wá, òun óo sì dá arakunrin wa pada fún wa, a óo sì ní anfaani láti máa ṣòwò ní ilẹ̀ Kenaani.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ìjọba orílẹ̀èdè Naijiria ní àwọn tí gba àgbo Madsagascar tó ń kójú àjàkálẹ àrùn Coronavirus.
Mo si mọ pe awọn ọmọ orilẹede Naijiria yoo lee mọ bi nnkan ṣe n lọ ni ipinlẹ Imo.
Awọn pupọ ninu mọlẹbi wa n jẹ Afọdunrinmi,ṣugbọn mo fẹran orukọ naa bi baba mi ṣe n jẹ ẹ l'emi naa ṣe gba a bẹẹ.
apapọ ti sọọ di ofin” .
Awọn ọmọ awọn oloogbe naa lo wa yirapada di ọmọ onilẹ to n ṣoro bi agbọn, pẹlu ẹsun wi pe ọna aitọ ni wọn gba ra awọn ilẹ naa.
Kí á má tilẹ̀ wá sọ ti eniyantí ó jẹ́ aláìmọ́ ati ẹlẹ́gbin,tí ń mu ẹ̀ṣẹ̀ bí ẹni mu omi!
Wọ́n ti jẹ àwọn eniyan run, wọ́n ń fi ipá já ohun ìní ati àwọn nǹkan olówó iyebíye gbà, wọ́n ti sọ ọpọlọpọ obinrin di opó nílùú.
Aare Muhammadu Buhari ti kedun pelu aare orile-ede France, Emmanuel
Ẹ lọ bá àwọn oriṣa tí ẹ ti yàn, kí ẹ ké pè wọ́n, kí àwọn náà gbà yín ní ìgbà ìpọ́njú.
O ṣe é ki ẹni náà maa sọ̀rọ̀ nípa ikú ṣaa , àwọn àmi rèé láti mọ̀ pé ẹni náà fẹ́ pa ara rẹ̀.
Mr Macaroni ní ìgbé ayé àlááfíà ni olúkúlùkù ń wá ti wọ́n fi jáde láti bẹ̀rẹ̀ ìwọ́de yìí, nítori náà kí gómìnà ìpińlẹ̀ Eko yọju si àwọn.
Nígbà tí ó bá dé ibẹ̀, tí ó rí i pé a ti gbá a, a sì ti ṣe é lọ́ṣọ̀ọ́, 
OLUWA àwọn ọmọ ogun, Ọlọrun Israẹli ní, ‘Ẹ̀yin ati àwọn iyawo yín ti fi ẹnu ara yín sọ, ẹ sì ti fi ọwọ́ ara yín mú ohun tí ẹ wí ṣẹ pé, “Dájúdájú a ti jẹ́jẹ̀ẹ́ sí oriṣa ọbabinrin ojú ọ̀run láti sun turari sí i, ati láti rú ẹbọ ohun mímu sí i.
Ọpọ agbẹ ni ẹkun Ila Oorub Ariwa orilẹede yii ti oko wọn ti di apati bayii ni ko le kore eso to kere ju loko wọn nitori iklu awn agbesunmọmi.
Ó wá bá àwọn eniyan náà sọ̀rọ̀.
"Wo àwọn ìṣesí ojoojúmọ́ mẹ́wàá tó le ṣàkóbá fún ọpọlọ rẹ Gomina Sanwo-Olu sún ọjọ́ ""ṣiṣẹ́ láti ilé"" síwájú fún àwọn òṣìṣẹ́ ìjọba Opral Benson, ẹni ti oge ṣíṣe sọ di gbajúmọ̀ àti Yeye Oge ìlú Eko Ǹjẹ́ ó ṣeéṣe kí ìyáwò rẹ gbé ọmọ àlè wá sílé láì mọ̀?"
 eléyìí ni wọ ́ n ṣe máa ń pe Òkènísà tí wọ ́ n dó sí yìí ní orí ayé .
Yorùbá gbàgbọ́  pé ẹni ti kò ri jẹ loni, bi kò bá kú, ti ó tẹpá-mọ́ṣẹ́, lè di ọlọ́rọ̀ ni ọ̀la.
Ṣugbọn bí o bá kìlọ̀ fún eniyan burúkú, tí kò bá yipada kúrò ninu iṣẹ́ burúkú tí ó ń ṣe, tabi ọ̀nà ibi tí ó ń tọ̀; yóo kú sinu ẹ̀ṣẹ̀ rẹ̀, ṣugbọn ìwọ óo gba ara rẹ là.
Ó kó àwọn eniyan tí wọ́n wà ninu ìlú náà, ó sì ń fi wọ́n ṣe oríṣìíríṣìí iṣẹ́: Àwọn kan ń lo ayùn, àwọn kan ń lo ọkọ́, àwọn mìíràn sì ń lo àáké.
ipinle Abia , Orji Kalu ni aare  Muhammadu Buhari  ti se gudu gudu meje, yaya mefa lati igba ti
Ìlù Ìjẹ̀bú - Jẹ̀ṣà jẹ́ ìlú kan pàtàkì ní ilẹ̀ Ìjẹ̀ṣà.
Ọgbẹni Olalekan ṣe atupalẹ ohun ti ẹ ko gbọ ri nipa itan Egungun, orin eegun ati ọpọlọpọ nkan to rọ mọ ọ.
Ọgbẹni Sanwo ni ni kete ti baalu naa balẹ, ni ilẹkun yi sadede fo yọ funra rẹ, lai jẹpe ẹnikẹni tii fọwọ kan-an, eyi to mu kawọn ero inu baalu naa gba ilẹkun ẹyin jade.
OLUWA, títí lae ni ọ̀rọ̀ rẹ fìdí múlẹ̀ lọ́run.
Ireti wa tele pe, ojoRU(Wednesday), ojo kerinlelogun odun ti a wayii, ni o ye ki ipade igbimo FEC waye, ti o si ye ki minisita kookan sagbakale bi o se tuko ekun re, sugbon ti won sun di oni ojoBo(Thursday), latari ayeye ajoyo odun ajinde.
Kò tilẹ̀ lè yé e, nítorí pé ẹni tí ó bá ní Ẹ̀mí ni ó lè yé.
Ṣe gbogbo ohun tí OLUWA Ọlọrun rẹ pa láṣẹ fún ọ pé kí o ṣe, máa tẹ̀lé ọ̀nà rẹ̀, sì pa àwọn òfin ati ìlànà rẹ̀ mọ́, gẹ́gẹ́ bí a ti kọ́ ọ sinu ìwé òfin Mose, kí gbogbo ohun tí o bá ń ṣe lè máa yọrí sí rere, níbikíbi tí o bá n lọ.
5 bilionu, eka ofin ati eto idajo N1.
agbaye ni orile ede Naijiria, Myrta Kaulard wa gbosuba fun orile ede Korea fun
Iroyin kan to n ja rainrain labẹlẹ ni wi pe, o ṣeeṣe ki ileeṣẹ aarẹ pagidina agbekalẹ eto aabo Amọtẹkun lẹkun iwọ oorun guusu Naijiria.
Kí ló dé tí ẹ fi mú wa wá láti Ijipti sí ibi burúkú yìí, kò sí ọkà, kò sí èso ọ̀pọ̀tọ́, tabi èso àjàrà tabi èso pomegiranate, bẹ́ẹ̀ ni kò sí omi mímu.
O ni atẹlẹwọ ẹni kii tan ẹni jẹ, ki onikaluku lọ gbajumọ iṣẹ rẹ.
Irufẹ obinrin bẹẹ si ni wọn kii jẹ ko fi ọwọ tabi ara kan oogun ibilẹ nitori igbagbọ pe oogun naa yoo bajẹ ni.
Oríṣun àwòrán, @PoliceNGLagos Bakan naa ni wọn ri igi kan ti wọn fi iso gun kaakiri eyi ti ẹjẹ wa lara rẹ, ẹrọ ilọsọ to ni ẹjẹ lara, asọ inuju funfun kan to fẹ fi nu ẹjẹ iya rẹ ati igo to kun fun ororo ti wọn kọ ‘back to sender’ si lara.
Obasanjo ni oun ko pada lo aaye atipo oloselu nile America ti Walter fun oun nigba naa.
O fikun pe ade ori awọn wa titi laelae ni, ko si si ohunkohun to lee yẹ ade lori awọn nitori awọn yoo pada lọ pe ẹjọ miran lori igbesẹ tijọba gbe naa ni.
Ṣé àsọtẹ́lẹ̀ ìjàmbá iná kò tíì máa ṣe báyìí?
Ile olorogun ni mo ti wa, mo si fẹran ọmọ pupọ.
ipinlẹ Ogun,  ki o to lọ si ile-iwe giga
Lai Mohammed soro lori igbese tijoba apapo ti n gbe lati wa ojutu soro yii pe: Igba ikeji ti asoju ijoba apapo yoo wa si Yobe ni yii lati gba ti oro yii ti sele nitori pe o n konilominu gidigidi.
Gege bi atejade kan lati odo oga agba fun eto iroyin ati igbode gba nile ise omo ogun naa, ogagun Texas Chukwu  pe, “awon omo ogun olote ohun ti won jowo ara, ni awon alase ti n fi oro wa won lenu wo lowo bayii,”.
Ẹgbẹ́ APC dá ọmọ Alao Akala padà sípò alága Ogbomọṣọ North Ètò tí mo ní fún Kwara yàtọ̀ sí ti ANRP ni mo ṣe fẹgbẹ́ wọ́n sílẹ̀ - Yinka Ajia Ọjọ́ Àbámẹ́ta la ó mọ ẹni tí yóò lékè láàrín bàbá ìsàlẹ̀ àti àwọn mẹ̀kúnnù nipinlẹ̀ Ọyọ.
Laipẹ yii ni Chioma bọ lọwọ arun Coronavirus lẹyin ọpọlọpọ ọjọ ti aisan naa fi daa wolẹ.
Láti inú ẹ̀yà Lefi: Haṣabaya, ọmọ Kemueli; láti ìdílé Aaroni: Sadoku; 
“Bí ẹrú kan bá sá kúrò lọ́dọ̀ ọ̀gá rẹ̀, tí ó bá tọ̀ yín wá, ẹ kò gbọdọ̀ lé e pada sọ́dọ̀ ọ̀gá rẹ̀.
Lẹsẹkẹsẹ àwọn Farisi jáde lọ láti gbìmọ̀ pọ̀ pẹlu àwọn alátìlẹ́yìn Hẹrọdu lórí ọ̀nà tí wọn yóo gbà pa á.
Ninu esi ayẹwo tuntun naa, ipinlẹ Eko ni apapọ eeyan 37, Abuja ni 16 nigba ti ipinlẹ ogun n sare tete tẹle wọn lẹyin pẹlu eeyan mọkanla.
Ní ìbò kọ̀la, àwọn agbébọn gbẹ̀mí èèyàn 66 ní Kaduna Ẹmi marun sọnu ninu ija Kaduna Atunto Naijiria yoo fun ijọba ipinlẹ lagbara Ọlọ́pàá dóòlà àgùnbánirọ̀ 5 lọ́wọ́ ajínigbé Aafa nla oniwaasu naa ni bakan naa ni ofin yii ko ba ilana Islam mu rara.
Nigba to n sọ ohun ti oju rẹ ri ninu ile naa fawọn akọroyin salaye pe ẹni ta gboju okun le, ko jọ ẹni agba lọrọ awọn eeyan ti wọn ni ki wọn maa se akoso ile alaigbọran naa, nitori iwa aidaa nidi ibalopọ lọna ti ko tọ gan lawọn naa n hu.
Laasigbo eto oro-aje ti n koju orile-ede Zimbabwe, ninu eyi ti a ti ri airise-se awon eniyan ti sokunfa bi awon eniyan se n ko awon ile-itaja silu Harare lona aibofin mu, bakan naa ni o tun sokunfa alekun awon awako aladani.
Ajimobi ninu atẹjade to fi lede ni gbogbo isẹ Makinde lo n fihan wi pe, o fẹ fi ọwọ rọ gbogbo isẹ ti oun ti se fun ọdun mẹjọ ni ipinlẹ Ọyọ.
Ẹgba ọwọ onirọba Ara awọn nkan idamọ tẹẹ le fi mọ awọn to lọ fun ipade adura yii ni ẹgba ọwọ Wrist Band ti wọn maa n tẹ ọrọ adura, ọrọ bibeli tabi akori ipade adura naa si.
Ìpínlẹ̀ méjìla tó di òpó ìhà aárèwá mu ní wọ́n ti ń lo òfin Sharia, àwọn musùlùmí to sì wà ni àwọn ìpínlẹ̀ yìí nikan ni òfin Sharia le báwí.
Jàǹdùkú ìlú méjéèjì jó ààfin ọba àti ọkọ̀ níná Oríṣun àwòrán, Paradisenews Ibi ti a ba pe ni ori, ẹnikan kii fi ibẹ tẹlẹ ni Yoruba n wi, bẹẹ si ni wọn ni Ọba lo ba lori ohun gbogbo.
Oṣiṣẹ papakọ naa fi idi ọrọ mulẹ wi pe aigbepẹli eto ọrọ aje ni papakọ naa lo mu ki ọga agba ileeṣẹ to n ṣe akoso irina ofurufu lorilẹede Naijiria, Captain Rabiu Yadudu ṣe abẹwo si ilu Ibadan l'Ojoru lati pe fun ajọṣepọ laarin ijọba apapọ ati ijọba ipinlẹ Ọyọ lori papakọ ofurufu naa.
Kò ní fi ojú rí i, bẹ́ẹ̀ sì ni ibẹ̀ ni yóo kú sí.
Nínú esi idanwo ọmọdékùnrin náà lo tí jókòó ṣe idanwo fún isẹ mẹ́jọ àmọ́ to kùnà nínú isẹ mẹ́fà, tó sì yege pupọ nínú idanwo imọ nípa orin taa mọ si Music, bẹ́ẹ̀ lo tún yege díẹ̀ nínú idanwo Georgeraphy Oríṣun àwòrán, others Nínú fídíò náà sì ni ìyá ọmọ ọhun tí ń pariwo pé kí bàbà rẹ má gba ni igbaju mọ.
a lé mú nomba gidí wa gégé bí àkótán àwon nomba oniìpín ni ònà tó jé pé ìtèntèle nomba kan se fẹsíwájú pèlú nombámèwa tàbí nombáméjì ( binary ) báyí { 3 , 3.
Èèyàn mẹ́rin míì tún ni Coronavirus nípìnlẹ́ Oyo, ó di èèyàn 97 tó níi ní Nàìjíríà Fíímù ṣíṣe dáwọ́ dúró, Joke Muyiwa di 'grandma', Lizzy Anjorin sọ pé coronavirus ko gbọdọ̀ díwọ́ ọjà títà Irọ́ ní, kìí ṣe àdó olóró ló bú gbàmù ní Akure - Ọ̀gá Ọ̀lọ́pàá Ondo!
Gomina Makinde gbàlejò àwọn Imam lásìkò àjàkálẹ̀ àrùn Coronavirus Aláàfin gbé àṣẹ kalẹ̀ láti dènà àtúnṣẹ̀ ìṣẹ̀lẹ̀ 'Soka'nílùú Ọ̀yọ̀ Ninu atẹjade kan, kọmiṣọna feto iroyin ni ipinlẹ Ondo, Donald Ojogo ni kọmiṣọna feto iṣuna lo ṣawari owo naa nibi to farasin si.
Yóo fi ọ̀nà àrékérekè burúkú lóríṣìíríṣìí tan àwọn ẹni ègbé jẹ, nítorí wọn kò ní ìfẹ́ òtítọ́, tí wọn ìbá fi rí ìgbàlà.
 O ni: “Lati fi igbagbọ wa han ninu Ọlọrun Allah, o ṣe pataki
Adari ijọba orile ede Ethiopia Abiy Ahmed, ni o wa pade Minisita fun oro ile okeere  ti orile ede Eritrean Osman Sale ati awon eniyan miiran naa ni papa ofurufu lati wa ki won kaabo, ko sai tun salaye ipa pataki ti ipade naa yoo ko.
"Ki awọn eeyan yee naka ẹsun si wa lọna aitọ"" Oríṣun àwòrán, @Govt of Nigeria Mo kọ̀ láti kópa nínú ìpàdé orí ayélujára Nàìjíríà yìí- Falz Lẹyin gbogbo iwọde lorisiirisi ati ọrọ #End Sars / End SWAT yii, Ileeṣẹ ijọba apapọ to n risi ọrọ awọn ọdọ pe ipade apero lori ayeluja."
17 Bélú 2020 Ki ni idi ti aṣọ fi maa n pọ lara Egungun ju Oro lọ́?
a ko ba gbagbe wipe, enu ijo meta yii ni iko agbaboolu Everton di eru iya ru iko
Ọ̀rọ̀ ẹ̀tàn tí kò lè mú èrè wá ni ẹ gbójú lé.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ewó ninu àwọn wọ̀nyí ni yóò wà níní ẹgbẹ́ agbábọ́ọ́lù ààyò rẹ?
O soro yii nigba ti o n ba awon oniroyin ile-aare soro , leyin ti o jabọ isele naa fun awon igbimo ijoba apapo orile ede yii lojoRu.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Gẹgẹ bi iroyin to tẹ wa lọwọ lati orilẹede Argentina, Maradona sọ fun ọmọkunrin to wa pẹlu rẹ ni ede ilu rẹ pe ''Me siento mal,'' eyi to tumọ si ''o n rẹ mi.
Amọṣa, ileeṣẹ aarẹ ṣalaye lori pe wọn fa iwe naa ya lati lee fun laaye lati funra rẹ kọwe fipo silẹ ki o lee lọ gba ipo tuntun to ṣi silẹ fun un ni ajọ iṣọkan agbaye.
“ “Bi a se n gbe igbese lori
Wo àwọn oúnjẹ márùn ún tó ń mú kí àtọ̀ ọkùnrin dára síi ‘Sim Card’ títà àti ìforúkọsílẹ̀ rẹ̀ dèèwọ̀ ní Nàíjíríà - NCC Wo ìgbà tí Ààrẹ Buhari yóò ṣí 'bọ́dà' padà Ọmọ ẹgbẹ́ òkùnkùn ṣoro ní Ijebu Ode, ọ̀pọ̀ ẹ̀mí sọnù Wo diẹ lara awọn adele obinrin to wa ni ilẹ Yoruba lasiko yii.
"Iṣẹ jibiti wọn lo bẹrẹ yẹ "" Nkan itiju ni"" sebi Naijiria yii ti da tẹlẹ rii, ""kilo de ti a le gbe ogo orilede yii"" Jegede ni ki ẹnikẹni ma sọ pé ǹkan idi kankan jona oo, "" ṣe bi wọn ni ilé iṣẹ́ ni Abuja, ki wọn ya ko àwọn nkan miran wa lati Abuja fun eto idibo to n bọ."
 O ni, “lorukọ awọn ẹgbẹ mi ni Ile Igbimọ Aṣofin Ipinlẹ Eko, mo ki yin ku ọdun Aawẹ Ramadan yii o.
mo fi ri awon eniyan lasiko eto ipolongo ibo aare .
 O wi pe iṣẹlẹ na buru jọjọ, bo ti lẹ ṣe pe o gboriyin fun Ile Igbimọ Aṣofin-agba naa fun iwa akin wọn ti wọn ko jẹ ki iṣelẹ naa jẹ irẹwẹsi ọkan fun wọn, ti wọn si n ba ojuṣe wọn lọ ninu Ile.
Nibẹrẹ saa bọọlu yi, ko ribi kopa nitori pe o farapa lori ẹsẹ ọtun rẹ ti o si fagidi gba nigba mẹta pere ki o to ko arun Covid-19 nibẹrẹ oṣu Kọkanla Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Diego Maradona: Báyìí ni àgbàọ̀jẹ̀ agbábọ́ọ̀lù Diego Maradona ṣe wọ káà ilẹ̀ lọ lólú ìlú Argentina27 Bélú 2020 Hisbah Kano fi òfin de lílo èdè 'Black Friday', àwọn ọmọ Naijiria kan yarí lórí ayélujára29 Bélú 2020 Yoruba Taboo: Èèwọ̀ ni fún ọba láti gbé Bibeli tabi Kurani dání dípò ifá- Elebuibon, Agẹṣin Àdìmúlà29 Bélú 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Arabinrin Akinbile-Yussuf sọ pe awọn ilana tuntun naa, yatọ si eyi to ti wa nilẹ tẹlẹ bii ọwọ fifọ ni gbogbo igba, lilo sanitaisa, titakete sira ẹni, lilo ibomu-b'ẹnu, ṣiṣe ayẹwo bi ara ṣe gbona si, fifin oogun apakokoro si ayika, ati bẹẹ bẹ lọ.
Nítorí Tẹmpili rẹ tí ó wà ní Jerusalẹmu,àwọn ọba yóo gbé ẹ̀bùn wá fún ọ.
Má bẹ̀rù, nítorí Ọlọrun ti gbọ́ ẹkún ọmọ náà níbi tí ó wà.
Oríṣun àwòrán, Screenshot Gẹgẹ bi ileesẹ Channels ti n kede loju mohunmaworan rẹ, o ni oun le ma sisẹ mọ nitori idunkooko pe awọn janduku fẹ wa ba ileesẹ naa jẹ.
ifehonuhan naa, ni eyi ti won ti wa ro igbimo to n se atunse lori abadofin naa
OLUWA fi iṣẹ́ lé Joṣua ọmọ Nuni lọ́wọ́, ó ní, “Múra gírí kí o sì mú ọkàn gidigidi, nítorí ìwọ ni o óo kó àwọn ọmọ Israẹli wọ ilẹ̀ tí mo ti búra láti fún wọn.
Kí ló kàn fún Arsenal báyìí lẹ́yìn tí Burnley yẹ̀yẹ́ wọn mọ́lé ní Emirates?
Ibojì wọn yí ibojì rẹ̀ ká, gbogbo wọn ni wọ́n kú lójú ogun ní aláìkọlà.
Igbeyawo naa yoo waye ni oṣu kẹwa ọdun yi.
Ọlọrun Ológo Israẹli kò jẹ́ parọ́, kò sì jẹ́ yí ọkàn rẹ̀ pada; nítorí pé kì í ṣe eniyan, tí ó lè yí ọkàn pada.
"Ààrẹ ilẹ ̀ gríìsì tabi Ààrẹ ilẹ ̀ hẹ ́ llẹ ́ nìkì olómìnira ( "" president of the hellenic republic "" ) ( ) , ni olori orile-ede ile gríìsì ."
nipinle Zamfara, iwe ohun bere fun ikunwo awon omo ogun lojuna ati da igbe-aye
Ohun tí ojú ìyàwó mi rí lọ́wọ́ SARS kò ṣe é fẹnusọ- Poju Oyemade Wo ìsọ̀rí àwọn tó jẹ́ kí ìwọ́de End SARS / end SWAT lárinrin àti ìtumọ̀ Ajínigbé tú ìyá àti ọmọ ọdún mẹ́ta sílẹ̀ lẹ́yìn tí wọ́n gba ₦1.
Ọlọrun ìfẹ́ ati alaafia yóo wà pẹlu yín.
Baba ati ọmọ yóo máa kọlu ara wọn.
Ṣugbọn ọba yóo máa yọ̀ ninu Ọlọrun;gbogbo àwọn tí ń fi orúkọ OLUWA búrayóo máa fògo fún un;ṣugbọn a ó pa àwọn òpùrọ́ lẹ́nu mọ́.
Awọn ọlọpaa ẹsìn si maa n mojuto bi awọn eniyan ṣe n pa awọn ofin yii mọ si.
Ọ̀tá tí ó fọ́n èpò ni èṣù.
Bi awọn kan ṣe n kowo le e, ni ọpọ gbagbọ pe ko yatọ si awọn okowo sogun-dogoji bi i MMM, ti ọpọ eeyan padanu owó si nigba to forisanpọn.
Àwọn ìlú ọ̀hún ni ìlú ààbò tí wọ́n yàn fún àwọn ọmọ Israẹli, ati fún àwọn àlejò tí wọ́n ń gbé ààrin wọn.
Buhari Fidio naa si lo fi oju rẹ han sita pe, baba Fatima, iyẹn Mamman Daura to jẹ bi aburo fun aarẹ, ti ko gbogbo awọn eeyan to wa ni ile aarẹ, titi kan awọn agbofinro, ni papa mọra.
Ninu esi rẹ si ọrọ ti minisita fun ọrọ iṣẹ ati ileegbe, Babatunde Fashola sọ pe ohun tawọn ọdọ n wo ninu ere tiata lo jẹ ki wọn maa ṣoogun owo, Okunnu ọrọ ko rii bẹẹ.
#KẹmiAdeọṣunNYSC: Ìwádìí yóò bẹ̀rẹ̀ lóri ayédèrú iwé
Bakan naa ni wọn tun ba mọlẹbi awọn eeyan to padanu ẹmi wọn lasiko rogbodiyan naa kẹdun.
Bi o tilẹ jẹ pe ote ti aarẹ Trump gbe le irina wọ ilẹ Amẹrika yii ko ba ti ẹni to ba wa ṣe iṣẹ wi, oniṣowo, igbafẹ ati ọmọ ile iwe wi.
''Ki o tó di pé kòkòrò náà wọ inú okò, a gbọ́dọ̀ tí rà àwọn òògùn apá kòkòrò kì a sì máà fin wọn lóòrèkóòrè sí nnkan ọ̀gbìn wà.
Ọjẹwẹwẹ agbabọọlu Chelsea, Mason Mount gbayo wọ le eleyi ti Chelsea fi tun wa niwaju ṣugbọn ẹlẹsẹ ayo Teemu Pukki sọ ere bọọlu ọhun ọmi alayo mejimeji.
Bakan naa, ni o tun ni iwe ase ajo CAF nikawo re.
Bí ẹnikẹ́ni tí ó yẹ bá wà ninu ilé náà, kí alaafia tí ẹ ṣe kí ó wà níbẹ̀.
Gẹ́gẹ́ bí ọkan lára àwwọn tó kópa níbi ìpàdé náà ṣe sọ ọ́, gómìnà ọ̀hún tó jábọ̀ àbábọ̀ ìpàdé rẹ̀ pẹ̀lú ààrẹ Buhari kò ta ẹnikẹ́ni lólobó ẹgbẹ́ t íyóò ṣẹ̀ṣẹ̀ dara pọ̀ mọ́.
Bi ẹ ko ba gbagbe, lọjọru ọsẹ to kogba wọle ni fasiti naa jawe maa lọle fun akẹkbinrin kan to wa ninu fidio ibalopọ kan to tan kaakiri ayelujara.
Yóo tú dà sí orí àwọn eniyan burúkú.
"Mad Melon ati Mountain Black gba igboriyin kaakiri to bẹẹ ti wọn lo orin wọn lẹgbẹkẹgbẹẹ ""African Queen ti olorin 2Face kọ ninu fiimu ilẹ Anerica kan."
Ó pa àtíbàbà kan sibẹ, ó jókòó ní ìbòòji lábẹ́ rẹ̀, ó ń retí ohun tí yóo ṣẹlẹ̀ sí ìlú náà.
Kò sì sí ẹnikẹ́ni tí ó lè gbà wọ́n sílẹ̀, nítorí pé wọ́n jìnnà sí ìlú Sidoni, wọn kò sì bá ẹnikẹ́ni ní àyíká wọn da nǹkankan pọ̀.
Wọ́n ní wọ́n ma gbé e lọ sí pálọ̀.
O ti wó gbogbo odi rẹ̀;o sì ti sọ ilé ìṣọ́ rẹ̀ di ahoro.
O ni iṣẹ wiwa ọkọ agbepo ati ọkọ akẹru jẹ iṣẹ to dara ṣugbọn to ga ero.
Abiola Ajimobi: Ẹbí Kolapo Isola ṣẹ́ pé òun kò gba ₦30m lọ́wọ́ Ajimobi fún ìsìnkú bàbá wọn
Kanga ọhun si ni wọn gbẹ lati fi ri omi kọ pẹtẹsi akọkọ lorilẹede Naijiria to wa nilu Badagry, ta si tun gbọ pe kanga yii mọ ju ọpọ kanga ti wọn sẹsẹ gbẹ ni Badagry lọ nitori ko ni eroja iyọ ninu gẹgẹ bii awọn yoku.
ẹyẹ òwìwí, ẹyẹ òòyo, ati ẹyẹ kan bí igún, 
Oríṣun àwòrán, @Olatunde Àkọlé àwòrán, Àkójọpọ̀ mẹ́wàá lára àwọn Ọba Ilẹ̀ Yorùbá tí wọ́n lé kúrò ní ipò Ọba.
Nítorí pé wọ́n lọ sí Asiria, wọ́n dàbí kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ ìgbẹ́ tí ń dá rìn; Efuraimu ti bẹ àwọn olólùfẹ́ rẹ̀ lọ́wẹ̀ fún ààbò.
"Muyiwa ni ""ẹ ṣeun fun gbogbo ifẹ ti ẹ fi han si mi, ẹ ṣeun fun adura yin ati ọrọ ikini, mo dupẹ gidi gan""."
Ó ní, “Gbà, kí o jẹ ẹ́.
3 352860 Orilẹede Algeria 2564 6.
Ọkunrin kan wà tí ó ń jẹ́ Sakiu.
"Ni Oṣu Kẹwa, ọdun 2018 ni ikọ BBC Africa Eye lo imọ ẹrọ ofintoto igbalode lati tọ pinpin bi ipaniyan naa ṣe waye, ati awọn to wa nidi ipaniyan naa, ti wọn si pe akọle rẹ ni ""Anatomy of a killing'."
Kí á tó fẹ yín dànù, bí ìgbà tí afẹ́fẹ́ ń fẹ́ ìyàngbò káàkiri, kí ibinu Ọlọrun tó wá sórí yín, kí ọjọ́ ìrúnú OLUWA tó dé ba yín.
Wọ́n rú gbogbo òfin OLUWA Ọlọrun wọn; wọ́n yá ère ẹgbọ̀rọ̀ akọ mààlúù meji, wọ́n ń sìn wọ́n.
 a gbọ ́ dọ ̀ ṣe èyí ní ìdàpọ ̀ pẹ ̀ lú gbígbé àwọn ohun bíi fífún ọmọ lọ ́ yàn , fífọ ọwọ ́ ẹni , àti lílo omi tó mọ ́ àti ìmọ ́ tótó lárugẹ .
Odunlade Adekola, Femi Adebayo, Jenifa ṣi aṣọ lójú àwọn fíìmù tuntun tẹ́ẹ ti ń retí Ìdí ti mo fi da sọ́ọ̀sì rú lásìkò ìgbéyàwó ìyáwó mi tó ló fẹ́ ọkọ míran- Osadebe Tinubu tun kesi awọn gomina nilẹ Yoruba lati ṣiṣẹ papọ, lori bi wọn yoo ṣe ma a ri owo labẹle ni agbegbe naa.
 ní ilẹ ̀ amẹ ́ ríkà àti àwọn erékùsù káàkiri , a lè rí wọn ní jàmáíkà , kúbà , trínídáádì àti tòbégò pẹ ̀ lú bùràsíìlì àti bẹ ́ ẹ ̀ bẹ ́ ẹ ̀ lọ .
KChinese cultural centre ni ibasepo ti o donmonran pelu egbe Nigerian Union of Journalist (NUJ), ti eka FCT.
satileyin fun awon ti wọn ko lọ si ile iwosan naa, ni eyi ti jẹ pe pupọ ninu
Wọ́n ń wí fún gbogbo àwọn tí wọn ń tẹ̀lé àìgbọràn ọkàn wọn pé ibi kò ní bá wọn.
 Àtàdá ati johnson tilẹ ̀ maa ń to aré àti Ẹ ̀ fọ ̀ n tẹ ̀ lé ara wọn .
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Itan Omi Erin Ileesẹ Fajemirokun tun lo kọkọ jẹ ileesẹ aladani akọkọ to gba asẹ lati wa epo rọbi loju omi lọdun 1970, to si tun jẹ oludari banki First Bank Ileesẹ rẹ naa lo tun kọkọ gba iwe asẹ lati pin ẹrọ Rank Xerox, to si tun jẹ ara awọn oludasilẹ to kopa to giriki ninu agbekalẹ banki ajọ ECOWAS, bi o tilẹ jẹ pe oun gan an ti jade laye ki agbekalẹ banki naa to bẹrẹ Ileesẹ Henry Fajemirokun yii naa jẹ oludokoowo gboogi nileesẹ Johnson Wax ati Fan milk, pẹlu ileesẹ nla meji mii to nimọ nipa ẹrọ abanikọle.
Nigba to pe ọmọ ọdun mẹfa, awọn obi rẹ ko lọ si ilu Eko nibi ti baba rẹ ti ṣiṣẹ pẹlu ile ọkọ ofurufu orilẹede Naijiria ti Mama rẹ si ba ile isẹ ọkọ oju irin ṣiṣẹ.
Bakan naa ni idibo ti bẹrẹ ni ipinlẹ Sokoto pẹlu.
Ìwà burúkú yín yóo fìyà jẹ yín,ìpadà sẹ́yìn yín yóo sì kọ yín lọ́gbọ́n.
Kọmisana feto iroyin nipinlẹ naa Murtala Olanrewaju sọ pe awọn ko fẹ ki ikọlu waye lawọn fi wo ile naa loruganjọ.
Bí àwọn ìjòyè tilẹ̀ gbìmọ̀ràn ọ̀tẹ̀ nítorí mi,sibẹ, èmi iranṣẹ rẹ yóo ṣe àṣàrò lórí ìlànà rẹ.
L'owurọ ọjọ rẹ, o wu u lati lọ si fasiti ki o lọ gboye ẹkọ isiro owó, ṣugbọn ko wa si imuṣẹ nitori awọn obi rẹ ko lowo lati ran an lọ, o tun wọ Fasiti Obafemi Awolowo ṣugbọn ko ri owo ile iwe san mọ lo fi kuro ti ko ka a pari.
”O tun tesiwaju pe,bo tile je pe ara awon eniyan si n gbona gidigidi nipa isele buruku yii , sibe, gbigbẹsan pada , ko lee mu eto alaafia pada si ilu naa.
Lẹ́yìn rẹ̀ ni Meṣulamu, ọmọ Berekaya, ṣe àtúnṣe ibi tí ó kọjú sí yàrá rẹ̀.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Alága NURTW gba ìdájọ́ ikú 'torí ẹ̀sùn pípa ọlọ́pàá 7 Èrèlè 2019 Oríṣun àwòrán, @LagosCReporters Àkọlé àwòrán, Olùjẹ́jọ́ Ile ẹjọ giga kan ni Ikeja, ipinlẹ Eko ti dajọ iku nipa yiyẹgi fun Saheed Arogundade to jẹ alaga ẹgbẹ awọn awakọ ibudo Boudary/Aiyetoro nipinl Eko.
Chioma Okoye to je gbaju gbaja osere Nollywood, ti parowa fawon lobaloba nipinle Anambra lati sagbateru ede ati asa iran Igbo gege bi awon iran to ku ni Naijiria se n se.
Nígbà náà ni OLUWA sọ fún un pé, “Mọ̀ dájúdájú pé àwọn ọmọ rẹ yóo lọ gbé ní ilẹ̀ tí kì í ṣe tiwọn, wọn yóo di ẹrú níbẹ̀, àwọn ará ibẹ̀ yóo sì mú wọn sìn fún irinwo (400) ọdún.
Títí a fi padà dé ilé bí ọmọ kan bá wí pé òun kì ní í mu oògùn kan, a máa ń pe ọmọ náà ní Àgùntàn-ìnàkí.
Ọjọ mẹta naa ti tẹnubodo lọjọ kẹẹdogun.
Ó sàn fún ọ kí o wọ inú ìyè pẹlu àbùkù ọwọ́ tabi ti ẹsẹ̀, jù pé kí o ní ọwọ́ meji tabi ẹsẹ̀ meji kí á sọ ọ́ sinu iná àjóòkú lọ.
 àwọn ìdaramọ ́ ra f fọ ́ tòkẹ ́ míkà , àwọn ìyípadà nínú ojúwà èlò , ìyàsọ ́ tọ ̀ àwọn àdàlú , àwọn ìní pólímẹ ̀ r , at.
Ọpọ awọn eniyan jankajankan lo wa nibi eto yii, bi awọn lọbalọba, awọn oloṣelu ati awọn miiran bẹẹ.
" O tun fi aidunnu rẹ han lori bi ọmọ naa ko ṣe ti i gba abẹrẹ ajẹsara kankan.
- Ọọ̀ni Ife Kunle Afolayan, Tope Alabi, Fathia Balogun sọ̀rọ̀ lórí ikú Alabi Yellow Wọn pa ọlọ́pàá kan níbi tí wọ́n ti dáná sun ìjọ Sotitobire l'Akurẹ - Police PRO Kunle Afolayan, Tope Alabi, Fathia Balogun sọ̀rọ̀ lórí ikú Alabi Yellow Ijọba ipinlẹ Ondo lo gbe pasitọ ijọ Sọtitobire Miracle Centre, Woli Alfa Babatunde lọ ile ẹjọ fun ẹsun ijọmọgbe.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Revolution Now: Ẹgbẹ́ òṣèlú AAC lé Ṣowore àti àwọn 28 mííràn 9 Ògún 2019 Oríṣun àwòrán, OTHERS Àkọlé àwòrán, Láìpé yìí ni Olùdíje lábẹ́ ẹgbẹ́ òsèlú AAC, Ọmọyẹle Sowore di èrò àtìmọ́lé Àjọ DSS nítorí pé ó pè fún àyípadà ètò ìsèjọba lórílẹ̀èdè Naijiria.
Bi o ti ṣe n wọ iya ija ariyanjiyan pẹlu awọn adari ẹgbẹ oṣelu rẹ, APC naa loun atawọn ti ipinlẹ rẹ pẹlu n waa ko.
Ohun tí ó wọ́pọ̀ ni orilẹ̀-èdè Naijiria ni kí àwọn olórí Ilé Ijọsìn kọ̀ọ̀kan sọ àsọtẹ́lẹ̀ nípa ọdún tuntun ní ìbẹ̀rẹ̀ ọdún.
Ẹgbẹ̀rún méje aṣojú ti yan Buhari lẹyin ti awọn ọmọ ẹgbẹ ti kọkọ dibo to ti ni 14, 842, 072 ìbò ki wọn to wa kéde rẹ̀ bayii ni Eagle Square.
Rasheed Tijani: Ìpèníjà ojú kìí ṣe ìdènà sí ọ̀nà àtijẹ mi
Arun iba ọrẹrẹ Lassa: dokita kan jalaisi nipinlẹ Kogi
Oríṣun àwòrán, Oyo amotekun Igba akọkọ kọ niyii ti ikọ Amotekun naa ti ke gbajare.
Iwe yii jẹ itan arosọ to da lori ọrọ ifẹ laarin awọn ọdọ mẹta ati ipa obi, ẹbi, ara, awujọ ati ọlaju aye igba naa lori ipinnu awọn ọdọ ọhun.
 Ọdún 1942 ni ìjọba portugal bẹ ̀ rẹ ̀ síí darí ilẹ ̀ yìí .
Àwọn kan fọwọ́ fún wọn lọ́mú, wọ́n fọwọ́ pa orí ọmú wọn nígbà tí wọn kò tíì mọ ọkunrin.
Èmi Johanu ni mo gbọ́ nǹkan wọnyi, tí mo sì rí wọn.
Ninu ọrọ ti ajọ NERC fi si oju opo Twitter rẹ, o ṣalaye pe awọn mẹkunnu ni afikun owo ina tuntun yoo ṣe lanfaani.
Ọmọ náà sín lẹẹmeje, ó sì la ojú rẹ̀.
Oríṣun àwòrán, others Àkọlé àwòrán, Modele yari pe kò ṣeeṣe fun ọkọ oun lati fipa ba ẹnikẹni lo pọ O ni ọkọ oun ko lee fipa ba ẹnikẹni lo pọ nitori oun jẹri ọkọ oun.
Mose kò sì lè wọ inú rẹ̀ nítorí ìkùukùu tí ó wà lórí rẹ̀, ati pé ògo OLUWA kún inú rẹ̀.
Bí ìtàn náà tì lọ nì yí.
Ẹ fọkànbalẹ̀, kọ́bọ̀ kò ní gun owó epo pẹtiró - NNPC Irọ́ ni pé a fẹ́ fowó kún owó iná mọ̀nàmọ̀nà- NERC NLC: Ọ́nà àti mú òṣìṣẹ́ ìpínlẹ̀ lẹ́rù ni àwọn Gómìnà fẹ́ dá, a ò sì ní gbà!
Oríṣun àwòrán, Getty Images Iroyin ọwọn gogo ipawọ apakokoro ti mu ki oriṣiriṣi ọna lati ṣe agbelẹrọ rẹ ti wa kaakiri lri ayelujara.
 Àwọn ọkùnrin tó bọ ́ lọ ́ wọ ́ ewu àrùn náà ṣì lè kó àrùn bá ẹlòmíràn nípasẹ ̀ àtọ ̀ wọn fún bí oṣù méjì .
Ẹ fi ògo fún OLUWA, gbogbo ayé,ẹ gbé ògo ati agbára wọ̀ ọ́!
 Nadal ti o je olukopa ti
Iṣẹlẹ yi to se awọn eeyan ni haa, waye lẹyin ọjọ mẹta ti Arabinrin Florence jade ile opo iku ọkọ rẹ, Sẹnẹtọ Abiola Ajimobi .
n óo sì mú kí o búra ní orúkọ OLUWA Ọlọrun ọ̀run ati ayé, pé o kò ní fẹ́ aya fún ọmọ mi lára àwọn ọmọbinrin ará Kenaani tí mò ń gbé, 
Bi o tilẹ jẹ pe agbẹnusọ fun ijọba ipinlẹ Ondo sọ fun awọn akọroyin pe, wọn ko ni yọ igbakeji gomina naa nipo nitori pe o fi ẹgbẹ oselu APC silẹ.
soro , ni eyi to tun gbe asai egbe naa fun oludije fun ipo gomina ninu egbe APC,
Arọwa temi ni wipe ki ijọba tun fi oju miran wo ọrọ yii""."
Coronavirus treatments: Lẹ́yìn ìgbélé Coronavirus, ọ̀nà wo ni mo lè gbà láti bọ́ l'ọ́wọ́ níní Covid-19.
Kwesi Nyantakyi, tó tún jẹ́ igbákejì ààrẹ àjọ tó n ṣe kòkáàrí bọ́ọ̀lù aláfẹsẹ̀gbá ní ilẹ̀ Afrika, ni wọ́n fi ẹ̀sùn kàn pé, ó hu ìwà jẹgúdújẹrá.
"Ọlọ́run nìkan ló mọ bí ìrìnàjò ìfẹ́ ẹ̀dá á ṣe rí láyé, ọ̀dọ́ Aláàfin ní orí gbémí yà sí, ó sì tẹ́milọ́rùn- Olorì Aanu Èèyàn 334 ló gbàwòsàn lọ́wọ́ Covid-19 l'Ọjọru, 453 míì tún lùgbàdì rẹ̀- NCDC Ó takò òfin kí àwọn obí jẹ̀yà ti ọmọ ba darapọ̀ mọ́ ẹgbẹ́ òkùnkùn- Ajàfẹ́tọ̀ọ́mónìyàn Nkiru ni: ""Bi a ṣe de papakọ ofurufu lati lọ wọ baalu ti ijọba ṣeto ni wọn ni awọn ko ni faaye gba wa, awa marun, wọn ni Madaamu wa wa fi ẹjọ wa sun toripe a kuro nile."
Igbakeji aarẹ ni, wọn gbọdọ jabọ ni ọjọ Kẹrinlelogun oṣu kẹfa ọdun 2019 bayii.
Ó ní, ‘Ọjọ́ ń bọ̀ tí a óo ru gbogbo ohun tí ó wà láàfin rẹ lọ sí Babiloni, ati gbogbo ìṣúra tí àwọn baba ńlá rẹ ti kó jọ títí di òní.
ọpọlọpọ ẹgbẹ awọn akọṣẹmọṣẹ ninu iṣẹ epo bẹntiroo ati afẹfẹ gaasi lorilẹ-ede
Mose ju igi náà sinu omi, omi náà sì di dídùn.
CBN dín owó sísan lóri lílo ATM kù Sambo Dasuki gbòmìnira lẹ́yìn ọdún mẹ́rin Kò sí nǹkan tí yóò ṣe Goodluck Jonathan lábẹ́ ìṣèjọba mi-Buhari Olè yabo báńkì.
Ọba rán Hadoramu tí ó jẹ́ olórí àwọn akóniṣiṣẹ́ sí àwọn ọmọ Israẹli, ṣugbọn wọ́n sọ ọ́ lókùúta pa.
Ó tún fi kún un pé, “A ní ọpọlọpọ koríko ati oúnjẹ ẹran, ààyè sì wà láti sùn ní ilé wa.
Ìrísí àwọn àgbá kẹ̀kẹ́ náà ati bí a ti ṣe wọ́n nìyí: wọ́n ń dán yànrànyànràn bí òkúta kirisolite.
Bakan naa ni awọn to lowo pupọ naa wa, alaafo to si wa laarin olowo ati talaka ko farapamọ rara, gbogbo oju lo n ri ni awọn ilu nlanla to wa ni Naijiria.
Ẹsita tún rán an pada sí Modekai pé, 
Gbé ẹbọ àwọn eniyan náà wá, kí o sì ṣe ètùtù fún wọn, gẹ́gẹ́ bí OLUWA ti pa á láṣẹ.
Ilé ẹjọ́ sún ẹjọ́ Sẹ́nétọ̀ Abbo síwájú pẹ̀lú béèlì mílíọ̀nù márùn-ún Amuneke fipò sílẹ̀ gẹ́gẹ́ bí akọ́nimọ̀ọ́gbá Tanzania Kí l'ànfàní àdéhùn okoòwò kan l'Afíríkà, AfCFTA tí Buhari tọ́wọ́ bọ̀?
Ọjọgbọn iṣegun naa ṣalaye pe ti ajakalẹ aarun ba bẹ silẹ lẹẹkeji, ọwọja rẹ maa n ṣaa ba le ju ti igba akọkọ lọ.
Mo kan gbe, mo si ju u si ibi ti awọn oṣiṣẹ ileewosan ti ri.
OLUWA ní, “Ṣugbọn àwọn ọmọ Lefi tí wọ́n pada lẹ́yìn mi, tí wọ́n ṣáko lọ kúrò lọ́dọ̀ mi, tí wọ́n sì ń tẹ̀lé àwọn oriṣa wọn nígbà tí Israẹli ṣáko lọ, yóo jìyà ẹ̀ṣẹ̀ wọn.
Ọmọ Ibadan, Peace Busari tí wọ́n fẹ́ tà lórí Facebook ti dé sí Naijiria láti Lebanon Ìjí líle, Cyclone Fani, kọlu Ìlà-Oòrùn India Ileesẹ BBC gbọ pe, o kere tan, eeyan mẹrindinlogun, to fi mọ awakọ ofurufu naa, lo ti jade laye.
 Ìkíní ni , Àṣà àti ìsẹ yorùbá lórí Ìkíni .
Ìtàn ayé Shina Rambo, adigunjale tó fi oyún 27 gún ọṣẹ Ninu ọrọ rẹ, Akintayo salaye pe lootọ ni awọn kanda kan wa laarin awọn nọọsi sugbọn eyi ko ni ki wọn tabuku gbogbo olutọju alaissn bii aṣẹwo.
Bí wọn bá ti bá mi pé ní ìgbìmọ̀ ni, wọn ìbá kéde ọ̀rọ̀ mi fún àwọn eniyan mi, wọn ìbá yí wọn pada kúrò lọ́nà ibi tí wọn ń rìn, ati iṣẹ́ ibi tí wọn ń ṣe.
Won tun ni lojojumo o fẹrẹẹ to omo ẹgbẹrin ti ọjọ ori wọn ko tii to ọdun marun ti wọn ma nse alaisi lataari aarun igbẹ gbuuru ti omi idọti ati ayika ti ko mo ma nse okunfa rẹ.
Wọ́n ní, ‘A ti ṣẹ̀, nítorí pé a ti kọ OLUWA sílẹ̀, a sì ń sin oriṣa Baali, ati ti Aṣitarotu.
Lówùúrọ̀ ọjọ́ keji, bí ó ti ń pada lọ sinu ìlú, ebi ń pa á.
Ìfihàn yìí ni a fi fúnni ní àkókò tí à nṣe àkójọ ìjọ, ní ọjọ́ tí a dárúkọ yìí, nínú ilé Peter Whitmer Àgbà.
Ẹrí rè é, Sanwo-Olu ṣèlérí lóòtó lórí súnkẹrẹ-fàkẹrẹ Apapa Ẹ yé irọ́ pa, mí o fún Super Eagles ní ẹbùn owó kánkan -Sanwo Olu Kí ni Bode 'Thomas' ní ṣe pẹ̀lú ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ Nàìjíríà àti South Afrika?
a ba n sọrọ iṣẹ aabo ilu, o gbọdọ jẹ eyi ti wọn yoo le mojuto adugbo
shaikh hassan zaruq bẹ ̀ rẹ ̀ ẹ ̀ kọ ́ lárúbáwá ( arabic school ) nínú ẹ ̀ sìn músùlùmí ní ilé-kéwú ọ ̀ dọ ̀ àbúrò bàná rẹ ̀ ní pàkátà ìyẹn shaikh suleiman ẹni tí ó kọ ní kìkà alùkùránì ṣájú kí ó tó lọ sílé ẹ ̀ kọ ́ lárúbáwá ( shuban arabic school ) , ní pàkátà .
Ọ̀gá ọlọ́pàá pàṣẹ kí wọ́n ṣé ìwádìí ọlọ́pàá inú àwòrán 4+4
Ilẹ̀ tí gègé olukuluku bá mú ni yóo jẹ́ tirẹ̀, láàrin àwọn ẹ̀yà yín ni ẹ óo ti pín ilẹ̀ náà.
Lawan  lo ka awon leta ti won ri gba lati
Ti ẹ ko ba gbagbe, Arsenal lo kọkọ digbaju ru Chelsea laipẹ yii pẹlu ami ayo mẹta si ẹyọkan.
’ rèé Ọ̀gá ọlọ́pàá Adamu Pàṣẹ́ iṣẹ́ àkànṣe nílẹ̀ Yorùbá Ta ni Ọgágun àgbà Lamidi Adeosun tó ṣẹṣẹ gba ìgbéga?
Ọwọ palaba oludari NURTW tẹlẹri kan, Rafiu Akanni ti wọn npe ni Ọlọrunwa naa se'gi pẹlu.
- MC Oluomo Ṣé òògùn Chloroquine lè dènà ààrùn Coronavirus bí?
Sugbọn lati igba ti isẹlẹ ọhun ti waye, ko si Olori Alaafin kankan to ki Ayaba Badrat ku ayẹyẹ ọjọ ibi rẹ, ti oun naa ko si ki ẹnikẹni ninu wọn.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù AfricanDrumFestival: Àwọn àwòrán tó làmìlaaka níbi ayẹyẹ 20 Ìgbé 2018 Awọn aworan to lamilaaka nibi ayẹyẹ ajọ̀dún ìlù nílú Abẹ́òkúta.
’ Sọ fún wọn pé: Ọjọ́ ń súnmọ́lé tí gbogbo ìran àwọn aríran yóo ṣẹ.
Àwọn olóyìnbó ń pe ọ̀rọ̀ kan ní vaginismus.
Owo to to aadọjọ miliọnu le mẹta owo dọla ($153m) ni EFCC fẹsun kan minisita epo rọbi tẹlẹ pe o ji ko Wọn ni o ko owo yii sa lọ ṣaaju idibo gbogboogbo ọdun 2015.
Ṣe ni Ọba ilu Benin ni lati tu u loju pẹlu ọpọlọpọ ilẹkẹ, ẹru, atawọn ohun pataki miiran pe ko ma gbe ogun de ọdọ awọn eeyan oun.
Nígbà tí àwọn olórí ogun tí wọ́n wà ní ìgbèríko pẹlu àwọn ọmọ ogun wọn gbọ́ pé ọba Babiloni ti fi Gedalaya ọmọ Ahikamu ṣe Gomina ní ilẹ̀ Juda, àwọn pẹlu àwọn eniyan wọn wá sí ọ̀dọ̀ Gedalaya ní Misipa.
Amosa, egbe oselu Chadema ti  fesun kan awon olopaa pe awon ni won ji Mdude
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ballon D'or 2019: Ronaldo ló dáńtọ́ jùlọ (GOAT), bó tilẹ̀ jẹ́ pé Messi ló gb'àmì ẹ̀yẹ Ballon D'or 3 Ọ̀pẹ̀̀ 2019 Oríṣun àwòrán, Instagram/cristiano Lootọọ ni aramọnda agbabọọlu Lionel Messi gba ami ẹyẹ Ballon D'or fun igba kẹfa bayii, ṣugbọn aṣoju orogun rẹ, Jorge Mendes faake kọri.
5m owó oyè tó gbà lọ́wọ́ òkú padà, àwọn ará ilé rẹ̀ ń bèèrè - Olúbàdàn Oyè Ibadan kò sí fún títà - Otun Olubadan, Lekan Balogun Owó àwọn aṣòfin kò pọ̀jù, iṣẹ́ kàbàtì tí wọn ń ṣe ju owó oṣù wọn lọ - Buhari Kò síbi tó dàbí ilé, tìlù-tìfọn ni wọ́n fi kí Anthony Joshua tó bẹ ìlú rẹ̀, Ṣágámù wò káàbọ̀ Àbòsí ló wà níbẹ̀ tí ìpínlẹ̀ Eko ò bá ṣe Amotekun- Bode George O fikun pe, igbesẹ tijọba gbe naa lo n mu ominira ba awọn awakọ gan ni, owo ẹẹkan pere ti wọn ba san wa lati aarọ titi di alẹ, pẹlu afikun pe awọn to n dunkoko mọ ijọba ko mọ ohun ti wọn n sọ ni.
Ifeanyi Ejiofor tó jẹ́ agbẹjọ́rò Ọ̀gbẹ́ni Kanu ti saaju sọ wí pé olórí IPOB náà ti pe òun lórí ẹ̀rọ ìbánisọ̀rọ̀ lẹ́yìn fídíò bí ó ṣe ń gbàdúrà ní ilẹ̀ Jerusalem lórí ìtàkùn ayélujára.
Wọ́n fi iná sun gbogbo ìlú wọn ati àwọn abúlé wọn, 
China, Nàìjíríà, kò s'áyè òwò mọ́ ní Ghana!
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ìbejì Oníbẹ̀mbẹ́ Òru tí kò yara wọn lẹ́yìn ọgọ́ta ọdún Ohùn ìjálá lásán ni mo fi ń pa ẹran nínú igbó - Ọdẹ Oníjàálá Mo fẹ́ ọkọ mi torí bó se ń kọrin, kìí se torí owó - Ìyàwó Aràrá Mo fẹ́ kí àyẹyẹ ìgbeyàwó mi dùn ni mo se bú sẹ́kún - Ọkọ ìyàwó ẹlẹ́kún Samuel Ladoke Akintọla jẹ́ Agbẹjọ́rò àti Akọ̀ròyìn tí ọ̀rọ̀ dá lẹ́nu rẹ̀ Hubert Ogunde rèé, baba àwọn òsèré tíátà Ìyàtọ̀ wà nínú ìlépa àwọn òṣèré tíátà ayé àtijọ́ àti ìsisìnyí-Papalolo O mọ oge se, kii jẹ ounjẹ iwọsi, ko si si ẹni ti ko lee wo oju rẹ.
Ipinnu awọn asofin yii ko sẹyin bii wọn se fẹsun kan minisita fun ọrọ isuna, sẹnetọ Udo Udoma wi pe o bu ẹnu atẹ lu wọn.
àní, àwọn tí mo ti pamọ́ de àkókò ìyọnu,fún ọjọ́ ogun ati ọjọ́ ìjà?
Àwọn kan ń kó ọpọlọpọ wúrà jáde ninu àpò,wọ́n sì ń wọn fadaka lórí ìwọ̀n.
“Olùkọ́ni, Mose sọ pé bí ẹnìkan bá kú láì ní ọmọ, kí àbúrò rẹ̀ fẹ́ aya rẹ̀ kí ó lè bí ọmọ fún ẹ̀gbọ́n rẹ̀.
Eyi ni ọrọ to ṣe kongẹ awọn eeyan ileto Sagbokodji ni ipinlẹ Eko.
' Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Coronavirus in Lagos: 'Bí Covid19 bá peléke síi l'Eko, ilé la ó ti máa tọ́jú àwọn kan'
Ó ṣe ni laanu pé fún ọdún mẹ́rìndínlógún ti Òṣèlú ti gba Ìjọba, wọn kò fi hàn pé wọn ni àánú ará ilú rárá.
Ẹnikẹ́ni tí ó bá sùn ninu ilé náà tabi tí ó bá jẹun ninu rẹ̀ gbọdọ̀ fọ aṣọ rẹ̀.
Oríṣun àwòrán, Alaafin Oba Adeyemi 111 Facebook Gẹgẹ bi iwadii wa ti safihan rẹ, diẹ lara awọn olori yii lo jẹ akẹkọọ nilu Oyọ, ti ifẹ Ọba Adeyemi si gba ọkan wọn.
ibi òkùnkùn ati ìdàrúdàpọ̀,níbi tí ìmọ́lẹ̀ ti dàbí òkùnkùn.
 O ni:“Awon agbasese to je eniyan orile ede yii tijoba je lowo to din logorun un milionu naira ni won ti san gbese won fun.
Naijiria to n gbe ni orile ede Austria.
Wọn ṣa omii ni ada ti wọn si tun ṣa èyi to kù wẹlẹ wẹlẹ.
Afẹ́fẹ́ yóo fẹ́ gbogbo àwọn olórí yín lọ,àwọn olólùfẹ́ yín yóo lọ sí ìgbèkùn.
Oríṣun àwòrán, @others Àkọlé àwòrán, A gbọ ẹjọ ẹnikan da.
Mò ń ṣe nǹkan titunó ti yọ jáde nisinsinyii,àbí ẹ kò ṣe akiyesi rẹ̀?
Ileesẹ ologun Orilẹede Russia lo fidi isẹlẹ yii mulẹ.
Ọ̀rọ̀ kàǹkà-kàǹkà lásán, tí kò ní ìtumọ̀, ní ń ti ẹnu wọn jáde.
 ) ( don ' t encourage bad habits in a child .
yoo maa tuko iko naa fun idije saa 2018/2019 to n bo yii, (Nigeria Women Premier
Joabu gbógun ti Raba, ó sì ṣẹgun rẹ̀.
O gbàgbé pé òun ti dẹ pàkúté sí ojú ọ̀nà dè mí, ibi tí o ti ní kí òun kọjá ní ojú ọ̀nà wá bá mi ni pàkúté mú u, ọ̀ràn mi wa túbọ̀ lẹ, ìjàngbọ̀n ń le mi bọ̀ mo pàdé ìjàngbọ̀n lọ́nà àti kúrò lọ́wọ́ ìjàngbọ̀n di ìjàngbọ̀n fún mi.
Ọjọgbọn Akintoye jẹ ọkan lara awọn agba ọjẹ alakada to n ṣiṣẹ lori itan iran Yoruba.
A kọ àkọsílẹ̀ wọn ní àkókò Jotamu, ọba Juda, ati ní àkókò Jeroboamu ọba Israẹli.
Sunday Igboho: Alukoro ọlọ́pàá Ọyọ ní àwọn ọlọ́pàá kọ́ ló kọlu aráàlú, iṣẹ́ wọn ni wọ́n ń ṣe
Jẹ ẹni tí ó bá jẹ̀bi ní ìyà gẹ́gẹ́ bí ẹ̀ṣẹ̀ rẹ̀; dá ẹni tí ó bá jàre láre, kí o sì san ẹ̀san òdodo rẹ̀ fún un.
Agbẹnusọ àjọ ọlọ́pàá Jimoh Moshood nínú àtẹ̀jáde kan tó fọ́wọ́ sí sàlàyé pé àwọn ti kọ̀wé sí àkọ̀wé ilé ìgbìmọ̀ aṣòfin pé kí Dino Melaye fójú kàn ilé iṣẹ́ ọlọ́pàá tó wà ní ìpínlẹ̀ Kogi láti sọ tẹnu rẹ̀ sùgbọn ó fààké kọ́rí kò yojú.
Àwọn èèyàn tí bẹ̀rẹ̀ sì ní gba abẹ́rẹ́ àjẹsára fún ìdènà àrùn Coronavirus ni ilẹ̀ Gẹ̀ẹ́sì Ìjọba àpapọ̀ ti kéde àdínkù owó epo bẹntiróòlù sí N162.
Adajọ to n gbọ ẹjọ naa, Bode Adegbehingbe ṣe idajọ ọkunrin naa lẹyin ọdun mẹji ti ẹjọ ọhun ti wa niwaju rẹ.
Oríṣun àwòrán, Twitter Àkọlé àwòrán, INEC ní ìwé ìfitónilétí ti ó tẹ òun lọ́wọ́ ní ọjọ́ kejìdínlógún oṣù kẹfà ọdún yìí kò ni àbuwọ́lù àlága àpapọ̀ ẹgbẹ́ náà.
Bakan naa lo fikun pe ọwọ sinku ọlọpaa ti ba eeyan mẹrindinlogun, ti wọn si ba awọn ohun ija oloro lọwọ wọn.
Mo fẹ kí o rántí pé àṣà burúkú àwọn ọmọ ènìyàn kò fún obìnrin ni àyè àti yan ọkọ tí ọkàn rẹ̀ fẹ́, àwọn ọkùnrin ni ó ní àyè àti kọ́ wí fún obìnrin wí pé kí ó fẹ́ àwọn.
Ọ̀rẹ̀ yin ni mo fẹ́ ṣe.
Dìde, gbọnranù kúrò ninu erùpẹ̀,ìwọ Jerusalẹmu tí ó wà ninu ìdè.
Ẹsita tún bẹ ọba, ó wólẹ̀ ní ẹsẹ̀ rẹ̀, ó sì bẹ̀ ẹ́ pẹlu omijé, pé kí ọba yí ète burúkú tí Hamani, ará Agagi, pa láti run àwọn Juu pada.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ogun Majek: Lórí ọ̀rọ̀ Ogun Majek, mi ò lọ́rọ́ láti sọ, ẹ lọ pe ẹni tára rẹ̀ kò yá- Mr.
–ise ologun ofurufu, Air Vice Marshal Kingsley Lar, ati awon akegbe re fun aseyori
O parowa pe, “Mo fe ro yin lati sa gbogbo ipa yin, tori pe aarun kogbogun HIV je otito, aarun kogbogun yii wa pelu wa, o si n ba wa gbe, mo ni igbagbo pe, pelu erongba isakoso ijoba to wa lori alefa, orile-ede Naijiria yoo kuro nipo ti o buru ju lagbaye”.
Wọn n pe e ni ẹṣin iwaju sibẹ o n mu igbo o si n kọrin nipa ẹya ara.
Ọbabinrin Elizabeth sọ pe awọn ọrọ to so mọ ipinnu Harry ati Meghan pọ, to si n pe fun ọpọlọpọ iṣẹ la ti ṣe Oríṣun àwòrán, EPA Awọn tọkọtaya naa tun fidi rẹ mulẹ lẹẹkan sii pe awọn ko fẹ gboju le owo ilu.
Awọn alasẹ ileewe naa sọ fún bbc Pidgin pe wọn ko ji ẹni kankan gbé.
" Nollywood: Joke Silva ní ọkọ òun ni ìtànsán òòrùn tó ṣe iyebíye Oríṣun àwòrán, joke silva Gbaju-gbaja oṣere Nollywood, Olu Jacobs pe ọdun mẹtadinlọgọrin loni, ọjọ Kọkanla, oṣu Keje, ọdun 2019.
Bakan naa, Obayi tun je ki o di mimo pe gege bi iwadii Nigeria
Asẹyinwa-asẹyinbọ, ileẹjọ kede pe Kabiyesi Ọba Samuel Adeniran Asusumasa Atewogboye Keji, Alaaye kẹtalelogoji nilu Efon Alaaye ati babalawo rẹ, awọn iransẹ ati Gabriel Olabinrinjo jẹbi ẹsun ijọmọgbe ati ipaniyan.
Àwọn tí wọ́n jẹ́ ọmọ alufaa ninu wọn nìwọ̀nyí: àwọn ọmọ Habaya, àwọn ọmọ Hakosi, ati àwọn ọmọ Basilai (tí ó fẹ́ aya ninu ìdílé Basilai ará Gileadi, tí wọ́n sì ń fi orúkọ àna rẹ̀ pe àwọn ọmọ rẹ̀).
Gbogbo wọn jẹ, wọ́n yó; wọ́n sì kó àjẹkù wọn jọ, ó kún apẹ̀rẹ̀ meje.
A ó san ẹ̀san ire fún ẹbí Richard, a ó sí san owó gbogbo ètò ìsìnkú - Iléesẹ́ ọṣẹ tí akẹ́kọ̀ọ́ UI kú sí Àgbà òṣèré tíátà míràn tún jáde láyé!
Bẹẹ na lo tun sọ lọdun 2019 pe oun yoo du ipo aarẹ ninu idibo ọdun 2020, ṣugbọn o pa ọrọ da pe o di ọdun 2024 ki oun to dije.
    Ki n má tàn yín jẹ, bí o tilẹ̀ jẹ́ pé awa ọpdé pàtẹ́wọ́ nígbà tí wọ́n sọ bẹ́ẹ̀, bí ẹni pé ó dùn mọ́ wa nínú, síbẹ̀ àyà olúkúlùkù já láti bá ẹranko jà.
Ṣugbọn Sila ati Timoti dúró ní Beria.
Ijọba apapọ sọ wipe awọn o san owo kankan lati gba awọn akẹẹkọ naa kuro ni igbekun Boko Haram.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù NYSC: ìdí tí a fí gba Davido láàyè láti jade 9 Èbibi 2018 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 3 Owewe 2018 Oríṣun àwòrán, Instagram/Davido official Àkọlé àwòrán, Davido ti di asoju fun ile-isẹ ẹrọ ibaraẹnisọrọ, Infinix Ilé iṣẹ́ agùnbánirọ tí ìpínlẹ̀ Eko sàlàyé pé àwọn fún Davido láàyè láti kúrò ní àagọ agùnbánirọ nítorí pé ó gbààyé pé ààbo àti aláfíà ẹmi oun kò gbópọn tó.
Orilẹede Norway ti si'de idije erebọọlu awọn abinrin ni agbaye, Women's World Cup pẹlu bi wọn se naa ikọ Super Falcons Naijiria pẹlu ami ayo mẹta si odo.
Bí èyí kò bá rí bẹ́ẹ̀, alaimỌlọrun ni àwọn ọmọ yín ìbá jẹ́ ṣugbọn nisinsinyii ẹni Ọlọrun ni wọ́n.
 bàba rẹ ̀ jẹ ́ mínísítà fún ilé ìjọsìnn greek orthodox church tí ó sì tún jẹ ́ olùkọ ́ nílé ìjọsìn kan náà.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ọmọge Campus: Lọla Alao ní Aisha ti ni àìsàn jẹjẹrẹ ti pẹ́ Ẹwẹ, o jẹ minisita fun eto ẹnawo lọdun 1971 si 1975.
Àwọn aya Dafidi mejeeji, Ahinoamu ará Jesireeli ati Abigaili ará Kamẹli, opó Nabali, sì wà pẹlu rẹ̀ níbẹ̀.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Dino Melaye: Mò ń bọ wá yojú sí yin lágọ́ọ̀ ọlọ́pàá 29 Ọ̀pẹ̀̀ 2018 Oríṣun àwòrán, @dinoofficial Àkọlé àwòrán, Dino Melaye: Mò ń bọ wá yojú sí yin lágọ́ọ̀ ọlọ́pàá Sẹnatọ Dino Melaye tí fẹ̀sì sí àtẹ̀jáde àjọ ọlọ́pàá, ó no òun kìí ṣe ọdaràn nítori náà láìpẹ́ òun yóò yọju sí àgọ́ ọlọ́pàá.
’ rèé Afọnja, ẹni tó finú wénú ní Ilọrin, àmọ́ tó jẹ iwọ Ẹfunsetan Aniwura, obìnrin tó ju ọkùnrin lọ Ọ̀rọ̀ǹpọ̀tọ̀niyùn, Aláàfin obìnrin àkọ́kọ́ rèé, tó ní nǹkan ọkùnrin Díẹ̀ lára ǹkan to yé kí o mọ̀ nípa Kanu Nnwankwo rèé Kanu Nwakwo tó mílíọ̀nù mẹ́sàn-an naira ní ti gbogbo ǹkan ìní àti owó ti ìròyìn fi ye ni pé Kanu tí gbogbo ènìyàn máa ń pe ni Papilo ní ilé ni Victoria Island, Owerri, ipinle Eko, Dubai, àti London, o ni ọkọ̀ Ferrari, Mercedes Benz ati Audi, ó ni ilé iṣẹ́ mohunmaworan fún ere ìdárayá .
eyi ti won pese fun anfaani won.
Ọpọlọpọ awuyewuye lo ti n lọ lori lilo ẹrọ to n pa ọjọ ori ẹni da FaceApp, ti o le mu ki aworan eniyan kere sii ni ọjọ ori, abi ki o dabi arugbo.
Ikenga Imo Ugochinyere ni tirẹ gboriyin fun Obasanjọ pe o sọju abẹ niko lori ọrọ naa lai parọ nitori oloogbe Kashamu.
Wọ́n ta ère Ọ̀ṣun Osogbo sí Togo - Bàbá Ọṣun figbe ta Baṣọ̀run Gáà, tó yan ọba mẹ́rin, pa ọba mẹ́rin àmọ́ ọba karùn-ún ló pa á Ọbasanjọ sọ àsírí sàgbàdèwe rẹ̀ Jesu Oyingbo rèé, pásítọ̀ tó láṣẹ ìbálòpọ̀ lóri ọmọ ìjọ obìnrin Igbó mímu lè ṣe kóríyá, kò lé fi kún orín ẹnu òṣèré - 9ice Atawẹwẹ sọ pe, ati ọmọ ọdun mẹrin ni oun ti n kọrin, orin kikọ si lo gbawe kika lọwọ oun.
Iṣẹju karundinlogoji ifẹsẹwọnsẹ naa ni Salah gba ayo akọkọ wọle ko to gba ikeji wọle ni iṣẹju karundinlaadọta.
Ó jà kíkankíkan, ó sì pa àwọn ará Filistia.
Kí àwọn eniyan tí ń gbé inú wọnmá ní agbára mọ́,kí wọ́n wà ninu ìdààmú ati ìpayà.
 kò pẹ ́ , ìròhìn ti tàn ká pé àjìji kán fẹ ́ gbọ ́ gun wọ ̀ lú .
Dípò bẹ́ẹ̀, gbogbo èrò wọn di asán, òye ọkàn wọn sì ṣókùnkùn.
Wọn bẹrẹ adura kikan pe ki gnogbo ipinu mọndaru ma waye ninu eto isin igbeyawo naa.
Èyí jẹ́ ìdáhun sí igbé àwọn ọmọ Nàìjíríà lori àba ti ilé iṣẹ́ MTN dá pé, yóò bẹ̀rẹ̀ si ni yọ ààdọta naira láti ọjọ kọkanlélogun osù yìí.
Wọn sì ṣe é ní àṣáálẹ́ ọjọ́ kẹrinla oṣù kinni ní aṣálẹ̀ Sinai.
Nítorí náà nígbà tí àwa ti mọ ohun tí ìbẹ̀rù Oluwa jẹ́, a mọ̀ pé eniyan ni a lè gbìyànjú láti yí lọ́kàn pada.
Òun pàápàá ti múra sílẹ̀ dè mí, bí mo sì ti béèrè ti mo bú sí ẹ̀rín tí mo wí pé, ‘O káàbọ̀ o, ṣe àlàáfíà ní ayédèrú ẹ̀gbọ́n rẹ wà?
 omowe Zhou Pingjian so pe, orile-ede Nigeria ati orile-ede China ti ni ajosepo to fese mule latigba ti orile-ede mejeeji ohun ti bere ajosepo won.
Nígbà tí wọ́n mú dé ọ̀dọ̀ Ọba, Ọba bi ìgbín léèrè bóyá òun ni ó pa abúlé Ọba.
Manchester United ni lati pari ifẹsẹwọnsẹ naa pẹlu agbabọọẹu mẹwa dipo mọkanla nitori ọkan lara awọn agbabọọlu rẹ, Jesse Lingard to fara pa to si ni lati fi ori papa silẹ ṣaaju opin ifẹsẹwọnsẹ naa.
 A wa sibi gege bi omo onilu ati lati jo  sajoyo odun ere-idaraya Uyo todun ti a wayii.
Èṣù tún mú un lọ sórí òkè gíga kan; ó fi gbogbo àwọn ìjọba ayé ati ògo wọn hàn án.
Ti a ko ba gbagbe, saa mọkanla ni Ole Gunnar Solskjaer fi jẹ agbabọọlu Manchester United to si jẹ ẹni to gba bọọlu wọnu awọn ni ọdun 1999 ti wọn fi gba ami ẹyẹ Champions League ti ọdun naa.
pataki akọkọ ninu ayẹyẹ naa, ti wọn jẹ Oludari ẹka
Nínú àtẹjáde kan ti Garba Sheu, to jẹ oluranlọwọ pataki fún ààrẹ kọ láti fi ki ààrẹ ànà Olusegun Obasanjo fún ayẹyẹ ọjọ́ ìbí ọdún kẹrìnlélọgọrin rẹ, ni Buhari ti woye ọrọ yii.
Ṣugbọn ni ọjọ Abamẹta to kọja, Obi, to jẹ ọkan pataki ninu idije Trabzonspor, kọ ọ si ori ayelujara pe oun ko faramọ igbesẹ naa.
Nígbà náà ni ìkùukùu bo àgọ́ àjọ náà, ògo OLUWA sì kún inú rẹ̀.
OLUWA bá wí fún mi pé, “Kò burú, n óo jẹ́ kí o fi ìgbẹ́ mààlúù dáná láti fi dín àkàrà rẹ, dípò ìgbẹ́ eniyan.
Amọ, Funkẹ ya ọpọ eeyan lẹnu nigba ti o pe apejẹ lati dupẹ lọwọ awọn ololufẹ rẹ.
Ẹ ṣe bí àdàbà, tí ó kọ́lé rẹ̀ sí ẹ̀gbẹ̀ẹ̀gbẹ́ ẹnu ihò àpáta.
 Awon mii ti won wa nibe ni Oludari agba, Ogbeni Nsima Ekere, Oludari eka ise akanse, Ogbeni Samuel Adjogbe, asoju ipinle Bayelsa ni ajo NDDC, Ojogbon Nelson Brambaifa ati awon oludari eka miranninu ajo NDDC.
‘Dandan ni kí á fi Ọmọ-Eniyan lé àwọn eniyan burúkú lọ́wọ́, kí wọ́n kàn án mọ́ agbelebu, ati pé kí ó jí dìde ní ọjọ́ kẹta.
Nígbà kan, ẹnìkan wá sọ́dọ̀ Jesu, ó bi í pé, “Olùkọ́ni, nǹkan rere wo ni kí n ṣe kí n lè ní ìyè ainipẹkun?
Wayi o, awọn ololufẹ Bukunmi lo ti n ki ku oriire lori isẹ ti Funke Akindele, ti ọpọ eeyan mọ si Jenifa, ran si ọhun, ti wọn si tun n ba dupẹ lọwọ osere-binrin naa pe o ku ọmọ se.
Sááju ni agbẹ́jọ́rò fún àjọ ọlọ́pàá Simon Lough ti sọ fún àdájọ Binta Nyako pé ilé iṣẹ ọmọogun kò jọ̀wọ́ àwọn ọmọogun tọ́rọ̀ kàn láti waá sílé ẹjọ́.
Wọ́n tún ṣe’kan tó jọ dùndú anọ̀mọ́ tí wọ́n ń pè ní “fries”.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Myanmar: kékeré ni wọ́n ti n kọ́ àwọn ọmọ nípa ọ̀nà oge ṣiṣe Amọṣa, ninu ọrọ to ba awọn oniroyin kan sọ, alukoro ileewe gbogboniṣe Poly Iree, Tọpẹ Abiọla ṣalaye fawọn akọroyin pe ko si ẹbi lọwọ awọn oṣiṣẹ ileewosan to jẹ ti ileewe naa.
Oríṣun àwòrán, yorubyte O wa yẹ ko ye gbogbo wa bayii pe, ka ma se ilakaka pe a ko bi ọkunrin, tabi obinrin nikan la n bi jọ, nitori gbogbo lọmọ, ko si eyi ti ko wulo ninu wọn.
Gege bi atejade kan se so,ogbeni Dare ni iwe ase ti won
Wọ́n bá lọ, wọ́n sì ṣe bí OLUWA ti pàṣẹ fún Mose ati Aaroni.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Building Collapse: Ìdí tí ilé fi ń wó nìyí' 15 Ẹrẹ̀nà 2019 Oríṣun àwòrán, Reuters Àkọlé àwòrán, Ile wo pa ọpọ eeyan l'Eko Lẹyin ti ile alaja mẹta da wo ni Ita-Faji lagbegbe Lagos Island niluu Eko, ile iṣẹ iroyin BBC ṣe iwadii ohun to le maa ṣokunfa ile wiwo.
Fun Falz, eyi nikan lo le mu nkan pada bọ sipo.
Oríṣun àwòrán, Getty Images O sọ pe idi ti awọn eeyan fi fẹ́ ẹ pada sori papa ye mi, sugbọn wọn gbọdọ ṣe e ni ọna to mu ọgbọ́n dani, ati ni asiko to tọ́, ni ọna ti aabo yoo fi wa fun gbogbo eniyan, nitori pe kaakiri agbaye ni awọn agbabọọlu yoo ti wa, ko si si ẹni to mọ àwọn to ni i""."
"Ẹnikan fidi rẹ̀ múlẹ pẹ: ""ASD motors, iyẹn Alhaji Sani Dauda, fẹ́jọ sùn pé Sani gba ẹgbẹ̀run mẹ́wàá dọla lọ́wọ oun nítori pé ó sọ pé òun jẹ ọ̀rẹ́ tímọtímọ pẹ̀lú adele alaga àjọ EFCC."
Ikede yii si ni adajọ naa tun fi n sọ ero ọkan rẹ, lori bi awọn ẹlẹrii ti olujẹjọ naa pe, se n mu isunsiwaju ati ifasẹyin ba ẹjọ naa.
Èyí sì fẹ́ mí ìfura dání nítorí owó tí ó sonù.
Jesu dá a lóhùn pé, “Ta ni ìyá mi?
com, NCS Official Àkọlé àwòrán, Ipaniyan ajọ ẹṣọ aṣọbode Pẹlu iṣẹlẹ bi awọn oṣiṣẹ ajọ ẹṣọ aṣọbode ṣe yinbọn pa ara ilu kan laipẹ yii, oniruuru ibeere lo ti n jẹ jade.
Awọn cardinal naa ni oore-ọfẹ lati mu iwe idibo kan pere dani ni ọsan ọjọ akọkọ.
Ondo politics: Fayose ní ìkọjá àyè ni kọmíṣọ́nà ọlọ́pàá tó lọ de igbákejì gómìnà, Agboola Ajayi lọ́nà l'Ondo Oríṣun àwòrán, other Gomina tẹlẹ fun ipinlẹ Ekiti, Ayọdele Fayoṣe naa ti da si ọrọ to n lọ laarin igbakeji gomina ipinlẹ Ondo, Agbooọla Ajayii ati ọga rẹ, Gomina Rotimi Akeredolu eleyi to ti mu ki igbakeji naa o kọwe fi ẹgbẹ oṣelu APC silẹ.
Ẹwẹ, ọkọ akero mẹfa lo ti wa nilẹ lati ko awọn eeyan naa lọ si ibudo iyasọtọ nibi ti wọn yoo wa fun ọjọ mẹrinla aibaamọ aarun coronavirus le wa lara wọn.
17 Bélú 2020 9ice Marriage: Ẹ ba mi bẹ ìyàwó mi, òun ni igi lẹ́yìn ọgbà mi22 Bélú 2020 Akomolede Eko round up: Àwọn Olùkọ́ ìpínlẹ̀ Eko dárà lórí Akọ́mọlédè àti Àṣà lórí BBC7 Bélú 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù APC kéde ìkànì ẹ̀rọ ayélujára tuntun 15 Ìgbé 2018 Oríṣun àwòrán, Twitter.
Ṣugbọn ọmọ-ogun kan fi ọ̀kọ̀ gún un lẹ́gbẹ̀ẹ́, ẹ̀jẹ̀ ati omi bá tú jáde.
"Mo gbọ pe abẹrẹ yẹn gan-an lo da gbogbo nkan ru, ti mo fi di ẹni ti ko le rin mọ.
Wọ́n kò pa ẹnikẹ́ni sí ààfin Ṣọun Ogbomosọ, òkú tí àwọn ọdọ́ gbé wa ni ọlọ́pàá wọ́ jáde- Agbẹnusọ Ṣọ̀un Wo àwọn kọ̀ndísàn tuntun tí àwọn olùwọ́de #ENDSARS gbé jáde lẹ́yìn tí wọ́n tú SARS ká Wo ìgbà mẹ́rin tí ìjọba ti tú ikọ̀ ọlọ́pàá SARS ká sẹ̀yín ṣùgbọ́n.
Lapaapọ eeyan 63,036 ni ayẹwo ti fihan pe wọn ti ko aarun corinavirus lorilẹede Naijiria.
Èmi OLUWA tí mo ṣàánú fún ọ ni mo sọ bẹ́ẹ̀.
Buhari ni oun fẹ ki ẹka eto aabo ṣiṣẹ takuntakun sii, lati ri pe eto aabo duro daada l'orilẹede Naijiria.
Nígbà tí ó kún, wọ́n fà á lọ sí èbúté, wọ́n jókòó, wọ́n ṣa àwọn ẹja tí ó dára jọ sinu garawa, wọ́n sì da àwọn tí kò wúlò nù.
Wo àwọn oúnjẹ márùn ún tó ń mú kí àtọ̀ ọkùnrin dára síi Mi ò le tòṣì láéláé!
Mose bá wí ninu ara rẹ̀ pé, “N óo súnmọ́ kinní yìí, mo fẹ́ wo ohun ìyanu yìí, ìdí tí iná fi ń jó tí igbó kò sì fi jóná.
Ohun kan ṣoṣo ni wọ́n ní kí á ṣe kí á lè jọ máa gbé pọ̀, kí á sì di ọ̀kan, wọ́n ní olukuluku ọkunrin wa gbọdọ̀ kọlà abẹ́ gẹ́gẹ́ bíi tiwọn.
Yíjú kúrò lọ́dọ̀ mi,nítorí wọn kò jẹ́ kí n gbádùn.
N óo jẹ́ baba fún un, yóo sì jẹ́ ọmọ fún mi.
Ni ọdun 2008, o ri aridaju ayipada ninu ofin Algeria eyi to yọ gbedeke saa meji ti aarẹ le lo, igbesẹ yii si ni ile igbimọ aṣofin wọn ṣe atunṣe rẹ lọdun 2008.
Mo jẹ́ kí àwọn ọ̀tá rẹ fi ìwọ̀ra gba ohun ìní rẹ, àwọn ará Filistini tí ìwà burúkú rẹ ń tì lójú.
Idris fi awọn nọmba yii lede lati pe ti ẹnikẹni ba n huwa aitọ: (i) 08037025670 (ii) 08037160989 (iii) 08033415589 (iv) 08032451594.
Àwọn ọmọ Elifasi ni: Temani, Omari, Sefo, Gatamu ati Kenasi.
Ẹ óo máa fi ẹgbọ̀rọ̀ akọ mààlúù kan, àgbò kan ati ọ̀dọ́ àgbò meje ọlọ́dún kọ̀ọ̀kan tí kò ní àbààwọ́n rú ẹbọ sísun, olóòórùn dídùn sí OLUWA.
Ki a ba le mu ọjọ ni wọn fi ni awọn sun siwaju titi di igba miran.
Kí gbogbo ayé bẹ̀rù OLUWA,kí gbogbo aráyé dúró níwájú rẹ̀ pẹlu ọ̀wọ̀ ati ìbẹ̀rù!
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Imperial Majesty ni Olubadadan, Royal Majesty làwa, òfin sì tẹ̀lé e - Ọtun Olubadan Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Ẹ ti rí ìwé gbà nípa rẹ̀.
'Mo kan sara sawọn ayasọlo' Iya Rainbow, Jide Kosoko, Ọga Bello, yóò polongo Buhari fún 2019 Wo bí ilé ìtajà ńlá yìí ṣe di ọ̀run àpáàdì O sọrọ nipa ipa ti iṣẹ obi maa n ni lori igbiyanju ọmọ wọn.
Ẹwẹ, eyi ti mu iriwisi ọtọọtọ jade latẹnu awọn Naijiria ati pe bi iṣẹlẹ naa ko ba fidi mulẹ, eeṣe ti awọn alaṣẹ tọrọ kan bii Sunday Dare to jẹ minisita fun ọrọ ọdọ ati idagbasoke ere idaraya, gomina Eko Babajide Sanwoolu fi da si i ati lasiko yii gan?
O ni: Ni kete ti a bere ise lojo kokandinlogun osu kokanla odun 2015 ni a ti seleri lati je asoju rere fawon eniyan ti a n soju fun.
ee Àkọlé àwòrán, Estonia pàdánù owó gọbọi látàri Eku tó gba ìjọba ní Estonia O ni inu wọn dun pe iṣẹlẹ yii ko da akọsilẹ idanimọ awọn olugbe Estonia lori ayelujara ru tabi ko ba nkan jẹ ju bayii lọ.
O ni eyi ko yọ ti ẹgbẹ okunkun Buccaneer naa, to ma n waye ni ọjọ Kẹjọ, oṣu Kẹjọ silẹ.
Aare Muhammadu Buhari yoo bere iponlongo idibo re fun saa keji lori aleefa lojo Eti(Friday), ojo kẹ́rìndínlọ́gbọ̀n osu kejila odun ti a wayii, niluu Uyo, olu ilu ipinle Akwa Ibom.
 Ile ise iroyin Anadolu ni won je ara ile okeere ti won n wa ona lati gba awon eniyan wo inu egbe naa.
Ọga agba Mohammed bu ẹnu ẹ̀tẹ́ lu isẹlẹ yii, paapaa awọn to n wa lati ọwọ awọn ọlọpaa, o ni eyi ko jẹ itẹwọ gba rara.
Kùdìẹ̀kudiẹ wà nínú ìbò abẹ́nú APC tó yan Akeredolu, ṣùgbọ́n.
Ẹgbẹ́ IPOB ò tako Ààrẹ Buhari ní Japan- Iléeṣẹ́ Ààrẹ Òfin nìkan ló lè gbadé lórí àwa Ọba ìlú lbadan- Oba Lekan Balogun Irọ́ ló pa, a kò mọ̀ ọ́ rí tàbí fún ọ ní ₦13m - APC tako afurasí ajínigbé Fowler ni ọpọ awọn orilẹede lo ri ilẹ wa Naijiria bii ọja nla ti wọn ti lee se okoowo wọn lori afẹfẹ, idi si ree ti Naijiria naa fi gbọdọ lo anfaani yii lati pawo wọle.
awon  fayawo ohun fi ko eru wole si orile
Nígbà tí Dafidi gbọ́ pé Nabali ti kú, ó ní, “Ìyìn ni fún OLUWA tí ó gbẹ̀san lára Nabali nítorí àfojúdi tí ó ṣe sí mi.
Ojọgbọn Chidi Ugwu fidi ọrọ yi mulẹ ninu ifọrọwanilẹnuwọ pẹlu BBC ni idahun si ọrọ ti Ooni Ifẹ Oba Enitan Ogunwusi Adeyeye sọ laipe yi pe ọkan naa ni ẹya Yoruba ati Igbo.
 WamakkoIla oorun Ariwa: Asofin  Muh’d Ali NdumeAarin Gbungbun: Asofin  Abdullahi AdamuIwo oorun: Sola Oke, SANIla oorun
Nibayii, eeyan 945 lo ti ba ajakalẹ arun naa lọ ni Naijiria.
lorile ede Naijiria , ti o tun je alakoso ana fun ile –ise redio ti ipinle Kano
Pọtifari yìí ni olórí àwọn tí wọn ń ṣọ́ ààfin ọba.
OLUWA, orúkọ rẹ yóo wà títí lae,òkìkí rẹ óo sì máa kàn títí ayé.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Osinbajo: Idasilẹ ọlọpa agbegbe yoo dẹkun ikọlu lorilẹede Naijiria 8 Èrèlè 2018 Oríṣun àwòrán, @ProfOsinbajo Àkọlé àwòrán, Igbakeji aarẹ Ọsinbajo ni ọrọ abo ti di agbatẹru gbogbo ọmọ orilẹede Naijiria Igbakeji aarẹ orilẹede Naijiria, Ọjọgbọn Yẹmi Ọsinbajo ti yanana rẹ wipe bi orilẹede Naijiria ba fẹ bọ kuro lọwọ wahala ikọlu ati ipaniyan to n fojojumọ waye, idasilẹ ọlọpa agbegbe ati tipinlẹ di ọranyan.
Lẹ́yìn náà, mo lọ sí Ẹnubodè Orísun ati ibi Adágún ọba, ṣugbọn kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ tí mo gùn kò rí ọ̀nà kọjá.
Má ṣe jẹ́ kí ẹnu yà ọ́ nítorí mo wí fún ọ pé: dandan ni kí á tún yín bí.
Yóo wà pẹlu àwọn òṣìṣẹ́ tí baba mi ti pèsè sílẹ̀, tí wọ́n wà pẹlu mi ní Juda ati Jerusalẹmu.
Bẹ́ẹ̀ ni kí o ṣe ya Aaroni ati àwọn ọmọ rẹ̀ sí mímọ́, atọmọdọmọ wọn yóo sì máa ṣe alufaa mi.
Ijoba orile ede Naijiria ti ni awon si ni igbagbo lori ile –ise to n
Iru igbesẹ kiakia yi naa ko jẹ nkan ti Hong Kong naa fi sere ti eleyi si ranwọn lọwọ lati le dẹkun ajakalẹ naa.
Ikolu naa ti n waye ni lemo-lemo, ti o fi je pe osise akoroyin ile Amerika siluu Afghan ti pe fun ijiroro alafia pelu iko olote Taliban.
Ó ń rú ẹbọ sísun gẹ́gẹ́ bí ìlànà tí Mose ti fi lélẹ̀, lojoojumọ, ati ní gbogbo ọjọ́ ìsinmi, ati ní ìbẹ̀rẹ̀ oṣù tuntun ati àwọn àjọ̀dún mẹta pataki tí wọ́n gbọdọ̀ ṣe lọdọọdun: àjọ àìwúkàrà, àjọ ìkórè ati àjọ ìpàgọ́.
Gbin nǹkan ọ̀gbìn káàkiri lọpọlọpọ, o óo sì kórè ọpọlọpọ èso nígbà tó bá yá.
Hesekaya bá kó gbogbo fadaka tí ó wà ninu ilé OLUWA ati ti inú ilé ìṣúra tí ó wà ní ààfin ranṣẹ sí i.
Ojò ìbùkùn ṣú dẹ̀dẹ̀, yóó sì rọ̀ lé orí yín.
Àwọn orísun ti a o lè dárúkọ: Àwọn àlàkalẹ̀ ìmúṣe àti ìtọ́sọ́nà lóri lílo àwọn orísún ti kò lórúkọ wà ni ẹ̀kúnrẹ́rẹ́ nibi yìí Editorial Guidelines.
Ileewe alakọbẹẹrẹ St Michael Primary School, Yemetu ati I.
amayedẹrun niluu Abuja to jẹ olu-ilu  orile ede Naijiria .
Nigbati o n se afihan awon afurasi odaran ohun ati awon
 Bee si ni won si n gbero lati tun pese ise ti o to egberun lona
“Ẹ fetí sí ọ̀rọ̀ mi dáradára,kí ẹ sì jẹ́ kí ó jẹ́ ìtùnú fun yín.
Bashir, to jẹ musulumi  ati omo Ologun,
Wọn óo jáde, wọn óo sì fojú rí òkú àwọn tí ó ṣọ̀tẹ̀ sí mi; nítorí ìdin tí ń jẹ wọ́n kò ní kú, bẹ́ẹ̀ ni iná tí ń jó wọn kò ní kú; wọn óo sì jẹ́ ohun ìríra lójú gbogbo eniyan.
Nibayi naa, aarẹ Emmanuel Macron ti gunlẹ si ilu Nice, to si n sepade pẹlu awọn osisẹ Ọlọpaa nibi ti ikọlu naa ti waye.
Seyi Makinde n gbaradi fun ayẹyẹ ibura rẹ Àkọlé àwòrán, Awọn ara ipinlẹ Ọyọ ti ni gomina tuntun Àkọlé àwòrán, Makinde n yan fanda lori papa saaju ọjọ iburawọle Àkọlé àwòrán, Papa isere idaraya Obafemi Awolowo gbe awọ tuntun wọ fun ayẹyẹ ibura Seyi Makinde Àkọlé àwòrán, Atibaba ree fun awọn alejo, o lee daboo bo awọn ero lọwọ ojo ati oorun Àkọlé àwòrán, Papa isere Obafemi Awolowo ti yatọ gbaa fun ibura Seyi Makinde Àkọlé àwòrán, Pẹpẹyẹ yoopọn ọmọ nibi ibura Seyi Makinde lọla.
Ìpèníjà ni èyí jẹ́ fún awa ògidì ọmọ Odùduwà tí èdè yìí jẹ lógún jùlọ.
Eto idana iyawo lo kọkọ waye, ti isin igbeyawo ati wẹjẹ-wẹmu si waye lọjọ Satide.
O óo pàdé àwọn ọkunrin mẹta kan, tí wọ́n ń lọ rúbọ sí Ọlọrun ní Bẹtẹli.
Awọn iroyin ti ẹ lee nifẹẹ si: Lẹyin orẹyin, ala d'ohun Kini 'pen' lede Yoruba?
Awọn aba ati amọran to mu wa fun ṣiṣe labẹ atunto naa ni: Imugboro ipese ina ọba ni ida aadọta ninu ọgọrun (50%) laaarin ọdun mẹrin si asiko yii.
Lẹyin ọse kan ni ijọba orilẹede Naijiria to panupọ wipe lootọ ni pe awọn ọmọ sọnu ati wipe awọn ti bẹrẹ lati wa awọn ọmọ naa lawari.
Lẹyin eyi ni ile ẹjọ wa ran an l si ẹwọn ọdun mẹta fun ẹsun kọọkan, eyi to jasi ẹwọn ọdun mejidinlogun.
 Eyi ni a pe ipejo yii fun lori eto madanidofo ẹka eto Ilera ni Ipinlẹ Eko.
Oríṣun àwòrán, Kwara State Bureau of Lands Àkọlé àwòrán, Oloye Olusọla Saraki kọ ile naa fun ra rẹ, eleyi ti wọn maa n fi n ṣe iranwọ fun awọn eeyan ti ko ri ọwọ họri.
Ní orí òkè mímọ́ ni ìlú tí OLUWA tẹ̀dó wà.
 Ọ ̀ nà tí Ẹi ń gbà tọ ́ ka ibá-ìṣẹ ̀ lẹ ̀ yìí yàtọ ̀ gédéńgbé sí ti ya .
₦400 péré ni àfẹ́sọ́nà mi nílò, ìfẹ́ obìnrin yìí sì ló sọ mi di adigunjalè - Iṣọla Oyenusi Ẹ̀ṣẹ́ ju ẹ̀ṣẹ́ lọ!
Wọ́n a bẹ̀rẹ̀ si ni pe wa ní ẹyọ kọọkan láti sọ orukọ wa, wọ́n a fẹ ki a jẹ ki ìjọba àti àwọn obi wá mọ pe àwọn ò fi ìyà jẹ wá.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù MMM: Àìsàn ọkàn ló pa Mavrodi lẹ́ni ọdún méjìlélọ́gọ́ta 26 Ẹrẹ̀nà 2018 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Àìmọye mílíọ̀nù ọmọ ilẹ̀ Russian lo pàdánù owó wọn sọ́wọ́ Sergei Mavrodi ní sáà ọdún 1990 Olókoòwò ọmọ ilẹ̀ Russian kan, Sergei Mavrodi, tíí se olùdásílẹ̀ ìlànà sogúndogójì MMM, ti àìmọye mílíọ̀nù ọmọ ilẹ̀ Russian àti Nàìjíríà pàdánù owó wọn sọ́wọ́ rẹ̀ ní sáà ọdún 1990 àti 2017, ti járe láyé láti pasẹ̀ àìsàn ọkàn.
Alufaa Isreal Akanji ati Alufaa Jonah Samson ni wọn n kede atilẹyin wọn ninu fọnran naa.
Kí o kọ̀wé náà wéré-wéré bí o bá ti rí ìwé mì yìí.
Obẹ oṣiki, ẹfọ riro, ẹgusi, ila asepọ ati bẹẹ bẹẹ lọ lo maa n kọwọ rin pẹlu iyan Oba ounjẹ.
Lẹ́yìn náà, ó rán wọn jáde ní ìpín mẹta, ó fi Joabu, ati Abiṣai, ọmọ Seruaya, àbúrò Joabu, ati Itai, ará Gati, ṣe ọ̀gágun àgbà ìpín kọ̀ọ̀kan.
Ọ̀dọ́mọkùnrin náà ni òun kò ṣetan láti ṣe ẹjọ́ ṣùgbọ́n òun rọ gbogbo àwọn tí irú ìṣẹ̀lẹ̀ bẹ́ẹ̀ bá ṣẹlẹ̀ si kí wọn máa jáde láti wá sọ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Gani Adams: Femi Adesina, sọ fún Buhari pé ebi ń pa ọmọ Nàìjíríà 19 Ìgbé 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 20 Ìgbé 2019 Aarẹ Ọna Kakanfo ti ilẹ Yoruba, Oloye Gani Adams ta mọ olugbani nimọran pataki fun aarẹ lori ọrọ iroyin ati ọrọ to kan ara ilu, Femi Adesina lori ohun to sọ pe igba Buhari dẹ awọn araalu lara.
Nigba to ya, ọkan lara awọn oyinbo pọtugi to jẹ gbajugbaja onisowo nilu Eko, tii tun ṣe ọrẹ ọba Eshinlokun beere lọwọ ọba pe ko fun oun ni ọmọkunrin rẹ meji lati tẹle oun lọ si orilẹ-ede oun tii ṣe Portugal.
Ṣugbọn nígbà tí Sanbalati ará Horoni ati Tobaya iranṣẹ ọba, ará Amoni ati Geṣemu ará Arabia gbọ́, wọ́n ń fi wá ṣe yẹ̀yẹ́, wọ́n sì ń pẹ̀gàn wa pé, “Kí ni ẹ̀ ń ṣe yìí?
Ẹfunsetan Aniwura, obìnrin tó ju ọkùnrin lọ Ọ̀rọ̀ǹpọ̀tọ̀niyùn, Aláàfin obìnrin àkọ́kọ́ rèé, tó ní nǹkan ọkùnrin Lẹyin ọdun meji lo dari Naijiria lọ si idije FIFA U- 17 ẹlẹẹkarun un ni chile eyi to mu ki o gba igbega di akọnimọọgba fun ikọ Flying Eagles U- 20.
Morrocco - Achraf Bencharki, Jawad El Yamiq: Bencharki ti gba lati darapọ mọ Al Hilal Riyadh Saudi Arabia, lakoko ti El Yamiq nlọ si Genoa ni Italy.
Asofin ti o n soju ekun Florida tisele naa ti sele, Marco Rubio fi sinu itakun isoro re pe onise ibi naa pinnu lati se ose yii ni.
Olùjẹ́jọ ní yóò kọkọ tọ ilé ẹjọ lọ́ laáti bẹ̀bẹ̀ pé mó jébi ẹsùn yìí ẹ jẹ ki a jọ wọ́ inú àdéhùn lọ Kí ènìyàn tó le lọ bẹ̀bẹ̀ fún adéhùn, o ṣe pàtàkì ko ni ǹkan to fẹ́ dá pada O pọ́ndandan pẹ̀lú latí kọ́kọ́ dé ilé ẹjọ ki olùjẹ́jọ sí Pẹ̀lú gbogbo àlà silẹ̀ yìí, Agbẹ́jọrò Tayo Fatogun ni pe, o túmọ si pé kò sí ẹniti kò le bèèrè fún mo jẹbi ẹsùn , sùgbọ́n ẹ jẹ ki a ṣe adéhun àti pe mo ṣetan láti dá ǹkan to mo jí pàda.
OLUWA ní, “Nígbà tó bá yá, orísun omi kan yóo ṣí sílẹ̀ fún ilé Dafidi, ati fún àwọn ará Jerusalẹmu láti wẹ̀ wọ́n mọ́ kúrò ninu ẹ̀ṣẹ̀ ati ìwà èérí wọn.
Ẹwẹ, onimọ nipa eto iṣuna kan, Olumide Ibikunle nigba to n da si ọrọ naa sọ fun BBC pe, ohun to fa ọrọ naa ni pe awọn ileeṣẹ naa ko gba awọn awakọ rẹ gẹgẹ bi oṣiṣẹ, nitori naa ko lee gba owo ori lori wọn.
Àwọn àgbààgbà Gebali ati àwọn ọ̀jọ̀gbọ́n oníṣẹ́ ọwọ́ wà lọ́dọ̀ rẹ,àwọn ni wọ́n ń fi ọ̀dà dí ọkọ̀ rẹkí omi má baà wọnú rẹ̀.
Agbebọn kọlu ileewe girama ni Yobe Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Osisẹ alarina fun ileesẹ ọlọpaa ipinlẹ Ogun, Abimbola Oyeyemi lo kede aseyọri yii ninu atẹjade kan to fisita lọjọ Aje.
Ni asiko ti ajakalẹ arun Coronavirus wọle de, oniruuru ilana eto ẹkọ nijọba ti gbe sita, eyi to wa lati daabo bo awọn akẹkọọ.
2020 Public Holidays: Àwọn ọjọ́ ìsìnmi tó máa wà nínú ọdún 2020 ní Nàìjíríà
Mose sọ èyí fún àwọn ọmọ Israẹli.
gbe gbogbo awon oludupu labe egbe oselu naa wọle, ti ile-ejo si ni ki gbogbo lọ
sori awon ise akanse ti o ye ki ijoba apapo se, leyin ti igbimo to mojuto ise
Nítorí àwọn mìíràn ti yipada, wọ́n ti ń tẹ̀lé Satani.
Aisi iṣẹ́ n pọ si lojoojumọ lasiko yii.
Jẹ́ kí á pa àgọ́ mẹta, ọ̀kan fún ọ, ọ̀kan fún Mose, ati ọ̀kan fún Elija.
 ) , pelu idiye olugbe to to 330,000 .
Oṣun State: Gómìnà Oyetola ní 167,000 yàrá ìkàwé ni òun kọ́ sí 32 iléẹ̀kọ́
Lori ọrọ abo, Sarumi ni aisi olori gidi ni kii mu ki ilu toro.
Aye su u, nitori pe ko ni itura ibalopọ (orgasm) ri pẹlu nkan ọmọkunrin.
Nínú owó yi, wọn a ronú àti ran àwọn ẹbí àti ọ̀rẹ́ lọ́wọ́, ṣùgbọ́n ọ̀pọ̀lọpọ̀ àwọn ti wọn gbìyànjú lati ràn lọ́wọ́, ki i wo ìya ti ojú wọn rí.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ronke Oshodi-Oke: Ọkọ mi kò mọ̀ pé òṣèré ni mi nígbà tí a pàdé- Ojo 8 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Oríṣun àwòrán, Ronke oshodi oke/instagram Gbajugbaja oṣerebinrin, Ronke Ojo, ti awọn eeyan tun mọ si Oshodi-Oke, ti sọ pe oun ko ro pe o yẹ bojumu ki eeyan o ma ṣe afihan dukia rẹ lori ayelujara ibaraẹnidọrẹ.
Ẹ jẹ́ ká fi ìyẹn sílẹ̀ ná.
Àwọn yìí ṣe onínú rere ju àwọn Juu ti Tẹsalonika lọ.
Nítorí èyí ni Ìwé Mímọ́ ṣe sọ pé, “Nígbà tí ó lọ sí òkè ọ̀run,ó kó àwọn ìgbèkùn lẹ́yìn,ó sì fi ẹ̀bùn fún àwọn eniyan.
Mo wa wo pe , ọrọ naa kọja bi mo ṣe ro, igba yii ni mo wa lọ ka awọn nkan to ti sẹlẹ ati idi ti awọn eniyan fi jade lati fẹhonuhan.
Àbí ẹ rò pé nígbà tí mò ń ṣe ètò, mò ń ṣe é bí ẹni tí kò ṣe é gbẹ́kẹ̀lé ni, tí ó fi jẹ́ pé ẹnu kan náà tí mo fi pe “bẹ́ẹ̀ ni” ni n óo tún fi pe “bẹ́ẹ̀ kọ́?
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Olisa Metu: Ilé ẹjọ́ rán Olisa Metuh sẹ́wọ̀n ọdún méje 25 Èrèlè 2020 Oríṣun àwòrán, @FocusOgun ile ẹjọ giga ilu Abuja ti ran agbẹnusọ tẹlẹ fun ẹgbẹ oṣelu Peoples Democratic Party, Olisa Metuh lọ si ẹwọn ọdun meje.
Chelsea ti kọkọ gba kaadi yẹlo ni abala akọkọ, ti wọn si tun gba omiran laipẹ ti abala keji bẹrẹ.
Awọn obi Andrew fẹran pe ko kawe ṣugbọn agbara ni ko si ni eyi ti wọn jọ n sa ipa wọn pe ki o le mọọkọ ko mọọ ka.
“Àwọn ọba Pasia ati Media ni àgbò tí o rí, tí ó ní ìwo meji lórí.
Bí ọ̀dàlẹ̀ ṣe ki eré mọ́lẹ̀ tí ó ń sálọ, ǹ jẹ́ kí ó tó gbé ẹsẹ̀ kẹta ni, kùkùté(àgékù igi) kan bá kọ ní aṣọ, igi yìí kọ́ aṣọ ọ̀rẹ́ yìí dé bi pé tí èèyàn bá ríi, yóò rò pé ṣe ni wọ́n mọ̀ọ́ mọ̀ wé aṣọ náà mọ́ ara igi.
Ninu oro Aare egbe ICSAN ogbeni Samuel Kolawole pe, erongba ipade ohun ni lati siju awon olukopa ni ilana igbalode ati ona ati wa iyanju si isoro awon akowe ile-ise gbogbo ati awon isoro miiran.
23 Bélú 2020 Fídíò, Akomolede ati Aṣa lori BBC:Wo ìrúfẹ́ ìgbeyàwó méje tó wà nílẹ̀ Yorùbá àti ojúṣe Alárinà10 Bélú 2020 Fídíò, Erelu Elemure: Ìyá mi rò pé mi ò lè tibi kíkọrin bíi bàbá mi là21 Bélú 2020 Fídíò, Akomolede Yoruba: Kí ni ìdí tí aṣọ fi máa ń pọ̀ lára Egúngún ju Orò lọ́?
Wọn óo sọkún tẹ̀dùntẹ̀dùn,nígbà tí wọn ba ranti àkàrà Kiri Heresi,tí ó ní èso àjàrà ninu.
 O ni bo tilẹ jẹ pe ajọṣepọ pẹlu EU ni anfani tirẹ, ṣugbọn lati nnkan bi aadọta ọdun sẹyin ni ibi ti ajọ EU n doju kọ kodun mọ orilẹ-ede Gẹẹsi ninu mọ."
" Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Oluwo: Mo lè jẹ Ọba ní Ile Ife BBC Yoruba tun kan si Oluwo lori ẹrọ ibaraẹni sọrọ rẹ lati mọ iha to kọ si bi Agbowu se gbe lọ sile ẹjọ, amọ ko gbe ipe wa, nigba ta si fi atẹjisẹ ransẹ si lori foonu, Oluwo ni oun ko ni esi kankan lati sọ lori ọrọ naa.
O fi kun ọrọ rẹ pe omimi kan ko ni mi ibo ọjọ Abamẹta.
Lẹ́yìn náà, ó bí ọmọkunrin mìíràn, ó sọ ọ́ ní Abeli.
“Ṣugbọn bí ó bá jẹ́ pé obinrin ni ó bí, ọ̀sẹ̀ meji ni yóo fi wà ní ipò àìmọ́ bí ó ti jẹ́ aláìmọ́ nígbà tí ó bá ń ṣe nǹkan oṣù rẹ̀; yóo sì wà ninu ẹ̀jẹ̀ ìwẹ̀nùmọ́ rẹ̀ fún ọjọ́ mẹrindinlaadọrin.
Sugbọn aṣa igba titi yii yoo fun wọn ni anfaani lati wọ aṣọ to jẹ oju ni gbese, to si saba maa n jẹ aṣọ ẹgbẹjọda, lati yọju sita fun ọpọ eeyan lati ri wọn Igba titi tun n fun awọn ayaba ni anfaani lati sọrọ nipa iwa aidaa to n lọ lawujọ, ti wọn yoo si fi ewi, oriki, rara ati orin sọ ero wọn jade.
Rwanda: Àjẹ́ tó dóòlà ẹmí àwọn ènìyàn rèwàlẹ̀ àsà Ìkọlù Zamfara: Àwọn ará ìlú fárígá lórí ìpànìyàn 9) Tiwa Savage to ṣe pẹlu Duncan Mighty - Lova lova Ajọṣepọ yii jẹ ọkan lara awọn to mu eso rere jade julọ lọdun 2018.
Ojiṣẹ Ọlọrun naa ti sọ tẹlẹ pe, Ọlọrun lo fi iran han oun pe ẹlẹmi Eṣu ni Naira Marley.
Ki lo fẹ mọ nipa Madam Sajẹ?
Ẹbun rẹ lati lo ẹsẹ mejeeji fi gba bọọlu àti bi o ṣe tete maa n ronu si jẹ diẹ̀ lara awọn ohun to mu ki o jafafa.
” Ọ̀rọ̀ náà sì dùn mọ́ àwọn arakunrin rẹ̀.
Gbogbo àgbáyé ni olúkúlùkù tí n wá ọ̀nà láti fòpin si òṣì lágbègbè wọ́n.
to wa lorile ede yii ayafi awon ipinle to ba nifee si eto yii nikan.
 yéwándé ni ó mú wọn wọlé kọ ́ kọ ́ rọ ́ ojú ńlá séèfù yìí kìí ya orímóògùnjẹ ́ .
Ọrọ coronavirus , to pa eeyan to le ni 230,000, lo mu ayipada ba igbeaye ni America ati ọrọ oṣelu lọdun 2020.
Ṣugbọn ko to o di ọjọ naa ni ijọba ti n gbe igbesẹ lati dena rẹ.
Ta ni mo rẹ́ jẹ rí?
Nítorí èyí, ní ọjọ́ kan náà ni oríṣìíríṣìí òfò yóo dé bá a,ati àjàkálẹ̀ àrùn, ati ọ̀fọ̀, ati ìyàn.
Nígbà náà ni Ahabu ọba ranṣẹ pe gbogbo àwọn àgbààgbà ilẹ̀ náà, ó wí fún wọn pé, “Ṣé ẹ rí i pé ọkunrin yìí ń wá ìjàngbọ̀n?
Wo ohun tó yẹ kó mọ̀ nípa Gomina Imo ti ilé ẹjọ́ giga ye àga mọ́ nídí Irọ̀ ni ìjọba ń pa, Ikọ Amọtẹkun ba ofin Naijiria mu- Ìgbìmọ̀ Yoruba Ọ̀pọ̀ àwòrán tó ń ṣeni láàánú rèè nípa ogun abẹ́lé Nàíjíríà Èyí ni bí ogun abẹ́lé Biafra ṣe bẹ̀rẹ̀ ní Nàìjíríà Oríṣun àwòrán, @others Àkọlé àwòrán, Ìjàmbà ọkọ̀ akẹ́rù ní Ikòròdú fa súnkẹrẹ-fàkẹrẹ ọkọ̀ ní Márosẹ̀ Awọn eniyan ti n gbọ sọ fun ara wọn lati yago fun opopona Ikorodu bayii nitori pe ijamba to ṣẹlẹ nitosi agbegbe Obanikoro naa ko kere Oríṣun àwòrán, @others Àkọlé àwòrán, Ìjàmbà ọkọ̀ akẹ́rù ní Ikòròdú fa súnkẹrẹ-fàkẹrẹ ọkọ̀ ní Márosẹ̀ Àwọn ọjọ́ ìsìnmi tó máa wà nínú ọdún 2020 ní Nàìjíríà Ọdún 21 tí mo fí sun inú mótò- Ọmọ Naijiria ní Ilẹ̀ Gẹ̀ẹ́sì Ǹjẹ́ o mọ ipa tí ẹja Panla kó lásìkò ogun abẹ́lé Biafra?
Mo mọ bí eniyan ti ń gbé ìgbé-ayé ninu àìní, mo sì mọ bí eniyan ti ń gbé ìgbé-ayé ninu ọpọlọpọ ọrọ̀.
“Ẹ óo ti ni mí lára pẹ́ tó,tí ẹ óo máa fi ọ̀rọ̀ yín bà mí ninu jẹ́?
Ajumọyan ni awọn ọmọ ẹgbẹ PDP fi yan ohun naa si ipo gẹgẹ bi oludije ẹgbẹ.
 Lara won ni  “forbidden romance, polygamy ati inter-generational drama”.
Yasin sọ èyí di mímọ̀ lásìkò tó ń ba àwọn akọròyìn sọ́rọ̀ lẹ́yìn ìpàdé rẹ̀ pẹ̀lú gómìnà ní ilé ìjọba ni agodi Ibadan.
Messi dagbere fun Russia lẹyin ti orilẹede rẹ Argentina fidi rẹmi ninu ifẹsẹwọnsẹ ipele keji wọn pẹlu ikọ France.
Jẹ́ kí orísun rẹ ní ibukun,kí inú rẹ sì máa dùn sí iyawo tí o fi àárọ̀ gbé.
”Aare tun so pe “ibanuje lo je fun ijoba yii pe opolopo emi ati dukia lo padanu nibi ikolu awon olote ati obayejẹ ni awon agbegbe kan lorile ede yii.
Koda awọn iwe iroyin kan tiẹ sọ pe awọn ẹṣọ Ọgbẹni Magu atawọn DSS fija pẹta nigba ti wọn fẹ mu un.
Ti Sulaimon si fesi pe Ayobami fúnra rẹ lọ ṣèlérí fún òun pé yóò lo ipò ìyá rẹ̀ to jẹ adari oṣiṣẹ ìjọba láti fún òun ní iṣẹ ghost worker"" ọhun."
" Arteta ti n ṣe iṣẹ tẹlẹ gẹgẹ bi adari labẹ Pep Guardiola ni Manchester City lẹyin to darapọ mọ ikọ ọhun lọdun 2016.
Orílẹ̀-èdè mẹ́wàá tí ẹgbẹ́ alákatakítí Islamic State n fínna mọ́ ní àgbáyé Ìtàn ayé Henry Fajemirokun, olówó tó fi owó mọ Olúwa àti ènìyàn Diẹ lara awon Amuyẹ ki wọn to gba eeyan siṣẹ ree: Ileeṣẹ ọlọpaa ni ẹni to ba fẹ kopa ninu eto igbanisi iṣẹ naa gbọdọ ni esi idanwo WAEC rẹ pe iṣẹ marun un, Ki o da pe lọmọkunrin tabi lọmọbinrin laini aisan kankan lara.
 Ó tún máa n sáábà bẹ ́ ṣílẹ ̀ bí àjàkálẹ ̀ àrùn ní àwọn orílẹ ̀ -èdè tí n gòkè-àgbà lọ ́ wọ ́ níbi tí àìsàn náà kò ti ṣe àwọn ọmọ náà ní èwe tí abẹ ́ rẹ ́ àjẹsára kò sì tún kárí níbẹ ̀ .
Mose wá, ó sì ka gbogbo ọ̀rọ̀ orin yìí sí etígbọ̀ọ́ àwọn eniyan náà, òun ati Joṣua ọmọ Nuni.
Ní àkókò yìí ó wá ṣàìsàn, ó sì kú.
Ṣugbọn àkókò ń bọ̀, ó tilẹ̀ dé tán báyìí, nígbà tí àwọn tí ń jọ́sìn tòótọ́ yóo máa sin Baba ní ẹ̀mí ati ní òtítọ́, nítorí irú àwọn bẹ́ẹ̀ ni Baba ń wá kí wọ́n máa sin òun.
Awọn iwe akagbadun ti a si fẹ gbeyẹwo naa ni: Aja lo lẹru, Eegun Alare, O le ku, Ogboju Ọdẹ ninu igbo Irunmọlẹ ati Ọmọ Olokun Eṣin.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Oyinlọlá kúrò ní APC, PDP ní kó padà wálé Ìdìbò abẹ́nú APC Ekiti: Ta ní yóò borí?
Ọba Èkó; Ẹ dìbò fún Bùhárí, ó dára ju Ọbásanjọ́ lọ
Sugbon ijoba fi han pe, erongba won ni lati wa bi irorun yoo tun se de ba eto idibo ohun.
Kii ṣe ilu Kano nikan ni yoo ṣafẹẹri ọdun adura Eid, ọrọ yii kan awọn ilu nla bi i Rano, Gaya, Karaye, ati Bichi to wa ni ipinlẹ Kano.
''O fi nkan ọmọkunrin rẹ pa mi ni oju, o ti mi subu, o bọ aṣọ l'ọrun mi, ko to o ba mi lopọ.
 Remi Tinubu tun ṣalaye pe oun ko fi igba kankan ni iṣoro ri, nitori pe oun fẹ Musulumi lọkọ, bakna naa ni ọkọ rẹ ko fi agidi mu awọn ọmọ wọn lasi ṣe ẹsin Islam."
Ninu ẹ̀sìn Juu, mo ta ọpọlọpọ àwọn ẹlẹgbẹ́ mi ninu orílẹ̀-èdè mi yọ.
Oríṣun àwòrán, @Paul Àkọlé àwòrán, Paul Onuachu ni agbábọ́ọ̀lù Super Eagles Nàìjíríà àkọ́kọ́ tó lùgbàdì Covid 19 Lọjọ kẹtadinlọgbọn, oṣu karun un ni Onuachu rinrin ajo lati Belgium lọ si Naijiria.
Ọmọ olowo jalumọ biliọnia ni, iyẹn Oloye Vincent Obianodo to ni ileṣẹ Young Shall Grow Transpot ni Ebuka fẹ.
" Òṣìṣẹ́ ẹka arinrinajo ọkọ̀ òfúrufú Nàìjíríà fẹ́ gún lè iyanṣẹlodi A kò tíì gbọ́ nípa ikú aṣòfin Ayeọla -INEC 'Logo Benz yóò lẹ́yìn fún àwọn ọ̀dọ́ tó bá ṣògùn owó' 'Shehu Shagari dáríji Buhari kó tó kú' Biṣọọbu David Oyedepo, Ijọ Winners Chapel Oríṣun àwòrán, David oyedepo min Àkọlé àwòrán, Biṣọọbu David Oyedepo, Ijọ Winners Chapel Ninu ọrs asọtẹlẹ tirẹ Biṣọọbu agba David Oyedepo ti Ijọ Winners Chapel ni awọn ẹri awoyanu ni yoo farahan ninu ọdun 2019.
Awọn ọmọbinrin Dapchi de s'Abuja Ijinigbe Dapchi: Bo ṣe ṣẹlẹ Awọn akẹkọ Dapchi pada s'ọdọ obi wọn Awọn olori ileesẹ aabo tẹdo si Dapchi Boko Haram Bayii: Iroyin to n lọ lasiko yii ni pe awọn Boko Haram ti pin si ẹya meji pẹlu olori ọtọọtọ.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ooni Ogunwusi àti Wole Soyinka kòrò ojú sí ìṣẹ̀lẹ̀ Lekki Tollgate Ọ̀rọ̀ Nàíjíríà kúrò ní sinimá àwòrẹ́rìn-ìn, Buhari gbé ìgbésẹ̀ bíi òbí àti olórí - Obasanjo gbarata Ilẹ̀ Amẹ́ríkà wà lẹ́yìn àwọn olùwọ́de, Buhari dẹ́kun ìpànìyàn - Joe Biden Mọ̀ nípa DJ Switch, akíkanjú obìrin sàfihàn fídíò ìpànìyàn Lekki bó ṣe ń wáyé Buhari, máṣe gbá ìpànìyàn Lekki sórí ààtàn, kò yẹ́ kí ológun yin ọ̀dọ́ níbọn - Bode George Ọ̀kan lára olùwọ́de tó fara gbọgbẹ́ ní Lekki jáde láyé - Sanwo-Olu Igbakeji aarẹ wa fi ika hanu pe, ọpọ awọn ohun ta padanu lati ipasẹ iwọde naa ni a ko le ri wọn pada mọ titi laelae.
Ko le m'ofin tire wa yato si eyi to wa ninu ofin'' Akintola ni asiko ti to bayi lati wa wọrọko fi sada lori ofin ile Naijiria eyi ti ''ọpọ ninu wọn ko ba ilana ofin ode oni mu'' Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ìgunnukó: Àwọn Tápà gbà pé ẹni tó bá ń sin Ìgunnukó kò ní ráùn ohun rere Idajo pataki re fun awọn osisefeyinti Ajo to ngbogun ti iwa ibaje lorileede Naijiria, EFCC kan sara si idajọ tuntun naa loju opo twita re Awọn ọmọ Naijiria naa si f'ero ọkan wọn han O ti to ọdun marun ti wọn ti wa lori ẹjo ọgbẹni Yakubu Yusuf.
Kwara Coronavirus death: Aminu Adisa Logun ti d'olóògbé lẹ́yìn tó lùgbàdì àrùn Covid-19
Lẹ́yìn tí Peteru ati Johanu ti jẹ́rìí tí wọ́n ti sọ ọ̀rọ̀ Oluwa tán, wọ́n pada sí Jerusalẹmu.
kì í ṣe ohun tó dájú ni pé akẹ ́ kọ ̀ ó èdè kọ ̀ ọ ̀ kan yóò jiyàn pé ọ ̀ rọ ̀ ni wúnrèn ìpìlẹ ̣ ̀ fún ìtúpalẹ ̀ nínú àwọn gírámà .
Arsenal ti ẹru wọn n ba gbogbo ikọ agbabọọlu tẹle lo wa jẹ pe Souuthampton ti wọn gba pe ko jamọ nkankan pupọ lo wa na wa pẹlu ami ayo mẹta si meji.
Batiṣeba bá dá a lóhùn pé, “Ó dára, n óo bá ọba sọ̀rọ̀.
Ẹ máa yọ̀ ní ọjọ́ náà, kí ẹ sì máa jó, nítorí èrè pọ̀ fun yín ní ọ̀run.
Ọkan lara awọn aya Baba, Moteniola ni iya ko le jẹ ọmọ Baba kankan nitoir pe gbogbo wọn lo kọ ni ẹkọ iwe bo ṣe yẹ.
Má ṣe dá àwọn ọdọmọkunrin rẹ̀ sí,pa gbogbo àwọn ọmọ ogun rẹ̀ run patapata.
Iná ń jó àjórun níwájú wọn,ahọ́n iná ń yọ lálá lẹ́yìn wọn.
Ki ijọba yọ awọn ẹlẹgbẹjẹgbẹ to jẹ isẹ aayan laayo, professional bodies, kuro ninu isuna ijọba.
“Bí eniyan meji bá ń jà, tí ọ̀kan bá fi òkúta tabi ẹ̀ṣẹ́ lu ekeji, tí ẹni tí wọ́n lù náà kò bá kú, ṣugbọn tí ó farapa, 
O ni igbesẹ kokan mi ti Ajimobi hu yii lo sin oun ni gbẹrẹ ipakọ lori nkan to n bọ.
nigba ti o n dahun si ibere pe lojuna ati ni eto ilera ti o peju owo, ijoba ipinle
 O ni awọn ko si siyemeji peawọn akẹkọ Dapchi yoo ri idande gba lọwọ Boko Haram."
Ó pé ọdún kẹrin tí àwọn ọmọbìnrìn Chibok nù Chibok Girls: ilé ejọ́ ju ajínigbe sẹ́wọ̀n Ikọlu mẹfa ti o ti waye lawọn ileewe girama 'Mẹ́ẹ̀dógún lókù láàyè nínú àwọn ọmọ Chibok' Ẹgbẹ̀rún mẹ́ta ààbọ̀ ni Boko Haram ji gbe ní ọdun mẹrin - Ajọ Iṣọkan Agbaye Ninu iroyin miiran, ajọ Iṣokan Agbaye, (UN) ti ni awọn ọmọde ti ọjọ ori wọn jẹ mẹtala si mẹtadilogun bii ẹgbẹrun mẹta ati aabọ ni awọn janduku ji gbe ni aarin ọdun 2013 si 2017.
"Nigba ti akọroyin BBC sọ iha ohun ti awọn ara adugbo sọ fun alukoro ọlọpaa pe jẹjẹ ni awọn meji to ku hun n ṣe faaji ọdun Eid lọwọ, esi ti o fọ ni pe ""a n ṣe iwadii lọwọ, a o si fi ọrọ sita bi a ba ṣe tan""."
Sì ranti pé àwọn eniyan rẹ ni àwọn eniyan wọnyi.
Ẹkọ ti Musulumi le kọ lasiko ajakalẹ arun yii Ẹkọ kinni, gẹgẹ bi Sheik ọhun ṣe sọ, ni pe Allah nikan lọba lori ohun gbogbo ati lori gbogbo ẹda alaaye.
Amọ lawọn ilẹ mii, niṣe ni wọn maa n fi ọjọ yi ṣe agbeyẹwo awọn ohun to kan ọdọ.
Ninu ọrẹ fún ẹbọ sísun, ati àwọn ọrẹ mìíràn tí àwọn eniyan Israẹli bá mú wá fún OLUWA, ni àwọn ẹ̀yà Lefi yóo ti máa jẹ.
Frank ni oye to jinlẹ gidigidi nipa ẹgbẹ agbabọọlu yii ati bi nnkan ṣe lọ si ni saa bọọlu to kọja, si ti fihan pe oun wa lara awọn ojẹwẹwẹ olukọni ti ọpọlọ wọn pe ninu ere bọọẹu afẹsẹgba.
Ko pẹ, ko jinna ni awọn mejeeji fi ọrọ ifẹ didun bori ogun inu ẹbi mejeeji ti wọn si ṣe igbeyawo.
Ó bá sọ fún Jeremaya pé kí ó fi àwọn àkísà ati àwọn aṣọ tí wọ́n ti gbó náà sí abíyá mejeeji, kí ó fi okùn kọ́ ara rẹ̀ lábíyá.
Adajọ naa tun sọ wi pe wọn yoo taari ẹjọ naa si ọdọ adajọ miran nitori awọn igbẹjọ to pọ ni iwaju oun ki igbẹjọ naa maa baa falẹ.
Ile ọti ni Bayewu ati Ayinla ti fi oju rinju, ti ija si sọ laarin wọn.
O figbakan jẹ iyawo aarẹ orilẹede South Africa tẹlẹri, Nelson Mandela ti o ku ni ọjọ keji oṣu kẹrin ọdun 2018.
Nígbà tí ó ku òun nìkan, àwọn tí ó wà pẹlu rẹ̀ ati àwọn ọmọ-ẹ̀yìn mejila bèèrè ìtumọ̀ àwọn òwe tí ó fi ń sọ̀rọ̀.
" Bakan naa lo salaye pe, kii ṣe Abacha nikan lo da pinnu lati ko owo pamọ sáwọn banki loke okun, nitori níbi ipade awọn eeyan ti ọrọ Naijiria gberu, to fi mọ awọn ọba alaye ni wọn ti ṣe ipinnu naa.
Brighton vs Tottenham: Aṣọ́lé Tottenham, Hugo Lloris dèrò ilé ìwòsàn lẹ́yìn ìyà àjẹtúnjẹ lórí pápá Brighton
Bí OLUWA bá fẹ́ ran eniyan lọ́wọ́, kò sí ohun tí ó lè dí i lọ́wọ́, kì báà jẹ́ pé eniyan pọ̀ ni, tabi wọn kò pọ̀.
Oun pẹlu idile rẹ lo wa ninu fidio ọhun.
Ìgbà tí ilé-aiyé kórí sí òòrùn yìí ni a máa nrí ìgbà ooru.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Senate Hearing: Iléeṣẹ́ epo rọ̀bì ná ₦14.
Ó ní kànga ti wà fún ọ̀pọ̀lọpọ̀ ọdún, ó sì ní bí wọ́n ṣe n gbẹ́ ẹ, tí wọ́n sì ti lo ọ̀pọ̀ ọdún tí ẹnikẹ́ni kò sì kú sínú wọn.
wọ́n kó gbogbo àwọn ọmọ ogun wọn lọ gbógun ti Iṣimaeli, wọ́n bá a létí odò ńlá tí ó wà ní Gibeoni.
 Esi ifesewonse yii ko yii ife yin lokan wa pada.
ni ipinle mefa lorile ede Naijiria nibi ti ajo eleto idibo INEC ti kede pe idibo
 Awon to ran mi lowo dara, won tete n gbo eko, ise ona yii mu India wa si Naijiria ni nigba ti a se ayajo odun aadorin ominira India ti a lo eedegberun egberun ise ona fi safihan isokan ile India pelu onhiruuru asa, ede, esin, ati idagbasoke bii ti Naijiria”.
 a rí àwọn ìjòyè àdúgbò tàbí abúlé pàápàá tí ó máa ń bá ọba ṣe àpérò tàbí láti jábọ ̀ ìlọsíwájú agbègbè wọn fún un .
Ni ọdun to kọja, iroyin ni Reyes yoo pada si Arsenal gẹgẹ bii akọnimọọgba labẹ Unai Emery to jẹ ọga rẹ nigba to wa ni Sevilla.
Ẹni tí ó ba lu ofin yìí yóò wọ ẹ̀wọ̀n ìṣẹ́jú mẹ́wàá.
Alaafin pari ọrọ rẹ pe ki ẹnikẹni to ba ni ikunsinu pẹlu Wasiu lọ pari rẹ pẹlu rẹ.
Nítorí náà, ẹ mọ̀ dájú pé, kì í ṣe nítorí ìwà òdodo yín ni OLUWA Ọlọrun yín fi ń fun yín ní ilẹ̀ dáradára yìí, nítorí pé, olórí kunkun eniyan ni yín.
Jẹ́ kí ọ̀rọ̀ ibi ẹnu àwọn tí ó yí mi kádà lé wọn lórí.
Eniyan mọ́kànléláàdọ́ta  lo ti padanu emi
O ni ''nise ni wọn tun gba ẹgbẹrun kan aabọ Naira lọwọ oun fun ayẹwo ẹjẹ, lai fi ti pe oun ti san owo eto ilera mọ owo ileewe ṣe.
Bo tilẹ jẹ pe ileeṣẹ ọlọpaa kede laipẹ yii pe ọwọ tẹ awọn afurasi kan lori awọn ipaniyan naa, ipaniyan ko ti i dawọ duro.
Wọ́n yà sibẹ, láti sùn di ọjọ́ keji.
Saaju asiko yii, ni abenugan ile igbimo asofin kẹ́sán án ni
Bí wọ́n ṣe mọ ògiri àgbàlá inú ilé ìsìn náà ni pé, bí wọ́n bá mọ ìlè òkúta mẹta wọn a mọ ìlè igi kedari kan.
Iroyin so pe, aare ati awon adari iko agba-boolu naa, ti se ifenuko saa olodun meji pelu akonimoogba agba fun iko agba-boolu Athletic Bilbao, Ernesto Valverde.
8 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Ronke Oshodi-Oke: Ọkọ mi kò mọ̀ pé òṣèré ni mi nígbà tí a pàdé- Ojo8 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Gómìnà ìpínlẹ̀ Benue, Samuel Ortom ti parí ìjà láàrin akọ̀ròyìn Channels TV, Pius Angbo àti Ifeyinwa Angbo, ìyàwó rẹ̀8 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Borno Zabamari Massare: Àjọ NCC fẹ́ tú ìwé owó àwọn olúpèsè ìtàkùn ìbánisọ̀rọ̀ wo10 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 APC NEC Meeting: Ẹkúnrẹ́rẹ́ ọ̀rọ̀ ìkini PDP sí APC bí àwọn adarí ẹgbẹ́ lápapọ̀ ṣe túká rèé8 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
awon gomina ipinle lorile ede Naijiria ,ko se kọbiara si ile-iwosan abẹle lo
Ọ̀kan ninu àwọn wolii tí à ń pè ní Sedekaya, ọmọ Kenaana ṣe àwọn ìwo irin kan, ó sì sọ fún Ahabu pé, “OLUWA ní, pẹlu àwọn ìwo wọnyi ni o óo fi bi àwọn ará Siria sẹ́yìn, títí tí o óo fi run wọ́n patapata.
Níbi tí owú ati ìlara bá wà, ìrúkèrúdò ati oríṣìíríṣìí ìwà burúkú a máa wà níbẹ̀.
Nupeng àti Pengassan gùnlé ìyanṣẹ́lódì Làásìgbò ọ̀tun súyọ nínú ẹgbẹ́ òṣèlú APC Báwo ni Joe Biden yóò ṣe mú ìyípadà bá òfin tí Trump fi de orílẹ̀èdè àgbáyé?
Níwọ̀n ìgbà tí òde ti já ọgbọ́n àtamátàsè, ẹyẹ Eneke náà ti kọ́ fífò láì bà.
Àpá àwòrán wá láti REAL TV ẹ̀rọ-alátagbà
lorile ede yii, yala ni ipinlẹ  ati ileto
Returning Officer (RO) (Oṣiṣẹ Ajo INEC) : Eyi ni osisẹ Ajo INEC
Ọdun meji-meji ni idije naa maa n waye.
 ohun tí a fi mò pé ìwo ni a pa je ni pé a máa n lò ó nínú gbólóhùn àkésí .
Ọwọ àjọ NYSC tẹ ayédèrú àgùnbánirọ̀ 65 Ajọ agunbanirọ, NYSC ti fi awọn ayederu akẹkọjade Fasiti ti wọn gbamu le awọn agbofinro lọwọ.
Oloye Alli ni Oba Adeyemi yatọ ninu awọn ọba alaye nilẹ Yoruba nipa gbigbe aṣa ati iṣe Yoruba larugẹ.
Oríṣun àwòrán, Reproduction / Facebook Àkọlé àwòrán, Sandra Lucia Hammer Moura Sandra Lucia Hammer Moura, ọmọ ọdun mọkandinlogoji lati orileede Brazil Sandra Lucia Hammer Moura fẹ Augusto Aguiar Ribeiro lẹni ọmọ ọdun mẹrindinlogun.
Adajọ ni ko si to le fidi rẹ mulẹ pe magomago wa ninu eto idibo Amẹrika.
Tosin Olaoluwa ni aini baba laye oun lo ṣakoba fun oun yatọ si nini ọrẹ tuntun ni adugbo tuntun.
Oyo Schools: Onírúurú ìbòmú ló gbòde, bí àkẹ́kọ̀ọ́ ṣe wọlé padà
Lori ọna oju irin ti Itakpe si Warri, Amaechi ni, o di Osu Karun ọdun yii ki wọn to pari oju irin naa, lati bẹrẹ si ni gbe awọn eniyan.
Orọ ọhun ti wa di ti ẹni to kan lo mọ lasiko yii.
Èmi sì ní Oluwo tilẹ̀ Iwo, kò sí ìgbìmọ̀ ọba kankan tó lè ní kí ń rọ́ọ́kún nílé - Oluwo Toyin Abraham ọkọ rẹ̀ àti Ire ní London, Odunlade 'kòlábò' pẹ̀lú Mercy Aigbe Èlé owó iná ọba kọ́ ló kàn, ẹ kọ́ ṣàtúnṣe sí ìlànà àdánú tẹ́ ń ṣe fún wa - Iléeṣẹ́ apínná sọ fún ìjọba Àdínkù bá owó ojúmọ́ ọlọ́kadà l‘Ọyọ láti ₦200 si ₦100, owó gbígbà bẹ̀rẹ̀ lónìí A fẹ́ ìtọ́jú fún Boko Haram tó bá ronúpìwàdà, ẹ dá iléeṣẹ́ sílẹ̀ fún ìtọ́jú wọn - Ilé aṣòfin Toyin Abraham ọkọ rẹ̀ àti Ire ní London, Odunlade 'kòlábò' pẹ̀lú Mercy Aigbe Maryam Sanda pe ẹjọ́ kòtẹ́milọ́rùn lóri ìdàjọ́ ikú Ọmọ rẹ, Faure to ti ṣe ijọba fun saa mẹta ọtọọtọ, n gbegba ibo aarẹ fun saa kẹrin lati tẹsiwaju ijọba ẹbi Gnassingbe lorilẹede Togo.
17 Èrèlè 2018 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Ẹ̀yin ọmọ mi, mò ń kọ ìwé yìí si yín, kí ẹ má baà dẹ́ṣẹ̀.
Ìdí rẹ̀ nìyí tí wọ́n fi ń pe ibẹ̀ ní Beeriṣeba, nítorí pé níbẹ̀ ni àwọn mejeeji ti búra.
Nigba ti BBC Yoruba kan si agbẹnusọ aafin Soun Ogbomoso, Toyin Ajamu sọ pe lootọ ni gomina ti ṣabẹwo si aafin ni nkan bii aago mọkanla owurọ si mejila lati wa ba wọn kẹdun iṣẹlẹ to ṣẹlẹ.
èèyàn mẹ́rin míràn móríbọ́ lọ́wọ́ Coronavirus l'Eko Àwòrán ìhòhò: Salawa Abeni ti sọ̀rọ̀, ẹgbọ́ ohun tó wí 1.
Olódodo a máa yipada kúrò ninu ibi,ṣugbọn ìwà ẹni ibi a máa mú un ṣìnà.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Gẹgẹ bo ṣe sọ, o ni ohun kan ti oun kabamọ ni bi wọn ṣe gbe oku awọn eeyan lọ ba awọn sọja ọhun.
Ní àkókò yìí ni Joṣua pa ìran àwọn Anakimu run patapata ní gbogbo àwọn ìlú tí ó wà lórí òkè, àwọn ìlú bíi: Heburoni, Debiri, Anabu, ati àwọn ìlú tí wọ́n wà lórí òkè Juda, ati àwọn ìlú tí wọ́n wà lórí òkè Israẹli, gbogbo wọn patapata ni Joṣua parun, ati gbogbo ìlú wọn.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 2020: Oloye Awurela Ifaleke ti wúré ọdún ìgbéga fún kóówá Hawkins parọwa pé ki asiko ọdun tuntun to tun jẹ ibẹrẹ ọdun mẹwaa miran yii jẹ asiko ironu ati asiko ti eeyan n ṣe isiro ni gbogbo ọna.
Ó fi okùn ìwọ̀n wọ̀n ọ́n,kò sì rowọ́ láti parun.
Adeleke ni oun lọ si fasiti kan ni ilẹ Amẹrika lai lo iwe ẹri oniwe mẹwaa WAEC ti oun ni.
Ṣugbọn ẹ̀yin ń wá ọ̀nà láti pa mí, bẹ́ẹ̀ sì ni òtítọ́ tí mo gbọ́ lọ́dọ̀ Ọlọrun ni mo sọ fun yín.
NMA: Buhari ni iṣẹ ṣe lori ilera alabọde #BBCGOVDEBATE: Kò sí ètò ilera ọfk fun àwọn obinrin- Ogunbanjọ 'Eefin oluṣosun lewu' Ìjọba ìpínlẹ̀ Èkó: èèyàn ogun lo kú ní ilé alájà tó wó l'Eko Pọ̀nmọ́ olóró ni!
Ijọba orilẹede Ghana ti kede fawọn ileesẹ ọkọ ofurufu pe ki wọn mase gbe ero wa si orilẹede Ghana, lati awọn orilẹede ti arun Coronavirus n ba finra.
Elebuibon tun rọ wọn ki wọn wa ni iduro deede ati ṣiṣe ododo pẹlu awọn eeyan lati jẹ eeyan ire lawujọ.
Ganiyat tó fi irin gbígbóná àti àdá ya ara ọmọ àbúrò ọkọ rẹ ti dèrò àgọ́ ọlọ́pàá l' Ogun Nàìjíríà fohùn ránṣẹ́ padà sílé aṣofin UK pé ọ̀rọ̀ EndSars kò sí lẹ́nú wọn láìgbọ́ ìwádìí tán!
Ijọba ipinlẹ Eko kede pe oun ti n pin oúnjẹ bi irẹsi, sipagẹti, éwà, gàárì, ororo, ati tomato lílọ̀ fun awọn arugbo, akanda ẹ̀dá ati awọn alaini ni ipinlẹ naa.
Bí Nàíjíríà ṣe jáwée jókòo jẹ́ fún South Afrika rèé Ọmọ Nàìjíríà ń retí ifẹ ẹ̀yẹ AFCON lọ́dọ̀ yín - Aarẹ́ Buhari Ijọba ipinlẹ Eko pa aṣẹ irina ọfẹ fun wakati mẹta laarọ ati nirọlẹ lago mẹrin abọ si mẹjọ abọ eyi to jẹ asiko ti ero maa n wọ pọ ju lati le mu adinku ba sunkẹrẹ fakẹrẹ ọkọ.
Alaye rẹ ni pe iye eeyan to n ko arun naa se n pọ si, eyi to n da jinni-jinni bo ọpọ eeyan bayii.
Oríṣun àwòrán, @aishambuhari Bakan naa lo fi kun un pe ihuwasi oun ko ṣẹyin bi oun ṣe ri wi pe awọn awọn to sun mọ ọkọ oun n lo agbara ti ara ilu gbe e wọ ni ilokulo.
A kò lè gba àwọn jandùkú Fulani láàyé nílẹ̀ Yoruba -Awọn gómínà Iṣẹ́ bọ́ lọ́wọ́ ọ̀gá ilé iṣẹ́ ológun lórí ikú Fulani 134 Gani Adams kilọ f'awọn darandaran O fẹ́ yọ wọ́ ààyè ibùsùn àwọn obìnrin lọwọ́ ọlọ́pàá ba tẹ!
Eyi to tumọ si pe Adesọji, ọmọ tuntun jojolo to gbe lọwọ, yoo gun ori itẹ awọn baba nla rẹ.
Olorí ogun Ethiopia f'arapa nínú rògbòdìyàn tó wáyé ni Addis Ababa
Àìṣàn ráńpẹ́ ṣekú pa ijàpà ẹni ọdún 344 ní Ààfin!
Ṣebí ẹni tí ó dá mi ninu oyún,òun kan náà ló dá iranṣẹ mi?
Ṣe awọn agbegbe to ti n ni iriri alaafia ko tun ni bọ si inu ibẹru ohun ti awọn onijagidijagan naa le ṣe lati de ipo, tabi fun oludije wọn lati de ipo?
Ni abala awọn agbabọọlu obinrin, Asisat Oshoala, agbabọọẹu Super Falcons Naijiria ati ikọ Dilian Quanjian ti orilẹede China, Desire Oparanozia ti falcons ati ẹgbẹ agbabọọli Guingamp, Francisca Ordega lati ikọ agbabọọlu Washington Spirit, ati Onome Ebi lati ikọ Hekan Huisanhang ni wọn wa lori orukọ ti ajọ CAF fi sita.
Gege bi oro iwe mimo ti so ninu iwe Timoti ori keji, ori keta, ese kerindinlogun, eyi to so pe, igboran ati titele oro Olorun ni ona kan gboogi lati wa alaafia.
Queen Badra Olaitan: Ọ̀pọ̀ nnkan tó bàmí nínú jẹ́ ni ojú mi rí lọ́dún 2020
5 882418 Orilẹede Turkey 23664 28.
Ninu atejade kan ti agbẹnuso fun Gomina Ahmed El Rufai, Samuel Aruwan fi sọwọ si awọn akọroyin,o ni Gomina El Rufai ti bọ kanje lori isele naa o si pe fun, to si pe fun ifọwọsowọpọ pelu awọn eleto aabo lati koju iwa janduku.
Dafidi bá fún Solomoni ní àwòrán tẹmpili náà tí wọ́n fi ọwọ́ yà, ati ti àwọn ilé mìíràn tí yóo kọ́ mọ́ tẹmpili, ati ti àwọn ilé ìṣúra rẹ̀, àwọn yàrá òkè, àwọn yàrá ti inú, ati ti yàrá ìtẹ́ àánú; 
Ipò obinrin kò pin si idi àdìrò àti inú ilé yókù gẹ́gẹ́ bi Olóri Òṣèlú Nigeria, Muhammadu Buhari ti sọ.
9 Owewe 2018 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Naomi Osaka se afihan ife ẹyẹ to gba han lẹyin to gbewuro soju Serena Williams Kaakiri oju opo ayelujara ni orukọ ọdọmọbirin ọmọ ogun ọdun kan ti n ja ranyin ranyin.
Ọrọ pada yi pada ti wọn si da a silẹ ninu oṣu kẹta ọdun 2017.
Wọ́n sanra tóbẹ́ẹ̀ tí ojú wọn yíbò;èrò òmùgọ̀ sì kún ọkàn wọn ní àkúnwọ́sílẹ̀.
Wọn fi ọrọ yi sita lẹyin ti awọn Gomina ipinlẹ kan kilọ fun ijọba pe, ko ma ṣe daba lati da awọn agọ wọnyii silẹ lagbegbe awọn.
Mose bí ọmọkunrin meji: Geriṣomu ati Elieseri.
Ọmọ Nàíjíríà mọ̀ pé ìjọba mi gbìyànjú, mo ṣapá mi lórí ètò ààbò - Buhari Buhari ṣ'eleri iṣẹ f'awọn ọdọ Yóò ṣe sáà kẹta, kò ṣe sáà kẹta, Femi Falana àti Garba Shehu tahùn sí ra wọn Iléeṣẹ́ ààrẹ yínmú sí àwọn amòfin lórí ìrìnàjò Buhari ‘Ọ̀rọ Baba Ọbasanjọ kò jọ wá lójú mọ́’ Adesina tunbọ mu akawe ọrọ ọmọde kan ti fọnran fidio rẹ gbode kan nibi to ti n sọ fun iya rẹ to fẹ na wi pe ko ''calm down'' O ni gẹgẹ bi ọmọ naa ti ṣe sọ, awọn ọmọ Naijiria ni lati farabalẹ.
Ohun tí ó jẹ́ ọgbọ́n fún ọlọ́gbọ́nni pé kí ó kíyèsí ọ̀nà ara rẹ̀,ṣugbọn àìmòye àwọn òmùgọ̀ kún fún ìtànjẹ.
Pín fídíò 'ayédèrú' kó o ríjà ológun Nàìjíríà Ọlọ́pàá Adamawa ni #30,000 ni wọ́n fi bọ́ igún látìmọ́lé Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Abdulfatah Ahmed: Àwọn Kwara fẹ́ dán ilé ọkọ kejì wo ni lásìkò yí Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Bode George: òòtọ́ ni ìkìlọ̀ Obasanjọ ati Soyinka Maikaba fí kún-un pé fún ìgbà díẹ̀ báyìí, fíìmù àgbẹ́léwò eléré ìfẹ́ ló kó ìdá ọgọ́rin nínú ìdá ọgọ̀ru fíìmù tó ń jáde ní Aréwà, ṣùgbọ́n èyí kò yẹ ko ri bẹ́ẹ̀.
Ó wí fún wọn pé, “Ẹnikẹ́ni tí ó bá gba ọmọde yìí ní orúkọ mi, èmi ni ó gbà.
Mo máa ń ronú jinlẹ lati se òun tuntun tí ẹnikan kankan kò ṣe rí, ìdí sì nìyí tí mo fi ṣe sinima tó jẹ́ èmi nìkan ni lo jẹ ọkùnrin ní odidi ìlú kan."
Rakẹli ń sunkún nítorí àwọn ọmọ rẹ̀;ó kọ̀, kò gba ìpẹ̀,nítorí wọn kò sí mọ́.
Má ṣe fi ààyè sílẹ̀ fún ìsọkúsọ nípa àwọn ohun tí ẹ kà sí nǹkan rere.
Ni asiko yii ni iṣẹlẹ ẹsun ifipabanilopọ awọn ọd\\ọkunrin marun un naa ṣẹlẹ lọdun 1989 ni central Park Ẹnu kò sìn lára Olúwòó lórí oyè Emir ‘Ìjọba Buhari kò lé è dá ààbò bo àwọn ará ìlú’ Wọ́n jí ọmọ yìí gbé láti máa fi tọrọ bárà l'Eko Olùdíje mẹ́rin ti Gbajabiamila lẹ́yìn ṣáájú ìbò ilé aṣojú ṣòfin Lọdun 2002 ni Matias Reyes, to jẹ ẹni ti wọn mọ ni afipabanilopọ to tun jẹ apaayan jẹwọ pe oun loun ṣe iṣẹ buruku yii.
ládípọ ̀ gbìyànjú gidi tí ó sì lààmì laaka látàrí ìgbìyànjú rẹ ̀ láti tan àṣà , ìṣẹ ̀ se àti àkọmọ ̀ nà yorùbá jákè jádò àgbáyé kódà nígbà tí ó wà ní abẹ ́ àṣẹ àwọn ̀ òbí rẹ ̀ gẹ ́ gẹ ́ bí onígbàgbọ ́ .
Ayé á pé o máa lọ
O pada si ilẹ Afrika lọdun 1843 pẹlu Henry Townsend, to da ijọ ẹlẹsin Kristi silẹ nilu Abẹokuta nipinlẹ Ogun.
Agbaboolu owo eyin naa teleri, Yobo gboriyin fun akonimoogba agba iko ohun, Gernot Rohr, fun akitiyan re ti o sa lati ko olokan-o-jokan agbaboolu ti o danto jo lati figagbaga fun aaye saaju idije ohun.
Báyìí ni àwọn ẹlòmíràn wà nínú ayé ti wọ́n da bi gbòǹgbò ojú ọ̀nà ti wọ́n jẹ́ ohun ìdíwọ́ fún àwọn ọmọ Olódùmarè.
Àwọn méjéèjì ti gbéyàwó, ọmọbinrin tí Ìṣubú tilẹ̀ kọ́ fẹ́ ni ẹni tí orúkọ rẹ̀ ń jẹ́ ìtìjúparẹ̀ tí ó jẹ́ ọmọ olórúkọ mi ni ọ̀rùn Àpáàdì, èyí ni pé bpabá rẹ̀ náà a máa jẹ́ Ìgbéraga Ìbànújẹ́, ṣùgbọ́n nígbà tí a lọ tọrọ ọmọ náà ni wọ́n wí fún wa pé ìbátan wa ni ìyá rẹ̀ nítorí ilé kan náà ni wọ́n gbé bí Ahọ́ndiwúra tíí ṣe ìyàwo mi àti ìyàwó ọmọ náà.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù NBC ní kí àwọn ilésẹ to tẹ ofin lóju san #500,000 2 Ẹrẹ̀nà 2019 Oríṣun àwòrán, NBC Àkọlé àwòrán, 2019 Elections: NBC na ilí iṣẹ́ ìròyìn 45 ní pàsán Ile ise iroyin marundinlaadota ni ajọ NBC ni ko sanwo ìtanran fún àwọn aṣe máse tó wáye lásiko ìdìbò gbogboogbo tó wáye lọ́jọ́ kẹtalélógún oṣu tó kọja.
Ìbẹ̀ jẹ́ ibi ti àwọn musùlùmí maa n dárijọ si láti kírun, èyí lo si jẹ ki wọ́n lérò pe ilẹ̀ àwọn ní.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fọ́nrán ohùn, Ruga settlement: YCE ní ìjọba àpapọ̀ ko tó bẹ̀ẹ́ láti kọ́ àgọ́ Fulani sílẹ̀ Yoruba Ninu alaye rẹ to ṣe, Garba ni awọn oludokowo lati ile ati lẹyin odi, yoo laanfaani lati ṣowo ẹran ati awọn nnkan miran to maa n ti ati ara rẹ jade bi awọ.
Obey sọ pe iru ọdọmọbinrin bẹ ẹ ṣẹṣẹ bẹrẹ aye ni, to si l'agbara ibalopọ ati okun.
OLUWA bá sọ iná sílẹ̀, iná náà sì jó ẹbọ náà ati igi, ati òkúta.
Kò sí ẹni tí yóo gba ẹjọ́ yín rò,kò ní sí òògùn fún ọgbẹ́ yín,kò ní sí ìwòsàn fun yín.
Tinubu to jẹ ọkan lara awọn olori ẹgbẹ oṣelu APC sọ pe ahesọ ọrọ lasan lawọn eeyan kan n gbe kiri.
Nigba ti Boris Johnson ṣàpèjúwe alátakò rẹ̀ bíi ọlọ́pọlọ pípé ninu ọrọ akọsọ rẹ, bẹẹ naa lo fimoore han fun gbogbo eniyan pe: Kini o ti ṣẹlẹ sẹyin?
Arsenal fẹ́ ṣe bíi Barcelona Eléré ìdárayá Cameroon mẹ́jọ di àwátì Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Salah yoo koju Roma, ẹgbẹ agbabọọlu rẹ tẹlẹ Ọrọ kò rí bẹẹ fun Barcelona lasiko ti wọn gbe goolu mẹrin si ọkan lọ ka Roma mọle nitori gbogbo rẹ ni Roma da pada ti wọn si ja Messi atawọn akẹgbẹ rẹ ju silẹ.
tun wa ni awon ile ẹjọ to wa ni  ekun
Ilé ẹjọ́ sún ẹjọ́ Sẹ́nétọ̀ Abbo síwájú pẹ̀lú béèlì mílíọ̀nù márùn-ún Wo àwọn gómìnà PDP tó ti darapọ̀ mọ́ ẹgbẹ́ òṣèlú APC láti ọdún 1999 sí àsìkò yìí Ẹ má bínú, mo kábàmọ́ pé mo na obìnrin -Elisha Abbo Èrò àwọn ọmọ Naijiria ṣọ̀tọ̀ọ̀tọ̀ lórí Tinubu àti Abbo Àwọn aṣòfin àgbà yóò wádìí ohun tó wáyé láàrín Sẹ́nétọ̀ Abbo àti obìnrin ilé ìtajà l'Abuja Kete to kede ọrọ yi lawọn ọmọ ẹgbẹ APC to wa nile figbe bọ nu lati baa yọ pe o darapọ mọ awọn.
Awọn ẹri dabi ẹni ti n farahan lori idi ti iyawo gomina ipinlẹ Ọyọ nigba kan, Florence Ajimobi, fi tahun si ijọba ipinlẹ Ọyọ lọjọ Aiku lẹyin isinku ọkọ rẹ.
70 Àti nísisìyí, rantí àwọn ọ̀rọ̀ ẹni náà tí íṣe ìyè àti ìmọ́lẹ̀ ayé, Olùràpadà rẹ, Olúwa rẹ àti Ọlọ́run rẹ.
Lalong sọrọ kayeefi yii nibi ayẹyẹ ọgọrun ọjọ ti adari ajọ irin ajo afẹ ti ipinlẹ naa, Salome Bidda ti lo lori aleefa.
Oríṣun àwòrán, AP Àkọlé àwòrán, Àwọn arìnrìàjò ní pápákọ̀ òfúrufú MMA2 Páropáro ni gbogbo ìnú ọgbà àti ibi ìgbàléjò pápákọ̀ òfúrufú náà dá.
Bẹẹ ba si gbagbe, ẹkun ariwa Naijiria yii naa ni aarẹ Muhammadu Buhari ti wa.
Muhammadu Buhari yoo bere iponlongo idibo re fun saa keji lori aleefa lojo Eti(Friday),
Àwọn ìròyìn tí ẹ lè nífẹ̀ẹ́ sí: Ọmọ ọdún márùn-ún wọ gàú ajínigbé ní Warri, ọlọ́pàá ri he ní Lafia Fatai Olumegbon, àgbà oyè nílùú Eko, jáde láyé Ilé kẹta da wó l'Eko láàrin ọsẹ méjì Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Èré Ọṣun: Àtáója ní wọn kò jí ère Ọṣun, ó sì wà níbi tó wà Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
naa tun ni ile-itura ati ibi igbafẹ, awon lo tun ni Rotana Hotel.
Ewe, olukopa ti o ba gba ami-eye goolu(Gold) yoo lanfaani si ẹ̀gbẹ̀rún marun-un owo dola ($5,000), ami-eye ipo keji(Silver) yoo gba ẹ̀gbẹ̀rún meta owo dola($3,000), beesini ami-eye ipo keta(bronze) yoo gba ẹ̀gbẹ̀rún meji owo dola($2,000).
"Iniesta dágbére fun Barcelona Abramovich rí ìdíwọ́ lórí ìwé ìgbéèlú ilẹ́ Gẹ̀ẹ́sì Ninu ọrọ ti oun pẹlu sọ ninu fidio kan to fi si ori ikanni twitter ẹgbẹ agbabọọlu Arsenal, Santi Cazorla ni 'ibanujẹ ọkan lo jẹ fun oun lati fi ẹgbẹ naa silẹ' ṣugbọn oun ko lee gbagbe Arsenal laelae""."
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ọlọpa kan yinbọn mọ ọga rẹ nitori obinrin nipinlẹ Adamawa 31 Sẹ́rẹ́ 2018 Oríṣun àwòrán, AFP Àkọlé àwòrán, Ogogoro boju ọlọpa kan to fi yinbọn m ekeji rẹ Agbẹnusọ fun ileesẹ ọlọpa ipinlẹ Adamawa, Othman Abubakar, ti fidi rẹ mulẹ pe ẹmi ọlọpa kan ti bọ sinu ede aiyede kan to bẹ silẹ laarin ọlọpa meji.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Intersex: Kò dẹrùn láti sọ wí pé kòjako-kòjabo ni mí Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Intersex: Kò dẹrùn láti sọ wí pé kòjako-kòjabo ni mí 5 Èbibi 2019 Babalwa ti ni ko dẹrun lati sọ wi pe kojako-kojabo(intersex) ni oun, amọ pẹlu igboya ni oun fi sọ jade.
to n waye ni orilẹ-ede South Africa ati awọn orilẹ-ede miiran ni ilẹ
Ìdájọ́ ọwọ́ tó di lemọ́-lemọ́ n'Ibadan, ohun tó fà á rèé Oríṣun àwòrán, Plustv africa Ohun to n mu ki ọpọ eeyan maa dawọle idajọ ọwọ ara ẹni, taa mọ si Jungle Justice, ni ainigbagbọ to kuna ninu eto idajọ ododo ti ofin gbe kalẹ.
'Ìdùnnù wa kọ́ ni kí á má fún ọmọ Nàìjíríà ní 'Visa' US Shut down: iṣẹ́ ń lọ ní Abuja àti Eko Ọmọ Nàìjíríà r'ẹ́wọ̀n he ní Amẹ́ríkà Oríṣun àwòrán, US Embassy in Nigeria Ilana to wa nilẹ tẹlẹ fayegba ki awọn eeyan to ba fẹ tun iwe irina( B1/B2 fun awọn arinrinajo igbafẹ) gba fi iwe wọn ranṣẹ sinu apo iwe si ileeṣẹ to n ṣoju Amerika ni Naijiria.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Afeez Agoro: O ṣòro fún mi láti wọ Danfo jáde Àwọn ipinlẹ ti Covid-19 ko ti i de ni NaijiriaBi aarun yii ṣe n tankalẹ to naa ni a ṣi ni awọn ipinlẹ ti ko tii de ni Naijiria.
Nígbà tí ó yá, ó kan ìpín àwọn Sakaraya láti wá ṣe iṣẹ́ alufaa níwájú Ọlọrun ninu Tẹmpili.
 Yusuff Alli, lo jẹ alaga  ile-ise naa, o so fun aare Buhari pe olu-ilu
Gbogbo owó tí àwọn ará ilẹ̀ Ijipti ati àwọn ará ilẹ̀ Kenaani ní patapata ni wọ́n kó tọ Josẹfu wá láti fi ra oúnjẹ.
Ondo Accident: Kíní ọ̀nà àbáyọ sí ìjàmbá ọkọ̀ tó ń wáyé lemọ́lemọ́ ní Ọjà Akungba,ní Ondo?
Ta ni aláìkọlà Filistini yìí tí ń pẹ̀gàn àwọn ọmọ ogun Ọlọrun alààyè?
Olori egbe oselu alatako kan gboogi lorile-ede Sierra Leone, ti a mo si Sierra Leone Peoples Party (SLPP) ni o yan ajagun feyinti Julius Maada Bio gege bi oludije fun egbe naa, eyi ti won leto wi pe, won yoo gbakoso ijoba naa leyin ti won wa gege bi alatako fun odun pipe.
"Mo dupẹ lọwọ Ooni ti Ife, awọn lọbalọba, ijoye ilu ati awọn ara Ife.
Ṣugbọn ó dáhùn pé, “Ò ń sọ̀rọ̀ bí ìgbà tí ọ̀kan ninu àwọn aláìmòye obinrin bá ń sọ̀rọ̀.
Kí ó má jẹ́ pé nígbà tí wọn bá ń ṣọ́ yín nìkan ni ẹ óo máa ṣiṣẹ́, bí ìgbà tí ó jẹ́ pé eniyan ni ẹ̀ ń fẹ́ tẹ́ lọ́rùn.
Wole Soyinka rèé láti kékeré Lasiko naa, Ọlọyọ, ti a n pe ni Alaafin lasiko yii, ti fi awọn Ajẹlẹ ati Ilari sọwọ silu Ẹgba lati maa gba isakọlẹ loore koore lọwọ wọn, ki wọn si maa fi isakọlẹ naa ransẹ si Ọlọyọ Awọn Ilari yii n mu ki aye le fun awọn Ẹgba nitori aye familete ki n tutọ ti wọn n jẹ laarin awọn Ẹgba.
Èmi àti Bọla Tinubu fẹ́ lo ‘German Mercenaries’ láti gbé MKO Abiọla kúrò lẹ́wọ̀n - Dele Momodu Irọ́ ńlá!
Nígbà tí ó bá ń yọ kíndìnrín rẹ̀, yóo yọ ẹ̀dọ̀ rẹ̀ mọ́ ọn láti fi rú ẹbọ sísun sí OLUWA.
N óo fihàn bí orúkọ ńlá mi, tí ó ti bàjẹ́ láàrin àwọn orílẹ̀-èdè ti jẹ́ mímọ́ tó, àní orúkọ mi tí ẹ bàjẹ́ láàrin àwọn orílẹ̀-èdè tí ẹ wà.
Èyí ni ìdí tí àwọn obìnrin kan to n ṣe nkan oṣù fi n yọ ilé ọmọ wọn kúrò ní India
Àwọn kan ninu àwọn ọmọ alufaa tẹ̀lé wọn pẹlu fèrè.
O ni oun pada pọ oruka ọhun ti oun si fun ikẹta wọn ti orukọ rẹ n jẹ Young Boy, eyi to sa lọ nigba ti ọlọpaa n le wọn.
Nigba to n ba BBC Yoruba sọrọ, osisẹ alarina fun ile iwosan UCH, Toye Akinrinola salaye pe eroja ti ko ju miliọnu kan naira ni UCH gba lọwọ ijsba ipinlẹ Oyo.
N óo bukun wọn, wọn óo di pupọ,n óo sọ wọ́n di ẹni iyì, wọn kò sì ní jẹ́ eniyan yẹpẹrẹ.
Bi o ti le jepe, ondupo akegbe re, Aleksander Ceferin so pe, won ko ni se amulo ero igbalode naa ninu idije UEFA Champions League ni saa to n bo.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Female Driver: Sokunbi ni obìnrin àwakọ̀ Dáńfó l‘Eko, tó ń lọ̀ láti ìpínlẹ̀ kan sí òmíì Bakan naa ni ijọba ipinlẹ Eko tun ya awọn nọmba ibanisọrọ kan silẹ fun ipe pajawiri lori aisan Lassa nipinlẹ naa.
Nígbà tí OLUWA wà pẹlu mi, ẹ̀rù kò bà mí.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Jiti Ogunye: Ìjọba àkóbá lológun gbé kalẹ̀ ni 1999 Agbẹjọro Jiti Ogunye ni iyalẹnu ni wi pe awọn ti wọn dibo yan ko ṣe ifẹ awọn ara ilu, wi pe ni ṣe ni ijọba n tan ara ilu jẹ.
Níbo ni àwọn wolii rẹ wà, àwọn tí wọn ń sọ àsọtẹ́lẹ̀ fún ọ pé, ‘Ọba Babiloni kò ní gbógun ti ìwọ ati ilẹ̀ yìí?
Owurọ kutu ọjọ Aje ni iroyin gba igboro pe ile itaja naa fẹ ẹ kuro.
Bakan naa ni Dokita King ni yoo ṣe wọn ni anfaani ti awọn eniyan ba ran wọn lọwọ nipa sisọrọ iwuri si wọn lai dẹyẹsi wọn.
Jesu bi wọ́n pé, “Burẹdi mélòó ni ẹ ní?
Orilẹede Amẹrika gb'ogo lọwọ ẹgbẹ agbabọọlu obinrin orilẹede Thailand pẹlu ami ayo mẹtala ninu ifẹsẹwọnsẹ akọkọ wọn ni idije ife ẹyẹ fawọn obinrin to n lọ lọwọ lorilẹede France.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Twin Festival 2019: Ṣé ọbẹ ìlasa àti àmàlà ló ń ṣokùnfà bíbí ìbejì ní ìlú Igboọrà?
Ṣebí ìbátan ọba ni yín, ẹ̀jẹ̀ kan náà sì ni yín?
Àwọn ènìyàn ń gbé súnmọ́ ara wọn, àmọ́ síbẹ̀, wọ́n jìnà sí ara wọn.
Gbogbo ìlú péjọ sí ẹnu ọ̀nà.
Ìwádìí BBC: Àwọn ará Èkìtì ń sáré gba N4,000 sáájú ìbò Àwòrán ìbò Èkìtì lọ́dún 2014 fún àwòkọ́gbọ́n John ọmọ Fayẹmi sin ilẹ Naijiria ilẹ baba rẹ̀ gẹgẹ bii olukọni ni Police College to wa niṢokoto lapa ariwa Naijiria.
Ipo Kẹfa: Owona fun isẹ akanse nlanla Owona fun isẹ akanse nlanla lo se ipo kẹfa ninu eto isuna ọdun 2020 nipinlẹ Ọyọ pẹlu ida ogun, eyi to kere si owo ti wọn ya sọtọ fun ẹka naa ninu isuna ọdun to kọja, eyi to ko ida mẹtadinlaadọta ati diẹ.
tabi awon osise ijoba, eleyi ti o le tabuku ba isakoso ijoba re.
Oun si ni alaga ajọ ECOWAS to n ri si ọrọ aje awọn orilẹede to wa ni iwọ oorun ilẹ Afirika bayii.
O kò lè ṣọ́nà fún wakati kan péré?
Aṣofin Braimoh sọ pe awọn aṣofin to wa ninu Ile yii jẹ ẹni to n fara ṣiṣe lati ṣe awọn ofin to dara fun ipinlẹ yii, ti wọn si n jẹ ki awọn ara ilu mọ si akitiyan yii loorekoore lati le jẹ ki awọn naa kopa ninu igbesẹ yii.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ọ̀ràngún ti Ila: Èdè àti àṣà Yorùba ní láti jọ wá lójú Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Ọ̀ràngún ti Ila: Èdè àti àṣà Yorùba ní láti jọ wá lójú 8 Sẹ́rẹ́ 2019 Ọrangun ti ilu Oke Ila fi tinu tinu rẹ gba awọn ọmọ Yoruba nimọran lati ma jẹ ki aṣa adayeba wọn parun.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Làá hàn mí: Ètò yìí ló ń kìlọ̀ fún wa láti mú ìmọ́tótó ní pàtàkì láti dènà Coronavirus Esi ayẹwo to ṣe nileewosan si fihan pe o ni arun Coronavirus lara.
Prem Chand sọ wípé ó kan apá kan nínú àwọn ọmọ ìlú:
Eleyii lo mu ki awọn ijoba ipinlẹ fun awọn eniyan ni gbedeke lati da awọn ohun ini ti wọn ji gbe pada, lai jẹ bẹẹ awọn yoo ma a ya ojule si ojule lati fi panpẹ ọba mu awọn ti wọn ba ba awọn ohun ini wọnyii ni ile wọn.
Ustaz Dahiru Rabi'u (1948-2020) O figba kan ri jẹ adajọ Agba ipinlẹ Kano.
Lẹyin naa ni ọkọ naa pada si papakọ Eko, ti awọn ero ọkọ baalu naa si sọ wi pe awọn koju ọpọlọpọ idaamu lati wọ ọkọ miran.
To ba jẹ iku ti Covid 19 fa ni, ninu ki wọn sin oku ẹni bẹẹ si ibi ti o ku si tabi bi ẹbi ba fẹ, wọn lee gbe e lọ fun wọn ṣugbọn ilana yii le pupọ tori wọn ni lati forikori pẹlu gbogbo awọn alaṣẹ tọrọ kan.
Coronavirus: Ìjọba ní kò sí ìrìn-àjò sílẹ̀ òkèrè mọ́ fáwọn òṣìṣẹ́ ìjọba lásìkò yìí
Ṣemaaya, Eleasari ati Usi, Jehohanani, Malikija, Elamu, ati Eseri.
Akọ̀wé ni, ó sì já fáfá ninu òfin Mose, tí OLUWA Ọlọrun Israẹli fún wọn.
Nigba ti Ebuka bere lọwọ rẹ boya o kabamọ ere ifẹ rẹ ati Eric, Lilo sọ pe ehmm… a ko lee pe ni ikabamọ naa… ṣugbọ mo mọ pe mo ṣu saga."
Jesu wá pa òwe kan fún wọn pé, “Kò sí ẹni tí ó jẹ́ ya lára ẹ̀wù titun kí ó fi lẹ ògbólógbòó ẹ̀wù.
Ọbasanjọ ni ọmọ òrùkàn tó di olóri orílẹ̀èdè lẹ́ẹ̀mẹ́ta ọ̀tọ̀ọ̀tọ̀ Ọkọ̀ dáńfó tí mò ń wà ní mo fi kọ́lé, rán ọmọ mẹ́ta ní fásitì - Obìnrin àkọ́kọ́ tó ń wa dáńfó l‘Eko Ìpínlẹ̀ Ogun fẹ́ fi òfin wọ́gilé ìsìnkú ọba lọ́nà ìṣẹ̀mbáyé Odunlade fẹ jẹ ọba ni ilu rẹ?
O ni oko oju irin lo je oko irinna to fi okan awon eniyan bale  nipa pipese  aabo fun emi ati dukia won.
Obi ni  eto iwa ibajẹ ti egbe APC
Ojoojumọ ni ijọba apapọ n ṣeleri pe awọn yoo wa a ri, awọn n duna dura pẹlu awọn to ji i gbe, ṣugbọn a ko tii gbọ nkankan titi doni.
2 74294 Orilẹede Zambia 364 2.
Ìpínlẹ̀ Oyo àti Eko kò nífẹ̀ẹ́ láti gba 'Ruga Settlement' láyè O ni ọrọ ti ijọba n sọ pe irọ ni pe wọn n ji awọn eniyan gbe tabi pe ko to odiwọn ti awọn eniyan n pariwo n kọ oun lominu pupọ.
 ‘‘Iko ile-ise NEPAD  yoo beere irin –ajo itaniji lo si awon ipinle kaakiri lorile-ede Nigerial odun yi.
Ayefele fi orin ẹ ṣeun sẹ́nu kí Ajimobi Iléẹjọ́ kòtẹ́milọ́rùn ti ní Ajimobi létọ̀ọ́ láti yan ọba l’Ọyọ Seyi Makinde, bàtà tí Ajimobi bọ́ sílẹ̀ ni ko tẹsẹ̀ bọ̀ fún àṣeyọrí Ọyọ - APC Arisekola ló fún mi ní ilẹ̀ tí ìjọba Ọyọ gbẹ́sẹ̀ lé, ń kò ní gbà - Ajimobi Mí ò bẹ̀bẹ̀ fún oyè igbákejì alága APC kí wọ́n tó ó fún mi - Abiola Ajimobi Lọdun 2003 ni Abiola dibo sile asofin agba labẹ ẹgbẹ oselu Alliance for Democracy AD, to si wọle lati soju ẹkun idibo guusu ipinlẹ Oyo, to si ṣe ọdun mẹrin gbako nibẹ.
Peter Okoye, ìyàwó àti ọmọ lùgbàdì ààrùn Coronavirus Oríṣun àwòrán, others Ìjọba Ondo ní òun kò sọ pé Agboola Ajayi kìí ṣe igbákejì gómìnà mọ́ Ijọba ipinlẹ Ondo ti sọ pe, ọdalẹ ni igbakeji gomina ipinlẹ naa, Agboola Ajayi, lẹyin to fi ẹgbẹ oṣelu APC silẹ lọ si ẹgbẹ oṣelu PDP.
Nítorí OLUWA ni ó sọ bẹ́ẹ̀.
Tayo sọ pe oun ko le tori bi ilu ṣe ri ki oun maa dunnu lọjọ ibi oun, bẹẹ lo gbadura pe ki Ọlọrun tubọ maa fi ere si iṣẹ ọwọ oun.
Oríṣun àwòrán, Alaafi ObaAdeyemi III Pẹlu bi iroyin nipa ajọṣepọ ohun ati ọkan lara awọn olori rẹ ṣe n ja ranyinranyin lori ayelujara bayii, Kabiyesi iku baba yeye, Alaafin ti ilu Ọyọ ti pin awọn ounjẹ fun idẹrun awọn eeyan ilu Ọyọ lasiko ajakalẹ arun Coronavirus yii.
Ko si parọ Oríṣun àwòrán, Google Njẹ a tíì ri ẹni to ń kọrin bii tirẹ di oni?
Láìpẹ́ wọ́n yọ si igbó Olódùmarè ṣùgbọ́n ilẹ̀ ń ṣu lọ bẹ́ẹ̀ ni ẹnikẹ́ni kò le wọ igbó burúkú náà ní òru àfi ẹni tí gọngọ bá máa sọ mọ́ lára.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù #2019NigeriaDecides Ìká wò ló lérò wí pé o yẹ láti fí dibo?
Àwọn tí wọn ń kó wọn ṣiṣẹ́ a máa fi ipá mú wọn pé, lojumọ, wọ́n gbọdọ̀ mọ iye bíríkì tí wọ́n máa ń mọ tẹ́lẹ̀, nígbà tí wọn kò tíì máa wá koríko fúnra wọn.
Koda minisita fun ere idaraya ati ọrọ ọdọ, Sunday Dare sọ pe lori iduro l'oun ti wo ifẹsẹwọnsẹ naa to fi pari nitori ẹru.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ọ̀rọ̀ lórí Brexit Ṣugbọn oun ti a le mọ lakọkọ ni bi awọn aṣofin ṣe le gbogun ti awọn adehun ti Theresa May ni pẹlu EU ati pe boya o tilẹ ni eto kankan lori ọrọ naa.
Bí ẹ bá pa á mọ́, ẹ óo wà láàyè, ẹ óo sì pẹ́ lórí ilẹ̀ tí ẹ̀ ń rékọjá Jọdani lọ gbà.
” OLUWA tún dáhùn, ó ní, “N kò ní pa á run nítorí ogoji eniyan náà.
Sugbon si iyalenu awon eniyan, oun funrarẹ ku ni aadọta ọdun ṣaaju ọdun to sọ nitori naa ko si laye lati ri i pe aye ṣi n tẹsiwaju.
Lọ́wọ́lọ́wọ́: Ìjọ àgùdà tó ti wà lát'ayédáyé ǹ jóná Ni kete lẹyin rẹ ni ileeṣẹ aarẹ da a pada sipo.
Ṣugbọn olórí agbọ́tí kò ranti Josẹfu mọ, ó gbàgbé rẹ̀ patapata.
Toyin, ti ọkọ rẹ, Kola Ajewọle duro ti lẹgbẹ timọtimọ lati gba ami ẹyẹ ọhun, ni wọn fun ni ami ẹyẹ osere-binrin to dangajia julọ lọdun 2019 .
Ó Bẹ̀rẹ̀ eré rẹ̀ pẹ̀lú ẹ́gbẹ́ eléré ìtàgé kan tó ń jẹ́ Star Parade lábẹ́ ìdarí Fadeyi t'òun náà jẹ́ òsèrè.
" Ọ ̀ pọ ̀ ikú ni o ń wáyé nípa "" p."
Sugbọn lero ti Ọgbẹni, gbese ayọ ni oun jẹ si wọn lọrun ni ipinlẹ Ọsun, tori awọn akanse isẹ ribiribi ti oun fi gbese naa se wa nilẹ bii ẹri maa jẹ mi niso.
ni  awon adajo meta  ati  osise ile ejo nilẹ Afirika, minisa fun oro ilẹ
Atiku Abubakar ti fi igba kan jẹ igbakeji Aarẹ lorileede Naijiria ti o si wa lara awọn ti o ṣetan lati gba agbara lọwọ Aarẹ Muhammadu Buhari.
"Lẹyin naa ""lo fi ipa fun un ni oogun amaraji pepe mu."
Ọ̀pọ̀lọ àti akèré, ìgbín àti ìjàpá, àdán àti òwìwì, èkúté àti òkété, òjòlá àti àjànàkú – gbogbo wọ̀nyí ni yóò gbógun tí ọ́ ní ọjọ́ ìbẹ̀wò rẹ.
Kia ni awọn to n fi koko ọrọ ṣe ọfintoto ṣafihan pe iroyin ofege ni.
Ìdí tí mo fi fẹ́ di Gómìnà Kogi - Dino Melaye Ọmọ Nàíjíríà gba àmì ẹ̀yẹ akẹ́kọ̀ọ́ tó pegedé jùlọ ní fásitì òkè òkun Ajọ to n mojuto ọrọ to kan awọn ọmọ orilẹede Naijiria nilẹ okeere, sọ ninu atẹjade kan to fi sita pe, eto ti n lọ lati ko awọn eniyan naa pada si Naijiria ki wọn tun to kagbako iku ojiji.
FIBAN: Ìpàdé àláàfíà wáyé láàrin KWAM 1 àti FIBAN, ìjà pari
nítorí ó sàn kí ó wí fún ọ pé,“Máa bọ̀ lókè níhìn-ín”,jù pé kí ó rẹ̀ ọ́ sílẹ̀ níwájú ọlọ́lá kan lọ.
Ọjọ kérinla, oṣu kerin, ọdun 1965 ni wọn bi Mohammed.
 o ko ipa pataki ni britani ati amerika ninu awon egbe sosialisti ati ironu marksisti , bakanna ati lori ero to le mu opin iseamusin wa .
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Visa to Nigeria: Ó lé gba ìwé ìrìnnà (Visa) láti wá fẹ̀yìntì sí Naijiria 28 Ọ̀wàrà 2019 Oríṣun àwòrán, NIGERIAN IMMIGRATION SERVICE Àkọlé àwòrán, Ilé isẹ́ ìrìnnà Naijiria ti setán láti fi ààyè sílẹ̀ fún àwọn ènìyàn láti má a wọ Naijiria fún ìfẹ̀yìntì.
Bakan naa ni Ole Gunnar Solskjaer ni atilẹyin awọn agbabọọlu Man United tẹlẹri, ati awọn to wa nibẹ lọwọlọwọ.
Lamidi Ọlayiwọla tun gbe ni ọdọ Alake tilẹ Ẹgba, Ọba Ọladepo Ademọla, ko to di pe wọn tun rọ Alake yii loye O tun lọ gbe lọdọ Ọlọla-binrin Kofoworọla Abayọmi ladugbo Keffi, ni Ikoyi nilu Eko, to si lọ sile ẹkọ Mọda, Ọbalende Modern School Lẹyin eyi lo morile ileẹkọ girama St.
Aya aarẹ orilẹede Naijiria ṣalaye wi pe, aarẹ Buhari gan ti iroyin n sọ pe o fẹ gbe iyawo tuntun ko mọ ohun to n lọ.
"Dino, èyí o ṣe yìí kù díẹ̀ káàtó"" Àdó olóró dáhùn lára èèyàn mẹ́ta ní ìlú Konduga Ṣé ẹ̀mí Super Falcons gbé e lálẹ́ òní pẹ̀lú France?"
Ó jẹ́ ohun ìgboyà tí àwọn akọni mẹta náà ṣe.
O le ni ọgọrun eniyan to ku ninu iṣẹlẹ naa, ti eniyan to le ni ẹgbẹrun mẹrin si farapa.
Wọ́n gbẹ́ àwòrán igi ọ̀pẹ, ati ti òdòdó, ati ti Kerubu yípo ara ògiri yàrá tí ó wà ninu ati èyí tí ó wà lóde; 
Ní orílẹ̀-èdè South Africa ni ọkọ̀ òfurufú tó n lọ lati ìlú Durban si Johannesburg ti di ilé igbẹbi fún ikoko kan.
Àwòrán bí ẹ̀kún omi ti ṣọṣé l'Eko àtàwọn ìlú míì nílẹ̀ Yorùbá rèé ‘A ó ran àwọn tó lùgbàdì omíyalé ìpínlẹ̀ Kogi lọ́wọ́’ Omiyalé Àkútè: N50 si N100 làwọn èèyàn fi ń kọjá lórí ẹ̀kún omi l'Ákútè È gbọ òun ti ojú awọn ara ipinle Ogun rí lọwọ ìṣẹlẹ omiyale Ki lo máa n fa ijamba omiyale ni Naijiria?
Àwọn ará Ninefe yóo ko ìran yìí lójú ní ìdájọ́, wọn yóo sì dá a lẹ́bi.
Osun Election: Secondus sèpàdé pẹ̀lú Adeleke àtàwọn tó ń fapá-jánú
Alaafin of Oyo: Kà nípa ohun mẹ́ta tí o kò mọ̀ nípa Ọba Lamidi Adeyemi III àtàwọn olorì rẹ̀ Oríṣun àwòrán, Alaafin Kii ṣe iroyin tuntun mọ pe Alaafin tilu Oyo, ọba Lamidi Olayiwola Adeyemi Kẹta ni ọpọ olori ni aafin, ti ọjọ ori wọn kere jọjọ si ti baba.
Boya nitori pe gbogbo aye lo n ṣe bi i wọn bayii.
Big Brother Naija: O tó gẹ́; a kò fẹ́ ìwòkuwò mọ́ ní Nàijíríà
Amọṣa, kii ṣe tori eyi ni iroyin yii ṣe jẹyọ bi ko sẹ ohun to pa Bobrisky ati iyawo Alaafin, Olori Aanu Adeyẹmi pọ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, AFCON 2019: Ọmọ Nàijíríà rọ Super Eagles lati tubọ sápa wọn pẹlú Madagascar Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
awon adari ekun Ila Gusu lalejo nile aare to wa niluu Abuja,lojo Aje, ni eyi ti
Oríṣun àwòrán, LASEMA Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Oríṣun àwòrán, Twitter Àwọn tó wà nínú ìjàmbá ọkọ̀ órí afára Otedola ń lọ ìpínlẹ̀ míì láti Eko ni - LASTMA Ileeṣẹ to n risi irinkerinko ọkọ oju popo ni ipinlẹ Eko, LASTMA ti sọ pe arinrin ajo ni awọn eeyan to wa ninu ijamba ọkọ to waye lori afara Otedola ni owurọ Ọjọbọ.
Bí ẹnikẹ́ni bá gbé òkú wọn, kí ẹni náà fọ aṣọ rẹ̀, yóo jẹ́ aláìmọ́ títí di ìrọ̀lẹ́.
Nítorí náà, kabiyesi, gba ìmọ̀ràn tí n óo fún ọ yìí; jáwọ́ ninu ẹ̀ṣẹ̀, sì máa ṣe òdodo, jáwọ́ ninu ìwà ìkà, máa ṣàánú fún àwọn tí a ni lára, bóyá èyí lè mú kí àkókò alaafia rẹ gùn sí i.
Baba Ijẹṣa ṣalaye pe ko si idi fun oloogbe naa lati ku kani awọn ohun elo irapada ẹmi gbogbo to yẹ ba wa lawọn ileewosan lorilẹede Naijiria ni.
Ẹwẹ, o kere tan, ẹgbẹrun meji eeyan lo ti lugbadi arun Coronavirus ni Naijiria nigba ti a n kọ iroyin yii lọwọ.
Osimhen tun ṣe bẹẹ gbayo ẹkẹrim wọle ni Naijiria ba jawe olubori pẹlu ami ayo mẹrin si meji.
“Ninu erongba aare Muhammadu Buhari lojuna ati gbogun ti iwa ibajẹ, O fi apere rere lele labele ti o fi mo nile okere.
O ṣalaye pe idi kan gboogi ti awọn ibode ọhun ṣe di titi pa ni eto aabo to mẹhẹ, paapaa julọ nitori bi awọn kan ṣe n ko ohun ija ogun ati egboogi oloro wọ orilẹede yii.
Ní àkókò náà Menahemu pa ìlú Tapua run, ati àwọn ìlú tí wọ́n yí i ká láti Tirisa, nítorí pé wọn kò ṣí ìlẹ̀kùn ìlú náà fún un, ó sì la inú gbogbo àwọn aboyún tí wọ́n wà níbẹ̀.
Hassan Adan Isaq, ti o je omo odun metalelogun ni won fi esun kan pe, o je omo-egbe omo-ogun olote al-Shabab, ti o wa nidi ikolu ti o buru-jai naa.
Lasiko igbẹjọ Lavona, o ni wi pe nọọsi ti orukọ rẹ n jẹ Sylvia, ti o n fun oun ni itọju iwosan ki oun le bimọ lasiko lo lọ gbe ọmọ jojolo naa wa, ti o si sọ fun oun pe iya rẹ kọ ọ silẹ ni.
O ba awọn ti eeyan wọn toi ku sọwọ coroanvirus.
Òun ati àwọn ọmọ ogun rẹ̀ bá lọ sí ìlú Amaleki, wọ́n ba ní ibùba, ní àfonífojì.
Àwọn iròyin tì ẹ leè nífẹ̀ síí: 'Ẹ jẹ́ kí Buhari lọ jókòó' Buhari kéde pé òun yóò se sáà kejì nípò Ààrin àwa àti Bùhárí kò léè gún - Sàràkí Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí kan sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
Fayoṣe bẹ̀rẹ̀ ìjẹ́jọ́ ní ilé ẹjọ́ gíga Eko Àkọlé àwòrán, Fayoṣe ní ilé ẹjọ́ gíga ìpínlẹ̀ Eko Ní òwúrọ̀ ọjọ́ ajé, ọgbà ilé ẹjọ́ gíga ìpínlẹ̀ Eko níbi tí ìjẹ́jọ́ Fayose yóò ti wáyé ti ń kórajọ́ fún iṣẹ́ òòjọ́.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Kayefi BBC Yorùba: Bàbá ọmọ, Mọ́ṣúárì, Ọlọ́pàá kẹ́jọ́ rò nípa òkú ọmọ tó pòórá Iṣọla Oyenusi rèé, ẹnití ìfẹ́ obìnrin ṣun dé ìwà ìdigunjalè Ayinla Ọmọwura, orin èébú àti oríyìn lo fi di ọ̀rẹ́ àwọ̀n obìnrin Ẹfunroye Tinubu - Ògbóǹtagí oníṣòwò, olówò ẹrú àti afọbajẹ Samuel Ajayi Crowther, òjíṣẹ́ Ọlọ́run tó gbé èdè Yoruba lárugẹ Ta ba si n sọ itan idagbasoke orilẹede Naijiria, titi de ibi ta de duro yii, ti a ko ba tii ranti Taiwo Akinkunmi, itan wa ko tii kun to, nitori ipa to ko lati ri si ifilọlẹ ilẹ Naijiria pẹlu agbekalẹ asia ilẹ wa to rẹwa, ta n pe ni National Flag.
OLUWA ló ń ṣe ìdájọ́ àwọn orílẹ̀-èdè ayé;dá mi láre, OLUWA, gẹ́gẹ́ bí òdodo mi ati ìwà pípé mi.
Ninu ifọrọwerọ pẹlu alukoro ileeṣẹ ọlọpaa nipinlẹ Kwara, Ajayi Ọkasanmi, ileeṣẹ ọlọpaa ṣi n ṣe akojọpọ iroyin ti ati iwadi lori iṣẹlẹ naa.
Bakan naa ni ilumọọka osere tiata miran, Femi Adebayo fi fidio kan to se si oju opo Instagram rẹ, to si n rọ awọn eeyan pe ibasepọ lọkọlaya kii se tipa tikuuku.
Awọn ohun eelo yii mu awọn adura ati asọtẹlẹ da ni fun ẹjẹ ọrun tuntun naa ni eyi to n mu aṣẹ dani ninu igbagbọ iran Yoruba.
"Sextuplet: Àdúrà Ìbùkún ló kú lẹ́yìn ọmọ mẹ́fà yìí- Ifeoma Thelma àti Onyemaechi Chiaka Joe Biden kéde Kamala Harris, obìnrin aláwọ̀ dúdú gẹ́gẹ́ bí igbákejì rẹ̀ nínú ìdíje sípò Ààrẹ Amẹrika Wo ìdí tí Risikat Moromoke Azeez n'Ilorin fi ní ""Blue Eyes"" - Dókítà NCDC kéde èèyàn 423 míràn tó ṣẹ̀ṣẹ̀ lùgbàdì Covid-19 ní Nàìjíríà, 263 gbàwòsàn Obasa ni ijọba lo kọkọ gbe abadofin naa wa fun wọn, ki ọmọ ile kan to da a laba pe ki awọn obi ni ipin ninu ijiya to tọ si ọmọ, nitori awọn obi naa kọ lati tọ awọn ọmọ wọn daradara."
Wọn gba awọn eeyan niyanju lati ni ẹmi ifarada ki Naijiria le tẹsiwaju.
Kí Olódùmarè má jẹ́ káa rí irú èyí mọ́ láíláí.
O ni awọn figilante, sọludẹrọ ati awọn ọdẹ to ti n gbogun ti iwa ọdaran lati ẹyin wa, naa yoo lanfani lati darapọ mọ ikọ Amọtẹkun, ti wọn yoo si maa gba owo oṣu labẹ ijọba ipinlẹ Ọyọ.
Àwọn ènìyàn yìí wà ní abala àríwá congo , wọ ́ n sì tó ọ ̀ kẹ ́ méjì ni iye .
Akẹkọ Dapchi pada de Awọn olori ileesẹ aabo tẹdo si Dapchi Okiki kan nigba naa kakiri agbaye lori bi ijọba to wa lode lorilẹede Naijiria lasiko naa ṣe kuna lati daabo bo awọn akẹkọ naa.
“Bí wọ́n bá ṣẹ̀ ọ́ (nítorí pé kò sí ẹni tí kì í ṣẹ̀), tí inú bá bí ọ sí wọn, tí o sì mú kí àwọn ọ̀tá wọn ṣẹgun wọn, tí wọ́n sì kó wọn lẹ́rú lọ sí ọ̀nà jíjìn tabi nítòsí, 
Ọlọ́pàá kọlu àwọn ọmọ onílẹ̀, ní ìbọn àṣìyìn pa ènìyàn méjì Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Ondo Election 2020: Ẹ wo àwọn olùdíje sípò gómìnà nípínlẹ̀ Ondo tó takò bàbá ìsàlẹ̀26 Owewe 2020 Fídíò, Wole Soyinka sọ ìdí tó fi ni òun a fi màálù Fulani ṣe súyà fáwọn èèyàn abúlé23 Owewe 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Baba ijẹṣa ṣalaye pe ohun to n ba awọn oṣere ninu jẹ pups julọ ni pe ijọba orilẹede Naijiria ko ṣai maa ja araalu to dibo fun wọn kulẹ.
Ẹlẹ́sìn Aghoris: Wọ́n ń jẹ ènìyàn, wọn a sì fi orí rẹ̀ mumi
Nígbà tí Paulu mọ̀ pé àwọn ọmọ ẹgbẹ́ Sadusi ni apá kan ninu àwọn tí wọ́n wà ninu ìgbìmọ̀, àtipé àwọn ọmọ ẹgbẹ́ Farisi ni àwọn mìíràn, ó kígbe pé, “Ẹ̀yin ará, Farisi ni mí.
Pẹlu awọn ilu, fere ati ohun to rinlẹ ni Lira ati Waje fi ṣe awo orin ti kii ṣe dandan ko sọ oke iṣoro di ipẹtẹlẹ ṣugbọn fi igbagbọ si ni lọkan pe pẹlu ọkan alafia, oke iṣoro le di ipẹtẹlẹ.
O pe ẹjọ yii tako ẹni ti wọn kede gẹgẹ bi olubori ninu idije si ipọ Sẹnetọ ẹkun idibo guusu ipinlẹ Ọyọ, Sẹnetọ Kọla Balogun.
Ìgbẹ́jọ́ Naira Marley sún síwájú bí àwọn agbẹjọ́rò ṣe ń jà sí àga ìjókòó EFCC ti mú Mínísítà ètò ìdájọ Nàìjíríà tẹlẹ lórí ẹsùn ajẹbanu $1.
Van Persie kii ṣe asiko ti ẹgbẹ agbabọọlu Man U ṣẹṣẹ fidi rẹmi tan lo yẹ ki Ole maa rẹrin nigba to n dahun ibeere awọn akoroyin.
Alaafin ko darukọ ọba kankan pe Mayegun ko gbọdọ bọwọ fun wọn ṣugbọn gẹgẹ awọn iwe iroyin Naijiria kan ti ṣe sọ, Alaafin ni oun ko sọ fun Wasiu Ayinde ko tabuku si awọn ọba bi Ooni Ife, Orangun Ila, Awujale Ijebu-Ode, Owa Obokun Ilesa, ati Alake Egba pẹlu awọn miran to fi ara wọn si ipo ọwọ.
Ẹ fi wọ́n sílẹ̀ fún àwọn àlejò ati àwọn aláìní baba ati àwọn opó.
Awọn ọmọ Naijiria gboriyin fun Super Eagles 'N2,500 ni mo raa mo si fẹran rẹ' #Russia2018: Super Eagles ti koju Argentina rí 'Awọn kan n gba’bọde fun Super Eagles' Nigba ti BBC Yoruba fọrọ wa awọn ololufẹ Super Eagles lẹnu wo lori idije toni, ọpọ wọn lo fadura ranṣẹ si awọn agbabọọlu wa ni Egypt Kíló burú nínú kí Sanwo-Olu fún Super Eagles lówó?
Genesis Global: Ṣé lóòtọ́ ni pásítò ìjọ Celestial, Israel Oladele Ogundipe rẹ́wọ̀n hẹ?
Lọdun to kọja, lorilẹede France yii kan naa ni ileẹjọ ti gbe idajọ kalẹ lẹyin t'awonaladugbo pariwo pe akukọ kan n fi kikọ rẹ di awọn lọwọ lowurọ kutukutu.
Ẹkẹtala mú Ṣubaeli, òun ati àwọn ọmọ rẹ̀ ọkunrin, ati àwọn arakunrin rẹ̀ jẹ́ mejila.
"Ọrẹ wa ni Lawrence o, amọ o gbe n kan gbẹyin wa.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Inú mí dùn láti kọrin pẹlú Beyonce nílẹ̀ Amerika- Ìyá àgbà láti Nàíjíríà Àwọn òṣèré tíátà Yorùbá kọjú ìjà síra wọn lórí ìdárò akẹẹgbẹ́ wọn tó kú Ìpàkọ́ kò gbọ́ sùtì ní ọ̀rọ̀ ẹ̀yin tí ẹ̀ ń bú mi- Oyedepo Mo kọ̀ láti pín ọkọ mi pẹ̀lú ẹnikẹ́ni, nítorí náà ẹ tú wa ká- Abílékọ Idowu faraya ní kóòtù kọkọ-kọkọ Walter Carrington ràn mí lọ́wọ́ kí ń lè sá àsálà lásìkò tí Abacha ń wá mí kiri- Obasanjo Kíákíá lọ daṣọ bo igbá àyà rẹ to ṣí kalẹ̀!
Malam Hussaini wa ro awọn  to n gbe ilu Abuja ati awọn  to nile niluu Abuja  lati tete san owo ti wọn  jẹ ijọba ati awọn owo miiran, nitori pe ijọba nilo owo naa lati pese ohun amayedẹrun .
aidunnu re han lori ikolu to sẹlẹ ni ipinle Sokoto nibi ti ọpọlọpọ awon eniyan
Iye awon omo orile ede Naijiria ti won forukosile lati dibo jẹ milionu
Awọn obirin naa to ba BBC sọrọ sọ pe, ko din ni ọmọ wẹwẹ marun un ti wọn ti ji gbe lagbegbe ọhun.
5 túbọ̀ ń rinlẹ̀ sí i ní ìlà-oòrùn Caribbean, níbi tí àwọn ọ̀kọrin ti ṣe àlọ́pọ̀ ọ̀rọ̀ akéwì St.
Awọn ohun eelo ati ohun ti ẹnu n jẹ ni awọn agba maa n ko sita fi ṣadura fun ikoko tuntun ti a ba bi nilẹ oodua.
2bn naira) ninu rẹ ni wọn fi n san owo oṣu awọn ọmọogun ilẹ naa.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìjọba ìpínlẹ́ Kaduna: A kò dá olùkọ́ míì dúró 19 Ìgbé 2018 Oríṣun àwòrán, Nasir El-Rufai/Twitter Àkọlé àwòrán, Gómínà Nasir El-Rufai bu ẹnu àtẹ́ lu ìròyìn pe àwọn dá ogunlọ́gọ́ olùkọ́ tí wọ́n sẹ̀sẹ̀ gbà ní ìpínlẹ̀ náà dúró Ìjọba ìpínlẹ́ Kaduna ti bu ẹnu àtẹ́ lu awuyewuye tó ń lọ lóde wí pé wọ́n dá ẹgbẹgbẹrún àwọn olùkọ́ tí wọ́n ṣẹ̀ṣẹ̀ gbà dúró.
Laipẹ yii ni awọn ọmọ ofun Naijiria foju wina ọpọlọpọ nkan loju ogun to bẹẹ ti awọn kan ti n boju wẹyin loju ogun ti wọn si n fiṣẹ wọn silẹ.
Ó fún Nàìjíríà l'èsì àwọn ẹ̀sùn tó fi kàn-án Ọba ni mí, mi ò le b'ọ̀rìṣà, Olorì tuntun tó ń bọ̀ já gbogbo ''scale''- Oluwo ti Iwo Èèyàn méjì kú, méjìdínlógóje míì ṣẹ̀ṣẹ̀ kó COVID-19 lọ́jọ́ Àìkú Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Fídíò, Natalia Mufutau ìyá Yakub, Kamil àti Adam sọ̀rọ̀ lórí bí wọ́n ń sọ èdè mẹ́rin pàpọ31 Ògún 2020 Oluwo: Èmi l'ọba lórí òrìṣà, oṣó àti ajẹ́, Olorì tuntun tó ń bọ̀ lẹ́tikẹ31 Ògún 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 3 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 5 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Kábíyèsì fẹnu ara rẹ̀ tú àṣírí àwọn Fulani Daran daran tó ń ṣọṣẹ́ nílùú rẹ̀ Èmi àti Saheed kìí ṣe ọmọdé, a ti jọ ṣe Sinimá papọ̀, èyí túmọ̀ sí pé ìjà ti parí - Fathia Balogun Àjẹ́ àti Aṣẹ́wó ní ìyá Rainbow - Òjòpagogo Ọ̀pọ̀ èèyàn bẹnu ẹ̀tẹ́ lu Mercy Aigbe lórí bó ṣe ki Adeniyi Johnson Sibẹ, wuyewuye lori ọrọ Tacha ti wọn ti ṣe fọwọ osi juwe ile fun un kuro lori eto agbelewo BBNaija ko tii tan o.
Ìjòyè yìí yóo bá ọpọlọpọ dá majẹmu ọdún meje tí ó fẹsẹ̀ múlẹ̀.
Chloroquine for coronavirus: Njẹ Chloroquine nipa kankan láti kojú Coronavirus?
Dafidi tẹ́ pẹpẹ níbẹ̀, ó rú ẹbọ sísun ati ẹbọ alaafia, ó bá képe OLUWA.
O lọ sileewe alakọbẹrẹ ati girama nilu Kano ki o to lọ kẹkọ gboye ijinlẹ ni iṣẹ iroyin ni fasiti Bayero ni ilu Kano.
Nítorí pé ó ti bá mi sọ̀rọ̀,òun fúnrarẹ̀ ni ó sì ṣe éOorun kò kùn mí nítorí pé ọkàn mi bàjẹ́.
Lẹyin iku rẹ, pupọ awọn agbabọọlu ẹgbẹ Stationery Stores to jẹ ọmọ ilẹ Ghana pada sile ti awọn miran si lọ gba fun ẹgbẹ ECN ati Ngeria Airways.
Wọ́n ṣe làálàá, ṣugbọn wọn kò jèrè kankan.
Nítorí Jesu ti pàṣẹ fún ẹ̀mí àìmọ́ náà láti jáde kúrò ninu ọkunrin yìí.
Bí ẹnikẹ́ni kò bá fẹ́ràn Oluwa wa, ẹni ègún ni!
Mo rí i pé mo wà létí odò Ulai.
0 16 Orilẹede Anguilla 0 0.
Sibẹ ẹ tún wà ninu àwọn tí a óo máa kọ́ ní “A, B, D,” nípa nǹkan tí ó jẹ mọ́ ti Ọlọrun.
Ahesọ nipe tori wọn n sọrọ sijọba ni.
Ṣugbọn OLUWA Ọlọrun mú kí ọkàn Farao le, kò sì jẹ́ kí wọ́n lọ.
Jesu ará Nasarẹti ni ẹni tí Ọlọrun ti fihàn fun yín pẹlu iṣẹ́ agbára, iṣẹ́ ìyanu, iṣẹ́ abàmì tí Ọlọrun ti ọwọ́ rẹ̀ ṣe láàrin yín.
Kò sí iye tí eniyan ní tí ó le kájú rẹ̀,
 ilé-iṣẹ ́ fíìmù yorùbá ti tóbi si ; àkóónú fíìmù wọn sì ti ń yípadà sí ti àtijọ ́ tí ó jẹ ́ wí pé ọ ̀ rọ ̀ ẹ ̀ sìn ìbílẹ ̀ , ẹ ̀ fẹ ̀ àti bẹ ́ ẹ ̀ bẹ ́ ẹ ̀ lọ , ni ó ń jẹ ẹ ́ lógún .
14 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 20 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Ile iṣẹ ologun Naijiria ti ṣipaya awọn nkan kọọkan lorii bi wọn ṣe ri awọn akẹkọọ to le ni ojilelọọdunrun ti awọn ajinigbe ji gbe ni ileewe Kankara, ipinlẹ Katsina doola pada.
Faṣọla ni olori awọn oṣiṣẹ labẹ gomina ipinlẹ Eko lasiko to fi n ṣe akoso ijọba ipinlẹ Eko.
Àkọlé àwòrán, Ki ni ounjẹ ti ẹ ro pe N117,000 na le ra ni ojoojumọ?
Ṣugbọn Ọlọrun ṣe ìlérí láti fún òun ati ọmọ rẹ̀ tí yóo gbẹ̀yìn rẹ̀ ní ilẹ̀ náà, bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé kò ní ọmọ ní àkókò náà.
Iran ti jáwọ nínú ìlù ogun tó n lù -Trump Ẹ̀jẹ̀ yóò sàn pẹ̀lú bí Amerika se pa Ọ̀gáagún wa - Iran Soleimani Killing: Ẹgbẹ́ Shiites wọ́de l'Abuja, wọ́n jó Àsìá Amẹ́ríkà Amẹrika àti Faranse fẹnu ọ̀rọ̀ jóná lórí Iran Ṣaaju ni adari Iran ni awọn yoo ṣe iwadii ohun to ja ọkọ ofurufu naa bọ ki wọn to tun ni awọn ọmọ ogun Iran lo ṣeeṣi ja ọkọ naa bọ.
N kò mọ ẹni tó fẹ́ gba ìyàwó mi, àmọ́ wọn máa ń sọ pé ó rẹwà - Mike Bamiloye Wo bí ìtàkurọ̀sọ láàrin Donald Trump àti Joe Biden yóò ṣe wáyé Àríyá yá!
O ni lootọ, awọn nkan mii le ṣẹlọ ti obinrin yoo fi san owo ile iwe awọn ọmọ ṣugbọn kii ṣe ẹtọ ẹ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù FIFA kò ní le f'òfin de Nàìjíríà lẹ́yìn tíjọba gba Amaju Pinnick ní Ààrẹ NFF 20 Ògún 2018 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Amaju Pinnick nàá tún ni ìgbákejì ààrẹ àjọ tó n mójútó bọ́ọ̀lù gbágbá ní ilẹ̀ Afrika, CAF Naijiria ti bọ lọwọ igbesẹ ti ajọ FIFA fẹ ẹ gbe lati f'ofin de bọọlu alafẹsẹgba l'orilẹede naa.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Delta petrol tanker explosion: O ti lé ní ènìyàn mẹ́wàá tí ina jó gúrúgúrú nínú ìjàmbá tó wáyé ní Delta 23 Agẹmo 2020 Àkọlé àwòrán, O ti lé ní ènìyàn mẹ́wàá tí ina jó gúrúgúrú nínú ìjàmbá tó wáyé ní Delta O le ni eniyan mewaa ti ina jo guruguru ninu ijamba ọkọ.
Ẹni tí ó fi ọ̀dọ́ aguntan rúbọ,kò yàtọ̀ sí ẹni tí ó lọ́ ajá lọ́rùn pa.
Nigba to n dahun ibeere wa lori aago, Olori Anu sọ pe ọrọ igbesi aye oun ni, ati pe oun ko ni ohunkohun sọ nipa iroyin naa.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ogun flood: ọ̀ps àwọn olùgbé agbegbe yii ti fi iṣẹ́ sílẹ̀ nítorí wọn kò lè jáde Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Oríṣun àwòrán, others Alukoro ileeṣẹ ọlọpaa ni ipinlẹ Eko, Bala Elkana to ba ikọ BBC news sọrọ ṣalaye pe wọn ti da ikọ ọlọpaa kogberegbe kan si agbegbe naa ti wọn si ti pana wahala ọhun.
Kanu Nwankwo fẹ Amarachi lọdun 2004 nígbà tó wà ni ọmọ ọdún mẹ́jìdínlógun, ọlọrún fi ọmọ mẹ́ta ta wọ́n lọ́rẹ.
Bakan naa iye ọjọ ti wọn fi n ṣe Garri ko kere ṣugbọn ko le din ni ọjọ mẹfa rara.
Bi irinajo aye Apamọlẹkun jaye ẹda naa si ṣe lọ ree, gẹgẹ bi oju opo Wikipedia atawọn oju opo miran lori itakun agbaye ti ṣe akọsilẹ rẹ.
Ti awon eniyan ko ba mo ibi ti orisun re gbe sẹ wa , o ti sọ ara nu niyẹn.
Ó ní, “Baba, bí o bá fẹ́, mú kí ife kíkorò yìí fò mí ru.
Ajọ eleto idibo, INEC ti kede Fayẹmi ati ẹgbẹ oṣelu rẹ, APC gẹgẹ bii olubori ibo gomina ipinlẹ Ekiti pẹlu ibo 197, 459 lati bori Ẹlẹka to ṣe ipo keji pẹlu ibo 178,121.
Itan aye Eji Gbadero tun kọ wa pe asegbe kankan ko si, aṣepamọ lo wa, nitori naa, ko yẹ ka maa gbe inu okunkun ṣe iwa ibi.
Ṣé ibi ni eniyan fi í san rere?
Sọ̀rọ̀ kí o kígbe sókè, ìwọ tí kò rọbí rí.
Oríṣun àwòrán, Twitter/instagram Lara wọn lati ri awọn olorin, agbabọọlu, oṣere ati awọn mii.
2 mílíọ́nù owó ìtanràn Cardi B ṣàlàyé ohun tó gbé fọ́tò ìhòhò rẹ̀ d'órí ayélujára Instagram Ẹ ṣọ́ra ní òpópónà AIT, ọkọ̀ agbépo kan ti yí dánù lọ́nà agbègbè Alagbado Àjẹ́ àti Aṣẹ́wó ní ìyá Rainbow - Òjòpagogo Ìjọba ìpínlẹ̀ Eko ti kéde orúkọ àwọn ọlọ́pàá tó fi ìyà jẹ àwọn olùwọ́de #EndSARS O ti lé ni ọsẹ kan ti awọn ọdọ naijiria ti gunlẹ iwọde End SARS, eyii ti wọn fi n bere fun opin si ẹka ileeṣẹ ọlọpaa to n gbogun ti iwa idigunjale, SARS.
Kí ni ìdí rẹ̀ tí n kò fi ní lè lọ bá àwọn ọ̀tá rẹ jà, nígbà tí o kò rí ẹ̀bi kan lọ́wọ́ mi láti ìgbà tí mo ti dé ọ̀dọ̀ rẹ?
Ogun Anglo àti Francophones Cameroon mú ẹ̀mí 23 lọ INEC lẹ orúkọ àwọn olúdíje sípò gómìnà ní Ọsun Ọdún Ọṣun Oṣogbo wọlé dé wẹ́rẹ́, Òyìnbò gan dáwọ́ọ̀ ìdùnnú N kò nílò ìwé ẹ̀rí Waec ní fásitì Amẹrika - Adeleke Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí 2 sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
Ni bayii, ajọ isọkan orilẹede agbaye ti dẹkun kiko eroja iranwọ lọ si agbegbe naa Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Mama Arsenal: Màmá àgbà yìí máa ń lọ sí ìbùdó tí wọ́n ti ń wo bọ́ọ́lù láti wòran Buhari se'pade pajawiri Saaju la ti mu iroyin wa fun yin pe aarẹ Muhammadu Buhari ti n ṣe awọn ipade pajawiri nilu Abuja loni latari ipo ati irisi orilẹ ede Naijiria.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Aarẹ Buhari re e ni ibi ayẹyẹ June 12 ni papa isere Eagle Square ni ilu Abuja to jẹ olu ilu orilẹede Naijiria.
lára ìdẹ ́ kun ni díndín àwọn ìbújẹ ẹ ̀ fọn kù ní àwọn agbègbè tí àrùn ti wáyé .
Àṣé wọ́n fẹ́ tètè ta gbogbo ẹ̀ kúrò lórí igbá ni.
PTF ni o ṣe pataki ki awọn ọmọ ile iwe to wa ni ipele kẹta akọkọ ile iwe girama, JSS 3, ati awọn to wa ni ipele kẹta keji, SSS 3 pada sile iwe.
Soyinka sọ ọrọ yii ninu atẹjade to fi lede to pe akọle rẹ ni Between 'Dividers-in-chief' and Dividers-in-law,"" ni ile rẹ ni Ijegba, Idi-Aba Estate, Abeokuta."
Awọn to ni i lasiko ooru ko pọ.
Ninu gbogbo iṣẹlẹ iroyin igbeyawo ofege Aarẹ Buhari yii ni fidio kan ti n tan kalẹ pe wọn ti ti Aisha Buhari mọle ninu ile ijọba ni Abuja.
"Onome pari ọro rẹ pe wọn ti bẹrẹ igbesẹ lati dari ẹjọ naa si ẹka ileeṣẹ ọlọpaa to n ri si iwa ọdaran, CID.
Bẹẹ naa ni ẹnu ko sin lẹyin ikọ naa lori iku ọlọpaa kan to waye ni agbegbe Sango ni ilu Oyo lọjọ Kẹrin osu Kini.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ibo Italy: Ọmọ Naijiria di asofin agba ni Italy 6 Ẹrẹ̀nà 2018 Oríṣun àwòrán, Iwobi facebook Àkọlé àwòrán, O le ni ọgbọn ọdun ti Tony Iwobi ti ngbe lorilẹede Italy Ọmọ Naijiria kan to ti di ọmọ orilẹede Italy bayii, ẹni tii se agbẹnusọ fawọn atọunrinwa ninu ẹgbẹ oselu League, Tony Iwobi ni wọn ti dibo yan gẹgẹ bii asofin agba alawọ dudu akọkọ lorilẹede naa.
Àwọn orílẹ̀èdè àjọ ECOWAS yóò máa ná owó kan nàá l'ọ́dún 2020 Ìjọ Satani dá MI lóhùn lórí ọ̀rọ̀ Fatoyinbo US-North Korea: Trump ati Kim John-un bẹ̀rẹ̀ ìpàdé Damasus, Omotola, Ezekwesili, Funmi Iyanda dá sí ẹ̀sùn ìfipábánilòpọ̀ Fatoyinbo Orilẹ-ede Madagascar ko kopa ninu idije FIFA lati ọdun 1950 si 1970.
Fatai Rolling Dollar: Baba 70 jayé kọjá 70 kó tó dágbére fáyé pé ó dìgbóṣe!
Ijoba apapọ fọwọ́ sí àdínku owo foomu idanwo oniwe mẹwa WAEC ati NECO, ẹdinwo naa ko ṣai tun kan fọọmu idanwo aṣewọ ileewe giga, JAMB.
Gómìnà mẹ́rin yóò jẹ́jọ́ lẹ́yìn sáà wọn - EFCC Ìjọba South Africa pèpàdé lórí ìkórìíra àlejò #Mothersday2019: Àwọn ìpèníjà obìnrin láwùjọ Odo adagun meji lo jẹ iru eyi to wa ni gbogbo agbaye.
Already, President Muhammadu Buhari has sent his greetings and best wishes to Muslims in Nigeria and across the world as they commence the 30-day Ramadan fast.
Ilé alájà méjì wó lu ọmọ mẹ́rin ni Bariga Ọlọ́pàá fi páńpẹ́ ọba mú ọmọ ogun ilẹ̀ Naijiria Dalung, Audu Ogbe, Shittu Adebayo àti Isaac Adewole kò wọlé Ṣé irúfẹ́ oúnjẹ tí ò ń jẹ́ lè jẹ́ kí o gbádùn ìbálòpọ̀ rẹ síi?
Ìdí tí a ṣe yọ ọwọ́ Naira Marley kúrò láwo Headies Award ọdún yìí rèé - HipTV Kò sí àrùn 'Monkey Pox' ní Naìjiria- NCDC Jumọkẹ Odetola ṣe ọjọ́ ìbí, Wumi Toriola bímọ, Ṣé ẹ fẹ́ tẹ̀lẹ́ Funkẹ Akindele lọ si Dubai?
Nípasẹ̀ èyí ni a ti gba àwọn ìlérí iyebíye tí ó tóbi jùlọ, tí ó fi jẹ́ pé ẹ ti di alábàápín ninu ìwà Ọlọrun, ẹ sì ti sá fún ìbàjẹ́ tí ìfẹ́kúfẹ̀ẹ́ ti mú wọ inú ayé.
Ṣàánú mi, OLUWA, nítorí àárẹ̀ mú ọkàn mi,OLUWA, wò mí sàn nítorí ara ń ni mí dé egungun.
Dapo Abiodun - BBC News Yorùbá BBC News, YorùbáFò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Anthony Joshua vs Pulev highlights: Ẹ̀bùn ọdún Kérésìmesì ni àseyọrí Joshua lẹ́yìn tó na Pulev lálùbolẹ̀ - Dapo Abiodun 13 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 14 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Oríṣun àwòrán, Getty Images Gomina ipinlẹ Ogun, Dapo Abiodun ti ki abẹṣẹkubiojo,Anthony Joshua ku oriire lẹyin to bori ojugab rẹ lati orilẹ-ede Bulgaria, Kubrat Pulev ni gbagede SSE Arena ni ilu London lalẹ ọjọ Abamẹta.
Alukoro ajọ naa, arabinrin Millicent Umoru to fi idi rẹ mu lẹ wi pe lootọ ni wọn gba owo to to ẹgbẹrun lọna ogoji naira lọwọ awọn ọdọ naa sugbọn kii se owo afi ipa gba.
Ko si iru ipaya ti aarun coronavirus le mu ba ọ, boya nípa ilera rẹ, pipanu isẹ, faaji, oun ti o ni lati mọ nipe kii se iwọ nikan lo n laa kọja.
'Alagbalúgbú' jẹ́ ọ̀rọ̀ tí Yorùba fi ń ṣàpèjúwe agbára òkun
lorile ede yii lati wa woroko fi sadaa lori eto aabo, ni eyi ti
Ijọba ipinlẹ Kwara tun kede pe oun yoo tu awọn ẹlẹ́wọ̀n kan silẹ lati le dena itankalẹ aarun coronavirus.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, LASU Ritual: Àwọn akẹẹgbẹ́ akẹ́kọ̀ọ́ LASU tí wọn fi ṣowó sọ̀rọ̀ lórí ìgbé ayé olóògbé Ni ọdun 2017 ni Maina ba tun wọle pada sẹnu iṣẹ ọba, koda ipo oludari kan ni ileeṣẹ ọrọ abẹle ni wọn da a pada si ki ariwo to sọ.
Ajọ to n ri si akoso isẹlẹ pajawiri nipinlẹ Eko, LASEMA to fidi rẹ mulẹ loju opo Twitter rẹ, salaye pe opopona Afariogun ladugbo Ajao Estate nilu Eko ni isẹlẹ naa ti waye.
coronavirus updates: TB Joshua, Apostle Suleman, Odumeje, D.
Mose bá gun orí òkè náà lọ, ìkùukùu sì bo orí òkè náà.
O ni ipade ẹgbẹ osṣelu PDP naa ni ọkọ oun lọ ni Eti ọsa ki wọn to yinbọn paa lọsan gangan.
Ninu àwọn ọmọ Itamari, Daniẹli ni olórí.
Lóòótọ́ lòògùn owo wà ṣùgbọ́n ayédèrú aláwo ló ń lo ẹ̀yà ara -Ẹlẹ́búìbọn Kò tíì sí àrùn Coronavirus ní ìpínlẹ̀ Oyo, a ṣi ń retí èsì àyẹ̀wò - Ijọba Oyo Alagba Peter Fatomilsla, ọkan lara awọn odu elere tiata lorilẹede Naijiria, toun pẹlu kopa lasiko ere itage ṣalaye ohun to ṣẹlẹ ati ibi ti ọrọ ti wọ wa.
Wọ́n ń lù ú ní igi lórí, wọ́n ń tutọ́ sí i lára, wọ́n wá ń kúnlẹ̀ níwájú rẹ̀, wọ́n ń júbà yẹ̀yẹ́.
Olólùfẹ́ míì tó ń dọ́fun tòló láti fẹ́ ọmọ ààrẹ tún yọjú síta Oríṣun àwòrán, Abdullahi Bashir Ọrọ ifẹ, bii adanwo ni, bẹẹ si ni oro ọfa ifẹ ju oro ibọn lọ fun ẹni to ba ni iriri rẹ.
Arun Iba: Naijiria gbaradi fun eto ajẹsara to pọ julọ
Lẹ́yìn èyí arii, ikùn rẹ̀ fà, àti ọjọ́ náà lo sì ti dàbí gbogbo ènìyàn tí o ń jẹun bí gbogbo ayé ti ń jẹun.
Àwọn ọmọ Dedani ni Aṣurimu, Letuṣimu ati Leumimu.
Awọn iroyin miran ti ẹ le nifẹ si: Eeyan mẹrin ku ninu ijamba ọkọ l'Eko Wọn ri oku ọmọ to sọnu ninu ọkọ orogun iya rẹ O see se ki ọti ati siga gbowoleri Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Òun ni orísun ìyè, ìyè náà ni ìmọ́lẹ̀ aráyé.
ile igbimo asofin agba  lo n soju fun Ila
Oríṣun àwòrán, AFP Àkọlé àwòrán, Awọn oṣiṣẹ pajawiri ni ẹkun Kozhikode fun awọn ara ilu lounjẹ Akoroyin BBC to wa nibẹ sọ pe, awọn ara ilu ni Cochin ta okun si awọn adugbo ki awọn ti o ba fẹ sa asala fun ẹmi wọn baa ri nkan di mu.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Mayowa Omoniyi: Kò sí orin Obey, Sunny Ade abí tàkasúfèé tí ń kò le ta gìtá sí Wọ́n má n bínú jù tàbi ki wọ́n ma bá àwọn ènìyàn ṣe mọ́.
Sùgbọn èyí ṣẹlẹ̀ lọ́dùn yìí nítori pé kò sí kọnu-kọhọ nínú ètó àjọ náà àti pé owó tó ń wole sápò ìjọba kò dínkù, ó fi kún-un pé ààrẹ Muhammadu Buhari tí ń wà gbogbo ọ̀nà láti mú àdínkú ìṣẹ́ tó wà láwùjọ.
Mo mọ wipe ọpọlọpọ ni yoo ranti bi gbogbo aye ṣe fẹran akọroyin ọmọ Saudi Jamal Khashoggi.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Iya Rainbow, Jide Kosoko, Ọga Bello, yóò polongo Buhari fún 2019 Djxgee kéde ikú ara rẹ̀ lórí Instagram kó tó gbé májèlé jẹ Àwọn àṣà àti ìse tó yọ obìnrin sílẹ̀ nílẹ̀ Yorùbá Amọṣa, ọkan lara awọn ọrọ rẹ, Moshood Abiọdun, ti ọpọ eeyan mọ si DJ Sosogee, ṣalaye fun BBC News Yoruba pe, eeyan ti o fẹran lati maa mu inu awọn eeyan to wa layika rẹ dun ni Djxgee.
Agbegbe Karaye ni ipinlẹ Kano ni ilu awọn omugọ yii wa Idunnu ati ayọ lo ba de fun awọn ara ilu Unguwar Wawaye, ti orukọ wọn tumọ si ilu awọn omugọ lẹyin ti wọn pa orukọ ilu naa da, lẹyin aadọrin ọdun.
“Ẹ kò gbọdọ̀ yí ìdájọ́ òdodo tí ó tọ́ sí àlejò tabi aláìníbaba po, bẹ́ẹ̀ sì ni, tí ẹ bá yá opó ní ohunkohun, ẹ kò gbọdọ̀ gba aṣọ rẹ̀ gẹ́gẹ́ bí ohun ìdógò.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù APC Kogi Primaries: Yahaya Bello la àwọn olùdíje mẹ́sàn án mọ́lẹ̀ fún àṣíá gómìnà ìpínlẹ̀ Kogi 30 Ògún 2019 Oríṣun àwòrán, others Gomina Yahaya Bello lawọn ọmọ ẹgbẹ oṣelu APC ni ipinlẹ Kogi tun gbe aṣia ẹgbẹ oṣelu naa le lọwọ.
Ti a kò bá gbàgbé oríṣiríṣi iriri lo tí n waye lati ọdọ ara ìlú nípa ìhùwàsí àwọn oṣiṣẹ SARS Ẹsun iseku pa awọn ọmọ Naijiria nipakupa jẹ ọrọ ti awọn ọmọ Naijiria ko le mẹnu kuro nibẹ lati bii oṣu meloo kan.
Nibi ipade naa, ileeṣẹ aarẹ ni aarẹ Buhari yoo ṣepade ti yoo mu agbega ba ọrọ aje Naijiria pẹlu awọn olori ile iṣẹ ati olori orileede lagbegbe naa.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ó di dandan kí ará India yìí sọ ìdí tó fi ń sìn kìnìhún- Egbeyemi Sani ni ọpọlọpọ igba, loun kii le pe orukọ ilu oun ni ita gbangba nitori itiju naa pọju.
Coronavirus Update: Omi mímu wọ́n ju owó ilé lọ nílùú yìí
O ni won ti fi to ile –ise agbofinro
Òjò ti fẹ́rẹ̀ kásẹ̀ kúrò ni ilẹ̀ ni oṣù kẹsan ọdún nitori àsikò ìkórè sún mọ́lé lẹhin òjò.
Nígbà náà ni OLUWA fara han Abramu, ó wí pé, “Àwọn ọmọ ati ọmọ ọmọ rẹ ni n óo fi ilẹ̀ yìí fún.
#SoarSuperEagles #NGA #Training #Team9jaStrong #NGAARG pic.
Ọlọrun rán an lọ sí ọ̀dọ̀ wundia kan tí ó jẹ́ iyawo àfẹ́sọ́nà ọkunrin kan tí ń jẹ́ Josẹfu, ti ìdílé Dafidi.
Ní ọjọ́ kan tí mo lọ sí ilé Ṣemaaya, ọmọ Delaaya, ọmọ Mehetabeli, tí wọ́n tì mọ́lé, ó ní “Jẹ́ kí á jọ pàdé ní ilé Ọlọrun ninu tẹmpili, nítorí wọ́n ń bọ̀ wá pa ọ́, alẹ́ ni wọ́n ó sì wá.
‘Àwọn wo ni wọ́n ṣẹ́kù ninu yín tí wọ́n rí i bí ẹwà ògo ilé yìí ti pọ̀ tó tẹ́lẹ̀?
Trump ni orílẹ̀-èdè Merika yóò túbọ̀ fi ọwọ́ líle mu Iran pàáp['aa jùlọ lori isúna àti ọrọ ajé, eyi yóò si wà bẹ́ẹ̀ titi iwá wọ́n yóò fi yí pada Sááju ní ààrẹ ilẹ̀ Amerika ti halẹ̀ mọ wọ́n pé oun yóò da ọmọogun ilẹ̀ Amerika sita ti Iran ba gbìyànju láti gbẹ̀san igbésẹ̀ Amerika, sùgbọ́n lẹ́yin o rẹyin ti Iran náà ju adó olóro si ibudo àwọn ọmọogun ilẹ̀ Amerika, Trump ti sinmi Èrè ti Nàìjíríà yóò jẹ nínú ọ̀rọ̀ Iran àti US Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ìkọ̀lu Iran àti US: Báwò lọ̀rọ̀ yìí ṣe kan ilẹ̀ Afirika Pípa ti orílẹ̀-èdè Amẹrika pa igbákeji olóri ogun orilẹ̀-èdè Iran Quasim Soleimani àti ibẹ̀rù bojo ti ọ̀rọ̀ náà ti n dá silẹ̀ láàrin àwọn orilẹ̀-èdè méèjèjì maa le di ǹkan ti yóò dá yánpọyánrin silẹ̀ fún gbogbo àgbaye.
Ikede yii bere lati ojo karundinlogbon osu kokanla  ti yoo si pari ni ojo kewaa ,osu kejila.
 Ẹ ̀ kọ ́ abínimọ ́ , àwòse , erémọdé , ìsírò , ìkini , ìwà ọmọlúàbí , èèwọ ̀ , òwe yorùbá , ìtàn àti àlọ ́ jẹ ́ ẹ ̀ kọ ́ -ilé .
Ọjọ kẹjọ, oṣu kẹsan an, ọdun 2020 yii lo yẹ ki ija naa waye tẹlẹ, ṣugbọn ọjọ kejidinlọgbọn, oṣu kọkanla ni ija ọhun yoo waye bayii.
Ọkùnrin tí ó wí pé ọmọ òun kò mọ ìwé nígbà tí aṣojú-Olódùmarè kọ́ wá rí i pé ọmọ tí òun kọ̀ sílẹ̀ ní ìjọ́ sí ti di ènìyàn pàtàkì.
Bakan naa, ni yoo sona ati je ki ijoba apapo ati ipinle  saleku atileyin owo fun itoju awon ti o n gbe pelu aarun HIV/AIDSAtejade ohun so ohun ti abileko Buhari pe, “o je ohun iwuri ati ojuse lati gba ipo asoju pataki ajo UNAIDS naa.
 Ó tó sẹ ́ ńtúrì kẹtàdúnlógún ( 17th century ) kí a tó rí àkọsílẹ ̀ kanka nípa manchu .
India election results 2019: Hema Malini, òṣèré Bollywood n léwájú nínú ìbò India
Ọmọkunrin meji ni Dagunro bi, awọn mejeeji naa si lo n se isẹ tiata.
Ṣugbọn ẹni tí yóo bá ṣe ìgbéraga, Oluwa ni kí ó fi ṣe ìgbéraga.
Ní ọdún keje tí Jehu jọba ní Israẹli ni Joaṣi jọba ní ilẹ̀ Juda, ó sì wà lórí oyè ní Jerusalẹmu fún ogoji ọdún.
 ""Awọn ohun to kan wa ju ni aisan awọn owo ti wọn yọ ninu owo oṣu awọn oṣiṣẹ fun ifẹyinti, alajẹṣẹku, ọdun ileya, keresi ati bẹẹbẹẹlọ fun oṣu marunlelọgọrun lai san an pada fawọn oṣiṣẹ."
Ọlọ́pàáa Sichuan fi ọwọ́ọ ṣìgún òfin mú Deng ní ilée rẹ̀ ní Yibin ní ọjọ́ Ẹtì tí ó kọjá, lẹ́yìn wákàtí díẹ̀ tí ó ṣe àtúnpín àwòrán-an Twitter kan tí ó jẹ́ ti ìgò ọtí-líle 64, gẹ́gẹ́ bí Iléeṣẹ́-tí-kìí-ṣe-tìjọba, Adáààbòbo Ẹ̀tọ́ Ọmọ ènìyàn ti China (CHRD).
tí arakunrin ẹni tí ó pa bá rí i tí ó sì pa á, olùgbẹ̀san náà kì yóo ní ẹ̀bi; 
Abramu ati Nahori ní iyawo, Sarai ni orúkọ iyawo Abramu, orúkọ iyawo ti Nahori sì ni Milika, ọmọbinrin Harani.
RUGA: Gbogbo ọmọ Nàìjíríà ló lásẹ láti gbé ìlú tó bá wù ú
Oṣiṣẹ alarena fun Ileesẹ ọlọpaa nipinlẹ Oyo, Olugbenga Fadeyi, lo sísọ loju ọrọ yii lasiko itakurọsọ pẹlu ikọ iroyin BBC Yoruba lori iwa ifipabanilopọ ati ipaniyan nipinlẹ Oyo.
A ti gùnlé ìyanṣẹ́lódì ọlọ́jọ́ gbọọrọ ní ìpílẹ̀ Eko- NUPENG Àwọn aláànú dìde ìrànlọ́wọ́ fún tìyá-tọmọ olójú búlúù Buruji Kashamu jẹ́ ènìyàn tó nífẹ̀ aráàlú- Gómínà Dapo Abiodun Diezani gan an ní Hushmummy tó ń bú àwọn Yahoo boys- Àwọn Ọmọ Naijiria lórí Twitter Alẹ́ ọjọ́ Àìkú ní àwọn ọmọ Lebanon tún bẹ́rẹ̀ ìfẹ̀hhónú hàn míràn ní olúùlùú Beruit tí àwọn àti ọlọ́pàá sì ń kojú ara wọ́n.
Dogara ni o ti han gbabgba pe, awọn aṣofin korira ki ẹgbẹ oṣelu kan yan awọn olori fun wọn ninu ile.
Abraham ni eyi ko ṣẹyin bi ijọba ko ṣe mojuto ọna ti awọn ileeṣẹ n gba ti eefin sita.
Ile ẹkọ fasiti Cranfield si lo ti gba oye ọmọwe ninu imọ ẹrọ Ọdun 1999 ni Ahmed Lawan kọkọ dibo wọle sile asoju-sofin, to si soju ipinlẹ Yobe, nibẹ si lo ti se alaga awọn igbimọ to wa fun eto ẹkọ ati eto ọgbin Ọdun 2007 ni Lawan tun dibo pada, amọ ile asofin agba lo gbe apoti ibo fun nigba naa, to si wọle lati soju ẹkun idibo ariwa ipinlẹ Yobe, lati igba naa wa, eyiun ọdun mẹrindinlogun sẹyin ni aarẹ ile asofin agba tuntun naa, ti wa nile asofin apapọ ilẹ wa bii gomina Ti yoo ba fi di ọdun 2023 ti saa eto isejọba yii yoo pari, Senetọ Ahmed Lawan yoo ti lo ọdun mẹrinlelogun nile asofin apapọ ilẹ wa, eyi to fihan pe oun ni asofin to tii ni iriri julọ nile asofin apapọ ilẹ wa.
Ó bá fi èdìdì dì í kí ó má baà tan àwọn eniyan jẹ mọ́ títí ẹgbẹrun ọdún yóo fi parí.
bí ẹ bá dé ilẹ̀ tí mo fún yín láti máa gbé, 
 Ìran àwọn tí o ń sọ èdè yìí wá ní orílẹ ̀ èdè olómìnira congo àti portuguese .
”Eliṣa tún ní, “Kó wọn fún àwọn ọmọkunrin kí wọ́n jẹ ẹ́, nítorí pé OLUWA ní, ‘Wọn yóo jẹ, yóo sì ṣẹ́kù.
Nípasẹ̀ wọn ni n óo bukun gbogbo orílẹ̀-èdè ayé, 
Toyin Abraham pé 40, wo ohun márùn ún tó mú dá yàtọ̀ láàrín ogójì ọdún Bí mo bá wọlé padà, mí ò lè yàn Ize Iyamu tàbí Osagiobare sípò olùbádámọ́ràn- Obaseki Facebook mú àyípadà bá àtẹ̀jíṣẹ́ síra ẹni lórí òpó Instagram, wo àwọn ǹkan tó kàn ọ níbẹ̀ Iléeṣẹ́ ọlọ́pàá ní Kano tí ṣe àyẹ̀wò àwọn 13, 048 tó fẹ́ darapọ̀ mọ́ wọn Owó oúnjẹ ni mo lọ ọ gbà, oyún ọmọ tí mo jù sí àkìtàn ni mó gbé wálé- Dupe, ìyá Muiz Iroyin ni, ni kete ti afurasi ọhun ri ara rẹ lori CCTV naa, ni ṣe lo yi ohun pada to si bẹrẹ si n bẹbẹ pe iṣẹ eṣu ni, ki awọn agbofinro to wa fi panpẹ ofin mu un.
0 2933 Erekusu Channel 76 44.
Lásìkò tí rògbòdìyàn lorisirisi ń wáyé sì ọba Olagbegi, ọ̀pọ̀ ẹ̀mí àwọn èèyàn tó sunmọ lo ṣòfò, tí wọ́n sì jó àwọn dúkìá wọn nínà pẹ̀lú.
Oṣu kẹrin, ọdun 2020 Ni osun kẹrin ọdun 2020, itakun ina pinpin lorilẹede Naijiria daku patapata lẹyin tawọn eeyan to lẹnulọrọ lẹka naa ni awọn ohun elo fun ina pinpin lẹka naa nilo ayipada lati lee ba igba mu.
Kì í ṣe àfipáṣe ṣugbọn tinútinú bí Ọlọrun ti fẹ́.
Ìkòkò tí ń bá amọ̀kòkò jà.
"APC kò ní olórí tí yòó tọwọ́ bọ̀wé, INEC yarí fún ìbò abẹ́nú l‘Ondo Ìhòhò ọmọlúàbí ni mo má a ń bá àwọn ọmọkùnrin mi wí - Elesho Ọ̀dàlẹ̀ ni Igbákejì Gómìnà, kìí ṣe pé a dẹ́yẹ si - ìjọba Ondo ""Ni deede aago mẹfa ku ogun isẹju ni idaji Ọjọruni wọn kọlu obinrin kan, Olusayo Fagbemi, ẹni ọdun mejilelogoji, lasiko to n fọ abọ niwaju ile rẹ, to si ni ọgbẹ lori."
Àwọn aláṣẹ ilé ìwé gíga Fásitì náà tó wà ní Jacksonville ní Alabama, United States ló sọ ọ̀rọ̀ yìí.
Lẹta Ọbasanjọ si Buhari Buhari dasi ipaniyan Benue Inec yoo bẹrẹ iwadi lori oludibo Kano Oríṣun àwòrán, @BuhariSallau Àkọlé àwòrán, Ninu awọn alejo ti wọn ti de ibi igbeyawo na ni Aarẹ Muhammadu Buhari ati awọn ọba-alade Oríṣun àwòrán, @Dawisu Àkọlé àwòrán, Gomina ipinlẹ Ọyọ, Abiọla Ajimọbi lọ sibi igbeyawo naa pẹlu awọn gomina ẹgbẹ rẹ atawọn eeyan jankan-jankan miiran Oríṣun àwòrán, @bukolasaraki Àkọlé àwòrán, Wọn ṣe igbeyawo naa loju awọn eeyan jankan-jankan ti wọn lọ sibẹ Oríṣun àwòrán, GovKaduna Àkọlé àwòrán, Gomina ipinlẹ Eko, Akinwumi Amọde, ko gbeyin ninu awọn ti wọn lọ sibi igbeyawo naa ni Kano Oríṣun àwòrán, @bukolasaraki Àkọlé àwòrán, Niwaju Aarẹ Muhammadu Buhari ni wọn ti ṣe igbeyawo naa Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Ori ọpọ eeyan si lo maa n wu lati ri pe ẹni kan n jẹ Alhaji ati Alhaja, ti aimọye eeyan miran si maa n lakaka lati lọ si Mecca, ki araye lee maa fi Alhaji ati Alhaja si ẹyin orúkọ wọn.
Báyìí ni ògo Baba mi yóo ṣe yọ, pé kí ẹ máa so ọpọlọpọ èso.
Ọpọlọpọ dukia ati ile to ti fi ọna eru gba lọwọ awọn eniyan to lu ni jibiti si ni wọn ka mọ lọwọ, tijọba si ti gbẹsẹle.
Nigba to n sọrọ lẹyin ti wọn yọ tan, Gedoni wi pe, ọpọlọpọ ẹkọ ni oun ti kọ ninu ile Big Brother.
OLUWA sì fara hàn án ní òru ọjọ́ tí ó rin ìrìn àjò náà, ó ní, “Èmi ni Ọlọrun Abrahamu, baba rẹ, má bẹ̀rù, nítorí mo wà pẹlu rẹ, n óo bukun ọ, n óo sì sọ àwọn ọmọ rẹ di pupọ nítorí ti Abrahamu iranṣẹ mi.
Nígbà tí ó di ọjọ́ keji, Agiripa ati Berenike bá dé pẹlu ayẹyẹ.
Nígbà tí ilẹ̀ mọ́ tí Josẹfu rí wọn, ó rí i pé ọkàn wọn dàrú.
Ní ọjọ́ náà, àṣẹ àkọ́kọ́ tí Dafidi pa ni pé kí Asafu ati àwọn arakunrin rẹ̀ máa kọ orin ìyìn sí OLUWA.
 Ọ ̀ kọ ̀ ọ ̀ kan àwọn ìlù òkè yí ni wọ ́ n jẹ ́ ìwọ ̀ n ọ ̀ tọ ̀ ọ ̀ tọ ̀ , sì ìyá ìlù tó ma ń ṣáájú nínú eré tí àwọn tókù yóò sì ma kọ ́ wọ ̀ ọ ́ tẹ ̀ le .
Ko din ni oṣiṣẹ eto ilera meje ti wọn ti pa ni ọdun yii nikan.
Iroyin iku Alhaji da rogbodiyan silẹ ni oke ọya, eyi to yọri si iditẹgbajọba miran loṣu keje, ọdun kan naa.
Nígbà tí wọ́n gbọ́ tí ó ń bá wọn sọ̀rọ̀ ní èdè Heberu, wọ́n pa lọ́lọ́.
Aare orile-ede America, Donald Trump, ti yan adari eto idibo re fun idije odun 2020.
Tiriliọnu to din diẹ ni marun un ni yoo ba owo sisan lọ ninu eto iṣuna na, nigba ti tiriliọnu meji pere wa fun iṣẹ akanṣeBuhari ti fòfin de àwọn mínísítà láti rìnrìn àjò lọ sí ilẹ̀ òkèrè.
Wọn salaye pe, awọn gbiyanju lati sare ko awọn ohun elo to n bẹ ninu ile naa jade lasiko eefin bẹrẹ sini ru, ṣugbọn pupọ ninu awọn ohun elo naa ni ina ọmọ ọrara ti sọ di eeru, ki awọn aladugbo to gbe omi ati awọn ohun elo mii ti wọn fẹ fi pa ina to de.
ṣugbọn wọn kò rí ọ̀nà, nítorí gbogbo eniyan ń fi ìtara gbọ́ ọ̀rọ̀ rẹ̀.
Iroyin naa jẹ eyi to ti mu iriwisi orisirisi wa latari fọnran fidio arakunrin kan tawọn oluwọde n gbe digba digba pẹlu ẹjẹ lara rẹ.
Lagos building collapse: LASEMA ní ìwadìí yòó yàtọ̀ lórí ilé tó wó nítorí ààrẹ àtàwọn èèkàn ti gbọ́ sí ìsẹ̀lẹ̀ náà
Aṣọ títa yóo wà ní ẹ̀gbẹ́ ìwọ̀ oòrùn àgbàlá náà, gígùn rẹ̀ yóo jẹ́ aadọta igbọnwọ, yóo ní òpó mẹ́wàá, òpó kọ̀ọ̀kan yóo ní ìtẹ́lẹ̀ kọ̀ọ̀kan.
Electricity Tarrif: A kò tíì gbé àwọn oníbàrà wa sórí tàríìfù tuntun
Àsìkò tó láti fi ìwọ́de gba ara wa sílẹ̀ lọ́wọ́ ebi àti oko ẹrú - Sowore Oloyede tun fikun pe, ohun to mumu ju laya awọn bayiii ni bi awọn yoo se gba idande awọn ọmọ ẹgbẹ Revolution Now tawọn ọlọpaa mu si ahamọ, ti awọn yoo si fi isu si ina, maa fi inu wa ọbẹ lori igbesẹ to ku ti awọn yoo tun mu pọn lori ifẹhonuhan wọn ọhun.
Èrò ẹ̀tàn ti ṣì í lọ́nà, kò sì lè gba ara rẹ̀ kalẹ̀ tabi kí ó bi ara rẹ̀ pé, “Ǹjẹ́ irọ́ kọ́ ni ohun tí ó wà lọ́wọ́ mi yìí?
Ninu ifọrọwanilẹnuwo to waye pẹlu Oluwo, Oba Alade naa ṣalaye pe ko si eleyi ti oun ko bọwọ fun laarin awọn ọba to wa labẹ ohun ṣugbọn iwa arifin awọn kan ti fẹ pọju.
yóo fi ìyè ainipẹkun fún àwọn tí ń fi sùúrù ṣe iṣẹ́ rere nípa lílépa àwọn nǹkan tí ó lógo, tí ó sì lọ́lá, àwọn nǹkan tí kò lè bàjẹ́.
S Embassy Gbogbo igbiyanju BBC lati ba awọn agbofinro sọrọ lori iṣẹlẹ paapaa olobo ti wọn ni ẹnikan tawọn yii ja si pabo Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Ẹni tí ó ní òye a máa tẹjúmọ́ ọgbọ́n,ṣugbọn ojú òmùgọ̀ kò gbé ibìkan,ó ń wo òpin ilẹ̀ ayé.
se ni itesiwaju nipa eto oro aje won , ni eyi ti awon omo orile ede won yoo se  maa jegbadun eto oro aje.
Àti pé ó kanlẹ̀ ti kọjú ìbọn sírarẹ̀, ó ti dágbére sí ilé-ayé kí àwọn agbófinró tó dé.
Nigba ti ajọ WAEC si ti fun aarẹ ni iwe ẹri rẹ, le tọ wọn lọ fun aridaju tabi alaye.
Ọdọmọkunrin tí ó ti kú yìí bá dìde jókòó, ó bẹ̀rẹ̀ sí sọ̀rọ̀.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Brexit: Ọ̀rọ̀ kò yé wa mọ́!
O ni nitori ara idamọ ti wọn mọ iran Yoruba mọ ni orin Fuji jẹ́, gẹgẹ bi wọn se mọ awọn orilẹede bii Jamaica, Amẹrika, India ati Brazil mọ irufẹ orin ti wọn n kọ ni ikọọkan awọn orilẹede yii.
Ẹni naa, Dauda Lawal, to ti fi igba kan jẹ Ọga Agba ni ile ifowopamọ First Bank, fun'ra rẹ n jẹjọ lọwọ nile ẹjọ giga ijọba apapọ.
Ọ̀kẹ́ àìmọye sì ni owó àwon ọkọ̀ àti pátákó ìpolówó ọjà tíigi wó lù lásìkò tí ìjì náà fi jà.
Gomina ipinlẹ Obaseki naa wọ awọn obi lati bojuto ọmọ wọn ki wọn si kilọ fun wọn lati duro silẹ lasiko ofin konile o-gbele ti wọn kede naa.
Ikilọ yi waye lasiko ti Dagvin Anderson, ọgagun ikọ ọmọ ogun Amẹrika ni ilẹ Afrika n ba awọn akọroyin sọrọ loju opo ibanisọrọ Zoom lọjọru.
Igbakeji alakoso eto ile-ìkàwé aare ana, (Olusegun Obasanjo Presidential Library), ọgbẹni Ayọdele Aderinwale sọ fun BBC Yoruba wi pe ifilọlẹ ile-isẹ isakoso fun agbarijọpọ ẹgbẹ awọn ọmọ Naijiria (Coalition for Nigeria Movement) ni ile isẹ Iwe iroyin nilu Abeokuta.
Aare wa gbadura pe ki olorun tu gbogbo awon omo orile-ede naa ninu , ki o si te oloogbe naa safefe rere.
Alukoro ileesẹ ọlọọpa lorilẹede naa ti fi idi isẹlẹ yii mulẹ to si ni awọn ọkunrin meji ni wọn ti fi si ahamọ lori ọrọ naa titi di igba ti iwadi yoo fi pari.
Ó mú kí ayé ati àwọn tí ó ń gbé inú rẹ̀ júbà ẹranko àkọ́kọ́, tí ọgbẹ́ rẹ̀ ti san.
Femi, Tope àti Biola Adebayo: Oríṣun àwòrán, other Femi, Tope àti Biola Adebayo, ti wọn ń ṣe gudugudu méje àti yà yà mẹ́fà lagbo tíátà báyìí, ní wọn jẹ ọmọ bibi àgbà ọjẹ kan lagbo ere tíátà, Adebayo Salami, tí ọ̀pọ̀ èèyàn mọ si Ọga Bello.
Gẹ́gẹ́ bí ọmọ tí ń gbọ́ràn, ẹ má gbé irú ìgbé-ayé yín ti àtijọ́, nígbà tí ẹ̀ ń ṣe ìfẹ́kúfẹ̀ẹ́ ara yín tí ẹ kò mọ̀ pé àìdára ni.
Kí ìjọ mi ní Sagamu le gbòòrò ni mo fi ń ṣiṣẹ́ ajínigbé pawó - Pásítọ̀ Aàre Donald Trump pàrọwà pé kí wọ́n sún ìdìbò Aàrẹ 2020 síwájú ní America Àwọn akópa tó ti jáwé olúborí ní BBNaija sẹ́yìn àti ibi tí wọ́n wà báyìí Ológun kan tí ọpọlọ rẹ̀ kò pé, ló pa akẹẹgbẹ́ rẹ̀ tó ṣẹ̀ṣẹ̀ ṣègbéyàwó - Iléeṣẹ́ ológun jẹ́wọ́ Gẹgẹ bi ọrọ ti ọkọ iya ibẹrin ọhun sọ fun awọn akọroyin, o ni iye owo itọju iya atawọn ọmọ naa le ni miliọnu mọkanlelogoji naira, ti oun ko si ni kobo lọwọ.
Fi igi akasia ṣe àwọn ọ̀pá, kí o sì yọ́ wúrà bò wọ́n.
Lẹ́yìn ọdun mẹ́ta tó kú, ilé ẹjọ́ dájọ́ ikú fún alásè tó pa Temidayo Adeleke Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Ohùn gooro ló gbé mi dé ọ̀dọ̀ ààrẹ̀ Bush, Obama, Obasanjo, Goodluck, Buhari' Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Ẹnikẹ́ni tí mo bá wí fún ọ pé yóo lọ, òun ni yóo lọ, ẹnikẹ́ni tí mo bá sì wí fún ọ pé kò ní lọ, kò gbọdọ̀ lọ.
Bi o tilẹ jẹ pe ileeṣẹ ọlọpaa ko tii fi iroyin tuntun sita lori ibi ti iṣẹ de duro lori ṣiṣe awari awọn akẹkọ ati olukọ naa, awọn obi ati alaṣẹ ileewe naa fi to awọn oniroyin leti pe ijiroro ṣi n ls lori iye owo ti wọn yoo gba fun itusilẹ wọn.
OLUWA yóo bukun ẹni tí ó ṣàkíyèsí rẹ.
Lanre Kuti ni mo fẹ́ - Jaiye Kuti Ohun tó yẹ kóo mọ̀ nípa Fásitì Babcock rèé Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Àfi bí mo bá sunkún mọ́ títọrọ̀ owó, tórí gbobo wa ni ìyà ń jẹ níbí' O fi atilẹyin ijsba ipinlẹ Ọṣun da wọn loju ninu adanu wọn naa bi o tilẹ jẹ pe ko sọ ni pato ọna ti atilẹyin naa yoo gba.
Delta petrol tanker explosion: O ti lé ní ènìyàn mẹ́wàá tí ina jó gúrúgúrú nínú ìjàmbá tó wáyé ní Delta
Àwọn akópa tó ti jáwé olúborí ní BBNaija sẹ́yìn àti ibi tí wọ́n wà báyìí Ìwé èsì àyẹ̀wò arùn Covid-19 lè di kòṣeémàní fáwọn tí o bá fẹ́ rìnrìn àjò sí ilẹ̀ òkèèrè Kaakiri oju opo ayelujara paapaa ni Instagram lawọn eeyan ti n ṣe alabapin fidio ibi ti Big Brother ti paṣẹ ki Dorothy lọ parọ aṣọ fun yi.
Gbogbo igbiyanju awọn oninuure layika to fi mọ ọrẹ rẹ, Kazeem Okikiola lati doola ẹmi ọmọkunrin naa lo ja si pabo nitori o pada gbẹmi mi.
Iroyin ti a gb ni pe aisan jẹjẹrẹ lo n ba a ja.
Shehu to fọrọ yii lede loju opo Twitter rẹ ṣalaye pe awọn ologun ti ṣe akitiyan lati doola awọn akẹkọọ to wa lakata awọn janduku ọhun.
Atẹjade kan ti agbẹnusọ fun gomina ipinlẹ naa, Crusoe Osagie, fisita ni ọjọbọ sọ wipẹ, ijoba ipinle naa ti yan igbimọ ẹlẹni meje nijọba ibilẹ kọọkan nipinlẹ Edo lati dẹkun ikọlu awọn agbẹ ati darandaran.
Yóo mú òun Sedekaya lọ sí Babiloni, ibẹ̀ ni òun óo sì wà títí OLUWA yóo fi ṣe ẹ̀tọ́ fún òun.
Ó wáá tún fún wa ní òfin kan lẹ́hìn èyí wí pé a kò gbọdọ̀ pa ejò kan rárá ní ìlú wọn ó sì tẹ̀ ẹ́ mọ́ wa létí gbọingbọin.
Iku wọle mu Robert lọ ṣaaju irinajo wọn lojo keji.
fe mo nipa aseyori owo iranwo (Tradermoni) fun awon olutaja beere lowo awon
A kì í bàá mọ̀, bí aadọta olódodo bá wà ninu ìlú náà, ṣé o óo pa ìlú náà run, o kò sì ní dá a sí nítorí aadọta olódodo tí ó wà ninu rẹ̀?
Absalomu kọjú sí Ahitofeli, ó sì bi í pé, “Nígbà tí a ti dé Jerusalẹmu báyìí, kí ni ìmọ̀ràn rẹ?
ba to kede rẹ lati sii, bakana naa ni won tun ti gbogbo oju ona oko ofurufu pa
Ni ọjọ́ kọkandinlọgbọn oṣù keje ọdún Ẹgbàálémẹ́rindinlógún, ilú péjọ pẹ̀lú ẹbi àti ará ni Adó-Èkìtì lati ṣe iranti Olóògbé Ọ̀gágun Adékúnlé Fájuyi fún iranti iwà iṣòótọ ti ó hù titi dé ojú ikú pẹ̀lú àlejò àti ọ̀gá rẹ Olóri Ogun Aguiyi Ironsi ni aadọta ọdún sẹhin.
Muslim Girls High School lo soo di odidi alagbara obinrin pẹlu iṣẹ takuntakun to fi jẹ adari gbogbo ọmọ ile iwe ni kilaasi aṣekagba rẹ.
Bẹẹ si lo tako gbogbo iṣekupani to waye kaakiri orilẹede Naijiria gba ọwọ awọn janduku ati awọn ọlọpaa lorilẹede Naijiria.
O dun mi pe n ko mọ tẹlẹ pe itọju ara mi gan se pataki, eyiun ti ko ba se pataki ju itọju ọmọ gan lọ nitori iya to ni ilera to peye, to si n sun daradara san ju iya to n ronu lọ.
Mo wò yíká bóyá ẹni kan ló ni àwọn igi eléso wọ̀nyí n kò sì rí nǹkan kan láti fi hàn mí pé ó wà ní ìkáwọ́ ẹnikẹ́ni.
O ni oun kọ lati ṣe ojuṣaju nitori ẹbi.
28 Owewe 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 29 Owewe 2020 Inu ẹni kii dun, ka pa mọra ni ọrọ awọn ololufẹ Olalekan Agbeleshebioba, ti sps eeyan mọ si Leycon, to gbegba oroke ninu asekagba idije BB Naija fun tọdun 2020.
Ẹni tí ó rán ikọ̀ lọ sí òkè odò Naili,tí wọ́n fẹní ṣọkọ̀ ojú omi.
Inu ija naa ni wọn ti yinbọn si ẹsẹ Aborisade to jẹ ọkan gboogi ninu awọn alaga ijọba ibilẹ PDP n'Ipinlẹ naa.
Ṣugbọn àṣẹ tí ọba pa ni ó borí.
"Adugbo Soka nilu Ibadan ni mo n gbe, ti awọn agbegbọn kan si ya wọ adugbo mi lati maa dunkoko mọ awọn eeyan mi, n ko si lee la oju mi silẹ, ki n wa larọwọto, kawọn eeyan kan maa se awọn eeyan mi lese tabi pa wọn ni ipakupa.
“Ẹ gbọ́, èmi Nebukadinesari, fi ìyìn, ògo, ati ọlá fún ọba ọ̀run.
Kò sí ìwé ẹ̀rí fun olùdíje tí tó ba wóle lábẹ hílàhílo Bílíọ̀nù kan náírà ni INEC ń san fún CBN àti ọmọogun oju òfurufú Kashamu ṣì ni olùdíje PDP fún ipò gómìnà l'Ogun"" Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, BBC Yorùbá: Àwọn akọ̀ròyìn wa ti lọ káàkiri láti jábọ̀ ìròyìn ìbò O ni: ""Bẹẹni, mo ṣetan lati gba bi esi idibo naa ba ti ṣe lọ si gẹgẹ bii ifẹ Ọlọrun, mo si ni igbagbọ to jinlẹ ninu ifẹ Ọlọrun."
awon omo orile ede Naijiria lati ni suuru fun ajo eleto idibo lorile ede
Oluwo wá gba àwọn Mùsùlùmí to bẹ̀rẹ̀ aawẹ Ramadan nímọ̀ràn, láti kó owó síta fún àwọn aláìní, pàápàá àwọn èèyàn tó fẹ́ lọ sí Mecca, tí wọn kò leè lọ mọ.
O mẹnuba awọn idojukọ to n koju igbo Kruger National Park ati ipa ti ijọba orilẹ-ede South Africa n ko lasiko yii lati wa ojutu sii.
Wọn ti bẹrẹ si ni dan abẹrẹ kan wo lori covid-19 lorilẹede South Africa nigba ti omiiran yoo bẹrẹ ni Kenya lẹyin iyọnda ijọba.
 Ìwọ ̀ n egbògi mẹ ́ ẹ ̀ ta tí a bẹ ̀ rẹ ̀ lọ ́ gán tí ọmọ bá ti pé ọmọ ọ ̀ sẹ ̀ mẹ ́ ẹ ̀ fà ni a má a ń sábà dámọ ̀ ràn fún àwọn ọmọdé kékèké .
aabo to monyan lori ni gbogbo papa ofurufu to wa lorile ede Naijiria paapaa
níbi tí ìdin wọn kì í kú, tí iná ibẹ̀ kì í sì í kú.
han lataari ipo ti ko bojumu ti won wa, paapaa julo bi oro eto aabo se mehe
Nítorí Farao yóo wí pé, ‘Ilẹ̀ ti ká àwọn eniyan Israẹli mọ́, aṣálẹ̀ sì ti sé wọn mọ́.
Sola Sobowale gbàmì ẹ̀yẹ òṣèré tíátà obìnrin tó dáńtọ́ jùlọ Ileẹjọ naa ni ilana ti ajọ INEC fi sita ni pe ki orukọ gbogbo awọn oludije to ti wọle sikawọ ajọ naa, o pẹ ju, agogo mẹfa irọlẹ ọjọ kẹsan oṣu kẹsan ọdun 2019.
Ẹni tí ó bá gbẹ́kẹ̀lé ọrọ̀ rẹ̀ yóo rẹ̀ dànù bí òdòdó,ṣugbọn olódodo yóo rú bí ewé tútù.
Jakọbu bí àwọn baba-ńlá wa mejila.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù EFCC: A fẹ́ mọ bí Saraki ṣe gb'owó osù gómìnà, ààrẹ ilẹ́ asòfin 9 Èbibi 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 13 Èbibi 2019 Oríṣun àwòrán, Google Àkọlé àwòrán, Ààrẹ Ilé Ìgbìmọ̀ Àsòfin.
Ibọn ba awọn eeyan mii, ṣugbọn wọn ko ku Agbegbe Bono East, Northern region, Central region, ati Greater Accra, ni awọn iṣẹlẹ yii ti waye.
Ọpọ ọdọ ni ẹnu ya nigba ti wọn kede pe wọn yọ odidi ọba lapa oke ọya, ti wọn si n sọ pe eyi ko le e sẹlẹ nilẹ Kaarọ oojire.
Ó ń mú kí àwọn odò rẹ̀ ṣàn yí ibi tí a gbìn ín sí ká.
Wọn ni wọn ji ọpọlọpọ nkan ni ajọ to n ri si pasiparọ owo ilẹ okere, wọn ji owo ni ẹrọ ATM atawọn ibomii ni orilẹede naa ni oṣu kejila ọdun 2016.
Diẹ lára àwọn jẹsí tó mi ìgboro tìtì ní agbo bọ́ọ́lù
Atẹjade kan ti agbẹnusọ fun Seyi Makinde, eyiun Ọmọọba Dọtun Oyelade fisita , lo sisọ loju ọrọ yii.
láti inú ìdílé Elisafani, igba (200) ọkunrin, Ṣemaaya ni olórí wọn, 
Àkọlé àwòrán, Wan ni kí alága APC ní Ìpínlẹ̀ Kwara lọ rọ́ kún ńlé Bósẹnlọ l'áwọn ìpínlẹ̀: Rivers: Awọn ẹka ti Abe ti n dibo lọ nipa lilo ìbò gboogbo ti yoo fun gbogbo awọn ọmọ ẹgbẹ laaye lati dibo nigba ti awọn ẹka ti Rotimi Amaechi n péjọ si olu ilé ẹgbẹ APC ni Porthacourt lati dibo nipa lilo ibo awọn aṣoju.
Ṣé ojúlówó ìwé ìdánwò ìṣìro WAEC tí yóò wáyé lónìí ló lu ayélujára pa bí?
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Grace aya Robert Mugabe dagbere igbẹyin fun ọkọ rẹ.
Jesu dá wọn lóhùn pé, “Ẹ lọ ròyìn ohun tí ẹ ti gbọ́ ati ohun tí ẹ ti rí fún Johanu.
Gẹ́gẹ́ bí ó ti wà ní àkọsílẹ̀ pé, “Jakọbu ni mo yàn, Esau ni mo kọ̀.
Gbogbo eniyan ló kà á kún; ati àwọn eniyan yẹpẹrẹ ati àwọn eniyan pataki wọn.
awon apa ibikan , nitori pe won ko ri  irinse to n se ayewo kaadi  naa lo ati awon ibo to ni kohun-kohun ni
Ayọ̀ ń bẹ fún ẹni tí ó bẹ̀rù OLÚWA,tí ó sì ń tẹ̀lé ìlànà rẹ̀.
OLUWA ló sọ bẹ́ẹ̀,OLUWA tí iná rẹ̀ wà ní Sioni,tí ojú ààrò rẹ̀ wà ní Jerusalẹmu.
Yoruba sì ni bí onirese kò bá fín igbá mọ, èyí tó ti fin silẹ kò leè parun, ìdí si nìyí tí BBC Yoruba fi ń mú àwọn iṣẹ́ akainiye tó jẹ́ manigbagbe fún àwọn ọmọ Nàìjíríà, tí Ààrẹ Yar'adua gbé orí àkóso ṣe nígbà ayé rẹ.
bi aare orile ede yii fun saa keji.
Ní òru, egungun ń ro mí,ìrora mi kò sì dínkù.
Nítorí OLUWA kórìíra alárèékérekè,ṣugbọn ó ní igbẹkẹle ninu àwọn tí wọn dúró ṣinṣin.
Nǹkan mẹ́sàn án tí Mùsùlùmí gbọdọ̀ ṣe nínú oṣù Dhual- Hijjah Ilé ẹjọ́ wọ́gilé ìgbẹ́jọ́ Olalekan 'Woodberry' Pọnle Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Kogi vs Bayelsa: Primate Ayodele sọ àsọtẹ́lẹ̀ Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Wo àwọn ibùdó ìtàn Mánigbàgbé ni Ìbàràpá méjèèje O ti lé ni ọdún kan ti mo ti n jí pátá l'ádugbò- Chukwajekwu Eziigbo Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Eduardo: Mo ń jí mọ́tò pẹ̀lú àwọn ọ̀rẹ́ mi nítorí pé mo fẹ́ di 'Big boy' Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Ibẹ̀ ni yóo jẹ́ ibi ààbò fun yín tí ọwọ́ ẹni tí ń gbẹ̀san ẹ̀bi ẹ̀jẹ̀ kò fi ní máa tẹ̀ yín.
5 biliọnu ninu rẹ leyii ni o si ti n mu inira ba eto sisan owo oṣu awọn oṣiṣẹ nibẹ.
''Iwọ ni tiẹ, ijo ati mu ọmọlakeji ṣubu ni iwọ mọ ọ jo ni tiẹ ti wọn ba n kọ irin ninu isin,'' Bamiloye lo sọ bẹẹ.
Wọn kò fò ju igbọnwọ meji lọ sílẹ̀, wọ́n wà ní ẹ̀yìn ibùdó káàkiri ní ìwọ̀n ìrìn ọjọ́ kan.
Ẹni tí ó bá gbàgbọ́, tí ó bá ṣe ìrìbọmi, yóo ní ìgbàlà.
Progressives Congress pe oun kọ lo jawe olubori ninu eto idibo to waye ni
Kí gbogbo ọjọ́ ayé mi lè kún fún ìtìjú?
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Akomolede ati asa Yoruba: Ẹ wá kọ́ nípa àpòtí ìṣura èdè wa lórí BBC Yorùbá Awọn ohun ti o nilo lati fi orukọ silẹ niyii: Aworan pelebe.
Fẹliksi bá sún ọjọ́ ìdájọ́ siwaju.
Amọṣa, iṣẹ kolẹ-kodọti lo ri ṣe eyi ti ko si lee fun un ju aadọta si ọgọrun un naira.
Ẹsun ti wọn ni wọn n wa fun ni ipaniyan, idigunjale, ati awọn iwa to ni i ṣe pẹlu ẹgbẹ okunkun.
Ẹni ti ó gbàdúrà dàńdógò mẹ́wàá bí olúwaarẹ̀ kò ni dàńdóógó mẹ́wàá yóó ni dàńdógó mẹ́jọ, ẹni ti ó ń gbadura ṣòkòtò mẹ́fà bí olúwaarẹ̀ kò ní ṣòkòtò mẹ̀fà yóó ní ṣòkòtò márùn-ún, ṣùgbọ́n ẹni ti ó tọrọ ṣòkòtò kan lọ́wọ́ Olódùmarè, bi eléyìínì bá ni méjì ó yẹ ki ó dúpẹ́ lọ́wọ́ Ọlọ́run Ọba.
2019 election: Àwọn olùdíje fún ipò gómìnà nípínlẹ̀ Kwara sọ̀rọ̀ lórí ohun tí wọ́n fẹ́ ṣe
Ọga Adamu paṣẹ fun gbogbo awọn kọmiṣọnna ọlọpaa lorilẹ-ede Naijiria lati ri pe wọn tu ikọ naa ka.
Èdè nílò kíkọ́ ọ fún ìgbà pípẹ́ díẹ̀ kí ènìyàn tó le sọ ọ́.
Àsìkò tó láti fi ìwọ́de gba ara wa sílẹ̀ lọ́wọ́ ebi àti oko ẹrú - Sowore Ìjọba Buhari ń wùwà bíi ìjọba Abacha lórí ọ̀rọ̀ Ṣoworẹ- Ṣoyinka Iléẹjọ́ gba onídùròó El-Zakzaky, ó ní kó lọ gba ìtọ́jú lókè òkun O ni ounjẹ aṣara loore nikan lo lee le aisan jinna si agọ ara wa.
Ẹ gbọ́ ohun tí OLUWA sọ, gbogbo ẹ̀yin tí OLUWA kó ní ìgbèkùn láti Jerusalẹmu lọ sí Babiloni.
Tí ó pe ìran dé ìran láti ìbẹ̀rẹ̀?
 Àdàlù àwọn mẹ ́ tẹ ̀ ẹ ̀ ta yìí pẹ ̀ lú àjẹsára varicella ( kòkòrò àrùn àìlèfojúrí tí ń fa ọfà ṣọ ̀ pọ ̀ nna tàbí ilẹ ̀ gbóná ) tí a mọ ̀ sí mmrv náà wà pẹ ̀ lú .
Ki lo de ti ko si aabo to peye ni ile-iwe?
A ko ni ohunkohun lati fi pamọ.
Ó rán Eliakimu ati Ṣebina ati àwọn àgbààgbà alufaa, tí wọ́n fi aṣọ ọ̀fọ̀ bo ara wọn, lọ sọ́dọ̀ wolii Aisaya ọmọ Amosi.
Eli, alufaa wà ní ìjókòó lórí àpótí, lẹ́bàá òpó ẹnu ọ̀nà ilé OLUWA.
Mú Maku lọ́wọ́ bí o bá ń bọ̀ nítorí ó wúlò fún mi bí iranṣẹ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù India: Àwọn ọmọ ilé ìwé fi páálí bojú láti má se jí ìwé wò!
Tẹ ba danwo pẹrẹ, a o fimu yin danrin.
Bi ọjọ se n gori ọjọ, ti oṣu si n gori oṣu, lawọn eeyan ba sọ di owe ati aṣa obinrin ẹlẹwa naa.
Èmi ní mo fún Afeez Abiodun ní orúkọ 'Ọwọ' tó ń jẹ́ -Yemi my Lover Amọ ọrọ yii ko bọ si ibi to dara lara Ole, nisẹ lo tutọ soke to si fi oju gba a.
Ẹ máa súre fún àwọn tí ó ń gbe yín ṣépè.
Sirika tun so pe ajo agbaye to n ri si eto irinna oko oju ofurufu  ni yoo maa samojuto bi  awọn  ile-ise ijọba ati aladaani yoo se maa se ise wọnAsofin Sirika wa fokan  awọn  omo orilẹ ede  Naijiria  ati  ilẹ okeere balẹ pe ijọba ti kọgbọn nipa asise to jẹ ki ile-ise to n mojuto baalu orilẹ ede  yii kogba wọle, idi niyi ti wọn  fi se atunse to mọnyan lori , ni eyi ti wọn  ko fi ni se iru asesi bẹẹ mọ ọn.
gẹ́gẹ́ bí Baba ti mọ̀ mí, tí èmi náà sì mọ Baba.
Gẹg bi iroyin ti a gbọ, ninu ibo mẹtadinlaadọsan, Folashade nikan ni ibo marunlelaadoje.
Láti òkè ni gbogbo ẹ̀bùn rere ati gbogbo ẹ̀bùn pípé ti ń wá, a máa wá láti ọ̀dọ̀ Baba tí ó dá ìmọ́lẹ̀, baba tí kì í yí pada, tí irú òjìji tíí máa wà ninu ìṣípò pada kò sì sí ninu rẹ̀.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Coronavirus in Africa: Wo ìdí tí coronavirus kò fi ṣọṣẹ́ púpọ̀ jù nílẹ̀ Africa bí i tàwọn tó kù 11 Ọ̀wàrà 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 13 Ọ̀wàrà 2020 Oríṣun àwòrán, Getty Images BBC se ayẹwo idi marun un ti ajakalẹ̀ arun coronavirus to n ba gbogbo agbaye finra lati ibẹrẹ ọdun 2020 yii ko fi rinlẹ̀ ju bayii lọ ni awọn orile-ede ile adulawọ.
Gbogbo awọn ayalegbe to kù naa ti salọ, nitori ibẹru pe ki ọlọpaa o ma mu wọn.
Ninu ahesọ ọrọ to gbode yii, ni wọn ti sọ pe awọn aṣofin mẹfa, ninu awọn to kọwọrin pẹlu Gomina Akeredolu lati lọ gba fọọmu idibo Gomina, ni wọn ti lugbadi Covid-19.
ti awon osise ijoba ti won fe lo dibo niluu won ku.
Olori ile aṣofin ipinlẹ naa, Adebọ Ogundoyin, kede orukọ awọn eniyan naa sita l'Ọjọbọ.
Àdó olóró pa èèyàn méjìlélọ́gọ́ta ní Mọ́ṣáláṣí Afganistan ní àsìkò Jimoh Yahaya Bello, Gomina ìpínlẹ̀ Kogi kéde Onoja ní ìgbákejì tuntun Ilé ìgbìmọ̀ aṣòfin ìpínlẹ̀ Kogi júwe ilé fún ìgbákejì Gómìnà Kò sí àrùn 'Monkey Pox' ní Naìjiria- NCDC Funke Adesiyan Ọjọ kẹtadinlogun oṣu yii nile iṣẹ iyawo aarẹ orilẹ-ede Naijiria, Aisha Buhari kede oṣere tiata yii gẹgẹ bi ọkan lara awọn oluranlọwọ pataki rẹ Funke Adesiyan, òṣèré Yollywood tó di olùrànlọ́wọ́ aya ààrẹ, Aisha Buhari.
Wayi o, awọn ọmọ ile igbimọ asofin ipinlẹ Oyo naa ti da si ọrọ ọhun, ti wọn si ti pe ọga agba fun ileesẹ ọlọpaa nilẹ wa, Mohammed Adamu lati ṣe iwadii finni-finni lori ọrọ naa.
Sibẹsibẹ ọkàn Farao tún le, kò sì gbọ́ tiwọn, gẹ́gẹ́ bí OLUWA ti sọ tẹ́lẹ̀.
Minisita ṣalaye oun mọ pe awọn ọjẹwẹwẹ agbabọọlu Naijiria yoo fakọyọ ninu idije FIFA U-17 World nitori oun wo wọn nigba ti wọn n gbaradi niluu Abuja.
Ó jẹ́ ààlà ilẹ̀ ẹ̀yà Bẹnjamini ní apá ìhà gúsù.
Tani Oke Obi-Enadhuze: tí orúkọ rẹ̀ gba orí ayélujára kàn lẹ́yìn wàhálà #Lekki tollgate?
"Akeredolu ò ṣe ǹkan àrítọ́kasi ni Ondo- Komísọnà ọ̀rọ̀ to n lọ tẹ́lẹ̀rí Ààbò tó péye wà fún àwọn okòwò ará South Africa ni Eko -Sanwo Olu Bianca júwe ilé fún Serena Williams nínú ìdíje l'America Àwọn ọmọ Naijiria kóju ija sí àwọn South Africa wọ́n ní ""Ó tó gẹ́"" Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, ọpọ ero ni wọn ko ri ọna wọle wọn mọ lẹyin ti omi ti gab gbogbo oju ọna Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Awọn oṣiṣẹ panapana n wa ojutu si iṣoro awọn eniyan Niamey."
Àwọn nǹkan tí obìnrin lè ṣe pẹ̀lú olólùfẹ́ oníwà ipá lásìkò ìgbélé Coronavirus yìí 'A gbudọ rán BBC Yoruba lọ́wọ́ láti gbé Yorùbá ga'.
Dárí gbogbo ẹ̀ṣẹ̀ wọn jì wọ́n, ati gbogbo àìdára tí wọ́n ṣe, kí o sì jẹ́ kí àwọn tí wọ́n kó wọn lẹ́rú ṣàánú wọn.
Lẹ́yìn oṣù mẹta tí a ti wà níbẹ̀, a wọ ọkọ̀ ojú omi Alẹkisandria kan tí ó ti dúró ní erékùṣù yìí fún ìgbà òtútù.
Ahasaya bá Joramu, ọba Israẹli lọ, wọ́n gbógun ti Hasaeli, ọba Siria, ní Ramoti Gileadi.
Akeredolu, lásìkò to ń kopa lórí eto kan lórí ìkànnì BBC Yoruba taa pé ní 'Sọ tiẹ̀' ni opo owo wa nídìí lílo èròjà igbó fún eto oko-owo.
Ní kété ti wọ́n kéde pé ki Ozo máa lọ ilé ni ó gbìyànjú láti f'ẹ́nuko Nengi lẹ́nu bi ikíni ìdágberé Nínú ìfọ̀rọ̀wánilẹ́nu wò ti Ebuka ṣe fún Ozo, ó ni ìṣesí Nengi àti àwọn ǹkan to ni òun fẹ́ dà láyé wà lára ǹkan tó fi ìfẹ́ rẹ̀ sí.
 wọ ́ n ń sọ wọ ́ n ní new guinea , gbogbo àwọn erékùsù bí ẹgbẹ ̀ rún méwàá ní melanesia , micronesia àti polynesia ṣùgbọ ́ n àwọn tí ó ń sọ wọ ́ n kò ju mílíọ ̀ nù méjì àbọ ̀ lọ ( 2.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù New date for School resumption: Ìjọbá àpapọ̀ tún yíhùn padà lórí ọjọ ìwọlé àwọn akẹ́kọ̀ọ́ 5 Sẹ́rẹ́ 2021 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 14 Sẹ́rẹ́ 2021 Oríṣun àwòrán, Ogun govt Ijọba apapọ lorilẹede Niajiria ti paṣẹ ki gbogbo ileewe wọle pada ni Ọjọ Kejidinlogun, Oṣu Kini, Ọdun 2021.
Orilẹede Naijiria ṣi n ba wahala ati ipenija ikọ agbebọn Boko Haram finra bayii eleyii to ti mu ọpọlọpọ ẹmi lọ ti pupọ si ti di alainilelori.
Aworan Afrika: Ọkọ alarabara at'ọna to kun f'agba AU: Kagame di alaga ajọ awọn orilẹede Afrika Wo àwọn ìlérí tàwọn Gómìnà tuntun ṣe nínú ìbúra wọn Orilẹẹde 44 t'ọwọ bọ'we lori AfCFTA O ni oun kan fẹ ṣe iwadii sii lori abajade iru igbesẹ bẹẹ ni.
Wọn óo wá bá Babiloni jà.
Nítorí pé mo wà pẹlu yín, n óo gbà yín là.
Nítorí pé ninu Kristi tí ó jẹ́ eniyan ni ohun tí Ọlọrun fúnrarẹ̀ jẹ́, ń gbé lẹ́kùn-únrẹ́rẹ́.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Àrà meèrírí!
Afrika: Awọn aworan awodamiẹnu lọsẹ yi
” Nítorí náà bí OLUWA ti pa á láṣẹ, wọ́n pín ilẹ̀ fún àwọn náà gẹ́gẹ́ bí wọ́n ti pín fún àwọn ìbátan wọn tí wọ́n jẹ́ ọkunrin.
” Saulu dáhùn pe, “Pe Samuẹli fún mi.
“Ẹnikẹ́ni tí ó bá gbé baba tabi ìyá rẹ̀ ṣépè, pípa ni kí wọ́n pa á.
Ọba gba ẹnu ọ̀nà àwọn olùṣọ́ wọlé, ó sì jókòó lórí ìtẹ́.
Gẹ̀ẹ́sì gbẹ́sẹ̀ lé ₦82bn owó Abacha Abacha Loot: Ilẹ̀ Gẹ̀ẹ́sì rí owó Abacha bíi owó ọ̀daràn, ló ṣe gbẹ́sẹ̀ le Wọ́n tún ti rí lára owó tí olórí orílẹ́èdè Nàìjíríà tẹ́lẹ̀, olóògbé Sani Abacha kó lọ sílẹ̀ òkèrè.
Nigba to n kede pe oun ti ru re, ti oun si sọ re, Bidemi kede loju opo ikansira ẹni Instagram rẹ pe ọmọkunrin tuntun jojolo ni ọba oke fi ta oun lọrẹ.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Irú ẹ̀dá wo ni aṣòfin Bukola Saraki jẹ́?
Wọ́n máa n bawa sọ̀rọ̀ nípa ìgbéyàwó.
 Ìfèsì ara lọ ́ nà tó burú láàárín àwọn ọmọ tí ìyá wọn gba àjẹsára náà nígbà tó lóyún ; ni a kò tíì ní àkọsílẹ ̀ kankan nípa rẹ ̀ .
Nigeria new ministers: Obìnrin méje pèrè nínú ìgbìmọ̀ ìṣèjọba kì í ṣe ìlérí tí Buhari ṣe ní 2015
Má kọ̀wé fipò sílẹ̀, àwọn àgbààgbà Yorùbá sọ fún Osinbajo Ohun tó yẹ kóo mọ̀ nípa Fásitì Babcock rèé Pasuma kìí ṣe ọkọ mi o!
Ẹgbẹ́ àpapọ̀ àwọn òṣìṣẹ́ ṣì dúró lórí ọ̀rọ̀ wọn
Ẹni tí ó bá gba wolii ní orúkọ wolii yóo gba èrè tí ó yẹ wolii.
Serena to bẹrẹ si maa dije pada lẹyin to bimọ lọdun to lọ, wọ aṣọ dudu iru eyi ti oṣere kan wọ ninu fidio 'Black Panther' nibi idije French Open t'ọdun yii.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Gba owó lọ́wọ́ àkẹ́kọ̀ọ́ ìjọba, ko rugi oyin - Seyi Makinde Dúkìá àti ọkọ̀ jóná, ọlọ́pàá mẹ́sàn-án fara gbọta lásìkò ìwọ́de Shiite Àgùnbánirọ̀ gbẹ́mìí mì látàrí 'Snipper' tó fi fọ irun rẹ̀ Ìjọba ló ń ṣe kóríyá fún àlàfo ńlá láàrin ọlọ́rọ̀ àti mẹ̀kúnnù - Oxfam A gbọ pe ni kete ti mọto naa de oju titi Ikoyi ni ọmọdekunrin yii figbe ta pe, kawọn eeyan gba oun kalẹ lọwọ ajinigbe.
Moorer ni tirẹ gba igbanu IBF to ṣofo lasiko naa nigba to fi na Axel Schulz Nítorí Anthony Joshua borí, Keyamọ fori kó 'ẹsẹ lórí twitter Buhrai, Atiku ko dakẹ Oríṣun àwòrán, Getty Images Kii ṣe iroyin mọ pe Anthony Joshua ti gba igbanu ogo rẹ pada lẹyin to bori Andy Ruiz ninu idije ẹṣẹ kikan to waye ni lu Riyadh ni Saudi Arabi lọjọ Abamẹta.
Tí ètò àwọn ọjọ́ wọnyi bá ti parí, bẹ̀rẹ̀ láti ọjọ́ kẹjọ, àwọn alufaa yóo máa rú ẹbọ sísun yín ati ẹbọ alaafia yín lórí pẹpẹ náà, n óo sì máa tẹ́wọ́gbà wọ́n.
Lati ọdun 2016, ni awọn alasala ti wọn le ni ẹgbẹrun meji ti sa wọ orilẹede naa.
Ajọ EFCC fi ẹsun meje tan yanyan kan Metuh ti o jẹjọ papọ pẹlu ile iṣẹ rẹ, Destra Investment.
Ìròyìn ta gbọ ni pé sadede ni awon ọlọpa gba ipe láti ìdílè kan pé ọmọ ọdún méjì kan ti fara gbọta ìbon ti o si n pọkaka ikú.
N óo fòpin sí àṣejù àwọn onigbeeraga,n óo rẹ ìgbéraga àwọn tí kò lójú àánú sílẹ̀.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Ní ti Kabiru Tunde, igbele fun òun àti àwọn ọmọ oun ni ìṣòro nítorí pé òun dojú kọ wàhálà púpọ bii ariwo pipa lórí àwọn ọmọ wẹ́wẹ́ tó wà nílè.
Peteru ati Johanu tẹjú mọ́ ọn, Peteru ní, “Wò wá!
"Wọn ni o seese ko ti ni ààrún ti wọn ń pè ní ""Stockholm"", tí ènìyàn yóò máà nífẹ̀ si ẹni to mú ní tipatipa."
Ge irugbọn rẹ ko ma baa ko arun Coronavirus: Awọn eeyan Afrika lo ti n lo aworan kan lo, eyi ti awọn alasẹ eto ilera nilẹ Amẹrika fisita lori irun to maa n hu loju bii irungbọn, irun imu, irun ẹba eti ati bẹẹ bẹẹ lọ.
Akinsanya ni wọn yoo foju ba ile ẹjọ ki Adajọ ṣe idajọ to yẹ fun wọn lẹyin ti iwadii ba pari pata ṣugbọn awọn mẹtẹẹta ti jẹwọ pe lootọ lawọn ji Maalu mejeeji.
 ṣé ẹwà la á sọ pé kò ní ni ?
Oríṣun àwòrán, Nysome Wike/twitter Atiku rọ àwọn ènìyàn ìpińlẹ̀ Ondo láti gba ara wọ́n kúrò lọ́wọ́ bàbá ìsàlẹ̀ bi àwọn ènìyàn Edo ṣe ṣe.
Ayafi nigba ti wọn ba pari iwadii.
 O ni ijoba aare Buhari mo riri ipa Pataki ise awon osise ijoba nile yii.
Ekejilelogun mú Gidaliti, òun ati àwọn ọmọ rẹ̀ ọkunrin, ati àwọn arakunrin rẹ̀ jẹ́ mejila.
Ninu ifẹsẹwọnsẹ to waye ni papa isere Arsenal ni Emirates, apọnkun iya goolu mẹta sookan ni Arsenal fi jẹ ikọ Frank Lampard.
Ẹ wo àwòrán ìkọlù sí aya Fayemi ní Ọyẹ-Ekiti!
“Ẹ kò gbọdọ̀ gbin igikígi bí igi oriṣa Aṣera sí ẹ̀bá pẹpẹ OLUWA Ọlọrun yín, nígbà tí ẹ bá ń kọ́ ọ.
Bí aiṣododo wa bá mú kí òdodo Ọlọrun fi ẹsẹ̀ múlẹ̀, kí ni kí á wá wí?
Kọmísọ́nà ètò ìlera ìpińlẹ̀ Eko ọjọ̀gbọ́n Akin Abayomi ti lùgbàdì ààrùn Covid-19 Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Ìgbà tí mo máa fi lajú sáyé padà, ọ̀fọ̀ ikú mi ní wọ́n ń kígbe' Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
" Àwọn awakọ èrò náà wá ń rawọ ẹbẹ sì ìjọba Ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́ pé kò dá sí ọ̀rọ̀ náà, kò sì ṣàánú àwọn, nítorí àwọn tí setan láti san ọọdunrun náírà tí ìjọba ni kí àwọn san.
Ijọba ko ka wa kun Jack Lampang, to je alamojuto eto iroyin fun Johesu ni, ko si nnkan ti ẹgbẹ naa n beere fun, bi ko se ki ijọba fun awọn ni ẹto awon.
9 fm  , ní abẹ ́ òkúta , níbi tí ó tí ṣètò "" rock game "" tí ó sì tún jẹ ́ aka ìròyìn "" ."
O ṣeeṣe ki awọn obinrin to ko arun naa ma ri apẹrẹ ṣugbọn awọn mii yoo maa ri oorun to n bu tii jade pẹlu nkan to n jade lati oju ara wọn.
" Wọn ti maa n wọ inu ile naa tẹlẹ lati ṣe igbọnsẹ.
Ẹgbẹ osisẹ nilẹ Burundi pẹlu pe wọn n se ijiroro pẹlu ijọba ti ni ki wọn dawọ yiyọ owo ninu owo osu osisẹ duro.
Gbígba onídùròó Zakzaky ṣàfihàn àṣeyọrí ìfaradà wa lásìkò ìfìyajẹni - Shiite Ìwọ́de #RevolutionNow forí ṣánpọ́n ní Ibadan, àgbófinró gbàkóso ojú pópó Ọdún iṣu tuntun wáyé ní Ilé Ifẹ̀, Ọọ̀ni rawọ́ ẹ̀bẹ̀ sáwọn àgbẹ̀ àti darandaran Ọlọ́pàá àti àwọn olùfẹ̀hónúhàn gbéná wojú ara wọn níbi ìwọ́de Revolution Now Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Ọjà Ajégbémilékè ni Yéwándé fẹ́ lọ ní ọjọ́ tí ọkọ rẹ̀ kú.
Wọ́n ń sọ̀rọ̀ ní gbangba, ẹ̀rù kò sì bà wọ́n nítorí wọ́n gbójú lé Oluwa tí ó jẹ́rìí sí ọ̀rọ̀ oore-ọ̀fẹ́ rẹ̀ nípa iṣẹ́ abàmì ati iṣẹ́ ìyanu tí ó ń ti ọwọ́ wọn ṣe.
ẹ ṣọ́ra, kí ẹ má baà ṣìnà, lẹ́yìn tí Ọlọrun bá ti pa wọ́n run tán, kí ẹ má baà bèèrè pé, ‘Báwo ni àwọn orílẹ̀-èdè wọnyi ṣe ń bọ àwọn oriṣa wọn?
Ó sì wà lórí oyè fún bíi ogoji ọdún.
Ni ipinlẹ Eko, eeyan mẹrin miran tun ti ruu la lọwọ arun Coronavirus.
Nitorin naa o fẹ ki awọn eeyan ipinlẹ Ondo ni adari daada.
Ayaba Mẹmunat Adeyẹmi lo kọkọ bi ibeji obinrin meji ni ọjọ aje, ọjọ kọkandinlogun osu keji ọdun 2018 ti Ayaba Badrat Adeyẹmi naa tun fi ibeji ọkunrin meji lee lọjọ keje lẹyin ibeji akọkọ.
LUTH: Nítorí àìsan owó oṣù, àwọn dókítà ARD da iṣẹ́ sílẹ̀ ní ilé ìwòsàn LUTH nílùú Èkó
”Eto idibo ni ipinlẹ BauchiAjo INEC ti gba iwe ipẹjọ lati
Kò sí ewu ilẹ̀ mímì mọ́ ní ìlú Abuja Ìpàdé ìtagbangba ní Ọṣun, ṣẹ́ ti fi orúkọ sílẹ̀ ?
Ibi tí wọ́n sin wọ́n sí ni mo fẹ́ kí o sin èmi náà sí.
won, bakan naa , ni won tun n se olusakoso awon ile –iwosan ti ipinle, sugbon
Ẹni Mímọ́ Israẹli ni Olùràpadà rẹ,Ọlọrun gbogbo ayé ni à ń pè é.
Amọ o fikun pe olori osisẹ ni ọọfisi aarẹ wa pe oun pada lẹyin ipade igbimọ alasẹ ijọba naa.
Eliṣa sì lọ sí òkè Kamẹli, láti ibẹ̀, ó lọ sí Samaria.
Asuquo tun ro awon ti oro kan, lati jawo nipa rira epo lona aibofin mu, eyi ti o le sakoba fun awon irinse won , bakan naa , o tun le se ijamba  fun emi awon ara ilu.
Oríṣun àwòrán, Nff Àkọlé àwòrán, Samuel Okwaraji: Ó pé ọgbọ̀n ọdún tí lónìí ti akọni àgbábọ̀ọ̀lù papo dà Ọ̀pọ̀ ọmọ Nàìjíríà ló ti ń ṣelédè lẹ́yìn Okwaraji bí wọ́n ṣe n ṣe ayájọ́ ọgbọ̀n ọdún to ti papo dà, sùgbọ́n wọ́n fi ẹdùn ọ̀kan wọ́n hàn pé, NFF àti ìjọba ko ti ṣe tó: Àkọlé àwòrán, Samuel Okwaraji: Ó pé ọgbọ̀n ọdún tí lónìí ti akọni àgbábọ̀ọ̀lù papo dà Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Ẹni tí kò bá gba Ọlọrun gbọ́ mú Ọlọrun lékèé, nítorí kò gba ẹ̀rí tí Ọlọrun ti jẹ́ nípa Ọmọ rẹ̀ gbọ́.
Paul Pogba gbé ètò owó dídá kalẹ̀ fún ààrùn Coronavirus Wọ́n ti wọ́gilé ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ Arsenal àti Brighton lẹ́yìn tí Mikel Arteta lùgbàdì àrùn Coronavirus Àyẹ̀wò gbogbo irinṣẹ́ ètò ìlera ti di dandan báyìí lẹ́yìn ikú Chineme Martins- NFF Láì lo Kakulétọ̀, mo ní ọpọlọ ìṣirò, tábìlì ìṣirò wà lórí mi - Human Calculator Ọjọ Iṣẹgun ni ẹgbẹ agbabọọlu rẹ fi ikede sita pe o ti fi opin si adehun iṣẹ to wa laarin wọn, lai boju wo owo ti yoo padanu.
Inú mi kò dùn láti jẹ́rìí tako Fayoṣe - Obanikoro Iléẹ́jọ́ gbégi lé owó Ayodele Fayose Fayoṣe fapájánú, o ni kí EFCC kọwe tọrọ àforíjìn NLC, TUC: Àwa ò gba owó lọ́wọ́ Fayose ooo Atẹjade kan ti agbẹnusọ ajọ to n gbogun ti iwa jẹgudujẹra fi sita ṣalaye EFCC fidiẹ mulẹ ni.
Ṣugbọn awọn ipinlẹ mii bii Pennysylvania ati Wisconcin kii gba ki wọn ka awọn ibo ti wọn ba tete di afi ni ọjọ idibo gangan.
kí ó tó já Ọ̀jọ̀gbọ́n onímọ̀ ẹrọ tí o ní kí wọ́n wọgi lè ìbò Ààrẹ Nàìjíríà Ọjọgbọn Omọtayọ tun gba igbega sii lẹnu iṣẹ ni Ikẹrẹ, nigbati o di adari fun ileewe naa laarin ọdun 1995 si 1997.
Wo ohun tó mú kí Ṣèyí Makinde ó tẹ̀síwájú pẹ̀lú ìpàdé ìtagbangba níbàdàn láàrín ìṣẹ̀lẹ̀ àrùn Coronavirus Naira marundinlaadoje ni wọn n ta epo nibẹ lẹyin ti awọn amojuẹrọ ti yi iye ti wọn ta jala epo kuro ni naira marundinlaadọjọ ti o wa tẹlẹ.
niluu Ibadan to je ipinle Oyo ni ekun Gusu orile ede Naijiria, lati ko awon
Oríṣun àwòrán, Getty Images ‘Buhari ti wọnu ẹmi lọ’ Soyinka s'ọrọ lori ipaniyan awọn darandaran EFCC ń wádìí iléeṣẹ́ Bola Tinubu,' Alpha Beta Consulting Ltd' 'Ẹnikẹ́ni ò lè tì mí gbọ̀ngbọ̀n láti gbé orúkọ mínísítà jáde' Ninu itan oṣelu Naijiria, o kopa ipa ribiribi paapaa ninu jija fitafita fun gbigba ominira lọwọ awọn oyinbo amunisin.
Ètò ìsìnkú Abba Kyari tako ìlànà ìjìnàsíraẹni lórí ààrùn covid-19- Àwọn ọmọ Nàìjíríà yarí Wo àwọn ọ̀nà tí o le fi mú ara rẹ gbá yágí-yágí lásìkò ìgbélé yìí Fidio yii n se atọka si oriṣiriṣi ọna ti awọn eniyan fi n dun ara wọn ninu lasiko iporuru ọkan ti coronavirus mu ba ọpọ eniyan.
Aláàfin tó rí ìbẹ̀rẹ̀ àti opin sáà gómìnà mọ́kànlélógún l‘Oyo14 Sẹ́rẹ́ 2021 Èyítí A Ń Kà Jùlọ 1 Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún un 2 Kí ló ma n fa Àkúfà nílẹ̀ Yorùbá, àti ọ̀nà àbáyọ?
O gbọdọ̀ san ẹ̀jẹ́ tí o bá jẹ́ fún Oluwa lẹ́kùn-únrẹ́rẹ́.
Siwaju si, ile-ise panapana tenumo pe, opo eniyan ti o ba isele ohun lo ni anfani ko ti si lati ka won, beesini won ro awon akoroyin ati awon eniyan lati se suru.
A jókǒ sí ẹ̀hìnkùlé, a n gbọ́ ìkini òkú àti ìdánilóhùn oríṣiríṣi.
Gbogbo ọmọ inú ilé rẹ ni wọn yóo fi idà pa ní ọjọ́ àìpé.
O gbìn wọ́n, wọ́n ta gbòǹgbò;wọ́n dàgbà, wọ́n so èso;orúkọ rẹ kò jìnnà sẹ́nu wọn,ṣugbọn ọkàn wọn jìnnà sí ọ.
N kò lè sọ iye àwọn ẹ̀gbọ́n, àbúrò, ìbátan, ọ̀rẹ́ àti ojúlùmọ̀ mi tí ń kú lọ́dọọdún.
Yóo jẹ́ ibi ààbò fún ẹni tí ó paniyan, bí arakunrin ẹni tí ó pa bá fẹ́ gbẹ̀san, nítorí pé ẹ kò gbọdọ̀ pa ẹni tí ó bá ṣèèṣì paniyan títí yóo fi dúró níwájú ìjọ eniyan Israẹli fún ìdájọ́.
Nítorí èyí ni mo fi rán àwọn wolii, àwọn ọ̀jọ̀gbọ́n ati àwọn amòfin si yín.
Àwọn ọ̀dọ́ dáná sun ọkọ̀ akérò tó ṣekúpa ọlọ́kadà ní Ibadan Awọn ọdọ kan to n fapajanu ti dana sun ọkọ akero kan lowurọ Ọjọru nilu Ibadan lẹyin ti awakọ naa kọlu ọlọkada kan ti o si da ọmi rẹ legbodo.
Kí á wí pé Ọlọrun ń ṣe àìdára ni bí?
Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Fídíò, Natalia Mufutau ìyá Yakub, Kamil àti Adam sọ̀rọ̀ lórí bí wọ́n ń sọ èdè mẹ́rin pàpọ31 Ògún 2020 6:18 Fídíò, Akomolede: Bolaji Faleke ni Olùkọ́ tó ń kọ́ wa ní àṣà oge ṣiṣe lórí BBC Yorùbá, Duration 6,181 Owewe 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Ewe, ogoro awon olugbe agbegbe Essentuki ni o ti n wa wo igbaradi iko naa.
Buhari ti fòfin de àwọn mínísítà láti rìnrìn àjò lọ sí ilẹ̀ òkèrè Ìdẹ̀ra dé l'Eko!
Ọkunrin kán wà tí orúkọ rẹ̀ ń jẹ́ Simoni, tí ó ti máa ń pidán ní ìlú náà.
Ọlọ́pàá ní àwọn ṣì ń ṣèwádìí ẹni tó bẹ́rí ní Alasiya l'Eko Àyẹ̀wò òkú tú àṣírí bí òṣìṣẹ́ NSCDC tí ọlọ́pàá lù ní Abuja ṣe kú 'Ìdùnnù wa kọ́ ni kí á má fún ọmọ Nàìjíríà ní 'Visa' Lẹ́yìn oṣù márùn ún, Buhari kọ̀ láti yọ ọ̀ga NHIS Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Segalink:ìkùnsínú pọ̀ láàrin àwọn agbófinró bẹ́ẹ̀ wọn kò ni agbẹnusọ O ni awọn n ra ike rọba miliọnu kan lagbaye ni isẹju aaya kan, ti awọn si n lo to triliọnu marun un ike rọba lọdọọdun.
Mo gbọn àpò ìgbànú mi, mo ní, “Báyìí ni Ọlọrun yóo gbọn gbogbo ẹni tí kò bá mú ẹ̀jẹ́ yìí ṣẹ kúrò ninu ilé rẹ̀ ati kúrò lẹ́nu iṣẹ́ rẹ̀.
Ooni Ile ife, Ààrẹ Gani Adams fárígá lórí ikú ọmọ Fasoranti Ooni Ife fohùn ránṣẹ́ sí Boris Johnson, ó ní, bóo bá joun gbé, má johùn gbé"" Ipò ètò ààbò ń já àwa gómìnà láyà, ó ń kọ wá lóminú - Àwọn gómìnà Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Iya Adura Esther Ajayi sọ àṣírí owó rẹ̀ tó fi ń ṣàánú Ọba alade naa sọ pe, wọn yoo ṣe agbekalẹ ẹrọ ayaworan CCTV kaakiri opopona marosẹ."
Ilé Iṣẹ́ BBC ti kan si Busy Bee fun ọ̀rọ̀ lẹnu wọ́n Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí DR Congo: Military plane crash don kill 12 people30 Owewe 2017 Ivory Coast: Plane wey carry load crash enter sea, kill 414 Ọ̀wàrà 2017 Mexico plane crash: How 103 passengers take survive1 Ògún 2018 Iran: Plane crash don kill 66 people18 Èrèlè 2018 Cuba plane crash kill pass 10019 Èbibi 2018 Algeria military plane crash: 257 pipo don die near Algiers11 Ìgbé 2018 Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Ìjọba Amẹrika fi ojú àwọn ọmọ Yahoo mẹ́fà léde, wọ́n gbẹ́sẹ̀ lé dúkìá wọn Abdulrahaman, Ọmọ ọdún 17 kó sí páńpẹ́ EFCC lórí ẹ̀sùn yahoo-yahoo ní Ibadan Diezani gan an ní Hushmummy tó ń bú àwọn Yahoo boys- Àwọn Ọmọ Naijiria lórí Twitter Pósí ní mo fi ṣe igbá ọṣẹ́ - Afurasí ọmọ ‘Yahoo’ kà fún EFCC Ọmọbìnrin tó tayọ nínú ìdànwó WAEC ọdún 2019 pẹ̀lú A1 méje ti kú Nàìjíríà fohùn ránṣẹ́ padà sílé aṣofin UK pé ọ̀rọ̀ EndSars kò sí lẹ́nú wọn láìgbọ́ ìwádìí tán!
O wó orí aṣiwaju ilẹ̀ àwọn ẹni ibi wómúwómú,o tú u sí ìhòòhò láti itan dé ọrùn.
Ààrẹ Buhari buwọ́lu gbígbé ìṣàkoso nọ́mbà ìdánimọ̀ (NIMC) lọ sí ẹ̀ka ìjọba tó ń rí sí ìbáraẹnisọ̀rọ̀ Wọ́n ti sún ìdájọ́ àwọn sójà tó pa ìyá àti ọmọ ní ọdun 2018 sí oṣù tó m bọ̀ Sugbọn bi alufa ṣe fẹ so tọkọtaya pọ bayii ni awọn ẹbi Osadebe mu ori pẹpẹ ijọ gun ti wọn si kede pe obinrin naa ti ni ọkọ tẹlẹ nitori naa wọn ko le so wọn pọ ninu igbeyawo mimọ.
Florence Ajimobi: Àwọn Káfíńtà ti kó igi dé láti tún òrùlé ilé ìtajà tó jóná ṣe
Lorii bi owo tabua yii yoo ṣe jade, Ọba Adeyeye ni ọlọdani atawọn ileeṣẹ nile ati loke okun lawọn yoo kan si fun aṣeyọri igbesẹ naa.
O yẹ́ mi sí bí ó ti yẹ kí o yẹ́ mi sí, o bá mi siré nígbà tí iré tọ́, o bá mi kẹ́dùn ni àkókò ìbákẹ́dùn, bẹ́ẹ̀ ni o kòo sì wí fún mi lọ́jọ́ kan wí pé kí ni mo máa ṣe.
’’O ni ilu Eko ti se gudugudu meje , yaya mefa lati lee mu iwuri ba awon onisowo ni ipinle naa.
"O ni ""Ọkunrin naa ko ni arun Coronavirus lara mọ, ṣugbọn idi ti a ṣi fi da duro ni pe a fẹ ṣe ayẹwo miran fun ki a to fi silẹ ko maa lọ ile rẹ."
Fẹran jẹkọ gbaa ni idije naa jẹ fun Chelsea.
Ṣugbọn ọjọ́ ń bọ̀, tí a óo gba ọkọ iyawo kúrò lọ́dọ̀ wọn, wọn óo gbààwẹ̀ nígbà náà.
 Àwọn òpìtàn mìíràn ń fi aláké Ẹ ̀ gbá àti obòkun ti Ìjẹ ̀ ṣà mọ ́ wọn .
Sadi Mane agbawaju Liverpool lo jẹ goolu mejeeji to mu ki Liverpool gunke si ipo kẹẹta lori afara Liigi.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Bukola Saraki: Ìwà àrékérekè ni ilé mi tí EFCC tì pa 14 Èbibi 2019 Oríṣun àwòrán, WIKIPEDIA Àkọlé àwòrán, Ajọ to n gbogun ti iwa jẹgudujẹra, efcc ti ile saraki to wa ni 15a, 15b ati 17 to wa ni agbeegbe MacDonald Road, Ikoyi, Lagos.
Guus Hiddink yoo lo darapo mo akegbe re Marcello Lippi, ti oun tuko agbaboolu agba orile-ede naa, papa julo lati gbaradi ni kikun fun idije boolu Asian ti yoo waye lorile-ede United Arab Emirates ninu osu kinni odun to n bo.
 apá ìwọ ́ oòrùn ni ilẹ ̀ Ìjẹ ̀ ṣà wà ní ilẹ ̀ yorùbá tàbí káàárọ ́ - oò- jíire .
Ede aiyede to waye laarin Lawal ati baba rẹ lo ṣokunfa bi Bukọla ṣe rọwọ mu di gomina pẹlu atilẹyin Baba Oloye fun ọmọ rẹ.
26 Agẹmo 2020 Oríṣun àwòrán, Others Se ni oju opo Twitter n gbona fẹlifẹli ni aarọ ọjọ Aiku, nigba ti ọmọbinrin kan fi ọrọ aburo rẹ, tii se abikẹyin ile wọn, to araye leti.
Àgùnbánirọ̀ akọ̀ròyìn Channels náà ti dágbére fáyé látààrí ìkọlù Shiite l'Abuja Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ẹ̀mí sùn níbi ìkọlù Shiite àti ọlọ́pàá Ẹwẹ, Comrade Muftau ni igbesẹ yii kan da bii ki wọn gbe ote le awọn ẹgbẹ tabi ijọ ẹlẹsin Kristẹni ni tori Naijiria nikan kọ ni ọmọ ẹgbẹ Shiite wa.
Ohun ti mo ranti gbẹyin ki n to ba ara mi nile iwosan ni pe mo ri tirela to rọ lu wa, ti ohun gbogbo si pada dudu.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, World Diabetes Day: Ọdún kọkandinlogun ti mo ti wà lẹ́nu itọ ṣúgà nìyí Ọdun 1982 ni wọn gba Andrew si iṣẹ aran olukọ agba fasiti lọwọ ninu eyi to ti bẹrẹ iṣẹ lati di olukoni.
CONDOLENCE MESSAGEI write to convey, on behalf of my family and on my own behalf, our profound sympathy and solidarity with you over the death of your beloved husband and one of the most outstanding diplomats of our time in the world, Amb.
O wó odi gíga àwọn àjèjì, kúrò lẹ́yìn ìlú,ẹnikẹ́ni kò sì ní tún un kọ́ mọ́.
Ṣugbọn kí ó fi omi fọ nǹkan inú rẹ̀ ati ẹsẹ̀ rẹ̀, kí alufaa fi gbogbo rẹ̀ rúbọ, kí ó sì sun ún lórí pẹpẹ náà.
Opo nkan ni awọn agbofinro fi di opopona ni Beijing ṣaaju ayẹyẹ ominira naa.
Bàbà ọmọ ọdún 75 kó HIV ran ọmọ ọdún 14 lẹ́yìn tó fi ipá báa lò Ṣe ẹ ti gbọ́ ri?
Bakan naa ko ni le kopa ninu ifẹsẹwọnsẹ Juve ati Dynamo Kiev ninu Champios League logunjọ oṣu Kẹwa.
nipa isele naa ati awon eniyan ti ọwọ awon ọlọpaa ti tẹ lori isele yii, aare wa
’’Osinbajo, ti o je okan lara awon onigbonwo  Simmons Cooper Advocacy Initiative naa ,ni eto yii  ti o maa n waye ni ẹẹkan lọdun meji fun awon akekoo lori eto ofin lorile ede Naijiria, so pe ohun ti o faa ti awon fi n se iru eto bayii ni fun idagbasoke eto ofin.
Akonimoogba agba iko Super Eagles,  Gernot Rohr, ti pe agbaboolu marunlelogun fun ifesewonse olorejore ti iko naa yoo gba pelu Poland ati Serbia, fun igbaradi idije boolu agbaye to n bo lona, loiile-ede Russia.
PDP:Buhari ni kẹ dalẹ́bi tí wahala ìdìbò bá bẹ́ sílẹ̀
His works, values, and principles have had and will continue to have a great influence and impact in Africa and beyond.
Bakan naa ni olori ile aṣofin ni Ambọde ko gba ifọwọsi ile aṣofin ọhun ki o to rawọ le rira awọn ọkọ nla akero BRT okoolelẹgbẹrin to ra.
OLUWA ti na ọwọ́ rẹ̀ sórí òkunÓ ti mi àwọn orílẹ̀-èdè jìgìjìgì.
Kódà gbogbo àwọn olóṣèlú wa ni à n ri lóri amóhùnmáwòràn bi wọ́n ṣe n ṣe ètò òṣèlú láì tẹ̀lé òfin Covid-19 sùgbọ́n tó bá ti di ọ̀rọ̀ sọ̀ọ́sì.
Tí a fiṣọwọ́ ní 5:25 10 Sẹ́rẹ́ 20215:25 10 Sẹ́rẹ́ 2021 Buhari, pa ìtìjú mọ́ra láti sanwó fáwọn ajaguntà tí yóò kojú Boko Haram - Soyinka Wole Soyinka wa daba sise idanilẹkọ nipa ibọn lilo fawọn agbẹ, ki wọn le fi ọwọ kan mu ọkọ lati roko, fi ọwọ keji mu ibọn, ti yoo fi daabo bo ẹmi ati ire oko rẹ.
Bẹ́ẹ̀ ni ẹ óo ṣe sí àwọn ìlú tí ó jìnnà sí yín, tí kì í ṣe àwọn ìlú orílẹ̀-èdè tí ó wà níhìn-ín.
Wo pàtàkì ayájọ́ ‘Má wọ kọ́mú’ tó kò lónìí Ènìyàn 26,000 ni àìsàn jẹjẹrẹ ń pa lóòjọ́ Kíni ìdí ti wọn fi ń lọ ọmú obinrin nílẹ Adúláwọ?
Nígbà náà ni àwọn orílẹ̀-èdè yóo máa pè yín ní ẹni ibukun, ilẹ̀ yín yóo sì jẹ́ ilẹ̀ ayọ̀.
Opolopo awon omo orile ede Naijiria
Ninu ọrọ rẹ to fi sita, agbẹnusọ fun aarẹ Buhari, Garuba Shehu ni aṣa lilo rogbodiyan ati ikọlu lati yanju aawọ laarin awọn eeyan lorilẹede Naijiria ko ṣai maa kọ aarẹ orilẹede Naijiria lominu.
Roshan ti n ṣiṣẹ ni abule yii ki iṣẹ tó gbe Gauri lọ si abule yii.
Ọ̀fẹ́ ni China yóò kọ́ fásítì $50M ètò ìrìnnà sí Daura ìlú Ààrẹ Buhari- Amaechi Họnọrebu Agunbiadeto ni oun fẹ pin Paliatiifu lasiko ọjọ ibi Ọmọ ile aṣojuṣofin to n ṣoju ẹkun idibo Ikorodu nile igbimọ aṣojuṣofin ipinlẹ Eko kan ni Họnọrebu SOB Agunbiade.
Oríṣun àwòrán, Ifayemi Elebuibon O ni ọfọ ni oun mu bọnu nigba ti oju ibi ti ọrẹ oun fi ṣeṣe naa n ṣẹjẹ.
gbe lati lee jẹ ki awon eniyan pada si ilu won lati dibo.
Ipade ti igbimo to n ri si eto oro aje se lojo Aje nile aare , ni won ko fenuko lori ekunwo naa.
Ọpọlọpọ orílẹ̀-èdè ati àwọn ọba alágbára yóo sọ àwọn ará Babiloni pàápàá di ẹrú, gẹ́gẹ́ bí ẹ̀san ìṣe wọn ati iṣẹ́ ọwọ́ wọn.
Ni kete ti ajọ naa ba ti pari atunse lori wọn, ni awọn akẹkọọ naa yoo ni anfaani si i.
Awọn oṣiṣẹ ile ifowopamọ ati awọn oṣiṣẹ ti iṣẹ wọn jẹ ko ṣe maa ni bi awọn oṣiṣẹ ilera, ati awọn agbofinro ko ni lanfaani isinmi yii.
Ó pẹ́ díẹ̀ tí a dé ìlú náà kí a to mọ ọba wọn.
Ó fi igi akasia ṣe pẹpẹ turari kan, bákan náà ni gígùn ati fífẹ̀ rẹ̀ rí, wọ́n jẹ́ igbọnwọ kọ̀ọ̀kan, gíga rẹ̀ sì jẹ́ igbọnwọ meji.
St Michael Primary School, Yemetu ati I.
Bi èniyàn bá kọ́ ọgbọ́n ninú ọ̀rọ̀ Yorùbá ti ó sọ pé “Iwájú lèrò mbá èro” yi, à ri pé, kò si ipò ti òhún wà ti kò si ẹni ti ó wà nibẹ̀ ṣáájú tàbi lẹhin òhun.
Amọ awọn alatako ati ajafẹtọ eeyan kan a ma bẹnu atẹ lu bi wọn ti ṣe n lo Sharia.
Eyi jẹ jade ninu ikede ti agbẹnusọ fun ajọ ọlọpaa, Frank Mba fi sita.
Ìdíje AWCON: Nàìjíríà fi ẹ̀yìn Cameroon janlẹ̀
Ifesewonse olorejore mejeeji ohun ni o wa lara ifigabaga igbaradi ti ajo NFF ti seto sile fun iko ohun saaju idije agbaye ti yoo waye ni Ruusia.
Bi a ba kan fẹ tan ara wa loku, ko si agbara lọdọ ẹnikẹni yatọ si igbimọ iṣẹdajọ lati yọ adajọ''.
igun kan naa lemi ati aarẹ ana, Jonathan wa.
Oríṣun àwòrán, Reuters Àkọlé àwòrán, Olootu Ijọba Jacinda Ardern O ni ''loni, laaye ibi ti o ti hu iwa laabi yi, mo ri ifẹ laarin awọn eeyan'' ''Ọkan wa bajẹ sugbọn a ko ba ara jẹ.
Bí ẹ ti gbọ́ láti ìbẹ̀rẹ̀, òfin yìí ni pé kí ẹ máa rìn ninu ìfẹ́.
 “Ki igbimo asoju se atileyin fun gomina  Oluwarotimi Akeredolu lona ti yoo se fontẹ lu
Kò sí ohun tí ó wà ní ìpamọ́, tí kò ní fara hàn.
Ọjà Àgbáláta ní Badagry rèé, níbití ẹran ejò ti dùn ju ẹran adìẹ lọ Lórí ìmọ̀ràn Sunday Igboho, Ẹlẹbubọn ní yóò dára kí Yorùbá padà sí àmúlò èròjà ìbílẹ̀ fún ààbò A kò mọ̀ọ́mọ̀ pa ọlọ́pàá mẹ́ta, aráàlú kan, ó ṣèèsì ni, ajínigbé la pè wọ́n - Iléeṣẹ́ ológun Lara wọn la ti ri Ogun, Sango, Ọbatala ati bẹẹ bẹẹ lọ, ti wọn n ya kẹtikẹti wa silu Iwo pẹlu erongba lati fi Wuraọla se aya, sugbọn ibinu nla ni wọn n ba kuro, ti ibanujẹ yoo si dori agba wọn kodo tori Wuraọla ko setan lati fi eyikeyi wọn se ade ori rẹ.
Ọ̀pọ̀lọpọ̀ ilé la ti pa asa yìí rẹ, ṣùgbọ́n ọ̀pọ̀lọpọ̀ ìdílé wà tí kò fẹ́ fi àṣà yìí sílè rárá.
" Ó ní èyí kò wu etí gbọ rárá, bẹ́ẹ̀ ni kò dára, òun kò sì fẹ́ bẹẹ torí àwọn náà kò tọrọ oúnjẹ àti owó lọ́wọ́ òun rí.
 Oga-agba ajo ti o n samoju to oro aarun kogbogun HIV/AIDS lorile-ede Naijiria (NACA), omowe Sani Aliyu, ro awon ijoba ipinle lati fowosowopo  pelu ijoba apapo gbogun ti itankale aarun HIV.
Ìjọba Nàìjíríà ti parí ìwádìí lórí àgbo Covid-Organics ti Madagascar kó ránṣẹ́ sí i Wo iye owó tó wọlé fún ìjọba lórí COVID-19 àti bí wọ́n ṣe ná an Wole Soyinka rèé láti kékeré Bakan naa ni aarẹ ile igbimọ aṣofin tẹlẹ, Bukola Saraki ba ẹbi oloogbe naa kẹdun lẹyin to dagbere faye.
Auntie Remmie Ọlọyan nla sọ iriri rẹ gẹgẹ bi ẹni ti ọyan tobi gan ati ohun toju rẹ maa n ri pẹlu awọn ọkunrin.
Àwọn ìròyìn mìíràn tí ẹ lè nífẹ̀ẹ́ sí: Coronavirus ti di ara wa, kò le è kúrò mọ láéláé - WHO Àpanisáyé ni ẹ̀wà tí wọ́n n fí 'sniper' sí Wo ibi tí ayédèrú ìròyìn bá Áfíríkà dé láàrin ọdún kan Ìdí rèé tí ilẹ̀ Afirika fi gbọdọ̀ kópa nínú dídán abẹ́rẹ́ coronavirus wò Àwọn arẹwà obinrin Yollywood, tá ló mọ iṣẹ́ rẹ̀ jù?
Ẹ wo Daniel tí wọ́n fẹ́ yẹgi fún lẹ́yìn tí US kò ṣe irú ẹ̀ fún odidi ọdún 17 Kò sí ìfòyà, ọkọ̀ bààlù wà tí ìjọba ba ti afárá 3rd Mainland lósù yìí Sọ́ọ́bù irun tí ọmọ àarẹ ṣí sílẹ̀ Amerika fa awuyewuye Wole Soyinka rèé láti kékeré ''Awọn dokita fẹ ki ijọba pese aṣọ idaabobo to peye, eto adojutofo ati eto lati maa ṣe ayẹwo deedee fawọn dokita atawọn oṣiṣẹ eleto ilera,'' Dokita Sodipo lo woye bẹẹ.
Bákan náà, n óo da gbogbo ọrọ̀ ìlú yìí, ati gbogbo èrè iṣẹ́ tí wọ́n ṣe lé àwọn ará Babiloni lọ́wọ́, pẹlu gbogbo nǹkan olówó iyebíye wọn, ati gbogbo ìṣúra àwọn ọba Juda; gbogbo rẹ̀ ni àwọn ọ̀tá wọn, àwọn ará Babiloni yóo fogun kó, wọn yóo sì rù wọ́n lọ sí Babiloni.
Ilé wo pà 'yàn meji l'Èkó Ilé wó pa Jide, ọmọ ọdún mọ́kànlá, l'Oṣogbo Bi o tilẹ jẹ wi pe a ko tii le fi aridaju ohun to ṣokunfa ile wiwo naa, iroyin sọ pe lasiko ti ojo n rọ lo ṣẹlẹ lowurọ ọjọ abamẹta.
Ẹwẹ, oludije si ipo gomina ninu ẹgbẹ oṣelu SDP, Iyiọla Omiṣore ṣi yẹnu mọ ọrọ rẹ wipe ijọba ti yoo ṣe anfani fun awọn eeyan ipinlẹ Ọṣun ni yoo ri ojurere oun gba ninu atundi ibo si ipo gomina ipinlẹ Ọṣun.
Ọjọ keje, oṣu Kẹrin, ọdun 2020 ni awọn ajinigbe gbe awọn akẹkọọ naa, Nelson Nwafor, Fortune Obemba ati Joy Adoki, nilu Choba to jẹ ọẹan lara awọn ilu to yii fasiti naa ka.
Wahala ija to bẹ silẹ waye lẹyin ede aiyede kan to waye ninu ọja kan ni ẹkun ariwa ipinlẹ Kaduna ti o si mu ẹmi eeyan marundinlọgọta lọ.
Wọn óo máa tàn ní ilẹ̀ rẹ̀,bí òkúta olówó iyebíye tíí tàn lára adé.
Oríṣun àwòrán, @others Àkọlé àwòrán, Nọ́mbà 9: Nilu afọju, oloju kan lo n jọba lorọ amohunmaworan yii jẹ lasiko to n lo igba.
Bauchi woman: Balaraba Ibrahim tó jẹ́ Olùrànlọ́wọ́ pàtàkì fún ọ̀rọ̀ àwọn obìnrin tí a kọ̀ sílẹ̀ jẹ́ kàyééfì ní Nàìjíríà
Ikeji ni pe, ijọba tabi awọn banki kọ lo n tẹ owó Bitcoin.
Amọ ki eeyan kan wa woye pe agbekalẹ ikọ alaabo Amotekun to wa lati gbe ijọba nigbọnwọ, ni yoo ba ọrọ aje awọn eeyan kan jẹ, jẹ iwa aimọkan ati ọna lati ba erongba rere agbekalẹ ikọ Amotekun jẹ."
Lẹyin naa lo ṣiṣẹ akọwe nileeṣẹ ologun Naijiria lasiko ogun abẹle.
Obìnrin tó lówó jùlọ ní Africa 'ja orílẹ̀-èdè rẹ̀, Angola lólè' fi kó ọ̀rọ̀ jọ ni Ẹwẹ, alaga ẹgbẹ awọn gomina ilẹ Yoruba to tun jẹ gomina ipinlẹ Ondo, Ọgbẹni Rotimi Akeredolu ti sọ pe awọn ko ṣe agbakalẹ Amọtẹkun lati tako iran mii ni Naijiria.
Oríṣun àwòrán, AFP Orilẹede Lebanon lo ṣi n koju ọrọ aje to dẹnukọlẹ ati arun Coronavirus to n ba wọn finra ki ibugbamu naa to waye.
Oríṣun àwòrán, @ekitistategov O rọjo adura aṣeyọri fun gomina o si dupẹ lọwọ rẹ fun ọwọ ifẹ to na si ọmọ rẹ.
jinna si ila Ariwa Goma, nibi ti o ti sagbako awon eniyan to ni aarun Ebola .
Ninu fidio kan to ti di tọrọ fọn kale bayii, ni a ti ri Beckham to n lewaju ipolongo tuntun lati gbogun ti aisan iba, to si sọ ede mẹsan-an gbako ọtọọtọ ninu fidio naa.
Ileeṣẹ Aarẹ Naijiria naa fi ikede yi sita loju opo wọn ni Twitter.
” Àwọn àgbààgbà mẹrinlelogun sì dojúbolẹ̀, wọ́n júbà Ọlọrun.
Tí ó bá jẹ́ pé olóòótọ́ eniyan ni yín, kí ọ̀kan ninu yín wà ninu ẹ̀wọ̀n, kí ẹ̀yin yòókù ru ọkà lọ sí ilé fún ìdílé yín tí ebi ń pa, 
Àwọn Juu dá a lóhùn pé, “Kì í ṣe nítorí iṣẹ́ rere ni a fi fẹ́ sọ ọ́ ní òkúta, nítorí ọ̀rọ̀ àfojúdi tí o sọ sí Ọlọrun ni; nítorí pé ìwọ tí ó jẹ́ eniyan sọ ara rẹ di Ọlọrun.
Nípa ọgbọ́n ati ìmọ̀ rẹ, o ti kó ọpọlọpọ ọrọ̀ jọ fún ara rẹ, o sì kó wúrà ati fadaka jọ sinu ilé ìṣúra rẹ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Aràrá bíi tèmi, kó má rò pé kò sì ǹkan tó lè ṣe láyé ju iṣẹ́ agbe lọ' Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Apá kan lára àwọn ilé àwòṣífìlà tí ó wà ní Sutrapur kò ṣe é rí mọ́n.
Amọ bi iye eniyan ṣe n peleke si to ni arun Coronavirus naa ni Aarẹ Andry Rajoelina n sọ wi pe agbo Madagascar yii ni ọna abayọ si arun Coronavirus, ti o si ṣe ifilọlẹ rẹ ni Oṣu Kẹrin.
Wọn jẹ ọkan lara awọn ẹmi airi, ti a n pe ni Ajogbo - awọn ẹmi airi to ma n yọ da eeyan laamu Kii ṣe gbogbo ajẹ lo ma n ṣe buruku, tako bi awọn eeyan ṣe ma n bẹru ti wọn ba gbọ nipa ajẹ Ajẹ wa fun rere ati buburu Obinrin lo ma n jẹ ajẹ, ọkunrin ni oṣo.
Agbaọjẹ agbabọọlu Argentina yẹlẹ ri, Diego Maradona ti wọ kaa ilẹ lọlẹyin to papoda lẹni ọgọta ọdun.
Eleyi ti o jasi ikọlu lojiji, ti o si la ẹmi eniyan meje lọ.
bí orílẹ̀-èdè ọ̀hún bá yipada kúrò ninu ìwà burúkú rẹ̀, n óo dá ibi tí mo ti fẹ́ ṣe sí i tẹ́lẹ̀ dúró.
Ní ọdún 1926 ni ẹgbẹ́ tí a mọ̀ sí “Ìjẹ̀bú - Jẹ̀ṣà Progressive Union” yí orúkọ ìlú náà kúrò láti Ìjẹ̀bú - Ẹrẹ̀ sí Ijẹ̀bú - Jẹ̀ṣà nítorí pé ilẹ̀ Ìjẹ̀ṣà ni Ìjẹ̀bú yìí wa.
Inu ikọlu naa ni wọn ti yinbọn pa ọkan lara awọn janduku ti fara gbọta.
Laarin ọdun 1990 si 1995, Kyari jẹ oye akọwe fun igbimọ oludari African International Bank Limited.
Kò sò jẹ́ kí inú Olódùmarè kò dùn sí mi, bẹ́ẹ̀ ni ẹni tí iní Olódùmarè kò dùn sí kan ìjàngbọ̀n.
“Mo wò yíká nítorí ọ̀rọ̀ ńláńlá tí ìwo kékeré yìí ń fi ẹnu sọ, mo sì rí i tí wọ́n pa ẹranko náà, tí wọ́n sì jó òkú rẹ̀ níná.
Olúwó - BBC News Yorùbá BBC News, YorùbáFò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Mo ti ṣetán láti daríi ìfẹ̀họ́nú hàn lòdì sí ìpànìyàn - Olúwó 20 Ògún 2019 Oríṣun àwòrán, INSTAGRAM/OLUWO OF IWOLAND Àkọlé àwòrán, Moti setan lati dari ifehonu han leyin ti ijọba ti kọ lati ri si eto aabo Oluwo ti ilu Iwo, Ọba Abdulrasheed Adewale Akanbi, ti sọ pe oun ti ṣetan lati daríi ifẹhonuhan lodi si ipaniyan ati iwa ibajẹ ti o gbode kan lorilẹ-ede Naijiria.
Ó ṣeéṣe kí a pàṣẹ òfin Kónílé-ó-gbélé tuntun láìpẹ́ - Ìjọba ìpínlẹ́ Ekiti Àwọn ọlọ́pàá kò kọbiara si ọ̀rọ̀ ìwà ipá lásìkò ìgbéle Covid -19 ni ìwà ipá ṣe pọ̀ - Ajàfẹ́tọ obìnrin Àwọn 'ẹ̀bùn' tí ikú George Floyd fún àgbáyé Ìmọ̀ràn márùn ùn láti ẹnu olùkọ́ni tó fakọyọ lágbàyé lórí kíkọ ọmọ lásìkò yìí Eeyan 4,351 lo ti ri iwosan gba, nigba ti awọn 382 ti papoda nitori arun ọhun.
Aláàfin gbé àṣẹ kalẹ̀ láti dènà àtúnṣẹ̀ ìṣẹ̀lẹ̀ 'Soka'nílùú Ọ̀yọ̀ Ọjọ́ tí inú mi dùn jùlọ láyé lọjọ́ tí mo gba físà Amẹ́ríkà- Sanyeri Ètò ìsìnkú Abba Kyari tako ìlànà ìjìnàsíraẹni lórí ààrùn covid-19- Àwọn ọmọ Nàìjíríà yarí Kò yẹ kí ààrẹ fi ìlú silẹ̀ láì gbé ìjọba lé ẹnikẹ́ni lọ́wọ́ -Agbẹjọ́rò Kíni àwọn ojúṣe olórí àwọn òṣìṣẹ́ ààrẹ̀ Nàìjíríà?
Emeka Agaba - Ọmọ ẹgbẹ́ O ní adelé alága APC yóò maa ṣàfilọ́lẹ̀ àwọn ọmọ ìgbìmọ̀ méjèèjì ní olú ilé ]ẹgbẹ́ ni ilú Abuja ní aago mẹta ọ̀sán ọjọ́ Ẹti, ọjọ́ kẹtàdinlógun, oṣù keje, ọdun 2020 Mi ò tíì gba ìwé ìfitónilétí pé wọ́n fẹ́ yọ mí nípò- Igbákejì gómìnà ìpínlẹ̀ Ondo Oríṣun àwòrán, @RotimiAkeredolu Igbakeji gomina ipinlẹ Ondo, Agboola Ajayi ti sọ pe oun ko tii gba iwe ifitonileti pe ile igbimọ aṣofin ipinlẹ ọhun fẹ yọ oun nipo.
Ajo eleto-ilera lagbaye, World Health Organisation (WHO) ti ro awon adari orile-ede lagbaye lati mu ileri ti won se se, lojuna ati mu igberu ba eto-ilera fun gbogbo eniyan lasiko ti won n fowosi iwe adehun erongba elegberun odun ni odun 2015Ajo WHO pe ipe yii ninu atejade kan saaju ayeye isami ayajo adorin odun ajo naa ti yoo waye lojo keje osu kerin odun 2018.
Awọn ọdọ naa ko jẹki ọkọ lọ tabi ki wọn kọja lọ si ibi kankan, oju kan naa ni gbogbo wọn fi ọkọ wọn silẹ loju popo.
Ọlọ́pàá kọ́ lo pa olórí àwọn ''One Million Boys'' Ebila n'Ibadan- Ọ̀gá ọlọ́pàá Oyo Kí ló fa ìjà láàrin Wunmi Toriola àti Seyi Edun?
Bakan naa ni wọn fẹ ki ile ẹjọ o paṣẹ fun ajọ INEC lati yọ orukọ Buhari kuro gẹgẹ bi oludije ẹgbẹ oṣelu All Progressives Congress, APC.
ó wọ aṣọ aláràbarà, a mú un lọ sọ́dọ̀ ọba,pẹlu àwọn wundia ẹlẹgbẹ́ rẹ̀ tí wọn ń sìn ín lọ.
Eyi ni koko ohun to fa ifẹhonu naa han ti o si ti iṣu ata yanyan.
Gbogbo owó tí ó kó jẹ ni ó tún ń pọ̀ jáde;Ọlọrun ní ń pọ̀ wọ́n jáde ninu ikùn rẹ̀.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Alagbafọ ko le ṣai ṣere eti odo Tinubu: Kò ṣéèṣe fún aláǹgbá láti bá ẹtu jà Àjínigbé tó mu Tramadol tojú orun dójú ikú Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Bimpe: Èèyàn bíi tiyín ni àfín, ẹ dẹ́kun dídẹ́yẹsí àfín Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, SMS alert: Wo ọ̀nà láti dẹ́kun jìbìtì lórí àṣùwọ̀n báǹkì rẹ Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Ṣaaju nigbati igbẹjọ naa ṣẹṣẹ bẹrẹ lowurọ ọjọ Iṣẹgun ni adajọ ti yọnda fun agbẹjọro naa ko ṣe gaafara fun awọn ninu ile ẹjọ nigba tọrọ fẹ di aawọ laarin oun atirẹ.
Bí ẹnìkan bá ṣe aládùúgbò rẹ̀ léṣe, tí ó sì di ohun àbùkù sí i lára, ohun tí ó ṣe sí aládùúgbò rẹ̀ ni kí wọ́n ṣe sí òun náà.
Awọn sẹnetọ tuntun ọgọrun o le mẹsan ti bẹrẹ pada lati lo ilana idibo onibonkẹlẹ lati dibo fun ẹni to wu wọn gẹgẹ bi igbakeji ile igbimọ aṣofin agba.
Oun yoo ṣiṣẹ pọ pẹlu awọn agbofinro lati mu eto abo gbopọn sii.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Gẹgẹ bi awọn kan ṣe sọ, lara akitiyan Biden lati wọle ni bo ṣe yan obinrin to jẹ alawọm dudu gẹge bi igabkeji rẹ, iyẹn Kamala Harris.
Keshi, to jẹ adiẹyinmu fun ikọ Super Eagles tẹlẹ ri, ṣoju orilẹ-ede Naijiria ninu idije ife ẹyẹ Ilẹ Afirika lẹẹmẹrin ati ife ẹyẹ agbaye lẹẹkan l'ọdun 1994.
Èyí rí bẹ́ẹ̀, gẹ́gẹ́ bí ó ti wà ninu ìwé ọ̀rọ̀ wolii Aisaya pé,“Ohùn ẹni tí ń kígbe ní aṣálẹ̀ pé,‘Ẹ la ọ̀nà fún Oluwa,ẹ ṣe ojú ọ̀nà tí ó tọ́ fún un láti rìn!
Àkọlé àwòrán, Nnkan ọkunrin ti obinrin ge jabọ Ninu ibẹru ṣi ni Juanita wa, to fi lọ fi ọrọ naa to awọn ọlọpaa leti.
Ile ẹjọ naa pasẹ fun gomina naa lati da gbogbo nkan pada si bose wa tẹlẹ ki igbẹjọ fi le waye lori igbesẹ gomina to yan Emir tuntun.
Aworan ise akanse ohun ni kikun:.
OLUWA ní n óo bí ọmọkunrin kan tí ìjọba rẹ̀ yóo jẹ́ ìjọba alaafia, ó ní òun óo fún un ní alaafia, gbogbo àwọn ọ̀tá rẹ̀ yíká kò sì ní yọ ọ́ lẹ́nu.
O ni, o jẹ ohun to ba ijọba ninu jẹ pe awọn agbofinro lo n ru ofin ti ijọba gbe kalẹ lori ọkada ati kẹkẹ maruwa nipinlẹ ọhun.
Ọkunrin náà pada lọ sọ fún àwọn Juu pé, Jesu ni ẹni tí ó wo òun sàn.
Efuroni alára wà ní ìjókòó pẹlu àwọn ará Hiti yòókù, lójú gbogbo àwọn ará ìlú náà ni ó ti dá Abrahamu lóhùn, ó ní, 
Bẹẹ ni ọrọ naa ri pẹlu abule kan ni orilẹede India, ti wọn n pe ni Kong Thong, to wa nilu Meghalaya.
william john harper ( Ọjó kejìlélógún oṣù keje Ọdún 1916 - Ọjó kẹjọ oṣù kọkànlá ) jẹ ́ olóṣèlú , agbaṣẹ ́ ṣisẹ ́ , àtí awakọ ̀ òfúrufú ológun royal air force tí ó jẹ ́ ìránṣẹ ́ óṣèlú ilẹ ̀ rhodesia láti ọdún 1962 sí 1968 tí ó tọwọ ́ bọ ìwé tí ìlú náà fí gba òmìnira lati ọwọ ́ gẹ ̀ ẹ ́ sì ní ọdún 1965 .
Kọ́kọ́ fọ inú ife ná, òde rẹ̀ náà yóo sì mọ́.
Ẹgbẹ́ òṣìṣẹ́ ìpínlẹ̀ Ọyọ bẹ̀rẹ̀ ìyanṣẹ́lódì aláìní gbèdéke Àwọn àdúgbò Ibadan gborúkọ tuntun látẹnu Ajimobi Seyi Makinde, yé é sọ̀rọ̀ mi láìdà - Gomina Ajimobi Children's Day: Àwọn ọmọdé tó ń ṣe bẹbẹ láwùjọ Afíríkà Lara awọn ohun to fa a ti awọn oṣiṣẹ naa fi yanṣẹlodi gẹgẹ bi Titilọla-Sodo ṣe sọ ni ajẹsilẹ owo oṣu ati owo ifẹhinti awọn oṣiṣẹ fẹhinti, eyi toto ọgọta billiọnu Naira.
Ẹgbẹ oselu mejeeji lasiko ti wọn n ba BBC Yoruba sọrọ ni ẹgbẹ oselu APC ati PDP lọ n fa wahala, nitori naa ko tọ, ki wọn fagile iwọde fun gbogbo ẹgbẹ oselu to ku.
(Wọ́n fi pákó bo àwọn fèrèsé náà).
Zlatan: Èyí mo ṣé tó, àsìkò tó láti tèsíwájú nínú ìrìnàjò mi Òjò ló lè mú kí ìtànkálẹ̀ àrun ìgbẹ́ ọ̀rìn má tètè dópin ni Eko- Iléeṣẹ́ ìlera Ta ni Ken Saro-Wiwa tí ìjọba ológun sekúpa?
Àwọn tí wọ́n bọ́ lọ́wọ́ idà, rí àánú OLUWA ninu aṣálẹ̀;nígbà tí Israẹli ń wá ìsinmi,
Ọlọ́gbọ́n ọmọ a máa mú inú baba rẹ̀ dùn,ṣugbọn òmùgọ̀ ọmọ níí kẹ́gàn ìyá rẹ̀.
Jesu kò fẹ́ kí ẹnikẹ́ni mọ̀, 
Orúkọ iwin burúkú yìí ni Ìbínú-ẹkùn tíí ṣe ìbátan Ìgbéraga-Ìbànújẹ́ ní ìdí ìya Ìbínú-ẹkùn ni ẹni tí ó lè bínú jùlọ láàrin ohun gbogbo ti ń bẹ lójú omi tàbí ní ìsàlẹ́ ilẹ̀, tí ó wà lófuurufú tàbí ní ìyàngbẹ ilẹ̀.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ẹ dín agbára ìjọba àpapọ̀ kù, kẹ ṣì ṣe àgbékalẹ̀ ọlọ́pàá ìpínlẹ̀ - Tinubu bẹ̀bẹ̀ Wo ìdí tí ààrẹ Buhari kìí fi ṣe ẹ̀dà Jubril láti Sudan Wo eyi to súnmọ́ ọ nínú àwọn ibùdó 203 fún ìforúkọsílẹ̀ fún NIN rẹ Adigunjalè méjì ko ìjàmbá ọ̀kadà lẹ́yìn ìṣẹ́ ibi n‘Ibadan, ọ̀kan kú lójijì, aráàlú dáná sun èkejì Àwọn ohun kàyéèfì tó le mú kí ọmọbìnrin ní oyún ìju Ìrẹ̀sì kò gbọdọ̀ wọlé níbáyìí ta ṣí ẹnu bodè padà - Ìjọba àpapọ̀ Jide Kosoko forin sẹ́nu pé òun ni igi lẹ́yìn ọgbà Mr Latin lórí ipò ààrẹ TAMPAN tó wà Ó pé ọdún mẹ́wàá tí Barrister kú; wo ǹkan tó yẹ láti mọ̀ nípa rẹ̀ gẹ́gẹ́ bíi olórin, tẹ̀wé-tẹ̀wé, akọ̀wé àti sọ́jà Àìmọ̀kan ló mú mi hu ìwà tí mo hù kọjá sẹ́yìn, Jonathan dárí jì mí - Dino Melaye Nigba ti wọn n foju rẹ han faye ri, EFCC ni oniruuru ọgbọn arumọjẹ ni Jamiu ti fi gba oyinbo Koraa naa, ti orukọ rẹ n jẹ, Keun Sig Kim lati orilẹede South Korea.
Fún un ninu iṣẹ́ rẹ, kí àwọn ọmọ Israẹli lè tẹríba fún un.
"O ni ka tilẹ gba pe gomina ti bẹrẹ saa rẹ daadaa, ""fun emi o, mo ro pe o ti ya ju."
0 27 Erekusu Kitts and Nevis 0 0.
anfaani naa lati ro awon adari won, ki won so fun awon eniyan won lati maa gbe
1 684 Orilẹede Comoros 7 0.
Ẹwẹ, ọga agba ileeṣẹ ọkọ ofurufu ni Naijiria (FAAN), Rabiu Yadudu sọ pe lilọ bibọ baalu silẹ okeere to gberasọ pada ni Naijiria tẹ oun lọrun.
Awọn ikọ to lọ South Africa fidiẹ mulẹ fun Aarẹ Buhari pe orilẹ-ede South Africa ko ni akọsilẹ odiwọn iye awọn ti ikọlu naa kan.
" Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, COZA: Ọpọ èrò ló jáde ṣe lòdì sí ẹ̀sùn ìfipábánilòpọ̀ Fatoyinbo Iwadii ẹgbe PFN lo waye nitori awuyewuye awọn eniyan ati awọn oniroyin lori ẹsun naa.
Eyi lo mu ki wọn ran awọn ọmọ ogun pupọ lọ sibẹ lẹyin idibo to gbe oludije APC ati PDP jade lọpọlọpọ.
 Aṣofin Ọbasa tun fi kun ọrọ rẹ bayii.
Ju gbogbo rẹ̀ lọ, ẹbí náà ń gbìyànjú láti má fèsì sí àtẹ̀jáde kankan èyí tó ti ń jà kálẹ̀ láti ìgbà tí ọmọ ọdún kan ọmọ D'banj, Daniel Oyebanji kẹta ti dákẹ́.
Bí mo bá fẹ́ fọ́nnu, kò ní jẹ́ ọ̀rọ̀ aṣiwèrè ni n óo sọ; òtítọ́ ni n óo sọ.
Gẹ́gẹ́ bí ìṣe rẹ̀, nígbà tí ó di ọjọ́ ìsinmi, ó lọ sí ilé ìpàdé.
Lójú yín ni mo wádìí ọ̀rọ̀ lẹ́nu rẹ̀, tí n kò sì rí àìdára kan tí ó ṣe, ninu gbogbo ẹ̀sùn tí ẹ fi kàn án.
Lọjọ Aje ni ina deede sọ ninu ile ijọsin naa ni Paris.
Ko si idi meji ti iroyin naa fi lu oju opo ayelujara pa ju pe orukọ awọn ilumọọka ọlọpaa meji kan wa nibẹ.
sibẹsibẹ oúnjẹ rẹ̀ a máa dà á ninu rú,ó sì ti dàbí oró ejò paramọ́lẹ̀ ninu rẹ̀.
Niseju merin gbara ti saa keji bere, Koke tun se iranwo ami-ayo miiran fun Griezmann, bee si ni,  Gabi gba ami ayo miiran wole lati so apapo esi ifesewonse ohun di meta sodo(3-0).
Pẹlu eyi, o da mi loju pe awọn obinrin yoo le jade lati fi ẹsun ilọkulọ ibalopọ sun Ọna abayọ si fifi ilọkulọ lọ awọn obinrin elere ori papa Alatẹjade lori ẹrọ ayelujara nipa ere bọọlu lorilẹede Naijiria, China Acheru sọ fun akọroyin BBC, Busayọ Iruemiobe wipe oun gbagbọ wipe iru ayipada to nsẹlẹ loke okun yii ma nira lorilẹede Naijiria nitori asa wa ati igbe aye wa ti fi awọn ọkunrin si ipo akọkọ ti wọn si le se ohun to wu wọn sugbọn awọn obinrin, ẹyin ni wọn wa."
Mo fẹ́ kí ẹ mọ̀ dájúdájú pé bí ẹ bá ní igbagbọ tí kò ju wóró musitadi tí ó kéré pupọ lọ, tí ẹ bá sọ fún òkè yìí pé, ‘Kúrò níbẹ̀,’ yóo sì kúrò.
Kekere ninu agbami ọrọ wa ni awọn apẹrẹ ti Toke Makinwa ka silẹ yii tori ṣe ni awọn eniyan gba a lẹnu rẹ ti wọn si bẹrẹ si ni wu iriri tiwọn naa sita.
Nítorí mo ti gba àyà tí a fì ati itan tí a fi rúbọ lọ́wọ́ àwọn eniyan Israẹli lára ọrẹ ẹbọ alaafia wọn, yóo sì jẹ́ ti Aaroni, alufaa, ati àwọn ọmọ rẹ̀.
Botkilẹ jẹ pe o ni ti ijọba ṣeleri fun wọn lati maa ṣe bẹẹ, ṣugbọn ko si iyatọ kankan ti wọn ri lẹyin ti wọn ti gọ ọpọlọpẹ iwe ẹdun.
Ṣugbọn ẹ fi ààyè fún Kristi ninu ọkàn yín bí Oluwa.
Presidential inauguration #presidentialinauguration today Wednesday, 29th May 2019 at the Eagles Square Abuja.
awon iwadii eleyii to fi ise ibi ti awon afurasi odaran ohun ti a mo si
@BashirAhmaadCopyright: @BashirAhmaad Article share tools Facebook Twitter ṢàpínlòView more share options Share this post Copy this linkKà síwájú síi nípa àwọn ìtọ́kasí wọ̀nyí.
Igbakeji ọ̀gá fasiti UNN, Ọjọgbọn Charles Arizechukwu Igwe ti wa ṣẹ kan lẹ pe ko s'ohun to jọ iru iṣẹlẹ bẹ ẹ ni fasiti naa.
Iyaafin Ajoke soro yii nibi ifilole ile ikawe-yawe ti iyaafinEugina Abu sedasile re niluu Abuja.
5bn (£980m) Iwe iroyin nipa ọrọ aje, iyẹn Forbes Magazine so pe biliọnu dola kan le diẹ ni ọrọ Mohammed ti o si jẹ wi pe oun nikan lo ni owo to to bẹ ni Tanzania.
" Àwọn ọmọ Naijiria sọ Ahmed Musa di àkúnlẹ̀bọ Ahmed Musa gbéré bọ́ọ̀lù lọ Saudi Arabia Ahmed Musa gbéré bọ́ọ̀lù lọ Saudi Arabia Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Obasanjo: Atiku kìí se Áńgẹ́lì, àmọ́ yóò se dáadáa ní ìlọ́po méjì ju Buhari lọ O ti sọ tẹlẹ pe iya oun ṣaarẹ ko to di pe o ku.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Osinbajo yẹ́ Woli Arole sí níbi ìṣíde The Call"" Ninu itan yii, Jesu sọ fun awọn ọmọ ẹhin rẹ pe bi oun ti o jẹ olukọ wọn ba le ṣe eyi, o yẹ ki awọn naa ṣe e fun ara wọn."
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Odumakin sọrọ lori Fulani darandaran Ogagun agba Zakari Abubakar to jẹ adari ikọ ọmọ ogun ni ẹkun yii ṣalaye pe awọn ẹrọ yii a maa ṣiṣẹ laarin ipinlẹ mejeeji tọrọ kan ni Ọ̀gá àgbà FRSC Ondo jáde láyé Àwọn adigunjalè pa èèyàn mẹ́fà ní báńkì kan nìpínlẹ̀ Ondo Fayẹmi sèbúra l‘Ekiti, àwọn èèkàn ìlú péjú Kí ló sẹlẹ̀ sí àwọn àlùmọ́ọ́nì tó wà n'ípínlẹ̀ Ondo?
Bakan naa ni awọn kan ṣalaye pe oniruuru aṣemaṣe bii jibiti ati riba gbigba lawọn ọmọ Naijiria n dojukọ labẹ eto naa.
Sunday Igboho yarí, ó fohùn ránsẹ́ sáwọn èèyàn tó ń pẹ̀gàn rẹ̀ Aàrẹ Buhari buwọlu yíyí orùkó àwọn ibùdókọ ọkọ ojú ìrìn bíi ti Apapa padà fi sọrí àwọn èèkàn ìlú Ileesẹ ijọba apapọ to n risi igbokegbodo ọkọ ati eto irinna ni Naijiria ti fi atẹjade kan sita.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Lanko Adeọla Ṣorẹmi: Ọlọrun nìkan ló ń bá wa to ilé wa Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Lanko Adeọla Ṣorẹmi: Ọlọrun nìkan ló ń bá wa to ilé wa 6 Owewe 2018 Adeọla Ṣorẹmi ti gbogbo ènìyàn mọ̀ sí Princess Lanko ti bu ẹnu àtẹ́ lu kí àwọn òṣèré má máa ráyé fún ẹbí wọn léyìí tó ni òun náà jẹ́ ọ̀kan.
Ọmọ ọdún mẹ́rìnlá kàwé gboyè jáde ni Oxford N650,000 péré ni mò ń gbà gẹ́gẹ́ bíi owó oṣù -Gomina Ọyọ BBC ba ara ile, ọrẹ, ojulumọ ati awọn agbofinro sọrọ lori iṣẹlẹ kayeefi yii to gba ẹmi odindin iyale ile.
 ( ojoibi september 25 , 1968 ) je osere , olootu , rapper , alawada ati ako-orin ara amerika .
Olukọ wa lọsẹ yii, Arabinrin Funke aya Falade-Young si ti wa nikalẹ lati kọ wa nipa orisirisi asa iran ara ẹni lọwọ to wa ati anfaani wọn.
Lẹyin iṣẹju diẹ lo figbe inu rirun sẹnu ti wọn si gbe e digba digba lọ ile iwosan ti ile iwe naa nibi ti nọọsi ti sare bojuwo ki lo ṣẹlẹ gan si Favour.
Àwọn ọmọ Reubẹni ati Gadi sì dá Mose lóhùn, wọ́n ní, 
O ni  lati odun 2015 ni ijoba  orile ede Naijiria ti n se gudugudu meje .
“Nítorí pé òfin tí mo fun yín lónìí kò le jù fun yín, kì í sìí ṣe ohun tí apá yín kò ká.
Ni agbegbe Agọ Palace, Ọkọta nilu Eko, rogbodiyan to waye nibẹ mu ẹmi eeyan kan lọ, ti ọ̀pọ ibo ti wọn di lawọn agọ idibo to wa nibẹ si sofo.
Ilẹ̀ náà tẹ́jú, ó parọ́rọ́, alaafia sì wà níbẹ̀; àwọn ọmọ Hamu ni wọ́n ti ń gbé ibẹ̀ tẹ́lẹ̀ rí.
Gbogbo àwọn agbára tí ó wà ní ọ̀run ni a óo mì jìgìjìgì.
Àwọn ọmọ Nàìjíríà ṣe ìwọ́de l'Osogbo lórí àfikún owó epo bẹntiróò Ọwọ́ ọlọ́pàá tẹ afurasí olóògùn owó tó fẹ́ gé ọmú obìnrin kan nílé ìtura Oríṣun àwòrán, @allwell Ṣaaju lọsẹ yii ni Ademola Allwell naa ti sọrọ lori ọjọ ibi rẹ pe: Ìdí tí mo fi ń ṣe ayẹyẹ ọjọ́ ìbí 35 lọ́dọọdún rèé- Allwell Ademola Gbajugbaja oṣere to tun n kọrin ni Allwell Ademola ni ọpọ eeyan n sọrọ lori ayelujara latari ayẹyẹ ọjọ ibi ọdun marundinlogoji lọdọọdun.
Bí àjèjì kan tí ń gbé ààrin yín, tabi ẹnikẹ́ni tí ó wà láàrin yín bá fẹ́ rú ẹbọ sísun, tí ó jẹ́ òórùn dídùn sí OLUWA, irú ẹni bẹ́ẹ̀ yóo tẹ̀lé ìlànà tí mo fi lélẹ̀ fun yín, ìlànà yìí yóo wà fún ìrandíran yín.
"Oríṣun àwòrán, Yinka Ayefele ""Ọdun mẹjọ ti Abiola Ajimobi lo gẹgẹ bii gomina nipinlẹ Oyo lo fi tun ilu se."
Ninu ikede ti Ajọ to n gbogun ti ajakalẹ arun lorilẹede Naijiria, NCDC fi sita ni oju opò ikansiraẹni Twitter wọn ni wọn ti fi lede bẹẹ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ilé Aṣòfin Eko: A fẹ́ mọ̀ bí Ambode ṣé nà ₦45b tó fi ra BRT 28 Ògún 2019 Oríṣun àwòrán, Lagos Eye News Igbimọ ti Ile Aṣofin ipinlẹ Eko gbe kalẹ lati ṣe iwadii lori bi Gomina ana nipinlẹ naa, Akinwunmi Ambode, ṣe na owo lati ra ọkọ akero BRT, ti wi pe, iwadii wọn kii ṣe lati dẹyẹ si gomina ana ọhun.
Ile ẹjọ to gajulọ ni Naijiria ti dajọ lọjọ Ẹti pe ki gomina nigba kan, Jolly Nyame o lọ si ẹwọn ọdun mejila.
Bawo ni Amina Zakari ṣe tan mọ Buhari?
Ninu isiro owo dọla kọọkan ti wọn ba na lori ilera,nnkan bi ida mẹta owo naa ni awọn alaisan fun ara wọn ma n na lati inu apo wọn ti ijọba si n na ida kan pere ninu rẹ.
Jallow sọ pe aarẹ gba oun ni eti, o si tun gun un ni abẹrẹ kan ni apá.
"Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Prince Malik Ado Ibrahim: Wo bí Adama Indimi àti Prince Malik Ado ọmọ Ọba Ohinoyi ilẹ Ebira ṣe fa ayélujára ya 10 Ògún 2020 Oríṣun àwòrán, Instagram Ileeṣẹ BBC ri i ko jọ kaakiri pe Adama Indimi to jẹ ọmọ ọlọrọ to ni ileeṣẹ ""Oil Magnate, Mohammed Indimi ṣẹṣẹ fẹ ọmọkunrin akọkọ Ọba Ohinoyi ti ilẹ Ebira nipinlẹ Kogi, Ọmọwe Ado Ibrahim."
Ẹ wo, ilẹkun yii fidi rẹ mulẹ.
O bu enu ete lu ipa ti asa ti ise Yoruba nko nipa gbigboriyin fun ode aperin laye atijo, eyi ti o sapejuwe gegebi ohun atijo ti ko bojumu ati eyi ti o lodi sofin igbalode.
Laipẹ yii ni awuyewuye waye lori esi idanwo WAEC ti Buhari ṣe nigba to pari ileewe girama.
Kò sí ẹyọ kan ninu wọn tí wọ́n fi fadaka ṣe, nítorí pé fadaka kò já mọ́ nǹkankan ní àkókò Solomoni.
Nítorí pé kì í ṣe ẹ̀yin ni ẹ gbé e lákọ̀ọ́kọ́, OLUWA Ọlọrun wa jẹ wá níyà, nítorí pé a kò tọ́jú rẹ̀ bí ó ti tọ́.
Ìjọba gbé ilé ijó oníhòhò tì pa lórí ẹ̀sùn títàpá sí ìlànà àti dẹ́kun coronavirus Ilé aṣòfin Amẹ́ríkà yọ ààrẹ Donald Trump nípò fún ìgbà kejì Ìdí mẹ́fà rèé tí Instagram, Facebook le fi wọ́gilé ojú òpó ìkànsíraẹni rẹ Ìdí tí àwọn èèyàn kan kò fí le ni àrùn Coronavirus Gomina makinde sisọ loju ọrọ yii lasiko to n se ipade akọroyin lori arun Coronavirus ati eto aabo ipinlẹ Oyo.
Ó rán ẹyẹ ìwò kan jáde.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Osogbo Photographer: O gbọdọ ni ìmọ iṣẹ náà, o kere tan ọdun mẹwàá, ti abadofin náà si kan kọmisona ọlọpàá ipinlẹ náà àti adele ilé iṣẹ́ ọmọogun.
Ẹni to ṣe e ṣe ko pilẹ ọrọ naa lori Twitter, Bowale @Son_of_a_O, sọ pe oun n wo isin Shiloh lori ayelujara ni alẹ Ọjọru.
Nigeria Police Recruitment 2020: Àwọn ohun tí ẹ nílò fún àyẹ̀wò ìgbanisíṣẹ́ ọlọ́pàá tí yóò bẹ̀rẹ̀ ní Mon, Aug 24 Ó ṣéeṣé ká fí owó kún #500,000 owó móríya ti a fi ń wá Sunday Shodipe- Ilé iṣẹ́ ọlọ́pàá Majek Fashek tí wọ káà ilẹ̀ lọ!
Ki Ọlọrun Olodumare o fi ọrun kẹ wọn.
"Oríṣun àwòrán, CBN Àkọlé àwòrán, Igbesẹ owona tuntun ""Igbesẹ yii ti bẹrẹ ni ọjọ iṣẹgun, gbogbo ẹni to ba ni owo idọti lee lọ bẹrẹ si ni parọ rẹ si tuntun"" Okoroafor ṣalaye."
Ninu atẹjade ti Gomina Akeredolu fi lede lati ọwọ akowe eto iroyin rẹ, Arakunrin Segun Ajiboye to sọ pe gbogbo agbegbe to wa ni ipinlẹ Ondo ni awọn yoo ri daju pe awọn ṣe idaabobo to peye fun.
Awọn oṣiṣẹ kan kan daṣẹ silẹ, bẹẹ lawọn mii ti lugbadi arun naa iha ila-oorun Cape Town, ko da, awọn nọọsi kan funra wọn lo n gbalẹ, awọn to n ṣiṣẹ abẹ lo n fọ aṣọ ti wọn n wọ, bẹẹ la tun gbọ iroyin pe ọpọ awọn alaboyun kun ẹka ti wọn ti n bimọ ti ko si si ẹni ti yoo da si wọn.
Bi alẹ ọjọ igbeyawo Somayya se ri ree nigba ti ibale ko se ẹjẹ: Somayya ja fitafita pẹlu awọn obi rẹ lati ri pe o fẹ Ibrahim, tii se ololufẹ rẹ nile iwe fasiti tori pe o dara lọmọkunrin, to si ni amuyẹ ọkọ rere.
lagbegbe ohun ati bi won ko se ri itoju ti o peye gba”.
N óo sọ òkùnkùn di ìmọ́lẹ̀ níwájú wọn,n óo sì sọ àwọn ibi tí ó rí pálapàla di títẹ́jú.
Oríṣun àwòrán, Instagram/gloriabamiloye Bakan naa ni gbajumọ osere tiata ti ẹmi naa ni oun ko da ijọ kankan silẹ o.
“Bí ẹnìkan bá fi owó tabi ìṣúra kan pamọ́ sí ọwọ́ aládùúgbò rẹ̀, tí olè bá gbé e lọ mọ́ aládùúgbò rẹ̀ yìí lọ́wọ́, bí ọwọ́ bá tẹ olè yìí, ìlọ́po meji ohun tí ó gbé ni yóo fi san.
Oríṣun àwòrán, Kubrat Pulev Twitter Àkọlé àwòrán, Pulev fi atẹjade sita loju opo Twitter Iṣẹlẹ ifipafẹnukọonilẹnu yi waye lẹyin igba ti Pulev na Bogdan Dinu ọmọ orileede Romania ni Costa Mesa nilu California lọjọ abamẹta Ninu atẹjade kan ti o fi sọwọ lasiko to n ba awọn akọroyin sọrọ Ravalo ni ohun ti Pulev ṣe ''doju ti oun'' ti o si ''mu abuku ba oun'' Ravalo salaye pe ''nigba ti a n ṣe ifọrọwanilẹnuwo lo ṣadede bu mi so ti o si fi ipa fẹnuko nu mi.
O ni o ṣeni laanu pe, bi igba ti eeyan n ta tẹtẹ ni ilana ọrọ aje ti Naijiria n lo, kii ṣe eto to ṣe e tọka si.
Ẹni tí ó bá gba agbádá yín, ẹ má ṣe du dàńṣíkí yín mọ́ ọn lọ́wọ́.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Emmanuel Adebayor: Agbábọ́ọ̀lù Togo rántí ìṣẹ̀lẹ̀ tó wáyé lásìkò AFCON 2010 8 Sẹ́rẹ́ 2020 Oríṣun àwòrán, Getty Images Ọjọ buruku eṣu gbomi mu, oni ọjọ kẹjọ oṣu kinni ọdun 2020 lo pe ọdun mẹwaa tawọn agbebọn kan kọlu awọn agbabọọlu ilẹ Afirika lorilẹede Angola.
“Nígbà tí ọba wọlé láti wo àwọn tí wọn ń jẹun, ó rí ọkunrin kan níbẹ̀ tí kò wọ aṣọ igbeyawo.
 Nigba ti awon miran ti seto eko ofe lorisiirisii fawon akekoo nipele eko”Bakna naa ni Osinusi gboriyin fawon to n pese itanlowo fun ayeye odun ojude Oba bii Globacom ati First City Monument Bank Plc atawon mii lori ipa ti odun naa n ko lori asa ati ise Yoruba.
Nígbà tí àwọn ará Siria rí i pé, àwọn ọmọ ogun Israẹli ti ṣẹgun àwọn, wọ́n kó gbogbo àwọn ọmọ ogun wọn jọ.
Ààlà ilẹ̀ wọn ní apá ìlà oòrùn bẹ̀rẹ̀ láti Atarotu Adari, títí dé apá òkè Beti Horoni.
Ẹ gbọdọ̀ fi ọ̀dọ́ aguntan ra gbogbo àkọ́bí kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ yín pada, bí ẹ kò bá sì fẹ́ rà wọ́n pada, dandan ni pé kí ẹ lọ́ wọn lọ́rùn pa.
Tí a fiṣọwọ́ ní 12:0612:06 Jubril Martins-Kuye ti jáde láyé Martins-Kuye ti fi igba meji di ipo minisita mu lati igba ti iṣejọba tiwantiwat ti bẹrẹ pada lọdun 1999.
Wò ó, bẹ́ẹ̀ ni OLUWA yóo kẹ́ ẹni tí ó bẹ̀rù rẹ̀.
Sísun ni kí ẹ sun gbogbo àwọn ère oriṣa wọn; ẹ kò gbọdọ̀ ṣe ojúkòkòrò wúrà tabi fadaka tí ó wà lára wọn.
Ohun ti awọn eniyan maa n saaba ranti ti wọn ban sọ itan jija fun ijọba tiwa n tiwa ni ọna aburu ati ailaanu ti wọn gba pa arẹwa akinkanju obinrin to jẹ iyawo Abiola.
Ènìyàn 653 míràn tún kún iye àwọn tó ní COVID-19 ní Nàìjíríà Ilé Aṣòfin yóò pe Godswill Akpabio l'ẹ́jọ́ fún ìbanilórúkọ jẹ́ Kí ló pa Bobrisky àti Olorì Aláàfin Oyo pọ̀?
Ranti pé nítorí rẹ ni wọ́n ṣé ń fi mí ṣẹ̀sín.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Revolution Protest: Wámú-wámú ni àwọn òsìsẹ́ aláàbò dúró nibí tí ìwọ́de Revolution Now ti fẹ́ wáyé 5 Ògún 2019 Àwọn ọlọ́pàá sọ pé ìwọ́de Revolution Now jẹ́ ìdìtẹ́ mọ́ ìjọba orílẹ̀èdè Nàìjíríà.
ipinle Bauchi ayafi ijoba ibile Tafawa Balewa  (LGA) ti ẹjọ rẹ wa nile ẹjọ.
Aaroni ati àwọn ọmọ rẹ̀ gbé ọwọ́ wọn lé e lórí.
Ṣe òfintótó/ ṣe ìwádǐ láti mọ kúlẹ̀kúlẹ̀ ọ̀rọ̀
Ọlọ́run, Ọlọ́run gbà mí o; lọ́wọ́ Òjòlá-ìbínú, gbà mí o, Ọlọ́run, Ọlọ́run gbà mí o; lọ́wọ́ ọlọ́pàá ejò, gbà mí o, Ọlọ́run, Ọlọ́run gbà mí o; lọ́wọ́ ìtìmọ́lé ọ̀sán gangan, gbà mí o, Ọlọ́run, Ọlọ́run gbà mí o.
Ojiṣẹ Ọlọrun naa woye pe, awọn alaṣẹ ijọba lo n tiwọn lẹyin, bibẹẹkọ wọn o ba ti dẹkun ipaniyan.
" Alẹ Ọjọbọ ni iroyin naa jade sori ayelujara.
4m Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Oladeji ní gẹ́gẹ́ bi ìròyìn tó tẹ́ ẹgbẹ́ CAN àpapọ̀ lọ́wọ́, ìjọba apapọ̀ kò fi ìgbà kankan sọ pé ki àwọn ìjọ máse péjú fún ètò ìsìn ìrékọjá sínú ọdún tuntun, sùgbọ́n àwọn ìpińlẹ̀ kan sọ pé, lá kò sí ǹkan tó jọ ọ́.
Wọn wa ri aato atunṣe rẹ bi eyi ti ko to nkan to si pẹ, awọn ara Algeria paapaa ọdọ ko wa ni suuru mọ pẹlu ohun ti wọn ri gẹgẹ bii ipinu rẹ lati lo ilana to lodi si ijọba awa ara wa lati tẹ ẹ pa sori alefa gẹgẹ bi aarẹ lai kuro nibẹ mọ.
Awọn agbebọn kan lo da awọn eeyan to n gbe oku lọ sin naa lọna.
O ni ajọṣepọ laarin LASEMA, ileeṣẹ irinna oju omi nipinlẹ Eko, ẹka ileeṣẹ ọlọpaa ori omi, ileeṣẹ ọlọpaa oriilẹ, ileeṣẹ panapana pẹlu awọn omuwẹ lagbegbe naa ni iṣẹ awari awọn eeyan to da somi naa jẹ.
mọnyan lori rẹ, ni eyi ti awon oga ile-isẹ ọlọpaa to n gbogun ti iwa odaran ati
Ẹ̀jẹ̀ àwọn talaka tí kò ṣẹ̀, wà létí aṣọ yín;bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò bá wọn níbi tí wọ́n ti ń fọ́lé.
Jonatani bí ọmọ meji: Peleti ati Sasa.
Oríṣun àwòrán, Twitter/FRSC Àkọlé àwòrán, Ijamba ọkọ A o le sọ boya ẹmi ba isẹlẹ naa lọ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ẹ̀yin ẹ máà wò ó, ó ṣeéṣe kí APC túká lẹ́yìn ìṣèjọ́ba Buhari!
Bákan náà ni kí àwọn diakoni jẹ́ oníwà pẹ̀lẹ́.
Àkọlé àwòrán, ìpàdé ìfọ̀rọ̀wérọ̀ BBC Yorùbá Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Aare Buhari so pe, a gbodo sise po lati ri pe, a gbegba oroke ninu idibo ohun.
Fun apẹẹrẹ, Ajimobi gba alejo awọn akẹkọọ fasiti imọ ẹrọ Ladoke Akintola nilu Ogbomoso, ti wọn wa fi ẹhonu han lọgba Secretariat, Asiko yii si lo koro oju si akẹkọọ kan lori bo ṣe sọrọ si bii gomina lọna tí ko yẹ, Ajimobi wa beere pe Ṣe Aláṣẹ ti ofin gbe kalẹ (Constituted Authority) lo n sọrọ si baun""?"
Ilé ẹjọ́ kéde Ademọla Adeleke gẹ́gẹ́ bíi gómìnà ìpínlẹ̀ Ọṣun Ademọla Adeleke, Fayoṣe, Atiku sọ̀rọ̀ lórí ìdájọ́ ilé ẹjọ́ Èmi ṣì ni Gómìnà ìpínlẹ̀ Ọṣun-Oyetọla Ṣugbọn abala ẹtalelogoje (143) iwe ofin naa, sọ wipe, ti ile ẹjọ ba ti ri aridaju wipe oludije to wa lori aleefa kọ́ ni ojulowo gomina, ti ẹni naa ba si lọ ile ẹjọ kotẹmilọrun wipe idajọ ile ẹjọ lori esi idibo naa ko tẹ oun lọrun laarin ọjọ mọkanlelogun (21) ti idajọ naa ti waye, ẹni tí ilé ẹjọ ní kìí ṣe ojúlowo gomina naa kò ní fipo silẹ titi di igba ti ilẹ ẹjọ kotẹmilorun ba to da ẹjọ tirẹ.
Ṣugbọn nígbà tí àwọn ará Gibeoni gbọ́ ohun tí Joṣua ṣe sí ìlú Jẹriko ati Ai, 
 Ijamba Ogun ati eto aabo to
Àwọn ọmọ Lodi, Hadidi ati Ono jẹ́ ẹẹdẹgbẹrin ó lé mẹẹdọgbọn (725)
Oríṣun àwòrán, Mike bamiloye/facebook Àkọlé àwòrán, Bayii ni iya Lawrence ṣe fi owo yẹ ọmọ rẹ si, lasiko to n jo nibi eto idana naa Akọrin Kristẹni lawọn mejeeji.
“Ni ipinle Anambra eto iforukosile maa n waye lati ojo Aiku titi di Ojo Abameta lati aago mesan an aaro titi di aago marun un irole, A ni awon  osise ni gbogbo ijọba ibilẹ méjìlélógún to wa ni ipinle naa.
Bẹ́ẹ̀ náàni ènìà á tún máa láti fo àwọn odi kékèké tí àwọn onílẹ̀ kọ́ yí ilẹ̀ wọn po.
Iroyin ni awọn mejeeji ko ja rara ṣaaju iṣẹlẹ naa.
Jesu dá a lóhùn pé, “Ó wà ní àkọsílẹ̀ pé, ‘Oluwa Ọlọrun rẹ ni kí o máa júbà, òun nìkan ni kí o sì máa sìn!
Ẹnikẹ́ni ninu wọn kò ní lè ṣẹgun rẹ.
Audrey Andrews sọ fun iwe iroyin Daily Mail UK oriṣiriṣi ọna ti awọn obinrin fi le mọ pe awọn ti gba itura lasiko ibalopọ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Jiti Ogunye: Ẹgbẹ́ tó ní Asojúsòfin tó pójú ló lè yan Ààrẹ Ilé Asòfin àpapò 28 Ẹrẹ̀nà 2019 Àkọlé àwòrán, Àríyànjiyàn ńlọ nínú ẹgbẹ́ òsèlú APC àti ẹgbẹ́ òsèlú PDP lórí ẹni tí yóò dí Ààrẹ Ilé Asòfin àpapò lórílẹ̀èdè Nàíjíríà.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Coffee Painter: Adebukola ní kò sí ìrànwọ́ lẹ́yìn ẹ̀kọ́ girama lòun ṣe ń ya àwòrán Isẹlẹ yii si lo ti n fa awuye-wuye laarin awọn ọmọ ilẹ Yoruba.
 Aare ni ijoba oun yoo tubo maa
Àwọn olórìṣànlá a máa tọ́ka sí AMÚṢAN gẹ́gẹ́ bí SÀLÀKỌ́.
O wa ro awon eniyan lati tubo lowo ninu ise agbe.
Ikọkandinlogun mú Maloti, òun ati àwọn ọmọ rẹ̀ ọkunrin, ati àwọn arakunrin rẹ̀ jẹ́ mejila.
Wọ́n ń bọ àwọn oriṣa tí wọn kò mọ̀ rí, tí OLUWA kò sì fi lé wọn lọ́wọ́.
"O sọ pe, ""A ti gba iparun oko awọn agbẹ lọna ti eyikeyi iru agbegbe ti ọrọ ba kan ko lee f'arada mọ, eyi ti o si jẹ ohun meeriri fun ọpọlọpọ wọn."
Àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ sọ fún un pé, “Olùkọ́ni, láìpẹ́ yìí ni àwọn Juu ń fẹ́ sọ ọ́ ní òkúta, o tún fẹ́ lọ sibẹ?
Ohun ti awọn baba nla wa se ree, a si gbọdọ dide si ipenija yii, nitori nkan ko sẹnu re rara ni, Tẹ ba si dakẹ, ti ẹ ko dide lati seranwọ fun awọn oloselu lori isẹlẹ yii, a jẹ pe awa gangan jẹ ara isoro naa.
Bẹ́ẹ̀ ni mo pinnu lọ́kàn mi pé bi ó bá ṣe ibẹ̀ ni n ó ti lo ìyókù ìgbésí-ayé mi n ó gbíyánjú àti lò ó tayọ̀tayọ̀, ṣùgbọ́n bí Ẹlẹ́dàá mi bá wí pé kì í ṣe ibẹ̀ ni, ọjọ́ ń bọ̀ tí yóó yọ mí jáde.
Mo lóyun fun un nígbà náà ni àwọn obi rẹ̀ ni mí o le fẹ́ ẹ nitori mo dàgbà jù ú lọ àti pé dàndàn ni ki ó fẹ́ ìyàwó láti abúlé wọ́n.
Ẹ ó bọ́ lulẹ̀ ninu pápá tí ó tẹ́jú.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Expired goods in Nigeria: Jíjẹ tàbí lílo nkan tí ọjọ́ ti lọ lórí rẹ̀ le fa àìsàn tàbí ikú 15 Ògún 2020 Ọjọbọ ni ajọ to n daabo bo ẹtọ awọn onibaara ni Naijiria, FCCPC, ti ẹka ileeṣẹ Apples and Pears Limited pa nilu Abuja.
O ni, “Akinkanju ni awọn oṣiṣẹ orilẹ-ede Naijiria.
Ileeṣẹ yii kan naa lo gba ile fun arakunrin naa.
Ninu awọn fiimu naa ni Mr India, Chandni, ChaalBaaz ati Sadma.
Kii ṣe iroyin mọ pe inira ni fun ọpọ eeyan lati mọ aala laarin ipinlẹ Eko ati Ogun nitori awọn eeyan ti kọle wọnu ara wọn ni ipinlẹ mejeeji.
3 5324 Erekusu Cape Verde 109 20.
Joṣua ni baba Joiakimu, Joiakimu ni baba Eliaṣibu, Eliaṣibu ni baba Joiada, 
Aya gomina ipinlẹ Nassarawa, Silifat Bello, ti wa gbarata lori awọn isẹlẹ ifipabanilopọ nipinlẹ naa, to si n beere fun ijiya to gbopọn fawọn ọdaran naa.
Aṣọ tẹ́ẹ́rẹ́ aláwọ̀ aró ni wọn yóo máa fi bọ inú àwọn òrùka ara efodu ati àwọn òrùka ara ìgbàyà, láti dè wọ́n pọ̀ kí ó lè máa wà lórí àmùrè tí ó wà lára efodu náà, kí ìgbàyà náà má baà tú kúrò lára efodu.
Gẹgẹ bi ọrọ kan to fi sita loju opo Instagram rẹ, Lizzy Anjọrin ni oun ti n foju wina ipenija igbeyawo bayii, paapaa julọ igbeyawo pẹlu ọkọ oun to jẹ ọmọ ilu Ibadan.
, Duration 5,5712 Òkùdu 2020 6:56 Fídíò, Wòlíì Kasali sọ̀rọ̀ nípa awuyewuye pé ó lé ìyàwó rẹ̀ jáde nílé, Duration 6,5628 Ọ̀pẹ̀̀ 2018 BBC News, Yorùbá Ìdí tí ẹ fi le è nígbàagbọ́ nínú ìròyìn BBC Ìlànà Lílò Nípa BBC Òfin Àṣírí Cookies Kàn sí.
Aisha sọrọ naa nibi ipade apero kan to waye nilu Abuja pe awọn mejeeji ọhun, to kọ̀ lati darukọ, lo jẹ idiwọ ati idena fun idagbasoke orilẹede Naijiria.
Simeone ati Miguel Angel, ti o je oludari agba iko naa soro tan, loun se ikede
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Oluwo Ìwo ṣ'àlàye lori oyé oba oni lawàni Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Oluwo Ìwo ṣ'àlàye lori oyé oba oni lawàni 1 Ìgbé 2018 Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí 2 sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 2:23 Fídíò, Water Generator: Ó leè ṣiṣẹ fún wákàtí mẹfà, kó tó sinmi, Duration 2,2310 Òkùdu 2020 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
Ẹ kò gbọdọ̀ yà sí ọ̀tún tabi sí òsì ninu ẹjọ́ tí wọ́n bá dá fun yín.
NASS: San 2 Mílíọ́nù tàbí lọ ẹ̀wọ̀n ọdún méjì fún ìlòkulò Codeine
Jesu bá mú burẹdi marun-un yìí ati ẹja meji, ó gbé ojú sókè ọ̀run, ó gbadura sí i, ó pín wọn sí wẹ́wẹ́, ó bá fún àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ pé kí wọ́n fún àwọn eniyan.
Awọn miran si ni awọn ko ni tẹle e mọ nitori pe o n gbe igbe aye féèkì ti ko ki n ṣe ootọ.
 nítorí ìwà rẹ ̀ tó dára , ó kọ ̀ láti tàá tí ̣ rú yìí sì ń báa gbé .
Van Dijk gbadé UEFA mọ́ Messi àti Ronaldo lọ́wọ́ Japan ṣèrànwọ́ N149m fún Nàìjíríà lórí ètò ààbò!
Olori Abibat ko si ju ọmọ ọdun mẹtadinlogun lọ nigba ti wọn mọ ara wọn, ti wọn si se igbeyawo lasiko ti obinrin naa wa nile ẹkọ girama.
Nípasẹ̀ mi ni àwọn olórí ń ṣe àkóso,gbogbo àwọn ọlọ́lá sì ń ṣe àkóso ayé.
Kò kan ẹnikéni bóyá èèyàn féràn àjọyọ̀ tàbí kò fẹ́, kí ni ó dé tí àwọn ènìyàn ṣe fẹ́ràn láti máa fi túláàsì mú ẹlòmíràn gba èròńgbà ti wọn?
” Saulu ṣèlérí fún Dafidi lẹẹkeji pé, “O óo di àna mi.
Gígùn ibi mímọ́ ti inú yìí jẹ́ ogún igbọnwọ, ó fẹ̀ ní ogún igbọnwọ, gíga rẹ̀ náà sì jẹ́ ogún igbọnwọ.
’ ” Wọ́n bẹ̀rù àwọn eniyan nítorí gbogbo eniyan ni ó gbà pé wolii tòótọ́ ni Johanu.
Ẹgbẹ awọn olufifunni -Awọn to wa ninu ẹgbẹ yii lo ma n ṣoju ijọ lati fun awọn ọmọ ijọ ti ko ni i, ni ounjẹ, owo ati aṣọ.
Fẹstu forí-korí pẹlu àwọn olùbádámọ̀ràn rẹ̀, ó wá dáhùn pé, “O ti gbé ẹjọ́ rẹ lọ siwaju ọba Kesari; nítorí náà o gbọdọ̀ lọ sọ́dọ̀ ọba Kesari.
Awọn kan si gba pe iṣakoso rẹ ko so eso rere fun orilẹede Naijiria.
O ṣe e ṣe ki ijọba o gba iwe aṣẹ kuro lọwọ ileeṣẹ ti ko ba tẹle ilana yii, tabi ijiya nla miran.
Ife ẹyẹ Afrika ti 2013 ni idije ti Moses kọkọ gba fun ikọ Super Eagles.
OLUWA, ranti bí ọjọ́ ayé ẹ̀dá ti gùn mọ,ati pé ẹ̀dá lásán ni ọmọ eniyan!
"Ìtàn ayé Shina Rambo, adigunjale tó fi oyún 27 gún ọṣẹ Àgbáríjọ àwọn nọ́ọ̀sì fẹ́ gbé Olamide Baddo lọ sílé ẹjọ́ fún ìbanilórúkọjẹ́ Wo atẹ àlàkalẹ̀ ìdánwò WAEC fún ọdún 2020 tí yóò bẹ̀rẹ̀ ní August 17 Ṣọ́ọ̀ṣì tí wọ́n ti ń fi ọtí àmupara bá Ọlọ́run sọ̀rọ̀ ní kí ìjọba dẹwọ́ọ òfin títà ọtí lásìkò Covid-19 Bí Ẹ̀ka aláṣẹ́ ti já agbára gbà mọ́ ìgbìmọ̀ olùdarí APC lọ́wọ́ ""Aug 2018 ni ìgbìmọ̀ aláṣẹ APC ti ṣe ìpàdé kẹ́yìn, Oshiomole ti kùnà"" Àwọn gómìnà lábẹ́ àsía ẹgbẹ́ òṣẹ̀lú All Progressive Congress (APC) tí kési alága ẹgbẹ́ òṣèlú APC, Adams Oshiomole lati pe ipade igbimọ alakoso ẹgbẹ́ tàbi kó kọ̀wé fipò sílẹ̀."
O fi awọn maaki to gba ninu awọn idanwo to ṣe kọja sẹyin 2015 - 189 2016 - 202 2017 - 233 O ni igba yii ti awọn eniyan fẹ ran oun lọwọ lati kawe ni oun wa gba maaki mẹtadinlaadọsan (167).
Bí Ayédèrú ẹ̀dá ti já bọ sí odò tán ni a fá tí ó dá ti o tún sopọ̀, púpọ̀ nínú àwọn sì dé òdì kejì ní àlàáfíà.
    Ọ̀rọ̀ mi kò jù báyìí lọ,
Múra, kí o sì ṣe ọkàn gírí, má bẹ̀rù, má sì ṣe jẹ́ kí àyà fò ọ́.
Ẹẹkẹta nìyí tí mo múra tán láti wá sọ́dọ̀ yín.
Ẹẹmeji ni ile aṣofin agba kọ lati buwọlu iyansipo rẹ, nitori iwe 'ẹ fura' ti awọn ọlọpaa ọtẹlẹmuyẹ DSS kọ nipa rẹ.
Online VAT: Sísan owó orí ọjà lórí ayélujára yóò mú kí ọrọ̀ ajé rú gọ́gọ́ si
" Oríṣun àwòrán, @realFFK Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 3 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 5 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
O kéré tán, ènìyàn 5 ló ti jáláìsí níbi ìṣẹ̀lẹ̀ ilé tó wó ọ̀hún Àṣìta ìbọn pa èèyàn kan lásìkò tí SARS ń kojú adigunjalè l'Eko Sanwo Olu yan kọ̀míṣọ́nnà 25 àtàwọn olùbádámọ́ràn Ẹ padà sílé èyin ọmọ wa tó n ṣiṣẹ́ darandaran - NEF ti Fulani Bi ẹ ko ba gbagbe laipẹ yi ni iroyin kan ti kọkọ jade pe iyawo onkọrin yii bimọ ṣugbọn ti oun pẹlu tete bọ si igboro lati salaye pe iyawo oun ko tii bimọẸ dákẹ́ àhesọ ọ̀rọ̀, n kò bí ìbẹta - Yinka Ayefẹlẹ.
 ovale  , àti "" p."
A óo kó wọn ní ìgbèkùn lọ sí gbogbo orílẹ̀-èdè.
Ṣe kíá, lọ sọ́dọ̀ àwọn eniyan náà láti ṣe ètùtù fún wọn nítorí ibinu OLUWA ti ru, àjàkálẹ̀ àrùn sì ti bẹ́ sílẹ̀ láàrin wọn.
Lẹyin ija ọhun, ti wọn si kede Fury bi ẹni to moke julọ, lo gba igbanu gẹgẹ bi ẹni to le ja ẹṣẹ ju ninu idije WBC lagbaye, eyi ni WBC World Heavyweight.
Rotimi Paseda Àkọlé àwòrán, #BBCGOVDEBATE: Awọn àrá ipínlẹ̀ Ogun ti bẹ̀rẹ̀ ìjíròrò Wọn ò fi ọgban ori gbé [pawọn ilé ìwé wa kalẹ, kò si sí ìdí ti wọn ó ṣe kó ilé [piwé si ojú kan kò tọna láti maa ya owo ṣe ǹkan, dandan ni ètò ẹkọ ọfẹ́ ni ìpínlẹ̀ Ogun Ilé iwe ẹkọ ní ọpọ̀ lọ kini ìdí ti à kò ṣe gbọdọ ṣe ní asìkò yìí.
Amọ, awọn ọmọ ti wọn wa lati ile ẹru ti wọn tu silẹ yii laaarin awọn ẹya Igbo ṣi n tẹle ohun ti awọn baba nla baba wọn ṣe ni igba aye wọn, eleyii to tumọ si wi pe ẹru ko le fẹ ọmọ laarin awọn ẹya Igbo.
Amọ, o wa kesi awọn ọmọ Naijiria lati dide iranwọ fun oun nitori ọna kan soso ti oun gba fi tọju ẹbi ati ara oun niyẹn.
Mo kú, ṣugbọn mo ti jí, mo sì wà láàyè lae ati laelae.
O Fagunwa, Adebayo Faleti, Akinwumi Iṣọla, Lawuyi Ogunniran àti Oladejo Okediji ṣiṣẹ silẹ ki wọn to lọ3 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Akomolede Oyo round up: Àwọn Olúkọ ìpínlẹ̀ Oyo fakọyọ lórí ètò Akọ́mọlédè àti Àṣà púpọ̀27 Bélú 2020 Adeyeye Ile Ife: Kílódé tí Ọọni Ife, Oba Ogunwusi kò fi gbọdọ̀ rí ọmọ rẹ̀ tuntun títí di ẹ̀yìn oṣù mẹ́fà?
Ọpọlọpọ ọkọ: Gbogbo eeyan lo mọ pe ninu awọn ilu to tobi lagbaye ni ilu Eko wa.
Nígbà tí Eliṣa gbọ́ pé ọba Israẹli ti fa aṣọ rẹ̀ ya, ó ranṣẹ sí i pé, “Kí ló dé tí o fi fa aṣọ rẹ ya?
Derek Chauvin to gbe orunkun le ọrun rẹ lo n jẹjọ iwa ipaniyan pẹlu awọn to ku.
" Lẹyin to fi mail ransẹ si olukọni naa tan, onitọun ni ko si wahala, ti oun ko ba ni owo lọwọ, o si gba Tani sagbo wọn lọfẹ.
Iṣẹ́ tí wọ́n jẹ́ náà dùn mọ́ àwọn ọmọ Israẹli ninu, wọ́n sì fi ìyìn fún Ọlọrun; wọn kò sì ronú ati bá wọn jagun mọ́, tabi àtipa ilẹ̀ wọn run níbi tí wọ́n ń gbé.
Bakan naa ni ọmọ ṣori nipinlẹ Katsina nibi ti Buhari ti ni ìbò 802, 819 ninu gbogbo awọn 813, 877 to forukọ silẹ.
Ọlọ́rọ̀ a máa fi ohun ìní rẹ̀ ra ẹ̀mí rẹ̀ pada,ṣugbọn talaka kì í tilẹ̀ gbọ́ ìbáwí.
Àwọn jàǹdùkú kọlu gómìnà Oyetola, 'èèyàn méjì kú' níbi ìwọ́de l'Osogbo Ori lo ko gomina ipinlẹ Ọṣun, Gboyega Oyetọla yọ lasiko to fi lọ darapọ mọ awọn oluwọde ENDSARS nilu Osogbo.
MC Oluomo: Agbálẹ̀ títì ni ìyá mi, ọmọ ọdún 13 ni mo sì ti sá nílé lọ bẹ̀rẹ̀ iṣẹ́ kọ̀ǹdọ́
Bí angẹli tí ó ń bá a sọ̀rọ̀ ti lọ tán, ó pe meji ninu àwọn iranṣẹ rẹ̀ ati ọmọ-ogun olùfọkànsìn kan, ọ̀kan ninu àwọn tí ó máa ń dúró tì í tímọ́tímọ́.
 a ti sòrò díè nípa àpólà àpèjúwe àti àfòmó .
Mo ṣi nifẹ rẹ, oun naa si n sọ fun mi ni gbogbo igba pe oun nifẹ mi.
Eléyìí ni ìtàn kín-ín-ní tí èmi àti ìyàwó mi gbọ́ lẹ́nu Ìtándìran ti ń gbé ilé Òpìtánparapọ̀.
Àwọn Ọlọ́rọ̀ àná bi Candido Joao Da Rocha, Ọlọ́rọ̀ owó ọ̀kẹ́ aimoye àkọ́kọ́ ni orilẹ̀ èdè Nigeria ti ilú Èkó, Olóyè Adéọlá Odùtọ́lá ọ̀gá Oníṣòwò ti Ìjẹ̀bú-Òde ti ìpínlẹ̀ Ògùn, Oloye Àjàó, S.
Dafidi bá pàṣẹ fún Joabu, ati àwọn ọ̀gágun rẹ̀, tí wọ́n wà pẹlu rẹ̀, ó ní, “Ẹ lọ sí gbogbo ẹ̀yà Israẹli, láti Dani títí dé Beeriṣeba, kí ẹ sì ka gbogbo àwọn eniyan tí wọ́n wà níbẹ̀, kí n lè mọ iye wọn.
Aare Buhari ni: “Naijiria asiko yii ko rorun, emi naa mop e nkan fe le die sugbon gbogbo wa gbodo jo fowosowopo lati fi gbogun ti awon jegudujera onibaje eniyan lawujo wa”.
Hanuni bá ki àwọn oníṣẹ́ Dafidi mọ́lẹ̀, ó fá apá kan irùngbọ̀n ẹnìkọ̀ọ̀kan wọn, ó gé aṣọ wọn ní déédé ìbàdí, ó sì tì wọ́n jáde.
Amọ, asoju olubadan lori ọrọ iroyin, Deola Oloko sọ fun BBC wi pe oun yoo kan si wa lẹyin ti oun ba ti fi idi idajọ naa mulẹ tan.
OLUWA ṣe bẹ́ẹ̀; ọ̀wọ́ eṣinṣin wọ inú ilé Farao ati ti àwọn ẹmẹ̀wà rẹ̀ ati gbogbo ilẹ̀ àwọn ará Ijipti.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Human trafficking: Ààrẹ Buhari, ẹ̀yin gómìnà ìpínlẹ̀ Yorùbá, ẹ rántí wa ní Oman, àwọn ọmọ Nínú ọ̀rọ̀ tí Lizzy kọ sórí Instagram rẹ̀, ó dúpé púpọ̀ lọ́wọ́ ọkọ rẹ̀, tí a kò tíì mọ orúkọ rẹ̀, fún gbogbo oore tó ṣe fún òun (Lizzy) àti ìyá òun tó ti kú.
Gbogbo èyí wáye lẹ́yin ti abẹnugan ilé Femi gbajabiamila sọ pé òun yóò fi ọwọ́ òfin mu Akpabio ti ko bá dárúkọ àwọn ọmọ ilé to n gba iṣl kọngila NDDC Oríṣun àwòrán, NDDC Àkọlé àwòrán, Ọjọgbọ́n Kemebradikumo Pondei Sáájú ni adarí àjọ NDDC Kemebradikumo Pondei, ti sọ fun ile ìgbìmọ̀ asòfin pé àwọn náà bíliọnù kan àbọ̀ fún àwọn òṣìṣẹ́ nítori ààrùn Covid-19''.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Awọn eniyan to ju ẹgbẹrunmarundinlaadọta lo fọwọ si lori ẹrọ ayelujara Change.
Wọ́n ń bọ nǹkan tí Ọlọrun dá, wọ́n ń tẹríba fún wọn, dípò èyí tí wọn ìbá fi máa sin ẹni tí ó dá wọn, ẹni tí ìyìn yẹ fún títí lae.
Egbule ni Ìjọba àpapọ́ ní ẹgbẹ́ òsìsẹ́ tún bèrè fún àfikún owó osù fún àwọn tó ń gba owó osù tó ju 30,000 Naira tí wọn béré fún lọ.
Aare Buhari so pe,“Gege bi eleran ara, o je ohun ibaje fun mi pupo ni igba ti mo gbo oro yii, mo mo bi isele buruku yii se maa nipa lara awon ti o fara kaasa isele naa”.
Oríṣun àwòrán, Facebook/@OfficialOAU Àkọlé àwòrán, Fasiti OAU: À wádìí olùkọ́ tó fẹ́ bá akẹ́kọ̀ọ́ lò fún máákì Nínú ìfòròwánilẹ́nuwò rẹ̀ pẹ̀lù BBC Yorùbá, alukoro fásitì OAU ni àwọn aláṣẹ fásitì náà yóò ṣe ohun gbogbo tó bá tọ́ lórí ọ̀rọ̀ náà.
Awọn asofin ni k'ijọba apapọ o dawọ owo ori ọja lati okeere duro
Ó ní ṣùgbọ́n àjọ INEC n ṣiṣẹ́ gẹ́gẹ́ bi ẹ̀ka kan nínú ẹgbẹ́ òṣèlú tó wà ní ìṣàkóso.
Xeno watch ti wọn n lo fi woye irufẹ iṣẹlẹ bayii lati ara iroyin to n jade ṣafihan awọn ikọlu naa ati awọn to ti lugbadi wahala lati ara irufẹ ikọlu yii.
Irufẹ igba nla to wa niwaju wọn bẹẹ ni wọn yoo doju rẹ de bolẹ, awọn ayaba yoo si maa kọrin bi wọn ṣe n fi ọwọ ọtun ati osi wọn gba igba naa pẹ pẹ pẹ.
Biṣọọpu Greek ni aye atijọ, to maa n wọ aṣọ pupa ni gbogbo igba to ba ti fẹ ẹ fun awọn alaini ni ẹbun.
ipenija to n koju wa bayii.
o gbiyanju lati tẹpẹlẹ mọ ife ati isokan lorile ede yii,
29 Èbibi 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 30 Èbibi 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Iya jẹ Arsenal Alubami ni ẹgbẹ agbabọọlu Chelsea na Arsenal pẹlu ami ayo mẹrin si ẹyọ kan ni ifẹsẹwọnsẹ asekagba ti Europa League fun ọdun 2019.
Ajo ijoba apapo to n risi awon fiimu agbelewo ati ere sinima ni Naijiria ti a mo si: The National Film and Video Censors Board (NFVCB), ti ni awon ere olosoose agbelewo tile Mexico ti won n safihan re ni Naijiria ko ni iwe ase rarai ajo naa lo so eyi di mimo ninu iforowanilenuwo pelu awon akoroyin nilu Abuja.
Ǹjẹ́ kò ti fun yín ní ìfọ̀kànbalẹ̀ káàkiri?
Ọpọlọpọ ibeere lo wa ni ọkan rẹ lati beere.
Ewe, igbakeji oludari eka OCHA nile-ise ajo isokan agbaye,  Crispen Rukasha, fi idunnu re han pupo fun ibasepo pelu ile-ise omo ogun, ti O si tun dupe lowo adele oga agba awon omo ogun ohun fun  kikopa lojo keyin idanileko naa.
Orukọ awọn mẹrin ti wọn jigbe ọun ni Seyit Keklik, Yasin Colak, Ergun Yurdakul, ati Senerapal.
Nígbà tí ó bá wá rí i, yóo gbé e kọ́ èjìká rẹ̀ pẹlu ayọ̀.
Oríṣun àwòrán, Islamic State Propaganda Àkọlé àwòrán, Ọpọlọpọ eeyan lo ti jẹjẹ atilẹyin fun ISIS Pakistan: Ọjọ kẹẹdogun, oṣu Karun, ọdun 2019, ni wọn da ẹka IS silẹ ni Pakistan.
Aarẹ orile ede Naijiria Muhammadu Buhari ti ki iko agbaboolu Super Eagles lorile ede Naijiria ku ori-ire fun aseyori ti won se lojo Eti, nibi ti  iko naa ti fagba han akegbe won ti iko agbaboolu , orile ede Iceland latari ifese-iwonse eleekeji ti ife eye agbaye ti odun 2018, to n lo lowo  lorile ede Russia.
O parọwa fun ẹnikẹni to ba fẹ gbọ ootọ ọrọ to n fọnrere iwa akin oun lẹyin iku rẹ pe ko ṣe rere lori oke eepẹ ko to ku.
Osinbajo àti PDP ń jiyàn lórí ìkówójẹ́ lábẹ́ àwọn adarí wọn
“Aare yoo wa lati wa kede ipolongo
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Buhari: Isa Funtua ti wọ káà ilẹ̀ sùn ní ìlú Abuja 21 Agẹmo 2020 Oríṣun àwòrán, Twitter/@ibrahimado__ Wọn ti ṣeto isinku amugbalẹgbẹ aarẹ Muhammadu Buhari, Isma'ila Isa Funtua ni mọṣalaṣi Shehu Shagari, to wa ni Area 1, Abuja.
Sugbọn lootọ ni alajọ Somolu wa, Alphaeus Taiwo Olunaike ni orukọ rẹ, to si gbe aarin wa nilẹ Yoruba, o bimọ, o laya, o kọle, to si tun se awọn ohun rere miran ti eeyan n gbe ile aye se.
” Wọ́n bá mú okùn titun meji, wọ́n fi dì í, wọ́n sì gbé e jáde láti inú ihò àpáta náà.
lati sun eto idibo siwaju di ose yii, aare wa lo anfaani naa lati tun ran ajo
Dafidi, iranṣẹ mi ni yóo jọba lórí wọn; gbogbo wọn óo ní olùṣọ́ kan.
Sugbọn awọn ara ipinle Ogun nikan ko ni ìṣẹlẹ náà kàn.
Mo kórìíra ìṣe àwọn tí wọ́n tàpá sí Ọlọrun.
Ẹ̀bùn ni ó fún gbogbo ọmọ tí àwọn obinrin mìíràn bí fún un, kí ó tó kú ni ó sì ti ní kí wọ́n jáde kúrò lọ́dọ̀ Isaaki, kí wọ́n lọ máa gbé ní apá ìlà oòrùn ilẹ̀ náà.
mali ni agbegbe mejo be sini awon bode re ni ariwa sun de arin sahara , nigbati agbegbe apaguusu , nibi ti opolopo eniyan ngbe , ni awon odo niger ati sénégal .
Agege Motor Road / Oshodi Loop, Oshodi, Ijọba ibilẹ Ikeja / Mushin 5.
Gẹgẹbi ẹnikan ti isẹlẹ naa soju rẹ, Ọgbẹni Dapọ Sanwo ti fidi isẹlẹ naa mulẹ fun ileesẹ BBC, o ni ariwo lasan lawọn kan gbọ to gbalẹ kan ninu baalu naa, to si n mi laimọ pe ilẹkun iwaju naa lo fẹ fo yọ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, CJ Gold: ẹ̀rù kọ́ka ba ìyá mi nígbà ti mo fẹ́ bẹ̀rẹ̀ iṣẹ́ ìjà jíjà Ati ti ijọba ba ri gba lara awọn owo ti ijọba apapọ jẹ ipinlẹ Ekiti.
Àwọn mààlúù meje mìíràn tún jáde láti inú odò náà, gbogbo wọn rù hangangan, wọ́n rí jàpàlà jàpàlà, n kò rí irú rẹ̀ rí ní gbogbo ilẹ̀ Ijipti.
Ó sọ fún àwọn oníròyìn pé dípò kí ìgbìmọ̀ amúṣẹ́ yá yanjú ọ̀rọ̀ náà, ṣe ni wọ́n ní kí òun pín tíkẹ̀ẹ̀tí ilé àṣòfin àpapọ̀ àti ti ìpínlẹ̀ pẹ̀lú àwọn kan tó ní wọn ò bá wọn kópa nínú ìdìbò abẹ́lé ti gómìnà àti ti aṣòfin ìpínlẹ̀.
Isọri mẹrin ni wọn pin awọn ikọ agbabọọlu ti yoo kopa ninu idije AFCON 2019 si.
Iyawo Samsoni bá bẹ̀rẹ̀ sì sọkún níwájú rẹ̀, ó ní, “O kò fẹ́ràn mi rárá, irọ́ ni ò ń pa fún mi.
Hamani tún fi kún un pé “Ayaba Ẹsita kò jẹ́ kí ẹnikẹ́ni bá ọba wá sí ibi àsè rẹ̀, àfi èmi nìkan.
Tí èèyàn bá kọ́kọ́ wọnú igbó náà, yó rí àpẹrẹ pé ọkọ̀ a máa rin ọ̀nà tó wọnú igbó náà lọ.
Afojusun awọn eto yi gẹgẹ bi ijọba ti ṣe sọ ni ki wọn ba le mu adinku ba iye awọn ti ko niṣẹ lorile-ede Naijiria.
Ẹkọ kejì ni pe, o yẹ ki awọn agbofinro wa maa fi pẹlẹ putu huwa si araalu, ko dara to ki wọn maa sare yin ìbọn pa eeyan, eyi to le fa rogbodiyan.
Iye asiko wo ni wọn fi wa nibẹ 3.
22 Lõtọ́, lõtọ́, ni mo wí fún ọ, bí ìwọ bá fẹ́ ẹ̀rí síwájú síi, mú ọkàn rẹ lọ sí òru ọjọ́ tí o kígbe pè mí nínú ọkàn rẹ, pé kí ìwọ le mọ̀ nípa òtítọ́ àwọn nkan wọ̀nyí.
Buhari buwọ́ lu òfin ọ̀dọ́ leè dupò Uganda gbówó orí lé Whatsapp, Facebook Níbo ní Buhari tí sọ ọrọ̀ náà Gẹ́gẹ́ bí Dino ti ṣe sọ, ọ ni Ààrẹ sọ ọrọ náà nígbà tí o gba àlejò awọn ọmọ ẹgbẹ tó n ṣé ìpolongo fún ùn Buhari (Buhari Campaign Organisation), ti olórí ilé iṣé aṣobode, Ọgagun Hameed Ali ko sódì.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Háà Ibadan!
Lẹyin naa, Ọbabinrin Daurama fẹ Bayajidda l'ọkọ.
Ẹni tí ó ń ṣọ́ ilé ẹ̀wọ̀n náà bá lọ jíṣẹ́ fún Paulu pé, “Àwọn adájọ́ ti ranṣẹ pé kí á da yín sílẹ̀.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ondo Election: Akeredolu f'ògún ikọ̀ Àmọ̀tẹ́kùn Ondo gbárí fún ìdìbò tó ń bọ̀ 23 Sẹ́rẹ́ 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 12 Ògún 2020 A o ni faaye gba lilo janduku tabi iwa ọdaran lasiko idibo to n bọ lọna."
Bi akọsilẹ naa ṣe lọ niyii pẹlu ipinlẹ kọọkan ti wọn ti ri awọn eeyan naa Lagos-87 Edo-63 FCT-60 Ondo-41 Benue-32 Abia-31 Ogun-29 Oyo-19 Kaduna-17 Delta-16 Enugu-15 Borno-14 Plateau-9 Nasarawa-8 Kano-5 Bauchi-4 Gombe-2 Katsina-1 Kogi-1 Titi di oni, ọjọ Abamẹta, ọjọ kẹrin, oṣu keje, ọdun 2020, iye awọn to ti lugbadi Covid 19 ni Naijiria lapapọ jẹ 27,564.
O Fágúnwà máa ń sùn sí ibojì, aginjù tàbí ti ara rẹ̀ mọ́lé láti kọ̀wé 12 Ọ̀wàrà 2018 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 9 Bélú 2019 Àkọlé àwòrán, Ẹmi kan lo maa n dari Fagunwa, to si maa n ba ẹmi airi sọrọ Ọpọ ọdọ lode oni ni ko mọ ohunkohun nipa gbaju-gbaja Onkọwe nni, to kọkọ kọ iwe ni ede abinibi nilẹ adulawọ, eyiun Daniel Ọlọrunfẹmi Fagunwa.
"Ohun tí o kò mọ̀ nípa Ebila ""One Million Boys"" àti Ekugbemi, olórí ẹgbẹ́ òkùnkùn méjì tó da ìlú Ibadan rú Ẹgbẹ́ òkùnkùn yìnbọn lu ọmọ kan ní ikùn lásìkò ìdárò akẹẹgbẹ́ wọn Àwọn agbófinró ti mú Eji tó jẹ́ igbákejì Ebila, olórí ẹgbẹ́ òkùnkùn ""One Million Boys"" sí gbaga Ọmọ ẹgbẹ́ òkùnkùn ṣoro ní Ijebu Ode, ọ̀pọ̀ ẹ̀mí sọnù ""Òògùn ni wọ́n fi bò mí lójú tí mo fi bá ara mi láàrin àwọn ẹlẹ́gbẹ́ òkùnkùn"" Ayẹyẹ ìgbaniwọlé sínú ẹgbẹ́ òkùnkùn bẹ́yìn yọ, wọ́n lu ọmọ ẹgbẹ́ tuntun pa Ọwọ́ tẹ 'pásítọ̀' tó ń ṣe ẹgbẹ́ òkùnkùn ní Bàrígà Ẹ̀yin ẹlẹ́gbẹ́ òkùnkùn tẹ fẹ́ ṣe àjọ̀dún lónìí, lákọ la ń dúró dè yín - Iléeṣẹ́ ọlọ́pàá Ajogun ni ileesẹ ọlọpaa yoo tẹsẹ bọ sokoto kannaa pẹlu awọn ẹlẹgbẹ okunkun, to si ni awọn ti wọn se afihan wọn yii pẹlu awọn mii to si ti na papa bora, lo lọwọ ninu pipa awọn eeyan mẹẹdọgbọn naa."
Ekiti Election: Bọ́mọ kò bá bá ìtàn ó di dandan kó bá àrọ́bá
Ogbẹni Akinbole Idowu to je igbakeji adari ajọ to n mojuto ẹjẹ gbigba ni ipinlẹ Eko ṣalaye kikun fun BBC lori idi to fi yẹ ki eeyan maa fi ẹjẹ silẹ.
eto ipolongo to waye ni ipinle naa gbomimu.
Irun ti Ọlọrun fun mi ko duro lori mi ri.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Akure Kidnap: E túbọ̀ ní sùúrù, a máa wá ọmọ náà rí- Alukoro ọlọ́pàá Lati ọdun naa ni El-Zakzaky ti bẹrẹ si ni foju wina ijọba Naijiria.
Bẹẹ ba gbagbe, irọlẹ ọjọ Ẹti la kọkọ mu iroyin wa fun yin pe awọn Oso ati Ajẹ naa se ipade nilu Osogbo nile baba Awo, Elebuibon.
Anthony Joshua: Mí ò mọ̀ pé ọ̀rọ̀ ọlọ́pàá ni ìwọ́de #EndSars níṣe pẹ̀lú
"Ìró ìbọn dún lákọ ní Iwo road n‘Ibadan, Seyi Makinde yọjú síbẹ̀ Àwọn jàndùkú kọlu ọgbà ẹ̀wọ̀n Ikoyi, agbófinró gba àkóso ibẹ̀ ""7000 Jàǹdùkú ló fọ́ ọgbà ẹ̀wọ̀n Okitipupa, jó mọ́tò, tí wọn si se òṣìṣẹ́ léṣe"" ""Buhari, ìwọ́de yóò yíwọ́, tó ba jẹ́ ki ológun bẹ̀rẹ̀ 'Operation Crocodile Smile' "" Operation Crocodile Smile: Ọmọ Nàíjíríà ní àsìkò ìwọ́de kọ́ ló yẹ kí ológun ṣe àkànṣe ètò Awọn oluwọde ri ikede ileesẹ ologun lati bẹrẹ operation Crocodile Smile bii ara ọna lati da awọn ologun sita, ki wọn lee bomi pa ina iwọde to n lọ lọwọ."
 bákan náà , alhaji ahmad zaruq tún jẹ ́ oníṣòwò tí ó lààmì-laka nínú iṣẹ ́ aṣọ ìbílẹ ̀ aṣọ Òfì tàbí aṣọ Òkè .
Bi mo ṣe jade nile iwẹ mo rii pe yara mi ti n jo.
Ṣugbọn èmi jẹ́ eniyan ẹlẹ́ran-ara, tí a ti tà lẹ́rú fún ẹ̀ṣẹ̀.
Bàbà ọmọ ọdún 75 kó HIV ran ọmọ ọdún 14 lẹ́yìn tó fi ipá báa lò Okunrin naa ni awọn agbofinro ṣapejuwe ni oyinbo alawọ funfun ti ọjọ ori rẹ wa laarin ọgbọn si ogoji.
Ẹlẹ́dàá tó dá ayé òun ọ̀run.
Iwọ́de ń wáyé ní Abuja, Eko ati Enugu Iroyin to n tẹ BBC Yoruba lọ́wọ́ fi han wipe iwọde n lọ lọwọ ni Abuja, Ilu Eko ati Enugu lati fi ẹhonu han lori bi Buhari ṣe yọ Onnoghen.
Wọ́n yá ère ẹgbọ̀rọ̀ mààlúù ní Horebu,wọ́n sì bọ ère tí wọ́n dà.
Aare wa fi da alaga ajo CCB
Ilé ìwòsàn UNN: Lóòótọ́ ọjọ́ ti lọ lórí omi náà, ẹ ma bínú
Lara awọn ileri ti Boris Johnson ṣe ṣaaju idibo ni pe oun ṣetan lati fi ẹmi oun wa ojutu si ọrọ Brexit.
Osere tiata naa wa n beere pe ki lo de tijọba Naijiria ko maa se ayẹwo arun Covid 19 fawọn arinrinajo to gunlẹ ni papakọ ofurufu gẹgẹ bi wọn ti n se nilẹ Turkey?
Iroyin to tẹ wa lọwọ sọ pe ọga ọlọpaa Idris wa nile iṣẹ aarẹ lọjọ Aje nibi to ti ṣepade idakọkọ pẹlu Aarẹ Buhari.
Ija ẹlẹya mẹya ti o ti gbilẹ ni ipinlẹ naa lati igba pipẹ ni o fa ipade alaafia ti awọn olori ẹlẹsin ipinlẹ naa pe.
Eyi si yaayi gbaa Oríṣun àwòrán, Fellipe Abreu Àkọlé àwòrán, Posi yii lo n salaye iru ẹda ti oku ti wọn fi sin jẹ.
Igbakeji aare so pe”otito oro ni pe, aseyori maa n wa ni ila si ila, ipele si ipele, ki a mo biriki le ori ara won , ise aselaagun, ogbon atinuda ati iwa rere nikan ni osunwon si aseyori.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù BBNaija 2019: Gedoni kúrò ní BBNaija.
Àfi ẹran ọ̀sìn ati dúkìá ìlú náà ni àwọn ọmọ Israẹli kó ní ìkógun gẹ́gẹ́ bí OLUWA ti pàṣẹ fún Joṣua.
ÌGBÉYÀWÓ ÌRÌNKÈRINDÒ PẸ̀LÚ ÀBÚRÒ OLÓKUN IWIN INÚ OMI
Nítorí náà, o fi wọ́n lé àwọn ọ̀tá wọn lọ́wọ́, àwọn ọ̀tá sì jẹ wọ́n níyà, nígbà tí ìyà ń jẹ wọ́n, wọ́n ké pè ọ́, o sì gbọ́ igbe wọn lọ́run, gẹ́gẹ́ bí àánú rẹ ńlá, o gbé àwọn kan dìde bíi olùgbàlà láti gbà wọ́n lọ́wọ́ àwọn ọ̀tá wọn.
Bakan naa lo ni ọwọ ti tẹ afurasi miran lori iku to pa Azeezat Somuyiwa, ẹni to ni oyun osu meje ti wọn fọ okuta mọ lori ninu yara rẹ.
Oníṣẹ́ Ìjoba kò ri owó-oṣ̀ù gbà déédé, àwọn ti ó fi ẹhin ti ni iṣẹ́ Ìjọba kò ri owó ifẹhinti wọn gba, owó ilú bàjẹ́, bẹni àwọn Òṣèlú bú owó oṣ́u rẹpẹtẹ fún ara wọn.
Oríṣun àwòrán, Ojude Oba Facebook Amọ kẹrẹkẹrẹ, se ni ọdun yii n fẹju si bi ọdun se n gori ọdun, to si kọja ọdun ẹlẹsin kan, lojumọ toni yii, ọdun Ojude Ọba ti di aayo nilẹ Ijẹbu, eyi ti oniruuru ẹlẹsinjẹsin, ẹlẹyamẹya, tọmọde tagba n peju lati se ajọyọ rẹ, koda, awọn eeyan, paapa awọn ọmọbibi ilu Ijẹbu maa n ti ẹyin odi wa se ayẹyẹ naa.
fi ọwọ ọkunkundun mu, lẹyin ti iwadii fi mulẹ gẹgẹ bi eyi ti awọn ara
Aje ni Fafiti ipinle Eko (University of Lagos) lasiko ti fafiti naa n se ayẹyẹ
2 Àti nísisìyí, kíyèsíi, èyí ni ìwọ ó sọ fún un—ẹnití o bá ọ sọ̀rọ̀, sọ fún ọ pé: Èmi, Olúwa, èmi ni Ọlọ́run, mo sì ti fi àwọn nkan wọ̀nyí fún ọ, ìránṣẹ́ mi Joseph Smith, Kékeré, mo sì ti pàṣẹ fún ọ pé o níláti dúró bíi ẹlérìí àwọn nkan wọ̀nyí.
Wọ́n kọ orúkọ àwọn alufaa ní ìdílé ìdílé, ṣugbọn àwọn ọmọ Lefi tí wọ́n tó ẹni ogún ọdún sókè ni wọ́n kọ orúkọ wọn sílẹ̀ gẹ́gẹ́ bí ipò wọn ati ìpín wọn.
O ni lẹyin ifikunlukun pẹlu ijọba ipinlẹ Eko ati ti ipinlẹ Oyo lori ọna lati sin oloogbe Ajimọbi bi o ti tọ ati bi o ti yẹ ni wọn fẹnuko lori ọna ti wọn fẹ gba yii.
Oun lọmọ Belarus to kọkọ gbe ogo wale to si kọkọ gba ipo akọkọ lagbaye gẹgẹ bi agbabọọlu tẹniisi.
Ẹ wo èrò bìbà níbi ìwọ́de #EndSARS ní ìlú Ibadan Ẹfunsetan Aniwura, ọmọ Ẹ̀gbá tó di akíkanjú obìnrin nílẹ̀ Ibadan Ẹgbẹ́ Agbẹjọ́rò NBA ti kéde pé àwọn yóò ṣojú awọn Olùwọ́de #EndSARS lọ́fẹ̀ẹ́ nílé ẹjọ́ Bàbá ọlọ́mọ méjì fi ipá bá ọmọ ọdún mẹ́rin lò pọ̀; Adájọ́ rán an ní ẹ̀wọ̀n gbére Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Eegunjobi Omotanbaje Ajobiewe- Èébú ní wọ́n kọ́kọ́ ń bù mí nígbà tí mo bẹ̀rẹ̀ ẹ̀ṣà pípé ní Awọn to n fi ẹbun ta oluwọde ati agbofinro lọrẹ naa ko gbẹyin: Lasiko iwọde #End SARS yii naa ni awọn ọmọ Naijira n nawọ iranwọ sawọn oluwọde.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Brazil police brutality: Awuyewuye ti n wáyé lórí bí ọlọ́pàá ṣe fún obìnrin kan ní ọrùn pa 14 Agẹmo 2020 Oríṣun àwòrán, FANTÁSTICO Ọlọpaa meji ni yóò koju ẹsun iwa ọ̀daràn lẹyin ti aworan to safihan wọn nibi ti wọn ti n fun obinrin aláwọ̀ dúdú kan ni ọrùn mọ́lẹ̀.
Ọjọ Ẹti nikan ni wọn n ṣi mọsalasi, nitori isede coronavirus.
Wọ́n wá ń bẹ̀rù pé kí ọkọ̀ má forí sọ òkúta.
Ó sọ èyí di mímọ̀ lẹ̀yìn ìpàdé pẹ̀lú àjọ tó ń mójú tó ààbò oúnjẹ tó wáyé ní ilé ìjọba nílù Abuja.
Idi si ree ti ọpọlọpọ eeyan fi n pe e ni Gomina Kosẹlẹri nitori oun ni ẹni akọkọ ti yoo wọle fun ipo gomina ni saa keji ninu itan oselu ipinlẹ Oyo, nitori saa kan pere ni awọn gomina to wa niwaju rẹ ṣe.
Ooni Ifẹ bu ẹnu ẹ̀tẹ́ lú ètò BBNaija nítorí ó tàbùkù àsà Yoruba Ẹgbẹgbẹ̀rún ọmọ Naijiria ní yóò má a kú lójoojúmọ́ tí wọn bá gbà wọ́n láàyè láti gbébọn dání- Amofin Ṣé ìrànwọ̀ ni Kamala, ìgbákejì tí Biden yàn yóò jẹ́ fún un tàbí ìpalára?
Bí mo bá wí fún eniyan burúkú pé yóo kú, tí o kò sì kìlọ̀ fún un pé kí ó yipada kúrò ní ọ̀nà ibi rẹ̀, eniyan burúkú náà yóo kú nítorí ẹ̀ṣẹ̀ rẹ̀, ṣugbọn ọwọ́ rẹ ni n óo ti bèèrè ẹ̀jẹ̀ rẹ̀.
Ṣebí Solomoni ọba pàápàá dẹ́ṣẹ̀ nítorí ó fẹ́ irú àwọn obinrin bẹ́ẹ̀.
Bakan naa lo tun kawe ni ile iwe eto abo to wa ni Jos, Abuja ati Accra, ni Ghana.
Amọṣa, fidio ọjọ to ti pẹ sẹyin ni lasiko ti agbẹnusọ fun aarẹ Buhari, Fẹmi Adeṣina fi n ba ikọ ileeṣẹ iroyin abẹle Channelstv sọrọ lori iwọde miran to waye nigba naa.
Ó sì pín oúnjẹ fún gbogbo wọn, lọkunrin ati lobinrin.
AFCON: Amuneke lọmọ Nàìjíríà kejì tó gbé orílẹ́èdè míì lọ sí ìdíje ilẹ̀ Afirika
lee ni tori pe a n dije ninu ibo, ki a wa fi aabo ara ilu ṣere”Lara awon eniyan jankan-jakan ti peju ninu ipade ohun ni, igbakeji
Torreira lanfaani lati pada si ẹgbẹ agbabọọlu Arsenal lẹyin ọdun kan.
Òrò Yorùbá: fún ìgbé láruge èdè, ìse, àsà àti lítírésò Yorùbá.
Bakan naa s ni, lati jo jiroro po lori awon ona ti won tun le gba lati gbogunti iwa-ibaje.
Ambode  wa pe awon onile-ise aladani lati fowosowopo, toripe, ijoba nikan ko le da eru naa gbe.
Ọ̀yàyà a máa mú inú dùn,ìròyìn ayọ̀ a sì máa mú ara yá.
Zamfara Food Poisoning: Iyọ̀ onímájèlé tí wọn fi se oúnjẹ fa inú rírun fún mọ̀lẹ́bí kan
Abewo Alhaji Atiku Abubakar sipinle Benue niroyin fi mule pe O waye lati fi bere fun atileyin ipinle naa, bee si ni saaju idibo abele egbe oselu PDP fun ipo aare ti yoo waye lojo kefa osu kewa odun ti a wayii.
Lakotan, ijọba Eko fi opopona kan ladugbo Ikoyi sọri Oyinkan Abayomi lati fi bu ọla fun akọni obinrin naa, eyi to gbajumọ nilu Eko Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Kid boxer: Ọmọọba 'The Buzz' Larbie rèé, ọmọ ọdún méje tó ń fi ẹ̀ṣẹ́ dá bírà Iku Oyinkan Abayomi ati ẹkọ ti igbe aye rẹ kọ wa: Ọjọ Kọkandinlogun, osu Kẹta, ọdun 1990 ni akọni obinrin, ololufẹ mẹkuunu ati asaaju obinrin naa, Ọlọla Oyinkansola Abayomi jade laye lẹni ọdun mẹtalelaadọrun.
“Ọmọ-ọ̀dọ̀ tí ó bá mọ ohun tí oluwa rẹ̀ fẹ́, ṣugbọn tí kò múra sílẹ̀, tí kò sì ṣe ìfẹ́ oluwa rẹ̀ yóo jìyà pupọ.
Kò sí ọjọ́ kan láti ìgbà tí mo ti kúrò lọ́dọ́ yín tí n kò rántí rárá, wákàtí kan kò tilẹ̀ rékọjá láì pé mo ronú nípa yín, orí ẹ̀mí mi ni ẹ dúró lé, n kò sò le mu yín kúrò lọ́kàn rárá.
12 Ògún 2019 Oríṣun àwòrán, Others Àkọlé àwòrán, Ìjọba àpapọ́ ní ẹgbẹ́ òsìsẹ́ tún bèrè fún àfikún owó osù fún àwọn tó ń gba owó osù tó ju 30,000 Naira tí wọn béré fún lọ.
Ẹ wò wá ẹ wo iṣẹ́ ọwọ́ wa Yàtọ̀ sí eku gọ́tà tàbí èku inú ilé, kò sí eku téèyàn ò lè jẹ - Òǹtajà Eléwé ọmọ Aláàfin ìlú Oyo, Ikú Bàbá Yèyé tún bímọ tuntun làǹtì lanti 'Mi ò fẹ́ gbé àrùn Coronavirus lọ sí Áfíríkà' O wa rọ gbogbo awọn olugbe ipinlẹ Eko lati tete fi to ijọba leti, bi wọn ba kẹẹfin ẹnikẹni to n ṣafihan awọn aisan iba ti ko fẹ gbọ ogun ati itọju, ki ijọba lee tete gbe wọn lọ fun ayẹwo ati itọju to ba yẹ.
Àwọn ilé iṣẹ́ kan ti kéde pẹ̀lú pé àwọn ni ọ̀nà àbáyọ míràn, wọ́n ni àwọn ti ṣe ètò láti máa fí ọkọ̀ òfurufu.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Yorùbá tone mark: Fífi àmì ohùn sí orí ọ̀rọ̀ Yorùbá ṣe pàtàkì Ororo Awọn eeyan maa n ri ororo jala mẹẹdọgbọn ni ẹgbẹrun mẹsan an aabọ naira ki ibode to di titi pa ṣugbọn bayii o gbọdọ ni ẹgbẹrun mọkanla si mẹẹdogun lọwọ koo to le ra ororo to tẹ ẹ lọrun.
Wọ́n mú aadọrin owó fadaka ninu ilé oriṣa Baali-beriti fún Abimeleki.
Má jẹ́ kí Ọlọrun bínú sí ọ, kí ó má baà pa iṣẹ́ ọwọ́ rẹ run.
Ara àwọn ọmọ ogun Israẹli ti hù ní ọjọ́ náà, àárẹ̀ sì mú wọn, nítorí pé Saulu ti fi ìbúra pàṣẹ pé ẹnikẹ́ni tí ó bá fi ẹnu kan nǹkankan títí di àṣáálẹ́ ọjọ́ náà, títí tí òun yóo fi gbẹ̀san lára àwọn ọ̀tá òun, olúwarẹ̀ gbé!
Mo sọkun, mo si ro pe maa ku.
Awọn ẹja inu odo ati awọn ẹranko inu okun ma n jẹ nylon ati rọba ti wọn ba ri i nitori o dabi ounjẹ, amọ iku lo jẹ fun wọn.
aimọye eniyan to fara won jin, awon egbe, ati  ọmọ orilẹ ede Naijiria ti won fi akoko won sile  fun aseyọri eto idibo yii.
 Ó jọ bí àkọkọ ́ kòkòrò àkóràn àrùn láti yọkúrò .
Biliọnu meji naira ni ajọ naa ni oludari yi ati awọn miran lu ni ponpo.
9 99155 Orilẹede Ireland 2099 43.
Asole iko ohun, Igor Akinfeev, ti oun wo aso orile-ede Germany, ti n se iko agbaboolu orile-ede ti o darajulo lagbaye, soro leyin aworan naa pe,“A ki iko agbaboolu orile-ede kookan ti yoo maa kopa ninu idije yii,”“eleyi yoo si tun fi han won pe, a ti setan lati gbawon laleejo.
 yàtọ ̀ sí èyí , owó tí olóyè ogunde fi ṣe fíìmù yìí fẹ ́ ẹ ̀ lè má pé nígbà tí wọ ́ n tà á tán .
sunkere- fakere to ma n waye ni ibudo ọkọ oju omi, to wa ni Apapa pelu sunkere
Àwọn obìnrin orílẹ̀-èdè Iran ti lè wo bọ́ọ̀lù aláfẹsẹ̀gbá báyìí
Àwọn óo kọsẹ̀, wọn óo sì ṣubú,ṣugbọn àwa óo dìde, a óo sì dúró ṣinṣin.
"Nítori àwọn àtúgbẹ́yẹ̀wò, o níra láti ṣe àkójọpọ fún àwọn ọkọ́ naa Orisun: Johns Hopkins University atawọn ajọ eto ilera ilu Iye akọsilẹ to waye gbẹyin 15 Oṣù Ṣẹ́rẹ́ 2021 20:44 WAT+3 "" Àárín èmi àti àwọn tó jí ọmọ gbé nìkan ni mo fẹ́ kí idunadura náà wá, mo sì ní ẹtọ láti lo ọna ti mo ba mọ pe o dara, láti dáàbò bo ohun tí Ọlọ́run fún mi."
olubori ninu eto idibo  ile igbimo asofin
Oríṣun àwòrán, Getty Images Alaga ajọ NAHCON naa ni ipinnu rere ni nkan ti awọn alaṣẹ ijọba ilẹ naa ṣe lati da abo bo awọn ti wọn wa lorilẹede naa.
Coronavirus: Àwọn ohun tí a kò tíì mọ̀ nípa àrùn Covid-19 Àrùn Coronavirus fa'lẹ̀ya láwọn ìletò aláwọ̀dúdú ní Amẹ́ríkà Kí lo mọ̀ nípa fẹntilétọ̀, ohun èlò aṣèrànwọ́ èémí Èyí ni ìdí tí coronavirus ṣe n pa àwọn kan, tí kò sì pa àwọn kan Coronavirus, ti orukọ taa mọ si a si ma jẹ Sars-CoV-2,le gba ijọba ara rẹ ti o ba mii si inu lẹyin ti eeyan kan ba wu sita bi ikọ tabi ti o fọwọ kan kokoro naa ti o si mu ọwọ rẹ fi kan oju.
Wọ́n jẹ́ ẹ̀bùn fún OLUWA, wọn óo sì máa ṣiṣẹ́ ninu Àgọ́ Àjọ.
Abramu gba OLUWA gbọ́, OLUWA sì kà á sí olódodo.
"Oríṣun àwòrán, Marvi Lacar Àkọlé àwòrán, ""Àlùfàá méjì wà lára àwọn mẹ́rin tó fi ipá bámilòpọ̀"" Ẹgbọn mi ọkunrin a ti ẹ tun maa na mi, ibaṣepọ pẹlu awọn obi mi paapa ko dara."
Kí o tó dá àwọn òkè,ati kí o tó dá ilẹ̀ ati ayé,láti ayérayé, ìwọ ni Ọlọrun.
Nurudeen Adam ti n ṣe ohun elo orin yii fun ogun ọdun o le bayii ṣugbọn ko ri iranwọ latọdọ ijọba.
Ọba Ilọrin sọ pe ohun ti oun yoo se niyẹn, oun gbẹsẹ le.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Yoruba Culture: ọjọ́ méje ni wọ́n fí n rẹ ẹ̀kú Danafojura kó tó jáde Nigba to di ọjọ kan, Lisabi kọlu awọn Ilari to wa ni adugbo to n gbe ni Igbẹyin.
Iyalẹnusi lo jẹ ni ọsan oni nigba ti ikọ iroyin BBC se awari awọn eeyan kan ti wọn n rọ kẹti-kẹti lọ si ile ijọba atijọ to wa ladugbo Okesha ni ilu Ado Ekiti, tii se olu ilu ipinlẹ Ekiti.
Ẹnu yà wọ́n pé obinrin ni ó ń bá sọ̀rọ̀.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Claudiah: ìrẹ̀wẹ̀sì ọkàn bá mi fínra fún ọpọlọpọ ọdún Onnoghen ṣalaye ninu iwe awijare to fi sọwọ si ile ẹjọ to n gbẹ ẹsun aṣemaṣe awọn to di ipo ilu mu, CCT pe iyapa to wa laarin fọọmu ikede dukia meji, No.
Bakan naa ni awọn oluwọde sọ iloro ti ijọba ipinlẹ Eko ti n gba owo ibode ni Lekki di ile, nitori ọpọ ninu wọn lo kọ lati pada sile wọn, bakab naa ni wọn sọ ibẹ di ile ijọsin lọjọ Isinmi.
Ibeere to wa lọkan àwọn akọroyin ni pe ṣe a kò gbodo gbe iroyin iṣẹ iwadii to ba ti ṣe lodi si ọlọpaa tabi ijọba sita mọ ni?
Àkójọ́pọ̀ àwòrán rèé lórí bí ìwọlé akẹ́kọ̀ọ́ ṣe lọ sí ní Oyo Bí àwọn adarí ìjọba ṣe ń kó Coronavirus, ń kọ wá lóminú - Ìjọba àpapọ̀ Ẹ̀yin ẹlẹ́gbẹ́ òkùnkùn tẹ fẹ́ ṣe àjọ̀dún lónìí, lákọ la ń dúró dè yín - Iléeṣẹ́ ọlọ́pàá Ìjọba Akeredolu kò ní omi àánú lójú, a kò tọ́jú alárùn Coronavirus mọ́ - Dókítá Ondo Bi abadofin naa ba di gbigba wọle nile igbimọ aṣofin agba ti wọn si fi ṣọwọ si ile igbimọ aṣojuṣofin, ti awọn mejeji ati aarẹ si fọwọ si i ko fi di ofin.
Asoju ilẹ Naijiria ni Ghana, Ambassador Micheal Abikoye lo sọ eyi di mimọ lasiko to n se ipade pẹlu adari eto irinna ni ilẹ Ghana, Kwame Takyi.
Lagos Building Collapse: Ìjọba ìpínlẹ̀ Eko gbé ìgbìmọ̀ olùwádìí kalẹ̀
"Gẹgẹ bi gomina ipinlẹ Edo ṣe sọ, ""Adams Oshiomhole atawọn ọmọ ẹgbẹ oṣelu APC kan, pẹlu gomina Hope Uzodinma lo wa nidi iṣẹlẹ naa."
Ó dàgbà, ó darúgbó lọpọlọpọ kí ó tó kú.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Sotitobire: Ọkọ mi kò mọ̀ Jegede PDP rí, kódà kò fa ẹnikẹ́ni kalẹ̀ dípò Akeredolu- Bisola Bi idanilẹkọ naa yoo ṣe ti niyii: Awọn ọlọpaa lati ẹkun Ila oorun Gusu ati Gusu-Gusu Naijiria yoo gba idanilẹkọ ti wọn ni Counter Terrorism College, to wa ni Nonwa-Tai, ipinlẹ Rivers.
orilẹ-ede Naijiria lati tete gbe igbesẹ lati daabo bo awọn ọmọ orilẹ-ede
Ayẹyẹ àmì ẹ̀yẹ AMVCA elekeeje irú rẹ ni ti ọdun 2020 yìí, ọ̀pọ̀ àwọn òṣèré Nollywood lo ti péjú sibẹ̀, lára wọ́n ni àwọn adẹ́rin pa òṣónú, àwọn olorin àti awọn oni tiata, olóṣèlu gan kò gbẹ́yin níbẹ̀.
Oríṣun àwòrán, NCDC Àkọlé àwòrán, Àjọ NCDC kéde èèyàn 239 míràn tó ni ààrùn Covid-19 lórílẹ̀-èdè Naijíríà Oríṣun àwòrán, NCDC Àkọlé àwòrán, Àjọ NCDC kéde èèyàn 386 míràn tó ni ààrùn Covid-19 lórílẹ̀-èdè Naijíríà Èsì àyẹ̀wò àwọn ènìyàn to ni ààrùn Corornavirus fi hàn pé ènìyàn ọ̀ọ̀dùrún lémẹ́rìdíláàdọrun lo tún ti lùgbàdì àrùn náà.
Alaga ajo to n mojuto eto idibo lorile-ede Naijiria, (INEC) ojogbon Mahmud Yakubu, yoo sepade pelu apapo awon oludari ile-igbimo asofin lojo isegun(Tuesday) ni erongba lati panupo bowolu òjìlénígba lé meji bilionu Naira(N242 billion) ti n se owo isuna fun eto idibo odun 2019.
O tun wa dupe lowo komisona  naa fun gudu gudu-meje ,yaya-mefa ti won n se lati pese eto aabo ni ipinle naa , bo tile je pe omi poju oka lo.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ọlọ́pàá 30,000 ní yóò mójútó ìdìbo Ekiti Wo Ọ̀jọ̀gbọ́n Eleka tó ń díje fún ipò gómìnà Àwọn ṣajẹ tó gbayì jù láwùjọ FFK ni 'mo sunmọ Buhari, ṣugbọn ko ṣiṣẹ to yẹ nijọba to ń darí'.
Ajọ WHO ni bi a ba wa ri awọn asiko ti awọn eeyan na owo beba, ki wọn rii daju pe wọn n fọ ọwọ wọn ni kiakia.
5 Lõtọ́, ni mo wí fún ọ, pé ègbé yíò wá sí ọ̀dọ̀ àwọn olùgbé orí ilẹ̀ bí wọn kò bá fetísílẹ̀ sí àwọ̀n ọ̀rọ̀ mi;
Nítorí ìjọba Ọlọrun kì í ṣe ọ̀ràn nǹkan jíjẹ ati nǹkan mímu, ọ̀ràn òdodo, alaafia ati ayọ̀ ninu Ẹ̀mí Mímọ́ ni.
Àmọ́ àwọn ìdàkejì wí pé láyé àtijọ́, kò tíì sí àwọn ìbọn alágbára ti òde òni.
Yóo ní alufaa gẹ́gẹ́ bí olùdámọ̀ràn, wọn yóo sì máa ṣiṣẹ́ pọ̀ ní alaafia.
 gbogbo ìṣẹ ̀ lẹ ̀ tí ó ṣẹlẹ ̀ sí i yìí ni ó ń hàn nínú ọ ̀ pọ ̀ lọpọ ̀ ewì tí ó kọ .
Olodumare sọ fun wọn pe ọtọ ni iroyin ti ikọ oun mu wa.
Oríṣun àwòrán, @jorowasinda A gbọ pe wakati mẹfa gbako ni wọn fi da ilu Garkida naa, to wa loju ọna Damaturu laamu, eyi ti ko jinna si guusu Borno ati igbo Sambisa.
Osinbajo ta kété sí ọ̀rọ̀ 'Ruga Settlement' Sọ àsọtẹ́lẹ̀ orílẹ̀èdè tí yóò borí ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ t'òní Taiwo Akinkunmi, ọmọ Ibadan tó ya àsìá Nàíjíríà Ni ọjọ Ẹti iroyin lu ori ayelujara pa nipa Busọla Dakolo to fi ẹsun kan alufaa Fatoyinbo pe o fi ipa ba oun lo pọ ni ọdun diẹ sẹyin.
Iru awọn iroyin ti ẹ le nifẹ si: 'Esi Jamb ko nii jade lẹsẹkẹsẹ' 'Akonimu BBC' Jamb padanu owo s'ikun ejo Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí 2 sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 2:23 Fídíò, Water Generator: Ó leè ṣiṣẹ fún wákàtí mẹfà, kó tó sinmi, Duration 2,2310 Òkùdu 2020 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
MC Oluọmọ ni o ti kọkọ fi igba kan jẹ ọmọ egbe awakọ ni agbegbe Oshodi ni Ilu Eko to si jẹ mọlumọọka.
Ìyá mi dáhùn, ó sì wí pé:
Alagbawi ati ajafẹtọ fun awọn ọmọde, Oluwatoyin Ojo ti bu ẹnu atẹ lu iwa aitọ ti baba naa hu si ọmọ rẹ.
Aridaju aseyoriDanbatta salaye pe, nigbati ile-ifowopamo agba ba n se agbeyewo olowo to pegede julo lati ra oja basa 9mobile, ajo NCC yoo maa wa onibara ti o le pese ise to yanranti, “ eyi ni awon igbese ti a gunle lati fese ile-ise etisalat mule ati lati dena asise ti o waye seyin”.
Emerole ni obinrin tawon ọlọpa gbamu naa ko ni pẹ foju bale ẹjọ, ati wipe awọn to ma n tọju awọn ọmọ ti ko ni obi, ti bẹrẹ sini fun ọmọ ti wọn jigbe naa ni itọju.
lati yan an gege bi abenugan ile igbimo asofin kẹ́sán án fun ipinle Oyo.
Ọlọ́pàá kọlu àwọn ọmọ onílẹ̀, ní ìbọn àṣìyìn pa ènìyàn méjì Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Ondo Election 2020: Ẹ wo àwọn olùdíje sípò gómìnà nípínlẹ̀ Ondo tó takò bàbá ìsàlẹ̀26 Owewe 2020 Fídíò, Wole Soyinka sọ ìdí tó fi ni òun a fi màálù Fulani ṣe súyà fáwọn èèyàn abúlé23 Owewe 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
 kò pé púpò , ni wón bá ń pe àwon ará òkè yìí ní awon onílé ìdòtí àgbàrá-òkè .
Oludari eka to n mojuto ilana eto ile-ise ni ipinle Kaduna ,ogbeni Uday Mishram lo soro yii ni ipinle Kaduna to je ila- oorun orile ede Naijiria lo so eleyii nigba to n ba awon oniroyin  soro lati salaye awon isoro to n dojuko ile-ise naa.
Nisinsinyii lọ kọ ọ́ sílẹ̀ níwájú wọn,kí o sì kọ ọ́ sinu ìwé,kí ó lè wà títí di ẹ̀yìn ọ̀la,gẹ́gẹ́ bí ẹ̀rí títí lae;
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ikú ọkọ mi ṣì n dàbí àlá l'ójú mi àtawọn ọmọ Ikọ̀ ẹlẹ́sìn Hàkíkà rèé, níbití wọn ti ń pààrọ̀ ìyàwó láàrín ara wọn Àwọn ọmọ Iyabọ Ojo rí Bàbá lẹ́yìn ọdún mẹ́fà Ìwọ́de, ìkọ̀wéfipò sílẹ̀, ìdìbò abẹ́lé Osun kò fé bí'mọ re O ni awọn ọkẹẹgbẹ oun ni ile ẹkọ girama naa da oun mọ, bii isana ẹlẹẹta, nitori odu ni oun nile ẹkọ naa, kii se aimọ fun oloko, taa ba n sọrọ ọrọ idaraya.
Kódà aiyé tó d’aiyé aiyélujára yìí, ó tún nṣiṣẹ́ ẹ̀rọ ìbánisọ̀rọ̀.
Olukuluku wọn gbé obinrin kọ̀ọ̀kan sá lọ ninu àwọn tí wọ́n wá jó, gbogbo wọn sì pada lọ sí ilẹ̀ wọn, wọ́n tún ìlú wọn kọ́, wọ́n sì ń gbé ibẹ̀.
Bi ó tilẹ̀ jẹ́ pé orí ibùsùn aláìsàn ló wà lásìkò nàá, èyí kò dáwọn dúró láti gbé aṣòfin nàá, tí wọn fẹ̀sùn ìwà ọ̀daràn kàn lọ síwájú ilé ẹjọ́.
Oríṣun àwòrán, Oyo state ministry of education Isọri alakọkọ ni yoo wọle sile ẹkọ lati aago mejọ aarọ si aago mẹwa abọ aarọ, ti wọn yoo si pada sile wọn.
Oluwakaponeski ní ọmọogun ilẹ̀ Amẹ́ríkà ni òun tẹ́lẹ̀ kí òun tó di aláwàdà
Egbe UFUK ti kii se ti ijoba ati fun ere ,
Boko Haram: Pásítọ̀ Adeboye ní Ikọ̀ Boko Haram àti gbogbò àwọn tó ń sàtìlẹyìn fún wọn kò ní rí ọdún tuntun
Nike Davies-Okundaye: Àṣírí tó wà nídìí ìmúra mi
Òun ni olùṣọ́nà ń ṣí ìlẹ̀kùn fún.
Russia 2018: Aare Buhari pase ki wọn lọ ko awọn alátilẹyin àgbabọọlu pada sílé
“Bákan náà, nígbà tí àlejò kan, tí kì í ṣe ọmọ Israẹli, bá wá láti ilẹ̀ òkèèrè nítorí orúkọ rẹ, 
June 12 èso àwọn ohun málèègbàgbé nípa MKO Kò sí ìwé ìrìnnà 'VISA' fáwọn ọmọ Naijiria tó hùwà àìtọ́ nígbà ìdìbò A ó gbé'gbésẹ̀ lẹ́yìn ìwádìí fídíò tí Dino ti ń náwó lójú agbo- Ọlọ́pàá EFCC kó akẹ́kọ̀ọ́ fásitì UNIOSUN Àwọn adarí ìhà gúúsù, àti àrin gbùngbùn Nàìjíríà to fi mọ Pa Adebanjo tó jẹ adarí ẹgbẹ́ Afẹnifẹre kọọ nínú àtẹjisẹ kan pé àwọn ò ni kópa nínú àpérò náà.
Lẹ́hìn eléyìí pàápàá, nígbà tí bàbá mi ṣìnà sí inú Igbó Olódùmarè  tí ó sí fi di pé ó pa Òjòlá-ìbínú tí í ṣe olórí ejò ayé gbogbo, bàbá mi tún rí àdó kan mú bọ̀ tí ó ń mú owó fún un.
Ní ìmọ̀ síi nípa bí BBC ṣe ń rí owó ìsúná rẹ̀ yálà ní ilẹ̀ Gẹ̀ẹ́sì tàbí láwọ́n orilẹ̀-èdè òkè òkunBBC Charter on the independence of the BBC.
Aare teleri Laurent Gbagbo  n koju igbejo nile-ejo ti o n ri si iwa odaran lagbaye ti o fidi kale si ilu Hague, latari esun ti won fi kan pe, o n sagbateru laasigbo leyin eto idibo, leyin ti o padanu ipo naa fun alatako re Ouattara.
Sugbọn sa, awọn ijọba kan ni igbagbọ pe bi wọn ba tẹle ilana itakete-sira-ẹni eyi le daabo bo awọn akẹkọọ lọwọ arun yi.
Èmi àti Sanyeri ti tọrọ oúnjẹ jẹ rí nílé oninawo torí ebi, ká tó di gbajumọ oṣere Ta ni Yusuf Satia ti iku mu lọ?
Nígbà tí àwọn ará Amoni rí i pé àwọn ará Siria ń sá lọ, àwọn náà sá fún Abiṣai, wọ́n sì pada sinu ìlú.
Awon osise ile-ise to n ri si isele pajawiri lorile-ede naa ti bere ise ni gbayawu bayii ni ona lati wa awon ti o fara kaasa isele ohun, leyin ti opo eniyan ti di awati.
Iṣẹ́ tí OLUWA rán Joẹli, ọmọ Petueli nìyí:
Wọ́n ti kéde Mohammed Umar gẹ́gẹ́ bí alága fìdíhẹ àjọ EFCC Saaju la ti mu iroyin wa fun yin pe ijọba apapọ ti kede Mohammed Umar gẹgẹ bi alaga fidi hẹ ajọ to n gbogun ti iwa ibajẹ ni Naijria, EFCC.
Igbakeji Adari ẹka naa, Hannah roberts lo sọ bẹẹ lasiko to n ba awọn oniroyin jomitoro-ọrọ ni Abuja, olu ilu Naijiria.
Ẹgbẹ Afẹnifẹre ṣalaye pe niwọn igba ti ijọba apapọ ba ṣi ni i lero ati gbe igbesẹ naa dide lọjọ iwaju, awọn ko lee fi gbogbo ara dunnu si ikede naa.
Ipinlẹ Eko, Ogun, Abuja ati Kano ni wọn ti kede pe awọn afurasi naa wa ṣugbọn ko tii si ẹni ti wọn ri to ti ni arun Coronavirus ni pato ni Naijiria.
Ta ló lè ka àwọn ọmọ ogun rẹ̀?
Alhaji Bello Bala,alaga egbe oselu People Democratic Party (PDP), Alhaji
Gege bi ajo FIFA se so ninu oro won lojo abameta(Saturday), won ni, won yoo faye gba opo eniyan lati wa wo ife-eye ohun lofe, ti o fi mo awon oniroyin.
" A n se akojọpọ ẹkunrẹrẹ iroyin yajoyajo lọwọ, a o maa gbe ẹkunrẹrẹ iroyin naa sori atẹ iroyin wa laipẹ.
Ṣugbọn wọn pinya lẹyin bii ọdun mẹwaa.
Alaye awọn to ṣe agbatẹru iwọde naa nipa ohun to mu wọn gunle iwọde ọhun ni wi pe ko bojumu ki ijọba apapọ to n ṣe atilẹyin fun ikọ HISBAH ni ẹkun ariwa orilẹede yii, kede pe ifilọlẹ eto AMỌTEKUN nilẹ Yoruba ko ba ofin Naijiria mu.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Nigeria Democracy: Buhari buwọ́lu àbádòfin 'June 12' gẹ́gẹ́ bí àyájọ́ ọjọ́ ìjọba àwarawa 11 Òkùdu 2019 Oríṣun àwòrán, Twittter/Muhammadu Buhari Lẹyin ọ rẹyin, ''June 12'' pada ayajọ ọjọ isinmi ijọba awarawa lorilẹede Naijiria lẹyin ti Aarẹ Muhammadu Buhari buwọ lu abadofin naa.
A gbọ pé awọn ọmọ ogún ìjàyè, Ẹ̀gbá, Ìjẹ̀bú àti Fulani di ọ̀nà mọ àwọn ọmọ ogún Ibadan, ki wọn máa leè ni anfaani sì àwọn èròjà tí àwọn oyinbo aláwọ̀ funfun ń kó wá bíi iyọ̀, ẹtu àti bẹẹ bẹẹ lọ.
Ajọ LASTMA ni awọn yoo ṣewadii iwa ti awọn oṣiṣẹ wọn hu yii, awọn yoo si fi ẹni ti igba ọrọ naa ba ṣi mọ lori jofin.
’ Ogun ati ìyàn ati àjàkálẹ̀-àrùn ni yóo pa ilé Israẹli nítorí ìwà ìríra wọn.
Lopin odun ni a maa n lo anfaani yii lati wo awon
bi aare Buhari“Mo finu-fido ki o ku oriire.
 Ọrangun fikun pe, ti isẹlẹ naa ko ba tiẹ to awọn loju, amọ mọ igba ti Oluwo lọ fi abuku kan Alake nilu Abẹokuta, nibi eto kan ti onitọun pe si, to si ni ori aga ti wọn pese silẹ fun Ọọni, ni oun fẹ joko le lori nitori Ọọni ko ju oun lọ."
Gbogbo ohun tí wọn ń ṣe, wọ́n ń ṣe é kí eniyan lè rí wọn ni.
to n mojuto boolu afesegba nile Afriks, CAF won ni o seese ki o je pe orile-ede
Awọn ti ọrọ naa soju Wọn ni ọkunrin naa ti sọ ọ́ bi ọjọ meji sẹyin pe iyawo oun ń dún kooko mọ́ oun pẹlu ọbẹ nitori iwe ogún ti o fẹ ṣe fun ọmọ rẹ̀ lati ọdọ iyawo tó kọ silẹ, ki o to fẹ oun.
"O ṣalaye pe ""Lara awọn eto ti a pinnu lati ṣe ni lati lo ọjọ Isẹgun ati Ọjọru lati ṣagbeyẹwo bi awọn eeyan yii ṣe de ipo giga ti wọn wa, ati awọn ẹkọ ti a lee kọ lara wọn, ṣugbọn a ni lati gbe aba naa ti sẹgbẹ kan nitori ibẹru arun Coronavirus to n ja nilẹ."
Oríṣun àwòrán, Reuters Àkọlé àwòrán, Caracas, Venezuela Iṣoro ọrọ aje ati oṣelu Igbe aye awọn eniyanm ni Venezuela bẹrẹ́ si ni le koko plu ifasẹyin ọrọ aje, aito ounjẹ ati oogun to fi mọ ọrọ iṣẹ oojọ ti gbogbo ti fẹ di akurẹtẹ.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ìdí tí Obìnrin fi lé saǹ ìdajì owó láti ra fọ́ọ̀mù ìfèróngbà han Sùgbọ́n ní báyìí ọ̀rọ̀ náà ti di ẹni bá láyà ka wá wọ̀ọ́ bí àwọn ọkunrin náà ṣe ń gbin láti dupò ààrẹ, nítori olówó nìkan ni ipò náà wà fún bayíì.
ṣugbọn wọn yóo máa búra pé, ‘Bí OLUWA tí ń bẹ, ẹni tí ó kó àwọn ọmọ Israẹli jáde láti ilẹ̀ àríwá ati láti gbogbo orílẹ̀-èdè tí ó lé wọn lọ.
Ikọ agbabọọlu mejeeji gbiyanju lati bori ninu ifẹsẹwọnsẹ yii titi ṣugbọn o dabi ẹni pe ko si ọna abayọ.
ibi ti wọ́n ọ̀rọ̀ náà de ni èyí tí ọ̀gbọ́n obìnrin náà dáhùn tí ó wí pé:
"Bákan náà, ó ni, ""àwọn òṣìṣẹ́ àjọ nàá tó fi àwọn ilé tí wọn yá ṣe ọ́fíìsì nílùú Abuja, yóò ṣì maa lo àwọn ilé nàá."
Lójijì ọpọlọpọ àwọn ogun ọ̀run yọ pẹlu angẹli náà, wọ́n ń yin Ọlọrun pé,
Nínú ọ̀rọ̀ rẹ, ààrẹ ẹgbẹ́ IPMAN ní Nàìjíríà Chinedu Okoronkwo sàlàyé pé, ẹ̀dínwó epo látọ̀dọ̀ ìjọba tí kásẹ̀ nílẹ̀, síbẹ̀ àjọ tó n rí si iye owó ti wọ́n n ta epo lábẹle náà n fi gbédéke iye tí ilé epo aladáni gbọdọ̀ ta epo síta.
Bí ó bá jẹ́ pé mo ti jẹ ẹran ẹbọ ìmúkúrò ẹ̀ṣẹ̀ lónìí ni, ǹjẹ́ ẹbọ náà lè jẹ́ ìtẹ́wọ́gbà níwájú OLUWA?
Jesu bá pa òwe yìí fún wọn.
Oríṣun àwòrán, khafibbn_officialfanpage O wa pari ọrọ rẹ pe o ṣeeṣe ko jẹ pe Mike lo maa jawe olubori ninu idije Big Brother naa.
'Ológun kò ṣe àyọjúràn sí ìdìbò 2019' Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Seyi Makinde: Màá fẹ́ káwọn aráàlú mọ ìpa ìjọba mi lára sí rere Ní àgbo àwọn ọmọwe, wọn ni ọjọgbọn Adesanmi ni wọn woye pé yóò ropò ọjọgbọ́n Wole Soyinka, nígbà ti wọn ba lọ ibi àgbà ń rè.
ó jíròrò pẹlu àwọn òṣìṣẹ́ ati àwọn ọ̀gágun rẹ̀ bí wọn yóo ti ṣe dí ìṣàn omi tí ó wà lẹ́yìn odi ìlú; wọ́n sì ràn án lọ́wọ́.
Ìkọlu tuntun yìí wáyé lẹ́yìn ọjọ́ díẹ̀ tí ọ̀kan wáyé.
kaakiri awọn ibudo idibo to wa jake-jado orile-ede Naijiria.
Ki ni o fẹ́ pa ara rẹ lọ́jọ́ àìpé fún?
Nígbà tí Mose dàgbà tán, nípa igbagbọ ni ó fi kọ̀, tí kò jẹ́ kí wọ́n pe òun ní ọmọ ọmọbinrin Farao.
Amọ wahala nla kan bẹ silẹ lọdun 1969 nilu Ogbomoso to wa nipinlẹ Oyo bayii, eyi to kọja agbara ọba, koda, o tun mu ẹmi rẹ lọ pẹlu.
 pe ki won maa  sami  ayeye
Oko tí talaka dá lè mú ọpọlọpọ oúnjẹ jáde,ṣugbọn àwọn alaiṣootọ níí kó gbogbo rẹ̀ lọ.
Abuja-Kaduna: Àwọn arìnrìn àjò ní àwọn ọlọ́pàá kò leè ta pútú
Ṣe ni awọn ọmọ ogun tirẹ ba iṣẹ naa jẹ.
Fayose: Ojuti nla ni aawọ nipa ibiti Leah Sharibu wa
Èyí ẹ̀kẹta jẹ́ ońwàpẹ̀lẹ́ ènìyàn, ṣùgbọ́n baba tíó bí baba rẹ̀ burú ju májèlé lọ, bẹ́ẹ̀ ni Ẹlẹ́dàá tí ṣe ìlérí náà pé, òun kò nì ṣàìbẹ ẹ̀sẹ̀ baba wò lára ọmọ títí dé ìran kẹta àti ẹ̀kẹrin nítorí ẹni tí ó bá ń hùwà tí ó fẹ́, ọmọ olúwaarẹ̀ ń bọ̀ wáá jèrè ìwà náà lẹ́hìn ọ̀la.
Wọ́n jáde lọ sọ́dọ̀ àwọn ọba ní gbogbo ayé, láti kó wọn jọ fún ogun ní ọjọ́ ńlá ti Ọlọrun alágbára jùlọ.
Ni ọdun 1959 ni Awolowo da ileeṣẹ amohunmaworan Naijiria silẹ, eyi to jẹ akọkọ iru rẹ nilẹ Afirika.
Iru ẹni bẹẹ ko lee yee rara.
Ẹ̀kọ́ nípa Ipò Ọkọ ati Aya sí Ara Wọn.
Alamojuto agba Ile-isẹ Rite Food Ltd, Ọgbẹni Saleem Adegunwa fi mulẹ pe ile-iṣẹ naa n sa gbogbo ipa lati ṣatilẹyin fun ohun ti yoo gbe ogo orilẹ-ede Naijiria ga.
Wọ́n fún àwọn ará Sidoni ati àwọn ará Tire ní oúnjẹ, ohun mímu, ati òróró; wọ́n fi ṣe pàṣípààrọ̀ fún igi kedari láti ilẹ̀ Lẹbanoni.
Ní ti àwọn ẹranko tí ó kù, a gba àṣẹ wọn, ṣugbọn a dá wọn sí fún àkókò kan, àní fún ìgbà díẹ̀.
Iya Welder bi ọpọ ṣe n pe Omolola Arohunmolase ṣalaye fun BBC Yoruba nipa irin ajo aye rẹ ko to di ogbontarigi ajorin-mọrin bayii.
Ẹni tí ó bá gba ọ̀kan ninu irú àwọn ọmọde wọnyi ní orúkọ mi, èmi ni ó gbà.
Ó fi ọ̀ṣọ́ wúrà sára pẹlu oríṣìíríṣìí ìlẹ̀kẹ̀ olówó iyebíye.
Oríṣun àwòrán, @IzetQuotes Fún ẹni tó bá lọ̀ fun Hajj, àwọn iṣẹ kan ṣé kókó tí wọn gbọdọ kopa nínú rẹ tí Hajj náà bá fẹ jẹ itẹwọgbà, ní meni méjì, àwọn iṣẹ náà ree pẹlu àlàyé ṣókí.
Kí o wọ́n omi ìwẹ̀nùmọ́ sí wọn lára, kí wọ́n fi abẹ fá gbogbo irun ara wọn, kí wọ́n sì fọ aṣọ wọn, kí wọ́n sì di mímọ́.
Oríṣun àwòrán, @others Àkọlé àwòrán, Awọn ẹlẹsin Islam lo pọ ju ni orilẹ-ede Morocco Awọn agbẹjọro ti wọn n ṣoju fun Hajara ni irọ ni wọn pa mọọ.
Ni ifẹsẹwọnsẹ to waye lalẹ ọjọ Aiku ni papa iṣire Anfield, ami ayo kan si odo ni Liverpool fi gbẹyẹ mọ Manchester united lọwọ.
Kí á má tún máa fi ìpìlẹ̀ lélẹ̀ mọ́, ìpìlẹ̀ bí ẹ̀kọ́ nípa ìrònúpìwàdà kúrò ninu àwọn iṣẹ́ tí ó yọrí sí ikú, ẹ̀kọ́ nípa igbagbọ ninu Ọlọrun; 
Ẹ̀rù àwọn onigbagbọ wá ń ba gbogbo eniyan.
Ẹni ọdún mẹẹdọgbọn ni Amasaya nígbà tí ó jọba; ó sì wà lórí oyè fún ọdún mọkandinlọgbọn ní Jerusalẹmu.
Iroyin to tẹ wa lọwọ tun sọ pe awon oniṣango lọ ṣe etutu to yẹ ko to di pe wọn gbe oku wọn fun ijọba.
Wọn ri nibi to ti n gbadura ni ilana ẹ̀sìn Juu ni orilede Israel.
Ní ọdún tí Sagoni, ọba Asiria, rán olórí ogun rẹ̀ pé kí ó lọ bá ìlú Aṣidodu jagun, tí ó gbógun ti ìlú náà, tí ó sì gbà á, 
O ni àwọn àgbẹ̀ náà kò rí eré tó yẹ kí wọn rí latari ìpeníjà kòkòrò ajokorun yìí.
Iṣẹ́ Kudirat Abiọla ṣì ń fọhùn síbẹ̀, lẹ́yìn ọdún 23 tó papòdà Ìtàn tó wà nídi òwe ‘Sebótimọ Ẹlẹ́wà Sàpọ́n’ Ẹ dákẹ́ àhesọ ọ̀rọ̀, n kò bí ìbẹta - Yinka Ayefẹlẹ 'Ọmọ Naijiria 25,794 ló kú sí rògbòdìyàn láàrin ọdún mẹ́rin' Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Pẹ̀lú gbogbo bùkátà, Bàbá 80 gboyè Masters Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Adamu ṣeleri yi nigba ti o n ba awọn akoroyin sọrọ nilejọba labuja ni kete ti o ṣe ipade tan pẹlu aarẹ Buhari.
"Oluwo ni ""kò sẹ́ni tó lè bá Fulani tàbí ọmọ wọn jà nínú igbó"" tori naa ọgbọn laa fi n ṣe gbogbo nkan."
Ọlọ́pàá Uganda rí ohun ìpara olóró nínú ‘baby’ tí ẹnìkan pọ́n sẹ́yìn bí ọmọ Ikọ̀ Àmọ̀tẹ́kùn tí ó bá gbé ìbọn yóò wọ gàù- Ọlọ́pàá Naijiria Lord Lucifer ni ó kọkọ ni ènìyàn mílíọnù kan to wòó lóri Youtube- Yekini Bakare O ti lé ni ọdún kan ti mo ti n jí pátá l'ádugbò- Chukwajekwu Eziigbo Ayajọ ọjọ Ẹti Rere: ọjọ kẹwaa, oṣu kérin Ọjọ kẹwaa, oṣu kẹrin, ọdun 2020 ni ayajọ sisami ọjọ Ẹti rere yoo waye ni Naijiria.
Àwọn olùdíje ètò ilé Ẹlẹ́gbọ́n Àgbà BBNaija 2020 wo ni wọ́n yóò fọwọ́ òsì júwe ilé fún lòníì?
Bo tilẹ jẹ pe eeyan 80,491 lo ti ri iwosan gba, awọn 1,361 lo ti jẹ Ọlọrun nipe.
Osun Election Results 2018: Adeleke ní òun yóò gba ipò gómìnà padà, ó sì rí bẹ́ẹ̀
Ṣama ati Elika, àwọn mejeeji jẹ́ ará Harodu; 
Weah ni aarẹ ikẹẹdọgbọn lorilẹede naa lẹyin to gba ipo lọwọ Ellen Johnson Sirleaf to jẹ aarẹ obinrin akọkọ nilẹ Afirika.
Aladesewa ṣalaye pe oun gba ipe pajawiri kan latọdọ aladugbo rẹ kan, Toyin Ilori ni nkan bii agogo meji oru lọjọ aje ti ile rẹ wa lẹyin ile ẹjọ giga ti ilu Ikire.
2 - Ṣé ìtàkùn àgbáyé kan ṣoṣo ló gbé ìròyìn nàá jáde?
atileyin won fun aare lati se ohun malegbagbe lorile ede Naijiria.
Owó iṣẹ́ àwọn òṣìṣẹ́ tí wọ́n ṣiṣẹ́ ní oko yín, tí ẹ kò san fún wọn ń pariwo yín.
Nítorí ẹrú tí a pè láti di onigbagbọ di òmìnira lọ́dọ̀ Oluwa.
o tun wa ro won lati lowo ninu eto iselu abẹle, nitori pe ibẹ ni oselu ti bẹrẹ.
Dókítà yọ oyin mẹ́rin tó n gbé nínú ẹyinjú arábìnrin kán Ọwọ́ tẹ afurasí méjì tó nííṣe pẹ̀lú ìjínígbe Ọgá panápaná l'Eko Kíni ìdí tí àwọn ẹbí àwọn ọmọ Chibok fi ń tọ woli lọ?
Bẹẹ ba gbagbe, asiko rogbodiyan to tẹle iwọde EndSARS ni ọjọ Kọkanlelogun osu Kẹwaa ọdun 2020, ni awọn janduku kan ya bo aafin ọba naa, ti wọn si ji ọpa asẹ ati bata rẹ gbe lọ.
com Saaju la ti sọ fun yin pe, ina nla kan ti ṣẹyọ to si ṣakoba fun ọpọ dukia ni ile itaja iyawo Gomina ipinlẹ Oyo tẹlẹ, arabinrin Florence Ajimobi.
“Ijoba apapo mo riri isinlu won, adura wa ni pe, ki olorun ki O tu awon obi, ebi ati ojulumo won ninu, bee si ni a ko ni ri iru isele buruku yii mo.
9 118432 Orilẹede Morrocco 6245 17.
 nínú ìfọ ̀ rọ ̀ wánilẹ ́ nu wò pẹ ̀ lú olóyè Ọbadio , ó ní ìtàn yorùbá bẹ ̀ rẹ ̀ láti ilé-ifẹ ̀ gẹ ́ gẹ ́ bí oríṣun .
Ati pe, o di dandan fun ijọba Naijiria lati pese awọn ohun eelo iwadii lori bi iṣẹlẹ naa ṣe ṣẹlẹ gangan fun awọn to yẹ ninu ijọba ki wọn to gbe igbesẹ kankan.
Ninu ọdun yii ni aṣọ ti maa n pe aṣọ ran niṣẹ ti awọn eeyan maa n foju lounjẹ lori awọn nkan to n lo igba lọwọ Oríṣun àwòrán, @abe Àkọlé àwòrán, Àṣà isinku agba naa jẹ ọkan lara ayẹyẹ ti Yoruba ka si pupọ pe ọmọ rere a gbẹyin gbogbo wa ati pe ẹni ti ọmọ ba sin lo bimọ nilẹ Yoruba.
#FreeSowore: Àwọn ọmọ Naijiria fi gbe ta lórí Sowore ti DSS mú!
pé bí eniyan burúkú bá tilẹ̀ rú bíi koríko,tí gbogbo àwọn aṣebi sì ń gbilẹ̀,ó dájú pé ìparun ayérayé ni òpin wọn.
10 Ọ̀wàrà 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ọkùnrin náà ní ilé isẹ́ ìpoogùn náà kò fi ìkìkọ̀ léde pé ọmú àyà òun yóò tóbi si lẹ́yìn tí òun bẹ̀rẹ̀ sí ní lo òògún náà.
O ni wọn ko ṣẹṣẹ maa yan idile Kuti ni Grammy, 'wọn ti yan ẹ̀gbọ́n mi Femi Kuti náà tẹ́lẹ̀ fún Grammy' ki idile wa gba ami ẹyẹ yii lo ku lasiko yii.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Olusegun Obasanjo: Ọmú ìyá mi ti mo fi ń mùkọ ni kekere ló jẹ ki ń lókun Lasiko iṣejọba rẹ, o da ajọ meji to n gbogun ti iwa jẹgudujẹra silẹ - EFCC ati ICPC.
Igbakeji akọwe apapọ fun ẹgbẹ naa, Adamson Momoh sọ fun BBC Yoruba pe, idi iyanṣẹlodi naa ko ṣẹyin bi ijọba Eko ṣe kọti ikun si gbogbo ibeere wọn atẹyinwa.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Lebanon: Peace Busari àti àwọn 28 míràn ló padà sí Naijiria 23 Ìgbé 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 12 Agẹmo 2020 Oríṣun àwòrán, Twitter Arabinrin Peace Busari ti olowo rẹ lorilẹede Lebanon fẹ ta loju opo Facebook ti pada wale si Naijiria.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Waris Kareem: Emmanuel Macron kan sáárá lórí àwòrán tó yà Àwọn òṣìṣẹ́ pàjáwìrì ti pa'ná tó jó ìjọ àgùdà tí wọ́n f'igba ọdún kọ́.
O ni lọpọ igba ti ọwọ sinkun ọlọpa ba tẹ awọn ọdaran yii, awọn olowo ni yoo maa bẹbẹ pe ki wọn tu wọn silẹ, ki awọn maalu wọn ma baa jiya.
kí wọ́n kó wọn fún ọ̀kan ninu àwọn ìjòyè ọba tí ó ga jùlọ, kí ó fi ṣe ẹni náà lọ́ṣọ̀ọ́, kí ó gbé e gun ẹṣin, kí ó sì fà á káàkiri gbogbo ìlú, kí ó máa kéde pé, ‘Ẹ wo ohun tí ọba ṣe fún ẹni tí inú rẹ̀ dùn sí láti dá a lọ́lá.
Nkan ti awọn onwoye n wi ni pe ọwọ yẹpẹrẹ ti wọn fi mu ọrọ ibi ti awọn akẹkọ naa wa lo fa ti ko fi ti ni ojutu bayii.
” Dafidi bá lọ sí igbó Hereti.
Àbí ta ló ta okùn ìwọ̀n sórí rẹ̀?
Ọjọgbọn Abayọmi ni ẹni naa ti wa labẹ itọju nileewosan nla fasiti ilu Eko, LUTH.
Nigba to n sọrọ lori ẹsun ti wọn fi kan minisita naa, Aarẹ Widodo sọ pe oun ko ni bo aṣiri ẹnikẹni ti wọn ba ka iwa ibajẹ mọ lọwọ.
Ni odun 2015, ajo eleto ilera lagbaye World Health Organisation (WHO) yo oruko orile-ede Naijiria kuro ni awon orile-ede ti won ni aarun ropa-rose  yii, amo akotun aarun yii tun seyo ni odun 2016, eyi ti o da oruko orile-ede ohun pada sinu iwe akosile naa.
Ni ọjọ karundinlogun, oṣu kinni, ọdun 1966 ni awọn ologun kan to ditẹgbajọba ṣeku pa Balewa pẹlu awọn adari miran.
Ohun ti awọn ọmọ Naijiria n sọ ni pe kii ṣe igba akọkọ niyi ti orilẹede Naijiria yoo lọ ya owo lọwọ orilẹede miiran pẹlu fifi eto idagbasoke boju.
 O ni:“Ipinlẹ Eko jẹ eyi ti ọpọ eniyan mọ fun pipese awọn
Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Shiloh 2020: Oyedepo ní òun kò le tòṣì láéláé!
Ibo Gomina nipinlẹ Ekiti, gẹgẹ bi ajọ eleto idibo se laa kalẹ, yoo waye ni ọjọ kẹrinla osu keje ọdun yi.
#MeToo movement: Harvey Weinstein tó fi ipá bá àwọn ènìyàn lòpò ti rí ẹ̀wọ̀n ọdún 23 he!
"Eto oselu Nàìjíríà lágbára pupọ, tẹ́lẹ̀ tẹ́lẹ̀ boo bá ọ pá, boo bá o bù lẹsẹ wá, sugbon ìjọba tó wà lóde báyìí tí dènà irú ìwà yìí, tí kò sì tún faaye silẹ fún ajẹbanu.
Kí ẹ lè jẹ́ aláìlábùkù, kí ẹ sì wà láìsí ohun ìkùnà kan ní ọjọ́ tí Kristi bá dé.
Eyí ní ẹgbẹ́ òṣèlú PDP fí ìdí rẹ̀ múlẹ̀ níní àtẹjáde kan tí wọn fi sita ní ààgo kan àbọ owúrọ oni tí àkọwé àpapọ̀ ẹgbẹ́ sẹnatọ Umar Ibrahim Tsauri sí fọwọ́ sí Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Mo ń ṣa ike jọ láti san owó ilé iwé ọmọ mẹ́ta' Àwọn to ti jẹ Agbẹnusọ láti ọdún 1999 Salisu Buhari 1999-2000 PDP Iwọ-òòrun -Arewa Ghali Umar Na'Abba 2000-2003 Iwọ-òòrun -Arewa Aminu Bello Masari 2003-2007 Ìwọ-òòrun -Arewa Patricai Etteh 2007 Iwọ-òòrun -Guusu Dimeji Bankole 2007-2011 Iwọ-òòrun- Guusu Aminu Waziri Tambuwal 2011-2015 wọ-òòrun -Arewa Yakubu Dogara 2015-2019 Ila-òòrun Arewa Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Iba Gani Adams: Bẹ́ẹ gbé màláíkà kan lọ sí Aso Rock, kò lè ṣàṣeyọrí Àwọn tó ń dupo agbénusọ ilé ìgbìmọ̀ aṣojú-ṣòfin Ẹgbẹ́ òṣèlú APC tí pín ipò agbẹnusọ sí ìwọ̀-òòrun -Guusu tí wọ́n sì yan asoju ọmọ ilé to pọ jù lọ, Femi Gbajabiamila gẹgẹ́ bi ẹni tí wọ́n fọ́wọ́ sí nígbà ti wọ́n pín ìgbá keji sí gbùngbùn Ariwa.
Ẹgbẹ naa, to n fẹ kijọba apapọ se afikun ipese awọn ohun eelo idagbasoke sagbegbe Niger Delta, tun fikun pe, lara awọn ibudo ti wọn yoo kọlu ni Bonga, Agbami, papa EA, papa Brittania-U ati papa Akpo.
Nígbà tí OLUWA pàṣẹ fún ọkunrin tí ó wọ aṣọ funfun náà pé kí ó mú iná láàrin àwọn àgbá tí ń yí, tí ó wà láàrin àwọn Kerubu, ọkunrin náà wọlé, ó lọ dúró lẹ́gbẹ̀ẹ́ àgbá náà.
South Africa: Báwo ni ìkọlù sáwọn àjèjì ṣe wọ́pọ̀ tó?
Galiiki Ọpọlọpọ iroyin lo ti jade pe jijẹ galiiki, ti Yoruba n pe ni ata'lẹ lati dena arun ti gbale-gboko lori ayelujara Facebook.
Tí ẹ bá dé’bẹ̀ ẹ ó rí ìdí abájọ.
Lẹ́yìn náà, ó wọn òòró ilé ní ìhà tí ó dojú kọ àgbàlá tí ó wà ní apá ìwọ̀ oòrùn ati àwọn ògiri rẹ̀; ẹ̀gbẹ́ kinni keji gùn ní ọgọrun-un (100) igbọnwọ (mita 45).
Oríṣun àwòrán, Karen Charmaine Chanakira Amọ, atẹranṣẹ ori ẹrọ ayelujara rẹ wa ni ṣiṣi silẹ, ọkan lara rẹ fa oju mi mọra; mo ri pe o ti sanwo ile itura kan silẹ nilu London.
Ní àkókò náà, àwọn wolii kan wá láti Jerusalẹmu sí Antioku.
Khafi Ọmọ ipinlẹ Ekiti ni Khafi Kareem ti o si jẹ ọlọpaa nilu Ọba.
Ẹgbẹ oṣelu PDP ni nṣe ni awọn ọlọpaa fẹ wa ọna bomi pa igbẹj ile ẹjọ lori esi ibo gomina ipinlẹ Ọṣun.
tí wọ́n bá wá yipada kúrò ninu ìsìn igbagbọ, kò sí ohun tí a lè ṣe tí wọ́n fi lè tún ronupiwada mọ́, nítorí wọ́n ti tún fi ọwọ́ ara wọn kan Ọmọ Ọlọrun mọ́ agbelebu, wọ́n sọ ikú rẹ̀ di nǹkan àwàdà.
”Aare Buhari ni iru iwa odaran bayii ko ni je ki orile ede lee tesiwaju
Lẹyin ti o ti sọrọ lori eto mohunmaworan abẹle kan lorilẹede Naijiria pe ọpọ ipinlẹ lorilẹede Naijiria ni wọn ti n ni ina ọba fun bii wakati mẹrinlelogun bayii lojumọ, ẹnu o si lẹyin minisita fun ipese ina ọba lorilẹ€de Naijiria, Raji Fashọla.
Àwọn eniyan tí ó jókòó ní òkùnkùnrí ìmọ́lẹ̀ ńlá.
World Cancer Day: Ènìyàn 26,000 ni àìsàn jẹjẹrẹ ń pa lóòjọ́
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, The Polytechnic Ibadan: Ẹ̀rọ abẹ́lé tó ń fọ ọwọ́ àti ‘Ventilator’ ló ṣẹ̀ṣẹ̀ gbé jáde Lafikun, o rọ awọn ọmọ ẹgbẹ Oso ati Ajẹ lati ni ifarajin ninu ilu pẹlu bi ohun gbogbo ṣe le to.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Sextuplet: Àdúrà Ìbùkún ló kú lẹ́yìn ọmọ mẹ́fà yìí- Ifeoma Thelma àti Onyemaechi Chiaka Awọn akẹkọọ to ba gba maaki 160 soke ninu esi idibo JAMB 2020 ni anfaani lati ra fọọmu post UTME ti ileewe Akwa Ibom State University (AKSU) ati awọn akẹkọọ Direct Entry (DE) naa.
Bakan naa lo mẹnuba ọrọ Abubakar Atiku to n dije dupo lẹgbẹ oṣelu PDP.
Báálẹ Sulaiman wà lórí òyè di ọdún 1974 tí ó fi wèwàlẹ̀ àsà, bí ẹ ti mọ̀ pé nílẹ̀ Yorùbá pé ikú nìkan ló lè yẹ Ọba tàbi Báálẹ̀ kúrò lórí oyè.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Coronavirus in Lagos: Sanwo-Olu ti ilé ẹ̀kọ́ pa, fòfin de ayẹyẹ àdúgbò àti òde fàájì torí ọwọ́jà àrùn 15 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 19 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 O n bọ, o n bọ, awọn laa dẹ de e, eyiun laye ijọun amọ lode toni, oju ni wọn n mu to.
Kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ náà dáhùn pé, “Ṣebí kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ rẹ ni mí, tí o sì ti ń gùn mí láti iye ọjọ́ yìí títí di òní?
Lẹyin ti Akanbi Oluwasegun pari ile iwe ati ẹkọsẹ, o ti ṣiṣẹ kaakiri plu awn eniyan o si ti rii wi pe ko sohun to da bii iṣ ara ẹni.
Laycon ni ọmọ ológo tó jáwé olúborí ní ètò BBNaija season 5 'Lockdown' Oríṣun àwòrán, BBNaija/twitter Olamilekan Agbelesebiọba 'Laycon', lo jawe olubori lori eto ori amohunmaworan, BBNaija season 5 Lockdown.
Ìró ìbọn dún lákọ ní Iwo road n‘Ibadan, Seyi Makinde yọjú síbẹ̀ Àwọn jàndùkú kọlu ọgbà ẹ̀wọ̀n Ikoyi, agbófinró gba àkóso ibẹ̀ Kò sí rògbòdìyàn tó lè sẹlẹ̀ ju wákàtí 24 lọ láì ní ọwọ́ ìjọba níbẹ̀- Ogagun Ibrahim Babangida 7000 Jàǹdùkú ló fọ́ ọgbà ẹ̀wọ̀n Okitipupa, jó mọ́tò, tí wọn si se òṣìṣẹ́ léṣe"" Mo fura pé ẹ fẹ́ da Nàíjíríà rú, ń kò ṣe ìwọ́de mọ́ - Segalink, agbátẹrù ìwọ́de yọwọ́ End SARS Protest: Segalink yọ ara rẹ̀ kúrò nínú ìfẹ̀họ́núhàn EndSARS Ajafẹtọ ọmọniyan, Segun 'Segalink' Awosanya ti yọ ara rẹ kuro ninu ifẹhọnuhan EndSars to n lọ lọwọ."
Nígbà tí àwọn tí wọ́n bẹ̀rù OLUWA bá ń bá ara wọn sọ̀rọ̀, OLUWA a máa tẹ́tí sí wọn, yóo sì gbọ́ ọ̀rọ̀ wọn.
Ṣugbọn gbogbo àwọn tí wọ́n bá ké pe orúkọ OLUWA ni a óo gbàlà.
Josaya wó pẹpẹ ìrúbọ tí ó wà níbẹ̀, ó fọ́ òkúta rẹ̀ túútúú, ó lọ̀ wọ́n lúbúlúbú, ó sì jó ère Aṣera pẹlu.
 hazel ( ìyàwó rẹ ́ ) kú ní oṣù karun odún 2000 , oṣù díẹ sí ìgbà tí rotimi kú .
Bakan naa, awọn ilana ta gba da owoya naa pada ati isunsiwaju akoko to yẹ ki a da owoya naa pada, ko nira rara, a si ri pe owoya ti China fẹ fun wa rọrun.
O ni ipinlẹ eko ṣe pataki nitori awọn ile alarambara  atawọn ohun iṣẹmbaye to kun inu rẹ.
Ní òwúrọ̀ ọjọ́ keji, Balaamu di kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ rẹ̀ ní gàárì, ó sì bá àwọn àgbààgbà Moabu lọ.
Coronavirus Update in Namibia vs elephant: Ṣé òótọ́ ni pé ìgbẹ́ erin le è wo arùn Covid-19 sàn?
Igboke gbodo ọkọ lọna yii ti awọn eniyan n pe ni Link Bridge lọ bo ṣe yẹ lonii ti igbesẹ ti gomina Sanwoolu gbe silẹ naa bẹrẹ.
Ẹni tí ó sá kúrò lọ́nà òyeyóo sinmi láàrin àwọn òkú.
 O tun dara fun lilo ki irun le gun ati ipara lasiko oye yii.
''A rọ awọn ara ilu Kwara lati ma ṣe korẹwẹsi ọkan ki wọn si gbaruku ti wa ninu ilakaka ati tu Kwara ninu oko amunisin'' Bi a ko ba gbagbe,ikọ Ishola Balogun Fulani ti saaju ṣeto idibo abẹnu eleyi to gbe AbdulWahab Omotose Kayode jade gẹgẹ bi ẹni to jawe olubori nínu idibo abẹnu ẹgbẹ APC ni ipinlẹ Kwara.
Gómìnà àná míì, Joshua Dariye, tún rẹ́wọ̀n he A gbọ́ pé, àwọn túbú àwọn ọlọ́pàá tó ń gbógun ti àwọn adigunjalè (SARS) wà lára àwọn tí wọn yóò wò.
Níbo láyé kọjú sí: Kí ni ohun àmúyẹ tí ò ń wa lára ẹni tí o fẹ́ fẹ́?
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Yemen Water Child: Ọmọdé 44 ni Sọ́jà pa, tí 100 míì sì kú látọwọ́ ohun ìjà olóró Ọpọ eeyan to si ti n ro pe 'tọkọtaya' naa yoo tun pada da wọn laraya ti ni ijakulẹ bayii, nitori pe awọn mejeeji ti ja kuro ninu eto naa.
Ní òkè àpótí yìí ni àwọn kerubu ògo Ọlọrun wà, tí òjìji wọn bo ìtẹ́ àánú.
O ni ẹbi bi nkan ṣe ri ki ṣe awọn ileeṣẹ ologun nikan.
Bẹẹ naa ni awọn mii ni niṣe lo poora ti wọn si tun rii.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Oyin lé àwọn ènìyàn kúrò l'ábúlé kan ní Plateau Àwọn ọmọ Nàìjíríà tahùn sí SERAP lórí ẹjọ́ Onnoghen Àwọn òṣèré, olórin Yorùbá gbàdúrà fún MC Oluomo Fayemi ṣèlérí owó ìtọ́jú àwọn tó fara gbá nínú ìjámba l'Ékiti Igbakeji Kọmiṣọna Ọlọpaa, DCP Kayọde Ẹgbẹtokun ni ọga agba ọlọpaa tuntun ti wọn yan fun ileeṣẹ ọlọpaa ipinlẹ Eko.
Nígbà tí àkókò ìbẹ̀rẹ̀ ìkórè súnmọ́ tòsí, mẹta ninu àwọn ọgbọ̀n akọni náà lọ sí inú ihò àpáta tí ó wà ní Adulamu, níbi tí Dafidi wà nígbà náà, nígbà tí ọ̀wọ́ àwọn ọmọ ogun Filistini pàgọ́ wọn sí àfonífojì Refaimu.
Oríṣun àwòrán, Getty Images O sọ fun BBC Yoruba pe ninu ibẹru lawọn n gbe nilẹ Geẹṣi bayii nitori yala o wa ninu ọkọ, tabi oun n wo ẹrọ amohunmaworan, ọrọ coronavirus lawọn eeyan n sọ.
Ni ipilẹ sinima ni ilẹ Yoruba, gbogbo awọn onworan ni igba naa ni wọn maa n foju wa arakunrin rọgbọdọ aboju dudu họhọhọ pẹlu ṣokoto ti o tobi juu lọ, ti o fi okun ẹran nla so pẹlu ẹwu agbotutu lọrun.
won lasiko ti ikolu naa waye pelu iko omo ogun orile ede Naijiria , ni eyi ti
Tí ọdún iléya bá ti dé, gbogbo àwọn ọmọdé yálà Mùsùlùmí tàbí Onígbàgbọ́ Kìrìstẹ́nì ni, wọ́n a máa kọrin bẹ́ẹ̀.
Loṣu Kejila, ọdun 2018 ni awọn alaṣẹ ni orilẹede Saudi Arabia mu Zainab lasiko to lọ kopa ninu ijọsin Umrah pe o gbe oogun oloro.
Ó kó gbogbo rẹ̀ lé Aaroni ati àwọn ọmọ rẹ̀ lọ́wọ́, wọ́n sì fì wọ́n gẹ́gẹ́ bí ẹbọ fífì níwájú OLUWA.
Ó fi igi akasia ṣe àwọn ọ̀pá rẹ̀, ó sì yọ́ wúrà bò wọ́n.
Wọ́n tún bẹ̀rẹ̀ sí rúbọ sí àwọn ẹ̀mí burúkú, Àwọn oriṣa tí wọn kò mọ̀ rí,tí àwọn baba wọn kò sì bọ rí.
Ni apapọ ẹniyan mejidinlogojilenigba lo ti ni arun Coronavirus ni Naijiria, ti ẹniyan marundinlogoji si ti ri iwosan gba, amọ ti ẹniyan marun si ti ku.
Ọkunrin náà sì dá a lóhùn pé òun ni.
Ìbúrawọlé Nàìjíríà ṣojú àgbáyé Irọ́ ni o!
Gomina ipinlẹ wa ṣeleri owo iranwọ biliọnu meji naira fawọn ti wọn fara kaasa ninu iṣẹlẹ naa.
Ẹgbẹ oṣelu Botswana Democratic Party, (BDP) lo ti n bori gbogbo idibo to n waye lorilẹede Botswana lati igba ti wọn ti gba ominira lọdun 1966, amọṣa lọdun yii, o ṣeeṣe ki ọrọ ba ibomiran yọ fun wọn.
Gomeri ati gbogbo àwọn ọmọ ogun rẹ̀, ati Beti Togama láti òpin ilẹ̀ ìhà àríwá ati gbogbo àwọn ọmọ ogun rẹ̀; bẹ́ẹ̀ náà ni ọpọlọpọ orílẹ̀-èdè, wọ́n wà pẹlu rẹ̀.
Aarẹ tuntun yii lo n gba akoso orilẹ-ede ti awujọ agbaye ti dẹyẹ si, ti adehun rẹ pẹlu awọn to n saanu fun si buru jai.
 ajíbógun dúró níbi tí a ń pè ní iléṣa lónií yìí , òun sì ni Ọwá iléṣà kìíní .
Nigba ti ko sohun ti mo le ṣe mọ, mo pada si ẹsẹ aarọ ki n maa nu bata.
Owolabi fikun pe, awọn eniyan to ku naa wa lati ijọba ibilẹ Ọse, ati wipe aisan iba ọrẹẹrẹ naa ti tan yika awọn ijọba ibilẹ to wa nipinlẹ Ondo.
Tesiwaju si, eyi je igba akoko ti orile-ede Japan yoo fagbahan orile-ede ti o wa lati guusu iwo oorun Amerika ninu itan boolu afesegba.
”Àwọn ọkunrin náà wá wọn títí, ṣugbọn wọn kò rí wọn.
Wọn kẹjọ lọ ba Aarẹ Buhari sugbọn ko ribi yi ipinnu to wa nilẹ pada pe Ambode ko ni le dupo labẹ asia ẹgbẹ APC.
Jesu wí fún un pé, “Ẹni tí ó bá ti wẹ̀ nílé, tí ó bá jáde, kò sí ohun tí ó kù jù pé kí á fọ ẹsẹ̀ rẹ̀ lọ, gbogbo ara rẹ̀ á wá di mímọ́.
Ìjòyè náà wádìí lọ́wọ́ wọn nípa àkókò tí ọmọ náà bẹ̀rẹ̀ sí gbádùn.
Ilà abẹ́ tí ẹ gbọdọ̀ kọ yìí ni yóo jẹ́ àmì majẹmu tí ó wà láàrin mi pẹlu yín.
Nígbà tí wọ́n dé Samaria, Jehu pa gbogbo àwọn ìbátan Ahabu, kò sì fi ọ̀kankan ninu wọn sílẹ̀, gẹ́gẹ́ bí OLUWA ti sọ láti ẹnu Elija.
Yàrá mẹta mẹta wà ní ẹ̀gbẹ́ kọ̀ọ̀kan ẹnu ọ̀nà náà.
Ati wi pe ijọba ibilẹ kan lo ku ki awọn gbe awọn ohun iranwọ naa fun , nitori marundinlogun ninu wọn ti gba ohun iranwọ ti wọn.
Taa ba si gbe eyi fẹgbẹkẹgbẹ pẹlu apapọ ibo taa di lasiko ibo aarẹ ni Naijiria, ọna jin si ara wọn nitori ibo miliọnu mejidinlọgbọn o le diẹ ni ajọ eleto idibo kede pe ọmọ Naijiria di lasiko ibo aarẹ to kọja.
Nigeria Yahoo Boys: Ìjọba Amẹrika fi ojú àwọn ọmọ Yahoo mẹ́fà léde, wọ́n gbẹ́sẹ̀ lé dúkìá wọn
Saulu ati iranṣẹ rẹ̀ bá gòkè wọ ìlú lọ.
” Bẹ́ẹ̀ ni baba rẹ̀ sọkún rẹ̀.
Ìre tí Mose eniyan Ọlọrun sú fún àwọn ọmọ Israẹli kí ó tó kú nìyí.
Arabinrin naa sọ fun ik iroyin BBC Yoruba to ṣebẹwo si ile wọn ni ilu Sagamu pe ọmọ rẹ ọhun ti ṣeleri oke okun fun oun ki iṣẹlẹ iku ojiji to de ba a.
ti o je omo egbe igbimo ohun ni: gomina ipinle Ekiti, Bayelsa, Ebonyi,
O óo sọ ohun tí mo bá wí fún wọn, wọn ìbáà gbọ́, wọn ìbáà má gbọ́; nítorí pé ìdílé ọlọ̀tẹ̀ kúkú ni wọ́n.
"ìfipábánilòpọ̀: Má dákẹ́ - Oluwaseun Wọ́n ta ère Ọ̀ṣun Osogbo sí Togo - Bàbá Ọṣun figbe ta World TB Day: ""Ó dùn mí jù pé ń kò rí ọmọ mi fún ọdún kan"" 'Iléèṣẹ́ ọlọ́pàá ló gbégbà orókè nínú ìwà jẹgudujẹra ní Nàìjíríà' Oshisko twins, àwọn 'ìbejì' tó ń dẹ́rìn ín p'òṣónú Mo fẹ́ sálọ torí ìpèníjà àkójọpọ̀ èsì ìbò gómìnà Ọyọ - Kọ̀misánà INEC l‘Ọyọ Àwọn àmì tó fi mọ̀ pé wọn ń fipá bá ọmọdébìnrin rẹ lòpọ̀ Ìyá àgbà Ọlayinka, arúgbó tó ń ṣoge bí omidan World water day: Ẹrin Ijesa, Ọ̀ṣun Oṣogbo, àwọn ibùdó ìgbafẹ́ omi tí ó yẹ kí o mọ̀ Baṣọ̀run Gáà, tó yan ọba mẹ́rin, pa ọba mẹ́rin àmọ́ ọba karùn-ún ló pa á Èmi ṣì ni Gómìnà ìpínlẹ̀ Ọṣun-Oyetọla ""Ìlú mímọ́ nibí, wọn kò gbọdọ̀ bímọ, sin òkú àbí ẹran síbẹ̀"" Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí kan sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn."
Siasia bẹ̀bẹ̀ ìrànwọ́ N100m lọ́wọ́ ọmọ Nàìjíríà láti ṣejọ́ jìbìtì tí FIFA fi kàn án Van Persie gbàgà lẹ́nu rẹ!
Nígbà tí ó wà ninu ìpọ́njú ó wá ojurere OLUWA Ọlọrun, ó sì rẹ ara rẹ̀ sílẹ̀ patapata níwájú Ọlọrun àwọn baba rẹ̀.
 bákan náà ni ó tún lọ sí ilé-ẹ ̀ kọ ́ gbogbo-nìṣe ( ui ) ti ìlú Ìbàdàn níbi tí ó ti kẹ ́ kọ ̀ ọ ́ gbàwé ẹ ̀ rí dípúlọ ́ mà , gboyè àkọ ́ kọ ́ ( b.
Igi to tọ kii pẹ ni igbo Ọjọgbọn Awojobi dagbere fun ye lọjọ aiku ti ṣe ọjọ kẹtalelogun Osu Kẹsan dun 1984 lẹni ọdun mẹtadinlaadọta.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Funmi Adewara: Tele Medicine' ní a fi ń ṣàyẹ̀wò èèyàn ìdá ọgọtá láti dènà ìtànkálẹ̀ Covid 'Ọkọ̀ ọ̀rẹ́ àtijọ́ rẹ̀ kan tó fẹ́ tàdímẹ́yìn láti kì í, ló kọ lù ú tó pa á' 'Tolu rín ẹ̀rín múṣẹ́ kí ẹ̀mí tó bọ́ lára rẹ̀' Ọmọluabi ni Tolu, ẹni to sun mọ Ọlọrun lo jẹ, ọmọ to mu inu obi, ara, ọrẹ ati gbogbo eeyan dun si ni o jẹ.
O fikun-un pe, O ni iwa ati ise oloogbe naa to-o wo lawokose fun awon onkowe ati iran Yoruba lapapo.
Èmi Paulu fi ìrẹ̀lẹ̀ Kristi ati àánú rẹ̀ bẹ̀ yín, èmi tí ẹ̀ ń sọ pé nígbà tí mo bá wà lọ́dọ̀ yín mo jẹ́ eniyan jẹ́jẹ́, ṣugbọn nígbà tí mo bá kúrò lọ́dọ̀ yín mo di ògbójú si yín.
Èmi ni ọba Israẹli lónìí, ẹnìkan kò sì ní pa ẹnikẹ́ni ninu àwọn ọmọ Israẹli.
Ni orilẹede ti banki agbaye sọ pe ibẹ ni o dara lati dokowo nilẹ Afirika.
Ó fún ẹnubodè rẹ ní agbára,ó sì bukun àwọn tí ń gbé inú rẹ.
Adajọ ri idi okodoro ọrọ, to si dajọ pe Eji Gbadero jẹbi ẹsun iditẹ lati pa eniyan ati ipaniyan, to si ni ki wọn lọ yẹgi fun, titi ti ẹmi yoo fi bọ lara rẹ.
Kini o le fa a ki toko-tayo yọ ọbẹ si ara wọn?
AIG Folawiyo David, mni - AIG Training & Development xix.
Awọn ya mi yatọ si Yoruba wa ninu wọn ṣugbọn gbogbo wọn ti da papọ mọ ara wọn'' O ṣalaye pe inu awọn dun si igbese yi ti awọn si lero pe yoo mu adinku ba iye awọn ọmọ ti ko si ni ile ẹkọ nipinlẹ naa.
Burna Boy fẹ́ yọ̀ǹda owó tó bá pá lóde àríyá f'áwọn tó farakásá ìṣẹ̀lẹ̀ Xenophobia Àwọn ọ̀rọ̀ gbànkọgbì tó ti bọ́ lẹ́nu Tunde Bakare Ni ti Aidan, ifẹ ọkan rẹ ni lati gba ipo awọn ọba omuwẹ lagbaye bii Michael Phelps ko si gba ami ẹyẹ idije agbaye Olympics.
Èrè yín yóo pọ̀, ẹ óo wá jẹ́ ọmọ Ọ̀gá Ògo nítorí ó ń ṣoore fún àwọn aláìmoore ati àwọn eniyan burúkú.
Olórí Alufaa bá dìde, ó ní, “O kò fèsì rárá?
Ó fún wọn ní agbára ati àṣẹ láti lé gbogbo ẹ̀mí èṣù jáde ati láti ṣe ìwòsàn oríṣìíríṣìí àìsàn.
Ní ọjọ́ kẹwaa oṣù kinni, ọdún kẹẹdọgbọn tí a ti wà ní ìgbèkùn, tíí ṣe ọdún kẹrinla tí ogun fọ́ ìlú Jerusalẹmu, agbára OLUWA sọ̀kalẹ̀ sára mi.
Ajimobi figbe ta, ó ní 'èmi kọ́ ló pa Ṣugar o!
Haa, iwa alọni lọwọ gba ati irẹnijẹ gbaa ni eleyi.
“Ni bayii, mo ti pase fun minisita to n mojuto eto agbe lati lo kakiri awon ipinle ati ijoba ibile lati ya awon eniyan lowo fi bere ise agbe.
Ninu alaye ti Fayose sọ nínú atejade rẹ,o ni igba toun n rin lọ si ori aaye t'awọn alejo wa ni janduku kan sadede sun mọ oun to si ṣi fila ori oun.
Ọba alaye naa ṣalaye pe koda, ọrẹ ni iyawo oun akọkọ jẹ pẹlu aburo oun obinrin.
Bakan náà lóri atẹ̀jíṣẹ́ facebook ọ̀pọ̀ àwọn ọmọ Yorùbá ló ti gbóríyìn fún alaafin fun iṣẹ́ ribiribi ti ó ti ṣe lọ́dún méjìdínláàdọ́ta sẹ́yìn, wọn ni Ọba Lamidi ní ó mú aláfíà àti ìtẹ̀síwájú bá Ọyọ Wọn gbàdúrà kí ọlọrun fún baba ní ẹ̀mí gígùn lórí ilẹ̀ Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Ọmọge Campus fayé sílẹ̀ ní Canada
Sugbọn o di bi dandan ki wọn ba ṣe e lọna ti o tọna nitori lọpọlọpọ igba Ifa gan an le e ni ki wọn ma tete fi abẹ kan ọmọ miran lori.
Eleyi ló sọ gbi gbẹ́ ihò fún omi àti kànga lati wá omi fún mi mun di àṣà.
OLUWA Ọlọrun, ìwọ ni o yà wọ́n sọ́tọ̀ láàrin gbogbo àwọn orílẹ̀-èdè ayé, pé kí wọ́n jẹ́ ìní rẹ, gẹ́gẹ́ bí o ti sọ fún wọn láti ẹnu Mose, iranṣẹ rẹ, nígbà tí ó kó àwọn baba ńlá wa jáde ní ilẹ̀ Ijipti.
to waye lati yan asofin miran sipo, lẹyin iku ẹni to wa nibẹ tẹlẹ.
Obasanjo: Ìdùnnú ọmọ Nàìjíríà ló jẹ́ mí lógún ní 2019
Inú yóo bí ọba Ijipti, yóo sì lọ bá ọba Siria jagun.
Abumere Àkọlé àwòrán, Yatọ si pe wọn n ra awo orin, wọn mọ iyi orin nitori pe wọn ti wo oniruuru olorin.
to koja ni aare Buhari pase fun awon minisita re lati jabo lori bi won se tuko
Ṣekemu tún wí fún baba ati àwọn arakunrin omidan náà pé, “Ẹ jọ̀wọ́, ẹ yọ́nú sí mi, ohunkohun tí ẹ bá ní kí n san, n óo san án.
Ileeṣẹ Brothers Keeper to n ṣe ọti naa eyi ti Mọtara mu lọwọ ninu fidio ọhun ti fi atẹjade sita gbangba pe awọn yoo da gbajugbaja ori ayelujara yii duro gẹgẹ bii alukoro ati agbẹnusọ ileeṣẹ awọn.
O tẹsiwaju ninu ẹkọ rẹ nigba to gboye akọkọ ni fasiti ninu ẹkọ nipa ọrọ aje nileewe London School of Economics lọdun 1968.
Ki Ozo to di olori ile ati Nengi di igbakeji, awọn mejeeji ko tii jọ sun papọ ri lori ibusun kan naa, bi o tilẹ jẹ pe wọn sun mọ ara wọn.
Wọ́n ń sọ fún Ọlọrun pé, ‘Fi wá sílẹ̀!
Àdéhùn OLUWA pẹlu Israẹli ní Ilẹ̀ Moabu.
Oríṣun àwòrán, Bashit Ahmad/Twitter Iroyin ni ọgọrọ awọn ọmọ ẹgbẹ oṣelu PDP lo fi ẹgbẹ naa silẹ lọ APC.
Pákó igi kedari ni ó fi bo ara ògiri ilé náà ninu, láti òkè dé ilẹ̀.
ẹ ranti ohun tí OLUWA Ọlọrun yín ṣe sí Farao ati gbogbo ilẹ̀ Ijipti.
Rẹgi ni ọrọ r ṣe pẹlu ọjọgbọn Nazif Abdullahi Darma to ni iIpenija nla ni ọrọ to wa nilẹ yi nitori abaṣepọ to wa laarin ọrọ aje ati ilera kii ṣe kekere.
Ẹ jẹ́ kí á máa rò nípa bí a óo ti ṣe fún ara wa ní ìwúrí láti ní ìfẹ́ ati láti ṣe iṣẹ́ rere.
Mọ̀ sí i nípa àwọn ọmọ Nàìjíríà mẹ́sàn-án tó ń díje nínú ìdìbò ilẹ America lọ́jọ́ Ìṣẹ́gun Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Kété tí wọ́n bá ti báa yín sùn tàn torí pé ẹ tóbi, ẹ gbà pé ìfẹ́ yẹn ti parí - Auntie Remi Ọlọ́yàn ńlá Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí US presidential election 2020: Bí ààrẹ Trump kò ṣe gbé ipò sílẹ̀ yóò ṣe àkóbá fún ọ̀pọ̀ ènìyàn17 Bélú 2020 Fídíò, Soyinka Cancer: Àṣe ara mi ni iso ti n run gbogbo bí mo ṣe n ṣèrànwọ́ lórí jẹjẹrẹ27 Bélú 2019 Fídíò, John Amanam: Ìfẹ́ tí mo ní sí àbúrò mi ló sọ mi dí ẹni tó ń ṣe 'Prosthetic' báyìí1 Bélú 2020 AFCON Qualifier: Kò séwu fún gbogbo àwọn tí yóò kópa nínú ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ Naijiria àti Sierra Leone ní Benin - Obaseki1 Bélú 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
 a lè nílò àwọn wọ ̀ nyí fún àsìkò pípẹ ́ .
Ọlọrun yọ ọ́ kúrò ninu gbogbo ìpọ́njú tí ó rí.
Ireti wa pe awọn aṣofin yoo gbe aba kan kalẹ ninu eyi ti wọn yoo ti rọ igbakeji aarẹ Mike Pence pe, ko gbe igbesẹ yiyọ aarẹ nipo ni ibamu pẹlu alakalẹ atunṣe ofin ikarundinlọgbọn ilẹ Amẹrika.
Oniruuru iroyin lawọn eeyan n gbe lori ẹyẹ igun naa ati ohun to gbe e de atimọle.
“N kò ní yé sọ̀rọ̀ nípa ẹsẹ̀ rẹ̀,tabi nípa agbára rẹ̀ tabi dídára ìdúró rẹ̀.
Ibẹru-bojo mu awọn ara adugbo agbegbe Abraham Adesanya ni Ajah, nilu Eko bi wọn ṣe ji ni aarọ ọjọ Aiku ti wọn si ba awọn oku arakunrin mẹta kan ti wọn ti ge ori wọn silẹ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Onnoghen: Àjọ NJC fún Onnoghen lọ́jọ́ méje láti wá sọ tẹnu rẹ̀ 29 Sẹ́rẹ́ 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 30 Sẹ́rẹ́ 2019 Oríṣun àwòrán, Nigeria Bar Association Àkọlé àwòrán, Ajọ NJC pe awọn adajọ agba mejeeji Ajọ to n ri si idajọ lorilẹede Naijiria NJC ti fun adajọ agba Walter Onnoghen ti Aarẹ Muhammadu Buhari ni ko lọ rọku nile ati adajọ agba tuntun to gba ipo rẹ Ibrahim Tanko Mohammed lọjọ meje lati fesi si awọn ẹsun ti wọn fi kan wọn.
"O ni ""ki gbogbo awọn to yege ninu iforukọsilẹ ọhun lọ si ile ẹkọṣẹ awọn olukọ, Emmanuel Alayande, to wa ni ilu Oyo laago mẹsan owurọ lọjọ kẹta, oṣu Kọkanla, ọdun 2020, fun eto iforukọsilẹ ni kikun."
Nígbà tí ó di òru tí kò í tíì rí àlàáfíà ni wọ́n ṣe ìpínnu láti gbé e lọ sí ilé ìwòsàn ní kùtùkùtù ọjọ́ kejì.
"Akinwumi Isola dárà nínú ìwé ""Nítorí Owó"" lórí Akomolede Yoruba Kí ni ""Future tense"" lédè Yorùbá?"
Nǹkan márùn ún tó yẹ kí o mọ̀ nípa Ọ̀gá Àgbà fásitì UNILAG tẹ́lẹ̀rí, Ibidapo Obe tó jáde láyé ni opin ọsẹ to kọja ni ijọba ipinlẹ Eko ti kọkọ kede pe gbogbo awọn ileewe alakọbẹrẹ ati girama ko ni lee wọle bayii ayi pe iwọle wọn di ọjọ mii ọjọ ire.
Kì í ṣe ìtàn àròsọ ni a gbójú lé nígbà tí a sọ fun yín nípa agbára ati wíwá Oluwa wa Jesu Kristi, ṣugbọn ẹlẹ́rìí ọlá ńlá rẹ̀ ni a jẹ́.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Buhari kí àwọn kìrìsìtẹ́nì kú ọdún Buhari, Atiku fẹ́ tú Afẹ́nifẹ́re ká Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Èpo ọwọn, sunkere-fakere ọkọ àti àwọn olósà jẹ́ ipenija lójú pópó Amọ bayii, Kọmisọna Uko ṣalaye pe ile iṣẹ naa lati yọnda awọn oṣisẹ rẹ lati mojuto papa isere naa lẹyin ti wọn ba lo tan.
 Ṣùgbọ ́ n ọ ̀ rùnmìlà fún àwọn ọ ̀ mọ rẹ ̀ méjẹ ̀ ẹ ̀ jọ náà ní ikin mẹ ́ rìndínlọ ́ gùn ó ní bẹ ẹ délé bẹẹ bá fówóó ní , ẹni tẹ ̀ ẹ ́ maa bi ninu .
O fi kun pe e ija gbogbo agbaye ni ohun to n lọjẹ.
When I was in prison, he was one of the few foreign Ambassadors who regularly visited my wife to encourage her and to find out how I was doing in prison.
Eden hazard Agbawaju to pegede: 1.
siwaju ile igbimo asoju-sofin, ki o to di ọjọ isẹgun to n bọ yii.
Bakan naa, ni ijoba tun ya owo
"Lasiko ti Oluwo ba fi n sinmi nile, a sọ fun pe ko gbọdọ ba awọn akọroyin sọrọ, tori to ba sọrọ, yoo tun maa ba ẹjọ ara rẹ jẹ ni, ko gbọdọ kọrin owe abi eebu, o gbọdọ maa lọ jẹẹjẹ, ko si maa ba isẹ rẹ lọ, amọ ko gbọdọ wa si ipade awa lọbalọba tipinlẹ Ọsun.
Ọ̀pọ̀ èèyàn farapa nínú ìwọ́de Shiite Agbebọn pa ọmọ ogun mejila Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Kaduna ni àjọ NYSC pín mi sí sùgbọ́n.
 nígbà tí ilẹ ̀ mọ ́ , wọ ́ n rí pópóọlá .
 Oyetola ni oun gbagbe pe kii ṣe awọn ọdọ to dibo yan oun sipo gomina, ni yoo tun gbiyanju lati gba ẹmi oun, nitori kii ṣe igba akọkọ ti wọn yoo ṣe iwọde ree."
Òun ni agbára wà fún laelae.
O bu ẹnu atẹ lu ipo ti ibudokọ oju omi Ijede si Ikorodu wa o si lo anfani yii lati parọwa si ijọba Naijiria.
 Bi e ba duro pe die sii, e si le wo iran ere sisa olopo kilomita tipinle Eko tidije ohun n bo lojo kewaa osu keji odun yii naa ni.
SERAP ní ìjà ṣẹ̀ṣẹ̀ bẹ̀rẹ̀ ni lórí owó tí àwọn olóṣèlú ń bù fúnra wọn Ipinlẹ wo ni yoo tẹle igbesẹ awọn aṣofin Kwara?
D, lati Fasiti Johns Hopkins, ati imọ nipa ofin, Widener University, ni Delaware.
Ó fi apá kan ninu wọn sí ọ̀dọ̀ ara rẹ̀ ní Jerusalẹmu, ó sì kó àwọn yòókù sí ìlú ńláńlá tí ó ń kó àwọn kẹ̀kẹ́ ogun sí káàkiri.
Oríṣun àwòrán, Facebook/Urueme Adu Àkọlé àwòrán, Urueme Adu ti se atona fun ọpọlọpọ awọn ọjẹwẹwẹ eléré ìdárayá Ọ́pọ̀ ninu wọn ni erongba lati je ilumoka eléré ìdárayá sugbon Adu ni ẹni ti yóò jẹ̀yin inú àpáta ninu wọn ko gbọdọ wo ẹnu ake.
EFCC vs Naira Marley: Nítorí ẹ̀sùn 'yahoo-yahoo' Adájọ́ ní kí Naira Marley ó máa gbatẹ́gùn láhámọ́ ọgbà ẹ̀wọ̀n
Danny Welbeck lo kọkọ gba góòlù akọkọ wọlé ní abala keji ifẹ̀sẹ̀wònse náà .
Ẹ yára, ẹ wá,gbogbo ẹ̀yin orílẹ̀-èdè tí ẹ wà ní àyíká,ẹ parapọ̀ níbẹ̀.
Oríṣun àwòrán, Instagram/oluwoofiwoland Kọmiṣona naa pari ọrọ rẹ pe, ijọba ipinlẹ Osun yoo kede igbesẹ to kan fun awọn eeyan ipinlẹ Osun, ni kete to ba ti ṣe ipinnu lori ọrọ naa.
Jeroboamu náà kó ogoji ọ̀kẹ́ (800,000) akọni ọmọ ogun jọ.
Valencia vs Chelsea: Oró tó dá mi ni mo dá ọ ni Chelsea àti Valencia fi ṣe fún ra wọn
Tóò bá kí ń ṣe ọ̀daràn, kò yẹ kó o sanwóo béélì l‘ágọ̀ọ́ ọlọ́pàá - Agbẹjọ́rò Àwọn aláìsàn yabo Seyi Makinde fún owó ìtọ́jú, ẹnìkọ̀ọ̀kan gba ₦50,000 Ìjà ìgboro rèé o, ṣe bí ọkùnrin ni Bobrisky ṣe bá ọkùnrin ẹgbẹ́ rẹ̀ jà ní?
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ilé asòfin àgbà: Omo-Agege ló gbé ọ̀pá àsẹ ilé lọ 18 Ìgbé 2018 Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ilé asòfin àgbà: Omo-Agege ló gbé ọ̀pá àsẹ ilé Fídíò òkè yìí ló ń se àlàyè bí awọn jàǹdùkú se yabo ilé asòfin àgbà ní ìlú Àbújá, ti wọ́n sì gba ọ̀pá asẹ ilé lọ.
Okan lara awon omo-egbe oselu alatako so pe, oun ti ba awon olopaa kan ja nibi ipago idibo nilu Freetown, toripe, inu awon eniyan ko dun bi awon olopaa ati ologun se gbarodan si awon ibi ipago idibo naa lasiko atundi idibo si ipo Aare ohun.
Èyí ni omi Meriba, nítorí níbẹ̀ ni àwọn ọmọ Israẹli ti ṣe gbolohun asọ̀ pẹlu OLUWA, tí OLUWA sì fi ara rẹ̀ hàn wọ́n pé mímọ́ ni òun.
Ìdájọ́ bẹ̀rẹ̀, a sì ṣí àwọn ìwé sílẹ̀.
"Elkana ni ""a mú afurasí mẹ́rin ti wọ́n maa n fi iṣẹ́ ìyanu òfége lo gbájuẹ̀ fún àwọn ara ilú ti ko fúra, wọ́n ṣe asọtẹlẹ, awọ́n miran a jẹri èké, èyi ni wọn n lò láti gbowó lọ́wọ wọ́n ti wọ́n a sì tún maa lo àwọn ọna miran láti kó ọrọ̀ jo."
“Awọ kò ká Ojú ìlù, Ọmọ Onílù ni òhun fẹ́ má a sun Awọ jẹ – Ojúkòkòrò àwọn Òṣèlú Nigeria”:
Oríṣun àwòrán, AFP Àkọlé àwòrán, Diẹ ninu awọn ti o ni aṣọ ti o ni aworan ti Ms.
Ní tiwa, ó tọ́ bẹ́ẹ̀, nítorí èrè iṣẹ́ wa ni à ń jẹ.
Ọluwo jẹ ọkan lara awọn ọba to jẹ ọdọ to si tun maa n sọrọ daadaa lori ayelujara.
Àṣẹ tí mo pa fún wọn ni pé kí wọn gbọ́ràn sí mi lẹ́nu.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù PDP: Àrà tó bá wu Gomina Ajimobi kó dá lọ́sẹ̀ kan tó kù yìí 23 Èbibi 2019 Oríṣun àwòrán, Google Àkọlé àwòrán, Gomina Ajimobi ti yóò fi ipò rẹ̀ sílẹ̀ lẹ́nu ọjọ́ diẹ sí ìsìnyín ló sẹ̀sẹ̀ yan olórí òsìsẹ́ tuntun ní ìpínlẹ̀ Ọyo.
Ti ẹ ko ba gbagbe, ile igbimọ asofin agba kọ lati yan ọga ajọ EFCC gẹgẹ bi ojulowo alaga,.
"Nitori pe, ni ibẹrẹ itankalẹ coronavirus, ni aarẹ ti pàṣẹ pe ki opin o deba ariya orin ita gbangba.
Wo ìyàtọ̀ ńlá tó wà láàrin Oṣó, Àjẹ́ àti Emèrè Lati ọjọ pipẹ ni ọrọ oṣo, ajẹ ati emere ti ma n jẹyọ ni aarin awọn ọmọ Yoruba, ati kaakiri ilẹ adulawọ.
asofin lorile ede Naijiria, Ike Ekweremadu;aare ana lorile ede Naijiria, Yakubu
Kódà, ní kété tó bá ti dé ni gbogbo èèyàn yóò ti mọ̀ torí gbogbo ọmọ kékeré inú ìletò náà ni yóò tẹ̀le e tí wọn yóò máa ba gbé ìpolówó ọjà rẹ̀.
Ileeṣẹ ọlọpaa ipinlẹ Eko lo kede ọrọ yi lasiko ti wọn ṣafihan awọn afunrasi ọdaran tọwọ tẹ fun orisi ẹsẹ.
Ewe, alaga yanyan fun igbimo asoju-sofin lori oro ifitonileti, ogbeni Suleiman Adokwe fi da awon ara-ilu loju pe, ile-igbimo asofin yoo sa gbogbo ipa re lati satileyin mimu ero igbalode Digital Switch Over project naa de bi ipele ipari ti o lapere.
Wọ́n fún un ní ọtí pé kí ó mu ún.
Oríṣun àwòrán, Alaafi ObaAdeyemi III Coronavirus: Àwọn ohun tí a kò tíì mọ̀ nípa àrùn Covid-19 Kí lo mọ̀ nípa fẹntilétọ̀, ohun èlò aṣèrànwọ́ èémí A fẹ́ lo ẹ̀jẹ̀ àwọn èèyàn tó ye àrùn Coronavirus láti fi ṣe ìwòsàn fún àwọn tó wà lórí àárẹ- UK Coronavirus: Kíni àwọn àmì tuntun tó n fihàn?
Kiakia ni Tiwa Savage naa da esi pada fun Awọn ololufẹ awọn ol;orin mejeeji ko gbeyin ti awọn naa si n fi ọrọ sita lori ija bum bum ohun Awọn kan tilẹ ni ainiṣe lo n da awọn to n sọ ọrọ nipa idi nla laamu.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Aminat Abiọdun: Ọjọ́ Satide ni Iyalode kí ayé pé ó dìgbóṣe 9 Ọ̀pẹ̀̀ 2018 Àkọlé àwòrán, Òní ní ìṣìnkú ìyálódé Ibadan Eto ti n lọ lọwọ ni igbaradi fun isinku Iyalode ilẹ Ibadan, Alhaja Aminat Abiodun ẹni to jade laye lọwurọ ọjọ ẹti l'ẹni ọdun mẹtalelaadọrun.
Ile aṣofin pe Jubrin pada Naijiria gbe ile-ẹkọ giga okeere lọ ile-ẹjọ Jesu Oyingbo rèé, pásítọ̀ tó láṣẹ ìbálòpọ̀ lóri ọmọ ìjọ obìnrin Ohun tó wù kí ileẹjọ́ kòtẹ́milọ́rùn sọ, Adeleke kò lè di gómínà Ọ́ṣun - APC Oríṣun àwòrán, Wellcome Collection Àkọlé àwòrán, Nigba kan, taba jẹ ohun ti wọn maa n fun awọn ti wọn ba doola ẹmi wọn ninu omi lati jẹ ki ara wọn bọ sipo Pẹlu bi awuyewuye ṣe pọ to lori rẹ taba di oun ti gbogbo aye n wa kiri nigba naa nitori pataki rẹ si ilera awọn ẹda.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Fayoṣe: Bẹ́ẹ ṣe yọ fìlà lórí Bola ige tó pa òwe ikú rẹ̀, kò lè ṣiṣẹ́ fún mi 5 Ọ̀wàrà 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 8 Ọ̀wàrà 2020 Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Fayose gọ̀, ó fẹnu họra, Ọlọ́run á gbẹ̀san lára rẹ̀, àdàbí.
Akosilẹ iwadii fihan pe ika alebu na si Hussaini Akwanga to jẹ minisita fun oro oṣiṣẹ nigba naa, Sunday Michael Afolabi to jẹ minisita fun ọrọ abẹlẹ pẹlu Mahmud Shata to jẹ igbakeji rẹ.
Wọ́n ti rí òkú Alága ẹgbẹ́ APC ní Nasarawa tí àwọn agbébọn jí gbé lọ́jọ́ Satide Oríṣun àwòrán, Twitter screenshot Fidio to tan kalẹ yii jade lẹyin ọjọ diẹ ti Motara ṣẹṣẹ kọ itan soju opo rẹ to n ṣalaye bi nkan ṣe le fun oun ati iya rẹ ti iya n kiri ọja loju popo ko to wa di pe papa oko rẹ di tutu to di ọlọrọ.
O ni, Àwọn obi awọn ọmọbinrin to ku ni ijọba ti pa wọn ti kan."
Oríṣun àwòrán, AFP Tẹle, nise ni awọn ojupopo maa n kun fọfọ nilu Eko nitori bi awọn Kristẹni se maa n se iwọde pẹlu ìmọ̀ ọpẹ lọwọ lati fi sami bi Jesu se gun kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ wọ Jerúsálẹ́mù saaju ki wọn o to kan mọ agbelebu.
Ati paapaa nitori ija to wa laarin oun ati Olori egbe oselu Action Group nigba naa, Bode Thomas.
” Lẹsẹkẹsẹ ni igi ọ̀pọ̀tọ́ náà bá gbẹ!
awon eniyan soro lede Yoruba, o wa ro awon eniyan lati tun dibo fun egbe oselu APC
 Sibẹ a o ni sai maa bẹbẹ atilẹyin yin bayii siwaju.
Nibayii, kiniun to n sin naa, lo papa ran an sọrun ọsan gangan.
" Aburo ọkọ naa lo sọ pe bi ọjọ mẹta ni iya awọn ti n ṣaarẹ, ti wọn si n fa omi si lara.
Igba ti mo maa fi laju, mo rii pe ero ti pọ gan ti wọn n kigbe pe Haa, obinrin yii ti lọ, oloyun dẹ ni o!"
Child Safety: Òkú Seyi ọmọ ọdún mẹ́ta tó kó ni wọ́n rí
Restructuring: Àgbékalẹ̀ orílẹ̀èdè Nàìjíríà lọ́wọ́ yìí kò lè fàyè ìdàgbàsókè sílẹ̀ fún ẹ̀yàkẹ́yà-Ọ̀jọ̀gbọ́n Banji Akintoye Owó tó kàn mí nínú N4 mílíọ̀nù ìbejì Akeugbagold tí a jí gbé, bàtà ni mo fi rà-Afunrasí Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo Nibayii iye awọn to ti ni arun naa lorilẹede Naijiria ti le ni ẹgbẹẹta bayii.
Ikú keji kò ní ní àṣẹ lórí wọn.
 Wayii o, Iyaafin Murtala ni opolopo nnkan lo ti baje pupoki won o to yan aare Muhammadu Buhari sipo lodun 2015, ni eyi ti yoo si gbaa niakoko pupo ki atunse to monyan lori to lee de baa awon n nkan wonyi.
Election Tribunal: INEC ní òfin kò ní kí èsì ìbò ààrẹ wà lórí ''server''
"Oríṣun àwòrán, Marta Moreiras ""Ẹnu maa n ya mi lati ri ọpọ aworan awọn iya to pọn ọmọ sẹyin amọ ti ko si aworan kankan nipa awọn baba to pọn ọmọ sẹyin."
OLUWA, o óo gbọ́ ohùn mi ní òwúrọ̀,ní òwúrọ̀ ni n óo máa sọ ẹ̀dùn ọkàn mi fún ọ;èmi óo sì máa ṣọ́nà.
Hiramu, ọba Tire kó àwọn òṣìṣẹ́ ranṣẹ sí Dafidi, pẹlu igi kedari ati àwọn ọ̀mọ̀lé ati àwọn gbẹ́nàgbẹ́nà láti bá a kọ́ ilé rẹ̀.
Àyà fi to ba jẹ́ pe ìrú ìròyìn bẹ́ẹ̀ kìí ṣe fún ìgbà pípẹ́ a nígbàgbọ́ pé irú àkọsílẹ̀ yìí ti a gbé jáde lóri ẹ̀rọ ayélujára yóò dí ǹkan ti yóò ma wa titi fún àtúnlò àti pé a kò ní yọọ́ kúrò.
Ọkan lara awọn oṣojumikoro to jẹ oṣiṣẹ ajọ EFCC lo sọ bẹẹ ni ile ẹjọ giga to wa ni ilu Abuja.
Loju opo ẹyẹnkọrin Twitter wọn ni wọn ti kọ ọ si pe ẹnikẹni to ba nilo fọọmu naa lee daa latori ikanni wọn.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Àsìkò Amojúẹ̀rọ Seyi ni ló fi wọlé l'Oyo, kìí ṣe àsìkò èmi Omobolanle' Ọọ̀ni Ilé Ifẹ̀ gbàlejò àwọn èwé sí ìdùnnú àwọn ọ̀dọ́ tilu tifọn ni ile Ifẹ.
Ọkọ rẹ ribisa asala ṣugbọn Hosne ko si ọwọ agbebọn ọhun, ti o si yinbọn pa.
Ìyàlẹ ́ nu ńláńlá lọ ́ jẹ ́ fún agígírí láti rí lúmọ ̀ ogun pẹ ̀ lú àwọn ọdẹ mélòó kan , Ó ti para pọ ̀ pẹ ̀ lú àwọn ọdẹ wọ ̀ nyí ó sì ti gbàgbé iṣẹ ́ tí wọ ́ n rán an nítorí tí ibẹ ̀ dùn mọ ́ ọn fún ọwọ ́ ìfẹ ́ tí àwọn ọḍẹ náà fi gbà á .
Àwọn ìròyìn mìíràn tí ẹ lè nífẹ̀ẹ́ sí: Wọ́n ti rí ọ̀dọ́mọkùnrin olówó Afrika tí wọ́n jí gbé ASUU ń lérí ìyanṣẹ́lódì lórí ọwọ́jà ìjínigbé lórílẹ̀èdè Nàìjíríà Naijiria k'ọmọogun lati wa'wọn ọmọ Dapchi Niger-Delta: Ẹ maa reti ikọlu Fadá méjì, ọmọ ìjọ 13 kú nínú ìkọlù darandaran Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Ṣugbọn kí ẹ mọ̀ dájú pé bí ẹ bá pa mí, ẹ óo fa ẹ̀bi ẹ̀jẹ̀ aláìṣẹ̀ sórí ara yín, ati ìlú yìí ati àwọn ará ìlú yìí, nítorí pé nítòótọ́ ni OLUWA rán mi pé kí n sọ gbogbo ohun tí mo sọ kí ẹ gbọ́.
 Orí tí yóò gbeni ní gbé aláwo ‘re ko ni 
Ìgbà tí iwin yìí rí fìlásayépọ̀ wọ̀n yọ̀ mọ́ ara wọn, wọ́n sì kí ara wọn dáadáa.
A kó ìkógun jọ bí ìgbà tí tata bo oko,àwọn eniyan dà bo ìṣúra, bí ìgbà tí eṣú bo oko.
4 13997 Orilẹede Bahrain 347 22.
Ni bayii, iko agbaboolu Falcons ti gba ife eye idije AWCON ni igba mesan an otooto, ti won si gba ni igba meta otooto lori ara won.
Ajo ti o n ri si oro isiro lorile-ede Nigeria, ti a mo si National Bureau of Statistics (NBS) so pe, owon-gogo owo ori oja ja wale ninu osu kinni odun 2018 lati iko marundogun o le to 15.
Dokita Maymunah Yusuf Kadiri to jẹ onimọ nipa aarun ọpọlọ sọ pe ibanujẹ ọkan, ijakulẹ, airiṣẹṣe, ọti mimu ati oogun oloro wa lara awọn idi to n mu ọpọ gba ẹmi ara wọn.
Inu mọsalasi kan to wa ni agbegbe New Road, Kurmi Mashi, ni ijọba ibilẹ Kaduna North ni wọn ti ri oku ọmọ naa.
Oludije fun ipo aare  ninu egbe PDP ,Atiku Abubakar, so pe afojusun
Àkọlé àwòrán, Dokita igbekele salaye awon ipenija to maa n koju awon alaarun foniku fọladide Awọn eyi to yẹ ni mimọ lasiko yii ni: 1.
Bí bẹ́ẹ̀ kọ́, irú ẹ̀gbìn yìí ò ní káwọ́ nílẹ̀ bọ̀rọ̀.
ní ọjọ́ náà, ẹnìkan tí yóo sá àsálà ni yóo wá fún ọ ní ìròyìn.
Ọ̀pọ̀ dẹ́yẹ sí ni mo ti ri nítori mó ni ààrún ori pípa- Liliya Kukushkina
Ó ní, “Ìwọ̀n ọkà Baali mẹfa ni ó dì fún mi, nítorí ó sọ pé n kò gbọdọ̀ pada sí ọ̀dọ̀ ìyá ọkọ mi ní ọwọ́ òfo.
Mo  tun fe fi daa yin loju pe, a o ni kaare lori ojuse wa lati ri I pe eto idibo odun 2019 lo ni irowo-irose, niwon igba ti, a ba ti ri atileyin lati odo yii”.
1 Àwọn iṣẹ́, àti àwọn àgbékalẹ̀, àti àwọn èrò Ọlọ́run kò ṣeé bàjẹ́, wọn kò sì le di asán.
Ní bayìí aṣoju ọmọ ile to kéré jùlọ nígbà kan rí George Akime ti rọ gbogbo ọmọ ilé ìgbìmọ̀ aṣofin àgbà àti aṣojú-ṣòfin láti ri dáju pe wọn bọ̀wọ̀ fún ipinu ẹgbẹ́ láti dibò fún Ahmed Lawan gẹ́gẹ́ bi ààrẹ ilé ìgbìmọ aṣòfin àti Femi Gbajabiamila bi agbẹ́nusọ aṣoju-ṣòfin kí ǹkan tó ṣẹlẹ̀ ní ọdún mẹ́rin sẹyìn máà tún wáye.
Saaju, ogbeni Edward Ubosi ti o je agbenuso fun ile-igbimo asofin ipinle naa so pe, awon asofin ni ipade ifenuko lati je ki alekun ba isuna owo ohun.
Lori oro aabo ati alaafia nile Afrika, ogbeni Faki pe fun mimu igberu ba igbe-aye alaafia ati eto aabo ninu igbimo ajo isokan AU.
A máa tẹ̀síwajú láti béèrè fún àwùjọ tí a ti lè gbáyé pẹ̀lú ààbò tó péye.
Ọ̀tọ̀ lọ̀rọ̀ táa ń pè yín sí - Aráa Ketu Iroyin fihan pe ọwọ ọlọpaa tẹ Jolaosho nigba ti awọn agbaagba ẹlẹsin ibilẹ fi ọrọ naa to awọn ọlọpaa leti.
Wolii àgbàlagbà yìí gbé òkú ọkunrin náà sí ẹ̀yìn kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ rẹ̀ ó sì gbé e pada wá sí ìlú Bẹtẹli láti ṣọ̀fọ̀ rẹ̀, ati láti sin ín.
Ile ẹjọ naa ni ipẹjọ ẹgbẹ oṣelu All Progressives Congress (APC) ati oludije wọn ko ni ojun kankan to ṣee di mu lọwọ bẹẹ si ni wọn ko laṣẹ lati ṣagbeyẹwo ofin ara wọn.
Àwọn aṣọ́nà ni, Akubu, Talimoni ati àwọn arakunrin wọn, àwọn ni wọ́n ń ṣọ́ àwọn ẹnu ọ̀nà, wọ́n jẹ́ mejilelaadọsan-an (172).
26 Ọ̀wàrà 2019 Oríṣun àwòrán, @Haramainsharifain Àkọlé àwòrán, Sheik Abdul Rahman Al sudais lasiko irun Jimoh ni mọṣalaṣi Ka'bah Opọlọpọ awuyewuye lo ti n waye ti ọpọ n beere idi ti awọn ọmọ ogun ilẹ fi n ṣọ awọn aafa to n ṣaaju irun ni Mẹka ati Medina.
"Iyé ènìyàn to sọ pe ""ọlọpàá"" jẹ ìdá mẹ́tà lé lọgọta nínú ida ọgọrun tí ìbèrè míràn tún sọ pé, ẹka wo ni àwọn ènìyàn ti san rìbá jùlọ?"
Ṣamai náà bí ọmọ meji: Nadabu ati Abiṣuri.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Àkòjọpọ́ àwọn nkan tó ṣẹ́lẹ̀ lágbo tíátà Yoruba lọ́sẹ̀ yìí 27 Ẹrẹ̀nà 2020 Oríṣun àwòrán, Instagram Awọn oṣere Yollywood ti dawọ sinima yiya duro bayii nitori itankalẹ aarun coronavirus.
Eeyan melo ni yoo maa wa ninu ọkọ Danfo atawọn bọọsi akero nigboro lasiko ti wọn ba dẹ ọwọ aṣẹ naa diẹ bẹrẹ lati ọjọ kẹrin oṣu karun un ọdun 2020.
Ìran Keji tí Ọlọrun Fi Han Isikiẹli.
Àwọn agbénipa tún ti pa ọmọ ọdún márùn ún kan ní Ibadan Wo bí ìpinu Amẹ́ríkà lórí gbígba físà ṣe kan ọ́ Ohun tí a mọ̀ nìyí nípa àwọn tí yóò láǹfàní àti lọ sí Hajj lọ́dún yìí Ìjọba Nàìjíríà ránṣẹ́ pe aṣojú Ghana lórí ilé Nàìjíríà tí wọ́n wó lulẹ̀ ní Ghana Olamide, aburo rẹ ati awọn ọmọ rẹ mejeeji sun mọju nile Chris, nigba ti ilẹ si mọ ni aburo Olamide gbọ orin kan to lagbara lati inu yara ti Chris ati ẹgbọn rẹ sun si, igba to de ibẹ lo ri pe awọn mejeeji ti ku.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Transfer deadline day: Man United ra arúgbó ọjọ́ Cavani, Arsenal bínú ra Partey, Walcott padà sí ẹsẹ àárọ̀ 6 Ọ̀wàrà 2020 Oríṣun àwòrán, Getty Images Ẹni to ba foju ana wo oku, ẹbọra ni yoo bọ oluwa rẹ laṣọ.
Ò sì máa kìlọ̀ fún wọn kí wọ́n lè yipada sí òfin rẹ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Àìsàn dá Ààrẹ àná ni Zimbabwe, Robert Mugabe, dùbúlẹ̀ 21 Ìgbé 2018 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 25 Bélú 2018 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ara Robert Mugabe ti di ara agba ti pẹ ṣugbọn o kọ lati fi ijọba silẹ Igba kan ko lọ bi orere.
Ṣe a mọ pe ayederu iroyin ni?
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ruga Settlement: Ganduje ní káwọn Fulani darandaran kúrò lápá gúúsù Nàìjíríà 28 Agẹmo 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Gomina ipinlẹ Kano, Abdullahi Ganduje ti woye pe tawọn Fulani darandaran ko ba kuro lapa Guusu Naijiria, ọrọ ruga ko le lojutu.
COZA: Wo ohun tó ṣẹlẹ̀ ni ṣọ́ọ́ṣì COZA láàrọ́ yìí
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Celestine fa adá yọ, ó sì gé orí ọmọ mi méjì' Bayii lo ṣe ṣẹlẹ lọjọ abamẹta Ọkan lara awọn afẹhonu han sọ fun BBC pe awọn ọkọ ajagbe nla ṣi wọle ti wọn si bẹrẹ si ni fi afẹfẹ tajutaju ati ibọn si awọn ti wọn ṣe ifẹhonu han ni olu ilu orilẹede Sudan.
"Ìró ìbọn dún lákọ ní Iwo road n‘Ibadan, Seyi Makinde yọjú síbẹ̀ Àwọn jàndùkú kọlu ọgbà ẹ̀wọ̀n Ikoyi, agbófinró gba àkóso ibẹ̀ ""7000 Jàǹdùkú ló fọ́ ọgbà ẹ̀wọ̀n Okitipupa, jó mọ́tò, tí wọn si se òṣìṣẹ́ léṣe"" Kini Ijoba sọ?"
Èèyàn 38,344 ló ti ní COVID-19 ní Nàìjíríà lẹ́yìn tí 543 kún un lọ́jọ̀rú 8) Olubowale Victor Akintimeyin: Ọjọ Kọkanlelogun, oṣu Kẹwaa, ọdun 1984 ni tọkọtaya kan to jẹ ọmọ ilẹ Kaarọ Oojiire, bi gbajumọ akọrin takansufe kan, Olubowale Victor Akintimeyin.
Bi igbe aye Oyinkansola Ajasa Abayomi si ṣe lọ ree, eyi to yẹ kawọn obinrin iwoyi fi kọgbon ati awokọse rere.
Ati pé, bí ó bá kọ̀, tí kò jẹ́ kí wọ́n lọ, 
Ẹ̀yin amòfin ati ẹ̀yin Farisi, ẹ̀yin aláṣehàn wọnyi.
Nitorinaa, ohun akọkọ ti a maa n wo ni pe ṣe irufẹ ẹni bẹẹ nikun oju iwọn ati di eyikeyi ninu ipo ilu mu lorilẹede Naijiria.
WhatsApp: Ìgbésẹ̀ tó gbé rèé láti mọ̀ bóyá fóònù rẹ̀ kò ní lo áàpù yìí mọ́
Mọrèmi Àjàṣorò, akọni obìnrin tó gba Ilé Ifẹ̀ sílẹ̀ lóko ẹrú Ọ̀rọ̀ǹpọ̀tọ̀niyùn, Aláàfin obìnrin àkọ́kọ́ rèé, tó ní nǹkan ọkùnrin Ṣé ìwọ mọ odò adágún Adó Àwáyè tí kò ní òpin ní ìsàlẹ̀?
Àwọn ìdílé ẹ̀yà Lefi nìwọ̀nyí gẹ́gẹ́ bí arọmọdọmọ wọn.
Labani wí pé, “Òkítì yìí ni ohun ẹ̀rí láàrin èmi pẹlu rẹ lónìí.
Liverpool fí ogun ẹ̀yìn ja Barcelona Ilé ẹjọ́ kòtẹmilọ́rùn yóò dajọ́ ìdìbò gómìnà Oṣun ọdún 2018 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ajax ló kọ́kọ́ gbá góòlù méjì sáwọ̀n Ni bayii, Tottenham ni yoo koju Liverpool ninu aṣekagba idije Champions League ti yoo waye ni papa iṣere Real Madrid ni ọjọ kinni oṣu kẹfa ọdun yii Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Alaafin Sango ki i ku ogun ajaye amọ isẹlẹ naa ko dun mọ ọ ninu rara, to si pe awọn Ọyọmesi rẹ lati fun un ni imọran lori ohun to yẹ ko se lati rẹyin awọn jagunjagun alagbara mejeeji.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Premier League: Salah, Mane fi àmì tuntun lélẹ̀ 15 Ìgbé 2018 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Salah àti Mane ti di èèkàn nínú ikọ̀ agbábọ́ọ̀lù Liverpool Ìlúmọ̀ọ́ká agbábọ́ọ̀lù orílẹ̀èdè Egypt nì, Mohammed Salah ti di agbábọ́ọ̀lù ọmọ ilẹ̀ Áfíríkà tó gbá góòlù tó jẹ góòlù tó pọ̀jù ní sáà ìdíje bọ́ọ̀lù kan ní líìgì Premiership.
Inú odò ni wọ́n ti rí òkú ọmọ ọdún méjì tó sọnù l'ọ́jọ́ ọdún Eid nílùú Ibadan Coronavirus já wá sílẹ̀ ju ti àt'ẹ̀yìn wá lọ, kò ju èèyàn 288 tó kó o lọ́jọ́ Ajé A ṣe sùúrù tó, ọmọ wa ló gbọ́dọ̀ jẹ́ ọ̀gá fásitì UI lọ́tẹ̀ yìí - àkóríjọ́ ẹgbẹ́ ọmọ Ibadan 'Irọ́ ni o, àò pinnu láti kógbá Shoprite wọlé ní Nàìjíríà' Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'A ò tíì rí omi mu, ẹ ní ká máa fọwọ́ tóríi Coronavirus' Ohun ti ajọ LASEMA gaan ba nigba ti wọn debẹ ni pe ibugbamu gaasi ọhun ti ṣẹlẹ eyi to n lo lati fi jo irin ninu ọkọ akẹru nla torii pe gaasi naa n yọọ jo jade.
Ó wá hàn kedere pé Ọlọrun kì í wo iṣẹ́ ọwọ́ eniyan kí ó tó yàn wọ́n; àwọn tí ó bá pinnu tẹ́lẹ̀ láti yàn ní í pè.
Lọwọ-lọwọ bayii, awọn aṣofin mẹrinla ninu mẹtalelogun ti buwọlu yiyọ Igbakeji Gomina ipinlẹ Ondo, Agboola Ajayi ni ipo.
Kò sì sí iṣẹ́kan tí àwọn ará àdúgbò mọ̀ ọ́n mọ́.
Amọ BBC ko ti le fi idi ẹsun tuntun yii mulẹ, nitori pe a ko ti i gbọ ọrọ lẹnu kọmisana naa.
Ijoba to n tuko Abuja ati agbegbe re, FCTA ti gbe owo naira to to milionu metalelogun sile fun abere ajesara lati gbogun ti arun igbona losu keji odun yii.
Nígbà tí ó si kà á tán ó dáhùn, ó ní:
“Ǹjẹ́ eniyan lè wúlò fún Ọlọrun?
Mo rí gbogbo àwọn nǹkan tí wọ́n ti rà láti fi sin òkú náà kí wọ́n tó sin ín.
"Yasin ni "" Èrèdí ìrìnàjo mi si ìpínlẹ̀ Ọyọ ni láti rí Gomina Makinde lóri ọ̀rọ̀ àwọn ẹgbẹ́ awakọ, sùgbọ́n gomìnà ni òun fofin de ẹgbẹ awakọ, nítori àláfíà àwọn ènìyàn ìpínlẹ̀ Ọyọ ni."
Oríṣun àwòrán, Getty Images Wọn kò fẹnu ọ̀rọ̀ jóná lórí ohun tó ń kọ Egypt àti Sudan lóminú níbi ìpàdé ọjọ́ Ajé Minisita fun ọrọ ohun alumọọni inu omi ati ohun amusagbara lorile-ede Ethiopia, Sileshi Bekele, ti kede lori redio ati tẹlifisan orilẹede naa, EBC pe awọn ti n fa omi sinu ibudo iṣe omi lọjọ si, ti wọn kọ si ẹba odo Nile.
Ọ̀rọ̀ ìfẹ́ ti wọn fi ń lọ̀ mí lágbo àmúlùúdùn ni ìṣòro kan tí mo ní - Lizzy Jay ọmọ Ibadan 'Èèwọ̀!
Igba ọkunrin ni Absalomu pè, tí wọ́n sì bá a lọ láti Jerusalẹmu.
Ninu esi ayẹwo to fi sita lọjọ Aiku, ajọ NCDC sọ pe ipinlẹ Eko nikan ní eeyan 255 lara awọn to ni i bayii.
Wọ́n rán àwọn amí láti lọ wo Bẹtẹli.
Nigbakugba ti aarẹ ba ti wa si ilu Eko, iya maa n jẹ awọn olugbe ilu Eko ni atari sunkẹrẹ-fakẹrẹ ọkọ.
Minisita fun oro abele lorile-ede naa so pe, Abol Fotouh se “ipade idakonko”pelu awon adari egbe Brotherhood lagbaye, lasiko abewo re si ilu London ni ibere osu ti a wa yii, lati se agbateru laasigbo ni orile-ede naa.
Àwọn ọmọ Etamu ni: Jesireeli, Iṣima, ati Idibaṣi.
agbaboolu mefa miiran ko gbeyin ninu iko naa.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù LASU Murder: Àwọn ẹbí ní ìwádìí ọlọ́pàá ṣì ń tẹ̀síwájú ni wọn kò ṣe rí òkú gbà 7 Sẹ́rẹ́ 2020 Oríṣun àwòrán, @femiadi Eto isinku Favour Daley-Oladele, ti iya, ọmọ pẹlu Pasitọ sekupa lati fi se oogun owo, to yẹ ko waye lọsan ọjọ Isẹgun, ni wọn ti sun siwaju.
Ile rẹ lagbegbe Ijẹtu nilu Osogbo ni Mama dakẹ si.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Andrew Haruna: So-bàtà tó di ọ̀jọ̀gbọ́n fásitì tó di ọ̀gá àgbà 22 Bélú 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 9 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Oríṣun àwòrán, @others Àkọlé àwòrán, Ko si ẹni ti ko lè gòkè àgbà láyé tóo bá ti ní ifọkansìn.
BBCCopyright: BBC Kii ṣe akọkọ ree ti Gbajabiamila yoo du ipo olori ileImage caption: Kii ṣe akọkọ ree ti Gbajabiamila yoo du ipo olori ile Article share tools Facebook Twitter ṢàpínlòView more share options Share this post Copy this linkKà síwájú síi nípa àwọn ìtọ́kasí wọ̀nyí.
EFCC: Akala se magomago biliọnu mọkanla at‘aabọ naira
Ile iwe Kings College ni ipinlẹ Eko ni Bukọla lọ feto ẹkọ girama lọdun 1973 si 1978, ile ẹkọ naa kìí ṣe f'awọn ọmọ kola-kosagbe ẹda, nitori ‘yapo-rẹ-wo’ ni nigba naa.
Oun nikan si lo ku laye ninu gbogbo awọn to fi ọwọ si iwe igbọraẹniye lori idasilẹ rẹ Oríṣun àwòrán, @followlasg Àkọlé àwòrán, Àwọn ènìyàn nlanla ló péjú sí ibi ayẹyẹ ọdún mọ́kàndínlọ́gọ́rùn Akintọla Williams Alaga igbimọ to n riṣi gbigba owo ori fun ijọba apapọ laarin ọdun 1958 - 1968 Igbimọ oluwadi Coker Commission, to ṣe iwadi awọn awọn ileeṣẹ to jẹ ti ẹkun Western Region of Nigeria l'ọdun 1962 Ọmọ igbimọ majẹobajẹ fun ajọ Commonwealth Foundation laarin ọdun 1966-1975 O jẹ Alaga ajọ to ṣe atunṣe si kudiẹ-kudiẹ to wa ninu eto sisan owo oṣu awọn oṣiṣẹ ijọba ti ajọ Udoji Salary Review Commission ṣe( 1975) Oun naa ni oludasilẹ ati alaga igbimọ majẹobajẹ fun Ẹgbẹ awọn Akọrin ni Nigeria, MUSON.
Ṣùgbọ́n tòun ti pé kò kìn ín gba ìgbàkugbà nínú eré, Sobowale ṣàlàyé fún BBC pé òun kìí ṣe ènìyàn tó burú.
Gbogbo ẹni tí kò bá jẹ́wọ́ bẹ́ẹ̀ kì í ṣe ti Ọlọrun.
Toyin Abraham: Oríṣun àwòrán, Toyin abraham Toyin Abraham jẹ ẹni taye n fẹ ninu tiata Yoruba, to si ti ṣe ọpọ sinima jade ni ede Yoruba.
Oríṣun àwòrán, Twitter/Muhammadu Buhari O ti di ogoji eeyan to ti lugbadi arun coronavirus bayii lorilẹ-ede Naijiria, lẹyin ti ajọ to n gbogun ti ajakalẹ arun ni Naijiria, NCDC kede awọn mẹrin mii to ti ni aisan naa lalẹ ọjọ Aje.
Josẹfu bá mú Jakọbu baba rẹ̀ wọlé láti fihan Farao, Jakọbu sì súre fún Farao.
Ṣugbọn nigba to n ba BBC Yoruba sọrọ lori eto kan ta se fun l‘Ọjọru, Adebimpe sọ pe iṣu Ọlọrun ti ko ṣe e fi ọwọ bo ni ọrọ oyun nini, ati ọrọ ọkọ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Oronpoto Animation: Akin Alabi ní kò dára bí eré aláwòrán fáwọn ọmọdé ṣe jẹ́ aláwọ̀ funfun Oyinkan pinnu pe oun ko ni fẹ ọkọ miran mọ nitori iku ọkọ rẹ aarọ ba a lojiji, to si dun wọnu egungun.
Àwọn yàrá ti àgbékà kẹta kéré, nítorí ibùjókòó-òkè ti àgbékà kẹta fẹ̀ ju àwọn tí wọ́n wà níwájú àwọn yàrá àgbékà kinni ati ti àgbékà ààrin lọ.
Loni o ti gbe orukọ ẹbi rẹ ga.
Àkọlé àwòrán, Gbogbo ori aga ni BBC Yoruba ti gbe apo ẹbun si fun awọn olikopa lati mọ riri wiwa wọn.
Àwọn ta sì ni arakunrin mi?
Iko agbaboolu orile-ede France di iko agbaboolu Germany mu lati gba oomi ayo (0-0), ninu ifesewonse idije Nations League ti o waye lojoBo(Thursday), eleyi ti o je ifesewonse akoko ti won yoo gba lati igba ti iko naa ti idije boolu agbaye.
Baba rẹ̀ bá lọ sí ọ̀dọ̀ obinrin náà.
Lọwọlọwọ bayii, ijọ̀ba orilẹede Naijiria ti ransẹ ke si asoju ijọba ilẹ SZouth Africa to wa ni naijiria si ibi ipade kan.
mẹjọ-le-mẹrin-din-ẹẹdẹgbẹrun (8,896), nigba ti akẹgbẹ rẹ lati ẹgbẹ
Visa Application: Amẹ́ríkà ń béèrè ìròyìn ojú òpó arìnrìnàjò
Orile ede mejeeji naa jọ tọwọbọ iwe adehun
Wọ́n ni wọ́n ti ṣetò ibùdó wọ́n sínú igbó Kunyan lópópónà Airport.
Yorùbá bọ wọn ni oríṣiríṣi ọ̀bẹ làári lọ́jọ́ ikú erín.
Ohun ti o ma n saba ṣẹlẹ ni ki awọn eeyan ma ri iwe pelebe ti a ṣafihan rẹ loke ti o ni nọmba NIN lara.
O yọju lọsẹ to kọja pẹlu awọn ẹri kan lati fi ti ọrọ rẹ lẹyin, ko to o di pe o bẹrẹ si ni wo odi ti wọn mọ yi ile naa ka lulẹ.
"Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ọ̀pá àṣẹ Ọba Akiolu tẹ gbé, a kò ní fọwọ́ yẹpẹrẹ mu - Ìgbìmọ̀ Ọba l‘Eko yarí ""Ìfẹ́ akọ sákọ àti abo sábo tó wọ́pọ̀ ní Àríwá Nàíjíríà ló fa ìbínú Ọlọ́run"" Olori Badra sọ̀rọ̀ nípa ayé rẹ̀, ó ní ẹ́ bá òun sọkún Ìjọba Eko fẹ́ tú olùwọ́de EndSARs 253 sílẹ̀ lọ́jọ́ Ajé nínú 361 tó wà láhàámọ́ Bàyíì ni mo ṣe kílọ̀ fún Donald Trump, àmọ́ kò gbọ́rọ̀ - Primate Ayodele Akọ tó fẹ́ akọ ṣayẹyẹ ìgbéyàwó ọdún kẹrin, wọ́n ra ilé kejì Jàndùkú ṣọṣẹ́ lọ́jà Agbeni, àwọn àti agbófinró kọjú ìbọn síra wọn Díẹ̀ ló kú kí owó tán l‘ápò mi torí ìrànwọ́ Coronavirus - Pasuma Mo ṣèlérí láti rí sí ìrẹ́pọ̀ àti ìwòsàn Amẹ́ríkà - Joe Biden Ìjọba Oyo gbé ilé ẹ̀kọ́ gíga kan tìpa torí àrùn Coronavirus Olori ọwọ kẹsan ileesẹ ologun (9 Brigade) naa sọ ọrọ yii, ninu iwe ijẹri to kọ siwaju igbimọ oluwadi ọhun lọjọ Ẹti."
Nítorí àwọn erékùṣù yóo dúró dè mí,ọkọ̀ ojú omi Taṣiṣi ni yóo ṣiwajuwọn óo kó àwọn ọmọkunrin rẹ wá láti ilẹ̀ òkèèrè,wọn óo kó wúrà ati fadaka wá pẹlu wọn;nítorí orúkọ OLUWA Ọlọrun rẹ,ati Ẹni Mímọ́ Israẹli,nítorí ó ti ṣe ọ́ lógo.
Ile-ise omo-ogun Naijiria ti benu ate lu iroyin kan ti o so pe, iko omo ogun naa ti gbegi dina opopona oko lati ilu Maiduguri siluu Monguno.
Má jẹ́ kí ojú ti àwọn tí à ń pọ́n lójú;jẹ́ kí àwọn tí ìyà ń jẹ ati àwọn aláìní máa yin orúkọ rẹ.
Ta ni ìgbẹ́jọ́ ìbò gómìnà Ondo yóó gbè nínú Akeredolu àti Jegede?
Ẹnikẹ́ni tí kì í ṣe ọmọ Lefi kò gbọdọ̀ bá ọ ṣiṣẹ́.
Ile Igbimọ Aṣofin Ipinlẹ Eko ṣagbatẹru idanlẹkọọ ọlọjọ mẹta fun awọn oṣiṣẹ wọn lati tubọ mu igberu ba iṣẹ wọn ti wọn fi n ṣatilẹyin fun ofin ṣiṣe ni ipinlẹ yiiNinu ayẹyẹ ibẹrẹ Idanilẹkọọ naa ti wọn pe akori rẹ ni “Jijabọ , Kikọ ati Gbigba awọn iṣẹ ati Ijiroro Ile silẹ fun aṣeyọri iṣẹ” ni Agbẹnusọ Ile Igbimọ Aṣofin Ipinlẹ Eko, Aṣofin Mudashiru Ọbasa ti sọ pe awọn oṣiṣẹ Ile naa n ṣe gudugudu meje yaaya mẹfa ninu ojuṣe lati ṣatileyin iṣẹ ofin ninu Ile Igbimọ Aṣofin Eko.
A óo fi ìjọba ati àṣẹ, ati títóbi àwọn ìjọba tí ó wà láyé fún àwọn eniyan mímọ́ ti Ẹni Gíga Jùlọ, ìjọba ayérayé ni ìjọba wọn yóo jẹ́, gbogbo àwọn aláṣẹ yóo máa sìn ín, wọn yóo sì máa gbọ́ tirẹ̀.
Hesekaya pín àwọn alufaa ati àwọn ọmọ Lefi ní ọ̀wọ̀ọ̀wọ́, olukuluku ní iṣẹ́ tirẹ̀.
 oṣù kéjìlá ọdún 2007 bí ó fi ipò àrẹ ilẹ ̀ slovenia sílẹ ̀ .
Titi di asiko ti a fi n ko iroyin yii jọ, ko tii si ẹni lee sọ ni pato ohun gan to n ṣokunfa iku ọwọọwọ to n waye ni ipinlẹ Kano naa bi o tilẹ jẹ wi pe iku naa n ṣe kongẹ asiko ajakalẹ arun Coronavirus lorilẹede Naijiria.
nile-igbimo asoju-sofin ati awon omo egbe miiran sabewo sile re niluu Minna ti
Ṣugbọn Jehoṣeba, ọmọbinrin Jehoramu ọba, tí ó jẹ́ iyawo Jehoiada alufaa, gbé Joaṣi ọmọ Ahasaya sá kúrò láàrin àwọn ọmọ ọba tí wọ́n fẹ́ pa, nítorí pé àbúrò rẹ̀ ni Joaṣi yìí.
OLUWA sì ní òun óo gbé yín sọnù.
"Àsìkò tó láti fi ìwọ́de gba ara wa sílẹ̀ lọ́wọ́ ebi àti oko ẹrú - Sowore Aáwọ̀ ọ̀dọ́ Yorùbá àti Hausa ló dá wàhálà sílẹ̀ ní Ṣásá - Ṣeriki Hausa Osere tiata naa, ti oju rẹ ti gun rege pada ni ""Mo fẹ lo akoko yii lati dupẹ pupọ lọwọ awọn ọmọ Naijiria fun ifẹ, adura ati igbarata wọn lasiko ti mo fi ni iba, ori mi wu fun iru ifẹ ti ẹ fi han si mi."
Bakanna lo ṣọ pe ijọba n ṣe eto ilanilọyẹ fawọn ile iwosan aladani lori ati maa tẹle Ilana ati gbogun ti ajakalẹ arun covid-19.
Ṣugbọn ibi tí OLUWA bá yàn láti gbé ibùjókòó rẹ̀ kà láàrin gbogbo àwọn ẹ̀yà, ibẹ̀ ni kí ẹ máa lọ.
O ni, agbára oyin náà ni pe a o lè yí ara wa padà sí ohun kóhun tí a bá fẹ́ nígbà tí ìjàkadì bá le ni ọjọ́ kejì.
Asoju orile ede Serbia so pe “ E je ki n so fun yin pe orile ede Serbia ti setan lati se atileyin fun iko awon omo-ogun orile ede Naijiria ,ati pe lati ojo to ti pe ni ajosepo orile ede mejeeji yii ti wa.
“ ‘Ẹni ìfibú ni ẹnikẹ́ni tí ó bá ṣi afọ́jú lọ́nà.
”  “O je ohun ti o bani ninu
Minisita fun ile-ise ti o n ri si eto isuna lorile-ede Egypt Amr El Garhy so lojo-Ru pe, ile-ise fun eto isuna ohun  ti setan lati bere ijiroro ninu osu ti a wa yii pelu awon ile-ifowopamo ile Europe, lati se agbekale eto eya-wo naa, ti osuwon re to bilionu kan o-le owo ile Euro ti won yoo bere si tita re ninu osu kerin.
Drogba kopa fun iko agbaboolu Le Mans, Guingamp, Marseille ki o to lo darapo mo iko agbaboolu Chelsea lodun 2004.
ní ọdún 2004 , wọ ́ n dá ọkọ ̀ yìí dúró ní kuwait lẹ ́ yìn ìgbà tí ó ṣe sábàbí jìbìtì .
 bí ìtàn náà ṣe só síwájú , tami onírè aládésogun tí ó ṣèrìn àjò pẹ ̀ lú ẹ ̀ gbọ ́ n rẹ ̀ kan olú-Ìwà àti àwọn amojú òrìṣà kan láti waddai ní ilẹ ̀ sudan ní orílẹ ̀ -èdè ijípítì .
Nitori eyi, ni wọn fi n pe wa ni Awọn Alufa oju popona.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Rape: Ó kéré tán wọ́n ń fipá bá obìnrin kan lòpò láàrín wákàtí márùn ún ní Naijiria 15 Òkùdu 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 16 Òkùdu 2020 Oríṣun àwòrán, Twitter/nigeria police Iye eniyan to to 717 ni wọn ti fipa ba lọpọ lorilẹede Naijiria laaarin Osu Kini si Osu karun un ọdun yii, ti osi fihan pe laarin wakati marun, won fi ipabaobinrin lọpọ.
Àbí ti àwọn Juu nìkan ni Ọlọrun, kì í ṣe ti àwọn orílẹ̀-èdè yòókù?
Ajanaku kọja mo ri nkan fìrí ni ohun ti àwọn akọni mẹrin yii ṣe.
Mose bá na ọwọ́ sórí òkun, òkun bá bẹ̀rẹ̀ sí ṣàn gẹ́gẹ́ bí ó ti ń ṣàn tẹ́lẹ̀ nígbà tí ilẹ̀ ọjọ́ keji yóo fi mọ́; àwọn ará Ijipti gbìyànjú láti jáde, ṣugbọn OLUWA pa wọ́n run sinu òkun náà.
Ohun ti Pasito Adeboye n gbiyanju lati sọ ni wi pe yatọ si iwa mimọ, gbigbe igbe aye imọtoto ṣe pataki lati bori arun Coronavirus.
Sugbọn, ipade naa ko le waye nitori 'wahala kan' to waye nile aṣofin naa ni ọjọ ipade.
Kí ni kí á wá wí sí èyí?
Wọn de ọdọ babalawo kan ti orukọ rẹ n jẹ Abẹ.
Lati ọdun 2005 ni Yemi Blaq ti kara bọ awujọ awọn elere Yoruba, Yollywood àti ti gbogbo Naijiria lapapọ, Nollywood to si ti ṣe deedee lati igba naa ti awọn ololufẹ rẹ gẹgẹ bi oṣere si n gbayii awọn ere rẹ Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí kan sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
Ofin konile-o-gbele yoo ṣi wa nikalẹ ni ipinlẹ Eko, Ogun ati Abuja Ofin konile-o-gbele kogberegbe yoo tẹsiwaju ni ipinlẹ Kano fun ọsẹ meji gbako, gẹgẹ bi ijọba ipinlẹ naa ti ṣe gbe e kalẹ Awọn gomina ipinlẹ kọọkan lee wa ṣe eto bi awọn aṣẹ wọnyii yoo ṣe ba awọn eeyan wọn lara mu ati aṣẹ miran ti ko gbọdọ tako eyi ti aarẹ la kalẹ wọnyii.
Afenifere fara ya lórí bí Tinubu ṣe jókòó kí Ooni Oríṣun àwòrán, Others Ẹgbẹ ọmọ Yoruba lorilẹede Naijiria, Afẹnifẹre ti bu ẹnu atẹ lu ihuwasi adari ẹgbẹ oṣelu APC, Bola Tinubu pẹlu bi ko ṣe dide lati ki Ooni ti Ife, Oba Adeyeye Ogunwusi, lasiko ti wọn n fi Ọba oniru ti Iru, Oba Omogbolahan Lawal jẹ ni Eko.
Àtẹ̀gùn kan wà lẹ́gbẹ̀ẹ́ Tẹmpili náà tí ó lọ sókè.
Farao bá ranṣẹ pe Mose ati Aaroni ní òru ọjọ́ náà, ó ní, “Ẹ gbéra, ẹ máa lọ, ẹ jáde kúrò láàrin àwọn eniyan mi, ati ẹ̀yin ati àwọn eniyan Israẹli, ẹ lọ sin OLUWA yín bí ẹ ti wí.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Coronavirus: Àwọn ìlana to tọ̀nà lati tọ ti o ba fún pe o ni ààrun Dokita Ehanire jẹ ko di mimọ pe, awọn to wa lolu ilu orilẹede Naijiria, iyẹn Abuja ninu awọn eeyan naa ti n gba itọju nileewosan nla fasiti ilu Abuja ni Gwagwalada nigba ti awọn to wa nilu Eko n gba itọju nileewosan fun itọju awọn to ba ni ajakalẹ arun.
kí wọn má jókòó ti àwọn ìtàn tí kò lẹ́sẹ̀ nílẹ̀ ati ìtàn ìrandíran tí kò lópin, tí ó máa ń mú àríyànjiyàn wá, dípò ẹ̀kọ́ nípa Ọlọrun tí a mọ̀ nípa igbagbọ.
O ni ko si ija tabi ikunsinu laarin awọn Ọbalaye ni ilẹ Yoruba mọ nitori alaafia ti jọba.
Àwọn arúgbó lọkunrin, lobinrin, tí wọn ń tẹ̀pá yóo jókòó ní ìgboro Jerusalẹmu, 
Oríṣun àwòrán, @unilag Àkọlé àwòrán, Koda UNILAG ti iyara Cold Room pa lẹyin fidio BBC Odindin ọdun kan ni BBC fi ṣe iṣẹ iwadii yii to ṣafihan iwa buruku awọn olukọ kọọkan ni fasiti iwọ oorun ilẹ Adulawọ yii.
Ẹ péjọ kí ẹ gbọ́, ẹ̀yin ọmọ Jakọbu,kí ẹ sì fetí sí ọ̀rọ̀ Israẹli, baba yín.
Abi nnkan kan sẹlẹ ti Alhaji ko ri ni, abi nnkan ti ko yẹ ki wọn sọ fun wọn ni wọn gbọ ni, ko tiẹ ye mi.
Inú gbogbo Juda sì dùn sí ẹ̀jẹ́ náà, nítorí pé tọkàntọkàn ni wọ́n fi jẹ́ ẹ.
Bí ẹ bá wá a, ẹ óo rí i.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Alápinni: Kò sí ẹni to fẹ́ kọ́kọ́ kọ́ iṣẹ́ òṣèré bíi ti àtẹ̀yìnwá Oríṣun àwòrán, Twitter Ko ti daju oun to mu ki awọn olukọni naa binu jade ninu ipade ohun ṣugbọn saaju ipade naa la gbo wi pe ọgbẹni Ngige ti sọ wi pe ohun ni ireti wi pe ọrọ yoo ni iyanju.
Awọn alaga ijọba ibilẹ naa ni se ni gomina ati ẹgbẹ oselu rẹ, PDP, n lo awọn janduku lati maa wa dun mahuru mahuru mọ awọn lati mase yọju si ọọfisi gẹgẹ bii alaga ijọba ibilẹ.
Ìbàlòpọ̀ pẹ̀lú ọ̀rẹ́kùnrin kìí ṣe ìfẹ́, bẹ́ẹ̀ ni ìfẹ́ kọ́ ni ìbálòpọ̀ - Genevieve Nnaji Wo ọ̀rọ̀ tí Asiwaju Bola Tinubu fi síta lórí ìṣòro ètò àbò Nàìjíríà Mi ò to iṣẹ́ Regina Daniels rárá kí n tó fẹ́ ẹ láàrin ọ̀sẹ̀ mẹ́ta, mo sì tún le fẹ́ ìyàwó míì - Ned Nwoko Àyà mi já nígbà tí Ganduje rọ Sanusi lóyè Emir Kano tó fi Bayero síi, ṣùgbọ́n.
Wọ́n tún fi Solomoni, ọmọ Dafidi, jẹ ọba lẹẹkeji.
Ile nlanla, adugbo ati ile isẹ Maina to wa ni Abuja, Kaduna, Borno ati Nasarawa wa lara awọn dukia naa ti wọn ri pe Maina lo nii.
Mẹwaa lo larun coronavirus lati Plateau, mẹrin l'Edo, eeyan mẹta lo larun naa nipinlẹ Ekiti ati Ogun.
"Oríṣun àwòrán, Bobrisky ""Iyawo mẹta ni baba mi ni, iya mi ni iyawo kekere laarin wọn, emi si ni abikẹyin rẹ."
Minisita feto idajọ nilẹ Ireland, Helen McEntee ni owo naa jẹ eyi ti orilẹede rẹ gbẹsẹle lara owo ti Abach ji ko.
Apata ni koda, ẹgbẹ NBA ti gbe igbesẹ pẹlu agbẹjọrọ agba awọn ipinlẹ bii Ogun, Eko ati Edo.
'Mo máa tó dìde lórí àìsàn', Muyiwa Ademola sọ̀rọ̀ látorí àkéte àìsàn rẹ̀ Ẹ̀yin ṣọ́ọ̀ṣì àti Mọ́ṣáláṣí, mo wọ́gilé ìsìn àṣálẹ́ àìsùn ọdún àti ìṣọ́ òòru - Sanwo-Olu Ohun márùn ún tóo gbudọ̀ mọ̀ nípa ìtàn àti ayẹyẹ ọdún Kérésì Àwọn Tíṣà Oyo kó owó tó wà fún àkóso iléèwé jẹ, ni wọ́n fi ń fọwọ́ kọ ìdánwò pẹ̀lú ṣọ́ọ̀kì - Seyi Makinde 4.
Balogun tí ó wà fún oṣù keje ni Helesi, ará Peloni, láti inú ẹ̀yà Efuraimu; iye àwọn tí wọ́n wà ninu ìpín rẹ̀ jẹ́ ọ̀kẹ́ kan ó lé ẹgbaaji (24,000).
Samsoni bá lọ, ó mú ọọdunrun (300) kọ̀lọ̀kọ̀lọ̀ láàyè, ó wá ìtùfù, ó sì so àwọn kọ̀lọ̀kọ̀lọ̀ náà ní ìrù pọ̀ ní meji meji, ó fi ìtùfù sí ààrin ìrù wọn.
Ọba wọn ni angẹli kànga tí ó jìn tóbẹ́ẹ̀ tí eniyan kò lè dé ìsàlẹ̀ rẹ̀.
Wọn ni eto idibo naa le jẹ ki aarẹ orilẹede naa wa lori aleefa di ọdun 2034.
Wọ́n ń san ìṣákọ́lẹ̀ fún un, wọ́n sì ń sìn ín ní gbogbo ọjọ́ ayé rẹ̀.
Wọn tun ta gìtá adaṣe fun ni ti Fender Mustang ṣe fun Cobain naa nibẹ.
Ó ké lóhùn rara wí pé: ‘Ènìyàn!
O ni ki Buhari dẹkun fifi ọwọ musulumi ati fulani ni mi mu ọrọ itajẹ silẹ yii mọ.
Lafikun o ni awọn ṣọọsi to jẹ pe ọjọ Satide ni wọn maa ṣe isin naa lanfani lati bẹrẹ pada ṣugbọn ni itẹle ofin ti awọn ti ọjọ aiku naa n tẹle ni o.
Láti ìgbà Gibea ni Israẹli ti ń dẹ́ṣẹ̀; sibẹ wọn kò tíì jáwọ́ ninu ẹ̀ṣẹ̀.
Ọmọ mi, pa ọ̀rọ̀ mi mọ́,kí o sì fi òfin mi sinu ọkàn rẹ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Aisha Buhari tutọ sókè fojú gbà à, ó ní kí Garba Sheu kọ́we fipolẹ́ 11 Ọ̀pẹ̀̀ 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Aisha Buhari tutọ sókè fojú gbà à, ó ní kí Garba Sheu kọ́we fipolẹ́ Orukọ iyawo aarẹ orile-ede Naijiria, Aisha Buhari lawọn eeyan n lọgun tantan loju opo Twitter lataari ọrọ to sọ pe ki agbẹnusọ aarẹ Buhari Garba Sheu kọwe fipo silẹ.
Gẹgẹ bi alaye Ọọni,lati Ile Ifẹ ni awọn Igbo to lọ tẹdo si Olugbo ti kuro ti itan si fihan pe awọn ni wọn pada wa n damu Ile Ifẹ.
Dokita Anigbamkpu Obinnaadigo, sọ fun BBC pe inu rirun le jẹ àpẹẹrẹ aisan bi òkúta inu kíndìnrín, appendicitis, iba jẹdọjẹdọ (typhoid) àti ọgbẹ́ inu.
Ṣugbọn lẹyin ti wọn gbẹ lọ si ọọfisi lo tun ṣubu lẹẹkeji, to si n mi gulegule bi ẹni ẹmi fẹ bọ lẹnu rẹ.
APC kò ni ṣe ìdìbò nípínlẹ̀ Ondo ti ìgbìmọ̀ bá yọ mi kúrò nínú ìdíje- Segun Abraham Ìyàwó mi ló ṣì ń dáná, bu oúnjẹ mi, gé èékáná fún mi - Pásítọ̀ Adeboye Sotitobire: Ẹlẹ́rìí mẹ́rìn ló tẹ̀lé Alfa Babatunde wá síwájú ilé ẹjọ́ lonìí Ọlọ́pàá kọ́ lo pa olórí àwọn ''One Million Boys'' Ebila n'Ibadan- Ọ̀gá ọlọ́pàá Oyo Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Ẹlẹ́ẹ̀kẹjọ t'óyún máà bàjẹ́ lára mi ni mo tó rí àànú gbà' Wọ́n ni Keyamo kò fi ọ̀rọ̀ náà tó àwọn léti lórí bi wọ́n ṣe yan ìgbìmọ̀ ti yóò mójútó ètò ìgbanisíṣẹ́ náà nínú oṣù kèje ọdún yìí.
Láì san owó oṣù tẹ jẹ wá, kò sọ́rọ̀ kankan - ASUU sọ fún ìjọba ASUU Strike: Àwọn olùkọ́ fásitì ní àmúṣẹ àdéhùn ọdún 2019 làwọn dúró lé lórí Adari ẹgbẹ awọn olukọ nile ẹkọ fasiti nilẹ wa (ASUU), Ọjọgbọn Biodun Ogunyemi ti sọ fun ijọba apapọ ati ti ipinlẹ pe ki wọn san owo oṣu oṣiṣẹ ti wọn gbe ẹsẹ le fun awọn ọmọ ẹgbẹ naa.
Ni ipari o ro awon eniyan orile ede Naijiria lati tubo maa gbe ni alaafia pelu ileri lati se idajo to ye sawon onise ibi ti oro kan.
Gbajumọ oṣere binrin kan, Foluke Daramola si lo tete ke gbajare sita pe irọ nla ni pe Majek ku, nitori baba naa wa laaye bi o tilẹ jẹ pe o n ṣe aarẹ.
Oríṣun àwòrán, LASEMA Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Bakan naa ni ẹni ti o jẹ alaga awọn alapata ni agbegbe naa, Arakunrin Kabiru Ismaila sọ pe, gbogbo ipa ni wọn yoo sa lati ri i pe iru ẹran bẹẹ ko wọ ọja.
Lẹ́yìn náà, Mose gbà á kúrò lọ́wọ́ wọn, ó sun wọ́n lórí pẹpẹ, pẹlu ẹbọ sísun bí ẹbọ ìyàsímímọ́, ẹbọ olóòórùn dídùn, tí a fi iná sun sí OLÚWA.
“Kò sí ẹnìkan tí ó jẹ́ tan fìtílà tán, kí ó fi àwo bò ó mọ́lẹ̀, tabi kí ó gbé e sábẹ́ ibùsùn.
Dogara tun salaye pe “Gege bi adari nile igbimo asofin , a o sa gbogbo ipa wa lati pese gbogbo ohun ti e nilo labe ohun to wa nikawo orile  ede lati le je ki aseyori to monyan  lori wa , idi niyi ti a se wa nibi ipade yii.
Nkan bí oṣù kan àbọ̀ ni ọgbà yìí ṣí fún.
Ohun tó ṣẹlẹ̀ láàrin Ozo àti Nengi olórí àti igbákejì nílé BBNaija rèé Awọn ololufẹ eto ile ẹlẹgbọn agba, BBNaija ti n sọrọ lori ohun to ṣẹlẹ laarin olori ile, Ozo ati igbakeji rẹ, Nengi lalẹ Ọjọru mọju Ọjọbọ.
"Ni ti aye to daye ọlaju, Elebuibon ni ""Kii ṣe gbogbo nnkan ni a gbọdọ maa tẹle pẹlu ọlaju, a ko le sọ pe aye ti daye ọlaju, ka foju ẹgbo tẹ ilẹ."
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Jubril Martins-Kuye: Mínísítà lẹ́ẹ̀méjí, Jubril Martins-Kuye ti jáde láyé wákàtí 6 sẹ́yìn Oríṣun àwòrán, Premium times Eekan oloṣelu kan ni ipinlẹ Ogun to tun ti fi igbakan ri jẹ minisita fun karakata ati idaleeṣẹsilẹ lorilẹede Naijiria, Jubril Martin Kuye ti jade laye.
Ikede yii lo bi awọn oluwọde ninu ti wọn si n lẹ awọn abọ ati ike omi naa mọ ọkọ ti wọn fi gbe e wa pe majele ni ọga ẹgbẹ NURTW ko ranṣẹ si awọn.
Wọ́n jẹ́ ọmọ Esau, tí àdàpè rẹ̀ ń jẹ́ Edomu, àwọn sì ni ìjòyè tí wọ́n ti ọ̀dọ̀ rẹ̀ ṣẹ̀.
''Gbogbo ọna to wọ agbegbe Challenge, Orita, Toll gate ati New Garrage ilu Ibadan ni awọn ọdọ to n ṣe ifẹhonuhan #ENDSARS ti di pa lati owurọ oni, lilọbibọ ọkọ si ti dawọ duro pẹlu.
Ọpọ̀ ìgbà ni àwọn akẹ́kọ̀ọ́ máa ń da oògùn ikọ́ olómi Codeine papọ̀ mọ́ ẹlẹ́rìndòdò wọn.
lorile ede Naijria, mo fẹ ki ile igbimo asofin agba se atunse si iwe ofin nipa
Thomas Crowther ṣe àtúpalẹ̀ ìwádìí yìí ni orilẹ-ede àádọrin ní àgbáyé
Ọwọ́ tẹ awakọ̀ tó ń ra ọjà olè Seyi Awolowo, ọmọ-ọmọ Awolowo, kí ló ń wà lórí ètò BB Naija?
Aṣofin Kuinyi-Owaji Ibani, agbẹnusọ Ile Igbimọ Aṣofin Ipinlẹ Rivers lo ṣoju  ẹkun Gusu-gusu, Arabinrin Rita Maduagu, agbnusọ Ile Igbimọ Aṣofin Ipinlẹ Anambra lo ṣoju ẹkun Ila-oorun Gusu, Wooli Oloyelogun, agbẹnusọ Ile Igbimọ Aṣofin Ipinlẹ Ondo lo ṣoju ẹkun Iwọ-oorun Gusu.
Awọn alatilẹhin aarẹ gbagbọ pe o le ṣe e, ati pe yoo ṣe amulo ilana isejọba tuntun to ni ìtọ́ni Ọlọrun ninu, to si wa ni ibamu pẹlu aini awọn ọmọ orilẹ-ede Malawi.
Israẹli di gbogbo ohun tí ó ní, ó kó lọ sí Beeriṣeba, ó lọ rúbọ sí Ọlọrun Isaaki, baba rẹ̀.
Àmọ́ èmi Alákọ̀wé, nkan arẹwà gbáà ni mo kà á kún.
Ninu àwọn arakunrin Ṣebueli, láti ìdílé Elieseri, a yan Rehabaya ọmọ Elieseri, Jeṣaaya ọmọ Rehabaya, Joramu ọmọ Jeṣaaya, Sikiri ọmọ Joramu ati Ṣelomiti ọmọ Sikiri.
INEC yóò ṣàmúlò ẹ̀rọ ayélujára láti fi gba fọ́ọ̀mù àwọn olùdíje fún ìbò gómìnà Ondo àti Edo Makinde ni gómìnà, èmi ni igbákejì rẹ̀; kò sí ìjà láàrin wa-Rauf Adeniyan, igbákejì gómìnà ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́ Ṣé lóòtọ́ ni Kayode Fayemi, gómìnà ìpínlẹ̀ Ekiti fẹ́ du ipò ààrẹ orílẹ̀èdè Nàìjíríà?
eleto idibo Independent National Electoral Commission (INEC) ti fagile abajade
Alukoro ileeṣẹ ọlọpaa nipinlẹ Ogun, Abimbola Oyeyemi, sọ pe ẹni to lọ fi ẹjọ sun ni oun ri ọkunrin kan to gbe apo dani, ti oun fura si pe ẹru ẹlẹru lo wa ninu rẹ.
Wo àwọn tí wòlíì ríran sí pé COVID-19 yóò pa ní ìpínlẹ̀ Edo l'óṣù kẹsàn án Ibo pataki meji ni awọn oloṣelu Naijiria n gbaradi fun lorilẹede yii bayii lọdun yii.
Ni bayii, Venus yoo lo koju omo ile Latvia Anastasija Sevastova, leni ti o fagbahan Julia Goerges lati pegede sipele ti o kan.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Nigeria movie industry: Àgbà òṣèré, Lere Paimo ní àìgbọràn ló ń da ọ̀pọ̀lọpọ̀ àwọn Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Ondo Election 2020: Ẹ wo àwọn olùdíje sípò gómìnà nípínlẹ̀ Ondo tó takò bàbá ìsàlẹ̀26 Owewe 2020 Fídíò, Wole Soyinka sọ ìdí tó fi ni òun a fi màálù Fulani ṣe súyà fáwọn èèyàn abúlé23 Owewe 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Yọ ara rẹ kúrò nínú ìgbèkùn.
O ni babalawo ọhun gan an lo ni ki oun fi ọmọ oodo lu akẹkọọ naa pa to ba ti ṣabẹwo si i.
Ilé ẹjọ́ tó ń gbọ́ ẹ̀sùn ìwà ọ̀daràn l'àgbáyé, ICC bẹ̀rẹ̀ ìwádìí lórí ìpànìyàn tó wáyé lásìkò ìwọ́de EndSARS
Mo ti sọ ohun gbogbo fun yín tẹ́lẹ̀.
Ayọ̀ọlá: Rárá o, ‘thirty nairà’ ni mo sọ; múrí kan jẹ́ ‘twenty nairà, àbọ̀ rẹ̀ jẹ ‘ten nairà’, tí a bá ṣí i pọ̀ yóò fún wa ní , ‘thirty nairà’ , múrí mẹ́ta á sì jẹ ‘sixty naira’.
Àwọn ará Filistia bá lọ tẹ̀dó sibẹ.
Igbagbọ rẹ mú ọ lára dá.
Iranṣẹbinrin náà tún bẹ̀rẹ̀ sí sọ fún àwọn tí ó dúró pé, “Ọkunrin yìí wà ninu wọn!
Oríṣun àwòrán, Il'e Oòduà Àkọlé àwòrán, Wọ́n fa ayaba Naomi lé Ọ̀ọ̀nirìṣà lọ́wọ́ Iyawo ọba tuntun naa, Shilekunola Naomi jẹ woli ati ajihinrere ni Ijọ En-Herald Ministries to ti jẹ adari ijọ naa.
NBC: ìdí ti a fi ní kí AIT lọ rọọ́kún ná Ọjọ́ tí inú mi bàjẹ́ jùlọ gẹ́gẹ́ bíi ààrẹ ilé aṣòfin àgbà-Saraki Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Yoruba World Congress:Akintoye yarí pé ọmọ ẹgbẹ́ mẹ́rin kò le yọ òun nípò Oríṣun àwòrán, @deji_of_lagos Awuyewuye to n lọ lọwọ ninu ẹgbẹ Yoruba World Congress, YWC, ti gbọna miran yọ, lẹyin ti awọn eekan inu ẹgbẹ naa faake kọri pe dandan ni ki wọn yọ ọjọgbọn Banji Akintoye nipo, gẹgẹ bi Aarẹ ẹgbẹ ọhun.
“Ọjọ́ mẹfa ni kí o fi ṣe iṣẹ́, ṣugbọn ní ọjọ́ keje, kí o sinmi; àtìwọ ati akọ mààlúù rẹ, ati kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ rẹ; kí ara lè tu ọmọ iranṣẹbinrin rẹ ati àlejò rẹ.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Agbófinró, tó bá wa ọkada àbí kẹkẹ maruwa l'Eko, o rugi oyin - Sanwo-Olu Ará Yúróòpù ẹ fìdí mọ́lé yín, mo ti gbé ìlẹ̀kùn Amẹ́ríkà tìpa torí Coronavirus - Trump Ìjọba ń ṣe afárá Eko Bridge l'Eko, àwọn ọ̀nà àbùdá tí ẹ lèè gbà nìyí Gómìnà ìpínlẹ̀ Kaduna, El-Rufai fi ipò míì dá Sanusi lọ́lá Ganduje fún Aminu Ado Bayero ní ìwé ìyannisípò gẹ́gẹ́ bí Emir ìlú Kano Bakan naa ni aba ọhun n kesi awọn araalu pe ki wọn dẹkun lilo ẹrọ amunawa naa eyi to n lo epo disu, pẹtiro abi ebo eebo karosini lọgan lorilẹede Naijiria.
5 Áà, rantí àwọn ọ̀rọ̀ wọ̀nyí, kí o sì pa àwọn òfin mi mọ́.
Bẹẹ lọrọ ri fun Chelsea nigba ti wọn gbalejo Liverpool ni ifẹsẹwọnsẹ kẹfa, saa idije liigi ti ọdun yii ni ilẹ Gẹẹsi.
Loju opo Twitter rẹ,Ronaldo ni inu oun dun lati pada wa si Old Trafford.
Ẹjọ owo yi nii ṣe pẹlu owo ti ijọba ni gomina ana nipinlẹ Ekiti, Ayodele Fayose gba lọwọ oludamọran lori ọrọ aabo fun aarẹ tẹlẹri Dasuki Sambo.
O gba ijọba nimọran lati ṣamulo abọ iwadii awọn igbimọ Orosaye Stephen.
Àwọn ọmọ ológo Liverpool lé kúrò ní ìdíje Carabao Cup Yoruba bọ, wọn ni aileja lojude ile baba me ko de bi.
Akẹ́kọ̀ọ́ ìmọ̀ òfin kọ̀ọ̀kan yóò gba ₦500,000 owó ìrànwọ́ l‘Oyo Bí ọdún Ọ̀ṣun Oṣogbo ṣe bẹ̀rẹ̀ rèé àti pàtàkì rẹ̀ fún Nàíjíríà Wayi o, Tekno tọrọ aforiji lori ayelujara Instagram, fun ẹnikẹni ti fidio naa ba bi ninu.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, International Day Against Drug Abuse and Trafficking: ìdí ti mo fi ń mu oògùn olóró Agbamu ni ti orilẹ-ede Naijira ba gba ọlọpaa ipinlẹ laaye, ti ẹgbẹ oṣelu to wa lori aleefa ba ni aawọ pẹlu ẹgbẹ oṣelu alatako ninu ipinlẹ kan naa, ko si bi ojuṣaaju ko ṣe ni wa ninuu bi awọn ọlọpaa naa yoo ṣe ṣe iṣẹ wọn.
'Ò ń f'ẹ̀mí ara rẹ wéwu tó bá fẹ́ kọ́kọ́ yẹ ọlọ́pàá wò' Má jẹ́ kí Whatsapp rẹ gbàbọ̀dè, tètè ‘Update’ 6.
Lara ohun ti wọn n beere lọwọ ijọba atunṣe owo idojutofo fu itọja coronavirus, sisan owo oṣu ti ijọba n jẹ awọn oṣiṣẹ eleto ilera to fi mọ owo oṣu wọn kẹrin ati ẹkarun un ọdun 2018 to wa nilẹ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Tory leadership: Àwọn olùdíje náà ni Boris Johnson, Michael Gove àti Jeremy 20 Òkùdu 2019 Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Boris Johnson, Jeremy Hunt and Michael Gove are voted through to the final round of the Tory leadership race Awọn mẹta lo ku to n dije dupo fun Olotu Ijọba ilẹ Gẹẹsi, lẹyin ti Theresa May fi ipo silẹ.
Ninu ọrọ tirẹ, Agbẹnusọ fun ile iwe fasiti Akungba, Shola Imoru sọ pe lootọ ni isẹlẹ naa waye, ati wi pe eto aabo to peye wa fun awọn akẹkọọ fasiti naa, sugbọn isẹlẹ naa waye ni awọn ibugbe to wa ni ita ọgba ile iwe naa.
 wọ ́ n gbàgbọ ́ pé àwọn jẹ ́ ìran tó sẹ ̀ lára olóyè kan láti agbègbè cóńgò , ni ñǹkan ẹgbẹ ̀ rún ọdùn mẹ ́ rìndínlógún sẹ ́ yìn ni wọn tẹ ̀ síwájú sí gúsú .
Ki a yabara kuro nidi ọrọ yi lati gbọ nnkan mi to sọ nibi apero naa.
Lẹyin naa lo k nipa bi iwe titẹ ati awọn iṣẹ ọfiisi mii nile ẹkọ giga Yaba Polytechnic.
Ko si ẹni to kopa ri ninu idije Winter Olympics lati orilẹẹde Nigeria.
Àkọlé àwòrán, Awọn ọmọ Naijiria kan sẹ iwọde lọ si ile ijọsin COZA ni Abuja, Eko, ati Port Harcourt Ninu fidio ifọrọwanilẹnuwo naa, Busola ni igba ti oun wa ni ileewe girama, ni oun kọkọ pade Fatoyinbo ni Ilorin, Ipinlẹ Kwara, nigba to ṣẹṣẹ bẹrẹ ijọ COZA.
Ṣebí àwọn ni wọ́n máa ń sọ̀rọ̀ ẹ̀gàn sí orúkọ rere tí a fi ń pè yín!
Nígbà tó bá yá, orin inú tẹmpili yóo di ẹkún, òkú yóo sùn lọ kítikìti níbi gbogbo, a óo kó wọn dà síta ní ìdákẹ́ jẹ́ẹ́.
Sugbọn awọn osere yii lo maa n kigbe lọpọ igba pe okiki nikan ni awọn ni, awọn ko fi bẹẹ ri taje se, idi si niyi ti ọpọ awọn osere naa se mu ọna mii pọn lati ni owo lọwọ nitori ọna kan ko wọ ọja.
China ko wa si orile ede Naijia ninu osu kẹ́fà, odun 2019
Ọwọ́ tẹ́ àwọn ọkùnrin Fulani mẹ́ta tí wọ́n jí Màálù méjì kó ní Ogbomọṣọ- Àjọ NSCDC Nibayii eeyan 868 lo ti ṣe alaisi nipasẹ ajakalẹ arun naa lorilẹede Naijiria.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Chef Adefunkẹ: Òórùn ewé tí wọ́n n pọ́n ìrẹsì ọ̀fadà si jẹ́ adùn lọ́tọ̀ Iriri Ọlọwọ idan tẹlẹ: Wọn ni eyi kọ ni igba akọkọ ti Mandrake ọlọwọ idan ti maa n ko somi pidan rẹ tẹlẹ.
Victoria Kolawole: Òṣèré tíátà Yorùbá ní òun kò tíì ṣe ìgbéyáwó àmọ́ òun kò wá ọkọ''
"Ninu ọrọ rẹ, Odumakin ni, ""Ni ọdun 2015, Buhari da bi angeli, t'o n bọ wa yi gbogbo wahala Naijiria pada, ti ẹ ba wo ibo ti wọn di ni ilẹ Yoruba, Buhari ni ida mejilelaadota ibo, nigba ti, aarẹ ana Goodluck Jonathan, ni mejidinlaadota, ká má ṣẹṣẹ wa sọ isinyi."
 Èkíní ni ohùn pàtàkì ni a ń bá pàdé nínú eré àpíìrì .
”OLUWA wí pé,“Ìdí rẹ̀ ni pé,nígbà tí ẹ bá ń gbààwẹ̀, ẹ̀ máa ṣe ìfẹ́ ọkàn yín.
Yóo mú ẹyẹ tí ó wà láàyè ati igi kedari, ati aṣọ pupa tẹ́ẹ́rẹ́, ati ewé hisopu, yóo pa wọ́n pọ̀, yóo sì tì wọ́n bọ inú ẹ̀jẹ̀ ẹyẹ tí wọ́n pa lórí odò tí ń ṣàn.
 fún àpẹrẹ , díámọ ́ ndì jẹ ́ híhannú , nígbàtí gráfáìt jẹ ́ dídinú tó sì dúdú .
Igún l’ẹ́bọ jíjẹ ò ṣe ǹkan,
“Ní tèmi, mò ń sọ fun yín, fún anfaani ara yín, ẹ fi ọrọ̀ ayé yìí wá ọ̀rẹ́ fún ara yín, tí ó fi jẹ́ pé nígbà tí owó kò bá sí mọ́, kí wọn lè gbà yín sí inú ibùgbé tí yóo wà títí lae.
Oríṣun àwòrán, @BashirAhmaad Àkọlé àwòrán, Adura ko ran ọrọ to wa nilẹyi bi kii ṣe ki atunto eto ọrọ aje waye O ni gbogbo igba ti nkan ba ti deba owo epo rọbi lagbaye yala owo rẹ lọ si oke tabi o walẹ, o di dandan ki Naijiria mọ lara.
Ọkùnrin yìí ni a ba ni orí ogiri.
Àkọlé àwòrán, Lẹyin iku Ọgaagun Murtala Muhammed ni ikọ ọmọgun Naijiria yan Obasanjọ gẹgẹ bi adari orilẹede Naijiria.
Bayii o ti di ilu mooka to n gbe ogo orin atinuda jade nipa sisere pelu awon agba oje olorin lagbaye.
'A sinmi ìwádìí lóri Kemi Adeosun' Ilé ẹjọ́ rán ọjọ̀gbọ́n fasiti OAU lọ sẹ́wọ̀n ọdún méjì Magu,'estimated billing' àti àwọn ohun míràn tí ilé aṣòfin Nàìjíríà kò rí yanjú Àwọn èèyàn ilé ifẹ̀ kan da májèlé sómi iléèwé wa - OAU Lara awọn ẹgbẹrun lọna ogoji naa, ICPC ni awọn ti gbe iwe ẹri ẹgbẹrun mejila yẹwo lara eyi ti wọn ti ri iye ayederu iwe ẹri yi.
Ó pín àwọn ọọdunrun (300) náà sí ọ̀nà mẹta, ó fi fèrè ogun ati ìkòkò òfìfo tí wọn fi ògùṣọ̀ sí ninu lé ẹnìkọ̀ọ̀kan wọn lọ́wọ́.
Ó ṣe, ní òkè àwọn odò kan ní ilẹ̀ Sudaniibìkan wà tí àwọn ẹyẹ ti ń fò pẹ̀ẹ̀rẹ̀pẹ̀.
Yatọ si alaye yi gẹgẹ bi kan lara idi ti ko yẹ ki wọn fi gba iyansipo Akeredolu wọle, Jegede tun ni iwa janduku waye lawọn ijọba ibilẹ kan ati aaye idibo lawọn ibomiran.
Oríṣun àwòrán, AFP Àkọlé àwòrán, Ẹgbẹ Super Falcons ti wa laini olukọni fun bii ọdun kan Dennerby, ti o lo ọdun mẹsan pẹlu Hammarby IF ti Allsvesnkan ti o dẹ gba bọọlu ninu idije fun Ife ẹyẹ ilẹ Yuroopu ni ọdun 1983 ati 1985.
Jẹ́ kí ojú ti gbogbo àwọn tí ń yọ̀ pé ìpọ́njú dé bá mi;kí ìdààmú bá wọn;bá mi da aṣọ ìtìjú ati ẹ̀tẹ́ bo àwọn tí ń gbé àgbéré sí mi.
Bi o tile je pe, iko Yobe Desert se gudugudu meje ohun yaya mefa lati gba ami-ayo kan wole niseju mokandinlogorin saa keji ifesewonse naa, sugbon omi poju oka lo, leyin ti Abia Warrios tun gba ami-ayo miran wole, eyi ti o kase ifesewonse naa nile.
Oòrùn ń yọ, oòrùn ń wọ̀, ó sì ń yára pada sí ibi tí ó ti yọ wá.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, World Cup: Ambode sanwo ènìyàn 50 ní Russia O fi kún un pé, ọpẹ́lọpẹ́ Gomina ìpínlẹ̀ Eko Akinwumi Ambode tó wá sí Russia fún àṣekágbà ìdíje ifé ẹ̀yẹ àgbáyé ti 2018 ló síjú àànú wo àwọn ènìyàn lórúkọ ara rẹ̀.
Ìwà ipá àwọn ọmọ Seruaya yìí ti le jù fún mi.
Èéṣe tí o kò fún mi ní anfaani láti fi ẹnu ko àwọn ọmọ mi lẹ́nu kí n fi dágbére fún wọn?
Olorì Anu Adeyemi ń ṣe ọjọ ìbí, ẹ gbọ́ ǹkan tò sọ sí Kábíyésì Òṣèré tíátà míì ń ṣàìsàn láti ọdún kẹta, ó bẹ̀bẹ̀ f'ówó Nàìjíríà kò ní olórí, ẹ pín sí ẹlẹ́kùnjẹkùn - Soyinka Nǹkan oṣù obìnrin le jáde ní imú tàbí ìdodo yàtọ̀ sí ojú ara - Dókítà Oluwo bẹ Ìjọba àpapọ̀ láti ṣe òfin tí yóò mú àdínkù ba ìwà ìfipá báni lòpọ Ọjà Ọba ní Akure ni ọwọ́ ọloọ́pàá ti tẹ aláàrùn Covid-19 tó sá kúrò ní ilé àyẹ̀wò – Akeredolu Ìdájọ́ ikú ni a fẹ́ fún àwọn afipábánilòpọ̀ - Ẹgbẹ́ ajàfẹ́tọmọnìyàn Gomina gba Oniru tuntun nimọran lati jẹ ki alafia tẹsiwaju ni ilu naa.
Ìbúgbàmù àdó olóró pá èèyàn 27 nílé ìjọsìn Ọgọ́ta ẹ̀mí tún bá àdó olóró Adamawa lọ 'Ejò lọwọ nínú lórí ikọlù àwọn ọmọ ogun Nàìjíríà' Ko ti daju iye eeyan to padanu ẹmi wọn ṣugbọn ikede ti a gbọ kẹyin sọ pe eeyan ọgọrun lo ti ba iṣẹlẹ naa lọ.
"Soleimani n gbimọran ọtẹ lati kọlu awọn eekan ati ologun Amẹrika a si gba a mu lọrun ọwọ eyi la si ṣe pari ẹmi rẹ.
' Wo atẹ àlàkalẹ̀ ìdánwò WAEC fún ọdún 2020 tí yóò bẹ̀rẹ̀ ní August 17 Ṣọ́ọ̀ṣì tí wọ́n ti ń fi ọtí àmupara bá Ọlọ́run sọ̀rọ̀ ní kí ìjọba dẹwọ́ọ òfin títà ọtí lásìkò Covid-19 DSS tún ti mú Olawale Bakare tó jẹ́jọ́ pẹ́lúu Sowore nítorí ìwọ́de Revolutionnow 'Ọ̀rọ̀ Amotekun ti dàrú bíi ẹsẹ̀ télọ̀ ní ìpínlẹ̀ Oyo' Amọ arun Coronavirus ti fa ifasẹyin ba ẹka iṣẹ naa, eleyii to fa idaduro ati airiṣẹ ṣe fun awọn ileeṣẹ ọkọ ofurufu ni Naijiria, eleyii ti Bristow wa lara wọn.
Ọlọrun tí ó dá ọ̀run ati ayé,òkun ati gbogbo ohun tí ó wà ninu rẹ̀;Ọlọrun tíí máa ń pa àdéhùn rẹ̀ mọ́ títí lae, 
Oríṣun àwòrán, Lumumba Okugbawa ''A ko lodi si lilo IPPIS ṣugbọn ijọba ko fẹ seto bi yoo ti ṣe jẹ ki a ri gbogbo awọn ajẹmọnu ati owo miń to tọ si wa gba.
Ati pe o ṣe e ṣe ko jẹ oun nikan lo bi iru ọmọ bẸẹ ninu itan awọn ọba nilẹ Yoruba.
A kò rí àsíá wa mọ́,kò sí wolii mọ́;kò sì sí ẹnìkan ninu wa tí ó mọ bí ìṣòro wa yóo ti pẹ́ tó.
Ó sì ṣí wúrà tí ó wà lára ìlẹ̀kùn ilé OLUWA ati wúrà tí òun tìkararẹ̀ fi bo àwọn òpó ìlẹ̀kùn, ó kó wọn ranṣẹ sí Senakeribu.
Kí Olódùmarè gba ni lọ́wọ́ àgbàbàgebè obìnrin, ẹnu àwọn ènìyàn bẹ́ẹ̀ dùn ju oyin ìrèké wọ́n sì lè tọ́jú ọkùnrin ju ẹnikẹ́ni nínú ayé lọ, orúnkún wọn kò jìnà sì ilẹ̀, wọ́n lọ kúnlẹ̀ ní ìgbà ẹgbàágbèje lọ́jọ́ kan.
Maryam Sanda, ìyàwó tó pa ọkọ rẹ, ri ìdájọ ikú he Ẹ ta kété sí àjọṣepọ̀ tí kò bá fún yín láyọ̀ torí ẹ̀mí kò ní ààrọ̀ - Àwọn òṣèré tíátà gbarata lórí ìdájọ́ ikú Sinimá tí Lateef Adedimeji dá nikan jẹ́ òṣèré yóò jáde, Yemi Solade fi ọ̀pọ̀ fọ́tò dẹngẹ pó"" lọ́jọ́ ìbí rẹ̀ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Maryam Sanda: Ṣe ló ń wa ẹkún mu nílé ẹjọ́ lórí ìdájọ́ ikú tí wọn fun Femi fi ọrọ iṣẹ ti wọn gẹgẹ bi oṣere naa we iṣẹ awọn oṣiṣẹ banki."
Gomina ohun ni igbakeji re, Philip Shaibu soju fun so pe, ile-ise iwadii egbogi ibile ohun ni lati satileyin fun akitiyan ijoba lati mu igberu ba eto ilera awon ara-ile.
Samsoni bá baba ati ìyá rẹ̀ lọ sí Timna ní ọjọ́ kan.
Òru òní ní ìjọba á ti afárá 'Third Mainland' ní Eko; Wo àwọn ọ̀nà míràn tí o leè gbà lẹ́yìn tí wọ́n bá tìí Afárá Third mainland gba ẹ̀gbọ́n Ìgbésẹ̀ wo ní aláboyún lé gbé láti dẹ́kun ìjẹkújẹ nínú oyún?
Ò kéré tán N1million là ń ná lórí alárùn Coronavirus kọ̀ọ̀kan; àlàyé rèé- Ìjọba Eko Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí kan sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Sowore: Garba Shehu ni ijọba Buhari ko tii fi akọroyin kankan satimọle lati ọdun 2015 25 Ọ̀pẹ̀̀ 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 26 Ọ̀pẹ̀̀ 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Garba Shehu ni ijọba Buhari ko tii fi akọroyin kankan satimọle lati ọdun 2015 Olubadamọran pataki fun aarẹ Muhammadu Buhari lori iroyin, Garba Shehu ti sọ pe ijọba Buhari ki n ṣe ijọba to n ti awọn akọroyin mọle.
Ní báyìí ó ti ṣípò-padà, òkìkí Abacha tàn káàkiri ó sì di ìlú-mọ̀-ọ́-ká nípa ìtẹrí ẹ̀tọ́ ọmọ-ènìyàn mọ́lẹ̀ àti ìjẹgùdùjẹrà.
Wọn kò gbọdọ̀ bẹ̀rù àwọn oriṣa, 
Nítorí nípa ọ̀rọ̀ rẹ ni a óo fi dá ọ láre; nípa ọ̀rọ̀ rẹ ni a óo sì fi dá ọ lẹ́bi.
A ń ṣe ìrànwọ ètò ẹkọ ní àwọn gbùngbùn ilẹ Hausa, à ń ṣe ìrànlọ́wọ́ fún àwọn ohun èlò ìkẹ́kọ̀ọ́ fún àwọn ọmọde , yàrá ìkẹ́kọ̀ọ́, aga ìkọwé, pápá iṣere àti ètò ààbo fún àwọn ọmọ Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 3 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 5 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Dájúdájú èrò ẹni tí ó ṣiṣẹ́ tọkàntọkàn yóo yọrí sí ọ̀pọ̀,ṣugbọn ẹni tí ó bá ń kánjú jù kò ní ní ànító.
Ajikanle ní òun ti ta ọ̀pọ̀ dúkìá lórí apá àti ẹsẹ̀ tó rọ láti ọdún kẹta náà
Kí Ọlọrun lù mí pa, bí n kò bá ṣe gbogbo ohun tí ó wà ní ìkáwọ́ mi, láti mú ìlérí tí OLUWA ṣe fún Dafidi ṣẹ, 
Ọnà tí mo fẹ́ gbà láti fòpin sí súnkẹrẹ fàkẹrẹ ọkọ̀ l'Eko rèé - Sanwo-Olu Èyí ni ìdí tí a kò fi yọ̀nda El-Zakzaky pẹ̀lúù Sowore àti Dasuki- Malami Agbẹnusọ rẹ, Gboyega Akọsile naa fidi ọrọ yi mulẹ fun BBC ninu ifọrọwanilẹnuwo pẹlu rẹ.
Yorùbá rẹwà, kọ́ nípa àwọn ọ̀rọ̀ tí ìró ẹnu wọn jọra àmọ́ tí ìtumọ̀ wọn yàtọ̀ Àwọn jẹsí tó gbajúmọ̀ nínú ìtàn ìdíje bọ́ọ́lù Wo àwọn nkan tí o le ṣe gẹ́gẹ́ bi aláboyún lásìkò àjàkálẹ̀ ààrùn Covid-19 FRSC o gbọdọ ni ju 500 naira lọwọ Lasiko to n ba BBC Yoruba lalejo lo ti mẹnuba pataki Baba Isalẹ ati irufẹ ajọṣepọ to yẹ ko wa laarin wọn.
Mo lòdì sí ọ,ìwọ Òkè Seiri.
Alukoro ọlọpaa sọ pe''niṣe ni dokita naa ati awọn ọrẹ jade faaji lalẹ Ọjọb, ki awọn janduku to pade wọn ti wọn si da ọgbẹ si lara lẹyin ti wọn gba dukia wọn.
“Ẹ wo bí àwọn akikanju tí ń ṣubú lójú ogun!
Oríṣun àwòrán, Ikechukwu Oha Ṣaaju ni ilé-iṣẹ́ ọmọogun orílẹ̀-èdè Nàìjíríà sọ pe àwọn rí sàárè tí wọn sin Alkali tó ó sọnù sí lẹ́yìn tí wọ́n paá tán.
Iba Gani Adams ni ohun to n ṣẹlẹ lẹnu oṣelu ati iṣejọba lorilẹede Naijiria bayii fihan pe pataki ni atunto ilana iṣejọba ki gbogbo ẹya ati ede lee tubọ ni ipin to yẹ ninu eto Naijiria gbogbo.
Awọn mejeeji ja fitafita lati jẹ ki ẹjọ ọhun gbe awọn onibara wọn, amọ awọn ẹri to wa niwaju ile ẹjọ fihan pe ẹpa ko boro mọ.
Ààrẹ Buhari kí Akeredolu kú orííré bí ó ṣe jáwé olúborí nínú ìdìbò sípò gómínà Ìdí márùn ún tí agbára Covid 19 ní ilẹ̀ Adúláwọ̀ kò fi tó tí àwọn ilẹ̀ àgbáyé míràn Aarẹ ni oun ti paṣẹ ki iwadii bẹrẹ lati tọ piinpin iku to pa.
Eyi ni ibeere ti BBC Yoruba jade lọ ṣe iwadii rẹ.
Wahala ipese ina ẹlẹntiriki lorilẹede Naijiria jẹ eyi ti ọpọ onwoye ti tọka si gẹgẹ biara ohun to n da họwuhọwu silẹ lẹka ọrọ aje, paapaajulọ ẹka idaleeṣẹ silẹ.
Lati igba to ti jẹ ọmọde ni baba rẹ ti ku to si ti n gbe pẹlu awọn obi baba rẹ ni agbegbe Fogera ni ẹkun Amhara.
" wọ ́ n gbàá gẹ ́ gẹ ́ bí "" obìnrin tó yára jùlọ títí aye "" nítorí pé àwọn rẹ ́ kọ ́ ọ ̀ dù àgbáyé tó dà ní 1988 fún ìsáré 100 m àti 200 m kò tíì yipadà , kọ ́ sí ti sí èni tó lè yípadà ."
Agbenuso fun asoju agba ni o so fun awon akoroyin ti won ba kowo rin irina abewo naa pe, ayipada ti ba irinajo abewo Tillerson lati le tete pada sorile-ede America laro kutu ojo-Isegun, dipo asale ti o fi irinajo naa si tele.
Nigba ti ọwọ ba Adamu, o ni ẹni to ni ile ti wọn n kọ na jẹ oun ni ẹgbẹrun marundinlọgbọ owo oṣu.
Oluwo ní Aso Rock: Ààrẹ gbàléjò Ọọ̀ni, Oluwo, àtàwọn ọba Yorùbá mìí
 wọ ́ n gbá adénlé tí ó fẹ ́ là là wọ ́ n ní ẹ ̀ sẹ ̀ nínú .
Orúkọ mìíràn tí Àkàngbé Orímóògùnjẹ́ tún ń jẹ́ ni Bándélé.
Ki lo de ti ibo yi ṣe ṣe pataki Idibo yi le jẹ laarin awọn oludibo ẹgbẹ APC ati PDP ṣugbọn ọrọ naa tan de ori Aarẹ ile asofin agba Bukola Saraki ati Aarẹ orileede Naijiria iyẹn Muhammadu Buhari.
Ṣugbọn èmi sọ pé:“Mò ń rù, mò ń joro,mò ń joro, mo gbé!
Nibayii iye awọn to ti lugbadi arun naa lorilẹede Naijiria ti le lẹgbẹrun mẹtadinlaadọrin.
Fún wọn ní àsìkò, jẹ́ kí wọ́n dàgbà àti ga
ati ìdámẹ́wàá òṣùnwọ̀n efa fún ọ̀dọ́ aguntan kọ̀ọ̀kan, 
"Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Wùnmí Toríọlá: Toyin Abraham kìí se ọ̀gá mi nínú tíátà Àwọn ohun to yẹ ko mọ nipa Aisha Abimbọla Njẹ o mọ oju yi ni ""Yollywood"" Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ope Aiyeọla: Nkan pa emi ati Baba Suwe pọ Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?"
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Àwọn oṣiṣẹ feyinti ni Osun ṣé iwọde O salaye pe '' Gomina Arẹgbẹsọla ni erongba lati san gbese ti a jẹ silẹ sugbọn ti a ko ba le san,adehun wa laarin ijọba lati san owo fun awọn osisẹ'' Laipẹ yi ni Ìgboro ìlú Oṣogbo kún fọfọ pẹlú bí awọn oṣiṣẹ feyinti ni ìpínlẹ̀ Osun ti ṣe wọde láti fí ehonu hàn sí bí wọn ti ṣe ní Gómìnà Aregbesola kò sàn owó oṣu awọn.
A ó máa mú ẹ̀kúnrẹ́rẹ́ ìròyìn wá fún un yín bó ṣe ń lọ látẹnu àwọn akọ̀ròyìn wá.
Awọn alakatakiti Islamic West Africa Province yii ni iroyin ni wọn ti gba awọn ọkọ ijagun awọn ọmọ ogun ilẹ Naijira ati awọn irinṣẹ ogun miran lọwọ awọn ọmọ ogun ilẹ Naijiria bayii.
Keyamo àti Fani-Kayode faraya Ilé asòfin Èkìtì yọ igbákejì olórí ilé Wọn tún ti ji ọ̀pọ̀ èrò kó ni Birnin Gwari Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Kí ẹnìkọ̀ọ̀kan yín máa bá ẹnìkejì rẹ̀ sọ òtítọ́, nítorí gbogbo wa jẹ́ ẹ̀yà ara kan náà.
Ó ti àwọn iranṣẹbinrin ati àwọn ọmọ wọn ṣáájú, Lea ati àwọn ọmọ rẹ̀ sì tẹ̀lé wọn, Rakẹli ati Josẹfu ni wọ́n wà lẹ́yìn patapata.
Òṣùmàrè yí ìtẹ́ náà ká, ó ń tan ìmọ́lẹ̀ bí òkúta iyebíye.
iṣuna owo ti awọn ara ilu, ti wọn san owo-ori yoo fi ni igbẹkẹle ninu
Gẹgẹ bi a se ka itan igbe aye akọni olokoowo naa loju opo Wikipedia lori itakun agbaye, Fajemirokun ko ipa ribiribi si agbega ọrọ aje lẹkun Iwọ Oorun ilẹ Afirika.
kí ó sọ fún Aaroni pé, nígbà tí Aaroni bá tan fìtílà mejeeje, kí ó gbé wọn sórí ọ̀pá fìtílà kí wọ́n lè tan ìmọ́lẹ̀ siwaju ọ̀pá náà.
Ọwọ tẹ àwọn ọlọ́pàá tó fìyà jẹ obìnrin kan lọ́nà àìtọ́ n'Ibadan Yakubu Dogara padà sí APC, Buhari kí i kúàbọ̀ ní Aso Rock Wo àwọn tí wòlíì ríran sí pé COVID-19 yóò pa ní ìpínlẹ̀ Edo l'óṣù kẹsàn án Nǹkan mẹ́sàn án tí Mùsùlùmí gbọdọ̀ ṣe nínú oṣù Dhual- Hijjah Awọn olugbe agbegbe atawọn to n gbe inu ile naa sọ pe o ti n fi ami han pe agara ti da a fun igba diẹ.
níbo ni mo fẹ́ fi ojú sí láàrin gbogbo eniyan?
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Akomolede ati Aṣa lori BBC:Wo ìrúfẹ́ ìgbeyàwó méje tó wà nílẹ̀ Yorùbá àti ojúṣe Alárinà Loni Oladele Ogundipe lo ń dari dari ìjọ Celestial to pọ julọ lagbaye pẹlu ọmọ ìjọ to to ẹgbẹrun mẹta ninu isin kan ṣoṣo.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Coronavirus in Nigeria: Èèyàn mẹ́jọ kú, 1,024 míràn tún lùgbàdì ààrùn náà ní Nàìjíria 20 Agẹmo 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 11 Sẹ́rẹ́ 2021 Oríṣun àwòrán, @Chikwe_I Arun Coronavirus tun ti mu ẹmi eeyan mẹjọ miran lọ ni Naijiria.
Ó tún fi ọgọrun-un ìwọ̀n talẹnti fadaka lọ bẹ ọ̀kẹ́ marun-un (100,000) akọni lọ́wẹ̀ ninu àwọn ọmọ ogun Israẹli.
Jẹ́ kí ojú ti gbogbo àwọn tí wọ́n fẹ́gba ẹ̀mí mi,kí ìdàrúdàpọ̀ bá gbogbo wọn patapata,jẹ́ kí á lé àwọn tí ń wá ìpalára mi pada sẹ́yìn,kí wọ́n sì tẹ́.
"A kò fẹ́ 23% tẹ fẹ́ yà sọ́tọ̀ bíí owónàá fáwọn ìjọba ìbílẹ̀ - ALGON Á máa ṣíjú àánú wo ẹlẹ́wọ̀n láti mú àdínkù bá ọgbà ẹ̀wọ̀n - Ìjọba Ọyọ PFN: Fatoyinbo kọ̀ láti yọjú ni ìwádìí wa kò ṣe parí Toyin Abraham kìí bá èmi náà yọ̀, ni kò jẹ́ kí ń gbé e lárugẹ fún ayọ̀ ọmọ - Lizzy Anjorin Ọlọ́wọ̀ tìlú Ọ̀wọ̀ tuntun gorí ìtẹ́, idà àlááfìà ló mú ní Ìpèbí Ní ìdáhùn sí ìbéèrè ti àdárí BON bèèrè, minisita ní ""Mo fẹ́ lo ànfàni yìí lati sọ fun yin pé, ààrẹ Buhari ti búwolu àtuntò ilana igbohun sáfẹfẹ ti yoo si moju to àwọn ibèerè yín"" Oríṣun àwòrán, lAI MOHAMMED Àkọlé àwòrán, Gbogbo àwọn oníròyìn ayálujara ni ó ma sanwo ori-Lai Mohammed Ní pàtàkì jùlọ ààrẹ ti buwọ́lu pé, o ti pọn dandan fún àwọn ilé ìròyìn ori ayélujura yala tẹlẹfisan tabi rediò, tó fi mọ awọn ti ilẹ okeere, tí ohun wọn n wọ orílẹ̀ èdè yìí, lati gba iwe aṣẹ lọdọ ijọba."
meji  lo ti gbẹmi mi ninu ifehonuhan naa.
Ninu atẹjade ti wọn fi lede, ile-iṣẹ ilẹ Amerika ni Naijiria ni o di igba ti wọn ba fi iwe ranṣẹ si awọn ni awọn yoo yọ afikun owo iwe irinna ti awọn fi le owo fun awọn ọmọ Naijiria to ba fẹ wa si ilẹ Amerika.
Ilu Alexandria ni wọn ti bẹrẹ lasiko awọn aposteli.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Itaniji: Oluwo sọ ìtàn bí Orunmila ṣe jìyà nílùú Iwo àti ayọ̀ tó gbẹ̀yìn rẹ̀ torí sùúrù Elebuibon ni oun jẹ paanu iya, nitori ki oun le mọọ kọ, mọọ ka.
Apakiṣadi ni baba Ṣela, Ṣela ni baba Eberi, 
"A ń fikunlukun pẹ̀lú FBI láti mú àwọn ""Yahoo Boys"" tó kù- EFCC Ijọba tí júwọlẹ̀ fún Amẹrika lóri iwé ìrìna!"
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Widows Day 2019: Mo máa ń sá kiri wá owó ilé ni -Opó O fikun un pe ọpọ ile ifowopamọ lo gbe ilẹkun wọn ti nitori eto aabo to mẹhẹ nigba naa, ti ko si sẹni to lee sun, ti yoo di oju mejeeji lasiko ọhun.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Dubai: Wo nkan tó yẹ kí o mọ̀ nípa ìwé ìrìnnà ọlọ́dún márùn ún tí UAE n fún arìnrìnàjò 8 Sẹ́rẹ́ 2020 Oríṣun àwòrán, Twitter Àkọlé àwòrán, Ilẹ UAE sọ pe awọ̀n n gba alejo arinrinajo igbafẹ to le ni miliọnu mọkanlelogun lọdọọdun.
O yẹ ki gbogbo wa ri ọgbọn kọ ninu itan igbe aye akọni ọmọ Oodua yii, ẹni to jẹ ẹru, amọ to ta ara rẹ yọ.
1 2352423 Orilẹede France 69313 106.
Àwa mọ̀ pé a ti rékọjá láti inú ikú sí inú ìyè, nítorí a fẹ́ràn àwọn arakunrin.
Egbo Ewa ati agbado ni Egbo, o si jẹ ounje ilẹ Yoruba.
Tẹsiwaju lọ si iwaju lati lọ ṣe ayẹwo bi ara rẹ ṣe gbona si.
A se afiwe akosile idagbasoke 1.
Ṣé lootọ ni Aarẹ Buhari ko lẹnu ninu ọrọ ẹgbẹ oṣelu APC?
Ẹ má jẹ́ kí á máa ṣe ògo asán, kí á má máa rú ìjà sókè láàrin ara wa, kí á má sì máa jowú ara wa.
Oríṣun àwòrán, screenshot/@channels television Wọn ni iwadii ti n lọ lori ẹsun iwa ipa ti wọn fi ẹsun rẹ kan akọroyin wọn kan, ati pe igbesẹ to yẹ yoo waye lori ọrọ naa.
Ronaldo ti gbaa ni ẹẹmẹta iyẹn ọdun 2014, 2016 àti 2017.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ẹ wá gbọ òwe lẹnu ọmọ Igbo bíi àgbà ilẹ Yoruba Wọn fi orukọ Sudan sinu iw gẹgẹ bii ọkan lara awọn orilẹ-ede to n ṣagbatẹru awọn ẹgbẹ agbesumọmi lọdun 1993 pẹlu Iran, North Korea ati Syria.
Awọn ẹbi oloogbe ni ko si awọn oloṣelu kankan ni Malta to gbọdọ wa sibi isinku rẹ.
Ninu atẹ tabili fun bi ẹkọ yoo ṣe ri ni saa yii, ni wọn ti fagile saa kẹta fun saa 2019 si 2020.
Oríṣun àwòrán, @BashirAhmaad Àkọlé àwòrán, Awọn alakoso aabo fun aarẹ Buhari ni idokukọ awọn eeyan ti wọn rọ jade soju ọna.
Ọdun 2000 ni Ọbabinrin Ilẹ Gẹẹsi fun un ni Ami Ẹ̀yẹ ''Knight'' ti aafin Holyrood Palace.
COZA: Fatoyinbo yẹ̀bá fún pẹpẹ ìwàásù fún ìwadìí ẹ̀sùn ìfipábánilòpọ̀ tí wọ́n fi kàn án
Bẹ́ẹ̀ ni Oluwa wí,ó sì jẹ́ kí á mọ ọ̀rọ̀ náà láti ìgbà àtijọ́-tijọ́.
Aare  Buhari  tun bu enu ate lu iwa igbesunmomi to n sele ni
Torinaa, nigba ti awọn to sa lọ lo anfani ẹkun omi to ya ogiri sa lọ, awọn marunlelọgọrun duro sinu ọgba lai sa lọ.
Makinde ni, èyí ni láti mu ìdàgbàsókè bá igun mẹ́rẹ̀rin ìpińlẹ̀ Oyo àti pé, òpó mẹ́rìn ní ìpínlẹ̀ Oyo dúró lé lórí.
Babatunde Omidina (Baba Suwe) Oríṣun àwòrán, Others Baba Suwe ṣe aisan to le diẹ, eyi to mu ki awọn eeyan kan maa ro iku roo nigba to si wa ni ààyè, sugbọn iroyin iku gbajumọ oṣere tiata naa ko tii rin jinna, toun gan-an fi pariwo sita pe alaaye ni oun, oun kii ṣe oku.
Oríṣun àwòrán, @thisislagos1 Kowee ke, ko ha nilu Lafiagi nipinlẹ Kwara lopin ọsẹ nigba ti ọkọ oju omi kan, to ko ero mejilelogun, ti ọpọ wọn jẹ ọmọde, danu ni agbami odo Niger, lasiko ti wọn bọ lati ibi ayẹyẹ igbeyawo kan.
"Ọdun 1987 ni mo ti bẹrẹ si nii ṣe ere itage.
NCDC lo kede bẹẹ loju opo Twitter rẹ loru ọjọ Aje, ipinlẹ Eko lo si wa loke tente awọn ipinlẹ ti arun naa tun kọlu lọtun, nigba ti Plateau n tẹle e lẹyin.
Akọroyin wa to jabọ lati awọn Mosalasi to wa ladugbo Pakata ni aarin gbungbun Ilorin so pe ọpọ àwọn olujosin ni wọn ni inú awọn dun lati ki Irun pada ni mosalasi Jimọ.
Ninu ọrọ to ba BBC sọ, onwoye isuna ati okoowo lagbaye kan, Bisi Iyaniwura ni lati ibẹrẹ lo ti yẹ ki orilẹede Naijiria mọ wi pe oun o ni eto ọrọ aje to duro deede lati fi se agbatẹru agbekalẹ adehun yii.
Iṣoro ti Sarki Waka ni jẹ pẹlu ajọ to n bojuto aṣẹ gbigba lorii awọn orin ati ere sinma to n jade latari awo orin meji to gbe jade lai gba lansẹẹsi lọwọ wọn iyẹn Gidan Saratu ati ""Sai Hakuri""."
Wọ́n bá ń wá ọ̀nà láti mú un, ṣugbọn wọ́n bẹ̀rù àwọn eniyan, nítorí àwọn eniyan gbà á bíi wolii.
Fun idi eyi, awọn ọmọlẹhin rẹ, IMN ni ko si iru idiwọ tabi ohun ti yoo na awọn, wọn yoo tẹsiwaju pẹlu iwọde titi wọn yoo fi tu u silẹ.
Èyí tí a wò jùlọ 5:03 Fídíò, Omolola Arohunmolase Welder: Mo ti fí iṣẹ́ 'Welder' gbayì láwùjọ, tó mo fi tọ́ ọmọ yanjú, Duration 5,039 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 5:39 Fídíò, Akomolede ati Asa lori BBC: Olùkọ́ Kikelomo Ogunboye tan ìmọ́lẹ̀ sí ìwà olè ọ̀gá ọlọ́pàá Audu gẹ́gẹ́ bí àwòkọ́ṣe àsìkò yìí, Duration 5,398 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 4:11 Fídíò, Oba Adeyeye Ogunwusi: Ojú mi ti rí lọ́pọ̀ lọpọ̀, ọ̀pọ̀ èèyàn ni kò tilẹ̀ gbàgbọ́ pé mo lè jọba- Ooni, Duration 4,117 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 4:43 Fídíò, Promise Akinlade: ọmọ ọdún mọ́kànlá tó ń fi ìlù dárà bíi àgbàlagbà sọ̀rọ̀ nípa tálẹ́ǹtì rẹ̀, Duration 4,437 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 0:59 Gbọ́, Ìsẹ̀lẹ̀ jákèjádò orílẹ̀èdè àgbáyé láàárín ìṣẹ́jú kan, Duration 0,59wákàtí 6 sẹ́yìn 7:03 Fídíò, Olumuyiwa Bolade Adedeji Military Bruitality: Bí arákùnrin onípèníjà ara tí sọ́jà lù ṣe dé, Duration 7,035 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 4:45 Fídíò, Yoruba Films: Ẹ̀ẹ́ bẹ̀ mi kúrò láyé ni, mi ò lè kú - Fadeyi Oloro, Duration 4,4526 Èrèlè 2020 2:48 Fídíò, Esther Ajayi: Èmi náà ti borí ìṣòro rí ló ń mu mi ṣojú àánú, Duration 2,481 Ògún 2019 6:08 Fídíò, Adebola Ademilua: Àìrísẹ́ ṣè lẹ́yìn ìwé kíkà ló sọ mi dí ìyá onírú, mo dúpẹ́ tèmi, Duration 6,0827 Bélú 2020 5:55 Fídíò, Soyinka Cancer: Àṣe ara mi ni iso ti n run gbogbo bí mo ṣe n ṣèrànwọ́ lórí jẹjẹrẹ, Duration 5,5527 Bélú 2019 BBC News, Yorùbá Ìdí tí ẹ fi le è nígbàagbọ́ nínú ìròyìn BBC Ìlànà Lílò Nípa BBC Òfin Àṣírí Cookies Kàn sí.
ẹni tí ó ń fẹ́ẹ́ gbé ni lúlẹ̀ ìyàwó ẹni o kò rí i pé eléyìínì ń fẹ́ẹ́ dójú ti ni ńdan?
 Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Oyenusi ló mú mi wọ ẹgbẹ́ adigunjalè kó tó di pé mo b'Ólúwa pàdé' Kia ni mo ta ilẹ ti mo ni, ni milionu kan Naira ti mo si fun ni ẹgbẹrun lọna ẹẹdẹgbẹta Naira lati fi pamọ nitori ati san nkan ori rẹ.
Ninu alaye rẹ to ṣe, o ni awọn onimọ nipa bi oju ọjọ ti ṣe ri sọ pe, omiyale agbara ya ṣọbu yoo waye ni awọn ijọba ibilẹ mejilelọgọrun ni ipinlẹ mejidinlọgbọn Naijiria.
Ìfihàn tí a fi fúnni nípasẹ̀ Wòlíì Joseph Smith, ní ìlú Harmony, Pennsyvania, Oṣù Kejì ọdún 1829, tí Martin Harris béèrè fún.
Ẹ kò ì tíì bèèrè ohunkohun ní orúkọ mi títí di ìsinsìnyìí.
Dafidi bá sọ fún gbogbo àwọn iranṣẹ rẹ̀, tí wọ́n wà pẹlu rẹ̀ ní Jerusalẹmu pé, “A gbọdọ̀ sá lọ lẹsẹkẹsẹ, bí a kò bá fẹ́ bọ́ sọ́wọ́ Absalomu.
Reuben Fasoranti ní ìlú Akure, tíí ṣe olú ìlú ìpínlẹ̀ Ondo.
Nígbà tí ó tú èdìdì keji, mo gbọ́ tí ẹ̀dá alààyè keji ní, “Wá!
Ìjọ 10,000 tuntun ni a dá sílẹ̀ láì gba owó ọrẹ lọ́wọ́ ọmọ ìjọ lásìkò àrùn Coronavirus- Oyedepo Kí gan ló pa Dapo Ojora, ẹ̀gbọ́n ìyàwó Bukola Saraki l'Eko?
8 10268 Orilẹede Malawi 186 1.
O fi lede pe ijọba ti pari gbogo eto bi wọn yoo ṣe ko awọn oṣiṣẹ alaabo lọ maa ṣọ awọn ileewe to ku ti wọn ko tipa.
Ileeṣẹ ọlọpaa sọ pe iyansipo rẹ ko ba ofin mu.
O níláti máa ṣe àjọ̀dún àìwúkàrà; gẹ́gẹ́ bí mo ti pa á láṣẹ fún ọ; ọjọ́ meje ni o gbọdọ̀ fi jẹ burẹdi tí kò ní ìwúkàrà ninu, ní àkókò tí mo yà sọ́tọ̀ ninu oṣù Abibu, nítorí pé ninu oṣù náà ni o jáde ní ilẹ̀ Ijipti.
Lara ohun ti wọn tun kesi ijọba lati ṣe ki iwa ọdaran naa le kasẹ nilẹ ni agbekalẹ ofin ti yoo maa da sẹria fun awọn afiabanilopọ, ati ibawi to peye fun gbogbo ẹni ti aje iwa ibajẹ ba ṣi mọ lori.
Ikoro ni awọn agbebọn naa ji wọn gbe ni agbegbe ijọba ibilẹ Isua-Akoko ni ipinlẹ Ondo.
Ile-ise amohun-maworan Black Entertainment sagbekale ami-eye BET Awards lati safihan onkorin ti o kaju osuwon julo nile Afrika, bee si ni,  ti o tun mu ibasepo ti o donmonran jeyo pelu awon onkorin loke okun.
"Ọba aláde o gbọdọ kọ iyàwó rẹ̀ sílẹ̀- Bakare, Iba àṣà Yorùbá Oluwo Divorce: ko si ẹni ti kò mọ pé ọmọ ilẹ̀ òkèèrè ni mó fi ṣe aya Ààrẹ Muhammadu Buhari ti buwọ́lu owó ìṣúná ọdún 2020 Chike sọ fun ile ẹjọ pe ""Nigba ti mo bi leere, ko ri idahun to ni itumọ fun mi."
Nitotọ àti ṣe ẹ̀yà orí tẹlẹ ṣugbọn a lérò wípé orúkọ gbogbo ẹ̀yà ara lati orí dé ẹsẹ á wúlò fún kíkà.
Bakan naa ni Russia ni iriri pupọ lẹka ohun amusagbara eyi to lee lee fi fa oju awọn orilẹede to ni ohun alumọọni lọpọ loju mọra.
Kani wipe ọdun 1296 lo ti bẹrẹ isẹ, ẹ ba tii maa gba iye owo ti wọn n gba bayii.
” (Báyìí ni ó pe gbogbo oúnjẹ ní mímọ́.
“Èyí Farisi dá dúró, ó bẹ̀rẹ̀ sí gbadura pé, ‘Ọlọrun, mo dúpẹ́ pé ń kò dàbí àwọn yòókù, àwọn oníwọ̀ra, alaiṣootọ, alágbèrè.
Wọ́n ń fi ẹnu wọn sọ̀rọ̀ òdì sí Ọlọrun;wọn a sì máa sọ̀rọ̀ ìgbéraga káàkiri ayé.
"Live: Àwòrán bí ìjọba ìpínlẹ̀ Ekó ṣé ń wó ilé ládùgbóò Lagos Island Deji Adeyanju: Ìdí ìpinyà láárìn èmi àti ""Our Mumu don Do'' Wo ọjọ́ tí àfikún ìdìbò gómìnà yóò wáyé nìpínlẹ̀ mẹ́fà - INEC Èsì ìdìbò sípò gomina lórílẹ̀èdè Nàíjíríà Ìròyìn tó ń tẹ̀ wa lọ́wọ́lọ́wọ́ ní wí pé ilé alájà mẹta náà ni ilé ìwé alakọbẹrẹ kan wà nínú rẹ̀ ní agbègbè Ita faji ipinlẹ Eko."
Ọjọ́ meje ni ẹ óo fi se àsè yìí fún OLUWA Ọlọrun yín níbi tí OLUWA bá yàn pé kí ẹ ti máa jọ́sìn, nítorí OLUWA Ọlọrun yín yóo bukun gbogbo èso yín, ati gbogbo iṣẹ́ ọwọ́ yín, tóbẹ́ẹ̀ tí ẹ óo láyọ̀ gidigidi.
Wo ibẹrẹ aye Bianca: Awọn ara Romania ni obi Bianca jẹ.
Agbegbe Oke Ado ni wọn ti kọkọ dana sun ọkunrin kan ki ekeji to waye lagbegbe ASAS ni Molete.
Joela, ati Sebadaya, àwọn ọmọ Jehoramu, ará Gedori.
Lọ́la ni ọjọ́ yín mọ ní orí ilẹ̀ ayé, tí agbárí yín yóò dé inú ìṣaasùn ọbẹ̀ mi, bí mo bá ṣáìpa gbogbo yín jẹ́ lọ́la pátápátá, a jẹ́ wí pé bàbá mi kọ́ ló bí mi.
Tọkọ tiyawo ni Alaaji Kolington Ayinla ati Salawatu Abẹni tẹlẹ, ki tirela to gba aarin wọn kọja lọpọ ọdun sẹyin.
Lẹ́hìn igbe tí ọkùnrin yìí ń ké tí iná kú tán ni mo rí ọwọ́ kan tí ó di pàṣán mú bẹ́ẹ̀ n kò sí rí ẹni tí ó ni ọwọ́ yìí, ọwọ́ náà sì bẹ̀rẹ̀ sí fi pàṣán na ọkùnrin tí ń bbẹ nínú ìhámọ́ náà.
O le ni ida marunlelọgọrin awọn ijọ onihinrere to kan sara si bi aarẹ Trump ṣe n koju aarun Coronavirus yii.
Okan lara awon gbaju-gbaja akorin lorile-ede Egypt ni won ti fi sewon osu mefa bayii, nipa sise awada alufansa nipa ipo omi odo NileIroyin lori ero BBC so pe, Sherine Abdel Wahab,  eni ti o dajo naa, leyin ti o wo aworan naa nibi ti o ti n so fun ore re kan pe, eni ti o ba mu omi odo Nile yoo di aaro/ afomoO sawada pe, “mu omi Evian dipo re”.
Dafidi tún ní ọmọkunrin mìíràn tí ń jẹ́ Amnoni.
Atilẹyin ijọba ipinlẹ Ọsun si se pataki fun aseyọri ọdun Ọsun Osogbo lọdun 2019 yii, baa se n dijọ se agbelarugẹ, itaniji, idaabobo ati ifẹsẹmulẹ ọdun Ọsun Osogbo to se ara ọtọ naa.
"Yorùbá si ní ebi kii wọnú, kí ọ̀rọ̀ miran wọ, ebi sì ni ìṣòro ni orílẹ̀ èdè wa""."
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Coronavirus in Nigeria: Ènìyàn 653 ló tún ṣẹ̀ṣẹ̀ lùgbàdì ààrùn Coronavirus ní Nàìjíríà, 129 láti Eko nìkan 5 Agẹmo 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 19 Agẹmo 2020 Ayẹwo tun fihan pe eeyan ọtalelẹgbẹta o din meje lo ti kun iye awọn to ni arun coronavirus lorilẹede Naijiria lọjọ Abamẹta.
Ṣugbọn Jehu ti fi ọgọrin ọkunrin yí ilé ìsìn náà po, ó sì ti pàṣẹ fún wọn pé kí wọ́n pa gbogbo àwọn tí wọ́n wá jọ́sìn níbẹ̀.
Ní ọjọ́ kẹjọ Solomoni tú àwọn eniyan náà ká lọ sí ilé wọn.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Fayose si Buhari: Kí ló fa ìdíwọ́ àfihàn ìwé ẹ̀rí rẹ di àsìkò yí?
padanu  ẹmi won niluu Eko lojoRu oni, nibi ti ile alaja mẹta ti wo pa awon omo ile
Adari Ajọ JAMB, Ishaq Oloyede sọ eyi lasiko to n kede wi pe awọn ti fi esi idanwo JAMB sita fun awọn akẹẹkọ lati mọ bi wọn se yege si ninu idanwo naa.
Kí alufaa jáde kúrò ninu ilé náà, kí ó lọ síbi ìlẹ̀kùn, kí ó ti ìlẹ̀kùn ilé náà fún ọjọ́ meje.
julo lasiko ajodun keresimesi ati odun to n bo lona.
Iru igbese yi daa pupọ ti a ba fẹ dẹkun iwa ibaje ka ma yagbẹ sita gbangba.
Arinrinajo mii to ye e, Dmitry Khlebushkin sọ wi pe oun dupẹ pupọ lọwọ awọn oṣiṣẹ inu ọkọ baalu naa.
Ẹgbẹ osisẹ NLC  ti ni awon ko ni yi enu pada lori  ọgbọ̀n ẹ̀gbẹ̀rún naira  ẹkunwo ti awon igbimo meta ti ijoba apapo yan,
Yóo máa jẹ́ ìpín ìran wọn títí lae, bẹ́ẹ̀ ni àwọn ọmọ Israẹli yóo ṣe máa fún àwọn alufaa lára ẹbọ alaafia wọn; ẹbọ wọn sí OLUWA ni.
Ọlọrun tún fara han Jakọbu, nígbà tí ó jáde kúrò ní Padani-aramu, ó súre fún un.
Má dáwọ́ àánú rẹ dúró lórí mi, OLUWA,sì jẹ́ kí ìfẹ́ rẹ tí kì í yẹ̀ ati òtítọ́ rẹ máa pa mí mọ́.
Ẹ kọ orin ìyìn sí OLUWA, ẹ̀yin olùfọkànsìn rẹ̀,kí ẹ sì fi ọpẹ́ fún orúkọ mímọ́ rẹ̀.
NCDC àti NYSC bẹ̀rẹ̀ ìpàdé lórí ṣíṣí ìpàgọ́ àwọn àgùnbánirọ̀ Ajọ to n gbogun ti ajakalẹ arun ni Naijiria, NCDC, ti kede pe awọn yoo ṣiṣẹ papọ pẹlu ajọ agunbanirọ, NYSC, lori ṣiṣi ipagọ awọn agunbanirọ abala keji ti ọdun 2020 kaakiri Naijiria pada.
Àwọn Yorùbá ti a ko l’éní lo si ilẹ̀ Amẹ́ríkà tí a sì wá dá padà sí sàró lẹ́hìn tí òwò ẹrú tí tán ni àwọn òyìnbó Ìjọ C.
gẹ́gẹ́ bí ó ti búra fún Abrahamu baba wa,
"Gbogbo ọ̀wọ̀ to tọ si iru eeyan to jẹ́, ni ao nawọ rẹ si ẹbí rẹ̀.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Aarẹ Ọna Kakanfo kilọ fun awọn darandaran fulani 9 Èrèlè 2018 Àkọlé àwòrán, Awọn darandaran ti sekupa ogunlọgọ eniyan lawọn agbegbe kan lorilẹede Naijiria Aarẹ Ọna Kakanfo ti ilẹ Yoruba, Otunba Gani Adams ti kilọ fun awọn fulani darandaran wipe ilẹ Yoruba ko ni i faaye gba pipa awọn eniyan bi adiyẹ nigba kugba.
“Ṣé ẹni tí ń bá eniyan rojọ́ lè bá Olodumare rojọ́?
Gẹgẹ bi awọn alakoso iwọde naa ti wi, ida mẹrinlelọgọrin ninu ọgọrun awọn ọmọ orilẹede Naijiria ni wọn ti setan lati darapọ mọ iwọde naa ni orilẹede Mọkanlelogun yika Naijira.
Ogbeni Boris Johnson n gbero ki ipade ile bẹrẹ pada ni ọjọ kẹrinla, oṣu kẹwaa ọdun.
Ifẹsẹwọnṣẹ naa gbona ju ina lọ.
Ikubabayeye, Alaafin Ilu Oyo, Ọba Lamidi Adeyemi sọ pe Ọba ti o ba n mu ọti nita gbangba ko yẹ ni ni aa bọwọ fun .
Ko ko ko ni Ọba Adeyemi, Alaafin Iku Baba Yeye ṣi le lori alefa pẹlu bi baba ṣi ṣe n bi sii to si n rẹ sii.
Àwọn ọmọ Israẹli ṣe akiyesi ojú Mose, pé ó ń kọ mànàmànà; Mose a sì máa fi aṣọ ìbòjú bo ojú rẹ̀ títí yóo fi di ìgbà tí yóo tún wọ ilé lọ láti bá OLUWA sọ̀rọ̀.
Ó tún wá, ó rí i pé wọ́n tún ń sùn, nítorí pé oorun ń kùn wọ́n pupọ.
Alufaa tí ó bá fi rúbọ fún ìmúkúrò ẹ̀ṣẹ̀ ni yóo jẹ ẹ́; níbi mímọ́, ninu àgbàlá Àgọ́ Àjọ ni kí ó ti jẹ ẹ́.
Èmi, Paulu, ni mo fi ọwọ́ ara mi kọ ọ́ pé, n óo san án pada fún ọ.
Amọ eyi ko ri bẹẹ fun awọn ọba alaye nilu Ode ati Isinigbo ti wọn mule tira wọn nijọba ibilẹ Ariwa Akure nipinlẹ Ondo.
OLUWA yóo sọ ara rẹ̀ di mímọ̀ fún àwọn ará Ijipti, wọn óo sì mọ OLUWA nígbà náà.
Ààrẹ Buhari buwọ́lu gbígbé ìṣàkoso nọ́mbà ìdánimọ̀ (NIMC) lọ sí ẹ̀ka ìjọba tó ń rí sí ìbáraẹnisọ̀rọ̀ Wọ́n ti sún ìdájọ́ àwọn sójà tó pa ìyá àti ọmọ ní ọdun 2018 sí oṣù tó m bọ̀ Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí 6:18 Fídíò, Natalia Mufutau ìyá Yakub, Kamil àti Adam sọ̀rọ̀ lórí bí wọ́n ń sọ èdè mẹ́rin pàpọ, Duration 6,1831 Ògún 2020 6:10 Fídíò, Yoruba Language: Akomolede ati Asa Yoruba tọ̀sẹ̀ yí rèé lẹ́nu olùkọ́ wa, Duration 6,1030 Ògún 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
00 Lọdun 2015,wọn woye pe lati tọju awọn ti ko to ọmọ ọdun maarun ti iye wọn jẹ 31,109,000,ijọba yoo na $6,750,653,000.
Ọmọ ẹgbẹ Boko Haram ogun gba'dajọ ẹwọn
Oríṣun àwòrán, @Police_CRU Iroyin ni ileeṣẹ ọlọpaa ti mu awọn oniṣẹ ibi kan ni agbegbe H Command ni Ogudu to gba owo lọwọ ninu awọn to n kọminu yii.
O da yatọ ninu gbogbo awọn ọmọde ti mo n kọ, oun lo yara ju, oun ti mo n kọ wọn tete maa n ye e""."
Rán Lasaru kí ó ti ìka rẹ̀ bọ omi, kí ó wá kán an sí mi láhọ́n, nítorí mò ń jẹ ìrora ninu iná yìí.
Ṣugbọn ó wí fún wọn pé, “Ẹ jẹ́ kí á lọ sí àwọn abúlé mìíràn tí ó wà ní ìtòsí kí n lè waasu níbẹ̀, nítorí ohun tí mo wá sí ayé fún ni èyí.
Nítorí náà, ẹ má ronú tẹ́lẹ̀ ohun tí ẹ óo sọ láti dáàbò bo ara yín, 
Lẹyin igba naa ni wọn yẹ ara mi wo finifini.
Kollington tun yannana rẹ pe oun n selede lẹyin Barrister, ti oun ko si jẹ ki ile rẹ daru, koda, awọn ọmọ rẹ gan ti ri oun bii baba wọn, ti wọn si maa n wa fi ọrọ ati ise wọn lọ oun lati tọ wọn sọna.
ìmọ́lẹ̀ láti fi ọ̀nà han àwọn kèfèríati ògo fún Israẹli, eniyan rẹ.
Ki o to di aarẹ, minisita fun ọrọ ilẹ pokeere ni ipo to di mu laarin ọdun 1963 si 1979.
Aarẹ Buhari ni iṣẹ oun yatọ si ti adajọ ile ẹjọ ati pe ẹlẹsin Shiite kọ ni adajọ dajọ funÀgùnbánirọ̀ akọ̀ròyìn Channels náà ti dágbére fáyé látààrí ìkọlù Shiite l'Abuja .
Ti oun si ti n fi ẹsẹ Bibeli ṣe atilẹyin fun nkan ti oun ba sọ.
Kò sí ẹni tí ó lè wọ inú Tẹmpili títí tí àwọn àjàkálẹ̀ àrùn meje ti àwọn angẹli meje náà fi parí.
Mi o ran ẹnikẹni lati lọ ji apoti ibo gbe o.
Ó sì mú akọ mààlúù meji, àgbò marun-un, òbúkọ marun-un ati ọ̀dọ́ àgbò marun-un ọlọ́dún kọ̀ọ̀kan wá fún ẹbọ alaafia.
O ni wọn yoo kede ọjọ tuntun to ba ya.
Osusan Oluwatobi tricycle accident: Ààrin ìṣẹ́jú kan tí mo wọ 'Maruwa' ni ìjàmbá tó gbá ẹsẹ̀ mi wáyé
Kí ló dé tí o fi ń ṣe inúnibíni sí mi?
Akọtun isẹlẹ yii ni wọn lo waye ni aago meje owurọ ọjọ Satide, nigba ti awọn agbebọn naa kọlu abule mẹta, ti wọn si pa eeyan mẹsan.
"5 fm , níbi tí ó ti ṣ ̀ ètò "" midday belt "" tí ó sì tún ka ìròyìn ojoojúmọ ́ , ṣáájú kí ó tó ta àtapò sí ilé iṣẹ ́ ìgbóhùn-sáfẹ ́ fẹ ́ "" rainbow 94."
11 Sẹ́rẹ́ 2020 Ẹni to nilo oju lati fi ṣe iṣẹ ọwọ rẹ ṣugbọn to ti bábá padanu oju.
Gẹgẹ bi atẹjade ti awọn alaṣẹ orilẹede Amerika fi lede, arakunrin ti wọn jigbe naa, ti orukọ rẹ n jẹ Philip Walton lo n ṣiṣẹ agbẹ lorilede Naijiria.
Àwọn ìròyìn míì tí ẹ tún le nífẹ́ sí: Harry Kane fọ́ Ronaldo àti Juventus lẹ́nu pẹ̀lú góòlù àràmọ̀ndà Iheanacho ẹlẹ́sẹ̀ ayò tún ti dábírà Mo ṣe tán láti padà sórí pápá - Enyeama Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Kizito ni “Mathew Kolawole pada gẹgẹ bii ẹni
Wọn kò gbọdọ̀ dé ibi pẹpẹ mi láti ṣe iṣẹ́ alufaa, wọn kò gbọdọ̀ súnmọ́ àwọn ohun mímọ́ mi ati àwọn ohun mímọ́ jùlọ; ojú yóo tì wọ́n nítorí ohun ìríra tí wọ́n ṣe.
Lati iṣejọba aarẹ oluṣẹgun Obasanjọ ni ọrọ yii ti n wọ bọ lati labẹ eto iṣejọba alagbada tuntun yii.
OLUWA yóo fara han àwọn eniyan rẹ̀,yóo ta ọfà rẹ̀ bíi mànàmáná.
Wọ́n ti kú, wọn kò ní wà láàyè mọ́,ẹ̀mí wọn kò ní dìde mọ́ ní isà òkú.
1 lowó àdéhùn tó wà láàrin wa àti Buhari, kìí ṣe bílíọ́nù N208 16 Òkùdu 2019 Oríṣun àwòrán, BASHIR AHMAD Àkọlé àwòrán, ASUU ni ijọba kan fẹ fi ikede yi wa oju rere awọn arailu ni ati pe kii ṣe owo tawọn beere ni ijọba san.
Leah Sharibu ṣì wà láàyè - Iléeṣẹ́ Aarẹ Buhari Ǹkan mẹ́jọ tó máa kọ́kọ́ ṣẹlẹ̀ kí olólùfẹ́ méjì tó pa ara wọn Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
ẹmi won,bakana naa , o le ni egberun mọ́kàndínlógún
Afárá já sódò lẹyìn tí ọkọ̀ ojú omi kọlùú ní Brazil
Malikiramu, Pedaaya, ati Ṣenasari, Jekamaya, Hoṣama ati Nedabaya.
 Oríṣun àwòrán, The Park Management Oyo State Facebook Àkọlé àwòrán, Ọmọ mi ni Sunday Igboho, kò sì tó dúró de mi, òun gan ló ń dá Ibadan ru - Auxiliary Auxilliary ni: Ọmọ mi ni Sunday Igboho, to sì tún rán àwọn agbenipa si mi lọ́nà Iwo, níbi ìsìnkú Alhaji Táwa, tí wọn dibọn bíi ọlọ́pàá SARS, àmọ́ mo fọwọ́ lẹran, mo ń wo ó ní.
CBN gbé òfin tuntun jáde fún àwọn Báǹkì Banki agbayẹ pẹsẹ iranwọ fun Naijiria 'Ìdùnnù wa kọ́ ni kí á má fún ọmọ Nàìjíríà ní 'Visa' Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Àmì ohùn ṣe pàtàkí nínú èdè Yoruba púpọ̀ Ṣugbọn ṣa, eto imọ ẹrọ̀ gbigba owo l'ẹnu ATM lai lo kaadi ti wa ni orilẹ-ede Naijiria lati ọdun 2014.
com/yoruba/46008107 Ìlú Igbo-Ọra: Ijọba ipinlẹ Ọyọ ṣe ayẹyẹ ọdun ibeji fún ìgbà àkọ́kọ́ Àkọlé àwòrán, Ìlú Igbo-Ọra: Ijọba ipinlẹ Ọyọ ṣe ayẹyẹ ọdun ibeji fún ìgbà àkọ́kọ́ Ilu igboọra jẹ ilu kan lagbaaye to gbajugbaja fun ọwọja ibi ibeji nibẹ.
GAMBIA - Oṣu mẹta pere naa ni ohun ti o si wa ni Iwọ Oorun Afrika bakan naa.
 Ọ ̀ kan nínú àwọn tí ó rà á lẹ ́ rú ni cardoso jẹ ́ , ní tòótọ ́ cardoso fi ìyà jẹ ̀ ẹ ́ ṣùgbọ ́ n òun náà ni ó jẹ ́ kí gama ka ìwé .
Gomina Ipinlẹ Ondo naa wa parọwa si awọn ọdọ lati ri wi pe wọn se isẹ takuntakun lati jẹ eniyan nla lai gba ọna ẹburu, ki ọjọ iwaju wọn le dara.
N óo mú kí àwọn ọmọ rẹ pọ̀ bí erùpẹ̀ ilẹ̀, tí yóo fi jẹ́ pé, àfi ẹni tí ó bá lè ka iye erùpẹ̀ ilẹ̀ ni yóo lè kà wọ́n.
OLUWA fún wọn ní ìsinmi ní gbogbo àyíká wọn gẹ́gẹ́ bí ó ti búra fún àwọn baba wọn.
Kí ló dé tí o fi fẹ́ pa nǹkan OLUWA run?
“Mo sọ fun yín nígbà náà pé, èmi nìkan kò ní lè máa ṣe àkóso yín.
Dandan ni fun araalu lati lo ibomu-bẹnu lasiko ti wọn ba wa ni ita gbangba.
Ebi àṣeyọrí ló n pa mí báyìí lẹ́yìn àkókò mi tó ti ṣòfò - Paul Pogba ''Ronaldo ṣì lè padà sí ẹgbẹ́ agbábọ́ọ̀lù Real Madrid'' Màmá Guardiola d'olóògbé lẹ́yìn tó lùgbàdì Coronavirus Agbábọ́ọ̀lù Brazil tẹ́lẹ̀, Ronaldinho gba ìtúsílẹ̀ kúrò lọ́gbà ẹwọ̀n, àmọ́.
Amọ Olori ni okun to sọ igbeyawo awọn papọ le ju ohun ti ọta tabi awọn eni ibi le e ja lọ.
Ẹwẹ, minisita eto ilera, Dokita Ehanire Osagie ti sọ tẹlẹ pe awọn eleto ilera yoo ṣe ayẹwo agbo naa.
Beckham, àgbábọ́ọ́lù tẹ́lẹ̀ rèé tó ń sọ èdè Yorùbá Sàǹgbá fọ́!
Awọn asofin apapọ n ni ifọwọsowọpọ pẹlu ẹka isakoso gbe apero ọrọ aabo kalẹ latari ipenija to n de ba ibagbepọ alaafia ati aabo ẹmi ati dukia kaakiri awọn agbegbe kan lorilẹede Naijiria.
Abájáde náà nàka si àwọn koko mẹ́rìnlélógun gbòógi to nílò sàgbéyẹwò eyi to fi mọ mímú àyípada ba wíwọ aṣọ ilé iwé kan náà jákejádo gbogbo ìpínlẹ̀ Osun.
TSAIGUMI, ọmọ tuntun ileesẹ ọmọogun ofurufu Naijiria
Akowe agba naa, eni ti igbakeji oga agba ajo naa  Winners Anayo soju fun, pe fun sise adinku awon ajo ti o n sise ni awon enu ibode ohun.
O gbé ìgò kan fún mi oyin ni ó wà nínú ìgò náà, o ní kí ń fi ọwọ́ bà á, ki n tọ sí ẹnu, mo sì ṣe bẹ́ẹ̀, ó tún wí fún mi pé igba tí ilẹ̀ bá mọ́ ki n gbe fún àwọn ènìyàn mi kí wọ́n tọ́ oyin inú rẹ̀ sí ẹnu.
Col Musa sọ pe awọn omogun oriilẹ Naijiria duro gbọingbọin lẹyin Aarẹ Buhari ati iwe ofin orilẹede Naijiria bakan naa.
O ni Islam jẹ ẹsin ti ko fun ẹnikẹni ni inira ju ohun ti agbara rẹ gbe lọ, ko da wọn le e ṣẹ ẹsin ninu ile, ti wọn ba ṣe aisan, wọn le e dubulẹ kirun bo ba ṣe rọ wọn lọrun si.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Sallah: Ẹyin ará Ondo, Eko, Ogun, Osun, Ọyo, ẹ gbàdúrà ò!
Yóo fi òdodo ṣe ìdájọ́ ayé;yóo sì fi ẹ̀tọ́ ṣe ìdájọ́ àwọn eniyan.
ajo eleto idibo lati tete yanju awon isoro wonyi lọjọ iwaju.
Lẹ́yìn rẹ ni ìjọba mìíràn yóo dìde tí kò ní lágbára tó tìrẹ.
Wo àmúyẹ kí o tó lè di ọmọ ogun ilẹ̀ Nàìjíríà pẹ̀lú fọ́ọ́mù tó jáde yìí Adamu Adamu, Minista ètò ẹ̀kọ́ ti fi òfin àátẹ̀lẹ́ síta kí àwọn ilé ìwé lè wọlé Ṣé òótọ́ ni pé ìgbẹ́ erin le è wo arùn Coronavirus sàn?
Oríṣun àwòrán, @IamOhmai A gbọ pe deede aago mẹwa kọja isẹju marun ni alaga tẹlẹ fun ajọ to n sakoso owo ifẹyinti daku lasiko ti agbẹjọro rẹ, Anayo Adibe n sọrọ niwaju adajọ Okon Abang.
" Ṣe ẹda ofin orilẹede Singapore ni abadofin naa?
Amaju Pinnick ni lati foju ba ile ẹjọ lori ọrọ yii.
“eto ijọba rere ni ojutuu si  awọn  isoro ti a n koju ni  awọn  apa ibikan lorilẹ ede  yii;ti eto ijọba rere ba wa, o daju pe gbogbo  awọn  isoro ti a n koju ni yoo di afiseyin ti eegun n fi aso.
Ṣugbọn ohun tí ó ní Ọlọrun wí fún Israẹli ni pé, “Láti òwúrọ̀ títí di alẹ́ ni mo na ọwọ́ mi sí àwọn aláìgbọràn ati alágídí eniyan.
Ileeṣẹ ijọba to n risi idena ati amojuto ajakalẹ aarun, NCDC lo fi ikede naa sita loju opo Twitter rẹ lalẹ Ọjọru.
Senetọ Dino Melaye ni oun n lọ si ile ẹjọ kotẹmilọrun lati gba idajọ to yẹ.
(Iwe ilana ohun ṣiṣe fun aarẹ lẹgbẹ oṣelu PDP) Ayẹwo<br>lati mọ otitọ.
Saaju ni baba rẹ, Ọbasanjọ, ti bu ẹnu atẹ lu iṣakoso Buhari, to si gba a nimọran lati ma dije fun ipo fun igba keji.
Orilẹede Amẹrika ni Hafeez ti kawe, ko to o pada si Pakistan.
Egbo to ti fẹẹ́ jina ni ọrọ ti ẹ tun n fi eekan te yii""."
Eleyii ti wọn ti yii lata.
ó ṣe akiyesi Jeroboamu pé ó jẹ́ ọdọmọkunrin tí ó ní akitiyan.
Ganduje ti wa ke pe gbogbo awọn Fulani ti o wa ni ipinlẹ miiran, paapa awọn ti ipinlẹ Benue ati Taraba, lati wa si ipinle rẹ ni Kano nitori ipinle naa ni ilẹ-ọsin pupọ lati gba wọn ati awọn ẹran wọn.
O fi iporuru ọkan sọrọ pe bi obinrin ba niwa rere ko ni ki wọn ma fipa ba a lo pọ, kii ṣe tori obinrin n mu ọti tabi gbe ogun oloro ni wọn fi n fipa ba wọn lo pọ kii si i ṣe tori wọn ko ṣọra ni obinrin fi n ṣagbako ifipabanilopọ.
Zuma ko so ohun-kohun lati ojo kerin osu keji, nigba ti adari egbe oselu naa so pe, ki o fi ori alefa sile.
Ọlọrun Allah, o wa rọ ijọba lapapọ pe kikọ mọṣalaṣi bayii nikan ko
o tako eto ilana ajo to n mojuto ẹran ọsin ati ohun abiyẹ , ni eyi ti ijoba
Láìpẹ́ yìí ọ̀kan nínú òṣìṣẹ́ ilé ìwòsàn FMC náà kú nípa ààrùn Coronavirus, èyí sì ló fàá ti ọ̀pọ̀ àwọn òṣìṣẹ́ ṣe fẹ́ ṣe ìpàdé láti sọ ẹ̀dùn ọkàn wọ́n fú ìjọba.
Sọ fún wọn pé ó jẹ́ àpẹẹrẹ fún wọn.
Ẹ̀mí Mímọ́ kò gbà wọ́n láàyè láti lọ waasu ọ̀rọ̀ Oluwa ní Esia.
B Joshua-Angel Gomes Elébi ní iléeṣẹ́ bàlúù yín, Naira Marley fèsí sọ́rọ̀ aláṣẹ bàlúù Executive jet tó pèé ní ọmọ játijàti Ohun mẹ́wàá pàtàkì tí Ṣẹnetọ Osinowo fi ta yọ Kí ló kàn fún Godwin Obaseki lẹ́yìn tó kúrò lẹ́gbẹ́ òṣèlú APC?
Gbogbo ọrọ̀ rẹ, ati gbogbo ọjà olówó iyebíye rẹ,àwọn tí ń tu ọkọ̀ rẹ ati àwọn tí ń darí rẹ;àwọn tí ń fi ọ̀dà dí ihò ara ọkọ̀ rẹati àwọn tí ń bá ọ ṣòwò.
Ọkọ̀ akérò BRT gbiná lórí afárá 3rd Mainland
Wọn ni bi a ba de idi iṣẹ ṣiṣe laa ṣe e, amọṣa awọn kan ti n kọminu lori bi awọn gomina kan lorilẹede Naijiria, paapaa julọ lagbegbe iwọ oorun gusu orilẹede Naijiria, ṣe n fi ọrọ agbekalẹ igbimọ iṣejọba wọn falẹ.
Ko si ibi ti imisi orin ko ti le wa fun mi.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Akomolede àti Aṣa: Ọ̀rọ̀ Ẹ̀yán ni Bunmi Femi Amao ń kọ́ wa lórí ètò Akọ́mọlédè àti Àṣà lóri BBC Yoruba Okuta inu kindinrin: Aisan yii ma n fi ara rẹ han bi irora ni ẹyin ikùn, o le jẹ ni ẹgbẹ ọtun tabi ti òsì.
Awọn alaboyun naa npe akiyesi Gomina ipinlẹ Ondo, arakunrin Rotimi Akeredolu si ọrọ naa wipe ki o yi ofin naa pada.
 bí babaláwo méjì bá pàdé ara wọn , wọ ́ n le sun ìyẹ ̀ rẹ ̀ ifá .
Ẹ óo mọ̀ pé èmi OLUWA gbọ́ gbogbo ohun tí ẹ̀ ń sọ sí àwọn òkè Israẹli, pé wọ́n ti di ahoro ati ìkógun fun yín.
Bakan naa ni orilẹ-ede ọhun to n wọya ija pẹlu ajakalẹ arun Coronavirus, eyi ti aarẹ to jẹ saaju, foju tẹnbẹlu rẹ.
“Mo fi irú àwọn àjàkálẹ̀ àrùn tí ó jà ní Ijipti ba yín jà, mo fi idà pa àwọn ọdọmọkunrin yín lójú ogun; mo kó ẹṣin yín lọ, mo mú kí òórùn àwọn tí wọ́n kú ninu àgọ́ yín wọ̀ yín nímú; sibẹsibẹ ẹ kò pada sọ́dọ̀ mi.
"Lai ṣapejuwe Kyari gẹgẹ bi ọkan pataki ninu iṣejọba Aarẹ Muhammadu Buhari, ""nitori pe ko si nkankan ti aarẹ fẹ ẹ ṣe ti ko ni i fi to o l'eti."
Ṣebí ǹ bá fi ayọ̀, ati orin ati ìlù ati hapu sìn ọ́.
Ijamba ina naa waye ni ọja Ochanya la gbọ pe o bẹrẹ lati nnkan bi aago mejila ọsan Ọjọru ti awọn kan si ni o jo titi wọ alẹ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù EndSARS: Àwọn ayédèrú ìròyìn tó gbà'gboro kan lásìkò ìwọ́de #EndSARS 25 Ọ̀wàrà 2020 Oríṣun àwòrán, Reuters Awọn ọdọ kan lorilẹede Naijiria ya wọ igboro lati wọde tako wahala ati iwa kotọ awọ ọlọpaa lorilẹede Naijiria fun bi ọsẹ meji ki awọn janduku to ja a gba mọ wọn lọwọ.
 bí ó tilẹ ̀ jẹ ́ pé o tún maa ń wáyé lẹ ́ yìn ìtọ ́ jú .
Lara awon eniyan ti o tun ti gba ami eye ohun ni adari ijoba orile ede Japan Shinzo Abe, adari orile ede Germany  Angela Merkel ati akowe agba fun ajo agbaye teteleri Ban Ki-Moon.
L'àbáwọlé fáfitì kan ní Orílẹ̀-èdè South Africa, àwọn ọ̀rọ̀ ìṣínilétí wọ̀nyìí ni wọ́n kọ sóde fún àròjinlẹ̀:
Olùfẹ́, nisinsinyii ọmọ Ọlọrun ni wá.
Amọ, o ṣeni laanu pe ẹni ọdun mẹtadinlaadọta pere ni Ayinla Ọmọwura ni ọjọ Kẹfa, osu Karun un, ọdun 1980 to dagbere faye pe o digbose.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Aranṣọ, olórin àti àwọn mì í ti ko fẹ́ kí ìdìbò kásẹ̀ nílẹ̀ ní Nàìjíríà Ìjìyà Amosun n dúró dè é di ẹ̀yìn ìdìbò - APC Inec: Kò sí ìká tí o kò lè fí dìbò, ṣáà tí tẹ̀ ẹ́ sójú ẹ dáadáa Ìjọba àpapọ̀ fẹ́ dènà lílo ayélujára àti ẹ̀rọ ìbáraẹnisọ̀rọ̀ lọ́jọ́ ìbò - Fayose Bí ọkọ mi bá fìdírẹmi, màá gbà f'Ọ́lọ́run - Titi Abubakar Ajọ UN ati INEC gbé ìlanilọ́yẹ̀ lọ Kwara Ọ̀rọ̀ bọ́ lórí òjò òkò tó rọ̀ lé àwọn asaájú APC l‘Abeokuta Ẹfunroye Tinubu - Ògbóǹtagí oníṣòwò, olówò ẹrú àti afọbajẹ Olúwa mi, n kò jẹ̀bí ẹ̀sùn àjẹbánu - Babachir Lawal Madam Sajẹ si ti kopa ninu awọn ere tiata to le ni ọgọrin.
Torinaa, ileeṣẹ ọlọpaa ni awn eeyan awọn ti kan si agbami iṣẹ fun itusilẹ awọn ọmọ India naa ti wọn jigbe ni ile ita ogun kan lagbegbe Toll Gate ni opopona Eko si Ibadan ni nkan bii ago mẹrin irọlẹ.
Ṣé Festus Keyamo ni yóò yanjú aáwọ̀ lórí owó òṣìṣẹ́ ni?
44 Kíyèsíi, abala kan péré ni wọ́n ti gbà, tàbí akékúrú ti àkọsílẹ̀ ti Néfì.
Wo ìdí ti ìjọba ṣe ka ẹ̀sùn méje tán yányán mọ́ Sowore lẹ́sẹ̀ Ẹ lọ́ jáwé gbé jẹ́ẹ́ sọ́wọ́ bí bẹ́ẹ̀ kọ́.
"Àkọlé àwòrán, Ko si aye fun ifitonileti miran ti ko ba ofin mu Àwòrán àwòdamiẹnu rèé lásìkò ọdún Ọ̀ṣun Osogbo Àwọn èèyàn ń san ìdámẹ́wàá tó ""Heavy"" fún mi ni mo fi ń r'áànú ṣe - Iya Adura Esther Mo ti kó kúrò nílé Olu Jacobs rí lẹ́ẹ̀mejì- Joke Silva Èmi àti Saheed kìí ṣe ọmọdé, a ti jọ ṣe Sinimá papọ̀, èyí túmọ̀ sí pé ìjà ti parí - Fathia Balogun Ẹ wo adúrú ẹnu tí mó n bọ́ - Jaiye Kuti Iroyin to tẹ wa lọwọ sọ pe ajọ to n ṣagbatẹru ifẹhonu han lati ja fun ẹtọ awọn ọmọ Naijiria, CORE lo fẹ pade ni Lagos Centre fun apero naa."
Ìjọba sàlàyé pé, lọ́dún tó kọjá àkànṣe isẹ mẹ́rin péré nínú àwọn àkànṣe iṣẹ́ náà, ni ile asofin àgbà tó kogba wọlé fi àṣẹ si láti gbọ bukata rẹ lọ́dún 2016, nígbà tí àwọn àkànṣe isẹ yoku tí wọn kò buwọlu sì ṣe koko fún idagbasoke Naijiria.
 “Won se agbekale ajo UNRSTF ninu osu kerin odun 2018 lati wa ojutu si idi ti isele ijamba se n waye ni awon opopona jakejado, eleyi ti o sokunfa pipadanu emi ti o leni milionu kan le legberun lọ́ọ̀dúnrún ti àádọ́ta milionu eniyan si n farapa yanayana lodoodun.
Iwa aburu ti awọn ọlọpaa n hu si awọn ara ilu kan.
Ọọmi odo sodo ni wọn ta nigba ti iṣẹju aadọrun akọkọ kọkọ pari, lẹyin naa ni wọn tun gba bọọlu fun ọgbọn iṣẹju miran.
Òwe ńlá sì ni bí wọn se lọ yẹ ilé Gómìnà Tambuwal wò, lọ́sẹ̀ díẹ̀ sẹ́yìn, ń pa fún ni.
Kí ló dé tí obinrin tó ní HIV/AIDS fi pọ̀ ju ọkunrin lọ ní Nàìjíríà?
Wọ́n bá pàgọ́ kan fún Absalomu, lórí òrùlé ààfin, ó wọlé lọ bá àwọn obinrin baba rẹ̀ lójú gbogbo àwọn eniyan, ó sì bá wọn lòpọ̀.
 Ìwà òjòwú láàrin ayaba , ìṣàfihàn ipò ọba láàrin ìlú .
Ninu aworan isalẹ yii, iyalnu lo jẹ lọjọ yii to yẹ ki Olisa Metuh fara han nile ẹjọ ti gbogbo eeyan si dede ri i lori ibusun alaarẹ ati ike iwosan lọrun rẹ.
agbegbe Mokola niluu Ibadan, tii se okan lara awon ile eko ti isejoba re kọ.
Oríṣun àwòrán, @T_Bakare A gbọdọ maa se iranti awọn ologun to ti ku soju ogun, ka si mase gbagbe awọn ẹbi wọn.
Israẹli jẹ́ mímọ́ fún OLUWAÒun ni àkọ́so èso rẹ̀.
 ( july 10 , 1943 - february 6 , 1993 ) jẹ ́ agbábọ ́ ọ ̀ lù aláfasẹ ́ gbá tenis , tí wọ ́ n bí , tó dàgb ̀ a , sí richmond , virginia .
Boya awọn obinrin ti ẹ le maa lo o pẹlu aṣọ iyawo fun ayẹyẹ igbeyawo wọn.
Ọpẹlọpẹ ileesẹ ọlọpaa to parọwa si ọkunrin naa, ti ko fi se bo se wi.
Ma ṣe jẹ Onimọ nipa ounjẹ Oluwatobi kilọ pe ki ẹni to ba n gbawẹ ṣọra fun ounjẹ lile gẹgẹ bi ohun akọkọ lati fi ṣinu aawẹ.
Iṣọwọ ta bi ẹṣin rẹ pẹlu bi o ṣe n kan ẹṣẹ ni ki-ki loju agba ko jẹ ki Ruiz raye ṣe irufẹ ọṣẹ ti o ṣe fun un ni osu mẹfa sẹyin.
APC: A kò ní ìjìyà kankan fún Amosun lórí ìgbésẹ̀ rẹ̀
Láti ìgbà tí mo ti gba àwọn ọmọ Israẹli kúrò lọ́wọ́ àwọn ará Ijipti títí di àkókò yìí, n kò fi ìgbà kan gbé inú ilé rí, inú àgọ́ ni mò ń gbé káàkiri.
Ohun tó yẹ kóo mọ̀ nípa Fásitì Babcock rèé Wo àwọn akọrin Nàìjíríà tó fakọyọ ní àmì ẹ̀yẹ AFRIMA Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, O jẹ okan lara ounjẹto lewu julọ lagbaye 4.
Fidio naa to gba gbogbo ori ayelujara kan lati igba to ti jade ni ọjọ Aiku to kọja ti n fa arinyanjiyan laarin ọmọ Naijiria, ọpọ to n sọ wipe baba olowo kan ni baalu naa wa gbe nitori sunkẹrẹ-gba-kẹre ọjọ naa.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Àwọn ọ̀dọ́ Nàìjíríà fohùn ránṣẹ́ sí ìjọ̀ba tí yóò wọlé Ni ipinlẹ Ọyọ, ibanujẹ gbalẹ kan ni nkan bii oṣu mjọ sẹyin ti wọn fi ẹsun kan pe awọn ẹṣọ aṣọbode yii kan naa gba ẹmi agbẹ ẹni aadọrin ọdun kan, Lamidi Oke pe o da si ọ̀rọ̀ aawọ laarin wọn pẹlu awọn ọdọ ilu kan bi o tilẹ jẹ wi pe agbẹnusọ fun ajọ ẹṣọ aṣọbode ni ko si oṣiṣ awọn kankan to lọwọ ninu ẹsun naa.
Gbogbo àwọn ọ̀rẹ́ mi tímọ́tímọ́ ti rí mi sá,àwọn tí mo nífẹ̀ẹ́ ti kẹ̀yìn sí mi.
O fikun oeo re pe, iko marundinlogbon ninu ida ogorun (25%) ohun afefe gassi ti o n fe sinu afefe ni awon ayika ipese epo robi, o je ohun ti o n se akoba fun ilera awon ti o n gbe agbegbe naa pupo.
Ṣelomiti yìí ati àwọn arakunrin rẹ̀ ni wọ́n ń bojútó àwọn ẹ̀bùn tí Dafidi ọba, ati ti àwọn olórí àwọn ìdílé, ati èyí tí àwọn olórí ọmọ ogun ẹgbẹẹgbẹrun ati ọgọọgọrun-un, ti yà sọ́tọ̀ fún Ọlọrun.
Yóo jókòó bí ẹni tí ń yọ́ fadaka, yóo fọ àwọn ọmọ Lefi mọ́ bíi wúrà ati fadaka, títí tí wọn yóo fi mú ẹbọ tí ó tọ́ wá fún OLUWA.
Àlùfàá méjì wà lára àwọn mẹ́rin tó fi ipá bámilòpọ̀ Wo àwọn míniístà mẹ́fà tí ẹnu ń kùn jùlọ Gbọ́ ọ̀rọ̀ sáwọn tó yan ẹ sípò lẹ́nú bí wọ́n ṣe n sojú abẹ níkòó Ọlọ́pàá Adamawa ni #30,000 ni wọ́n fi bọ́ igún látìmọ́lé Ìjọba Buhari kìí ṣe ọ̀nà àbáyọ síṣòro Naijiria -Jiti Ogunye Bode George ni Tinubu kò mọ pé ebi n pa àwọn ara ilu rara.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Coronavirus update in Nigeria: Àwọn akẹ́kọ̀ọ́ 181 pẹ̀lú Olùkọ́ lùgbàdì Covid 19 níléèwé kan nípinlẹ̀ Eko 22 Agẹmo 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 17 Ọ̀wàrà 2020 Oríṣun àwòrán, Google Akẹkọọ mọkanlelọgọsan pẹlu olukọ ileewe aladani lo ti lugbadi arun Coronavirus ni ipinlẹ Eko lorilẹ-ede Naijiria.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Water Generator: Ó leè ṣiṣẹ fún wákàtí mẹfà, kó tó sinmi Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Water Generator: Ó leè ṣiṣẹ fún wákàtí mẹfà, kó tó sinmi 25 Ògún 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 10 Òkùdu 2020 Ara meeriri, a ti ri ori ologbo lori atẹ.
Ara to jọlọ Nitori pe sisun ni ihoho le fun ọ ni oorun to gbamuṣe, o tun le mu ki awọ ara rẹ ko jọlọ.
Nígbà tí ẹ pada dé, ẹ bẹ̀rẹ̀ sí sọkún níwájú OLUWA, ṣugbọn OLUWA kò gbọ́ tiyín, bẹ́ẹ̀ ni kò fetí sí ẹkún yín.
Awọn olokiki eniyan Yatọ si wi pe ìtàn fi Daura si ipo pataki ni ilẹ Hausa ati Naijiria, Daura tun ni ọpọlọpọ awọn olokiki eniyan.
ọrọ aje ti ko lowo –ori-ninu , iru adehun bayii ni o jẹ ikẹ́tàléláàdọ́ta ti
"Pẹlu Hashtag, ti iyawo aarẹ kọ ni ede Hausa, to si pe ni ""#AChechijamaa"", eyi to tunmọ si ipe fun itusilẹ awọn eniyan."
Bí a bá tún yẹ àwọn òwe àti àṣàyàn ọ̀rọ̀ mìíràn wò, a ó rí irú ìgbàgbọ́ yìí kan náà.
” Kalebu bá fún un ní àwọn orísun omi tí ó wà ní òkè ati ní ìsàlẹ̀.
Ìfihàn tí a fi fúnni nípasẹ̀ Wòlíì Joseph Smith, ní Manchester, New York, ó ṣeéṣe kí ó jẹ́ ìgbà ooru 1829.
Wo ohun tuntun tó n ṣẹlẹ̀ lágboolé CAF Super Falcons gòkè odò bọ́ sípele ìkẹrìndínlógún ní France Kò dùn mí pé mo sọ̀rọ̀ tako Buhari -Adedayo Festus Aisha Buhari sàtìlẹyìn fáwọn ọ̀dọ́ tó fọnmú lórí ìyànsípò àwọn alátakò sínú ìjọba APC A ni awọn kinihun oloola iju ti wọn n sọju orilẹ-ede wọn bii: Atlas Lions ni Morocco, Teranga Lions ti Senegal ati Indomitable Lions ni Cameroon.
Arsenal and Chelsea will continue to battle for European places.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, East Africa: Àwọn kokoro ti ba èrè oko jẹ nílẹ̀ Afirika Nigba to di ọjọ keje ti Ọrunmila ti n fi ara da iya yii ni ọba Iwo fa Wuraọla fun bii aya.
 ) ( the child is very bright .
Nicholas Ibekwe lero tiẹ lori Twitter, @nicholasibekwe salaye pe gẹgẹ bi ise rẹ, Buhari tun n bọ ni Eko lati wa si awọn akanse isẹ ti ko tii pari rara.
Oluranlọwọ agba si Aarẹ Buhari lori ọrọ ilẹ okere Abike Dabiri ni Aarẹ ti paṣẹ ki olugbẹjọ agba wa wọrọkọ fi ṣada ki wọn si rii wi pe o lojutu.
Bí o bá fẹ́, o lè mú un.
Ó wà pẹlu Dafidi nígbà tí Dafidi bá àwọn ará Filistia jagun ní Pasi Damimu, wọ́n wà ninu oko ọkà baali kan nígbà tí àwọn ọmọ ogun Israẹli bẹ̀rẹ̀ sí sá fún àwọn ará Filistia.
Bakan naa, o tun ṣalaye awọn igbesẹ ti ijọba rẹ n gbe lati fopin si iwa iṣoro yii.
Nítorí náà bí ẹ̀yin tí ẹ burú báyìí bá mọ̀ bí a tií fún àwọn ọmọ yín ní ohun tí ó dára, mélòó-mélòó ni Baba yín ọ̀run yóo fi Ẹ̀mí Mímọ́ fún àwọn tí ó bá bèèrè lọ́wọ́ rẹ̀!
Auxiliary ní òun yóò lé àwọn ọmọ ẹ̀yìn òun tó ń hùwà tọ́ọ̀gì dànù
Yoruba ni ẹla lọrọ, ti a ko ba laa, kii tete ye ni.
Nítorí pé ìjọba ọ̀run dàbí ọba kan tí ó fẹ́ yanjú owó òwò pẹlu àwọn ẹrú rẹ̀.
Joseph Yobo ni igbákejì akọ́nimọ̀ọ́gbá Super Eagles tuntun
Adajo  Mojisola Olatoregun sọ pe wọn ji owo naa ni
Tẹ nọ́mbà mọkanla to jẹ NIN rẹ, ki o si tẹ 'Next', lẹyin naa tẹ 'I Agree'.
O ni iṣẹ ati oṣi ko mọ Musulumi abi Kritẹni, nitori naa ki ara ilu maa fi aaye gba awọn ti wọn maa n fi ẹsin da ilu ru lati da isọkan ipinlẹ Oyo ru.
Josẹfu bá kúrò lọ́dọ̀ wọn, ó lọ sọkún, ó tún pada wá láti bá wọn sọ̀rọ̀.
Bi awọn eeyan kan ti isẹlẹ naa soju wọn ṣe n wipe ajinigbe ni Saheed, lawọn miran n wipe kii ṣe ajinigbe, aarẹ ọpọlọ diẹ lo n ṣe e.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù FIFAWWC: Ifẹsẹ̀wọnsẹ̀ Germany ati Naijiria ti parí pẹ̀lú àmi ayò ìbànújẹ́ mẹ́ta 22 Òkùdu 2019 Oríṣun àwòrán, Fifa Women World Cup/Twitter Àkọlé àwòrán, Germany fun Naijiria ni ayo mẹta si odo Ikọ Germany ati Super Falcons Naijiria wako ni France ninu idije ife ẹyẹ agbaye ti awọn obinrin to n lọ lọwọ ni ọjọ Abamẹta, ṣugbọn lẹyin ò rẹyin, Germany fi agba han Naijiria pẹlu ami ayo mẹta si odo.
Ẹwẹ gomina Eko kede irina ọfẹ yii lọjọru ọsẹ nigba to ṣebẹwo sibẹ lẹyin ipade pẹlu awọn tọrọ kan lori agbende agbegbe Lekki-Oniru ati awọn agbegbe Victoria Island.
– nítorí èṣù ti gbé àga ìjàngbọ̀n, ó jókkòó pẹ̀lú ayọ́, ó fi ẹ̀hìn tì ní inú wọn, ìgbà tí ibẹ̀ si rọ èṣù lọ́rùn, ó tún gbé ibùsùn wá, ó sún, ó ń han-anrun.
“Awon alase ajo ECOWAS ti ro ijoba orile-ede Naijiria ati Senegal, ti o fi mo awon ajo toro kan gbongbon lorile-ede naa kookan to n mojuto eto idibo,  lati ri daju pe eto idibo won waye nirowo-rose lai fi igba kan bo kan ninu.
"Thailand Oríṣun àwòrán, AFP/Getty Images Àkọlé àwòrán, Awọn eeyan ti lọ si ẹwọn nitori aja Ọba torukọ rẹ n jẹ Tongdaeng Thailand naa ni ofin to jọ mọ ""lese majeste"" to ni eeyan ko le bu mọlẹbi idile awọn alaṣẹ ilẹ naa ti wn si ti fi iya j ọpọ eeyan lati igba ti awọn ologun ti gba ijọba ldun 2014."
Èèyàn 576 míràn tún kún àwọn tó ní àrùn COVID-19 ní Nàìjíríà A yìnbọn lu Precious láti dáa dúró ni, akò mọ̀ pé o máa kú- Ọlọ́pàá Ìjọba Nàìjíríà ti parí ìwádìí lórí àgbo Covid-Organics ti Madagascar kó ránṣẹ́ sí i Mo ti bẹ̀rẹ̀ sí ń bá àwọn tí a jọ díje nínú ìdìbó abẹ́lé sọ̀rọ̀ kí àláàfíà léè jọba - Akeredolu Ènìyàn 653 míràn tún kún iye àwọn tó ní COVID-19 ní Nàìjíríà Nitori naa, esi idanwo ti wọn ṣe kọja ni saa eto ẹkọ kini ati saa eto ẹkọ keji ni wọn yoo lo lati fi ṣe idanwo fun wọn.
Ninu eyi ni wọn si tun ti fi idi rẹ mulẹ pe orukọ ọmọdekunrin Gold Kọlawọle ti wọn n wa naa wa ni nọmba kẹtadinlaadọrun ninu iwe ọhun.
Ṣugbọn Jesu mọ̀ ninu ara rẹ̀ pé wọ́n ń ro èrò báyìí ninu ọkàn wọn.
 Ìfara-fọkàn sáṣà yí ni ó jẹ ́ kí ó ma patú oríṣi ríṣi nínú eré oníṣe orí-ìtàgé àti àwọn àpilẹ ̀ kọ rẹ ̀ lọ ́ kan ò jọ ̀ kan .
Gẹ́gẹ́ bi àwọn tí ọ̀rọ̀ kan ṣe sọ àwọn ilẹ̀ Afirika, ni ànfani púpọ nínú iọ̀ẹ̀lẹ̀ náà bákan náà ni àwọn ǹkan to pọ̀ wà láti pàdánù.
O ni oun pinnu lati wa jẹwọ niwaju ijọ nitori wipe oun fẹ alaafia fun ọkan oun.
Gbogbo ọkọ̀ ojú omi ati àwọn tí ń tù wọ́nwà lọ́dọ̀ rẹ, wọ́n ń bá ọ ra ọjà.
Bẹ́ẹ̀ kẹ̀, n a máa rí ẹwà nínú àwọn nkan kékèké tí àwọn míràn ò kà kún nkankan.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù #RevolutionNow: Ṣowore ké pe ilééjọ́ láti yọọ́ látìmọ́lé DSS nítorí ó lòdì s'ẹ́tọ̀ọ́ rẹ̀ 10 Ògún 2019 Oríṣun àwòrán, Facebook/Omoyele Sowore Àkọlé àwòrán, #RevolutionNow Oludije fun ipo aarẹ fẹgbẹ oselu The African Action Congress to sun ṣagbatẹru iwọde RevolutionNow, Ọmọyẹle Sowore ti ke pe ileẹjọgiga l'Abuja lati yi aṣẹ to pa pe ki ile iṣẹ ọtẹlẹmuyẹ DSS tii mọ le fun ọjọ marundinlaadọta.
Wọ́n kígbe pè wọ́n, àwọn ará Dani bá yipada, wọn bi Mika pé, “Kí ní ń dà ọ́ láàmú tí o fi ń bọ̀ pẹlu ọpọlọpọ eniyan báyìí?
15 Nítorí kíyèsíi, òun ti fi sí ọkàn wọn láti mú kí ìwọ ó dán Olúwa Ọlọ́run rẹ wò, nípa bíbéèrè lati tún ìtúmọ̀ rẹ̀ ṣe lẹ́ẹ̀kan síi.
Nígbà tí wọn kò rí i, wọ́n pada lọ sí Jerusalẹmu, wọ́n ń wá a.
”Jesu dá a lóhùn pé, “O ti fi ẹnu ara rẹ sọ ọ́.
janduku sẹyin lati ji apoti ibo tabi da ibo ru n fi ẹmi ara rẹ ṣere ni.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù BB Naija winner 2020: Laycon ní òun kò lérò pé òun le mókè, àgbéga orin lòun bá lọ sílé náà 29 Owewe 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 9 Ọ̀wàrà 2020 Oríṣun àwòrán, Instagram/itslaycon Ẹni to gbegba oroke ninu idije BB Naija fọdun 2020, Olamilekan Agbeleshebioba, ti gbogbo eeyan mọ si Laycon ti kede pe oun ko bun iya oun gbọ, ki oun to lọ kopa ninu eto naa.
Bí bẹ́ẹ̀ kọ́ nígbà tí ó bá ń tanná lọ́wọ́,yóo rọ ṣáájú gbogbo ewéko,láìjẹ́ pé ẹnikẹ́ni gé e lulẹ̀
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ondo State Election result 2020: INEC kéde èsì ìbò gómìnà níjọba ìbílẹ̀ méjìlá 11 Ọ̀wàrà 2020 Oríṣun àwòrán, @R_Akeredolu Ajọ eleto idibo nilẹ wa, INEC, ti bẹrẹ ikede esi ibo gomina nipinlẹ Ondo bẹrẹ lati oru ọjọ Satide si Aiku.
Ọmọbìnrin ọdún 25 gún ọ̀rẹ́kùnrin rẹ̀ pa nítorí ó ní ko lọ ṣẹ́ oyún Èèyàn 125 míràn ṣẹ̀ṣẹ̀ kó COVID-19 ní Nàìjíríà A kú oríire!
Tems ti gba ìtúsílẹ̀ lọ́gbà ẹ̀wọ̀n Uganda Wo ohun tí yóò ṣẹlẹ̀ ní ìpàdé àwọn èèkàn Yorùbá láti mú kẹ́ẹ dìbò fún Tinubu ní 2023 Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Kollington ṣàlàyé bí orin Fuji ṣe bẹ̀rẹ̀ gan an ní Nàiìjíríà Oṣu to kọja ni Olootu ijọba, Imran Khan ati awọn ọmọ igbimọ rẹ buwọlu aba ofin yii, ki Aarẹ Arif Alvi to sọ ọ di ofin lọjọ Iṣẹgun.
“OLUWA, gbọ́ adura mi,tẹ́tí sí igbe mi,má dágunlá sí ẹkún mi,nítorí pé àlejò rẹ, tí ń rékọjá lọ ni mo jẹ́;àjèjì sì ni mí, bíi gbogbo àwọn baba mi.
Desmond Elliot, Mojisola Alli-Macaulay fa ayélujára ya torí ọ̀rọ̀ wọn níle aṣòfin Eko
Anane fikun pe iwadii ti bẹrẹ ni pẹrẹwu lori iṣẹlẹ naa, ati ohun to fa iṣẹlẹ naa gangan.
Irú ènìyàn báyìí ni Àgùntàn-ìnàkí jẹ́, nítorí náà nígbà tí mo rí i imú ni mo fi kí i.
Awọn olosẹẹlu alatako meji ni wọn mu pẹ wọn kopa ninu ayẹyẹ iburasipo naa.
Àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ ń bi í pé, “Kí ni ìdí rẹ̀ tí àwọn amòfin fi sọ pé Elija ni ó níláti kọ́kọ́ dé?
Lẹyin gbogbo wahala naa ni alaga igbimọ to ṣagbeyẹwo owo iṣuna naa nile igbimọ aṣoju-ṣofin, Abdulmumin Jibrin tu aṣiri ọrọ sita pe lootọ ni ile igbimọ aṣoju-ṣofin ṣe mago-mago owo iṣuna naa.
Bi ẹ ko ba gbagbe bi ọdun mẹta sẹyin ni iroyin lu igboro pa pe Aarẹ yan ọpọ awọn eeyan to ti jalaisi sipo akoso loniran-an-ran.
Ogu yìí nìkan ṣoṣo ni ó ṣẹ́kù ninu ìran Refaimu yòókù.
N kò kó èrò lẹ́yìn, bẹ́ẹ̀ ni n kò fa ìjàngbọ̀n.
"O fi kun un wipe, ""Nigba ti mo ni ngo se, o kọ ko fẹ gbọ, o le mi tiiti lori ẹrọ ibanisọrọ pe ki ngba f'oun sugbọn mo pada yọ nọmba rẹ kuro lori ẹrọ ibanisọrọ mi ni""."
Oríṣun àwòrán, @ogbeni_Skrtel twitter Àkọlé àwòrán, Arakunrin Ondo àti awọn gomina ilẹ Yoruba Oko iyawo ti n mura bayii: Láti ori ìwé ìpè àlejo tó si mo adari ètò ounjé, àti adari ounjẹ ní wọ́n ti fóju wọ́n han bàyìí: Oríṣun àwòrán, QOlakul Àkọlé àwòrán, Oko iyawo ti wọ agbo Oríṣun àwòrán, Imaam Shams Àkọlé àwòrán, Eto iyawo ti bẹ̀rẹ̀ ni pẹrẹwu Nínú ètò ti yóò wáye ni mọsàlási Jimoh nílùú Abuja lásìkò irún Jimoh toni ní wọn ti maa so wọn pọ.
"Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Kayeefi: 'Ọkọ mi ṣẹ̀ṣẹ̀ ní kí n lọ se mọ́í-mọ́í, tó ṣẹ̀ bá mi ṣeré tán ni mo gbọ́ pé ""Mopol"" yìnbọn pa á' Cross River Idibo naa yoo waye ni ijọba ibilẹ marun un lati rọpo awọn aaye to ṣofo ni ẹkun Ariwa Cross River nile aṣofin agba Naijiria ati ile igbimọ aṣoju-ṣofin."
Ayọ̀ kún ọkàn àwọn ọmọ-ẹ̀yìn Jesu.
 iru ijoba yi lo wopo laye nigba ijoun ati oju dudu .
Dókítà Òbílàdé: Ẹni tó bá lo Tramadol lálòjù leè sùn, kó má jí mọ́
24 Owewe 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 26 Owewe 2020 Oríṣun àwòrán, Twitter/Nigeria Railway Corporation Ẹgbẹ osẹlu alatako PDP ti bu ẹnu atẹ lu bi ijọba apapọ orilẹ-ede Naijiria ti buwọlu $1,959,744,723.
A kò mọ̀ bóyá a le è san owó osù tuntun fún òsìsẹ́ - Ìjọba Ondo, Oyo, Kwara jẹ́wọ́ 'Àwọn ti Micra ló jẹ̀bi rògbòdìyàn awakọ̀ tó wáyé lánàá n'Ìbàdàn' Ìgbẹ́ àá f'éwé!
" Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Baby abandoned on dunmpsite: Mo ti bímọ mẹ́rin tẹ́lẹ̀ fún bàbá méjì nínú òṣí- Dupe Ogbomos O tẹsiwaju pe alupupu alagbara bii ẹẹdẹgbẹta ati awọn ohun ija oloro to jẹ ti awọn ọmọ ẹgbẹ agbesumọmi naa ni wọn ti foju gaani loju ọna Lusada si Sokoto, eyii to jẹ apa kan ọna to gba Igbo-Ora kọja ni ipinlẹ Oyo.
Igboho ni ara Abiamọ tá òun nígbà tí òun gbọ nípa iṣẹlẹ náà, tó sì tún bá òun lójijì, pẹlu àfikún pé, ìwà ajọmọgbe náà kò bójú mu rárá.
Lẹsẹkẹsẹ naa ni wọn yan Leonard Nzenwa gẹgẹ bi adari ẹgbẹ oselu tuntun.
Eleyi ko ni nkankan se pẹlu boya eeyan jẹ obinrin tabi ọkunrin.
Ó wá kan ọ̀rọ̀ nípa àwọn nǹkan tí a fi rúbọ fún oriṣa.
Awọn eniyan buta sẹnu nibi ayẹyẹ ọjọ ibi.
Gbogbo ilẹ̀ yìí yóo di àlàpà ati aṣálẹ̀.
Àwọn ọkunrin meji náà sọ̀kalẹ̀ láti orí òkè, wọ́n lọ bá Joṣua, ọmọ Nuni, wọ́n bá sọ gbogbo ohun tí ó ṣẹlẹ̀ sí wọn fún un.
Ọlọ́gbọ́n obinrin a máa kọ́ ilé rẹ̀,ṣugbọn òmùgọ̀ a máa fi ọwọ́ ara rẹ̀ tú tirẹ̀ palẹ̀.
Nítorí pé mo ti dójú lé ìlú yìí láti ṣe ní ibi, kì í ṣe fún rere.
Joṣua rán àwọn ọkunrin kan láti Jẹriko lọ sí ìlú Ai, lẹ́bàá Betafeni ní ìhà ìlà oòrùn Bẹtẹli, ó wí fún wọn pé, “Ẹ lọ ṣe amí ilẹ̀ náà wá.
Gbogbo orin egúngún bìkiafù tí wọ́n kọ sí mi l'étí nípa Ajayi tí mi o gbọ̀ ló bu mí lọ́wọ́- Akeredolu Ǹjẹ o yẹ kí èèyàn máa sùn lẹ́nu iṣẹ́?
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ọgbà ẹ̀wọ̀n ni Naira Marley yóò ti wo ìbúra Buhari ní May 29 'Lóòtọ́, Gómìnà ko lẹ́tọ́ lórí owó ìjọba ìbílẹ̀ ṣùgbọ́n.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìtàn Mánigbàgbé: Ìtàn tó rọ̀ mọ́ ìdí tí wọn ṣe ń pe aya ní ìyàwó 9 Ògún 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 13 Bélú 2020 Oríṣun àwòrán, @jenneric Ni aye ode oni, ede to wọpọ julọ ti awọn eeyan maa fi n pe obinrin ta ba fẹnisu-lọka, to n ba ni gbe inu ile ni 'Iyawo' eyi ti a lee sọ pe ko ri bẹẹ ni aye atijọ, tori aya ni wọn n pe obinrin ta fẹ sile, gẹgẹ bii ojulowo ede Yoruba ti kọ ni.
Lasiko ayẹwo to waye niwaju ile aṣofin agba fawọn ti aarẹ Buhari yan sipo Minisita ni o ti lede ọrọ yi ni ọjọ Aje.
Bèèrè lọ́wọ́ àwọn ọdọmọkunrin rẹ, wọn yóo sì sọ fún ọ.
Ní kúkúrú, bí ìṣẹ̀lẹ̀ ọhun sì ṣe wáyé rèé Nígbà tí eto ìṣèlú bẹ̀rẹ̀ ni ẹkún ìwọ oòrùn gúúsù Nàìjíríà ijọun lọ́dún 1951, tí wọn sì dá ẹgbẹ́ oselu Ọlọpẹ, Action Group (AG) silẹ, ọba James Titus Olateru-Olagbegi Kejì lọ́wọ́ nínú oselu, koda, inú ààfin rẹ ni wọn ti dá ẹ̀ka ẹgbẹ́ òṣèlú Ọlọpẹ ni ilu Ọwọ silẹ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù LASU student killing: Ilé ẹjọ́ pàṣẹ kí wọ́n fi àwọn tó pa àkẹ́kọ̀ọ́ LASU sí ẹ̀wọ̀n 10 Sẹ́rẹ́ 2020 Oríṣun àwòrán, Nigeria Police Àkọlé àwòrán, Bàbá akẹ́kọ̀ọ́bìnrin LASU tí ọ̀rẹ́kùnrin rẹ̀ fi ṣ'òògùn owó ń bèèrè fún ìdájọ́ òdodo Ile ẹjọ ti ni ki wọn o fi awọn ti wọn fi ẹsun kan pe o pa akẹkọbinrin Fasiti ipinlẹ Eko, Favour Oladele.
O ni aarẹ ko sọrọ tori pe ki lo fẹ sọ to jẹ́ wi pe irọ ni gbogbo rẹ.
Ijọba Lebanon fi lede pe iye nkan ti ibugbamu to waye ni ibi ile ti wọn ko ado oloro ammonium nitrate naa bajẹ yoo lẹ ni iye owo biliọnu marundinlogun lọ.
Wọ́n fi ẹṣin gbé òkú rẹ̀ wá sí Jerusalẹmu, wọ́n sì sin ín sí ìlú Dafidi ní ibojì àwọn baba rẹ̀.
 “Ni bayii, mo gbọ pe awon eniyan márùndínlọ́gbọ̀n
Àwọn kan ń sọ̀rọ̀ nípa Tẹmpili, wọ́n ń sọ nípa àwọn òkúta dáradára tí wọ́n fi ṣe é lọ́ṣọ̀ọ́ ati ọrẹ tí wọ́n mú wá fún Ọlọrun.
4 75 Orilẹede Montserrat 1 20.
Ile rẹ to wa ni adugbo Akobọ Ojurin nilu Ibadan, ni wọn sin si.
Ó sun ilé OLUWA níná, ati ilé ọba ati gbogbo ilé tí ó wà ní Jerusalẹmu.
Lagos Explosion: Sanwo-Olu rọ olùgbé Eko láti mú ààbò ẹ̀mí ní pàtàkì
Àwọn ìdílé Lefi nìwọ̀nyí gẹ́gẹ́ bí ilé baba wọn.
Koda, oriṣiriṣi ounjẹ ni awọn obinrin miran ti ẹ maa n jẹ lasiko ti wọn ba loyun nitori eyi.
Bẹ́ẹ̀ ni wọ́n ń tutọ́ sí i lára.
Nígbà náà ni Aisaya sọ fún Hesekaya ọba pé, “Ohun tí yóo jẹ́ àmì fún ọ nípa àwọn ohun tí yóo ṣẹlẹ̀ nìyí.
Pe iṣẹ́ ọwọ́ ni o yẹ ki èèyàn fi ẹgbẹrun mẹwaa naa dá silẹ̀ ki o le maa mu owó wole sii.
Mohammed Inuwa Yahaya to n dije fun ipo gomina labe asia egbe naa.
Ìṣẹ́ tó mu ọmọ Nàíjíríà lómi ti gba oorun lójú mi - Osinbajo Àríyànjiyàn Osinbajo àti PDP Buhari ba osinbajo sayẹyẹ igbeyawo ọmọ rẹ Ogbeni Laolu Akande to jẹ olubadamọran igbakeji aarẹ ni abẹwo ọlọjọ mẹrin naa a bi eso rere si eto ọrọ aje Naijiria.
Ohun ti Sunday Igboho gbe igbesẹ ati ọrọ to sọ le lori ni gulegule ijinigbe to n waye lẹkun Ibarapa lẹnu lọwọlọwọ yii.
Òun àti Ilésanmí ni wọ́n jọ lọ.
 Gomina Ambode gbagbo ninu irinajo afe ati asa pupo.
 Ere ayo wa yii lo ko awọn orilẹede yii papọ lati doju kọ ara wọn, ka le mọ eyi ti intanẹti rẹ yara julọ, eyi ti ẹmi awọn eeyan rẹ n gun julọ, orilẹede ti iwa ajẹbanu ti kere julọ laarin wọn ati awọn ilana igbelewọn miran to se pataki."
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, International Day Against Drug Abuse and Trafficking: ìdí ti mo fi ń mu oògùn olóró Taiwo Akinkunmi ti pe ẹni ọdun mẹtalelọgọrin, eyiun 83 bayii, ti ogbo si ti de si baba.
Solomoni ati àwọn eniyan rẹ̀ sin OLUWA níbẹ̀.
Inu mi dun pe pupo ninu awon to n dije fun ipo aare lorile ede yii lo ti
Oríṣun àwòrán, AFP/Getty Images Àkọlé àwòrán, Ipaniyan kaakiri Naijiria ti sọ ọpọ sinu ibanujẹ Ninu ọrọ kan to tẹ ransẹ si ori ikanni ayelujara twitter rẹ, Gomina Fayose ni lootọ iwa buruku to buru jai ni pipa ti wọn pa awọn Fulani meje kan ni ilu Gboko ni ipinlẹ Benue, eyi to ni ko see fi ọrọ meji juwe ju wipe iwa ti ko see maa fi ọwọ ra lori ni.
, oun yoo jawe olubori ninu eto idibo aare odun  2019 yii.
Àwọn tí wọ́n jẹ oúnjẹ jẹ́ ẹgbaaji (4,000) ọkunrin láì ka àwọn obinrin ati àwọn ọmọde.
Ìyàwò lárìnlọọ̀dù mi pè mí ní akálòlò ni mo ṣe paa - Afurasí Buhari, pe ìpàdé àpérò ọmọ Nàíjíríà fún àgbékalẹ̀ òfin tuntun - Afe Babalola ‘Kò sí ohun tó lè yẹ ìfèhọnú ọjọ karun un Oṣu Kẹsan lórí àtìmọ́lé Omoyele Sowore’ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Badagry Historical Wells: Omi inú kànga Wawú ló ń kó ọpọlọ àwọn ẹrú lọ Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Wọn yóo tú ọ sí ìhòòhò, gbogbo ayé yóo sì mọ̀ pé aṣẹ́wó ni ọ́.
“OLUWA ni àpáta mi,ààbò mi, ati olùgbàlà mi;
O tun sọ siwaju sii pe, ọpọ igba l'awọn alaboyun naa maa n bimọ loju ọna.
Irọ́ ni, mi ò sọ pé mọ fẹ di Ààrẹ ní 2023- Tunde Bakare Ẹ wo ìyá ẹni ọdún 81 tó sẹ̀sẹ̀ parì ilé iwé alákọ̀bẹ̀rẹ̀!
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Covid Update: Ṣé orílẹ̀èdè míì wà l'Áfíríkà tó ń lo rọ́bọ́ọ̀tì ní pápákọ̀ òfurufú bíi ti Nàìjíríà?
Makinde sọ eyi lasiko to n sọrọ lori mimu imugbooro ba igbe aye awọn oṣiṣẹ ijọba ni ipinlẹ naa.
78 millio ninu owo ti o je N250.
Ọkọ ijagun nla ati kekere si lo wa nilẹ ti awọn ọlọpa gbe wa, ti wọn si n sọ agbegbe ibudo itaja naa bii ajẹ ti n sọ ile Olodumare, pe bi esinsin ba ta firi, awọn yoo wọn.
Awọn ọmọ ile igbimọ asofin naa sọ ọ di mimọ lasiko ti wọn pe ipade awọn akọroyin nile igbimọ asofin ipinlẹ Oyo wipe, iyalẹnu lo jẹ pe iru ọdaran bẹẹ n bọ mọ ọlọpaa lọwọ.
Nígbà tí Jesu pada dé, àwọn eniyan fi tayọ̀tayọ̀ gbà á, nítorí gbogbo wọn ti ń retí rẹ̀.
 Ilé iṣẹ́ BBC ni, A máa gbé ìgbesẹ̀ tó bá yẹ fún àtúnṣe tí ètò wa kankan kò bá kún ojú òṣùnwọ̀n gbèǹdéke ìlàna ètò bí ó ti tọ́ àti bí ó ti yẹ.
Kí Pirisila ati Akuila ati ìdílé Onesiforosi.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Christmas: Ìdí rè é tí Gómìnà Sanwo-Olu ṣe buwọ́lùú kí wọn tú ẹléwòn sílẹ 26 Ọ̀pẹ̀̀ 2019 Oríṣun àwòrán, @jimidisu Àkọlé àwòrán, Awọn mẹta mìí ni wọn yi idajọ iku wọn pada si ẹwọn gbeere.
Ṣebí nípa ìfẹ́kúfẹ̀ẹ́ yín tí ó ń jagun ninu àwọn ẹ̀yà ara yín ni.
Oríṣun àwòrán, Twitter Àkọlé àwòrán, Ọpọlọpọ iroyin lo ti n jade nipa awọn oludije bii Jide Sanwoolu Obafemi Hamzat Hamzat jẹ kọmiṣọna fun ọrọ sayẹnsi ati imọ ẹrọ lati ọdun 2005 titi di 2011 labẹ ijọba gomina ipinlẹ naa nigba kan ri, Bola Tinubu.
Oun kan naa lo da ile itaja The Palms Mall silẹ, lẹyin naa lo tun ṣi awọn ile itaja miran ni ilu Enugu, Kwara, Ota ati Ibadan.
" Òyìnbó sísọ di èèwọ̀ ní ìpínlẹ̀ Ekiti Bàbá ọlọ́mọ márùn-ún pokùn so ní Ekiti A fẹ́ kí a máa tẹ àwọn afipábánilòpọ̀ lọ́dàá ni báyìí - Ìjọba Ekiti 'Títẹ àwọn afipábánilopọ̀ lọ́dàá kọ́ ni ọ̀nà àbáyọ sí ìwà ìfipábánilopọ̀' Omowe Rhoda ni yatọ si pe ki ijọba ran irufẹ eeyan bẹẹ lẹwọn, iru ẹni bẹẹ tun nilo ayẹwo ọpọlọ.
Ó gba gbogbo ìlú olódi Juda títí ó fi dé Jerusalẹmu.
N óo sọ ọ́ di ahoro láti Temani títí dé Dedani.
Mi o gbagbọ ninu ki a ba obinrin rinrinajo ifẹ, ka to o gbe niyawo.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Iléesẹ́ Ọlọ́pàá: Ọwọ́ wa ti tẹ afurasí márùn-ún lórí ẹ̀sùn náà 7 Èrèlè 2018 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 19 Owewe 2018 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ileesẹ ọlọpaa ti wa rọ awọn ara ilu lati maa sọra se nipa awọn eeyan ti wọn yoo maa tọ lọ fun aajo ẹmi Ileesẹ ọlọpaa nipinlẹ́ Ọ́sun ti kede pe, ọwọ ti tẹ eeyan marun-un lori ẹsun pe wọn lu olori ile asofin ni ipinlẹ Ọsun, Hon Timothy Owoẹyẹ, ní jibiti owó tó lé ní miliọnu mejidinlogoji naira, ti gbogbo wọn si ti foju ba ile ẹjọ.
Ninu fọnran fidio kan to fi sita loju opo Twitter rẹ, Ighalo ni inu oun bajẹ nitori nnkan to n waye ni Naijiria.
Awọn iroyin ti ẹ le nifẹ si: Awọn alabojuto ṣe'pade lori ibo Sierra Leone Buhari yoo lọ sibi ayẹyẹ igbominira Ghana Dino Melaye: Mi o du ipo aarẹ ni 2019 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Ó ni ki Ẹkùn fi ọgbọ́n tan Ọ̀bọ, ki ó si gba ni ikùn diẹ ki ó lè ṣu igbẹ́ aládùn fun.
Ó bá pa àlọ́ náà fún wọn, ó ní,“Láti inú ọ̀jẹun ni nǹkan jíjẹ tií wá,láti inú alágbára sì ni nǹkan dídùn tií wá.
Pabambarì ni ìfojúrí ẹyẹ tí kò sí ní ibòmíràn lórí ilẹ̀ ayé, Spiny Babbler.
A máa ń fi èdè fa ẹwà yọ nínú afọ̀.
Farao bá sọ fún Josẹfu pé, “Ọ̀dọ̀ rẹ ni baba rẹ ati àwọn arakunrin rẹ wá.
Kíkó ara ẹni níjàánu láti tún orúkọ ẹni ṣe ló ń mú wọn máa pa á lówe pé ‘orúkọ ọmọ ni ìjánu ọmọ’.
Wọ́n bẹ̀rẹ̀ sí fi ara wọn sí ipò tí ó yẹ kí wọ́n wà, gẹ́gẹ́ bí òfin Mose, eniyan Ọlọrun; àwọn alufaa bẹ̀rẹ̀ sí wọ́n ẹ̀jẹ̀ tí wọ́n gbà lọ́wọ́ àwọn ọmọ Lefi sí orí pẹpẹ.
’Eto idanileko ohun ma n waye lodoodun lati jo jiroro po, se idanileko awon ona miiran ti igberu tun le gba de ba iko omo ogun naa.
Ernestina Díaz ti ori rẹ wu lori aseyori naa n gbe ni agbegbe Chihuahua, ti o si gba iwe ẹri rẹ lati ile-ẹkọ agba Adult Education Institute ni agbegbe naa ni Mexico.
O ni wọn jale ibo naa ko si ẹni to ko kawọn mọ bẹ, Trump ṣalaye pe awọn to dibo pẹlu ẹrọ ifọrọranṣẹ iyẹn Mail-in pa ni lẹrin.
“Nítorí àwọn eniyan ń wí pé ò ń paniyan, ati pé ò ń run àwọn ọmọ orílẹ̀-èdè rẹ.
Joaṣi, ọba Juda, kó gbogbo àwọn ẹ̀bùn mímọ́ tí Jehoṣafati ati Jehoramu ati Ahasaya, àwọn baba ńlá rẹ̀ tí wọ́n ti jọba ṣáájú rẹ̀ yà sọ́tọ̀ fún OLUWA, ati èyí tí òun pàápàá ti yà sọ́tọ̀ ati gbogbo wúrà tí ó wà ninu àwọn ilé ìṣúra ilé OLUWA ati èyí tí ó wà ní ààfin, ó fi wọ́n ranṣẹ sí Hasaeli, ọba Siria.
Oṣu Kẹfa ati Ikeje loyẹ ki idije naa waye, ṣugbọn ajọ Fecafoot sọ pe ayipada naa waye nitori bi oju ọjọ ṣe maa n ri ni orilẹ-ede naa ni akoko ti wọn n ṣe e.
Lara irinajo rẹ naa ni iṣẹgun yii jẹ, ṣugbọn , ao maa wo ibi ti yoo ba a de.
eyawo ti ijoba ti n se fun won.
gẹ ́ gẹ ́ bí àlàyé tí mo ṣe ṣáájú , ọ ̀ nà tí àwọn alápíììrì ń gbà ṣe eré wọn ni kí olórí eré máa lé orin fún àwọn elégbè tí yíò máa gbe orin tí ó bá dá .
Wọ́n waasu ìyìn rere ní ìlú náà, àwọn eniyan pupọ sì di onigbagbọ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Alaafin Oyo: Ọmọ Yorùbá sọ fún olorì Anu pé kò yẹ kó tú àṣírí ìkọ̀kọ̀ ìgbéyàwó rẹ̀ sí gbangba 12 Bélú 2020 Oríṣun àwòrán, Instagram/queen__aanu Awọn ọmọ Naijiria ti bẹrẹ si ni wi tọkan wọn jade nipa igbesẹ olori Aanu, ayaba Alaafin Oyo, to sa kuro ni aafin tọmọtọmọ.
Ọpọlọpọ ariyanjiyan n lọ lori ipa ti ijọba ko lati gba itusilẹ Zainab lọwọ ijọba Saudi nigbati Sharibu ṣi wa ni panpẹ Boko Haram.
Oluwo wipe olori awọn ẹsọ alaabo Ọọni, t'orukọ rẹ njẹ Kọlawọle fa ohun kuro lọna ki Ọọni le e kọja, eleyi ti o fẹsun kan Ọọni wipe ohun ni o ran awọn ẹsọ alabo rẹ lati ti ohun kuro lọna.
Nítorí kò ní sí àánú ninu ìdájọ́ fún àwọn tí kò ní ojú àánú, bẹ́ẹ̀ sì ni àánú ló borí ìdájọ́.
Ohun tí o óo kọ nípa Jehoiakimu ọba Juda, nìyí: sọ pé èmi OLUWA ní, ṣé ó fi ìwé ti àkọ́kọ́ jóná ni, ó ní, kí ló dé tí a fi kọ sinu rẹ̀ pé dájúdájú, ọba Babiloni ń bọ̀ wá pa ilẹ̀ yìí run ati pé, yóo pa ati eniyan ati ẹranko tí ó wà ninu rẹ̀ run?
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Nigeria Police Recruitment 2020: Iléeṣẹ́ ọlọ́pàá ní Kano tí ṣe àyẹ̀wò àwọn 13, 048 tó fẹ́ darapọ̀ mọ́ wọn 11 Agẹmo 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 5 Owewe 2020 Oríṣun àwòrán, others Àkọlé àwòrán, Ẹ wo ìgbésẹ̀ tí ẹ máa gbé láti di ọlọpàá Naijiria bayii.
Bakan naa, agbekalẹ ile ẹkọ fasiti Ifẹ silu naa tun jẹ ọkan lara awọn ohun ilọsiwaju to waye lasiko ti Ọba Adesọji Aderẹmi wa lori itẹ, eyi ti ko sẹyin aayan rẹ Ìtàn ayé Taiwo Oredein rèé, àgbà òṣèlú tó parí ayé rẹ̀ sọ́gbà ẹ̀wọ̀n Ìtàn ìgbé ayé Bode Thomas rèé, ó kọ́ wa láti máa kó ẹnu wa ní ìjánu O tun jẹ alaga titi laelae fun igbimọ awọn lọbalọba lẹkun Iwọ Oorun Guusu Naijiria, bẹrẹ lati ọdun 1966 si 1980 to darapọ mọ awọn baba nla rẹ Ọba Adesọji Aderẹmi jẹ gomina fẹkun Iwọ Oorun Guusu Naijiria ijọun laarin ọdun 1960 si 1962, nitori pe o tun jẹ ogbontarigi oloselu yatọ si pe o jẹ ọba alaye Oun si ni alawọ dudu akọkọ ti yoo jẹ gomina ni awọn agbegbe ti ilẹ Gẹẹsi n dari, ọwọ eebo Ọlọla John Ranklin si lo ti gba ipo naa Lasiko isejọba amunisin, Ọba Adesọji Aderẹmi gba agbara kun agbara lọwọ awọn ajẹlẹ, tawọn oyinbo gan si kọ nipa asa ati ise ilẹ Kaarọ Oojire lọwọ rẹ Ẹkọ wo ni a ri kọ lara Ọba Adesọji Aderẹmi?
O ni eeyan mọkandinlaadọjọ(149) pere ni ijọba fun ni iṣẹ ninu awọn ti wọn ṣẹṣẹ gba.
Nibẹ naa ni a ti ri eyi ti awọn gbajumọ osere ori itage lọkan o jọkan, awọn akọroyin pẹlu sọrọ-sọrọ peju si.
Cute Abiola: Mo ti n bá agbẹjọ́rò mí sọ̀rọ̀ láti gbé ìgbésẹ̀ òfin lórí ẹ̀ṣùn náà
idunnu re han lori ibasepo to wa laarin orile ede India ati orile ede Naijiria,
orúkọ ìnagijẹ ni orúkó tí wọ ́ n ma ń fúni látàrí ìhùwà sí , ìrísí àti bẹ ́ ẹ ̀ bẹ ́ ẹ ̀ lọ .
Omotara ṣalaye siwaju fun ileeṣẹ BBC pe ''Nigba ti mo pada de ibẹ ni mo to mọ bi iwa ti mo hu ti ṣe buru to.
Ó ṣe ohun tí ó burú lójú OLUWA, ó tẹ̀lé ìwà ẹ̀ṣẹ̀ Jeroboamu, ọmọ Nebati, tí ó mú Israẹli dẹ́ṣẹ̀.
Ileesẹ ologun orilẹede Russia naa fikun wipe, iwadi si isẹlẹ naa ti bẹrẹ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, afin pupa Ẹni to ba ti pe ọmọ ọdun mẹrindinlogun, o keere tan, lo le fi ẹjẹ silẹ nitori ofin to rọ mọ igbesẹ naa.
Bí àwọn ènìyàn yòókù ṣe ń jáde síta, àwọn ẹ̀ṣọ́-aláàbò ilé ìtajà náà ní kí ó dúró tí wọ́n sì tẹ̀síwajú láti yẹ ara rẹ̀ wò ní gbangba tí àwọn òǹwòran bẹ̀rẹ̀ sí í fi ṣe yẹ̀yẹ́.
” Gideoni bà mú Pura, iranṣẹ rẹ̀, wọ́n jọ lọ sí ìpẹ̀kun ibi tí àwọn tí wọ́n di ihamọra ogun ninu àgọ́ wọn wà.
Wọ́n sì sin ín sórí ilẹ̀ rẹ̀ ní Timnati Sera, ní agbègbè olókè ti Efuraimu ní ìhà àríwá òkè Gaaṣi.
Ileewe alakọbẹrẹ Lagos University Staff School ni o lọ ki o to kọri si ileewe girama King's College ni ilu Eko kan naa.
Òun sì ni wọ́n fi ń ṣe àwọn eniyan léṣe.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ibadan Divorce: Abílékọ Idowu faraya ní kóòtù kọkọ-kọkọ n'Ibadan, Ó ní òun ò leè pín ọkọ òun pẹ̀lú ẹnikẹ́ni 18 Ògún 2020 Oríṣun àwòrán, others Olukọni kan nilu Ibadan, arabinrin Idowu Oluokun ti rọ ile ẹjọ kọkọ-kọkọ kan ni Mapo nilu Ibadan pe ki wọn tu igbeyawo ọlọdun mẹrindinlogun oun ati ọkọ oun ti orukọ rẹ n jẹ Oyetunji ka dipo ki oun maa pin ọkọ naa pẹlu iyawo keji to fẹ.
Oríṣun àwòrán, Rufus Giwa Polytechnic Àkọlé àwòrán, Lẹta Bakan naa ni ẹgbẹ ASUP fi iwe sita to ṣalaye bi awọn ati awọn alaṣẹ ile iwe naa ṣe jọ tọwọ bọ'we adehun lori awọn koko ti wọn bere fun ati esi awọn alaṣẹ naa.
Yatọ si eyi, o ni fifi orukọ silẹ lori ayelujara ko ni jẹ ki wọn fi igba kan bo ọkan ninu nigba eto igbanisisẹ naa nitori awọn eeyan to fi ara wọn jin si iṣẹ ilu lo fẹ ṣe Amotekun.
to jawe olubori ninu eto idibo ti ile igbimo asofin ti ipinlẹ, nitori pe o ni
Wọn ri iyoku ara rẹ ninu alopati kọnga kan ni abule ọhun to wa ni agbegbe Shen, ijọba ibilẹ Guusu Jos.
Fún ìdí èyí ni arábìnrin Buhari pàṣẹ pé kí ọ̀gá àgbà àwọn ọlọ́pàá, Ibrahim Idris fi òfin mú Ọ̀gbẹ́ni Baba-Inna láti dá owó náà padà èyí tí ó tó bílíọ̀nù méjì àbọ̀ Náírà.
Orin yii gba ami ẹyẹ meji nibi eto ifami ẹyẹ dani lọla forin to pegede julọ lọdun 2018 nilẹ Adulawọ.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Àwujọ ẹ rọra ṣe ìdájọ́ ẹni tó kọ ọkọ / aya sílẹ̀ nítorí pé kò wùú- Odumosu Lai Mohammed: A kò ní bojú wẹ̀yìn lórí àbádòfin ìṣàkóso ẹ̀rọ ayélujára Ẹ̀yin ẹ̀ṣọ́, ẹ kò gbọdọ̀ fààyè gba jíjí àpótí ìdìbò ní Kogi àti Bayelsa- Buhari Ọlọ́pàá kan jáde láyé, èèyàn méjì fara gbọta lásìkò ìdigunjalè ní Falomo l‘Eko Idi ni pe wọn lu obinrin yii bi ẹni lu bara ni olu ileesẹ ajọ INEC nibi ipade kan ti alaga apapọ fun ajọ naa pe, ti ọgọọrọ awọn ọlọpa si wa, ti wọn ko si ri janduku kankan to sisẹ naa mu sahamọ.
O bu ẹnu atẹ lu awọn ojiṣẹ Ọlọrun kan ti wọn sọ pe ko yẹ ki ọja wa ni ṣiṣi nigba ile ijọsin wa ni titipa.
Joshua to ti gba ami ẹyẹ to ga ju lagbo ere idaraya ẹṣẹ kikan lagbaye lẹẹmẹta ọtọọtọ fidirẹmi, to si jẹ iya ajẹbolori lọwọ ẹni ti ko to o, Andy Ruiz lasiko ti wọn koju ara wọn ni Madison Square Garden lọjọ Abamẹta.
Kí Ọlọrun alaafia, ẹni tí ó jí Jesu Oluwa wa dìde ninu òkú, Jesu, Olú olùṣọ́-aguntan, ẹni tí ó kú, kí ó baà lè fi ẹ̀jẹ̀ rẹ̀ ṣe èdìdì majẹmu ayérayé, kí ó mu yín pé ninu gbogbo ohun rere kí ẹ lè ṣe ìfẹ́ rẹ̀, kí ó lè máa ṣe ohun tí ó wù ú ninu yín nípasẹ̀ Jesu Kristi ẹni tí ògo wà fún lae ati laelae.
 Ọladapọ ṣalaye siwaju pe awọn ẹbi afurasi naa wa, ti wọn si n ṣẹ epe fun pe o ti jẹ eewọ."
Atẹjade ọhun wa n rọ awọn oludije labẹ ẹgbẹ oselu kọọkan lati fi orukọ awọn asoju wọn lọjọ idibo sọwọ, o pẹtan, ọjọ Keji, osu Kẹ́wa ọdun yii.
emi won lenu ise lati daabobo orile ede yii, .
Ẹnu yóo ya gbogbo àwọn tí ó bá wò ọ́, wọn yóo máawí pé: ‘Ninefe ti di ahoro; ta ni yóo dárò rẹ̀?
Deji Adeleke lo sọ wi pe, Sẹnetọ Adeleke fẹ sinmi fun igba diẹ, nitorina, ki ẹgbẹ oselu PDP dawọ duro lori ero wọn lati fa a silẹ gẹgẹ bi oludije fun ipo gomina ni ọdun mẹrin si isinyi.
Ohun tí ó yani lẹ́nu ni pé Ogóje náírà (N140.
Mose bá kọ gbogbo ọ̀rọ̀ OLUWA sílẹ̀.
Dájúdájú ìwọ ti bá ọ̀pọ̀lọpọ̀ ìyọnu pàdé, òòrùn ti pa ọ́ ní ìgbà ọ̀sán, ìwọ sì ti sọ òṣùpá di àtùpà ní ìgbà òru, ṣùgbọ́n lórí ìwọ̀nyí, mo wífún ọ, ìwọ ọmọ ènìyàn, ìforítì lẹbọ.
Esi ayẹwo naa waye lẹyin ti ajọ to n ṣamojuto ajakalẹ arun, NCDC, kede esi ayẹwo eeyan 112 to tun ṣẹṣẹ ni i.
ìyàwó kú sínú kàngà nígbeyàwó kú ọ̀la Kò sí ọkùnrin tí yóò fún obìnrin tó halẹ̀ bíi tèmi lówó - Lizzy Anjorin Gómìnà Kwara kéde àgùnbánirọ̀ àtàwọn míì gẹ́gẹ́ bí kọmíṣọ́nnà tuntun Táyà ọkọ̀ agbépo tó fọ́ fa ìjàmbá ọ̀kọ̀ l'Ékò, èèyàn kan farapa Boris Johnson àti ẹgbẹ́ rẹ̀ wọlé ìbò, Trump àtàwọn ààrẹ míì kíi kú oríire Van Dijk gbadé UEFA mọ́ Messi àti Ronaldo lọ́wọ́ Laipẹ yii ni Messi gbami ẹyẹ Ballon D'or nilẹ Faranse fun igba kẹfa, amọ Ronaldinho t'oun naa gbami ẹyẹ Ballon d'or lọdun 2005 sọ pe oun ko le pe Messi ni agbabọọlu to dara julọ lagbaaye ninu itan.
Ilé Aṣòfin Àgbà fòǹtẹ̀ lu N30,000 owó oṣù òṣìṣẹ́ Afurasi kan fipá bá akẹ́kọ̀ọ́ UNILAG lò pọ̀, ó tún jí pátá rẹ̀ - Iléeṣẹ́ ọlọ́pàá Seyi Makinde figbe ta lórí bí Ajimobi ṣe ń ná owó ìlú Iwadii fihan pe owo ti Musa ni nigba naa, to bi biliọnu lọna irinwo dọla ($400bn) owo ode oni.
Adeniran ṣe alaye wi pe awọn basejẹ naa ti ṣi ilekun ewu to pọ silẹ fun ile ẹkọ naa pẹlu afikun wi pe awọn yara ikẹkọọ, ile igbọnsẹ ati kọnga igbalode ti wọn kọ si ile ẹkọ naa ni awọn onile iṣẹ bulọku naa ti bajẹ.
Mi ò fẹ́ sọ fún ẹnikẹ́ni nítorí àwọn ọ̀rẹ́ mi ma ń sọ̀rọ̀ rẹ̀ bíi pé gbogbo ìgbà làwọn ma ń gbádùn ìbálòpọ̀.
Ọmọde ni Kayode nigba naa ṣugbọn itan bi ẹgbẹ awọn agbalagba ọdaran ṣe fi owo tan an toun naa bẹrẹ si ni gbe ibọn to si n mu igbo jẹ ibanujẹ to dori agba kobo.
Bakan naa ni wọn koro oju si bi awọn eeyan kan ṣe kọlu gomina ipinlẹ naa, Gboyega Oyetọla lopin ọsẹ to ksja, eleyi ti wọn ni o ku diẹ kaa to gidigidi.
Super Falcons: Wọn nfi ilọkulọ ibalopọ lọ wa Buhari ki Super Falcons kú oríire ife ẹ̀yẹ AWCON Cardi B ti pín yà pẹ̀lú ọkọ rẹ̀ Offset lẹ́yìn ọdún kan Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Asisat Oshoala: ìbẹ̀rẹ̀ mi kò rọrùn rárá nínú eré bọ́ọ̀lù Awọn mi i ti orukọ wọn tun wa ninu ikọ naa ni Tochukwu Oluehi, Chiamaka Nnadozie, Alaba Jonathan, Osinachi Ohale, Faith Michael, Chidinma Okeke, Rita Chikwelu, Ngozi Okobi-Okeoghene, Halimatu Ayinde, Ogonna Chukwudi.
Ní ọdún kejidinlogun ìjọba Josaya, lẹ́yìn tí ó ti pa ìbọ̀rìṣà rẹ́ ní ilẹ̀ náà, ó rán Ṣafani ọmọ Asalaya láti tún ilé OLUWA Ọlọrun rẹ̀ ṣe pẹlu Maaseaya, gomina ìlú, ati Joa, ọmọ Joahasi tí ó jẹ́ alákòóso ìwé ìrántí.
N óo máa ké kiri bí ọ̀fàfà, n óo sì ṣọ̀fọ̀ bí ẹyẹ ògòǹgò.
Èyí ni yóo jẹ́ ààlà ilẹ̀ náà ní apá ìhà gúsù.
Alaafia yóo sì wà, òun gan-an yóo sì jẹ́ ẹni alaafia.
Àwọn akọ̀wé ati àwọn olórí alufaa gbèrò láti mú un ní wakati náà, nítorí wọ́n mọ̀ pé àwọn ni ó pa òwe yìí mọ́; ṣugbọn wọ́n bẹ̀rù àwọn eniyan.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Unicycle School: Olùdarí ibùdó ìkẹ́kọ̀ kẹ̀kẹ́ alájọwà ń fẹ́ ìrànwọ́ ìjọba Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Unicycle School: Olùdarí ibùdó ìkẹ́kọ̀ kẹ̀kẹ́ alájọwà ń fẹ́ ìrànwọ́ ìjọba 17 Owewe 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 18 Èbibi 2020 Nigba ti ọlaju kọkọ de silẹ Yoruba, kẹkẹ ologeere lo gbajumọ ti awọn eeyan si mọ dunju, amọ lode oni yii, ilana kẹkẹ wiwa kan tun ti de, eyi to n mu owo wa fun ni.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìjọba àpapọ̀ buwọ́lu $1.
O rin irinajo lati ipinlẹ Eko lọ si Abuja lati ṣe ariya itagbangba lasiko ti ijọba fi ofin de iru nkan bẹ ẹ.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Wo aláànú tó n wa ọkọ̀ tí wan fi n gbé aláìsàn lọ́fẹ̀ẹ́ Oniṣegun oyinbo alaanu yii ni oun kii san owó oṣù fawọn oṣiṣẹ naa.
Fani Kayode ti ní kí iléeṣẹ́ Daily Trust san 6 bilion Naira nítorí ọ̀rọ̀ kùbákùngbé tí wọ́n sọ sí i Oríṣun àwòrán, Others Minisita fun ọrọ irinna ọkọ ofurufu tẹlẹri ni Naijiria, Femi Fani-Kayode ti ni oun yoo gbe ileeṣẹ Iroyin Daily Trust lọ si ileẹjọ nitori wọn ba orukọ oun jẹ ninu iroyin ti wọn gbe jade.
Dokita Rebecca Dewey ti fasiti Nottingham to jẹ onimọ nipa bi ọpọlọ ṣe n gbọ ohun ni ọpọlọ rẹ maa fi gbogbo igba wa bo ṣe lee da ariwo mọ eyi si maa n ṣe idiwọ lasiko iṣẹ.
Abrahamu bí Isaaki, Isaaki bí Jakọbu, Jakọbu bí Juda ati àwọn arakunrin rẹ̀.
"Ìwádìí fi hàn pé, ìdá ọgójì sí ọgọ́tà àwọn tí kò ni ààrun Coronavirus ló ni ""T Cell"" lara."
Nígbà tí ó yá, ó rò ninu ara rẹ̀ pé, “Ìjọba yìí yóo pada di ti ilé Dafidi.
“Bẹ́ẹ̀ sì ni èmi ni mo pa àwọn ará Amori run fún wọn, àwọn géńdé, tí wọ́n ga bí igi kedari, tí wọ́n sì lágbára bí igi oaku; mo run wọ́n tèsotèso, tigbòǹgbò-tigbòǹgbò.
”Omowe Onu tun so pe orile ede
Lara awọn eekan to peju sibẹ naa ni MC Oluọmọ, ẹni to jẹ ilumọọka aṣiwaju ẹgbẹ ọlọkọ ero NURTW nipinlẹ Eko.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ruga Settlement: Iléeṣẹ́ ààrẹ ní àgbékalẹ̀ àgọ́ Fulani lọ̀nà àbáyọ sí wàhálà àgbẹ̀ àti Fulani 27 Òkùdu 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 28 Òkùdu 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Aworan awọn darandaran Fulani Ileeṣẹ aarẹ orileede Naijiria ni ohun iyalẹnu lo jẹ fawọn bi awọn Gomina ipinlẹ kan ti ṣe n tapa si idasilẹ agọ Fulani, eyi ti wọn pe ni ''Ruga Settlement.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Tọkọtaya láti Najiria wọ wahálà torí ààwẹ̀ p'ọmọ wọn ní Amẹrika 5 Owewe 2018 Oríṣun àwòrán, Sauk County Sheriff's Office Tọkọtaya kan lati orilẹede Naijira, Kehinde Omosebi ati iyawo rẹ Titilayo Omosebi ti foju ba ile ẹjọ kan ni Ipinlẹ Wisconsin, orilẹede Amẹrika nitori ọmọ wọn ẹni ọdun marundinlogun gbẹmi mi nigba ti wọn n gba aawẹ.
Fetí sí mi, kí o sì dá mi lóhùn;ìṣòro ti borí mi.
Lọsẹ yii ni ile ẹjọ kan ni orilẹede Amerika dajọ ẹwọn ọdun marun-le-laadọsan fun dokita ikọ agbabọọlu USA Olympic tẹlẹ ri, Larry Nassar latari pe o fi ilọkulọ ibalopọ lọ ọpọlọpọ obinrin elere ori papa.
Oríṣun àwòrán, Ibrahim Chatta/Instagram Nínú àwòràn tó gbé sójú opo instagram rẹ lọjọ Abamẹta, a ri ti ó sùn si orí ibùsùn, tí wọ́n si fa gbogbo oníruuru ọkun àti omi síi lára, gẹgẹ bi wọn se maa n se fawọn alaisan.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Temidayo Adeleke: Ilé ẹjọ́ ní kí wọ́n yẹgi fún ọmọ Cameroon tó pa ọ̀gá rẹ̀ ni Ikoyi 21 Èbibi 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 22 Èbibi 2019 Odindi ọdun meji ati aabọ ni igbẹ́jọ lori bi ọmọ Cameroon kan ṣe sẹku pa ọga rẹ Dayo Adeleke, ni oṣu kejila ọdun 2016, ṣugbọn ni ọjọ Iṣẹgun, ile ẹjọ agba kan ni Ipinlẹ Eko ti dajọ iku fun Leudjoe Koyemen Joel.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Kenyan Woman: Aláboyún fi bílédìì gbé ọmọ jádé nínú ara a rẹ̀ ní Tanzania 31 Èbibi 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 1 Òkùdu 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, N ṣe ni Joyce mu bileedi, to si fi la ara a rẹ ni ikun ko to o gbe ọmọ tuntun naa jade.
@Dami nínú ọ̀rọ̀ rẹ̀ ni ìyàlẹ́nu ló jẹ́ pé ìjọba tó lọ dóòlà àwọn ọmọ tó le ni ọ̀ọ̀dúnrun, kò gba Leah silẹ.
Gomina Abdurazaq fi eyi lede lasiko ti o lọ ṣe abẹwo ikini si minisita fun ere idaraya ati idagbasoke awọn ọdọ, Sunday Dare ni ofisi rẹ ni ilu Abuja.
Ṣáájú àkókò yìí, nígbà tí Dafidi gbógun ti àwọn ará Edomu, tí ó sì ṣẹgun wọn, Joabu balogun rẹ̀ lọ sin àwọn tí wọ́n kú sógun, ó sì pa gbogbo àwọn ọmọkunrin Edomu; 
Ninu atejade kan ti o pe ni ‘Awon obinrin se dandan’,
Awon ololufe iko agbaboolu Pleateau united ti bu enu ate lu, bi iko naa se padanu ifesewonse ese keji won ninu idije CAF Champions League latari papa isere ipinle Kano ti iko ohun ti lo gba ifesewonse naa, eyi ti o jina si ile won.
Kò sí ohun tí ó dára fún eniyan ju kí ó jẹun kí ó sì máa gbádùn iṣẹ́ ọwọ́ rẹ̀ lọ.
" 'Kò si ẹ̀ri fún ìbò ọmọ kékèké ni Kano' Ganduje Video - Ìwádìí ilé aṣòfin foríṣánpọ́n Bí wọ́n ṣe ń ta káádì ìdìbò ní Kano nìyì Bawo ni igbaradi ṣe n lọ fun atundi ibo naa?
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Iléẹ̀kọ́ gbogboùnṣe ìgbájọ lé gíwá rẹ̀ lórí ẹ̀sùn ayédèrú ìwé ẹ̀rí 8 Agẹmo 2018 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ọgbẹni Akinọla Ọlaolu ni oun gba iwe ẹri gboye ọmọwe ni fasiti ilu Ibadan ki iwadi to sọ pe ko ri bẹẹ Igbimọ iṣakoso ileewe gbogboniṣe aladani kan nipinlẹ Ọun, Igbajọ Polytechnic ti le sga agba ileewe naa, Ọgbẹni Akinọla Olugbenga Ọlaolu ti wọn fi ẹsun kan pe o lo ayederu iwe ẹri ikẹkọ gboye smọwe lati fasiti Ibadan Igbakeji alaga igbimọ majẹobajẹ ileẹkọ naa, Oloye Inaọlaji Abọaba to ba awọn oniroyin sọrọ lọgba ileewe naa ni nigba ti iroyin naa lu sita pe ayederu ni iwe ẹri imọ ijinlẹ ọmọwe ti ọgbẹni Akinọla Olugbenga Ọlaolu n gbe kiri ni wọn ti yara kọwe si fasiti Ibadan nibi ti o ni oun ti gba iwe ẹri naa lati lee fidi otitọ ọrs mulẹ.
Alaye ree lori bi awọn isẹlẹ ifipabanilopọ naa se waye, ẹ wo o.
Wọn le Ọba Adediran kuro nilu Ọyọ ninu osu Keje, ọdun 1955.
Yóo gbé ikú mì títí lae, OLUWA yóo nu omijé nù kúrò lójú gbogbo eniyan.
Aarẹ Weah kede eyi lasiko to n bawọn ọmọ orilẹede Liberia sọrọ nibi to ti sin wọn ni gbẹrẹ ipakọ pe sanmọni yoo lọ tinrin fun wọn nitori pe ojojo owo nse orilẹede naa.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Gomina ipinlẹ Yobe di ẹbi iṣẹlẹ Dapchi ru ileeṣẹ ologun 26 Èrèlè 2018 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ijọba ipinlẹ Yobe ati ileesẹ ọmọogun lorilẹede Naijiria n tako arawọn lori ohun to sokunfa isẹlẹ ilu Dapchi Gomina ipinlẹ Yobe lẹkun ila oorun ariwa orilẹede Naijiria nibiti o le lọgọrun akẹkọ ti di awati lọsẹ to kọja lẹyin ikọlu awọn agbebọn ikọ Boko Haram ti di ẹbi ohun to sẹlẹ ru awọn ologun o.
A gbé, nítorí ìparun dé bá wa.
Bí ọba bá ṣe nǹkan, ta ló tó yẹ̀ ẹ́ lọ́wọ́ rẹ̀ wò?
Ẹ̀tanú náà pọ̀ sí wọn tó bẹ́ẹ̀ tí mo fi lé wọn dé ìlú òkèèrè pàápàá.
Wo àwọn Ṣọ́ọ̀ṣì Nàìjíríà àti l'Áfíríkà tó ń wólẹ̀ àdúrà kí Trump lè wọlé ìbò ààrẹ America Àwọn akẹ́kọ̀ọ́ 181 pẹ̀lú Olùkọ́ lùgbàdì Covid 19 níléèwé aláàdáni kan nípinlẹ̀ Eko Bayii si ni ileeṣẹ ayelujara gẹgẹ bi salaryexpert.
Ipaniyan: Ẹ̀wọ̀n gbére ni adájọ́ fún ọkùnrin náà pé ó jí olólùfẹ́ rẹ̀ gbé
Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí End SARS protest: Lára àwọn ìlú tí ìwọ́de ti wáyé ní Ibadan, Ado Ekiti, Osogbo, Ado Ekiti ati Eko19 Ọ̀wàrà 2020 10:43 Fídíò, Wole Soyinka sọ ìdí tó fi ni òun a fi màálù Fulani ṣe súyà fáwọn èèyàn abúlé, Duration 10,4323 Owewe 2020 Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí 2 sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
Àwọn ohun ipèsè wọnyi jẹ èrè lati ọ̀dọ̀ Òṣèlú tó fẹ́ràn ilú ti ó gbé wọn dé ipò, eleyi jẹ àwò kọ́ iṣe fún àwọn Òṣèlú ẹ̀yà ilẹ̀ Nigeria yókù.
Muhammadu Buhari naa wa rọ omo orile ede Naijiria lati maa je ki eto idibo ti
 gbogbo ìwọ ̀ nyí wà fún ṣíṣe ìfẹ ́ rẹ ̀ .
 botileje alafileyika , orile-ede yi jamo okun dudu lati inu odo danubi .
Sẹ́nátọ̀ Elisha Abbo kési Naira Marley láti ṣe àríyá fún Leycon tó borí ní BB Naija Ṣó yẹ kí akẹ́kọ̀ọ́ tàbùkù mi torí mo ya ‘Tatoo’ sí gbogbo ara?
Iba ọrẹrẹ pa eeyan kan l'Ọsun Awọn asofin Naijiria jiroro lori iba ọrẹrẹ Ipinlẹ mejidinlogun ni itankalẹ aisan naa ti de lati igba to ti bujade lọjọ kinni, osu kinni 2018, eyi to yọri si iku eniyan mejilelaadọrin latipasẹ iba to mu ki ẹjẹ maa da lara wọn.
Eeyan mẹrin ku ninu ijamba ọkọ l'Eko Ibugbamu ibudo epo ni Ijegun O ṣalaye siwaju sii wipe awọn ọkunrin mẹta miran pẹlu obinrin mẹrin tun fara kaaṣa yanyan ti wọ̀n si ti gbe wọn lọ si ile iwosan fun itọju pipe.
O ni èrè ti oun jẹ lara MMM ki se die.
Ó bi mí pé: “Ọmọ eniyan, ṣé o rí ohun tí wọn ń ṣe yìí?
9 85805 Orilẹede Azerbaijan 1632 16.
Mane ni agabọọlu ọmọ orilẹede Senegal ti goolu rẹ pọju lọ bayii ni idije premiership pẹlu goolu mẹrinlelogoji to ti gba wọle.
Fifi ẹjẹ silẹ maa n doola ẹmi Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Blood donation rules relaxed for gay men and sex workers23 Agẹmo 2017 Fídíò, Blood donation: 'For two weeks she lived life to the full'11 Ẹrẹ̀nà 2019 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Ileeṣẹ ọmọogun oriilẹ ni awọn ọdọ ti wọn n fẹhonu han kan ni wọn pa a nitori lọjọ ti wọn ṣe iwọde wọn naa ni ọgagun Alkali gunle irinajo aremabọ rẹ naa.
”Bẹ́ẹ̀ náà ni gbogbo àwọn ọmọ-ẹ̀yìn yòókù ń wí.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Lacazette lo jẹ goolu kan ṣoṣo ti Arsenal jẹ ninu ifẹsẹwọnsẹ naa Emery ti gba ife Europa lẹmẹẹta pẹlu Sevilla nigba to n dari wọn laarin ọdun 2013-2016.
Níbo ni ewu coronavirus pọ̀ sí jùlọ lásìkò tí ìjọba ń dẹ okùn kónílé-ó-gbélé wálẹ̀ yìí?
Awọn Asofin ni Ile Igbimọ Asofin ti sọ wi pe awọn ko ni joko ni Ọjọru, ọsẹ to n bọ ti Aarẹ Buhari ni ohun yoo wa salaye bii owo isuna ọdun 2019 yoo se lọ.
Ṣùgbọ́n ni ọ̀pọ̀ ìgbà ọwọ́ àwọn ìjọba ìbílẹ̀ mẹ́ta yìí ni ọ̀rọ̀ wà.
Amọ, aarẹ ti wọn ṣẹṣẹ dibo yan, Joe Biden ti ni igbesẹ ti oun yoo yatọ patapata si aarẹ Trump, o ni gbogbo idọrẹpọ pẹlu orilẹede to ṣe pataki lagbaye, ti aarẹ Trump gbegile ni oun yoo tun to pada.
N jẹ ẹ mọ pe ọmọ ti Ọlọrun fi ta idile Toyin Abraham ati ọkọ rẹ lọrẹ ti ṣ'ayẹyẹ ọjọ ibi ọdun kan.
Yorùbá ni “Ẹ̀bẹ̀ là nbẹ òṣikà, ki ó tú ilú ṣe”.
Ẹ fi wọ́n sílẹ̀ fún àwọn àlejò ati àwọn opó ati àwọn aláìní baba.
Akopa ogun lo peju fun eto naa ti wọn ni afoju sun lati gba ẹbun miliọnu marundinlọgbọn naira bakan naa.
CAN ní kí wọn fágile ìdánwò ọlọ́pàá Lori ọrọ owo ajọ JAMB ti wọn fẹsun kan awọn kan pe wọn ṣe ni kumọkumọ, ni Ojogbọn Oloyede fi ara balẹ ṣalaye fun BBC Yoruba pe iṣẹ ti lọ jinna lori ẹ.
Gẹ́gẹ́ bí ọmọ ẹgbẹ́ Ohùn Àgbáyé ṣe ìpolongo àti ìpanupọ̀ ajàfúnẹ̀tọ́ ọmọnìyàn àgbáyé gẹ́gẹ́  bi agbẹnusọ láti ọjọ́ tí wọ́n dé akoto ọba.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Soyinka Cancer: Àṣe ara mi ni iso ti n run gbogbo bí mo ṣe n ṣèrànwọ́ lórí jẹjẹrẹ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Soyinka Cancer: Àṣe ara mi ni iso ti n run gbogbo bí mo ṣe n ṣèrànwọ́ lórí jẹjẹrẹ 26 Bélú 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 27 Bélú 2019 Ko ko koo, lọdun 2014 bi ana ni arun buruku yii wọle tọ mi wa""."
to n gba alejo alaga ile-ise onimo ero Kongila China Railway Construction
Àwọn eniyan bá wá sí Bẹtẹli, wọ́n jókòó níwájú Ọlọrun títí di ìrọ̀lẹ́, wọ́n sì sọkún gidigidi.
Ile naa, El Helicoide ti figba kan jẹ ohun to n soju orilẹede naa gẹgẹ bi ilu ọlọrọ to si ni ọjọ iwaju rere.
Iná orí pẹpẹ náà gbọdọ̀ máa jó nígbà gbogbo, kò gbọdọ̀ kú.
Afẹ̀hónúhàn - BBC News Yorùbá BBC News, YorùbáFò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ẹ yé fipá bá obìnrin lòpọ̀ mọ́, ìbálòpọ̀ kìí ṣe dandan - Afẹ̀hónúhàn Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Ẹ yé fipá bá obìnrin lòpọ̀ mọ́, ìbálòpọ̀ kìí ṣe dandan - Afẹ̀hónúhàn 12 Òkùdu 2020 Ẹgbẹ to n ja fun idagbasoke ati igbeaye awọn ọdọ, YISED ẹka ipinlẹ Oyo ti ṣe iwọde lati fi aidunu wọn han lori ifipa bani lopọ ati iṣekupani to n peleke si ni Naijiria.
Jẹ́ kí adura mi dé ọ̀dọ̀ rẹ;tẹ́tí sí igbe mi.
Awọn aladugbo to de sibẹ lo ransẹ pe awọn ọlọpaa to gbe iya Taiwo lọ sile iwosan, amọ ko tii yaju titi di akoko yii.
Oore-ọ̀fẹ́ si wa fun Chelsea lati gba ipo kẹta.
" Àwọn tó wà ni "" brazil ' ni wọ ́ n ń pè ni "" nàgó ' ."
Orúkọ ìnagijẹ mẹ́jọ tí wọ́n fi ń pe Abiola Ajimọbi nígbà ayé rẹ̀ Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
padanu emi won ninu ijamba oko naa ni wahala be sile ni aarin ilu naa, ni eyi
oniruru nnkan ni a n ṣe ti o buru.
Oríṣun àwòrán, Ololufe BBC Àkọlé àwòrán, Ike omi ni ọ̀rọ̀ kan fún ẹni yi láti fi dáa bo bo ara rẹ Oríṣun àwòrán, Ololufe BBC Àkọlé àwòrán, kọmu ni awọn tun fi bomu, njẹ eyi le e daabo bo wọn lọwọ arun Coronavirus.
Ọpọlọpọ eniyan sì tẹ̀lé e, ó sì wo gbogbo wọn sàn.
Bayìí ni àwọn ọlọpàá Akure ṣe ko àwọn ará ìlú ti o ji ẹrù ni sọọsi Sotitobirẹ Tápà sí ìlànà tuntun CBN kí o fí owó ìtanràn ₦2m gbára Kò sí nǹkan tí yóò ṣe Goodluck Jonathan lábẹ́ ìṣèjọba mi-Buhari Kò tíì pẹ́ jù bí ìjọba bá leè sọ ẹni tó pa olóògbé Bola Ige- Gani Adams Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Christmas: Jesu ni ọjọ́ ọ̀la àti ibi ìyanu mi- Jaga Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Nígbà tí obinrin náà dé, Eliṣa wí fún un pé kí ó gba ọmọ rẹ̀.
O fi gbogbo nǹkan sí ìkáwọ́ rẹ̀.
Awọn Ọba tuntun ti ile ẹjọ paṣẹ pe ki wọn wọgile iyansipo wọn ni Emir Aminu Ado Bayero to jẹ Emir agbegbe Bichi, Ibrahim Abubakar to jẹ Emir agbegbe Karaye; Tafida Abubakar Ila tii se Emir agbegbe Rano ati Ibrahim Abdulkadir to jẹ Emir agbegbe Gaya.
“Wolii tí yóo máa sọ àsọtẹ́lẹ̀ irọ́ ati ẹ̀tàn ni àwọn eniyan wọnyi ń fẹ́, tí yóo sì máa waasu pé, ‘Ẹ óo ní ọpọlọpọ waini ati ọtí líle.
Mo rí Oluwa tí ó ń sọ fún mi pé, ‘Jáde kúrò ní Jerusalẹmu kíákíá, nítorí wọn kò ní gba ẹ̀rí tí ò ń jẹ́ nípa mi.
Omolola Arohunmolase Welder: Mo ti fí iṣẹ́ 'Welder' gbayì láwùjọ, tó mo fi tọ́ ọmọ yanjú
Oríṣun àwòrán, Instagram/queen aanu O fi kun un pe pupọ awọn to wa n sọrọ yii ni wọn maa n gba ẹyin wa bẹbẹ fun ohun kan tabi omiran lọwọ oun.
Ajijagbara Mufuliat Fijabi salaye ona ti awon omo orile ede Naijiria lee gba lati maa lo awon ojo wonyii, ni eyi ti won yoo fi maa gbokun ti iwa aito si awon obinrin.
Ṣugbọn ní ìlú Ekibatana, olú-ìlú tí ó wà ní agbègbè Media, ni wọ́n ti rí ìwé àkọsílẹ̀ kan tí ó kà báyìí pé:
" Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Akomolede ati Asa lori BBC: Olùkọ́ Kikelomo Ogunboye tan ìmalẹ̀ sí ìwà olè ọ̀gá ọlọ́pàá O fi kun un pe mama oun ati awọn arabinrin rẹ lo maa n ba oun tọju idile oun lasiko to ba wa ni ẹnu iṣẹ.
Nigba to n sọrọ lorukọ awọn olutọju alaisan, Alaga Igbimọ to n duna-dura fun alekun owo osu nipinlẹ Ondo, to tun jẹ Alaga ẹgbẹ awọn Nọọsi nipinlẹ Ondo, Ọpẹyẹmi Oloniyo sọ fun BBC Yoruba pe, awọn oṣiṣẹ ileewosan naa ti pada sẹnu iṣẹ wọn, ati pe ijiroro ṣi n lọ lọwọ lori awọn ẹsun ti wọn fi kan ijọba.
Afurasí Fulani ṣekú pa ọmọ olórí ẹgbẹ́ Afẹ́nifẹ́re, Fasoranti Ooni Ile ife, Ààrẹ Gani Adams fárígá lórí ikú ọmọ Fasoranti Ẹgbẹ́ Ilẹ̀ Yorubà gba Aṣíwájú tuntun!
Homosexualism: Ofin ti f'àyè gba ìbálòpọ̀ Akọs'akọ, Abos'abo ní Botswana
A ńsa ipá wa a ó sì tẹ̀síwájú láti dá àbò bo ẹ̀mí àti dúkìá àwọn ènìyàn.
Bakan naa lo ni o ṣeeṣe ki wọn gbe eto konileogbele yẹwo lawọn agbegbe ti wọn ba rii pe awọn eeyan ti n ko ori js lati mu ọti niwaju awọn ile itaja, gẹgẹ bi iwe iroyin Chicago Sun-Times ṣe gbee jade.
US Election 2020: Ṣé èsì ìdìbò Ààrẹ Amẹrika yóò jáde lálẹ́ ọjọ́ ìdìbò?
Bí o sì ti rí ìsàlẹ̀ ẹsẹ̀ ati ìka ẹsẹ̀ rẹ̀ tí ó jẹ́ àdàlú irin ati amọ̀, bẹ́ẹ̀ ni ìjọba yìí yóo pín yẹ́lẹyẹ̀lẹ.
Olùkọ́ fásitì méjì ń bèèrè ìbálòpọ̀ lọ́wọ́ akẹ́kọ̀ọ́ fún máákì Fídíò rèé nípa bí Aláké tuntun ṣe ń gba ìwúre lábẹ́ Olúmọ kó tó gba adé Toyin Adegbọla, taa mọ si Asẹwo to re Mecca salaye pe, aya gidi ati iya rere ni Mama Rainbow jẹ, to si maa n gba eeyan ni imọran nipa bi sjọ iwaju yoo se dara, ti kii si kanra mọ ẹnikẹni.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ibi gbogbo lo gba alagbara Àwọn oniṣowo kan sọro lori tita ohun mimu tutu bii ẹlẹrindodo ati omi tutu ninu ọ̀rá àti nínú ike.
Àbẹ̀wò Buhari: Gómìnà márùn-ún ki káábọ̀
Shiite: Ìjọba Kaduna ní òun yóò pe ẹjọ́ láti tako El-Zakzaky tó fẹ́ gba ìtọ́jú ní India
Oríṣun àwòrán, Hajara Habib Àkọlé àwòrán, Zainab,,Iya rẹ ati ọmọ iya rẹ saaju ki wọn to mu Awọn wọ lo ṣakoba fun Zainab?
95bn sórí reluwé làti Kano sí Niger Republic- PDP Oluwo kọ̀ láti sọ̀rọ̀ lórí àwọn afọbajẹ tó fẹ́ yọ ọ́ nípò, aráàlú fọ́n síta láti fẹ̀hónú hàn Wo ìlànà tí ìjọba Saudi Arabia fi síta fún Umrah tí yóò bẹ̀rẹ̀ padà l'óṣù Kẹwàá Ade Ajayi to jẹ agbodegba ẹgbẹ sọ sinu atẹjade yii pe awọn gbe igbesẹ yi lẹyin ti igbimọ iwadii sọ pe lootọ ni wọn tapa si asọtẹlẹ ẹgbẹ pe ki wọn maa se tako ẹgbẹ nile ẹjọ.
Dípò ohun tí wọ́n fi ń ṣe ògo,ajónirun yóo jó wọn bí ìgbà tí iná bá jóni.
 oríṣiríṣi iṣẹ ̀ ni àwon olóòtú wikipedia ń ṣe .
Ọlawuyi sọ eyi lasiko to n fesi si abajade idibo ti Ajọ INEC ti kede rẹ gẹgẹbi ẹni to jawe olubori ninu atundi ibo naa.
” Ṣugbọn Jehu ń ṣe èyí láti rí ààyè pa gbogbo àwọn olùsìn Baali run ni.
Ẹru n ba mi lati lọ si fasiti nitori yẹyẹ ti wọn maa fi mi se, koda, mo lee pa ara mi ti ẹsin yii ba tun pọ si, idi si ree ti n ko se ba wọn ya fọto nile ẹkọ girama nitori ila ti mo kọ."
’ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Colorado ni Amẹrika àti odò Awaye ní Naijiria nikeji àdágún órí àpáta ní gbogbo àgbáyé!
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Àwọn ọmọ Iyabọ Ojo rí bàbá wọn fún ìgbà àkọ́kọ́ ní ọdún mẹ́fà 30 Agẹmo 2018 Oríṣun àwòrán, Priscilla Ojo Àkọlé àwòrán, Awọn mejeeji naa, ti wọn lọ lo isinmi wọn ni orilẹ-ede Amẹrika lo se alabapin awọn aworan ti wọn ya pẹlu baba wọn nibẹ.
Tí àwọn kan tún wá ṣa ọkà yòókù,tí àwọn tí wọn kọ́ kórè ọkà gbàgbé ní àfonífojì Refaimu.
o fẹ ́ òyìnbó , dr.
Kí ni Ọlọ́run Ọba jẹ́ níbi tí èmi wà!
ibo aarẹ fun egbe oselu, All Progressives Congress, APC ti fẹsun kan egbe oselu PDP  ati oludije 
Bi o ti le je pe Arsenal
Nípa ríra òògùn ìṣẹyún lórí ayélujára àtí ṣíṣe ìwádìí nípà ìṣègùn lóri àtèjíṣẹ́ WhatsApp, ọ̀pọ̀ àwọn obirìn ló ti di onímọ̀ nípa ọ̀nà ìmọ̀-ẹ́rọ, tí wọn sì tí gbé ìdíwọ́ òfin tó de ìṣẹ́yún tì sẹ́gbẹ̀ kan.
Atiku ló lè fòpin sébi tó ń pa ọmọ Nàìjírìa- Titi Ṣé àdúrà aṣaájú ẹ̀sin lórí olùdíje kan leè nípa lórí èsì ìbò?
Bí ẹ bá mọ nǹkan wọnyi, ẹ óo láyọ̀ bí ẹ bá ń ṣe wọ́n.
2 Flyover bridges along Alhaji Masha Rd, Ijọba ibilẹ Surulere20.
Èyí ni ìdí tí Bàbá Kérésì fi máa n wọ aṣọ pupa àti funfun nígbà gbogbo Funke Akindele, Toyin Abraham, Bimbo Oshin ṣe Kérésìmesì lọ́nà àrà Ìjọba Buhari kò tíì fi akọ̀ròyìn kankan sátìmọ́lé láti ọdún 2015 - Garba Shehu Ilorin gbàlejò Wizkid, àwọn olólùfẹ́ rẹ̀ fẹ́ ẹ̀ gbée lójú agbo Koda, a kan si agbejọro Wolii So titobi rẹ, Alukoro awọn agbofnro, Femi Joseph, ẹbi ọmọ to sọnu ati gbogbo awọn ti iṣẹlẹ yii kan.
12 Èbibi 2019 Ọmọ orilẹede Togo ni iwọ oorun Afirika ni Tété-Michel Kpomassie ṣe, ṣugbọn oun ni akọkọ adulawọ to kọkọ de ilu Greenland nibi ti otututu ti maa mu gidi gan an.
“Ijipti óo di ahoro patapata àwọn ìlú rẹ̀ yóo wà lára àwọn ìlú tí yóo tú patapata.
Akonimoogba agba Abia Warriors’ Emmanuel Deutsch gbosuba kare lai fun iko re leyin ti won jawe olubori ninu ifigagbaga naa.
Orílẹ̀-èdè tí ó kún fún ẹ̀ṣẹ̀,àwọn eniyan tí ẹrù ẹ̀ṣẹ̀ ń pa lọ,ìran oníṣẹ́ ibi;àwọn ọmọ tí ó kún fún ìwà ìbàjẹ́!
Ṣe ṣaaju ni olori orilẹ ede naa, Aarẹ Ramaphosa ti bẹ ijọba ati gbogbo ọmọ orilẹ ede Naijiria fun ikọlu to waye naa.
Gẹ́rẹ́ ti Ọ̀bọ sún mọ́ Ẹkùn, o fã lati gba ikùn rẹ gẹ́gẹ́ bi Ìjàpá ti sọ, ki ó lè ṣu di dùn fún òhun.
Amọṣa diẹ lara awọn asiko ti wọn ti dẹyẹsi rẹ pẹlu ariwo ṣiọ ṣiọ ni igba ti o farahan nibi ajọdun Edinburgh Festival Fringe.
Ọdún yìí náà ni wọ́n tún Obama yàn gẹ́gẹ́ bí ààrẹ orílẹ̀ èdè Amẹrika.
 ní ọjọ ́ ogún oṣù kínín ọdún 1925 , ó fẹ ́ Àlùfáà israel oludotun ransome-kuti .
"Miliọnu meji owo ìwé àṣẹ ti wọn ni ka ma a san ti pọju fun awọn to n ba n fi nkan ránṣẹ labẹle ni Naijiria.
Nígbà tí baba rẹ̀ kú, ó kúrò níbẹ̀ láti wá máa gbé ilẹ̀ yìí, níbi tí ẹ̀ ń gbé nisinsinyii.
Dafidi sọ fún Abiṣai ati àwọn iranṣẹ rẹ̀ pé, “Ṣebí ọmọ tèmi gan-an ni ó ń gbìyànjú láti pa mí yìí, kí ló dé tí ọ̀rọ̀ ti ará Bẹnjamini yìí fi wá jọ yín lójú.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Iléeṣẹ́ ọlọ́pàá ní ọwọ́ ko ti tẹ àwọn afurasí to jí olórí ìlú Buhari gbé 2 Èbibi 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Ileeṣẹ ọlọpaa nipinlẹ Katsina State Policeti ke gabjare pe irọ balawu ni ọrọ to n ja rain-rain pe awọn ti mu awọn afurasi to ji ana ẹsọ aarẹ Buhari gbe.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Flood: Ọ̀pọ́ Dúkìá ló sọnù ní 2019 lásìkò tí ìjọba ṣí ’dáàmù Ọyan’ Nibayi aya ti mọ oju ọkọ, ọkọ naa si ti mọ oju aya, awọn iyawo naa ti bi isun, wọn ti bi iwalẹ fun Alaafin, awọn alarena naa si ti yẹba.
Èyí ni bí o ṣele dá ayédèrú ìròyìn mọ̀ A kú ewu ọmọ Linda Ikeji ooo Ọ̀rọ̀ LAUTECH gba àpérò f'áwọn Olúdíje Ọṣun A kò ní ǹkan ṣe pẹ̀lú ẹgbẹ́ òsèlú -Adeboye Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ìkọ BBC Yorùbá ṣe àbápade ọkùnrin tó ní òún le darí òjò síbi tó wù òun Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Ilẹ̀ tí ẹ óo pín láàrin àwọn ẹ̀yà Israẹli nìyí; bẹ́ẹ̀ sì ni ètò bí ẹ óo ṣe pín in fún olukuluku wọn, OLUWA ló sọ bẹ́ẹ̀.
Olamide gbe fidio orin naa sita ni oṣu keji ọdun lẹyin to sọ pe oun n fi orin naa kilọ oogun oloro ni.
Ó dá wọn lóhùn pé, “Ẹ lọ sọ fún ọlọ́gbọ́n ẹ̀wẹ́ yẹn pé, ‘Mò ń lé ẹ̀mí èṣù jáde, mo tún ń ṣe ìwòsàn lónìí ati lọ́la.
Igbati a gba fọọmu tan, wọn ni a maa san ẹgbẹrun lọna ogoji naira fun owo ẹkọsẹ.
Wọ́n bá ju irin ìdákọ̀ró mẹrin sinu omi ní ẹ̀yìn ọkọ̀; wọ́n bá ń gbadura pé kí ilẹ̀ tètè mọ́.
Tí o kò bá rí owó san fún olówó,olówó lè pé kí wọn gba ibùsùn rẹ.
Ǹjẹ́ o mọ̀ pé àwọn tó wá láti ìdílé ẹrú kìí lọ́kọ tàbí aya láyé òde òni ní Nàìjíríà!
 nítorí náà , Ẹni tí ó ni ilẹ ̀ wá di Ọọ ̀ ni ilẹ .
Bi o ba rọrun bayi lati ri iwe afihan pe lootọ ni o ṣe idanwo, ki lo de ti o fi pẹ bayii?"
Ó ń jó bíi igbó ńlá, ó sì ń yọ èéfín sókè lálá.
Ó bá bèèrè, ó ní, “Kí ni o ti fẹ́ ṣe gbogbo àwọn agbo ẹran tí mo pàdé lọ́nà?
Wọn ni awọn n ṣe iwadi lati fidi ọrọ mulẹ boya lootọ ni iku naa ṣẹlẹ latari ọti to mu tabi amuwa Olohun nii.
ẹgbẹrun mejidinlogun-le-ọọdurun ati meje (18,307) esi ibo to fi tayọ
“Ìwé òfin Mose ati ìwé àwọn wolii ni ó wà fún ìlànà títí di àkókò Johanu.
 Ó jẹ ́ àkọkọ ́ àṣeyọrí ìfipá gba ọkọ ̀ ojú omí tí yio ṣélè ́ lati bíi ọ ̀ kànlélógun ọgọrún ọdún sẹ ́ yìn .
OLUWA Ọlọrun wa kò rán ọ láti sọ fún wa pé kí á má lọ ṣe àtìpó ní Ijipti.
Èèyàn 125 míràn ṣẹ̀ṣẹ̀ kó COVID-19 ní Nàìjíríà Ìjọba Nàìjíríà ti kéde pé kí ilé ìtura ṣí padà, kí ìlé ìwé máa palẹ̀mọ́ ìwọlé àwọn akẹ́kọ̀ọ́ Ara ló ń ta àwọn ẹgbẹ́ NURTW tó ń pariwo mi kiri, APC ni wọ́n bá lọ nígbà náà l'Oyo- Auxiliary Daniel Prude: Ìbòjú tí àwọn ọlọ́pàá New York fi bo ọkunrin ọhun ló ṣe ikú pà á Mo ṣetán láti fi ẹ̀ṣẹ́ dín dòdò ìyà fún Anthony Joshua- Efe Ajagba Adebayo Orisameyitimi to jẹ baba Ojo ni Ọgọtun Ekiti naa sọrọ pe diẹ lo ku ki oun ku nitori airi owo gba lọya fun Ojo Ọjo ṣalaye bi o ṣe kawe pada lati J S 3 pẹlu iranlọwọ Cottage of Hope Institute ninu ọgba ẹwọn to fi kawe gboye jade ninu Criminology ni National Open University .
waye ni  ojo kéjìlá, osu kẹ́fà.
Ariwo iba ni wọn ni oloogbe naa pa eleyi to sọs di ero ileewosan fun ọsẹ kan gbako ki o to jade laye ni ọjọ karundinlọgbọn oṣu kẹrin ọdun 2020.
Ilé ẹjọ́ wọ́gilé ìgbẹ́jọ́ Olalekan 'Woodberry' Pọnle Wo bí ètò ìsìnkú Tolulope Arotile ṣe lọ nílùú Abuja Nǹkan mẹ́sàn án tí Mùsùlùmí gbọdọ̀ ṣe nínú oṣù Dhual- Hijjah Ènìyàn 653 míràn tún kún iye àwọn tó ní COVID-19 ní Nàìjíríà Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí kan sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
'APC kò fẹ́ ire fún mi mọ́ nínú ìṣesí wọn' Tinubu dagbere fawọn to n ya kuro ni APC 'Kò ṣéèṣe fún aláǹgbá láti bá ẹtu jà' ni ọrọ idagbere Bola Tinuba fun àwọn to n ya kuro ni ẹgbe oselu APC ni eyi to tun fi n ki awon to ṣẹṣẹ n darapọ mọ ẹgbẹ kaabọ sile.
Ile ijọba 'White House' sọ pe o fọwọ rọri ku ni gẹgẹ bi arugbo, pe kii ṣe coronavirus lo pa.
Kí gbogbo ẹni pípé máa ṣògo.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Iwode fun Ochanya ti won ba lopo waye nilu Eko Nitori ọwọja keji ti aarun coronavirus n ba de bayii, ijọba ipinlẹ Kaduna ti kede pe ki gbogbo awọn ileewe titi kan fasiti o wa ni titipa bẹrẹ lati Ọjọru, ọjọ kẹrindinlogun oṣu kejila ọdun 2020.
Mímọ́ ni ojú rẹ, o kò lè wo ibi o kò lè gba ohun tí kò tọ́.
O ni pé àwọn ẹgbẹ́ agbábọ̀ọ̀lù obinrin Nàìjíríà yóó wọ́ ipele tó kángun sí àṣekágbá nínú ìdíjẹ ifé ẹ̀yẹ àgbáyé tawọn obinrin tó n lọ lọ́wọ́ ní France.
Awọn ọba Pelupelu ọhun ni Ajero ti Ijero, Alara ti Aramọkọ, Ewi ti Ado Ekiti, Ogoga ti Ikẹrẹ, Olomuo ti Omuo, Attah ti Ayede, Onitaji ti Itaji, Ọlọyẹ ti Ọyẹ, Arinjalẹ ti Isẹ, Ọlọgọtun ti Ọgọtun, Elemure ti Emure, Alaaye ti Ẹfọn, Ọwa Ooye ti Okemẹsi, Olojudo ti Ido Faboro, Ẹlẹkọle ti Ikọle ati Onisan ti Isan.
Ibèérè ti ọ̀pọ̀ ń bèèrè ni pé, ṣe à ti bori ààrùn náà ni tàbi kò sí àyẹwò bó ti tọ́ àti bóti yẹ mọ́?
Kí Ọlọ́run wà pẹ̀lú àwọn ẹbí, ará àti ọ̀rẹ́ àwọn tí wọ́n pàdánù ẹ̀mí wọn.
Àkọlé àwòrán, Minimum Wage: Owó oṣù òsìṣẹ́ tó kéré jùlọ yòó dí sísan nínú osù kẹ̀sán Ọ̀pọ̀ ìgbà ní ìjọba àti àwọn olórí òṣìsẹ́ ti jà túka lái fẹ́nu ọ̀rọ̀ jọ́nà lórí owó òṣìsẹ́ tó kére jùlọ.
Buhari gẹgẹ bi ohun to ko si inu iwe naa ni ijọba ohun yoo ya gba awọn ọdọ sinu ajọ alasẹ ijọba ati wi pe awọn yoo ya ida márùndínlógójì ninu ida ọgọ́rùn ún ipo ijọba kalẹ fun awọn obinrin.
Bí ìwọ bá ní ìforítì, ìyókù kéré, àsẹ̀hínwá-àsẹ̀hìnbọ̀ ìwọ ń bọ̀ wáá jèrè ohun tí ó ṣe pàtàkì jùlọ lórí ayé, eléyìínì si ni èyí pé, kí olúwaarẹ̀ má ṣe lo ayé ara rẹ̀ fún ara rẹ̀ nìkan, ṣùgbọ́n kí ó lò ó fún àwọn ẹlòmíràn, tó bẹ́ẹ̀ tí, nígbà tí oúwaarẹ̀ bá pa ojú dé, àwọn ọlọgbọ́n kò ní ṣàì máa wí lẹ́hìn rẹ̀ pé, Ọkùnrin náà ṣe ìwọ̀n tí ó lè ṣe.
com Ti o ba ti ṣe bẹ ẹ, lo atanpako rẹ ati ika rẹ keji ti Yoruba n pe ni o dun-un labẹ lati fi fa a sita diẹ ni gongo imu rẹ.
Àwọn ìpànìyàn mánigbàgbé tó wáyé lọ́dún 2018 'Ẹ̀ ń fi ẹ̀wọ̀n run imú o' Ẹ̀yin Olóyè Ibadan mọ́kànlélógún tẹ ń pe ara yin lọ́ba Lórúkọ ìdílé Diya, a gbúdọ̀ ti ẹsẹ̀ òfin bọ ìkú tó mú ọkọ àti ọmọ méjì lọ - Agbẹjọ́rò Àfàìmọ̀ kí Naira Marley má fi ẹ̀wọ̀n bẹ̀rẹ̀ ọdún 2020 Oríṣun àwòrán, Gabriel Afolayan Àkọlé àwòrán, Gabriel Afọlayan, Gfresh Gabriel Afọlayan, Gfresh Ọkan lara awọn ọmọ agba oṣere tiata Yoruba ti o ti doloogbe, Adeyẹmi Josiah Afọlayan, ti ọpọ mọ ni Ade Love ni Gabriel, ti ọpọ mọ si Gfresh.
Aare orile-ede Djibouti ati orile-ede Eritrea pade fun igba akoko lati odun melo kan seyin.
Ninu ọrọ rẹ Ọgagun Musa Etsu-Ndagi sọ pe, Gomina Babajide Sanwo-Olu pe oun lori ago lalẹ ọjọ Isẹgun ti isẹlẹ Lekki naa waye, to si ni ọgagun kan torukọ rẹ n jẹ Bello, ti n yinbọn lu awọn oluwọde ni Lekki.
Yemisi Adeoye Ẹlomiran tun ni Arabinrin Yemisi Adeoye, to ti pe ẹni ọdun marundinlaadọta bayii.
O ní Ori lo tobi ju nínú Ifa, Ọba kìí ṣe ẹgbẹ́ Orisa nítori náà kò tọ̀na láti maa bọ oriṣa nítori ènìyàn gan ju oríṣà lọ.
Lẹ́yìn gbogbo nǹkan wọnyi, Jeroboamu, ọba Israẹli kò yipada kúrò ninu ìwà burúkú rẹ̀.
Buhari àti Abubakar ni afigagbága ìdíje ìbò aré yìí.
Amọsa, minisita feto abo, Dan Ali salaye fawọn akọroyin wipe koko to jẹyọ nibi ipade oniwakati mẹta naa ni awọn ofin massu-maa tọ ti ilẹ Amẹrika gbe kalẹ fun orilẹede Naijiria ki o to lee ta awọn baluu ijagun Super Tucano A29 mejila ati awọn ohun ijagun miran fun ilẹ Naijiria ni miliọnu marundinlẹẹdẹgbẹta dọla, owo ilẹ Amẹrika.
gudu-gudu meje, yaya mẹfa ti won se lasiko eto idibo to waye lorile ede
nígbà náà ni ìbẹ̀rù OLUWA yóo yé ọ.
Ẹ má máa gbèrò ibi sí ẹnikẹ́ni.
Wò ó ọ̀nà láti mú ara rẹ dé ibi tó ga jùlọ nínú ìbálòpọ̀ pẹ̀lú ìlànà Tantra Wo bí o ṣe lè ṣe eré ìdárayá tí yóò fún ọ ní adùn àti okun fún ìbálòpọ̀ Àjọ ọlọpàá Eko kédé pé ìbalòpọ̀ nítà kò bójúmu Bíbéèrè fún ìbálòpọ̀ gbogbo ìgbà sọ ìyàwó ilé dèrò ilé ìwòsàn Dokita Issa Dahabreh ti ile iwosanTufts Medical Center to wa ni Boston, Amẹrika ri ẹri pe irẹwẹsi ọkan a maa ṣe okunfa iku awọn eeyan lasiko ibalopọ.
asa , Lai Mohammed, ti soro idaniloju yii pe awon ẹsọ  eleto aabo yoo sa ipa won lati rii pe awon
Oríṣun àwòrán, Ooni ogunwusi Àkọlé àwòrán, Orukọ oye ọjaja keji ni Ọọni nlo Ọọni Derinọla Ọlọgbẹnla ni Ọọni to jẹ kẹyin ni idile Ọba Giesi ni aarin ọdun 1880 si 1894.
Oyo Coronavirus: Makinde ní kò sí ọwọ́jà Coronavirus ẹlẹ́ẹ̀kejì ní ìpínlẹ̀ Oyo
Awọn alasẹ ọkọ baalu Azman fi ontẹ lu u pe lootọ ni isẹlẹ naa waye, ati wi pe Ajọ to n risi irinkerindo ọkọ ofurufu, NCAA ti fi panpẹ ọba mu obinrin naa fun iwadii kikun.
"Sheikh Othman pari ọrọ rẹ pe ""Adura wa ni pe ki Ọlọrun ba wa dawọ iji arun naa duro."
lara awon to tele igbakeji aare ni Minisita fun eto agbe oloye  Audu Ogbeh; oludari ajo to n mojuto isele pajawiri(National Emergency Management Agency (NEMA), Mustapha Maihaja;ati awon oludari ile-ise ijoba apapo.
Ìwọ kò ṣá ju Jakọbu baba-ńlá wa, tí ó gbẹ́ kànga yìí fún wa lọ, tí òun ati àwọn ọmọ rẹ̀ ati ẹran-ọ̀sìn rẹ̀ sì ń mu níbẹ̀?
Lọjọ Aiku ni wọn bẹrẹ isẹ haji wọn nigba ti wọn pejọ silu Mina.
Nigba ti wọn ka iye ofo to ba wọn, ọkan lara awọn aladugbo naa, Oluwo Alapinni ni awọn eeyan to n ko epo pẹtiroolu pam fun tita lna aitọ lo sokunfa bi ọwọja ina ọhun se di rẹpẹtẹ.
Orúkọ tí a óo máa pè é ni ‘OLUWA ni òdodo wa.
Fagunwa ni ẹẹkan ninu ọdun kan si ni Ojola ibinu naa maa n jade sita, ẹni to sọ pe o ni ori bii ti eeyan.
Champions league: Athletico bomi paná ayọ̀ Juventus ní ìpadàbọ̀ Ronaldo sí ìlú Madrid
Obinrin ohun ní ọpọ nínú wọn ló tí lọkọ ti wọn sì ti bímọ.
Ninu ọrọ rẹ, Olaniyan sọ wi pe ẹru ati ibẹrubojo ma a n fa a ki awọn eniyan ṣe aṣemaṣe lasiko idanwo.
ede yii tun se aseyori ni awon agbegbe Sabon Gari ati Shetimeri  nibi ti won gbe dana sun awon ibudo ti iko
Oyin ní ń kán ní ètè rẹ, iyawo mi,wàrà ati oyin wà lábẹ́ ahọ́n rẹ,òórùn dídùn aṣọ rẹ dàbí òórùn Lẹbanoni.
O gba oye Grand Commander of the Fedral Republic (GCFR) ati ọpọlọpọ oye idalọla mii.
ni ekun Gusu iwo-orun orilede Naijiria ni gbongan ipade ile -itura Golden Tulip
Má kọ orúkọ ẹnikẹ́ni sílẹ̀ bí opó àfi ẹni tí ọjọ́ orí rẹ̀ kò bá dín ní ọgọta ọdún, tí ó sì jẹ́ aya ọkọ kan, 
Awon agbaboolu ninu idije English Premier League pade aare Erdogan nilu London losu ti o koja, eyi ti o mu Gundogan fi ewu igbaboolu iko Manchester City re ranse si aare ohun, ti O si ko “si aare mi” si ewu ohun lara.
Ẹ kò gbọdọ̀ ṣe iṣẹ́ kankan ní ọjọ́ náà, ọjọ́ ìsinmi ni fún OLUWA ní gbogbo ibùgbé yín.
Ibí yìí kò lè jẹ́ ibòmíràn bíkòṣe ilé Ọlọrun, ibí gan-an ni ẹnu ibodè ọ̀run.
Arsenal fidi rẹmi ninu ifẹsẹwọnsẹ kan, bẹẹ ni ni wọn ta ọmi ninu ere bọọlu meji.
Òógùn ojú rẹ̀ dàbí kí ẹ̀jẹ̀ máa kán bọ́ sílẹ̀.
Sáájú àsìkò yìí Tola Adeniyi àti àwọn míràn ti máa ṣe ìpàdé tẹ́lẹ̀.
com/fIvcOiHj2iBi a ko ba gbagbe wipe, iseju  mẹ́tàdínlọ́gọ́rin ni iko Super Eagles gba ami ayo kan soso ti won fi fagba han Burundi ninu ifesewonse akoko, Super Eagles tun se bebe lati gba ami ayo miiran wole niseju  mẹ́tàléláàdọ́rin  lati fi gbo ewuro soju iko Guinea.
Àwọn kan ń sọ pé, “Àwa, ati àwọn ọmọ wa, lọkunrin ati lobinrin, a pọ̀, ẹ jẹ́ kí á lọ wá ọkà, kí á lè máa rí nǹkan jẹ, kí á má baà kú.
Ogbontarigi olorin naa ti o gba ami eye “bongo flava” so fun awon akoroyin wi pe ,oun ri wi pe iwa yi ko bojumu rara gege-bi eni ti awon odo n wo lawokose.
Ikọ Amotekun ko ni gbe ibọn - DAWN commission Oríṣun àwòrán, @DAWNCommission Ọpọ ibeere to ti n jẹyọ nipa ikọ alaabo fun ẹkun Ila Oorun Naijiria ti a mọ si Amotekun ni Ọgbẹni Seye Oyeleye ṣalaye lẹkunrẹrẹ.
Nengi yoo figa gbaga pẹlu Dorathy fun ipo keji, ṣugbọn Ozo to fi ifẹ han si Nengi nigba to si wa nile BBNaija ti rọ awọn ololufẹ rẹ, lati dibo fun Nengi.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Àṣírí tú!
Onkorin omo orile-ede Naijriia, David Adedeji Adeleke  ti awon eniyan tun mo si Davido, ti gba ami-eye “Best International Act ni gbagede BET nilu Los Angeles.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Bí ìrẹsì tèmi Ayinde bá ń pàkùta, kò tọ́ sẹ́nu aláàrù Barrymaade' Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Bi wọn ṣe pari ifẹsẹwonsẹ naa ni adari ajọ to n mojuto ọrọ ere bọọlu ni Egypt, Egypt Football Association (EFA) ti kọwe fipo rẹ silẹ.
’’A o se atileyin si I fun awon agbe.
Ṣùgbọ́n lọ́tẹ̀ yìí ìpò kẹrin ni ìpińlẹ̀ Eko to jẹ́ orírun ààrùn náà ni Nàìjíríà wà ní ipò kẹrin lonìí, nígbà ti Ipinlẹ Plateau wà lókè ténté pẹ̀lú ààdọ́ta ènìyàn.
Nig-Ghana: Ìjọba àpapọ̀ faraya lórí bí Ghana ṣe lé àwọn ọmọ Naijiria padà sílé
Oríṣun àwòrán, @MR_LanreHabeeb Àkọlé àwòrán, Ajọdun Dubar nilu Ilọrin Oríṣun àwòrán, @MR_LanreHabeeb Àkọlé àwòrán, Ajọdun Dubar nilu Ilọrin Oríṣun àwòrán, @onile050 Àkọlé àwòrán, Ajọdun Dubar nilu Ilọrin Bakan naa ni olori ile aṣofin ipinlẹ Kwara, họnọrebu Ali Ahmad pẹlu wa nibẹ.
Coronavirus Updates in Nigeria: Baba Obasanjọ kò ní àrùn Coronavirus
Èdè Yorùbá: Àjọ̀dún àádọ́ta ọdún Ẹgbẹ́ Akọ́mọlédè àti Àṣà Yorùbá Nàìjíríà
L'ọdun yii, o yẹ ki gbogbo rẹ yanju paapa lẹyin ti Boris Johnson wọle gẹgẹ bi Olootu ijọba lasiko idibo gbogboogbo to kọja.
Ibikunle Amosun: Ǹ ó fi ẹgbẹ́ òsṣèlú APC sílẹ̀'
Ẹ̀kúnwọ́ kan yìí ni alufaa yóo sun fún ìrántí, ẹbọ olóòórùn dídùn, tí a fi iná sun sí OLUWA.
 láti oṣù kárùn-ún ọdún 1975 ni ó ti di ara grampian .
Oyeleye ni idasilẹ Amotekun ko le ṣe idiwọ fun eto ọlọpaa agbegbe ti ijọba apapọ fẹ da silẹ.
Bi awọn kan se n ya fọto lai wọ Kọmu ni awọn miran wa soju opo yii lati wa wo aworan awọn obinrin ti ko wọ kọmu.
His legacies will live on and continue to touch many lives and generations to come.
" Amofin Dorothy Njemanze to jẹ Oludari ajọ aṣeranwọ , Dorothy Njemanze foundation tun ṣalaye fun BBC pe awọn fura pe ọrọ naa ti n ni iwa mago-mago ninu ni.
Nigba ti BBC kan si awọn ọlọpaa ni ẹkun yii, wọn ni iwadii ṣi n lọ lọwọ.
Ninu ifọrọwerọ rẹ pẹlu BBC, arabinrin Modupẹ Mujọta ni ijọba ipinlẹ naa ti n ṣe atunto eto abo lawọn ileewe rẹ gbogbo lẹyin isẹlẹ naa."
Èmi Paulu ni mò ń fi ọwọ́ ara mi pàápàá kọ ìwé yìí.
Ta wọ́n nù nítorí ọ̀pọ̀ ìrékọjá wọn,nítorí pé wọ́n ṣọ̀tẹ̀ sí ọ.
'Adùn ni fún mi kí ń ran ìyàwó mi lọ́wọ́' Orí kó Ààrẹ yọ lọ́wọ́ àdó olóró Kí lẹ ò mọ̀ nípa àwọn obinrin Yollywood yìí?
Ekeji dé, ó ní, ‘Alàgbà, mo ti fi owó wúrà rẹ pa owó wúrà marun-un.
OLUWA sọ fún Mose ní Midiani pé, “Pada lọ sí Ijipti, nítorí pé gbogbo àwọn tí wọn ń lépa ẹ̀mí rẹ ti kú tán.
Ìwadìí ti bẹ̀rẹ̀ lórí àrá tó sán pa òṣìṣẹ́ FRSC mẹ́ta nípínlẹ̀ Ogun- Ọ̀gá àjọ FRSC Ohun tí a mọ̀ nìyí nípa ìròyìn Ajimobi kú, kò kú, táyé ń gbé kiri Yẹ̀kínì kan kò lè yẹ ipinnu wa láti ṣí iléèwé pàda lóṣù yí - ìjọba ìpínlẹ̀ Oyo Invictus Obi, Hushpuppi, àwọn ọ̀dọ́ Nàìjíríà méjì tí ẹ̀sùn gbájúẹ̀ wà lọ́rùn wọn Ọjọru ọjọ kẹtadinlogun oṣu kẹfa ọdun 2020 ni wọn ṣe eto aṣalẹ orin onigbagbọ fun oloogbe naa.
Eeyan 47,743 ni apapọ ni arun naa ti fara kan labẹ ayẹwo, ti awọn 33,943 si ti ri iwosan gba lọwọ ajakalẹ arun ọhun.
Adajọ agba Naijiria, Adajọ Tanko Muhammad lo pa aṣẹ naa lẹyin ti awọn oniṣẹ aabo ko lee kapa aduru ero to wa nibẹ ati ariwo pupọ ninu ile ẹjọ.
Gbogbo Igba lo maa n ni ọna abayọ si ọrọ to ba n ru ni loju, o sọ eyi fun ọkọ rẹ.
Ó ní ìloro kan tí wọ́n kọ́ sórí òpó; wọ́n ta nǹkan bò ó lórí.
Gbogbo nǹkan yòókù tí Amasaya ṣe ni a kọ sinu Ìwé Ìtàn Àwọn Ọba Juda.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ooni: Mo ti fi ọ̀rọ̀ obinrin tó ń parọ́ ìfẹ́ mọ́ mi sun agbófinró Arabinrin Elizabeth Ọdunlami ni okiki kan lori iroyin kan to fi si ori itakun facebook rẹ pe oun ati Ọọni ni adehun lati fẹ ara wọn pẹlu ẹsun pe kabiyesi naa ti fi orukọ oun ṣe ọpọlọpọ idundura okoowo.
Fi mí sílẹ̀, jẹ́ kí n pa wọ́n run, kí n sì pa orúkọ wọn rẹ́ kúrò láyé.
Bí a bá sọ pé, ‘Láti ọ̀dọ̀ eniyan ni,’ gbogbo àwọn eniyan yóo sọ wá ní òkúta pa, nítorí wọ́n gbà dájú pé wolii ni Johanu.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Brexit: Theresa May yóò ṣèpàdé pẹ̀lú àwọn olórí EU láti dóòlà ìpinnu rẹ̀ 11 Ọ̀pẹ̀̀ 2018 Oríṣun àwòrán, Reuters Àkọlé àwòrán, May yoo kọkọ jiroro pẹlu Olootu ijọba orilẹede Netherlands, Mark Rutte Olootu ijọba orilẹede United Kingdom, Theresa May yoo ṣapade pẹlu awọn olórí àjọ iṣọkan ilẹ Yuroopu, EU ni Ọjọ Iṣẹgun fun ijiroro lati doola igbesẹ ti yoo yọ orilẹede Britain kuro ninu ajọ naa.
Bo ti lẹ jẹ pe Super Falcons ja kulẹ ninu ifẹsẹwọbnṣẹ wọn pẹlu France, wọn ṣi ni anfani lati wa lara awọn ikọ mẹrindinlogun akọkọ ti wọn si tun le gbe ipo kẹta.
Mò bẹ̀ wọ́n kí wọ́n bá mi rẹ́ ata rodo sórí Pizza mi o jàre.
com/Cekbd0G7MbNi bayi, ipo kẹfa ni Chelsea
adari awon obinrin ninu egbe APC, Salamatu Eluma, o wa tun  gbosuba fun awon to farajin yii fun
O ṣeleri lati ri si itọju awọn obinrin, ati lati mojuto eto ilera awọn ewe sii.
"A n ṣe gbogbo iranwọ ati itọju fun oṣiṣẹ naa, a o si f'ọwọsowọpọ pẹlu awọn alaṣẹ lori iwadi wọn.
lo gba alejo ogagun Dambaza lasiko abewo re.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 2020: Oloye Awurela Ifaleke ti wúré ọdún ìgbéga fún kóówá Ilu gangan ni ọrọ naa, nitori bayiìí kọ lo ṣe koju si lọ́dọ́ Darfamola Adewale to ni bí ìrẹsi tiwantiwa ko ba di ẹgbẹ̀run mẹ́sàn an ki wọn kuku ṣi ẹnu bode pada Oríṣun àwòrán, Tweet Àkọlé àwòrán, Ẹ̀kọ́ ọ̀fẹ́, ètò iléra ọ̀fẹ́ àti iná ọba lo jé wá lo jẹwa lógu Olori Yemisi nítirẹ̀ ní kò si ǹkan ti ọmọ Naijiria le kọ ti yòó ni ìtumọ si ààrẹ, O ni ọ̀rọ̀ ààrẹ dabi eleti kan to n ṣe òkú ìyá rẹ̀ ni, tí wọ́n ba n pee níbi ounjẹ yóò ma a lọ si ọ̀dọ̀ olorin.
OLUWA ní kí Mose ati Aaroni 
 O rọ awọn ara ilu naa ki wọn ri wi pe wọn mu imọtoto wọn lokunkundun."
Iroyin sọ pe ni ilu Venice ni ọmọ ọkunrin naa ti n gba ilẹ adugbo ti igbimọ alaṣẹ to wa nibẹ si ni ko gba aṣẹ ko to maa gba a.
Ohun ti awọn kan fẹ ni iru erongba yi sugbọn gẹgẹ bi a ti ṣe sọ saaju, ẹnu lasan ko ni le ṣe ni orileede Naijiria nibi ti awọn ẹgbẹ oselu bi PDP ati APC ti fẹsẹ rinlẹ gidigba.
Àwọn iranṣẹ tẹmpili nìwọ̀nyí: àwọn ọmọ Siha, àwọn ọmọ Hasufa, ati àwọn ọmọ Tabaoti, 
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Wo àwọn orílẹ̀èdè tí wákàtí ààwẹ̀ wọn gùn ju ti Nàìjíríà lọ 6 Èbibi 2019 Àkókò: Oòrùn ràn: :Oòrùn ràn Oòrùn wọ̀: :Oòrùn wọ̀ Afghanistan Australia Brazil Canada Chile China Egypt France Greenland Iceland India Indonesia Kenya Libya Morocco Nigeria Russia Saudi Arabia Senegal South Africa Tanzania UK USA Àkókò: Oòrùn ràn: :Oòrùn ràn Oòrùn wọ̀: :Oòrùn wọ̀ Àkókò: Oòrùn ràn: :Oòrùn ràn Oòrùn wọ̀: :Oòrùn wọ̀ Afghanistan Àkókò: 15hrs 31mins Oòrùn ràn: 04:45 Oòrùn wọ̀: 18:55 Australia Àkókò: 11hrs 25mins Oòrùn ràn: 06:46 Oòrùn wọ̀: 16:58 Brazil Àkókò: 11hrs 57mins Oòrùn ràn: 06:37 Oòrùn wọ̀: 17:29 Canada Àkókò: 17hrs 2mins Oòrùn ràn: 05:15 Oòrùn wọ̀: 20:28 Chile Àkókò: 11hrs 25mins Oòrùn ràn: 07:33 Oòrùn wọ̀: 17:46 China Àkókò: 16hrs 11mins Oòrùn ràn: 04:51 Oòrùn wọ̀: 19:30 Egypt Àkókò: 15hrs 5mins Oòrùn ràn: 04:57 Oòrùn wọ̀: 18:47 France Àkókò: 17hrs 44mins Oòrùn ràn: 05:59 Oòrùn wọ̀: 21:37 Greenland Àkókò: 20hrs 48mins Oòrùn ràn: 03:44 Oòrùn wọ̀: 23:06 Iceland Àkókò: 20hrs 47mins Oòrùn ràn: 03:46 Oòrùn wọ̀: 23:06 India Àkókò: 14hrs 58mins Oòrùn ràn: 05:26 Oòrùn wọ̀: 19:10 Indonesia Àkókò: 12hrs 50mins Oòrùn ràn: 05:55 Oòrùn wọ̀: 17:44 Kenya Àkókò: 13hrs 17mins Oòrùn ràn: 06:27 Oòrùn wọ̀: 18:32 Libya Àkókò: 15hrs 48mins Oòrùn ràn: 06:03 Oòrùn wọ̀: 20:05 Morocco Àkókò: 15hrs 28mins Oòrùn ràn: 05:21 Oòrùn wọ̀: 19:28 Nigeria Àkókò: 13hrs 29mins Oòrùn ràn: 06:30 Oòrùn wọ̀: 18:57 Russia Àkókò: 18hrs 35mins Oòrùn ràn: 04:04 Oòrùn wọ̀: 20:50 Saudi Arabia Àkókò: 14hrs 38mins Oòrùn ràn: 05:06 Oòrùn wọ̀: 18:34 Senegal Àkókò: 14hrs 12mins Oòrùn ràn: 06:40 Oòrùn wọ̀: 19:34 South Africa Àkókò: 11hrs 50mins Oòrùn ràn: 06:43 Oòrùn wọ̀: 17:26 Tanzania Àkókò: 13hrs 3mins Oòrùn ràn: 06:39 Oòrùn wọ̀: 18:29 UK Àkókò: 18hrs 1mins Oòrùn ràn: 04:57 Oòrùn wọ̀: 20:58 USA Àkókò: 15hrs 29mins Oòrùn ràn: 05:46 Oòrùn wọ̀: 19:54 Kókó ọ̀rọ̀: Wíwo àkókò dá lórí olú ìlú orílẹ̀èdè kọ̀ọ̀kan Orísun: aladhan.
Ìfihàn tí a fi fúnni nípasẹ̀ Wolíì Joseph Smith sí David Whitmer, ní Fayette, New York, Oṣù Kẹfà 1829.
Bẹ́ẹ̀ ni wọ́n ṣe takété sí ara wọn.
6 billion naira ) ko ti ni ipa gbogi lara biliọnu 116,100,000,000.
Oríṣun àwòrán, Olu Alebiosu Àkọlé àwòrán, Nǹkan méjì ló so Ẹrin Ijesa, Ọ̀ṣun Oṣogbo gẹ́gẹ́ bíi ibùdó ìgbafẹ́, ó sì yẹ kí o mọ̀ nípa rẹ̀ Ko si bi a ṣe lee sọ itan Ọdun Ọṣun Oṣogbo lai mẹnu ba arabing ọmọ orilẹede Austria ni, Susanne Wenger ti ọpọ mọ si Adunni oloriṣa.
Ó dá mi lóju’pé bí òṣìkà ti ń bọ̀ wáá kèrè ìkà, bẹ́ẹ̀ náà ni ẹni rere ń bọ̀ wáá jèrè ohun rere.
Ọjọ́ keje yìí nìkan ṣoṣo ni wọ́n yípo rẹ̀ lẹẹmeje.
 olúwo ni olórí àwọn ògbóni .
N óo rẹ̀ yín lẹ́kún bí ọmọ tí ìyá rẹ̀ rẹ̀ lẹ́kún,bẹ́ẹ̀ ni n óo ṣe tù yín ninu ní Jerusalẹmu.
Ó sọ fún ọba pé: “Kabiyesi, mo ti rí ọkunrin kan ninu àwọn tí wọ́n kó lẹ́rú wá láti Juda, tí ó le túmọ̀ àlá náà fún ọba.
Wọn ni eyi ti awọn ẹru ti awọn gba lọwọ awọn to'n ta ogun oloro naa se lọdọ awọn to gee ki ẹnikẹni to ba mọ awọn to ni ẹru naa sọfun wọn pe ki wọn wa gbẹẹru wọn.
Àkọlé àwòrán, South Africa niṣẹ lati ṣe Bakan naa ni arakunrin naa sọ pe ohun to janilaya ni iṣẹlẹ naa.
Oríṣun àwòrán, AFP Mba wa rawọ ẹbẹ sawọn araalu lati gba alaafia laaye, nitori ileesẹ ọlọpaa ko ni segbe sẹyin igun kankan amọ yoo ri daju pe idajọ ododo fẹsẹ mulẹ lori isẹlẹ naa.
 bó ba rí bẹ ́ ẹ ̀ á jẹ ́ pé ìlú Ẹ ̀ fọ ̀ n tí wá kí modákẹ ́ kẹ ́ tó dáyé .
A Adamu kede pe ileesẹ ọlọpa ti n finmu finlẹ lori isẹlẹ naa lati se awari awọn ọbayejẹ ẹda to sisẹ laabi naa, ti wọn yoo si fi imu wọn ko ata ofin.
Oga ile ise asobode fun ekun ipinle  Oyo/Osun, Abdullahi Zulkifli ti salaye  pe idi ti awon se da eka to wa ni agbegbe
pe awon yoo tun gbiyanju lati  jẹ ki iye
Nebukadinesari ọba Babiloni pàṣẹ fún Nebusaradani olórí àwọn ẹ̀ṣọ́ pé 
Igbesẹ naa ti bẹrẹ lati ọdun 2016 nilẹ Gẹẹsi, ti wọn si ti pinnu pe awọn yoo kuro.
Jesu dá wọn lóhùn pé, “Mo fẹ́ kí ẹ mọ̀ dájúdájú pé, kì í ṣe nítorí pé ẹ rí iṣẹ́ ìyanu mi ni ẹ ṣe ń wá mi, ṣugbọn nítorí ẹ jẹ oúnjẹ àjẹyó ni.
Òkèlè wo ló dára jù láti fi jẹ ọbẹ̀ yìí
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Shehu Sani: Àwọn gómìnà ẹgbẹ́ APC l'ágbara ju Buhari lọ Ọ̀pọ̀ ẹ̀mí sọnù sínú ìjàmbá ọkọ̀ ojú'rin lásìkò tí wọ́n n wòran ọdún Bakan naa lawọn alaṣẹ ti fi ofin konile-o-gbele sita nibẹ.
Sabudu, ọmọ Natani, ni alufaa ati olùdámọ̀ràn fún ọba.
Ajọ Eto Ilera Lagbaye, WHO ti pe akiyesi awọn eniyan si ipa ti aisan jẹjẹrẹ n ko lawujọ, pẹlu akiyesi pe miliọnu mẹjọ eniyan ni yoo ku lọdun yii nipa aisan jẹjẹrẹ.
Wọn ni eyi yẹ lori fidio kan to jade ninu eyi ti o ṣafihan sẹnetọ naa to n lu obinrin kan nilu Abuja.
DSTV Price Hike: Ọmọ Nàìjíríà faraya lórí èlé owó DSTV tó ń wáyé ní ẹ̀ẹ̀kan lóṣù mẹ́rin
Makinde ṣe agunbanirọ ni ile iṣẹ epo Shell lọdun 1990, lati ibẹ
Ọbẹ̀ tó dùn, Owó ló pá: Àwòrán àti pi pè Èlò Ọbẹ̀
Mo wọ̀ ọ́ ní aṣọ funfun, mo sì dá ẹ̀wù siliki fún ọ.
Àwọn mejeeji ń rìn déédé níwájú Ọlọrun, wọ́n ń pa gbogbo àwọn àṣẹ ati ìlànà Oluwa mọ́ láì kùnà.
Àkọlé àwòrán, ìfọ̀rọ̀wérọ̀ BBC Yorùbá l'Ọyọ Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Oòrùn yóo ṣókùnkùn, òṣùpá yóo di ẹ̀jẹ̀,kí ó tó di ọjọ́ ńlá tí ó lókìkí, ọjọ́ Oluwa.
Èyí èkejì kọ́ jókòó nígbà tí a wọ ibẹ̀ ṣùgbọ́n lẹ́hìn eléyìí ó dìde, lẹ́hìn èyìínì pẹ̀lú ó ń sáré káà kiri inú ilé, lẹ́hìn eléyìínì ó ń rìn, lẹ́hìn èyí pẹ̀lú ó tún jòkòó, ara rẹ̀ kò sì balẹ̀, ó dà bí ẹni tí ń bẹ̀rù ohun ńlá kan.
Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Regent female kings: Wo àwọn Adelé-Ọba aládé méje tó jẹ́ obìnrin nílẹ̀ Yorùbá15 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 NÍ YÀJÓYÀJÓ Coronavirus in Nigeria: Ọ̀gágun sọ́jà méjìdínlógún kó covid-19 lẹ́yìn tí coronavirus ṣekúpa akẹgbẹ́ wọn l'Abuja Tinubu 2023: Àwọn èèkàn ilẹ̀ Yorùbá ń ṣèpàdé ṣáájú dídìbò fún Tinubu ní 202315 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Fídíò, Fuji Music: Kollington Ayinla sọ ẹni tó dá orin Fuji sílẹ̀ gan an ní Nàiìjíríà16 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
6 Ẹrẹ̀nà 2020 Oríṣun àwòrán, Others Ki agbado to daye, nkankan ni adiẹ n jẹ, ki itakun agbaye si to de, eyi tawọn ọdọ fi n se ere idaraya lode oni, ni ọpọ ere idaraya ti wa nilẹ Yoruba, tawọn ọmọde n se.
Gani Adams ni ipade apero kan n bọ laipẹ 'Yoruba Summit', ti gbogbo ẹgbẹ to ni nkan ṣe pẹlu aato aabo yoo ti jiroro lori eto aabo.
” Nígbà tí Benhadadi dé, Ahabu ní kí ó wọ inú kẹ̀kẹ́ ogun pẹlu òun.
Laarin awọn akẹgbẹ rẹ nile aṣofin, ọpọ lo ma n fi oju ọlọgbọn wo Gbajabiamila, ti wọn a si ma bọwọ fun, nipa bo ti ṣe ma n se agbekalẹ ọrọ rẹ.
Orúkọ Àwọn Alufaa ati Àwọn Ọmọ Lefi.
Oríṣun àwòrán, Others Amọ, Agbẹnusọ awọn ọlọpaa ni ipinlẹ Ondo naa wi pe awọn ọlọpaa kaakiri ni Naijiria n ṣiṣẹ takuntakun lati ri i pe eto aabo to nipọn wa kaakiri awọn ipinlẹ ni Naijiria.
Iṣẹlẹ naa to wayẹ ni aago mejila ọsan ni o da ipaya silẹ ni gbogbo agbeegbe naa ti awọn eniyan si sa asala fun ẹmi wọn.
Osu Kẹwaa, ọdun 1919 ni Olabode Thomas de ile aye, iyẹn lẹyin ọdun marun un ti baba Naijiria, Lord Lugard so ẹkun ariwa pọ mọ guusu, ti wọn si di Naijiria kansoso Olokoowo to gbajugbaja nilu Eko ni Andrew Thomas ati iyawo rẹ ti wọn jẹ obi Bode Thomas, ilu Ọyọ Alaafin ni wọn si ti wa sisẹ aje nilu Eko.
Àkọlé àwòrán, Awọn ọmọ Nàìjíríà bá aarẹ Buhari sọ̀rọ̀ lójú òpó BBC lórí ètò ààbò ìlú Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, #Queen Dihya: Obinrin tó gbógun tàwọn agbésùnmọ̀mí ni Algeria Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
”Nítorí pé ó fi gbogbo nǹkan wọnyi sí ìkáwọ́ rẹ̀, kò ku nǹkankan tí kò sí ní ìkáwọ́ rẹ̀.
Amọ obinrin naa ṣalaye pe, Salisu gan lo kọkọ yọ ọbẹ jade, ki oun to gba ọbẹ naa lọwọ rẹ ṣugbọn oun ko mọ pe igbesẹ ọhun ko ni bimọ ire.
Ìjọba Ológun àkọ́kọ́ ni abẹ́ Olóògbé Ọ̀gágun Aguiyi Ironsi, da gbogbo ipinlẹ̀ pọ si abẹ́ Ìjọba àpapọ̀.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Wòlíì Kasali sọrọ nípa awuyewuye pé o lè ìyàwó rẹ̀ jáde nílé Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Òun ati àwọn ará ilé rẹ̀ gba ìrìbọmi.
A ti gbọ́ ìròyìn ìgbéraga Moabu,bí ó ṣe ń ṣe àfojúdi tí ó sì ń sọ ìsọkúsọ:ṣugbọn lásán ni ìgbéraga rẹ̀.
Ẹwẹ, mẹrindinlogoji ninu mọkandinlọgọrin isẹlẹ yii ni wọn ti ni aridaju rẹ pẹlu iwadii nile iwosan to fi mọ eniyan mẹsan toku bayii.
Awọn eeyan yii ko sọ ireti nu lori idibo, wọn si duro lati ki igbakeji olori igbimọ ologun kaabọ Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Haa, wahala de.
 yorùbá tún bọ ̀ wọ ́ n ní ẹni tí sàngó bá tojú rẹ ̀ jà rí kò ní báwọn bú olúkòso .
Ẹwẹ, bi a ba gbe e yẹwo laarin gbogbo awọn ti igba iwa yii n ṣi mọ lori pẹlu iṣọri wọn lawujọ, yala agbalagba oloṣelu tabi ọdọ,awọn ti ko ṣe oṣelu lo wọpọ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ọba Abdulrasheed Akanbi rọ àwọn Ọba aláde yoruba láti dẹ́kun ẹgbẹ́ òkùnkùn síṣe 12 Òkùdu 2019 Oríṣun àwòrán, emprotelu1 Àkọlé àwòrán, Ọba Abdulrasheed Akanbi rọ àwọn ọba aláde yoruba láti dẹ́kun ẹgbẹ́ okunkun síṣe Olúwo ti ìlú Iwo Oba Abdulrasheed Akanbi ti ké si àwọn Ọba aládé ní gbogbo ilẹ̀ Káàrọ oò-jííre láti kúrò nínú ẹgbẹ́ òkùnkùn ti wọ́n ń ṣe.
Ọ̀dọ̀ Ẹ̀mí kan ṣoṣo ni gbogbo ẹ̀bùn wọnyi ti wá; bí ó sì ti wù ú ni ó pín wọn fún ẹnìkọ̀ọ̀kan.
Mo ri Alaafin àti Awùjalẹ̀ gẹ́gẹ àwọn tí wọ́n ni ìgboyà.
Ó jọba fún ọdún mẹtadinlogun ní Jerusalẹmu, ìlú tí OLUWA yàn láàrin àwọn ẹ̀yà yòókù, pé kí wọ́n ti máa sin òun.
Nítorí ti Sarai, Farao ṣe Abramu dáradára.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù FIFAWWC -Ọ̀rọ̀ ti yanjú dé ibì kan lórí owó àjẹmọ́nú àwọn Super Falcons 23 Òkùdu 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ko si iṣẹ ajé tó rọrun ni ọrọ awọn Super Falcons Awọn agbabọọlu obinrin Naijiria joye Akintọla taku ni France.
Dídógùn-ún wọn ni yóo jẹ́ ẹ̀rí fun yín, nítorí yóo jẹ ara yín bí ìgbà tí iná bá ń jó nǹkan.
Iroyin to ni leti wipe bi Ọọni Ifẹ se pari ọrọ idupẹ tan ti o npada lọ si aye rẹ ni olori ẹsọ rẹ ni wọn sọ wipe ọgbẹni Emmanuel Ọlawale Kọlawọle to dari awọn ẹsọ to ku fara gba Oluwo to da bi ẹni pe o ndi Ọọni lọna ati lọ jokoo si aye rẹ.
Eyi ko si nii fi ṣe irufẹ ẹgbẹ oṣelu to ba wa ni ijọba bikoṣe ka ni ifọwọsowọpọ lagba BBC News, Yorùbá Ìdí tí ẹ fi le è nígbàagbọ́ nínú ìròyìn BBC Ìlànà Lílò Nípa BBC Òfin Àṣírí Cookies Kàn sí.
Bí ó ti ń sọ̀rọ̀ lọ́wọ́ ni Natani wolii wọlé.
Ṣugbọn o ni awọn akẹgbẹ oun lo ni ko lọ ṣe ayẹwo ti esi rẹ si jade lọjọ to gbẹyin ninu oṣu kẹfa eyi to fi han pe o ti lugbadi rẹ.
OLUWA Ọlọrun rẹ gbọ́, pé ọba ti wá ọ káàkiri gbogbo orílẹ̀-èdè ayé.
Lojiji ní ọkan lára àwọn tó ń tójú àyíka ke gbàjare lẹ́yìn to lọ toju ọkọ̀ bàálu ti yóò rin ìrìn ajo ọhun.
Dafidi pàṣẹ fún gbogbo àwọn àgbààgbà Israẹli pé kí wọ́n ran Solomoni, ọmọ òun lọ́wọ́.
Kí ni Toyin Abraham ń sọ lórí àrùn Coronavirus ná?
Oniruuru awọn aarẹ orilẹede Afirika ni o ti ṣiṣẹ fun gẹgẹ bii olubadamọran ptataki.
bíi 17 sí 25 mílíọ ́ nù àwọn ènìyàn ni o ní àkóràn jìgá , pẹ ̀ lú ìdá bíi 0.
Bí o bá fẹ́ darapọ̀ mọ́ ikọ̀ ọlọ́pàá SWAT tí yóò rọ́pò SARS, wo àmúyẹ tí o gbọ́dọ̀ ní Oríṣun àwòrán, PMNews Lẹyin ti ọga ọlọpaa patapata lorilẹede Naijiria wọgile ikọ SARS gẹgẹ bi ara ipe awọn ọdọ to n wọde fun fifi opin si iwa aṣemaṣe ikọ naa ati ileeṣẹ ọlọpaa lapapọ, ikọ tuntun ti wọn fẹ da silẹ yoo bẹrẹ igbaradi ni ọjọ Aje.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, John Amanam: Ìfẹ́ tí mo ní sí àbúrò mi ló sọ mi dí ẹni tó ń ṣe 'Prosthetic' báyìí Kini o ti kọkọ ṣẹlẹ sẹyin: Gómìnà Sanwo-Olu dẹ okùn ìséde l'Eko, ó gbé ìlànà tuntun jáde: Aago mẹ́wàá alẹ́ sì mẹ́fà àárọ̀ ni ìséde yóò ma wáyé Ijọba ipinlẹ Eko tun ti dẹ ọwọ okun ofin konile o gbele to n waye nipinlẹ Eko.
Olόwό-Ìbínú fẹ́ obìnrin yìí nítorí ό rò wí pé tí àwọn àna òun bá kú, owó-o wọn yόò di ti òun ni.
Ọmọ ogun Nàìjíríà bẹ̀rẹ̀ lílo 'Drone' láti gbógun tàwọn ajínigbé ni Ondo àti Ekiti Dagunro ní ìtẹríba, tó sì ń gbé àṣà lárugẹ - Ọ̀gá Bello Ọ̀nà márún-ún láti mú àdínkù bá dátà (Data) lílò rẹ Fowler kò sí lábẹ́ ìwádìí kankan-Garba Sheu Oladele tesiwaju wí pé, ó wá nínú ẹ̀kọ́ tí wón ń kó gbogbo oṣiṣẹ FRSC pe wọn ko gbọdọ gba riba lọwọ ẹnikẹni.
Ko da awọn eekan ninu ẹgbẹ PDP gbadura fun un bi wọn ti fi kaadi ọmọ ẹgbẹ le e lọwọ.
Àwọn Dókítà eyín náà wà nínú ewu yìí nítorí irú isẹ́ wọn.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: PDP: A ò fẹ́ ẹ̀jẹ̀ Buhari gẹ́gẹ́ bí alábojútó ìbò kíkà Toyin Abraham jọ̀wọ́ dáríjì mí - Yomi Fabiyi Ilé ẹjọ́ fagilé ìpè Dino láti wá kó Ọlọ́pàá kúrò nílé rẹ̀ Iya Rainbow, Jide Kosoko, Ọga Bello, yóò polongo Buhari fún 2019 Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ìgunnukó: Àwọn Tápà gbà pé ẹni tó bá ń sin Ìgunnukó kò ní ráùn ohun rere Minisita fun eto irina naa fikun wi pe, oun n pada bọ fun ayẹwo oju irin naa ni Ọjọ Kẹrinla, Osu Kini, ọdun 2019, lati ri daju pe won ti pari ọna naa.
Àkọlé àwòrán, Olanipekun ni iye awọn to pegede ninu esi idanwo naa ni Ọkunrin jẹ 389, 655 (ida 47.
O wipe ijiya t'o tọ wa fun ọlọdẹ naa, pẹlu alaye wipe ijọba ipinlẹ Ondo ti n ṣ'eto aabo t'o peye fun agbegbe naa.
Wọn kò gbọdọ̀ jẹ́ onísọkúsọ tabi ẹrú ọtí.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Yahaya Jammeh: Obìnrin mẹ́ta ọ̀tọ̀ọ̀tọ̀ fẹ̀ṣùn ìfipábánilòpọ̀ kan ààrẹ Gambia 26 Òkùdu 2019 Oríṣun àwòrán, Fatou Jallow Àkọlé àwòrán, Fatou Jallow sọ pe oun sa kuro ni Gambia lẹyin ti aarẹ fi ipa ba a lopọ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù US election 2020 polls: Taa ló ń léwájú- Trump tàbí Biden?
Minisita fọ́rọ̀ ilẹ̀ òkèèrè kọ̀wẹ́ fipò sílẹ̀ Ileẹjọ pasẹ igbejọ ọtọ fun Nnamdi Kanu Áfíríkà yóò gba ife ẹ̀yẹ UEFA Champions league lónìí Wọ́n ti ni kí àwọn alága ìjọba ìbílẹ̀ Ogun lọ rọọ́kún nílé Loṣu kẹwaa, ọdun 2015 ni NCC bu owó itanran to le ni tiriliọnu kan naira fun ileeṣẹ MTN.
Nigeria Army: Bàbá Adamu tó jẹ́ ọmọ ogun Nàìjíríà tó dàgbà jùlọ jáláìsí
Ni gbogbo igba ti mo ba wo o to n rẹrin, to si n mu ọmọ mii rẹrin maa n fun mi layọ.
nipa bi aaare orile ede Naijiria Muhamadu Buhari yoo se  yan awon alakoso ti yoo maa baa se isẹ papọ ,
Má jẹ́ kí òdodo rẹ pọ̀ jù, má sì gbọ́n ní àgbọ́njù; kí ni o fẹ́ pa ara rẹ fún?
Laye ode oni ni oju awọn eniyan tun ṣẹṣẹ n ṣí si wiwa kẹkẹ pada.
Pẹ̀lú abẹ̀rẹ̀ àjẹsára yìí, ẹ̀fọn kankan kò lè mú àìsàn ibà wá Ninu ọrọ rẹ, Soyinka ni ''mo fi oni we igba ti a n d'agba, ti ọpọlọpọ wa lọ kawe nilẹ okeere, nigba ti gbogbo wa sare pada sile lẹyin ti a kẹkọọ nilẹ okeere.
Iroyin naa sọ pe baalu ayara fefe ẹlikọpita ni wọn fi gbe kuro ni abule Loko ti wọn fi pamọ si lati ọjọ Aje.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Akomolede àti Asa lórí BBC Yorùbá: Mọ̀ síi nípa ẹ̀kún ìyàwó níbí Gomina Wike ni nkan ti oun sọ ni pe ki awọn eleto aabo ri i daju pe wọn fidi ofin to de IPOB mulẹ, ati lati ri i pe ko si ikorajọpọ awọn ọmọ ẹgbẹ naa ni gbogbo ijọba ibilẹ to wa nipinlẹ Rivers.
Ní ọdún 2014, àwọn òǹkọ̀wé ọmọ bíbí Ethiopia mẹ́sàn-án lọ sí ẹ̀wọ̀n àti jìyà oró látàrí iṣẹ́ àjọṣepọ̀ tí wọ́n jọ kọ nípa ìtẹsẹ̀ àgẹ̀rẹ̀ sí ẹ̀tọ́ ọmọ-ènìyàn ìjọba àná ìlú Ethiopia, kí òótọ́ ó di mímọ̀.
Gold Kolawole, ọmọ tó sọnù ní ṣọ́ọ́ṣì Sotitobire kò bá pé ọdún méjì ni 12/09/2020 Kọlọrun jẹ ki abiyamọ o jeere ọmọ.
Bí ó ti ń lọ, àwọn iranṣẹ rẹ̀ wá pàdé rẹ̀, wọ́n wí fún un pé, “Ọmọ rẹ ti gbádùn.
Nígbà tí Mose bá gbé ọwọ́ rẹ̀ sókè, àwọn ọmọ Israẹli a máa borí àwọn ará Amaleki, nígbà tí ó bá sì rẹ ọwọ́ sílẹ̀, àwọn ará Amaleki a máa borí àwọn ọmọ Israẹli.
“Ọjọ́ ayé mi ti dópin, èrò ọkàn mi ti dàrú,àwọn ohun tí ọkàn mi ń fẹ́ sì ti di asán.
 O tun so pe, ibudo Tumbun Rego ti ko jina siluu Maiduguri, je ibudo pataki ti ipade awon omo ogun olote ohun ti ma n waye.
Àwọn ọmọ-ogun ẹlẹ́ṣin bá a lọ sí Kesaria.
 Buhari ti tun ti  jawe olubori ni awon ipinle  Ekiti ati Osun bakan naa.
Ní ọjọ́ kẹrinlelogun oṣù kẹsan-an, ní ọdún keji ìjọba Dariusi, OLUWA sọ fún wolii Hagai pé, 
Ẹ̀rù tí ó wà lára rẹ, ati ìgbéraga ọkàn rẹ ti tàn ọ́ jẹ,ìwọ tí ò ń gbé pàlàpálá àpáta,tí o fi góńgó orí òkè ṣe ibùgbé.
Gomina Ọbaseki sọ wipe ijọba yoo gba orukọ awon asaaju Fulani silẹ ni gbogbo agbegbe to wa nipinlẹ naa ati wipe, awọn Seriki Fulani naa ni wọn yoo maa ba gbogbo darandaran sọrọ l'agbegbe wọn.
Alakoso ajọ Nibucaa, Gbenga Alabi naa tun  so pe ifọwọsowọpọ awon ile-ise aladaani pelu  ijoba lati gbogun ti aarun kogboogun se pataki pupo nitori pe ọwọ kan ko gberu dori.
    Mo tún dìde ní òwúrọ̀ ọjọ́ kejì, ó di ilé Ìbínú ẹkùn.
Nítorí náà a rán Juda ati Sila, láti fẹnu sọ ohun kan náà tí a kọ sinu ìwé fun yín.
Kí ló ń sọ ọmọ Nàìjíríà d'èrò ilẹ̀ òkèrè tí ìjọba kò ronú sí?
Ajọ UN to ni ko to di ọdun 2050, eniyan to le ni billiọnu mẹsan ni yoo ma rin loke eepẹ, fikun wi pe, iyẹfun ti wọn fi kokoro ati aayan se dara fun eniyan, nitori eroja protein to pọ lara rẹ ju ti awọn eranko lọ.
Bo tilẹ̀ jẹ́ pé Toke Makinwa sọ gbogbo ǹkan wọ̀nyi, o fi kun un pé elòmíran ko ba ti maa bugi jẹ bayii ti kìí ba ṣe pe àwọn obi rẹ̀ o buru mọ ọ.
 nítorípé bẹ ́ rílíọ ̀ mù yíówù tó bá jẹ ́ kíkódájọpọ ̀ ní inú àwọn ìràwọ ̀ kì í pẹ ́ tí ó fi túká , nítoríẹ ̀ ó jẹ ́ ẹ ́ límẹ ̀ ntì tó sọ ̀ wọ ́ n gidigidi ní àgbàlá-ayé ati ní ilẹ ̀ -ayé .
Nibo ni Meghan yoo bimọ si?
Orisirisi ijamba lo ti n waye nipinle Florida lati odun melo kan seyin, ti o fi mo ijamba ti o waye ni gbagede igbafe ale niluu Orlando lodun 2016 (Pulse nightclub), isele ti o seku pa eniyan mọ́kàndínláàdọ́ta, bee si ni isele ti o tun seku pa eniyan mẹ́tàdínlógún nile iwe (Marjory Stoneman Douglas School) ni agbegbe Parkland ninu osu keji odun ti a wayii.
Ṣugbọn awọn ikọ agbabọọlu kọ jalẹ, wọn ni o wu awọn lati gba awọn ifẹsẹwọnsẹ to ku nile awọn.
O ro awon loba-loba ohun lati
Jean Mensa tun kẹkọ siwaaju si ni Harvard Business School (2018).
 Fun idi eyi mo gbe oṣuba sadankata fun ẹyin ara ipinlẹ Eko ati awa ọmọ orilẹ-ede Naijiria lapapọ pe ẹ ku aduroti ẹgbẹ oṣelu APC ni gbogbo ipele ijọba wọn.
Ẹ fọ́nnu pé ẹ̀yin ni ẹ ṣẹgun ìlú Lodebari, ẹ̀ ń wí pé: “Ṣebí agbára wa ni a fi gba ìlú Kanaimu.
Olori abule Ouenkoro to sunmọ ibẹ ṣapejuwe iṣẹlẹ naa, gẹgẹ bi ohun to buru pupọ.
Ó bá sọ fún wọn pé, “Ẹ gbé mi jù sinu òkun, ìjì náà yóo sì dáwọ́ dúró, nítorí mo mọ̀ pé nítorí mi ni òkun fi ń ru.
”Ti a ba tun lo sori eto Eko aare Buhari ti se gudu-gudu meje yaya mefa lati ri daju pe idagbsoke ba eka naa ju bi o se wa tele lo.
” Ọmọ Sara ni yín, tí ẹ bá ń ṣe dáradára, tí ẹ kò jẹ́ kí nǹkankan bà yín lẹ́rù tabi kí ó mú ìpayà ba yín.
Sotitobire latest news: Adájọ́ ṣí àṣùwọ̀n ìfowópamọ́sí Wòlíì Sotitobire, ṣùgbọ́n kò fàyè béèlì sílẹ̀ fún un
Àkọlé àwòrán, Papa iṣere yii lo gbalejo idije Super Eagles lọdun 2003 nigba ti ijọba ṣiju kuro ni papa iṣere Eko Papa iṣere yii ni ibudo ìwẹ̀ igbafẹ tinu ile, o ni papa fun gbigba bọọlu ẹlẹyin tori tabili, bọọlu alajusawọn, ati bọọlu ẹlẹyin alafiigi gba.
4 Òkùdu 2019 Oríṣun àwòrán, @BashirAhmaad Àkọlé àwòrán, Buhari tẹ́wọ́ gba àbájáde ìwadìí ìgbìmọ̀ lórí àtúntò ikọ̀ ọlọ́pàá SARS Iroyin ayọ meji lo gbode kan fun ọpọ awọn ọmọ Naijiria ni ṣisẹ n tẹle lọjọ aje ṣugbọn ko pẹ ti awọn ọmọ Naijiria fi gbọ pe ahesọ lasan ni ekeji ninu iroyin naa.
O ni lara awọnm iranlọwọ ti ijọba le ṣe fun ẹka tiata ni ko ba wọn gbogun ti awọn to maa n ṣe ayederu fọran sita.
Lẹsẹkẹsẹ wọ́n sọ fún Jesu nípa rẹ̀.
Iṣẹ́ ńlá ni kiní bíntín yìí ń ṣe fúni o.
6-3; 7-5 ni wọn pada jọ gba ninu idije aṣekagba naa ni New York.
Jọ̀wọ́, má bínú mọ, yí ọkàn rẹ pada, má sì ṣe ibi tí o ti pinnu láti ṣe sí àwọn eniyan rẹ.
Kádàrá ní ọ̀rọ̀ ẹ̀dá láyé, Mo gbà pé Ọlọrun ló kọ ikú ọkọ mi ni Saudi Eyi ni itan Obinrin kan ti o di alabọ ara nitori ijamba ọkọ to waye ni ilẹ Saudi, ninu eyi ti ọkọ rẹ, Dokita Ajani Raji ti di oloogbe.
Ki àyipadà rere lè dé bá ilú, ó yẹ ki onikálukú yẹ ara rẹ̀ wò fún àtúnṣe kúrò ninú àbẹ̀tẹ́lẹ̀ gbi gbà, iwà ibàjẹ́, ai ṣojú ṣe ẹni ninú ẹbi, ai bẹ̀rù àgbà, ji ja ilú lólè, ki kó owó ilú lọ si òkèèrè, ki kọ oúnjẹ ilú ẹni silẹ̀ fún oúnjẹ òkèèrè, ayẹyẹ àṣejù, ni ná owó ti èniyàn kò gbà àti ai ni ìtẹ́lọ́rùn.
CCC Genesis Global: Ǹkan mẹ́wàá tí ẹ ò gbọ́ rí nípa Israel Oladele, Woli ìjọ Genesis Global Ko yẹ ki ibalopọ ju iṣẹju marun un pere lọ Oṣu kọkanla ọdun 2019 ni fidio iwaasu wolii Oladele kan fa oju ayelujara ye, nibi to ti sọ pe ko yẹ ki ibalopọ laarin lọkọlaya ju iṣeju marun un pere lọ.
Bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé nígbà tí ó wà láàyè,ó rò pé Ọlọrun bukun òun,bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé ayé a máa yin eniyannígbà tí nǹkan bá ń dára fún un,
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Kìnìhún joko jẹ ẹran ara afurásí ọdẹ tí kò gbààyè kó tó ṣọdẹ 8 Ìgbé 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Oloola iju pa Ajanaku to pa ode inu igbo Bi irin ba ko irin, ọkan maa tẹ fun ikeji ni.
Akitiyan ọmọ'ṣẹ́ mi tó wà lára àwọn tó jí ìbejì mi gbé kò kéré nígbà tí á n wá wọn- Akeugbagold Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Inú jìn!
Ẹ̀dá tí ó ba ni lẹ́rù gbáà ni, ó ní ìwo kan ṣoṣo lórí, iní sì ń jò lára ìwo náà bẹ́ẹ̀ ni ìwo pàápàá kò jóná, ó ní ìyẹ́ méjì kùọ̀kùọ̀ kan báyìí ní apá, èékan rẹ̀ sì gùn, ó dàbí èékán àwòdì, eyìn ẹnu rẹ̀ pupa ó dàbí ẹ̀jẹ̀, ẹ̀jẹ̀ ló wà lẹ́nu rẹ̀ tí ó ddúró bí itọ́ ẹnu, eyín wọ̀n-ọnní gbòòrò ọ̀kọ̀ọ̀kan to eyín mẹ́ta papọ̀ ṣe ọ̀kan ṣoṣo, gbogbo eyín náà sì mú bérébéré bí abẹ ìfárí.
”Aare Buhari wa sapejuwe ami-eye(National Order of Merit Award) gege bi ami-eye ti enikeni lorile-ede yii leto si lati gba fun sise agbekale olokan-o-jokan imo, eto tabi awon igbese miiran ti o le mu idagbasoke ba orile-ede Naijiria atiaworan wa loke okun.
Aare Muhammadu Buhari ti so pe orilẹ ede to wa labẹ ajo ECOWAS yoo tesiwaju lati maa se okoowo pelu orile ede China nitori ibasepo to dan monran to wa laarin won ati awon orile ede Asian.
Lẹ́yìn èyí, Dafidi bèèrè lọ́wọ́ OLUWA pé, “OLUWA, ṣé kí ń lọ sí ọ̀kan ninu àwọn ìlú Juda?
orile ede Naijiria, Samuel Orthom ti fokan awon ara ipinle naa bale pe aabo to
Má bẹ̀rù àjálù òjijì,tabi ìparun àwọn ẹni ibi,nígbà tí ó bá dé bá ọ,
Gbẹ̀san lára wọn kí n fojú rí i,nítorí ìwọ ni mo fi ọ̀rọ̀ mi lé lọ́wọ́.
Ati aṣoju ninu ijọ naa, to ma n fi adura jagun.
13 Agẹmo 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 14 Agẹmo 2019 Oríṣun àwòrán, Ooni of ife Àkọlé àwòrán, Ọọni Adeyẹye Ogunwusi ati Iba Gani Adams ni Yoruba lee gbe igbesẹ to le da iṣọkan Naijiria laamu bi ijọba ko ba tete gbe igbesẹ to tọ Ọọni ile ifẹ, Ọba Adeyẹye Ogunwusi Ọjaja II pẹlu Aarẹ Ọna kakanfo ilẹ Yoruba, Iba Gani Adams ti fariga lori iku ọmọ alagba Rueben Faṣọranti, Funkẹ Olukunrin.
Ọjọ ti wọn bi yi ṣe rẹgi pẹlu ayajọ ọdun kejila iklu 9/11 to waye lorileede Amerika.
Oludari ajọ apapọ to n mojuto iṣẹlẹ pajawiri ni Naijiria, Ibrahim Farinloye, sọ fun BBC pe lati ibi idanilẹkọ kan nilu Port Harcourt ni ẹlikọpita naa ti n bọ.
Ọrọ itaporogan laaarin araalu ati ọlọpaa lasiko ti wọn ba fẹ mu wọn ti di yanpọnyanrin ni ọpọlọpọ igba, koda o ti ja si iku fun ọpọ ti awọn miran si ti di alaabọ ara.
Minisita ṣalaye pe bo tilẹ jẹ wi pe ifẹsẹwọnsẹ ọlọọrẹsọọrẹ ni, awọn agbabọọlu Naijiria yoo fi taratara sii.
“Bí wolii kan bá jẹ́ kí á ṣi òun lọ́nà, tí ó sì sọ̀rọ̀, a jẹ́ pé èmi OLUWA ni mo jẹ́ kí wolii náà ṣìnà, N óo na ọwọ́ ìyà sí i, n óo sì pa á run kúrò láàrin àwọn ọmọ Israẹli, eniyan mi.
Awon alatako so pe, orile-ede Egypt ni alakoso awon odo naa lati odun 1906, ki won to da Saudi Arabia sileAwon alase ile Saudi  ati orile-ede Egypt so pe, awon odo naa je ti ijoba, ati pe, won wa labe akoso orile-ede Egypt, botile je pe Saudi Arabia ti bere fun idaabobo lati orile-ede Egypt ni odun 1950.
Àwọn mìíràn tí wọ́n tún jẹ́ ara “Àwọn Ọgbọ̀n Akọni” náà nìwọ̀nyí: Asaheli arakunrin Joabu, ati Elihanani, ọmọ Dodo, ará Bẹtilẹhẹmu.
Orukọ rẹ n jẹ Rafiu Balogun Ọkọ Madam Sajẹ jẹ ọga fun iyawo rẹninu isẹ tiata, ki wọn to fẹ ara wọn Inu isẹ tiata ni awọn ọmọ Madam Sajẹ meji wa, ọkan jẹ oludari ere itage, nigbati ekeji jẹ osere obinrin ninu tiata Orukọ ọmọkunrin Sajẹ ni Azeez Balogun, ti orukọ ekeji si n jẹ Bintu Balogun Madam Sajẹ ti gba ọpọ ami ẹyẹ ninu ere sise nilẹ yii ati loke okun Ahesọ ọrọ kan n ja nilẹ pe Madam Sajẹ ti di ọmọlẹyin Kristi nitori aworan kan to ya nibi to ti gbe bibeli lọwọ, sugbọn awọn eeyan kan ni aworan ninu ere tiata ni Madam Sajẹ kii bawọn se ere oloyinbo rara.
" Àkọlé àwòrán, Aisi owo nṣakoba fun itọju aisan owo lorilẹede Naijiria Ninu ọrọ tirẹ, Dokita iwosan oju, Echetta Ugonna ṣalaye pe aimọkan, aisi iroyin to to ati ọwọngogo itọju aisan oju n ṣe akoba fun awọn ti oju n yọ lẹnu lorilẹ-ede Naijiria, paapaa lẹsẹ pupu.
Bi awọn kan to ti ṣe iyawo tẹlẹ ṣe n pariwo pe orin naa ati ajọṣepọ awọn mejeeji ki wọn to di lọkọlaya mu ori awọn wu, igbeyawo wọn pẹlu ko si ja wọn kulẹ Ohun ti awọn miiran n sọ ni pe orin yii ni orin igbeyawo ti awọn lọkọlaya to ba fẹ ṣayẹyẹ igbeyawo lọdun 2019 yoo maa lo.
Nigba to n sẹ lori awọn ikede kan tawọn araalu fi soju opo Twitter ni alẹ ana, ileesẹ ologun Naijiria ni iroyin ede gbaa ni iroyin naa.
Àbí ọmọ gbẹ́nà-gbẹ́nà yẹn kọ́ ni?
Ó ń fi èrò oríṣìíríṣìí ìfẹ́kúfẹ̀ẹ́ sí mi lọ́kàn.
Oríṣun àwòrán, Others O ni ti ko ba si ti arun coronavirus ni, awọn iba ti pari iṣẹ oju ọna reluwe Eko si Ibadan, bi o tilẹ jẹpe o ku diẹ ki iṣẹ akanṣe naa pari.
Samuẹli bá wí fún àwọn eniyan náà pé, “Ẹni tí OLUWA yàn nìyí.
Ọlọrun, má dákẹ́;má wòran; Ọlọrun má dúró jẹ́ẹ́!
Lasiko to si wa ni ibudo naa, lo se idanilẹkọ nipa bi eto igbaradi naa yoo se waye.
 Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Wo bí Sunday Orimola ṣe gba ikú ẹranko kú ní Ifon ni Ondo lórí ọ̀nà àtijẹ A gbọ pe ni nkan bi aago meji òru ni ija naa waye."
Ọjọ kejidinlọgbọn, oṣu Keje, ni iṣẹlẹ naa waye ni ilu Ibadan.
Láìjẹ́ pé mo ṣẹ̀, wọ́n ń sáré kiri, wọ́n múra dè mí.
Laarin ọdun mẹta to mbọ, Macilau yio se afihan ipa ribiribi ti ipese omi abumu ati ile igbọnse nko ni igbesi aye awọn ara adugbo ẹkun Cuamba ni ilu Mozambique.
Nigba ti o sọ nipa bi o ṣe bẹrẹ ere ori itage, Victoria ni awọn obi oun ko kọkọ gba pe ki oun ṣe ere ori itage.
Bakanna lo le ti ri ri ninu Steel Magnolia ati Pariah.
OPC: Bí a ṣe gbéná wojú awọn ọ̀daràn tó ń d'àlú Ikire rú rèé Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Kayefi BBC Yorùba: Bàbá ọmọ, Mọ́ṣúárì, Ọlọ́pàá kẹ́jọ́ rò nípa òkú ọmọ tó pòórá Awọn orílẹ̀-èdè to jáde wá náà ni Algeria, Angola, Burundi, Benin, Cameroon, Democratic Republic of Congo, Eygpt, Ghana, Guinea, Guinea Bissau, Ivory Coast, Kenya, Madagascar, Mali, Mauritania, Morocco, Namibia, Nigeria, Senegal, South Africa, Tanzania, Tunisia, Uganda ati Zimbabwe.
Baba ọlọmọ mẹwa yii, to ni iyawo meji sọ fun BBC pe awọn agbebọn to le ni aadọta lo yabo abule awọn ni ipinlẹ Katsina, nila oorun ariwa Naijiria.
 Awọn ọlọja naa beere pe ki wọn da ọja Ketu lẹbaa agọ olopaa Ketu pada fun awọn to ni i.
Wọn to lọ Naomi Uzor Oríṣun àwòrán, Facebook/Naomi Uzor Naomi Uzor to jẹ akọroyin nipa ọrọ aje nile iṣẹ Vanguard.
Akọ̀wé àgbà ìgbimọ náà, Dokita Kunle Olajide ba BBC Yoruba sọ̀rọ̀ lori ọ̀rọ̀ náà.
Ile iṣẹ BBC gbiyanju lati ba Dimeji Bankole to jẹ olori ile nigba naa sọrọ lori igbesẹ tuntun yi amọ o ni ohun kolọrọ sọ nipa rẹ aya fi ti ile ba pari iwadi ti wọ́n lawọn fẹ ṣe yi Bi ẹ ba ṣe iwadii, ẹ ri pe ẹ se de oju ami-SERAP Imọran re e lati ọdọ adari ajọ SERAP, Adetokunbo Mumini fawọn aṣojuṣofin Naijiria ti wọn lawọn fẹ se iwadi owo ti ijọba ti na lori ẹka ina ọba.
Omojokun ni awọn gba ibọn ati ada lọwọ awọn ajinigbe lasiko ti wọn ṣe iṣẹ naa.
Kí ó rún bàbá mi mọ́ inú ìpàǹtí, kí ó bẹ̀rẹ̀ si fi ìyà jẹ ẹni-ẹléni, ṣùgbọ́n eléyìínì ṣòro gidigidi: nítorí bí òun ti ń pa èrò wọ̀nyí, bẹ́l náà ni bàbá mi tún ń ronnú èrò tọ̀hún, tí ó ń wwá ọ̀nà àti mu Èṣù-kékeré ni ibi èjìká kí ó gbé ẹbọra kúkúrú kúrò ní ilẹ̀ tán, kí ó gbe olórí burúkú rékọja àtàrí, kí ó sọ alákọrí sí ọ̀nà jínjín réré, kí Èṣù-kékeré ti ọ̀run dé ọ̀run.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fọ́nrán ohùn, Bayo Sanwo salaye lori ilẹkun baalu Dana to fo yọ nilu Abuja Ọpọlọpọ awọn eeyan to wa ninu baalu Dana naa lasiko isẹlẹ yi si lo ti n fi oniruuru iroyin sọwọ sori opo ikansiraẹni twitter wọn .
13 Ògún 2020 US Elections 2020: Primate Ayodele ní òun ti sọ àsọtẹ́lẹ̀ pé Trump yóò fìdírẹmi, tí kò bá ṣọ́ra ṣe8 Bélú 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Banki kan ni wọn ja lole nilẹ okeere l'oṣu Keji, ọdun 2019.
Kò jẹ́ kí àwọn eléré ṣe eré níwájú rẹ̀, bẹ́ẹ̀ ni kò sì lè sùn.
A rí àwọn oniṣẹ-ọwọ́ bíi, alágbẹ̀dẹ, onílù.
Ọ̀rọ̀ tí Mose bá àwọn eniyan Israẹli sọ ninu aṣálẹ̀ nìyí, ní òdìkejì odò Jọdani, ní Araba tí ó kọjú sí Sufu, láàrin Parani, Tofeli, Labani, Haserotu ati Disahabu.
Ẹkùn tọ́ igbẹ́ Ọ̀bọ wò, inú rẹ bàjẹ́, ojú ti i pé òhun gba ọ̀rọ̀ Ìjàpá gbọ.
Wo eyi to súnmọ́ ọ nínú àwọn ibùdó 203 fún ìforúkọsílẹ̀ fún NIN rẹ Minisita fun ibaraẹnisọrọ ati ọrọ aje ori ayelujara, Ọmọwe Isa Pantami ti buwọlu aṣoju 173, ati ileeṣẹ ijọba ọgbọn lati ma a ṣe iforukọsilẹ gbogbo ẹni to n gbe ni Naijiria lọna to ba ofin mu, fun ajọ National Identity Management Commission (NIMC).
Nigba ti yoo fi de ọdọ ẹni to pee, ẹsun ti wọn fi kan an ni pe irun to gbe si ori ti kun ju.
Aare wa fi idunnu re han si asoju ile Denmark ni fun ibasepo ti o donmonron, eleyi ti o wa laarin orile-ede Naijiia ati ile Denmark, bee si ni aaye si wa ni pereu fun orile-ede mejeeji lati tun bo mu igberu ba asojepo won ni eka eto oro aje.
”Ṣugbọn àwọn mìíràn ń sọ pé “Báwo ni ẹni tí ó jẹ́ ẹlẹ́ṣẹ̀ ṣe lè ṣe irú iṣẹ́ ìyanu yìí?
Nítorí wọ́n ń ṣe akitiyan láìṣe àárẹ̀ láti tọ́jú yín, pẹlu ọkàn pé wọn yóo jíyìn iṣẹ́ wọn fún Ọlọrun.
Ero peju sibẹ lati ba Risikat ati Wasiu yọ ni Ilọrin ni ipinlẹ Kwara ni aarin gbungbun Naijiria.
Adajọ Ekwo ni nitori idi eyi, ẹjọ ti awọn oludije ẹgbẹ oṣelu naa fun ipinlẹ Bayelsa ati Kogi, Ebi Peretiemo ati Samuel Alfa pawọ pọ pe ko lẹsẹ n lẹ.
Wọn yóo pada sọ àwọn tí ó kó wọn lẹ́rú di ẹrú, wọn yóo sì jọba lórí àwọn tí ó ni wọ́n lára.
Ṣé kí n sọ fún Ọlọrun pé n ó bá a sọ̀rọ̀ ni?
Ni eyi to si ti n bi eso rere ti gbogbo oju le ri ka ninu okowo ati eto aabo Naijiria.
ti a n ko wole lati oke okun wa si orile ede Naijiria ti dinku bayii lati odun
Wo ìdí tó fi tọrọ àforíjì fún ọ̀rọ̀ ẹ̀gbin tó sọ sí Pásítọ̀ David Oyedepo 'Àgbàrá òjò wọ́ ọmọ méjì lọ ní Ketu l'Eko lálẹ́, a ṣì ń wá wọn di òní' Mercy Aigbe ṣá ọmọ rẹ̀ sínúu fíìmù tuntun, wo itú tí ọmọ ọdún mẹ́wàá náà pa ''Ṣugbọn nigba ti iṣẹ iwadii ṣi n lọ lọwọ, o ṣe pataki lati jẹki awọn araalu mọ pe ohun ti ọkunrin to wa ninu fidio naa n ṣe lodi si ilana ati ofin to de awọn ọlọpaa orilẹede Naijiria,'' Ọgbẹni Uba lo sọ bẹẹ.
Kinniun alágbára a máa kú,nítorí àìrí ẹran pa jẹ,àwọn ọmọ abo kinniun a sì fọ́nká.
lọ́wọ́ àwọn eniyan burúkú tí ó gbé ìjà kò mí,àní lọ́wọ́ àwọn ọ̀tá apani tí ó yí mi ká.
Kọmiṣọnna eto aabo ni Kaduna, Samuel Aruwan gboṣuba fawọn oṣiṣẹ iṣẹlẹ pajawiri pé wọ́n tètè dìde si iṣẹlẹ naa.
Wọn bẹ̀rẹ̀ si gbé àpèjẹ lọ si ọgbà ilé-iwé, ilé ìjọ́sìn tàbi ọgbà ilú àti ilé-ayẹyẹ.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ìwọ́de EndSARS ló ń sọ pé inú ń bí àwọn ọ̀dọ́, ìjọba, ẹ náání wọn - Obasanjo Ẹni iyì àti akíkanjú tó ṣe gbẹ́kẹ̀lé làwọn èèyàn Akure, ilú ìyá mi - Seyi Makinde Ẹ̀yin ọ̀dọ́ ti rí èrè ìwọ̀de yín lórí EndSARS àmọ́ ẹ ṣọ́ra, kẹ má baà sọ èrè náá nù - Tinubu Owó ìrànwọ́ Covid-19 dé, ìjọba fẹ́ san ₦75bn fún 54,000 olókoòwò Ìjọba ìpínlẹ̀ Eko ti iléèwé pa nítorí ìwọ́de #EndSARS Ìrẹ̀wẹ̀sì ń bá wa torí ìdánwò NECO tẹ ń ṣún síwájú lọ́pọ̀ ìgbà - Akẹ́kọ̀ọ́, ọ̀gá iléèwé Agbára ìgbìmọ̀ ìdájọ tí mo gbé kàlẹ̀ yóò dé ọ̀dọ̀ àwón ólọ́pàá tó ti kúrò lẹ́nu iṣẹ́ tẹ́lẹ̀- Sanwo Olu Wo àwọn orílẹ̀èdè míràn tó ń fojú winá ìwọ́de bíi ti ENDSARS Nigba to n sọrọ lori iwọde EndSARS to n lọ lọwọ naa, gomina ipinlẹ Eko ni pẹlu iyalẹnu ni oun fi n tọpinpin bi iwọde naa, to bẹrẹ ni alaafia se wa di eyi to n dunkoko mọ awọn araalu ati igbayegbadun awujọ.
Àwọn ìlú mẹtẹẹta yìí wà ní ilẹ̀ Babiloni.
O ni ọpọ ti wọn fẹ ta ẹyin lọpọ yanturu ni ko ri ọjọ ti wọn ti le taa, bakan lawọn ti wọn fẹ ta nnkan oko mii.
[Ìròyìn tí ó tẹ̀ wá lọ́wọ́:  wọ́n pàpà jẹ́wọ́ wípé [Diaz wà ní akolóo wọn]
Sir, the achievements under your able & dynamic leadership are remarkable,unbeatable & indelible.
Ṣebí ẹlòmíràn ni a ṣe èyí tí ó jù bẹ́ẹ̀ lọ fún, tí ó rí ni ní ọjọ́ kejì tí kò wo ni ní pìnṣín imú, tí a béèrè pé, O kò tilẹ̀ kí wa ni?
Jákèjádò, ènìyàn 134 di ẹni ẹbọra-ń-bá-jẹun látàrí èsùn-un lílo “ògùngùn” ní ọdún-un 2016, ìyẹn gẹ̀gẹ̀ bí Àjọ Aṣàkọsílẹ̀ Ẹ̀ṣẹ̀ Orílẹ̀-èdè náà ṣe kọ́ ọ sílẹ̀.
Ṣugbọn àwọn tí ó bá dúró de OLUWAyóo máa gba agbára kún agbára.
Iṣuna owo ti awọn sẹnetọ gba wọle jẹ N8.
Mo fún wọn ní ìyè ainipẹkun, wọn kò lè kú mọ́ laelae, bẹ́ẹ̀ ni ẹnikẹ́ni kò lè já wọn gbà mọ́ mi lọ́wọ́.
Oríṣun àwòrán, Naptip Gẹgẹ bi iroyin ṣe sọ, iwadii ileeṣẹ abo ara ẹni labo ilu fi kun un pe, yatọ si arabinrin Ajayi, eeyan mejidinlọgbọn ni awọn eeyan mẹta yii ti ran lọ soko ẹru loke okun labẹ pe wọn fẹ lọ ṣiṣẹ kore oko dele.
Ṣùgbọ́n kò sí àlàyé tó kún lóríi ibi tí wọ́n gbée lọ tàbí irú ipò tó wà lọ́wọ́lọ́wọ́.
Kí ó má ṣe jẹ́ pé nígbà tí wọ́n bá ń ṣọ́ yín nìkan ni ẹ óo máa ṣiṣẹ́ bí ìgbà tí ẹ fẹ́ gba ìyìn eniyan.
 oruko abiso re ni freda josephine mcdonald ni st.
Jehoramu, ọmọ rẹ̀ sì jọba lẹ́yìn rẹ̀.
Kabiyẹsi fidiẹ mulẹ pe lootọ ni iṣẹlẹ naa waye ṣugbọn ilu ko ṣe ohunkohun lati ba ẹnikẹni ja rara.
O fikun pe oun tun pada pe lori aago, amọ ti wọn sọ fun oun pe o wa ni ipade igbimọ alasẹ ijọba ilẹ yii to n waye lana.
Ewéko ibẹ̀ tutù yọ̀yọ̀, o dára bí iwájú ile òyìnbó, ibi kékeré sì pọ̀ ju igi ńlá lọ bẹ́l ni àwọn igi kọ̀ọ̀kan ti ń bẹ láàárin àwon ayika náà lẹ́wà púpọ̀,  wọ́n dúró wọn rí gbọnrangandan, ara òmíràn funfun, ara òmíràn dúdú, ara òmíràn sì dàbí òṣù,àrè àwọsánmọ̀ tí ó ni dúdú tí ó tun ní pupa.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ekiti Bishop: Ìjọ Anglican pàṣẹ lọ rọọ́kún nílé fún Bíṣọ́ọ̀bù tó ń bá ìyàwó àlùfáà abẹ́ rẹ̀ sùn l'Ekiti 16 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Oríṣun àwòrán, Newsdayng.
Orukọ miran ti ọlọwọ idan yii n jẹ ni Mandrake.
Alufaa yóo fi ọ̀kan rú ẹbọ ìmúkúrò ẹ̀ṣẹ̀, yóo fi ikeji rú ẹbọ sísun láti ṣe ètùtù fún un nítorí pé ó ti ṣẹ̀ nípa fífi ara kan òkú; yóo sì ya orí rẹ̀ sí mímọ́ ní ọjọ́ náà.
” Èyí níí ṣe òfin kinni pẹlu ìlérí, pé 
Guure so pe, “Ikolu ohun bere laago meje owuro, nigba ti awon omo ogun olote al-Shabab sekolu si awon ara ilu lataari kikuna won lati sanwo ori ni tipatipa, eleyi ti won bere fun awon ohun osin won.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Domestic Violence: Ǹkan mẹ́jọ tó máa kọ́kọ́ ṣẹlẹ̀ kí olólùfẹ́ méjì tó pa ara wọn 1 Owewe 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 17 Òkùdu 2020 Oríṣun àwòrán, @others Àkọlé àwòrán, Ija kò dọlà, orúkọ lo n sọ ni Ọpọlọpọ iṣẹlẹ lo maa n bi ija ati aigbọra-ẹni ye laarin ololufẹ meji.
Kò sí ẹni tí ó lè dé ọ̀dọ̀ Baba bíkòṣe nípasẹ̀ mi.
Olùpẹjọ́ ni olùdíje dùpò gómìnà míràn lábẹ̀ ẹgbẹ́ òṣèlú APC Nathaniel Adijutelegan tó díje pẹ̀lu Akeredolu lásìkò ìdìbò abẹ́lé láti yan ẹni ti yóò dupò gómìnà nínú ẹgbẹ́ náà.
Jẹ́ kí wọn mọ̀ pé iṣẹ́ ọwọ́ rẹ ni èyí,kí wọn mọ̀ pé, ìwọ OLUWA ni o ṣe é.
ilanilọyẹ, Festus Okoye  lo kede yii
Kwara Assembly: Ilé Arúgbó Saraki la fẹ́ lò fún ilé ìwòsàn àwọn òṣìṣẹ́
Ó wí fún wọn pé, “Ọkàn mi bàjẹ́ tóbẹ́ẹ̀ tí mo fẹ́rẹ̀ lè kú.
    Nígbà tí a kúrò ní ìgbìmọ̀, mo padà lọ sí ibùdó wa, mo ròyìn ohun tí mo rí fún gbogbo wọn.
O salaye pe, “oja idokowo n ko ipa pata ki ninu idagbasoke oro-aje ati awon ohun amayederun miiran, siseto idokowo fun ojo pipe maa n dara lopo igba, ni eyi ti o si se pata ki”.
Nigba ti wọn n tahun si ara ṣaaju ija ọjọ Aiku, Costa oun yoo gbe Israel tọrọ ba doju rẹ tan nitori ko lara.
wọ ́ n bí saifi ní ìlu mila ní orílẹ ̀ èdè algeria ní ọdún 1988 .
Aarẹ Ghana, Nana Akufo-Addo ti ni oju lalakan fi n ṣọri fun gbogbo awọn to n mojuto kika esi idibo naa to n lọ lọwọ.
Ẹ̀yà Reubẹni, ẹ̀yà Gadi, ati ìdajì ẹ̀yà Manase gba ilẹ̀ tí Mose, iranṣẹ OLUWA, fún wọn, tí ó wà ní ìhà ìlà oòrùn, ní òdìkejì odò Jọdani; 
Nítorí ẹ̀tọ́ rẹ ni;kò sì sí ẹni tí ó gbọ́n tó ọláàrin àwọn ọlọ́gbọ́n tí wọ́n wà ní àwọn orílẹ̀-èdè,ati ni gbogbo ìjọba wọn.
Gbìyànjú àwọn òwé Yòrúbà yìí wò Báyìí ni ayẹyẹ wíwé láwàní Mike Zhang ọmọ China ṣe lọ Ọmọ̀dé 20 kú sínú kànga láàrin osù márùn-ún Aisha Buhari ké gbàjare pé ètò ìjọba Buhari kò ṣànfàní f'óbìrin Aṣoju awọn ọlọpaa ni ẹkun Kano, Abdullahi Haruna ṣalaye fun akọroyin BBC pe wọn ti ko awọn meje to ṣeṣe lọ si ile iwosan Aminu Kano fun itọju to peye.
Wọ́n tún wí fún Farao pé, àwọn wá láti ṣe àtìpó ní ilẹ̀ rẹ̀ ni, nítorí pé ìyàn ńlá tí ó mú ní ilẹ̀ Kenaani kò jẹ́ kí koríko wà fún àwọn ẹran àwọn.
Abi ẹ o wa tun ri ẹni to fi agadagodo ṣe ibomu-bẹnu.
A tun rii kọ pe, ka maa ri ibi ti a ba tẹdo si gẹgẹ bii ilu wa, ka si maa wa alaafia rẹ.
 agbára káká ni a fi ń ṣe alábàápàdé igbó jìnrìngbòdò .
Owó oúnjẹ ni mo lọ ọ gbà, oyún ọmọ tí mo jù sí àkìtàn ni mó gbé wálé- Dupe, ìyá Muiz Olórin Kano tí wọ́n dájọ́ ikú fún pe ẹjọ́ kòtẹ́milọ́rùn Àṣìṣe ọlọ́pàá àti Adájọ́ sọ mí di ẹni tí wọ́n dájọ́ ikú fún, ọpẹ́lọpẹ́ Fayoṣe tí ko buwọ́lù ú Nàìjíríà làwọn ní ìfẹ́ sí ìpèsè abẹ́rẹ́ àjẹsára Covid-19 tí Russia ṣe Wọn fikun un wi pe lara awọn ti wọn ti ṣe ayẹwo fun naa wa lati ijọba ipinlẹ Takai, Tarauni, Tofa, Tsanywa, Tudun Wada, Warawa, Wudil, ati Ungogo Bakan naa ni ileeṣẹ ọlọpaa ni ipinlẹ Kano naa ṣeleri lati ṣe ayẹwo awọn ti wọn ba kuna lati wa fun eleyii ti wọn n ṣe lọwọlọwọ laipẹ.
À máa ṣẹ́ gègé kí á lè mọ ìdí ọ̀ràn,ṣugbọn OLUWA nìkan ló lè pinnu ohunkohun.
 títa lẹ ́ rú rẹ ̀ jẹ ́ kí ó ní ọ ̀ pọ ̀ lọpọ ̀ ìrírí tí ó dìrọ ̀ mọ ́ òwò ẹrú .
bere si n ju okuta ati apo omi sibi ti aare Muhammadu Buhari waa.
Bi o tilẹ ṣe pe idẹyẹsi ati ẹlẹyamẹya yii ko wọpọ ni awọn ẹya miran ni orilẹede Naijiria bii Yoruba ati Hausa, awọn orilẹede miran ni Iwọ-oorun Ilẹ Afrika bii Mali ati Senegal naa ṣi n dẹyẹ si awọn eniyan nitori wọn wa lati idile ẹru.
Muhammad Ali mú adùn wọ iṣẹ́ akànṣẹ́, ó fi ọlà rẹ ṣe àánú fún ọ̀pọ̀lọpọ̀ aláìní, ó si jẹ àwòkọ̀ṣe fún àwọn ọ̀dọ́ pàtàki Aláwọ̀-dúdú ti ó fi hà̀n pé ‘kò si ohun ti kò ṣe é ṣe, bi enia bá fi ọkàn si’.
ba ka ajere iwa ibaje mo lowo, iru eni be ko ni salai mai foju jofin.
"Buhari ni awọn ile ti Daura, ""àmọ̀ ni wọ́n fi kọ́ ọ""."
Awọn kan ninu awọn ti wọn ko idanwo na ti kọkọ sọ wipe awọn ko ri esi idanwo wọn gba.
Wọ́n óo fọ́n fadaka wọn dà sílẹ̀ láàrin ìgboro.
Wọn gbé ni kété to balẹ̀ si pápáko òfurufú àgbáyé Kotoka láti irinajo tó ṣe sí orílèèdè Morocco.
Ní báyìí, wọ́n tí n ṣọ́ àwọn ẹbí àwọn aláìsàn mẹ́tẹ̀ẹ́ta, tí díẹ̀ lára wọn sì ti gba abẹ́rẹ́ àjẹsára nítorí Ebola.
Isẹlẹ yi dẹrin pẹkẹ awọn to'n sọ bi ere idaraya naa ti se'n lọ ti ọrọ naa se wọn ni kayefi.
6 124921 Orilẹede Albania 965 33.
ti egbe naa ni iye ibo  283,847.
22 Owewe 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ikọ ọmọogun òfúrufú Naijiria pàrọwà sí àwọn ènìyàn ní ìhà Àríwá láti má a gbé àmìn ìdánimọ̀ wọn dání.
Ṣọ́ra, 'Loom Money Nigeria' kọ́ ni ètò sogún-dogójì tí yóò kọ́kọ́ wọ Nàìjíríà Ọwọ tẹ akẹkọ to fowo ileewe rẹ ta MMM Agbébọn pa ọmọ asòfin àpapọ̀ kan ní ìlú ọba Ilé ẹjọ́ dájọ́ ikú fún èèyàn mẹ́ta nítorí ikú akẹ́kọ̀ọ́ fásitì UNIOSUN Àwọn òṣèré Yollywood tó ń pàrònú rẹ́ O salaye pe o ṣoro lati gba awọn to wa nidi eto yi mu nitori pe oju opo ayelujara ni wọn ti n ṣe eto naa.
Onírúurú Fẹntíletọ̀ lọ wà nínu ìṣẹ́gùn òyìnbó.
Díẹ̀ lara awọn orilẹede ti wọn sọ sí ọ̀rọ̀ naa nìyí: Oríṣun àwòrán, Getty Images Orilẹede Amerika Aarẹ Donald Trump sọ pe, ìgbésẹ̀ naa jẹ èyí to mu èròngbà awọn wá sí ìmúsẹ.
Bí ẹnikẹ́ni bá rò pé òun ní ìdí láti fi gbára lé nǹkan ti ara, mo ní i ju ẹnikẹ́ni lọ.
Nígbà tí ó dé ọ̀dọ̀ rẹ̀, ó bá a lòpọ̀.
Lẹyin ọdun mẹrinlelogun ti wọn sekupa Ken Saro-Wiwa, awọn ọmọ Naijiria ti n sọrọ nipa rẹ, ti wọn si n beere fun idajọ otitọ lori isekupani naa.
Oun ni aarẹ igbimọ alaṣẹ ajọ UNICEF to n ri si ọrọ awọn ọmọde lọdun 1999.
Bí ó bá jẹ́ pé wọ́n ta tọkunrin tobinrin wa bí ẹrú lásán ni, n kì bá tí yọ ìwọ kabiyesi lẹ́nu rárá, nítorí a kò lè fi ìnira wa wé àdánù tí yóo jẹ́ ti ìwọ ọba.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù World Smallest Baby: Dípò oṣù mẹ́sàn-án, wọ́n bí ọmọ yìí ní oṣù mẹ́rin àbọ̀ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ World Smallest Baby: Dípò oṣù mẹ́sàn-án, wọ́n bí ọmọ yìí ní oṣù mẹ́rin àbọ̀ 29 Òkùdu 2019 Saybie ni inagijẹ ti wọn fun un.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ladoja Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Ayẹyẹ ifilọlẹ ileeṣẹ BBC Yoruba nipinlẹ Eko
Eyi to ya ni lẹnu ju ni ti Mu'azu to jẹ alaga ẹgbẹ oṣelu PDP nigba kan ri.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Macron yoo jẹ aarẹ akọkọ ti yoo kọkọ wa si ile igbafẹ ti wọn mọ si agbegbe ti wọn ti n mu ogun oloro bi igbo.
Tọkọtaya láti Najiria wọ wahálà torí ààwẹ̀ p'ọmọ wọn ní Amẹrika
Lara awọn obinrin to jẹ iys oṣelu ni ipinlẹ Eko ni Sanwo-olu babes wa.
    Kò sí ààyè nísisì yìí láti tún sọ gbogbo ohun tí oju wa rí lẹ́yìn ìgbà tí mo padà dé ọ̀dọ̀ àwọn ọdẹ tán titi a tún fi padà dé ìlú wa.
Bo tilẹ jẹ pe gomina Makinde funrarẹ ko tii fi ọrọ sita, iroyin taa gbọ ni pe Mama Abigail dakẹ lowurọ ọjọbọ ọjọ kẹẹdogun oṣu kẹwa ọdun 2020.
 Eleyii ni iru iwa ti a naa nilo lati le ni ẹmi ifarada lati fi bara wa gbe ninu alaafia”“Agbara wa gẹgẹ bi orilẹ-ede kan wà ninu irẹpọ wa gẹgẹ bi iṣọkan awọn ẹya, ẹsin ati aṣa wa loriṣiriṣi ki a le ṣaṣeyọri ninu ilepa wa.
 gusu Ìlà oòrùn orílẹ ̀ èdè nigeria ni wọn ti ń sọ èdè yìí .
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Olubadan: ìbànújẹ́ ọkàn ló jẹ́ fún mi pé Ọlọwọ ti Ọwọ jade láyé 18 Ìgbé 2019 Oríṣun àwòrán, Google/Sola Ilesanmi Àkọlé àwòrán, Olowo ti Owo, oloogbe Folagbade Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Awọn ara ilu kede ipapodaba ọba wọn nipa gige igi nla to wa laafin.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìjọ Redeem: Á se àyẹ̀wò ojú ara fáwọn àfẹ́sọ́nà sáájú ìgbeyàwó 22 Èbibi 2018 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 23 Èbibi 2018 Oríṣun àwòrán, @PastorFOdesola Àkọlé àwòrán, Ìgbésẹ̀ náà ló wà láti dènà ọ̀pọ̀ lààsígbò ló ń mi ìgbeyàwó lògbò-lògbò Ìjọ Ìràpadà ti ẹ̀mi, táa mọ̀ sí The Redeemed Christian Church of God (RCCG) ti fi àtẹ̀jáde kan síta pé, láti àkókò yìí lọ, àwọn àfẹ́sọ́nà tó bá fẹ́ se ìgbeyàwó nínú ìjọ náà, ni wọn yóó máa se àyẹ̀wò fúń ṣáájú ìgbeyàwó lórí àwọn ohun to so rọ̀ mọ́ ìbálòpọ̀ àti ìbímọ wọn.
Ṣùgbọ́n, ìjà nàá ṣì n lọ lọ́wọ́ ní àsìkò tí a kó ìròyìn yíì jọ.
Ileeṣẹ yii ni pẹlu ayẹwo awọn, eeyan le gba fidio oni 20 gig laarin iṣẹju aaya marundinlaadọta.
Ní pẹ̀tẹ́lẹ̀ Moabu ní ìhà ìlà oòrùn Jọdani ní òdìkejì Jẹriko, OLUWA sọ fún Mose pé, 
Indeed, it gladdens my heart to know not only Nigeria and Africa, but many nations around the world had a friend in him.
11 Ògún 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 13 Ògún 2020 Gbogbo ohun ti mo fẹ́ ni mo n ri laafin Oba Lamidi Adeyemi- Olori Aanu Ohun to wu mi ko wu ọ ni ọrọ Ayaba Aanuoluwapọ Adenike Adeyemi nigb ati BBC kan si Aafin Kabiesi ni ilu Oyo.
Nígbà tí Adonisedeki, ọba Jerusalẹmu, gbọ́ bí Joṣua ṣe gba ìlú Ai, ati pé ó pa ìlú Ai ati ọba rẹ̀ run, bí ó ti ṣe sí ìlú Jẹriko ati ọba rẹ̀; ati pé àwọn ará Gibeoni ti bá àwọn ọmọ Israẹli dá majẹmu alaafia, wọ́n sì ń gbé ààrin wọn, 
Iroyin naa waye lẹyin wakati diẹ ti ọrẹbinrin rẹ, ti wọn tun mọ si ‘personal assurance‘, Chioma Avril Rowland, bu ọwọ lu iwe ibasepọ lori isẹ́ ìdáná rẹ, ti Davido si di asoju fun ile-isẹ ẹrọ ibaraẹnisọrọ, Infinix.
Lẹ́yìn náà, ó bẹ̀ wá pé, bí a bá gbà pé òun jẹ́ onigbagbọ nítòótọ́, kí á máa bọ̀ ní ilé òun kí á máa bá àwọn gbé.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù 8TH Assembly: FRSC kò yan Saraki sọjú pé kó dá nọ́mbà ọkọ̀ tó lò padà 14 Òkùdu 2019 Oríṣun àwòrán, Facebook/Bukola Saraki Àkọlé àwòrán, 8TH Assembly: FRSC kò yan Saraki sọjú pé kó dá nọ́mbà ọkọ̀ tó lò padà Ko si idi kankan fún wa lati yan Saraki sọju -FRSC Ajọ to n ri si igbokegbodo ọkọ lorilẹ-ede Naijiria, FRSC ti sọ pe oun ko yan adari ile igbimọ aṣofin ana ṣoju.
Amọṣa, ọrọ yii  buru ju eyi lọ lawọn igberiko.
Pẹlu iye awọn eeyan tuntun yii, o ti pe 89,163 eeyan to ti ni arun naa ni orilẹede Naijiria bayii.
Lisabi Agbongbo Akala rèé, ẹni tó fi ìfẹ́, ìṣọ̀kan àti ìrẹ́pọ̀ gba ilẹ̀ Ẹ̀gbá lọ́wọ́ ìmúnisìn A jọ ṣe ìyàwó pọ̀, a jọ bímọ ní ọjọ́ kan náà, a tún jọ máa ń ṣàìsàn pọ̀ ni Wo ìlú tí wọ́n tí ń ta ọmọ ọ̀dọ̀ kan fún #1.
Gbenga Adeboye:Àwọn olúlufẹ rẹ̀ sọ̀rọ̀ lóri ǹkan ti wọn pàdánù
Apapọ gbogbo eeyan to ni aarun covid 19 ni Naijiria bayii jẹ ọrin le lugba o din mẹrin.
Ó bá là wọ́n lọ́yẹ kí Ìwé Mímọ́ lè yé wọn.
Ọ̀kan ninu àwọn arúfin tí wọ́n kàn mọ́ agbelebu pẹlu rẹ̀ ń sọ ìsọkúsọ pé, “Ṣebí ìwọ ni Mesaya!
Ìfẹ́ ati Igbagbọ Tí Filemoni Ní.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Shiite: Ojú Zakzaky kan ti fọ́, májèlé sì wà nínú ara rẹ̀, ìyàwó rẹ̀ kò sì le è rìn mọ́ 5 Ògún 2019 Oríṣun àwòrán, @Shuleman El-zakzaky Awọn ọmọ ẹgbẹ Shiitee sọ pe idajọ ileẹjọ giga ipinlẹ Kaduna lọjọ Aje jẹ idajọ ododo to lodi si iwa ika ati iwa tani yoo mu mi.
Òwe:- Orísirísi ọ̀nà ni a le gbà pa òwe.
Hesekaya bá bèèrè pé, kí ni àmì tí òun óo fi mọ̀ pé òun óo tún fi ẹsẹ̀ òun tẹ ilé Olúwa?
igbakeji aarẹ Osinbajo ni alaga awọn eeyan kukuru lọwọ yii.
Àsìkò tó láti fi ìwọ́de gba ara wa sílẹ̀ lọ́wọ́ ebi àti oko ẹrú - Sowore Ìjọba Buhari ń wùwà bíi ìjọba Abacha lórí ọ̀rọ̀ Ṣoworẹ- Ṣoyinka Falọdun ẹni to woye ọrọ yii lasiko to n gbalejo ileesẹ to n fọnrere ajọdun Ọsun Osogbo fun tọdun yii, Esquire Global, tun fọwọ gbaya pe ajọ naa ti setan lati sugba ijọba ipinlẹ Ọsun ati igbimọ to wa fun agbega asa ni Ọsun lọna ati jẹ ki ajọdun ọdun yii kẹsẹ jari.
“N óo darí àwọn afọ́jú,n óo mú wọn gba ọ̀nà tí wọn kò mọ̀ rí,n óo tọ́ wọn sọ́nà,ní ọ̀nà tí wọn kò mọ̀ rí.
Wọ́n pa àwọn ọmọ Sedekaya lójú rẹ̀, lẹ́yìn náà ni Nebukadinesari ọba yọ ojú Sedekaya, ó fi ẹ̀wọ̀n dè é, ó sì mú un lọ sí Babiloni.
Ọba Soun tilẹ Ogbomoso nigba naa ni Ọba Immanuel Olajide Olayode Keji, o si wa laafin rẹ to n dari ilu, bẹẹ lo n fi oye da awọn ọtọkulu ilu lọla.
Má wulẹ̀ wọn àgbàlá Tẹmpili tí ó wà lóde, nítorí a ti fi fún àwọn alaigbagbọ.
Yatọ si pe awọn orile-ede wọnyi ni obinrin gẹgẹ bi adari wọn, awọn orile-ede wọnyi ni nkan miran to pa wọn pọ eleyi to mu ki wọn le koju isẹlẹ yi.
E ma jẹ ki o yọ awọn ọmọ yin silẹ: Awọn to ba n sisẹ lati ile ti awọn ọmọ wọn wa lọdọ wọn a maa ronu bi awọn yoo ti se sisẹ pẹlu wahala itọju ile.
Àsọtẹ́lẹ̀ nípa Àkókò Ìyapa ninu Ẹ̀sìn.
Bakanna ni ọrọ tun kan sẹnatọ Godswill Akpabio toun pẹlu ti figbakanri jẹ gomina ipinlẹ Akwa Ibom ki o to wa di asofin agba bayii ati sẹnatọ Bukọla Saraki ti oun pẹlu ti jẹ gomina ri ni ipinlẹ Kwara ki o to di aarẹ ile-asofin agba orilẹede Naijiria.
Òkú tó jí lọ́jọ́ kejì ní mọ́ṣúárì padà kú síléèwòsàn Ṣé lóòtọ́ ni àjọ ọlọ́pàá dá Abayomi Shogunle àti Dolapo Badmus dúró?
Ẹ bámi dé abúlé kan ní Lọndọn tí wọ́n ń pè ní Stratford.
O ti fi ògo rẹ wọ́lẹ̀ fún àwọn àjèjì oriṣa,lábẹ́ gbogbo igi tútù;o kò sì gbọ́ràn sí mi lẹ́nu.
Nígbà tí àwọn ọjà rẹ bá dé láti òkè òkun,ò ń tẹ́ ọpọlọpọ eniyan lọ́rùn.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Àwọn ọmọ Nàíjíríà ló ṣiṣẹ́ takò mí ní Ireland kí ń má baà wọlé ìbò Káńsélọ̀ - Yemi Adenuga Ọkọ̀ akẹ́rù Dangote rọ́lu BRT lọ́nà Ikorodu, èèyàn kan kú, 59 farapa, ẹsẹ̀ dẹ́rẹ́bà gé Ìrẹsì jọ̀lọ́ọ̀fù Ghana la jọ̀lọ́ọ̀fù Nàìjíríà mọ́lẹ̀ nínú ìdíje Ìyá tó lu ọmọ ọdún mẹ́rin pa l‘Akurẹ bọ́ sọ́wọ́ ọlọ́pàá Ọjọ Kẹtadinlọgbọn osu Kẹjọ ọdọọdun, eyiun ayajọ oni, si ni orilẹede Amẹrika ya sọtọ fun ayajọ ọjọ ibaradọgba awọn obinrin pẹlu ọkunrin ninu eto oselu.
ó ní, “Ìwọ yìí, tí ó jẹ́ kìkì oríṣìíríṣìí ẹ̀tàn ati ìwà burúkú!
Esi idibo naa fihan pe Prince lo ni ibo mẹfa, Dorothy tẹle pẹlu ibo mẹrin, Kiddwaya pẹlu ibo mẹta, Ozo ati Neo pẹlu ibo meji, nigba ti Nengi ati Vee ni ibo kọọkan.
Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Amotekun Oyo: Iṣẹ́ ti bẹ̀rẹ̀ ní pẹrẹu fún Àmọ̀tẹ́kùn ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́ lẹ́yìn ìdánilẹ́kọ̀ọ́ ọlọ́sẹ̀méjì gbáko18 Bélú 2020 Gómìnà Kwara: A kò ní w'ojú olóṣèlú kankan to bá pín nínú owó N5bn ní Kwara30 Bélú 2019 Oyo SSG Office Burgled: Ìjọba Oyo dúnkookò mọ́ iléeṣẹ́ tó bá gbé ìròyìn èké síta2 Sẹ́rẹ́ 2021 Kwara; Ìpínlẹ̀ Kwara yọ orukọ Saraki kúrò lára fasitì wọn4 Ẹrẹ̀nà 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 3 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 5 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Nígbà náà ni àwọn olórí àwọn ìdílé, àwọn olórí àwọn ẹ̀yà Israẹli, àwọn ọ̀gágun ẹgbẹẹgbẹrun ọmọ ogun ati ti ọgọọgọrun-un ọmọ ogun, ati àwọn alabojuto ohun ìní ọba, bẹ̀rẹ̀ sí dá ọrẹ àtinúwá jọ.
Ohun to n ṣẹlẹ yii ṣe apẹẹrẹ aitọ ati aibojumu to gbilẹ si ẹka ilana iṣejọba wa.
Mo mọ àbúrò bàbá mi tí mo fẹ́ sọ̀rọ̀ nípa rẹ̀ yìí dáradára.
Ninu awọn fọnran fidio to gbe sita Dokita Stella sọ pe ohun kẹkọ gboye ni orileede Naijiria.
" Anfaani nla n bẹ fawọn obinrin lagbo oselu - INEC Ninu iroyin miran ẹwẹ, àjọ elétò ìdìbò Nàìjìria, INEC ti fi dá àwọn obìnrin lójú wí pé àǹfànì aláìlẹ́gbẹ́ ńbẹ fún wọn lẹ́ka ètò òṣèlú orílẹ́èdè Nàìjíríà gẹ́gẹ́bí ó ti wà fún àwọn akẹgbẹ́ wọn lọ́kùnrin.
Nígbà tí mo dàgbà ní mo rí i pé oore ńlá ní Olorun ṣe mi pẹ̀lú aàbọ̀ ara mi- Bose Okeowo Èèyàn méjì àti ọkọ̀ 29 ló jóná níbi ìṣẹ̀lẹ̀ táńkà agbépo tó gbiná ní mọ́rosẹ̀ Eko sí Ibadan Ẹ gbà mí o!
Òun gan kò lè dúró de mi láéláé àmọ́ wọn tí se àwọn ọmọ wa léṣe gan."
Dandan ni bàyíì fún àwọn màálù ni Uganda láti gba ìwé ọjọ́ ìbí
Ọjọ Aje ni eto idibo naa tawọn ọmọ orilẹede Ghana ti tu yaya tu yaya jade dibo waye.
Mo ti fi gègé fín orúkọ rẹ sí àtẹ́lẹwọ́ mi,àwọn odi rẹ sì ńbẹ níwájú mi nígbà gbogbo.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù 774,000 Jobs: Muhammadu Buhari ti paá láṣẹ fún mínísítà fún ètò ìgbanisíṣẹ́ láti tẹ̀síwájú lórí ètò ìṣẹ́ 774,000 27 Òkùdu 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 14 Agẹmo 2020 Ààrẹ Muhammadu Buhari tí ti paá lásẹ fún mínísítà tó n ri si ọ̀rọ̀ iṣẹ́ àti ìgbanisíṣẹ́ lórílẹ̀- èdè Nàìjíríà láti tẹ̀síwájú lórí ètò ìgbanisíṣẹ́ ènìyàn ẹẹ́dẹ́gbẹ̀rin o lé mẹ́rìnléláàdọ́rin lábẹ́ ètò (SPW) ti àjọ NDE yóò sì máa mójú tó ètò náà.
Guinea ati Madagascar ninu idije AFCON ohun ni ilu merin otooto lorile-ede
N kò fi ojú ba oorun ní gbogbo òru,kí n lè máa ṣe àṣàrò lórí ọ̀rọ̀ rẹ.
" Oríṣun àwòrán, daddyfreeze Sugbọn awọn oko ọrọ ti Daddy Freeze fi ransẹ si gbajugbaja ojisẹ Ọlọrun naa lo fa ibinu ojisẹ Ọlọrun miran yọ, eyiun Ibiyeomie.
Buhari tun gbosuba fun aarẹ orilẹede Ghana, Akufo-Ado fun aayan rẹ lati gbogun ti iwa ijẹkujẹ to ti di arun jẹjẹrẹ to jẹ tọrọ fọnkale.
O ni ile oun ti EFCC ti pa naa wà ni Ọja Okeṣa ni Ado-Ekiti.
Ẹ kò gbọdọ̀ yí ìdájọ́ po, ẹ kò gbọdọ̀ ṣe ojuṣaaju, ẹ kò sì gbọdọ̀ gba àbẹ̀tẹ́lẹ̀; nítorí pé àbẹ̀tẹ́lẹ̀ a máa fọ́ ọlọ́gbọ́n lójú, a sì máa yí ẹjọ́ aláre pada sí ẹ̀bi.
Lẹ́yìn náà Abramu kúrò níbẹ̀, ó lọ sí orí òkè tí ó wà ní ìhà ìlà oòrùn Bẹtẹli, ó pàgọ́ sibẹ.
Ọlọrun kò bèèrè ohun tí eniyan kò ní.
igbimo asofin, ti asofin Ajayi Boroffice (Ondo North) si jẹ igbakeji rẹ.
Oró agbọ́n leè wo àìsàn jẹjẹrẹ ọmú sàn, wo ohun tí wàá lò pọ̀ mọ́ra wọn Minisita naa ni papakọ ofurufu Muritala Muhammed ti ilu Eko ati Nnamdi Azikiwe ti ilu Abuja yoo di ṣiṣi.
“Bi a bà jẹ̀kọ à dári ji Ewé”: À-lò-tún-lò
Apẹ̀rẹ̀ èso àjàrà kan ni a óo rí ká ninu ọgbà àjàrà sarè mẹ́wàá.
Ó bẹ̀rẹ̀ ó yọjú wo inú ibojì, ó rí aṣọ-ọ̀gbọ̀ tí ó wà nílẹ̀, ṣugbọn kò wọ inú ibojì.
Asoju naa wa ro orile ede 
High blood pressure: Lílo òògùn ẹ̀jẹ̀ ríru sùn lálẹ́ ló lè mú un ṣiṣẹ́ jùlọ
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Jega: Àwọn olùkọ́ fásitì sisẹ́ fáwọn olóṣèlú láti sèrú ìbò 17 Ìgbé 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 18 Ìgbé 2019 Oríṣun àwòrán, @Prof_AJega Alaga tẹlẹ fun ajọ eleto idibo nilẹ wa, Ọjọgbọn Attahiru Jega ti n naka aleebu sawọn olukọ ileẹkọ fasiti nilẹ wa pe awọn ni igi wọrọkọ to n da ina ru, nidi eto idibo ta sẹsẹ di ksja yii.
Isakoso re fun osu meji ni o ti yan Ogbeni Kamara gege-bi minisita fun eto esuna owo.
Èyí yóo jẹ́ ìlànà ati òfin fun yín láti ìrandíran yín níbikíbi tí ẹ bá ń gbé.
Ṣugbọn bí ọkọ rẹ̀ bá lòdì sí ẹ̀jẹ́ náà lẹ́yìn èyí, ọkọ náà ni yóo ru ẹ̀bi ẹ̀ṣẹ̀ obinrin náà nítorí pé kò jẹ́ kí ó san ẹ̀jẹ́ rẹ̀.
Obayi wa fi kun pe, ijoba apapo ti fowo si iwe adehun
O ṣiṣẹ to fi di akọwe agba lọdun 2012 nileeṣẹ adari ẹka oṣiṣẹ ọba ni Naijiria Ọkọ Toyin Abraham pẹ́ ọ̀rọ̀ sọ lórí aáwọ̀ láàrin ìyàwó rẹ̀ àti Lizzy Anjori 'Torí N2,500 owó irun, ọmọ Fásitì EKSU gún ọ̀rẹ́kùnrin rẹ̀ pa Ìjọba Nàìjíríà mọ̀ọ́mọ̀ fẹ́ tẹ ẹ̀tọ́ ṣòwòrẹ́ mọ́lẹ̀ ni-Amnesty International Ṣòwòrẹ́, káàbọ̀ ságbo àwa tí wọ́n ti fẹ̀sùn kàn rí -Soyinka Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, South Africa: Àwọn ọmọ Nàìjíríà tó kù ní ìjọba SA ń kó ọ̀pọ̀ tó fẹ́ wále sí ọgbà ẹ̀wọ̀n Oun lo jẹ oludari ni ẹka iroyin nile aarẹ ni olu ilu orilẹede yii laarin ọdun 2012 si ọdun 2014.
92 odun 2017, ju bi o se wa 1.
 Àwọn orílẹ ̀ -èdè àgbáyé gbìyànjù láti pẹ ̀ tù sí wàhálà yìí .
Ní kutukutu òwúrọ̀ ọjọ́ kinni ọ̀sẹ̀, wọ́n wá sí ibojì, wọ́n mú òróró olóòórùn dídùn tí wọ́n ti tọ́jú lọ́wọ́.
 Okiki Afolayan Okiki Lawrence Afolayan jẹ́ gbájúgba oludari eré ti ọ̀ps ènìyàn kò sì mọ̀ wọ́n nítori wọ́n sába máa n wà lẹ́yìn ìtàgé O tí dari eré tó lé ni àádọ́jọ."
'Obinrin jẹ amuludun' 'Obinrin lo mu mi fẹran orin kikọ' 'Awọn obinrin nilo ajọ iranwọ fun oṣelu' ‘Ẹsẹ kikan kọ mi lati di alagbara’ Richard Moore to jẹ ọkọ ati olukọni fun Ramla sọrọ lori igbagbọ rẹ nipa ki obinrin ni ominira lati ṣe ohunkohun to ba wuu fun itẹsiwaju.
Àwọn ìròyìn mìíràn tí ẹ lè nífẹ̀ẹ́ sí Ilé ẹjọ́ rán ọjọ̀gbọ́n fasiti OAU lọ sẹ́wọ̀n ọdún méjì Iléẹjọ́ fi Ọ̀jọ̀gbọ́n tó bèérè fún ìbálòpọ̀ ní fásitì OAU pamọ́ sọ́gbà ẹ̀wọ̀n Àjọ ọlọpàá Eko kédé pé ìbalòpọ̀ nítà kò bójúmu Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Gbara rẹ sile Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
N kò le è dìbò yan Buhari tàbí Atiku ní olórí mi láéláé - Soyinka Soyinka: Ọ̀pọ̀ ìgbà ni ayédèrú ìròyìn ti pa mí A kò ṣẹ̀ṣẹ̀ jọ máa pàdé ara wa!
Lọwọlọwọ bayii orilẹede Ghana, to mule ti ilẹ wa Naijiria ti sọ agadagodo sawọn ẹnu ọna ileẹkọ rẹ, to fi mọ awọn ileẹkọ giga fasiti, titi di ọjọ mii, ọjọ re.
Ikọ iroyin BBC to wa ni ipinlẹ́ Ekiti ni, ajọ NBC pasẹ pe ki wọn ti ileesẹ igbohun-safẹfẹ naa pa nitori pe o n hu awọn iwa to tako ofin isẹ igbohunsafẹfẹ.
Ẹni tí ó bá fẹ́ràn arakunrin rẹ̀ ń gbé inú ìmọ́lẹ̀, ohun ìkọsẹ̀ kò sí ninu olúwarẹ̀.
Bayọde di ẹni akọkọ ti yoo ṣe iru ẹyi ni ileikawe YouRead to wa ni Yaba, l'Eko lago mẹta-abọ lọjọ Abameta.
Ní ọjọ́ kẹta ati ọjọ́ keje, yóo wẹ ara rẹ̀ pẹlu omi ìwẹ̀nùmọ́, yóo sì di mímọ́.
Gomina Yahaya Bello ti Kogi àti David Lyon ti Bayelsa gba ìwé ẹ̀rí INEC Ọkan ninu ibeji to lẹpọ ye isẹ abẹ ni Bauchi Ayẹyẹ ọdún ìbejì dùn, ó lárinrin nílùú Igbó-ọrà Ìbejì yóò mú àìsàn bá òbí tí kò bá gbé wọn jó kiri - Àwọn ìbejì Àkọlé àwòrán, Ko si ẹni to le ya wa layelaye Awọn ọkọ awọn mejeeji to jẹ pasitọ ijọ Olorun naa ni awọn ti gba wọn papọ ati pe ọrọ awọn jọ ye ara wọn ni Ojo kan naa ni wọn jọ ṣe igbeyawo, ọjọ kan naa ni wọn tun jọ bimọ laiki n ṣe pẹlu iṣẹ abẹ.
Ẹ óo rí i bí yóo ṣe gbà yín là lónìí; nítorí pé àwọn ará Ijipti tí ẹ̀ ń wò yìí, ẹ kò tún ní rí wọn mọ́ laelae.
Charles Okah gba'dajọ ẹwọn gbere Lush beauties: Ara sisan kii n ṣe arun Oríṣun àwòrán, Reuters Àkọlé àwòrán, Ọgbẹni Rex Tillerson ni ikilọ ti Amẹrika se kii se ọgbọn ati di ọna mọ owo orilẹede China ti o n regun silẹ Afirika O ni ewu to wa ninu rẹ ni wi pe orilẹede to ba kuna lati san owo to ya pada lasiko lee padanu awọn ohun amayedẹrun gbogbo to na owo le lori.
Ni ilu Akurẹ tii ṣe olu ilu ipinlẹ Ondo, nṣe ni pasitọ kan gbiyanju lati fo fẹnsi to yi ijọ rẹ ka nibi to ti n gbiyanju ati sa mọ awọn agbofinro ikọ amuṣẹya lori ofin gbele ẹ ti ijọba ipinlẹ Ondo gbe kalẹ lọwọ.
 O doloogbe lojo Abameta to koja.
Olùrànlọ́wọ́ pàtàkì sí ààrẹ Muhammadu Buhari lóri ìgbóhùn sáfẹ́fẹ́ Garba Sheu, sàlàyé ọ̀rọ̀ náà nínú àtẹjáde kan to fi síta.
Coronavirus: Èèyàn 49 tó bá ọmọ orílẹ̀èdè Italy tó kó coronavirus Nàìjíríà wọ bàlùú làjọ WHO ti rí, wọ́n ń wá èèyàn 35 míràn Oríṣun àwòrán, Getty Images Ijo wa ajọ jo, awẹ wa ajọ gba ni ọrọ gbigbogun ti arun Coronavirus bayii.
 síbẹ ̀ náà ẹ ̀ rù kò bà á , àyà kò fò ó .
Oríṣun àwòrán, @others Àkọlé àwòrán, Buhari kirun Jimoh laiṣe igbeyawo gẹgẹ bi awọn kan ṣe n sọ kiri Iroyin naa ni Hajiya Sadiya Umar Farouq ni aarẹ fẹ gbe ni ọsingin ni eyi ti awọn eniyan si fẹ mọ sii nipa rẹ pe Ta ni Sadiya Umar Farouq tí ìròyìn ẹlẹ́jẹ̀ ń gbé pé òun ló fẹ́ dí ìyàwó tuntun Buhari?
Abẹ́rẹ́ àjẹsára Covid-19 yóò dé sí Nàìjíríà nínú oṣù kíní ọdún 2021 Ìpínlẹ̀ Kano Ní ìpińlẹ̀ Kano tó ni àwọn akẹ́kọ̀ọ́ tó pọ̀ jùlọ ni agbègbè náà, ọjọ́ Isẹgun ni wọ́n pa á láṣẹ láti ti ilé ẹ̀kọ́.
" Àlàyé rèé lórí bí wọ́n ṣe mú mi lẹ́rú ní 1837 - Ajayi Crowther Ìkúnlẹ̀ àbiyamọ o!
Amọ ṣa ileesẹ wa kò ti ribi fidi ọrọ bayi mu'lẹ.
Ọmọbinrin yìí sì bí ọmọkunrin kan fún un tí orúkọ rẹ̀ ń jẹ́ Segubu.
wa de gongo imu bayi, ni eyi ti a si nilo lati mu lele eto aabo aarin ilu ati
Bakan naa, Harris jẹ ẹni ti ẹ o le wa ọrọ ti lẹnu ẹ koda Donald Trump gan ti gbọ iṣẹẹ rẹ wo ri.
Yọmi Fabiyi lo kọ ere naa, Abbey Lanre lo si dari rẹ.
OLUWA Ọlọrun ní: “Ẹ káwọ́ lérí kí ẹ máa fi ẹsẹ̀ janlẹ̀, kí ẹ sì wí pé, ‘Háà!
Argentina v Nigeria 12 June 2010 (1-0) Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, ife ẹyẹ agbaye FIFA ti ọdun 2018 ni yoo jẹ igba kẹfa ti orilẹede Naijiria ati Argentina yoo maa waako ninu idije FIFA fun awọn agbalagba agbabọọlu lagbaye Ni ọdun 2010 ni ikọ Super eagles ati Argentina tun pade ara wọn ni idije ife ẹyẹ agbaye FIFA to waye lorilẹede South Africa.
Ọdun 2007 ni idibo ijọba ibilẹ waye kẹhin lasiko ti Adebayọ Alao Akala fi wa ni ipi gomina.
Ẹbi ati ara gbajugbaja oṣere, Oloye Abdul Tawab Olaitan Ile-Aje Adeniyi ti kede iku rẹ ni ẹni mẹtalelọgọta.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Rehab Homes: Ọmọdébìnrin kan sọ bí òun ṣe di ẹ̀rọ ìbálòpọ̀ níbùdó aláìgbọràn 27 Ọ̀wàrà 2019 Oríṣun àwòrán, @nigeria_true Obinrin kan, ẹni ogun ọdun ti ori ko yọ nile awọn ọmọ alaigbọran to wa nilu Ilọrin, Laide Arikewuyọ, ti salaye ohun ti oju rẹ ri lasiko to wa nile naa.
Nimrodu yìí ni ẹni kinni tí ó di akikanju ati alágbára lórí ilẹ̀ ayé.
 james cathedral , oke bola , nílùú Ìbàdàn láti lo ọkàn , ọwọ ́ , àti ẹ ̀ yà ara gbogbo láti fi sin jesu kristi .
Ibùsùn tí ó bá dùbúlẹ̀ lé lórí, ní gbogbo ọjọ́ tí nǹkan yìí bá fi ń dà lára rẹ̀ yóo jẹ́ aláìmọ́; ohunkohun tí ó bá sì fi jókòó di aláìmọ́ gẹ́gẹ́ bíi ti àkókò tí ó ń ṣe nǹkan oṣù rẹ̀.
 gbogbo bọ ́ ọ ̀ lù tí ó gbá nínú ìdíje league jẹ ́ mẹsàán tí ti challenge cup sì jẹ ́ mẹ ́ rin nínú ìpele ìbẹrẹ ̀ ọdún .
Ọkùnrin kan da ṣọ́ọ̀ṣì rú lásìkò ìgbéyàwó, Ó ní òun lọkọ àárọ̀ ìyàwó tuntun Mi ò fẹ́ ìrànwọ́ ẹgbẹ́ òṣèré, àwọn kọ́ ló kóbá mi- Chief Kanran Ohun tí a mọ̀ nìyí nípa gbọ́nmi síi omi ò tó lórí ọ̀rọ̀ oyè Babaloja-General ní ìpínlẹ̀ Oyo YWC yọ Ààrẹ Banji Akintoye nípò àbi Akintoye tú ìgbìmọ̀ aláṣẹ YWC ká?
Ní ọjọ́ kan, bí Jakọbu ti ń se ẹ̀bẹ lọ́wọ́ ni Esau ti oko ọdẹ dé, ebi sì ti fẹ́rẹ̀ pa á kú.
Bí wọn bá ti gbọ́ èyí, ohun tí ó ń ṣe wọ́n tán.
Wọn yóo di ẹni ìfibú, ẹni àríbẹ̀rù, ẹni ègún ati ẹni ẹ̀sín.
Eeyan melo lo mọ to fẹ dije gomina ladugbo rẹ ?
Aṣọ inujú yìí ni wọ́n máa ń pè ní “àkísà”, èyí tí wọn máa fi ń nu àágùn bí wọ́n bá ń “fò sókè”.
Bakan naa la gbọ wi pe orin asalatu ọlọpẹ lo gba ẹnu awọn abọde ilẹmimọ naa kan ni kete ti koowa wọn n sare bọ silẹ lati inu baluu naa.
Ṣugbọn ìwọ, wọ aṣọ oyè rẹ.
Ni bayii, awọn olugbe Kaduna, Kasuwan Magani, Kajuru to fi mọ Kateri ati Kachia ni idapada konileogbele yi kan bayi.
O ni O lodi si ofin ati pe ijiya n bẹ fun ẹnikẹni ti ọwọ ofin ba tẹ pe o wọ aṣọ ologun ti ko si jẹ ọkan lara ọmọ ogun Naijiria."
"Lasiko iwadii, wọn ti mu ẹni to ni sọọbu Sharwama Chimezie Amaechi, ọrẹ oloogbe Kazeem Okikiola, alabojuto ile ọti naa, Olayinka Oyedokun ati awọn ọrẹ rẹ Femi Victor, Taiwo Morokola ati Omole Wasiu.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù #KẹmiAdeọṣunNYSC: Ìwádìí yóò bẹ̀rẹ̀ lóri ayédèrú iwé 8 Agẹmo 2018 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 10 Agẹmo 2018 Oríṣun àwòrán, NYSC/twitter Àkọlé àwòrán, Wọn ni ìwádìí yóò bẹ̀rẹ̀ ní perewu láti mọ bi omi ṣe tẹ̀yìn wọgbín lẹ́nu lóri ọ̀rọ̀ náà.
oludari ikọ  naa  lalejo nile aare to wa niluu Abuja lojoBọ ,ni
L'oṣu Kinni ọdun 2016, ni Palmatah ati awọn akẹkọọ meji mi i to bọ lọwọ Boko Haram, bẹrẹ eto ẹkọ wọn ni ileewe Community College kan ni Washington.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, EndSars Protest:Ọ̀gá Àgba Ọlọ́pàá ṣàbẹ̀wò sí ìpínlẹ̀ Eko lẹ́yìn ìfẹ̀họ́núhàn EndSars Owolewa gbegba oroke ninu odibo naa lẹyin to fi ẹyin awọn alatako rẹ, Joyce Robinson-Paul ati Sohaer Syed gbolẹ.
Oríṣun àwòrán, Air peace Àkọlé àwòrán, Baluu Air Peace ṣetan lati gbe àwọn eniyan Naijiria Alaye yii lo tẹnu alaga igbimọ to wa fun ibojuto ọrọ ọmọ Naijiria loke okun, Abike Dabiri jade ni ilu Abuja lọjọ Aje.
Ababọ esi idbo yi ni yoo tọka awọn oludije ti yoo kẹru kuro ninu ile ẹlẹgbọn agba.
Biden to kede bẹ́ẹ́ ninu atẹjade kan to fisita lori rogbodiyan Naijiria wa sọ̀ fun Buhari atawọn ologun lati dawọ ipaniyan naa duro.
 Bee si ni, bi a ba ri pe ede geesi ati ede faranse n figagbaga laarin ara won, anfaani n la lo je bi eniyan ba ni oye ede mejeeji,” Ewe, oludari agba eka iroyin nile ise Voice of Nigeria, ogbeni Ahaziah Suleiman so pe, ayeye ifigagbaga ere itage ni ede faranse laarin awon ile-eko sekondiri lorile-ede Naijiria ni won sagbekale re lojuna ati gba awon ile-iwe niyanju lati ma a tesiwaju ninu kiko awon akeeko ni ede faranse nile eko won kookan.
Ikú Ope Bademosi la ṣe fagilé ọdún Ekimogun 2018 Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ìnú mi kìí dùn nígbà trí mo ń ṣiṣẹ́ ni bánkì tó ìgbà ti mo bẹ̀rẹ̀ mẹkáníìkì Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 3 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 5 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Oríṣun àwòrán, Instagram/queenola2 Sọọbu onibeji, nibi ti wọn yoo ti maa ta asọ ati se ara loge si ni ayaba naa sẹsẹ fẹ si, nibiti wọn yoo ti maa se eekanna, din irun, lu eti, imu ati se irun lọsọ.
orile-ede FranceGuingamp 1-3 Marseille Nice 0-1 Caen Nimes 2-1 Bordeaux Strasbourg 1-3 Montpellier Nantes 3-2 Amiens Toulouse 0-0 Lille Reims 0-2 Saint-Etienne Paris Saint-Germain 3-1 Monaco Idije Bundesliga(Germany) Freiburg 0-4 Borussia Dortmund Hertha BSC 0-0 Hannover 96 Mainz 05 3-1 Fortuna Düsseldorf Bayer Leverkusen 2-0  FC Nürnberg Augsburg 6-0 VfB Stuttgart FC Bayern München 1-0 Werder Bremen Borussia Mönchengladbach 1-2 RasenBallsport
O ṣalaye pe awọn ẹgbẹ oṣelu PDP lo n ṣe ipolongo ibo wọn ni ilu Ọba Akoko nigba ti ẹgbẹ oṣelu APC n kọja laarin ilu naa lọ si ilu Ikare Akoko.
Àkọlé àwòrán, Ẹgbẹjẹgbẹ ati awọn iyalode naa kọ gbẹyin nibi ayẹyẹ ojo ibi ọdun mọkandinlaadọrin ti gomina ipinlẹ Ọyọ, Sẹnetọ Abiọla Ajimọbi.
ni ipade ohun ni yoo tun gbe awon akonimoogba mejeeji pade ara won lati igba ti
Ọpọlọpọ ere ibilẹ Yoruba lo ti kopa oun naa si ti ṣe agbejade ere tirẹ gangan.
Bi o ba ṣe pe ki ẹ tẹni si abẹ igi ni tabi ki ẹ duro ni faranda yin, eyi ko ni mu ki isẹ tete su u yin.
Jehoiada kò fẹ́ kí wọ́n pa Atalaya ninu ilé OLUWA, nítorí náà ó pàṣẹ fún àwọn olórí ogun, ó ní, “Ẹ mú un jáde, kí ó wà ní ààrin yín bí ẹ ti ń mú un lọ; ẹnikẹ́ni tí ó bá fẹ́ gbà á là, pípa ni kí ẹ pa á.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ta ni Naira Marley jẹ́ gan?
Mo fẹ́ kí ẹ mọ̀ dájúdájú pé, ẹni tí ó bá gba ẹnikẹ́ni tí mo rán níṣẹ́, èmi ni ó gbà.
Duro Ladipọ, ìlúmọ̀ọ́ká òṣèré tíátà àti ọmọ àlúfà tí kò gbàgbé àṣà ìbílẹ̀ Hubert Ogunde rèé, baba àwọn òsèré tíátà Botilẹ jẹ pe ile igbimọ aṣoju-ṣofin sọ pe ẹdà iwe naa to wa lọwọ oun ko sọnu, oriṣi aba owo iṣuna meji lo wa nita.
Ní ọdọọdún ni wọ́n máa ń ṣọ́nà ní òru ní ìrántí òru àyájọ́ ọjọ́ náà.
Wọn óo máa pa akọ mààlúù rẹ lójú rẹ, o kò ní fẹnu kàn ninu rẹ̀.
Koda, ọrọ naa le debi i pe ọna ẹburu ni a n gba rira lẹẹkan l'oṣu mẹfa.
O si ṣeleri pe oun ko ni ṣe bẹ ẹ.
Ìfihàn tí a fi fúnni nípasẹ̀ Wòlíì Joseph Smith sí Oliver Cowdery, David Whitmer, àti Martin Harris ní Fayette, New York, Oṣù Kẹfà 1829, síwájú kí wọ́n ó tó wo àwọn àwo tí a fín nínú èyí tí àkọsílẹ̀ Ìwé Ti Mọ́mọ́nì wà.
 gbólóhùn lè wà ti yóò bá òfin mu sùgbon tí ó lè máà jé àtéwógbà fún àwon tí ń so èdè .
Mú mi pada, kí n lè pada sí ààyè mi,nítorí pé ìwọ ni OLUWA, Ọlọrun mi.
Nígbà tí Saulu dé ibi tí àwọn agbo aguntan kan wà lẹ́bàá ọ̀nà, ó rí ihò àpáta ńlá kan lẹ́bàá ibẹ̀, ó sì wọ inú rẹ̀ lọ láti sinmi.
Àwọn ọkunrin tí wọ́n lọ ṣe amí náà bá wọlé, wọ́n mú Rahabu jáde, ati baba rẹ̀, ati ìyá rẹ̀, ati àwọn arakunrin rẹ̀, ati gbogbo àwọn ìbátan rẹ̀, wọ́n sì kó wọn sí ẹ̀yìn àgọ́ àwọn ọmọ Israẹli.
Bakan naa ni eto orin iyin ati adura waye lati mu ki ijọ̀ba gomina Seyi Makinde se aseye ti alakan n sepo.
Olórí àwọn tí wọn ń tu ọkọ̀ wá sí ọ̀dọ̀ rẹ̀, ó wí fún un pé, “Kí ló ṣe ọ́ tí ò ń sùn, olóorun?
wọ́n ń sọ pé, “OLUWA kò rí wa;Ọlọrun Jakọbu kò ṣàkíyèsí wa.
” Ọba bá dúró ní ẹnu ibodè, bí àwọn ọmọ ogun rẹ̀ tí ń tò kọjá lọ ní ọgọọgọrun-un (100) ati ẹgbẹẹgbẹrun (1,000).
Mo rí i nígbà tí ó tú èdìdì kẹfa pé ilẹ̀ mì tìtì.
 Femi, ẹni tó kọ orin Sakara lórí ayélujára lásìkò ígbélé Covid-19 yìí ni, òun kò ní ẹ̀bùn orin kíkọ, àmọ́ osere gidi yẹ kó leè dibọn, kò sì farajọ ẹni tó ń sìn jẹ́."
Usman Mohammed tó jẹ alága ilé iṣẹ to ń pin ina mọnàmọná sí ilé tó n fún ojúle kọ̀ọ̀kan ni ina mọnàmọ̀nà (TCN), jẹ́ ọkàn nínú àwón tó n ké gbàjàre pé ki ìjọba gbé igbésẹ ti yóò so eso rere láti wá ojúutu si isòrò airina lò náà to sọ orílẹ̀-èdè yiìí sínú òkùnkun.
 kì í ṣe orílẹ ̀ èdè mẹ ́ ta yìí nikan ni yorùbá wà .
85) ran ipolongo mi lowo lodun 2015.
Loṣu to kọja ni ileeṣẹ to n risi ọrọ Hajji ati Umrah gbe awọn ilana mẹjọ kan jade ti yoo de sise Hajj ọdun 2020 kalẹ.
Boo ba ko nkan ọgbin bii ewe atawọn aworan tabi nkan ti Ọlọrun da wọ inu ile rẹ too ti n ṣiṣẹ, o lee ko ipa gidi.
Amọ, Ajọ Amnesty International ko le e sọ pato, boya orilẹede ti ogun ti n sẹlẹ lọwọlọwọ bii Libya ati Syria n se idajọ iku fun awọn eniyan.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ruga Settlement: Ààrẹ Muhammadu Buhari ti dá èròǹgbà láti dá àgọ́ daran-daran sílẹ̀ dúró 3 Agẹmo 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 4 Agẹmo 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Ileeṣẹ aarẹ Naijiria ti fidi rẹ mulẹ fun BBC pe Aarẹ Muhammadu Buhari ti da erongba lati ṣe idasilẹ Agọ daran-daran, RUGA, silẹ duro.
Awọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Akeredolu, aya àti ẹbí rẹ̀ ló ń ṣèjọba ni mo ṣe fipò sílẹ̀ - Akọ̀wé ìjọba tẹ́lẹ̀ l‘Ondo Àlàyé rèé lórí ìdí tí Magu àti awọn alága EFCC míràn ṣe bá ìtìjú kúrò nípò Àwọn ẹlẹ́sìn ìbílẹ̀ ń bèèrè owó lọ́wọ́ àwọn Alfa lórí ìsìnkú ẹni tó pokùnso Hushpuppi di gbajúmọ̀ ẹlẹ́wọ̀n tó ní nọ́ńbà l‘Amẹrika, orúkọ̀ rẹ̀ wà lórí ayélujára Nǹkan tí ojú rí rè é bí pápákọ̀ òfurufú ṣe di ṣíṣí padà ní Nàìjíríà Ṣé lóòtọ́ ni Lateef Adedimeji àti Adebimpe Oyebade ṣe ìgbéyàwó?
Inú bí mi sí àwọn eniyan mi,mo sì sọ nǹkan ìní mi di ohun ìríra.
Ninu atejade kan, eyi ti o so pe, “o dabi pe, osise oun ti si lekun enu ona pajawiri naa sile, amo o seni laanu pe, “o jabo ninu oko oju ofurufu naa ti o ti gunle lalaafia”.
Awọn asofin okoolerugba ati mẹta, 223 lo dibo pe ki wọn yọ Trump laarọ ọjọru nigba ti asofin marunlerugba 205, ko fara mọ̀ igbesẹ naa.
Bẹ́ẹ̀ ni àwọn nǹkan wọn-ọnnì kò lè pẹ́ lọ́wọ́ rẹ̀, òun ní wọn kí ìwólulẹ̀ rẹ̀ baà lè pọ̀ gidigidi.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Police Brutality: Ojú mi rí tó lọ́wọ́ ọlapàá nítorí Múrí màrùn ún- Adebayo Olaide 4.
Se ni awọn agbofinro ọhun tun lo afẹfẹ tajutaju ati omi lati fọn awọn eeyan to n fẹhonu han naa ka, amọ ti wọn n lọ korajọ pọ si ẹgbẹ keji lai lọ sile koowa wọn.
Oríṣun àwòrán, Bauchi Àkọlé àwòrán, Wọn ṣalaye pe iwadii ti fidiẹmulẹ pe awọn ọmọ ati ẹbi rẹ wa ni alaafia lai ni aarun coronavirus.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù NFF: Olóògbé Taiwo Ogunjobi gbá bọ́ọ̀lù fún Nàìjírìa nígbà ayé rẹ̀ 11 Èrèlè 2019 Oríṣun àwòrán, NFF Àkọlé àwòrán, Taiwo Ogunjobi papoda Ọpọ lo n ṣedaro akọwe ajọ to n ri si ere bọọlu lorilẹede Nàìjíríà, NFF tẹ́lẹ̀rí, Taiwo Ogunjobi.
O ni oun dupẹ fun atilẹyin ti oun ti ri gba lọwọ awọn to ti wo fidio naa lori ẹrọ ayelujara Youtube.
Ko ti sọrọ naa tan ti awọn eeyan bẹrẹ si ni fun ni esi pada Ọrọ naa ṣi n ja rain-rain ti ko si ti si ni to mọ ibi ti yoo kangun si.
Ìgbáradì yóò gbérasọ l'Ekiti lọ́jọ́ Àìkú tó ń bọ̀
To ba jẹ ọkan lara awọn to maa n pẹ, ko to jẹun alẹ, ajẹ pe o ni lati tun ero ara rẹ pa.
Abumere/BBC Àkọlé àwòrán, The Jazzhole houses jazz music from different eras Orin Jazz ni iyi pupọ lawọn ọdun ogun si ọgbọn sẹyin ṣugbọn o ti di agbọnrin eṣi bayii.
Amotekun: Ọmọ ilẹ̀ China mẹ́jọ, ọmọ orílẹ̀èdè Ghana mẹ́ta wọ gàù Àmọ̀tẹ́kùn ní ìpínlẹ̀ Ọ̀ṣun Oríṣun àwòrán, Amiloaded O dabi pe erongba awọn ọmọ Yoruba lori idasilẹ ikọ alaabo Amọtẹkun ti bẹrẹ si ni fidi mulẹ bayii o.
Jehoṣafati, ọmọ rẹ̀ sì gorí oyè lẹ́yìn rẹ̀.
Abdullahi ni oun ti fibinu ká eyin lẹnu iyawo kí iroyin ija naa to kàn dé ọdọ awọn obi oun.
"Ifilọlẹ eto aabo alajumọse ti awọn gomina ẹkun iwọ oorun guusu Naijiria se agbatẹru rẹ, ti wọn pe ni ""Amọtẹkun"" ti gbinaya bayii."
kì í tún ṣe gẹ́gẹ́ bí ẹrú mọ́, ṣugbọn ní ipò tí ó ga ju ti ẹrú lọ, bí àyànfẹ́ arakunrin, tí ó ṣọ̀wọ́n fún mi, ṣugbọn tí ó ṣọ̀wọ́n fún ọ jù mí lọ, gẹ́gẹ́ bí eniyan sí eniyan ati gẹ́gẹ́ bí onigbagbọ.
Nígbà náà ni mo tẹríba, mo sì sin OLUWA, mo yin OLUWA Ọlọrun Abrahamu, oluwa mi lógo, ẹni tí ó tọ́ mi sí ọ̀nà tààrà láti wá fẹ́ ọmọ ẹbí oluwa mi fún ọmọ rẹ̀.
Ó sì tún gbọ́ ọ̀rọ̀ OLUWA ní ìgbà ayé Jehoiakimu, ọmọ Josaya, ọba Juda títí di òpin ọdún kọkanla tí Sedekaya ọmọ Josaya jọba ní ilẹ̀ Juda, títí tí ogun fi kó Jerusalẹmu ní oṣù karun-un ọdún náà.
Akọroyin BBC to ba awọn to wa nibẹ ni gbolohun fabọ jẹ ni pe ni kete ti wọn dawọ gbigba owo duro, ọna ṣi, igboke gbodo si n lọ bo ṣe yẹ ni wọọrọwọ.
"O fi kun un pe wamuwamu lawọn wa ''pẹlu aṣẹ igbimọ amuṣẹya ti gomina Mai Mala Buni dari bi aarẹ Buhari ṣe rọ awọn, ki awọn ọmọ ẹgbẹ l'Ekiti si rọra ṣe""."
Ikọlu yi waye lẹyin ọjọ diẹ ti awọn musulumi to pọ lagbegbe naa dibo lati faye gba iṣejọba tara wọn.
Bótilẹ̀ jẹ́ pé àwọn tí ọjọ́ orí wọn kéré le má fi àmì hàn, wọ́n le pín kiri láí mọ̀.
ami eye fun awon onise iwadii ati alatinuda eniyan pelu iye owo ti iye re le ni
"Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Fulani Kidnapping: Owó púpọ̀ la san kí wọ́n tó fi mi sílẹ̀ Bo tilẹ jẹ wi pe Elisha ti tọrọ aforijin pe ""Ẹ má bínú, mo kábàmọ́ pé mo na obìnrin -Elisha Abbo"" lọwọ awọn ọmọ orilẹede Naijiria, awọn abiyamọ, ati obinrin to na pe ki wọn fi ori ji oun, oun ko ni hu iru iwa aidaa bayii mọ, o f da bi ẹni pe eyi ko ta leti awọn ọmọ Naijiria."
Wọ́n ń sin oriṣa lásánlàsàn, àwọn pàápàá sì di eniyan lásán.
Ó yẹ ki wọn ronú bi wọn yio ti ṣe Ìjọba ti yio mu irọ̀rùn ba gbogbo ipinlẹ Nigeria.
Apapọ awọn to ti ni arun naa kaaakiri orilẹ-ede Naijiria ti wa di 16,082 bayii.
Yoruba ni iroyin ko to afojuba, ọkan lara awọn ile iwe ti ijọba Aregbesola pese, ti wọn si maa n tọka si ree: Oríṣun àwòrán, @raufaregbesola Àkọlé àwòrán, Osogbo High School Lara awọn aseyọri to tun wa ni akọsilẹ fun ijọba Arẹgbẹsọla lẹka ipese eto ẹkọ ni ipese ọpọn imọ (IPAD) fawọn akẹkọ ile ẹkọ girama.
Emi ati awon omo orile ede Naijiria dupe lowo yin pupọ.
ó bá pe gbogbo àwọn ọmọ Israẹli jọ, àwọn àgbààgbà, ati àwọn olórí, àwọn onídàájọ́, ati àwọn alákòóso, ó wí fún wọn pé, “Mo ti di àgbàlagbà, ogbó sì ti dé sí mi; 
Awọn ti a n wo mọ Ibadan lara ree laye isin'' Nigba ti BBC beere boya Covid-19 lo sokunfa iku olokoowo yi, Soladoye ni ohun ko le sọ sugbọn o ni arun Covid-19 ko jẹ ki ọpọ awọn agbalagba ko ribi gba itọju to yẹ.
A kó ní sanwó oṣú ASUU láìjẹ́ pé wọ́n gba IPPIS- Ìjọba Àpapọ̀ Ìdájọ́ ikú ló bá dé fáwọn méjì tó fipá bá ọmọ ọdún mẹ́rìnlá lò pọ̀ 'Àwọn ọlọ́pàá tó farapa nínú ìwọ́de EndSARS yóò gba ìgbéga, a ó ṣèrànwó f'ẹ́bí àwọn tó kú' Wo bí àwọn ọmọ Nàìjíríà ṣe n kí fún ìjọba nítorí $1.
Bẹẹ si ni iyawo rẹ, Adeola naa n dinju si, to si n na ika soke pe o kare lae fun bo se sọ ẹjẹ rẹ ọhun.
 stuart high school ní fairfax , ìlú virginia .
Jakejado agbaye,Naijiria ni orileede to wa ni ipo kẹjọ.
" Kíni ẹ mọ̀ nípa àwọn gbajúgbaja Yollywood?
Dafidi ati gbogbo ọmọ Israẹli lọ sí ìlú Baala, tí à ń pè ní Kiriati Jearimu, ninu ilẹ̀ ẹ̀yà Juda, wọ́n lọ gbé Àpótí Majẹmu tí à ń fi orúkọ OLUWA pè, OLUWA tí ó jókòó, tí ó fi àwọn Kerubu ṣe ìtẹ́.
Àwọn olórí alufaa ati gbogbo Ìgbìmọ̀ ń wá ẹ̀rí tí ó lòdì sí Jesu, kí wọ́n baà lè pa á, ṣugbọn wọn kò rí.
Wọn gbe Ọgbeni Adam lọ sile iwosan nibi to ti faye silẹ nitori bo se sese lowuro kutu-kutu Ojoru.
Bẹ́ẹ̀ ni irọ́ ni: àparò tí ó bá ń fi ara rẹ̀ wé àgbébọ̀ ń fi ikú ṣiré, ọmọdé tí ó bá ń fi ara rẹ̀ wé àwọn agbàlagbà ń fa ìjàngbọ̀n lẹ́sẹ̀ nítorí inú ọmọdé ń bẹ́ lóké bẹ́ẹ̀ ni inú àwọn àgbàlagbà jìn ó ju omi òkun lọ.
Ni ọjọ kẹẹdogun oṣu kẹwa ọdun 2018 ni wọn kede pe arabinrin Meghan ti fẹraku, iyẹn lasiko abẹwo wọn si orilẹede Australia ati New Zealand.
Dhul Hijjah: Ninu oṣu yi lawọn musulumi maa n ṣe irinajo Hajji lọdọọdun.
Eyi ko sẹyin bi Ajọ Ilera Lagbaye, W.
Ṣé Ijipti ni ó gbójú lé pé yóo ran òun lọ́wọ́?
N óo ṣàánú ẹni tí a tí ń pè ní ‘Kò sí àánú’,n óo sì sọ fún ẹni tí a tí ń pè ní ‘Kì í ṣe eniyan mi’ pé eniyan mi ni;òun náà yóo sì dá mi lóhùn pé,‘Ìwọ ni Ọlọrun mi.
 Buhari ni alase rẹ ọhun ti ọpọ mọ si 'Commander' jẹ ẹni to tọju ile oun ni ilu Daura nipinlẹ Katsina daadaa ti ko si jẹ ki iya jẹ idile oun."
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, APC Primaries: 'Kò sí 'Faction' ni Kwara APC rárá, NWC ti sọ̀rọ̀' Dapọ Abiọdun jáwé olúbori pẹ̀lú ìbò ẹgbẹ̀rún lónà ọgọ́rùn o lé méjì àti márùnlélọ́ọ̀dúrúǹ, nígbà ti Jimi Lawal to pọwa lée ní ẹgbẹ̀rún mọ́kànléní ààdọ́ta àti ẹ̀tàléláàdọ́jọ, Bimbo Ashiru tó ní ìbò ẹgbẹ̀rún makàndínlọ́gbọ̀n àti ẹ̀rìnlélọ́gọ́talélẹ́ẹ̀dẹ̀gbẹ̀rin.
Imam agba to wa niluu Ilorin, Muhammed Soliu Bashir ati awon onimo ninu eko Islam lo wa nibi adura ikeyin naa.
Ìṣẹ abẹ ikebe nla ti Brazil (BBL) jẹ ọkan lara awọn ọna ti awọn obinrin fi n ṣafikun ẹwa ẹya ara paapaa idi wọn ko lè tobi sii.
Orilẹede Amẹrika lo fi ṣe ibugbe, amọ ilu Auchi nipinlẹ Edo ni wọn ti bi Usman, lọjọ kọkanla oṣu karun un ọdun 1987.
Ileeṣẹ aṣoju ijọba Amẹrika lorilẹede Naijiria ti kan sara si Onyema Ogbuagu to jẹ dokita iṣegun oyinbo kan.
Ikọgosi Ekiti: Itan nipa omi gbigbona ati omi tutu
bi ipade naa se n lọAdemola Adepoju.
Minisita ni oṣuwọn idagbasoke ọrọ aje ni Naijiria laarin oṣu mẹta to kọja, GDP ko wu ni lori rara.
Ninu awọn aṣa isinku lati gbọ pe awọn kan a ma ni ki wọn sin eeyan pẹlu ọba to ba ku iyẹn ta mọ si abọbaku.
 Bee si ni awon miiran gba igbega lati inu idije Nationwide League One (NLO), ti awon miiran si ra aaye iko agbaboolu miiran lati darapo mo idije ohun.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ọmọ Ọgọta Ọdún kú sórí obínrin ní ilé ìtura ní Èkó 25 Owewe 2019 Oríṣun àwòrán, @Leohoppus Àkọlé àwòrán, Orisírísí nkan lo maa n ṣẹlẹ lori ibusun ṣugbọn bii ti ere ifẹ di ero ọrun kọ ni kal;uku fẹ.
Alhaji Lai Mohammed ti kọkọ kede wi pe awọn akẹkọbirin mẹrindinlọgọrin ni ikọ Boko Haram tu silẹ l'owurọ Ọjọru ki wọn o to kede wi pe mọkanlelọgọrun ni awọn akẹkọbirin ti wọn da silẹ.
koju iko ti o ba jawe olubori ninu iko agbaboolu Porto ati Liverpool nipele ti
Nigba ti Akintola wa ni kekere ni baba rẹ to jẹ oniṣowo ko ẹbi rẹ lọ si ilu Minna.
OLUWA yóo fẹ́ràn ìwọ náà, yóo sì dúró tì ọ́.
5m owó oúnjẹ El-Zakzaky lè bọ́ ẹlẹ́wọ̀n 208 ní oṣù kan Ikọ̀ aláàbò Nàìjìríà dojú kọ Shiite Ọmọlẹ́yín El Zak-zakky ṣè‘wọ́de ní Ábújá Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Obasanjo: Atiku kìí se Áńgẹ́lì, àmọ́ yóò se dáadáa ní ìlọ́po méjì ju Buhari lọ Ninu ọrọ rẹ, Falana ni airi itọju to peye lasiko ni Elzakzaky se padanu oju rẹ kan, ati wi pe ọta ibọn si wa lara iyawo rẹ.
O dije dupo aṣojuṣofin, o si wọle lati ṣoju awọn eniyan ẹkun ila oorun ipinlẹ Ogun nibi to ti ni ibo 99, 540 lati bori akẹgbẹ rẹ ti wọn jọ dije dupo.
Oríṣun àwòrán, BBC Sport Àkọlé àwòrán, Man City n lewaju Ninu awọn ifẹsẹwọnsẹ miran to n waye wọn yi ni esi ti a ri ni abala kini Brighton1 Man City 2 Burnley 0 Arsenal0 Crystal Palace 3 Bournemouth 0 Fulham 0 Newcastle 2 Leicester0 Chelsea 0 Liverpool 1 Wolves 0 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 3 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 5 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Gomina ipinlẹ Osun fi ikilọ yii lede lasiko to n ba awọn oniroyin sọrọ ni ile ijọba ni ilu Osogbo.
Òkú ọmọ tuntun pòórá nílé ìgbókúpamọ́sí nílùú Akurẹ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Nígbà tí mò ń wà Awolowo, Gowon, Babangida, mo fi ara mi sípo ọ̀wọ̀ tóri .
Ẹ wá ń sọ pé, ‘Bí ó bá jẹ́ pé a wà ní ìgbà àwọn baba wa, àwa kò bá tí lọ́wọ́ ninu ikú àwọn wolii.
Lẹ́yìn ọjọ́ mẹta Farao yóo yọ ọ́ jáde, yóo dáríjì ọ́, yóo sì fi ọ́ sí ipò rẹ pada, o óo sì tún máa gbé ọtí fún Farao bíi ti àtẹ̀yìnwá.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ronke Oshodi Oke: N kò ṣe mọ́na-mọ̀na púpọ̀ ni ìgbéyàwó mi ṣe tọ́jọ́ 14 Ẹrẹ̀nà 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 31 Agẹmo 2020 Oríṣun àwòrán, Instagram/ronkeoshodioke Gbajugbaja oṣere tiata, Ibironke Ojo-Anthony, ti gbogbo eniyan mọ si Ronke Oshodi-oke, ti sọ idi ti ọpọ igbeyawo awọn oṣere fi n fori sanpọn.
OLUWA àwọn ọmọ ogun, Ọlọrun Israẹli ní, “Lẹ́ẹ̀kan sí i, wọn yóo tún máa lo gbolohun yìí ní ilẹ̀ Juda ati ní àwọn ìlú rẹ̀, nígbà tí mo bá dá ire wọn pada, wọn óo máa wí pé,‘OLUWA yóo bukun ọ, ìwọ òkè mímọ́ Jerusalẹmu,ibùgbé olódodo.
” Ó bá lọ tọ́jú kẹ̀kẹ́ ogun, ati àwọn ẹlẹ́ṣin ati aadọta ọkunrin tí yóo máa sáré níwájú rẹ̀.
Ki lo ṣẹlẹ ni idibo abẹlé Kwara tẹlẹ?
paapaa julo ni eka ila oorun orile-ede yii.
Ojú ẹni tí ó rí mi nisinsinyii kò ní rí mi mọ́;níṣojú yín báyìí ni n óo fi parẹ́.
O ni awọn ẹya kan wa to maa n dide iranwọ si ẹbun ẹni.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Kogi Election: Dino Melaye náà pariwo pé àwọn apanìyàn ti gbòde ní ìbò ku ọ̀la 15 Bélú 2019 Oríṣun àwòrán, Dino Melaye Nibayii ti eto idibo gomina ni ipinlẹ Kogi ku wakati mẹrinlelogun ko bẹrẹ, oniruuru ariwo ni awọn oloselu kan ti n fi sita nipa ihuwasi awọn janduku to gboke.
O ni nikete ti oun di gomina loun ti sọ ọ fun ara oun pe oogun ti Jonathan lo lori ọrọ Sanusi ṣe pataki pupọ.
Ṣùgbọ́n nnkan tí o tún sẹlẹ lẹ́yìn èyí mú kí emi àti oun da ẹ̀yìn kọ ẹ̀yìn gan-an.
Ninu fidio ti minisita naa fi lede loju opo Twitter rẹ lo ti sọ wi pe ayẹwo ti fihan pe oun ni aarun naa lara.
”O mẹnu ba iṣẹ akinkanju Oloogbe Oloye Ọbafẹmi Awolọwọ, ti o jẹ Olori Ijọba Ẹkun Iwọ Oorun orilẹ-ede Naijiria nigba naa, ẹni ti gbogbo agbaye ko gbagbe iṣẹ ribiribi rẹ di oni.
O ni ọgbọnjọ oṣu kẹsan Ọjọru ni ọjọ to kẹyin tawọn to forukọ silẹ naa ni lati de si ibi igbaradi ọhun.
” Láti ìgbà náà ni ó ti di àṣà kí àwọn eniyan máa wí pé, “Àbí Saulu náà ti di wolii ni?
Bọla Tinubu: Ìpínlẹ̀ Ọ̀ṣun kò ní owó mi lọ́wọ́
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Àwọn ọlọ́pàá tó mú Evans 'ajọ́mọgbé' gbá igbega 20 Ìgbé 2018 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Iwuri nla ni ikọ yii jẹ fun ileeṣẹ ọlọpaa Naijiria Àwọn ọlọ́pàá márùnlélógójì lábẹ́ ìdarí Abba Kyari tí wọ́n ṣiṣẹ́ ní ẹ̀ka ìdáhùn ní kíákíá sí ìpè pàjáwìrì (ITR unit) gba ìgbéga tuntun látàrí ìṣẹ́ ribiribi tí wọ́n ti ṣe fún àjọ ọlọ́pàá pàápàá jùlọ nípa mímú àwọn ògbóǹtarìgì olè àti ajínigbé.
Wọn ni bawo ni wọn ṣe n ri kaadi itakun ibanisọrọ ti wọn forukọ wọn silẹ nigba ti wọn ra a lo ṣugbọn ti o nira fun awọn oṣiṣẹ alaabo lati fi ọwọ ofin mu wọn.
Wabba  tun wa fokan awon osise balẹ pe ko si mago-mago
Lootọ ni aworan naa han pe arabinrin yii darapọ mọ iwọde ni ẹkun ila oorun gusu orilẹede Naijiria, ṣugbọn ikọ ọlọfintoto BBC ti a mọ si BBC Reality Check kan si arakunrin kan to sun mọ arabinrin Ugochukwu, ti wọn pe orukọ́ rẹ ni Gideon Obianime.
Ilééṣẹ́ Facebook leè mọ ìgbà tí àwọn tó wà lójú òpó wọn ń ní ìbálòpọ̀ Awakọ̀-èrò, ọlọ́kadà farakásá àṣẹ ìjọba Ekiti láti dẹ́kun Coronavirus Èṣi àyẹ̀wò jáde, Gómìnà Bauchi ti ní aàrùn coronavirus báyìí Àrùn Coronavirus ti gba ẹ̀mí ẹni àkọ̀kọ̀ ní Zimbabwe Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí kan sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
Kristi jẹ ami pataki fun alaafia, ifẹ, ifarada ati ifaraji ni gbogbo igba aye
Wo bí ìwọ́de #ENDSARS tí Toyin Abraham ṣe nípínlẹ̀ Oyo ṣe lọ Ọgbọ́n àti kówójẹ n'ìgbèsẹ̀ ìjọba láti ná $1.
Wọ́n fi agídí sé ọmọ Naijiria mọ́lé ní China nítorí àrùn Coronavirus Àwọn Ìpínlẹ̀ tí coronavirus kò tíì dé ní Nàìjíríà, àti ìgbésẹ̀ tí wọ́n ń gbé láti dènà rẹ̀ Wo àwọn ọmọbìnrin tó mu ìtọ̀ ara wọn nítorí òùngbẹ aṣálẹ̀ Sahara Ta ló ga jù lábà?
Jesu wí fún un pé, “Èmi tí ò ń wò yìí, tí mò ń bá ọ sọ̀rọ̀ yìí ni ẹni náà.
- Ọọ̀ni Ife Kí a tó dá ẹjọ́ Pásítọ̀ ìjọ Sọ titobi rẹ, ó di 2020- Adájọ́ ní Akurẹ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Sotitobire church: Àwọn ọ̀dọ́ ilu dáná sun ilé ìjọsìn Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Akure Kidnap: E túbọ̀ ní sùúrù, a máa wá ọmọ náà rí- Alukoro ọlọ́pàá Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Sotitobire church: Àwọn ọ̀dọ́ ilu dáná sun ilé ìjọsìn ---------------------------------------------------------------------------------------------------------------- #Sex for Grade Iṣẹlẹ miran to tun mi igboro Naijiria ni ti fidio iwadii ikọkọ kan ti BBC Africa Eye ṣe lori awọn olukọ fasiti to maa n beere fun ibalopọ lọwọ awọn akẹkọọ obinrin, ki wn o to o fun wọn ni maaki gidi.
Ó lé mi wọ inú òkùnkùn biribiri.
Ìgbésẹ̀ wo ní aláboyún lé gbé láti dẹ́kun ìjẹkújẹ nínú oyún?
Àsọtẹ́lẹ̀ nípa àwọn ẹranko ilẹ̀ Nẹgẹbu nìyí:“Wọ́n di àwọn nǹkan ìní wọn sí ẹ̀yìn kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́,wọ́n sì di ìṣúra wọn sí ẹ̀yìn ràkúnmí.
Awọn asofin agba orilẹede yi ni wọn ti kọkọ lodi si iyansipo Magu nitori abọ iwadi awọn ọtẹlemuyẹ ilẹ wa lori rẹ.
Diẹ lara awọn idahun wọn niyii:Yetunde Olatile sọ pe ẹsẹ agbere lagbara pupọ debi pe o le tu igbeyawo ka.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Ida mẹtalelogun awọn to nii lo jẹ alalwọ funfun ti ida mejidinlọgbọn awọn to ku ni ipinlẹ Michigan.
Lẹsẹkẹsẹ tí wọ́n ka ìwé ọba tán sí etígbọ̀ọ́ Rehumu ati Ṣimiṣai ati àwọn ẹlẹgbẹ́ wọn, Rehumu ati Ṣimiṣai yára lọ sí Jerusalẹmu pẹlu àwọn ẹlẹgbẹ́ wọn, wọn sì fi ipá dá iṣẹ́ náà dúró.
Nítorí ìwé ẹ̀rí Adeleke, Shuaib ní wọ́n pa irọ́ mọ́ òun láti tako Sẹ́nétọ̀ Adeleke ní ilé ẹjọ́ ASUU ń lérí ìyanṣẹ́lódì lórí ọwọ́jà ìjínigbé lórílẹ̀èdè Nàìjíríà Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, N1 mílíọ́nù leè mú kí, orílẹ̀èdè Nàìjíríà, Pẹ̀lúmi Akínṣọlá ó pàdánú àmì ẹ̀yẹ Olympiad Ile isẹ Facebook so ni oju opo rẹ pe awọn ti yọ oju opo ayederu ti ko din ni aadọrinlenigbadinmarun un ti orisun rẹ wa lati orilẹede Isreal lọ si awọn orilẹede ni Afrika kuro ori ẹrọ ikansiraẹni rẹ.
Nítorí pé ìwà àgbèrè jẹ́ nǹkan kékeré lójú rẹ̀, ó ṣe àgbèrè pẹlu òkúta ati igi ó sì ba ilẹ̀ náà jẹ́.
Bakan naa ni baba ọmọ yii fi ina jo ọwọ pẹlu ẹnu ọmọ naa, ti awọn ọlọpaa si ti gbe ọmọ ọhun lọ si ile iwosan fun itọju to peye.
Downsyndrome: Dayo ń wa mótò, ó fẹyawọ, o tún lọ ilú òyìnbó
World suicide prevention day: Iye àwọn tó ti gbẹ̀mí ara wọn rèé láàrin ọdún mẹ́rin ìjọba Buhari ní Nàìjíríà rèé
Minisita feto ilera lo kede eyi Nínú ọkùnrin àt'obìnrin, ta ni Coronavirus yóò tètè ṣe lọ́ṣẹ́?
Arẹwà Ibidunni Ighodalo wọ káà ilẹ̀ lọ nílùú Eko Laipẹ yii ni ijọba orilẹede Naijiria naa ya ida mẹtalelogoji ipin sọtọ fun ẹka eto ilera, papaajulọ nitori ipa ti ajakalẹ aarun covid-19 ni lori ọrọ-aje ati bi ọrọ-aje ebpo rọbi ṣe ri lọja agbaye.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Tayọ̀tayọ̀ ni mó fẹ́ ṣiṣẹ́ pẹ̀lú INEC ki ìdìbò 2019 lé dára' Lati igba to ti di gomina ipinlẹ Ekiti l'ọjọ kẹrindinlogun, oṣu Kẹwa, Akọwe fun ijọba ipinlẹ, olori awọn oṣiṣẹ, ati Akọwe oniroyin agba fun ijọba nikan ni wọn jọ n dari ilu.
Gbogbo ìlú ńláńlá yín ni wọn óo dó tì, títí tí gbogbo odi gíga tí ẹ gbójúlé, tí ó yí àwọn ìlú ńláńlá yín po, yóo fi wó lulẹ̀, ní gbogbo ilẹ̀ yín.
Ẹyẹ náà ti ń dínkù látàrí ìgbẹ́ pípa fún iṣẹ́ ọ̀gbìn àti ìtẹ́lọ ìgbèríko di ìgboro.
Ibeere ti ọpọ eeyan wa n beere ni pe, ki lo pa Sẹnatọ Elisha Abbo, Naira Marley ati Lekan pọ?
Abenugan tun so pe “Igbe aye ojise Olorun Muhammad  ati eko re nipa aanu, isokan, ife ibagbepo ati iwa rere si alabaagbe papo gbodo je eko , ti a o maa tele lati gbe orile ede wa de ebute ogo”.
Wo ohun tí Adájọ́ ṣe sí àṣùwọ̀n ìfowópamọ́sí Wòlíì Sotitobire Òwò mẹ́wàá tí yóò pàdánù àìsí ìpéjọpọ̀ ńlá RCCG lọ́dún yìí Ọkọ̀ tírélà agbépo ṣubú lulẹ̀, awakọ̀ sá lọ, obìnrin kàn pàdánù ẹ̀mí rẹ̀ nílùú Èkó Mọ́ṣáláṣí yóò kí ìrun Jumat padà ní Èkó lẹ́yìn oṣù mẹ́rin ìséde ààrùn Coronavirus Kii ṣe ọrọ irọ mọ pe ọrọ esi idibo a maa fa ọpọlọpọ edeaiyede lorilẹede Naijiria, ajọ INEC ni idi niyi ti awọn fi ṣagbekalẹ oju opo naa.
Ẹgbẹ osisẹ nipinlẹ Ondo wa n leri leka pebi gomina Akeredolu ko ba ṣe bẹẹ, ojo wahala osisẹ to ṣu, yoo bẹrẹ si ni rọ nipinlẹ naa.
Tí o ba tún pàdé elòmírà to ni ààrun náà, o mọ pé onirúuru ọ̀na ni o lé gbà láti gbe igbe aye rẹ̀ Nkan tó ṣe pàtàkì ni pé kìi'ṣe dandan ni kí o maa dá gbe wàhálà náà.
Fi Ọlọrun bú, kí o kú.
Ó fi ayérayé sí ọkàn eniyan, sibẹ, ẹnikẹ́ni kò lè rídìí ohun tí Ọlọrun ṣe láti ìbẹ̀rẹ̀ dé òpin.
àwọn onífèrè ati àwọn akọrin pa ohùn pọ̀ wọ́n ń kọ orin ìyìn ati orin ọpẹ́ sí OLUWA).
6bn, ti adinku si ba gbese ti Naijiria jẹ lati $36bn si $27bn Iwa ajẹbanu gba ilẹ kan laye isejọba Abacha, ti oun funra rẹ si ko ọpọlọpọ owo Naijiria lọ fi pamọ fúnra rẹ ni oke okun, tawọn aya, ọmọ, ọrẹ ati alabasisẹ pọ rẹ naa si n ko owo ilu pẹlu, ninu eyi ti ijọba apapọ rí diẹ gba pada ninu owo naa to wa loke okun Abacha sọ ẹkun to wa ni Naijiria di mẹfa, to si tun da ipinlẹ tuntun miran silẹ Ijọba Sani Abacha lo tii buru julọ ninu iwa títẹ ẹtọ ọmọniyan loju mọlẹ, to si pasẹ ki wọn yẹgi fun Ken Saro Wiwa atawọn Ogoni marun-un miran, to si tun ṣe idajọ Wole Soyinka lai si nile Abacha ko ipa manigbagbe si ogun to waye ni Liberia, to si ko awọn ọmọ ogun apẹtu-saawọ ransẹ Abacha ṣe agbekalẹ eto ipadabọ si eto oselu alagbada, ti oun naa si díje lati gbegba ibo aarẹ alagbada Amọ ọjọ kẹjọ osu kẹfa ọdun 1998 ni iku pa Sani Abacha nile ìjọba Aso Rock, ti wọn si lọ sin sile rẹ nilu Kano.
" aarẹ Buhari koro oju si rogbodiyan naa pẹ̀lu afikun pe o yẹ̀ kawọ̀n aṣaaju ileto gbogbo o maa ba awọ̀n eeyan wọn sọrọ̀ lorore koore lati maa pinwọ irufẹ iṣẹlẹ bẹẹ ko to suyọ.
Eyi lo jẹ ki ọrọ ọpọ ẹ̀mí àti dukia sọnu ni Naijiria.
Ibikíbi tí wọn kò bá ti gbà yín, nígbà tí ẹ bá jáde kúrò ninu ìlú náà, ẹ gbọn eruku ẹsẹ̀ yín sílẹ̀ gẹ́gẹ́ bí ẹ̀rí sí wọn.
Ní alẹ́ yìí, ìbà lọ́wọ́ Dángbọ́ngbọ́n baba kóko
Pẹ̀lúmi lu odindi ìlú kan ní jìbìtì ẹgbẹ̀lẹ́gbẹ̀ owó Ọkọ̀ dáńfó tí mò ń wà ní mo fi kọ́lé, rán ọmọ mẹ́ta ní fásitì - Obìnrin àkọ́kọ́ tó ń wa dáńfó l‘Eko Ohun si ni ọmọ orilẹede Naijiria akọkọ ti yoo jẹ aarẹ gẹgẹ bii ologun ati gẹgẹ bii alagbada.
Lati okeere, ko si apẹrẹ pe ko ni irun lori, ṣugbọn ti eeyan ba sunmọ daada, yoo ri wi pe o n koju ipenija ainirun lori.
Yóo dàbí igi tí a gbìn sí etí odòtí ń so ní àkókò tí ó yẹ,tí ewé rẹ̀ kì í rẹ̀.
Eyi ko ṣeyin pe awọn agbesunmọmi fẹran lati maa ṣekọlu si ibi tawọn eeyan ba pejọ pọ bi ṣọọṣi, mọṣalaaṣi, ile itaja, ibudokọ ati bẹẹbẹẹ lọ.
Ọgbẹni Trump si ti sọ pe oun ko ni fara han nibi eto iburawọle sipo fun Biden.
Zainab Habib: Bí ẹ se gba Zainab sílẹ̀, ẹ gba Leah Sharibu lọ́wọ́ Boko Haram’
Russia Covid 19 Vaccine: Ẹ wo ohun tó yẹ kí ẹ mọ̀ nípa oògùn 'Sputnik V' Russia tó ń wo àrùn Coronavirus
Kò sí ohun tí a gbọdọ̀ kọ̀ bí a bá gbà á pẹlu ọpẹ́, 
Abíọ́sẹ̀/ Abọ́sẹ̀dé/Ajọ́ṣẹ̀/ Jọ́ọ̀ṣẹ̀ (Ọjọ́- ọ̀sẹ̀): Ọmọ tí a bí lọ́jọ́ ọ̀sẹ̀ Òrìṣà-ńlá; tàbí lọ́jọ́ ọ̀sẹ̀ òyìnbó lóde òní.
Gbogbo ẹ̀sùn ti Akpabio fi n kan tabi o sọ ko ní ìtumọ̀."
Ṣugbọn kì í ṣe gbogbo wọn ni ó gba ìyìn rere yìí gbọ́.
Èèyàn 14 mííràn tún ti lùgbàdì ààrùn Coronavirus ní Naijiria Ajọ to n risi idẹkun itankalẹ arun lorilẹede Naijiria, NCDC ti kede pe eniyan mẹrinla miran tun ti ni arun Coronavirus lorilẹede Naijiria.
23 Bélú 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 3 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 5 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Charles Folayan, to jẹ ọkan lara awọn ọmọ ẹgbẹ APC lo salaye ọrọ yi fun BBC ninu ifọrọwanilẹnuwọ kan.
Tammy Abraham dáná sun Wolves, ni Twitter bá ń lọgun rẹ̀ tan-tan Ronaldo, Messi ẹ yàgò lọnà fagbábọ́ọ̀lù Nàìjíríà tó n gbowò julọ!
Sirika fikun un wi pe gbogbo ọ̀wọ̀ tó tọ́ si Atiku ni awọn fi fun un, ati pe ko si ohun to jọ bii arifin ninu iṣẹlẹ naa.
fun aare Muhammadu Buhari fun iwa akitiyan re lati gbogun ti iwa ibaje lorile
Ikọ Arsenal bi jabọ si ipo kẹfa lori tabili liigi, ti wọn to s'ẹhin ikọ Liverpool ti o wa ni ipo kẹrin.
Lai Mohammed: Ọbasanjọ, bí ìwo bá ṣé réré, Ara kì yóò yà ọ?
ewu nípa lílo Àjẹsára jẹ ̀ dọ ̀ jẹ ̀ dọ ̀ b ò wọ ́ pọ ̀ .
O ti pe ogoji ọjọ lonii Ọjọbọ ti gomina ana nipinlẹ Oyo, Sẹnetọ Abiola Ajimobi dagbere faye.
Àkọsílẹ̀ àwọn nǹkan yòókù tí Manase ṣe, ati adura rẹ̀ sí Ọlọrun, ati àwọn ọ̀rọ̀ tí aríran sọ fún un ní orúkọ OLUWA, Ọlọrun Israẹli, gbogbo rẹ̀ wà ninu ìwé ìtàn àwọn ọba Israẹli.
Oríṣun àwòrán, Ilorin Àkọlé àwòrán, Alhaja Aishat Nma Sulukarnaini Ta ló fẹ́ ki bọwọ́bọwọ́ ọlọ́pàá agbègbè bọ Buhari lọ́wọ́?
Rogbodiyan ọhun lo jẹ ki ile aṣofin ijọba apa iwọ oorun Naijiria pin si meji.
Lẹ́yìn náà kí àwọn ọkunrin ìlú sọ ọ́ ní òkúta pa.
Ilé aṣofin Ondo fọwọ́ òsì júwe ilé fún aṣòfin mẹ́ta pé wọ́n tàpá sí òfin ilé Ó ṣeéṣe kí àrùn Coronavirus tànkálẹ̀ gba inú afẹ́fẹ́- WHO Àwọn ilé ìwé Unity School kò ni kópa nínú ìdánwò WAEC nítorí Coronavirus - Ìjọba àpapọ̀ Ọwọ́ ọlọ́pàá ìpínlẹ̀ Oyo ti tẹ àwọn aṣekúpani tó ń ṣọṣẹ́ ní Akinyele Ọjọ Aje, ọjọ Kẹfa oṣu Keje ọdun 2020 ni wọn fi panpẹ ofin mu Magu, ti wọn si gbe e lọ si ile aarẹ ni Abuja nibi ti igbimọ kan ti aarẹ gbe kalẹ ti fọrọ wa lẹnu wo.
Nígbà tí wọ́n dé ibi tí wọn yóo sùn lálẹ́ ọjọ́ náà, ọ̀kan ninu wọn tú àpò rẹ̀ láti fún kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ rẹ̀ ní oúnjẹ, ó bá rí owó rẹ̀ tí wọ́n dì sí ẹnu àpò rẹ̀.
Má yọ̀ mí, ìwọ ọ̀tá mi; bí mo bá ṣubú, n óo dìde; bí mo bá sì wà ninu òkùnkùn, OLUWA yóo jẹ́ ìmọ́lẹ̀ mi.
Ìdí sì nìyí tí mo fi sọ fun wọn pé wọn kò lè ní ohun ìní kan mọ́, láàrin àwọn ọmọ Israẹli.
Wọ́n pa àwọn alágbára ati akikanju bí ẹgbaarun (10,000) ninu àwọn ará Moabu, kò sì sí ẹnìkan tí ó là ninu wọn.
Ọpọ lo maa n tan kamẹra foonu wọn silẹ nitori pe iṣẹju kọọkan ni wọn fi n ya fọto.
Kí o sì wà lọ́dọ̀ rẹ̀ fún ìgbà díẹ̀ títí tí inú tí ń bí arakunrin rẹ yóo fi rọ̀, 
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Awọn aadọfa akẹkọ ni ijọba kede wipe wọn ko tii ri bayi Bi o tilẹ jẹ wi pe ijsba orilẹede Naijiria ti kede wipe gbogbo ohun elo to yẹ pata ni wọn yoo da sita lati sawari awọn ọmọ naa, ẹgbẹ oselu PDP ni ejo ijọba Aarẹ Muhammadu Buhari lọwọ ninu pẹlu awọn iroyin asini-lọna ti o n jade eleyi to n se adinagbooku fun eto ati sawari awọn ọmọ naa.
Kíni àwọn ọmọ Naijiria ń sọ lori ayélujára Ariwo gomina ipinlẹ Kogi, Yahaya Bello lawọn eeyan n pa bayii lori itakun ayelujara.
Ǹjẹ́ o tọ̀nà kí ọkùnrin máa náà obìnrin.
Ó mú Joṣua wá siwaju Eleasari alufaa ati gbogbo àwọn eniyan, 
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Promise Akinlade: ọmọ ọdún mọ́kànlá tó ń fi ìlù dárà bíi àgbàlagbà sọ̀rọ̀ nípa tálẹ́ǹtì rẹ Ọkan lara awọn agbofinro to yọju sibi iṣẹlẹ ọhun sọ fun awọn akọroyin pe awọn ọdọ ilu Akure kora wọn jọ lati ṣakọlu si awọn oniṣowo naa to jẹ Igbo.
Lẹ́yìn náà, Joṣua ní, “Ẹ ṣí ẹnu ihò náà, kí ẹ sì kó àwọn ọba maraarun náà wá fún mi.
Pa Kasumu,gbajúgbajà òṣèré tíátà Yorùbá jáde láyé Ooni Ile Ife pàdánù Màmá àgbá Olùdámọ̀ràn Gómìnà Ekó d'olóògbé lórí pápá Fatai Olumegbon, àgbà oyè nílùú Eko, jáde láyé Ìwọ tó ń ṣí ara sílẹ̀ lọ ṣọ́ọ̀ṣì, ṣé apàyàn kọ́ ni ẹ́ báyìí?
Damilọla ni ọda owo lo sun oun de idi lilo iyarun lati maa fọn fere si orin Fẹla.
 Awon miiran ni Minisita fun eto irinna oju ofurufu(Aviation), eleyi ti aare yo kuro labe ajo to n mojuto eto irinna oko(Transportation), ti aare si tun yo Minisita  fun iṣẹ ode ati ile gbigbe soto, eleyi ti o wa labe isakoso ajo to n mojuto eto ina mona-mona.
Lojukooju ni èmi í máa bá a sọ̀rọ̀; ọ̀rọ̀ ketekete sì ni, kì í ṣe àdììtú ọ̀rọ̀.
Ìtànṣán ògo Ọlọrun Israẹli yọ láti apá ìlà oòrùn, ìró bíbọ̀ rẹ̀ dàbí ti omi òkun, ìmọ́lẹ̀ ògo rẹ̀ sì tàn sórí ilẹ̀.
omo ogun ofurufu orile ede Naijiria,Air Marshal Sadique Abubakar lati fi ami
Ìrònú dorí Adéláyò kodò lórí ohun tí ó lè tókasí, nígbà tí ó se ó ro àwon àgbà àti olóyè tí ó wà níkàlè láti fún òun láàyè láti ronú lórí ohun tí òun yóò mú.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Sogidi Lake: Kòṣẹja-kòṣèèyàn lá bá nínú adágún odò náà -Ojedele Amọ ko baa le ṣe bi Akọni eyi ti a mọ awọn Ọba alaye mọ, Afonja pinnu lootọ lati si igba wo, ko si fi aye silẹ.
Àjàkálẹ̀ àrùn sì dúró láàrin àwọn ọmọ Israẹli.
Ìròyìn wá kàn dé ọ̀dọ̀ ọba ìlú.
"O tun ṣe e ṣe ko jẹ pe ibasepọ rẹ pẹlu Obama, to ma n pe e ni ""arakunrin"" mi, jẹ ọkan lara awọn nkan to mu ko ṣe itẹwọgba lọdọ àwọn oludibo to jẹ ọmọ Africa, to tun jẹ ọmọ ilẹ America bakan naa."
O ni eyi lo mu ki oun faake kọri pe oun ko lee jẹ ki Dokita ajeji ti abẹrẹ bọ oun lara o.
"Ilu London ni mo ran an ko lọ afi ti mo ji ti lọjọ kan ti mo n wa a ni wọn ni o ti lọ si Eko, ọrẹ mi lo ṣeto baalu to gbe e lọ ti mi o si mọ""."
Eléyìí wá nínú ẹgbàwá ọrọ Imam Muslim pé: Anabi (S.
Alaafin: Ẹ máa kọ́ àwọn ọmọ wa ní èdé àti àṣà Yorùbá
Tí a fiṣọwọ́ ní 12:4512:45 Wo ìgbéyàwó olówó iyebíye tí awakọ̀ Kabúkabú ti jẹ̀bùn ọkọ N3.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, EkitiRapeCastration: ìgbésẹ̀ míì lè dẹ́kun ìwà ìfipábánilòpọ̀ Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Eṣú bo gbogbo ilẹ̀ Ijipti, wọ́n sì bà sí gbogbo ilẹ̀.
Ìtàn Mánigbàgbé: Aláàfin Ọ̀rọ̀ǹpọ̀tọ̀niyùn, jagun-jagun orí ẹṣin tí kò ṣe fi ṣeré
N óo gbé wolii kan dìde gẹ́gẹ́ bíì rẹ, láàrin àwọn arakunrin wọn, n óo fi ọ̀rọ̀ mi sí i lẹ́nu, yóo sì máa sọ ohun gbogbo tí mo bá pa láṣẹ fún wọn.
Ó ní òun se iwadii oun laarin àwọn tó ṣe ìdánwò ní Port Harcourt, Gombe, Osun àti Umuahia, tí wọn sì jẹ́rìí pé, Arabic wà nínú ìdáwò náà.
Ṣaaju ni dokita Ezenwakwo Francis ṣalaye fun BBC pe, isẹlẹ naa ko lọwọ aye ninu, kii si se Magun, gẹgẹ bi ẹya Yoruba ti maa n pe e.
Fidio ọhun ṣafihan bi awọn eeyan ṣe fara gba ọta ibọn, ti awọn oluwọde to wa nibẹ si n gbiyanju lati yọ ọta ibọn naa, ati lati doola ẹmi awọn eeyan miran to farapa.
Ọlọ́pàá Ondo sọ ohun tí wọ́n mọ̀ nípa ẹni tó pa Ọmọ Fasoranti Ajibade Ogunoye di Ọlọ́wọ̀ tuntun fún ìlú Ọwọ Àríyá ò lópin láti ìgbà tí Nàìjíríà ti júwe ilé fún South Africa Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fọ́nrán ohùn, Ìgbárùn ni ètò BB Naija kíì ṣe ìgbádùn - MURIC Ninu atẹjade ti awọn mejeeji fi sita lọjọ Abamẹta lori iṣẹlẹ iku ọmọ aṣiwaju ẹgbẹ Afẹnifẹre naa ni wọn ti fi ibanujẹ wọn han.
Ti ayé yìí ni yín, èmi kì í ṣe ti ayé yìí.
Gomina  Ortom jawe olubori ninu eto idibo naa ,nigba
Bẹ́ẹ̀ ni àkókò dídé Ọmọ-Eniyan yóo rí.
Àwọn olórí ogun láti inú ẹ̀yà Bẹnjamini ni: Eliada, akọni ọmọ ogun, ọ̀kẹ́ mẹ́wàá (200,000) àwọn ọmọ ogun tí wọn ń lo apata ati ọrun ni wọ́n wà lábẹ́ rẹ̀.
Ní ọjọ́ tí bàbá rẹ wá sí ìhín gbẹ́yìn, ó kó ó rò, bí ó ti jẹ́ pé ó ń ṣe sí òun, tí ó ń hùwà ọmọ dáadáa, tí ó fẹ́ràn òun dé góngó tí òun náà sì fẹ́ràn rẹ.
Buhari ni oloogbe naa gbiyanju agbara rẹ lati ṣe iranwọ fawọn eeyan to layika rẹ eleyi ti awọn eeyan yoo maa fi ṣe iranti rẹ lọ laelae.
Ó wuyì púpọ̀, kódà nkan ẹwà gidi gan-an ni.
Iṣi sì ni baba Soheti ati Benisoheti.
Iṣẹ ati oṣi to ba awọn obi rẹ finra ko jẹ ko lọ si ileewe tayọ ileewe girama.
bi adari awon ẹsọ  eleto aabo  ni ipinle yii, mo gbodo fi apeere rere lelẹ,
Oríṣun àwòrán, AFP Àkọlé àwòrán, Eto isinku igbakeji aare tẹlẹri yoo waye laipẹ Gẹgẹ bi ọrọ adari ẹgbẹ ti o pọ julọ nile igbimọ asofin, asofin Ahmed Lawan, sisun ijiroro lori eto aabo siwaju yoo faye silẹ fun awọn asofin agba lati fi gbogbo ara ko'pa ninu eto isinku igbakeji aare tẹlẹri naa.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Èyí kìí sì se ìgbà àkọ́kọ́ tí irúfẹ́ ìsẹ̀lẹ̀ bẹ́ẹ̀ yóò wáyé Se ni àwòrán oogún oloro náà gba ori ẹrọ ayelujara kan lẹyìn ìṣẹlẹ náà.
Ní àkókò náà, Hẹrọdu ọba gbúròó Jesu.
Sibẹ o di orúkọ mi mú, o kò bọ́hùn ninu igbagbọ ní ọjọ́ tí wọ́n pa Antipasi ẹlẹ́rìí òtítọ́ mi ní ìlú yín níbi tí Satani fi ṣe ilé.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Working religious women: Ẹ̀lẹ́hàá kìí ṣe ọ̀lẹ- Aminat Adegoke Lara wọn ni Dayo Adeneye, Foluke Daramola, atawọn eeyan Kunle Afod, atawọn eeyan jankan jankan miran.
Wo baba rẹ, ṣé kò rí jẹ ni,tabi kò rí mu?
Òun ni ó wu Paulu láti mú lọ sí ìrìn-àjò rẹ̀, nítorí náà, ó mú un, ó kọ ọ́ nílà nítorí àwọn Juu tí ó wà ní agbègbè ibẹ̀; nítorí gbogbo wọn ni wọ́n mọ̀ pé Giriki ni baba rẹ̀.
Kashim Shettima, Yobe ati Ibrahim Geidam, ati alaga eto ipolongo fun asofin Ahmad
Ogbeni Folabi Fasanmi to jẹ ọkan lara awọn ọma baba naa lo salaye fawọn akọroyin bẹẹ nile Baba Fasanmi to wa ni Osogbo nipinlẹ Osun.
le ni igba(200 ) awon akekoo to se idanwo UTME ti o waye ni Abameta, ojo kẹ́tàdínlọ́gbọ̀n,
Emir of Kano: Gómìnà Kaduna, El-Rufai fi ipò kejì dá Sanusi lọlá láàrin ọjọ́ méjì
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Idije Premier League Ẹlẹsẹ ayo Richarlison lo kọkọ gba bọọlu sawọn Man U lẹyin iṣẹju mẹtala ti ere bọọlu ọhun bẹrẹ.
O salaye pe, “oun ni igbagbo si ipade ti won se naa, ati eyi ti a o tun se ni sise-n- te le yoo so eso rere, nipa wiwa iyanju ti yoo so awon ipenija naa di afiseyin teegun n fiso”.
Lẹyin ọsẹ meji ti isẹlẹ yii waye, Adesanya sọ wipe awọn daran daran naa doju ija ibọn kọ ọkọ baalu ti awọn ọmọ ogun fi nsisẹ ti wọn si ni fidio gbogbo eyi.
"kìí ṣe èmi nìyí"" ǹkan ti Kelly sọ niyi lásìkò tó ń ṣe ìfọ̀rọ̀wánílẹ́nuwò pẹlú ilé iṣẹ́ ìròyìn CBS, ó fi kún pé ""mò ń gbìyànjú láti móríbọ nínú ẹ̀sùn yìí."
  Tí ènìà bá sọ̀kalẹ̀ láti orí òkè náà, á bọ́ sí ojú ọ̀nà tí àwọn àgbẹ̀ nlò fi kó ẹrù àti irinṣẹ́ wọn pẹ̀lú ọkọ̀ akẹ́rù.
Osinbajo tun pase fun awon ajo to n ri si itoju paja-wiri NEMA lati pese itoju to peye fun awon ti isele naa sele si.
Baba da gbere faye ni nkan bi agogo kan oru lẹni ọdun mejidinlọgọrin ni ile rẹ to wa ni ilu Ibadan lẹyin aisan ranpẹ.
Ọba burúkú tí ó jọba lórí àwọn talaka,dàbí kinniun tí ń bú ramúramù,tabi ẹranko beari tí inú ń bí.
Ewe, bi o ti le je pe, ninu osu ti o koja, lasiko abewo awon toro kan naa sibi ise akanse ohun, won fi mule pe asiko ti won fi sile lati pari ise ohun ko ni ye rara.
Òbí ọmọ Chibok kú nínú ìjàmbá ọkọ̀
    Nígbà tí iwin náà rí mi, ó yara ju Ayédèrú-ẹ̀dá sínú àpò ó ń sáré bọ̀ lọ́dọ̀ mi.
Amọ, ojuṣe awọn obi ni lati du ẹmi awọn ọmọ naa.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Gbajúgbajà òsèré tó tún mọ́ ọbẹ̀ sè Ọkan lara awọn oludari ileesẹ to n se agbatẹru eto naa, Arabinrin Juliana Afọ́nrewó kede pe, ọpọ ayẹyẹ ọjọ ibi ni wọn ti se fun Iya Rainbow lorilẹede Naijiria, ọna lati mu iyatọ baa, si lo mu kawọn gbe ti ọdun yii lọ si Dubai.
Kini akọṣẹmọṣẹ sọ nipa iyipada ọkan ẹni ti wọn fi ipa balopọ tabi hu iwa ipa si?
'Yato si wi pe o fun Naijiria lorukọ buruku laarin awọn orileede to ku,iwa yi a ma ṣe ipalara fun ilera ati alafia ara ilu.
Ninu leta ti ogbeni Gidado ko, lo ti salaye pe ,oun kowe fise sile lati tele ipinnu oun pe eekansoso ni oun yoo se ijoba gege bi igbakeji gomina fun ipinle naa.
"Ko si igba kankan ti agbẹnusọ fun aarẹ Buhari, Fẹmi Adeṣina pe iwọde #EndSARS ni ""ere Ọmọde"" Nigba ti iwọde naa kọkọ bẹrẹ, fidio kan jade sita eyi to ṣafihan agbẹnusọ fun aarẹ Buhari, Fẹmi Adeṣina bi ẹni pe o n pe iwọde naa ni ere ọmọde Ọpọ lo n wo Fẹmi Adesina gẹgẹ bi ẹni to n fi iwọde naa ṣe yẹyẹ."
Ghana election: Ààrẹ Akufo-Addo la Mahama mọ́lẹ̀ wọlé ìbò ààrẹ Ghana fún sáà kejì
N kò lè sọ onírúurú nǹkan abàmì ti a fi ojú wa rí nínú igbó burúkú yìí tán, nítorí àwọn iwin ìbẹ̀ pọ̀ gidigidi, bí a sì ti ń lọ ni wọn ń yọ sí wa.
Obitibiti owo, miliọnu marunlelọgọrin naira(N85m) ni ẹni to ba jawe olubori ninu awọn oludije marun un to ku, Laycon, Nengi, Vee, Neo ati Dorathy yoo gba lọle.
Oríṣun àwòrán, NIGERIA SENATE/TWITTER Àkọlé àwòrán, Awọn gomina nigbakanri ti wọn ti di asofin agba pẹlu n janfani owo ọya meji.
O kọ, pe ki lo de ti wọn ni ki oun wọle.
Àwọn ìròyìn mìíràn tí ẹ lè nífẹ̀ẹ́ sí: Ọlọ́pàá gbé àwọn tó yìnbọn lu olólùfẹ́ ní Ajegunle Ọ̀wọ́ngógó epo bẹntirò: NNPC ni 'ìròyìn ẹlẹ́jẹ̀' ni Kíni ìdí tí àwọn ẹbí àwọn ọmọ Chibok fi ń tọ woli lọ?
Ẹ kò ranti nígbà tí mo bu burẹdi marun-un fún ẹgbẹẹdọgbọn (5,000) eniyan, agbọ̀n mélòó ni àjẹkù tí ẹ kó jọ?
Ó ní, “Mo dúpẹ́ lọ́wọ́ rẹ, Baba, Oluwa ọ̀run ati ayé, nítorí o ti pa nǹkan wọnyi mọ́ fún àwọn ọlọ́gbọ́n ati àwọn olóye; ṣugbọn o fi wọ́n han àwọn òpè.
Jin rẹ́rìn-ín músẹ́ ó bẹ̀rẹ̀ sí í jẹun lọ.
Nígbà tí Jesu kúrò lọ́dọ̀ àwọn eniyan, ó lọ sinu ilé.
 Yetunde Olugbenga: 'Nigba ti mo gbọ nipa agbekalẹ ikanni kan ti wọn pe ni BBC Yoruba, Mo ni whao, awọn tia ni eleyi.
Inagijẹ ti ọpọ eeyan mọ si ni Mo.
Ajo agbaye United Nations UN ti ni bi eto idibo odun 2019  se n sunmo ile, o ti di  dandan ki won satunse si igbimo alaafia to wa lorile ede Naijiria, ti won je ki eto idibo aare  odun 2015 lo ni irowo-irose.
Gẹgẹ bi iwe akọroyin fun iwe iroyin Punch ti salaye isẹlẹ isẹlẹ naa, se ni dokita obinrin naa bu sẹkun nigba to de ile iwosan, to si gbọ nipa ohun to sẹlẹ si tiya tọmọ.
Àwọn ẹ̀yà Israẹli mejeejila ni a ti dárúkọ yìí, ati ohun tí baba wọn wí nígbà tí ó súre fún wọn.
Ojurere Ọlọrun ni lati jẹ osisẹ BBC.
Ko sẹ ni to lee yan wa jẹ, a ko lee gba.
Afonja, lasiko to n kopa lori eto ori redio kan nilu Ibadan ni, ko si ẹni ti ijọba ko lee paarọ, yoo si daa ki Auxiliary ati isọmọgbe rẹ so ewe gbejẹ mọ wọ.
Gege bi aare ajo to n mojuto boolu afesegba lorile-ede Amerika, Carlos Cordeiro “Inu wa dun lopolopo lati yan Gregg gege bi olukonimoogba tuntun fun iko agbaboolu okunrin agba orile-ede yii.
Ẹsun ti DPO naa, Alex Gwazarzah fi kan Adeniyi ni pe o gbe aṣọ oun fun ọmọṣẹ rẹ lati ran.
Láti ìgbà náà ni omi náà ti dára títí di òní olónìí gẹ́gẹ́ bí Eliṣa ti sọ.
O ni ọkan lara awọn ẹkùn to wa ni ọgba naa ku ni ọdun meji sẹyin.
 Awon iko omo ogun 177 ati awon to
Lagos Marathon: Abraham Kiprotich se ipò Kíní ninu ìdíje ọ̀uń
wọ́n sì wí fún Mose pé, “Ìwọ ni kí o máa bá wa sọ̀rọ̀, a óo máa gbọ́; má jẹ́ kí Ọlọrun bá wa sọ̀rọ̀ mọ́, kí a má baà kú.
Ajọ eleto idibo orilẹede yii, INEC ẹka ti ipinlẹ Ọyọ ṣe akanṣe apero pẹlu awọn aṣoju ẹgbẹ oṣelu ati awon agbofinro ti yoo kopa ninu eto idibo gbogbogbo ti yoo waye lọjọ Abamẹta.
4 6371 Orilẹede ajikistan 90 1.
Ìròyìn fi ìdí rẹ̀ múlẹ̀ fún wa pé l'Ọjọru tó kọjá ni ẹgbẹ́ òkùnkùn méjì ló kọlu ara wọn lásìkò tí ẹgbẹ́ òṣèlú kan tí iléeṣẹ́ ọlọ́páà fi orúkọ bò láṣírí, ń ṣe ìwọ́de òṣèlú nú agbègbè náà.
N óo já ẹ̀wọ̀n tí wọ́n fi so wọ́n,wọn kò sì ní ṣe iranṣẹ fún àjèjì mọ́.
Bakan naa ni ọkan lara awọn to ṣeto adura naa fun ẹgbẹ APC, Comrade Sikiru Tijani sọ fun BBC pe awọn gbagbọ pe adura to gba ẹtọ awọn fun wọn pada lọdun 2007 yoo tun ran awọn lọwọ lori ẹjọ ti Adeleke pe.
Ìtàn Mánigbàgbé: Ìtàn Adegbọrọ kọ́ wa láti ṣiṣẹ́ kára pẹ̀lú ìforítì
Gẹgẹ bi o ṣe sọ, o ni iyatọ wa laarin oṣo, ajẹ, ati emere.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Anthony Joshua vs Andy Ruiz Jr: AJ lóun ṣetán láti kojú Ruiz nínú ìjà ọjọ́ Sátidé 6 Ọ̀pẹ̀̀ 2019 Oríṣun àwòrán, Instagram/Anthony Joshua Ọjọ nii pẹ, ipade kii jina.
Ẹni tí ó bá kọ́kọ́ rojọ́ níí dàbí ẹni tí ó jàre,títí tí ẹnìkejì yóo fi bi í ní ìbéèrè,
“Lọ sọ fún Dafidi, iranṣẹ mi, pé, èmi ‘OLUWA sọ pé kì í ṣe òun ni óo kọ́ ilé tí n óo máa gbé fún mi.
FCT-416 Eko -324 Kaduna-68 Plateau-42 Kwara-32 Kano-24 Gombe-14 Sokoto-12 Yobe-12 Akwa Ibom-11 Bayelsa-10 Rivers-7 Bauchi-7 Ogun-6 Oyo-5 Edo-4 Taraba-4 Jigawa-1 Èèyàn mẹ́fà kú, 356 tuntun míràn tún fara kásá Coronavirus ní Naijiria Oríṣun àwòrán, @NCDCgov Ajọ to n gbogun ti itankalẹ ajakalẹ arun ni Naijiria, NCDC, ti kede esi ayẹwo ẹrindinlọgọtalelọọdunrun eeyan to tun ṣẹṣẹ lugbadi Coronavirus ni Naijiria.
Awọn ọmọ ìjọ sàtánì ń bínú sí Nàìjíríà Àwọn ìgbà tí ìmọ̀ràn Pásítọ̀ Adeboye lóri igbéyàwó ti fa àríyànjiyàn Àlùfáà ìjọ Redeem àti ọmọ rẹ̀ méjì kú sílé ìgbafẹ́ kan lásìkò Kérésì Ìlànà tí ìjọba Eko gbé kalẹ̀ fún ìjọsìn lásìkò Covid-19 kò bá wa lára mu - Chris Okotie Wọn sọ pe esu duro gẹgẹ bi awokọṣe fun igberaga, ominira, ati gbigbe igbe aye ẹni lọna to wu ni - awọn amuyẹ ti awọn kan n pe ni iwa buburu.
Eyi lo mu ki awọn ẹlẹsin ibilẹ yika ipinlẹ Ọyọ fi n rawọ ẹbẹ si gomina Seyi Makinde lati ya Ogunjọ osu Kẹjọ ọdọọdun sọtọ gẹgẹ bii ọjọ isinmi lẹnu isẹ fun ayajọ ọdun awọn onisẹse.
Ẹ máa hùwà bí iranṣẹ Ọlọrun.
 Àwọn ìgbìyànjú míìràn láti dẹ ́ kun àkóràn ni láti dín pípọ ̀ si àwọn ẹ ̀ fọn aṣòkunfà kù .
Saraki sọ pe ẹni iyi ni Funtua, o si jẹ orisun ọgbọn fun awọn to n bọ lẹyin ko to faye silẹ.
Pupọ ninu àwọn alufaa ni wọ́n sì di onigbagbọ.
Nigba miran awọn eeyan maa n fi oju onisekuse ati alagbere wo awọn ololufẹ ti isẹlẹ naa ba sẹlẹ si, ti wọn ko si mọ pe ko si wahala kankan nibẹ.
Awọn to ti ba Coronavirus lọ ti wọ mẹtadinlọgọfa ti awọn ti ara wọn ya lẹyin itọju si jẹ 679.
Ṣugbọn òun ní tirẹ̀ kò ṣẹ̀ rárá.
Gbajugbaja oṣere naa ni o jẹ iyalẹnu fun oun pe awọn kan n sọ kaakiri wi pe oun maa n ju idi oun fun ṣe ki a ri mi ṣugbọn o sọ pe ọrọ ko ri bẹẹ rara.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Awọn ẹbi ati ọrẹ rẹ naa ko gbẹyin.
Bakan naa, aarẹ Muhammadu Buhari ti fi ikini ku oriire iṣẹ takun takun ti wọn n ṣe ranṣẹ si wọn fun ayẹyẹ ọdun kan ti wọn pe.
Ijọ mimọ St John Anglican Church to wa ni Iye Ekiti ni yoo seto kookari isinku naa.
Amọṣa, akọwe ajọ eleto ilera alabọde ni ipinlẹ Jigawa, Dokita Kabir Ibrahim salaye pe, o ti le ni ọgọfa ọkọ ti wọn ni kaakiri ọkan o j'ọkan awọn ileto nibẹ.
Fun Morufudeen Olabanjo, iwa ki ọkọ tabi iyawo gbá òbí ẹnikeji l'eti buru ju aale yiyan lọ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù NURTW: Agbẹnusọ Sanwo-Olu ní gómínà ti gbé ọ̀rọ̀ ìjà NURTW lé ọlọ́pàá lọ́wọ́ 20 Òkùdu 2019 Oríṣun àwòrán, Nurtw Àkọlé àwòrán, Sanwo-Olu kò lè tori ìjà Ojota fòfin de NURTW ní Eko Ọrọ ija NURTW tijọba ipinlẹ Oyo ati Ogun ti fofin de lo n kọ àwọn eniyan lominu ni Eko.
irọsẹAare Muhammadu Buhari wa seleri fun awon omo ipinle  Ogun lati dibo fun awon oludije ninu egbe APC ,
Lọwọ-lọwọ, Aarẹ Muhammadu Buhari ti sọ pe oun ko le gba ki wọn o lo agbo naa fun ọmọ Naijiria kankan lai ṣe ayẹwo to yẹ fun agbo naa.
Kí àwọn mààlúù wa lóyún,kí wọ́n má rọ́nú, kí wọ́n má bí òkúmọ;kí ó má sí ariwo àjálù ní ìgboro wa.
Orílẹ̀-èdè Amẹrika kò ṣọ́ wọlé-wọ̀de mi àti ìdílé mi- Atiku fèsì Ọ̀wọ́ngógó oúnjẹ, epò, iná ọ̀ba ti sọ owó oṣù N30,000 da N9 nitórí náà kò ní sí ọjà, epo, iléèwòsàn láti Ọjọ́ Ajé - NLC Ǹjẹ́ o ti gbọ́ nípa Da Rocha?
Iroyin so pe, opolopo ile ni omiyale naa ti gbe lo, bayii.
Oludari agba ajọ LASEMA, Ọmọwe Olufemi Oke-Osayintolu ni awọn ti di gbogbo ibi ti iṣẹlẹ yii ti waye pẹluu kiki foomu ki iṣẹlẹ naa ma tun lọ bi omii.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù RCCG: Adeboye ní ó sàn láti sọ̀rọ̀ ìgbéyàwó f'àlúfà ju òbí lọ 17 Owewe 2018 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 4 Ọ̀wàrà 2018 Oríṣun àwòrán, Facebook/Foluke Adeboye Àkọlé àwòrán, Foluke Adeboye gba àwọn ọ̀dọ́ ní ìmọ̀ràn O ṣe pataki fun awọn ọdọ to ba ṣetan lati ṣe igbeyawo lati kansi alufa ijọ wọn saaju obi wọn.
lorile ede naa  ati awon eniyan
Ṣugbọn oúnjẹ tí ó ń ti ọ̀run sọ̀kalẹ̀ ni èyí tí ó jẹ́ pé bí ẹnìkan bá jẹ ninu rẹ̀, olúwarẹ̀ kò ní kú.
Lọdun to tẹle e, o di minisita fun ọrọ ilẹ okere.
Oríṣun àwòrán, Twitter/governor kaduna Atẹjade kan ti ileeṣẹ eto ẹkọ ijọba ipinlẹ naa fi sita rọ awọn ileewe lati rii daju pe wọn bẹgi le eto ẹkọ ninu ileewe, ki wọn wa ọna abayọ miran lati fi ṣeto ẹkọ fun awọn akẹkọọ to ba di dandan.
Ṣùgbọ́n kò tó ìṣẹ́jú méjì tí wọ́n mu-ẹmu yìí tí àwọn náà pa ojú dé, wọ́n kú gàlàtì ti owó lọ́rùn.
Eto Akomolede ati Asa lori ikanni BBC Yoruba lo n ṣagbeyẹwo Ekun Iyawo fun ẹyin ololufẹ wa.
Ṣugbọn ede-ai-yede saba maa n ṣẹlẹ lori itumọ ifipagbajọba, koda awọn ọga ologun ti koro oju si ifipagbajọba.
" india  ( ) gege bi oruko wa lati "" indus "" , to wa lati oro persia atijo "" hindu "" , lati sanskrit सिन ् धु "" sindhu "" , oruko ibile fun odo indus ."
Ẹni tí ó mú àwọn eniyan rẹ̀ la aṣálẹ̀ já,nítorí pé ìfẹ́ rẹ̀ tí kì í yẹ̀ wà títí lae;
O wa se idaniloju pe awon osise alaabo ko ni kaare lati  mu  awon odaran naa, ki won si jiya labe ofin.
Orúkọ àwọn ẹ̀yà Israẹli ni a fi sọ àwọn ẹnu ọ̀nà ìlú.
Aregbesola ni ijọba oun na owo pupo lori pipese oun amayederun lo faa ti sisan owo oṣu fi mẹhẹ fawọn oṣisẹ.
 Odun 2009 ni ile ise Empire Mates Entertainment, ti Banky W.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Yemi Alade: Bí a bá ní ìdí nlá bàa ní, kó sí ẹni tí kò rẹ́wà 22 Ọ̀pẹ̀̀ 2018 Oríṣun àwòrán, Tiwa Savage/Yemi Alade/ Instagram Àkọlé àwòrán, Ija ti pari Ija to waye lori Twitter laarin gbajugbaja akọrin Tiwa Savage ati Yemi Alade jọ bi ẹni pe o ti pari.
 obama- àgbà fi arapa nínú àgbákò ọkò nípa èyí tí ó sọ ẹsè méjèjì nù .
Òun ati Filipi bá sọ̀kalẹ̀, wọ́n lọ sinu odò, Filipi bá rì í bọmi.
Síwájú sí i, oríṣìíríṣìí ọ̀nà tí ó bá òde òní mu ni wọ́n ti là sí àárín ilú láìní ọwọ́ ìjọba kankan nínú fún ìdàgbàsókè àti ìlọsíwájú ìlú wọn.
Jesu jókòó létí kànga náà ní nǹkan bí agogo mejila ọ̀sán, àárẹ̀ ti mú un nítorí ìrìn àjò tí ó rìn.
Baa ba n sọ̀rọ̀ awọn agba olorin ni Naijiria, ara ọ̀tọ̀ ni Fatai Rolling Dollar tori ọna to ń gba kọrin tiẹ̀ yatọ gedegbe.
O fi kun ọrọ rẹ pe, gbogbo iwadii oun fihan pe gomina ipinlẹ, Babajide Sanwo-olu, ko lọwọ si bi awọn sọja ṣe kọlu awọn ọdọ to ṣe iwọde ni Lekki.
Ọmọ Yorùbá tó bá ti rú òfin, ẹ gbé e jàntò - Oluwo Israel Adebajo: Ìlúmọ̀ọ́ká oníṣòwò tó fi òkò Stationery Stores pa ẹyẹ púpọ̀ 'Nàìjíríà, ṣọ́ra, ogun ń sọ ilé ọlá di ahoro!
Paralimpics yìí jẹ́ Ìdíje àwọn àkàndá àti abarapa ẹ̀dá.
Ikolu awon omo ogun olote ti o waye nila oorun ilu Ghouta je ikolu ti o lagbara, leyin ti ogooro eniyan filu naa sile losi ilu Douma, lataari ikolu tio waye ohun lojo Aje(Monday).
Iwadii fihan pe ida mẹtala ninu awọn ọmọbinrin ẹni mẹẹ̀dogun si mọkandinlaatọta ni oun lo ifetosọmọbibi bayii lorilẹede Naijiria.
Oríṣun àwòrán, AFP Àkọlé àwòrán, Ogunlogo awọn eniyan lo n gba ori okun Libya k'oja si ile Yuroopu Ajọ Alaanu kan ti Arabinrin Motilola Adekunle n dari rẹ ni Adeola pade ni ori ẹrọ ikansiraẹni Instagram nibi ti o ti ke sita, ti wọn si seranwọ fun lati pada wa si orilẹede Naijiria ni Osu Kejila, Osu 2019.
Oríṣun àwòrán, Kola Ologbondiyan/Facebook O sọ pe awọn ti gbo iroyin pe ijọba Buhari ti paṣẹ fun Inec lati ṣe atunto aaye ti wọn gbe awọn ọga eleto idibo nipinlẹ kọọkan si ki wọn ba le ṣe wuruwuru lasiko ibo.
A sùn gbàgbé iná táa gbé sórí òrùlé.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù World Press Freedom Day: Akọ̀ròyìn tó tó 95 ló kú lọ́dún tó kọjá!
Ondo West Lẹ́yìn ìjọba ìbílẹ̀ Ilajẹ ìjọba ìbílẹ̀ Ondo West lo tún kan, èyí sí ni ìjọba ìbílẹ̀ kẹ̀ta to tóbi jùlọ ní ìpínlẹ̀ Ondo.
” Ni ó bá da ẹnu dé e ní ẹ̀rẹ̀kẹ́.
"China ṣe àgbéjáde ""App"" tí ẹ lè fi mọ̀ bóyá ẹ súnmọ́ aláàrùn Coronavirus Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ọja Arena Oshodi ni àwọn èèyàn ti ń r'aja Ohun ti itan Ọọni Lúwòó Gbàgídà kọ wa: O kọ wa pe gbogbo lọmọ, ko baa jẹ ọkunrin abi obinrin, ko si eyi ti ko lee jẹ olokiki Itan yii tun kọ wa lati mase jẹ okuroro A tun ri kọ ninu itan yii lati maa jẹ onimọtoto Duro Ladipọ, ìlúmọ̀ọ́ká òṣèré tíátà àti ọmọ àlúfà tí kò gbàgbé àṣà ìbílẹ̀ Ìtàn tó rọ̀ mọ́ òwe ‘aṣọ kò bá Ọ́mọ́yẹ mọ́."
Dókítà Trump: Trump ló kọ èsì ìlera rẹ̀ lásìkò ìbò
Ààrẹ George Weah padà sórí pápá Òhun tí o sẹlẹ nigba ti Buhari lọ China Iwà akin tí Mamoudou Gassama hu yìí tí ṣokunfa ìpàdé pẹlú Ààrẹ France, Emmanuel Macron, ni ilé ìjọba Elysee Palace, to sì fún un ní ẹ̀tọ́ àti gbe ilu.
 It was an honour to host African football legends at Lagos House, Alausa this morning, ahead of the testimonial football match in my honour scheduled for tomorrow at the Agege Stadium.
Ni bayii eyi tumosi pe, awon mejeeji yoo wa lara isakoso katakara iko agbaboolu ti awon agbaboolu ba fe kopa fun.
Ẹ̀yin ará, mo fi ara mi ati Apolo ṣe àpẹẹrẹ ohun tí à ń sọ nítorí yín, kí ẹ lè kọ́ ẹ̀kọ́ lára wa, pé kí ẹ má ṣe tayọ ohun tí ó wà ní àkọsílẹ̀.
Ṣugbọn o ṣeni laanu pe eyi ko fi opin si awọn imọran iwosan to lewu, ati awọn eyi to dara loju ṣugbọn to lewu.
Coronavirus lè tara òkú Abba Kyari ran àwọn tó péjú síbi ìsìnkú rẹ̀- Ààrẹ ẹgbẹ́ dókítà ní Nàìjíríà Ìyàwó mi ṣẹ̀ṣẹ̀ bímọ tuntun, kò si oúnjẹ fún wa torí ìgbélé Coronavirus- Yakubu Irufẹ iwadii yii wa láti fi ṣe itọju àwọn èèyàn tó ń ṣe àìsàn Coronavirus lọ́wọ́ lọ́wọ́.
Àwọn tí ń fi ìlara jẹ́rìí èké dìde sí mi;wọ́n ń bi mí léèrè ohun tí n kò mọ̀dí.
" Asẹ naa to wa lati ọdọ ọga agba pata fun ileesẹ ọlọpaa ilẹ wa, Ibrahim Idris, tun fewe ọmọ mọ awọn osisẹ Sars leti pe eyikeyi ninu wọn, to ba kọ eti ikun si asẹ tuntun naa yoo jẹ iyan rẹ ni isu, ti oga to n sisẹ labẹ rẹ naa yoo si ru igi oyin.
Ẹnikẹ́ni tí ó bá fọwọ́ kan òkú, tí kò bá fi omi ìwẹ̀nùmọ́ wẹ̀, yóo sọ ibi mímọ́ OLUWA di aláìmọ́.
Muktar tun fi kun ọrọ rẹ pe, ofin ọun ti fẹsẹ mulẹ lati igba Hajj ọdun to kọja, ati pe, awọn gbe eto ọun kalẹ lati fi to awọn ti wọn o rinrinajo lọdun 2018 leti.
Lẹ́yìn náà ni wọn tún ri pé, èlòmíràn tó tún ni èròjà tó n gbògun ti ààrun covid-19 lára, pàdánù rẹ̀ láàrín oṣù mẹ́ta péré.
Ati wi pe lẹyin ipade pẹlu awọn ti ọrọ naa kan ni gomina naa gbe igbesẹ naa pe ki gbogbo awọn akẹkọọ pada si ileewe ni Ọjọ Kẹrinla, Osu Kẹsan an, ọdun 2020 ""."
Ni ti ipinlẹ Abia, o ti gbogbo ẹnu ibode ipinlẹ naa pa fun ọsẹ mẹrin, o si tun pasẹ pe ki gbogbo araalu o joko sile.
Ko fẹẹ si agbabọọlu Arsenal tẹlẹ abi lọwọlọwọ bayii ti mama naa ko lee darukọ, to si ni oun maa n wo bọọlu ninu ile oun tabi lọ sawọn ibudo ti wọn ti n wo bọọlu.
Nígbà tí ó sàmì sí ibi tí ìpìlẹ̀ ayé wà,
naa ti wa ba mi , pelu ile-ise eleto aabo , won si ti yanju isoro to wa laarin
" Igbesẹ kẹta: kọ ohun gbogbo to ba yẹ si inu apoti ọrọ ti igbesẹ keji naa ba gbe sita, lẹyin eyi tẹ akori ibi to kọ Sign in"" Igbesẹ kẹrin: Kọ orukọ ipinẹ ibinibi rẹ sibẹ ko si tun tẹ ibi ti wọn kọ akori ""Continue"" si."
Nítorí náà, ẹ dúró jẹ́ẹ́, kí ẹ wo iṣẹ́ ńlá tí OLUWA yóo ṣe.
Àkọlé àwòrán, Awọn obinrin le ni idaji awọn to ma n ku lọwọ ololufẹ wọn Iku awọn okunrin ṣi pọ ju tobinrin lọ Iwadi UNODC fi han wi pe ''awọn okunrin wa ninu ẹwu ki awọn ololufẹ wn ṣe iku pa wọn ju awọn obinrin lọ'' Ajọ isọkan orileede agbaye,UN, tọka si wi pe ninu awn eeyan ti wọn ṣe iku pa lagbaye,awọn ọkunrin ko mẹjọ ninu isẹlẹ mẹwa bẹẹ to n waye lojumọ.
Àwọn apẹja tí ń fi ìwọ̀ ninu odò Nailiyóo ṣọ̀fọ̀,wọn óo sì sọkún tẹ̀dùntẹ̀dùn;àwọn tí ń fi àwọ̀n pẹja yóo kérora.
N óo fún Edomu mu, ati Moabu, ati àwọn ọmọ Amoni; 
Ṣugbọn, tí kò bá fọ aṣọ rẹ̀, kí ó sì wẹ̀, yóo jìyà ẹ̀ṣẹ̀ rẹ̀.
Face App: Ẹ wo báwọn òṣèré tíátà kan yóò ṣe rí lọ́jọ́ ogbó Oríṣun àwòrán, LATEEF ADEDIMEJI Àkọlé àwòrán, Oṣere Nollywood Pitimu ni awọn oju opo ayelujara Facebook, Instagram ati Twitter kun fun App ori ayelujara kan ti wọn n pe ni Face App lọsẹ yii.
yoo soro ki o to le so wi pe ohun mu eeyan kan ti o j aayo rẹ.
O tún pè fún ìwádìí tó péye lóri ikú to pa ìgbákeji àdári àgbà ilé iọ̀ẹ́ tó ń ri sí ètò adójutofo ní Nàìjíríà Elizabeth Ndubuisi- Chukwu.
Kí alufaa tún ti ẹni náà mọ́lé fún ọjọ́ meje sí i.
Awọn kan lara wọn faramọ, nigba ti awọn kan si kesi ijọba lati fun awọn ṣọọṣi naa ni asiko si lati tẹle awọn ilana naa.
Ó da agbo ẹran náà lọ sí ìhà ìwọ̀ oòrùn aṣálẹ̀, títí tí ó fi dé òkè Horebu ní Sinai, tíí ṣe òkè Ọlọrun.
Sunday James ṣalaye fun BBC pe awọn darndarn to n wọ Naijiria jẹ eyi ti adehun ECOWAS faaye gba lati wọle.
Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Seyi Makinde: Gbogbo ìgbà ni ìyá mi máa ń sọ fún mi pé díẹ̀ ló kù kí àwa méjèjì kú lọ́jọ́ tó bí mi4 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Fídíò, Rashidi Ladoja: Nígbà tí Ajimobi fìdí rẹmi ló ṣẹ̀ṣẹ̀ yan àwọn akọ̀wé16 Òkùdu 2019 Seyi Makinde ṣèlérí owó oṣù kẹtàlá fáwọn òṣìṣẹ́ Amotekun l' Oyo10 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Yemi Osinbajo: Seyi Makinde, mo gbà fún ọ lórí ẹ̀kọ́ ọ̀fẹ́ tó o ṣe l‘Ọyọ20 Ọ̀wàrà 2019 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 3 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 5 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Aláàfin ń se ọgọ́rin ọdún, àwọn àwòrán mánigbàgbé Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ìjọba Ọ̀yọ́: Kò sí ilé kan tí wọn kò tíì bí ìbejì ní Igbó Ọrà Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ṣọla Allyson: Obìnrin tí kò bá rẹwà ni yóò máa ṣí ara sílẹ̀ Fẹla dagbere faye lọjọ Keji, Oṣu kẹjọ ọdun 1997 ni ẹni ọdun mejidinlọgọta nilu Eko.
Ẹ wo ẹkunrẹrẹ fidio yii, lati mọ ohun ti oju awọn ọmọ Yoruba to wa ni Egypt n ri lọwọ awọn ọmọ onilu.
Aarẹ sọ pe aigbọra ẹni ye to waye lọpọ igba laarin iṣejọba oun ati awọn aṣofin naa ṣe idiwọ fun awọn anfaani to yẹ ki awọn ọmọ Naijiria jẹ.
Pàtàkì Ìwé Kíkọ Àti Kíkà Ní Èdè Abínibí
Bakan naa ni akọsilẹ fihan pe saaju ki ijọba to kede konile o gbele ni awọn eniyan ti din irinajo wọn ku.
nítorí kò sí ẹni tíí fi ohun tí ó bá ń ṣe pamọ́, bí ó bá fẹ́ kí àwọn eniyan mọ òun.
Níbẹ̀ ni OLUWA ti sọ fún Mose ati Aaroni pé, 
Nítorí náà, mo bá àwọn olórí wí, mo ní “Kí ló dé tí ilé Ọlọrun fi di àpatì?
Ọmọba Ṣẹ ́ gun adéwálé ni wọ ́ n bí sí ilé ọÓba tí òun náà sì jẹ ́ ọrùn ìlẹ ̀ kẹ ̀ pẹ ̀ lú nílùú Ògbómọ ̀ ṣọ ́ ní ìpínlẹ ̀ Ọyọ ́ , ní orílẹ ̀ èdè nàìjírìà .
Lara iru aṣa bẹẹ to wọpọ nilu Oyo ati ni awọn agbegbe miran nilẹ Yoruba ni Igba Titi jẹ.
Lori ipese awọn ohun elo idaabo bo ara ẹni bii ibomu, iboju ati ogun apakokoro, awọn aṣoju ile ẹkọ naa sọ fun akọroyin wa wi pe, lati ọwọ ara wọn ni wọn ti pese awọn ohun elo naa.
"'Logo Benz yóò lẹ́yìn fún àwọn ọ̀dọ́ tó bá ṣògùn owó' Àwọn olórin Nàìjíríà kẹ́dùn ikú ọmọ DBanj Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Mo máa n forin mi kìlọ̀ ìwà ìbàjẹ́ láwùjọ ni -Hameen ""Ijiya si wa fun olutọju alaisan kankan to ba lo ipo rẹ gẹgẹ bi olutọju lati gbiyanju tabi ni ibalopọ pẹlu alaisan to n tọju."
Kii ṣe owo wọn tori naa bawo ni wọn ṣe fẹ buwọlu aba lati ya owo ti wọn ko da sinu rẹ?
Yahya Jammeh ti Senegal Yahya Jammeh wọle gẹgẹ bi olori ijọba ologun ni ọdun 1994 ki o to sọ ara rẹ di olori ijọba alagbada ati aarẹ orilẹede Gambia ni ọdun 1996.
Bi a ṣe n sisẹ bayii Bi awọn orilẹ-ede ṣe d'ẹnu kọlẹ, ọpọ oṣiṣẹ ti gbiyanju lati tẹsiwaju pẹlu isẹ wọn lati ile.
Olusola Isola Ogunsola fi ọpọ ọmọ silẹ saye lọ.
Coronavirus updates and palliative: Gomina Dapo Abiodun ti APC kéde àdínkù owó orí nípinlẹ̀ Ogun
Iná náà mọ́lẹ̀, ó sì ń kọ mànàmànà.
ile-ise miiran kan je pọ ,to jẹ pe won ko ti i ri da pada.
O ni Lahiri ni oun fẹ pidan yii wo ki ọkan awọn onworan le fà si iṣẹ ọlọwọ idan pada ni.
Ìròyìn burúkú ni mo ní fún ọ.
2 Kíyèsíi, èmi ni Ọlọ́run; tẹ́tí sí ọ̀rọ̀ mi, èyí tí ó jẹ́ alààyè àti alágbára, ó mú ju idà olójú méjì lọ láti pín sí ọ̀tọọ̀tọ̀ oríkèé àti mùndùnmúndùn; nítorínáà tẹ́tí sí ọ̀rọ̀ mi.
Asofin Enang so pe, aare pelu awon emewa re, alaga egbe oselu APC, ogbeni Adams Oshiomhole ati adari egbe APC lorile-ede Naijiria, asiwaju Bola Tinubu  yoo jo wa niluu Uyo lojo naa ni.
Owo to n wọle lati awọn ile itawe rẹ, Stationery Stores ti o da silẹ nilu Eko, Ibadan, Enugu ati Port Harcourt ni Adebajo fi n tukọ ẹgbẹ naa.
Aarẹ ọna kakanfo Yoruba Iṣẹ́ Kudirat Abiọla ṣì ń fọhùn síbẹ̀, lẹ́yìn ọdún 23 tó papòdà Oshisko twins, àwọn 'ìbejì' tó ń dẹ́rìn ín p'òṣónú Wọ́n ta ère Ọ̀ṣun Osogbo sí Togo - Bàbá Ọṣun figbe ta Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí 2 sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 2:23 Fídíò, Water Generator: Ó leè ṣiṣẹ fún wákàtí mẹfà, kó tó sinmi, Duration 2,2310 Òkùdu 2020 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
Kò sí ẹnìkan tí ó lè gba eniyan kalẹ̀ lọ́wọ́ mi:Ta ni le dínà ohun tí mo bá níí ṣe?
"Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Àródan jẹ́ ọ̀rọ̀ Yorùbá tí ìtúmọ̀ rẹ̀ fara sin Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àródan jẹ́ ọ̀rọ̀ Yorùbá tí ìtúmọ̀ rẹ̀ fara sin 11 Agẹmo 2019 Gbajugbaja ni ọrọ yii, ""Arodan"" paapaa ninu agbo ile nilẹ Yoruba."
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Bukola Saraki: Kí ló dé tí Adams Oshiomole n fẹ́ kó gbé adé APC sílẹ̀?
nítorí náà, ẹ wò ó, OLUWA yóo gbé ọba Asiria ati gbogbo ògo rẹ̀ dìde wá bá wọn, yóo sì bò wọ́n mọ́lẹ̀ bí omi odò Yufurate, tí ó kún àkúnya, tí ó sì kọjá bèbè rẹ̀.
“Bí irú ẹni bẹ́ẹ̀ bá bí ọmọ, tí ọmọ yìí ń fi ipá jalè, tí ń pa eniyan, tí kò ṣe ọ̀kankan ninu gbogbo ohun tí a kà sílẹ̀ pé baba ń ṣe, 
N óo sì fi àjàkálẹ̀ àrùn ati ikú ogun ṣe ìdájọ́ wọn.
tí o bá ń tẹ́tí rẹ sílẹ̀ sí ọgbọ́n,tí o sì fi ọkàn sí òye,
Bo ṣe n wa iṣẹ mi i, mo rọ ọ lati maa ranmi lọwọ nileewe ti mo da silẹ.
Siwaju si, Shehu so pe, ninu erongba aare lati gbogun ti iwa ibajẹ, orisirisi atunse lo ti ba awon ofin ati ilana lojuna ati ri daju pe ise akanse gbigbogun ti iwa ibajẹ naa fese mule sinsin.
Ajọ to n mojuto eto ilera l'agbaye, WHO, to fi mọ UNICEF, ni omi ọyan ni awọn eroja aṣaraloore fun awọn ọmọde.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Tantra: Ìlànà yìí ló ń kọ́ wa láti fi èémí àti ìṣẹ́po ara gbádùn ìbálòpọ̀ O si ṣeni lanu pe, oṣu kan lẹyin ti wọn bi, ni iya rẹ ku.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ẹ má sọ Amotekun di ẹgbẹ́ OPC, ẹ fi wá sínú ẹ̀ṣọ́ aláàbò - Miyetti Allah Buhari, kí ló dé tó fẹ́ dá $100m owó Abacha padà fún gómìnà Kebbi?
”Agbaboolu iko Super Eagles teleri, Waheed Akanni, ti o je alejo pataki lasiko iyikoto ifigagbaga idije ohun, gboriyin pupo fun Bishop Mike Okonkwo  fun akitiyan to n ko lati gbe idije ohun laruge lodoodun.
”“oloogbe Akanbi je olooto , ti ko si ni iwa ojusaaju fun awon eniyan.
ise akanse ba isẹ won de , won yoo gbe abajade won wa sibi  ipade awon aare orile ede ,ile Afirika lasiko
Bakan naa ni arabinrin Rukiya McNair ni inu awọn ọmọ oun dun pupọ lati gbe nilẹ adulawọ.
Ọmọ ipinlẹ River ni obinrin naa, eyi ko si ṣẹyin bi gomina ipinlẹ rẹ, Nyesom Wike ṣe gba a silẹ ninu ahamọ ti wọn fi si ninu ile to wa lẹyin awuyewuye to waye lẹyinn to kuro ni NDDC.
Nebukadinesari ọba Babiloni yan Gedalaya ọmọ Ahikamu, ọmọ Ṣafani ní gomina lórí àwọn tí wọ́n kù ní ilẹ̀ Juda.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Helen Paul sọ idi tó fi gba orúkọ ní kékere Eyi kii ṣe igba akọkọ nilẹ Afirika ti ẹranko ti ko yẹ ko ba ni gbe ninu ile le adari orilede sita ni ọfiisi rẹ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Awọn maalu sediwọ fun ọkọ ofurufu nilu Akurẹ 18 Èrèlè 2018 Oríṣun àwòrán, Getty Images Awọn maalu kan ti wọn rin wọ papa ọkọ ofurufu to wa ni Akurẹ ni ipinlẹ Ondo dina ati balẹ fun baalu ileesẹ Airpeace kan.
Ìgbá tí ó wá oúhnjẹ tán, ó ké sí mi, bí o sì ti Ké bẹ́ẹ̀ ṣe ni mo rí ti ogiri bìlà sẹ́yìn tí mo fa ẹsẹ̀ mi yọ.
awon omo orile ede Senegal fun aseyori eto idibo orile ede naa to lọ ni irọwọ
“A ni lati ni iwa Olọrun lookan aya wa pẹlu suuru ati ifarada eleyii ti Anabi Ibrahim, iyawo rẹ, Hajarat ati ọmọ wọn, Ismaila wu.
Òwú tí ìyá gbọ̀n, lọmọ ó ran ni ọ̀rọ̀ Saraki nínú òṣèlú
"rọ ́ síà ( , , "" rossiya "" ) tabi orile-ede Ìparapọ ̀ rọ ́ sìà ( , ) , je orileijoba ni apaariwa eurasia ."
Adebo bórí l'Oyo, Oluomo ní ìpínlẹ̀ Ogun gẹ́gẹ́ bí adarí ilé aṣòfin Ó dára kí ìjọba ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́ ní àjọ tó ń gbógun ti ìwà ìbàjẹ́!
“Bí ọkunrin tabi obinrin bá ní àrùn kan ní orí tabi ní irùngbọ̀n, 
Awọn orilẹede ti wọn ti fofin de lilo nylon Bangladesh lo kọkọ fofin de li lo rọba tabi nylon ni ọdun 2002.
Sugbọn aroye pupọ wa lori boya wọn o yara da awọn ọmọ yi pada si ile ẹkọ ni tabi bẹẹkọ ati iru aabo ti yoo wa fun wọn nibẹ Naijiria ati Ghana nkọ ?
Oríṣun àwòrán, Facebook Ni bayii, ipinlẹ Kogi ati Cross River ni ipinlẹ meji ti aarun covid-19 ko tii wọ lorilẹede Naijiria.
Nígbà tí àwọn ará Siria dé láti Damasku tí wọ́n ran Hadadeseri, ọba Soba lọ́wọ́, Dafidi pa ẹgbaa mọkanla (22,000) ninu àwọn ọmọ ogun wọn.
Buhari dasi ipaniyan Benue Soyinka s'ọrọ lori ipaniyan awọn darandaran Alukoro ileesẹ ọlọpa ni arakunrin naa tun gbiyanju ati sa awọn ọlọpa to fẹ mu u pẹlu ada ki wọn to kapa rẹ pẹlu iranlọwọ awọn ọdẹ agbegbe naa.
Àgbàdo ni wọn fi nṣe Ògì.
Awọn aworan inu itan yii wa lati ọwọ oṣiṣẹ BBC, Manuella Boloni Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
nítorí ìfẹ́ Kristi ni ó ń darí wa, nígbà tí a ti mọ̀ pé ẹnìkan ti kú fún gbogbo eniyan, a mọ̀ pé ikú gbogbo eniyan ni ó gbà kú.
Akọwe ijọba ipinlẹ Kano ninu atẹjade kan ṣalaye pe igbimọ iṣejọba ipinlẹ naa yọọ loye lori ẹsun pe o n tako aṣẹ ti gomina ipinlẹ naa n pa.
Àtẹjàdè náà kà báyìí pé: A ṣe àkíyèsí pé àwọn kan ń ṣe àhesọ ọ̀rọ̀ lórí àwọn ẹ̀rọ àkànsiraẹni káàkiri pe MURIC gbá ẹgbẹ̀rún lọ́nà igba dọ́là lọ́wọ́ ISWAP.
Ni aṣalẹ Ọjọbọ lawọn kan bẹrẹ lori ayelujara pe agba oṣelu naa ti jade laye.
Awọn ọlọaa naa ni Insipekitọ Adamu Usman, Sajẹnti Adeyeye Adeoye, Sajẹnti Kashim Tijani, Sajẹnti Lucky Akigbe ati Sajẹnti Paul Adeoye.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Báyìí ni mo ṣe gbẹ̀san lára ọ̀rẹ́kùnrin mi tó kó HIV ràn mí 23 Ọ̀wàrà 2018 Oríṣun àwòrán, Alyssa Vincent Photography Àkọlé àwòrán, Diane Reeve today Diane Reeve ko mọ pe oun tun le ni ololufẹ mọ lẹyin ti igbeyawo ọlọdun mejidinlogun rẹ tuka.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ọkẹ aimọye ẹmi, dukia ati ohun amusajejẹun awọn eeyan Niger Delta lo ti ba wahala ifọnka epo rọbi lọ Ẹsun ti ajọ Amnesty International fi kan awọn ileesẹ ipọnpo mejeeji yii ko kere rara.
 Eyi to tumọ si pe awọn oṣiṣẹ alabo ni agbegbe naa ko mọ iṣẹ wọn niṣẹ, o yẹ ki wọn le gegi dina iru iṣẹlẹ yii.
Àwọn mejeeji bẹ̀rẹ̀ sí sáré; ṣugbọn ọmọ-ẹ̀yìn keji ya Peteru sílẹ̀, òun ni ó kọ́ dé ibojì.
Àkọlé àwòrán, BBC, erin nla to n ṣeun nla lawujọ Izeowayi lo gba ami ẹyẹ naa ninu awọn akẹẹkọ mejidinlogun to kopa ninu idije naa.
Oníròyìn aládàádúró mìíràn, Sevinc Osmangizi, fi ṣe àgbékalẹ̀ ìpè kan ní oríi YouTube tí ó ń pè fún ìda-ọ̀rọ̀-wo lórí ìfọ̀rọ̀wáni-lẹ́nuwo ọ̀hún lẹ́yìn tí Ìgbóhùnsáfẹ́fẹ́ parí.
APC yoo dide lodi si ijọba laipẹ nitori pe Osinbajọ àti Buhari yoo ri wahala Primate Ayodele wa kesi awọn ọmọ Niajiria lati gbohun adura soke fun orilẹ-ede naa, ki ijamba, ikọlu ati ibugbamu oloro ma ba a peleke si lorilẹ-ede Naijiria.
Ohun marun ti ejo n jẹ ni: Ẹyin adiyẹ Kokoro Ẹlẹdẹ Ẹja Owo ti o to miliọnu mẹrindinlogoji naira?
Ijoba orile ede ti ni ohun ko ni kaare lati tubo lowo ninu idagbasoke ohun amayederun ni  jake-jado orile ede Naijiria.
Igbeyawo lo so Buhari ati Amina Zakari pọ.
Ogboju ọdẹ ninu igbo irunmole je itan awon akoni meje ti wọn lo sinu igbo ibẹru, igbo to kun fun awọn ẹbọra lorisiirisii ni eyi ti wọn lọ́ wa nkan iyebiye fun Oba ilu wọn ki alaafia le jọba ni ilu wọn, iyẹ́n Eso Ironu.
Ẹnikẹ́ni tí ó bá gba ọ̀dọ̀ mi wọlé yóo rí ìgbàlà, yóo máa wọlé, yóo máa jáde, yóo sì máa rí oúnjẹ jẹ.
Oba Folagbade Olateru-Olagbegi wàjà lẹ́ni ọdún 77 Ìlú kò mọ ohunkóhun nípa iṣẹlẹ màálù tó kú nilu Ikarẹ- Oba Olukarẹ Ó ti di ẹ̀ṣẹ̀ láti bẹ̀bẹ̀ fún afipábánilòpọ̀ nípìnlẹ̀ Ekiti- Ìjọba ìpínlẹ̀ Ekiti Ìbálòpọ̀ ọ̀lọ́jọ́ méje mú kí ilé ẹjọ́ tú ìgbéyàwó ọdún mẹ́wàá ká ní Ibadan Kí lo mọ̀ nípa ìbẹta kan ṣoṣo tí Alaafin Oyo bí?
, oju to n sọrọ Oríṣun àwòrán, @GovAyoFayose Àkọlé àwòrán, Ololufẹ, maa fẹ ọ titi aye ni tọkọ-taya tuntun n sọ fun ara wọn Oríṣun àwòrán, @Emmadex Àkọlé àwòrán, Ijo shaku-shaku baba iyawo yii, ara ọtọ ni Oríṣun àwòrán, @Eletiọfẹ Àkọlé àwòrán, Haa, o ga ju.
OLUWA bá sọ fún Solomoni pé, “Nítorí pé o ti ṣe ìfẹ́ ọkàn rẹ, o kò pa majẹmu mi mọ́, o kò sì tẹ̀lé ìlànà tí mo pa láṣẹ fún ọ, dájúdájú n óo gba ìjọba náà kúrò ní ọwọ́ rẹ, n óo sì fi fún ọ̀kan ninu àwọn iranṣẹ rẹ.
, Duration 3,5413 Bélú 2020 6:48 Fídíò, Akomolede ati Aṣa lori BBC:Wo ìrúfẹ́ ìgbeyàwó méje tó wà nílẹ̀ Yorùbá àti ojúṣe Alárinà, Duration 6,4810 Bélú 2020 Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí kan sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
Oríṣun àwòrán, SEYI MAKINDE Nibayii, BBC News Yoruba ṣe atupalẹ bi irinajo Gomina Seyi Makinde ṣe lọ laarin akoko naa ati awọn eeyan to ṣeeṣe ki wọn ti ko arun yii lati ara rẹ.
Wọn á kú ikú òjijì, ní ọ̀gànjọ́ òru;á mi gbogbo eniyan jìgìjìgì, wọn a sì kú.
Ẹnu àwọn àgàbàgebè eniyan ni ẹ̀kọ́ burúkú wọnyi yóo ti wá, àwọn tí wọn ń sọ̀rọ̀ èké; àwọn tí Satani ń darí ẹ̀rí-ọkàn wọn.
O ni 'iwa ibajẹ ni igbesẹ naa jẹ fun aarẹ lati maa lo irinsẹ ijọba lati mojuto aawọ ẹgbẹ oselu rẹ ati pe lai fọtape, igbesẹ yii ti kuna ko to tilẹ gberasọ' Oríṣun àwòrán, @APCNigeria Àkọlé àwòrán, Ọpọ awọn to darapọ mọ ẹgbẹ oselu APC saaju idibo 2015 lo ti n kun fun idi kan tabi omiran Ileesẹ aarẹ si ni isẹ lati se lori sise idamọ awọn to ni ẹhonu ati awọn ti yoo lewaju eto ipẹtu si aawọ yii, igbayi gan an ni a to lee mọ boya Tinubu gan lo tọ si lati lewaju eto ọhun.
Ajọ eleto idibo INEC nipinlẹ Kano sọ pe oun ti gbaradi fun atundi ibo naa.
Olukopa kan ninu idije ere-idaraya ori fonran niluu Jacksonville, nipinle Florida, lorile-ede Amerika ti gbemi ara re leyin ti o yinbon mo eniyan meji ti won si padanu emi won lesekese.
Stella Damasus, Omotola Ekehinde, Ezekwesili, Funmi Iyanda dá sí ẹ̀sùn ìfipábánilòpọ̀ Fatoyinbo Ìjọ Satani dá MI lóhùn lórí ọ̀rọ̀ Fatoyinbo Ò ti pé ọdún 27 tí Shah Rukh Khan ti ń se fíìmù India Àwọn orílẹ̀èdè àjọ ECOWAS yóò máa ná owó kan nàá l'ọ́dún 2020 Àkọlé àwòrán, Awon obinrin ti n pe siwaju ijo COZA Awọn obinrin ti pejọ pọ siwaju ijọ COZA ni Guzape ni Asokoro ni Abuja to jẹ olu ilu Naijiria fún iwọde lori ọrọ ifipabanilopọ.
Ó tó fún ọmọ-ẹ̀yìn bí ó bá dàbí olùkọ́ rẹ̀.
Àwọn ọ̀ràn ìpànìyàn tí a yàn wáyé ní àárín-in ọdún-un 2012 to 2016.
Wòlíì Arole, lásìkò to ń bá BBC Yoruba sọ̀rọ̀ ṣàlàyé pé, isẹ awada sise tí gbé òun de ibi gíga, tí òun kò lérò pé òun leè de rí, tí òun ṣi tún mọ àwọn èèyàn ńlá-ńlá pẹ̀lú.
Àwọn àṣà wọ̀nyí náà ló tàn dé ilẹ̀ Amẹ́ríkà.
Iye owo kan naa ni ọkunrin ọkunrin ati obinrin to jawe olubori ninu ere eje-gigun naa jọ gba.
Arabinrin naa sọ fun BBC Yoruba pe o yẹ ki ijọba pese iṣẹ ọwọ fun awọn ọmọ Naijiria to ti kẹkọ gboye ṣugbọn ti ko ni iṣẹ lọwọ.
1/115, ni adari awọn osise nipinlẹ Eko, Muri Okunọla fi ọwọ si.
Àwọn olódodo rí i, inú wọn dùn,a sì pa àwọn eniyan burúkú lẹ́nu mọ́.
A gbo pe o tó èèyàn mílíọ̀nù meẹdọgun tó bá ajakalẹ àrùn onigbameji náà lọ, kò tó di pé ó kasẹ nilẹ.
Alaga egbe naa ti o je oludari eka to n mojuto oro ayika ati imo-ero, Peter Ekweozo so pe, oun ati awon omo egba ti o ku yoo ri daju lati sise won bi o ti to ati bi o se ye lojuna lati bere si ni samulo kemika epo robi lorile-ede yii.
Nigeria 2019 Elections: Ṣé ọwọ́ ti ká Boko Haram ní Nàìjíríà
O fikun pe bakan naa lawọn agbébọn ọhun tun tẹdo sinu igbo igbafẹ Old Oyo National Park lagbegbe Oke Ogun yii kan naa.
re pe, aare yoo wa ni kale lojo ayeye ayajo odun awon osise, ti yoo waye lojo
Ó jẹ́ kí á fi idà pa àwọn eniyan rẹ̀;ó sì bínú gidigidi sí àwọn eniyan ìní rẹ̀.
Nítorí pé ó fi omi tẹ́ àwọn tí òùngbẹ ń gbẹ lọ́rùn,ó sì fi oúnjẹ dáradára bọ́ àwọn tí ebi ń pa ní àbọ́yó.
Samuel Olasehinde: Oríṣun àwòrán, others Samuel ni ọmọ bibi àgbà ọjẹ kan lagbo osere tíátà, Kayode Olasehinde, tí inagijẹ rẹ sì ń jẹ Ajirebi.
 ara ìwàrẹ ̀ fà mẹfà ni Ọ ̀ gbọ ́ ni méjèejì yí wa ni iléṣà ṣùgbọ ́ n Ọ ̀ gbọ ́ n Ìjẹ ̀ bú - jẹ ̀ ṣà ni aṣáájú àwọn ìwàrẹ ̀ fà náà.
Mo kọ̀ láti yí ọ̀rọ̀ mi padà lórí ètò ẹ̀kọ́ ọ̀fẹ́ - Gómìnà Dapo Abiọdun A fẹ́ ìdájọ́ òdodo lórí ìsẹkúpani- àwọn akẹ́kọ̀ọ́ FUOYE Gbàgbé ẹ̀sọ́ ara $40m rẹ pátápátá - Ilé ẹjọ́ sí Dienzani Ẹ wo márùn ún lára àwọn tí ilé ẹjọ́ ti yọ kúrò nípò lẹ́yìn ìdìbò ọdún 2019 Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Awọn di wonyi jẹ lara idi ti ẹgbẹ naa fi pe fun iyapa kuro lara orilẹede Naijiria.
Awọn oludije mejila ni gbogbo awọn to n dije dupo naa bayi.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù premier league: Liverpool to ọrẹ́ sí ẹ̀yìn Manchester United pẹ̀lú àmì ayò méjì sí òdo 19 Sẹ́rẹ́ 2020 Oríṣun àwòrán, Getty Images Itakun Manchester United gbiyanju titi ṣugbọn ko lee da erin Liverpool duro lọna pe ko maa tẹsiwaju ninu ilepa rẹ lati gba liigi Gẹẹsi ti saa yii.
Ìráhùn Ẹni tí Ó Wà ninu Ìṣòro.
O tun gba wọn niyanju pe pẹlu adura ati iforiti, ohun gbogbo ni ṣiṣẹ fun ẹda.
Nítorí Mẹlikisẹdẹki yìí jẹ́ ọba Salẹmu ati alufaa Ọlọrun Ọ̀gá Ògo.
Pẹlu awọn eniyan to wa ninu igbimọ yii, ireti wa wi pe atunse to monyan lori yoo wa fun ile-isẹ  ọlọpaa, lati lee se ohun to tọ.
orile ede Naijiria balẹ pe, iwa odaran ati apaniyan ti dopin lorile ede yii ‘‘Ọjọ
‘Hanameli ọmọ Ṣalumu, arakunrin baba rẹ, yóo wá bá ọ pé kí o ra oko òun tí ó wà ní Anatoti, nítorí pé ìwọ ni ó tọ́ sí láti rà á pada.
₦30,000 owó oṣù yòó bẹ̀rẹ̀ ní September - Alága ẹgbẹ́ òṣìṣẹ́ l‘Ekiti Ẹgbé agbábóólù orílẹ-èdè Naìjíríà gba ẹbuǹ wúrà ilẹ Afrika Wọn gbe e pada wa si orilẹ-ede Naijiria lẹyin ibi rẹ, ṣugbọn o pada si ilẹ Gẹẹsi nigba ti o pe ọmọ ọdun mẹrindinlogun.
Àìsàn tó ń ṣe ọ ní ohun ṣe pẹlú oorun rẹ - Onímọ Ó ṣe f'ọ́mọ tó n jeérú!
 ní ọdún 1967 ó sì bá lolo soetoro lọ sí indonesia .
Ọba bá wólẹ̀ níwájú Daniẹli, ó fi orí balẹ̀ fún un, ó sì pàṣẹ pé kí wọ́n rúbọ kí wọ́n sì sun turari sí Daniẹli.
Oku arakunrin naa to lọmọ maarun ti o si n ṣiṣẹ ọlọdẹ pẹlu ijọba ipinlẹ Ekiti lawọn eeyan sadede ri nirọlẹ ọjọ iṣẹgun.
Ki Yobo to de ipo tuntun yii, o ti fi igba kan jẹ balogun ikọ Super Eagles to si ṣe aṣeyọri ninu idijẹ ifẹ ẹye ti ilẹ Afrika to waye lọdun 2013.
Mi ò nígbàgbọ́ nínú agbára bàbá ìsàlẹ̀ Jegede ti ni ko sohun kankan to n jẹ baba isalẹ ninu oṣelu.
Mutiu Agboke: Ìbanilórúkọjẹ́, ìjínigbé, àti ìdúnkookò mọ́ni la kojú lásìkò ìbò
Ìyìn ni fún OLUWA, àpáta mi,ẹni tí ó kọ́ mi ní ìjà jíjà,tí ó kọ́ mi ní iṣẹ́ ogun.
Àkàngbé Ọrímóògùnjẹ́: Òun ni wọ́n jí owó rẹ̀ gbé tí Akin Olúṣínà wá ṣe ìwádìí rẹ̀.
 ohun tí gírámà tí a ń lò nínú ìdánilékòó yìí so ni pé ( 58 ) ni ìpìlò ( 55 ) , ìyen ni pé ní ìhun ìpìlè , ( 58 ) nìkan ni a ní .
Kò sí ohun kan tí ó nù, Dafidi gba gbogbo àwọn ọmọkunrin ati ọmọbinrin rẹ̀ pada, ati gbogbo nǹkan tí àwọn ará Amaleki kó.
Iroyin ni ọpọlọpọ gomina Nyesome Wike to n tukọ ipinlẹ Rivers lo wa gbaa silẹ lọ sile ijọba ni Pọta.
Ni otitọ irufẹ alekun bayi ninu owo isuna yoo jẹ ki wọn le mu idagbasoke ba awọn nkan amulo to nilo atunṣe lẹka ilera.
Wọn ti kọkọ bẹrẹ pẹlu ikunsinu lorisiirisii.
Ko si ẹni ti ko nii ku.
Níkọ̀kọ̀ ni o dá ẹ̀ṣẹ̀ yìí, ṣugbọn níwájú gbogbo Israẹli, ní ọ̀sán gangan, ni n óo ṣe ohun tí mò ń sọ yìí.
yoo maa gba ijoba nimoran lona ti won yoo gba lati maa san ekunwo owo awon
com/CAspWe0mFK❄️ I C E C O L D ❄️Big moment.
Iroyin sọ pe wọn gbe aarẹ Essbsi lọ sileewosan ni oṣu to kọja nitori ohun ti awọn alaṣẹ orilẹede naa kan pe ni 'wahala ilera to lagbara gidigidi' Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Yoruba Culture: àṣà ìkínni ṣe pàtàkì nílẹ̀ Oodua Nigba naa, olotu ijọba orilẹede ọhun, Youssef Chahed to bẹẹ wo nileewosan rọ awọn eeyan lati yẹra fun iroyin irọ nipa ipo ilera rẹ nigba naa.
Ọ̀kan ninu wọn yóo fa ọ̀dọ́ ewúrẹ́ mẹta lọ́wọ́, ekeji yóo kó burẹdi mẹta lọ́wọ́, ẹkẹta yóo sì gbé ìgò aláwọ kan tí ó kún fún ọtí waini lọ́wọ́.
Bí a ti ní oríṣìíríṣìí ẹ̀bùn gẹ́gẹ́ bí Ọlọrun ti pín oore-ọ̀fẹ́ rẹ̀, bẹ́ẹ̀ ni kí á lò wọ́n.
“Ìrànlọ́wọ́ wo ni ẹ ti ṣe fún àwọn tí wọn kò lágbára?
Bí agbára Dafidi ti ń pọ̀ sí i, bẹ́ẹ̀ ni agbára àwọn tí wọ́n wà lẹ́yìn Saulu ń dínkù.
Coronavirus in Nigeria: Àwọn Ìpínlẹ̀ tí coronavirus kò tíì dé ní Nàìjíríà, àti ìgbésẹ̀ tí wọ́n ń gbé láti dènà rẹ̀ Oríṣun àwòrán, others Àkọlé àwòrán, Wo ipinlẹ ti ko tii ni coronavirus ni Naijiria Titi di ọjọ Kejila, oṣu Kinni, ọdun 2020, orilẹ-ede China nikan lo tii ni awọn to ni aarun coronavirus.
Bákan náà, ọ̀dọ́kùnrin kan ní ìlú Kánò, ti wọn fi sẹkẹ́sẹkẹ̀ so mọ́lẹ̀ ní ibùdó ìfiniwọ̀ kan, ní esinsin ń kùn, tí oògùn ikọ́ olómi tó ní èròjà codeine nínú tó ń mu fún ọ̀pọ̀lọpọ̀ osù pẹ̀lú àwọn ọ̀rẹ́ rẹ̀, sì ti sọ di alárùn ọpọlọ.
Má ba ara jẹ́ bí ẹnìkan bá di olówó,tí ọrọ̀ rẹ̀ ń pọ̀ sí i.
Awọn ololufẹ Jean-Pierre Bemba, tii se oloselu alatako ree, ti wọn lọ ki olori wọn kaabọ, nigba ti ileẹjọ to wa fẹsun ọdaran lagbaye kede pe Bemba ko lẹbi ẹsun ti wọn fi kan Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, O ba ni, ko tii bajẹ, lawọn eeyan orilẹede Sudan n pariwo lẹyin tawọn ologun le aarẹ wọn.
Adebajo se ikede yii lasiko ti o n gbalejo awon alase eka idagbasoke Ogun-Osun ni oofiisi re nilu Abeokuta to je olu ilu ipinle Ogun.
Aare Muhammadu Buhari ti bọwọlu ọgbọ̀n ẹ̀gbẹ̀rún
Ohun ẹnu rẹ ti o dabi ti ọmọde ni o da Dẹjọ yatọ laarin awọn adẹrinpoṣonu yooku.
“Ṣugbọn Abrahamu dá a lóhùn pé, ‘Ọmọ, ranti pé nígbà tí o wà láyé, kìkì ohun rere ni o gbà, nígbà tí ó jẹ́ pé nǹkan burúkú ni Lasaru gbà.
Ìdí rèé tí Aisha Buhari kò tíì padà sí Nàìjíríà- Iléeṣẹ́ ààrẹ Ǹ jẹ́ o mọ ọ̀rọ̀ tí Ààrẹ Buhari sọ fún Ọọ̀ni níbi ọdún Ọlọ́jọ́?
Eyi jẹyọ ninu esi ayẹwo ti ajọ to n mojuto ajakalẹ aarun ni Naijiria, NCDC.
Abiṣai, ọmọ Seruaya, ṣẹgun àwọn ará Edomu ní àfonífojì Iyọ̀, ó pa ẹgbaa mẹsan-an (18,000) ninu wọn.
O ní ìlera sẹnatọ, jijẹ àti mimu, pẹ̀lú ìléra rẹ̀ ló jẹ àwọn lógún báyìí.
ninu idije Africa Cup of Nations to n lo lowo, eleyi ti o waye lojoAiku(Sunday).
Ifa ni ọhun yoo dara, eyiun ti ọrunmila ba ti lee se suuru pẹlu Wuraọla.
Bí wọ́n ti ń lọ, mo gbọ́ ariwo ìyẹ́ wọn, ó dàbí ariwo odò ńlá, bí ààrá Olodumare, bí ariwo ìdágìrì ọpọlọpọ àwọn ọmọ ogun.
Obinrin gbo‘rinyin l'ayajọ awọn obinrin Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Obinrin jẹ amuludun' O ní àwọn obìnrin máà ń yàn láti tọ ọmọ ju kí wọn yan iṣẹ̀ kan láàyo lọ Bótilẹ̀ jẹ́ pé Manglin Pillay tọrọ àforijì sùgbọn ẹgbẹ́ SAICE sọ pé àwọn ti yọ̀nda rẹ̀ lẹ́nu iṣẹ́ nítori ìhà tí àwọn ọmọ ẹgbẹ́ kọ ọ̀rọ̀ náà.
co/SFaua5DR8s #WorldCup #KSAEGY #KSA #EGY pic.
Lori eleyii, Kabiyesi Saliu Adetunji ti ṣaaju fi ọrọ lelẹ pé bi wọn ba fẹ ma wọ afin oun gẹgẹ bii Olubadan, wọn gbudọ gbe ade wọn silẹ.
Bakan naa ni ikọ naa tun koro oju si bi awọn ọlọpaa to n ṣọ ibode ipinlẹ naa ṣe n gba owo lọwọ awọn ọlọkọ ero latijẹ ki wọn wọ ipinlẹ Ondo.
Àwọn ọmọ Geriṣoni gba ìlú mẹtala lọ́wọ́ àwọn ẹ̀yà Isakari, ẹ̀yà Aṣeri, ẹ̀yà Nafutali, ati ìdajì ẹ̀yà Manase tí wọ́n wà ní Baṣani.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù COZA: Fatoyinbo yẹ̀bá fún pẹpẹ ìwàásù fún ìwadìí ẹ̀sùn ìfipábánilòpọ̀ tí wọ́n fi kàn án 1 Agẹmo 2019 Oríṣun àwòrán, Biodun fatoyinbo Àkọlé àwòrán, Ni ọjọ Ẹti iroyin jade nibi ti Busọla Dakolo ti fi ẹsun kan alufa Fatoyinbo ti ijọ COZA pe o fi ipa ba oun lo pọ Mo yẹba fún pẹpẹ ìwáásù fún ìgbà dié- Pasitọ Biodun Fatoyinbo.
ipinle naa, lọjọ Aje Amosun ni awon omo ipinle Ogun yoo tun dibo fun aare Buhari fun igbakeji
Erongba lati gbe igbesẹ yi waye nibi ipade kan tawọn alaṣẹ ijọba ṣe eleyi to n gbero pe ki wọn ti awọn ile ẹkọ pa titi di aarin oṣu Kẹta.
Omọwe naa ni : Bi a ko ba gbagbe bẹẹ lo se nigba to wa ninu ẹgbẹ oselu CPC lasiko ti aawọ n koju ẹgbẹ naa kaakiri ipinlẹ.
Ẹ̀mí Ọlọrun ati Ẹ̀mí Alátakò Kristi.
Nítorí láti inú ẹ̀kún ibukun rẹ̀ ni gbogbo wa ti rí oore-ọ̀fẹ́ gbà kún oore-ọ̀fẹ́.
Àkọlé àwòrán, Obitibiti idọti ti o gba inu igboro kan le ṣe akoba fun ilera awọn ara ilu.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Owo ori lona abayọ si isoro l' Eko Bakan naa, ijọba ipinlẹ Eko ti din iye owo to to ida marundinlogun kuro lara iye owo ori ilẹ to yẹ ki awọn onile tẹlẹ, eleyii yoo mu ki wọn O san N7,752 lọdọọdun.
Awọn oniṣowo mii to maa n pawo lasiko ipade adura yii ree gẹgẹ bi awọn eeyan ṣe maa n dura lati wọ wọn lọ sibi ipejọpọ.
O wu u lati kawe lati kekere ṣugbọn ko si agbara lọwọ awọn obi rẹ ni eyi to fi ko awọn kan jọ ti wọn fi bẹrẹ ẹgbẹ elere ti wọn pe ni Oyo Operatic Society lọdun 1949.
Ìdigunjale Offa: Ọlọ́pàá gbé N5m sílẹ̀ Àwọn adigunjalè pa èèyàn mẹ́fà ní báńkì kan nìpínlẹ̀ Ondo Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Offa Robbery: Àwọn aráàlú ṣi n gbé nínú ìpaya lẹ́yìn ọdún kan Ninu idajọ rẹ, o ni ki wọn fi awọn adigunjale naa si ahamọ titi di ọjọ keji oṣu Karun un titi di igba ti adari ẹka olupẹjọ yoo fi gbawọn ni imọran to yẹlori ẹjọ naa.
Abike Dabiri-Erewa,alaga ajọ NIDCOM ti wa kesi ijọba Amẹrika lati se iwaadi to peye lati le tu isu de isalẹ koko nipa ohun to sokunfa iku arabinrin Slau.
Má dáwọn lẹ́bi, máa tẹti sí wọ́n: Tétí si ǹkan ti wọ́n ń sọ, má sì dáwọ́n lẹ́bi.
Awon apapo egbe naa ni awon oniroyin ti won wa nipinle Kaduna lati awon ile-ise iroyin ori ero radio ati amohun maworan, ile-ise iwe iroyin olojoojumo ati ti ori ero ayelujara, eyi ti won fenuko lati se ipade miiran lojo-Eti, ojo ketadinlogbon osu kerin odun 2018.
Nigba to n ba BBC sọrọ, Hanna Kosinah to diwọ-disẹ sinu salaye pe, oju oun ri mabo, ki oun to ri ọkọ ti yoo gbe oun lọ si ilu miran, lasiko ti oun n rọbi lati bi akọbi oun.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Tanzania: Lẹ́yìn ọjọ́ mẹ́wàá, ajínigbé dá Dewji olówó sílẹ̀ 11 Ọ̀wàrà 2018 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 20 Ọ̀wàrà 2018 Oríṣun àwòrán, AFP Àkọlé àwòrán, Iwe iroyin nipa ọrọ aje iyẹn Forbes Magazine ni biliọnu dola kan le diẹ ni ọrọ Mohammed Ọ̀dọ́mọdekùnrin olówó ilẹ̀ Áfíríkà Mohammed Dewji tí wọ́n jí gbé ní ọjọ́ mẹ́wàá sẹ́yìn ti di rírí báyìí.
Lawan, ọmọ ẹgbẹ iselu APC ati Ali Ndume, latinu ẹgbẹ oselu APC kan naa, ni wọn dijọ figagbaga lati du ipo naa, amọ ori Lawan ni wọn gbe ade aarẹ ile asofin agba le lori pẹlu ibo mọkandinlọgọrin, nigba ti alatako rẹ ni ibo mejidinlọgbọn pere.
Ó tóbi pupọ tóbẹ́ẹ̀ tí ó fi ń bá àwọn ogun ọ̀run jà, ó já àwọn kan ninu àwọn ìràwọ̀ lulẹ̀, ó sì fi ẹsẹ̀ tẹ̀ wọ́n mọ́lẹ̀.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ọmọ Nàìjíríà fárígá lórí olú iléeṣẹ́ Nàìjíríà tí wọ́n wó ní Ghana Iṣẹlẹ naa mu ki awọn ọmọ Naijiria kan to n gbe ni Ghana o ṣe iwọde lati tako iṣẹlẹ naa, ti awọn kan lara wọn to ba akọroyin BBC, Favour Nuno, sọrọ pe ijọba Ghana ti ti ile itaja wọn pa lati bi oṣu mẹjọ, ti wọn kii ṣi tun fi oju're wo awọn ọmọ Naijiria nibẹ.
Ninu fidio kan to fi sita, niṣe ni awọn ọrẹ rẹ fi omi wẹ ẹ lati ṣajọyọ ọjọ naa.
Aworan Oloye Akinjide n bẹ lorii tabili pẹluu iwe nla kan ti awọn olubanikẹdun n kọ ikini ati idagbere ikẹyin si.
Wọn tun da aso ebi paapa.
Nnkan to jẹ ki ọba o yatọ si eeyan lasan niyẹn.
Àwọn ọmọ Ramu, àkọ́bí Jerameeli ni: Maasi, Jamini ati Ekeri.
Bí ẹnìkan bá bá aya arakunrin baba rẹ̀ lòpọ̀, ohun ìtìjú ni ó ṣe sí arakunrin baba rẹ̀.
Ta ni yóo fi ẹ̀sùn kan kan àwọn ẹni tí Ọlọrun ti yàn?
A kò ní pada sí ilẹ̀ wa títí olukuluku àwọn ọmọ Israẹli yóo fi ní ilẹ̀ ìní tirẹ̀.
PDP: A fẹ́ gba odindin Imo padà ni lọdún tó n bọ
Àjọ NIMC ni kí àwọn ènìyàn máa lo *346# láti ri nọ́mbà NIN.
Awọn alatako rẹ fi ẹsun ole ibo kan an bi o tilẹ jẹ pe ko ni aridaju awọn onwoye lati ilẹ okere to mojuto idibo naa.
Àwọn tí kò ní àròjinlẹ̀ tẹ́lẹ̀ yóo ní òye,àwọn akólòlò yóo sì sọ̀rọ̀ ketekete.
Abdulsalam lo ede rẹ lati fi gba awọn ọmọ ogun Afọnja, ti wọn si gba ẹmi Afọnja lọdun 1817 Nigba to di ọdun 1824 lẹyin ti Afọnja papoda, ti Abdulsalam si ti n dari ilu Ilọrin, lo ba kede ara rẹ bii Emir fun ilu Ilọrin, to si sọ pe lati akoko naa lọ, ilu Ilọrin ti wa labẹ akoso Emir ilu Sokoto Lati igba naa wa ni akoso ilu Ilọrin ti bọ mọ ẹya Yoruba lọwọ titi di oni oloni, bi o tilẹ jẹ pe awọn iran Yoruba n tiraka lati gba ipo wọn pada lọwọ ẹya Fulani nilu Ilọrin, amọ wọn kan n le ni, wọn ko tii ba Ọpọ ẹkọ lo wa lara itan Afọnja yii, eyi to yẹ ka mu lo lode oni nitori ẹni to jin si koto, yẹ ko kọ awọn ara yoku lọgbọn, itakun kansoso ko si yẹ ko da wa lepo nu lẹẹkeji.
Ni orilẹede Canada, o ti to eeyan mẹtalelọgọrun ti arun Coronavirus naa ti n ba wọja ija.
Bí ó bá jẹ́ pé àlejò ni ó jẹ ẹni náà ní gbèsè, olúwarẹ̀ lè gbà á, ṣugbọn ohunkohun tí ó bá jẹ́ tiyín, tí ó wà lọ́wọ́ arakunrin yín, ẹ kò gbọdọ̀ gbà á pada.
Má ṣe fi àwọn nkan wọ̀nyí ṣe eré; má ṣe bèerè fún èyí tí kò yẹ.
Ṣùgbọ́n kí á tóó ṣe èyí, èmi àti Ènìyàn-ṣe-pẹ̀lẹ́ lọ wo Òjòlá-ìbínú níbi tí ó kú sí, nígbà tí a sì wo inú ìfun rẹ̀ a bá àdó méjì, ọ̀kan jẹ́ ti wúrà ọ̀kan sì jẹ́ ti fàdákà.
Aburu ka ma di ẹru pupọ ni pe e o ni ri ilẹkun ọkọ pade daada ati pe ọkọ naa ko ni gbera bo ti ṣe yẹ 'Tàpá sófin ojú pópó kóo ṣọdún lẹ́wọ̀n' Ẹ̀wọ̀n oṣù mẹ́ta àti #3,000 ni awakọ̀ tí kò bá ní ‘speed limiter’ yóò fi jura- FRSC FRSC dá N443,180 padà fún ẹbí ẹni to ní ìjàmbá mọ́tò Arsenal ti padà júwe ilé fún Unai Emery O gbọdo ni iwe aṣẹ awakọ: Bi eeyan ba fẹ wa ọkọ, o di dandan ko jẹ awakọ to dantọ.
N óo pa àwọn oṣó run ní ilẹ̀ yín, ẹ kò sì ní ní aláfọ̀ṣẹ kankan mọ́.
Ki lo n fa a, ti nnkan ọkunrin fi n ha soju ara obinrin: Sugbọn ninu iwadii awọn onisegun oyinbo, alaye ti wa pe, ko si ohun to buru ninu ki nnkan ọkunrin ha soju ara obinrin.
OLUWA ní, “Tí ó bá di ìgbà náà, n óo fún Gogu ní ibi tí wọn yóo sin ín sí ní Israẹli, àní àfonífojì àwọn arìnrìnàjò tí ó wà ní ìlà oòrùn Òkun Iyọ̀.
Obanise, lo sọrọ yii lasiko to n se ayẹwo si awon irinsẹ ohun elo ounjẹ ti won
Wo àwọn òfin tuntun tíjọba fí síta lórí lílọ ìrìnàjò sílẹ̀ òkèèrè Ó tó gẹ́ẹ́!
"Ọọfiisi wọn lemi ti se ẹkọsẹ ni temi fun ọsẹ meji.
Ẹnikẹ́ni kò lè jáde, bẹ́ẹ̀ ni ẹnikẹ́ni kò lè wọlé.
Èdè bantu ni èdè yìí .
Lẹ́hìn èyí mo mú háhá mi náà lọ sí inú ihò mi mo sì sùn mọ́jú ọjọ́ náà.
 awon naa ni : Gege bi atejade kan lati odo oludari ile-ise to n mojuto iroyin ni ajo ile-idajo lorile ede Naijiria,Soji Oye.
si ilana ti egbe ba la sile yoo je iyan rẹ nisu.
Emir Daura, Alhaji Umar Farouk Umar, o  so
Lọdun 2018, wọn yọwọ atilẹyin wọn lara ileeṣẹ foonu Blackberry atawọn foonu to n lo Windows ti atijọ.
Ìmọ́lẹ̀ mọ́ sórí àwọn tí ó jókòóní ilẹ̀ tí òjìji ikú wà.
Samsoni ṣe aṣiwaju ní Israẹli ní àkókò àwọn Filistini fún ogún ọdún.
O pa mí mọ́, níwájú ati lẹ́yìn;o gbé ọwọ́ ààbò rẹ lé mi.
Ọmọ-Eniyan yóo rán àwọn angẹli rẹ̀, wọn yóo kó gbogbo àwọn amúni-ṣìnà ati àwọn arúfin kúrò ninu ìjọba rẹ̀.
 Àrokò ńlá ni ọmọ tó bẹ ́ tọ ́ sí ọ lára pa fún ọ ti o ò mọ ̀ .
MC Oluomo fara pa nibi ipolongo idibo ẹgbẹ oṣelu APC to waye nipinlẹ Eko lọjọ diẹ sẹyin o si ti wa nile iwosan nipinlẹ Eko lati igba naa.
“Mú ọ̀pá tí ó wà níwájú Àpótí Majẹmu, kí ìwọ ati Aaroni kó àwọn eniyan náà jọ, kí o sọ̀rọ̀ sí àpáta níwájú wọn, àpáta náà yóo sì tú omi jáde.
Lara awọn to wa nibi eto naa ni igbakeji aarẹ, Yẹmi Oṣinbajo ati aya rẹ, awọn gomina ipinlẹ atawọn ti wọn ṣẹṣẹ dibo yan to fi mọ awọn ọbalaye gbogbo.
Ìyá àgbà Saray ní ìfọkàntẹ̀ pé ìjọba yóò dúró tì òun.
Ẹwẹ nigba ti akọroyin bere boya lootọ ni wọn tun ji awọn ọlọpaa gbe nigba ti wọn n gbiyanju lati doola awọn ọmọ orilẹede India ọhun, alukoro ọlọpaa ni oun lee sọ dajudaju pe irọ ni.
Eni to ba fẹ pegede gbọdọ ni ibo ọtalenigbalemẹwaa ki o to le di aarẹ.
 Ṣadé hàn nínú  the view "" gẹ ́ gẹ ́ bí olùgbàlejò lórí october 27 , 2006 ."
Bí kò bá rí bẹ́ẹ̀, kí àwọn oriṣa pa mí.
Oríṣun àwòrán, AFP Àkọlé àwòrán, Ilu Maiduguri lorilẹede Nigeria ni ibudo afojusun Boko Haram julọ Awọn wo gan la n pe ni Boko Haram?
Ó ṣeéṣe kó má sí ẹ̀ṣọ́ aláàbò Amotekun l‘Eko - Ìjọba Eko Ẹgbẹ́ alátakò ló sanwó fáwọn èèyàn kan láti pariwo lé ààrẹ Buhari lori - Iléeṣẹ́ ààrẹ Arisekola ló fún mi ní ilẹ̀ tí ìjọba Ọyọ gbẹ́sẹ̀ lé, ń kò ní gbà - Ajimobi Ta ni wọn yóò búra fún bíi gómínà Bayelsa lónìí, olùdíje PDP ni àbí olórí ilé aṣòfin?
Asofin Ayo Da-Silva soro ohun di mimo lasiko abewo re sile akoroyin Voice of Naijiria lojoAje(Monday), niluu Abuja.
Ẹ kò gbọdọ̀ jẹ ẹlẹ́dẹ̀, lóòótọ́ ó ní ìka ẹsẹ̀, ṣugbọn kì í jẹ àpọ̀jẹ, nítorí náà, ó jẹ́ aláìmọ́ fun yín.
Nisinsinyii, OLUWA Ọlọrun yín ti fún àwọn arakunrin yín ní ìsinmi gẹ́gẹ́ bí ó ti ṣe ìlérí fún wọn; nítorí náà, ẹ pada lọ sí ilẹ̀ yín, níbi tí ohun ìní yín wà, àní ilẹ̀ tí Mose iranṣẹ OLUWA fun yín ní òdìkejì odò Jọdani.
Ati pe, ọmọ ọhun si ti n gbe pẹlu oun fun igba pipẹ.
Nígbà tí Solomoni di àgbàlagbà, àwọn iyawo rẹ̀ mú kí ọkàn rẹ̀ ṣí kúrò lọ́dọ̀ OLUWA, ó ń bọ àwọn oriṣa àjèjì, kò sì ṣe olóòótọ́ sí OLUWA Ọlọrun rẹ̀ mọ́, bíi Dafidi, baba rẹ̀.
Àwọn ọmọ Dani ní ìdílé-ìdílé nìwọ̀nyí: ìdílé Ṣuhamu.
Ọ̀rẹ́ ọ̀dàlẹ̀ yìí kò mọ ohun tí yóò ṣe, inú ibojì ò ṣeé kó sí, kò sí ọgbọ́n tí owó le fì di ṣíṣà kúrò nínú ibojì, ọ̀rọ̀ wá dàbí ti akúwárápá tó gbé nǹkan adẹ́tẹ̀ sọnù ni, àìlọ́wọ́ kò jẹ́ kí wọn ó lè lura wọn pa!
Ó kọ́ gbọ̀ngàn kan fún àwọn alufaa, ati òmíràn tí ó tóbi, ó ṣe ìlẹ̀kùn sí wọn, ó sì yọ́ idẹ bo àwọn ìlẹ̀kùn náà.
Ni ayé àtijọ́, ìnáwó igbéyàwó kò tó bi ó ti dà ni ayé òde òni.
Lasiko iyaraẹnisọtọ, ṣe ni Ọgbẹni El-Rufai n fi ọrọ sita loju opo Twitter rẹ ni gbogbo igba nipa ipo ti ilera rẹ wa.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ìdílé tí ọkọ da ọmọ síta tóríi ojú Búlùú tí wọ́n ní bá BBC sọ̀rọ̀ Ki lo ti ṣẹlẹ sẹyin?
 Kọmiṣọnna ọhun tẹsiwaju pe Ni erongba temi ni pe, afojusun NCDC ni lati pin arun Covid-19 kaakiri orilẹ-ede yii.
"Wo ìdí tí Risikat Moromoke Azeez n'Ilorin fi ní ""Blue Eyes"" - Dókítà Àjọ JAMB kéde ìlànà ìgbà ni wọlé tuntun fún àwọn ilé ẹ̀kọ́ gíga Asojú ìjọba orílẹ̀-èdè Lebanon ti kọ̀wé fipò silẹ̀ nítorí ìbágbàmù tó gbẹ̀mi ènìyàn 200 Dẹ́rẹ́bà kẹ̀kẹ́ Maruwa rí ẹ̀wọ̀n gbére he lẹ̀yìn tó fi ipá bá ọmọ ọdún mẹ́rìnlá lòpọ̀ O fi kun ọrọ rẹ pe nigba ti yoo ba fi to awọn asiko tuntun ti wọn kede, gbogbo akẹ́kọ̀ọ́ yoo ti gba esi idanwo ti wọn ṣe silẹ."
Oriṣiriṣii awón igbagbọ ti iwadii ko fidiẹ mulẹ ni awọn eeyan ti n gbe jade.
Lẹ́yìn ò rẹyìn, Wasiu Ayinde sọ̀rọ̀ nípa Ayinde Barrister Ta ni obìnrin tó fẹ́ bá Dino Melaye ṣe ìgbéyàwó lọ́jọ́ kejì Kérésì?
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Shiite: Ẹ̀mí àti ara wa kọ ohun tí ìjọba ń ṣe sìwa láti 2015 Boko Haram loni: Lẹyin iku Yusuf, pupọ ninu awọn ọmọ ẹgbẹ Boko Haram fọn kaakiri.
n mojuto papa ofurufu  lorile ede
tí wọ́n ti tọ́ ire tí ó wà ninu ọ̀rọ̀ Ọlọrun wò, ati agbára ayé tí ó ń bọ̀, 
Ètò sogúndogójì 'MMM' tún ti padà dé, rọ́bọ́ọ̀tì ni yóò maa ṣàkóso Ọ̀rọ̀ ti yanjú dé ibì kan lórí owó àjẹmọ́nú àwọn Super Falcons Ọmọ ogun Nàìjíríà bẹ̀rẹ̀ lílo 'Drone' láti gbógun tàwọn ajínigbé ni Ondo àti Ekiti Asamnew Tsige ni wọn sọ wi pe o se olori akitiyan lati gbe ijọba ologun kalẹ nipa isekupa awọn adari ologun.
 wọ ́ n tún ránṣẹ ́ padà pé kí onítọ ̀ hún dá ara rẹ ̀ lójú kí ó tó máa bọ ̀ , bí bẹ ́ ẹ ̀ kọ ́ , àwọn ò ní í jáde síta .
Tomas Soucek lo kọkọ gba bọọlu sawọn fun West Ham nigba ti ifẹsẹwọnsẹ naa di iṣẹju mẹrinlelọgbọn, ṣugbọn ẹrọ VAR wọgile goolu ọhun.
Gbé ìgbàlà rẹ wọ àwọn alufaa rẹ bí ẹ̀wù, kí o sì jẹ́ kí àwọn eniyan mímọ́ rẹ yọ̀ ninu ire rẹ.
" Ènìyàn tó tó igba ló ti bá ìṣẹ̀lẹ̀ ìbúgbàmù tó wáyé ni Lebanon rin báyiìí Àwọn aláànú dìde ìrànlọ́wọ́ fún tìyá-tọmọ olójú búlúù A ti gùnlé ìyanṣẹ́lódì ọlọ́jọ́ gbọọrọ ní ìpílẹ̀ Eko- NUPENG Ìdí rèé tí igbákejì Gómìnà Ondo Agboola Ajayi tún ṣe fi ẹgbẹ́ òṣèlú PDP sílẹ̀ O ni o jẹ ibanujẹ pe ijọba ko awọn eeyan naa si ahamọ, lai bikita fun aarun coronavirus to wa l'ode.
Aworan yi wa lati ile-isẹ iroyin BBC.
Kí ni mo tún lè sọ nípa iyì tí o bù fún èmi, iranṣẹ rẹ?
Favour Oladele: Bó ṣe kàgbákò ikú gbígbóná lọ́wọ́ ọ̀rẹ́kùnrin rẹ̀- Kayeefi
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ọti lile ko ni anfaani f‘ara 16 Èrèlè 2018 Àkọlé àwòrán, Oniruuru ijamba ni awọn ọti pẹlẹbẹ ati tinu ike yi ti se fun ara ọpọ eeyan.
Ajọ WHO sọ pe ki o kọkọ pe ileewosan rẹ na, wọn le dari rẹ si ibi to yẹ.
Fadaka ati wúrà tí ó bá ṣẹ́kù, ìwọ ati àwọn eniyan rẹ, ẹ lò ó bí ó ti yẹ lójú yín ati gẹ́gẹ́ bí ìfẹ́ Ọlọrun yín.
Oríṣun àwòrán, @aishambuhari Àkọlé àwòrán, Aisha Buhari dupẹ lọwọ ọmọ Naijiria fun aduroti wọn Mama rẹ Aisha Buhari kede ipadade rẹ lori oju opo twita re.
Iṣẹ́ náà ni pé Ọlọrun wà ninu Kristi, ó ń làjà láàrin aráyé ati ara rẹ̀.
Oun ni agbabọọlu tẹnisii to ṣẹṣẹ ko aarun covid-19 lẹyin ti Grigor Dimitrov, Borna Coric ati Viktor Troicki sọ pe awọn ni coronavirus lẹyin ti wọn koju Djokovic ninu idije Adria Tour.
Ile ẹjọ to n gbẹjọ iwa ibajẹ, ti ni dandan ni Adajọ Agba Naijiria, Walter Onnoghen ni ẹjọ lati ro lori ẹsun irọ pipa ti wọn fi kan an.
A kò fipá mú ẹnikẹ́ni láti dá Ruga, aàgọ́ Fulani sílẹ̀ -Iléeṣẹ́ aàrẹ O ni oun ko gbagbọ ninu ẹsin igbagbọ, musulumi tabi abalaye ṣugbọn oun gba Olorun gbọ.
Ọpọlọpọ ninu awọn ti a gbọ ọrọ wọn ni wọn ni wọn ko mọ anfani kan pato ti ijọba Naijiria n ṣe fun wọn to mu sisan owo ori tuntun yii dani.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Oladapo Adu: Nàíjíríà já mi kulẹ̀ torí wọn kò wá gbé mi Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Oladapo Adu: Nàíjíríà já mi kulẹ̀ torí wọn kò wá gbé mi 8 Agẹmo 2020 Yoruba ni bi eegun ẹni ba joo re, ori a maa ya atọkun amọ eyi ko ri bẹẹ fun Oladapo Adu, to lọ soju Naijiria ninu idije Chess ni Sierra-Leone.
A gbọdọ koju irufẹ iwa bayii lẹsẹkẹsẹ.
Iroyin fi han wipe iṣẹlẹ naa ṣẹlẹ ni bi aago mẹrin ọjọ Iṣẹgun nigba ti ojo arọọrọda kan rọ ni ilu Otu-Jeremi.
Níbo sì ni ẹni tí ń ka ilé ìṣọ́ wà?
Ṣugbọn ṣa, awọn onimọ ti sọ pe awọn eniyan ko gbọdọ ri oogun remdesivir gẹgẹ bi ajẹ bi idan"" fun coronavirus."
Adeyinka ni ara afojusun oun gẹgẹ bi ẹnikan ni lati di ipo oṣelu mu lọjọ iwaju.
Fẹntíletọ̀ melo ni gbogbo ilé Gẹ̀ẹ́sì ni ati pe mélòó lọ yẹ kí o wà?
itan, eleyii ti Aarẹ ana lorilẹ-ede South Africa, Oloogbe Nelson Mandela fi
nipa ẹkunwo owo osu awon osisẹ, ekunwo owo osu awon osise wa lokan mi.
Igbakeji gomina to wa lori ipo lọwọlọwọ fẹ lọ tọwọ bọwe lọdọ ẹgbẹ oṣelu APC ki o le lọ darapọ mọ ẹgbẹ oṣelu PDP to si fẹ gbe ọkọ to n lo lọfiisi rẹ jade lawọn ọlọpa o jẹ ko jade nile ijọba.
Nígbà tí Joabu pada lẹ́yìn Abineri, tí ó sì kó gbogbo àwọn eniyan rẹ̀ jọ, ó rí i pé, lẹ́yìn Asaheli, àwọn mejidinlogun ni wọn kò rí mọ́.
Jesu dá wọn lóhùn pé, “Àwọn tí ara wọn le kò nílò oníṣègùn, bíkòṣe àwọn tí ara wọn kò dá.
Beyonce New Album: Ìyá àgbà láti Nàíjíríà ní inú òun dùn láti kọrin pẹlú Beyonce nílẹ̀ Amerika
Ogun, Shehik Mayaleke sọ pe ile ijọsin akọkọ ti Ọlọrun mẹnu ba ninu Kurani ni Kabbah ni ilu
Iroyin ni ọpọ ninu awọn ẹru ti awọn eeyan ji ko ni wọn n fi silẹ ni oriṣiriṣi kọrọ adugbo lẹyin ti ileeṣẹ ọlọpaa bẹrẹ ayẹwo ojule si ojule.
Kí ni ìwọ rò pé yóo fẹ́ fi bá oluwa rẹ̀ làjà?
 a ṣe àgbéjáde àjẹsára náà pẹ ̀ lú àwọn kòkòrò àìlèfojúrí afàìsàn ibà pọ ́ njú-pọ ́ ntọ ̀ , àwọn èyítí a ti sọ di aláìlágbára .
Emma Cantril, to jẹ oludasilẹ ileesẹ Intelligent Profile ni ilẹ Gẹẹsi ni oun ti ni isẹ toun ya sọtọ fawọn ọmọ oun lojojumọ.
Bi awọn kan ṣe ti n gbadura pe ori a ṣọ awọn ọmọ yii de ile pada layọ ni awọn miran n ke si ijọba Naijiria lati tete ran wọn lọwọ.
Lẹyin eyi, nibi apejẹ alẹ kan ti ọkan lara awọn amugbalẹgbẹ aarẹ ṣeto , o ni aarẹ sọ pe ki oun fẹ oun.
Aare dibo ni ward A Sarkin Yara Ward , nile idibo ti 003 ni ijoba ibile  Daura ni ipinle  Katsina , ekun ila oorun orile ede Naijiria.
Lawan ṣalaye pe ile ti ya oṣu kẹwaa yii sọtọ fun ẹlẹkajẹka ileeṣẹ ijọba lati wa sọ nipa eto isuna wọn ki o le ya kiakia.
Gẹ́gẹ́ bi ìròyin ṣe sọ Joshua Beckford ni ààrún to níiṣe pẹ̀lú ọpọlọ.
" O ni lẹyin ijoko naa, awọn ọmọ orilẹede Naijria gbọdọ lee mọ pato iye owo iranwọ to wa lori epo bẹntiroolu ati epo kẹrosiini, to fi mọ igbimọ gan-an to nse amojuto epo kaakiri ilẹ Naijiria.
NLC: Àwọn òsìsẹ́ Naijiria ló ń gba owó osù tó kéré jù!
Lara awọn idile to gbajumọ fun owo ẹru sise nigba naa ni idile Ọba Sunbu Mobee, Idile yii to ni gbọngan nla nilu Badagry ti wọn n ko ọpọlọpọ ẹru pamọ si, ki wọn to ko wọn lọ soke okun.
Kí ló dé tí ó fi pa á?
Ìṣòro Nàíjíríà kọjá kí Bobrisky àtàwọn ẹlẹgbẹ́ rẹ̀ dá ní ilé ìgbọ̀nsẹ̀ lọ́tọ̀ ""Èmi ò r'óhun tó burú kí obìnrin opó fẹ́ ọkọ míì sínú ilé ọkọ rẹ̀"" Ará ìlú fárígá, wọ́n wọ́ alàkóso ìlú nilẹ́ pẹ̀lú ọkọ̀ UNILAG ní kí olùkọ́ míì, Samuel Oladipo to ń bèèrè ìbálòpọ̀ lọ́wọ́ akẹ́kọ̀ọ́ lọ fìdí mọ́lé Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Kini Yoru[bá ń pe Necklace?"
Emmanuel Adebayor: Agbábọ́ọ̀lù Togo rántí ìṣẹ̀lẹ̀ tó wáyé lásìkò AFCON 2010
Ní ọdún 2017, ìgbìmọ̀ àgbà àti àjọ ìpínlẹ̀ lábẹ́ ẹgbẹ́ olóṣèlú Communist ìlú China kọ ìwé àṣẹ kan tí a pe àkọlée rẹ̀ ní “Ìmọ̀ràn lórí imúdiṣíṣẹ iṣẹ́ ìgbélárugẹ àti ìdàgbà àṣà ìbílẹ̀ China dé ibi gíga “.
Ìwọ ọmọ mi , máṣe jẹ́ kí ẹ̀rù bà ọ́, ayé rẹ kò ní í ṣàìdára.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Yollywood: Ẹ wo àwọn gbajumọ òṣèré tíátà tó jogún ere ṣíṣe lọ́dọ̀ òbí wọn 29 Ìgbé 2020 Yorùbá ní tí iná bá kú, á fi eérú bo ojú, bí ọ̀gẹ̀dẹ̀ bá kú, yóò fi ọmọ rẹ rọ́pò, bí aladi kò bá sí nílé, ọmọ wọn lo ń jogún ẹbu.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Coronavirus: Wo ilé ìwòsàn kan ti tọmọ-tìyà ti ń kú lẹ̀yìn tí Covid-19 búrẹ́kẹ 16 Agẹmo 2020 Iwadii ikọkọ ileeṣẹ BBC ti tu aṣiri awọn ile iwosan kan ni South Africa nipa ohun toju awọn dokita ati nọọsi n ri lati ṣetọju awọn alaarun Coronavirus.
Ó bi í pé, “Ǹjẹ́ o rí ohunkohun?
Awọn kan ninu awọn ọmọbirin naa maa n de si ilẹ Yuroopu nigba ti awọn ọmiraa maa n ha mọ orilẹede Libya.
Won ti n gbe igbesẹ akin to jẹ pe okunrin nikan lo n gbe tẹlẹ ni ẹkun yii.
egbe APC  ti ni ki wọn yọ Mahmood Yakubu , alaga ajo eleto idibo lorile
Ǹkan mẹ́jọ tó máa kọ́kọ́ ṣẹlẹ̀ kí olólùfẹ́ méjì tó pa ara wọn Laipẹ́, ọmọ tí kò bá pé ọdún méjìdínlógún kò ní leè jáde girama l’Ọṣun Wọ́n ti pa ẹni to yìnbọn pa ará Texas márùn ún -ọlọ́pàá Adeboye sọ̀rọ̀ lórí ètò pápá ìjẹko RUGA Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, VAT: Kò sí àǹfàní kankan tí ìjọba ti ṣe fún mi sẹ́yìn Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Ninu oro Emir ilu Kano, O so pe, asiri mimu igberu ba oro ilu, o niise pelu bi awon eniyan se le gba tabi ba ara won gbe papo.
"Mo ti pinnu láti túṣu dé ìsàlẹ̀ ìkòkò lóríì ìdí tí kò sí ìdàgbàsókè ní Niger Delta - Buhari Ènìyàn 156 ló tún ṣẹ̀ṣẹ̀ lùgbàdì ààrùn Coronavirus ní ìpínlẹ̀ Eko A fura pé ejò lọ́wọ́ nínú ikú Tolu Arotile, ẹ ṣe ìwádìí ikú rẹ̀ - Afenifere, Gani Adams, Huriwa Ohun tí o kò mọ̀ nípa Ebila ""One Million Boys"" àti Ekugbemi, olórí ẹgbẹ́ òkùnkùn méjì tó da ìlú Ibadan rú Adari ileeṣẹ to n risi ọrọ awọn ọmọ Naijiria to wa ni oke okun, Abike Dabiri-Erewa lo fi oju opo ikansiraẹni Twitter rẹ."
Kí ni èèwọ̀ lọ́jọ́ Eérú fáwọn ọmọlẹ́yìn Kristi?
Joṣua ọmọ Nuni kún fún ọgbọ́n nítorí pé Mose ti gbé ọwọ́ rẹ̀ lé e, nítorí náà àwọn ọmọ Israẹli ń gbọ́ tirẹ̀, wọ́n sì ń ṣe gẹ́gẹ́ bí àṣẹ tí OLUWA pa fún Mose.
Ògo Ọlọrun ń tàn lára rẹ̀.
Joẹli ọmọ Sikiri ni alabojuto wọn, Juda ọmọ Hasenua ni igbákejì rẹ̀ ní ìlú náà.
OLUWA, ìwọ ni o ti jẹ́ ibi ààbò wa láti ìrandíran.
A ti ní mílíọ̀nù 11 Naira láti se ẹjọ́ pẹlú ilé-isẹ́ ọlopaa Naijiria!
Lagos Marathon: awọn to jawe olubori rèé Kínni ife ẹ̀yẹ ti Tiger Woods gbà ní Augusta fi yàtọ́?
Wo àwọn bẹbẹ tí Umar Musa Yar'adua ṣe lórí àlééfà Iye ìgbà tí Sani Abacha tí fi owó ransẹ si Nàìjíríà láti ọrun Ìlúmọọká akọròyìn NTA Nàìjíríà, Ayinde Soaga lùgbàdì Covid 19 Báyìí ni àwọn agbófinró ṣe dá ìrìnkèrindò ọkọ̀ dúró lẹ́nu ibodè Nasarawa sí Abuja Lẹyin itakurọsọ pẹlu awọn arinrin ajo naa, Gomina ipinlẹ Oyo, Seyi Makinde sọ pe oun ko ni yọnda wọn fun ijọba ipinlẹ Sokoto, ayafi ti wọn ba kọkọ ṣayẹwo arun Coronavirus fun wọn.
Ní ọjọ́ kan, Jese sọ fún Dafidi pé, “Jọ̀wọ́, mú ìwọ̀n efa àgbàdo yíyan kan, ati burẹdi mẹ́wàá yìí lọ fún àwọn ẹ̀gbọ́n rẹ ní ibùdó ogun.
Àwọn èèrò ìwòran ní kóótù gbalé ẹjọ́ dọ́gbà ẹ̀wọ́n l'Ọṣun Wo àwọn ọmọbìnrin tó mu ìtọ̀ ara wọn nítorí òùngbẹ aṣálẹ̀ Sahara 'Dokita ilé ìwòsàn ló gba ẹsẹ̀ lọ́wọ́ mi' ‘Pussypedia’ rèé, ojú òpó tó ń mú àdínkù bá ìṣòro ìmọ̀ nípa ẹ̀yà ara obìnrin Lórí ọ̀rọ̀ Ogun Majek, mi ò lọ́rọ́ láti sọ, ẹ lọ pe ẹni tára rẹ̀ kò yá- Mr.
Nigba ti Ogbeni Agbaje eni ti omowe Vincent Nwani gbenu
Komisọnna fun eto ẹkọ nipinlẹ Delta, Patrick Ukah lo fi lede bẹẹ ninu atẹjade ti wọn fi lede.
Ipe ohun waye lojo keji ti ijoba orile-ede Naijiria fi oye nla ye oloogbe oloye MKO Abiola pelu oye ti o lagbara julo lorile-ede yii ti n se oye adari awon iko omo-ologun ti orile ede Naijria(The Grand Commander of the Federal Republic, GCFR).
Igbakeji aarẹ ile aṣofin agba tẹlẹ, Sẹnetọ Ike Ekweremadu lawọn ọmọ ẹya apa ila oorun gusu orilẹ-ede Naijiria kan din dundu iya fun lọjọ Abamẹta ni ilu Nuremberg lorilẹ-ede Germany.
Òmíì fífẹ̀ gbàràgàdà bí igi osè tó tan gbòngbò kálẹ̀ káàkiri.
Olùkọ́ Bunmi Femi Amao ló ń kọ́ wa ní Ọ̀rọ̀ Ẹ̀yán lonìí Kìí ṣe gbogbo ohun tí dókìtà ni kí n má jẹ torí àìsàn jẹjẹrẹ ni mo tẹ̀lé- Soyinka Ẹ̀gbọ́n mi tán ìṣòro mi nípasẹ̀ ṣíṣe ẹ̀ya ara àtọwọ́dá fún mi- Ubokobong Sunday Ẹ̀ gbọ́ ọ̀rọ̀ lẹ́nu Adelé Ọba Alade Idanre ló rí ohun tó ṣẹlẹ̀ láàárín òun àti Ọba Aroloye Ta ni Wolii Olapade Agoro tó re ibi àgbà ń rè tí ayé ń pariwo rẹ̀ yìí?
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Oba Adedokun Abolarin ti Oke Ila: Ó ya ọ̀pọ̀ tó súnmọ́ mi lẹ́nu bí mo ṣe ń kọ́ Ijinigbe jẹ nkan to n waye ni ipinlẹ Ondo, lati bi ọdun diẹ.
Èèyàn 20 ni coronavirus pa l'Ọ́jọ́bọ nìkan Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Kilomita marundinlọgọta ni gigun rẹ, Ogun biliọnu dọla $20b ni wọn si fi kọọ Kini awọn ohun aramanda to rọ mọ afara yii?
Nítorí pé, iranṣẹ mi ni wọ́n, tí mo kó jáde wá láti ilẹ̀ Ijipti, ẹnìkan kò gbọdọ̀ tà wọ́n lẹ́rú.
Ìwádìí níbi ìjòkó ìfẹ̀hónúhàn yii ní Brig.
" Ọjọ́ burúkú, èṣù gbomi mu ní Ṣagamu nígbà tí agbábọ́ọ́lù kan dèrò ọ̀run Fásitì UI f''orin tàkasúfèé wá ojúùtú si ìṣòro ẹ̀kọ́ ìṣirò Akọ ìbẹ́pẹ ni Yorùbá yóò pè é, ẹ wo bí òṣèré yìí ṣe ń ní ọgbẹ́ ọkàn pé kò tíì r'ọ́mọ bí Ààrẹ Buhari ti ṣàlàyé ìdí tí kò ṣe tíì ṣí ibodè tó tì pa Elédùmarè ló rán mi sí gbogbo Ọba Yorùbá - Oluwo Amofin ọhun tẹsiwaju pe o yẹ ki wọn fi pampẹ ofin mu ọlọpaa to ba lu eeyan nitori pe o wọ aṣọ ologun.
7 Ma ṣe lépa fún ọrọ̀ ṣugbọ́n fún ọgbọ́n, àti kíyèsíi, àwọn ohun ìjìnlẹ̀ Ọlọ́run ni a ó ṣí fún ọ, àti nígbànáà ni a ó sọ ìwọ di ọlọ́rọ̀.
Bí ó ti ṣe ọba Jẹriko, náà ló ṣe sí ọba ìlú náà.
igbimo asofin sọ fun wọn pe , ki won tun yẹẹ si egbe kan .
Yatọ si eyi, o ni niwọn igba to jẹ pe ẹsin Kristiẹni ati Islam ti wa bayii, ẹbi ti ọrọ ba kan le gbadura nilana ẹsin wọn.
Ẹ kò lè sin Ọlọrun, kí ẹ tún sin owó.
Ẹnìkan kò ní ṣọ̀fọ̀ wọn, bẹ́ẹ̀ ni wọn kò ní sin wọ́n; bí ìgbọ̀nsẹ̀ ni wọn yóo rí lórí ilẹ̀.
Latin lórí àìsàn Ogun Majek Wo bí ìgbé ayé Richard Akinjide ṣe lọ gẹ́gẹ́ bí agbẹjọ́rò àti olóṣèlú tó mòye Auxiliary lo ń jà káàkiri ìlú Ibadan lọ́jọ́ Aje, ẹgbẹ́ ọlọkọ èrò NURTW kọ - Ejiogbe Ewu ń bẹ!
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù South Africa:Ọpọ àlejò ló fara káása nínú wàhálà túntun 30 Ògún 2018 Ọ́lọ́pàá ti mú ènìyàn mẹ́tàdínlọgbọn tó lọ́wọ́ nínú ìwà jàgídíjàgan àti olè jíja tó wáyé.
Ile itaja igbalode taa n sọ yi ni Grandex Supermarket to wa ni agbegbe Bodija nilu Ibadan.
Lesotho ti ilẹkun ile iwe lọjọ kejidinlogun, oṣu kẹta ọdun ti wọn si kede isede ọlọsẹ mẹta pẹlu awọn orilẹ-ede ila oorun Afirika miran.
Doyin Okupe: Oríṣun àwòrán, Twitter Arakurin Okupe to jẹ agbẹnusọ tẹlẹri fun aarẹ ana lorilẹede Naijiria, Good luck Jonathan, ni wọn fẹsun kan pe o pin ninu owo ti wọn ji ko ni ileeṣẹ oludamọran fun eto abo ni Naijiria.
Èmi náà bọ́ sọọ ara mi sílẹ̀, àfi ṣòkòtò ló kù sí ìdí mi, èmi tí mo ti dé fìlà ri, tí mo tẹ fìlà mi siwaju kọ̀ǹgọ̀, ṣí fìlà kuro ní àtàrí, atẹ́gùn àlàáfìà sì ń fẹ́ sí ,i ní ìpàkọ́.
itanran gba maa-binu ti iye re je mejidinlaadorin pounds owo ile okeere fun
Ààwẹ̀ ọjọ́ 43 ni àwọn Krìstẹ́ní yíì n gbà kí wọ́n tó ò ṣe Kérésì ní January 7 'Kristẹni lo n fara kaaṣa ikọlu fulani ju' Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Orangun: Èdè àti àṣà Yorùba ní láti jọ wá lójú Itan sọ pe irinajo ihinrere lo gbe John Mark lọ si orilẹede Egypt, ti awọn to ti n ṣe ẹsin yii si tẹwọ gbaa.
“Awon iko agbaboolu tuntun ti yoo darapo mo idije naa, ni o wa lati inu idije Nigeria Professional Football League (NPFL).
O fi kun ọrọ rẹ pe ọdọkunrin to yinbọn fun lẹsẹ naa wa nile iwosan nibi to ti n gba itọju.
Oríṣun àwòrán, davidoyedepomin Afolabi Idris Wayforward ń tiẹ̀ ń béèrè pé kí ló dé tí Oyedepo fi fẹ́ kí jọba si sọọsi pẹ̀lú tipátipá, ṣe nítorí owó tí kò wọlé fún àwọn ojisẹ Ọlọ́run mọ ni?
Alaafia ni èmi fẹ́,ṣugbọn nígbà tí mo bá sọ̀rọ̀, ìjà ṣá ni tiwọn.
”Gehasi sì jáde kúrò lọ́dọ̀ Eliṣa ní adẹ́tẹ̀, ó funfun bíi ẹ̀gbọ̀n òwú.
    Nígbà tí ó pẹ́ díẹ̀ tí a ti dé ààfin ni ọba ránṣẹ́ sí ìyàwó rẹ̀ à gbà kí ó fi ilé òun hàn wá.
Ni nkan bi aago mọkanla alẹ ni ọmọ bẹrẹ si ni i mu mi."
Ènìyàn 452 ni èsì àyẹ̀wò sọ pé ó tún ṣẹ̀ṣẹ̀ ní Covid-19 ní Nàìjíríà Ọwọ́ ti tẹ àwọn afurasí tó wó iléeṣẹ́ aṣojú Nàìjíríà ní Ghana Abiola Ajimobi kò gbọdọ̀ kú, ẹ lọ wọlé àdúrà - APC Oyo pariwo Ìhòhò ọmọlúàbí ni mo má a ń bá àwọn ọmọkùnrin mi wí - Elesho Awọn mẹrin lo wa ninu ọkọ oju omi naa lasiko ti ijamba naa fi waye ṣugbọn wọn ṣi n wa ẹni kẹrin wọn bayii.
Di last one wey happun na on 20 August and na from dat time di tok begin say di Rivers state goment scata di Mosque.
Orí irú àwọn eniyan bẹ́ẹ̀ ti kú, a sì ti ṣá wọn tì ní ti igbagbọ.
APC NEC Meeting: Ẹkúnrẹ́rẹ́ ọ̀rọ̀ ìkini PDP sí APC bí àwọn adarí ẹgbẹ́ lápapọ̀ ṣe túká rèé
40ninu ida ogorun ni saa keta odun 2017, si iko 4.
Eyín ọ̀ọ́kán mi ni Barakat tí wọ́n pa lẹ́yìn tí wọ́n fipá bá a lòpọ̀- Ìyá Barakat Ṣé ó tọ́ kì Ààrẹ Trump máa fi Bíbélì jẹ́rìí?
Ìwọ ẹni tí Ọlọrun kọjú sí ṣe ní oore, Oluwa wà pẹlu rẹ.
Iroyin kan tun sọ pe, ọwọ ti tẹ awọn meji to wa lara awọn to ṣagbatẹru iṣẹlẹ laabi yii.
Nitorina a o ni ohunkohun lati sọ sii.
Ẹwẹ, onimọ nipa bi eto oṣẹlu ṣe n lọ ni ipinlẹ Ondo, Sola Akinbinu sọ pe ko yẹ ko jẹ asiko ti eto idibo sun mọle yii lo yẹ ki igbakeji gomina fi ẹgbẹ oṣẹlu APC silẹ lọ si PDP.
Ni idahun si ibeere yii, Adedibu ni to ba fẹ ki awọn jẹ ko ṣeeṣe, yoo wọle ibo naa.
Ní ọjọ́ náà gan-an ni Farao pàṣẹ fún gbogbo àwọn ọ̀gá tí wọn ń kó àwọn ọmọ Israẹli ṣiṣẹ́ pé, 
Offa robbery: Saraki, NOPRIN ní ọlọ́pàá gbọ́dọ̀ ṣàlàyé bí Adikwu ṣe kú
pe pupo ninu awon obinrin to je adari ninu eto isejoba ni saa kinni aare Buhari
 Bí o bá sunkun ó tumọ si pé ó ti mu ìtìjú ba ẹbi náà nìyẹn ati pe O kìí ṣe akọni ọmọbinrin Àkọlé àwòrán, Kinaya àti ọmọ rẹ̀ Ní bayi Kinaya ti dàgbà ó si ti bi ọmọ ara rẹ.
Ọna abayọ ni lati ma a mu omi deede lasiko ni igba gbogbo Ibẹru: Ẹni to ba n bẹru lati igba de igba le e ku ojiji.
Esau sọ fún Jakọbu pé, “Jọ̀wọ́ fún mi jẹ ninu ẹ̀bẹ tí ó pupa yìí nítorí pé ebi ń pa mí kú lọ.
Ilu Atorin ni Ilesha, ipinlẹ Oṣun ni Eleduwa ti fi Ogedengbe ta awọn obi rẹ alagba Apasanforijiwa ati iyaafin Falupo lọrẹ.
Lẹ́yìn tí Ṣaharaimu ti kọ àwọn iyawo rẹ̀ mejeeji, Huṣimu ati Baara sílẹ̀, ó fẹ́ Hodeṣi, ó sì bímọ ní ilẹ̀ Moabu.
Wọn yoo ṣe isinku ọgbọn lara awọn to ku ninu iṣẹlẹ naa lọjọ ẹti, to fi mọ Mucaad Ibrahim, ọmọ ọdun mẹta ti o ku ni Mọṣalaṣi Al Noor.
Bí ìmọ̀ mi ṣe ń lé kún sí i nínú àṣà ìbílẹ̀ẹ mi, ní ìgboyà mi ṣe ń pọ̀ sí i.
“Èyí kò dára, kò dára” ni ẹni tí ń rajà máa ń wí,bí ó bá lọ tán, a máa fọ́nnu ọjà ọ̀pọ̀ tí ó rà.
baku ( ) , nigba miran bi baqy , baky , baki tabi bakou , ni oluilu , ilu totobijulo ati ebute totobijulo ni orile-ede azerbaijan ati ni gbogbo kaukasu .
’’Bakan naa , ni aare Buhari  ti tẹwọgba iwe ifeyinti adajo  Walter Onnoghen gege bi adajo to ga julo
Oríṣun àwòrán, @SeimenBurum Ti gbogbo wọn si jẹ Ọlọrun nipe ni ile iwosan kan ti wọn gbe wọn lọ.
BBCCopyright: BBC Ipinlẹ EkoImage caption: Ipinlẹ Eko BBCCopyright: BBC olori ikọ ogun amuṣẹyaImage caption: olori ikọ ogun amuṣẹya BBCCopyright: BBC Ọlọpa Eko mura bi asiko ijọba ologunImage caption: Ọlọpa Eko mura bi asiko ijọba ologun Article share tools Facebook Twitter ṢàpínlòView more share options Share this post Copy this linkKà síwájú síi nípa àwọn ìtọ́kasí wọ̀nyí.
Hudson Odoi farapa ti wọn si gbe jade ki Pedro to wọle fun.
Ó ní kí ẹ lọ máa wá koríko fúnra yín níbikíbi tí ẹ bá ti rí.
FGM: Èyí ni bí àwọn obìnrin kan ṣe n fi abẹ̀ dídá sọ ara wọn di 'fágìn' lẹ́ẹ̀kejì
Ǹjẹ ́ tí abá dé ilé ẹ ̀ kọ ́ gíga , ọ ̀ pọ ̀ lọpọ ̀ ìyàtọ ̀ ni yóò ti wà nínú bi ase ń kọ ́ ni .
Ohun fúnra rẹ ra oko kún oko bàbá rẹ ti wọn pín fun.
O kere tan egberun un márùndínlọ́gọ́rin awon omo ile iwe alakobere ni ẹgbẹ̀rin din márùndínlọ́gbọ̀n orisirisi ile iwe otooto nipinle Ekiti, ni yoo je anfaani eto ipese ounje to yaranti ti won pe ni National Home Grown School Feeding Programme, NHGSFP, eleyi ti igbakeji aare ojogbon Yemi Osinbajo siso loju eegun re lojo Isegun(Tuesday) niluu Ado Ekiti, ti n se olu ilu ipinle Ekiti.
Obìnrin tó bá fẹ́ wọn, igbó Sambisa ló lọ - Lizzy Anjorin Ìbẹ̀rù bá olùgbé Eko torí àwọn ọ̀dọ́ Òkè Ọya tó dìhámọ́ra Ninu fọnran fidio kan taa ti ri bawọn ọlọpaa ṣe gba mu, niṣe ni ẹjẹ wa lara Bobosky torukọ rẹ gangan n jẹ Honest Digbara.
'Báyìí la ṣe rìn ín láti pápákọ̀ òfurufú Abuja sí Eko bí ìrìnà òfurufú abẹ́lé ṣe bẹ̀rẹ̀' Bí àrùn Coronavirus ṣe dá gbogbo àgbáyé gúnlẹ̀ sójú kan náà nìyí Fọwọ́ kan obìnrin lọ́nà àìtọ́, kí o rẹ́wọ̀n ọdún mẹ́rìnlá he- Àwọn aṣòfin yarí Kò ní sí ayẹyẹ ọdún Ojúde Oba lọ́dún yìí- Awujale ilẹ̀ Ijebu Awọn okoowo nlanla ti Henry Fajemirokun dawọle: Niwọn igba to jẹ pe ọna kan ko wọ ọja, Henry bẹrẹ isẹ okoowo aladani tiẹ lọdun 1955 lati inu owoya to gba lọwọ mọlẹbi rẹ kan ni idile iya rẹ O bẹrẹ okoowo kiko awọn ire oko lọ soke okun, okoowo egungun maalu lo kọkọ fi bẹrẹ, ko to tun fi awọ maalu kun un.
Olukọ ko gbọdọ ran ẹlomiran si akẹkọọ lati ba a lopọ.
Ọlọ́pàá ni wọ́n mú ọdaran náà lásìkò tó n gbìyànjú láti sálọ, ti wan sì gbà fóònù náà lọ́wọ́ rẹ̀ Wo bí o ṣe lè ṣe eré ìdárayá tí yóò fún ọ ní adùn àti okun fún ìbálòpọ̀ Iléeṣẹ́ ọlọ́pàá ṣàfihàn ojú àwọn afurasí tó se ẹran ara ọlọ́pàá jẹ ní Ibadan Iṣu ata yáan yàan!
Kọmiṣona ọrọ to n lọ ni ipinlẹ naa, Donald Ojogo lo sọ bẹ ninu ifọrọwerọ kan pẹlu BBC.
Gbajúmọ̀ gbọdọ̀ jẹ́ àwòkọ́ṣé rere torí bí ìràwọ̀ ṣe ń kú, ni òmíràn ń tàn - Foluke Daramola Tọwọ́ tẹsẹ̀ laá fi gba ìrànwọ́ owó ẹ̀kọ́ Almajiri ní ìpinlẹ̀ Oyo- Alága Subeb Ilẹ̀ Gẹ̀ẹ́sì yóò kúrò pátápátá lára àjọ EU ní Jan 31 ọdún 2020 Lẹ́yìn ìpàdé òní l‘Abuja, ṣé ASUU yóò yanṣẹ́ lódì àbí bẹ́ẹ̀kọ́?
Laarin ọdun 1981 si 1983, ayẹyẹ Hawan Sallah ko waye, nitori aawọ to wa laarin gomina igba naa, Abubakar Rimi, ati Emir to wa lori oye.
Ọkọ mi kò le f'ipá bá ẹnikẹ́ni lò pọ̀ láíláí - Modele Fatoyinbo Ọlọ́pàá ìpínlẹ̀ kọ́ ní ojútùú ìṣòro ìjínigbé ilẹ̀ Yoruba - Onímọ̀ ọ̀rọ̀ ààbò Akọni ṣubú l'ójú ìjà, Madagascar fi 2-0 la Super Eagles mọ́lẹ̀ Iwadii ṣi n lọ lọwọ gẹgẹ bi ohun ti LASEMA sọ.
Ọfọ nla ti sẹ ni agbo ere tiata ni ọjọ Aje, eyi to dori awọn irawọ osere kodo.
Naijiria, Voice of Nigeria (VON)ti gba olu ile-ise tuntun niluu Abuja, to jẹ
O ni o ṣe pataki ki awakọ maa ni suuru to ba fẹ de orita.
Àìronú níí’mú kí ènìyàn jalè, ti ń mú kí ènìyàn ṣèké, tí ń mu kí ènìyàn ṣáá tá ọmọ nìkejì, tí ń mú kí ènìyàn rẹ̀ ọmọnìkejì jẹ, ìrònú ni ó wà ni ìdí ẹ̀rọ mọ́tò, òun ni gbòǹgbò reluwé, òun ni ọmọ-ènìyàn fi ń fò lójú ọ̀run, ìrònú ni pàtàkì ohun ìjà oníṣègùn, òun ni ó wà ní idi egbòogi, paríparí gbogbo rẹ̀, bí ènìyàn bá wà tí ó wí pé kò sí nǹkan tí Olódùmarè lè ṣe, aláìronú ni.
Agbébọn jí alága káńsù tẹ́lẹ̀ gbé Wọ́n ti yìn'bọn lu mínísítà ní Pakistan Oríṣun àwòrán, Google Àkọlé àwòrán, Ile Ijọsin Sinagọọgu Tree of Life ni Pittsburg ti iṣẹlẹ naa ti ṣẹlẹ Awọn Ọlọ́pàa si n to pinpin agbegbe ile ijọsin Tree of Life Synagogu ti iṣẹlẹ naa ti waye.
 Òun náà gba ọ ̀ nà ilé-ifẹ ̀ , ó sì yà kí odùduwà .
Àwọn tí wọn tí ń fi aṣọ àlàárì boradi ẹni tí ń sùn lórí òkítì eérú.
Ohun tó yẹ kí o mọ̀ nípa ìbòmú tí ń lò yẹ́n ''Olóde'' ni Yorùbá ń pe coronavirus, iléeṣẹ́ Yemkem ti rí òògùn rẹ̀ báyìí- Olùdásílẹ̀ Yemkem Ki enikeni ma ṣe ro ara rẹ pin nile aye, nitori bi oni ti ri ọla ko ri bẹẹ Iru awọn iroyin ti ẹ le nifẹ si: ‘Èpè ni Toyin Abraham sẹ́ fún mi nínú ìgbìyánjú mi lórí ìgbeyàwó rẹ̀ tó dàrú’ Ǹ jẹ́ o leè fi àmì sórí ‘Àgbàlagbà-akàn’ ?
“Ko ye wa rara bi arakunrin naa se yo wole.
gẹ ́ gẹ ́ bí a ti sọ ṣaájú ní 3.
Oyè Ibadan kò sí fún títà - Otun Olubadan, Lekan Balogun Àbòsí ló wà níbẹ̀ tí ìpínlẹ̀ Eko ò bá ṣe Amotekun- Bode George BBC Yorùbá pé ọdún méjì!
“Bákan náà mo sọ fun yín, ẹ bèèrè, a óo fi fun yín; ẹ wá kiri, ẹ óo rí; ẹ kanlẹ̀kùn, a óo sì ṣí i fun yín.
Tí R Kelly bá jẹ̀bi àwọn ẹsun ti wọn fi kàn án , ó ṣeeṣe kí ó lọ ẹwọn ọdun mẹ́ta sí méjé fún ẹsun kọ̀ọ̀kan.
Ẹ wo oun ti awọn ọmọ Naijiria miran sọ lori atẹjade ọhun.
Yorùbá ni bi wọn ti ma nṣe ìṣirò ki wọn tó bẹ̀rẹ̀ si ka ni èdè Gẹ̀ẹ́sì.
Ni ọdun 2018, ileeṣẹ eto ilera nijọba apapọ ṣeto iwadi kan lori ilera ẹbi Wọn rii pe ilaji iṣẹlẹ aisan igbẹ gbuuru to n ṣe awọn ọmọde lorilẹede Naijiria n ṣẹlẹ ni ẹkun iwọ oorun ariwa orilẹede Naijiria, paapaa julọ ni ipinlẹ Sokoto ati Kebbi.
Oríṣun àwòrán, Twitter/gbajabiamila O ni wọn ti yọ ọgbẹni naa kuro lara awọn ẹṣọ olori ile aṣojuṣofin naa ati wi pe, ni ibamu pẹlu ilana ibawi lẹnu iṣẹ, wọn ti fi si ahamọ, ileeṣẹ agbofinro DSS si ti bẹrẹ iwadii pẹlu ileri pe ko ni si kọnu n kọhọ ninu iwadii lori bi afunrasi naa ṣe lo ibọn rẹ.
Guinea Ọjọ kẹrin, oṣu karun un, ọdun 2020 ni ilẹ New Guinea ṣilẹkun ile iwe rẹ pada.
Bí ó bá gbà sí ọ lẹ́nu, o ti tún sọ ọ́ di arakunrin rẹ tòótọ́.
”Ogbeni Shehu tenumo oro re pe,
Oriṣi ọna meji - àpò to ni oogun apẹfọn ati fi fi oogun apẹfọn fin inu ile - mejeeji maa n ṣiṣẹ daada l'oriṣiriṣi igba Sisun si abẹ apo apẹfọn le mu adinku ba ifarakanra laarin ẹ̀fọn ati eniyan nipa pipese idiwọ to ṣe e fi oju ri ati oogun to le kapa kokoro.
Deontay Wilder lu Dominic Breazeale bí aṣọ òfì Ta ni Naira Marley jẹ́ gan?
Kọmisọna ọlọpa npinlẹ Ọsun, ọgbẹni Fimihan Adeoye ni, gbogbo awọn afunrasi ti ọwọ ba naa, ni wọn ti fi igbakan ri sa lọgba ẹwọn ki wọn to tun jade pada si ẹnu isẹ alọkolounkigbe ti wọn yan laayo.
“Bí Ọlọrun bá dákẹ́,ta ló lè bá a wí?
Àwọn tí ó bí ní Jerusalẹmu nìwọ̀nyí: Ṣamua, Ṣobabu, Natani, ati Solomoni; 
O ni pẹlu bi gomina Babajide Sanwo-Olu si ti kede ofin konile o gbele bayii, ileeṣẹ ọlọpaa ti ko awọn ọlọpaa kogberegbe da sigboro lati lati rii daju pe aṣẹ koni o gbele ọlọjọyipo naa fidi mulẹ daadaa.
Gomina ipinlẹ Ekiti tẹlẹri, Ayodele Fayose lo ti fi eebu ransẹ si awọn to n pẹgan rẹ nise ti ọdun tuntun bẹrẹ naa.
Amọ ko si akọsilẹ fun orilẹede Namibia Orilẹede wo ni awọn eeyan ibẹ ti n pẹ laye julọ?
Wọn a máa bẹ̀ ẹ́ pé kí wọn ṣá lè fi ọwọ́ kan ìṣẹ́tí ẹ̀wù rẹ̀.
Mose lọ mú ọ̀pá náà níwájú OLUWA gẹ́gẹ́ bí OLUWA ti pàṣẹ fún un.
Osun Osogbo: Àwọn èèbó aláwọ̀ funfun gbé Ọ̀ṣun lárugẹ
 Ó kú nígbà tí ó di ọmọ ọdún mẹ ́ tàdínlógọ ́ ta .
Eniyan 3535 lo ti ri iwosan gba, nigba eniyan 323 si ti papoda nitori arun Coronavirus.
Rochas Okorochas ní ìlàkàkà àti gbé ìpínlẹ̀ Imo sókè ti sọ mí di ọlọ́dẹ orí
Ìwọ ọ̀rẹ́ mi, ọ̀rọ̀ pọ̀, kò yẹ kí n tilẹ̀ máa sọ ìyókù ipọ́njú wọ̀n-ọnnì fún ọ níssìyí.
Ona merin ọtọtọ ni won pin ami
Ati pe wọn ko le sọ ni pato bi ikọlu naa ṣe bẹrẹ.
Nitori naa ki o to lọ si oju opo wọn lati bẹrẹ eto iforukọsilẹ,wọn yi lawọn nkan to yẹ ni mimọ ti ko ni jẹ ki o kuna .
Iná jó àwọn ènìyàn 10 tó ń gbà ìwòsàn arùn Coronavirus níbùdó ìtọ́jú Mo ti buwọ́lu àdínkù owó orí nítorí ìrọ̀rùn àwọn èèyàn ìpínlẹ̀ Ogun lásìkò Covid 19- Dapo Abiodun Àwọn adarí lágbàyé ṣèpàdé láti ṣèrànwọ́ fún Lebanon lẹ́yìn ìbúgbàmù tó pa ènìyàn 158 Wo ohun tí Adájọ́ ṣe sí àṣùwọ̀n ìfowópamọ́sí Wòlíì Sotitobire Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Teach your children Yoruba: Wo àwọn òyìnbó tó ń kẹ́kọ̀ọ́ èdè Yorùbá ní Michigan, America Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
 Ó jẹ ́ ìkan lára àwon oògún tí Àjọ Ìlera Àgbáyé ṣàkójọ ẹ ̀ sí oògún tó wúlò jùlọ fún ìlera .
Asoju orile ede Russia si orile ede Naijiria, ogbeni Alexey Shebarshin lo so eleyi lasiko ayeye ajodun ominira orile ede naa.
Asuqou so pe akitiyan  won ti je ki igberu ba ibi ti won n ko epo pamo si , tita jade ati bi won se n gbe won kaakiri , bakan naa , nipa pipese ise lopo yanturu fun awon omo orile-ede yii.
OLUWA Ọlọrun bá sọ fún ejò náà pé,“Nítorí ohun tí o ṣe yìí,o di ẹni ìfibú jùlọ láàrin gbogbo àwọn ẹran ọ̀sìn ati àwọn ẹranko.
Awọn mejeeji naa, lasiko ti wọn fẹ ji obinrin onisowo ọhun, Modupeoluwa Oyetoso gbe salọ, tun ni wọn yinbọn pa afẹsọna rẹ, Opeoluwa Oladipo.
Abajade naa ti wọn pe orukọ rẹ ni 'Goalkeepers Report' ti ọdun 2018 ni ebi, iku awọn iyalọmọ, iku ọmọ ọwọ ni o jẹ oun ti ko jẹ ki igbe aye ni orilẹede Naijiria muna d'oko.
Mo wà ní ìhòòhò, ẹ kò daṣọ bò mí.
Bakan naa si ni ko ṣeeṣe fawọn ọmọde lati ku nipasẹ arun naa to bi awọn agba lọ.
 o un so opo awon elimenti metali ati alaije-metali di oksidi , bi karbonu , to unfa agberu asodi re ninu opo awon adapo organosulfuru , sugbon o un se iresile opo awon olusodioksidi alagbara bi oksijin ati fluorini .
Ojú àti aṣọ ni púpọ̀ nínú àwọn ọmọdé ìwòyí ń wò tí wọ́n fi ń fẹ́ràn ènìyàn, ìwà òmùggọ̀ pátápátá gbáà ni.
Obinrin náà wí fún ọba pé, “Kabiyesi, gbogbo ohun tí o bá ṣe nípa ọ̀rọ̀ yìí, èmi ati ìdílé mi ni a ni ẹ̀bi rẹ̀, ẹ̀bi rẹ̀ kò kan kabiyesi ati ìdílé rẹ̀ rárá.
O fi kun pe lẹyin ti wọn fojuwo bi oju ọjọ ṣe ri lọja epo ni wọn fi gbe ẹdinwo naa kalẹ.
2020 Budget: 'Owó oṣù sísan ni ọ̀pọ̀ àbá ètò ìṣúná fún iléeṣẹ́ ọlọ́pàá àtàwọn ológun yóò bá lọ'
Aarẹ Trump fi kun ọrọ rẹ pe, oun yoo da iṣẹ awọn ọmọ ogun ilẹ America duro ni orilẹede South Korea.
Yewande bí'mọ tuntun jòjòló, Mercy Aigbe pàdánù èèyàn rẹ̀, Toyin Abraham fèsì lórí aṣoju NCDC Ìtàn Manigbagbe: Àwọn àjakalẹ-àrun to ti wáyé rí ṣáájú Coronavirus Ohun to ya ọpọ eeyan lẹnu ni wi pe awọn obi ni lati sanwo ile iwe awọn ọmọ wọn fun saa eto ẹkọ tuntun to maa bẹrẹ lọjọ Aje to n bọ.
Ó yan àjọ̀dún fún àwọn ọmọ Israẹli, ó sì lọ sun turari lórí pẹpẹ.
Aaroni bá súnmọ́ ibi pẹpẹ náà, ó pa ọ̀dọ́ mààlúù fún ẹbọ ìmúkúrò ẹ̀ṣẹ̀ fún ara rẹ̀.
Yóo gba gbogbo oúnjẹ tí wọ́n gbójúlé,ati gbogbo omi tí wọ́n fi ẹ̀mí tẹ̀.
Ní ìgbà yẹn, Lhamo jẹ́ ọmọ ọdún 12.
4m Ìwọ́de ńlá yóò bẹ́rẹ̀ lọ́jọ́ táwọn gómìnà bá yá ₦17trn nínú owó ìfẹ̀yìntì òṣìṣẹ́ - NLC Atẹjade ọhun fi kun pe wọn ti bẹrẹ ti n tọpasẹ gbogbo awọn to lọwọ ninu rogbodiyan naa.
Ethiopia Airlines Crash: Iyanrìn làwọn ẹbí olóògbé bàálù Ethiopia rí gbà dípò òkú èèyàn wọn
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Nigeria Elections 2019:Muhammadu Buhari, olùdíje ẹgbẹ́ òṣèlú APC 17 Sẹ́rẹ́ 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ààrẹ Muhammadu Buhari Wọn bi Aarẹ Muhammadu Buhari ni idile ẹya Fulani kan ni ọjọ kẹtadinlogun oṣu kejila ọdun 1942 ni ilu Daura ipinlẹ Katsina.
Ni ti awọn mẹta to ku, ida lare ni wọn ri gba nitori adajọ ni ko si aridaju to fi han pe ọdaran niwọn tabi pe wọn wa nibi iṣẹlẹ Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Akẹ́kọ̀ọ́ ìmọ̀ òfin kọ̀ọ̀kan yóò gba ₦500,000 owó ìrànwọ́ l‘Oyo Fulani kò leè dúró, táa bá lo ohun ta jogún lọ́dọ̀ àwọn bàbá wa - Sunday Igboho Aarẹ ẹgbẹ Akọmọlede, ẹni to mọ riri awọn ijọba ipinlẹ to sọ ede Yoruba sisọ ati kika lawọn ileewe di kanpa, tun mọọmọ gbe osuba fun ijọba ipinlẹ Eko fun igbesẹ naa, to si rọ awọn ipinlẹ yoku ti ko ba tii se bẹẹ lati fi ipinlẹ Eko ṣe awokọṣe rere.
Mpape Crushed Rock: Àrímáleèlọ, àwòpadàsẹ́yìn ni ẹwà ibùdó yìí
Ọ̀fọ̀ ńlá ṣẹ̀ sí Amosun: Akọ̀wé Adeoluwa àti Adesanya ṣàgbákò ìjàmbá Ará ìlú dájọ́ oró fún ọkùnrin to bẹ́ orí ẹ̀gbọ́n rẹ̀ ní Cross River Àràmọ̀ǹdà àwòràn láti ilẹ̀ àdúláwọ̀ lọ́sẹ̀ yìí Àrà kengé!
Bẹnabinadabu, ọkọ Tafati, ọmọ Solomoni, ni alákòóso gbogbo agbègbè Nafati-dori.
Jẹ́ kí àwọn eniyan túká, kí wọn lè lọ sí àwọn abà ati abúlé tí ó wà yíká láti ra oúnjẹ fún ara wọn.
Dípò kí ó wu ìwà òòtọ́, kò ṣojú ṣẹ̀yìn ọ̀rẹ́ rẹ̀, ṣe ni ó kó gbogbo owó tó wà níbi tí wọ́n ra sí(èyí ni ibi tí wọ́n kówó pamọ́ sí) tó sì dà á sápò, ló bá gbérà ló darí sí ilé ọ̀rẹ́ re tó dolóògbé níbi tó gbé dara pọ̀ mọ́ àwọn èèyàn tó ń ṣòwò lọ́wọ́.
Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí DNA Paternity: Tó bá wáyé pé ẹ kò mọ ẹni tó lọmọ, ohun tí àwọn àgbààgbà Yorùbá máa ń ṣe rèé5 Sẹ́rẹ́ 2021 Paternal DNA Test: Ẹ wo àlàyé lórí àyèwò DNA tó ń jà rànyìn lórí àyélùjàra4 Sẹ́rẹ́ 2021 Vaccine rumours debunked: Àwọn ìròyìn òfegè nípa abẹ́rẹ́ àjẹsára Covid-194 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Àwọn àpẹẹrẹ mẹ́sàn-án tí yóò fihàn pé o ti n darúgbó26 Ọ̀wàrà 2018 Àyẹ̀wò DNA ti fẹ́ bẹ̀rẹ̀ fún àwọn àlùfá Kátólíìkì tó bímọ27 Ògún 2018 DNA: Njẹ́ o mọ pé obìnrin lè bí Ìbejì tí wọ́n yóò sì ní bàbá ọtọ́ọ̀tọ̀?
Oríṣun àwòrán, Ogun State House of Assembly Ìdí tí a fi pa àwọn àgbẹ̀ onírẹ̀sì ní Borno, Boko Haram ṣàlàyé nínú fídíò tuntun Olorì Aláàfín tẹ́lẹ̀, Anuoluwapo Adeyemi gba àmì ẹ̀yẹ lórí ipa tó kó nínú oge ṣíṣe O fi kun un pe koda wọn koi tii san awọn owo ajẹmọnu kọọkan to yẹ ki wọn san fun awọn aṣofin.
O sọ wipe kii ṣe ootọ pe awọn to ba jẹ oye Aarẹ Ona Kakanfo kii pẹ laye.
Ìgbà tí ó sì dé ibi kọ̀rọ̀ kan báyìí tí ó dúró, ṣe ni mo rí Ayédèrú-ẹ̀dá tí í dé, ó ti yí aṣọ padà, kò sì jọ oun mọ́ rárá, ni òun àti àbúrò ìyàwó mi bá bẹ̀rẹ̀ síí lọ́ mọ́ ara wọn wọn n fi ẹnu ko ara wọn lẹ́nu.
Ọdun 1970 ni Faleti gbe iwe naa jade fun igba akọkọ.
Gẹ́gẹ́ bí ẹ ti gbọ́ pé Alátakò Kristi ń bọ̀, nisinsinyii ọpọlọpọ àwọn alátakò Kristi ti ń yọjú.
Olúṣẹ́gun Ọbásanjọ́, tí ó jẹ́ Ààrẹ ìjọba ológun àná (láti ọdún 1976 sí 1979), tí ó sì tún ṣe  Ààrẹ ìjọba alágbádá tí ìbò gbé wọlé (ní ọdún 1999 sí 2007), kúndùn láti máa bu ẹnu àtẹ́ lu àwọn ètò ìjọba Ààrẹ orílẹ̀-èdè Nàìjíríà tí ó jẹ tẹ̀lé e.
Titi di igba naa, o ni ki wọn da awọn afunrasi ọhun pada si ọgba ẹwọn Olokuta.
Ki lo mu ki ilẹ America o ṣe ayipada si idajọ ikú?
Bẹẹ ba gbàgbé, a ti mú ìròyìn wá fún yín ṣáájú nípa bí àwọn agbebọn kan ṣe ya wọ ilé Sheikh Taofeeq Akeugbagold ni alẹ ọjọ́ Satide, tí wọn si gbe ìbejì rẹ, takọtabo lọ Ibadan Kidnap: Ọdún méjìlá ni mo fi ní ìdádúró ki nto fi IVF bi àwọn ìbejì yìí - ìyàwó Akeugbagold ẹ̀bẹ̀.
Ni ba ti se n sọrọ yi, ile ẹjọ giga ti yẹ aga nidi Oshiomole ti awọn miran si ti n ja witiwiti lati wa ni ipo alaga.
Ẹ̀kọ́ tí mo rí kọ́ ni pé rere ni Ọlọrun dá eniyan, ṣugbọn àwọn ni wọ́n wá oríṣìíríṣìí ọ̀nà àrékérekè fún ara wọn.
Nibẹ ni adajọ yoo ti sọ boya ki wọn muu lọ si ileewosan ayẹwo ọpọlọ abi ki wọn fi silẹ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Bolaji Faleke ni Olùkọ́ tó ń kọ́ wa ní àṣà oge ṣiṣe lórí BBC Yorùbá Gẹgẹ bi o ṣe sọ, ijọba oun yoo sa gbogbo ipa rẹ lati fun awọn ori ade ipinlẹ naa ni aaye lati ṣe nkan to ba wu wọn to si mu idẹrun ba ara ilu, ati pe ẹni a bi ire ni oun oun ko le fi awọn agba wọlẹ.
Iya Gold salaye bi ko ṣe ki n fẹ fi ọmọ rẹ silẹ ati bi awọn ẹṣọ ijọ ṣe ni o yẹ ko maa gbe ọmọ rẹ lọ si yara ti wọn n ko awọn ọmọ wẹwẹ si.
"Ninu atẹjade kan ni pasitọ Adeboye ti sọ pe ""Ijọ gbọdọ tẹle ofin ti ijọba fi sita""."
Atiku Vs Buhari: Bulkachuwa yọra rẹ̀ nínu ìgbẹ́jọ́ èsì ìdìbò ààrẹ
‘Iṣẹ́ orí rán mi ní mo fi n jẹun’ Irú ẹ̀dá wo ni aṣòfin Bukola Saraki jẹ́?
Bi aladugbo wa ṣe mọ pe Saheed fẹ ji ọmọde naa gbe ni, ko tii si ẹni to le sọ.
Dino Melaye ni ẹru ko ba odo oun rara lori ipo aṣojuṣofin oun ni abuja.
2bn fún Obanikoro Dapo Abiodun wà lára àwọn tó ta ohun ìjà olóró fún mi - Amoṣun Ò ti pé ọdún 27 tí Shah Rukh Khan ti ń se fíìmù India Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, International Day Against Drug Abuse and Trafficking: ìdí ti mo fi ń mu oògùn olóró O fí kún-un pé, àwọn ọdaran náà fi ìmọ̀ sọ̀kan láti ṣẹ̀ sófin lọ́na ti ó le da omi àláfíà ìlú rú, ti wọn si wọ oko tó jẹ ti Oluwadare Olowokere àti Adekunle Olowokere.
Wọ́n ń yan àwọn aláṣẹ, ṣugbọn n kò mọ̀ nípa rẹ̀.
Mo rántí ní àìpẹ́ yìí tí mo ń ti ọkùnrin kan kí ìjà bẹ́ sílẹ̀ láàrin òun àti aya rẹ̀, ṣùgbọ́n ìwà alákọrí obìnrin yìí tutù jù fùn mi, bí ọkọ ba ti ń sọ̀rọ̀ líle ni òun ń sọ̀rọ̀ rírọ̀, bí ọkọ ti ń fajúro ni òun ń rẹ́rìn-ín, ìgbà tí ó ṣe, ọkọ pàápàá lé mi kúrò lọ́dọ̀ ara rẹ̀, mo ba tún bá ìrìnkiri mi lọ.
 Teleri,won ma n se amulo oorun lati gbe awon biriki ,ti o si n pese ategun ti a mo si carbondioxide.
Boasi wọn ìwọ̀n ọkà Baali mẹfa sinu aṣọ náà, ó dì í, ó gbé e ru Rutu, Rutu sì pada sí ilé.
Lara awon toro kan gbangban lorile-ede yii ti o lo pade re lati ri, oga agba awon osise, Abba Kyari ati minisita ilu fct Mohammed Bello abbl.
Loju opo ileeṣẹ iroyin Naijiria, ati itakun agbaye wọn ni Arabi ti ṣalaye lọjọ Aiku pe afikun owo ina mọnamọna to gbode kan kii ṣe tuntun.
"Ninu atẹjade kan ni ẹgbẹ CCII ti sọ pe awọn kọkọ n gbero lati ṣe ayẹyẹ naa pẹlu titẹle amọran awọn eleto ilera, ṣugbọn wọn yi ọkan wọn pada lẹyin apero laarin awọn adari ẹgbẹ naa, botilẹjẹ pe ""wọn ti ra nkan ipawọ apakokoro, iboju ati irinṣẹ ayẹwo ilera""."
Eliṣa gé igi kan, ó jù ú sinu omi, irin àáké náà sì léfòó lójú omi.
Awọn onimọ gbagbọ pe ẹya Coronavirus tuntun yii ti tan ka kọja awọn ibi ti wọn ti kede pe o de, won gboriyin fun ilẹ gẹẹsi to kọkọ mọ.
Ati pé ọ̀gbun ńlá kan wà láàrin àwa ati ẹ̀yin, tí ó fi jẹ́ pé àwọn tí ó bá fẹ́ kọjá sí ọ̀dọ̀ yín kò ní lè kọjá; bákan náà àwọn tí ó bá fẹ́ ti ọ̀hún kọjá wá sí ọ̀dọ̀ wa kò ní lè kọjá.
Titi di oni, iyalẹnu lo ni iku rẹ si n jẹ fun ọpọlọpọ to gbagbọ pe ko yẹ ki ada o ran an, nitori agbara ibilẹ to ni.
ko ọgbọn,imọ, oye ati iriri ti o ni gege bi asaaju egbe awon osise wọnu eto
Bẹẹ ba si gbagbe, Adebayọ Shittu gan ti sọ loju-taye pe, oun ko kopa ninu eto sinru ilu, nitori bi oun se jade fasiti, ni wọn dibo yan oun sile asofin ipinlẹ Ọyọ.
Dafidi ati àwọn eniyan rẹ̀ bá lọ gbógun ti àwọn ará Filistia ní Keila, wọ́n pa ọpọlọpọ ninu wọn, wọ́n sì kó àwọn ẹran ọ̀sìn wọn.
Àwọn ará Juda pàápàá yóo máa bá àwọn ará Jerusalẹmu jà.
Ẹni to bori: Nigeria Angola vs Algeria.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ikú alaga PDP: Niyi Aborisade ni alága PDP ní ìjọba ìbílẹ̀ Apápá 22 Agẹmo 2018 Àkọlé àwòrán, Wọn gbe Niyi Aborisade lọ ile iwosan kan ni Obalende, sugbọn ẹ̀pa kò bóró mọ́ Àlaga ẹgbẹ oṣelu PDP ni ijọba ibilẹ Apapa ni Ipinlẹ Eko, Niyi Aborisade, ti gbẹmii mi bayi, lẹyin ti awọn janduku ti yinbọn pa nibi ipade kan to waye ni ọjọ Abamẹta ni Eti Osa.
Ni igbakan ri, Siasia fi Obi we agbaboolu owo arin iko agbaboolu Real Madrid, Luka Modric ati awon agbaboolu jankanjankan miran lagbaye.
Ta òróró sí ara agbada náà pẹlu ati gbogbo ìtẹ́lẹ̀ rẹ̀, kí o sì yà á sí mímọ́.
Ọmọ gbàsè gbàsè kẹ́ ṣọbinrin lọyin
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù High blood pressure: Lílo òògùn ẹ̀jẹ̀ ríru sùn lálẹ́ ló lè mú un ṣiṣẹ́ jùlọ 25 Ọ̀wàrà 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, High blood pressure: Lílo òògùn ẹ̀jẹ̀ ríru sùn lálẹ́ ló lè mú un ṣiṣẹ́ jùlọ Awọn ọnimọ sayẹnsi ti sọ wi pe lilo oogun ẹjẹ ruru lalẹ lo le mu oogun naa ṣiṣẹ lara ju.
Buhari yan Kyari ní olùdarí tuntun fún àjọ NNPC Ọ̀wọ́ngógó epo bẹntirò: NNPC ni 'ìròyìn ẹlẹ́jẹ̀' ni Kí ló mú bàbá àti ọmọ rẹ̀ méjì rẹ́wọ̀n oṣù mẹ́fà he ?
Ewe, iko agbaboolu orile-ede Russia gbe ara tuntun mi yo, leyin ti agbaboolu kookan wo aso igba boolu orile-ede kookan ti yoo maa kopa ninu idije naa, lati ya aworan, ati ni papaajulo lati se ikinni kaabo awon orile-ede ohun.
"Orin naa ni: ""Awọn ẹda kan lo wa, ti wọn n fẹ ki ẹnikeji jẹ, iru wọn ni ti Fajemirokun, To fi owo mọ Oluwa, to tun fi mọ eniyan, ile isẹ rẹ, aimọye eniyan ni wọn n jẹ, ti wọn n mu."
Adájọ́ sọ wòlíì Sotitobire àtàwọn olùjẹ́jọ́ márùn-ún míì sẹ́wọ̀n gbére!
Omah Lay àti Tems yóò tó darí padà sí Nàìjíríà
Ìfẹ̀hònúhàn ni àwọn ará UK fi ki Donald Trump káàbọ̀ 'Ọmọ SS 1 mu èso olómi, ṣùgbọ́n ilé ìwé wa kọ́ ló kú sí' ìjọba Nàìjíríà ti kéde ìsinmi lọ́jọ́ Ìṣẹ́gun àti Ọjọ́rú Nàìjíríà yóò dá ṣèríà fún Senegal lónìí- Balógun Flying Eagles Amọṣa awọn alaga ẹgbẹ oṣelu APC lẹkun aaringbungbun Gusu ti dide atilẹyin fun un.
Hushpuppi di gbajúmọ̀ ẹlẹ́wọ̀n tó ní nọ́ńbà l‘Amẹrika, orúkọ̀ rẹ̀ wà lórí ayélujára Wo àwọn ìlànà tó dé wíwọ bàálù fún arìnrìnàjò ọkọ̀ òfurufú ní Nàìjíríà Ṣé lóòtọ́ ni Lateef Adedimeji àti Adebimpe Oyebade ṣe ìgbéyàwó?
Nígbà tí a kúrò lọ́dọ̀ àwọn ọlọ́pàá ejò wọn-ọnnì a bẹ̀rẹ̀ sí pàdé ejò lọ́kọ̀ọ̀kan ṣùgbọ́n wọn kò bù wá jẹ, wọ́n lọ ní ti wọn ṣáá ni.
" Tiwa Savage tọwọ́ bọ'wé àdéhùn pẹ̀lú àwọn onígbọ̀wọ́ orin lágbàyé #Bum bum war:Yemi Alade tọrọ àforíjìn lọ́wọ́ Tiwa Savage Adekunle Gold, Simi tú àṣírí ètò ìgbéyàwó wọn = Ṣugbọn ko ṣalaye idi to fi n ju owo lu awọn obirnin naa lasiko ti wọn n rinrinajo.
Oga agba ile-iwosan ibile lorile-ede Naijiria, dokita Faisal Shuaib so pe, laasigbo awon omo-ogun olote  n mu ifaseyin ba abere ajesara fun awon omode ti iye won je egberun lona egbeje, ti won wa ni awon agbegbe ti gbominira nipinle Borno.
Bakan naa, ni ijoba orile ede
Nítorí ìfẹ́ Ọlọrun ni pé kí ẹ ya ara yín sí mímọ́: ẹ jìnnà sí àgbèrè.
Lara wọn sọ wipe, inu awọn dun si iyanṣẹlodi naa nitori wipe yoo fun wọn l'anfani lati lọ sinmi fun igba diẹ, sugbọn wọn ko fẹ ki isinmi naa kọja ọsẹ meji si mẹta.
 ní ìparí , òǹkọ ̀ wé ṣe àfikún díẹ ̀ sí ìwé yìí ó sì ṣe àtúnṣe àwọn àṣìṣe tí ó ṣe àkíyèsí nínú ìwé náà .
Sisanra ju ati aisan ẹjẹ riru naa ti n ṣakoba Iwadii kaakiri awọn ileewosan South Africa di han pe ara sisan ju to fi mọ ẹjẹ riru ati itọ ṣuga lara awọn ọdọ to ni arun Coronavirus ni i ṣe pọlu ọpọ to gba ibẹ ku.
Wọn ni lasiko ti Rob n pada lọ si ile ilẹ Gẹẹsi to tun jẹ ẹmbasi ilẹ Gẹẹsi ni Tehran to jẹ olu ilu Iran ni wọn deede gbee.
Ṣé ẹ fẹ́ máa ṣe ojuṣaaju fún Ọlọrun ni?
 a ṣe ìṣirò pé àjẹsára náà ti dáàbò bo iye ẹ ̀ mí tó ju ìdajì mílíọ ̀ nù lọ ní ọdún 2002 .
asán ni sísìn tí wọn ń sìn mí,ìlànà eniyan ni wọ́n fi ń kọ́nibí òfin Ọlọrun.
Iko agbaboolu Real Madrid kopa ribiribi ninu ifigagbaga ifesewonse ipele keji si asekagba idije Uefa Champions League to n lo lowo yii.
Wo iye tí ọkọ̀ òfurufú náà yóò máa gbé èrò láti MM1 sí Island Oríṣun àwòrán, others Làìpẹ́ yìí ni ìjọba apapọ ati ijọba ipinlẹ Eko ti kede pé àwọn yóò gbé afára 3rd Mailand tì pa fun oṣù mẹ́fà lójúnà àti ṣe àtúnṣe sí àwọn ibi tó mẹ́hẹ nibẹ fún ìgbáyégbádùn àwọn ará ìlú.
Àwọn mìíràn sọ wípé ibà ẹ̀fọn ti ọdún nìí ń ṣekú paon
Ewe, opo ololufe boolu afesegba lagbaye ni igbese aare Weah yalenu, leyin odun mẹ́rìndínlógún ti o ti gba boolu keyin.
gbogbo iwa odaran to n sẹyọ ni awon agbegbe 
: Eyi ni eto idibo ti o sẹle leyin ti iye awọn to se iforukọsilẹ lasiko idibo
Ajax naa ko ṣe foju di nitori awọn lo ran Real Madrid ti ife ẹyẹ Champions League wa lọwọ rẹ lọ sile.
Boko Haram tún ṣọṣẹ́ ní Adamawa, ọ̀pọ̀ òkú ṣùn, àìmọye dúkìá jóná Oluwo kò gbọdọ̀ kọrin òwe tàbí bá àkọ̀ròyìn sọ̀rọ̀, kó má baà ba ẹjọ́ ara rẹ̀ jẹ́ - Ọ̀ràngún ṣàlàyé Lampard àtàwọn agbábọ́ọ̀lù Chelsea dọ́wọ́jọ di ẹrù wíwo lé Mourinho àti Tottenham lórí Ààrẹ Gnassingbe díje fún sáà kẹ́rin, òun àti bàbá rẹ̀ ti ṣèjọba Togo fún àádọ́ta ọdún lé mẹ́ta Lẹyin naa ni aarẹ Buhari wa parọwa si awọn orilẹede ti ọrọ naa kan lati ni suuru.
Ọ̀gá ọlọ́pàá túntún ṣèlérí láti kojú ipenija ààbò àti ìdìbò 2019 Buhari pàṣẹ́ kí ojú ọ̀nà Apapa gba ìdáǹdè ní kíákíá Tinubu gbéra lọ odidi Mecca láti lọ ṣàbòsí - PDP Ọlọ́pàá mú ẹyẹ igún sí àtìmọ́lé ní ìpínlẹ̀ Adamawa Ọlọ́pàá tó mú àwọn obinrin wọ gau -Ọ̀gá ọlọ́pàá Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Nígbà tí mò ń wà Awolowo, Gowon, Babangida, mo fi ara mi sípo ọ̀wọ̀ tóri .
Ikọlu awọn Fulani darandaran ati agbẹ: Ikọlu miran to tun n fẹju mọ isọkan orilẹede Naijiria ni aawọ ojoojumọ to n waye laarin awọn Fulani darandaran ati awọn agbẹ.
N óo dá ìwọ ati àwọn ọ̀rẹ́ rẹ lóhùn.
Ṣùgbọ́n òun náà kò jáfara rárá, nítorí tí ó gbé ẹbọra náà lu inú ìtakùn, ẹ̀gún gún onítọ̀hún ní ẹsẹ̀, ẹbọra sí fi ara bó fẹ́lẹfẹ̀lẹ.
…If I have to sacrifice for this team to progress, I will.
SERAP fẹsun kan ijọba apapọ pe o lo awọn janduku atawọn ologun lati mọọmọ pa awọn oluwọde l'Eko.
Awọn ohun awari ijinlẹ́ yii lo fidi rẹ́ mulẹ pe Ile Ifẹ ni orirun iran ọmọniyan lagbaye.
 nigba to gbeyin gbera ni 1990 , awon onimo sayensi ri pe jigi iwaju re ko duro daada , eyi fa ko mo sise boseye .
O wa ni ko din ni Igba awọn iru ọmọ bẹẹ ti wọn yoo foju ba ile ẹjọ.
Kinniun ẹ̀yà Juda, ọmọ Dafidi, ti borí.
4 3090 Orilẹede Guinea Bissau 44 2.
Nípa báyìí Dafidi dá àwọn eniyan rẹ̀ dúró, kò sì jẹ́ kí wọ́n pa Saulu.
Popona ti gbẹmi ọpọ awọn arinrin ajọ ni ni aarin ọdun meloo kan sẹyin a yii.
Ọba bá pàṣẹ fún Jerameeli ọmọ rẹ̀, ati Seraaya ọmọ Asirieli, ati Ṣelemaya ọmọ Abideeli, pé kí wọn lọ mú Baruku akọ̀wé, ati Jeremaya wolii wá, ṣugbọn OLUWA fi wọ́n pamọ́.
Afẹ́fẹ́ ìlà oòrùn á fẹ́ ẹ sókè,á sì gbé e lọ,á gbá a kúrò ní ipò rẹ̀.
Ní ọjọ́ tí ìwọ bá sì ń bọ̀ pẹ̀lú, máṣe gbàgbé àti di ẹrù mi tí ó kù bọ̀, kí ìwọ gbé e lé àtàrí rẹ, kí inú baálé mi ba a lè dùn sí ọ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìjínigbé Kaduna: Àwọn agbébọn jí ènìyàn tó lé ní ọgọ́rin 15 Èbibi 2018 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ọ̀gá àwọn ọ̀mọ̀ ogun Nàìjíríà ti sèbẹ̀wò síbi ìsẹ̀lẹ̀ náà Ò lé ní ọgọ́rin ènìyàn tí àwọn agbébọn jí gbé ní ìpínlẹ̀ Kaduna, tó wà ní apá ìwọ̀ oòrùn àríwá orílẹ̀èdè Nàìjíríà.
Ẹ súnmọ́ Ọlọrun, òun óo sì súnmọ́ yín.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Uganda: Á lo owọ́ orí náà láti san gbèsè táa jẹ 31 Èbibi 2018 Oríṣun àwòrán, AFP Àkọlé àwòrán, Igba ṣílẹ̀, eyiun dọ́là márùn-ún àbí pọ́ùn mẹ́rin, làwọn èèyàn tó bá ń lo Whatsapp àti Facebook yóò máa san Ilé asòfin lórílẹ̀-èdè Uganda ti buwọ́lu òfin kan tó ń fa awuye-wuye èyí tó ní káwọn èèyàn tó ń lo ojú òpò ìkànsíraẹ́ni lórí ìtàkùn àgbáyé bíi Whatsapp àti Facebook máa san owó orí.
Ìwọ ni o ni mí, gbà mí;nítorí pé mo ti kọ́ ẹ̀kọ́ rẹ.
Ẹ̀mí OLUWA yóo bà lé e,ẹ̀mí ọgbọ́n ati òye,ẹ̀mí ìmọ̀ràn ati agbára,ẹ̀mí ìmọ̀ ati ìbẹ̀rù OLUWA.
Ṣugbọn, o ya oun lẹnu nigba ti Pasitọ Oyedepo pe Biodun Fatoyinbo sori pẹpẹ, lati ba ijọ sọrọ.
Àwọn ará ile rẹ̀ sọ wípé lọ bí ó ṣe lọ sí ẹ̀hìnkùle ni wọ́n gbọ́ ìró ìbọn.
Praise ni olukopa ẹlẹẹkefa ti yoo kogba lọle kuro lori eto BBNaija alagbelewo to n lọ lọwọ.
Lẹ́yìn ọjọ́ mẹta ati ààbọ̀ yìí, èémí ìyè láti ọ̀dọ̀ Ọlọrun wọ inú wọn, ni wọ́n bá jí, wọn bá dìde dúró.
Ìran Peresi ni Jaṣobeamu, òun sì ni balogun fún gbogbo àwọn ọ̀gágun fún oṣù kinni.
CAF kéde orúkọ àwọn olùdíje àmì ẹ̀yẹ agbábọ́ọ̀lù Áfíríkà Super Falcons pegedé fún àṣekágbá AWCON Victor Moses, Oshoala gba ami ẹyẹ Ojú tirọ́ wọn!
Ọlọrun ṣe èyí gẹ́gẹ́ bí ètò rẹ̀, láti ayérayé, tí ó mú ṣẹ ninu Kristi Jesu Oluwa wa.
Ọwọ́ ọlọ́pàá ìpínlẹ̀ Oyo ti tẹ àwọn aṣekúpani tó ń ṣọṣẹ́ ní Akinyele Ìpínlẹ̀ Eko kéde ọ̀nà àbáyọ sí súnkẹrẹ-fàkẹrẹ ọkọ̀ lásìkò àtúnṣe afárá Third Mainland Wo ìgbẹ́sẹ̀ méjọ tí ilé aṣòfin ìpínlẹ̀ gbọdọ̀ tẹ̀lé láti yọ igbákejì gómìnà Ilé aṣofin Ondo fọwọ́ òsì júwe ilé fún aṣòfin mẹ́ta pé wọ́n tàpá sí òfin ilé Amọ, awọn agbẹjoro Chauvin ko i tii fesi si iwadii tuntun naa, lati igba ti o ti wa ni ikawọ awọn eniyan lawujọ.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Arsenal àti Liverpool gbéná wojú ara wọn Ikọ Arsenal ko lanfani lati na Liverpool lati igba ti Klopp ti di akọnimọọgba wọn titi digba ti Arsene Wenger fi dagbere fun Arsenal.
Mose bá gba àwọn ọkọ̀ ẹrù ati àwọn akọ mààlúù náà, ó kó wọn fún àwọn ọmọ Lefi.
Muhsin Ibrahim ni ko si Musulumi ododo to yẹ ko sọrọ odi si Anọbi labẹ bo ti wu ko ri.
Dípò kí ó jẹun ní àjẹyó,ibinu ńlá ni Ọlọrun yóo rán sí i,tí yóo sì dà lé e lórí.
“Mo jẹ́ kí nǹkan oko yín ati èso àjàrà yín rẹ̀ dànù, mo mú kí wọn rà; eṣú jẹ igi ọ̀pọ̀tọ́ ati igi olifi yín, sibẹsibẹ ẹ kò pada sọ́dọ̀ mi.
nipa sise idasilẹ ibugbe awon daran-daran (Ruga) , ni eyi ti ajo to n mojuto
 Àwọn ẹni kẹta ni àwọn ọkùnrin tí kò ń lú sí tiwọn .
Àkọlé àwòrán, Nkan ko fẹ ṣẹnu re fun Gomina ana Akinwumi Ambode lati igba to ti kuro lori alefa nipinlẹ Eko Lẹnu lọọlọ yii, Gomina tẹlẹri Ambode ti n koju awọn ipenija lọdọ awọn agbofinro paapaa julọ, lọdọ ajọ to n gbogun ti iwa jẹgudujẹra EFCC to yabo ile rẹ ni Epe.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: England yẹ̀yẹ́ Panama pẹ̀lú àmì ayò 6-1 Super Eagles vs Argentina: Òní lòní ń jẹ́ Awọn ikọ àgbábọ́ọ̀lù Nàìjíríà ń gbáradì fún ifẹsẹwọnsẹ oni Nigeria v Argentina, 25 June 2014 (2-3) Goolu meji ọtọọtọ lo waye laarin iṣẹju marun ti ifẹsẹwọnsẹ yii bẹrẹ ni papa iṣire Estadio Beira-Rio lorilẹede Brazil.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Aishat Lola: Kò s'óhun tí mo ṣe tó tẹ́ ìyá mi lọ́rùn 27 Ọ̀pẹ̀̀ 2018 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 28 Ọ̀pẹ̀̀ 2018 Oríṣun àwòrán, @Aishatlola Àkọlé àwòrán, Aishat Lola Aishat Ọmọlọla to jẹ akẹkọọ ipele kẹta ni ile iwe giga fasiti Ahmadu Bello gba ẹmi ara rẹ lọjọru ọj kẹtadinlogun oṣu yii.
'Jibiti ni iṣẹlẹ Dapchi, kii ṣe ootọ' Oríṣun àwòrán, Reuters Ni bayi, awọn ọmọbinrin ile-iwe ti awọn Boko Haram tu silẹ ni Dapchi, nipinlẹ Yobe ti wa ni'lu Abuja lati pade Aarẹ Muhammadu Buhari, ṣugbọn ọpọlọpọ ariyanjiyan lo wa lori itusilẹ awọn ọmọbinrin naa.
wọ́n sì ń fòòró ẹ̀mí wọn pẹlu oríṣìíríṣìí iṣẹ́ líle.
Aminat Abiodun: Òun ni Iyalode kẹtàlá, tó sì ń gun àkàsọ̀ láti ọdun 1971
Nígbàkúùgbà tí ẹ̀mí burúkú bá ti ọ̀dọ̀ OLUWA wá sórí Saulu, Dafidi a máa ta hapu fún un, ara Saulu á balẹ̀, ẹ̀mí burúkú náà a sì fi í sílẹ̀.
Ìwé orin, ìwé àti àpò-àpawómọ́-ìléwọ́ ni wọ́n rí nínú àpò-àgbékọ́yìn-in rẹ̀.
Ní ọjọ́ kinni oṣù, yóo fi ọ̀dọ́ akọ mààlúù kan ati ọ̀dọ́ aguntan mẹfa ati àgbò kan tí kò lábàwọ́n rúbọ.
Onimọ ẹrọ ni Daoud ti a si gbọ pe o bẹ si iwaju agbebọn naa, ki awọn eeyan to ku ba le ribi sa.
World Cup 2018: France fàgbà hàn Croatia pẹ̀lú àmì ayò 4-2
Ẹ̀gbọ́n mi ní kí èmi máa tọ́jú àwọn àbúrò wa, kí òun tún padà lọ sí ilé àbúrò baba mi yìí láti lọ wo àwọn òbí wa.
Kò si bí a ṣe máa gba tirela Irẹsi mẹta, tí a kò ní rí èyí tó ti bajẹ nibẹ nítorí wọn tí kò àwọn Irẹsi náà kalẹ, ọjọ́ tí pẹ.
Lizzy Anjorin: Ẹ má bú mi, ọ̀pọ̀ òṣèré tíátà ni kìí bá mi yọ̀ fún ire mi
A ṣá fẹ́ ní ọba ni.
Ọrọ ti D'banj kọ sori ayelujara yii lo bi Ese ninu.
 ""Iroyin yii ni ẹnikeji ti mo fẹ n gbọ, to fi ko kuro ninu ile ti a jọ n gbe, to si fẹ obinrin mii."
Ará ìlú fárígá, wọ́n wọ́ alàkóso ìlú nilẹ́ pẹ̀lú ọkọ̀ Lẹ́yìn ọ̀ rẹyìn, 'June 12' di àyájọ́ ọjọ́ ìjọba àwarawa Àwọn aṣòfin àgbà yóò wádìí ohun tó wáyé láàrín Sẹ́nétọ̀ Abbo àti obìnrin ilé ìtajà l'Abuja\\ Abọ iwadii Orosaye ni pe ki wọn da awọn ileeṣe ijọba apapọ ti ṣe wọn jọra wọn di ọkan ṣoṣo ki wọn le gbooro sii.
Judasi wá ń wá àkókò tí ó wọ̀ láti fi Jesu lé wọn lọ́wọ́.
Ìbẹ̀rù tó gbòde ayé òde òni ni pé “Ayé Móoru”, nitori iṣẹ̀lẹ̀ ti o nṣẹlẹ̀ ni àgbáyé bi òjò àrọ̀ irọ̀ dá ni ilú kan, ilẹ̀-riru ni òmìràn, ọ̀gbẹlẹ̀, omíyalé, ijà iná àti bẹ́ ẹ̀ bẹ́ ẹ̀ lọ.
Ẹlẹbuibọn ni bi ọrọ yii ba ja asi ootọ̀ọ, ifasẹyin nla lo lee mu ba ilu Osogbo.
''Ti wọn ba n wọ moto naa, inira yoo dinku fun irinkerindo fun awọn eniyan naa'' ''Kii ṣe ọfẹ ni o ma ba de, owo ti awọn eniyan ba n san gẹgẹ bi owo ọkọ ni a ma a fi san owo naa pada.
Ìdámẹ́wàá òṣùnwọ̀n ìyẹ̀fun tí ó kúnná dáradára, tí a pò pọ̀ mọ́ idamẹrin òṣùnwọ̀n hini ojúlówó epo olifi, ni kí o fi rúbọ pẹlu àgbò kinni, pẹlu idamẹrin òṣùnwọ̀n hini ọtí waini fún ìtasílẹ̀.
'Àwọn SARS ló yìnbọn pa ìyá mi' SARS já wọ ilé àwọn akẹ́ẹ̀kọ́ fásitì Akungba Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Segalink:ìkùnsínú pọ̀ láàrin àwọn agbófinró bẹ́ẹ̀ wọn kò ni agbẹnusọ Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Awọn ọbi ko janu kuro lori wipe o le ni ọgọrun akẹẹko ti won jiigbe ni ile ẹko naa, ninu ọmọ ile ẹko toto ẹẹdẹgbẹrun-le-mẹrindinlọgbọn Oríṣun àwòrán, Reuters Àkọlé àwòrán, Awọn ẹbi ati ara awọn woye ibi ti wọn yoo ti ri awọn ọmọ naa Awọn alasẹ ni iye ẹniyan ti wọn ji gbe ko ju ogoji lọ ati wipe ọpọ to sa wọ inu igbo ko ni pe pada de.
A o le sọ lagbaye o.
Collapse Building: Àjọ LASEMA ti gbe ọkùnrin náà lọ sílé ìwòsàn
Ó ṣe ìtọ́jú wa púpọ̀, ó tọ́jú wa gan-an ni.
Oríṣun àwòrán, @Naomi_Osaka_ Àkọlé àwòrán, Naomi se afihan asia orileede Japan to jẹ ilu to n soju fun Ọmọ orileede Japan ati Amerika ni Naomi sugbọn Japn lo n soju fun.
Nígbà tí ó jẹ́ pé ẹ̀yin ni ẹ óo ṣe ìdájọ́ ayé, ó ti wá jẹ́ tí ẹ kò fi lè ṣe ìdájọ́ àwọn tí ó kéré jùlọ?
Wo àwọn àwòrán ìgbà ayé Aretha Franklin Awọn ọmọ ìjọ sàtánì ń bínú sí Nàìjíríà Iyàwó dùn lọ́sìngín ni ọ̀rọ̀ aṣọ òkè lásìkò yí Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí kan sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
 Wayii o, e jeka ni lookan aya wa pe,  gbogbo wa patapata la je gbese iku, amo adura wa nipe ki eledumare maje ka fi ojo olojo lo.
O maa n da abo bo ẹran ara lodi si awọn aisan asare ja.
Bí mo ti júwe fún ọ gan-an ni kí o ṣe àgọ́ náà ati gbogbo àwọn ohun èlò inú rẹ̀.
1 13308 Orilẹede Aruba 46 43.
Eyi ṣẹlẹ̀ lẹ́yìn tí ìpínlẹ̀ Kaduna pàṣẹ kónílé ó gbélé wákàtí mẹ́rìnlélógún ní ìlú náà àti agbègbè rẹ̀ nítorí ìdàrúdàpọ̀ titun tó ń jà rọ̀ìn rọ̀ìn ní ìhà àríwá náà lórí kíkásẹ̀ rògbòdìyàn nílẹ̀ ní agbègbè Kasuwan Magani n'ípinlẹ̀ náà l'ọ́jọ́ ẹtì.
Aare tun wa  ro awon ẹsọ eleto aabo ati agbofinro lati gbe
4 177719 Orilẹede Jordan 3056 30.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Lagos Lion: BBC ṣèwádìí ibi tí aráa India tó ń sin Kìnìhún wà 19 Bélú 2019 Adari igbimọ amuṣẹya fun ajọ alatunṣe agbegbe ni ìpínle Eko, Lagos Environmental Sanitation & Special Offences, Yinka Egbeyemi salaye fun BBC Yoruba pe awọn n reti olowo Kinihun VI.
Ẹgbẹ oṣelu Democrat gbe igbeṣẹ yii lẹyin ti wọn ni ile aṣofin agba naa ko ni ṣe igbẹjọ to ye kooro, nitori pe awọn ọmọ ẹgbẹ oṣelu Republican ti Trump jẹ ọkan lara wọn lo pọju nibẹ.
Lówùrọ̀ ọjọ aje ni wọn ṣe ìpàdé kan ti igbimọ aláṣe si fẹnukò pé kí wọn mú àdínkù bá iye wákàti tí ètò kóníléógbélé yóò fi wà.
Wọn n reti pe wọn yoo wa mu idagbasoke ba iwadii nipa ẹka yi.
Tottenham sọ ọjọ́ ìsinmi olóyin di ''Black Sunday'' mọ́ Arsenal lọ́wọ́ pẹ̀lú ìgbájú-ìgbámú
Bakan ni o tun jewo pe, oun ti kopa ni orisirisi iwa odaran egbe naa, eyi ti won ri aridaju re lori ero alagbeka re”.
Oṣiṣẹbirin ọkọ ofurufu jabọ lati inu baalu
Gẹgẹ bi ohun ti a ri gbọ, alaga igbimọ to n gbẹjọ naa T.
Lẹsẹkẹsẹ ara ọkunrin náà dá, ó ká ẹni rẹ̀, ó bá ń rìn.
Ọ̀rọ̀ tí ó ń lọ nípa Deng Chuabin: Ní ọjọ́ 20 oṣù Èbìbì ọdún-un 2019: Àwọn ọlọ́pàá àgọ́ọ Peizhi ránṣẹ́ sí bàbáa Deng.
" Àwọn àgbà sì bọ ̀ wọ ́ n "" àìfàgbà fẹ ́ nìkan ni kò jẹ ́ káyé ó gún "" ."
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Peters Ijagbemi dá àrá lórí ètò 'Ṣé o láyà' ti BBC Yorùbá lọ̀sẹ̀ yìí Òwò mẹ́wàá tí yóò pàdánù àìsí ìpéjọpọ̀ ńlá RCCG lọ́dún yìí Wo iye àwọn ilé ìjọsin ìlú Eko ti wọ ko ni ṣí ìlẹ̀kùn ilé ìjọisin wọ́n lẹ́yìn ti ìjọba ti ni wọ́n le máa jọ́sìn Mo ti buwọ́lu àdínkù owó orí nítorí ìrọ̀rùn àwọn èèyàn ìpínlẹ̀ Ogun lásìkò Covid 19- Dapo Abiodun Wo ǹkan méjìlá nípa Buruji Kashamu tí ikú wọlè dé wẹ́rẹ́ mú lọ Oríṣun àwòrán, @Kashamu Buruji Kashamu: Wo díẹ̀ lára ohun tí Senato Buruji gbé ilé ayé ṣe kí ọlọ́jọ́ tó dé Ta ni Buruji Kashamu?
Eyi lo mu ki igbakeji akọwe alukoro fẹgbẹ oselu APC, Yekeen Nabena se fi atẹjade kan sita pe ki ajọ EFCC tete bẹrẹ lori ọrọ Hushpuppi.
 Àtire àtìkà wa nìyí kò sí ọ ̀ ken tó gbé ; a ó jèrè rẹ ̀ láyé níbí .
Nígbà tí ẹni tí ó ń ṣọ́ ilé ẹ̀wọ̀n jí lójú oorun, tí ó rí i pé ìlẹ̀kùn ilé ẹ̀wọ̀n ti ṣí, ó fa idà rẹ̀ yọ, ó fẹ́ pa ara rẹ̀, ó ṣebí àwọn ẹlẹ́wọ̀n ti sálọ ni.
6kg), saaju akegbe re Lucy Ejike, ti o gbe ikun irin ti o le mọ́kànlélàádóje Kilo(131.
Àlàyé rèé lórí bí wọ́n ṣe mú mi lẹ́rú ní 1837 - Ajayi Crowther Awọn iwe miran ti Oloogbe Lawuyi Ogunniran tun kọ ni: Ọmọ Alátẹ Ìlẹ̀kẹ̀ Níbo Láyé Dori kọ?
Toyin Abraham bí ọmọkùnrin jòjòló Khafi wọ gàu lẹ́nu iṣẹ́ lórí ẹ̀sùn ìbálòpọ̀ ní BB Naija Gbígba onídùròó Zakzaky ṣàfihàn àṣeyọrí ìfaradà wa lásìkò ìfìyajẹni - Shiite Ijọba sàlàyé ọ̀rọ̀ yìí ninu àtẹjáde kan tó akowe ilé iṣẹ́ ìròyìn àti àsà Grace Isu Gekpe fi síta sàlàyé pe ìwà tí El-Zakzaky gbé wọ̀ ní India jẹ èyí to le tàbùkù orílẹ̀-èdè Nàìjíríà.
 Ó nì àwọ ́ pupa nì apá òkè pẹ ̀ lú eye góólù tí , ó fò lórí ìtànsán òòrùn pèlú àwọ ̀ bọ ́ ọ ̀ lù ní apá ìsàlẹ ̀ àti ìlà funfun tẹ ́ ẹ ́ rẹ ́ mẹ ̀ ta .
Samuẹli bá gbadura, ní ọjọ́ náà gan-an, OLUWA sán ààrá, ó sì rọ òjò.
Báwo ni a ṣe lè mọ̀ pé yóo sọ pé kí á mú àbúrò wa wá?
Amọṣa o ni ojo arọọrọda ọjọ meji to rọ ni ilu ile ifẹ lo dẹkun wahala ti ko ba waye lori iṣẹlẹ ọhun.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Richard Gbadebo: Ìjọba ìpínlẹ̀ Oyo yóò ṣe ìwádìí ikú tó pa akẹ́kọ̀ọ́ Fásitì Ibadan 30 Agẹmo 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 8 Ògún 2020 Oríṣun àwòrán, OTHERS Ijọba ipinlẹ Oyo ti bẹrẹ iwadii lori iku to pa akẹkọọ Fasiti Ibadan, Richard Gbadebo, to ku nile iṣẹ kan ti wọn ti n ṣe ọṣẹ.
kí ó ṣe wá ní ẹni tí yóo gbọ́ràn sí òun lẹ́nu, kí á lè máa tọ ọ̀nà rẹ̀, kí á lè máa pa àwọn òfin ati ìlànà rẹ̀ tí ó fi fún àwọn baba ńlá wa mọ́.
"Sẹnetọ naa to n ṣoju ipinlẹ Kano lọwọ bayii, ṣalaye lori opo twitter rẹ pe ""awọn ipinlẹ ti o ti lee gbadun ina fun wakati mẹrinlelogun lojumọ ni Uranus, Venus, Mars, Saturn ati Neptune."
Yóo ṣẹlẹ̀ bẹ́ẹ̀, n óo sì mú un ṣẹ.
'Ẹ má ṣi Fayemi túmọ̀ lórí àṣẹ tó pa nípa sísọ èdè Yorùbá' Ọlọ́pàá ti mú afurasí ajínigbé Hamisu Wadume Ta ni Seun Fakorede, ọmọ ọdún 27 tó fẹ́ di kọmiṣọna?
Ẹ má fi mí ṣe olórí yín.
FIFA ban: Siasia ní kò sí ìgbà tí òun àti FIFA kò ní pàdé ní kóòtù
Bi ọrọ Olamide Odukọya se ri gẹlẹ ree, ẹni to ti n se awọn baalu kekere lorisirisi, ọkọ oju omi, mọto ati ile lati ọmọ ọdun mejila.
Ọlọpàá tó wà nídi ẹjọ náà, Olubu Apata sàlàyé fún ilé ẹjọ pé, àwọn ọdaran náà tẹ ofin lóju ninú oṣù kejì ọdun 2019, ní oko Awuloju ní Igede-Ekiti èyí to lòdì sofin ipinlẹ̀ Ekiti.
Ṣugbọn ẹ kò fetí sí ọ̀rọ̀ mi, ẹ kò sì gbọ́ràn sí mi lẹ́nu.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Kayeefi: Facebook ni Wolii Arole Jesu fi tàn an wọ agbo, orí rẹ̀ ni wọ́n fi s'owó Gẹgẹ bi ajọ WAEC ṣe sọ ọ, ida mejilelọgọrin ni awọn akẹkọọ to gba ami o kare, iyẹn credit ni awọn iṣẹ ọpọlọ marun un tabi ju bẹẹ lọ.
wa ro awon omo ogun ohun lati ri daju pe won se amulo ile iwosan tuntun ohun,
Ohun miran to tun dakun darudapọ nipa iye eeyan to ni ni pe awọn mi ti arun yi mu wọn ko fi apẹrẹ han-awọn wọn yi ni arun naa ṣugbọn wọn ko ṣaare .
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Àìsàn ibà; Àwọn ènìyàn sọ̀rọ̀ nípa lílo ewé áti egbò Sọ́ra, òògùn ikọ́ codeine lee yi ọ lórí Ohun t'ójú oníròyìn ń rí kúrò ní kèrémí Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
1 7300 Orilẹede Niger 137 0.
Àjọ tó n rí si ọ̀rọ̀ fásitì (NUC) kéde ayédèrú Ọjọ̀gbọ́n tó tó ọgọ́rùn ún LASTMET kọ́ ló kó Opay nílẹ̀ ṣùgbọ́n ọlọ́kadà kò láṣẹ látigba ọ̀nà mọ́rosẹ̀ l'Eko- Opeifa Mọ̀ síi nípa Oyedele Adedokun tó ya àwòràn Donald Trump tó lu ayélujára pa Ọjọgbọn yii gba awọn ọdọ nimọran lati tẹra mọ iṣẹkiṣẹ ti onikaluku yan laayo nitori pe ohunkohun ti o ba dawọle yẹ koo ṣee daadaa de ibi ere.
Eyi ni ero aṣoju ilẹ Naijiria sorileede Uganda tẹlẹ ri, Ambassador Omolade Oluwateru, ẹni to tun ti jẹ igbakeji gomina tẹlẹ nipinlẹ Ondo.
Àwọn ìmúra tó lààmìlaka ní Nàìjíríà lọdún 2018 Àwọn òṣèré tíátà Yorùbá ọkùnrin tí ó rẹwà Gómìnà Oyetọla tìpínlẹ̀ Ọ̀ṣun leè fipò sílẹ̀ nítorí ìbúra Ariṣe ni arika, arika ni baba iregun, awọn ọmọ Naijiria n sọrọ lori iṣẹ ti Shagari ṣe nigba to wa lori oye pe: Wọn ti sin oku aarẹ Shehu Shagari ni Sokoto Okú ààrẹ Nàìjíríà nígbà kàn rí, Alhaji Sheu Shagari tó jẹ́ Ọlọ́run nípè lálẹ́ ọjọ Ẹti tí wọ káà ilẹ̀ sùn ni ààgo mẹ́ta àbọ̀ ọ̀sán ọjọ Abamẹta nílé rẹ̀ tó wà ní ìjọba ìbílẹ̀ Sheu Shagari ní ìpínlẹ̀ Sokoto.
" Fatai Akinbade kọ ni oloṣelu akọkọ ti yoo fi ẹgbẹ oṣelu rẹ silẹ lẹyin eto idibo lati yan awọn oludije fun ipo gomina l'Ọṣun.
Ó fi igi gbẹ́ kerubu meji, ó yọ́ wúrà bò wọ́n, ó sì gbé wọn sí ibi mímọ́ jùlọ.
Ọpọ eeyan lo n fi o oju kan naa wo Tantawi ati Aarẹ Hosni Mubarak.
Wọ́n bi í pé, “Olùkọ́ni, a mọ̀ pé tààrà ni ò ń sọ̀rọ̀, tí o sì ń kọ́ àwọn eniyan lẹ́kọ̀ọ́.
Wo ojú ọmọbìnrin 4 tí afipa báni lòpọ̀ pa ní Nàìjíríà Wọ́n ti gbé òkú Ibidunni Ighodalo sílé ìgbókúpamọ́sí l'Eko Ni irọlẹ ọjọ Aje ni minisista fun eto irinna ofurufu, Idi Sirika ṣalaye pe ọtọ ni ẹni ti wọn fun ni aṣẹ lati rin pẹlu baluu naa.
Àwọn tí ó sin Paulu lọ mú un dé Atẹni.
Èmi kò forí ṣọta ìjàmbá ọkọ̀ òfúrufú kankan - Obasanjo Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Jiti Ogunye: Ìjọba àkóbá lológun gbé kalẹ̀ ni 1999 Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Ẹ̀yin ará, n kò fẹ́ kí nǹkan nípa ẹ̀bùn Ẹ̀mí Mímọ́ ṣókùnkùn si yín.
Ilé ìgbọ̀nsẹ̀ kan ṣoṣo ni aṣòfin mẹ́rin ń pín lò!
Ẹni àgbéga ni Ọlọrun ìgbàlà mi!
Nibayii, Super Eagles ti bọ si ipele keji (Round of 16) idije Afcon 2019.
Inu mi dun lati pade wọn ọrẹ tuntun lori eto yii, ti agbega si ba igbe aye mi, bakan naa ni mo di gbajumọ lawujọ."
CCVR :Card reader (Kaadi itẹka) : Kaadi itẹka ni ohun elo
Gege bi agbenusoro fun ile-ise alaabo oju popo, Bisi Kazeem se so,”Oko epo robi ohun kunfun lita epo ẹ̀gbẹ̀rún lona mẹ́tàlélọ́gbọ̀n, ti isele ijamba ohun si waye laago marun un aabo osan, ni opopona afara Michael Otedola ilu Eko si Ibadan.
8 Mo ti ní ìyàwó àfẹ́sọ́nà, ayẹyẹ ìgbeyàwó mi ń bọ̀ láìpẹ́ - Lateef Adedimeji 9 Ọwọ́ tẹ ènìyàn méjì tó ń ta ayédèrú aṣọ iṣẹ́ ikọ̀ Àmọ̀tẹ́kùn 10 Covid-19: Ilé aṣojú-ṣòfin l'Abuja dábàá kí ìjọba sún ìwọlé àwọn akẹ́kọ̀ọ́ síwájú pẹ̀lú oṣù mẹ́ta BBC News, Yorùbá Ìdí tí ẹ fi le è nígbàagbọ́ nínú ìròyìn BBC Ìlànà Lílò Nípa BBC Òfin Àṣírí Cookies Kàn sí.
" Ọọni Ogunwusi ṣalaye pe lara ohun to mu alaafia jọba lorilẹede Naijiria ni irẹpọ to wa laarin awọn ọbalaye, paapaa julọ gẹgẹ bi Ọọni ana, Okunade Sijuwade Olubuse II, Emir ana ni ilu Sokoto, Alhaji Ado Bayero pẹlu Obi ana ni ilu Onitsha ṣe ba ara wọn dọrẹ pọ, eleyi to ni o ṣe ọpọlọpọ anfani fun orilẹede Naijiria.
Nipasẹ bẹẹ kokoro arun yii lee wọ ara rẹ ki o si sọ ọ di alailera.
Ẹ̀rù ba àwọn obinrin náà, wọ́n bá dojúbolẹ̀.
Awọn eleto ilera sọ pe lilo ibomu-bẹnu ko le daabo bo ọ patapata lọwọ Covid-19.
orile ede Britain lojo kàrúndínlógún osu keje odun ,1947.
Valencia lanfaani lati gbayo mii sawọn lẹyin ti rẹfiri fun wọn ni pẹnariti, ṣugbọn aṣọle Chelsea Kepa Arizabalaga mu pẹnariti ọhun.
Ṣugbọn wọn n sọ lọwọ lẹsẹ titi to fi lọ fun irinajo hajj lorilẹede Saudi Arabia losu kẹjọ ọdun 1985, ti wọn si doju ijọba Buhari-Idiagbon bolẹ, eyi ti Ọgagun Ibrahim Babangida lewaju rẹ.
 king tún jẹ ́ akọrin tó lo orin nínú iṣẹ ́ rẹ ̀ fún àwọn ẹ ̀ tọ ́ aráàlú .
 Àṣà ilà Kíkọ ní Ilè Yorùbá Bí a bá wo ojú ọ̀pọ̀lọpọ̀ àwọn ọmọ Yorùbá ní Orílè-èdè Nàìjíríà, á ri wípé oríṣiríṣi ilà lọ máa ń wà lójú àwọn ènìyàn.
Bakan naa, o ṣe apẹrẹ awọn nkan dindin gẹgẹ bi ohun ti ko yẹ keeyan kọkọ fi ṣinu.
Wo ohun mẹ́wàá tó yẹ kóo mọ̀ nípá ọmọ ọdún mẹ́wàá Emmanuella tó kọ́ ilé ńlá fún ìyá rẹ̀ Tí mi ò bá fẹ́ ìyàwó mi, n ó tí di àgbégbìn- Ayodele Fayose Àwọn oniròyìn ló tú àṣírí ààbò Prof Peller, tí wọn fi ri pa - Lady Peller Pásítọ̀ Sam Adeyemi, Taaooma, Falz àti gbogbo àwọn tí ilé ẹjọ́ fẹ́ rí nìyìí Oríṣun àwòrán, Twitter:thefaridaadamu/slay_jimmy Farida sọ pe oun ko ni pada ba banki naa dowopọ lẹyin ti oun ti gbe agadagodo sẹnu apoti oun to wa nileeṣẹ ọhun.
Eleyi yoo jẹ osu mẹtadinlogun ti Ayew ti o fi South Wales silẹ fun ẹgbẹ agbabọọlu West Ham.
Èmi àti Sanyeri ti tọrọ oúnjẹ jẹ rí nílé oninawo torí ebi, ká tó di gbajumọ oṣere Díẹ̀ lára àwọn òṣèré Nollywood ti wọ́n ti ṣe ìgbéyàwó lẹ́ẹ̀kejì Mi ò kí n ṣe afẹfẹ-yẹ̀yẹ̀ lórí ayélujára nítorí pé mí ò ní dúkìá tí mó le fihàn- Ronke Oshodi-Oke Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Lateef Adedimeji and Adebimpe Oyebade: Ohun tí BBC mọ̀ nìyí nípa àjọṣepọ̀ òṣèré tíátà méjéèjì25 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Yollywood: Awọn oṣere sinima ti wọn ti rinrin ajo ifẹ lẹẹmeji2 Ọ̀wàrà 2019 Lateef Adedimeji: Nkan tí a mọ̀ nìyíì nípa ìgbéyàwó tí Lateef àti Adebimpe Oyebade7 Agẹmo 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Ṣugbọn, o ni ẹgbọn, ẹ jọwọ, ẹ pada wa."
Ẹgbẹ agbabọọlu Tunisia kuna lati de ipele aṣekagba lẹyin ti Senegal fagba han wọn pẹlu ami ayo kan sodo.
Ọrọ rẹ ta daadaa leti awọn mẹkunnu ti a si ri ka pe awọn ọdọ to kawe miran naa to fi mọ awọn tori jajẹ lawujọ a ma tẹti gbọ waasi rẹ.
O tun ni iko omo oogun orile ede Naijiria tun kolu iko omo oogun olote Boko Haram  ni agbegbe  Gbamjimba-Akor  to wa ni ijọba ibilẹ  Guma ni ipinle Benue.
”Ni ọkunrin náà bá ń káàkiri gbogbo ìlú, ó ròyìn ohun tí Jesu ṣe fún un.
Wọ́n sọ fún un pé, “Jesu ará Nasarẹti ní ń kọjá.
Àkọlé àwòrán, Bi o tilẹ́ jẹ́ pe a tiraka lati mọ ẹgbẹ oselu to n pin owo naa fawọn oludibo, sugbọn idahun ikọọkan wọn yatọ sira.
AFCON 2019: Àwọn ikọ̀ Super Eagles ti gbà lára owó àjẹmọ́nú wọn
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Nigeria Swearing in 2019:Olókoòwò tó dáńtọ́ ni gómìnà Ogun tuntun 30 Èbibi 2019 Àkọlé àwòrán, Ori lo mọ ọlọrọ, ori lo mọ ọba.
6 June 2019 - BBC News Yorùbá BBC News, YorùbáFò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ọ̀sẹ̀ ilẹ̀ Afíríkà rèé nínú àwòràn: 31 May - 6 June 2019 8 Òkùdu 2019 Oríṣun àwòrán, AFP Àkọlé àwòrán, Arìnrìn oge Ọmọ bíbí South Sudan Alek Wek takes tyan fanda ni ibi ayẹyẹ CFDA fún àmì ẹ̀yẹ fún ohun àmusoge tó wáye ní New York lọ́jọ́ ajé Oríṣun àwòrán, FIFA/Getty Images Àkọlé àwòrán, Ní ọjọ́rú, àgbábọ̀ọ̀lù ọmọ ilẹ̀ South Africa fẹ́yin kẹẹ si ẹ̀rọ ayàwòràn sáájú ife ẹ̀yẹ àgbáye àwọn obìnrin tó ń lọ niFrance.
Simeoni ati Lefi jẹ́ arakunrin,ìlò ìkà ati ipá ni wọ́n ń lo idà wọn.
leti pe , ile-ejo ti pase pe ki olufisunu naa yọju sile ejo.
Oríṣun àwòrán, SUNDAY DARE/TWITTER Àkọlé àwòrán, Eto D Royal African Leadership Forum ti Arole Oodua Ooni Ife ṣe agbátẹru rẹ̀ Tani ó tọ́ sí àti pé báwo ni o ṣe le fi orúkọ sílẹ̀ fún ètò Nigeria Youth Investment Fund O yẹ ki ètò náà bẹ̀rẹ̀ nínú oṣù kẹ̀sán nítori náà àwọn ǹkan ti àwọn ọ̀dọ́ yóò nílò rèé láti fi orúkọ silẹ̀ fún ètò náà.
eto aibo ti ko fẹsẹ mulẹ duro.
Ilé ẹjọ́ ju olè orí omi mẹ́ta sí ẹ̀wọ̀n, ó tún ní kí wọ́n san 60 miliọ̀nù Àlàyé rèé lórí bo ṣe le è dá Emèrè mọ̀ tàbí dara pọ̀ mọ́ ẹgbẹ́ wọn Ìdè jáá!
Ibrahim El-Zakzaky Olori ẹlẹsin Musulumi Shia ni Ibrahim El-Zakzaky, oun si ni adari awọn Islamic Movement of Nigeria to da silẹ lọdun 1970.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù CAN: Darandaran ti ran ida aadọrun ninu ọgọrun ọmọlẹyin Kristi s'ọrun 19 Èrèlè 2018 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, CAN ni ijọ Kristi gbọdọ parapọ nitori awọn ipenija tuntun Ida aadọrun ninu ọgọrun awọn to ku ninu ọkan-o-jọkan ikolu ipaniyan to waye ni apa ariwa orilẹede Naijiria lo jẹ ọmọlẹyin kristi.
Aisha Buhari gbarata lórí fídíò Codeine Aya aàrẹ Nàìjíríà, Aisha Buhari lórí instagram @aishambuhari, ti ké gbàjàrè sí àwọn òṣìṣẹ́ elétò ààbò, àwọn iléeṣẹ́ apoogùn, olùkọ́, alágbàtọ́, òbí, alájọgbélépọ̀ àti àwọn aṣòfin Nàìjíríà láti fọwọ́sowọ́pọ̀ pẹ́lú ìjọba ja ogun yíì lájàyè.
Oun naa raaye jẹ ẹbun miliọnu meji aabọ Naira.
O fikun un wi pe iku rẹ dun oun, ati wi pe, agbo osere tiata Nollywood ko lee gbagbe rẹ mọ lai.
Ninu ojo ni awọn agbabọọlu France ti gba ife ẹyẹ naa lẹyin ti wọn na ikọ Croatia pẹlu ami ayo 4-2 ninu ifẹsẹwọnsẹ aṣekagba idije naa.
Egbe awon osise meteeta n bere fun ẹ̀gbẹ̀rún márùndínláàdọ́rin(N65,500) gege bi owo osu tuntun naa, bee si ni awon ile-ise aladaani ati awon gomina ipinle kookan so pe ẹ̀gbẹ̀rún márùndínlọ́gbọ̀n(N25,000) ni awon le lanfani ati san.
kò túmọ̀ si pé ènìyàn buruku ni mí.
Ìjọba ń ṣe afárá Eko Bridge l'Eko, àwọn ọ̀nà àbùdá tí ẹ lèè gbà nìyí Ko tan sibẹ, ajọ to n ri si ere bọọlu lagbaye, FIFA sọ pe, o ṣeṣe ko sun awọn igbaradi fun idije bọọlu agabye, Qatar 2022 siwaju.
Kanye West da àrínyànjiyàn silẹ́ nipa Trump Kanye West pa orúkọ dà sí 'Ye' Àwọn 'ẹ̀bùn' tí ikú George Floyd fún àgbáyé Ibú-owó Bloomberg fẹ́ ta kànùngbọ̀n pẹ̀lú Trump nínú ìbò ààrẹ Amẹrika Oriṣiriṣi eniyan lo si ti n sọ eero ọkan wọn lori ikede ti West fi sita.
Ogunbowale  so pe,”Lati se iru eleyi ninu ose kan pere, o je ohun itan ninu idije boolu afowogba yii,” Ogunbowale, ju boolu ami metadinlogbon wole ninu ipele keji asekagba ohun lojo Eti(Friday), leyi ti o mu n gba ami-eye olukopa ti o ta yo julo ninu idije ohun.
A gbiyanju lati gbe awọn ohun to n lọ lagbo oṣelu kalẹ lai ṣegbe, lori awọn ohun to wa lojutaye jade.
Eleyii n waye lẹyin wakati diẹ ti awọn aṣofin ipinlẹ naa yọ igbakeji abẹnugan ile igbimọ aṣofin ipinlẹ naa.
OLUWA ni agbára ati asà mi,òun ni mo gbẹ́kẹ̀lé;ó ràn mí lọ́wọ́, ọkàn mi sì kún fún ayọ̀;mo sì fi orin ìyìn dúpẹ́ lọ́wọ́ rẹ̀.
Ṣugbọn òfin kì í ṣe igbagbọ, nítorí a kà á pé, “Ẹni tí ó bá ń pa gbogbo òfin mọ́ yóo wà láàyè nípa wọn.
79 egbegberun ilopomeji maili ( 9.
Ọjọ́ ayé mi ń sáré ju ọ̀kọ̀ ìhunṣọ lọ,Ó sì ń lọ sópin láìní ìrètí.
Basiri sọ pe bi awọn awọn ọkọ memeji ṣe fori sọra lo fa ṣababi ina to ṣeyọ.
’ Wí fún olúwarẹ̀ pé, ‘Kò sí.
Ọkọ arabinrin naa to ti di oloogbe Noah Chelugui jẹ oloye kan ni agbegbe rẹ nigba ti Moi jẹ aarẹ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Nigeria Election Update: 'Ilé iṣẹ́ DSS kò mú òṣìṣẹ́ INEC kankan lórí ẹ̀sùn Atiku' 20 Ìgbé 2019 Irọ ni wọn n gbe kiri!
O ní àwọn ọlọ́pàá wọ̀nyiì fi ẹ̀mi wọn rúbọ láti dáàbò bò ẹmi àti ǹkan ìní ará ìlú, ó ní owó náà wà fún ẹ̀san iṣẹ́ ribiribi tí wọ́n ti ṣe.
Awọn aṣofin to fi ẹgbẹ oṣelu APC silẹ naa ni: Họnọrebu Debo Akanbi ti o n ṣoju ẹkun idibo Ariwa Ẹdẹ, (Ede North) Họnọrebu Tajudeen Famuyide to n ṣoju ẹkun idibo iwọ oorun iléṣà (Ilesha west) ati Họnọrebu Abdullahi Ibrahim ti ẹkun Iwo.
Àwọn ọ̀nà ti ẹ lè gbà kojú omí yale àgbára ya ṣọọbù Sowore àti àwọn ọmọ ẹgbẹ Revolution Now kò ṣẹ̀ ṣófin lórí ìwọ́de, ẹ tú wọn sílẹ̀ - NLC Yàtọ̀ sí Ọ̀ṣun Òṣogbo, Ṣàǹgó pẹ̀lú a máa ní arugbá lóde Ọ̀yọ̀ Ìpínlẹ̀ Ọ̀ṣun kéde ìsinmi lẹ́nú iṣẹ́ nítorí ọdún Ìṣẹ̀ṣe O ni ìgbákeji ààré fi kún un pé bi ǹkan bá ń lọ bẹ́ẹ̀, wàhálà yóò súyọ ninu ètò ìsúná orílẹ̀-èdè yìí laipẹ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, World Diabetes Day: Ọdún kọkandinlogun ti mo ti wà lẹ́nu itọ ṣúgà nìyí Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Obinrin ilẹ Gẹẹsi kan ni oun ṣe iṣẹ abẹ toun ni Turkey lọdun meji sẹyin nitori pe, o dinwo ni Turkey daadaa.
5 221604 Orilẹede Oman 1509 31.
Adura àtọkànwá olódodo lágbára, nítorí Ọlọrun a máa fi àṣẹ sí i.
O ni wi pe lasiko ti wọn yan Sanusi Lamido Sanusi gẹgẹ bii Emi ilu Kano loṣu kẹfa, ọdun 2020, lẹyin oṣu meji ti aarẹ Jonathan yọọ nipo gomina banki apapọ Naijiria, oun mọ pe kii ṣe igbesẹ to tọ nigba naa.
Wọn sọ wipẹ ''idokowo naa labẹ isẹ akanse pipin ina ọba jakejado orilẹẹde naijiria yoo mu ilọsiwaju ba pipin ina ọba ti yoo si je ki awọn ile ise to'n pin ina ọba maa le fina sọwọ si awọn onibara wọn deede.
Ibi to ti n kọrin ni White House re ni ọdun 2016 nigba ti Barack Obama jẹ aarẹ.
Eyi to kan ma n jẹ jade ju ni aini ifọkanbalẹ pe aabo wa fun mi lọwọ aarun.
 Àwọn hausá pàápàá wà ní ìlú Ọ ̀ ra báyìí , ṣùgbọ ́ n èdè Ìgbómìnà ni èdè tí ó gbégbá oróke láàrin wọn .
"Ọ̀rọ̀ LAUTECH gba àpérò f'áwọn Olúdíje Ọṣun A kò ní ǹkan ṣe pẹ̀lú ẹgbẹ́ òsèlú -Adeboye Àwọn olùdíje Ọṣun jẹ́wọ́ ara wọ́n Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'A máa ń bẹ́ orí ẹni tó bá gbé imọlẹ̀ ọdún ìjẹṣu tó bá ṣubú ni' ""Ọ̀pọ̀lọpọ̀ ìgbà ni ọ̀rọ̀ tó l'ágbára maa n di yẹ̀yẹ́ lórí ayélujára."
Sọ fún àwọn ọmọ Israẹli pé kí olukuluku tọ aládùúgbò rẹ̀ lọ, ati ọkunrin ati obinrin wọn, kí wọ́n lọ tọrọ nǹkan ọ̀ṣọ́ fadaka ati ti wúrà.
Nipost, tíí ṣe orogún wa, kò lẹ́tọ̀ọ́ láti díye lé wa - Iléeṣẹ́ abáni fi ẹrù ránṣẹ́ yarí Láti January lọ, gbogbo ẹni tó bá ra ọjà lórí ayélujára yóò máa sanwó orí - FIRS Èrò ọmọ Nàìjíríà sọ̀tọ̀tọ̀ lórí fàákájáa láàrin Abike Dabiri-Erewa àti mínísítà ètò ìbárẹ̀nisọrọ̀, Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, VAT: Kò sí àǹfàní kankan tí ìjọba ti ṣe fún mi sẹ́yìn O ni o ṣeni laanu pe Alaga ileeṣẹ NIPOST ko mọ iyatọ laarin iwe ontẹ 'postage stamp' ati owo ori 'Stamp Duty', ti ijọba ni ki FIRS o ma a gba fun fifi iwe ranṣẹ.
Op si jẹ ko di mimọ pe aarẹ ti paṣẹ fun gbogbo awọn gomina lati da igbimọ oluwadi silẹ lati boju wo awọn ẹsun aṣemaṣe gbogbo ti wọn ba fi kan iks SARS ni ipinlẹ koowa wọn.
Mi o ni iru aarun bẹ ẹ ri, l'oju ẹsẹ ni mo si ti mọ pe oun lo ko o ran mi.
Ẹ súnmọ́ mi, kí ẹ gbọ́ ọ̀rọ̀ yìí,láti ìbẹ̀rẹ̀ wá, n kò sọ̀rọ̀ ní àṣírí,láti ìgbà tí ọ̀rọ̀ náà ti ṣe ni mo ti wà níbẹ̀.
Atẹjade kan eyi ti olubdamọran agba lori ọrọ iroyin, Fẹmi Adeṣina fi sita leyi ti jẹyọ.
Ní òwúrọ̀ ẹ̀wẹ̀, ẹ máa ń sọ pé, ‘Ìjì yóo jà lónìí nítorí pé ojú ọ̀run pupa, ó sì ṣú.
A tii bẹrẹ si ni gbọn epo naa kuro nibi to da si, ki ijamba ina ma ba a waye.
Ikede naa jẹ iyalẹnu fun ọpọ eeyan bo tilẹ jẹ pe kii ṣe igba akọkọ rẹ ti yoo sọ pe oun fẹ di aarẹ ni eyii.
Iṣẹ́ ni oògùn ìṣẹ́, múra si iṣẹ́ rẹ ọ̀rẹ́ mi, iṣẹ́ ni a fi i di ẹni gíga
Ìkọlù Plateau: Ẹyìn aṣáájú ìlú gbọdọ mojuto àlàfíà
Igba wo ni ileewe n wọle?
Àwọn orílẹ̀-èdè yóo ràn wọ́n lọ́wọ́ láti pada sí ilẹ̀ wọn, àwọn orílẹ̀-èdè wọnyi yóo sì di ẹrú fún àwọn ọmọ Israẹli.
Ṣugbọn, ìwọ dìde, di àmùrè rẹ, kí o sì sọ gbogbo ohun tí mo pa láṣẹ fún ọ fún wọn.
" Bakan naa lo ni ijọba gbọdọ yẹra fun ohunkohun ti o lee fa iyapa lorilẹ-ede Naijiria.
Koda ni Taiwan Singapore ati Hong Kong wọn ya awọn to ba ni arun yi sọtọ niile wọn ti wọn si fi ijiya owo itanran ẹgbẹrun mẹta dọla lelẹ fẹnikẹni to ba tapa si ofin yi 3.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Seyi Makinde: Gómìnà ìpínlẹ̀ Oyo kéde dúkìá tó tó #48bn 16 Agẹmo 2019 Oríṣun àwòrán, @Seyi Àkọlé àwòrán, A ju ara wa lọ ijakadi kọ Gomina ipinlẹ Oyo, Seyi Makinde ti kede dukia rẹ eyi to to ogoji biliọnu naira.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Osun-Osogbo Festival 2020: Àwọn ẹlẹ́sìn àdáyébá rú òfin Covid-19 níbi àṣekágbá ọdún Osun Osogbo 18 Agẹmo 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 16 Ògún 2020 Oríṣun àwòrán, Others Pupọ ninu awọn eeyan to peju sibi aṣekagba ọdun Osun-Osogbo to waye ni ipinlẹ Osun, lo tapa sofin ijinasiraẹni.
Osise oun tun so pe, lara esun ti won fi kan awon odaran naa ni: didarapo mo egbe omo-ogun olote, nini awon ohun ija ogun ni ikawo, sise ku pani ati gbigbero iseku-pani.
Iko omo-ogun Naijiria ti ise akanse Operation LAFIYA DOLE seku-pa ogoro omo ogun olote boko haram ninu ikolu ti o waye niluu Tumbun Rego nipinle Borno.
Adamuni eto ipese ounje fun awon to wa nile-iwe
N óo ko yín jọ, n óo fẹ́ ìrúnú mi si yín lára bí iná, ẹ óo sì yọ́.
Gbogbo ọkọ ti wọn gba lọwọ awọn afunrasi ọhun lo jẹ ayọkẹlẹ, ti wọn gba kaakiri tibu toro ipinlẹ Ọsun.
Benue clashes: Àwọn agbébọn yìnbọn pa èèyàn mẹ́sàn án ni Benue
Báwo ni ìlù gángan se bẹ̀rẹ̀ ?
Adamawa Ijọba ipinlẹ Adamawa kede igbele oni wakati mẹrinlelogun lẹyin ti awọn eeyan ya bo ile to ko ounje naa pamọ si lọjọ Aiku.
Oludije labẹ ẹgbẹ oṣelu ADC yii ni oun gbagbọ pe orí kan kò ju ikeji lọ nipinlẹ Ọṣun fún ìdí eyi, iwọ oorun Ọṣun ni gomina tuntun kan lasiko yii.
Shonibare ni eyi to ya oun lẹnu ju ni pe, awọn ọlọpaa naa ko sọ nkankan nipa pe aṣẹwo naa n ṣe iṣẹ to lodi s'ofin.
Oríṣun àwòrán, @FriendsofKashm2 Wayi o, ọpọ ọmọ Naijiria taa gbọ pe wọn ti fi orukọ silẹ pe awọn n pada bọ nile pẹlu baalu ọfẹ tijọba gbe kalẹ lati ko wọn wale lati orilẹede South Africa.
Ọdun 2018 Ọjọ 19, Osu Keji Awọn afunrasi ikọ agbẹsunmọmi Boko Haram se ikọlu si ile-ẹkọ Girama fun awọn obinrin ni ilu Dapchi, nipinlẹ Yobe, ni ila-ariwa orilẹede Naijiria.
Ìjìyà ń bẹ fún àwọn ti adé ọ̀rọ̀ náà bá ṣí mọ́ lóri -Ọga àgbà FRSC Wo ohun tó yẹ kí o mọ̀ nípa àwọn obìnrin méje ti Buhari fẹ́ yàn sípò minista Ìpínlẹ̀ Ondo ti ní gómìnà tuntun Wilfred Ndidi, ọmọ Nàìjíríà pa iná ògo Chelsea ní Stamford bridge Fowler kò sí lábẹ́ ìwádìí kankan-Garba Sheu Ilé iṣẹ́ tó ń ri sí ìrìn ojú furufu, ti wà lára iléṣẹ́ ìrìnnà tẹ́lẹ̀, èyí ti Hadi Sirika ń sojú lásìkò tó tó jẹ mínísítà abẹ́lé fún ìrìnnà ojú ofúrúfu.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Adamu: Olùkọ̀ 2,295 ni Boko Haram pa láàárín ọdún mẹ́sán 3 Èbibi 2018 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Àwọn olùkọọ́ tí orí kó yọ ti fọ́n káàkiri àwọn ìpínlẹ̀ Yobe, Borno àti Adamawa Ǹjẹ́ o mọ̀ pé Olùkọ́ tó lé ni ẹgbẹ̀rún méjì ló ti kú sínú làásìgbò ìkọlù Boko Haram lẹ́kùn ìlà oòrùn àríwá Nàíjíríà?
Nítorí ó jẹ́ ẹ̀ṣẹ̀ tí ó burú jù,ẹ̀ṣẹ̀ tí adájọ́ gbọdọ̀ jẹ mí níyà fún.
Ṣùgbọ́n, lọ́nà kìíní ná, kò fẹ́ rìn jìnnà púpọ̀ sí àbúrò rẹ̀ gẹ́gẹ́ bi ìpinnu wọn pé àwọn kò gbọdọ̀ jìnná sára wọn bí ó ti lẹ̀ jẹ́ wí pé àwọn méjèè jì kò jọ fẹ́ gbé ibùdó kan náà.
Bí kò bá gba tiwọn, sọ fún ìjọ.
Lẹ́yìn náà yóo fi ẹyẹ keji rú ẹbọ sísun, gẹ́gẹ́ bí ìlànà.
Gẹ́gẹ́ bí àgbẹnusọ fún gọ́mìnà Abbaa Anwar ṣe sọ gbájúgbaja ọmọ bibi Kano àti alága àwọn gomina Nàìjíríà Kayode Fayemi ló pe ìpàdé ti wọ́n fi pẹ̀tù sí ààwọ̀ àwọn méèjì.
”Joramu dáhùn pé, “Rán ẹlẹ́ṣin kan láti bèèrè bóyá alaafia ni.
Ẹni to bori: South Africa Nigeria vs Côte d'Ivoire.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Èmi gan máa ń béèrè lọ́wọ́ ara mi pé ta ni Wole Soyinka gangan' Ìṣẹ̀lẹ̀ náà kò sì sẹ́yìn bí ọba alaye náà ṣe lọ́wọ́ nínú ètò òṣèlú.
O ni niwọn igba to jẹ pe wọn ti gbe Onidajọ Liman ga lọ si ile ẹjọ kotẹmilọrun ṣaaju igba naa, ko lẹtọ mọ lati pada lọ gbọ ẹjọ naa tabi gbe idajọ kalẹ lori rẹ.
Ninu ìdílé Elamu: Matanaya, Sakaraya, ati Jehieli; Abidi, Jeremotu, ati Elija.
Ó dígbà o, máa retí mi ni àfẹ́mọ́júmọ́ ọ̀la.
ojuse rẹ lati fọwọsowọpọ pelu awon orile ede miiran lati gbogun ti aisan iba
ẹ̀ báà bú mi di ọ̀la - Ọ̀gá Amotekun l'Osun Àwọn èèkàn ìlú péjú s'Ibadan níbi ìsìnkú màmá Omotola àkọ́bí obìnrin Awolowo tó wọ káà ilẹ̀ lọ Ninu atẹjade ti akọwe iroyin fun Gomina ipinlẹ Oyo, Taiwo Adisa fi sita lorukọ Gomina, Makinde gbadura pe ki Eleduwa tẹwọ gba Akande, ki O si tu awọn ẹbi rẹ ninu.
29 Èmi kan náà ni ẹnití ó wá sí ọ̀dọ̀ àwọn tèmi tí àwọn tèmi kò sì gbà mí;
Ladọja: A ṣe awa naa lee ni BBC tiwa
Oya se idiwọn owo yi pẹlu owo osu rẹ?
ìjọba náà ń gbìyànjú ni láti kó owó yìí kalẹ̀, èyí ni ìgbà àkọkọ ti ìjọba yóò fórí lá ewu nítori àwọn ọ̀dọ́,ànfani rèé fún ọ̀dọ́ láti ṣe oríire.
Ìbáà jẹ́ rere ni OLUWA Ọlọrun wa tí a rán ọ sí sọ, kì báà jẹ́ burúkú, a óo gbọ́ràn sí i lẹ́nu; kí ó lè dára fún wa; nítorí pé ti OLUWA Ọlọrun wa ni a óo gbọ́.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Mò ń fi lẹ̀kẹ̀ ya àwọnran láti jèrè ǹkan méjì - Olaniyi Olaniyan Ajọ ọlọ́pàá fi kún un pé àtúnto to gbópọ̀n ni ọlọpàá tun ti se láti dènà irú ìṣẹ̀lẹ̀ yii lọ́jọ́ iwáju jákèjádò ìpínlẹ̀ Eko.
Ẹyin naa mọ ibi ti ọrọ pada ja si pẹlu abajade ibo.
Ǹjẹ́, nisinsinyii, jọ̀wọ́ ṣe ohun tí mò ń tọrọ lọ́wọ́ rẹ fún mi.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Àwọn akẹ́kọ̀ọ́ fásitì Adekunle Ajasin, Akungba-Akoko fẹ̀hónú hàn ní ìpínlẹ̀ Èkó Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àwọn akẹ́kọ̀ọ́ fásitì Adekunle Ajasin, Akungba-Akoko fẹ̀hónú hàn ní ìpínlẹ̀ Èkó 12 Ìgbé 2018 Àwọn akẹ́kọ̀ọ́ fásitì Adekunle Ajasin, Akungba-Akoko tú síta kẹ̀tí-kẹ̀tí lónì''i láti fẹ̀hónú hàn lórí i àfikún owó iléèwé tí ìjọba ìpínlẹ̀ Òndò paláṣẹ.
Oríṣun àwòrán, AFP Àkọlé àwòrán, Uganda nílò owó orí náà láti fi san díẹ̀ lára gbèsè tó jẹ Ọjọ́ kìnní osù keje ọdún 2018 ni òfin náà yóò fẹsl múlẹ̀ sùgbọ́n iyèméjì wà lórí ọ̀nà tí wọn yóò gbà se àmúsẹ rẹ̀.
Ó wá wí fún wọn pé, “Ẹ̀yin, ní tiyín, ìsàlẹ̀ ni ẹ ti wá, ṣugbọn ní tèmi, òkè ọ̀run ni mo ti wá.
4 Àti pé ìwọ ní ẹ̀bùn láti túmọ̀ àwọn àwo àkọsílẹ̀ náà; èyí sì jẹ́ ẹ̀bùn àkọ́kọ́ tí èmi fi fún ọ; àti pé mo ti paá láṣẹ pé ìwọ kò gbọdọ̀ ṣebí ẹnipé o ní ẹ̀bùn míràn títí tí èrò mi yíó fi wá sí ìmúṣẹ nípa èyìí; nítorí èmi kì yíò fi ẹ̀bùn míràn fún ọ títí tí yíò fi parí.
Ibudo idibo mẹrin le lugba ni atundi ibo gomina ti waye ni ijọba ibilẹ mejilelogun nipinlẹ Benue Bala Mohammed, olùdíje PDP, la gómìnà Bauchi mọ́lẹ̀ nínú àtúndì ìbò Bala Mohammed ti ẹgbẹ oṣelu PDP lo wọle ninu atundi ibo gomina to waye lọjọ Abamẹta to kọja ni ipinlẹ Buachi.
Fayemi ṣèlérí owó ìtọ́jú àwọn tó fara gbá nínú ìjámba l'Ékiti Ajọ LASEMA sọ̀rọ̀ lórí okùnfà iná to jó l'Abule Ẹgba.
Jesu dá wọn lóhùn pé, “Àwọn eniyan ayé yìí ni wọ́n ń gbeyawo, tí wọn ń fi ọmọ fọ́kọ.
Gomina ipinlẹ Kano, Abdullahi Ganduje ti kọ lati yọju si Ile Igbimọ Asofin ipinlẹ Kano lori ẹsun ajẹbanu ti wọn fi kan an.
Ijọba n yin tajútajú fi tú wọn ka pẹlu kóńdó àti kùmọ̀ ni.
Ọrọ naa ko dun mọ awọn to n tukọ igbimọ ninu, koda wọn gbiyanju lati pa ọrọ ọhun mọ ọ lẹnu.
Amọ inu wa dun lati fi too yin leti pe ina ti de pada ni agbegbe Maryland ati Ilupeju ti yoo si de pada diẹdiẹ sawọn apa ibi to ku."
Kí ló fàá tí owó oṣù tuntun fi ṣòro?
Adájọ́ tó ń gbọ́ ẹjọ́ náà, Halima Salman mú Ìgbẹ́jọ́ náà wá sí òpin lẹ́yìn wákàtí méje tí ilé ẹjọ́ náà fí ọ̀rọ̀ wá afurasí náà lẹ́nu wò.
Abubakar to jawe olubori laipẹ yii gẹgẹ bi aṣoju ẹgbẹ PDP fun idibo aarẹ ti yoo waye ni Naijiria l'ọdun 2019, lo ṣeeṣe ko bẹ Ọbasanjọ wo pẹlu ireti pe yoo ṣe atilẹyin fun erongba rẹ lati di aarẹ orilẹede Naijiria.
Eeyan mẹrinlelọọdunrun lo ti lugbadi arun Coronavirus lorilẹede ọhun.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ounje aarọ re e ni Ilẹ Gẹẹsi.
Awọn eeyan kan bii @yjpictures, @Wande_SHO, @lgc_pacman, @iam_ABC12 atawọn miran woye pe ṣe kamẹra naa ni ogun asọ ina di omi ni tabi ayẹta to fi jẹ wipe gbogbo bi wọn ṣe dana sun ibudo igbowo ode naa ina ko kan an rara.
Àwọn ǹkan tí yóò t'ẹyin kíkógbá iléeṣẹ́ tó n sójú Nàìjíríà nílẹ̀ láwọn orílè-èdè márùn
Àwọn wo ni Krìstẹ́ní Coptic tó ń ṣe Kérésìmesi ní January 7?
Ninu osu Kinni odun 1996 ,o daari ifipagbajoba lakoko to fesun kan adari orile-ede naa Ogagun Valentine Strasser wi pe o ko lati gbe ijoba fun awon oloselu ti won dibo yan.
Iwadii fihan pe o ni eroja ifẹ ti wọn npe ni Phenylethylamine (PEA).
"Nigba ti wọn bere orukọ igbakeji kọmisọna naa, alukoro ọlọpaa ni nkan ṣoiṣo ti oun gbọ ni pe wọn ṣa a lada; ""mi o mọ orukọ rẹ, iwadii kikun yoo si bẹrẹ laipẹ""."
Ogun apakokoro (Insecticide) Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Fifin oorun awọn ogun apakoro paapa ju ti ẹfọn ninu ile le sakoba fun ara Lai pẹ yii la gbọ iroyin bi awọn ọmọ mẹta kan ṣe di ero ọrun lẹyin ti iya wọn fin ogun apẹfọn sile.
Ọjọ ọhun tun jẹ ọjọ isinmi lorilẹ-ede Naijiria ati ni awọn orilẹ-ede miran lagbaye.
O ni bo se wáyé rèé láyé ìjọba Abiola Ajimobi to koja, to fi dé Ekiti àti Osun, ìdí sì rèé tí Ajimobi fi fà Fẹlẹ silẹ bíi alaga NURTW láyé ijoba rẹ.
O salaye pe, ijoba ti bere ayewo awon ile-ise ijoba ati awon eka won, ni eyi ti a o se amulo awon eka to ti wa nile tele, titi di igba ti atunto ohun yoo fi pari.
Àwọn ìlú tó darapọ mọ ogún ìjàyè:Bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé ìlú ìjàyè, Ọ̀yọ́ àti Ibadan lo dojú kọ ara wọn lórí ogun náà, tó wáyé laarin Ààrẹ Kurunmi tí ìjàyè àti Balogun Ibikunle pẹ̀lú Basọrun Ogunmola tí ìlú Ibadan; síbẹ̀ àwọn ìlú miran nilẹ Yoruba naa darapọ mọ ogun ìjàyè nítorí onírúurú ìdí.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Sotitobire: Adájọ́ dá Pásítọ̀ Alfa Babatunde padà s'ẹ́wọ̀n fún ọjọ́ mọ́kàndílógún Njẹ́ ẹ mọ̀ pé orílẹ̀-èdè Nàìjíríà ló n wo 'Blue film' jù?
Agbẹnusọ fun ileeṣẹ Amerika, Morgan Ortagus lo ṣo eyi di mimọ ninu atẹjade to fi sita ni Washington lorilẹ-ede Amerika.
Òṣìṣẹ́ Àjọ Ìlú kan ti sọ wípé yóò tó ọ̀sẹ̀ mélòó kan kí egbògi ìdáààbòbò tí yó sì dín ẹ̀fọn kù.
Ṣugbọn bí ìkòkò amọ̀ ni àwa tí ìṣúra yìí wà ninu wa rí, kí ó lè hàn gbangba pé Ọlọrun ni ó ní agbára tí ó tóbi jùlọ, kì í ṣe àwa.
Bakan naa, ni aare tun so pee to lati di ise ati osi ku ti awon gunle yoo mu igbe aye iderun ba awon ara ilu.
Lasiko abewo re naa, yoo tun se ipade pelu asoju orile-ede America ati awon nnkan miiran ti o je mo oro orile-ede America.
sise atilẹyin fun awọn ọlọtẹ nipa owo iranwọ to n fun wọn.
Coronavirus ti tú àṣírí gbogbo pásítọ̀ àti àlfáà fáyérí-Akeugbagold Ìdì abájọ mẹ́ta táwọn arẹwà fi ń gba ti Aláàfin Olori awọn oṣiṣẹ nileeṣẹ aarẹ tun dupẹ lọwọ Eleduwa fun anfaani lati sin orilẹede Naijiria.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Hakeem: Idán inú eré sinimá ti gbàràdá ní Nàìjíríà Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Hakeem: Idán inú eré sinimá ti gbàràdá ní Nàìjíríà 10 Ìgbé 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 14 Ìgbé 2020 Hakeem Onilogbo to jẹ gbajugbaja apidan lori sinima ni òun ti wa lẹnu iṣe yii lọjọ tó ti pẹ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Alaafin: Ọ̀sán ọjọ́ Àìkú ní Ọba Adeyemi gbalejo Kayode Fayemi 15 Ẹrẹ̀nà 2020 Oríṣun àwòrán, @ekitistategov Yoruba ni baba ba sẹ ọmọ, ọmọ ni yoo bẹ baba, bi ọmọ si sẹ baba, ọmọ naa ni yoo bẹ baba, nitori agba ni agba yoo maa jẹ.
Ohun ni aarẹ to dẹkun ogun abẹle to waye lorilẹede naa lọdun 2002.
Ọrọ aarin mọlẹbi leleyii to ṣẹlẹ a si ti n yanjuẹ laarin agbo ile.
Jẹ́ olõtọ́ àti alãpọn ní pípa àwọn òfin Ọlọ́run mọ́, èmi yíò sì yí ọ ká pẹ̀lú apá ìfẹ́ mi.
Ṣugbọn ajá kò tilẹ̀ ní gbó ẹnikẹ́ni tabi ẹran ọ̀sìn kan, jákèjádò ààrin àwọn ọmọ Israẹli; kí ẹ lè mọ̀ pé OLUWA fi ìyàtọ̀ sí ààrin àwọn ará Ijipti ati àwọn ọmọ Israẹli.
Minisita ohun wa n ro awon ti oro kan lati fowosoeo po pelu ijoba ni iyanu ati se aseyori erongba naa.
Ìlú kò mọ ohunkóhun nípa iṣẹlẹ màálù tó kú nilu Ikarẹ- Oba Olukarẹ Ondo: Dejí sun ọmọ méje àtagbalagba meji mọ́lé nítorí pé ó ń bínú Tẹgbọn-taburo se igbeyawo ni Anambra Ti ibọn ba ba a ni ẹsẹ, to ba gba ibẹ ku, ko buru.
Kehinde sọ fun awọn ọlọpaa pe adari ijọ ni oun ni ile ijọsin Cornerstone Reformation Ministries, ṣugbọn awọn ọlọpaa ni o jọ pe ofege ni ọrọ rẹ.
O tesiwaju pe, o ti yẹ ki awon osise orile ede Naijiria ti maa
Nítorí pé òkùnkùn yí mi ká,òkùnkùn biribiri sì ṣú bò mí lójú.
Awakọ èrò - BBC News Yorùbá BBC News, YorùbáFò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Oyo drivers'crisis: Auxiliary ń ní wá lára pẹ̀lú gbígba owó aitọ, a ń ko ọkọ̀ wa kúrò lójú pópó - Awakọ èrò 11 Ìgbé 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 6 Èbibi 2020 Oríṣun àwòrán, others Àwọn awakọ èrò kan tó ń ná àdúgbò Bẹẹrẹ si Omi-Adio n'ilu Ibadan tí fi igbe ta pé, àwọn kó ni ṣiṣẹ mọ, tí àwọn si n kó ọkọ àwọn kúrò lójú pópó nítorí owó aitọ táwọn alakoso gareji ọkọ ńi kí àwọn máa san.
Èmi Ọba tí wọ́n ń kó jẹ nígboro- Oluwo ti ilú Iwo Nǹkan mẹ́sàn án tí Mùsùlùmí gbọdọ̀ ṣe nínú oṣù Dhual- Hijjah Wo bí ètò ìsìnkú Tolulope Arotile ṣe lọ nílùú Abuja Donald Trump ti gbà pé Coronavirus yóò burú jáì kí ǹkan tó dára fún Amẹ́ríkà Ṣé lóòtọ́ ni pé Hushpuppi ti kúrò ní ọgbà ẹ̀wọ̀n l'America?
Ile igbimo asoju ti ilu Abuja ti
Má jẹ́ kí ìgbì omi bò mí mọ́lẹ̀,kí ibú omi má gbé mi mì,kí isà òkú má sì padé mọ́ mi.
Hemani ati Jedutuni ní fèrè, aro, ati àwọn ohun èlò ìkọrin mìíràn tí wọ́n fi ń kọrin ìyìn.
Laipẹ ni wọn ṣẹṣẹ tu ọjọgbọn ile iwe giga fasiti Obafemi Awolowo, Ile-Ifẹ ni ipinlẹ Oṣun silẹ lẹyin owo itanra gọbọi ti a gbo pe wọn san.
Ariwo tí wọn ń pa pọ̀ tó bẹ́ẹ̀ tí ilẹ̀ fi mì tìtì.
Bi a ba ṣafiwe paapa julọ lawọn orileede to wa ni Afrika ati Asia iye ti Huawei n ta ọja wọn si ti eyi to n wa lati Amerika tabi Yuroopu,iku ko ṣe fi we oorun lọrọ awọn mejeeji.
Papa iṣere Parc Olympique Lyonnais ti wọn tun n pe ni Groupama ni wọn yoo ti gba aṣekagba.
Oríṣun àwòrán, Hushpuppi/Instagram Ifedayo Olarinde a.
Oríṣun àwòrán, @aishambuhari Àkọlé àwòrán, Aisha Buhari ni o wu ohun lati pe gbogbo awọn to dibofun Aarẹ Buhari wa si ibi apejẹ naa Oríṣun àwòrán, @aishambuhari Àkọlé àwòrán, Iyawo Igbakeji Aarẹ Dolapo Osinbajo wa nibi ayẹyẹ naa Oríṣun àwòrán, @aishambuhari Àkọlé àwòrán, Aisha ba awọn ọdọkunrin ya aworan nibi ayẹyẹ naa Oríṣun àwòrán, @aishambuhari Àkọlé àwòrán, Awọn oṣere tiatia Yoruba naa ko gbẹyin Oríṣun àwòrán, @aishambuhari Àkọlé àwòrán, Oga Bello,Jide Kosoko ati Ebun Oloyede naa peju sibẹ Oríṣun àwòrán, @aishambuhari Àkọlé àwòrán, Oju tiyin emi ni Aisha bibo fun un o !
se lati pada sinu iwa ibi ti a ti kọ sile lasiko aawẹ, nitori eleyii yoo tun ba
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Lásìkò ààwẹ, ara rẹ yóò kọ́kọ́ sàmúlò súgà inu ẹjẹ rẹ láti fún ẹdọ ni àgbara to nilo.
O ma n dena ki ọkunrin tete dà àtọ lasiko ibalopọ, to si ma n din iṣoro ki ọkunrin o ma le ṣe ku.
Odiwọn iye owo gbogbo nkan to ji jẹ ẹgbẹrun mejidinlogun o le ni irinwo ati ọgbọn naira (18, 430 naira).
A mọ sá, ọ̀kan nínú àwọn arìnrìnajò láti ilẹ̀ gẹ̀ẹ́sì to ba BBC Yoruba sàlàyé pe bi ìjọba ṣe n ṣe awọn ko bá ojúmu rárá.
’ Bakan naa ni awọn ẹbi naa wa kesi Gbade Ojo lati sọra nipa ọrọ ẹnu rẹ, nitori pe ko si ẹni ti ko ni ku.
Wọ́n gbéra láti ibẹ̀, wọ́n lọ sí Gudigoda.
Láti apá kan ojú ọ̀run ni ó ti ń yọ wá,a máa yípo gbogbo ojú ọ̀run dé apá keji;kò sì sí ohun tí ó bọ́ lọ́wọ́ ooru rẹ̀.
Ekinni sọ fún un pé, ‘Mo ra ilẹ̀ kan, mo sì níláti lọ wò ó.
Àgọ́ ti àwọn ará Filistia wà ní Mikimaṣi.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Jide Kosọkọ: Isẹ́ tíátà yóò gòkè tíjọba bá gbówó kalẹ̀ láti seré Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Wọn fikun wi pe awọn ko ṣe ikọlu si ile iṣẹ iroyin naa lati pa wọn le nu mọ, amọ lati ṣe iwadii bi wọn ṣe ri awọn iroyin ti ko yẹ ko jade sita naa.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù African Drum Festival 2019: Orílẹ̀èdè 23 ló kópa níbi àjọ̀dún ìlù ọdún 2019 26 Ìgbé 2019 Ni aye atijọ, awọn ìlú nilẹ Yoruba ati kaakiri ilẹ Afrika maa n lo ìlù lati ba ara wọn sọrọ.
Wọ́n gbógun tì wọ́n, wọ́n run wọ́n patapata, wọ́n sì sọ ìlú náà ní Horima.
Agbẹnusọ awọn Igbimọ̣ Aṣofin Ipinlẹ Lorilẹ-ede Naijiria rọ awọn ọmọ
    Ìgbà tí o kù díẹ̀ gan-an kí a dé odò ẹ̀jẹ̀ tí à ń wo irin tẹ́ẹ́rẹ́ kan ṣoṣo tí ó dúró bí afá sí orí odó náà ni a tún rí ẹnìkan níwájú tí ó gbé àáké lọ́wọ́ ti o ń dúró de ni.
 kòkòrò àifójúrí dìgbòlugi maa ń lọsí ọpọlọ nípa àwọn ọ ̀ nà yíì ẹ ̀ yà ara bí ọpọlọ àti egungun ẹ ̀ hìn .
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Nigerians in Oman: Ààrẹ Buhari, ẹ̀yin gómìnà ìpínlẹ̀ Yorùbá, ẹ rántí wa ní Oman, àwọn ọmọ Nàìjíríà Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Nigerians in Oman: Ààrẹ Buhari, ẹ̀yin gómìnà ìpínlẹ̀ Yorùbá, ẹ rántí wa ní Oman, àwọn ọmọ Nàìjíríà 19 Agẹmo 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 20 Agẹmo 2020 'Ẹ gbà wá o, á ti há sí Oman, ẹ dákun ẹ wá kó wa jáde o'- Awọn ọmọ Naijiria to ha si Oman Oriṣiiriṣii ọrọ lo ti n jade lati igba ti BBC ti gbe iroyin yii soju opo rẹ pe awọn ọdọbinrin Naijiria n fẹ kuro ni Oman lasiko yii.
Alase ati oludari ajo to n mojuto ririsi amuye awon nnkan to n wo orile-ede Naijiria atawon nnkan ti a n se nile lati rii pe won koju osuwon to ye, Ogbeni Osita Aboloma ti kede pe ile ise ijoba apapo yii ti setan lati bere si ni n fi ofin amuye de gbendeke awon ohun eelo inu eto-ogbin.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Dòdò Ìkirè: Ó dúdú lára sùgbọ́n oyin ni lẹ́nu Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Dòdò Ìkirè: Ó dúdú lára sùgbọ́n oyin ni lẹ́nu 17 Ìgbé 2018 Dòdò Ìkirè jẹ́ ohun ìpanu pàtàkì nílẹ̀ Yorùba.
láti inú ìdílé Hemani: Jeueli ati Ṣimei; láti inú ìdílé Jedutuni: Ṣemaaya ati Usieli.
Òsìsẹ́ ilé-wòsàn Ondo: Gbogbo ìgbà ni alárùn ọpọlọ ń kọlù wàá
Eyi wa lara awọn ilana ti wọn fi lelẹ lati daabo bo awọn ti yoo kopa ninu ijọsin ọlọdọọdun nitori ajakalẹ Covid-19.
Nígbà náà ni àwọn eniyan mi yóo mọ̀ pé èmi OLUWA àwọn ọmọ ogun ni mo rán ọ sí wọn.
Wo bí èsi ìdìbò UK ṣe fi hàn pé Boris Johnson ń gbégbá orókè lọ́wọ́ Owó rèé, ọjà rèé: Aládùúgbò le kórajọ̀ láti ra iná ọba lọ́wọ́ GenCos tààrà Makinde kò gbé àjọ ìwà ìbàjẹ́ kalẹ̀ torí ìfẹ́ aráàlú, ó ń fẹjú mọ́ alátakò ni - Ọmọ ẹgbẹ́ APC Òṣìṣẹ́ INEC méjì yóò ṣẹ̀wọ̀n ọdún 21 nítorí owó ẹ̀yìn N362m Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Àwọn ọ̀jọ̀gbọ́n Yorùbá foríkorí gbé ìwé tó lè sọ ẹ̀yà ara yín lédè Yorùbá.
Wọ́n wá ń kọ orin titun kan, pé,“Ìwọ ni ó tọ́ sí láti gba ìwé náà,ati láti tú èdìdì ara rẹ̀.
Ẹ kọ ọ́ sí ara òpó ìlẹ̀kùn ilé yín ati sí ara ẹnu ọ̀nà àbájáde ilé yín.
Bi Naijiria ni ti o je okan gbogi lara awọn orilẹẹde ti karakata re munadoko nile Afrika ko se kopa je ipenija nla fun adehun naa.
Bo tilẹ jẹ wi pe awọn akẹkọọ ninu ọgba naa ko fẹ ki a gba ohun wọn silẹ, alaye wọn ni wi pe ki ijọba apapọ gbe igbesẹ ti o tọ lati rii daju wi pe rogbodiyan naa di ohun igbagbe.
 wàhálà máa ń fa ọ ̀ tẹ ̀ , ọ ̀ tẹ ̀ ń di ogun , ogun sì ń fa ikú àti fífi dúkàá sòfò .
Àṣé àgbọnrín ni, àwọn ẹranko ni ó ń rán an kí ó lọ máa ra ẹmuu fún wọn níi àkókò ìpàdé, wọn a sì máa fún un ní owó ni, wí pé, kí ó tóó jáde sí ìlú kí ó sọ ara rẹ̀ di ènìyàn kí ó sì ra ẹmu, ṣùgbọ́n dípò kí ó ṣe bẹ́ẹ̀ àgbọ̀nrín a fi owó sí àpò ara rẹ̀, a máa jí ẹmu ẹlẹ́muu káàkiri orí ọ̀pẹ a sì wáá máa sọ fún àwọn ẹranko pé rírà ni òun rà á.
Lójijì ìró kan dún láti ọ̀run, ó dàbí ìgbà tí afẹ́fẹ́ líle bá ń fẹ́, ó sì kún gbogbo inú ilé níbi tí wọ́n gbé jókòó.
m),ti iyawo  rẹ  Patience Jonathan naa si dibo ni aago mẹ́sán
Ro ohun tí o fẹ́ sọ dáradára,kí o sì múra láti wí àwíjàre.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Coronavirus in Nigeria: Amúgbálẹ́gbẹ́ Gómìnà SanwoOlu kó àrùn COVID-19 ràn án, àmọ́ wọ́n ní àrùn náà kò dá a wólẹ̀ 12 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 13 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Oríṣun àwòrán, Twitter/babajide sanwoOlu Ni ọjọ Abamẹta ni iroyin gbode pe gomina ipinlẹ Eko, Babajide SanwoOlu ti ko arun COVID-19.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Gbogbo igbiyanju Arsenal lati gbayo wọle Tottenham ni ipele keji ifẹsẹwọnsẹ ọhun, pabo lo ja si.
Elon Musk, Ọ̀gá àgbà iléeṣẹ́ SpaceX, Tesla CEO ń bá Bill Gates du ipò ẹni tó lówó jùlọ ṣèkejì lágbayé
Èémí ẹ̀ẹ̀kan ṣoṣo le tí láàrin àádọ́ta sí ẹgbẹ̀rún márùn-ún kòkòrò naa síta, ṣùgbọ́n kíá lo sábà máa jábọ́ sílẹ̀ Nítorí naa díẹ̀ nínú kòkòrò yii ni a o ríi tobba jáde láti ara èémí gẹ́gẹ́ bi àlàyé rẹ̀ fún BBC.
Àwọn ìròyìn mìíràn tí ẹ lè nífẹ̀ẹ́ sí: Asiri ibudo igbafẹ ẹranko ni Naijiria Akẹ́kọ̀ọ́ kan bá ìṣẹ̀lẹ̀ Unijos rìn Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Òkè Ìdànrè: Òkè tó kéré jùlọ jẹ́ ẹsẹ̀ bàtà 3000 Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Fídíò, Colorado ni Amẹrika àti Adò Awaye ní Naijiria nìkan ni àdágún órí àpáta ní gbogbo àgbáyé!
Ọmọdé tó ń ṣeré pẹ̀lú àdò olóró ló fa ìbúgbàmu Borno- Cameroon Ìwà ọ̀dàlẹ̀ ni bí ẹ kò bá gbé iléèwé ìkọ́ṣẹ́ olùkọ́ni kalẹ̀ sí ìlú Ìwó- Oluwo Wọ́n tẹ àádọ́ta olùdárò pa níbi ìsìnkú Qasem Soleimani tí kò wáyé mọ́ Àbọ̀ ìpàdé bòńkẹ́lẹ́ láàrin Tinubu àti Buhari rèé Lẹyin Naijiria lo kan orilẹ-ede Ghana, Kenya, Egypt, Morocco ati awọn miran lori atẹ naa.
Láti ibẹ̀, Dafidi lọ farapamọ́ sí Engedi.
Meta ninu awọn mọkanla to lọ lo jẹ fidihẹ ni wọn, pẹlu Guus Hidink, to was ni Chelsea fun ifẹsẹwọnṣẹ mẹtadinlọgbọn.
Tí àríwá àti gùsù aiyé kọ ara sóòrùn ní dọ́gba-dọ́gba, tí wakàtí ìmọ́lẹ̀ òòrùn àti òkùnkùn ṣì jẹ́ méjìlá gérégé.
OLUWA ti dìde láti ro ẹjọ́ tirẹ̀;ó ti múra tán láti dá àwọn eniyan rẹ̀ lẹ́jọ́
Ọjọ Satide ni awọn akẹkọọ lorilẹ-ede Naijiria, ati awọn mẹrin miran ni iwọ oorun ilẹ Afrika, Ghana, Liberia, Sierra Leone ati Gambia, pari idanwo WAEC ti ọdun 2020.
Lẹ́yìn tí Abimeleki kú, Tola ọmọ Pua, ọmọ Dodo, láti inú ẹ̀yà Isakari ni ó dìde tí ó sì gba Israẹli kalẹ̀.
Pasitọ Adeboye woye ọrọ yii lasiko iwaasu isin ọjọ isinmi, eyi to ṣe lori ayelujara.
 léhùn tí bàbá yìí kú tán , ni wón bá ń pe àdúgbò ibè ní ilé-ológbà .
Bakanna lo jẹ osise a wa aye fun ni si ẹka ilera.
" Ṣugbọn o fi kun un pe o yọ jo laarin ọjọ diẹ sira wọn lai ṣaisan ṣaaju.
Koda, owe kan wa, to jẹ mọ iwa ati ise Basọrun Gaa, eyi to ni ‘Boo laya koo ṣe ika, too ba ri iku Gaa, ko sootọ’, eyi to ṣe alaye nipa awọn iwa ika ti Basọrun Gaa hu lasiko to gbe ile aye.
Iná ńla sọ ní ọjà pákó Mushin Amu l'Eko!
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù 'Ohun tí àwọn adarí ilẹ̀ Europe fẹ́ jẹ ni wọ́n fi ń wá sí Nàìjíríà' 31 Ògún 2018 Oríṣun àwòrán, @FannyFacsar Adarí orílẹ̀èdè Germany, Angela Merkel ní Ilẹ̀ Germany àti Naijiria yóò fọwọ̀sowọ́pọ̀ lórí ọ̀rọ̀ ajé Olootu ijọba orileede Germany, Angela Merkel, ni o jẹ orileede oun logun lati pese awọn ilana to ba ofin mu fun awọn ọmọ Naijiria to fẹ ẹ rinrinajo lọ si orileede Germany.
Ìròyìn ayọ ni èyí jẹ́, ó sì tún dára fún àwọn tó bá fẹ́ gba abẹ́rẹ́ àjẹsára, nítori pé ó túmọ sí pé wọn le ri antibodies"" ti yóò mu ki ""T Cell le sàwári ààrun náà ""èyí dára""."
Ninu ilé kan náà ni kí ẹ máa gbé.
Bah N'Daw àti Assimi Goita di adarí tuntun láti tukọ̀ orílẹ̀-èdè Mali ní ọdún kan àti aàbọ̀ Wo àwọn ìlúmọ̀ọ́ká tó ṣe ìgbéyàwó ní ọdún 2020 yìí Ọ̀rọ̀ Soyinka àti Obasanjo papọ̀ lórí pé Buhari n ṣe ìpínyà Nàìjíríà Awọn akẹkọọ to wọle lọjọ Aje lawọn ileewe alakọbẹrẹ ati girama kan niluu Eko ko pọ rara.
Amọ, Kwankwanso naa lo fa ọwọ rẹ soke ni idibọ ọdun 2016.
Awọn sọọbu naa wa ni titipa ni awọn agbegbe wọnyii, ti awọn afẹhọnuhan naa si gbe tabili wọn, to fi mọ awọn ohun elo mii lati fi ṣe ifẹhọnuhan.
Awọn mejeeji wa n rawọ sawọn ẹlẹyinju aanu ọmọ orilẹede yii, lati dide iranwọ owo fun wọn ki wọn le pari ile wọn ti wọn n kọ lọwọ.
“Lẹ́yìn tí gbogbo àwọn ọkunrin tí wọ́n tó ogun-ún jà ti kú tán láàrin àwọn ọmọ Israẹli, 
Ṣaaju ni ileeṣẹ aarẹ ṣalaye pe awọn ọmọ orilẹede Naijiria yoo mọ boya ijọba apapọ yoo tẹsiwaju pẹlu eto naa ti o ti n da ọpọ awuyewuye silẹ, l'Ọjọru.
Ara rẹ̀ dàbí eyín erin tí ń dántí a fi òkúta safire bò.
Oríṣun àwòrán, @flysafariofficial Àkọlé àwòrán, South Africa: Oyún inú nínú ilé ìgbọ̀nsẹ ọkọ̀ bàálú tó fẹ rinrin àjò Ilé iṣẹ́ ọlọ́pàá ní ó jọ bi ẹni pé ẹnikan ń gbìyànjú láti ma jẹ ki ẹnikẹni mọ pé òún bímọ.
ni Fafiti ipinle Osun lọjọ Abamẹta ,niluu Osogbo.
Lati le fi ọrọ yi rinlẹ daada, Yakubu Nabena to jẹ igbakeji alukoro ẹgbẹ APC lapapọ naa n fi ọrọ sita loju opo Twiter Nabena ni ki awọn ọmọ ẹgbẹ APC ni Ekiti ma ṣe mikan nitori awọn ko mọ si iyọni kuro lẹgbẹ Gomina Fayemi ati awọn mii to n ja rain.
Kò séwu nínú ìdìbò tó ń bọ̀ l'Ondo àfi gìrì àparò- Akeredolu ‘Àwọn òlóṣèlú kò ní ìwà ọmọlúwàbí ló jẹ́ kí wọ́n má a lọ láti ẹgbẹ́ òṣèlú kan lọ sí òmìràn’ Òògùn ìtura dé fún Coronavirus!
Ìjọba yóò ti Afára Sagamu pa nítorí ìjàmbá iná- FRSC Ọkan ninu wọn to sọrọ pẹlu awọn akọroyin sọ pe ''Eeyan ki ṣe nkan ti eeyan ko to lati ṣe .
" Alufaa naa ni ki ọmọ Naijiria bu ọla fun ẹni ti ọla ba tọ si.
Òun sì dáhùn ó wí pé, ‘Kábíyèsí, èmi ni.
Aug 2018 ni ìgbìmọ̀ aláṣẹ APC ti ṣe ìpàdé kẹ́yìn, Oshiomole ti kùnà"" Òbítíbitì ẹ̀gbin ti sọ ìlú Ibadan di ààtàn - Aráàlú figbe bọnu Àwọn ẹni òkùnkùn ló já ìṣẹ́gun mi gbà, mò ń lọ sílé ẹjọ́ tó ga jùlọ - Bayo Adelabu Ọ̀pọ̀ àwòrán rèé tó ń sàfihàn bí Ibadan se kún fún ẹ̀gbin àti òórùn Nomba ọkọ akero naa ni Mazda KTU 93 XW ati bọọsi Toyota KEY 847 XA Ọga agba FRSC ipinlẹ Ogun, Clement Oladele ni ijamba naa jẹ eyi to bani ninu jẹ pupọ, o si ba ẹbi awọn to jẹ Ọlọrun nipe kẹdun."
O ni abere ajesara naa yoo waye lojo kejo si ogunjo osu keji odun yii pelu afojusun fifun eedegberin omo ti ojo ori won wa laarin osu mesan an si odun marun un.
Nítorí náà, ẹ̀yin ará mi olùfẹ́, ẹ dúró gbọningbọnin, láì yẹsẹ̀.
Ninu ere to ṣe ti wọn pe akọle rẹ ni Olaitan Sugar ni wọn ti bẹrẹ si ni pe e ni orukọ naa Bakan naa ni Gbajugbaja osere Bimbo Osin ko danikan waye o, nise lo mu Doris Simeon naa dani ni Ọjọ Kẹrinlelogun, ni Osu Keje.
Iṣọla Oyenusi rèé, ẹnití ìfẹ́ obìnrin ṣun dé ìwà ìdigunjalè Ẹfunroye Tinubu - Ògbóǹtagí oníṣòwò, olówò ẹrú àti afọbajẹ Samuel Ajayi Crowther, òjíṣẹ́ Ọlọ́run tó gbé èdè Yoruba lárugẹ Gẹgẹ bi alakalẹ ofin naa, Aarẹ laṣẹ lati yan adele alaga.
Àwọn méjì yìí fẹ́ràn ara wọn dé góńgó wọ́n sì ń fẹ́ láti fẹ́ ara wọn kí wọ́n di tọkọtaya.
Bi àwọn ènìyàn ṣe to láti ra asọ náà Aṣọ tó kọ́kọ́ dàlú rú lọdún 2018 ní jẹsí (jersey) ikọ̀ super Eagles ti wọn polongo títà rẹ̀ lọ́jọ́ kini, osù Kẹ́fà ọdún 2018.
Bí ẹ bá fẹ́ rí àwọn tí ó wọ aṣọ fẹ́lẹ́fẹ́lẹ́ olówó iyebíye, ẹ lọ sí ààfin ọba.
Nígbà tí a bá ń dá ẹjọ́ rẹ̀,jẹ́ kí wọn dá a lẹ́bi;kí ẹ̀bẹ̀ rẹ̀ di ọ̀ràn sí i lọ́rùn.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ibikunle Amosun: Owo adani ni'ṣẹ ẹran dida, ko kan ijọba Gomina Makinde rọ awọn alabaṣiṣẹpọ rẹ lati ṣe bakan naa Owo Zimbabwe: Ijọba gborukọ jade N13.
27 Bélú 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 3 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 5 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
"Ni ọdun 2017, wooli naa tun ni oun ko kabamọ pe oun ri ""iran"" yii."
OLUWA ní, “Edomu yóo sì di ibi àríbẹ̀rù, ẹ̀rù yóo máa ba gbogbo àwọn tí wọ́n bá gba ibẹ̀ kọjá, wọn yóo máa pòṣé nítorí ibi tí ó dé bá a.
Gbogbo àwọn ẹyẹ, àwọn ẹran ọ̀sìn ati àwọn ẹranko tí wọ́n bá yín jáde ninu ọkọ̀, 
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Sagay: olùdámọ̀ràn Buhari wọ gàu lórí ọ̀rọ̀ Adeosun 10 Ògún 2018 Oríṣun àwòrán, Twitter/Sagay Àkọlé àwòrán, Àwọn èèyàn sí ọ̀jọ̀gbọ́n Itse Sagay sọ lórí ẹ̀sùn ìwé ẹ̀rí mínísítà ètò ìnánwó Kemi Adeosun Ọpọ eeya lo ti bu ẹnu atẹ lu bi Itse Sagay to jẹ oludamọran pataki fun Aarẹ Muhammadu Buhari lori igbogu ti iwa ibajẹ ṣe sọ pe ki minisita fun eto inanwo maa ṣe fipo rẹ silẹ koda to ba jẹbi ẹsun ti wọn fi kan pe ko ni iwe ẹri agunbanirọ nigba ti o sọ fun Aarẹ ile Asofin Agba l'Abuja Bukola Saraki pe ko kọwe fipo silẹ.
Àwọn ni wọ́n la odò Jọdani kọjá ninu oṣù kinni, ní àkókò ìgbà tí ó kún bo bèbè rẹ̀, wọ́n sì ṣẹgun gbogbo àwọn tí wọ́n wà ní àfonífojì, ní apá ìhà ìlà oòrùn ati apá ìwọ̀ oòrùn.
 Àwọn ìpèle yìí náà ni fònẹ ́ tíìkì tàbí ètò ṣíṣàpèjúwe ìró , fonọ ́ lọ ́ jì tàbí ìbáṣepọ ̀ ìró ; sẹ ̀ méńtíìkì tabí èt ' o ìtumọ ̀ ; síntáàsì tàbí ètò tí ó dale gbólóhùn , àti mọfọ ́ lọ ́ jì tabí ètò nípa ṣíṣẹ ̀ dá ọ ̀ rọ ̀ .
“Nebukadinesari ọba Babiloni ti run Jerusalẹmu,ó ti tẹ̀ ẹ́ mọ́lẹ̀,ó ti sọ ọ́ di ohun èlò òfìfo,ó gbé e mì bí erinmi,ó ti kó gbogbo ohun àdídùn inú rẹ̀ jẹ ní àjẹrankùn,ó ti da ìyókù nù.
sẹlẹ ni ekun Ariwa, ni eyi ti o n mu ki ẹsẹ eto aabo ni ekun naa maa se
"Ko ni pẹ ẹ mọ"" lalaye to ṣe fun akọroyin wa."
"Oríṣun àwòrán, Oluwo ""Ile ifẹ ni mo ti gbade lọdọ iya mi, tori ọmọ alade ni mi nile Ifẹ, emi ko gba ade ni Ọyọ, ipinlẹ Ọyọ ni Alaafin wa, ko si lee maa gbe ade le Onikoyi to wa labẹ mi lori."
Awọn arinrinajo Hajj yoo bẹrẹ si sanwo ori 'Buhari wá sọ tẹnu ẹ' Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Zainab Aliyu: Mo sọkún títí, ojé tán lóju mi ni àhámọ Saudi Aarẹ pẹlu awọn oluranlọwọ pataki to jẹ tirẹ ni wọn yoo jọ kọwọ rin lọ ni ọjọbọ, ọjọ kẹrindinlogun oṣu karun.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Isẹlẹ Iran: Ijamba baalu pa eeyan 66 18 Èrèlè 2018 Oríṣun àwòrán, Konstantin von Wedelstaedt Àkọlé àwòrán, Kurukuru oju ọjọ sediwọ pupọ lati sawari ibi tisẹlẹ naa ti sẹlẹ Awọn osisẹ ileesẹ baalu kan lorilẹede Iran ti sọ wipe eeyan mẹrindinladọrin lo jẹ Ọlọrun nipe ninu baalu kan to jabọ l'orilẹede Iran.
Ahija, láti inú ẹ̀yà Lefi, ni ó ń bojútó àwọn ibi ìṣúra tí ó wà ninu ilé OLUWA ati ibi tí wọn ń kó àwọn ẹ̀bùn tí a yà sọ́tọ̀ fún Ọlọrun sí.
Ọrọ yii ni Kunle Afọlayan ba gbe si ita gbangba loju opo Instagram rẹ, eyi to bi Mike ninu.
Ileẹjọ giga l'Abuja ni ohun ti ṣe afikun igba ti Ọgbẹ Giadom yoo nipo adele alaga gbogbogbo APC pẹlu ọsẹ meji.
Ẹ wó iye àsìkò ti yóò gba ọkọ panapana kio to de ibi ti ina ti n jó Bawo ni ile iṣẹ Panapana to wa ṣe sun mọ ẹ to?
'Ọdún 2019 pẹ̀lú àwọn àsọtẹ́lẹ̀ tó kó lọ́wọ́ dé' Amọṣa ko daju pe idunnu to fi ẹsẹ rinlẹ ni eyi yoo jẹ nitori ASUU ti sọ laifọtape pe yatọ si pe awọn ko tii mọ si owo ti wọn ni ijọba apapọ gbe silẹ naa, owo naa, to ba jẹ lootọ jinna si ohun ti o so adehun to wa laaarin awọn ati ijọba apapọ rọ.
ó ní, “OLUWA Ọlọrun àwọn baba wa, ṣebí ìwọ ni Ọlọrun ọ̀run.
Orile ede Naijria wa lara orile ede ti  May fẹ kan si nile Afirika.
A ti gba oúnjẹ lẹ́nu yín, níṣojú yín,bẹ́ẹ̀ ni a gba ayọ̀ ati inú dídùn kúrò ní ilé Ọlọrun wa.
Kii ṣe igba akọkọ ree ti Ọgbẹni Job wa si ilẹ Afirika, o ti wa si orilẹede Togo nibẹrẹ ọdun yii ṣugbọn ko wọ iru aṣọ bayii nigba naa, kootu lo wọ.
títí tí n óo fi wá ààyè fún OLUWA,àní, tí n óo fi pèsè ibùgbé fún ìwọ Alágbára, Ọlọrun Jakọbu.
“Bákan náà, nígbà tí àwọn àjèjì, tí kì í ṣe ara àwọn ọmọ Israẹli, eniyan rẹ, bá ti ọ̀nà jíjìn wá, láti gbadura sí ìhà ilé yìí, nítorí orúkọ ńlá rẹ, ati iṣẹ́ ńlá, ati agbára rẹ, 
Igbesẹ tuntun yii ti ile ẹjọ Botswana gbe waye lẹyin ti orilẹede Kenya ni awọn ko ni yi ofin tiwọn pada lati jẹ ki ibalopọ akọs'abo ba ofin mu.
Ó sì tún npòòyì yí òòrùn po.
Minisita ohun jabo naa lasiko to n ba akoroyin ile-ise aare soro pe, aare ti sise lopolopo lati ibere saa re, bee si ni o leto si saa keji lati le tesiwaju ninu isejoba rere re ti o yan laayo fun orile-ede Naijiria.
a ma n pe ọrọ yii lowe o ma n laro ninu.
Ọjọ́ kẹta lọ́dọ̀ baba-Onírùngbọ̀n-Yẹ́úkẹ́ ẹni tí ń gbé ibi gegele òkúta
Lakotan, ẹgbẹ Shiite kẹdun pẹlu awọn ẹbi awọn to ku ninu ikọlu ọjọ Aje papaajulọ ẹbi ọga ọlọpaa ati oniroyin to ṣagbako iku ojiji ninu iṣẹlẹ ọhun.
Tacha tọrọ àforíjí, ó da gbogbo ẹ̀bi lé ara rẹ̀ lórí Osinbajọ ní Ọlọrun ṣetán láti mú Nàìjíríà d'élẹ̀ ìlérí, TUC ní Nàìjíríà ti kùnà lẹ́ni ọdún 59 Ilé ẹjọ́ kọ̀ láti tú Omoyele soworẹ sílẹ̀ Inú mí dùn bí ìpínlẹ̀ Ọyọ se setán láti bẹ̀rẹ̀ ilé-ìwé tí àwọn akẹkọ̀ọ́ ń gbé- Òbí Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ìdílé tí ọkọ da ọmọ síta tóríi ojú Búlùú tí wọ́n ní bá BBC sọ̀rọ̀ Gẹgẹ bi iroyin naa ti wi, Kaosara ati aburo rẹ wa lara awọn akẹkọọ mẹfa ti oludasilẹ ile ẹkọ naa, Harb fun ni ẹbun ẹkọ ọfẹ lọjọbọ lasiko ayẹyẹ opin ọdun.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù BBC 100 Women 2019: Wo ọmọ Nàíjíríà kan tó wà nínú wọn 16 Ọ̀wàrà 2019 Ileesẹ BBC ti si asọ loju awọn obinrin ọgọrun to lami laaka juls yika agbaye fun ọdun 2019.
45% lati odun 2015, nigba ti owon-gogo owo ori oja wale lati iko mejidinlogu to n o-le ninu ida ogorun 18.
Bíótilẹ̀jẹ́pé ànfàní mélòókan wà  nínú bí wọ́n ṣe kó wa pọ̀ yìí, àlébù tí nbẹ́ níbẹ̀ kò níye.
Mose bá wí fún Joṣua pé, “Yan àwọn akọni ọkunrin láàrin yín kí o sì jáde lọ láti bá àwọn ará Amaleki jagun lọ́la, n óo dúró ní orí òkè pẹlu ọ̀pá Ọlọrun ní ọwọ́ mi.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ethiopian Airlines crash: Èèyàn 157 dèrò ọ̀run nínú bàálú tó já 10 Ẹrẹ̀nà 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 11 Ẹrẹ̀nà 2019 Àkọlé àwòrán, Ajọ iṣọkan agbaye n ṣọfọ àwọn eniyan wọn to lọ Bayii, apero ajọ iṣọkan agbaye to yẹ kó bẹ̀rẹ̀ loni ti mọ iṣẹlẹ ijamba yii lára pupọ.
Ẹlòmíràn kò tiẹ̀ ní bìkítà nípa ìrun kíkí, wọ́n yóò sì wá pa ẹni tó ń kí irun.
Aare Muhammadu Buhari kan si alakoso ijoba orile ede Britain Theresa May, niluu London.
 “Gbogbo wa la mo erongba aare lati igba ti o ti gori alefa, afojusun re da lori ise akanse meta otooto, eto aabo, gbigbogun ti iwa ibajẹ ati mimu igberu ba eto oro aje, eleyi ti o si ti saseyori ninu ise akanse meteeta.
Bi akojọpọ esi ayẹwo tuntun naa ṣe lọ niyii: Lagos-230 Rivers-127 Delta-83 FCT-60 Oyo-51 Edo-31 Bayelsa-27 Kaduna-25 Plateau-13 Ondo-6 Nasarawa-3 Ekiti-2 Kano-2 Borno-1 Eeyan 667 tuntun mii ni ajọ NCDC kede pe o ni arun Coronavirus ni Naijiria lọjọ Ẹti.
O fi bọọlu silẹ fun Richarlison, to gba siwaju, to si paasi rẹ si Dominic Calvert-Lewin, ṣugbọn niṣe ni oun yi bọọlu roborobo lati ọna jijin.
kí wọ́n sọ fún Sedekaya pé OLUWA Ọlọrun Israẹli ní, “N óo gba àwọn ohun ìjà tí ó wà lọ́wọ́ yín, tí ẹ fi ń bá ọba Babiloni ati àwọn ará Kalidea tí wọn gbógun tì yín lẹ́yìn odi jà, n óo dá wọn pada sí ààrin ìlú, n óo sì dojú wọn kọ yín.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìtàn Mánigbàgbé: Àáró tó yẹ kí Lisabi gbà, ló fi bẹ ọ̀wẹ̀ láti kọlu Ìlàrí Ọlọyọ fún ìdáǹdè Ẹ́gbá 22 Bélú 2019 Oríṣun àwòrán, Others Àkọlé àwòrán, Ìtàn Mánigbàgbé: Àáró tó yẹ kí Lisabi gbà, ló fi bẹ ọ̀wẹ̀ láti kọlu Ìlàrí Ọlọyọ fún ìdáǹdè Ẹ́gbá Abẹokuta jẹ ilu to gbajumọ nilẹ Yoruba, a si mọ ilu naa bii ilu Ẹgba, ilu ta tẹdo labẹ Olumọ, ti wọn si maa n ki awọn ọmọ Ẹgba ni ọmọ Lisabi.
Jesu bá wí fún àwọn Juu tí ó gbà á gbọ́ pé, “Bí ẹ̀yin bá ṣe gẹ́gẹ́ bí ọ̀rọ̀ mi, ọmọ-ẹ̀yìn mi ni yín nítòótọ́; 
''Ṣugbọ̀n ijọba apapọ ati ipinlẹ ni ilana ọtọọtọ ti wọn yoo gbe e gba.
26 Bélú 2020 Elon Musk, Ọ̀gá àgbà iléeṣẹ́ SpaceX, Tesla CEO ń bá Bill Gates du ipò ẹni tó lówó jùlọ ṣèkejì lágbayé26 Bélú 2020 Ilé ẹjọ́ tú ìgbéyàwó ọdún mẹ́wàá ká nítorí ẹ̀sùn ìbálòpọ̀ ọlọ́jọ́ gbọọrọ àti òògùn owó26 Bélú 2020 Fídíò, Akọ́mọlédè àti Àṣà lórí BBC Yorùbá: Kọ́ síi nípa iṣẹ́ tí oúnjẹ ń ṣe lára níbí24 Bélú 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Umar bura pe igba akọkọ ti oun yoo hu iru iwa bẹẹ niyii ati pe iya baba oun lo ni hijab ati niqob ti oun wọ lọ ṣe iṣẹ ibi naa.
Opopona Mobolaji Bank Anthony ti ijọ COZA wa ni ipinlẹ Eko ni wọn pejọ pọ si fi n ṣe iwọde pe ko yẹ ki a gbọ iru eyi ninu ijọ Olorun.
Nígbà tí Dafidi kúrò ní Heburoni lọ sí Jerusalẹmu, ó fẹ́ àwọn obinrin mìíràn kún àwọn aya rẹ̀.
Oyeyẹmi fikun ọrọ rẹ pe awọn eniyan meji miran to farapa lasiko iṣẹlẹ ijinigbe naa ti n gba itọju nileewosan.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Hanan Buhari: Ìjọba ní Ọmọ Buhari lásẹ láti wọ bàálú Nigeria Air force 12 Sẹ́rẹ́ 2020 Oríṣun àwòrán, Hanan Buhari/Instagram Àkọlé àwòrán, Hanan Buhari ni àwọn ènìyàn rí tó ń bọ́lẹ̀ nínú ọkọ baalu ní Bauchi níbí tò ti lọ ya fọ́tọ̀.
- Iya Rainbow Mi ò fẹ́ dá sí ìjà Toyin ati Lizzy!
"Abiodun sọ pe ""Mo ti paṣẹ ki wọn ti gbogbo ibode to wọ ipinlẹ yii lati awọn nipinlẹ to yi wa ka ati awọn orilẹ-ede mii."
O sọ ninu iwe ifẹhonu han naa pe igbe ti ẹgbẹ PDP n pa pe ki aarẹ Buhari buwọlu atunto ofin eto idibo eleyi to fi aye kalẹ fun fifi esi ibo ransẹ pẹlu ẹrọ ayarabiaṣa ko koja wi pe wọn ṣe eru.
22 Owewe 2019 Láti Tunisia lọ si Zimbabwe ti a ti sìnkú Robert Mugabe títí lọ sí ọ̀dọ̀ ìyá ẹlẹ́ja àsun ni Kenya, ẹ fun ojú lóúnjẹ ayọ̀.
To si ki i ku ayẹyẹ ọjọ ibi.
Kò sì sí ọ̀kankan nínú yin tí mo dá lẹ́bi.
Ṣé o wà ninu ìgbìmọ̀ Ọlọrun?
O ku diẹ ki wọn ri i da pada wa sile ṣugbọn ijọba ilẹ Gẹẹsi ni ki baalu ti wọn fẹ fi ji i gbe ma gbera lẹyin ti wọn ri i nibi ti wọn di i sinu paali papọ mọ ẹru.
 Ìhun òkè ni ( 55 ) .
Àì pèsè ààbò tó múná dókò, èyí tó fà á tí alágbàtà rẹ̀ tí ìwádìí BBC ṣe àfihàn ojú rẹ̀ fi ráyè sálọ.
Labani lé Jakọbu bá níbi tí ó pàgọ́ rẹ̀ sí ní orí òkè náà, Labani ati àwọn ìbátan rẹ̀ sì pàgọ́ tiwọn sí agbègbè olókè Gileadi.
Awọn alaṣẹ ni ipinlẹ Eko, Ondo ati Oyo ti fi lede ọna ti wọn yoo gba lati sin awọn ile ijọsin pada ni ipinlẹ wọn.
Ọ́ ọ̀pọ̀ àwọn òṣèré tíátà sába máa n hùwà àìtọ́ kí wọn ba lé rí àwọn ènìyàn ra ọkọ àti àwọn ǹkan mèremère aye yìí fún wọ́n.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Buhari yọ adájọ́ àgbà Onnoghen, PDP so ìpolongo ìbo rọ̀ 25 Sẹ́rẹ́ 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 26 Sẹ́rẹ́ 2019 Oríṣun àwòrán, AsoRockVilla Àkọlé àwòrán, Aa Buhari yan Tanko Ibrahim lati dele de adajọ Onnoghen Ẹgbẹ oṣelu PDP ni awọn ti so ipolongo ibo wọn rọ̀ tori ipinnu Aarẹ Muhammadu Buhari lati jáwe gbélé ẹ lé Adajọ Agba Walter Onnoghen lọwọ.
se wa, ko ni si onisowo kankan ti yoo fi kun owo oja.
Owó tí aṣẹ́wó yóo gbà kò ju owó burẹdi lọ,ṣugbọn gbogbo ẹ̀mí rẹ ni alágbèrè yóo fi ọgbọ́n gbà.
Alhaji Razaq ni ìpàpara ni awakọ̀ náà fi bá iṣẹ́ rẹ̀ jẹ́ nítorí pé ó yẹ kí ó dúró de àwọn ti yoo gbé aṣọ ìdáàbò tó yẹ kí o wọ̀ wá, súgbọ́n ko fi àrà balẹ̀ Kíni ìlànà tó tọ́ láti gbé aláàrùn Covid-19 nílé wọn Nínú ọ̀rọ̀ rẹ̀, Kọmísọnà ní tí wọ́n ba ti pé ilé iṣẹ́ ètò ilera bẹ́ẹ̀, ọ̀dọ̀ ọ̀gá àgbà ni ìpè náà yóò dé sí ti yóò si pàsẹ fún àwọn to wà ni ìdí, ètò pàjáwìrì láti lọ́ṣe iṣẹ́ wọn.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Oluwo: Ẹ má gbé ẹ̀kú eégún 1960, tó ń rùn wọ ààfin mi 27 Èbibi 2018 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 12 Ògún 2018 Ilu Iwo, nipinlẹ Ọsun sọkutu wọwọ fun ajọyọ ọdun Egungun lọjọ Ẹti, eyi to jẹ arimaleelọ, awo pada sẹyin.
Ẹgbẹ́ Boko Haram pa àwọn òṣìṣẹ́ UN márùn ún tó wá ṣiṣẹ́ ìrànwọ́ ní Nàìjíríà Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Working religious women: Ẹ̀lẹ́hàá kìí ṣe ọ̀lẹ- Aminat Adegoke Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Ìjàpá ṣe ojú àánú, ṣùgbọ́n ó padà ṣe àdúrà ti ó gbà ni ọjọ́ ti Obo kò ṣe “Amin”, pé ọgbọ́n wà ninú ki èniyàn mã ṣe “Àmin” si àdúrà àwọn àgbà.
Nwachukwu ni òun kò tí rí i gbọ́ pé ọmọ ogun Nàìjíríà kankan kú níbi ìjà nàá.
Lati igba naa ni ọlọpaa ti bẹrẹ si ni wa arakunrin yii titi ti ọwọ fi wa tẹ ẹ bayi.
Lojọru ni wọn ti n duro de aarẹ wọn lasiko isinku awọn panapana.
Ẹ̀rù ńlá ba gbogbo àwọn aládùúgbò wọn.
Olajide wa gba Aarẹ nimọran pe o yẹ ki atunto de ba bi ijọba Naijiria ṣe n lọ, ki alaafia le jọba.
Oríṣun àwòrán, @Abdulrazak Abdulrahman Awọn iyoku ni Asofin Abdulrasak Atunwa, ti ẹgbẹ oṣelu PDP, ati Ọmọwe Abdulmunin Yinka Ajia, ti ẹgbé oṣelu ANRP.
egbe oselu APC yoo lo anfaani ohun fi si aso ipolongo idibo nipinle Akwa Ibom,
Eyi ti mu ki gbogbo awọn ọmọ ile atawọn oṣiṣẹ lọ ṣe ayẹwo Covid-19.
"Wabba ní ""Ẹgbẹ́ òṣìṣẹ́ yóò ri dájú pé ohunkóhun kò pagidínà àsìkò tí ìgbìmọ̀ tó wà fún ètò owó oṣù ní Nàìjíríà ti là kalẹ̀."
Iye ti wọn n ta ipapanu Pizza lorilẹede Naijiria wa laaarin ẹgbẹrun meji naira si ẹgbẹrun mẹrin naira.
Awọn ọmọ ẹgbẹ Republican to jẹ ti aarẹ Trump naa, ni inu wọn ko dun si bibu ẹnu atẹ lu aarẹ ọhun nibi ipade apero ẹgbẹ awọn Democrats.
Ìwọ ni asà mi,má fi mí sílẹ̀ láìní ààbò.
 How much of our money is he still safekeeping for us?
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ikogosi-Ekiti: Ilu ti omi tutu ti dapọ mọ gbigbona Lucky Igbinedion: Gomina ipinlẹ Edo tẹlẹ, Lucky Igbinedion ni Gomina akọkọ ti yoo ri pipọn oju ofin fun kiko owo ilu jẹ.
Nígbà tó yá, mo bá tún dìde, mò ń bá iṣẹ́ tí ọba yàn mí sí lọ, ṣugbọn ìran náà dẹ́rù bà mí, kò sì yé mi.
Awọ ewurẹ ni wọn maa n lo lati ṣe, ọwọ ni wọn n lo lati lu pẹlu, yatọ si gangan ti wọn lo gọngọ fun.
Àti àwọn ìbéèrè míràn Coronavirus: Kíni àwọn àmì tuntun tó n fihàn?
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Murombedzi ni wọn gbe oku aarẹ Robert Mugabe lọ si itẹ.
Sibẹsibẹ, lọ́dọ̀ ọkọ rẹ ni ìfẹ́ rẹ yóo máa fà sí,òun ni yóo sì máa ṣe olórí rẹ.
Ọwọ́ ọlọ́pàá tẹ afurasí ọkùnrin tó gé akẹ́kọ̀ọ́ ọ̀rẹ́bìnrin rẹ̀ wẹ́lẹ́ wẹ́lẹ́ fún òògùn owó ní Ikorodu Ilé ìjọsìn lè bẹ̀rẹ̀ ìsìn àárín ọ̀sẹ̀ padà, Mọ́sáláṣí àti Ṣọ́ọ̀ṣì lé gba iye èèyàn tó wù wọ́n ṣùgbọ́n.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Adewale Ayuba: Ogun ń ja àgbo Fújì, ni wọ́n ṣe ń jà 7 Òkùdu 2019 Oríṣun àwòrán, @officialayuba Ilumọọka olorin Fuji, to jẹ odu, ti kii se aimọ fun oloko, Ọmọwe Adewale Ayuba ti woye pe, ogun lo n ja awọn olorin to wa ni agbo ile Fuji lo sokunfa ede aiyede ati ariyanjiyan to n waye lori ẹni to da orin Fuji silẹ atawọn aawọ miran.
Ti àkọ́kọ́ ṣẹlẹ̀ nigbati wọn fi ibọn lé àwọn Òṣèlú àkọ́kọ́ lẹhin òmìnira kúrò ni ọjọ́ karùndinlógún, oṣù kini ọdún Ẹdẹgbaalemẹrindinlaadọrin.
Márosẹ̀ Eko sí Ibadan àti Ibadan sí Eko dí pa fún ṣúnkẹrẹ́-fàkẹrẹ ọkọ̀ Àwọn omidan Naijiria ni wọ́n fi ń ṣerú ní Lebanon- Ọmọlọla Bí ìtàn ayé Toyosi Arigbabuwo ṣe lọ rèé láti ẹnu Musiliu Dasofunjo àti Ogun Majek Falae fikun ọrọ rẹ pe laye ọjọ-un, ilu kọọkan lo ni ọlọpaa tirẹ, o ni ofin wa fun igbayegbadun awọn ilu ni kii ṣe pe awọn araalu lo wa fun ofin.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: ‘Buhari gbà wá o, Seyi Makinde n fi jàǹdùkú halẹ̀ mọ́ wa láti kúrò lọ́ọ́fìsì’ Lẹ́yìn-ọ̀-rẹyìn, bàbá ọgọ́rùn-ún ọdún gba ìdáǹdè l‘ẹ́wọ̀n Ẹ dákẹ́ àhesọ ọ̀rọ̀, n kò bí ìbẹta - Yinka Ayefẹlẹ Ọba Adesoji Aderemi, Ọọ̀ni Ifẹ̀ tó gba ipò ọba mọ́ tòṣèlú Ẹ wo fídíò to ti sọrọ naa lori akanse eto BBC Yoruba nibi: O fikun pe bi awọn olorin to n kọ Fuji se n lo ohun to kẹ bii tawọn ọmọ isọta, ko sọ pe ọmọ buruku ni wọn, amọ ohun ti wọn fi n sọrọ tabi kọrin lo mu kawọn eeyan maa fi wọn we ọmọ onimọto.
Asuquo ti ko riran, lo so eyi di mimo nigba ti INEC n se ipolongo ni fafiti Abuja lati fi sami ayajo ojo Yuroopu todun 2018.
Eid-Al-Fitr: ìjọba Nàìjíríà ti kéde ìsinmi lọ́jọ́ Ìṣẹ́gun àti Ọjọ́rú
Ọpọ ọdọ South Africa to ni aisan ni ko ṣe ayẹwo ohun to n ṣe wọn pato.
Ileeṣẹ Privacy International to wa nilu ọba lo ṣe iwadii lori awọn oun kan, lori ẹrọ ayelujara ti o ma n ṣe atọka igba ti obirin yoo ṣe nkan oṣu.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Abìjà: Bàbá mi fi iṣẹ́ ọdẹ ti ń pa lémi lọ́wọ́ ni nítorí babaláwo ni O ni kii ṣe imọ oun nikan bikoṣe pẹlu aṣẹ Alaafin ati Ọyọmesi, oun si tun fi to Ọọni ile Ifẹ pẹlu leti.
Lẹhin awọn iro ibọn akọkọ yi, a ko gbọ nnkan kan mọ, o sọrọ.
9 4,744 French Polynesia 126 45.
Lẹ́yìn náà, bí ó ti ń gbadura, ọ̀run ṣí sílẹ̀.
Ẹni to bori: Tanzania Côte d'Ivoire vs Ghana.
Ohun tí ń mú ìparun bá wọn nìyí.
Lawal sọ pe, oun ko deede gba owo naa.
Babajide ṣe àwọn ìlérí yìí lásìkò to sàbẹ̀wò sí olú ilé iṣẹ́ ọlọ́pàá ní ìlú Ikeja láti báwọn sọ̀rọ̀ ìwúrí.
Ọlọrun da wa ni laigbọ aroye ẹnikẹni, yoo si mu koowa lọ nigba to ba wuu.
Fun apẹẹrẹ, ni ipinlẹ Benue, awọn kristẹni lo pọ ju pẹlu bi ida mejidinlọgọrun ninu ọgọrun awọn eeyan to n gbe ni bẹ, bakanna ni ipinlẹ Taraba bi ida aadọrun ninu ọgọrun awọn eeyan to n gbe ipinlẹ yii ni wọn jẹ Kristẹni nitori asiko ree fun gbogbo wa lati parapọ fi ohun sọkan klori awọn nkan ti o n sẹlẹ ti a ko faramọ.
Lẹ́yìn tí èyí wáye ní wọ́n ni àwọn ọdọ́ Delta náà yin ọlọ́pàá míràn níbọ̀n níbẹ̀ pẹ̀lú.
 Àkóràn àrùn náà kò ní ààmì àìsàn kankan lára marundinlaadọrun nínú ọgọrun ( 85 % ) àwọn ènìyàn tó ti ní àrùn náà , pàápàá bí iye àwọn aràn náà bá kèrè .
Oríṣun àwòrán, Paradisenews O ni isẹlẹ naa waye mọjumọ ọjọ Ẹti oni, ti Ọba awọn si wa lẹsẹ kan aye, ẹsẹ kan ọrun.
Trump: Bí wọn se ń pa Kristiẹ́ni kò jẹ́ ìtẹ́wọ́gbà
Gbogbo orí yín jẹ́ kìkìdá egbò,gbogbo ọkàn yín sì rẹ̀wẹ̀sì.
Bakan naa, ni igbakeji aare ana lorile ede  Naijiria ,Atiku Abubakar fe  jide fun ipo aare.
Àwọn ọmọ Noa tí wọ́n jáde ninu ọkọ̀ ni: Ṣemu, Hamu ati Jafẹti.
O wa rọ gbogbo awọn akọwe agba atawọn adari ẹka ileeṣẹ ijọba lati sọ fawọn oṣiṣẹ to wa labẹ wọn pe ki wọn rii pe awọn oṣiṣẹ lọ sibi iṣẹ lọjọ Aje to n bọ.
O ni wọn ko fún Ogundipe láàyè láti sọ tẹnu rẹ̀, bákan náà ni wan ko láti tẹ̀lé ìlànà tí o yẹ kí wọ́n tó gbé irú ìgbẹ́sẹ̀ bẹ́ẹ̀ niru iṣẹlẹ fasiti nla bii ti Eko yii.
Bí ẹ bá ṣe làálàá láti fún ẹni tí ebi ń pa ní oúnjẹ,tí ẹ sì wá ọ̀nà ìtẹ́lọ́rùn fún ẹni tí ìyà ń jẹ,ìmọ́lẹ̀ yín yóo tàn ninu òkùnkùn,òkùnkùn biribiri yín yóo dàbí ọ̀sán.
Àwọn jíjẹ-oyè-àlùfáà wọ̀nyìí jẹ́, ni tòótọ́, ìmúpadàbọ̀-sípò àṣẹ àtọ̀runwá fún ènìyàn lórí ilẹ̀ ayé.
Gbogbo ẹyin tẹ jẹ baba wa, tẹ wa lọ fi wa gba owo, gbogbo ẹyin tẹ jẹ ẹgbọn wa, ẹ salọ, o yẹ kẹ ronu ẹyin Yoruba, sugbọn awa fidi rẹ mulẹ pe, ọmọ ọkọ lawa.
“Bẹ́ẹ̀ ni Baba mi ọ̀run yóo ṣe si yín bí ẹnìkọ̀ọ̀kan yín kò bá fi tọkàntọkàn dáríjì arakunrin rẹ̀.
Bá àwọn ẹranko ẹ̀dá tí ń gbé inú èèsún ní Ijipti wí;àwọn akọ mààlúù, láàrin agbo ẹran àwọn orílẹ̀-èdè.
Ìfibú ni ibinu wọn, nítorí pé ó le,ati ìrúnú wọn, nítorí ìkà ni wọ́n.
"Owo osu ọna meji ko lẹtọ Èrò ṣe ọ̀tọ̀ọ̀tọ̀ lóri yíyára sàn owó oṣù òṣìṣẹ́ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Onídájọ́ Fọlahanmi Oloyede léwájú ìwọ́de òṣìṣẹ́fẹ̀yìntì fún ọjọ́ mẹ́ta l'Ọ́ṣun ""Lọwọlọwọ, miliọnu mẹsan awọn to n dawo la ni ṣugbọn a ni iṣẹlẹ awọn eeyan to ni nọmba aṣiri to pe oriṣiriṣi""."
Kí ló dé tí Ilé ẹjọ́ sún ìgbẹ́jọ́ Naira Marley sí ọ̀la?
Iyansẹlodi naa wa ni ibamu pẹlu asẹ ti awọn olori ẹgbẹ osisẹ pa ki awọn osisẹ bẹrẹ iyansẹlodi ọlọjọ meta ọhun.
America yóò tutù ju bó ti yẹ lọ Jẹ́ kí a jọ sọ àǹfàní US fún Nàìjíríà -Osinbajo Wọn ṣi aworan Obama ati Michelle Titi di asiko yii, ilẹ Amerika ko tii gbe orukọ àwọn ti ọrọ naa kan sita fun araye lati ri.
Bẹ́ẹ̀ ni igi náà ga tó bẹ́ẹ̀ ara rẹ̀ sì dán tó bẹ́ẹ̀ tí kò sí ẹni tí ó lè sọ̀kalẹ̀ fún ara rẹ̀ rárá.
Mò ń gbọ́ tí ọ̀pọ̀ eniyan ń sọ̀rọ̀ kẹ́lẹ́kẹ́lẹ́,bí wọ́n ti ń gbìmọ̀ pọ̀ nípa mi,tí wọ́n sì ń pète ati pa mí;wọ́n ń ṣẹ̀rù bà mí lọ́tùn-ún lósì.
Bakan naa ni wọn fikun wi pe ,ikọ Amọtẹkun ko ni koju wọn pẹlu ibọn, amọ awọn yoo lo ohun ija ibilẹ lati fi koju awọn Fulani Darandaran naa.
sọ pe Ramoni Abbas Igbalode, ti gbogbo eeyan mọ si Hushpuppi gbiyanju lati ji miliọnu mẹrinlelọgọfa Dọla lati ara Premier League.
“Bí àwọn ọmọ rẹ̀ bá kọ òfin mi sílẹ̀,tí wọn kò sì tẹ̀lé ìlànà mi,
Sibẹ ẹ̀rù kò ba ọba tabi àwọn iranṣẹ rẹ̀ tí wọ́n gbọ́ gbogbo ọ̀rọ̀ yìí, wọn kò sì fa aṣọ wọn ya.
 Ó tún se isé olùkó ní ìwé girama abeokuta , níbi tí ó to kó èkó àti èkó biology .
Ki onikaluku maa palẹmọ di iru ọjọ bayii ti ina a dilẹ̀ leyin asunṣujẹ.
Níwọ̀n bí ó ti jẹ́ pé ẹ kò fẹ́ nǹkan burúkú sími, mo fẹ́ kí ẹ ṣe ọ̀ràn mi yìí ní àṣepé, kí ọjọ́ náà kí ó lè dé, ti èmi àti èyin yóò wà bíi tọkọtaya.
Wọ́n rí i bí wọ́n ti jìnnà sí ibi tí àwọn ará Sidoni wà tó, ati pé wọn kò bá ẹnikẹ́ni da nǹkan pọ̀ ní gbogbo àyíká wọn.
Atiku, ninu ifọrọwanilẹnuwo kan pẹlu iwe iroyin ori ayelujara, African Reports, eyi ti oun paapa fidirẹ mulẹ l'oju òpó Twitter rẹ, sọ pe oun mọ bi Boko Haram ṣe bẹrẹ.
Ṣugbọn níwọ̀n ìgbà tí Ọlọrun ti yàn wọ́n nítorí àwọn baba-ńlá orílẹ̀-èdè wọn, wọ́n jẹ́ àyànfẹ́ rẹ̀ sibẹ.
Ẹnikẹ́ni tí ó bá pa ẹran ẹlẹ́ran, yóo san án pada.
O Fagunwa: Ó kó ipa sí àgbéga Yorùbá àmọ́ dúkìá rẹ̀ kò tó nkàn8 Bélú 2018 D.
Ọ̀rọ̀ tí OLUWA ti kọ́ sọ nípa Moabu tẹ́lẹ̀ nìyí.
Ijọba ipinlẹ Eko ti kede pe ki awọn ile ijọsin bẹrẹ isin aarin ọsẹ pada ni ipinlẹ naa.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Nigeria Borders open: Onímọ̀ ọrọ̀ ajé ní ìlànà tẹ́tẹ́ títa ní ìjọba ń lò fétò ọ̀rọ̀ ajé 16 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 17 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Oríṣun àwòrán, Getty Images Ọjọru ni ijọba orilẹ-ede Naijiria kede pe ki awọn ẹnu ibode mẹrin di ṣiṣi pada.
Iléeṣẹ́ Ọmọogun ní òun yóò bẹ́ 'speaker' lórí ìṣẹ̀lẹ̀ Lekki ṣùgbọ́n.
ipinle naa ,Loveth Odah lo fi idi eleyii mulẹ lasiko to n ba awon akoroyin soro
Odi Babiloni tí ó fẹ̀, yóo wó lulẹ̀,a óo sì dáná sun àwọn ẹnubodè rẹ̀ tí ó ga fíofío.
Wọn dajọ ẹwọn fun nitori ẹsun jibiti ati ole jija lori owo to ya nile ifowopamọ.
Bakan naa ni ile ẹjọ tun bere fun oniduro meji ti wọn gbọdọ ni dukia bi ile tabi ilẹ ni ilu Eko ti wọn si gbọdọ ni ẹri owo ori sisan fun ọdun mẹta sẹyin.
Awọn eeyan kan ti kọkọ ṣe ifẹhonuhan nileeṣẹ Ijọba niluu Ibadan l'Ọjọbọ pe awọn ko faramọ pe ki Seun Fakorode ẹni ọdun mẹtadinlọgbọn naa di kọmiṣọna.
nígbà tí ilẹ̀ bá gbẹ,tóbẹ́ẹ̀ tí ó dì, tí ó sì le koko?
"Sani Abacha tún gbé owó míì dé láti Ireland Ire ṣ'ọjọ́-ìbí, Mide àti ọkọ rẹ̀ lẹ̀pọ̀, Iyabo Ojo f'aṣọ ilẹ̀ Afirika dárà Èèkàn ẹgbẹ́ òṣèlú APC mií Lanre Razak jáde láyé lẹ́yìn àìsàn ráńpẹ́ Lai tẹsiwaju pe ""Ko si ohun to buru ninu ki a ya owo, niwọn igba to ba jẹ pe awọn ohun amayedẹrun la fẹ fi owo ọhun ṣe, paapaa to ba jẹ eyii ti yoo pese iṣẹ fun awọn eeyan, ti yoo gbe ọrọ aje wa soke."
Ààrẹ Muhammadu Buhari ti rọ àwọn ọmọ Nàìjíríà láti dìde nínú ìṣòkan ati ìfọwọ́sowọ́pọ̀, kí wọn si yàgò fún ìwà ẹlẹ́yàmẹ̀ya àti ìmọ tara ẹni níkan, kí orílẹ̀-èdè yìí báa lè 'd èbúté ògo.
Ìgbà tí a dé ibẹ̀ ńlá kan wà báyìí, orí àga yìí ni mo jókòó lé àwọn ènìyàn mi náà sì jókòó lé àga tí o tẹ̀lé tèmi.
O ṣalaye pe alaafia ni aafin wa ki awọn ọdọ naa to yawọ aafin.
Nítorí pé kì í ṣe láti ìlà oòrùn,tabi láti ìwọ̀ oòrùn,bẹ́ẹ̀ ni kì í sì í ṣe apá gúsù tabi àríwá ni ìgbéga tií wá.
Opolopo ise la ti se, lori eto idajọ, inu adari ijoba orile ede Britain si dun si eleyii.
To ba wa lati ita ni ọta ti wa wa nkọ, ki la maa kọ si wọn?
"Sẹ́nétọ̀ Dino Melaye kéde láti dupò gómìnà Kogi ""Họ́wù!"
Bi awọn kan ṣe n sọ nipa awọn ore to ti ṣe fun tile-toko, lawọn miran n sọ nipa awọn iwaasu manigbagbe to ti ṣe ati awọn to da lọla lori aga iwaasu.
Gẹgẹ bi awọn ọmọ ile iwe ṣe n mura ati wọle sẹnu ẹkọ wọn pada eyi to ja si pe awọn obi gaan ku igbaradi lati san owo ile iwe tuntun, o ru ifọrọwerọ jade lori ta lo yẹ ko maa san owo ile iwe.
Zaara fi ẹsun kan baba rẹ wi pe o ni oun yoo ko ile igbọnse ti oun ba se daradara ni ile iwe, amọ baba rẹ kọ, botilẹ jẹ pe ọmọ naa ti n gbe gba oroke tipẹtipẹ.
Aare Muhammadu Buhari ti ba awon ẹbi eniyan ti won padanu ẹmi ninu
Wọn ri iwa ti aarẹ Trump hu pẹlu bi o ti ṣe beere iranwọ lọdọ aarẹ Ukraine gẹgẹ bi aṣilo ipo fun imọtaraẹni nikan.
Aare soro ebe yii nipade to se pelu awon agbaagba ni Daura nipinle Katsina pe ko sigba ti ara ilu ko ni farada awon nnkan igbadun kan lati fi ni nnkan amayederun miran fun ojo iwaju.
    Nígbà tí mo bá a, ìbàǹtẹ́ nìkan ni ó sán mọ́ ìbàdí, òkú àgbọ̀nrín méjì ni mo sì bá níwájú rẹ̀ tí ó n jẹ wọn.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Èmi gan máa ń béèrè lọ́wọ́ ara mi pé ta ni Wole Soyinka gangan' Ogagun Abdulssalam Sani ṣalaye fun BBC pe awọn ọmọ ogun ofurufu tete dide iranwọ lasiko ikọlu yii ni kete ti wọn ri ipe pajawiri awọn ọmọ ogun ilẹ̀ Naijria gba.
idagbere fun asoju orile ede Equatorial Guinea, ogbeni Job Mbengono, nile aare
Manchester City gba fújà lọ́wọ́ Chelsea n'íbẹ̀rẹ̀ ọdún tuntun3 Sẹ́rẹ́ 2021 Ṣé Pochettino lè gba ife ẹ̀yẹ UEFA Champions League tí PSG ń wá fún wọn?
Ẹnikẹ́ni tí ó bá gbà mí, kì í ṣe èmi ni ó gbà, ṣugbọn ó gba ẹni tí ó rán mi wá sí ayé.
O ni aworan oun ati iyawo oun ti wọn lo lati fi kọ iroyin naa jẹ eyi ti awọn jọ ya ni ọdun meje sẹyin lasiko ikomọ ọmọ aburo oun nilu Ibadan.
Loju ẹsẹ ni wọn si bẹrẹ igbesẹ iwadi lori ọrọ naa gẹgẹ bi ọga awọn ọtẹlẹmuyẹ ṣe ti gun le iṣewadii.
Eyi ko tilẹ yọ awọn ọdọ silẹ.
Èèyàn mẹ́jọ míràn tún ti ní àrùn Coronavirus ní Naijiria Ajọ to n risi idẹkun itankalẹ arun lorilẹede Naijiria, NCDC ti kede pe eniyan mẹjọ miran tun ti ni arun Coronavirus lorilẹede Naijiria.
Kí irú ẹni bẹ́ẹ̀ pada sí ilé rẹ̀, kí ó má baà jẹ́ pé bí ó bá kú sí ogun, ẹlòmíràn ni yóo jẹ èso ọgbà àjàrà rẹ̀.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Arabinrin naa tun ta Mark Zuckerberg yọ, ẹni to da oju opo ikansiraẹni Facebook silẹ, ti wọn si ri bii ọdọmọde olowo to ni ọpọ biliọnu dọla lẹni ọdun mẹtalelogun.
Angẹli Ọlọrun náà wí fún un pé, “Da ẹran náà ati burẹdi tí kò ní ìwúkàrà ninu náà sí orí àpáta yìí, kí o sì da omi ọbẹ̀ náà lé gbogbo rẹ̀ lórí.
A tun sise lori eto eko ati ile-iwosan .
Lọjọ  Aje, ni Ile-ẹjọ ilu Eko gbẹse le owo to le ni milionu mẹ́jọ dola ($8.
ỌDẸ APERIN ṢÌNÀ SÍNÚ IGBÓ OLÓDÙMARÈ: GỌNGỌ SỌ
wipe, iyansipo dokita Fayemi ko je ohun to ba oun lo jiji, nitori pe odu ni
Èyí ni àkójọ ìrírí tí àwọn ènìyàn fi sowo sì ilé ose BBC News Yorùbá àwọn ọ̀nà tí wọn gba láti lọ ojo kini igbele wọn.
Ni ọjọ kẹrindinlọgbọn oṣu kẹsan 2019 ni ariwo he sọ ni agbo ile olorin Raggae kan Oghenemaro Emeofa, ti gbogbo eniyan mọ si Mad Melon ni agbegbe Ajegunle ni ipinlẹ Eko.
Aare Muhammadu Buhari wa ni owo ti orile ede Naijiria n ri
Momofuku Ando, tó jẹ́ ọmọ Taiwan-Japan sùgbọ́n tó kùnà nínú ìṣòwò rẹ̀, ń wá ọ̀nà láti fún àwọn ọmọogun Japan tó wà nínú ìyàn lẹ̀yìn ogunàgbáye ẹlékejì, pẹ́lú èrò pé àláfíà yóò jọba tí àwọn ènìyan bá ti n jẹ àjẹyó àti àjẹ ṣẹ́kù Nítori náà, ó lo ọdún kan nílẹ̀ àhéré lẹ́yìkùlé Osaka, láì ṣe àárẹ̀ bótilẹ̀ jk pe bó ṣe ń ṣe àsìṣe bẹ́ẹ̀ ló ń gbàyànjú sìí, àṣẹ̀yìnwá àṣẹ̀yìn bọ̀ ọ́ ṣe àṣeyọri láti ní ilé ounjẹ tí gbogbo ènìyàn mọ jùlọ lágbàyé.
Ṣe ni ileẹjọ ti igbẹjọ Pasito Alfa Babatunde ti ile Ijọsin Sotitobirẹ yoo ti waye ti kun fọfọ pẹlu awọn to n reti Pasitọ naa.
Yíyí ètò ẹ̀kọ́ padà nàá n ṣe àkóbá fún ẹ̀ka ètò ẹ̀ka Nàìjíríà.
Bakan naa lo ni ajọ to n bojuto ọrọ epo bẹntirol ni Naijiria, NNPC gbe jade pe, iye owo to le ni triliọnu mẹwaa naira ni awọn ti na lori owo iranwọ epo lati ọdun 2006 si 2019.
Pẹlu eleyi, o fihan pe awọn alagbata epo ni anfani bayii lati diye le ori epo bẹntiro ki wọn si lee taa ju iye ti ajọ PPPRA ba gbe kalẹ lọ.
, aare so pe: “Mo mo pe iru igbese yii yoo waye” Ni ede geesi kan si.
“O kò gbọdọ̀ fẹ́ iyawo tabi kí o bímọ ní ibí yìí.
Iya Daniel sin ọmọ rẹ lọ ati olukọ rẹ, arabinrin Dupe Adeosun si ọfiisi gomina eleyi si wa di anfani banta banta fun Daniel lati sare jẹ gomina fun akoko ranpẹ.
Nígbà tí wọ́n ti gbadura, tí wọ́n sì ti gbààwẹ̀, wọ́n fi wọ́n lé ọwọ́ Oluwa tí wọ́n gbẹ́kẹ̀ wọn lé.
Ohun rere ni ó ṣe sí mi.
Edo election 2020: Ọlọ́pàá méjì kú nínú ìjàmbá ọkọ̀ tó ṣẹlẹ̀ sí Adams Oshiomole, APC ní kìí ṣe ojú lásán
Bùhárí: Ariwo ọmọ Nàìjíríà ló mú mi fẹ́ díje lẹ́ẹ̀kejì
Ẹ̀sùn olè, ipaniyan àti iba dúkìá jẹ́ ní wọn fi kàn wọ́n, to fi mọ igbabode fawọn agbofinro ni wọn tun ni wọn ṣe si.
O ní ìwọlé yìí wà fún àwọn tọ fẹ́ ṣe ìdánwò àṣe kágbágbá nìkàn ni.
O si lọ ya aworan tattoo naa lati fi pa ironu rẹ lori ọmọ rẹ to n se aisan ni.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Olumo Rock: Òrìṣà Igùn lọba ọ̀pọ̀ òrìṣà tó wà lábẹ́ Olúmọ tó ń dáhùn àdúrà Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Olumo Rock: Òrìṣà Igùn lọba ọ̀pọ̀ òrìṣà tó wà lábẹ́ Olúmọ tó ń dáhùn àdúrà 8 Ọ̀wàrà 2019 Ẹnikẹni to ba lọ silu Ẹgba, eyiun Abẹokuta, ti ko si de ori oke Olumọ, a jẹ pe abẹwo rẹ ko tii pe.
Wo nọ́mbà tí o le è pè láti gba owó gbà-má-bínú tí ọlọ́pàá bá fìyà jẹ ọ́ lọ́nà àìtọ́ l'Eko Wo diẹ lara awọn eeyan to wa ninu igbimọ tuntun naa: Doris Okuwobi Wọn bi adajọ-fẹyinti Doris Okuwobi ni ipinlẹ Eko ni ọjọ Kẹwaa, oṣu kinni, ọdun 1955.
Ó sì ti wá fi ọ̀rọ̀ ìlàjà lé wa lọ́wọ́.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù EFCC: Ọ̀gá ẹlẹ́wọ̀n àti dókítà gba ẹlẹ́wọ̀n láàyè láti kúrò láhàmọ́ọ́ fún ìtọ́jú 26 Bélú 2019 Oríṣun àwòrán, EFCC Ajọ to n gbogun ti iwa jẹgudujẹra ni Naijiria EFCC ti kede pe oun ti mu ọga awọn oṣiṣẹ ẹlẹwọn Kirikiri nilu Eko nitori pe o ṣe iranwọ iwe aṣẹ ayederu fun ẹlẹwọn kan lati gba itọju nile iwosan.
Comrade Adeniyi ni gbogbo eto lo si ti to fun ifẹhọnu han naa latari ifiyajẹni lọna aitọ ti ijọba apapọ gunle fun Oludari ikọ Revolution Now, Omoyele Soworẹ.
Ìró ìyẹ́ àwọn ẹ̀dá alààyè náà ni mò ń gbọ́ tí wọn ń kan ara wọn, ati ìró àgbá wọn; ó dàbí ìró ìṣẹ̀lẹ̀ ńlá.
Bẹ́ẹ̀ ni alufaa yóo ṣe ṣe ètùtù fún ẹ̀ṣẹ̀ rẹ̀, OLUWA yóo sì dáríjì í.
Ó bá fọwọ́ kàn mí, ó sì gbé mi dìde, 
Abubakar ni igbá-kejì ààrẹ ìgbà kan àti òǹdíje lábẹ́ àsíá PDP.
  “Iko omo ogun seku pa omo ogun olote boko haram merinla, bee si ni won tu awon eniyan mokanlelogun ti o kun fun obinrin mefa ati awon omode mokanla sile kuro nipo ahamo.
N óo jẹ́wọ́ orúkọ rẹ̀ níwájú Baba mi ati níwájú àwọn angẹli rẹ̀.
Aarun coronavirus maa n ran nipa ikọ tabi ikun ẹni to ba ni i.
Tọkunrin-tobinrin lo ma n jẹ emere, ṣugbọn obinrin lo pọju ninu wọn.
Ṣugbọn obinrin yìí kò dẹ́kun láti fi ẹnu kan ẹsẹ̀ mi láti ìgbà tí mo ti wọ ilé.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Báwo ló ṣe n tànkálẹ̀ l'Afrika?
Sibẹsibẹ wọn yóo jẹ́ ẹrú rẹ̀, kí wọ́n lè mọ ìyàtọ̀ ninu pé kí wọ́n sin òun OLUWA, ati kí wọ́n sin ìjọba àwọn ilẹ̀ mìíràn.
Koko ọrọ ni pe bi ẹjẹ ba n tu yaya ninu ara pupọ, ti ko ba si atẹgun to n gba inu ẹjẹ naa bo ti ṣe yẹ, eeyan n kọ lẹta si iku ni yẹn.
” Ahabu bá bá a dá majẹmu, ó sì fi sílẹ̀ kí ó máa lọ.
O ni 'ohun to ṣẹlẹ yii yoo mu irẹwẹsi ba a (Joshua), ṣugbọn, irawọ rẹ yoo pada tan.
Ègún ni fún ọjọ́ tí a bí mi,kí ọjọ́ tí ìyá mi bí mi má jẹ́ ọjọ́ ayọ̀.
Davy ko goke naa pada bọ o, ori ẹlẹẹkeje lẹmi ti bọ.
Kini o le ṣe ti o ba n ri ami?
Ayew to jẹ ọmọ ọdun mejidinlọgbọn, sọ wipe inu baba ohun dun lọpọlọpọ bi ohun se pada wa si ẹgbẹ agbabọọlu Swansea City, ti o si fi kun un wipe, nigba to n fi ẹgbẹ agbabọọlu naa silẹ lọdun 2016, inu baba ohun ko dun.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Mo kẹ́kọ̀ọ́ fásitì sùgbọ́n aṣọ òké ló ń jáwó báyìí' Minisita fi kun ọrọ rẹ pe ifọrọwerọ si n lọ lọwọ, ṣugbọn o fidi rẹ mulẹ pe ohun ti o ṣe pataki ju nipe maa fọwọ si owo oṣu ti o ba lagbara lati san.
Ọpọ lo n sọ pe aitun ilu ṣe, ati ileewosan to wa ni Naijiria ko ṣẹyin wọn.
Bakan naa lo jẹ minisitita feto ẹkọ nigba iṣejọba saa oṣelu akọkọ lorilẹede Naijiria labẹ olootu ijọba naa, Alaaji Tafawa Balẹwa.
Abayọmi Shogunlẹ to jẹ olori ikọ agbohungbaroye (Police Public Complaint Unit) nileeṣẹ ọlọpaa tẹlẹ ati Dọlapọ Badmus to figbakan ri jẹ alukoro ileeṣẹ ọlọpaa ni ipinlẹ Eko ati ni ẹkun keji, Zone II wa lara orukọ awọn mẹtadinlogoji ti wọn da oruks wọn sinu iwe naa.
A óo yọ ẹnikẹ́ni tí ó bá jẹ ẹ̀jẹ̀ kúrò lára àwọn eniyan Ọlọrun.
O ra ọwọ ẹbẹ si ijọba ati awọn ẹlẹyin ju aanu lati ṣe iranlọwọ fun wọn lasiko yii.
Òun ni ó ti là wá níjà pẹlu ara rẹ̀ nípasẹ̀ Kristi.
3 7570 Orilẹede Nicaragua 161 2.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Lion Air Crash: Arákùnrin kàn tórí kó yọ nínú ìjàmbá ọkọ̀ òfurufú rèé 11 Èrèlè 2018 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 29 Ọ̀wàrà 2018 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Sony Setiawan di ẹni apewo Bi sunkẹrẹ-fakẹrẹ ọkọ ba da ọ duro, ma fi ṣe ibinu nitori ó le ṣe okunfa idoola ẹmi rẹ.
Awọn ajajngbara ni igbesẹ ijoba yii dara ṣugbọn wọn nilo lati gba pe awọn eniyan South Africa n ṣe ikọlu ti ko yẹ sawọn ajoji.
Ọjọ Aiku, ti i ṣe ọjọ keji ni ojo naa bẹrẹ.
 leyin awon orundun meta ati abo iseamusin awon ara hollandi , indonesia gba ilominira re leyin ogun agbaye 2k .
Iṣẹlẹ ọhun mu ki ọlọla ati ẹni ẹyẹ di ẹni abuku, o si yẹ kawọn ọdọ ati ewe iwoyi, to fi mọ awọn eeyan to n lo igba lọwọ lagbo oselu wa fi kọgbọn.
Nibi ti wọn ti n gbiyanju lati rii wi pe ọmọ erin naa ko ku lawọn naa gbọjọ iku wọn.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Olofa ina: ẹ parí òwe yìí pé ìgbà tí ara bá tu ìgbẹ́ láà ri eṣú.
Àṣé ẹ kò mọ Ìwé Mímọ́ tabi agbára Ọlọrun?
Àwọn agbébọn tí jí àwọn ọmọ fásitì Zaria mẹ́jọ ní òpópónà Abuja sí Kaduna - Gomina El- Rufai Àwọn ọmọ Naijiria kó owó wọn kúrò ní Access Bank lẹ́yìn tó gbẹ́sẹ̀lé àpò owó àwọn olùwọ́de EndSARS Joke Silva: Olu, ó tó gẹ́ pẹ̀lú obìnrin yìí níkan tó ń ba ẹ ṣeré ìfẹ́ nínú sinimá!
’’Sugbon Ojogbon Mojeed Alabi to n soju fun Ipinle Osun ati Sadiq Ibrahim to n soju fun ipinle Adamawa ko faramo aba yii , won ni aare lagbara lati lo ofin to ro mọ asẹ ijọba.
Bẹ́ẹ̀ ni wọ́n ń ṣe ní ojoojumọ, wọ́n sì rí ọpọlọpọ owó kó jọ.
lati mọṣalaṣi ni ilu  Mecca lọ si
Kí ó tó di ọjọ́ igbeyawo, 
Orukọ akọkọ ti omidan Meghan n jẹ ni Rachel ṣugbọn ni ẹnu iṣẹ rẹ gẹgẹ bii gbajugbaja oṣiṣẹ mohunmaworan ni orilẹede Amẹrika, orukọ rẹ keji lo mu lọkunkundun ni jijẹ, ohun si ni ọpọ eniyan mọọ mọ.
Awon olopaa meta tun farapa, bi awon eniyan se n ju okuta si ile-ise olopaa to wa nitosi won, bakan naa ni won si dana sun awon oko.
Wo àwọn ìṣẹ̀lẹ̀ tó mú Naira Marley di òrìṣà àkúnlẹ̀bọ ní 2019 Ọgbà ẹ̀wọ̀n ni Naira Marley yóò ti wo ìbúra Buhari ní May 29 'Soapy', àwo orin tuntun Naira Marley tó ń milẹ̀ tìtì Agbèfọ́ba ní òun kò leè sọ bóyá Naira Marley wọ́ ike owó àbí bẹ́ẹ̀kọ́ - Agbẹjọ́rò Ilé ẹjọ́ gba onídúró Naira Marley pẹ̀lú mílíọ́nù méjì náírà Iṣẹ elere itage ni Baba awọn Marlian n ṣe jẹun.
Púpọ̀ nínú wọn ni ó ti ń gbógun wípé kí ó máa lọ'lé.
Ẹ lè jẹ àwọn wọnyi ninu wọn: Oríṣìíríṣìí eṣú ati oríṣìíríṣìí ìrẹ̀ ati oríṣìíríṣìí tata.
N kò ṣe ojúkòkòrò owó tabi aṣọ tabi góòlù ẹnikẹ́ni.
”Ọdọmọkunrin náà dáhùn pé, “Ọmọ àlejò ará Amaleki kan, tí ń gbé ilẹ̀ Israẹli ni mí.
Nitori naa, o gba ẹjọ ti ajọ EFCC pe wi pe ki Patience padanu owo naa pata pata.
Ti wọn ba fi le yan-an, ẹni ọgbọn ọdun ọhun ni yoo jẹ ọmọ Naijiria akọkọ nile aṣofin ilẹ America.
bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé mo ti gbára lé nǹkan ti ara nígbà kan rí.
Ọgbà ẹ̀wọ̀n ni Naira Marley yóò ti wo ìbúra Buhari ní May 29 Tinubu gbéra lọ odidi Mecca láti lọ ṣàbòsí - PDP Daddyshokey ni iwa ibajẹ wọpọ lawujo wa, amọ ko ye ki EFCC lo aduru eso alaabo to po to bẹ ẹ lati mu ọdọ ti fẹsun asemase kan lọ si ile ẹjọ.
Ni òun náà bá ṣubú lulẹ̀ lẹsẹkẹsẹ níwájú Peteru, ó bá kú.
Gbogbo aáyan BBC Yorùbá láti gbọ́ ti ẹnu Olùsọ́ àgùtàn J F Ọdẹ́sọlá ló já sí pàbó nítorí kò gbé ìpè wa lórí ẹ̀rọ ìbáraẹni sọ̀rọ̀.
Isolation Center: Minisita feto ìlera ni ìjọba fẹ́ ṣe àyẹ̀wò fún èèyàn mílíọ̀nù méjì láàárín oṣù mẹ́ta tó ń bọ̀, tí wọn sì nílò ibùdó iyasọtọ sì Oríṣun àwòrán, others Minisita feto ìlera, Dókítà Osagie Ehanire tí rawọ ẹ̀bẹ̀ sáwọn ọmọ Nàìjíríà láti gbé ilegbe wọn kalẹ fún ibùdó iyasọtọ.
Ẹnu agba lobi tii gbo ni ọrọ Ronaldo lori idije Champions League yii.
”Alexey tun tesiwaju pe:” lati ni ibasepo to monyan lori pelu orile ede Naijiria je  idunnu wa ,nitori pe awon ni eerin lakatabu ni orile ede Afirika.
Mo rán wọn láti gbógun ti àwọn tí kò mọ Ọlọrun,ati àwọn eniyan tí wọ́n bá mú mi bínú.
Tí wọn ń wí pé:“Kí ó tilẹ̀ ṣe kíá,kí ó ṣe ohun tí yóo ṣe, kí á rí i.
Nigba ti Ayariga n dahun  si ibeere lasiko ti igbimo asoju -sofin pe, awon ti yanju awon isoro lori oro naa.
Ó mú kí iná sọ̀kalẹ̀ láti ọ̀run wá sí ayé lójú àwọn eniyan.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Oba Folagbade Olateru-Olagbegi wàjà lẹ́ni ọdún 77 17 Ìgbé 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 18 Ìgbé 2019 Oríṣun àwòrán, Google Ọlọ́wọ̀ ti Ọ̀wọ̀, Oba Folagbade Olateru Olagbegi CFR ti darapọ mọ awọn baba nla rẹ lẹni ọdun mẹtadinlọgọrin.
Èrò mi l ' órí ẹ ́ kọ ́ ( 1693 ) ni ìwé kan tí àmoye omo ilé gèésì , john locke kò .
Wọn ni orilẹede Naijiria ko tilẹ tii goke rara nipa awọn to n lugbadi arun ọhun torinaa o rọ awọn tọrọ kan ki wọn maa tẹle ofin bo ṣe yẹ.
Baba rẹ, Richard Addo sọ fun BBC pe igba to pe ọmọ ọdun kan ati osṣu mẹẹrin lawọn ti ṣakiyesi pe o tete n mọ nkan.
Gomina ipinlẹ Cross River to gbelejo eto naa, Ben Ayade, sọ pe eto naa ni afojusun lati ṣafihan ẹwa ilẹ Afrika ati ohun to yẹ ki ọkunrin mọ tabi reti lati ọdọ obinrin ilẹ Afrika.
Oríṣun àwòrán, @NGRPresident Bakan naa ni awọn igbimọ amuṣẹya naa ni ibaṣepọ to danmọran ti wa laarin awọn olootu ijọba mẹfa naa, ti wọn si jọ panupọ lori isoro naa.
Alhaja Adeola Agoro JP to jẹ ọmọ oloogbe naa fi soju opo facebook rẹ pe iku ti wọle mu ẹni rere naa lọ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Atiku Vs Buhari: Bulkachuwa yọra rẹ̀ nínu ìgbẹ́jọ́ èsì ìdìbò ààrẹ 22 Èbibi 2019 Lẹyin ọpọlọpọ awuyewuye to rọ mọ wiwa ninu igbimọ ti yoo gbẹjọ esi idibo aarẹ Naijiria to waye ni oṣu kẹta ọdun yii, Aarẹ Ile Ẹjọ Kotẹmilọrun, Adajọ Zainab Bulkachuwa, ti yọ ara rẹ ninu igbẹjọ naa.
A kó dúnkoòkò mọ́ Ambode, isẹ́ wa là ń ṣe - Ilé Aṣòfin Eko Amẹ́rika dá akẹ́kọ̀ọ́ padá nítori Facebook Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
    Nígbà tí àbúrò rẹ lọ tán tí a bẹ̀rẹ̀ síí sọ̀rọ̀ ọmọ náà kò si ẹnìkan ṣoṣo nínú wa tí kò gbádùn rẹ.
Mo dáríjì àwọn IPOB tó nà mí ní Germany nítorí wọn o m'ohun tí wọ́n ń ṣe- Ekweremadu Ọlọ́pàá Ogun gb'ọmọ Ìmáàmù lọ́wọ́ ajínigbé, ṣùgbọ́n wọ́n gbé ọkọ̀ ojú omi ọlọ́pàá lọ Wilfred Ndidi, ọmọ Nàìjíríà pa iná ògo Chelsea ní Stamford bridge Ọlọ́pàá Ogun gb'ọmọ Ìmáàmù lọ́wọ́ ajínigbé, ṣùgbọ́n wọ́n gbé ọkọ̀ ojú omi ọlọ́pàá lọ Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Àwọn ọmọ Elamu keji jẹ́ ẹgbẹfa ó lé mẹrinlelaadọta (1,254).
David Ugolor ni epo buruku ti awọn to n gbepo rọbi wọ Naijiria fun lilo awọn ọkọ jẹ ọkan lara ohun to n ba atẹgun orilẹede yii jẹ.
Buhari ransẹ ayọ sikọ Naijiria Saraki kan saara si awọn ọmọ Naijiria mẹta Àwọn olùgbé Tarkwa Bay ń fọ́ ọ̀pá epo, jí epo ta, la ṣe lé wọn - Iléeṣẹ́ Ológun Àkíyèsí nípa àìsàn ‘Coronavirus’ tó ń ṣàkóbá fún ba ṣe ń mí Naijiria yoo ma a koju ikọ Australia ninu ipele akọkọ fun idije agbaye naa.
ife orile ede yii lokan, ki won si yago fun iwa eleya-meya ati iwa esin.
Ṣíṣọ́ ni OLUWA ń ṣọ́ wọn ní gbogbo òru ọjọ́ náà títí ó fi kó wọn jáde kúrò ní ilẹ̀ Ijipti.
Wọ́n da ara wọn pọ̀ mọ́ Baali ti Peori,wọ́n sì ń jẹ ẹbọ tí wọ́n rú sí òkú.
Nígbà tí ó tún yá tí àwọn ọmọ Ọlọrun wá farahàn níwájú OLUWA, Satani náà wà láàrin wọn.
O tubs yannana rẹ siwaju sii pe, Abayoọmi Shogunlẹ ati Dọlapọ Badmus ko si lara awọn ti wọn le lẹnu iṣẹ ọlọpaa, ara awọn ti wọn gba ni ikilọ atawọn ti wọn ja okun wọn ni awọn mejeeji yii wa.
Lawrence Oyor to jẹ afẹsọna Darasimi jẹ ẹni ọdun mejidinlọgbọn.
N kò ní máa bínú lọ títí lae.
bayii,All Progressives Congress (APC) ti a  tun mọ si Progressives Governors Forum (PGF)
Mo tún fun yín ní àṣẹ lórí gbogbo agbára ọ̀tá.
"Iya rẹ ni, ""Nazaninn sọ fun mi: Mama mi, ẹ ta mi lọmọde ṣugbọn ara ẹgbọn mi ko tii ya."
Ohun to fa ki baalu naa ti wọn ti n lo lati ọṣu kẹjọ ja ko ti daju ṣugbọn awọnb alaṣẹ ni ẹnikankan ko ribi jajabọ ninu iṣẹlẹ naa.
Ninu atẹjade kan to fi ori ayelujara Twitter rẹ l'Ọjọbọ, ajọ NIMC sọ pe ẹwọn ọdun meje ni ofin ajọ to n gbogbun ti iwa ibajẹ, ICPC, la kalẹ fun ẹni to ba gba owo lati fi orukọ eeyan silẹ fun nọmba NIN.
Mo tọ orílẹ̀ yìí dé ìpẹ̀kun àríwá mo kan agbami
 Owo atunse ona ni bilionu meji din logorun milionu naira.
blanche kelso bruce ( 1 oṣù kẹta , 1841 - 17 oṣù kẹta , 1898 ) je oloselu ara u.
Awọn eeyan naa sọ fun BBC pe eredi ti wọn ṣe fi Amẹrika silẹ ko ṣẹyin bi iwa ẹlẹyamẹya ṣe di tọrọfọnkale nibẹ.
Alaye yii ko fidi mulẹ to, nitori ọpọ eeyan lo n beere pe ṣe ife ọti lasan to lati gbẹmi eeyan, amọ awọn eeyan kan woye pe o ṣeeṣe ki Ayinla Ọmọwura ti ṣe oogun abẹnu gọngọ debi pe ko gbọdọ kan ẹjẹ.
Ajọ NBC jẹ ko di mimọ pe iru iwe aṣẹ yii kan naa ni wn ti fun awọn ile ẹkọ giga atawọn ile iṣẹ ijọba mii lati maa gbohun safẹfẹ eyi to da lori ohun ti wọn nilo rẹ fun.
Bẹẹ naa ni wọn sọ pe Al-Qaeda n lo anfaani pe awọn ilẹ Afrika ko ribi koju ipenija Covid-19 lati pẹka de awọn aaye wọn mi.
Lati igba naa lo si ti n ṣe ikọlu si awọn oṣiṣẹ eleto aabo, Kristẹni, ati awọn ọmọ ogun ilẹ okeere.
Awọn ẹgbẹ́ agbabọ́ọ̀lù Chelsea ń woye lati wọ asekagba, lẹ́yin ti wọn gba ọmi ayo ni ìgbà ti wọn lọ Germany, Leyin ti Luka Jovic ti peto ààye fún Frankfurt niwaju ni Pedro ba gbẹ̀yin yọ láti gba bọọlu sáwọn nibi ipele akọkọ.
'Irọ ni, ko si ologun kankan ni Dapchi' ‘ Awọn ọmọ Yobe’ Kini yoo pada jasi?
Ẹ fi aro olóhùn òkè yìn ín;ẹ fi aro olóhùn gooro yìn ín.
O le ni ogbon ero din ni oodunrun eniyan ti ile iwosan ijoba ti fafiti ologba eranko ni Ibadan, UCH, seto ayewo awon aisan kindinrin fun lofe lojo  Abameta ni Ibadan to je olu ilu ipinle Oyo.
Aworan si fihan pe Davido ati Chioma iya ọmọ rẹ, ti ba Hushpuppi ni alejo ri.
"Oríṣun àwòrán, Getty Images Ọjọgbọn Wallen sọ pe ""ninu iwe naa, o kọ ọ pe bi ara ṣe ri ko ni nkankan ṣe pẹlu itura ibalopọ, ati pe ọkan eniyan ni gbogbo ẹ wa""."
- Madam Saje Àwa kìí jà lásìkò tiwa, ta ló bí ẹ tí wàa máa jà?
Gbọ́, ìwọ Lemueli,ọba kò gbọdọ̀ máa mu ọtí,àwọn aláṣẹ kò sì gbọdọ̀ máa wá ọtí líle.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Sogidi Lake: Kòṣẹja-kòṣèèyàn lá bá nínú adágún odò náà -Ojedele Koda, o tun tọrọ aforijin pe oun sọ fun wọn saaju lati maa pe oun ni aya aarẹ dipo obinrin akọkọ ni Naijiria.
Ọgbẹni Fadeyi ni ọrọ bẹyin yọ nigba ti Adeniyi gbe aṣọ ọhun fun ọmọ iṣẹ rẹ lati ran.
Ọkunrin kan tí ń gbé ibẹ̀ bèèrè pé, “Ta ni baba àwọn wolii wọnyi?
Àwọn tí wọn kò tíì ya ara wọn sí mímọ́ pọ̀ níbi àpéjọ náà, nítorí náà, àwọn ọmọ Lefi bá wọn pa ẹran wọn kí àwọn ẹran náà lè jẹ́ mímọ́ fún OLUWA.
Bí ọdún ṣe ń gorí ọdún ni ìpòruru ọkàn m bá Leanne nítorí àìlè jí pépé imọ̀lára rẹ̀ fún ìbálòpọ̀.
Akọ̀ròyìn Morocco, Hajar gbà ìdájọ́ ẹ̀wọ̀n lórí ẹ̀sùn àgbèrè àti pé o ṣẹ́yún Nǹkan kò tíì ṣẹnu ire fún àwọn ọmọ orílẹ̀-èdè yìí - Atiku Ninu atẹjade kan ti Lisa fun ile iṣẹ iwe iroyin: The Paper lo ti tọrọ aforijin to ṣalaye pe ọpọ atẹjiṣẹ ni oun ti ri gba lati ọdọ awọn ololufẹ rẹ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Pistachio Green Puppy: Àwọn ẹgbẹ́ rẹ̀ jẹ́ aláwọ̀ funfun, tí òun sì jẹ́ aláwọ̀ ewé Ohun to jẹyọ ninu ọrọ awọn ọgagun wọnyi ni pe, iwọde naa to kọkọ n lọ nirọwọrọṣẹ, pada di onijagidijagan.
Mo ni igbagbo pe awon yoku ti won si wa ninu igbekun, ni won yoo wale layo ati alaafia.
Ó fi èyí wá Filipi lẹ́nu wò ni, nítorí òun fúnrarẹ̀ ti mọ ohun tí òun yóo ṣe.
“Ṣugbọn níbo ni àwọn oriṣa yín tí ẹ dá fún ara yín wà?
bẹrẹ lati so fun un yin pe ipinnu aare ni lati mojuto igbaye-gbadun gbogbo omo
"Olatunji ni: ""Toyin lo fi atẹjisẹ kan ránsẹ sí mi lọpọlọpọ ọdún sẹ́yìn lórí ẹ̀rọ ilewọ BBM, pé ki ileesẹ mi wá máa ṣe àkóso àti alarina isẹ rẹ."
lori ero ayelujara lati paro gba owo fun iwe irinna lati se abewo sile okeere lọwọ
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Ibrahim Chatta: Tí olólùfẹ́ méjì bá ti ń na ara wọn, ọ̀kan má a pa èkejì!
Kí ló mú kí àwọn èèyàn máa jẹ ọ̀rọ̀ Adeboye lẹ́nu lórí Twitter Awọn agbanisiṣẹ naa kii fẹ ẹ gba awọn obinrin, nitori pe iṣẹ agbara ni ireke gige, ati nitori pe awọn obinrin si maa n pa iṣẹ jẹ lasiko ti wọn ba n ṣe nkan oṣu wọn.
Ó ṣeéṣe kí a pàṣẹ òfin Kónílé-ó-gbélé tuntun láìpẹ́ - Ìjọba ìpínlẹ́ Ekiti Olu Jacobs: Ipò wo ni gbajúmọ̀ òṣèré tíátà yìí wà?
Ẹ ta àsíá ní orí òkè gíga,ẹ gbóhùn sókè sí wọn.
Iyale iya ọmọ naa ti o ba wa sọrọ, Arabinrin Arowolo ṣe alaye wi pe ọmọ naa ati awọn ọmọ oun ni wọn jọ n ṣere ni iwaju ṣọọbu wọn ni ọjọ ọdun ileya ku ọla ki o to di wi pe wọn ko dede rii mọ laarin awọn ọmọ to ku.
Gbogbo awon to lo dibo ni agbegbe  ati ekun won , lo je pe won ka ibo won.
won tun yin ibọn pa okan lara osise aabo-ara- ni-aabo ẹmi ( Civil
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ibo gomina Ondo: Akeredolu fidirẹmi nileẹjọ 23 Ẹrẹ̀nà 2018 Oríṣun àwòrán, ONDO STATE GOVERNMENT Àkọlé àwòrán, Akeredolu ati Abraham ni wọn jọ figagbaga fun asia ẹgbẹ oselu APC fun ipo gomina ipinlẹ Ondo lọdun 2016 Ileẹjọ to ga julọ lorilẹede Naijiria ti da ẹjọ kotẹmilọrun ti gomina ipinlẹ Ondo, Rotimi Akeredolu gbe wa siwaju rẹ nu pẹlu alaye pe ko lẹsẹ-n-lẹ.
"O ni ""O yẹ ki Naijiria ni ẹka ile iwosan to le koju iṣẹlẹ pajawiri, ile oogun ati awọn irinṣe to dantọ lati koju ajakalẹ arun bi Coronavirus, ṣugbọn niṣe ni ijọba fi ẹtẹ silẹ, to n mojuto lapalapa."
igbakeji abenugan to kogba wọle bayii , asofin Ike Ekweremadu to wa niluu
Lẹ́hìn èyí, mo mú àdá mo ń fi fá ’rùngbọ̀n mi.
O wa ro egbe APC lati dake ariwo pipa lori awon ipenija ti won ba nile.
Bẹ́ẹ̀ ni n óo máa kọ orin ìyìn orúkọ rẹ títí lae,nígbà tí mo bá ń san ẹ̀jẹ́ mi lojoojumọ.
 ikini ni awori , ikeji si ni ogu tabi egun .
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Níbo lórí n gbé Zlatan Ibrahimovic lọ nínú ìrìnàjò eré bọ́ọ̀lù 14 Bélú 2019 Oríṣun àwòrán, Ibra_official Àkọlé àwòrán, Níbo lórí n gbé Zlatan Ibrahimovic lọ nínú ìrìnàjò eré bọ́ọ̀lù Lẹyin nnkan bi ọdun kan le diẹ to darapọmọ ẹgbẹ agbabọọlu LA Galaxy, agbabọọlu ọmọ orile-ede Sweden nii, Zlatan Ibrahimovic ti dagbere o digba fun ẹgbẹ naa.
Awọn obinrin l'orilẹ-ede naa n lo oogun naa pẹlu ireti pe yoo mu ki ara ọmọ inu wọn o pupa.
2 131,264 El Salvador 1,469 22.
Lasiko iwaadi wọn ri oku meji ni agbegbe naa.
Ní àkókò kan, àwọn ará Filistia kó ara wọn jọ sí Lehi, níbi tí oko ewébẹ̀ kan wà.
Ọgbẹni Joseph sọ pe, ijọba nikan lo laṣẹ lati sọ pe ki ẹnikẹni kuro ni ipinlẹ kan tabi nibikibi lorilẹede Naijiria.
Awọn eniyan mejila si mọkanlelogun lo maa n kopa, ti wọn o si maa lo igbe aye wọn ojoojumọ loju gbogbo aye, lati gba ẹbun owo nla ati awọn nkan iyebiye miran.
Ipe yii lo waye nibi ipade apero awọn alẹnulọrọ ti Ile Igbimọ Aṣofin Ipinlẹ Eko maa n ṣagbatẹru rẹ loṣu mẹta mẹta kaakiri awọn ogoji ẹkun idibo to wa ni Ipinlẹ Eko, eyi to waye ni Ile-iṣẹ ẹkun idibo Alimoṣọ kinni, ni Alimọṣọ.
O ni ikọ Amotekun ti ni atilẹyin ofin bayii bẹẹ si ni ko di iṣẹ awọn oṣiṣẹ alaabo to ku lọwọ bikoṣe ko tun fi kun akitiyan riran iṣẹ wọn lọwọ fun aabo ilu eyi ti yoo tilẹ tun le fun awọn oludokoowo ilẹ okeere lalafia ati wa dokoowo.
" Amọ nigba taa bii pe ki lo fẹ ki wọn seto, ko to pada sọdọ ọkọ rẹ, Risikat ni ti wọn ba pari ija tan laarin awọn mejeeji, ko sẹni ti yoo ya si ọdọ awọn mọ.
Oríṣun àwòrán, @SavvyRinu Rinu jẹ akikanju ti ko fi igba kankan tura silẹ lori ṣiṣe deede laarin ijọba ati ara ilu.
Hilikaya, Sakaraya ati Jehieli, àwọn alákòóso ninu ilé Ọlọrun, fún àwọn alufaa ní ẹgbẹtala (2,600) ọ̀dọ́ aguntan ati ọmọ ewúrẹ́ ati ọọdunrun (300) mààlúù fún ẹbọ Ìrékọjá.
 Ìlànà ṣíṣe súúfí rẹ ̀ ni ó ràn-án lọ ́ wọ ́ jùlọ láti lo òfin àti ìlànà ẹ ̀ sin mùsùlùmí láì yan ìkan ní pọ ̀ sìn .
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù New electricity tariff: Wo ọ̀nà ìsanwó tuntun fún àwọn oníbàárà iná mọ̀nàmọ́ná Eko, EKDC 1 Owewe 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 4 Owewe 2020 Oríṣun àwòrán, EKDC Awọn araalu ni ipinlẹ Eko ti n pariwo sita pe inira nla lawọn n dojukọ nigbakugba ti awsn ba fẹ san owo ina mita tuntun alasansilẹ wọn iyẹn Prepaid meter.
Pupọ ninu ibudo idibo to wa ni Maiduguri, ni ipinle
Bákan náà lo fi ọ̀rọ̀ ránṣe si pé, kó ri àṣeyọri rẹ̀ gẹgẹ bi anfaani lati fi ọkan idupẹ àti ìrẹ̀lẹ̀ han Bákan náà ni igbákeji ààrẹ Nàìjíríà nígbà kan rí Atiku Abubakar náà ti gboriyin fún àwọn ènìyàn ìpinlẹ̀ Edo fún iṣẹ rere ti wọ́n ṣe láti gbé Obaseki wọlé fún sáà keji.
AMAA 2018 Ami eye fun ise ti won ya lona oto
Onimọ kan nipa isegun ẹranko ati awọn ohun ọsin abiyẹ ti ni, ko si oogun fun aisan lukuluku (bird flu), lẹyin ti aisan lukuluku pa adiye ẹgbẹrin o din ọgọrun ni ipinlẹ Plateau.
Akinwunmi Ambode: Ìsúná 2019 fi N1trn kéré sí ti 2018
Ó sọ fún wọn pé, “Ohun tí ẹ óo sọ fún Esau, oluwa mi nìyí, ẹ ní èmi, Jakọbu iranṣẹ rẹ̀, ní kí ẹ sọ fún un pé mo ti ṣe àtìpó lọ́dọ̀ Labani, ati pé ibẹ̀ ni mo sì ti wà títí di àkókò yìí.
Nígbà tí Satani parí gbogbo ìdánwò yìí, ó fi Jesu sílẹ̀ títí di àkókò tí ó bá tún wọ̀.
Ẹrin ati ọpọ idẹyẹsi ni awọn ero ti o n wo o ifọrọwerọ rẹ lọjọ naa fi pade rẹ.
Ẹ̀mí Oluwa gbé Filipi lọ, ìwẹ̀fà náà kò sì rí i mọ́.
Eyi lo mu ki awọn asaaju ẹgbẹ awakọ meji nipinlẹ Ọyọ, Alhaji Lateef Akinsọla, ti gbogbo eeyan mọ si Tokyo, ati igbakeji rẹ lasiko to fi jẹ alaga, Alhaji Lamidi Mukaila, to tun n jẹ Auxillary, fi foju rinju lẹyin ọdun mẹwa ti wọn fi n bara wọn ja.
OLUWA, ó tó àkókò fún ọ láti ṣe nǹkankan,nítorí àwọn eniyan ń rú òfin rẹ.
Èyí tó tún ṣẹ̀ṣẹ̀ bẹ̀rẹ̀ yìí fojú hàn nínú oṣù kọkanla ọdún yìí.
Bakan naa lo fa omi ẹrọ sile mọlẹbi rẹ.
Wo bí o ṣe le fi ẹjọ́ sun àjọ FCCPC tí o bá ra ọjà tó ti 'expire' Mi ò tí ì mọ obìnrin rí; kódà, mí ò ní 'Girlfriend'- Mr Macaroni Mọ̀ síi nípa Shina Rambo tó pàdé Jesu lọ́gbà ẹ̀wọn lẹ́yìn tó ti jalè Ilé ẹjọ́ ní kí ''Yahoo boy'' lọ darí ọkọ̀ f'óṣù mẹ́ta pẹ̀lú N50,000 owó ìtanràn 'Àwa ọmọ Nàìjíríà tó farapa fẹ́ wálé láti Lebanon, ìjọba kó wa pamọ́' Èèkàn ẹgbẹ́ òṣèlú APC mií Lanre Razak jáde láyé lẹ́yìn àìsàn ráńpẹ́ Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí 6:10 Fídíò, Yoruba Language: Akomolede ati Asa Yoruba tọ̀sẹ̀ yí rèé lẹ́nu olùkọ́ wa, Duration 6,1030 Ògún 2020 Chadwick Boseman wife: Simone Ledward ni ìyàwó Chadwick Boseman, wọ́n sì 'sègbéyàwó kó tó jáde láyé31 Ògún 2020 Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí 3 sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 2:23 Fídíò, Water Generator: Ó leè ṣiṣẹ fún wákàtí mẹfà, kó tó sinmi, Duration 2,2310 Òkùdu 2020 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
 O tenumo pe,“Mo ti ni ipalara yii lati odun meji seyin, besini ni gbogbo akoko yii, mo ti n ri orisirisi dokita.
Òun nìkan ló lè gbà mí là nípa Jesu Kristi Oluwa wa.
Gbàrà tí ilẹ̀ mọ́, àwọn olórí alufaa pẹlu àwọn àgbà ati àwọn amòfin ati gbogbo Ìgbìmọ̀ yòókù forí-korí, wọ́n de Jesu, wọ́n bá fà á lọ láti fi lé Pilatu lọ́wọ́ fún ìdájọ́.
Mose ati Aaroni bá dojúbolẹ̀, wọ́n gbadura sí OLUWA, pé, “Ọlọrun, ìwọ ni orísun ìyè, ìwọ yóo ha tìtorí ẹ̀ṣẹ̀ ẹnìkan bínú sí gbogbo ìjọ eniyan bí?
Nítorí mo wá láti dá ìyapa sílẹ̀, láàrin ọmọkunrin ati baba rẹ̀, láàrin ọmọbinrin ati ìyá rẹ̀, ati láàrin iyawo ati ìyá ọkọ rẹ̀.
Èyí ni ilẹ̀ tí a pín fún ẹ̀yà Bẹnjamini ní ìdílé-ìdílé, pẹlu àwọn ààlà ilẹ̀ ìdílé kọ̀ọ̀kan.
Ìkún omi bò wọ́n mọ́lẹ̀,wọ́n rilẹ̀ sinu ibú omi bí òkúta.
Ẹlòmíràn fi orí-fífọ́ sílẹ̀ ó béèrè inú-rírún, òmíràn fi ẹ̀hìn-dídùn sílẹ̀ ó béèrè ẹsẹ̀-dídùn, afọ́jú mìíràn ń béèrè etí-dídi, onísòbìyà míràn ń béèrè làkáràgbé, adẹ́tẹ̀ míràn ń béèrè wárápá - ọjọ́ ńlá ni ọjọ́ náà fún àwọn aráyé, wọ́n tú àṣírí tí Olódùmarè fi sí ìpamọ́ fún wọn.
Bí wọ́n ti ń lọ, wọ́n rí Samuẹli tí ń jáde bọ̀ wá sí ọ̀nà ọ̀dọ̀ wọn, ó ń lọ sí orí òkè tí wọ́n ti ń rúbọ.
Ogogo ṣe ọjọ́ ìbí, Toyin Adegbola fọmọ fọkọ, àtàwọn ohun mìràn lágbo òṣèré lọ́sẹ̀ yìí Kò sí aàyè fún ìbò rírà àti títà ni Kogi àti Bayelsa- IGP Àṣírí pásìtọ̀ tó ń fí sọ́ọ̀si ṣe ọ̀gbà wèrè tú!
ijosin Notre Dame Cathedral, ni olu ilu orile-ede ohun, ti n se Paris, lojo
O sọ aṣiri bi awọn Pasitọ ati Wolii nla nla ṣe maa n sẹri ibukun sori ibọn wọn ati ifami ororo yan ki wọn to jade lọ ja ole bi wọn ba si dari wọn a wa fi idamẹwa silẹ.
 ni odún 2000 , ó padà sí ilè ifẹ ̀ , ó darapọ ̀ ẹ ̀ ka èkọ ́ Ọbáfẹ ́ mi awólòwọ ̀ yunifásit ̀ ì níbí tí ó tí ṣisẹ ́ olùkọ ́ tí ó fi kú .
Wọ́n wá gbogbo agbègbè Ṣaalimu, ṣugbọn wọn kò rí wọn níbẹ̀.
Ìdí rẹ̀ ni pé, Dafidi ṣe ohun tí ó dára lójú OLUWA, kò sì ṣàìgbọràn sí àṣẹ rẹ̀ rí ní gbogbo ọjọ́ ayé rẹ̀, (àfi ohun tí ó ṣe sí Uraya ará Hiti).
Lulu padà ṣàlàyé fún màmá rẹ̀ pé, aṣọ ìgbéyàwó jẹ́ àpẹrẹ pé òun ti ṣetan láti l'ọ́kọ.
5 16244 Orilẹede Estonia 133 10.
Ṣugbọn yóo dára fún àwọn tí wọ́n bá dá ẹ̀bi fún ẹni tí ó jẹ̀bi,ibukun Ọlọrun yóo sì bá wọn.
Mo rí pẹpẹ ìrúbọ kan tí ẹ kọ àkọlé báyìí sí ara rẹ̀ pé: ‘Sí Ọlọrun tí ẹnìkan kò mọ̀.
O ni awọn ololufẹ oun yoo mọ boya lootọ ni oun loyun tabi bẹẹkọ, nigba ti oṣu mẹsan ba pe.
Ògo ilẹ̀ Ibadan míì lọ, Pàràkòyí Olóyè Bode Akindele dágbére fáyé Oríṣun àwòrán, thisdaylive.
A kò fipá mú ẹnikẹ́ni láti dá Ruga, aàgọ́ Fulani sílẹ̀ -Iléeṣẹ́ aàrẹ Ọ̀pọ̀ ẹ̀mí sọnù sínú Ọkọ̀ ojú omi to dànù l'Eko 'Ìfẹ̀hónúhàn ti àwọn kan ṣe ń bí èsò ìrònúpìwàdà lójú wọn' Donald Trump kéde pé ìpàdé òun pẹ̀lú Kim já si rere Koda wọn fi awọn agbabọọlu Naijiria wé ipa ti awọn ọmọ awọn keekeeke le ko lawujọ.
Ọgbẹni Benjamin Ọlasunkanmi ni ẹgbẹrun mẹta-le-ẹgbẹrinlemejidinlọgbọn
INEC Amina Zakari: Mi ò tan mọ́ ààrẹ Buhari rárá o!
 gege bi  forbes "" se gbe jade , o ni iwon toto $ 650 million gege bi oun ini ."
Ofin mẹrin ọtọọtọ ni ijọba ko papọ di odidi kan si abadofin lori omi fun ọdu n 2020.
Ẹwẹ, iwadi fi han wipe laarin ọdun kan ti awọn aṣofin agba ati awọn aṣojuṣofin ti bẹrẹ iṣẹ ni wọn ti n da aba, ṣe ijiroro ati ṣe amuṣẹ awọn iṣẹ akanṣe to nilo amojuto lawọn ẹkun ti wọn n ṣoju kaakiri Naijiria.
”Ó dá ọba lóhùn pé, “Kabiyesi, opó ni mí, ọkọ mi ti kú.
Àwọn ọmọ-ẹ̀yìn bá ń lọ láti abúlé dé abúlé, wọ́n ń waasu ìyìn rere, wọ́n sì ń ṣe ìwòsàn níbi gbogbo.
Agbenusọ ilé isẹ́ náà, Ben Gong ṣàlàyé fún BBC pé àsìkò tí ilé isẹ́ ètò ìlera ba sọ pé kò séwu mọ ni àwọn ilé ẹ̀kọ́ yóò tó padà di ṣíṣí.
Adajọ agba tuntun yii ni ẹni kẹta ti ààrẹ Trump yoo fa kalẹ lẹyin Neil Gorsuch lọdun 2017 ati Brett Kavanaugh ni 2018.
Ọlọ́pàá ní kí n bọra sílẹ láti mọ bóyá obìnrin ní mí torí mo ní irùngbọ̀n Ọjoọ́ mélòó ni Coronavirus ń lò lára kí ènìyàn tó gba ìwòsàn?
"Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù End SARS protest: Nítorí ""Access Bank"" gbẹ́sèlé owó àwon olùwọ́de EndSARS ni a ṣe kó owó wa kúrò níbẹ̀ 16 Bélú 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 17 Bélú 2020 Oríṣun àwòrán, @JoeJoeSegun Awọn ọmọ Naijiria kan ti bẹrẹ si n ti apo ifowopamọ wọn nile ifowopamọ Access lẹyin ti banki naa gbẹsẹle owo awọn onibara wọn to lọwọ ninu iwọde EndSARS."
Ṣugbọn kabiyesi ní ọgbọ́n bí angẹli Ọlọ́run, láti mọ ohun gbogbo lórí ilẹ̀ ayé.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Amotekun Oyo: Ọwọ́ tẹ ènìyàn méjì tó ń ta ayédèrú aṣọ iṣẹ́ ikọ̀ Àmọ̀tẹ́kùn 9 Sẹ́rẹ́ 2021 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 16 Sẹ́rẹ́ 2021 Oríṣun àwòrán, AMOTEKUN Ikọ Amọtẹkun nipinlẹ Oyo ti fi lede pe ọwọ awọn ti ba afurasi meji to n ṣe aṣọ iṣẹ Ikọ Amọtẹkun ti wọn si n ta wọn.
Iṣẹ́ ìwádìí fi yé wa pé fún gbogbo ọdun tí kò fi sí Báálẹ̀ lórí ìtẹ́, igbimọ fìdí hẹ́ ni ó ń tukọ̀ ìlú.
Coronavirus in Kenya: Ojú òpó Facebook Live ni mo ti wo ìsìnkú ìbátan mi 'Bí Covid19 bá peléke síi l'Eko, ilé la ó ti máa tọ́jú àwọn kan' - Ìjọba ìpínlẹ̀ Eko Ikú tó pa Igbákèjì adarí òṣìṣẹ́ ní Osun kìí ṣe Coronavirus - Gomina Oyetola Nǹkan oṣù obìnrin le jáde ní imú tàbí ìdodo yàtọ̀ sí ojú ara - Dókítà Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí 3 sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
Oríṣun àwòrán, twitter/Babajide sanwo-olu Bi o tilẹ jẹ pe o jẹ igbesẹ to le koko gẹgẹ bi ajọ naa ṣe sọ ọ, wọn ti ṣe alakalẹ ilana ti yoo ṣamojuto irinajo lati gbe wọn wale ni ibamu pẹlu ofin to wa nilẹ.
Àtẹ́rígbà ìlẹ̀kùn náà rí ṣóńṣó ní ààrin, 
Sela, Haelefi, Jebusi (tí à ń pè ní Jerusalẹmu) Gibea, ati Kiriati Jearimu, gbogbo ìlú ati ìletò wọn jẹ́ mẹrinla.
“Bí ẹ bá rò ní ọkàn yín pé àwọn eniyan wọnyi pọ̀ jù yín lọ, ati pé báwo ni ẹ ṣe lè lé wọn jáde, 
“N óo sọ ilé Juda di alágbára,n óo sì gba ilé Josẹfu là.
Ó wá pa òwe yìí fún wọn.
Egbe oselu  PDP tun yan asofin  Sahabi Yau lati  Zamfara North gege bi igbakeji  adari eto igbimo asofin.
Bakan naa la ri ninu ere ori itage Edo yi pe Adams Oshiomole to ti kẹyin si Ize Iyamu to ko ipa ribi ribi nigba ti Oshiomole fi dupo Gomina ti wa pada wa fontẹ lu Iyamu gẹgẹ bi ayanfẹ rẹ bayi.
Ó wó gbogbo àwọn pẹpẹ oriṣa, ó wó gbogbo àwọn òpó tí wọ́n fi òkúta ṣe, ó sì gé gbogbo àwọn ère oriṣa Aṣera.
Lọdọ Funke Akindele n kọ lọsẹ yii?
Ireti ọpọ lori ifẹsẹwọnsẹ naa ko kuku ja sofo nitori bi ajere lo ṣe gbona janjan ṣugbọn lẹyin o rẹyin.
Ṣugbọn ori ko awọn to wa ninu ile yọ bo tilẹ ina mu Jude eyi to mu ki ara rẹ bo yanayana.
"Ìjọba Eko kọ orúkọ sí ""Palliatives"" tiwọn lára o, mo ní ẹrù tèmi f'ọjọ́ ìbí mi tí wọ́n jí - Họ́nọ́rébù Agunbiade Àkùkọ dojú ìjà kọ ọlọ́pàá, ikú ló já sí fún agbófinró Wo ìdí tí orílẹ̀-èdè America ṣe tako ìyànsípò Okonjo-Iweala gẹ́gẹ́ bi olórí ajọ WTO Wo ohun tí Fashola rí níbi ìṣẹ̀lẹ̀ Lekki Tollgate tó ń fa ariwo lórí ayélujara Ṣe lootọ ni ọpa aṣẹ Ọba ilu Eko ti pada si afin?"
 O ni nibi ti ọrọ de bayii, awọn alaga ti Makinde sọ pe ko fi ipo silẹ ni ẹtọ lati lọ sile ẹjọ.
“Bí ẹnìkan bá ṣẹ aládùúgbò rẹ̀, tí a sì mú un wá kí ó wá búra níwájú pẹpẹ rẹ ninu ilé yìí, 
Ṣugbọn iroyin sọ pe George bẹrẹ si ni jara mọ iṣẹ lẹyin to jade lẹwọn tan.
20 Bélú 2020 Èyí tí a wò jùlọ 5:03 Fídíò, Omolola Arohunmolase Welder: Mo ti fí iṣẹ́ 'Welder' gbayì láwùjọ, tó mo fi tọ́ ọmọ yanjú, Duration 5,039 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 5:39 Fídíò, Akomolede ati Asa lori BBC: Olùkọ́ Kikelomo Ogunboye tan ìmọ́lẹ̀ sí ìwà olè ọ̀gá ọlọ́pàá Audu gẹ́gẹ́ bí àwòkọ́ṣe àsìkò yìí, Duration 5,398 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 4:11 Fídíò, Oba Adeyeye Ogunwusi: Ojú mi ti rí lọ́pọ̀ lọpọ̀, ọ̀pọ̀ èèyàn ni kò tilẹ̀ gbàgbọ́ pé mo lè jọba- Ooni, Duration 4,117 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 4:43 Fídíò, Promise Akinlade: ọmọ ọdún mọ́kànlá tó ń fi ìlù dárà bíi àgbàlagbà sọ̀rọ̀ nípa tálẹ́ǹtì rẹ̀, Duration 4,437 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 0:59 Gbọ́, Ìsẹ̀lẹ̀ jákèjádò orílẹ̀èdè àgbáyé láàárín ìṣẹ́jú kan, Duration 0,59wákàtí 5 sẹ́yìn 7:03 Fídíò, Olumuyiwa Bolade Adedeji Military Bruitality: Bí arákùnrin onípèníjà ara tí sọ́jà lù ṣe dé, Duration 7,035 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 4:45 Fídíò, Yoruba Films: Ẹ̀ẹ́ bẹ̀ mi kúrò láyé ni, mi ò lè kú - Fadeyi Oloro, Duration 4,4526 Èrèlè 2020 2:48 Fídíò, Esther Ajayi: Èmi náà ti borí ìṣòro rí ló ń mu mi ṣojú àánú, Duration 2,481 Ògún 2019 6:08 Fídíò, Adebola Ademilua: Àìrísẹ́ ṣè lẹ́yìn ìwé kíkà ló sọ mi dí ìyá onírú, mo dúpẹ́ tèmi, Duration 6,0827 Bélú 2020 2:36 Fídíò, Sotitobire: Ìdájọ́ òdòdò ló fẹsẹ̀ múlẹ̀ lórí ọ̀rọ̀ Pásítọ̀ Sotitobire - Agbẹjọ́rò fún ìjọba, Duration 2,367 Ọ̀wàrà 2020 BBC News, Yorùbá Ìdí tí ẹ fi le è nígbàagbọ́ nínú ìròyìn BBC Ìlànà Lílò Nípa BBC Òfin Àṣírí Cookies Kàn sí.
Ṣugbọn abawọn naa ṣi wa nibẹ - eyi si lo le ju to si buru jai nipa titan iroyin ayederu kalẹ paapaa to tun wa bọ si asiko idibo.
Jesu bi í pé, “Kí ni orúkọ rẹ?
Ile Igbimọ Aṣofin Ipinlẹ Eko sọ pe awọn ti ṣetan lati mu ọrọ aabo ati irọrun ile pẹlu erongba wọn lati ṣe idasilẹ Ilana Akọsilẹ awọn oṣiṣẹ Olutọju ile ni Ile kọọkan ni Ipinlẹ Eko.
Bí ẹnìkan bá ṣẹ eniyan, Ọlọrun lè parí ìjà láàrin wọn; ṣugbọn bí eniyan bá ṣẹ OLUWA, ta ni yóo bá a bẹ̀bẹ̀?
Ọ̀gá àgbà FRSC Ondo jáde láyé Ìdùnnú ni yóò jẹ fún wa ti wọn bá ṣe àwọn ọnà tí kò dára wọnyíì-Bosun Aguda 60,000 àwakọ ló ń lo iwé ìrinà ọ̀kọ̀ tí kò k'oju oṣùwọn ní ìpínlẹ̀ Eko - FRSC Ìjọba Ondo kéde ìsimi ọ́sẹ̀ mẹ́ta fún àwọn ilé ìwé to lùgbàdì omíyalé!
Ṣugbọn nigba ti o ku iṣeju mẹrin ki ifẹsẹwọnsẹ ọhun pari ni Michy Batshuayi fi ibinu sọ ami ayo kan sinu awọn ikọ Ajax.
Nitori ọrọ ẹ ba mi sọ fisa igbelu mi dọtun - a o fun ọ, Oswald yii tun daran o ge ọrun ọwọ ọga ileeṣẹ to bẹẹ ṣugbọn ko ma baa si ija ilu si ilu, wọn dari ji i.
Moshood Kashimaawo Olawale Abiola ni wọn bi nilu Abẹokuta nipinlẹ Ogun lọdun 1937.
Ẹ óo ṣẹgun àwọn ìlú olódi ati àwọn ìlú dáradára wọn, ẹ óo gé gbogbo igi dáradára, ẹ ó dí gbogbo orísun omi wọn; ẹ óo sì da òkúta sí gbogbo ilẹ̀ oko wọn.
Orúkọ ìyá rẹ̀ ni Abi, ọmọ Sakaraya.
Mẹta ninu awọn eeyan naa lo wa lati ipinlẹ Ọṣun, eeyan kan yooku si wa lati ipinlẹ Ogun.
Ṣugbọn wọ́n lépa rẹ̀ lọ sí Lakiṣi, wọ́n sì pa á níbẹ̀.
Aarẹ Buhari gbe igbimọ naa kalẹ labẹ akoso onidajọ Ayọ Salami.
 iké-ẹ ̀ kọ ́ náà wà ní ilé-ifẹ ̀ ní ìpínlẹ ̀ Ọ ̀ ṣun .
Báyìí ni ìlù ń dún kíkankíkan tí àwọn méjéèjì ń mí hẹlẹ, tí ilẹ̀ ń mì tìtì, tí gbogbo igbó sì dákẹ́ minimini.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Akọ̀wé àgbà ìgbìmọ̀ ilé ìwòsàn ìpínlẹ̀ Ondo sọ̀rọ̀ lórí ìkọlù ilé ìwòsàn àwọn alárùn ọpọlọ Wọn ni ọpọ ọjọ lawọn alaboyun yii lo lai ri eeyan kankan ti yoo tọju wọn, ki awọn ọmọ wọn to wa ku lasiko ibi.
Oríṣun àwòrán, Eleta mike Idibo yii n waye lẹyin ti ẹgbẹ oselu APC ti ys ọwọ gomina Godwin Obaseki atawọn oludije meji miran, Chris Ogiemwonyi ati Mathew Iduoriyekenwen lawo idije naa.
Ṣugbọn ó tẹ àwọn díẹ̀ tí a yàn ninu wọn lọ́wọ́.
tun jẹ akoko fun wa lati ṣatunṣe iwa wa paapaa ninu ẹmi.
Aguda Ogba Fire: Iná míì tún sọ ní Ọgba, nílùú Eko!
Ninu ọrọ rẹ to fi sita loju opo Twitter, Dokita Stella kesi aarẹ Trump lati gba ohun lalejo ni olu ilu Amẹrika ti ṣe Washington DC nibi ti ohun ati awọn Dokita kan ti n sọrọ nipa lilo hydroxychloroquine.
Osun Osogbo festival 2019: Báwo ni àjọ̀dún Ọ̀ṣun Òṣogbo ṣe lọ lọ́dún yìí?
Àwọn oníṣẹ́ ọba lọ láti ìlú kan dé ekeji jákèjádò ilẹ̀ Efuraimu ati ti Manase, títí dé ilẹ̀ Sebuluni.
Oun naa ba BBC sọrọ pe oun loun ya fidio naa lọdun 2017.
5 ni agbegbe ilopomeji kilomita kan .
OLUWA ní, “Yóo máa pèsè ọ̀dọ́ aguntan ọlọ́dún kan tí kò lábàwọ́n fún ẹbọ sísun sí OLUWA lojoojumọ.
Ọgagun Abdulsalami Abubakar di olori ijọba ologun ni Naijiria, to si ṣeto idibo aarẹ miran, eyi to gbe oloye Olusẹgun Ọbasanjọ wọle bii aarẹ orilẹede Naijiria.
Nítorí pé Ọba Ìjẹ̀bú -Jẹ̀ṣà àti Ọwá Iléṣà jẹ́ tẹ̀gbọ́n tàbúrò látàárọ̀ ọjọ́ wá, àjọṣe tiwọn tún lé igbá kan ju ti gbogbo àwọn ọbà ilẹ̀ Ìjẹ̀ṣà tó kù lọ nítorí pé “Ọwá àti Ògbóni Ìjẹ̀bù -Jẹ̀ṣà ló mọ ohun tí wọ́n jọ dì sẹ́rù ara wọn”
Ilẹ̀ Tí Wọ́n Pín fún Ẹ̀yà Juda.
Sarumi ṣalaye fun BBC Yoruba idi ti oun ṣe darapọ mo ẹgbẹ oṣelu PDP bayii.
Rivers Police:wọ́ ọlọ́pàá ti tẹ àwọn afurasí tó lọ gbin ǹkan abúgbàmù sí ṣọ́ọ̀ṣì bàbá gómìnà Wike
Agbẹjọro mọlẹbi oloogbe naa lo ti kọkọ kowe beere fun igba miliọnu Naira lọwọ ile iwosan UCH, fun bi ile iwosan naa ṣe ja igbẹkẹle awọn kulẹ pẹlu bo ṣe jẹki aworan iku rẹ lu sita.
Nítorí Olodumare ti ṣe ohun ńlá fún mi,Mímọ́ ni orúkọ rẹ̀;
Ọmọkunrin kan ree, Jeewan, to gba ibiti ori daa si ni ori oke Himalayas lorilẹede Nepal tii se ilu abinibi rẹ, to si gbọdọ gun ori oke yii fun ọjọ marun ko to le fi oju kan awọn obi rẹ Ọmọ ọdun marun si lo wa to fi jade lọ kawe ni Snowland nilu Kathmandu, lẹyin ọdun mejila to si n pada bọ wale, o nilo lati pọn oke naa pada fun odidi ọjọ marun, ko to de ilu wọn.
Ohun to ku bayi ni ki ijọba se amojuto nina owo naa fun anfaani ara ilu.
Alamojuto ifehonu han naa,Brigitte Adjamagbo Johnson baa awon akoroyin soro pe, egbe alatako naa ko yiioro won pada, bee si ni ifehonu han ohun yoo waye.
Ṣebí bí iná ni ọ̀rọ̀ mi rí, ati bí òòlù irin tíí fọ́ àpáta sí wẹ́wẹ́?
Itz Yemi Abiola Black fẹran esi yi debi wi pe ohun naa pa ''suna'' orukọ miran fun Micheal Jackson, ti o si sọ ni orukọ ''Mukaila Sẹnwẹlẹ'' A ko mọ daju ẹni to da ọrọ naa silẹ ṣugbọn ninu awọn esi to wa loju opo BBC Yoruba Facebook, ko fẹ si ẹni ti o gbe lẹyin Beyonce, pe o ga ju Michael Jackson lọ.
Àwọn ni yóo máa ṣe iṣẹ́ ìsìn fún àwọn ọmọ Israẹli ní ibi mímọ́.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Coronavirus in Nigeria: Àwọn awakọ̀èrò, ọlọ́kadà arìnrìnàjò faragbá nínú ìpa Coronavirus 21 Ẹrẹ̀nà 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 23 Ẹrẹ̀nà 2020 Oríṣun àwòrán, Ekiti state government Gẹgẹ bii ara igbesẹ lati dena arun Coronavirus ni ipinlẹ Ekiti, ijsba ipinlẹ naa ti ti gbogbo ileewe to wa nibẹ pa.
Afẹ́fẹ́ gáàsì tí gbiná ní Ijora ìpínlẹ̀ Eko, bó ṣe n ṣẹlẹ̀ rèé Ẹkún àti ìbànújẹ́ láwọn mọ̀lẹ́bí fi sìnkú ọmọ méje ní Kumba, Cameroon lónìí Ìdájọ́ ikú ló bá dé fáwọn méjì tó fipá bá ọmọ ọdún mẹ́rìnlá lò pọ̀ Oyinkan Abayomi, akọni obìnrin tó fi ìfẹ́ pa orúkọ ọkọ kejì dà sí ti ọkọ àárọ̀ Bi wọn ṣe n gbe e lọ sẹwọn lo sọ ọrọ sorii Whatsapp to si ka ohun ara rẹ silẹ pe oun ṣetan lati lo gbogbo aye oun lẹwọn fun ohun ti oun gbagbọ ninu rẹ.
Kì í ṣe tiwa nìkan, ṣugbọn ti gbogbo ayé pẹlu.
Njẹ́ ọ̀dà tí wọ́n kun àgádágodo yìí rẹwà àbí kò rẹwà?
“Gbogbo ègún wọnyi ni yóo ṣẹ si yín lára, tí yóo sì lẹ̀ mọ́ yín pẹ́kípẹ́kí títí tí ẹ óo fi parun, nítorí pé ẹ kò gbọ́ ti OLUWA Ọlọrun yín, ẹ kò pa òfin rẹ̀ mọ́, ẹ kò sì tẹ̀lé àwọn ìlànà tí ó pa láṣẹ fun yín.
ígbà tí a kúrò ní ibi tí àwọn ẹranko wọ̀nyí wà tí a túbọ̀ rìn díẹ̀ síwájú si a rí ọ̀nà kékeré kan báyìí tí ó yà bá apá òsì lọ.
    Nígbà tí o di agogo márùn-ún láàátọ́, gbogbo ìlú bẹ̀rẹ̀ sii jó a si ń gbọ́ ìlú lọ́tùn-ún lósì.
Bakan naa nile ise Aare fi sinu ero ayelujara pe awon omo kan ni won ni won ti di awati latowo awon onise ibi boko haram lojo Aje nile iwe won ni Yobe ni eyi ti ijoba yoo ri aridaju pe won ri ominira won gba pada.
'Mo fi ẹsẹ min rin ninu igbo fun ọjọ mejọ' Ogunlọgọ awọn eeyan ni wọn padanu ile wọn ni agbegbe guusu Cameroon to gba ominira lọwọ eebo amunisin.
Arakunrin mi, mo fẹ́ kí o yọ̀ǹda ọ̀rọ̀ yìí fún mi nítorí Oluwa.
Wọn ni eroja ara ti orukọ rẹ n jẹ lycopene, eleyii to n mu ki ara ji pepe.
Oríṣun àwòrán, Others Garba Shehu fikun wi pe, nigba ti ẹgbẹ oṣelu APC gba iṣejọba ni ọdun 2015, awọn ṣeleri ati mu igbe aye rọrun fun awọn eniyan, ọdun marun si igba ti awọn wọle, awọn si n n gbe igbesẹ lati mu ohun gbogbo pada si ipo lorilẹede Naijiria.
Aarẹ orilẹ-ede China, Xi Jinpin ṣi afara naa ni ọjọ Iṣẹgun lẹyin ọdun mẹsan an ti wọn bẹrẹ kikọ rẹ.
Aare ana lorile ede Naijiria , Goodluck
Kò ní sí òru mọ́, bẹ́ẹ̀ ni wọn kò ní nílò ìmọ́lẹ̀ àtùpà tabi ìmọ́lẹ̀ oòrùn, nítorí Oluwa Ọlọrun wọn ni yóo jẹ́ ìmọ́lẹ̀ fún wọn.
Awọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ìdá àádọ́rin akẹ́kọ̀ọ́ pegede ní èsì ìdánwò NECO Wọ̀bìà, àjẹbánu ti mú káwọn èèyàn kọ ẹ̀sìn sílẹ̀ - Buhari Èèwọ̀!
Wọ́n rìn wọnú àfonífojì bíi mààlúù,Ẹ̀mí OLUWA sì fún wọn ní ìsinmi.
Nítorí náà, àwọn ẹ̀yà Dani rán akikanju marun-un láàrin àwọn eniyan wọn, láti ìlú Sora ati Eṣitaolu, kí wọ́n lọ ṣe amí ilẹ̀ náà kí wọ́n sì yẹ̀ ẹ́ wò.
, Duration 8,0016 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 6:56 Fídíò, Wòlíì Kasali sọ̀rọ̀ nípa awuyewuye pé ó lé ìyàwó rẹ̀ jáde nílé, Duration 6,5628 Ọ̀pẹ̀̀ 2018 2:59 Fídíò, Paystack Shola Akinlade: Ìgbésẹ̀ 5 yìí ni mo gbé tíléeṣẹ́ Stripe fi dókòwò $200m pẹ̀lú mi, Duration 2,5916 Sẹ́rẹ́ 2021 3:24 Fídíò, Àmì ohùn ṣe pàtàkí nínú èdè Yoruba púpọ̀, Duration 3,2422 Èbibi 2020 BBC News, Yorùbá Ìdí tí ẹ fi le è nígbàagbọ́ nínú ìròyìn BBC Ìlànà Lílò Nípa BBC Òfin Àṣírí Cookies Kàn sí.
Awon miran ti won dije pelu onluko orin Assurrance ni: Tiwa Savage, Booba (France), CassperNyovest (South Africa), Dadju (France), DistructionBoyz (South Africa), FallyIpupa (DR Congo), J Hus(UK), Niska (France), Stefflon Don (UK) ati StormzyEyi ni igba akoko ti Naijiria yoo gba ami eye BET ri pelu opo ero nikale.
Àwa méjèèjì lọ sí yàrá wa, a lọ kúnlẹ̀, a sì gbàdúrà wí pé kí Ọlọ́run dá ẹ̀mí rẹ̀ sí, kí ó má kǔ.
Nígbà tí ọ̀gágun náà kò lè mọ òtítọ́ ọ̀rọ̀ náà nítorí ariwo èrò, ó pàṣẹ pé kí wọ́n mú Paulu lọ sí àgọ́ àwọn ọmọ-ogun.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Coronavirus ti di ara wa, kò le è kúrò mọ láéláé - WHO Ìdí rèé tí ilẹ̀ Afirika fi gbọdọ̀ kópa nínú dídán abẹ́rẹ́ coronavirus wò Ẹ wo adúrú ẹnu tí mó n bọ́ - Jaiye Kuti Wo orílẹ́èdè tí wọ́n tí ń dáwó ìsìnkú ara wọn pámọ́ ''Àwọn ọmọ wa ma ń wọ ọkọ̀ ojú omi láìsí ẹ̀wù ìdàábòbò nítorí àti kàwé'' Tinubu ní kò jẹ́ kí àwọn ọmọ bíbí Eko gbérí nínú òṣèlú O salaye pe ẹrọ naa le sisẹ fun wakati mẹfa, ko to sinmi, ti ko si ni lo ju lita omi kan lọ.
Ìjì líle kan bá bẹ̀rẹ̀ lójú òkun, omi bẹ̀rẹ̀ sí ya wọ inú ọkọ̀; ẹ̀mí wọn sì wà ninu ewu.
Ọmọ iya kan naa ni wa.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Gbogbo agbára ni ọrọ bọọlu gba bayii, nilẹ tabi lojú ofurufu Bọọlu gbígbá ti di, 'A ju ara wa lọ; ìjàkadì kọ́'!
“Gbogbo ìdámẹ́wàá ilẹ̀ náà, kì báà jẹ́ ti èso ilẹ̀, tabi ti èso igi, ti OLUWA ni; mímọ́ ni fún OLUWA.
OLUWA bá sọ fún mi pé, “Àsọtẹ́lẹ̀ irọ́ ni àwọn wolii ń sọ ní orúkọ mi, n kò rán wọn níṣẹ́, n kò fún wọn láṣẹ, n kò tilẹ̀ bá wọn sọ̀rọ̀.
Ní gbogbo orílẹ̀-èdè tí a dárúkọ, yàtọ̀ sí orílẹ̀-èdè Nàìjíríà, òwò ẹrú ni ó gbé àwọn ẹ̀yà Yorùbá dé ibè
Orisun: Banki agbaye, 2018 Orilẹede wo ni wọn woye pe isẹlẹ iwa ajẹbanu ko ti wọpọ?
Ẹ sọ ǹkan ẸYỌ KAN tí ẹ mọ̀ NÍPA Olóògbé 
Mumini ni o ṣeni laanu pe Naijiria ko ti ri ọrọ yanju nipa ẹka yi ati pe bi eeyan ba ṣẹṣẹ n ronu ati ṣe iwadii dipo ko ma mu ọrọ abayọ wa,apẹrẹ pe ko ni nnkan ṣe ni.
Ojo Eko ṣe idiwọ fún káràkátà Ẹ ma tii dako nitori ojo akọrọ - Nimet Àwọn ọmọ Iyabọ Ojo rí Bàbá lẹ́yìn ọdún mẹ́fà ‘Ẹsẹ kikan kọ mi lati di alagbara’ Bóò ṣe lè yẹra fún ikú nígbà òjò - Onímọ̀ Ehi Iden 'Ewu ńlá ń bẹ nínú àṣìlò òògùn' Loni, BBC Yoruba jade lọ beere nipa irufẹ ọmọ ti orukọ amutọrunwa wọn jẹ Ajayi ni igboro.
Gẹgẹ bi adele Alaga, Giadom ti da gbagbo igbese ti Oshiomọle ru patapata lati Osu Kẹta, to fi mọ ayẹwo awọn oludije fun ipọ gomina ninu idibo sipo gomina nipinlẹ Edo.
"France Vs Nigeria: Super Falcons takú síbẹ̀, àmọ́ ẹ̀pa kò bóró mọ́ Àwòran bí Yorùbá ṣe gbayì ní Austria Ìtàn tó wà nídi òwe ‘Sebótimọ Ẹlẹ́wà Sàpọ́n’ Comrade Abioye ni ""idabobo Naijiria wa nilo ọgbọn inu ati ọgbọn ori, eleyi ti awọn agbaagba ẹgbẹ wa ni agbara ati ọgbọn inu bii oogun abẹnugọngọ ti wọn le lo lati dẹkun rẹ""."
Ìtàn ìgbé ayé Isola Ogunsola 'I-sho Pepper', ògbóǹtagí òṣèré tíátà tó s'eré Yorùbá yíká Nàìjíríà Ènìyàn 229 ló tún ṣẹ̀ṣẹ̀ ní ààrùn Covid-19 ní Nàìjíríà A óò dá ẹnikẹ́ni tó bá gbé ìwé àti àṣírí ìjọba síta lórí ayélujára lọ́nà àìtọ́ dúró - Ìjọba àpapọ̀ Èrò ọmọ Nàìjíríà sọ̀tọ̀tọ̀ lórí fàákájáa láàrin Abike Dabiri-Erewa àti mínísítà ètò ìbárẹ̀nisọrọ̀, Ẹni ti ọrọ naa ṣoju rẹ sọ pe awọn mọlẹbi ologbe ọhun pada wa si ilẹ isinku naa lati mọ biriki le iboji rẹ, ni wọn ba ka awọn ọkunrin naa mọ ibi ti wọn ti n gbiyanju lati ge ori oku ti wọn sin ni wakati diẹ sẹyin.
Awọn alaṣẹ ijọba ti kọkọ sọ wipe ko si ẹni to ji awọn ọmọ naa gbe, atipe se ni wọn sa lọ farapamọ kuro lọwọ awọn agbebọn naa.
Ṣùgbọ́n ó ní òun kò jẹ̀bi.
Oku iya ọmọ tuntun, oku ọmọ ikoko naa ati olubi rẹ ni wọn tọju pamọ sile igbokusi naa, amọ oku ọmọ yii nikan lo poora.
Oríṣun àwòrán, @pius Àkọlé àwòrán, Ojogbon to mọ oyun inu ikarahun igbin ninu imọ aṣa ilẹ Adulawọ Nitori naa o ṣeeṣe ko jẹ pe wọn ka Ọjọgbọn Adesanmi mọ awọn ọmọ Canada to ku ninu iṣẹlẹ ọhun nitori fọto rẹ to wa loju opo Facebook rẹ gan fihan pe iwe irinna rẹ si wa lọwọ rẹ nigba to wa ni papakọ ofurufu lọjọ Abamẹta.
Ó ròyìn ohun gbogbo fún wọn, ó bá rán wọn lọ sí Jọpa.
Buhari tó bá àwọn èèyàn orílẹ̀èdè South Africa kẹ́dùn lórúkọ àwọn ọmọ orílẹ̀èdè Nàìjíríà, wa rọ wọ́n láti gba ìmúlọ́kànle nínú onírúurú ìdáwọ́lé olóògbé Winnie, lásìkò tó ń sa ipá tiẹ̀ fún òmìnira orílẹ̀èdè South Africa kúrò nínú ìgbèkùn un amúnisìn.
    Lẹ́yìn èyí, ọkùnrin náà wá bẹ̀rẹ̀ síí sọ ìtàn ìgbésí ayé rẹ̀ gan-an ó dáhùn ó ni:
30 Àti pé àwa mọ̀ pé ìdáláre nípasẹ̀ ore ọ̀fẹ́ ti Olúwa àti Olùgbàlà wa Jésù Krístì jẹ́ títọ́ àti òtítọ́;
”Ṣugbọn baba iyawo rẹ̀ kò jẹ́ kí ó wọlé lọ bá a.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Akinwumi Adesina: Ọdún márùn ún ní Adesina yóò lò ní sáà kejì ipò adarí Báńkì AFDB 5 Òkùdu 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 1 Owewe 2020 Oríṣun àwòrán, OTHERS Ọmọwe Akinwunmi Adesina ti da Aarẹ Banki Ilẹ Afrika, AfDB lẹyin ti wọn bura wọle fun un ni Ọjọ Kinni, Oṣu Kẹsan an, ọdun 2020.
Nígbà tí Boasi jẹ, tí ó mu tán, tí inú rẹ̀ sì dùn, ó lọ sùn lẹ́yìn òkítì ọkà Baali tí wọ́n ti pa.
Fún àgọ́ tí ó wà ní ìwọ̀ oòrùn, àwọn mẹrin ń ṣọ́ ojú ọ̀nà, àwọn meji sì ń ṣọ́ àgọ́ alára.
Ọgbẹni Odumosu to ti n ṣaisan lati bi ọdun mẹwaa sẹyin ṣalaye pe ijọ RCCG ni ṣọọṣi akọkọ ti oun yoo lọ fun ẹbẹ adura lati igba ti aisan naa bẹrẹ.
Ó gbé e, ó sì lọ sílé.
Bi ayeye odun Eko Theatre Carnival se n sunmole ni won ti seto atileyin fawon ere alagbeka bii Saro, Waka ati Kakadu, eyi ti won pe ni ‘KultureFest’ ti yoo fun ayeye odun asa ni oriki tuntun.
Gbogbo eniyan a máa tètè jí láti lọ gbọ́ ọ̀rọ̀ rẹ̀ ninu Tẹmpili.
Ìgbà tí abàmì ẹ̀dá yìí dé ibi ọ̀pẹ́ wọn-ọnnì ó bẹ̀rẹ̀ sí gún wọ́n lọ́kọ̀ọ̀kan ó ń gbé ẹmu orí wọn, ìgbà tí ó bá sì da ẹmu inú akèǹgbè orí ọ̀pẹ kan sí inú akèǹgbè ńlá tí ó gbé lọ́wọ́ tán, a ju akèǹgbè ti orí ọ̀pẹ sílẹ̀ eléyìínì a sì fọ́.
Iwe iroyin Telegraph fi kun un pe, awọn ti ki i ṣe ọmọ orilẹede to jẹ ọmọ ẹgbẹ́ Commonwealth, ko ni le kopa ninu eto igbanisiṣẹ ọhun.
2020 Budget Defence: Buhari láwọn mínísítà kò gbọdọ̀ rìnrìn àjò lọ sí ilẹ̀ òkèrè
Ó bá jù ú sinu kànga tí ó jìn pupọ náà, ó pa ìdérí rẹ̀ dé mọ́ ọn lórí.
NCDC lo kede bẹẹ loju opo Twitter rẹ loru ọjọ Ẹti, ipinlẹ Kaduna si ni iye eeyan to pọ ju to ṣẹṣẹ ni arun ọhun ti wa.
Ṣugbọn àwọn tí wọn kò mọ Ọlọrundàbí igi ẹ̀gún tí a gbé sọnù,kò sí ẹni tí ó lè fi ọwọ́ lásán gbá wọn mú.
O tun wipe, ki ijọba ipinlẹ̀ naa da awọn osise ti wọn da duro lẹ́nu isẹ́ ni Ile-Iwosan Ikẹ́ẹ̀kọ́ Isegun ti ijọba ipinlẹ̀ Ọ́yọ̀ LAUTECH, pada sẹnu ise.
O ni ipinlẹ Eko ti ṣe ayẹwo to le ni ẹgbẹrun mejilelogun bẹẹ si ni wọn n tẹsiwaju tori eyi ni wọn ṣe gbudọ mura silẹ de afikun iye awọn to lugbadi arun yii.
Oríṣun àwòrán, AFP Àkọlé àwòrán, Boko Haram ti ngbogun ti orileede Naijiria Bii ọdun mẹrin sẹyin ni wọn ti ji awọn ọmọdebinrin ọrinlerugba din mẹrin lati ile-iwe kan ni Chibok, eyiti o yọri si ipolongo #BringBackOurGirls ni agbaye.
Nipa ti Black Panther to wọ yi,ẹgbẹ agbabọọlu rẹ salaye lọju opo wọn pe o ni ohun wọ awo naa lati fi sapejuwe orukọ ikọ agbagbọọlu orileede wọn ti orukọ rẹ n jẹ ''Black Panthers'' Aseyọri ẹgbẹ Arsenal ninu ifẹsẹwọnsẹ wọn yi tunmọ si wi pe awọn ati ẹgbẹ Chelsea yoo jijọ siwaju lati kopa ninu abala komẹsẹoyọ idije Europa League.
Makinde ṣalaye pe ipinlẹ Oyo ṣe ayẹwo Coronavirus fun ẹgbẹrun lọna ogun eeyan láàrin oṣu kẹta si oṣu kejila ọdun 2020.
“Fi awẹ́ aṣọ mọkanla tí wọ́n fi irun ewúrẹ́ ṣe, ṣe ìbòrí kan fún àgọ́ náà.
O ni iṣẹlẹ yi jẹ eyi ti ko yẹ ko waye ati pe oun ti kan si Kọmiṣọnna ọlọpaa ipinlẹ Oyo lati tọ pinpin ohun to fa iṣẹlẹ yi.
Buhari, Osinbajo, ẹ̀yin gómìnà, ẹ kéde dúkìá yín kọ́jọ́ méje tó pé-SERAP Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Fadele: Dán an wò, lóbí ìyá ọ̀kẹ́rẹ́ ni a fi ọ̀rọ̀ ọ̀kadà náà ṣe Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
    Wéré tí a ti ri ọkùnrin yìí la ti ṣo fún un pé a fẹ́ kí o ba ni wọlé lọ̀ sọ fún ọba pe a ti de.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ọ̀pọ̀ ìgbà ni Àtíkù Abubakar ti ń gbìnyànjú láti di ààrẹ Nàíjíríà Sé Ọbásanjọ́ jẹ́ Ọlọ́run ni?
Nítorí ìwọ ni o ti jẹ́ odi miìwọ sì ni ààbò mi nígbà ìpọ́njú.
Olorì Anu Adeyemi ń ṣe ọjọ ìbí, ẹ gbọ́ ǹkan tò sọ sí Kábíyésì Mo ti gbà báyìí pé ohun gbogbo tó n dán kọ́ ni wúrà - Olori Badirat Adeyemi Kí ló wà láàrin Olorì Badra àti Bobrisky, tí ọ̀rọ̀ wọn fi wọ̀?
Amọ bi arun naa ṣe buru to, awọn eniyan miran ṣi n ru ye, ti wọn si n sọ iriri wọn.
Awọn ọlọ́pàá fi aworan àwọn olè naa sita ninu ẹrọ ayelujara pẹlu ileri owo miliọnu marun un naira fun ẹnikẹni to ba kẹfin wọn nigboro tẹlẹ.
”Ṣugbọn wọ́n ní, “A kò ní dẹtí sílẹ̀.
Afẹ́nifẹ́re: A kò tíì ní ẹnìkankan táá gbè lẹ́yìn rẹ̀ fún ipò Ààrẹ
Àwọn obinrin mejeeji yìí han Isaaki ati Rebeka léèmọ̀ tóbẹ́ẹ̀ tí ayé sú wọn.
Aarẹ Ọna Kakanfo:Isẹ rẹ ni ko dena idunkoko ajeji nilẹ Yoruba
láti máa ṣe olórí àwọn ìjòyè rẹ̀,kí ó sì máa kọ́ àwọn àgbà ìlú ní ìmọ̀.
Tí ó bá wá láti Gbọ̀ngán, ó máa ń lò tó ọjọ́ márùn-ún ní Ifẹ̀ tàbí ọ̀sẹ̀ kan.
Bẹẹ si ni Sonko gba pe lootọ ni oun sa kuro lọgba ẹwọn lasiko ifọrọwanilẹnuwo kan lori mohunmaworan.
Awọn ohun ti wọn n sọ Aarẹ tẹlẹ, Oluṣẹgun Ọbasanjọ to n ṣatilẹyin fun oludije ẹgbẹ alatako, Atiku Abubakar, ti bu ẹnu atẹ lu Aarẹ Buhari lori igbesẹ gbigbogun ti Boko Haram.
Lẹyin ti o kuro ni ijọba, Ọjọgbọn Dora Akunyili wa lara awọn ti wọn yan fun igbimọ apero ti ijọba apaps gbe kalẹ fun agbeyẹwo ẹhonu awọn ẹya lorilẹede Naijiria.
Ẹnìkan ṣoṣo tí wọ́n ká ife náà mọ́ lọ́wọ́ ni yóo di ẹrú mi, ní tiyín, ẹ máa pada tọ baba yín lọ ní alaafia.
"Leanne sọ pé ""ẹ̀gbẹ́ ibùsùn mi ni mo ma ń fi ǹkan ìṣeré ìbálòpọ̀ mi sí ojoojúmọ́ sì ni mò ń lò ó""."
“Ìgbésí ayé eniyan le koko,ọjọ́ ayé rẹ̀ sì dàbí ti alágbàṣe.
Àkọlé àwòrán, Ààrẹ Muhammadu mú àdínku ba owó ìdánwo fún ìr'srún òbí-JAMB Nínú ọ̀rọ̀ tirẹ ọgbẹni Mubaraq Akintola tó jẹ onímọ nípa ètò ẹkọ nínú ọ̀rọ̀ tirẹ̀ sàlàyé pé ìgbésẹ̀ ààrẹ yìí jẹ ohun ìwúri sùgbọn kìí ṣe èyí níkan ní ǹkan tí ètò ẹkọ́ orílẹ̀-èdè yiìí nílo rèé lásìkò yìí.
Kò kọ ìwà àgbèrè rẹ̀ tí ó ń hù nígbà tí ó ti wà ní ilẹ̀ Ijipti sílẹ̀.
Máa bá ọ̀rọ̀ rẹ ǹṣó, ó ń dùn mọ́ mi, kò sú mi.
 Ajo UNRWA bere ise lati odun 1950 ni eyi ti o ti pese iranlowo fun o le ni milionu marun un Palestine.
Victor Osimhen Salary: $96m ni wọ́n ra atamátàsé náà láti Lille
Amoye  lori eto oro-aje Jamie Murray ati Tom Orlik so pe, botile je pe, “oro ohun je opin awada, “o je ohun ti ko le seese mo”.
A jẹ́ pé fún bíi ọdún kan péré náà ni ẹ̀rọ yìí fi nyára bí àṣá.
Obìnrin olówònààbí ta ọmọ rẹ̀ oṣù mẹ́rin ní N300,000 Iná sọ ní abáwọlé Eko, ọkọ̀ agbépo tún tí gbiná lórí afárá Magboro Ìdí tí a fi pa àwọn àgbẹ̀ onírẹ̀sì ní Borno, Boko Haram ṣàlàyé nínú fídíò tuntun Ṣé lóòtọ́ ni ìjà ti parí láàrin ìdílé Ayinde Barrister àti Kwam 1?
Ilu Ilọra ni itan sọ wipe Latoosa ti wa si ilu Ibadan nibi ti o ti darapọ mọ ikọ ọmọogun Ogunmọla, akọni jagunjagun ni ilu Ibadan.
Nígbà tí Jesu ṣe akiyesi bí àwọn tí a pè sí ibi àsè ti ń yan ipò ọlá, ó wá pa òwe kan fún wọn.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Eyi waye nitori bi o ṣe maa n fa ariyanjiyan laarin igbimọ ajọ to n mojuto idije naa, CAF ati awọn ẹgbẹ agbabọọlu nilẹ Yuroopu, to ni lati yọnda awọn agbabọọlu wọn fun idije naa lai jẹ pe saa bọọlu gbigba nilẹ Yuroopu ti pari.
Àkọsílẹ̀ gbogbo àwọn nǹkan yòókù tí Josaya ṣe ati iṣẹ́ rere rẹ̀, gẹ́gẹ́ bí a ti kọ ọ́ sinu ìwé òfin OLUWA, 
Ní àná, a gba ìhàlẹ̀ kan tí ó ń lérí mọ́ àwa àti àwọn àlejòo wa tí a bá tẹ̀síwajú pẹ̀lú ètò ìfọ̀rọ̀wọ́rọ̀ọ wa nípa LGBT.
Bí ó bá jẹ́ pé ẹ̀ ń gbẹ̀san nǹkankan ni, n óo da ẹ̀san tí ẹ̀ ń gbà le yín lórí kíákíá; 
Ninu ọkọ̀ yìí ni àwọn eniyan díẹ̀ wà, àwọn mẹjọ, tí a fi gbà wọ́n là ninu ìkún omi.
Ṣùgbọ́n nígbà tí a gbọ́ ọ̀rọ̀ tí ẹ̀dá pàtàkì náà sọ, ó dùn mọ́ ni nínú, àti pàápàá ní ìbẹ̀rẹ̀ ìrìnàjò wa, a mọ̀ pé Oládùmarè tí ó fẹ́ràn ọmọ ènìyàn to bi óo ti sọ yìí, kò ni jẹ fi wá ssílẹ̀ ní àkókò ìyọnu.
"Ọpẹ mi lọ si ọdọ baba mi Asiwaju Bọla Tinubu ati gomina ipinlẹ Eko, Babajide Sanwo-Olu fun agbekalẹ ayika to jiire ati iwuri ti wọn se fun isipo rọpo awọn asaaju ẹgbẹ NURTW nipinlẹ Eko.
”Leyin idibo ti awon eniyan ba se agbeyẹwo rẹ,ayọ ati ifẹ ni yoo
Lẹẹmẹji ni ile aṣofin agba Naijiria tako iyansipo Ibrahim Magu gẹgẹ bi alaga ajọ EFCC.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ooni Ogunwusi: Ìròyìn òfégè ló ń lọ kiri pé ìyàwó mí bimọ tuntun 2 Ọ̀wàrà 2020 Oríṣun àwòrán, INSTAGRAM Àkọlé àwòrán, Ọdun 2018 ni Ooni ti Ile Ifẹ, Oba Adeyeye Ogunwusi gbe Olori Naomi Silekunola Ogunwusi ni iyawo.
Aaroni ju ọ̀pá rẹ̀ sílẹ̀ níwájú Farao ati àwọn ẹmẹ̀wà rẹ̀, ọ̀pá náà di ejò.
Nibayii, gbogbo oju lo wa lara idibo sipo Ondo ti yoo waye ni Ọjọ Kẹwa, Oṣu Kẹwa, ọdun 2020.
Àwọn ìjòyé wọ̀nyí dúpẹ̀ lọ́wọ́ ọba wọn wọ́nj sì fi ohùn kan wí bàyìí pé, Aláṣẹ, èkejì òrìṣà, a dúpẹ́, a óò dúró kí ọ̀ràn ṣe ojú wa.
Igibmo naa ni awon seto idanwo
Bakan naa ni Chief Kanran fikun wi pe lọpọ igba ijọba kii ṣe iranwọ fun awọn oṣere bi ko ṣe pe asiko ti wọn ba ṣe aisan tabi ti wọn ba ku , ki wọn to dide iranlọwọ si wọn.
Nígbà náà ni mo wí pé, “Wò ó, mo dé;a ti kọ nípa mi sinu ìwé pé:
104 billion), ti won yoo si pese owo ti o ku ti n se bilionu méjídínlọ́gọ́rin le ọ́ọ̀dúnrún o le logójì  (N78.
Aṣofin Sunday Akinniyi to n ṣoju ẹkun keji Ikẹrẹ lawọn aṣofin akẹgbẹ ni awọn ko gbọdọ gburo rẹ ni agbegbe gbagede ile igbimọ aṣofin ipinlẹ naa.
Ọdún meje ati oṣù mẹfa ni ó fi jọba lórí ẹ̀yà Juda ní Heburoni.
Alcohol Sanitizer: Èèyàn 86 tó mu ọtí ayédèrú d'èrò ọrùn ní India, ìwádìí bẹ̀rẹ̀
Àwọn lè wọlé nítorí pé wọ́n mọ́.
Oríṣun àwòrán, CHESTER ZOO Àkọlé àwòrán, Awọn akika n koju isoro kíkó kuro ni ibùgbé wọn Erọ ayaworan ọhun ká ẹranko to le ni ẹgbẹrun lọna aadọta laarin ọdun 2015 ati 2017.
Ilé ẹjọ́ rán àwọn mérìndínlógún lẹ́wọ̀n gbére fún dídáná-sun Nusrat Àrá tún ti sán pa màálù mẹ́jọ ní ìpínlẹ̀ Ondo Idi ti ọgba ẹwọn fi nkun akunfaya ni Naijiria Sophie ri ibi kan ni ilẹ Turkey ti won ti le ṣe iṣẹ abẹ naa ṣugbọn ti owo rẹ fẹ wọn ko too ri ọna abayọ.
Ibalu jẹ, ibẹbi jẹ, ibara jẹ, ibadugbo jẹ ni."
Aarẹ Macro ni ni wọnti ri ina naa pa ko to jo inu ile ijọsin nla gangan.
Oríṣun àwòrán, APC Ni ibi eto idibo naa to ṣi n lọ lọwọ lasiko ti a n ko iroyin yii jọ, gbogbo awọn aṣoju to wa dibo nibẹ ni wọn lo ibomu wọn ni ibamu pẹlu ilana ofin COVID-19 ni ipinlẹ Edo.
Bakan naa si ni iwadi kan ti banki agbaye gbe sita lọdun 2011 fihan pe ida mọkandinlaadọta ninu ọgọrun un awọn to n bimọ lorilẹ-ede Naijiria lo jẹ wi pe kii ṣe ileewosan ni wọn bimọ si.
Ẹrú ni wá; sibẹ ìwọ Ọlọrun wa kò fi wá sílẹ̀ ninu oko ẹrú, ṣugbọn o fi ìfẹ́ ńlá rẹ tí kì í yẹ̀ hàn sí wa, lọ́dọ̀ àwọn ọba Pasia; o sọ wá jí láti kọ́ ilé Ọlọrun wa, láti tún àwọn àlàpà rẹ̀ mọ ati láti mọ odi yí Judia ati Jerusalẹmu ká.
Àwọn ǹkan tí ó yẹ kí o mọ̀ nípa 'Sharia Law' ní Nàìjíríà Ọwọ́ ọlọ́pàá ìpínlẹ̀ Kebbi tẹ bàbá àti ìyàwó rẹ̀ méjì fún pé wọn so ọmọ pọ̀ mọ́ ewúrẹ́ fún ọdún méjì Orílẹ̀-èdè Chad pé ọgọ́ta ọdún, àwọn ara ìlú ń pariwo lábẹ́ Aàrẹ Deby tó gba 'Field Marshal' Belarus tó ń gbóná lọ́wọ́ torí ààrẹ tó ti lo ọdún 25 lórí oyè, nkan márùn ún tí o kò mọ̀ rèé Thelma ni awọn mọ pe Olorun to fun awọn ni awọn ọmọ mẹfa yii lẹẹkan ṣoso naa ni yoo pese owo ti awọn yoo fi tọ wọn bi o ṣe yẹ!
Ta ló ti kó afẹ́fẹ́ jọ sí ọwọ́ rẹ̀?
14 Bélú 2019 Oríṣun àwòrán, Google Àkọlé àwòrán, Aworan Ernest Okonkwo ati awọn kọmẹntátọ̀ miran nibi ti wọn ti n pitu Lara akoko ti awọn ọmọ Naijiria maa n ṣafihan idunnu ni igba ti ikọ agbabọọlu Naijiria ba n jade sori papa ere bọọlu.
Mo sì mọ̀ pé wíwẹ̀ ni wọ́n lọ wẹ̀ ẹ́ nítorí mo ri àwọn ènìyàn wa tí wọ́n ń gbé kàn-ìn-kàn-ìn, igbá omi, aṣọ ìnura, wọ ilé.
Buhari nikan ni ẹgbẹ oṣelu naa fa kalẹ lati dije.
7 344497 Orilẹede Portugal 4963 48.
Omíyalé gbẹ̀mí èèyàn méje, o tún ba dúkìá púpọ̀ jẹ́ Kínni ife ẹ̀yẹ ti Tiger Woods gbà ní Augusta fi yàtọ́?
Nigba ti awọn Gomina ri ohun to n sẹlẹ ti ẹru si ba wọn pe awọn ọmọ yi le ko arun yii, ni wọn ba pinnu lati da awọn alumajiri pada si ilu wọn.
O ni lọwọlọwọ bayii, ọpọlọpọ awọn agbẹ lo ko le de oko wọn mọ nitori awọn janduku to n dunkoko mọ wọn lọna.
Èrò ti èmi pàápàá ni pé ki ń sa ipá mi tó bí ó ti yẹ láti lè mú kí àwọn ọmọ ilé ìwé wa lè máa fẹ́ láti ka ìwé ní èdè wọn, ìdí rẹ̀ sì ni èyí tí o fi jẹ́ pé bí ọmọ kan ba ti bẹ̀rẹ̀ sí ka ìwé wọ̀nyí, yóò fẹ́ kí òun mọ ibi ti ó gbẹ́yìn sí, ìgbà tí ọmọ kan ba rí i pé Ìrìnnkèrindò wọle dé, yóò fẹ́ kí òun lè mọ ohun gbogbo tí ó wá ṣe.
Bi awọn kan ṣe gboriyin fun un lawọn kan n bu ẹnu atẹ luu.
" Nigba to n sọrọ lori aheso ọrọ kan to ni Baba Suwe lo lu iyawo rẹ titi ti onitọun fi jade laye, Baba Suwe ni eyi ko ri bẹẹ rara nitori ko si ija abi ita ni aarin awọn, oun ko si lọwọ ninu iku obinrin naa.
Gbogbo àwọn eniyan wọnyi yóo sì mọ̀ dájú pé OLUWA kò nílò idà ati ọ̀kọ̀ láti gba eniyan là.
Lẹ́yìn èyí ó wọ àgbàlá rẹ̀ lọ o sì bẹ̀rẹ̀ síí wá igi láti ffi dáná sun mi, ṣùgbọ́n kí ó tó padà dé, atẹ́gùn ti fẹ́ sí mi mo sì ti dìde, mo sálọ.
Bí wọ́n ti wí ni ọ̀rọ̀ yóo rí fún wọn.
Nítorínáà ènìà ní látimáà fo àwọn odi wọ̀nyìí kọjá nígbà kọ̀ọ̀kan.
Oríṣun àwòrán, @Bashir Ahmaad Atẹjade kan ti Oludamọran agba rẹ feto iroyin, Muyideen AKorede fisita ni, ijọba ti ko awọn agbofinro sita lati fi ẹsẹ eto aabo mulẹ dain-dain, eyi ti yoo fun awọn oludibo lanfaani lati wa se ojuse wọn.
Bakan naa, ni ọba alaye ọhun ẹni to tun gbarata lori ebu ẹyin to n ba ipese awọn ohun eelo amayedẹrun lorilẹede yii, wa ran awọn ọba alaye leti pe lati ọdun gbọọrọ wa ni wsn ti n se akoso awujọ wọn, ki ijọba to gba wọn sẹyin lọdun 1914, ti isopọ waye ni Naijiria.
Ọjọ kẹrinla oṣu kẹfa, ọdun 2020 ni arabinrin Ibidunni dagbere faye lẹni ọdun mọkandilogoji to ku oṣu kan pere ko ṣe ayẹyẹ ọjọ ibi ogoji ọdun.
Ní ọjọ́ keji, bí Johanu ati àwọn meji ninu àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ ti tún dúró, 
Naijiria bẹrẹ iwadi lori owo iranwọ epo A kò tí ì gbọ́ ǹkankan lórí owó ìwé ìrìnnà sí Naijiria - U.
Gbogbo awọn olorin naa lo si ni ode wọn jẹ manigbagbe.
Ó dàbí ìwúkàrà tí obinrin kan mú, tí ó pò mọ́ òṣùnwọ̀n ìyẹ̀fun ńláńlá mẹta títí gbogbo rẹ̀ fi wú sókè.
Tí a fiṣọwọ́ ní 8:54 8 Ọ̀pẹ̀ 20208:54 8 Ọ̀pẹ̀ 2020 Àwọn èèyàn tí bẹ̀rẹ̀ sì ní gba abẹ́rẹ́ àjẹsára fún ìdènà àrùn Coronavirus ni ilẹ̀ Gẹ̀ẹ́sì Ilẹ Gẹẹsi ni orileede akọkọ lagbaye to ti bẹrẹ si ni lo abẹrẹ ajẹsara ti Pifizer pọn lẹyin ti ijọba fontẹ lu lilo rẹ lọsẹ to kọja.
''Mi o lero wi pe yoo ṣe daada nidi ẹṣẹ jija yi nitori ko lara pupọ.
Ẹni tí ó bá ṣẹgun ni a óo wọ̀ ní aṣọ funfun bẹ́ẹ̀.
Nigba to tun n dahun ibeere lori itọju awọn akanda ẹda, Akeredolu ni oun kii ta awọn akanda ẹda nu rara.
 Òun àti ilésanmí ni wọ ́ n jọ lọ .
Local Flight: Àyípadà tó bá pápákọ̀ òfurufú Abuja rèé bí ìrìnà òfurufú abẹ́lé ṣe bẹ̀rẹ̀
 fún ni okun ; fún ní agbára .
Báyìí, a kò sin Ọlọrun lọ́nà àtijọ́ mọ́, àní lọ́nà ti Òfin àkọsílẹ̀, ṣugbọn ní ọ̀nà titun ti Ẹ̀mí.
ati gbogbo òpó àgbàlá yíká, pẹlu àwọn ìtẹ́lẹ̀ wọn, èèkàn wọn, ati okùn wọn.
Wọn yóo kó ninu àwọn ọmọ rẹ lọ fi ṣe ìwẹ̀fà ní ààfin ọba Babiloni.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Taba pe oriṣiriṣi ti wọn n ri l'agbegbe Amerika nibi ti awọn ara ilu ti n lo o gẹgẹ bii oogun ki awọn oyinbo alawọ funfun to de ibẹ WHO sọ pé Taba n pa to ilaji awọn to n mu siga lọdun, eyi ti numba wọn to miliọnu mẹfa eniyan.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù ALGON: 35% la fẹ́ kíjọba àpapọ̀ máa pín bíi owónàá fún ìjọba ìbilẹ̀ 24 Ògún 2019 Oríṣun àwòrán, Algon Àkọlé àwòrán, A kò lé fáramọ bí ẹ sé fẹ́ maa pín owó Nàìjíríà: ALGON Agbarijọpọ ẹgbẹ́ awọn ìjọba ìbílẹ̀ jákèjádò orílẹ̀-èdè Nàìjíríà (ALGON), tí ké sí ìjọba apapọ̀ pé, ìlànà ti wọ́n fẹ́ máà fi pín owónàá oṣooṣù ko tẹ́ àwọn lọ́rùn rárá, àfi kí wọ́n máa pín ni ìdá márùndínlógójì nínú ìdá ọgọ́rùn.
Oríṣun àwòrán, Others Nigba to n kẹdun iku to mu akikanju osere naalọ, Foluke sọ loju opo Instagram rẹ pe kii dun mọ oun ninu lati ri ki awọn agba osere maa jade laye.
Ile ijo naa to wa niluu Paal lorilẹede Belgium di titi pa lọjọ Ẹti to lọ ni deedee ago mẹsan an aabọ.
Ara olúwarẹ̀ a wá yá gágá.
Jẹ́ kí ojurere OLUWA Ọlọrun wa wà lára wa,fi ìdí iṣẹ́ ọwọ́ wa múlẹ̀,jẹ́ kí iṣẹ́ ọwọ́ wa fi ìdí múlẹ̀.
 Opolopo awon akekoo ro pe igbaradi fun eto aabo kuro ninu ijamba ina ni agogo ikilo to dun naa je ni.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Minimum Wage: Ààrẹ Buhari ti buwọ́lu #30,000 owó oṣù òsìsẹ́ 18 Ìgbé 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 19 Ìgbé 2019 Oríṣun àwòrán, PIUS UTOMI EKPEI Àkọlé àwòrán, Iye owo oṣu oṣiṣẹ́ jẹ nnkan ti o n kọ ọpọ oṣiṣẹ lominu ni Naijiria Aarẹ Muhammadu Buhari ti buwọlu eto owo oṣu tuntun fun awọn oṣiṣẹ ijọba.
Ti a ba si fi bi mo ti ṣe ka nipa arun yi ati imọ ti mo ni,mo lero pe lilo hydroxychloroquine lati tọju awọn eeyan nibẹrẹ ni anfaani to pọ'' ''Mi o lero pe eeyan le padanu nkankan ti o ba lo bi kii ṣe pe lọdọ awọn oloṣelu ọrọ yii ko ta leti wọn'' Trump fi kun pe ''Bi mo ba daba nkan , wọn maa n fẹ lati sọ pe 'ẹ ma tẹlẹ ọrọ rẹ' .
 lẹ ́ yìn ìwọ ̀ n egbògi náà kanṣoṣo , iye àwọn ọmọ oṣù mẹ ́ ẹ ̀ sán tó pọ ̀ tó 85 % àti àwọn ọmọ tó ti ju oṣù méjìlá lọ tó pọ ̀ tó 95 % ni yóò ní agbára tó péye láti kojú àrùn náà .
N kò sì gbàgbé ààfin náà láéláé, ọba Igbó Olódùmarè ṣe ìtọ́jú mi.
Lara awon to wa nibi isin idupe ohun naa ni adari awon osise orile ede Naijiria , arabinrin Winifred Oyo-Ita,minisita fun Niger-Delta , Pasito Sani Uguru, asoju ile –ise awon omo ogun oju omi ati ti omo ogun ile.
Ìtàn ayé Henry Fajemirokun, olówó tó fi owó mọ Olúwa àti ènìyàn Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Má pa wọ́n, kí àwọn eniyan mi má baà gbàgbé;fi ọwọ́ agbára rẹ mì wọ́n,ré wọn lulẹ̀, OLUWA, ààbò wa!
 ní ilẹ ̀ amẹ ́ ríkà iye owó rẹ ̀ bíi 50 sí 100 usd .
Ti a ko ba gbagbe, igbakeji aare, Yemi Osinbajo nigba to hun si ipade eto aabo ti ile igbimo asofin gbe kale, sowipe idasile olopa ipinle yoo bojuto wahala to n sele laarin awon darandaran ati agbe lorileede Naijiria.
''Ati ẹni to n ta ata lọja ati awọn ti ko ni nkan ṣe pẹlu dọla, gbogbo wọn ni yoo gbe owo ọja lọ soke.
Wasiu lo gboṣuba kare naa fun Barrister nibi ayẹyẹ iranti ọdun kẹwaa to jade laye, eyii to waye ni Ikoyi, ni ipinlẹ Eko.
Ó sọ fún wọn pé, “Ó ye yín pé ó lòdì sí òfin wa pé kí ẹni tíí ṣe Juu kí ó ní nǹkan í ṣe pẹlu ẹni tí ó jẹ́ ẹ̀yà mìíràn, tabi kí ó lọ bẹ̀ ẹ́ wò ninu ilé rẹ̀.
Egbe ohun tun sapejuwe iwa ti o gbode kan laarin awon egbe oselu kookan lati maa ra ibo lakoko idibo gege bi iwa ibajẹ, eleyi ti o si le e dena ilosiwaju orile-ede.
Ọmọ Yorùbá mẹ́wàá tó jẹ́ àmúlùúdùn ní Amẹ́ríkà àti Yúróòpù Àwọn alágbára ni mo bá díje ṣùgbọ́n mo ti gbà f'Olọrun- Agboola Ajayi Ènìyàn 653 míràn tún kún iye àwọn tó ní COVID-19 ní Nàìjíríà Bàbá mi Aláàfin, ẹ ṣeun ẹ̀bùn owó tí ẹ fún èmí àti ọkọ mi- Lizzy Anjọrin Agbẹjọrọ ijọba naa fikun pe ijinigbe ọmọ naa ko ni nkankan ṣe pẹlu oun, nitori naa ko kan oun.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Gọngọ sọ, ẹlẹ́há pàdé àwọn tó lùú ní jìbìtì nílùú Eko lọ́jà Ibadan Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Gọngọ sọ, ẹlẹ́há pàdé àwọn tó lùú ní jìbìtì nílùú Eko lọ́jà Ibadan 14 Agẹmo 2019 Gbẹgẹdẹ gbina lọja awọn olohun eelo iranṣọ ni Ogunpa nilu Ibadan nigba ti ẹlẹha kan ṣa deede fi igbe ta to n pariwo mo ti ri ọ!"
Coronavirus: Àwọn ohun tí a kò tíì mọ̀ nípa àrùn Covid-19 Àrùn Coronavirus fa'lẹ̀ya láwọn ìletò aláwọ̀dúdú ní Amẹ́ríkà Kí lo mọ̀ nípa fẹntilétọ̀, ohun èlò aṣèrànwọ́ èémí Èyí ni ìdí tí coronavirus ṣe n pa àwọn kan, tí kò sì pa àwọn kan Yewande bí'mọ tuntun jòjòló, Mercy Aigbe pàdánù èèyàn rẹ̀, Toyin Abraham fèsì lórí aṣoju NCDC Àkọlé àwòrán, Yewande bi'mọ tuntun jòjòló, Mercy pàdánù èèyàn rẹ, Toyin Abraham fèsì lórí ìi asoju NCDC Toyin Abraham Gẹ́gẹ́ bi ilé iṣẹ́ BBC News Yoruba lọ́jọọ́jọ́ Jímọ ni a tún mú àwọn ǹkan ti o ṣẹlẹ̀ láàrin àwọn òsèrè Nollywood Naijiria.
Lọjọ Aiku ni iroyin gba gbogbo ori ayelujara pe awọn ọlọpaa SARS yinbọn pa ọkunrin kan, Kolade Johnson, ni agbegbe Onipẹtẹsi, Mangoro niluu Eko.
O fikun pe, obinrin to ba wa ninu isẹ tiata gbọdọ ko ara rẹ nijanu, ko si mọ ibi to n lọ.
Won ko afara oni mita meta le laadota ohun ki o le fi rorun fun awon ero ti won n fese rin lati maa tete koja ni paapaa lati ogba fafiti naa lo si odi keji ni eyi ti won si lojo Abameta to koja.
Lailai Apostle Suleiman kò lè gba onídùúró mí!
Ìran ti ẹbọ àṣáálẹ́ ati ti òwúrọ̀ tí a ti là yé ọ yóo ṣẹ dájúdájú; ṣugbọn, pa àṣírí ìran yìí mọ́ nítorí ọjọ́ tí yóo ṣẹ ṣì jìnnà.
Ó kó wa wá sí ìhín, ó sì fún wa ní ilẹ̀ yìí; ilẹ̀ tí ó ní ọ̀rá tí ó kún fún wàrà ati oyin.
Ọlọrun mi yóo pèsè fún gbogbo àìní ẹ̀yin náà, gẹ́gẹ́ bí ọpọlọpọ ọrọ̀ rẹ̀ tí ó lógo nípasẹ̀ Jesu Kristi.
Awọn alaṣẹ Taliban ni tootọ ni ijiroro n waye.
Alaga ẹgbẹ Christian Association of Nigeria sọrọ lori iriri rẹ nipa awọn to ti kagbako agbebọn fulani darandaran ni eyi to jẹ ki oun le fi gbogbo énu sọ pe oniṣẹ ibi wa ninu wọn.
Gẹ́gẹ́ bí akọ̀ròyìn ilé isẹ́ BBC tó wà nílu Abuja, Chris Ewokor se sọọ́, adarí àjọ tó ńrísí ìkànìyàn lórílẹ́èdè Nàìjíríá sọ wípé, péréte mílíọ̀nù mẹ́jì ló kù kó ká ígba mílíọ̀nù.
Ìyàwò kejì tó fi owú ré ọkọ bọ́ láti òkè pẹ̀tẹ́sì gba ìdájọ́ ikú Ẹ̀wọ̀n gbére ni fún ẹnikẹ́ni tó bá fipá bánilòpọ̀ ní ìpínlẹ̀ Ọ̀ṣun Lẹ́yìn tó ṣá Monisola aya rẹ̀ ládá, Oniya ní iṣẹ́ èṣù ni Wèrè tí mò ń ṣe ní Facebook ló pawó fún mi-Esabod Èèyàn 104 kó covid-19 ní iléeṣẹ́ kan ṣoṣo ní Sagamu- Ìjọba Ogun Bí Gómìnà Makinde bá ṣẹ̀ mí, lẹ́tà lásán ló jẹ mí- Aláàfin Ọ̀yọ́ Kónílé-ó-gbélé Covid 19 ló tú àṣírí àwọn àfipábánilòpọ̀ láwùjọ- Mínísítà ọ̀rọ̀ àwọn obìnrin Ọjọ kejila oṣu kẹfa ọdun 1993 lawọn ọmọ Naijiria dibo aarẹ ninu eyi ti MKO Abiola ti ẹgbẹ SDP ti waako pẹlu Alhaji Bashir Tofa ti ẹgbẹ NRC.
" Bakan naa lo tun ti paṣẹ fun Kọmisanaa ọlọpaa nipinlẹ Delta lati ṣewadii iṣẹlẹ naa, ko si ri i pe ọwọ tl awọn to hu iwa naa.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Election 2019 Updates: Atiku n ṣé iranran lórí ìbò 1.
Ẹ mú owó fadaka kan wá fún mi kí n rí i.
Ìbosí o, ìbòsí o, Ẹlẹ́gbára ń bọ̀ lọ́nà o- a kì í wò ó, ẹni wòó á kú, ẹni kò ó ìjàngbọ̀n lọ́nà, ẹni ríi, rí ìbànújẹ́ ọ̀ṣán gangan, a kìí wò ó!
Wọ́n ní dandan kí ń fa ọmọ mi kan yòókù kalẹ̀ fún àwọn, kí wọ́n lè pa á nítorí arakunrin rẹ̀ tí ó pa.
Kí Israẹli máa yọ̀ ninu Ẹlẹ́dàá rẹ̀,kí àwọn ọmọ Sioni máa fò fún ayọ̀ pé àwọn ní Ọba.
Ṣugbọn gbogbo àwọn àgbààgbà dá ìjọ eniyan náà lóhùn pé, “A ti búra fún wọn ní orúkọ OLUWA Ọlọrun Israẹli, a kò sì gbọdọ̀ fọwọ́ kàn wọ́n mọ́.
Ọrọ ina mọna-mọna Naijiria lo ba lọ sibẹ.
” Ìdí nìyí tí wọ́n fi ń pe ibẹ̀ ní Giligali títí di òní olónìí.
Dokita Okonjo-Iweala, ti o sise lasiko isakoso ijọba aare Goodluck Jonathan, ni igbimo to n sakoso Twitter yan pelu Robert Zoellick gege bi oludari eka iforotonileti ile-ise naa.
Ẹgbẹ agbabọọlu ilẹ Sweden, Ostersunds FK, na Arsenal pẹlu ami ayo meji si ẹyọkan, ṣugbọn ẹgbẹ Wenger naa tẹsiwaju si ipele ẹgbẹ mẹrindinlogun ikayin ninu idije Europa.
Ọmọ-ẹ̀yìn keji tí ó kọ́kọ́ dé ẹnu ibojì náà bá wọ inú ibojì; òun náà rí i, ó wá gbàgbọ́.
Arsenal gbẹ̀yìn gbé ru Aston villa Ọpẹ́ o!
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ African in Greenland: Kí ló sún ilẹ̀ Afirika dénú gbígbé inú yìnyín?
Madueke ni idanilekoo yii yoo je ki awon odo naa ni imo kikun si I ki awon naa di akosemose ki won le maa gba awon eniyan sise laipe ojo fun ogo orile ede Naijiria.
3 1856 Orilẹede Guinea 76 0.
O ni ohun meji to ṣe pataki lori ṣiṣe ipilẹ ile ni bi ilẹ ba ṣe lagbara to ati bi ile naa maa ṣe tobi to.
N kò lọ́wọ́ nínú ìpànìyàn, kò dáa bí wọn ṣe lo ọta ìbọn ní Lekki - Tinubu Oríṣun àwòrán, @AsiwajuTinubu Aṣiwaju ẹgbẹ oṣelu APC, Bola Ahmed Tinubu ti sọ pe, oun ko lee ba ẹnikẹni lọwọ ninu iṣekupani ọpọ eniyan.
Nítorí náà, lọ wẹ̀, kí o sì fi nǹkan pa ara.
Ohun tí wọ́n fi ń ṣe báàgì, bàtà ni wọ́n ń tà bíi ‘pọ̀ǹmọ́’— NAFDAC Ṣé o mọ̀ pé ìwé ẹ̀rí ìgbéyàwó rẹ lè jẹ́ ayédèrú?
Omoyele Sowore ti pari gbogbo eto beeli rẹ lọjọru ṣugbọn awọn alaṣẹ kọ lati tu u silẹ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Àsìkò Amojúẹ̀rọ Seyi ni ló fi wọlé l'Oyo, kìí ṣe àsìkò èmi Omobolanle' Láti ìgbà náà ni ìjọba ti ya ọjọ́ náà sọ́tọ̀ fún síse àyájọ́ ọjọ́ àwọn èwe àti yíyẹ́ wọn sí láì ya ọmọ kan sọ́tọ̀.
 Bi ẹ ko ba gbagbe, ni alẹ ọjọ aiku ni INEC kede esi idibo sile aṣofin agba lẹkun aringbungbun Kwara ninu eyi ti oludije ẹbẹ oṣelu APC, Oloriẹgbẹ ti fagba han Bukọla Saraki."
Má fi kún ọ̀rọ̀ rẹ̀,kí ó má baà bá ọ wí,kí o má baà di òpùrọ́.
Ọlọrun dá ìmọ́lẹ̀ ńlá meji: ó dá oòrùn láti máa jọba ọ̀sán, ati òṣùpá láti máa jọba òru, ó sì dá àwọn ìràwọ̀ pẹlu.
Àkókò yíì gan-an ni olórí-burúkú yìí wá mú mi, ó lé mi ó bá mi nibi tí mo ti ń sálọ.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ukraine ti ri ọpọ iranwọ gba lẹyin ti orileede Russia gba akoso iṣejọba Crimea lọdun 2014 Ki lawọn oloṣeeelu US miran n sọ?
” Jakọbu dáhùn pé, “Jakọbu ni.
Kii ṣe Adebimpe nikan ni iroyin jade pe oun ati Lateef n fẹra.
Oríṣun àwòrán, EPA Lasiko to n dari ipade pajawiri kan lorileede naa, aarẹ Aoun ni ''eeyan ko le ṣe apejuwe iru ajalu nla to rọlu ilu Beirut eyi to ti da ibẹrubojo silẹ nibẹ'' Awọn onimọ ni fasiti Sheffield nilẹ Gẹẹsi sọ pe bi eeyan ba foju sun, ibugbamu Beirut lagbara ni iwọn igba ida mẹwa ninu ọgọrun ibugbamu Atomic Bomb ti orileede Japan ju lu Hiroshima.
Àpapọ̀ gbogbo àgọ́ Efuraimu ní ìsọ̀rí-ìsọ̀rí, jẹ́ ọ̀kẹ́ meje ó lé ẹẹdẹgbaasan-an ati ẹgbẹta (157,600).
Gomina ipinle Benue, Samuel Ortom ti dupe pupo lowo Aare Muhammadu Buhari fun atileyin re fun awon asafogun ni ipinle naa.
Lẹ́yìn ìkéde Buhari, ta ni yóò kojú rẹ̀ nínú ẹgbẹ́ APC?
Wo àwọn nkan tí o le ṣe gẹ́gẹ́ bi aláboyún lásìkò àjàkálẹ̀ ààrùn Covid-19 Wọ́n ta ère Ọ̀ṣun Osogbo sí Togo - Bàbá Ọṣun figbe ta Baṣọ̀run Gáà, tó yan ọba mẹ́rin, pa ọba mẹ́rin àmọ́ ọba karùn-ún ló pa á Ọbasanjọ sọ àsírí sàgbàdèwe rẹ̀ O ya, ẹ jẹ ka sere ọwọ, bawo lẹyin se gbọ Yoruba si, ẹ fi ami si ori irokotọla.
Ninu ọrọ to ba BBC Yoruba sọ, Aarẹ ẹgbẹ nọọsi, Abdrafiu Adeniji sọ pe isẹ Oluwa ni isẹ awọn olutọju alaisan ati igbẹbi.
Yóo ṣe ìdájọ́ láàrin ọpọlọpọ orílẹ̀-èdè,ati láàrin àwọn orílẹ̀-èdè tí ó lágbára ní ọ̀nà jíjìn réré;wọn yóo fi idà wọn rọ ọkọ́,wọn yóo sì fi ọ̀kọ̀ wọn rọ dòjé;àwọn orílẹ̀-èdè kò ní yọ idà sí ara wọn mọ́,wọn kò sì ní kọ́ ogun jíjà mọ́.
Abinadabu ni ti ekeji, Ṣama sì ni ti ẹkẹta.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ọmọ ogun ilẹ to duro wamu lẹnu iṣẹ ni Sousse ni orilẹ-ede Tunisia.
O ni Sholaye tun sọ fun oun pe ẹru n ba oun lati foun ṣaya nitori ilumọka ni oun jẹ.
Abilekọ ẹni ọdun mọkandinlogun kan, Azeezat Dhikirullahi to jẹ oloyun oṣu meje ni wọn ṣaa dede ba oku rẹ nilẹ ninu yara rẹ ti wọn ti fọ ori rẹ.
Ọrọ tirẹ dabi eyi to wa latọdọ alatako.
'Ọlọ́pàá kò yìnbọn pa olùwọ́de EndSARS kankan' Oríṣun àwòrán, Mojisola Alli-Macaulay Bakan naa lo lọ si ileewe giga Lagos State University to si kẹkọ jade ni ọ̣dun 2015 (History and International Relations) ati ileewe giga The Open University Milton Keynes, Upon Tyne Uk (2002-2003), Arabinrin Mojisola Alli-Macaulay ti gba iwe eri Diploma In Social Science UK 2002-2003, amọ o si n kẹkọ lati gba iwe ẹri imọ ofin ni University of Lagos, O ṣiṣẹ gẹgẹ bi akọroyin ni ileeṣẹ MITV/STAR FM, O ṣiṣẹ gẹgẹ bi Ọga Ẹka Idokowo Ileeṣẹ D.
Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Scientific Reports: Ìgbẹ́ ọmọdé ní àǹfààní púpọ̀ lára28 Ògún 2018 Ìjọ Redeem: Á se àyẹ̀wò ojú ara fáwọn àfẹ́sọ́nà sáájú ìgbeyàwó23 Èbibi 2018 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Ipilẹ tuntunAmọsa ipile tuntun yii yoo pari lọdun 2021.
Ó gbé èpè wọ̀ bí ẹ̀wù,kí èpè mù ún bí omi,kí ó sì wọ inú egungun rẹ̀ dé mùdùnmúdùn.
"Wọn ti bẹrẹ idarudapọ laarin ilu tẹlẹ, emi ati awọn oloye si lọ sibẹ lati pẹtu si wọn ninu l'orukọ kabiesi, amọ wọn ko ti ẹ jẹ ki a sọrọ.
Agbẹnusọ fun Agboola Ajayi, Allen Sowore ni awọn araalu lo ma a yan ẹni ti wọn fẹ ko ṣe adari fun wọn ninu idibo to n bọ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, EndSARS protest in Nigeria: Mr Macaroni, Falz, Wizkid, Tiwa Savage àtàwọn míì ṣe ìwọde Fọnran kan to lu ayelujara pa ṣafihan bi awọn alaanu kan ṣe gbe obinrin naa digba digba lọ sile iwosan nigba to n jẹ irora ni ibudokọ ọhun.
Ìtàn Ọba Yorùbá tí wọ́n yẹgi fún torí ó jí ọmọ gbé ṣe ètùtù Boko Haram da ìbọn bo ọkọ̀ gómìnà Borno, ẹ̀ṣọ́ àláàbò rẹ̀ farapa Ẹ káàbọ̀ sọ́jọ́ Arafat, tí Ọlọ́run yóò fi ààwẹ̀ Mùsùlùmí pa ẹ̀ṣẹ̀ wọn rẹ́ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Justice for Richard: Òbí àkẹ́kọ̀ọ́ tó kú síléeṣẹ́ ọṣẹ ń bèèrè fún ìdájọ́ lórí ikú ọmọ wọn Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Fulani kò leè dúró, táa bá lo ohun ta jogún lọ́dọ̀ àwọn bàbá wa - Sunday Igboho Sunday Igboho gba àwọn èèyàn Soka n‘Ibadan sílẹ̀ lọ́wọ́ àwọn ọmọ onílẹ̀ tó wá ṣọṣẹ́ Àwọn ọmọ onílẹ̀ lọ ṣe àmúṣẹ àṣẹ iléẹjọ́ ní Soka, làwọn ‘Jàǹdùkú’ fi dá wọn lọ̀nà - Iléeṣẹ́ ọlọ́pàá Ọyọ Sunday Igboho kìí ṣe ọmọ ìbàdàn, òun gan ló ń dá Ibadan ru, Auxilliary fún Sunday Igboho lésì Sunday Igboho yarí, ó fohùn ránsẹ́ sáwọn èèyàn tó ń pẹ̀gàn rẹ̀ O wa fi ọwọ gbaya pe oun funra oun gan setan lati lọ sere ọwọ ninu igbo pẹlu awọn ọdaran, ti wọn ba kan bura fun awọn nikan.
Ní ìkẹhìn nígbà tí ara rẹ̀ kò gbà á mọ́, ó díde ó jí igbí kejì rẹ̀, ó wí fún un pé òun ń wádìí odò náà lọ, àti pé bí ilẹ̀ bá mọ́ tí òun kò bá sì tí ì dé, kí igbá kejì òun wí fún àwọn ènìyàn pé ó ṣe òun bí àárẹ̀ àti pé òun sùn sí inú ilé kékeré tí òun yára kọ́ sí etí odò náà ni.
Apeja orukọ Alaafin akọkọ ni Aláàfin Àjíún Ọ̀rọ̀ǹpọ̀tọ̀niyùn, to si maa n ki ara rẹ ni 'Ajiun, a rí òbò sẹgun ọtẹ' Aláàfin Ọ̀rọ̀ǹpọ̀tọ̀niyùn jẹ Alaafin laarin ọdun 1554 si 1562, nigba ti ko si ọkunrin mọ ni idile ọba to lee jẹ Alaafin Orukọ baba Aláàfin Ọ̀rọ̀ǹpọ̀tọ̀niyùn ni Alaafin Onigbogi, to n gbe ni ilẹ Ibariba, o tẹri gbasọ, ti arole rẹ, Alaafin Ofinran si jọba lẹyin rẹ Nigba ti Alaafin ofinran wa lori itẹ, ni wọn pinnu lati kuro ni ilẹ Ibariba lọ si Ọyọ, to si ko awọn eeyan rẹ ati awọn aburo rẹ lọwọ, ti orukọ wọn n jẹ Ọmọọba Eguguoju, Ọmọọbabinrin Ọ̀rọ̀ǹpọ̀tọ̀niyùn ati Ọmọọba Ajiboyede Loju ọna ni ọkan lara olori Alaafin ofinran to loyun ti bi ọmọkunrin kan ti wọn pe orukọ rẹ ni Ọmọọba Tella Abiipa Loju ọna ni Alaafin Ofinran ti waja, ti Alaafin Oguguoju si gori itẹ lẹyin rẹ, oun lo si lewaju awọn eeyan rẹ de ilu Ọyọ Igboho, ti wọn tẹdo si lẹyin irinajo ọlọjọ gbọọrọ, ibẹ naa si loun naa ku si pẹlu Ọkunrin to kan to yẹ ko jọba ni Ọmọọba Ajiboyede, amọ ọmọde patapata ni, ti ọkunrin miran to tun wa nilẹ, Ọmọọba Tella Abiipa, si wa lọmọ irakoro, ti ko si tun si ọkunrin miran ni didle Alaafin to lee gun ori itẹ Idi ree ti awọn Ọyọmesi, to jẹ Afọbajẹ, fi pinnu lati mu ọmọ oye laarin ara wọn, sugbọn ti obinrin kan soso to dagba ni idile ọba, Ọ̀rọ̀ǹpọ̀tọ̀niyùn fi aake kọri, to si ni oun ni oun yoo gun ori itẹ Alaafin Awọn Ọyọmesi naa taku pe eewọ, ko si ninu itan ri pe obinrin jẹ Alaafin, ti wọn si sọ fun Ọ̀rọ̀ǹpọ̀tọ̀niyùn pe ko seese, afi ko jẹ ọkunrin ni yoo jẹ Alaafin Ọ̀rọ̀ǹpọ̀tọ̀niyùn wa seleri fun wọn pe oun yoo fi han wọn pe ọkunrin ni oun, oun kii se obinrin, ati idi ti oun fi lẹtọ lati jẹ ọba.
Mi ò tíì gba ìwé ìfitónilétí pé wọ́n fẹ́ yọ mí nípò igbákejì gómìnà ìpínlẹ̀ Ondo- Agboola Ajayi Fọwọ́ kan obìnrin lọ́nà àìtọ́, kí o rẹ́wọ̀n ọdún mẹ́rìnlá he- Àwọn aṣòfin yarí Ọwọ́ ọlọ́pàá ìpínlẹ̀ Oyo tẹ àwọn afurasí lórí ìpànìyàn tó wáyé ní Akinyele Ọwọ́ ọlọ́pàá ìpínlẹ̀ Oyo tẹ àwọn afurasí lórí ìpànìyàn tó wáyé ní Akinyele Awọn nkan ti a mọ nipa igbeaye Gal Pissetzky Gal Pissetzky ti n ṣiṣẹ amofin fun ogun ọdun.
Bákan náà ni ìbú ati òòró rẹ̀ yóo rí, ìṣẹ́po meji ni yóo jẹ́, ìbú ati òòró rẹ̀ yóo sì jẹ́ ìká kọ̀ọ̀kan.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ìtàn rèé nípa bí Ogbomoso ṣe pa ọba, yọ nǹkan ọkùnrin rẹ jó kiri ìlú Àìsí iṣẹ́ nígboro lọ̀pọ̀ ọ̀dọ́ fi fẹ́ gba iṣẹ́ Amotekun - Toogun Wo àwọn obìnrin abúlé kan tó dáwó ra ọkọ̀ láti máa gbé aláboyún lọ ilé ìwòsàn Alámì ẹ̀yẹ Scrabble Paul Sodje àti ọ̀rẹ́ rẹ́ kú lásìkò tó fẹ́ lọ́ sanwó ìdóòlà ẹ̀mí àbúrò rẹ̀, tí afurasí darandaran jí gbé Ìjàmbá iná míràn tún wáyé ní pápákọ̀ ojú omi Beirut Ẹ fi dókítà àgùnbánirọ̀ rọ́pò àwọn dókítà tó ń yanṣẹ́ lódì - Ìjọba àpapọ̀ pàṣẹ Afenifere fara ya lórí bí Tinubu ṣe jókòó kí Ooni Aáwọ̀ oyè PDP gbé Fayose àti Seyi Makinde kọlu ara wọn, ìjà ń bọ̀ Ṣugbọn nigba ti apa ile iwosan Argungu ko kaa mọ ọ, ni olowo ijapa yii to fẹran ẹranko gbe e lọ sí Sokoto, nibi ti wọn ti ṣiṣẹ abẹ fun un.
N óo fun yín ní àwọn olùṣọ́ aguntan tí ó wù mí, tí yóo fi ìmọ̀ ati òye bọ yín.
Kí ni kí á rí dìmú ninu ọ̀rọ̀ yìí?
idibo naa si n lọ irọwọ ati irọsẹ Ademola Adepoju.
Ọwọ́ ba òsìsẹ́ SARS tó pà akẹ́ẹ̀kọ́ ní Iwo Oríṣun àwòrán, Joshua Adetunji Àkọlé àwòrán, Ọwọ́ àwọn ọlọ́pàá ti ba ọlọ́pàá SARS tó yìnbọn pa akẹ́ẹ̀kọ́ kan ní ìlú Iwo Afurasi ọlọpaa kogbereegbe SARS kan to yinbọ pa akẹẹkọ Tunde Nafiu nilu Iwo, nipinlẹ Osun lọwọ sinkun ofin ti ba bayi.
Wéré a sáré lọ sí ibẹ̀, nígbnà tí a sì máa dé ọ̀hún ìyàwó ọba ti gbé ọba lulẹ̀, orí rẹ̀ ni a sì ti bá a tí o ní gbá ọba létí léraléra, a bá mu wọn ti a gba ọba lọ́wọ́ rẹ̀.
‘Mo ké bòòsí tòò bí mo ṣe bí ìbejì, ti ọ̀kan jẹ́ àfín, ìkejì jẹ́ dúdú’ Ìdààmú ńlá ńbọ̀ fún Nàíjíríà lábẹ́ ìjọba Buhari - Ọbasanjọ Èèwọ̀ ni láti pa ẹja nínú odò Sogidi ni Aáwẹ́ nipinlẹ Oyo Àfi ìgbà tí mo bọ́ sọ́wọ́ ọ̀tá mí nínú ìrìnàjò ìfẹ́- Roshan Aina ni ọmọbinrin ti o gbe ibi kọrun wa sile aye nigba ti a bi i.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Babatunde Olatunji pẹlu Martin Luther King (L) ati Malcolm X (R) ni 1964 Ọdun 1927 ni wọn bi Olatunji to jẹ ọmọ Yoruba nipinlẹ Eko, ko to di wi pe Olatunji gba ami ẹyẹ lati lo kawe ọfẹ ni oke okun ni ''Morehouse College'' ni Atlanta, lorilẹede America ni ọdun 1950.
Awon miran ti won safihan ise won nibi eto naa ni Promise Utojuiba to n yaworan aso ki won to ran an, pelu Olubunmi Awokoya to sese n dide ninu ise amunidara tigbalode olopo yanturu.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ayédèrú Afenifere ló bá Buhari ṣépàdé - Odumakin gbanájẹ Dapo Abiodun wà lára àwọn tó ta ohun ìjà olóró fún mi - Amoṣun 'A máa ń fí oògùn olóró 'ginger'ká tó ka ẹsẹ bíbélì ni ṣọ́ọ̀ṣì' Orin kíkọ kò dí ìwé mi lọ́wọ́ rárá -Hameen School Boy Fidio mu ki ọpọ bẹnu atẹ lu bi awọn olowo Naijiria ṣe n jaye alábátá.
Ẹni tí ó gúnwà lọ́run ń fi wọ́n rẹ́rìn-ín;OLUWA sì ń fi wọ́n ṣe yẹ̀yẹ́.
 Iṣẹju mejidinlọgọrin ni idije naa wa lasiko ti Odion
Ó bi wọ́n pé, “Kí ni ẹ̀yin ati àwọn ọmọ-ẹ̀yìn mi ń jiyàn lé lórí?
Ọ̀rọ̀ Baba mi tí mo bá gbọ́ ni mo fi ń ṣe ìdájọ́, òdodo sì ni ìdájọ́ mi; nítorí kì í ṣe ìfẹ́ tèmi ni mò ń wá bíkòṣe ìfẹ́ ẹni tí ó rán mi níṣẹ́.
Gbajumọ òṣèré tíátà miran, Sunday Omobolanle, tí gbogbo èèyàn mọ si Pappy Luwẹ, sì ló fẹ́ Peju Ogunmola bíi aya.
Ni fasiti Howard to jẹ gbajugbaja fasiti awọn alawọdudu lo ti kawe gboye imọ ofin .
ikọlu  yii tun wa lara ohun to faa ti
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Divorcee: Ó sàn kí wọ́n yàgò fúnra wọn ju ki wọ́n ṣe ara wọn léṣe- Fisayo Aisha ni igba ti oun ri koko ni omu oun ni oun bẹrẹ si ni kiyesi irufẹ ounjẹ ti oun n jẹ.
Ọmọ ọdún mẹ́wàá ń jẹ ìrora lẹ́yìn tí ọ̀gá tì í sínú iná àrò búrẹ́dì Ọmọ ọdún márùn-ún, àgbà mẹ́rin ló bá ìṣẹ̀lẹ̀ ọ̀pá bẹntiróò tó gbiná ní Abule Egba lọ - LASEMA Mo kàn fẹ́ fi ọmọ tó sọnù gba owó lọ́wọ́ Sọtitobire ni - Afurasí Hepatitis: A kò leè kóo nípa dídìmọ́ ara ẹni Àwọn ará South-Africa yarí 'torí gbọ̀ngàn kọ̀ ìgbéyàwó abo-sábo Ẹ̀yin ẹ máà wò ó, ó ṣeéṣe kí APC túká lẹ́yìn ìṣèjọ́ba Buhari!
ati aarin ọna ni awon agbegbe to tun sunmo won.
Gẹgẹ bi wọn ṣe kọ ẹkunrẹrẹ rẹ ninu bibeli, iwe Johanu ori ikẹtala, alufa agba ni ọjọ yii tun jẹ iranti ọjọ ti Jesu Kristi wẹ ẹsẹ awọn ọmọ ẹhin rẹ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Presidency: Kí ló dé tí Ààrẹ Buhari tún ń dá àwọn tó fúnrarẹ̀ yọ nípò pàdà 8 Sẹ́rẹ́ 2020 Oríṣun àwòrán, @NGRPresident Aarẹ Muhammadu Buhari ti fa iwe aṣẹ gbele ẹ ti wọn fun oludari agba ajọ ipese ina igberika lorilẹ-ede Naijiria, REA, Arabinrin Damilọla Ogunbiyi ya.
Ile igbimọ asofin naa lasiko ti wọn n fi abadofin naa le le ni yoo koju ijamba ti lilo nylon tabi rọba n se si awọn ẹja inu okun, eniyan ati agbeegbe naa.
Toyin Abraham Gbajugbaja oserebinrin lo njẹ Toyin Aimakhu tẹlẹ.
95bn sórí reluwé làti Kano sí Niger Republic.
 Ó jẹ ́ oògùn tí a lè rí káàkàkiri .
Lati ọdun 1994 ni wọn ti n lo Xenowatch tracker to n ṣe akosile awọn iroyin ikọlu to n jade ati awọn ti ikọlu naa ṣẹlẹ si ni igba kọọkan.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Premier League: FIFA f'òfin de Chelsea kí wọ́n má lè ra agbábọ́ọ̀lù 22 Èrèlè 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Chelsea wọ gau lori ọrọ rira agbabọọlu Ikọ Chelsea ko ni lanfani lati ra agbabọọlu kankan titi yoo fi di ipari oṣun kinni ọdun to n bọ, lẹyin ti ajọ FIFA f'ofin de ẹgbẹ agbabọọlu naa.
Wọ́n gbé agbada yìí ka orí akọ mààlúù mejila, tí wọ́n fi bàbà ṣe.
”Àwọn babalóòṣà dá wọn lóhùn pé, “Ẹ fi wúrà yá ère kókó ọlọ́yún marun-un, ati ti èkúté marun-un, kí ẹ fi ranṣẹ.
Abiola Ajimobi: Àwòrán rèé nípa ìgbé ayé Abiola Ajimobi
Ọjọ kẹrin oṣu kẹsan ni Gomina Rotimi Akeredolu yoo pada si ẹnu iṣẹ.
SERAP fẹ́ pe UI, AAUA lẹ́jọ́ lórí àfikún owó iléẹ̀kọ́ OAU: Ohùn ọ̀jọ̀gbọ́n Richard Akindele ni wọ́n ká sílẹ̀ Khafi wọ gàu lẹ́nu iṣẹ́ lórí ẹ̀sùn ìbálòpọ̀ ní BB Naija Àṣìta ìbọn ló pa obìnrin nílùú Eko lọ́jọ́ Satide- Ọlọ́pàá Lórí ìmọ̀ràn Sunday Igboho, Ẹlẹbubọn ní yóò dára kí Yorùbá padà sí àmúlò èròjà ìbílẹ̀ fún ààbò Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, CS Mum: Omotolani Ekene ní ọ̀pọ̀ èèyàn gbà pé ọ̀lẹ, arugún, aláìlera ni ẹni tó fi abẹ bímọ Ofin yii yoo si bẹrẹ loru ọjọru.
Ati pé dájúdájú, ìlú yìí yóo bọ́ sọ́wọ́ àwọn ọmọ ogun Babiloni, wọn yóo sì gbà á.
Nígbà tí Juda ṣọ̀fọ̀ rẹ̀ parí, òun ati Hira ará Adulamu, ọ̀rẹ́ rẹ̀ bá múra, wọ́n lọ sí Timna lọ́dọ̀ àwọn tí wọn ń rẹ́ irun aguntan Juda.
Ó mú kí ẹ rí i pé ẹ ṣe ẹ̀tọ́ ninu ọ̀ràn náà.
OLUWA jọba; ó gbé ọlá ńlá wọ̀ bí ẹ̀wù;OLUWA gbé ọlá ńlá wọ̀,ó sì di agbára ni àmùrè.
Yóo jẹun, yóo jẹran, yóo yó; yóo tún yáná.
Reluwé Abuja: Amaechi ní èrò pọ̀ ní ojú ìrìn Abuja si Kaduna nítori ìjínigbé lójú pópó
Lẹ́yìn náà àwọn olórí ìdílé ninu ẹ̀yà Lefi wá sí ọ̀dọ̀ Eleasari alufaa, ati sí ọ̀dọ̀ Joṣua ọmọ Nuni, ati àwọn olórí ìdílé ní gbogbo ẹ̀yà Israẹli, 
Ninu atẹjade ti Aarẹ Buhari fi lede lo ti ni Ọjọgbọn Charles Uwakwe, Bamidele Olure, Shina Adetona, Tayo Odukoya ati Babatunde Aina ni wọn ti kọkọ fun ni iwe lo gbele rẹ fun igba diẹ ki wọn fi ṣe iwadii finifini ẹsun iwa ajẹbanu ti wọn fi kan wọn.
Ẹ̀mí 45 bọ́ nínú ìkọlù Kaduna Wọ́n ti yìn'bọn lu mínísítà ní Pakistan Tunisia dìbò abẹ́lé lẹ́yìn ọdún méje Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Lati bii ọdun mẹtadinlogoji sẹhin ni papakọ ofurufu naa ti wa nilu Ibadan, ṣugbọn irinajo ofurufu ko fi bẹẹ ja gara ni papakọ naa bii ti awọn ilu nla ti o ku.
Ọjà Enugu dahoro tórí ókú ọ̀pọ̀ ẹyẹ igún tó balẹ̀
Ìbúrawọlé Nàìjíríà ṣojú àgbáyé Dúkìá mi ò lé kan o, mo ti dá fọ́ọ̀mù padà bó ṣe wà tẹ́lẹ̀ - Buhari, Osinbajo Iroyin naa ni, ọkọ tanka epo meji lo fi ori sọ ara wọn lojiji, ti ina si dahun lara wọn, eyi to mu ki eeyan marun fi ara pa yanna-yanna, ti ọpọ ọkọ ayọkẹlẹ, ọkọ akẹru ati awọn ọkọ nla-nla si jona kọja ala.
Aare wa ro gomina Fayemi lati
Tìrẹ ni ọ̀sán, tìrẹ náà sì ni òru,ìwọ ni o gbé òṣùpá ati oòrùn ró.
 A nigbagbo wipe wiwa sibi yii loni
Àwọn ọmọ Aaroni meji kan, ọkunrin, tí wọn ń jẹ́ Nadabu ati Abihu, mú àwo turari wọn, olukuluku fọn ẹ̀yinná sinu tirẹ̀, wọ́n da turari lé e lórí, wọ́n sì fi rúbọ níwájú OLUWA, ṣugbọn iná yìí kì í ṣe irú iná mímọ́ tí OLUWA pa láṣẹ fún wọn.
OLUWA ní, “Nígbà tí àkókò tí mo yà sọ́tọ̀ bá tó,n óo ṣe ìdájọ́ pẹlu àìṣojúṣàájú.
Mudashiru Ọbasa fi ọrọ tirẹ naa ṣegbe fun ti awọn ọmọ ẹgbẹ to ku.
 wọ ́ n bí débọ ̀ ní ọjọ ́ kejìdínlógún oṣù kejì ọdún 1988 ( 18 02 , 1988 ) , òun ni ó jẹ ́ aṣòfin àti agbẹnusọ ́ fún ilé aṣòfin ìpínlẹ ̀ Ọ ̀ yọ ́ tí ó jẹ ́ ọ ̀ dọ ́ nínú ìtàn iké ìgbìmọ ̀ aṣòfin ìpínlẹ ̀ Ọ ̀ yọ ́ .
#StopRobbingUs: Ilé-isẹ́ ọlọ́pàá Naijiria gbọdọ̀ jáwọ́ nínú ìfìyajẹni
Wọ́n lé Ẹranko Ewèlè náà jáde–ejò àtijọ́ nì tí à ń pè ní Èṣù, tabi Satani tí ó ń tan àwọn tí ó ń gbé inú ayé jẹ.
 Àjàkálẹ ̀ lè wáyé ní àdúgbò àwọn tálákà ní àwọn orílẹ ̀ -èdè tó ṣì ń dàgbàsókè .
Kloe: Èmi kìí mu òògùn olóró, àmọ́ mo fẹ́ràn láti máa wà lẹ́bà omi
  Nṣe ni wọ́n dákẹ́ rọ́rọ́ tí wọ́n njẹ koríko lọ.
Lati le dẹkun awọn alatako rẹ, aarẹ Gnassingbe ṣe agbekalẹ ofin kan eyi to sọ pe aarẹ ilẹ Togo ko le lo ju saa meji ọlọdun marun un marun un lọ.
OLUWA rán Mose pé, “Sọ fún Aaroni pé kí ó na ọwọ́ rẹ̀ ati ọ̀pá rẹ̀ sórí àwọn odò ati àwọn adágún tí wọ́n gbẹ́, ati sórí gbogbo ibi tí omi dárogún sí, kí àwọn ọ̀pọ̀lọ́ lè jáde sórí ilẹ̀ Ijipti.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Mo fẹ́ máa polongo oúnjẹ ilẹ̀ wa ló jẹ́ kí n máa fi oúnjẹ bíi àmàlà ya àwòrán Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
20 Lõtọ́, lõtọ́, ni mo wí fún ọ, pé Sátánì ti gba ọkàn wọn; ó rú ọkàn wọn sókè sí àìṣedéédé ní ìlòdì sí ohun èyítí ó dára;
Àkọlé àwòrán, Isa, ẹni ọdún mẹ́rìndínlọ́gbọ̀n fẹ́ ẹ́ fẹ́ ọmọ America, Janine Sanchez, tó jẹ́ ẹni ọdún mẹ́rìndínláàdọ́ta.
 Joshua Ajayi: ""Nigba ti mo gbọ pe ileesẹ agbohunsafẹfẹ BBC fẹ da oju opo Yoruba silẹ, ọkan mi lọ sọdọ awọn babanla mi, ti wọn ko mọọkọ-mọọka lede oyinbo ati ilakaka wọn lati gbọ ojulowo iroyin to wulo."
Wọ́n ní, “Ẹ wá, ẹ jẹ́ kí á pa orílẹ̀-èdè wọn run;kí á má ranti orúkọ Israẹli mọ́!
Laipẹ yii ni awọn oṣisẹ labẹ asia awọn oṣiṣẹ agba fun awọn to n pese iṣẹ lẹka ofurufu, ATSSSAN ati awọn oṣiṣẹ ẹka ofurufuru Naijiria, NUATE sọ fun awọn oniroyin nipa ipinnu wọn lati bẹrẹ iyanṣẹlodi lọjọ keji, oṣu kinni, ọdun 2019.
Monguno ni ijọba fẹ lo apero lori eto aabo lati wa ojutuu si iṣoro eto aabo to mẹhẹ, eto ẹkọ ti ko munadoko ati awọn idojukọ pẹlu eto ilera ni Naijiria.
Badagry Historical Wells: Omi inú kànga Wawú ló ń kó ọpọlọ àwọn ẹrú lọ
” Wayii o, ti iko agbaboolu Leganes ba nife lati ra Omeruo, won yoo san
Bí Coronavirus kò bá pa wá, ẹ má fi aisun pa wá torí ìbẹ̀rù olè - Àwọn olùgbé Ibadan figbe ta Àwọn Ìpínlẹ̀ tí coronavirus kò tíì dé ní Nàìjíríà, àti ìgbésẹ̀ tí wọ́n ń gbé láti dènà rẹ̀ Èyí ni ìdí tí coronavirus ṣe n pa àwọn kan, tí kò sì pa àwọn kan Celtic (1967) Ẹgbẹ́ agbabọọlu Celtic 'Lisbon Lions' lọ wọ gbajugbaja jẹsi naa, lasiko ti wọn fi kọ orúkọ wọn sinu iwe ìtàn nipa lilu ẹgbẹ́ agbabọọlu Inter Milan pẹlu ami ayo meji sẹyọkan Eyi to si sọ wọn di ẹgbẹ́ agbabọọlu Britain akọkọ to gba ife European Cup.
A dá àwọn mìíràn lóró títí wọ́n fi kú.
Yemi Elebuibon: Babaláwo èké kò le è kii ẹsẹ mẹ́rin nínú odù ifá
Wọ́n dá a lóhùn pé, “Àwọn kan ń pè ọ́ ní Johanu Onítẹ̀bọmi, àwọn mìíràn ní Elija ni ọ́, àwọn mìíràn tún ní ọ̀kan ninu àwọn wolii ni ọ́.
Won ni won dana sun awon iwe idibo .
Gbogbo ẹni tí ó bá fẹ́ràn baba yóo fẹ́ràn Ọmọ rẹ̀.
Baba ọmọde kan ti Mammadou Gassama, ọmọ orilẹede Mali doola ẹmi rẹ nigba to gun ile alaja mẹrin lati gbe ọmọ na sọ kalẹ, lọ ẹwọn bayii.
Wọn kò mọ ohun tí ó ń sọ.
Israel Adebajo: Ìlúmọ̀ọ́ká oníṣòwò tó fi òkò Stationery Stores pa ẹyẹ púpọ̀ Bíbéèrè fún ìbálòpọ̀ gbogbo ìgbà sọ ìyàwó ilé dèrò ilé ìwòsàn Ìjọba ti bẹ̀rẹ̀ sí báwọn tó gbé òṣìṣẹ́ aláàánú mẹ́fà sọ̀rọ̀- Garba Shehu Waec f'ofin de ile'we mẹtadinlaadọta Àwọn akẹ́ẹ̀kọ́bìnrin fakọyọ ju akẹ́kọkùnrin ní'dánwò WAEC Ajọ naa ti wa rọ awọn akẹkọọ to joko ṣe idanwo naa lati bẹrẹ si nii lọ wo ori ayelujara fun esi wọn.
Wọn ni owo yii tun wa fun bi ajọ DSS ti fi ẹtọ wọn dun wọn lẹyin ti ile ẹjọ paṣẹ idasilẹ wọn latimọle, ti wọn ko si jẹ kawọn lanfaani si eto ilera, ati ẹtọ awọn lati rin lọ si ibikibi to ba wu awọn.
Nigba ti BBC yoo fi kan si ileesẹ ọlọpaa agbẹjọro wọn O.
Ibudo naa, ti ọpọ eeyan mọ si Kuari lo ti wa di ibi ti ọwọ eeyan n peju wa wo lẹyin ti awọn eeyan kan ju aworan naa sori ayelujara.
Lati ọdun 1980 ti Malagu Emmanuel ti bẹrẹ iṣẹ oniroyin, o ni ọ̀rọ̀ pọ ninu iwe kọbọ lo ṣe tẹnu bọ ọ̀rọ̀ pẹlu BBC Yoruba.
kan pada ninu ami ayo naa, ki Kristoffer Nordfeldt o to gba ayo miiran wo
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìpànìyàn Akinyele: Àwọn ìgbésẹ̀ tí ọlọ́pàá ń gbé lórí ikú Mujeeb tí wọ́n pa nílùú Ibadan 23 Òkùdu 2020 Oríṣun àwòrán, @PoliceNG Ileesẹ ọlọ́pàá ìpínlẹ́ Oyo ti ké gbàjarè pé, adiyẹ ń làágùn, sùgbọ́n ìyẹ́ ara rẹ̀ ni kò jẹ́ kí ènìyàn mọ̀, pàápàá jùlọ, nidii igbesẹ rẹ láti dẹ́kun ìwà ìbájẹ́ àti fífi ẹ̀mi àwọn ènìyàn sòfò ní ìpínlẹ̀ Oyo.
 Asofin ohun wa ro awon asoju sofin lati gba abadofin yii wole ,nitori pe yoo se gbogbo awon omo orile ede Naijiria ni anfaani ati pe yoo tun je  ki eto aabo orile ede Naijiria tubo fese mule si i.
Ṣugbọn o sọ pé, ‘Kò sí ìrètí,nítorí àjèjì oriṣa ni mo fẹ́,n óo sì wá wọn kiri.
Dafidi gbọ́ ninu aṣálẹ̀ pé Nabali ń gé irun aguntan rẹ̀, 
Eyi ti wu ọpọlọpọ ọrọ sita latọdọ awọn ọmọ Naijiria.
gbọdọ rẹwẹsi rara, ao gbobo ri I pe a se isẹ, a ni ohun ti pọ lati se.
OLUWA bá ṣẹgun àwọn ará Bẹnjamini fún àwọn ọmọ Israẹli.
gbogbo ewì alohùn yorùbá ló ní kókó tí wọ ́ n má ń dá lé lórí .
Mo sọ fún wọn pé, wọn kò gbọdọ̀ ṣí ẹnu ibodè Jerusalẹmu títí tí oòrùn yóo fi máa ta ni lára, kí wọ́n sì máa ti ibodè náà, kí wọ́n fi ọ̀pá ìdábùú sí i lẹ́yìn kí àwọn olùṣọ́ tó kúrò lẹ́nu iṣẹ́.
Kí ló tún ṣe Òṣèré fíìmù Yorùbá míì tó ń gba ẹ̀jẹ̀ àtomi níléèwòsàn?
Theo Walcott pada si Southampton Oríṣun àwòrán, Getty Images Ẹlẹsẹ ayo Theo Walcott ti pada si ẹgbẹ agbabọọlu Southampton lati Everton fun ọdun kan.
Ọjọ diẹ lo lo ninu rẹ lẹyin to lo bii ọdun meji ninu ahamọ lasiko to n reti igbẹjọ rẹ.
Naijiria: Ẹ wo iyé minisita tó ti kòwé fipò sílẹ̀ lásìkò Buhari
awon ile idibo ti iye wọn jẹ ọ̀rìnlénígbalémetalelẹgbàá (2,283) ni awon
Oríṣun àwòrán, Getty Images Wọn gba awọn eeyan niyanju lati maa fọwọ ati tabili ikọwe wọn loorekoore.
Atẹjade naa ti Kọmisana feto ẹkọ nipinlẹ Ọyọ, Olasunkanmi Olaleye fọwọsi sisọ loju rẹ pe, wakati meji ati aabọ pere lawọn akẹkọọ yoo maa fi kawe bayii, ti wọn si pin wọn si isọri meji.
Àkọlé àwòrán, Kii si akọsilẹ odiwọn iye ero to n wọnu ọkọ oju omi ni Bakana Ṣugbọn, ọkọ rẹ ni ko fi ọkan balẹ, pe nkankan ko ni i ṣẹlẹ.
Bẹ́nìkan ò rí wa, Ọba lókè ń wò wá dájúdájú.
9th Assembly: Èrò ṣe ọ̀tọ̀ọ̀tọ̀ lórí ẹní tí àṣẹ ilé aṣòfin àgbà Nàìjíríà yóò já mọ́ lọ́wọ́
Bi ẹ ko ba gbagbe, LUTH wa lara awọn ile iwosan to n ṣetọju awọn alarun Covid-19 ni ipinlẹ Eko.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Onikaluku ti n yara ra ounjẹ sile de ibẹrẹ ofin konileogbele Minisista Guiseppe Conte sọ pe ''a fẹ daabo bo ẹmi awọn ọmọ ilẹ wa.
Amọṣa, ṣe gbogbo ailera ni Coronavirsu bayii ni abi bawo?
Bẹẹ, ti a ba fi ọmọ we ọmọ ni owe awọn agab n wi.
"Gbogbo awọn obinrin to kopa lori eto naa si lo kin dokita Ogunbayo lẹyin pẹlu afikun pe ọpọ mẹkunnu ni ko ri owo ra paadi fun nnkan oṣu wọn, ti wọn si n lo awọn eroja ti ko ni imọtoto.
OLUWA dá wọn lóhùn pé, “Ẹ̀yà Juda ni kí ó kọ́ dojú kọ wọ́n, nítorí pé, mo ti fi ilẹ̀ náà lé wọn lọ́wọ́.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Flood: Ọ̀pọ́ Dúkìá ló sọnù ní 2019 lásìkò tí ìjọba ṣí ’dáàmù Ọyan’ O ni o ti jẹwọ fawọn pe, lootọ ni wọn gba oun wọle si ileẹkọ giga fasiti ipinlẹ Ekiti lati kẹkọọ imọ ofin sugbọn oun ko pari ẹkọ oun nibẹ debi ti yoo lọ si ile iwe imọ ofin (Law School).
A kò tilẹ̀ mọ ẹni náà tí ó tọ́ láti tukọ̀ orílẹ̀-èdè Angola, báwo ni ọ̀dọ́ tí kò níṣẹ́ tí kò lábọ̀ yóò ṣe rí owó gba ìwé ẹ̀rí?
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Christmas: Ẹni ti ọdun ba ti bá láyé yẹ kó dúpẹ́ 1.
Ohun tí mo sọ fun yín níkọ̀kọ̀, ẹ sọ ọ́ ní gbangba.
Eyi ko ṣẹyin bi Aarẹ Muhammadu Buhari ṣe tu igbimọ amuṣẹya ẹgbẹ oselu APC ka, ti o si fi igbimọ fidiẹ sibẹ.
O sọrọ lori awọn nkan to ni lọkan lati ṣe fun ipinlẹ Ọṣun ti o ba jawe olubori ninu eto idibo fun ipo gomina to m bọ lọjo kejilelogun, oṣu kẹsan an yii.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ghana f'ofin de gbogbo ọ̀rọ̀ eré bọ́ọ̀lù torí rìbá lásìko yìí 7 Òkùdu 2018 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 8 Òkùdu 2018 Àkọlé àwòrán, Ogunlọ́gọ̀ àwọn adarí ni àwọn akọ̀róyin fún ní owó láti ṣe màgòmágó ṣùgbọ́n wọ́n ya àwòrán wón laí mọ̀.
Naijiria , Muhammadu Buhari ti ni ki won yi oruko papa isere  National Stadium , ilu Abuja
Gomina Sanwo-Olu sọ eyi di mimọ lasiko to n ba araalu sọrọ lori ibi ti nkan de duro lori aarun coronavirus nipinlẹ naa.
Àwọn ọlọ́kadà alákatakítí ẹ̀sìn tí wọ ìpínlẹ̀ Eko - Charly Boy Ọlọ́pàá tó pa èèyàn pokùnso lọ́jọ́ kejì tó dé àhámọ́ àwọn ọ̀tẹlẹ̀múyẹ́ Àwọn ọlọ́kadà alákatakítí ẹ̀sìn tí wọ ìpínlẹ̀ Eko - Charly Boy Bàálù já lulẹ̀,o pín sí mẹ́ta,èèyàn 52 f'arapa Íbùdó amúnáwá to gbiná sọ Ibadan,Ṣakí àti Ìséyìn si òkùnkùn biribiri Ajayi lero pe nnkan to le din iwa ibajẹ ku ni ki ijọba mu aye dẹrun fun awọn eeyan, ki wọn si fi ọrọ siimu silẹ.
Ọkọ̀ òfúrufú gbiná nítorí obìnrin tó ń fa Shisha!
Ó ní, “Nígbà pupọ ẹ̀mí náà á gbé e sọ sinu iná tabi sinu omi, kí ó lè pa á.
Aláìṣẹ̀ ṣì ni Onyema Air Peace títí America afí fìdí ẹ̀sùn jìbìtì $20m múlẹ̀- America Amẹrika fẹ̀sùn jìbìtì $20m kan olùdàsílẹ̀ Air Peace, Allen Onyema Iroyin to n tẹ wa lọwọ sọ pe ilẹ Amẹrika ti fi ẹsun jibiti ogun miliọnu dọla ati kikowo pamọ silẹ okeere lọna aitọ kan oludasilẹ ile iṣẹ ọkọ ofurufu, Air Peace, Allen Onyema.
ní Lodi, ati Ono, àfonífojì àwọn oníṣọ̀nà.
Iroyin so pe, awon merin miran ni o tun gbemi mi lasiko iwaako pelu awon olopaa.
Ó bá jáde, ó lọ sí ibòmíràn.
igbimo asofin Kabiru Garba Marafa ti gbosuba fun ajo to n ri si eto idibo
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Aràrá bíi tèmi, kó má rò pé kò sì ǹkan tó lè ṣe láyé ju iṣẹ́ agbe lọ' Ninu ero tirẹ, Bisọọbu Agba Ijọ Aguda ni ilu Imo, Anthony Obinna sọ wi pe opin gbọdọ de si idẹyẹsi ni yii ati ọrọ ẹlẹyamẹya nitori ọgbọgba ni Olorun da wa.
 ní ilẹ ̀ amẹ ́ ríkà iye owó rẹ ̀ jẹ ́ 25 sí 50 usd .
Tẹle ọlọpaa naa de agọ wọn.
“Nígbà tí ọjọ́ rọ̀, ẹni tí ó ni ọgbà àjàrà náà sọ fún iranṣẹ rẹ̀ pé, ‘Pe àwọn òṣìṣẹ́, kí o fún wọn ní owó wọn, bẹ̀rẹ̀ láti ọ̀dọ̀ àwọn tí ó dé gbẹ̀yìn, títí dé ọ̀dọ̀ àwọn tí ó kọ́kọ́ dé.
Àwọn ọdọmọbinrin tí kò tíì mọ ọkunrin jẹ́ ẹgbaa mẹrindinlogun (32,000).
Àkọlé àwòrán, Ile ijosin kan rèé lórí òkè ona Ado Ekiti ni ilu Àkúré tí òjò àná sose fun Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Ọlọrun ti fi ohun gbogbo sábẹ́ ẹsẹ̀ Kristi yìí kan náà ó fi ṣe orí fún gbogbo ìjọ onigbagbọ.
Àdúrà wa ni wí pé kí a máse subú fún ọ̀tá yọ̀!
 Eto idbo tii niiṣe pẹlu ti Naijiria lapapo nitoripe o lọ nirọwo rọsẹ ti ko si wahala kankan.
Tabi ayùn lè fọ́nnu sí ẹni tí ó ń fi rẹ́ igi?
Bí ẹni fi èékánna buyọ̀ ni iye èèyàn ti wọ́n ń sàyẹwò fún bi Chiedo Nwankwor olùkọ́ ni Fásìtì John Hopskin ni America ṣe sọ."
Frank Rajah Arase – In My Country
Oludije lẹgbẹ oṣelu APC naa lo asiko naa lati kede ipolongo rẹ ati awọn ohun ti yoo gbeṣe ti oun ba bori ninu idibo to n bọ naa.
Fún ọjọ́ kẹ́ta, ìpínlẹ̀ Plateau gbé ipò kínní lórí àtẹ COVID-19!
Bí ó ti wí báyìí ní ẹ̀ẹ̀kan ṣoṣo tí ó gba ìyàwó mẹ́tẹ́ẹ̀ta bọ́ síwájú ọbha tí o ń bú ọba pé wọnn kò níí padà, owó ọba ni wọ́n máa san.
O le ni eniyan mọkanlelogun ti wọn farapa ninu iṣẹlẹ buruku naa ti ọlọpaa mẹta ṣi wa lara wọn.
“Dìde, mú aṣọ funfun tí o rà, tí o lọ́ mọ́ ìdí, lọ sí odò Yufurate, kí o lọ fi pamọ́ sí ihò àpáta níbẹ̀.
’“Gbogbo eniyan yóo sì dáhùn pé, ‘Amin.
Ileeṣẹ naa lo ti wa ṣeleri lati san ẹsan ire fun ẹbi oloogbe Richard.
wọ́n kó gbogbo àwọn ère tí wọ́n wà níbẹ̀ jáde, wọ́n sì sun wọ́n níná.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Iṣẹ́ abẹ láti ya ìbejì tó lẹ̀pọ̀ yọrí sí rere l'Abuja 31 Ọ̀wàrà 2018 Oríṣun àwòrán, Dogara media office Àkọlé àwòrán, Àwọn ìbejì tí wan yà sọ́tọ̀ Awọn dokita kan ṣe iṣẹ abẹ lati ya awọn ibeji ti wọn lẹpọ ni ile iwosan ikọni Fasiti Ilu Abuja to wa ni Gwagwalada lọjọ Iṣẹgun.
Bẹẹ naa ni, amofin agba kan lorilẹede Naijiria Olisa Agbakoba ni aarẹ Buhari ko ni aṣẹ kankan lati yọ Onnoghen.
'Pọ́ńbélé Yorùbá ni mí, n ò sì ní tijú rẹ níbikíbi' Àwọn nǹkan tí obìnrin lè ṣe pẹ̀lú olólùfẹ́ oníwà ipá lásìkò ìgbélé Coronavirus yìí Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ibadan expressway: Àwọn olè Fulani ló ń jí ènìyàn, pànìyàn ní òpópópónà!
Ọba sọ fún Ẹsita Ayaba pé, “Àwọn Juu ti pa ẹẹdẹgbẹta (500) ọkunrin ati àwọn ọmọ Hamani mẹ́wẹ̀ẹ̀wá ní Susa.
Bí ọkùnrin yìí tí parí ọ̀rọ̀ wọ̀nyí, ó ṣubú lulẹ̀ ó sì kú.
Ilẹ̀ ṣú, ilẹ̀ sì tún mọ́, ó di ọjọ́ karun-un.
Ti awọn ọba kan si n fẹsun kan pe wọn n gbe awọn ọba ga lai tẹle aṣa ati ilana ibilẹ.
Ó kó ẹran tí ó sè sinu agbọ̀n kan, ó da omi ọbẹ̀ rẹ̀ sinu ìkòkò kan, ó gbé e tọ Angẹli OLUWA náà lọ ní abẹ́ igi Oaku, ó sì gbé wọn kalẹ̀ níwájú rẹ̀.
O sọ pe ''mo sọ fun wọn pe ki wọn ma a lọ, ṣugbọn wọn sọ pe awọn ṣa a fẹ duro ti mi l'aafin gẹgẹ bi iyawo mi.
Awọn kan sọ pe wọn ṣe eyi lati da omi siwaju ki wọn o ba a le tẹ ilẹ tutu ti coronavirus ba tán nilẹ ni.
Tabi mo bẹ̀ yín pé kí ẹ mú ninu owó yín,kí ẹ fi san àbẹ̀tẹ́lẹ̀ nítorí mi?
Jamaica, Andrew Holness,  se ni Kingston,lorile
Lẹyin naa lo wọ yaara rẹ balopọ ni tipatipa.
Nítorí náà, Jesu kò rìn ní gbangba mọ́ láàrin àwọn Juu, ṣugbọn ó kúrò níbẹ̀, ó lọ sí ìlú kan lẹ́bàá aṣálẹ̀, tí ó ń jẹ́ Efuraimu.
Wọn kesi aarẹ Buhari lati bojuwo awọn mẹkunu nitori ibi n pa mọ.
Lọdun 1999 ni wọn yan an sile igbimọ lati ṣoju ẹkun Asa / Ilorin nipinlẹ Kwara.
N óo rán ìyàn ati àwọn ẹranko burúkú si yín, wọn óo sì pa yín lọ́mọ.
Egbe Alajeseku ti won n je HAAB Domestic Services Cooperative Society ti se idanilekoo fawon obinrin to le ni igba lori sise adin-agbon fun tita lopo yanturu.
"Oríṣun àwòrán, FG Ki ni itumọ ""payroll support""?"
Àkọ́bí Kenaani ní Sidoni, lẹ́yìn rẹ̀ ó bí Heti, 
Ṣugbọn bí ìwọ tabi arọmọdọmọ rẹ bá yapa kúrò lẹ́yìn mi, tí ẹ bá ṣe àìgbọràn sí àwọn òfin ati ìlànà tí mo fi lélẹ̀ fún yín, tí ẹ bẹ̀rẹ̀ sí bọ oriṣa, 
"Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Èmi àti Saheed kìí ṣe ọmọdé, a ti jọ ṣe Sinimá papọ̀, èyí túmọ̀ sí pé ìjà ti parí - Fathia Balogun ""Mo fẹ́ pa ara mi torí ojú àbùkù tí wọn ń fi wò mí pé mo fi iṣẹ́ abẹ bímọ"" Fulani kò leè dúró, táa bá lo ohun ta jogún lọ́dọ̀ àwọn bàbá wa - Sunday Igboho Ọjà Àgbáláta ní Badagry rèé, níbití ẹran ejò ti dùn ju ẹran adìẹ lọ Ninu atẹjade kan ti ijọba ipinlẹ Kaduna fisita lati ipasẹ Kọmisana rẹ fun eto iroyin, Samuel Aruwan ni eyi ti jẹyọ pẹlu afikun pe ijọba ipinlẹ Kaduna yoo pe ẹjọ tako asẹ ileeẹjọ naa, eyi to fun El Zakzaky ati iyawo rẹ laaye lati lọ gba itọju loke okun."
"Lọtun losi lo n yinbọ, o daju pe o ti gbero bo ṣe fẹ ṣe ọṣẹ naa tẹlẹ.
Ó kọ́ ibi mímọ́ jùlọ, gígùn rẹ̀ ṣe déédé ìbú tẹmpili náà, ó gùn ní ogún igbọnwọ (mita 9).
Wo ìdí to fi gbọdọ̀ yàgò fún Bobrisky, akọ tó ń ṣe bíi abo Kí ni ó gbé ọlọ́pàá dé ibi àjọ̀dún ọjọ́ ìbí i Bobrisky?
lọjọ kẹ́tàdínlọ́gbọ̀n , osu kẹ́sán án, odun  2016 , ni aare orile ede Naijiria ,Muhammadu
Wọ́n mú ọ̀pá, wọ́n ń kán an mọ́ ọn lórí.
Nígbà tí ó yá, Eleasari, ọmọ Aaroni kú; wọ́n sì sin ín sí Gibea, ìlú Finehasi, ọmọ rẹ̀, tí ó wà ní agbègbè olókè Efuraimu.
Lara awọn nnkan to sọ nigba ti Aarẹ Buhari n kede igbimọ naa lọjọ kẹsan an, oṣe kẹsan an, ọdun 2020 ree: Lati yọ ọgọrun miliọnu ọmọ Naijiria kuro ninu iṣẹ laarin ọdun mẹwaa sasiko yii, paapaa lẹyin ti banki agbaye ti sọ asọtẹlẹ pe Naijiria yoo jẹ ọkan pataki lara awọn orilẹ-ede ti eeyan rẹ yoo pọju lagbaye ko to di ọdun 2050.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù UNILAG Child Molestation: Ọ̀jọ̀gbọ́n Fagbohungbe ní àwọn òbí ayé òde òní kò ṣiṣẹ wọn bí iṣẹ́ 8 Ìgbé 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, ohun buruku ni agba fipa ba ọmọde lo pọ tabi tami oge sii lara Ọjọgbọn Fagbohungbe Bankole Oni sọ pe awọn obi aye ode oni ko ṣiṣẹ wọn bii iṣẹ mọ.
Ṣugbọn ò ń ṣe kinní kan tí ó dára: o kórìíra iṣẹ́ àwọn Nikolaiti, tí èmi náà kórìíra.
Tí a bá sì gbìyànjú láti pa ojú dé, àwọn ẹ̀ṣọ́ á da iyẹ̀pẹ̀ sí wa.
Ẹkunrẹrẹ alaye re e lori bi ọrọ naa ṣe lọ: Ibẹrẹ oṣu Kẹfa, ọdun 2020 ni wahala naa bẹrẹ, lasiko ti olootu arinrinoge kan, Benjamin Ese, sọ pe D'Banj fi ipa ba ọrọ oun kan lopọ nile itura kan ni Eko l'ọdun 2018.
Sunday ni kii ṣe ọlọpaa lo mu oun ni Bodija.
Ìyípadà orírsirísi ló le wáyé sí gbólóhùn wọ̀nyí tí yóò sì da ètò wọn ní, síbẹ̀síbẹ̀, yóò ní ìtumọ̀.
Kí ó má jẹ́ pé, nígbà tí ẹni tí yóo gbẹ̀san ẹ̀jẹ̀ ẹni tí ó ṣèèṣì pa bá ń lé e lọ pẹlu ibinu, bí ibi tí yóo sá àsálà lọ bá jìnnà jù, yóo bá a, yóo sì pa á; bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé kò yẹ kí wọ́n pa ẹni tí ó ṣèèṣì paniyan yìí, níwọ̀n ìgbà tí ó jẹ́ pé òun ati aládùúgbò rẹ̀ kìí ṣe ọ̀tá tẹ́lẹ̀.
Lady Gaga ṣubú yakata níbi tó tí ń kọrin Islam kọ́ ló ni kí ọmọ ọdún méjìlá lọ sílé ọkọ- Ààrẹ ilẹ̀ Niger Ilé ìgbìmọ̀ aṣòfin ìpínlẹ̀ Kogi júwe ilé fún ìgbákejì Gómìnà Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Akomolede Oyo round up: Àwọn Olúkọ ìpínlẹ̀ Oyo fakọyọ lórí ètò Akọ́mọlédè àti Àṣà púpọ̀
Ẹgbẹ́ òṣèlú PDP sún ìdìbò abẹ́nú Edo síwájú síi Oríṣun àwòrán, facebook/godwin obaseki Ẹgbẹ oṣelu Peoples Democratic Party PDP nipinlẹ Edo to sun ọjọ idibo abẹnu fun awọn to fẹ dipo Gomina ni ipinlẹ naa siwaju.
Ibeji to lepo ni Bauchi: Ọkan ninu re ye ninu isẹ abẹ
Ṣùgbọ́n ìwọ ọ̀rẹ́ mi, nígbà tí mo wà ní ààrin àwọn ọmọ ènìyàn, mo rí púpọ̀ nínú àṣírí wọn.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, coronavirus prevention badge update: Wo òótọ́ àti irọ́ tó wà nínú báàjì àyà náà Bakan naa ni ile tun pinnu lọjọ keji oṣu kẹfa pe ki ileeṣẹ DSTV wa wi tẹnu rẹ lori ọrọ tariifu naa.
Onílé tí ó bá fé se wón ní ìjànbá ni won máa n dojúko àwon yàtò sí àwon agbanipa, kí ipá onílé ó má baà ká won ni wón fi n di ìhámóra Ogun.
Laasigbo eleyameya be sile lorile-ede naa lodun 2013 leyin laasigbo oloselu laarin Aare Salva Kiir ati igbakeji re Riek Machar.
Ọmọ ẹgbẹ́ òkùnkùn ṣoro ní Ijebu Ode, ọ̀pọ̀ ẹ̀mí sọnù Ara mi rẹwà ló jẹ́ kí n máa ṣí ara sílẹ̀- Victoria Kolawole Èyí ni àwọn aṣíwájú ìjọba tí ajé ìwà ìjẹkújẹ ti ṣí mọ́ lórí láàrin ọdún 1960 sí àsìkò yí Mo ti kúrò ní ààfin Oyo, kí ìròyìn tó ò jáde pé èmi àti Wasiu Ayinde n fẹ́ ara wa - Olori Badirat Ṣé lóòtọ́ ni tírélà ti gba ààrín Ronke Odusanya àti bàbá ọmọ rẹ̀, Jago?
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Omiyalé Àkútè: N50 si N100 làwọn èèyàn fi ń kọjá lórí ẹ̀kún omi l‘Ákútè Agbẹnusọ ẹka eto ilera ni ipinlẹ Eko tun mẹnuba awọn ile kan ti ko si ile igbọnsẹ nibẹ tabi ti awọn eniyan kii lo lawọn adugbo kan ni ipinlẹ Eko ni eyi to n jẹ ki arun naa tan sii paapaa ojo to ṣi n rọ bayii.
 a ò le sọ ̀ rọ ̀ nípa orin-ifá kí á yọ ti Ẹ ̀ dú sílẹ ̀ .
Ìdí rẹ̀ ni pé, Ọlọrun ń fẹ́ irú ọmọ tí yóo jẹ́ tirẹ̀.
Tottenham ya aṣọ iyì mọ́ Manchester United lára nírọ̀lẹ́ ọ̀jọ́ ìsinmi Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ojú àwọn èèyàn Ondo ti là pé ìnira ni ẹgbẹ́ APC mú wá - Jegede PDP Lásìkò ìfilọ́lẹ̀ ìgbìmọ̀ ìpolongo fún àtúndi ìbò sẹnatọ ni ẹkun ìlàoorùn ìpínlẹ̀ Eko to wáye ni ọjọ ìṣẹ́gun tó kọjá, níbi tó tí gba àwọn ọdọ́ nímọ̀ràn pé kí wọ̀n fún igbákejì alága ẹgbẹ́ nígbàkan rí olóyè Bode George ní ìsìnmi kúrò nínú ètò òṣèlú.
Oríṣun àwòrán, @Akinwumi Ambode Sẹnẹtọ Isiaka Adeleke to ti doloogbe, Bisi Akande, Olagunsoye Oyinlola ati Rauf Aregbesola lawọn Gomina Osun to n jẹ mula yii.
Dokita Aliyu rọ awọn ọmọ Naijiria ti wọn ni Haji lati ran ara wọn leti iṣepataki titẹle atunṣe tuntun nigba ti asiko ba to lati lẹ oko mọ Asitani lọjọ kẹwaa oṣu kẹjọ.
 "" Lẹsẹkẹsẹ ni a ti fi ikede sita pe, ni ọjọ Iṣẹgun, tii ṣe ọjọ kẹjọ oṣu Kinni ọdun 2019, iwọde apapọ yoo waye lati fi ẹhonu han kaakiri gbogbo ipinlẹ lorilẹede Naijiria."
"Kii ṣabaa rẹ Muyiwa tori aṣiṣẹ-bi-ago ni""."
O ni ọdun Magbo maa n ko ibi kuro ni ilu ni, ti yoo si ko ire wọle, bẹẹ ni ilu yoo tuba, tuṣẹ laisi ewu.
Ọ̀pọ̀ eniyan péjọ sọ́dọ̀ rẹ̀ tóbẹ́ẹ̀ tí ó fi wọ inú ọkọ̀ ojú omi kan.
Theresa May kọwe fipo rẹ̀ silẹ lọsẹ keji lẹyin to kede lati ṣe bẹẹ.
Ṣugbọn ẹni tí ó dá wà gbé!
Nígbà tí ó di òwúrọ̀, bí wọ́n ti ń kọjá lọ, wọ́n rí i tí igi ọ̀pọ̀tọ́ àná ti gbẹ patapata láti orí dé gbòǹgbò.
Kò sì sí èrè tí ọlọ́rọ̀ yìí ní ju pé ó fi ojú rí ọrọ̀ rẹ̀ lọ.
Bí o bá ní ohunkohun láti sọ, dá mi lóhùn;sọ̀rọ̀, nítorí pé mo fẹ́ dá ọ láre ni.
" Ó kọ tó ẹgbẹ ́ rún ewì irú èyí tí a máa ń pè ní "" short lyrics ' ."
O sọrọ naa lasiko ifọrọwanilẹnuwo kan to ṣe pẹlu BBC loṣu Kẹwa, 2016.
Nígbà tí Toi ọba Hamati gbọ́ pé Dafidi ti ṣẹgun gbogbo àwọn ọmọ ogun Hadadeseri, 
Etí odò Naili yóo di aṣálẹ̀,gbogbo ohun tí wọ́n bá gbìn sibẹ yóo gbẹ,ẹ̀fúùfù óo sì gbá wọn dànù.
Bẹ́ẹ̀ náà ni Lukiusi ati Jasoni ati Sosipata, àwọn ìbátan wa.
2021 Prophecies: Ayodele ní ọwọ́ pálábá Abubakar Shekau yóò ségi lọ́dún tuntun
Ta ni ninu wa ló lè gbé inú iná àjóòkú?
Ida mejilelaadọrin ninu ọgọrun idile lawọn ipinlẹ naa lo sọ pe awọn ko ri ọwọ mu lọ sẹnu mọ daadaa.
Ibadan Jungle Justice: Àwọn èèyàn kan ní alárùn ọpọlọ ni Saheed, tawọn mii ni ajínigbé ni
Ajọ naa ni o bani ninu jẹ pe aarun iba lassa ko ti i di ohun igbagbe pẹli akitiyan ijọba apapọ lati ri i wi pe aarun naa ati iba pọnju kasẹ nlẹ ni Niaijiria.
 - Mo kede ayọ nla fun un yin.
O mẹnuba awọn igbesẹ ti oun ti gbe lati fi ya igbeyawo naa ṣugbọn ti obi Damilọla n bẹbẹ pe wọn ko mọ ibi to ti kọ iwakiwa yii.
“Ẹ ka iye àwọn ọmọ Kohati láàrin àwọn ọmọ Lefi, ní ìdílé-ìdílé, gẹ́gẹ́ bí ilé baba wọn.
Wọn ni iwadi fihan wi pe saare yi ni awọn afunrasi kọkọ sin ọ̀gágun Muhammed si ki wọn to wu oku rẹ lo si ibomiran.
Oríṣun àwòrán, other Ki lo ti ṣẹlẹ sẹyin?
A ko le ko iye owo kankan le nini alafia nilu'' Ko ti daju bi ikede yi yoo ti ṣe lapa lara owo irina amọ awọn eeyan n reti ki awọn awakọ din owo irina ọkọ ku nigba ti wọn ko nira epo to iye ti wọn n ra tẹlẹ.
 “A ti n jiroro pẹlu orile ede Sudan; A ti pese
Awọn lọkan-o-jọkan naa lo ti n sọrọ pe ojọ iwaju Naijiria si maa dara lẹyin ọdun mọkandinlọgọta to ti gba ominira.
Babárínsá/ Babárímisá/ Òkúgbésàbí: Ọmọ tí a bí lẹ́yìn ikú bàbá rẹ̀, bí ọmọ bẹ́ẹ̀ bá jẹ́ ọkùnrin
0 88252 Orilẹede Kazakhstan 2488 13.
 Nitori kii se asa wa, tabi ise awọn asaaju ijọba yii, bẹẹ ni awọn asaaju ijọba Eko ko ni faramọ irufẹ iwa yii.
"Mo ṣi maa n lọ wo awọn patako ti wọn ti n polowo iṣẹ,"" Chekole sọ."
Oríṣun àwòrán, Alaafin Bawo ni baba ṣe wa n ṣe e.
 nì ìlú Èkó yí ni ó ti pàdé olórin jùjú tí a mọ ̀ sí s.
Bashir Ahmad to jẹ oluranlọwọ fun Aarẹ Buhari sọ pe lootọ ni ijọba ti da eto RUGA duro naa.
Ileeṣẹ ọlọpaa ko ṣai fikun ọrọ rẹ pe ọtọọtọ loun ya fọto awọn mejeeji ki oun to lẹ wọn pọ.
Solomoni ranṣẹ sí Huramu, ọba Tire pé, “Máa ṣe sí mi gẹ́gẹ́ bí o ti ṣe sí Dafidi, baba mi, tí o kó igi kedari ranṣẹ sí i láti kọ́ ààfin rẹ̀.
Lati bii ọdun mẹrin sẹyin lo ti n ṣe ayẹyẹ ọdun yii laipaarọ iye ọjọ ori rẹ.
- Madam Saje Owó ilé ìwé gbígbà ní ìpínlẹ̀ Ogun ti di ìtàn - Gómìnà Ẹ lọ́ jáwé gbé jẹ́ẹ́ sọ́wọ́ bí bẹ́ẹ̀ kọ́.
Adeniran ni irọ patapata ni wi pe, awọn n gba eniyan si isẹ ni ipinlẹ naa, nitori naa ki awon araalu mase jẹ ki wọn lu wọn ni jibiti owo, lasiko ti wọn ba n wa isẹ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Revolution Now: NLC ní bí agbófinró ṣe mú Soworẹ àti àwọn yókù rẹ̀ sí àhámọ́ tẹ ẹ̀tọ́ ọmọnìyàn lójú 8 Ògún 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Ẹgbẹ oṣiṣẹ l'orilẹede Nigeria, NLC, ti keboosi pe ki wọn o tu Omoyele Sowore ati awọn oludije miran silẹ ni kiakia.
A kò mọ̀ọ́mọ̀ pa ọlọ́pàá mẹ́ta, aráàlú kan, ó ṣèèsì ni, ajínigbé la pè wọ́n - Iléeṣẹ́ ológun Ileeṣẹ ologun Naijiria ti sọ pe awọn ọmọ ogun oun ko mọọmọ yinbọn pa awọn ọlọpaa ati araalu to ku ní ìpinlẹ Taraba.
Ninu atẹjade naa ni Tinubu ti fi lede wi pe oun ati iyawo oun ko ni arun Coronavirus lẹyin ti awọn ṣe ayẹwo.
”O fikun un pe, awon iko osise ina monamona ti n bere ise bayii lati lo ri opo ina miiran, leyin ti ikolu iji ohun wo opo ina ti o to ọ́ọ̀dúnrún niye.
Aarẹ Buhari sọ nipa igbese naa lẹyin ti ẹgbẹ́ òṣìṣẹ́ NLC fagile ìyansẹ́lódì ti wọn fẹ gunle ní Ọjọ́ Ìṣẹ́gun láti bèèrè fún àfikún owo oṣù òsìsẹ́ ní Naijiria.
Fashọla: Àwọn ọmọ Nàìjíríà sọ̀rọ̀ lórí ìpèsè iná ọba tí mínísítà Fashọla ní ó ti ń ṣe dédé
Ẹ lo ìfẹ̀họ̀núhàn #EndSARS lati fí tún gbogbo ohun tó bàjẹ́ ṣe ní Naijiria- Pásítọ̀ Sam Adeyemi Ẹ wo èrò bìbà níbi ìwọ́de #EndSARS ní ìlú Ibadan Pẹlu ikede yi, ohun to ku ni boya awọn oluwọde yoo fọwọ wọnu dẹkun iwọde tabi ki wọn ṣi tẹsiwaju.
títí n óo fi sọ àwọn ọ̀tá rẹ di àpótí ìtìsẹ̀ rẹ.
Ẹ tẹti si ìfọ̀rọ̀wanilẹnuwò pẹlu Oba Àkanbi nibi: Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fọ́nrán ohùn, Oluwo Ìwo ṣ'àlàye lori oyé oba oni lawàni Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Asán ni gbogbo ọ̀ṣọ́ tí o ṣe,àwọn olólùfẹ́ rẹ kò kà ọ́ sí,ọ̀nà ati gba ẹ̀mí rẹ ni wọ́n ń wá.
OLUWA, ìyanu ni iṣẹ́ ọwọ́ rẹ!
" O tun sísọ lójú rẹ pé, inu sinima 'Ilé Tí A Fi Itọ́ mọ' ní òun ti ń jẹ orúkọ Baba Wande, èyí tó wà di Gbajumọ títí di òní, kii sì ṣe wípé òun bí ọmọ kankan tó ń jẹ Wande.
Láàrin wákàtí mẹ́ta, wọ́n dá ₦4m fún àkàndá ẹ̀dá tó kópa nínú ìwọ́de Wo ohun tí ìwọ́de ENDSARS ṣé fáwọn akẹ́kọ̀ọ́ tó fẹ́ ṣèdánwò NECO Iná jó dórí kókó, Buhari pe Lawan, Gbajabiamila sí ìpàdé lórí ìwọ́de àwọn ọ̀dọ́ Lizzy Anjorin ń kiri àgọ́ ọlọ́pàá láti gba ọ̀dọ́ afẹ̀hónúhàn, tó wà láhàámọ́ sílẹ̀ Ọga agba patapata nileeṣẹ ọlọpaa Naijiria, Muhammed Adamu ṣalaye ni ọjọ Aiku pe awọn ọlọpaa ti yoo darapọ mọ ikọ kogberegbe ti wọn fẹ fi rọpo SARS naa gbọdọ ni awọn amuyẹ wọnyii.
Mọremi ko jẹ ki ohunkohun jọ oun loju lati fi gba ilu rẹ silẹ lọwọ awọn ọta, bakan naa lo yẹ kawa pẹlu fi ifẹ orilẹede wa siwaju ju ohunkohun lọ, ti a ko si gbọdọ maa ko dukia jọ lati pa orilẹede wa lara.
Ṣugbọn nígbà tí àwọn alágbàro yìí rí i, wọ́n bà ara wọn sọ pé, ‘Àrólé rẹ̀ nìyí.
Wọn ni o ma n sisẹ fun aisan ikọfe e ati aisan jẹdọjẹdọ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Otedola Bridge accident: Èèyàn méjì bá ìjàmbá ọ̀kọ̀ tó ṣẹlẹ̀ lórí afárá Otedola lọ 4 Sẹ́rẹ́ 2020 Oríṣun àwòrán, LASEMA Eeyan meji ti dero ọrun ninu ijamba ọkọ to ṣẹlẹ lori afara Otedola lopopona marosẹ ilu Eko si Ibadan lọjọ Satide.
Ninu ilẹ̀ wọn ni Mahalabu, Akisibu; 
Loju opo Twitter rẹ o sọ wi pe ki awọn eeyan ma se ka ọrọ ti awọn kan n sọ wipe panpẹ ni ẹ̀yáwó $328 million ti Nàìjíríà fẹ yà lọ́wọ́ orílẹ̀èdè China jẹ kun.
Alhaji Taofeek Oyerinde Fẹ́lẹ́, ti o jẹ alaga ẹgbẹ awọn awako NURTW ipinlẹ Ọyọ jade laye lọjọ isegun, nile iwosan to n risi itọju kindinrin nilu Abuja nipasẹ aisan kindinrin to baa finra.
Ọgbẹni Ajayi rọ awọn alatilẹyin rẹ pe ki wọn ma ni ọkan, o ni oun yoo kede igbesẹ to kan fun oun laipẹ.
 Ìwádí àrùn yìí dá lórí àmi àwọn àrùn àti ṣíṣe àyẹ ̀ wò omi tí ó jáde láti ojú ara , láti ri bóyá ph rẹ ̀ pọ ̀ ju bóṣeyẹ lọ .
Bayii ni n o ṣe nakn mii, kuku yatọ si bayii ni a o ṣe nkan wa.
eniyan ati ohun ini  won ati awon ti won tun
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Unilag VC: Folasade Ogunsola ni obìnrin àkọ́kọ́ tó jẹ ọ̀gá àgbà fún ibùdó ẹ̀kọ́ṣẹ́ ìṣègùn Fáṣítì Eko 12 Ògún 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 24 Ògún 2020 Oríṣun àwòrán, @Anisformat Ọdun 1958 ni wọn bi Ọjọgbọn Folasade Tolulope Ogunsola, ọmọ Mabogunje sile aye.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Dogara: Ohunkóhun kò gbọdọ̀ ṣe Dino Melaye 3 Èbibi 2018 Oríṣun àwòrán, @HouseNGR Àkọlé àwòrán, Àwọn aṣojú-ṣòfin gbarata lórí ọ̀rọ̀ Dino Olórí ilé aṣojú-ṣòfin lórílẹ̀-èdè Nàìjíríà, Yakubu Dogara, ti f'ohùn ránṣẹ́ s'awọn agbófínró pé ohunkóhun kò gbọdọ̀ ṣe Sẹ́nétọ̀ Dino Melaye ti wọ́n gbé lọ sílé ẹjọ́ lórí kẹ̀kẹ́ aláìsàn lọ́jọ́ ọ̀rú àti ọjọ́bọ.
Channels Television gba aami-eye “Developmental Award”.
Oluwatoyin Olanipekun: Wo àwọn òyìnbó tó ń kẹ́kọ̀ọ́ èdè Yorùbá ní Michigan, America Iná sọ nínú ilé Big Brother tó ń lọ lọ́wọ́ ní Cameroon Ta ló ń lọ sílé lónìí nílé ẹlẹ́gbọ̀n ọ́n àgbà?
Ṣùgbọ́n o, Ṣèyíówùú Ọlọ́run kìí ṣe àìfagbára rẹ̀ han ọmọ ènìyàn lẹ́kọ̀kan.
 oún ni ìyálódè Ègbá àkòkó .
ṣaaju ọjọ abamẹta, ibo to le ni ẹgbẹrun mẹta lo la wọn laaarin.
Ijọba orilẹede naa ohun ti fi agbo naa to jẹ ti Naijiria ranṣẹ si Equitorial Guinea nibi yio ti wọ ilu Abuja.
Àkọlé àwòrán, Ìpínlẹ̀ Kano: Ọmidan tó ba rín láago 8 alẹ́ yóò derò ẹwọn Ó ní '' ojoojúmọ ní àwọn ọkùnrin máa ń jáde láti da ǹkan pọ̀ pẹ̀lú àwọn ọmọ wọn yìí, tí a bá mú wọn, ti a sì rii dájú pé wọn kìí ṣe àṣẹ́wo, a ó fi wọn sílẹ̀ láti máa ba tiwọn lọ.
Ipinlẹ Kano ni o ti pari ileewe alakọbẹrẹ rẹ.
Obedi ni baba Jehu, Jehu sì ni baba Asaraya.
Ni o bá dàgbà, o ga, o sì di wundia, ọyàn rẹ yọ, irun rẹ sì hù, sibẹ o wà ní ìhòòhò.
Solomoni kan ọpọlọpọ ọkọ̀ ojú omi ní Esiongeberi lẹ́bàá Eloti, ní etí Òkun Pupa ní ilẹ̀ Edomu.
Gbogbo Israẹli bá pada sílé wọn; ṣugbọn Rehoboamu ń jọba lórí àwọn ọmọ Israẹli tí wọ́n wà ní ilẹ̀ Juda.
Ileeṣẹ aarẹ ni wọn yoo ṣe iwadii lori ijamba naa gẹgẹ bii ilana iru iṣẹ bẹẹ.
Èyí ló mú kí wọ́n dábàá pé kijọba apapọ ṣe adínkù owó tó ń pínfun ara rẹ, eyi to jẹ́ ìdá méjìléláàdọ́ta, ko si sọ di ìdá mẹ́tàdínlógójì.
Èsì li sunkún ètìtù kọ gbà àrán bora li Gèsan Ọba
Nkan tí ẹ̀rọ yìí nlò ṣiṣẹ́ sì ni epo-rọ̀bì.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Obasanjọ: Ọbasanjọ ní òhun yóò fi ìyókù ayé òun san oore Ọlọrun ni Minisita feto ilera ṣalaye ninu ọrọ rẹ fawọn oniroyin pe ogoji eeyan ni wọn ti fi sahamọ ayẹwo lori arun yii nipinlẹ Ogun; ogun miran pẹlu ṣi wa labẹ ayẹwo nipinlẹ Eko.
iṣamojuto lẹnu iṣẹ ijọba, iṣẹ ilu tabi idagbasoke awujọ.
Ninu atẹjade kan ti ileeṣẹ ọmọ ogun ofurufu fi sita bayii ni wọn ti kede pe igbesẹ yii di dandan lasiko yii.
Ipinlẹ Eko lo tẹlee pẹlu ọgọrun eeyan ti ipinlẹ Plateau si ni mejilelaadọta.
Àjọ NDE ni yóò máa dari ètò náà, à ó si ṣíṣẹ́ takuntakun láti rii dájú pé a bá àsìkò tí a pinu fún ètò náà.
Nigbà tí ìyípadà sì ń dé tí ojú ń là á sí i ni wọ́n sọ orúkọ ìlú da ÌJẸ̀BÚ dípò Ìjẹ̀bú tí wọ́n ti ń pè tẹ́lẹ̀.
Ṣugbọn ìfẹ́ mi tí kì í yẹ̀ kò ní kúrò lára rẹ̀,bẹ́ẹ̀ ni n kò ní yẹ òtítọ́ mi.
Lẹ́yìn ti ìwọ́de ti FALZ àti Runtown pè ti wọn sì fi àdàgbá ètò náà rọ síbì kan, tí olúkúlùkù sì gba ọ̀nà ilé wọ́n lọ láti fí orí lélẹ̀ ní gbájúgbajà adẹ́rìn pòsònú Debo Adebayo ti gbogbo ènìyàn mọ̀ sí Mr Macaroni náà bẹ̀rẹ̀ tirẹ̀.
Akin Alabi, to sẹsẹ se ere alaworan kan fawọn ọmọde ni ede Yoruba sọ fun BBC pe ko dara to bo se jẹ ere alaworan tawọn alawọ funfun se jade ni ede wọn nikan lawọn ọmọde wa n wo.
Ogunoye, tii se oludari eto isuna ati akoso nipinlẹ́ Ondo ki wọn to yan sipo naa, ni yoo jẹ Ọlọwọ kejilelọgbọn.
Nígbà tí ó fẹ́rẹ̀ tó àkókò Àjọ̀dún Ìrékọjá ti àwọn Juu, ọ̀pọ̀ eniyan gòkè lọ sí Jerusalẹmu láti ìgbèríko, kí ó tó tó àkókò àjọ̀dún, kí wọ́n lè ṣe ìwẹ̀mọ́ fún àjọ̀dún náà.
Temilolu sọ pe awọn tọọgi naa fi iya jẹ oun atawọn eeyan miran to wa ni afin lọjọ naa ki wọn to gbe oun sori ọkada lọ afin Aroloye.
Ẹ fetí sí ètò Yorùbá Gbòde níbi tí olóòtú Ṣọla Yusuf ti gba amòye onímọ̀ nípa Ebola, tí wọ́n sì làwá lọ́yẹ̀ dáadáa.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Lock down: ìjọba àpapọ̀ Nàìjíríà ní ẹnìkan ṣoṣo nínú ìdílé kan ni yóò gbà N20, 000 owó ìdẹ̀rùn igbele Covid-19 13 Ìgbé 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 22 Ìgbé 2020 Oríṣun àwòrán, Sadiya_farouq Ìjọba àpapọ̀ Nàìjíríà tí kéde pé, èèyàn kan ṣoṣo ni yóò gbà owó ìdẹ̀rùn tí ìjọba ń pèsè fún ìdẹ̀rùn igbele àrùn Coronavirus.
Àgàn ti di ọlọ́mọ meje,ọlọ́mọ pupọ ti di aláìní.
Ṣé àwa Juu sàn ju àwọn orílẹ̀-èdè yòókù lọ ni?
A ti n sọ eleyii ni ipinle mi pe ẹ̀gbẹ̀rún  méjìdínlógún 
‘Kìí ṣe ẹ̀yin nìkan ni mò ń bá dá majẹmu yìí, tí mo sì ń búra fún, 
Ní àríwá Thailand, àlọ́ àwọn aráa Akha kan nípa ìpilẹ̀ṣẹ̀ swing tí ó sọ iṣẹ́ takuntakun ìfaraẹnisílẹ̀ t'ẹ̀gbọ́ntàbúrò tí ó mú ayé rọrùn.
Baba ọkọ afẹsọna Favour sọ fun wi pe ti o ba fẹ Favour, yoo tete ku , nitori idile Osu lo ti wa.
Wọ́n ni ẹnu ní i jẹ́ bẹ́ẹ̀ Ǹjẹ́ kí ni wọ́n ní bọ n'ife?
lu iroyin aheso kan ti o so pe oun fe fi orile-ede ohun sile, bee si ni o tun
Wọn sọ pe fẹntilatọ awọn yoo mu ki ara tu awọn ti ko ba le mi daadaa lawọn aaye ibi ti ojulowo fẹntilatọ ko ba si.
Kí oṣù kọkànlá ọdún tó parí, ààrun náà ti tan ka ìpínlẹ̀ márún ni Nàìjíríà, Delta, Enugu, Benue, àti Ebonyi.
Yoruba Movies: Àwọn òṣèré Yollywood tó ń pàrònú rẹ́
Oríṣun àwòrán, @pdp Àkọlé àwòrán, Ọkan lara ẹgbẹ oṣelu Naijiria Ojọgbọn Oluṣọla lo n ṣamojuto eto ẹkọ ipinlẹ Ekiti labẹ Fayoṣe, eyi to mu idagbasoke ba àṣeyọri awọn akẹkọọ loriṣiiriṣi Ekiti lọdun 2016.
 Mbaka wa gbe imọran kalẹ pe ohun to yẹ ko jẹ wa logun bayii ni eto ti Naijiria ni fawọn ọdọ rẹ ati ipese awọn ohun eelo amayederun."
Àwọn dókítà Nàìjíríà ti fòpin sí ìyanṣẹ́lódì wọn Wo iye àwọn tó ti gbẹ̀mí ara wọn ní Nàìjíríà láàrin ọdún mẹ́rin ìjọba Buhari Gbèsè Nàìjíríà ti lé ní 18 tírílíọ́ọ́nù lábẹ́ ìṣèjọba Ààrẹ Buhari- DMO Wo bí iṣẹ́ abẹ wákàtí mẹ́fà, tí wọ́n fi dóòlà ẹ̀mí ìjàpá tí ọkọ̀ tẹ̀, ṣe lọ Kò sóhun tó ń jẹ́ ‘Captivus’ nílẹ̀ Oodua, mágùn ni mágùn ńjẹ́ - Babaláwo Wo àwọn obìnrin abúlé kan tó dáwó ra ọkọ̀ láti máa gbé aláboyún lọ ilé ìwòsàn Ni ibẹ ni o ti kọkọ jẹ ẹni akọkọ ti yoo gba bọọlu wọ inu awọn fun Naijiria ninu Idije Agbaye.
Àwọn Juu bẹ̀rẹ̀ sí wá a níbi àjọ̀dún náà, wọ́n ń bèèrè pé, “Níbo ni ó wà?
Àkọlé àwòrán, Aworan afikun iroyin nipa ajakalẹ arun coronavirus ni Naijiria Ipinlẹ Eko lo n lewaju loke tente ni iye awsn to ti ni arun naa.
Lọpọ igba awọn fasiti Naijiria a ma ni fakinfa lori yiyan ọmọ ilu gẹgẹ bi ọga fasiti ijọba apapọ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Jolo church attack: Ọpọ èèyàn kú nínú ilé ìjọsìn ní Philippines 27 Sẹ́rẹ́ 2019 Oríṣun àwòrán, AFP/Getty Images Àkọlé àwòrán, Ibugbamu naa ṣe akoba fun ile ijọsin ohun ni Jolo Eeyan mẹtadinlọgbọn ti padanu ẹmi wọn nigba ti ado oloro meji dun ni ile ijọsin iya ijọ Katoliki kan ni guusu orileede Philippines.
Ohun ti eyi tumọ si ni pe wọn ko ni yọju lati ṣe ifọrọwanilnuwo kankan titi ti wọn yoo fi gba iwe irina tuntun mi.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Olaitan Olamide: mò lè má nílò ìwé ẹ̀rí mi tí mo bá parí ní LASU Alaga igbimọ to n dundura pẹlu ijọba atawọn oṣiṣẹ, Abdulrafiu Adeniji ni o ṣeni laanu pe ijọba le sare kede afikun owo ina nigba ti ko ti yawo kan dejo lori ẹkunwo owo oṣu oṣiṣẹ kaakiri Naijiria.
Isaaki bá mú Rebeka wọ inú àgọ́ Sara ìyá rẹ̀, Rebeka sì di aya rẹ̀, Isaaki sì fẹ́ràn rẹ̀.
Agbeyẹwo fọọmu fun nọmba adani Ni ipele yii ni awọn oṣiṣẹ ajọ ẹṣọ oju popo yoo ṣe ayẹwo fọọmu ti wọn fi ṣọwọ si wọn finifini.
Mo rí I pé wọ́n ń palẹ̀mọ́ níilé wa, wọ́n kó gbogbo ǹkan ìtúnlé ṣe tí ó wà nínú pálọ̀ wa pamọ́ ní ilé wa pa mọ́.
" Ileeṣẹ aarẹ tẹsiwaju pe kii ṣe asiko yii lo yẹ ki awọn eniyan o maa bu aarẹ, ṣugbọn o yẹ ko jẹ akoko iṣọkan tako arun naa.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Faye Mooney: Ìlú Eko ló ti lọ sóde àríyá ní Kaduna ni wọ́n yìnbọn fun 22 Ìgbé 2019 Oríṣun àwòrán, @thenewsnigeria Ọlọrun ma jẹ ka rin ni ọjọ ti ebi yoo pa ọna tabi ti a se agbako iku ojiji.
Nítorí náà, ogun kò ní kúrò ní ìdílé rẹ títí lae; nítorí pé o ti kẹ́gàn mi, o sì ti gba aya Uraya.
Aare Buhari ati awon amugbalegbe re gbogbo, bale si papako ofurufu awon omo ogun (Military Base Balice International Airport), niluu Krakow, nirole ojo abameta(Saturday).
Oo le maa rin regberegbe iri pẹlu akọ kaakiri tabi ki obinri ṣe idakeji rẹ lasiko ti ko tun tọ - Ọrọ wahala nla ni o.
Ti ọdun 2020 yii ṣeeṣe ko bọ si ọjọ kẹrinlelogun, oṣu karun un.
 awakọ ̀ , john johnston lati stoke-on-trent farapa púpọ ̀ sùgbọ ́ n kò kú .
Ṣugbọn ikọ amuṣẹya ti aarẹ yan ni iṣẹ ṣi ku lati jẹ ki awọn eeyan mọ sii paapaa lawọn igberiko.
Òkúta tí àwọn ọ̀mọ̀lé kọ̀ sílẹ̀,ni ó di pataki igun ilé.
ÒJÒLA-ÌBÍNÚ TÍ Í ṢE OLÓRÍ EJÒ AYÉ GBOGBO
A Mú Jesu Lọ Siwaju Pilatu.
Àwọn ọmọ ti Rakẹli ni Josẹfu ati Bẹnjamini.
“Ẹ má rò pé mo mú alaafia wá sáyé.
Ó dàbí wóró musitadi tí ẹnìkan gbìn sinu oko rẹ̀.
Àwọn èèyàn ìpínlẹ́ Ondo kò gbàgbọ́ pé Coronavirus wà lọ jẹ́ kó máa pọ̀ síi - ìjọba Tinubu, ojú tì ẹ́, o ta Yorùbá fún ọ̀tá torí àdánìkànjẹ - Fani-Kayode Wo bí o ṣe lè fí orúkọ rẹ sílẹ̀ fún iṣẹ́ N Power tuntun ti ọdún 2020 Iré dé!
orúkọ  boko haram "" yìí túmọ ̀ sí "" Èèwọ ̀ ni ẹ ̀ kọ ́ ọ ̀ làjú "" ."
Ile itoju awon to ni aarun
Bi o tilẹ jẹ wi pe iroyin miran jade lati sọ pe gomina Ambode n gbeero lati gba ẹgbẹ oṣelu miran lọ bi APC ba kọọ, sugbọn ohun ti igun rẹ n sọ yanya ni pe ko si igba kan ti gomina ipinlẹ Eko naa sọ tabi pete-pero ati lọ si ẹgbẹ oṣelu miran.
“Bí àwọn ọmọ Reubẹni ati Gadi bá bá yín ré odò Jọdani kọjá láti jagun níwájú OLUWA, bí wọ́n bá sì ràn yín lọ́wọ́ láti gba ilẹ̀ náà, ẹ óo fún wọn ní ilẹ̀ Gileadi gẹ́gẹ́ bí ìní wọn.
Lákòókó tí ó fi dúró yẹn, ó rò wí pé òun ti rìn jìnnà díẹ̀ sí àbùrò òun kò mọ̀ wí pé nnkan ibùsọ̀ mẹ́fà péré ni òun tí ì rín.
 Ìyàtọ ́ yìí le hàn ketekete tàbí kí ó farasin .
Oríṣun àwòrán, Twitter Gomina ipinlẹ Ondo to paṣẹ ọjọ isinmi lo ni fun awọn ara ilu lati gbalejo aarẹ Muhammadu Buhari, rọ awọn araalu lati lo ile itaja naa fun idagbasoke ipinlẹ Ondo ati Naijiria lapapọ.
Yàtọ̀ f'àwọn mẹ́fà tó m bọ̀ láti ìpàgọ̀ àdúrà tó kú, àjọ FRSC Osun sọ ipò táwọn tó fara pa wà báyìí Bàbá fìdí ọmọ ọdún márùn ún jó sítóòfù gbígbònà, ó di aláàbọ̀ara nítorí ó jí ẹja Ẹ ṣọ́ra fún ayédèrú ìròyìn, mi ò pe Buhari ní alákatakítí ẹ̀sìn láéláé- Tinubu ṣàlàyé Ìgbìmọ̀ ọ̀tẹ̀ ní ọ̀rọ̀ àwọn àgbààgbà ẹkùn àríwá pé ìjọba Buhari ti kùnà- Femi Adesina Buhari ń fowó aráàlú gbàtọ́jú nílùú òyìnbó nígbà táwọn ilé ìwòsàn wa ti di mọ́ṣúárì - Falana Àṣírí èèyàn kan tó dìbò ní ìgbà 89 tú, Ọlọ́pàá gbé e jàǹtò!
“Ẹ gbọ́ Israẹli: OLUWA Ọlọrun yín, OLUWA kan ṣoṣo ni.
Noodles: Oúnjẹ aládùn ni àgbáyé mọ Nódùùlù sí
ó sì mú àwọn ọmọ Israẹli kọjá láàrin rẹ̀,nítorí pé ìfẹ́ rẹ̀ tí kì í yẹ̀ wà títí lae;
Wọnyi ni awọn kọmiṣọna mẹrinla naa atawọn ileeṣẹ ẹnikọọkan ti wọn yoo di mu gẹgẹ bi Gomina Ipinlẹ Oyo ti kede rẹ.
 Lara awọn nnkan eelo iṣisẹ ti o fun awọn ara ilu ninu eto naa ni awọn ẹrọ iranṣọ, awọn ẹrọ ilọta, awọn ẹrọ ti awọn aṣerunloge n lo, àwọ̀n apẹja, awọn ẹrọ amunawa, awọn ike igalode a-mu-nnkan tutu pẹlu awọn ọja bii ọti ẹlẹrin dodo ti awọn olowo keekeekee fi le bẹrẹ owo, abbl.
Òṣìṣẹ́ reluwé tó bá gbé owó gun tíkẹ́ẹ́tì, yóò gé ìka jẹ - Amaechi Ọ̀sẹ̀ méjì péré la fẹ́ kí iṣẹ́ reluwe Eko sí Ibadan parí - Amaechi Ọkọ̀ ojú irin pa ènìyàn mẹ́rin ní Eko Rélùwéè tẹ alágbe kan pa ní Eko Bakanna ni wọn ṣe iru ikede yi nigba ti wọn ṣe ayẹwọ irinajo Eko si Abeokuta to jẹ abala kini oju irin to lọ laarin Eko si Ibadan.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Kogi elections: Ilé ẹjọ́ ní ẹgbẹ́ AA kùnà ìlànà INEC fún ìbò gómìnà ní Kogi, Bayelsa 29 Ọ̀wàrà 2019 Oríṣun àwòrán, @AllianceAa Ile ẹjọ giga apapọ kan nilu Abuja ti paṣẹ pe ẹgbẹ oṣelu Action Alliance (AA) ko lẹtọ lati fa oludije silẹ fun eto idibo sipo gomina ni ipinlẹ Kogi ati Bayelsa.
Oríṣun àwòrán, AFP Àkọlé àwòrán, Awọn ọmọ kekere ilẹ Congo kan ni ibudo awọn atipo ni Kalemie to wa ni orilẹede Ijọba-ara-ẹni Congo.
Iroyin to n tẹ wa lọwọ sọ pe ni ila oorun ariwa Naijiria ni awọn oniṣẹ ibi yii kọlu ni ipinlẹ Borno.
fún nǹkan bí irinwo ọdún ó lé aadọta (450).
"Wọn ko nile iwosan ti wọn ti n wo were, amọ awa ni nilu Eko nibi, a si mu Fayose lọ sibẹ pe ki wọn lọ yẹ ọpọlọ rẹ wo, ologun si ni emi, emi kii gba igba kugba, mo si kọja ẹni ti ọmọ kan maa yọ ẹnu si tabi fi tayin.
Ọkan mi bajẹ lati gbọ iro iku oserebirin to mọ ere se to baun."
Ni bayii, iroyin fihan pe ile iṣẹ ọlọpaa ni ipinlẹ Eko ti fi panpẹ ọba mu awọn ọlọpaa ti wọn fi ẹsun kan naa, ati wi pe iwadii n tẹsiwaju.
Oríṣun àwòrán, kunle afod/instagram Afod sọ pe oun gbiyanju lati kàn si Satia ninu ọdun yii, ṣugbọn ko ṣeeṣe.
 n ò sì bá wọn wí bí ẹní fọmọ fọ ́ kọ lóru .
Ajọ NLC fi ẹsun kan MTN wi pe ileesẹ naa kọ lati fun awọn osisẹ won laaye lati darapọ mọ ajọ osisẹ lorilẹede Naijiria lati le ja fun ẹtọ wọn.
Wọn ko ṣẹṣẹ bẹrẹ, sugbọn eleyi ti wọn ni mo ku yi ṣe mi ni kayeefi pupọ'' Ebenezer Obey ṣalaye pe, n ṣe ni awọn eeyan n pe oun lori aago ilewọ kaakiri agbaye, ti ''ẹlomiran si n bu sẹkun lori foonu nigba ti wọn gbọ ohun mi'' ''Iṣẹ ti mo wa ṣe laye ṣi ku, bi mi o si pari rẹ, mi o ni kuro lori eepẹ, orin ṣi ku ti mo ma kọ, ko tii tan'' Ọ̀pá epo NNPC bú gbàmú ní Benin, òṣìṣẹ́ méje kàgbákò ikú òjijì Ọ̀fọ̀ ńlá ṣẹ̀ ní Ivory Coast, Olóòtú ìjọba, Amadou Gon Coulibaly jáde láye Tó o bá fẹ́ wọ bàálù lásìkò yìí, wo òfin tuntun tó tẹ̀lé Ọwọ́ ọlọ́pàá ìpínlẹ̀ Oyo ti tẹ àwọn aṣekúpani tó ń ṣọṣẹ́ ní Akinyele Ìpínlẹ̀ Eko kéde ọ̀nà àbáyọ sí súnkẹrẹ-fàkẹrẹ ọkọ̀ lásìkò àtúnṣe afárá Third Mainland Wo ìgbẹ́sẹ̀ méjọ tí ilé aṣòfin ìpínlẹ̀ gbọdọ̀ tẹ̀lé láti yọ igbákejì gómìnà Ilé aṣofin Ondo fọwọ́ òsì júwe ilé fún aṣòfin mẹ́ta pé wọ́n tàpá sí òfin ilé Irọ́ ni o, Ebenezer Obey ò kú!
”OLUWA dá a lóhùn pé, “Kọlù wọ́n, n óo fún ọ ní ìṣẹ́gun lórí wọn.
Ṣugbọn bí inú rẹ̀ kò bá dùn sí mi, kí ó ṣe mí bí ó bá ti tọ́ ní ojú rẹ̀.
Ta ló pàṣẹ nǹkankan rí tí ó sì rí bẹ́ẹ̀,láìjẹ́ pé OLUWA ló fi ọwọ́ sí i?
Amọṣa lara wọn ni awọn ti o nii ṣe pẹlu omi wa.
Gomina ipinle Eko, ogbeni Akinwunmi Ambode ti gba pe oun fiidi re mi ninu idibo abele fun ipo gomina labe asia egbe oselu APC nipinle Eko.
O ni o yẹ ki Rochas o mọ pe irufẹ ọjọ bayii yoo waye lai jẹ pe ẹnikẹni wi fun un.
Ṣugbọn nítòsí yín ni ọ̀rọ̀ náà wà, ó wà lẹ́nu yín, ó sì wà ninu ọkàn yín, tí ó fi jẹ́ pé ẹ lè ṣe é.
Wọ́n dúró lẹ́nu ọ̀nà ilé OLUWA tí ó kọjú sí ìhà ìlà oòrùn, ìtànṣán ògo Ọlọrun Israẹli sì wà lórí wọn.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Buhari kò leè ṣàtìlẹyìn fún olùdíje Amosun l'Ogun Mi ò tan mọ́ ààrẹ Buhari rárá o!
Ènìyàn 156 ló tún ṣẹ̀ṣẹ̀ lùgbàdì ààrùn Coronavirus ní ìpínlẹ̀ Eko Ẹbí Tolulope Arotilẹ ń bèrè fún iwadii lórí ìkú tó pa á!
Àwọn metẹẹta ni: Àjàyí Bembe tó wá láti aarin gbùngbùn Ikoyi; Olanrewaju Sanusi láti ẹkùn Ikorodu àti Obafemi George láti ijoba ibile Eti Ọsa.
Àwọn aṣọ títa ti àgbàlá ati àwọn òpó rẹ̀ ati ìtẹ́lẹ̀ àwọn òpó ati aṣọ títa fún ẹnu ọ̀nà àgbàlá náà.
Jesu bá yipada, ó rí obinrin náà, ó ní, “Ṣe ara gírí, ọmọbinrin.
"Awọn eeyan to ba ri mi loju titi yoo rin tọ mi wa, ti wọn yoo si sọ fun mi pe mo da bii ọdaran.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Tinubu: Nítorí Tinubu, àwọn ọmọge Sanwo-Olu da ìlù bolẹ̀ Olùgbékalẹ̀ ètò náà Victor Taiwo ní ìgbésẹ̀ náà di dandan ní àsìkò yìí nítori pé iná ìran Yorùbá tí ń jó àjórẹ̀yìn.
Paul Sodje lo dari ikọ Naijiria lọ si idije Alawọ dudu ilẹ Afrika to waye ni orilẹede Zambia ni ọdun 2012.
Ó pada lọ sí ọ̀dọ̀ àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ mẹta, ó rí i pé wọ́n ti sùn lọ!
Ọ̀pọ̀ àwọn obìnrin ni wọn ń gbé ilé tí ó súnmọ́ ara wọn èyí sì mú kí ìsúnfúnraẹni kí ó nira díẹ̀.
Nígbà tí ó ṣe tí ó bẹ̀rẹ̀ sí rẹ̀ wá, Ènìyàn-ṣe-pẹ̀lẹ́ tí kò ti jẹ epo tí kò jẹ iyọ̀ ti mú ọ̀pọ̀lọpọ̀ọ̀ yanrìn ó bù ú sí inú ìkòkò ńlá lọ, lẹ́hìn èyìínnì ó mú omi tí ó wà nínú ìgò tí Baba-onírùngbọ̀n-yẹ́úkẹ́ fi fún wa, ó wọ́n omi náà sí àwọn yanrìn náà lára ó sì kígbe lóhùn rara, ó wí pé: Mo pa á láṣẹ lórúkọ Olódùmarè, Ọlọ́run, Alààyè, Ẹni Mímọ́, Ọ̀gá Ògo, Alátùnúnṣe, Aláfẹ̀hìntì, Aláàánú, Ẹni Ìyanu, Ẹlẹ́dáà Ènìyàn, Ẹlẹ́dàá Ayé, Ẹlẹ́dàá Ọ̀run, Ẹlẹ́dàá ohun gbogbo tí à ń rí, Ẹlẹ́dàá èyí tí a kò rí, Ẹni tí Òjòlá-ìbínú ń ṣáátá, tí àwọn ẹ̀dá ìyókù ń bu ọlá fún, wí pé, lónìí, tí mo wà nínú ìyọnu, kí àwọn yanrìn wọ̀nyí yípadà kí wọ́n di èèrè olóró kí wọ́n máa bu ejò wọ̀nyí jẹ.
OLUWA, ìwọ ni mo sá di,má jẹ́ kí ojú tì mí lae;gbà mí, nítorí olóòótọ́ ni ọ́.
Kunlere ni lẹyin ti wọn ba ti da ọpa aṣẹ naa pada si ijoko rẹ ti wọn ṣe fun, o n tumọ si pe abẹnugan ti ṣetan lati jabọ ipade igbimọ naa fun awọn ọmọ ile aṣofin lori abadofin ti wọn n daba le lori.
Wọ́n gbé e kalẹ̀ títí tí gbogbo àwọn eniyan náà fi jáde kúrò ní ìlú.
Nígbà tí inú fi bí ọba sí àwa iranṣẹ rẹ̀ meji, tí ọba sì gbé èmi ati alásè jù sẹ́wọ̀n ní ilé olórí àwọn tí wọn ń ṣọ́ ààfin, 
Bẹẹ sini awọn ọdaran naa tun dana sun agọ ọlọpaa marun un ọtọọtọ, ti wọn si tun ji awọn nnkan ijagun lọ.
Ẹ jáde, ẹ jáde ẹ kúrò níbẹ̀, ẹ má fọwọ́ kan ohun àìmọ́ kan,ẹ jáde kúrò láàrin rẹ̀, kí ẹ sì wẹ ara yín mọ́,ẹ̀yin tí ẹ̀ ń gbé ohun èlò OLUWA.
ICC pari iwadi lori pipa Shiites, Ipob Shekau: Ileesẹ ologun nfẹ oku abi aaye rẹ O fikun wipe, ohun ko figba kan ni itakurọsọ pẹlu iyawo Nnamdi Kanu ri, atiwipe ohun ko si nipọ lati wa olori ikọ Ipob naa jade.
Ọmọ Yorùbá mẹ́wàá tó jẹ́ àmúlùúdùn ní Amẹ́ríkà àti Yúróòpù Wo ohun tí ìrìnàjò ààrẹ Buhari fún ìgbà àkọ́kọ́ lásìkò Coronavirus lọ sí Mali yóò bá bọ̀ Àwọn alágbára ni mo bá díje ṣùgbọ́n mo ti gbà f'Olọrun- Agboola Ajayi Nǹkan mẹ́sàn án tí Mùsùlùmí gbọdọ̀ ṣe nínú oṣù Dhual- Hijjah Ipinẹ Borno lawọn alakatakiti naa ti ji awọn ọkunrin marun gbe.
Ilé-Ifẹ̀ tàbi Ifẹ̀ jẹ ilú àtijọ́ ti Yorùbá kà si orisun Yorùbá.
O pín òkun sí meji níwájú wọn, kí wọ́n lè gba ààrin rẹ̀ kọjá lórí ilẹ̀ gbígbẹ, o sì sọ àwọn tí wọn ń lé wọn lọ sinu ibú bí ẹni sọ òkúta sinu omi.
 Sugbon ti a ba wo ohun ti aare
Gígùn rẹ̀ jẹ́ aadọta igbọnwọ, ìbú rẹ̀ sì jẹ́ ọgbọ̀n igbọnwọ.
Oríṣun àwòrán, Reuters Àkọlé àwòrán, Ipade alaafia pẹlu Moon, Kim ati Trump yoo bi eso rere Aarẹ South Korea, Moon Jae-in naa darapọ mọ KIm Jong Un ati Donald Trump ni DMZone ti won ti pade.
 Àwọn bitcoin únjẹ ́ dídá gẹ ́ gẹ ́ bi ẹ ̀ san fún ìgbéṣẹ ̀ kọ ̀ mpútà tí à ùn pè ní mining .
Kí làwọn ìdàmú tí Coronavirus n mú bá àgọ́ ara?
    Bí ìtàn ibẹ̀ ti lọ, ìlú náà ni o tóbi jù ni òde ayé ni ayé àtijọ́, odidi ọjọ́ mẹta ni wọ́n fi ń rìn láti apá kan dé apá kejì ṣùgbọ́n nǹkan tí o sọ wọ́n dì bí wọn ti wa yìí ni ìrẹ́pọ̀ tí kò sí láàrin wọn.
ṣugbọn ọjọ́ keje jẹ́ ọjọ́ ìsinmi fún OLUWA Ọlọrun rẹ.
Ọlọrun ti yọ yín kúrò ní ilẹ̀ Ijipti, ilẹ̀ tí ó dàbí iná ìléru ńlá, ó ko yín jáde láti jẹ́ eniyan rẹ̀, gẹ́gẹ́ bí ẹ ti jẹ́ lónìí.
Sopata ọmọ Pirusi ará Beria bá a lọ.
nígbà tí wọ́n bá ń wọ inú àgọ́ àjọ lọ, ati ìgbà tí wọ́n bá fẹ́ súnmọ́ ìdí pẹpẹ, wọn á fọ ọwọ́ ati ẹsẹ̀ wọn gẹ́gẹ́ bí OLUWA ti pàṣẹ.
Ó ń kọ́ àwọn eniyan ninu àwọn ilé ìpàdé wọn.
Abramu bá dojúbolẹ̀, Ọlọrun tún wí fún un pé, 
Àwọn oníṣẹ́ náà pada sọ́dọ̀ ọba, ọba bá bèèrè pé, “Kí ló dé tí ẹ fi pada?
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, #Queen Dihya: Obinrin tó gbógun tàwọn agbésùnmọ̀mí ni Algeria Kini Sharia?
“N óo sì gbé àmì kan kalẹ̀ láàrin wọn.
Irú ọjọ́ bẹ́ẹ̀ kò wáyé rí ṣáájú ìgbà náà, bẹ́ẹ̀ sì ni, láti ìgbà náà, kò sì tíì tún ṣẹlẹ̀, pé kí OLUWA gba ọ̀rọ̀ sí eniyan lẹ́nu, èyí ṣẹlẹ̀ bẹ́ẹ̀ nítorí pé, OLUWA jà fún Israẹli.
Coronavirus: Báwo ni o ṣe le mọ̀ pé o ní àrùn Coronavirus?
Osun governorship election: PDP àti APC fàdúrà jagun ṣáàjú ìdàjọ́ ìgbìmọ̀ tó n gbẹ́jọ́ ìdìbò Ọṣun
Gbogbo eré géle tí àwọn ẹ̀gbọ́n rẹ̀ kò lè ṣe ni ó máa ń ṣe.
ó bèèrè pé, “Ọ̀wọ̀n ibojì ta ni mò ń wò lọ́ọ̀ọ́kán yìí?
Bi iko Super Eagles ati apapo awon omo orile-ede Naijiria se n gbaradi fun idije boolu afesegba ile Afrika to n bo lọdun 2019 (2019 Africa Cup of Nations), olukoni agba iko naa Gernot Rohr n dunnu lopolopo lori awon agbaboolu re ti o wa nile ti yoo kopa fun idije ohun.
Bi awọn ayaba naa si ṣe n tigba yii, ti inu Alaafin n dun lati jo, ni inu gbogbo ero to wa ni aafin pẹlu yoo maa dun, ti wọn yoo si maa jo.
ate lu pe o n satileyin fun Khalifa Haftar ti o alatako re lorile-ede naa.
A gbé ọwọ́ ọ̀tún OLUWA ga,ọwọ́ ọ̀tún OLUWA ti ṣe iṣẹ́ agbára ńlá!
Ohun ti wọn gbagbọ ni wi pe eniyan ko gbọdọ bẹru iku tabi oku ni wọn se n jẹ eniyan lati bori ibẹru iku.
Olori ọdọ ni ohun to ku tawọn yoo ṣe ni ki onikaluku maa ja funra wọn.
 ní Ìlọrin , tí ó jẹ ́ olú ìlú ìpìnlẹ ̀ kwara , ibẹ ̀ ni séù adam al-ilory ti parí ìmọ ̀ kùránì kíkà rẹ ̀ tí ó sì ti mumi ìmọ ẹ ̀ kọ ́ kéú láti kọ ́ àti mọ ̀ nípa ẹ ̀ sìn islam .
oríṣìíríṣìí òróró ìkunra, turari ati òjíá, ọtí, òróró olifi, ọkà, ati àgbàdo, ẹṣin, kẹ̀kẹ́ ogun, ẹrú, àní ẹ̀mí eniyan.
Gbogbo àwọn ọmọ Lefi tí wọ́n wà ní ìlú mímọ́ náà jẹ́ ọrinlerugba ó lé mẹrin (284).
Oríṣun àwòrán, Gboyegaoyetola, @IsiakaAdeleke1 Àkọlé àwòrán, Oyetola ati Adeleke Latari eyi, Adeleke ki gomina Gboyega Oyetola ku oriire o si ni oun fẹ rere fun un."
Wọ́n Ju Jeremaya sinu Kànga Gbígbẹ.
Wọ́n sì kọ gbogbo rẹ̀ sílẹ̀ ninu ìwé ìtàn ìjọba níwájú ọba.
Efuraimu ní, ‘Mo ní ọrọ̀, mo ti kó ọrọ̀ jọ fún ara mi, ṣugbọn gbogbo ọrọ̀ rẹ̀ kò lè mú ẹ̀bi rẹ̀ kúrò.
Lónìí yìí ni OLUWA yóo fà ọ́ lé mi lọ́wọ́, n óo pa ọ́, n óo gé orí rẹ, n óo sì fi òkú àwọn ọmọ ogun Filistini fún àwọn ẹyẹ ojú ọ̀run ati ẹranko ìgbẹ́.
Rabi tawọn eeyan mọ si Rabi Cecilia ninu sinima, tan ọrẹkunrin rẹ lọ si adagun omi kan, ti o si fun ni majele jẹ ki o to ju oku rẹ sinu omi.
Ni ọjọ kọkanlelogun, oṣu Kejila, ni awọn alaṣẹ ijọ Deeper Life Bible Church fi atẹjade kan si ori ayelujara Twitter ijọ naa pe, iwadii ti bẹrẹ lori ọrọ naa.
Musa ni bo tilẹ jẹ pe awọn ko ri ajẹmọnu gba, awọn ko ni i jẹ ki eyi da omi tutu si wọn l'ọkan.
Ọjọgbọn yii sọrọ lori ibi ti iṣẹ de duro ati iṣẹ iwadii to ṣi n tẹsiwaju kaakiri ki batiri le maa pẹ ko too jo tan lasiko yi.
Borno lo jẹ pe eto idibo ti pari.
61 Àti pé èmi yíò mú un wá sí ìmọ́lẹ̀ àwọn iṣẹ́ ìyanu wọn, tí wọn ṣe ní orúkọ mi.
Bí a bá dákẹ́, tí a sì dúró di òwúrọ̀ a óo jìyà.
Ron Jeremy: Òṣèré tó ti ṣe ''Blue film'' fún ọdún 40 ti wọ gàù pẹ̀lú ẹ̀sùn ìfipábánilòpọ̀
Dókítà Daniel Ajayi tó jẹ́ ọ̀gá àgbà nílé ìwòsàn tí wọ́n ti ń rí sí ààrùn ọpọlọ ní ìpínlẹ̀ Eko.
Ọ̀gá Ilé-Ẹ̀kọ́ gíga ní Gbóbì ni ọkùnrin náà ti jẹ́ rí, ṣùgbọ́n lónìí, o ń ṣiṣẹ́ ní ibib ti wọn ti ń tẹ ìwé ní ilẹ́ Gẹ̀ẹ́sì.
Mo kọ́ rò ó pé kí n bínú sí wọn, kí n sì tẹ́ ibinu mi lọ́rùn lára wọn ní ilẹ̀ Ijipti.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Pẹ̀lú gbogbo bùkátà, Bàbá 80 gboyè Masters Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
parau ti ko si ooto ninu re rara “Iro
Bí ẹnikẹ́ni bá wà tí kò ṣi ọ̀rọ̀ sọ rí, a jẹ́ pé olúwarẹ̀ pé, ó lè kó gbogbo ara rẹ̀ níjàánu.
Awọn orukọ oriṣa ni wọn si n pe, dipo orukọ Ọlọrun awọn Kristiẹni.
 Ìtàn ti a kà nínú ìwé tí ó sì tún ṣe rẹ ́ gí pẹ ̀ lú èyí tí a gbà láti ẹnu àwọn abẹ ́ nà ìmọ ̀ wa kò ju ìtàn méjì péré tí í ṣe ìtàn atẹ ̀ wọ ̀ nrọ ̀ àti ìtàn mẹ ́ kà .
N óo gbé ọ ga:n óo yin orúkọ rẹ.
Nítorí pé, OLUWA Ọlọrun wa ni ó kó àwa ati àwọn baba wa jáde ní oko ẹrú ilẹ̀ Ijipti, òun ni ó sì ṣe àwọn iṣẹ́ ìyanu wọ̀n-ọn-nì lójú wa.
Nígbà tí wọ́n dé, wọ́n gbadura fún wọn kí wọ́n lè gba Ẹ̀mí Mímọ́, 
L'ọ́jọ́ Aiku ni wọn ji obinrin naa gbe pẹlu awakọ rẹ ni opopona Augu-Ise si Akoko.
Ìwádìí ọlọ́pàá fi hàn pé l'ọjọ́ kéjìdínlọ́gbọ̀n, oṣu karùń ùn tí Adebisi àti Julian dàwáti, ni àwọn onisẹ ibi mẹ́ta ọhun yọ ìbọn sí wọn bí wọ́n ṣe kọrí sí ìyànà Oru, ti wọ́n si fi ipá gbé wọn lọ́ inú igbó.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ilé Asòfin: Buhari kò fi asojú South-South, South-East sínú olùdarí EFCC 12 Ọ̀pẹ̀̀ 2018 Oríṣun àwòrán, Twitter/The Seante Àkọlé àwòrán, Awọn sẹnẹtọ woju ara wọn Ede-aiyede bẹ silẹ nile aṣofin agba l'Abuja lọjọ Iṣẹgun lori orukọ awọn eeyan mẹrin ti Aarẹ Muhammadu Buhari fi sọwọ fun igbimọ oludari ajọ EFCC.
Àkọlé àwòrán, Ikọ̀ ọmọ ogun Naijiria ni awọn ti lé ikọ̀ Bokoharam jinna Nicholas fi kun ọrọ rẹ̀ pe, oun tó tó ọgórùún ọmọ ikọ Bokoharam ni wọn jọwọ ara wọn fun ikọ̀ ọmọ ogun ti ọpọ wọn si juba ehoro, nigba ti awọn da ọpọ eniyan to ti wa ninu igbekun awọn Bokoharam ọun silẹ.
A gbọ pe aisan naa ti n se Fẹlẹ, to tun jẹ alaga ẹgbẹ ọlọkọ ero lẹkun iwọ oorun ilẹ yii, lati bii ọjọ melo kan, ti wọn si ni ni ode lọsẹ mẹfa sẹyin lasiko ipade igbimọ alasẹ ẹgbẹ naa nipinlẹ Ọyọ, eyi to waye ni olu ileesẹ Nurtw tuntun ni adugbo Ọjọọ, nilu Ibadan.
Jẹ́ kí ojú ọ̀run máa kọrin ìyìn iṣẹ́ ìyanu rẹ, OLÚWA;kí àwọn eniyan mímọ́ sì máa kọrin ìyìn òtítọ́ rẹ.
Bamidele Olumilua, gómìnà ìpínlẹ̀ Ondo nígbàkanrí jáde láyé Òṣìṣẹ́ ètò ìlera méjì ló wà nínú àwọn tó lùgbàdì àrùn coronavirus ní Ekiti Eyín ọ̀ọ́kán mi ni Barakat tí wọ́n pa lẹ́yìn tí wọ́n fipá bá a lòpọ̀- Ìyá Barakat Amọ aarẹ Trump bu ẹnu atẹ lu Mattis ati ipo rẹ gẹgẹ bi ọgaagun.
Ẹgbẹ onkọwe ajafẹtọ ẹni HURIWA n tiẹ n kesi ile asofin apapọ ilẹ wa lati tọpinpin awọn iṣẹlẹ to rọ mọ iku Tolulope Arotile.
Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Yoruba Film: Wo àwọn òṣèré tíátà Yorùbá mẹ́fà tó bẹ̀rẹ̀ eré ṣíṣe láti kékéré29 Bélú 2020 Ginimbi Genius Kadungure: Ẹ wo àwọn ọkọ̀ bọ̀gìnì tí ọ̀dọ́mọdé olówó kó jọ lẹ́ni ọdún 3614 Bélú 2020 Rape: ‘Uncle àti Granpa’ mi máa ń fi owó àti ẹ̀bùn fa ojú mi mọ́ra3 Agẹmo 2019 Rape: Ọmọ tí wọn ń fipá bá lòpọ̀ yóò máa ní ìrora ọkàn nígbà gbogbo26 Ẹrẹ̀nà 2019 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 3 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 5 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
”Ìyá rẹ̀ dá a lóhùn pé, “OLUWA yóo bukun ọ, ọmọ mi.
Ìjọba Kaduna kéde ọjọ́ mẹ́ta fún ìdárò Emir Zazzau, Buhari, Tinubu, Babangida náà ń ṣèdárò Èèyàn mẹ́jọ jónà ráúráú nínú ìjàmbá ọkọ̀ akérò tó ṣẹlẹ̀ ní mọ́rosẹ̀ Eko sí Ibadan Sudan tí bẹ̀rẹ̀ ìjìròrò lórí bí US yóò ṣe yọ òrúkọ̀ wọn kúrò nínù ikọ̀ agbẹ́sùnmọ̀mí àgbáyé Igbakeji gomina ipinlẹ Ondo, Agboola Ajayi naa ko gbẹyin nibi idibo sipo gomina nipinlẹ Ondo naa, ẹgbẹ oṣelu ZLP niawọn yoo ti dije dupo.
Igbakeji Aare ojogbon Yemi Osinbajo ti se ifilole ilana ati mu igberu ba eto oro-aje, bi: oro ina mona-mona, eto ogbin ati awon ile-ise ipese nnkan, ni iyanju ati tete mu igberu ba eto oro-aje orile-ede Nigeria.
Coptic Christian: January 7 ni ọjọ́ àjọ̀dún kérésìmésì fún ẹ̀yà Krìstẹ́ní lágbègbè Lárúbáwá
 O ka Aare lara pe orile-ede Naijiria padanu akoni yii paapaa awon eniyan ipinle Plateau.
Rebeka alára nìyí níwájú rẹ yìí, máa mú un lọ kí ó sì di aya ọmọ oluwa rẹ, bí OLUWA ti wí.
Apapọ awọn to ti ni arun naa kaaakiri orilẹ-ede Naijiria ti wa di 16,658 bayii.
Vice Presidential Debate: Osinbajo,Peter Obi ko yọju Ọmọ Nàíjíríà fèsì lórí ààrẹ NANS tó ń sèlérí ìbò fún Buhari El-Rufai, lọ tọwọ́ ọmọ rẹ bọ aṣọ!
Dokita Abolarin lasiko to n sọrọ ni efọn to ni iba lara nikan lo lee fa iba si ara eniyan, ati wi pe iru ẹjẹ ti eniyan ni lee jẹ ki iba tete wọ eniyan lara.
àwọn ọmọ Ṣefataya, àwọn ọmọ Hatili, àwọn ọmọ Pokereti Hasebaimu, ati àwọn ọmọ Amoni.
Ìjàmbá ọkọ̀ tó ṣẹlẹ̀ sí Adams Oshiomole kìí ṣe ojú lásan, àwọn kan ló fẹ́ pa á- APC Ọba Saudi Arabia yọ ọmọ rẹ̀ àti àbúrò rẹ̀ kúrò nípò nítorí ìwà àjẹbánu lórí owó tó yẹ fún ààbò ìlú Èèyàn 239 míràn ṣẹ̀ṣẹ̀ kó COVID-19 ní Nàìjíríà Ọkùnrin kan di èrò ọ̀run nítorí pé o fi ẹ̀sùn kan alájọgbélé rẹ̀ pé o n yan ìyàwó ẹnìkan lálè Victoria Rubadir ọmọ Kenya ló gba àmì ẹ̀yẹ Komla Dumor BBC World News Babatunde Olatunji fi orin ati ilu ja fun ẹtọ alawọdudu Ọlatunji wa nibẹ pẹlu awọn gbajugbaja ajafẹtọ to jẹ ilumọọka bii James Baldin, Harry Belafonte ni ọdun mẹtadinlọgọta sẹyin nigba ti Martin Luther King Jr sọ ọrọ akinkanju lasiko ifẹhọnuhan to waye nigba naa lati fopin si idẹyẹsini nitori ẹya lorilẹede America.
Ṣugbọn àwọn eniyan bá wọn wí pé kí wọ́n panu mọ́.
Ẹni tí ó bá wọ́n omi ìwẹ̀nùmọ́ náà sí aláìmọ́ lára gbọdọ̀ fọ aṣọ rẹ̀.
"òṣèré àti ọ̀jọ̀gbọ́n Tiatia Unilorin, Ayo Akinwale jáde láyé Iléeṣẹ́ ọlọ́pàá ti bẹ̀rẹ̀ ìwádìí lórí fídíò ọkùnrin kan tó ń fi ""shisha"" ṣagbeji ara Wo nǹkan tí ìjọba àpapọ̀ yóò ṣe fáwọn tó ń ta 'pẹlẹbẹ', 'pàrágà' àti 'fònàgáú' Daddy Freeze túbá!"
 Ni ẹkun idibo Lagos Mainland keji, Aṣofin Moshood Oshun ni ẹgbẹrun
Ẹ óo kú nígbà tí ẹ bá ń bá àwọn ará Amaleki ati Kenaani jagun.
Kí ó lè mú ìjọ wá sọ́dọ̀ ara rẹ̀ bí ìjọ tí ó lọ́lá, tí kò ní àléébù kankan, tabi kí ó hunjọ, tabi kí ó ní nǹkan àbùkù kankan, ṣugbọn kí ó lè jẹ́ ìjọ mímọ́ tí kò ní èérí.
agbo ilée bajimọn ní Òkè -Ọjà ni agígírì sọ ́ kọ ́ fi ṣe ibùjókòó .
Peteru dá a lóhùn pé, “Bí gbogbo àwọn yòókù bá tilẹ̀ pada lẹ́yìn rẹ, bíi tèmi kọ́!
Pasitọ Bakare wa koro oju si ofin ti awọn aṣofin fẹ ṣe lati de ọrọ lori ayelujara.
"Sowore àti àwọn ọmọ ẹgbẹ Revolution Now kò ṣẹ̀ ṣófin lórí ìwọ́de, ẹ tú wọn sílẹ̀ - NLC Òṣùká kékeré kò rẹrùn àgbà, orílẹ́èdè Nàìjíríà ṣòro púpọ̀ láti darí - Ibrahim Babangida Sowore ṣèpàdé pẹ̀lú Nnamdi Kanu láti dojú ìjọba Nàíjíríà bolẹ̀ - Àjọ DSS Ọrunmila wa nahun ke si Wuraọla pe""Iya ti mo jẹ ni Iwo"", lati igba naa wa ni wọn ti n pe Wuraọla ati gbogbo obinrin to ba wọle ọkọ ni 'iyawo' tabi 'Iya-Iwo', eyi tii se agekuru ""Iya ti mo jẹ ni Iwo."
Ó ń ṣọ́ àwọn orílẹ̀-èdè lójú mejeeji,kí àwọn ọlọ̀tẹ̀ má gbéraga sí i.
Wọn yóo sì fi awọ dídán dì wọ́n, wọn yóo sì gbé wọn ka orí igi tí a óo fi gbé wọn.
"Ọpọ wọn ya bo mi, wọn gun mi lọbẹ lori ati ni ibi ikun mi.
Ó tún fa àwọn eniyan Juda sinu ẹ̀ṣẹ̀ ìbọ̀rìṣà; nípa bẹ́ẹ̀ ó mú kí wọ́n ṣe ohun tí ó burú lójú OLUWA.
Ẹgbẹrun (1,000) yòókù wà lọ́dọ̀ Jonatani, ọmọ rẹ̀, ní Gibea, ní agbègbè ẹ̀yà Bẹnjamini.
Ko tan sibẹ o, wọn ni awọn fẹ àtúnṣe ati afikun si owo oṣu awọn ọlọpaa Naijiria, boya ti wọnba n gba owo oṣu to dara bii ti agbofinro ilẹ okeere, ori wọn yoo pe sii ni bi wọn a ṣe maa ba ara ilu to pọ fun aabo to peye Ati pe ki wọn ṣe ayẹwo ilera ọpọlọ fun awọn ọlọpaa SARS tẹlẹ, ki wọn o si tun ṣe idanilẹkọ fun wọn, ki wọn o to darapọ mọ ẹka ileeṣẹ ọlọpaa miran.
Wọ́n fún ra pe àìsàn ọkan lo pàá, òun náà kú ni ọjọ kẹẹdogun ọdun 2016 Oríṣun àwòrán, other Àkọlé àwòrán, Àwọn ọmọ Naijiria to ti kú lóri pápá lásìkò ìfẹsẹwọ́nsẹ Amir Angwe: Agbábọọlu Julus Berger náà kú lóri pápa lọ́dun 1995.
Sharibu Nathan ni ọrọ naa ba ni ninu jẹ gan ṣugbọn awọn fi gbogbo rẹ le Ọlọrun lọwọ.
Oshoala yoo kopa ninu olokan-o-jokan ifesewonse ti iko naa yoo
0 716 Orilẹede Papua New Guinea 7 0.
 ohun lo siwaju orile-ede olominira ile kroatia ode oni .
Gideoni dá wọn lóhùn pé, “Kò burú, nígbà tí OLUWA bá fi Seba ati Salimuna lé mi lọ́wọ́, ẹ̀gún ọ̀gàn aṣálẹ̀ ati òṣùṣú ni n óo fi ya ẹran ara yín.
lo wa ninu ikede kan ti Alukoro agba fun Agbẹnusọ naa, Ọgbẹni Musbau Rasak
Kí àwọn eniyan lè rí i, kí wọn sì mọ̀,kí wọ́n rò ó wò, kí òye lè yé wọn papọ̀,pé ọwọ́ OLUWA ni ó ṣe èyí,Ẹni Mímọ́ Israẹli ni ó ṣẹ̀dá rẹ̀.
Ọkọ ofuurufu naa balẹ ni deede agogo mọkanla ku iṣẹju mẹẹdogun.
Gbogbo àwọn wọnyi kú ninu igbagbọ.
O salaye pe, CBN fun awon olokowo kekeke ati nla ni milionu marundinlogota $55 owo dollars ,  nigba ti milionu marundinlogota $55 yoku wa fun sisan owo ile-ile, sisan owo ile-iwosan ati fun awon arinrinajo.
 Èyí mú kí odùduwà yọ ̀ ǹda adé fún ọmọ náà nígbà tí ó jí .
Ẹ jẹ́ ká gbé òsùbà fún Ààrẹ orílè èdè Nàìjíríà Muhammad Buhari fún tí GCFR tí ó fi dá Mashood Kashimawo Olawale(MKO) lọ́lá àti yíya ọjọ́ Kejìlá oṣù kẹfà (June12) sì ọjọ́ ayẹyẹ ìjọba tiwantiwa.
Olódùmarè fẹ́ràn ènìyàn ṣùgbọ́n àwọn ènìyàn a máa fi ìwà wọn pín ara wọn ní ìyà sí Ọlọ́run Ọba, bẹ́ẹ̀ ni ẹlẹ́ṣẹ̀ kì í lọ ní ájìyà, ẹ̀ṣẹ̀ àwọn ará ayé kò jẹ́ ki ayé dùn mọ́ wọn.
Gege bi Shehu se so:“Ile-ise aare benu ate lu oro ti aare orile-ede Naijiria teleri, Goodluck Jonathan so pe awon obaye je, a sowo ilu moku-moku po laarin ijoba ti o wa lori aleefa yii ju tisakoso ijoba re lo.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Meghan and Harry: Ohun tó yẹ kí o mọ̀ nípa ọmọ ọba tí wọ́n fẹ́ bí 20 Ìgbé 2019 Oríṣun àwòrán, AFP Lẹyin oṣu mọkanla ti wọn ṣe igbeyawo, Ọmọ ọba Sussex ati aya rẹ, Harry ati Meghan n reti ọmọ tuntun laipẹ.
Imo Airport Fire Outbreak: Iná sọ ní pápákọ̀ òfurufú ìpínlẹ̀ Imo
 Àwọn Auxiliary náà ni, òun àti àwọn 'boys' rẹ ni wọn jọ ń ja, kódà, laarọ yìí ni àwọn èèyàn pe wa pe wọn tí ń já ní Iwo Road ó, à wa pé awon eeyan wá tó wà nibẹ, wọn ní Mukaila àti 'boy' rẹ kan to wa ni ile epo kan ni Iwo Road ni wọ́n jọ ń ja, wọn ṣe é lese, wọn si gbe lọ, kò sì sí ẹnì tó mọ ibi tí wón gbé lọ""."
Bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé Asa kò pa gbogbo àwọn ojúbọ oriṣa wọn run, ó jẹ́ olóòótọ́ sí OLUWA ní gbogbo ọjọ́ ayé rẹ̀.
” Aare Buhari ti kọkọ se ipolongo fun idije si ipo aare ni ipinle Maiduguri ati
O ni iṣẹ ijọba apapọ ni lati ri i pe ẹnu ibode ilu wa daadaa.
Pẹlu àtìlẹ́yìn Ọlọ́run, a óo ṣe akin;nítorí òun ni yóo tẹ àwọn ọ̀tá wa mọ́lẹ̀.
Bàbá mi fún mi ní kíndìnrín rẹ̀ láti dóòlà ẹ̀mí mi- Sam Mọ̀ síi nípa Oyedele Adedokun tó ya àwòràn Donald Trump tó lu ayélujára pa LASTMET kọ́ ló kó Opay nílẹ̀ ṣùgbọ́n ọlọ́kadà kò láṣẹ látigba ọ̀nà mọ́rosẹ̀ l'Eko- Opeifa Àjọ tó n rí si ọ̀rọ̀ fásitì (NUC) kéde ayédèrú Ọjọ̀gbọ́n tó tó ọgọ́rùn ún Papakọ ofurufu Nnamdi Azikwe, (Nnamdi azikiwe airport ) Abuja Oríṣun àwòrán, others Papakọ ofurufu Abuja ni orukọ papakọ ofurufu yii ni igba ti wọn kọ ọ ni ọdun 2000.
Ẹfunsetan Aniwura, obìnrin tó ju ọkùnrin lọ Akpan wa rọ aarẹ Muhammadu Buhari pe to ba lee lo ẹka yii bo se yẹ, oun n fi da loju pe, yoo ri ibo ti yoo to ogun miliọnu laarin awọn ọdọ naa.
Ọlọrun a máa ṣí wọn létí,a máa kìlọ̀ fún wọn, a sì máa dẹ́rùbà wọ́n,
Pulu, tí à ń pè ní Tigilati Pileseri, ọba Asiria, gbógun ti ilẹ̀ Israẹli; kí ó baà lè ran Menahemu lọ́wọ́ láti fi ìdí ìjọba rẹ̀ múlẹ̀, Menahemu fún un ní ẹgbẹrun (1,000) talẹnti owó fadaka.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, FA Cup Aguero tun ṣe bẹẹ lo ba tun gbayo wọ le fun Man City eleyi to mu wọn jawe olubori ninu ifẹsẹwọnsẹ ọhun.
O fi oju han ninu atupalẹ kan ti ajọ NERC fi sita lori ilana naa, nipa bi awọn ọmọ Naijiria ṣe le lo ilana naa lẹyin ti aarẹ Buhari paṣẹ.
Gege bi Edeh se so, “Egbogi oloro ti ikunwon re to kilo 194.
Ẹgbẹ agbabọọlu Malaga ti sọ wipe awon ti tọwọ bọwe adehun pelu Atamatase ọmọ orilẹẹde Naijiria naa,ti agbabọọlu ọhun yoo si wa pẹlu wọn fun osu mẹfa.
Kò sì tíì sí ọba kankan ní Israẹli tí ó tíì ṣe àsè Àjọ Ìrékọjá bí Josaya ti ṣe pẹlu àwọn alufaa, àwọn ọmọ Lefi, àwọn eniyan Juda, àwọn tí wọ́n wá láti Israẹli ati àwọn ará Jerusalẹmu.
Bayii, àwọn dókítà náà tí tẹpẹlẹ mọ pe, àwọn yóò dá ìṣe silẹ tí ìjọba kò bá dasi owó wọn ní sísan.
Yàtọ̀ si Ìjọba Ológun lábẹ́ Ọ̀gágun Yakubu Gowon, ti ó lo ọ̀pọ̀ owó epo rọ̀bì dáradára lati pèsè ohun amáyédẹrùn ti igbàlódé ti ilú ngbádùn titi di ọjọ́ oni,  ọ̀pọ̀lọpọ̀ àwọn Ìjọba Nigeria yókù ti ó ré kọjá lábẹ́ Ológun àti Òṣèlú kùnà nipa ipèsè ohun amáyédẹrùn fún orilẹ̀ èdè nitori iwà ibàjẹ́.
O ni ọjọ Aiku ni ọkọ oloogbe naa atawọn mọlẹbi gbe oku rẹ Kí ló ṣokùnfà afárá tó já tó pa ènìyàn kan ní Ilorin?
Gomina Ahmed wa rọ awọn olugbe ẹkun idibo naa lati tu jade sita wa kopa ninu atundi ibo ọhun, ki wọn si fi ibo wọn yan oludije ti ọkan wọn n fẹ.
Ọmọ ìkà ń d’àgbà, ọmọ ìkà ń gbèrú
lowo lati pese ise lopo janturu fun awon akekoo jade nile iwe.
Awọn orilẹede ti wọn ti se bẹẹ ni: Kenya Rwanda South Africa Morocco Taiwan New Delhi France Montreal China Israel Netherlands Mauritania Sri Lanka Papua New Guinea, Vanuatu Albania Georgia Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Àwọn ọbá aláye ilẹ̀ Yorùbá márùn-ún pẹ̀lú ọ̀pá àṣẹ wọn Ọ̀nà láti sọ ọ̀rọ̀ ajé ilẹ̀ Yorùbá di akúrẹtẹ̀ ni àwọn ìkọlù tó wáyé ní Eko - Àwọn gómìnà Ìjọba ìpínlẹ̀ Eko tí kéde ìlànà ìséde tuntun fún ará ìlú Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Egbò tó ti fẹ́ẹ̀ jiná ni ìtàn bí wọ́n ṣe pa Soun Ogbomoso, Ọba Olayode tẹ ń bèrè' Kwara Ọjọ Ẹti, ọjọ kẹtalelogun, oṣu Kẹwaa ọdun 2020 ni awọn eeyan ipinlẹ Kwara ya bo ibi ti ijọba ko ounjẹ iranwọ Covid-19 si niluu Ilorin.
Sanwo-Olu lo sọ ọrọ naa loju opo Instagram rẹ, nibi to ti sọ pe ara oun bu maṣọ lẹyin ti oun wo fidio ọmọdekunrin naa tan.
Oríṣun àwòrán, Other Oríṣun àwòrán, Other Laipẹ yii si lo ṣe ayẹyẹ aadọrin ọdun loke eepẹ.
Ayajọ ọjọ yii wa fun pipe akiyesi awọn eniyan si awọn ohun to le fa aarun naa, ati itọju to peye to wa lati tọju wọn.
Aida Parra, ni oun foju ri omo oun , ko to di ojo ti isele naa waye: “mi o mo boya omo mi ti ku tabi o wa laaye.
Òkú aláǹtakùn kì í bónílé wíjọ́
Ó wólẹ̀ níwájú Paulu ati Sila.
Ìdí ni pé ọrọ̀ wọn ti pọ̀ ju kí wọ́n jọ máa gbé pọ̀ lọ, ilẹ̀ tí wọ́n sì ti ń ṣe àtìpó kò gbà wọ́n mọ́, nítorí pé wọ́n ní ẹran ọ̀sìn tí ó pọ̀.
Awọn obi kan bi Shafiu Yau ni awọn ko fẹ ki wọn wọgile eto alimajiri.
"Lori ẹsun pe awọn oṣiṣẹ alaabo n gba owo lọwọ awọn awakọ lati wọ ipinlẹ naa, o sọ pe lootọ ni iru nkan bẹ ẹ waye, ṣugbọn ""a ti mojuto, o ti dawọ duro."
Ni ọjọ Aje, ọjọ kẹtadinlọgbọn oṣu kẹrin ọdun 2020 lo jade laye.
Etutu arugba: Eleyi ti gbogbo agbaye fẹrẹ mọ niyi.
awon obayejẹ kan ti se lati da oju eto idibo bolẹ.
Efem Esege ,  ni o dari awon eniyan naa wa si ilu naa,nigba
ẹ óo máa fi ojurere wo ẹni tí ó wọ aṣọ dídán, ẹ óo sọ fún un pé, “Wá jókòó níbi dáradára yìí.
"Ẹyin ọmọde isinsinyii, ẹ o mọ itan lẹ fi n lọ sori ẹrọ ayelujara lọ kọ ohun to wu yin nipa ọrọ aabo to da orilẹ-ede Naijiria laamu lọwọlọwọ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Sola Kosoko: ọlá bàbá mi ni mò n jẹ́ nínú iṣẹ́ tíátà Biola Bayo Oríṣun àwòrán, Biola Bayo Biola Adebayo naa kii ṣe aimọ fun oloko laarin awọn oṣere Yoruba.
Esi ijọba Minisita eto iroyi ati aṣa, Lai Mohammed ati minisita to n ri si ọrọ omi, Amojuẹrọ Suleiman Adamu ṣalaye pe awọn to n bu ẹnu atẹ lu u ko tilẹ tii joko ka anfani rẹ, wọn kan n ka ohun tawọn eniyan n sọ ni.
O tún ṣe àgbèrè ẹ̀sìn pẹlu àwọn ará Ijipti, àwọn aládùúgbò rẹ, oníṣekúṣe.
Bí eniyan bá ń fi baba tabi ìyá rẹ̀ bú,àtùpà rẹ̀ yóo kú láàrin òkùnkùn biribiri.
Ìparun yóo kọlù wọ́n, nítorí pé wọ́n ń bá mi ṣọ̀tẹ̀!
Ni idahun si ọrọ to n ja rainrain nipa pe awọn kan n gba owo itọju lọdọ awọn to farapa,Idris ni awọn ti fọwọ r ahesọ yi sẹgbẹ kan nitori pe Gomina Ambode tio psaẹ ki wọn ma ṣe gba owo lọwọ ẹnikẹni to ba farapa.
Ó lọ siwaju OLUWA ní Misipa, ó sì sọ àdéhùn tí ó bá àwọn àgbààgbà Gileadi ṣe.
Ninu ifọrọwanilẹnuwo kan to ṣe pẹlu BBC News, gomina Ganduje ni bi ọrọ ṣe n fojoojumọ buru sii ni ipinlẹ Kano O ni ko ṣẹyin bi igbimọ amuṣẹya ti ijsba apapọ gbe kalẹ lori arun COVID-19 ṣe kuna lati mojuto ọrọ ipinlẹ Kano.
F Odunjo kó ipa ribiribi sí àgbéga èdè Yorùbá 8 Sẹ́rẹ́ 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 12 Sẹ́rẹ́ 2020 Oríṣun àwòrán, JF Odunjo Ta ba n sọrọ nipa awọn onkọwe nilẹ Yoruba, a ko lee ka orukọ wọn lai ma fi orukọ Joseph Folahan Odunjo si aarin wọn nitori odu ni, kii se aimọ laarin awọn oloko onkọwe.
“Ìbá jẹ́ tún rí fún mi, bí ìgbà àtijọ́,nígbà tí Ọlọrun ń tọ́jú mi;
O ni oun ati awọn ẹgbọn oun ni awọn dijọ jogun iwe akọsilẹ ere ti baba awọn fi silẹ, owo nla ti awọn ere naa si nilo ni ko tii jẹ ki awọn gbe sinima rẹ jade.
Bí wọ́n bá ṣe bẹ́ẹ̀ wọn kò ní fi ààyè sílẹ̀ fún ọ̀tá láti sọ̀rọ̀ ìbàjẹ́.
Gege bi aare se so, “ki won bowo fun eniyan nitori iwa ooto ati ifokansin, je ogún ati ohun molegbagbe  ti eniyan lee fi sile .
Ileẹjọ ti kọkọ dajọ ẹwọn ọdun mejila fun Kalu ti o si dero ẹwọn lẹyin naa.
Àwọn eniyan náà bá dáhùn pé, “Ẹ̀yin eniyan Israẹli, ọlọrun yín tí ó mu yín jáde láti ilẹ̀ Ijipti nìyí.
Abdullahi Aliyu - Ọmọ ẹgbẹ́ 9.
Aṣòfin ìpínlẹ̀ Èkìtì tí wọ́n yìnbọn fún ti dolóògbé 'Súnkẹrẹ-fàkẹrẹ ọkọ̀ ló kó mí yọ lọ́wọ́ ìjàmbá ọkọ̀ òfurufú' Fayoṣe ti gba ìtúsílẹ̀ kúrò l'ẹ́wọ̀n Akọ̀ròyìn BBC, Ahmed Wakili tí ìṣẹ̀lẹ̀ nàá ṣojú rẹ̀ jábọ̀ pé níṣe ni àwọn ọmọ ogun n yìnbọn sí afẹ́fẹ́, kí ìbọn nàá tó bá àwọn ọmọ ẹgbẹ́ Shiite lásìkò tí wọ́n kọ̀ láti mú àṣẹ tí àwọn ọmọ ogun pa fún wọn ṣẹ.
Oríṣun àwòrán, NAtasha Akpoti Nigba to n ba BBC sọrọ, Akpoti ni lẹyin ti wọn na oun tan ni wsn tun ti ina bọ ibujoko ẹgbẹ oselu SDP to wa nilu Lọkọja, ti wọn si jo kanlẹ.
Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Nnamdi Kanu: Ilé ẹjọ́ wọ́gilé béèlì Nnamdi Kanu28 Ẹrẹ̀nà 2019 Fashọla: Àwọn ọmọ Nàìjíríà sọ̀rọ̀ lórí ìpèsè iná ọba tí mínísítà Fashọla ní ó ti ń ṣe dédé1 Ìgbé 2019 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
    Ibi tí ó tẹ́jú pẹrẹsẹ báyìí ni wọ́n mú wa lọ, ó tẹ́jú tí n kòi rí ibi ti ó tẹ́jú tó bẹ́ẹ̀ rí, ó gùn tó ogún ìsẹ́jú ní ìbú, ó sì tó bẹ́ẹ̀ ní òró, bẹ́ẹ̀ bi aṣọ àrán tí àwọ̀ rẹ̀ jẹ́ búùlù tí ó sì nípọn tó ẹsẹ̀ bàtà kan ni wọ́n tẹ́ tí ó bo gbogbo ibẹ̀ po.
Ó wá sọ pé, “Ẹ̀yin ará Efesu, ta ni kò mọ̀ pé ìlú Efesu ni ó ń tọ́jú ilé ìsìn Atẹmisi oriṣa ńlá, ati òkúta rẹ̀ tí ó bọ́ sílẹ̀ láti ọ̀run?
Àwọn ẹyẹ ológoṣẹ́ pàápàá a máa kọ́ ilé,àwọn alápàáǹdẹ̀dẹ̀ a sì máa tẹ́ ìtẹ́níbi tí wọ́n ń pa ọmọ sí, lẹ́bàá pẹpẹ rẹ,àní lẹ́bàá pẹpẹ rẹ, OLUWA àwọn ọmọ ogun,ọba mi, ati Ọlọrun mi.
Àwọn olùdíje Ọṣun jẹ́wọ́ ara wọ́n Awon ọtẹlẹmuyẹ CID aati IRT pẹlu FCIID naa ti de sipinlẹ Ọṣun bayii.
Oludamọran Aarẹ ni alakalẹ kan naa ni ọlọpaa agbegbe ti ijọba apapọ fẹ da silẹ laipẹ yoo maa tẹle.
Ọba nìkan ṣoṣo ni n óo pa.
'Mi ò ní wo bọ́ọ̀lù mọ́ ti Nàìjíríà bá fìdírẹmi ni Russia 2018'
Bẹẹ naa ni yoo jẹ ki awọn eeyan gbọ ojulowo iroyin lawujọ lasiko yii ti o jẹ pe ayederu iroyin ti gbalẹ kaakiri.
2019 Election: Reuben Abati ni igbakeji gomina fún Kashamu
Àkọlé àwòrán, Akojọpọ esi ayẹwo aarun Covid-19 ni orilẹ-ede Naijiria gẹgẹ bi ajọ NCDC ṣe n kede rẹ.
Gẹgẹ bi ọrọ to sọ, ọga ọlọpaa Kwajafa ṣalaye pe iye ọlọpaa to bẹrẹ ikọ naa ko ju marundinlọgọrin nigba naa, oun loun si fi ọwọ ara oun yan wọn.
Ìdájọ́ rẹ, Ọlọrun, ga pupọ, ó ju òye rẹ̀ lọ;ó ń yọ ṣùtì ètè sí gbogbo àwọn ọ̀tá rẹ̀.
Duro Ladipọ, ìlúmọ̀ọ́ká òṣèré tíátà àti ọmọ àlúfà tí kò gbàgbé àṣà ìbílẹ̀ Adájọ́ pàṣẹ kí wọ́n fi ọlọ́pàá tó lọ́wọ́ nínú ikú Kolade Johnson sí àhámọ́ Duro Ladipọ, ìlúmọ̀ọ́ká òṣèré tíátà àti ọmọ àlúfà tí kò gbàgbé àṣà ìbílẹ̀ Gbogbo òṣìṣẹ́ kọ́ ni #30,000 owó oṣù tuntun yóò kan"" Ejò lé ààrẹ Liberia kúrò ní ọ́fíìsì Ọgbẹni Peter Afunanya to buwọ lu atẹjade DSS ti INEC fi sita sọ pe awọn ti wọn fẹ da rogbodiyan silẹ ni wọn n gbe iru iroyin ofege yii kaakiri."
Igbekun itiju Ko roo lẹẹmeji to fi fiwọn pamọ, bayii ni iku si ṣe fori awọn ọmọ naa.
Kòkòrò oyin sọ ọ̀pọ̀ èèyàn di aláìrílégbé, àwọn míràn tún farapa Gbajugbaja òṣèré ''Toromagbe'' nínú fíìmù ''Arelu'' ti jáde láyé Baba rẹ sọ pe kilaasi to kan gun si asekagba nile ẹ̀kọ́ girama agba (SS2) ni ọmọ naa wa, àmọ́ o tun fẹran lati ma a sisẹ yatọ si ẹ̀kọ́.
Gbogbo aṣeyọri Stationery Stores wọnyii ko ṣẹyin Israel Adebajo.
Ọrọ̀ ati iyì wà níkàáwọ́ mi,ọrọ̀ tíí tọ́jọ́, ati ibukun.
Gẹgẹ bo ṣe sọ, o ni kii ṣe igbakeji gomina nikan ni wọn le pada lẹnu ọna ile oloogbe naa.
Ó rán wọn láti waasu ìjọba Ọlọrun ati láti ṣe ìwòsàn.
Ogbeni Maduekwe ni ajo naa n se ajosepo pelu awon ipinle kookan lati fi seto idanilekoo fawon odo won nipa ise tiata ati gbigbe fiimu agbelewo sita.
Ile ẹjọ da Olorin Small Doctor silẹ lẹyin ti wọn mu u lopopona kan l'Eko to n fi ibọn dẹru ba awọn ọlọpaa to da ọkọ rẹ duro.
Nagoda kọwe fipo rẹ silẹ lọdun 2018.
Wo bi wọ́n ṣe sìnkú Kashamu ní Ijebu-Igbo Iná sọ nínú ilé Big Brother tó ń lọ lọ́wọ́ ní Cameroon Ta ló ń lọ sílé lónìí nílé ẹlẹ́gbọ̀n ọ́n àgbà?
Oríṣun àwòrán, @Elrufai Àkọlé àwòrán, Ijọba mi ko ni gbe igbesẹ ipanilara ni saa keji yii Nasir El Rufai ni oun n bẹbẹ silẹ nitori pe ijọba oun ti ṣetan lati gbe awọn igbesẹ akin to yẹ ni saa yii.
Gbogbo ibi ààbò rẹ yóo dàbí igi ọ̀pọ̀tọ́ tí àkọ́so èso rẹ̀ pọ́n bí wọn bá ti gbọ̀n ọ́n, bẹ́ẹ̀ ni èso rẹ̀ yóo máa jábọ́ sí ẹnu ẹni tí yóo jẹ ẹ́.
Ó wá fi odò omi ìyè hàn mí, tí ó mọ́ gaara bíi dígí.
Switzerland: Owo t'awon ọlọpaa n gba ni Switzerland le ni ẹgbẹrun lọna aadọrin dọla to tumọ si bii miliọnu mọkandinlọgbọn o le diẹ naira owo Naijiria.
Oríṣìíríṣìí eranko ni ó wà nínú igbó náà.
iforowanilenuwo ni ibudo iko omo ogun naa, Maimalari Barrack niluu Maiduguri, ti
Ó mú ohun òkùnkùn wá sí ìmọ́lẹ̀,ó sì tan ìmọ́lẹ̀ sí òkùnkùn biribiri.
Gẹgẹ bii ọga agba fun imọtoto ati omi to mọ gaara lajọ UNICEF, Zaid Jurji ṣe sọ, ogoje miliọnu lawọn ọmọ orilẹ-ede Naijiria to ni ẹrọ ibanisọrọ, ṣugbọn miliọnu mẹtadinlọgọrun lawọn to ni anfani ile igbọnsẹ.
Sisi ni ireti wa pe yoo jawe olubori ninu eto idibo si ipo Aare ti yoo waye ni ojo kerindinlogbon si ojokejidinlogbon osu keta odun, amo ni bayii, awon egbe ajafeto omo eniyan ti n bu enu ate lu eto idibo naa, leyin ti awon ogbonta-rigi ti n dato lenu igbin, ti won jo n figa-gbaga fagile eto ipolongo idibo naa, ninu eyi ti won ti safihan iwa inini-lara ati fifi owo sinkun ofin mu enikan gboogi ti o le koju ijoba to wa lori alefa.
eto ọrọ aje lorile ede Naijiria.
dípò kí ó bèèrè ìtọ́sọ́nà lọ́wọ́ OLUWA.
Nígbà náà ni Jobu dáhùn pé,
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Cancer: Àṣe ara mi ni iso ti n run gbogbo bí mo ṣe n ṣèrànwọ́ lórí jẹjẹrẹ Meloo la fe ka leyin adipele.
Buhari san lára owó àjẹmọ́nú Super Eagles!
Àwọn mìíràn wà ninu yín tí wọn ń hu irú ìwà báyìí tẹ́lẹ̀.
Ẹnu ya àwọn ìjòyè Edomu,ojora sì mú gbogbo àwọn olórí ní ilẹ̀ Moabu,gbogbo àwọn tí ń gbé Kenaani sì ti kú sára.
Lọdun 2014 ni Ọba Vajiralongkorn yan Suthida Tidjai, to figba kan jẹ oṣiṣẹ ile iṣẹ ọkọ ofurufu si ipo igbakeji olori awọn ẹsọ Ọba.
Ṣugbọn ẹni tí ó gbọ́ tèmi,yóo máa wà láìléwu,yóo máa gbé pẹlu ìrọ̀rùn, láìsí ìpayà ibi.
2m dọlà ni obìnrin yìí ń gbà tó bá kọ ǹkan sí ojú òpó Instagram rẹ̀ O lé ni ènìyàn ẹgbẹ̀jọ ènìyàn tó ti kú nítori àìsàn Ebola láti ìgbà to ti bẹ́ sílẹ̀ ní nínú oṣù kẹrin ọdún 2018 ní àwọn abúle DRC.
Aṣẹ yii jade lẹyin wakati diẹ ti ijọba ilu New York naa ṣe bẹ ẹ.
Ṣugbọn ọpọlọpọ àwọn alufaa, àwọn ẹ̀yà Lefi, ati àwọn olórí ìdílé, àwọn àgbàlagbà tí wọ́n gbọ́njú mọ ilé OLUWA ti tẹ́lẹ̀ sọkún, wọ́n kígbe sókè nígbà tí wọ́n rí bí a ti ń fi ìpìlẹ̀ ilé OLUWA náà lélẹ̀, bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé àwọn mìíràn hó fún ayọ̀.
Igbesẹ yìí ni awọn eeyan kan ti ri gẹgẹ bi aṣeyọri nla fun ìṣèjọba ààrẹ Donald Trump ni báyìí ti idibo sipo ààrẹ orílẹ̀-èdè náà kù ọsẹ kan.
Àwọn ará Dani dá a lóhùn, wọ́n ní, “Má jẹ́ kí àwọn eniyan gbọ́ ohùn rẹ láàrin wa, kí àwọn tí inú ń bí má baà pa ìwọ ati gbogbo ìdílé rẹ.
"Àgbo Madagascar ti wà ní Nàìjíríà ṣùgbọ́n kìí ṣe ọ̀fẹ́, a ní láti sanwó-Mínísítà Kí ló wà ní ìdí igbá tí àwọn olorì Aláàfin máa ń tí lóde Ọ̀yọ̀ Wo ìgbà márùn ún tí àwọn ọmọ ọ̀dọ̀ ti gé ẹ̀mí ọgá wọn kúrú Wo bí o ṣe lè jẹ́ kí bátììrì fóònù rẹ pẹ́ síi ""Ọmọkunrin naa ni ẹkọ gan-an ni, o gbọn pupọ, eyi to mu ki n tete fa a mọra, koda o n dun mi pe o fẹ fi gbogbo ẹbun rere ti Ọlọrun fun ṣofo ni, tori mo ti fi oju ṣun-un pe ọjọ iwaju rẹ yoo dara."
 nígba tí ọ ̀ rọ ̀ adé gbé ìjà sílẹ ̀ ní Ọ ̀ ra-Ìgbómìnà láìpẹ ́ yìí , ìjọba ìpínlẹ ̀ Ọ ̀ yọ ́ gbé ìgbìmọ ̀ kan dìde láti wádìí ìtàn Ọ ̀ ra .
Iranṣẹ náà dá a lóhùn pé, “Bí ọmọbinrin náà bá kọ̀ láti bá mi wá sí ilẹ̀ yìí, ṣé kí n mú ọmọ rẹ pada sí ilẹ̀ tí o ti wá síhìn-ín?
Oríṣun àwòrán, Masjid Àkọlé àwòrán, Apa ibomii ni Raudah ti awọn miran ti maa n lọ gbadura bẹ Olorun Oríṣun àwòrán, @masjid Àkọlé àwòrán, Nkan miran ti awọn eniyan fẹran nipa Medina ni ọna ara ti wọn fi n pe irun ninu mọṣalaṣi naa Oríṣun àwòrán, @masjid Àkọlé àwòrán, Awọn alejo to wa wo iboji anobi Muhammed (SAW) Oríṣun àwòrán, @masjid Àkọlé àwòrán, Awọn olutọju mọṣalaṣi yii n ṣe itoju Rauda tọwọtọwọ ni Medina Oríṣun àwòrán, @masjid Àkọlé àwòrán, Okan pataki ninu awọn ẹnu ọna mọṣalaṣi Medina ti wọn n pe ni abawọle ti Oba Fahd Oríṣun àwòrán, @Masjid Àkọlé àwòrán, Aworan mọṣalaṣi Medina lati oke pẹlu awọn ohun meremere to yii ka nilu nla BBC News, Yorùbá Ìdí tí ẹ fi le è nígbàagbọ́ nínú ìròyìn BBC Ìlànà Lílò Nípa BBC Òfin Àṣírí Cookies Kàn sí.
’ Ṣugbọn ẹ kò mú àṣẹ tí mo pa fun yín ṣẹ.
Lẹ́yìn náà ni wọ́n dé Elimu, níbi tí orísun omi mejila ati aadọrin igi ọ̀pẹ wà, wọ́n sì pàgọ́ sẹ́bàá àwọn orísun omi náà.
Liverpool fi agba han Manchester city ninu ifẹsẹwọnsẹ mejeeji tí wọn gba lati tẹsiwaju si ipele yii.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù #justiceforstephen: Ọlọ́pàá ìpínlẹ̀ Èkó láwọn ti mú afunrasí méjì tó mọ̀ nípa ikú Dókítà Stephen Urueye 5 Ìgbé 2019 Oríṣun àwòrán, Stephen Urueye/Facebook Àkọlé àwòrán, Stephen Urueye pari ẹkọ rẹ lọdun 2018.
ede naa bayii, awon ala orile ede naa, ni won tun ti pa , titi di igba ti won
, Ṣe Ijebu ń ṣe ayájọ́ ọjọ́ ìgbéyàwó pẹ̀lú aya rẹ̀ ní?
Àwọn àṣẹ wádìí ni Fáṣítì East Angellia náà ń wá onímọ̀ 3D láti ṣe Fẹntílàtọ̀ àti ìbòjú-bomu pelu gbogbo àwọn irinsẹ míràn.
Ó tó agogo méjìlá ọ̀sán báyìí.
 Àwọn alágbẹ ̀ dẹ ìlú ifẹ ̀ yóò kó àdá tuntun , ọkọ ́ àti saworo wá , wọ ́ n ó sì fi ẹfọ ́ n , owó ẹyọ àti àwọn nǹkan mìíràn ṣe ẹwà sí ojúbọ .
Mo jẹ́ kí ẹbọ wọn sọ wọ́n di aláìmọ́, mọ jẹ́ kí wọ́n máa sun àkọ́bí wọn ninu iná, kí ìpayà lè bá wọn, kí wọ́n lè mọ̀ pé èmi ni OLUWA.
Fasoranti sọ pe nkan itiju ni bi ọkunrin to sọrọ ninu fidio naa, ṣe fi orin ẹgbẹ Afenifere bẹrẹ ọrọ rẹ, eyi to mu ko da bi ẹni pe ẹgbẹ naa lo wa nidi ikilọ.
Lẹyin naa lo tun pada si ipo to fi silẹ gẹgẹ bi Igbakeji Akọwe Apapọ ẹgbẹ.
Mò ń tara gidigidi,nítorí pé àwọn ọ̀tá mi gbàgbé ọ̀rọ̀ rẹ.
Bakan naa ni awọn ẹsun rẹ ti ẹnikan to jẹ lowo fi sun ijọba, ran lọ sẹwọn fun osu mẹfa gbako.
Ìwádìí tí fi hàn pé, àwọn aláboyún kò sì lára àwọn tí àsìkò yìí ni ewu fún jùlọ láti ni ààrùn Coronavirus ṣùgbọ́n nítorí àwọn àyípadà tó dé bá ara ati èròjà tó ń f'ára lókun tí yóò ti gbọ̀jẹ̀gẹ́, ó ṣe pàtàkì lat ṣọ́ra.
Àìsí iṣẹ́ nígboro lọ̀pọ̀ ọ̀dọ́ fi fẹ́ gba iṣẹ́ Amotekun - Toogun Wo iye àwọn tó ti gbẹ̀mí ara wọn ní Nàìjíríà láàrin ọdún mẹ́rin ìjọba Buhari Gbèsè Nàìjíríà ti lé ní 18 tírílíọ́ọ́nù lábẹ́ ìṣèjọba Ààrẹ Buhari- DMO Wo bí iṣẹ́ abẹ wákàtí mẹ́fà, tí wọ́n fi dóòlà ẹ̀mí ìjàpá tí ọkọ̀ tẹ̀, ṣe lọ Ogbẹni Fetsus Okoye to jẹ kọmiṣọnna agba fun idanilẹkọọ lori eto idibo ati oludibo sọ eyi di mimọ nibi idanilẹkọọ ọlọjọ kan ti wọn ṣe pẹlu awọn akọroryin.
Oríṣun àwòrán, Others Ṣugbọn ṣa, eniyan 13,999 ti ri iwosan, awọn 760 si ti ku.
Ileeṣẹ ologun orilẹ-ede Naijiria lo fọrọ naa lede ninu atẹjade kan ti wọn fi sita.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ileeṣẹ ọkọ-ofurufu Dana d'awọn ero lẹbi ilẹkun to yọ 8 Èrèlè 2018 Oríṣun àwòrán, @NaijaFlyingDr Ile isẹ ọkọ-ofurufu kan ni Naijiria ti dẹbi ilẹkun baalu rẹ t'o ṣi nigba ti ọkọ naa balẹ ru ero kan.
Bẹ́ẹ̀ ni àwọn ọmọ Israẹli ṣe ṣẹgun wọn ní ọjọ́ náà, ilẹ̀ náà sì wà ní alaafia fún ọgọrin ọdún.
Nitori naa, a o pẹjọ kotẹmilọrun lori rẹ.
- Amina Zakari Akoroyin kan pẹlu ileeṣẹ Daily Trust sọ fun BBC pe awọn akegbe oun nileeṣẹ iroyin naa l'Abuja wa ni ibẹrubojo lẹyin ti awọn ologun ya bo ileeṣẹ wọn.
Kí àwọn tí wọ́n wà lábẹ́ àsíá ẹ̀yà Juda máa pàgọ́ wọn sí ìhà ìlà oòrùn ní ìsọ̀rí-ìsọ̀rí; Naṣoni ọmọ Aminadabu ni yóo jẹ́ olórí wọn.
nínu orí kẹta yìí , a ti gbìyànjú láti ṣe àgbékalẹ ̀ bí ìyísódì ṣe ń jẹ yọ nínu Ẹi .
Ile to jona ni aafin naa ni wọn sọ wi pe o jẹ ile Saarun Oodua, ẹni to jẹ ẹṣọ iṣẹdalẹ fun Ọọni ile Ifẹ.
South Sudan ti iléesẹ́ BBC torí àìsanwó Ṣé ìfipágbàjọba àwọn ológun kò maa pọ̀ si l'Afirika?
Orilẹede Cameroon ti darapọ awọn orilẹede bii Egypt, Nigeria, Algeria ati South Africa to ti ni arun Coronavirus.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ibe Kachikwu ,Mínísítà fún epò rọ̀bì sọ pé òun kò parọ́ ìwé ẹ̀rí 11 Ọ̀wàrà 2018 Oríṣun àwòrán, @IbeKachikwu Àṣìwí kò tó àṣìsọ l'ọ̀rọ̀ tó wà nílẹ̀ nípa mínísítà kejì fún epo rọ̀bì Nàìjíríà, Ibe Kachukwu, tí ìwé ìròyìn kan sọ wí pé ó parọ́ nípa irú ìwé ẹ̀rí tó gbà jáde ni yunifásitì.
Wọ́n tún ṣẹ́ gègé láti fún wọn ní àwọn ìlú ńláńlá tí a dárúkọ wọnyi lára ìlú àwọn ẹ̀yà Juda, Simeoni ati ti Bẹnjamini.
A kọ ọ́ nítorí ti àwa náà tí a óo kà sí ẹni rere, gbogbo àwa tí a ní igbagbọ ninu ẹni tí ó jí Jesu Oluwa wa dìde kúrò ninu òkú, 
 yorùbá , pèlú ọ ̀ pọ ̀ lọpọ ̀ àwọn nupe , Ìbàrìbá àti fúlàní díẹ ̀ ni wọ ́ n tẹ ̀ dó síbẹ .
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Lagos Fire Service: Ẹ máse tan àbẹ́là lórí ike tàbí pákó 21 Sẹ́rẹ́ 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 24 Sẹ́rẹ́ 2019 Oríṣun àwòrán, @LAG_FireService Ọga agba fun ile-isẹ panapana ni ipinlẹ Eko, Rasaki Musibau ti darukọ awọn nkan kekeeke ti a le se, lati dẹkun ijamba ina ninu ile.
Ati ẹyẹ, ati ẹranko, gbogbo wọn ti sá lọ.
Ọlọrun sọ fún Abrahamu pé, “Ní ti Sarai aya rẹ, má ṣe pè é ní Sarai mọ́, Sara ni orúkọ rẹ̀ yóo máa jẹ́.
Alufa naa tẹsiwaju pe Ọlọrun lo le aisan Ebola lọ, nitori naa Ọlọrun nikan naa lo le ṣegu arun Coronavirus.
Ìwádìí ti fihàn pé Ajá n gbọ́ òórùn àìsàn ibà Kí ló yẹ ká se sí ẹkùn tó pa ènìyàn márùń?
mm ni amioro orile-ede ti top-level domain lori internet ( cctld ) fun burma ( loni gege bi isokan ile myanmar ) .
Ẹnikẹni to ba si fẹ paarọ owo ni banki kọja ẹgbẹrun marun naira, yoo salaye ibi to ti ri owo ọhun fun ijọba, ki wọn to le fun ni iwe àṣẹ lati paarọ rẹ.
Ijọba orile ede Niajiria  yoo da ile-ise meji tuntun sile –ile-ise ti yoo maa ri si  bi won se  n se  iwadii lori  igbό ati omiyale(National Agency for Desertification and Erosion Research), bakan naa ni won yoo tun maa da ile-ise ijọba ti yoo maa se isẹ iwadii lori ẹda irin amusẹse ati ọtẹlẹmuyẹ (National Agency for Research in Robotics and Artificial Intelligence ) lorile ede Naijiria sile .
Mo ṣebí Mose ti fun yín ní Òfin?
Àwọn ìròyìn mìíràn tí ẹ lè nífẹ̀ẹ́ sí: Jesu Oyingbo rèé, pásítọ̀ tó láṣẹ ìbálòpọ̀ lóri ọmọ ìjọ obìnrin D.
Lẹyin iṣẹlẹ yii lo wa di ẹni ti awọn ọlọpaa yoo san owo gba ma binu ẹgbaa le ẹdẹgbẹta pọun fun un.
Adajo agba kan nile-ejo ibile ti o wa ni Mbeya, Michael Mteite dajo tako  omo ile-igbimo asofin kan, Joseph Mbilinyi ti gbogbo eniyan mo si “Sugu”Mbilinyi ti o je omo egbe alatako kan gboogi lorile-ede Tanzania ni won fi sewon pelu  Emmanuel Masonga.
"Ko si awo kankan ninu awo ẹwa lori bi olusiro owo agba naa se kọwe silẹ, amọ o se bẹẹ, nitori pe o ti le ni ẹni ọgọta ọdun ni.
Oyinkan Abayomi, akọni obìnrin tó fi ìfẹ́ pa orúkọ ọkọ kejì dà sí ti ọkọ àárọ̀ Àlàyé rèé lóríi ìdí tí wọ́n fi ń pe aya ní ìyàwó Ẹ wo ẹyẹ ayékòótọ́ tó kó olówó rẹ̀ yọ lọ́wọ́ ikú gbígbóná Wo àwọn ọmọ Naijiria mẹ́ta tó jáwé olúborí nínú ìdìbò sílé aṣòfin ilẹ̀ Amẹrika Ọ̀rọ̀ ìjókòó ìgbìmọ̀ ìwádìí #EndSARS náà dé ìpínlẹ̀ Ogun A ti gbé ìwádìí dìde lórí ìpànìyàn tó wáyé lásìkò ìwọ́de EndSARS- Ilé ẹjọ́ àgbáyé, ICC Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Fídíò, Orlando Owoh: Ayé ti sú mi, àdúrà ikú ìrọ̀rùn ló wù mí- Christiana, Ìyá Orlando Owoh tó ti pé ọdún 1105 Bélú 2020 Fídíò, Soyinka Cancer: Àṣe ara mi ni iso ti n run gbogbo bí mo ṣe n ṣèrànwọ́ lórí jẹjẹrẹ27 Bélú 2019 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 3 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 5 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Ẹnikẹ́ni tí ó bá ṣèèṣì paniyan lè sá lọ sibẹ.
Egbe awon akoroyin lorile-ede Naijiria, NUJ(The Nigerian Union of Journalists), ti eka ile-ise akoroyin Voice of Nigeria, nipinle eko pelu ifowosowopo ile-ise Live Well Initiative, ti pese eto ilera ofe fun awon omo egbe re.
Bẹẹ na lo tun gba awọn okunrin ni imọran lati maa ni suuru fun awọn iyawo wọn ti iṣẹ wọn gbomi mu.
Oríṣun àwòrán, Kannywood Àkọlé àwòrán, Alága ẹgbẹ́ àwọn óní fíìmù ní ìpínlẹ̀ Kano ti a mọ si Motion Pictures Practitioners Association of Nigeria (MOPPAN) ọgbẹni Kabiru Maikaba kílódé to jẹ pe fíìimù ìfẹ́ ni wọn a máa ṣe, ni ìgbà tó yẹ kí wọn móju tó àwọn àgbègbè tó kù."
Olubadan ti ilu Ibadan ni o ya oun lẹnu bi awọn ọba mẹtadinlọgbọn ti gomina ana yan ṣe tun faake kọri pe awọn ko ni gbe ade ori wọn silẹ lati sisẹ pọ pẹlu Olubadan, Oba Saliu Adetunji.
Oríṣun àwòrán, Fayose/ Facebook Ẹgbẹ́ òṣèlú APC tí lé gómìnà ìpínlẹ̀ Ekiti, Kayode Fayemi kúrò ní APC Aawọ to n lọ lẹgbẹ oṣelu APC tun ti gba ọna miran yọ pẹlu bi apa kan ẹgbẹ amuṣẹya ẹgbẹ APC nipinlẹ Ekiti ṣẹ ni ki gomina Kayode Fayemi lọ rọkun nile.
Ó bá fi ara pamọ́ fún oṣù marun-un.
waye, aare naa si tun ki mi.
Ẹbí Melaye: Ẹ̀rù ń bá wá lóri ilera Dino, ìgbésẹ̀ ọlọ́páà sì jẹ́ ìpálara fún
Irú àwọn bẹ́ẹ̀ ní Himeneu ati Alẹkisanderu, àwọn tí mo ti fà lé Satani lọ́wọ́ kí ó lè bá wọn wí kí wọn má ṣe sọ̀rọ̀ àbùkù mọ́.
Gbogbo ẹ̀yin ọmọ Israẹli, ẹ gba ọ̀rọ̀ yí yẹ̀wò, kí ẹ sì mú ìmọ̀ràn yín wá lórí rẹ̀ nisinsinyii.
Nígbà náà ni àwọn ọmọ Israẹli bá OLUWA jẹ́jẹ̀ẹ́ pé, Bí ó bá ti àwọn lẹ́yìn tí àwọn bá ṣẹgun àwọn eniyan náà, àwọn óo pa àwọn eniyan náà run patapata.
 agbè àti ṣẹ ̀ kẹ ̀ rẹ ̀ jẹ ́ ohun èlò ìlù lílù àti ijó jíjó tí a dá sílẹ ̀ ní àkókò Ẹ ́ mpáyà bìní .
O fi kun un pe laipẹ ni wọn yoo gbe abajade iwadii wọn tọ aarẹ lọ.
Fasoranti: Wọn ní kí Buhari kìlọ̀ fáwọn darandaran tó n tẹ Yorùbá lójú mọ́lẹ̀ bí bẹ́ẹ̀ kọ́.
Oriṣiriṣi iran fun oju ni yoo ṣẹlẹ ninu eto naa nitori sinima awootunwo ni o maa n ṣẹlẹ nibẹ bii ọrọ ifẹ, ija, asọ, ere, ẹrin pẹlu ayẹyẹ.
Lẹ́yìn tí wọ́n gba ilẹ̀ náà tán, wọ́n ń gbé ibẹ̀.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, loju ọna ni ọmọ ti n mu wọn Buhari ní ìdìbò 2019 kìí ṣe tikú-tìyè 'Logo Benz yóò lẹ́yìn fún àwọn ọ̀dọ́ tó bá ṣògùn owó' 'Ọlọ́pàá Nàìjíríà ti dí agbẹnusọ ijọba Buhari' Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Alapinni Oosa ṣàdúrà fún gogbo ọmọ kúoótù, oò jíire bí?
Wọ́n bá sọ ọkọ̀ kékeré sórí òkun bí ẹni pé wọ́n fẹ́ sọ ìdákọ̀ró tí ó wà níwájú ọkọ̀ sinu òkun.
”Isa naa wa gbosuba fun asofin naa lori  iwe ikedun ti o  fi ranse  si egbe naa.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Umbilical cord: Àìsàn Màrùndíláàdọ́rùn ni ìwọ́ ọmọ tuntun le wòsàn 8 Ògún 2020 Oríṣun àwòrán, Others Adarí ilé iṣẹ́ ìṣègùn kan Toluwalope Ogunlẹyẹ ti rọ àwọn abiyamọ láti máa yọ̀nda ìwọ́ (Umbilical Cord) ọmọ wọn si àwọn ilé ìkẹjẹ̀ sí jákèjádò Naijiria.
odun keresimesi, odun a yabo, emi wa yoo si se opolopo odun laye,”
Lẹ́yìn igbe Atiku, Ààrẹ Ilé Ẹjọ́ kòtẹ́milọ́rùn yọra rẹ̀ nínú ìgbẹ́jọ́ èsì ìdìbò ààrẹ Wọ́n jí ọmọ yìí gbé láti máa fi tọrọ bárà l'Eko Àwọran bí àwọn òṣìṣẹ́ Ìpínlẹ̀ Oyo ṣe f'aṣọ ìbílẹ̀ rántí àyájọ́ ọjọ́ àṣà Eko, Oyo, Kwara, Anambra gba Ọ̀gá Ọ̀lọ́pàá tuntun Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Contortionist: Mo lè gbé ìfun mi pamọ́ ki n tún se èémí!
Ninu fọnran fidio rẹ́ to wa lori ayelujara o sọ pe ''Lọdun maarun un sẹyin mo sọ bẹ nipa Atiku,lọdun mrin sẹyin Olorun sọ b fun mi nipa Atiku'' Abalọ ababọ asọtẹlẹ r ni pe Atiku fidirẹmi ninu idibo aarẹ ọdun 2019.
Belgore tun so pe awon omo orile ede Naijiria je omo orile ede rere, ti ko lẹgbẹ, ti won si wa jake-jade agbaye.
O gba akọkọ ni ọdun 1997 nigba to wa ni ọmọ ọdun mọkanlelogun pere.
"Seyi ni ""mo fẹ ko jẹ wi pe bi mo ba ṣe ohunkohun emi, Seyi ni mo ṣe e kii ṣe Awolowo""."
lati fun adari ile ifowopamo ijoba apapo, Godwin Emefiele ni anfaani lati tun
Àwọn ọmọ Juda ni: Peresi, Hesironi, Kami, Huri, ati Ṣobali.
Obafemi Awolowo University: Olùkọ́ fásitì OAU gbòmìnira lọ́wọ́ àwọn ajínigbé
Ni ọjọ kẹta oṣu kẹjọ ọdun 2020 ni idibo abẹnu ẹgbẹ oṣelu APC fun awọn oludije ipo gomina nipinlẹ Ondo waye ti Akeredolu si bori.
Ìdí tí a fi ṣe òfin tuntun fún àwọn akọ̀ròyìn tí yóò ṣiṣẹ́ nílé aṣòfin - NASS Ta ni Naira Marley jẹ́ gan?
Ẹ jẹ́ aláàánú gẹ́gẹ́ bí Baba yín ti jẹ́ aláàánú.
 “mo lee fi daa yin loju pe ijoba apapo ti n ko afara keji ti Niger ati awon  oju popo bi I mọ́kàndínláàdọ́rin  bayiini ekun ila oorun.
Bákan náà, nígbà tí gbogbo àwọn ará Juda tí wọn wà ní ilẹ̀ Moabu, ati àwọn tí wọn wà ní ilẹ̀ àwọn ará Amoni ati ti Edomu ati àwọn tí wọ́n wà ní gbogbo ilẹ̀ káàkiri gbọ́ pé ọba Babiloni dá àwọn eniyan díẹ̀ sí ní Juda, àtipé ó fi Gedalaya, ọmọ Ahikamu, ọmọ Ṣafani, ṣe gomina wọn, 
Báwo ni àwa tí a ti fi ayé ẹ̀ṣẹ̀ sílẹ̀, ṣe tún lè máa gbé inú ẹ̀ṣẹ̀?
Pàá lẹ́ẹ̀kíní, pàá lẹ́ẹ̀kejì, nígbà wo gan ni Madrid fẹ́ jẹ àǹfàní £150m tí wọ́n kó lè Eden Hazard?
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Kashamu àti ìjọba àpapọ̀ ń pète láti fi ọlọ́pàá mú wa - PDP Gomina Ortom ti Benue fi APC sílẹ̀ lọ PDP Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Àwọn oṣiṣẹ feyinti ni Osun ṣé iwọde Bakannaa ni wọn tun beere fun sisan ẹgbẹrun marun owo irinsẹ fun awọn oṣiṣẹ, sisan ajẹẹlẹ owo ajẹmọnu igbega laarin ọdun 2012 si 2017 pẹlu adinku to waye lori ajẹẹlẹ owo ajẹmọnu igbega laarin ọdun 2014, 2015 ati 2016 atawọn nnkan miran.
Ó ní, “Bí àwọn eniyan wọnyi bá ń lọ rúbọ ní ilé OLUWA ní Jerusalẹmu, ọkàn gbogbo wọ́n lè tipa bẹ́ẹ̀ pada sẹ́yìn Rehoboamu, oluwa wọn; wọn óo sì pa mí, wọn óo sì pada tọ Rehoboamu, ọba Juda, lọ.
Ọ̀gá ICPC wa rọ ààrẹ Buhari láti dá àwọn ọga ajọ ati ilé iṣẹ́ ti igbá ọ̀rọ̀ náà ṣí mọ lórí dúró titi ti ìwádìí yóò fi parí.
ẹni tí kì í ṣe ojuṣaaju fún àwọn ìjòyè,tí kì í sì í ka ọlọ́rọ̀ sí ju talaka lọ,nítorí iṣẹ́ ọwọ́ rẹ̀ ni gbogbo wọn.
“Ohun ti a n se labe ofin ni lati du ẹmi awon eniyan ati dukia won.
Nígbà tí ó dé, ó dúró ní ẹnu ọ̀nà.
Iṣẹlẹ yii ṣẹlẹ ni ọjọ Iṣẹgun ọsẹ yii ni ẹkan -ile, ti o jẹ pe ni kete ti iṣẹlẹ naa ṣẹlẹ ni awọn Fulani darandaran bẹrẹ si ni ta oku ẹran naa fun ara ilu jẹ.
leyin ti Ferrer jawe olubori ninu ikolu pelu Lucas Pouille ti o wa lati
“Ẹni tí ń bá ẹlẹ́dàá rẹ̀ jà gbé!
O ni awọn ọlọdẹ atawọn oloko maa n ri awọn ero to bọ sọwọ ajinigbe ninu igbo, ti wọn yoo ti fẹẹ na ẹlomiran ninu wọn pa.
Lasiko irinajo lo si Morocco, orile ede Naijiria ati Morocco towobo iwe adehun lati tubo tesiwaju nipa ibasepo won lori afefe gaasi , epo robi, ise agbe ati eto eko.
Ṣe ẹ dẹ mọ pe o ti dawọ duro niluu Wuhan lootọ.
Bí ó ti ń kọjá ní gbogbo agbègbè náà, bẹ́ẹ̀ ni ó ń gba àwọn eniyan níyànjú pẹlu ọ̀rọ̀ ìwúrí pupọ títí ó fi dé ilẹ̀ Giriki.
Ọwọ́ àwọn ọmọ ogun Kalidea tẹ Sedekaya ọba, wọ́n sì mú un lọ sọ́dọ̀ ọba Babiloni ní Ribila, ní ilẹ̀ Hamati, ọba Babiloni sì ṣe ìdájọ́ fún un.
O ni bo ti wu ko ri, ijọba ni lati rii daju pe eto ọrọ aje n lọ bo ti yẹ gẹgẹ bi awọn onimọ ti ṣe fi to ijọba leti.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ogun Stolen Mace: Bí wọ́n ṣe rí ọ̀pá àṣẹ ìpínlẹ̀ Ogun ní Eko rèé 3 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 11 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Oríṣun àwòrán, Lagos PPRO Iroyin ayọ lo de ba awọn ọmọ ile igbimọ aṣofin ipinlẹ Ogun gẹgẹ bi awọn ọlọpaa ṣe sọ lọjọ Ẹti pe wọn ti ri ọpa aṣẹ ti wọn jigbe pada.
Alaga ile-ise Dalian Shipbuilding Industry  to n ri si kiko oko oju-omi, Liu Zheng so pe ile-ise naa ati ile-ise to n ko oko oju-omi ni China so pe awon ti setan lati jo sowopo lati ko oko oju-omi nla tuntun miran.
Àwọn àwòrán yìí wá láti ileesẹ Google ati Instagram Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
0 509 Orilẹede Liechtenstein 17 44.
Bí wọn kò bá tilẹ̀ tíì hàn, wọn kò ṣe é bò mọ́lẹ̀ títí.
16 Èbibi 2019 Oríṣun àwòrán, Facebook/KayodeFayemi/Ayodele Fayose Àkọlé àwòrán, Ijọba awọn Gomina mejeeji yi dabi ẹni pe wọn taka ẹni to le yọ oṣiṣẹ laarin wọn Bi erin meji ba n figagbagba, dajudaju koriko ibẹ ni yoo fori ko.
Ajọ naa ni ti gbogbo agbaye ba le e maa fara balẹ, tii se calm down, gbogbo iwa ipa to n sẹlẹ lagbaye ni yoo dopin.
Èdùmàrè jọ̀wọ́ báwa dẹlẹ̀ fún Èlíjà
Oladele salaye pe ere asapajude lo ṣokunfa iṣẹlẹ yi ti ọkọ meje si farakasa ijamba naa.
 O ni “o ṣe pataki ki iru ajọ yii wa lati ṣegbe fun ere ti o ti n foju han ni ẹka yii lati bi ọdun mẹta sẹyin.
O tẹsiwaju pe epo ẹgbẹrun kan naira ko le de ibi kankan mọ ninu ọkọ nibayii ti epo ti gbowo lori.
Àwọn ni wọ́n tún ń ṣe ètò ṣíṣe burẹdi ìfihàn, ìyẹ̀fun fún ẹbọ ohun jíjẹ, àkàrà tí kò ní ìwúkàrà ninu, àkàrà díndín fún ẹbọ, ẹbọ tí a po òróró mọ́, ati pípèsè àwọn oríṣìíríṣìí ìwọ̀n.
Shiite kọ̀wé pe àwọn pásítọ̀ láti darapọ̀ mọ́ ìwọ́de wọn Ìbọn ọlọ́pàá ló pa èèyàn, ẹgbẹ́ wa kìí lo ìbọn - Shiite fárígá ‘Buhari ti gbàbọ̀dè fún Nàìjíríà’ Ẹni orí yọ, ó dilé!
Jesu fa ọmọ náà lọ́wọ́, ó sọ fún un pé, “Ọmọ, dìde.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Gbara rẹ sile Ninu fidio naa ti Deborah Okezie fi sori ayelujara Facebook lọjọ kọkandinlogun, oṣu Kejila, amọ to pada yọ kuro nibẹ, lo ti n fi ọrọ wa ọmọ rẹ, Don David lẹnu wo.
Wọ́n nífẹ̀ẹ́ owó, wọ́n ń gba àbẹ̀tẹ́lẹ̀, wọ́n sì ń dájọ́ èké.
Nítorí náà, ẹ jẹ́ kí á pa ẹ̀kọ́ alakọọbẹrẹ ti ìsìn igbagbọ tì, kí á tẹ̀síwájú láti kọ́ ẹ̀kọ́ tí ó jinlẹ̀.
Oríṣun àwòrán, Instagram/djokernole Lati oṣu keji ọdun 2020 ni ajọ to n ri si ere idaraya tẹniisii, ATP ti fote le tẹniisii gbigba nitori ajakalẹ aarun coronavirus.
wa pe fun ṣiṣe amugbooro agbara awọn ẹṣọ alaabo abẹle yii lati le tubọ
Láàrin kádijúkálàá, ojó ìpíngún pé, esè gbogbo àwon àgbà sì kò.
Ní ìgbà ayé ogun, ọ̀tún ogun, ni Ìjẹ̀bú-Jẹ̀ṣà jẹ́ ní ilẹ̀ Ìjẹ̀ṣà, wọ́n sì ní ọ̀nà tiwọn yàtọ̀ sí ti àwọn yòókù.
Fún odidi ọgọsan-an (180) ọjọ́ ni ọba fi ń fi ògo ìjọba rẹ̀ hàn, pẹlu ọrọ̀ ati dúkìá rẹ̀.
Ọwọ ọlọpaa tẹ ẹ lẹyin ti Assange sa asala lọ si ile isẹ asoju ilẹ Ecuado ni ọdun 2012 lati yẹra fun igbesẹ ilẹ Sweden to ti fẹ jẹjọ iwa ẹsun ifipabanilopọ.
Lọwọlọwọ, o ti pe ọrinlelẹgbẹrin din meje eniyan to ti ni aarun naa ni Naijiria.
Plateau-50 Enugu-35 Rivers-27 Lagos-26 FCT-18 Kaduna-18 Ekiti-10 Kano-10 Taraba-9 Anambra-8 Edo-8 Oyo-8 Delta-7 Ogun-6 Abia-5 Bayelsa-5 Ebonyi-1 Osun-1 NCDC ní ènìyàn 321 míràn ló tún fara kásá Covid-19 ní Nàìjíríà Iye ènìyàn to tún lùgbàdì ààrùn Coronavirus tun dín ẹyọkan si ti àná.
Inu mi maa n dun, inu ti ẹ naa si dun.
Ekiti Election: Èyí ni àwọn olóṣèlú Nàìjíríà tó tí 'fọ́gbọ́n ṣàìsàn'
Oríṣun àwòrán, Instagram/asoebimercy Bi awọn akẹẹgbẹ rẹ se mu na kan pọn, ni oun naa gba ọna keji yọ, to si lọ si sọọbu asọ tita.
Ní ọdọọdún ni ọpọlọpọ eniyan máa ń mú ọpọlọpọ ẹ̀bùn àwọn nǹkan tí wọ́n fi fadaka ati wúrà ṣe wá sọ́dọ̀ rẹ̀, pẹlu ẹ̀wù, ati turari olóòórùn dídùn, ẹṣin, ati ìbaaka.
Lootọ ni Ayinla Ọmọwura jẹ ọmọ atapata dide amọ, o koju ọpọ ipenija to ba nile aye, to si bori wọn.
Awọn ọmọ ìjọ Sàtánì tí bẹ̀rẹ̀ sí ni bínu sí orílẹ̀-èdè Nàìjíríà lóri ọ̀rọ̀ kan ti Femi Fani-Kayode sọ tó si ń dà èbi ru Sàtánì nínú ọ̀rọ̀ rẹ̀, láwọn ọmọ ìjọ̀ Sàtánì bá fárígá.
" Lati bi ọdun diẹ ni ọpọ ọmọ Naijiria ti n polongo pe, ki ijọba o fi opin si ẹka ọlọpaa SARS, nitori awọn iwakiwa to kun ọwọ wọn.
Ó tọ́ka síi pé Nàìjíríà ń koju àwọn ǹkan to lòdí pàápàá jùlọ lórí ètò ààbọ.
 Mo n dupe lowo Aare fun igbese ipese iranlowo yii fawon agbe olohun ogbin lasiko yii.
Ni ilu yii,gbogbo igba ni wọn maa n ni iriri abami loru ti wọn yoo kan maa gbọ ohun to n dẹru ba ni nita ile wọn ti ibẹrun bojo yoo si de ba wọn ninu ile.
Iroyin so pe, “Ninu abajade osuwon odun2017, ajo FAO safihan akosile odun 2015, ati ipinnu lati so ipo tie to ogbin wa leyin ajalu naa ni awon orile-ede ti o ku die kaa to fun, o se agekale akoko iru re, ni eyi ti o salaye ni kikun lori akoba ti ti o waye ni awon agbegbe osin eja, awon ohun osin omi ati igi-gbigbin, eyi ti ko si abo lati odo PDNA, bakan naa ni o safihan awon ogbon miiran fun osuwon ati adanu ti isele ohun sokunfa re, ni eyi ti o wa se alekun agboye lori akoba ti o ni lori eto oro-aje ati awon ohun osin”.
” Nítorí náà OLUWA fi àmì sí ara Kaini kí ẹnikẹ́ni tí ó bá rí i má baà pa á.
Ẹ̀mí gbé mi lọ sí ẹnu ọ̀nà ilé OLUWA tí ó kọjú sí ìhà ìlà oòrùn.
Ṣé Akpabio ṣetán láti dárúkọ àwọn Aṣòfin tó gba iṣẹ́ àkànṣe lọ́wọ́ NDDC?
O salaye pe, o je ohun edun okan lati ri pe, gbogbo igbese ti ipinle naa la kale fun aseyori eto ogbin ni won ti pati, ni eyi ti o n sakoba fun idagbasoke eto ogbin lati bi odun die bayii.
 Ile-isẹ naa maa n pese  ina mona-mona ti wọn , ni eyi ti o wa ni Afrika, aarin gbungbun ile Afrika ati  Asia.
Koda, Ifa ni yoo jẹ olokiki, ti yoo si ni ibasepọ pẹlu awọn iran ajeji ni ọna jinjin rere, eyi ti a lee pe ni awọn oyinbo alawọ funfun Kia si ni baba rẹ ti ni ki wọn gbe ilẹkẹ si Adesọji lọrun, lati fihan pe ọmọ ọba ati ọba lọla ni Ẹ pèsè ẹlẹ́rìí púpọ̀ bí bẹ́ẹ̀ kọ́, Sotitobire yóò jẹ́rìí fúnrarẹ̀ o!
Ṣùgbọ́n, ìgbéyàwó kò ti lee sí ní ọkàn rẹ̀ rárá, nítorí pé óun kẹ́kọ̀ọ́ láti gba oyè ìmọ̀ ìjìnlẹ̀ kejì nínú iṣẹ́ tó yàn láàyò ní fásitì Oxford, tó wà ní ilẹ̀ Gẹ̀ẹ́sì.
Atiku lo fi ọọ naa lede loju opo Twitter rẹ nigba to n sọrọ lori awọn kudiẹkudiẹ ti orilẹ-ede yii n dojukọ.
Orukọ naa si wa lati orukọ ẹgbẹ tiata ọkọ Mama Rainbow tẹlẹ ri.
OLUWA ní,“Wọ́n ń tinú ibi bọ́ sinu ibi,wọn kò sì mọ̀ èmi OLUWA.
“Ìwọ ọmọ eniyan, máa mí ìmí ẹ̀dùn, bí ẹni tí ọkàn rẹ̀ ti dàrú, tí ó sì ń kẹ́dùn níwájú wọn.
Yóo fi àwọn ọba wọn lé yín lọ́wọ́, ẹ óo sì pa orúkọ wọn run ní gbogbo ayé, kò ní sí ẹyọ ẹnìkan tí yóo lè dojú kọ yín títí tí ẹ óo fi pa wọ́n run.
Majẹmu tí mo bá wọn dá ní ọjọ́ tí mo kó wọn kúrò ní ilẹ̀ Ijipti, ilẹ̀ tí ó gbóná bí iná tí alágbẹ̀dẹ fi ń yọ́ irin.
Ó sì ti fi ibinu gbígbóná rẹ̀,kọ ọba ati alufaa sílẹ̀.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Akomolede àti Asa lórí BBC Yorùbá: Mọ̀ síi nípa ẹ̀kún ìyàwó níbí Ọfisa SWAT meloo lo wa ni Nasarawa?
Káyé ó máse má a lé ipa rẹ̀!
Alagba Kisira ni ipinle Kwara pa aala pelu orile ede marun un ni eyi to je ko se Pataki ki awon eniyan re ni imo kikun lori eto idibo ni alaafia.
Hajiya Binta Salihu - Ọmọ ẹgbẹ́ 6.
Kì í ṣe ẹ̀yin nìkan, ṣugbọn gbogbo àwọn tí ó ń gbọ́ ọ̀rọ̀ mi lónìí.
Amuneke àti olóògbé Keshi ló gbé orílẹ́èdè míì lọ sí ìdíje AFCON Super Eagles fi iyọ̀ sójú Seychelles pẹ̀lú àmì ayò 3-1 Ẹnu ń kun ààrẹ Burundi tó jú akẹ́kọ̀ọ́ mẹ́ta sẹ́wọ̀n nítorí wọ́n fi nǹkan kun àwòrán rẹ̀ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Èré Ọṣun: Àtáója ní wọn kò jí ère Ọṣun, ó sì wà níbi tó wà Libya lo jawe olubori pẹlu ami ayo meji sodo ninu ifẹsẹwọnsẹ akọkọ ti wọn gba lorilẹede Libya lọsẹ to kọja.
Lójú ọ̀nà Efurati náà ni mo sì sin ín sí.
Ègbé ni fún àwọn tí wọn ń gbìmọ̀ ìkà, tí wọ́n sì ń gbèrò ibi lórí ibùsùn wọn.
Àwọn obinrin náà bá yára kúrò níbi ibojì náà pẹlu ìbẹ̀rùbojo ati ayọ̀ ńlá, wọ́n sáré lọ sọ fún àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀.
Àwọn aposteli tí Jesu rán níṣẹ́ pada wá sí ọ̀dọ̀ rẹ̀, wọ́n ròyìn gbogbo ohun tí wọ́n ti ṣe fún un.
Oludije dupo fun ipo gomina ni ipinle Oyo, ni ekun Gusu
O ri ara rẹ bi ajumọ bani ṣiṣẹpọ to se e gbọkanle to si le ba ẹnikẹni ṣe.
Kamaru Usman: Ọmọ Áfíríkà àkọ́kọ́ tó gba ìgbànú ẹ̀yẹ ẹ̀ṣẹ́ kíkàn Ó tó gẹ́!
Ẹ wo tọkọtaya tí kò ríran amọ́ tí wọn jẹ́ olùkọ́ Ìpèníjà ojú kò ní kí ń má ṣiṣẹ́ ‘DJ’ - Etu Sodiq Omotayo 5:30 p.
00 ọrọ na ko le ye yin daada.
0 10718 Orilẹede Jamaica 265 9.
ede Naijirialati gbogun ti aisan ebi ati osi lorile ede Naijiria.
Iyawo ile ni Jummai, diẹ lara awọn ọmọ rẹ to ti dagba si maa n wa iṣẹ ṣe lati pese ounjẹ ati owo fun oun ati ọkọ rẹ pẹlu awọn ọmọ to ku.
Ó gbé ẹran ẹbọ sísun wá, ó sì fi rúbọ gẹ́gẹ́ bí ìlànà.
Nígbà tí ó rú ẹbọ tán, ó súre fún àwọn eniyan náà ní orúkọ OLUWA àwọn ọmọ ogun.
Ohun ìríra ni ẹbọ eniyan burúkú lójú OLUWA,ṣugbọn adura olódodo jẹ́ ìdùnnú rẹ̀.
Wazo bi ọmọkunrin tuntun: Oríṣun àwòrán, others Gbajugbaja oṣere tiata lọkunrin kan, Owokoniran Razak, ti ọpọ eeyan mọ si Wazo, ni ọba oke fi ọmọkunrin lanti lanti ta lọrẹ ni aarin ọsẹ yii, ti awọn akẹẹgbẹ rẹ si n ki ku oriire.
“OLUWA yóo mú ọjọ́ burúkú dé bá ìwọ ati àwọn eniyan rẹ ati ilé baba rẹ, ọjọ́ tí kò ì tíì sí irú rẹ̀ rí, láti ìgbà tí Efuraimu ti ya kúrò lára Juda, OLUWA ń mú ọba Asiria bọ̀.
Ìgbà mélòó ni mo ti fẹ́ kó àwọn ọmọ rẹ jọ, bí adìẹ tí ń kó àwọn ọmọ rẹ̀ sí abẹ́!
Àìsàn burúkú jẹ awọ ara rẹ̀,àkọ́bí ikú jẹ ẹ́ tọwọ́ tẹsẹ̀.
Ẹ kíyèsí àwọn ohun tí ń ṣẹlẹ̀ si yín.
Ọdun to lọ lo tilẹ pinnu pe oun yoo fi adagba orin kikọ rọ.
Baba naa, ninu aworan yii lo de fila, ti irungbọn rẹ si gun lọ gbọọrọ, bẹẹ lo dudu pẹlu.
Òun ni Ẹ̀mí tí ń fi òtítọ́ Ọlọrun hàn.
Ìkíni tí èmi Paulu fi ọwọ́ ara mi kọ nìyí.
2m dọlà ni ìgbàkúgbà tó bá kọ ǹkan sórí Instagram rẹ̀ 28 Agẹmo 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Àwọn míràn tó ń gba owó gọbọi ni Ariana Grande tó ń gba $ 966,000, nígbà tí Cristiano Ronaldo ń gba $ 975,000.
    Èmi ni ọ̀rẹ́ rẹ lójú méjèèjì,
Inú bí mi gan-an, mo bá fọ́n gbogbo ẹrù Tobaya jáde kúrò ninu yàrá náà.
“Wọn kò gbọdọ̀ fá irun orí wọn tabi kí wọn jẹ́ kí oko irun wọn gùn, wọn yóo máa gé díẹ̀díẹ̀ lára irun orí wọn ni.
” Abrahamu dáhùn, ó ní, “Èmi nìyí.
Oríṣun àwòrán, @Musk Ta ni Elon Musk?
O so pe : “Bo tile je pe, ko rorun fun awa naa.
apero lori eto oro aje laarin orile ede Naijiria ati UK , ni eyi ti o jẹ akọkọ
 a gbà wọ ́ n pẹ ̀ lú ìgbàgbọ ́ , wọ ́ n jẹ ́ ẹ ̀ kọ ́ tó wà láti gbàgbọ ́ ; a lè fi wọ ́ n ṣe ẹ ̀ rí àìmọ ̀ kan , iyèméjì tàbí àìgbàgbọ ́ .
Nígbà tí ọkàn bàbá rẹ̀ sì fà á, ó tọrọ ààyè lọ́dọ̀ ìyàwó rẹ̀ láti lọ̀ bẹ ilé wò, òun náà sì gbà pé ó dára, ṣùgbọ́n ofin kan ni o fún ọkọ rẹ̀, ó wí fún un pé kò gbọdọ̀ sọ ibi tí òun wà fún ẹnikẹni, ṣùgbọ́n kí ó fi han bàbá rẹ̀ pé ọkàn òun balẹ̀ nibi tí òun wà, àti pé ayé òun ti dára.
 Olórí ilé aṣòfin ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́ jáde láyé Mọ̀lẹ́bí Adéyẹmọ fẹ wadi ikú rẹ̀ Aṣíwájú ẹ̀sìn náà tó ń sọ̀rọ̀ lórí ìròyìn kan tó jáde láìpé yìí ni oun ko lee ku rara o nitoripe, gẹ́gẹ́bi o ṣe sọ àwọn ẹlẹ́ṣẹ̀ níí kú."
Àwọn ẹlẹ́ṣẹ̀ pàápàá ń ṣe bẹ́ẹ̀.
Sadio Mane gba ami-ayo kinni wole niseju meta ti ifesewonse ohun bere, ti James Milner si se asise da ami-ayo naa pada wonu agbon re, wakati die ki saa akoko ifesewonse ohun o to wa si ipari, Georginio Wijnaldum tun fori gba ami-ayo miiran wole lati so esi saa kinni ohun di ami-ayo meji sookan (2-1).
Eliṣa rán iranṣẹ kan kí ó sọ fún un pé kí ó lọ wẹ ara rẹ̀ ninu odò Jọdani ní ìgbà meje, yóo sì rí ìwòsàn.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìyàwó: Ọkọ mi kúndùn ìbálòpọ̀ kọjá sísọ lẹ́yìn ìgbeyàwó ogun ọdún 17 Bélú 2018 Oríṣun àwòrán, Karen Charmaine Chanakira Awuyewuye n waye pe, boya awọn kan wa to kundun ibalopọ kọja bo ṣeyẹ.
Nisinsinyii tí a ti gbé e ka ọwọ́ ọ̀tún Ọlọrun, ó ti gba ìlérí Ẹ̀mí Mímọ́ láti ọ̀dọ̀ Baba, ó wá tú u jáde.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: NURTW yóò fikùlukù pẹ̀lú Gómìnà Makinde láìpẹ́ Iṣẹ́ Kudirat Abiọla ṣì ń fọhùn síbẹ̀, lẹ́yìn ọdún 23 tó papòdà Kini Pásítọ̀ Kumuyi fi ṣẹ ọmọ Naijiria?
Bi o tilẹ jẹ pe ọpọlọpọ wọn ni ede Yoruba dantọ ni ẹnu wọn lasiko ti wọn ba n ṣe sinima, sugbọn iyalẹnu lo jẹ pe awọn kan wa ninu wọn, ti kii ṣe ọmọ Yoruba.
O si fi asiko kan naa gba awọn ọlọpaa to ti kuro lẹnu iṣẹ wọn loju popo fun bii ọjọ marun un latari pipa ọlọpaa to le ni ogun lasiko ifẹhonuhan to jade jakejado Naijiria.
Jẹ́ kí àwọn orílẹ̀-èdè ayé ó rọ̀gbà yí ọ ká,kí o sì máa jọba lé wọn lórí láti òkè wá.
Lara awon to peju sibi eto naa ni a ti ri awon ori ade ati orun ileke,
Wọ́n gbé wọn lọ́wọ́ lọ sí ibi tí wọ́n sùn ní alẹ́ ọjọ́ náà, wọ́n sì tò wọ́n jọ sibẹ.
Saulu dá a lóhùn pé, “Mo mọ̀ pé mo ti ṣẹ̀, ṣugbọn bu ọlá fún mi níwájú àwọn àgbààgbà, àwọn eniyan mi ati gbogbo Israẹli.
ati òbúkọ kan fún ẹbọ ìmúkúrò ẹ̀ṣẹ̀.
Nítorí Ọlọrun sọ pé, “Mo gbọ́ ẹ̀bẹ̀ rẹ nígbà tí o bá ojurere mi pàdé;mo ràn ọ́ lọ́wọ́ ní ọjọ́ ìgbàlà.
Àwọn ni wọn óo máa wọ ibi mímọ́ mi, wọn óo máa lọ sí ibi tabili mi, tí wọn óo máa ṣiṣẹ́ iranṣẹ, wọn óo sì máa pa àṣẹ mi mọ́.
Arsenal padà sórí pápá, Premier League lè bẹ̀rẹ́ padà lóṣù kẹfa Oríṣun àwòrán, Mikel Àkọlé àwòrán, Coronavirus: Arsenal padà sórí pápá, Premier League lè bẹ̀rẹ́ padà lóṣù kẹfa O ṣeeṣe ki idije Premier League bẹrẹ pada laipẹ, lẹyin ti o ti wa ni idaduro lati inu oṣu kẹta nitori ajakalẹ aarun coronavirus.
Buhari ti gba iwe ifiranse lati odo oba orile ede Saudi Arabia , Salman Bin
Ọlá ati ọlà yóo wà ní ilé rẹ̀,Òdodo rẹ̀ wà títí lae.
Jaṣobeamu, ọmọ Sabidieli, ni olórí ìpín kinni, fún oṣù kinni; iye àwọn tí wọ́n wà ninu ìpín rẹ̀ jẹ́ ọ̀kẹ́ kan ó lé ẹgbaaji.
Oríṣun àwòrán, falzthebahdguy Ṣaaju ki a to bẹrẹ si ni gbe iroyin igbẹjọ igbimọ yii, a ni ki a se atupalẹ iroyin nipa awọn ti wọn yan lati ṣoju ọdọ ati iru akitiyan wọn to mu ki ipo yi tọ si wọn.
Àkọlé àwòrán, Ìyálóde Ìbàdán: Ètò tí bẹ̀rẹ̀ ní perewu fún ìsìnkú Awọn asiwaju ẹsin, aṣoju ijọba, oniṣe ọwọ, oniṣowo ati awọn ẹgbẹ awujọ ni ireti wa wipe wọn yoo peju pesẹ lati ṣe ẹyẹ ikẹhin fun Iyalode ilẹ Ibadan.
Kí ló dé tí òun ati àwọn ọmọ rẹ̀fi di ẹni tí a kó lẹ́rú lọ sí ilẹ̀ tí wọn kò mọ̀ rí?
Ayodele Fayose and Seyi Makinde: Màá fidán han Seyi Makinde, tó bá yọjú sí Ekiti
Mose gbà fún baba iyawo rẹ̀ pé kí ó máa pada lọ sí ìlú rẹ̀, baba iyawo rẹ̀ gbéra, ó sì pada sí orílẹ̀-èdè rẹ̀.
O ni oun fẹ ki Risikat ko pada wa sile ṣugbọn kii ṣe nitori owo ti o ti pa lọwọ awọn eeyan rara.
Mo fara han Abrahamu, Isaaki, ati Jakọbu gẹ́gẹ́ bí Ọlọrun Olodumare, ṣugbọn n kò farahàn wọ́n gẹ́gẹ́ bí OLUWA tíí ṣe orúkọ mi gan-an.
Wooli yii ti ri awọn iran kan sẹyin.
Isẹ orin kikọ gbe Ayinla Ọmọwura pupọ, ka si to sẹju pẹ, o ti se awo orin to to mejilelogun ko to papo da, ti okiki rẹ si gba gbogbo ilẹ Yoruba kan nigba aye rẹ, boya nitori ede Ẹgba to fi n kọ orin Apala tiẹ ni, ko sẹni to ye Ayinla Ọmọwura jẹ akọrin makọtisẹ ninu awọn awo orin to gbe jade naa, orin rẹ si ti yi igbe-aye ọpọ eeyan pada si rere, paapa awọn obinrin ojowu, obinrin to n bóra ati awọn onipanle obinrin, tii se ori bẹnbẹ si ọkọ.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Wo àwọn èèyàn jáńkán tí yóò ṣe ọdún tuntun ní ọgbà ẹ̀wọ̀n Wo àwọn èèkàn tí ikú mú lọ lọ́dún 2019 Bàbá akẹ́kọ̀ọ́bìnrin LASU tí ọ̀rẹ́kùnrin rẹ̀ àti pásítọ̀ fi ṣ'òògùn owó ń bèèrè fún ìdájọ́ òdodo Àwọn fóònù wọ̀nyìí kò ní lè ṣe WhatsApp láti ọdún 2020 Oríṣun àwòrán, Odunlade Adekola Àkọlé àwòrán, Ọdunlade Adekola Odunlade Adekọla: Odunlade Adekọla ni a lee pe ni irawọ ti o n tan lagbo ere tiata Yoruba bayii.
Erusu Eko kinni, Aṣofin Wasiu Sanni Ẹshinlokun ti ẹgbẹ oṣelu APC ni esi
Má gbára lé aládùúgbò rẹ, má sì ṣe gbẹ́kẹ̀lé ọ̀rẹ́; ṣọ́ra nípa ohun tí o óo máa bá iyawo rẹ sọ.
Oríṣun àwòrán, EPA Awọn ọlọpaa da ifẹhọnuhan naa ru, ti wọn si fẹ afẹfẹ gaasi tajutaju si awọn eniyan to n fẹhọnuhan naa.
Chisom Chukwuneke jẹ ìrora jẹjẹrẹ inú ẹjẹ̀ lásìkò tó n ṣe ìdánwò WAEC
Buhari  ti o fi ilu Abuja  sile lo si UK lojo Aje , ni yoo tun lo fun ipade awon adari orile ede ti won gba ominira lowo awon oyinbo alawo funfun    (Commonwealth Heads of Government Summit) ti yoo bere niluu London, lojo kéjìdínlógún osu kerin, ti yoo  si pari  ni  ogúnjọ osu yii.
Oríṣun àwòrán, @BBNaija Àkọlé àwòrán, Olukayode Ogundamisi ti ní kí àwọn ọmọ Naijiria yé bu ẹnu àtẹ́ lu Big Brother Naija, nítorí óhún mú inú àwọn ènìyàn dùn.
Josẹfu tún Dá Àwọn Arakunrin Rẹ̀ Lọ́kànle.
”Fayemi wa fokan awọn eniyan bale pe ẹgbẹ  APC naa ni yoo tun jawe olubori nibi eto idibo odun 2019 to n bo.
Bakan naa ni ileesẹ ọlọpaa ni aayan ti n lọ lati tanna wadi isẹlẹ naa siwaju si.
"Wo ìdí tí wọ́n fi dá Alága àjọ EFCC Ibrahim Magu sílẹ̀ Taa ni Ebila ""One Million Boys"" àti Ekugbemi, olórí ẹgbẹ́ òkùnkùn míì tó da ìlú Ibadan rú?"
Ohun tí wọn ń retí ni kí ẹ ṣe ìlérí pé ẹ óo fi Paulu ranṣẹ sí ìgbìmọ̀.
Premiership: Arsenal ta ọ̀mì 1-1 pẹ̀lú Bournemouth ní ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ àkọ́kọ́ Arteta
 Ó gbà pé akéwì ni òun .
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Wasiu Ayinde: Èmi àti Aláàfin sọ fún Gani Adams nípa oyè Mayegun, a kò jà rárá Gbogbo eyi ni ẹ lee wo ni oju opo facebook BBCNewsYoruba tabi ki ẹ tẹ adirẹsi ayelujara to wa ni isalẹ yii: Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Gbogbo olórí orílẹ̀-èdè Íjípìtì ni ó ti ṣe ìwádìí tàbí rán Alaa ní ẹ̀wọ̀n ní ojú ayée rẹ̀.
Àwọn mọ̀lẹ́bí ajínigbé tó pàdánù ẹ̀mí l'Ondo kò tí ì yọjú Kíni iyatọ tó wà láàrin FSARS àti SARS?
Wọ́n ní, “Juu ni àwọn ọkunrin wọnyi, wọ́n sì ń da ìlú wa rú.
Super Eagles kò ní já àwọn ọmọ Nàìjíríà kulẹ̀- Musa Ta ni Ọgágun àgbà Lamidi Adeosun tó ṣẹṣẹ gba ìgbéga?
 wọ ́ n ń ṣe èyí láti lè rí ẹ ̀ bùn gbà lọ ́ wọ ́ àwọn àlejò náà ; àti láti lè jẹ ́ kí aláàfin mọ irú àlejò tí ń bò .
Àwọn tí ó kórìíra mi láìnídìí pọ̀,wọ́n pọ̀ ju irun orí mi lọ.
A ri i ọmọkunrin náà tó ti kegungun ti gbogbo egungun ara rẹ han sita.
2 bílíọnù fi tún wáyà iná àti inú ilé Aso Rock ṣe- Buhari Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí ENDSARS: Wo ìgbà mẹ́rin tí ìjọba ti tú ikọ̀ ọlọ́pàá SARS ká sẹ́yìn ṣùgbọ́n.
Ta ni yóò jáwé olúborí nínú Ayẹyẹ ijó ìta-gbangba orílẹ̀-èdè Trinidad àti Tobago ọdún-un 2019?
Ìgbà tí ìyàwó mi wí báyìí tán emi náà dá a lóhùn mo ni, ‘mo dúpẹ̀ lọ́wọ́ rẹ fún ìmọ̀ràn ńlá yìí, mo mọ tìrẹ bẹ́ẹ̀, n ó máa bá iṣẹ́ lọ, èmi ọkùnrin ni mo wí bẹ́ẹ̀, ìwọ máa ṣiṣẹ́ rẹ lọ, kí emi náà máa ṣe tàmi, ọkùnrin ń bẹ lára mi, bẹ́ẹ̀ ni obìnrin ń bẹ lára rẹ, a ó fi ìgbàdùn ilé wa hàn fún àlejò wa.
Iwin tí wọ́n yàn kí o bá kùkùté jà ga ó sígbọnlẹ̀, ó sanra, o rí mùkùtùn, déẹ̀ sì ni kùkùté fi ga ju ìdí rẹ̀ lọ.
Nítorí kì í ṣe gbogbo àwọn tí a bí sinu ìdílé Israẹli ni ọmọ Israẹli tòótọ́.
Ko to lọ si Tijjani Boloni College fun ẹko keu ati imọ lọdun 2006 si oṣu kẹsan an, ọdun 2009.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Adeleke vs Oyetola: Ilé ẹjọ́ kòtẹmilọ́rùn yóò dájọ́ ìdìbò gómìnà Oṣun ọdún 2018 8 Èbibi 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 9 Èbibi 2019 Ile ẹjọ kotẹmilọrun to n gbejọ lori ọrọ ẹni tó lẹtọ lati jẹ Gomina nipinlẹ Osun laarin Gboyega Isiaka Oyetola ati Ademola Adeleke yo gbe idajọ kalẹ lọjọru.
Kí ló dé tí kò fi ye yín pé kì í ṣe ọ̀rọ̀ oúnjẹ ni mò ń sọ?
6m lórí ètò BBNaija torí pó sọ̀rọ̀ ìwúrí nípa Nàíjíríà Bí mo ṣe dúró ti Toyin nílé ìgbẹ̀bí jẹ́ kí ń mọ̀ pé ó yẹ kí ọkùnrin máa bọ aya wọn - ọkọ Toyin Abraham Iṣẹ́ ọpọlọ ló yẹ ká ṣe nínú tíátà, kìí ṣe àfihàn ara bíbó àbí ìhòòhò wa - Binta Mọgaji Ìjọba, ẹ yé fi ọlọ́pàá àtàwọn ológun dúnkokò máwọn èèyàn- Ṣoyinka Irọ́ ló pa, a kò mọ̀ ọ́ rí tàbí fún ọ ní ₦13m - APC tako afurasí ajínigbéAṣírí ìdí ti El-Zakzaky fi padà si Nàìjíríà láti India Awọn onisẹse naa, ti wọn korajọpọ si abẹ aburada ẹgbẹ kan ti wọn pe ni Traditional Religious Worshippers Association Of Nigeria (TRAWASSO) parọwa naa lasiko ti wọn ls se ago laafin si Olubadan tilẹ Ibadan, Ọba Saliu Akanmu Adetunji ni aafin rẹ lati fi sami ọdun Isẹse ti ọdun yii.
Ní ọdún kejidinlogun tí Jehoṣafati jọba ní Juda, Joramu, ọmọ Ahabu, jọba lórí Israẹli ní Samaria.
mọlẹbi rẹ lori ẹrọ ayeluja Whatsapp, pe ‘‘Eru n ba oun pupọ bi oko ofurufu naa se n
“Báyìí ni ẹ óo ṣe pín ilẹ̀ náà láàrin ara yín, gẹ́gẹ́ bí iye ẹ̀yà Israẹli.
Jakande: Osinbajo, Tinubu, Osoba kọwọrin lọ ki Jakande ọlọ́jọ́ ìbí
Oúnjẹ tí a bá rí lọ́nà èrú máa ń dùn lẹ́nu eniyan,ṣugbọn nígbà tí a bá jẹ ẹ́ tán, ẹnu ẹni a máa kan.
Ile-ise Total padanu N11 to pajude si N217, nigba ti ile-ise Mobil Oil shed  wa ni N9.
Nígbà tí gbogbo àwọn eniyan tí wọ́n péjọ, tí wọn wá wòran, rí ohun tí ó ṣẹlẹ̀, ńṣe ni wọ́n pada lọ, tí wọ́n káwọ́ lérí pẹlu ìbànújẹ́.
Nígbà tí Jesu jáde kúrò ninu ilé, àwọn amòfin ati àwọn Farisi takò ó, wọ́n ń bi í léèrè ọ̀rọ̀ pupọ, 
Láràárọ̀ ni yóo máa pèsè rẹ̀.
Níbẹ̀, ọ̀kọrin ọmọ Jamaica Aaron Silk darapọ̀ mọ́ àwọn olórin mìíràn  pẹ̀lú eléré Belizean Adrian Martinez  láti ṣe alágbàáwí ìdínkù fún ìgbóná àgbáyé sí ìwọ̀n-ọn ojúàmì 1.
Àwọn ẹni ibi óo pòfo;gbogbo ọ̀nà tí wọ́n lè gbà sá àsálàni yóo parẹ́ mọ́ wọn lójú,ikú ni yóo sì jẹ́ ìrètí wọn.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Inu mi bàjẹ́ nígbà tí mo bí i, odidi oṣù mẹ́ta, mi ò lè gbàdúrà s'Ọ́lọ́run' Pirhossein Koulivand to jẹ adari ajọ aṣeiranwọ ninu iṣẹlẹ pajawiri ni orilẹ-ede Iran sọ pe o ṣeeṣe ki a ṣi ri awọn ero naa doola ṣugbọn ko tii si ẹni to le sọ bayii ibi to maa ja si.
Oríṣun àwòrán, Facebook/Oyo State House of Assembly Àkọlé àwòrán, Ayẹwo fawọn kọmiṣọna tuntun Adari ile, Asofin Debọ Ogundoyin, ninu ọrọ tiẹ ṣapejuwe gbogbo awọn kọmiṣọna tile buwọlu iyansipo wọn naa, gẹgẹ bi awọn to kọṣẹ mọṣẹ ti wọn si jẹ olori pipe ẹda ninu iṣẹ ti wọn yan laayo.
 agbajo sisokan awon orile-ede diye pe iye awon eniyan ni 2009 je 154,729,000 , ti 51.
Àwọn ehoro ìgbẹ́ kò lágbára,sibẹsibẹ wọ́n ń kọ́ ilé sí pàlàpálá òkúta.
 sị ́ bẹ ̀ síbẹ ̀ , àwọn Ògbóni lágbára ju ọba lọ .
akoroyin soro leyin ti o dibo re tan nile idibo to wa ni  Opobiyi (005/006),ni wodu Ajikobi ni ekun iwo
"O ni nigba ti a o ba fi ri ojọ meji si asiko yii, oun yoo ṣe ikede miran, ""ki gbogbo awọn eeyan lee ri ọmọ tuntun naa soju""."
Ọdun 2019 ni Regina Daniels ati Ned Nwoko segbeyawo, wọn si ti bi ọmọkunrin kan.
Bakan naa lo sọ pe yoo tun jẹ ẹ̀kọ́ fun ẹnikẹni to ba fẹ ẹ hu iwa ọdaran to jọ idigunjale ati ijinigbe lori omi.
Lakoko iwode awon olopaa sagbegbe Salisbury, ni Britain lojo keje osu keta odun yii, ti n se agbegbe oloogbe ohun ti o sunmo ile olonje kan, ni won sakiyesi iku Sergei Skripal, ati omo re Yulia ti n won je irora iku leyin ti aisan aramanda ohun gbe won sanle.
Ambọde: Kò sí ìjà láàrin èmi àti Tinubu Gómìnà Ambode gbà pé òun fìdí rẹmi nínú ìdìbò abẹ́nú APC l'Eko 'Okù 11 ni mo rí níbi tí iléeṣẹ́ ológun àti ẹgbẹ́ Shiite ti kọlu ara wọn' Taofiq ní òṣèlú lọrọ to wa nilẹ yí ati wí pé ẹgbẹ́ àwọn n na ọwọ sí gbogbo àwọn tí ẹgbẹ òṣèlú APC dojú tí nílu Èkó.
Nigba ti ile iṣẹ BBC kan si ilé iṣẹ́ tó n rísí ìwọlé-ìjáde ní Naijiria lori ọrọ yii ni Ogbeni Sunday James to jẹ alukoro NIS sọrọ ni kikun lori ọrọ naa.
Oju re e, iran ree lọrọ to wa nilẹ yi.
Ó sọ gbogbo ìṣòro tí wọ́n rí lójú ọ̀nà, ati bí OLUWA ti kó wọn yọ.
“Ní ọjọ́ karun-un, ẹ óo máa fi ẹgbọ̀rọ̀ akọ mààlúù mẹsan-an, àgbò meji ati ọ̀dọ́ àgbò mẹrinla ọlọ́dún kọ̀ọ̀kan, tí kò ní àbààwọ́n rúbọ.
"Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Akomolede ati Asa Yoruba: Kí ni ""Future tense"" lédè Yorùbá?"
HK$5,780 (US$720) ni owó oṣù àwọn àgbàlagbà tí í ṣe òṣìṣẹ́-fẹ̀yìntì ní ọdún-un 2016  àti owó ìrànwọ́ ìjọba lápapọ̀.
Mo ti fi ọ́ ṣe ẹni tí yóo máa dán àwọn eniyan mi wò,o óo máa dán wọn wò bí ẹni dán irin wò,o óo gbìyànjú láti mọ ọ̀nà wọn,kí o lè yẹ ọ̀nà wọn wò, kí o sì mọ̀ ọ́n.
O ni awọn mu awọn ọmọ ẹgbẹ okunkun naa, lẹyin ti eeyan kan lọ fẹjọ sun lagọ ọlọpaa pe wọn yinbo lu ọmọ ọdun mẹrindinlogun kan ni ikun.
Bí ó bá ń rìn lọ, ipa ọ̀nà rẹ̀ a máa hàn lẹ́yìn rẹ̀,eniyan á rò pé òkun ń hó bí ọṣẹ ni.
Olori Abibat tẹle ọkọ rẹ silu Eko nibi to ti n sisẹ bii osisẹ nileesẹ adojutofo kan.
O ni ọpọ igba ni oun maa n se ounjẹ wa fun Roshan nigba ti ifẹ wọn ti n fẹsẹ mulẹ.
Wọ́n kọ́ àwọn pẹpẹ ìrúbọ sinu àwọn ìlú wọn: wọ́n kọ́ sinu ilé ìṣọ́, títí kan àwọn ìlú olódi.
 Ó lé ni egbàárùn ( 10,000 ) òsísé ìjoba tí murtala yo lénu isé nítorí àìsòótó lénu isé , àbètélè , jegúdú-jerá , síse ohun ìní ìjoba básubàsu , àìlèsisé-lónà-tó ye tàbí ojó orí láìfún won ní nkankan .
BBC Yoruba yoo maa mu bi ohun gbogbo ba ṣe n lọ wa si oju opo yii.
Èmi Jakọbu, iranṣẹ Ọlọrun, ati ti Oluwa wa, Jesu Kristi, ni ó ń kọ ìwé yìí sí àwọn ẹ̀yà mejila tí ó fọ́nká gbogbo ayé.
Iwe iroyin Punch lo gbe e jade wi pe, ọkunrin naa gba itusilẹ lai pe wakati mẹrinlelogun ti wọn jigbe lọ.
Bẹẹ ni ọ̀rọ̀ ṣe ri bi Isreal Adesanya ṣe n sele ri pe ajẹku iya ni Yoel Romero yoo jẹ ninu idájukọ ti yóò wáye lola ode yiì.
Fojú àti ọkàn sí láti mọ bóyá ó ní àpẹẹrẹ, tí ó bá wà tí fi idi rẹ múlè pé ó ní aarun náà, ó jí láti sọra ṣe kí ó sì pe lọ sí orí ayélujára NCDC láti pé àkíyèsí wọn.
Wọn a máa fi àwọn ìlú olódi ṣe ẹlẹ́yà, nítorí òkítì ni wọ́n mọ sí ara odi wọn, wọn a sì gbà wọ́n.
Ìjàpá múra, ó di ilé Ọba.
Oríṣun àwòrán, Facebook/Dan Foster Daniel Foster Dan Foster , Gbajugba sọrọsọrọ lori redio ti gbogbo eeyan mọ si Big Dawg lokiki rẹ kan pe o ku lọjọ kejidinlogun osu yii pe o ti gbkruje lọwọ ẹbọra.
Kí oore-ọ̀fẹ́ wà pẹlu yín ati alaafia láti ọ̀dọ̀ Ọlọrun Baba wa, ati Oluwa Jesu Kristi.
Alẹ ọjọ Iṣẹgun ni ajọ to n gbogun ti itankalẹ ajakalẹ aarun ni Naijiria, NCDC, kede eyi lori ayelujara Twitter rẹ.
Kíní àwọ́n aṣeyori to ti wáye?
’ Òmùgọ́diméjì náà wa rọra rẹ́rìn-ín díẹ̀ báyìí ó ní, ‘Dájúdájú, bí o bá tún lè yọ sí mi n ó lù ú, n ó fẹ́rẹ̀ pa á nítorí, mo ti mọ ọwọ́ rẹ̀ nísisì yyìí, n kò jẹ́ bẹ́ẹ̀ rárá, n kò jẹ́ bẹ́ẹ̀ rárá, bí ẹ ti ń wò mi yìí o, ẹ máṣe fi ojú di mi o, tàbí ẹ rò pé ọkọ yẹpẹrẹ kan lásán ni mi ni?
Àwọn ọmọ Nàìjíríà bínú sí olóngbo àti ẹlẹdẹ to sọ àsọtẹlẹ
Ààrẹ orílẹ̀-èdè Algeria Abdulaziz Bouteflika ti kọ̀wé fipo silẹ̀
Lẹ́yìn náà kí alufaa sun ún lórí igi tí ó wà ninu iná lórí pẹpẹ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 2020: Ọdun 2020 yii ko nìí nira fún àwọn tó bá bẹ̀rù Olorun Rasaq Ọlayiwọla (Ojopagogo) ati Moji Afọlayan Rasaq Ọlayiwọla ti ọpọ eeyan mọ si Ojopagogo fẹ Mojirọla Afọlayan ti oun pẹlu jẹ oṣere tiata.
Nítòótọ́, bí eniyan tilẹ̀ jẹ́ ọlọ́gbọ́n, ara rẹ̀ ni ó wúlò fún.
O ni ọpọ awọn banki ni ẹkun idibo guusu ipinlẹ Kwara ni wọn ko ṣi banki wọn mọ lẹyin idigunjale to waye ni ilu Offa naa.
Asiko to bimọ ọhun si ni ọpọ eeyan to o mọ ẹni ti ololufẹ rẹ jẹ, nitori pe o fi aworan ọkunrin naa ati ọmọ rẹ si ori ayelujara.
Nígbà tí ó rí i, ó bí i pé, “Ìwọ gba Ọmọ-Eniyan gbọ́ bí?
Bakan naa ni wọn yoo gbe igbesẹ lori lilo agbo tabi ọna ibilẹ lati fi koju arun Coronavirus.
lẹyin ti  won pese aabo loju popo ọhun , ni gonima pasẹ
Ẹbọ olóòórùn dídùn ni, àní ẹbọ tí a fi iná sun sí OLUWA.
Oríṣun àwòrán, @police Igbe ọmọdebinrin ọhun lo pa akiyesi awọn ara adugbo to sare ls si ibi ti iṣẹlẹ naa ti n waye nibi ti wọn ti gba arakunrin naa mu bi o ti n gbiyanju ati salọ.
Daddy Freeze ni iṣẹlẹ buruku kan to dabi owo ori sisan ninu Bibeli ni eyi ti Dafidi fi pa igba eeyan to si tun ge nnkan ọmọkunrin wọn nitori o fẹ fi ọmọbinrin Ọba Sọọlu ṣe aya.
Amọ Akinrinola ṣalaye pe, gbogbo aṣọ PPE naa ko to miliọnu kan naira lọja.
Wọn gba ijọba to wa lori aleefa lasiko yii lati gbe igbesẹ to yẹ lati jẹ ki alaafia jọba kaakiri Naijiria lẹyẹ o sọka.
Bákan náà lo ni ìwádìí ti fi ìdí rẹ̀ múlẹ pé ìwọ́ yìí le dí egungun, ẹran ara, ọkan, àti oníruyuru ẹ̀yà ara.
Buhari, iye owó oṣù tí wọ́n ń san ni Saudi kọ́ ní wọ́n ń san ní Naijiria, má fi wá wé ara - Femi Falana Oríṣun àwòrán, @perlikspictures Amofin agba ati ajafẹtọ ọmọniyan, Femi Falana ti sọ fun BBC pe ominira ti Naijiria n ṣajọyọ rẹ kii ṣe ominira rara, bikoṣe omi inira.
Adesoji Aderemi: Ọba Yorùbá tó tiraka láti dí àlàfo láàrin olówó àti olòṣì
Ó si lé ni trílíọnu iru T Cell yii tó wà nínú ara.
2 48116 Orilẹede Paraguay 1914 27.
Jesu bá wí fún wọn pé, “Ẹ lọ!
Coroavirus drugs: Àwọn aláṣẹ̀ America fọ́wọ́ sí lílo òògùn Ebola fí tọ̀jú Coronavirus
Ọkunrin náà dáhùn pé, “Mo gbàgbọ́, Oluwa!
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, È gbọ òun ti ojú awọn ara ipinle Ogun rí lọwọ ìṣẹlẹ omiyale Ileeṣẹ ijọba yii ni arọọrọda ojo to n rọ ati wahala omiyale to n ṣẹlẹ ni ipinlẹ Eko lo tun jẹ ki arun naa tete tankalẹ sii.
Iwe iroyin English newspaper ni orilẹede UAE ni ọkan lara awọn ọdaran naa tilẹ ni oun ṣi le pe ẹjọ mii lori ẹjọ ni ile ẹjọ kotẹmilọrun ti idajọ ti wọn fun oun yoo si dinku si ẹwọn gbere dipo idajọ iku.
Iyaafin Jessica Ilunga, ti o je agbenusoro ajo to n mojuto eto ilera lorile-ede naa so pe, ikolu ohun tun waye ni ariwa ila oorun ilu Mbandaka, eleyi ti noosi alabere kan padanu emi re ni agbegbe ilu Bikoro.
OLUWA bá mú kí Adadi dojú ọ̀tá kọ Solomoni; Adadi yìí jẹ́ ìran ọba ní ilẹ̀ àwọn ará Edomu.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù 'Awọn agbabọọlu Super Eagles kan n gba‘bọde fun Naijiria' Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ 'Awọn agbabọọlu Super Eagles kan n gba‘bọde fun Naijiria' 23 Ẹrẹ̀nà 2018 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 31 Ẹrẹ̀nà 2018 Alakoso ikọ agbabọọlu Super Eagles tẹlẹ ri, Adegboyega Onigbinde, sọ wipe ifura pe awọn agbabọọlu kan n gbabọde fun Naijiria lo faa, ti oun fi fun Vincent Enyeama ni anfaani ati mu ile fun Naijiria ninu idije ife ẹyẹ agbaye ti ọdun 2002.
Gbogbo awọn oniṣowo yii atawọn mii ni ko ba ti maa wọ́'wó to ba ṣe pe ipade adura naa waye lojukoroju lonii ṣugbọn ori amohunmaworan ijọ naa ati lori ayelujara nikan lo ti n waye.
Ẹgbẹ agbabọọlu kankan ko ti i bori Madagascar lati igba ti Afcon 2019 ti bẹrẹ.
Dakarta ni koda ki aarẹ gba iṣẹ lọwọ gbogbo awọn olori ologun Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí 3:46 Fídíò, Gender Based Violence: Àjàkálẹ̀ àrùn míì ní ìfìpábánilòpọ̀ níbí pẹ̀lú adúrú obìnrin tí wọ́n ṣeé sí, Duration 3,4629 Bélú 2020 Omo Ghetto: Funke Akindele ṣàlàyé bí àwọn agbébọn ṣe kọlù wọn làsíkò tí wọ́n ń ya fíìmù29 Bélú 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Adajọ Ibrahim Galadima gbe igbeṣẹ naa lẹyin ti Ajọ Peace and Unity Ambassadors Association pe fun ki ẹgbẹ NLC jawọ ninu iyanṣẹlodi ti wọn fẹ gunle ni ọjọ Aje.
 itàn sọ fún wa pé alákùnrẹ ́ fi tọ ̀ wọ ̀ tọ ̀ wọ ̀ kúrò fún Àjàpadá aṣọdẹbóyèdé .
Lọjọ kinni oṣu keje ọdun 2020 ni gomina Delta fi si oju opo Twitter rẹ pe Èmi àti ìyàwó mi ti lùgbàdì àrùn CoronaVirus.
Awọn ipinlẹ to ku ni: Oyo-15 Rivers-11 Bauchi-7 Kwara-2 Bayelsa-1 Edo-1 Plateau-1 Èèyàn 94 míràn ló ni coronavirus ní Nàìjíríà ní 09/11/2020 Bayii ni esi ayẹwo coronavirus ti ajọ NCDC gbe sita lọjọ Aje, ọjọ kẹsan-an, oṣu Kọkanla, ṣe lọ.
Baba to bi Awolowo jẹ agbẹ, sugbọn o doloogbe nigba ti Awolowo wa ni ọmọ ọdun mẹwaa pere.
Oríṣun àwòrán, @NGRSenate Àkọlé àwòrán, Awọn ti wọn fẹ fi se owo koto maa n mulẹ ki wọn to kuro lorilẹede Naijiria O ni orilẹede Naijiria lo tun se ipo karun un laarin awọn orilẹede Afirika to n gba oju oku mẹditarenia lọ si ilẹ Yuroopu.
Nígbà tí wọ́n bá dé ibẹ̀, wọn óo ṣa gbogbo ohun ẹ̀gbin ati ìríra rẹ̀ kúrò ninu rẹ̀.
Nítorí Ìwé Mímọ́ sọ pé, “Ó ti fi gbogbo nǹkan sí ìkáwọ́ rẹ̀.
bí ẹnìkan bá gbọ́ ìró fèrè náà, ṣugbọn tí kò bá bìkítà fún ogun àgbọ́-tẹ́lẹ̀ yìí, bí ogun bá pa á orí ara rẹ̀ ni ẹ̀jẹ̀ rẹ̀ yóo wà.
tí o kò bá yipada ninu àwọn òfin tí mo ṣe fún ọ lónìí, tí o kò sì sá tọ àwọn oriṣa lọ, láti máa bọ wọ́n.
Jonathan  naa bu enu ate lu iwa ti awon oloselu maa  n hu lati fowo ra ibo, o ni iru wa bayii lodi si eto ijoba tiwa –n-tiwa.
Eliṣa wí fún un pé, “Lọ ta àwọn òróró náà kí o sì san gbèsè rẹ ninu rẹ̀, kí ìwọ ati àwọn ọmọ rẹ máa ná ìyókù.
A ba tún ń lọ, kò pẹ́ púpọ̀ a dé ilé mìíràn a rí obìnrin arẹwà kan tí ó dára púpọ̀ a sì rí ọkùnrin kan tí ó dúró titi, bí a ti dé ibẹ̀ Èṣù dáhùn ó ni, ‘Ṣiṣẹ́ rẹ ki n rí ọ’ bi o ti wi báyìí, ṣe ni a rí obìnrin náà tí ó rẹ́rìn-ín sí ọkùnrin náà tí ó dúró, ó ni, ko sí ọkùnrin náà láyé tí ó dára tó ọ, kò sì sí ẹni náà tí mo fẹ́ràn tó ọ lóde ayé títí dé ara ìyá àti bàbá mi, fi ẹnu kò mi lẹ́nu, olùfẹ́ mi ọ̀wọ́n jùlọ.
Ati pé nígbà tí wọn bá ń tọ ojúlé kiri, wọ́n ń kọ́ láti ṣe ìmẹ́lẹ́.
apapo  (FEC) yoo maa se isin idagbere lọjọRu
Ìwúkàrà díẹ̀ níí mú kí gbogbo ìyẹ̀fun wú sókè.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ekiti Election: Kọmísánà fétò ìdìbò ní jàǹdùkú já àpótí gbà ní wọ́ọ́dù mẹ́fà Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Ekiti Election: Kọmísánà fétò ìdìbò ní jàǹdùkú já àpótí gbà ní wọ́ọ́dù mẹ́fà 14 Agẹmo 2018 Kọmísánà fétò ìdìbò nípìnlẹ̀ Èkìtì, Ọ̀jọgbọ́n Abdulganiyu Raji, lásìkò tó ń bá BBC Yorùbá sọ̀rọ̀, ti se káre sétò ìdìbò tó wáyé ní ìpínlẹ̀ Èkìtì ní ọjọ́ àbámẹ́ta.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Babatunde Olatunji ati Malcolm X ni Nigeria ni 1960 Bawo lo ṣe bẹrẹ?
Ẹni ọdun mẹrinlelọgọta ni Sẹnẹto Osinowo ki ọlọjọ to de.
Gbọ́ ohun tí OLUWA, Olùràpadà rẹ wí,ẹni tí ó ṣẹ̀dá rẹ láti inú oyún.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Àwọn ọ̀dọ́ kojú ààrẹ́ Buhari 20 Ìgbé 2018 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Àwọn ọ̀dọ́ kojú ààrẹ́ Buhari Ariwo awuyewuye to n lọ kaakiri ori ẹrọ ayelujara bayii nipa ọrọ kan ti wọn ni Aarẹ Buhari sọ ni ilu London pe awọn ọdọ orilẹede Naijiria ko kawe wọn o si fẹ iṣẹ ṣe ko tii jẹ rodo lọ mumi o.
Ṣí ìlẹ̀kùn òdodo fún mi,kí n lè gba ibẹ̀ wọlé,kí n sì máa dúpẹ́ lọ́wọ́ OLUWA.
ìwọ̀n ojúlówó wúrà fún àwọn àmúga tí a fi ń mú ẹran, àwọn agbada, àwọn ife, àwọn abọ́ wúrà ati ti ìwọ̀n abọ́ fadaka kọ̀ọ̀kan, 
Oluwo ni Olodumare lo ni aafin, ki ṣe awọn oriṣa nitori naa eeyan ko le sin ọlọrun pẹlu mamoni.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù USOpen: Tání Naomi Osaka to gbewúro sójú Serena Williams?
56 Àti pé òun ni yíò darí àwọn ìpàdé bí alàgbà tàbí àlùfáà kankan kò bá sí níbẹ̀—
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù 2019 Elections: Ṣé òṣì n pọ̀ si tàbí o n dínkù láwùjọ?
Sìgá mímu ń di èèwọ̀ oògùn ìlera pípé lagbaye Egbẹrun owo dọla kan lori nọmba kọọkan ti MTN ko forukọ wọn silẹ ni ajọ NCC kọkọ sọ pe ki wọn san gẹgẹ bii owo itanran.
BBC Yoruba ti mu ọrọ wa latẹnu awọn agbabọọlu gangan funra wọn bẹẹ si ni awọn alatilẹyin ikọ Super Eagles atawọn ọmọ Naijiria to wa lorilẹede Egypt naa ti n sọ ero wọn.
Awa kii ṣe ẹgbẹ oṣelu kankan Nitootọ ni wọn ti sọ ado oloro to pọ si Mogadishu lati ọwọ awọn Al-Shabab ti wọn jẹ ọmọ ogun ọlọtẹ.
Ẹni to ba ni aisan Iba, Dengue ati Zika ko gbọdọ fi ẹjẹ silẹ.
 O dun wa pe a gbo pe Gilbert ku lasiko yii.
Nígbà tí wọ́n gbọ́, wọ́n bẹ̀rẹ̀ sí lọ lọ́kọ̀ọ̀kan, àwọn àgbààgbà ni wọ́n kọ́ lọ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Yoruba Culture: àṣà ìkínni ṣe pàtàkì nílẹ̀ Oodua Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Yoruba Culture: àṣà ìkínni ṣe pàtàkì nílẹ̀ Oodua 24 Agẹmo 2019 Ayọ abara tíntín ni Yoruba ka ọmọ tuntun sí.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ilé ńlá àràmàndà tó di ọgbà ẹ̀wọ́n 25 Sẹ́rẹ́ 2019 Oríṣun àwòrán, ARCHIVO FOTOGRAFÍA URBANA / PROYECTO HELICOIDE Àkọlé àwòrán, Caracas, Venezuela Ni aarin gbungbun olu ilu orilẹede Venezuela, Caracas ni ile aramanda yii wa.
 wọ ́ n máa ń bọ odò , ayélála , arẹdẹ-lẹ ́ rọ ̀ n bẹ ́ ẹ ̀ bẹ ́ ẹ ̀ lọ .
" Ẹgbẹ́ àwọn agbẹjọro kan ti kede pe wọn ti gba beeli awọn ọdọmọkunrin naa.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Wo àwọn nǹkan mẹ́rin tó yẹ kó wà nínú báàgì rẹ lásìkò Covid-19 yìí Bishop Oyedepo: Ìlẹ̀ Amẹrika ní ìròyìn òfegè ní pé àwọn fi físà dun Bísọ̀bù Oyedepo Oríṣun àwòrán, Twitter/US Mission Nigeria Irọ lasan ni, iroyin ofege lawọn eeyan kan n gbe kaakiri.
Femi Adebayo, Bimbo Akinsanya sọ ìdí tí wọ́n ṣe fi ìgbéyàwó wọn àkọ́kọ́ sílẹ̀ kó tó bọ́ sórí Ìdí tí Ààrẹ Trump fi dínà mọ́ Nàìjíríà àtí orílẹ̀èdè márùn ún míì láti má wọ Amẹ́ríkà Láé láé, ìjọba Buhari kò tẹ ojú ẹ̀tọ́ ará ìlú mọ́lẹ̀ - Lai Mohammed Òfin lè má mọ ògùn ṣùgbọ́n èmí gbàgbọ́ pé ǹkan wà nídìí bí wọ́n ṣe pa ọmọ mi - Baba Favour O fihan gbangba pe idunu Yemi Solade ko ṣee fi mọra tori ọjọ ibi rẹ.
Kí ni anfaani turari,tí wọn mú wá fún mi láti Ṣeba,tabi ti ọ̀pá turari olóòórùn dídùn tí ó ti ilẹ̀ òkèèrè wá?
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Sunday Shodipe: Iléèṣẹ́ ọlọ́pàá ìpínlẹ̀ Oyo ṣe àfihàn afurásí tó n pààyàn ní Akinyele 23 Ògún 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 26 Ògún 2020 Ileeṣẹ ọlọpaa ipinlẹ Ọyọ ti ṣe afihan Sunday Shodipẹ, afurasi ọdaran ti wọn fi ẹsun kan wi pe o n da ẹmi awọn eeyan legbodo ni ijọba Ibilẹ Akinyẹle.
Àwọn ìṣẹ̀lẹ̀ mánigbàgbé tó wáyé nínú oṣù Kẹ́wàá ọdún 2020 Àwọn ọmọ Nàìjíríà yarí lórí èròngbà ilé aṣòfin pé kí àjọ FRSC má a lo nkan ìjagun Ko awọn ohun idabobo mọ ẹru rẹ: Lasiko to ba n rin irinajo ri daju pe o mu awon eelo idaabobo ara ẹni lọwọ arun Coronavirus, bi ibomu lasiko to ba wa ni gbangba, oogun apakokoro ati ofin ijinasiraẹni ni iwọn mita meji.
Ṣé ẹ mọ̀ pé Ẹ̀wà Sóyà, Ẹja Puffer, àti ewébẹ̀ yìí lè ṣekú pa'ni kíákíá?
Yahaya Bello lẹ́ẹ̀kan síi ni APC ṣe ní ìdìbò abẹ́lé ní Kogi 'Òṣòkòmọlẹ̀' ní ẹjọ́ láti jẹ́ lórí owó Káńsù l'Ekiti Japan ṣèrànwọ́ N149m fún Nàìjíríà lórí ètò ààbò!
 Awon eniyan wa n ku lataari epo robi ati afefe gaasi to n ya ti awon kan si n ji laisi ere fawon eniyan agbegbe naa.
 O ni awọn ti tẹwọ gba isunsiwaju idibo naa latọwọ ajs INEC nitori ọdọ ajọ INEC ni ofin fi si lori irufẹ iṣẹlẹ ba waye."
Owoseni sọ pe ileeṣe ọlọpaa yoo fi awọn afurasi naa lede laipẹ.
se idanwo naa ni orile ede  Ghana, United
1 - Ṣe àyẹ̀wò orísun ìròyìn nàá Nkan àkọ́kọ́ tó sẹ pàtàkì ni láti yẹ orísun tí ìròyìn nàá ti wá wò, láti mọ̀ bóyá èyí tó ṣe é f'ọkàn tán ni.
Bakan naa ni awọn ilu to wa lagbeegbe Puri ati agbeegbe miran n ri atẹkun lile to to iwọn 175 km/h (108mph) ati 200 km/h.
"Ilé ìwé gíga fásitì OAU ní ààbò àṣírí wà fún akẹ́kọ̀ọ́ yóówù tó bá ta àwọn aláṣẹ fásitì náà lólobó ìwà ìbàjẹ́ lọ́gbà fásitì náà.
Ẹ dúpẹ́ lọ́wọ́ OLUWA, nítorí pé ó ṣeunnítorí ìfẹ́ rẹ̀ tí kì í yẹ̀ wà títí lae.
Angẹli OLUWA bá dáhùn pé, “OLUWA àwọn ọmọ ogun, yóo ti pẹ́ tó kí o tó yọ́nú sí Jerusalẹmu ati àwọn ìlú Juda, tí o tí ń bínú sí láti aadọrin ọdún sẹ́yìn?
N óo sì mú gbogbo ìbàjẹ́ rẹ kúrò.
OLUWA Ọlọrun ní, “Ó tó gẹ́ẹ́, ẹ̀yin ọba Israẹli, ẹ má hùwà ipá ati ìninilára mọ́, ẹ máa hùwà ẹ̀tọ́ ati òdodo, ẹ má lé àwọn eniyan mi jáde mọ́.
Ohun kan ti awọn adajọ naa tun sọ ni pe awọn obinrin maa n lo ofin naa lati mọọmọ f'iya jẹ ọkunrin tabi gbẹsan ti irinajo ifẹ ba daru laarin a Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Wọ́n ń wí pé, ‘OLUWA kò rí wa, ó ti kọ ilẹ̀ wa sílẹ̀.
15, nigba ti ile-ise NASCON naa gbe peeli N1.
Rev Fr Ejike Mbaka: Ìfọ̀rọ̀wánilẹ́nuwò ní BBC bá dé ọ̀dọ̀ òjíṣẹ́ Ọlọ́run, ìyà ló fi pàdé wọn
” Ẹ̀wẹ̀ Yemi-Ẹsan ṣàpèjúwe àwọn ǹkan wọ̀nyí gẹ́gẹ́ bíi ǹkan to burú jáì lẹ́nu iṣẹ́ ìjọba tó sì pè fún yíyọ eni ti aje ọ̀rọ̀ náà bá sí mọ́ lórí ní ṣẹ́ gẹ́gẹ́ bí òfin iṣẹ́ ìjọba ṣe gbe kalẹ.
Jẹ́ kí igbọnwọ kọ̀ọ̀kan tí ó kù ní ẹ̀gbẹ́ kinni keji àránpọ̀ aṣọ náà ṣẹ́ bo ẹ̀gbẹ́ kinni keji àgọ́ náà.
Irinajo Eritrea lo maa je akoko iru re , leyin ogun to sele lọdun 1998.
OLUWA wí fun mi pé, “Sọ fún wọn pé,‘Kí omijé máa ṣàn lójú mi tọ̀sán-tòru,kí ó má dáwọ́ dúró,nítorí ọgbẹ́ ńlá tí a fi tagbára tagbára ṣá eniyan mi.
Ó mú kí gbogbo eṣinṣin náà kúrò láìku ẹyọ kan.
''Ẹka wa yatọ nitori awọn oṣiṣẹ wa a maa wa lori omi fun ọjọ to pẹ, ti wọn a si maa san awọn owo ajẹmọnu kan fun wọn.
Oriṣiriṣi ewé ló wà ni ilẹ̀ Yorùbá ti wọn fi má ńpọ́n oúnjẹ bi: ẹ̀kọ, ọ̀ọ̀lẹ̀/mọ́in-mọ́in, irẹsi sisè (ọ̀fadà), obì àti bẹ̃bẹ lọ.
Ìgbàtí tí wọ́n yọọ́ jáde lówá dàbí ẹni pé ṣe ni wọ́n gbe jáde nínú omi gbígbóná.
Jesu wí fún wọn pé, “Ohùn yìí kò wá nítorí tèmi bí kò ṣe nítorí tiyín.
O ni nitori eyi, oun a si tun maa fun wọn lowo nigbakigba toun ba kọja.
Àkọlé àwòrán, Gbongan Theophilus ni UCH kun fọfọ lataari ohun to n kọ awọn eeyan lominu Awọn gomina ipinlẹ guusu iwọ oorun Naijiria ti ri ọrọ awọn ọdaran Fulani darandaran pe o gba ajọrọ gbogbo ile ni.
Oṣu kejila, ọdun 2017 lo jade ṣugbọn ọdun 2018 ni fidio ẹ jade sita.
N óo kọ́ ọ, n óo sì tọ́ ọ sí ọ̀nà tí o óo rìn;n óo máa gbà ọ́ ní ìmọ̀ràn;n óo sì máa mójútó ọ.
Sanusi Adebisi Idikan rèé, olówó tó ń san owó orí fún gbogbo ọkunrin ilẹ̀ Ibadan Lẹ́yìn ọdún méjìlá, mo gun òkè fún ọjọ́ márùn-ún kí ń tó rí ìyá mi"" Ṣé ìwọ leè wa kẹ̀kẹ́ lórí ìgò?"
Ṣugbọn nígbà tí ó bá ṣetán ati sáré,a máa fi ẹṣin ati ẹni tí ó gùn ún ṣe yẹ̀yẹ́.
8 1396 Orilẹede Sao Tomẹ́ and Principe 17 8.
Obasanjo: Buhari ní àìlera lẹ́mìí, lára, àti lọ́kàn Ninu ifọrọwerọ BBC News pẹlu aarẹ Naijiria nigbakan ri, Oloye Oluṣẹgun Ọbasanjọ, ẹ ri bi o ṣe lọ kaakiri agbaye.
Muhammadu Buhari ti gbosuba o kaare fun ikọ agbabọọlu orile ede Naijiria, Super Eagles fun jijawe olubori ninu ipele
Ọjọ Iṣẹgun ni awọn olori ẹgbẹ oṣiṣẹ kede ninu atẹjadẹ kan ki awọn osisẹ yan isẹlodi lataari bi ijọba ti ṣe kuna lati san owó oṣù to le ni osu mẹrinlelọgbọn ati owo oṣu awọn oṣisẹ fẹyinti nipinle naa.
" Onímọ̀ nípa ẹṣin Islam náà tún rawọ ẹbẹ ṣi ìjọba pé kò pèsè gbogbo nkan ti àwọn ọlọ́pàá bá nílò, to si tún rọ gbogbo abiyamọ láti máa gbe ọmọ wọn pamọ fún ààbò tó péye.
Oríṣun àwòrán, Twitter/@Julisco O ni aarẹ ti sọ fun minisita ọrọ ilẹ okere, Geoffrey Onyeama pe ko ranṣẹ pe aṣoju orilẹede South Africa ni Naijiria pe ko wa sọ tẹnu rẹ, bi o tilẹ jẹ pe aṣoju South Africa oun ti sọ pe ohun to n ṣẹlẹ kii ṣe ikoriira awọn ọmọ Naijiria.
Minisita to n ri si eto ibanisoro lorile-ede Naijiria, Dokita Adebayo Shittu ti sefilole awon omo egbe merindinlogoji sinu awon ile-ise ijoba ti o wa labe ajo to n ri si eto ibanisoro lorile-ede Naijiria Nigerian Ministry of Communications.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fọ́nrán ohùn, Joe Igbokwe kò yẹ́ fún ipò ti wọ́n fún nípìnlẹ̀ Eko - Babatunde Gbadamosi Ni ipari ọgbẹni Abayọmi parọwa fawọn arinrinajo ati awakọ lati ṣe pẹlẹ loju opopona nitori pe ẹmi ko laarọ.
Ti Ẹkùn nikan ló yàtọ̀, nitori Ọlọrun fún ni ẹ̀bùn igbóyà, idi niyi ti a fi ńpè ni “Baba Ẹranko”, ti a ńpè Kìnìún ni “Ọlọ́là Ijù”.
Lasiko ti wọn n ba BBC Yoruba sọrọ, awọn olugbe inu ile naa rawọ ẹbẹ si awọn ẹlẹyinju aanu ọmọ ilẹ yii lati se iranwọ fun wọn, lori awọn dukia wọn to jona mọle.
Ògiri kan wà níwájú àwọn yàrá ẹ̀gbẹ́ náà, ó ga ní igbọnwọ kan ní ẹ̀gbẹ́ kinni keji.
 idurole alanidekun awujo ati arewaju egbe na je gbigba bi arin-owo-osi ninu ibu oselu amerika .
Wọn yóo jóná bí igbó ẹlẹ́gùn-ún tí ó dí,àní bíi koríko gbígbẹ.
Pataki ninu eto ọdun yii ni arugba, iyẹn wundia ti ifa ba yan laarin awọn ọmọ ọba lati ru igba etutu ọdun eyi ti yoo gbe lọ si idi odo tilutifọn.
Sááju àsìkò yìí ni ìròyìn ti kan pé Kasamu wá ni ẹsẹ̀ kan ayé, ẹsẹ̀ kan ọrún nítori àwọn ààrùn míràn ti Coronavirus bá lára rẹ̀.
edo fooro ati kidirin awon eniyan lorile ede Niajiria.
Oun lo rọpo Quique Setien ti wọn ṣẹṣẹ fọwọ osi juwe ile fun un ni kopẹ kopẹ.
#Russia 2018: Belgium kojú France n'ìpele ''semi finals''
Títí lae ni ó ń ranti majẹmu rẹ̀,ó ranti àṣẹ tí ó pa fún ẹgbẹẹgbẹrun ìran,
OLUWA sọ fún Mose pé, “Kí olukuluku olórí mú ọrẹ ẹbọ tirẹ̀ fún ìyàsímímọ́ pẹpẹ wá ní ọjọ́ tirẹ̀.
Ikọ Alaabo yii dipo ki wọn maa ri iṣẹ pe ki I ṣe deedee.
Ọgagun Adeyinka Adebayo sì ni wọn yàn pé ko gba ipò Fajuyi, tó sì gbé ẹsẹ kúrò lórí òfin tó yọ ọba Olateru-Olagbegi kejì lórí ìtẹ́, àmọ́ eto ààbò ìlú Ọwọ kò tíì fararọ nígbà náà, eyi to mu kí ojú ọjọ́ má dáa fún ọba Olagbegi láti padà sí ààfin rẹ n'ilu Ọwọ.
 Lara awon gomina to wa nibi
Ẹ̀yin ọmọ Jakọbu, ẹ óo pada máa gbé ní ìrọ̀rùn.
Arọ náà bá dìde, ó lọ sí ilé rẹ̀.
Ise akanse ipese damu omi naa wa lara ise akanse ti ijọba apapo ti se ifilole re, ti won si tun n gbero lati se awon ise akansesi miiran si awon ijọba ibilẹ kookan jake-jado orile-ede yii lojuna lati koju idojuko omiyale ati bi omiyale se n ba awon ayika wa gbogbo je.
Kaakiri agbaye ni iroyin kan nipa iṣẹlẹ yii, ti awọn eeyan si ti n bu ẹnu atẹ lu arakunrin to wu iwa laabi yi.
Obìrin kò pọ̀ nínú iṣẹ́ ọkọ̀ òfuurufú, bẹ́ẹ̀ ni ó sì ṣe rí káríayé.
won n gbe lati bi odun mejidinlogbon ti won ti wa niluu Abuja, Federal Capital Territory.
Nígbà náà ni mo dá ọ̀pá mi keji tí ń jẹ́ “Ìṣọ̀kan,” mo fi fi òpin sí àjọṣe tí ó wà láàrin Juda ati Israẹli.
Mose fi pẹ̀lẹ́pẹ̀lẹ́ wádìí nípa ewúrẹ́ tí wọ́n fi rú ẹbọ ìmúkúrò ẹ̀ṣẹ̀, ó sì rí i pé wọ́n ti dáná sun ún.
Wọ́n kó fadaka ati wúrà ati aṣọ tí wọ́n rí níbẹ̀, wọ́n lọ kó wọn pamọ́.
40 dola , amosa orile ede Naijiria ta agba epo robi tire naa  ni 74.
Abajade ipinlẹ kọọkan ninu esi tuntun naa re e: Eko-230 Oyo-69 FCT-51 Edo-43 Osun-35 Rivers-30 Ebonyi-30 Kaduna-28 Ogun-27 Ondo-23 Plateau-20 Benue-17 Enugu-16 Imo-10 Delta-6 Kano-4 Nasarawa-2 Kebbi-1 Ekiti-1 Àpapọ̀ àwọn tuntun to ṣẹṣẹ lugbadi ààrùn Coronavirus ní Nàìjíríà jẹ 463 ní 14/07/2020 Ninu ikede ti Ajọ NCDC fi sita ni Ọjọ Ìṣẹgun lo ti fojuhan pe , awọn to ti ni aarun naa ti pe 33,616 bayii.
Nkan tí a mọ̀ nìyíì Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ọgbà ẹ̀wọ̀n ni wọ́n ti já àbálé Esra lábẹ́ àwáwí àyẹ̀wò wúndíá Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Anthony Joshua vs Pulev highlights: Ẹ̀bùn ọdún Kérésìmesì ni àseyọrí Joshua lẹ́yìn tó na Pulev lálùbolẹ̀ - Dapo Abiodun14 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Victoria Kolawole: Òṣèré tíátà Yorùbá ní òun kò tíì ṣe ìgbéyáwó àmọ́ òun kò wá ọkọ''9 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 World Aniti-Corruption day: Awolowo, Azikwe, Abacha àtàwọn olórí ìjọba tí aje ìwà ìjẹkújẹ ti ṣí mọ́ lórí rí ní Nàìjíríà14 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Ronke Odusanya sọ̀rọ̀ lórí ìròyìn tó ní ó ti jẹ bàbá ọmọ rẹ̀, Jago run9 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ṣé lóòtọ́ ni Lateef Adedimeji àti Adebimpe Oyebade ṣe ìgbéyàwó?
13  ninu osu kinni odun 2018.
Lilo aiyelujara 5G yi yoo yara gaan lawọn ibi ti wọn ba ti n lo wọn.
Sibẹ Ọlọrun wá ẹ̀sùn sí ọ lẹ́sẹ̀,ó sọ ọ́ di ọ̀tá rẹ̀,
O ni iyalẹnu lo jẹ f'oun pe ile iṣẹ ọlọpaa le sọ pe ile iṣẹ ologun n huwa ta ni yoo mu mi.
Adeọsun kọwe f'ipo silẹ lọjọ kẹrinla, oṣu kẹsan an, ọdun 2018 lori ẹsun pe o lo ayederu iwe-ẹri agunbanirọ.
Ìwà tí ẹ̀gbọ́n rẹ hù ni ìwọ náà ń hù, nítorí náà, ìyà tí mo fi jẹ ẹ̀gbọ́n rẹ ni n óo fi jẹ ìwọ náà.
Ọkùnrin kan pa ara rẹ̀ sínú ọgbà àjọ TRACE tó n mójútọ ìrìnnà ọkọ̀ nípìnlẹ̀ Ogun Omotara pàdánù isẹ́ olówó ńlá nítorí ó fi ọtí ẹlẹ́rìndòdò sódà lá ọmọ alágbe lójú Eyi lo mu ki awọn ọlọpaa ọtẹlẹmuyẹ lọ si ibẹ, ti wọn si ba awọn ẹya ara eeyan to ti gbẹ ninu apo naa.
Lẹyin ti BBC gbe fiimu ọhun jade ni Fasiti naa ni ki Igbeneghu lọ rọkun nile fun igba diẹ, latari ọpọlọpọ awuyewuye to tẹle fiimu naa.
Kí ló dé tí o fi gbàgbé wa patapata?
 ní ọjọ ́ kan , wọ ́ n dá ìmọ ̀ ràn láàrin ara wọn pé ó yẹ kí wọ ́ n dá ibìkan sílẹ ̀ tí àwọn yóò fi ṣe ìbùgbé lẹ ́ yìn tí wọ ́ n bá ṣe ọdẹ lọ .
”Ó dáhùn, ó ní, “Èmi nìyí.
Ayeye ayajo odun tuntun orile-ede China, eyi ti won mo si Spring Festival, ni o maa n waye ni ojo ketalelogun si ojo kejila osu lunar ninu kalenda orile-ede China.
“Dájúdájú, n óo kó gbogbo yín jọ, ẹ̀yin ọmọ Jakọbu, n óo kó àwọn ọmọ Israẹli yòókù jọ: n óo kó wọn pọ̀ bí aguntan, sinu agbo, àní bí agbo ẹran ninu pápá, ariwo yóo sì pọ̀ ninu agbo náà, nítorí ọ̀pọ̀ eniyan.
Alufaa kọ̀ọ̀kan ni yóo máa tọ́jú owó tí wọ́n bá mú wá sí ọ̀dọ̀ rẹ̀, yóo sì lo owó náà láti máa tún ilé OLUWA ṣe bí ó ti fẹ́.
7 4,498 Sao Tome and Principe 17 8.
Ni ọjọ Satide loun pẹlu jade laye lẹni ọdun mẹtadinlaadọrin.
Àwọn ògo Ibadan márùn ún tí ikú mú lọ lọ́dún 2020 Sanusi Adebisi Idikan rèé, olówó tó ń san owó orí fún gbogbo ọkunrin ilẹ̀ Ibadan Àwọn aláṣẹ kéde ìséde lọ́gbà fásitì Ibadan Kínla!
Àwọn Dókítà Nàìjíríà bẹ̀rẹ̀ ìyànṣẹlódí lẹ́yìn tí ìjọba àpapọ̀ yẹ àdéhùn rẹ̀ pẹ̀lú wọn Oríṣun àwòrán, others Ẹgbẹ awọn dokita ni Naijiria ti bẹrẹ iyanṣẹlodi loni ọjọ aje.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Widows Day 2019: Mo máa ń sá kiri wá owó ilé ni -Opó Kii ṣe ẹni to kọla tẹlẹ, lataari eyi lawọn ara Ibadan bu ila si oju rẹ ki wọn to tu u silẹ.
Nítorí èmi ni Ọlọrun,kò tún sí ẹlòmíràn mọ́.
Ọ̀pọ́ jàǹdùkú l‘Ọṣun bọ́ sí gbaga ọlọ́pàá lórí ìwà ọ̀daràn FRSC: Èèyàn mẹ́jọ ló kù nínú ìjàmbá ọkọ̀ nípìnlẹ̀ Ògùn 'Inú wa dùn pé wọ́n mú àwọn oniṣẹ́ ibi náà' O ni mẹnuba bi oun ṣe fẹ ko sọwọ oniṣekuṣe nigba kan.
Awọn naa n sọ pe opin gbọdọ de ba ijọba buruku lorilẹede Naijiria gẹgẹ bi awọn oluwọde mii ṣe n sọ.
Mubaraq dáhùn ìbéèré yìí Akure Ọ̀rẹ́ mi tímọ́tímọ́ tí a jọ ń ja ogun Biafra ní kí n yìnbọn pa òun- Gabriel Aladejebi Irọ̀ ni ìjọba ń pa, Ikọ Amọtẹkun ba ofin Naijiria mu- Ìgbìmọ̀ Yoruba Ọ̀rọ̀ di kọ̀!
Yakubu ni awọn ọlọpaa kọkọ fiya jẹ oun ki wọn to mu oun lọ.
idagbasoke ba orile ede Naijiria, bo tile je pe ko rọrun rara.
Wọ́n rí i kà ninu òfin tí OLUWA fún Mose pé kí àwọn ọmọ Israẹli máa gbé inú àgọ́ ní àkókò àjọ̀dún oṣù keje, 
Olori ile asoju-sofin tun fọwọ gbaya pe atunse ofin ilẹ wa yoo waye, eyi ti yoo mu ko dangajia lati fidi ẹtọ ọmọniyan mulẹ.
Pàápàá tí ó jẹ́ pé èmi ati àwọn arakunrin mi ati àwọn iranṣẹ mi ni à ń yá wọn ní owó ati oúnjẹ.
Awon omo egbe naa wa seleri
Odun Fatchue"" ni ọdun ti awọn ọmọde fi n palẹmọ de ipo adari lọjọ iwaju."
Adekunle Gold: Ọdún márùn ún ni mo fi mọ Simi ká tó ṣègbéyàwó
Ẹni ọdun mọkanlelogun ni Grace Oshiagwu nigba ti wọn pa lẹyin ti wọn fi tipa ba a lopọ ninu ile baba rẹ Agbegbe Akinyele nilu Ibadan ni wọn tun ti gba ẹmi Grace, níbi ti wọn ti pa Barakat ati Azeezat bakan naa Akẹkọọ ọlọdun kinni ni ẹka imọ nipa akoso oko-owo, Business Administration, nile ẹkọ gbogbonse Poly Oke Ogun si nii ṣe, to si jẹ ọmọ bibi ilu Oguta nipinlẹ Delta Awọn ọlọpaa ko tii ri afurasi kankan mu nipa ẹni to pa Grace Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Omi pọ ju ọka lọ ṣugbọn.
Ninu ifọrọwerọ pẹlu awọn akọroyin awọn Iya arugbọ naa parọwa si Gomina ipinlẹ Kwara lati ma ṣe wo ile to wa lori ilẹ naa nitori pe ibẹ lawọn ti n ri jijẹ mimu.
"Ọ̀gá àgbà fún àjọ náà ní ìpínlẹ̀ Eko Hyginus Omeje sọ fún BBC pé àwọn yóò bẹ̀rẹ̀ ètò ààbò tuntun, ti wọn pè ni operation ""Show your Driver's license"" ní ìpínlẹ̀ Eko ti yóò sì bẹ̀rẹ̀ ni ọjọ ajé to n bọ, ogúnjọ́ oṣù kaarun."
“Kí ló dé tí a fi ìmọ́lẹ̀fún ẹni tí ń kérora,tí a fi ẹ̀mí fún ẹni tí inú rẹ̀ bàjẹ́;
Ààrẹ Buhari yan Ibrahim Gambari gẹ́gẹ́ bíi olórí àwọn òṣìṣẹ́ lọ́fíìsì Ààrẹ Wo àwọn orílẹ̀-èdè márùn ún tó fún àwọn obìnrin làńfàní tuntun sí ẹ̀tọ́ wọn Ọ̀nà márún-ún láti mú àdínkù bá dátà (Data) lílò rẹ Àjọ NCDC kéde èèyàn 146 míràn tó ni ààrùn Covid-19 lórílẹ̀-èdè Naijíríà Bi ẹ ko ba si ni gbagbe iṣẹlẹ kan to ṣẹ ni agbegbe Soka ni ilu Ibadan lọdun diẹ sẹyin nibi ti wọn ni awọn agbenipapawo fi ṣe ibuba ti wọn ti n pa awọn eeyan ti wọn si n ṣe karakata ẹya ara eniyan.
Ọjọ mẹta ni aarẹ ati awọn iṣọmọgbe rẹ lo niluu New York lorilẹ-ede Amẹrika ki wọn to pada sile.
Eliṣa dáhùn, ó ní, “Ẹ bu oúnjẹ díẹ̀ wá.
Ojogbon Banji Akintoye ninu oro apileko re lo so eyi di
Ṣugbọn o dami loju pe wọn mọ pe ẹni ibi ti ko ṣee ma ni niwọn.
  Saraki  sọrọ yii lasiko to n ba awon akoroyin sọrọ lẹyin
O ménuba ajọṣepọ oun ati Baba Ajobiewe Arẹmu Ayilara, ogbontarigi akewi ti ọpọ n wari fun.
Ọrọ ba di pe ọkọ yan, iyawo naa yan, awọn mejeeji, ọna ọtọtọ ni wọn gba.
O ni eyi yoo jẹ iwuri nla fun ọpọlọpọ awọn ọmọ Naijiria yoku paapaa julọ awọn ọdọ.
Àarẹ ilẹ̀ Amẹrika wá bu ẹnu àtẹ́ lu dídáná sun ṣọ́ọ̀ṣì nílẹ̀ Nàíjírià, o sì rọ ìjọba àpapọ̀ l'áti ṣe ètò ààbò tó múnádóko fún àwọn àwùjọ tọ́rọ̀ kàn.
Osun Police: Ọlọ́pàá gba òògùn ìbílẹ̀, ìbọn, àáké àti àdá lọ́wọ́ egúngún
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Blood Donor Day: Láìsí ẹ̀jẹ̀ kò sí ẹ̀mí Títẹ fóònù máa ń dùn mọ ènìyàn gan an ni tí ọ̀pọ̀ dátà ba wà láti wo gbogbo ǹkan to n lọ lágbàyé.
O si pa aala pẹlu orilẹ-ede Niger lati Damagaram.
Ní ọjọ́ kan, Rekabu ati Baana, àwọn ọmọ Rimoni ará Beeroti, gbéra, wọ́n lọ sí ilé Iṣiboṣẹti, wọ́n débẹ̀ ní ọwọ́ ọ̀sán, ní àkókò tí Iṣiboṣẹti ń sun oorun ọ̀sán lọ́wọ́.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Lagos Chinese restaurant: Ayorinde ní Ìpínlẹ̀ Eko ń gbé ìgbésẹ̀ nípa ilé oúnjẹ elẹ́yàmẹ̀yà Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Lagos Chinese restaurant: Ayorinde ní Ìpínlẹ̀ Eko ń gbé ìgbésẹ̀ nípa ilé oúnjẹ elẹ́yàmẹ̀yà 20 Ẹrẹ̀nà 2019 Komiṣọna fun eto igbafẹ ní Ipinlẹ Eko, Steve Ayorinde, ti ni ijọba kò tíì pari iwadii rẹ lori ile ounjẹ China kan ni ipinlẹ Eko to n gbe igbesẹ ẹlẹyàmẹya ti ko jẹ ki awọn ọmọ Naijiria ra ounjẹ.
Jesu wá sọ́dọ̀ wọn, ó sọ fún wọn pé, “A ti fún mi ní gbogbo àṣẹ ní ọ̀run ati ní ayé.
Gómìnà Oyetọla tí yi ìlànà ètò ẹ̀kọ Rauf Aregbesola pada
" Gomina tẹlẹ nipinlẹ Ondo naa ni orileẹ-ede Naijiria maa mọ ipapoda Olumilua lara nitori oloselu bii tiwọn ko pọ mọ, to jẹ pe bi wọn ṣe n fi tọkan-tara sin araalu, ni wọn n sin Ọlọrun.
Mo bá gbadura pé, “Gbọ́, Ọlọrun wa, nítorí pé wọ́n kẹ́gàn wa.
Ni bayii, o le ni egberun mefa awon omo egbe oselu alatako ti won ti gba ominira lati osu kini bi ijoba se n tiraka lati foju awon eniyan mora, ni paapaa awon alatako.
 fún àpẹẹrẹ wọn a máa pa àwọn kóńsónàntì kan bíi  w ' jẹ ."
Oríṣun àwòrán, Instagram/oluwoofiwoland Bakan naa ni wọn lo sọ ọrọ abuku si Alaafin Ọyọ, Oba Lamidi Adeyemi ; Ooni Ile-Ife, Oba Adeyeye Ogunwusi ; Orangun Ila, ati awọn ọba miran nipinlẹ Osun.
– Àwọn ọmọ aráyè kì í ní ìtẹ́lọ́rùn rárá - ṣíọ́.
    Ìyàwó mi pẹ̀lú, ko yàtọ̀ sí mi jù bẹ́ẹ̀ lọ, bọ̀kìní òun ọlọ́rọ̀ ẹgbẹ́ra, ọ̀bún ùn asiwèrè ọ̀kanùn, ọ̀kańjúà òun olè, déédéé ni wọ́n já sí.
Kọ́ ọmọ rẹ lẹ́kọ̀ọ́ ìbálòpọ̀ láti kékeré- Ọ̀jọ̀gbọ́n Fagbohungbe 'Ọkọ̀ la rí, a ò tíì rí adárí Ilé iṣẹ́ pána-panà Eko àtàwọn mẹ́fà' - Ọlọ́pàá Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí kan sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
Nítorí ìfẹ́ rẹ tí kì í yẹ̀ tóbi sí mi;o ti yọ ọkàn mi kúrò ninu isà òkú.
Ewe, ireti wa tele pe ipade ohun yoo waye niluu Benin, nipinle Edo sugbon won sun sipinle Borno lati buyi fun ogoro omo ogun ti o padanu emi won soju ogun nipinle naa.
ti ṣe ileri lati gbe gbogbo inanwo eto isinku George Floyd eyi ti yoo waye lọjọ Iṣẹgun ọjọ kẹsan an oṣu kẹfa.
Oríṣun àwòrán, AFP Àkọlé àwòrán, Ó ṣeesẹ kí Gómìnà ìpínlẹ̀ Imo, Rochas Okorocha buwọ́ lùú pé kí wọ́n tú Alàgbà Egbuchune sílẹ̀.
"Emi ati iya mi ti di alainile lori bayii amọ a wa ni alaafia, a si n dupẹ lọwọ gbogbo awọn eeyan to wa ba wa kẹdun lasiko ọfọ yii.
Minisita fun eto ilẹra lorilẹ-ede Naijiria, Osagie Emmanuel to ṣe abẹwo si ile iwosan naa gboriyin fun iṣẹ ti awọn dokiat naa ṣe.
Ṣeṣibasari bá wá, ó sì fi ìpìlẹ̀ rẹ̀ lélẹ̀ ní Jerusalẹmu.
Akure shooting: Àlááfíà ti padà sí ìlú Akure, ẹnikẹ́ni kò kú
Bakan naa ni wọn ri ọkọ oju omi gba pada to si kun fun lita to le ni ẹgbẹrun mẹrin.
Nítorí gbogbo ẹ̀dá ayé ló ń fi ìwàǹwára nàgà, tí wọn ń retí àkókò tí Ọlọrun yóo fi àwọn tíí ṣe ọmọ rẹ̀ hàn.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Lọjọ Abamẹta ni Johannesburg ni awọn ti wọn n ja ti n da awọn onworan laraya.
Oloye Alabi fikun pe ipa ribiribi ni oloogbe Ajimobi ko si idagbasoke ilu Ibadan ati ipinlẹ Oyo lapapọ.
Aarẹ Buhari sọ lẹyin ti Kyari ku pe, ọpọlọpọ ọdun ni awọn ti jọ n ṣe ọrẹ, titi di akoko iku rẹ.
Ruga Settlement: Ìpínlẹ̀ Oyo àti Eko kò ní èròǹgbà láti kópa nínú ètò Ruga Settlement
Kí wa ni idí ti ènìyàn yóò fi ma kó òòrun didun si inu ounjẹ púpọ lásiko kan náà?
“Kí ó rí fún ọ̀tá mi gẹ́gẹ́ bí í ti í rí fún ẹni ibi,kí ó sì rí fún ẹni tí ó dojú kọ mí bí í ti í rí fún alaiṣododo.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ifẹ́ Yorùbá ló mú mí fi ẹ̀mí mi wéwu láti koju ajínigbé ní Kishi - Sunday Igboho €10,000, ara owó tí wọn fi ra Ighalo pòórá, Ilé aṣòfin Osun bẹ̀rẹ̀ ìwádìí Ìwádìí BBC rèé lórí ẹ̀sùn gbájuẹ̀ $120,000 tí wọ́n fí kàn igbákejì olórí òṣìṣẹ́ ìjọba l‘Osun PDP àti APC fi ìbọn dárà l'Ondo, ọ̀pọ̀ èèyan farapa, àìmọye dúkìá ṣòfò Dípò ìnákúnàá lórí ìgbéyàwó ọmọ mi, mo lò owó fún ìgbéyàwó ọmọ òrukàn mẹ́tàlá"" Àwàdà kẹríkẹrì nígbà táwọn olùdíje ààrẹ́ Amerika méjì kọjú ìjà síra wọn Ìjọba àpàpọ̀, jọ̀ọ́ máṣe yẹ̀ lórí àdéhùn rẹ fẹ́gbẹ́ òṣìṣẹ́ - Ile aṣojú-ṣòfin Ọgọ́rin arìnrìnàjò tó padà wá sí Nàìjíríà ló ní Coronavirus - PTF Bakan naa lo ṣalaye pe, biliọnu mẹta aabọ Naira ni wọn fi gbọ bukaata eto Big Brother Naija Lockdown 2020."
Ọ̀pọ̀ eniyan wá ń péjọ láti gbọ́ ọ̀rọ̀ rẹ̀ ati kí ó lè wò wọ́n sàn kúrò ninu àìlera wọn.
Ìfọ̀rọ̀wọ́rọ̀ Ààrẹ Ilham Aliyev àti amóhùnmáwòran REAL TV ní Oṣù Èrèlé 12.
Awon eso oju-omi orile-ede Greece kede pe, won gbese le oko oju omi kan ti o ni asia orile-ede Tanzania, eyi ti o ko awon ohun elo ti won fi n se ado-oloro, n lo si orile-ede Libya.
Aare Buhari wa dupe lowo Olorun fun anfaani ati tun sayeye odun ajinde miiran lagbami awon ipenija ti o n koju orile-ede naa lowo-lowo.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Transfer Window: Pogba, Maguire, Bale, Neyman, báwo ni nkan ṣe ń lọ?
nínú gbólóhùn ( 66 ) , a ò lè so pé se àti rí kò ní apor àbò nítorí ta àti kí ni ó jé àbò fún òkòòkan won , òrò-orúko sì ni ta àti kí yìí .
Gègé sì mú àwọn yòókù wọnyi tẹ̀léra wọn báyìí: 
Bi o tilẹ jẹ pe ọpọ dukia ileesẹ naa lo jona mọle amọ ko si ẹmi to bọ ninu isẹlẹ ile jijo naa, ti ijakulẹ si ba ọpọ awọn onibara ileesẹ MTN to de sẹnu ọna ileesẹ ọhun ni aarọ Ọjọru.
Ẹnìkan tí ń ṣe ìdájọ́ ẹ̀tọ́ ati òdodo yóo jókòó lórí ìtẹ́ náà,Yóo dúró lórí òtítọ́ ní ìdílé Dafidi.
Pẹlu ìbànújẹ́ ni o óo máa fi ìlara wo bí OLUWA yóo ṣe bukun Israẹli, kò sì ní sí àgbàlagbà ọkunrin ninu ìdílé rẹ mọ́ lae.
pe,  “Fonron ti o jani laya!
Muhaleem, ti itumọ rẹ jẹ olukọ, ni wọn sọ di Malam.
Bakan naa ni ẹgbẹ APC tun ni idije abẹnu fawọn oludije gomina rẹ ni ipinlẹ Ondo yoo waye ni ọjọ Aje, ogunjọ oṣu Keje ọdun 2020 yii kan náà.
Kò sì ní igi tí ó lágbára mọ́,tí a lè fi gbẹ́ ọ̀pá àṣẹ fún ọba.
“Ṣe àjàgà kan pẹlu okùn rẹ̀ kí o sì fi bọ ara rẹ lọ́rùn.
Ẹ̀yin ará mi, ìfẹ́ ọkàn mi, ati ẹ̀bẹ̀ mi sí Ọlọrun fún àwọn Juu, àwọn eniyan mi ni pé kí á gbà wọ́n là.
Gbogbo gomina ipinlẹ mẹrindinloji ni Naijria pẹlu miniita ọrọ abẹle, Ajagun Fẹhinti, Abdulraham Dambazau lo peju sibi ipade naa.
Ipo ate miiran yoo tun jade lojo keje osu kefa odun ti a wa yii.
lojo ti ajo eleto idibo naa mu, nitori pe ojuse wọn ni lati dibo fun eni ti ọkan
Wo àwọn ìpínlẹ̀ tó ti gbé ìgbìmọ̀ olùwádìí SARS kalẹ̀ fún àwọn ará ìlú: EndSARS panel update: Wo àwọn ìpínlẹ̀ tó ti gbé ìgbìmọ̀ olùwádìí SARS kalẹ̀ fún àwọn ará ìlú Lẹyin ti ijọba apapọ paṣẹ fun awọn ijọba ipinlẹ lati gbe igbimọ ti yoo bojuto ẹka SARS to tuka, pupọ ninu awọn gomina lo ti gbe igbimọ naa kalẹ lawọn ipinlẹ wọn.
”Wolii náà dáhùn pé, “OLUWA ní, àwọn iranṣẹ gomina ìpínlẹ̀ ni.
" Ni ti pe awọn eeyan naa tapa sofin to tako irinajo lati ipinlẹ kan si omiran lasiko Coronavirus yii, Oduyoye ni ofin naa yoo ṣoro lati tẹle.
 yàtọ ̀ sí èyí , yẹmí fáróunbí ṣe fíìmù kan tí ó pè ní  Ẹ ̀ bùn olúwa "" ní ọdún yìí kan náà ."
Nígbà tí àwọn olórí alufaa ati àwọn ẹ̀ṣọ́ rí i, wọ́n kígbe pé, “Kàn án mọ́ agbelebu!
Àwọn onwòye ní, inú Senato Dino kò dùn sí bí ẹgbẹ oselu APC pàápàá jùlọ Ààrẹ Buhari, kò ṣé kò ọgá ọlọ́pàá ni ijanu lórí ọrọ rẹ.
Lọpọ igba, idibo lorilẹede Ghana maa n gbona janjan ṣugbọn fun ọdun diẹ bayii, apapọ awọn ọlọpaa atawọn ologun ti n ṣiṣẹ lati ṣe aridaju alafia lorilẹede naa lasiko idibo.
Akowe agba wa so pe ijọba meteeta , iyen ijọba apapo, ijọba ipinle ati ijọba ibilẹ ni yoo jo fowosowopo lati pese owo ti won yoo maa lo lati mu idagbasoke ba eto ẹkọ lorile ede yii.
Abiola ni bi oun ṣe maa n tọju awọn araalu, owo ti oun ni ko lee gbe e tan.
Nítorí náà, ni a ṣe wí pé, ‘Ẹ jẹ́ kí á tẹ́ pẹpẹ kan,’ kì í ṣe fún ẹbọ sísun tabi ẹbọ mìíràn, 
Nítorí pé OLUWA àwọn ọmọ ogun, Ọlọrun Israẹli ní: ‘Wò ó!
Baba mímọ́, ayé kò mọ̀ ọ́, ṣugbọn èmi mọ̀ ọ́, ó ti yé àwọn wọnyi pé ìwọ ni ó rán mi níṣẹ́.
"Àkọlé àwòrán, Àwọn àlejò níbi ìdíje Ìjọba Nàìjíríà fẹ́ dín iye ọmọ tí obìnrin lè bí kù Ilé ẹjọ́ ti gba béèlì Ayọdele Fayoṣe Alága ẹgbẹ́ Àtúnbí, Ọ̀jọ̀gbọ́n Kayọde Oyediran, sọ pé ""lẹ́yìn àròjinlẹ̀ ni a rí pèé ogúnlọ́gọ́ ọmọ Yorùbá, lọ́mọdé àti lágbà lo ti kọ àṣà àti ìṣe Yorùbá sílẹ̀, tí kò sì ìwà ọmọlúàbí l'áwùjọ mọ́."
"Oríṣun àwòrán, @SPNigeria Àtẹjáde náà ni "" kò sí ohunkohun miran, to ba ti yàto si ìpàdé ẹlẹgbẹ́jẹgbẹ́ tàbi ìpáde àpérò gbogboogbo, to lee parí ǹkan to ti dàrú nínú ètò ẹgbẹ́"" ""O sàn kí Oshiomhole bìkítà fún ilana ẹgbẹ́ to wa nínú iwe ofin ẹgbẹ́, láti pe ìpade àwọn èèkàn ẹgbẹ ki wọn lee sọ̀rọ̀ lórí gbogbo kùdìẹ̀kudiẹ̀ to n ba ẹgbẹ́ APC fínra, tàbi ko gba pé òun ko kunju òṣùwọ̀n láti tukọ ẹgbẹ̀, ko sì kọ̀wé fipò sílẹ̀."
Ọga agba fun ẹgbẹ naa, Onallo Akpa lo kede bẹẹ pẹlu afikun pe ijọba ko gbọdọ yẹsẹ kuro lori ileri to se lati se ọna mọ awọn ohun abiyẹ lati oke okun.
tun wa ọkọ orile ede Najiria seyin.
"Èèyàn kan ṣi ha s'ábẹ́ ilé tó wó n'Ikoyi, Àjọ LASEMA ẹ bá wa wá ǹkan ṣe o!
 Ìlú kan rèé l'Abuja tí kò mọ̀ rárá nípa Covid-19 Ohun tí a rí nílé Ajimobi rèé lẹ́yìn ìròyìn òfégè pé ó jáde láyé Ẹ wo òtítọ́ ọ̀rọ̀ nípa bí àwọn agbébọn ṣe wó ile ní iléèṣẹ́ aṣojú Nàìjíríà ní Ghana Ize-Iyamu borí ìbò abẹ́nú fún idíje gómìnà l'Edo Nǹkan márùn ún tí awuyewuye òṣèlú ìpínlẹ̀ Edo kọ́ wa nípa òṣèlú Nàìjíríà Eniyan 161,005 lo ti ni coronavirus ni Saudi Arabia, 1,307 si ti ku."
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: 'Àwọn ṣọ́ọ́bù ń ta ìrẹsì olóró ní Akwa Ibom' 'Ayélujára la fi rí ọmọ wa tó sọnù!
Wọn gbe abọ iwadi wọn naa jade ninu iwe apilẹkọ kan ti wọn fi sọri ibaṣepọ to wa laarin asiko ti awọn eniyan n jẹun ati jẹjẹrẹ ọyan pẹ̀lú asetọ̀ fun ọkunrin.
 Ilana eto nini apo ifowopamosi kan ti dekun iwa sise owo ilu moku-moku.
Asiko yii lo maa n sami ibẹrẹ ayajọ keresi to jẹ ọjọ ibi Jesu Kristi ni America.
N kò wá láti pa wọ́n run; mo wá láti mú wọn ṣẹ ni.
Amọ, ile isẹ ọlọpaa ni Naijiria ti ni iwadii si n lọ lọwọ lori ẹsun ifipabanilopọ naa, pe awọn ko i tii pari isẹ lori rẹ.
Òṣì ati àbùkù ni yóo bá ẹni tí ó kọ ìmọ̀ràn,ṣugbọn ẹni tó bá gba ìbáwí yóo gba iyì.
Iroyin ni ọpọ awọn ọmọ orilẹ-ede ọhun lo jade lati kopa ninu idibo naa.
Ẹ máa kọrin; ẹ máa fi ìyìn fún Oluwa ninu ọ̀kan yín.
Wí fún wọn pé èmi OLUWA ní, mo fi ara mi búra pé inú mi kò dùn sí ikú eniyan burúkú, ohun tí mo fẹ́ ni pé kí ó yipada kúrò ninu ẹ̀ṣẹ̀ rẹ̀, kí ó sì yè.
Mo mọ Buhari pe ko lee gbinyanju iru rẹ laelae.
Ninu atẹjade kan ti alukoro ọlọpaa nilu Eko DSP Bala Elkana fi sọwọ sawọn oniroyin, o ni obinrin kan ti orukọ rẹ n jẹ Chukwunonso Blessing lawọn gba awọn ọmọ naa lọwọ rẹ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Fasoranti: Àwọn ọ̀dọ́ Ondo fárígá lórí ikú Funke Olakunrin Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Fasoranti: Àwọn ọ̀dọ́ Ondo fárígá lórí ikú Funke Olakunrin 15 Agẹmo 2019 Àwọn ọ̀dọ́ ipinlẹ Ondo tu sita lati fẹhonu han lori ọpọ ọsẹ ti awọn to n pa eeyan ni ipinlẹ wọn paapaa nigba ti awọn ba n rinrinajo.
Gẹ́gẹ́ bí wọ́n ti ṣe sí Heburoni, ati Libina ati ọba rẹ̀, bẹ́ẹ̀ náà ni wọ́n ṣe sí Debiri ati ọba rẹ̀.
" ìgbà yẹn ni yóò mọ pé àwọn ọgá rẹ̀ nijọba ni mò ń ba ṣe; kìí ṣe irú àwọn ọjẹ̀ wẹ́wẹ́ bí tí rẹ̀.
Ṣugbọn Mikali ọmọbinrin Saulu nífẹ̀ẹ́ Dafidi; nígbà tí Saulu gbọ́, inú rẹ̀ dùn sí i.
OLUWA a máa dáni lárea sì máa ṣe ìdájọ́ òdodo fún gbogboàwọn tí a ni lára.
''Gbigba owo lọwọ awọn to farapa kii ṣe nnkan to buru nikan bii kii ṣe iwa ọdaran'' O kesi gbogbo awọn mọlẹbi ẹni to ba fara pa kankan ti awọn oṣiṣẹ ilera ba fẹ gba owo lọwọ wọn lati mu eriwa fun awọn.
Casemiro lo pada wa jẹ goolu dondo fun Madrid ni nkan bii iṣẹju diẹ ti ifẹsẹwọnsẹ naa yoo fi pari.
Ọ̀rọ̀ ti ń gba ibòmíràn yọ lórí ẹ̀ṣùn ìfipábánilòpọ̀ - Timi Dakolo Pariwo Mr Latin: Ó ṣeéṣe kí TAMPAN àti ANTP di ọkàn lọ́jọ́ iwájú, tí.
fafiti ti fenuko lori adehun won, ni eyi ti awon oluko fafiti ko ni pe pada
Ilé ìwòsàn ọhun ti wọ́n da silẹ̀ ni inú oṣù kẹwàá ọdun 1907 láti maa ko ènìyàn mejìdinláàdọta si ti di èyi ti wọ́n ń ko ènìyàn ojílelẹẹdẹgbẹtà o din máàrun (535) lọdun 2020.
Ọmọ ilẹ Afrika ni wa, awọn obinrin si gbọdọ maa hu iwa to dara.
OLUWA fojú sí àwọn aṣebi lára,láti pa wọ́n rẹ́, kí á má sì ṣe ranti wọn mọ́ lórí ilẹ̀ ayé.
Ogagun Dambazau ni awon ibon yii n wole fun ogun boko haram ati awon ajijangbara ti ekun Naija-Delta ni ni eyi ti ijoba ti n fofin de bayii.
Ẹ máa fi ọkàn bá adura yín lọ.
”Pẹlu ìbẹ̀rù ati ìyanu, wọ́n bẹ̀rẹ̀ sí bá ara wọn sọ pé, “Ta nì yìí?
Ẹni tí ó ń fi ohun dáradára tẹ́ ọ lọ́rùn,tí ó fi ń sọ agbára ìgbà èwe rẹ dọ̀tun bíi ti idì.
Àtẹ̀yin ati àwọn ọba yín, ati àwọn ìjòyè yín,ati àwọn alufaa yín, ati àwọn wolii yín;
Kò dájú pé ẹgbẹ́ òṣèlú APC yóò ní olùdíje lábẹ́ Asíà ẹgbẹ́ wọ́n nípìnlẹ̀ Ondo Ọ̀dàlẹ̀ ni Igbákejì Gómìnà, kìí ṣe pé a dẹ́yẹ si - ìjọba Ondo Ìgbésẹ̀ míràn ṣúyọ lórí ọ̀rọ̀ Abiola Ajimobi Wó ohun tó ṣokùnfà ọkọ̀ ojú omi to dójúdé l'Eko Seyi Makinde ni ìjọba ti ránṣẹ́ si àwọn ti ọ̀rọ̀ náà kan, títọpasẹ ibi ti wọ́n ti rìn sí náà ti bẹ̀rẹ̀, bákan náà ni ọfíìsì wọ́n tí wà ni títìpa fún àtúṣe tó yẹ.
ni aare Buhari yan sinu igbimo rẹ.
 so pe, aare ajo NFF, Amaju Pinnick ni o dari awon igbimo ohun, ti o kun fun igbakeji aare kinni ajo NFF, Seyi Akinwunmi, akowe agba ajo naa Mohammed Sanusi,  olusakoso iko Super Eagles,  Dayo Enebi ati akonimoomu Alloy Agu lo si ile iwosan naa.
Ẹ fi ara yín sábẹ́ òfin ìjọba ilẹ̀ yín nítorí ti Oluwa, ìbáà ṣe ọba gẹ́gẹ́ bí olórí, 
Nigba ti wọn bi wọn boya ajẹsara dara: Ida mọkandinlọgọrin ninu ọgọrun, (79%), lo fara mọọ.
Ọpọlọpọ awọn ọmọ Naijiria to fesi si ọrọ Fashola yii lo fi ṣe yẹyẹ, ti wọn si fi dapara lori ẹrọ ayelujara pe irọ patapata ni ọrọ naa.
Bí ọdọmọbinrin kan, tí ń gbé ilé baba rẹ̀ bá bá OLUWA jẹ́jẹ̀ẹ́ tabi tí ó ṣe ìlérí láti yẹra fún ohunkohun, 
Awọn gomina lawọn o le san ọgbọn ẹgbẹrun naira Ẹgbẹ oṣiṣẹ ti fesi si ọ̀rọ̀ ti awọn gomina sọ pe ''awọn ko le san ju ẹgbẹrun mejilelogun ati ẹẹdẹgbẹta Naira gẹgẹ bi owo oṣu oṣiṣẹ to kere ju.
Kódà, òun a máa rí ìrísí OLUWA.
Akọnimọọgba Pochettino naa ti figba kan ri ṣoju PSG gẹgẹ bi agbabọọlu laarin ọdun 2001 si 2003.
Onyeama ti o soju fun  akowe agba fun
Iná sọ ní ọjà Kara l'Eko l'ọ́dún ku ọ̀la Odunlade Adekola, Femi Adebayo: Ìdí tí áwọn obìnrin ṣe máa ń kú fún ẹ̀wà àti ìdúró ọmọkùnrin wọn Àwọn fóònù wọ̀nyìí kò ní lè ṣe WhatsApp láti ọdún 2020 'Ilé aṣòfin àgbà l'Abuja leè dà wó lulẹ̀ láì ṣe àtúnṣe rẹ̀ ní kíákíá o' 'Ẹ̀ ń fi ẹ̀wọ̀n run imú o' Ẹ̀yin Olóyè Ibadan mọ́kànlélógún tẹ ń pe ara yin lọ́ba Bàbá akẹ́kọ̀ọ́bìnrin LASU tí ọ̀rẹ́kùnrin rẹ̀ àti pásítọ̀ fi ṣ'òògùn owó ń bèèrè fún ìdájọ́ òdodo Naira Marley n jẹjọ ijọkọgbe niwaju adajọ majisireeti Tajudeen Elias pẹlu awọn mọlẹbi rẹ, Idris Fashola, babatunde Fashola ati Kunle Obere.
Bo tilẹ jẹ pe a ko lee fidi rẹ mulẹ pe Funke ni yoo san owo irinajo naa, ṣugbọn eyi jẹ anfani nla fun awọn ololufe rẹ lati lati rinrin ajo lo oke okun lai san kọbọ.
Eeyan ẹgbẹrun un lọna ọtalelẹgbẹrin o din mẹwa (850,000) lo n tẹle e loju opo Instagram rẹ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Use of hijab: Ìjọba ti buwọ́lu lílo hijab láwọn iléèwé ní ìpínlẹ̀ Osun 3 Bélú 2020 Oríṣun àwòrán, Getty Images Lẹyin atotonu fun ọpọlọpọ ọdun, ijọba ipinlẹ Osun ti fọwọ si kawọn akẹkọọbinrin maa lo hijab nipinlẹ naa.
Ó sọ fún un pé, ‘Jáde kúrò ní ilẹ̀ rẹ, láàrin àwọn ẹbí rẹ, kí o lọ sí ilẹ̀ tí èmi yóo fihàn ọ́.
Nígbà tí mo ń ka ìwé rẹ̀ náà ṣe ló dà bí ẹni pé mo rí ọ gan-an.
 eze nri ni o joba ilu-oba nri .
Fayemi, Fayose ń tahùn sí ara wọn nítorí gbèsè owó oṣù òṣìṣẹ́ Liverpool ṣubú dàánù ní Napoli Àwọn ará ń kẹ́dùn ọ̀pọ̀ ẹ̀mí tó ṣòfò lópòpónà Ọrẹ̀ si Èkó Kini awọn eeyan n sọ?
Oríṣun àwòrán, Getty Images Laarin osu kẹsan si ikẹwa ọdun 2020 ni awọn ọdọ yii fi n se iwọde alagbara eyi to mu ki ijọba kede pe oun tu ikọ SARS naa ka.
Gomina naa ni oun yoo ṣe ipade pẹlu awọn adari ile ijọsin ni ipinlẹ naa ki ọsẹ yii to pari lati fi igbesẹ oun han si awọn eniyan.
Awọn inaki naa, ni wọ̀n n tọ̀ju nibudo igbafẹ yii lẹyin ti ẹranko buruku kan awọn obi wọn.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Aṣọ àti bàtà tọ́ka sáwọn afurasí gbéwiri lábúlé Bugaje 4 Èbibi 2018 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Owọ́ ọlọ́pàá tẹ afurasí mẹ́ta níbi tí gbéwiri ti ṣọṣẹ́ Àwọn géńdé mẹ́ta d'èrò ilé ẹjọ́ látàri bàta àtí aṣọ ti Sani, ọ̀kan lára àwọn afurasí ọ̀daràn bọ́ sílẹ̀ Owọ́ ọlọ́pàá tẹ afurasí mẹ́ta níbi tí gbéwiri ti ṣọṣẹ́ ni Nassarawa Bugaje nijọba ibilẹ́ Jibia ìpínlẹ̀ Katsina.
Ẹsun kiko owu ilu lọ si ilẹ okeere ni wọn fi kan Alison-Madueke pẹlu awọn eeyan mii lọdun 2018.
Ninu ilé ìpàdé ati ninu Tẹmpili ni èmi tí máa ń kọ́ àwọn eniyan nígbà gbogbo, níbi tí gbogbo àwọn Juu ń péjọ sí, n kò sọ ohunkohun níkọ̀kọ̀.
A ti pàṣẹ kí àwọn ọmọ má ṣe lọ sí ilé ẹ̀kọ́ nítorí Coronavirus, ó sì ti ṣe ìpalára fún ọrọ aje wá, a sì ti ń fún àwọn èèyàn ní èròjà oúnjẹ, láti mú kí ayé dẹrun fún wọn""O ṣàlàyé pé, àwọn ọlọ́pàá méjì tí wọn wá láti Eko sì Ondo lo mú kí owoja àrùn Covid-19 lè sì ni Ondo, tí àwọn fi ní alárùn mẹ́jọ, tí mẹta sì yí lọ sílè nínú wọn."
Ṣé wọ́n sàn ju àwọn orílẹ̀-èdè yín lọ ni?
Ṣugbọn to ba jẹ pe ibomu-bẹnu ti o le lo ju ẹẹkan lọ̀ ni, bi i eyi ti wọn fi aṣọ ṣe, fọ ọ ni kiakia pẹlu omi gbigbona ati ọṣẹ, ki o si sa a sinu oorun.
Bẹ́ẹ̀ ni a ṣe kó àwọn eniyan Juda ní ìgbèkùn kúrò ní ilẹ̀ wọn.
Ọfọ ṣi ki si baba lẹnu, o sọ ọ tan lo ni ohun ti di Pasitọ bayii ki a sọ nkan mii.
 Ó jé òkan lára àwon tí ó sèdá ohun tí a n pè ní scholastic theology .
igbesẹ ti ko bojumu ni eyi.
Lakotan, Ajọ WAEC ni idanwo naa lọ ni irọwọ-rọsẹ kaakiri gbogbo ojuko ti idanwo naa ti waye laisi magomago tabi rogbodiyan kankan.
Ninu ọrọ rẹ Amofin Oyinlade ni ko si irọ ninu awọn abajade igbelewọn eyi ti awọn ajọ ajafẹtọ lagbaye bii Amnesty International n gbe jade lori ibi ti ọrọ de duro lori ibọwọ fẹtọ araalu lorilẹede Naijiria.
Oríṣun àwòrán, Oluwo's palace Ẹ jẹ́ ká dá ìbọn kọjá, tó bá jẹ́ pé Oluwo kò fìyà jẹ́ mí - Agbowu Ọba ni mí, mi ò le b'ọ̀rìṣà, Olorì tuntun tó ń bọ̀ já gbogbo ''scale''- Oluwo ti Iwo Eyitayo Jegede gbé Akeredolu lọ síwájú ìgbìmọ̀ tó n gbọ́ ẹ̀sùn ìdìbò Ẹ fi Ọba alayé sínú ìgbìmọ̀ olùwádìí aṣemáṣe àwọn ọlọ́pàá - Oluwo Oríṣun àwòrán, Oluwo's Palace O ni asawọ oselu ninu aato ipo ọba ilẹ Yoruba kun ara ohun to n fa wahala ati edeaiyede laarin ilẹ Yoruba.
Ẹnikẹ́ni tí ó bá jẹ́ mímọ́ ninu wọn lè jẹ ẹ́.
Amọ atẹjade naa ni ọjọ mejila gbako ni yoo fi wa ni igbele, ti ko si si aayan lati se ayẹwo rẹ boya o ni arun ọhun.
Transfer Window: Pogba, Maguire, Bale, Neyman, báwo ni nkan ṣe ń lọ?
Peteru wá ranti ọ̀rọ̀ tí Jesu sọ fún un pé, “Kí àkùkọ tó kọ ní ẹẹmeji, ìwọ yóo sẹ́ mi ní ẹẹmẹta!
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Wòlíì bá obìnrin 300 lò pọ́, ó gba ìdájọ́ ẹ̀wọ̀n ọ́dún 19 20 Ọ̀pẹ̀̀ 2019 Oríṣun àwòrán, AFN/GETTY IMAGES Palaba wolii eke kan to pe ara rẹ ni Johannu inu bibeli 'John of God' ti ṣegi ti adajọ si ti dajọ ẹwọn ọdun mọkandilogun fun un lori ẹsun ibalopọ pẹlu awọn obinrin to le ni ọọdunrun lọna aitọ.
Mélòó lo lè parí nínú òwe Yorùbá yìí?
Najiria ko ni suuru, won fe ki aare so oke dile laarin odun meta ti o ti lo,
Oríṣun àwòrán, Getty Images Ọna kan lati mu ọkan kuro nibi asajě ni lati wa nkan ti wa a maa se lati gbe okan rẹ kuro nibẹ, iwadii kan fihan pe lolo awin nkan ti a le foju ri ati oorun didun.
Nípínlẹ̀ Ògùn, Ọ̀gá ọlọpàá yìnbọn jẹ
Idi ni pe iwadi BBC fidi rẹ mulẹ pe ile asofin fi awọn akansẹ isẹ kan sinu aba isuna naa, eyi ti owo rẹ to biliọnu mẹwa naira, ti apapọ owo aba isuna naa si fo soke lọ si biliọnu lọna ọrinlerugba o din meje naira (N273bn).
Àwọn òṣìṣẹ́ ìjọba ìpínlẹ̀ Oyo láti ipele kẹtàlá yóò padà sí ẹnu iṣẹ́ lọ́jọ́ ajẹ́ Ọ̀pọ̀ òjò lo ti rọ láàrin emi àti Olúwòó- Olorì chanel Àwọn tó lùgbàdì coronavirus ní àgbáyé ti lé ni mílíọnu mẹta, Wo wọn níbí.
Lẹyin ti ayẹwo fihan pe Chioma ti ko arun Coronavirus, igba meji ọtọọtọ ni Davido ni oun ti ṣe ayẹwo lati lee mọ boya oun ni arun naa tabi oun ko ni.
Ẹ̀yin ọmọ Israẹli, ẹ gbẹ́kẹ̀lé OLUWA,òun ni olùrànlọ́wọ́ ati aláàbò yín.
Àjálù ń bọ̀, tí Buhari kò bá ṣàtúnṣe lórí ètò ààbò- Obasanjo Àwọn Fulani gbọdọ kúrò ní ìpínlẹ̀ Ondo -Àwọn ọ̀dọ́ Ondo Fulani nìkan kọ́ ló ń pa ènìyàn ní Naijiria -Tinubu Ìtàn tó rọ̀ mọ́ òwe ‘aṣọ kò bá Ọ́mọ́yẹ mọ́.
Èdè yorùbá tí wọ ́ n fi ń gbé ìtàn wọn kalẹ ̀ yìí jẹ ́ kí ó yé gbogbo mùtúmùwà ohun gbogbo tí wọ ́ n ń sọ .
Ọ̀dọ̀ fásitì jànkàn Oxford ló ti jáde NCDC kéde èèyàn 423 míràn tó ṣẹ̀ṣẹ̀ lùgbàdì Covid-19 ní Nàìjíríà, 263 gbàwòsàn À kò gba owó kankan lọ́wọ́ àwọn ẹgbẹ́ agbésùmọ̀mí ISWAP- MURIC Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 3 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 5 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Kí ló dé tí o fi ojú pamọ́ fún mi?
Àwọn ará Sodomu yìí jẹ́ eniyan burúkú, wọn ń dẹ́ṣẹ̀ sí OLUWA lọpọlọpọ.
Irọ́ ni, mi ò sọ pé mọ fẹ di Ààrẹ ní 2023- Tunde Bakare Kíni àwọn ìpèníjà ẹtọ ààbò ṣáájú òmìnira Nàìjíríà?
Eegun ikọ Arsenal to fagba han Napoli lati tẹsiwaju lọ abala to kangun si aṣekagba idije Europa Liigi lo mu ki awọn alatilẹyin ẹgbẹ agbabọọlu naa maa gara.
Eyi si ti fa ọpọlọpọ awuyewuye laarin awọn ẹgbẹ, ọgba, ileeṣẹ lajọlajọ ati mutumuwa.
Wọ́n bá dá ọjọ́ tí wọn yóo wá fún un.
Ti ẹru ile ba wuwo ju bo tiyẹ lọ Awọn onimọ ẹrọ nipa ile kikọ sọ pe kosi bi ile ko ṣe ni wo lulẹ nigba ti ẹru to wa lori ipilẹ ba ti wuwo ju.
Gẹ́gẹ́ bí àṣà púpọ̀ nínú àwọn arẹwà obìnrin, ìyá mi jẹ́ onígbèéraga, àwọn iwin pàtàkì pàtàkì ti wọ́n sì ń fẹ́ ẹ nígbà tí òun wà ní wúndíá kò bá ojúrere rẹ̀ pàdé títí àwọn ọlọ́lá wọn-ọnnì fi fi í sílẹ̀ tí àti ní ọkọ di ìṣòro fún un.
"Àwọn tuareg ( bakanna bi "" twareg "" tabi "" touareg "" , beriberi : imuhagh ) je awon eniyan beriberi adaeran alarinka ."
Awọn ounjẹ ọlọra aṣaraloore Oríṣun àwòrán, Getty Images Awọn ounjẹ bi ẹpa, ororo olifi, ẹja mọnkẹrẹ ati avocado ni ọra to le ṣe ara loore ninu.
kíni ọ̀nà àbáyọ sí àìsàn Lassa Fever?
Wọn kọ wọn bi wọn ṣe n yinbọn ati lilo awọn nkan ijagun mii.
Ṣugbọn Juda dá a lóhùn, ó ní, “Ọkunrin náà kìlọ̀ fún wa gidigidi pé a kò ní fi ojú kan òun láìjẹ́ pé a mú arakunrin wa lọ́wọ́.
Nítorí ó mọ̀ pé àwọn olórí alufaa ń jowú Jesu, wọ́n sì ń ṣe kèéta rẹ̀, ni wọ́n ṣe fà á wá siwaju òun.
Xenophobia: Alùpùpù ni wọ́n fi gbé epo pẹtiró wá dáná ṣun iléeṣẹ́ MTN
“Ẹni tí ó bá ṣẹgun, Èmi óo fún un ní mana tí a ti fi pamọ́.
Loni, ajo awon gomina lorileede yii faramo idasile oloopa ipinle gegebi igbakeji aare se so.
353 ni odiwọn iye ìbo ti PDP fi ju APC lọ nigba ti ìbò 3, 498 ni wọn wọgile eyi ti wọn ṣe atundi rẹ loni.
8 94507 Orilẹede Honduras 2946 30.
OLUWA Ọlọrun Israẹli bá Jeremaya sọ̀rọ̀:
Ninu gbogbo ogun tí wọ́n bá àwọn ara Filistia jà, Dafidi ní ìṣẹ́gun ju gbogbo àwọn olórí ogun Saulu yòókù lọ.
Tọkọ taya kú lọ́jọ́ kan náà l'Abeokuta lẹ́yìn ìgbéyàwó ọdún méjìléláàdọ́rin 72 Kíní ọ̀nà àbáyọ sí ìjàmbá ọkọ̀ tó ń wáyé lemọ́lemọ́ ní Ọjà Akungba,ní Ondo?
àní, gbogbo ohun tí kò bá ti lè jóná ni a óo mú la iná kọjá, kí á lè sọ wọ́n di mímọ́; a óo sì fi omi ìwẹ̀nùmọ́ fọ àwọn ohun èlò tí wọn bá lè jóná.
Ki ni awọn ohun to n fa iṣoro?
Mo ti fi ẹnìkan jọba lórí yín.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù International Day for Elimination of Violence against Women: Àlùfáà Joel Olugbenga: Bíbélì kò ní kéèyàn dúró títí ọkọ rẹ̀ yóò fi lù ú pa Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ International Day for Elimination of Violence against Women: Àlùfáà Joel Olugbenga: Bíbélì kò ní kéèyàn dúró títí ọkọ rẹ̀ yóò fi lù ú pa 10 Ọ̀wàrà 2018 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 25 Bélú 2020 Ìwà ipá nínú ilé ti rìn jìnà gẹ́gẹ́ bíi kòkòrò ajẹnirun tó ti ń tú ọ̀pọ̀lọpọ̀ ìdílé ká.
inu aare wa dun si yin pupo, o si ni ki  n maa ki i yin.
Aarẹ Keita wọle saa keji lọdun 2018 ṣugbọn ọpọ lo ti kọminu lori bi iwa ibajẹ ṣe n gogo sii ati bi ijọba ṣe n ṣakoso ọrọ aje Mali lọna aitọ.
Ṣugbọn o daju pe awọn ọmọ Naijiria ko ni pada s'ijọba PDP mọ.
Biṣọbu Adepọju lo n ṣakoso daosisi ijọ naa to wa lẹkun Iwọ oorun Ekiti ni ipinlẹ naa.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Chef Adefunkẹ: Òórùn ewé tí wọ́n n pọ́n ìrẹsì ọ̀fadà si jẹ́ adùn lọ́tọ̀ Ọdun 1985 ni iṣẹlẹ arun gastroeniteritis to n tankalẹ nipinlẹ Eko yii kọkọ ṣẹlẹ ni orilẹ-ede Naijiria.
 Àṣà yìí wọ ́ pọ ̀ ní gúúsù , ìwọ ̀ oòrùn gúúsù , gúúsù ìlà oòrùn nàìjíríà .
Handshake goals 🤝Paul Pogba x Romelu Lukaku 🔥 pic.
Fun eyi, awọn eniyan roo latẹwọ waa waa.
Idí ilé òrìsà ni ọ̀rọ̀ náà yoò ti yànju - Ọọni Ife Bakan náà ni àkọròyìn BBC ní Akurẹ sàlàyé pé ìyá ọmọ to sọnú fi ìròyìn sọwọ́ sí òun pé àwọn ti lọ ri Ọni ilé Ifẹ̀ Ọba Adeyeye Enitan Ogunwusi lóri ọ̀rọ̀ ọmọ náà ati pé Kabiyesi ti ṣe iléri pé òun yóò tu iṣu dé ìsàlẹ̀ ikoko lóri ọ̀rọ̀ náà ati pé ìpè yòó lọ si ọdọ àwọn àjọ DSS láti ma jẹ́ ki àwọn alagbara kankan o yọ woli náà kuro latimọle titi ti ọ̀rọ̀ yòó fi yanju.
Mracus Rashford lo kọkọ gbayo wọle lẹyin iṣẹju mẹẹdọgbọn ti wọn bẹrẹ ere bọọlu ọhun.
Oga agba oludari eka iforotomileti ile-ise omo ogun ofurufu NAF, ogagun Ibikunle  Daramola lo so oro ohjun di mimo fun awon akoroyin.
Alleged incest: Ọkùnrin kan dèrò àtìmọ́lé lórí ẹ̀sùn fífi ipá bá ọmọ bíbí inú rẹ̀ méjì lájọṣepọ̀ ní ìlú Akure
Dangote: Mo ti gbà $10m ri ní bánkì kí n lè mọ bí o tí ṣé rí lójú Ilé ẹjọ́ kòtẹ́milọ́rùn yá lórí ọ̀rọ̀ Adeleke- PDP Kíni ìlànà tí o dé yíyọ adájọ ilé ẹjọ kánkan ní Nàìjíríà?
Alaafin Oyo kò dàgbà jù fún mi, ohun tó wù mí ní mo ṣe pẹ̀lú ayé mi- Olori Aanu Ileeṣẹ aarẹ gan sọ pe awọn ri igbesẹ ti ile aṣofin gbe, wọn si sọ pe yiyan tabi dida ọga awọn ologun duro, ọwọ aarẹ lo ti n wa bẹẹ si ni pe aarẹ yoo ṣe oun to tọ bi asiko ba ti to.
Gẹ́gẹ́ tí mo rí Ìyá àgbà Saray, àrídájú mi lórí bí àwọn ọmọ Azerbaijan ṣe ṣ'èèyàn sí l'ékún sí i.
" Risikat fikun pe lootọ ni aya gomina n sọ pe ki awọn mejeeji pari ija, ki awọn si maa sọrọ si ara awọn, ti wọn si ya fọto fun awọn.
Bukola Saraki naa n dije ipo Aarẹ Naijiria Ti a ba tun wo wi pe gbogbo awọn to n du ipo yi naa ni wọn ti n ba Bukola Sraki se po ti pe.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ọmọ ẹgbẹ APC faramọ iwoye Obasanjo 24 Sẹ́rẹ́ 2018 Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fọ́nrán ohùn, Lori lẹta Obasanjọ Olori osisẹ lọofisi gomina ipinlẹ Oyo, Ọmọwe Gbade Ojo wipe oun faramọ ọpọ ohun ti Obasanjọ sọ ninu lẹta Buhari.
Awọn nkan to ṣẹlẹ yii, mu ki a gbagbọ pe ọrọ naa kii ṣe oju lasan."
Sọ̀kalẹ̀ kúrò ninu ògo rẹ, kí o jókòó lórí ìyàngbẹ ilẹ̀, ìwọ tí ò ń gbé Diboni!
Àwọn ọdọmọkunrin Damasku yóo ṣubú ní gbàgede rẹ̀ ní ọjọ́ náà,gbogbo àwọn ọmọ ogun ibẹ̀ yóo sì parun ni;Èmi OLUWA àwọn ọmọ ogun ni mo sọ bẹ́ẹ̀.
Awọn ADP ni inu Olorun kod un si ipinlẹ Ondo bayii.
Mo pàṣẹ fún Baruku níṣojú wọn pé, 
Ẹsìn onigbàgbọ́ lo wọ́pọ̀ jùlọ ní ìpinlẹ̀ Rivers nígbà ti mUsulumi pọ ní ìpiínlẹ̀ Kano.
Sabidieli ọmọ Hagedolimu ni alabojuto wọn.
Mo da òkùnkùn bo ojú ọ̀run bí aṣọ,mo ṣe aṣọ ọ̀fọ̀ ní ìbora fún wọn.
  Gbẹrẹfụ ni mo jẹ ẹ́ 🙂
 Ó máa n yọrí sí pípàdánù biliọnu 8 owó ilẹ ̀ amẹrika lọ ́ dọọdún .
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ọjọgbọn Wọle Soyinka bu ẹnu ẹtẹ lu aarẹ Buhari fun ipaniyan awọn fulani darandaran Soyinka tun sọ wipe awọn ọmọ-ogun orilẹede Naijiria ni lati mu awọn alamojuto eto aabo ṣinṣin ati pe wọn gbọdọ daabo bo ẹmi awọn ara ilu ati dukia wọn pẹlu.
O ni ṣugbọn kii ṣe lagbo osere tiatia nikan ni wọn wa bii kii se pe wọn pọ ninu oṣelu ati awọn iṣẹ miran ni Naijiria.
Kí OLUWA wà pẹlu ẹ̀yin tí ẹ dúró ṣinṣin.
Àwọn ọmọ Rama ati Geba jẹ́ ẹgbẹta ó lé mọkanlelogun (621)
Àwọn alufaa pa àwọn òbúkọ náà, wọ́n sì fi ẹ̀jẹ̀ wọn rúbọ lórí pẹpẹ fún ìmúkúrò ẹ̀ṣẹ̀ gbogbo ọmọ Israẹli, nítorí ọba ti pàṣẹ pé wọ́n gbọdọ̀ rú ẹbọ sísun ati ẹbọ ìmúkúrò ẹ̀ṣẹ̀ fún gbogbo eniyan.
Ọkùnrin to máa ń sọ sọọsi wa ni alẹ si owurọ lo de si ibi'ṣẹ ni irọlẹ, to si lọ si ọdọ awọn to maa n tọju kọ́kọ́rọ́.
Wọn a máa jẹ oúnjẹ wọn, wọn a sì ma bá wọn bọ oriṣa wọn.
Bí ọ̀rọ̀ bá ti pọ̀ jù, àṣìsọ a máa wọ̀ ọ́,ṣugbọn ẹni tí ó bá kó ẹnu ara rẹ̀ ní ìjánu, ọlọ́gbọ́n ni.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Yoruba Movie Actors On Set vs Off Stage: Bí àwọn òṣèré fíìmù ṣe rí láì mura gegege 31 Ọ̀wàrà 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 1 Bélú 2020 Oríṣun àwòrán, Aisha Lawal Pẹlu bi awọn oṣere ṣe rẹwa to ti awọn eeyan si maa n wari fun wọn lori itage paapaa nigba ti wọn ba ti kun oju kun ara fun wọn tan ti aṣaraloge si ti ṣe iṣẹ tirẹ, ati wa maa tun sọ airẹwa wọn maa n jẹ iyalẹnu.
Ṣùgbọ́n ẹgbẹ́ orin yìí sì ń tà wàrà wàrà títíi 1960s kanlẹ̀ amọ ti yoo fi di ipari 60s, awọn ẹ̀yà orin Juju míì tó ń jáde bẹ̀rẹ̀ si ni bo irawọ rẹ mọ́lẹ̀ nitorinaa láti rí jẹ, O bẹ̀rẹ̀ si nii ṣòwò yiya awọn eeyan ni awọn irinṣẹ rẹ lágbègbè Moshalashi lẹgbẹ Fela Kuti Kalakuta Republic ni ilu Eko.
“Ó ti tó ọdún mélòó kan tí mo ti dé Jerusalẹmu gbẹ̀yìn.
Foniimu yìí sún mọ́ ti àwọn ẹranko ṣùgbọ́n ó sì tún rọ̀ jut i ẹranko lọ.
Kí ni ẹ̀ ń dásí ọ̀rọ̀ èmi onírora sí?
Ranti láti gbé iṣẹ́ rẹ̀ ga,tí àwọn eniyan ń kọrin nípa rẹ̀.
EFCC ni awọn eeyan yii se magomago owo to to biliọnu mọkanla ati aabọ naira.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù NAF: Iléeṣẹ́ ọmọ ogun dá Bashir tó ri owó he lọ́lá 26 Agẹmo 2019 Oríṣun àwòrán, @NAF Àkọlé àwòrán, Naijiria bu ọla fún ọmọ ogun to da owo to ri he pada Ile iṣẹ ọmọ ogun ofurufu Naijiria ti ṣe koriya fun akinkanju ọmọ ogun Bashir Umar.
Wakil ni Ọmọ ọdun mẹtadinlogun ni ọmọbinrin rẹ ki wọn to fi ipabalopọ ni Oṣu Kini, ọdun 2020, to si loyun.
Ogbontarigi olootu orin to ti gba ami eye oniruuru, Cobhams Asuquo, ti parowa fun ajo to n mojuto eto idibo Naijiria, INEC, pe ki won tete se atunse si awon ona idibo ti won ti la kale bi o ti ye, ki o le je ki idibo rorun sii f’awon akanda eda ni 2019.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Wo imọran Fọlọrunṣọ Alakija fun awọn ọdọ adulawọ Khadijah, ọmọ ọdún mọ́kàndínlógún tó kó àwọn ọgọ́rùn ún ènìyàn lọ sílé ọkọ àfẹ́sọ́nà rẹ láti ṣí ojú àwọn obìnrin sí àṣà yii.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Gorillas in Nigeria: Orí àwọn Ìnàkí náà kéré, ọwọ́ wọn gùn, tí irun wọn sì funfun 10 Agẹmo 2020 Oríṣun àwòrán, WCS Wọn ti gbe aworan awọn inaki kan jade lori ayelujara fun igba akọkọ ni ọpọ ọdun.
Ninu atẹjade ti EFCC fi sita, ajọ naa sọ pe Olawale lo ayederu oju opo Williams Angellina ati Omolola Adebayo lati tan Hayatou jẹ wi pe baba oun ni ileeṣẹ loke okun.
Peteru bi í pé, “Sọ fún mi, ṣé iye tí ẹ ta ilẹ̀ náà nìyí?
Bi àwọn kan ṣe n bè[rè pé abi ijanu ọkọ ti awọn ọmọ ile iwe Tolulope wa ja ni naa ni awọn miran ni ko ri bẹẹ nitori pe ohun to daju ni pe kii ṣe pe ijanu ọkọ Sienna naa ja rara.
Kò sí òpin sí iye ọdún rẹ.
Ohun ti Yorùbá mọ̀ si àròkàn n irònú igbà gbogbo.
 Ó jé kí gbígbé ìròyìn jade wa làbé ìjoba àpapò nìkan .
1 349149 Orilẹede Pakistan 10863 5.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Coronavirus update: Akọrin tàkasúfé, Tommy Kuti tó ń forin ṣèkìlọ̀ COVID-19 lágbáyé Kò tán síbẹ̀, orílẹ̀-èdè Amẹ́ríkà náà tí ń gbé irufẹ ìgbésẹ yìí, tó sì ti ń ṣe ayẹwo ẹ̀jẹ̀ àwọn alárùn Coronavirus làwọn ilé ìwòsàn to to ẹẹdẹgbẹjọ.
gomina labe asia egbe  SDP, Eyo Ekpo ati
Òun ni ó jí dìde kúrò ninu òkú.
"Mo dẹ ro wi pe wọn ṣe bẹ́ẹ́.
 hébéérù ni ó wá gba ipò rè gégé bí èdè tí àwon júù ń so .
2020 in Retrospect: Abiola Ajimobi, Ibidunni Ighodalo, Buruji Kashamu wà lára àwọn tó bá ọdún yìí lọ
Mo bá lọ sọ́dọ̀ angẹli náà, mo ní kí ó fún mi ní ìwé kékeré náà.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Alaafin: Olori Aanu Adeyemi ṣàlàyé ìdí tó ṣe gẹ́ Oba Lamidi Adeyemi ti ìlú Oyo Agbejọro fun awọn mẹtẹẹta, Abimbola Akeredolu, sọ pe oun yoo pe ẹjọ kotẹmilọrun, nitori owó itanran naa.
Ṣé kí n lè máa fojú rí ìṣẹ́ ati ìbànújẹ́ ni?
Ara ọ̀nà láti máa rán àwọn ọmọ Yorùbá léti pàtàkì àmì ọ̀rọ̀ ló mú kí BBC Yorùbá bọ́ síta láti máa bèèrè pé káwọn èèyàn kan fi àmì sí orí ‘Àgbàlagbà-akàn’ .
ija to maa n waye laarin awon daran-daran ati awon agbe lorile ede Naijiria.
N óo rán ọmọkunrin kan láti wá àwọn ọfà náà.
Awọn ọlọ́pàá ti mu àwọn ole ti won ja ni Ọffa ti wọn ṣe ikú pa ọpọlọpọ ènìyàn.
Guterres so pe  asoju oun nile afirika ati Sahel ,Mohammed Chambas , ti n se opolopo atileyin fun awon orile ede Afirika ni eyi ti o n mu idagbasoke ba eto iselu, alaafia , atunse si eto ofin ati eto idibo.
Ilé ẹjọ́ ni yóò sọ bóyá Fayoṣe yóò j'ẹ́jọ́ - EFCC Ẹwẹ, ajọ EFCC ti fesi lori ikede kan to fi sita lori Twitter nipa Gomina Ayọdele Fayose.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Fulani kò leè dúró, táa bá lo ohun ta jogún lọ́dọ̀ àwọn bàbá wa - Sunday Igboho Ọjà Àgbáláta ní Badagry rèé, níbití ẹran ejò ti dùn ju ẹran adìẹ lọ Ọlọ́run yóò ṣe ìdájọ́ nkan tó wà láàrin èmi àti Ireti Ajanaku - Tope Alabi A kò jáde ṣe ìwọ́de ìtagbangba mọ́, inú ọkàn wa lá ti máa ṣe ìfẹ̀hónú hàn - Revolution Now O salaye pe, ọpọ eeyan gba pe ọlẹ, arugun, alailera ati obinrin ti ko pe ni ẹni to ba fi isẹ abẹ bimọ.
Ọ̀gá ọlọ́pàá kan tí kò dárúkọ ara rẹ̀ sọ pé, àwọn agbófinró fi ipá tú àwọn ọmọ egbẹ́ Shiites náà ká, nígbàtí wọ́n kọ̀ láti kúrò níwájú ilé National Human Rights Commission.
Iléeṣẹ́ asọ́bodè ṣe agbéga fún òṣìṣẹ́ rẹ̀ tó kọ̀ rìbá Ẹgbẹ́ òsìsẹ́ NLC ti kọ #27,000 owó osù òsìsẹ́ Àwòrán ìwọ́de NLC, TUC, ULC lónìí NLC, TUC: Àwa ò gba owó lọ́wọ́ Fayose ooo Awọn ti ọrọ naa kan ni awọn oṣiṣẹ ijọba apapọ to wa lori (CONPSS), awọn oṣiṣẹ eto ilera to wa lori ilana owo osu (CONHESS), awọn oṣiṣẹ ẹka miran to wa lori ilana owo osu (CONRAISS).
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Buns ni ọmọ mi jẹ tán ní ṣọ́ọ̀ṣì, ló bá di àwátì' Lara ẹsun ti wọn fi kan awọn ara ìlú ti ọwọ tẹ naa ni pe wọn ji awọn ohun ini wolii So titibi rẹ to n jẹ ẹjọ lori ọmọkunrin Gold Kolawole to dawati nile ijósin rẹ bayii.
Gbogbo àwọn tí wọn wà ní Ṣeba yóo wá,wọn óo mú wúrà ati turari wá;wọn óo sì máa pòkìkí OLUWA.
PDP ni ṣe o yẹ ki ọmọ aarẹ maa gun ọkọ ofurufu ijọba nigba ti eyi ti igbakeji aarẹ n gun n dẹnukọlẹ lojoojumọ?
Oríṣun àwòrán, @NGRSenate Àkọlé àwòrán, Ayẹwo wa lati rii pe awọn eeyan ti wọn jẹ ọdaran ko bọ si ipo ọṣelu.
Nítorí náà, kí ẹ mọ̀ lónìí pé, OLUWA Ọlọrun yín ni ó ń lọ níwájú yín, bíi iná ajónirun.
Mose bá sọ fún OLUWA pé, “Ní ààrin àwọn ará Ijipti ni o ti mú àwọn eniyan wọnyi jáde pẹlu agbára.
Oríṣun àwòrán, Reuters Àkọlé àwòrán, Ọpọ ara Algeria n sọ pe ko ṣe nkankan lati mu ọrọ aje gberu sii Bakan naa, o ṣe iṣẹ lati dọrẹ pẹlu orilẹede aladugbo wọn, Morocco.
Producer Yemisi Oyedepo àti Bayo Odukoya Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí 3 sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 2:23 Fídíò, Water Generator: Ó leè ṣiṣẹ fún wákàtí mẹfà, kó tó sinmi, Duration 2,2310 Òkùdu 2020 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
Ekiti: Ìyàwó gómìnà Èkìtì rọ àwọn obìnrin lóríi gbígbẹ̀bí sílé
ẹwọn odun meje ni won fun
A dúpẹ́ lọ́wọ́ rẹ, Ọlọrun; a dúpẹ́.
Arábìnrin Monica Osagie fìdí ọ̀rọ̀ náà múlẹ̀ nígbà tó farahàn níwájú ìgbìmọ̀ tí àwọn aláṣẹ fásitì náà gbé kalẹ̀ fún ìwádìí lórí ìṣẹ̀lẹ̀ náà.
Buhari: Àì lè ṣe dáradára tó mi wà lọ́wọ́ àwọn aṣòfin àpapọ̀
O ni ọpọlọpọ igba ti oun ba n rin laarin igboro ni oun maa n ri idẹyẹsi ti ko ṣee ka.
Kò sí ẹni tí ó ní ìfẹ́ tí ó ju èyí lọ, pé ẹnìkan kú nítorí àwọn ọ̀rẹ́ rẹ̀.
Eyín akọ̀ròyìn fò yọ lásìkò tó n ka ìròyìn lọ́wọ́ lórí tẹlifísàn Èèyàn 576 míràn tún kún àwọn tó ní àrùn COVID-19 ní Nàìjíríà Mo ti bẹ̀rẹ̀ sí ń bá àwọn tí a jọ díje nínú ìdìbó abẹ́lé sọ̀rọ̀ kí àláàfíà léè jọba - Akeredolu Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, JusticeforBarakat: O lé lọ́mọ ọdún mọ́kànla kí n tó rí abúrò rẹ̀ bí lée Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Bí àwọn ọkunrin wọnyi bá kú ikú tí kò mú ìbẹ̀rù lọ́wọ́ láti ọ̀dọ̀ Ọlọrun, a jẹ́ wí pé kì í ṣe OLUWA ni ó rán mi.
Awọn ara agbegbe Agbado, Sango ati Ijoko to wa ni ibode ipinlẹ Ogun ati Eko n sọ lori ẹrọ ayelujara pe awọn n gburo ibọn, ti awọn eniyan si n kọlu awọn eniyan ni inu ile.
O ni ọkọ kan ṣoṣo yii ko to lati pa ina ọhun, nitori ina naa pọ ju iṣẹ ọkọ panapana kan ṣoṣo lọ.
Awọn oṣiṣẹ kolẹ-kodọti wa lara awọn to n foju wina lasiko ajakalẹ arun yii.
 Aṣofin Ọlẹyẹloogun ni ko si ohun to jọ janduku ni ile aṣofin naa ati pe awọn agbofinro wa nikalẹ."
Alukoro fun ẹgbẹ to n risi idagbasoke ilu Numana jakejado agbaye, John Bature Mazo ni, awọn f'aramọ igbesẹ ileesẹ ologun lori idasilẹ eto naa ti wọn pe ni 'Operation Cat Race'.
Ẹlẹ́wọ̀n tẹ́lẹ̀ gboyè ìmọ̀ ìjìnlẹ̀ méjì lọ́gbà ẹ̀wọ̀n Òní ni ẹ̀bí akọni Pius Adesanmi n ṣètò ìkẹyìn fún ogbontarigi náà Wo àwòdamiẹnu àwòrán Mọ́ṣáláṣí Ànọ́bì ní Medina!
Oríṣun àwòrán, Reuters Àkọlé àwòrán, Inu Minisita fọrọ abo ni ilẹ Amẹrika dun si igbaradi naa eleyi ti wọn fi kasẹ abẹwo ọlọjọ mẹta to se si orilẹede Indonesia nilẹ Ki se igba akọkọ niyi fun awọn eekan nileesẹ ọmọogun ilẹ Amẹrika lati ri awọn isẹ igbaradi awọn ologun ti wọn rinrinajo lọ si ilẹ okeere, amọ awọn igbaradi bii kikoju awọn ajinigbe lawọn ikọ oniroyin to ba minisita ilẹ Amẹrika naa kọwọrin nreti.
Eeyan meje lo ku lọdun 2015 nigba ti iru ija ẹlẹyamẹya bayii ṣẹlẹ niluu Johannesburg ati Durban.
Nígbà, tó bá yá, Tire yóo di ìgbàgbé fún aadọrin ọdún gẹ́gẹ́ bí iye ọjọ́ ọba kan; lẹ́yìn aadọrin ọdún ohun tí yóo ṣẹlẹ̀ sí Tire yóo dàbí orin kan tí àwọn aṣẹ́wó máa ń kọ pé:
Lẹ́yìn náà ni ọ̀rọ̀ náà bẹ̀rẹ̀ sí ní jà rain-raín lórju opo twitter.
Joshua lọ lati ba wọn sawari awọn ọmọ wọn to wa ni panpẹ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Lagos Building Collapse: Ìjọba ìpínlẹ̀ Eko gbé ìgbìmọ̀ olùwádìí kalẹ̀ 21 Ẹrẹ̀nà 2019 Àkọlé àwòrán, Ọpọ obi lo ya bo awọn ileewosan lati mọ ipo ti awọn ọmọ wọn wa ti awọn miran ṣi n wa eeyan wọn Ijọba ipinlẹ Eko ti yan igbimọ ẹlẹni maarun ti yoo ṣewadii awọn nkan to fa a ti ile alaja mẹta kan fi wo nipinlẹ naa.
Awọn alatakọ sọ pe, ni ṣe ni aarẹ Trump mura mọ aarẹ Zelensky ki o ba le ṣe iwaadi ọmọ alatako rẹ, lọna ati ṣe akoba fun un.
Ati ‘fifty nairà’ ni ẹ̀wà ti bẹ̀rẹ̀, ṣíbí kan sì ni
Àkọlé àwòrán, Igbe aye ode oni, ko fi aaye silẹ fun ọpọlọpọ lati tete maa jẹun l'alẹ Igbagbọ awọn onimọ ni pe pipẹ jẹun lalẹ maa n mu ki ara ko wu, to si maa n mu iyatọ ba iye suga to wa ninu ẹjẹ.
Joṣua kúrò ní Lakiṣi, ó lọ sí Egiloni pẹlu gbogbo àwọn ọmọ Israẹli, wọ́n dó ti Egiloni, wọ́n sì bá a jagun.
Ǹjẹ́ irú ìṣẹ̀lẹ̀ yìí ti ṣẹlẹ̀ rí ní àkókò yín,tabi ní àkókò àwọn baba yín?
Ọlọ́rọ̀ ati talaka pàdé,OLUWA ló dá ekinni-keji wọn.
Ayọ̀ ń bẹ fún ẹni tí ó ń bẹ̀rù OLUWA nígbà gbogbo,ṣugbọn ẹni tí ó sé ọkàn rẹ̀ le yóo bọ́ sinu ìyọnu.
“Ife mi ati atileyin mi fun iko yii, yoo wa ti ti ayeraye.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìtàn Mánigbàgbé: Lúwòó Gbàgídà ló bí Adékọ́lá Telú tó tẹ ìlú Ìwó dó 13 Owewe 2019 Oríṣun àwòrán, Facebook/OMO Lamurudu Media Ni aye atijọ, ọpọ ọkunrin ni ọkan wọn maa n rẹwẹsi, ti wọn kii si dunnu ti wọn ba gbọ pe wọn bi obinrin gẹgẹ bii ọmọ tuntun.
 lọ ́ nà kejì , ò lè jẹ ́ wí pé bóyá nítorí pé ẹsẹ ̀ lásán tó fi rín nígbà náà tàbí nítorí pé aginjù tó fi orí là nígbà náà ló ṣe rò wí pè ibi tí òun ti rìn ti nàsẹ ̀ díẹ ̀ sí ọ ̀ dọ ̀ àbúrò òun lo ṣe dúró ni ibi tí a ń pè ní ijẹ ̀ bú-jẹ ̀ ṣà lónìí .
A o mu ẹkunrẹrẹ iroyin wa fun yin bo ba ṣe n lọ.
Wọ́n bá fi òróró yan Dafidi ní ọba lórí Israẹli.
Nitori awọn orilẹede ti o n tẹ oju ẹtọ ominira ati ṣe ẹsin to ba wuni mọlẹ nikan lofin orilẹede Amẹrika faye gba lati wa ninu iwe akọsilẹ bẹẹ.
OLUWA ta ìkùukùu bò wọ́n,ó sì pèsè iná láti tan ìmọ́lẹ̀ fún wọn lóru.
O ṣalaye pe ko ṣẹyin bi ajọ NNPC ṣe gba pe oun le din owo ti wọn fi n gbe epo wọle, ati eyi to n gba lori iye asiko ti awọn alagbata ba fi gbe epo si ọds rẹ.
Nkankan tó máa ń wuni púpọ̀ láti yà láwòrán ní àsìkò ìkórè tí a wà yìí ni àwọn ewéko àti àwọn igi.
0 162774 Orilẹede Ethiopia 1779 1.
Dafidi dáhùn pé, “Ìwọ ń bọ̀ wá bá mi jà pẹlu idà ati ọ̀kọ̀, ṣugbọn èmi ń bọ̀ wá pàdé rẹ ní orúkọ OLUWA àwọn ọmọ ogun, Ọlọrun àwọn ọmọ ogun Israẹli, tí ò ń pẹ̀gàn.
Gẹgẹbi, àgbà ninu olórin Yorùbá “Délé Òjó” ti kọ ni ọpọlọpọ ọdún sẹhin pe “Ilú Oyinbo dára, ọrẹ mi òtútù pọ̀, à ti gbọmọ lọwọ èkùrọ́ o ki ma i ṣojú bọ̀rọ̀”.
Amọ, o ni gẹgẹ bi ọrọ awọn agbofinro, ọkọ ileeṣẹ to n ṣẹ okuta, lo gbe awọn ohun elo ibugbamu ti wọn fi n sisẹ, eleyii to fa ibugbamu naa.
Ati awọn orilẹ-ede ti wọn ni awọn ofin isalẹ wọnyii: GHANA - Iwọ Oorun Afrika ni ilu yii wa.
Kami ni baba Akani; Akani yìí ni ó kó wahala bá Israẹli, nítorí pé ó rú òfin nípa àwọn ohun ìyàsọ́tọ̀.
Ọkàn rẹ̀ fà sí Dina ọmọ Jakọbu, ó nífẹ̀ẹ́ rẹ̀, ó sì sọ ọ̀rọ̀ rere fún un.
Nibayii, ikọ alaabo ti gba gbogbo agbegbe naa kan ti wọn ko si fun eeyan tabi ọkọ kankan laye lati gba ibi ti nkan ti ṣẹlẹ yii kọja.
Èmi gan ni mo pàdànù nípa ikú 'Chief Protocol mi' - Gomina Akeredolu Agbabọọlu aarin gbungbun Ilkay Gundogan lo kọkọ gba goolu sawọn Chelsea fun Manchester City lẹyin isẹju mejidinlogun ti ere bọọlu ọhun bẹrẹ ni papa iṣere Stamford Bridge.
Kí alufaa yẹ̀ ẹ́ wò, tí ibi tí àrùn yìí ti wú ní orí tabi iwájú rẹ̀ bá pọ́n, tí ó sì dàbí ẹ̀tẹ̀ lára rẹ̀, 
 Oríṣun àwòrán, AFP Àkọlé àwòrán, Ọpọ ẹmi lo ti bọ, ti aimọye dukai si sofo latọwọ awọn Fulani darandaran Bakannna ni Ọgbẹni Usman lati ipinlẹ Nasarawa ninu ọrọ to ba BBC Yoruba sọ ni emi naa fi ara mọ igbesẹ yi.
“Iná ni mo wá sọ sí ayé.
Ọba Jẹriko bá ranṣẹ sí Rahabu ó ní, “Kó àwọn ọkunrin tí wọn dé sọ́dọ̀ rẹ jáde wá, nítorí pé wọ́n wá ṣe amí ilẹ̀ yìí ni.
Lẹ́yìn àwọn alákòóso mejeejila wọnyi, alákòóso àgbà kan tún wà fún gbogbo ilẹ̀ Juda.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Tí mo ba ti múra bí ọkùnrin fi kọrin, kò sí ọ̀dọ̀ ààrẹ́ tí mi ò lè wọ̀- Erelu, ọmọ Elemure Ekiti Ohun to ṣẹlẹ lọjọ naa ni pe bi wolii ọhun ṣe n waasu lọwọ ni awọn ọmọ ijọ bẹrẹ si n fi owo si ẹsẹ rẹ gẹgẹ bi iṣe wọn.
OLUWA sì fi gbogbo ilẹ̀ náà hàn án láti Gileadi lọ, títí dé Dani, 
Nítorí náà ẹ má gbà fún ẹnikẹ́ni kí ó máa darí yín nípa nǹkan jíjẹ tabi nǹkan mímu, tabi nípa ọ̀rọ̀ àjọ̀dún tabi ti oṣù titun tabi ti Ọjọ́ Ìsinmi.
Ọkàn ilé fa Dafidi pupọ tóbẹ́ẹ̀ tí ó fi wí pé, “Báwo ni ìbá ti dùn tó, kí ẹnìkan bu omi wá fún mi mu, láti inú kànga tí ó wà ní ẹnubodè Bẹtilẹhẹmu.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Wùnmí Toríọlá: Toyin Abraham kìí se ọ̀gá mi nínú tíátà Oríṣun àwòrán, MERCY AIGBE/FACEBOOK Àkọlé àwòrán, Mercy Aigbe Mercy Aigbe Ọmọ ìlú Benin ní ìpínlẹ̀ Edo ni Mercy Aigbe sùgbọ́n tí a mọ̀ bí ẹni ń mowó nínú àwọn eré elédè Yorùbá.
Gómìnà fi kú pé àwọn yóò dẹ ọwọ́ òfin kóníléógbélé díẹ̀ ti àwọ̀n ènìyàn yóò maa jáde láàrin ààgo méje alẹ́ sí aago mẹ́fà ìdájí kí àwọn àgbẹ le maa ri iṣk wọ́n ṣe.
Oríṣun àwòrán, Instagram/hushpuppi Ninu awọn aworan rẹ nigba to wa ni kekere, a ri ibi to ti duro lara ọkọ nilu Eko ati awọn omiran to tọka si pe o ti gbe Naijiria daada, ki o to lọ si ilu okere.
Mọ Ọlọrun ní gbogbo ọ̀nà rẹ,yóo sì mú kí ọ̀nà rẹ tọ́.
Nítorí náà, OLUWA Ọlọrun àwọn ọmọ ogun ní,“Nítorí ohun tí wọ́n sọ yìí,wò ó, n óo jẹ́ kí ọ̀rọ̀ mi di iná lẹ́nu rẹ.
Pilatu dáhùn pé, “Èmi í ṣe Juu bí?
Bí ojú ọ̀tún rẹ bá mú ọ kọsẹ̀, yọ ọ́ sọnù.
Bakan naa ni Minisita fun ọrọ oṣiṣẹ, Chris Ngige; Minisita fun ọrọ epo bẹntirol, Timipre Silva; Festus Keyamo (SAN) wa nibi ipade naa.
 Ọmọ ọdún mẹ ́ fà ni .
Atọmọdọmọ yín yóo máa rúbọ sísun náà nígbà gbogbo lẹ́nu ọ̀nà àgọ́ àjọ, níwájú OLUWA, níbi tí n óo ti máa bá yín pàdé, tí n óo sì ti máa bá yín sọ̀rọ̀.
Owurọ ọjọ Abamẹta ni iroyin gbe e pe orilẹede Amẹrika ti fi ẹsun jibiti ogun miliọnu dọla ati kikowo pamọ silẹ okeere lọna aitọ kan oludasilẹ ile iṣẹ ọkọ ofurufu Air Peace.
Nigba to n ba BBC Yoruba sọrọ, Dokita Faduyile ni bawọn eeyan ti pejọ leti iboji ati bawọn agboku naa ṣe gbe oku Abba Kyari tako ilana ijina sira ẹni ti ajọ to n gbogun ti ajakalẹ aarun, NDCD la kalẹ.
Ẹni tí kò bá ṣiyèméjì nípa mi ṣe oríire!
Ahabu bá pàṣẹ fún ọ̀kan ninu àwọn òṣìṣẹ́ rẹ̀ ní ààfin pé kí ó lọ pe Mikaaya, ọmọ Imila, wá kíákíá.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ilé aṣòfin àgbà takò ìdájọ lori Omo-Agege Ẹgbẹ́ Alájùmọ̀se Ọbasanjọ́ di ẹgbẹ́ òsèlú ADC Íyanṣẹ́lòdì Johesu: Ìnira ará ìlú pọ síi Bakan naa lo ni awọn ọmọ 419 yii kan sa mọ awọn lọwọ, ti wọn si fi ọkọ ayọkẹlẹ, olowo iyebiye wọn silẹ, fẹsẹ fẹẹ.
 lẹ ́ yìn ọ ̀ pọ ̀ iṣẹ ́ abẹ àti àyẹ ̀ wò ìgb ̀ a-dégb ̀ a , physical therapy ,.
Èémí rẹ̀ dàbí odò tí ó ṣàn kọjá bèbè rẹ̀tí ó lè mu eniyan dé ọrùn.
Ìlẹ̀kùn ilè náà ṣí sílẹ̀ ó sì wọ inú rẹ̀ lọ.
AFCON 2019: Wo àwọn ẹranko tí wọ́n máa figagbaga ni Egypt
Ninu ọrọ rẹ, o sọ pe nilẹ Gẹẹsi ko si awọn ipenija ti awọn ara ilẹ Naijiria n koju bii ti ijinigbe tabi aisi eto ilera to peye.
Amọ osisẹ alarin fun ileesẹ to n sakoso oju popo nipinlẹ Ogun, Babatunde Akinbiyi ni wọn ti doola ẹmi obinrin ti ẹsẹ rẹ ha sabẹ ile ẹru naa, ti wọn si ti gbe lọ sile iwosan.
Àwọn aṣọ́de rí mi,bí wọ́n ṣe ń lọ káàkiri ìlú.
OLUWA ti ṣe sí ọ gẹ́gẹ́ bí ọ̀rọ̀ tí ó sọ láti ẹnu mi.
Ọmọwe Samuel Ọmọtọṣọ, tun ṣalaye pe wọn ti kọkọ yọ aṣofin Akinniyi ni ipo gẹgẹ bii akojanu ile loṣu karun un lati fi faa leti pe boya yoo yiwa pada.
Wọ́n ń sọkún níwájú mi; wọ́n ń wí pé kí n fún àwọn ní ẹran jẹ.
Gege bi abajade ipo ate ajo FIFA ti o jade lojoBo(Thursday), Naijiria dipo mẹ́tàdínláàdọ́ta mu lagbaye ninu ipo ate ajo ohun ti o sese jade.
Má kọ̀wé fipò sílẹ̀, àwọn àgbààgbà Yorùbá sọ fún Osinbajo Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
abadofin owo ekunwo osu ranse sile igbimo asoju-sofin laipẹ yii.
Ilẹ Afrika gbagbọ ninu agbara, ìṣe ati ihuwasi ẹranko ati ẹyẹ inu igbo pupọ yatọ si awọn ti Yuroopu ti wọn n fi orukọ à[wọ̀ pe ẹgbẹ ti wọn.
Má ta wá nù nítorí orúkọ rẹ,má sì fi àbùkù kan ìtẹ́ rẹ tí ó lógo.
Ó kọ́ mi ní ogun jíjàtóbẹ́ẹ̀ tí mo fi lè fa ọrun idẹ.
Amẹrika ti yọ àfikún owó Físà kúrò fún arìnrìnàjò Nàìjíríà Ọlọ́jọ́ padà dé!
wa lara iko agbaboolu merinla ajo CAF ti o fi mo balogun iko naa, Ikouwem Udoh
Iléeṣẹ́ ológun òfúrufú ti dárúkọ ẹni tó fi ọkọ̀ pa Tolulope Arotilẹ Ko pe ti abala keji ifẹsẹwọnsẹ ọhun bẹrẹ ti Mason Mount naa tun dana sun ile Manchester United lẹẹkeji.
“Ní ti ilé ìsìn tí ò ń kọ́ yìí, bí o bá pa gbogbo òfin mi mọ́, tí o sì tẹ̀lé ìlànà mi, n óo ṣe gbogbo ohun tí mo ṣèlérí fún Dafidi, baba rẹ, fún ọ.
Mo mọ̀ láti òní lọ pé, ìyàwó yìí lè lọ bímọ fún mi, bí ó bá bímọ fún mi, ki ń dúpẹ́ lọ́wọ́ Ọlọ́run ọba ki ń tọ́jú ọmọ tí o fi jínkí mi.
Ni ti obinrin to wa laarin wọn, oun sọ pe kọndọmu naa ti ko ṣiṣẹ daada mu ki oun ni oyun airotẹlẹ.
Ẹ kò sì gbọdọ̀ mú ohun ìríra wọ ilé yín, kí ẹ má baà di ẹni ìfibú gẹ́gẹ́ bí wọ́n ti jẹ́ ohun ìfibú.
Ìròyìn Kàyééfì BBC Yorùbá: Bí Ọba aládé ṣe jàjà bọ́ lọ́wọ́ àwọn afurasí ajínigbé
Òṣùpá dà bí ọ̀sán, bẹ́ẹ̀ ni bí wọ́n ti sùnlọ wọn-ọnnì, ọba kò lè sùn rárá, ó ń ytí gbiri káà kiri orí ibùsùn nítorí ìtumọ̀ adágùn odò yìí kò yé e.
Ezekwesili ti ṣe bẹbẹ nínú akitiyan ìdásílẹ̀ àwọn akẹ́kọ̀ọ́-bìnrin 200 tí ọmọ ẹgbẹ́ afẹ̀míṣòfo Ẹlẹ́sìn ìmale jí gbé ní ọdún 2014.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Badagry: Erékùṣù tí àwọn ọmọde ti n wọ odo ńlá láti lọ sílé ìwé Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Bakan naa lo sọ pe awọn olugbe inu ile ti ẹlikọpita naa ja lulẹ si, ti pada sile wọn.
Emi kii sun sita ni alẹ, mo maa n pada sile lẹyin ti mo ba jale tan ni ọ̀san gangan.
Yatọ si Tiamiyu Kazeem to dologbe yii, ọpọ igba lawọn eeyan ti fẹsun kan awọn oṣiṣẹ SARS yii pe wọn n tẹ oju ẹtọ awọn ọmọ Naijiria mọlẹ.
Eto ayẹwo ilera meji ọtọọtọ fi idi rẹ mulẹ pe ọkan lara awọn kindinrin obinrin naa ti poora.
Ọlọrun, Olùmọ̀ràn ọkàn, mọ èrò tí ó wà lọ́kàn Ẹ̀mí, nítorí Ẹ̀mí níí máa bẹ̀bẹ̀ fún àwọn eniyan Ọlọrun bí Ọlọrun fúnrarẹ̀ ti fẹ́.
ó ní, “Mo fẹ́ kí ẹ mọ̀ dájúdájú pé, bí ẹ kò bá yipada kí ẹ dàbí àwọn ọmọde, ẹ kò ní wọ ìjọba ọ̀run.
Ramadan bẹ̀rẹ̀ jákè-jádò àgbáyé Ramadan 2018: Wákàtí àwẹ̀ káàkiri àgbáyé Àdó olóró parí ọdún ìtúnu ààwẹ̀ Ramadan Wo àwọn orílẹ̀èdè tí wákàtí ààwẹ̀ wọn gùn ju ti Nàìjíríà lọ Ile iṣẹ ijọba apapọ yii tun paṣẹ pe ki awọn oṣ\\iṣẹ eleto aabo Naijiria fọwọsowọpọ ṣiṣẹ papọ lasiko ọdun itunnu aawẹ yii.
Bí ẹni tí ń rú ẹbọ náà bá dá a lóhùn pé “Jẹ́ kí á kọ́kọ́ sun ọ̀rá ẹran náà, lẹ́yìn náà kí o wá mú ohun tí ó bá wù ọ́.
"Ti ọkọ mi akọkọ ba pade mi lọna, yoo ma sọ fun mi pe ki n ko pada si ọdọ rẹ.
Ṣugbọn àwọn eniyan Juda tẹ̀lé Dafidi, ọba wọn, pẹlu ẹ̀mí òtítọ́, láti odò Jọdani títí dé Jerusalẹmu.
Awọn alasia: Isọri awọn miran to jẹ ki iwọde End SARS ni itumọ ni bi awọn eeyan kan ṣe n gbe asia orile¬̣-ede Naijiria lojuko iwọde naa.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Africa Eye: Wo ìtàn ìyá kan ìyá kan àtàwọn olè ajọ́mọgbé tó n ta ọmọ ní Kenya Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Secret Cults in Nigeria: Ìyá àti ọmọ tó wà nínú Márúwá bá ìjà ẹgbẹ́ òkùnkùn lọ10 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Border Closure reoppening: Àarẹ Buhari ní àti dẹ́kun fàyàwọ́ ogun ati ìbọn ló fa títi ẹnubodè pa, ṣùgbọ́n yóò di ṣíṣí padà láìpẹ́9 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Badirat Ajoke sọ pé òun fínnú-fíndọ̀ fi ààfìn Oyo sílẹ̀ ni, wọ́n kò lé òun9 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Victoria Kolawole: Òṣèré tíátà Yorùbá ní òun kò tíì ṣe ìgbéyáwó àmọ́ òun kò wá ọkọ''9 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Nítorí àwọn tí Ẹ̀mí Ọlọrun bá ń darí ni ọmọ Ọlọrun.
Agbẹnusọ ileeṣẹ ọlọpaa, Nnamdi Omoni lo fidi ọrọ naa mulẹ fawọn akọroyin.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ǹkan o rọgbọ níbi ìdìbò abẹ́lé PDP l'Osun Oyetola ni yóò sójú APC nínú ìbò Gómìnà Osun PDP yan awọn adari tuntun ni Ọsun Adeleke ni yóò kojú ọgbẹni Gboyega Oyetola ti ẹgbẹ òṣèlú APC nínú ìdìbò Gómìnà ìpínlẹ̀ Osun tí yóò wáyé ní ọjọ kejilelogun oṣù kẹsán ọdún 2018.
Lizzy Anjorin yóò jàre Toyin Abraham tó bá jẹ́ pé wọ́n lọ sílé ẹjọ́ - Yomi Fabiyi Ọ̀pọ̀ èèyàn ń bá mi ṣùn, ṣẹ́yún fún mi níbùdó ọmọ aláìgbọràn"" Irinajo Buhari silẹ okeere Akọsilẹ fihan pe Aaarẹ Buhari ti rinrin ajo lọ silẹ okeere nigba mọkanlelaadọta lati igba to ti di aarẹ Naijiria lọdun 2015."
Ó fi àyè gba ibinu rẹ̀;kò dá ẹ̀mí wọn sí,ó sì fi àjàkálẹ̀ àrùn pa wọ́n.
10 Àti pé, kíyèsíi, Sátánì ti fi sí ọkàn wọn láti pààrọ̀ àwọn ọ̀rọ̀ èyí tí ìwọ ti mú kí a kọ, tàbí tí ìwọ ti túmọ̀, àwọn èyí tí wọn ti lọ kúrò ní ọwọ́ rẹ.
Ọwọ́ tẹ́ àwọn ọkùnrin Fulani mẹ́ta tí wọ́n jí Màálù méjì kó ní Ogbomọṣọ- Àjọ NSCDC Ọmọ́ Yorùbá korò ojú sí Buhari bí kò ṣe fi orúkọ Obasanjo sọ ibùdókọ̀ ojú'rin Ọ̀nà tó fi le è mọ gbájúẹ̀ babaláwo - Ẹlẹ́buìbọn Bo tilẹ jẹ pe nnkan to fa ariyan-jiyan naa ko han si wa, amọ o foju han pe ìbọn ba ọ̀kan lara awọn ọmọde to wa ninu ọkọ ayọkẹlẹ naa, ti awọn ọlọpaa SARS da duro.
Bakan naa ni ọga ọlọpaa tun sọ pe ọlọpaa SARS ko gbọdọ da awọn araalu duro lati maa tu ẹru wọn mọ.
 Babajide Sanwo olu  wa fi idunnu re han bi awon eniyan  se n dibo won ni irọwọ ati irọsẹ.
Ó ti tó ìgbà díẹ̀ kan tí ó ti ń ṣiṣẹ́ pẹ̀lú ìyàwó rẹ̀ àti olùdásọ́rọ̀ òṣèlú tí ó gbajúmọ̀ n nì, Naky Soto, tí wọn sì ń ṣe ìgbéjáde àwọn fídíò àti ètò Ìgbóhùnsáfẹ́fẹ́ lórí ayélujára èyí tí ó dá lórí ìṣèlú àti ẹ̀tọ́ ọmọ ènìyàn ní Venezuela.
”Angẹli náà dá Gideoni lóhùn, ó ní, “N óo dúró títí tí o óo fi pada dé.
Òkété bórù mọ àwọn ọjọgbọ́n méji lọ́wọ́, UNIABUJA jù wọ́n síta Wọ́n f'ẹ̀sùn ọkọ̀ jíjí kan Naira Marley; Ó ní òun ni Buhari yóò gbé ìjọba fún Mo ṣẹ̀ṣẹ̀ já ọjà 10 mílíọ̀nù ní iná jó, ẹ dákún é gbà wá-Ọlọ́jà Mo ti gba pé ológun ni ọkọ mí- Aisha Buhari Iṣẹ̀dá fọ́nrán láti ọ́wọ́ Damilọ́la Oduolowu àti Yemisi Oyedepo Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí kan sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
Kì í ṣe pé kí n lè lo anfaani yìí ni mo ṣe ń sọ ohun tí mò ń sọ yìí.
Mo rí Ọ̀dọ́ Aguntan náà tí ó dúró lórí òkè Sioni, pẹlu àwọn ọ̀kẹ́ meje ó lé ẹgbaaji (144,000) eniyan tí a kọ orúkọ rẹ̀ ati orúkọ Baba rẹ̀ sí wọn níwájú.
Wọ́n ti ṣí ilé oúńjẹ oní ọgbọ̀n náírà (N30) ní Kano Ìdí tí mo ṣe fẹ́ yọ ayédèrú ìdí ńlá tí mo ní- Sophie Ìlú kò mọ ohunkóhun nípa iṣẹlẹ màálù tó kú nilu Ikarẹ- Oba Olukarẹ Ìgbà tí òògùn ẹ̀jẹ̀ ríru lè ṣiṣẹ́ jù rèé- Onímọ̀ Ẹkọ nipa ipẹtusaawọ lo kọ to si yege pẹlu ami keji nileewe giga fasiti, iyẹn second class upper (2.
Kí ni àjọ ajàfẹ́tọ́, Amnesty International, sọ?
"Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ààrẹ Buhari ní awọn eeyan Naijiria gbọdọ di opo iwa ootọ mu ki wọn si gbe igbe aye to duro daadaa Atẹjade naa fikun wipe, ohun ti aarẹ so ni pe pupọ ninu awọn ọdọ wọnyii ti ọjọ ori wọn kere ju ọgbọn ọdun lọ ni wọn ko kawe, sugbọn ti wọn n pariwo epo rọbi wa lorilẹede Naijiria, nitorina ki wọn joye ajinasẹ, ki eto ileegbe, ilera ati ekọ ọfẹ o maa wọle tọ wọn wa bẹẹ"" Atẹjade naa ni ko si bi aarẹ Buhari yoo na ika kòtọ si àwọn ọdọ orilẹede Naijiria nitoripe baba awọn ewe ati ọdọ orilẹede Naijiria ni."
O fí ǹkan tó ṣe pàtàkì kálẹ̀ nínú ọ̀rọ̀ Nàìjírríà láti maa rojọ́ Bobrisky.
O ni ẹnikẹni to ba ni ohun kan lati fi to ọlọpaa leti le fi ranṣẹ si adirẹsi yii- pressforabuja@police.
Ijọba naa si ni aṣẹ lati gba ọmọ lọwọ obi rẹ, ti wọn ba fi iya jẹ ẹ ni ọna aitọ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Coronavirus: Ẹ wo àwọn ìròyìn èké tó gbòde ní Áfíríkà torí àjàkálẹ̀ àrùn 6 Ẹrẹ̀nà 2020 Oríṣun àwòrán, Getty Images Yoruba ni ọrọ okeere, bi ko ba le kan, yoo din kan, bẹẹ si lo ri fun arun Coronavirus, nitori oniruuru awọn ayederu iroyin lo n lọ kiri nipa arun naa, tawọn eeyan ko lee fidi rẹ mulẹ nilẹ adulawọ.
Irọ́ ni pé a fẹ́ fowó kún owó iná mọ̀nàmọ̀nà- NERC Baṣọ̀run Gáà: Ó yan ọba mẹ́rin, tó sì pa ọba mẹ́rẹ̀ẹ̀rin àmọ́ ọba karùn-ún ló pa á Obabinrin Elizabeth II ṣàfihàn àwòrán orí adé mẹ́ta tó lè jé lẹ́yìn rẹ̀ Ìjàmbá ọkọ̀ òfurufú dínkù lọ̀dún 2019 pẹ́lú ìdá àádọ́ta nínú ọgọ́rùn ún Opin ọsẹ to kọja yii ni orilẹ-ede Amerika fi ibugbamu oloro pa Ọgbẹni Soleimani lori ẹsun pe o ti pẹ ti ọgagun naa ti n wa nidi iṣekupani awọn ọmọ ilẹ Amerika.
Lesser/Getty Àkọlé àwòrán, Ìgò ọtí méje àti sìgá ṣokùnfà ẹjọ́ ikú Ọkunrin kan ni ipinlẹ Ekiti, lorilẹede Naijiria ti ri idajọ iku he lẹyin to ji ọti ẹlẹrin dodo meje ati paali siga kan.
Àwọn Farisi bi Jesu nípa ìgbà tí ìjọba Ọlọrun yóo dé.
Awọn alabagbe Funmilayo ni l'owurọọjọ to pade iku gbigbona lọwọ Sunday Shodipẹ, ohun at'awọneeyan rẹ ni wọn jọ wa ni iyẹwu ki ki o to tọrọ gafara pe oun fẹ lọ tọ.
Aare tun so pe ijoba ko ni kaare lati mojuto eto aabo, ati idagbasoke  ekun naa.
Lilo awọn oogun oyinbo ti yoo mu ki homoonu ara o ji pepe.
•Ida marunlelaadọta ninu ọgọrun awọn osisẹ eleto ilera ni yoo gba ile wọn joko lẹka eto ilera, tawọn to ba wa lẹnu isẹ, yoo maa sisẹ diẹdiẹ, bẹẹ ni wọn ko ni gba alaisan tuntun wọlesileiwosan.
Nítorí náà ni àwọn ọmọbinrin yín ṣe di aṣẹ́wó, àwọn aya yín sì di alágbèrè.
Ẹ̀kọ́ kejì ni pé ogun Ìjàyè kọ wa lati gba àlàáfíà láàyè láàárín ara wa, lai fi ààyè gba èdè aiyede àbí ìkùnsínú.
Coronavirus tips: Kí ni a ń pè ní fẹntilétọ̀ àtipé kí ni pàtàkì rẹ̀?
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù George Weah se ibura wọlẹ gẹgẹ bi aarẹ orilẹede Liberia 22 Sẹ́rẹ́ 2018 Oríṣun àwòrán, AFP Àkọlé àwòrán, George Weah ibura gege bi aare ni papa isere niwaju awon eniyan bi egberun marundinlogoji Wọn ti bura wọle fun George Weah gẹgẹ bi aarẹ tuntun fun orilẹede Liberia.
Sọ pé, OLUWA ní kí o sọ fún un pé ṣé o ti pa ọkunrin yìí, o sì ti gba ọgbà àjàrà rẹ̀?
92%, eyi ti o gbe peeli ju ti ateyinwa lo, bi 1.
nítorí pé ohunkohun tí a bá fẹ́ ń bọ̀ síwájú wa ni, kò sí pé à ń bèèrè lọ́wọ́ ẹnikẹ́ni, kí a tó rii.
Tabi títí ayé ni o óo fi máa bínú?
Ó mú mi wọ inú gbọ̀ngàn tí ó wà ninu ilé OLUWA; mo bá rí àwọn ọkunrin mẹẹdọgbọn kan, wọ́n dúró lẹ́nu ọ̀nà tẹmpili ilé OLUWA, láàrin ìloro ati pẹpẹ.
mi ni pe Allah  yoo gbọ adura ati ẹbẹ gbogbo
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Victor Moses: Ọmọ pásítọ̀, ìjà ẹ̀sìn ni Kaduna fa ikú àwọn obí rẹ̀ 15 Ògún 2018 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 17 Ògún 2018 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Victor Moses ni ile ti ya Victor Moses kede pe oun ti fẹ̀yinti lẹyin to ti gba idije mẹtadinlogoji fun Naijiria ní Ọjọru.
” OLUWA bá sọ fún un pé, “Bẹ́ẹ̀ ni àwọn ọmọ rẹ yóo ṣe pọ̀ tó.
Ọjọ Aiku, ọjọ Kẹfa, Osu Kẹwa, ọdun 2019 ni gbajugbaja agbohunsafẹfẹnaa, Kunle Olasope jade laye lẹni ọgọrin ọdun amọ bi onirese rẹ ko ba fin igba mọ, eyi to ti fin silẹ ko yẹ ko parun.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù #FreeOurGirls: Àwọn ènìyàn n fi nkan kun àwòrán àarẹ Pierre Nkurunziza 25 Ẹrẹ̀nà 2019 Oríṣun àwòrán, @iburundi Ọpọlọpọ eniyan lo ti n bu ẹnu ẹtẹ lu aarẹ orilẹede Burundi, Pierre Nkurunziza fun bo ṣe paṣẹ pe ki wọn fi awọn ọmọdebinrin mẹta sẹwọn nitori pe wọn fi nnkan kun aworan rẹ ninu iwe kika wọn.
Kò sí ìdí méjì ti EU fi yọ àwọn orílẹ̀-èdè ilẹ̀ Afírika yìí sílẹ̀ ju bí ààrùn Coronavirus ṣe n tànkálẹ̀ àti bi ìjọba kò ṣe kọbi ara sí ọ̀nà ti yóò fi dáwọ́ rẹ̀ dúró lọ.
Nígbà náà ni Dariusi ọba désì ìwé Tatenai pada, ó ní,“Sí Tatenai, gomina agbègbè òdìkejì odò, ati Ṣetari Bosenai ati àwọn gomina ẹlẹgbẹ́ rẹ̀ tí wọ́n wà ní agbègbè òdìkejì odò.
Auxiliary lo ń jà káàkiri ìlú Ibadan lọ́jọ́ Aje, ẹgbẹ́ ọlọkọ èrò NURTW kọ - Ejiogbe Ìyàwó mi ṣẹ̀ṣẹ̀ bímọ tuntun, kò si oúnjẹ fún wa torí ìgbélé Coronavirus- Yakubu Atirobẹ́lẹ́ṣindọ́gba ni ọ̀pọ̀ ọ̀dọ́ ní ìsin yìí-Ọlọ́fàiná Baba Latin ṣe bẹbẹ lori èto Se o láya, sùgbọ́n.
Bẹ́ẹ̀ náà ni ó rí fún àwọn eniyan wọnyi lónìí.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Awọn arinrinajo Hajj orilẹede Naijiria yoo bẹrẹ si sanwo ori ni Saudi 3 Ẹrẹ̀nà 2018 Àkọlé àwòrán, Ijọba ilẹ Saudi mu ni dandan fun awọn aririnajo Hajj lati san ẹgbẹrun meji owo Riyal Awọn alasẹ ilu Saudi Arabia ti sọ pe, o di dandan fun awọn arinrinajo ti wọn ba wa lati orilẹede Naijiria, ni pataki, awọn ti wọn ti lọ fun Hajj tabi Umrah ni bi ọdun meji sẹyin lati maa san owo to to ẹgbẹrun mẹtalelọgọjọ ni owo Naira.
O sọ eyi nibi ipade oniroyin kan, ti wọn ti pin ẹbun fun awọn to jẹ lori eto naa, eyi to wa sopin lọjọ Aiku.
Obinrin naa ni tirẹ n fẹ lati ta awọn ọmọ ti wọn ti bi eyi si lodi si imọran ati ẹkọ ti a n gba wọn.
Ẹ jẹ́ kí ìmúrasílẹ̀ láti waasu ìyìn rere alaafia jẹ́ bàtà ẹsẹ̀ yín.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Tanzania: Àwọn Ìbejì tó so papọ̀ dolóògbẹ́ lọ́mọ ọdún 22 3 Òkùdu 2018 Àkọlé àwòrán, Ààrẹ orílẹ̀èdé Tanzania, John Magufuli bànújẹ́ nípa ikú àwọn Ìbejì tó so papọ̀ náà Awọn ibeji to so papọ lorilẹede Tanzania, Maria ati Consolata Mwakikuti ti di oloogbe lẹyin ti ọkan wọn kọo lati sisẹ(heart failure).
Mò ń bèèrè, àwọn ta ni ó gbọ́ tí wọ́n ṣọ̀tẹ̀?
Mo tún bèèrè: ǹjẹ́ nígbà tí àwọn Juu kọsẹ̀, ṣé wọ́n ṣubú gbé ni?
ó bá lọ sí ọ̀dọ̀ ọba Israẹli pẹlu ìwé náà.
ni ijoba aare Muhammadu Buhari ti se lara rẹ ni gbigbokun ti iwa ibajẹ ,
Akọsilẹ ajọ isọkan agbaye fihan pe ẹgbẹrun lọna ẹgbẹ̀ta ọmọ ni ko ti i le lọ sileewe.
Àbàlúyẹ̀gẹ̀, lásán kí ‘Gún ò n’írun lórí.
ero igbalode silẹ, ni lati se agbekalẹ imọ ẹrọ  ti awon ile-ifowopamọ yoo maa lo.
"Bayii ni àtẹjáde Airpeace ṣe lọ ""Ní òwúrọ òni, ní dédé ààgo mẹsàn kọja iṣẹ́jú mẹwaà ni MMA1 nílù Eko ni bàà'lú Airpeace to n lọ Owerri n gbìyànju láti gbéra nigbati ọkunrin kan ti ko ti to ọmọ ogun ọdun bẹ jáde lati inu igbó lójú ọ̀nà ti bààlu yòó gbà láti sá tèlé bàálú náà."
”Ẹ yipada sí OLUWA Ọlọrun yín,nítorí olóore-ọ̀fẹ́ ati aláàánú ni.
Bi aje gbogbo ẹsun yii ba wa si mọ Ibrahim Magu lori, o tumọ si pe, ijọba ti bọs'ọja bayii lati wa elomiran ti yoo rọpo rẹ gẹgẹ bi alaga ajọ EFCC.
Oríṣun àwòrán, Facebook/ANFASC Owo ti ẹgbẹ ololufẹ agbabọọlu Naijiria naa fun mama Arsenal ni ṣe ẹgbẹrun un lọna ọta le lugba o din mẹwaa.
"Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Mo fẹ́ ọkọ mi torí bó se ń kọrin, kìí se torí owó - Ìyàwó Aràrá Mo fẹ́ kí àyẹyẹ ìgbeyàwó mi dùn ni mo se bú sẹ́kún - Ọkọ ìyàwó ẹlẹ́kún ""Ọ̀pọ̀ ń gbàdúrà kí àwọn ní HIV báyìí"" Beautiful Nubia - Orin mi kìí ṣe orin lásán Ìtàn tó wà nídi òwe ‘Sebótimọ Ẹlẹ́wà Sàpọ́n’ O fikun pe Ọ̀nà ni oun maa n rọ fun Ọọ̀ni ti Ilé Ifẹ̀, Ọba Adeyẹye Ẹnitan Ogunwusi, Ọ̀jájá Kejì, lasiko to ba n jade bọ, ti gbogbo awọn eeyan to ba si ni lero lati se ibi yoo gbagbe ti oun ba ti n mi sẹ́ẹ́rẹ́ oun."
Atẹjade kan ti ijọba ipinlẹ Eko fisita lọjọ Etí kede pe ofin konile o gbele naa yoo maa mulẹ bayii lati aago mẹwa alẹ si mẹfa owurọ.
eto idagbasoke yoo se deba  orile ede
” Àwọn ẹbọ tí wọn ń rú nìyí gẹ́gẹ́ bí ìlànà ti Òfin.
'Àrùn Coronavirus ló pá adarí ètò ìṣúná Àjọ NDDC ' Ajọ Niger Delta Development Commission ti kede pe arun Coronavirus lo pa adari eto isuna, Ibanga Etang.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Contortionist: Mo lè gbé ìfun mi pamọ́ ki n tún sé èémí pẹ́!
Aarẹ wa se apejuwe isẹlẹ naa to waye ni nipinlẹ Borno to wa ni ẹkun ariwa orilẹede Naijiria bii 'isẹlẹ laabi' ti ko ni lọ lasan, lai ni 'ipa buruku'.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Taiwo Akinkunmi, ọmọ Ibadan tó ya àsìá Nàíjíríà Ayinla Ọmọwura, orin èébú àti oríyìn lo fi di ọ̀rẹ́ àwọ̀n obìnrin Iṣọla Oyenusi rèé, ẹnití ìfẹ́ obìnrin ṣun dé ìwà ìdigunjalè 'Èèyàn mi mẹ́ta ló wà nínú ọkọ̀ ojú omi tó dà nù l'Eko!
Jehoṣafati, ọmọ Parua, ni alákòóso agbègbè Isakari.
Ni wọn ba yii si iyanṣẹlodi ọlọjọ mẹta lẹyin eyi ti Emmanuel sọ pe awn yoo pada sẹnu iṣẹ ṣugbọn bi ijọba ba kọ ti wọn o si ṣe nkankan, iyanṣẹlodi ọlọjọ gbọin ni yoo ku.
Àwọn ìloro wà yí i ká, ọ̀kọ̀ọ̀kan wọn gùn ní igbọnwọ mẹẹdọgbọn (mita 12½), wọ́n sì fẹ̀ ní igbọnwọ marun-un (mita 2½).
Ó rí àwọn tí ń ta mààlúù, aguntan, ati ẹyẹlé ninu àgbàlá Tẹmpili, ati àwọn tí ń ṣe pàṣípààrọ̀ owó.
Bakan naa ni kikọ ile si awọn agbegbe ti ọdọ wa naa le fa ijamba omiyale ati agbara ya sọọbu.
Ǹ jẹ́ bí ọ̀rẹ́ ẹni tó kú yìí ṣe bẹ̀rẹ̀ pé kí òun náà ó bá wọn da yẹ̀pẹ̀ sínú ibojì pẹ̀lú ẹkún èké lójú ni gbogbo owó tí òun àti ọ̀rẹ́ rẹ̀ dà sínú ibojì òkú.
Wọn ti kọkọ ni irọ ni iroyin naa ti wọn si gba mọ awọn oniroyin ṣugbọn wọn pada rẹ ara wọn silẹ nigba ti fasiti naa tun funa mọ ọ̀rọ̀ ọhun.
Àwọn àsọtẹ́lẹ̀ tó já s'ófo lórí ìdìbò 2019 Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Lọjọ Aje yi ni adajọ ni ki wọn fi Sẹnẹtọ Ali Ndume to ṣe oniduro Maina naa si ọgba ẹwọn to wa ni Kuje titi ti yoo fi san owo oniduro aadọta miliọnu Naira.
Trump ti gbé òdòdó ìrántí sójú oórì akọni lójú ìjà Iléeṣé MTN ti san bíliọnù N55 owó ìtanràn wọn tó kù -MTN Atẹjade naa tun tẹsiwaju, o ni bi o ba si jẹ pe oṣupa ko le ni ọjọ aje, a jẹ wi pe, ọjọru, ọjọ karun oṣu kẹfa ni ọdun itunu awẹ fawọn Musulumi yoo bọ si.
Eeyan marundinlaadọrun un ninu wọn lo wa lati ipinlẹ Eko nikan, nigba ti mejilelaadọrin wa lati ipinlẹ Oyo.
"Eyitayo Jegede ni lootọ Covid 19 n ṣọṣẹ lagbaye lọwọ lọwọ, amọ ""lagbara Ọlọrun, a o pese iṣẹ ọwọ pupọ fawọn ọdọ""."
Fún igba akọkọ ni ọdun mẹwàá, Messi ko sí ninu awọn mẹta akọkọ.
Àwọn ọmọge wọ gàù l'Abuja nítorí asọ péńpé Ninu ifọrọwerọ rẹ pẹlu BBC news Yoruba, alukoro ileewe fasiti OAU, Abiọdun Olarewaju ṣalaye pe ni nnkan bi agogo mẹjọ abọ si mẹsan alẹ ọjọ aiku ni wọn ji ọjọgbọn naa gbe.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Mercy Aigbe, Lateef Adedimeji, Ayoola Ayolola kó sọ́wọ́ ìbéèrè kàbìtì, ó di gbọin!
Adagun odo ti wọn fi biliọnu marun-un dọla kọ naa lo n fa aawọ laarin orilẹ ede Ethiopia, Egypt ati Sudan.
Ìtàn kẹta jẹ ́ èyí tí baba mí gan-an sọ fún mi kí títán tó dé sí i ní dún 1966 .
Ọrọ Ibori naa si ni ọpọ gbagbọ pe o fa yiyọ ti wọn yọ nipo alaga EFCC.
O ni eyi lo mu ki awọn ọdọ ilu fariga ti wọn lọ ya bo agọ ọlọpaa Elimgbu.
O ni ẹyẹ igun, awọ erin, ifun erin, ori ẹkun ati ẹdọ inaki loun fi owo gbajuẹ ọhun ra.
O fikun ọrọ rẹ pe Bibeli ko sọ nibi kankan pe o di dandan fun ẹnikẹni lati san owo ori niwọn igba to jẹ pe gbogbo awọn onigbagbọ ti di ọkan ṣoṣo ninu Kristi.
Angelique kidjo ni asiko to fun idọgba laarin akọ ati abo
Ǹjẹ́ o mọ ìyàtọ̀ ojúṣe ọlọ́pàá, VIO, FRSC àti LASTMA lójú pópó?
ipade naa ni oludamoran fun ijoba lori eto aabo , Babagana Monguno, adele oludari
Esi adari ikọ Amọtẹkun ni ipinlẹ Ọyọ lori ọr naa.
Ọba bá bèèrè pé, “Irú ọkunrin wo ni ó wá pàdé yín lójú ọ̀nà, tí ó sọ bẹ́ẹ̀ fun yín?
Wọn fi ye ni pe aarẹ Trump ko darapọ mọ ijọ kankan ni pato, ẹẹkọọkan lo maa n lọ jọsin to si ti sọ ọ ni ọpọ igba pe oun ko fẹran lai maa tọrọ idarijin ẹṣẹ lọwọ Ọlọrun.
Pẹlu bẹ́ẹ̀ náà, ajá a máa wá lá egbò ara rẹ̀.
”O fikun un pe, o je ohun ibanuje pupo fun oun, bi orisirisi ikolu se n waye lorile-ede yii lotun-losi.
Ẹ gbọdọ̀ pa àwọn ìlànà, ati àwọn òfin mi wọnyi mọ́, ẹ kò gbọdọ̀ ṣe èyíkéyìí ninu àwọn ohun ìríra wọnyi, kì báà jẹ́ onílé ninu yín, tabi àlejò tí ń ṣe àtìpó láàrin yín.
Omi ara Ọ̀pọ̀lọ́ jẹ́ ẹlẹ́rìndòdò tó ń mára jípépé, ẹ máa mú Iya Rainbow jẹ́ gbajúmọ̀, àmọ́ kí lo mọ̀ nípa rẹ̀?
Ààrẹ ẹgbẹ́ nàá, Ayuba Wabba, fi ìkìlọ̀ nàá síta láìpẹ́ yìí lásìkò ìpàdé ìjíròrò t'ẹ́gbẹ́ nàá ṣe nílùú Abuja ní ìmúrasílẹ̀ fún ayẹyẹ ọjọ́ àwọn òṣìṣẹ́ fún ọdún 2018.
Ọrọ pọ ninu iwe kọbọ fọnran ifọrọwanilẹnuwo pẹlu Wole Soyinka.
- Mala Gomina Mala Buni to maa tukọ ipinlẹ Yobe di 2023 ni oun ti ṣetan lati kọ opọlọpọ ile iwe alakọbẹrẹ ati ti girama pupọ sii.
Òun yóo sì fi ọmọbinrin òun fún olúwarẹ̀, ilé baba rẹ̀ yóo sì di òmìnira ní ilẹ̀ Israẹli: kò ní san owó orí mọ́.
Ogbeni Flake ti o n daari igbimo to n risi oro ile-okeere  nile igbimo asofin orile-ede naa ni o se agbekale awon ofin afiyajeni ti o wa lori orile-ede naa ninu osu keeji odun yi labe isakoso Aare Robert Mugabe ti o lo ogun odun lori aleefa latari laasigbo oloselu  to be sile  lorile-ede Zimbabwe.
Bẹẹ ni ọjọ naa wa to si tun lọ, ko ma sohun to ṣẹlẹ; koda, awọn ẹrọ ayarabiaṣa gan an ko pafuka.
Tabi kí ni ẹ óo fi bora?
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Kayode Abiara: Ọmọ Nàíjíríà, ẹ má ba ọkàn jẹ́ lórí ààbò tó mẹ́hẹ, ewu ìgbà ìkẹyìn ló jẹ́ Ọba Lamidi Adeyẹmi, òṣìṣẹ́ adójútòfò àti Abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò kó tó jọba Daura kò tan mọ́ Buhari àmọ́ òun àti ọmọ rẹ̀ ti fẹ́ ba ẹbí mi jẹ́ - Aisha figbe ta Ọdún ìbejì sọkutu-wọ̀wọ̀ ní Igboọrà, àṣírí bí wọn ṣe ń bí ìbejì tú Taló ya fídíò ibi tí Aisha Buhari ti ń bínú ní Aso Rock?
Gbogbo wọn ni wọ́n mu omi ẹ̀mí kan náà, nítorí wọ́n mu omi tí ó jáde láti inú òkúta ẹ̀mí tí ó ń tẹ̀lé wọn.
Kò gbọdọ̀ lọ sí ibi tí wọ́n bá tẹ́ òkú sí, tabi kí ó sọ ara rẹ̀ di aláìmọ́, kì báà jẹ́ òkú baba rẹ̀ tabi ti ìyá rẹ̀.
Ẹni tí ó jókòó lórí ìtẹ́ náà sọ pé, “Mò ń sọ ohun gbogbo di titun.
Ogun ti Ìjọba tuntun ni Nigeria gbé ti iwà ibàjẹ́ lati igbà ti ará ilú ti dibò yan Ìjọba tuntun -Muhammadu  Buhari àti Yẹmi Osinbajo, ni bi ọdún kan sẹhin ni lati jẹ ki àwọn tó hu iwa ibaje jẹ èrè iṣẹ́ ibi, ki wọn si gba owó iwà ibàjẹ́ padà si àpò ilú.
Oríṣun àwòrán, Other Aarẹ tẹlẹri lorilẹede Naijiria, Olusegun Obasanjo ti sọ idi ti oun fi ti ilẹkun ile ijọsin mọ awọn oṣiṣẹ rẹ ati ojulumọ, to wa si ibi ayẹyẹ oku iya iyawo rẹ ni Ọjọ Ẹti.
Oríṣun àwòrán, Screenshot/twitter Àkọlé àwòrán, Toyin poora lẹyin to figbe ta nipa ifipabanilopo loju opo Twitter - ka ohun ta mọ nipa iku rẹ Oluwatoyin Salau jẹ ọkan gbogi ninu awọn to n fẹhonu han lori iwa ifiyajẹni si ara ilu lati ọwọ awọn ọlọpaa.
Nigba ti wọn n ba BBC Yoruba sọrọ, tọkọtaya Abdulquadri ni ọpọ ikorira, idẹyẹsi ati aropin lawọn n koju lọdọ awọn eeyan awujọ, ti wọn ro pe awọn ko le se rere laye.
Lẹ́gbẹ̀ẹ́ ìpín ti Juda ni ilẹ̀ tí ẹ óo yà sọ́tọ̀ fún OLUWA yóo wà.
Igbakeji aare orile-ede Naijjiria teleri, ti O tun je okan gbogi lara awon oludije dupo aare orile-ede Naijiria, Alhaji Atiku Abubakar ti sabewo sipinle Benue.
Eyi lo mu ki awọn ara ilu lẹkun Guusu Iwọ-Oorun, Guusu Iwọ-Oorun ati Ariwa Naijira figbe sita lorii iya ti wọn n jẹ leyii ti ijọba si n kigbe ẹ ma fọwọ loorekoore.
Inec wa rọ awọn oloselu to n kopa ninu eto idibo 2019, lati seto ipolongo ibo wọn ni pẹlẹ-putu, ki wọn si yago fun iwa jagidijagan ni gbogbo ọna, tabi awọn ọrọ alufansa.
Ko pẹ ti abala keji idije naa bẹrẹ ni William tun fi kun omije oju ẹgbẹ agbabọọlu Everton nigba to gba bọọlu sinu awọn.
Àfi bí ẹ bá ti kùnà nígbà tí ẹ yẹ ara yín wò!
Ọdaran náà ni asẹ ǹkan ti ìyàwo rẹ̀ fi n gbowo ni Banki lọ́wọ́ nínú ọgbà ẹwọn to n lo lati rà tàbi ta bo ṣe wù ú nínú ọgbà ẹwọn to wá.
Oríṣun àwòrán, TWITTER ''Richard ni ọmọ ọkunrin kan ṣoṣo ti awọn obi rẹ bi.
Ki lawọn ọmọ Naijiria sọ Awọn ọmọ Naijiria ko jẹ ki ọrọ Adesina balẹ ki wọn to bẹrẹ si ni fun lesi pada loju opo Twitter.
Abẹsẹkubiojo naa ni igba ti ẹbi oun kan pe akiyesi oun si ifẹhonuhan naa lo mu oun ka itan Naijiria ati ọrọ SARS daada.
Gómìnà sọ èyí di mímọ lónìí ọjọ́bọ̀ lásìkò to n ba awọn alatilẹyin sọrọ nibi ti wọn ti ń dáwọ̀ọ́ ìdùnù lóri abájade ìdájọ ilé ẹjọ kòtẹ́milọ́rùn to wáyé nílùú Abuja.
Ẹ mọ̀ dájú pé OLUWA ni Ọlọrun,òun ló dá wa, òun ló ni wá;àwa ni eniyan rẹ̀,àwa sì ni agbo aguntan rẹ̀.
Oríṣun àwòrán, Islamic State Propaganda Àkọlé àwòrán, Bayii ni IS ṣe maa n kóra jọ ko to o ṣe ikọlu to ba l'agbara Central Africa: Wilayah Wasat Ifriqyah ni IS pe orúkọ rẹ ni orilẹ-ede Democratic Republic of Congo (DRC) ati Mozambique.
Iroyin sọ pe Testimony, ọmọ ọdun mẹrin ti wọn lu pa, ni wọn gbe lọ si ileewosan ijọba to wa nilu Akurẹ lọjọru ọsẹ to kọja pẹlu oniruru apa lara rẹ.
Ó ṣe nǹkan burúkú lójú OLUWA; ó tẹ̀lé ìwà ẹ̀ṣẹ̀ Jeroboamu, ọmọ Nebati, tí ó mú Israẹli dẹ́ṣẹ̀.
Afunrasí ẹ̀sùn jìbìtì ló ni iléeṣẹ́ tó ń ṣe ìwé àṣẹ wọléwọ̀de ní Nàìjíríà Òfìfo ṣọ́ọ̀ṣì pa aṣọ dà fún àwọn Páṣítọ̀ Nàìjíríà Èèyàn 16 míràn tún ti ní àrùn Coronavirus ní Naijiria Àwọn olùgbé ìpínlẹ̀ Ọ̀ṣun ya bo ibùdó ìdìbò láti gba oúnjẹ Coronavirus Cristiano Ronaldo ti gba gbajugbaja ami ẹyẹ Ballon d'Or fun igba marun un ọtọtọ, Lionel Messi nikan lo gba a juu lọ pẹlu mẹfa to gba.
Ọlọrun Tún Dá Babiloni lẹ́jọ́ sí i.
Dafidi wà ní orí òkè kan tí wọ́n mọ odi yípo, ọ̀wọ́ àwọn ọmọ ogun Filistini kan ti gba Bẹtilẹhẹmu, wọ́n sì wà níbẹ̀.
A o maa mu esi wọn wa fun yin ni kete ti wọn ba ti fesi lori ọrọ yi.
Bakan naa lo sọ pataki gbigbe aṣa Yoruba ga to maa n hande ninu iṣẹ oun Àwọn orílẹ̀èdè àjọ ECOWAS yóò máa ná owó kan nàá l'ọ́dún 2020 Ta ni awàdà rẹ̀ wú u yín lórí jù ní Yollywood?
Bi nkan ṣe ri gẹlẹ, nigba mii ẹfẹ, ọrọ to le koko ati bẹẹ bẹẹ lọ a maa jẹyọ ninu itan rẹ.
Lasiko ti awọn ọmọ ẹgbẹ akọroyin ni ipinlẹ Ọyọ fi bẹẹ wo nilee rẹ to wa lagbegbe Oluyọle nilu ibadan ni arabinrin Florence Ajimọbi sọrọ idaniloju naa.
Ali ni:“A ti pese eto aabo to peye si gbogbo ijọba ibilẹ ogún to wa ni ipinle Bauchi.
Wọn yóo wí pé, ‘A ti parun patapata; ó ti pa ìpín àwọn eniyan mi dà; ẹ wò bí ó ti yí i kúrò lọ́dọ̀ mi, ó pín ilẹ̀ wa fún àwọn tí wọ́n ṣẹgun wa.
kikopa ninu idibo naa, ti won yoo si tun ri daju pe eto idibo waye nirowo-rose
Tẹlẹ, o ti jẹ alaga ile igbimọ aṣofin agba nipa ibaṣepọ ilẹ okere to si ti fi eyi yangan gan pe oun ti pade awan adari pataki lagbaye ni gbogbo ọdun marundinlaadọta sẹyin.
Iyawo gomina ipinle Eko, iyaafin Bolanle Ambode ti ro awon alaboyun ati awon ti o n to omo lowo lati mu fifun omo loyan lokunkundun.
Ẹ̀nìà ní láti tọ ọ̀nà tààrà tó wà létí odò títí dé òpin rẹ̀ kí ó tó tún sọdá afárá kọjá odò.
Ẹ gbọ́ ohun tí Desmond Elliot sọ lórí ayélujára tó bí àwọn ọmọ Nàìjíríà nínú Bọ́ọ̀sì ìrìnà 106 tuntun yóò máa ná Ibadan sí Eko àtàwọn ìpínlẹ̀ míì - Seyi Makinde Kìí ṣe ebi, ìyà tàbí ìṣẹ́ ló mú kí wọ́n yabo àwọn ilé ìkẹ́rùsí - Femi Adeshina Wo bí o ṣe le fi orúkọ sílẹ̀ láti gbà nínú N75b tí ìjọba fẹ́ ẹ̀ fún àwọn ọ̀dọ́ láti dá iṣẹ́ sílẹ̀ Pẹlu bi awọn oloṣelu ati araalu ṣe n takurọsọ lẹnu lọọlọ yi, a ṣe akojọpọ awọn oloṣelu marun un ti ọrọ ẹnu wọn tabi ihuwasi wọn ti mu ki ara ilu gbena woju wọn ni Naijiria.
Ẹnìkejì, Haruna Abubakar, rí ikú tirẹ̀ he nígbà tí ó súnmọ́ erin náà láti ya foto, ti ọkan nínú wọn si ta nípàá, èyí ló ṣe okùfà ikú rẹ̀ ní dédé ààgo mẹ́rin ìrọ̀lẹ́ Ólóri òun ni aláṣẹ Yankari ló ti ló kí àwọn ẹbí àwọn tí ìṣẹ̀lẹ̀ náà ṣẹ̀lẹ̀ sí.
Won da ipinle Osun to wa ni ila Gusu sile ni osu kejo, lojo kẹ́tàdínlọ́gbọ̀n  ọdun 1991, lati ara ipinle Oyo.
Oríṣun àwòrán, Garba Shehu Àkọlé àwòrán, Aarẹ Buhari nigba ti o n gba abọ iwadi igbimọ to ṣiṣẹ lori ẹkunwo owo oṣu oṣiṣẹ Bakan naa ni o tun ṣe pataki, ki awọn ijọba ipinlẹ gba lati mu ofin naa lo.
Wọ́n bá mú un, wọ́n wọ́ ọ jáde kúrò ninu Tẹmpili.
Ninu idije agbaye to n lo lowo lorile-ede Russia, France yoo maa waako pelu Belgium nipele keji si asekagba idije agbaye ni papa isere Saint Petersburgh.
O Fagunwa, Adebayo Faleti, Akinwumi Iṣọla, Lawuyi Ogunniran àti Oladejo Okediji ṣiṣẹ silẹ ki wọn to lọ3 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Akomolede Oyo round up: Àwọn Olúkọ ìpínlẹ̀ Oyo fakọyọ lórí ètò Akọ́mọlédè àti Àṣà púpọ̀27 Bélú 2020 7:03 Fídíò, Olumuyiwa Bolade Adedeji Military Bruitality: Bí arákùnrin onípèníjà ara tí sọ́jà lù ṣe dé, Duration 7,035 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 1:29 Fídíò, India: Ẹ wo bí àwọn ènìyàn ṣe dóòlà èmí erin tó jálulẹ̀, Duration 1,296 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Èyí tí a wò jùlọ 5:03 Fídíò, Omolola Arohunmolase Welder: Mo ti fí iṣẹ́ 'Welder' gbayì láwùjọ, tó mo fi tọ́ ọmọ yanjú, Duration 5,039 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 5:39 Fídíò, Akomolede ati Asa lori BBC: Olùkọ́ Kikelomo Ogunboye tan ìmọ́lẹ̀ sí ìwà olè ọ̀gá ọlọ́pàá Audu gẹ́gẹ́ bí àwòkọ́ṣe àsìkò yìí, Duration 5,398 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 4:11 Fídíò, Oba Adeyeye Ogunwusi: Ojú mi ti rí lọ́pọ̀ lọpọ̀, ọ̀pọ̀ èèyàn ni kò tilẹ̀ gbàgbọ́ pé mo lè jọba- Ooni, Duration 4,117 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 4:43 Fídíò, Promise Akinlade: ọmọ ọdún mọ́kànlá tó ń fi ìlù dárà bíi àgbàlagbà sọ̀rọ̀ nípa tálẹ́ǹtì rẹ̀, Duration 4,437 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 0:59 Gbọ́, Ìsẹ̀lẹ̀ jákèjádò orílẹ̀èdè àgbáyé láàárín ìṣẹ́jú kan, Duration 0,59wákàtí 5 sẹ́yìn 7:03 Fídíò, Olumuyiwa Bolade Adedeji Military Bruitality: Bí arákùnrin onípèníjà ara tí sọ́jà lù ṣe dé, Duration 7,035 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 4:45 Fídíò, Yoruba Films: Ẹ̀ẹ́ bẹ̀ mi kúrò láyé ni, mi ò lè kú - Fadeyi Oloro, Duration 4,4526 Èrèlè 2020 2:48 Fídíò, Esther Ajayi: Èmi náà ti borí ìṣòro rí ló ń mu mi ṣojú àánú, Duration 2,481 Ògún 2019 6:08 Fídíò, Adebola Ademilua: Àìrísẹ́ ṣè lẹ́yìn ìwé kíkà ló sọ mi dí ìyá onírú, mo dúpẹ́ tèmi, Duration 6,0827 Bélú 2020 2:36 Fídíò, Sotitobire: Ìdájọ́ òdòdò ló fẹsẹ̀ múlẹ̀ lórí ọ̀rọ̀ Pásítọ̀ Sotitobire - Agbẹjọ́rò fún ìjọba, Duration 2,367 Ọ̀wàrà 2020 BBC News, Yorùbá Ìdí tí ẹ fi le è nígbàagbọ́ nínú ìròyìn BBC Ìlànà Lílò Nípa BBC Òfin Àṣírí Cookies Kàn sí.
Aseyori awọn ọmọ obirin naa, ti mu ikinni ku orire wa lati ọdọ awọn ọmọ Naijiria atawọn asaaju wa.
Àwọn ọmọ ọmọ rẹ yóo máa ṣẹgun àwọn ọ̀tá wọn ní gbogbo ìgbà.
Láti ìgbà náà ni ọba sì ti mú Modekai wá siwaju rẹ̀.
Wí fún un pé ó ka ara rẹ̀ kún kinniun láàrin àwọn orílẹ̀-èdè.
’ rèé Afọnja, ẹni tó finú wénú ní Ilọrin, àmọ́ tó jẹ iwọ Ẹfunsetan Aniwura, obìnrin tó ju ọkùnrin lọ Ọ̀rọ̀ǹpọ̀tọ̀niyùn, Aláàfin obìnrin àkọ́kọ́ rèé, tó ní nǹkan ọkùnrin Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí kan sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
Ẹsira Ka Òfin fún Àwọn Eniyan náà.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Awọn agbabọọlu Naijiria Bakan naa, oloogbe Keshi ni akọnimọọgba orilẹede Togo nigba ti wọn pegede fun ife ẹyẹ agbaye fun igba akọkọ eyun ni 2006 FIFA World Cup ti orilẹede Germany gbalejo rẹ, bi o tilẹ jẹ pe wọn gbaṣẹ lọwọ rẹ ki idije naa to bẹrẹ.
O lo iriri rẹ gẹgẹ bii ọmọ ọdun mẹrinla ti wọn fi tipa mu lati fẹ ọmọ ọga kan ninu ẹgbẹ awo mafia , lati fi maa beere fun ẹtọ awọn eeyan to n se ofofo fun awọn ọlọpa ati mọlẹbi wọn.
Wọn si tun dana sun ile awọn obi rẹ lagbegeb Sharifa ni Kano nitori ẹsun kan naa.
Ninu oro tire, asoju orile-ede China si orile-ede Nigeria .
A mọ odi náà parí ní ọjọ́ kẹẹdọgbọn oṣù Eluli.
Bakan naa, Abayomi ni fidio naa ko ni ọrọ labẹ tori awọn kan fi n wo igbokegbodo ọkọ ni.
 rẹ lori iroyin ati ikede Yusuph
Ṣùgbọ́n ibi tí a ti ń ronú bẹ́ẹ̀ ni ọkùnrin ti à ń bá sọ̀rọ̀ wí fún èyí tí ó ṣẹ̀ṣẹ̀ dé pé àwa tí à ń lọ sí ìdálẹ̀ ni o rí níwájú òun àti pé a kò tilẹ̀ mọ òun pàápàá.
“A rí àwọn tí wọ́n kọ ìmọ́lẹ̀,tí wọn kò mọ ọ̀nà rẹ̀,bẹ́ẹ̀ ni wọn kò dúró ní ọ̀nà náà.
Alaga ẹgbẹ oṣelu SDP Lẹyin ti ajọ INEC kede Rotimi Akeredolu pe oun lo wọle ibo lẹẹkeji ni ipinlẹ Ondo lọjọ Aiku ni awọn eeyan sọ ohun to wa ni ọkan koowa wọn.
Oríṣun àwòrán, AfricanDrumFestival Àkọlé àwòrán, Àgba awọn to wa nipo aṣẹ lẹka iṣejọba gbogbo niyanju lati rii wei pe wọn n ṣe koriya fun igbedide aṣa ilẹ Yoruba.
O jẹ oluṣọagutan pẹlu ijọ Christ Apostolic Church nibi to ti jẹ ọkan lara awọn igbimọ alakoso wọn.
Ó fún ọ̀kan ni àpò owó marun-un, ó fún ekeji ní àpò meji, ó fún ẹkẹta ní àpò kan.
Njẹ a le pe ijọba to n jẹ gbese ni onitẹsiwaju?
Oríṣun àwòrán, Reuters Bawo ni abẹrẹ ajẹsara yii yoo ṣe ṣiṣẹ si ni agọ ara?
5 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 UK Covid Vaccine: Abẹ́rẹ́ àjẹsára Covid-19 yóò dé sí Nàìjíríà nínú oṣù kíní ọdún 202116 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 3 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 5 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Ko si ẹnikẹni ti mo mọ ninu ẹbi mi ti wọn ya aworan wọn bayi,Aarẹ Obama sọrọ.
Gẹgẹ bi nkan ti wọn kọ si ori iwe ipolongo fun ariya naa, awọn ti yoo ba wa sibẹ gbọdọ wa ni ihoho goloto.
Ṣeba ati Dedani ati àwọn oníṣòwò Taṣiṣi, ati àwọn ìlú agbègbè wọn yóo bi ọ́ pé, ‘Ṣé o wá kó ìkógun ni, ṣé o kó àwọn ọmọ ogun rẹ jọ láti wá kó ẹrú, fadaka ati wúrà, ati mààlúù, ọrọ̀ ati ọpọlọpọ ìkógun?
Ìbẹ̀rù-bojo gbalẹ̀ ní Oyigbo lẹ́yìn tí ọlọ́páà mẹ́ta àti sọ́jà kú nínú rògbòdìyàn EndSARS Banki Nàìjíríà, CBN ṣàlàyé nípa àwọn tó máa rí gbà nínú owó ìrànwọ́ N75b tíjọba gbé kalẹ̀ Ta ni Wolii Olapade Agoro tó re ibi àgbà ń rè tí ayé ń pariwo rẹ̀ yìí?
Ohun ìdọ̀tí kan kò ní wọ inú rẹ̀.
Dokita Brown ni afojusun oun fun arabinrin naa ni ki o yege, ki o si di ẹni nla ni awujọ lọjọ iwaju.
Awọn dokita rẹ sọ wipe ara Trump n dahun si itọju ti wọn n fun un, amọ Adari Ile Ijọba, White House sọ wi pe o ṣeeṣẹ ki ilera rẹ buru jai si.
Ọlọrun bá rán Gadi, aríran Dafidi pé, 
Púpọ̀ nínú àwọn tó pàdánù ẹ̀mí wọn ni ìròyìn sọ pé, wọ́n jẹ́ ọmọ ẹgbẹ́ ọdẹ ìbílẹ̀ kan, èyí tí wọ́n dásílẹ̀ láti maa pèsè ààbò fún àwọn abúlé tó wà ní agbègbè nàá, lẹ́yìn ti onírúùrú ìkọlù ti wáyé níbẹ̀.
Iroyin to tẹwa lọwọ so pe ko si osisẹ to lo si ibisẹ bi ki sẹ awọn osisẹ alaabo.
Won fi esun kan ajo naa pe, won ko lati se ojuse won nipa sise ikilo ati ipolongo lori ajakale aarun naa to waye ni osu kejila odun 2013 ti awon eniyan bi egberun mokanla si padanu-emi won.
Ṣé o fẹ́ pa èmi náà bí o ti pa ará Ijipti níjelòó ni?
Gbọ́ ohun tí n óo sọ fún ọ yìí, ìmọ̀ràn ni mo fẹ́ gbà ọ́, Ọlọrun yóo sì wà pẹlu rẹ.
“A nilo itesiwaju ninu eto oro aje nipa ibasepo awon ise akanse ati idagbasoke
Akeugbagold ni òun sì ń bẹ àwọn ajomogbe yìí, kí wọ́n dakun, ṣàánú òun, kí àwọn èèyàn sì bá òun bẹ wọn láti gba owó tó mọ niwọnba lọ́wọ́ òun, òun kò sì fẹ́ kí àwọn ọlọ́pàá dá sí ọ̀rọ̀ náà.
Saulu pàṣẹ pé kí wọ́n pa gbogbo àwọn tí wọn ń gbé Nobu, ìlú àwọn alufaa, atọkunrin atobinrin, àtọmọdé, àtọmọ ọwọ́, ati mààlúù, ati kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́, ati aguntan, wọ́n sì pa gbogbo wọn.
“Kí gbogbo ọkunrin tí ó bá mọ iṣẹ́ ọwọ́ ninu yín jáde wá láti ṣe àwọn nǹkan tí OLUWA pa láṣẹ wọnyi: 
Idà yìí wọlé tèèkùtèèkù, ọ̀rá sì padé mọ́ ọn, nítorí pé kò fa idà náà yọ kúrò ní ikùn ọba, ìfun ọba sì tú jáde.
Saulu ṣẹgun àwọn ará Amaleki láti Hafila títí dé Ṣuri ní ìhà ìlà oòrùn Ijipti.
Igi inú oko yóo máa so; ilẹ̀ yóo sì máa mú ọpọlọpọ irúgbìn jáde.
wọ́n sọ fún wọn pé, “Ẹ ka iye àwọn eniyan náà láti ẹni ogún ọdún lọ sókè,” gẹ́gẹ́ bí OLUWA ti pàṣẹ fún Mose.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Fídíò òògùn ikọ́ Codeine: Àpọ̀jù rẹ̀ ń ya ọ̀dọ́ ní wèrè Iwe iroyin Nigerian Tribune jabọ pe, Ọjọgbọn Adewọle sọ eyi di mimọ nilu Abuja lasiko to n tẹwọ gba abọ iwadi igbimọ ti ileeṣẹ eto ilera gbe kalẹ lati mojuto aṣilo oogun ikọ olomi to ni eroja codeine ninu.
Lara awọn ọna abayọ ti wọn wa ni abẹrẹ ajẹsara, eyii ti yoo lagbara lati koju arun ọhun.
Babandede rọ awọn to kogoja to jẹ ẹleekẹrinlelogoji iru rẹ lati gbiyanju lori ipese aabo fun gbogbo olugbe Naijiria.
" Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Kí ló ṣe Ibrahim Chatta tó fi dèrò ilé ìwòsàn?
Sugbọn àwọn agbegbe ti ojo ti ma n rọ, to si sunmọ aarin, n ni ìrírí kan naa.
Numba yii ni o lo nidi ẹrọ ATM.
Olówó rẹ̀ kò ní ẹ̀tọ́ láti tà á fún àjèjì nítorí pé òun ló kọ̀ tí kò ṣe ẹ̀tọ́ fún un.
Taribo West: Agbábọ́ọ̀lù Nàìjíríà wọ gàu lọ́wọ́ ọmọ Náìjíríà lórí àsọtẹ́lẹ̀ pé Trump yóò wọlé ìbò ààrẹ Amerika
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Òun tọjú àwọn ọmọ Nàìjíríà n rí ní South Áfríkà kọjá afẹnusọ Se ni jẹbẹtẹ si gbe ọmọ le ọpọ awọn onibara MTN lọwọ nigba ti wọn ri pe ileesẹ naa jona kọja aala.
Yoruba World Congress: Banji Akintoye ní àwọn ọlọ́pàá fẹ́ sọ àwọn ọmọ ẹgbẹ́ òun sá àhámọ́
A fẹ ẹ mọ boya lootọ lo ni aarun naa, a si fẹ ẹ ms nkan ti a le ṣe lati fi opin si bo ṣe n pa awọn obinrin lẹkun.
Lapapapọ bayii ẹgbẹwadinmejidinladọrin (1932) eeyan ni ayẹwo fihan pe wọn ti ko arun yii lorilẹede Naijiria bayii.
 Ni bayii a ti dana sun oko ipese egbogi yii.
Ìjọba Akwa Ibom yọ̀ǹda kí Buhari lo pápá ìṣeré fún ìpolongo ìbò Ẹ̀kọ́ mẹ́fà tó jáde nínú ìdíje Premier League òpin ọ̀sẹ̀ Àwọn sinimá tó pegedé ni 2018 lágbàyé Dandan ní kí a mú Dino sí àhámọ wa- Ọlọ́pàá Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ti irin ba kan irin, ọkan a tẹ fun ikeji Ere ni ẹgbẹ agbabọọlu Arsenal kọkọ pe idije naa titi ti Sadio Mane fi gba a fun Mohammed Salah ni eyi ti wọn fi sọọ di ami ayo mẹta sookan labala saa akọkọ idije naa.
Aarẹ kede eyi lasiko ti o fi n gbe abadofin iṣuna naa kalẹ niwaju awọn aṣofin apapọ ni ọjọru.
Nigba to n dahun ibeere lori boya lootọ lo ti di ẹlẹsin Kristi, Ayuba ni lootọ ni oun jẹ Musulumi, amọ oun ko mọ keu ka, awọn Aafa ni oun maa n pe lati wa gbadura fun oun, ti oun si lọ sin Ọlọrun ni ilu Mecca.
Ìtàn ayé Abiola Peller, ọlọ́wọ́ idán tó fi ọ̀bẹ gé ìyàwó rẹ̀ sí méjì Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ọọni Ogunwusi Adeyẹye pe fun itọju awọn ọdọ A n se akojọpọ ẹkunrẹrẹ iroyin yajoyajo lọwọ, a o maa gbe ẹkunrẹrẹ iroyin naa sori atẹ iroyin wa laipẹ.
ko sai gbosuba fun adari ile-ise awon ọlọpaa , ile-ise ọtẹlẹmuyẹ  ati ile-ise to n mojuto iwe eto irinna lati wa
naira ti igbimo ipinle fenuko le lori.
Igbimo to n mojuto eto aabo agbaye ninu ajo isokan agbaye, The United Nations yoo dibo lojo Eti lori ipinnu agbaye lati pase alaafia ologbon ojo ni Syria ki won le fi fun awon ajo arannilowo lati gbe ohun lilo, oogun atawon nnkan miran wo inu Syria.
Lẹyin naa lo ke pe awọn oṣiṣẹ eto ilera ilẹ Amẹrika lati doola ẹmi awọn ọmọ orilẹede naa to n ku nitori arun ọhun pe, oogun Hydroxychloroquine ni idahun si arun Covid-19.
Ṣugbọn oun ni adari ẹgbẹ osẹlu AG nile aṣoju-ṣofin Naijiria lapaapọ nibi to ti jẹ olori ẹgbẹ oṣelu alatako.
Ko sẹni to sọ fun mi ri pe, oun yoo gba iyawo mi o, abi boya awọn to n beere ibeere yii naa lo ni i lọkan."
Àti ẹni ti ó ta ohun ìní àti ẹni ti ó ra, kò si ninú wọn ti ó ma mú nkankan lọ ti ayé bá parẹ ni tootọ.
Kí ẹ múra láti lọ ní agogo mẹsan-an alẹ́.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Seyi Makinde: PMS kò ní ohun ṣe pẹ̀lú NURTW, ìṣẹ́ rẹ̀ ni láti pawó wọlé fún ìjọba 11 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Oríṣun àwòrán, Facebook/ The Park management Oyo state Gomina ipinlẹ Oyo, Seyi Makinde ti sọ pe ọna lati dena wahala ni ẹka igboke-gbodo ọkọ, lo mu ki oun ṣe ayipada ẹgbẹ NURTW.
Mo rí i tí àgbò náà bẹ̀rẹ̀ sí kàn sí ìhà ìwọ̀ oòrùn, ati sí ìhà àríwá ati sí ìhà gúsù, kò sí ẹranko tí ó lè dúró níwájú rẹ̀, bẹ́ẹ̀ ni kò sí ẹni tí ó lè gbani sílẹ̀ lọ́wọ́ rẹ̀.
Eyi ni won pe o mu ki ọpọ ero lagbegbe naa ya bo o.
Dafidi kúrò níbẹ̀ lọ sí Misipa ní ilẹ̀ Moabu, ó sọ fún ọba Moabu pé, “Jọ̀wọ́ jẹ́ kí baba ati ìyá mi dúró lọ́dọ̀ rẹ títí tí n óo fi mọ ohun tí Ọlọrun yóo ṣe fún mi.
Ọlọ́pàá mú ẹyẹ igún sí àtìmọ́lé ní ìpínlẹ̀ Adamawa Ọmọogun pa darandaran mẹwa ni Adamawa Ẹ̀mí sọnu nínú ìkọlù ìpínlẹ̀ Adamawa Ikọ̀ ẹlẹ́sìn Hàkíkà rèé, níbití wọn ti ń pààrọ̀ ìyàwó láàrín ara wọn Oga ọlọpaa ni iṣẹ iwadii naa ṣi n lọ lọwọ nitori awọn olugbe agbegbe Mahia n fura si obinrin to ni ẹyẹ igun naa.
Ẹwẹ, ile ẹjọ ni awọn yoo gba beeli rẹ pẹlu oniduro meji to gbudọ jẹ awọn to ni ileeṣẹ ara wọn.
Àkókò láti fi ìfẹ́ hàn wà àkókò láti kórìíra sì wà;àkókò ogun wà, àkókò alaafia sì wà.
Bo ṣe pada to ni oun yoo pada wa lati gbẹsan tori oun ko tilẹ mọ idi ti gbogbo wọn fi n lu oun lo ba ri i ti obinrin naa ti wa ninu aṣọ sọja.
Aarẹ Buhari ni ifọwọsowọpọ lo le mu alaafia j'ọba
Ṣùgbọ́n ẹ̀gà bú sí ẹ̀rín ó ni, ‘Ẹ máṣe jẹ́ kíi a lọ níto’ri ìba díẹ̀ ni ọ̀rẹ́ tí ó fẹ́ràn àwọn ènìyàn, àwọn tí àgbẹ́ ránṣẹ́ sí kò níí wá, níto’ri ènìyàn kò ṣe e gbẹ́kẹ̀lé, ẹ jókòó ẹ̀yín ọmọ mi.
 Ojuṣe Igbimọ Alakoso Agbeyẹwo Isuna Owo Ilu lo yẹ ko jẹ.
Sanusi rọpo Oba Alaye, Malam Tagwai Sambo to ti wa nipo naa lati ọdun 2005.
DNA: Wo àkójọpọ̀ ọ̀nà méje tí ọmọ àlè fi le wọnú ilé láì jẹ́ pé ìyàwó ṣe aṣemáṣe
Kayeefi nla miran tun ni eyi jẹ Bakan na ni ko si aworan awọn ẹbi wọn, eyi ti a gbagbọ pe ko ṣeeṣe ki wọn o se igbeyawo lai si pe awọn ẹbi wọn kopa nibẹ Irun ori Lateef naa tun tọka si pe, o ṣeeṣe ko jẹ pe sinima kan ni wọn ya awọn fọto naa fun.
Suicide attack: Ìlú Konduga Pàdánù ọ̀gọ̀ọ̀rọ̀ ènìyàn
Akosile ikede ti Malabo ti fihan pe awon orile-ede to wa ni ekun ila oorun ile Adulawo ni won ti gbegba oroke lori sise amulo awon ilana ofin fun ayipada rere ninu eto ogbin nigba ti awon orile-ede ekun guusu ile Adulawo se ipo keji.
Sofa bí Ṣua, Haneferi, ati Ṣuali; Beri, ati Imira; 
Ó súre fún ẹ̀yà Juda pé:“OLUWA, gbọ́ igbe ẹ̀yà Juda,nígbà tí wọ́n bá pè fún ìrànwọ́,sì kó wọn pada sọ́dọ̀ àwọn eniyan wọn.
Awọn kan tiẹ sọ pe, awọn janduku naa sọna sawọn ṣọọbu ọhun lati le bo iṣẹ ibi ti wọn ṣe mọlẹ.
Àwọn ọmọ Aaroni ni a pín àwọn ìlú ààbò wọnyi fún: Heburoni, Libina, Jatiri ati Eṣitemoa, pẹlu àwọn pápá oko tí ó yí wọn ká.
láti inú ẹ̀yà Simeoni, ó rán Ṣafati ọmọ Hori; 
Bakan naa ni ọga agba ileeṣẹ ọlọpaa naa fi awọn kan ranṣẹ si wa lati ilu Abuja.
Adájọ gbà ìdájọ ikú lọ́wọ́ ejò Ta ni yóò borí láàrin Aisha Buhari àti ọkọ rẹ̀ lórí ọ̀rọ̀ ‘First Lady’?
Kò sí ẹda tí Ẹlẹ́dàá fẹ́ràn tí o ta ẹ̀yin ènìyàn yọ, nítorí Ẹlẹ́dàá kò lè fi yín sílẹ̀ bẹ́ẹ̀ nígbà tí àwọn alátùn-úunṣe ba ra àìsàn tí mò ń tà, wọ́n a mú u lọ, wọn á ló fii ṣe igi, nígbà tí àìsàn yìí bá mu igi wọ́n á mú dígí pẹlẹbẹ tí Olódùmarè fún wọn, wọ́n a fi wo kòkòrò ti o ń dá àìsàn náà sílẹ̀ lẹ́yìn èyí, wọ́n á mú kòkòrò náà tọ Ọlọ́run ba lọ.
Gbajabiamila ,wa fi idunnu re han si awon ẹbi, ọrẹ ati ojulumọ fun atileyin ti
Gomina Obiano ni oun ni lati gbaruku ti awọn ọdo naa nítori pe awọn gan ni igi leyin ọgba aṣeyọri oun nibi ibo.
Sanwo-Olu kò lè tori ìjà Ọjọta fòfin de NURTW ní Eko - Agbẹnusọ gómínà Àwọn àṣà àti ìse tó yọ obìnrin sílẹ̀ nílẹ̀ Yorùbá Lẹ́yìn ọlọ́pàá, VIO nìkan ló láṣẹ láti dá ọkọ dúró láìṣẹ̀ - Ọ̀gá VIO Eko Mà á fún àwọn ọba alayé ní ojúṣe nínú ìjọba mi - Seyi Makinde Ẹnikẹni lo le jẹ koriya fun awọn akẹgbẹ rẹ lasiko idije.
“Bí ẹnìkan bá ya apá kan ninu ilẹ̀ tí ó jogún sọ́tọ̀ fún OLUWA, ìwọ̀n èso tí eniyan bá lè rí ká lórí ilẹ̀ náà ni wọn yóo fi díye lé e.
Wọn kii ku iṣẹ ti ijọba n ṣe lori ọkọ oju irin ati ọna marosẹ Ibadan.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Òsìsẹ́ ilé-wòsàn Ondo: Gbogbo ìgbà ni alárùn ọpọlọ ń kọlù wàá 10 Ògún 2018 Oríṣun àwòrán, Getty Images Ọkunrin alarun ọpọlọ kan lu awọn oṣiṣẹ ileewosan ti wọn ti n tọju awọn alarun ọpọlọ ni alubami.
    Ìgbà tí ó ṣe, a yọ sí Igbo Elégbèjè.
Kíákíá wọ́n bẹ̀rẹ̀ orin kíkọ tí wọ́n máa nkọ fún ọba ní ilẹ̀ náà.
Abija gun orí òkè Semaraimu tí ó wà ní agbègbè olókè Efuraimu lọ.
Nítorí náà, jẹ́ kí ó wù ọ́ láti bukun ìdílé èmi iranṣẹ rẹ, kí ìdílé mi lè wà níwájú rẹ títí lae, nítorí ẹnikẹ́ni tí o bá bukun, olúwarẹ̀ di ẹni ibukun títí lae.
“besini a o mu iyipada otun de ba eto oro aje orile-ede yii lapapo.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Kidnapping: Kò sẹ́ni tó mọ̀ bóyá àwọn ajínigbé gba owó ìtúsílẹ̀ 19 Òkùdu 2019 Oríṣun àwòrán, @IsaacFAdewole Iroyin to n tẹ wa lọwọ ni ọmọ minisita tẹlẹri fun eto ilera, Dayọ Adewọle ti gba itusilẹ lọwọ awọn ajinigbe.
Bi BBC si se pe mi fun ifọrọwanilẹnuwo jẹ iwuri fun mi.
6 69255 Orilẹede El Salvador 1164 18.
imoriya fun awon agbe lorile  ede
Jehoiada bá àwọn eniyan náà dá majẹmu pẹlu ọba, pé ti OLUWA ni àwọn yóo máa ṣe.
Diẹ lara wọn si le wọ ẹnu rl, ṣugbọn omi mimu lera-lera ko ni i dena rẹ pe ko ma ni i.
Ìbànújẹ́ ló bá mi, tóbẹ́ẹ̀ tí mo fi ń gbadura, tí mo sì ń tú ọkàn mi jáde fún OLUWA.
apá àríwá ìsàlẸ ̀ Èkó ni ọ ̀ pọ ̀ ilé òun ọjà ti kò gbòòrò wà tí ó sì ma ń sábà kún fọ ́ fọ ́ fún èrò tí ẹsẹ ̀ kò sì gbèrò níbẹ ̀ .
Ẹ bẹ̀rù OLUWA, ẹ̀yin eniyan mímọ́ rẹ̀,nítorí pé kò sí àìní fún àwọn tí ó bá bẹ̀rù rẹ̀!
Lati igbà ti iròyin ibo ti jade pé Donald J.
Kọmiṣọna eto ilera ipinlẹ Eko, Akin Abayomi sọ fun awọn akọroyin nibi ifọrọwerọ kan pe ẹni ọdun mẹrinlelogoji naa ko ni arun ọhun lara mọ.
Ewe, ogbeni Felix Nwosu ti fi
Gulegule awọn ọlọpaa, paapaa julọ ẹka adamọlẹkun ariṣe kandu-kandu, SARS ti mu ki ipe fun idasilẹ ọlọpaa agbegbe tubọ peleke sii.
, ajakalẹ aarun kan to bẹ silẹ ko fawọn musulumi lanfaani lati ṣiṣẹ Hajj.
Ipinlẹ Edo si tun ti fofin de igbesẹ kawọn Ọdẹ ibilẹ lati ipinlẹ mii maa se ọdẹ wa si ipinlẹ naa.
Àwọn eniyan kò sì ní fi ẹsẹ̀ da omi rú mọ́, bẹ́ẹ̀ ni àwọn ẹranko kò ní fi pátákò da odò rú mọ́.
Awọn agbebọn ti wọn fi oju wọn pamọ ti yabo ile itura ti gomina ipinlẹ Ọyọ, Seyi Makinde wa ni Ilu Lokoja saaju idibo sipo gomina.
káàkiri àgbáyé , bí i miliọnu kan àbọ ̀ ènìyàn ni àìsàn yìí n bá fínra lọ ́ dọọdún èyí tí ó jẹ ́ díẹ ̀ lára ọ ̀ kẹ ̀ àìmọye tí àìsàn náà kọlù lápapọ ̀ .
Bí eniyan bá wọ ilẹ̀ náà yóo rí òkùnkùn ati ìnira.
Rọ ọhun di ile ẹjọ, bi o tilẹ jẹ pe gbogbo iyanju awọn asọbode nigba naa pe ko su oogun oloro ọhun mọ igbẹ lo ja si pabo.
ofin, ti o tun ni ibo to  pọ ju ,
Aare Muhammadu Buhari ni yoo  dari ipade ti  igbimo ijoba  ti  yoo  waye lojoru  oni  nile aare niluu Abuja.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Colorado ni Amẹrika àti Adò Awaye ní Naijiria nìkan ni àdágún órí àpáta ní gbogbo àgbáyé!
Lasiko ti Fani Kayode n ba awọn akọroyin naa sọrọ lori iṣẹ ti gomina ipinlẹ Cross River n ṣe ni akọroyin naa bere lọwọ Fani Kayode wi pe tani o ran an niṣe to n ṣe.
O ni nipa atunto eko awon omo yahoo yoo lee sise ni stock exhange.
 Ọjọ ́ orí gbogbo àwọn ajalèlókun mẹ ́ ẹ ̀ rin wà láàrín mẹ ́ tàdínlógún sí ọ ̀ kàndínlógún , gẹ ́ gẹ ́ bí akọ ̀ wé olùgbèjà u.
Àwọn iranṣẹ mi yóo bá wọn ṣiṣẹ́ pọ̀, n óo sì san iyekíye tí o bá bèèrè fún owó iṣẹ́ wọn.
Aliyu ati baba isalẹ rẹ, Aliyu Wamakko lati inu ẹgbẹ  All Progressives Congress, APC .
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù US visa fee for Nigeria: Amẹrika ti yọ àfikún owó Físà kúro fún arìnrìnàjò Nàìjíríà 6 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Oríṣun àwòrán, Buhari/twitter Orílẹ̀-èdè Amẹrika ti yọ afikun owó fisa tó ṣe nítori èdè àìyedè tó wáye láàrìn òun àti ìjọba Nàìjíría kúrò láti ọjọ́ kẹta, oṣù kejìlá.
Ìbẹ̀rùbojo gba ọkàn àwọn olùgbé Eko àti Ogun nítorí adágún omi Ọ̀yan tí yóò di ṣíṣí láìpẹ́ Bàbá ẹni ọdún 61 bá ọmọ rẹ̀ lopọ̀, ó fún un lóyún l'EkoOṣu Keji, ọdun 2020, ni ijọba Makinde, gbẹsẹ le ilẹ naa, ti wọn sọ pe ọna ti ko ba ofin mu ni Ajimobi fi gba a.
'Kìí ṣe gbogbo ohun tí dókìtà ni kí n má jẹ torí àìsàn jẹjẹrẹ ni mo tẹ̀lé' Àwọtẹ́lẹ̀ ọkùnrin àti Ìdọ̀tí Kilo méje ṣekú pa Ìgalà Ẹ wo iye t'óúnjẹ dà báyìí lọ́jà lẹ́yìn tí ìjọba ti ibodè Ẹni bá láyà kó fi àmì ohùn sí ọ̀rọ̀ Konko-jabele!
Oríṣun àwòrán, @Oluwo O ni ọba meji ko le wa laafin papọ, ati pe oun jẹ aṣoju Eleduwa to da gbogbo aye.
Lara awọn ere to ti ṣe ni Koto Aye, Koto Ọrun, Ide, Ẹran Iya Osogbo, Aye Alaye ati bẹẹ bẹẹ lọ.
"O ni awọn olokoowo kekeke, ""o yẹ ki ijọba ran wọn lọwọ kawọn naa le gba eeyan siṣẹ, ki ijọba si ko awọn oniṣẹ aladani wa si Ondo lai san owo ori""."
Kaduna , nipa isoro ti won n dojuko nipa eto aabo ni ekun naa.
Àwọn tí a ti kọ orúkọ wọn sinu ìwé ìyè Ọ̀dọ́ Aguntan nìkan ni yóo wọ ibẹ̀.
Ilu Abuja lo sagbateru awon iko olorin, ti won je gbaju-gbaja ninu ise  orin kiko, ni eyi ti won pe akole re  ni“ojo iwaju orin kiko: Ojo awon   olugbesan”.
Eeyan meji mii tun ti ni aarun coronavirus lorilẹ-ede Naijiria, ajọ to n gbogun ti ajakalẹ arun ni Naijiria, NCDC to kede ọrọ naa loju opo Twitter rẹ.
Wo nǹkan tí yóò ṣẹlẹ̀ sí ọba tí wọ́n bá gbé ọ̀pá àṣẹ rẹ̀ lọ nílẹ̀ Yorùbá Buhari kò láànú ọmọ Nàìjíríà lójú - Aisha Yesufu Àìsọ̀rọ̀ Buhari lórí ìṣẹ̀lẹ̀ Lekki, ìkọjú ìjà sí Yoruba ni - YWC Kò sọ́rọ̀ nínú ọ̀rọ̀ Buhari, àtúntò Nàíjíríà nìkan lọ̀nà àbáyọ - Àgbà Yorùbá Àwọn Janduku ya bo Ede wọ́n pin ohun eelo idera ajakale arun Covid 19.
Ọba Babiloni kó gbogbo ohun èlò ilé OLUWA, ati ńláńlá, ati kéékèèké, ati àwọn ìṣúra tí ó wà níbẹ̀, ati àwọn tí wọ́n wà ní ààfin ati ti ilé àwọn ìjòyè; ó kó gbogbo wọn patapata lọ sí Babiloni.
Yoruba Language: Ṣé ẹ mọ ìdí tí ọmọ fi ń jẹ́ orúkọ yìí?
Wọn ni wọn o yẹ ki wọn ṣọ ibi iwọde naa daadaa.
Gẹgẹ bi ololufẹ ikọ Arsenal fun ọjọ pipẹ, Dangote soju abẹ niko loni lori eto kan pe ọdun 2021 loun yoo ra Arsenal bayii.
"Awọn eeyan mẹtẹẹta kọ iwe ẹsun si ile ẹjọ nitori pe ""ijọba ko ṣe ayẹwo lati mọ boya kọndọmu naa poju owo, ki wọn o to bẹrẹ si ni ta fun ara ilu""."
" Adeleke ni ọpọlọpọ ere lo n bẹ ninu ijo jijo.
Abasido fi kún pé, gẹ́gẹ́ bi ọlọdan ni o ṣe pataki láti nawọ ìrànwọ si ijọba náà lori àwọn nàkan kan , nítori ijọba nikan ko le dá gbogbo rẹ ṣe.
Ni bayii, wọn ti da pasitọ naa atawọn mẹfa mii ti wọn fẹsunkan ṣogba ẹwọn Olokuta to wa nilu Akure titi di Oṣu Kẹrin ti igbẹjọ mii yoo waye.
Lori ọrọ Brexit, Buhari ni anfaani nla ni eleyi jẹ fun awọn mejeji lati tun tẹsiwaju ninu ajosepo wọn.
OLUWA Ọlọrun àwọn baba wọn kò dẹ́kun láti máa rán wolii sí wọn, nítorí pé àánú àwọn eniyan rẹ̀ ati ibùgbé rẹ̀ ń ṣe é.
OLUWA yóo rán àjàkálẹ̀ àrùn sí ọ títí tí yóo fi pa ọ́ run patapata, lórí ilẹ̀ tí ò ń wọ̀ lọ láti gbà.
Pe ka ni wọn tun orilẹ-ede Naijiria ṣe boṣeyẹ ni, nkan i ba wa daada lẹka eto ilera.
Bí ó ti ń gbadura, ìwò ojú rẹ̀ yipada, aṣọ rẹ̀ wá funfun bí ẹ̀gbọ̀n òwú.
Fásitì UNIOSUN ṣètò ìgbaniwọlé orí ayélujára fáwọn akẹ́kọ̀ọ́ tuntun fún ìgbà àkọ́kọ́ ní Nàìjíríà, Ohun tí a mọ̀ nípa rẹ̀ nìyí Àwọn àṣà àti ìse tó yọ obìnrin sílẹ̀ nílẹ̀ Yorùbá Abu Muhammad si kesi awọn imaamu ati Alfa ti gomina naa pe wi pe ki wọn ma da gomina naa lohun lasiko yii fun anfaani ara wọn.
 lára àwọn ìmọ ̀ rẹ ̀ nípa àwon òrò wònyí ni pé a lè fún wón ni àwon ipa kan láti kó ; tí a bá ní ká wò ó kí ni ìwúlò wọn tí wọn kò bá kó ipa kankan ní àyíká gbólóhùn tàbí ọfọ ̀ wọn .
Òfin rẹ dára,nítorí náà ni mo ṣe ń pa wọ́n mọ́.
Bí wọn bá sì kó ọjà tabi oúnjẹ wá tà ní ọjọ́ ìsinmi, a kò ní rà á lọ́wọ́ wọn ní ọjọ́ ìsinmi tabi ní ọjọ́ mímọ́ kankan.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Ìgbà tí mo máa fi lajú sáyé padà, ọ̀fọ̀ ikú mi ní wọ́n ń kígbe' Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 3 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 5 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
“Ẹ̀yin eniyan ni mò ń pè,gbogbo ọmọ eniyan ni mò ń ké sí.
Tithing: Daddy Freeze àtàwọn ọmọ Nàìjíríà míì ta gbá òjíṣẹ́ Ọlọ́run torí ègún ìdá mẹ́wàá
Ni bayi o ti wa pinnu lati kan si awọn mọlẹbi ọmọdekunrin ti wọn yinbọn pa yi to si ni oun yoo ri i pe iwadii ọfintoto waye lori awọn to mọ nipa iku rẹ.
Gbogbo eniyan ń hó ìhó ayọ̀, wọ́n ń fọn fèrè, àwọn tí ń lo ohun èlò orin ń fi wọ́n kọrin, àwọn eniyan sì ń gberin.
Minisita ohun eni ti alukoro ile-ise naa abileko Boade Akintola wa ro awon akoroyin naa lati se ojuse ti o to, nipa fifun awon omo orile-ede Naijiria ni iroyin ti yoo mu igberu ba eka eto-ilera.
Láàárín ọjọ́ díẹ̀, àwọn ènìyàn tí ó tó bíi ẹgbẹ̀rún 60 ti wo fídíò rẹ̀, tí wọ́n sì pín in lọ́nà 350, tí ó sì gba èsì tí ó tó 700.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìtàn Mánigbàgbé: Hubert Ogunde jẹ́ kọ́sítébù ọlọ́pàá àti olùkọ́, kó to bẹ̀rẹ̀ eré síse 18 Bélú 2018 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 18 Ọ̀pẹ̀̀ 2019 Oríṣun àwòrán, @hubertogunde Àkọlé àwòrán, Ere tiata ti di gbajugbaja ti ọpọ n fi le ọmọ lọwọ bayii Yoruba ni odo kii gun, ko ma ni orirun.
Gbogbo ìwà àìdára yín ni mo mọ̀, mo sì mọ̀ bí ẹ̀ṣẹ̀ yín ti tóbi tó, ẹ̀yin tí ẹ̀ ń fìyà jẹ olódodo, tí ẹ̀ ń gba owó àbẹ̀tẹ́lẹ̀, tí ẹ sì ń du àwọn aláìní ní ẹ̀tọ́ wọn lẹ́nu ibodè.
 O ni “Mo fi gbogbo ara mọ gbogbo ọrọ yin lori iṣelẹ buruku yii pe o jẹ ohun itiju patapata.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ẹka eto ọgbin wa lara awọn ẹka ti afikun owo ori ọja to n wọle lati ilẹ okeere n se akoba fun Bakanaa ni ileegbimọ asofin agba orilẹede Naijiria tun pasẹ awọn igbimọ ti ọrọ kan naa lati ransẹ pe gbogbo awọn ileesẹ ijọba, lajọlajọ ati awọn alẹnulọrọ to wa lẹka ọrọ owo ori lori ọja okeere lati se iwadi si ọrọ naa ki wọn si wa ojuutu si afikun owo ori ẹru to n wọ orilẹede Naijiria lati okeere.
” Ó wá sọ fún Jesu pé, “Oluwa, o mọ ohun gbogbo, o mọ̀ pé mo fẹ́ràn rẹ.
Kérésìmesì ń sún mọ́ dẹ̀dẹ̀ ṣùgbọ́n kàkà kí inú àwọn tí ó ń gbé ní orí-ilẹ̀ ìlú China ò dùn, ọ̀pọ́ ti fi ẹ̀hónú-u wọn hàn lórí ìpolongo tí ó tako ayẹyẹ Kérésìmesì tí ó kà á sí àjọ̀dún Òyìnbó.
EFCC ni isẹ pipaarọ owo Naijiria si tilẹ okeere ni Mompha fi n boju lati fi se isẹ gbajuẹ ati 419 ti wọn fi kan an.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Àgbà ni Obasanjo, oun tó ń sọ yé e, ìjọba ni kó tají - Wale oke Ọrọ lori awọn gbajumọ ati ọmọwe Aarẹ Buhari sọ pe ata akara ti ko ran ikọ ni ọrọ awọn gbajumọ ati ọmọwe to n tako ijọba oun jẹ.
FT Nigeria U20 1-2 Saudi Arabia U20.
3 Bélú 2020 Fídíò, Soyinka Cancer: Àṣe ara mi ni iso ti n run gbogbo bí mo ṣe n ṣèrànwọ́ lórí jẹjẹrẹ27 Bélú 2019 Yoruba Movie Actors On Set vs Off Stage: Bí àwọn òṣèré fíìmù ṣe rí láì mura gegege1 Bélú 2020 Fídíò, End bad government: Wọn rò pé a maa jà tàbí ba ǹkan jẹ́ ni ṣùgban ọmọlúwàbí ni wa-Afẹ̀hónúhàn17 Ọ̀wàrà 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Lasiko sísọ oko lu Asetani ní Jamrah, o ṣé pàtàkì láti lọ sibẹ lásìkò tí wọn bá kéde fún orílèèdè rẹ, bi bẹẹkọ, o lè sọnù lójú ọnà tí o bá dá lọ fúnra rẹ.
Oun ṣiṣẹ ni ṣọọbu aranṣọ kan lati maa ri owo pẹẹpẹpẹ lasiko igba naa t'oun duro de iwe igbani wọle si yunifasiti.
Gege bi ile-ise akoroyin Reuters, won ni  Iko omo ogun ajo U.
Kí ẹnikẹ́ni tí ó bá ṣèèṣì pa eniyan sá lọ sí ọ̀kan ninu àwọn ìlú ọ̀hún, kí ó dúró ní ẹnubodè ìlú, kí ó sì ro ẹjọ́ fún àwọn àgbààgbà ibẹ̀.
“Julen Lopetegui ni yoo je akonimoogba agba iko Real Madrid leyin idije agbaye.
Nígbà tí àwọn olórí alufaa ti forí-korí pẹlu àwọn àgbà, wọ́n wá owó tí ó jọjú fún àwọn ọmọ-ogun náà.
Nitori naa ni wọn ṣe ke gbajare si ijọba ipinlẹ Eko lati ri pe eto aabo gbokun si lasiko yii nitori awọn janduku yoo mu aye le fun awọn eniyan lasiko ti wọn ba n wa ọna ati jẹ ati mu lọ.
Ẹ dẹ́kun àbùkù tẹ fi ń kan Nàíjíríà, ẹ fi Sowore sílẹ̀ láhàmọ́- Soyinka Aug 2018 ni ìgbìmọ̀ aláṣẹ APC ti ṣe ìpàdé kẹ́yìn, Oshiomole ti kùnà"" Òbítíbitì ẹ̀gbin ti sọ ìlú Ibadan di ààtàn - Aráàlú figbe bọnu Àwọn ẹni òkùnkùn ló já ìṣẹ́gun mi gbà, mò ń lọ sílé ẹjọ́ tó ga jùlọ - Bayo Adelabu Royal beere pe, ""Nigba wo ni ileeṣẹ NTA yoo ṣatunṣe si igbohunsafẹfẹ wọn?"
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Mummy calm down: Ìyá Ore sọ pé gbogbo ìgbà tí óun bá n bá a wí ló ma n ṣe àwàdà Ko tan sibẹ o, Shina tun wa agbara lọ silu Ogoja nipinlẹ Cross Rivers, to si setan lati di ilumọọka ogbontagi adigunjale to n dẹru ba araye.
Daniẹli, ati Hananaya, ati Miṣaeli ati Asaraya wà lára àwọn tí wọ́n ṣà ninu ẹ̀yà Juda.
Mo kan gbe ju si ibi ti wọn ti gbe e ni.
 Àwọn Ẹ ̀ gùn àti pópó ni ó dá a sílẹ ̀ ní àkókò ọba oníṣílè .
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ọọ̀ni: Gbogbo ẹni tó rí tajé se ló yẹ kó tọ́jú ọmọ òrukàn 13 Ògún 2018 Ọọni Ile-Ifẹ Ọba Enitan Adeyeye Ogunwusi, Ọjaja keji ti dẹrin pa ẹkẹ awọn ọmọ orukan atawọn ọmọ to ku diẹ kaato fun nilu Ibadan lọjọ aiku, nibi iṣile tuntun fawọn ọmọ orukan.
Oríṣun àwòrán, @CBNOFFICIALS Àkọlé àwòrán, CBN gbé ofin tuntun sílẹ̀ fún àwọn Báǹkì Ilé ìfowópamọ àpapọ ọ̀hún sọ èyí dí mímọ nínú àtẹjáde kan tí Dípò Fatokun, olùdarí àwọn ilé ìfowópamọ àti ẹka owó sísan fi sọwọ sí àwọn ilé ìfowópamọ nínú oṣù yìí.
"Lórí ìdí tó fi ń jẹ Okunnu, ó ṣàlàyé pé orí bíbá àwọn èèyàn kọ ìtàn ni òun ti bẹ̀rẹ̀ isẹ tíátà, kí oun tó máa kopa ninu ere, 'Isẹ Imọlẹ ' sì ni ère tòun kọ́kọ́ ṣe síta.
Báwo ni Barack Obama, Bill Gates, Elon Musk, Jeff Bezos ṣe lùgbádì àwọn gbájúẹ̀ orí ayélujára?
EFCC pa ìkéde Twitter rẹ́ nípa Fayoṣe Bkannnaa, ajọ EFCC, ti pa ikede kan to fi sita lori Twitter lọjọ isinmi pe 'awọn ti gbọn awọn iwe to wa lọwọ awọn lori magomago to waye lori awọn ile adiyẹ ti wọn dá sílẹ̀ l'Ekiti.
LASTMA Yesufa: Àwọn dókítà gbìyànjú lórí ojú mi ṣùgbọ́n.
Ṣugbọn nítorí ìṣìnà wọn ni ìgbàlà fi dé ọ̀dọ̀ àwọn orílẹ̀-èdè yòókù, kí àwọn Juu baà lè máa jowú.
Amẹrika ni ṣe ni awọn yoo kawọ ko lori fifun awọn eeyan to wa lati Nigeria, Eritrea, Kyrgyzstan, ati Myanmar ni iwe aṣẹ irina to lee sọ wọn di olugbe ilu naa.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Bí ẹ ṣe mọ̀wé tó, ẹ wá dánrawò níbí pẹ̀lú Àpólà Ọ̀rọ̀ Orúkọ - Noun Phrase O fikun wi pe ninu ipọnju yii ni oun wa fun ọpọlọpọ igba, ti iyawo meji ti oun ni si saisan ti wọn si ku."
Ìmọ̀ràn mi ni pé, kí eniyan máa gbádùn, nítorí kò sí ire kan tí ọmọ eniyan tún ń ṣe láyé ju pé kí ó jẹ, kí ó mu, kí ó sì gbádùn lọ; nítorí èyí ni yóo máa bá a lọ ní gbogbo ọjọ́ tí Ọlọrun fún un láyé.
A dúro bí iké lẹ́yìn ìròyìn táa gbé jáde nípa Lekki Tollgate; CNN tako Lai Mohammed Báyìí ni olùwọ́de EndSARS, Eremosele Adene ṣe gba òmìnira lọ́wọ́ ọlọ́pàá Nàìjíríà Ṣé Sanwo-Olu, gómìnà Eko yóò farahàn níwájí ìgbìmọ̀ olùwádìí ìṣẹ̀lẹ̀ Lekki Tollgate?
Matitaya, ọ̀kan ninu àwọn ọmọ Lefi tí ó jẹ́ àkọ́bí Ṣalumu ará Kora níí máa ń ṣe àkàrà ìrúbọ.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ọ́mọ márùn-ún sọnù ní Otto l‘Eko, àwọn ìyá wọn kò jẹ́ èèyàn mọ́ lẹ́yìn ọdún kan Ilé ẹrù míì tó jábọ́ l‘Eko tún mú ẹ̀mí obìnrin méjì lọ Àwọn ọmọ orílẹ̀èdè Mali ń fò fáyọ̀ pé ológun gba ìjọba mọ́ alágbádá lọ́wọ́ Ọkọ̀ rélùwéè 16 yóò ná Eko sí Ibadan láti oṣù tó ń bọ̀ lọ - Iléeṣẹ́ Rélùwéè kéde Ọba Ilorin ló pàṣẹ pé kí ń padà sọ́dọ̀ ọkọ mi - Risikat olójú búlúù A fí ara mọ́ ìdájọ́ ikú Sharia tó tọ́ sí Olórin Yahaya- ẹgbẹ́ Amòfin Mùsùlùmí ẹ̀ka ìpínlẹ̀ Kano Wo bí ọkùnrin ọmọ òrukàn yìí ṣe ń ran àwọn opó tí ọkọ wọn kú sójú ogun lọ́wọ́ Deji Akure pàṣẹ kí wọ́n ti gbogbo ọjà pa fún ọjọ́ méjì, ohun tó fàá nìyí Wo ohun tó ṣẹlẹ̀ sí Saka, Sunkanmi Omobolanle àtàwọn òṣèré sinimá míràn lọ́sẹ̀ yìí Bakan naa ni wọn sọ pe Insipẹkitọ ọlspaa kan naa fara gbọgbẹ ọta ibọn, ti wọn si ti gbe lọ sile iwosan fun itọju.
Ọga agba ọlọpaa Adamu ko ṣai ki ẹbi awọn ọlọpaa ati araalu to doloogbe nitori ati mu afurasi naa.
Ìrísí wọn bani lẹ́rù; wọ́n ń fi ọlá ńlá wọn ṣe ìdájọ́ bí ó ti wù wọ́n.
Dokita Wilson ṣalaye pe o ṣeeṣe ki eeyan ti ipasẹ ere idaraya ko aarun covid-19 nitori sisun mọ ẹni to ni aarun naa lara.
Ewe, Oyebanji ti figba kan je, olukoni nile iwe giga fafiti.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Akinyele Killings: Ilé iṣẹ́ ọlọ́pàá Ibadan fẹ́ fi owó kún móríya ẹni tó bá rí Sunday Shodipe 15 Ògún 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 23 Ògún 2020 Oríṣun àwòrán, OTHERS Ilé iṣẹ́ ọlọ́pàá ìpinlẹ̀ Oyo ni ọ̀rọ̀ Sunday Shodipe tó sálọ ní àhámọ́ ọlọ́pàá jẹ́ ǹkan to n kọ àjọ ọlọ́pàá lóminú gidigidi.
Mẹ́ta nínú àwọn ọmọ Whitmer, tí ọkọ̀ọ̀kan nínú wọn ti gba ẹ̀rí nípa bí ìwé náà ṣe jẹ́ òtítọ́ tó wá wòye bí ó ṣe kàn wọ́n tó láti mọ́ ojúṣe tí wọ́n ní kárakára gẹ́gẹ́bí olúkúlùkù.
Aare Buhari fi iwe ikedun naa ranse si awon omo orile ede Amerika, ore  ati ebi oloogbe naa,  ti o je aare  ikokanlelogoji ni orile ede naa , eni ti gbogbo awon eniyan  n kan saara si fun ipa pataki ti o ko lagbaaye.
 ní ọ ̀ nà , ní ibi tí alágbẹ ̀ dẹ ́ ti fi kọ ́ lá sí ọkọ ̀ ní ìjelòó , wọ ́ n rí àwọn méjì tí wọ ́ n ń jà Ògúndélé ni orúkọ alágbẹ ̀ dẹ yìi .
Eyi lo si fa a ti wọn fi yinbọn pa awọn ti wọn pa.
EndSARS: Makinde kéde ìrànwọ́ fáwọn ẹbí ọlọ́pàá tó bá rògbòdìyàn EndSARS lọ láti inú N500m tí a yà sọ́tọ̀
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Abìjà: Bàbá mi fi iṣẹ́ ọdẹ ti ń pa lémi lọ́wọ́ ni nítorí babaláwo ni Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
 kìkì ṣẹ ̀ kẹ ̀ rẹ ̀ là ń lù nìbi ti a ba nsere apíìri .
Bí orílẹ̀-èdè Nàìjíríà ṣe ń múra fún ètò ìdìbò sí ipò Ààrẹ nínú Oṣù Èrèlé, àwọn ọ̀gágun tí ó ti jagun fẹ̀yìntì tí wọn di olóṣèlú, jẹ́ igi gbòógì fún òye ètò òṣèlú orílẹ̀-èdè Nàìjíríà.
 “A gboriyin fun ijoba orile-ede Naijiria fun iyanju won lati gba awon omo ile-iwe naa, ni eyi ti won seleri atileyin lati gbe igbese ni kankan, lati maa je ki iru isele anjini-gbe yii waye mo.
Winnie Madikizela-Mandela, ajajangbara ni South Africa naa ṣalaisi ni oṣu kẹrin ọdun.
Aworan yi jade si oju opo Twitter wọn lati bẹnu atẹ lu Aarẹ Buhari lori iku awọn ọmọ ogun ṣugbọn iwadi fi han wi pe aworan naa ki ṣe ti awọn ọmọ ogun to ku ni Metele.
EndSARS: Olatunde Abolarinwa London Tailor ní òun á ṣe baba fún mi, kò tilẹ̀ dúró ṣe bàbá àwọn ọmọ tirẹ̀ tóríi ìwà Ọlọ́pàá Mopol
Ẹ̀yin ará ilé Lefi, ẹ yin OLUWA,ẹ̀yin tí ẹ bẹ̀rù OLUWA, ẹ yìn ín!
West Brom - Daniel Sturridge: Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Daniel Sturridge ti bọ lọwọ Newcastle ati Inter Milan West Brom ti ọmọ ẹgbẹ agbabọọlu Liverpool ati England, Daniel Sturridge yoo si wa ninu ikọ naa ni ipo ayalo titi.
Gbogbo àwọn atukọ̀ ni yóo jáde kúrò ninu ọkọ̀.
ni eka ila oorun orile-ede Naijiria.
“Mo ti rú ẹbọ alaafia,mo sì ti san ẹ̀jẹ́ mi lónìí.
Wo àwọn olóríire tó borí nílé BB Naija sẹ́yìn àti iye òjò owó tó rọ̀ fún wọn Àwọn afọbajẹ wọ́ Oluwo relé ẹjọ́, ìjọba Osun kò tíì fọùn Ẹ gbà mí, Nàíjíríà gbá mi lórí àyẹ̀wò Covid-19 - Iyabo Ojo figbe ta Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 3 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 5 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
"Awọn akọnimọọgba yoo ti fa wọn leti wipe bi wọn ba fọhun, isẹ wọn tan""."
Ajakale àrùn yìí ló sọ ara rẹ di ojo láwùjọ agbaye, tí kò sì bá orile-ede kankan ṣe ọ̀tá, tó sì ń pá ọmọdé àti àgbà.
Nígbà ti ọ̀rọ̀ ọ̀un jẹyọ, ààrẹ Buhari dáwọ́ ìgbanisísẹ́ ọ̀hún dúro Keyamo bẹ́nu àtẹ́ lu àwọn tí wọn sọ pé, ààrẹ ń fárí apa kan, dá apákan sí láti máa yan àwón èèyàn apá Aréwa nìkan sí ipò to ga jù.
Nígbà tí àwọn eniyan rí i, wọ́n yin oriṣa wọn; wọ́n ní, “Oriṣa wa ti fi ọ̀tá wa lé wa lọ́wọ́, ẹni tí ó sọ ilẹ̀ wa di ahoro tí ó sì pa ọpọlọpọ ninu wa.
O ni inu oun dun wipe ọrọ naa ti ni iyanju gẹgẹ bi ilana ofin ṣugbọn oun ko fẹ ki adajọ obinrin miiran foju ri oun ti oun ti koju.
O ni owo ori sisan da bi keeyan maa ta tabi ra ọmọbinrin to n lọ sile ọkọ, nitori naa o yẹ kawọn obi dẹkun ori gbigba.
ìjọba Tanzania ko 30 Mílíọ̀nù rẹ̀ wọ̀lú Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Wọn pin ẹgbẹrun lọna aadọfa rọba idaabobo nibi idije Olympic Awọn eleto ilera orilẹede Tanzania ti ko rọba idaabobo ọgbọn miliọnu wọ orilẹede wọn lati mu adinku ba Ni orilẹede naa, ṣe ni awọn eniyan n kun yunmu yunmu nipa bi rọba idaabobo ṣe n gbowo lori sii plu bi ijọba ṣi ṣe n pese rẹ fun awọn eniyan to.
Èmi bẹ̀ ọ́, yan ẹnìkan tí yóo máa ṣáájú àwọn eniyan wọnyi: 
Nítorí pé gbogbo ẹ̀dá ayé ló ti pasán, kì í ṣe pé ẹ̀dá ayé fúnra wọn ni wọ́n fẹ́ pasán, ṣugbọn bẹ́ẹ̀ ni ó wu Ẹlẹ́dàá láti yàn án.
10 Kíyèsíi, ìwọ ní ẹ̀bùn kan, tàbí ìwọ yíò ní ẹ̀bùn kan bí ìwọ bá fẹ́ lati ọwọ́ mi nínú ìgbàgbọ́, pẹ̀lú ọkàn òtítọ́, ní gbígbàgbọ́ nínú agbára Jésu Krísti, tàbí nínú agbára mi èyí tí ó nbá ọ sọ̀rọ̀;
Atẹjade naa to fi sita ni ọjọ aje tun ṣalaye siwaju sii pe laipẹ laijina ni agọ asofin agba Saraki yoo sọrọ lori iha ti wọn kọ si eto idibo naa.
Wọn a ma fi da ọmọ ẹgbẹ wọn loju pe mimi kan ko le mi wọn lati ọdọ awọn ẹgbẹ to ku.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù ₦50 Duty Stamp: Iléẹjọ́ korò ojú sí CBN bó ṣe ń yọ owó táwọn báńkì olókoòwò fi pamọ́ sọ́dọ̀ rẹ̀ 12 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Oríṣun àwòrán, @cenbank Ileẹjọ giga ilu Asaba ti kede pe ko tọna rara kawọn banki maa yọ aadọta naira lori iwe ifowopamọ ti onibara kọọkan ba kọ tabi fi ransẹ lati ori foonu wọn.
Yaba Left: Awon àṣírí ìkọkọ to jẹyọ nínú ìwádii
Lootọ, Luka Modric lee lewaju awọn ti wọn n du ami ẹyẹ yii ṣugbọn awọn ti yoo ba du u niwọnyii: 1.
Gẹgẹ baa ti ka ninu itan awọn nkan to ti sẹlẹ siwaju laye atijọ, awọn obinrin ti jẹ Alaafin ri, ti ko si gbọdọ jẹ ajeji si wa mọ lode oni.
Nítorí náà, nígbà tí wọ́n rí Jehoṣafati ọba, wọ́n ní, “Dájúdájú ọba Israẹli nìyí.
Lẹ́yìn ìgbà díẹ̀, aya Juda, tíí ṣe ọmọ Ṣua kú.
mokanla laarin odun 2013 ati 2016 nilẹ Afirika.
Ọ̀pá ọ̀kọ̀ rẹ̀ sì dàbí igi òfì, irin tí ó wà lórí ọ̀kọ̀ rẹ̀ jẹ́ ẹgbẹta (600) òṣùnwọ̀n ṣekeli.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Àwọn mùsùlùmí Shiite kọlu àwọn ọlọ́pàá lọ́pọ̀ ìgbà nibi tí wọ́n ti ṣe ìwóbi pé k'ìjọba tú olórí wọn sílẹ̀ Iroyin fikun un wi pe, awọn ẹgbẹ Shia to wa se ifẹhọnu han naa le ni ẹgbẹẹrun, ti wọn si koju awọn ọlọpaa, ki o to di wi pe awọn ọlọpaa koju wọn.
ayokele, ororo, aso aloku, aloku taya oko, suga ati awon aso tuntun ti apapo
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Awọn eku ọlọmu rọọrọ lo n fa iba Lassa Wọn sọ pe awọn onisẹ igbohunsafẹfẹ ipinlẹ naa ti gbe iroyin pe mejilelọgọrun awọn isẹlẹ mii ni wọn ti ro pe o jẹ iba Lassa ni ijọba ibilẹ mẹjọ ni ipinlẹ naa.
Lati igbayii wa lawọn ọmọ Naijiria ti n kebosi sigboro aye ti koowa si n gbe amọran tirẹ kalẹ lori ipo ti eto abo wa lorilẹede Naijiria bayii.
Ikọ tuntun yi ni yoo gba iṣẹ SARS ti wọn tọkaabuku si laipẹ yi to si fa ifẹhonuhan loriṣiiriṣii 'Mo jíṣẹ́ ẹ rán mi'!
Ni ọjọ Ẹti lawọn alaga kansu ọhun kọkọ gba ile ẹjọ lọ, lati fi to ile ẹjọ giga ipinlẹ Ọyọ leti pe awọn ti tẹwọgba eto ti ijọba fi silẹ fun yiyanju aawọ naa, ṣugbọn awọn ko tii yiri rẹ wo.
Ohun to yẹ ko ṣe ree: Kan si oju opo http://cac.
Àwọn mẹ̀kúnnù ati àwọn eniyan pataki pataki jọ wà níbẹ̀,àwọn ẹrú sì bọ́ lọ́wọ́ oluwa wọn.
 ifá tí a ń sọ ̀ rọ ̀ rẹ ̀ yí ni ó ní odù tí ó tó igba ó lé mẹ ́ rìnlélọ ́ gọ ̀ ta odù , tí ìkọ ̀ ọ ̀ kan rẹ ̀ sì ń dá lórí ènìyàn , ẹranko , àti àwọn Òrìṣà pẹ ̀ lú ìṣòro àti ọ ̀ na àbáyọ sí ìṣòro wọn èyí ìṣẹ ̀ lẹ ̀ tí ó ti ṣẹ ̀ sẹ ́ yìn .
”O tesiwaju lati so fun awon akegbe re pe “mo fi ara mi sile lati sin yin, ati lati baa yin sisẹ papọ ni eyi ti , alaafia, aabo to peye , ijọba rere, ati bi igbe aye idẹrun yoo see wa’’ ni awon ekun wa ati lati mu eto idagbasoke ba ajo naa.
O wa ro ijoba to n kogbawole pelu eleyii to n bo lati
Ní ọjọ́ ìgbéyàwó  wa, Àjàkálẹ́-àrún tí í ṣe ìyá òun gba agbára lọ́wọ́ Èṣù, ó fa ahọ́n ìyàwó mi yọ.
Oríṣun àwòrán, EPA Àkọlé àwòrán, Awọn ọkọ to gbina lasiko ibugbamu to waye ni Beirut lọjọ kẹrin, oṣu Kẹjọ Nitori eyi lo ṣe ni awọn ilana to yẹ ki ẹnikẹni to ba fẹ ẹ ko pamọ tẹle.
Pẹlu eyi, ẹgbẹ awọn dokita oníṣegun oyinbo lorilẹede Naijiria ti fi ikilọ sita bayii pe, bi ijọba ko ba gbe igbesẹ lati daabo bo awọn dokita kaakiri ileewosan, ko si igba ti awọn dokita lorilẹede Naijiria ko ni maa kẹyin si awọn alaisan ti wọn ba funra si wi pe wọn ni arun Iba Lassa.
"Igbagbọ wa ni pe akanse owo osu fawọn olukọ (TSS) yoo mu ki isẹ olukọ da yatọ, ti yoo si tun fun isẹ olukọ ni idamọ to dara, taa si to si ipo ẹyẹ lawujọ, a wa n rọ ijọba lati tete buwọlu ibeere yii.
Ó ní tí wọn ò bá jó àgọ́ ọlapàá ni, ètò ààbò kò ni dojúbolẹ̀, àwọn ọ̀daran kò sì ni rí iṣẹ́ ṣe.
Lẹ́yìn tí Kọ́lá Akínlàdé gba ìwé-ẹ̀rí yìí ni ó dá ìwé ìròyàn kan sílẹ̀ tí ó pe orúkọ rẹ̀ ní ‘Ẹ̀gbádò Progressive Newspaper: Lẹ́yìn èyí ni ó wá bẹ̀rẹ̀ iṣẹ́ gẹ́gẹ́ bi akọ̀wé ìjọba.
Ẹ wo àwọn gbajúmọ̀ òṣèré tíátà tó jogún eré ṣíṣe lọ́dọ̀ òbí wọn $30bn owoya ti Buhari fẹ́ gbà, kí ló wà fún?
Bí ẹrí ènìyaǹ tó sọ̀rọ̀ àtàtà lẹ́nu
Ohun tí ó ṣe burú lójú OLUWA bí ìdílé Ahabu ti ṣe, nítorí pé lẹ́yìn ikú baba rẹ̀, àwọn ará ilé Ahabu ni olùdámọ̀ràn rẹ̀, àwọn ni wọ́n fa ìṣubú rẹ̀.
O wà lórí òkè mímọ́ èmi Ọlọrun, o sì ń rìn láàrin àwọn òkúta olówó iyebíye tí ń tàn yinrinyinrin.
Eekan ori ayelujara yii tawọn eeyan mọ si Motara fi fidio bi o ṣe n fi mínírà la ọmọdebinrin kan to n bẹ ẹ loju.
” Gideoni bá dán wọn wò lóòótọ́, ọ̀kẹ́ kan ati ẹgbaa (22,000) ọkunrin ninu wọn sì pada sí ilé.
Ṣe wọn ko ni awọn olori ọja nibi ti wọn ti wa ni?
iwa ibajẹ , eto ẹkọ  ati isẹ.
Taiwo Akinkunmi, ọmọ Ibadan tó ya àsìá Naijiria Ayinla Ọmọwura, orin èébú àti oríyìn lo fi di ọ̀rẹ́ àwọ̀n obìnrin ''Wàhálà Ikẹja ló sọ mí di oníṣẹ́ ọwọ́ àgbọn ní Badagry'' Ìtàn tó rọ̀ mọ́ òwe ‘aṣọ kò bá Ọ́mọ́yẹ mọ́.
Àwọn tí a kà ninu àwọn ọmọ Merari, ní ìdílé-ìdílé gẹ́gẹ́ bí ilé baba wọn, 
“Ìwọ ọmọ eniyan, fi nǹkan ìríra tí Jerusalẹmu ń ṣe hàn án, 
Ọ̀lẹ ti ọwọ́ bọ àwo oúnjẹ,ṣugbọn kò lè bu oúnjẹ sí ẹnu ara rẹ̀.
Wọn óo kọ̀ mí sílẹ̀, wọn óo sì da majẹmu tí mo bá wọn dá.
Ọrẹ yìí yóo dàbí ọrẹ ọkà titun, ati ọtí waini titun, tí àwọn àgbẹ̀ ń mú wá fún OLUWA.
Gege bi asofin Garba se so: “Ibere fun ketekete loja po lataari awon ohun asara lore ti o n tara re jade.
Òkú ọmọ ọdún mẹ́ta tó kó sí kàǹga ní Ipaja ni wọ́n yọ' A n ṣe akojọpọ ẹkunrẹrẹ iroyin yajoyajo lọwọ, a o maa gbe ẹkunrẹrẹ iroyin naa sori atẹ iroyin wa laipẹ.
Lọwọ lọwọ bayii, okun irẹpọ Naijiria ti yinrin, Ọba oke nikan si lo lee se ti okun irẹpọ naa ko fi ni rẹ ja laipẹ, gẹgẹ bi igbakeji aarẹ, Yemi Osinbajo se woye.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù ECOWAS: Aàrẹ Ghana, Nana Akufo-Addo ti di aàrẹ ẹgbẹ́ ìṣọ̀kan ilẹ̀ adúláwọ̀ tuntun 7 Owewe 2020 Oríṣun àwòrán, @moigovgh Ajọ orilẹ-ede iwọ oorun ilẹ Adulawọ, Economic Community of West Afircan State ti yan Aarẹ ilẹ Ghana, Nana Akufo-Addo lati ma tukọ ajọ ECOWAS bayii.
Yatọ si Olivier Giroud, Alonso ati Callum Hudson-Odoi naa o
Ènìyàn 5,162 ló ti ní ààrùn Coronavirus ní Nàìjíríà, ti èèyàn 167 sì ti bá ààrùn náà rìn.
Ẹni ọdun mejilelogun olorin naa sọ pe bi ile ẹjọ Sharia ṣe n ṣe ẹjọ ni ipinlẹ naa ko tọna ko si ba ofin ijọba awarawa mu.
Subriel Matias to jẹ ẹlẹṣẹ lati Puerto Rico lo ti na Maxim pupọ ni Maryland.
Oríṣí ìjìyà ní àwọn bíi Gómìnà El Rufai àti Fayemi ń bèèrè f'àwọn afipábánilòpọ̀ Àjọ NCDC kéde ènìyàn 790 tó tún ṣẹ̀ṣẹ̀ ní Coronavirus ní Nàìjíríà Ètò ìgbani sísẹ́ yìí yóò wà ni ìdádúró náà - Ilé ìgbìmọ̀ aṣòfin àgbà Níbẹ̀rẹ̀ oṣù tuntun, jálá epo bẹtiróò fò fẹ̀rẹ̀ sí ₦143.
6 113295 Orilẹede Slovenia 1744 83.
Èmi OLUWA ni mo sọ bẹ́ẹ̀,bẹ́ẹ̀ ni n óo sì ṣe.
Ogun Police: Ọlọ́pàá Ogun rí ₦2m, oògùn olóró ₦10m àti ọ̀pọ̀ ohun ìjà olóró kó níbùba olóògùn olóró
oṣelu PDP ni ẹgbẹrun mẹta-le-ọtalenigba din ookan.
GGeneral Elections (Idibo gbogboogbo) : Idibo gbogboogbo jẹ
Ọlọrun ni ó gbà wọ́n sí iṣẹ́ láti fi ibinu gbẹ̀san lára àwọn tí ó bá ń ṣe nǹkan burúkú.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Tóyìn Adégbọlá: Kò yẹ kí obìnrin fi ìdí gba ipò tíátà Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Tóyìn Adégbọlá: Kò yẹ kí obìnrin fi ìdí gba ipò tíátà 27 Ẹrẹ̀nà 2018 Ìlùmọ̀ọ́ká òsèré tíátà kan, Yèyé Tóyìn Adégbọlá ti késí àwọn akẹẹgbẹ́ rẹ̀ lóìinrin àti àwọn aráàlú tó bá ní ìfẹ́ láti di òsèré orí ìtàgé láti m''ase gbé ara wọn sílẹ̀ fún ọkùnrin kankan, kí èròǹgbà wọn tó leè jọ.
Iroyin kan to faharan lori opo ikansiraẹni tuwita ti ileesẹ aarẹ Naijiria fisita salaye wipe Aarẹ Buhari yan asiwaju Bola Tinubu lati se aayan ijiroro, ifinukonu, ati irapada igbẹkẹle awọn ọmọ ẹgbẹ ninu isọkan ẹgbẹ oselu naa.
Cardi tun fun ẹnikan to gbiyanju lati bu ẹnu atẹ lu irisi rẹ ninu fọto naa, l'esi pe ori ọyan mi tobi, nitori pe mo fun ọmọ mi, Kulture l'ọmu fun oṣu mẹta""."
Àkọlé àwòrán, Ibadan, Ipinlẹ Oyo Àkọlé àwòrán, Ko si alaabọ ara niwaju Eleduwa Àkọlé àwòrán, Yidi Ibadan ni Ipinlẹ Oyo BBC News, Yorùbá Ìdí tí ẹ fi le è nígbàagbọ́ nínú ìròyìn BBC Ìlànà Lílò Nípa BBC Òfin Àṣírí Cookies Kàn sí.
àwọn ẹranko ìgbẹ́ ati ìkookò yóo jọ máa gbé ibẹ̀,àwọn ewúrẹ́ igbó yóo máa ké pe ara wọn.
Nitori idi eyi, gbogbo awọn alaga ni gbogbo ijọba ibilẹ meejidinlogun to wa nipinlẹ naa ni wọn ti pasẹ fun lati ri daju pe ofin yi fẹsẹ mulẹ digbin lawọn ijọba ibilẹ wọn.
Ǹ jẹ́ o leè fi àmì sórí ‘Àgbàlagbà-akàn’ ?
ki ni oju rẹ ṣe ran mọ ti Tamil?
Araale: Awọn ileewe wo ni ẹ lọ?
Ẹ di ẹni ìparun, ẹ̀yin ọmọ oriṣa Kemoṣi!
- Amina Zakari Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Mọrèmi: Ọọ̀ni ní láìsi Mọrèmi, kò leè sí ilẹ̀ Yorùbá Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ronke Oṣodi: òótọ́ ọ̀rọ̀ máa ń korò gan ni f'áwa èèyàn Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Atẹjade kan ti ajọ to n ri si igbogun ti ajakalẹ arun lorilẹede Naijiria, NCDC fi sita loju opo twitter rẹ ṣalaye pe, meje ninu awọn eeyan naa wa ni ipinlẹ Eko, ati mẹta ni Abuja.
Ni bayii, iyikoto ipele keta yoo waye lojo Eti(Friday).
orile ede yii, bakan naa , ni o tun dupe lowo oludari eka bi oro ile ise se n lọ,nile
Alaga Ajọ Nigerians in Diaspora Commission, Abike Dabiri-Erewa, lo fi lede bẹẹ ni oju opo Twitter rẹ.
Oríṣun àwòrán, Others Lori pe boya nitori pe Obasanjo ma n bu ẹnu ẹtẹ lu isejọba Aarẹ Buhari, o sọ pe eyi ko yẹ ko ribẹ.
O ni wọn ko jẹ ki ẹnikẹni sunmọ tosi ẹnu ọna ibẹ rara nitori pe ẹru n ba wọn pe ki iwọde tabi biba nkan jẹ ma lọ ṣẹlẹ lataari ile Arugbo ti wọn wo ni idaji oni.
Amọ orilẹede South Africa ti sọ igbó lilo di ofin ni ìkọ̀kọ̀.
Abala 292 (1) (a) (i) ati 292 (1) (b) iwe ofin Nigeria ti ọdun 1999 laa yekeyeke.
Ọjọ yii ni wọn gba pe Jesu ku lọwọ Pọntiu Pilatu gẹgẹ bi o ṣe hande ninu Bibeli.
Gbogbo àkókò tí Jehu fi jọba lórí Israẹli ní Samaria jẹ́ ọdún mejidinlọgbọn.
Aráyé ń sọ Ọ ́sí láburú, aráyé ń sọ Ọ ́sí rere
Idi ni pe oju awọn obinrin ri mabo lọdun to kọja naa nitori awọn isẹlẹ hihu iwa ipa si awọn obinrin ati ifipabanilopọ, eyi to mu ki awọn obinrin pinnu lati maa da wa laisi ọkunrin.
Bí wọ́n tilẹ̀ gbẹ́ ilẹ̀ tí ó jìn bí isà òkú, ọwọ́ mi yóo tẹ̀ wọ́n níbẹ̀; bí wọ́n gòkè lọ sí ojú ọ̀run, n óo wọ́ wọn lulẹ̀ láti ibẹ̀.
Ṣugbọn nígbà tí wọ́n dé, ó bẹ̀rẹ̀ sí fà sẹ́yìn, ó ń ya ara rẹ̀ sọ́tọ̀, nítorí ó ń bẹ̀rù àwọn tí wọ́n fẹ́ kí gbogbo onigbagbọ kọlà.
Ile iṣẹ iroyin BBC ṣe agbekalẹ rẹ lati gbogun ti awọn ayederu iroyin.
" Otitọ to wa nibẹ ni pe, ọkọ mi pọn ẹsin mi le gan-an, emi naa si pọn ti ẹ le.
Ohun ti Wunmi kọ yii lo fidi rẹ mulẹ pe aarin oun ati ọrẹ rẹ naa, Seyi Edun ko gun rara, ti aawọ si wa laarin wọn gẹgẹ bi ẹnu ṣe n kun wọn.
A ri i wipe ọpọlọpọ awọn ipinlẹ wsnyii ni wọn jẹ awọn osisẹ lowo osu, ti wọn ko si tun lee san owo ifẹyinti fun awọn to ti fi irun dudu sin ilu ti wọn wa n fi irun funfun jiya.
tubọ tẹpẹlẹ mọ igbesẹ won nipa ọrọ eto aabo lorile ede Naijiria , ni eyi ti yoo
ati sí ara pẹpẹ ẹbọ sísun, ati gbogbo àwọn ohun èlò rẹ̀, ati sí ara agbada omi, ati ìtẹ́lẹ̀ rẹ̀.
Ṣugbọn mo sọ fun yín dájúdájú, àwọn mìíràn wà ninu àwọn tí ó dúró níhìn-ín tí wọn kò ní kú títí wọn óo fi rí ìjọba Ọlọrun.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ẹ wo adúrú ẹnu tí mó n bọ́ - Jaiye Kuti Wo orílẹ́èdè tí wọ́n tí ń dáwó ìsìnkú ara wọn pámọ́ Ayédèrú Ọ̀ṣun ni wọ́n ń bọ lónìí, kìí ṣe ojúlówó - Bàbá Ọlọ́ṣun tún figbe ta ''Àwọn ọmọ wa ma ń wọ ọkọ̀ ojú omi láìsí ẹ̀wù ìdàábòbò nítorí àti kàwé'' Tinubu ní kò jẹ́ kí àwọn ọmọ bíbí Eko gbérí nínú òṣèlú Bẹẹba gbagbe, laipẹ yii ni awọn afọbajẹ kede pe wọn yan Ọmọọba Ogunoye gẹgẹ bii Ọlọwọ tuntun, to si ti wa ni Ipebi lati igba naa, ko to wa jade sita lọjọ Ẹti, to si gun ori itẹ awọn baba nla rẹ.
Ipinlẹ Eko, ẹlẹẹkẹsan-an yii yoo tẹ siwaju lati ṣatilẹyin fun ẹka
Esi ayẹwo yi ni ẹnikẹni to ba fẹ rinrin ajo yoo mu wa si papakọ ofurufu ki o to le wọ baalu.
yoo tun ran orile ede Naijiria lọwọ lati ni awon ohun elo ti a ko ni lorile ede
Ki Ọlọrun bu kun yin ni gbogbo igba.
Oríṣun àwòrán, Omoyele Sowore Àkọlé àwòrán, Ninu ojo Sowore ati awọn alatilẹyin rẹ ko sọ ireti nuu ti wọ́n si gbagbo wi pe ọ́dun 2019 yoo jẹ ọdun ti awọn ọdọ Naijiria yoo kopa ribiribi ni isejọba.
Àròsọ ni Olófin-íntótó àti ilésanmí ti wokò.
Amọ, Ọjọgbọn Adepoju sọ pe awọn mii ti wọn ba loju buluu lai ṣe wi pe wọn bi mọ wọn ni gbọdọ lọ si ile iwosan fun itọju.
'Mo ti gba kádàrá lórí bí Ọlọrun ṣe dá mi' Gómìnà ìpínlẹ̀ Osun wọ́gilé ìrìnàjò àwọn alága sí Dubai Onnoghen k'ọ̀wé ìfẹ́yìntì, Buhari tẹ́wọ́ gbà á Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Iba Gani Adams: Bẹ́ẹ gbé màláíkà kan lọ sí Aso Rock, kò lè ṣàṣeyọrí O ni ijọba oun ṣe tan lati gbogun ti iwa ibajẹ, nitorina ni awọn yoo ṣe rii daju wi pe awọn gbe abadofin jade ti yoo se ifilọlẹ ile-iṣẹ ijọba ipinlẹ ti yoo maa gbogun ti iwa ibajẹ.
18 Òkùdu 2018 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 29 Òkùdu 2018 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Rẹfiiri Milorad Mazic fun Johan Mojica Colombia ni kaadi Yelo Èsì ìdíje ti gba omi ẹkún lójú ọpọlọpọ agbábọ́ọ̀lù atawọn olólùfẹ́ wọn ni Russia 2018.
Mi ò fẹ́ di ọlọ́lá jùlọ tí mo bá di gómìnà Ondo, màá tẹ̀lé ìfẹ́ aráàlù póńbélé - Ojon YPP Ojú àwọn èèyàn Ondo ti là pé ìnira ni ẹgbẹ́ APC mú wá - Jegede PDP Àwọn kan ṣónú bí wọ́n bá di gómìnà, ẹ fún wa láyè láti wá parí iṣẹ́ táa bẹ̀rẹ̀ - Akeredolu 'N500 dé fún gbogbo ọmọ tuntun lóṣooṣù bí mo bá di gómìnà Ondo - Adeleye AAC Èyí tí a wò jùlọ 5:03 Fídíò, Omolola Arohunmolase Welder: Mo ti fí iṣẹ́ 'Welder' gbayì láwùjọ, tó mo fi tọ́ ọmọ yanjú, Duration 5,039 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 5:39 Fídíò, Akomolede ati Asa lori BBC: Olùkọ́ Kikelomo Ogunboye tan ìmọ́lẹ̀ sí ìwà olè ọ̀gá ọlọ́pàá Audu gẹ́gẹ́ bí àwòkọ́ṣe àsìkò yìí, Duration 5,398 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 4:11 Fídíò, Oba Adeyeye Ogunwusi: Ojú mi ti rí lọ́pọ̀ lọpọ̀, ọ̀pọ̀ èèyàn ni kò tilẹ̀ gbàgbọ́ pé mo lè jọba- Ooni, Duration 4,117 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 4:43 Fídíò, Promise Akinlade: ọmọ ọdún mọ́kànlá tó ń fi ìlù dárà bíi àgbàlagbà sọ̀rọ̀ nípa tálẹ́ǹtì rẹ̀, Duration 4,437 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 0:59 Gbọ́, Ìsẹ̀lẹ̀ jákèjádò orílẹ̀èdè àgbáyé láàárín ìṣẹ́jú kan, Duration 0,59wákàtí 5 sẹ́yìn 7:03 Fídíò, Olumuyiwa Bolade Adedeji Military Bruitality: Bí arákùnrin onípèníjà ara tí sọ́jà lù ṣe dé, Duration 7,035 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 4:45 Fídíò, Yoruba Films: Ẹ̀ẹ́ bẹ̀ mi kúrò láyé ni, mi ò lè kú - Fadeyi Oloro, Duration 4,4526 Èrèlè 2020 2:48 Fídíò, Esther Ajayi: Èmi náà ti borí ìṣòro rí ló ń mu mi ṣojú àánú, Duration 2,481 Ògún 2019 6:08 Fídíò, Adebola Ademilua: Àìrísẹ́ ṣè lẹ́yìn ìwé kíkà ló sọ mi dí ìyá onírú, mo dúpẹ́ tèmi, Duration 6,0827 Bélú 2020 5:55 Fídíò, Soyinka Cancer: Àṣe ara mi ni iso ti n run gbogbo bí mo ṣe n ṣèrànwọ́ lórí jẹjẹrẹ, Duration 5,5527 Bélú 2019 BBC News, Yorùbá Ìdí tí ẹ fi le è nígbàagbọ́ nínú ìròyìn BBC Ìlànà Lílò Nípa BBC Òfin Àṣírí Cookies Kàn sí.
Àwọn alufaa ati àwọn wolii bá sọ fún àwọn ìjòyè ati gbogbo àwọn eniyan pé, “Ẹjọ́ ikú ni ó yẹ kí a dá fún ọkunrin yìí nítorí àsọtẹ́lẹ̀ tí ó ń sọ nípa ìlú yìí, ẹ̀yin náà sá fi etí ara yín gbọ́.
Ibẹ si ni maa ti maa ṣe iṣẹ, pada sileewe, nitori pe ileewe girama ni mo kawe de.
nítorí pé àkókò ń bọ̀ tí n óo dá ire àwọn eniyan mi, Israẹli ati Juda pada.
Oshisko twins: Ojú wa rí, ṣùgbọ́n ìgbọ́raẹniyé ló ń ràn wá lọ́wọ́
Oladẹjọ ni awọn kan n pe James Hadley Chase ti iran Yoruba fun awọn iwe ọdaran to n munilọkan loriṣiiriṣii to ti kọ sẹyin.
Ișẹ́ ńlá tó yakin ni wọ́n ń ṣe.
Ẹkunrẹrẹ lori iroyin yii wa ni: Ẹ wo báwọn òṣèré tíátà kan yóò ṣe rí lọ́jọ́ ogbó Ǹjẹ́ ewu wà nínú lílò ẹ̀rọ FaceApp?
Ẹgbẹ agbabọọlu Manchester City ọhun lo n leke tabili pẹlu ami ayo marunlelọgọta (65) lori atẹ tabili Premier League.
0 137112 Orilẹede Slovakia 1018 18.
Buhari tọ ilana ti o tọ nipa titẹle ọgbọ̀n egberun ti awon igbimo elenu meta
Mo di ẹni ìgbàgbé bí ẹni tí ó ti kú;mo dàbí àkúfọ́ ìkòkò.
Nígbà tí ẹ bá wá jọ́sìn níwájú mi,ta ló bẹ̀ yín ní gbogbo gìrìgìrì lásán, tí ẹ̀ ń dà ninu àgbàlá mi.
Igbimo to n sagbateru idije  British Open, ti kede bayii pe, olukopa ti o darajulo lagbaye ninu ere idaraya Golf teleri, Tiger Woods ti so pe, oun yoo kopa ninu idije mẹ́tàdínláàdọ́jọ British Open ti igbimo naa yoo sagbateru re, eleyi ti yoo waye ni gbagede Carnoustie.
Àkọlé àwòrán, Gomina Ben ayade ati ẹni to di Omidan Afrika tuntun Oríṣun àwòrán, Miss Africa Àkọlé àwòrán, Diẹ lara awọn oludije pẹlu asia orilẹede ẹnikọọkan wọn Oríṣun àwòrán, Miss Africa Àkọlé àwòrán, Ẹbun ẹgbẹrun marundinlogoji Dọla ni ẹni to bori gba pẹlu ọkọ ayọkẹlẹ SUV kan Orilẹede mẹẹdọgbọn lo kopa ninu idije naa.
Àṣàkẹ́ máa ń ràn án lọ́wọ́.
ipinnu egbe APC wa si imuse laarin odun merin sẹyin, paapaa julọ lasiko ti o jẹ
Bí àwọn iléeṣẹ́ ṣe ń ṣiṣẹ́, ìyá ń ké.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Bolaji Faleke ni Olùkọ́ tó ń kọ́ wa ní àṣà oge ṣiṣe lórí BBC Yorùbá Awọn eekan inu ẹgbẹ YWC bii Akin Adejuwon, Ariyike Obet, Nureen Soludero, Bunmi Abidogun, Kunle Adesokan, Muda Ogunsola, Oloye Aduranigba, Imaamu Iyanda Wasiu Abiodun, Paul Bankole, ati Ọmọbabinrin Oyeronke Akinlolu lo wa nibi ipade ti ọrọ naa ti jẹ jade niluu Ibadan.
Burundi: Ìbẹ̀rù bojo gbilẹ̀ bí ẹ̀mí se sòfò sáájú ìdìbò
Mínísítà fún ètò ẹ̀kọ́, Adamu Adamu ló sọ èyí di mímọ lásìkò tó n dáhùn ìbéèrè àwọn akọròyìn níbi ìpàdé àwọn oníròyìn ti ìgbìmọ̀ amúṣẹ́ ṣe lórí Covid-19 ti ààrẹ yan nílùú Abuja.
Dẹtí sílẹ̀ OLUWA, kí o gbọ́.
20 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Sudan removed from terrorist list: America yọ Sudan kúrò nínú ìwé orílẹ̀-èdè tó ń ṣagbátẹrù ẹgbẹ́ agbésùnmọ̀mí lágbàyé14 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 US election 2020: Àlàyé rèé lórí bí èèyàn 538 ṣe ń yan ààrẹ lé èèyàn mílíọ̀nù 331 ní Amẹ́ríkà15 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Bakan naa, awọn eekan ilu kan ni Naijiria ti fidi rẹ mulẹ pe ahamọ awọn agbofinro ni Magu sun mọjumọ ọjọ Isẹgun.
Kíà ni wọ́n bá gbé àwọn oúnjẹ ọ̀hún wá lọ́kọ̀ọ̀kan.
Wọ́n jọ dé pẹlu Serubabeli, Jeṣua, Nehemaya, Asaraya, Raamaya, Nahamani, Modekai, Biliṣani, Misipereti, Bigifai, Nehumi, ati Baana.
Sotayo ni ile iṣẹ nla kan ti wọn ti n ṣagbejade ere tabi orin nilu Eko.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Eye maa gba bọọlu ni Egypt Eyẹ Crane ni awọn Uganda fi pe awọn ẹgbẹ agbabọọlu ti wọn.
Gbogbo eku-ú jẹjẹ jẹ wọ́n yó; àwọn ẹyẹ jẹ èso títì wọ́n fi orí sọgi.
Buhari so pe eto isejoba tiwa-n-tiwa ni anfaani lopo janturu lati goke agba si lorile-ede
Boko Haram: Ìjọba ṣetán láti ra irinṣẹ́, sanwó oṣù fún adúnkookò mọ́ni tẹ́lẹ̀
Àwọn ọmọ Bigifai jẹ́ ẹgbaa ó lé mẹrindinlọgọta (2,056)
Atẹjade kan lati ọdọ igbákejì alága ẹgbẹ́ náà, Ogbonna Chimela ní, ti ìjọba ba je ki iyanselodi náà tẹsiwaju lẹyìn ọsẹ méjì, gbogbo awọn ile iwosan ìjọba ìpínlè àti tìbílẹ̀ ni yóò darapo mo iyanselodi náà.
Olùfẹ́ mi dàbí àpò òjíá,bí ó ti sùn lé mi láyà.
Nítorí ẹ̀yẹ wo ni ó wà ninu pé ẹ ṣe àìdára, wọ́n lù yín, ẹ wá faradà á?
Ní ọjọ́ keji, nígbà tí àwọn ará Filistia wá láti kó ìkógun, wọ́n rí òkú Saulu ati ti àwọn ọmọ rẹ̀ mẹtẹẹta lórí Òkè Giliboa.
Bákan náà, wọn ní àwọn kò ní dáhùn ìfọ̀rọ̀wánilẹ́nuwò kankan lórí ọ̀rọ̀ náà.
Kini ileẹjọ n sọ nipa ẹjọ ti aarẹ Trump n pe lori esi idibo to gbe Joe Biden wole?
 Bo tilẹ jẹ pe o sọ pe oun ko le fidi rẹ mulẹ boya wọn ju bẹẹ lọ, ṣugbọn o fi kun pe ọpọ eeyan lo fara gbọta ibọn."
“Ẹni tí ó bá ṣẹgun kò ní kú ikú keji.
Wọn ni ipade ori ayelujara naa yoo waye laago mẹta oni lori facebook.
Igbagbọ wa ni pe ẹnu wọn a kò si ojutu iṣoro to n koju iran Yoruba ati Naijiria lapapọ yii.
Wọn ko tidarukọ ọkunrin agbebọn naa ti wọn fura si pe o wa nidi iyinbọn naa Saaju olootu ijọba orileede New Zealand kede pe eeyan mọkandinlaadọta lo ti padanu ẹmi wọn lẹyin ti awọn agbebọn yinbọn lu awọn to n kirun ni mọsalaṣi meji ni Christchurch.
Nígbà tí wọ́n rí ìràwọ̀ náà, inú wọn dùn gan-an.
Àjọ NBC fi ẹgba ìbáwí rẹ̀ na AIT, Arise TV àti Channels nítorí ìwọ́de ENDSARS
Abi ẹ n ro wi pe Jacksonville ni inagijẹ Jackson rẹ ti waye ni?
Ẹni ọdun mẹtadinlaadọta ni wọn pe Emmanuel, ti Patricia si jẹ ẹni ọdun mẹtadinlogoji.
Awọn ajọ isọkan agbaye (UN) fi ẹsun kan awọn ijọba ilẹ Yuroopu pe wọn ko kọ'bi ara si ọrọ naa.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, FUTA: Àwọn mẹ́jọ ló ṣíná ìyà fún Bolu ní FUTA Faakinfa laarin Saraki ati Ijọba Naijiria ko ṣẹṣẹ bẹrẹ.
Koda ikọ kan ti wọn n pe ni Black Hedge Fund Group ti figbe ta pe Adekunle ni ẹni naa ti oju gbogbo yoo maa wo lọdun 2018 lẹka imọ ẹrọ.
' Àwọn èèyàn dáná sun ilé ìjọsìn Sọtitobirẹ tí Gold ti sọnù nílú Akure Awọn koko bii iyatọ laarin orin rẹ atawọn ẹya orin yoku, ajọṣepọ rẹ pẹlawọn ololufẹ orin rẹ titi kan bi o ṣe n ṣe amojuto iṣẹ orin rẹ ati ẹbi ni o sọrọ nipa rẹ.
O ni Aarẹ Buhari ti kọkọ sọ wi pe oun fẹ ya owo lasiko Saraki ni eyi ti awọn si fi owo osi da a nu wi pe ko tọna nitori owo ti wọn jẹ silẹ tẹlẹ ti pọju.
Owó ọ̀hún ní wọn ni wọn ri ni àwọn ile iṣẹ́ méji kan tó wọn si tọpasẹ̀ rẹ̀ dé ọ̀dọ gómìnà Yari.
Ní orílẹ̀ èdè Nàìjíríà, àwọn ọba alaye bíi Ọọni tilu Ilé-Ifẹ̀, Ọba Adeyeye Enitan Ogunwusi, Ọjaja Kejì àti Aláàfin tilu Ọ̀yọ́, Ọba Lamidi Olayiwola Adeyemi Kẹta, to fi mọ ojisẹ Ọlọ́run bíi Fada Anselm Adodo àti oniṣẹ ìwádìí Isegun bíi Ọjọgbọn Maurice Iwu, lo fi ọwọ gba àyà pé, òògùn ìbílẹ̀ yóò ṣe ìwòsàn àrùn Coronavirus.
Má sọ̀rọ̀ létí òmùgọ̀,nítorí yóo gan ọgbọ́n tí ó wà ninu ọ̀rọ̀ tí o sọ.
Naira Marley sọ pe oun wọgile iwọde ti oun gbero lati ṣe tẹlẹ nitori aabo awọn eeyan kii ṣe pe bo ya ẹru n ba oun.
Eyi lo jẹ ki ile iṣẹ ọlọpaa orilẹ-ede Naijiria kede awọn nọmba ti ẹnikẹni le pe wọn si ti wọn ba ni ẹsun ti wọn fẹ fi kan ọlọpaa SARS.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Lagos Lion: Kìnìhún ti jí lẹ́yìn abẹ́rẹ́ orun méjì tí wọ́n yìn lù ú Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Lagos Lion: Kìnìhún ti jí lẹ́yìn abẹ́rẹ́ orun méjì tí wọ́n yìn lù ú 20 Bélú 2019 Nibi yii ni ibugbe tuntun ti wọn gbe Kinihun ti awọn ara adugbo figbe ta pe awọn ko fẹ layika awọn si.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Lagos tanker accident: Ọkọ̀ àjàgbé agbépo kan tún dànù l'Eko 15 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Oríṣun àwòrán, lasema Ọkọ ajagbe agbepo kan ti ṣubu lagbegbe Shasha nitosi Akowọnjọ nilu Eko.
Eré bọ́ọ̀lù, ìpàdé ìta gbangba àtàwọn nǹkan míì tó di àpatì torí Coronavirus Ori aga ti awọn ti wọn ba n ṣe aisan ma n joko si ni Weinstein ẹni ọdun mẹtalelaadọrin ọun lo wa si ile ẹjọ naa.
Funmilayo Ransom Kuti: Funmilayo ti orukọ abisọ rẹ n jẹ Francis Abigail Olufunmilayo Thomas jẹ akinkanju obinrin bi okunrin nigba aye rẹ Kíni ìwọ mọ̀ nípa Funmilayọ Ransome-Kuti?
O salaye pe, “a n reti ikore repete lasiko ikore odun 2017, amo eyi ko ri bee latari ikolu ti o waye nini osu kinni odun 2017 ati eyi ti o tun tele ni sise-ntele.
"Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Láàrín ìṣẹ́jú díẹ̀, ẹ ka ìwé Akinwumi Ishola, ""Nítorí Owó"" lórí Akomolede Yoruba 4) Paul Akinjo Ọgbẹni Paul Akinjo, lati ipinlẹ Ondo, n dije fun ile igbimọ aṣofin ipinlẹ California, lati ṣoju ẹkun idibo kejila."
Ikọ BBC Yoruba ṣe abẹwo si agbegbe naa l'owurọ Ọjọ Aiku lati mọ ohun to ṣẹlẹ gaan.
4 Ẹrẹ̀nà 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 5 Ẹrẹ̀nà 2019 Àkọlé àwòrán, Guru Maharaj: Buhari ní yóò wolé nínú ìdìbò 2019 Ko jẹ tuntun mọ pe awọn wolii orilẹ-ede Naijiria a máa riran nipa ohun gbogbo.
Awọn igba miiran ti Shogunle kọ ọrọ to bi ọmọ Naijiria ninu lori Twitter Oun to kọ sọri atẹ Twitter rẹ ree nipa Segun Awosanya ti gbogbo eniyan mọ si Segalink, ajafẹtọ kan ti o maa n gba ọpọ ọdọ silẹ nigba ti ọlọpaa ba mu wọn lọna aitọ.
Ìgbà tì ó ma fi di ọdún 1957 lẹ́yìn ìgbà tí ẹlòmíì ti jẹ oyè Elétǔ Òdìbò (Olóyè) Ámúsà Gbádéṣeré ti jẹ oyè Elétǔ, wọ́n fi Olóyè Sulaiman Balógun Elétǔ Òdìbò jẹ báálẹ.
Ṣùgbọ́n ọmọbìnrin yìí kò mọ ìgbà tí kìnnìún lọ, ó jókòó sí inú ihò lọ́hùn-ún.
Lẹ́yìn ìbúgbàmù ọ̀ún ni iná rọ́kẹ̀tì láti ìlú míì tún tú jáde.
"Ọlọpọlọ pipe, to ni ilana isejọba to pegede ati eto Ọlọrun fun Naijiria ni Ezekwesili.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Femi Gbajabiamila: DSS ti fi ẹ̀sọ́ àbò Gbajabiamila tó pa fẹ́ndọ̀ l'Abuja sátìmọ́lé 20 Bélú 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 23 Bélú 2020 Oríṣun àwòrán, Femi Gbajabiamila Abẹnugan ilé ìgbìmọ̀ aṣojú-ṣòfin l'Abuja, Femi Gbajabiamila ti ṣèlérí pé òun ṣetan láti tọ́ àwọn ọmọ fẹ́ndọ Ifeanyi Okereke ti ẹ̀ṣọ́ rẹ̀ yìnbọ̀n pa titi ti wan yóò fi dàgbà.
the kaaba ( / : / / ) ni ile bi apoti ni mekka , saudi arabia , besini o je ibi mimo julo ninu esin imale .
6 7759 Orilẹede Uganda 304 0.
Bóyá ìdí nìyí tí ó fi sá kúrò lọ́dọ̀ rẹ fún ìgbà díẹ̀, kí o lè jèrè rẹ̀ ní gbogbo ìgbà; 
Ṣugbọn awọn kan wọn fi aidunnu wọn si bi wọn ti gbe wọn lọ si Abuja, wọn ni awọn ko lara tabi iyekan niluu Abuja.
Sowore takú, kò jẹun ní àgọ́ ọlọ́pàá torí májèlé - Deji Adeyanju Ọlọ́pàá àti àwọn olùfẹ̀hónúhàn gbéná wojú ara wọn níbi ìwọ́de Revolution Now Soworẹ ń déte láti dìtẹ̀ gba ìjọba Nàíjíríà lá ṣe gbé e - DSS NLC tọka si i pe, ẹtọ gbogbo ọmọ Naijiria ni labẹ abala ofin ikọkandinlogoji ati ogoji ninu iwe ofin Naijiria, lati ṣe iwọde ti ko ni jagidijagan, ti wọn si tun ni ẹtọ lati korajọpọ tabi darapọ mọ ipejọpọ to ba wu wọn.
Ní àkókò náà, Abimeleki ati Fikoli, olórí ogun rẹ̀, sọ fún Abrahamu pé, “Ọlọrun wà pẹlu rẹ ninu ohun gbogbo tí ò ń ṣe.
Ofin afikun isede ti Aarẹ Buhari kede ko yọ ipinlẹ Ogun naa silẹ.
Gomeri ni baba ńlá àwọn ọmọ Aṣikenasi, Difati ati Togama.
Awọn aṣofin sọ pe awọn jaguda ti bẹrẹ si nii dena de awọn ologun ninu igbo.
Ǹjẹ́ o mọ̀ pé ètò ìdìbò kan wà tí erin àti òkúta Dáyámọ́ǹdì leè yí èsì rẹ̀ padà Oríṣun àwòrán, Emperor telu 1 Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Funmi Adewara: Tele Medicine' ní a fi ń ṣàyẹ̀wò èèyàn ìdá ọgọtá láti dènà ìtànkálẹ̀ Covid Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Baba Kabiyesi oni to jẹ Jagunjagun lo pade rẹ leti igbo to si mu u bọ wale latoju ogun.
A fẹ́ bẹ̀rẹ̀ òfin má lo fóònù mọ́ fàwọn ọmọ wa -Òbí Òní nilé ẹjọ́ tó ga jùlọ yóò gbẹ́jọ́ ẹ̀sùn ayédèrú sabuké tí wọ́n fi kan Buhari Àwọn akọni Nàìjíríà padà sílé pẹ̀lú àmì ẹ̀yẹ 121 láti Morocco Wike kìí ṣe dọ́là tí Ganduje leè kó sápò- Agbẹ́nuso ìjọba ìpínlẹ Rivers Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ẹja jẹ aayo ọpọ eniyan kaakiri agbaye.
Siwaju sí i, ẹ kò gbọdọ̀ jẹ ẹ̀jẹ̀ ní gbogbo ibùgbé yín, bí ó ti wù kí ó rí; ìbáà jẹ́ ti ẹyẹ tabi ti ẹranko.
Ìjọba ìpínlẹ̀ Kogi kéde ọjọ́ ìwọlé àwọn akẹ́kọ̀ọ́ padà sí iléèwé Iléeṣẹ́ ìròyìn Daily Trust gbọdọ̀ san N6 bilion nítorí ìbanilórúkọjẹ́- Femi Fani Kayode Sinimá àwòdamiẹnu, Ẹ̀fáńjẹ́líìsì jìyà àjẹmumi nílé aṣẹ́wó l'Ejigbo ní ìlú Eko Ìjàmbá ọkọ̀ tó ṣẹlẹ̀ sí Adams Oshiomole kìí ṣe ojú lásan, àwọn kan ló fẹ́ pa á- APC Ọba Saudi Arabia yọ ọmọ rẹ̀ àti àbúrò rẹ̀ kúrò nípò nítorí ìwà àjẹbánu lórí owó tó yẹ fún ààbò ìlú Bí ìjà bá wà láàrin èmi àti Olubadan, a ó yanjú ẹ ní pẹ̀lẹ́kùtù, ọ̀rọ̀ bàbálọ́jà kò lè dìjà Ṣugbọn ọgbọn ọjọ, ninu oṣu kẹfa, ọdun 2020, Adajọ Harrison tako arabinrin Adekoya ni apa ibikan to si da iwe ẹbẹ pe ki ile ẹjọ ma sọrọ lori igbẹjọ naa nu.
n óo fà ọ́ lulẹ̀ lọ bá àwọn ẹni àtijọ́ tí wọ́n wà ninu ọ̀gbun.
Lagos-Ibadan Repair: Àwọn ọ̀ná míràn ti e lè gba jáde tàbi wolé si ìpínlẹ̀ Eko
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Sextuplet: Àdúrà Ìbùkún ló kú lẹ́yìn ọmọ mẹ́fà yìí- Ifeoma Thelma àti Onyemaechi Chiaka Yatọ si ọmọdebinrin naa, iya rẹ, dokita to ṣe ayẹwo fun ati ọlọpaa meji, lo tun jẹri tako Adanlawọ nile ẹjọ.
Mo rí i pé ẹ̀sùn tí wọ́n ní jẹ mọ́ ọ̀rọ̀ òfin wọn; kò ṣe ohunkohun tí a lè fi sọ pé kí á pa á tabi kí á jù ú sí ẹ̀wọ̀n.
Bí ó ti lẹ̀ jé pé Ọbásanjọ́ ti Buhari lẹ́yìn láti leè yege ní ọdún 2015, a kò leè sọ pé àtìlẹyìn rẹ̀ nìkan ni ó gbé e dé ipò Ààrẹ.
Weah gba bọọlu fun awọn ikọ bi Monaco, Paris Saint-Germain ati Marseille nilẹ Faranse ati AC Milan orilẹede Italy ki o to fẹyinti.
Ninu lẹta naa si ni abikẹyin naa ti gbe awọn ofin tuntun kalẹ, to si n sọ nipa awsn isẹ ile ti yoo maa se ati eyi ti yoo pa ti.
Bẹẹ ba si gbagbe, ara aawọ abẹnu to n waye ninu ẹgbẹ oselu APC yii lo mu ki wọn padanu ipo gomina nipinlẹ Edo.
Ninu Idajọ naa, ile ẹjọ wọgile awọn ipinlẹ ti magomago ti waye ninu idibo naa, eleyii ti o si mu ki Olujimi ko bori pẹlu ibo to to 54,894 nigba ti Adeyeye ni ibo to to 52,243.
Ọ̀pọ̀ ará ilú ti wọn mọ̀ pé èèwọ̀ ni lati jẹ Igún paapa, jẹ ninú rẹ, ṣùgbọ́n wọn kò mọ pé Igún ni àwọn jẹ, wọn rò wi pé adiẹ ni.
Koda nigba to ni Naijiria ko ni bojuwẹyin lori abadofin iṣakoso ẹrọ ayelujara, ibinu lawọn ọmọ Naijira fi da lohun.
Ọba tó gbọ́n a máa fẹ́ eniyan burúkú dànù,a sì lọ̀ wọ́n mọ́lẹ̀.
Oríṣun àwòrán, ABS Àkọlé àwòrán, Anthony Obiagbaoso Enukeme wọlẹ lọ pẹlu oriyin nla lati ọdọ awọn eeyan ilu rẹ, atawọn oloselu Oríṣun àwòrán, ABS Àkọlé àwòrán, Lara awọn eeyan jankan jankan to peju sibi isinku Anthony Obiagbaoso Enukeme ni gomina ipinlẹ Anambra, Willie Obiano Oríṣun àwòrán, ABS Àkọlé àwòrán, Posi awodamiẹ́nu naa ree, to n wọ ẹsẹ mẹfa lọ, eyi ti yoo gbe Anthony Obiagbaoso Enukeme re ile ayeraye Oríṣun àwòrán, ABS Àkọlé àwòrán, Iroyin kan ni miliọnu mẹrinlelọgbọn naira ni wọn fi ra posi ti wn sin Anthony Obiagbaoso Enukeme si Oríṣun àwòrán, ABS Àkọlé àwòrán, Iyawo ati awọn ọmọ lo n selede tẹyinse fun Anthony Obiagbaoso Enukeme Oríṣun àwòrán, ABS Àkọlé àwòrán, Awọn agba bisọọbu ijọ aguda meji lo lewaju isinku fun Anthony Obiagbaoso Enukeme BBC News, Yorùbá Ìdí tí ẹ fi le è nígbàagbọ́ nínú ìròyìn BBC Ìlànà Lílò Nípa BBC Òfin Àṣírí Cookies Kàn sí.
Nígbà tí ẹ̀ka rẹ̀ bá ṣẹ̀ṣẹ̀ yọ, tí ó bá bẹ̀rẹ̀ sí rúwé, ẹ mọ̀ pé ìgbà ẹ̀ẹ̀rùn súnmọ́ tòsí.
'Kọ́ ọgbà fún ẹran ọ̀sìn rẹ' Iniesta: Mò ṣetán láti fi Barcelona sílẹ̀ ‘Louis Arthur Charles lorúkọ ọmọ-ọmọ ọbabìnrin Gẹ̀ẹ́si’ A kò tíì rì agbẹnusọ àpapọ̀ ẹgbẹ́ òṣèlú All Progressives Congress bá sọ̀rọ̀ di ìsinyìí.
Àkọlé àwòrán, Ìjọba ìpínlẹ̀ Eko ti ni ki gbogbo ọjà wà ni títì pa, sùgbọ́n.
Adajọ to n gbọ ẹjọ naa kede bi idajọ ẹjọ naa yoo ṣe lọ lẹyin ti gbogbo awọn agbẹjọro fun igun gbogbo ti ọrọ kan ti fi ẹnu awijare ati atotonu wọn lori ẹjọ naa jona sibi kan.
Atiku náà kéde àtìlẹ́yìn rẹ̀ fún ẹ̀ṣọ́ alábòò Amọtẹkun Obìnrin tó lówó jùlọ ní Africa 'ja orílẹ̀-èdè rẹ̀, Angola lólè' fi kó ọ̀rọ̀ jọ ni Ariwo kò jẹ́!
Òun náà tilẹ̀ fi ọmọ rẹ̀ rú ẹbọ sísun sí oriṣa gẹ́gẹ́ bí àwọn orílẹ̀-èdè oníwà burúkú tí OLUWA lé kúrò lórí ilẹ̀ náà fún àwọn ọmọ Israẹli.
iso 639-1 : 2002 ,  Àwọn àmìọ ̀ rọ ̀ fún ìṣojú àwọn orúkọ àwọn èdè apá 1 : àmìọ ̀ rọ ̀ alpha-2 "" ni apa kinni iso 639 awon eseese opagun kariaye fun awon amioro ede ."
"Afurasi tó fa ìpayà nílé ìwé Port Harcourt ti wọ gàù Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Àsìkò Amojúẹ̀rọ Seyi ni ló fi wọlé l'Oyo, kìí ṣe àsìkò èmi Omobolanle' Orọ awọn agbofinro ni pe: ""Lọ́wọ́ ti a wà yìí, ìgbẹ́kèlẹ̀ ọlọ́pàá ni abájáde ǹkan ti àwọn oníṣègùn oyinbo bá sọ lẹ́yìn àyẹwò wọ́n, nítori à ti gbé òkú náà lọ si ilé ìwòsàn fún àyẹwò""."
Amọ, nigba to de yara igbalejo rẹ lo bẹrẹ aisan ranpẹ, ti ayewo si fi han pe arun Coronavirus ti n ba finra.
Bọ́ síta láti ṣe ìwọ́de mọ́ ìjọba Nàìjíríà lónìí, ko rugi oyin - Iléeṣẹ́ ọlọ́pàá Ileeṣẹ ọlọpa ipinlẹ Eko ti fi ikilọ sita pe, ki ara ilu kankan maa ṣe kopa ninu iwọde loni tii ṣe ayajọ ominira Naijiria.
" Awọn ẹgbẹ ọmọbibi Yoruba bii Afẹnifẹre ati ẹgbẹ agba Yoruba ni wọn ti pin lori oludije ipo aarẹ ti ilẹ Yoruba yoo tẹle.
Small Doctor ní omi máa ń bọ́ lójú òun lásìkò tí òun bá rántí àkókò ìbẹ̀rẹ̀ òun tí kò rọrùn rárá, àti bí wọn kìí ṣe pe òun sí agbo eré.
bi wn ṣe n ji awọn ara ilu ti ko mọwọ mẹsẹ gbe ni wọn n ji awọn lọba lọba gbe.
fagile iwọle pajawiri  ti won kede rẹ di
 Ju gbogbo rẹ lọ, to ba jẹ pe igbeyawo tootọ ni, tabi ayederu, ọrọ yoo to fi oju han."
Ọmọ Nàìjíríà ní ọjọ́ tirẹ̀ l'Ámẹ́ríkà Tunde Idiagbon, ọ̀gágun kògbagbẹ̀rẹ́ tó ní ẹ̀ẹ̀kan lóṣù ló yẹ kí ológun máa rẹ́rìín Awọn afurasí Babaláwo pa ìyáwó Ìmáàmù àgbà ìlú Ayere ní Kogi, Alayere dá sọ́rọ̀ Wo àṣẹ tuntun tí Buhari gbé síta nípa owó iná ọba Bí ó ṣe lọ lágbo àwọn òṣèré Yollywood lọ́sẹ̀ yìí rèé Iroyin sọ pe ni ilu Los Angeles lo ku si, iyawo ati awọn mọlẹbi rẹ gbogbo lo si wa lẹba rẹ nigba to mi eemi igbẹyin.
Ẹ má jẹ́ kí ìfẹ́ owó gbà yín lọ́kàn.
 Opolopo ise akanse lo n lowo ti o si je pe awon omo orile ede China ni won n see awon ise akanse bi i:eto oju-irin,ina mona-mona,papa ọkọ oju ofurufu ati opolopo oju ona ọkọ   Ile-ise ECOWAS tuntunAare Muhammadu Buhari tun ran orile ede ede China leti nipa kikọ ile-ise  ajo ECOWAS tuntun , aare wa seleri pe awon omo egbe ECOWAS yoo maa se ohun iwuri  lati je ki awon onisowo ile okeere wa da ile-ise sile ni ekun won.
Ẹ̀yin Oníbàárà wa ọ̀wọ́n, ẹ má mikàn, a ti ń dá gbogbo iná yín padà - TCN Ẹ wo ìdí tí Oby Ezekwesili ṣe ń pè fún àyẹ̀wò ọpọlọ fún Ààrẹ Buhari 110 ni ìyè àwọn àgbẹ̀ tí Boko haram dúmbú ní Borno tí dì báyìí-UN Gbajugbaja òṣèré ''Toromagbe'' nínú fíìmù ''Arelu'' ti jáde láyé O ni ohun ti oun ṣi n tẹnumọ ni pe awọn eeyan Ugbo lo ni ifẹ ti wọn si ti tẹdo sibẹ ki Oduduwa atẹwọnrọ to de lati tẹdo sibẹ.
Lọti bá jáde lọ bá àwọn ọkunrin tí wọ́n fẹ́ àwọn ọmọbinrin rẹ̀ mejeeji sọ́nà, ó sọ fún wọn pé, “Ẹ dìde, ẹ jáde kúrò ninu ìlú yìí nítorí OLUWA fẹ́ pa á run.
Alao Akala: Èmi àti Ajimọbi kò ṣe ìlérí kankan fúnra wa
OLUWA ní,“Ẹ wò ó bí ogun ti kó Babiloni,Babiloni tí gbogbo ayé ń pọ́nlé!
Gbájugbàja òṣere Yomi Fabiyi náà ti bọ sita láti pẹtu sí ààwọ̀ àwọn òṣèré tíátà méjèèjì láti fi òpin si ááwọ̀ to wà láàrin wọ́n, pàápàá jùlọ wọn le sàlàyé oun to ń jẹ wọ́n lọkan fún àwọn asaaju ẹgbẹ òṣèré tíátà.
Gbogbo àwọn ọmọ Lefi lọkunrin, láti ọmọ oṣù kan sókè tí Mose kà ní ìdílé-ìdílé, gẹ́gẹ́ bí àṣẹ OLUWA jẹ́ ẹgbaa mọkanla (22,000).
O ṣiṣẹ ontẹwe nile ipọnti Nigerian Breweries ko to darapọ mọ awọn ologun ni Naijiria gẹgẹ bii ontẹwe ranṣẹ si ni.
    Eléyìí jẹ́ ìyàlẹ̀nu fún wọn pée owó ṣílè ní iwin ń pè ní ikú.
ni angẹli OLUWA náà yọ sí i, ó sì wí fún un pé, “OLUWA wà pẹlu rẹ, ìwọ akikanju ati alágbára ọkunrin.
11 Ìgbé 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 12 Ìgbé 2019 Ọlọpaa ilu ọba ti fi panpẹ ọba mu oludasilẹ ẹrọ iroyin Wikileaks, Julian Assange ni ilu London.
 2015 ni ati bere ipolongo fifi opin si igbeyawo awon omode ki won le gbadun igba ewe won.
Ọkan lara awọn ololufẹ Toyin Abraham lo wa ta gba Lizzy pe ki lo de to fi n ba Ronkẹ yọ, to si kọ lati ba Toyin yọ lasiko to bimọ tiẹ.
Peter Njonjo, ti o je aare Coca-Cola nile Afrika lo dari igbimo ajo FIFA lati sagbekale ife-eye ohun fun aare Buhari ati awon miran torokan gbangban lorile-ede Naijiria.
Gauri ni ẹru iku awọn eniyan lo n ba oun nitori ẹni to ba ti ri ogun ri, ko ni gbadura ogun mọ.
Oríṣun àwòrán, @bola are Àkọlé àwòrán, Oriṣirisi orin ni Yoruba maa n gbadun bii juju, apala, orin ẹmi, fuji, ṣakara abbl.
Lẹ́yìn náà, wọn yóo da aṣọ pupa ati awọ dídán bò ó.
O ni awọn kan ti wọn ko sinu odo naa ko pada jade bẹẹ nigba ti wọn sọ okuta sinu odo adagun ọhun, ìlú jinjin si Oyo ni wọn ti lọ ri awọn nkan naa.
Alakoso fun eto kata-kara oro ile okere lorile-ede Japan, Taku Miyazaki  ni o seleri yii nigba ti o n soro lojo-Bo (Thursday), nipinle Eko.
Ọmọ ṣá bàbá rẹ̀ pa, ohun tó sọ pé ó ṣe nìyí.
Ti wọn si parọwa si eniyan to le ni biliọnu kan to n lo ‘Whatsapp’ lati lọ tẹ ‘Update’ ẹrọ ikansiẹni yii ki awọn asebi ma baa ri gbogbo ohun ti wọn n ko pamọ si ori ẹrọ ilewọ wọn.
Lílo nkan ìbomú kò tóò láti dènà pé kóò má á nìí coronavirus Alagba Ojẹdele ṣalaye bi gbogbo ọrọ ti ri lati ọdun 1750 ti wọn ti wa lati Ile Ifẹ to jẹ orisun Yoruba.
Ninu oṣu Kẹjọ bakan naa, awọn mejeeji jọ ya fọto fun ayẹyẹ ọjọ ibi ọdun kan ọmọ wọn ni.
Iko agbaboolu Italy, ti awon eyan tun mo si The Azzurri, nireti wa pe, won yoo koju iko agbaboolu Argentina ni papa isere Manchester lojoEti(Friday), bee si ni won yoo tun lo koju England ni papa isere Wembley lojo kerin-in si ifesewonse akoko.
Agbẹjọ́rò sọ̀rọ̀ lórí ìtumọ̀ nǹkan kò fararọ táwọn gomina kéde lórí ìfipá báni lòpọ̀
Oríṣun àwòrán, Facebook/@OfficialOAU Àkọlé àwòrán, Fasiti OAU: À wádìí olùkọ́ tó fẹ́ bá akẹ́kọ̀ọ́ lò fún máákì Ní báyìí, àwọn aláṣẹ fásitì náà ti gbé ìgbìmọ̀ ẹlẹni-márùn ún kalẹ̀ láti ṣèwaàdí sí ọ̀rọ̀ náà.
Tí ẹ ò bá gbàgbé, lásìkò ti àwọn jàndùkú ja ọ̀rọ̀ ìwọ́de ìfẹ́hónúhàn #EndSars gbà, lọ́jọ́ kẹtàdínlógún, oṣù kẹwàá ti wọ́n si lọ n já ilé ìtajà ńla ni Osogbo.
apapo to wa ni Eko ati ilu Abuja(Murtala Muhammad
Èso àjàrà ti rọ,igi ọ̀pọ̀tọ́ sì ti ń gbẹ.
O ní agogo láraà rẹ Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Gbàgbé nípa agogo GMT, agogo to jà jù fún ara rẹ ni igun ọpọlọ rẹ tí wọ́n pe ní hypothalamus Ó wà ní igun tí hypothalamus nínú ọpọlọ rẹ, gẹ́gẹ́ bíi atọ̀nà, tó ń fi ojú sí bí àlàyé ṣe ń lọ sí gbogbo ara ní àsìkò ọ̀tọ̀tọ̀.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Tramadol: Orísun ikú, àìní-rètí àti Boko Haram 1 Òkùdu 2018 Àkọlé àwòrán, Ìlú Maiduguri ló ń forí sọta làásìgbò Boko Haram fún ọ̀pọ̀lọpọ̀ ọdún - bákan náà ló tún ń ja ìjà abẹ́nú pẹ̀lú àsìlò òògùn Òògùn Codeine nìkan kọ́ ni òògùn táwọn èèyàn sọ di bárakú jákè-jádò ẹkùn ìwọ̀ òòrùn Afrika.
Àti bí ó jẹ́ pé alágùúgbò òun kan ló ṣàánú òun tí òun fi bẹ̀-rẹ̀ sí dá ẹmu, àti bí bí àgbọ̀nrín kan ti ń fọ òun ni akèǹgbè tí òun sì bẹ̀rẹ̀ sí lé e títí àwọn fi dé iwájú ogunlọ́gọ̀ àwọn ẹranko.
lọna ẹgbẹrin le aadorin le mẹta ati miliọnu marun naira (N873.
Oríṣun àwòrán, Ojude Oba Facebook Ọdun Ẹsin ni Ojude Ọba fi bẹrẹ: Awọn ẹtahoro musulumi kan lo bẹrk ọdun Ojude Ọba, ko to di pe o di itẹwọgba nilẹ Ijẹbu.
kódà òun kò se àìsùn kankan lórí ọ̀rọ̀ yìí.
Okeke fẹ̀sùn kàn pé lásìkò ìfẹ̀hónú hàn náà, ọ̀pọ̀ dúkìá ló sòfò, ìdí sì nìyìí tí wọn fi gbọdọ̀ fi àwọn tó wà lẹ́yìn ìwọ́de náà jófin.
Oluranlọwọ agba fun gomina ọhun, Mukhtar Gidado sọ ninu atẹjade kan pe gomina naa ti ṣalapade ọmọ igbakeji aarẹ tẹlẹri, Atiku Abubakar, ti oun naa ni arun ọhun.
Bàba Kérésìmesì, jọ̀wọ́ fún mi ní ìbọsẹ̀ nílá gbàngbà pẹ̀lú òmìnira nínúu rẹ̀.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, EndSars Protest:Ọ̀gá Àgba Ọlọ́pàá ṣàbẹ̀wò sí ìpínlẹ̀ Eko lẹ́yìn ìfẹ̀họ́núhàn EndSars Ẹwẹ, alukoro ileeṣẹ ọlọpaa ipinlẹ Oyo, Olugbenga Fadeyi sọ fun BBC Yoruba pe kii ṣe ohun to bojumu ki awọn ara ilu maa ṣe idajọ lati ọwọ ara wọn.
Apa ina ko pọju lara mama rẹ ati aburo rẹ ọkunrin ti wọn jọ wa nile lasiko iṣẹlẹ naa.
Aare soro ohun di mimo wipe,”ẹnikẹni to ba ro wi pe ohun lee ko awọn
Mo rí i pé gbogbo làálàá tí eniyan ń ṣe ati gbogbo akitiyan rẹ̀ lẹ́nu iṣẹ́ rẹ̀, ó ń ṣe é nítorí pé eniyan ń jowú aládùúgbò rẹ̀ ni.
Ileeṣẹ ọlọpaa lawọn si n ka awọn akẹkọọ lati mọ bo ya awọn janduku agbebọn naa ri awọn akẹkọ ji gbe lọ.
 aké ni olú ìlú wọn .
" Agbowu wa fi idaniloju han pe awọn ẹri to daju wa nilẹ lati fi gbe ẹjọ oun nidi nitori ọpọ awọn ọba to wa nibẹ nigba to n na oun lo setan lati jẹri gbe oun, bẹẹ si ni kọmisana fun ọrọ oye jijẹ nipinlẹ Ọsun ati akẹẹgbẹ rẹ fọrọ ilẹ naa wa nibẹ pẹlu alaga ijọba ibilẹ Iwo.
Coronavirus ti di ara wa, kò le è kúrò mọ láéláé - WHO A kò tíì fi ìdí ẹ̀ múlẹ̀ pé ògùn Dexamethsaone ń ṣiṣẹ́ fún àrùn coronavirus- WHO Yẹ̀kínì kan kò lè yẹ ipinnu wa láti ṣí iléèwé pàda lóṣù yí - ìjọba ìpínlẹ̀ Oyo Ohun tí a rí nílé Ajimobi rèé lẹ́yìn ìròyìn òfégè pé ó jáde láyé 6.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ọ̀dọ́mọkùnrin ẹni ọdun mẹ́rìndínlọ́gbọ̀n ṣá bàbá rẹ̀, ẹni ọdún àádọ́rin pa 28 Owewe 2020 Oríṣun àwòrán, Martenslawfirm.
Kò pẹ́ lẹ́hìn èyí ni ìyàwó náà kó ẹja tútù mẹ́ta wá sí iwájú ọba yìí - ọ̀kan dúdú, ọ̀kan pupa, ọ̀kan funfun.
Àjàkálẹ̀-àrùn ni yóo pa àwọn tí wọ́n wà lókèèrè; idà yóo pa àwọn tí wọ́n wà nítòsí, ìyàn yóo sì pa àwọn yòókù tí ogun ati àjàkálẹ̀-àrùn bá dá sí.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Seun Fakorede: Iṣẹ́ tí Seyi Makinde rán mi nipínlẹ̀ Oyo níkan ní màá jẹ́ 27 Ògún 2019 Oríṣun àwòrán, @seyiamakinde Seun Fakorede ẹni ọdun mẹ́tàdínlọ́gbọ̀n tí gómìnà ìpínlẹ̀ Oyo ṣẹ̀ṣẹ̀ yàn bíi Kọmísọna fún ìròyìn àtí eré ìdáráya ti ní, ẹní ran ni níṣẹ́ làá bẹ̀rù, à kìí bẹ̀rù ẹní tí àà jẹ fún.
Ọ̀rọ̀ náà bí Abineri ninu gidigidi, ó bi Iṣiboṣẹti pé, “Ṣé o rò pé mo jẹ́ hu ìwà ọ̀dàlẹ̀ sí Saulu laelae?
Ìjọba Naijiria faraya nínú lẹ́tà tó kọ sí CNN lórí ìwádìí rẹ̀ nípa ìṣẹ̀lẹ̀ Lekki Toll Gate Omotara pàdánù isẹ́ olówó ńlá nítorí ó fi ọtí ẹlẹ́rìndòdò sódà lá ọmọ alágbe lójú Ilé aṣòfin orílẹ̀-èdè UK n gbèrò fífí ìyà jẹ àwọn adarí Naijiria tó lọ́wọ́ nínú rògbòdìyàn ENDSARS Jemila dáná sún ilé ọ̀rẹ́kùnrin rẹ̀ àti ọ̀rẹ́bìnrin tó bá nílé Adájọ́ ti pàṣẹ pé kí wọ́n mú ọmọ Rasheed Maina, Faisal, tó sá mọ́ ilé ẹjọ́ lọ́wọ́ O le ni igba awọn abẹrẹ ajẹsara miran ti iwadii lori wọn n lọ kaakiri agbaye lati koju arun COVID-19.
'Ohùn Leah mi ni mo gbọ́ nínú fọ́nran Boko Haram' Oríṣun àwòrán, ISAAC LINUS ABRAK Àkọlé àwòrán, Baba Leah Sharibu rọ ìjọba lati gba ọmọ oun Ọmọ kan tó kù ni àhámọ́ Boko Haram nínú àwọn akẹ́kọ̀ Dapchi, Leah Sharibu ti rọ ijọba lati gba kúro ninu àhámọ.
Ninu wọn, Mose mú ọ̀kọ̀ọ̀kan ninu araadọta ninu àwọn eniyan ati ẹranko, ó sì kó wọn fún àwọn ọmọ Lefi tí ń ṣe ìtọ́jú ibi mímọ́ OLUWA, bí OLUWA ti pàṣẹ fún un.
Àwọn eniyan bá dáhùn pé,“Nítorí náà ni ìdájọ́ òtítọ́ fi jìnnà sí wa,tí òdodo kò sì fi dé ọ̀dọ̀ wà.
Ọjọ keje oṣu Karun ni wọn yoo kede awọn to jawe olubori ni papa iṣere King Power l'opin saa yii.
Ẹka idajọ nipinlẹ Wisconsin ti bẹrẹ iwadii lori iṣẹlẹ naa, bakan naa lọgọrọ eeyan ti buwọlu aba lati gbe awọn ọlọpaa ti ọrọ kan sile ẹjọ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ìdílé tí ọkọ da ọmọ síta tóríi ojú Búlùú tí wọ́n ní bá BBC sọ̀rọ̀ Ẹ̀mí aláìsàn là ń gbà là, ẹ yé fojú aṣẹ́wó wò wá - Nọ́ọ̀sì yarí Ganduje àtàwọn èèkàn ìlú míì sàmì ogójì ọjọ́ tí Ajimobi dará ilẹ̀ Àwọn agbófinró ti gbé Naira Marley lọ sílé ẹjọ́ fún ẹ̀sùn tí tàpá sí òfìn ìséde Ìdí rèé tí mo fi ṣẹ̀ṣẹ̀ sọ̀rọ̀ lẹ́yìn tí wọ́n fipá bámi lopọ̀ lọ́mọ ọdún méje lọ́gọ́ta ọdún sẹ́yìn-Eli Gẹgẹ bi o ṣe sọ, àwọn ayipada ti yoo kan wa ni pe wọn yoo bẹrẹ si ni ṣi papakọ ofurufu fun irinajo si ilẹ okeere diẹdiẹ, ni ibamu pẹlu awọn ilana to yẹ.
I Language Centre: Yorùbá ló làṣà àti èdè
Ní ọjọ́ keji, nígbà tí ìjì túbọ̀ le pupọ, a bá da ẹrù inú ọkọ̀ sinu òkun.
Fulani Kkwajafa to wa ni ipo kọmiṣọnna ọlọpaa nigba naa ni wọn yan lati ko ikọ naa jọ.
Ati wi pe, kii se gbogbo aworan ti eniyan ba fi si oju opo ikansiraẹni, ni o jẹ otitọ tabi ki awọn eniyan ma a sọ ohun ti oju wọn ko ri.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Wo bí Sunday Orimola ṣe gba ikú ẹranko kú ní Ifon ni Ondo lórí ọ̀nà àtijẹ Ki lo tun ti ṣẹlẹ sẹyin lori ifipabanilopọ?
 díámọ ́ ndì ní ìgbéwọra oníṣetanná tó kéré gidi , nígbàtí gráfáìt jẹ ́ olùgbéwọra tó dára gidigidi .
Lilo ominira rẹ lati jọsin ko gbọdọ tẹ ẹtọ ẹlomiran loju mọlẹ.
 léyìn èyí , ó lo sí ilé èkó girama àtivilé èkó àwon olùkó ( n.
Kí á lè gba àyànfẹ́ rẹ là,fi ọwọ́ agbára rẹ ṣẹgun fún wa,kí o sì dá wa lóhùn.
ẹ má bá wọn jà, nítorí n kò ní fun yín ní ilẹ̀ wọn, bí ó ti wù kí ó kéré tó.
’’Asofin naa tun ni “Ogbeni Oshiomhole ni gbogbo ohun to yẹ ki o lo lati yanju awọn ipenija to n sẹlẹ ninu egbe APC.
Oba Abd-Ganiyu Adekunle Salaueen Oloogunebi Ajinese 1 ti kéde pẹ orò ló kù láti lé àwọn ajínigbé
Amọ agbẹnusọ fun ẹgbẹ oṣelu rẹ, APRC, ti sẹ lori awọn ẹsun ifipabanilopọ naa.
Wo àwọn gómìnà Naijiria tí àrùn Covid-19 ti bá fínra Nǹkan oṣù obìnrin le jáde ní imú tàbí ìdodo yàtọ̀ sí ojú ara - Dókítà Ọmọ pupa làwọn olólùfẹ́ wa fẹ́ wò nínú fíìmù làwọn òṣèré tíátà fi ń bóra- Muka Ray Wọ́n tún ti pa ọmọbìnrin míì lásìkò ìbálòpọ̀ tipá nílùú Ibadan Wàhálà tí àwọn ẹgbẹ́ òkùnkùn àt'àwọn ẹgbẹ́ ìjayà míràn ń dá sílẹ̀ láwọn ọgbà fásitì Nàìjíríà Irú kí lèyì!
Pa òfin mi mọ́, kí o lè yè,pa ẹ̀kọ́ mi mọ́ gẹ́gẹ́ bí ẹyin ojú rẹ,
Ìwọ ni o ní ọ̀rọ̀ ìyè ainipẹkun.
Òun óo mú kí òjìji oòrùn ìrọ̀lẹ́ pada sẹ́yìn ní àtẹ̀gùn mẹ́wàá lórí àtẹ̀gùn Ahasi.
Nigba to n ba awọn oniroyin sọrọ nilu Eko lọjọ ẹti, kọmisọna eto ilera nipinlẹ Eko, Ọjọgbọn Akin Abayomi tẹnu mọ ọ pe alaye kikun yoo wa lori itọju alaisan nile ki awọn eeyan le mọ ẹni to tọ si gan lati gba itọju nile tabi nibudo iyaraẹnisọtọ.
” Wọ́n sì jọ gun kẹ̀kẹ́ ogun rẹ̀ lọ sí Samaria.
Àwọn alufaa yóo máa fọn fèrè gbogbo eniyan yóo sì dìde dúró.
A rin títí ilẹ̀ ọjọ́ kéjì fi ṣú láàrí ìyọnu kan àfi ti Ìbẹ̀ǹbẹ́ olókùnrùn tí o ń kígbe ebi.
O na Jessica Pegula ninu idije to waye ni Auckland pẹlu ami ayo Mẹfa si mẹta ati mẹfa si mẹrin.
Má fi ìwàǹwára fa ẹnikẹ́ni lọ sílé ẹjọ́,nítorí kí ni o óo ṣe nígbà tí aládùúgbò rẹ bá dójútì ọ́.
Ààlà ilẹ̀ náà bẹ̀rẹ̀ ní Helefi, láti ibi igi oaku tí ó wà ní Saananimu, Adaminekebu, ati Jabineeli, títí dé Lakumu, ó sì pin sí odò Jọdani.
Bàbá mi pe àwọn oníṣègùn ìlú wa jọ ó wá oúnjẹ fún gbogbo wọn, bẹ́ẹ̀ ni egbòogi àtìrandíran sì kún ilẹ̀ wa kítikìti; fún odidi oṣù mẹ́fà ni òun fi ń sá kiri nítorí ọ̀ràn Igbó Olódùmarè yí nítorí ẹni tí ó bá lọ kì í padà bọ̀, wọn a máa ti ọwọ́ ẹbọra dé ọwọ́ ẹbọra.
Amọ gbogbo igbiyanju awọn agbofinro lati yanju ọrọ yii ni pẹlẹ putu lo ja si pabo.
idagbasokeO tun so pe ijọba ibilẹ merin tuntun naa , yoo tun je ki idagbasoke ba igberiko to wa niluu Abuja.
Nígbà tí mo gbọ́, tí mo sì rí wọn, mo dojúbolẹ̀ níwájú angẹli tí ó fi wọ́n hàn mí.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Waste to Wealth: Ẹ̀gbin tìrẹ ni èròjà táwọn èèyàn míràn fi n ṣiṣẹ́ ajé, okoòwò ńlá ni Ṣaaju ni ijọba ipinlẹ Eko ti kọ sọ pe o ṣoro lati wa awọn eeyan ọhun ri, nitori pe ọpọ ninu wọn ni ko fi ojulowo adirẹsi ile wọn silẹ.
igbimo asofin agba,Ahmed Lawan tun yan igbimo ẹlẹnu méjìlá  lati jiroro lori
Oga-agba ti o n samojuto awon ile-ise iroyin, Modibbo Kawu so pe, ayipada lilo ero igbalode tuntun naa yoo mu igberu ba eto ori ero amohun-maworan, aworan to mo gaara, yoo tun pese ise lopo yanturu ni eka ile-ise naa.
Tí ó bá nà kalẹ̀, tí ó sì lúgọ,kò sí ẹni tí ó jẹ́ tọ́ ọ.
Ẹni kọọkan wọn si san ẹgbẹrun kan Naira lati fi orukọ silẹ.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ronke Oshodi Oke ṣe àwo orin jáde fún MC Oluomo fún ọjọ́ ìbí rẹ̀ N kò kọ̀ kí ń kú, ìfẹ́ tí mo ní sí Buhari ni mo ṣe sáré dì mọ"" Láì lo Kakulétọ̀, mo ní ọpọlọ ìṣirò, tábìlì ìṣirò wà lórí mi - Human Calculator Eré apanilẹ́rìn ké kè ké lórí ayélujára ti ṣí ọ̀pọ̀ ìlẹ̀kùn fún mi - Mr Macaroni Chatta bímọ tuntun, Mide àti Osupa lẹ̀pọ̀, Sanwo-Olu fún Sola Sobowale lámì ẹ̀yẹ Osinbajo wọ́gilé ìrìn-àjò rẹ̀ lẹ́yìn tí ọ̀kan lára ẹ̀ṣọ́ rẹ̀ kú nínú ìjàmbá ọkọ̀ Alaafin wa n rọ̀ Fayemi lati mase gbe igbesẹ to lee tabuku awọn awọn ọ̀ba alaye nilẹ Yoruba nitori a ni asa to n bu ọwọ ati apọnle fun awọn oriade wa, ju awọn ẹya miran nilẹ Naijria lọ."
Ṣé ó le má ṣàánú ọmọ bíbí inú rẹ̀?
Àkọlé àwòrán, Ìtàn Manigbagbe: Àwọn àjakalẹ-àrun to ti wáyé rí ṣáájú Coronavirus Ó kéré tán, ẹgbẹ̀rún méjì èèyàn ló ń jẹ́ Ọlọ́run nipe lójúmọ́ nítorí àrùn Sanponna ọ̀hún, tó sì ń tàn kalẹ kiri bíi owara ojo.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Tani olóṣèlú tó ṣewọn ọjọ mẹta torí pé o ní orí ààrẹ dàrú 26 Ẹrẹ̀nà 2019 Oríṣun àwòrán, AFP/GETTY IMAGES Àkọlé àwòrán, Awọn ọlọpaa ati awọn ẹgbẹ alatako ko ṣeṣẹ maa ba ara wọn wọ iya ija lorileede Zambia Ọmọ ẹgbẹ alatako kan lorileede Zambia ti sun orun ọjọ mẹta lagọ ọlọpaa tori pe o ni ori aarẹ orileede,Edgar Lungu, ko pe.
Ajeyẹmi ohun toju awọn obinrin n ri nigba ibimọ ti to kawọn ọkọ wọn maa dariji wọn nigba ti wọn ba ṣẹ wọn.
Nítorí náà ègún ń pa ayé run lọ.
Àwọn ìròyìn mìíràn tí ẹ lè nífẹ̀ẹ́ sí: Aare Kenya ati Adari alatako di ore Ọlopaa Kenya kolu awọn oluwọde 'Aarẹ Zuma gbọdọ lọ' Ijọba ti ileesẹ amohunmaworan mẹta ni Kenya Ọmọ oloogbe naa David Chelugui fi ẹsun kan aarẹ ana naa wipe o gba ilẹ idile wọn lẹyin ti baba oun ku.
Ọkọ Risikat ní ojú búlúù tí ìyàwó òun ní gan an lòun ṣe fẹ́ ẹ Ọwọ́ ikọ̀ aláàbò STF tẹ afurasí mẹ́jọ tó lọ́wọ́ nínú ìpànìyàn lemọ́-lemọ́ọ Gúúsù Kaduna Diezani gan an ní Hushmummy tó ń bú àwọn Yahoo boys- Àwọn Ọmọ Naijiria lórí Twitter Olùrànlọ́wọ́ pàtàkì fún ọ̀rọ̀ ibojì òkú, àti àwọn ipò òṣèlú mìíràn tó jẹ́ kàyééfì ní Nàìjíríà Asojú ìjọba orílẹ̀-èdè Lebanon ti kọ̀wé fipò silẹ̀ nítorí ìbágbàmù tó gbẹ̀mi ènìyàn 200 Amotekun: Ẹ lọ gba fọ́ọ̀mù ìgbanisíṣẹ́ ikọ̀ Amotekun - Ìjọba ìpínlẹ̀ Ondo Ijọba ipinlẹ Ondo ti sọ pe awọn eeyan to ba nifẹ lati darapọ mọ ikọ aalabo Amotekun ipinlẹ naa le lọ gba fọọmu.
Oríṣun àwòrán, OTHERS Wọn ni ohun to fa iṣẹlẹ naa ni wi pe ọkọ oju omi gbe ju iye eniyan to yẹ lọ, ti iji si bẹ silẹ laarin omi naa.
Kii ṣe tori asiko ajakalẹ arun yii nikan ṣugbọn tori mo ti yan lati gbe iyoku aye mi pẹlu Reme.
Bi a ba ni ka maa p'ori akọni laarin awọn akọroyin orile-ede Naijiria, ko si igba ti ida Dele Giwa ko ni lalẹ gaaraga.
Ọmọọbabinrin Alaafin, Olubunmi Labiyi bá BBC Yoruba sọ̀rọ̀ nínú fọ́nrán tó wà l'ókè.
Mo fẹ́ kí o lọ pe iwin kan kí ó wá fi ojú kàn mi, mo ti ń gbúròó iwin náà ti pẹ, kò ga ju ẹsẹ̀ bàtà méjì lọ, irungbọ̀n rẹ̀ gùn tó ọgbọ̀n ẹsẹ̀, o sì gbe irin kan lé èjìká tí ó wúwo tó àpò èkùrọ́ mẹ́jọ tí ó kún dé ẹnu.
Ati pe kò sí nkan ti kò ṣeeṣe ti o ba ti ni àfokansi ati ipinnu rere.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Cultism in Nigeria: Afurasí sọ fúnlé ẹjọ pé ẹgbẹ́ búburú tóun kó ló ṣàkóbá fún òun 3 Òkùdu 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 29 Agẹmo 2020 Àkọlé àwòrán, Awọn ẹgbẹ okunkun fasiti Naijiria: Buccaneers,Black Axe ati awọn ẹgbẹ ijaiya mìíràn Ile ẹjọ ti ni kí ọkùnrin, ẹni ọgbọn ọdun, Nwali Kingsley, ma a gbatẹ́gùn ni ọgbà ẹ̀wọ̀n, fun pe o lu ọkunrin kan, Victor Nwafor pa, lasiko to n seto igbaniwọle sinu ẹgbẹ okunkun fun.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Coronavirus: Àjọ NYSC ké ètò ìfinimọ̀ fáwọn àgùnbánirọ̀ kúrú nítorí Coronavirus 18 Ẹrẹ̀nà 2020 Wọn ni ki oju maa ribi, ẹsẹ loogun rẹ.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Àwa ò ri lẹ́ta kankan gbà láti ọ̀dọ̀ Malami lóri ọ̀rọ̀ àwọn alága Kansu - Makinde Àwọn nkan tó yẹ kí o mọ̀ nípa ìgbẹ́jọ Trump tí yóò blrẹ̀ l'ọ́dọ̀ àwọn Sẹ́nétọ̀ Mí ò le nífẹ̀ẹ́ obìnrin Nàìjíríà kankan mọ lẹ́yìn ti mo ti tọ́ obìnrin òyìnbó wò- Issa Mo kàn fẹ́ fi ọmọ tó sọnù gba owó lọ́wọ́ Sọtitobire ni - Afurasí Ẹ̀yin ẹ máà wò ó, ó ṣeéṣe kí APC túká lẹ́yìn ìṣèjọ́ba Buhari!
Àdídùn tí ń bẹ nínú oyin dára púpọ̀, ó sì kún nkan tí ara ẹni ń fẹ́.
Nígbàtí mo dé ẹ̀bá igbó kan, mo ṣàdédé rí nkan tó jọ agbárí ìkookò tí ẹnìkan gbé kọ́ igi.
ko labawon eleyi ti e fi timi leyin di akoko yii.
O ti figba kan ko sinu odo yii kan naa ni nkan bii ogun ọdun sẹyin.
Nítorí pé o ti ṣe àwọn nǹkan ìyanu,o ti ṣe àwọn ètò láti ìgbà àtijọ́,o mú wọn ṣẹ pẹlu òtítọ́.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Hakeem: Mo lè sọ arúgbó dí ọmọge nígbà tó bá wù mí Ọkan lara awọn to ri Mandrake nigba to bẹ sinu odo naa, Jayanta Shaw to jẹ ayaworan sọrọ lori iṣẹlẹ ọhun.
Aare orile ede  Muhammadu Buhari  ti ni bi awon omo  orile ede Naijiria se n pọ si, ti eto
Awọn orilẹede Afirika buwọlu adehun AfCFTA Oríṣun àwòrán, AFP/Getty Images Àkọlé àwòrán, Naijiria ati awọn orilẹede mẹsan miran wa ninu awọn ti ko tii tọwọ bọ iwe adehun AfCFTA Amọsa, awọn ogoji orilẹede ilẹ Afirika tọwọ bọ iwe adehun eto karakata ọfẹ ni ilẹ Afirika, (AfCFTA) eleyi to seese ko se atọna fun idasilẹ agbegbe karakata to tobi julọ lagbaye.
Ewen gba pe eka irinajo afe ninu ajo isokan agbaye yoo di alafo to wa ni Naijiria bayii pelu sise idanilekoo losu kefa odun 2018 nigba ti Naijira ba n gbalejo UNWTO tile Adulawo.
Ni bayii, gege bi oro lati enu osise ajo naa niluu Abuja, o ni, won yoo fenuko lai pe lori oro ohun, nitori pe ijoba ipinle Delta ti gba lati gbe iko àádọ́rin ninu ogorun un iye ti papa isere naa yoo na
Lori ẹsun wi pe Agboola fẹ fi ẹgbẹ oṣelu APC silẹ lọ PDP, Akeredolu ni igbakeji oun le lọ si ibi kibi to ba wun u.
Wọn si fikun un wi pe ọlọpaa miran to ṣe nkan to buru ju bẹẹ lọ, ki wọn kọ iwe lọ rọkun nile fun un.
Ọ̀dọ́mọkùnrin náà, tó lo ọdún mẹ́jọ nínú ẹgbẹ́ Boko Haram sọ pé, inú òun kọ́kọ́ dùn pe ẹ̀sìn Islam ni òun ń ṣiṣẹ́ fún.
jàmbá ọkọ̀ ṣẹlẹ̀ s'áwọn tó ń lọ dìbò ní ìpínlẹ̀ Kwara Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ìbádọ́gba nínú ìsèlú àti iṣẹ́ láwùjọ ṣe pàtàkì fún ìdàgbàsóké Ọdun mẹta sẹyin ni iroyin gbe e wi pe ọkunrin ẹni ọdun mọkanlelaadọta kan ti lu iyawo rẹ pa ni ile wọn ni agbeegbe ẹgbẹda-idinmu ni ipinlẹ Eko.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Oyenusi ló mú mi wọ ẹgbẹ́ adigunjalè kó tó di pé mo b'Ólúwa pàdé' Awọn MAN ni ohun to yẹ ki ijọba o ṣe ni lati rii pe ina ọba duro deede lati mu ki awọn eeyan o dẹkun rirọgbọku le epo.
Iroyin ni imaamu naa jẹ Ọlọrun nipe laarọ ọjọ Iṣẹgun ni ile rẹ to wa ni ilu Abeokuta lẹni ọdun mejidinlọgọrun un.
“Ẹ kò gbọdọ̀ ba ọmọbinrin yín jẹ́, nípa fífi ṣe aṣẹ́wó; kí ilẹ̀ náà má baà di ilẹ̀ àgbèrè, kí ó sì kún fún ìwà burúkú.
Ó bá gba ẹ̀yìn wá, ó fi ọwọ́ kan ìṣẹ́tí ẹ̀wù Jesu, lẹsẹkẹsẹ ìsun ẹ̀jẹ̀ náà bá dá lára rẹ̀.
28 Àti lẹ́ẹ̀kansíi, èmi pàṣẹ fún ọ pé kí ìwọ ó máa gbàdúrà ní gbígbé ohùn sókè àti bẹ́ẹ̀ gẹ́gẹ́ nínú ọkàn rẹ; bẹ́ẹ̀ni, níwájú àwọn ènìyàn àti ní ìkọkọ̀, ní gbangba àti nínú ìyẹ́wù.
Gomina Oyo tẹlẹ ni oun rawọ ẹbẹ si awọn mii pe ki wọn j'eburẹ ki wọn to gba lati pada sinu ẹgbẹ.
Gege bi Garba se so, “Iko Falconets gbaradi gidigidi fun idije FIFA Women U-20 World Cup yii.
RRS: Ọwọ́ tẹ olè tó gbé òrùka ìgbéyàwó obìnrin kan mì ní Eko
Meji ninu awọn eeyan ọhun wa ni Abuja, mẹrin ni ipinlẹ Oyo, ẹnikan lati Kaduna ati ẹnikan mii lati ipinlẹ Osun.
" Kí ló mú àwọn adarí Nàìjíríà tako ra wọn lórí ikú ọmọ alága ẹgbẹ́ Afenifere?
 olórí ológun ní ó jé .
Orin ẹyẹ Spiny babbler (Turdoides nipalensis), ẹyẹ tí a kò le è rí níbòmìrán àyàfi ní Nepal tí a ti mọ̀ lọ́jọ́ tí ó pẹ́
mo lo si odo oludari ile-ise ifowopamo lorile ede Niajiria (CBN),lati beere pe ,se a ni owo nibi ipamo wa, o so pe ko si ,ona oju popo wa, lo ti baje , ti ko ni atunse lati ojo ti a ti lo owo ori epo robi.
29 Ìgbé 2019 Oríṣun àwòrán, Wikipedia Àkọlé àwòrán, Ìwé kíkà Yorùbá ni Ìrèké Oníbùdó tó sọ ìtàn akínkanjú arákùnrin Ìrèké tó kúrò nípò ẹ̀gbin láti di ọ̀ba.
Awọn aṣatipo naa ni a gbọ pe wọn wa lati orilẹede Senegal, Mali, Chad ati Ghana.
OLUWA fọhùn,ogunlọ́gọ̀ sì ni àwọn tí ó kéde ọ̀rọ̀ rẹ̀.
To ba ni baba bi, to ba ni, mu baba rẹ jade.
US Embassy: Ìdùnnù wa kọ́ ni kí á má fún ọmọ Nàìjíríà ní 'Visa
Ganduje tun sọ pe awọn Fulani ti wọn jẹjẹ ọmọbibi ipinlẹ Kano ko jade kuro ni ipinlẹ naa lọ si awọn ilu miiran nitoripe Kano ni ni ilẹ ti wọn fi n ṣe ounjẹ ati awọn ọpa ounjẹ ẹranko.
Kíkọ́ ati Yíya Àgọ́ Ìpàdé OLUWA sí Mímọ́.
Tí a bá sì fẹ́ mú àdínkù bá àsà lílu èèyàn ní jìbìtì, àwọn olórin gbọdọ̀ kó ara wọn ní ìjánu nípa orin tí wọn ń kọ lórí ìwà lílu jìbìtì.
Ó fi eré sí mi lẹ́sẹ̀ bíi ti àgbọ̀nrín,ó sì fún mi ní ààbò ní ibi ìsásí.
 O ni ise rere ti aare ti se ni yoo je ki o ri opolopo ibo lọdun 2019.
Ẹ̀wẹ̀, MURIC ti ké gbàjàré pé òun kò mọ ǹkan kan nípa rẹ̀.
Láì ka àwọn tí àwọn ará Bẹnjamini náà kó jọ, àwọn ọmọ Israẹli kó ogún ọ̀kẹ́ (400,000) jagunjagun tí wọn ń lo idà jọ.
Lati ọpọ agbegbe nilu Eko si lawọn akanda ẹda naa, ti ọps wọn jẹ ẹya Hausa, ti wa se ifẹhonu han, koda, wọn tun lẹ awọn akọle wọn si ara kẹkẹ Maruwa ti wọn gbe wa se ẹhonu ọhun.
O fi akoko ikini rẹ́ ki awọn ololufẹ rẹ kuu ọdun Keresimesi o si ni ki wọn ma binu si oun pe kii ṣe ẹbi oun lati ma jade sọrọ si wọn latọjọ yii ṣugbọn ara n fẹ isinmi.
Ṣiṣe amulo awọn anfani ninu ẹka irinajo-afẹ yoo mu igberu ba ọrọ-aje Ipinlẹ EkoAgbẹnusọ Ile Igbimọ Aṣofin Ipinlẹ Eko, Aṣofin Mudashiru Ọbasa sọrọ yii nibi  ipade itangbangba awọn alẹnulọrọ lori abadofin ṣiṣe agbekalẹ Ajọ ti o n ṣe igbelarugẹ Irinajo-afẹ ati awọn ọrọ ti o nii ṣe pẹlu  rẹ”, eleyii ti Igbimọ Tẹẹkoto fun Aṣa, Iṣe ati Aṣa ni Ile Igbimọ Aṣofin Ipinlẹ Eko ṣe agbatẹru rẹ.
Nígbà tí àwọn èrò rí ọ̀gágun ati àwọn ọmọ-ogun, wọ́n dáwọ́ dúró, wọn kò lu Paulu mọ́.
Gege bi ebi Bush lapapo, won ni oloogbe naa jade laye ni omo odun méjìléláàdọ́rùn ún.
Bẹ́ẹ̀ ni Abrahamu ṣe gba ìlérí náà pẹlu sùúrù.
Bákan náà, mo rí i pé, láyé, ẹni tí ó yára, tí ó lè sáré, lè má borí ninu eré ìje, alágbára lè jagun kó má ṣẹgun, ọlọ́gbọ́n lè má rí oúnjẹ jẹ, eniyan lè gbọ́n kó lóye, ṣugbọn kí ó má lówó lọ́wọ́, ẹni tí ó mọ iṣẹ́ ṣe sì lè má ní ìgbéga, àjálù ati èèṣì lè ṣẹlẹ̀ sí ẹnikẹ́ni.
Minisita fun oro sayensi ati imo ero lorile ede Naijiria ,
ọkọ̀ ojú omi tuntun bẹ̀rẹ̀ iṣẹ́ Ìgbẹ̀yìn ọkùnrin tó pa obìnrin 93 ni America Lati igba ti NLC ati TUC ti ni wọn maa gunle iyanṣẹlodi lọjọ kẹrindinlogun, oṣu kẹwaa ọdun yii ni ijọba ti n ṣe ipade pẹlu wọn.
A ní dandan àfi ká ṣe tí inú wa.
Bakan naa ni awọn to ji ohun ini ijọba gbe ati awọn ohun amayedẹrun fun ajakalẹ aarun Coronavirus naa ti bẹrẹ si ni da pada, lẹyin ti ijọba halẹ mọ wọn.
Buhari: Ẹ̀yin Mínísítà, ẹ lọ gbe ìjọba mi níjà lọ́dọ̀ aráàlú pẹ̀lú àfihàn àṣeyọrí mi Oríṣun àwòrán, Others Aarẹ Muhammadu Buhari ti sisọ loju rẹ pe oun ni ori n ta julọ nidi wahala igba gbogbo to n waye laarin awọn agbẹ ati darandaran.
ti ṣalaye ni kikun lori awọn nkan to yẹ ki eeyan maa ṣọra fun ki wọn ma baa ṣẹ si ofin oju popo.
Ìdílé Lefi yóo ṣọ̀fọ̀ tiwọn lọ́tọ̀, bẹ́ẹ̀ sì ni àwọn iyawo wọn, àwọn náà óo ṣọ̀fọ̀ tiwọn lọ́tọ̀.
Oríṣun àwòrán, Queenola2 Ni ẹnu lọwọlọwọ yii ni iroyin kan jade si igboro aye pe nnkan n ṣẹlẹ laafin iku baba yeye, Alaafin ti ilu Ọyọ, Ọba Lamidi Adeyẹmi III lode Ọyọ.
Oju ti ọpọ eeyan fi n wo Buhari nigba naa ko dara rara, eyi to ṣeeṣe ko ṣe idiwọ fun jijawe olubori rẹ"" Kọmísọ́nà ètò ìlera ìpińlẹ̀ Eko ọjọ̀gbọ́n Akin Abayomi ti lùgbàdì ààrùn Covid-19 Àwa la mọ báa ṣe mú Sunday Shodipe táa fà a lé ọlọ́pàá lọ́wọ́ - Ọlọ́dẹ Soludero Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Ìgbà tí mo máa fi lajú sáyé padà, ọ̀fọ̀ ikú mi ní wọ́n ń kígbe' ""Nitori naa, ti a ko ba fẹ pe ibinu Ọlọrun si ori wa, eyi ti a ko fẹ, a gbọdọ fi aaye gba ẹnikẹni to ba fẹ dije, to fi mọ Tinubu."
O ni ọgọta dọla fun agba epo rọbi kan ni wọn gbe eto isuna ọdun 2020 le lori amọ lọwọ lọwọ bayii, owo agba epo kan ti ja wa silẹ di ọgbọn dọla, to si tun seese ko ja wa silẹ ju bẹẹ lọ.
Ìgbẹ̀yìn ẹni náà á wá burú ju ti àkọ́kọ́ lọ.
Wọ́n kórìíra ẹni tí ń bá ni wí lẹ́nu ibodè, wọ́n sì kórìíra ẹni tí ń sọ òtítọ́.
Ni tiwọn, ami mẹta pere lo n dabu Arsenal ninu ilepa wọn lati ri aaye fun idije Europa ni saa to n bọ, gbogbo ipa ni wọn yoo fẹ sa lati lee kopa ninu awọn idije ilẹ Yuroopu ni saa to n bọ.
Deng ti wà ní Àtìmọ́lé Agbègbè Nanxi nítorí wípé “ó ń bá ìjà bọ̀” – ẹ̀sùn tí wọ́n sábà máa ń kà mọ́ àwọn ènìyàn tí ó ń takò ìjọba lẹ́sẹ̀.
 Àwọn ará Ọ ̀ yọ ́ wà ní Ọ ̀ ra , àwọn árá ilé-ifẹ ̀ sì wà ní Ọ ̀ ra pẹ ̀ lú .
Fún ọba ní ìṣẹ́gun, OLUWA;kí o sì dá wa lóhùn nígbà tí a bá ń ké pè ọ́.
Nígbà tí a padà ti ilé Ikú dé tí a tún jẹun lẹ́ẹ̀kejì, Baba-onírùngbọ̀n mú mi gun òkè peẹ̀tẹ́eẹ̀sì rẹ̀ lọ, nígbà tí a sì dé ọ̀hún tàn tí ó jókòó tí èmi náà jókòó  tí a kọjú sí ara wa tán ó wí fún mi pé nǹkan pàtàkì tí a ó ṣe lọ́jọ́ náà kò ju ọ̀rọ̀ tí òun óò bá mi sọ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Nigeria road accident record in 2020: Èèyàn 1,076ni ìjàmbá mọ́tò ti sọ di olóògbé láti oṣù mẹ́ta sẹ́yìn ní Nàìjíríà- FRSC 11 Bélú 2020 Oríṣun àwòrán, FRSC Ajọ ẹṣọ oju popo ni Naijiria, The Federal Road Safety Corps, FRSC ti kede pe ijamba ọkọ 2,656 lo ti ṣẹlẹ loju popo Naijiria ni eyi to si ti fa iku awọn eeyan 1,076 laarin oṣu kẹta sẹyin.
Lọjọ Abamẹta ni igbakeji aarẹ, ọjọgbọn Yẹmi Ọṣinbajo kan si Alaafin Ọyọ, Ọba Lamidi Olayiwọla Adeyẹmi.
Ize-Iyamu borí ìbò abẹ́nú fún idíje gómìnà l'Edo Mọ̀ síi nípa Oyedele Adedokun tó ya àwòràn Donald Trump tó lu ayélujára pa Àwọn agbénipa tún ti pa ọmọ ọdún márùn ún kan ní Ibadan Gbọ́yì-sọ̀yí àti ìròyìn èké láti ọ̀dọ̀ àwọn olólùfẹ́ wa ló ṣáábà ma ń da ìgbéyàwó àwọn òṣèré rú- Ọpẹ Ayeola Súgbọ̀n àwọn onímọ̀ ti bẹ̀nu àtẹ́ lú nǹkan ti Trump sọ yìí, wọ́n ní ó kàn n lọ́ ọ̀rọ̀ àrùn Coronavirus lọ́rùn láti gbé èrò rẹ̀ jáde lórí òfín láti dènà àwọn arìnrìn àjò tó ń wá sí ilẹ̀ Amẹrika ní.
Bakan naa lo ti ṣiṣẹ olukọ imọ iṣiro fun igba diẹ ni ilẹkọṣẹ gbogbonṣe YABATECH ki o to darapọ mọ iṣẹ ọlọpaa.
Oríṣun àwòrán, @kwas Àkọlé àwòrán, Igba finfin wa lara iṣẹ ajogunba awọn ọmọ Oodua.
 Àdìmúlà bàbá tó ju bàbá lọ tún fi ààlà sáààrin ilẹ ̀ , omi òkun , àti sánmọ ̀ .
Àwọn wọnyi ni àwọn tí wọn ń kùn ṣá, nǹkan kì í fi ìgbà kan tẹ́ wọn lọ́rùn.
Vincent Enyeama: Aṣọ́lé Nàìjíríà tẹ́lẹ̀ rí ṣe tán láti padà sórí pápá
Ẹsun mọkanla ni wọn fi kan an eyi to da lori gbigbimọ pọ lati huwa ibi, ninu ayederu kaadi igbawo lọwọ pẹlu iwa jibiti.
Rírun ni kí ẹ run gbogbo wọn patapata, gbogbo àwọn ará Hiti, ati àwọn ará Amori, ati àwọn ará Kenaani, ati àwọn ará Perisi, ati àwọn ará Hifi, ati àwọn ará Jebusi; gẹ́gẹ́ bí OLUWA Ọlọrun yín ti pa á láṣẹ.
Ó fẹ́ràn mi tóbẹ́ẹ̀ tí ó fi ẹ̀mí rẹ̀ lélẹ̀ nítorí mi.
" Oríṣun àwòrán, @AmnestyNigeria Akọwe Afenifere naa ni ohun to yẹ ki ijọba ṣe ni ko wa ọna lati yanju iṣoro to wa nilẹ dipo ko maa yinbọn pa awọn eeyan ilu.
Kábíyèsì fẹnu ara rẹ̀ tú àṣírí àwọn Fulani Daran daran tó ń ṣọṣẹ́ nílùú rẹ̀ Èèmọ̀ rèé!
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Ọwọ́ tó bá dilẹ̀ ni èṣù ń bl ní iṣẹ́kíṣẹ́' 'Orin tàkasúfèé ló wù mí kí n máa kọ ṣùgbọ́n Hijab kò jẹ́' Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Aarẹ Buhari ti sunmọ ọgọrin ọdun o si le wa ni bebe aisan to ba n ran."
Ọmọọba Dapọ Ọjọra: Oríṣun àwòrán, Twitter/bukaola saraki Ni alẹ ọjọ Ẹti, ọjọ Kọkanla osu Kejila ọdun 20202 ni iroyin jade sigboro pe, ilumọọka ọmọ jayejaye ilu Eko nni, Dapọ Ọjọra ti jade laye.
Oríṣun àwòrán, Maikaba facebook O kawe ni fasiti ilu ibadan naa ki o to dori kọ iṣẹ iṣẹ olukọ imọ iroyin ni fasiti Bayero.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Tá ló pá olùrànlọwọ Segun Oni ?
Nibo ni ó ti wá gan:Kòkòrò aifojuri Corona jáde láti ìlú Wuhan, ní China ni opin ọdún 2019 nigbati onírúurú rẹ ń jeyo laarin awọn ènìyàn nínú ọjà kan tí wón ti ń tà nkan ọ̀sìnAarun tí wọn koko npe orúkọ rẹ ni Sars-Cov-2 fara pé kòkòrò aifojuri tí wọn rí lára àdán, èwe, wọn ní gbagbọ pé kòkòrò náà tí ara àdán bo si ara ẹranko miran ti o fi wá dé ara ènìyàn.
Bí ẹnìkan bá ní ẹ̀bùn ìsọtẹ́lẹ̀, kí ó lò ó gẹ́gẹ́ bí igbagbọ rẹ̀ ti mọ.
Ile iṣẹ agbaṣe ilẹ China, China Civil and Construction Company (CCECC) ni yoo kọ fasiti yi.
7 103127 North Macedonia 2682 128.
Bakan naa lo fikun pe awọn oṣiṣẹ naa ti gba owo ajemonu ìsinmi lẹ́nu isẹ, ti oun ko si ni jẹ oṣiṣẹ ni owo osu rara, bi wọn ba dibo fun oun sipo gomina ni eekeji.
O ni iyatọ yo de ba awọn oṣiṣẹ ni ipinlẹ naa lasiko ti oun bura wọle fun awọn kọmiṣọnna tuntun ti wọn ṣẹṣẹ yan ni ipinlẹ naa.
Kíni Prince Harry, Meghan aya rẹ́ àti ọmọ wá ṣé ní Áfríkà?
Bẹẹ lo se ni laanu pe, aaye ẹgbẹrun meji pere lo wa nilẹ ninu ikọ alaabo naa, ti wọn fẹ gba osisẹ si.
WHO - BBC News Yorùbá BBC News, YorùbáFò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Yellow Fever in Nigeria: Àrún ibà pónjú ti pa ènìyàn 172 ni Nàìjíríà - WHO 5 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Oríṣun àwòrán, WHO Ààrùn ibà pónjú tó bẹ́ sílẹ̀ lórílẹ̀-èdè Nàìjíríà láìpẹ́ yìí tí mú ẹ̀mí ènìyàn méjìléláàdọ́jọ lọ báyìí.
Ni igba miiran, wọn a ni irọ ni wọn pa mọ awọn.
Awọn aladugbo tun dari rẹ lọ si ileewosan nla ti LAUTECH, ṣugbọn Jide jade laye ki wọn to gbe e de'bẹ.
Awọn meji to kọwọrin pẹlu rẹ wu iwa buruku yi naa ri ẹwọn he.
Iroyin naa ni ẹgbẹ okunkun Eiye ati Aiye ni wọn n doju ija kọ ara wọn, eyi to mu ki ohun gbogbo poluku musu lawọn agbegbe kan nilu naa.
Inec kéde pé kí ìpolongo ìbò 2019 gbérasọ Mimiko jáwọ́ nínú ìdíje fún ipò ààrẹ Davido gba aago, góólù ọrùn olówó iyebiye bíi ẹ̀bùn ọjọ́ ìbí 'Àṣírí ọkọ mi tú sími lọ́wọ́, ṣé mo le dáríjì í?
"Adajọ paṣẹ $25,000 fun oloyun ti wọn fiya jẹ Ọkùnrin kan gbé ‘búrọ́ọ̀ṣì ìfọyín’ mì ""Ọlọ́pàá ní kí n bọra sílẹ láti mọ bóyá obìnrin ní mí torí mo ní irùngbọ̀n"" Wo àwọn ìbejì tó mú ẹ̀dọ̀ àti egungun àyà kan ṣoṣo wá látọ̀run Uhuru ni ''Ileeṣẹ ilera gbọdọ ṣe afihan ọna igbowojade ti ko lẹja n bakan ninu jade laarin ọgbọn ọjọ eyi ti gbogbo eeyan yoo ri loju opo ayelujara'' Awọn alaṣẹ ti wọn fi ẹsun yi kan sọ pe awọn ko mọwọ mẹsẹ."
N óo fẹsẹ̀ àwọn eniyan mi múlẹ̀lórí ilẹ̀ tí mo fún wọn,a kò sì ní ṣí wọn nípò pada mọ́lórí ilẹ̀ tí mo fún wọn.
Buhari, ayẹyẹ kí là ń ṣe gan, ṣé ti ìpànìyàn àbí ìjínigbé?
A ti dá ọ lẹ́bi nítorí àwọn eniyan tí o pa, o sì ti di aláìmọ́ nítorí àwọn ère tí o gbẹ́.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: ‘Ajìjà-gbara fun ijọba tiwantiwa ni Gani’ MKO Abiọla gba oyè GCFR tó ga jùlọ ní Nàìjíríà Ìwádìí nípa eré bọ́ọ̀lù Ghana di ọ̀rọ̀ ọlọ́pàá Ọjọgbọn Yẹmi Ọsinbajo lo bawọn peju si ibi ayẹyẹ ikẹkọjade fawọn lọga-lọga osisẹ asọbode.
Wo aworan Afrika l'ọsẹ yii Mo ni ọwọ nla fun Afrika-Trump Buhari gbe igbimọ kalẹ lori okoowo Afrika Buhari jawọ ninu ilana okoowo Afrika Ni oru Ọjọru, ọjọ Kọkandinlọgbọn, osu Karun un, ọdun 2019 mọjumọ ọjọ keji rẹ, tii se Ọjọbọ, ni agbekalẹ ibudo okoowo ọfẹ fun ilẹ Afirika, ti ko ni owo ori ninu gberasọ, eyi to jẹ eto okoowo to tii tobi julọ lati igba ti wọn ti bẹrẹ ajọ eleto okoowo lagbaye (World Trade Organisation).
Ninu ẹjọ naa, ti nọmba rẹ jẹ 1/421/2020, ti agbẹjọro fun Oniyide gbe lọ sile ẹjọ ni ọjọ kẹrinla oṣu karun ọdun 2020, lo ti n beere miliọnu lọna mẹrinlelaadọjọ naira, N156m owo itanran fun onibara rẹ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Africa Eye: Ọwọ́ tẹ ayédèrú dókítà Abdallah tó ń tà oògùn Coronavirus Laipẹ yi ni ilumọọka oniṣowo ọmọ ilẹ Ibadan yi da ọgọrun miliọnu naira fun ijọba apapọ ati ti ipinlẹ Oyo lati fi koju arun Covid-19.
Arabinrin yii s fun BBC pe jẹjẹ loun wa nilu wọn ti wọn sọ fun un pe iṣẹ wa ni orilẹede kan ti wọn yoo ti maa san owo to to igba miliọnu naira fun un.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Adio Atawẹwẹ: Orin Fuji ló gba iwé kíkà lọ́wọ́ mi 24 Agẹmo 2019 Oríṣun àwòrán, Facebook/Atawewe Àkọlé àwòrán, Atawẹwẹ Gbajugbaju olorin Fuji, Alhaji Sulaimọn Adio Atawẹwẹ sọ pe lati igba t'oun ti gbọ́nju, oloogbe Dr Sikiru Ayinde Barrister ni akọkọ olorin Fuji.
Wọn si pasẹ fun lati san owo itanran eyi ti iye rẹ lé diẹ̀ ni miliọnu mejidinlogun naira.
 Nitori naa,ohun ti awon adari orile ede agbaye ni lati wa ojutuu si  bi  imọ ẹrọ igbalode yoo se wa larọwọto awon eniyan ati eyi ti eto aabo to peye yoo tun wa nibẹ.
Òkè-Ìdèra : gégé bí ìtàn ìsèdálè àdúgbò yìí , àdúgbò imojì ni àwon wònyí ti wá .
Ki i ṣe igba akọkọ ree ti wọn yoo da si ọrọ Naijiria.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ẹ wo àwọn èèkàn eléré ìdárayá tó bá ọdún 2020 lọ Wo ọ̀pọ̀ àsọtẹ́lẹ̀ igba tí Primate Ayodele gbé síta fọ́dún 2021 ₦9.
Awon yoku ni egbe oselu ti o ya kuro ninu egbe oselu ti o n se ijoba, Alliance Democratic Party Mohamed Kamaraimba Mansaray, Coalition for Change (C4C) ti o kuro lara egbe oselu APC Samuel Sam – Sumana, igbakeji aare teleri ti ,Aare ti o n kogba wole Koroma yo kuro nipo.
 Àwon òbí rẹ ni jen amundsen àti hanna sahlqvist .
 Awon ewebe bii efo lorisiirisi, ewedu, ila, eso bii osan, ogede, agbalumo, mangoro atawon miran dara fun ara.
Ṣugbọn nisinsinyii tí ọ̀rọ̀ kàn ọ́,o kò ní sùúrù;Ó dé bá ọ, ìdààmú bá ọ.
Bí o tilẹ̀ jẹ́ wípé òun àti ọkọ rẹ̀ ti pínyà, kó tó di wípé wọ́n kọ ara wọn sílẹ̀ ní 1996, Winnie Madikizela Mandela, bí gbogbo ènìyàn ṣe mọ̀ ọ́, jẹ́ gbajú-gbajà nínú ìgbéayé Nelson Mandela.
Àkọlé àwòrán, Ikanni Twitter APC n polówó Bitcoin Ni ọjọ́ ìsinmi ni agbẹnusọ ẹgbẹ APC Bolaji Abdullahi fi àtẹ̀jáde kan síta pe, awọn ti polongo lai mọye ìgbà pe ẹgbẹ APC kò ní ounkóhun se pẹlu ikanni Twitter yii, ati pe awọn rí oun to sẹlẹ̀ yii gẹ́gẹ́ bi iwa ọ̀daràn to lágbára.
gbe lati palẹ ẹmi awon to padanu ẹmi won  ninu ikọlu naa.
Wo àwọn olùdíje < Padà lọ sí ọ̀dọ̀ Olùdíje Ìkádìí Oríṣun àwòrán, @NajeemFSalaam Àkọlé àwòrán, Awọn Gomina ẹgbẹ APC naa wa gbaruku ti akẹgbẹ wọn Rauf Aregbesola nibi ipolongo ohun O rọ awọn eeyan ipinlẹ Ọṣun lati jade dibo wọn fun ẹgbẹ oṣelu APC lọjọ kejilelogun oṣu kẹẹsan ọdun yi, ki oṣẹ rere ẹgbẹ naa le tẹsiwaju.
Ẹni tí ó ń ṣe òfófó káàkiri a máa tú ọpọlọpọ àṣírí,nítorí náà má ṣe bá ẹlẹ́jọ́ kẹ́gbẹ́.
Ó ṣí kànga náà, èéfín bá yọ láti inú kànga yìí, ó dàbí èéfín iná ìléru ńlá.
Bayii, awọn siga igbalode (e-cigarettes) ti n rọpo taba.
Ìjọba Buhari: Orúkọ Adeọsun tún wà lórí òpó ayélujára lẹ́yìn tó fipò sílẹ̀
Oríṣun àwòrán, @NPOWER_NG TWITTER Bí o bá ń se N-Power tóo sì ti ríṣẹ́ sí ibòmíràn, olè ni ọ́!
Ileeṣẹ kan ti wọn darukọ ninu rẹ Oxfam sọ fun mi pe awọn ko gba owo kankan lọwọ ileeṣẹ epo ṣugbọn awọn ti ṣagbatẹru sisanwo ri fun idanilẹkọ kan fun Ọgbẹni Sonko.
Joṣua sọ fún àwọn ẹ̀yà Reubẹni, ati ti Gadi, ati ìdajì ẹ̀yà Manase pé, 
Ọ̀pọ̀ èèyàn bẹnu ẹ̀tẹ́ lu Mercy Aigbe lórí bó ṣe ki Adeniyi Johnson Arsenal domi sí Burnley lára lórí tiransifọ́mà ní Emirates Wo àgbáríjọpọ̀ àwọn Arugbá Ọ̀ṣun Òṣogbo látìgbà tó ti bẹ̀rẹ̀ Aṣírí ìdí ti El-Zakzaky fi padà Nàìjíríà láti India Gomina ipinlẹ Ondo gangan ni Rotimi Akeredolu, ṣugbọn Akeredolu n ls fun isinmi ọsẹ meji to ja si ọjọ mẹrinla ni o fi fa iṣejọba le igbakeji rẹ, Agboọla Ajayi lọwọ gẹgẹ bii adele gomina lẹyin to ti kọwe si ile aṣofin ipinlẹ naa gẹgẹ bi iwe ofin orilẹede Naijiria, ti ọdun 1999 ṣe laa kalẹ,pe igbakeji oun ni yoo maa ṣe iṣẹ gomina titi ti oun yoo fi pada de.
O ni oun ko ni baba isalẹ ninu ẹgbe PDP ayafi Ọlọrun ọba.
kekere :Chukwuka Onyema lati ipinle Anambra,igbakeji adari aato , ogbeni Yakubu
Nígbà tí wọ́n dá wọn sílẹ̀, wọ́n lọ sọ́dọ̀ àwọn ẹgbẹ́ wọn, wọ́n ròyìn ohun gbogbo tí àwọn olórí alufaa ati àwọn àgbààgbà sọ fún wọn.
Ẹ̀yin ọmọ Jakọbu, ẹ fi ògo fún un,ẹ dúró tọ̀wọ̀tọ̀wọ̀ níwájú rẹ̀, gbogbo ẹ̀yin ọmọ Israẹli!
”Peters tesiwaju pe, inu ohun dun pupo, besini o je ohun iwuri lati ri awon oludari agba tuntun ajo to n ri si boolu afesegba nile Afrika CAF fun atileyin ati akitiyan won lati gbe boolu eya Afrika de ipele ti o lapere, bakan naa, ajo FIFA fun igberu ti o se ye sile ti won mu ba boolu afesegba lagbaye.
Seyi Makinde wa n mu da awọn araalu loju, to fi mọ awọn iyalọja, lati maa ba isẹ oojọ wọn lọ̀, ti ijọba oun si ti pinnu lati jẹ ki eto aabo fẹsẹ rinlẹ ni ipinlẹ Ọyọ.
Gẹgẹ bi wọn ti ṣe sọ, wn ni igbesẹ yi yoo jẹ ọna kan gbogi lati dẹkun ajakalẹ aarun naa.
"Mo wá rí isẹ yìí bíi anfaani fún mi láti ṣe àtúnṣe si ìwà ìgbéraga tí mo hù sí osere-binrin náà ṣáájú nígbà tí mo ní owó isẹ wa wọ́n pupọ.
Club/ RD Congo),, Fabrice Ngoma Luamba (AS V.
Tabi èrè wo ni ó wà ninu pé asán ati ìmúlẹ̀mófo ni gbogbo làálàá wa láyé.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù World Aniti-Corruption day: Awolowo, Azikwe, Abacha àtàwọn olórí ìjọba tí aje ìwà ìjẹkújẹ ti ṣí mọ́ lórí rí ní Nàìjíríà 9 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Oríṣun àwòrán, others Èyí ni àwọn aṣíwájú ìjọba táje ìwà ìjẹkújẹ ti ṣí mọ́ lórí láàrin ọdún 1960 sí àsìkò yí Ọrọ iwa ijẹkujẹ kii ṣe ajeji lorilẹede Naijiri.
Ẹgbẹ oselu APC, ninu igbe to fi bọnu faraye ni ẹgbẹ oselu PDP to n se ijọba lọwọ ni ipinlẹ Kwara ti fọn awọn janduku soke lati maa dunkoko mọ awọn alatako rẹ ninu atundi ibo ọhun.
Akọroyin BBC Yoruba to wa nibi iwọde naa jabọ pe ada, okuta ati awọn nkan ija mii ni awọn janduku naa ko dani.
Bakan naa ni irufẹ isl yii waye ni ilu Eko laipẹ yii, eyi to mu ẹmi eeyan mẹsan lọ.
Sùgbọ́n gẹ́gẹ́ bi ǹkan ti ọgbẹ̀ni Adedimeji sọ, ó ni gbígba àdúra ni ńkan ti àwọn ènìyàn ń rí tori ìpólówó ọja ni àwọn ń se.
william adams wọ ́ n bí adams ní 1564 .
O ni,  Eni to ba ran ni niṣẹ laa bẹru ni ọrọ baba isalẹ."
Coronavirus Cases in Africa: Adarí àwọn agbóòkú tó ń fi ijọ́ dárà ní ilẹ̀ Ghana sọ bí àwọn ṣe da ìlúmọ̀ọ́ká
Àwọn tí a bá ní àgbàlá ọba ejò náà tí wọn kò ì ti í kú dàpọ̀ mọ́ wa.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Àìmọ̀kan ló mú mi hu ìwà tí mo hù kọjá sẹ́yìn, Jonathan dárí jì mí - Dino Melaye Ẹ́ tú èékánná lọ́rùn Sowore, ẹ kò ní ẹ̀rí láti ba ṣẹjọ́ - Ẹgbẹ́ Amòfin Amẹ́ríkà Irú iṣẹ́ wo ní Funke Akindele rán sí Bukunmi Oluwasina, tó fa ariwo lórí ayélujára?
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ogun flood: ọ̀pọ̀ àwọn olùgbé agbegbe yii ti fi iṣẹ́ sílẹ̀ nítorí wọn kò lè jáde Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Ogun flood: ọ̀pọ̀ àwọn olùgbé agbegbe yii ti fi iṣẹ́ sílẹ̀ nítorí wọn kò lè jáde 24 Ọ̀wàrà 2019 Omiyale ati agbara ya ṣọọbu sọ awọn eniyan ipinlẹ Ogun di alinilelori.
Awọn ọkunrin lo gbiyanju julọ ninu idahun wọn lasiko ti BBC Yoruba jade lọ beere idahun naa Wọn fihan pe awọn ko gbagbe ede Yoruba ti wọn ti kọ.
Ileesẹ ọlọpaa ti wa rọ awọn ara ilu lati maa sọra se nipa awọn eeyan ti wọn yoo maa tọ lọ fun aajo ẹmi, nitori awọn gbajuẹ naa ti n se bi eeyan Ọlọrun.
Sisera wó, ó ṣubú lulẹ̀,ó nà gbalaja lẹ́sẹ̀ Jaeli,ó wó lulẹ̀ lẹ́sẹ̀ rẹ̀, ó ṣubú lulẹ̀.
N kò bèèrè ibi tí ó ti wá, kò sì sọ orúkọ ara rẹ̀ fún mi.
”Aarẹ ana fun orile ede Amerika ,John F Kennedy ati iyawo rẹ ,ni won  mu ọda yii lọdun 1960.
Ni Ọjọ Aje awọn janduku ni ipinlẹ Edo ya bo awọn ọgba ẹwọn meji ti wọn si tu awọn ẹlẹwọn to wa nibẹ silẹ.
Ògbómọ ̀ sọ ́ jẹ ́ ìlú ní ìpínlẹ ̀ Ọ ̀ yo ní apá ìwò-oòrùn oriĺè-èdè nàìjíríaì .
Aare Buhari so eleyii lasiko ayeye ajoyo eto ijoba tiwa-n-tiwa to waye ni Natioan Stadium, niluu Abuja.
Asofin Awoleye fikun-un oro re pe,  “ atunse gbodo ba ofin 214 ofin orile ede yii ki won si yo oro Ipa (Force) to wa ninu oruko , Ile ise olopaa (Nigeria police force ) kuro ki won si yii si Ile ise olopaa to n sin awon ara ilu ( Nigeria police service),Atunse yii, yoo tun je ki ,oju ti awon ara ilu fi n wo awon olopaa tun yii pada , bakan naa,  atunse si ofin naa yoo tun je ki won da awon olopaa ipinle sile ni gbogbo awon ipinle to wa lorile ede yii”.
O fi kun oro re pe, oun mo akitiyan ti isakoso ijoba orile-ede Tunisia ti gbe lori eto ogbin, irinajo afe, ati eto-ilera, laipe ojo, a o se agbekale iko kan ti yoo se abewo si orile-ede ohun lati mo awon eka ti awon orile-ede mejeeji ohun yoo ti sise papo.
Irọ ni wọn pa mọ mi - Melaye Ni opin ọse, awọn ileesẹ iroyin ilẹ Amẹrika meji, The Guardian ati The New York Times fi awọn iroyin sita to fihan wipe Facebook ko se gbogbo ohun to yẹ ko se lati daabobo awọn ohun to jọ mọ iroyin ti awọn eniyan fi si oju opo wọn.
Wòlíì Kasali ní Dolapo Awosika kò lé ìyàwó òun jáde Gbogbo aṣa ati iṣe Yoruba ni a n ṣi aṣọ lawọn oju opo rẹ fun igbadun ati idanilẹkọ fawọn eeyan kaakiri.
O mọ ìtẹ́ gíga ní òpin gbogbo òpópó.
Oríṣun àwòrán, Twitter/Super Eagles Àkọlé àwòrán, Naijiria fidi rẹmi Ni bayii, Naijiria yoo koju Tunisia l'Ọjọru lati ja fun ipo kẹta, nigba ti Algeria yoo ta kangbọn pẹlu Senegal ninu ifẹsẹwọnsẹ aṣekagba idije AFCON 2019.
NNomination (Yiyan oludije) : Yiyan oludije sipo jẹ
Iṣẹ́ ṣẹ̀ṣẹ̀ bọ́ lọ́wọ́ Seth Ator tó yìnbọn pa ọ̀pọ̀ èèyàn ní Texas ni- ọlọ́pàá Ìfẹ̀hónúhàn l'Abuja lórí ìdájọ́ ilẹ̀ Gẹ̀ẹ́sì tó gbẹ́sẹ̀ lé $9.
O ni Luminee ni oun ko sọ nipa ile naa, amọoun n sọ̀ nipa ile to rwea, ti oun yoo ra si agbegbe to jẹ oju ni gbese ni ilu Eko, ti oun si jaa niyan pe nibo ni oun ti fẹ́ ri owo banta-banta lati iru ile bẹẹ.
Bẹ́ẹ̀ gan-an ni, kì í ṣe ìfẹ́ Baba yín tí ń bẹ ní ọ̀run pé kí ọ̀kan ninu àwọn kékeré wọnyi kí ó ṣègbé.
Èdè Èkìtì nì òdè Àdúgbọ ̀ wọn .
Dagunro ní ìtẹríba, tó sì ń gbé àṣà lárugẹ - Ọ̀gá Bello Wo àwòrán pápá ìṣeré MKO Abiola National Stadium Kókó ọ̀rọ̀ tí Buhari sọ ní àyájọ́ June 12 ‘Mo ké bòòsí tòò bí mo ṣe bí ìbejì, ti ọ̀kan jẹ́ àfín, ìkejì jẹ́ dúdú’ Èyí tí a wò jùlọ 5:03 Fídíò, Omolola Arohunmolase Welder: Mo ti fí iṣẹ́ 'Welder' gbayì láwùjọ, tó mo fi tọ́ ọmọ yanjú, Duration 5,039 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 5:39 Fídíò, Akomolede ati Asa lori BBC: Olùkọ́ Kikelomo Ogunboye tan ìmọ́lẹ̀ sí ìwà olè ọ̀gá ọlọ́pàá Audu gẹ́gẹ́ bí àwòkọ́ṣe àsìkò yìí, Duration 5,398 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 4:11 Fídíò, Oba Adeyeye Ogunwusi: Ojú mi ti rí lọ́pọ̀ lọpọ̀, ọ̀pọ̀ èèyàn ni kò tilẹ̀ gbàgbọ́ pé mo lè jọba- Ooni, Duration 4,117 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 4:43 Fídíò, Promise Akinlade: ọmọ ọdún mọ́kànlá tó ń fi ìlù dárà bíi àgbàlagbà sọ̀rọ̀ nípa tálẹ́ǹtì rẹ̀, Duration 4,437 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 0:59 Gbọ́, Ìsẹ̀lẹ̀ jákèjádò orílẹ̀èdè àgbáyé láàárín ìṣẹ́jú kan, Duration 0,59wákàtí 5 sẹ́yìn 7:03 Fídíò, Olumuyiwa Bolade Adedeji Military Bruitality: Bí arákùnrin onípèníjà ara tí sọ́jà lù ṣe dé, Duration 7,035 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 4:45 Fídíò, Yoruba Films: Ẹ̀ẹ́ bẹ̀ mi kúrò láyé ni, mi ò lè kú - Fadeyi Oloro, Duration 4,4526 Èrèlè 2020 2:48 Fídíò, Esther Ajayi: Èmi náà ti borí ìṣòro rí ló ń mu mi ṣojú àánú, Duration 2,481 Ògún 2019 6:08 Fídíò, Adebola Ademilua: Àìrísẹ́ ṣè lẹ́yìn ìwé kíkà ló sọ mi dí ìyá onírú, mo dúpẹ́ tèmi, Duration 6,0827 Bélú 2020 5:55 Fídíò, Soyinka Cancer: Àṣe ara mi ni iso ti n run gbogbo bí mo ṣe n ṣèrànwọ́ lórí jẹjẹrẹ, Duration 5,5527 Bélú 2019 BBC News, Yorùbá Ìdí tí ẹ fi le è nígbàagbọ́ nínú ìròyìn BBC Ìlànà Lílò Nípa BBC Òfin Àṣírí Cookies Kàn sí.
Kò sí ẹni tí ó mọ Ọmọ àfi Baba; bẹ́ẹ̀ ni kò sí ẹni tí ó mọ Baba, àfi Ọmọ, àtúnfi àwọn tí Ọmọ bá fẹ́ fi Baba hàn fún.
Ó ti jẹ́ kí n rù kan egungun,ó sì ti fọ́ egungun mi.
Ọsinbajo tun lo anfaani akoko abẹwo naa lati jẹ ko di mimọ fun araye pe, okun ajọsepọ to wa laarin gomina Ambọde ati oludije fun ipo gomina labẹ ẹgbẹ oselu APC nipinlẹ Eko, Babajide Sanwo-Olu si yi dain-dain sii.
 fún orí pí pé àti ìmọ ̀ ìjìnlẹ ̀ rẹ ̀ tí ó fi hàn ní ilẹ ̀ germany .
Fetí sí adura mi nítorí kò sí ẹ̀tàn ní ẹnu mi.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ètò ìsìnkú Abba Kyari tako ìlànà ìjìnàsíraẹni lórí ààrùn covid-19- Àwọn ọmọ Nàìjíríà yarí Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Fídíò, Coronavirus Vaccine: Ṣé abẹrẹ àjẹsára ti wà fún àrùn COVID-19?
Wọ́n bi í pé, “Níbo ni, Oluwa?
Aṣofin Oshinọwọ fi han ninu ọrọ rẹ pe ni tootọ ni ọrọ owo-ori naa ti da ọpọ ifẹhonuhan silẹ, o si ṣe pataki pe ki ijoba gbe igbesẹ ọna abayọ si ọrọ naa.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ìpínlẹ̀ méjìlá nínú ewu àgbárá òjò ní Nàìjíríà EFCC f'orúkọ Fayose sórí ìwé afurasí 'A simi ìwádìí lóri Kemi Adeosun' CBN gbé òfin tuntun sílẹ̀ fún àwọn Báǹkì Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ọṣun Decides:'Màá san gbogbo owó oṣù òṣìṣẹ́ lékunréré'-Akinbade Amọṣa awọn onka ti ajọ UNICEF wa fi sita nibi idanilẹkọọ kan lo tun da bi ẹni pe o kọ ọpọ onwoye nibi idanilẹkọọ naa ni ominú.
Jọ̀wọ́ o, Ìyábọ̀, ṣe ọmọ dáadáa o.
Mose bá pe Joṣua, ó sọ fún un níwájú gbogbo àwọn eniyan Israẹli, pé, “Múra gírí, kí o sì mú ọkàn gidigidi nítorí ìwọ ni o óo kó àwọn eniyan wọnyi lọ sí ilẹ̀ tí OLUWA Ọlọrun ti búra fún àwọn baba wọn pé òun yóo fi fún wọn.
Ẹbi ọ̀tún àti ti òsi yio joko fún ètò igbéyàwó lati gba ẹbi ọkọ ni àlejò fún àdúrà gbi gbà fún àwọn ọmọ ti ó nṣe igbéyàwó àti lati gbà wọn ni ìyànjú bi ó ṣe yẹ ki wọn gbé pọ̀ ni irọ̀rùn.
Oríṣun àwòrán, Bauchi Ninu oṣu kẹrin ni gomina Bala Mohammed wa fi sita loju opo Twitter pe oun ti pada bọ lọwọ arun naa lẹyin to ṣe iyasọtọ to si gba itọju.
Àwọn ará Filistia ti gbógun ti àwọn ìlú tí ó wà ní ẹsẹ̀ òkè, ati ní agbègbè Nẹgẹbu, ní Juda.
Ọjọ Aje, ọjọ kẹtadinlọgbọn oṣu kẹrin ni iku muu lọ.
Èmi náà sì fèsì mo wí pé: Èmi Olówó-ayé ni mo ń pè ọ́, Èmi ọmọ Akọ̀wédìran, èmi ọdẹ aperin, ọkọ Àjẹ́dìran, ẹni tí ó wáá ṣe ọdẹ nínú igbó, tí ìwọ bá téńté lórí igi.
Amọṣa, o ni ohun to ṣẹlẹ lori ọrọ minisita tẹlẹ Kẹmi Adeọṣun jẹ ohun to ku diẹ kaa to ṣugbọn to jẹ pe laifọta pe abawọn nla lo jẹ fun ile aṣofin apapọ orilẹede Naijiria.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Segun mu òògùn apakòkòrò tórí máàkì 167 nínú JAMB Èmi ṣì ni alága ẹgbẹ́, wọn ò tó bẹ́ẹ̀ - Sowore Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Lórí iṣẹ́ ikàn yìí, a ti kọ́ ilé, ọmọ ti lọ ilé ìwé' Alukoro fun ileeṣẹ to n pin ina ọba lorilẹede Naijiria, TCN, Ndidi Mbah ni awọn alaṣẹ ẹgbẹ oṣiṣẹ TUC lapapọ lo n ṣe kokari ifẹhonu han naa,eleyi to ni awọn ọmọ ẹgbẹ oṣiṣẹ naa to wa ni ileeṣẹ to n pin ina ọba, TCN gangan ti ọrọ naa gbe ru gbọn-gbọn-gbọn ko fara mọ.
Ileewosan gba ọmọ silẹ nitori airowo san Ẹ̀bùn Ọlọ́run ni ọmọ bíbí ni mo ṣe bí ọmọ 17 A kú ewu ọmọ Linda Ikeji ooo Tọkọtaya lu ọmọ ni gbanjo fun 400k Dokita ọmọ Naijiria jàjàbọ́ nílẹ̀ Ọba ''Mo ti n gbebi ọmọ lati nnkan bi ọdun marundinlogoji ti mi o si ri ki ọjọ ibi asiko ati iwọn ọmọ papọ bayi ri'' Ayajọ ọjọ 9/11 lọjọ ti eeyan to le ni ẹgbẹrun mta padanu ẹmi wọn nigba ti awọn agbesunmọmi wa baalu kọlu ile nla World Trade Centre Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ki ina ọkọ rẹ mọlẹ kedere jẹ ọna kan lati dena ijamba ọkọ loju popo Yatọ si pe wọn yoo jẹ ki wiwakọ lalẹ ninu okunkun rọrun, awọn ina ara ọkọ tun jẹ atọna fawọn awakọ mii lati mọ ti eeyan ba n duro tabi to ba fẹ gbera.
Mo kábámò pé mo fipá bá Ìyá ẹni ọgọrin ọdún sún ní Kano- Muhammad Zulfara'u Iyabo Ojo, Toyin Abraham, Mercy Aigbe, ta làwọn òṣèrébìnrin yìí gbè lẹ́yìn lórí ọ̀rọ̀ ìfipábánilòpọ̀?
Sùgbọn nínú ìwádìí BBC a ri i pé àwọn tó ń ti òjò ti wọn sì ń ṣí òjò pọ̀ jántìrẹrẹ ní orílẹ̀-èdè Nàìjíríà.
    Ẹ̀rù bà mí nígbà tí mo gbọ́ ọ̀rọ̀ yìí, kí Olódùmarè gba ni lọ́wọ́ ọ̀rẹ́ àìròtẹ́lẹ̀ ti ń dá ni lóhùn lọ́gànjọ́ òru.
Bi gbigba rẹ ṣe yara si lori ayelujara, oṣu karun, ọdun 2019.
Soyinka: Ohun gbogbo ti dẹnu kọlẹ̀ la ṣe gbọdọ̀ gbé ìgbésẹ̀ pàjáwìrì
Ẹgbẹrun lọna ọgọrun-un naira lo fẹ gba lori ṣiṣe akoso awọn oju opo itakun agbaye ti mo ti n ṣe waasi, yatọ si owo kaadi deta to n lo, to si ti gba ida mẹẹdọgbọn ninu owo naa.
"Ìya ọrẹ mi kan lọba oun ati kọ rẹ lalejo ma ni op.
Oun ni gbogbo aye n sọrọ nipa rẹ lori ayelujara lasiko yii pe ko si ohun ti ọdọmọde ko le ṣe yanju!
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Kemi Dairo: Iṣẹ́ abẹ nínú ọpọlọ àti ẹ̀rọ ni mo fi ń gbọ́ ọ̀rọ̀ báyìí Ikilọ alaga yii ko sẹyin bi awọn gomina ipinlẹ lọkan o jọkan, ṣe n lugbadi arun naa ni lọọlọ yii.
 Anthony Ejiofor,  wa rọ awon omo  Ndigbo nile ati ni okeere lati lọwọ ninu idagbasoke orile ede Naijiria nitori pe , “Ko si  Egbe kan to lee ba wa se e’’.
Awa kọ lo n pagidina bi iyanju yoo ṣe de ba iyanṣẹlodi yii bi ko ṣe ijọba."
Awọn onimọ ijinlẹ kaakiri agbaye ṣi n ṣiṣẹ iwadii lati wa oogun tabi abẹrẹ to le wo aarun coronavirus, ṣugbọn ko ti si oogun aarun naa di akoko yii.
Festus Keyamo, to jẹ  agbẹnusọrọ  eto ipolongo fun aarẹ Buhari ,lo kọwe naa lati
 ohun tó fà á ni pé èdè kọ ̀ ọ ̀ kan ló ní ìwọ ̀ nba ìrú tó ń mú lò .
Pẹ́pẹ́yẹ gbé ọmọ pọ̀n nínú oṣù Ẹrẹ́nà ọdún-un 2018 nígbàtí a gba Ìlànà Ẹ̀rọ Ayárabíàṣá (Ohun orí ayélujára) àti Ìtàkùrọ̀sọ Ìfìwéránṣẹ́ wọlé tí ó mú un ní túláàsì fún àwọn akọbúlọ́ọ̀gù láti fi orúkọ sílẹ̀ tí wọ́n á sì san owó orí tí ó tó bíi US $900 lọ́dún kí wọn ó tó lè gbé àtẹ̀jáde sí orí ayélujára.
Ní ilẹ̀ Gẹ́ẹ̀sì, wọ́n fun àwọn ọmọ ilé iwé alákọ̀ọ́bẹ̀rẹ̀ àti girama ni inú oṣù kíní ọdún.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìwádìí ICPC fi hàn pé ènìyàn 721 fi ayédèrú ìwé ẹ̀rí gba iṣẹ́ ìjọba àpapọ̀ 20 Òkùdu 2019 Oríṣun àwòrán, Ht Àkọlé àwòrán, Ìwádìí ICPC fihàn pé ènìyàn 721 fi ayédèrú ìwé ẹ̀rí gba iṣẹ́ ìjọba àpapọ̀ Bá wó ni òṣìṣẹ ẹẹdẹgbẹrin ati mọkanlelogun ṣe gba iṣẹ ijọba apapọ pẹlu iwe ayederu?
kí ó tó di pé àṣírí ìwà burúkú rẹ wá tú?
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Adájọ́ pàṣẹ kí wọ́n fi Naira Marley sí àhámọ́ ọgbà ẹ̀wọ̀n 'Lóòtọ́, Gómìnà ko lẹ́tọ́ lórí owó ìjọba ìbílẹ̀ ṣùgbọ́n.
Mààlúù kan ati aguntan mẹfa tí ó dára ni wọ́n ń bá mi pa lojumọ, wọn a tún máa bá mi pa ọpọlọpọ adìẹ.
“Ẹ fetí sí mi, ẹ̀yin eniyan mi,ẹ tẹ́tí sí mi, ẹ̀yin orílẹ̀-èdè,òfin kan yóo ti ọ̀dọ̀ mi jáde,ìdájọ́ òdodo mi yóo jẹ́ ìmọ́lẹ̀ fún àwọn eniyan.
Ọmọ Yorùbá, àti gbogbo adúláwọ̀ ẹgbẹ́ ẹ wa, a ti sùnlọ.
Messi, Ronaldo ati Van Dijk ni awọn agbabọọẹu mẹta ti wọn yan fun ami ẹyẹ yii.
Nigba naa ni mo maa raye lati bẹrẹ si ni ṣe ohun ti mo fẹran lati maa ṣe.
Joe Igbokwe kò yẹ́ fún ipò ti wọ́n fún un nípìnlẹ̀ Eko
A ò fẹ àwáwí, owó wa ni ẹ san - àwọn òṣìṣẹ́ ilé aṣòfin Ẹ wo àwòrán tó làmìlaaka níbi ọjọ́ ìbí Gomina ìpínlẹ̀ Ọyọ Ẹ̀kọ́ mẹ́fà tó jáde nínú ìdíje Premier League òpin ọ̀sẹ̀ Àkọlé àwòrán, Awọn oṣìṣẹ́ fẹ̀hónú hàn níle ìgbìmọ̀ Aṣofin Saaju ni wọn ti gbe awọn ìgbésẹ̀ kan to fi mọ bi wọn ti ṣe ṣe iwọ́de ìfẹ̀hónú hàn láti dí ìgbòkègbòdò ilé ìgbìmọ̀ àsṣòfin lọ́wọ́ lọjọ́ kerin àti ọjọ́ kẹjọ oṣù kejila, ọdún 2018.
 ní ìbẹ ̀ ẹ ̀ rẹ ̀ ààrún yìí , oun tí a máa ń sábà rí ni kí ara máa gbọ ̀ n , kí ó máa le kakaraka , kí ènìyàn má lè rìn dáradára .
Ǹkan tí a mọ̀ nípa kọ́lẹ̀jì olùdìbò tó ń fìdì ẹni ti yóò jẹ ààrẹ ilẹ̀ Amérika múlẹ̀ Ẹ wo bí orílẹ̀èdè Amẹrika ṣe dóòlà ẹ̀mí ọmọ ilẹ̀ wọn tí wọ́n jígbé ní Naijiria Amy Coney Barrett di adajọ́ àgbà nílé ẹjọ́ tó ga jùlọ l'Amẹrika Wo àwọn Ṣọ́ọ̀ṣì Nàìjíríà àti l'Áfíríkà tó ń wólẹ̀ àdúrà kí Trump lè wọlé ìbò ààrẹ America Agbára wa kò ká àrùn Covid-19 mọ́ - Ìjọba ilẹ̀ Amẹrika Iroyin sọ pe ikọ ipolongo Aarẹ Donald Trump na obitibiti owo fun ipolongo lori Super Bowl loṣu keji ọdun 2020.
Ogbeni Yakubu Dogara ni apapo ibo ti o le die leẹ̀gbẹ̀rún mẹ́tàléláàdọ́rin(over 73 thousand votes), ti akegbe re ti o wa labe asia egbe oselu APC, ogbeni Dalhatu Abubakar Kantana si ni apapo ibo ti o le leẹ̀gbẹ̀rún làádọ́ta(over 50 thousand votes).
Ajọ EFCC lo fi ẹsun kan an pe o lu owo ilu to le ni biliọnu lọna ọgọrun naira ni ponpo ni ọdun 2010 to wa ni ipo ọga agba ajọ naa.
Ìgbà tí ó di wí pé àwọn tẹ̀gbọ́n tàbúrò yí máa fi Ifẹ́ sílẹ̀, ìgbà kan náà ni wọ́n gbéra kúrò lọ́hùnún, apá ibì kan náà ni wọ́n sì gbà lọ láti lọ tẹ̀dó sí.
Agbẹnusọ fun ẹgbẹ Afnifẹre ni agbara ojo awọn darandaran yii ko ni oun ko nile wo, amọ awọn onile ni ko ni gba fun.
Aarẹ Trump ni lootọ loun ba aarẹ Zelensky sọrọ nipa ọgbẹni Biden, ṣugbọn ohun ko dunkoko mọ pe ki o we ẹsun mọ alatako rẹ lẹsẹ Njẹ aarẹ Trump ti fidi ọrọ yi mulẹ?
Kí lo mọ̀ nípa Eniọla Badmus?
" Gẹgẹ bi atẹjade kan lati ọdọ olubadamọran fun aarẹ lori ọrọ iroyin ati ipolongo, Fẹmi Adeṣina ṣe sọ, aarẹ Buhari ni iṣejọba oun yoo tubọ gbajumọ eto abo, gbigbogun ti iwa ijẹkujẹ ati tita eto ọrọ aje ji fun alekun idagbasoke ati ilọsiwaju.
Eyi si lo mu ki ajọ na wá olu ileeṣẹ na kan ni opopona Ibadan si Eko, ṣugbọn, ilẹkun ibẹ wa ni titi pa.
Ni alẹ ọjọ kẹta ti ifẹhonuhan naa bẹrẹ ni iroyin sọ pe ọmọ ọdun mẹtadinlogun kan yinbọn lu awọn olufẹhonuhan, ti meji ninu awọn eeyan ọhun gbẹmi mi, ti ẹnikan si farapa yanayana.
Bẹẹ ni wọn se lọdun meji sẹyin nigba ti kiniun marun sa kuro ni ọgba ẹranko naa, amọ wọn ri wọn he pada.
NIPOST àti FIRS ń fi ọ̀rọ̀ kòbákùngbé tú ara wọn làṣìírí lórí ayélujáraTwitter
Ohun ikeji ni lati ma ṣe gba ibẹru laaye nitori ti o ko ba bẹru wa a le rọnu lati wa ọna abayọ kuro ninu ijamba naa, amọ ibẹru yoo jẹ ki o gbagbe gbogbo ẹkọ ti o ti kọ lati da abo bo ara rẹ.
Ó dìgbà o, kí ìyàwó rẹ̀ fún mi.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Afárá Marina àti Eko yóò di ṣíṣí padà lọ́la Wo àwọn Ṣọ́ọ̀ṣì Nàìjíríà àti l'Áfíríkà tó ń wólẹ̀ àdúrà kí Trump lè wọlé ìbò ààrẹ America Iléeṣẹ́ ológun bẹ̀rẹ̀ 'Operation Crocodile Smile' yíká Naijiria fún oṣù méjì Òkú tó jí lọ́jọ́ kejì ní mọ́ṣúárì padà kú síléèwòsàn Ṣé lóòtọ́ ni àjọ ọlọ́pàá dá Abayomi Shogunle àti Dolapo Badmus dúró?
Oun si ni akọbi awọn obi rẹ.
Lagos Theft: Ẹrù olè gbé ẹ̀ṣọ́ ilé wọ kóló olọ́pàá
Gomina Makinde tun ni dukia to to miliọnu lọna ẹgbẹrun mẹrin o le nirinwo owo dọla nipamọ.
Ọba fún un ní gbogbo nǹkan tí ó bèèrè, nítorí pé ó rí ojurere OLUWA Ọlọrun rẹ̀.
Ó pé ọdún mẹ́rìnlélàádọ̀ta tí Akintola kú, ìdí abájọ ìja rẹ̀ pẹ̀lú Awolowo rè é Ìtàn Gbọnka àti Timi, akọni méjì tó borí Aláàfin Ṣango Òkè Idanre rèé tí odidi ìlú kan ló ń gbé lórí ẹ̀ Eji Gbadero, ọmọ Ibadan àti jayé-jayé ọmọ ónílẹ̀ ti wọn yẹgi fun l'Eko Lisabi Agbongbo Akala rèé, ẹni tó fi ìfẹ́, ìṣọ̀kan àti ìrẹ́pọ̀ gba ilẹ̀ Ẹ̀gbá lọ́wọ́ ìmúnisìn Simon ni ọjọ igbeyawo naa ni inu oun dun julọ, paapaa, nigba ti oun n wo aya oun bo se n rin ati bo se n rẹrin musẹ.
Nítorí nǹkan àṣírí kan tíí máa fa rúkèrúdò ti bẹ̀rẹ̀ sí ṣiṣẹ́, ṣugbọn ẹni tí ó ń ká a lọ́wọ́ kò wà, kò ì kúrò lọ́nà.
O ni labẹ ofin, awọn ọmọ Naijiria ni aṣẹ lati fi ẹhọnuhan lai mu laisigbo dani.
OLUWA ní, “O kò lè rí ojú mi nítorí pé eniyan kò lè rí ojú mi kí ó wà láàyè.
Ninu oro agbateru ipade apero naa, Akanbi Afonja pe, ipade apero ohun ti o ti di olodoodun ni lati fi dupe lowo Tinubu fun ipa ti o ko lori eto ijoba tiwa-n-tiwa.
ṣe ohun to tọ”Lori awuyewuye pe awọn ọmọ
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Samson Siasia: Orí ti kó ìyá Siasia yọ lọ́wọ́ àwọn ajínigbé lẹ́yìn oṣù méjì ààbọ̀ 29 Owewe 2019 Oríṣun àwòrán, Facebook/Samson Siasia Lẹyin bi oṣu meji ati aabọ, awọn ajinigbe ti fi iya akọnimọọgba ẹgbẹ agbabọọlu Naijiria tẹlẹ ri, Samson Siasia silẹ.
Bẹẹni, 'Kẹkẹ Napep' ti n na igboro ilu Liverpool nilu Ọba.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Obìnrin akunlé ìgbàlódé Lọdun 2018 ni Aarẹ Eton ni ko yẹ ki ẹru ba obi ati ile iwe lati gba ẹrọ ibanisọrọ kuro lọwọ awọn ọmọ wọn.
Ní ọdún karun-un ìjọba Rehoboamu, Ṣiṣaki, ọba Ijipti, gbógun ti Jerusalẹmu.
O ni bakan naa ni wọn n jo ile, fọ sọọbu, ti wọn si tun pa ọlọpaa eyi to mu ki awọn ọlọpaa naa bẹrẹ si ni gbe ìbọn kaakiri ilu.
Àwọn tí ń ṣe òfin tí kò tọ́ gbé!
Inter-family marriage: Wo oríṣìí àrùn márùn ún tí ìgbéyàwó láàrin ìbátan máa ń fà
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Erin wó, gómìnà ológun àkọ́kọ́ ní kwara jáde láyé Ra ibo l‘Ọ́sun, ko ru'gi oyin - INEC Àwọn àwòrán tó gbayì níbi ọdún Ọ̀ṣun Òṣogbo Ọmọ Yorùbá ni onímọ̀ ẹ̀rọ ‘Rọ́bọ́tì’ tó ń gbowó jùlọ ní UK Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Osun Election 2018: Aráàlú ní àwọn kò fẹ́ ìjọba elébi mọ́ Emefiele ni A fẹ fi ọ̀kan awọn onibara banki Skye atijọ balẹ pe labẹ eto tuntun yii, mimi kankan ko ni mi owo wọn to wa ni ipamọ, ti isẹ sise yoo si bẹrẹ ni pẹrẹu lọjọ aje to n bọ ni awọn ẹka banki Skye lai si idaduro kankan."
Oloye Ayo Adebanjo ati agbẹnusọ Afénifẹ́re, Yinka Odumakin Adebanjo, sọ fun BBC pe awọn Ọba ode oni ń beru ijọba ni wọn ṣe n sọrọ atileyin fun Buhari lọdun 2019.
Igba mẹrinla ni Adesanya ti lu alatako rẹ lalubami ti wọn maa n pe ni TKO ninu ija mọkandinlogun to ti ja.
Okunnu, nígbà tó ń ṣàlàyé bo se n ló àkókò igbele yìí ni, òun ni àǹfààní láti kọ àwọn ere tuntun, tí òun sì ṣe àtúnṣe sì àwọn ere tí òun ti kọ tẹ́lẹ̀.
“Ìwọ, ọmọ mi,wolii Ọ̀gá Ògo ni a óo máa pè ọ́,nítorí ìwọ ni yóo ṣáájú Oluwa láti palẹ̀ mọ́ dè é, 
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Buhari, máṣe gbá ìpànìyàn Lekki sórí ààtàn, kò yẹ́ kí ológun yin ọ̀dọ́ níbọn - Bode George Ọ̀kan lára olùwọ́de tó fara gbọgbẹ́ ní Lekki jáde láyé - Sanwo-Olu Kò sí olùwọ́de tó kú ní Lekki - Sanwo-Olu N kò lọ́wọ́ nínú ìpànìyàn, kò dáa bí wọn ṣe lo ọta ìbọn ní Lekki - Tinubu Ọjọ́ Ìsẹ́gun di ọjọ́ ìbànújẹ́ fún ọ̀pọ̀ ìdílé ní Nàíjíríà torí òkú tó ṣùn Ọ̀dọ́ 30 ń gba ìtọ́jú lọ́wọ́ nílé ìwòsàn torí ọ̀gbẹ́ ìbọn ní Lekki - Sanwo-Olu ṣàlàyé Àwọn ṣọ́jà ṣíná ìbọn bolẹ̀ ni Lekki Tollgate Àwọn ọlọ́dẹ darapọ̀ mọ́ ìwọ́de #EndSARS l'Osogbo, wọ́n ní kò sáyè fún jàǹdùkú mọ́ Bo tilẹ jẹ pe ileeṣẹ ologun ti sẹ pe oun ko mọ ohunkohun nipa iṣẹlẹ naa, ṣugbọn ibeere ti awọn eeyan n bere bayii ni pe, ta ni akinkanju obinrin DJ Switch yii gan?
Àjọ NAFDAC ti bẹ̀rẹ̀ àyẹ̀wò àgbò mẹ́rin tí wọ́n ṣe ní Nàìjíríà fún Covid-19 Àgbéyẹ̀wò àṣà: Ìdí tí Yorùbá kìí fí tufọ ikú òjìji fún èèyàn Ọkùnrin kan gbé ‘búrọ́ọ̀ṣì ìfọyín’ mì Àwọn dókítà ìpínlẹ̀ Eko tó ń yanṣẹ́lódì ti padà s'ẹ́nu iṣẹ́ Bawo ni wọn ṣe n san gbà-má-bínú fún ẹni ti wọn bá fi dán abẹrẹ tàbí oògùn wò lára rẹ?
 A ko le kuna lati mu ileri wa se gege bi a se soo ninu egbe fawon ara ilu lasiko ipolongo lodun 2015.
Ile iwosan First Cardiology to wa ni Ikoyi niluu Eko ni Ajimobi dakẹ si lẹyin ti o ti n gba itọju nile iwosan.
"Nigba to n sọrọ lori igbeyawo to sẹsẹ se, Lizzy ni ""ọrẹ mi ni mo fẹ lọkọ, awọn obinrin ti wọn si ni awọn ti bimọ fun ọkọ mi, wọn ko ti kan si wa tabi ko ọmọ wọn wa sinu ile wa."
Iṣẹlẹ yi waye lẹyin igba diẹ ti ileeṣẹ ologun Naijiria ti ileeṣẹ Action Against Hunger pa ni Maiduguri.
Ọba rékọjá odò Kidironi, àwọn eniyan rẹ̀ sì tẹ̀lé e.
Wọn óo fá irun orí wọn nítorí rẹ,wọn óo sán aṣọ ọ̀fọ̀ mọ́ ìdí,wọn óo sì fi ìbànújẹ́ ọkàn sọkún nítorí rẹ,inú wọn yóo sì bàjẹ́.
Adari Ẹgbẹ Musulumi Shia, Sheikh Ibraheem El-Zakzaky ati iyawo rẹ, Zeena ti setan lati bẹrẹ irinajo lọ si India, lẹyin ọdun mẹta ti wọn ti wa ni atimọle Ajọ eleto aabo, DSS.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Coronavirus tips: Kìí ṣe gbogbo ìbòmù ló ń dá coronavirus dúró Ẹkọ ti itan Adebisi Idikan kọ wa: O kọ wa lati maa ṣiṣẹ kara, ka lee ni owo lọwọ lọna to tọ yatọ si owo ojiji tawọn ọdọ iwoyi n wa kiri Itan Adebisi Idikan tun kọ wa lati maa ṣe aanu, ka si maa ran awọn alaini lọwọ nitori pe ika ko dọgba Bakan naa tun ni itan igbe aye rẹ kọ wa lati maa ṣe iṣẹ loriṣiriṣi nitori ọna kan ko wọ ọja, eyi ti yoo jẹ ka tete jana Coronavirus ti di ara wa, kò le è kúrò mọ láéláé - WHO Ẹfunroye Tinubu - Ògbóǹtagí oníṣòwò, olówò ẹrú àti afọbajẹ Samuel Ajayi Crowther, òjíṣẹ́ Ọlọ́run tó gbé èdè Yoruba lárugẹ Mọrèmi Àjàṣorò, akọni obìnrin tó gba Ilé Ifẹ̀ sílẹ̀ lóko ẹrú Ọ̀rọ̀ǹpọ̀tọ̀niyùn, Aláàfin obìnrin àkọ́kọ́ rèé, tó ní nǹkan ọkùnrin Itan Adebisi tun kọ wa lati gbe ile aye se rere nitori a ko mọ igba ti ọlọjọ yoo de, boya ni igba ewe ni abi ni ọjọ ogbo, a ko gbọdọ fi isẹ rere falẹ Itan naa tun kọ wa pe ba ba lowo lọwọ, o yẹ ka fi jo nkan ni, ko si yẹ ka maa na ina apa Eeyan kii sunkun wọ ile adebisi, ko ma rẹrin jade, tori naa, ẹ jẹ ka maa ran awọn alaini to ba ba iranwọ wa sọdọ wa.
Láti ibẹ̀ ó lọ títí dé Òkun Mẹditarenia.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Beere fun iranlọwọ: Ironu nla ni eto ifọmọlọyan lee jẹ nigba miran, ti eeyan ko ba si beere fun iranlọwọ, o lee gba owo nla lọwọ ẹni.
Inú mi kọ́ dùn nígbà tí mo dé òkè lọ́hùn-ún nítorí mo rí gbogbo àgbègbè ibẹ̀ kedere, ewéko gbogbo dúdú mirinmirin, àyíká náà sì lẹ́wà gidigidi.
Bí Gómìnà Makinde bá ṣẹ̀ mí, lẹ́tà lásán ló jẹ mí- Aláàfin Ọ̀yọ́ Buhari yóò báwọn ọmọ Nàìjíríà sọ̀rọ̀ lọ́la 'June 12' tí ṣe àyájọ́ ìjọba àwarawa Èèyàn 104 kó covid-19 ní iléeṣẹ́ kan ṣoṣo ní Sagamu- Ìjọba Ogun Wèrè tí mò ń ṣe ní Facebook ló pawó fún mi-Esabod Irinajo igbeyawo ati ifẹ pẹlu MKO Ọmọ ọdun mọkanlelogun lo fẹ Oloye Moshood Abiola.
Nígbàkúùgbà tí mo bá mú kí òjò ṣú ní ojú ọ̀run, tí òṣùmàrè bá sì yọ jáde, 
Bẹẹ ni awọn kan rọ Segun Awosanya lati tun ero rẹ pa nitori awọn ni igbagbọ ninu rẹ, ti awọn ko si fẹ ki o yipada kuro lẹyin awọn.
A o fun lasiko lati da ọrọ yi wo ki a to gbe igbesẹ'' Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 3 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 5 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Ní àkókò kan náà, wọ́n kan àwọn ọlọ́ṣà meji kan mọ́ agbelebu, ọ̀kan ní ọwọ́ ọ̀tún, ọ̀kan ní ọwọ́ òsì rẹ̀.
’ rèé Afọnja, ẹni tó finú wénú ní Ilọrin, àmọ́ tó jẹ iwọ Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Báwo ni ọdọmọkunrin ṣe lè mú kí ọ̀nà rẹ̀ mọ́?
Bakan naa lo fikun un pe ki ijọba lọ awọn eleto aabo labẹle to wa ni ijọba ibilẹ kọọkan lọna ati koju eto aabo to dẹnukọlẹ naa.
Ẹ kò gbọdọ̀ ṣe iṣẹ́ kankan, ẹ níláti ya ọjọ́ ìsinmi sí mímọ́, bí mo ti pa á láṣẹ fún àwọn baba ńlá yín.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Baby abandoned on dunmpsite: Mo ti bímọ mẹ́rin tẹ́lẹ̀ fún bàbá méjì nínú òṣí- Dupe Ogbomos Bakan naa ni Olatunji to ma n kọrin ilẹ Afrika ni Amerika ni awọn ile ijọsin ati fasiti ni awọn agbẹgbẹ ilu Atlanta, ni ilẹ Amẹrika.
Koda, awọn eeyan miran kii ranti jẹun rara ni aarọ.
Ile-ise ologun lorile-ede Egypt so lojo-Aiku pe, awon alakata-kiti elesin Islam merindinlogun, osise ijoba kan ati ologun kan won ti padanu-emi won, lati bi ojo merin ti awon omo-ogun ijoba ti n sigun mo awon alakata-kiti naa ni agbegbe Sinai.
Báyìí, wọ́n a le rí bàtà tà dáadáa síi, nítorípé díẹ̀ náà ni iye àwọn oníbàárà wọ́n tí ẹsẹ̀ ẹ wọ́n ju 10 lọ.
Ṣugbọn àwọn ọmọ Israẹli rìn kọjá lórí ìyàngbẹ ilẹ̀ ninu Òkun Pupa, omi rẹ̀ sì dàbí ògiri ní ẹ̀gbẹ́ ọ̀tún ati ní ẹ̀gbẹ́ òsì wọn.
ohun ni yoo so bi ojo iwaju orile ede yii yoo se ri.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ìtàn ayé Taiwo Oredein rèé, àgbà òṣèlú tó parí ayé rẹ̀ sọ́gbà ẹ̀wọ̀n Ìtàn ìgbé ayé Bode Thomas rèé, ó kọ́ wa láti máa kó ẹnu wa ní ìjánu Ṣo mọ̀ pé J.
Bakannaa ni olori awọn akoroyin ẹka ofurufu nigba kan ri, Chuks Iwelumo sọ fun BBC Yoruba ninu ifọrọwanilẹnuwo pe oun ni igbagbo pe ọrọ naa yoo niyanju ki o to di gbedeke ọjọ keji osu kini ti awọn ọmọ ẹgbẹ naa fẹ bẹrẹ iyanṣelodi.
Èyí yóo sì mú kí aifinipeni ati ibinu pọ̀ sí i.
Wayi o, inu buruku ti bi Erica ninu ile BB Naija to si sọ kobakungbe ọrọ si akẹẹgbẹ rẹ, Laycon, ẹni to se apejuwe bii oburẹwa ẹda.
Akọwé gómìnà Crusoe Osagie lo fìdí ọ̀rọ̀ náà múlẹ̀ fún BBC Sáájú ni Obaseki ti kéde lọ́jọ́ ìsẹ́gun ọjọ́ kẹrindinlógún, oṣù kẹfa ọdún 2020 pé òún yóò kòwé fi ẹgbẹ́ òṣèlú APC silẹ̀ tẹ́lẹ̀.
Obasanjo tun gba igbega si ipo lieutnant colonel lọdun 1967 wọn si fi ṣe adari ẹkun kaakiri orilẹede Naijiria.
Ìjọba Akeredolu kò ní omi àánú lójú, a kò tọ́jú alárùn Coronavirus mọ́ - Dókítá Ondo Ẹ̀yin ẹlẹ́gbẹ́ òkùnkùn tẹ fẹ́ ṣe àjọ̀dún lónìí, lákọ la ń dúró dè yín - Iléeṣẹ́ ọlọ́pàá Bí àwọn adarí ìjọba ṣe ń kó Coronavirus, ń kọ wá lóminú - Ìjọba àpapọ̀ Bí Hushpuppi ṣe tiraka rèé l‘Eko, kí ọlà ‘òjijì’ tó dé Ṣaaju ni Ijọba Kano na ti paṣẹ pe: Ijọba Kano wọgile ayẹyẹ to maa n waye lẹyin irun ọdun Ileya: Ko tan sibẹ o, ijọba ipinlẹ naa tun ti wọgile ayẹyẹ ọdun ileya ọdun 2020 nitori Covid-19.
Olóyè Hannah Ìdòwú Dideolú Awólọ́wọ̀, Iyalode Rẹ́mọ, Yèyé Oòduà relé pẹ̀lú ijó àti ayọ̀
Sọ fún ìlú Tire tí ó wà ní etí òkun, tí ń bá gbogbo àwọn tí wọn ń gbé etí òkun ṣòwò.
 Ni bayii ti a ti ni oludije wa, a ni lati fowosowopo lati ri pe, egbe yii jawe olubori ninu eto idibo ohun.
FUOYE: Fayemi ní ìṣẹ̀lẹ̀ bí àwọn ìrètí ọ̀la náà ṣe kú ba òun nínú jẹ́
wọn kò sì ní ẹ̀rí ọkàn.
ekun won kookan si, awon ise akanse ti won ti gbese, awon eto ti won laa sile
sáájú kí ogun tó bẹ ̀ rẹ ̀ , ilẹ ̀ belgium tí kọ ̀ wé ránṣẹ ́ sí àwọn orílẹ ̀ -èdè tó kù pé tí ogun bá bẹ ̀ rẹ ̀ , àwọn kò ní lọ ́ wọ ́ síi .
Mo bi angẹli náà pé, “Oluwa mi, kí ni ìtumọ̀ ìwọ̀nyí?
Lọjọ Aje, ọjọ Kinni, oṣu Kẹrin ọdun 2019 ni wọn ṣe ifillọlẹ awọn ọmọ igbimọ ẹlẹni mẹwaa kan ti yoo ri si eto igbejọbakalẹ naa.
Eruku ìjà sọ lálá lórí ayelujára láàrin Bíṣọ́ọ́bù méjì àti Daddy Freeze Oríṣun àwòrán, Others Saaju ni ati mu iroyin wa fun yin wi pe ija ṣẹlẹ lori ayelujara laarin pasitọ ijọ meji ati Daddy Freeze.
Mo tẹjú mọ́ ọn láti wo ohun tí ó wà ninu rẹ̀.
Manchester City vs Manchester United: Man United fọ́ Man City lẹ́nu yánkanyànkan mọ́lé
Kọmiṣọna fun ọlọpa ni ipinlẹ Ogun, ọgbẹni Ahmed Iliyasu ti o ṣe afihan afusari apaniyan yi ṣalaye wipe pasitọ naa pa ololufẹ rẹ lati fi ṣe aajo owo gẹgẹbi iwadi wọn ṣe sọ.
Ohun ti ipade  naa da le lori ni lati jiroro nipa ipenija to n dojukọ awọn ile-iṣẹ  eleto aabo  lorile ede yii , paapaa julo lati koju ija pẹlu awon agbesunmọmi
”Jehoṣafati bá dá a lóhùn pé, “Bí ó bá ti yá ọ, ó yá mi.
Awọn ti wọn n se ẹsin yii ko pọ rara.
Àkọlé àwòrán, Sùgbọn nínú ìwádìí BBC a ri pé àwọn tó ń ti òjò ti wọn sì ń sí òjò pọ̀ jántìrẹrẹ ní orílẹ̀-èdè Nàìjíríà.
"O sọ pe ""awọn obinrin ma n ṣe e, amọ wọn kii ṣaba sọrọ nipa rẹ""."
Mo rìn káàkiri àwọn ìsọ̀ aláṣọ kọ̀ọ̀kan.
Xenophobia: Abala kíní àwọn ọmọ Nàìjíríà yóò padà wálé láti South Africa lọ́jọ́rú
 Àkọ ́ lé àwọn eré tí wọ ́ n máa ń gbé jáde nínú fíìmù máa ń ní ìtumọ ̀ , ó sì máa ń pe èrò sọ ́ kàn òǹwòran .
Nisinsinyii, mo ti di ẹni ọdún marundinlaadọrun, 
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù World Isese Day: Àwọn oníṣẹ̀ṣe ṣàlàyé pàtàkì ọdún ìṣẹ̀ṣe àti ìdí tí ìjọba fi gbọdọ̀ kéde ìsinmi lẹ́nu iṣẹ́ bí àwọn ọdún ẹ̀sìn míràn 25 Ògún 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 20 Ògún 2020 Oríṣun àwòrán, Alaafin oyo Ogunjọ oṣu kẹjọ ọdun ni awọn ẹlẹsin abalaye ya sọtọ fun ayajọ ọdun iṣẹṣe lati ṣajọyọ ẹsin abalaye lagbaye.
Wọn ni awọn eni naa ko nkan bii amohunmaworan, ohun eelo igbohunjade, awọn ẹya ara ọkọ ti wọn ko jona tan ati awọn nkan miran nile ijọsin Miracle Center.
Ìpàdé náà la gbọ́ pé ó jẹ́ àkọ́kọ́ tí Olúwó ti ìlú Iwò, Oba Abdulrasheed Akanbi, yóò báwọn ṣe lati ìgbà tó ti gun orí oyé ni ọdún 2015.
    Bí a ti padà dé Àjùlé ọ̀run tí a ṣí fìlà àìrí orí wa, tí ìyá Adéforítì wá tí Adéforítì ń jíṣẹ́ fún un, ni ọkùnrin arẹwà aláṣọ funfun kan wọlé, àṣé ìránṣẹ́ Olódùmarè ni bí ó ti wọlé ni a ri i tí ó ba adéforítì sọ̀rọ̀ ní èdè tí àwa kò gbọ́, àfi ìgbà tí ó sì máa jáde tí ó ju ọwọ́ sí apá kan báyìí tí a déédéé wo ibi tí ó ju ọwọ́ sí tí a rí ogunlọ́gọ̀ ohun èlò iṣẹ́.
Ẹni tí ń dárí ji ni ń wá ìfẹ́,ẹni tí ń tẹnu mọ́ ọ̀rọ̀ a máa ya ọ̀rẹ́ nípá.
Nítorí náà, wọ́n lọ sọ fún Hamani, wọ́n fẹ́ mọ̀ bóyá ohun tí Modekai sọ ni yóo ṣẹ, nítorí ó sọ fún wọn pé Juu ni òun.
A bá sọ ìrètí nù pé a tún lè là mọ́.
 E yẹ fun atileyin awon eniyan yin lati tesiwaju.
Ọna kan to ti ṣe bi awọn alatako rẹ, Sanders ati Warren, ni lori ọrọ ayika ati ayipada oju ọjọ - boya nitori a ti ri ibo lati ọdọ awọn ọdọ ti ọrọ naa jẹ logun, lai bikita fun pipadanu ibo ni awọn ipinlẹ ti ileeṣẹ pọ si.
Ọjọ kẹtala oṣu karun un ọdun 2018 ni Wunmi ṣe igbeyawo pẹlu ọkọ rẹ to fi oke okun ṣe ibugbe.
''A ko le fọwọ leran ki a jẹki ohun ti ko f'ogo fun Ọlọrun, to si tun le ṣakoba fun ọjọ iwaju ṣẹlẹ nipinlẹ Enugu,'' alaga ajọ PFN Bisọbu Godwin Madu, lo woye bẹẹ.
Omi odò Naili yóo gbẹ,yóo gbẹ, àgbẹkanlẹ̀.
Láti inú ẹ̀yà Aṣeri, a yan Ahihudu ọmọ Ṣelomi.
Èmi OLUWA yóo pàṣẹ pé kí ibukun mi wà lórí yín ní ọdún kẹfa tóbẹ́ẹ̀ tí ó fi jẹ́ pé ilẹ̀ yóo so èso tí yóo to yín jẹ fún ọdún mẹta.
Bẹ́ẹ̀ ni Ọlọ́run Ọba ti fi àwọnobìnrin méje wọn-ọnnì gégùn-ún nítorí pé wọn kò náání Ẹni tí ó dá wọn.
fun awon akoroyin ati awon omo orile ede yii lati jawọ nipa gbigbe asọ iyi wọ
ara rẹ̀ ń dán fún sísanra,ara sì tù ú dé mùdùnmúdùn.
Àbà ètò ìṣúná 2020 tó kéré yóò mú kí ètò ààbò mẹ́hẹ síi ní Nàìjíríà-Onwoye Buhari ti fòfin de àwọn mínísítà láti rìnrìn àjò lọ sí ilẹ̀ òkèrè Ìdẹ̀ra dé l'Eko!
Ọgagun Dambazau tọka rẹ wipe ohun gan an to n se okunfa bi awọn ọdọ wọnyii se n gba lati kuro ni ilẹ baba wọn lọ si irinajo si inu ẹru lo yẹ ki tolori tẹlẹmu o yẹ wo.
O si fi to awọn eeyan leti wipe ilera pipe ni iya ati ọmọ wa.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù #EndSars Lagos Judicial Panel: Iléeṣẹ́ ológun ní òtítọ́ làwọn sọ́jà gbé ìbọn tó lọ́ta gidi nínú lọ sí Lekki Toll Gate 14 Bélú 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 22 Bélú 2020 Oríṣun àwòrán, Twitter/Nigerian Army Ileeṣẹ ologun oriilẹ ti sọ pe awọn sọja gba ibọn to ni ọta to le ṣekupa eeyan lọ si Lekki Toll Gate nibi tawọn oluwọde EndSARS ti n ṣe ifẹhonuhan ogunjọ oṣu kẹwaa ọdun 2020.
Bianca júwe ilé fún Serena Williams nínú ìdíje l'America Ohun to jẹ iyalẹnu ni pe awọn to kopa fun Norwhich kọ ni ojulowo awn agbabọọlu wọn nitori pe awn wn yẹn farapa.
Ṣugbọn ẹnikẹ́ni tí ó bá pàdánù ẹ̀mí rẹ̀ nítorí mi ati nítorí ìyìn rere, yóo gba ẹ̀mí rẹ̀ là.
Ronaldo darapọmọ Manchester United lati ẹgbẹ Sporting Lisbon fun miliọnu mejila poun o le die lọdun 2003.
Èèyàn 789 gbèkuru jẹ lọ́wọ́ ẹbọra nítorí COVID-19 ní Nàìjíríà Ènìyàn 653 míràn tún kún iye àwọn tó ní COVID-19 ní Nàìjíríà Ǹjẹ o yẹ kí èèyàn máa sùn lẹ́nu iṣẹ́?
Àwọn òlóṣèlú oníwàìbàjẹ́ ò yéé hùwà wọn.
Adari ileeṣẹ ẹgbẹ awọn oṣiṣẹ NLC ni ipinlẹ Eko, Onyeka Chris lọ sọ bẹẹ fun BBC News Yoruba lasiko to n sọrọ lori igbaradi wọn fun ifẹhọnuhan ọlọgọọrọ naa.
Bi a ko ba gbagbe iru ina bayi sọ ni ọọfisi ajọ to n mojuto ere bọọlu lorile-ede Naijiria, NFF lọdun 2014.
Awọn kan a máa mọọmọ je ounjẹ ti suga pọ ninu rẹ nigba ti awọn miran kò sí ni mọ pe awọn ti tẹri sinu rẹ.
bí ọ ̀ pọ ̀ ènìyàn bá n gbé papọ ̀ , ó rọrùn lati jọ parapọ ̀ dojú kọ ogun tàbí ọ ̀ tẹ ́ tí ó bá fẹ ́ wá láti ibikíbi .
pé kí wọ́n lọ mú Ayaba Faṣiti wá siwaju òun, pẹlu adé lórí rẹ̀, láti fi ẹwà rẹ̀ han gbogbo àwọn eniyan ati àwọn olórí, nítorí pé ó jẹ́ arẹwà obinrin.
Ninu fidio ati awọn aworan ti aarẹ ẹgbẹ naa fi sita ti o kọ akọle si pe ipade idanilẹkọ naa jẹ aṣeyọri.
Ọlọrun náà kò sì jẹ́ fi nǹkan burúkú dán ẹnikẹ́ni wò.
Yóo máa wá ọ̀nà ti yóo fi gba àwọn ìlú olódi; ṣugbọn fún ìgbà díẹ̀ ni.
Tori eyi, eeyan miliọnu meji ninu eyi ti ẹgbẹrun lọna ẹẹdẹgbẹta ara orilẹede Belarus pọ ju lo n gbe ni awọn agbegbe to lewu.
Ọkunrin náà dáhùn pé, “Rárá, mo wá gẹ́gẹ́ bíi balogun àwọn ọmọ ogun OLUWA ni.
''Eyitayo Jegede naa ko i tii ṣetan lati sọrọ lori esi idibo naa, ti asiko ba to, yoo sọrọ'' Ololufẹ Eyitayọ Jegede miran to sọrọ ni oun ko tun ṣe oṣelu mọ lẹyin bi Eyitayọ Jegede ṣe fidirẹmi.
Baba Sala jáde láyé, ni nnkan bi ago mẹwa alẹ ọjọ aiku .
 Ti ọsẹ meji ba pe, ti ko si si aṣeyọri kankan, awọn ọmọ Naijiria ko ni da wa loun mọ, ti a ba pe wọn fun iyanṣẹlodi tabi ifẹhọnu han.
Josẹfu bá dá wọn lóhùn pé, “Bí kò bá sí owó lọ́wọ́ yín mọ́, ẹ kó àwọn ẹran ọ̀sìn yín wá, n óo sì fun yín ní oúnjẹ dípò wọn.
Layajọ iya tabi Baba ti a mọ si Father's Day ati Mother's Day, Hushpuppi kii kọ nkankan nipa awọn obi rẹ debi ti awọn eeyan yoo fi le sọ pe, bi awọn obi rẹ ti se ri ree tabi nibi ni wọn n gbe.
Toyin,Ọmọ ọdun mọkandinlogun ajafẹtọmọniyan ọmọ Naijiria ọhun to fi ilẹ Amẹrika se ibugbe bawọn se iwọde Black Lives Matter to waye ni Florida ni Amẹrika.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Murder In Ibarapa: Aborode tó tún jẹ́ olóṣèlú kàgbákò ikú òjijì lọ́nà oko 12 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 14 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Oríṣun àwòrán, Facebook/Fatai Aborode Agbébọn tún gbẹ̀mí àgbẹ̀ míì lọ́nà oko lágbègbè Ibarapa Awọn agbebọn ṣekupa oludije fun ile igbimọ aṣojo-ṣofin agba l'Abuja nigba kan ri labẹ asai ẹgbẹ oṣelu Accord, Ọmọwe Fatai Aborode Ọmọwe Aborode to jẹ oludari ileeṣẹ Kunfayakun Green Treasures Ltd ni a gbọ pe awọn afurasi ti irisi wọn jọ tawọn Fulani darandaran yinbọn pa lẹba oko rẹ, lọna ilu Apodun ni Igangan, ijọba ibilẹ Ariwa Ibarapa.
Ọpọ igba ni awọn eeyan maa n sọ pe awọn ọmọ Oodua kan nilẹ okeere maa n ba oju iran Yoruba jẹ.
Igbimọ Alakoso Agbeyewọ Isuna Owo Ilu yii ati bi wọn ṣe ṣeto awọn ọmọ
Adájọ́ fún Dino Melaye ni beeli N100,000 Dino Melaye f'oju ba'le ẹjọ Dino ni akin ni oun, ati pe, oun mọ asiko ti o yẹ oun ti oun ba fẹ du ipo aarẹ.
Agbẹnusọ ilé ẹjọ́, Sharia ní ìpińlẹ̀ Kano, ni ilé ẹjọ́ náà ri pé lẹ́yìn gbogbo ẹ̀ri to wà níwájú rẹ̀, ọkùnrin náà jẹ̀bi ẹ̀sùn ti wọ́n fi kàn.
N óo dáàbò bo ìlú yìí, n óo sì gbà á sílẹ̀ nítorí tèmi ati nítorí Dafidi iranṣẹ mi.
Ìtàn Mánigbàgbé: Ọ̀rẹ́ àjèjì ló kóbá Afọnja, tí Ilọrin fi bọ́ lọ́wọ́ Yorùbá
"Arike Abiodun Best lo sọrọ pe: ""Ti mo ba ku loni, ti o ko si gbe aworan mi soju opo ayelujara rẹ ri tẹlẹ , paapa lajọ ibi mi, ma wulẹ sopo gbe aworan mi lẹyin ti mo ba ku tan nitori maa ri ninu saare mi, ti maa si di igbaju olooyi lu ọ lati inu saare mi."
Nígbà náà ni àwọn ọmọ Israẹli kọ orin yìí pe:“Ẹ sun omi jáde, ẹ̀yin kànga!
Láì lo Kakulétọ̀, mo ní ọpọlọ ìṣirò, tábìlì ìṣirò wà lórí mi - Human Calculator Eré apanilẹ́rìn ké kè ké lórí ayélujára ti ṣí ọ̀pọ̀ ìlẹ̀kùn fún mi - Mr Macaroni Chatta bímọ tuntun, Mide àti Osupa lẹ̀pọ̀, Sanwo-Olu fún Sola Sobowale lámì ẹ̀yẹ Osinbajo wọ́gilé ìrìn-àjò rẹ̀ lẹ́yìn tí ọ̀kan lára ẹ̀ṣọ́ rẹ̀ kú nínú ìjàmbá ọkọ̀ Okúnrin náà fi kún pé, àti ọkọ̀ ofurufu, àti reluwe ni wọn ti tì pà, káràkáta náà ti dẹnu kọlẹ, ko si si ẹni to le wọle láti ilẹ̀ okere rara, konile o gbéle ni gbogbo ènìyàn wà.
Labe ise akanse iranlowo lori ise ti a mo si Government Enterprise Empowerment Programme, o le ni egberun lona oodunrun ti won je anfaani eto eyawo yi,ni awon egbejegbe won ni awon ipinle merindinlogoji ati ni ilu Abuja , nigba ti awon ipele miran ti yo to egberun lona irinwo yo tun je anfaani ti.
O tun tesiwaju pe “Gege bi e se ri I, iwa odaran yii si n tesiwaju, koda, ko si enikan ti o lee fura nipa  ohun ti won se yii.
 Wọn ti gbe ọkunrin naa lọ ile iwosan, awọn agbofinro si ti pari aawọ ọhun.
Ni bayii, ijoba ile Syria ti setan lati fopin si ikolu ti o ye ko tun waye lolu ilu orlle-ede ohun, Damascus.
Ó ní ọ̀pọ̀lọpọ̀ ọrọ̀ ìṣẹ̀dá abẹ̀mí àti ewéko tí ó jẹ́ ohun ìsayéró fún ẹgbẹẹgbẹ̀rún àgbẹ̀ àti apẹja.
Bi o si ti n ṣe eyi naa lo n ranti igba ewe rẹ.
OLUWA wí nípa Kalidea pé:“Jókòó kí o dákẹ́ jẹ́ẹ́, kí o sì wọ inú òkùnkùn lọ,ìwọ ọmọbinrin Kalidea.
Bí ẹsẹ̀ bá sọ pé, “Èmi kì í ṣe ọwọ́, nítorí náà èmi kò sí ninu ara,” èyí kò wí pé kì í tún ṣe ẹ̀yà ara mọ́.
Wọ́n fi okùn sọ Jeremaya kalẹ̀ sinu kànga náà, kò sí omi ninu rẹ̀, àfi ẹrẹ̀ nìkan, Jeremaya sì rì sinu ẹrẹ̀ náà.
Lasiko to n ba BBC sọrọ, Ọmọ Abacha ni eniyan daadaa ni Baba oun, to fẹ ki ohun gbogbo lọ bo ṣe yẹ kori.
Ìrẹ̀wẹ̀sì ń bá wa torí ìdánwò NECO tẹ ń ṣún síwájú lọ́pọ̀ ìgbà - Akẹ́kọ̀ọ́, ọ̀gá iléèwé Wo àwọn orílẹ̀èdè míràn tó ń fojú winá ìwọ́de bíi ti ENDSARS Ọ̀rọ̀ ajé dẹnu kọ̀lẹ̀ yíká Nàíjíríà, àkẹ́kọ̀ọ́, olókoòwò àti òṣìṣẹ́ ọba jókòó sílé Ọlọ́pàá fi afẹ́fẹ́ gáàsì tú àwọn olùwọ̀de #EndSARS ká ní Abuja O wa rọ awọn obi ati alagbatọ lati mojuto awọn ọmọ wọn ki wọn maa baa di ohun elo fawọn to lee fẹ sa asawọ wọ inu iwọde naa lati sọọ di ọna ati da rugudu silẹ lawujọ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Kunle Afolayan: èmi kò fẹ́ fi ogún sílẹ̀ fún ọmọ mi Arabinrin Boade Akinola to jẹ oludari eto ifitonileti fun ileeṣẹ ijọba apapọ to n mojuto eto ilera ni Abuja lo fidi ọrọ yii mulẹ.
Ní oṣù kẹfa, Ọlọrun rán angẹli Geburẹli lọ sí ìlú kan ní Galili tí wọn ń pè ní Nasarẹti.
Iroyin tún sọ pé àwọn ọmọ orileede Uganda miran ti ko tilè rìn ìrìn-àjò kúrò ní Uganda farakasa aisan naa.
Nibayii, orilẹede Amerika ni awọn faramọ abajade tuntun yii pẹlu igbagbọ pe, otitọ ni wi pe Akinwunmi Adesina ko jẹbi ẹsun iwa ibajẹ ati magomago ti wọn fi kan an.
Bi eeyan ba si rin jina, yoo ri abuke ọkẹrẹ.
Nigeria 2019 Elections: Ọkọ àti ìyàwó sọ àsọtẹ́lẹ̀ tani yóò wọlé nínú PDP tàbí APC
"Nigba ti BBC beere lọwọ Ayalogu pe bawo wa ni awọn eniyan ṣe n ri tomato alagolo ti wọn ko ṣe l'orilẹede Naijiria ra ni ọja, o sọ pe ""mi o ni idahun kankan fun ibeere yii, amọ o ṣeeṣe ki wọn o ti wa ni ọja ka to o fi ofin de e."
Wọ́n bi í pé, “Obinrin, kí ló dé tí ò ń sunkún?
O ni eleyii yoo mu ki awọn basejẹ ti o ku so ewe agbejẹ mọwọ.
Nigba ti wọn kuro nibẹ ni aago marun abọ idaji, wọn fi ẹsun kan wọn pe, wọn gbe ọkọ takisi naa, wọn si i wa a lọ si ile itura wọn laisi awakọ naa nibẹ.
Lara awọn awakọ to n gba ọna ibode naa kọja ni inu awọn ko dun ki awọn maa san owo ki awọn si tun maa jiya sunkẹrẹ fakẹrẹ ọkọ.
Èyí ni ìlànà ẹbọ sísun ti ìbẹ̀rẹ̀ oṣù.
Nígbà náà ni Jesu wá wí fún wọn pàtó pé, “Lasaru ti kú.
Ohun mẹ́wàá tó yẹ kóo mọ̀ nípa Kunle Afod Wo àdẹ́hùn méje tí Buhari ṣe pẹ̀lú ilẹ̀ Russia Kí ni àwọn olórí Áfíríkà ń wá lọ sí Russia?
Alufa Foluke Adeboye to jẹ aya alakoso ijọ Redeem lo gba awọn ọdọ l'Ọjọbọ pe, oniwaasu ijọ wọn lọ yẹ ki wọn kọkọ ri fun imọran nigbati wọn ba n mura lati gbeyawo ki wọn to sọ fun obi wọn.
ìbànújẹ́ ń já lura wọn,ìdààmú sì ń dà gììrì,wọ́n bò mí mọ́lẹ̀ bí ìgbì omi òkun.
Nínú èsì tí rè, Ọgbẹni Kola Bankole to je onimo nipa eto inawo so pe òun tó dáa ní kí ìjọba san owó ní kété ti oṣù bá parí fún àwọn oṣiṣẹ ṣugbọn ọ ti ya ju bi Fáyẹmí ti ṣe n ṣé ìlérí yí.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Gọngọ á sọ láàrín Lewandowski àti Ronaldo Ìdààmú Sẹ́nétọ̀ Dino Melaye Siasia kọ̀wè fún ipò akọ́nimọ̀ọ́gbá Cameroon Àjànàkú nipò adarí rere, ó kúrò lẹ́rù ọmọdé Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 3 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 5 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Biotilẹjẹpe ero awọn ọmọ Naijiria se ọtọọtọ, bi asọ naa se jọ eyi ti ikọ Golden Eagles wọ nibi ifarahan wọn akọkọlasiko ipolongo fun idije ife ẹyẹ agbayelorilẹede Amẹrika lọdun 1994, lo seese ko mu ki awọn ololufẹ Super Eagles mase kọbi ara sii.
Jerusalẹmu, ìlú ńlá tí a kọ́,tí gbogbo rẹ̀ já pọ̀ di ọ̀kan.
Ẹ óo ṣe ọdún Àjọ̀dún Ìrékọjá náà gẹ́gẹ́ bí òfin ati ìlànà rẹ̀.
Ó sọ ọ́ ní Seti, ó ní: “Ọlọrun tún fún mi ní ọmọ mìíràn dípò Abeli tí Kaini pa.
A si ti fọwọsowọpọ pẹlu awọn miiran lati ri pe a wu aisan ki eniyan ma ni ominira lati fi ero rẹ han, ki a si fi igba tuntun han gbogbo aye.
Bi awọn oloselu ṣe n ko owo ilu mi, ni wọn n jẹ aye familete ki n tutọ, ti iwa ibajẹ lorisirisi si gogo laarin ọmọ Naijiria pẹlu, ti orilẹ-ede Naijiria si ti wọnu gbese ati ọrọ aje to dẹnu kọlẹ, ti gbogbo ọjà si gbe owo lori.
Ajimobi Burial: Ẹbí Abiola Ajimobi kéde bí ètò ìsìnkú rẹ̀ yóò ṣe rí pé.
Ẹ óo máa rú ẹbọ yìí pẹlu ẹbọ ohun jíjẹ ati ẹbọ ohun mímu rẹ̀, gẹ́gẹ́ bíi ìlànà ti ọjọ́ kinni; 
Olùdíje lábẹ́ ẹgbẹ́ PDP, Ademọla Adeleke ló jáwé olúborí nínú ètò ìdìbò tó kọ́kọ́ wáyé.
Okanojọkan egungun lo wọ aṣọ alarambara lọ si ojude ọba lati ṣoju agbo ile wọn, bẹẹ ṣi ni gbogbo igboro ilu Iwo lo kun fọfọ fun ọgọrọ awọn eeyan to lọ fun oju lounjẹ.
“Ipele keta ninu idije yii la wayii, o da mi loju pe, bi iko Falconets ba le fara si ifesewonse yii, o seese ki a fagbahan Spain,’’.
Awọn olugbe ilu Jabiya nipinlẹ̀ Katsina, ṣi n ka ofo wọn lori iṣẹlẹ omiyale to waye nibẹ.
Oríṣun àwòrán, EPA Àkọlé àwòrán, Ẹwọn ọdun marun ni wọn fun gbajugbaja oniroyin alaworan kan ti orukọ rẹ njẹ Mahmoud Abu Zeid.
Awon alamojuto abo ri fonran naa gege-bi eyi ti o tabuku omoluabi, tabuku asa ati ise orile-ede Tanzania ati ofin lori ero alatagba.
Akoko ati igbeaye le ṣe idiwọ fun aṣẹ ti ara ba pa a.
Orí yìí ni a ti mọ ìdí tí Ọ̀sanyìnnínbí fi fẹ́ràn Orímóògùnjẹ́.
Ṣugbọn beeyan ba gbojule gbogbo asọtẹlẹ to ti kuna yii, koko idahun si ibeere ni wi pe ko sẹni to mọ igba ati bi aye yoo ṣe wa sopin?
Ẹyẹ ju ẹyẹ lọ, Super Eagles fi àmì ayò kan gbé ẹyẹ Swallow ti Burundi mì Ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ parí, Germany di ẹrù ìyà aláwẹ́ mẹ́ta lé Najiria lórí Cameroon nikan ni ikọ orileede Afrika to ṣẹku ninu idije naa amọ bayi,wọn ti darapọ mọ orileede Naijiria lati ko ẹru wọn pada wa sile.
“Ẹ dù láti gba ẹnu ọ̀nà tí ó há wọlé, nítorí mò ń sọ fun yín pé ọpọlọpọ ni ó ń wá ọ̀nà láti wọlé ṣugbọn wọn kò lè wọlé.
Láti ìgbà ti ọ̀rọ̀ yìí ti jẹ jáde ni ọ̀ṣẹ̀ to kọjá ni àwọn ọmọ Naijiria ti dìde láti gbárùkù ti obìnrin náà àti àwọn ọmọ rẹ̀.
Ajo EU ohun so pe, gbogbo awon odomode ni won ni eto si eto-eko, ni eyi ti won seleri ati fowosowopo pelu ijoba orile-ede Naijiria, lati le se aseyori ninu erongba won ohun.
Nígbà ayé Absalomu, ó ṣe ọ̀wọ̀n ìrántí kan fún ara rẹ̀ ní àfonífojì ọba, nítorí kò ní ọmọkunrin kankan tí ó le gbé orúkọ rẹ̀ ró.
Awọn ile itaja nla nla yatọ fun ti Naijiria lo n kopa ida to fẹrẹẹ to mejila ninu itaja ọlọwọọwọ eyi ti ere wọn si ti n ja walẹ lati ọdun 2018.
Bakan naa, Bukola Saraki to jẹ aarẹ ile igbimọ aṣofin nigba naa ni ki wọn ni ki wọn kọkọ gbe abadofin ọhun ti na ki ijọba fi ṣe awọn atunṣe kan ki wọn wa gbe e pada wa ṣugbọn eleyi ko ṣẹlẹ titi ti saa wọn fi pari.
Ta ni ò ń ṣíjú wò pẹlu ìgbéraga?
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Àwọn ọkùnrin sọ èrò wọn lórí àríyànjiyàn ẹni tó ni ọyàn obìnrin láàrin bàbá àti ọmọ.
Asiko ọdun wa fun Oṣun Oṣogbo, ọdun Sango ni Oyo, ọdun Obalufọn, Olọjọ, Olóro ati bẹẹ bẹẹ lọ kaakiri ilẹ Oodua lo tun n ṣafihan asa ẹsin abalaye wa.
Nígbà tí wọ́n wà ní ilé Mika, wọ́n ṣàkíyèsí bí ọdọmọkunrin tí ó wà ní ilé Mika ṣe ń sọ̀rọ̀, wọ́n sì mọ̀ pé ọmọ Lefi ni.
Ọjọ ẹti ni Ọgagun, Brigade Commander, Zakari Abubakar fi aridaju kan pe wọn ti fi ọwọ ofin mu awọn sja to ṣiṣẹ laabi ọhun wọn si ti bẹrẹ iwadii lori ẹsun naa.
 nígbàtí májẹ ̀ mú títun n ṣe àmúşę ohun tí màjèmú làìlàì sọ .
Shehu salaye pe, igbesẹ Obasanjo ko ya Aarẹ Buhari lẹnu, nitori o fi han gbangba pe, oye nipa eto oṣelu ode oni ko ye e.
Ọpẹ́ ni fỌlọrun, nítorí pé ẹ̀yin tí ẹ̀ ń ṣẹrú ẹ̀ṣẹ̀ tẹ́lẹ̀ rí, ti wá ń fi tọkàntọkàn gba irú ẹ̀kọ́ tí a gbé kalẹ̀ níwájú yín.
Àwọn ará Iṣimaeli mú Josẹfu lọ sí Ijipti, wọ́n sì tà á fún Pọtifari ará Ijipti.
Ó ṣe agbada omi mẹ́wàá ati ìtẹ́dìí kọ̀ọ̀kan fún wọn.
Ìjọba Giriki ni òbúkọ onírun jákujàku tí o rí.
Ní ọjọ́ náà gan-an ni Abrahamu ati Iṣimaeli ọmọ rẹ̀ kọlà abẹ́, 
Aminat Abọdun: Ọ̀pọ̀ èèyàn se ẹ̀yẹ ìkẹyìn fún akọni obìnrin tó lọ
Ṣugbọn Wilder si gbagbọ pe oun si le ba Fury ja ki ọdun 2020 to pari bo tilẹ jẹ pe ko tii gbadun ọwọ rẹ tan.
Ọ̀kan nínú àwọn abúlé náà ni Youlegrave.
murtala mohammed yo òpòlopò àwon ògá ise ijoba tí ó ti wà níbè láti ìgbà ìjoba gowon .
Ẹmẹẹta ni wọn kede pe iwa idẹyẹsi yi n ṣe akoba fun ifẹsẹwọnsẹ naa.
O si jẹ ọmọ ilu Abeokuta, nipinlẹ Ogun.
Nítorí náà ayọ̀ mi yìí di ayọ̀ kíkún.
A kò ṣe ọgbà àjàrà, tabi kí á dá oko, tabi kí á gbin ohun ọ̀gbìn.
O ka iwe nilẹ yii bii ile iwe alakọbẹrẹ niluu Abeokuta ati Girama ni Abeokuta ko to lọ si Government College, Ibadan ko to mori le oke okun fun ile iwe giga fasiti University College and University of Leeds, England.
Akori ipade apero ti odun 2019
Lorii pe o lee jẹ bi ipolongo fun ẹgbẹ to wa lori alefa, Kayode ni ko lee ri bẹẹ nitori wipe ati ẹgbẹ to wa lori alefa ati awọn ẹgbẹ oṣelu to ku ni yoo jẹ anfani rẹ.
Kọmiṣọna ọhun sọ pe ijọba paṣẹ ofin gbele ẹ laarin aago meje alẹ si meje owurọ nitori awọn onifaaji to n gbafẹ lawọn agbegbe kan nilu Akure.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Mí ò ya wèrè, mí ò burú, ọ̀nà àtijẹ là ń wá' Black Panther Fiimu yii jẹ akọkọ fun ọpọlọpọ idiyele ni gbogbo agbaye.
ile iṣẹ ọlọpaa Naijiria lo bẹrẹ ipẹjọ yii lori sẹnetọ to n ṣoju ẹkun ariwa ipinlẹ Adamawa lẹyin ti fọnran kan jade to safihan bi o ti n lu obinrin kan ni ile itaja nkan iṣere ibalopọ lAbuja.
Èmi yóo fun yín ní ìsinmi.
Ifẹ̀họ̀núhàn ń lọ lọ́wọ́ ní Belarus lẹ́yìn tí ìdìbò tùn gbé Ààrẹ̀ Lukashenko tó ti wà nípò fún ọdún 26 wọlé Àjọ JAMB kéde ìlànà ìgbà ni wọlé tuntun fún àwọn ilé ẹ̀kọ́ gíga Oríṣun àwòrán, @AbujapeopleO Katsina: Àwọn agbébọn gbẹ̀mí àgbẹ̀ márùndínlógún ní Katsina Ileeṣẹ ọlọpaa ariwa-iwọ oorun Naijiria ti sọ pe awọn agbebọn ti pa awọn agbẹ marundinlogun labule kan ni ipinlẹ Katsina.
Imọran deede nipa agbara ojo: Ehi ni ọpọlọpọ igba ni iroyin ti fi han bi awọn ọmọ ile iwe ṣe ba agbara ojo lọ nigba ti wọn ba n bọ nile iwe.
Ọna abayọ ni lati lọ si ile iwosan lati igba de igba fun itọju to peye Idide pajawiri lori ibusun: Bi a ṣe n dide lori ibusun sé koko si ilera ara eniyan.
Ọkan lara awọn olugbe agbegbe naa, ti o ni ki a fi orukọ bo oun laṣiri ṣe alaye wi pe, igba mẹfa ọtọọtọ ni awọn ọmọ onilẹ ti lọ gba aṣẹ ile ẹjọ lati gbẹsẹ le awọn ilẹ ti awọn eeyan ti kọle si lori, ni agbegbe Soka.
Ayeye olodoodun ti Africa Magic Viewers Choice Awards AMVCA to wa fun awon osere, onkorin ati gbogbo awon to n sise idanilaraya ti ero iworan n wo waye ni ilu Eko lorile ede Naijiria ni ile itura Eko Hotel and Suites.
Ìbẹ̀rẹ̀ ìjà dàbí kí eniyan ya odò tí wọn sé,dá a dúró kí ó tó di ńlá.
Ọba Etteidung Ebong dúpẹ lọ́wọ́ àwọn adájọ́ tó si ni ìgbàgbọ́ òun nínú ètò ìdája Nàìjíríà túbọ̀ ru sókè síi ni, o fí kun pé, òjú òun ri tó lásìkò tí ẹja náà ń lọ lọ́wọ́ lọ́wọ́ olùjẹ́jọ́.
Àwọn ará Filistia pada, wọ́n tún dúró sí àfonífojì Refaimu.
Arakunrin ohun, Fehmi Lassoued ati orebinrin re Anabel Salipada ni won mu nile re ti ko jina si U.
''Òsìsẹ́ Custom tó déédé sọ ara rẹ̀ di Ọ̀gá Àgbà CG ní ìdàmú ọpọlọ'' Iṣẹ́ bọ́ lọ́wọ́ ọ̀gá ilé iṣẹ́ tó bẹ́nu àtẹ̀ lu Obinrin Iṣẹ iwadii ti wọn ṣe lori ile to wo naa fihan pe ile naa ti la ni awọn ibi kan tẹlẹ ni eyi ti ọgbẹni Ayilara to nii ko tete ṣatunṣe to yẹ si.
"Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ọlọ́pàá sálọ fún aráàlú l‘Okeho, nígbà tí wọn yari láti ṣun olè méjì tó kù Kí ìjọ mi ní Sagamu le gbòòrò ni mo fi ń ṣiṣẹ́ ajínigbé pawó - Pásítọ̀ Àwa àti fijilanté pẹ̀lú ọdẹ́ ìbílẹ̀ ló dojú kọ adigunjalè ní First Bank Okeho - Iléeṣẹ́ ọlọ́pàá Ìtàn ọba Yorùbá tí wọn yẹgi fún torí ó jí ọmọ gbé ṣe ètùtù Ẹ káàbọ̀ sọ́jọ́ Arafat, tí Ọlọ́run yóò fi ààwẹ̀ Mùsùlùmí pa ẹ̀ṣẹ̀ wọn rẹ́ ""Ọmọ mi kò tíì mọ̀ pé òun ti di ìlúmọ̀ọ́ká, ó ń wádìí bó ṣe ń rí ara rẹ̀ lórí ayélujára"" Boko Haram da ìbọn bo ọkọ̀ gómìnà Borno, ẹ̀ṣọ́ àláàbò rẹ̀ farapa Nigba to n kede eyi loju opo Instagram rẹ, Ayefele ni inu oun dun pe iya ọmọde naa ti 'Calm Down' bayii, ti oun si n ke si ẹnikẹni to ba mọ nọmba obi ọmọde naa, lati fi ransẹ si oun."
Isẹ̀ ọnà 'Aztec-style' ti wọn se si ara aṣọ naa mu ko rẹwa pupọ.
    Ewé-ẹ̀yẹ tí o tilẹ̀ jẹ́ olóògùn dáadáa kò kú sí odò Ẹ̀jẹ̀.
Orílẹ̀-èdè tí ó lágbára, tíí sìí máa ń ṣẹgun ọ̀tá,àwọn tí odò la ilẹ̀ wọn kọjá.
Ikọ D'Tigress yoo koju orilẹede Greece bayii ni iplele kọmẹsẹọyọ ẹlẹni mẹjọ(quarter finals).
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ọmọ Yorùbá ni onímọ̀ ẹ̀rọ ‘Rọ́bọ́tì’ tó ń gbowó jùlọ ní UK Àṣìlò òògùn burú, ṣùgbọ́n ṣé ẹ̀bi ará ìlú nìkan ni?
Akẹkọ ọgbọn pere lo lee wa ninu kilaasi kan naa ni ẹka awọn wẹwẹ ni girama onipele ikeji.
Emmanuel Macron di aarẹ ilẹ Faranse ni ọmọ ọdun mọkandinlegoji (39) gẹgẹbi aarẹ to kereju lati di aarẹ orilẹede naa.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ole wọ gàu!
Sharia ni ilana ofin awọn musulumi to n tẹle aṣẹ́ lati inu iwe mimọ al Quran ati ọrọ Anabi Muhammad ti wọn n pe ni Hadith.
Esi ti maa gbọ ni pe mo ti ni aarun AIDS.
Gbogbo wọn bá sọ àpò wọn kalẹ̀, wọ́n tú wọn.
INEC , ogbeni  Kizito Sunday,lo kede abajade
Ikọ ọmọogun Naijiria ni, awọn ti wọn sagbako ado iku naa n sa asala fun ẹmi wọn, lẹyin ti ikọ Lafia Dole da ina bo wọn ni agbeegbe Jakana-Mainok ni ipinlẹ Borno, ti wọn sa pamọ si.
Gbogbo ile lo tẹwọgba aba naa ti aṣofin Umar Sarki to gbe e wa pe akori rẹ ni ''Kepe ile iṣẹ ijọba to n ri si ọrọ ilera lati wa ọna ati dẹkun aarun arunmọleegun ni Naijiria.
Gẹgẹ́ bi o ṣe wa ninu ofin, kikede dukia pọn dandan ṣaaju eto ibura wọle rẹ eyi ti yoo waye lonii ọjọ kọkandinlọgbọn oṣu karun.
Awọn mejeeji gbiyanju ọrọ aje wa si Amẹrika ni.
Àwọn ará Sidoni ati Arifadi ni atukọ̀ rẹ.
Ó ní, “Lé ẹrubinrin ati ọmọ rẹ̀ jáde, nítorí ọmọ ẹrubinrin kò ní bá ọmọ obinrin tí ó ní òmìnira pín ogún baba wọn.
"Bi osisẹ Amotekun ko ba mọọkọ tabi mọọka, bawo la ṣe fẹ ṣe idanilekọọ fun wọn, bawo ni yoo ṣe kọ akọsilẹ nipa awọn iṣẹlẹ to ba waye ati ẹri to ni?
Ṣugbọn bí ó ti rí látijọ́, tí ọmọ tí a bí nípa ìfẹ́ ara ń ṣe inúnibíni ọmọ tí a bí nípa Ẹ̀mí, bẹ́ẹ̀ náà ni ó wà títí di ìsinsìnyìí.
Oríṣun àwòrán, @arsenal Àkọlé àwòrán, Odo ti a ba foju rénà le gbe eniyan lọ 5) Araba tunra mu, odo n gbe arere lọ ati pe ọpọ igba lo jẹ pé Igi ti a foju rénà a maa gbe ni ṣubu.
Àríyànjiyàn kan bẹ́ sílẹ̀ láàrin àwọn ọmọ-ẹ̀yìn Jesu lórí pé ta ló ṣe pataki jùlọ láàrin wọn.
Ọpọ eniyan lo si tun padanu ẹmi ati dukia wọn.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Myanmar: kékeré ni wọ́n ti n kọ́ àwọn ọmọ nípa ọ̀nà oge ṣiṣe Agbabọọlu orilẹ-ede Guinea, Nabi Keita (lootọ oun ko ni kopa ninu ifẹsẹwọnsẹ yii nitori o fara ṣeṣe), Sadio Mane lati orilẹede Senegal, Joel Matip lati orilẹ-ede Cameroun pẹlu Mohammed Salah to jẹ agbabọọlu ọmọ orilẹ-ede Egypt.
A ki I se oloselu nitori naa, ki a yago fun sisọrọ lori ayelujara.
Ati wi pe ẹgbẹ́ awọn gomina ọhun, NGF, kiiṣe ẹgbẹ ti ofin da mọ, bikose ikorajọpọ awọn oloṣelu.
Kí ló dé tí o fi ń wá ọ̀nà láti pa Dafidi láìṣẹ̀?
Leyin ti Liverpool jawe olubori ninu ifesewonse akoko pelu ami-ayo meta sodo(3-0) ni papa isere Anfield.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Mama Arsenal: Màmá àgbà yìí máa ń lọ sí ìbùdó tí wọ́n ti ń wo bọ́ọ́lù láti wòran Awọn ti iṣẹlẹ naa soju wọn ni ohun to sokunfa ijamba ọkọ oju omi naa ni pe awọn eniyan to wa ninu ọkọ oju omi naa pọ ju bo ṣe yẹ lọ.
 o si ti a kà ni adajọ ọlọrun .
Ẹwẹ, Aisha ni ki wọn tu awọn ẹṣọ oun silẹ ki wọn ma ṣi wọn silẹ si arun Coronavirus.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìlérí Fayemi lati san owó oṣù oṣìṣẹ́ l'Ekiti: ẹnu lásán kò lè ṣe é 16 Agẹmo 2018 Oríṣun àwòrán, @nbs Àkọlé àwòrán, Odu ni Kayode Fayemi jẹ nidi iṣejoba ṣugbọn nnkan yato lasiko to pada wa yi Àáyá bẹ sílẹ̀, ó bẹ́ sí aré ní Kayode Fayemi fẹ fí ipadabọ rẹ sì orí aleefa gẹgẹ bí Gómìnà ìpínlẹ̀ Èkìtì ṣé.
Kọmiṣọna fun ọrọ abẹle, Anofiu Elegushi lo fi ọrọ naa lede lẹyin apero pẹlu awọn olori ẹlẹsin nipinlẹ naa.
Iroyin ti o tẹ wa lọwọ ni pe Fada David Tanko n lọ si ilu Takum fun ipade alaafia laarin Tiv ni Benue ati ẹya Jukun ni Taraba pelu awon olori ẹlẹsin miran.
Koda awọn ohun to kọ nigba mii a maa ta ba orilẹ-ede mii yatọ si Naijiria.
Alaafin Oyo: Àwọn onílù mí ló ń tú àṣírí ìkà èèyàn tó bá wọ ààfin mi
O tesiwaju pe, won ji awon ohun elo ija naa nibi ti won ko won si, kii won to ti ibe pa pada.
Onidajọ David Oladimeji, ti ile ẹjọ giga ipinlẹ Ọṣun, ninu idajọ to gbekaẹ lọjọọru ile ẹjọ naa ko lee kaa lọwọ ko lori erongba rẹ lati dije fun ipo gomina nitoripe olupẹjọ kuna lati fi idi ẹsun ayederu iwe ẹri to fi kan an mulẹ.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Ọgagun Muhammadu Buhari: Olori ijọba ologun nigba kan ni Naijiria, to si tun jẹ aarẹ lọwọlọwọ.
 Àjọ ọlọpàá Eko kédé pé ìbalòpọ̀ nítà kò bójúmu Ilé aṣọ̀fin Nàìjíríà ń gbèrò ẹ̀wọ̀n f'áwọn olùkọ̀ tó bá dẹnu ìfẹ́ kọ akẹ́kọ̀bìnrin Arákùnrin tó bá wọ́n ṣàgbékalẹ̀ òfin ẹgba jíjẹ lórí ìwà àgbèrè kó sínú àgbèrè Pope Francis wọ́gilé òfin tó n dáàbò bo àlùfáà tó bá bá ọmọdé l'òpọ̀ Lara awọn ẹsun ti Chike fi kan iyawo rẹ Chioma ni pe, o maa n ja ija igboro, to si tun jẹ ọlẹ ti kii dana ounjẹ tabi f'ọṣọ fun oun."
Yọ ìwo kọ̀ọ̀kan sí igun rẹ̀ mẹrẹẹrin, àṣepọ̀ ni kí o ṣe àwọn ìwo náà mọ́ pẹpẹ, kí o sì yọ́ idẹ bo gbogbo rẹ̀.
Aare orile ede Naijiria Muhammadu Buhari ni yoo lo si Jos, ni ipinle Plateau lati wo bi eto aabo se ri nibẹ, leyin ipaniyan to waye ni ipinle naa.
Omorinbola ni abikẹyin baba rẹ ṣugbọn iroyin ni oun ni ifa mu ninu awọn ọmọ obinrin mẹfa baba rẹ lati gori itẹ naa.
Ní ọjọ́ kinni oṣù náà ni ṣóńṣó orí àwọn òkè ńlá hàn síta.
Olugbani-nimoran pataki si aare lori oro ifitonileti, ogbeni Femi Adesina, so eyi di mimo fun awon akoroyin gbara ti aare se bale silu Abuja.
Ẹwẹ, lonii idaji iye awọn to wa ni orilẹede naa lo nira fun lati ri ounjẹ jẹ, ọwọn gogo to tun wa ba ọrọ aje wọn jẹ ni o le lọdun mẹwaa sẹyin.
Kì í ṣe pé mo fẹ́ dójú tì yín ni mo fi ń kọ nǹkan wọnyi si yín, mò ń kìlọ̀ fun yín gẹ́gẹ́ bí àyànfẹ́ ọmọ mi ni.
'' Niṣe lawọn ọmọ ilẹ Ghana gba ori opo ayelujara lọ lati fi ẹhonu han nitori ina ọba ti ko si fun wakati mẹrinlelogun yii.
" Gbogbo orin egúngún bìkiafù tí wọ́n kọ sí mi l'étí nípa Ajayi tí mi o gbọ̀ ló bu mí lọ́wọ́- Akeredolu Ènìyàn 653 míràn tún kún iye àwọn tó ní COVID-19 ní Nàìjíríà Ṣé ẹ mọ̀ pé Ẹ̀wà Sóyà, Ẹja Puffer, àti ewébẹ̀ yìí lè ṣekú pa'ni kíákíá?
Awọn alaṣẹ ti saaju fi ireti han pe ibo abẹnu naa yoo mu opin ba ija ọlọjọgbọọrọ to ti n waye laarin awọn musulumi ati ọmọogun orileede Philippine nibi ti awọn ọmọ ijọ katoliki pọ si julọ.
Aláàfin Ọyọ: Ọba tó bá n mú ọtí ní ìta kò yẹ ní ẹni tàá bọ̀wọ̀ fún Gbàjarè!
O ni a o ni tọwọ ofin bọ o bẹẹ si ni ao ni pa awọn ọmọ wa ṣugbọn mo n fi daa yin loju wipe iranti ati agbara awọn alalẹẹlẹ yoo dari rẹ pada wa""."
"Ìpinu yìí jẹ́ eyí tó ""dára jùlọ tó sì mọ́gbọ́n dáni"" ""eyí tó níye lórí gidi fún ètò ọ̀rọ̀ ajé wa "" èyí ni ọ̀rọ̀ ọ̀gá àgba alásẹ ìjọba ti a pè."
Lọwọlọwọ, wọn ti n dawọn pada si ibikibi ti wọn ba wa.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù 2020 WASSCE: Àjọ WAEC sọ pé ìdánwò tó ṣẹ̀ṣẹ̀ parí nàá lọ ní ìrọwọ́-rọsẹ̀ 7 Èrèlè 2018 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 14 Owewe 2020 Oríṣun àwòrán, Getty Images Ajọ to n ṣeto idanwo aṣekagba ileewe girama ni ilẹ Afrika, WAEC ti sọ ọjọ ti yoo gbe esi idanwo ti awọn akẹkọọ ṣẹṣẹ pari, jade.
Awọn eeyan kan to bawọn akọroyin sọrọ ni awọn ko lee sọ ohun to sokunfa aawọ ọtun yi.
Oríṣun àwòrán, @Sunchine Ikorita tani ki n fẹ́ lo da irinajo Ajani to jẹ́ oluda itan naa ru lẹ́yin to setan ni Fasiti.
Abudu Balogun, to kọwọrin pẹlu akẹẹgbẹ rẹ ni ẹka to n seto aato ilu ati idagbasoke, Tunji Odunlami, tun ṣabẹwo si awọn agbegbe bi Ijeja, Ijeun Titun, Gbangba, Odo-Eran, Isale-Oja Kuto, Sokori ati Ago-Ijesa .
Awọn ọmọ orilẹ-ede Naijiria kan ti wọn ha si orilẹ-ede Oman ni wọn ti n rawọ ẹbẹ si ijọba apapọ Naijiria.
Àwọn àràmọ̀ndà ìbomú-bẹnu tó gbòde lásìkò Coronavirus yìí Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 3 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 5 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Benhadadi gba ọ̀rọ̀ Asa, ó bá rán àwọn ọ̀gágun rẹ̀ jáde láti lọ gbógun ti àwọn ìlú Israẹli.
Ayinla Ọmọwura, orin èébú àti oríyìn lo fi di ọ̀rẹ́ àwọ̀n obìnrin Duro Ladipọ, ìlúmọ̀ọ́ká òṣèré tíátà àti ọmọ àlúfà tí kò gbàgbé àṣà ìbílẹ̀ Ọọ̀ni obìnrin, Lúwòó Gbàgídà rèé, akọni tó ń gun ọkùnrin ní ẹṣin rìn Koda ti ọjọ ba pe lori awọn elo idanimọ to ku bi kaadi idibo,iwe irina, tabi iwe aṣẹ iwakọ,bi eeyan ko ba ni NIN,ko ni le gba omiran ninu awọn eleyi ti a ka kalẹ Ni soki, bi eeyan ba ti ni NIN, ọrọ buṣe amọ bi kaadi idanimọ rẹ ba sọnu, o di dandan ki o fi owo gba omiran.
Bakan naa ni iyawo rẹ, Melania Trump gaan ko aarun ọhun.
Ko sẹni ti yoo baa yin gbe ẹru kankan afi tẹ o ba san asanle Àkọlé àwòrán, Lẹyin ọjọ mẹrin ti wọn ṣi irina ọkọ ofurufu labẹle ree ni papakọ ofurufu ti Abuja Àkọlé àwòrán, Lati ẹnu ibode gan lẹ o ti gba apẹrẹ onirin ẹlẹsẹ mẹta too fi ti ẹru rẹ funraraa rẹ Àkọlé àwòrán, Lara eto ti ijọba gbekalẹ fun imọtoto ni pe waa fọ ọwọ rẹ tonitoni koo to wọ inu gbọngan papakọ ofurufu Àkọlé àwòrán, Iṣẹ ko pọ rara fun awọn oṣiṣẹ papakọ ofurufu ti awọn naa ṣẹṣẹ wọle iṣẹ Àkọlé àwòrán, Akọle ti wa kaakiri ibi ti ẹ ba n lọ tabi gba kọja pe ki ẹ maa tẹle ofin injinasiraẹni, lilo ibomu, ati oogun apakokoro fi pawọ.
Iyi obi ni ki ọpọlọ ọmọ o ji pepe ki o si kogoja ninu ẹkọ rẹ.
SIB je ile ise tii ki se ti ijoba ti o n ri si ekunrere
Ní ọjọ́ ìpọ́njú mo ké pè ọ́,nítorí pé o máa ń gbọ́ adura mi.
"Àkọlé àwòrán, Trump àti Melania aya rẹ gbé òdòdó ìrántí sójú oórì akọni lójú ìjà Àkọlé àwòrán, Wọn yan bi ológun ki Aarẹ Donald Trump kaabọ silẹ̀ Gẹẹsi Oríṣun àwòrán, Reuters Àkọlé àwòrán, Awọn oluwọde fọn feere to jọ Aarẹ Trump lọmọ ọwọ́ ni Parliament Square Oríṣun àwòrán, Reuters Àkọlé àwòrán, Aarẹ Trump ṣe ipade pẹlu Theresa May ni St James Palace lẹyin to kuro ni Buckingham Palace lọdọ Obabinrin Elizabeth Oríṣun àwòrán, Reuters Àkọlé àwòrán, Okọ ayọkẹlẹ Cardillac ""Beast' ni o gbe Aarẹ Trump ati aya rẹ lọ si Downing street fún ipade naa."
Nígbà tí Saulu jókòó ní abẹ́ igi tamarisiki ní orí òkè kan ni Gibea, ọ̀kọ̀ rẹ̀ wà ní ọwọ́ rẹ̀, àwọn olórí ogun rẹ̀ sì dúró yí i ká, ó gbọ́ pé wọ́n rí Dafidi ati àwọn ọkunrin tí wọ́n wà lọ́dọ̀ rẹ̀.
Tambuwal  ni o tun jawe olubori fun ipo
 Wọn ko ri ẹsun kankan fi lọ wọn, ṣugbọn ile ẹjọ ti gba beeli wọn bayii.
"19 Èrèlè 2018 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 9 Èbibi 2020 A wadi boya awọn eniyan mo nkan ti wọn n pe ""pen"" ni ede Yoruba."
Mi ò ṣe ẹ̀tánú Ọọ̀ni ilé Ifẹ̀, ọmọ ìyá mi ni ṣùgbọ́n.
Oyo: Laipe ni ijọba ipinlẹ Oyo yoo gbe ti wọn jade naa ni esi ti agbẹnusọ Gomina Seyi Makinde,Taiwo Adisa fọ nigba ti BBC kan si lori ago.
Ti asise ba si waye, o see se ki wsn pe ọmọ ọkọ ni ọmọ ale tabi ọmọ ale ni ọmọ ọkọ eyi to lewu pupọ.
Ọkunrin kan wà ninu ilé ìpàdé náà tí ó ní ẹ̀mí èṣù.
Ijọ Aguda Adoration Ministry Oríṣun àwòrán, Rev Fr Ejike mbaka Àkọlé àwòrán, Fada Mbaka.
Kò ní páyà lákòókò ọ̀gbẹlẹ̀,nígbà gbogbo ni yóo sì máa so.
Ijọba ipinlẹ Delta naa ti dẹwọ okun isede ti wọn naa.
Gomina ipinle Katsina, Aminu Masari, awon minisita ati awon osise ijọba apapo kookan lo lo pade aare ohun ni papako ofurufu, bee si ni awon osise alaabo omo-ogun ati awon osise oloopa naa ko gbeyin nibe.
Oba Abdulrasheed Akanbi sọ ìrẹ́pọ̀ tó wà láàrin Iwo àti Ife
Mo rò pé ẹ o ranti irú ọ̀rọ̀ burúkú tí ó sọ níwájú Òmùgọ́diméjì ọba ìlú àwọnn Èdìdàrẹ́ ẹ ó sàkíyèsí pé ọ̀rọ̀ rẹ̀ kò ju àti fi wa ojú Òmùgọ́diméjì mọ́ra lọ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù US presidential election 2020: Kíni Kọ́lẹ̀jì ìdìbò, àwọn ìpińlẹ̀ tó le gbé olùdíje wọlé àti àwọn ǹkan ti o yé kí o mọ̀ nípa ìdìbò ilẹ̀ Amerika.
"Ti mo ba fi lee de ipo giga yii ninu ẹsin, maa gba ẹlomiran ni aaye lati maa sun ti iyawo mi, amọ emi ko ti de ipo naa bayii.
Awujọ kọọkan ni o ni ofin ti rẹ."
Àgùnbánirọ̀ mẹ́san pàdánù ẹ̀mí wọn Ọmọ ẹgbẹ́ mẹ́sàn-án tún fí APC sílẹ̀ Ọ̀pọ̀ ẹ̀mí sọnù sínú ilẹ̀ rírì Indonesia Olùdíje gbé APC lọ sílé ẹjọ́ nítorí èsì ìbò Irú ẹ̀dá wo ni aṣòfin Bukola Saraki jẹ́?
Awọn gómìnà naa sàlàyé pé, bi alága apapọ ẹgbẹ kò se lee pe àwọn àgbàgbà ẹgbẹ́ sí ìpàdé, ti n mú idàrúdàpọ̀ bá ètò ẹgbẹ́.
'Ọmọdé tó fẹ̀ràn sínsín èèyàn jẹ ní Ikorodu ni wá'
Olódodo a máa bìkítà fún ẹ̀tọ́ àwọn talaka,ṣugbọn àwọn eniyan burúkú kò ní òye irú rẹ̀.
Bí bẹ́ẹ̀ kọ́, oore-ọ̀fẹ́ kò ní jẹ́ oore-ọ̀fẹ́ mọ́.
Bakan naa, wọn yoo gba ẹru itọju ati ogun eyi ti ogun apa irora ati aṣaraloore wa nibẹ.
 fún ẹ ̀ kọ ́ nípa bí o ṣe lè ṣe àtúnṣe sí àyọkà , yẹ ẹ ̀ kọ ́ ṣíṣe àtúnṣe sí àyọkà wò .
Lara awon to soro nibi ayeye ohun ni: Minisita to n mojuto oro ina mona-mona, ise  ati ipese ile, ogbeni Babatunde Fashola, Minisita to n ri si oro irin-ajo, Rotimi Amaechi ati amugbalegbe aare pataki, iyaafin Maryam Uwais.
Wọ́n fipá bá ọmọbìnrin ogún ọdún lò pọ̀, wọ́n sì pa á Oríṣun àwòrán, FACEBOOK Àkọlé àwòrán, Gomina Ìpínlẹ̀ Ondo tí kẹ́dùn pẹ̀lú ẹbí arábìnrin tí àwọn agbẹ́nipa fibá ba lopọ̀ tí wọ́n sí pa á ní ìlú Akure.
Àwọn àkàndá ẹ̀dá gbarata lórí ìpèníjà tó ń kojú wọn láwùjọ Wo ìdí tí Tẹni, ọ̀dọ́mọdé olórin obìnrin kìí fi ń ṣí ìhòhò rẹ silẹ̀ Ilé ẹjọ́ ní kí wọ́n lọ yẹgi f'ọmọ Ọba ìlú Eko tẹ́lẹ̀ Wọn pa ọlọ́pàá kan níbi tí wọ́n ti dáná sun ìjọ Sotitobire l'Akurẹ - Police PRO Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí kan sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
Sugbọn Ayuba ni o rọrun fun oun lati ka bibeli lai ke si ẹnikẹni, ti bibeli funrarẹ si maa n fa oun, eyi to mu ki oun fara mọ ẹsin Kristiẹni.
 Àwọn ìtọjú yíì jẹ ́ ọ ̀ fẹ ́ láti ọwọ ́ Àjọ Ìlera Àgbayé .
OLUWA àwọn ọmọ ogun ní: “Àwọn eniyan wọnyi ní, kò tíì tó àkókò láti tún Tẹmpili kọ́.
Ọwọ Ọlọpàá ti tẹ ilé ìfìyà jẹni tí wọ́n fi ń pe ilé kéú ní Katsina Àgungùnlá!
Ẹni tó bá ń bínú kàn ń bínú lásán ni- Oyedepo Ṣé lóòtọ́ ni tírélà ti gba ààrín Ronke Odusanya àti bàbá ọmọ rẹ̀, Jago?
Gbogbo àwọn ọmọ ogun Israẹli bá sá, olukuluku gba ilé rẹ̀ lọ.
Ẹwẹ, ẹbi Ajimobi ti sọ pe aago mẹwaa ọjọ Ẹti leto isinku Ajimobi yoo waye ni ilana ẹsin musulumi.
Lọpọ igba awọn to n fi akukọ ja a maa so abẹ to mu mọ awọn akukọ lẹsẹ.
Nígbà mìíràn, ìkùukùu náà lè má dúró lórí Àgọ́ Àjọ ju àṣáálẹ́ títí di òwúrọ̀ lọ, sibẹsibẹ, nígbàkúùgbà tí ìkùukùu bá kúrò lórí Àgọ́ Àjọ ni àwọn ọmọ Israẹli máa ń tẹ̀síwájú.
“Ìwọ̀nba àwọn tí wọ́n bá kù, n óo da jìnnìjìnnì bo ọkàn wọn ní ilẹ̀ àwọn ọ̀tá yín, tóbẹ́ẹ̀ tí ìró ewé tí afẹ́fẹ́ ń fẹ́ lásán yóo máa lé wọn sá; wọn yóo sì máa sá àsá-dojúbolẹ̀ bí ẹni pé ogun ní ń lé wọn.
Oríṣun àwòrán, Others Onimọ nipa eto oṣelu lorilẹede Naijiria, Dokita Olugbenga Abimbola naa ni awọn oludije mẹta gboogi lo ti suyo ninu idibo ipinlẹ Ondo bayii.
Oríṣun àwòrán, @Naomi_Osaka_ Àkọlé àwòrán, Naomi Osaka ati ẹgbọn rẹ Mari Venus loruko ẹgbọn Serena nigba ti orukọ ẹgbọn Naomi si n jẹ Mari Lori akasọ ipo ti wọn wa ninu ere Tennis lagbaye fun ọdun 2018(WTA Women's Single)Naomi wa ni ipo kọkandinlogun (19th) nigba ti ẹgbọn rẹ Mari si wa ni ipo ọ̀rìnlénígba lé mesan (289th) Owo Tabua ni Naomi gba pẹlu ife ẹyẹ rẹ akọkọ Lati igba ti wọn ti n fun oludije ni owo ẹbun asyeori,Naomi Osaka ni yoo gba owo to poju .
Police Attack: Kọ́bùrù ọlọ́pàá kú, Insipektọ farapa nínú ìkọlù agbébọn n'Ibadan Oríṣun àwòrán, Getty Images Ileesẹ ọlọpaa ipinlẹ Oyo ti fi fesi lori ikọlu kan to waye sawọn osisẹ ọlọpaa lagbegbe Ikolaba nilu Ibadan.
da omi alaafia orile ede yii laamu, ki a won si wa ona lati ran won lọwọ.
 Ọ ́ tún gbá bọ ́ ọ ̀ lù àkọ ́ kọ ́ rẹ ̀ sínú àwọn lẹ ́ yìn ìfọwọ ́ bọ ̀ wé rẹ ̀ nị ́ gbà tí wọ ́ n gbá pẹ ̀ lú ikọ ̀ la rochelle níbi ìdíje 2014-15 rugby challenge cup .
"Ọgbẹni Sowore, to jẹ oludasilẹ ileeṣẹ iroyin Sahara Reporters, jẹ ọkan lara awọn to ṣe agbatẹru iwọde kan ti ẹgbẹ Global Coalition for Security and Democracy in Nigeria, fẹ ẹ ṣe ni ọjọ Aje, ọjọ karun un oṣu Kẹjọ ọdun 2019 ṣugbọn ileeṣẹ ọlọpaa sọ pe ""ete iditẹ gba ijọba ni iwọde naa."
A le sọ pe wahala naa bẹrẹ lati ọjọ ti wọn ti yan awọn olori ile aṣofin naa.
Wọ́n ń retí ọjọ́ tí ọlọ́pàá yóò tẹ̀ ẹ́.
O buru jai lati maa sọ pe ile igbọnsẹ kan ṣoṣo lawọn họnọrebu mẹrin n pin lo ninu ile igbimọ aṣofin wa.
ofurufu ogbeni Sam Adurogboye soro lojo Aiku ,pe ile-ise ti bẹrẹ iwadii lori
Duro Ladipọ, ìlúmọ̀ọ́ká òṣèré tíátà àti ọmọ àlúfà tí kò gbàgbé àṣà ìbílẹ̀ Dapọ Abiọdun ree, ẹni tó dépò gómìnà ní àyájọ́ ọjọ́ ìbí rẹ̀ Hubert Ogunde rèé, baba àwọn òsèré tíátà Buhari mórí lé Saudi lẹ́yìn ìbúrawọlé fún sáà kejì Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí kan sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
Bakan naa ni wọn ba awọn mọlẹbi tọmọ wọn sọnu kẹdun ati awọn ẹsọ alaabo to padanu ẹmi wọn ninu iṣẹlẹ yii.
1–5, Ìfihàn máa nwá nípa agbára Ẹ̀mí Mímọ́, 6–12, Ìmọ̀ nípa àwọn ohun ìjìnlẹ̀ Ọlọ́run àti agbára láti lè túmọ̀ àwọn àkọsílẹ̀ ìgbàanì nwá nípa ìgbàgbọ́.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Kíni ìdí tí àwọn ẹbí àwọn ọmọ Chibok fi ń tọ woli lọ?
Nígbà tí Baali Hanani kú, Hadadi, jọba tẹ̀lé e.
Èèyàn 789 gbèkuru jẹ lọ́wọ́ ẹbọra nítorí COVID-19 ní Nàìjíríà Èmi ni 'Bàbá àwọn Marlians' - Jude Chukwuka Kanye West ti bẹ̀rẹ̀ ìpolongo àti díje dupò aàrẹ ilẹ̀ Amẹrika Lẹ́yìn gbogbo sinimá oríta ní Ondo, Akẹti jáwé olúborí ní APC Òògùn ìtura dé fún Coronavirus!
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Highlighlight of Liverpool vs Chelsea: Liverpool pègúnrẹ́, wọ́n gbé ife ẹ̀yẹ̀ Premier league lẹ́yìn ọgbọ̀n ọdún 23 Agẹmo 2020 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Igba akọkọ rèé ti wọn ti n duro de ife yii ko tẹ wọn lọwọ lati igba ti Premier league ti bẹrẹ.
Èmi ni OLUWA Ọlọrun yín tí ó ko yín jáde wa láti ilẹ̀ Ijipti, láti jẹ́ Ọlọrun yín: Èmi ni OLUWA Ọlọrun yín.
Onimo ero Seyi Makinde ni o gba ijoba lowo gomina Abiola Ajimobi gege
Dokita yọ góòlù àti owó ṣílè nínú obìnrin kan Ẹ ṣọ́ra fún ìròyìn ẹlẹ́jẹ̀ lórí ètò ààbò - Ọlọ́pàá Etí ìjọba Buhari di sí ìmọ̀ràn àwọn ará ìlú -Jiti Ogunye Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Arabinrin Aisha Buhari ni oun rinrinajo lọ si orilẹede naa lati lọ fun itọju to so pada wale pẹlu ọkọ ofurufu ileeṣẹ ogun ofurufu Naijiria.
Àwọ́n èèyàn Benue ńbẹ àwùjọ àgbáyé láti gba àwọn Ààrẹ ẹgbẹ́ PFN ni ìpínlẹ̀ Benue, Àlúfà Felix Omobude àti amúgbálẹ́gbẹ̀ẹ́ ààrẹ CAN, Báyọ̀ Ọládèjì ní àwọn iléesẹ́ agbófinró ti já àwọn ọmọ orílẹ̀èdè yìí kulẹ̀.
Oga agba iko ti o n ri si oro HIV/AIDS ninu ajo isokan orile-ede agbaye UNAIDS, Erastus Morah, ro ijoba orile-ede Naijiria lati je ki owo re soro, nipa sise alekun itoju awon alarun HIV/AIDS lorile-ede Naijiria.
"Riyas Mohammed to jẹ alakoso ìdáhun pàjáwiri ni ìhà Plan International Nigeria ni "" ètò ẹkọ jẹ ọkan pàtàkì nínú ǹkan ti àjọ náà ń mójú tó ní ila-oorrun Arewa Nàìjíríà."
Wọn si tun ni ẹwọn ọdun marundinlọgbọn ni ijiya ẹni to ba n ta kaadi ti wọn ti fi orukọ rẹ silẹ ki ẹni to ra to de.
Lero tawọn onimọ ọrọ aje yii, Buhari gbọdọ tete ta mọra lati fi orukọ awọn minisita rẹ sọwọ sile asofin apapọ, ki wọn to lọ fun isinmi, bi bẹẹ kọ, ọfọn lee fi iru nagba nidi ọrọ aje wa, kawọn asofin naa to pada de.
Ìpàdé àpérò kọ́ ló kàn, àdánìkànjẹ ẹ̀yà kan ni ká dẹ́kun ní Nàíjíríà - Òǹwòye Ìyàwò lárìnlọọ̀dù mi pè mí ní akálòlò ni mo ṣe paa - Afurasí UK fẹ́ so ìjókòó ilé rọ̀, kíni èyí túmọ̀ sí?
Àwọn ará Gibeoni kì í ṣe ara àwọn ọmọ Israẹli.
Gbogbo ìṣọ̀wọ́ àwọn tí wọ́n mọ OLUWA ati ohun tí ó ti ṣe fún Israẹli patapata ni wọ́n kú, àwọn ìran mìíràn sì dìde lẹ́yìn wọn, wọn kò mọ OLUWA, ati gbogbo ohun tí ó ti ṣe fún Israẹli.
Ọdun yi jẹ eleyi to jẹ ọdun to lamilaaka fun jija fun ẹtọ obinrin.
Ó ní láti jẹ́ pé ẹkún ni mo sun lọ sùn.
Àwọn àwòrán tó làmìlaaka níbi ayẹyẹ àpéjẹ ìdúpẹ́ Aisha Buhari
Wọn á máa pa wọ́n báyìí, èmi náà á sì ní bẹ́ẹ̀ gan-an ló yẹ wọ́n.
Ninu ifọrọwerọ kan to ṣe lọjọbọ, alakoso eto iroyin lolu ileeṣẹ ọmọogun Naijiria, Ọgagun John Enenche ṣalaye pe, niwọn igba ti gomina ipinlẹ Eko ti gbe igbimọ oluwadi kalẹ, ọrọ yowu ti awọn ba sọ bayii, lee pagidina iṣẹ igbimọ naa.
Àwọn eniyan mi ké pè mí wí pé,‘Bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé ẹ̀ṣẹ̀ wa ń jẹ́rìí lòdì sí wa,sibẹsibẹ, nítorí orúkọ rẹ, gbà wá.
World Sickle Cell Day: Àwọn ǹkan ti alárùn SS kò gbọdọ̀ ṣe fún alááfíà ara- Dókítà Igbekele
orile ede Afirika, ni eyi ti yoo waye ni Dead Sea ni Jordan.
Yatọ fun eyi, gẹgẹ bi ajọ ẹṣọ oju popo ṣe sọ ọ, o le ni ọkọ miliọnu meje to n gba awọn ọna Naijiria kọja eyi ti ida mẹta wọn si wa ni Eko.
Gba aawẹ lọjọ Arafa Gẹgẹ bi Sheikh Daurawa sr sọ, nkan ikeji ni lati gba aawẹ lọjọ Arafa.
Àkọlé àwòrán, Laago merin idaji oni ni ijọba gbe katakata wa wo ile Wrugbo ni Ilorin Àkọlé àwòrán, Ile arugbo loke to wa nitosi Radio Kwara ni ijọba Ramoni Razaki wo Àkọlé àwòrán, Gomina Abdul Razaq fihan pe ijọba amuni-mu-oogun ni ijọba ki ijoba to ba wa lori aleefa lasiko ki asiko Àkọlé àwòrán, Goo goo go ni awọn eeyan duro kaakiri agbegbe yii lẹbaa Civil service clinic Àkọlé àwòrán, Ilé arugbo di ohun itan ni Kwara, Bukola Saraki ko ri nkan ṣe sii Àkọlé àwòrán, Gomina Rasaq ko gbọ ọrọ sawọn arugbo Kwara lẹnu o wo ile naa Àkọlé àwòrán, Awọn ara Ilorin ko ri nkankan ṣe si aṣẹ gomina Razak ti Kwara, onikaluku fọwọ lẹran ni Àkọlé àwòrán, Lati ipilẹ ni wọn ti wo ile Arugbo Ilorin ti ọrọ si pin bayii Àkọlé àwòrán, Ko si ẹni to lagbara kọja ijọba to ba n tukọ orilẹ ede tabi ipinlẹ kan.
tun fi mo awon ile-ise ijoba kekekee yooku.
Igbesẹ yii fihan pe o ti di igba mẹta ọtọọtọ bayii ti ijọba ti ṣe afikun owo ina laarin ọdun marun un sẹyin ni Naijiria.
4 6129 Orilẹede Mayotte 49 18.
Nítorí náà, àwọn alabojuto ati àwọn gomina gbìmọ̀ pọ̀, wọ́n kó ara wọn jọ sọ́dọ̀ ọba, wọ́n wí fún un pé “Dariusi ọba, kí ọba pẹ́, 
Àlàyé rèé lóríi ìdí tí wọ́n fi ń pe aya ní ìyàwó Èrò ọmọ Nàìjíríà ṣ'ọ̀tọ̀ọ̀tọ̀ lórí ọ̀rọ̀ Bíṣọ́ọ́bù Oyedepo pé kò sí ìdí tí iléèjọ́sìn láti wà ní títì pa Àwọn ọmọ Nàìjíríà tó há sí ilẹ̀ Gẹ̀ẹ́sì padà sílé Kọmíṣọ́nà Ọlọ́pàá kó gbogbo ọlọ́pàá ẹkùn Ondo lọ fún àyẹ̀wò COVID-19 O ṣoju mi koro ṣe alaye fun awọn oniroyin pe eeyan mẹrin lo ku loju ẹsẹ gẹgẹ bi wọn ṣe ko awọn ti o fi ara pa lọ si ile iwosan ẹkọṣẹ iṣegun Oyinbo, LAUTECHTH to n bẹ niluu Ogbomọṣọ.
Níbo ni ọba yín wà nisinsinyii, tí yóo gbà yín là?
Ọlọ́pàá Nàìjíríà àti Ẹgbẹ́ IMN n ṣé fakinfa lórí ikú àwọn olùwọ́de ìdárò Ashura Gbàgbé ẹ̀sọ́ ara $40m rẹ pátápátá - Ilé ẹjọ́ sí Dienzani 'Operation Rewire' EFCC / FBI sèso owó tó lè ní mílíọ̀nù N153 Ẹ ṣèwádìí ikú Ọ̀jọ̀gbọ́n Gideon Okedayọ - ASUU Ile ẹjọ naa kede Chinedu Ogah, lati ẹgbẹ APC, gẹgẹ bi ojulowo ẹni to jawe olubori ninu idibo naa.
” Ọgbẹni Olumẹkun lo fọrọ yii mulẹ.
“Ile-igbimo asofin fowo sii ninu oro ti ipo orile naa wa, Aare Ramaphosa fi ipinnu re mule pe, ijoba yoo gbe igbese to nipon lori atunse si oro ile ohun, eyi ti yoo faye gba gbigba awon ile naa pada lai san owo gba mabinu,,,,,” Ronke Osundiya.
Beti Dagoni, Naama, ati Makeda; gbogbo ìlú ati ìletò wọ́n jẹ́ mẹrindinlogun.
Ninu atẹjade rẹ kan loju opo twitter lo ti kọkọ kede pe eeyan oun kan 'ti ko ja oun kulẹ ri' sọ pe Abiọla Ajimọbi ti jade laye, Amọṣa ni kia masa werewere lawọn ẹbi oloogbe naa ti bọ sigboro lati bu omi pa iroyin naa eyi ti wọn ni irọ gbuu lasan ni.
Wọn tilẹ tun fi ọlọpàá mẹjọ si atimọle pẹlu rẹ.
Ní bayii ọ̀pọ̀ awon eniyan lo ti n wa láti wa ran obinrin náà lọwọ pẹlú oniruuru ounjẹ ati nkan iranwọ.
Oludaru agba ajo ohun, Dokita Betta Edu ni o tuko awon osise re lo silu Ukelle ti o wa nijoba ibile Yala Local Government nipinle Cross River, loile-ede Nigeria.
"Ọkọ Funke Akindele kó eléré àti òṣìṣẹ́ jọ fi ṣe ""Surprise Pato"" fún un lọ́jọ́ ìbí rẹ̀ Èkúté gbà ìjọba ilé ìwòsan, Mínísítà ìlera fárígá, ó ní k'àwọn alákóso wà jẹ́jọ́ Irú ẹ̀dá wo ni Ọjọgbọn Folasade Ogunsola jẹ́?"
Odò kan yóo bẹ̀rẹ̀ sí ṣàn láti ilé OLUWA,yóo sì bomi rin àfonífojì Ṣitimu.
Ìdí tí ó fi ṣàánú mi nìyí, pé èmi ni Kristi Jesu kọ́kọ́ yọ́nú sí ju ẹnikẹ́ni lọ.
"O ní ìyá òun sọ fún òun pé "" tí ǹ kò bá lọ ọmu rẹ̀ àwọn ọkunrin yóò bẹrẹ̀ si ni wá ọ wá láti le ba ọ ni àjọṣepọ̀"" Iyá ọmọ náà lo máa ṣe ètò ọmú lílọ yìí nígba ti wọn ba mú òkúta gbigbona tabi ṣíbi gbigbona láti fi lọ ọmu ọmọbinrin náà mọlẹ̀, wọn máà ń ṣe èyí fun bii oṣù kan tàbi jù bẹ ẹlọ O ṣalaye pe : ""ohun máa le gbàgbé ní irú ǹkan báyìí"" ""Kódà kò si ààye fún ẹkún sísun."
Agbarijọpọ awọn ẹgbẹ naa labẹ asia Coalition of United Political Parties (CUPP) ni awọn lodi si esi ibo naa to waye lọjọ kẹtalelogun Osu kẹta.
Láti ìgbà yìí ní àwọn ènìyàn ti ya June 12 sọ́tọ̀ láti máa'fi ṣe àyájọ ìjọba àwa ara wa.
Ṣùgbọ́n, ìwọ lágbára nínú àwọn ẹranko, ìwọ lè sáré ju púpọ̀ nínú wọn, etí rẹ kò sì kéré bí a bá fi wé bí ìwọ pàápàá ti tóbi mọ.
com/nin/ Òó ri fọ́ọ̀mù tí ó kọ orúkọ rẹ sí lẹ́kúnrẹ́rẹ́.
"Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Fayose koro oju si Buhari lori pipa awọn Fulani 2 Èrèlè 2018 Oríṣun àwòrán, @GovAyoFayose/@NGRPresident Àkọlé àwòrán, Gomina Ayọ Fayose ati Aarẹ Muhammadu Buhari ti di sonso meji ti kii fi oju ko oju lori ọrọ ilu Gomina ipinlẹ Ekiti, Ayọdele Fayọse ti bu ẹnu atẹ lu Aarẹ Muhammadu Buhari fun ohun to pe ni iha ""kokanmi"" ti o n kọ si ọkan-o-jọkan ipaniyan to n lọ kaakiri orilẹede Naijiria."
Awa tí a lọ tó mẹ́rìnlélógùn ṣùgbọ́n àwọn tí a fi sí ibùdó wà ní ojú ọ̀nà òkè Ìrònù tó àádọ́jọ nítorí ọ̀pọ̀lọpọ̀ ènìyàn ló bá wa jáde ní ìlú àwọn Alásejù tí ó jẹ́ pé wọn kò bá wa ti ilé lọ.
O ti ṣe oniruuru ere tiata pẹ̀lú àwọn òṣeré jankanjankan to fi mọ funke Akindele atI Adebayo Salami.
Eyi ni pe ko sẹni to yẹ ko ro ara rẹ pin laye.
Èyí ẹ̀kẹta wà ní ìdúró, ó wọ ṣòkòtò tuntun àti ẹ̀wù tuntun ṣùgbọ́n ó dé fìlà àgbàlagbà, fìlà náà sì burú ó dà bí fìlà ayé àtijọ́.
”Atejade kan lati odo oluranlowo igbakeji aare lori iroyin ati ikede , Laolu Akande so pe igbakeji aare tun ba awon ara ilu ati awon ti oro naa  kan se ipade po ni yara igbalejo won ni olu-ilu ipinle naa.
pese eto didbo to le lọ ni irowo-irose ni orile ede ,ijoba mọ ohun ti won lee
Elija sọ fún Eliṣa pé, “Dúró níhìn-ín nítorí pé OLUWA rán mi sí Bẹtẹli.
Issa kede ọrọ yi ninu ifọrọwanilẹnuwo pẹlu ile iṣẹ BBC Yoruba.
Tí a fiṣọwọ́ ní 17:0317:03 Ìṣẹ́jú kan BBC Video content Video caption: Ìsẹ̀lẹ̀ jákèjádò orílẹ̀èdè àgbáyé láàárín ìṣẹ́jú kanÌsẹ̀lẹ̀ jákèjádò orílẹ̀èdè àgbáyé láàárín ìṣẹ́jú kan Àkójọpọ̀ ìsẹ̀lẹ̀ jákèjádò àgbáyé láàárín ìṣẹ́jú kan lórí BBC.
"Wo ojú àwọn òṣèré yìí láì lo ""Make-up"" orí ìtàgé bó ṣe rí gẹ́lẹ́ Wumi Toriọla ti sọ̀rọ̀ sóke láti fi idí rẹ̀ múlẹ̀ pé òun àti ọ̀rẹ́ òun níjà Mo pinu láti dá Iphone tì mo mú padà kí ọlọ́pàá tó mú mi Ẹ gbọ́ Ohun tí Desmond Elliot àti Mojisola Alli-Macaulay sọ lórí ayélujára táwọn ọmọ Nàìjíríà fi ìbínú Ìrànwọ́ ikú fàwọn tó bá wà lórí àkéte àìsan tó leè já sí ikú ti di òfin tuntun tí wọ́n fẹ́ fọwọ́ sí!"
Ìṣòro tí a kò lágbára láti gbé kí Ọlọ́run Ọba má ṣe gbé e kà wá láyà.
Ileeṣẹ ọlọpaa to wa ni Mile 1 Diobu, ni Port Harcourt, iyẹn ni ipinlẹ Rivers ti palẹ oku ọmọ ọjọ kan mọ, eyii ti ẹnikan gba ju si ile idalẹsi ni opopona Ikwerre.
Bẹẹ ni ọrọ ri fun gbajumọ oṣere tiata kan, Mufutau Ajikanle, ẹni ti apa ati ẹsẹ rẹ ti rọ lati ọdun mẹta sẹyin.
Ohun tí a mọ̀ nìyí nípa àwọn tí yóò láǹfàní àti lọ sí Hajj lọ́dún yìí Àìmọ̀kan ló ń ṣe ìjọba Oyo tó fẹ́ ṣí iléèwé, gbogbo ìpínlẹ̀ ló ní àrùn COVID 19- Ijọba àpapọ̀ Lórí bóyá igbákejì gómìnà Ondo yóò fipò sílẹ̀ tàbí rárá, ohun tó lu sí wa lọ́wọ́ nìyí Ènìyàn 675 ni èsì àyẹ̀wò sọ pé ó tún ṣẹ̀ṣẹ̀ ní Covid-19 ní Nàìjíríà Iroyin naa ni iṣẹlẹ naa waye lọjọ aiku, ọjọ kọkanlelogun oṣu kẹfa ni abule Victory Park, agbegbe Ilasan ni Lekki ni ipinlẹ Eko, ti Olamide to jẹ́ alaisi naa, si wa se abẹwo si Chris, to bi ọmọ meji fun lati agbegbe Ọgba.
27 Èyítí ó jẹ́ ọ̀rọ̀ mi sí àwọn Kèfèrí, pé láìpẹ́ kí ó le lọ sí ọ̀dọ̀ àwọn Júù, tí àwọn ará Lámánì jẹ́ ìyókù wọn, pé kí wọn ó le gba ìhìnrere náà gbọ́, ati kí wọ́n ó sì má baà tún fi ojú sọ́na fún Messia kan lati wá ẹni tí ó ti wá tẹ́lẹ̀.
Ikọlu ati ọyaju si gomina ipinlẹ Ekiti, Ayọ Fayose lati ọwọ awọn ọlọpaa, osisẹ ọtẹlẹmuyẹ, awọn ologun ati ẹgbẹlẹgbẹ ọlọpaa kogberegbe.
Nítorí àwọn tí wọn bá ṣe iṣẹ́ diakoni dáradára ti ṣí ọ̀nà ipò gíga fún ara wọn.
 egbe yi ni rekodu isise ni amerika togunjulo , be sini o je ikan larin awon egbe oloselu to gbojulo lagbaye .
Joṣua bá àwọn ọba wọnyi jagun fún ìgbà pípẹ́.
Òun ní tirẹ̀, apànìyàn ni láti ìbẹ̀rẹ̀, ara rẹ̀ kọ òtítọ́ nítorí kò sí òtítọ́ ninu rẹ̀.
Lojo Isegun ,ni Ile-ẹjọ to wa niluu  Abuja, ni ijoba
Ẹwẹ, igbimọ amuṣẹya COVID-19 gba awọn ọmọ Naijiria niyanju lati ma bẹru ṣiṣe ayẹwo paapaa julọ tori arun naa kii kuku ṣe idajọ iku.
 ti won wa nibi ipolo  naa wa ro awon
"Gẹgẹ bi pasitọ ti ko gbajugbaja, iroyin fi han pe iye owo ti wọn wọ sinu asuwọn owo rẹ to N573,228,040.
Fidio aladun kan bayii lo fi ki awọn tirẹ ku ọdun Keresi.
Ti wọn ba yọ Trump ti igbakeji rẹ Pence di aarẹ toun naa wa yan Trump ni igbakeji ti Pence si tun wa kọwe fipo silẹ nkọ?
Bi eeyan ba ti wo awọn ere ileeṣẹ sinima Mainframe ni nkan bi ọdun meloo kan sẹyin, yo ranti arakunrin kan to kopa ribiribi ninu awọn ere ti Tunde Kelani dari wọnyi.
Balaamu sọ fún Balaki pé, “Kọ́ pẹpẹ ìrúbọ meje kí o sì mú akọ mààlúù meje ati àgbò meje wá.
Ó ṣeéṣe kí ènìyàn 12,000 máa kú lójoojúmọ́ lẹ́yìn Covid-19 Orílẹ̀-èdè mẹ́wàá tí ẹgbẹ́ alákatakítí Islamic State n fínna mọ́ ní àgbáyé Ẹgbẹ awọn to n ṣetọju ẹranko ni Naijiria, WCS sọ pe, o ṣeeṣe ki awọn ẹranko naa maa bimọ sii, ki ẹya wọn ma baa parun.
Bakan naa lo parọwa fun awọn eniyan lati ma a jẹ ounjẹ to n ṣe ara loore pẹlu eso jijẹ lasiko.
Kìnìún mẹ́rìnlá bọ́ sígboro Lẹ́yìn-ọ̀-rẹyìn, bàbá ọgọ́rùn-ún ọdún gba ìdáǹdè l‘ẹ́wọ̀n Boeing lo ṣe ọkọ ofurufu 737 Max 8 naa to pa eniyan metadinlọgọjọ, ki awọn oluwadii to wa fi han pe, ọkọ naa ni abawọn.
Ologbondiyan ni, nítori pé awọn araalu ṣe ẹ̀tọ́ wọn nínú ìfẹ́ ọ̀kan wọn, kìí ṣe ǹkan ti ko bójú mu rárá.
 ( he fired a hayatick .
Nígbà tí a pàdé èkíní, kò kí wa; nígbà tí ó sì rékọjá wa tán ó pòṣé.
A ní láti pèsè ìtó̩jú àti ìrànló̩wó̩ pàtàkì fún àwo̩n abiyamo̩ àti àwo̩n o̩mo̩dé.
lorile ede Naijiria, ni  aseyori odun
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Corona virus:Agbeegbe Wuhan ni China da bi ilu awọn oku Arun coronavirus to bẹrẹ ni ilu Wuhan, lorilẹede China ti pa ọpọlọpọ eniyan ni ilu naa, ti o si ti tyan kale ka oko.
o óo wí ninu ara rẹ pé, ‘N óo gbógun ti ilẹ̀ tí kò ní odi yìí; n óo kọlu àwọn tí wọ́n jókòó jẹ́ẹ́jẹ́ wọn láìléwu, gbogbo wọn ń gbé ìlú tí kò ní odi, kò sì ní ìlẹ̀kùn, kí á má ṣẹ̀ṣẹ̀ sọ ti ọ̀pá ìdábùú ìlẹ̀kùn.
OLUWA fẹ́ràn ẹnubodè Sioni ju gbogbo ìlúyòókù lọ ní ilẹ̀ Jakọbu.
Ta ni yó wa tawá jí pẹ́pẹ́ kúrò lójú orun òfò yìí adúláwọ̀?
Ṣugbọn atẹjade tuntun latọdọ ẹgbẹ ti ni ko sohun to jọ pe wọn yọ gomina Kayode Fayemi kuro lẹgbẹ APC.
Ni kete ti ile ẹjọ kotẹmilọrun fi idi idaduro alaga ẹgbẹ APC tẹlẹ mulẹ ni Giadom ti kede ara re, Adams Oshiomole ni ile ẹjọ yọ l'ọsẹ to kọja ti Giadom si ni oun ni Adele Alaga ẹgbẹ ni kete ti.
Amọ Ọgbẹni Lawal kọ lati ṣalaye ohun to fa a ti igbimọ alaṣẹ ile iwe naa fi sọ fun Adekolawole lọ rọkun nile.
 O sọ pe ẹyin o rẹyin ni oun to o mọ pe ẹgbọn oun ti oun fi fidio naa ranṣẹ si lo fi si ori ayelujara."
Kini awọn eeyan n sọ nipa fọnran fidio yi?
Dafidi bá lọ kọlù wọ́n ní Baali Perasimu, ó sì ṣẹgun wọn, ó ní, “Ọlọrun ti lò mí láti kọlu àwọn ọ̀tá mi bí ìkún omi.
Máà jìyà nínú ìdákẹ́rọrọ  máa wí lọ 
Ibadan Airport: Ìdí rèé tí pápákọ̀ ofurufú Ibadan ṣe n dá paroparo ní gbogbo ìgbà
Ni bayii, iko agbaboolu Super Eagles duro soke tabili ipegede fun idije naa pelu ami mesan an, ti won yoo si lo koju iko Bafana Bafana lojo ketadinlogun osu kokanla odun yii, niluu Johannesburg, lorile-ede South Africa.
Kí wọ́n mú akọ mààlúù kékeré kan ati ìyẹ̀fun kíkúnná tí a fi òróró pò fún ẹbọ ohun jíjẹ wá.
Ètò ìgbóhùn s’áfẹ́fẹ́ kan ni mo s’àwáàrí ní’jọ́kan.
Àwọn ọmọ ẹgbẹ Shiite náà ń fẹ́ kí Tinubu bá Buhari sọ̀rọ̀, kó tètè tú Zakzaky sílẹ̀ ní àhámọ́, kó tó pẹ́ jù.
Ọwọ́ ọlọ́pàá tẹ Ganiyat tó ń n fi irin gbigbona ati ada da sẹria fun un.
 Ọmọ inú lámilámi lè wà láyé fún bí oṣù mẹ ́ rin .
Ninu ọrọ rẹ to ba awọn aṣofin apapọ sọ nibi agbekalẹ aba eto iṣuna ọdun 2019 ni aarẹ Buhari ti kede eyi.
''Lati ọdun 1863 lawọn baba nla temi temi ti wa niluu Ibadan, wọn jọ tẹ Ibadan do ni, ẹba ọdan ni wọn n pe nigba naa, nitori naa ko si ẹni to le le mi kuro ni Ibadan,'' Oloye Balogun lo sọ bẹẹ.
Minister f'ọrọ abele ni Kenya, Fred Matiang ti o sọrọ yin fun awọn oniroyin, wipe awọn ile-isẹ amohunmaworan naa yoo wa ni titi d'igba ti awọn yoo fi pari iwadi.
15 Owewe 2018 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 23 Ọ̀wàrà 2018 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ipadabo Ronaldo si Manchester United.
Yàrá náà ni àwọn fèrèsé fífẹ̀ tọ́n fúnni láàfàní láti wo ìta.
Ní ọjọ́ kinni, Naṣoni ọmọ Aminadabu, olórí ẹ̀yà Juda mú ẹbọ tirẹ̀ wá.
Afínjú Àdàbà tí ń jẹ́ láàrín ín òrófo
Ọlabisi Ajala rèé, ó gun ọ̀kadà yíká àgbáyé, tó sì dé orílẹ̀èdè 87 Ta ló leè rò pé ọmọ mẹ̀kúnnù bí èmi leè dé ipò alága NURTW?
" Kayeefi: Deji pa èèyàn mẹ́sàn án nítorí ìfẹ́ Wòólì Ajayi kú ní ìlú Àgelú, òkú rẹ pòórá, ìjọ sin pósí lásán!
 ní ilẹ ̀ amẹ ́ ríkà iye owó rẹ ̀ jẹ ́ 25 sí 50 usd fún oríṣi tí a fi kòkòrò tí a ti pa ṣe .
Ọdun mẹta lẹyin iku Arisekọla: Kin lo ranti nipa rẹ
ohun ti o n lọ lagbaaye.
Bi awọn kan ṣe n rin sokesodo ninu awọn akẹkọ naa, ni awọn ẹlomii n gba bọọlu lori papa iṣere ile ẹkọ giga naa nitori airi iṣẹ ṣẹ lowurọ ọjọ Aje.
“Eyi ni iwe ikedun akoko ti a ri gba nipa iku oloogbe Jonathan Gopep; inu wa dun fun ikedun ti e fi ranse si egbe naa lasiko ipenija yii.
Nitori naa la fi fi si ahamọ'' Ile iwosan ti ọrọ naa kan ti ṣe agbekalẹ igbimọ kan lati wadi ohun to ṣe okunfa iku iya ati ọmọ naa Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 3 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 5 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Bá mi dá majẹmu, n óo wà lẹ́yìn rẹ, n óo sì mú kí gbogbo Israẹli pada sọ́dọ̀ rẹ.
O ti yọ mí ninu gbogbo ìṣòro mi,mo sì ti fi ojú mi rí ìṣubú àwọn ọ̀tá mi.
Ẹnìkejì rẹ̀ dá a lóhùn, ó ní, “Èyí kì í ṣe ohun mìíràn, bíkòṣe idà Gideoni, ọmọ Joaṣi, ọ̀kan ninu àwọn ọmọ Israẹli.
Iṣẹ́ tí Natani Jẹ́ fún Dafidi.
Ọkàn wọn dàrú pupọ; ẹnìkọ̀ọ̀kan wọn ń bèèrè pé, “Kò sá lè jẹ́ èmi ni, Oluwa?
Nítorí pé mo wà fun yín, n óo ṣí ojú àánú wò yín, wọn óo dá oko sórí yín, wọn óo sì gbin nǹkan sinu rẹ̀.
Iwọde ẹgbẹ ASUP tun da lori owo oṣu ti wọn n jẹ wọ fun odidi oṣu mẹfa, ai ṣe igbega lẹnu iṣẹ lati ọdun 2017 wọn si tun din yọ ninu owo oṣu wọn.
(nítorí wọn óo gbọ́ òkìkí rẹ, ati iṣẹ́ ìyanu tí o ti ṣe fún àwọn eniyan rẹ); tí ó bá wá sìn ọ́, tí ó bá kọjú sí ilé yìí, tí ó gbadura, 
Bí mo bá gbá eniyan mú,kò sí ẹni tí ó lè gbà á sílẹ̀ lọ́wọ́ mi.
Ebedimeleki bá mú àwọn ọkunrin mẹta náà, wọ́n lọ sí yàrá kan ní ilé ìṣúra tí ó wà láàfin ọba.
Ni oṣù kínní ọdún 2019 won tu sile pe kò jẹbi amọ ọ di wa ni àhámọ́ láti jejo ko-te-mi-lorun Nínú inu fo àyà fò ni ilẹ Ivory Coast wa lo in I ṣugbọn awọn èèyàn ilẹ náà kò ní gbàgbé ipá ribiribi tí Didier Drogba àti àwọn akẹgbẹ rey ko lati mu alaafia ba ile won.
Àwọn tí wọ́n jẹ́ ọ̀gá ninu ọtí mímu gbé;tí wọ́n jẹ́ akikanjubí ó bá di pé kí á da ọtí líle pọ̀ mọ́ ara wọn!
Sanwo-Olu: Kò ní sí súnkẹrẹ-fàkẹrẹ ọkọ mọ́ l‘Eko tí mo bá dé ipò
Kí wọ́n má lè ṣí mi nípò
A maa yí ayé po láti wá wò bí àwọn aráyé bá tì ń ṣe.
Wọ́n fún obìnrin kan lọrùn pa, awuyewuye ti ń wáyé Wo iye owó tó wọlé fún ìjọba lórí COVID-19 àti bí wọ́n ṣe ná an Háà, àṣé Pastor Adeboye kò léè dá èékánná ara rẹ̀ gé, àwọn ọmọ Nàìjíríà kan pariwo Àwọn àádọ́ta ọ̀dọ́ wọ gàù nítorí ilé ijó ní Ilorin Báwó ni òògùn dexamethasone ṣe ń ṣiṣẹ́ lára Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Ní àkókò kan, ìyàn ńlá kan mú ní ilẹ̀ náà, yàtọ̀ sí ìyàn tí ó mú ní ìgbà Abrahamu.
Owo oṣu meji ni wọn jẹ Yari ti o si kọwe pe ki wọn san owo naa fun ohun ni ibamu pẹlu ofin to wa nilẹ.
Diego Maradona ṣiṣẹ́ abẹ lórí ẹ̀jẹ̀ tó dì sí i lọ́pọlọ lẹ́yìn ọjọ́ ìbí ọgọ́ta ọdún Láéláé!
Ibidun Ituah Ighodalo, ìlúmọ̀ọ́ká arẹwà tí fáyésilẹ̀ Àjọ ọlọ́pàá, Ìjọba ìpínlẹ̀ Ọyọ jẹ́jẹ̀ẹ́ láti ṣàwárí òòsà tó ń mu ẹ̀jẹ̀ nílùú Ìbàdàn Kollington, Bàbá Suwe, Ogun Majek wà lára àwọn gbajúmọ̀ òṣèré tí ayé ti parọ́ ikú mọ́ sẹ́yìn Èèyàn 501 ló lùgbàdì àrùn Coronavirus ní Naijiria ní Ọjọ́ Abámẹ́ta Wọn ni ara ile aarẹ kan lo ta awọn lolobo pe Tunde ṣẹṣẹ de lati ipinlẹ mii ni, o ṣabẹwo si oludari ileeṣẹ ipọnpọ NNPC, Maikanti Baru to ṣẹṣẹ ku nipasẹ COVID-19.
Ondo State Election result 2020: INEC kéde èsì ìbò gómìnà níjọba ìbílẹ̀ méjìlá
Yóo bú ramúramù mọ́ àwọn eniyan inú agbo rẹ̀.
Owo awọn ọti lile wọnyi ko ju ara lọ rara, o si bẹrẹ lati aadọta naira si igba naira.
Bakan naa ni ijọba apapọ tun woye pe, irinwo miliọnu dọla ni owo ori ti ijọba yoo maa pa lọdọọdun lara igbó tita.
54 Nísisìyí, èmi kò sọ èyí láti pa ìjọ mi run, ṣùgbọ́n mo sọ èyí láti gbé ìjọ mi ró;
A ma mu ẹkunrẹrẹ iroyin naa wa fun yin.
Eyi tumọ si pe ẹni bẹẹ ti ko nkan ninu ọna ti igbẹ n gba jade.
O ni a o le ya ara wa kuro lara orilẹede wa."
Koda o fi da BBC News Yoruba loju pe lọwọ yii, ko soun to jọ bi aawọ laarin kabiyesi ati olori rẹ tabi laarin kabiyesi ati Mayegun ileẹ Yoruba, iyẹn KWAM 1 Ninu atẹjade kan eleyii ti agbẹnusọ fun KWAM 1 , Ọgbẹni Kunle Rasheed fi sita lọjọbọ, irọ lasan ni iroyin naa eleyii ti awsn eeyan kan kan n gbe kiiri lati ba awọn eekan kan lorukọ jẹ.
Kò gbọdọ̀ mu ọtíkọ́tí, ìbáà jẹ́ líle tabi èyí tí kò le.
O ni awon ti oro kan naa si n jiroro lowo.
Eyi ki se akọ̀ko irufẹ ìṣẹlẹ bè.
O ni: '''inu mi dun wi pe awọn akẹkọọ to lugbadi arun naa ko fi ami han, bẹẹ si ni ko buru pupọ lara awọn to fi ami han lara wọn' 'Bakan naa ni wọn si ti pe awọn obi awọn ọmọ naa lati le fi ọkan wọn balẹ, ki wọn si gba wọn ni iyanju pe, ki wọn ma mikan nitori alaafia ni awọn ọmọ naa wa.
“Ẹnikẹ́ni tí ó bá gba ọ̀kan ninu àwọn ọmọ kékeré yìí nítorí orúkọ mi, èmi ni ó gbà.
Ibi yòówù tí OLUWA bá fọn yín ká sí ninu ayé, bí ó tilẹ̀ jẹ́ òpin ayé, OLUWA yóo wa yín rí, yóo sì ko yín jọ.
Philippe n ṣiṣẹ pẹlu ileeṣẹ nla kan gẹgẹ bi olugbani nimọran lori eto aabo, ṣugbọn wọn da a duro lẹnu iṣẹ lẹyin ọdun kan ti a bẹrẹ si ni fẹra wa.
Ikọ agbabọọlu Naijiria ti gba ife ẹyẹ naa lẹẹmẹsan an ọtọtọtọ bayii, nigba ti alatako wọn South Africa ko tii gba ri rara.
Dẹtí sílẹ̀, ìwọ olùṣọ́-aguntan Israẹli,Ìwọ tí ò ń tọ́jú àwọn ọmọ Josẹfu bí agbo ẹran.
Iye epo rọ̀bì tí wọ́n ń kó níbùdó ìpọnpo ti dínkù, ṣé ẹ fẹ́ mọ ìdí i rẹ̀?
Awọn mejeeji yii lo n kọlu ara wọn, ti wọn si n tahun si ara wọn lori ayelujara lori awọn atẹjade kan ti awọn mejeeji gbe jade loju opo ayelujara wọn.
OLUWA níí darí ìgbésẹ̀ ẹni;a sì máa fi ẹsẹ̀ ẹni tí inú rẹ̀ bá dùn sí múlẹ̀.
Mo wí ninu ìdààmú ọkàn pé,“Èké ni gbogbo eniyan.
Oríṣun àwòrán, @inecnigeria Àkọlé àwòrán, Atẹjade Inec Amọ ṣa ajọ naa ni awọn yoo ṣi yi ba awọn oṣiṣẹ alabo ilu gbogbo jiroro lori bi awọn eeyan wọn ko ṣe ni ma ṣegbe lasiko idibo.
Oku mẹẹdọgbọn mii tun sun ni Plateau Ọpọ èèyàn ló ti pàdánù ẹmí wọn nínú ikọlù láàrin àgbẹ àti darandaran.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ọdọmọkunrin kan ree to n rin lojri omi ni ọna Kirkissoye.
Oríṣun àwòrán, @SpursOfficial Àkọlé àwòrán, Igba akọkọ ree fun Tottenham ni ipele aṣekagba UEFA Champions league Eyi si tumọ si pe ikọ yoo wu to ba bori ninu ifẹsẹwọnsẹ naa, ọmọ Afrika yoo wa nikalẹ lati gba ife ẹyẹ naa.
73ni saa kerin odun 2016, pelu igberu iko1.
“ijoba yii ti n sa ipa re lati mu atunse to monyan lori ba eto oro aje  to n se seke-seke , ti a jogun lodun 2015.
Àwọn tí wọ́n jẹ́ ọlọ́gbọ́n láàrin wọn óo máa la ọpọlọpọ lọ́yẹ, ṣugbọn fún ìgbà díẹ̀, wọn óo kú ikú idà, a óo dáná sun wọ́n, a óo kó wọn lẹ́rù, a óo sì kó wọn ní ẹrú lọ.
Lẹ́tà Obasanjo: Àjálù ń bọ̀ bíi ti Rwanda, tí Buhari kò bá ṣàtúnṣe ètò ààbò EFCC ń wádìí iléeṣẹ́ 'Bola Tinubu,' Alpha Beta Consulting Ltd' O fikun ọrọ rẹ pe ile iṣẹ ọlọpaa yoo ṣa ipa rẹ lati mọ orisun fidio ti Sẹnẹtọ Dino Melaye ti nanwo loju agbo naa.
Gómìnà Makinde fẹ́ dá àjọ tó ń gbógun ti ìwà ìbàjẹ́ sílẹ̀ l'Oyo
Ẹ wo ohun tí baba Adeboye sọ lórí ọ̀rọ̀ Coronavirus Ìjọ kò ní tilẹ̀kùn ilé ìjọsìn nítorí àrùn Coronavirus - Ondo PFN Ọkùnrin kan kú lẹ́yìn tí wọ́n lù ú 'fún pé ó ní coronavirus' Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Elebuibon: Àwọn àṣà àtọ̀húnrìnwá ló fa títa ẹ̀jẹ̀ nítorí ògùn owo O ṣalaye pe gbogbo awọn to wa sibi ipade itagbangba naa ni awọn fun ni ọṣẹ apakokoro (hand sanitiser) l'ẹnu ọna abawọle sibi ipade.
"Báyìí ni 50k ṣe dá ìfẹ̀hónú ""Ali Must go"" sílẹ̀ tó mú ọ̀pọ̀ ẹ̀mí akẹ́kọ̀ọ́ lọ Tunde Idiagbon, ọ̀gágun kògbagbẹ̀rẹ́ tó ní ẹ̀ẹ̀kan lóṣù ló yẹ kí ológun máa rẹ́rìín Kí lo mọ̀ nípa Olùṣirò owó Àgbà àkọ́kọ́ ní Afrika?"
Nígbà tí àwọn ọmọ Israẹli pín gbogbo agbègbè tí ó wà ninu ilẹ̀ náà ní ẹ̀yà kọ̀ọ̀kan tán, wọ́n pín ilẹ̀ fún Joṣua ọmọ Nuni pẹlu.
Kò sí ẹni tí ó kẹ́dùn iṣẹ́ ibi rẹ̀,kí ó wí pé, ‘Kí ni mo ṣe yìí?
Oluwa tún sọ fún un pé, ‘Bọ́ sálúbàtà tí ó wà lẹ́sẹ̀ rẹ, nítorí ilẹ̀ mímọ́ ni ibi tí o dúró sí.
Àkọlé àwòrán, Àwọn tí kò ráàyè wọlé sí pápá ìṣeré bu ẹnu ẹ̀tẹ́ lu bí àwọn òṣìsẹ́ aláàbò kò ṣe jẹ́ kí wọ́n o wọlé Àkọlé àwòrán, Awọn ọmọ ileeṣẹ ologun naa kò gbẹ́yìn níbẹ̀.
Wọn óo jẹ́ oníhàlẹ̀, onigbeeraga, ati onísọkúsọ.
A kò gbo̩dò̩ dá e̩nì ké̩ni lóró tàbí kí a lò ó ní ìlò ìkà tí kò ye̩ o̩mo̩ ènìyàn tàbí ìlò tó lè tàbùkù è̩dá ènìyàn.
Igba ti awọn ọlọpaa to kapa wọn ni awọn ara ilu to sun oorun asun forile oṣuka.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Fuji Music: Kollington Ayinla sọ ẹni tó dá orin Fuji sílẹ̀ gan an ní Nàiìjíríà Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Fuji Music: Kollington Ayinla sọ ẹni tó dá orin Fuji sílẹ̀ gan an ní Nàiìjíríà 15 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 16 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Agbaọjẹ olorin Fuji ni Naijiria, Alhaji Kollington Ayinla tun ti yanna na bi orin Fuji ṣe bẹrẹ lorilẹede Naijiria.
Alaafin: Oluwo àti Sunday Dare sọ irú ẹ̀dá ti Aláàfin jẹ́
Nomyange yii ni awọn ti ọrọ naa ṣoju wọn sọ wipe o ti ni iyawo pẹlu ọmọ, amọ o bẹrẹ si ni fẹ orẹbinrin rẹ yii, to si gba ile to n gbe fun un pẹlu dukia.
Ọjọ́ kẹtalelogun oṣù kẹta, tíí ṣe oṣù Sifani ni Modekai pe àwọn akọ̀wé ọba, wọ́n sì kọ òfin sílẹ̀ nípa àwọn Juu gẹ́gẹ́ bí Modekai ti sọ fún wọn.
"Tí mo bá ti múú, mo máa ń gbàgbé gbogbo nkan ni.
Ni bayii to wa ni Big brother Naija naa, afojusun rẹ ni lati gbadun ara rẹ ni ti ọdun 2020 yii.
Jonatani tún sọ fún un pe, “Yára má ṣe dúró.
Ṣugbọn nisinsinyii, mo ti gba àwọn ọmọ Lefi dípò gbogbo àkọ́bí ninu àwọn ọmọ Israẹli.
Ewe, balogun Akinjobi ko lati so pato iru ohun ija ogun ti o wole, sugbon O so pe, “atileyin ni awon ohun ija ogun naa je”  fun ise akanse ti won pe ni “operation Lafiya Dole ati “Operation Last Hold”  eleyi ti o n lo lowo nipinle Borno North ati ekun Lake Chad.
26 Ọ̀wàrà 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 3 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 5 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Alukoro ileeṣẹ ọlọpaa ipinlẹ naa, Fẹmi Joseph sọ fun BBC Yoruba pe, ọdọmọkunrin naa, Deji Adenuga ti awọn eniyan tun mọ si Dakar, ni wọn fura si pe o dana sun mọlẹbi naa ni ilu Igbodigo, nijọba ibilẹ Okitipupa l'oru ọjọ Aiku mọju ọjọ Aje, laarin aago meji si mẹta.
Ní alẹ́ ọjọ́ náà ni angẹli OLUWA lọ sí ibùdó ogun Asiria, ó sì pa ọ̀kẹ́ mẹsan-an lé ẹẹdẹgbaata (185,000) àwọn ọmọ ogun, wọn kú kí ilẹ̀ ọjọ́ keji tó mọ́.
 a sọ ni pakistan ati indian-ti a nṣe kashmir ati pe ede ede ti orilẹ-ede naa ni .
OLUWA Ọlọrun, ṣé o óo pa gbogbo àwọn tí wọ́n kù ní Israẹli nítorí pé ò ń bínú sí Jerusalẹmu ni?
Ó bọ́ aṣọ tí ó wọ̀ fún Dafidi, ó sì kó ihamọra rẹ̀ pẹlu idà ati ọfà ati àmùrè rẹ̀ fún un.
Kìnìún mẹ́rìnlá bọ́ sígboro Àwà gómìnà PDP ṣetán láti san #30,000 owó oṣù fáwọn òṣìṣẹ́- Dickson Ọjọ́ tí inú mi bàjẹ́ jùlọ gẹ́gẹ́ bíi ààrẹ ilé aṣòfin àgbà-Saraki Chris Isiguzo to jẹ aarẹ ẹgbẹ naa lo ni awada ni oun kọkọ pe ọrọ naa tẹlẹ nigba ti oun gbọ ki oun to fidiẹ mulẹ pe ootọ ni.
Ni Lyon ni France ni papa iṣerẹ ti wọn yoo ti gba aṣekagba idije naa lọjọ keje, oṣu keje, ọdun 2019.
Deontay Wilder blasted out Dominic Breazeale in one round to retain his WBC heavyweight crown at the Barclays Center in Brooklyn in the early hours of Sunday morning: https://t.
N óo ha erùpẹ̀ inú rẹ̀ kúrò, n óo sì sọ ọ́ di àpáta lásán.
Ẹ sì ranti pé OLUWA wà lọ́dọ̀ yín bí ẹ ti ń ṣe ìdájọ́.
Fún apá kẹfà Ìgbésí-ayé Alákọ̀wé, ẹ fìkàlẹ̀ lé e pẹ̀lú mi nínú ọkọ̀ ayọ́kẹ́lẹ́ yìí.
isele buruku ti o maa n waye naa .
Ní báyìí, Ó jé ọkàn pàtàkì lára àwọn àgbààgbà egbe oselu APC ni orílè-èdè yìí.
Nígbà tí Apolo wà ní Kọrinti, Paulu gba ọ̀nà ilẹ̀ la àwọn ìlú tí ó wà ní àríwá Antioku kọjá títí ó fi dé Efesu.
’ rèé Afọnja, ẹni tó finú wénú ní Ilọrin, àmọ́ tó jẹ iwọ Ẹfunsetan Aniwura, obìnrin tó ju ọkùnrin lọ Ọ̀rọ̀ǹpọ̀tọ̀niyùn, Aláàfin obìnrin àkọ́kọ́ rèé, tó ní nǹkan ọkùnrin Nigba ti akọroyin beere boya wọn ti wa bu omi suuru mu paapaa ti ijọba ko yi igbesẹ pada lori itusilẹ El-Zakzaky.
World water day: Ẹrin Ijesa, Ọ̀ṣun Oṣogbo, àwọn ibùdó ìgbafẹ́ tí ó níi ṣe pẹ̀lú omi ní ilẹ̀ Yorùbá
Lọdun 2000, 2002, 2004, 2006, 2008, 2010, 2012, 2013, 2015, 2017 ti wọn gbiyanju ẹ ni wọn ko ti bori lati dije rara.
30 Agẹmo 2020 Oríṣun àwòrán, others Ẹbi Oloogbe Ayo Fasanmi to doloogbe ti kede bi eto isinku rẹ yoo se ri lọjọ Isẹgun, ọjọ kẹrin, osu kẹjọ, ọdun 2020 yii.
7 2773 Orilẹede Burkina Faso 97 0.
Nígbà tí mo súnmọ́ ọ̀n díẹ̀ sí i, mo ṣàkíyèsí àwọn ènìyàn kọ̀ọ̀kan èjèèjì tí àwọn náà ń tọ ilé gogoro náà lọ.
Maa fun ẹ, mi o ni fun ẹ ni ere ti mo n ba ọmọ naa ṣe ti mo si n sọ fun awọn ọrẹ mi pe ki wan fun mi lowo ninu baagi mi""."
Ẹlẹgbọn agba funra rẹ, Biggie lo mu ayipada yi ba ofin idije naa.
Ọlọ́pàá ní àwọn ṣì ń ṣèwádìí ẹni tó bẹ́rí ní Alasiya l'Eko Lọdun to kọja ni ijọ naa ṣe ikowojọ oni pajawiri ni orilẹ-ede France lati wa owo ti wọn yoo fi tun ijọ to ti pe ọdun ẹgbẹjọ o le aadọta naa kọ eyi to ti bẹrẹ si ni da wo.
Ẹ sọ fún àwọn tí àyà wọn ń já pé:“Ẹ ṣe ara gírí, ẹ má bẹ̀rù.
Ninu idibo naa ni Akintoye ti jawe olubori to si di olori YorubaẸgbẹ́ Ilẹ̀ Yorubà gba Aṣíwájú tuntun!
19 Owewe 2019 Oríṣun àwòrán, Arsenal portal Àkọlé àwòrán, Arsenal Football club Ẹgbẹ agbaboolu Arsenal ti fi agba han ojugba wọn Eintracht Frankurt pẹlu amin ayo mẹta si odo.
BBC News Yoruba ṣe awari diẹ lara awọn igbeyawo wọnyii, awọn si niyii: Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ayẹyẹ ọjọ́ ìbí rẹpẹtẹ sọ̀ nílé Femi Abebayo, Iyabo Ojo àtàwọn òṣèré míì Níbo làwọn òṣèré apanilẹ́rìn ín wọ̀nyí tó pilẹ̀ sínima àgbéléwò Yorùbá wà?
Oríṣun àwòrán, @InsideMainland Gẹgẹ baa ti gbọ, asẹ yii lo mu ki ọga ọlọpaa ni ipinlẹ Eko, Edgal Imohimi, pasẹ fawọn osisẹ Sars to wa labẹ rẹ lati tete gbe asọ ọlọpaa wọ, eyi ti ko ba awọn osisẹ naa lara mu, ti wn si n beere pe ki isẹ tete gbe awọn kuro ni ipinlẹ Eko ni kia-kia.
igbalode konputa (laptops) pelu awon ohun elo miiran ti won fi n se isẹ ibi
Ọjọ kejidinlọgbon, oṣu kẹfa lo lanfaani lati pada si Belgium lẹyin ti o ha si ilu Eko fun ọsẹ kan ti ko ri baalu wọ nitori ajakalẹ arun coronavirus.
Idi rẹ niyi ti mo fi n wọọ kaakiri, ṣugbọn eyi ko ni pe ki n yan ẹni ti ko ba wọọ ni pọṣin o.
Ọlọrun mi, ranti mi, nítorí nǹkan wọnyi, kí o má sì pa gbogbo nǹkan rere tí mo ti ṣe sí tẹmpili rẹ rẹ́ ati àwọn iṣẹ́ ìsìn rẹ̀.
Ruga Settlement: A kò fipá mú ẹnikẹ́ni láti dá Ruga, àgọ́ Fulani sílẹ̀ -Iléeṣẹ́ aàrẹ
Igba ti ọkan lara wọn lọ fun ayẹwo ni ayẹwo fi han pe o ni kokoro aarun HIV.
Nítorí náà, OLUWA fi àjàkálẹ̀ àrùn bá Israẹli jà.
A fí ara mọ́ ìdájọ́ ikú Sharia tó tọ́ sí Olórin Yahaya- ẹgbẹ́ Amòfin Mùsùlùmí ẹ̀ka ìpínlẹ̀ Kano Ilé ẹjọ́ ju olè orí omi mẹ́ta sí ẹ̀wọ̀n, ó tún ní kí wọ́n san 60 miliọ̀nù Àlàyé rèé lórí bo ṣe le è dá Emèrè mọ̀ tàbí dara pọ̀ mọ́ ẹgbẹ́ wọn Ìdè jáá!
Ẹnìkan bá fi ohùn líle sọ̀rọ̀ láti ibi ìtẹ́ tí ó wà ninu Tẹmpili, ó ní, “Ó ti parí!
Lara eto naa, ni yoo  tun je ki UK tun se awon atunse kan ti yoo je ki won tun eka to n mojuto iwa ibajẹ lori ero ayelujara kọ si olu-ilu naa to wa ni, Nairobi.
Bí kò bá gbọ́, tún lọ bá a sọ ọ́, ìwọ ati ẹnìkan tabi ẹni meji; gẹ́gẹ́ bí ó ti wà ninu àkọsílẹ̀ pé, ẹ̀rí ẹnu eniyan meji tabi mẹta ni a óo fi mọ òtítọ́ gbogbo ọ̀rọ̀.
Igbimọ PCARA fẹsun kan pe Magu ko fọwọsowọpọ pẹlu awọn alaṣẹ tọrọ kan ni ilu London lati tete bẹrẹ ilana idajọ rẹ.
tóbẹ́ẹ̀ tí ohun tí ẹ óo máa fi ojú yín rí yóo yà yín ní wèrè.
Èyí tí ó gùn jù ni ó hù kẹ́yìn.
Oríṣun àwòrán, BASHIR AHMAD/TWITTER Abba Kyari Oṣu mẹta sẹyin ni aarun coronaviru pa olori awọn oṣiṣẹ fun Aarẹ Buhari tẹlẹ, Abba Kyari.
Reuters fi-kun un pe, “ikolu ohun waye lasiko aloole abewo omo ogun U.
Jesu dá a lóhùn pé, “Ẹnikẹ́ni tí ó bá fẹ́ràn mi yóo tẹ̀lé ọ̀rọ̀ mi.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Super touch: Roller Blader ni mí láti ọdún mẹ́jọ sẹ́yìn Wọn fi lede wi pe oju opo ayelujara gbọngan naa ni wọn ṣẹṣẹ mọ wi pe wọn ko faramọ igbeyawo akọ si akọ tabi abo si abo.
Àwọn nǹkan akikanju ti Bẹnaya ṣe nìwọ̀nyí, ó sì ní òkìkí, yàtọ̀ sí ti “Àwọn Akọni Mẹta”.
Samaria ni yóo ru ẹ̀bi ẹ̀ṣẹ̀ rẹ̀, nítorí ó ti ṣọ̀tẹ̀ sí èmi Ọlọrun rẹ̀, ogun ni yóo pa wọ́n, a óo ṣán àwọn ọmọ wọn mọ́lẹ̀, a óo sì la inú àwọn aboyún wọn.
5bn) owó tí Sani Abacha kó pamọ sókè òkun gba.
Nígbà kan, ogun bẹ́ sílẹ̀ láàrin Abija ati Jeroboamu.
"Bí mo ṣe ń tako Buhari bá ìjọba tiwantiwa mu - Ọbasanjọ Ọbasanjọ ni ọmọ òrùkàn tó di olóri orílẹ̀èdè lẹ́ẹ̀mẹ́ta ọ̀tọ̀ọ̀tọ̀ Ẹ̀yin ọba alayé ló mọ ọ̀daràn, ẹ ti mí lẹ́yìn láti wá wọn rí - Buhari Seyi Makinde làwa ń bá lọ lọ́jọ́ Satide - Ladọja Kìnìún tí wọn ń sìn yarí, ó pa olówó ati ọmọ olówó rẹ̀ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Olusegun Obasanjo: Ọmú ìyá mi ti mo fi ń mùkọ ni kekere ló jẹ ki ń lókun Ààrẹ Buhari ni ""bó tilẹ jẹ pé èmi àti Obasanjo ò jọ dúró si ibi kan náà lórí ọ̀rọ̀ ètò òṣèlú, síbẹ̀ mi ò fi ọwọ́ yẹpẹrẹ múu nítori gbogbo àwọn iranwọ rẹ̀ lórí ìdàgbàsókè Nàìjíríà."
 wọ ́ n kọ ́ ilé yìí sí ẹ ̀ gbẹ ́ agbègbè ọrọ ̀ ajé lagos island : victoria island , ( tí ó jẹ ́ agbègbè ibi ọjà títà àti ibùgbé ) ṣùgbọ ́ n ó jìnà sí agbègbè aláriwo .
Iṣẹ́ ọwọ́ eniyan ni àwọn oriṣa wọnyi; wọn kò lè gbọ́ràn, tabi kí wọn ríran; wọn kò lè jẹun, bẹ́ẹ̀ ni wọn kò lè gbóòórùn.
Ọpọ lara wọn wa lati awọn ibudo t'awọn to sa kuro nile wọn lẹyin ti Naijiria jọwọ ilu Bakassi to kun fun epo rọbi fun orileede Cameroon to lmule ti i llyin idajọ ile ẹjọ agbaye.
"A ṣe awa naa lee ni BBC tiwa.
Oríṣun àwòrán, DANIEL NWACHUKWU Àkọlé àwòrán, Papakọ ofurufu Imo Ipaya bẹ silẹ gẹgẹ bi ina naa ṣe bẹrẹ si ni jo wii wii ni ẹnu ọna abawọle papak ofurufu Sam Mbakwe ni ilu Owerri, ipinlẹ Imo.
Uche Okechukwu, Garba Lawal, Peter Rufai(Asole), Nwankwo Kanu, Augustine
Zulkifli wa fi asiko ohun lu gomina ipinle Oyo logo enu fun bi o se parowa
Àwọn dókítà Nàìjíríà ti fòpin sí ìyanṣẹ́lódì wọn Wo iye àwọn tó ti gbẹ̀mí ara wọn ní Nàìjíríà láàrin ọdún mẹ́rin ìjọba Buhari Gbèsè Nàìjíríà ti lé ní 18 tírílíọ́ọ́nù lábẹ́ ìṣèjọba Ààrẹ Buhari- DMO Wo bí iṣẹ́ abẹ wákàtí mẹ́fà, tí wọ́n fi dóòlà ẹ̀mí ìjàpá tí ọkọ̀ tẹ̀, ṣe lọ Kò sóhun tó ń jẹ́ ‘Captivus’ nílẹ̀ Oodua, mágùn ni mágùn ńjẹ́ - Babaláwo Wo àwọn obìnrin abúlé kan tó dáwó ra ọkọ̀ láti máa gbé aláboyún lọ ilé ìwòsàn ''Eto ọgbin ti ran Naijiria lọwọ nigba kanri, yoo tun ran wa lọwọ ti ijọba ba ṣe oun to tọ fun awọn ọdọ'' ''Ijọba gbọdọ pese awọn ẹrọ igbalode bii eleyii to n yọ okuta kuro ninu irẹsi abẹle ati bẹẹ bẹẹ lọ'' ''Ko dara bii Naijiria ṣe ni awọn eso ọgbin to pọ janturu, amọ ti ko si ohun elo igbalode lati yii awọn ohun ọgbin yii pada si oun jijẹ abi ohun ti awọn eniyan nilo ni ojoojumọ'' Bakan naa ni ọdọmọde agbẹ yii fikun wi pe ọpọlọpọ iṣẹ lo wa ninu ẹka agbẹ to fi mọ rira ati tita, abi kiko ounjẹ lọ si oke okun.
Ṣíṣí ni ìlẹ̀kùn rẹ yóo máa wà nígbà gbogbo, a kò ní tì wọ́n tọ̀sán-tòru;kí àwọn eniyan lè máa kó ọrọ̀ orílẹ̀-èdè wá fún ọ,pẹlu àwọn ọba wọn tí wọn yóo máa tì siwaju.
Afẹ́fẹ́ lásán ni ẹ̀ ń sọ̀rọ̀ sí.
Àwọn òbí mi rò pé ẹ̀jẹ́ ti ta sí ọpọlọ mi nígbà tí mo bẹ̀rẹ̀ sí ba ẹranko igbó ṣọ̀rẹ́
Ati pe wọn ti n gbe igbesẹ si n lọ lọwọ lati mọ awọn to ba wọn ṣiṣẹ, bi itọju ile, aṣọ fifọ lasiko ti wọn fi wa nilu ibadan l'agbegbe Bodija.
 Àmọ ́ ṣáájú ìgbàyí , ó ma ń ṣe ìpolongo àti ìpolówó ọjà lórí ẹ ̀ rọ asọ ̀ rọ ̀ -mágbèsì , tí ó sì tún bá àwọn ẹlòmíràn gné àwo orin wọn jáde farayé gbọ ́ .
Aare wa ro awon asofin lati ma se fi oro ohun fale, ki won tete panupo bowolu bilionu mẹ́rìnlélọ́gọ́jọ le mẹ́rìnlélọ́gọ́rùn ún Naira(N164 billion) eyi ti ajo INEC nilo lati bere igbaradi, sepese awon ohun elo saaju apapo eto idibo naa.
Bí ó bá jẹ́ pé ìtumọ̀ gbolohun yìí ye yín ni, pé: ‘Àánú ṣíṣe ni mo fẹ́, kì í ṣe ẹbọ rírú’ ẹ kì bá tí dá ẹ̀bi fún aláìṣẹ̀.
Amọ, Minisita fun ọrọ isẹ ati ile gbigbe, Babatunde Fashola sọ eyi lẹyin ipade awọn minisita se pẹlu Aarẹ Muhammadu Buhari nilu Abuja.
Ninu oro re, O so pe, asiko ti to wa yii, lati tun tesiwaju pelu aye miran.
Àwọn eniyan náà kó ẹyẹ ní ọ̀sán ati ní òru, ẹni tí ó kó kéré jù ni ó kó òṣùnwọ̀n homeri mẹ́wàá.
Ni tirẹ, ọmọ ile igbimọ aṣofin agba, Ben Murray Bruce ni, Bi aarẹ @Mbuhari ba lee na N3."
Ilẹ̀ náà sì wà ní alaafia fún ogoji ọdún.
Wọn yóo wá wá àwọn òkúta mìíràn, wọn yóo fi dípò àwọn tí wọ́n yọ kúrò, yóo sì fi ohun ìrẹ́lé mìíràn tún ilé náà rẹ́.
Oríṣun àwòrán, Reuters Àkọlé àwòrán, Awọn ẹlẹsin Kristiani ko pọ ni Sri Lanka Lẹyin ikọlu naa ni ọjọ Aiku, olori orilẹede naa, Ranil Wickremesinghe ni awọn agbofinro mọ wipe ikọlu le waye, ṣugbọn wọn ko gbe igbesẹ kankan lori ọrọ naa ki o to ṣẹlẹ.
Lara awọn iṣẹlẹ to ti waye ni bi wọn ṣe yọ olori ile aṣofin ipinlẹ naa.
Koda Gomina Babajide Sanwo-Olu ipinlẹ Eko naa wa lara awọn eeyan ọhun.
O Abiola’ Kò tọ̀nà láti gbé adájọ́ Onnogben lọ síwájú CCT - Adájọ́ fẹ̀yìntì Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Oduduwa Alphabet: òmìnira èdè ti dé fún Port Novo báyìí O yé ki Aarẹ Muhammadu Buhari kede adele ọga ọlọpaa miran ki o to digba ti ajọ to n risi ọrọ ọlọpaa buwọ lu iyansipo rẹ.
Wọn kò gbọdọ̀ fi ìwúkàrà sí i, bí wọ́n bá fi ṣe burẹdi, èmi ni mo fún wọn, gẹ́gẹ́ bí ìpín tiwọn ninu ẹbọ sísun mi; ó jẹ́ ohun mímọ́ jùlọ, gẹ́gẹ́ bí ẹbọ ìmúkúrò ẹ̀ṣẹ̀ ati ti ìmúkúrò ẹ̀bi.
Amugbalẹgbẹ aarẹ lori ọrọ ayelujara, Tolu Ogunlesi lo fi ọrọ naa lede loju opo Twitter rẹ.
Ghana, ti won ko lanfaani lati pegede fun idije agbaye wa ni ipo mẹ́tàdínláàdọ́ta lagbaye, ti won si di ipo kefa mu nile Afrika.
Aarẹ gbogboogbo fun ẹgbẹ olukọ fasiti lorilẹede yii, ASUU, Ọjọgbon Biodun Ogunbiyi sọ wi pe, ipade naa si n tẹsiwaju lọjọ miran nitori pe wọn ko i tii yanju aawọ naa.
Oríṣun àwòrán, APC Àkọlé àwòrán, Iroyin fi idi rẹ mulẹ pe awọn eekan oloṣelu lẹgbẹ oṣelu naa kaakiri awọn ipinlẹ ni wọn pin eto idibo naa mọ ara wọn lọwọ Hamzat fikun pe, itẹsiwaju ipinlẹ Eko pọn dandan ju ẹnikẹni lọ, nitorina ni oun se yẹba fun ẹnikeji oun ti awọn ti wa tipẹtipẹ.
O ni igbese ajo Inec lati sun ibo siwaju ku die kaato, o si di
ifilole awon ise akanse oju ona ọkọ meji ti o lo si Deba , ijoba ibile Yamaltu
Ogbeni Mohammed Bello labule Bolorunduro nijọba ibilẹ Oriire ni Ogbomọṣọ ni wọn lo ni Maalu meji ti awọn oniṣẹ ibi yii ko lọ.
Ẹ̀wẹ̀, lọ́nìí ọjọ keji, oṣù kẹta ọdun yìí ni gómìnà lásìkò ìpàdé ìgbìmọ aláṣẹ́ ìjọba ni wọ́n ti pa ohùn pọ láti gba aba ìgbìmọ ìwádìí wọ́n wọlé, paàpàá jùlọ lóri èyi to jẹ mọ ìlàna ẹkọ ni ìpinlẹ̀ Osun.
Amadou Sagna lo ṣide iya fun ikọ Flying Eagles lẹyin to gba goolu akọkọ sawọn fun Senegal ni iṣẹju mẹrindinlogoji.
”Ikeme dahun pe, “Inu mi dun pupo fun ife n la ti ajo NFF ati ijoba fi n han mi.
Ìrètí nínú ènìyàn, irọ́ funfun gbáláhú!
Lọkan awọn Gomina wọnyi, anfaani lati da awọn ọmọ yii pada si ipinlẹ wọn lo de yi, Awọn kan gba pe dida wọn pada yoo jẹ ọna lati koju ipenija eto ẹkọ alimajiri ti wọn ti fẹ wọgile tipẹ ni ariwa Naijiria tawọn musulumi pọ si.
Èyí ni ó sún mi dé etí bèbè ìparun,láàrin àwùjọ eniyan.
Ọba Babiloni kó ẹẹdẹgbaarin (7,000) àwọn akọni ní ìgbèkùn ati ẹgbẹrun kan (1,000) àwọn oníṣẹ́ ọwọ́ ati alágbẹ̀dẹ, gbogbo wọn jẹ́ alágbára tí wọ́n lè jagun.
Tinubu rọ ijọba aarẹ Muhammadu Buhari ati igbakeji rẹ, Yẹmi Osinbajọ lati yago ketekete si erongba yoowu to ba nii ṣe pẹlu afikun owo ori ọja, VAT.
Haruna n ta igi idana to ba ṣe ta lati oko fun ọpọlọpọ ọdun.
Àwọn ọmọ Bẹtilẹhẹmu jẹ́ mẹtalelọgọfa (123)
Ó ṣe ni laanu pé àwọn Aláwọ̀-dúdú ni Ọlọpa nda dúró jù ni ojú ọ̀nà ọkọ̀, ti ó dẹ̀ n kú ni irú idá dúró bẹ́ ẹ̀.
" lẹ ́ yìn ìyanu tí ó gbé ọmọ rẹ ̀ tí kò lè rìn dìde ní port-royal , ó ya àwòrán ẹ ̀ yẹ yìí "" ex-voto de 1662 "" , tí ó wà ní louvre , tí wọ ́ n fi ṣàpèjúwe ọmọ ayàwòrán yìí pẹ ̀ lú ìyá olọ ́ lájùlọ agnès arnauld ."
Bẹ́ẹ̀ ni àwọn ti orí ilẹ̀ wà.
3 146385 Orilẹede Phillippines 8709 8.
5 5011 Orilẹede Benin 44 0.
Ẹkunrẹrẹ ọ̀rọ̀ rẹ n bẹ ninu fọnran yii: Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ayefẹlẹ - Ara ìjọba ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́ kọ òtítọ́ ní wọ́n ṣe fẹ́ wó iléèṣẹ́ rédíò mi Ọjọ kẹtala, oṣu Kẹjọ ni ijọba kọ lẹta si ileeṣẹ redio Fresh FM pe ko 'gbe ile naa kuro nibi to wa laarin ọjọ mẹta, bi bẹ ẹ kọ, wọn yoo wo ni.
ibile Bwari fagile yiyan asofin  Ademola
Ilé ìṣe náà yoo bere si ki ṣe egberun kan rẹ ni ojúmọ́ láti ọ̀sẹ̀ tó ń bọ̀ lọ (6 April).
8bn owó àìtọ́ lọ́wọ́ mi ní tipá - Ẹlẹ́rìí Ọ̀pọ̀ ohun tó gbé mi kúrò nínú ẹgbẹ́ PDP rèé - Dogara ṣàlàyé Kayefi nla lo jẹ nigba ti Sani ṣalaye idi to fi hu iwa buruku to hu naa.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ile ejo kan ti so ni odun to koja pe ijoba ipinle ati ibile ko le se igbeyawo Ni kete ti Ọgbẹni Siddiqi si yọju sita ni wọn kọlu u - wọn ju u si abẹ ọkọ bọọsi kan.
O ni ohun to dara ni pe orilẹede Naijiria jawọ 'boya nitori pe o ti yee pe ọrọ aje rẹ ko lee duro ni ifẹgbẹkẹgbẹ pẹlu awọn orilẹede yooku ninu adehun naa.
Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Fídíò, Nigeria movie industry: Àgbà òṣèré, Lere Paimo ní àìgbọràn ló ń da ọ̀pọ̀lọpọ̀ àwọn òṣèrè sinimá láàmú11 Ọ̀wàrà 2020 Fídíò, Wole Soyinka sọ ìdí tó fi ni òun a fi màálù Fulani ṣe súyà fáwọn èèyàn abúlé23 Owewe 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Apá ọ̀tún tí mo wò, mo tún rí kábá
O fi ọrọ yii sita ninu fọnran fidio kan lẹyin ti Twitter yọ fidio to kọkọ ti sọrọ nipa lilo oogun yii lati tọju arun Covid-19.
ohun ni asoju orile ede Naijiria ni United Stated adajo, Sylvanus Nsofor,
Loju opo twita wọn ni wọn fi ikede naa si.
Ìṣòro jíjẹ́ ìyá n dáàgbé ló sọ mí di àtúnbí krístíẹ́nì - Remi Tinubu Kí ló ń fa wàhálà láàrín Kunle Afolayan àti Mike Ezuruonye lórí ayélujára?
Ó pe ọba nísàlẹ̀, ó sì sọ fún un, ọba bá dáhùn pé, “Bí ó bá jẹ́ òun nìkan ni, ìròyìn ayọ̀ ni ó ń mú bọ̀.
” Nítorí náà, ó kọ̀, kò mu ún.
BBC and MTN: ọ̀fẹ́ ni ẹ o máa gbọ́ ìròyìn Yorùbá, Pidgin, Igbo àti Hausa lórí 'MyMTN App' yìn!
Nitori naa,won ti pasẹ fun  gbogbo minisita lati “ri
Eji Gbadero, ọmọ Ibadan àti jayé-jayé ọmọ ónílẹ̀ ti wọn yẹgi fun l'Eko Ogun Àgbẹ́kọ̀yà, ìjà òmìnira fáwọn àgbẹ̀ ni àbí ìfẹ̀míṣòfò?
Gbajugbaja asole ohun kede ifeyin ti re lori ero ayelujara Twitter,
Wọn wa n fewe ọmọ mọ aarẹ Buhari leti pe bawọn ologun ba tun bẹrẹ akanse eto lasiko yii, ọrọ naa lee yiwọ pupọ.
oṣelu APCEto ibo didi naa ko yọ Babatunde Fasọla silẹMinisita feto ohun amusagbara, ile-igbe ati eto ina mona-mona, Babatunde Raji Fashola ati aya rẹ, Emmanuella Abimbola Fashola, lo dibo ni wọọdu G3, agọ idibo keji, nile ẹkọ girama kekere to wa ni opopona ltolo, ladugbo Surulere, niluu Eko.
Covid-19 Wedding: Ọkọ àti Ìyàwó yìí ti dájọ́ sọ́ná ṣáájú Coronavirus
Gege bi O se so, “Fifun omo loyan lati ipo oojo si osu mefa, yoo ran omo ohun lowo lati dagba, yoo mu igberu ba ogbon ori, bee si ni yoo mu ilera ti o peye ba omo naa.
Gege bi aare Buhari se so,”Lataari ikede ajo NEMA pe, o seese ki isoro omiyale sekolu si awon ipinle kookan lorile-ede Naijiria.
Ọmọ inu obinrin naa ku ni kete ti o pari iṣẹ abẹ yi ti iya ọlọmọ ọhun naa si gbẹmi mi lẹyin igba diẹ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ondo Accident: Agbègbè Awoyaya ní gáréjì Ifẹ l‘ondo ní ìjàǹbá náà ti wáyé 21 Ọ̀wàrà 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ìsẹ̀lẹ̀ ìjàmbá ọkọ̀ náà wáyé ní aago mẹ́rin àárò èyí tó mú ẹ̀mí ènìyàn márùn ún lọ, tí ènìyàn méjì sì farapa.
Bi ere bi ere ni iroyin yi ṣe bẹrẹ ṣugbọn ka to diju ka to ya, o ti di nkan tawọn eeyan n ṣalabapin rẹ kaakiri ayelujara.
Fayemi salaye pe panti lasan ni won n da si ori ilẹ naa ti ko si si aridaju pe ohunkohun bii ile wa lori ilẹ ọhun ri.
Ikọ agbabọọlu Super Eagles ti Naijiria ti gba ife ẹyẹ yii lẹẹmẹta sẹyin ni eyi ti wọn dẹ tun fẹ fi tọdun 2019 ṣe ikẹrin wọn.
Adari ile-ise ọlọpaa lorile ede Naijiria, Mohammed
Diẹ nibẹ ni: Àkọlé àwòrán, bbc news Yoruba/facebook Bee naa ni àwọn mii gba pe igbesẹ to dara fun un lo gbe pe: Àkọlé àwòrán, Awọn kan gba pe o ti n re Moses ni Ẹ wo ọrọ awọn mii ni ori bbc news Yoruba ni facebook yin ati @bbcnewsYoruba lori instagram wa.
Àrẹ̀mọ Ooni Adeyeye Ogunwusi ti wọ Ààfin Ile Ife fún ìgbà àkọ́kọ́ Èyí ni ìtàn Ọkùnrin tó rí ẹ̀wọ̀n he nítorí àkùkọ aládúgbò rẹ̀ tó pa Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Gómìnà ìpínlẹ̀ Benue, Samuel Ortom ti parí ìjà láàrin akọ̀ròyìn Channels TV, Pius Angbo àti Ifeyinwa Angbo, ìyàwó rẹ̀8 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Ronke Oshodi-Oke: Ọkọ mi kò mọ̀ pé òṣèré ni mi nígbà tí a pàdé- Ojo8 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 5:03 Fídíò, Omolola Arohunmolase Welder: Mo ti fí iṣẹ́ 'Welder' gbayì láwùjọ, tó mo fi tọ́ ọmọ yanjú, Duration 5,039 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 4:11 Fídíò, Oba Adeyeye Ogunwusi: Ojú mi ti rí lọ́pọ̀ lọpọ̀, ọ̀pọ̀ èèyàn ni kò tilẹ̀ gbàgbọ́ pé mo lè jọba- Ooni, Duration 4,117 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Èyí tí a wò jùlọ 5:03 Fídíò, Omolola Arohunmolase Welder: Mo ti fí iṣẹ́ 'Welder' gbayì láwùjọ, tó mo fi tọ́ ọmọ yanjú, Duration 5,039 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 5:39 Fídíò, Akomolede ati Asa lori BBC: Olùkọ́ Kikelomo Ogunboye tan ìmọ́lẹ̀ sí ìwà olè ọ̀gá ọlọ́pàá Audu gẹ́gẹ́ bí àwòkọ́ṣe àsìkò yìí, Duration 5,398 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 4:11 Fídíò, Oba Adeyeye Ogunwusi: Ojú mi ti rí lọ́pọ̀ lọpọ̀, ọ̀pọ̀ èèyàn ni kò tilẹ̀ gbàgbọ́ pé mo lè jọba- Ooni, Duration 4,117 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 4:43 Fídíò, Promise Akinlade: ọmọ ọdún mọ́kànlá tó ń fi ìlù dárà bíi àgbàlagbà sọ̀rọ̀ nípa tálẹ́ǹtì rẹ̀, Duration 4,437 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 0:59 Gbọ́, Ìsẹ̀lẹ̀ jákèjádò orílẹ̀èdè àgbáyé láàárín ìṣẹ́jú kan, Duration 0,59wákàtí 5 sẹ́yìn 7:03 Fídíò, Olumuyiwa Bolade Adedeji Military Bruitality: Bí arákùnrin onípèníjà ara tí sọ́jà lù ṣe dé, Duration 7,035 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 4:45 Fídíò, Yoruba Films: Ẹ̀ẹ́ bẹ̀ mi kúrò láyé ni, mi ò lè kú - Fadeyi Oloro, Duration 4,4526 Èrèlè 2020 2:48 Fídíò, Esther Ajayi: Èmi náà ti borí ìṣòro rí ló ń mu mi ṣojú àánú, Duration 2,481 Ògún 2019 6:08 Fídíò, Adebola Ademilua: Àìrísẹ́ ṣè lẹ́yìn ìwé kíkà ló sọ mi dí ìyá onírú, mo dúpẹ́ tèmi, Duration 6,0827 Bélú 2020 2:36 Fídíò, Sotitobire: Ìdájọ́ òdòdò ló fẹsẹ̀ múlẹ̀ lórí ọ̀rọ̀ Pásítọ̀ Sotitobire - Agbẹjọ́rò fún ìjọba, Duration 2,367 Ọ̀wàrà 2020 BBC News, Yorùbá Ìdí tí ẹ fi le è nígbàagbọ́ nínú ìròyìn BBC Ìlànà Lílò Nípa BBC Òfin Àṣírí Cookies Kàn sí.
Lara awọn sinima ti Ade Love ṣe, ko to silẹ bora ni Ija Ominira, Ajani Ogun, Kadara, Taxi Driver ati Iya ni Wura.
Wọn ni eniyan mẹwa ni ipinlẹ Eko, méjì ní Abuja, meji ni Oyo, ẹyọkan ni Delta ati ẹyọkan miran ni Katsina.
Oríṣun àwòrán, Twitter/Pep Team Manchester City lo papa jawe olubori lẹyin ti wọn gba pẹnariti wọ le ti Liverpool si le da mẹrin pada.
Ẹ̀wẹ̀, ọ̀rọ̀ náà ti ńtàn kálẹ̀ débi pé lorí ẹ̀rọ ayélujára, àti Kẹ́mi Adeọsun, àti ìjọba àpapọ̀ ni àwọn ọmọ Nàìjíríà ti ń nàka sí.
Oríṣun àwòrán, @Gospel film Aṣọ bi oriṣi mẹta ni tọkọtaya tuntun naa wọ fun eto idana naa, ti wọn si wọ kaba funfun ati kootu funfun lọ si ṣọọṣi lọjọ Satide.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Lẹyin naa lo sọ fun ẹbi rẹ kan pe o n rẹ oun ki o to pada sori ibusun rẹ ki ẹlẹmi to gba a.
Awọn ohun amayedẹrun bii ina ati bẹẹbẹẹ lọ ko duro deede.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, What causes coronavirus: Akeugbagold sọ àṣírí ohun ti àrùn coronavirus ń dá lárá f Kosoko lo kan lati gun ori itẹ sugbọn ogun ati ọtẹ dìde sii, ti Oluwole si jọba lẹyin rẹ lọdun 1836 sugbọn digbi ni Oshodi wa lẹyin Kosoko, ko le de ori itẹ, ti ko si gbagbe ajọsepọ rẹ pẹlu baba Kosoko.
Ṣugbọn wọ́n gbé ọ sọ sinu pápá, nítorí pé wọ́n kórìíra rẹ ní ọjọ́ tí wọ́n bí ọ.
Wọ́n sọ ohun tí ó ṣẹlẹ̀ fún obinrin náà.
Gómìnà Sanwo-Olu pàṣẹ pé kí wọn tú ẹléwòn 6 sílẹ lásìkò Kérésìmesì Funke Akindele, Toyin Abraham, Bimbo Oshin ṣe Kérésìmesì lọ́nà àrà Ninu abala keji ifẹsẹwọnsẹ ọhun ni Redmond naa sọ goolu tirẹ sinu awọn.
Ki Ighalo to kuro ni ikọ Supper Eagles, oun ni ẹni to gba bọọlu to pọju sinu awọn ninu idije AFCON to waye lọdun 2019 pẹlu bọọlu meje.
Bi ẹ ti mọ pe, ilu Eko ni orile ede Britain fi se olu-ilu lasiko ijoba amunisin, Idi niyi ti a gbodo se ri i pe opolopo okoowo lati orile ede Britain lo gbodo wa niluu Eko.
"Olùdíje gbé APC lọ sílé ẹjọ́ nítorí èsì ìbò Secondus pẹtu saawọ nínú PDP Ọ̀sun ""Ó ní ìdí tí mo fi ń padà sí PDP"" Àwọn obìnrin gba Naijiria lọ́wọ́ ìdójútì Asaba 2018 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!"
Kíni ìdí ti àwọn ọmọ ogun fi n ṣọ́ àwọn Imaam ni Mecca?
Dipo ki o ko ba ọrọ aje, enelamah ni kiko ọja ilẹ okere wọle lọna aitọ gan la gbudọ mu kuro lọna.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìjọba: Zakzaky ń kó èrò jọ lọ́nà tó lòdì sófin 15 Èbibi 2018 Oríṣun àwòrán, @ELBINAWI Àkọlé àwòrán, Ọjọ́ Ajé ni wọ́n ti gbé asaájú ẹgbẹ́ Shiite naa wá sí ìlú Kaduna, Asáájú ẹgbẹ́ ẹlẹ́sìn Shiite, Sheik Ibrahim Zakzaky yọjú sílé ẹjọ́ giga ti Kaduna lọ́jọ́ ìsẹ́gun.
Bo tilẹ jẹ pe, kii ṣe fun nkan to dara.
 Ẹ ̀ sìn ìbílẹ ̀ kò jẹ ́ alátakò fún ẹ ̀ sìnkẹsìn ni wọ ̀ ngbà tí ẹ ̀ sìn náà bá lé mú ire bá àwọn olùsìn .
Awọn awakọ ero naa ko gbẹyin ninu awọn eeyan to n rawọ ẹbẹ s'ijọba lori iyanṣẹlodi Asuu, gẹgẹ bi wọn ṣe fi kun ọrọ wọn wipe, wọn ko ni ri iṣẹ ṣe ti gbogbo akẹkọ ba fi ọgba ile ẹkọ naa silẹ nipasẹ iyanṣẹlodi awọn olukọ wọn.
9 188969 Orilẹede Costa Rica 2401 48.
Ọyọ: Adebayọ Adelabu ni wọn dibo yan lati dije fun ipo gomina ipinlẹ Ọyọ l'ọdun 2019.
Wo àwọn gómìnà Nàìjíríà tó tí lùgbàdì Covid-19 àti ipò tí ìlera wọ́n wà Ìjọba ilẹ̀ Canada bẹ̀rẹ̀ iṣẹ́ lórí fọ́ọ̀mù àwọn tó fẹ lọ sí orílẹ̀-èdè náà Pásítọ̀ tó bá Ọlọ́run jiyàn kó tó di Ààrẹ Ǹjẹ o yẹ kí èèyàn máa sùn lẹ́nu iṣẹ́?
Lati igba ti ọrọ igbẹjọ rẹ naa ti bẹrẹ lo si ti di gbajugbaja ni aarin awọn ọdọ, paapaa julọ awọn to rii gẹgẹ bii ẹni to n ja fun awọn ọdọ nitori aarin awọn ọdọ ni yahoo-yahoo pọ si julọ.
Bí atẹ́gùn ṣe ń fẹ́ ni àwọn igi náà ń fì sọ́tùn-ún sósì pẹ̀lú ẹ̀lẹ̀.
27 Agẹmo 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Oluwo ti ilu Iwo, Oba Abdulrasheed Akanbi ti kìlọ̀ fún ìjọba láti dojú kọ ètò ààbò tó mẹ́hẹ kí ogun ó má báa wáyé.
Ṣe ìlérí fún mi pé, ìwọ ni olùgbàlà mi.
Inú mi dún púpọ̀ bí mo ti ri yín yìí.
Bakan naa ni wọn fikun pe, laipẹ ni wọn yoo fi kede ọjọ ti wọn too ṣe ipade apapọ ẹgbẹ.
Ṣugbọn kí olukuluku ronú níwọ̀n, kí ó máa ṣe jẹ́jẹ́, níwọ̀nba bí Ọlọrun ti pín ẹ̀bùn igbagbọ fún un.
Bi orilẹ-ede Naijiria ti darapọ mọ gbogbo agbaye lati ṣe ayajọ didena gbigba ẹmi ara ẹni, akọsilẹ ti fihan pe ọta le lugba eeyan o le mẹrin ni wọn ti ṣekupa ara wọn lorlẹede yìí lọdun mẹrin ṣẹyin.
Nigba ti ọpọ ọdọ ko fi ayọ ominira yii han to pe o yẹ ki nkan ti ṣẹnu re ju bayii lọ ni China lẹyin aadọrin ọdun ominira.
PẸ̀LÚ ÀWỌN ÀFIKÚN LÁTI ỌWỌ́ ÀWỌN ÀTẸ̀LÉ RẸ̀ NÍNÚ ÀJỌ ÀÀRẸ TI ÌJỌ NÁÀ
"#BBCNigeria2019 ""Ohun to kun fun Naijiria lati ṣe ni ilana idibo igbalode (electronic voting) ki awọn eeyan lee wa ninu ile wọn ki wọn si dibo lai si inira."
Amọ, gbogbo ọrọ to sọ yi bi awọn ọmọ Naijiria ninu, ti wọn si fi ọrọ gun un lara lori ẹrọ ayelujara.
Nipinlẹ Imo, awuyewuye waye ni ọdun 2017, nigba ti gomina wọn tẹlẹ, Rochas Okorocha ṣe idasilẹ ileesẹ idunnu, Ministry of Happiness.
Bẹẹ ba gbagbe, laipẹ yii ni ẹgbẹ NURTW lẹkun iwọ oorun guusu Naijiria ni oun ko faramọ iyansipo alaga tẹlẹ fẹgbẹ awakọ ero nipinlẹ Ọyọ, Mukaila Lamidi, ti gbogbo eeyan mọ si Auviliary gẹgẹ bii oludari awọn alakoso gareji tijọba sẹsẹ yan.
Akọwe iroyin fun Gomina ipinlẹ, Taiwo Adisa lo fi idi ọrọ naa mulẹ fawọn akọroyin lọjọ Iṣẹgun.
Síbẹ̀ náà ṣáá, ìwọ̀ntúnwọ̀nsì ni ohun gbogbo.
Ìròyìn sọ pé ẹgbẹ̀rún lọ́nà ogójì dọ́la ni ìjọba ń pàdànú láàrin ọdún mẹrin.
Wọn fi i silẹ lọdun kan naa.
Ààrẹ sọ èyí di mímọ̀ lóri ẹ̀rọ twitter rẹ̀.
 Òun ni gómìnà tí ó ń bẹ lórí àléfà lọ ́ wọ ́ lọ ́ wọ ́ ní ohun ni gomina ìpínlẹ ̀ Ọ ̀ yọ ́ in south-western nigeria .
5 Àti, kíyèsíi, nítorípé ìwọ kò tẹ̀síwájú gẹ́gẹ́bí o ṣe bẹ̀rẹ̀, nígbàtí o dáwọ́lé lati máa túmọ̀, ni mo ṣe gba ànfàní yìí kúrò ní ọwọ́ rẹ.
Ìrańńṣẹ́ náà jẹ́ ọ̀kan nínú àwọn ẹ̀dá ọ̀run, àwọn ará ayé a sì máa pè é ní Aṣojú-Olódùmarè.
5 billion) lati maa se pasipaaro owo ninu osu karun un odun ti a wayii.
Ní gbogbo ọjọ́ ayé rẹ̀ ó ṣe ohun tí ó tọ́ lójú OLUWA nítorí pé Jehoiada alufaa ń tọ́ ọ sọ́nà.
Èré Ọṣun: Àtáója ní wọn kò jí ère Ọṣun, ó sì wà níbi tó wà
Ọba Ijẹ̀bú-Jẹ̀ṣà ló máa ń fi Ọwá tuntun han gbogbo Ìjẹ̀ṣà gẹ́gẹ́ bí olórí wọn tuntun lẹ́hìn tí ó bá ti ṣúre fún un tán.
Oga agba ekun GOC 2 Division, ogagun Okwudili Fidelis Azinta dupe pupo lowo COAS fun sise afihan ipilese didawole ohun osin yii, ti  o si je pe bi won ba mojuto daradara awon ti o je anfaani ninu re yoo po, ti yoo si tun se anfaani fun idagbasoke ogbin ati pipese ounje lopolopo lorile-ede yii.
Nígbà tí ó sì jẹ́ pé Amnoni lágbára jù ú lọ, ó fi tipátipá bá a lòpọ̀.
Diego Maradona: Àgbàọ̀jẹ̀ agbábọ́ọ̀lù Argentina ṣiṣẹ́ abẹ lórí ẹ̀jẹ̀ tó dì sí i lọ́pọlọ lẹ́yìn ọjọ́ ìbí ọgọ́ta ọdún
APC supporters from all the 33 Local government arears of Oyo state are already gathered at Adamasingba Stadium, Ibadan, Oyo state capital for the governorship primaries.
Ajọ JAMB sọ siwaju pe lori ẹrọ alagbeka awọn aṣedanwo ni wọn yoo ti kọkọ ṣe iforukọsilẹ ki wọn tilẹ to yọ owo lapo lọ fọọmu.
Oríṣun àwòrán, AFP Àkọlé àwòrán, Alaṣẹ Luxemburg, Xavier Bettel ṣafihan ero rẹ ni kikun lasiko to n ṣe ipade pẹlu awọn akọroyin.
Awọn ọdọ wa ko ri ọjọ ọla ti o dara ni ilẹ baba wọn, idi si niyi ti wọn fi n sare gba oke okun lọ.
Kí sì ni ìrètí mi, tí n óo fi tún máa ní sùúrù?
Nítorí náà, wọ́n sọ orúkọ ibẹ̀ ní Mara, ìtumọ̀ èyí tíí ṣe ìkorò.
Àgbo tí mò ń lò láti jò kó bá mi, ìdí mi ti yọ́ tán - Nkechi Blessing figbe ta Lọsẹ to kọja si ni ariwo ta pe awọn gomina ipinlẹ ni Naijiria ti n gbero lati lọ ya Trilliọnu mẹtadinlogun naira ninu owo ifẹyinti awọn osisẹ ti wọn n da pamọ.
Ṣugbọn níbi tí mo ti ń lọ sókè sódò, tí mò ń ṣe àwọn nǹkan mìíràn, ọkunrin yìí sá lọ.
Ìwọ tí ò ń gbé inú ọgbà,àwọn ẹlẹgbẹ́ mi ń dẹtí,jẹ́ kí n gbọ́ ọ̀rọ̀ rẹ.
Aare soro ohun di mimo fun
“Nítorí náà, lójú gbogbo ọmọ Israẹli, lójú ìjọ eniyan OLUWA, ati ní etígbọ̀ọ́ Ọlọrun wa, mò ń kìlọ̀ fun yín pé kí ẹ máa pa gbogbo òfin OLUWA Ọlọrun yín mọ́, kí ẹ̀yin ati arọmọdọmọ yín baà lè máa gbé ilẹ̀ yìí títí lae.
Oríṣun àwòrán, @jidesanwoolu O ni lootọ loun kii dá si ọrọ oṣelu ṣugbọn eyi to nsele yii, oun ko le dakẹ.
Kilo fa mimu akọroyin, Tony Ezimakor?
Imọ tuntun ti fihan wipe igbẹ ọmọde le koju awọn aarun bii jẹjẹrẹ, sisanra l'asanju, aisan ìtọ̀ suga ati awọn aisan ẹjẹ miran.
Gomina Sanwo-Olu ni ko si aniani pe iye awọn to n ni arun naa n peleke sii, sibẹ iroyin aṣeyọri itọju awọn wsnyii n fihan pe iroyin ibanujẹ nikan kọ lo sodo si ọrs arun naa bayii.
Ṣebí ó sọ pé ọmọ Ọlọrun ni òun.
Gbogbo ọdún tí Seti gbé láyé jẹ́ ẹẹdẹgbẹrun ọdún ó lé mejila (912), kí ó tó kú.
Àwọn ìpẹ́ náà lẹ̀ mọ́ ara wọn tímọ́tímọ́,tóbẹ́ẹ̀ tí afẹ́fẹ́ kò lè fẹ́ kọjá láàrin wọn.
Ohun tí ó ṣe pataki ni pípa àwọn òfin Ọlọrun mọ́.
Gbogbo wọn jẹ́ arọmọdọmọ Makiri, baba Gileadi.
Oríṣun àwòrán, Lizzy Anjorin A kii ri ẹfọn ta lẹẹmeji lawọn eeyan fi fọto yiya se pẹlu Alaafin.
Mọ̀ sí i nípa díẹ̀ lára àwọn èèyàn tí ikú wọn 'láti ọwọ́ ọlọ́pàá' milẹ̀ tìtì ní Nàìjíríà Àwọn aṣòfín ní ìpínlẹ̀ Edo ti yọ Abẹnugan Ilé, Francis Okiye bí jìgá Inú mi dùn sí iwọ́de EndSARS tàwọn ọdọ́ Nàìjíríà ń ṣè - Ooni Ogunwusi Àìbìkítà yíì gbọ́dọ̀ dópin, ìjọba gbọdọ̀ mú ẹ̀dùn ọkàn àwọn aráàlú lọ́kùnkúndùn- Agbẹjọ́rò Àgbà Ìfẹ́hònúhàn 'End SARS' ń tẹ́síwájú láì jẹ́ pé Buhari ṣe.
Àwọn ọkunrin wọnyi bá kó ara wọn jọ.
adari ile-eko fafiti ti Fountain , to wa ni Osogbo ni ipinle -Osun,ojogbon
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, AFCON 2019: Inú mi dùn pé mo jẹ́ ẹni àkọ́kọ́ tó ṣojú Nàíjíríà fún ìgbà 100 Wo ohun tó yẹ ki o mọ̀ nípa Burundi: Swallow ti Burundi ni wọn n pe orukọ inagijẹ ẹgbẹ agbabọọlu to n gba fun orilẹ-ede Burundi.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ondo Kidnap: Géńdé agbébọn jí adájọ́ gbé lọ ní ìpínlẹ̀ Ondo 23 Ọ̀wàrà 2019 Oríṣun àwòrán, @HQNigerianArmy Iroyin kan to n tẹ wa lọwọ ni yajoyajo ti ni awọn eeyan kan ti wọn fura si bii ajinigbe ti ji adajọ ile ẹjọ giga ijọba apapọ kan gbe lọ nilu Akurẹ.
Ofin ifẹyinti fun awọn gominani ipinlẹ Eko: Ida ọgọrun Iye owo osu ti gomina to ba wa lori oye ngba Ọkọ ayọkẹlẹ tuntun mẹfa, lọdun mẹta-mẹta Ọkọ ayọkẹlẹ tuntun marun fun igbakeji gomina, lọdun mẹta-mẹta Ile nla kan nilu Eko, ọkan ni ilu Abuja Ile kan soso ni ilu Eko nikan ni igbakeji gomina yoo lẹtọ si Eto iwosan ọfẹ fun awọn gomina, igbakeji gomina ati awọn ẹbi i wọn titi di ọjọ iku wọn Awọn osisẹ atọju ile marun ti awọn pẹlu lẹtọ sii owo ifẹyinti Owọ ọjẹmọnu fun rira ijoko ati ohun elo ile miran.
O ni anfani ti Gboyega Oyetọla fi tayọ awọn oludije ti o ku ni oye ati iriri rẹ nipa eto iṣejọba.
- Aráàlú ń bèèrè Bakan naa lo rọ awọn ọga ile ẹkọ, olukọ ati awọn akẹkọọ lati tẹle awọn ofin to dena arun Coronavirus lasiko tawọn ile ẹkọ naa ba di sisi pada.
O ni ki a si wo ọna taa fi ṣatunṣe ki a ba le jẹ ọmọ orile-ede to dara ju ti tẹlẹ lọ'' Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ohun mẹ́jọ tóo ní láti mọ̀ bí o bá fẹ́ lọ ilé ọdun Akọsile sọ pe Gomina Sanwo- Olu ti tẹlẹ ohun ti ofin gbaa laaye lati ṣe ati pe ọwọ awọn to n dari eto idajọ nipinlẹ Eko ni itẹsiwajuọrọ naa kan tofi de ori adari awọn ẹlẹwọn naa.
Obateru Akinruntan: Olugbo Obateru akinruntan ṣalaye ìdí ohun tó ń ṣẹlẹ̀ láàrín òhun àti Ooni Ile Ife
 “Gbogbo omo orile ede Naijiria lo ni ẹtọ si ibọwọfun
"Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ìjọba da ológun sí Abuja láti dẹ́kun ìwọ́de Mo fura pé ẹ fẹ́ da Nàíjíríà rú, ń kò ṣe ìwọ́de mọ́ - Segalink, agbátẹrù ìwọ́de yọwọ́ Ìwọ́de EndSARS gboró n‘Ibadan, kò sẹ́ni tó le wọlé tàbí jáde ""Buhari, ìwọ́de yóò yíwọ́, tó gbá jẹ́ káwọn ológun bá bẹ̀rẹ̀ ‘Operation Crocodile Smile’ "" Ìjọba Eko pàdánù ₦234m láàrín ọ̀sẹ̀ kan torí ìwọ́de End SARS Bí o bá fẹ́ darapọ̀ mọ́ ikọ̀ ọlọ́pàá SWAT tí yóò rọ́pò SARS, wo àmúyẹ tí o gbọ́dọ̀ ní Aisha Buhari polongo àwo orin tó ní Nàíjíríà ń ṣun ẹ̀jẹ̀ lásìkò ìwọ́de Iṣẹlẹ yii waye laarin iwọde ifẹhọnuhan tako ifiyajẹni awọn ọlọpaa kaakiri orilẹede Naijiria."
Awọ ara kọ lo ṣe pataki julọ fun eeyan lati ṣe oriire laye, bi eeyan ṣe mọ iṣẹ rẹ daju si lo ṣe koko.
Ninu ìwé mejeeji, mò ń ji yín pẹ́pẹ́, láti ran yín létí àwọn ohun tí ẹ mọ̀, kí ẹ lè fi ọkàn tòótọ́ rò wọ́n jinlẹ̀.
Ó bá sọ fún obinrin náà pé, “A dárí ẹ̀ṣẹ̀ rẹ jì ọ́.
Bakan naa ni ibinu ma n mu gbogbo awọn isan ati orikerike ara, oju ati ẹrẹkẹ gbooro si, ti eniyan a si dabi ni pe ara rẹ pe perepere.
" Mi ò mọ ohunkóhun nípa Aketi Whyski"" - Akeredolu ké gbàjarì Oríṣun àwòrán, others Saaju la ti mu iroyin wa fun yin pe gomina ipinlẹ Ondo, Rotimi Akeredolu ti ke gbajari sita pe, oun ko mọ ohunkohun nipa ọti lile kan ti wọn kọ akọle ""Aketi"" si lara."
Wọn ni, o ṣiṣẹ takuntakun lati fopin si aarun kogboogun (HIV), igbesunmọmi kaakiri agbaye ati lati fopin si titẹ ẹtọ ọmọniyan loju mọ'lẹ.
Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kan
Ahmed ní China yóò lo ànfani náà láti wọ ààrin àwọn orilẹ̀-èdè ìwọ̀ òòrun ilẹ̀ Afirika eyi ti ilẹ̀ Amẹrika ti n dari láti ẹ̀yìn wá lọ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Chadwick Boseman wife: Simone Ledward ni ìyàwó Chadwick Boseman, wọ́n sì 'sègbéyàwó kó tó jáde láyé 29 Ògún 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 31 Ògún 2020 Oríṣun àwòrán, Getty Images Gbajugbaja oṣere sinima ni, Chadwick Boseman to ku laipẹ yii ko ku laapọn o, o ṣe igbeyawo pẹlu iyawo rẹ Taylor Simeone Ledward ki o to jade laye.
Òun ni a ní ìrètí ninu rẹ̀; yóo sì tún máa yọ wá, 
ní ìgbà èkó rè ní howard , obama- àgbà fé ruth nidesand , ẹni tí ó bá padà sí orílè èdè kenya léhìn ìparí èkò rè .
 Oga agba Sadiq tun se ifilole ise akanse tuntun ti eka(465 NAFH).
Oríṣun àwòrán, METHODIST HEALTHCARE Àkọlé àwòrán, Aramanda ọmọ Baba ikoko naa Justin Brown ni awọn ṣe emo nigba ti wn kede asiko ti wn bi Christina ti o si ya awọn lẹnu pe ''o wọn wọn bi ni 9/11,wọn bi ni 9/11 ni ọjọ 9/11'' ''Ohun idunnu ni iru iroyin yi jẹ layajọ ọjọ ibanujẹ '' Racheal Laughlin to jẹ olori awọn agbẹbi ni o ṣọwọn ki iru nnkan bayi ṣẹlẹ.
John Marshall , lorile ede  United States
Rafael Nadal omo orile-ede Spain, ti bo sipo kinni-in ninu ipo ate ATP saaju akegbe re, Roger Federer ti o di ipo ohun mu tele, lataari pipadanu asekagba idije Halle lojo aje(Monday).
Wọn ni awọn ko ni gba ki ẹnikẹni dunkoko mọ awọn ni ọnakọna.
Nigeria Army: Ta ni Ọgágun àgbà Lamidi Adeosun tó ṣẹṣẹ gba ìgbága?
Aarẹ Alpha Conde ti orilẹede Congo lo ti wa ni ipo yii tẹlẹ.
Nítorí náà, OLUWA àwọn ọmọ ogun bínú sí wọn gidigidi.
Ní àkókò yìí, Labani wà níbi tí ó ti ń gé irun àwọn aguntan rẹ̀, Rakẹli bá jí àwọn ère oriṣa ilé baba rẹ̀ kó.
Omololu Akinwale: Ọ̀tá ìlú ni àwọn adarí tó ń lọ sèpàdé nílẹ̀ òkèèrè
Nínú àwọn báǹkì ilú Ọ̀ffa ni àwọn adigunjalè yìí tí sọsẹ́ sùgbọ́n ibi tí ọwọ́ ti tẹ̀ wọ́n ni ilú Èkó, Ìbàdàn, Ìlọrin àti Ọ̀ffa pẹ́lú àwọn ǹkan ìjà olóró bíi ìbọn gbúntú alágbára àti àwọn ọta ìbọn.
Ó gé igi fún ẹbọ sísun, lẹ́yìn náà wọ́n gbéra, wọ́n lọ sí ibi tí Ọlọrun ti júwe fún Abrahamu.
Ile isẹ ọlọpaa ni ipinlẹ Ondo ti ni eto aabo wa ni sẹpẹ fun awọn ara ilu ati awọn arinrinajo ni ipinlẹ naa.
Botile jẹ wi pe awọn olugbe kan ti n ṣe atunṣe orule wọn, awọn kan ṣi wa ni gbayawu.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Makinde: Ẹgbẹ́ òṣèlú PDP ní àwọn kò padà lẹ́yìn Seyi Makinde, gómìnà ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́ 8 Owewe 2019 Oríṣun àwòrán, @oyostategovt Ọrọ Ẹgbẹ oṣelu PDP ati APC nipinlẹ Ọyọ ti di ti ologbo ati eku bayii paapaa julọ lori ọrọ gomina Ṣeyi Makinde ati iṣejọba rẹ nipinlẹ naa.
"Ẹlòmíràn tún ti lùgbàdì àrùn Corona Virus nílùú Abuja Ìgbésẹ̀ ìjọba láti kojú àrùn coronavirus ń pani lẹ́rìn ín- Pásítọ̀ Adeboye Báwo ni àrùn coronavirus ṣe ń wọ Nàìjíríà Ọ̀rọ̀ Coronavirus kì ń ṣe ṣeréṣeré o-K1 de Ultimate, Toyin Abraham "" a mọ bi ǹkan to wà ni ìwáju wa ṣe toni tó a si ti ṣetan láti koju rẹ, a ti n ba àwọn asoju àwọn ọlọja sọ̀rọ̀ àti àwọn olóri awakọ láti ri dáju pé wọ́n tẹle ìlàna jijina si ẹnikeji."
Ẹ kò ì tíì kà ninu Ìwé Mímọ́, pé,‘Òkúta tí àwọn ọ̀mọ̀lé kọ̀ sílẹ̀ni ó di pataki igun ilé.
Ẹyọ ẹnìkan ṣoṣo ninu yín ni ó ń bá ẹgbẹrun eniyan jà, nítorí pé OLUWA Ọlọrun yín ni ó ń jà fun yín, gẹ́gẹ́ bí ó ti ṣèlérí fun yín.
Oríṣun àwòrán, @YorubaHistory Bi itan igbe aye rẹ si se lọ ree: Ibẹrẹ aye, eto ẹkọ ati isẹ oojọ ti Henry Fajemirokun se: Daniel Famakinwa ati Felicia Adebumi Fajemirokun ni orukọ awọn ọlọkọ to wa Henry Oloyede wa sile aye.
Ọwọ́ òfin ti tẹ ọ̀pọ̀ ọmọ Nàìjíríà lórí ẹ̀sùn jìbìtì l'Amẹrika- FBI Iṣẹ́ bọ́ lọ́wọ́ ọlọpàá mẹ́rìn to pa afurasí, wọ́n tún dèrò ẹ̀wọ̀n A kò tí ẹnu Bodè pa rárá- iléeṣẹ́ Aṣọ́bodè Oríṣun àwòrán, @FBI Àkọlé àwòrán, Ogọ́rin ọmọ Nàìjíríà ni Iléesẹ́ ọ̀tẹlẹ̀múyẹ́ ilẹ̀ Amẹ́ríkà FBI, ti forúkọ wọn léde lórí èṣùn jìbìtì Iwa buburu bayi lee mu ki awọn ọmọ Naijiria koju ọpọlọpọ isoro nigba ti wọn ba n lọ si ilẹ okeere, paapaa julọ nibudokọ ofurufu.
wako pelu orile ede Naijiria lonii yii.
Oríṣun àwòrán, others Akọroyin BBC ni, gbogbo igbiyanju oun lati ya awọn agbofinro to pọ bii esú naa lo ja si pabo, nitori wọn ko gba akọroyin kankan laaye lati duro sẹba ibi ti wọn wa.
Eyi ko ṣẹyin bi awọn eniyan ilẹ South Korea ṣe ti ni awọn eniyan perete to ti ni arun naa.
Èmi ni mo wí fún ọ, iwin búburú ni ẹbọra kékeré inu ọ̀gán, orúkọ ẹni tí ń jẹ́ Èṣù-kékeré-òde.
Nígbà tí àwọn ará Amoni rí i pé àwọn ará Siria sá, àwọn náà sá fun Abiṣai, wọn sì wọ ìlú wọn lọ.
Wọn ni lẹyin ti ọkọ ofurufu to gbe wọn balẹ tan naa ni wọn rii pe ko si ẹru wọn kankan ninu ọkọ ofurufu ọhun South Africa gbọ́dọ̀ dá owó ìtanràn padà kí wọ́n si fìyà jẹ àwọn ti ọ̀rọ̀ kàn -Sen Basiru Wike kò wó Mọṣáláṣi rárá o -Fayẹmi lórúkọ gbogbo Gómìnà Nítoríi fóònù ìbánisọ̀rọ̀, géńdé méjì kú sínú u kọ̀ǹga l'Ékìtì Òfin ṣì gbẹ́sẹ̀lé Ẹgbẹ́ awakọ̀ èrò NURTW ní ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́ Olori awọn ti wọn jọ kọwọ rin de ilu Dnipro, ni orile ede Ukraine, Dayọ Achor wi pe awón alaṣẹ ọkọ ofurufu Turkey yoo ṣe iranlọwọ to yẹ lati ko ẹru naa pada wa.
Àwọn igi Sipirẹsi ń yọ̀ yín;àwọn igi Kedari ti Lẹbanoni sì ń sọ pé,‘Láti ìgbà tí a ti rẹ ọba Babiloni sílẹ̀,kò sí agégi kan tí ó wá dààmú wa mọ́.
Igbesẹ tuntun naa waye latari bi awọn ẹgbẹ ajafẹtọ ọmọniyan, Amnesty International se fajuro si bi ileesẹ ologun se n se igbẹjọ ida kọnkọ fun awọn afunrasi ikọ Boko Haram naa.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Wọn yi lawọn ariran ti o kùnà lórí ẹni tí yóò di ààrẹ Naijiria.
Ọ̀rọ̀ púpọ̀, irọ́ ló ń mú wá, ọ̀rọ̀ mi kò ní gùn gbọ̀ọ̀rọ̀, mo dúpẹ́ lọ́wọ́ rẹ nítorí o moore ṣùgbọ́n ko tíi sí nǹkan tí mo ṣe fún ọ rárá, bí a bá fi ọ́ wé ogunlọ́gọ̀ àwọn ẹlòmíràn tí wọ́n ti de sàkání ilé wa.
Ẹ̀yin tí ẹ̀ ń gbé Ṣafiri ẹ máa rìn ní ìhòòhò pẹlu ìtìjú lọ sí ìgbèkùn.
 púpọ ̀ nínú àbájáde ìwádìí wọn ni kò sí ní àrọ ́ wọ ́ tó àwọn akẹ ́ kọ ̀ ọ ́ èdè yorùbá .
apapo ibo (259, 997votes)Egbe oselu APC jawe olubori ninu abajade esi idibo
Awọn ọmọ mejeeji ti gbaju gbaja osere tiata lobinrin, Iyabọ Ojo bi, eyiun Priscilla ati Festus ti bẹrẹ si ni sọ bi inu wọn ti dun to lati fi oju kan baba wọ̀n lẹyin ọdun mẹfa ti wọn ti foju-rinju kẹyin.
Mali: O kéré tán, ẹ̀mí 95 ti sọnù ní Mali
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Iya Adura Esther Ajayi sọ àṣírí owó rẹ̀ tó fi ń ṣàánú Ẹni orí yọ, ó dilé!
Ẹwọn Odun meje leeyan kookan gba.
ni ìbéèrè tí spọ̀ ń bèèrè Ijọba rọ awọn alaṣẹ ileewe ijọba lati maa kọ eti ikun si aṣẹ ileẹjọ lori lilo hijab, bi bẹẹ kọọ, aigbọran si ileẹjọ ni irufẹ iwa bẹẹ yoo jẹ.
Ọgagun Sani Abacha lo ra Ken Saro-Wiwa ati awọn mẹjọ miran lọ si ẹwọn ni Ọjọ Kokandinlogbo, oṣu Kẹwaa, ọdun 1995 lori ẹsun pe o kopa ninu isekupani awọn oloye mẹrin lati ilẹ Ogoni.
Abajade ipinlẹ kọọkan ninu esi tuntun naa re e: Eko-224 Abuja-105 Edo-85 Ondo-64 Kaduna-32 Imo-27 Osun-19 Plateau-17 Oyo-17 Ogun-17 Rivers-14 Delta-11 Adamawa-10 Enugu-7 Nassarawa-6 Gombe-3 Abia-3 Ekiti-3 Àpapọ̀ àwọn tuntun to ṣẹṣẹ lugbadi ààrùn Coronavirus ní Nàìjíríà jẹ 575 ní 11/07/2020 Ninu ikede ti ajọ NCDC fi sita ni Ọjọ Ẹti lo ti fojuhan pe , awọn to ti ni aarun naa ti pe 31,323 bayii.
Kò ní sí ayẹyẹ ọdún Ojúde Oba lọ́dún yìí- Awujale ilẹ̀ Ijebu Wọ̀nyí ni àwọn ẹjọ́ tó làmìlaaka ti EFCC ṣe lásìkò Ibrahim Magu Ṣé lóòtọ́ ni Lateef Adedimeji àti Adebimpe Oyebade ṣe ìgbéyàwó?
Nígbà tí ó di Ọjọ́ Ìsinmi, ó bẹ̀rẹ̀ sí kọ́ àwọn eniyan ninu ilé ìpàdé.
    Nígbà tí ilẹ̀ mọ, mo pe àwọn ènìyàn mi, mo rò fún wọn, olúkúlùkù sì tọ́ nínú oyin yìí lá.
’’Igbakeji aare ni o koko se akanse adura lasiko iwasu lati fi dupe lowo Olorun fun aanu ati oore ofe re fun orile ede Naijiria.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Owó tí mo ń rí lórí Garri ni mo fi ń ran ọkọ lọ́wọ́' O ni oun beere idi ti Lahiri ṣe fẹ fẹmi ara rẹ wéwu nipa idán ṣiṣe.
Yóo wà níbẹ̀ títí yóo fi run ilé náà patapata, ati igi ati òkúta rẹ̀.
Yóo máa jẹ́ ohun ayọ̀ fún mi láti ṣe wọ́n lóore, n óo fi tẹ̀mítẹ̀mí ati tọkàntọkàn fi ìdí wọn múlẹ̀ ninu jíjẹ́ olóòótọ́ ní ilẹ̀ yìí.
Amọ, o gba baba niyanju lati mu ki ọrọ ilẹ Yoruba jẹ ẹ logun, ki o si ba wọn gbe ọrọ atuntọ orilẹede Naijiria lọ si awọn ibi giga ti wọn ti n fọhun, ki orilẹede Naijria le di atunto.
OLUWA Ọlọrun ní, “Lẹ́yìn gbogbo iṣẹ́ ibi wọnyi, o gbé!
Ìjọba ìpínlẹ̀ Kogi kéde ọjọ́ ìwọlé àwọn akẹ́kọ̀ọ́ padà sí iléèwé Iléeṣẹ́ ìròyìn Daily Trust gbọdọ̀ san N6 bilion nítorí ìbanilórúkọjẹ́- Femi Fani Kayode Sinimá àwòdamiẹnu, Ẹ̀fáńjẹ́líìsì jìyà àjẹmumi nílé aṣẹ́wó l'Ejigbo ní ìlú Eko Wo ojú Akeem t'Ọlọ́pàá mú pé ó fipá bá ọ̀dọ́mọbìnrin kan sùn létí odò l'Oṣun Ìjàmbá ọkọ̀ tó ṣẹlẹ̀ sí Adams Oshiomole kìí ṣe ojú lásan, àwọn kan ló fẹ́ pa á- APC Itumọ eyi ni pe, bi o ṣe n lo ina si lojumọ ni yoo sọ isọri owo ina sisan ti o o wa.
Aroye ati ọrọ ileejọ ti pọ ju lori awọn isẹ to wa laarin ijọba ati ẹka adani.
 iṣẹ ́ àwọn obìrin sì ni aṣọ híhun , irun dídì , òwò ṣíṣe àti àwọn oríṣìíríṣìí iṣẹ ́ ìjọba ti ọkùnrin àti obìnrin ń ṣe .
1957 Oṣiṣẹ ilu naa to jẹ ọdọ pade Nelson Mandela, to jẹ amofin ati gbajugbaja alatako iṣejọba awọn alawọ funfun.
Lasiko ti won n jiroro yii ni awon asofin kan dabaa pe , ki won yo awon olori eso eleto aabo  ati adari oga olopaa orile ede yii, pe won kunna lati daabo bo emi ati dukia awon omo orile ede yii, ni eyi to je  ojuse won to wa labe ofin.
"Romero ni, ""nṣe lo kan n sare kaakiri oju agbo ija"" o fi kun un pe ija ajakuorogbo lawọn eeyan wa wo, ohun si ni wọn sanwo fun lati wo kaakiri agbaye."
Ojú tí ó ti ń rí i tẹ́lẹ̀ kò ní rí i mọ́,ààyè rẹ̀ yóo sì ṣófo.
Ondo disability day: Ijọba ẹ gbà wá ní ariwo tí àkàndá ẹ̀dá ń pa
Àwọn tí wọ́n tún wà pẹlu mi nìwọ̀nyí: 
Wọ́n to ẹrù igi wọn jọ sí ara ibi ààbò náà, wọn sọ iná sí i.
Baba rẹ̀ bá ní kí ó máa lọ fún oṣù meji.
"Tẹlẹ, oun naa lo maa n ṣe ọpọlọpọ nkan nile, oun lo n san owo ileewe awọn aburo rẹ.
Ọjọ iṣẹgun ọsẹ yii lawọn ile igbimọ aṣofin fẹnu ko lori ọrọ yii pe yala ki awọn ọga ọga lẹnuuṣẹ ogun yii kọwe fipo silẹ tabi ki wọn gba idaduro tori iṣoro aabo lorilẹed yii ti n pọ ju ko si fẹ lopin.
Babachir Lawal bọ lọwọ EFCC EFCC p'oṣiṣẹ banki l'ẹjọ Amọ Agbẹnusọ fun ajọ EFCC, Wilson Uwajeren ko dahun ipe BBC Yoruba lati sọ ni pato ero ajọ naa lori ọrọ yii.
Arabinrin kan so fun awon oniron  ile-iwe irioyin olojoojumo orile-ede Kenya pe, “Odoodun ni awon eniyan n soro ti ojo ba ti bere bayii, eyi ti ko si iyato naa ninu eyi ti o n ro yii.
Iṣẹlẹ naa waye nile ẹni ọdun mejidinlaadọta ọhun lagbegbe Oluwatuyi nilu Akure.
Orukọ awọn ti yoo tẹle Aarẹ Buhari lọ si China.
Ṣùgbọ́n bí èmi ti ń ronú wọ̀n-nnì, èdè Ẹlẹ́dàá yatọ sí tèmi, bẹ́ẹ̀ni Ẹlẹ́dàá gbọ́n jù mí lọ; ìgbà tí ó sì di òwúrọ̀ ọjọ́ kaan báyìí, wọ́n wi fún mi lati ile pé, bàbá mi ti lọ sí ọ̀run alákeji.
 Omowe  Briyai “A ti n sọ fun  awọn ọmọ ipinlẹ Cross River  pe a ti gbaradi fun eto idibo ti yoo waye ni ọjọ
Ẹ máa lọ, ẹ kò gbọdọ̀ padà sí ọ̀run mọ́, ẹ lọ sí inú igbó lọ́hùn-ún nì, ẹ máa sáré kiri títí ọjọ́ ayé yín, kí ẹ jẹ́ ẹ̀kọ́ fún àwọn aláìgbọ́ran, àti òye fún àwọn elétí dídi, ẹ̀yin kì yóó sì kúrò nínú ipò ìbànújẹ́ tí ẹ̀yin wà yìí, títí yóó fi di ọjọ́ àyípadà ohun gbogbo.
Ó dára kí eniyan foríti àjàgà ìtọ́sọ́nà ní ìgbà èwe.
Bí gbogbo ènìyàn ṣe n lọgun pe, sebi ilú Wuhan ní China ni arun Coronavirus ti bẹ̀rẹ̀, sùgban báwo lo ṣe wá jẹ pé orilẹ̀-èdè Italy lo n pín ààrùn náà kiri laarin àwọn orilẹ̀-èdè to ko arun ọhun.
Iru awọn iroyin ti ẹ le nifẹ si: Kín lo fa orogún àwọn dókítà àti Johesu?
BBNaija 2020: Ta ni ₦85m tọ́ sí láàrin Laycon, Dorathy, Nengi, Vee àti Neo?
Bakan naa, oja idokowo ti o si sile ni iye owo ti o je N15.
 Aworan fonran kan fihan pe won ti n ro okunrin naa ko bale laalaafia ko to dip e oko naa ja moo lowo.
Owó ti ó yẹ ki Olóri Ijọ fi tọ́jú aláìní, tàbi ki Òṣèlú fi pèsè ohun amáyédẹrùn bi omi mimu, ọ̀nà tó dára, ilé ìwòsàn, ilé-iwé, iná mọ̀nàmọ́ná àti bẹ ẹ bẹ ẹ lọ ni wọn kó si àpò, ti wọn nná èérún rẹ fún ijọ tàbi ará ilú ti ó bá sún mọ́ wọn.
2019 Nigeria Election: Àgbùnbánirọ̀ pàdánù ẹ̀mí rẹ̀ nínú ìjàmbà ọkọ̀ ojú omi l'Ondo
Oríṣun àwòrán, Getty Images Fun apẹrẹ, ogoji kilo tomato ti wọn n ta ni ẹgbẹrun un mẹfa aabọ naira lọja Bodija niluu Ibadan ti di ẹgbẹrun un mẹjọ le laadọrin naira.
Gbogbo èyí rí bẹ́ẹ̀ kí Ìwé Mímọ́ lè ṣẹ tí ó wí pé, “Kò sí egungun rẹ̀ kan tí wọ́n ṣẹ́.
Ẹ gbọ mi, ẹ gbadura fun orilẹede Naijiria nitori idaru-dapọ, rogbodiyan nibi gbogbo."
Ẹ̀wẹ̀, àwọn agbófinró tí wọn fi sí ilé ìfowópaamọ àti àwọn ọlọ́dẹ àdúgbò ni wọn fìjà pẹ́ẹ́ta pẹ́lú wọn, èyí sì ló mú kí àwọn olè náà pẹ̀yìnda.
"Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Iná ṣe ọṣẹ́ ní Mile 12 l‘Eko, ọ̀pọ̀ ilé àti ìsọ̀ jóná PDP ṣe èrú ìbò gómìnà ní Benue àti Sokoto, a kò ní gbà - APC yarí Gómìnà Ganduje wọlé fún sáà kejì ní ìpínlẹ̀ Kano Kò sí ilé ẹjọ́ kankan tó yọ mí - Gboyega Oyetọla Leah Sharibu ni wòlíì wa ní àgọ́ Boko Haram - Obìnrin tó jàjàbọ́ Ìpínlẹ̀ Ọ̀ṣun ń sàìsàn, òṣìṣẹ́ ọba ti pọ̀ jù - Oluwo ""Eyi to ya ni lẹnu julọ ni isẹ agbase towo rẹ to biliọnu lọna ọgbọn naira ti Ajimọbi kede rẹ lẹyin ipade igbimọ alasẹ ijọba to waye lọsẹ lọsẹ to kọja, mu ifura dani, paapa nigba to jẹ pe awọn gbese kan wa nilẹ lati 2011 tijọba Ajimọbi ko san."
Ipaniyan ti mo ṣe n le mi kiri Meji niyi ninu awọn ẹgbẹrun lọna ẹgbẹrin awọn ẹya Tutsis àti diẹ ninu awon Hutus ti wahala naa si waye fun ọgọrun ọjọ.
Nigba ti wọn ni a maa ṣe iṣẹ abẹ, ẹru ba mi diẹ tori eeyan ẹlẹran ara lemi naa ati pe gẹgẹ bii abiyamọ, ẹru ba mi.
Àwọn tí ó fẹ́ pa mí run lágbára.
Angẹli OLUWA yí àwọn tí ó bẹ̀rù rẹ̀ ká,a sì máa gbà wọ́n.
Àwọn wo ni wọn yóo lè dúró ní ọjọ́ tí ó bá yọ?
"Mo rii bi oju awọn ọdọ naa ṣe pọn rẹrẹ fun ibinu to si jẹ pe kii ṣe gbogbo wọn ni oniwa jagidijagan.
Nadia (ti a fi orukọ bo ni aṣiri) jẹ́ ẹni ọdun mọkanlelogun, to si n siṣẹ nileesẹ kan nilu Yaoundé Cameroun, ti koju ifipanilopọ lẹẹmẹrin ọtọọtọ.
“Sọ fún wa, nígbà wo ni àwọn nǹkan wọnyi yóo ṣẹ ati pé kí ni àmì tí yóo hàn kí gbogbo àwọn nǹkan wọnyi tó rí bẹ́ẹ̀?
ISIS àti Boko Haram fẹ́ ṣoro lásìkò ìbò 2019 - Amẹrika Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ezekwesili: Àfojúsùn mi ni láti mú ààbò ẹ̀mí ọmọ Nàíjíríà ní ọ̀kúnkúndùn Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Kinni wọn n pè ni oṣupa déjé ní kíkún?
Ẹ kò gbọdọ̀ fi wúrà tabi fadaka yá ère láti máa bọ, àfi èmi nìkan ni kí ẹ máa sìn.
Ó ṣeéṣe kí àrùn Coronavirus tànkálẹ̀ gba inú afẹ́fẹ́- WHO Bí àrùn Coronavirus ṣe dá gbogbo àgbáyé gúnlẹ̀ sójú kan náà nìyí Lẹ́yìn tí wọ́n fi kakata hú gbogbo iṣú àti ẹ̀gẹ́ mí, wọ́n tún ṣá àwọn ọmọ mi ládàá-Guru Maharaj Ji Wo agbábọ́ọ̀lù Super Eagles Nàìjíríà àkọ́kọ́ tó lùgbàdì coronavirus Gbogbo òṣìṣẹ́ àjọ tó ń rí sí ìwọléwọ̀dé àjòjì yóò ṣe àyẹ̀wò òògùn olóró - Babandede Ati ọga patapata ati ọmọ iṣẹ tabi oṣiṣẹ to kere ju ni ileeṣẹ to n ri si iwọlewọde ajoji ni Naijiria ni yoo ṣe ayẹwo oogun oloro.
OLUWA gbé Joṣua ga ní ojú gbogbo àwọn ọmọ Israẹli ní ọjọ́ náà, wọ́n sì bẹ̀rù rẹ̀, bí wọ́n ti bẹ̀rù Mose ní gbogbo ọjọ́ ayé rẹ̀.
Ẹ̀wù ẹlòmíràn dàbí fàdákà, kò sì sí èyí tí ó wọ bàtà tí a fi awọ ṣe.
Àkùkọ gàgàrà ati ẹran òbúkọ,ati ọba tí ń yan níwájú àwọn eniyan rẹ̀.
Iranṣẹ bí ìwọ ati àwọn arakunrin rẹ, tí wọ́n jẹ́rìí igbagbọ ninu Jesu, ni èmi náà.
Ó tún wí fún wọn pé, “Mo fẹ́ kí ẹ mọ̀ dájúdájú pé, àwọn kan wà ninu àwọn tí ó dúró níhìn-ín tí wọn kò ní kú títí wọn óo fi rí ìjọba Ọlọrun tí yóo dé pẹlu agbára.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Alaafin: Olori Aanu Adeyemi ṣàlàyé ìdí tó ṣe gẹ́ Oba Lamidi Adeyemi ti ìlú Oyo Awọn oṣiṣẹ Uber ati Bolt to n wa ọkọ naa ti a ba sọrọ ṣugbọn ti wọn ko fẹ ki BBC darukọ awọn ṣalaye pe nkan ko rọgbọ lasiko ajakalẹ arun coronavirus yii nitori ọpọ eeyan ko jade, awọn miran ti padanu iṣẹ wọn.
Gbajumọ oṣere, adari ere, olotu ere ati akọtan ni Afeez ọwọ ti iyan Mide Martins pẹlu ko ṣee kọ kere rara.
O fikun pe, gbogbo awọn igbesẹ naa lo wa lati pese isẹ oojọ fun araalu.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Adekunle Gold: Ọdún márùn ún ni mo fi mọ Simi ká tó ṣègbéyàwó 17 Sẹ́rẹ́ 2019 Oríṣun àwòrán, @adekunleGOLD Àkọlé àwòrán, Iyalẹnu lo jẹ fawọn ololufẹ wọn nigba ti wọn fi eto igbeyawo naa ṣe bonkẹlẹ.
Baba Wole, Samuel Ayodele Soyinka jẹ olufọkansin alufa ijọ Anglican ati adari ile iwe alakọbẹrẹ ti iya rẹ, Grace Eniola Soyinka si jẹ ontaja o tun jẹ ajafẹtọ nipa oṣelu laarin awọn obinrin.
Premier League yóò bẹ̀rẹ̀ padà lóṣù kẹfà Lẹ́yìn tí wọ́n yọ ọ́ nípò, Sanusi Lamido Sanusi gba ẹ̀bùn tuntun Amọ ẹgbẹ NASU ni ìjọba fẹ lo abọ iwadii Orosanye naa lasiko yii ti ajakalẹ arun Coronavirus ti mu ki ọrọ aje Naijiria dagun, lati da awọn ẹka ileeṣẹ ijọba kan papọ lọna ati gba isẹ lọwọ awon oṣiṣẹ ọba.
Gbogbo ohun tí ó ṣe ninu iṣẹ́ ìsìn ilé OLUWA, gẹ́gẹ́ bí òfin ati àṣẹ Ọlọ́run, ati wíwá tí ó wá ojurere Ọlọrun, gbogbo rẹ̀ ni ó ṣe tọkàntọkàn, ó sì dára fún un.
Fatima ọhun lo bọ sita loju opo twitter to kọkọ wi pe, 'Alhamdulilah, baba wa ṣi wa laye' Bakan naa ni agbẹnusọ fun Abiọla Ajimọbi, Tunji Bọlaji ṣalaye pe ko si ootọ ninu rẹ.
A sí wo ìlànà ati òté tó de sísọ̀rọ̀ ni àwùjọ Yorùbá.
O ṣalaye pe, ti ibẹru-bojo ni Adebayor fi n sọ ohun to sẹlẹ ṣawọn agbabọọlu Togo, koda Adebayor sọ ninu ifọrọwanilẹnuwo naa pe, ẹru ṣi n ba oun lẹyin tawọn akẹgbẹ rẹ meji ṣagbako iku ninu ikọlu naa.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Timothy Omotosho: Ó pàdánù ìwé ìgbélú ní South Africa t'orí ẹ̀sùn ìfipábánilòpọ̀ 2 Ògún 2019 Oríṣun àwòrán, Soweta/getty images Ẹjọ kotẹmilọrun ti ọmọ orilẹede Naijiria kan, to jẹ oniwaasu ori amohunmaworan ni South Africa, pe tako idajọ to sọ pe o ti padanu iwe igbelu rẹ ti foriṣanpọn.
aga onifoomu dẹmu dẹmu, rọọgi kiki ati aṣoọ ferese to nipọn ni gbogbo ohun ti yoo ṣiṣẹ yẹn lati gba ariwo sara.
Awọn onimọ sayẹnsi ṣalaye pe aago to wa lara eeyan niiṣe pẹlu bi oogun ṣe maa n ṣiṣẹ lara eeyan.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fọ́nrán ohùn, Idanilẹkọ fún àwọn àgbẹ̀ lórí kòkòrò ajokorun Ati okere loloju jinjin ti''n mekun sun Àwọn onímọ̀ nípa ètò nnkan ọgbin ṣàlàyé pé òun tí àwọn àgbẹ̀ lè ṣe láti dẹ́kun ìpeníjà kòkòrò yii kò jù wí pé kí wọn tètè yà owó kikoju rẹ bọ inu ìṣirò.
Nítorí náà kò mọ ìwọ̀n bàbà tí ó lò.
Xenophobia: Àbọ̀ ààrẹ Muhammadu Buhari rèé láti ilẹ̀ South Africa
‘Angel’ lori ero ayelujara ti o si fi n lu awon eniyan ni jibiti.
Wọ́n ń wá ọ̀nà láti gbé e dé iwájú Jesu.
Nítorí náà, Dafidi fún Onani ní ẹgbẹta (600) ìwọ̀n ṣekeli wúrà, fún ilẹ̀ ìpakà náà.
Kìí pé àlejò pé ibo lóti wá
Esther Agbaje lo dije lati ṣoju ẹkun 59B ni Minnesota, iyẹn nile igbimọ aṣoju-ṣofin labẹ asia ẹgbẹ Democratic, to si ni ibo 17,396.
O ni bẹrẹ lati ọjọ Aje, ao bẹrẹ si ni da gbogbo ọkọ duro laarin ilu, ao wọ ileeṣẹ, ọja ati awọn ibi gbogbo lati wo awọn ẹya to wa nibẹ."
Ohun to fa eleyii ni iwode ati ifehonuhan ti o waye loju popo , nitori pe won fe dena aare lati inu egbe alatako dije , ki won si yo aare naa kuro lori aleefa.
si lori rẹ lati ile ẹjọ.
Fi ara balẹ lori ibusun lai maa yi kaakiri - Jẹ ki ibusun rẹ sun nipa ko ma yi kaakiri tabi maa ba irọri rẹ ja To ba sun sori ibusun, ti oorun ko ba wa, dide nilẹ, ko maa se nkan miran bii kika iwe tabi rin kaakiri Se adinku awọn eroja amu oorun da loju ẹni bii, obi ati 'Coffee', ki orun lee tete wa O nilo wakati mejila ki eroja kọffi to lee kuro ni ara rẹ, tori naa, ma mu ksffi tabi jẹ obi lọwọ irọlẹ.
Abenugan ile igbimo asofin, Bukola Saraki,wa ro awon akegbe re lati tubo maa fowosowopo pelu ijoba apapo lori ise akanse ti won n se nipa oju irin igbalode.
Homepage Accessibility links Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Ìrànlọ́wọ́ Ìwọlé News Sport Weather Radio Arts Ààtò BBC News Yorùbá BBC Yoruba ÀkọléÀkọlé abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Àkọlé bọ̀tìnnì síwájú síi Olùmúdọ́gba bọ́tìnnì síwájú síi Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Media player Close player Close player Close player Lọ́wọ́lọ́wọ́Lọ́wọ́lọ́wọ́ Nàíjíríà jẹ gbèsè ₦6tr láàrin ọdún kan ṣoṣo - NBS I'll sign in later And we'll keep you signed in.
Ninu atẹjade kan ti aarẹ ẹgbẹ naa, Ọjọgbọn Olufemi Babalola fọwọ si ni ilu Abuja, o ni ko si ẹri aridaju to fidi rẹ mulẹ pe awọn oogun ti dokita naa darukọ lee wo arun Coronavirus.
Isà òkú ati ìparun kò pamọ́ lójú OLUWA,mélòó-mélòó ni ọkàn eniyan.
Dickson Agbaye sọ bi ọ̀rẹ́ ati akẹgbẹ ẹ ṣe sọọ di ọmọ ẹgbẹ okunkun to n fa oogun oloro pa.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Àwọn ohun kàyéèfì tó le mú kí ọmọbìnrin ní oyún ìju Ìdí tí àwọn ìpińlẹ̀ se ń ti ilé ẹ̀kọ́ ní ìhà ìwọ̀ Oòrun-Àríwá Nàìjíríà rèé Abẹ́rẹ́ àjẹsára Covid-19 yóò dé sí Nàìjíríà nínú oṣù kíní ọdún 2021 Jide Kosoko forin sẹ́nu pé òun ni igi lẹ́yìn ọgbà Mr Latin lórí ipò ààrẹ TAMPAN tó wà Ó pé ọdún mẹ́wàá tí Barrister kú; wo ǹkan tó yẹ láti mọ̀ nípa rẹ̀ gẹ́gẹ́ bíi olórin, tẹ̀wé-tẹ̀wé, akọ̀wé àti sọ́jà Àìmọ̀kan ló mú mi hu ìwà tí mo hù kọjá sẹ́yìn, Jonathan dárí jì mí - Dino Melaye Awọn ọja naa ni Irẹsi, awọn ohun abiyẹ ati awọn eroja miran tijọba ti fofin de saaju lasiko to n ti awọn ẹnu bode wa pa.
Ẹni tí ó bá kó baba rẹ̀ nílé, tí ó sì lé ìyá rẹ̀ jáde,ọmọ tíí fa ìtìjú ati àbùkù báni ni.
bii gomina kejidinlogbon ni Ipinle Oyo.
Àkọlé àwòrán, Àjọ ọlọ́pàá, Ìjọba ìpínlẹ̀ Ọyọ jẹ́jẹ̀ẹ́ láti ṣàwárí òòsà tó ń mu ẹ̀jẹ̀ nílùú Ìbàdàn Adedigba ni awọn ti fi orikori bẹẹ sini eto ti to lati ṣe awari awọn oniṣẹ ibi ti iru iṣẹlẹ bẹẹ ko fi ni waye mọ ninu ajọṣepọ pẹluu awọn Ọlọpaa, figilante, ọlọde ati awọn adari agbegbe.
A mọ̀ pé ẹni tí ó jí Oluwa Jesu dìde yóo jí àwa náà dìde pẹlu Jesu, yóo wá mú àwa ati ẹ̀yin wá sí iwájú rẹ̀.
Nígbà tí àwọn ará Ai bojú wẹ̀yìn, tí wọ́n rí i tí èéfín yọ ní ìlú wọn, wọn kò ní agbára mọ́ láti sá síhìn-ín tabi sọ́hùn-ún, nítorí pé àwọn ọmọ Israẹli tí wọ́n sá gba ọ̀nà aṣálẹ̀ lọ yíjú pada sí wọn.
Koda , awọn ile ẹkọ kan gbe ẹrọ ti yoo maa sọ bi ara awọn akẹkọọ ba ti se n gbona si kalẹ si ẹnu ọna abawọle ileewe wọn.
Ẹ júbà ọmọ náà, kí ó má baà bínú,kí ó má baà pa yín run lójijì;nítorí a máa yára bínú.
O ṣoju mi koro naa fi idi ọrọ mulẹ wi pe lori ere ni ọkọ naa ti kọlu ọlọkada ti gbemi mi loju ẹsẹ.
yóo ṣòfò títí lae bí ìgbọ̀nsẹ̀ ara rẹ̀,àwọn tí wọ́n mọ̀ ọ́n yóo bèèrè pé, ‘Níbo ló wà?
Ìdí tí mo fi ń ṣe ayẹyẹ ọjọ́ ìbí 35 lọ́dọọdún rèé- Allwell Ademola Yàtọ̀ sí Eko, wo ohun t'áwọn ìpínlẹ̀ meje míràn ń sọ nípa ìwọlé àwọn akẹ́kọ̀ọ́ Ta ni ìyàwó Chadwick Boseman, tó jẹ́ àwòkọ́ṣe rere f'áwọn ọ̀dọ́ Adúláwọ̀?
Wọ́n ní tí ẹni náà bá padà, àwọn yó dá owó rẹ̀ padà fún un.
Ko pẹ lẹyin eyi ni Shekau gbe fidio miran sita to fi yẹyẹ awọn ọmọ ogun orilẹ-ede mejeeji pe oun kú tì!
Ṣugbọn nítorí kò ní gbòǹgbò ninu ara rẹ̀, ọ̀rọ̀ náà yóo wà fún ìgbà díẹ̀.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Mobile App: Àsìkò tó wu àwọn akẹ́kọ̀ọ́ ni olùkọ́ máa jáde wa kọ́ wọn láti inú fóònù wọn Pẹlu iyọkuro nipo rẹ yii, Donal Trump ti di sawawu kan naa pẹlu awọn aarẹ meji miran to ti jẹ ri nilẹ Amẹrika ninu itan orilẹede ọhun.
Ìpín ti Manase yóo wà lẹ́gbẹ̀ẹ́ ti Nafutali, láti ìlà oòrùn títí dé ìwọ̀ oòrùn, 
BBC 100 Women 2019: ọ̀pọ̀ obìnrin ilẹ̀ Afirika ń gbàràdá!
" Gẹgẹ bi awakọ naa ṣe sọ, Iyawo oloogbe lọ si ile ifowopamọ laarọ Ọjọru ti iṣẹlẹ yii ṣẹlẹ, lo fi jẹ wipe Oloye ati alase ti wọn furasi pe o pa oloogbe nikan ni o wa ninu ile.
Nítorí náà, ẹ san ohun tí ẹ bá jẹ ẹnikẹ́ni pada fún un.
Bí ó bá jẹ́ pé Joṣua fún wọn ní ìsinmi ni, Ọlọrun kò ní tún sọ nípa ọjọ́ mìíràn mọ́ lẹ́yìn ọjọ́ pupọ.
Èmi Paulu, òjíṣẹ́ Kristi Jesu nípa àṣẹ Ọlọrun Olùgbàlà wa, ati ti Kristi Jesu ìrètí wa, ni mò ń kọ ìwé yìí–
Kò ní já ọ kulẹ̀, bẹ́ẹ̀ ni kò ní kọ̀ ọ́ sílẹ̀, títí tí iṣẹ́ ilé OLUWA yóo fi parí.
Ṣugbọn nítorí pé ohun tí o ṣe yìí jẹ́ àfojúdi sí OLUWA, ọmọ tí ó bí fún ọ yóo kú.
ti omo egbe PDP , Abba Kabir loju nigba ti o ni iye ibo 1,024, 713 .
Europe fun iranwo ati ifowosowopo lojuna ati koju idojuko to n koju latowo
Eyi lo difa fun afurasi Ogbontarigi ajinigbe ni, Alhaji Hamisu bala Wadume.
N óo dá àwọn onídàájọ́ rẹ pada sí ipò tí wọn ti wà tẹ́lẹ̀.
Mo sì ṣe ìlérí, níwájù ènìyàn, àti níwájú iwin níwájú ẹ̀mí tí a rí àti èyí tí a kò rí, níwájú ejó àti níwájú ẹranko, níwájú ẹyẹ àti níwájú kòkòrò, níwájú ọ̀pọ̀lọ́ àti níwájú akán wí pé: bí mo ti gbà á yìí, mo mọ pé kìí ṣe ǹnkan ṣiré ṣiré, nǹkan pàtàkì ni.
Ó gbé agbada omi náà kalẹ̀ ní agbede meji àgọ́ àjọ ati pẹpẹ ẹbọ sísun, ó sì pọn omi sinu rẹ̀.
Ó lọ sí yàrá akọ̀wé ní ààfin ọba, ó bá gbogbo àwọn ìjòyè tí wọn jókòó níbẹ̀: Eliṣama akọ̀wé ati Delaaya ọmọ Ṣemaaya, ati Elinatani ọmọ Akibori, ati Gemaraya ọmọ Ṣafani, ati Sedekaya ọmọ Hananaya ati gbogbo àwọn ìjòyè.
Ṣùgbọ ́ n ijẹ ̀ bú - Ẹrẹ ̀ ni wọ ́ n kọ ́ kọ ́ máa ń pe ìlú yìí rí nítorí ẹrẹ ̀ tí ó ṣe ìdènà fún awọn Ọ ̀ yọ ́ .
A óo na okùn lé ọ lórí, a óo sì fi okùn náà dè ọ́, kí o má baà lè jáde sí ààrin àwọn eniyan.
Oríṣun àwòrán, Oba Adeyeye Ogunwusi Nigba to n se ago laafin si Ọọni, Emir ti Borgu safihan imọriri rẹ fun Ọọni ati awọn ọmọ igbimọ rẹ, to si kede pe awọn ọba alaye gbọdọ wa ni isọkan fun irẹpọ orilẹede yii.
Eyi si n ṣakoba fun ajọ naa nipa ṣiṣe iṣẹ rẹ lẹkunrẹrẹ.
 Ó kẹkọ jáde ní meiji unifásítì , tokyo .
Ninu iwe ofin Saudi ni Ọba Saudi, Alasẹ Salman ti ni ki ọmọ ọba Fahad bin Turki to jẹ olori ẹṣọ alaabo to tun dari awọn ogun lọ si Yemen pe ko kuro lẹnu iṣẹ rẹ bayii.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Yorùbá dùn lẹ́nu àwọn ọmọ yìí níbi ìdíje ẹgbẹ́ Àtúnbí Yorùbá 24 Ọ̀wàrà 2018 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 10 Èbibi 2020 Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Aláàfin Ọyọ: Pọ́ńbélé Yorùbá ni mí, n ò sì ní tijú rẹ níbikíbi Ẹgbẹ Atunbi èdè Yorùbá bẹ̀rẹ̀ látàrí àwọn ohun tí kò tọ́ ti a n fojú rí láwùjọ.
1 17916 Orilẹede Norway 354 6.
Ọjọ kẹrindinlogun, oṣu kejila, ọdun 2010 ni Barrister dagbere faye ni ile iwosan kan nilu London.
LASK vs Manchester United: Ighalo fi góòlù àrámọ̀ndà góòlù àrámọ̀ndà ló fi gbẹyẹ lọ́wọ́ LASK fún Manchester United
Ó kọ́ àwọn ìlú ní agbègbè olókè Juda ó sì kọ́ ibi ààbò ati ilé-ìṣọ́ ninu igbó lára òkè.
Àwọn ọmọ ogun Dafidi ṣẹgun àwọn ọmọ ogun Israẹli.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Bawo ni wọn ṣe n ka ibo?
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Agbenusọ fun ile isẹ ọlọọpa ni ipinlẹ Ondo ni iwadii ti bẹrẹ ni pẹrẹwu lori isẹlẹ naa.
Nigba ti wọn bi i, ọrọ o ba di nigbo lo ti gbe oyun wa fun mi too fi bi arara lọmọ, ṣugbọn o ni tori pe baba oun gbagbọ pe iya oun kii ṣe oniṣekuṣe lo ṣe gba pe sababi ni.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìbéèrè pọ̀ lórí òkú ọkùnrin kan tí ọlọ́pàá bá nínú àgbá ní Oyingbo 24 Òkùdu 2019 Àkọlé àwòrán, Ìbéèrè pọ̀ lórí òkú ọkùnrin kan tí ọlọ́pàá bá nínú àgbá ní Oyingbo Awọn ara ipinlẹ Eko n fooya lori oku ọkunrin kan.
Ko si si idi meji fun eyi ju igbẹkẹle ati igbagbọ ti o ni ninu ileeṣẹ BBC News Yoruba gẹgẹ bii ikanni ti ko ni fi igba kan bọ ọkan ninu.
Delila tún wí fún Samsoni pé, “Ò ń fi mí ṣe ẹlẹ́yà, o sì ń purọ́ fún mi.
Joe Biden kéde Kamala Harris, obìnrin aláwọ̀ dúdú gẹ́gẹ́ bí igbákejì rẹ̀ nínú ìdíje sípò Ààrẹ Amẹrika Ẹ wo ohun tó yẹ kí ẹ mọ̀ nípa oògùn 'Sputnik V' Russia tó ń wo àrùn Coronavirus Ìdí rèé tí a ṣe fẹ́ sin Majek Fashek sílẹ̀ Amerika- Randy Fashek Wo àwọn iléèwé gíga tó ti bẹ̀rẹ̀ sí ní ta fọ́ọ̀mù JAMB post UTME screening ní Naijiria Wo ìdí tí Risikat Moromoke Azeez n'Ilorin fi ní Blue Eyes"" - Dókítà Adajọ agba lorilẹ-ede Chad, Djimet Arabi ṣalaye fun ileeṣẹ iroyin AFP pe oun ti gbọ tọtun tosi bi o ṣe yẹ ni ilana ofin."
Ṣaaju ki Attah to sọrọ jade ni iroyin kan ti n lọ kaakiri pe awọn aṣọbode ti ti ẹnubode pa ni Sẹmẹ.
Gómìnà Sanwo-Olu pàṣẹ pé kí wọn tú ẹléwòn 6 sílẹ lásìkò Kérésìmesì Nitori pe ẹlomii ko fẹ rá, tabi rin ko to o de oke.
Ninu ifọrọwanilẹnuwo pẹlu BBC, Aisha sọ pe oun bi oun ṣe n 'fọ aṣọ idọti ọkọ oun ni gbangba' kii ṣe nitori afojudi, ṣugbọn nitori o jẹ otitọ ti oun gbọdọ sọ.
" Oríṣun àwòrán, AFP Àkọlé àwòrán, Orilẹede Libiya ti jẹ ọnọ pataki awọn aṣikiri ti n gbiyanju lati de okun gusu ilẹ Yuroopu lati ori okun.
Kiiṣe ilana tuntun ti ẹgbẹ APC gbekalẹ ni wọn lo fun eto idibo naa.
Ṣugbọn Joṣua dá àwọn eniyan náà lóhùn pé, “Ẹ kò lè sin OLUWA, nítorí pé Ọlọrun mímọ́ ni, Ọlọrun owú sì ni pẹlu, kò sì ní dárí àwọn àìṣedéédé ati ẹ̀ṣẹ̀ yín jì yín.
Oniruuru ni iroyin to ti n jade lati ṣapejuwe ohun to ṣẹlẹ gan ati iru ile ti o jẹ.
Àlàyé nípa Amúṣan Amúṣan ni ọmọkùnrin tí a bí, tí ó fi àpò rẹ̀ bo orí gẹ́gẹ́ bí eégún.
Àkọlé àwòrán, Akara oyinbo ọjọ ibi Ọọni gbayi, o gba ẹ̀yẹ Ọba Adeyeye pari ẹkọ́ rẹ̀ ní ilé ẹkọ́ gbogboniṣe Poly Ibadan (Ibadan Poly).
Ìhà wo ni àwọn ènìyàn kọ síi?
Iranṣẹ burúkú a máa kó àwọn eniyan sinu wahala,ṣugbọn ikọ̀ tí ó bá jẹ́ olóòótọ́ a máa mú ìrẹ́pọ̀ wá.
Abike Dabiri ní akẹ́kọ̀ọ́ 333 tí gba ìtúsílẹ, àmọ́ kò pẹ́ ló tún pahùndà Oríṣun àwòrán, Katsina govt Àwọn aláṣẹ ìjọba ni Nàìjíríà ti kéde pé àwọn ọmọ tó lé ní ọ̀ọ̀dúrún tí àwọn ajínígbé kó nílé ìwé ìjọba ni ìlú Kankara nípìnlẹ̀ Katsina, ti gba ìtússílẹ̀ Lórí àtẹ̀jíṣẹ́ twitter lọ́sàn òní ni, alága àjọ tó n ri sí ọ̀rọ̀ ilẹ̀ okere Abike Dabiri Erewa sàlàye pé, àwọn ti rí àwọn ọmọ náà gbà.
Adekunle Gold, Simi tú àṣírí ètò ìgbéyàwó wọn Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Omi titun ti rú nínú oríṣii ètò ìgbéyàwó Yorùbá lásìkò yí Nitori naa bi o ko ba ṣe igbeyawo nibi to ni iwe aṣẹ, o lee wọ pegé bii igba ti o ba fẹ gba iwe irina loke okun tabi bi o ba fẹ gba oku ọkọ tabi aya to papoda tabi nkan ini wọn.
Abileko Taiwo fi kun un wi pe ijiya ti wọn fi jẹ oun lasiko ibimọ naa jẹ ki oun dubulẹ aisan lẹyin ibimọ, eleyii ti o si da irẹwẹsi ọkan si oun lara nitori irora ati ifiyajẹni ti oun la kọja lasiko naa.
6 1048662 Orilẹede South Africa 35852 62.
Àwon ohun tí a fi sínú àkámọ ́ ni à n pè ní àwon ìsomọ ́ , wọn kò ní apíntúnpín sí ìsọ ̀ rí , wọn kì í ṣe dandan , wọ ́ n jẹ ẹ ̀ pọ ́ n -ọn wọ ̀ fún .
Nigba ti minisita fun eto inawo lorilẹ ede Naijiria, Kẹmi Adeọsun n sọrọ nibi ipade agbaye naa pe:’’ijọba n mu ohun amayedẹ run lọkunkundun.
O ni lorile-ede Naijiria, ijọba sapa lati mu irọrun ba awọn eeyan pẹlu ipese awọn eto kan eleyi to mu ki Naijiria ṣi sii fun karakata pẹlu awọn orile-ede miran.
26 Owewe 2020 Alaafin Oyo: Ọmọ Yorùbá sọ fún olorì Anu pé kò yẹ kó tú àṣírí ìkọ̀kọ̀ ìgbéyàwó rẹ̀ sí gbangba12 Bélú 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Ẹ kò mọ ọ̀nà alaafia, kò sí ìdájọ́ òdodo ní ọ̀nà yín.
anfaani iko Zimbabwe lati tesiwaju ninu idije AFCON.
INEC: Kò sí ìká tí o kò lè fí dìbò, ṣáà tí tẹ̀ ẹ́ sójú ẹ dáadáa 2019 Election: Àwọn oloṣelu tó yege àti àwọn to fidirẹmi Àwọn ohùn tó ṣé kókó tó yẹ ká mọ ṣáájú ìdìbò 2019 2019 Election: Àwọn oloṣelu tó yege àti àwọn to fidirẹmi Ǹjẹ́ o mọ̀ pé ọdọ 43m ló wà lára olùdìbò?
Sibẹ ọ̀kan ninu wọn kò lè jábọ́ sílẹ̀ lẹ́yìn Baba yín.
Wọn yóo ṣe ọgbà,wọn yóo sì jẹ èso rẹ̀.
Lasiko igbẹjọ to yẹ ko waye lọjọ Aje lori ẹsun ṣiṣe mago-mago dukia ti wọn fi kan Onnoghen ni Alaga igbimọ naa, Danladi Usman kede pe wọn ko ti i le sọ ọjọ ti igbẹjọ naa yoo tun tẹsiwaju nitori pe wọn n duro de idajọ ile ẹjọ kotẹmilọrun ti Onnoghen ti pe ẹjọ tako igbesẹ igbimọ naa.
Lọjọru ni awọn alaṣẹ Poly Ibadan da ina sun awọn foonu alagbeka ti iye owo wọn to miliọnu naira.
ati ohun tí ó ṣe sí Datani ati Abiramu, àwọn ọmọ Eliabu, ọmọ ọmọ Reubẹni.
Lọjọ iṣẹgun ni Jacob Frey fidi rẹ mulẹ pe iṣẹ ti bọ lọwọ awọn ọlọpaa mẹrin ti aje ọrọ naa si mọ lori.
Agbára àti ìwọ̀n omi òkun ni Yorùba maa n sáàbà lo 'alagbalúgbú' fi ṣapejuwe.
 Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: SERAP gbé ìjọba àpapọ̀ lọ ilé ẹjọ́ àgbáyé ICC lọrí ẹ̀sùn ìpànìyàn ""Jàǹdùkú gún ẹ̀gbọ́n mi lọ́rùn, jó ilé àti mọ́tò wa méjì, kòròfò la wà"" Olùwọ́de 12 kú ni Lekki, 38 lapapọ kú lọ́jọ́ Isẹ́gun, 56 ni àròpọ̀ àwọn tó bá ìwọ́de lọ - Amnesty International Osinbajo gbarata lórí ìṣẹ̀lẹ̀ Lekki, ó ní ìdájọ́ òdodo yóò wà Ooni Ogunwusi àti Wole Soyinka kòrò ojú sí ìṣẹ̀lẹ̀ Lekki Tollgate Ọ̀rọ̀ Nàíjíríà kúrò ní sinimá àwòrẹ́rìn-ìn, Buhari gbé ìgbésẹ̀ bíi òbí àti olórí - Obasanjo gbarata Ilẹ̀ Amẹ́ríkà wà lẹ́yìn àwọn olùwọ́de, Buhari dẹ́kun ìpànìyàn - Joe Biden Mọ̀ nípa DJ Switch, akíkanjú obìrin sàfihàn fídíò ìpànìyàn Lekki bó ṣe ń wáyé Bakan naa ni gomina ipinlẹ Eko ni wọn yoo daabo bo ẹrọ ayaworan CCTV to wa ni Lekki, tawọn yoo si pe awọn akọsẹmọsẹ lati ri daju pe wọn ko ba ẹrọ naa jẹ."
“Nígbà tí àkókò ìkẹyìn bá dé, ọba ilẹ̀ Ijipti yóo gbógun tì í; ṣugbọn ọba Siria yóo gbógun tì í bí ìjì líle, pẹlu kẹ̀kẹ́ ogun ati àwọn ẹlẹ́ṣin ati ọpọlọpọ ọkọ̀ ojú omi.
Àwọn eniyan ilẹ̀ náà sin OLUWA, ṣugbọn wọ́n ń bọ àwọn ère tí wọ́n gbẹ́ pẹlu.
NURTW Ekiti fẹgba yọ àwọn adarí kúrò ní gáréèjì!
Amọṣa, ninu ilepa ati mọ boya lootọ ni iroyin yii tabi irọ ni BBC News Yoruba ti fi ipe ṣọwọ si ọkan lara awọn eeyan to sun mọ igbakeji alaga ẹgbẹ oṣelu APC naa lati mọ ootọ ọrọ naa.
Idi ree ti ilumọọka alami ẹyẹ agbaye, Ọjọgbọn Wọle Ṣoyinka fi n lọgun pe aarẹ orilẹede yii, Mohammadu Buhari pe yoo dara ko kede pe nnkan ko fararọ lawọn ipinlẹ to wa nilẹ Yoruba lẹka eto aabo, ti ohun gbogbo si ti dẹnu kọlẹ.
Kí wọ́n yan àwọn olùṣọ́ láàrin àwọn ọmọ Jerusalẹmu, kí olukuluku ní ibùdó tirẹ̀, kí wọ́n sì máa ṣọ́ ibi tí ó bá kọjú sí ilé wọn.
Jẹ́ kí ojú rẹ máa wo ọ̀kánkán,kí o sì kọjú sí ibi tí ò ń lọ tààrà.
Ẹ tẹpá mọ́ṣẹ́, gẹ́gẹ́ bí a ti sọ fun yín.
Jesu bá tún sọ pé, “Ọkàn mí dàrú nisinsinyii.
Agbẹ lọ pọ ju ninu awọn ara ilu naa ti wọn a si maa gbin ohun jijẹ bi ọka baba, agbado ati alubọsa ti wọn si maa n kore fun tita Lẹnu ọjọ mẹta yi, ọrọ ifipabanilopọ jẹ eleyi to gbode kan kaakiri Naijiria ti awọn obinrin kan si ti padanu ẹmi wọn lọwọ awọn ika eniyan to fipa bawọn lo pọ yi.
“Akosile safihan pe, ile-ise ti o n ri si oro-omi ni anfaani ati je ona kan gboogi ti owo fi maa wole sapo ijoba orile-ede Naijiria.
Nisinsinyii, o rí i dájú pé OLUWA fi ọ́ lé mi lọ́wọ́ ninu ihò àpáta.
Adeọṣun Fọlaṣade ba BBC Yorùbá sọrọ lórí ìhùwàsí awọn eniyan ti wọn ba ti ri afin ati bi eyi ṣe le ṣakoba fun iru afin bẹẹ ni awujọ.
Nígbà tí wọ́n rìn síwá wọ́n rìn i pé adágún odò ní.
O sọrọ yii nibi ipade apero awọn iranṣẹ Ọlọrun gbogbo lorilẹ-ede Naijiria to waye niluu Eko.
8 164038 Orilẹede Croatia 2174 52.
Gbesa fikun pe ọba tuntun ti yoo ba jẹ nilẹ Ẹgba gbọdọ wa se awọn etutu kan loke naa, ki wọn to gbe ade lee lori, to si tun salaye lori awsn igbesẹ ti ọba naa yoo gbe labẹ Olumọ, ko to di ọba.
Naijiria yii si lo se ipo keji nilẹ Afirika, to si n tẹle orilẹede Mauritius lẹyin.
Nigba to n ṣi aṣọ loju akanṣe eto naa ni aafin rẹ, Ile Oodua ni ilu Ile Ifẹ, Ọọni kede ipo aidaa ti ọrọ aje orilẹede yii wa eyi to si jẹ ohun to gbe oun ninu lati ṣeranwọ fun awọn akẹkọọ ki wọn lee pada sẹnu ẹkọ wọn tori o fi aidunu rẹ han si ipo ti ọpọlọpọ akẹkọọ ile ẹkọ giga wa.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ọbẹ̀ ni, ẹran ni o, irú oúnjẹ wo lẹ́ fẹ́, ká báa yín sè é wá sílé yín?
Àwọn ọlọ́pàà yin afẹ́fẹ́ gáàsì #EndSARS lu àwọn olùwọ́de ní Abuja Oríṣun àwòrán, Channels Ọlọpaa nipinlẹ Abuja ti fin tajutaju si awọn afẹhọnuhan #EndSars ni ilu Abuja loju.
Ọkọ̀ òfurufu ọhun to gbéra lati Beirut, lebanon balẹ̀ si pápákọ̀ òfurufú Muritala Muhammed International nílùú Eko ni dede aago méjì kọjá ìṣẹ́jú mẹ́tàdínlógún lónìí ọjọ́ sátide.
Ise akanse yii je okan lara ise akanse amayederun ti won bere lodun 2016 ki sunkere fa kere oko le dinku ni Kano.
Ṣugbọn ẹnikẹ́ni tí ó bá fẹ́ jẹ́ pataki ninu yín níláti jẹ́ iranṣẹ yín.
Ajọ awọn orilẹede (UN), woye pe ida mọkandinlaadọrin awọn to n gbe ni igboro l'orilẹede Naijiria lo n gbe ni awọn agbegbe to ku diẹ kaato, ti awọn ti ko rile gbe si n lọ si bi miliọnu mejidinlogun.
Bẹẹ ba gbagbe, Sowore ni ọwọ awọn agbofinro tẹ lọjọ Kẹta osu Kẹjọ ọdun 2019 lori ẹsun o n gbidanwo lati se iwọde kan to pe Revolution Now.
Lori alaye bi o ṣe bẹrẹ tiata, Ronke oshodi ni iṣẹ karakata ni oun kọkọ n ṣe,lasiko naa ni oun fẹran lati ma a lọ si 'National Theatre' lati lọ wo fiimu, eleyii to mu ki oun ni ifẹ si ere ṣiṣe, ti oun si fẹran lati ma a rẹrin.
Bi a ba ni ki a wo ọrọ Europa yii, odu ni akọnimọọgba Arsenal, Unai Emery.
Nígbà tí Dafidi pada dé ààfin rẹ̀ ní Jerusalẹmu, ó mú àwọn obinrin rẹ̀ mẹ́wẹ̀ẹ̀wá tí ó fi sílẹ̀, pé kí wọ́n máa tọ́jú ààfin, ó fi wọ́n sinu ilé kan pẹlu olùṣọ́, ó sì ń pèsè oúnjẹ fún wọn, ṣugbọn kò bá wọn lòpọ̀ mọ́.
Ìlú wọn tóbi, wọ́n sì jẹ́ ìlú olódi, ó ṣeéṣe kí OLUWA wà pẹlu mi kí n sì lè lé wọn jáde, gẹ́gẹ́ bí OLUWA ti wí.
Oríṣun àwòrán, Aminu Ado Bayero/Instagram Oba Abdulkadir Baba Agba to jẹ oba Kẹẹwa ilu Ilorin si jẹ ẹgbọn Iya Aminu lọkunrin.
1936 Ọjọ kẹrindinlọgbọn oṣu Kẹsan Wọn bi arabinrin Madikizela-Mandela nilu Bizana, Transkei (Eastern Cape).
Nkan ti Sanusi ati awọn ọrẹ rẹ ṣe jẹ iwa yẹyẹ'.
 ilè-ìtayò nì wón ń kókó pè é kó tó di wí pé , wón kó ilé síbè gan-gan .
Bí mo ti ń ronú nípa àwọn ìwo rẹ̀, ni mo rí i tí ìwo kékeré kan tún hù láàrin wọn, ìwo mẹta fà tu níwájú rẹ̀ ninu àwọn ìwo ti àkọ́kọ́.
Àwọn ọmọ Lefi yóo sì jẹ́ tèmi.
EndSARS Protes Updatet: Aláàfin Ọyọ ní ọ̀dọ́ ìwòyí kò gba gbẹ̀rẹ́, kíjọba yé halẹ̀ mọ́ wọn
Ẹni tí ó ta ilẹ̀ lé rà wọ́n pada, ẹni tí ó rà á sì níláti jọ̀wọ́ wọn sílẹ̀ nígbà tí ọdún jubili bá dé.
Ọ̀kan ninu àwọn Farisi pe Jesu pé kí ó wá bá òun jẹun.
Fashola ni, idi ti wọn fi sun ọjọ ti wọn yoo ti afara naa si iwaju, nii se pẹlu igbiyanju ijọba ipinlẹ Eko lati mu idiwọ ati ipalara ti yoo jẹ fun awọn ara ilu kuro lasiko naa.
Ọọni ti Ile -Ife, Ọba Adeyẹye Ogunwusi, Ọjaja Keji ti kede arẹwa ọmọbinrin kan, Shilekunola Moronke Naomi gẹgẹbi olori laafin.
Dókítà Isah Shaedouw Baka, tó jẹ́ onímọ̀ nípa ààrùn ọpọlọ sàlàyè pé, àwọn ènìyàn tó fẹ́ gba ẹmi ara wọ́n jẹ́ àwọn tí ọ̀rọ̀ ara wọ́n tí sú wọ́n tàbí ti inú wọ́n ba tí dùn jù lórí ǹkankan.
Ilé-Ifẹ̀ ni Àlàó ti ń ta ojà.
Wọ́n bá sọ fún ọba pé Natani wolii ti dé.
5 Bélú 2018 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 7 Owewe 2019 Oríṣun àwòrán, Keystone-France Àkọlé àwòrán, • Asọ iran Yoruba, taa mọ si Agbada ati Sokoto ni Ajala wọ lori kẹkẹ to fi rin yika agbaye N jẹ ẹyin ti gbọ nipa ‘Ajala the Traveller’ tabi Ajala Travels’ ri?
4 1036 Orilẹede Taiwan 7 0.
Àwọn ọmọ Lefi ati àwọn alufaa gbé Àpótí OLUWA wá, ati Àgọ́ OLUWA, ati àwọn ohun èlò mímọ́ tí ó wà ninu rẹ̀.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ìjọba Eko fòfin de àgbò títà lójú pópó f‘ọ́dún Ileya Àwọn obìnrin tí kò lọ́kọ ń kojú ìsòro ilé gbígbà Èèwọ̀!
ó kó ẹẹdẹgbẹrun (900) kẹ̀kẹ́ ogun onírin rẹ̀ jọ, ó sì pe àwọn ọmọ ogun rẹ̀ jọ láti Haroṣeti-ha-goimu títí dé odò Kiṣoni.
Ó wá bi wọ́n pé, “Ẹ̀yin ńkọ́?
Jesu yipada sí àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ níkọ̀kọ̀, ó ní, “Ẹ ṣe oríire tí ojú yín rí àwọn ohun tí ẹ rí, 
Ìtàn Mánigbàgbé: Òwe ‘aṣọ kò bá Ọ́mọ́yẹ mọ́.
Ìdí ni pé, agbára Ẹ̀mí, tí ó ń fi ìyè fún àwọn tí ń bá Kristi gbé, ti dá mi nídè kúrò lọ́wọ́ ẹ̀ṣẹ̀ ati kúrò lábẹ́ àṣẹ ikú.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Nig-Ghana: Ìjọba àpapọ̀ faraya lórí bí Ghana ṣe lé àwọn ọmọ Naijiria padà sílé 20 Èrèlè 2019 Oríṣun àwòrán, @alessabocchi Àkọlé àwòrán, Kii se igba akọkọ ree ti wọn yoo le awọn ọmọ naijiria pada wa sile lati orilẹede miran Ijọba apapọ ni Naijiria ti fapa janu lori bi ilẹ Ghana se fọwọ osi juwe ile fawọn ọmọ Naijiria to le ni ẹẹdẹgbẹrin laarin ọdun 2018 si 2019.
Tí inú rẹ̀ bá bẹ̀rẹ̀ síí ru ayé á mì tìtì,àwọn orílẹ̀-èdè kò lè farada ibinu rẹ̀.
BBC Gov Debates: Ìṣẹ̀lẹ̀ mánigbàgbé níbi ìfọ̀rọ̀wérọ̀ BBC Yorùbá l'Ọyọ
Ó fẹ́rẹ̀ tó àkókò àjọ̀dún àwọn Juu nígbà tí wọn ń ṣe Àjọ̀dún Ìpàgọ́ ní aṣálẹ̀.
Ẹ̀rí-ọkàn bẹ̀rẹ̀ sí ní jẹ́ ẹ fún ohun tí ó ṣe, ó pinnu láti dá àwọn ewé kátabá náà padà sí ibi tí ó ti gbé ṣẹ́ ẹ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Coronavirus: Kínni ìtàkùn ayélujára 5G nííṣe gan na pẹ̀lú ààrùn coronavirus?
 Èyí lómú kí ó jẹ ́ wípé ọ ̀ pọ ̀ lọpọ ̀ kò leè sọ èdè yorùbá kó já gaara láì má fii èdè gẹ ̀ ẹ ́ sì kọ ̀ ọ ̀ kan bọ ̀ ọ ́ , bẹ ́ ẹ ̀ ni ọ ̀ pọ ̀ lọpọ ̀ kò sì leè sọ èdè gẹ ̀ ẹ ́ sì dáradára .
Koda awọn aisan bii foniku-fọla dide (Sickle cell), warapa (Epilepsy) ati Rọlapa-rọ lẹsẹ (Stroke) wa lara awọn aisan ti wọn n fi iwọ ati olubi ọms wo bayii.
Wọn kò lè dúró nítorí péOLUWA ni ó bì wọ́n ṣubú.
Ẹni ọdun mejidinlọgbọn ọhun to jẹ oniṣowo aṣọ sọ pe, oriṣirṣi eetu lo n jade ni idi oun ati irora ti ko ṣe fẹnusọ lẹyin iṣẹ abẹ naa.
Ninu iwe ẹbẹ kan to kọ si kọmisọnna ọlọpaa ipinlẹ Ondo, adele Ọba ọhun ṣalaye ohun ti oju rẹ ri lọwọ awọn janduku to kọlu afin naa.
Ẹ gbọ awijare wọn lori igbesẹ wọn yi i.
Olórí àwọn ìwẹ̀fà sọ ẹnìkọ̀ọ̀kan wọn ní orúkọ titun: Ó sọ Daniẹli ní Beteṣasari, ó sọ Hananaya ní Ṣadiraki, ó sọ Miṣaeli ní Meṣaki, ó sì sọ Asaraya ni Abedinego.
Ologbondiyan ni nibi ipade Ajọ amuṣẹya naa ni awọn yoo ti yanayan ipa ti ẹgbẹ oṣelu PDP ko ninu idibo sipo gomina to waye ni ipinlẹ Bayelsa ati Kogi.
Ọkan lara awọn obinrin naa, iya Halimat sọ fun BBC pe ojojumọ ni oun maa n sọkun ti oun si maa n gbadura ki oun le e ri ọmọ naa pada.
Wọn rò wi pé àwọn lè dá ilé-iṣẹ́ ti ó n pèsè iná mọ̀nàmọ́ná silẹ̀ ti ó lè lo atẹ́gùn, omi, epo rọ̀bì, oòrùn lati pèsè iná ti kò léwu bi ẹ̀rọ́ iná mọ̀nàmọ́ná.
Awọn ọlọpaa pada ri mu nínú fọran to le ni iṣeju mẹwaa, wọn fi ẹwọ de lọwọ wọn si fun mọlẹ , sugbọn o jọ bi ẹni pé o nilo iranwọ awọn eleto ilera.
olopaa kede iku osise re meta lojoru(Wednesday), eleyi ti awon osise omo ogun
NCDC kéde èèyàn 437 míràn tó ṣẹ̀ṣẹ̀ lùgbàdì Covid-19 ní Nàìjíríà, 142 gbàwòsàn Iná jó àwọn ènìyàn 10 tó ń gbà ìwòsàn arùn Coronavirus níbùdó ìtọ́jú Baba Obasanjọ kò ní àrùn Coronavirus- NCDC Buruji Kashamu jẹ́ ènìyàn tó nífẹ̀ aráàlú- Gómínà Dapo Abiodun Ijọba Bauchi ti ẹ sọ pe awokọse ipinlẹ Kano ni oun ṣe.
Saaju Baru, ti rawo ebe si oga agba  si eso enu ibode Hameed Ali lati ran won lowo nipa didena bi awon fayawo se n gbe epo koja awon enu ibode orile ede Naijiria.
Aarẹ Buhari sọ pe, oun ko ni ṣe aṣiṣe lati gbegba ibo aarẹ fun saa kẹta gẹgẹ bi aarẹ orilẹede Naijiria.
'Ẹnu lásán kò lè sàn owó oṣu oṣiṣẹ l'Ekiti' NLC: A ò ní dìbò wa fún àwọn gómìnà ọ̀tá òṣìṣẹ́ Ninu ifọrọwanilẹnuwo pẹlu BBC, Alaga ana fẹgbẹ oṣiṣẹ ni ipinlẹ Oyo, Siyanbade Waheed Olojede ni ko si ohun to buru ki wọn tete san owo oṣu fun oṣiṣẹ.
 Ali fi idunnu rẹ si bi igbesẹ atundi eto idibo
OLUWA, Ọlọrun, mú ìlérí tí o ṣe fún Dafidi, baba mi, ṣẹ nisinsinyii, nítorí pé o ti fi mí jọba lórí àwọn eniyan tí wọ́n pọ̀ bí erùpẹ̀ ilẹ̀.
Mùsùlùmí tó ń gbèrò láti lọ hajj ni Alhaji, Alhaja - Onímọ̀ Ọpọ musulumi ni ko ni lanfani lati kopa ninu Hajj tọdun yii, nitori bi Saudi ti kede pe, eeyan diẹ ni yoo kopa ninu ijọsin yii, to jẹ opo kan pataki ninu ẹsin Islam.
Jí pátá obìnrin ko jẹ́jọ́ ìpànìyàn - Dolapo Badmos Ṣé ó tọ̀nà kí obìnrin máa bímọ sílé?
Kunle Olasope: Lekan Alabi ní onírẹ̀lẹ bíi àgbà àgbóhùnsáfẹ́fẹ́ náà sọ̀wọ́n
Oríṣun àwòrán, Twitter Oju ọpọ ikansiraẹni Apple naa ko gbẹyin ni bẹ.
Idi ree ti BBC Yoruba fi jade sita lati mọero awọn araalu nipa isẹlẹ naa atawọn ọna to gba se akoba fun ọrọ aje wọn.
Ọjọ keji la to ri oku rẹni Madarumfa nibi ti ẹrọfọ ti bo mọle.
Ọpọ ni yoo maa ṣe iranti Maradona fun goolu rẹ to fọwọ jẹ ninu idije agbaye eyi ti Argentina fi gbewuro soju ilẹ Gẹẹsi ni Mexico 86.
"Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ọkúnrin kan gún àfẹ́sọ́nà rẹ̀ pa tán ló bá tún pa ara rẹ̀ náà Ohun tí a mọ̀ nìyí nípa àwọn tí yóò láǹfàní àti lọ sí Hajj lọ́dún yìí Àìmọ̀kan ló ń ṣe ìjọba Oyo tó fẹ́ ṣí iléèwé, gbogbo ìpínlẹ̀ ló ní àrùn COVID 19- Ijọba àpapọ̀ Lórí bóyá igbákejì gómìnà Ondo yóò fipò sílẹ̀ tàbí rárá, ohun tó lu sí wa lọ́wọ́ nìyí Ènìyàn 675 ni èsì àyẹ̀wò sọ pé ó tún ṣẹ̀ṣẹ̀ ní Covid-19 ní Nàìjíríà O ní ""kí ìwádìí ba lè já geere, a ò ni le sàlàye lẹkùnrẹ́rẹ́ ibi ti ìwádìí ti dé dúró, sùgbọ́n ti ìwádìí náá ba ti kẹ́sẹ jári tán, ileesẹ ọlọ́pàá yóò le sọ fún ará ilú bi gbogbo rẹ̀ ṣe jẹ́"" Nípa bóyá àwọn amọkùn ṣeka yìí fí n ṣe ètùtù ni gẹ́gẹ́ bi àwọn kan ṣe sọ, Ọ̀gá ọlọ́pàá ní ìwádìí ṣì ń lọ lọ́wọ́ lórí rẹ̀ náà."
Oríṣun àwòrán, @GovAyoFayose Bakan naa, wọn tun n lo ayajọ ọjọ yii lati se iwuri ati koriya fun awọn obinrin lati lọ se ayẹwo ọyan wọn aibaamọ, ẹlẹkẹru arun jẹjẹrẹ ti lee sagọ sinu ọyan wọn, nitori igbagbọ wa pe ti wọn ba tete kẹẹfin kokoro arun jẹjẹrẹ ọyan yii, eyi yoo mu adinku ba ewu tiru obinrin bẹẹ lee koju, to seese ko mu okun ẹmi rẹ lọ to ba ya.
Oríṣun àwòrán, Other Ọpọ ere sinima, fiimu agbelewo ati ere itage ni Efunsetan ti kopa ninu rẹ, ko si si ẹni to ri obinrin naa lori pẹpẹ iwaasu, ti ko ni maa ranti awọn ara manigbagbe to ti da ninu isẹ tiata.
"Mo gba iwọ Henry gẹgẹ bii ọkọ mi Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Kaakiri agbaye ni okiki ti kan de nípa igbeyawo Ọmọọba Harry ati Omidan Meghan ""Henry"" boo?"
Ohun tí Farao ń fún wọn yìí ni wọ́n sì fi ń jẹun.
Nígbà tí àwọn ènìyàn bẹ̀rẹ̀ sí ṣe ìbéèrè nípa àìsàn, wọ́n yí aṣojú-Olódùmarè ká, wọ́n bò ó bi ìgbà tí ogunlọ́gọ̀ àwọn èèrà bá bo ẹ̀rún oúnjẹe, wọ́n ń sọ̀rọ̀ bí ìgbà tí àwọn ẹyẹ ẹ̀gà bá ń ké lórí ọ̀pẹe, wọ́n ń rín síhìn-ín rìn sọ́hùn-ún bí ìgbà tí alápàádẹ̀dẹ̀ bá ń fò káà kiri ẹ̀hìnkùnlé, wọ́n ń ro ẹjọ́ bí ẹni pé Ẹni tí Ó dá wọn kò gbọ́n tó wọn.
Minimum Wage: Alága òṣìṣẹ́ Ekiti ní òǹyẹ̀ kò leè yẹ sísan ₦30,000 owó oṣù
Bí majẹmu ti àkọ́kọ́ kò bá ní àbùkù, kò sí ìdí tí à bá fi fi òmíràn dípò rẹ̀.
Mercy Aigbe: Asọ Ẹbi tita ni na tawọn mu pọn lẹyin fiimu sise Mercy Aigbe ti oun naa jẹ gbajumọ osere ko kawọ gbera rara nigba ti awọn akẹẹgbẹ rẹ n wa owo.
ó rán Hadoramu, ọmọ rẹ̀, pé kí ó lọ kí Dafidi ọba, kí ó sì bá a yọ ayọ̀ ìṣẹ́gun tí ó ní lórí Hadadeseri, nítorí Hadadeseri ti bá Toi pàápàá jagun ní ọpọlọpọ ìgbà.
Àgbo Madagascar ti wà ní Nàìjíríà ṣùgbọ́n kìí ṣe ọ̀fẹ́, a ní láti sanwó-Mínísítà Minisita naa sọ ọrọ yii lasiko ifọrọwanilẹnu kan pẹlu BBC lọjọ Iṣẹgun.
Awọn kan si ti n sọ pe ọrọ wọn ọhun ti wa si imuṣẹ nitori bi Buhari ṣe ti lọ si ilẹ okeere lati gba itọju ni awọn asiko kan.
Yóo bímọ tán, yóo sì jẹ ibi ọmọ tí ó jáde lára rẹ̀ ní kọ̀rọ̀, yóo sì tún jẹ ọmọ titun tí ó ṣẹ̀ṣẹ̀ bí, nítorí pé kò sí ohun tí ó lè jẹ mọ́, nítorí àwọn ọ̀tá yín tí yóo dó ti àwọn ìlú yín.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Lẹ́yìn rẹyìn Seyi Makinde búra fún ìgbìmọ̀ olùgbaninímọ̀ràn Ìgbà Marún-un ti Aisha Buhari ti tako ìjọba Buhari Oko òkú rèé, níbití òkú ti ń jẹrà mọ́lẹ̀ fún àyẹ̀wò Wo àwọn ẹranko tí wọ́n máa figagbaga ni Egypt Tani Femi Kuti ti yoo kọ orin iside Afcon 2019?
Àkọlé àwòrán, Abike Dabiri-Erewa to jẹ oluranlọwọ pataki fun Aarẹ Buhari lori ọrọ ilẹ okeere naa wa yẹ goimina Ajimọbi si Àkọlé àwòrán, Awọn elere ibiẹ to n fi gangan dabira naa o gbẹyin nibẹ.
Oríṣun àwòrán, Archive Bi ọlọpaa ati ologun ṣe kọlu awọn akẹkọọ lasiko iwọde: Ọjọ akọkọ ti iwọde naa bẹrẹ, ni awọn ọlọpaa ti kọlu awọn akẹkọọ naa, ti wọn si ta ọkan ninu wọn ni ìbọn ni ẹsẹ.
Mo kà á lẹ́ ẹ̀ kín-ín-ní, mo kà á lẹ́ẹ̀kejì, mo kà á lẹ́ẹ̀kẹta, n kò ṣàì lè sọ iye ìgbà tí mo kà á tán.
Ọ̀rọ̀ ń bọ́ lóríi fídíò Codeine Lọ́wọ́lọ́wọ́, awon ile ise ijoba apapo ni Naijiria to n mojuto gbigbogunti àṣìlò ohun jijẹ ati oogun lilo, NAFDAC, ti kede pe wọn ti bẹ̀rẹ̀ ìwádìí nínú awọn ilé isẹ́ mẹ́rẹẹrin ti Fídíò BBC menuba.
O je omo odun mejilelogoji ti won bi si Gussau ni ariwa Naijiria ko to ko lo si Italy nibi to ti koko je alaga woodu kansilo lodun 1995.
“Kí ó tó bẹ̀rẹ̀ sí rọbí, ó ti bímọ.
” O ni ile ise oun to je okan lara ile ise to n seto eyawo naa ti foruko agbe oniresi egberun metala sile bayii nipinle Borno ti won si ti ri ajile, eso, apako atawon ohun eelo igbalode miran gba lowo ijoba bayii,O ni awon agbe ti ko oko to to eeka egberun metala bayii ni ijoba ibile Mafa, Maiduguri, Monguno, Damboa, Hawul, Biu, Kwaya-Kusar ati Shani nipinle Borno leyin ti won ti pada sile kuro nibudo asatipo ti won sa lo doola emi won si tele.
Balaamu bá dáhùn pé: “Ṣebí mo ti sọ fún àwọn oníṣẹ́ tí o rán wá pé, 
85 Isẹ to jẹ mọ ọrọ aje - 381,852,747,856.
Ọmọkunrin kan ati ọmọbinrin kan si ni olori Anuoluwapo bi fun Alaafin lọwọ lọwọ bayii.
A gbodo fowosowopo lati je ki ife, isokan ati alaafia joba, ki a ni emi idariji ati ikoni-mora.
“Lai ki i ṣe pe wọn wa ṣagbekalẹ
Ayeye ohun waye nigba ti o ku osu meji ki ipade apero awon olori orilede ajo naa waye nilu London, irufe ipade ohun je igba akoko lati bi odun 1986, bakan naa ni o je akoko iru re  ti yoo waye ni ile-Geesi,lati odun 1997 ti ipade apero Edinburgh ti waye.
"Yínyínbọn síra ẹni wáyé lánàá láàrín ọlọ́pàá kògbéregbè SARS àti àwọn onípàáǹle kan tí ìbọn sì bá akẹ́kọ̀ọ́ náà""."
Bí okùn àwọn eniyan burúkú tilẹ̀ wé mọ́ mi,n kò ní gbàgbé òfin rẹ.
Ẹ yọjú sí FBI bí ẹ kìí bá ṣe ''yahoo boys'' - Abike Dabiri-Erewa Ta ni Ọjọgbọn Adebanji Akintoye tó borí Tinubu láti di olórí àwọn Yoruba?
Ta ni kò mọ irú nǹkan, tí ẹ̀ ń sọ yìí?
O oun ranti pe ninu ibẹru bojo ni oun wa ti oun fi pe ọkan ninu awọn ọmọ ẹni ti o pa to si jẹwọ fun pe ki o fori ji oun.
O ṣalaye pe ko si nnkankan ti awọn to wa n ṣe amojuto eto dibo fẹ jẹ lere ju pe ki eto idibo lọ ni irọwọrọsẹ.
Amotekun Oyo: Ọwọ́ tẹ ènìyàn méjì tó ń ta ayédèrú aṣọ iṣẹ́ ikọ̀ Àmọ̀tẹ́kùn
Ọjọru, ọjọ Kọkandinlọgbọn, oṣu Karun ọdun yii kanna si ni wọn bura fun gẹgẹ bii gomina alasẹ ipinlẹ Kwara.
Ohun to wa ṣe wa ni Kayefi ni wi pe iya awọn ọmọ yii funrarẹ gan, iru oju buluu yii kan naa lo ni.
Ó tẹ̀lé àpẹẹrẹ Dafidi, baba ńlá rẹ̀, nípa títẹ̀lé òfin Ọlọrun fínnífínní.
Nígbà tí à ń wí yìí ni Agabu aríran kan dé láti Judia.
Mo láyọ̀ pé mo lè gbẹ́kẹ̀lé yín ninu ohun gbogbo.
Bákannáà ló ní dípò ká máa fi òfin ìwà ọ̀daràn de lílò òògùn olóró, ńse ló yẹ kí orílẹ̀èdè Nàíjíríà máa fojú aláìsàn wo àwọn èèyàn tó bá kúndùn igbó mímu, ká sì sètọ́jú wọn bọ ti yẹ.
Lẹ́yìn náà, Ọlọrun sọ fún wọn pé: “Ẹ sọ ilé náà di aláìmọ́, ẹ kó òkú eniyan kún gbọ̀ngàn rẹ̀, kí ẹ sì bọ́ síta.
Davido àti Chioma aya rẹ̀ ti d'ọ̀rẹ́ padà ní Instagram Òyìnbó ẹni ọdún 46 wá ṣe mọ̀'mí n mọ̀ ọ́ ní Kano pẹ̀lú Isah olólùfẹ́ rẹ̀ Ìlẹ̀kẹ̀ ìdí mi ló kó mi yọ lọ́wọ́ àwọn afipábánilòpọ̀ ní Lebanon Ẹgbẹ́ kan fún Tinubu ní wákàtí mẹ́rìnlélógún láti sọ èrò rẹ lórí Amọtẹkun Iroyin sọ pe akẹkọọ kan ti orukọ rẹ n jẹ Motunrayọ lo tu aṣiri sita lori ohun to n lọ laarin oun ati olukọ fasiti naa.
Adajọ ile ẹjọ naa, Olusegun Odusola sun ẹjọ naa lẹyin wakati mẹjọ gbako ti wọn ti wa nile ẹjọ ọhun, lati le faye gba awọn ẹlẹri mẹrin ijọba lati wa sọ tẹnu wọn.
Ọna ti Baba Adeboye gba ṣe ayẹsi ọjọ ibi iyawo rẹ, Folu Adeboye lọtẹ yii to pe ọdun mejilelaadọrin ma nii- ni awọn ọdọ Naijiria ba tu sita loju opo Twitter Adeboye lati da si ọrọ naa yala ni ti ṣiṣi fila fun ohun ti Pasitọ yii ẹni ọdun mẹtalelọgọrin funrararẹ sọ nipa iyawo rẹ, Folu Adeboye tabi tita ko o.
9 l'ọdun 2018, tako lita 84.
awon osise lorile ede Naijiria ku ori –ire ayẹyẹ ayajọ ọdun awon  osisẹ
Isẹlẹ naa si way laarin osu mẹta ti wọn dibo yan Abbo sile asofin agba ilẹ wa, to si se ibura wọle lọjọ Kọkanla osu Kẹfa.
Ibrahim Lamorde (2011 - 2015): Wọn ni o kọ lati ko triliọnu meji aabọ si apo ijọba Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ọpọ ọmọ Naijiria lo sọ nigba naa pe ile aṣofin n fi oro ya oro lara Lamorde ni, fun bo ṣe n wadii awọn aṣofin kan.
Kwara àti Kebbi ni èèyàn mẹ́rin, Gombe, Taraba, Ogun, àti Ekiti ni èèyàn méji tuntun nígbà ti Osun àti Bayelsa ni ẹnì kọ̀ọ̀kan.
A ko ri iru eyi ri, a fi n dẹru ba ọlọrọ ni, BBC ba Afeez Oladimeji Agoro to jẹ Aguntaṣọlọ ọkunrin sọrọ lori bo ṣe jẹ akanda.
 Aare dibo ni ward A Sarkin
Ọjọ Kọkandinlọgbọn, osu Karun un, ọdun 1960, ni idile Ọba kan nilu Ipẹru Rẹmọ gba alejo ọmọ tuntun jojolo, eyi to tọ Dokita Emmanuel Abiodun ati aya rẹ, Victoria wa, eyi ti wọn pe orukọ rẹ ni Adedapọ Abiọdun.
Ko pẹ si asikọ ọhun ni akọwe ojọba rẹ, Ifedayo Abegunde naa kọ ẹyin si Akeredolu.
O ni oun gan an fẹ pa ara oun lori gbogbo ogun yii.
Oun ati ajọ EFCC naa jọ woju ara wọn.
I Language Centre: Yorùbá ló làṣà àti èdè Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
ede naa leyin iku baba rẹ lodun 2005, ni bayii o ti lo aadota odun lori ipo, ni
N óo ti wà pẹlu yín pẹ́ tó!
Nítorí bí eniyan bá gbọ́ ọ̀rọ̀ náà, tí kò fi ṣe ìwà hù, olúwarẹ̀ dàbí ẹni tí ó wo ojú ara rẹ̀ ninu dígí.
Esi ti awọn eeyan fọ si ọrọ yii loju opo Facebook wa kọja afẹnusọ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fọ́nrán ohùn, Agbẹnusọ Mélayé: Dino ti lọ yọjú sọ́dọ̀ ọlọ́paa SARS Ọmọọba Adélàjà @AdelajaAdeoye ní, pẹ̀lú bí wọn se gbé Dino yìí, màrìwò la tíì rí, egúngún sì ń bọ̀ nítorí ọ̀pọ̀ àwọn olùdíje fún ipò ààrẹ ni wọn yóò rán lẹ́wọ̀n.
 18 june 1928 ) je oniwakiri ara norway.
Akọroyin ere idaraya fun BBC, Janine Anthony, to wa ni papa iṣere ti idije naa yoo ti waye jabọ pe, awọn elere idaraya to n ṣoju orilẹede South Africa ati Botswana ti gunlẹ silu Asaba, ti awọn akẹgbẹ wọn lati Egypt ati Kenya si gunlẹ ni owurọ ọjọ Ọjọru.
Solomoni kúrò ní àgọ́ ìpàdé tí ó wà ní ibi ìrúbọ ní Gibeoni, ó wá sí Jerusalẹmu, ó sì jọba lórí Israẹli.
Ṣugbọn iwadii ikọkọ ti BBC Africa Eye ṣe ni orilẹ-ede Ghana fihan pe awọn oṣiṣẹ eleto ilera gan an n ṣe ara wọn ti wọn si n ji ohun eelo ko ta nigboro.
Oríṣun àwòrán, AFP Àkọlé àwòrán, Ni Ethiopia, awọn ajagunfẹyinti se iwọde iranti isekupani to waye nilu Addis Ababa (Addis Ababa Massacre) nibi tawọn eniyan to le lẹgbẹrun lọna ogun ti padanu ẹmi wọn sọwọ awọn ọmọogun orilẹede Italy, lọdun 1937.
2 1067870 Orilẹede Germany 18995 22.
Ni ayé òde òni kò si àṣiri mọ, àṣà yi ti yi padà nitori, ni àtijọ́, Ọba ki kú si àjò, bẹni kò si iwé-iroyin àti ẹ̀rọ ayélujára.
Kí ló dé tí a fi ń ṣe aiṣootọ sí ara wa, tí a sì ń sọ majẹmu àwọn baba wa di aláìmọ́?
gbọdọ fi otitọ inu ṣiṣẹ papọ.
Ní ìdílé Olú- òjé, Onígbẹ̀ẹ́tì, Olókùn- Ẹṣin, Arẹ̀sà, Oníkòyí àti Olúgbọ́n, ọjọ́ keje ni à ń sọ ọmọbìnrin lórúkọ.
Ọ̀pọ̀ ló mi ìgbàgbọ́ pé àwọn asojú ilé ìgbìmọ̀ asoin yiìí kan ń lọ síbẹ̀ láti ná owó ìlú ni kò sí ǹkan pàtó tí wọ́n n ṣe níbẹ̀ ju oorun lọ Oríṣun àwòrán, Others Oríṣun àwòrán, Others Rochas Okorocha bẹ̀rẹ́ iṣẹ́ nile ìgbìmọ̀ asofin kò tii ju oṣù mẹ́ta lọ tó ti bẹ̀rl iṣẹ́ oorun sìsùn Oríṣun àwòrán, Others Yoruba bọ̀ wọ́n ni kò si ẹni tó le yan ẹran ara jẹ́, asiko to ba ti ni ki ènìyàn sinmi, o dí dandan ki oluwa rẹ̀ ṣe bẹ́ẹ̀ Oríṣun àwòrán, Others Ní ọ̀pọ̀ ìgbà ni àwọn ọmọ Naijiria ti maa n gbarata lórí bi àwọn ọmọ ilé igbímọ̀ aṣofin àgbà ṣe ma sùn lásìkò ìjòkó ilé.
"Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: ""Ẹ̀yin obìnrin, ẹ lọ kọ́ iṣẹ́ káfíńtà torí ó lówó lórí ju iṣẹ́ aránṣọ lọ"" Ẹ máṣe gba àmúlùmálà ọmọ oyè lọ́wọ́ ìdílé ọba kankan nílẹ̀ Ijebu - Awujale Àwọn ọmọbíbí ìpínlẹ̀ Ọyọ nìkan ni yóò rí iṣẹ́ àgbàṣe gbà lábẹ́ ìjọba mi - Seyi Makinde Àwọn obìnrin yarí, wọ́n kò fẹ́ àwọn ọkùnrin ní òde ijó wọn Pàtàkì ọdún Ojúde Ọba fún ìran Yorùbá Atẹjade kan ti ẹgbẹ oselu PDP lẹkun iwọ oorun Guusu Naijiria fisita, eyi ti akọwe ẹgbẹ lẹkun naa, Ayọ Fadaka fọwọsi lo sisọ loju ọrọ yii, lasiko to n fesi si ọrọ kan ti Abiọla Ajimọbi sọ pe iti ọgẹdk lasan ni awọn ọkọ ayọkẹlẹ ti wọn lo sọnu, ko to ohun ti a n yọ ada si."
BBC Women's Footballer of the Year 2019: Wo bí o ṣe lè dìbò yan ẹni ti o bá fẹ́
Bakan naa ni wọn fi ẹsun kan awọn ọmọ ati iyawo rẹ pẹlu.
Bí a bá wí pé a kò lẹ́ṣẹ̀, ara wa ni à ń tàn jẹ, òtítọ́ kò sì sí ninu wa.
Amọ to ba di ọjọ Ẹti, isẹ marun ni wọn yoo maa se lojumọ, ti wọn si rọ awọn ọga lati tẹle ofin naa.
omo-ogun orile ede Naijiria ti won n pe ni LAFIYA DOLE ti mu awon omobinrin
Suicide: Ẹ wo ọkùnrin tó dáná sún ọ̀rẹ́bìnrin rẹ̀ nítorí kó gbà látí jẹ́ aya rẹ̀
2019 elections: Awọn jàǹdùkú yìnbọn f'éèyàn méjì nítorí owó ní Kwara
Bakan naa ni wọn salaye oniruuru anfaani ti ejo ati awọn ẹya ara rẹ n se fun ilera ọmọniyan.
"Ninu atẹjade kan, Theresa May ṣalaye pe, ""Bi a ṣe n gbaradi lati fi ajọ ilẹ Yuroopu silẹ, asiko niyi fun ilẹ Gẹẹsi lati tubọ mu ajọṣepọ rẹ pẹlu awọn orilẹede jakejado agbaye gbopọn sii."
Gòkè lọ sí Gileadi, kí o lọ wá ìwọ̀ra, ẹ̀yin ará Ijipti,asán ni gbogbo òògùn tí ẹ lò,ẹ kò ní rí ìwòsàn.
Solomoni ọba ṣa ẹgbaa mẹẹdogun (30,000) eniyan jọ lára àwọn ọmọ Israẹli, láti ṣe iṣẹ́ tipátipá.
Nkan ti o wa kan ni lominu ni pé tí kòkòrò na bá tún yà irú òmíràn, èròjà tó ń gbógun ti aarun lára kò ní damọ̀ mọ́ àwọn abẹ́rẹ́ tí wọn tí pèsè fún náà kò ní ṣıṣẹ́ mọ (Gege bí ó ṣe rí pelu ofinkin) Ilu Wuhan ni China lo ti jẹyọ niipari ọdun 2019 nibi ti a ti ri awọn iṣẹlẹ arun naa lọja lekulẹja nibẹ.
Òkúta olówó ńlá tí a wọ̀n kí á tó gé e, ati igi kedari, ni wọ́n fi ṣe ògiri rẹ̀.
Gẹgẹ bi ohun ti ile iṣẹ amohunmaworan orile-ede naa sọ aarẹ naa ti awọn ologun yẹ aga nidi rẹ ku nile ẹjọ loni.
Awn oṣiṣẹ to wa nidi ikoko ọbẹ to n dana agbọn-ọn-gbẹ iroyin wọnyii ṣalaye iriri wọn.
Bi Joshua ko tilẹ ṣe raye ri ipade ṣe pẹlu awọn ololufẹ rẹ nigba to wale ninu oṣu keji, ko sẹni to binu si i, ṣugbọn o ri ọba ati awọn ijoye ko to pada.
Bi onirese Abiola Ajimobi ko tiẹ fin igba mọ amọ eyi to ti fin silẹ ko le e parun, ti BBC Yoruba si n gbadura pe, ki Ọba oke tẹ agba oselu ati ojulowo ọmọ bibi ilẹ Ibadan naa si afẹfẹ rere.
Nítori àwọn àtúgbẹ́yẹ̀wò, o níra láti ṣe àkójọpọ fún àwọn ọkọ́ naa Orisun: Johns Hopkins University atawọn ajọ eto ilera ilu Iye akọsilẹ to waye gbẹyin 7 Oṣù Ọ̀pẹ̀ 2020 14:22 WAT+3 Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ẹ̀mí kan náà ló n darí ìrìnàjò wa táa fi jọ kọ́lé papọ̀- Ìbejì Coronavirus: Àwọn ohun tí a kò tíì mọ̀ nípa àrùn Covid-19 Kí lo mọ̀ nípa fẹntilétọ̀, ohun èlò aṣèrànwọ́ èémí Ṣé òògùn Chloroquine lè dènà ààrùn Coronavirus bí?
Iṣẹ́ bẹ̀rẹ̀ ní òpópónà Eko si Abeokuta Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Ìgbà tí ó pé ṣa, ọkàn rẹ̀ sọ fún un pé ìbẹ̀ ni mo níláti wà, nítorí kò rí mi ki ń jáde lágbègbè ibẹ̀, ó bá mu àdó kan jáde, nígbà tí ó sọ àdó sí abẹ́ ìtí, àdó gbiná, iná ń jò bọ̀ lọ́dọ̀ mi mo bá fò jáde tí Ẹlẹ́gbára náà gbá tẹ̀lé mi, èmi tí mò ń sáré ikú mo ń lọ nínú igbó gbururururururu.
Oro ohun lo ta mi lolobo pe, emi ti mo n tun ilu onilu se, paapaa julo pipese ayika to rorun fun awon omo orile-ede Naijiria niluu onilu, oro naa lo si mi leti, ki n wa si orile ede Naijiria lati wa tun ilu baba mi se.
Agbẹjọro agba, Chino Obiagwu sọ pe, ko lẹtọ labẹ ofin fun ileeṣẹ ọlọpaa lati gba iṣẹ ileẹjọ ṣe, nipa dida awọn oṣiṣẹ duro pẹlu iwọde ti wọn fẹ ṣe.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, RAMADAN: Onímọ̀ ẹ̀sin sọ nípa isẹ́ láádá àti làádà Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Eyi si sọ Fakorede di ọkan lara awọn kọmiṣọna nipinlẹ Oyo.
''O yẹ ki wọn ṣe atunṣe lawọn ibi ti o ba ku diẹ kaato amọ ara ilu naa nipa ti awọn naa le ko.
Bọọli ati ẹja tabi ẹran adiyẹ ti wọn yi lata naa ti n peju-pesẹ sibi ayẹyẹ bayii.
 “A ti pinnu lati maa san ẹkunwo ọgbọ̀n ẹ̀gbẹ̀rún naira(N30,000 ) fun awọn osisẹ wa losoosu; A ti se ipinnu yii ,ki
Awon Molebi  eniyan naa, lo pejo si iwaju ogba ewon pelu ibinu lati mo ohun to sele si awon eniyan won to wa latimole.
Aare Muhammadu Buhari yoo sagbekale iwe isuna odun 2019 fun igbimo to n mojuto oro ohun nile igbimo asofin lojoRu(Wednesday) ose to n bo.
Sẹneto Dino Melaye to n soju awọn eeyan iwọ oorun ipinlẹ Kogi ni gbungbun orileede Naijiria kii ṣe aimọ lagbo oṣelu Naijiria.
“Kí ló dé tí Olodumare kò fi yan ọjọ́ ìdájọ́,kí àwọn tí wọ́n mọ̀ ọ́n sì rí ọjọ́ náà?
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ọ̀bọ lé àwọn ènìyàn kúrò nílè Sé ẹ̀bẹ̀ PDP jẹ́ ìtẹ̀wọ́gbà bí?
Ohun tí àwọn olùdìbò fún ìgbà àkọ́kọ́ ńbèèrè lọ́wọ́ ìjọba tó ńbọ̀ Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí 2 sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 2:23 Fídíò, Water Generator: Ó leè ṣiṣẹ fún wákàtí mẹfà, kó tó sinmi, Duration 2,2310 Òkùdu 2020 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
Ọpọ eeyan lo ni o ṣeeṣe ki aarẹ ana naa rinrin ajo kuro ni Naijiria ṣugbọn, ọrọ agbẹnusọ rẹ fi han wipe, ile rẹ ni Abeokuta lo wa nigba ti iburawọle naa n lọ lọwọ ni Abuja.
Wọ́n wó àwọn oriṣa Baali lulẹ̀ níwájú rẹ̀; ó fọ́ àwọn pẹpẹ turari tí wọ́n wà lẹ́gbẹ̀ẹ́ rẹ̀.
" Bakan naa lo sọ pe, oun fẹ jẹri niwaju igbimọ ti Aarẹ Adama Barrow gbe kalẹ.
Ileẹjọ f'ofin de ọdun oro nipinlẹ Ogun Sanwo-Olu kò lè tori ìjà Ọjọta fòfin de NURTW ní Eko - Agbẹnusọ gómínà Buhari yan Kyari ní olùdarí tuntun fún àjọ NNPC Agbébọn kọlu àwọn ènìyàn níbi ìdíje eré sísá ẹṣin Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Xenophobia: Ezekwesili ní bá ṣe yanjú ìkọlù South Africa ló fa sábàbí
Kí ó tó dákẹ́ ọ̀rọ̀ sísọ, Jonatani, ọmọ Abiatari, alufaa, dé.
Nigba ti o n fesi si leta ti Olusegun Obasanjo ko si aare
O gba awọn obi nimọran lati ṣe atilẹyin to yẹ fun awọn ọmọ wọn to ba ni talẹnti to dara.
Nigba to n fidi iṣẹlẹ naa mulẹ fun BBC, agbẹnusọ fun ileeṣẹ ọlọpaa nipinlẹ Oyo, Olugbenga Fadeyi, sọ pe iwadii ti bẹrẹ lori iṣẹlẹ naa.
O ni, ẹẹkan loojọ ni etoounje
N jẹ lootọ ni ajọ Peace Corps gba owo ki awọn ọmọ ẹgbẹ rẹ to darapọ?
Boxing Day ko ni nnkankan ṣe pẹlu ẹṣẹ kíkàn gẹgẹ bi awọn eeyan kan ṣe lero.
Ta ni ó yá a ní ohunkohun rí tí ó níláti san án pada?
Ni ọjọ́ Ẹti, ọjọ́ keje, oṣù kẹwa ọdún Ẹgbàálémẹ̀rindinlógún, ìròyìn pé àwọn Ọ̀tẹlẹ̀múyẹ́ já lu ilé àwọn Adájọ́ ti wọn fi ẹ̀sùn iwà ibàjẹ́ kàn jade lẹhin ti wọn ti dúró titi ki “Ẹgbẹ́ Adájọ́” gbé àwọn iwé ẹ̀sùn iwà ibàjẹ́ yẹ̀wò .
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù FUTA: Àwọn mẹ́jọ ló ṣíná ìyà fún Bolu ní FUTA Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ FUTA: Àwọn mẹ́jọ ló ṣíná ìyà fún Bolu ní FUTA 2 Ọ̀pẹ̀̀ 2019 Wọn da ọgbọn tàn mi wa sinu iyara wa fiya jẹ mi- Boluwatifẹ Laipẹ ni fidio kan lu ori ayelujara pa pe awọn akẹkọọ ile iwe giga ti ijoba apapọ ni akurẹ ni ipinlẹ Ondo, iyẹn Federal University of Technology lu akẹgbẹ wọn kan FUTA pàṣẹ lọ rọọ́kún nílé f'ákẹ́ẹ̀kọ́ méje tó lu akẹgbẹ́ wọ́n.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'A rí wàhálà táwọn èèyàn ń kojú nilẹ̀ẹ̀ Yorùbá la ṣe fi Amotekun"" fi ọkàn wọn balẹ̀' Didi ti wọn ti awọn ọna to wọ ilẹ Igbo fa ìyàn kaakiri ilẹ naa, to si jẹ pe awọn akọsilẹ kan sọ pe eniyan to to ẹẹdẹgbẹta ẹgbẹrun (500 thousand) si miliọnu meji l'awọn ọmọ Biafra tó kú nitori airi ounjẹ jẹ."
O jẹ asiko ti gbogbo wa ni lati tubọ sunmọ Ọlọrun Allah, ki a si ma kaarẹ
Ní ọdún 2017 àti 2016, oníròyìn orí-ayélujára ọmọ bíbí ìlú Nàìjíríà àti akọbúlọ́ọ̀gù Abubakar Sidiq Usman àti Kẹ́mi Olúnlọ́yọ̀ọ́ tí ta ẹsẹ̀ àgẹ̀rẹ̀ sí òfin nípasẹ̀ ṣíṣe iṣẹ́ ìkóròyìnjọ lóríi Òfin Ẹ̀ṣẹ̀ orí-ayélujára.
Gbígbọ̀n ni gbogbo ara mi ń gbọ̀n látòkè délẹ̀.
Lẹsẹkẹsẹ angẹli Oluwa bá lù ú pa, nítorí kò fi ògo fún Ọlọrun.
Bakan naa lo ni Gomina Babajide Sanwo-Olu gboriyin fáwọn olugbe Eko fun bi wọn ṣe tẹle asẹ konile o gbele naa, eyi to mu ki alaafia pada sipinlẹ naa lẹyin rogbodiyan iwọde EndSARS.
" Oríṣun àwòrán, Nkechi Blessing Nkechi, ẹni to wa nilẹ Amẹrika bayii lati lọ se afihan sinima rẹ, lo tun lo anfaani irinajo naa lati ri ọkọ rẹ, ẹni to n gbe nilẹ Amẹrika.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Lẹ́yìn ti orílẹ̀-èdè náà ni àwọn ti lo àgbo náà o sì ṣiṣẹ ni ọ̀pọ̀ àwọn orílẹ̀-èdè ní Africa ti pè fún, eyí ti kò yọ orilẹ̀-èdè Nàìjíríà silẹ̀ Kíní àwọn èròjà tí wọ́n fi ṣe àgbo náà?
Àkọlé àwòrán, Ìwé àkọsílẹ̀ tí Naomi pamọ lásìkò tó wà ní àhámọ Boko Haram nínú ìgbó Sambisa Èdè Oyinbo àti Hausa ní wọ́n fi kọ ìwé àkọsílẹ̀ wọn yìí, bó tilẹ̀ jẹ́ pé kò sí àkọsílẹ̀ àwọn ọjọ ìṣẹ̀lẹ̀ sùgbọ́n ó dàbí ẹni pé àkọsílẹ̀ náà wáyé ni oṣù àkọ́kọ́ tí wọ́n wọ àhámọ Boko Haram Òṣèré tíátà, Kemi Afolabi dùbúlẹ̀ àìsàn ní ìlú Mecca Mohammed Yusuf: Irú èèyàn wo ní olùdásílẹ̀ Boko Haram?
Niseju mẹ́tàlélógún Diego Laxalt so ami ayo ohun di meji sodoEwe, àádọ̀rún iseju ki ifesewonse naa wa si ipari, Cavani gba ami-ayo miiran wole lati so esi ifesewonse ohun di ami-ayo meta sodo(3-0)Ni bayii, Uruguay ti bo si ori oke tente tabili ipele kinni-in(group A), pelu ami mesan-an lori tabili, ti won yoo si lo koju iko ti o ba pari sipo keji ipele keji(group B).
Wọ́n lágbára, wọn a sì ti máa bímọ kí á tó dé ọ̀dọ̀ wọn.
Bakan naa ni ẹnikan lara awọn to n ṣe iwọde farapa lasiko naa.
”Bakan naa ni akowe agba fun ajo SEMA to wa fun mimojuto isle pajawiri ipinle naa ni ajo ohun yoo pese iranlowo to ye fun igbimo ijoba apapo lori igbese titun ile ko yii ki ise naa le ya nipa dida awon agbe pada si oko won lasiko.
Asẹyinwa aṣẹyinbọ ọrọ yi ni ikede ile asofin eleyi ti wọn ti daba ki wọn yọ adajọ agba Nasir Ajana nipo lori ẹsun aṣemaṣe.
Bákan náà ni ọ̀rọ̀ sísọ lásan yìí jẹ ìyanu, èeyí ti mo sì gbọ́ ní ijọ́sí ni mo ni ki n bá yín sọ lónìí, ẹ̀yin ọmọ ènìyàn.
''Awọn akẹkọọ ati olukọ ti wọn ti ni arun Covid-19 naa lo ti wa ni yara iyasọtọ lọwọlọwọ, ti wọn si ti n gba itọju.
Pada sọ́dọ̀ wa nítorí àwọn iranṣẹ rẹ,nítorí àwọn ẹ̀yà Israẹli tíí ṣe ìní rẹ.
Aare tun so ipa pataki ti imo ero igbalode n ko lawujo , tun ni yoo tun dekun iwa ibajẹ.
Nínú ọ̀rọ̀ rẹ̀ lo ti sàlàyé pé, ilé iṣẹ́ ọlọ́pàá kọ̀ láti fi àwọn ọ̀daran méjì tí àwọn mú, ti wọ́n si ka ǹkan ìjà mọ́ lọ́wọ́ lọ́jọ́ Sátidé mọ́lé.
Ní àárọ̀ kutukutu, yóo dìde yóo rú ẹbọ sísun fún olukuluku wọn, yóo wí pé, “Bóyá àwọn ọmọ mi ti ṣẹ̀, wọ́n sì ti bú Ọlọrun ninu ọkàn wọn.
O jẹ ẹni to bẹru Ọlọrun, ati olori to bọwọ fun awọn obinrin ilẹ Gambia.
Yatọ si eyi, ọpọ igba ni wọn maa n fi awọn orin da awọn eeyan laraya, bii orin Fela Anikulapo, Naira Marley, Eedris Abdulkareem, ati bẹẹ bẹẹ lọ.
Ki lo ku ti a le fi se?
 lo ba aare yọ lori  ijamba ti Olorun ko o yọ lojo Abameta.
Omoyele Sowore ti wa ni ile ẹjọ lẹyin ti ijọba orilẹ-ede Naijiria gbe e lọ si ile ẹjọ lori ẹsun pe ile ẹjọ ko lasẹ lati da Sowore silẹ.
Àkọlé àwòrán, Ní ọdún 1994, Abiọla kéde ara rẹ̀ gẹ́gẹ́ bí ẹni tó jáwé olúbori ninu ìdìbò ààrẹ ọdún 1993 ní ìlú Ẹ̀pẹ́tẹ̀dó ní ìpínlẹ̀ Èkó Oríṣun àwòrán, Twitter/Lagos State Goverment Àkọlé àwòrán, Abiọla ni ọmọ kẹtalélogun fún bàbá rẹ̀.
Ọpọ wọn gan ni ko ni anfaani si ẹkọ iwe, to si jẹ pe aisi anfaani lati se rere ti da irẹwẹsi si awọn ọdọ to kawe lọkan, o si yẹ ko ye wa pe o di dandan ki wọn si ideri lori omi to n ho naa."
Kí ni Obasanjo sọ lórí ikú ọmọ aṣíwájú Afenifere, Rueben Fasoranti?
6 3670 Orilẹede Djibouti 61 6.
"Gbadamọsi ni ""awọn ile iṣẹ igbohun safẹfẹ mejilelogun ọtọọtọ ni ijọba kesi, lati ṣe afihan iwe aṣẹ ti wọn fi kọ ile iṣẹ wọn ninu osu Kaarun ọdun 2017."
ọ̀mì lakitiyan Super Eagles pẹ̀lú Brazil jásí ni Singapore Háà!
O ni nigba toun fi bẹrẹ oṣelu, wọn ni oloṣelu ori ayelujara ni awọn ṣugbọn wọn ko mọ pe ẹrọ ayelujara yẹn gan lo wulo tori ohun lo lu jara kari aye.
Kò sí ẹni tí ó tẹ̀lé ìdílé Dafidi, àfi ẹ̀yà Juda nìkan ṣoṣo.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Peters Ijagbemi dá àrá lórí ètò 'Ṣé o láyà' ti BBC Yorùbá lọ̀sẹ̀ yìí Bi ẹ ko ba ni gbagbe, laipẹ yii ni Agboọla fi ọga rẹ tẹlẹ, Rotimi Akeredolu silẹ ti o si ṣi wa si ẹgbẹ oṣelu PDP gẹgẹ bi ara ọna lati dije fun gomina ni ipinlẹ naa.
Ni bayii, iko agbaboolu Argentina yoo lo darapo mo Croatia ti o pari ifigagbaga ohun sipo kinni pelu ami mesan an lori tabili.
Ajínigbépawó jí akọ̀wé NURTW gbé l'Óǹdó
Ní pẹ̀tẹ́lẹ̀ Jọdani tí ó jẹ́ ilẹ̀ amọ̀, láàrin Sukotu ati Sereda ni ọba ti ṣe wọ́n.
Ọna to dara ju lati dabo bo ara ẹni ni lati maa fọ ọwọ ẹni, paapa pẹlu omi ati ọṣẹ.
Ó fi igi akasia ṣe pẹpẹ ẹbọ sísun, bákan náà ni gígùn ati fífẹ̀ pẹpẹ náà rí, wọ́n jẹ́ igbọnwọ marun-un marun-un, gíga rẹ̀ sì jẹ́ igbọnwọ mẹta.
" a gbọ ́ pé odùduwà fún Àjàpadá ní ẹ ̀ wù oògùn kan tí wọn ń pè ní "" Ẹ ̀ wù ogele ' tí Òduduwà fúnra rẹ ̀ fi ń ṣe ọdẹ , nígbà tí Àjàpadá pinnu láti dá ibùgbé tirẹ ̀ ní ."
Ilẹẹjọ́ gíga Akure ti kún fọ́fọ́ fún ìgbẹ́jọ́ olórí ìjọ Sotitobire Oríṣun àwòrán, Others Saaju lati kọ mu iroyin wa fun yin pe, ta ba da ọjọ, ọjọ a pe, ta ba da igba, igba yoo ko, bo si pẹ titi, ogun ọdun n bọ wa ku ọla.
Àwọn ọ̀rẹ́ kan wà, ọ̀rẹ́ àfẹnujẹ́ ni wọ́n,ṣugbọn ọ̀rẹ́ mìíràn wà tí ó fi ara mọ́ni ju ọmọ ìyá ẹni lọ.
Ṣùgbọ́n kò rí ẹ̀gà mú nítorí ẹ̀gà ti mọ ohun tí ọmọ-ènìyàn lè ṣe.
Usman ni igbanu ''UFC Welterweight'' wa lọwọ rẹ bayii.
Àwọn ará Arabia ati àwọn olóyè Kedari ni àwọn oníbàárà rẹ pataki, wọn a máa ra ọ̀dọ́ aguntan, àgbò, ati ewúrẹ́ lọ́wọ́ rẹ.
Ṣíṣe-ṣíṣe bá Arsenal,Wolves dá bàǹtẹ́ ìyà fún wọn
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Eduardo: Mo ń jí mọ́tò pẹ̀lú àwọn ọ̀rẹ́ mi nítorí pé mo fẹ́ di 'Big boy' Ibo gomina Ipinlẹ Imo Oludije ibo gomina fẹgbẹ oṣelu APC nipinlẹ Imo, Hope Uzodimma naa yoo mọ lonii bo ya oun lo wọle ibo gomina ipinlẹ Imo.
Àkọlé àwòrán, Maa nu gbogbo omije atẹyinwa nù loju àwọn eniyan ipinlẹ Ogun ni -Dapo Dapo Abiọdun ni oun bura lati fi ootọ inu ṣiṣẹ si alaafia ati idagbasoke awọn eniyan ipinlẹ Ogun lapapọ ni.
Ṣugbọn ó wí fún wọn pé, “Ẹ má bẹ̀rù, ṣé Jesu ará Nasarẹti tí a kàn mọ́ agbelebu ni ẹ̀ ń wá?
Bákan náà, Ẹ̀mí tún ń ràn wá lọ́wọ́ ninu àìlera wa.
Mo si maa nkopa ninu 'Tiata Ọmọde' lori ikanni Channel 7 mohumaworan apapọ ilẹ Naijiria, NTA .
Akeredolu ò ṣe ǹkan àrítọ́kasi ni Ondo- Komísọnà ọ̀rọ̀ to n lọ tẹ́lẹ̀rí Gómìnà ìpínlẹ̀ Ondo, Akeredolu sọ Amotẹkun di òfin!
Mú wa pada sọ́dọ̀ ara rẹ, OLUWA,kí á lè pada sí ipò wa.
Oríṣun àwòrán, Reuters Thailand Ọpọ ọdọ lorilẹede Thailand lo n wọde nibi ti wọn ti n ke si olotu ijọba orilẹede naa, Pratyuth Cha-ocha o kọwe fi ipo silẹ Awọn ọdọ naa n beere fun atunṣe iwe ofin orilẹede naa, ki wọn si ṣeto idibo tuntun, ki wọn si tun fi opin si idunmọhuru sawọn ajafẹtọ araalu nibẹ.
Ṣugbọn igbesẹ yii nikan kọ lo le fopin si àṣìlò oogun oloro ni Naijiria.
Ó kéré tán, ènìyàn mẹ́rìnlá tí kú nínú àjálù ọkọ̀ òfurufú tó já Èkìtì ṣé àgbéga àwọn Ọba Aládé mẹ́rìndínlógún Òṣèrébìnrin tí wọ́n bá fi ìbálòpọ̀ lọ̀ 'torí ìṣẹ́, kó bọ́ síta láti sọ̀rọ̀ - Kunle Afod Ìjọba Kano fi páńpẹ́ òfin mú Ọba àwọn Oṣó lórí ẹ̀sùn jìbìtì Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Akure Kidnap: E túbọ̀ ní sùúrù, a máa wá ọmọ náà rí- Alukoro ọlọ́pàá Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 3 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 5 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Oríṣun àwòrán, Getty Images Lọwọlọwọ, ajọ eto ilera l'agbaye, WHO, sọ pe ki ipese eroja iron ati folic acid wa fun awọn ọmọbinrin to ti balaga, paapa ni awọn orilẹ-ede ti aito ẹjẹ ti wọpọ to ìdá ogoji.
Orile-ede Naijiria ati orile-ede Tunisia ti fowo siwe adehun igbora-eni-ye mefa Memoranda of Understanding, MOUs, ni iyanju ati mu igberu ba ajosepo lori eto oselu, eto-abo ati idaabobo, ibara-eni gbe ati eto oro-aje, bakan naa ajosepo to muna doko laarin awon ile-ise asoju orile-ede mejeeji naa.
Àwọn mìíràn dàbí irúgbìn tí a fún sórí ilẹ̀ ẹlẹ́gùn-ún, wọ́n gbọ́ ọ̀rọ̀ náà, 
Lootọ awọn onimọ nipa ajakalẹ arun ti jẹ ko di mimọ pe ṣiṣe gaaya funra ẹni ati fifọ ọwọ wa ko mọ tonitoni nikan lo lee gba wa lọwọ arun yii, Sibẹ awọn wolii Ọlọrun kan ṣi n sọ pe awọn ni igbagbọ pe aawẹ ati adura n ṣe bẹbẹ.
''Ọpọ awọn ọmọ yi lo ti di janduku fawọn oloselu nitori wọn ko kọ kewu tawọn obi wọn ran wọn lati lọ kẹ'' Sugbọn kii se gbogbo eeyan lo lero bi tirẹ.
Nígbà tí Reu di ẹni ọdún mejilelọgbọn ni ó bí Serugi.
Àwọn ìròyìn mìíràn tí ẹ lè nífẹ̀ẹ́ sí: 'Oṣu mẹ́rin la fi jà kí wọ́n tó ó tú Zainab sílẹ̀ l'ẹ́wọ̀n' Bí Zainab ṣe dèrò ẹ̀wọ̀n Saudi lórí ẹ̀sùn ògùn olóró tí kò mọ̀ Ìjọ̀ba Saudi ti tú Zainab tí wọ́n fẹ̀sùn òògùn olóró kàn sílẹ̀ Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí kan sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Makinde: Ẹgbẹ́ òṣìṣẹ́ faramọ́ wíwọ́gilé ₦3000 táwọn akẹ́kọ̀ọ́ girama ń san Wọn ni kawọn ọmọ ile pade lọjọ keje, oṣu kẹfa ọdun fun ijoko ilé tuntun.
Ṣugbọn Jeremaya sọ fún àwọn ọmọ Rekabu pé, “OLUWA àwọn ọmọ ogun, Ọlọrun Israẹli ní, ‘Nítorí pé ẹ gbọ́ràn sí Jonadabu baba ńlá yín lẹ́nu, ẹ sì pa gbogbo òfin rẹ̀ mọ́, ẹ sì ń ṣe gẹ́gẹ́ bí ó ti pàṣẹ pé kí ẹ máa ṣe, 
Ìgbà tí ìlọsíwájú dé ni wọ́n bẹ̀rẹ̀ sí máa wá ọ̀nà fi ẹ̀rọ yìí ṣe onírúirú iṣẹ́ míràn bíi ìwé kíkọ, kíkà àti bẹ́ẹ̀bẹ́ẹ̀lọ.
 Ìtàn lè pa wọ ́ n pọ ̀ nipa àjọjẹ ́ orúkọ , àjọṣe kankan lè má sí láàárin wọn nígbà kan ti rí ju wí pé orúkọ yìí , tó wu Ògbóni kìíní Ọba Ìjẹ ̀ bú-jẹ ̀ ṣà nígbà tí ó bá àbúrò rẹ ̀ ajíbógun lọ bòkun , wọ ́ n gba ọ ̀ nà Ìjẹ ̀ bú-Òde lọ .
Àwọn ẹran náà ń gun ara wọn níwájú àwọn ọ̀pá wọnyi, wọ́n bá bẹ̀rẹ̀ sí bí ọmọ tí àwọ̀ wọn dàbí adíkálà ati àwọn tí wọ́n ní funfun tóótòòtóó.
Nigba ti eleyi n fun awọn oludibo ni igboya pe o ni iriri lati di aarẹ sibẹ, o nira lati sọ bi itan rẹ lori eyi yoo ṣe baa mu pẹlu awọn oludibo.
'Cartoon' nípa Anọbi Muhammed kó Ọ̀jọ̀gbọ́n kan sí ìyọnu ní Egypt Wo ìgbà márùn ún tí Buhari ti rìnrin àjò lọ sókè òkun fún ìtọ́jú ara rẹ̀ Bí àwọn kan tí ń ní àtimọ̀lé tí wọ́n sọ olorin Nazir sí ní Kano ni ọwọ́ kan òṣèlù ní àwọn mii ní.
Ìgbà tí òògùn ẹ̀jẹ̀ ríru lè ṣiṣẹ́ jù rèé- Onímọ̀ Ẹlẹ́wọ̀n tẹ́lẹ̀ gboyè ìmọ̀ ìjìnlẹ̀ méjì lọ́gbà ẹ̀wọ̀n Kíni ìdí ti àwọn ọmọ ogun fi n ṣọ́ àwọn Imaam ni Mecca?
Àwọn tí ń fi ibi san oore fún mi ní ń gbógun tì mí,nítorí pé rere ni mò ń ṣe.
Arakunrin baba tabi ìyá rẹ̀, tabi ọ̀kan ninu àwọn ìbátan rẹ̀ tabi ẹnìkan ninu àwọn ẹbí rẹ̀ le rà á pada.
Ìyá mi, ọ̀rẹ́rẹ́ oo, ooooo, ooooo
Oríṣun àwòrán, @Ostrov_A Joe Biden kéde Kamala Harris, obìnrin aláwọ̀ dúdú gẹ́gẹ́ bí igbákejì rẹ̀ nínú ìdíje sípò Ààrẹ Amẹrika US elections: Joe Biden kéde Kamala Harris, obìnrin aláwọ̀ dúdú gẹ́gẹ́ bí igbákejì rẹ̀ nínú ìdíje sípò Ààrẹ Amẹrika Oludije sipo Aarẹ ilẹ Amẹrika ninu ẹgbẹ oṣelu Democrat, Joe Biden ti yan obinrin alawọ dudu, Kamala Haris gẹgẹ igbakeji rẹ ti wọn yoo jọ dije.
ly/2Zim6Ua, ni wa a tẹle nibẹ lati seto iforukọsilẹ rẹ.
  Iroyin so pe, o kere tan ,awon
Èmi Ọba tí wọ́n ń kó jẹ nígboro- Oluwo ti ilú Iwo Nǹkan mẹ́sàn án tí Mùsùlùmí gbọdọ̀ ṣe nínú oṣù Dhual- Hijjah Ẹlẹ́rìí mẹ́rìn ló tẹ̀lé Alfa Babatunde wá síwájú ilé ẹjọ́ Nínú ìgbẹ́jọ́ tó ń lọ lọ́wọ́ lóri ọmọ tó sọnu nínú ilé ìjọsin Sotitobirẹ nílùú Akure, Alfa Babatude ló léwáju láti sọ tẹnurẹ lórí ǹkan tí ó ṣẹlẹ̀ lọ́jọ́ náà.
ti o sese gbele le ohun, dokita Maikanti Baru, ti  won si fi oro won mule wipe, ile-ise NNPC
Oṣu kẹwaa lẹyin ti wọn ṣe mọ mi n mọ o ni Chadwick jade laye .
Kí ilẹ̀ pápá tí yóo yí àwọn ìlú tí ẹ óo fún àwọn ọmọ Lefi ká jẹ́ ẹgbẹrun igbọnwọ láti ibi odi ìlú wọn siwaju.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Arsenal yoo dojukọ Atletico Madrid, nigba ti Red Bull Salzburg pade Marseille Marseile fi ajulọ han RB Leipzig ti RB Salzburg pẹlu yọ ọwọ kilanko Lazio lawo idije ife ẹyẹ UEFA naa.
Àwọn wọnyi ni àwọn ẹ̀dá alààyè tí mo rí lábẹ́ Ọlọrun Israẹli ní etí odò Kebari.
Bí ẹnikẹ́ni bá ṣe irú rẹ̀, láti máa lò ó gẹ́gẹ́ bíi turari, a óo yọ olúwarẹ̀ kúrò lára àwọn eniyan rẹ̀.
Ni ọjọ́ keji àwọn ará ilú ri iyẹ́ Igún wọn pariwo pé Moṣétán jẹ èèwọ̀, ó ni bẹni, ohun jẹ Igún.
27 Bélú 2020 Adeyeye Ile Ife: Kílódé tí Ọọni Ife, Oba Ogunwusi kò fi gbọdọ̀ rí ọmọ rẹ̀ tuntun títí di ẹ̀yìn oṣù mẹ́fà?
Oluṣẹyẹ Bamijoko, to jẹ agbẹjọrò olùjẹ́jọ́, bẹbẹ pe ki wón ti olùjẹ́jọ́ òun si ọgba ẹwọn ikoyi dipo ti kirikiri pèlú igbagbọ pe àwón onisegun oyinbo yóò le yẹ Udeme wo bi o ti yẹ.
Ko wa ni ju bayi lọ fun toni, ẹ se, ẹ ku atilẹyin wa.
Òun ni ó lókìkí jùlọ ninu àwọn ọgbọ̀n ọ̀gágun náà, ó sì di olórí wọn; ṣugbọn kò ní òkìkí tó àwọn akọni mẹta.
Onireke-Agbarigo Road yoo maa jẹ Onikepo Akande Road.
Ṣugbọn Mikaya dáhùn pé, “Mo fi orúkọ OLUWA búra pé ohun tí Ọlọrun bá sọ fún mi pé kí n sọ ni n óo sọ.
Ọlọrun Yóo Jẹ Siria ati Israẹli Níyà.
A ko fẹ fi awọn ọmọ wa sinu ewu'' O fi kun pe ''ko si ile ẹkọ kankan to le da isẹ se laifi ti oun sẹlẹ lawujọ se'' Aworan atọnisọna Iye awọn to ti ni arun naa lagbaye Sunmọ aworan Àgbáyé Orilẹede Afrika Ariwa Amẹrika Apa Latin Amẹrika ati Caribbean Ilẹ Asia Ilẹ Yuroopu Agbegbe Middle East Erekusu Oceania Fihan 69609761 iye iṣẹlẹ arun naa 1583112 Iye awọn to ku Group 4 Jọwọ ṣe atunṣe ilana ikansi ayelujara rẹ lati ri ẹkunrẹrẹ rẹ Aworan n ṣafihan awọn ti ayẹwo ti fi han lorilẹede kọọkan Orisun: Johns Hopkins University atawọn ajọ eto ilera ilu Igba ti wọn kede iṣiro awọn to nii kẹyin 11 Oṣù Ọ̀pẹ̀ 2020 13:00 WAT+3 Ẹkunrẹrẹ data Sun atẹ wa silẹ tabi oke lati ri ẹkunrẹrẹ akọsilẹ *Iye awọn to tọwọ aisan ku ni isọri eeyan ẹgbẹrun lọna ọgọrun Gbe e yẹwo: Àgbáyé Orilẹede Afrika Ariwa Amẹrika Apa Latin Amẹrika ati Caribbean Ilẹ Asia Ilẹ Yuroopu Agbegbe Middle East Erekusu Oceania Iye to ti ku Iye awọn to ku %* Apapọ awọn iṣẹlẹ arun Akọtun arun yii 0 10 100 1000 10000 ** Orilẹede Amẹrika 280985 85.
Mo lòdì sí ọ, ìwọ òkè ìparun,tí ò ń pa gbogbo ayé run.
" Awọn iroyin ti ẹ lee nifẹẹ si: Asiri ibudo igbafẹ ẹranko ni Naijiria Ọmọbinrin kan ku si sọọsi lasiko ijẹri Iroyin lati ori ẹrọ ayelujara ni ọmọkunrin naa, to jẹ ẹni ọdun marundinlọgbọn ti fun aburo rẹ naa l'oyun.
Saaju ki awọn olorin bi Olamide ati Whizkid to di ilumọka, ni Dagrin ti n dagboro ru pẹlu Rap rẹ, to n fi ede abinibi Yoruba kọ.
Ekeji ni Kileabu, ọmọ Abigaili, opó Nabali, ará Kamẹli.
Ohun ti a gbọ ni pe wọn fẹ ṣapero lori ohun ti wọn pe ni iwa tani yoo mu mi ti ijọba gunle lori bi wọn ṣe ti Omoyele Ṣowore to ṣagbatẹru iwọde Revolution Now atawọn ajijagbara mii mọ le.
O fikun ọrọ rẹ pe ẹka ijọba to n ri si ọrọ ilẹ naa lo kọwọ bọ iwe to sọ ilẹ naa di dukia Oloye nigba naa.
a lè dènà àkóràn àrùn bí ó ti yẹ nípasẹ ̀ ìmọ ́ tótó ara ẹni àti àbójútó ìlera .
Bí ẹgbẹ́ One Million Boys ṣe bẹ̀rẹ̀ rèé àti ọṣẹ́ tó ṣe n'Ibadan Wo ohun tó yẹ kí o mọ̀ nípa Laycon, akẹ́kọ̀ọ́jáde UNILAG tó ń kópa nínú BBNaija 2020 Ohun tí o kò mọ̀ nípa Ebila One Million Boys"" àti Ekugbemi, olórí ẹgbẹ́ òkùnkùn méjì tó da ìlú Ibadan rú Ọkùnrin kan pa ara rẹ̀ sínú ọgbà àjọ TRACE tó n mójútọ ìrìnnà ọkọ̀ nípìnlẹ̀ Ogun Ethiopia n fẹ ki wọn so odo naa pọ mọ adagun odo Aswam, Egypt ni lae lae."
Abiola naa dije dupo aarẹ Naijiria ninu idibo ọjọ kejila, oṣu kẹfa, ọdun 1993 ni eyi ti ọpọ gba pe o wọle.
Ìlú tí wúrà pọ̀ níbẹ̀ ati òkúta iyebíye ati ìlẹ̀kẹ̀!
Ẹni tí ó bá fi ìṣẹ́jú kan ṣáájú tàbí ìṣẹ́jú kan pẹ́ kí ó tó bu òkèlè, ẹ̀wọ̀n ni.
    Bàbá yìí ṣe ìtọ́jú ọmọ rẹ̀ púpọ̀, bàbá àti ìyá a maa pa àṣíírí ọmọ wọn mọ́, ìgbà tí bàbá sì ti béèrè ibi ti ọmọ náà wà tí onítọ̀hún sì ti wí pé òun kò le sọ àti pé àlàáffíà ni òun wà ni bàbá náà kò ti ṣe aápọn àti wádìí eléyìí mọ́, nítorí rírí tí ó tilẹ̀ rí ọmọ rẹ ti ta ohun gbogbo yọ.
Nítorí èyí, irú àwọn eniyan bẹ́ẹ̀ kò ní àwáwí.
Ètò ìyàwó náà jẹ́ ìyanu, kò sí pé ẹnìkan ń pẹ́ lẹ́yìn, kò sí pé ẹnìkan ń pariwo, kò sí pé ẹ̀rún oúnjẹ kan ṣoṣo ń ba ilẹ̀ jẹ́.
China, o ron mi lowo lati gbe igbese yii.
Ṣekanaya ní ọmọ kan, tí ń jẹ́ Ṣemaaya.
Aṣoju ijọba Habitegeko Francois tun wi pe, saaju isẹlẹ yii, ni ara kan ti kọkọ san pa akẹkọ kan ni agbegbe naa ni ọjọ ẹti.
Bakan naa lo ni idi ti o fi jẹ pe owo oṣu mẹrin ninu mẹtalelọgbọn ti ijọba jẹ ni ẹgbẹ oṣiṣẹ ati ijọba f'ẹnuko si fun sisan ko ju pe 'lẹyin ọpọ ijiroro, a wo aṣuwọn ijọba, a ko si lee maa beere ohun ti wọn ko ni la fi ni ki a gba si oṣu mẹrin ọhun.
Má jẹ ọ̀kùn, má jẹ ekòló, oun tí wọ́n bá ń jẹ ní àjùlé ọ̀run ni kí o máa bá wọn jẹ.
Ìdí nìyí tí ó fi rán ọwọ́ kan jáde láti kọ àkọsílẹ̀ yìí.
Oríṣun àwòrán, Instagram/Abiola Ajimobi Ipo oselu ti Ajimobi dimu: Baba Abiola, Ganiyu jẹ oloselu to gbajugbaja, to si dibo wọle sile asofin ẹkun ìwọ oorun Naijiria ijọhun laye saa isejọba alagbada kinni, Ti aburo baba rẹ naa si jẹ Minisita fun isẹ ode ati igbokegbodo ọkọ nigba naa.
Nigba to di oṣù kẹrin ọdun 1978, ni Minisita feto ẹkọ nigba naa, Ahmadu Ali, to ṣiṣẹ laye ijọba ologun Olusegun Obasanjo, kede afikun owo oúnjẹ ti akẹkọọ kọọkan yoo maa san.
Iṣiro yii wa fun ẹyọ ipapanu Pizza kan ṣoṣo.
[A fẹ́ jẹ ẹ́ níyà gẹ́gẹ́ bí òfin wa.
Wọn ni awọn ọmọ ogun meji kan naa farapa ninu ikọlu ohun púpọ̀.
Bẹ́ẹ̀ni, Olúwa ló fi fún mi kìí ṣe ènìyàn.
Àkọlé àwòrán, Odo Abonnema ni Bakana to di oju oori Blankson O ni awọn lọ sibi ayẹyẹ ọjọ ibi ni ọsẹ ti Joe ku.
 kín lo ti ṣe ọ ̀ ràn ọkọ fífẹ ́ yìí sí ?
Ìfiránṣẹ́ olórin náà, tí ó ṣe àtìlẹ́yìn, ipòo ti ìdásílẹ̀ Ìpínlẹ̀ Erékùṣù Kéékèèké Tí-ó-ń-gòkè, jẹ́ ohun àfiyèsí, tí ó ń ní ipa nínúu ìwé-ìpamọ́ ìkẹyìn-in ti COP21.
Baba ọlọmọ, ati iyawo pupọ ni.
” Samuẹli bá sọ fún àwọn ọmọ Israẹli pé kí olukuluku pada lọ sí ìlú rẹ̀.
Ibadan Murder: Shagbada pa ọ̀rẹ́bìnrin torí kò gbà kó bá a lò pọ̀
ti oju omi ti so pe ise ti pari lori oko -ogun oju omi ti won n pe ni NNS
Lateef kii ge iru irun yii loju aye Ara awọn nkan mirian tun ni ọrọ ti awọn akẹẹgbẹ wọn bi Bimbo Oshin, ati Debo, a.
Nítorí pé mo wà pẹlu rẹ láti gbà ọ́ kalẹ̀.
0 awon ohun ti won pese labele.
Bí ó tilẹ̀ ṣubú, kò ní lulẹ̀ lógèdèǹgbé,nítorí OLUWA yóo gbé e ró.
 wọ ́ n rúbọ gẹ ́ gẹ ́ bí ifá ti wí ; ni wọ ́ n bá dọlọ ́ mọ wẹẹrẹ lọ ́ ọ ̀ dẹ ̀ .
Niger Flood: Omíyalé àgbàrà ti ya ṣọ́ọ̀bù ní Niger
Òṣèrébìnrin tí wọ́n bá fi ìbálòpọ̀ lọ̀ 'torí ìṣẹ́, kó bọ́ síta láti sọ̀rọ̀ - Kunle Afod Aisha Buhari, ohun mẹ́fà tò fi yàtọ̀ sí àwọn aya ààrẹ tó ti jẹ kọjá!
Ẹ kò gbọdọ̀ jẹ ajá mọ́' Kí ló yẹ ká se sí ẹkùn tó pa ènìyàn márùń?
Àwọn ni kí o jẹ́ kí ó gba gbogbo àkókò rẹ, kí ìtẹ̀síwájú rẹ lè hàn sí gbogbo eniyan.
Mo ṣe bi ọ̀kan nínú àwọn olóye lórí ayé àtijọ́ tí wí fún  wa nínú ìwé ní ijọ́sí wí pé, ọmọ tí ó bá hùwà àìbìkítà sí òbí rẹ̀, ẹyẹ àkàlàmàgbò ni yóó yọ ojú ọmọ náà jẹ!
Iye àwọn nǹkan náà nìyí:Ẹgbẹrun kan (1,000) àwo wúrà,ẹgbẹrun kan (1,000) àwo fadaka,àwo turari mọkandinlọgbọn;
"Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Láàrin wákàtí mẹ́ta, wọ́n dá ₦4m fún àkàndá ẹ̀dá tó kópa nínú ìwọ́de 2015 ni mo ti ń kígbe pé gudugbẹ̀ máa já ní Nàíjíríà - Oyedepo Lizzy anjorin ń kiri àgọ́ ọlọ́pàá láti gba àwọn ọ̀dọ́ afẹ̀hónúhàn, tó wà láhàámọ́ sílẹ̀ Àwọn ọ̀dọ́ se ìrẹsì jọ̀lọ̀ọ́fù ní márosẹ̀ Benin sí Ore láti fẹ̀hónú hàn Afárá Marina àti Eko yóò di ṣíṣí padà lọ́la Wo àwọn Ṣọ́ọ̀ṣì Nàìjíríà àti l'Áfíríkà tó ń wólẹ̀ àdúrà kí Trump lè wọlé ìbò ààrẹ America Iléeṣẹ́ ológun bẹ̀rẹ̀ 'Operation Crocodile Smile' yíká Naijiria fún oṣù méjì Akọle awo orin naa ni ""Arewa na kuka"", eleyii to tun mọ si pe ''Ariwa Naijiria n sun ẹkun''."
Gege bi abajade iyikoto ohun, iko D’Tigress yoo maa waako pelu Australia ninu ifigagbaga kinni lojo kinni ti idije naa ba bere, ki iko ohun o to lo koju Turkey lojo keii, ti won yoo si gba ifigagbaga keta pelu Argentina lojo keta.
Èmi fúnra mi ni n óo jẹ́ olùṣọ́ àwọn aguntan mi, n óo sì mú wọn dùbúlẹ̀.
Ọpọ awọn alaboyun lo ti gbẹmi mi ni ilu naa ti wọn ba fẹ bimọ, nitori ko si opopona lati gbe wọn lọ si ile iwosan.
Ṣugbọn o, ọrọ naa ni Pasitọ Joshua tun fi gba ara rẹ silẹ.
    Lóòótọ́ bí ilẹ̀ ti ń mọ́ hàì ní ọjọ́ kejì ni àgbẹ̀ ti dé pẹ̀lú àwọn ọmọ rẹ̀, o sì ya àgbàdo rẹ̀ gbogbo.
A gbọ pe Alakoso agbo orin Ayinla Ọmọwura, Bayewu ni oun ati Ayinla jọ ni ikunsinu, ti Bayewu si fi ọdọ Ayinla silẹ lai gbe ọkada to fun un lati fi sisẹ silẹ nigba to n lọ.
Bẹ́ẹ̀ ni n óo ṣe tẹ́ ibinu mi lọ́rùn lára rẹ, n kò sì ní jowú nítorí rẹ mọ́.
Dafidi ati àwọn eniyan rẹ̀ bá ń bá tiwọn lọ, Ṣimei sì ń tẹ̀lé wọn lẹ́gbẹ̀ẹ́ keji òkè náà, bí ó ti ń tẹ̀lé wọn, bẹ́ẹ̀ ni ó ń ṣépè, ó ń sọ òkúta lù ú, ó sì ń da erùpẹ̀ sí wọn lára.
Yatọ si ikini ti aarẹ, awọn ọmọ Naijiria naa n gbe oṣuba kare fun ikọ Super Eagles.
Ìlú Ọsọsa lágbègbè Rẹmọ nipinlẹ Ogun ni àwọn Ogunde ti wá.
Ninú idúpẹ́ àti àjọyọ̀ yi ni ẹni ti inu rẹ bàjẹ́ miran ti lè ni ireti pé ire ti ohun naa yio dé.
Ní ojúmọ to mọ lónìí yìí, ènìyàn to lé ni ẹgbẹ̀run lọ́na mẹ́tàdinlógun lo ti ni ààrun náà, èníyan to le ni ẹgbẹ̀fà lo si ti ba iṣẹ̀lẹ̀ náà lọ nígbà ti ènìyàn ẹgbẹ̀run kan o lé márundinláàdọta rú ààrun náà là, ti wọn si pada si ilé wọ́n.
 A n fun wọn ni awọn nnkan wọnyii lati fi ṣe iranlọwọ fun wọn ni, ki I ṣe pe nitori pe wọn jẹ otosi.
Mo kí yín kú ìpalẹ̀mọ́ ọdún o.
Alaga ajo INEC kede yii nile
Ẹ gbìyànjú láti fi ọkàn yín balẹ̀.
wọ́n ń sọ̀kò ọ̀rọ̀ sí aláìṣẹ̀ láti ibùba wọn,láìbẹ̀rù, wọ́n ń ta ọfà ọ̀rọ̀ sí i lójijì.
Oríṣun àwòrán, Others Ọjọgbọn Oloyede ni ẹsin Islam fagbaye gba yiyago fun araẹni ti o ba ma a mu inira dani.
Àbí kí ni a óo fún un?
Sugbọn lasiko yii, ọdun Ojude Ọba ti tayọ ẹsin kan soso, ti awọn oniruuru ẹlẹsin si ti n tẹwọgba ọdun naa nilẹ yii ati lẹyin odi.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Cancer: Àṣe ara mi ni iso ti n run gbogbo bí mo ṣe n ṣèrànwọ́ lórí jẹjẹrẹ Baba Chisom, ti oun fun'ra rẹ jẹ onimọ iṣegun oyinbo ninu iṣẹ abẹ eyin ṣiṣe, to si tun jẹ olukọ ni Fasiti Naijiria, Nsukka, sọ pe asiko kan to sabi pe o ti n gbadun.
Wole Soyinka rèé láti kékeré Soyinka: Ọ̀pọ̀ ìgbà ni ayédèrú ìròyìn ti pa mí N kò le è dìbò yan Buhari tàbí Atiku ní olórí mi láéláé - Soyinka ‘Àwọn asèbàjẹ́ gbọ́dọ̀ fi ẹ̀wọ̀n ju 'ra’ Ìpànìyàn, ìjínigbé ti gbàkóso ilẹ̀ Yorùbá, Buhari, tètè kéde pé ètò ààbò kò fararọ - Soyinka Wole Soyinka ti a bi lọjọ kẹtala oṣu keje ọdun 1934 kii ṣe ọmọde mọ lonii ṣugbọn gbigba ami ẹyẹ gẹgẹ bi ọjọgbọn ko tii wọn lápó rẹ̀.
Americans in Africa: Wo ìdí tí àwọn ọmọ ilẹ̀ Amẹ́ríkà kan ṣe ń kó bọ̀ wá fi ilẹ̀ Áfríkà sebùgbé
Aarẹ Ile Igbimọ Asofin Agba, Bukola Saraki ti ni ìwà arekereke ati jibiti ni ile oun ti wọn ti pa ni Ikoyi ni ilu Eko.
Jesu wí fún un pé, “Ọ̀ràn bí èmi bá lè ṣe é kọ́ yìí, ohun gbogbo ni ó ṣeéṣe fún ẹni tí ó bá gbàgbọ́.
Wọ̀bìà ni wọ́n, alájẹkì,wọn kì í yó.
O ni oro apara lasan ni pe oun tabi Barrister ni awon jo da fuji sile.
Joshua àti Ruiz gbà láti jàjà mííràn lóṣù kọkànlá Liverpool da ata gúngún sójú Tottenham gba ife ẹ̀yẹ Champions League 'Ọmọ SS 1 mu èso olómi, ṣùgbọ́n ilé ìwé wa kọ́ ló kú sí' Owó wọgbó!
Industrial Development Income Tax Act Amendment Bill, Defence Research and  Development Bureau Bill, Animal Diseases
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, International Day Against Drug Abuse and Trafficking: ìdí ti mo fi ń mu oògùn olóró Ọgagun Bower to jẹ Kọmiṣọnna Ọlọpaa ilu Ibadan nigba naa lọhun lo pari aawọ ogun yii lọdun 1886.
Ó ń mú kí koríko dàgbà fún àwọn ẹran láti jẹ,ati ohun ọ̀gbìn fún ìlò eniyan,kí ó lè máa mú oúnjẹ jáde láti inú ilẹ̀;
lẹ ̀ yín tí àwọn akẹ ́ kọ ́ tí ilé ìwé alákọ ́ bẹ ̀ rẹ ̀ tí owu gbòòrò sí 150 , wọ ́ n sọ ́ fún Àlùfáà samuel george pinnock kí ó dá ilé ìwé tí ó ga ju alákọ ́ bẹ ̀ rẹ ̀ sílẹ ̀ .
 Ni bayii, Emi ni akoonimogba agba egbe Springdale Area Recreational, eyi ti o fun mi lanfani lati bere fun iranwo awon ohun Elo  lowo egbe naa lati pin fun awon odo to  n kopa ninu ere-idaraya yii.
Nibayii, eeyan 942 lo ti ba ajakalẹ arun naa lọ ni Naijiria.
Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Lekki Toll gate: Àwọn ọlọtẹ̀ ló ń gbìyànjú láti dá ọ̀tá sílẹ̀ láàrin èmi àti ẹ̀yin ènìyàn mi - Jagaban Asiwaju Tinubu sọrọ lẹyin ti awọn gomina atawọn eekan nilẹ Yoruba ṣe abẹwo ibanikẹdun si gomina ipinlẹ Eko.
Bakan naa leyin ipade ohun, aare Buhari yoo tun lo darapo mo awon adari miiran lagbaye lati lo sayeye iranti abadofin ti won bowolu lojo kokanla osu kokanla odun 1918 lati fopin si ogun agbaye kinni(First World War).
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Anthony Joshua ti na Joseph Parker nibi ìdijé ẹ̀ṣẹ 1 Ìgbé 2018 Oríṣun àwòrán, Reuters Àkọlé àwòrán, Eleyi ni akoko akọkọ ti Joshua pẹ to bayi ko to naa eeyan nibi ẹṣẹ Anthony Oluwafẹ́m Joshua ti sọ igbanu ẹyẹ ẹṣẹ WBA, IBF ati WBO di ọkan nigba to na Joseph Parker ni papa iṣere Principality nigboro Cardiff.
Atẹjade kan lori opo ayelujara twita fun ọkan ninu oluranlọwọ fun aarẹ, Bashir Ahmad sọ pe awọn gomina mẹfa se ipade ikọkọ pẹlu aarẹ ni ọjọbọ.
Ajo to n ri si ere-idaraya boolu afesegba lorile-ede Naijiria, NFF so pe, ipade awon toro kan gbangban ninu Ajo to n ri si boolu afesegba lagbaye, FIFA yoo waye nilu Eko, lorile-ede Naijriia, eyi ti yoo je ipade kejila irufe ipade ohun bayii, 12 FIFA Executive Football Summit (EFS).
O ní lẹ́yin ti wọ́n wá rojọ́ fun kábíyèsí tán, ní àwọn òbi ọmọ náà àti àwọn olùkọ ilé ìjọsìn ọmọdé mẹ́rìnlá wa búra ni ààfìn kábíyèsí Deji Akure tún pé Alfa Babatunde àti òbi ọmọ náà, ṣùgbọ́n Alfa Babatunde nìkan ló padà yọju Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Working religious women: Ẹ̀lẹ́hàá kìí ṣe ọ̀lẹ- Aminat Adegoke Ẹlẹ́rìí kaarún tó sọ̀rọ̀ nilé ẹjọ́ lónìí Ajíyìnrere Funmilayo Ogunlusi ṣàlàyé pé lẹ́yìn ti wọ́n jí ọmọ náà ní Alfa Babatunde pe fún àdúrà àti ààwẹ ọlọ́jọ́ mẹ́sàn-an pé kí Ọlọ́run ṣàwári ọmọ náà.
Ọkan lara awọn ọlọpa ti o ba wa sọrọ ti ko fẹ ki a darukọ oun salaye wi pe ọga ọlọpa ipinlẹ eko ti pasẹ fun awọn lati wa si agbegbe naa fun igbofinro ati lati pese aabo to peye fun awọn olugbe pẹlu onisowo.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Fiditi: Àwọn olùgbé rawọ ẹbẹ sí ìjoba lẹ́yìn tí ìjì ṣí òrùlé mọ́ wọn lórí 1 Ìgbé 2019 Awọn olugbe ilu Fiditi nipinlẹ Ọyọ ti rawọ ẹbẹ si ijọba lori akoba ti atẹgun ojo ṣe fun ọpọlọpọ ile ninu ilu naa lọjọ Abamẹta.
Iroyin naa fidirẹmulẹ pe Biṣọọbu Innocent Nzeyimana, aarẹ fẹgbẹ awọn ṣọọṣi to wa l'ẹkun Nyarugenge gbẹnu awọn ṣọọṣi naa sọrọ lati rawọ ẹbẹ pe ki wọn o fun awọn ni anfaani lati maa jọsin titi ti wọn o fi yanju awọn ohun to yẹ lati ṣe.
Ilé tí mo fẹ́ kọ́ yóo tóbi pupọ, nítorí pé Ọlọrun wa tóbi ju gbogbo oriṣa lọ.
Ilé aṣòfin Amẹ́ríkà yarí Mo ti gba ọmọ Igbo tó ń wá bàbá rẹ̀ bí ọmọ, kó má ba à pa ara rẹ̀ - Iba Oluyole Lẹ́yìn ọgọ́rùn ún ọjọ́ tí wọn ti Lekki Toll Gate pa, ẹ wo owó gọbọi tíjọba Eko ń pàdánù Ẹ́ ràgà bo ìṣọ̀kan Nàíjíríà, ìyàpà le mú ìṣẹ́ àwọn akọni wa já sásán - Osinbajo Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 3 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 5 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Ewe, Iran padanu ifesewonse olorejore ti o waye laarin iko ohun ati Turkey pelu ami-ayo meji sookan(2:1), bakan naa si ni, won yoo tun gba ifesewonse olorejore miiran pelu Lithuania lojo kejo osu kefa odun ti a wayii.
Agbẹnusọ fun ijọ Aguda nilu Makurdi, Fada Moses Iorapuu sọọ di mimọ pe awọn bisọbu ni wọn mu ọjọ isinku naa nibi ipade wọn nilu Rome.
Tirẹ̀ ni ilẹ̀ Hamati tí ó bá Israẹli pààlà.
Ninu ọrọ rẹ, o ni ẹgbẹ oselu PDP yẹ ki wọn bẹrẹ si ni sọ ohun ti wọn ni fun awọn eniyan, ati lati mọ le akasọ lori awọn ipinlẹ ti oun ti fi silẹ gẹgẹ bi isẹ ti oun ti se.
'A yin ibọn naa lati da duro pẹlu ada ọwọ rẹ, amọ o ṣeni laanu pe o gba ibẹ ku.
Ni iwaju ẹgbẹrun lọna ọgọrin awọn oluworan ni Kingston ti run Bryan mọlẹ to si fẹnu rẹ gbo lẹ, lẹyin naa ni oludari ija ọhun ka meni, meji, mẹta ti o si gbọwọ rẹ soke.
 Eleyii ti Igbimọ Tẹẹkoto fun ọrọ Ilera ninu Ile Ìgbìmọ Aṣofin yii, labẹ alaga wọn, Asọfin Ṣẹgun Olulade ṣe agbatẹru rẹ.
Nígbà tí ó dé ẹ̀bá ibẹ̀, ó kígbe pẹlu ohùn arò, ó ní, “Daniẹli, iranṣẹ Ọlọrun Alààyè, ǹjẹ́ Ọlọrun tí ò ń sìn láìsinmi gbà ọ́ lọ́wọ́ àwọn kinniun?
Ẹnikẹ́ni tí ó bá ń ṣe òdodo ni olódodo, bí Jesu ti jẹ́ olódodo.
Lara awon ti yoo tele aare lo irin ajo ohun ni: Gomina ipinle katsina, Aminu Masari, gomina ipinle Anambra, Willie Obiano ati gomina ipinle Ekiti, Kayode FayemiAwon miiran ni: Minisita to n ri si oro ile-okere, Geoffrey Onyeama, minisita to n mojuto eto idajo, Abubakar Malami, olugbani-nimoran lori eto aabo, ogagun Babagana Monguno (Rtd); ati oludari ile-ise otelemuye Ahmed Abubakar.
Ohun tí ó yẹ kí o ṣe nìyí, yan àwọn ọkunrin tí wọ́n lè jẹ́ alákòóso, àwọn tí wọ́n bẹ̀rù Ọlọrun, tí wọ́n ṣe é gbẹ́kẹ̀lé, tí wọ́n sì kórìíra àbẹ̀tẹ́lẹ̀; fi wọ́n ṣe alákòóso àwọn eniyan wọnyi, fi àwọn kan ṣe alákòóso lórí ẹgbẹẹgbẹrun eniyan, àwọn kan lórí ọgọọgọrun-un eniyan, àwọn kan lórí araadọta, ati àwọn mìíràn lórí eniyan mẹ́wàá mẹ́wàá.
Ọ̀rọ̀ kò wọ̀ láàrin ẹ́gbẹ́ olùkọ́ fásitì ASUU àti ìjọba àpapọ̀ Ilé ẹjọ́ rán ọjọ̀gbọ́n fasiti OAU lọ sẹ́wọ̀n ọdún méjì Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Yorùbá gbà pé òrìṣà bí ìyá kò sí!
Oríṣun àwòrán, Getty Images Oliver Langford ti wọn yan lati ran an lọwọ lo wa gba ipo.
Wá gbọ́ ìmọ̀ràn tí Jonathan fún Buhari lórí ọmọ Fasoranti tó kú!
OLUWA bá dá Jona lóhùn pé, “Ǹjẹ́ ó yẹ kí o bínú?
Ní ọdún keji tí Jehoaṣi ọmọ Jehoahasi jọba ní Israẹli ni Amasaya ọmọ Joaṣi jọba ní Juda.
Olódodo ni ọ́, OLUWA,nígbà tí mo bá ń fẹjọ́ sùn ọ́;sibẹ n óo ro ẹjọ́ mi níwájú rẹ.
Awọn ọmọ iya mẹta kan ni wọn ti di asínjẹ pọnbele lori ikanni ayelujara instagram.
18 Àti pé ẹ̀rí yìí yíò wá sí ìmọ àwọn ará Lámánì, àti àwọn ará Lẹ́múẹ́lì, àti àwọn Iṣmaẹ́lì, tí wọn ti rẹ̀hin nínú àìgbàgbọ́ nítorí àìṣedẽdé àwọn bàbá wọn, àwọn ẹnití Olúwa gbà láàyè láti pa àwọn arákùnrin wọn awọn ará Néfì run, nítorí àwọn àìṣedéédé àti àwọn ìríra wọn.
Bẹẹ ba gbagbe, igba akọkọ kọ ree ti isẹlẹ tanka epo yoo maa gbẹmi awọn eeyan.
Amọ Bashir, tii se ẹlomiran to tun sẹsẹ kede ifẹ rẹ si Hanan loju opo itakun agbaye, ni to ba jẹ pe ọmọ aarẹ fẹ oun ni, maalu aadọjọ ni oun ko ba fi san owo ori rẹ.
Buhari, o kò ṣe bẹbẹ kankan láì jẹ́ pé o gba Leah Sharibu náà sílẹ̀ Wo àwọn nǹkan to tún nílò NIN fún yàtọ̀ fún ìforúkọsílẹ̀ síìmù Wọ́n ni yàtọ̀ si àwọn igbésẹ̀ akin tó gbé, àwọn ènìyàn kò le gbàgbé bi àwọn jànduku ṣe pọ̀ tó lásìkò rẹ̀ àti àwọn ìwà ìbàjẹ́ míràn tó jẹyọ nílùú Ibadan àti ni ìpińlẹ̀ Oyo lápapọ̀, lasiko aye oloogbe naa.
Ṣugbọn ọpọlọpọ tí ó jẹ́ ẹni iwájú yóo di èrò ẹ̀yìn, àwọn èrò ẹ̀yìn yóo wá di ẹni iwájú.
Ní ọjọ́ kan, nígbà tí Jesu nìkan ń dá gbadura tí àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ wà lọ́dọ̀ rẹ̀.
Lẹ́yìn náà, wọn yóo kó àwọn nǹkan wọnyi lé e lórí: àwọn àwo turari, àwọn àwokòtò, ati àwọn ìgò fún ọtí ìrúbọ.
Ọjọ Iṣẹgun, ọjọ kọkanlelọgbọn, oṣu Keje, ni Saraki kede pe oun ti kuro ni APC lọ si ẹgbẹ oṣelu alatako, PDP.
O ni yatọ sí Ileeṣẹ ọlọ́pàá, ààfin awọn ọba ti ori wọn pe, naa jẹ ọkan gbóògì lara ibi ti awọn èèyàn maa n fi ori pamọ́ sí ti wọn ba wa nínú ìṣòro, paapaa eyii to le la ẹmi lọ.
Ileesẹ ọlọpaa ni iwadi ti n tẹsiwaju lori isẹlẹ naa.
•Oju opo Isẹ ati awọn iroyin miran: Awọn to n wa'sẹ ni lati dahun awọn ibeere kan ti wọn yoo si fi ẹda kaadi idanimọ wọn sọwọ.
Ọtọ tun ni ajoji kan, Lee Harvey Oswald to pa aarẹ Kennedy tan to wa ko wa si Minsk lati maa gbe nibẹ gẹgẹ bi ẹni tọwọ rẹ mọ.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Hmmmmn, igbesẹ yii ẹwẹ gbe ewu ru sori pupọ nitori pe awọn arugbo ni yoo pọ ju awọn si lo wa ni bebe kiko arun yii ju.
Láti igba ti Buhari ti de ori aleefa, iroyin fi han wipe, o ti lo ọdun kan, ati ọjọ mọkaindinlogoji lẹyin odi.
Erekuṣu Ìl-De-la Cité laarin Seine ni wọn kọ ilé ijọsin yii si lọdun 1163 lasiko Oba Louis keje niṣẹ bẹrẹ nibẹ.
Wọn kì í ní wahala bí àwọn ẹlòmíràn;ìyọnu tíí dé bá àwọn ẹlòmíràn kì í dé ọ̀dọ̀ wọn.
Ronaldo sọrọ lori opo Twitter ẹgbẹ agbabọọlu Juventus pe oun ti n ṣiṣẹ takuntakun lati igba t'oun ti darapọ mọ ikọ Juventus, bẹẹni awọn akẹgbẹ oun naa ṣi n ranwọ f'oun.
Igbesẹ yii ko ṣẹyin abajade igbimọ iwaadi ti ile ẹkọ naa gbe kalẹ, lati ṣe iwaadi bi awọn akẹkọọ naa ṣe lu akẹgbẹ wọn kan nilegbe awọn akẹkọọ.
Kí a tóó kúrò lọ́dọ̀ Baba-onírùngbọ̀n-yẹ́úkẹ́ ó ti sọ̀rọ̀ púpọ̀ fún wa nípa wọn ó sì ti pa á láṣẹ fún wa wí pé bí a bá ti ń sún mọ́ etí ọ̀dọ̀ wọn kí a fi aṣọ di etí wa, àti pé ìgbà tí a bá dé ọ̀dọ̀ wọn kí a má ṣe wo apá ibi tí wọ́n wà, àwọn ń bẹ ní apá òsì níbi tí wọn gbé ń sáré kiri tí wọ́n sì ń kọrin burúkú irú èyí tí ó jẹ́ pé tí etí bá gbọ́ ojú yóò fẹ́ẹ́ wo apá ibẹ̀, bẹ́ẹ̀ ni ẹni tí ó bá rí wọn kò ní í lè llọ mọ́.
Kenyatta  soro lasiko to n kan si adari ijọba orile ede Ethiopia
Awọn eniyan n beere pe ṣe o yẹ kori bẹẹ, koda lasiko ti awọn aafa yii ba n pe irun ninu mọṣalaṣi.
Kìnìhún joko jẹ ẹran ara afurásí ọdẹ tí kò gbààyè kó tó ṣọdẹ Dangote: Mo ti gbà $10m ri ní bánkì kí n lè mọ bí o tí ṣé rí lójú Nàìjíríà ló wà nípò kẹfà nínú ewu ikú àìtọ́jọ́ l'ágbàáyé nítorí nkan mímú tó ní ṣúgà Oyè Mọ́gàjí àti Báálẹ̀ ti di owó rèé, ọjà rèé ní Ibadan - Lekan Balogun Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ayekofẹnifọrọ: Ó yá, ẹ fi àmì sórí ọ̀rọ̀ náà.
awon ilana epo robi ohun di okan soso ki ilosiwaju le ba ile-ise naa.
Ajo to n ri si boolu afesegba lorile-ede Naijira, NFF ti safihan akonimoogba tuntun iko Super-Falcons ni papa isere ti o wa nilu Abuja lojo isegun (Tuesday).
 wọ ́ n jẹ ́ dídásílẹ ̀ ní ọdún 1895 latowo ara sweden onímọ ̀ ẹ ̀ kọ ́ ẹ ̀ lá ( kẹ ́ místri ) alfred nobel , olúṣé dynamite .
Nítorí OLUWA rí gbogbo ohun tí eniyan ń ṣe,ó sì ń ṣàkíyèsí gbogbo ìrìn rẹ̀.
Àwọn àìsàn mìíràn ati ìpọ́njú tí wọn kò kọ sinu ìwé òfin yìí ni OLUWA yóo dà bò yín títí tí ẹ óo fi parun.
ní Heburoni ati ní gbogbo ìlú tí Dafidi ati àwọn ọmọlẹ́yìn rẹ̀ ti rìn kiri.
Gege bi o se so, “Ihaholo
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ìwadìí gbogbo ń fi ìdí rẹ̀ múlẹ̀ pé ọ̀gọ̀ọ̀rọ̀ làwọn aboyún àti ọmọ wẹ́wẹ́ tó ń kú nítorí ìgbẹ̀bí lórílẹ̀èdè Nàìjíríà 'Ori kó awakọ̀ àti ọmọ mẹta yọ nínú ìjàmbá ọkọ' 'Logo Benz yóò lẹ́yìn fún àwọn ọ̀dọ́ tó bá ṣògùn owó' 'Ootọ ní fídíò ọmọogun Nàìjíríà tí kò fẹ́ kojú Boko Haram ṣùgbọ́n.
Ilé rẹ̀ wà ní Salẹmu,ibùgbé rẹ̀ wà ní Sioni.
Nítorí pé fún ìgbà díẹ̀ ni ibinu rẹ̀,ṣugbọn títí ayé ni ojurere rẹ̀;eniyan lè máa sọkún títí di alẹ́,ṣugbọn ayọ̀ ń bọ̀ fún un lówùúrọ̀.
8bn ni OAU jẹ lówó orí òsìsẹ́ rẹ̀
O kepe ile aṣofin agba l'Abuja lati maa beere ipa ti irinajo Buhari yoo ni lori ọrọ aje Naijiria, nigba kuugba to ba tajo de.
Ọ̀sẹ̀ tó kọjá ni Fayoṣe ti wà l'ọ́gbà ẹ̀wọ̀n Ikoyi nípìnlẹ̀ Eko, lẹ́yìn tí ilé ẹjọ́ gba onídúró rẹ̀ lórí ẹ̀sùn ṣíṣe owó ìlú báṣu-bàṣu lásìkò tó fi jẹ́ gómìnà ìpínlẹ̀ Ekiti.
7m kó sí páńpẹ́ EFCC MTN Dáa padà, o kò gbọdọ̀ gba owó orí lọ́wọ́ oníbárà tó bá fi owó ránṣẹ́ - Ìjọba àpapọ̀ Kí ni pàtàkì nọ́mbà 615 láàrín àwọn èèyàn ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ̀ Awọn ilana tuntun naa niyii: 1.
"Ebila of Ibadan: Ikọ̀ Operation Burst"" ní àwọn ló pa Ebila, olórí àwọn ""One million boys"" n'Ibadan"
Ẹni to bori: Guinea-Bissau Mali vs South Africa.
leyin ti won fagba han iko Real Madrid pelu ami ayo kan si merin(1-4) ni papa
Oríṣun àwòrán, Dillibe Onyeama Onyeama sọ fun BBC pe, ko si wahala kankan ati pe isẹlẹ naa ko mu iyipada si bi oun ti se n foju rere wo ile ẹkọ Eton.
Àṣírí tó ń bẹ láàrín Oluwo àtàwọn ọ̀dọ́ Iwo tí wọ́n fi fi ẹ̀mí wọn lélẹ̀ dáàbò bo ààfin rẹ̀ Taa gan ló ni Lekki Toll gate láàrin aráàlú àti Asiwaju Tinubu?
Koda, o ti bẹrẹ ileesẹ to n se ọti lile ati bia, to fi mọ isẹ idagbasoke awọn ibudo iwakusa lorisirisi bii kuari to n pese eroja ti wọn fi n se simẹnti Henry Oloyede Fajemirokun tun lewaju ijiroro lori agbekalẹ awọn banki olokoowo fawọn onileesẹ aladani laarin Naijiria ati Amẹrika, NAMBL Oun yii kan naa si ni ẹni akọkọ to sedasilẹ ẹka ileesẹ akoso oju omi ni Naijiria, to si tun kọkọ ni ọkọ oju omi to n gbe ẹru lọ soke okun.
 Bukola Saraki, igbakeji re, Ike Ekweremadu, agbenusoro fun ile igbimo asoju-sofin, Yakubu Dogara, igbakeji re, Kasun Yusuf ati awon merindinlogun miiran lati ile asofin mejeeji.
ọkùnrin náà sì ń tẹ̀lé e lọ.
O ni itiju ko fẹ ẹ jẹ ki oun lọ ma a gbe pẹlu iya oun, nitori pe awọn iyawo aburo oun n gbe pẹlu rẹ.
Ẹni to bori: Kenya Burundi vs Ghana.
Bakan naa, ni idije Olympics ti o waye naa tun mu ibasepo ti o donmonron jeyo larin orile-ede Korea mejeeji, leyin oniruuru aibale okan lori sise ifilole ohun ija oloro orile-ede North Korea, eyi ti o je ekeefa sise agbeyewo ohun ija oloro naa fun ipenija o ni kaan pa ajo isokan U.
Itumọ ti wọn fun fif ipa gbajọba ni ọna ti ko tọ lati yọ olori ijọba kuro lori ipo.
 Lojo Aiku ni ajo Onigbagbo aranilowo kan ni Siouxland ni Tanzania ati ajo Tanzania fun eto ilera ati eto eko seto lati gbe won lo sile America.
21 Àti pé nísisìyí mo pàṣẹ fún ọ, ìwọ ìránṣẹ́ mi Joseph, láti ronúpìwàdà kí o sì rìn ní ìdúró ṣinṣin ní iwájú mi, kí o má sì ṣe fi ààyè gba ìyínilọ́kànpadà awọn ènìyàn mọ́.
Buhari fi kun pe, awọn maa sa gbogbo agbara to ba wa nikawọ awọn lati ri daju pe finni ni adiẹ awọn akẹkọ yii ti oko eemọ bọ, ti wọn si fa wọn le awọn obi wọn lọwọ.
Joṣua bá wí fún wọn pé, “Ẹ̀yin ni ẹlẹ́rìí ara yín, pé OLUWA ni ẹ yàn láti máa sìn.
'Aibikita ileeṣẹ ijọba nkoba eto iṣuna 2018' AfCFTA: Kini yoo jẹ atubọtan fun Naijiria?
Adajo Shushaidah so pe o ni awọn idi kan ti adajọ gbọdọ wo ki o to le gba ọkunrin laaye lati fẹ iyawo meji tabi ju bẹẹ lọ.
Bàbà tí Solomoni fi ṣe àwọn òpó mejeeji, agbada omi ati ìtẹ́lẹ̀ rẹ̀ kọjá wíwọ̀n.
Ọkunrin náà dá wọn lóhùn pé, “Ohun ìyanu ni èyí!
Wọ́n tún ń fa àwọn arúfin meji kan pẹlu rẹ̀, láti lọ pa wọ́n.
Alufaa yóo ṣe ètùtù fún ẹni náà níwájú OLUWA, OLUWA yóo sì dárí ohunkohun tí ó bá ṣe jì í.
Lọjọ Iṣẹgun ni o sọ ọrọ yi lasiko ti ileeṣẹ ọlọpaa nilu Akure ṣe afihan rẹ.
Ní ti Amofin Suleiman Abaya, ó ṣàlàyé pé, ní ìlànà òfin, ìlànà tí wà pé àwọn tó bá dúró gẹ́gẹ́ bí ìpayà fún àwùjọ tàbí tó máa ń pá ènìyàn lai-nìdí, ó di dandan kí ìjọba polongo wọn gẹ́gẹ́ bii agbesumomi ṣùgbọ́n ó dàbí ẹni pé Ìjọba tó ń bẹ lóde tí kọ̀rọ̀ òṣèlú bọ̀ọ̀.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Increment in bread price: Ọ̀wọ́ngógó búrẹ́dì gbòde kàn lẹ́yìn tí àwọn oníbúrẹ́dì da iṣẹ́ sílẹ̀ 11 Owewe 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 21 Owewe 2020 Oríṣun àwòrán, Google Awọn olugbe ilu Abuja ati Eko ti ke gbajare sita lẹyin ti ọwọngogo burẹdi gbode kan.
Dakolo fi ẹsun ifapabanilopọ kan Fatoyinbo ni ogun ọdun sẹyin.
Ìparun wà ninu rẹ̀;ìnilára ati ìwà èrú kò sì kúrò láàrin ìgboro rẹ̀.
Tóbẹ́ẹ̀ tí ẹnu rẹ̀ yóo kọ oúnjẹ,oúnjẹ àdídùn óo sì rùn sí i.
Kíni ìwọ mọ̀ nípa Funmilayọ Ransome-Kuti?
Koda, Umar tun ni awọn yoo tun yọju si ileesẹ amunawa to yẹ ko pese ina silu Ọyẹ Ekiti, ijọba ipinlẹ Ekiti funra rẹ, ileesẹ ọtẹlẹmuyẹ ati ileesẹ ọlọpaa.
Eyi lo mu ki Onidajọ Oweibo o kede Ọgbọn ọjọ oṣu karun ọdun 2019 fun gbigbọ ẹjọ lori boya ki wọn gba oniduro rẹ titi ti igbẹjọ yoo fi maa waye.
Kàyééfì, oyún inú nínú ilé ìgbọ̀nsẹ ọkọ̀ òfurufú Ta ni yóò borí láàrin Aisha Buhari àti ọkọ rẹ̀ lórí ọ̀rọ̀ ‘First Lady’?
Oríṣun àwòrán, others Àkọlé àwòrán, Algeria pada ri maaki mẹta gba nitori Naijiria lo agbabọọlu ti wọn ti ni ko lọ rọọkun nile tẹlẹ.
Àjọ NCDC kéde èèyàn 260 tuntun míì tó ṣẹṣẹ ni ààrùn Covid-19 ní Naijiria Ooni Ile Ife pàdánù Màmá àgbá Òṣèré tíátà míì ń ṣàìsàn láti bí ọdún mẹ́ta, ọkan rèé tó ń bẹ̀bẹ̀ f'ówó ₦80m la fi rán ogún ìyàwó asòfin lọ Dubai - Obasa Amọṣa, lọwọ yii iroyin to n lọ kaakiri ni pe o ṣeeṣe ki ojojo maa ṣogun Abiọla Ajimọbi ki ara ogun rẹ o maa le.
Ewe, orisirisi ero ni yoo maa
Ṣugbọn bí ẹ̀yin bá fetí sí ọ̀rọ̀ mi, tí ẹ kò gbé ẹrù wọ inú ìlú yìí lọ́jọ́ ìsinmi, tí ẹ ya ọjọ́ ìsinmi sí mímọ́ láìṣe iṣẹ́ kankan lọ́jọ́ náà, 
“Mú ìwé kíká kí o sì kọ gbogbo ọ̀rọ̀ tí mo sọ fún ọ nípa Israẹli ati Juda ati gbogbo orílẹ̀-èdè sinu rẹ̀.
Wọnyi ni diẹ lara awọn ti awọn eeyan jakejado agbaye n gbosuba kare fun loju opo Twitter pe, wọn hu iwa akin lasiko ati lẹyin iṣẹlẹ naa.
Mo wá dáhùn, mo ní, ‘Ta ni ọ́, Oluwa?
Ó tẹ̀lé ìwà ẹ̀ṣẹ̀ Jeroboamu; ọmọ Nebati, tí ó mú Israẹli dẹ́ṣẹ̀.
Ninu iwe to fọwọ si lọjọ ẹti, o ni gbigba aṣẹ ile ẹjọ lati fi Ọgbẹni Adoke si ahamọ fun odidi ọsẹ meji gbako ko tọ rara.
awon eniyan jẹgbadun  eto isejọba rere
Ó sì sọ fún Balaamu pé: “Mo pè ọ́ pé kí o wá gbé àwọn ọ̀tá mi ṣépè, ṣugbọn dípò kí o gbé wọ́n ṣépè, o súre fún wọn ní ìgbà mẹta!
Baba Ijesha: Nigba ti ọga mi ti dide lọ la toosti ọrẹ rin, ẹ jẹ ki emi naa ti mo jẹ mọnija ki mo mọ nipa owo gan ka jọ maa fi kii, ka maa fi lu pọ Fathia: Are you mad?
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ohun tó wù kí ileẹjọ́ kòtẹ́milọ́rùn sọ, Adeleke kò lè di gómínà Ọ́ṣun - APC Ilé ẹjọ́ gba onídúró Naira Marley pẹ̀lú mílíọ́nù méjì náírà Ohun tó yẹ kí o mọ̀ nípa OIC rèé Fayose fi sita loju opo twitter rẹ pe, oun ki Rochas Okorocha kaabọ si ẹgbẹ awọn gomina ti EFCC n wa kiri.
O ni oun ṣẹṣẹ ba ẹlomii ti o fẹsun kan Fatoyinbo pe o tun fipa ba oun lo pẹ sọrọ tan ni o Ìtàn tó wà nídi òwe ‘Sebótimọ Ẹlẹ́wà Sàpọ́n’ Ṣẹ gbọ́ nípa Alájọ Ṣómólú, tó ta mọ́tò ra kẹ̀kẹ́?
O ni àwọn ise ìrànwọ ti Iya Adeboye ń se fawọn ọ̀dọ́ àti àwọn alaini kò lẹ́gbẹ́.
Lọsẹ yii lo di abiyamọ tuntun lagbo oṣere Yoruba, lẹyin ti Ọlọrun fun idile rẹ ni ọmọ okunrin lantilanti.
Àwọn ọmọ Nàìjíríà yarí lórí èròngbà ilé aṣòfin pé kí àjọ FRSC má a lo nkan ìjagun Àwọn ìwàásù akọnilẹ́nu hàà tí Prophet Israel Oladele CCC Genesis Global ti ṣe rèé Kí lo mọ̀ nípa ìgbeyàwó Àbẹ̀ẹ́lẹ̀, Àṣàǹte, Ọkọ Káalẹ́ àti Gbàmí o ràmí?
Oríṣun àwòrán, @BashirAhmaad Àkọlé àwòrán, Buhari fẹ san owo ti ijọba ipinlẹ Plateau na nipasẹ awọn ọna ilu ti o jẹ ti ijọba apapọ O so pe ijọba apapọ yoo san owo ti ijọba ipinlẹ Plateau na lori atunse oju ọna ti o jẹ ti ijọba apapọ.
 Arabinrin naa tun sọ pe ko si bi awọn eeyan ko ṣe ni sun mọ ara wọn ju bo ti yẹ lọ ninu isin Cross-over night.
Wọn ń mú imototo ara ní ọkunkundun, tí wọn kò sì kóra jọ pọ si oju kansoso lati farakinra.
Ó wọn ibẹ̀ láti inú ẹnu ọ̀nà kúkúrú títí dé iwájú ìta gbọ̀ngàn inú, ó jẹ́ ọgọrun-un (100) igbọnwọ, (mita 45), ní ìhà ìlà oòrùn ati ìhà àríwá.
Lẹ́gbẹ̀ẹ́ agbègbè Gadi ní ìhà gúsù, ààlà ilẹ̀ náà yóo lọ láti Tamari títí dé ibi àwọn odò Meriba Kadeṣi, títí dé àwọn odò Ijipti, tí ó fi lọ dé Òkun Ńlá.
Mi ò gbèrò láti lọ fún sáà kẹ́ta gẹ́gẹ́ bí ààrẹ - Buhari Iléẹjọ́, ẹ sọ fùn ọ̀gá DSS kó fún wa ní ₦1bn torí àhámọ́ lọ́nà àìtọ́ - Sowore àti Bakare Àgbẹdọ̀!
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Akomolede ati Aṣa lori BBC:Wo ìrúfẹ́ ìgbeyàwó méje tó wà nílẹ̀ Yorùbá àti ojúṣe Alárinà Ọdun 2002 ni aarẹ orilẹede Mali tẹlẹ naa jẹ aarẹ titi wọ osu kẹta ọdun 2012, tawọn ologun fi tipa gba ijọba lọwọ rẹ.
Oríṣun àwòrán, LASEMA Osanyintolu tun ṣalaye wi pe awọn oṣiṣẹ ijọba yoo ṣe ayẹwo ile mejeeji to wa ni ẹgbẹ ile ọhun lati mọ boya awọn naa ti di alapa.
Síwájú sí i, nípa ti ìlànà oyè jíjẹ, ó ní iye ọjọ́ tí Ọwá tuntun gbọ́dọ̀ lò ní Ijẹ̀bù - Jẹ̀ṣà láyé ọjọ́un.
Ẹ ranti ohun gbogbo tí ó ṣe fun yín ninu aṣálẹ̀ títí tí ẹ fi dé ìhín; 
Inú àwọn tí ó bẹ̀rù rẹ yóo máa dùnnígbà tí wọ́n bá rí mi,nítorí pé mo ní ìrètí ninu ọ̀rọ̀ rẹ.
5 21590 Orilẹede Swaziland 126 11.
Amaju Pinnick di ààrẹ àjọ NFF tuntun Victor Moses, Oshoala gba ami ẹyẹ Wahala rẹ pẹlu Amaju Pinnick ati Chris Giwa lo jẹ ki ajọ elere bọọlu lagbaye, FIFA kuku fofin de Naijiria ati ere bọọlu alafẹsẹgba ki Yẹmi Oṣinbajo igbakeji aarẹ to da sii.
LASEMA - BBC News Yorùbá BBC News, YorùbáFò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Lagos building collapse: Àtúnṣe tí kò bófin mu ló fa ilé tó wó lu ènìyàn méjì ní Oshodi - LASEMA 24 Òkùdu 2019 Oríṣun àwòrán, lasema Àkọlé àwòrán, Ile naa pa awọn eniyan meji lara Lọjọ Aiku ni ilé alaja kan wo lu awọn meji nipinlẹ Eko.
Ṣebí àwọn ọmọ mi ti kú, mo ti yàgàn,mo sì lọ sí ìgbèkùn lóko ẹrú.
A gbọ pe awọn janduku naa ma n kopa ninu gbígba ilẹ̀ onílẹ̀, ija àgbà, eyi to ma n yọrí sí iku, ati òfò dukia.
Igbesẹ naa ko dun mọ awọn agbẹ ninu rara, ti wọn si n wọna bi wọn yoo ṣe bọ lọwọ ajaga ijọba naa.
Josh Posh: Irun mií tó ‘Posh’, làwọn èèyàn se ń pè mí ní Josh Posh
Ṣe ìwọ mọ Ṣẹgun Adewale, olùdíje Ekiti yìí?
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 2020 in Retrospect: Ìjàmbá iná, ilé tó dàwó, ìwọ́de àti àrùn Covid-19 wà lára ìṣẹ̀lẹ̀ 2020 Idi ti ileẹjọ fi da ẹjọ naa nu ni wi pe, adajọ Mohammed Idris to gbọ ẹjọ naa ni oun ko ni aṣẹ mọ lori ẹjọ ọhun nitori wọn ti gbe e lọ si ileẹjọ kotẹmilọrun.
Baalu naa gbera lati ilu Dubai, ni ẹsẹ rẹ tase lasiko to n gbiyanju lati balẹ ni papakọ ọkọ ofurufu Calicut.
Ajọ isọkan agbaye si ti kede pe ti gbogbo awujọ agbaye ba n fun ọmọ lọyan, eyi lee doola ẹmi to to ẹgbẹrun lọna ẹgbẹrin.
OLUWA gbà wọ́n, ó sì fún wọn ní ìṣẹ́gun ńlá.
"Oríṣun àwòrán, LASMA Àkọlé àwòrán, Lagos-Ibadan Repair: Àwọn ọ̀ná míràn ti e lè gba jáde tàbi wolé si ìpínlẹ̀ Eko ""Grandpa àti Uncle mi, ń fipá bá mi lòpọ̀ láti ọmọ ọdún mẹ́rin"" Ta ni awàdà rẹ̀ wú u yín lórí jù ní Yollywood?"
" Sáájú àsìkò yìí ni ìjọba ti kéde pé, kí àwọn akẹ́kọ̀ọ́ ní gbogbo ipele padà sí ilé ẹ̀kọ́ ni ọjọ́ kejìdínlógún , oṣù kíní ọdún 2021.
Sáà keji rèé re ti Aubameyang ti darapọ mọ Gunners.
Bèèrè lọ́wọ́ àwọn tí wọ́n sálọ; bi àwọn tí ń sá àsálà pé, ‘Kí ló ṣẹlẹ̀?
o jawe olubori tabi ki awon kan maa sọ fun un , pe iwo lo jawe olubori, tabi ki
Àwọn tí ó sì dá láre ni ó dá lọ́lá.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Technovation 2018: Àwọn akẹ́kọ̀ọ́-binrin Naijiria gba ipò kínní 11 Ògún 2018 Oríṣun àwòrán, @technovation Àkọlé àwòrán, Áwọn akẹkọ obìnrin Nàìjíríà naa gbogbo Naijiria ga nínú ìdíje ìmọ ẹrọ l'amerika Ikọ àwọn akẹ́kọ̀ọ́ obìnrin kan to soju orileede Nàìjíríà ti ṣe bẹ fagba han orílèèdè Amerika, Spain,Turkey, Uzbekistan ati China lati gba ami ẹyẹ ipele àwọn ojẹ-wẹwẹ, nínú ìdíje ìmọ ẹrọ ''Technovation World pitch'' tọdun 2018, to waye nilu San Francisco, ni orilẹ-ede Amerika.
‘Jọ̀wọ́ jẹ́ kí n máa lọ ní tèmi, nítorí òní ni ìgbìmọ̀ àwọn ẹranko, àwọn àgbàlagba ni wọ́n rán mi ní iṣẹ́, bẹ́ẹ̀ ni ẹni tí ó bá ń fẹ́ kí òun dàgbà, olúwaarẹ̀ kò ní í fi nǹkan àgbà jáfara – pẹ̀lẹ́ o, ọdẹ aperin, ó kú làásìgbà náà, ó dìgbà díẹ̀ ná, kí orí rẹ má ṣàìgbé ọ kalẹ̀ ní ibni tí ìwà òmùgọ̀ gbé ọ lé téńté.
O ni ṣugbọn bibeli sọ pe ka mu idamẹwaa wa, emi naa si n san temi""."
Koko ohun to yẹ ki ẹ mọ nipa ogun Agbekoya: Aarin ọdun 1968 si 1969 ni ogun Agbekoya waye laarin awọn agbẹ ati ijọba ẹkun Iwọ oorun Naijiria ijọhun.
Bi ijọba tilẹ wo ileesẹ, redio Fresh FM ko lee wo lailai, tori araalu lo nii.
bin Al-Hussein  ati akowe agba fun ajo agbaye
Bi a ko ba gbagbe o sọ nigba kan pe ere oritage Nolywood n mu ki oogun owo ati ijinigbe gbilẹ si ni Naijiria.
Ninu rẹ o sọ wi pe iyawo rẹ n yan alẹ ti eyi si ba ninu jẹ.
Amrika wa tẹpẹlẹ mọ bo ti ṣe pataki to ki ile ẹkọ jẹ aaye ifọkanbalẹ tawọn ọmọ ti le kẹkọ, ti wọn yoo si ti gbooro si.
Agbẹnusọ gomina Babajide Sanwo-Olu, Gboyega Akosile sọ fun BBC pe, iwadii ṣi n lọ lọwọ, nitori naa yoo ṣoro lati sọ ohunkohun lasiko yii.
"Bi Biden ba jawe olubori, yoo jẹ ewe oye ajẹpẹ amọ to ba fidi janlẹ, yoo pese anfani ọdun mẹrin mii fun ẹni to ro pe ko kun oju osuwọn rara lati jẹ aarẹ Amẹrika - ""ẹni ti ko ṣee gbẹkẹle"" gẹgẹ bo ṣe sọ."
Banki agbaye se ẹyawo milionu 486 fun ina ọba ni Naijiria
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Man Utd Vs Man City: Kò ṣèlẹ́rí!
Ìdí márùn ún tí agbára Covid 19 ní ilẹ̀ Adúláwọ̀ kò fi tó tí àwọn ilẹ̀ àgbáyé míràn Akinola ni ni kete ti ọrọ naa ṣẹlẹ ni wọn ti gbe e lọ si ile iwosan Merit ti wọn si kọ ọ nibẹ pe ki wọn lọ mu iwe wa lati ọdọ ọlọpaa.
Ó ní kí ng jọ̀ọ́ ṣe ìrànlọ́wọ́ fún òun kí òun lè rí oúnjẹ jẹ.
Aare so pe gbogbo akitiyan ajo ECOWAS lati ri I pe idagbasoke ba eto oro aje orile ede naa, ko ja si asan.
Ẹ̀kọ́ ìtàn yi ni pé, àfojúdi kò dára, ó yẹ ki enia pa òfin mọ nitori “Bi a ti nṣe ni ilé wa, èèwọ̀ ibò miran”.
Ó wádìí ọ̀rọ̀ tí ó tuni lára ati ọ̀rọ̀ òdodo, ó sì kọ wọ́n sílẹ̀ pẹlu òtítọ́ ọkàn.
Mo kọ́ ẹ̀kọ́ kan nínú àṣà àwọn Tibet nípa àìwàfúnìgbàpípẹ́: gbogbo nǹkan ni òpin yóò dé bá.
- Adefila Mary Olaitan 15APPEkundayo Ademola Precious - Ojo Olugbenga Samuel 16BNPPOlapade Olajide Victor - Dunmade Adejoke Wuraola 17C4CIlori Titus Oluwafemi - Alabi Temitayo Kadijat 18DAMutiu Abiodun Ibrahim - Fafioye Hammed Abiodun 19DPCAderemi Aree - Onitayo Yemisi Mary 20DPPSolomon Ayodeji Oni - Issa Ademola Aderibigbe 21FIPBabatunde Salako Joseph - Onifade Saheed Alade 22GDPNAdetipe Adebodun Abiola - Ajiboye Funke 23GPNRafiu Shehu Anifowose - Oluwatoyin Adebayo 24HDPAdedoyin Adegoke Joshua Oluwole - Olawale Adesoye Adewumi 25KPFabiyi Oluseyi Olubunmi - Ibrahim Adekunle Akande 26LPBabatunde Olaniyi Loye - Aderonke Adebayor Jabar 27MMNRaphael A.
 Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Mobile Wash: iṣẹ́ fífọ́ mọ́tò tà ni mó yàn láààyò- Slay Mama Nigba ti ko si abala ati ẹsẹ ofin to yẹ fun agbekalẹ eto Amotekun, to fi mọ ilana isọwọsisẹ wọn, ojuse ti wọn yoo se, ilana eto akoso wọn, ipese ati owona, ni ọpọ awọn ẹlẹgbẹjẹgbẹ lorisirisi nilẹ yii se n tẹsiwaju lati maa sọ ero wọn lori awuyewuye ti ko nidi, eyi to n ti agbekalẹ eto Amotekun nidi.
Irinṣẹ ayẹwo Covid-19 laarin wakati kan: O maa n to aarin ọjọ mẹta ki esi ayẹwo Covid-19 to jade ki Daniel Ndima ati Dineo Lioma to ṣagbekalẹ irinṣẹ to le e sọ esi ayẹwo naa laarin wakati kan ati iṣẹju marun un.
Sugbọn o fi ifarajin rẹ han lati fi abadofin lori ẹkunwo oṣiṣẹ rinlẹ lọjọ waju.
 Bio seleri lati tẹle awon ipolongo re lasiko to n seleri pe oun yoo se atunse to monyan nipabi won se n gba ise akanse lori ohun alumooni ile ati atunse si awon wura  ati ohun alumooni  ile orile ede naa, lona ti yoo fi se awon ara ilu ni anfaani.
Iroyin to tẹ wa lọwọ sọ pe wọn ti le Emir Kano tẹlẹ, Lamido Sanusi lọ si ipinlẹ Nasarawa lẹyin ti ijọba Gomina Ganduje rọ ọ loye tan.
Gbogbo àwọn tí wọn farapamọ́ bá yára dìde ní ibi tí wọ́n wà.
Kí ló dé tí ìrora mi kò dáwọ́ dúró, tí ọgbẹ́ mi jinlẹ̀, tí ó kọ̀, tí kò san?
Bakan naa lo sọ wi pe iye owo kan naa kọ ni wọn o fi bẹrẹ fun gbogbo ẹni ti wọn ba gba.
Ko ti so boya ohun yoo du ipo aarẹ yala labe asia ẹgbẹ APC tabi ẹgbẹ miran.
Ipinlẹ mọkanlelogun ni awọn eeyan naa ti jẹyọ.
Paso ni ohun lawọn obinrin to bimọ fun oun o, ṣugbọn ọrọ iyawo afẹsile ko tii yọ fun oun bayii.
Ẹnìkan sì sọ fún un pé Batiṣeba ọmọ Eliamu ni, aya Uraya, ará Hiti.
Kíni ìdí ti wọn fi ń lọ ọmú obinrin Mo fẹ́ sálọ torí ìpèníjà àkójọpọ̀ èsì ìbò gómìnà Ọyọ - Kọ̀misánà INEC l‘Ọyọ Ilé ẹjọ́ dajọ ikú fun ọkunrin tó pa olólùfẹ́ rẹ̀ ''Ẹmi awọn ọdọ to jẹ ogo orilẹede Naijiria lọla, pẹlu agba ati ọmọde ko gbọdọ sofo mọ nitori awọn akọle ko sisẹ wọn kun oju iwọn.
“Ṣe bi o ti mọ ki i tẹ́ – Ọdún wọlé dé”
NGA vs RSA: 'Bode Thomas' àti àwọn àṣà mííràn tó jẹyọ nínú ìdíje AFCON
Nígbà tí Dafidi gbọ́, ó rán Joabu ati gbogbo àwọn akọni jagunjagun rẹ̀ jáde lọ bá wọn.
 Ó kéré jù , àjẹsára yìí ń ṣiṣé dáadáa láàrín 85 sí 100 % fún ọdún meji gbáko .
Gẹ́gẹ́ bi àjọ náà ṣe sọ lójú òpó twitter rẹ̀ lálẹ́ ọjọ́ ajé ènìyàn àádóje ló ti kún nígbà ti èjìlélẹ́ẹ̀dẹ́gbẹ̀rún ti ri ìwòsàn gbà.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù 67 year old mother: Ìdílé Otubusin yọ ayọ̀ ọmọ lẹ́yìn ìgbéyàwó ogójì ọdún 27 Ọ̀wàrà 2018 Àkọlé àwòrán, Iya ọmọ Ajibola Otubusin ti o jẹ ẹni ọdun mẹtadinlaadọrin ko le pa idunnu rẹ mọ ra ''Njẹ ẹ ti gbọ pe Ọlọrun kii kanju?
Mo wí fún Jin pé tó bá rí bẹ́ẹ̀ lóòótọ́ kó nìṣó níbẹ̀.
O ṣalaye pe gbogbo owo oṣu ti ijọba Fayoṣe jẹ ni wọn san pada lati igba ti wọn ti wa lori aga iṣejọba.
Buhari: Ẹ mu awọn darandaran to ba n gbe'bọn
5m owó oúnjẹ El-Zakzaky lè bọ́ ẹlẹ́wọ̀n 208 ní oṣù kan Ọlọ́pàá àti Shiites tún fìjà pẹ́ẹ́ta BBC Yoruba jade lọ ṣe ifọrọwanilẹnuwo pẹlu ọkan pataki lara awọn ọmọ ijọ ẹlẹsin Shiite, Zaynab Zakariyah lori ohun to n ṣẹlẹ gangan.
Itan tun sọ pe iyan ti o mu ni ilu ti wọn wa tẹlẹ lo mu wọn mu irin ajo pọn lati wa ibi ilẹ gbe dara.
” Ṣugbọn Saulu kò sọ fún un pé, Samuẹli sọ fún òun pé òun yóo jọba.
Bawo ni imurasilẹ Super Eagles ṣe ri?
Ẹni ọmọ ọdun merinlelogun naa ti wa pinnu bayii pe ki wọn gba abẹrẹ fun oun lori idi naa ki wọn si jẹki oun ru diẹ.
Ẹ̀yin ará mi olùfẹ́, ẹ má tan ara yín jẹ.
tí a bá fi ojú sùnnǹkùn woo gun àgbáyé kìíní , a óò rí wí pé gbogbo rògbòdìyàn , àjàkú akátá tó wáyé , kò sẹ ̀ yìn ìwà ìgbáraga , owú jíjẹ , èmi ni mo jùọ ́ lọ , ìwọ lo jùmí lọ láàárín àwọn ọmọ adárúwurun .
Oríṣun àwòrán, @inecnigeria Alaye wọn ni pe, to ba ku wakati mẹrinlelogun ki idibo waye, ni ofin Naijiria sọ pe ipolongo gbọdọ pari.
“Èmi Kirusi, ọba Pasia, ni mo pàṣẹ yìí pé, ‘OLUWA Ọlọrun ọ̀run ni ó fún mi ní ìjọba lórí gbogbo ayé, òun ni ó sì ti pàṣẹ fún mi pé kí n kọ́ ilé kan fún òun ní Jerusalẹmu ní ilẹ̀ Juda.
Àwọn ìjòyè bá fi ìwé náà pamọ́ sinu yàrá Eliṣama akọ̀wé, lẹ́yìn náà wọ́n lọ sí ọ̀dọ̀ ọba ní gbọ̀ngàn, wọ́n sì sọ gbogbo ọ̀rọ̀ náà fún un.
Ìwé ìrìnnà 'VISA' Amẹ́ríkà: PDP láwọn faramọ ìgbésẹ Amẹ́ríkà
Hushpuppi di gbajúmọ̀ ẹlẹ́wọ̀n tó ní nọ́ńbà l‘Amẹrika, orúkọ̀ rẹ̀ wà lórí ayélujára Ṣé lóòtọ́ ni Lateef Adedimeji àti Adebimpe Oyebade ṣe ìgbéyàwó?
Oun naa lo si tun gba bọọlu keji wọle fun wọn ni abala keji ifẹsẹwọnsẹ naa.
Nígbà tí ó ṣàlàyé tán, mo ri wí pé òótọ́ ni.
Àwọn eniyan sì bẹ̀rẹ̀ sí sọ wí pé, “Àbí Saulu náà ti di wolii?
"Oríṣun àwòrán, @Alhaja Adeola Agoro Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Láàrín ìṣẹ́jú díẹ̀, ẹ ka ìwé Akinwumi Ishola, ""Nítorí Owó"" lórí Akomolede Yoruba Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Ondo Accident: Kíní ọ̀nà àbáyọ sí ìjàmbá ọkọ̀ tó ń wáyé lemọ́lemọ́ ní Ọjà Akungba,ní Ondo?"
Dokita onimọ nipa obinrin ti sọ wi pe ọmọbinrin ti ko ba tete lo si ile ọkọ, le se alaibimọ lasiko to yẹ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Atiku sí America: Ẹ má fìyà ìjọba tó ń kùnà jẹ àwọn ọmọ Nàijíríà 2 Èrèlè 2020 Oríṣun àwòrán, @atiku Bi aarẹ orilẹede Amẹrika, Donald Trump ṣe gbe ote le lilọ si Amẹrikaa awọn ọmọ Naijiria lati lọ maa gbe nibẹ ti n da ori ayelujara laamu.
Oluranlowo aare  fun iroyin ati ipolongo, Femi Adesina, lo soro yii ninu atejade kan ti o gbe sita.
Mo ti buwọ́lu àdínkù owó orí nítorí ìrọ̀rùn àwọn èèyàn ìpínlẹ̀ Ogun lásìkò Covid 19- Dapo Abiodun Iná sọ nínú ilé Big Brother tó ń lọ lọ́wọ́ ní Cameroon Buruji Kashamu jẹ́ ènìyàn tó nífẹ̀ aráàlú- Gómínà Dapo Abiodun Iná jó àwọn ènìyàn 10 tó ń gbà ìwòsàn arùn Coronavirus níbùdó ìtọ́jú Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí kan sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ìyàwó ilé lu ọmọ ọkọ rẹ̀ pa ní ìpínlẹ̀ Ogun Maryam Sanda, ìyàwó tó pa ọkọ rẹ, ri ìdájọ ikú he Lateef Adedimeji rèé tó mú omi lójú àwon òbí rẹ̀ lọ́jọ́ ẹ̀yẹ Ẹ wo àwòrán ìgbé àyé ààrẹ ilẹ̀ Kenya tẹ́lẹ̀rí, Arap Moi tó papòpà Ọlọ́pàá fẹ̀sùn ìpànìyàn kan ìyawo olóòtú ilẹ̀ Lesotho pé ó pa ìyáálé rẹ̀ Rabi sọ di mimọ pe, ọkọ oun, Shamsu Salisu, ẹni ọdun mẹẹdọgbọn naa fẹ ti foonu tiẹ naa sina nigba kan naa pẹlu oun, eyi to fa aawọ laarin awọn mejeeji.
Lojukoroju kii ṣe lori ayelujara nikan o!
End SARS, End SWAT: MC Oluomo ní òun kọ́ ló rán àwọn jàǹdùkú sáwọn olùwọ́de l'Eko
Tí ó bá rú u fún ìdúpẹ́, yóo rú u pẹlu àkàrà tí kò ní ìwúkàrà, tí a fi òróró pò, ati àkàrà fẹ́lẹ́fẹ́lẹ́ tí kò ní ìwúkàrà, tí a da òróró lé lórí, pẹlu àkàrà tí a fi ìyẹ̀fun kíkúnná ṣe, tí a fi òróró pò dáradára.
Ẹgbẹ́ ajàfúnẹ̀tọ́ ọmọnìyàn sọ wípé, àwọn tí ìjọba rán ní ẹ̀wọ̀n ní Íjípìtì á tó 60,000.
Ogbeni Emmanuel Kucha to jẹ adari eleto idibo lasiko naa fun ipinlẹ Kogi sọ pe idibo naa ko kẹsẹ jari bo ṣe yẹ nitori pe ibo 41, 353 lo wa laarin awọn mejeeji bẹẹ ibo 49, 953 ni wọn wọgile ni eyi to fi jẹ pe ibo ibuso idibo mọkanlelaadọrun un ni wọn ṣi nilo.
“Ẹ mọ oríṣìíríṣìí ọ̀nà tí eniyan fi í wá olólùfẹ́ kiri,tóbẹ́ẹ̀ tí ẹ ti fi ìrìnkurìn yínkọ́ àwọn obinrin oníwà burúkú.
Ló bá di igi ọ̀gẹ̀dẹ̀ tí í gb’ódò tí Yoòbá ní kìí y’àgàn.
1 40131 Orilẹede Kosovo 1106 59.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Lekan Kingkong: Níbikíbi tí mo bá wà, màá gbé àṣà Yorùbá ga Aarẹ ẹgbẹ naa, Ayuba Wabba to kede ọrọ naa lalẹ ọjọ Aje sọ pe, igbesẹ ti ẹgbẹ oṣiṣẹ gbe waye lẹyin ti awọn ati ijọba fẹnuko, ti wọn si fi ọwọ si iwe adehun.
ṣugbọn lójú àwọn tí Ọlọrun pè, ìbáà ṣe Juu tabi Giriki, Kristi yìí ni agbára Ọlọrun, òun ni ọgbọ́n Ọlọrun.
Ni bayii, naira marundinlaadoje ni wọn yoo maa ta jaala epo bẹtiro kan.
Asa ọba ní ọ̀kẹ́ mẹẹdogun (300,000) ọmọ ogun ní ilẹ̀ Juda, tí wọ́n di ihamọra pẹlu apata ati ọ̀kọ̀ ati ọ̀kẹ́ mẹrinla (280,000) láti Bẹnjamini tí wọ́n di ihamọra pẹlu apata ati ọrun.
Aṣẹ yii kan awọn ileeṣẹ aladani gbogbo, ile itaja nlanla atawọn ọja gbogbo.
Mane, atamatase ẹgbẹ agbabọọlu Liverpool lo kọkọ mi awọn nigba ti ifẹsẹwọnsẹ naa wọ iṣẹju kẹta amọṣa, Michael Keane daa pada nigba ti ifẹsẹwọnsẹ naa de iṣẹju kọkandinlogun.
Mo ní, “Èmi ìbá ní ìyẹ́ bí àdàbà!
” O fikun-un pe, boolu afesegba je ere-idaraya kan gbogi ti o se fowo yepere mu lawujo, o maa n fi aye ibasepo ti o donmonran sile laarin awon odo ati awon eniyan lapapo.
Nígbà tí Ṣaulu kú, Baali Hanani, ọmọ Akibori, jọba tẹ̀lé e.
BBC News, Yorùbá Ìdí tí ẹ fi le è nígbàagbọ́ nínú ìròyìn BBC Ìlànà Lílò Nípa BBC Òfin Àṣírí Cookies Kàn sí.
Ohun tí a ṣe kì í ṣe ọ̀rọ̀ ọpẹ́.
Osu Kini, ọdun 2020 ni ipinlẹ mẹfa ni ẹkun iwọ orun Naijiria fowosowọpo lati da eto aabo awarawa silẹ , amọ wọn nilo ofin lati gbe duro daadaa.
Burna Boy fẹ́ yọ̀ǹda owó tó bá pá lóde àríyá f'áwọn tó farakásá ìṣẹ̀lẹ̀ Xenophobia Awọn miran ni tohun ti bi awọn ko ti ṣe fẹran rẹ, ipa to ko ko ṣe e fọwọ rọ sẹyin Oríṣun àwòrán, Ibra_official Àkọlé àwòrán, Zlatan: Èyí mo ṣé tó, àsìkò tó láti tèsíwájú nínú ìrìnàjò mi Ibeere tawọn kan n bere ni pe ki gan an lo gbe ṣe nigba to wa ni LAGalaxy tariwo rẹ si wa pọ to bayii Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, World Diabetes Day: Ọdún kọkandinlogun ti mo ti wà lẹ́nu itọ ṣúgà nìyí Goolu mẹtalelaadọta ni Zlatan Ibrahimovic jẹ ninu ifẹsẹwọnsẹ mẹrindinlọgọta to ti kopa nigba to wa ni LA Galaxy.
Apá ìwọ́ oòrùn ni ilẹ̀ Ìjẹ̀ṣà wà ní ilẹ̀ Yorùbá tàbí káàárọ́ - oò- jíire.
abenugan tun tẹpẹlẹ mọ ojuse lati mojuto isoro to n dojukọ awọn obinrin ati
Awọn oniroyin ni yatọ si igbe aye rẹ gẹgẹ bii adari Sudan fun ọgbọn ọdun, awọn oun ti awọn eniyan mọ nipa idile rẹ ko pọ.
Aarẹ ẹgbẹ awọn dokita onimọ iṣegun oyinbo ni Naijiria, Dayo Duyile sọ fun BBC pe ẹgbẹ naa sọ fun ijọba pe ko ti to asiko to yẹ ki wsn dẹ ofin konile-o-gble nitori pe ko si nkankan to fihan pe Naijiria ti n bori aarun naa.
Bisi Alimi, ẹni to n dupẹ lọwọ Eleduwa fun ayẹyẹ igbeyawo rẹ pẹlu Davis, to pe ọdun mẹrin lọjọ Aiku.
Ṣugbọn o dori akayin o, ni akara ba tu sepo.
Èdè , èdè , èdè láìsí èdè , èèyàn kò sunwòn láwùjo .
Lẹyin ti Augustine Ayanfemi Phillips to jẹ ọkọ Iya Rainbow jẹ Ọlọrun nipe ni o darapọ mọ iṣẹ oṣere tiata ni kikun.
Nǹkan meji ni mò ń tọrọ lọ́wọ́ rẹ,má ṣe fi wọ́n dù mí kí n tó kú.
Awọn iroyin ti ẹ lee nifẹẹ si: Ọlọpa yoo pada maa sọ awọn eekan ilu 'A o s'awari akẹkọ Dapchi to sẹku' Ibrahimovic dagbere fun Man Utd Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
 Àwọn agbè tàbí ṣẹ ̀ kẹ ̀ rẹ ̀ wọ ̀ nyí máa ń tóbi jura wọn , kí dídún wọn bàá lè yàtọ ̀ síra .
" Iṣẹ agbẹ jẹ ọkan gboogi ninu eto ọrọ aje Uganda, nitori pe o n gba to ìdá aadọrin awọn eniyan orilẹede naa si iṣẹ.
 Ó sábà maa ń ṣsẹlẹ ̀ láàrin àwọn tí o ń gbé nínu òsì a sì gbàgbọ ́ pé o maa ń ràn nípa àwọn mímí tí o ń wáyé .
Ṣugbọn ó ń yan ẹnikẹ́ni tí ó bá wù ú láàrin àwọn eniyan ó sì ń fi wọ́n jẹ alufaa ní àwọn ibi pẹpẹ ìrúbọ káàkiri.
Oun tí a ní là ń náání.
Wolves bu Arsenal jẹ bí ajá Irú kan-ùn.
Nikola Kalinic se asise gba ami ayo kan miiran wonu agbon re, lati so apapo esi ifesewonse naa di ami ayo merin sodo.
Nígbà tí ó tó nǹkan bí agogo mẹta ọ̀sán, Jesu kígbe ní ohùn rara pé, “Eli, Eli, lema sabakitani?
Gbogbo igbiyanju wa lati ba alukoro ileeṣẹ ọlọpaa nilu Ibadan ja si pabo pẹlu bi ko ti ṣe gba ipe wa lori ero ibanisọrọ rẹ.
Kò gbọdọ̀ jẹ́ ẹni tí yóo máa ṣe ti inú ara rẹ̀, tabi kí ó jẹ́ onínúfùfù.
Saulu bá sọ fún un pé, “Má bẹ̀rù, sọ ohun tí o rí fún mi.
Jọ̀wọ́ dáríjì mí fún gbogbo àìṣedéédé mi.
Wọ́n jẹ́ aláìmọ́ fun yín ninu gbogbo ohun tí ń rìn lórí ilẹ̀, ẹnikẹ́ni tí ó bá fi ọwọ́ kan òkú wọn di aláìmọ́ títí di ìrọ̀lẹ́.
Ta ni Oba Idowu Abiọdun Oniru tó wàjà nípinlẹ̀ Eko?
Àkọlé àwòrán, Itan nla ni igbe aye D.
Àkọlé àwòrán, Ọrọ ti o kọju si ori ade de ibi pe, wọn fajuro to eyi Oro to n gbomije loju arugbo ti di nkan mii fun ọdọ lawujọ.
Ọba bá pe gbogbo àwọn olórí alufaa ati àwọn amòfin láàrin àwọn eniyan, ó wádìí nípa ibi tí a óo ti bí Kristi lọ́wọ́ wọn.
Àwọn ìdílé tí ó wà ninu ẹ̀yà Lefi nìwọ̀nyí: ìdílé Libini, ìdílé Heburoni, ìdílé Mahili, ìdílé Muṣi ati ìdílé Kora.
Yatọ si eyi, akẹkọọ 81,718 ni wọn ko ti i gbe esi idanwo wọn jade, nitori pe àṣìṣe wa lori rẹ.
ó ranṣẹ pada ó ní, “Ẹ sọ fún ọ̀gá yín pé OLUWA ní kí ó má jẹ́ kí iṣẹ́ tí ọba Asiria rán sí i pé OLUWA kò lè gbà á dẹ́rùbà á.
Ọ̀gágun náà bá pe meji ninu àwọn balogun ọ̀rún tí ó wà lábẹ́ rẹ̀, ó ní, “Ẹ lọ mú igba ọmọ-ogun ati aadọrin ẹlẹ́ṣin ati igba ọmọ-ogun tí ó ní ọ̀kọ̀.
Ni bayii, ipinlẹ Kogi naa ti darapọ mọ awọn ipinlẹ ti aarun naa ti wọ l''orilẹ-ede Naijiria.
Gbèsè niye èèyàn tó pọ̀ ní Nàìjíríà kìí ṣe dúkìá- Emir Sanusi Ajọ EFCC ni ara fu awọn pe owo ti wọn ri yii ṣeeṣe ko jẹ ninu owo tijọba ko silẹ lati na lasiko idibo to kọja.
Ekiti Decides: Buhari ni òun kọ́ ló rán àwọn darandaran nisẹ
Ṣugbọn nisinsinyii tí ẹ sọ pé, ‘Àwa ríran’ ẹ̀bi yín wà sibẹ.
Àwọn ta ni Ọlọrun bínú sí ní ogoji ọdún?
Nítorí náà, Ọlọrun ṣe àwọn agbẹ̀bí náà dáradára; àwọn eniyan Israẹli ń pọ̀ sí i, wọ́n sì ń lágbára sí i.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Àyà mi kọ́kọ́ máa ń já nígbà ti mo ṣẹ̀ṣẹ̀ bẹ̀rẹ̀ -Alaga iduro ọkùnrin Igbẹjọ ati idajọ iku fun awọn ọdaran ajọmọgbe: Ọkan lara awọn ẹlẹrii ninu igbẹjọ yii ni Aina Ola, ẹni to fọwọ gbaya pe Falayi lo ji Adediwura gbe sabẹ agbada rẹ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Baby abandoned on dunmpsite: Mo ti bímọ mẹ́rin tẹ́lẹ̀ fún bàbá méjì nínú òṣí- Dupe Ogbomos Makinde ni wiwa ti oun wa si aafin ni lati fihan fun awọn oni gboyi sọyi to sọ pe nitori ija to wa laarin oun ati Kabiyesi ni oun ko fi yoju sibi ayẹyẹ ọjọ ibi Kabiyesi.
Lara idagbasoke ti o tun farahan ninu ipade ohun, igbimo naa tun bowolu pipari ile eko otooto meji ati gbagede igba afe ni ipago awon olopaa ti o wa nipinle kano, eyi ti apapo owo ti won yoo lo je òjìlénígba dín mẹfa milionu owo naira (N234 million).
Wọ́n kó èso méjìlélọ́gbọ̀n sílẹ̀ tí ó dúró fún ọ̀kọ̀ọ̀kan àwọn orílẹ̀èdè tó ń díje nínú ife ẹ̀yẹ̀ àgbáyé.
Kí ló ń pa àwọn ọkùnrin lọ́wọọ̀wọ́ ní Kenya?
Ẹ ṣọ́ra, kí ẹ má baà sọ ninu ọkàn yín pé agbára yín, ati ipá yín ni ó mú ọrọ̀ yìí wá fun yín.
Wọ́n bá lọ ròyìn fún ọba Asiria pé àwọn eniyan tí ó kó lọ sí ilẹ̀ Samaria kò mọ òfin Ọlọrun ilẹ̀ náà, nítorí náà ni Ọlọrun ṣe rán kinniun tí ó ń pa wọ́n.
Oríṣun àwòrán, others Ilé iṣẹ́ tó n ri si ọ̀rọ̀ abẹ́le ní Naijria, to sì tún ṣe àmújúto kóòtù to n ṣe ìgbéyàwó ti paa láṣẹ pé kí wọ́n mú ìdádúró ba ètò ìgbéyàwọ́ ti wọ́n forúkọsílẹ̀ láti inú oṣù kẹta nítóri àjàkálẹ̀ ààrùn Coronvirus.
Gbogbo dukia ọhun ti apapọ owo wọn jẹ ogoji miliọnu dọla ni Onidajọ Nicholas Oweibo, ti ile ẹjọ giga ijọba apapọ to wa ni Ikoyi nipinlẹ Eko sọ pe ko di ti ijọba.
Iṣẹ ni iṣẹ n jẹ ni ọrọ awọn agba nilẹ ku ootu, oojiire bi?
Abdullahi Haruna to jẹ ọga agba ọlọpaa to n ṣe iwadii ọrọ yii ni iwadii ṣi n lọ lọwọ nitori iyalẹnu lo jẹ fun gbogbo eeyan.
 Lẹyin naa lo sọ siwaju si pe ọpọ eeyan lo ti ri iwosan gba lọwọ arun Covid-19 ninu ijọ oun."
" Sultan ìlú Sokoto pàṣẹ kí àwẹ̀ Ramadan ó bẹ̀rẹ̀ lẹ́yìn tí wọ́n rí oṣù Oríṣun àwòrán, AFP Lẹyin to kofiri oṣu tuntun to le , Sultan ti ilu Sokoto, Saad Abubakar ti kede pe awẹ Ramadan fawọn Musulumi yoo bẹrẹ lọjọ Ẹti.
Máa rọra, máa wolẹ̀, kíyèsí kòtò, kíyèsí pàǹtí, kíyèsí gegele òkúta.
Lasiko ti BBC Yoruba kan si adugbo naa, a ri pe aloku ẹrọ amu omi di yinyin, taa mọ si ‘Fridge’, ti ko sisẹ mọ, ati ọpọn iwẹ, taa mọ si ‘Bath Tub’, to ti bajẹ́, lawọn kan n lo lati gbe awọn eeyan kọja lori agbara omiyale naa.
BBC Yoruba ba àwọn to ti ni ìbáṣepọ̀ kan tàbi omíràn pẹ̀lú olóògbé Gbenga Adeboye, nígbà ayé rẹ̀ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fọ́nrán ohùn, Gbenga Adeboye:Àwọn olúlufẹ rẹ̀ sọ̀rọ̀ lóri ǹkan ti wọn pàdánù Lárá àwọn iṣẹ́ ti Gbenga Adeboye ti ṣe ni ọmọ Majẹmu, ọ̀rọ̀sùnnùkùn 1&2 Ph.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù La liga: Barcelona lè téńté orí tábìlì pẹlú àmì ayo mọ̀kànlá 7 Ìgbé 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Messi dti jẹ goolu 33 ni saa bọọlu ọdun yi nikan Ẹgbẹ agbabọọlu Barcelona ti le iwaju awọn akẹgbẹ rẹ lori afara La liga pẹlu ami ayo mọkanla ti wọn fi n ja awọn iyoku silẹ.
Ní orílẹ̀èdè Saudi Arabia, ìyàwó tó bá ń fẹ́ kọ ọkọ rẹ̀, tó sì fẹ́ gba owó ìdákọmu lọ́wọ́ ọkọ rẹ̀, gbọdọ̀ fi ẹ̀rí tó dájú sílẹ̀ pé ọkọ òun ń fi ìyà jẹ òun tàbí pé ó ń se àgbèrè níta.
Nítòótọ́, ìgbàlà rẹ̀ wà nítòsí fún àwọn tí ó bẹ̀rù rẹ̀;kí ògo rẹ̀ lè wà ní ilẹ̀ wa.
Ìná sì wọ̀, bàbá gé ẹran fún onítọ̀ún ló bá tún gbé ẹrù rẹ̀ lórí ló ń kiri lọ.
Ewe, eyi yoo tun ta iko agbaboolu Super Eagles ji, lati lo soju orile-ede yii daradara lorile-ede Russia, ki won ko si gba ife-eye ohun pada wa sile.
Ojúlówó wúrà ni Solomoni fi bo gbogbo inú ilé ìsìn náà, wọ́n sì so ẹ̀wọ̀n kan, ó fi dábùú ẹnu ọ̀nà ibi mímọ́ ti inú, ó sì yọ́ wúrà bò ó.
Ojú pópó ni mo dàgbà sí àmọ́ n kò mu igbó, sìgá tàbí ọtí líle rí - MC Oluomo Ọ̀rọ̀ Sotitobire tí a dá sí, àwọn aṣòfin àtàwọn àjọ kan ló fi lọ̀ wá- DSS Iṣẹ́ ọpọlọ ló yẹ ká ṣe nínú tíátà, kìí ṣe àfihàn ara bíbó àbí ìhòòhò wa - Binta Mọgaji ₦35,000 ni mò ń gbà bíi Adelé ọba, kò sí ọkọ̀ ayọ́kẹ́lẹ́ - Adelé Olúbọ̀rọ̀pa Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Idije ju idije lọ Atrhletico ṣapa lati da goolu kan pada ṣugbọn pabo ni igbiyanju wn jasi.
jẹ́ kí á gbé wọn mì láàyèkí á gbé wọn mì lódidi bí isà òkú,
Ẹwẹ, kii ṣe ọrọ oni tabi ana ni iru iṣlẹ bayii ti n waye laarin awọn oṣere Yoruba ni Naijiria ko da nigba miiran, kii ṣe laarin awn ọdọ nikan fun idi kan tabi omiran.
Oríṣun àwòrán, others Atẹjade naa sọ pe nigba naa ni ikọ kan to n jẹ Operation Puff-Ader toju bọ ọrọ naa."
Ó ń fi ọwọ́ ha ìlẹ̀kùn ojú ọ̀nà ààfin, ó sì ń wa itọ́ sí irùngbọ̀n rẹ̀.
Ẹ yin Ọlọrun wa, ẹ̀yin orílẹ̀-èdè,ẹ jẹ́ kí á gbọ́ ìró ìyìn rẹ̀;
Igi tí o rí, tí ó dàgbà, tí ó lágbára, tí orí rẹ̀ sì kan ọ̀run dé ibi pé gbogbo eniyan lè rí i, 
Èyí èkejì fi ayé sílẹ̀ kí ó tóó di ìgbà tí Olódùmarè dá fún un: ó lójú kò fi ríran; ó ní ọgbọ́n kò lò ó; ó sì fi òmùgọ̀ ba ìgbésí-ayé ara rẹ̀ jẹ́.
Eyitayo Jegede, igabkeji gomina ipinlẹ Ondo, Agboola Ajayi atawọn mii lo n kopa ninu idibo abẹle naa lati le e dupo dije ninu idibo sipo gomina ti yoo waye loṣu kẹwaa ọdun 2020.
bí a bá ń sọ ̀ rọ ̀ nípa ìmọ ̀ ẹ ̀ rọ láwùjọ yorùbá bí a kò mẹ ́ nu bà isẹ ́ alágbẹ ̀ dẹ , a jẹ ́ pé àlàyé wa kò kún tó .
Iranṣẹbinrin Lea tún bí ọmọkunrin mìíràn fún Jakọbu.
Esi naa ti ajọ NCDC fi sori ayelujara Twitter rẹ fihan pe Lagos-71 Imo-26 Plateau-26 FCT-19 Ondo-17 Kaduna-14 Rivers-9 Oyo-9 Katsina-6 Osun-4 Bauchi-2 Ekiti-2- Nasarawa-2 Ogun-2 Kano-1 Kwara-1 Taraba-1 Coronavirus ran èèyàn 180 míì ní Nàìjíríà ní 11/11/2020 Apapọ awọn to ni coronavirus ni Naijiria ti pe 64,515 bayii.
Timothy Omotosho, to jẹ oludasilẹ ijọ Jesus Dominion International church l'orilẹede South Africa, ni wọn sọ fun l'Ọjọbọ pe, gbigbe rẹ ni orilẹede naa ti tako ofin bayii.
NLC: A fẹ́ kí ìjọba bẹ̀rẹ̀ sí san owó oṣù tuntun kíákíá Ayé le, ìbòsí ò!
fun iderun awon osise Ipinle naa.
 lẹyin tí àpá bá ti wà lára ìpéǹpéjú , ó máa nílò kí wọn fi iṣẹ ́ -abẹ ṣe àtúnṣe ipò tí awọn irun-ìpéǹpéjú wà lati dènà ìfọ ́ jú .
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Alao Akala:Èmi àti Ajimọbi kò ṣe ìlérí kankan fún ara wa Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 3 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 5 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Ruga Settlement: Kí ló ń mú ìkùnsínú wá ?
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Coronavirus Pandemic: Màmá Guardiola d'olóògbé lẹ́yìn tó lùgbàdì Coronavirus 6 Ìgbé 2020 Oríṣun àwòrán, Instagram/Per Guardiola Afẹfẹ aarun coronavirus to n fẹ kaakiri ti fẹ de idile akọnimọọgba ẹgbẹ agbabọọlu Manchester City,Pep Guardiola.
”Dafidi dáhùn pé, “Ọmọ Jese ni mí, iranṣẹ rẹ, tí ń gbé Bẹtilẹhẹmu.
 Ọṣìn tàbí Ọlọ ́ jà ni à ń pe olórí Ìjẹ ̀ bú-Òde .
Ọkunrin náà lọ sọ́dọ̀ ọmọ keji, ó sọ fún un bí ó ti sọ fún ekinni.
Lojo kejo osu keta, Aare Donald Trump fowo si atejade kan, eyi ti o fi gbe ofin sisan owo ori-oja irin ti o ba wole, lagbami aigbra-eni ye latodo awon alajosowopo kaakiri agbaye.
Ọba Lamidi Adeyẹmi, òṣìṣẹ́ adójútòfò àti Abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò kó tó jọba Kí ló ń ṣẹlẹ̀ láàfin Oyo táwọn èèyàn fi ń ki Alaafin ní mẹ́sàn án mẹ́wàá?
 odù ifá àti àwọn ẹ ̀ sẹ ̀ ifá tí wọ ́ n pín sí tún dá lórí ìmọ ̀ ìjìnlẹ ̀ nípa ayé , òdodo , tí ó kún fọ ́ fọ ́ fún àlàyé níoa àyànmọ ́ ẹ ̀ dá òun ọ ̀ nà ibùlà fún ọmọ adáríhurun .
Lẹ́yìn tí Amasaya, ọba Juda, ṣe àpérò pẹlu àwọn olùdámọ̀ràn rẹ̀, ó ranṣẹ sí Jehoaṣi ọmọ Jehoahasi, ọmọ Jehu, ọba Israẹli pé, “Wá, jẹ́ kí á kojú ara wa.
Gẹ́gẹ́ bí ìlànà ti òfin, ó fẹ́rẹ̀ jẹ́ pé gbogbo nǹkan pátá ni à ń fi ẹ̀jẹ̀ sọ di mímọ́, ati pé láìsí ìtasílẹ̀ ẹ̀jẹ̀ kò lè sí ìdáríjì ẹ̀ṣẹ̀.
Oríṣun àwòrán, @dondekojo Nigba to n fi ijọba Buhari we ti Sani Abacha, Ọbasanjọ ni o yẹ ki awọn ọmọ Naijiria dide lati se ohun ti wọn se lasiko ijọba Abacha, to fi mọ awujọ agbaye pẹlu.
Wọ́n ń lo ohun ọ̀ṣọ́ wọn dáradára fún ògo asán; òun ni wọ́n fi ń ṣe àwọn ère ati oriṣa wọn, àwọn ohun ìríra tí wọn ń bọ.
Ẹ̀yin tí ẹ ti di òkú nípa ẹ̀ṣẹ̀ yín, tí ẹ jẹ́ aláìkọlà nípa ti ara, ni Ọlọrun ti sọ di alààyè pẹlu Kristi.
NGARSA: Ọmọ Nàìjíríà ń retí ifẹ ẹ̀yẹ lọ́dọ̀ yín
Mo ha gbọdọ̀ ṣọ̀fọ̀ ẹ̀yin mejeeji lọ́jọ́ kan náà bí?
Nígbà tí Jesu tún rékọjá lọ sí òdìkejì òkun, ọpọlọpọ eniyan wọ́ jọ pọ̀ sọ́dọ̀ rẹ̀ lẹ́bàá òkun.
Reubẹni ni àkọ́bí Jakọbu, (Ṣugbọn nítorí pé Reubẹni fẹ́ ọ̀kan ninu àwọn obinrin baba rẹ̀, baba rẹ̀ gba ipò àgbà lọ́wọ́ rẹ̀, ó sì gbé e fún àwọn ọmọ Josẹfu.
Gorillas in Nigeria: Orí àwọn Ìnàkí náà kéré, ọwọ́ wọn gùn, tí irun wọn sì funfun
O jẹ ọkan lara awọn ti obinrin ko si lee fi oju kere nipa ti ẹwa.
Bakan naa ni Agbẹnusọ ileeṣẹ ọlọpaa ni ipinlẹ Ogun, Abimbola Oyeyemi sọ fun ileeṣẹ BBC pe awọn gba ipe to le ni igba lati ọdọ awọn araalu pe o le n ja, ti ko si si otitọ kankan ninu rẹ.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: ‘N5000 ni wọ́n ta ìbò Ondó,Edo àti Anambra’ Inec y'orukọ ajeji kuro ninu iwe idibo Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Bawo ni iforukọsilẹ awọn oludibo se n lọ pelu ajọ INEC?
Àwọn ọmọ ogun àwọn ọ̀tá jáde láti inú ìlú láti bá àwọn ọmọ ogun Joabu jà.
Ṣaa ti mu iwe ẹri ileeṣẹ to n fun ni laṣẹ idokoowo ni Naijiria CAC lọwọ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Paul Sodje: Ọjọ́rùú ló yẹ kó pé ẹni ọdun 55, amọ́ tó kú ikú àìròtẹ́lẹ̀ 10 Owewe 2020 Oríṣun àwòrán, Others Adari ikọ ere idaraya Scrabble ni Naijiria tẹlẹri, Paul Sodje ti ku lẹyin ti awọn afurasi darandaran ji gbe.
Tẹlẹ ni Ọga ọlọpaa ana, Ibrahim Idris gbe ẹka ileeṣẹ ọlọaa SARS sabẹ igbakeji Ọga Agba Ọlọpaa.
Wọn bẹrẹ si na Nnamdi, Solomon ati Ndubuisi.
Bẹ́ẹ̀ ni Jehoṣafati ṣe bẹ̀rẹ̀ sí lágbára sí i, ó kọ́ àwọn ilé ìṣọ́ ati àwọn ìlú tí wọn ń kó ìṣúra pamọ́ sí ní Juda; 
Joy Nunieh: Tani adarí àjọ NDDC tẹ́lẹ̀ to fẹ̀sùn jegúdújẹrá kan Godswill Akpabio?
Nkan tó tún ṣeni láàánú ni pé tálíkà paraku ni gbogbo àwọn ènìyàn wọ̀nyí jẹ́.
Ẹ̀mí kan náà ló n darí ìrìnàjò wa táa fi jọ kọ́lé papọ̀- Ìbejì
Jesu dá wọn lóhùn pé, “Iṣẹ́ Ọlọrun ni pé kí ẹ gba ẹni tí ó rán gbọ́.
Wọ́n kúrò níwájú Pi Hahirotu, wọ́n la ààrin òkun kọjá lọ sinu aṣálẹ̀.
Ṣugbọn bí eniyan bá fi wúrà tí ó wà ninu Tẹmpili búra, olúwarẹ̀ níláti mú ìbúra rẹ̀ ṣẹ.
Ẹgbọn baba rẹ to ba BBC sọrọ, Arakunrin Sarafa Arowolo, sọ pe okuta kan ninu odo naa lo da oku ọmọ naa duro lati ibi ti omi ti n gbe bọ.
Wọ́n ń sọkún lórí ibùsùn wọn, ṣugbọn ẹkún tí wọn ń sun sí mi kò ti ọkàn wá; nítorí oúnjẹ ati ọtí waini ni wọ́n ṣe ń gbé ara ṣánlẹ̀; ọ̀tẹ̀ ni wọ́n ń bá mi ṣe.
Lasiko ti Olusola n dabira lati gbe aṣa, ede ati ìṣe Yoruba larugẹ, ni iku ja ẹmi rẹ gba lairo tẹlẹ lasiko aisan ranpẹ lẹni aadọta ọdun, ni ọjọ kejidinlọgbọn, oṣu Kejila, ọdun 1992.
”Musa Shuabu wa dupe lowo gbogbo awon ile-ise ati ajọ fun atileyin won  lati bi odun màrúndínlógún seyin lati gbogun ti itankale aarun kogboogun lorile ede Naijiria, bi o tile je pe awon ipenija kan wa to n koju ajo naa.
Bakna naa ni Isa jẹ ọkan lara awọn to kọkọ lọ si ileewe ẹkọṣẹ ijọba ti Federal Training Centre, Kaduna ati ile iwe giga ti Zaria.
 Awon Asofin orile-ede naa ti fun won ni milionu lona ogorun un owo ile naa, eyi to tumo si eedegberin le ni merinle logoji egberun owo dola fawon ebi oloogbe.
Aisaya náà kéde nípa Israẹli pé, “Bí àwọn ọmọ Israẹli tilẹ̀ pọ̀ bí iyanrìn òkun, sibẹ díẹ̀ péré ni a óo gbà là.
Àwọn tí wọ́n dúró níbẹ̀ bá ní, “Olórí Alufaa Ọlọrun ni ò ń bú bẹ́ẹ̀?
com/yoruba/afrika-46744382 Kádàrá ní ọ̀rọ̀ ẹ̀dá láyé, Mo gbà pé Ọlọrun ló kọ ikú ọkọ mi ni Saudi Àkọlé àwòrán, Kádàrá ní ọ̀rọ̀ ẹ̀dá láyé, Mo gbà pé Ọlọrun ló kọ ikú ọkọ mi ni Saudi Yetunde Raji jẹ obinrin ti igbe aye rẹ yi pada si bi ko ṣe lero lẹyin ti oun ati ọkọ rẹ wa ninu ijamba ọkọ to waye ni orilẹede Saudi Arabia.
” Ó ti obinrin náà pada sinu agbọ̀n eefa náà, ó sì fi ìdérí òjé náà dé e mọ́ ibẹ̀ pada.
Saaju ni ileegbimọ aṣofin ni ipinlẹ naa ti buwọlu ofin to rọgba yii ka ati pe igbagbọ awọn ni pe iṣejọba gomina Seyi Makinde ko ni tọ ipasẹ rẹ.
Ọjọ kinni osu kesan ọdun 2020 si ni ele owo naa yoo bẹrẹ, eyi tii ṣe afikun ẹẹkeji laarin oṣù mẹrin pere.
''Awa ni igbagbọ ninu ẹka eto idajọ Naijiria ,awọn kan ṣi wa nibẹ ti wọn jẹ olootọ.
A gbọ pe lasiko ti wọn fẹ bẹrẹ si gbe eto safẹfẹ lori redio Fresh FM ni isẹlẹ naa waye, ti wọn si tete ti ileesẹ redio naa pa.
" wọn tọ ́ ka sí àkọsílẹ ̀ kan tí ọjọ ́ rẹ ̀ ti pé jọjọ tí ń jẹ ́ "" kano chronicles "" ."
Olukọ kan ati akẹkọ kansoso ni ori ko yọ ninu ijamba mọto naa.
Àwọn ìlú ńláńlá ati àwọn ìlú kéékèèké tí ó wà ninu ilẹ̀ náà jẹ́ ìpín ẹ̀yà Reubẹni gẹ́gẹ́ bí iye ìdílé wọn.
Ṣé ìrètí wà pé coronavirus yóò dínkù lásìkò ooru?
Lara  awọn  to soju orilẹ ede  Naijiria ni akowe agba, fun  ajo irinna Sabiu Zakari , alaga igbimo asofin fun  ọrọ  to je mo ti ofurufu, asofin  Adamu Aliero, alaga igbimo  asoju fun  ọrọ  to je mo ti ofurufu, arabinrin Nkeiru  Onyejiocha.
Gbogbo wọn ati àwọn iyawo wọn ati àwọn ọmọ wọn sìn wá dé ẹ̀yìn odi.
Koda, adari ile Sẹnẹtọ Bukọla Saraki naa yoo dagbere fun ile aṣofin lẹyin to fidi rẹmi ninu idibo gbogboogbo to lọ.
jẹ́ ẹgbaa mọkanlelọgbọn ó lé ẹẹdẹgbẹrin (62,700).
Ọgbẹ́ ọ̀hún tó ohun tí ó yẹ kí ó pa á ṣugbọn ó ti jinná.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Adédèjì: Ìse ilé ló gbé ọlọ́pàá tó ń gba rìbá dé ìta Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Adédèjì: Ìse ilé ló gbé ọlọ́pàá tó ń gba rìbá dé ìta 30 Ìgbé 2018 Adéwọlé Adédèjì Julius jẹ́ agbẹjọ́rò, tó sì tún jẹ́ ọlọ́pàá tí kìí gba àbẹ̀tẹ́lẹ̀.
Èyí ni yóo jẹ́ ẹ̀rí ìparun wọn, yóo sì jẹ́ ẹ̀rí ìgbàlà yín.
Ẹni tí n óo kà kún,ni onírẹ̀lẹ̀ ati oníròbìnújẹ́ eniyan, tí ó ń wárìrì nítorí ọ̀rọ̀ mi.
Chris Ndukwe and Olamide Alli: Ọkùnrin kan gún àfẹ́sọ́nà rẹ pa, òun náà gbé ògùn jẹ
Nígbà tí kìnnìún yìí dé ibi ti aṣọ yìí wà ó fi imú rùn ún, ó fi ẹnu rẹ̀ yí i, ẹ̀jẹ̀ sí bá aṣọ náà lára bálabála.
Inec ti saaju dawọ kika ati ikede ẹni to jawe olubori ninu idiboipinlẹ Bauchi ki ile ẹjọ to paṣẹ ki wọn da duro.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Yemi Adenuga: Olùdìbò Ireland kìí gba ìrẹsì, àmọ́ wàá dé ilé kọ̀ọ̀kan láti bèèrè ìbò Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Yemi Adenuga: Olùdìbò Ireland kìí gba ìrẹsì, àmọ́ wàá dé ilé kọ̀ọ̀kan láti bèèrè ìbò 27 Ògún 2019 Agbohunsafẹfẹ ni Yemi Adenuga lorilẹede Naijiria ko to lọ tẹdo si orilẹede Ireland lọdun 2000.
Lapapọ wọn ti ile iṣẹ orileede Naijiria mẹta pa.
N óo sọ ọ̀fọ̀ wọn di ayọ̀,n óo tù wọ́n ninu, n óo sì fún wọn ní ayọ̀ dípò ìbànújẹ́ wọn.
Má bẹ̀rù wọn,nítorí mo wà pẹlu rẹ, n óo sì gbà ọ́.
Ẹ sọ ọ́ ní Juda,ẹ sì kéde rẹ̀ láàrin Jerusalẹmu pé,“Ẹ fọn fèrè káàkiri ilẹ̀ náà,kí ẹ sì kígbe sókè pé,‘Ẹ kó ara yín jọ kí á lọ sí àwọn ìlú olódi.
"Amọṣa o ni kete ti oun ba ti darapọ mọ awọn alalẹ, ""ẹni to ba dantọ ni ki wọn yan si ipo naa"" lẹyin oun."
Osoba so eyi lasiko to n fi lede wi pe ọrọ Naijiria ko nii se pẹlu atunto orilẹede, afi ki awọn Naijiria dide lati gba ara wọn.
Wọn gbe e de ileewosan ijọba apapọ to wa nilu Owo, nibi to ti dagbere faye.
O ni ipinnu Naijiria yi ko ṣẹyin bi awọn orile-ede kan ti ṣe kọdi ọkọ ofurufu lati Naijiria si ilẹ wọn paapa julọ awọn ilẹ to wa ni ajọ Yuroopu (EU) Ipinnu ṣe fun mi ki n ṣe fun ọ yi ko ṣẹṣẹ maa waye laarin Naijiria ati awọn ilẹ miran.
Oríṣun àwòrán, @ProfOsinbajo Àkọlé àwòrán, Ọmọ kìí dàgbà lójú òbí ré, ìyá ni wúrà iyebiye ti a kò le fi owó rà Oríṣun àwòrán, @ProfOsinbajo Àkọlé àwòrán, Osinbajo a máa tẹti gbọrọ.
Ó fi oúnjẹ tí ó dára bọ́ àwọn tí ebi ń pa,ó mú àwọn ọlọ́rọ̀ jáde lọ́wọ́ òfo.
Bakanna ninu iwe eto isejọba naa Aarẹ Buhari ni awọn yoo pari afara 2nd Niger, ọna ọkọ ọju irin to lọ lati Eko si Ibadan titi de Kano,ti Eko si Calabar ati awọn miran.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù TOT vs CHE:Lampard tẹ ojú ọ̀gá rẹ̀ mọ́lẹ̀, ayò meji sodo ló kó lé Mourinho lọ́wọ́ 22 Ọ̀pẹ̀̀ 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Ibi tagbalagba Jose Mourinho de duro,ọmọde Frank Lampard to figba kan jẹ akọnimọọgba fun ti ba pẹlu bi Chelse ti ṣe da bantẹ iya ayo meji sodo fun Tottenham rẹ.
A máa fi àwọn pẹ̀gànpẹ̀gàn ṣe ẹlẹ́yà, ṣugbọn a máa fi ojurere wo àwọn onírẹ̀lẹ̀.
Mẹta ninu awọn eeyan ọhun wa ni Abuja ti ẹnikan to ku si wa ni ipinlẹ Eko.
- Trump Ìṣọ̀rí Amotekun táa pè ní ‘Irúnmọlẹ̀’ ní yóò máa gun ọ̀kadà kiri láti pèsè ààbò - Àjọ Dawn Ṣé lílo ìbòjú tàbí ìbòmú lèé dènà kíkó àjàkálẹ̀ àrùn?
Awọn onimọ kan nipa oṣelu ti ẹ sọ pe awọn olori tuntun naa gbọds bẹrẹ ijiroro pẹlu awọn adari ẹgbẹ ni gbogbo ipinlẹ, lati wa ọna ti iṣọkan yoo gba pada sinu ẹgbẹ.
Wọn kede iku igara ọlọsa ajinigbepawo Bobosky ti wọn mu lọjọ Abamẹta.
" lẹ ́ yìn ìgbà tí àwọn fascist rìn lọ sí róòmù ní 1922 ( "" fascist march on rome ' ) , Ọba victor emmanuel iii pe mussoline láti wá gbé ìjọba tirẹ ̀ kalẹ ̀ ."
Mo ronú jinlẹ̀ lóru,mo ṣe àṣàrò, mo yẹ ọkàn mi wò.
Ẹni tí ó bá fẹ́ràn mi, Baba mi yóo fẹ́ràn rẹ̀, èmi náà yóo fẹ́ràn rẹ̀, n óo sì fi ara mi hàn án.
Kí o lè ranti, kí ìdààmú sì bá ọ, kí ìtìjú má jẹ́ kí o lè lanu sọ̀rọ̀ mọ́; nígbà tí mo bá dárí gbogbo ẹ̀ṣẹ̀ rẹ jì ọ́.
a tún ń àwọn ẹ ̀ ṣọ ́ tí ó ń dáàbò bo ọba àti ìlú .
Sẹnẹtọ Ndume ni adisọkan oun ni bi ile aṣofin yoo ṣe ni ominira tirẹ ti ko si ni si wi pe eeyan kan yoo ma dunkoko mọ awọn aṣofin nidi iṣẹ wọn.
com/twitter Lasiko to n ba awọn akọroyin sọrọ nile ijọba, Ifeyinwa sọ pe oun dupẹ lọwọ gomina Ortom to ba wọn da si ọrọ naa.
Sugbon lai dena penu, awọn ta ba pade nileesẹ ọlọpa so pe, ede aiyede ni ohun to sele yi, to si ye ka yanju re lai si wahala kankan.
Orilẹ-ede Naijiria, Ghana, Liberia ati Senegal ni orilẹ-ede mẹrin ti awọn eniyan ti lanfani lati mu ọkan.
Bí ẹnìkan kò bá gbà yín sílé, tabi tí kò bá fetí sí ọ̀rọ̀ yín, ẹ jáde kúrò ninu ilé tabi ìlú náà, kí ẹ gbọn eruku ẹsẹ̀ yín sílẹ̀.
Ọwọ́ ta ni OLUWA ti gba ìmọ̀ràn tí ó fi ní òye,ta ló kọ́ ọ bí wọ́n ṣe ń dájọ́ ẹ̀tọ́,tí ó kọ́ ọ ní ìmọ̀,tí ó sì fi ọ̀nà òye hàn án?
Aare ajo to n ri si boolu afesegba lorile-ede Naijiria, Amaju Pinnick, ti kede pe, won yoo samulo ero igbalode Fonran ti a mo si, Video Assistant Referee (VAR) ninu ifesewonse olorejore ti yoo waye laarin iko agbaboolu Super Eagles ati orile-ede England lose to n bo ni papa isere Wembley.
Àkọlé àwòrán, Kano Sharia Police: Ènìyàn Kano ọgọ́rin lo ti dèrò ẹ̀wọ̀n nítorí wọn jẹun nínú.
Nibayi, awọn alaṣẹ ti fi ẹsun pipa ọmọ ti, ati igbiyanju lati ṣekupani kan iya ọmọ naa nile ẹjọ.
A gbé ọjọ́ mẹ́ta ní ààfin ọba yìí, nígbà tí mo wí fún un pé mo fẹ́ẹ́ lọ sí ilé kí n baà tètè lọ rí ìyàwó mi àti ọmọ rẹ̀ tuntun, òun náà sì gbà bẹ́ẹ̀ fún mi, ṣùgbọ́n bi kò bá sí ti ìyàwó mi ni kì bá tí jẹ́ kí n lọ nítorí ó ti wí fún mi ní ijọ́sí pé kí n máa gbé ọ̀dọ̀ òun.
 orúkọ yìí ni ó si fi lọ fi owó pamọ ́ sí báǹkì .
Awọn ajihinrere - Awọn to wa ni ẹka yii lo ma n kede ihinrere kaakiri lati jere ọkan fun Jesu.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Alao Akala: Èmi àti Ajimọbi kò ṣe ìlérí kankan fúnra wa Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Alao Akala: Èmi àti Ajimọbi kò ṣe ìlérí kankan fúnra wa 7 Sẹ́rẹ́ 2019 Gomina nigbakan ri fún ipinlé Oyo ni òun kọ ki Ajimọbi pa oun rẹ nínú ìṣelu.
Awakọ̀ òfúrúfú Agba, John Ojikutu sọ fun ikọ BBC wi pe, papakọ ofurufu mẹrindinlọgbọn lo wa ni orilẹede Naijiria, eyi ti ijọba apapọ, ijọba ipinlẹ ati awọn aladani da silẹ.
Ǹkan ti àjọ eleto ìdìbò ṣe ni pé wọn tẹ̀lé ìdájọ ilé ẹjọ to ga julọ tó jẹjọ náà ni ọjọ jimọ, èyí to sọ pe ìbò ẹgbẹ́ òṣèlú APC ni ]ipínlẹ̀ náà ko fẹsẹ múlẹ̀ ni ìpínlẹ̀ náa.
Coronavirus tún gbẹ̀mí dókítà míì l'Ondo Kò sí àjòjì darandaran kankan ní Nàìjíríà -NIS Akẹ́kọ̀ọ́ méjì tó há sí Bosnia ti gúnlẹ̀ padà sí Nàìjíríà Afunrasí ẹ̀sùn jìbìtì ló ni iléeṣẹ́ tó ń ṣe ìwé àṣẹ wọléwọ̀de ní Nàìjíríà BBC beere pe ṣe iru irinajo yi ko dẹru ba NMA pẹlu ewu to wa lasiko yi ti arun Covid-19 n ja ranyin-ranyin lagbaye.
Maharaji ní èyí se pàtàkì gẹ́gẹ́ bi àwọn ẹlẹ́sìn àti olóri ẹ̀sìn to kù ṣe ń kùnà, ó ní ọ̀kan nínú àwọn èròńgbà òun ni pe kí ààrẹ yan òun láti máá moju to ile iṣẹ́ ọ̀rọ̀ omi àti àlùmọ́ni, ilé iṣẹ́ ọ̀gbìn àti ọ̀rs epo rọ̀ọ̀bi àti afẹ́fẹ́.
Ó dàbí òwe Yorùbá kan “Ọwọ́ kò ní lọ sẹ́ nu kó má padà”.
oludari egbe oselu to kere julọ.
Àwọn òṣèré Nollywood tí wọn ò sí lóri amóhùmáwòrán mọ́ Ǹjẹ́ o mọ àwọn òṣèré bí Oyin Adejọbi, Funmi Martins àtàwọn míì tó ti dágbére fáyé?
Lọjọ Aje ni Buhari buwọlu owo iṣuna naa to ku diẹ ko pe triliọnu mẹsan an Naira (8.
Ni ọjọ kẹrinla, oṣu kini ọdun 1988 ni wọn fi Abiọla jẹ oye aarẹ ọna kakanfo.
pé kí ó sọ fún àwọn ọmọ Israẹli pé, “Ẹnikẹ́ni ninu wọn ati àwọn àlejò, tí wọn ń ṣe àtìpó ní ààrin wọn tí ó bá fi èyíkéyìí ninu àwọn ọmọ rẹ̀ fún oriṣa Moleki, pípa ni kí wọ́n pa á; kí àwọn eniyan ilẹ̀ náà sọ ọ́ ní òkúta pa.
Nwankwo  lo kede abajade esi idibo naa, o
O fi kun pé, ó pọn dandan lati gbìyànjú lati jẹ́ asoju rere fún ẹ̀sìn musulumi àti orílẹ̀-èdè yìí, nípa híwu ìwà tó kógojá ni àyíká wọn.
Bakan naa lo jẹ minisita ati ọmọ igbimọ oluṣakoso ninu ijọba apapọ lẹẹmeje laarin ọdun 1958 si 1975.
ni yoo maa fori-gbari ninu eto idibo yii, iye egbe oselu yii lo ti pọju lati
bí ẹ bá Pẹ̀gàn àwọn ìlànà mi, tí ọkàn yín sì kórìíra ìdájọ́ mi, tóbẹ́ẹ̀ tí ẹ kọ̀ láti pa àwọn òfin mi mọ́, tí ẹ̀ ń ba majẹmu mi jẹ́, 
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Badagry ní ogún àjogúnbá tó pọ̀ yàtọ̀ sí òwò ẹrú Ọga aṣọbode ọhun ni ajọ naa ko ṣetan lati ṣi ẹnu ibode to wọle si orilẹ-ede yii.
Ó wọ́ mi kúrò lójú ọ̀nà mi,ó fà mí ya pẹ́rẹpẹ̀rẹ,ó sì ti sọ mí di alailẹnikan.
Ọlọrun ko si ni fi iya jẹ.
Amẹrika àti Faranse fẹnu ọ̀rọ̀ jóná lórí Iran Ilé ijọsin Notre-Dame jẹ ikan lara awọn ile awo-dami-ẹnu to lokiki julọ ni Paris.
Ṣe ìlérí ìrànlọ́wọ́ fún ire èmi iranṣẹ rẹ,má sì jẹ́ kí àwọn onigbeeraga ni mí lára.
Wọ́n tì í kúrò lọ́dọ̀ wọn; ọkàn wọn tún pada sí Ijipti.
Ayé ni oko tí ó fúnrúgbìn sí.
"Gẹ́gẹ́ bi ọkùnrin tó ni ìpèníjà ara náà, Olumuyiwa Bolade Adedeji ṣe sọ fun akọroyin BBC niluu Ibadan, ""Pasitọ̀ ni mi, oluṣiro owo si ni mi pẹlu."
" Ti ẹ ko ba jẹ osere, iṣẹ wo lẹ ba ṣe?
Ẹ wo bí a ti ń se ilá alásèpọ̀ aládùn!
 Àwọn ísótòpù kárbọ ̀ nù mẹ ́ ta ni wọ ́ n wà fún ra wọn , c àti c jẹ ́ dídúró , nígbàtí c jẹ ́ onítítànyindin , tóúntúká díẹ ̀ díẹ ̀ pẹ ̀ lú àsìkò àbọ ̀ -ìgbéayé tó tó bíi ọdún 5,730 .
wọ́n ń wí pé, ‘Dájúdájú, àwọn ọ̀tá wa ti parun,iná sì ti jó gbogbo ohun tí wọ́n fi sílẹ̀.
Ọrọ yi mu ikunsinu wa fun awọn eeyan Ilorin paapa julọ awọn ti wọn kọrin o to gẹ fun Saraki.
Mission (CBM) lati orilede United Kindom se onigbowo re pelu ajosepo ile itoju
Ohùn ẹni tí ń kígbe ninu aṣálẹ̀ pé, ‘Ẹ la ọ̀nà tí Oluwa yóo gbà,ẹ ṣe é kí ó tọ́ fún un láti rìn.
 Eleyii ni wọn yoo ṣe alekun rẹ pẹlu awọn ibudo idibo ẹgbẹrun mẹjọ ati ọtalenirinwo-le-meji (8,462) to wa ni ipnlẹ Eko fun eto idibo gbogboogbo ọdun 2019.
Ile ẹjọ ni gẹgẹ bi ajọ EFCC ṣe sọ ọ, ọns ti Patience gba ri owo naa lodi si abala ofin ikẹtadinlogun to ni ṣe pẹlu jiji owo atawọn ẹsun mii to fara pẹ ẹ.
Atọ́kùn ètò bi i pé, ìgbàwo ni kí àwọn penpiypan ni sùúrù dà lórí ọ̀rọ̀ ètò ààbò tó mẹ́hẹ ni Nàìjíríà.
Ijọba kede pe oun yoo pin oúnjẹ fun awọn araalu.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Teachers‘ new salary in Nigeria: Wike ní owó oṣù tuntun fáwọn olùkọ́ tí Buhari kéde yóò dá aáwọ̀ sílẹ̀ 6 Ọ̀wàrà 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 13 Ọ̀wàrà 2020 Oríṣun àwòrán, Facebook/Nyesom Wike Gomina ipinlẹ Rivers, Nyesom Wike ja gudugbẹ ọrọ lulẹ lẹyin to sọ pe akanṣe owo oṣu fawọn olukọ ti ijọba apapọ kede rẹ laipẹ yii yoo da aawọ silẹ lẹka eto ẹkọ ni Naijiria.
Oríṣun àwòrán, Ololufe BBC Àkọlé àwòrán, Ike ni arakunrin yii fi ṣe ibomu ni ti wọn Oríṣun àwòrán, others Àkọlé àwòrán, Àwọn àràmọ̀ndà ìbomú-bẹnu tó gbòde lásìkò Coronavirus yìí Oríṣun àwòrán, ololufe BBC Àkọlé àwòrán, Awọn ti le wọ ike lati ori de ẹnu ni lati koju arun Coronavirus Oríṣun àwòrán, ololufe BBC Àkọlé àwòrán, bọAramọnda!
Odi ọjọ kejidinlọgbọn oṣu Kẹrin ki opin to o de ba a.
Ilé iṣẹ́ amóhùnmáwòrán ìbílẹ̀ kan gba Abódiakọ-akọ́diabo àkọ́kọ́ sí iṣẹ́ gẹ́gẹ́ bí atọ́kùn; Coke Studio, ètò orin, àwọn Abódiakọ-akọ́diabo méjì ni ó ti kópa ní orí ètò náà.
Ìdí tí Bàbá Leah Sharibu fi yarí pé ọmọ òun kò kú WAEC gbé èsì ìdánwò WASSCE jáde Dokita yọ góòlù àti owó ṣílè nínú obìnrin kan Ni Ọjọ Ẹti ni iroyin kan n tan kaakiri ori ẹrọ ayelujara wi pe ki awọn eniyan ko sora lati rin ni ilu Abuja, Lagos, Kaduna, Kano, Katsina, Gombe ati Bauchi, nitori iwọde awọn ẹlẹsin Shia.
Kò burú bí Twitter bá fòfin dè ìpolongo òṣèlú lójú òpó - Kayode Ogundamisi Kíni àwọn ohun tó yẹ kí ẹ mọ̀ nipa àjọ tó ń mójútó ọ̀rọ̀ ìjọba ìbílẹ̀?
Iro ibọn ti wọn si n yin si aja naa nibi ti wọn ti n lee kiri lawọn araalu gbọ ti wọn si n lero pe boya awọn adigunjale lo wọ aafin.
Wo ohun tí Adájọ́ sọ nípa ìgbẹ́jọ́ Wòlíì Sotitobire l'Ondo Ọmọ Yorùbá mẹ́wàá tó jẹ́ àmúlùúdùn ní Amẹ́ríkà àti Yúróòpù Iroyin abẹle sọ wi pe nṣe ni afunrasi naa ja wọ yara arabinrin naa ni ọjọ kejidinlogun oṣu keje ni nnkan bi agogo mẹrin abọ irọlẹ to si fi ipa baa lo pọ.
 bí orúko ilé yìí se jeyo nì yí nípasè pipe ilé yìí ní ejìlolá léyìn olùpilèsè rè .
Bẹ́ẹ̀ gan-an ni àwọn nǹkan Ọlọrun: kò sí ẹni tí ó mọ̀ wọ́n àfi Ẹ̀mí Ọlọrun.
Ìdààmú Sẹ́nétọ̀ Dino Melaye Dino Melaye f'oju ba'le ẹjọ Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Ní ọdún kejidinlogun tí Josaya jọba, ó rán Ṣafani, akọ̀wé rẹ̀, ọmọ Asalaya, ọmọ Meṣulamu, sí ilé OLUWA pé kí ó 
Nítorí èyí, kí ẹ ní ìtara láti fi ìwà ọmọlúwàbí kún igbagbọ yín, kí ẹ sì fi ìmọ̀ kún ìwà ọmọlúwàbí.
Aare Buhari so pe inu oun bajẹ
Lọwọ yii, apapọ awọn to ti ni arun Coronavirus kaaakiri orilẹ-ede Naijiria ti di 12486, awọn 3959 lo ti ri iwosan gba, nigba ti awọn 354 ti dero ọrun nitori arun ọhun.
O fikun-un pe “lose melo kan seyin, oko ofurufu Dana Air craft ni ilekun re si sile bi o se n bale si papako ofurufu Nnamdi Azikiwe International Airport, ni Abuja.
Fetí sìlẹ̀ kí n sọ ìtàn kékeré kan fún ọ.
Ṣugbọn awọn mii a maa fi iye igba ti ojo ti rọ sii lori igi mọ boya o ti ni adidun.
12 Èbibi 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Idije Premier League n yeruku lala Oni lonii jẹ ẹni a bẹ lọwẹ!
 Ki awon ti o n to omo lowo ma se fi ise won saaju fifun omo won loyan, nitori pe ise ti oyan n se lara omo ko lo n ka,”Iyaafin Ambode gboriyin fun akori todun yii, ti o so pe: “Fifun omo loyan: Ipile aye omo”, o je, otito ati igbese ti awon omo nilo fun idagbasoke.
Àwọn mejeeji yóo sì fi orí ara wọn ru ẹ̀bi ẹ̀ṣẹ̀ wọn, wọn yóo kú láì bímọ.
Ó yọ́ ojúlówó wúrà bò ó, ati òkè ati ẹ̀gbẹ́ ati abẹ́ rẹ̀, ati ìwo rẹ̀ pẹlu, ó sì fi wúrà ṣe ìgbátí rẹ̀.
Abija kó ogún ọ̀kẹ́ (400,000) akọni ọmọ ogun jọ láti bá Jeroboamu jagun.
Nibayii, ati yọnda wọn, wọn si ti wa lọna Abuja lati lọ ba awọn ọga wọn."
Seun Kuti to jẹ ọmọ bibi Fela ṣàlàyé fún BBC Yorùbá pé ògo ilé Kuti ni ti òun bá lè gbàmi ẹ̀yẹ Grammy fún afro beat rẹ̀.
Gbenga Adeyinka: Àwọn Adẹ́rinpòṣónú Nàìjíríà lè di ààrẹ Ìgbẹ́jọ́ EFCC kò ní jẹ́ kí ń péjú sí ìbúra Fayemi - Fayose Níbo làwọn òṣèré apanilẹ́rìn ín wọ̀nyí tó pilẹ̀ sínima àgbéléwò Yorùbá wà?
Hesiro, ará Kamẹli, ati Naarai ọmọ Esibai; 
Ẹ̀kọ́ mẹ́jọ tó yẹ kí ilẹ̀ Afirika kọ́ lára àjàkálẹ̀ aàrùn coronavirus Ìdí rèé tí ilẹ̀ Afirika fi gbọdọ̀ kópa nínú dídán abẹ́rẹ́ coronavirus wò Ọgbà ẹ̀wọ̀n ni Naira Marley yóò ti wo ìbúra Buhari ní May 29 Àgbáríjọ àwọn ajìjàgbara Niger Delta fẹ́ yapa kúrò ní Nàíjíríà Àwọn ohun tó ń fa ariwo nípa Huawei tó yẹ kóo mọ̀?
Wọ́n wá bi í pé, “Ta wá ni ọ́?
Ìròyìn yìí tàn ká gbogbo Jọpa, ọpọlọpọ sì gba Oluwa gbọ́.
Eji Gbadero, ọmọ Ibadan àti jayé-jayé ọmọ ónílẹ̀ ti wọn yẹgi fun l'Eko Ìpínlẹ̀ Oyo sọ àsìá Nàìjíríà kalẹ̀ láti dárò Abiola Ajimobi Kọmíṣọ́nà mẹ́ta lùgbàdì àrùn Coronavirus l'Ọyọ Tinubu, oju ti ẹ, o ta ilẹ Yoruba fun ọta rẹ nitori adanikanjẹ- Femi Fani-Kayode Wo odò tí wọ́n ti rí Aishat tí àgbárá òjò gbé lọ ní Eko Iṣẹ akanṣẹ lati mu awọn ọmọ Yahoo ori ayelujara yii ni awọn agbofinro Dubai pe ni: 'Operation Fox Hunt 2' Awọn ẹṣẹ bii jiji owo ko lati asuwọn kan si ikeji, jiji owo lori ayelujara, wiwọ akata ayelujara ati eto inawo ẹlomiran lọna aitọ, ṣiṣẹ gbajuẹ fun awọn eeyan ni awujọ ati fun awọn banki ni wọn mu wọn fun.
Jesu wí fún àwọn ọmọ-ẹ̀yìn pé, “Ọkunrin ọlọ́rọ̀ kan wà tí ó ní ọmọ-ọ̀dọ̀ kan.
Nkan i ba tun ṣẹnu're fun Chelsea nigba ti idije naa wọ iṣẹju mejidinlọgbọn.
" NCDC kéde èèyàn 437 míràn tó ṣẹ̀ṣẹ̀ lùgbàdì Covid-19 ní Nàìjíríà, 142 gbàwòsàn Iná jó àwọn ènìyàn 10 tó ń gbà ìwòsàn arùn Coronavirus níbùdó ìtọ́jú Eric ati Tochi ni wọ́n lé kúrò nílé ẹlẹ́gbọ̀n àgbà BBNaija lọ́sẹ̀ yìí Iná sọ nínú ilé Big Brother tó ń lọ lọ́wọ́ ní Cameroon O fi kun un pe ojuṣẹ ijọba Eko ni lati ṣatunṣe opopona to ti bajẹ nitori ọna ti ko dara lo n fa sunkẹrẹ-fakẹrẹ ọkọ.
Egbe alatako to wa lorile ede Uganda, MP  lo ti  pada si orile ede rẹ leyin itoju  ti o lo fun lorile ede United States, ni eyi to so pe oun farapa lasiko ti o wa ni atimole awon omo-ogun.
Nítorí Baba fúnrarẹ̀ fẹ́ràn yín nítorí pé ẹ̀yin náà fẹ́ràn mi, ẹ ti gbàgbọ́ pé láti ọ̀dọ̀ Ọlọrun ni mo ti wá.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Lọsan kan, osu kan ni UK yoo kuro ninu ajọ isọkan ilẹ Yuroopu, ti wọn ko ba fi ẹnu ọrọ jona titi di ọjọ Kọkanlelọgbọn osu Kẹ́wa ọdun 2019 N jẹ o seese lati yago fun?
Wo àwọn ọtí ẹlẹ́rìndòdò tó ń fa àrùn jẹjẹrẹ.
Bí wọn bá ti ọjà dé, wọ́n kò jẹ́ jẹun láìjẹ́ pé wọ́n kọ́kọ́ wẹ̀.
5 2079 Isle of Man 25 29.
Eyi lo n mu ki awọn eeyan sọji lati maa tete lọ si ile ẹjọ ti ijọba lati lọ ṣe igbeyawo ki a to gbe ara wa lọ si ṣọọṣi lati fi ibunkun de e lade tori ẹsin ṣe pataki si wa gẹgẹ bi ọmọ Naijiria."
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ìbejì Àyànbìnrin tó ti ń di gbajúgbajà Bi igbesẹ yii ṣe kan ọ Yoo fun ọ ni ẹtọ lati ko owo idọti rẹ lọ si banki lati gba tuntun dipo rẹ.
si ibi ti won maa n sa pamọ si ni agbegbe Wonaka, ni ijoba ibile Gusau ni ipinle
To si jẹ pe ọkọ naa bajẹ loju ọna, lẹyin naa si ni awọn ibugbamu to ko gbina, to si fa iṣẹlẹ alagbara naa.
Àkọlé àwòrán, Ní kété tí àjọ elétò ìdìbò Nàìjíríà kédé ọ̀jsgban Kayode Fayemi gẹ́gẹ́ bí eni tó jáwé olú borí ni àwọn ará ìlú ti bó sí ìgborláti dáwọ̀ọ́ ìdùnú.
DW sports fi idunnu won han lati ni ibasepo pelu awon agbaboolu mejeeji lori ero ayelujara Twitter won.
Gbà mí kúrò létí bèbè ikú,
Ẹsẹ̀ ẹni tí ń mú ìyìn rere bọ̀ ti dára tó lórí òkè, ẹni tí ń kéde alaafia,tí ń mú ìyìn rere bọ̀,tí sì ń kéde ìgbàlà,tí ń wí fún Sioni pé,“Ọlọrun rẹ jọba.
ati awon janduku oloselu lati Ikebiri 1 ni ekun Gusu ti ijoba ibilẹ Ijaw ni ipinle Bayelsa.
"Barry, Evans, Livermore and Myhill tọrọ aforiji lọjọ ẹti fun pe ""wọn tapa si ofin konile o gbele ẹgbẹ agbabọọlu naa ati fun awọn iṣẹlẹ to ti ta epo si aṣọ aala rẹ."
Àwọn ará Dani bá ń bá tiwọn lọ, nígbà tí Mika rí i pé wọ́n lágbára ju òun lọ, ó pada sílé rẹ̀.
Ile ẹjọ fi ẹsun idigunjale, fifi ipa da araalu laamu ati fifi ipa lọni lọwọ gba.
 ní ilẹ ̀ greece , àjọ náà ti náwó lọ ́ pọ ̀ lọpọ ̀ sórí iṣẹ ́ akíọ ́ lọ ́ jì tó pọ ̀ brẹpẹtẹ .
Ariwo ẹ ma a gbe lọ sile iwosan lo gba inu fidio naa, ti obìnrin kan to ṣe e ṣe ko jẹ iya ọmọ naa, si n sunkun.
Ta ni ó sì fún ọ ní agbára náà?
Wo aláànú tó n wa ọkọ̀ tí wọ́n fi n gbé aláìsàn lọ́fẹ̀ẹ́ Omíyalé gbẹ̀mí èèyàn méje, o tún ba dúkìá púpọ̀ jẹ́ Ìbọn ti kò lo ọ̀ta làwọn ọlọ́pàá a máa kọ́kọ́ yìn- IG Macron, aarẹ France ṣèlérí láti tún Notre-Dame kọ́ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ọ̀dọ́kùnrin tó kọ́kọ́ ṣe ẹ̀rọ tó ń tu ìyẹ́ lára adìyẹ Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
ohun amayederun, eto eko, ile-iwosan  ati
Lasiko igbe aye rẹ, o jẹ oye Gomina adulawọ akọkọ laye eebo amunisin.
, lati igba ti won si ti siso loju ise opolopo ose ni won ti gbese, nipase fifi
Àwọn ọmọ Nàìjíríà bu ẹnu àtẹ́ lu Ààrẹ Buhari lórí ọ̀rọ̀ tó bá ará ìlú sọ Oríṣun àwòrán, Femi Adesina Ọpọ awọn ọmọ Naijiria ti bẹrẹ si n fi ero wọn han lẹyin ti Aarẹ Buhari ba wọn sọrọ tan lalẹ Ọjọbọ.
Mò ń wo àwọn ọ̀dàlẹ̀ pẹlu ìríra,nítorí wọn kì í pa òfin rẹ mọ́.
A lè fi ìtàn yi wé àwọn Òṣèlú tó nsa lati ẹgbẹ́ kan si ekeji nitori ipò̀ ati agbára lati kó owó ìlú jẹ.
Ẹsun orisirisi ni wọn ti fi kan ile iṣẹ Huawei pe o lọwọ ninu titọ pinpin awọn ile iṣẹ ẹrọ amuṣẹya ati pe o n lẹdi apo pọ pẹlu Iran.
Alufa Adeboye ti ọpọ eeyan tun mọ si Mummy G.
Ẹ óo gbin ọgbà àjàrà, ẹ óo sì tọ́jú rẹ̀, ṣugbọn ẹ kò ní rí èso rẹ̀ ká, bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò ní mu ninu ọtí rẹ̀, nítorí pé àwọn kòkòrò yóo ti jẹ ẹ́.
Ati pe ẹnikẹni ti eroja yii ko ba pe ninu ẹjẹ rẹ ko gbọdọ fi ẹjẹ silẹ ni gbogbo agbaye.
‘Jí foonu ọkọ rẹ̀ wò, kóo fi ẹ̀wọ̀n jura’ Àwọn òṣìsẹ́ ètò ìlera tó n kojú ewu ikú láti gba ẹ̀mí là Mo rò pé mò ń jà fún Islam ni, ó pẹ́ kó tó yé mi – Boko Haram tẹ́lẹ̀ Èèmọ̀ rèé o, Dókítà yọ eyín 526 lẹ́nu ọmọ ọdún méje Òfin túntun yiìí ni wọ́n kéde ní ago mẹ́jìlà ọ̀sán ọjọ ajé ní Jiddah, ó ni ki wọ́n fi ààyè gbà àwọn ọmọ obinrin ti ọjọ́ ori wọn kò jú mọkánlélogun lọ láti gba forúkọsilẹ̀ láti gba ìwé ìrìnà kí wọ́n lọ sí òkè òkun.
Won n fẹhonu han lori aisi aabo fun awọn oṣiṣẹ ile iwosan naa.
Seyi Makinde gbàlejò Abdulsalami Abubakar ní Ibadan
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Collapsed Building: Ayálégbé ló dára bí ìjọba ṣe wólé àmọ́ wọ́n fẹ́ ìrànwọ́ ilé míràn Ninu iwadii tuntun yii ẹwẹ, ẹkun aringbungbun gusu orilẹede Naijiria ni ọwọja kokoro arun HIV/AIDS pọ ju si lorilẹede Naijiria, eyi si wa laaarin awọn ọdọ ti ọjọ ori wọn wa laaarin ọdun mẹẹdogun si mẹrinlelọgọta pẹlu ida mẹta o le ẹyọ kan ninu ọgọrun (3.
Ìtunmọ̀ àwọn ọ̀rọ̀ yìí lẹ́yọ kọ̀ọkan rèé
Àwọn Èèwọ̀ tí Ó Jẹmọ́ Bíbá Obinrin Lòpọ̀.
    Báyìí ni mo sọ fún ọba, inú rẹ̀ náà sì dùn sí mi, ó wò mi, ó bú sí ẹ̀rín.
Ẹwẹ, nigba to n da si ọrọ naa, akọwe ẹgbẹ Afenifere, Yinka Odumakin ni bo tilẹ jẹ pe o ti pe ọgọta ọdun ti Naijiria gba ominira kuro loko ẹru ijọba ilẹ Gẹẹsi, inu oko ẹru naa ṣi ni awọn ọmọ Naijiria wa sibẹ.
Jesu tí àdàpè rẹ̀ ń jẹ́ Jusitu náà ki yín.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Risikat Moromoke Azeez: Inú èmí àti Òbí mi dùn nígbà ti Risi bí ọmọ olójú búlù- Wasiu Ọjọ ti pẹ ti awọn ileesẹ ọkọ oju omi ti awọn olookowo maa n lo, ti n kesi ijọba Naijiria lati gbe igbesẹ, paapaa lati igba ti ajọ International Maritime Bureau ti sọ pe Naijiria lo ko ìdá aadọrun ninu ijinigbe to n waye lori omi, paapaa lori okun Gulf of Guinea.
Ó bá tún bẹ̀rẹ̀, ó ń fi ìka kọ nǹkan sórí ilẹ̀.
“Ẹ ta àsíá sórí ilẹ̀ ayé,ẹ fun fèrè ogun láàrin àwọn orílẹ̀-èdè;kí àwọn orílẹ̀-èdè múra láti gbógun tì í,ẹ sì pe àwọn ìjọba jọ láti dojú kọ ọ́;àwọn ìjọba orílẹ̀-èdè bíi Ararati, Minni, ati Aṣikenasi.
Ninu apilẹkọ kan to fi si oju opo rẹ, Adesina ni ọpọ iṣẹ ni aarẹ ti ṣe ṣugbọn aifarabalẹ awọn eeyan Naijiria kan ko jẹ ki wọn mọ pe o ti ṣiṣẹ.
Atiku ni, inu oun dun bi awon
Liverpool vs Arsenal: Liverpool kun Arsenal wẹ́lẹ́wẹ́lẹ́ bí ẹran àsun 'lójúbọ' Anfield
OLUWA yóo na ọ̀pá àṣẹ rẹ tí ó lágbára láti Sioni.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ibadan Sallah Killing: Ẹbí ọmọ tí wọ́n rí òkú rẹ̀ nínú odò ní Ibadan ní ikú rẹ̀ kìí ṣe ojú lásán 4 Ògún 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 6 Ògún 2020 Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ẹbí ọmọ ọdún méjì tí wọ́n rí òkú rẹ̀ nínú odò ní Ibadan sọ pé ikú rẹ̀ kìí ṣe ojú lásán Ẹbi ọmọ ọdun meji to di awati ni ọjọ ọdun Ileya ku ọla, Sukurat Arowolo, ti wọn si pada ri oku rẹ ninu odo kan ni adugbo Olodo ni Ibadan ti kẹdun iku rẹ.
Ohun to jẹ idunnu ni pe kii ṣe igba tawọn eeyan pọ nita nitori Covid-19.
Ọlọpaa Dubai ṣalaye bi wọn ṣe mu Hushpuppi ninu atẹjade ti wọn fi sita ti BBC ri.
N óo sọ ọ́ di odi alágbára tí a fi idẹ mọ, lọ́dọ̀ àwọn eniyan wọnyi.
Oriṣiiriṣii iṣẹlẹ lo ti ṣẹlẹ sẹyin nipa Kolawọle Gold, ọmọde to dawati ninu ijọ Sọ titobi rẹ ti Wolii Babatunde Samuel Alfaa ni tukọ rẹ nilu Akurẹ.
" Agba oye Balogun ni ọpọ ohun to n waye ni aafin Olubadan ko bojumu to, paapa nidi bi igbimọ Olubadan kii se seto ayẹwo mọ fawọn eeyan to fẹ jẹ Mọgaji ati Baalẹ, ko to di pe wọn jawe oye le wọn lori.
Wọ́n ń sọ pé, “Ìròyìn kò tó àfojúbà ni ohun tí a rí lónìí!
CPI n se igbelewon iyato to ba iye owo ori oja ati awon onibara lojoojumo.
Oríṣun àwòrán, Presidency Ọjọgbọn Gambari jẹ alaga igbimọ ajọ iṣọkan agbaye to n pẹtu sija laarin ọdun 1990 si ọdun 1999.
Bayii lọrọ ri pẹlu ilumọọka oniṣegun ibilẹ to tun jẹ agba babalawo, Araba ilu Osogbo, Oloye Ifayemi Elebuibon.
A lèè sọ pé àwọn tí wọ́n ń sọ èdè Yorùbá yàtọ̀ sí orílẹ̀ èdè Nigeria lé ní Ọgbọ̀n nílíọ̀nùn, àwọn orílẹ̀ èdè tí a ti ń sọ èdè Yorùbá yàtọ̀ sí Nigeria ni.
Ileesẹ to wa fun ipese ohun iranwọ nilẹ wa lo sisọ loju ọrọ yii ninu atẹjade kan tó fisita loju opo Twitter rẹ.
Iná ajónirun ni,tí yóo run gbogbo ohun ìní mi kanlẹ̀.
OLUWA yóo dá àwọn eniyan rẹ̀ láre,yóo sì ṣàánú àwọn iranṣẹ rẹ̀.
Bakan na lo tun ṣeleri lati tun awọn opopona ṣe ati mimojuto gbigbẹ odo Niger ki opin de ba omiyale ni Kwara paapaa lati ẹkun Patigi.
Loju opo Amazon nibi to ti polowo iwe kan ti o kọ, apejuwe nipa Dokita Stella sọ pe ọmọ ilẹ Cameroon nii ṣe.
Ohun tí o bá ná lé e lórí, n óo san án fún ọ nígbà tí mo bá pada dé.
Bakan naa, gege bi ile-ise akoroyin ori ero amohun-maworan  al-Arabiya ilu Dubai se so, won fi mule pe, awon apaniyan n I o sekupa oloogba naa”Iroyin miiran lori ero ayelujara so pe, won sekupa pelu obe (knife),Ni bayii, iku oloogbe naa ni yoo di asoju orile-ede Naijiria ati Russia ti o ti padanu emi won si agbegbe Khartoum laarin odun kan soso.
 Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ondo election 2020: Àwọn ara ìpínlẹ̀ Ondo ránṣẹ́ sí Akeredolu ohun ti wọ́n ń retí ní báyìí Ileeṣẹ ọlọpaa sọ pe awọn oluwọde #ENDSARS pa ọlọpaa kan ni Delta Ọga Agba fun ileeṣẹ ọlọpaa orilẹ-ede Naijiria, Mohammed Adamu ti bu ẹnu atẹ lu bi awọn oluwọde EndSars nipinlẹ Delta ṣe pa ọlọpaa kan."
2019 Elections: Àwọn òṣèré Yorùbá tó wà nínú ìgbìmọ̀ ìpolongo APC
Duro Ladipọ, ìlúmọ̀ọ́ká òṣèré tíátà àti ọmọ àlúfà tí kò gbàgbé àṣà ìbílẹ̀ Hubert Ogunde rèé, baba àwọn òsèré tíátà Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Éégún tó wà nídí Yoruba Bollywood, Samo Baba f'ojú hàn o!
Ẹ wo àwọn gbajúmọ̀ òṣèré tíátà tó jogún eré ṣíṣe lọ́dọ̀ òbí wọn Ìtàn ìgbésí ayé Oshodi, ọmọ Tápà léǹpe tó di akọni ní ìlú Eko Àwọn ìbejì Akeugbagold kò le rìn dáadáa mọ́ lẹ́yìn tí wọ́n dáwọn padà Òṣèré tíátà, Ọmọba Femi Oyewunmi tí ọ̀pọ̀ mọ̀ sí Laditi ti jáde láyé Sanusi Adebisi Idikan rèé, olówó tó ń san owó orí fún gbogbo ọkunrin ilẹ̀ Ibadan Irú ẹ̀dá wo ni olówó yalumọ àkọ́kọ́ nílẹ̀ Yorùbá, Candido Da Rocha?
Awọn ẹsun aṣemaṣe ti ijọba apapọ̀ fi n kan El-Zakzaky ni ilẹ India niyii: O fẹ funrarẹ yan dokita ti yoo tọju rẹ nibẹ eyi ti ijọba apapọ sọ pe 'o lodi si ilana iṣẹ iṣegun oyinbo' O fẹ ki wọn fi oun wọ si ile igbafẹ olowo nla 5-star hotel kan ni India dipo ile iwosan ti o yẹ ko wa fun itọju O fẹ ki wọn da iwe irinna silẹ okeere rẹ pada fun oun eleyi ti awọn oṣiṣẹ alaabo to ba a rinrinajo lati Naijiria lọ si India ni ko lee ṣeeṣe O n fẹ ki wọn ko awọn ẹṣọ alaabo ati ọlọpaa ti o n ṣọ ọ kuro O beere fun anfani ati maa gba alejo bo ba ṣe wu u ni India.
217tn 2015 -N654bn 2016 -Ko si akọsilẹ fun iye ti wọn na 2017 -N144.
nítorí pé ní ọjọ́ kẹta yìí ni èmi OLUWA óo sọ̀kalẹ̀ sórí òkè Sinai, lójú gbogbo wọn.
bí ìgbà tí iná ń jó igbó ṣúúrú,tí iná sì ń mú kí omi hó.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù School re-opening: Àwọn orílẹ-èdè tó ti ṣilẹkùn ilé ìwé padà 26 Èbibi 2020 Oríṣun àwòrán, Heiko Jung Awọn ileewe jakejado agbaye ti bẹrẹ si ni ṣi ilẹkun wọn pada lẹyin ti awọn ijọba ti n dẹwọ isede to tẹle ajakalẹ arun Covid 19.
Ní kékere, Tolulope rí ọkọ̀ bàálù kékeré kan ó sì sọ fún mi pé lọ́jọ́ kan, òun á wa bàálù yẹn mo si ṣe Amin nla.
Ṣebí ohun tí mo fẹ́ ni pé kí ó yipada kúrò lọ́nà burúkú rẹ̀, kí ó sì yè.
Àbí bí eniyan bá ṣìnà,kì í pada mọ́?
Oríṣun àwòrán, Twitter Ṣugbọn o, Melaye naa ti sọ pe oun ati ẹ kii ṣe ọrẹ, lẹyin ti ọwọ ọlọpaa tẹ Hush.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ọbasanjọ tako ìnáwó Ààrẹ Buhari fún ìpèsè inà ọba 23 Èbibi 2018 Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ọbasanjọ tako ìnáwó Ààrẹ Buhari fún ìpèsè inà ọba Awuyewuye kò tí ì tán lórí ọ̀rọ̀ ṣíṣe bílíọ́nù mẹ́rìndínlógún Naira tó n fa àríyànjiyàn láàrin Ààrẹ Muhammadu Buhari àti Oluṣẹgun Ọbasanjọ.
Papa iṣire King Fahd International Stadium ni Riyadh, orilẹede Saudi Arabia ni ifẹsẹwọnsẹ naa ti waye.
36bn ni Inec yoo fi tẹ iwe ti wọn yoo kọ esi ibo si N2.
 George Akume – Benue, Minisita fun akanṣe iṣẹ ati ọrọ ilẹ okeere(Special Duties)mẹ́wà) Mustapha Baba Shehuri – Borno, Minisita kekere fun eto ọgbin ati idagbasoke igberiko(Agriculture), State mọ̀kànlá) Godwin Jedi-Agba – Cross River, Minisita fun ipese ina manamana ni eka ijoba ipinle (Power), State méjìlá ) Festus Keyamo – Delta,  Minisita fun ẹkun Niger Delta ni eka ijoba ipinle (Niger Delta), State mẹ́tàlá  ) Ogbonnaya Onu – Ebonyi, Minisita fun imọ Sayẹnsi ati imọ ẹrọ (Science and Technology) mẹ́rìnlá ) Dr.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Trump picture: ọjọ́ tí Trump kí mi kú iṣẹ́ lórí 'twitter' ní inú mi dùn jù- Oyedele Bi wọn ba si ri iṣẹlẹ to waye loju ọna, loju igbo tabi ninu ilu, to kan iṣẹ ọlọpaa, wọn a fa iṣẹ naa le ọlọpaa lọwọ.
A óo mú ọ̀kan, a óo fi ekeji sílẹ̀.
Òní ni Shi'ite fẹ́ ṣe ìwọ́de ikú ọmọ ọmọ Anọ́bì ní èyí tí ó lòdí sí àṣẹ agbófinró Agbejọ́rò Dakolo:Mílíọ́nù mẹ́wàá náírà tí a béèrè kì í ṣe owó gbà má-bínú Iye epo rọ̀bì tí wọ́n ń kó níbùdó ìpọnpo ti dínkù, ṣé ẹ fẹ́ mọ ìdí i rẹ̀?
Oríṣun àwòrán, Diane Reeve Obinrin kan tun wa ti mo pada ba sọrọ.
 Iko awon onijo yii kopa ninu ayeye Wazobia olodoodun to waye ni ojo keta ati ojo kerin osu yii ni Muri Okunola Park ni victoria island nipinle Eko.
Ọba Lekan Balogun sọ pe ko si aawọ kankan laarin Olubadan ati awọn ọba yoku nitori idagbasoke ilẹ lbadan lo jẹ onikaluku logun.
Wakati diẹ lẹyin iṣẹlẹ ọun, o tun ti pada sori ayelujara lati fi ero rẹ han lori bi wọn ṣe fiya jẹ yii.
Wọ́n gbààwẹ̀ ṣúlẹ̀ ọjọ́ náà, wọ́n ní, “A ti ṣẹ̀ sí OLUWA.
Àwọn nǹkan tí obìnrin lè ṣe pẹ̀lú olólùfẹ́ oníwà ipá lásìkò ìgbélé Coronavirus yìí Coronavirus: Ǹjẹ́ àwọn dókítà tó ń tọ́jú eyín ń ṣisẹ́ lásìkò pàjáwìrì?
Lọdun 2011 si 2013 lo fi ṣe akapo ẹgbẹ oṣelu Congress for Progressive Change (CPC) ti aarẹ Buhari dije ninu rẹ fun ọpọlọpọ ọdun ko to darapọ mọ APC.
Wọ́n wọlé tọ Ohola ati Oholiba lọ, wọ́n sì bá wọn ṣe àgbèrè.
ko to di pe, o wa tun pada si opopona meji atijo.
Janduku oṣelu yọri si ija ẹsin laarin awọn kristẹni ati musulumi.
Nigba ti BBC Yoruba se abẹwo si ibudo itaja naa, wa wa wa ni awọn agbofinro gbarodan sẹnu ọna abawọle ibẹ, ti wọn si setan lati wọn esinsin to ba ta firi nibẹ.
8 Sẹ́rẹ́ 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Aarẹ Buhari Awọn oludibo ni Nigeria yoo ma a dibo sipo aarẹ ni 19 February lati yan ẹni ti wọn fẹ nitori ohun ti awọn oludije naa ti sọ.
Ninu oro ti awon asoju-sofin naa panupo si lasiko ipade won ti o waye lojoBo(Thursday), awon asofin ohun foro mule pe, opolopo egbe oselu nipinle kookan ni o koti ikun, ti won si tapa si ofin ati ilana ti o ro mo egbe oselu won ati titi ajo eleto idibo lataari gbigbogun ti isejoba tiwan-tiwan lorile-ede yii.
A ti fi orukọ rẹ silẹ gẹgẹ bii ẹni ti a n wa.
Nigba to n ba BBC srọ, Simon ni osu kan pere ni oun ati aya oun, Tash, fi se igbeyawo ko to dagbere faye, ọjọ mẹrin pere si ni awọn fi palẹmọ fun igbeyawo naa.
Ebi nìkan ni oúnjẹ wọn yóo wà fún, wọn kò ní mú wá fi rúbọ lára rẹ̀ ní ilé OLUWA.
Mo maa n duro ti i di alẹ ki n to sọ fun un pe o daarọ.
Mo lé àwọn ọ̀tá mi, ọwọ́ mi sì tẹ̀ wọ́n,n kò bojú wẹ̀yìn títí a fi pa wọ́n run.
Ó tún di ọdún mọ́kàndínláàádọ́rùn-ún, ní ọjọ́ kíní, oṣù kíní ọdún 2101, tí kíkọ sílẹ̀ rẹ̀ á jẹ́ 01/01/01.
meta ti ijoba yan ti fenuko lori ekunwo owo osu naa.
Ṣugbọn bí ẹ kò bá gbọ́ ti OLUWA Ọlọrun yín, tí ẹ kò sì pa òfin rẹ̀ mọ́, yóo dojú ìjà kọ ẹ̀yin ati ọba yín.
Missing Child: Òbí àti asọ́nà ṣọ́ọ̀ṣì 14, lọ́ búra nì'dí imọlẹ̀ l'Akure Arsenal ti padà júwe ilé fún Unai Emery Ilé ẹjọ lé Ọba Èrúwà kúrò lórí Àpèrè lẹ́yìn ọdun 21 Gbèsè Nàìjíríà yóò di $50b tí wọ́n bá tún yáwó- Shehu Sani Aarẹ Trump fi idunnu rẹ fawọn ọmọ ogun ilẹ America pe tayọtaọ loun fi n jẹun idupẹ tọdun 2019 pẹlu wọn.
Iker Casillas lo gba ami yi tẹlẹ ṣugbọn Messi ti lewaju rẹ pẹlu ifẹsẹwọnsẹ 335 to ti pegede ninu rẹ.
Ní ọ̀tunla n óo parí iṣẹ́ mi.
Minisita tesiwaju pe gbogbo eto fun ibura fun aare ni awon yoo pada
Kàkà bẹ́ẹ̀, ẹ kún fún Ẹ̀mí Mímọ́.
Ṣé lóòtọ́ọ́ ni Ọba Rilwan Akiolu padà sí ààfin lọ́jọ́ ọdún?
Òun ni mo sọ nípa rẹ̀ pé, ‘Ẹnìkan ń bọ̀ lẹ́yìn mi, ẹni tí ó jù mí lọ, nítorí ó ti wà kí á tó bí mi.
Sugbọn eyi to pabambari ninu awọn isẹlẹ naa, to fi mu ki ọjọ Isẹgun ana jẹ ọjọ buruku, esu gbomi mu ni bi awọn sọja ati ọlọpaa se da si iwọde to n waye ni Lekki, nipinlẹ Eko.
Alufaa pataki to tun wa nile ijosin naa ni, Bishop T.
OLUWA rán wolii kan sí wọn.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Aláàfin Ọyọ: Mí o ní kí Wasiu Ayinde má bọ̀wọ̀ fàwọn ọba ilẹ̀ Yorùbá ayafi.
''Iru ẹ ko ṣẹṣẹ ma a ṣẹlẹ ninu oṣelu Naijiria nitori eto oṣelu ni Naijiria ṣe n dagbasoke ni, nitori naa ni awọn oloṣelu ṣe n kaakiri lati ẹgbẹ kan si omiran.
Bíbéèrè fún ìbálòpọ̀ gbogbo ìgbà sọ ìyàwó ilé dèrò ilé ìwòsàn Ẹ wo ìṣẹ̀lẹ̀ nípa ẹ̀sùn ìfipábánilòpọ̀ tí wọ́n fi kan D'banj ní sísẹ̀-n-tẹ̀lé Ó ṣeéṣe kó jẹ́ pé àwọn alágbara ló ń fi agbára hàn lórí arábìnrin tó fẹ̀sùn ìfipábánilòpọ̀ kan kọmíṣọ́nà Kogi -Agbẹjọ́rò Iya ọmọdekunrin ọhun, Deborah Okezie ti kọkọ fi fidio kan sita, ninu eyi to ti fi ẹsun kan pe, awọn akẹkọọ ọkunrin kan to wa ni kilaasi agba nile ẹkọ naa fi ipa ba ọmọ oun lopọ, lai ti ju oṣu meji to wọ ile ẹkọ naa.
Bí ẹnìkan bá gba yín létí, ẹ yí ẹ̀gbẹ́ keji sí i.
Ni ipari awon omo ile fenuko lati pe minista fun eto irinna ni Naijiria lati wa salaye idi ti won fi yo guusu kuro ninu ise akanse eyi ti won fe lo owo tijoba ba ya lowo banki Exim ni China funWon ko fenuko si pe kile ma tii fowo si yiya owo naa laije pe awon toro kan se atunse bi o ti ye si eto irinna oju irin naa.
"Agbẹjọro naa ni ""Ẹni ti gbogbo eeyan nifẹ si, ti wọn si n bọwọ fun ni onibara oun, gbajumọ eeyan ni."
Health Barta gbé fídíò kan sí oríi YouTube tí ó ń ṣe àlàyé lẹ́kùnúnrẹ́rẹ́ ohun tí ó pọn dandan láti ṣe bí èèyán bá ní ibà-ẹ̀fọn:
Asofin Iyiola Omisore oludije fun ipo gomina labe asia egbe oselu Social Democratic Party SDP, seleri pe, bi oun ba jawe olubori ninu idibo gomina ipinle osun to n bo lona, oun yoo pese ayika ti yoo mu igberu ba awon olokoowo  nipinle naa.
Ọwọ palaba igara ọlọṣa ajinigbe kan ti n dẹru ba ara ilu ni ipinlẹ Rivers la gbọ pe o ti segi lẹyin tọwọ awọn agbofinro tẹ ẹ.
ṣugbọn òun alára wọ inú ijù lọ ní ìrìn odidi ọjọ́ kan kí ó tó dúró.
Sowore ṣèpàdé pẹ̀lú Nnamdi Kanu láti dojú ìjọba Nàíjíríà bolẹ̀ - Àjọ DSS Lórí ìmọ̀ràn Sunday Igboho, Ẹlẹbubọn ní yóò dára kí Yorùbá padà sí àmúlò èròjà ìbílẹ̀ fún ààbò Fulani kò leè dúró, táa bá lo ohun ta jogún lọ́dọ̀ àwọn bàbá wa - Sunday Igboho Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí kan sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
Nígbà tí wọ́n bá mi wá síhìn-ín, n kò fi ọ̀rọ̀ náà falẹ̀.
Gbogbo àwọn eniyan tí wọ́n wà ní ẹnu ọ̀nà ibodè ati àwọn àgbààgbà náà dáhùn pé, “Àwa ni ẹlẹ́rìí, kí OLUWA kí ó ṣe obinrin tí ń bọ̀ wá di aya rẹ bíi Rakẹli ati Lea, tí wọ́n bí ọpọlọpọ ọmọ fún Jakọbu.
” Gbogbo àwọn ọkọ̀ ojú omi náà rì, wọn kò sì lè lọ sí Taṣiṣi mọ́.
Ọladapọ ṣalaye pe nigba to ya, ẹnikan ninu ẹbi rẹ gbe ounjẹ rẹ wa, tawọn si ni ki wọn lọ mu wa, ko lee jẹnu.
Ṣugbọn Alátìlẹ́yìn náà, Ẹ̀mí Mímọ́ tí Baba yóo rán wá ní orúkọ mi, ni yóo kọ yín, tí yóo sì ran yín létí ohun gbogbo tí mo sọ fun yín.
Ile-igbimo ohun fenuko lati sun ipade re si ose to n bo lojo isegun(Tuesday), lataari oro ti asofin Bala Ibn Na’Allah fi le le.
Ẹ tàbùkù mi lójú gbogbo àwọn eniyan, ẹ kò bọ̀wọ̀ fún mi gẹ́gẹ́ bí ẹni mímọ́ níwájú àwọn eniyan náà.
Ìjọba orílẹ̀-èdè náà ati awọn aṣofin rẹ̀ ti ní kí ọlọ́pàá bẹ́rẹ̀ iṣẹ́ láti ṣe ìwádìí àwọn èèyàn tí ọ̀rọ̀ náà ta bá kiakia.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ibinu ma n mu ikunsinu ati asọ dani Njẹ a ni agbara lori ibinu fufu?
eniyan ti o padanu ohun ini won, Internally Displaced Persons (IDPs) camp, ati olu
Gomina ipinlẹ Jigawa, Mohammed Badaru Abubakar, Gomina Oṣun, Gboyega Oyetola ati Gomina ipinlẹ Niger, Abubakar Sani Bello wa lara awọn ti yoo kọwọ rin pẹlu aarẹ lọ ilẹ Saudi.
South Africa: Ọlọ́pàá South Africa rí ẹ̀wọ̀n ọgbọ̀n ọdún he torí ikú ọmọ Nàìjíríà
A ṣe yi ṣe àmọ́dún o.
Àwọn onimọ nípa isẹ agbẹ sapejuwe kokoro ajokorun to sẹ̀sẹ̀ sẹ́ wọlu gẹ́gẹ́ bi Arun Ebola fun àwọn agbẹ́.
Eyi jadẹ ninu atẹjade ti awn Gomina ipinlẹ mẹtẹẹta naa fi si oju opo ikansiraẹni Twitter wọn.
Bó sì jẹ́ àdàpọ̀ ẹsẹ̀ àti apá lẹ fẹ́, ìyẹn náà wà.
"Ọwọ́ tẹ́ àwọn ọkùnrin Fulani mẹ́ta tí wọ́n jí Màálù méjì kó ní Ogbomọṣọ- Àjọ NSCDC Ọmọ́ Yorùbá korò ojú sí Buhari bí kò ṣe fi orúkọ Obasanjo sọ ibùdókọ̀ ojú'rin O ṣalaye pe ""Gẹgẹ bi mo ṣe sọ tẹlẹ, ijọba to wa lode yii n doju ija kọ iwa jẹgudujẹra, a si ni ẹri lati gbe e lẹsẹ."
Oun yii kan naa ni igbakeji oloye Awolọwọ ni iṣejọba ẹkun iwọ oorun ilẹ Naijiria nigbanaa.
Abacha, to jẹ olori orilẹede Naijiria laarin ọdun 1993 si 1998 to ti jalaisi, niroyin sọ pe o kowo naa lọ si Channel Islands nilẹ Yuropu, lati ilẹ Amẹrika.
O bu ẹnu ẹtẹ lu iha ti ijọba kọ si ọrọ ipaniyan ṣowo, ati pe pipaniyan fun ṣiṣe oogun owo buru ju iwa ijinigbe lọ.
Wọn ti gbe oku awọn mejeeji lọ si ile igbokupamọsi Adeoyo to wa ni Ring Road nIbadan fun ayẹwo ti eeyan kan to ku to fara pa si ti wa ni ile iwosan fun itọju.
"Oríṣun àwòrán, Oyo state Government Bakan naa lo sọ pe ""Ajimobi ko ipa ninu idagbasoke ọrọ aje ati awujọ nipinlẹ Oyo, ati Naijiria lapapọ."
fe gbe ẹru won lati orile ede kan si ekeji nilẹ Afirika.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Abdullahi Olatoyan: Iṣẹ́ fífọ gíláàsì ọkọ̀ ń tì mí lójú láti dẹnu ìfẹ́ kọ obìnrin Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Abdullahi Olatoyan: Iṣẹ́ fífọ gíláàsì ọkọ̀ ń tì mí lójú láti dẹnu ìfẹ́ kọ obìnrin 3 Owewe 2019 Yoruba ni ma tiju isẹ rẹ, idi isẹ ẹni si laa mọ ni lọlẹ.
Ni bayii to ku wakati mẹrinlelogun pere ki eto idibo gomina ni ipinlẹ Ekiti bẹrẹ, BBC ri arigbamu pe awọn oloselu kan ti n pin owo fawọn oludibo ni ipinlẹ Ekiti.
Kia ti ikọ iroyin BBC News Yoruba gbọ iroyin yii nigba naa lo tọ awọn to sun mọ agba oṣelu naa bi iṣan ọrun lọ lati mọ ootọ ọrọ nigba naa ti wọn si fi to wa leti pe ko sohun to jọ bẹẹ ati pe ara rẹ ya gaga bi ara akẹkọọ aṣọ.
Gbogbo ilé ẹ̀kọ́ jákèjádò orílẹ̀ èdè yìí ni ìjọba tìpa láti ilé ẹ̀kọ́ alákọ̀bẹ̀rẹ̀, gírámà títí dé Fáṣítì láti ọjọ́ kẹrindinlọ́gbọ̀n oṣù kẹ̀ta ọdún yìí.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Premier League: Liverpool na Tottenham láti gòkè tábìlì EPL 31 Ẹrẹ̀nà 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Liverpool na Tottenham Oni lonii jẹ, ẹni a bẹ lọwẹ, ọjọ irọlẹ ọjọ Aiku yii ni ikọ Liverpoool yoo ta kangbọn pẹlu ẹgbẹ agbabọọlu Tottenham ninu idije Premier League.
Wọ́n dá Joṣua lóhùn pé, “Gbogbo ohun tí o pa láṣẹ fún wa ni a óo ṣe, ibikíbi tí o bá sì rán wa ni a óo lọ.
Ìwọ nìkan, àní, ìwọ nìkan ṣoṣo ni mo ṣẹ̀,tí mo ṣe ohun tí ó burú lójú rẹ,kí ẹjọ́ rẹ lè tọ́ nígbà tí o bá ń dájọ́,kí ọkàn rẹ lè mọ́ nígbà tí o bá ń ṣe ìdájọ́.
Custom: A ti gbẹ́sẹ̀ lé ọjà tí oye rẹ̀ lé ní bílíọ́nù kan náírà lẹ́yìn tí a ti ibodè
Ṣé ẹ rí ibi tí ọmọ Ilẹ̀ Gẹ̀ẹ́sì ti sọ irú ọ̀rọ̀ yìí nípà èdè Gẹ̀ẹ́sì kíkọ?
 Asiko to lati lo imọ ẹrọ tuntun ki alaafia lee jọba ki iwa ọdaran si lee wọlẹ.
Gomina tun tesiwaju pe oun ti na owo ti
Fún ọkunrin tí ó jẹ́ ẹni ogún ọdún sí ọgọta ọdún, yóo san aadọta ìwọ̀n ṣekeli fadaka.
NCDC ní ìpínlẹ̀ Eko ní ènìyàn mẹ́jìdínláàdọ́rùn, mẹ́rìnlélọ́gọ́ta láti Kano, nígbà tí ìpínlẹ̀ Katsina ni èèyàn mọ́kàndínládọ́ta tí Kaduna si ni mẹ́tàlá Oríṣun àwòrán, NCDC Àkọlé àwòrán, Àjọ NCDC kéde èèyàn 242 míràn tó ni ààrùn Covid-19 lórílẹ̀-èdè Naijíríà Ènìyàn mẹ́sàn ló tún jẹyọ láti Ogun, nígbà ti mẹ́fà wá lati Gombe, mẹ́rin láti Adamawa ti Abuja sì ní mẹ́ta.
Ọrọ owo awọn aṣofin yii hande lẹyin ti ọpọlọpọ ipinlẹ Naijiria ti ni awọn ko lagbara lati san ẹgbẹrun lọna ọgbọn owo oṣu oṣiṣe ti Owó dé!
' Ọdún 1955 ni wọ́n kọ́kọ́ se àyájọ́ yìí lágbayé lábẹ́ onígbọ̀wọ́ àjọ́ àgbáye kan tó ń rí sí ìtọ́jú àwọn èwe, International Union for Child Welfare ní Geneva.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ladoja: Àwọn èèyàn Oyo fì ìbò sọ̀rọ̀ pé ìjọba Ajimobi kò dára O sọ pe awọn esi ibo yii ni wọn fi ṣọwọ si ajọ INEC lawọn ipinlẹ to fi de olu ile iṣẹ INEC nilu Abuja.
Ninu wọn ni Maria tí à ń pè ní Magidaleni wà, tí Jesu lé ẹ̀mí èṣù meje jáde ninu rẹ̀, 
Mo fẹ́ kí o tẹnumọ́ àwọn nǹkan wọnyi, kí àwọn tí ó ti gba Ọlọrun gbọ́ lè fi ọkàn sí i láti máa ṣe iṣẹ́ tí ó dára.
Òun ni ó lọ sọ́dọ̀ Pilatu, tí ó bèèrè òkú Jesu.
Adeola wa n rọ awọn obi, alagbatọ ati ijọba lati dena iwa fifi ọmọ Naijiria sowo ẹru loke okun nitori ọpọ ewu to rọ mọ.
Ọmọ Ààrẹ lẹ́tọ̀ọ́ láti ṣe ìgbéyàwó yálà àwọn ará ìlú fẹ́ràn ìjọba bàbá rẹ̀ tàbí bẹ́ẹ̀ kọ́ - Aisha Buhari Ẹ wo nkan tí àwọn akẹẹgbẹ́ Lateef Adedimeji sọ nípa f'ọ́tò ìgbéyàwó òun àti Adebimpe tó jáde Kìí ṣe sinimá ni mò ń ṣe, ìṣẹ̀lẹ̀ ojú ayé gangan ní sùgbọ́n.
Samuẹli bá wí fún un pé, “OLUWA ti fa ìjọba Israẹli ya mọ́ ọ lọ́wọ́ lónìí, ó sì ti fi fún aládùúgbò rẹ tí ó sàn jù ọ́ lọ.
Ta ni Gómìnà Abdullahi Umar Ganduje, tí ilé ẹjọ́ gíga gbé adé fún ní ìpínlẹ̀ Kano?
Àwọn ẹlòmíràn wí pé ìgbà tí a dé ọ̀dọ̀ àwọn obìnrin wọn-ọnnì ọkùnrin náà wo ibi tí wọ́n wà ó sì yà sí ọ̀dọ̀ wọn; àwọn ẹlòmíràn wí pé ó ti yà kí á tóó dé ibẹ̀ àti wí pé ó ṣìnà sí inú igbó ni.
O mọ iṣẹ ti mo n ṣe lati ibẹrẹ, to si n ṣe atilẹyin fun mi.
Ẹ sá àwọn akẹ́kọ̀ọ́ sínú òòrùn fún ọgbọ̀n ìṣẹ́jú lójojúmọ́ - Ìjọba Oyo pàṣẹ Oríṣun àwòrán, @OfficialSeyiMakinde Ijọba ipinlẹ Ọyọ ti pasẹ fun awọn ọga agba ileẹkọ gurama ati ti alakọbẹrẹ jakejado ipinlẹ naa lati sa awọn akẹkọọ wọn sinu oorun fun ọgbọn isẹju lojooju.
Baruku, ọmọ Neraya, ni ó fẹ́ mú wa kọlù ọ́, kí o lè fà wá lé àwọn ará Kalidea lọ́wọ́, kí wọ́n lè pa wá; tabi kí wọ́n kó wa lọ sí ìgbèkùn ní Babiloni.
Ìwọ tó ń ṣí ara sílẹ̀ lọ ṣọ́ọ̀ṣì, ṣé apàyàn kọ́ ni ẹ́ báyìí?
jànkànjànkàn tí wọ́n tò lé arawọn ni.
Ariyanjiyan bẹrẹ lẹyin iwaasu ti Sheikh Abubakar Muktar ṣe lori lilo ẹrọ POS fun owo sise.
Naijiria ti fontẹ lu sisan ekunwo ọgbọ̀n ẹ̀gbẹ̀rún fun awon osise ipinle naa.
Ojọgbọn Pius Adesanmi kagbako ninu ijamba ọkọ to waye ni oṣu keje, ọdun 2018.
Ati pe omi t'ọjọ ti lọ lori rẹ ti wọn fa si lara ti mu ki kokoro kan, to n ba ile ìtọ̀ jẹ wọ agọ ara rẹ Titi di asiko yii, ileewosan fasiti UNN ko ti i fun Chidozie ni esi ayẹwo to ṣe.
Kọmiṣọna ọrọ ọrọ to n lọ ni ipinlẹ naa, Donald Ojogo lo sọ bẹ ninu ifọrọwerọ kan pẹlu BBC Yoruba.
Ọba bá rán Jehudi pé kí ó lọ mú ìwé náà wá, ó sì mú un wá láti inú yàrá Eliṣama, akọ̀wé.
Ẹ níláti ràn án lọ́wọ́ láti gbé kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ tabi akọ mààlúù rẹ̀ dìde.
N kò ní fẹ́ràn wọn mọ́, ọlọ̀tẹ̀ ni gbogbo àwọn olórí wọn.
Wo àwọn ẹranko tí wọ́n máa figagbaga ni Egypt nínú AFCON 2019 Oko òkú rèé, níbití òkú ti ń jẹrà mọ́lẹ̀ fún àyẹ̀wò Jẹ́ kí a jọ sọ àǹfàní US fún Nàìjíríà -Osinbajo Ọmọ ogun Nàìjíríà bẹ̀rẹ̀ lílo 'Drone' láti gbógun tàwọn ajínigbé ni Ondo àti Ekiti Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ebola Virus: ìdí tí Ebola fi ń tàn kálẹ̀ Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Ojoojumọ fun bi ọsẹ kan gbako ni ariwo fi n sọ ni awọn agbegbe ti a mẹnuba tẹlẹ, ati awọn miran to yi wọn ka.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Àwàdà kẹríkẹrì nígbà táwọn olùdíje ààrẹ́ Amerika méjì kọjú ìjà síra wọn Ọgọ́rin arìnrìnàjò tó padà wá sí Nàìjíríà ló ní Coronavirus - PTF Wo iye tí ìjọba yóò gbà lọ́wọ́ Laycon gẹ́gẹ́ bí owó orí ẹ̀bùn BBNaija tó jẹ Ilé ẹjọ́ gíga ní kí òsìsẹ́ First Bank tẹ́lẹ̀ lọ sí ẹ̀wọ̀n ọdún 98 lórí ẹ̀sùn pé o jí mílíọnù 49 àti $368, 000 níbẹ̀ Sadiya Umar Farouq ti ní pé ọwọ òun mọ́ lórí N2.
"Ìgbàgbọ ́ yìí ni pé ẹ ̀ mí náà ni pé ẹ ̀ mí náà ó pinnu láti dúró "" ṣe ayé "" síbẹ ̀ ó jẹ ́ sí ipò ( ti ìyá ) àti ìpọ ́ njú ìyá rẹ ̀ ."
Lẹta Iyabọ ọhun fa awuyewuye ni asiko naa, ti ọpọlọpọ si n sọ pe 'lẹta ti iyabọ kọ ṣeeṣe ko jẹ apejuwe itẹlẹ idi ẹni, kii ri ni ti.
Ise-ogbin ati ohun alumooni, Audu Ogbe lo sọ eleyii lasiko to n  jabọ ipade ti  igbimo ijoba apapo se  pelu aare Muhammadu Buhari fun awon akoroyin nile
Mi ò gbèrò láti lọ fún sáà kẹ́ta gẹ́gẹ́ bí ààrẹ - Buhari Iléẹjọ́, ẹ sọ fùn ọ̀gá DSS kó fún wa ní ₦1bn torí àhámọ́ lọ́nà àìtọ́ - Sowore àti Bakare Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Money transfer: Òdíwọn iye owó tí èèyàn n fi rànṣẹ́ sílé ń dínkù púpọ̀ jù Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Buhari kọ́ ni ìṣòro wa, bó ṣe wà láti láéláé rèé - Fr Mbaka Oríṣun àwòrán, Facebook/Adoration Ministry Enugu Ojisẹ Ọlọrun kan ninu ijọ Aguda, Fada Ejike Mbaka ti sọrọ lori iwọde EndSARS, to si ni ipo ti awọn ọdọ wa ni Naijiria ko dara rara.
O sọ ninu ọrọ rẹ wipe, o to ki eeyan yéra fun ẹgbẹ oṣelu naa.
Ọrọ naa mu ki ọpọlọpọ awuyewuye waye laarin awọn ọmọ bibi ilẹ Ibadan nile ati lẹyin odi.
Kò ní sí ayẹyẹ ọdún Ojúde Oba lọ́dún yìí- Awujale ilẹ̀ Ijebu Orílẹ̀-èdè mẹ́wàá tí ẹgbẹ́ alákatakítí Islamic State n fínna mọ́ ní àgbáyé Wo agbábọ́ọ̀lù Super Eagles Nàìjíríà àkọ́kọ́ tó lùgbàdì coronavirus Kò ní sí ayẹyẹ ọdún Ojúde Oba lọ́dún yìí- Awujale ilẹ̀ Ijebu Alaye lori awọn to ri ṣe lasiko Covid 19: Ajo Oxfam ni: Síbẹ̀ àwọn tó wà nípò gíga àti ipò òṣèlú ṣì ń lówó sii.
Ṣimei dá a lóhùn, ó ní, “Gbogbo ohun tí o sọ ni ó dára, oluwa mi, bí o ti wí ni èmi iranṣẹ rẹ yóo sì ṣe.
Oṣu kẹwaa ọdun naa lo padanu ẹmi rẹ nigba to lọ ileeṣẹ aṣoju orilẹede Saudi ni Turkey.
Mí ò mọ nípa ilé Bukola Saraki ti wọn ti pa- agbẹnúsọ EFCC
Dáàbò bo àwọn tí a lé jáde;má tú àṣírí ẹni tí ń sálọ.
O wa dupe lowo awon akegbe  re ati iko omo ogun naa fun ifowosowopo ti won fun un.
Nígbà náà ni mo sọ pé,‘Èmi nìyí.
Niwọn igba ti wọn ba ti lo ipa tabi ti wọn lo ohun ija, ofin yii fẹsẹ mulẹ ninu Suratuk Ma'idah ẹsẹ kẹtalelọgbọn.
Èèyàn 409 míì ti lùgbàdì àrùn Coronavirus ní Naijiria Àwọn nǹkan tí obìnrin lè ṣe pẹ̀lú olólùfẹ́ oníwà ipá lásìkò ìgbélé Coronavirus yìí Ìyàwò kejì tó fi owú ré ọkọ bọ́ láti òkè pẹ̀tẹ́sì gba ìdájọ́ ikú Ẹ̀wọ̀n gbére ni fún ẹnikẹ́ni tó bá fipá bánilòpọ̀ ní ìpínlẹ̀ Ọ̀ṣun Lẹ́yìn tó ṣá Monisola aya rẹ̀ ládá, Oniya ní iṣẹ́ èṣù ni Wèrè tí mò ń ṣe ní Facebook ló pawó fún mi-Esabod Kọmiṣọnna ni gbogbo awọn to laarun yii atawọn eeyan ti wọn ni ajọṣepọ lo n gbe ninu ọgbọn ileeṣẹ naa.
Koda o ni awọn fẹ ṣe lara ohun ti ileẹjọ beere fun ni Ọjọbọ ṣugbọn adajọ ti kuro nile ẹjọ nigba naa.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Nigeria Elections 2019: Àwọn ọmọ Nàìjíríà n ṣé hèèmọ̀ bí INEC ṣé dajọ sí ibo 16 Èrèlè 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Awón eeyan n faraya lori bi Yakub ṣe sun idibo Naijiria siwaju Kini ka ti ṣe eyi si?
Ẹ ranti iroyin kan nibi ti awọn onisẹ ibi ti da ẹmi ọmọbinrin kan, Barakat Bello legbodo lọjọ aipe, ladugbo Akinyele nilu Ibadan, to si fi tipa ba lopọ, ko to gba ẹmi rẹ.
 Bi eniyan ba ni ore ofe lati mo ede meji si meta yoo se anfaani pupo lati sise nibi yoowu lagbaye.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Olaitan Olamide: mò lè má nílò ìwé ẹ̀rí mi tí mo bá parí ní LASU Amọ o papa bọ si ọwọ àwọn ara ilú, wọ́n lùú, bó tilẹ̀ jẹ́ pé àwọn ọlọpàá gbìyànjú láti gba silẹ̀ sùgbọ́n ẹmi ti bọ lára rẹ̀ ki wọ́n to gbé de ilé ìwòsàn.
 Ìjòyè mẹ ́ fà tàbí méje ni wọn .
Lọjọ Ẹti ọjọ kẹẹdọgbọn oṣu kẹsan ọdun 2020, awọn olokoowo fun itura bii hotẹẹli, ile ọti, sinima, ile ounjẹ ati bẹẹ bẹẹ lọ ni iforukọsilẹ kan lati ago mejila oru.
Minisita fọ́rọ̀ ilẹ̀ òkèèrè kọ̀wẹ́ fipò sílẹ̀ Buhari nìkan kọ́ ni aṣíwájú táwọn èèyàn dẹ́yẹsí 'Ẹ kéde èsì ìdìbo àarẹ 1993' Theresa May bọ́ lọ́wọ́ ìgbésẹ̀ láti yọ́ nípò Awọn mii ti wọn tun jọ fẹ wọ bata ti Theresa May bọ silẹ lataari ọrọ Brexit ni Dominic Rab.
Àkọlé àwòrán, Alàyé lórí àwọn ènìyàn to ti pàdánù iṣk wọ́n láàrin oṣù kẹrin si oṣù kẹfa jẹ́ ẹgbẹ̀rún lọ́nà okòólénígba ènìyàn.
O ni aago mẹjọ abọ aarọ ni eto idibo naa yoo bẹrẹ ti yoo si pari ni aago meji abọ ọsan ọjọ naa.
Nibi ipade itagbangba ikọ PTF, oludari wọn, Sani Aliyu sọ alakalẹ tuntun fun awn arinrinajo to n bọ lati UK ati South Africa wa si Naijiria.
O da bi ẹni pe ọdọọdun ni iroyin iru ẹsun agbere naa maa n jade nipa awọn pasitọ olokiki ni orilẹede Naijiria.
cristina elisabet fernández de kirchner ( ; born 19 february 1953 ) , sometimes referred to by her initials cfk , je oloselu ati agbejoro ara argentina ati aare ile argentina tele .
Bẹ́ẹ̀ ni iranṣẹ náà ṣe mú Rebeka lọ.
Bákan náà, Oyetola ni gbogbo àwọn ọjà si lọ gbọ́dọ̀ wà ní títì pa.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Coronavirus tips: Kìí ṣe gbogbo ìbòmù ló ń dá coronavirus dúró ''Ti o ba jẹ ẹni ti o ni ifunpa to ga ti wọn wa lọ tufọ fun un lojiji, ki ni ẹ lero pe yoo tẹyin rẹ wa ti iru ni yẹn ba lọ daku?
Iya awọn ọmọ naa sọ fun awọn oniroyin pe awọn ọmọ mejeji sọ fun oun pe ootọ ni baba wọn ma n bawọn lopọ.
 Ó wà lórí Àkójọ Àwọn egbògi kòṣeémáàní ti Àjọ Ìlera Àgbáyé ( world health organization ' s list of essential medicines ) , àwọn òògùn tó ṣe pàtàkì jùlọ tí a nílò fún ètò ìlera ìbẹ ̀ rẹ ̀ pẹ ̀ pẹ ̀ yòówù .
Aṣọ àlàárì ati àwọn aṣọ olówó iyebíye mìíràn ni ó máa ń wọ̀.
Àmì ayò 2-1 ni Naijiria fi ṣàgbà Benin Republic Premier League: Arsenal jẹ àjẹkún ìyà lọ́wọ́ Leicester City pẹ̀lú àmì ayò 2-0 Madrid, ẹ mú £70m pẹ̀lú Hazard wá, tẹ bá fẹ́ ra Sterling- Guardiola Ẹ wo àwọn ààrẹ tí ikọ̀ ọmọ ogun ti gba ìjọba lọ̀wọ̀ wọn Ki lawọn eeyan n sọ nipa rẹ?
igbaradi won so le niluu Ismailia.
Kò pẹ́ pupọ lẹ́yìn náà ni Juda bá fi àwọn arakunrin rẹ̀ sílẹ̀, ó kó lọ sí ọ̀dọ̀ ará Adulamu kan tí wọn ń pè ní Hira.
Ará ìlú fárígá, wọ́n wọ́ alàkóso ìlú nilẹ́ pẹ̀lú ọkọ̀ Òpópónà àti afárá 19 níjọba fẹ́ ṣe nínú àbá ìṣúná ọdún 2020 Ilé-isẹ́ ìpòogùn Johnson & Johnson san biliọnu 8 dọ́là fún ẹni tóògùn gbòdì lára rẹ̀!
Ọ̀rọ̀ ẹnu eniyan dàbí odò jíjìn,orísun ọgbọ́n dàbí omi odò tí ń tú jáde.
Eyi ni igbakeji ti ẹgbẹ agbabọọlu mejeeji yoo koju ara wọn lati igba ti saa yii ti bẹrẹ.
Segalink ni ọpọ eeyan gba pe o jẹ ọkan lara awọn ọdọ to n se agbatẹru iwọde EndSARs, to si tun jẹ adari fun awọn afẹhọ̀nuhan to tako ifiyajẹni awọn ọlọpaa ni ọdun 2017, Segalink loju opo Twitter rẹ ni aarọ ọjọ Aje, lo kede pe oun ko lọwọ ninu iwọde naa mọ nitori oun n fura pe awọn eeyan kan ti n gbe igbesẹ lati da orilẹede Naijiria ru.
Oríṣun àwòrán, Seyi Makinde Ẹwẹ, gomina Seyi Makinde ti se abẹwo si ọja akẹsan nilu Ọyọ to jona lọjọ Aiku lati se abẹwo si awọn ohun to jona nibẹ.
Iroyin naa sọ pe ọgbẹni Malcolm papoda lẹyin ti o ti ba aisan kan finra fun ọjọ pipẹ ni ẹni ọmọ ọdun mẹtadinlogoji.
O wa fọwọ gbaya pe ileesẹ ọlọpaa yoo se iwadii to yẹ nipa awọn ikọlu yii, ti wọn si tun ti n saayan lati ri pe alaafia pada si agbegbe mejeeji naa.
Eré naa jẹ eré apanilẹrin to ta daada nile iworan sinima kaakiri Naijiria.
Eyi ko ṣẹyin ija ọrọ aje to n waye laarin orileede Russia ati Saudi Arabia, to fi mọ airi agba epo ta, ti aisan Coronavirus naa ṣokunfa rẹ.
”Alli,  tun fi idunnu re han bi awon opo eniya nse jade lati wa wo oko ojun irin paapaa julo awon onisowo, bo tile je pe awon ko se ikede pupo rara.
49 Àti pé òun ni yíò darí àwọn ìpàdé nígbàtí alàgbà kankan kò bá sí níbẹ̀.
Àdúrà ni mo nílò kìí ṣowó - Pa Kasumu Ọlọ́pàá fi pampẹ́ òfin mú Duncan Mighty lórí ẹ̀sùn jìbìtì mílíọ̀nù mọ́kànlá 'Penis Fish,' ẹ̀ja tuntun tó rí bí nǹkan ọmọkùnrin lúwẹ̀ẹ́ jáde nínú òkun Kamaru Usman, Ọmọ Naijiria f'ẹ̀ṣẹ́ gba ìgbànú ẹ̀yẹ mọ́ Covington lọ́wọ́ ní ìdíje UFC Ọ̀jọ̀gbọ́n fásitì OAU pàdánù ẹ̀mí lópoópónà Benin sí Auchi.
As one of the few credible voices, several attempts were made to silence me.
Ijọba apapọ ni awọn gbe igbesẹ yii lori awọn orilẹede to jẹ wi pe iye awọn eeyan to ti fara ko arun Coronavirus ti ju ẹgbẹrun kan lọ.
6 2466961 Orilẹede Argentina 39770 89.
Ọgbọ́n ni a fi ń kọ́lé,òye ni a fi ń fi ìdí rẹ̀ múlẹ̀.
Kò sí ohunkohun tí ojú mi fẹ́ rí tí n kò fún un.
Jọ̀ọ́, má wé orúkọ mi mọ́ ìjákulẹ̀ tó bá ọ - Seyi Makinde kìlọ̀ fún Lanlẹ́yin Wọ́n lu àbúrò mi ló jẹ́ kí ń fi ìbínú lu òǹtàjà l‘Abuja - Sẹ́nétọ̀ tó lu obìnrin ṣàlàyé Ìdí rèé táwọn ọmọ Nàíjíríà kan ṣe ń tako ìdásílẹ̀ ‘Ruga Settlement’ Ọlọ́pàá gba àna ADC Buhari silẹ̀ lọ́wọ́ ajínigbé Ṣugbọn nigba ti yoo fesi, Sẹnetọ Abbo sọ fun BBC pe, oun ko mọọmọ lu obinrin naa.
Gomina Abiodun sọ loju opo Twitter rẹ pe igbesẹ naa jẹ lati ṣadinku ba kiko arun Coronavirus wọ ipinlẹ ọhun lati awọn ipinlẹ to yi ka, papa julọ ipinlẹ Eko.
Port Harcourt: Afurasi tó fa ìpayà nílé ìwé ti bọ́ sọ́wọ́ ọlọ́pàá
"Ilé aṣọ̀fin Nàìjíríà ń gbèrò ẹ̀wọ̀n f'áwọn olùkọ̀ tó bá dẹnu ìfẹ́ kọ akẹ́kọ̀bìnrin Ìṣòro Nàíjíríà kọjá kí Bobrisky àtàwọn ẹlẹgbẹ́ rẹ̀ dá ní ilé ìgbọ̀nsẹ̀ lọ́tọ̀"" ""Èmi ò r'óhun tó burú kí obìnrin opó fẹ́ ọkọ míì sínú ilé ọkọ rẹ̀"" Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Kini Yoru[bá ń pe Necklace?"
Orúkọ tí ẹ óo fi sílẹ̀ fún àwọn àyànfẹ́ miyóo di ohun tí wọn yóo máa fi gégùn-ún.
Jesu bá sọ fún àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ pé, “Mo fẹ́ kí ẹ mọ̀ dájúdájú pé yóo ṣòro fún ọlọ́rọ̀ láti wọ ìjọba ọ̀run.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Sotitobire: Ọkọ mi kò mọ̀ Jegede PDP rí, kódà kò fa ẹnikẹ́ni kalẹ̀ dípò Akeredolu- Bisola Baba Sars ni agbegbe Adeniji Adele ni olu ileeṣẹ wọn wa nigba naa.
Ẹ̀mí OLUWA bá bà lé mi, ó sọ fún mi, pé, “OLUWA ní, Èrò yín nìyí, ẹ̀yin ọmọ Israẹli, mo mọ ohun tí ẹ̀ ń rò lọ́kàn, 
Ọpọlọpọ awọn ogiri ile ni wọn ṣe ami si wi pe, awọn ọmọ onilẹ ti gbẹsẹ lee pẹlu atilẹyin ile ẹjọ giga, lasiko ti ikọ BBC Yoruba ṣe abẹwo si agbegbe naa lowurọ Ọjọ Ẹti.
Eagles, Gernot Rohr ti kede awon agbaboolu merinlelogun ti yoo kopa fun idije
Lara awọn ọmọ igbimọ naa ni alaga ijọba ibilẹ kọọkan, ọga ọlọpa ni agọ ọlọpa gbogbo to wa nijọba ibilẹ ọhun, awọn asoju ileesẹ ọtelemuye ati awọn ara ilu mẹrin-mẹrin nijọba ibilẹ kọọkan.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Immigration: Bàyìí ni iṣẹ́ ajé ṣe sọ àwọn ọmọ Nàìjíríà nù sí London Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Immigration: Bàyìí ni iṣẹ́ ajé ṣe sọ àwọn ọmọ Nàìjíríà nù sí London 18 Bélú 2019 Owe Yoruba to ni ajo ko da bii ile, ile labọ isimi oko naa lo tun ni ooṣa boo le gbe mi ṣe mi boo ṣe ba mi.
Ẹgbẹ NUJ ni ẹnu n ya oun nipa bi aarẹ Buhari se dakẹ lai fọhun lori iwọde EndSARS to n lọ lọwọ, eyi to ti da omi alaafia orilẹede yii ru.
Ti ọsun yii ṣeeṣe ko bọ si ọgbọn ọjọ ati ọjọ kọkanlelọgbọn, oṣu kejila.
- Oluwo Agbára wo ni June 12 fún MKO Abiola tó ṣì ń fọhùn lẹ́yìn ikú rẹ̀?
Nígbà tí àwọn ọmọ Israẹli ti fi idà pa gbogbo àwọn ará Ai tán ninu aṣálẹ̀, ní ibi tí wọ́n ti ń lé wọn lọ, wọ́n pada sí ìlú Ai, wọ́n sì fi idà pa gbogbo wọn patapata.
Ṣugbọn èmi wá ń sọ fun yín pé ẹnikẹ́ni tí ó bá wo obinrin pẹlu èrò láti bá a lòpọ̀, ó ti ṣe àgbèrè pẹlu rẹ̀ ná ní ọkàn rẹ̀.
Àwòrán ìsàlẹ̀ yìí ni àwọn ilé àjogúnbáa Bangladeshi tí àdàwólulẹ̀ ń bá:
Òun ni ó mọ́ jùlọ lára ẹbọ tí a fi iná sun sí OLUWA.
Mo si dupẹ pe o ri bẹ ẹ fun wọn.
Àkọlé àwòrán, #BBCGOVDEBATE: Kò sí ètò ilera ọfk fun àwọn obinrin- Ogunbanjọ Pasẹda ni eto ilera alabode ko si ni ipo to daara.
- Ààrẹ Akufo-Addo Gbajabiamila balẹ̀ sí Ghana láti pẹ̀tù sááwọ̀ láàrin Nàìjíríà àti Ghana Ikú ni fífi oògùn 'Paracetamol' bọ ẹran tàbí se ẹ̀wà- Iléeṣẹ́ ìlera Nkan to kọkọ ya idibo yii sọtọ nipe idije naa tun dabi atunṣe bii ti atẹyinwa ni.
Oríṣun àwòrán, @SupportSeyi Oniṣowo ni Ṣeyi Makinde, oloṣelu si ni pẹlu.
 awon ileobaluaye ni apaguusu india je kikopomo gbogbo awon ti chalukya , ti cholas ati ti vijayanagara empire .
 O le ni egberun mejo awon to ti lami laaka lokunrin lobinrin ti won n risi i.
Kò ní jẹ èrè wahala rẹ̀,bẹ́ẹ̀ ni kò ní gbádùn èrè tí ó bá jẹ nídìí òwò rẹ̀.
ọmọ Melea, ọmọ Mena, ọmọ Matati, ọmọ Natani, ọmọ Dafidi, 
Ẹ̀yin ará, gbogbo yín ẹ máa fara wé mi, kí ẹ máa ṣàkíyèsí àwọn tí ń hùwà gẹ́gẹ́ bí àpẹẹrẹ tí a ti jẹ́ fun yín.
Iléya ti dé o, barika de Sallah .
Ìdí nìyí ti mo ṣe sọ pé ohun tí ó bá gbà láti ọ̀dọ̀ mi ni yóo sọ fun yín.
Ile iṣẹ Aisha n ṣiṣẹ pọ pẹlu awọn ajọ ilẹ okeere lati gbe iṣẹ ọgbin larugẹ.
Lẹyin ọ rẹyin, ẹlẹsẹ ayo, Romelu Lukaku fi ẹgbẹ agbabọọlu silẹ lọ ikọ agbabọọlu Inter Milan.
Ìyá rẹ dàbí àjàrà inú ọgbàtí a gbìn sí ẹ̀gbẹ́ odò;ó rúwé, ó yọ ẹ̀ka,nítorí ó rí omi lọpọlọpọ.
Awọn oyinbo alawọ funfun to ko orilẹ-ede Naijiria l'ẹru n wa ọna ti ilana iṣejọba wọn yoo fi fẹsẹmulẹ.
Domestic Violence: Obìnrin kan wọ gàù lẹ́yìn tó kan ìṣó mọ́ ọmọ ọ̀dọ̀ rẹ̀ lórí ní Enugu
Wọ́n ga, wọ́n ba eniyan lẹ́rù.
Oladeji ni awọn akẹkọọ ti ṣaaju yọju si awọn mọlẹbi Richard lati lọ bawọn kẹdun iku rẹ ati pe, nibẹ ni awọn ti gbọ pe ileeṣẹ to ti ṣagbako iku naa ko ti yọju si wọn lati bawọn kẹdun.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Covid-19 60seconds: Ṣé ìjìnà síra-ẹni ṣe paàtàkì lẹ́yìn lílo ìbòmú?
Bó tilẹ̀ jẹ́ pé ìyá àti bàbá Lulu kò wá fún ayẹyẹ nàá, Lulu padà sọ fún wọn.
Marosẹ Ibadan si Eko: Fashola sọ pe asepati rẹ yoo se akoba ọrọ aje
Ẹ máa ṣe àwọn àjọ̀dún yín, ẹ̀yin ará Juda, kí ẹ sì san àwọn ẹ̀jẹ́ yín, nítorí ẹni ibi kò ní gbógun tì yín mọ́, a ti pa á run patapata.
Lójùnà àti mójú tó ìpèníjà yìí, Aàrẹ Muhammadu Buhari ti buwọlu owó bílíọ̀nù márùndinlọ́gọ́jọ náírà láti bẹ̀rẹ̀ ilé iṣẹ́ ti yóò maa ri sí ọ̀nà ti àwọn ọdọ́ tó bá ni ǹkan ti wọ́n fẹ́ ṣe lọ́kan yóò ṣe ri owó tí wọ́n yóò maa fi ṣe owo ti wọ́n sì pe orúkọ rẹ̀ ní Nigeria Youth Investment Fund (NYIF).
Èrè gbogbo iṣẹ́ ọwọ́ mi nìyí.
"Ni bayii, atọkun ati adari ere ni isẹ to yan laayo, ti o si ti se awọn sinima bii ""Unwanted Guest"" ati Heven's Hell""."
Wọn óo wọ inú pàlàpálá àpáta,ati inú ihò àwọn òkè gíga;nígbà tí wọn bá ń sá fún ibinu OLUWA,ati ògo ọlá ńlá rẹ̀,nígbà tí ó bá dìde láti mi ayé tìtì.
Matawalle lo siwaju awon agbofinro lati koju ija si awon janduku ati odaran lo
DBanj gbé àwo tuntun jáde lẹ́yìn ikú ọmọ rẹ̀ Ohun tó wù kí ileẹjọ́ kòtẹ́milọ́rùn sọ, Adeleke kò lè di gómínà Ọ́ṣun - APC ‘Ibi a gbé dàgbà níi se pẹ̀lú ìhùwàsì wa’ Oró ò!
Ikeme ni awon dokita sayewo pe O ni aisan jejere ninu osu keje odun 2017, ti o si ti n gba itoju lati igba naa.
Ó bá jókòó lábẹ́ ìbòòji igi kan, ó wo ara rẹ̀ bíi kí òun kú.
Manchester City lo kọkọ lu Gunners ni alubami lẹyin ti wọn lu wọn pẹlu goolu mẹta eyi ti Arsenal ko si lee ta putu.
Ìgbàkúùgbà tí ẹ̀mí burúkú láti ọ̀dọ̀ Ọlọrun bá bà lé ọ, yóo máa fi hapu kọrin, ara rẹ yóo sì balẹ̀.
Nítorí ẹ̀sẹ̀ mi ńlá nì, mo ba inú ihò ìlẹ̀ lọ.
Helen Paul: Ọmọ atàpáta dìde ni mí, ẹ má fójú ajẹbọ́ wò mí Ibrahim Chatta fesi sí ẹ̀sùn pé òun na iyawo rẹ̀!
Nígbà tí Jesu rí i pé àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ ń kùn nítorí rẹ̀, ó bi wọ́n pé, “Ṣé ọ̀rọ̀ yìí ni ó mú kí ọkàn yín dààmú?
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Coronavirus tips: Kìí ṣe gbogbo ìbòmù ló ń dá coronavirus dúró Bayii, wọn jọ maa n mu ọmọ wọn lọ sile ijọsin Hindu ati Budhi ni nitori pe ọrọ wọn ti jọ ye ara wọn.
Ó ní, mo sọ pé, n óo fún wọn ní ọkàn kan, n óo fi ẹ̀mí titun sí wọn ninu.
Mo fún ọ ní ilé oluwa rẹ ati àwọn aya rẹ̀.
Aare orile ede Naijiria Muhammadu Buhari so pe ‘o ya oun lẹnu’ nigba ti oun
Omojuwa woye pe, awọn mejeeji kọ lati yọju nitori wọn ko le dahun awọn ibeere ti wọn yoo bi wọn nibi ijiroro naani.
 O ni “Ajo eleto idibo INEC gbọdọ wa ojutuu si bi won se n ra
Ìkéde Shebuyeva àkọ́kọ́ nípa ètò náà fa ẹgbẹlẹmùkù èébú ìkórìíra-ìbálòpọ̀-láàárín-akọ́-àti-akọ nínú àwọn èsì, tí èsì sì wá láti ọ̀dọ̀ àwọn òṣìṣẹ́ ọba kan bákan náà, ṣùgbọ́n ìyẹn ò mú ọkàn-an rẹ̀ kúrò, ó sọ fún Novaya Gazeta.
Ṣáájú ní Akin Ogunbiyi ti tapa sí àbájáde ìdìbò abẹnu naa eyi to wáyé lópin ọsẹ nílu Òṣogbo.
O ní: Ni ti fọ́nrán to jẹyọ láti ọdún 2016.
Gbogbo àwọn tí wọ́n ní òkúta olówó iyebíye ni wọ́n mú wọn wá tí wọ́n fi wọ́n sí ibi ìṣúra ilé OLUWA, tí ó wà lábẹ́ àbojútó Jehieli ará Geriṣoni.
Lọpọ igba ti o ba ti kuro ni Naijiria, o ku ọ ku iwa rẹ lẹyin odi'' Ọgbẹni ni ara kudiẹ́kudiẹ to wa lara ijọba nile lo lọ farahan han lẹyin odi.
Sáájú ni ìjọba ti kéde pé òun kò ni fún àwọn ènìyàn ni físà láti inú oṣù kẹrin ọdún.
Nítorí náà, OLUWA kò bínú sí wọn mọ́ ní ìgbà ayé Hesekaya.
 O le ni egberun mejidinlogun gabe to ti foruko sile labe eto ise akanse yii.
Sọ fún àwọn olódodo pé yóo dára fún wọnnítorí wọn yóo jèrè iṣẹ́ wọn.
"Bukọla n jẹ arugba gẹgẹ bii ipa ti o ko ninu ere ti ogbontagi akọtan ati adari ere, Tunde Kelani gbe jade ni saa kan pẹlu akọle ""Arugba""."
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Fasoranti: Dẹ́rẹ́bà tó wa ọmọ Fasoranti ṣàlàyé bí wọ́n ṣe pa Funke Olakunrin Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Fasoranti: Dẹ́rẹ́bà tó wa ọmọ Fasoranti ṣàlàyé bí wọ́n ṣe pa Funke Olakunrin 14 Agẹmo 2019 Ọpọ lo ti sọrọ lori bi iku Funkẹ Olukọrin ṣe lọ.
Fọláṣadé náà ni ó yí orúkọ padà sí fìlísíà Olówálàgbà.
Ẹ̀sùn àìmọ̀dí gbé Theophilous dọ́gbà ẹ̀wọ̀n, ìwé ẹ̀rí ìmọ̀ ìjìnlẹ̀ méjì ló gbé jáde
ni ekun mẹfa orile ede yii.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Boko Haram yóò dá Leah sílé Alága ẹgbẹ́ àwọn òbí ọmọbinrin Chibok tí wọn jigbe ṣàlàyé fún BBC pé àwọn gbà obinrin náà gbọ nitoripe o juwe àwọn ọmọ àwọn yékéyéké.
31 Ṣùgbọ́n bí wọn kò bá kọ àwọn ọ̀rọ̀ mi, èyí tí a ó fi ìdí rẹ̀ múlẹ̀ nípa ẹ̀rí èyí tí a ó fi fúnni, alábùkúnfún ni àwọn, àti nígbànáà ni ẹ̀yin yíò ní ayọ̀ nínú èso àwọn iṣẹ́ yín.
O ni eyi ribẹ ẹ nitori pe diẹ lara eroja ti wọn fi ṣe e wa ni orilẹ-ede Naijiria, eyi to tumọ si pe a ko fi bẹ ẹ kọbi ara si awọn nkan ti a ni ni Naijiria.
OLUWA ní: “Ẹ máa dá ẹjọ́ ẹ̀tọ́,kí ẹ sì máa ṣe òdodo;nítorí ìgbàlà mi yóo dé láìpẹ́,ẹ óo sì rí ìdáǹdè mi.
Ilẹ̀ tí ẹ wọ̀n yìí ni yóo jẹ́ ibùjẹ fún àwọn ẹran ọ̀sìn.
kika gomina ati ile igbimo asofin ni ipinle Rivers  yoo se lọ.
Iwe ẹri ilu ti wọn ti bi ọ.
Tillerson: Owo yiya lọwọ orilẹede China lewu fun Afirika
N óo fi ṣe àkọ́bí,àní, ọba tí ó tóbi ju gbogbo ọba ayé lọ.
Isele ohun sokunfa bi awon omo orile-ede Somalia se n bu enu ate lu awon omo-ogun al-Shabab naa latari bi won se n se ikolu lorile-ede naa, eyi ti ijoba kuna lati tiwo awon omo-ogun olote naa  boso.
Awọn ọlọkọ eero si gbọdọ tẹle ilana ijina sira ẹni.
O ti wá kún àwọn oníṣòwò rẹ, wọ́n sì pọ̀ ju ìràwọ̀ ojú ọ̀run lọ!
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ẹ̀rù ló n bà NEDG ni kò jẹ́ kí wọ́n pè mí sí ìfọ̀rọ̀wérọ̀ f'áwọn olùdíje 13 Ọ̀pẹ̀̀ 2018 Oríṣun àwòrán, @yelesho Àkọlé àwòrán, Ṣoworẹ sọ pe oun yoo sọ tita ati lilo igbó di ohun to ba ofin mu ni Naijiria ti oun ba fi di aarẹ Oludije fun ipo aarẹ ninu ẹgbẹ oṣelu African Action Congress, (AAC) ninu eto idibo aarẹ Naijiria l'ọdun 2019, Ọmọyẹle Ṣoworẹ sọ pe ẹrù ni ko jẹ ki ẹgbẹ to n ṣeto ifọrọwerọ lasiko eto idibo ni Naijria, Election Debate Group (NEDG) pe oun si ibi ifọrọwerọ laarin awọn oludije fun ipo aarẹ.
 Mo dupe gidi lowo olorun fun anfani titi di akoko yi.
Ori ayelujara lo ku ti awọn eniyan ti n gburo ara wọn bayii.
Ilu yii ko ju iwọn ogun kilomita lọ si Ileṣa tii ṣe ilu iya rẹ.
#Bum bum war:Yemi Alade tọrọ àforíjìn lọ́wọ́ Tiwa Savage Davido, Falz, Tiwa Savage tàn bí oòrùn ní AFRIMA Bakan naa, o ti ba awọn gbajugba olorin to lokiki kọrin kaakiri agbaye.
"Soyinka ni ""ko yẹ keeyan tilẹ maa ronu lọ sibẹ rara tori ibanujẹ gbaa ni."
Aarọ ọjọ Isẹgun oni ni Toure mi kanlẹ lorilẹede Turkey nibi to ti n gba itọju lọwọ.
Àwọn wòòlí ń takora lórí Atiku àti Buhari Àpanisáyé ni ẹ̀wà tí wọ́n n fí 'sniper' sí Kíni ìdí tí àwọn ẹbí àwọn ọmọ Chibok fi ń tọ woli lọ?
End Sars yii to waye lọjọ kejilelogun, oṣu kẹwaa, ọdun 2020, nbẹ ni wọn ti kagbako iku gbigbona naa Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Akomolede ati Aṣa lori BBC:Wo ìrúfẹ́ ìgbeyàwó méje tó wà nílẹ̀ Yorùbá àti ojúṣe Alárinà Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Fídíò, Akọ́mọlédè àti Àṣà lórí BBC Yorùbá: Kọ́ síi nípa iṣẹ́ tí oúnjẹ ń ṣe lára níbí24 Bélú 2020 Ekiti Shooting: A ò ni farapamọ́ fún ará ìlú lórí ìwádìí ọlọ́pàá to pa ènìyàn ni Ekiti23 Bélú 2020 Fídíò, The New Pandemic: Kíni àwọn onímọ̀ sáyẹ́ńsì ń sọ nípa rẹ̀?
“Ọwọ́ ọ̀tún OLUWA ti ṣe iṣẹ́ agbára ńlá.
Eto idanilekoo naa je okan lara ise akanse ti won gbero lati fi satunse si idagbasoke oro aje Naijiria eyi ti won pe akori re ni: ”Bo ojo iwaju Naijiria pelu awon ise akanse inu eto ogbin fun ilosiowaju”.
Evariste Ndayishimiye di ààrẹ tuntun lórílẹ̀èdè Burundi Òjò àrọ̀ọ̀rọ̀dá dá wàhálà sílẹ̀ l'Eko Bawo ni o ti ṣe ṣẹlẹ?
A kò tíì gbọ́ nípa ikú aṣòfin Ayeọla -INEC 'Logo Benz yóò lẹ́yìn fún àwọn ọ̀dọ́ tó bá ṣògùn owó' 'Shehu Shagari dáríji Buhari kó tó kú' Ṣé ìwọ ní ìpinnu ọdún tuntun?
Alátakò Kristi tí ẹ ti gbọ́ pé ó ń bọ̀ ni irú ẹni bẹ́ẹ̀.
Egbe ti won sese da sile naa so pe, awon ni won wa nidi ikolu ti o waye ni ojo kejila osu kejila odun 2016, eyi ti won fi dode ipago awon omo-ogun ijoba orile-ede Burkina Faso ti o wa ni apa ariwa enu ibode orile-ede Mali, ninu eyi ti awon omo-ogun ijoba mejila ti padanu-emi won.
Ẹ̀yí mú ìrìnàjò nínú igbó náà rọrùn púpọ̀.
Bakan naa lo kede pe dandan ni lilo iboju-bomu laarin igboro.
Eyi waye nibi ipade apero ẹgbẹ awọn oṣere Yoruba to n jẹ TAMPAN ni ilu Ibadan olu ilu ipinlẹ Oyo.
” Eyi tun mosi pe, iyanselodi si tesiwaju,”Awon oluko bere iyanselodi lojo karun un osu kokanla odun ti a wayii lataari kikuna ijoba apapo lati mu igberu ba ile-iwe giga fafiti ijoba eleyi ti won seleri lati se lodun 2009.
Ọ̀rọ̀ wọn dàbí egbò-rírùn tí ó ń kẹ̀ siwaju.
N óo gbàkóso ẹnu rẹ ati ẹnu rẹ̀; n óo sì kọ yín ní ohun tí ẹ óo ṣe.
Alafia ti yoo mu ba ilu ni ki ẹ jẹ ki a sọ.
Ogbeni Zoro Sani to ti figba kan je alaga egbe awon akoroyin to wa lara awon to side eto naa ni Kano soro lori awon ona igbalode ti iroyin fi n tan kaakiri laye ode oni ni eyi ti opo ninu awon iroyin naa je kikida iro ati oro asorege gbogbo.
Tí a fiṣọwọ́ ní 5:34 5 Ọ̀pẹ̀ 20205:34 5 Ọ̀pẹ̀ 2020 'Àwọn èèyàn sọ fún mi pé bí mo bá mọ ìyà ọmọ tó jáná, mi ò bá má bá a wí' Video content Video caption: Olumuyiwa Bolade Adedeji Military Bruitality: Bí arákùnrin onípèníjà ara tí sọ́jà lù ṣe déOlumuyiwa Bolade Adedeji Military Bruitality: Bí arákùnrin onípèníjà ara tí sọ́jà lù ṣe dé Arakunrin naa ti ṣaaju sọ pe òun yóò lọ fi ẹjọ sùn ni Bareke Letmack ni agbegbe Mokola gẹ́gẹ́ bi òfin ṣe láásílẹ̀ Article share tools Facebook Twitter ṢàpínlòView more share options Share this post Copy this linkKà síwájú síi nípa àwọn ìtọ́kasí wọ̀nyí.
Oniruuru ọrọ ni awọn eekan pẹlu n sọ lori rẹ lori oju opo twitter, Facebook, Instagram atawọn ọpọ miran, yala lati gbe sẹyin Busọla aya Dakolo abi Pasitọ Biọdun Dakolo.
Laipẹ yii ni awọn ọlọpa tu awọn inu kan to wa ni oju ọna marosẹ Ọwọ si Ikarẹ ati eyi to lọ lati Akurẹ si Ọwọ nibi ti igbagbọ wa pe awọn ajinigbe naa fi ṣe ibuba wọn.
Se oriire ni gbe alawore ko ni, asiko yii ni Catherine pade agbẹjọro ajafẹtọ ẹni kan, John Chigiti, ẹni to gbe ọrọ yii lọ sile ẹjọ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Owó tí mo ń rí lórí Garri ni mo fi ń ran ọkọ lọ́wọ́' Oríṣun àwòrán, NLC Àkọlé àwòrán, Jànduku yabo àwọn to ń fẹ̀honú han níle Míńísítà O ni ìṣẹ̀lẹ̀ to wáye lónii kìí ṣe èyí to ba oju mú níbi ti wọn ti n fi ipá mu òṣìṣẹ́ pẹ̀lu ìbọn, to si jẹ pe àwọn oṣiṣẹ́ lọ si ile minisita lái mu ohun ija kankan dáni.
53 Àti nítorí èyí ni èmi ti wí pé: Bí ìran yìí kò bá sé ọkàn wọn le, èmi yíò gbé ìjọ mi kalẹ̀ ní ààrin wọn.
5 1183963 Orilẹede Belgium 20294 176.
Olootu ajọ kan to n tọpinpin igbesunmọmi, Jamestown Foundation Terrorism Monitor, Jacob Zenn, sọ pe awọn iṣẹlẹ asiko yii jọ iṣẹ awọn agbesunmọmi.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Ni bayii ẹgbẹ agbabọọlu Barcelona yoo koju Liverpool tabi FC Porto ni ipele to kangun si aṣekagba idije Champions League Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Idije UEFA Champions League Ninu ifẹsẹwọnsẹ keji to tun wa lalẹ oni bakan naa, Cristiano Ronaldo gba goolu wọ le fun ikọ Juventus.
Eko-378 FCT-52 Delta-23 Edo-22 Rivers-14 Ogun-13 Kaduna-12 Kano-9 Borno-7 Katsina-6 Jigawa-5 Oyo-5 Yobe-3 Plateau-3 Osun-1 Iye awọn to ti ri iwosan ti jẹ 2856, ti awọn to si ti ku nitori arun naa lorileede Naijiria ti jẹ 273.
Gbogbo ọdún tí Jaredi gbé láyé jẹ́ ẹẹdẹgbẹrun ọdún ó lé mejilelọgọta (962) kí ó tó kú.
Bí orí ṣe yọ akẹ́kọ̀ọ́ Cameroon kan tó bọ́ lọ́wọ́ Coronavirus rèé Ìjọba Ọṣun ti dásí ìjà láàrin Oluwo àti Agbowu Aláàfin ìlú Oyo, Ikú Bàbá Yèyé tún bímọ tuntun làǹtì lanti Ìdí tí LASEMA fi dáwọ́ wíwá ọkùnrin tó bẹ́ s'ódò 3rd Mainland Bridge dúró Iroyin sọ pe wọ́n mu Chima àti awọn ọ̀rẹ rẹ mẹ́rin ni inú oṣu kejila, ọdun 2019 lẹ́yyin ti wọ́n fẹ̀sun kan wọ́n pe adigunjale ni wọ́n àti pe wọ́n n ṣe ẹgbẹ òkùnkun.
Awon meji ohun ni balogun iko naa Ikechukwu Ezenwa ati agbaboolu owo eyin Stephen Eze.
Àṣà ti ó wọ́pọ̀ ni ki Onilé gba owó ọdún kan tàbi meji.
 wón bí i ní 1940 fún ebí olówó kan ní chittagong .
Atẹjade kan ti ajọ to n ri si igbogun ti ajakalẹ arun lorilẹede Naijiria, NCDC fi sita loju opo Twitter rẹ ṣalaye pe, mẹtalelọgbọn ninu awọn eeyan naa wa ni ipinlẹ Eko, mẹẹdogun wa lati ilu Abuja, mọkanla lati ilu Borno ati meji ni ilu Gombe.
Ó wí pẹ̀lú pé nísisì yìí tí òun ti rí ohun èlò wọ̀n-ọnnì a kò ní ba òun lọ síbẹ̀ ní ọjọ́ kejì kí á wá lọ wòran.
Iru awọn iroyin ti ẹ le nifẹ si: Fọlọrunṣọ Alakija: Imọ ṣe koko 'Ara sisan kii ṣe arun' Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí kan sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
lati tubọ maa ta awon eniyan lolobo ti won ba gburo  ibi ti awon janduku tabi obayeje ba awa.
Nígbà tí Mata gbọ́ pé Jesu ń bọ̀, ó jáde lọ pàdé rẹ̀.
    Ìgbà tí ó tún di ọ̀sán ọjọ́ kejì ni nǹkan bí agogo méjìlá a tún rí nǹkan abàmì mìíràn.
Iroyin ohun fesun kan awon omo
Ko to di pe won bere si n lo ero igbalode lati dibo, opolopo  esi ibo ni won maa n se ayederu re,ni eyi to je pe ko si ohun ti enikankan lee se nipa re labe ofin, sugbon ni bayii, imo ero ti se gbogbo re ni irorun.
Oríṣun àwòrán, Thinkstock Fun idi eyi onimọ Chijioke ni asiko re ti aarẹ Naijiria ati awọn Gomina ni lati ṣan ṣokoto wọn daada ki wọn si mu adinku ba owo inakuna.
Igbakeji ọga awọn ọlọpaa Sharia ni Kano, Mallam Tasiu sọ pe ọwọ tẹ awọn ọkunrin naa nibi apejẹ ọjọ ibi ọkan ninu wọn ladugbo Badawa ni ilu Kano.
"Aarẹ Amẹrika tẹlẹri sọ pe aworan oun ti Kehinde Wiley, to jẹ ọmọ Nigeria ya jẹ ""eyi to dara""."
Ẹnikẹ́ni kò ní lè sọ nípa ìran rẹ̀.
lorun won,eyi ni eto ilanaati ofin wa sọ” .
Ìyapa bẹ́ sáàrin àwọn eniyan ninu ìlú; àwọn mìíràn fara mọ́ àwọn Juu, àwọn mìíràn fara mọ́ àwọn aposteli.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Coronavirus in Nigeria: Ǹjẹ àgbo lè ṣe òògùn coronavirus?
Rárá o, ẹ kò gbọdọ̀ sìnkú akẹ́kọ̀ọ́ LASU tí wọn fi ṣe òògun owó - Ìjọba Eko yarí Ọlọ́pàá hú òkú akẹ́kọ̀ọ́ fásítì LASU tí ọ̀rẹ́kùnrin rẹ̀ àti pásítọ̀ ṣekúpa Irọ́ ni pé a fẹ́ fowó kún owó iná mọ̀nàmọ̀nà- NERC Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Inu mi bàjẹ́ nígbà tí mo bí i, odidi oṣù mẹ́ta, mi ò lè gbàdúrà s'Ọ́lọ́run' Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 3 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 5 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Ìjà Awolowo, Akintola àti ogun 'Wẹtiẹ', ẹ̀kọ́ wo ló kọ́ wa?
Kì í ṣe ohun tí àwọn eniyan yóo máa sọ pé, ‘Ó wà níhìn-ín’ tabi ‘Ó wà lọ́hùn-ún.
Lẹ́yìn ọ rẹyìn, ìjọba Kwara wó Ilé Arugbó Saraki lulẹ̀ ní Ilorin Lẹyin ọ rẹyin, ijọba ipinlẹ Kwara ti pada wo 'Ile Arugbo' to wa ni ilu Ilorin.
Kété ni àwọn òṣìṣẹ́ pajáwìrì bọ sibẹ̀ láti gbé awọn ènìyàn to fara pa ti wọ́n sí gbé àwọn to ti kú náà kúrò.
Gbogbo ìdílé baba mi pátá ni ó yẹ kí o pa, ṣugbọn o gbà mí láàyè; o sì fún mi ní ẹ̀tọ́ láti máa jẹun níbi tabili rẹ.
Ẹni ọdun mẹtalelogoji ni Egbegbe ti ọwọ ofin tẹ lori ẹsun pe o fi ọna eru gba owo lọwọ awọn to n ṣe pasiparọ owo ti ko din ni ogoji kaakiri ilu Eko.
Oríṣun àwòrán, Ruth Procopi Awọn alaṣẹ Amerika ti fofin de awọn arinrinajo lati awọn orilẹ-ede mẹrindinlọgbọn to wa ni ilẹ Yuroopu, ṣugbọn ti ki ṣọmọ ilẹ Amerika.
Solomoni lọ sí Esiongeberi ati Elati ní etí òkun ní ilẹ̀ Edomu.
wahala sile ni awon apa ibi kan lorile ede yii bi awon ipinle  Borno, Yobe ati Adamawa laarin odun mesan an,tun
Ọgbẹni Ogundamisi ko sai ṣalaye pe , awọn ọmọ Ilẹ Gẹẹsi n jẹ anfani to pọ gan bi orilẹede naa si ti n ba ajọ EU ṣe papọ.
''Wọn ṣi n san owo fawa oṣiṣẹ ijọba ipinlẹ,ti ibilẹ ni a ti ni ipenija'' Ko si ofin kankan to lodi si ki owo oṣu oṣiṣẹ maa di sisan saaju ki o to ṣiṣẹ tan ni Naijiria amọ ohun ti o wọpọ ni ki awọn Gomina ma j oṣiṣẹ lowo oṣu.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Iye àwọn tó ń ní Covid-19 ti ń pọ̀ ju ilé ìwòsàn lọ, tó bá yá ọwọ́ wa ò ní ka mọ́ - NCDC Kí ló ma n fa Àkúfà nílẹ̀ Yorùbá, àti ọ̀nà àbáyọ?
Ẹni to bori: Madagascar Ghana vs Mali.
Inú bá bí Nebukadinesari gidigidi, ojú rẹ̀ yipada sí Ṣadiraki, Meṣaki ati Abedinego.
Kò sí súnkẹrẹ-fàkẹrẹ mọ lópópóna márosẹ̀ Eko si Ibadan Àwọn agbébọn pa ènìyàn mẹ́rinlá lásìkò ìjọsìn Erin mẹ́fa wó níbi tí wọ́n ti fẹ́ dóòlà ẹ̀mí ara wọn Àwọn ìmúra málegbàgbé Dino Melaye níle aṣòfin àgbà Awọn ọna wo ni batiiri rẹ ṣe fi le pẹ sii lọwọ rẹ?
Ortum ni Benue jẹ ipinlẹ to kun fun agbẹ alarojẹ ati alada nla, fun idi eyi awọn darandaran n ba ere oko wọn jẹ ni.
“Bí ẹnikẹ́ni ninu àwọn ọmọ Israẹli tabi àlejò tí ń ṣe àtìpó láàrin wọn bá jẹ ẹ̀jẹ̀, èmi OLUWA yóo bínú sí olúwarẹ̀, n óo sì yọ ọ́ kúrò láàrin àwọn eniyan rẹ̀.
Nítorí Ọlọrun fi sí ọkàn wọn láti ní ète kan náà, pé àwọn yóo fi ìjọba àwọn fún ẹranko náà títí gbogbo ohun tí Ọlọrun ti sọ yóo fi ṣẹ.
Gege bi omo orile-ede Naijiria, a ni ojuse lati dena kiko awon iru ounje bee wole, a n yii awon eniyan wa lokan pada, lati maa se ra iru awon ounje bee.
A kò sí lára àwọn tó ń ṣèwọ́de tako èlé owó epo àti iná ọba - NLC Ẹgbẹ awọn oṣiṣẹ lorilẹede Niajiria, NLC ti ni awọn ko gbero lati ṣe ifẹhọnuhan tako owongogo bẹntirol ati ina mọnamọna.
Ko si sẹni to le e sọ pe ti Basọrun Gaa ko jẹ eeyan gidi, ko sẹni to le fi jẹ oye Basọrun, to jẹ olori igbimọ lọbalọba fun Alaafin, tii se Ọyọmesi.
Ẹni to bori: Algeria Madagascar vs Ghana.
ọgbọ̀n ẹ̀gbẹ̀rún naira(N30,000 ) fun awọn osisẹ won
Àtìmọ́lé àti ìdápadà Wakabi sí Uganda jẹ́  ìtẹ̀síwájú ìdojú-ìjà-kọ òmìnira ọ̀rọ̀ tòun èrò ọkàn ẹni ní Tanzania.
Ti ẹni to n kọ idanwo ba si ti gbaaye lati lọ ṣe gáá, yo lọ pade wọn.
“Mo ti gbọ́ kíkùn tí àwọn ọmọ Israẹli ń kùn, wí fún wọn pé, ‘Ní ìrọ̀lẹ́, ẹ óo máa jẹ ẹran, ní òwúrọ̀, ẹ óo máa jẹ burẹdi ní àjẹyó.
Ta ba ni ka mọọ ka ni eni, eji, ẹta, o ni iye awọn obinrin to ti gbegba apoti ibo, ninu wọn si la ti ri Sarah Jubril, Olurẹmi Sonaiya, Oby Ezekwesili, Olurẹmi Tinubu, Olurẹmi Olujinmi, ati bẹẹbẹẹ lọ.
Iṣẹ́ Ọlọrun ni àwọn aláṣẹ ń ṣe, nǹkankan náà tí wọ́n tẹra mọ́ nìyí.
fihan awon eniyan mi pe , adari ni o gbọdọ saaju ogun.
Njẹ́ lóòótọ́ ni ayé máa parẹ́ bí?
Ṣùngbọ́n gbogbo oun tí ó njí ni ó nkó fún tálákà ati aláìní.
Ile ibi itoju naa ti o wa
ona aito ni won fi joye.
Abrahamu fún Abimeleki ní aguntan ati mààlúù, àwọn mejeeji bá jọ dá majẹmu.
Atẹjade naa tun sọ pe Tinubu ni ti wọn ba gba Buhari laaye pẹrẹ, afaimọ ko maa pin orilẹede Naijiria, ati pe iwa ẹlẹmyamẹya Buhari le ṣakoba fun iṣọkan fun Naijiria.
Stadium niluu Kiev, lorile-ede Ukraine, atamatase agbabboolu iwaju fun Chelsea Olivier
Nígbà tí ó di ọjọ́ kẹta tí wọ́n ti bá àwọn eniyan náà ṣe àdéhùn, ni wọ́n gbọ́ pé nítòsí wọn ni wọ́n wà, ati pé aládùúgbò ni wọ́n.
Iroyin ọhun tẹsiwaju pe, wọn gbe Patricia lọ sile iwosan fun itọju, ti wọn si ti gbe oku Emmanuel lọ sile igboku si.
Yinka Ayefele le è dúró kọrin pẹ̀lú kẹ̀kẹ́ tuntun O ni Akala ti da oun to fẹ da laye papaa julọ lagbo oṣelu, ''eyi gan lo jẹ ko pinnu lati fun awọn to wa lẹyin ninu ẹgbẹ lati dije.
Nigeria vs Madagascar: Super Eagles ń gbáradì fún ọjọ́ àìkù
Gẹgẹ bi ara igbesẹ lati dena ifẹmiṣofo, awọn ijọba ipinlẹ kọọkan ti n gbe igbesẹ nitori rẹ lati ti ileewe pa.
Ṣugbọn yóo kùnà ninu ète rẹ̀.
" Ọga agba nile ẹkọ Fasiti Ilorin nigba naa, Ọjọgbọn Abdulraman Oloyede lo paṣẹ pe a ko gbọdọ lọ sibi apejẹ mọ bii akẹkọọ.
Ènìyàn 838 míràn ló tún ṣẹ̀ṣẹ̀ lùgbàdì ààrùn Covid-19 ní Nàìjíria Oríṣun àwòrán, NCDC Ajọ to n gbogun ti ajakalẹ aarun lorilẹ-ede Naijiria, NCDC ti kede pe eeyan 838 miran ti kun iye awọn to ti ni aarun COVID-19 ni Naijiria.
Amọ, ni ile iwe ti ọlọdun mẹta akọkọ ni girama, awọn to mọ iwee ka ati kikọ jẹ 91% ati 96%.
Wọ́n mú àkọsílẹ̀ wọnyi ṣẹ nígbà tí wọ́n dá a lẹ́bi ikú.
Èyí ni àwọn ìdí tí ìjọba ìpínlẹ̀ Kano ṣe rọ Emir Sanusi Lamido l'óyè Báyìí ni ayẹyẹ wíwé láwàní Mike Zhang ọmọ China ṣe lọ Lẹ́yìn tí wọ́n yọ ọ́ nípò, Sanusi Lamido Sanusi gba ẹ̀bùn tuntun Àwòrán tó làmìlaaka níbi ọdún iléyá Bakan naa lọdun 2012, Igbimọ lọbalọba ilu Kano, fi ofin de adura Eid, nitori pe ara Emir ilu Kano nigba naa, Alhaji Ado Bayero ko ya.
Iko agbabọọlu Chelsea ti pegede bayii
Femi Adebayo, Bimbo Akinsanya sọ ìdí tí wọ́n ṣe fi ìgbéyàwó wọn àkọ́kọ́ sílẹ̀ kó tó bọ́ sórí 'Orin tàkasúfèé ló wù mí kí n máa kọ ṣùgbọ́n Hijab kò jẹ́' Ní ìgbẹ̀yìngbẹ́yín, orílẹ̀èdè UK fi àjọ EU sílẹ̀ Bí Favour ṣe sùn, mo gbá ọmọ odó mọ́ ọ lórí a sì gé orí, ọkàn àti ọyàn rẹ̀ fún àsèjẹ - Kayeefi Sinimá tí Lateef Adedimeji dá nikan jẹ́ òṣèré yóò jáde, Yemi Solade fi ọ̀pọ̀ fọ́tò dẹngẹ pó"" lọ́jọ́ ìbí rẹ̀ Lọdun 2017 ni Aarẹ Amẹrika, Donald Trump kọkọ gbe igbesẹ bibẹgi dina m awọn orilẹede ki wọn ma wọ Amẹrika."
Láti ilẹ̀ ni wọ́n ti ṣe àwọn agbè yìí ní àṣepọ̀ mọ́ agbada omi náà.
, igbimo naa ri i pe , o yege lati jẹ adari ajo ti yoo maa ri si oro omo orile
Adájọ́ pàṣẹ pé kí wọ́n o fi àwọn afurasí tó pa ọmọ Fasoranti sí ọgbà ẹ̀wọ̀n O ni ki wahala naa ma baa le fẹ se oun lese, oun a maa ri pe onikaluku lo ni isẹ tiẹ ti yoo ṣe lojumọ.
 ( ojoibi october 29 , 1950 ) ni aare ikokanla lowolowo orile-ede turki lati 28 august 2007 .
Fidio to n ja ranyin lori ayelujara ṣe afihan awọn eniyan to n ho ye e nigba ti awọn ẹlẹwọn naa n fo jade gba ogiri ọgba ẹwọn naa.
 Ìyàwó rẹ ni matusko miki .
Ejò lé àwọn aṣòfin ìpínlẹ̀ Ondo kúrò nípàdé Atamatase ni, Moussa Dembele naa yoo wa lara awọn to ṣeeṣe ki wọn o ta Romelu Lukaku.
Opeyemi Babalola bẹnu ẹtẹ lu bi awọn ohun amaye dẹrun gege bi ọkọ ojurin ati ile ise ipọnpo ko se sisẹ to ni Naijiria.
Àwọn àmì tó fi mọ̀ pé wọn ń fipá bá ọmọdébìnrin rẹ lòpọ̀ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fọ́nrán ohùn, Kọ́ ọmọ rẹ lẹ́kọ̀ọ́ ìbálọ̀pọ̀- Ọ̀jọ̀gbọ́n Fagbohungbe 'Ibi àríyá ni àbúrò mi d'ágbére kí ọlọ́pàá tó fi ẹ̀sùn ìbálòpọ̀ akọ-sí-akọ kàn án' Wo bí o ṣe lè kọ́ ọmọ rẹ lẹ́kọ̀ọ́ ìbálòpọ̀ Iléẹjọ́ fi Ọ̀jọ̀gbọ́n tó bèérè fún ìbálòpọ̀ ní fásitì OAU pamọ́ sọ́gbà ẹ̀wọ̀n Pásítọ̀ ọmọ Nàìjíríà, Omotoso, tí wọ́n fi ẹ̀sùn ìfipábánilòpọ̀ kàn pàdánù ìwé ìgbélùú ní South Africa A gbọ pe ṣe ni sọja kan, Lance Corporal mu akẹkọbinrin ọhun ni dandan lati bọ silẹ ninu ọkọ ero kan ti o si paṣẹ pe ki awọn to ku ninu ọkọ maa lọ.
 Ó gbà pe obinrin ni òdàlẹ ̀ ni wọn .
"Awuyewuye bẹrẹ lẹyin ti iwe iroyin Sahara Reporters, sọ pe ilu Dubai ni Aisha fi ṣe ibugbe bayii ""nitori pe ko si aabo fun un ni ile ijọ Aso Rock'."
Oríṣun àwòrán, Getty Images Bíbéèrè fún ìbálòpọ̀ gbogbo ìgbà sọ ìyàwó ilé dèrò ilé ìwòsàn Ẹ̀mi arákùnrin yìí kò gbé e, ó bá aláṣẹ́wò lò dórí ìgbà ìkéje ló bá ré sálákeji Wo bí o ṣe lè mọ orúkọ àwọn afípabánilòpọ̀ ní Nàìjíríà Wò ó ọ̀nà láti mú ara rẹ dé ibi tó ga jùlọ nínú ìbálòpọ̀ pẹ̀lú ìlànà Tantra Narasimhan fikun ọrọ rẹ pe ọpọ lọkọ-laya gan ni ko sun mọ ara wọn mọ bi ti tẹlẹ ki coronavirus to de.
Wayi o, ileesẹ ofurufu Dana ti wa sẹ kanlẹ pe ilẹkun baalu awọn kankan ko ja bọ rara.
Ẹwẹ, lẹyin ọpọlọpọ ọjọ ti ile ẹjọ di da a lẹbi pe o tapa si ofin konile o gbele nipinlẹ Eko, gbaju-gbaja oṣerebinrin, Funke Akindele-Bello ti sọrọ lori iṣẹlẹ naa.
ati ní Jeṣua, ati ní Molada, ati ní Betipeleti, 
Abenugan ile –igbimo asofin agba Bukola Saraki ti yan igbimo elenu-mewaa lati maa samojuto irinajo lo sile mimo musulumi ati kirisiteni.
Tí a fiṣọwọ́ ní 19:24 9 Ọ̀pẹ̀ 202019:24 9 Ọ̀pẹ̀ 2020 Ààrẹ Akufo-Addo la Mahama mọ́lẹ̀ wọlé ìbò ààrẹ Ghana fún sáà kejì Ghana election: Ààrẹ Akufo-Addo la Mahama mọ́lẹ̀ wọlé ìbò ààrẹ Ghana fún sáà kejì Facebook/Nana Akufo-AddoCopyright: Facebook/Nana Akufo-Addo Aarẹ orilẹde Ghana, Nana Akufo-Addo ti wọlẹ ibo aarẹ ilẹ fun saa keji.
5 Ẹrẹ̀nà 2018 Oríṣun àwòrán, Getty Images/Reuters Ami ẹyẹ Oscars waye mọju oni.
Ẹ̀yin olùṣọ́-aguntan, ẹ sọkún tẹ̀dùntẹ̀dùn, ẹ kígbe.
- Trump Ṣé Coronavirus leè tẹ̀lé ọjà Chinco wọ Nàìjíríà?
Gomina Fayose ke si ijọba apapọ lati ji giri si ọrọ abo ẹmi ati dukia paapaa julọ 'lọwọ awọn ọdaran to n pe arawọn ni darandaran ti wọn ti wa sọ ara wọn di adukulajamọni .
Nígbà náà ni àwọn tí wọ́n ti ń gbé ilẹ̀ náà mú ìrẹ̀wẹ̀sì ọkàn bá àwọn ará ilẹ̀ Juda, wọ́n sì dẹ́rùbà wọ́n, kí wọ́n má baà lè kọ́ tẹmpili náà.
29 Àti lẹ́hìn rírí àkọsílẹ̀ ti àwọn ará Néfì gbà, Bẹ́ẹ̀ni, àní ìránṣẹ mi Joseph Smith, Kékeré, lè ní agbára láti túmọ̀ Iwé ti Mọ́mọ́nì, nípa àánú Ọlọ́run, pẹ̀lú agbára Ọlọ́run.
"Ṣugbọn ṣa, gomina kilọ fun awọn obi, ati alakoso ileewe pe ""igba kuugba ni wọn le ṣe atunṣe tabi agbeyẹwo si igbesẹ naa."
Orúkọ ọmọbinrin Midiani náà ni Kosibi, ọmọ Suri, baálé ilé kan ní ilẹ̀ Midiani.
Lọ́jọ́ Ajé, agbára coronavirus já wálẹ̀, èèyàn 79 péré ni NCDC kéde pé ó ṣẹ̀ṣẹ̀ ní i O dabi ẹni pe itankalẹ aarun coronavirus ti n dinku lorilẹ-ede Naijiria bayii.
Adeleke ló ní ọmọ ẹgbẹ́ tó pọ̀jù l‘Ọṣun, nipò gómìnà ṣe tọ́ si ní 2022 - PDP Ọṣun Ìròyìn tó ní Tinubu fẹ́ díje sípò ààrẹ ń dá ìjà sílẹ̀ Àwọn obìnrin yarí, wọ́n kò fẹ́ àwọn ọkùnrin ní òde ijó wọn Gomina Oyetọla ni oun ṣi n wa awọn eeyan to ni iran kan naa pẹlu oun lori iṣejọba ipinlẹ naa ni.
Ninu fiimu mejeeji awọn ogbontagiri wọn ja ogun lọpọlọpọ lati bori gbogbo isoro to koju wọn ki o to di wi pe wọn yoo de ilẹ ileri.
Igbakeji adari ẹgbẹ NLC lorilẹede Naijiria, Comrade Joe Ajaero lo fi ọrọ naa lede lasiko to n ba BBC News Yoruba sọrọ lori boya ifẹhọnu han yoo waye ni ọjọ Isẹgun, Ọjọ Kẹjọ, Oṣu Kẹsan, ọdun 2020.
Wọn fikun wi pe kii ṣe awọn ọmọ Naijiria nikan ni ọran naa ba, ati awọn oṣiṣẹ wọn to wa loke okun naa faragba ninu iyoniniṣẹ naa.
Ninu atẹjade ti wọn fun lede gbatọwọ alukoro ile iṣẹ ọlọpaa nipinlẹ Ọyọ, Olugbenga Fadeyi ṣe alaye iṣẹ iwadii ti bẹrẹ ni pẹrẹu.
Kọ́ ọlọ́gbọ́n, yóo tún gbọ́n sí i,kọ́ olódodo, yóo sì tún ní ìmọ̀ kún ìmọ̀.
Ó bá rán àwọn kan ninu àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ kí wọ́n lọ bi í pé, 
 Ijoba ibile Igabi , Kajuru ati Chukum naa n fakoyo.
Awọn eeyan naa ṣalaye fun BBC pe ọpọ igba ni awọn eeyan l'Amẹrika ma na sọrọ abuku si wọn nitori awọ ara wọn.
Wá, jẹ́ kí n gbà ọ́ nímọ̀ràn kan, bí o bá fẹ́ràn ẹ̀mí rẹ, ati ẹ̀mí Solomoni, ọmọ rẹ.
Naomi Adamu se àkọsílẹ̀ ìgbé ayé rẹ̀ ni àgọ́ Boko Haram
Yóo ti ìka ọ̀tún rẹ̀ bọ òróró tí ó wà ní ọwọ́ òsì rẹ̀, yóo sì fi ìka rẹ̀ wọ́n òróró náà níwájú OLUWA ní ìgbà meje.
Won ni won yoo maa kede awon to ku ninu isele naa ni kete ti won ba ti n da won mo.
Ó bá dá wọn lóhùn pé, “OLUWA Ọlọrun Israẹli ní kí n sọ fun yín, kí ẹ sọ fún ẹni tí ó ran yín sí mi pé 
Iye àwọn tí wọ́n wà ninu ìpín rẹ̀ jẹ́ ọ̀kẹ́ kan ó lé ẹgbaaji (24,000).
ìjọba àpapò wa fikun wi pe ti awọn ba fikun owo bi ẹgbẹ osisẹ se beere rẹ, iye owo ti ijọba a ma a san fun owo osu.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Awọn olufẹhonu han naa fi ẹsun kan pe, ijọba n fi ẹmi wọn wewu lọwọ awọn alarun ọpọlọ ti wọn ba gbe wa sileewosan naa, nitori pe gbogbo igba ni wọn maa n kọlu wọn.
Lara iyalẹnu to wa lori ọrọ ẹgbẹ yii ni pe, tako igbagbọ pe ọkunrin nikan lo maa n wa nidi ipanle, ati ẹgbẹ okunkun, awọn ọdọmọbinrin naa wa ninu ẹgbẹ Awawa Boys.
Sibẹsibẹ ọkàn Farao le, kò sì jẹ́ kí àwọn eniyan náà lọ.
Gbogbo igbiyanju wa lati pa ina naa lo ja si ofo.
Mose bá tẹ́ pẹpẹ kan, ó sì pe orúkọ rẹ̀ ní “OLUWA ni àsíá mi.
Kò si ìyàlẹ́nu ni irú iwà ti àwọn ọmọ ọlọ́rọ̀ Nigeria wọnyi hù nitori ọ̀pọ̀lọpọ̀ wọn bàjẹ́, wọn kò ni ẹ̀kọ́, wọn kò mọ iyi owó nitori wọn kò ṣiṣẹ́ fun.
Ọkan lara awọn agbẹjọro to wa nibi igbẹjọ naa sọ pe ni ilana ofin, ko tii si aridaju kankan ti wọn fi lelẹ pe o jẹbi ẹsun ti wn fi kan an.
Ó tẹnu mọ́ ọn títí a fi gbà.
Nítorí olùgbẹ̀san ẹ̀jẹ̀ ranti,kò sì gbàgbé igbe ẹkún àwọn tí a pọ́n lójú.
Wọ́n ti ti ilé ìjọba Kwara pa ní Ilọrin nítorí ọ̀rọ̀ ilẹ Arúgbó!
Nítorí bí Jona ti di àmì fún àwọn ará Ninefe, bẹ́ẹ̀ gan-an ni Ọmọ-Eniyan yóo jẹ́ àmì fún ìran yìí.
Nígbà tí wọ́n gbọ́ pé Jesu ń kọjá lọ, wọ́n kígbe pé, “Ọmọ Dafidi, ṣàánú wa.
Ogun bẹ́ sílẹ̀ láàrin àwọn ará Filistia ati àwọn ọmọ Israẹli.
" Oríṣun àwòrán, Aketi Àkọlé àwòrán, Owó gọbọi wá nídìí oko-owo igbó gbingbin, Ìpínlẹ̀ Ondo kò ní pẹ gba àṣẹ láti gbin - Akeredolu Akeredolu, nígbà tó ń ṣàlàyé ìdí tí Ìpínlẹ̀ Ondo ṣe fà sẹ́yìn nínú èsi idanwo asejade làwọn ilé ẹ̀kọ́ gírámà, ó ṣàlàyé pé, àwọn akẹ́kọ̀ọ́ nipinlẹ náà ń ṣe daada àmọ́ ó ni bí ọmọ ṣe pọ sì láti jókòó ṣe idanwo asejade ilé ẹ̀kọ́ gírámà, ní wọ́n se n tó àṣeyọrí ìpínlẹ̀ kọ̀ọ̀kan sí.
Nínú àtẹ̀jáde kan tí igbákejì agbẹnusọ iléeṣẹ́ ọlọ́pàá, Abayomi Shogunle, gbé jáde lórukọ ọ̀gá ọlọ́pàá ní orílẹ̀èdè Naijiria, Ibrahim Idris ni Ọjọ́rú, ó ní NHRC yóò lọ wo ọ̀nà bí wọ́n ṣe ń ti àwọn ènìyàn mọ́'lé.
Wọn ní bi ọ̀rọ̀ ètò ẹ̀kọ́ ṣe ń lọ kò bá ojú mú rárá, nítorí pé iná ètò ẹkọ́ ń jó àjórẹ̀yìn.
Oríṣun àwòrán, Reuters Àkọlé àwòrán, T'ọmọdé tí agbà ló má n ṣé isẹ́ ibadah oríṣiríṣi nínú oṣù Ramadan Ẹyonda mi sir"" Oṣiṣẹ ilera nílu Abuja ni Ọgbẹni Jimoh Jeleel Anjọrin."
Ìkéde yìí jẹyọ lójú òpó twitter àjọ tó ń gbógun ti àjàkálẹ̀ ààrùn ní Nàìjíríà (NCDC) ní alé ọjọ́bọ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Fulani Kidnapping: Owó púpọ̀ la san kí wọ́n tó fi mi sílẹ̀ O wa pari ọrọ rẹ pe bi kii ba se pe ọkọ ọhun duro fun isẹju marun lati gbe eeyan kan nilu Efon Alaaye ni, ọwọ awọn ajinigbe naa ni oun ko ba ko si.
Ogbeni Osita fi ehonu re han pe, oun yoo lo anfaani yii bi o ti to ati bi o ti ye lati fi satileyin fun ipa aare Muhammadu Buhari lati mu atunse de ba ile-ise to n ri si ipese eedu ati mimu igberu de ba awon ohun amayederun ni agbegbe yii lolokan-o-jokan.
Ọkan lara awọn dokita ọhun to fi iwe ranṣẹ si BBC ni iṣẹ abẹ to ba ṣe koko julọ ni wọn ma n dojukọ nitori pe awọn oṣiṣẹ ko to.
K Odukoya 'ń gun orí òkè àdúrà nítorí COVID-19'-Wò báwọn èèyàn fi wò wọ́n Iléeṣẹ́ aṣọ́bodè yarí, kò gba ìrẹsì tó bàjẹ́ padà lọ́wọ́ Ṣeyi Makinde Aarẹ Buhari fi iwe kan ṣọwọ si ileegbimọ aṣofin agbalorilẹede Naijiria ni ọjọ Iṣẹgun ninu eyi to kọ orukọ awọn eeyan mẹtadinlogoji to fẹ yan si ipo lai mọ pe Ọgbẹni Okwuru ti jade laye loṣu keji ọdun 2020.
"Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: ""Mo fa Fayoṣe lé Ọlọrun lọ́wọ́"" Hubert Ogunde rèé, baba àwọn òsèré tíátà Ìpàdé ìjọba ati ASUU forí sánpọ́n Buhari buwọ́lu owó oṣù tuntun fáwọn ọlọ́pàá Buhari yarí, ó ní ẹni bá ń bínú ní APC leè lọ sílé ẹjọ́ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Jide Kosọkọ: Isẹ́ tíátà yóò gòkè tíjọba bá gbówó kalẹ̀ láti seré Bi awọn kan ṣe n kan saara si Arẹgbẹsọla fun iṣẹ ribiribi to ṣe nigba to jẹ Gomina, lawọn miran n bẹnu atẹ lu ijọba rẹ pe ki lo se gan?"
Ṣugbọn Eleasari dúró gbọningbọnin, ó sì bá àwọn ará Filistia jà títí tí ọwọ́ rẹ̀ fi wo koko mọ́ idà rẹ̀, tí kò sì le jù ú sílẹ̀ mọ́.
O ni igbesẹ ti Facebook gbe lati din ifihan fidio to ba wọpọ kuru, ti jẹ ki ida marun awọn eniyan o lọra lati ma lo akoko to pọ loju itana Facebook.
to wa ni Oshodi ati papa oko ofurufu ti ile okeere ati ọkọ  agbero nla to 
ede Naijiria naa, ko lee  se dibo lati ibikibi
 Ṣùgbọ ́ n nínú ìwé yìí mo ṣe àyẹ ̀ wò púpọ ̀ àwọn ẹ ̀ ka-ède yorùbá léte àti pe àkíyèsí sí fonẹ ́ tíìkì àti fonọ ́ lọ ́ jì ẹ ̀ ka-èdè wọ ̀ nyí .
Nítorí pé, nígbàkúùgbà tí àwọn ọmọ Israẹli bá gbin ohun ọ̀gbìn wọn, àwọn ará Midiani ati àwọn ará Amaleki ati àwọn kan láti inú aṣálẹ̀ tí ó wà ní ìhà ìlà oòrùn, a máa kó ara wọn jọ, wọn a lọ ṣígun bá àwọn ọmọ Israẹli.
Nígbà ti bàbá mi yọ ìhà ìhín, ti òun náà yọ ní ìhà ọ̀hún àwọn méjéèjì dúró wọ́n ń wo ara wọn: nítorí nígbà ti àjànàkú bá pàdé àjanàkú dandan ni kí igi máa wó lu ara wọn.
Ìrètí tí ó wà fun yín ni ọ̀run, tí ẹ gbọ́ nípa ọ̀rọ̀ òtítọ́ ìyìn rere, ni orísun igbagbọ ati ìfẹ́ yín.
 Àpẹẹrẹ kan ni fíìmù láídé bákàrè ; ijóyá .
Auxiliary ń ní wá lára pẹ̀lú gbígba owó aitọ, a ń ko ọkọ̀ wa kúrò lójú pópó - Awakọ èrò Ayinla Ọmọwura, orin èébú àti oríyìn lo fi di ọ̀rẹ́ àwọ̀n obìnrin Ọwọ́jà coronavirus yóò ṣì wà pẹ̀lú àgbáyé fún ìgbà pípẹ́- Ngozi Okonjo-Iweala Ìjọba àpapọ̀, ẹ so ifilọlẹ ẹ̀rọ alatagba 5G rọ na - ilé asofin àgbà Oríṣun àwòrán, others Àtakò tí aba náà ni lórí ayélujára pọ débi pé agbarijọpọ ẹgbẹ́ àwọn ọmọlẹ́yìn Kristi, CAN gan tí kesi ilé asofin pé ko jawọ nínú sísọ di òfin, tí sẹnatọ àná kan sì ti gbé ọ̀rọ̀ náà lọ sile ẹjọ́.
Aare tun tenumo oro re pe, erongba isakoso re lati koju iwa ibajẹ lorile-ede yii yoo tun tesiwaju si, bi o ti le je pe ko rorun rara.
Premier League: Everton da yẹ̀pẹ̀ sí gaàrí Manchester United
O wa ro akegbe re Aare putin oun pe, ki o ri ipo yii gege bi ona kan lati tesiwaju lori ipolongo fun isokan ati alaafia lagbaye.
Bayii wọn ti fẹ bẹrẹ igbẹjọ Mohammed Sheikh Khalid ti wọn ni oun ni ọpọlọ to wa nidi awọn agbesunmọmi iṣẹlẹ ọhun.
Osise ijoba kan tun fi ipo tuntun naa mule.
Ó bá sọ fún wọn pé, “Ẹ lọ sí gbogbo ayé, kí ẹ máa waasu ìyìn rere fún gbogbo ẹ̀dá.
Bákan náà ni aṣọ títa ẹ̀gbẹ́ kinni keji ẹnu ọ̀nà náà rí, wọ́n gùn ní ìwọ̀n igbọnwọ mẹẹdogun mẹẹdogun, wọ́n ní òpó mẹta mẹta ati ìtẹ́lẹ̀ mẹta mẹta.
Bakan naa ni Omowe Tedros tun salaye fun awon asoju orile-ede nibi ipade igbimo ajo agbaye ohun pe” ipinnu oun  ni gbogbo igba ni  lati mu ileri oun se nipa nimu  iyato wa lasiko isakoso oun naa”.
Ìjì líle kan bá dé, omi òkun bẹ̀rẹ̀ sí bì lu ọkọ̀ tóbẹ́ẹ̀ tí omi fi kún inú rẹ̀.
 Aare soro naa di mimo lasiko to n se ipade po pelu awon omo egbe tuntun ti won se dibo yan ohun, eleyi ti o waye ni gbogan ile ise aare, lojo isegun(Tuesday), niluu Abuja.
12 Ìgbé 2020 Ori eto ṣe o laya ti BBC News Yoruba lo ti dahun awọ̀n ibeere to jẹ mọ̀ asa, iṣesi ati owe Yoruba.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Fadá méjì, ọmọ ìjọ 13 kú nínú ìkọlù darandaran Fadá méji, ọmọ ìjọ 13 kú nínú ìkọlù darandaran ‘Àìtó ọlọ́pàá ló mú kí olè ja Ọ̀ffà’ Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Wọ́n dàbí ẹranko tí kò lè ronú, tí a bí gẹ́gẹ́ bí ẹ̀dá, tí a mú, tí a pa.
Ṣe ka sọ pe ileeṣẹ ọlọpaa ko ṣiṣẹ to ni?
Nítorí náà, ohun tí èmi OLUWA sọ ni pé, àwọn wolii tí n kò rán níṣẹ́, tí wọn ń jíṣẹ́ orúkọ mi, tí wọn ní èmi sọ pé ogun ati ìyàn kò ní wọ ilẹ̀ yìí, ogun ati ìyàn ni yóo pa àwọn gan-an run.
salaye pe ajo naa yoo tẹsiwaju ninu ojuse rẹ lati pese eto alaafia to peye ni ipinle
Olówó-ayé ń lọ, òun àti Ọlọ́run Ọba.
Oríṣun àwòrán, Seyi Makinde Lara awọn eeyan pataki to peju-pesẹ sibi ayẹyẹ iburawọle naa ni adajọ agba nipinlẹ Ọyọ, Muktar Abimbola ati aṣoju alaga apapọ ẹgbẹ oṣelu PDP ni ẹkun guusu orilẹede yii.
Ẹnikẹni ti ko ba kọ aja yii daadaa, o le e lugbadi ipalara lati ọwọ aja yii.
Olódùmarè ti fi àwọn ẹ̀dá ọ̀run méjì sí ìdí igi wọn-ọnnì kí wọ́n máa ṣọ́ ibẹ̀ kí ohunkóhun máa baà pa wọ́n lára.
Gbogbo obìnrin Azerbaijan ni ó fẹ́ fi ìwà jọ ìyá àgbà Saray.
Obinrin akọkọ to kọkọ kọja ori ila ni Meleka Meseret Dinke lati ilẹ Ethiopia bakan naa.
Oríṣun àwòrán, The LadyMOTARA Omotara ni: ''Gbogbo nkan ti mo gbe lọ bi i ọti ẹlẹrindodo niṣe ni mo maa n gbe e fawọn ti mo ba ri nibẹ.
Gani Adams: Ẹni ba fe pẹ laye, maa ra aye gbe ni
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Olórí ilé aṣòfin ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́ jáde láyé Èmi kò leè kú láéláé 'Àwọn aṣàtìpó àríwá yóò padà sílé láìpẹ́' Kenya rí akẹ́kọ̀ọ́ tó há sí Ṣáláńgá yọ Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Tinubu ni ''ero awọn ti wọn n tako Oshiomole ni pe o maa dina mọ wọn lati dije fun ipo kan tabi omiiran ninu idibo ọdun 2023.
Wọn yóo jẹrà, ìrísí wọn óo sì parẹ́,Àwọn olódodo yóo jọba lórí wọn ní òwúrọ̀,ibojì ni yóo sì máa jẹ́ ilé wọn.
igbimọ aṣofin ipinlẹ kaakiri orilẹ-ede Naijiria ni o sọ ọrọ yii.
Ní àkókò baba rẹ, a rí ìmọ́lẹ̀, ìmọ̀, ati ọgbọ́n bíi ti Ọlọrun ninu rẹ̀.
Ọkunrin náà bá tẹríba, ó sì sin OLUWA, 
Ọjọ́ ti pẹ́ tí a ti di yín létí,nítorí mo mọ̀ pé ẹ óo hùwà àgàbàgebè,ọlọ̀tẹ̀ ni orúkọ tí mo mọ̀ yín mọ̀,láti ìgbà tí ẹ ti jáde ninu oyún.
Igba miran o ti sọ wi pe ko si ohun to n jẹ ayipada oju ọjọ.
"Bakan naa ni ọwọja arun yii ko da orilẹede Brazil si, to fi mọ Pakistan ati Yemen, ""eyi to se okunfa ọpọ iku eeyan, ninu eyi ti ọmọde pọ si"", nigba ti iye eeyan to ni arun Ẹyi ni orilẹede Amẹrika ati Thailand naa pọ si, ti wọn si n fi abẹrẹ ajẹsara koju rẹ."
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Widows Day 2019: Mo máa ń sá kiri wá owó ilé ni -Opó Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Bi o ba wa sunmọ wọn ju bi o ti yẹ lọ, iwọ naa lee koo simu pẹlu kokoro arun yii bi o ba jẹ pe onitọun ni kokoro arun COVID-19.
Kété ti ọrọ náà bẹrẹ si ni ran ka ni BBC kan si àwọn to jẹ́ ti K1, nítori owe àgbà ló sọ pé agbẹ́jọ́ ẹnikan dájọ àgbà òṣìkà ni.
Ọkọ ati aya kò gbọdọ̀ fi ara wọn du ara wọn, àfi bí wọ́n bá jọ gbà pé fún àkókò díẹ̀ àwọn yóo yàgò fún ara àwọn, kí wọ́n lè tẹra mọ́ adura gbígbà.
Ẹgbẹ oselu APC pin iwe pẹlu asia ẹgbẹ pẹlu aworan aarẹ Buhari ati igbakeji Osinbajo lasiko idibo gbogboogbo lọdun 2019.
Lẹyin oṣù mẹta,owó náà di irú o digba mọ mi lọwọ.
O ni ti eeyan ko ba maa polowo sinima onihooho tabi asọ ti wọn fi n luwẹ, taa mọ si Bikini, ko si idi kankan fun obinrin lati si ara silẹ, fi polowo ọja kankan tabi fi fa oju awọn onibara rẹ mọra, Binta ni eyi ko nilo rarar nitori oju lasan ti to lati polowo ọsẹ tabi ipara.
Bí a bá ya gbòǹgbò igi sí mímọ́, a ti ya àwọn ẹ̀ka igi náà sí mímọ́.
N kò ní fojú fo ọ̀rọ̀ yín, n kò ní ṣàánú yín.
Pope Election: Èyí ni bí wọ́n ṣe n dìbò yan Póópù tuntun nínú ìjọ Àgùdà
Oluronbi ẹni ọgọ́tà ọdún ni wọ́n mú ní pápákọ ofurufu lásìkò tó n bọ wá sí Naìjìríà.
Coronavirus pandemic update: Wo àwọn orílẹ́-èdè tí kò ní coronavirus lágbàáyé
Ademola Adeleke to n soju ẹkun idibo Iwọ-Oorun ipinlẹ Osun ni Ile Igbimọ Asofin lo dije dupo gomina ni ọdun to kọja.
Àwọn ará Róòmù tí wọ́n tẹ̀ ẹ́ dó sọ ọ́ lórúkọ ‘Aquae Sulis’ (Àwọn Omi Sulis).
Àbí ẹ fẹ́ kó ẹ̀gàn bá ìjọ Ọlọrun ni?
Akeredolu ni igbalejo aarẹ naa pẹlu ayẹyẹ ọdun kẹta ti oun bẹrẹ iṣejọba ni ipinlẹ Ondo.
Òun ni ó ta awọsanma bí aṣọ títa,ó sì ta á bí àgọ́, ó ń gbébẹ̀.
Yoruba a maa fi ẹnu, oju, imu ati ọwọ tabi ẹya ara mii bi ẹsẹ ba ara wọn sọrọ to jẹ pe ajoji ko ni mọ ohun ti wọn n sọ.
Ilé náà gùn ní ọgọrun-un (100) igbọnwọ, fífẹ̀ rẹ̀ jẹ́ aadọta igbọnwọ, ó sì ga ní ọgbọ̀n igbọnwọ.
Ó sọ fún wọn pé, “OLUWA Ọlọrun Israẹli, ẹni tí ẹ ní kí n gbé ẹ̀bẹ̀ yín lọ siwaju rẹ̀ ní, 
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù FIFA ban: Siasia ní kò sí ìgbà tí òun àti FIFA kò ní pàdé ní kóòtù 17 Ògún 2019 Oríṣun àwòrán, others Siasia, olukọni bọọlu ọmọ Naijiria ti ajọ FIFA paṣẹ fun pe eegun rẹ ko gbọdọ ṣẹ mọ lagbo ere bọọlu lagbaye titi lahun sita pe oun afaims ki oun ati ajọ FIFA maa pade ni ile ẹjọ nitori ẹsun gbigba riba.
Nígbà tí àwọn oníṣẹ́ Dafidi dé Amoni, 
OLUWA sọ fún mi pé, “Má gbadura pé kí àwọn eniyan wọnyi wà ní alaafia.
Naijiria ko jiya yii gbe ni orilẹ-ede South Africa.
Bi o tilẹ jẹ pe Onirese Ọlabisi ọmọ Ajala ko fin igba mọ, amọ eyi to ti fin silẹ ko lee parun, nitori a ko tii ri eeyan miran to fi Ọkada rin yika agbaye mọ bii Ajala.
Ọkunrin kan wà tí ìyá rẹ̀ jẹ́ ọmọ Israẹli, ṣugbọn tí baba rẹ̀ jẹ́ ará Ijipti.
Nígbà ti a dé ìlú kan tí wọ́n wí fún mi pé etí ibẹ̀ ni ọkùnrin náà ń gbé, mo wáa lọ, èmi náà sì múra gidigidi kín tó lọ, wọ́n fi ọ̀nà inú igbó ti o ń gbé hàn mí, ó jẹ́ ojú ọ̀nà oko, nígbà tí mo sì rìn tó bí wákàtí méjì, ẹni ti ó ń ṣe amọ̀nà mi fi ojú ọ̀nà kékeré kan hàn mí tí ó yà ní apá òsì báyìí, ó dàbí ọ̀nà àwọn ọdẹ, ó bá inú igbó lọ.
Joṣua bá gégùn-ún nígbà náà pé, “Ẹni ìfibú OLUWA ni ẹnikẹ́ni tí ó bá dìde láti tún ìlú Jẹriko kọ́.
Ó ṣe pàtàkì kí a fi ọgbọ́n kún àwọn ọ̀rọ̀ náà pẹ̀lú ṣíṣe gidi.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Akomolede ati Aṣa lori BBC: Mọ̀ si nípa oríṣìí ẹ̀ka ìsọ̀rí ọ̀rọ̀ àti ìwúlò wọn Ọkunrin kan to de lati UK, Joe Ogwu bu ẹnu atẹ lu sisan owo naa.
Ṣugbọn Afẹnifẹre ni awọn to lọ ibi ipade naa, ba ọrọ ara wọn lọ ni.
Ile Igbimọ Asofin Agba ni, biliọnu mẹwaa lara afikun ti wọn se si iṣuna owo naa yoo wa fun awọn ti rogbodiyan Ipinlẹ Zamfara pa lara.
Tambuwal ti rọ awon oludamọran tuntun ti won sẹsẹ bura fun lati maa jiroro pelu
“O gbọdọ̀ ṣe àjọ̀dún ìkórè nígbà tí o bá kórè àkọ́so àwọn ohun tí o gbìn sinu oko rẹ.
Oríṣun àwòrán, @Bashir Ahmad Aarẹ Buhari wa gboriyin fun gomina Akeredolu fun iṣẹ akanṣẹ naa ti o gbe ṣe ni ipinlẹ naa, bẹẹ lo si ki ku oriire fun ayẹyẹ ọdun kẹta lori oye.
- Ìwádìí BBC Ẹ padà sílé èyin ọmọ wa tó n ṣiṣẹ́ darandaran - NEF ti Fulani O sọ pe ni Egypt lọdun 2006 loun ti ṣoju Naijiria ninu idije AFCON fun igba akọkọ, bakan naa ninu idije AFCON 2019 loun ti fi adagba rọ bọọlu gbigba fun Naijiria si.
Ìkamọ̀dù kì í lọ s’ógun àìm’ẹ́rú- bọ̀- wálé.
lára wọn ni ajá to ń lépa Ẹkùn , Ọ ̣ wọ ̣ ̣ ́ tẹ amòokùnṣìkà , Àgbákò nílé tẹ ́ tẹ ́ , baṣọ ̀ run olúyọ ̀ lé , ajayi , the bishop , chaka , the zulu , esther , the queen , abraham , the .
Nadal ti o wa ni ipo keji tele, bi o ti le je pe O tun gba ife eye igba kokanla idije French Open, ti Federer, omo odun mẹ́rìndínlógójì si gba ife-eye Stuttgart, lati di ipo kinni-in ohun mu fun igba kefa.
Ẹ ní ojú lásán ni, ẹ kò ríran?
Àwọn alufaa kò bèèrè pé, ‘OLUWA dà?
Iran Yoruba kii sọ ọmọ ni orukọ lai kọkọ wo nkan to n ṣẹlẹ ninu aye wọn, ninu ẹbi wọn ati ninu agboole wọn ki wọn to sọ ọmọ tuntun lorukọ.
Àkọlé àwòrán, Gbogbo oju popo lo kun fun omi Àkọlé àwòrán, Ọpọ ọkọ ni ojo naa tun bajẹ Bakan naa ni ojo ọhun ko ṣai tun da ọpọ iṣẹ ijọba lara.
Gege bi aare se so, ijoba yoo ri daju lati koju gbogbo idojuko to n koju eto abo lai gba iranwo nibi kankan.
O ti ro pe oun yoo di aarẹ lẹyin Boumedienne ṣugbọn awọn ẹgbẹ kan laarin awọn ologun yan Chadli Bendjedid dipo rẹ.
Ikọ̀ Boko Haram àti gbogbò àwọn tó ń sàtìlẹyìn fún wọn kò ní rí ọdún 2021 - Pásítọ̀ Adeboye Ayé má níkà o!
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Coronavirus tips: Kìí ṣe gbogbo ìbòmù ló ń dá coronavirus dúró Nigba to di ọdun 1862, wọn gba Kosoko laaye lati pada wale lẹyin to fọwọ si iwe adehun alaafia pẹlu gomina Eko, John Hawley Glover.
Ṣé ẹ lè fún gomina ní irú rẹ̀ kí inú rẹ̀ dùn si yín, tabi kí ẹ rí ojurere rẹ̀?
Atẹjade naa ni awọn afurasi mejeeji lo gba pe awọn jẹbi ẹsun naa, ti adajọ si ni ki wọn lọ san owo itanran ọgọrun naira ẹni kọọkan.
Lady Gaga ṣubú yakata níbi tó tí ń kọrin Islam kọ́ ló ni kí ọmọ ọdún méjìlá lọ sílé ọkọ- Ààrẹ ilẹ̀ Niger Bẹ̀rẹ̀ láti oṣù kẹrin ọdún yí ní ìjọba gbọ́dọ̀ tí sàn àfikún owó oṣù tuntun-NLC Àwọn arẹwà obinrin Yollywood, tá ló mọ iṣẹ́ rẹ̀ jù?
Dokita Jimoh ṣalaye pe ajọ NAFDAC mọ pe awọn ọmọ Naijiria fẹ gbọ esi ayẹwo ajọ naa lori agbo ilẹ Madagascar, o ni idi niyii ti ajọ naa yoo fi ṣiṣẹ lori rẹ kiakia.
Oluremi Adeleye: Ilẹ̀ Amẹríkà rán ọmọ Nàìjíríà lẹ́wọ̀n nítorí ó fọ́mọ lóunjẹ
Ogun kó Samaria nítorí pé àwọn ọmọ Israẹli kò pa òfin OLUWA Ọlọrun wọn mọ́, wọ́n si da majẹmu tí OLUWA bá wọn dá.
A lo kùmọ̀ títí ṣùgbọ́n àwọn èkúté wọ̀nyí ti pọ̀ ju, ko sì sí nǹkan tí a le ṣe titi ilẹ̀ fi ṣu lọ́jọ́ náà.
Joṣua ṣẹgun gbogbo wọn láti Kadeṣi Banea títí dé Gasa ati gbogbo agbègbè Goṣeni títí dé Gibeoni.
Ninu owo yi, awọn fasiti ijọba kọọkan gba N785,832,700,awọn ile ẹkọ gbogbo niṣe kọọkan gba N536,703,502 ti awọn ile ẹkọ olukọni si gba N510,084,900.
nítorí ọkàn wọn ń gbèrò ìparun,ẹnu wọn sì ń sọ̀rọ̀ ìkà.
O ṣalaye fun BBC Yoruba lórí èròńgbà rẹ̀ fún ìpínlẹ̀ Kwara pé ohun to lagbara loun ni lọkan lati ṣe fawọn eniyan Kwara ti oun ba wọle.
O ni ''awọn eniyan njowu mi ni'' ''ko ju bẹẹ lọ'' Isọwọ gba bọọlu Ronaldo lọjọ aiku se afihan rẹ gẹgẹ bi ogbontarigi agbabọọlu-emeji ọtọọtọ lo gba bọọlu wọnu awọn ki wọn to yọ jade lori papa.
Ẹni tí ó bá ní etí láti fi gbọ́ràn, kí ó gbọ́.
Ṣugbọn awọn oṣiṣẹ ni lati ka eyi ti ẹrọ o ba ri ka.
"Àwọn ọ̀nà tí obìnrin fi le gbádùn ìbálòpọ̀ Sisitá ìjọ Kátólíkì méjì wá ṣe iṣẹ́ ìhìnrere l‘Afirika, lóyún bá dé Wo bí àwọn obìnrin kan ṣe n sọ ara wọn di 'fágìn' lẹ́ẹ̀kejì Àwọn èèyàn kò fi bẹ́ ẹ̀ ní ìbálòpọ̀ lásìkò ìgbélé yìí - Iléèṣẹ́ kọ́ńdọ́ọ́mù Durex Kim Wallen to jẹ Ọjọgbọn nipa bi awọn eroja ara ṣe n ṣiṣẹ si ni Fasiti Emory, to wa ni Georgia America ṣe sọ fun BBC, Marie ""ko gbagbọ pe nipasẹ idọ 'clitoris' nikan ni obinrin fi le ni itura lasiko ibalopọ""."
Zalmanni ni obinrin naa burẹwa gidi gan ki oun to dawọ le iṣẹ abẹ naa, ṣugbọn ni bayii o tis ̣e e wo loju.
Oyinkan Abayomi, akọni obìnrin tó fi ìfẹ́ pa orúkọ ọkọ kejì dà sí ti ọkọ àárọ̀ 'Àwọn ọlọ́pàá tó farapa nínú ìwọ́de EndSARS yóò gba ìgbéga, a ó ṣèrànwó f'ẹ́bí àwọn tó kú' Àwọn agbébọn kọlu iléèwé, wọn bọ́ olùkọ́ àti akẹ́kọ̀ọ́ sí ìhòhò Wo àwọn ọmọ Naijiria mẹ́ta tó jáwé olúborí nínú ìdìbò sílé aṣòfin ilẹ̀ Amẹrika Dokita ọhun sọ fun BBC Yoruba pe, ni ọpọ igba ti awọn eeyan ba ko ẹjọ lọ si agọ ọlọpaa, awọn ọlọpaa naa kii ṣe idajọ ododo nitori bi wọn ṣe maan gbe ẹbi fun alare nigba miran lo n jẹ ki awọn eeyan ṣe idajọ funran wọn.
O digba ti wọn ba ṣe idata rẹ ni ọjọ kẹta ti wọn bii ati ẹsẹntaye rẹ ni ọjọ keje to ba jẹ obinrin tabi ọjọ kẹsan an to ba jẹ ọkunrin.
Abineri bá sọ fún Joabu pé, “Jẹ́ kí àwọn bíi mélòó kan ninu àwọn ọmọkunrin láti ẹ̀gbẹ́ kinni keji bọ́ siwaju, kí wọ́n fi ohun ìjà dánrawò níwájú wa.
Wọn ni ki ijọba UK ronu igbesẹ to yẹ ni gbigbe lati fiya jẹ awọn alaṣẹ Naijiria to ba tapa si ẹtọ ọmọniyan lasiko iwọde naa ni Naijiria.
Nígbà tí ó gbọ́ tí ọ̀pọ̀ eniyan ń kọjá lọ, ó wádìí ohun tí ó dé.
Ṣugbọn kì í ṣe èmi ni mo rán ara mi wá, olóòótọ́ ni ẹni tí ó rán mi, tí ẹ̀yin kò mọ̀.
Ṣugbọn bí ọkọ rẹ̀ bá kú, òfin tí ó de obinrin náà mọ́ ọkọ rẹ̀ kò ṣiṣẹ́ mọ́.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Saraki san owó oṣù òṣìṣẹ́ ní Kwara 8 Sẹ́rẹ́ 2019 Oríṣun àwòrán, Bukola saraki Àkọlé àwòrán, Ìṣòro ńlá ni sísan owó oṣù òṣìṣẹ́ jẹ́ fún ìpínlẹ̀ Kwara àti àwọn ìpínlẹ̀ gbogbo lórílẹ̀èdè Nàìjíríà.
Ó pọn dandan fún wa láti ka ìtàn àwọn ènìyàn Mekong kún, kí a dá wọn mọ̀, àti bọ̀wọ̀ fún wọn, papàá jù lọ ní òde òní tí wọ́n ti ń pàdánù àyè wọn ní ìrọ́pò ilé iṣẹ́ oníròyìn ìgbàlódé, tí wọn kò sì fi àjogúnbá lé ìran tí ó ń bọ̀ lọ́wọ́.
Dokita Shittu fikun pe, ajo ibanisoro n sise takuntakun lati ri pe, eto ibanisoro ni Naijria wa ni ibamu pelu ipo awon akegbe re lagbaye.
Wọ́n sì fi agogo ojúlówó wúrà kéékèèké la àwọn àwòrán èso Pomegiranate náà láàrin.
Ó wu Dafidi, baba mi, láti kọ́ ilé kan fún ìjọ́sìn ní orúkọ OLUWA Ọlọrun Israẹli.
Gomina ipinlẹ Ondo ni apẹẹrẹ ami Covid-19 na ko jẹ jade lara oun, ti oun ko si saisan lati fihan pe oun ni arun naa.
 Àsìá náà jáde ní ọjọ ́ kejìlá osù keje , ọdún 1979 .
Lẹ́yìn rẹ̀ Malikija, ọ̀kan ninu àwọn alágbẹ̀dẹ wúrà, ṣe àtúnṣe títí dé ilé àwọn iranṣẹ tẹmpili ati ilé àwọn oníṣòwò, níbi tí ó kọjú sí Ẹnu Ọ̀nà Mifikadi, ati títí dé yàrá òkè orígun odi.
Bakan naa ni wọn tun ni pe idanwo igbaniwọle si JSS1 yoo waye ni Ogunjọ, Oṣu Kẹjọ, nigba ti idanwo si awọn ileewe ẹkọṣẹ ti ijọba yoo waye ni Ọjọ Kejidinlọgbọn, Oṣu Kẹjọ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ladoja: Àwọn èèyàn Oyo fì ìbò sọ̀rọ̀ pé ìjọba Ajimobi kò dára Ijọba maa n lo iru owo bẹẹ fun idagbasoke agọ ọlọpaa kaakiri ilẹ Gẹẹsi, ati fun awọn oriṣiiriṣii akanṣe iṣẹ miiran.
Àwọn ni ọmọ Abihaili, ọmọ Huri, ọmọ Jaroa, ọmọ Gileadi, ọmọ Mikaeli, ọmọ Jeṣiṣai, ọmọ Jahido, ọmọ Busi.
Ogu yìí jẹ́ ọ̀kan ninu àwọn tí ó kù ninu ìran Refaimu tí ń gbé Aṣitarotu ati Edirei.
Dino Melaye: Ilé iṣẹ́ ọlọ́pàá yóò ṣèwádìí fídíò tí Dino ti ń náwó fún olórin kan
Ẹ yọ ẹni burúkú náà kúrò láàrin yín.
Ori ti gbe Ọmọọba tẹlẹ, Gbadegẹsin Ogunoye, to si ti gori itẹ awọn baba nla rẹ, oun si ni Ọlọwọ ti ilu Ọwọ tuntun bayii lẹyin awọn etutu ti wọn ti se fun ni Ipebi.
Eyii ko ṣeyin bo ṣe ma n sọrọ tako awọn to n ṣẹlẹ lagbegbe ọhun bii; igbeyawo ọmọbinrin ti ko tii balaga, bo ṣe yẹ ki ijọba kọ awọn ile iwe dipo Mọsalaṣi, eti awọn nkan mii.
Ọlọrun ni aláàbò mi,òun níí gba àwọn ọlọ́kàn mímọ́ là.
Owo kekere kọ ni ijọba maa n ya sọtọ fun ileeṣẹ eto aabo ninu owo iṣuna lọdọọdun, ṣugbọn awọn ọmọ ogun to wa ni oju ija, paapa, awọn to n doju kọ ikọ Boko Haram, maa n fi gbogbo igba pariwo pe, awọn ko ni irinṣẹ, awọn ko si ri owo ajẹmọnu gba.
Máalọ-máabọ̀ ojoojúmọ́ yìí a máa sú ọ̀pọ̀lọpọ̀ dé’bi pé wọn kìí kíyèsí nkan lọ titi lọ́nà ibi tí wọ́n ń lọ.
òògùn ààrùn ẹ ̀ dọ ̀ a dára fún ìdẹ ́ kun .
Alhaji Fatai Akinbade jẹ́ ọkan lára àwọn ti BBC Yorùbá pè sipade ita gbangba ti a ṣe lọjọ kẹrinla, oṣu kẹsan an ni gbọngan Olagunsoye Oyinlọla ni Fasiti ipinlẹ Ọṣun.
Ọkunrin yìí fi òru bojú lọ sọ́dọ̀ Jesu.
Nítorí kì í ṣe nípasẹ̀ ìfẹ́ ẹnikẹ́ni ni àsọtẹ́lẹ̀ kan fi wá, nípa Ẹ̀mí Mímọ́ ni àwọn eniyan fi ń sọ ọ̀rọ̀ tí ó ti ọ̀dọ̀ Oluwa wá.
Kí ẹni tí kì í jẹ má sì ṣe dá ẹni tí ó ń jẹ lẹ́bi, nítorí Ọlọrun ti gbà á.
Onijamba eniyan ni ọkunrin yìí; rúkèrúdò ni ó ń dá sílẹ̀ láàrin àwọn Juu ní gbogbo àgbáyé.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Mama Rainbow: Toyin Adegbola àti Razak Olayiwola ní ìyá rere àti àwòkọ́ṣe gidi ní Wumi Toriola Oríṣun àwòrán, Wumi Toriola Oṣere Naijiria to ti n gbori soke ni Wumi Toriola, Ọmọ ipinlẹ Ogun ni.
N kò lè ríran mọ́ nítorí ìmọ́lẹ̀ náà mọ́lẹ̀ pupọ.
Joke Silva sọrọ lori igbeyawo oun ati Olu Jacob pẹlu imọran fawọn ọdọ ninu igbeyawo to fi ni lọkan balẹ.
Ọrọ agbabọọlu Naijiria tẹlẹ ri, Taribo West lọpọ n gba bi ẹni n gba igba ọti lori ayelujara lẹyin to sọ asọtẹlẹ pe Aarẹ Donald Trump ni yoo wọle ibo aarẹ orilẹ-ede Amẹrika.
"Awọn ọdọmọde ni Ariwa-oorun orilẹede Naijiria lo ti foriko eyi to pọju ninu rogbodiyan yii.
Ó ń kọ́ àwọn eniyan lẹ́kọ̀ọ́ ní Ọjọ́ Ìsinmi.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Russia bọ sipele to ṣikeji kangun si aṣekagba Àwọn wo ló ti lọ sílé?
A ṣe ìrìbọmi fún àwọn tí wọ́n gba ọ̀rọ̀ náà.
Emperor Chris Baywood Ibe - Alága 2.
Gẹgẹ bi ajọ to n mojuto ajakalẹ aarun ni Naijiria (NCDC) se sọ loju opo twitter rẹ l'Ọjọru, ipinlẹ mọkanlelogun pẹlu olu ilu ilẹẹwa lawọn eeyan tuntun tun ti ṣẹyọ pẹlu arun naa lọjọ kẹrindinlogun oṣu kejila ọdun 2020.
Ile-ise to risi eto aabo soro
Wọ́n tú àṣírí ìfiyàjẹni àwọn Ológun àti SARS káàkiri Nàìjíríà Èèyàn mẹ́wàá tó m bọ̀ láti ìpàgọ́ àdúrà kú nínú ìjàmbá ọkọ̀ ojú pópó l'Osun Àwọn fíìmù Nollywood ń mú kí òògùn owó àti ìjínigbé gbilẹ̀ síi - Fashola Àwọn adájọ́ àgbà ilẹ̀ Yoruba dá àba kí ìkọ̀ Amotẹkun máa lo ìbọn Falana sọ pe ohun to kudiẹ kaato ni pe aarẹ Buhari n rinrin ajo lọ si oke okun fun itọju ara rẹ, nigba ti awọn ọmọ Naijiria n lọ si awọn ile iwosan to ti di mọṣuari bayii.
O ni : “A ti pinnu lati gbogun ti iwa ibajẹ.
Ọkunrin ọlọ́rọ̀ yìí ní ọpọlọpọ agbo mààlúù, ati agbo aguntan.
Kí OLUWA ṣe ilé ọkọ tí ẹnìkọ̀ọ̀kan yín bá tún ní, ní ilé rẹ̀.
Bi awọn obi ṣe n ko owo ilu, naa ni wọn n fi iwa àjẹbánu ọhun le awọn ọmọ wọn lọwọ, eyi ti ko ni jẹ ka tete ri ọna abayọ siwa ajẹbanu naa."
" Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ìtàn tó rọ̀ mọ́ òwe ‘aṣọ kò bá Ọ́mọ́yẹ mọ́.
Asiko yii yatọ si igba ti ẹgbẹ to n sejọba maa n tọwọ bọ apo ilu lati fi owo gbọ bukata ipolongo ibo ati idibo pẹlu, bi ọwọ eku ẹgbẹ oselu wa se mọ, lo fi n họri lasiko yii.
Ò máa ran àwọn tí ń fi inú dídùn ṣiṣẹ́ òdodo lọ́wọ́,àwọn tí wọn ranti rẹ ninu ìgbé ayé wọn,o bínú, nítorí náà a dẹ́ṣẹ̀,a ti wà ninu ẹ̀ṣẹ̀ wa tipẹ́.
Eliṣa pàṣẹ fún un pé, “Mú un.
Akọkọ ni eyi ti ileeṣẹ ọlọpa beere fun ati ti ile ẹjọ.
Ṣugbọn gbọ́ ohun tí n óo sọ fún ìwọ ati gbogbo àwọn eniyan wọnyi.
Nígbà ti BBC Yorùbá pé agbẹ́nusọ ilé iṣẹ́ ọlọpàá ìlú Abuja Anjuguri Manza,n láti mọ bóyá wọ́n ti ṣe awári ọkunrin náà, ìdáhun rẹ̀ ni pé,  ọ̀rọ̀ náà wà lábẹ́ ìwádìí."
”Bi o ti le je pe, Kane ro iko re lowo lati jawe olubori ninu ifigagbaga pelu iko agbaboolu Stoke City, leyin ti O gba ami-ayo kan wole ninu ifesewonse ohun, sugbon ti won ko lati ka ami-ayo ohun fun.
VAT: Kò sí àǹfàní kankan tí ìjọba ti ṣe fún mi sẹ́yìn
Alukoro ileeṣẹ ọlọpaa ni ipinlẹ Ọyọ, Gbenga Fadeyi to fi idi rẹ mulẹ fun BBC news Yoruba ṣalaye pe lootọ ni awọn aṣekupani pa Alhaji Fatai Ọkọ Oloyun ṣugbọn ileeṣẹ ọlọpaa ti bẹrẹ iwadii lori rẹ.
Adesanya ni ti oun ba le ki Costa lọrun mọlẹ pẹrẹ, o ni ọrun naa ko tun jẹ tirẹ mọ.
OLUWA Ọlọrun Israẹli, bí ó bá jẹ́ pé èmi tabi Jonatani ni a jẹ̀bi, fi Urimu dáhùn.
Surajo ni won yoo fi awon idanilekoo naa yi okan agbe pada kuro ni ti alaroje si ti alada nlanla.
Ọlọ́paàá ní wọ́n ṣèèṣì yìnbọn pa ọmọ mi tó ń tọ́ ọmọ oṣù mẹ́rin lọ́wọ́ ni- Ìyá Kager Wo Sultan Qaboos bin Said, ẹni tó gbàkóso ìgbé ayé òṣèlú Oman fún àádọta ọdún Obìnrin tó ń ṣiṣẹ́ ẹrú ní orílẹ̀èdè Oman tó bá fẹ́ ní òmìnira, gbọdọ̀ bá ọ̀gá rẹ̀ ṣùn - Obìnrin méjì tó ti Oman dé 'Mo fọ kọ́mú, pátá, ògiri ilé lórí N200,000 láìlèfọhùn lórílẹ̀èdè Oman' Mò ń tọ̀ s'ára ni mo fi gba ara à mi l'óko ẹrú ní Oman Ni afikun ijọba ni awọn miran di ẹru naa ru pe ko pese iṣẹ fun awọn ọdọ, bẹẹ ọdọ ni agbara orilẹ-ede.
"Akomolede ati Asa Yoruba: Kí ni ""Future tense"" lédè Yorùbá?"
Ní alẹ́, ìkùukùu náà dàbí ọ̀wọ̀n iná.
ogbeni Quadril n pe ara re ni angeli
Oríṣun àwòrán, AFP Àkọlé àwòrán, Igbakeji Aare orile-ede South Africa David Mabuza sọ fun ijọ eniyan pe Ms.
Gbogbo awọn ọta orilẹ-ede Naijiria wa lẹka ijọba gbogbo, ni opopona, ile ati ọja gbogbo atawọn to n ta orilẹ-ede wọn lati ni ọrọ 2.
Mo la ẹnu, mò ń mí hẹlẹ,nítorí pé mò ń lépa òfin rẹ.
Lẹ́yìn tí ó ti pàṣẹ pé kí wọ́n na Jesu ní pàṣán, ó fi í lé wọn lọ́wọ́ láti kàn mọ̀ agbelebu.
Ipo kẹfa ni Man U wa ki wọn to da Mourinho duro lẹnu iṣẹ, ṣugbọn ipo kẹwaa ni wọn wa bayii labẹ aṣẹ akọnimọọgba tuntun, Ole Gunnar Solskjaer.
Àwọn eniyan náà pọ̀, wọ́n ṣígbọnlẹ̀.
Loju opo Twitter COVID-19 ti wọn ti n dawọn eeyan lohun lori aarun coronavirus, wọn sọ nipa oogun Chloroquine pe o n dena aarun coronavirus.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Boko Haram yóò dá Leah sílé INEC: Ẹ tètè forúkọ àwọn aṣojú ẹgbẹ́ yín sílẹ̀ láàrin ọjọ́ kan, bí bẹ́ẹ̀ kọ́.
Ẹkunrẹrẹ re e ninu fidio ti BBC Yoruba mu bọ lati ilu Ọffa.
Hafiz kowe fipo sile lati darapọ mọ  asiwaju re ninu ipo oselu, iyen  asofin Rabiu Kwankwaso ti o kuro ninu egbe oselu APC lo sinu egbe PDP .
Dókítà Alex George to je oníṣègùn oyinbo àti Alix Fox tó jẹ́ akoroyin nípa ìbálòpọ̀ to sì tún jé sọ̀rọ̀ sọ̀rọ̀ lórí Radio BBC tí ṣàlàyé lórí àwọn ìbéèrè yìí.
Ẹ yọjú sí FBI bí ẹ kìí bá ṣe ''yahoo boys'' - Abike Dabiri-Erewa.
Mose iranṣẹ OLUWA kú ní ilẹ̀ Moabu gẹ́gẹ́ bí ọ̀rọ̀ OLUWA.
Ó bá sáré lọ siwaju, ó gun igi sikamore kan kí ó lè rí i, nítorí ọ̀nà ibẹ̀ ni Jesu yóo gbà kọjá.
Ọ̀pọ̀ eniyan ni wọ́n tẹ̀lé e lẹ́yìn, pẹlu àwọn ràkúnmí tí wọ́n ru oríṣìírìṣìí turari olóòórùn dídùn, ati ọpọlọpọ wúrà ati òkúta olówó iyebíye.
    Báyìí ni ìwé ọmọ náà lọ, n kò tilẹ̀ mọ̀ bí inú mi ti rí mọ́ nígbà tí mo gbà á, inú mi dùn tó bẹ́ẹ̀ tí n kò mọ nǹkan ti ń bá ṣe lẹ́sẹ̀ kan náà.
US election 2020 polls: Taa ló ń léwájú- Trump tàbí Biden?
awọn agunfọn yi mi ka nibi ti mo ti jẹun aarọ mi bayii!
7 2,773 Burkina Faso 97 0.
Gbogbo àwọn ìjòyè rẹ̀ yóo parẹ́.
Lẹyin eyii ni mo tun rin irinajo lọ si ilu Port Harcourt on lowurọ Ọjọru.
Bakan naa ni o ṣalaye pe awọn marundinlogoji ti wọn ni ajọṣepọ pẹlu arakunrin naa lasiko to fi lọ si ipinlẹ Ogun ṣi wa labẹ ayẹwo ọẹọ mẹrinla bayii lati mọ boya ara wọn mọ tabi awọn naa ti ko arun ọhun.
Igbakeji akọwe ẹgbẹ oselu APC tẹlẹri, Timi Frank ti kesi Aarẹ Muhammadu Buhari wi pe ko ti ọwọ ọmọ rẹ bọ asọ lori isesi rẹ si awọn alatako.
“Kí ni ǹ bá fi ìran yìí wé?
Wọn óo sì mọ̀ pé èmi ni OLUWA Ọlọrun.
Awọ̣n onwoye so wi pe to ba bọ si ipo naa, yoo ṣeeṣe fun lati dije dupo fun aarẹ orilẹede Naijiria ni ọdun 2023.
Iroyin fi mule, omidan Meghan Markle je osere omo ile Amerika ti o yofe pelu aremo oba ile kenya, eleyi ti o si sokunfa bi okiki igbeyawo naa se kan kakaakiri.
Ìpògùn tí ṣe ẹ ̀ ka sáyẹ ́ nsì oníṣeẹ ̀ dá , jẹ ́ ẹ ̀ kọ ́ ìwádìí ìkósínú , ìní àti ìwùwà ohun èlò .
Kete ti o ṣelẹ lawọn kan ti ọrọ naa soju wọn ti fi ọrọ sita loju opo Twitter O sọ ninu ọrọ rẹ pe o ṣeeṣe ki awọn si wa labẹ awoku ile naa.
Nibẹ ni wọn o ti gba akọsilẹ nipa rẹ, ti wọn o si fun ọ ni ọjọ ti o wa fun iforukọsilẹ fun NIN.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ọdọọdun ni gbogbo ẹlẹsin Kristẹni lagbaye ma n parapọ lati se ayẹyẹ Ọjọ ibi Jesu Kristi.
Awọn ọmo Naijiria ti fesi si ọrọ ti Adari ẹgbẹ oselu APC lorilẹ-ede Naijiria, Asiwaju Bola Tinubu to ni kii se Fulani darandaran lo pa ọmọ Baba Fasọranti.
OLUWA wí fún un pé, “Lọ dúró níwájú mi ní orí òkè yìí.
Ọpọ ọmọ Naijiria lo ti bẹrẹ si n fi erongba wọn lede lori ayelujara lori ọrọ ti ASUU sọ ọhun.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ijọba Ekiti ati alatako tahun sira wọn lori aworan ipolongo 9 Ẹrẹ̀nà 2018 Oríṣun àwòrán, Facebook/Femi Ojudu Àkọlé àwòrán, Ofin o f'ayegba ki Gomina Fayose kopa ninu ibo to'n bọ lọna sugbọn ko daju pe yoo gbe lẹyin Femi Ojudu Ijọba ipinlẹ Ekiti ti kilọ fun awọn ẹgbẹ oselu lati tọwọ ọmọ wọn b'asọ nipa lilẹ iwe ipolongo nilẹkulẹ tabi riri patako ipolongo si aaye to ba wuwọn paapa julọ ni ilu Ado Ekiti.
"Christiana Anuoluwapo naa sọrọ, o ni o "" dara bi Toyin ṣe fi ọrọ naa lọ agbẹjọro rẹ, nitori igbesẹ to yẹ ki ẹni to kawe gbe ni."
Wọn ko si ti i fi orukọ awọn to kagbako iṣẹlẹ naa sita.
Ojú rẹ̀ ń kọ yànràn bí iná.
Ẹni tí ó bá jẹ́ olóòótọ́ eniyan, yóo máa rìn láìfòyà,ṣugbọn àṣírí alágàbàgebè yóo tú.
21 Sẹ́rẹ́ 2019 Oloye Oluṣegun Obasanjọ ba BBC Yorùbá NIKAN sọrọ lori ọrọ Buhari, iṣẹlẹ oun ati Atiku to jẹ igbakeji rẹ nigba kan ri pẹlu iṣẹle Boko Haram.
Àwọn ọ̀dọ́ yóo jáde tọ̀ ọ́ wá bí ìrì òwúrọ̀.
eyi ni  bi eto idibo gomina se lo lorile ede Naijiria.
gbogbo  awon to bọwọlu ekunwo naa  mọ pe ekunwo naa ti bẹrẹ lasiko ti ijoba
Ni bayii, lara awon agbaboolu ti o ti gunle si ipago naa ni: Moses Simon, Joel Obi, Elderson Echiejile , Stephen Eze, Shehu Abdullahi, John Ogu ati Kenneth Omeruo.
Koda, atundi ibo tiẹ wa nipinlẹ Sokoto ati Kano, amọ ibi pẹlẹbẹ naa ni ọbẹ fi lelẹ.
Ìba díẹ̀ ni kúrúnà kù, egbò kò wọ́pọ̀ mọ́, ìfọ̀n ń tan lọ, bẹ́ẹ̀ ni ara mi si ń dán sii.
Lara awon ti o tẹle abenugan
Oríṣun àwòrán, AFP Àkọlé àwòrán, Ọkan nínú àwọn sọọbu àwọn atìpó tí wọn já, tó fi mọ èyí tó jk ti ọmọ Ethopia.
Bakan naa, ti asiko eto ogbin ba to, ijoba yoo tun ri da ju lati ya awon obinrin lowo fi bere ise agbe ni awon igberiko, ki won le maa je anfaani ere oko ohun.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Igba keji ree ti Algeria yoo gba ife ẹyẹ AFCON lẹyin ti wọn gbaa fun igba akọkọ lọdun 1990.
O ni iye owo ti oun na si ori sinima naa le ni ẹgberun lọna ẹgbẹta naira, ti awọn ero si pe jọ si bẹ, ki ijọba to wa le wọn danu.
Nurudeen Lawal adarí Elizabeth R tó jẹ́ ilé iṣẹ́ olóògbé sàlàyé fún BBC pé àwọn kò mọ ǹkan to ṣe ku paa nítori lẹ́yìn ti àwọn pari iṣẹ́ ní alẹ́ àná, olúkúlùkù wọ yàrá rẹ̀ lọ láti sù, sùgbọ́n nígbà ti ilẹ̀ mọ́ ni owúrọ̀ yìí ni kò jí mọ.
lati mu opin de ba  airise lorile ede
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Davido: Mo fẹ́ràn Chioma púpọ̀, ọ̀la wa máa dára 1 Èbibi 2018 Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Davido fi ọkọ̀ Porsche ṣe ayẹyẹ ọjọ́ ìbí fún Chioma Avril Davido ṣe ìpinnu láti bá Chioma Avril gbé títí láí.
”Bee si ni, kọmiṣọna FSARS tuntun ohun yoo maa jabo fun oga agba olopaa yanyan nipase igbakeji oga olopaa naa lati maa mojuto bi won se n se ise won.
Wọn ni awọn SARS naa ti pinnu lati gba ẹjẹ eeyan ninu ọrọ ẹnu wọn bi wọn ṣe de adugbo naa tẹlẹ.
”OLUWA, tan ìmọ́lẹ̀ ojú rẹ sí wa lára.
BB Naija winner 2020: Laycon ní òun kò lérò pé òun le mókè, àgbéga orin lòun bá lọ sílé náà
Wọ́n bá àwọn ọmọ ogun ninu ìdàrúdàpọ̀ níbi tí wọ́n ti ń pa ara wọn.
Àwọn Juu dá a lóhùn pé, “A ní òfin kan, nípa òfin náà, ikú ni ó tọ́ sí i, nítorí ó fi ara rẹ̀ ṣe Ọmọ Ọlọrun.
    Nígbà tí ó pẹ tí obìnrin náà padà lẹ́yìn ọba, a lọ bá a níbi tí ó sá pamọ́ sí nígbà tí a sì báa sọ̀rọ̀ ó ju ọwọ́ sí wa o ni kí a rọra máa sọ̀rọ̀ kí ẹni ti o ń lé òun má ba à gbọ́.
Awọn eeyan ti n ba mọlẹbi Minisita naa kẹdun iku awọn ọmọ rẹ loju opo Twitter Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Amọ awọn ọmọ ologun to n ditẹ gbajọba ati baba ogun wọn bii Ọgagun Sani Abacha, ko laya to bẹẹ lati gbena woju Tunde Idiagbon, tii ṣe igbakeji Buhari nigba naa, lati doju ijọba rẹ bolẹ.
Ninu iwe naa, olupẹjọ fi ẹsun kan Sowore ati ajumọja rẹ, Olawale Bakare pe wọn gbimọ pọ lati gba ijọba eyi to lodi si abala ofin 516 ninu ofin Naijiria nipa didari ifẹhonuhan lọjọ karun oṣu kẹsan pẹlu erongba lati yọ aarẹ orilẹede Naijiria loye.
Yatọ si awọn wọnyi, oludasilẹ oju opo ayelujara Twitter, Jack Dorsey paapa ti fi atilẹyin rẹ fun ipolongo #ENDSARS, han.
OLUWA, kí ni eniyan jẹ́, tí o fi ń náání rẹ̀?
Ẹ wo Ọlọrun mi, ọba mi,bí ó ti ń yan wọ ibi mímọ́ rẹ̀,
"Oríṣun àwòrán, @Harforbaje1 Ko tan sibẹ, atẹjade naa ni ""Awọn janduku ọhun tun dana sun banki mẹta, ti wọn si ji ẹgbẹlẹgbẹ owo ko lọ, ṣugbọn a ri diẹ lara mu ti a si gba ohun ija oloro ati owo ti wọn ji ko lọwọ wọn."
"Oríṣun àwòrán, Others O fikun ọrọ rẹ pe ""ko si bi a ṣe fẹ ẹ kọ ìtàn orilẹ-ede Naijiria, lai si orukọ Baba Obasanjo""."
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ni Russia, awọn eniyan n jẹ omi ara ẹja lasiko ti wọn ba n lopọ fi se ọbẹ ẹja.
Ajínigbé tú ìyá àti ọmọ ọdún mẹ́ta sílẹ̀ lẹ́yìn tí wọ́n gba ₦1.
ní ayé ìsin yìí a tún máa ń rí àwọn asunrárà nì ìgbà tí àwọn ènìyàn bá ń ṣe ọdún .
ẹ ti pa gbogbo ìmọ̀ràn mi tì,ẹ kò sì gbọ́ ọ̀kankan ninu ìbáwí mi.
 Anọbi Mohammed sọ nipa pataki mọṣalaṣi, pe awọn eniyan
Atẹjade naa wa n fa gomina leti titi di ọjọru, ọjọ kẹẹdogun osu Keje ọdun 2020, pe ko tete pe awọn si ipade lati fi ori kori lori ọrọ yii.
Oluwo ni niṣe lo yẹ ki atunṣe ilana ode oni ba awọn ọdun isẹnbaye nilẹ Yoruba ki o le di ohun tawọn maa fi owo wo.
" Izuagie ni ẹgbẹ Ancopss yoo pada se ipade lọjọ Ẹti pẹlu ẹgbẹ awọn olukọ, NUT, lati se agbeyẹwo gbogbo ọrọ naa, ti wọn yoo si fi ikede wọn sita fun araye.
Ó tó gẹ́ ní àṣà ìpolongo tó fakọyọ lásìkò ìbò 2019
OLUWA Ọlọrun tún fi ìran mìíràn hàn mí: mo rí i tí Ọlọrun pe iná láti fi jẹ àwọn eniyan rẹ̀ níyà.
Eto ilera adojutofo ni Fafowora yan lati ṣe leyi ti awọn eniyan yoo maa da owo kọbọ kọbọ bii irinwo naira si ibi ti wọn yoo ti maa mu u lo nigba ti ailera ba de.
 “A lero pe, bi eka ile-ise aladani ati ti ijoba ba se ojuse won, ti ile-ise oja idokowo naa ba se ojuse tire, orile-ede Nigeria yoo pada bo sipo ati pe, awon eniyan yoo ni ani to ati ajeseku”.
Kì í bá wọn sọ̀rọ̀ láì lo òwe.
Ẹgbẹ́ agbabọọlu Super Falcons to ṣoju Naijiria ninu idije ife ẹyẹ agbaye tawọn obinrin to n lọ lọwọ ni France ti já Ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ parí, Germany di ẹrù ìyà aláwẹ́ mẹ́ta lé Najiria lórí.
Nítorí pé ẹ̀ṣẹ̀ wọn pọ̀,nígbà pupọ ni wọ́n sì ti yipada kúrò ní ọ̀nà Ọlọrun.
BBC Yoruba ń pè yín sí ìpàdé ìtagbangba #BBCGOVDEBATE Ahmed Musa pàdánù ìyá rẹ̀ America àti Ilẹ̀ Gẹ̀ẹ́sì ní àwọn kò ní ààyò olùdíje ní Naijria Day 23: Àwọn nkan márùn ún tó gbajúmọ̀ nípa Daura #BBCNigeria2019 Awọn kan gba pe ko le rọrun rara lati fiṣẹ ilé bii ina dida kuniṣẹ ìlú ati pe Olorun ti gbe iṣẹ adari fawọn ọkunrin lati ibẹrẹ.
 Ọjọ Aje kọkanlelogun ọsu karun-un yii ni wọn ṣẹṣẹ fọwọ si wọn, ti wọn si gba wọn wọle.
ẹni tí ó lówó, àwọn ọmọ ènìyàn ko ni bá a wá ọ̀nà bí owó náà ti ṣe máa bí sii, àfi bí wọ́n ti ṣe máa da ojú ọwọ́ rẹ̀ dé ilẹ̀.
Ọmọ Ọlọrun ni wọ́n, nítorí pé wọ́n jẹ́ ọmọ ajinde.
Ààlà náà la àfonífojì Hinomu kọjá lọ sí apá ìhà gúsù ní etí Jebusi, ó tún lọ sí ìsàlẹ̀ títí dé Enrogeli.
agbabọọlu orile ede Burundi ati Guinea , nibi ti won ti fiya oloronbo na awon
Wọn óo kẹ́kọ̀ọ́ fún ọdún mẹta, lẹ́yìn náà, wọn óo máa ṣiṣẹ́ lọ́dọ̀ ọba.
Ile iwe girama Maryland Comprehensive Secondary School, Ikeja ni ipinlẹ Eko lo lọ.
lati tubo tesiwaju lori ise ti gomina Amosun ti se ni ipinle naa, ni eyi ti o
Demilade wa rawọ ẹbẹ si awọn obi lati maa ti ọmọ wọn lẹ́yìn nínú ohun gbogbo tí wọ́n bá fẹ́ ṣe, kò báà jẹ́ eré bọ́ọ́lù, àwòrán yíyà àbí gìtá títa.
Adamu Adamu, Minista ètò ẹ̀kọ́ ti fi òfin àátẹ̀lẹ́ síta kí àwọn ilé ìwé lè wọlé Ikú Williams Aanuoluwa lágbo òṣèré hú ọ̀pọ̀ ọ̀rọ̀ síta Boko Haram ṣọṣẹ́ ní Borno, wọ́n sé àwọn èèyàn mọ́lé ní Kukawa Wo ìdí tí Osun fi kede ìsinmi fún ọdún ìṣẹ̀ṣe, tàwọn ìpínlẹ̀ yókù kò dáhùn, Ilé ẹjọ́ yá lórí òfin CAMA tó fẹ́ gba àkóso ilé ìjọsìn, tẹ ẹ̀tọ́ aráàlú mọ́lẹ̀ - SERAP Lọwọ yii, eeyan 4,464 lo ti lugbadi arun Coronavirus ni Namibia, ti awọn mẹtadinlọgbọn si ti jẹ Ọlọrun nipe.
Kete ti obirin naa jabọ ni papa ọkọ ofurufu ni wọn gbe lọ si ile-iwosan kan lẹgbẹ olu ilu orilẹede naa, Kampala l'Ọjọru (Wednesday).
Nítorí ó wà ní àkọsílẹ̀ pé,“Ẹni tí ó bá fẹ́ ìgbé-ayé tí ó wù ú,tí ó fẹ́ rí ọjọ́ tí ó dára,ó níláti kó ara rẹ̀ ni ìjánupẹlu ọ̀rọ̀ burúkú sísọ,kí ó má fi ẹnu rẹ̀ sọ̀rọ̀ ẹ̀tàn.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Zoom Wedding: Àwọn ọkọ àti ìyàwò ló ní àwọn kò leè sún ọjọ́ ayọ̀ wọn síwájú.
Gani Adams: Femi Adesina, sọ fún Buhari pé ebi ń pa ọmọ Nàìjíríà
Agbẹjọro Kayọde Ajulo n fesi si igbesẹ Ile Igbimọ Asofin to buwọlu abadofin to nii ṣe pẹlu atunse ẹka epo bẹntiroo pẹlu awọn abadofin mẹfa miiran ti aarẹ kọ lati fi ọwọ si.
Opopona Eko si Ibadan ni wọn ti ji wọn gbe l'Ọjọru ọsẹ awọn eeyan wa si n ṣiṣẹ takun takun lati doola wọn pada ki wn lee wa pọ pẹlu ẹbi wọn"" Eyi ni alukoro ọlọpaa Oyo sọ."
Budget 2019: Wo àwọn aṣíwájú àgbáyé míràn táwọn èèyàn dẹ́yẹsí lágbayé
O ni lootọ igbeyawo awọn kii ṣe eyi to pe ni gbogbo ọna ṣugbọn oun ati Ọba Lamidi Adeyẹmi ti fi iṣọkan la awọn ipenija gbogbo to n jẹyọ nibẹ ja.
Arẹwà Ibidunni Ighodalo wọ káà ilẹ̀ lọ nílùú Eko O fikun un pe ohun kan lo ti ye oun bayii pe gbogbo ohun to n dan kọ ní wura, Orọ̀ kankan ko si ni wa titi aye amọ ohun to daju ni pe ko si ẹni to le ra aye gbe, oun si ti ri alaafia nipa mimọ Ọlọrun.
Erongba lati jẹ awon nkan didun ti a fi iyefun ṣe tabi ṣokoleeti tabi nkan dindin, o le bẹrẹ lati ara ero lasan ti yoo si maa dagba ti yoo fi di ko see ma ni ti yoo si di nkan ti obinrin naa o le se ko ma jẹ.
Wo ìdí tí àwọn obìnrin kan fi n yọ ilé ọmọ wọn kúrò Oga agba Adamu ni igbese yii di dandan lasiko yii kiru rẹ ma ba a tun ṣẹlẹ mọ ni Naijiria.
Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Fuel Price Hike: Onímọ̀ ní oṣooṣù ni owó lítà epò kan yóò máa yàtọ̀, ó le léwó tàbí dínwó16 Owewe 2020 6:30 Fídíò, Akomolede ati Aṣa lori BBC: Mọ̀ si nípa oríṣìí ẹ̀ka ìsọ̀rí ọ̀rọ̀ àti ìwúlò wọn, Duration 6,308 Owewe 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 3 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 5 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Kí ni ìdí tí o fi pè é ní arabinrin rẹ fún wa?
    Nípa ti ibi tí ẹ ní ki n lọ, n ó lọ.
Cowry Bridge (Officers Mess) Ijọba ibilẹ Ikeja Lagos Island / Eti-Osa.
Wọ́n kọjá ẹ̀ṣọ́ kinni ati ekeji, wọ́n wá dé ẹnu ọ̀nà ńlá onírin tí ó jáde sinu ìlú.
Eyi mu ki awọn ọmọ eniyan tun ma a ba iwa ọdalẹ wọn lọ.
UK Prime Minister: Boris Johnson, Olóòtú ìjọba Gẹ̀ẹ́sì tuntun sọ̀rọ̀ àkọ́kọ́
 Ọba si le è gbẹ ́ sẹ ̀ lé ìyàwó tàbí ohun ìní ẹlòmíì .
South Africa ti ni ènìyàn ẹgbẹ̀run lọ́nà mẹ́jìdínlógóje, ti Cameroon sì ti ni ẹgbẹ̀run méjìlá lé díẹ̀ ènìyàn to ko Coronavirus.
”Dokita Abari, leni ti oludari to n mojuto eka ilaniloye ati iwuwa si osise lenu ise, ogbeni Musa Chantu soju re, so ninu oro re ti o pe akori re ni:“SISE ISE NI IBAMU PELU OFIN ATIILANA ENU ISE- YE KO JE AFOJUSUN AWON OSISE.
"Gomina ṣepade pẹlu awsn eleto aabo ni kete to mọ pe wọn n ṣe bẹ, ko si si iru ẹ mọ""."
Àwọn onigbeeraga ti wé irọ́ mọ́ mi lẹ́sẹ̀,ṣugbọn èmi fi tọkàntọkàn pa òfin rẹ mọ́.
Ọlọrun, o kò ha ti kọ̀ wá sílẹ̀?
Nítorí Hẹrọdu kan náà yìí ni ó ranṣẹ lọ mú Johanu tí ó fi í sẹ́wọ̀n nítorí ọ̀ràn Hẹrọdiasi iyawo Filipi arakunrin Hẹrọdu tí Hẹrọdu gbà.
Sugbọn iroyin to wa n tẹ wa lọwọ bayii ni pe ba oke ti da alaafia pada si agọ ara Baba Suwe, to si ti pada si ẹnu isẹ tiata bayii.
 O wa fi da awon omo orile ede Naijiria loju pe  gbogbo alafo to fa ijakule yii ni awon yoo dena, ti iru isele bayii ko fi ni waye mo.
Nítorí èyí ni mo fi wà ninu ẹ̀wọ̀n.
Inu mi tun dun pe awon omo
Ẹ kọ orin ìyìn sí OLUWAnítorí ó ṣe nǹkan tí ó lógo,jẹ́ kí èyí di mímọ̀ ní gbogbo ayé.
Ọdun marun un ni McCain fi jẹ ẹlẹwọn ogun Vietnam, ti o si jẹ orisirisi iya ni ọwọ awọn ti o mu u pamọ.
Láti ìgbà náà lọ ni Jesu ti bẹ̀rẹ̀ sí máa fihan àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ pé dandan ni kí òun lọ sí Jerusalẹmu, kí òun jìyà pupọ lọ́wọ́ àwọn àgbà ati àwọn olórí alufaa ati àwọn amòfin; ati pé kí wọ́n pa òun, ṣugbọn ní ọjọ́ kẹta a óo jí òun dìde.
Nígbà tí aadọrin ọdún bá pé, n óo jẹ ọba Babiloni ati orílẹ̀-èdè rẹ̀, ati ilẹ̀ àwọn ará Kalidea níyà, nítorí ẹ̀ṣẹ̀ wọn.
Ṣùgbọ́n, ìbéèrè tó wà lẹ́nu ọ̀pọ̀ ènìyàn ni pé ṣe lóòtọ́ ni ààrẹ Donald Trump ṣe àìsàn.
Wọn ti sun igbẹjọ si ọjọ kẹrinla oṣu yii.
Oríṣun àwòrán, others Awọn isọri naa niwọnyii.
Wòlíì Genesis kan yẹra díẹ̀ ni, ó máa tó wọlé padà bí olè lóru- Adelé pásítọ̀ Oladele Wo àwọn ọmọ Naijiria mẹ́ta tó jáwé olúborí nínú ìdìbò sílé aṣòfin ilẹ̀ Amẹrika Ṣé Sanwo-Olu, gómìnà Eko yóò farahàn níwájí ìgbìmọ̀ olùwádìí ìṣẹ̀lẹ̀ Lekki Tollgate?
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ọmọ Yahoo Plus: Wọn ní kí ń pa ìyá mi, kí ń lè lówó si ni 11 Èbibi 2018 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 20 Ògún 2018 Oríṣun àwòrán, Lagos state police command Ileesẹ ọlọpaa ni Ipinlẹ Eko ti mu ọmọkunrin ẹni ọdun mọkandinlọgbọn kan ti orukọ rẹ njẹ Taiwo Akinola, ti o gbiyanju lati fi igi fọ ori iya rẹ ni adugbo Raji Ajanaku, ni Ayọbọ.
Agbẹjọrọ fun El-Zakzaky, Femi Falana lo sọ bẹẹ fun BBC Yoruba Falana ni asalẹ oni ni awọn mejeeji yoo gbera kuro ni ilu Abuja lọ si India lati lọ gba itọju.
Eyi tubọ jẹ ki ara o maa fu mi.
kí Sadoku, alufaa ati Natani wolii, fi àmì òróró yàn án ní ọba níbẹ̀, lórí gbogbo Israẹli.
Ìgbà tí àwọn náà bá ṣọdẹ lọ títí, wọn a tún padà sọ́dọ̀ olórí wọn yìí láti wá tójùu rẹ̀ àti láti wá simi lálẹ́.
Wọ́n sọ fún un pé, “Sọ ẹni tí ó lù ọ́ fún wa, wolii!
Oríṣun àwòrán, Getty Images Akíyèsí: àwọn àwọran tí a lò yìí ni à wá láti ibomíràn pàápàá jùlọ ti France yàtọ̀ si èyí ti fasiti John Hopkins lò, èsì náà kéré díẹ̀ s ti gbogboogbo.
Ó tún àwọn ilé oriṣa tí Hesekaya, baba rẹ̀ ti parun kọ́, ó kọ́ pẹpẹ ìrúbọ fún oriṣa Baali, ó sì gbẹ́ ère oriṣa Aṣera, bí Ahabu, ọba Israẹli, ti gbẹ́ ẹ.
Wale Adebanwi, ọkan ninu awọn to ṣe atupalẹ iwe tuntutn yii rii pe o sorọ kikun nipa agabra Ile Ifẹ lori Oyo ile ati Oyo oko.
Awon meta tori ko yo ti won n gba itoju ni– Doreen Elibariki (13), Saida Awadh (11) ati Wilson Tarimo (11).
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìjọba Nàìjíríà kìlọ̀ ìṣọ́ra ní ìlú London 10 Ìgbé 2018 Oríṣun àwòrán, @abikedabiri Àkọlé àwòrán, Abike Dabiri lon kede ikilo fun awọn ọmọ Naijiria ni ilu London Ijọba orilẹede Naijiria ti kilọ fun awọn ọmọ ilẹ naa to wa ni ilu London lati ma a sọ ara se nitori iṣekupani to n waye lagbeegbe naa.
Afurasí Boko Haram pa ogójì ọmọ ogun ilẹ̀ Nàìjíríà ní Borno: Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Afurasí Boko Haram pa ogójì ọmọ ogun ilẹ̀ Nàìjíríà ní Borno Awọn alakatakiti ẹsin Islam, boko Haram ni wọn fura si pe wọn ti ṣeku pa ọmọ ogun ilẹ̀ Naijiria to le ni ogoji nipinlẹ Borno.
Ó kú ènìyàn márun-ún ti yóò bá ètò náà de ìparí ní sáà BigBrother Naijia yìí.
O tun salaye lori idasile awon omo ogun onise akanse labule Kanfanin Doka, Birnin-Gwari, ati amulegbe re nipinle Kaduna ti satileyin to muna doko.
Ẹgbẹ naa ninu atẹjade kan to fi sita l'Ọjọru nilu Ibadan lati ọwọ Alukoro Apapọ rẹ, Comrade Adeshina Akinpẹlu, sọ pe awọn ọmọ ẹgbẹ awọn yoo bẹrẹ si ni le awọn Fulani darandaran to n hu iwa ọdaran ni gbogbo awọn ipinlẹ to jẹ ti ẹya Yoruba jade, to fi mọ awọn agbodegba wọn laarin awọn ọmọ Yoruba ati ẹya miran.
Ohun ti ọpọ n sọ nipe kii ṣe akoko yii ti ibẹru-bojo ajankalẹ arun coronavirus wa nita lo yẹ ki Makinde ṣe iru ipade bẹẹ.
Ní ọ̀pọ̀ ìgbà ní ìjínígbe àwọn ọmọ ilé ìwé tí ilé ìwé Chibok sì jẹ ọ̀kan lára wọn ti ero n sọrọ lori rẹ.
Ohun ti o jẹ èèwọ̀ tàbi òfin ni ilú kan le ma jẹ èèwọ̀/òfin ni ilú miran ṣùgbọ́n bi èniyàn bá dé ilú, ó yẹ ki ó bọ̀wọ̀ fún àṣà àti òfin ilú.
awon obinrin lawujo, ki won tewogba ifetosomo-bibi ki alaafia ati ifokanbale
Ọwọ́ ọlọ́pàá tẹ àwọn olè tó kó góòlù àti ẹgbẹ̀lẹ́gbẹ̀ mílíọ̀nù lọ nílé MKO Abiola l'Eko Ọmọ Nàìjíríà kan gbé Fásitì Oxford lọ sílé ẹjọ́ tàko oríkí ọrọ 'Mortgage' nínú ìwé àtúmọ̀ ọrọ E wo ọmọ Yorùbá àkọ́kọ́ tó jà fún ẹ̀tọ́ àwọn aláwọ̀dúdú ní America!
    “Nígbà tí ọjọ lílọ wa ku ọjọ méje ọba pàṣẹ kí wan lu agogo yíu ìlú ká pé kí gbogbo àwọn ará ìlú wa sí ààrín ọjà ní ọjọ tí a ó bá lọ kí á bà dágbére fún ara wa.
Ṣugbọn ó pè wá gẹ́gẹ́ bí ètò tí òun fúnrarẹ̀ ti ṣe, ati nípa oore-ọ̀fẹ́ rẹ̀ tí ó fi fún wa nípasẹ̀ Kristi Jesu láti ayérayé.
Èyí jẹ́ kí àwọn ọmọ Geriṣoni ati àwọn ọmọ Merari rí ààyè láti pa Àgọ́ Àjọ náà kí àwọn ọmọ Kohati tó dé.
pe ile akede Naijiria VON TI  jẹ ere
Shiite: Kò ní sí ìwọ́de mọ́ yíká Nàíjíríà láti bu ọ̀wọ̀ fáwọ̀n èèyàn tó dá sí wa
Cobain pa ara rẹ loṣu kẹrin, ọdun 1994 lọmọ ọdun mẹtadinlọgbọn.
World Habitat Day: 'Ìjọba, ẹ ṣèrànwọ́ fáwọn tí kò rílé gbé ní Nàìjíríà'
Nítotrí ore tí ó ṣe fún aláìní gbogbo ni wọ́n
Gbogbo ìpínlẹ̀ náà sì ni yóò ni iyé asójú bákan náà, gẹ́gẹ́ bi iyé ọmọ ilé ìgbìmọ̀ aṣòfin ti wọ́n ni ilé Amẹrika (representaives àti Senator) Califonia ló ni olùdìbò tó pọ̀ jù, tó jẹ́ -55- nígbà ti àwọn ìpínlẹ̀ tó kéré bi Wyoming, Alaska ati North Dakota (àti Washington DC) má a ń ni ènìyàn mẹ́ta-mẹ́tà.
Ààrẹ Buhari ṣèpàdé pẹ̀lú Ọ̀gá Àgba iléèṣẹ́ ọlọ́pàá lórí #ENDSARS, ẹ wo àbájáde ìpàdé wọ́n Wo bí ìwọ́de #ENDSARS tí Toyin Abraham ṣe nípínlẹ̀ Oyo ṣe lọ Ìdí tí Gúúsù Akure, Owo àti ìwọ̀orun Ondo yóò fi sọ ẹni tí yóò jáwé olúborí nínú ìbò gómìnà Ondo Ẹri ti a gbọ wi pe ikọlu waye ni eyi to han ninu fidio kan ti gbajumọ ori ayelujara Lekan King Kong fi sita nibi ti awọn oluwọde ti n figbe ta pe ọlọpaa n yinbọn lu awọn.
Lẹyin ogun ọdun to fi wa nipo alatako, Gbagbo bọ si ipo ijsba ni ọdun 2000 Ni oṣu kẹrin ọdun 2011 ni wọn fi tipatipa lee kuro nipo.
Ilu to fẹran ṣiṣe ẹsin pupọ ni orilẹede Naijiria ati Kenya.
Ó sì wà lórí oyè ní Jerusalẹmu fún ọdún mẹta.
Àwọn aláboyún f'ẹ̀hónú hàn ní ìpínlẹ̀ Òǹdó Ayédèrú onísòwò ẹ̀jẹ̀ bọ́ sọ́wọ́ ọlọ́pàá Adajọ paṣẹ $25,000 fun oloyun ti wọn fiya jẹ Dokita PJ Lakhani jẹ agba ọjẹ Dokita ti o ti n ṣiṣẹ fun ọdun mẹẹdogun ni ile iwosan ijọba Sonavala.
Kí a tó dìbò yìí, a ti yàn mí gẹ́gẹ́ bí igbá-kejì ààrẹ ìgbìmọ̀ akẹ́kọ̀ọ́ fún oṣù mẹ́jọ gbáko, kò sì sí ohun kan tí ó ṣẹlẹ̀.
'Ẹnikẹ́ni ò lè tì mí gbọ̀ngbọ̀n láti gbé orúkọ mínísítà jáde' Kí ló mú àwọn adarí Nàìjíríà tako ra wọn lórí ikú ọmọ alága ẹgbẹ́ Afenifere?
Mike Adenuga to jẹ alaṣẹ ati oludari ile iṣẹ Globacom pọnwọ le Dangote nipo keji pẹlu biliọnu mẹsan dọla.
Irun orí rẹ dàbí ọ̀wọ́ ewúrẹ́ ninu agbo,tí ń sọ̀kalẹ̀ ní gẹ̀rẹ́gẹ̀rẹ́ òkè Gileadi.
Bi o tilẹjẹpe ijọba ni awọn ti gbọ ọrọ si awọn ọdọ lẹnu, amọ awọn oluwode naa ni kii ṣe igba akọkọ niyii ti ijọba yoo gbesẹle ikọ ọlọpaa, amọ ti wọn yoo ṣi mọ ọ ṣọṣẹ.
Igbimọ naa ni awọn eekan ijoba Babangida nigba naa lẹdi apo pọ pẹlu awọn oṣiṣẹ banki apapọ Naijiria lati lu owo naa ni ponpo nipa ninaa sori awọn akanṣe iṣẹ ti ko ṣe e tọka si.
Jehoṣafati tún yan àwọn kan ní Jerusalẹmu ninu àwọn ọmọ Lefi, ati àwọn alufaa ati àwọn baálé baálé ní Israẹli, láti máa fi òfin OLUWA ṣe ìdájọ́ ati láti máa yanjú ẹjọ́ tí kò bá di àríyànjiyàn.
" wọ ́ n mọ kola oyewo sí Ọdẹ ́ wálé , ipa tí ó kó nínu "" the gods are not to blame "" , eré tí olá rótìmí kọ ."
Iyaniwura ni ''gbogbo irinajo ti aarẹ Buhari ti lọ ko ti mu ki ijọba da ile iṣẹ silẹ.
Àwọn orílẹ̀-èdè yóo dàbí ìgbà tí a sun wọ́n,tí wọ́n di eérú,àní bí igi ẹ̀gún tí a gé lulẹ̀, tí a sì dáná sun.
 Ìnira àti rírẹ ̀ -dòdò lè wáyé ní ojú ibi abẹ ́ rẹ ́ náà .
Ǹ bá gbọ́ èsì tí yóo fún mi,ati ọ̀rọ̀ tí yóo sọ fún mi.
O lee maa gbọ ọ bi o ba n ṣe nnkan miran.
Ìyè ainipẹkun ni yóo sì yọrí sí.
Ẹ̀ṣọ́ NSCDC ṣèèṣì yìnbọ̀n pa ọlọ́pàá ọ̀tẹlẹ̀múyẹ́ DSS l'Osun Pásítọ̀ CAC àti afurasí 'Yahoo boy' Olawale tó lu Hayatou ní jìbìtì N12.
“Ẹ̀yin òkè Giliboa,kí òjò má ṣe rọ̀ le yín lórí,bẹ́ẹ̀ ni kí ìrì má ṣe sẹ̀ sórí yín,kí èso kan má so mọ́ ní gbogbo orí òkè Giliboa,nítorí pé, ibẹ̀ ni apata àwọn akikanju ti dípẹtà;a kò sì fi òróró kun apata Saulu mọ́.
Ihò ni àwọn èèyàn ń gbẹ́ tí wọn ma ń kówó pamọ́ sí lẹ́yìn tí wọ́n bá ti fi ohun èlò tó nípọn bo ẹnu ihò náà, àwọn tó ní owó nìkan ló sì ń mọ́ èyí.
Ijọba fikun pe CNN ko sọ nkankan nipa rogbodiyan to tẹle iwọde END SARS, ti awọn ọlọpaa kan ti padanu ẹmi wọn.
Ẹ fi ìkóra-ẹni-níjàánu kún ìmọ̀, kí ẹ fi ìgboyà kún ìkóra-ẹni-níjàánu, kí ẹ sì fi ìfọkànsìn kún ìgboyà.
Bakanaa ni wọn tun si asọ loju eegun nipa ‘jẹẹsi‘ ti Super Eagles yoo wọ nibudo igbaradi wọn, ti iroyin kan si ni wọn yoo maa ta awọn asọ yi losu kẹrin si ikarun ọdun 2018.
Bákan náà ni ẹni tí ó wí pé ìlú òun kò dára àti pé òun ń fẹ́ẹ́ dì ọmọ ìlú mìírà.
Àwọn ìkọlù ọ̀hún ni wọ́n di ẹ̀bi rẹ̀ ru àwọn olè a-jí-máàlù Ṣaajú àsìkò yìí, inú fu, àyà fu, l'àwọn olùgbé ní àwọn abúlé tó wà ní tòsí Birnin Gwari wà.
Oríṣun àwòrán, ChibuikeAmaechi Ọpọ ko dunnnu si Amaechi ti o si ni lati ṣalaye daada itumọ nkan ti o gba lero lori ọrọ naa.
Apànìyàn náà yóo jẹ̀bi ẹ̀ṣẹ̀ ìpànìyàn, yóo sì kú fún ẹ̀ṣẹ̀ rẹ̀.
Awọn mejeeji yii yoo ba forikori fun igba akọkọ lẹyin ti Arteta fi Manchester city silẹ.
Orúkọ ìnagijẹ mẹ́jọ tí wọ́n fi ń pe Abiola Ajimọbi nígbà ayé rẹ̀ Kìí ṣe ẹ̀bi wa pé ètò ìsìnkú Abiola Ajimobi falẹ̀ - ìjọba ìpínlè Oyo Àwọn aṣòfin Naijiria ṣọ̀rọ̀ ìwúrí nípa Ajimobi Wo bí o ṣe lè fí orúkọ rẹ sílẹ̀ fún iṣẹ́ N Power tuntun ti ọdún 2020 Naijiria Ṣaaju ni ipinlẹ kan ṣoṣo to ni oun ko tii ni arun Coronavirus ni Naijiria, Cross Rivers ti pinnu lati ṣi awọn ile iwe rẹ lọjọ kẹrindinlogun, oṣu kẹfa, ọdun 2020, ṣugbọn o wọgi le ipinnu naa lẹyin akitiyan ijọba apapọ.
" Ṣaaju ki Aisha to sọrọ ni ita gbangba, ni ọpọlọpọ eniyan ti n fi ẹsun kan Aarẹ Muhammadu Buhari pe, ọwọ awọn ìbátan rẹ kan, bi i Mamman Daura, ni iṣakoso orilẹede Naijiria wà.
Ikú Adewole Oniluola, tó ní ẹ̀bùn ìlù lílù jùlọ lágbàyéé, yóò nípa lórí Yorùbá - Tunde Kelani Ayinla Ọmọwura, orin èébú àti oríyìn lo fi di ọ̀rẹ́ àwọ̀n obìnrin Ẹ wo ojú àwọn afurasí tí yóò rojọ́ ẹ̀ṣùn àjẹbánu lọ́dún 2021 Bí Nàíjíríà bá fẹ́ kí ọdún 2021 dára, ohun tí yóò ṣe rèé - Obasanjo Ẹgbẹ́ ọ̀dọ́ méjì fìjà pẹẹ́ta, ẹ̀mí kan bọ́, ọ̀pọ̀ farapa Nigba ti ikọ ọlọpaa Ikorodu yoo fi de ibẹ ni ọwọ tẹ arakunrin Taiye Lasisi, ti wọn mu pẹlu ibọn ilewọ lọwọ rẹ.
Latigba to ti wa ni ọmọ ọdun marun lo ti mọ pe oun ni ẹbun naa.
Iye awọn to ti ku lapapọ ti di ẹgbẹrun kan ati ọọdunrun o le ọgbọn, (1330) Lagos-807 FCT-236 Kaduna-79 Oyo-57 Plateau-47 Rivers-37 Katsina-35 Edo-30 Sokoto-30 Delta-26 Kebbi-23 Ondo-20 Enugu-18 Abia-17 Ogun-17 Benue-16 Bayelsa-15 Bauchi-14 Niger-13 Kano-10 Borno-6 Imo-5 Ekiti-4 Osun-2 Jigawa-1 COVID-19 pa èèyàn márùn ún, ènìyàn 1664 míràn tún ṣẹ̀ṣẹ̀ lùgbàdì ààrùn náà ní Nàìjíria Eeyan marun ni ajakalẹ arun COVID-19 tun ti pa bayii lorilẹede Naijiria.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Èlé orí owóyàá China rọjú la ṣe fẹ́ gbà á - Ìjọba àpapọ̀ N kò ri ipa ẹ̀jẹ̀ lára ọmọ mi tó kú sí iléeṣẹ́ ọṣẹ, èjò lọ́wọ́ nínú - Òbí àkẹ́kọ̀ọ́ UI Mò máa ń fọ àwọ̀tẹ́lẹ̀ ìyá mi, ni ìṣe àwọn obìnrin fi wù mí - Bobrisky Àlàyé rèé lóríi àjọṣepọ̀ tó wà láàrin èmi àti MC Oluomo - Ronke Oshodi Oke Ẹ bá mi wá nọ́ńbà ìpè òbí ọmọ Mummy Calm Down jáde - Yinka Ayefele Ọlọ́pàá sálọ fún aráàlú l‘Okeho, nígbà tí wọn yari láti ṣun olè méjì tó kù Mo fẹ kawọn ọmọ Naijiria mọ daadaa nipa orilẹede wọn ati awọn ohun ta ba nilẹ lọdun 2015."
Awọn ilu bii Nairobi ati Monbassa jẹ ibi ti o dara.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Awọn obi awọn akẹkọ kan nileewe naa niroyin sọ pe wọn fi idi eyi mulẹ fawọn iwe iroyin abẹle kan lorilẹde Naijiria.
Binea ni baba Refaaya, Refaaya ni ó bí Eleasa, Eleasa sì bí Aseli.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Eto yi la gbọ pe ipinlẹ mẹwaa yoo jẹ anfaani rẹ ti ipinlẹ Oyo si jẹ ọkan lara wọn.
N óo dá oríṣìíríṣìí ẹ̀rù ba Gogu, lórí òkè mi, àwọn ọmọ ogun rẹ̀ yóo fa idà yọ sí ara wọn.
Àwọn ará Jebusi tí wọn ń gbé ibẹ̀ nígbà náà wí fún Dafidi pé, “O kò lè wọ inú ìlú yìí wá, àwọn afọ́jú ati àwọn arọ lásán ti tó láti lé ọ dànù.
Eko ni osu kewaa, ojo kokanla , odun 1962.
Inu rẹ si maa n dun to ba ti pada sile.
Bakan naa, ọmọ yii yoo laṣẹ lati jẹ ọmọ orilẹede meji nitori baba rẹ Harry jẹ ọmọ ilẹ Gẹẹsi.
Ọkan lara awọn ẹbi obinrin naa, to fi orukọ bo ara rẹ laṣiri sọ fun BBC pe,''gẹgẹ bi ẹbi, a o ni ohunkohun lati sọ, ayaafi ti gbogbo awọn ọlọpaa, ati oṣiṣẹ adoola ẹmi, to fi mọ awọn oṣiṣẹ mọṣuari ba wa nijoko o.
Dickson ro gbogbo awon torokan pe:“Bi a ba se n bu ijoba apapo naa ni ki a maa ye ara wa wo ki ale sayipada rere to ye si ekun wa.
Kọmiṣọnna ohun amuṣagbara Aliyu Moro Sabi ni Gomina ipinlẹ Kwara yan gẹgẹ bi kọmoṣọnna ohun amiṣagbara.
Awọn ogo ọla orilẹede Naijiria lẹka eto ilera ni arun yii ti gba lọ tabi da wolẹ lọpọlọpọ igba.
BBC Kayeefi oṣu kẹfa yii lọ si Ado Ekiti nibi ti ọmọbinrin kan ti wọn fipa ba lopọ loke ọja ti ṣe iranlọwọ fun awọn agbofinro ti ọwọ si tẹ awọn ọdọmọkunrin oniṣẹ ibi naa.
Ṣugbọn nígbà tí oòrùn ń wọ̀ lọ, ó kú.
 Oun ni ololufẹ igba gbogbo fun Neymar ọmọ Brazil.
OLUWA, gbọ́ adura mi;fetí sí ẹ̀bẹ̀ mi!
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Alaafin: Olori Aanu Adeyemi ṣàlàyé ìdí tó ṣe gẹ́ Oba Lamidi Adeyemi ti ìlú Oyo Ọba Seriki Abass Williams lọla, o lowo, ti akọsilẹ kan si sọ pe o ni aya toto mejidinlaadoje pẹlu ọmọ mẹrinlelogoje.
Oríṣun àwòrán, @Fedfireoyo Ṣugbọn ọga agba ileeṣẹ panapana ipinlẹ Oyo, Ọgbẹni Moshood Adewuyi ṣalaye pe, awọn janduku ọhun kọju ija si awọn panapana pẹlu ada atawọn ohun ija oloro miran nigba ti wọn de ibẹ.
Nigba ti a kan si ile ise olopaa nipinle Ekiti, DSP Caleb Ikechukwu so pe isẹ aabo ilu lawọn n se ati wipe ko si nnkan to jo mo esun ti ẹgbẹ oseelu PDP fi kan wọn.
Nítorí bí ó ti rí ní ìgbà Noa, bẹ́ẹ̀ ni àkókò dídé Ọmọ-Eniyan yóo rí.
"O ni ""igbesẹ naa fi han pe Aarẹ Buhari ni afojusun ati ipinnu lati wa ojutu si eto abo to mẹhẹ ati lati kapa awọn ọmọ ẹgbẹ Boko Haram ati janduku to n da Naijiria ru."
Ẹ gbọ́, ẹ̀yin àgbà,ẹ fetí sílẹ̀, ẹ̀yin tí ẹ̀ ń gbé ilẹ̀ yìí!
Oríṣun àwòrán, @ABBAYOLA447 Àkọlé àwòrán, Awọn agbofinro ti wa sọ fun BBC pe awọn ti n finmu-finlẹ nipa ikọ ẹ́lẹsin tuntun naa, tawọn si ti n dọdẹ wọn.
Ẹni tí ó pèsè oúnjẹ fún gbogbo ẹ̀dá alààyè,nítorí pé ìfẹ́ rẹ̀ tí kì í yẹ̀ wà títí lae.
Juda ti lọ sí ìgbèkùn,wọ́n sì ń fi tipátipá mú un sìn.
), ni Ọlọrun parí sísọ àwọn òfin ẹsin Islam kalẹ.
Wọ́n bá kó wọn jáde, láti inú ihò: ọba Jerusalẹmu, ọba Heburoni, ọba Jarimutu, ọba Lakiṣi, ati ọba Egiloni.
"Lẹyin naa ni awọn tẹlẹ aṣẹ ilẹeṣẹ ijọba to n risi ẹka eto ẹkọ ni Naijiria, wi pe ki wọn ṣi ileewe alakọbẹrẹ fun awọn to wa ni Primary 6, JSS3 ati SS3 ni Ọjọ Kẹwaa, Oṣu Kẹjọ, Ọdun 2020.
Nígbà tí àwọn arakunrin Josẹfu rí i bí wọ́n ti tò wọ́n, wọ́n ń wo ara wọn lójú tìyanu-tìyanu.
 Gbagede idibo yoo si sile lola,
Ẹ̀rù ń bà mí pé kí ẹ̀tàn má wọ inú ọkàn yín, tí ẹ óo fi yà kúrò ninu òtítọ́ ati ọkàn kan tí ẹ fi wà ninu Kristi, bí ejò ti fi àrékérekè rẹ̀ tan Efa jẹ.
Ẹni tí ó fi í fún àwọn ọ̀tá ti fi àmì fún wọn pé, “Ẹni tí mo bá kí, tí mo fi ẹnu kàn ní ẹ̀rẹ̀kẹ́ ni ẹni náà.
Obasanjo fi ọrọ yii lelẹ lasiko ifilọlẹ iwe kan ni iranti Adedibu, ti wọn pe akori rẹ ni Adedibu The Strongman and Generallisimo of Nigerian Politics: An X-ray of the Political Life of a Colossus"", Lai Mohammed fèsì sí ọrọ Obasanjo Irọ́ ni o!"
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ìjọba ìpínlẹ̀ Eko ti iléèwé pa nítorí ìwọ́de #EndSARS Ìrẹ̀wẹ̀sì ń bá wa torí ìdánwò NECO tẹ ń ṣún síwájú lọ́pọ̀ ìgbà - Akẹ́kọ̀ọ́, ọ̀gá iléèwé Agbára ìgbìmọ̀ ìdájọ tí mo gbé kàlẹ̀ yóò dé ọ̀dọ̀ àwón ólọ́pàá tó ti kúrò lẹ́nu iṣẹ́ tẹ́lẹ̀- Sanwo Olu Wo àwọn orílẹ̀èdè míràn tó ń fojú winá ìwọ́de bíi ti ENDSARS Mo fura pé ẹ fẹ́ da Nàíjíríà rú, ń kò ṣe ìwọ́de mọ́ - Segalink, agbátẹrù ìwọ́de yọwọ́ SERAP pe Buhari, igbákejì rẹ̀ lẹ́jọ́ lórí àfikún owó iná àti epo bẹntiró Awọn olokoowo ke ke ke ati alabọde to to miliọnu kan ati ẹgbẹrun lọna ẹẹdẹgbẹrin si ni yoo jẹ anfaani eto naa.
Kí ó tó wí bẹ́ẹ̀ tán, ẹnìkan fọhùn láti ọ̀run, ó ní, “Nebukadinesari ọba, gbọ́ ohun tí a ti pinnu nípa rẹ: a ti gba ìjọba kúrò lọ́wọ́ rẹ, 
" nígbà tí ó di ọmọ ọdún mẹ ́ sàn-án ó ní "" shock ' nítorí ikú bàbá rẹ ̀ tí ó jẹ ́ Ọ ̀ jọ ̀ gbọ ́ n nínú bàọ ́ lọ ́ jì ní university ti bosston ."
"Bi mo se fẹ wọnu ibudo ipade naa, lawsn ọkunrin kan bẹrẹ si tabuku mi, ti wọn si n pe mi ni asẹwo, koda, wọn na mi, ti wọn si ti mi lulẹ ni igba meji niwaju awọn ọlọpa atawọn agbofinro, ti ko si si ẹni to sọ ohunkohun ninu wọn.
Nítorí Ọmọ-Eniyan ń lọ gẹ́gẹ́ bí àkọsílẹ̀ nípa rẹ̀, ṣugbọn ẹni tí yóo fi Ọmọ-Eniyan lé àwọn ọ̀tá lọ́wọ́ gbé!
Gẹ́gẹ́ bi àtẹjáde ti agbẹnusọ àjọ ICPC Rasheedat Okoduwa fọ́wọ́ si ṣe sọ ni pé wọn ti gbé iwé ẹ̀sùn onípele méjìlá síwaju adájọ Folashade Ogunbanjọ-Giwa tako adarí àgbà NBC Modibo Kawu, alága ilé iṣẹ̀ Pinnacle Communication, Lucky Omoluwa àti alábojutó ìgbòkègbodò ilé iṣẹ́ náà Dipo Onifade.
Àwọn oun àjòjì tó ṣẹlẹ̀ nígboro níbi àjọyọ̀ ìṣẹ́gun Buhari Àdéhùn èmi àti Ọlọ́run ni pé èèyàn láti Yewa yóò jẹ́ Gómìnà -Amosun 'A jẹ́ pé àwọn ọmọ Nàìjíríà fẹ́ràn Buhari' Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí kan sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
’ rèé Mo ká ọkùnrin mọ́ ìyàwó mi lórí, ẹ má gbọ́ ẹjọ́ ẹnìkan dá o!
Ko da, ile iṣẹ mohunmaworan Iraq royin pe ikọlu inu afẹfẹ kan ti waye lorilẹede naa lẹyin wakati mẹrinlelogun ti wọn pa Soleimani.
Ẹsẹ̀ ko gbero ninu ile ati ita ọgba ile ẹjọ Oke Eda niluu Akurẹ nibi ti ijọba gbe e lọ.
Ilé ẹjọ́ dá pásítọ̀ ìjọ Sotitobire àti àwọn tókù padà sọ́gbà ẹ̀wọ̀n, ó sún ẹjọ́ síwájú di ọ̀lá Ile ẹjọ giga ilu Akure to n gbọ ẹsun ijinigbe ti wọn fi kan pasitọ ijọ Sotitobire, Alfa Babatunde ti sun ẹjọ naa si Ọjọ Kẹfa, oṣu kẹrin ọdun 2020.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Cancer: Àṣe ara mi ni iso ti n run gbogbo bí mo ṣe n ṣèrànwọ́ lórí jẹjẹrẹ Kini o fa epe ti a n sọ yìí?
Àwọn ọmọ ti Nafutali ni Jaseeli, Guni, Jeseri, ati Ṣilemu.
Ní ọjọ́ kẹta, bí Abrahamu ti wo ọ̀kánkán, ó rí ibi tí Ọlọrun júwe fún un ní òkèèrè.
Atejade yii tun so pe ajo to n mojuto irinajo lo si Hajj lorile ede Naijiria  lo fi kun gbedeke ojo  to ye ki iforukosile naa wa si ipariAbdullahi so pe iforukosile awon arinrinajo naa yoo tun tesiwaju di ojo karundinlogbon ,osu kerin  lati le je ki igbimo naa le e se ojuse won ko to di ojo ti gbedeke  iforukosile naa yoo wa si ipari ati lati le  gba gbogbo owo ti won ti san wole si ajo NAHCON ko to di ogbon ojo , osu kerin.
 orin irinajo ti oto egberun lọ ́ na ogoji kilomita ( 40.
Ọ̀rọ̀ àwọn apẹ̀gàn ati apeni-níjà ṣẹ mọ́ mi lára,lójú àwọn ọ̀tá mi ati àwọn tí ó fẹ́ gbẹ̀san.
Bí o bá fẹ́ darapọ̀ mọ́ ikọ̀ ọlọ́pàá SWAT tí yóò rọ́pò SARS, wo àmúyẹ tí o gbọ́dọ̀ ní Wo ohun tí ìwọ́de ENDSARS ṣé fáwọn akẹ́kọ̀ọ́ tó fẹ́ ṣèdánwò NECO Láàrin wákàtí mẹ́ta, wọ́n dá ₦4m fún àkàndá ẹ̀dá tó kópa nínú ìwọ́de Aisha Buhari polongo àwo orin tó ní Nàíjíríà ń ṣun ẹ̀jẹ̀ lásìkò ìwọ́de Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 3 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 5 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
yan pada ni Aṣofin Oluyinka Ogundimu labẹ ẹgbẹ oṣelu APC lati ẹkun idibo
Ki Gate to sọrọ rẹ lawọn eeyan kaakiri orilẹede Naijiria ati loke okun ti n pariwo pe nkan o ṣe deede lẹka eto ilera lorilẹede Naijiria.
Ọmọ ọdun mọkanla ni, to si wa ni kilaasi akọkọ JSS1 nileewe girama naa.
Lara awon to wa nibi ipade
ero ayelujara(Twitter) iko Super Eagles, awon agbaboolu ti o ti de ipago ohun
Karolina Pliskova omo bibi orile-ede Czech ti pegede sinu ipele keji asekagba idije WTA, leyin ti o fagba han akegbe re Petra Kvitova, ninu ifigagbaga ti o waye lojoBo(Thursday).
Oríṣun àwòrán, AFP Àkọlé àwòrán, Awọn ọmọ ile-iwe tun wa ninu awọn alafọfọ, ti wn ṣe ayẹyẹ ikẹhin fun obinrin akinkanju ti o ja fun ominira lọwọ apartheid ni 1994.
Nítorí ẹni tí ó bá wọ inú ìsinmi rẹ̀ ti sinmi ninu iṣẹ́ rẹ̀ gẹ́gẹ́ bí Ọlọrun ti sinmi ninu tirẹ̀.
Kí ẹ sì wí pé, ‘Jakọbu alára ń bọ̀ lẹ́yìn.
Ewe ati egbo ni wọn gbẹkẹle.
Ta ni ó fọ́jú tó ẹni tí mo yà sọ́tọ̀,tabi ta ni ojú rẹ̀ fọ́ tó ti iranṣẹ OLUWA?
OLUWA ní, “Nítorí pé ó nífẹ̀ẹ́ sí mi,n óo gbà á là;n óo dáàbò bò ó, nítorí pé ó mọ orúkọ mi.
Ayọ̀ tó ń bẹ nínú orin Jazz- Olakunle Tejuoso Ọmọkùnrin kan sin Baba rẹ̀ láàyè torì pé ó gbàgbọ́ pé oṣó ni!
Pẹlu iye awọn eeyan tuntun yii, o ti pe 57, 613 eeyan to ti ni arun naa l'orilẹede Naijiria bayii.
#EkitiDecides: Oluṣọla Ẹlẹka sọ ibi tí ìjọbá àná bá Ekiti dé
Oríṣun àwòrán, Google Àkọlé àwòrán, Aworan mọṣalaṣi Al Noor Ninu rẹ o fi adisọkan rẹ han nipa titako gbigba awọn ara orileede miran wọ inu ilẹ wọn.
Tí ó bá jẹ́ pé pẹlu agbára káká ni olódodo yóo fi là, báwo ni yóo ti rí fún àwọn tí kò bọ̀wọ̀ fún Ọlọrun ati àwọn ẹlẹ́ṣẹ̀?
Ọpọ iyalọmọ lo maa n gbaradi lasiko ti wọn loyun lati fun ọmọ wọn lọyan, sugbọn o se ni laanu pe ọpọ wọn ni ko ni oye to nipa bo se yẹ ki wọn fun ọmọ ni ọyan, ko si mu amuyo.
Kí n baà le sọ̀rọ̀ láìbẹ̀rù,nítorí mo mọ inú ara mi.
Aare Muhammadu Buhari ti ni sise
Nígbà tí ó ti gba irú àṣẹ báyìí, ó sọ wọ́n sinu àtìmọ́lé ti inú patapata, ó tún fi ààbà kan ẹsẹ̀ wọn mọ́ igi.
Kìí ṣe ará ìlú wa, ṣùgbọ́n àna mi ni òun ni ó fẹ́ ẹ̀gbọ́n mi obìnrin tí ó jẹ́ ìyekan bàbá mì.
Ninu atẹjade kan ti Wole Soyinka fi lede fun awọn akọroyin lo ti kesi ijọba apapọ bẹẹ.
”Dafidi dá a lóhùn pé, “Ilẹ̀ ìpakà rẹ ni mo fẹ́ rà, mo fẹ́ tẹ́ pẹpẹ kan fún OLUWA, kí àjàkálẹ̀ àrùn yìí lè dáwọ́ dúró.
Kanu Nwakwo: Òní ni ọjọ́ ìbí Kanu, àwọn ǹkan tó ti gbé ṣe rèé
O ni lara awon ile-ise ati ajo
Eyi fihan pe gbogbo iroyin to ba jọ mọ Facebook, Twitter ni awọn to n wa iwe aṣẹ irinna sorilẹede Amẹrika bayii gbọdọ ṣetan ati fa le awọn oṣiṣẹ ileeṣẹ aṣoju ilẹ Amẹrika lọwọ lasiko eto naa.
O jẹ́ olùdíje fún ipò gómínà Ìpínlẹ̀ Eko lábẹ́ ẹgbẹ́ òṣèlú APC, eyí tó jẹ́ pé ẹni ọdún mẹ́rìnléláàdọ́ta ni.
O óo tún ṣàánú wa, o óo sì fẹsẹ̀ tẹ ẹ̀ṣẹ̀ wa ní àtẹ̀parẹ́.
Ọgbọn ọdun ni Aarẹ al-Bashir ti lo ni iṣakoso, ki awọn ọmọ ogun to o gba ijọba lọwọ rẹ.
Àwọn ọmọ Ateri láti inú ìran Hesekaya jẹ́ mejidinlọgọrun-un
Lẹ́yìn tí wọ́n ti wà fún ọpọlọpọ ọjọ́, láì jẹun, Paulu dìde dúró láàrin wọn, ó ní, “Ẹ̀yin eniyan, ẹ̀ bá ti gbọ́ tèmi kí ẹ má ṣíkọ̀ ní Kirete.
Bí Jehudi bá ti ka òpó mẹta tabi mẹrin ninu ìwé náà, ọba yóo fi ọ̀bẹ gé e kúrò, yóo sì jù ú sinu iná tí ń jó níwájú rẹ̀.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù N jẹ Arsenal ò ti dà òkùtà sí Newcastle nígbá báyìí?
Buhari, a rántí ìjọba rẹ̀ fún ìyà, ìṣẹ́ àti ebi tó peléke - Araàlú faraya Ẹ fún ọ̀já kó le, lítà epo kan le tó ₦250 àbí ju ₦300 lọ"" Buhari pàṣẹ lórí àdínkù owó bẹntiró, alágbàtà ń ṣe tiwọn Wo àwọn oúnjẹ márùn ún tó ń mú kí àtọ̀ ọkùnrin dára síi Ngige sọ pe ijọba tun ti yan igbimọ kan lati ri i daju pe owo epo pẹtiroolu duro sokju kan."
O fọ ilu Ibadan to kun fun ẹgbin mọ, Ajimobi fẹ ọpọ́ awọn oju popo to wa nipinlẹ Oyo loju, to si tun kọ afara abẹyẹfo silu Ibadan.
Ẹwẹ, akọnimọọgba Man City, Pep Guardiola ti sọ pe gbagbagba bii ike lawọn alatilẹyin City yoo ṣe gbaruku ti wọn nigba ti wọn ba koju Brighton.
Ewu tó rọ̀ mọ́ lilo oogun apakokoro Níwọ̀n ìgbà tí kò sí ibi tí ìṣe kò sí, ọ̀pọ̀ ènìyàn ló máa ń lo òògùn apakòkòrò ní órílẹ̀-èdè Nàìjíríà bákán náà, èyí ló mú kí BBC Yorùbá ṣe ìwádìí àwọn ewu tí àwọn ènìyàn ti bá pàdé nínú lílo òògùn apakòkòrò.
“Tí ó bá jẹ́ pé gbogbo ìjọ eniyan Israẹli ni ó ṣèèṣì dẹ́ṣẹ̀, ṣugbọn tí ẹ̀ṣẹ̀ náà kò hàn sí ìjọ eniyan, tí wọ́n bá ṣe ọ̀kan ninu àwọn ohun gbogbo tí OLUWA ti pa láṣẹ fún wọn pé wọn kò gbọdọ̀ ṣe, tí wọ́n sì jẹ̀bi, 
Ẹ yin OLUWA, gbogbo ẹ̀yin aráyé;ẹ kókìkí ògo ati agbára rẹ̀.
Ní ọjọ́ kan, nígbà tí ọpọlọpọ eniyan tún wà lọ́dọ̀ Jesu, tí wọn kò rí nǹkan jẹ, ó pe àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀, ó wí fún wọn pé, 
Nigba to n salaye koko ohun to n se Kẹmi Afọlabi, dokita kan to kọwọrin pẹlu awọn arinrinajo hajj to wa latilu Eko, Abideen Aro, sọ pe awọn ami ti osere tiata naa n fihan ni iba, ori fifọ, ailee jẹun daada ati ko maa rẹ.
Ohun ijọniloju nibẹ ni pe agbẹ paraku ni Diaz atawọn eniyan agbegbe rẹ ni abule to jẹ pe oju wọn ṣẹṣẹ n la ni.
Awọn ajinigbe ni apa iwọ oorun guusu Naijiria tun gba ọna ara ọtọ jade si ẹbi ẹni ti wọn ji gbe.
ọkọ̀ ojú omi tuntun bẹ̀rẹ̀ iṣẹ́ Ìgbẹ̀yìn ọkùnrin tó pa obìnrin 93 ni America Odunlade fijó bẹ́ẹ, Lizzy padà sọ́dún 2012, Toyin Abraham tọ̀ lẹ́ẹ̀mẹwàá Ninu awọn fọnran fidio to gba oju ayelujara niṣe ni awọn eeyan n sa asala fẹmi wọn ti awọn kan si n gbiyanju lati pa ina naa.
Nígbà tí ẹnìkan bá dì mọ́ arakunrin rẹ̀,ninu ilẹ̀ baba rẹ̀, tí ó sọ fún un pé,“Ìwọ ní aṣọ ìlékè,nítorí náà, jẹ́ olórí fún wa;gbogbo ahoro yìí yóo sì wà lábẹ́ àkóso rẹ.
Orilẹede Sudan ni iṣẹlẹ ifapajọba ti pọju ni gbogbo ilẹ adaluawọ, igba mẹẹdogun ni awọn ologun ti gbiyanju lati fipa gbajọba.
Oríṣun àwòrán, @PDPng O fikun pe gomina ipinlẹ Oyo naa ko gbọdọ wa tọwọ bọ ilana ipo asaaju to wa ninu ẹgbẹ oselu PDP lẹkun iwọ oorun guusu Naijiria.
7 535049 Orilẹede Serbia 3708 53.
Nígbà tí gbogbo àwọn eniyan ń ṣe ìrìbọmi, Jesu náà ṣe ìrìbọmi.
, Duration 0,593 Ìgbé 2020 Coronavirus: Ọṣẹ́ wo ni Coronavirus ń ṣe ní àgọ́ ara?
Lara awọn ohun to wa ninui fidio naa ni bi wọn ṣe yibọn pa ọkan lara awọn eeyan ọhun, ti wọn si bẹ awọn mẹwaa to ku lori.
Awọn ọrọ yii lo foju han ninu atẹjade kan ti gomina ipinlẹ Ogun, Dapo Abiodun funra rẹ fọwọsi nirọlẹ ọjọ Aje.
í òwúrọ̀ ọjọ́ kejì, kò pẹ́ púpọ̀ tí mo lọ̀ kí àlejò wa yìí tán tí wọ́n fi wí fún mi pé oúnjẹ ti ṣetán, gbogbo wa lọ sí tábìlì, a jẹun.
“OLUWA Ọlọrun, ìwọ ni orísun ìyè gbogbo nǹkan alààyè.
Nígbà tí ìkùukùu náà tilẹ̀ dúró pẹ́ ní orí Àgọ́, àwọn ọmọ Israẹli ṣe ìgbọràn sí OLUWA, wọ́n dúró ninu àgọ́ wọn.
 Idagbasoke ile-iseIgbese naa wa lara ipinnu ijoba apapo lati ran awon ile-ise keekeeke lowo, ni eyi ti idagbasoke yoo fi de ba eto oro aje orile ede yii.
Akeugbagold gbe ìmọ̀ràn náà kalẹ lásìkò to ń bá BBC Yoruba sọ̀rọ̀ ni àárọ̀ ọjọ́ Aiku, ní kété tí ó rí àwọn ìbejì rẹ, tí wọ́n jí gbé padà.
Wọn a máa pète ìkà,láti fi irọ́ pa àwọn talaka run,kì báà jẹ́ pé ẹjọ́ aláìní jàre.
O fí kún pé ìròyìn tó àwọn léti pe ètò ààbò kò gbópọn to ní agbégbè náà, èyí ló mu ki ìgbákeji ọgá àgbà ọlọ́pàá ṣe àbẹwò síbẹ̀.
 Ìlú tó sọ ̀ kalẹ ̀ sí ní ilé-ifẹ ̀ tó jẹ ́ orírun àwọn yorùbá .
Ohun méje tí o kò gbọ́ rí nípa aláìsàn arunmọ-léegun- Dókítà Igbekele Ìlànà ìjìnàsíraẹni 'social distancing' forí ṣánpọ́n bí ìrun Jímọ̀ ṣe bẹ̀rẹ̀ padà ni Ilorin Ètò ìsìnkú Ibidunni Ighodalo yóò wáyé lórí ẹ̀rọ amóhùnmáwòrán bó bá ṣe ń lọ Ohun tí a rí nílé Ajimobi rèé lẹ́yìn ìròyìn òfégè pé ó jáde láyé Pabanbari rẹ ni pe ninu orin yii, Burna Boy fi ede Zulu lati South Africa ati ede Yoruba Naijiria kọrin ninu awo orin naa pẹlu Nomcebo Zikode.
" Ìtọjú náà doxycycline , tí o maa ńpa ẹgbẹ ́ ńpè ní bakiteríà "" wolbachia "" , jọ èyí tí o lè gba agbára lọ ́ wọ àwọn aràn náà , àwọn kan sì gbaniníyànjú pẹ ̀ lú ."
Ṣugbọn n óo mú kí ọkàn Farao le, tóbẹ́ẹ̀ tí yóo fi jẹ́ pé, bí ó ti wù kí iṣẹ́ ìyanu tí n óo ṣe ní ilẹ̀ Ijipti pọ̀ tó, kò ní gbọ́ tìrẹ.
"Fún àpẹẹrẹ ""OMI tí èyàn máa mu, kò ní ṣàn kọjá rẹ̀."
Jehoṣafati ọmọ rẹ̀ ni ó jọba lẹ́yìn rẹ̀; ó sì bẹ̀rẹ̀ sí gbáradì láti dojú ìjà kọ Israẹli.
Oríṣun àwòrán, @Segunmimiko Àkọlé àwòrán, Mimiko ni Gomina akọkọ to wole labẹ asia ẹgbẹ Labour Party lorileede Naijiria Mimiko tó kúrò lẹ́gbẹ́ òṣèlú alátakò, PDP nínú oṣù kẹ́fà ọdún yìí láti dara pọ̀ mọ̀ ẹgbẹ́ òṣèlú Labour Party kéde ní ìlú Abuja.
"O ni, ""ti minisita ba fi bu ọwọ lu awọn aba naa, ajọ JAMB yoo da a awọn oṣiṣẹ rẹ ọhun duro lẹnu iṣẹ, lẹyin eyi ti wọn yoo fa wọn le awọn agbofinro lọwọ fun igbesẹ to ba yẹ lori ọrọ wọn."
Ọjọgbọn Fabian tun fi kun un pe lasiko ti esi yii ba jade, gbangba laṣa ta ni wọn yoo fi ṣe ati pe gbogbo akẹkọ toi ṣe idanwo naa ni wọn ti fi ọna ti wọn yoo gba ri esi wọn ṣọwọ si.
Fiimu Moms at war si lo mu ki mama ibeji naa, moke laarin awọn akẹẹgbẹ rẹ.
O sọ fawọn oniroyin nilu Abuja pe ileeṣẹ oluṣiro owo agba Naijiria ni yoo buwọlu owo naa bayii ni ibamu pẹlu asiko ti aarẹ fọwọ si sisan rẹ.
Fidio naa Laahanmi naa ree: Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Làáhànmí: Ìwádìí ní èèyàn 219 ni ibà Lassa pa lọ́dún tó lọ́, 29 lọ́dún yìí, tètè dènà rẹ̀ Iwadi fi ye wa pe awọn ekute ile lo n fa iba yii, eyi to n sekupa ọpọ eeyan lọwọlọwọ bayii.
India: Àwọn ọmọ ilé ìwé fi páálí bojú láti má se jí ìwé wò!
com/d8UXKn77aoBakan naa, iko agbaboolu Porto yi koto esi ifesewonse won pada, leyin ti boolu agbesile gba(Penalty Kick)15′  18′26′Tiquinho  1 – 037′ 1 – 1 (pen.
Ọlọ́pàá Eko: Afurasí náà ní ẹnìkan ló bẹ òun lọ́wẹ̀ láti lọ gba ilẹ̀ onílẹ̀
 governor of gyongsangbuk-do , jeollanam-do , pyongannam-do , chungcheongnam-do , hwanghae-do , chungcheongbuk-do province .
”Ó dáhùn pé, “Mò ń gbọ́, oluwa mi.
Kí ẹnikẹ́ni má baà ta ẹ̀jẹ̀ aláìṣẹ̀ sílẹ̀ ní ilẹ̀ tí OLUWA Ọlọrun yín fun yín láti jogún, kí ẹ̀bi ìtàjẹ̀sílẹ̀ má baà wà lórí yín.
Àwọn olè yóo máa kó Gadi lẹ́rù,ṣugbọn bí wọ́n ti ń kó o,bẹ́ẹ̀ ni yóo sì máa gbà á pada.
Nígbà tí Pilatu jókòó lórí pèpéle ìdájọ́, iyawo rẹ̀ ranṣẹ sí i, ó ní, “Má ṣe lọ́wọ́ ninu ọ̀ràn ọkunrin olódodo yìí.
Ní òdìkejì odò Jọdani, ní apá ìlà oòrùn, ní ilẹ̀ Moabu, ni Mose ti ṣe àlàyé àwọn òfin wọnyi.
58 Èmi ni ìmọ́lẹ̀ tí ó ńtàn nínú òkùnkùn, òkùnkùn kò sì mọ̀ ọ́.
Alukoro ilẹeṣẹ ọlọpaa, Frank Mba nigba ti ikọ BBC Yoruba ba sọrọ ni ''oun ko ti ri fọnran fidio naa'' tori eyi ''ohun ko le fesi si'' Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Akọwe ẹgbẹ naa ni ipinlẹ Kaduna, Muntari Saleh sọ fun BBC pe ijọba ṣeleri fun wọn ni awọn ipade ti wọn jọ ṣe latẹyinwa pe, òun ko ni i fi ofin mu ẹnikẹni lasiko yii.
 lanre towry-coker friba ni wọ ́ n bí ní ọdún ( 1944 ) , tí ó sì jẹ oníṣẹ ́ ayàwòrán ilé , olóṣèlú ọmọ ilẹ ̀ nàìjíríà , .
Aarẹ Buhari se ikilọ yii lasiko ti ẹgbẹ awọn surveyor lorilẹede Naijiria, se abẹwo si ile Aarẹ nilu Abuja.
OLUWA bá dáhùn, ó ní, “Nítorí pé wọ́n kọ òfin tí mo gbékalẹ̀ fún wọn sílẹ̀, wọn kò gbọ́ràn sí mi lẹ́nu, wọn kò sì ṣe gẹ́gẹ́ bí ọ̀rọ̀ mi, 
O ṣeé ṣe ko ko jẹ nitori aisi ọkọ to n bọ lati ibẹ, tabi nitori pe wọn o fẹ ẹ lọ gba ọna to jin de Lagos Island ni wọn ṣe ko ẹsẹ si.
Ṣebí wọ́n ní ọpọlọpọ kẹ̀kẹ́ ogun ati ẹlẹ́ṣin?
Alaafin sọ ọrọ yii nigba ti gomina Makinde bẹẹ wo laafin Ọyọ lasiko irinajo rẹ si ilu Iṣẹmbaye naa lati ṣi awọn akanṣe iṣẹ ti wọn fi n sọri ọdun kan iṣejọba Makinde gẹgẹ bii gomina ipinlẹ Ọyọ.
12,  nigba ti awon olugbe ipinle Bayelsa n san edegbesan Naira N193.
Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Secret Cults in Nigeria: Ìyá àti ọmọ tó wà nínú Márúwá bá ìjà ẹgbẹ́ òkùnkùn lọ10 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Boader Closure reoppening: Àarẹ Buhari ní àti dẹ́kun fàyàwọ́ ogun ati ìbọn ló fa títi ẹnubodè pa, ṣùgbọ́n yóò di ṣíṣí padà láìpẹ́9 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Badirat Ajoke sọ pé òun fínnú-fíndọ̀ fi ààfìn Oyo sílẹ̀ ni, wọ́n kò lé òun9 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Victoria Kolawole: Òṣèré tíátà Yorùbá ní òun kò tíì ṣe ìgbéyáwó àmọ́ òun kò wá ọkọ''9 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Àwọn ọba kórìíra ibi ṣíṣe,nítorí nípa òdodo ni a fìdí ìjọba múlẹ̀.
Yatọ si eyi, Dokita Tsafe sọ pe ere idaya naa ma n mu ki ọkunrin le pa itọ mọra fun igba pipẹ.
Dafidi bá ń gbadura sí Ọlọrun pé kí ara ọmọ náà lè yá, ó ń gbààwẹ̀, ó sì ń sùn lórí ilẹ̀ lásán ní alaalẹ́.
ọrọ aje naa  fun orile ede Naijiria lojo
Gomina Ekiti ni ko si ohun to buru ninu ifẹhonuhan EndSARS to waye nitori ohun ti yoo mu iyipada rere ba awujọ ni.
 ohun tí a gbọ ́ ni a kọ sílẹ ̀ ní éréfẹ ̀ ẹ ́ nítorí kì í kúkú ṣe orí ìtàn ìlú Ọ ̀ ra-Ìgbómìnà gan-an ni mo ń kọ ìwé lé , ṣùgbọ ́ n bí òǹkàwé bá mọ díẹ ̀ nínú ìtàn tó jẹ mọ ́ ìṣẹ ̀ dá ìlú Ọ ̀ ra-Ìgbómìnà , yóò lè gbádùn gbogbo ohún tí a bá sọ nípa Ọdún Òrìṣà Ẹlẹ ́ fọ ̀ n ní Ọ ̀ ra-Ìgbómìnà tí mo ń kọ Ìwé nípa rẹ ̀ .
Níbìkọ̀ọ̀kan, nṣe ni wọ́n fa ààlà s'ójú ọ̀nà, tí wọ́n ya ọ̀nà kẹ̀kẹ́ s'ọ́tọ̀, tí wọ́n kùn ún ní ọ̀dà tirẹ̀ fún àkíyèsí àwọn awakọ̀ pé ọ̀nà awakẹ̀kẹ́ rèé o.
Minisita fun ile-ise iwakusa teleri lorile-ede naa lo di minisita fun eto –abo ,nigba ti minisita fun eto isuna owo ati fun ile okeere si di ijoko won mu.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ìtàn tó wà nídi òwe ‘Sebótimọ Ẹlẹ́wà Sàpọ́n’ Mo fẹ́ ọkọ mi torí bó se ń kọrin, kìí se torí owó - Ìyàwó Aràrá Mo fẹ́ kí àyẹyẹ ìgbeyàwó mi dùn ni mo se bú sẹ́kún - Ọkọ ìyàwó ẹlẹ́kún Samuel Ladoke Akintọla jẹ́ Agbẹjọ́rò àti Akọ̀ròyìn tí ọ̀rọ̀ dá lẹ́nu rẹ̀ Hubert Ogunde rèé, baba àwọn òsèré tíátà Oyinbo sọ fun wa pe oke to kere ju lori Oke Idanre lo jẹ ẹgbẹ́run mẹta ẹsẹ bata nigbati eyi to ga julọ nibẹ jẹ ẹ́gbẹrun mẹfa.
Anu tun sọ pe iṣe Omohtee kọ ni akọja ewe oun, nitori oun ti ṣe awọn iṣe mii to lami laaka to bi ẹgbẹrun kan ṣaaju iṣẹ rẹ.
Ogungbile to jẹ ẹni ọgbọn ọdun sun sori aga nile ọrẹ rẹ fun oṣu marun-un gbako, lẹyin to ti wa ile ti ko si ri nilu Abeokuta.
Ó bá bèèrè fún nǹkan ìkọ̀wé, ó kọ ọ́ pé, “Johanu ni orúkọ rẹ̀.
Lẹ́yìn tí a gbé ọjọ́ bíi mélòó kan ni Kesaria, a palẹ̀ mọ́, a bá gbọ̀nà, ó di Jerusalẹmu.
Ẹ gbé ẹ̀bi fún aláre, ẹ sì pa á, kò lè rú pútú.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Past week events: Àwọn ìṣẹ̀lẹ̀ ńlà lọ́sẹ̀ tó kọjá tó fi mọ́ bí Covid-19 ṣe gbẹ̀mí èèyàn 23 lọ́jọ́ kan ṣoṣowákàtí 8 sẹ́yìn Marriage dispute: Ìyàwó mi fi mí sílẹ̀ kó lọ sílé ọkùnrin míì nínú báráàkì kan náà, àmọ́ mò sí tún fẹ́ràn rẹ̀16 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Fídíò, Akomolede ati Aṣa: Mọ̀ síi nípa ìró afárànma àti agbárànmọ́ fáwẹ́ẹ̀lì Yorùbá15 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Habits that damage brain: Wo àwọn ìṣesí ojoojúmọ́ mẹ́wàá tó le ṣàkóbá fún ọpọlọ rẹ16 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Arẹwà Ibidunni Ighodalo wọ káà ilẹ̀ lọ nílùú Eko Igbákejì gómìnà ìpínlẹ̀ Ondo Agboola Ajayi ti fẹgbẹ́ APC sílẹ̀ lọ PDP Christian Pulisic lo kọkọ dayo naa pada nigba ti ifẹsẹwọnsẹ naa di wakati kan.
"Mo n rọ awọn ijọba to n dari awọn ipinlẹ to wa nilẹ Yoruba lati sọ ede Yoruba sisọ ati kika di kanpa lawọn ileẹkọ alakọbẹrẹ ati girama ni ipinlẹ koowa wọn, ki gbogbo wa si pawọpọ maa polongo agbega ede Yoruba kari aye.
    Ọ̀pọ̀lọpọ̀ àwọn iwin ni a tún ba pàdé lẹ́yìn èyí, ìgbà tí o tilẹ̀ ṣe èrù wọn kò bà wá mọ.
Ẹ wá, ẹ̀yin ọmọ, ẹ tẹ́tí sí mi,n óo kọ yín ní ìbẹ̀rù OLUWA.
Alukoro ileṣẹ ọlọpaa ni ipinlẹ Ọyọ, SO Olugbenga Fadeyi ti salaye fawọn akọroyin pe lootọ ni o.
Ààrẹ Buhari kí Akeredolu kú orííré bí ó ṣe jáwé olúborí nínú ìdìbò sípò gómínà Bí èsì ìdìbò gómìnà ìpínlẹ̀ Ondo se ń jáde rèé.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Adigunjalè báńkì há sínú súnkẹ̀rẹ̀-fàkẹrẹ ọkọ̀ Ìgbà wo ni àjọ ọ́lọ́pàá yóò káwọ́ SARS?
N óo fi ohun ìyanu hàn lókè ọ̀run,ati ohun abàmì lórí ilẹ̀ ayé;ẹ̀jẹ̀, ati iná, ìkùukùu ati èéfín.
Ìdàrúdàpọ̀ ńlá ń bọ̀ láti ilẹ̀ àríwá,tí yóo sọ àwọn ìlú Juda di ahoroyóo sì di ibùgbé àwọn ajáko.
Aare Buhari ni awon iran onkowe yoo moo lar ape eekan pataki kan wole ninu asa iran Yoruba ati tile Adulawo lapapo.
Eyi ni iwadii BBC Yoruba latari rogbodiyan to jade lẹyin ti Minisita fun Iroyin ati Aṣa ni Naijiria, Lai Mohammed sọrọ lori iye owo ounjẹ El-Zakzaky.
Dafidi bá ranṣẹ lọ pè é.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Bauchi woman: Balaraba Ibrahim tó jẹ́ Olùrànlọ́wọ́ pàtàkì fún ọ̀rọ̀ àwọn obìnrin tí a kọ̀ sílẹ̀ jẹ́ kàyééfì ní Nàìjíríà 10 Ògún 2020 Oríṣun àwòrán, others Ṣaaju ni oriṣiriṣi ẹjọ ti jade lori bi gomina ipinlẹ Bauchi to wa ni ariwa Naijiria ṣe yan arabinrin Balarabe Ibrahim sipo oluranlọwọ pataki.
Ẹgbẹ́ méjèèjì tí ó gbajúmọ̀ jù lọ, Ìpéjọ Ìlọsíwájú Gbogboògbò APC àti Ẹgbẹ́-olóṣèlú Ìjọba-àwa-arawa PDP, láì ṣe àní-àní, yóò tari òǹdíje wọn sí gbangba wálíà:
Aug 2018 ni ìgbìmọ̀ aláṣẹ APC ti ṣe ìpàdé kẹ́yìn, Oshiomole ti kùnà"" Òbítíbitì ẹ̀gbin ti sọ ìlú Ibadan di ààtàn - Aráàlú figbe bọnu Ọ̀pọ̀ àwòrán rèé tó ń sàfihàn bí Ibadan se kún fún ẹ̀gbin àti òórùn Aàrẹ, igbákejì aàrẹ àti aàrẹ ilé ìgbìmọ̀ aṣòfin kọ̀wé fipò sílẹ̀ lọ́jọ́ kan náà Bakan naa ni Soyinka tun bu ẹnu atẹ lu bi awọn osisẹ ajọ ọtẹlẹmuyẹ DSS se da ibọn bolẹ lati le awọn afẹhọnu han ka nilu Abuja lọ̀jọ Isegun."
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Okei-Odumakin: Awọn obinrin Naijiria nilo ajọ iranwọ fun oṣelu' 8 Ẹrẹ̀nà 2018 Oríṣun àwòrán, @DrJoeOdumakin Àkọlé àwòrán, O yẹ ki opin de ba lilo awọn obinrin gẹgẹbii ohun elo amuludun nikan Bi awọn orilẹede agbaye ti ṣe n ṣe ayajọ ọjọ awọn obinrin, gbajugbaja ajafẹtọ kan lorilẹede Naijiria, Dokita Okey Okei-Odumakin ti ke gbare sita wi pe n kan o tii se ẹnure fun awọn obinrin lorilẹede Naijiria.
“Bí ọwọ́ tabi ẹsẹ̀ rẹ bá mú ọ kọsẹ̀, gé e sọnù.
Nítorí gbogbo èyí, mo fi lé àwọn olólùfẹ́ rẹ̀ lọ́wọ́, àwọn ará Asiria tí ó ń ṣẹ́jú sí.
John Bray, tii se oludari ileesẹ asoju ilẹ Amẹrika ni Naijiria, ẹni to ka abọ naa lorukọ awọn yoku ni, Awọn asoju ilẹ Amẹrika, ajọ isọkan orilẹede nilẹ Yuroopu ati United Kingdom tọpinpin bi atundi ibo se lọ si lawọn agọ idibo nipinlẹ Ọsun l‘Ọjọbọ.
Wọn gbe wọn lọsi ileẹjọ majisireti nibi ti wọn ti sọ pe awọn jẹbi ẹsun ti wọn fi kan awọn, adajọ ni ki wọn san owo itanran pẹlu tii ṣe ẹgbẹrun un lọna ọgọrun naira fun ẹnikọọkan wọn pẹlu iṣẹ sinsin ilu.
Ta ni Ọgágun àgbà Lamidi Adeosun tó ṣẹṣẹ gba ìgbéga?
Yorùbá dùn lédè, ẹ máa sọọ́ Amọ Araba tilu Osogbo, Oloye Ifayẹmi Ẹlẹbuibọn ti salaye pe, oun ti gbọ nipa fanfa naa, ti ipade si ti n lọ lati tu isu de isalẹ ikoko lori isẹlẹ yii, tawọn yoo si pari rẹ.
Ninu ìbẹ̀rù OLUWA ni igbẹkẹle tí ó dájú wà,níbẹ̀ ni ààbò wà fún àwọn ọmọ ẹni.
Èèyàn mẹ́tàdínlógóje 137 ló kó covid-19 lọ́jọ́ Ìṣẹ́gun ọgọ́ta wá láti ìpínlẹ̀ Eko O dabi ẹni pe coronavirus tun ti n gbilẹ si diẹ diẹ lorilẹede Naijiria.
‘OLUWA sọ fún Oluwa mi pé:Jókòó ní ọwọ́ ọ̀tún mitítí n óo fi sọ àwọn ọ̀tá rẹ di ohun ìtìsẹ̀ rẹ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Alaafin: Olori Aanu Adeyemi ṣàlàyé ìdí tó ṣe gẹ́ Oba Lamidi Adeyemi ti ìlú Oyo 'Kìí ṣe pé ìjánu Ọkọ̀ tó pa Tolulope Arotile já tàbí kò já, ìwádìí wà lọ́wọ́ ọlọ́pàá' Nileeṣẹ ologun ofurufu to wa ni Kaduna ni gbogbo ọrọ yii ti ṣẹlẹ.
geesi EPL, ti opo awon ololufe ere
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Bí ọwọ́ ọlọ́pàá Kano ṣe tẹ ọkùnrin tó fẹ́ yọ́ wọ ilé ibùsùn obìnrin 7 Agẹmo 2019 Oríṣun àwòrán, Abdullahi Haruna Àkọlé àwòrán, Ọjọ gbogbo ni to le Ọwọ ọlọpaa lorile-ede Naijiria ti tẹ arakunrin ọmọ ọdun mẹẹdọgbọn kan, Umar Ali to mura bi obinrin lati yọ wọ inu ile ibusun awọn akẹkọọ obinrin ile ẹkọ olukọni ijọba apapọ Kano ni ariwa ila oorun Naijiria.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ẹrọ amunawa lọpo a ma lo lati pese ina.
Àwọn ọmọ mẹsan-an mìíràn tí Dafidi tún bí ni: Ibihari, Eliṣua, ati Elipeleti; 
”O ni rira ibo je ohun ti o lee fa akoba ba eto idibo lorile ede Naijria yii.
Àwọn òjíṣẹ́ mejeeji yìí tún ń bá wọn sọ̀rọ̀, wọ́n ń gbà wọ́n níyànjú pé kí wọ́n dúró láì yẹsẹ̀ ninu oore-ọ̀fẹ́ Ọlọrun.
Ibo gomina Ondo: Akeredolu fidirẹmi nileẹjọ
Kogi Lockdown: Ǹkan tí a mọ̀ nípa àṣẹ kóníléógbélé níjọba ìbílẹ̀ Kabba-Kunnu Oríṣun àwòrán, Yahaya Bello Àkọlé àwòrán, Gómínà Kogi pàṣẹ kóníléógbélé ní ìjọba ìbílẹ̀ kan ní Kogi Gómínà ìpínlẹ̀ Kogi, Yahaya Bello ti kéde kóníléógbélé ọṣẹ̀ méjì níjọba ìbílẹ̀ Kabba-Kunnu , nípìnlẹ̀ Kogi nítori ààrùn coronavirus.
Israẹli, bí àwọn eniyan rẹ tilẹ̀ pọ̀ bí iyanrìn etí òkun, díẹ̀ ninu wọn ni yóo pada, nítorí ìparun ti di òfin ó sì kún fún òdodo 
Ati pe jakunmọ kii rinde ọsan, ẹni a bii re kii rinrin oru ni awọn agba maa n wi.
Alaga ajọ EFCC dupẹ lọwọ awọn oṣiṣẹ ajọ naa fun iṣẹ takuntakun ti wọn n ṣe eyi to jẹ ki EFCC ṣe aṣeyọri lọdun 2020.
Ṣugbọn bi nnkan oṣu obinrin ti ṣe pataki to fun ibisi ẹda yìí, sibẹ oniruuru awọn igbagbọ ti ko fi idi mulẹ lode oni, ni Yoruba so mọ, eyi ta mu lẹsẹ lẹsẹ wa fun yín.
Òtítọ́ ni mo jẹ́ ìbátan tí ó súnmọ́ ọkọ rẹ, ṣugbọn ẹnìkan wà tí ó tún súnmọ́ ọn jù mí lọ.
O ya, iṣẹ kàn yín, bawo ni ogidi ọmọ Yoruba ṣe n ki onidiri?
Àwọn Ọ̀yọ́ ní kọ oríṣiríṣi Àbàjà, Pẹ́lẹ́ àti Túré.
Àwọn ará àdúgbó Lekki rí orí àti ara ọkùnrin mẹ́ta ní àdúgbo wọn
 Mi o le ṣe ohunkohun nipa rẹ.
Kọ ohunkohun tí ó bá wù ọ́ nípa àwọn Juu ní orúkọ ọba, kí o sì fi òrùka ọba tẹ̀ ẹ́ bí èdìdì.
Gẹgẹ bi Fathia ṣe gbagbọ, ifura aijolootọ sira ẹni to jẹ kulẹ kulẹ ija wọn gan wa latọwọ oriṣiriṣi iroyin ti awọn oniroyin n gbe kiri eyi ti ko si jẹ ko tilẹ roju mojuto igbeyawo rẹ.
Ayédèrú Ọ̀ṣun ni wọ́n ń bọ lónìí, kìí ṣe ojúlówó - Bàbá Ọlọ́ṣun tún figbe ta Wo ọ̀nà tí orin gbígbọ́ fi ń ṣèrànwọ́ f'ọpọlọ ọmọ ìkókó Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí kan sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Lizzy Anjọrin: Ilé tuntun tí mo rà yìí jẹ́ oríire ìyá mi tó jáláìsí 11 Agẹmo 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 12 Agẹmo 2019 Oríṣun àwòrán, Lizzy Anjọrin Ọpọ eeyan lo n dawọ idunnu pẹlu ilumọọka osere ori itage lobinrin, Lizzy Anjọrin ni Ọjọbọ, nigba to kede loju opo Twitter rẹ pe, Ọlọrun se oore ile tuntun nla kan fun oun.
Ẹni to bori: South Africa South Africa Orilẹede South Afrika ni orilẹede ilẹ Afirika to ni ibudo ajogunba ti Unesco julọ lagbaye, ti apapọ wọn jẹ mẹwa.
ki ibasepo to monyan lori wa laarin ijoba ati awon ara ilu ni ipinle naa.
Tani àwọn ọ̀dọ́ méjì tí yóò darapọ́ mọ́ igbimọ́ iwadii iṣẹlẹ́ Lekki ní Eko?
Ati pe akọṣẹmọṣẹ mẹtadinlogun ni wọn fi ranṣẹ si ipinlẹ Kano lati ṣe iranwọ lori gbigbogun ti itankalẹ arun naa.
Jẹ́ olõtọ́, kí o má sì ṣe gba ìdánwò láàyè.
Adepoju Ademola fun orile ede  Angola , Manuel  Augusto, lọjọRu niluu Abuja.
Awọn orilẹede miran ti arun yii ti n ṣọṣẹ ni Japan, South Korea, France, Ilẹ Gẹẹsi, ati Amẹrika wa lara awọn orilẹede ti arun naa ti n ṣọṣẹ.
Ọjọ kẹsan an, oṣu keji, ọdun 1965 ni wọn bi Ọmọwe Fayemi.
O ni bayi ti ko tii si ẹkunrẹrẹ alaye, ohun ko tii le sọrọ nipa ilana tuntun naa.
Titi ti ayo naa fi pari ti o si lọ abala wọmi-n-gba-si-ọ, ikọ mejeeji ko gba ayo kankan wọle.
ìdá ọgọ́ta ní ilẹ̀ Afirika jẹ ẹni ọdún márùndinlọ́gbọ̀n.
BBC Gov Debate: Àwọn olùdíje gómìnà Oyo gbà lati san 30,000N owó osù òsìsẹ́
Ìdáhún àtàwọn ìbéèrè míì O tu aṣiri pe ẹba àti ọbẹ̀ ẹgusi olomi làrò ni wọn n fún àwọn ènìyàn to wà níbẹ̀ lẹ́yìn ti wọn gba ẹgbẹ̀run lọna ọgọfa naira gẹ́gẹ bi owo òunjẹ ati ogun.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Coronavirus: Àwọn ọmọ Nàìjíríà n polongo pé ibìkan nàá ni kí olórí àti ọmọ ìlú ní Nàìjíríà ti gba ìtọ́jú 25 Ẹrẹ̀nà 2020 Oríṣun àwòrán, others Lati igba ti ajọ to n dena ajakalẹ aarun ni Naijiria, NCDC, ti kede pe olori awọn oṣiṣẹ fun Aarẹ Muhammadu Buhari, Abba Kyari naa ti ni aarun coronavirus, ni awọn ọmọ Naijiria kan, paapa lori ayelujara ti n sọ pe asiko yii ni awọn alaṣẹ Naijiria yoo ni imọlara aitun ẹka eto ilera Naijiria ṣe.
Ẹ gbọ iriri rẹ: Àwọn olùgbé ìpínlẹ̀ Ọ̀ṣun ya bo ibùdó ìdìbò láti gba oúnjẹ Coronavirus Òfìfo ṣọ́ọ̀ṣì pa aṣọ dà fún àwọn Páṣítọ̀ Nàìjíríà Afunrasí ẹ̀sùn jìbìtì ló ni iléeṣẹ́ tó ń ṣe ìwé àṣẹ wọléwọ̀de ní Nàìjíríà Òfìfo ṣọ́ọ̀ṣì pa aṣọ dà fún àwọn Páṣítọ̀ Nàìjíríà Èèyàn 16 míràn tún ti ní àrùn Coronavirus ní Naijiria Àwọn olùgbé ìpínlẹ̀ Ọ̀ṣun ya bo ibùdó ìdìbò láti gba oúnjẹ Coronavirus Èyí tí a wò jùlọ 5:03 Fídíò, Omolola Arohunmolase Welder: Mo ti fí iṣẹ́ 'Welder' gbayì láwùjọ, tó mo fi tọ́ ọmọ yanjú, Duration 5,039 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 5:39 Fídíò, Akomolede ati Asa lori BBC: Olùkọ́ Kikelomo Ogunboye tan ìmọ́lẹ̀ sí ìwà olè ọ̀gá ọlọ́pàá Audu gẹ́gẹ́ bí àwòkọ́ṣe àsìkò yìí, Duration 5,398 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 4:11 Fídíò, Oba Adeyeye Ogunwusi: Ojú mi ti rí lọ́pọ̀ lọpọ̀, ọ̀pọ̀ èèyàn ni kò tilẹ̀ gbàgbọ́ pé mo lè jọba- Ooni, Duration 4,117 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 4:43 Fídíò, Promise Akinlade: ọmọ ọdún mọ́kànlá tó ń fi ìlù dárà bíi àgbàlagbà sọ̀rọ̀ nípa tálẹ́ǹtì rẹ̀, Duration 4,437 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 0:59 Gbọ́, Ìsẹ̀lẹ̀ jákèjádò orílẹ̀èdè àgbáyé láàárín ìṣẹ́jú kan, Duration 0,59wákàtí 6 sẹ́yìn 4:45 Fídíò, Yoruba Films: Ẹ̀ẹ́ bẹ̀ mi kúrò láyé ni, mi ò lè kú - Fadeyi Oloro, Duration 4,4526 Èrèlè 2020 7:03 Fídíò, Olumuyiwa Bolade Adedeji Military Bruitality: Bí arákùnrin onípèníjà ara tí sọ́jà lù ṣe dé, Duration 7,035 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 2:48 Fídíò, Esther Ajayi: Èmi náà ti borí ìṣòro rí ló ń mu mi ṣojú àánú, Duration 2,481 Ògún 2019 6:08 Fídíò, Adebola Ademilua: Àìrísẹ́ ṣè lẹ́yìn ìwé kíkà ló sọ mi dí ìyá onírú, mo dúpẹ́ tèmi, Duration 6,0827 Bélú 2020 5:55 Fídíò, Soyinka Cancer: Àṣe ara mi ni iso ti n run gbogbo bí mo ṣe n ṣèrànwọ́ lórí jẹjẹrẹ, Duration 5,5527 Bélú 2019 BBC News, Yorùbá Ìdí tí ẹ fi le è nígbàagbọ́ nínú ìròyìn BBC Ìlànà Lílò Nípa BBC Òfin Àṣírí Cookies Kàn sí.
Ǹjẹ́ kò ní sàn fún wa kí á pada sí Ijipti?
Bio ti le je pe, iko agbaboolu Super Eagles kuna lati tesiwaju ninu idije boolu agbaye to n lo lowo lorile-ede Russia, lataari pipadanu ifesewonse keyin ipele naa sowo iko agbaboolu orile-ede Argentina, ogoro milionu awon ololufe iko agbaboolu lo panupo pelu akowe agba ajo FIFA, Fatma Samoura ati ajo CAF lati gboriyin fun iko Super Eagles fun ipa ti won ko ninu idije ohun.
Asán ati ìmúlẹ̀mófo ni èyí pàápàá.
– Seyi Makinde Ẹgbẹ́ APC dá ọmọ Alao Akala padà sípò alága Ogbomọṣọ North 2019 Election: Àwọn oloṣelu tó yege àti àwọn to fidirẹmi Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Issa Aremu: ṣàlàyé kíkún nípa èròńgbà ẹgbẹ́ Labour to bá jáde Oludije ẹgbẹ oṣelu AAC nibi idibo sipo aarẹ naa tun ṣalaye siwaju sii pe ijọba paṣan ni ijọba Buhari ni saa keji rẹ yii yoo jẹ fun awọn ọmọ orilẹede Naijiria.
Àkọlé àwòrán, Ede-aiyede lo se atiwaye bi wọn ṣe gbe ilẹkun ilẹ ẹkọ naa ti lati le dena ija ẹsin Ninu iwe ti aṣoju igbimọ alakoso ile ẹkọ naa, Ọjọgbọn A.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ibrahim El-Zakzaky: 'Ó ṣeésẹ kí El-Zakzaky máa lọ òkè òkun fún ìtọ́jú mọ́' 17 Ògún 2019 Oríṣun àwòrán, Twitter/SayyidZakzakyOffice Àkọlé àwòrán, Ọrọ lori ailera Ibrahim El-Zakzaky O ṣeeṣe ki olori awọn musulumi Shiite, Ibrahim El-zakzaky maa lanfani mọ lati lọ gba itọju loke okun lẹyin to pada si Naijiria latorilẹede India Ijọba Naijiria fẹsun kan an pe o fẹ wa awọn orilẹede miiran kunra lati gbaruku tii.
Lọwọlọwọ bayii, alafia ti jọba lọja naa ati agbegbe rẹ.
yii ko yọ oun gege bii gomina sile.
Ṣugbọn Paulu dáhùn pé, “Kí ló dé tí ẹ̀ ń sunkún, tí ẹ̀ ń mú ìrẹ̀wẹ̀sì ọkàn bá mi?
Ajọ Movement for Transparent Election ke gbajare lori bi idiwo se n wa lori eto isuna fun Ajọ eleto idibo lorilẹede Naijiria, INEC saaju idibo gbogboogbo.
“A ni awon ojulowo akosemose ti o le ko oko oju-omi yii, yala awon ti o gbe aworan re kale tabi lilo awon ojulowo ero igbalode ati awon ti o mojuto ise naa finin-finin, gbogbo re la ni patapata, “ Ewe, awon akosemose lorile-ede China so pe, China nilo oko oju-omi nla o kere tan mefa, leyin ti Amerika ti ni orisi mewa oko oju-omi yii, ti won si tun gbero lati tun ko meji miran si.
Bẹ́ẹ̀ ni n óo ṣe, kí n lè dá ọkàn àwọn ọmọ Israẹli tí wọ́n ṣáko kúrò lọ́dọ̀ mi nítorí oriṣa wọn pada.
pin awon ohun elo ati irinse  ti won yoo
38 Àti nípa àwọn ìfẹ́ inú wọn àti àwọn iṣẹ́ wọn ni ẹ̀yin yíò mọ̀ wọ́n.
Ìṣẹ̀lẹ̀ burúkú kan gbọdọ̀ ṣẹlẹ̀ sí mi.
Lori ọrọ aifun awọn Ọba ni ipa ninu iwe-ofin, Aṣofin Ọbasa sọ pe Ile Igbimọ Aṣofin Ipinlẹ Eko yoo kaaramasi ọrọ yii.
Nígbà tí wọ́n ti dá a lu tán, wọ́n sọ ọkunrin arọ náà kalẹ̀ ti òun ti ibùsùn rẹ̀.
Agbẹnusọ ile isẹ ọlọpaa ni ipinlẹ Ondo, Femi Joseph to sọ pe lootọ ni isẹlẹ naa waye, ni iwadii nlọ lọwọ lori isẹlẹ naa.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, '500 level'' ni mo wà nígbà tí mo di adélé Ọba' Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Nítorí èyí, ní ọjọ́ ìjà Olówó-ayé pẹ̀lú oníbodè, ìdàrúdàpọ̀ gba inú igbó kankan.
Say no to rape: Àwọn òṣèrébìrin Yollywood sọ tiwọn lórí ìfipábánilòpọ̀ tó gbòde
Ile ijọsin naa ni awọn gbe igbesẹ yi lati le sẹ iwadii ẹkunrẹrẹ lori ẹsun ti wọn fi kan olukọ fasiti naa.
Ẹ ṣí ilé ìwé padà ní Áfíríkà torí ọjọ́ iwájú àwọn akẹ́kọ̀ọ́ yín - WHO, UNICEF Háà, èyí tún ga!
Oríṣun àwòrán, @bukolasaraki Àkọlé àwòrán, Temi to mi lẹru.
Ati wipe, o nilo atunṣe ni igba meji ni ọdun.
Gomìna Kayode Fayemi ti ìpinlẹ Ekiti naa diboAworan
Ọlọrun, ọpọlọpọ ni òjò tí o rọ̀ sílẹ̀;o sì mú ilẹ̀ ìní rẹ tí ó ti gbẹ pada bọ̀ sípò.
Adajọ Okong Abang tun ni ki wọn bẹrẹ igbẹjọ lori ẹsun ikowo ijọba pamọ ti wọn fi kan pẹlu titi ti awọn agbofinro yoo fi mu pada wa sile ẹjọ.
 nínú ìlò ni àwon kan ti lè so pé òkan jé ìtéwógbà , èkejì kò jé ìtéwógbà .
Asiko to fun aarẹ lati gbe igbesẹ to tọ ni kiakia!
Ó yẹ kí Buhari dá owó epo padà sí ₦97 tàbí kó kọ̀wé fipò sílẹ̀ - Àwọn akẹ́kọ̀ọ́ Wò ó bí Alaafin àti aya àkọ́fẹ́ rẹ̀, Olorì Abibat ṣe pàdé ní èwe Ọmọ Ààrẹ lẹ́tọ̀ọ́ láti ṣe ìgbéyàwó yálà àwọn ará ìlú fẹ́ràn ìjọba bàbá rẹ̀ tàbí bẹ́ẹ̀ kọ́ - Aisha Buhari Owó lítà epo ní Nàíjíríà ló kéré jùlọ l‘Áfíríkà - Lai Muhammed O ni gomina Dapo Abiodun ti buwọlu ṣiṣi gbogbo ile iwe pada bẹrẹ lati ile iwe alakọbẹrẹ titi de awọn ile ẹkọ giga.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Indonesia Sriwijaya Air: Ọkọ̀ bààlú tó gbéro àádọ́ta pòórá lẹyìn tó gbéra láti Jakarta 9 Sẹ́rẹ́ 2021 Oríṣun àwòrán, AFP Ọkọ baalu kan to gbe eeyan aadọta lati olu ilu Indonesia,Jakarta, la gbọ pe o ti di awati.
Lẹ́hìn eléyìí ọkùnrin náà wí fún mi kí n dìde ó sì la ẹnu rẹ̀ ó bẹ̀rẹ̀ sí ọ̀rtọ̀ í sọ, ó wí pé, ‘Dìde ìwọ ọmọ ènìyàn, èmi ni Baba – onírùngbọ̀n – yẹ́úkẹ́, ẹni tí ń gbé ibi gegele òkúta.
Aláàfin yẹ́ Lizzy Anjọrin sí níbi ayẹyẹ ìwúyè rẹ̀ BBC ti bẹ̀rẹ̀ sí ní kajọ́ de ìdìbò 2019 Nàìjíríà Comrade Emmanuel sọ pe lori ọr igbega lẹnu iṣẹ lawọn n ja fun eyi ti ijọba ipinlẹ Ọyọ si n fi ẹtọ awọn dun wọn.
Àwọn ìwàásù akọnilẹ́nu hàà tí Prophet Israel Oladele CCC Genesis Global ti ṣe rèé Báàgì Ghana Must Go pàwọ̀dà, ó di ohun táwọn ránsọ ránsọ fi ń dárà orísirísi Wòlíì míì, tún wọ gàù lẹ́yìn tó tàpá sí ìlànà béèlì tí wọ́n fún un nílé ẹjọ́ Àwọn ọmọ Nàìjíríà yarí lórí èròngbà ilé aṣòfin pé kí àjọ FRSC má a lo nkan ìjagun Fasola wa paṣẹ fun awọn ẹṣọ oju popo ti a mọ si Federal Road Safety Corps lati rii pe wọn mu aṣẹ ijọba ṣẹ.
Ṣowore to jẹ ọkan lara awọn to ṣagbatẹru ifẹhonu han naa ṣalaye pe, ipinlẹ mẹtalelogun ni ifẹhonu han naa yoo ti waye kaakiri orilẹede Naijiria.
Oríṣun àwòrán, EPA Àkọlé àwòrán, Ọkọ yii yatọ ni adugbo itan Bo Kaap nigboro Cape Town.
Bí ọ̀gangan ibi tí àrùn náà wà bá bẹ̀rẹ̀ sí wòdú, tí àrùn náà kò sì tàn káàkiri ara rẹ̀, kí alufaa pe ẹni náà ní mímọ́, ara rẹ̀ wú lásán ni; kí ó fọ aṣọ rẹ̀, yóo sì di mímọ́.
Àwọn àgbààgbà ìjọ eniyan náà bá bèèrè pé, “Níbo ni a óo ti rí aya fún àwọn tí wọ́n ṣẹ́kù, níwọ̀n ìgbà tí a ti pa àwọn obinrin ẹ̀yà Bẹnjamini run.
Wọ́n ń sọ pé, “Ó mà ṣe o, a kò rí ẹran jẹ!
Bakan naa ni o tesiwaju pe, lara awọn iwadii ti ajọ naa ti ṣe ti ranwọn lọwọ lati fi panpẹ ọba mu ọpọlọpọ awọn afurasi.
Bi o tilẹ jẹ wi pe Ken Saro-Wiwa ko mọ nkankan nipa rẹ, ijọba da ẹbi le e lori wi pe o mọ nipa isekupani naa.
Tí a fiṣọwọ́ ní 5:43 10 Ọ̀pẹ̀ 20205:43 10 Ọ̀pẹ̀ 2020 Ọmọ ẹgbẹ́ òkùnkùn ṣoro ní Ijebu Ode, ọ̀pọ̀ ẹ̀mí sọnù Iroyin naa ni ẹgbẹ okunkun Eiye ati Aiye ni wọn n doju ija kọ ara wọn, eyi to mu ki ohun gbogbo poluku musu lawọn agbegbe kan nilu Ijebu OdeKà Síwájú Síi next Article share tools Facebook Twitter ṢàpínlòView more share options Share this post Copy this linkKà síwájú síi nípa àwọn ìtọ́kasí wọ̀nyí.
Ilú miran ni ó njẹ èrè ìnáwó bẹ́ ẹ̀, nitori bi wọn bá ṣe e ni ilé, èrò púpọ̀ ni yio jẹ èrè, pàtàki Alásè àti Onilù.
àwọn akọrin níwájú,àwọn onílù lẹ́yìn,àwọn ọmọbinrin tí ń lu samba láàrin.
Bákan náà lo tun jẹ Kọmiṣọnna fún idagbasoke àwùjọ, Kọmiṣọnna feto ẹ̀kọ́ nigba méjì, Kọmiṣọnna fún àkànṣe isẹ àti Kọmiṣọnna fún ìjọba ìbílẹ̀ àti oye jíjẹ.
 ijinna to pojulo lati ariwa de guusu je 200 km ( 120 mi ) ati lati ilaoorun de iwoorun je 170 km ( 120 mi ) .
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Àṣìṣe ọlọ́pàá àti Adájọ́ sọ mí di ẹni tí wọ́n dájọ́ ikú fún, ọpẹ́lọpẹ́ Fayoṣe tí ko buwọlu Afurasi ọhun ni a gbọ pe o jẹwọ fawọn ọlọpaa wi pe oun gbimọ pọ pẹlu awọn mẹta mii ninu eyi ti babalawo kan ti wọn n pe ni Owonikoko wa.
Oba Alayeluwa naa ṣalaye pe ilu ko mọ ohunkohun nipa iṣẹlẹ naa.
  Egbe oselu ANC  lo wa niwaju nigba ti egbe alatako Democratic
Eléyìí á dẹ́kun ọkọ̀ gbígbiná lójú títì.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ijegun Fire: Ẹ̀mí méjì, ọgbọ̀n ọkọ̀ àti ọ̀pọ̀ ṣọ́ọ́bù ló bá ìjàmbá iná rìn 4 Agẹmo 2019 Oru Ọjọbọ ni ibugbamu ina waye ni adugbo Ijẹgun ni Eko, tileesẹ NNPC si kede pe awọn eeyan to n ji epo wa lo ṣe okunfa rẹ.
 Nigba ti asolo ti ilu Ado-Odo,
Àwọn tí ó túká nígbà inúnibíni tí ó ṣẹlẹ̀ ní àkókò Stefanu dé Fonike ní Kipru ati Antioku.
Ó bá kọ kókó ohun tí ó rí lójú àlá náà sílẹ̀.
Bakan naa, igba mẹrin ọtọọtọ ni Oshinowo ti soju ẹkun idibo Kosofe kinni nipinlẹ Eko nile asofin ipinlẹ laarin ọdun 2003 si 2019 Ibo to din diẹ ni ẹgbẹrun lọna ọtalerugba ni Oshinowo fi bori alatako rẹ, Gbenga Ashafa ninu ibo to gbe wọle asofin agba lọdun 2019, to si soju ẹkun idibo ila oorun ipinlẹ Eko, labẹ ẹgbẹ oselu APC Pepper abi Pepperito ni inagijẹ ti ọpọ eeyan mọ Oshinowo si, nigba miran, wọn tun maa n pe e ni Unifier abi Stabiliser Ile ẹkọ girama lo wa, ti wọn fi fun ni Inagijẹ Pepper eyes nitori ẹyin oju rẹ to maa n pọn bii ẹrẹ ina, ikekuru rẹ si ni Pepper Adebayo Oshinowo ni iyawo, to si bimọ mẹta, meji ninu wọn lo jẹ onimọ Isegun oyinbo.
naa yoo tubọ maa fọwọsowọpọ lati ri i pe won dekun awon obayejẹ to n gbe oogun
Lasiko to n bawọn akọroyin sọrọ, olori osisẹ lọọfisi gomina, oloye Bisi Ilaka salaye pe iwa idaluru ti awọn ẹgbẹ ọlọkọ ero yii n hu lawọn agbegbe kan nilu Ibadan lo fa sababi igbesẹ ijọba naa.
Lojo Bo to koja ni awon omo ile tewogba eto isuna wole leyin osu marun ti Aare Buhari ti gbe e fun won.
Apapọ awọn to ti ni arun naa kaaakiri orilẹ-ede Naijiria ti wa di 27,110 bayii.
Èèyàn 111 ní àrùn Coronavirus tún ṣẹ̀ṣẹ̀ ràn ní Nàìjíríà ní Ọjọ́ọ̀rú Ajọ to n gbogun ti ajakalẹ aarun lorilẹ-ede Naijiria, NCDC ti kede pe eeyan 111 miran ti kun iye awọn to ti ni aarun COVID-19 ni Naijiria.
Ọ̀rẹ́ kìn- ín- ní jẹ́ olóòótọ́ gidi, èkejì sì ń fi àṣírí rẹ̀ pamọ́ síkùn, kìí nà tán fọ́rẹ̀ rẹ̀, bẹ́ẹ̀ sì ni ọ̀rẹ́ yìí kò mọ̀.
Ijọba ipinlẹ Kano ni awọn gbe igbesẹ lati yọ Sanusi nipo Ẹmia ilu Kano lati daabo bo aṣa, iṣẹṣe ati ẹsin ti o mu iyi ba ilu Kano.
Ibas so pe : “Aare  ti pase fun gbogbo ile-ise to n pese aabo
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù AfCFTA: Buhari gbe igbimọ kalẹ lori adehun okoowo ọfẹ 22 Ẹrẹ̀nà 2018 Oríṣun àwòrán, @BashirAhmaad Àkọlé àwòrán, Naijiria dawọduro lori adehun naa lẹyin ariwo latọdọ awọn ẹgbẹ osisẹ ati olokoowo gbogbo Ijọba apapọ ti gbe igbimọ kan kalẹ ti yoo jiroro pẹlu awọn alẹnulọrọ atawọn leekan leekan to fimọ igun gbogbo to nii se pẹlu ọrọ titọwọ bọwe adehun eto karakata ọfẹ ni ilẹ Afirika, (AfCFTA).
'Gómìnà Akeredolu lọ́wọ́ nínú wàhálà ilé aṣòfin Ondo' Saraki àti Buhari fẹ́ wọ ìyá ìjà ní Kwara Lẹyin ti awọn aṣofin naa yọ Bamidele Ọlẹyẹloogun ati igbakeji rẹ Ogundeji Iroju nipo ni awọn janduku ti iroyin sọ pe wọn jẹ ọmọ ẹgbẹ awakọ ero NURTW nilu Akurẹ ya bo ile aṣofin naa ti wọn si lu awọn aṣofin ati oṣiṣẹ ti ọwọ wọn ba.
Olu ilu ilẹ Naijiria, FCT lo ṣe ipo keji nibi ti eeyan mẹrinlelọgọta ti lugbadi aarun ọhun.
Ronaldo ní Tottenham yóò jẹ moyó ìyà lọ́wọ́ Liverpool N kò lẹ́bi pé ejò kó ₦36m owó àjọ JAMB mì -Philomina Kíni N11trn owó ìrànwọ́ epo tí ìjọba àpapọ̀ san fún àwọn agbépo lè rà?
Léyìn gbogbo ètò tí ó ye léyìn ìgbésè oba, wón mú ojó láti pín ogún oba ni ìbámu pèlú àsosílè oba.
Atẹjade kan ti akọwe apapọ fẹgbẹ APC, Yekini Nabena fisita salaye pe ayafi ti aawọ abẹnu ẹgbẹ naa ba di afiẹyin, ni ipade apapọ ẹgbẹ yoo to waye.
Lóòótọ́ náà, mo fetí sílẹ̀ mo sì ń gbọ́ ohùn àwọn ẹranko inú igbó àti àwọn ejò inú aginjù, àwọn igi àti àwọn ọ̀pẹ̀, ewéko àti ìtàkùn, dúkìá gbogbo ti ń bẹ ní orí òké àti ohun àlùmọ́ọ́nì tí ó wà ní ìsàlẹ̀ ilẹ̀, àwọn ẹja inú omi àti àwọn kòkòrò orí ilẹ̀- gbogbo wọn ń kígbe wọn ń wí báyìí pé, ‘Lọ!
Fasiti OIlabisi Onabanjo lo ti kawe gboye ninu imọ Public Administration to si tun gboye Diploma ninu imọ ofin lati fasiti ilu Eko.
Ṣugbọn ṣa, o sọ pe dandan ṣi ni fun gbogbo eniyan lati maa tẹle awọn ilana ti ijọba la kalẹ.
“Ka iye àwọn ọmọ Geriṣoni ní ìdílé-ìdílé, gẹ́gẹ́ bí ilé baba wọn: 
A sọ fún wọn pé kí wọ́n má ṣe ohunkohun sí koríko orí ilẹ̀ tabi sí ewébẹ̀ tabi sí igi kan.
Onimọ nipa eto ilera, Onyeka Onwuegbunam ọmọ Naijiria to n ṣiṣẹ ni Fasiti ilu London sọ pe ''ko si itọju to peye lawọn ile iwosan ijọba nitori ọda owo na.
Ó mú kùmọ̀ ńlá kan sí ọwọ́ òsí, ó sì fi ọwọ́ ọ̀tún mú agbárí ènìyàn kan: nítorí ẹ̀dá búburú ni, a máa fi agbárí ènìyàn mu omi.
Won lo anfani pe won jo fowosopo gbalejo idije Olympics to sese pari ti won jo yan bi Ologun papo.
"Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Niyi Akinmolayan tó ṣe fíìmu àwòrán-dèèyàn Cartoon nípa COVID-19 tó la ayé já ní N ""Kò sí àìsàn tàbí àrùn ni orílẹ̀ ayé tí àwọn baba wa kò leè wòsàn, mo sì mọ pe àwọn agbára náà sì wà síbẹ̀ títí di òní."
Ninu ibanujẹ yi naa ni wọn tun kesi ijọba lati fidajọ ododo mulẹ lori iku awọn ọmọ yi.
Ẹ óo máa rú àwọn ẹbọ wọnyi kún ẹbọ sísun ati ẹbọ ohun jíjẹ ati ẹbọ ohun mímu ojoojumọ.
Ọlọrun, nígbà tí ò ń jáde lọ níwájú àwọn eniyan rẹ,nígbà tí ò ń yan la aṣálẹ̀ já,
Adugbo naa jẹ ibudo itan aṣa Malay nigboro Cape Town, osi jẹ ibudo mọṣalasi akọkọ ni orilẹede South Africa eleyi ti awọn ajeji kọ lọdun 1884 , gẹgẹ bi ileese iroyin EPA ṣe sọ.
Kò si igbà ti àlejò kò ni ri ibi ti wọn ti ńṣe ayẹyẹ kan tàbi èkeji ni gbogbo ilẹ́ Yorùbá.
Lẹ́yìn èyí, Ẹ̀mí Ọlọrun gbé Jesu lọ sinu aṣálẹ̀.
"Àjọ elétò ìlera lágbàáyé (WHO) ní Tramadol làwọn èèyàn lérò pé ó ""èèyàn leè má tètè kúndùn rẹ̀ táa fi wé Morphine"" Àmọ́ bí ọwọ́jà òògùn náà se ń jà rànìn-rànìn káàkiri ẹkùn ìwọ̀ òòrùn Afrika tako èrò yìí."
Coronavirus in South Africa: Ẹ̀kọ́ mẹ́jọ tó yẹ kí ilẹ̀ Afirika kọ́ lára àjàkálẹ̀ ààrùn coronavirus
ẹgbẹrun mẹrinlelogoji (44,000) ni iwadii naa gbe yẹwo ninu eyi to ti fihan pe ida mẹta din diẹ ninu ọgọrun (2.
O ni ni kete ti kọmiṣọna feto iṣuna kansẹ ba owo naa lo fi to ijọba leti ti wọn si ti ṣe akọsilẹ rẹ.
“Ẹ ti fetí ara yín gbọ́,nítorí náà, ẹ wo gbogbo èyí, ṣé ẹ kò ní kéde rẹ̀?
Bawo ni ààrẹ tó rọlápá-rọlẹ́sẹ̀, tí kò leè sọ̀rọ̀, ṣe fẹ́ darí ìjọba?
Solomoni fẹ́ràn OLUWA, ó sì ń tẹ̀lé ìlànà Dafidi, baba rẹ̀, ṣugbọn òun náà a máa rúbọ, a sì máa sun turari lórí àwọn pẹpẹ ìrúbọ.
Tẹ́tí sí mi OLUWA, kí o sì gbọ́ adura mi,nítorí òtòṣì ati aláìní ni mí.
Chelsea fẹyin Norwich City gba lẹ nile wọn ni Carrow Road lẹyin ti wọn ti ta ọmi kan ti wọn si jawe olubori ninu omiran ninu ifẹsẹwọnsẹ meji ti wọn ti gba lati igba ti idije Premier League ti bẹrẹ ni saa yii.
Ẹ kọrin sí i, ẹ kọrin ìyìn sí i,ẹ sọ nípa àwọn ohun ìyanu tí ó ṣe!
ó fún àwọn ọmọ Israẹli, iranṣẹ rẹ̀,nítorí pé ìfẹ́ rẹ̀ tí kì í yẹ̀ wà títí lae.
Iwe naa si wipe ki Keyamo fi alaye rẹ ranse si minista eto idajọ titi ogunjọ osu keji ọdun 2018.
Seyi Makinde: Ìyàtọ̀ yóò dé bá àwọn òṣìṣẹ́ lásìkò yìí
Jesu tó ẹni ọgbọ̀n ọdún nígbà tí ó bẹ̀rẹ̀ iṣẹ́ rẹ̀.
Lati kekere ni iwe kika ti wu Andrew ṣugbọn ko si agbara rara.
Nigba ti nnkan to di dojuru to bayi,ẹkun kan ni yoo fa Gomina kale ti awọn ẹkun miran naa yoo si di ipo miran mu gẹg biigbakeji tabi Minisita ninu ijọba apapọ.
kale fun omo ile igbimo asofin Ipinle Oyo.
”Gbogbo wọn dáhùn pé, “Kàn án mọ́ agbelebu.
Oríṣun àwòrán, @Dino Àkọlé àwòrán, Mo kọ lati jawọ nini idije Awọn wo lo n dije ninu PDP lati di gomina Kogi?
Bi aladi ko ba si nile, ọmọ wọn nii jogun ẹbu ni Funmilayọ fi ọrọ ijajagbara rẹ ṣe, Awọn ọmọ rẹ bii Bẹkọ Ransome - Kuti ati Fẹla naa tẹsiwaju lori eyi ni, sé ọmọ ti ẹya ba bi, ẹya nii jọ.
Ọ̀fọ̀ dípò orin ayọ̀ fún mi,ẹkún sì dípò ohùn fèrè.
Ẹ óo tún ṣe ọgbà àjàrà sórí òkè Samaria;àwọn tí wọ́n gbin àjàrà ni yóo sì gbádùn èso orí rẹ̀.
òṣùnwọ̀n yín gbọdọ̀ péye: ìwọ̀n efa tí ó péye ati ìwọ̀n hini tí ó péye ni ẹ gbọdọ̀ máa lò.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Makinde vs Adelabu: Makinde ní ìjọba Ọyọ yàtọ̀ sí ti Ọṣun àbí Ekiti tí APC lé dànù Ijamba naa ṣẹlẹ nigba ti taya ọkọ akoyọyọ kan, to n sare asapajude fọ lojiji, to si fori sọ ọkọ akero meji ti ohun naa n sare loju popo ọhun.
ó fún Nàìjíríà l'èsì àwọn ẹ̀sùn tó fi kàn-án Ta ni ìyàwó Chadwick Boseman, tó jẹ́ àwòkọ́ṣe rere f'áwọn ọ̀dọ́ Adúláwọ̀?
Buhari ṣe ìpàdé pẹ̀lù àwọn ọmọ Nàìjíríà ní China Aarẹ orileede Naijiria Muhammadu Buhari ti se ipade pẹlu awọn ọmọ Naijiria to wa ni orileede China.
Ikọ alakatakiti Al-Shabaab n gbimọran ati sefilọlẹ ijọba ẹsin Islam lorilẹede Somalia lati kọ ipakọ si ohun gbogbo to ba rọ mọ ti oyinbo nibẹ.
CP Abiodun Ige - CP Osun Command xxx.
Onisowo Mike Zhang to ti lo ọdun mẹtadinlogun ni Kano ni, niṣe ni inu oun dun pẹlu ọla ti wọn da oun yi.
Bakan naa ni awọn kan ni ko tọ si Mamman Daura lẹnu lati sọ iru ọrọ bẹẹ fun awọn ọmọ Naijiria.
Ṣugbọn ṣe wọn ni Satide ti yoo dun, ọjọ Jimọleyan tii mọ.
Ṣugbọn ẹyẹle New Kim naa ti fẹyin ti bayii.
Awokọṣe rere ti oun funra rẹ di itan to si tun gbe aṣa ga lati igba ewe rẹ titi to fi wọ kaa ilẹ ni Ogedengbe.
Ọ̀kan lára olùwọ́de tó fara gbọgbẹ́ ní Lekki jáde láyé - Sanwo-Olu Oríṣun àwòrán, @jidesanwoolu Iroyin to n tẹ wa lọwọ bayii lo ni ọkan ninu awọn ọdọ to fara gbọgbẹ ninu ipaniyan Lekki ti jade laye.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù India: Ó lé ní mílíọ́nù ènìyàn tí wọ́n kó kúrò lágbèègbè Orissa 3 Èbibi 2019 Oríṣun àwòrán, Reuters Àkọlé àwòrán, Àjọ tó ń rísí ojú ọjọ́ ní ìjì lílẹ Cyclone Fani ní agbéégbé Orissa ló wà ní ọ̀gangan ibi tí ìjì lílẹ náà ń gbà.
Wọ̀bìà, àjẹbánu ti mú káwọn èèyàn kọ ẹ̀sìn sílẹ̀ - Buhari Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ìwà ipá nínú ìdílé máa ń bí ìgè àti àdùbí ni tó lè já sí ikú Ko daju boya Aarẹ Buhari jan oludije ẹgbẹ yi ni òǹtẹ̀ nibi ipade naa ṣugbọn ko sọ bakan naa pe oun lodi si iwa Amosun ti awọn ọmọ ẹgbẹ APC kan ri gẹgẹ bi iwa to lodi si aṣẹ ẹgbẹ.
3 543 Orilẹede Antigua ati Barmuda 6 6.
Wọ́n sún ìsìnkú Abiola Ajimobi di ọ̀la Satide Ìtàn ìgbésí àyé olóògbé Isiaka Abiola Ajimobi Ìgbé ayé Abiola Ajimobi nínú àwòràn pẹ̀lú àwọn ǹkan tó ṣẹlẹ̀ Ajimobi kìí bá ọ̀lẹ, olè àti ọlọ́pọlọ kúkú ṣe ọ̀rẹ́ - Alaafin Ajimobi, ẹni tii ṣe onimọ nipa oko-owo epo rọbi ati oloselu to dantọ ṣe gudu gudu meje ati ya ya mẹfa nigba aye rẹ, Idi si ree ti BBC fi ṣe akojọpọ igbe aye agba oselu naa ati awọn ohun ribiribi to gbe ile aye ṣe.
 Ẹja eléèpo tí a kò sè dáadaa jẹ ́ orísun tí ó wọ ́ pọ ̀ .
Wike lo sọrọ yii nigba ti o n mu alaga ajọ awọn gomina, Kayode Fayemi rin lori ilẹ ti wọn ni o ti wo mọṣalaṣi naa.
18% Makinde awọn ileewosan to wa nipinlẹ Ọyọ ni wọn jẹ ibudo ibeere lasan tẹlẹ, amọ ti ijọba oun ti pese awọn irinsẹ feto ilera igbalode si ilewosan Adeọyọ, ti awọn irinsẹ igbalode naa yoo si kari gbogbo ilewosan ijọba to wa nipinlẹ Ọyọ bii Tede, Eruwa ati Isẹyin Ijọba yoo tun gba ẹẹdẹgbẹta awọn olukọ si nipinlẹ Ọyọ.
“Gbogbo àwọn tí wọ́n bá jẹ́ mímọ́ lè jẹ àwọn ẹran yòókù, 
Bẹ́ẹ̀ ni Jehoṣeba ṣe gbé ọmọ náà pamọ́ fún Atalaya, tí kò fi rí i pa.
Ogidi Olu ni apeja orukọ naa ti wọn n ki ni onikanga ajipọn.
Nínú gbogbo orílẹ̀-èdè márùndínlọ́gbọ̀n, tí ó ń wá òògùn ìṣẹ́yún jùlọ lórí goggle fún Misoprostol, mọ́kànlá nínú wọn wá láti ilẹ̀ Afíríkà, tí àwọn mẹ́rìnlá tó kù sì jẹ́ Latin America.
 iyá mi ní àwòrán ere aránso .
Osinbajo tun ni “Iyalenu  ati iberu ni yoo je bi  iye awon omo orile ede Naijiria yoo se po si, lojo iwaju.
Everton já Manchester United sí ìhòhò lọ́jọ́ Àjíǹde Irú kan-ùn.
gege bi onka 2002 se fihan , 42.
”Aare gboriyin fun awon alakoso egbe GOGAN, ti o sagbekale eto ohun fun akiityan ati ogbon ijinle won lojuna ati fese irepo mule sinsin lorile-ede Naijiria.
O ti di ẹni ẹlẹgẹ́ láti òní lọ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, ìpàdé ìtagbangba ìfọ̀rọ̀wánilẹ́nuwò pẹ̀lú àwọn olùdíje sípò gomina ní ìpínlẹ̀ Eko.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Akomolede ati Aṣa: Mọ̀ síi nípa ìró afárànma àti agbárànmọ́ fáwẹ́ẹ̀lì Yorùbá Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí School resumption: Ilé aṣojú-ṣòfin l'Abuja dábàá kí ìjọba sún ìwọlé àwọn akẹ́kọ̀ọ́ síwájú pẹ̀lú oṣù mẹ́ta torí covid-19wákàtí 7 sẹ́yìn Beer Belly: Wo ohun tó yẹ ko mọ̀ nípa ikun rẹ tó ń to tobi17 Sẹ́rẹ́ 2021 Past week events: Àwọn ìṣẹ̀lẹ̀ ńlà lọ́sẹ̀ tó kọjá tó fi mọ́ bí Covid-19 ṣe gbẹ̀mí èèyàn 23 lọ́jọ́ kan ṣoṣowákàtí 8 sẹ́yìn Association of Stingy Men: Akeugbagold ní àpẹẹrẹ wèrè díẹ̀díẹ̀ ni k'ẹ́ni tó lówó láhun sí obìnrinwákàtí 9 sẹ́yìn Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Ọmọwe Ngozi Okonjo Iwealla ni ko si aniani pe eto ọrọ aje agbaye gbogbo ni yoo dẹnukọlẹ eleyi to tums si pe kini naa yoo kan awọn orilẹede Afirika pẹlu.
pé yóo gbà wá lọ́wọ́ àwọn ọ̀tá waati lọ́wọ́ gbogbo àwọn tí ó kórìíra wa;
Sakaraya ni baálé ní ìdílé Ido,Meṣulamu ni baálé ní ìdílé Ginetoni,
Ṣa dede ni wọn ba oku rẹ ninu agbara ẹjẹ ninu ile to n gbe pẹluu awọn bi rẹ ni agbegbe Idi Ori, Ọjọọ, ijọba ibilẹ Akinyẹlẹ niluu Ibadan l'Ọjọ Abamẹta.
Kí Olúwa ṣọ́ wa jù’gbà náà lọ o.
Bakan naa laagbọ pe o ṣeeṣe ki Mourinho pada si ikọ Real Madrid eleyi to ti tukọ rẹ ri tẹlẹ.
Wọ́n gbé e lọ ilé- ẹjọ́.
Iwaadi ṣi n lọ lọwọ lori awọn iku wọn yi.
Iná mọ̀nàmọ́ná ló se mọ́namọ̀na Ìròyìn fi tóni létí pé, iná ẹ̀lẹ́tíríìkì tó lọ lójijì lẹyin ti iji kọlu ọkan lara awọn oun èèlò amunawa ti ko jinna si ibudo iwakusa ọun ló fàá tí awọn awakusa naa fi há lojiji sinu iho ilẹ, ti wọn si ti n sa'pá lati ìgbà naa lati fa wọ́n jade.
Ṣugbọn nígbà tí ẹ bá rékọjá sí òdìkejì odò Jọdani, tí ẹ sì ń gbé ilẹ̀ tí OLUWA Ọlọrun yín yóo fun yín, nígbà tí ó bá sì fun yín ní ìsinmi, tí ẹ bá bọ́ lọ́wọ́ gbogbo àwọn ọ̀tá tí ó yí yín ká, tí ẹ sì wà ní àìléwu, 
igbimo asofin Ike Ekweremadu lo soro yii lasiko ti o lọ si ipinle Gombe lati se
Ṣé o mọ àwọn òfin tí ó de ojú ọ̀run?
Ni ọpọ ile iwosan ijọba yii, ọpọ ọmọ tuntun ti wọn ba bi sile iwosan naa lasiko kan naa, ni wọn yoo gbe wa sibudo ti wọn ti n wẹ wọn.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Peter Fatomilola ní àìsí ẹ̀kọ́ ń mú káwọn òṣèré tíátà ó máá ṣe oun tí kò tọ́.
Awọn Okunrin to koju agbebọn naa pẹlu gba oriyin Eeyan pupọ la ri akọsilẹ pe wọn koju arakunrin to yinbọn pa awọn eeyan nigba ti ibọn wa lọwọ rẹ.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Michail Antonio ti ikọ West Ham ati Angelo ogbonna lo gba bọọlu wọle fun ikọ naa ti ayo fi pari si 3-2.
Gistloverszone tun sọ pe Ronke ni oun nilo miliọnu marundinlaadọrin (65million) Naira, lati ni awọn irin'ṣẹ fun sinima yiya gẹgẹ bi awọn akẹẹgbẹ oun.
Elijah sọ wipe ajọmọ oun ati iyawo oun ni lati ta ọmọ tuntun jojolo naa.
Ibi tí o kò fúnrúgbìn sí ni o tí ń kórè.
Oríṣun àwòrán, The Nigerian Senate Àkọlé àwòrán, Ali Ndume Akẹgbẹ rẹ ni Sẹnẹtọ Mohammed Ali Ndume lati ipinlẹ Borno to n soju ẹkun guusu Borno.
Wọ́n wí láàrin ara wọn pé, “Irú kí ni a ṣe yìí, tí a jẹ́ kí àwọn eniyan wọnyi lọ mọ́ wa lọ́wọ́, tí a kò jẹ́ kí wọ́n ṣì máa sìn wá?
Sọ fún ilẹ̀ náà pé OLUWA ní, ‘Wò ó, mo ti dojú kọ ọ́, n óo yọ idà mi ninu àkọ̀ rẹ̀, n óo sì pa àwọn eniyan inú rẹ: ati àwọn eniyan rere ati àwọn eniyan burúkú.
Ẹ jí ẹ̀yin ohun èlò ìkọrin ati hapu!
Alukoro ọlọpaa, DSP Yakubu Sabo lo fidi ọrọ yi mulẹ fun BBC.
Iṣẹ ti awọn aburo mi, baba mi ati emi ti file ara wa lọwọ lati igba ti wọn ti pa iya mi ni lati wa idajọ fun ipaniyan rẹ, ki a si ri pe nkan bi eyi ko ṣẹlẹ mọ.
Nígbà tí wọ́n dé Jerusalẹmu, wọ́n wọ inú tẹmpili lọ, pẹlu ìró hapu, ati ti dùùrù ati ti fèrè.
Mo n jiya ẹsẹ ti mo ṣẹ ni, ko yẹ ki n wa lẹwọn bi mo ṣe jẹ abiyamọ, o fi kun Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Bàbá mi náà sì dáhùn, ó wí pé: mo ni àfẹ́sọ́nà kan, òun náà ló sì jókòó ti mí nínú kẹ̀kẹ́ yìí.
Ni ọjọ kan, bi o ṣe p'ẹyinda lati maa lọ, ọmọ kan gba a lọwọ mu.
Emi kò jẹ́ dalẹ̀ ọga mi lẹ́nu iṣẹ́, ṣùgbọn mo fẹ́ tọ ipa ti ọkàn mi fẹ́ lásìkò yii ninu òṣèlu.
 Odun 2010 ni wón pade nibi idije ife ẹyẹ agbaye ni South Africa.
Ó jẹ́ aya Goriọla Hassan tẹ́ll ṣùgbọ́n wọn kò sí papọ̀ mọ́.
 Ẹ ̀ yìn èyí ni a wá ṣe àfiwé pọ ́ n-na pẹ ̀ lú àwọn ẹ ̀ yà Ìtumọ ̀ mìíràn tó ń bá a ṣé orogún .
Koda, wọn nawọ ifẹ ati iranlọwọ si awọn agbofinro pe iwọde yii a bi eso atunṣe owo oṣu fun awọn ọlọpaa ti ijọba ba gba ohun ti awọn oluwọde n fẹ ki alaafia ati abo to peye le wa fun gbogbo olugbe Naijiria.
Nigba ti Kabiyesi kopa ninu ijiroro Ile naa lede Yoruba, wọn ṣalaye pe ohun iwuri gbaa ni igbesẹ yii ti o yẹ ki awọn ipinlẹ yooku ni apa Iwọ-oorun Naijiria (ilẹ Yoruba) wo ṣe awokọṣe lati gbe ede ati aṣa Yoruba larugẹ.
bórọ ̀ nù ni ẹ ́ límẹ ̀ ntì kẹ ́ míkà kan tó ní àmì-ìdámọ ̀ b àti nọ ́ mbà átọ ̀ mù 5 .
Ko tan sibẹ o, wọn tun n beere iriri ti wọn ni nidi didaabo bo adugbo wọn, ati ipa ti wọn n ko ladugbo si aabo awujọ nijọba ibilẹ wọn.
Amọ, awọn alatako ati onwoye ọrọ ilu n sọ wi pe aarẹ Buhari ko ṣiṣẹ takuntakun nipa gbigbogun ti iwa ibajẹ, nitori wọn fi ẹsun kan awọn to wa ni iṣejoba rẹ fun iwa ibajẹ.
Ẹni tí ó ti kú náà bá jáde pẹlu aṣọ òkú tí wọ́n fi wé e lọ́wọ́ ati lẹ́sẹ̀ ati ọ̀já tí wọ́n fi dì í lójú.
Lara awọn ohun to ni ki awọn eeyan naa mu wa sojuko ti ayẹwo naa yoo ti waye ni yii: Orí àkìtàn ni wọ́n ti rí ọkùnrin tó ń fi ìgbẹ́ jẹ Búrẹ́dì -Iléeṣẹ́ ọlọ́pàá Oyo Bí mo ṣe mórí bọ́ nínú ọkọ̀ bàálù tí kò bá já - Aisha Buhari Ta ni Lisa Hanna, arẹwà obìnrin tí àwọn ọmọ Nàìjíríà fẹ́ kó di àárẹ wọn?
Àwọn eniyan náà gba ọ̀rọ̀ wọn gbọ́; nígbà tí wọ́n gbọ́ pé OLUWA wá bẹ àwọn eniyan Israẹli wò, ati pé ó ti rí ìpọ́njú wọn, wọ́n tẹríba, wọ́n sì sin OLUWA.
 ifá fi ẹ ̀ mí hàn gẹ ́ gẹ ́ bi ọ ̀ pọ ́ múléró .
Àwọn ni ìlú ati ìletò tí ó wà ninu ilẹ̀ tí ó kan ẹ̀yà Aṣeri gẹ́gẹ́ bí iye ìdílé wọn.
Ẹ kí Rufọsi, àṣàyàn onigbagbọ ati ìyá rẹ̀ tí ó tún jẹ́ ìyá tèmi náà.
gbagbe yin, a o tesiwaju lati maa  pese
" ni esi to fi da wọn lohun.
Ismail ti wọn gbà wle fun ètò ẹ̀kọ́ ọ̀fẹ́ tí pada si Lebanon.
Robert Mugabe, akọni òṣèlú tó lo ọdún mẹ́wàá lẹ́wọ̀n fún ìjìjàgbara Zimbabwe Ìkọlù sáwọn àjèjì kò tíì tán ní South Africa, ètò ń lọ láti kó ọmọ Nàíjíríà wálé Ẹ̀tanu ni àwọn ìmáàmù Yoruba fi yan Waziri míì, ojúṣe ọba ni - Oluwo Ọ̀nà láti sọ fásitì Lautech di ti Ọyọ nìkan ni Makinde ń sán - Ìjọba Ọṣun Ni ọjọ Satide ni minisita fun eto iroyin ati aṣa gbe atẹjade kan jade pe ko si ohun to jọ ibugbamu ado oloro ni ileeṣẹ aṣoju ijọba orilẹede South Africa ni Naijiria to wa nilu Abuja.
Egbe osise lorile ede Naijiria ti pinnu lati bere iyanselodi alailojo ni ojo kefam, osu kokanla, odun ti a wayii, ti ijoba apapo ba kunna lati mu ipinnu won se, nipa sisan ekunwo ogbon egberun naira, ni eyi ti won fenuko le lori.
OLUWA, yóo ti pẹ́ tó, tí o óo máa wò mí níran?
O tan o, nnkan ti wọn wa fun niyẹn.
Ọdun 1982 ni Osamenam, de si ilẹ America.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù NEMA, NHISA ní ó ṣeéṣe kí ẹ̀kun omi wáyé ní ìpínlẹ̀ méjìlá 8 Owewe 2018 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ki awọn eeyan orilẹede yii, paapaa awọn olugbe ipinlẹ ti ọrọ kan atawọn alẹnulọrọ lee gbaradi ni awọn ajọ tọrọkan yii fi ke ibosi sita Ajọ to n mojuto iṣẹlẹ pajawiri lorilẹede Naijiria, NEMA pẹlu ajọ to n ṣe iwadi nipa ọrọ omi lorilẹede Naijiria ti ṣekilọ pe awọn ipinlẹ mejila kan lorilẹede Naijiria ko ni pẹ foju wina ẹkunomi eleyi ti yoo waye nipasẹ arọọrọda ojo.
Oríṣun àwòrán, @SpeakerGbaja Ile igbimọ asofin ninu ijoko ile ṣe idakẹ jẹ iṣẹju kan, fun awọn ọmọ ile igbimo asofin agba meji to papoda, sẹnatọ Rose Okoh ati Buruji Kashamu.
Ọgbẹni Wode sọ pe ọpọlọpọ awọn ilu lo n sọ pe awọn ọmọ ogun ati ọlọpaa kii gbe igbesẹ kankan, nigba ti awọn ba fi to wọn leti pe awọn agbesunmọmi fẹ ẹ ṣe ikọlu nibi kan."
Awọn alafojuri ni bi Tanka epo naa ṣe yi danu ni awọn eeyan kan sare sibẹ lati gbọn epo ko to gbina.
Esi ayẹwo tuntun naa niyi: Lagos-52 Gombe-27 Plateau-17 Kwara-10 Enugu-9 Ogun-9 Katsina-3 Ekiti-2 Bauchi-1 Osun-1 Rivers-1 Ọmọkùnrin tó ya 'Blue film' nínú igbó Osun Osogbo ti bayé ara rẹ̀ jẹ́ - Yemi Elebuibon Ọwọ́ tẹ èèyàn kan pẹ̀lú orí ọmọdé nílé aṣòfin àpapọ̀ Ajínigbé kọlu òṣìṣẹ́ FRSC, èèyàn méjì kú, mẹ́rin farapa, mẹ́wàá di àwátì Ǹjẹ́ o mọ̀ pé àwọn tó wá láti ìdílé ẹrú kìí lọ́kọ tàbí aya láyé òde òni ní Nàìjíríà?
Àwọn Juu fi idà pa àwọn ọ̀tá wọn, wọ́n pa wọ́n run.
O maa n ji èròjà ara ti wọn n pe ni Oxytocin, ti i ṣe homoonu ìfẹ́.
Wọn yoo jẹ ki esi naa ma tete jade bayi ti o si ṣeeṣe ki awọn eeyan ma mọ esi ayẹwo laarin wakati mẹrinlelogun Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 3 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 5 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Kàkà kí àwọn ènìyàn sọ ǹkan ti wọ́n fẹ́ ki ìjọba ṣe ọ̀pọ̀lọpọ̀ l'órí twitter ló ni kìí ṣe ibi tí àwọn ènìyàn ti ọ̀rọ̀ náà kan wà ní ìjọba gbé ọ̀rọ̀ lọ àti pé o jọ bí ẹni pé ìjọba kò mọ ìbi ti ọ̀rọ̀ kù sí mọ́.
Ó jẹ́ mímọ́ jùlọ; níbi tí wọ́n ti pa ẹran ẹbọ sísun ni wọ́n gbọdọ̀ ti pa ti ẹbọ ìmúkúrò ẹ̀bi, wọn yóo sì wọ́n ẹ̀jẹ̀ rẹ̀ sí ara pẹpẹ yípo.
Ọpọlọpọ ìgbà ni a ti pada lẹ́yìn rẹ,a ti ṣẹ̀ ọ́.
Premier League: Liverpool na Tottenham láti gòkè tábìlì EPL
O so pe, “awon wase-wase, ti won nife lati bere ise agbe, ti won ko ni imo to jinle to, egbe ohun yoo seto idanilekoo fun iru eni bee ni agbegbe ti o ba nife si tabi yan laayo, bakan naa ni won yoo ro eni bee lagbara, gege bi okan lara omo egbe naa, ti o ko ba ni ise lowo, o ko mo ohun ti o fe se, ko si eto-eko to yanranti to, egbe AFCO yoo fun ni idanilekoo to muna doko”.
Nítorí alágbèrè ni ìyá wọn, ẹni tí ó bí wọn sì ti hùwà ainitiju.
9 Kíyèsíi, ìwọ ni Joseph, a sì ti yàn ìwọ láti ṣe iṣẹ́ Olúwa, ṣùgbọ́n nítorí ìrékọjá, bí ìwọ kò bá kíyèsára ìwọ yío ṣubú.
Igba akọkọ kọ niyii ti awọn ileeṣẹ ijọba Naijiria n fi ija pẹẹta lori ayelujara, lori ọrọ ti ọpọ gbagbọ pe o yẹ ki wọn o yanju ni ikọkọ.
Ṣugbọn mo ti gbọ́ adura rẹ̀ nítorí pé ó fa aṣọ rẹ̀ ya, ó sì sọkún níwájú mi.
Nítorí burẹdi kan ni ó wà, ninu ara kan yìí ni gbogbo wa sì wà, nítorí ninu burẹdi kan ni gbogbo wa ti ń jẹ.
Nígbà tí ilẹ̀ mọ́, wọ́n rí èbúté ṣugbọn wọn kò mọ ibẹ̀.
Ọgbẹni Usman sọ pe igbo wa ni agbegbe ti iṣẹlẹ yi ti waye, ti idile naa si ti gbe awọn igbesẹ kan, to fi mọ ni ilana abalaye lati dena ki ejo o maa ba wọ ile wọn.
Ipade ikẹ́tàlélọ́gọ́ta igbimo eto ẹkọ yoo bere ni ọgbọ̀njọ , osu keje ,niluu Abuja.
Nítorí náà mo fún un ní àyè kí ó lọ gbé òkú ẹ̀gbọ́n rẹ̀ náà wá, mo sì fún un ní díẹ̀ nínú àwọn ìrán\nṣẹ́ mi pé kí wọ́n bá alọ, gbogbo wọn sì lọ.
Òun ni ó yan ilẹ̀ ìní wa fún wa,èyí tí àwọn ọmọ Jakọbu, àyànfẹ́ rẹ̀, fi ń yangàn.
Fèrèsé wà lára rẹ̀ yíká ninu, bẹ́ẹ̀ náà sì ni ìloro rẹ̀.
Erongba mi ni lati pari ẹkọ mi kì n si darapọ mọ awọn ọmọ ogun Naijiria, kí n wọ inu baalu kí n sì sọ ado oloro lu awọn olubi yi ki wọn si parẹ tan yanyan ni Naijiria Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ó dára kí obìnrin níṣẹ́ lọ́wọ́ - Toyin Lawani Yatọ sí eto ẹkọ rẹ, o ni oun fẹ kọ iṣẹ ranṣọ ransọ laaye ikọsẹ to wa ní ibùdó awọn atipo.
Nnamdi Azikiwe to wa niluu  Abuja silẹ  ni deede aago  15:00 GYM.
Lara awọn ti wọn se afihan wọn ni awọn ọmọ ogun Boko Haram mẹrinla miran, ti ọlọpaa ni wọn ko ipa orisirisi ninu ikọlu, ijinigbe ati ilo eeyan gẹgẹ bi ado oloro.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Working religious women: Ẹ̀lẹ́hàá kìí ṣe ọ̀lẹ- Aminat Adegoke Gómìnà ìpínlẹ̀ Ekiti, Kayode Fayemi nàá ti ni aàrùn Coronavirus Gomina ipinlẹ Ekiti, Kayode Fayemi ti kede pe oun ti ni aarun coronavirus.
Buhari jawọ ninu ilana okoowo Afrika Buhari ransẹ ikini ku ọdun si orilẹede China Awọn ti o'n ṣagbatẹru adehun naa n lero wi pe aadọta orilẹẹde ni yoo la'nfaani karakata ti wọn ba fọwo si adehun naa.
Mose kò sì sọ ohunkohun tí ó jẹ mọ́ iṣẹ́ alufaa nípa ẹ̀yà yìí.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù One million boys nìkan kọ́ lẹgbẹ́ òkùnkùn tó n dá Eko rú, 'Awawa Boys' náà tún wà níbẹ̀ 21 Agẹmo 2020 Ibẹru Oluwa ni ipilẹṣẹ ọgbọn ni Bibeli wi, ṣugbọn ibẹru awọn Awawa Boys ni awọn agbegbe kan nilu Eko ni ipilẹṣẹ eto aabo.
 ní ilẹ ̀ amẹ ́ ríkà iye owó rẹ ̀ ju 200 usd lọ .
Àwọn ti ilẹ̀ dáradára ni àwọn tí ó fi ọkàn rere ati ọkàn mímọ́ gba ọ̀rọ̀ náà, wọ́n sì dì í mú ṣinṣin, wọ́n sì so èso nípa ìfaradà.
Ọba Ijipti óo máa gbéraga nítorí ìṣẹ́gun rẹ̀ lórí ọpọlọpọ ogun yìí, yóo sì pa ogunlọ́gọ̀ àwọn ọmọ ogun, ṣugbọn kò ní borí.
"Lẹ́yìn ọdun mẹ́ta tó kú, ilé ẹjọ́ dájọ́ ikú fún alásè tó pa Temidayo Adeleke Ìpínlẹ̀ Ogun, Eko ti gbáradì fún ẹ̀kún omi yalé ""Bí Zakzaky yóò bá lọ gba ìtọ́jú ní India, ó gbọdọ̀ ṣe àwọn nǹkan wọ̀nyìí"" Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Yollywood: Sinimá Ajé Ọjà tún so Fathia àti Saheed Balogun pọ̀ nínú Sinimá Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Asa Trokosi nibi ti ọmọde ti n jiyan ẹsẹ mọlẹbi rẹ , wọpọ ni Ghana, Togo ati Benin."
AWCON: Nàìjírìa gba ife ẹ̀yẹ AWCON fún ìgbà kẹsàn-án
Mí ò le nífẹ̀ẹ́ obìnrin Nàìjíríà kankan mọ lẹ́yìn ti mo ti tọ́ obìnrin òyìnbó wò- Issa
O wa gbadura pe ki olorun dawo iru isele buruku bayii duro.
Arakunrin naa ti awọn ọlọpaa pe orukọ rẹ ni Isau Yisah ni wọn sọ wi pe o n ṣe ṣọ ile epo kan lagbegbe naa lasiko ti awọn ọlọṣa fi ya bo adugbo naa lọjọ Abamẹta.
nígbà tí ó pààlà sí ibi tí òkun gbọdọ̀ kọjá,kí omi má baà kọjá ààyè rẹ̀.
Ẹni mejidinlogun lo ṣe kongẹ arun ọhun nipinlẹ Ondo, eeyan mẹjọ lo ni arun naa lati ipinlẹ Ogun.
Ìkórira pé mo jẹ Mayegun ni wọn ṣe parọ́ pé mo ń fẹ́ olorì Aláàfin, kò rí bẹ́ẹ̀ rárá- Kwam 1 A fẹ́ lo ẹ̀jẹ̀ àwọn èèyàn tó ye àrùn Coronavirus láti fi ṣe ìwòsàn fún àwọn tó wà lórí àárẹ- UK Ìkórira pé mo jẹ Mayegun ni wọn ṣe parọ́ pé mo ń fẹ́ olorì Aláàfin, kò rí bẹ́ẹ̀ rárá- Kwam 1 Ọjoọ́ mélòó ni Coronavirus ń lò lára kí ènìyàn tó gba ìwòsàn?
Ẹ má gbàgbé láti máa ṣe àlejò nítorí nípa àlejò ṣíṣe àwọn ẹlòmíràn ti ṣe àwọn angẹli lálejò láìmọ̀ pé angẹli ni wọ́n.
Ti Ọlọrun ba si fẹ ṣe ni loore, eeyan naa ni yoo lo.
Adilemu fun ẹgbẹ agbabọọlu, Jordan Pickford gọ ara rẹ, ko yara rara bi Mason Mount ọmọ ẹgbẹ agbọọlu Chelsea ṣe ya bara, to si gba bọọlu sinu awọn .
Ìbọn ọlọ́pàá ló pa èèyàn, ẹgbẹ́ wa kìí lo ìbọn - Shiite fárígá Dalung, Audu Ogbe, Shittu Adebayo àti Isaac Adewole kò wọlé PDP: Ẹní ṣe nǹkan ètùfù ní kíyèsí ẹ̀hìnkùlé, ọmọ ẹgbẹ́ wà kò hùwà àìtọ́ lásìkò ìdìbò Ṣé irúfẹ́ oúnjẹ tí ò ń jẹ́ lè jẹ́ kí o gbádùn ìbálòpọ̀ rẹ síi?
Mọgaji llu lbadan sọ pe oye ''His Imperial Majesty'' ti wọn fi n pe Oluban ko ni ohun kan ṣe pẹlu ọrọ to wa nilẹ yii.
Aare Muhammadu Buhari ti kedun pelu ebi, ara, ore, awon olubasise po oloogbe naa ati ijọba ipinle Edo fun iku oloogbe ohun.
Oríṣun àwòrán, @thenff Àkọlé àwòrán, Cameroun ti yege fun ipele to kan ṣugbọn nnkan ko tii ṣẹnuure fun Naijiria Ifagagbaga to waye laarin Thailand ati Chile lo sọ boya Naijiria ṣi maa tẹsiwaju ninu idije tabi bẹẹkọ nitoripe France ti na Naijiria ninu ikọ naa pẹlu ami ayo kan tẹlẹ.
  Gbogbo ibẹ̀ sì ti di kòtò nlá gidi gaan ni.
Quand je pense aux 20 dernières années de ma carrière professionnelle, regarder cette photo de ma première licence, ne peut que me rendre plus fier de ce que j’ai accompli en tant que joueur mais plus important encore, comment cette aventure à fait de moi l’homme que je suis aujourd’hui.
Ọpọ eeyan lo ti n pariwo pe kawọn agbofinro fọwọ sinku ofin mu obinrin yii.
Gbogbo ènìyàn lo mọ pé ọ̀rẹ́ kìí y'ọ̀rẹ́ ni Wumi Toriola àti Seyi Edun to jẹ́ ìyàwó Adeniyi Johnson ṣùgbọ́n lásìkò ayẹyẹ ọjọ́ ìbí Seyi Edun, Awọn kan ni Wumi Toriola kọ lati ki Seyi ku ayẹyẹ ọjọ ìbí àti ìgbà yìí si ni wọn ti n bèrè ǹkan to fa èdè àìyedè láàrin wọn.
Ireti awọn ọmọ orilẹede Liberia ni wipe Weah yoo mu ileri to se lati pese isẹ ati awọn ileewe to pojuowo sẹ.
Makinde wa fi asiko ohun tun  rawo ebe si gbogbo awon omo ile igbimo asofin
Mo bẹ̀ yín, ará, kí ẹ gba ọ̀rọ̀ ìyànjú wa yìí nítorí ìwé kúkúrú ni mo kọ si yín.
Omiyalé Àkútè: N50 si N100 làwọn èèyàn fi ń kọjá lórí ẹ̀kún omi
ijoba , ki awon ise akanse ti a ni lọkan le wa si imusẹ, paapaa julọ, oju ona
Wọn si fi ayẹyẹ naa si ọjọ kẹta ọdun Ileya lọna ati fun awọn musulumi ni aaye ati anfaani lati gbadun ọdun Ileya ni ọjọ meji akọkọ.
Nígbà tí ilẹ̀ mọ́ lóòótọ́ Ìrèké mú fèrè rẹ̀ o ń fọn ọn.
Ó fi mànàmáná yí ara rẹ̀ ká,ó sì bo ìsàlẹ̀ òkun mọ́lẹ̀.
Ahabu ọba lọ sí apá kan, Ọbadaya sì lọ sí apá keji.
aare nipinle NasarawaEgbe oselu APC ni apapo ibo (289,903
Ní ọjọ́ kan, bí Jesu ti ń kọ́ àwọn eniyan lẹ́kọ̀ọ́ ninu Tẹmpili, tí ó ń waasu ìyìn rere fún wọn, àwọn olórí alufaa, àwọn amòfin, ati àwọn àgbà wá sọ́dọ̀ rẹ̀.
Ọjọ kẹta, oṣu Kọkanla, ọdun 2020 ni eto idibo aarẹ ilẹ Amẹrika yẹ ko waye.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ǹjẹ́ ìwọ lè gbélé orí omi?
Agba osere naa wa gbadura pe ki Ọlọrun tẹ ọdọmọkunrin ọhun si afẹfẹ rere.
“Sioni na ọwọ́ rẹ̀ fún ìrànwọ́,Ṣugbọn kò sí ẹni tí ó ràn án lọ́wọ́,OLUWA ti pàṣẹ pé,kí àwọn aládùúgbò Jakọbu di ọ̀tá rẹ̀;Jerusalẹmu sì ti di eléèérí láàrin wọn.
 Àkọtọ ́ cyrillic ni wọ ́ n fi ń kọ ọ ́ sílẹ ̀ ní azerbaijan ṣùgbọ ́ n àkọtọ ́ arabic ni wọ ́ n fi ń kọ ọ ́ sílẹ ̀ ní iran .
Manchester City bẹrẹ idije naa daada, ṣugbọn wọn ko fi bẹ ẹ halẹ lawọn asiko ti bọọlu ba wa ni ikawọ wọn, ṣugbọn Manchester United ni tiẹ gboro pupọ.
Ìran Adamu títí Dé Orí Abrahamu.
Nítorí náà, mò ń fi ye yín pé kò sí ẹni tí ó lè máa fi agbára Ẹ̀mí Ọlọrun sọ̀rọ̀ tí ó jẹ́ fi Jesu gégùn-ún, bẹ́ẹ̀ ni kò sí ẹni tí ó lè wí pé, “Jesu ni Oluwa,” láìjẹ́ pé Ẹ̀mí Mímọ́ bá darí rẹ̀.
Àwọn ọkọ̀ mìíràn wà níbẹ̀ pẹlu.
Ẹ o ranti wi pe ile ẹjọ kotẹmilọrun l'Abuja da idajọ igbimọ igbẹjọ idibo gomina ipinlẹ Oṣun to waye lọdun 2018 to sọ pe Adeleke lo jawe olubori ninu ibo ọhun nu ti o si ni Gomina Gboyega Oyetola lo wọ le.
" Awọn Iroyin ti ẹ le nifẹ si Ìtàn tó wà nídi òwe ‘Sebótimọ Ẹlẹ́wà Sàpọ́n’ Ṣẹ gbọ́ nípa Alájọ Ṣómólú, tó ta mọ́tò ra kẹ̀kẹ́?
Iroyin naa tun sọ pe agunbanirọ miran tun ti dero ile iwosan nipinlẹ Ondo kan naa.
Ṣugbọn ẹni tí ó bá ń pa àwọn àṣẹ wọnyi mọ́, tí ó tún ń kọ́ àwọn eniyan láti máa ṣe bẹ́ẹ̀, òun ni yóo di aṣiwaju ní ìjọba ọ̀run.
Aarẹ Buhari sọ pe mo ti gba abọ lori ọrọ aawọ inu oṣelu to n ṣẹlẹ ni Mali a o si bere lọwọ aarẹ orilẹede Niger pe ko fun wa ni ẹkunrẹrẹ alayee iṣejọba rẹ""."
Bi won ba fe ṣe iwadi baa ti ṣe ṣe ijọba kiba jẹ ijọba ipinlẹ tabi lati ọdọ ijọba apapọ.
Bótilẹ jẹ je Arsenal si ni ànfàni láti pari si ipò keeje bi ìdílje ṣe ku méji sẹyi, èyi lé mu wọn kóju òsùwọn láti kopa ninu Europa League, wọn ni àmi àyo márun ti wọn fi n toò sẹ́yin Wolves Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Nínú owó tí Abacha jí kó lọ sókè òkun, ní oṣù kọkànlá ọdún 2003.
Ọpọlọpọ awuyewuye lo ti jẹyọ lori atẹjade ti Ajọ Ilẹ Yuroopu(European Union) fi lede nipa idibo ọdun 2019.
Bi awọn eeyan kan ṣe n sọ pe egungun agba oṣelu naa ṣe bi ẹni jinna si ode ijo fun igba pipẹ lawọn miran n sọ pe o ṣeeṣe ko jẹ pe ọrọ coronavirus yii to jawe joko jẹẹ fun gbogbo mutumuwa naa lo kan baba.
Sinimá àwòdamiẹnu, Ẹ̀fáńjẹ́líìsì jìyà àjẹmumi nílé aṣẹ́wó l'Ejigbo ní ìlú Eko Ìjàmbá ọkọ̀ tó ṣẹlẹ̀ sí Adams Oshiomole kìí ṣe ojú lásan, àwọn kan ló fẹ́ pa á- APC Bí ìjà bá wà láàrin èmi àti Olubadan, a ó yanjú ẹ ní pẹ̀lẹ́kùtù, ọ̀rọ̀ bàbálọ́jà kò lè dìjà Bàbá ẹni ọgọ́ta ọdún dèrò ilé ẹjọ́ nítorí ó wọ inú oko Obasanjo láì gba àṣẹ Ọba Saudi Arabia yọ ọmọ rẹ̀ àti àbúrò rẹ̀ kúrò nípò nítorí ìwà àjẹbánu lórí owó tó yẹ fún ààbò ìlú O salaye pe oun mọ pe ofin wa pe eniyan ko gbọdọ ta igbo sugbọn ko si iṣẹ ti ko mu ewu dani.
Progressive Union lo ṣagbatẹru Nikkah naa laarọ yii.
Awon eniyan bi ogoji ni ajo to n mojuto isele pajawiri( Red cross) lorile ede Kenya ti yo kuro ninu ewu bayii.
Tiamiyu Kazeem: Ọlọ́páà kò lẹ́tọ̀ọ́ láti fìyà jẹ ará ìlú tó bá wọ aṣọ ológun
Bo tilẹ jẹ wi pe ipa ti eyi yoo ni lori Omotosho ko ti i fi bẹẹ fi oju han, igbẹjọ rẹ yoo tun pada bẹrẹ lọjọ Iṣẹgun lẹyin ti igbẹjọ akọkọ dojubolẹ.
Awọn miran to jẹ ajijangbara bii Ken Saro Wiwa ti Orukọ ẹgbẹ wọn n jẹ Ogoni Nine ti ijọba da ẹjọ iku fun ni Saturday Dobee, Nordu Eawo, Daniel Gbooko, Paul Levera, Felix Nuate, Baribor Bera, Barinem Kiobel, ati John Kpuine.
Owó ìfẹ̀yìntì tún ti d’èèwọ̀ fáwọn gómìnà àná ní Kwara Wo ìdí márùn-ún tí Biden fi bórí nínú ìdìbò ààrẹ America Èlé owó epo míì dé!
O ni awon aarun bii arun HIV / AIDS naa maa n fa egbo inu iho eti.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Seun Fakorede di kọmísánà ní ìpínlẹ̀ Oyo Wọn ṣapejuwe Akintoye pe ó jẹ́ olóòtọ́ sí ìtẹ́siwáju ìràn Yorubá, ó maa ń sọ ojú abẹ níkòó, ó máà ń hùwà akọni, kìí gbọ̀jẹgẹ́, ó jẹ́ ọ̀rẹ́ ará ìlú, o ni okun, ó si tún jẹ ẹni ti ìlu ń fẹ́.
 Àkóónú eré wọn á máa lọ láti orí ìbálòpọ ̀ tí ò lẹ ́ tọ ̀ ọ ́ , ìwà ìbàjẹ ́ láwùjọ láàárín ọ ̀ tọ ̀ kùlú àti ìjọba , ìjà ìyálé àti ìyàwó , ìrirí ayé , àti bẹ ́ ẹ ̀ bẹ ́ ẹ ̀ lọ .
" Àráàlú yarí fún fásitì Babcock fún bo ṣe lé akẹ́kọ̀ọ́ tí wọn bá lòpọ̀ nínú fídíò Oral Sex: Bóo bá ń gba ẹnu ní ìbálòpọ̀, wo àìsàn tóo lè kó lójú ara rẹ Pásítọ̀ pe Naira Marley ní ẹlẹ́mìí èṣù, Marley fèsì padà pé kí pásítọ̀ gan tẹ èṣù mọ́lẹ̀ Bíbéèrè fún ìbálòpọ̀ gbogbo ìgbà sọ ìyàwó ilé dèrò ilé ìwòsàn Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ìtàn ọ̀rẹ́ tó fi ògùn gba ọkọ ọ̀rẹ́ rẹ̀ ni Akomolede BBC Yorùbá fẹ́ kọ́ wa lònìí Oríṣun àwòrán, @kingtblakhoc/twitter Àkọlé àwòrán, Tobi Jolaosho 'King Tblak' ni awọn kan gbagbọ pe o pilẹ sinima ibalopọ ni Naijiria Bakan naa ni o fi kun pe nigba ti ileeṣẹ ọlọpaa ba pari iwadii wọn lori ẹsun ti wọn fi kan Jolaosho, ni awọn ẹlẹsin ibilẹ yoo to o da sẹria to tọ fun.
bí kò bá rí i pẹlu wa, kíkú ni yóo kú.
Wọ́n dá a lóhùn, wọ́n ní, “Èéṣe tí o fi ń sọ̀rọ̀ sí wa báyìí?
Lara ohun to tun ṣẹlẹ ni pe igbimọ alaṣẹ jawe lọ gbele ẹ fun igbakeji alaga ẹgbẹ tẹlẹri ni ẹkun Guusu- Guusu, Hilliard Eta.
Oríṣun àwòrán, Others Àkọlé àwòrán, Ba o ri adan, a foobẹ ṣẹbọ ni iya ati ọmọ fi ọrọ ṣe.
 ) ( don ' t just stand there ' you dummy .
Koda ileeṣẹ ọlọpaa ni ọga ọlọpaa kan ASP Victor Ugbegun atawọn mii farapa nibi iṣẹlẹ ọhun bẹẹ ni wọn wa nile iwosan lọwọlọwọ.
O ni ida mọkandinlọgọrun ọmọ Naijiria lo ti gbọ.
Bí ọ̀rọ̀ náà ti rí nì yìí: Ọkùnrin kan wà tí ó ti jẹ́ ọ̀rẹ́ ọba kí ọba tó gun orí oy’w.
Oluwo tún kesi àwọn ọmọ Naijiria lati fara dà ohun tó ń ṣẹlẹ̀ yìí nítorí kò sí epo rọbi mọ ní Nàìjíríà.
Mamoudou Gassama, eni ti o gun ile alaja merin lati gbemi omode kan ti o ko igu ile, ni apa ariwa olu-ilu orile-ede naa la.
Lẹ́yìn wọn ni: Jesieli ati Peleti, àwọn ọmọ Asimafeti; Beraka, ati Jehu, ará Anatoti.
O tẹsiwaju wipe ajọ ọlọpa, ile isẹ ologun ati ajọ ọtẹlẹmuyẹ ti n sisẹ takuntakun lati mu idaabo bo ipinlẹ Benue ati lati fi oju awọn apaniyan wina ofin.
Ẹni tí ó bá talaka, tí kò lágbára nǹkan ìrúbọ, a wá igi tí kò lè rà, tí kò sì lè ju;a wá agbẹ́gilére tí ó mọṣẹ́,láti bá a gbẹ́ ère tí kò lè paradà.
Adajọ naa sọ pe ori àpèrè naa ko tọ sii.
Ṣugbọn ó kó àwọn ọmọ ogun rẹ̀, wọ́n sì bá àwọn ọmọ Israẹli jagun ní Jahasi ninu aṣálẹ̀.
Ko pe iṣẹju maarun ti William pa wọn lẹkun, ni Giroud tun bu iyọ si oju egbo adaa'jina wọn, ni Chelsea ba ni ami ayo mẹẹrin, ti odo si dagbada iya bọ Everton l'ọrun.
Àwọn ará Kenaani sì ń gbé lẹ́bàá òkun ati ní agbègbè Jọdani.
Atunṣẹ afara naa yoo bẹrẹ ni oru ọjọ kẹrinlelogun, oṣu Keje ọdun 2020, ṣugbọn ọpọ eeyan lo ti n bere pe, ṣe awọn olugbe Eko ti ṣetan fun idojukọ ti yoo waye nitori atunṣẹ naa.
Ó kó gbogbo àwọn ìṣúra ilé OLUWA ati àwọn ìṣúra tí ó wà ní ààfin.
Alaye ti kọmisana ọlọpaa ṣe yii ko da awuyewuye ati ibeere to n jẹyọ lori ohun to fa iṣẹlẹ naa gan an.
Ẹ̀yin gómìnà, ẹ bá wa bi Buhari pé kí ló ń bàá lẹ́rù lórí Amotekun - Aráàlú Fasola ló jẹ̀bi ìdákúrekú iná ọba - ọmọ Nàìjíríà fárígá lórí òkùnkùn biribiri Sotitobire: Adájọ́ dá Pásítọ̀ Alfa Babatunde padà s'ẹ́wọ̀n fún ọjọ́ mọ́kàndílógún Ìtàn ìgbé ayé Bode Thomas rèé, ó kọ́ wa láti máa kó ẹnu wa ní ìjánu Afurasi naa, to ni ilu Akure ni oun ti n pe awọn ọlọpa ọhun, lo tun fi ye wọn pe, awọn eeyan kan lo ni ki oun parọ mọ Alfa Babatunde, ti ojisẹ Ọlọrun naa ko si mọ ohunkohun nipa bi ọmọde naa se sọnu ninu ile ijọsin Sotitobire.
Ninu atẹjade ti Sẹsan Daini to jẹ alukoro ileeṣẹ ipolongo ibo fun sanwo -olu, oludije ẹgbẹ oṣelu APC fun ipo gomina ni ipinlẹ Eko, lootọ ni wahala bẹ silẹ ṣugbọn laarin awọn ọmọ ẹgbẹ kan ni.
Ohun tí wọ́n ti ń ṣe sí mi ni wọ́n ń ṣe sí ọ yìí.
Lẹ́hìn èyí ó tún padà tọ ọba nì tí ó ṣe bí olùfẹ́ òun.
Ọlọrun rán ẹ̀mí burúkú sí ààrin Abimeleki ati àwọn ara ìlú Ṣekemu.
Nileeṣẹ wa nibi, a o maa fọkan tẹle awọn akojọpọ ero oludibo yi lati le mọ ibi ti ọrọ naa yoo pada ja si.
fagbahan iko akegbe won lati orile-ede Ivory Coast ninu asekagba idije naa.
Èèyàn mẹ́tàlá dèrò ọ̀run nínú ìjàmbá ọkọ̀ lópòpónà Ìbàdàn s'ÈKó Zlatan: Èyí mo ṣé tó, àsìkò tó láti tèsíwájú nínú ìrìnàjò mi Osinbajo kò gbàdúrà ikú fún Buhari lórí àìsàn, ẹ sinmi ìbàjẹ́- Agbẹnusọ Osinbajo Àwọn tó jí ọmọ mi gbé nílé ìjọsìn ní ń kò gbọdọ̀ wa tàbí kí ẹ̀mí mi lọ si"" Bakan naa, wọn ni igbohunsafẹfẹ ti NTA ṣe lori ifẹsẹwọnṣe ri balabala, ti ko si ṣe e wo."
N kò mọ̀ pé nítorí mi ni wọ́n ṣe ń gbèrò ibi, tí wọn ń wí pé, “Ẹ jẹ́ kí á gé igi náà lulẹ̀ pẹlu èso rẹ̀, kí á gé e kúrò ní ilẹ̀ alààyè, kí á má sì ranti orúkọ rẹ̀ mọ́.
"Ijọba Osun ni ""Baba Fasanmi jẹ asaaju to maa n safihan ifẹ fun orilẹede wa lawọn ọna to pegede, to si tun maa n gbarata lori ipese eto idẹrun fawọn ọdọ."
Ti wọn ba si fa ẹlomiran silẹ ko dije ninu ẹgbẹ wa, yatọ si Akeredolu, a jọ maa se e daadaa ti yoo fi wọle, ti yoo si se daadaa ju bi Akeredolu ti se bayii lọ.
Naijiria bẹrẹ iwadi lori owo iranwọ epo Owo osu ọna meji ko lẹtọ Jamb padanu owo s'ikun ejo N13.
Àwọn nkan tó yẹ kí o mọ̀ nípa ṣíṣe ìṣirò àsìkò tí o bá n yé ẹyin Èèyàn méjì kú, méjìdínlógóje míì ṣẹ̀ṣẹ̀ kó COVID-19 lọ́jọ́ Àìkú Ìjọba ìpínlẹ̀ Eko kéde ọjọ́ tí àwọn iléèwé gígá yóò wọlé Wọ́n tún ti pa omidan ẹni ọdún 18 míràn l'Akinyele ní ìlú Ibadan Oríṣun àwòrán, @All well Bí ó ṣe lọ lágbo àwọn òṣèré Yollywood lọ́sẹ̀ yìí rèé Oríṣun àwòrán, Others Àkọlé àwòrán, Eyí jẹ́ ọ̀kan lára àwọn fótò ti Funke Akindele Bello ló láti fi sọ fún àwọn ọmọ Naijiara pé òun tún n pada bọ̀ Nollywood Round Up: Bí ó ṣe lọ lágbo àwọn òṣèré Yollywood lọ́sẹ̀ yìí rèé Oníruuru àwọn ìṣẹ̀lẹ̀ lo ti wáye láàrín ọ̀ṣẹ̀ yiìí lágbo òṣèré Nollywood.
Àwọn eṣú ti tú jáde láti inú èéfín náà, wọ́n lọ sí orí ilẹ̀ ayé.
Awọn tọkọtaya to ni ipenija oju naa ni kii se pe wọn bi awọn mọ ipo yii amọ ipenija lo de lasiko ti awọn wa nile ẹkọ, ti awọn ko si le riran mọ.
Ní ọjọ́ náà, n óo run àwọn ọmọ ogun Israẹli ní àfonífojì Jesireeli.
Ọkùnrin kan sálọ lẹ́yìn tó gbẹ̀mi ènìyàn mẹ́ta Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Port harcourt Bole: Mi kò mọ́ pé bọ̀ọ̀lì títà lè gbé mi dé ipò yìí láyé mi!
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Makinde fi orúkọ ọmọ ọdún 27 kan ránsẹ́ sílé aṣòfin ní ìpìnlẹ̀ Ọ̀yọ́ 20 Ògún 2019 Oríṣun àwòrán, @TopsyAshaolu Àkọlé àwòrán, Seun Fakorede ọdọmọde to fẹ maa gbe igbesẹ agba Ọdọmọde naa ni ọgbọn ti yoo wulo fun awujọ wa.
Èyí àkọ́bí bí ọmọkunrin kan, ó sọ ọ́ ní Moabu, òun ni baba ńlá àwọn ẹ̀yà Moabu títí di òní olónìí.
Nítorí odò ńlá yóo ṣàn jáde ninu aginjùàwọn odò kéékèèké yóo máa ṣàn ninu aṣálẹ̀.
Ní oṣù karun-un ọdún keje ìjọba Atasasesi ni Ẹsira dé sí Jerusalẹmu.
Gege bi iwe iroyin Herald se so , won ti  so fun okunrin arugbo omo odun mefadinlogorun naa lati farahan niwaju igbimo asofin,  lojo Aje , ni eyi ti o ko lati farahan leemeji.
Akọwe ẹgbẹ naa, Yinka Odumakin lo sọ bẹẹ ninu ifọrọwerọ rẹ pẹlu BBC Yoruba.
Awọn aṣofin ti wa kepe awọn ẹka ijọba to n ṣe eto igbeyawo, awọn ṣọọṣi atawọn mọṣalaaṣi wi pe ki wọn maa beere esi iyẹjẹwo ki wọn to so ẹnikẹni pọ.
Gbogbo àwọn eniyan tí wọ́n wà pẹlu rẹ̀, tí wọ́n ń bá a lọ náà fi aṣọ bo orí wọn, wọ́n sì ń sọkún bí wọ́n ti ń lọ.
Bẹẹ naa ni wọn ri aburo rẹ ọmọ ọdun mọkanla, ti ebi ti fẹ luu pa.
Nígbà tí ilẹ̀ mọ́, wọ́n rí Pópóọlá.
Òun ni ó gbọ́n jùlọ ní gbogbo ayé.
Awọn inaki naa ti wọn ri ni ipinlẹ Crosss River, ni awọn to n ri si ọrọ itọju ẹranko sọ pe o ṣọwọn lagbaye.
Ìyá mi ní kí n kàn ní ìyá àti bàbá mi fẹ́ ṣe sàráà fún mi.
Ẹ̀yà Gadi ati ti Reubẹni ati ìdajì ẹ̀yà Manase ti gba ìpín tiwọn tí Mose, iranṣẹ OLUWA, fún wọn ní apá ìlà oòrùn, ní òdìkejì odò Jọdani.
"Nigba miran to ba de lati ibi iṣẹ, nkan akọkọ ti yoo kọkọ beere fun ni ibalopọ.
Wo aláànú tó n wa ọkọ̀ tí wọ́n fi n gbé aláìsàn lọ́fẹ̀ẹ́ Omíyalé gbẹ̀mí èèyàn méje, o tún ba dúkìá púpọ̀ jẹ́ Kínni ife ẹ̀yẹ ti Tiger Woods gbà ní Augusta fi yàtọ́?
Aare Buhari ni opolopo awon eniyan ni won fe ki oun ti ku lasiko ti o n saisan.
Ìjà tó ròpọ̀ mọ́n ẹ̀sìn náà kọ́kọ́ bẹ̀rẹ̀ ní ìlú Kasuwar Magani tó wà ní ìjọba ìbílẹ̀ Kajuru n' Ọjọ́bọ.
1 Agẹmo 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 4 Owewe 2020 Oríṣun àwòrán, NPower Awọn to n ṣeto irọkun sapa awọn ọdọ Naijiria ti a mọ si N-Power ti sọrọ nipa iroyin to gbode nipa awọn ti wọn ti ya orukọ wọn sọtọ f'abala keji igbanisiṣẹ eto naa lọdun 2020.
 gbogbo ẹyẹ kọ ́ ló sì ṣe ń sùn lálẹ ́ .
Ọmọọdọ naa to wa lati orilẹ-ede Togo ni wọn fẹsun kan wi pe o hu iwa aitọ yii, ni ile Bademosi ni ile rẹ ni Parkview ni Ikoyi.
Elieseri bí ọmọkunrin kan tí ń jẹ́ Rehabaya, olórí ìdílé rẹ̀, kò sì bí ọmọ mìíràn mọ́, ṣugbọn àwọn ọmọ Rehabaya pọ̀.
Baba wa sọ fún wa pé a mọ̀ pé ọkunrin meji ni Rakẹli, aya òun bí fún òun, 
Awọn ni ọgba ẹwaọn orilẹ-ede Chad ti kun akunfaya ju ni eyi ti ko dara lasiko ooru ti oorun mu yanyanyii.
Ọgagun Muhammadu Buhari ja ijọba gba mọ lọwọ lọjọ kọkanlelọgbọn, oṣu Kejila, ọdun 1983.
Bi awọn ẹka ede gẹẹsi sisọ ṣe mọ yin lẹnu to n yọ jade fẹẹẹ, to n dan mọran mọran lẹnu yin bẹẹ naa lo ṣe yẹ ki ede Yoruba sisọ maa fo jade lẹnu yin lai kọsẹ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, World TB Day: Funkẹ Dosunmu ni ikọ́ ife kìí pani, ta bá lo òògùn rẹ̀ déédé Sani ni, ko si ẹgbẹkẹgbẹ tabi ẹnikẹni to wa eekanna mọ ẹgbẹ Arẹwa lọrun lati se atilẹyin fun Buhari amọ awọn aseyọri rẹ, afojusun rẹ ninu ileri ipolongo ibo rẹ ati agbara ti ẹgbẹ oselu kọọkan ni, ni awọn se agbeyẹwo rẹ.
Nínú ọ̀rọ̀ tirẹ̀, agbẹnusọ fún ọlọ́pàá ní ìpínlẹ̀ Ondo, Femi Joseph sọ pé, àwọn ti da àwọn ọtẹlẹ̀múyẹ́ síta láti ṣe àwári Fagoriola.
Ó ti ṣẹ́ wọn, bí ìgbà tí ó ṣẹ́ ti àwọn ará Midiani.
Panpẹ ologun mu Isa ọmọ ẹgbẹ Boko Haram Boko Haram kọlu abule Kofa ni Maiduguri Boko Haram tu awọn olukọni UNIMAID silẹ Chukwu ni àwọn afurasi náà tun so fun àwọn pe ijinigbe awọn akẹkòó Chibok kò sẹyìn àwọn.
Bi ẹgbẹ ba ti ri wà ni Saudi, mo wa ki anọbi Muhammad ni, mo wa rọgba yi Kaaba lati wa dupẹ ore ti Ọlọrun ṣe kí n si tun beere omiiran ni.
Ó ní, “Nítorí pé o darapọ̀ mọ́ Ahasaya, OLUWA yóo ba ohun tí o ti ṣe tẹ́lẹ̀ jẹ́.
Oríṣun àwòrán, Temilolu Akinboola O ni wahala bẹrẹ lẹyin ti wọn fi oun jẹ Adele Ọba tan, ti wọn si ti ọja ilu Alade.
Ṣugbọn mo ti sọ gbogbo nǹkan wọnyi fun yín, kí ẹ lè ranti pé mo ti sọ fun yín tẹ́lẹ̀, nígbà tí ó bá yá, tí wọn bá ń ṣe é si yín.
Ọmọlóòkú d'èrò ọ̀run níbi ìsìnkú ìyá rẹ̀ A ju ara wa lọ, ìjàkadì kọ́; àṣà Yorùbá yàtọ̀!
Oríṣun àwòrán, Getty Images Bi Coronavirus yoo ṣe mu ayipada ba Ramadan ọdun 2020 Itakete sira ẹni ti wa ninu ẹsin Imale ṣaaju akoko yii, fun apẹẹrẹ, ti eeyan ba jẹ alubọsa, iru ẹni bẹẹ ko le wọ Mọṣalaṣi nitori oorun rẹ.
Iwoye awọn ololufẹ ere ori itage eyi to si ti tan kanlẹ gidi gan ni pe Pasuma ati Jaiye n fẹ ara wọn, eyi si tilẹ ti di igbagbọ ọpọlọpọ.
‘Ọ̀rọ ẹnu lásán ni wàhálà tí Nnamdi Kanu ní òun lè dásílẹ̀ ní Nàíjíríà’ Ètò ti tò ki àjọ INEC bẹ̀rẹ̀ ìkéde èsì ìdìbò gómìnà Rivers Ààrẹ Algeria kò ní pẹ́ kọ̀wẹ́ fipò sílẹ̀ Àjọ INEC ti bẹ̀rẹ̀ ìkéde èsì ìdìbò gómìnà ìpínlẹ̀ Rivers Ọga ajọ NAFDAC ṣalaye pe ile iṣẹ to ṣe ojulowo oogun aarun onigbameji naa ni Valneva Sweden AB, ti awọn eeyan mọ si Crucell Sweden AB tẹlẹ.
pari awe Ramadan lojo kerin inu osu kefa odun ti a wayii.
Awọn liigi yooku nilẹ Yuroopu nkọ o?
“Ìwọ ọmọ eniyan, kọjú sí àwọn ará Amoni kí o sì sọ àsọtẹ́lẹ̀ nípa wọn.
Ṣugbọn ó fi ara hàn lẹ́ẹ̀kan ṣoṣo nígbà tí àkókò òpin dé, láti wẹ ẹ̀ṣẹ̀ nù nípa ẹbọ ẹ̀ẹ̀kan ṣoṣo tí ó fi ara rẹ̀ rú.
Ile ẹjọ orilẹede naa tun dajọ iku fun awọn márùndínlọ́gọ́rin bi awọn mẹtadinlaadọta ṣe gba ẹwọn gbere.
kinni osu karun un odun ti a wayii.
Àwọn ọmọ-ogun yìí máa nbá àwọn kòkòrò aṣekúpani jà tí wọ́n bá wọnú àgọ́ ara wa.
A ó gbé'gbésẹ̀ lẹ́yìn ìwádìí fídíò tí Dino ti ń náwó lójú agbo- Ọlọ́pàá Àwọn obìnrin ilé ìgbìmọ̀ aṣòfin Amẹrika fọnmú sí ọ̀rọ̀ Trump Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Afenifere: Ọ̀rọ̀ tó ń jáde lójú òpó ayélujára
Ṣùgbọ́n òbí àwọn méjèèjì kò fẹ́ kí wọ́n fẹ́ ara wọn nítorí kò sí ìrẹ̀pọ̀ láàárin àwọn obì wọn-ọnnì.
Coronavirus yii si lo mu ki ọkọ ofurufu oun wọgile eto irinna rẹ, ọkada si ni oun gun lati Freetown lọ si Abidjan ni ọjọ kẹrinlelogun osu kẹta ọdun yii.
, Ọgbni Abayomi ni ìbọ́n ba ní ikùn nígbà tí ìbọ́n ba Adebayo ni ẹsẹ̀.
- Ilé ẹjọ́ ìpínlẹ̀ Ondo Ilé ìwòsàn kan rèé tó ń fi àtùpà gbẹ̀bí aláboyún O wa kede pe oun ti ya ara oun sọtọ bayii fun itọju, ti awọn osisẹ eleto ilera fun arun Coronavirus yoo si maa tọju oun nile.
a maa ń ṣe ìwádìí àìsàn yìí làtàrí àwọn ààmì àti àpẹẹrẹ tí ó rọ ̀ mọ ́ ọ , yíyọ sẹ ́ ẹ ̀ lì jádé fún ìwádìí kìí sábà ṣeéṣe .
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù R Kelly: Èmi kò jẹ̀bi ẹ̀ṣùn fífi ipá bá ọmọdé lòpọ̀ 7 Ẹrẹ̀nà 2019 Oríṣun àwòrán, CBS Àkọlé àwòrán, R Kelly ń sukun lóri TV bó ṣe kọ ẹ̀sun ìfipábáni lòpọ̀ Olórin tàkasúfèé ọmọ ilẹ̀ Amẹ́ríkà ń sunkún pẹ̀lú ìbínú lóri ẹ̀sùn pé, ó fi tipá banilòpọ̀ lásìkò to ṣe ìfòrọ̀wánilẹ̀nùwò àkọ́kọ́ lẹ́yìn to ti wà lágọ̀ọ́ ọlọpàá láti oṣù tó kọja.
O ni akọkọ ninu wọn ni ọmọbinrin ọmọ orilẹede Naijiria kan to wọ orilẹede Naijiria lati orilẹede France pẹlu baluu ilẹ Turkey kan lọjọ kẹrinla oṣu kẹta ọdun 2020.
Ọpọ lo ri titako ti Emir tako igbesẹ ijọba lati ya owo lọwọ orilẹ-ede China fi ṣe oju'rin fun reluwe gẹgẹ bi didena idagbasoke ipinlẹ Kano.
”Wolii náà dáhùn pé, “Ìwọ gan-an ni.
Òyìnbó sísọ di èèwọ̀ ní ìpínlẹ̀ Ekiti Ìpínlẹ̀ Ọ̀ṣun kéde ìsinmi lẹ́nú iṣẹ́ nítorí ọdún Ìṣẹ̀ṣe Yàtọ̀ sí Ọ̀ṣun Òṣogbo, Ṣàǹgó pẹ̀lú a máa ní arugbá lóde Ọ̀yọ̀ Falana àtàwọn míì péjú síbi àpérò #RevolutionNow l'Eko SSANU, NASU gbé fásitì Ibadan tì pa Amọṣa o, ọjọ mọkanla pere ni Agboọla yoo lo ni ipo gomina ipinlẹ naa ti yoo tun fi pada si ipo rẹ gẹgẹ bi igbakeji gomina.
Eyi ko ṣeyin bi agbẹjọro agba fun orilẹ-ede Naijiria to tun jẹ minisita feto idajọ, Abubakar Malami, SAN ṣe kọwe ifisun si Aarẹ.
29 Ògún 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 30 Ògún 2019 Àkọlé àwòrán, Bobrisky fún ọ̀gá Arts & Culture lésì, ó ni àwọn ọgá rẹ̀ ló ń ba ṣe Ọrọ n ba ọrọ bọ laarin awọn mejeeji.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ikogosi-Ekiti: Ilu ti omi tutu ti dapọ mọ gbigbona O se ere pẹlu orin Yoruba Ronu ati Otitọ Koro nibi ayẹyẹ kan ti Oloogbe SL Akintọla peju si, eyi to fi n sọko ọrọ nipa aawọ Akintọla ati Awolọwọ, ti Akintọla si binu jade nibẹ Orin Yoruba Ronu wa lara idi to mu ki wọn kede ilu ko fara rọ lọdun 1963 lẹkun ilẹ Kaarọ Oojire Ọdun meji ni wọn fi fi ofin de Ogunde lati se ere tiata lẹkun iwọ oorun Naijiria, tii se ilẹ Yoruba, amọ ijọba ologun ti Fajuyi leawaju rẹ lẹkun naa, lo gbẹsẹ kuro lori ofin ọhun.
'App' naa n sisẹ lati dẹkun itankalẹ ayederu oogun oloro lorileede wọn.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Oba Olajide Olayode: Ó pe ọlọ́pàá láti yanjú aáwọ̀ ìlú lórí owó orí, bílísì bá dé 10 Owewe 2020 Awọn ọba alaye nilẹ Yoruba ni ọwọ nla gidi, tawọn araalu si maa n wa riri fun wọn.
“Ẹnikẹ́ni ninu ìran Aaroni tí ó bá ní àrùn ẹ̀tẹ̀, tabi tí ara rẹ̀ bá ń tú, kò gbọdọ̀ jẹ ninu àwọn ohun mímọ́ náà, títí tí yóo fi di mímọ́.
Egbe APC soro yii nibi Atejade kan ti won gbe sita lati fi kedun pelu ijọba ati awon omo ipinle Plateau nipa isele to waye lojo Abameta.
fe se lorile ede naa, ni yoo so nipato nipa 
Rasaki jẹ ọkan lara àwọn ti ajinígbé jígbé pẹ̀lú àwọn mẹ́fà míràn lọ́jọ́ kẹfà, oṣù yìí ní déédé ààgọ mẹ́jọ alẹ́ ní àgbègbè Kétu-Ereyun, Ikorodu.
Chelsea naa gba miliọnu mẹrin Euro.
Nítorí náà, ó fi ohun gbogbo tí ó ní sí ìkáwọ́ Josẹfu níwọ̀n ìgbà tí ó wà pẹlu rẹ̀, kò sì bìkítà fún ohunkohun mọ́, àfi oúnjẹ tí ó ń jẹ.
Kí wọn máa ṣe rere, kí wọn jẹ́ ọlọ́rọ̀ ninu iṣẹ́ rere, kí wọn fẹ́ràn láti máa ṣe ọrẹ ati láti máa mú ninu ohun ìní wọn fún àwọn ẹlòmíràn, 
Ondo Politics: Eyitayo Jegede gbé Akeredolu lọ síwájú ìgbìmọ̀ tó n gbọ́ ẹ̀sùn ìdìbò
Fun àpẹrẹ ti olukopa A ba ri atilẹyin to pọ ni ipinlẹ̀ kan ju asoju B lọ, wọn yoo fun asoju A ni ipò to pọ julọ, ti olukopa keji yoo si ni diẹ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Oyún ṣíṣẹ́: Wíwá òògun ìsẹ́yún lórí àyélujára peléke síi 6 Òkùdu 2018 Àkọlé àwòrán, Ìwádìí fi hàn pé àwọn orílẹèdè tó fi òfin de ìsẹ́yùn ni ó pọ̀jù nínú àwọn tó ń ṣe ìwádìí òògùn oyún ṣíṣẹ́ lórí ìtàkùn àgbáyé.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Yoruba Culture: ọjọ́ méje ni wọ́n fí n rẹ ẹ̀kú Danafojura kó tó jáde Adeniyi ni lootọ, wahala pe oun wa lẹwọn to domi tutu si ọkan oun ṣugbọn pẹlu ifaraẹnijin ati ilakaka gbogbo to yẹ oun bori nigbẹyin.
Eeyan mẹta lo lugbadi aarun naa lati Edo nigba ti eeyan meji meji ni aarun covid-19 lati Delta, Imo, Kano ati ipinlẹ Ogun.
2 15078 Orilẹede Malta 151 34.
Awọn afurasi ọhun to jẹ agbẹboji ni ilẹ isinku to jẹ ti ijọba ibilẹ Guusu Akure ni ọwọ palaba wọn segi nibi ti wọn ti n gbiyanju lati ge ori oku kan ti wọn ṣẹṣẹ sin.
A tun gbọ pe ile iṣẹ ọlọpaa n gbero lati gba awọn ọmọluabi eeyan bi alufa ijọ, imaamu, agbẹjọro, oniroyin, olukọ ati awọn ọdọ fun iṣẹ naa.
Se yoo kan maa lọ bẹẹ naa ni.
Sowore: olùdíje Ààrẹ tó fẹ gbà Nàìjíríà padà fún àwọn ọdọ Ọmọ ọdọ ji owo ọga, o tun p‘ago lori rẹ Àwọn ọmọ tó há sínú ilẹ̀ ti jáde!
Fun apẹẹrẹ, Iwe iroyin kan nilẹ Australia kọ soju opo Twitter rẹ pe Bi irungbọn rẹ se lee jẹ ko wa ninu ewu Coronavirus laimọ."
Manase ṣi àwọn ará Juda ati Jerusalẹmu lọ́nà, tóbẹ́ẹ̀ tí wọ́n fi ṣe burúkú ju àwọn orílẹ̀-èdè tí OLUWA parun fún Israẹli lọ.
Ori ko ẹgbẹta o din aadọta awọn abọde arinrinajo silẹmimọ Hajj yọ ni Minna.
Nígbà tí Hasaeli Ọba kú, Benhadadi ọmọ rẹ̀ jọba lẹ́yìn rẹ̀.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ǹjẹ́ o mọ ǹkan wọ̀nyíi nípa Kanu Nnwankwo?
O fi kun-un oro re pe, “ile-igbimo asofin elekejo yoo ri daju pe, won pese ilana ofin ti yoo je anfaani fun awon ara-ilu ni gbogbo igba”.
Oríṣun àwòrán, Brenda Biya/Facebook Awọn miran ti ẹ sọ pe owó orí ti awọn araalu n san lo fi lọ ọ ṣi ile itaja si orilẹ-ede miran.
a tún ni àwọn kan tí wọ ́ n níí ṣe pẹ ̀ lu híwu ìwà òdaràn .
E̩nì kò̩ò̩kan ló ní è̩tó̩ pé kí a má s̩àdédé s̩e àyo̩júràn sí ò̩rò̩ ìgbésí ayé rè̩, tàbí sí ò̩rò̩e̩bí rè̩ tàbí sí ò̩rò̩ ìdílé rè̩ tàbí ìwé tí a ko̩ sí i; a kò sì gbo̩dò̩ ba iyì àti orúko̩ rè̩ jé̩.
EPL: Asise rẹpẹtẹ s'okunfa ifidirẹmi fun Arsenal
Ewu ti ó wà ni ilé oníyàwó  púpọ̀ ju ire ibẹ̀ lọ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Yemi Elesho, ìlúmọ̀ọ́ká adẹ́rínpòṣónú jẹ́wọ́ pé ẹnu nìkan kọ́ lòun ní lórí 'Ṣé o láyà?
Ìdùnnú subú layọ̀ nípìnlẹ̀ Ọyọ́, àwọn tó dé láti Lebanon sọ ọmọ wọn ní Seyi Ìyàwó Banky Wellington tàbùkù ọbẹ̀ gbẹ̀gìrì Àwọn aláboyún f'ẹ̀hónú hàn ní ìpínlẹ̀ Òǹdó Obìnrin kan bí ibejì lẹ́yìn ọjọ́ 26 tó bí ọmọkùnrin Ni eero ti onimọ nipa ounjẹ ẹdá, lati Fasiti ilu Ibadan, ti oun naa ba Tribune sọrọ, Ọmọwe Oluwaseun Ariyo, sọ pe o dara ki obinrin bẹrẹ si ni lo awọn oogun to le fun un ni eroja folic acid ati iron, lati igba to ba ti balaga, nitori iṣoro aito ẹjẹ to wọpọ ni awọn orilẹ-ede kan, ti ko yọ Naijiria silẹ.
Bakan naa ni Sweden ati Russia to n gbalejo idije todun 2018 naa ti ja kuro ninu idije.
Gbogbo nǹkan yòókù tí Jehoaṣi ṣe, ati ìwà akọni rẹ̀ ninu ogun tí ó bá Amasaya jà, ni a kọ sinu Ìwé Ìtàn Àwọn Ọba Israẹli.
Títà ni mo fẹ́ kí ó tà á fún mi ní iyekíye tí ilẹ̀ náà bá tó, lójú gbogbo yín, n óo sì lè máa lo ilẹ̀ náà bí itẹ́ òkú.
 Agbara wa ni ki a wa ni isọkan .
 Òun ni olóòtú ìjọba Àríwá ilẹ ̀ nigeria .
CJ Gold: ẹ̀rù kọ́kọ́ ba ìyá mi nígbà ti mo fẹ́ bẹ̀rẹ̀ iṣẹ́ ìjà jíjà
Nígbà tí gbogbo Israẹli rí i pé, ọba kò gbọ́ tiwọn, wọ́n dá a lóhùn pé, “Kí ló kàn wá pẹlu ìdílé Dafidi?
Ninu atejade kan lori ero ayelujara Zimbabwe.
Ọrọ naa lagbara de bi pe awọn onwoye ni kete ti wọn ba ti ribi wa wọrọkọ fi ṣada lẹka yii ti ijọba si sọ ji pada, ohun gbogbo yoo bọ sipo pada.
lẹ́yìn tí awọ ara mi bá ti díbàjẹ́,ṣugbọn ninu ara mi ni n óo rí Ọlọ́run.
Àwọn agbègbè tí àtùndi ìbò yóò kàn lọ́jọ́ Àbámẹ́ta nípìnlẹ̀ Eko rèé Sójà obìnrin lù mí lálù bami nílùú Ibadan Bí mo ṣe pàdánù àǹfàní láti rí ìyá mi fún ìgbà ìkẹ́yìn - Makinde ṣàlàyé Irọ́ ni, abẹ́rẹ́ àjẹsára Covid-19 kò lè ṣàyípadà DNA rẹ Jalade lo fi eyi si oju opo ikansiraẹni Instagram rẹ laarin ọsẹ yii.
Òun ni ó gbé iwin ní ìyàwó létí adágún omi tí ó yá owó lọ́wọ́ ọ̀sanyìn tí ó gba ohun ọ̀sìn lọ́wọ́ Èṣù ti ń gbé ìkóríta.
esin naa  fi se rere ni gbogbo igba.
Wọ́n ń ṣe bí ẹni pé wọ́n gbọ́n, bẹ́ẹ̀ sì ni wọ́n ya òmùgọ̀.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Christmas & Border Closure: ìrẹsì dí góòlù fún Kérésì 2019 Ọgbẹni Moore jẹ ọ̀kan lara awọn to da Baba Keresimesi ti Amẹrika silẹ - ẹni mimọ to maa n wọ aṣọ pupa, ti yoo si maa fun gbogbo eniyan ni ẹbun, boya wọn fẹ tabi wọn ko fẹ ẹ.
”Ó sì dáhùn pé, “Kò séwu.
Oludasile ose oge, Omoyemi Akerele ti gboriyin fawon amunidara ni Naijiria pe ise won ti lami laaka lo si oke okun lasiko yii.
Ọkọ gomina ipinle Kaduna, Malam Nasiru El-Rufai bọ lọwọ ewu awọn agbesunmọmi loju ọna Kaduna-Abuja.
Gbogbo wọn ti ṣìnà,gbogbo wọn pátá ni wọ́n sì ti bàjẹ́;kò sí ẹnìkan tí ń ṣe rere,kò sí ẹyọ ẹnìkan ṣoṣo.
Lẹyin to lo ipara naa fun ọsẹ kan, oju rẹ pupa.
Lasiko ikọlu ọtun yii, to sẹlẹ laago meje irọlẹ ọjọ aje, ile mọkanla ni wọn jo kanlẹ.
Àgbo tí mò ń lò láti jò kó bá mi, ìdí mi ti yọ́ tán - Nkechi Blessing figbe ta 8 Kí làwọn nǹkan tó lè rán ọkùnrin sí ọ̀run alákeji lásìkò ìbálòpọ̀ pẹ̀lú obìnrin?
Ọ̀kan ninu àwọn amòfin sọ fún un pé, “Olùkọ́ni, nígbà tí ó ń sọ̀rọ̀ báyìí, ò ń fi àbùkù kan àwa náà!
Àwọn tí ó ń lọ sí Ijipti fún ìrànlọ́wọ́ gbé!
Nítorí bí kíkọ̀ tí Ọlọrun kọ̀ wọ́n sílẹ̀ bá mú kí aráyé bá Ọlọrun rẹ́, kí ni yóo ṣẹlẹ̀ nígbà tí Ọlọrun bá gbà wọ́n mọ́ra?
O sọ pe awọn eeyan awọn to mọ tibu toro agbegbe naa ni yoo wa nibẹ ti wọn yoo si le awọn ọdaran kuro ni ipinlẹ Ekiti.
Oríṣun àwòrán, Facebook Ọga ajọ eleto idibo INEC, Ọjọgbọn Ahmed Mohammed to kede Lukshi gẹgẹ bi ẹni to bori ninu ibo naa kede pe 12, 299 ibo ni Lukshi ni to fi jawe olubori.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Wòólì Alfred kú lọ́dún 1964, ó tún padà wà sí ìlú Agelu f'ọ́jọ́ mẹ́rìnlá!
Ìlànà tuntun ìjọba nítóri Covid-19 yóò pa iṣẹ́ wa lára ṣùgbọ́n ayé ò parẹ́ - Àwọn adarí ayẹyẹ Àìsàn Muyiwa kò lè la ẹ̀mí lọ - Agbẹnusọ Òṣèré, Muyiwa Ademola New Variant: Kí ni ìbẹ̀rù tó gbọkàn àwọn èèyàn lágbàáyé nítorí ẹ̀yà ààrùn Covid-19 tuntun?
Nígbà tí Olórí Alufaa dé pẹlu àwọn ẹlẹgbẹ́ rẹ̀, ó pe ìgbìmọ̀ ati gbogbo àwọn àgbààgbà láàrin àwọn ọmọ Israẹli jọ.
Ẹ óo jẹ́ ọlọ́rọ̀ ní gbogbo ọ̀nà tí ẹ óo fi lè máa lawọ́ nígbà gbogbo.
Nígbà náà ni wọ́n lu odi ìlú náà, ọba ati àwọn ọmọ ogun rẹ̀ sì gba ibẹ̀ sá jáde lóru.
àwọn ọmọ Gideli, àwọn ọmọ Gahari ati àwọn ọmọ Reaaya;
Akẹkọ naa ni asẹ 'Ẹ lọ gbele yin naa', ko yọ akẹkọ kankan silẹ, to fi mọ awọn akẹkọ to fẹ kẹkọ jade, bẹẹ lo tun sediwọ fun idanwo ti wọn fẹ bẹrẹ lọsẹ to n bọ.
Ambode sọ wi pe, awọn pese eto isuna naa lati le koju awọn ise akanse to niise pẹlu awọn opopona ti wọn n se, bii Oshodi si Murtala Mohammed International Airport Road ni agbeegbe Agege.
Oríṣun àwòrán, Instagram O ni ipade naa kun gan, ti awọn ọba to wa nibẹ si le ni ọgọrin, nigba ti Ọọni si n fi ẹdun ọkan rẹ han lori isẹlẹ naa, lo ti salaye pe oun ko si nile, Abuja ni oun wa, amọ oun sare wale ni, inu awọn ọba Arẹwa ati ila oorun ilẹ yii ko dun sawọn ni Ọsun, ti wọn si n rọ oun lati wa nkan se si bi ọba se n na ọba nilẹ Yoruba.
Ọjọ kẹjọ, oṣù Kẹwaa, ọdún 2005 ni ọjọ ta n wí yi.
“Èyí ni òfin Nasiri, ṣugbọn bí Nasiri kan bá ṣe ìlérí ju ẹbọ tí òfin là sílẹ̀ lọ, ó gbọdọ̀ mú ìlérí náà ṣẹ.
Awon ohun ti won yoo jiroro“Won yoo gbe abajade won wa siwaju  igbimo amusese lojo Aje ni ojo kesan an , a o si se ipinnnu to monyan  lori re.
Nitori naa, ọgba inu ile ijọsin Anglican ni wole Soyinka gbe ni kekere to si n kọ ẹkọ nipa ẹsin Kristẹni lọdọ awọn obi rẹ.
Ẹ ti kọ̀ mí sílẹ̀,ẹ sì ń pada lẹ́yìn mi; èmi OLUWA ni mo sọ bẹ́ẹ̀.
Nítorí OLUWA kò ní kọ àwọn eniyan rẹ̀ sílẹ̀;kò ní ṣá àwọn eniyan ìní rẹ̀ tì;
Ẹ̀yin ará, ohun tí mò ń sọ nìyí.
Awọn eeyan orilẹede India ni wọn kọkọ bẹrẹ si ni lo awọn ọkọ to jọ bi 'kẹẹkẹ Napep' fun awọn to n ṣe inaju ati igbafẹ.
Kòkòrò oyin sọ ọ̀pọ̀ èèyàn di aláìrílégbé, àwọn míràn tún farapa Gbajugbaja òṣèré ''Toromagbe'' nínú fíìmù ''Arelu'' ti jáde láyé Awọn agbebọn yinbọn lu Oba Adeusi ni agbegbe Elegbeka ni opopona Owo-Ifọn ni ipinlẹ Ondo.
Brexit: Ọ̀rọ̀ kò yé wa mọ́!
Afárá odo ọya keji :Ta ni yóò parí rẹ?
"'Iṣẹ́ tí Ọlọ́run kọ mọ́ mi ni mò ń ṣe' 'Èmi ò kí ń lu ìyàwó mi' Njẹ o mọ oju yi ni ""Yollywood""?"
ó sì gbé oúnjẹ aládùn tí ó sè ati àkàrà tí ó tọ́jú fún Jakọbu ọmọ rẹ̀.
Kò yẹ kí ìjọba máa ní àwọn mẹ̀kúnú lára lásìkò Coronavirus yìí- Rewane Àwọn àwòrán ìrántí tó ń sàmì ogójì ọdún tí Ọba Adesoji Aderemi jáde láyé Àjọ NCDC kéde ènìyàn 626 tó tún ṣẹ̀ṣẹ̀ ní Coronavirus ní Nàìjíríà Eeyan 626 tuntun mii lo ṣẹṣẹ lugbadi arun Coronavirus ni Naijiria.
Bakan naa ni iwadii ti n lọ lori iṣẹlẹ naa, ti awọn ẹbi rẹ si n fẹ mọ ohun to faa ti wọn fi kọkọ kede oku rẹ.
 bákan náà ni àjọ yí tú ṣe ìkúnlápá fú ìmọ ̀ ìwádìí nípa ààbò áwùjọ àti ìwádí nípa iṣẹ ́ ìlera .
Black Panther ni fiimu to ta julọ to jẹ pe alawọ dudu lo dari ẹ, Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ìsọ̀ oníwe ìròyìn àtàwọn tó ń kà a lọ́fẹ̀ẹ́ King of Boys Ọmọ Yoruba to n gbé ogo Naijiria ga ninu eré oniṣe lasiko yii, Kemi Adetiba lo dari sinima King of Boys.
 Èyí ń wáyé nítorí àwọn ènìyàn díẹ ̀ tí wọ ́ n ń fún ní àjẹsára , ọ ̀ pọ ̀ àwọn ènìyàn tí o ń gbé ní ìlú , àwọn ènìyàn tí o ńlọ káakiŕi , àti ìyípadà afẹ ́ fẹ ́ .
“OLUWA ti sọ fún ẹ̀yin tí ẹ ṣẹ́kù ní Juda pé kí ẹ má lọ sí Ijipti.
Bi ọrọ ti ṣe ri bayi, Aarẹ Jonathan ko jẹjọ kankan lori ọrọ naa.
O fi ero han wipe awọn gomina iru ipinlẹ wọnyii ni lati lọ kẹkọọ si nipa ṣiṣe iṣẹ akanṣe ni ilu.
Gẹ́gẹ́ bí àṣà wọ́n ní ilẹ̀ Yúróòpù, àwọn ìlú kọ̀ọ̀kan ní àjọ̀dún àti ìdúpẹ́ tí wọ́n máa nṣe ní àsìkò yìí.
Amọṣa, ajọ to n mojuto ọrọ awọn oṣiṣẹ lagbaye, ILO ti sọ pe ọgbọn ko digi lọrọ naa bayii nitoripe bi nnkan ṣe n lọ yii, igba o din marun miliọnu (195milion)lawọn eeyan ti yoo padanu iṣẹ wọn lagbaye nipasẹ ajakalẹ arun Coronavirus.
"Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, No reception wedding: Adewale ni àpèjẹ kò ṣe pàtàkì sí òun O ni: ""Mo mọ pe iṣẹlẹ yii dun awọn eeyan mi to wa nipinlẹ Benue, ṣugbọn mo bẹ yin pe ki ẹ dariji ọkọ mi."
Ìlú ò rẹ́rìn ín rárá, Alaafin Adeyemi III fárígá fún Buhari nínú lẹ́tà tuntun 'Kò sí ohun tó burú nínú bí Ajimobi ṣe dá Yewande tó pa ọkọ rẹ̀ sílẹ̀' Darandaran Fulani kìí lo ìbọn, 'pọ̀pá' la máa ń lò Lẹ́tà Obasanjo: Àjálù ń bọ̀ bíi ti Rwanda, tí Buhari kò bá ṣàtúnṣe ètò ààbò O ni eto akanṣe yii yoo jẹ iwuri ati koriya fawọn ọdọ Naijiria nipa ootọ inu ati iwa ọmọluwabi to ti n sọnu lawujọ.
Ohun to ṣe okunfa iwaadi yi ko silẹyin bi arakunrin kan ti ṣe fiwe ranṣẹ si ileeṣẹ ọlọpa loju opo Twitter nipa aitọ iwa ti awọn ọlọpaa to na ika 4+4 naa hu.
Iroyin to tẹle eyi ni wi pe lẹyin ti wọn jẹ ẹran maalu ni awọn ẹyẹ igun naa fo ṣanlẹ ku.
O ni lasiko ere ifẹ, ẹjẹ lo maa n rọ sinu nnkan ọkunrin, ti yoo fi le gbagidi, ti yoo si maa tobi si to ba wọ oju ara obinrin tan.
Ìdí tí mo fi pa irọ́ ìgbéyàwó lórí Facebook Awọn isẹlẹ to dun mi jọjọ - Ọbasanjọ Biodun Fatoyinbo fi ipò sílẹ̀ lorí ẹ̀sùn ìfipábánilòpọ̀ Wọ́n lu àbúrò mi ló jẹ́ kí ń fi ìbínú lu òǹtàjà l‘Abuja - Sẹ́nétọ̀ tó lu obìnrin ṣàlàyé Ọwọ́ Buhari kò lágbára láti buwọ́lu àdéhùn okoòwò - Ọbasanjọ Bi o tilẹ jẹ wi pe Sẹnetọ Abbo sọ pe arabinrin naa yọ ṣuuti ete si oun loun fi luu, awọn eekan bii Don Jazzy atawọn miran ti gba ori oju opo ayelujara lọ lati bu ẹnu ẹ̀tẹ́ lu iwa ti Sẹnetọ naa hu.
olubori ninu eto idibo gomina to waye ni ipinlẹ Rivers.
 Ẹ ̀ sìn mùsùlùmí àti ti ìbílẹ ̀ ni wọ ́ n ń ṣe papọ ̀ .
Ocheho so oro naa di mimo lasiko asekagba idije Sam Ocheho International Invitational Handball Championships, ti o sese pari nipinle Eko.
Ọjọgbọn Wole Soyinka ṣapejuwe ọdun 2020 gẹgẹ bi eyi to ti buru julọ ti oun mọ lorilẹ-ede Naijiria.
Ni ọ̀pọ̀lọpọ̀ ọdún sẹhin, Ijọba Ológun di Èkó lọ́wọ́ lati pèsè ọkọ̀ ojú irin ti ó ngbé èrò púpọ̀ ti Gómìnà Lateef Jakande bẹ̀rẹ̀.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Mo fara da ìsòro gan láwùjọ́ torí àwọn òbí mi di létí' Ajọ EFCC sọ pe ọga ileeṣẹ awọn, Ibrahim Magu ati awọn alaṣẹ Dubai ti ṣe ọpọlọpọ ipade lori agbẹjọro agba Naijiria tẹlẹ naa.
    Nígbà tí mo rí Ayédèrú-ẹ̀dá ti mo bẹ̀rẹ̀ ìjà, o ní òun kò mọ̀ pé àbúrò ìyàwó mi ló  wọ aṣọ ìyàwó mi, ibi ti òun jókòó sí lọ́jọ́ tí òun ti kọ́ ri wọn ni òun ní ki n jókòó sí, òun kò sì rò pé o yẹ́ kí òun rí ẹni ti òun rò pé ìyàwó mi ni kí ẹlòmìi’ràn máa lò ó bí òun ti rí wọn láì jẹ́ pé òun sọ fún mi, òun kò mọ̀ pé bẹ́ẹ̀ ni àbúrò ìyàwó mi ṣe máa ń lọ pàdé ọkùnrín ọlọ́kùnrin kiri.
 À ó pa àwọn ẹyin náà nínú ìfun , àwọn aràn náà a sì gbẹ ́ ihò sínú ògiri ikùn ènìyàn , wọn a sì gba ibẹ ̀ lọ sínú àwọn ẹ ̀ dọ ̀ fóró nípasẹ ̀ ẹ ̀ jẹ ̀ .
Ati pe awọn ọmọ ikọ Super Eagles yoo bẹrẹ si ni ṣe daada ju ti tẹlẹ lọ.
Wọ́n ń ṣọ́ àwọn ẹnu odi ìlú tọ̀sán-tòru kí wọ́n baà lè pa á.
Anthony Joshua: Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
A ti fi àwọn eniyan wọnyi tí kò mọ Òfin Mose gégùn-ún!
Ogbeni Bello salaye pe ise akanse ohun ni yoo na ijoba ni bilionu
Afara yii gba ọkọ mẹjọ papọ lẹgbẹkẹgbẹ, o si ṣafihan ilu eko lati or omi to fi kan Fasiti Eko ati Makoko lori omi.
Ọrọ naa ti de ibi pe, Unai Emery ti kilọ fun wọn ki wọn lọ tunra mu ti wọn ba fẹ kopa ninu idije sáà to m bọ.
Oriṣiriṣi ọba ati iṣakoso to ti ara Ayaba Daurama jade lo ti jẹ ni Daura titi di oni.
Bi ẹ ko ba gbagbe, lọsẹ to kọja ni gomina ipinlẹ naa, Godwin Obaseki kọwe fi ẹgbẹ oṣelu naa silẹ lọ darapọ mọ ẹgbẹ oṣelu APC.
Ijọba ipinlẹ Eko lo fi ikilọ sita fun awọn ara ilu pe ki wọn ṣọra lati maa jẹ awọn pọnmọ oloro kan to wa lọja bayii.
Nítorí náà, ẹ gba àpò kan náà lọ́wọ́ rẹ̀, kí ẹ fún ẹni tí ó ní àpò mẹ́wàá.
 Ìjọba Ìbílẹ ̀ mẹ ́ rin ọ ̀ tọ ̀ ọ ̀ tọ ̀ ni wọn ti ń sọ Ìgbominà .
O ni iwadii fihan pe o ṣeeṣe ki wọn ku ni 2074 nigba ti kò ri béé ni awọn orilẹ-ede mii.
Àwọn olùkọ́ mẹ́fà ni wọn sì gba ibẹ̀ ṣaláìsí.
A tú àgọ́ mi palẹ̀ bí àgọ́ darandaran,a sì ká a lọ kúrò lọ́dọ̀ mi.
O sọ fún awọn ọlọpaa pe baba oun ni oun yoo fi iya jẹ òun, to ba fi le sọ fun ẹnikẹ́ni.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Madam Sajẹ: Mò ń rọ àwọn akẹẹgbẹ́ mi nínú tíátà láti máṣe kánjú 13 Èrèlè 2019 Oríṣun àwòrán, Sajetiologa Ẹ ni ti ọdun ba ba laye, o yẹ ko maa dupẹ nitori aimọye ojo lo ti rọ ti ilẹ ti fi mu.
Awọn ẹya mii to tun wa ni AC SC ati bẹẹ bẹẹ lọ ṣugbọn ọmọ iya kan naa ni wọn pẹlu SS.
Aare ana lorile ede Naijiria, ti o tun jẹ alaga igbimo eto alaafia lo pe
Ọlọrun, agbára mi, n óo kọ orin ìyìn fún ọ,nítorí ìwọ, Ọlọrun, ni odi mi,Ọlọrun tí ó ń fi ìfẹ́ tí kì í yẹ̀ hàn mí.
Ọmọ ìbílẹ̀ Romu ni ọkunrin yìí o!
Nígbà tí wọn kò rí ọ̀nà ati san gbèsè wọn, ẹni tí ó yá wọn lówó bùn wọ́n ní owó náà.
Òjòlá-ìbínú tóbi púpọ̀, ẹ̀dá afàyàfá ni ṣùgbọ́n orí ènìyàn nió ní àfi wí pé ẹnu rẹ̀ tóbi ju ti ènìyàn lọ.
Yollywood òṣèrè, Dayọ Amusa: Ko si eni ti ko ni baba isalẹ
Ọ̀nà yín kún fún ìsọdahoro ati ìparun.
Títí di ìgbà wo ni ọkàn mi yóo gbọgbẹ́tí ìbànújẹ́ yóo gba ọkàn mi kan, ní gbogbo ìgbà?
Iwe iroyin ijọ Aguda ṣe apejuwe ofin naa bi eyi ti tawọn ileeṣẹ n lo lati fi daabo bo ara wọn tabi eyi ti awọn to di ipo ijọba mu naa n lo.
Coronavirus:Ọmọ mi to ṣẹ̀sẹ̀ dé láti UK ko fi àmi Coronavirus han, sùgbọ́n.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù NNPC: Òpó ọ̀pá epo tí wọn ń rì lọ́wọ́ ló fa ìṣẹ̀lẹ̀ ìbúgbàmú náà 20 Ọ̀pẹ̀̀ 2018 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 9 Agẹmo 2020 Oríṣun àwòrán, Others Ile iṣẹ to n risi ọrọ epo rọbi ni Naijiria, NNPC ti salaye bi iṣẹlẹ to pa oṣiṣẹ meje ṣe waye ni agbegbe Gbetiokun, OML 40, in ilu Benin, ipinlẹ Edo.
Ó nṣe dáradára ni ibi iṣẹ́ ki ó tó gbọ́ ìròyìn ikú bàbá rẹ.
Ọjọ́ méjì sẹ́yìn ni wọ́n ko àwọn kan de láti ìlú Dubai nítori ààrùn Coronavirus.
Ẹni to ba si rin yika tibu-tooro ipinlẹ Ọsun, yoo foju ganni ọpọ isẹ atunse awọn oju popo ati lila opopona tuntun to waye nibẹ.
Ọ̀rọ̀ náà ti wá jo dóri kókó ti ó sì n kọni lomiinu fún àjọ elétò ìlera ni àgbáye (WHO) ti wọn si ka àsà yìí si ọkan nínú ǹkan mẹ́wàá tó n dúnmọ̀huru mọ́ ètò ìlera lágbàye lọ́dun 2019.
Ewon osu mefa ni yoo si fi gbara, tabi ki o san owo itanran  ẹ̀ẹ́dẹ́gbẹ̀ta egberun naira.
Nítorí náà, n óo fi ẹ̀gún ṣe ọgbà yí i ká; n óo mọ odi yí i ká, tí kò fi ní rí ọ̀nà jáde.
Nígbà tí wọ́n bí èyí ekeji, rírọ̀ ni ó fi ọwọ́ kan rọ̀ mọ́ èyí àkọ́bí ní gìgísẹ̀.
Kí olukuluku ṣe bí ó bá ti pinnu ninu ọkàn rẹ̀, kì í ṣe pẹlu ìkanra, tabi àfipáṣe, nítorí onínúdídùn ọlọ́rẹ ni Ọlọrun fẹ́.
Nígbà náà, àwọn tí wọ́n sá àsálà ninu yín yóo ranti mi láàrin àwọn orílẹ̀-èdè tí a bá kó wọn ní ìgbèkùn lọ, nígbà tí mo bá mú ìfẹ́kúfẹ̀ẹ́ ọkàn wọn tí ó ń mú wọn kọ̀ mí sílẹ̀ kúrò, tí mo bá sì fọ́ ojú tí wọ́n fi ń ṣe àgbèrè tẹ̀lé àwọn oriṣa wọn.
Ṣugbọn àwọn amòfin kan jókòó níbẹ̀, wọ́n bẹ̀rẹ̀ sí kùn sinu pé, 
Ẹnu ọ̀nà àbáwọlé náà ni ọba yóo gbà wọlé, ibẹ̀ náà ni yóo sì gbà jáde.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Tomomewo Favour: olóṣèlú kìí ṣe ọ̀daràn tàbí alágbèrè Atẹjade naa fikun pe, Amosun tun tọ aarẹ orilẹ-ede yii nigba naa, Goodluck Jonathan lọ, lati beere asẹ fun agbekalẹ ajọ OP MESA, ti wọn si ra awọn ohun ija fun wọn pẹlu owo gọbọi.
Suleiman naa fi aidunnu re han lori bi Awon osise ajo eleto idibo se pẹ lati de
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù MSME free business registration: Oníṣẹ́ alàdáni, ẹ wo ọ̀nà láti jẹ ànfàní ìforúkọsílẹ ọ̀fẹ́ tí ìjọba gbékalẹ̀ 28 Ọ̀wàrà 2020 Oríṣun àwòrán, MSMES SURVIVAL FUND/TWITTER Aarẹ Muhammadu Buhari ti buwọlu anfani iforukọsilẹ ọfẹ fawọn to ba fẹ forukọ ileeṣẹ wọn silẹ pẹlu ileeṣẹ to n fontẹ lu orukọ ileeṣẹ ni Naijiria,CAC.
" Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, May yoo ṣ'abẹwo si erekuṣu Robben Island nibi ti wọn fi Aarẹ Nelson Mandela si fun ọpọlọpọ ọdun Lara awọn ibi ti olootu ijọba ilẹ Gẹẹsi, Theresa May yoo ṣe abẹwo si lorilẹede South Africa ni erekuṣu Robben Island nibi ti wọn fi Aarẹ Nelson Mandela si fun ọpọlọpọ ọdun lati fi ṣami ọgọrun ọdun ti wọn bi Mandela.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Idowu Olakunrin: Kò sí ẹni tó lé è dí àlàfo tí Funke fi sílẹ̀ 20 Agẹmo 2019 Oríṣun àwòrán, Google Àkọlé àwòrán, Ọkọ olóògbé Olufunke Olakunri bú sí ẹkún lásìkò tó ń se ìdárò ìyàwó rẹ̀ tí àwọn agbébọn pa ní ìpínlẹ̀ Ondo.
Ẹ wo àwọn ìlúmọ̀ọ́ká olórin, òsèré tó ti sẹ̀wọ̀n rí!
Lẹ́yìn náà, Solomoni dúró níwájú pẹpẹ lójú gbogbo eniyan, ó gbé ọwọ́ mejeeji sókè, ó sì gbadura sí Ọlọrun.
Iwọde naa bẹrẹ lati Computer Village, ni Ikeja lọ si olu ileeṣẹ awọn ọlọpaa to wa ni Ikeja, lati fi ẹhonu wọn han lori bi awọn ikọ ọlọpaa kogberegbe ṣe n paniyan bo ṣe wu wọn ni Naijiria.
Ó l'óun ò ní dákẹ́ ariwo ẹ̀fúùfùlẹ̀lẹ̀ tútù nini.
Iṣẹ rọbọọti naa ni lati mu ki awọn eeyan tẹlẹ ofin konile-o-gbele ti ijọba ilẹ gbe kalẹ.
Bi a ṣe n tọju alaisan kọọkan yatọ si ara wọn, bẹẹ si ni iye owo ti a n na lori wọn yatọ si ara wọn.
Nilẹ adulawọ, eewọ ni ki ọkunrin gbe ọmọ pọn sẹyin, nitori isẹ awọn obinrin ni ọmọ pipọn jẹ.
Kí o pa àṣìṣe rẹ̀ rẹ́
Lẹyin gbogbo wahala to ṣẹlẹ lọjọ Aje, gomina ipinlẹ naa, Godwin Obaseki kede ofin konile o gbele ọlọjọ yipo eleyi to tumọ si pe ko si si ijade lọ si ibikibi ti kan awọn ileewe.
Lẹyin naa ni Femi Gbajabiamiala to jẹ Abẹnugan ile aṣofin kekere fun Godswill Akpabio ni gbendeke ọjọ meji lati darukọ awọn Aṣofin ti NDDC gbe iṣẹ akanṣe fun.
Man City fìbínú gbẹ̀san lára Tottenham Omotola Jalade ní Nàìjíríà dàbí ọ̀run àpáàdì lábẹ́ ìjọba Buhari Àwọn wò ló ṣekú pá èèyàn 207 nílé ìjọsìn lọ́jọ́ Àjínde?
Ẹnu ya Farisi náà nígbà tí ó rí i pé Jesu kò kọ́kọ́ wẹwọ́ kí ó tó bẹ̀rẹ̀ sí jẹun.
 “Okan lara egbe awon olojo ori kan, iyen ‘Egbe Bobagbeye’, fun apere, ti ko ile iwosan igbebi ati ti itoju oju eyi ti a ko nip e si bayii.
Oro idupe yii ni Onimo ero Seyi Makinde so lasiko ti o n
Ọdun 2020 yii ni ajakalẹ arun Cornavirus tan kalẹ kaakiri agbaye, ti ko si mọ olowo tabi talika, amọ o wọle were, o si mu awọn eniyan to gbajumọ lọ kaakiri agbaye, to fi mọ Abiola Ajimobi.
Absalomu ọmọ Dafidi ní arabinrin kan tí ó jẹ́ arẹwà, orúkọ rẹ̀ ń jẹ́ Tamari.
’’“orisirisi igbese ni ijoba orile ede Ghana ti gbe lati yanju wahala to be sile ni orile ede naa lati ri i pe gbogbo awon omo orile ede ECOWAS to je onisowo lorile ede Ghana lowo ninu eto oro aje orile ede naa.
Gabola ti wọn fi sọri ile ijọsin naa tunmọ si ọti mimu ni ede SeTswana.
Lẹsẹkẹsẹ tí Baaṣa gorí oyè ni ó bẹ̀rẹ̀ sí pa gbogbo ìdílé Jeroboamu.
Bakan naa ni wọn kilo fun awọn janduku lati ti ọwọ ọmọ wọn bọ aṣọ, nitori awọn ko ni gba ki ẹnikẹni da rogbodiyan silẹ nipinlẹ naa.
Owó oúnjẹ ni mo lọ ọ gbà, oyún ọmọ tí mo jù sí àkìtàn ni mó gbé wálé- Dupe, ìyá Muiz Ènìyàn 156 míràn ló tún kó Coronavirus ní Nàìjíríà ní ọjọ́ Ẹtì Olórin Kano tí wọ́n dájọ́ ikú fún pe ẹjọ́ kòtẹ́milọ́rùn Nàìjíríà làwọn ní ìfẹ́ sí ìpèsè abẹ́rẹ́ àjẹsára Covid-19 tí Russia ṣe Wo ọ̀nà ìsanwó tuntun fún àwọn oníbárà iná mọ̀nàmọ́ná ní Eko (EKDC) Àwọn dókítà yóò bẹ̀rẹ̀ ìyanṣẹ́lódí lọ́jọ́ Ajé Iyawo Ajibade Babalade ati ọmọ rẹ mẹta ti wọn n gbe lorilẹ-ede Amerika lo gbẹyin rẹ.
Wo ìdí tí àwọn obìnrin kan fi n yọ ilé ọmọ wọn kúrò Kí ló mú ọmọ Nàìjíríà mẹ́sàn án forí la ikú nínú ìkọlù Libya?
ng Àkọlé àwòrán, Ni ọsẹ to kọja ni ẹgbẹ CONUA de'lẹ lẹyin ti awọn olukọni fasiti ọhun kan ti ni awọn o faramọ bi nkan se n lọ laarin ẹgbẹ ASUU Bi igun-igun kan an kan laarin awọn olukọ fasiti naa se faramọ ọkọọkan awọn to n du ipo ọhun nigba naa, lo fa iyapa to way laarin ẹgbẹ olukọni fasiti, ASUU nibẹ.
Ọlọrun fà mí lé eniyan burúkú lọ́wọ́,ó mú kí n ṣubú sí ọwọ́ àwọn ìkà.
End SARS protest: Nítorí \Access Bank\"" gbẹ́sèlé owó àwon olùwọ́de EndSARS ni a ṣe kó owó wa kúrò níbẹ̀"
Bakan naa ni afunrasi naa tun ṣalaye fawọn akọroyin pe ko din ni obinrin arugbo mẹta ti oun ti fipa ba lopọ ladugbo naa.
Tiamiyu Kazeem ni ọkọ oju popo pa lẹyin ti awọn ọlọpaa SARS ti i jabọ kuro ninu ọkọ wọn ni ọna Abeokuta-Sagamu ni ọjọ Satide.
billion dollars) lati odun  2019 si odun 2022
Nitori pe o ṣe akiyesi yi, pupọ awọn to wa nibẹ ni wọn ribi sa jade, ti iku si re ori wọn kọja.
Ọpọ orilẹ-ede nilẹ Adulawọ di dandan ki wọn si ibi iṣẹ okowo pada lẹyin ti iye nọmba naa n pọ sii.
Ubong Ekpo lero tiẹ ni se ko seese ki wọn pari awọn akanse isẹ naa ki Buhari to wa si Eko ni, paapa opopona to lọ si papakọ ofurufu to wa ni Oshodi.
Toyin Abraham Ilumọka oṣere ni Toyin Abraham.
Amọ, Lucas Torreira dayo naa pada nigba ti ifẹsẹwọnsẹ naa di iṣẹju mókandinlogun.
Oríṣun àwòrán, @Bashir Ahmad Bakannaa ni yoo ni lati wa wọrọko fi sada lori ohun ti awọn ẹgbẹ alatako n sọ paapa julọ nipa bi ileeṣẹ ọlọpaa labẹ ẹni to fi ipo naa silẹ, Ibrahim Idris ti ṣe n dun kukulaja mọ awọn ''Mi o ni dẹyẹ si ẹnikankan ma si ri wipe a tẹle ohun ti ọfin ba sọ'' ni ohun ti Adamu fẹsi nipa iṣedeede laarin gbogbo ẹgb oṣelu.
Ó wá wí fún wọn pé, “Nítorí èyí ni ẹ ṣe ń bá ara yín jiyàn, nítorí mo sọ pé, ‘Laìpẹ́ ẹ kò ní rí mi mọ́,’ ati pé, ‘Lẹ́yìn náà, láìpẹ́ ẹ óo tún rí mi?
 Ó gba oyè ẹ ̀ kọ ́ -kejì nínú iṣẹ ́ ìròyìn ní ilé-ẹ ̀ kọ ́ àgbà ti new york university , nígbà tí ó ti kọ ́ kọ ́ gba oyè ìmọ ̀ àkọ ́ kọ ́ nínú ìmọ ̀ lítíréṣọ ̀ gẹ ̀ ẹ ́ sì ( english literature ) nílé ẹ ̀ kọ ́ àgbà university of virginia .
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Èré Ọṣun: Àtáója ní wọn kò jí ère Ọṣun, ó sì wà níbi tó wà Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Èré Ọṣun: Àtáója ní wọn kò jí ère Ọṣun, ó sì wà níbi tó wà 25 Ẹrẹ̀nà 2019 Awuyewuye ti gbode lori ibiti ere Ọsun Osogbo wa, eyi to ti di fanfa laarin awọn Ọlọṣun, oloye ati Ataoja tilu Osogbo, idi ree ti BBC Yoruba fi gba ilu Osogbo lọ lati wadi hulẹhulẹ ọrọ naa.
Lẹ́yìn ọjọ́ kẹta, gbogbo àwọn olórí wọn lọ káàkiri àgọ́ náà.
Mo wá rí angẹli kan tí ó ti ọ̀run sọ̀kalẹ̀ wá, ó mú kọ́kọ́rọ́ kànga tí ó jìn pupọ náà lọ́wọ́ ati ẹ̀wọ̀n gígùn.
Nítorí náà, nígbà tí ẹ bá ta ilẹ̀ fún aládùúgbò yín, tabi tí ẹ bá ń ra ilẹ̀ lọ́wọ́ rẹ̀, ẹ kò gbọdọ̀ ṣe àìdára sí ara yín.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ẹ̀bùn Adégborúwà: Àwọn ọmọ-onílẹ̀ lo n fi tipa gba ilẹ̀ 11 Èbibi 2018 Oríṣun àwòrán, Betty Abah/twitter Àkọlé àwòrán, Àwọn ará Makoko so pé ìyàlẹ́nu lọ je lati ri awon ọmọ onílẹ̀ loni pẹ̀lú àwọn ọlọ́pàá Ènìyàn márùn-ún ló pàdé ólọ́jọ́ wọn, nígbà tí àwọn ọmọ onílẹ̀ àti ọlọ́pàá ya wọ agbègbe Makoko.
Níbẹ̀ ni OLUWA ti ṣe ìlérí ibukun,àní, ìyè ainipẹkun.
Ojisẹ Ọlọrun naa lo n n jẹjọ ẹsun ifipabanilopọ ati ṣiṣe fayawọ ọmọniyan nile ẹjọ kan ni Port Elizabeth lọwọ.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Bùhárí sọ ìdí tó fi ń díje lẹ́ẹ̀kejì ‘Buhari ti wọnu ẹmi lọ’ Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Oríṣun àwòrán, Olumide Akande Àgbà Oyè Ilẹ̀ Ibadan, Harry Akande ti jáde láyé Harry Akande ti o jẹ gbajugbaja Olokoowo ati Agba Oye ilẹ Ibadan ti di oloogbe.
Adéláyò ò fojú boorun páàpáà lórí ìrònú ohun kan soso tí ó le yàn nínú ògòòrò dúkìá tí baba rè fi sílè.
Ko ti daju boya wọn yoo ya ọjọ yi sọtọ lọjọ isinmi lẹnu iṣẹ ni Naijiria.
Ó dàbí ẹni pé àwọn Kerubu náà ní ọwọ́ bíi ti eniyan lábẹ́ ìyẹ́ wọn.
Ohun marun t'ejo n jẹ Ejò bu ìdí obìnrin kan jẹ nínú ilé ìgbọ̀nsẹ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Snake Market: Àwọn òńtàjà ẹran ejò ní ẹran ejò dùn ju ẹran adìẹ lọ Koda, o ti pada sori ibusun lati sun ko to o di pe oju ibẹ bẹrẹ si ni dun un gan, to si wú.
Buhari  to dije  fun ipo aare labẹ  egbe All Progressives Congress, gege bi ẹni to
Sunday Ayẹni, baba oloogbe sọ fun BBC Yoruba pé 'Ọjọ buruku eṣu gbomi mu ni ọjọ́ Ẹti to gbọ iroyin pe Damilọla aya ọmọ rẹ ti gun Olumide pa'.
Mathew Seiyefa ni Ọsinbajo yan lati ma de ile gẹgẹ bi ọga ile isẹ ọtẹlẹmuyẹ lorileede Naijiria.
Mo sì bi oluwa mi nígbà náà pé, ‘bí obinrin náà bá kọ̀ láti bá mi wá ńkọ́?
Ẹ wo ǹkan to sẹlẹ̀ sí ọmọ àti ìyàwó ọmọ Atikú tó lùgbàdì ààrun Coronavirus Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ẹ wo ǹkan to sẹlẹ̀ sí ọmọ àti ìyàwó ọmọ Atikú ti lùgbàdì ààrun Coronavirus Ìdúnú subú láyọ fún ẹbi àtikù nígbà ti èsì ayẹwò Coronavirus ìyáwó ọmọ Atiku àti ti àwọn ọmọ jáde ti wan ko si ni ààrun náà.
Ìwọ alágbára, kí ló dé tí o fi ń fọ́nnu,kí ló dé tí ò ń fọ́nnu tọ̀sán-tòru?
Wo ọ̀nà àbáyọ sí bo ṣe ń han‘run Ọ̀làjú sọ àṣà nù, wò ó báwọn obìnrin ṣe ń wà ọkọ kiri lórí ayélujára Nínú akànṣẹ́ mẹ́ta ọmọ Nàìjíríà tó dáńtọ́ lágbàáyé, Yorùbá méjì wà nínu wọn Minisita fun ọrọ iṣẹ ati igbanisiṣẹ, Chris Ngige to soju ijọba lo ka abajade ipade naa.
Emir Sanusi: Kò dára báwọn gómìnà, mínísítà kò se yọjú sípàdé ìdókòwò
Ishaq Oloyede: Jamb ko nii fi esi idanwo silẹ ni kiakia Lilo ede: Kini 'technology' ni ede Yoruba?
Wọ́n taná si ẹ́njìnì rẹ̀ ní ààgo mẹ́sàn kọjá ìṣẹ́ju mẹ́ẹ̀dógún, ó sì gbéra ni aago mẹ́sàn kọjá ogún ìṣẹ́jú.
“Ìwọ ọmọ eniyan, kọjú sí Jerusalẹmu kí o sọ àsọtẹ́lẹ̀ sí ibi mímọ́ Israẹli.
Oríṣun àwòrán, @Musk Eyi wa gẹgẹ bi atọna awọn ọlọrọ lagbaye, Bloomberg Billionaires index, ṣe gbe iwadii rẹ kalẹ lori awọn eeyan ẹẹdẹgbẹta to lowo julọ lagbaye.
Wọ́n bá mú Jeremaya, wọ́n jù ú sinu kànga Malikaya, ọmọ ọba, tí ó wà ní gbọ̀ngàn àwọn tí wọn ń ṣọ́ ààfin.
"Khadijah ṣalaye fawọn akọroyin BBC Bengali lẹyin igbesẹ rẹ yii pe: ""Ohun to difa fawọn ọkunrin lati ko ero wa dẹnu ifẹ kọ awa obinrin ki a le ṣe igbeyawo naa lo difa fawa obinrin lati ṣe nkan kan naa""."
Seyi Makinde, fún mi ní ₦156m lórí iṣẹ́ ọpọlọ mi to lò láì tọ́ - Agbaṣẹ́ṣe 'Èèwọ̀!
Sẹnetọ Shehu Sani naa sọ si ọrọ naa.
" Awọn iroyin ti ẹ lee nifẹẹ si: Tẹgbọn-taburo se igbeyawo ni Anambra Kano gbalejo igbeyawo ọmọ gomina Ọyọ Sugbọn Sẹkinat ni oun si nifẹ ọkọ oun, bẹẹ ni oun ko fẹ ki igbeyawo naa tuka.
Kara Bridge: Ó kéré tán, ọkọ̀ yóò lo wákàtí mẹ́ta kó tó bọ́ lójú ọ̀nà Kara tó dí pa
Àǹfàní n bẹ́ fun Naijiria nínú àdéhùn okòwò ní Afrika, AfCFTA ṣugbọ́n.
Aare wa tun seleri fun ijoba
Senator Elisha Abbo: Adájọ́ ní ọlọ́pàá kò fi ẹ̀rí tó dájú múlẹ̀ lórí ẹ̀ṣùn ìfìyàjẹni
Education Zaria) iwe abadofin idanimo fun ile ise National Security Agencies
Farao fi kún un pé, “Ṣé ẹ̀yin náà rí i pé àwọn eniyan yìí pọ̀ pupọ ju àwọn ọmọ-ìbílẹ̀ ilẹ̀ yìí lọ, ẹ sì tún kó wọn kúrò lẹ́nu iṣẹ́ wọn?
Ipe Fun Atileyin  Ogbeni Enang wa ro awon osise lapapo lati fun aare Buhari ni atileyin ti o peye saaju saa keji re ti o fe wonu re yii.
Ìbátan Saraki ní APC ló ni Kwara lọ́jọ́ Abamẹta tó m bọ̀ Ìjọba pàṣán ni ìjọba Buhari yóò jẹ́ fún Nàìjíríà ní sáà kejì- Ṣoworẹ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Buhari gbọ́dọ̀ yọ àwọn mínísítà tí kò wúlò ní sáà kejì yí-Ogundamisi Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Aare so fun awon ara ilu pe,”ole afajo ni awon okunrin to ba lu iyawo re, ni eyi tiru okunrin bee yoo foju wina ofin ijoba”.
Ojú wọn rẹ̀wẹ̀sì, nítorí kò sí koríko.
Sùúrù tí kò lópin ló ṣe pàtàkì, kìí ṣe pé ènìyàn yóò de ipò kan yóò sọ pé sùúrù ti pin."
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Diezani Madueke: Díẹ̀ lára ohun ìni Diezani tí ilé ẹjọ́ gbẹ́sẹ̀ lé 6 Agẹmo 2019 Oríṣun àwòrán, EFCC Àkọlé àwòrán, Diezani Allison Madueke Ile ẹjọ ti ni ki awọn ẹṣọ ara kan, ati ẹrọ ibaraẹnisọrọ iphone oni goolu kan to jẹ ti Minisita nigba kan ri fun ọrọ epo rọbi, Diezani Alison-Madueke di igbagbe.
Ninu atẹjade kan ti ileeṣẹ naa fi sita lori ẹrọ ayelujara rẹ, Ọga agba ileeṣẹ NNPC lẹka ibaṣepọ araalu, Ọgbẹni Ndu Ughamadu, sọ pe ileeṣẹ naa ni epo rọbi toto lo fun ọjọ mọkandinlogoji, ati pe epo rọbi to wa nilẹ lọwọlọwọ, yoo to lo fun ọjọ mẹẹdọgbọn.
Oniweeroyin ọhun ni, o da oun loju pe owo ti gomina gba ninu fidio naa jẹ ọkan lara awọn owo ti ko tọ, ti gomina maa n gba lọwọ oriṣiriṣi awọn kọngila to n ṣe awọn akansẹ iṣẹ ni ipinlẹ naa.
Mo wá gbọ́ nǹkankan tí ó dàbí ohùn láàrin àwọn ẹ̀dá alààyè mẹrin náà, ó ní, “Páànù ọkà bàbà kan fún owó fadaka kan.
Lẹyin igba diẹ wọn da awọn kan pada laaye ninu wọn ni oṣu kẹta ṣugbọn wọn ko tii da Leah Sharibu pada.
Ile Igbimọ Aṣofin Ipinlẹ Eko, Aṣofin
O din die legberun kan ojo saaju eto idibo odun 2020 ni Trump se ikede re yi ni eyi ti Obama kede oludari tire ni o din die logounrun mefa ojo saaju idibo 2012.
Bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé n kò lẹ́bi,sibẹsibẹ n kò lè dá a lóhùn.
Fatoyinbo ni, irọ pọnbele ni ẹsun Busola Dakolo, ati wipe yatọ si iṣẹ oun gẹgẹ bii pasitọ, oun ko ba arabinrin naa ni nkankan pọ ni ikọkọ.
’’Ogbeni Rassin wa gbosuba fun aare Buhari fun ise gudu gudu ,meje yaya mefa ti o n se lati dekun aarun romo lapa, romo lese lorile ede Naijiria.
Àwọn ọmọ Bẹnjamini rí i pé wọ́n ti ṣẹgun àwọn.
orile ede yii, Air Chief Marshal Alex Badeh (Rtd), ki won si
Ṣugbọn Rabuṣake dá wọn lóhùn pé, “Ṣé ẹ rò pé ẹ̀yin ati oluwa yín nìkan ni oluwa mi rán mi pé kí n jíṣẹ́ yìí fún ni?
Odò Naili yóo gbẹ kanlẹ̀,a óo rẹ ìgbéraga ilẹ̀ Asiria sílẹ̀,agbára óo sì kúrò lọ́wọ́ àwọn ará Ijipti.
Loni ọjọru, ọjọ kọkanlelogun, oṣu kẹjọ ọdun yii ni wọn yoo bura fun awọn minsita ti ile igbimọ aṣofina papọ ti ṣe ayẹwo fun.
Minisita to n mojuto oro asa ati iforotonileti, Alhaji Lai Mohammed lo so oro naa di mimo fun awon egbe alatako ti won n jabo oro eke naa kakaakiri.
3 53831 Orilẹede Ethiopia 2008 1.
Sugbọn nigba to di ọdun 1976, ile ẹjọ yii kan naa lo tun pada fi aaye gba àwọn ijọba ipinlẹ lati maa ṣe idajọ iku.
Àwọn ará Sifi kan lọ sọ́dọ̀ Saulu ní Gibea, wọ́n sọ fún un pé, “Dafidi sá pamọ́ sáàrin wa ní Horeṣi ní orí òkè Hakila tí ó wà ní ìhà gúsù Jeṣimoni.
Lẹsẹkẹsẹ bí Ahabu ti gbọ́ pé Naboti ti kú, ó lọ sí ibi ọgbà àjàrà náà, ó sì gbà á.
’’Lasiko ti an kọ iroyin yii lọwọ,ajọ to n mojuto
Oríṣun àwòrán, Instagram Bakan naa ni iroyin gbe e pe Obinanne Okeke, to jẹ ilumọọka onisowọ ti wọn mu fun ẹsun lilo ẹrọ ayelujara lati ṣe magomago, ti jẹwọ pe lootọ ni oun jẹbi ẹsun naa.
Bẹ́ẹ̀ náà ni mo búra nisinsinyii,pé n kò ní bínú sí ọ mọ́,pé n kò ní bá ọ wí mọ́.
Àwọn onímọ̀ Islam àti Oluwo takora lórí oyè Wàzírì Ani sẹ, Ọọni ran alaabo rẹ simi - Oluwo Oba náà si sọ pe ọmọ Yoùbá l'oun jà fún.
Ẹni mímọ́ wo ni o lè tọ̀ lọ?
Ọlọrun fún àwọn ọdọmọkunrin mẹrẹẹrin yìí ní ọgbọ́n, ìmọ̀, ati òye; Daniẹli sì ní ìmọ̀ láti túmọ̀ ìran ati àlá.
Láti ara orúkọ rẹ̀ Oluwaṣeyi Lawrence ni mọ̀lúmọ̀ọ́ká apanilẹ́rìín kan nígbà náà lọ́hùún, Jẹdi gbà á nímọ̀ràn kó lo orúkọ tó ṣeé tajà.
Arakunrin Nkeki ni awọn obi mẹrinlelọgbọn lo ti papoda lati igba ti ikọ Boko Haram ti ji awọn ọmọ wọn gbe si isinyii.
Nísisì yìí, ó ti kú, ó wá sí ọ̀dọ̀ mi, o ń wa kí òun tilẹ̀ bá ẹnìkan sọ gbólóhùn ọ̀rọ̀ kan ṣùgbọ́n kò rí, o di ẹ̀ẹ́dẹ́gbẹ̀ta ọdún tí o ti dé ibi tí ó wà yìí láì sọ̀rọ̀ sí ẹnikẹ́ni.
Labẹ ofin ẹni to ba bu aarẹ le lọ si ẹwọn ọdun mẹta tabi ko san owo itanran miliọnu meje Naira.
Ó wá wí fún wọn pé, “Lílò eniyan ni a dá Ọjọ́ Ìsinmi fún, a kò dá eniyan fún Ọjọ́ Ìsinmi.
“Àwọn ọ̀gágun yóo tún bá àwọn eniyan náà sọ̀rọ̀ pé, ‘Ǹjẹ́ ọkunrin kan wà ninu yín tí ẹ̀rù ń bà, tabi tí àyà rẹ̀ ń já?
”Gbogbo àwọn eniyan náà kígbe sókè pé, “Kí ọba kí ó pẹ́.
BBC 100 Women 2019: Wo ọmọ Nàíjíríà kan tó wà nínú wọn Ọpọ gbagbọ pe nitori pe Naijiria kii mura silẹ de ọjọ ogun lo n ṣokunfa wahala to n ṣẹlẹ yii Akẹ́kọ̀ọ́ Ilaro Poly tó pegedé jù jẹ ẹ̀bùn iṣẹ́ ọ̀fẹ́ lọ́wọ́ Gómìnà Abiodun World Food Day: Wo àwọn oúnjẹ ìṣẹ̀mbáyé Yorùbá tó ti ń di àpatì Ààrẹ Buhari wọ́gilé kí àwọn òṣìṣẹ́ ìjọba máa wọ ọkọ̀ bàálù olówó gọbọi Ìná ẹgbẹ́ òṣìṣẹ́ NLC ati ìjọba kò wọ̀ níbi ìpadé Ọkọ̀ agbépo tó gba iná ṣe àkóbá ní ọjà Onitsha Bi eeyan ba jẹ ori ahun lọjọ to ti pẹ; to ba kọkọ de ibi ijamba ina to waye nilu Onitsha, o di dandan ko kawọ le ori.
Gbogbo ọ̀rọ̀ ati èrò àwọn ọ̀tá mi sí mi:ibi ni lojoojumọ.
asofin  mejeeji to wa niluu Abuja,paa paa
Owoseni ninu ọrọ rẹ ni omi n bẹ lamu fun ilẹ Yoruba lori eto aabo nitori ofin ilẹ wa lo laa kalẹ pe ọmọ orilẹede yii kọọkan le yan lati gbe nibikibi to ba wu amọ kii se bi ti ọdaran.
Ṣebí ara kan náà ni wá?
Níbẹ̀ ni a lérò pé Paulu yóo ti wá bá wa tí òun náà yóo sì wọkọ̀.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Presidency: Akinkanju ológun ni Buhari, kìí ṣùn lójú ogun 23 Ìgbé 2019 Oríṣun àwòrán, Google Àkọlé àwòrán, Bishop ìpínlẹ Yola, Rev.
Kò sí ọmọ ogun kan tí ó ní apata tí yóo wá sí ẹ̀bá ìlú náà, bẹ́ẹ̀ ni kò ní lè gbìyànjú láti gbógun tì í.
Naira Marley: Àwọn agbẹjọ́rò ń jà sí àga ìjókòó níbi ìgbẹ́jọ́ Naira Marley
“Ní ọjọ́ náà, n óo jẹ́ kí àwọn ará Juda dàbí ìkòkò iná tí ń jó ninu igbó, àní, bí iná tí ń jó láàrin oko ọkà, wọn yóo jó gbogbo àwọn orílẹ̀-èdè káàkiri, ṣugbọn Jerusalẹmu yóo wà láàyè rẹ̀ pẹlu gbogbo àwọn tí ń gbé inú rẹ̀.
Ẹ óo máa fọn àwọn fèrè náà ní ọjọ́ ayọ̀, ní àwọn ọjọ́ àjọ̀dún yín ati ní ọjọ́ kinni oṣù.
Òun ni ó mú kí gbogbo ẹ̀yà ara wà ní ìṣọ̀kan, tí gbogbo oríkèé-ríkèé ara wa sì wà ní ipò wọn, pẹlu iṣan tí ó mú wọn dúró, tí gbogbo wọn sì ń ṣiṣẹ́ gẹ́gẹ́ bí ipò olukuluku wọn, tí gbogbo ẹ̀yà ara kọ̀ọ̀kan fi ń dàgbà, tí ó ń mú kí gbogbo ara rẹ̀ dàgbà ninu ìfẹ́.
Nígbà tí ọba gbọ́ ọ̀rọ̀ inú ìwé náà, ó fa aṣọ rẹ̀ ya láti fi ìbànújẹ́ rẹ̀ hàn.
Ori ko ni oun yoo ba ọrun duro ni akoko ti Bukọla lo gẹgẹ bii aarẹ ile asofin agba, ọpọ ete, iditẹ-mọni, oniruuru ẹsun, atako ati igbẹjọ si lo la kọja.
Nítorí náà ni OLUWA fi rán kinniun sí i, pé kí ó pa á, gẹ́gẹ́ bí OLUWA ti kìlọ̀ fún un tẹ́lẹ̀.
Ebenezer Obey ń wá ìyàwó , wo àmúyẹ tí o gbọdọ̀ ní tí o bá fẹ́ ẹ́ di aya lọ́ọ̀dẹ̀ baba Eruku 1-1 ni Chelsea àti Arsenal kù sí ara wọn l'ójú ní abala àkọ́kọ́ àṣekágbá ìdíje FA Wo àwọn nǹkan tí o kò mọ̀ nípa 'Church of Satan' Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Mummy calm down: Ìyá Ore sọ pé gbogbo ìgbà tí óun bá n bá a wí ló ma n ṣe àwàdà Amọ o, gbogbo awọn ti ijọba ti fun ni anfaani lati bẹrẹ iṣẹ wọn pada gbọdọ ma a tẹle awọn ilana bi i titakete siraẹni, lilo ibomu, ati ọwọ fifọ.
Awọn osere bii Iyabo Ojo, Biodun Okeowo ati bẹẹ lọ ni wọn ti jọ kopa ninu ere.
Bàbá Adamu tó jẹ́ ọmọ ogun Nàìjíríà tó dàgbà jùlọ jáláìsí Lagos-Ibadan Express: Ènìyàn mẹ́rin ti kú nínú ìjàmbá ọkọ̀ Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Alhaja Kudirat Abiola di ajafẹtọmọniyan nigba ti ijọba Naijiria bẹrẹ sii doju le e.
Agba Inaki maa n fi owe, ewi, ẹdọki ede ati awada se agbekalẹ awọn ọrọ rẹ, eyi to fi n se iwuri fun awọn ọdọ iwoyi ati gbogbo ọmọ Yoruba lapapọ lati mase gbagbe asa abinibi wa.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, May 29: Akala, Aleshinloye sọ̀rọ̀ lórí ọdún kan Seyi Makinde gẹ́gẹ́bíi gómìnà bayii, eniyan 2697 lo ti ri iwosan gba lọwọ arun Coronavirus, ti eniyan 261 si ti ku nitori arun naa.
Eyi di mimọ nibi ìpade igbimọ alaṣe to waye lána, nílé ìjọba nílù Abuja Lásìkò tí BBC bá àwọn tọ́rọ̀kàn lórí ọ̀rọ́ náà láti fi ìdí abájọ múlẹ lórí ìdí ti ìgbésẹ̀ yìí fi wáyé nírú àsìkò yìí.
6 Kíyèsíi, èyí jẹ́ àṣẹ mi, àti àṣẹ ti àwọn ìránṣẹ mi, àti ọ̀rọ̀ ìṣaájú mi sí ìwé àwọn òfin mi, èyí tí mo fi fún wọn lati tẹ̀ fún yin, Áà ẹ̀yin olùgbé ilẹ̀ ayé.
Ni nkan bi aago mejila kọja ogun iṣẹju l'oru ọjọ Aiku, ogunjọ, oṣu Kẹfa ni iṣẹlẹ naa waye.
Ile igbimọ aṣofin agba ni tiwọn to tẹnu mọ ọ́ pe ọrọ̀ aje orilẹede Naijiria ti wa di akurẹtẹ gbaa to bẹẹ to fi jẹ wipe awọn Boko Haram ti n gbe nkan di ọna lawọn apa ibi kọọkan ni Borno.
Hugo Weaving: Oríṣun àwòrán, EPA Àkọlé àwòrán, Bawo loyinbo ṣe jẹ ọmọ Yoruba?
Nibi ipade naa to waye, gẹgẹ bi a ti ṣe riika ni Ilu Ibadan,awọn agbagba ẹgbẹ naa fi ontẹ jan Dansaaki Agbede gẹgẹ bi Aarẹ ẹgbẹ naa.
Kí ó fihàn nípa ìgbé-ayé rere ati ìwà ìrẹ̀lẹ̀ tí ó fi ọgbọ́n hàn.
Oríṣun àwòrán, Reuters Àkọlé àwòrán, Aare Buhari yoo sepade fun pelu won loni Oríṣun àwòrán, Isaac Linus Abrak Àkọlé àwòrán, Ekun gba'gboro ka lori oro awon omobinrin Dapchi Ti ijọba apapọ si sọ pe oun ko san owo kankan fun igbasilẹ wọn.
kanu gba eso uefa champions league kan , eso ife-eye uefa kan , eso abori ife-eye fa meta ati ebun ara afrika agbaboolu-elese ododun meji .
Glucose to wa ninu ounjẹ ni ipa to n ko ki ọpọlọ wa le ṣiṣẹ bo ti ṣe yẹ.
a bí ní ìlú zaria ni ìpínlẹ ̀ ( kaduna ) bí o tiḷẹ ̀ jẹ ́ pé ( Èsà-òkè ) lébàá iléṣà ni ìlú rẹ ̀ .
Àwọn Juu bá pagbo yí i ká, wọ́n sọ fún un pé, “Nígbà wo ni ìwọ yóo tó fi ọkàn wa balẹ̀?
"Awọn ọmọbinrin mẹta yii la gbogbo wahala ati isoro to wa ni ọna wọn kọja lati kopa ninu idije kẹkẹ ori yinyin ti wọn npe ni ""Bobsledding"" eleyi ti yoo maa jẹ akọkọ iru rẹ ni orilẹde yoowu nilẹ Afirika yoo maa kopa nibi idije Olimpiiki oniyinyin."
Ninu omi wọn ni gbogbo ẹranko tí ń mu,ibẹ̀ sì ni àwọn kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ igbó tí ń rẹ òùngbẹ.
Lórí tabili yìí ni burẹdi máa ń wà, níwájú Oluwa nígbà gbogbo.
Nigeria (2018)Iyalẹnu lo jẹ fun ọpọ eniyan nigba ti ẹgbẹ́ agbabọọlu orilẹ-ede Naijiria kede jẹsi tuntun fun idije ife agbaye lọdun 2018.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Jiti Ogunye: Ọ̀jẹ̀lú ni àwọn tó ń fi APC sílẹ̀ fún PDP 26 Agẹmo 2018 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 27 Agẹmo 2018 Oríṣun àwòrán, APC Àkọlé àwòrán, Ajafẹtọ ọmọniyan, Jiti Ogunye ni ọna abayọ si eto oselu Naijiria ni ki awọn eniyan yan ẹgbẹ oselu tuntun.
iselu ni botswana unwaye labe eto orile-ede olominira oloselu asoju , nibi ti Ààrẹ ilẹ ̀ bòtswánà ti je olori orile-ede ati olori ijoba , ati labe sistemu egbe oloselu pupo .
Nebukadinesari, ọba Babiloni fi Sedekaya, ọmọ Josaya, jọba ní ilẹ̀ Juda dípò Jehoiakini, ọmọ Jehoiakimu.
  Arúgbó náà fẹ́ràn láti máà bá àwọn onírìnàjò rojọ́ púpọ̀ nítorípé òun nìkan ni ó wà ni ilé yìí tí ó dádúró tí ó sì jìnà sí abúlé adúgbò ibẹ̀.
Ọpọlọpọ eniyan yóo dúpẹ́ lọ́wọ́ Ọlọrun nígbà tí a bá fún wọn ní ẹ̀bùn tí ẹ gbé kalẹ̀ nítorí ìlawọ́ yín.
Tí a fiṣọwọ́ ní 4:574:57 Opral Benson, ẹni ti oge ṣíṣe sọ di gbajúmọ̀ àti Yeye Oge ìlú Eko ''Lakọkọ, imura rẹ ati bi o ṣe gboge lo jẹ ko di ẹni ti gbogbo eeyan fẹran, ati ọkunrin ati obinrin lo nifẹ rẹ,''Kà Síwájú Síi next Article share tools Facebook Twitter ṢàpínlòView more share options Share this post Copy this linkKà síwájú síi nípa àwọn ìtọ́kasí wọ̀nyí.
nítorí pé, nígbà tí ẹ̀ ń bọ̀ láti ilẹ̀ Ijipti, wọn kò gbé oúnjẹ ati omi pàdé yín.
N óo mú wọn dojú kọ ọ́ ní gbogbo ọ̀nà: 
Rose Odika: Oríṣun àwòrán, Rose Odika Agba ọjẹ pọnbele ni Rose Odika, to si ti di igi araba ninu sinima lede Yoruba bi o tilẹ jẹ pe ẹya miran lo ti wa.
Awọn akọṣẹmọṣẹ nipa onka awọn eeyan ilu fidirẹ mulẹ wi pe ilu Igbo Ọra lo ni onka awọn ibeji to pọ julọ l'agbaye, pẹlu alaye wipe okere tan, ibeji mejidinlọgọjọ lo ma a n wa ninu awọn ọmọ ẹgbẹrun kan ti wọn ba bi nilu Igbo-Ọra.
1 432327 Orilẹede Sweden 7354 73.
A fún wọn ní agbára bíi ti àkeekèé ayé.
"Orilẹede Amerika ko ni dẹkun lati ma a ṣe onwoye bi eto idibo ṣe n lọ lorilẹede Naijiria lọna ati ma a gba wọn ni imọran loore-koorẹ.
Toyin salaye ninu ọrọ rẹ naa pe awọn iṣẹlẹ ẹnu ọjọ mẹta yii n jẹ ki oun ronu jinlẹ, ki oun si fi oju ọtọ wo ohun ti wọn n pe ni aye taa wa yii.
Àkọlé àwòrán, BBC Fake News Conference Awọn akópa jẹ́ kó di mímọ̀ pé awọn iroyin ayederu ti n gbayi gaan laarin awujọ yala ọ̀rọ̀ ti wọn kọ, fọto tabi fidio bẹẹ si ni awọn mọ Naijiria gan ti ṣe tan lati gba a.
SERAP: Àwọn olósèlu ń fojú ará ìlú gbolẹ̀ pẹlu owó tí wọ́n bù fún ara wọn
Awọn eeyan to jẹ awọn alatilẹyin Bukola Saraki tu itọ soke foju gba a lori bi ijọba ipinlẹ Kwara ṣe wo ile Arugbo lulẹ laarọ Ọjọbọ niluu Ilorin.
Atiku kọ oniruuru ọrọ ati ero ọkan rẹ silẹ leyi ti awọn ọmọ Naijiria naa si gbọn ọn yẹbẹ lati sọ idi ti wọn fi ni ọrọ rẹ mu ọpọlọ dani fawọn tabi ta ko ohun to sọ.
Ṣugbọn bí o kò bá rí mi, o kò ní rí i gbà.
O ni asiko ti to fun gbogbo ọmọm ẹgbẹ APC lati fi iwa imọtara ẹni nikan silẹ, ki wọn si maa lepa ilọsiwaju ẹgbẹ naa.
Olówó kan ò lè dún kowéè lé ọ lérí mọ́
Awon ti won jo je sawawu nile Adulawo ni Miriam Makeba ile South Africa, Bi Kidude ti Tanzania ati awon miran.
Ilé alájà mẹ́ta tí wọn ń kọ́ lọ́wọ́ dàwó l'Eko, èèyàn kan há sínú rẹ̀ Oríṣun àwòrán, LASEMA Ile alaja mẹta ti wọn n kọ lọwọ lopopona Alasepe, ladugbo Agọ Ọkọta nilu Eko ti da wo lulẹ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Jimi Agbaje: èmi kò faramó owó ẹnubodè Toll Gate Eko rárá Sẹnetọ Gbemisola Saraki ti fi igba kan jẹ́ aṣoju ẹkun Asa/Ilorin ni ọdun 1999 ko to lọ ṣe senetọ lọdun 2003 si 2011.
Joṣua bá bi í pé, “Kí ló dé tí o fi kó wa sinu gbogbo ìyọnu yìí?
Òwò ẹrú pé irinwó ọdún tó bẹ̀rẹ̀, àwọn Amẹrika tó jẹ́ dúdú wá sí Afirika láti bẹ ilé wò Àwa ọmọ ẹgbẹ́ Shiite kò tíì sinmi ìwọ́de, a ṣì ń tẹ̀síwájú - Ọmọ El-Zakzaky Jesu orí ayélujára kan rèé tó wa fun isoji ni Afirika Ṣùgbọ́n ó sọ pé tití tó fi jáde kuro ninu ẹgbẹ́ náà, òun kò fi ojú kan ọ̀gá kan nínú ẹgbẹ́ náà rí, tí kìí bá ṣe àwọn kan tí wọn yóò gbé ìbọn ńlá-ńlá ní àwọn ìgbà kọ̀kan.
Wọ́n bá fi kinní kan bíi kànìnkànìn bọ inú ọtí náà, wọ́n fi sórí ọ̀pá gígùn kan, wọ́n nà án sí i lẹ́nu.
Láti Dani títí dé Beeriṣeba, gbogbo àwọn tí ó kú jẹ́ ọ̀kẹ́ mẹta ati ẹgbaarun (70,000).
Lẹ́yìn náà, àwọn ọmọ alufaa wọnyi: Seraya, Asaraya, ati Jeremaya, 
Judasi Iskariotu, ọ̀kan ninu àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀, ẹni tí yóo fi í lé àwọn ọ̀tá lọ́wọ́, sọ pé, 
Olukuluku wọn ṣe oriṣa tirẹ̀ sí ibi tí ó ń gbé.
O mẹnuba pataki titẹ̀lé àṣẹ́ ẹgbẹ́ boya o tẹ eeyan lọrun tabi bẹẹkọ nitori pe ifẹ ẹgbẹ lo ṣe pataki julọ.
Mo fẹ́ràn ìyá mi gan-an ni, Kò sì sí Wòlíì Arole lai si ọwọ màmá mi nibẹ.
1 Ìgbé 2020 Nollywood ń mú kí òògùn owó àti ìjínigbé gbilẹ̀ síi- Fashola9 Èrèlè 2020 Nollywood: Àwọn ǹkan pàtàkì tó yẹ kí o mọ̀ nípa Clarion Chukwura5 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
wọ́n kọ́kọ́ fà á lọ sí ọ̀dọ̀ Anasi tíí ṣe baba iyawo Kayafa, tí ó jẹ́ Olórí Alufaa ní ọdún náà.
Àwọn ọmọ Kalebu, arakunrin Jerameeli, nìwọ̀nyí: Mareṣa, baba Sifi ni àkọ́bí rẹ̀.
Láti ìgbà tí wọ́n ti bí i ni ó ti yarọ, kò fi ẹsẹ̀ rẹ̀ rìn rí.
Serena Williams: Wang tún da àlá Ife ẹ̀yẹ kẹrìnlélógùn fún Serena Williams rú
Chelsea fẹ́ Ajax dànú bí abẹ̀bẹ̀ nílé wọ̀n À ń gbé ìjọba ìpínlẹ̀ Ọyọ lọ si ilé ẹjọ- Ẹgbẹ́ Fulani darandaran Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Òwe: Kí ni ìtumọ̀ òwe ikú tó ń pa ojúgbà ẹni?
Bẹ́ẹ̀ ni mo ṣe bọ́ lẹ́nu kinniun.
Bí ó bá dàbí ẹni pé orí wa kò pé, nítorí ti Ọlọrun ni.
Amọṣa, Danny Ings ti oun pẹlu naa ti gba bọọlu ri fun ikọ Liverpool da ẹyọkan pada nigba ti ifẹsẹwọnsẹ naa de iṣẹju kẹtalelọgọrin.
Àmọ́ o, bí ó ti ntutù níbìkan ní í gbóná ní ibòmíràn.
Ojú àwọn tọ́wọ́ ti tẹ̀ lára àwọn tó jí 'tíá rọ̀bà ọ̀kadà', fíriìjì, ẹ̀rọ ata kó nílée Sẹ́nétọ̀ Teslim Folarin rèé Ohun tí gómìnà Seyi Makinde fẹ́ ṣe lórí ìwọ́dé EndSARS lẹ́yìn ìpàdé rẹ̀ pẹ̀ láwọn tọ́rọ̀ọ kàn Ẹni tó jí ọ̀pá aṣẹ ń bọ̀ wá túbá fúnrarẹ̀, mo fi dáa yín lójú gẹ́gẹ́ bí ìyá - Erelu Kuti Àwọn ọ̀dọ́ ya bo ààfin Akire láti jí oríadé gbé Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Láàrín ìṣẹ́jú díẹ̀, ẹ ka ìwé Akinwumi Ishola, Nítorí Owó"" lórí Akomolede Yoruba Kọmiṣọna ọlọpaa ni ipinlẹ Cross River, Abdulkadir Jimoh sọ pe ọpọ ninu ẹru ti awọn eeyan ji ko ni wọn ti ri pada."
èmi OLUWA àwọn ọmọ ogun ní kí ẹ pada wá sọ́dọ̀ mi, èmi náà yóo sì pada sọ́dọ̀ yín.
Àwọn ọmọ Nàìjíríà bu ẹnu ẹ̀tẹ́ lu NTA lórí ìgbóhùnsáfẹ́fẹ́ ìdíje bọ́ọ̀lù Ilé ẹjọ́ ni agbábọ́ọ̀lù ọmọ Nàìjíríà, Dickson Etuhu jẹ́bi ẹ̀sùn títa ìdíje Sweden Èèyàn mẹ́tàlá dèrò ọ̀run nínú ìjàmbá ọkọ̀ lópòpónà Ìbàdàn s'ÈKó Zlatan: Èyí mo ṣé tó, àsìkò tó láti tèsíwájú nínú ìrìnàjò mi Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Ninalowo Bolanle ati Olaitan Sugar jọ kọwọrin wa ni ọjọ kan naa ni: Oríṣun àwòrán, Instagram Àkọlé àwòrán, Ọjọ Keje, Osu Karun un, ọdun 1980 ni wn bi gbajugbaja oṣere Bolanle Ninalowo ti wọn bi ni agbeegbe Ikorodu ni ilu Eko si idile Alhaji Jamiu Ninalowo ati Alhaja Ninalowo Oríṣun àwòrán, Instagram Àkọlé àwòrán, Obinrin oṣere arẹwa, Olaitan Sugar ni wọn bi ọjọ keje, osu karun un, ni o wa lati Ile Ifẹ.
Wọ́n ṣebí ó wà láàrin ọ̀pọ̀ eniyan tí ń kọ́wọ̀ọ́ rìn ni.
Oríṣun àwòrán, Tope alabi Lórí igbele àrùn Coronavirus, Tope ni ori ayélujára ni òun ti ń ṣe ipagọ ìyìn, tí òun sì tún rí ààyè fi ara balẹ gba àdúrà sì Ọlọ́run, ti oun si tún ráyè sinmi, bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé asiko yii ko mú owó wá.
Láti ìbẹ̀rẹ̀ ni èmi tíí sọ ohun tí ó gbẹ̀yìn.
Nínú ọ̀rọ̀ tirẹ̀, Atiku ni Agbara àwọn bàbá ìṣàlẹ̀ ti dópin lórílẹ̀-èdè Nàìjíríà pẹ̀lú irú ìṣẹ̀lẹ̀ tó wáye ni ìpińlẹ̀ Edo lónìí àti pé agbára kan ti yóò dúró náà ni àgbàra àwọn oludibo.
Ajọ ìsọkan àgbáyé ní ó ṣe pàtàki láti ràn wọn lọ́wọ́ ki wọn si jẹ ki wọn maa kópa ninu nkan awujọ ki wọn le ṣe àṣeyori nínú òhun ti wọn ba dáwọlé.
Ẹni ogoji ọdun ni Ibidunnu i ṣe nigba ti ọlọjọ de.
Mínísítà feto ìrìnà, ọ̀gbẹ́ni Rotimi Amaechi, ló pàsẹ bẹ́ẹ̀ ni lásìkò tó ń sàbẹ̀wò si iṣẹ́ ojú irin tó ń lọ lati ilu Eko si Ibadan, ni adugbo Ologuneru ni ìlú Ibadan.
 lara ohun  màrúndínlógún  ti won n  beere fun, a ti se mẹ́rìnlá nibe, A si ti n se ise lori okan to ku”.
Ọrọ yi nkan awọn ara ilu lominu ni ikọ BBC ba lọ fi ọrọ wa awọn ti o n ṣe iforukọsilẹ kaadi wọn yi lẹnu wo.
Sugbọn o jẹ oun to n pani lẹrin.
O yẹ ki gbogbo wa sa ipa wa lati ran ilu wa lọwọ, ka si dide lati ja fun alaafia rẹ nibikibi.
Ìjọba ìbílẹ Owo Lọ́wọ́lọ́wọ́ báyìí, ìjọba ìbílẹ̀ Owo ló ni Gómìnà tó wà lórí àléfà nínú ọdún 2020.
Doka ati Mutu, ti won si wa ni ihamọ bayii.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Alhaji Smith ni ai kii ṣe ere idaraya deede lo faa ti awọn ọlọpaa fi n yọkun ayọju Ni aye atijọ gẹgẹ awọn agba ilẹ yii ṣe sọ, o ṣoro lati ri agbofin to yọ ikun ni igboro.
Lẹyin iwadii BBC Africa Eye yii, awọn alaṣẹ ile iwosan ti ọrọ kan ti ni ki awon ti BBC gba mu lọ rọọkun nile na titi wọn o fi pari iwadii ti wọn.
Lizzy Jay ọmọ Ibadan ni, iṣẹ orin kikọ gan ni oun fi bẹrẹ iṣẹ amuludun, ti oun ko si fi awada ti oun jọ ti ẹnikẹni, tabi fi ẹnikẹni ṣe awokọse.
Police brutality during lockdown: Nínú Ọlọ́pàá àti Coronavirus, èwo gan an laráàlú ń bẹ̀rù jùlọ?
O di àjàgà wúwo rẹ mọ́ àwọn arúgbó lọ́rùn.
Ewe, ope pataki lowo ami-ayo ti atamatase iko naa, Juliet Sunday gba wole sagbon niseju  méjídínláàdọ́ta saa kinni ifesewonse naa, eyi ti o ran iko ohun lowo lati gba ife-eye idije naa le ra won.
ng Iroyin kan jẹyọ lori ayelujara pe awọn ọlọpaa kan ti padanu iṣẹ wọn eleyi to ti wa di kale n kako lori ayelujara.
Lónìí gan-an ni ọba Babilonia gbógun ti Jerusalẹmu.
 Ó kàwé nípa okùn-òwò ní yaba college of technology .
Pilatu kọ àkọlé kan, ó fi sórí agbelebu.
inu egbe oselu PDP se pelu igbimo to n se ipolongo fun Ahmad, lojo Aiku nile
Daramola, ẹni tó kígbe síta bẹẹ lójú òpó Instagram rẹ lọ́jọ́ Ẹti ṣàlàyé pé, àwọn ènìyàn kan ló ń kígbe kiri pé ìyá ńlá lo ń jẹ àwọn àgbààgbà mẹtẹẹta nínú osere tíátà tí òun dárúkọ náà, torí òun ń tọrọ agbe fún wọn.
ninu inúnibíni, ninu irú ìyà tí ó bá mi ní Antioku, ní Ikoniomu, ní Listira, ati oríṣìíríṣìí inúnibíni tí mo faradà.
 Ṣùgbọ ́ n nígbà tí ogun bẹ ̀ rẹ ̀ , ilẹ ̀ germany pinu láti gba ilẹ ̀ belgium kọjá láti kọ lu ilẹ ̀ france .
Papa iṣere ẹgbẹ agbabọọlu Atletico Madrid, Wanda Metropolitano niluu Madrid tii ṣe olu ilu orilẹ-ede Spain ni ifẹsẹwọnsẹ naa yoo ti waye.
Rere kan kò ti ibẹ̀ wá, sibẹ n óo sọ ti ìran ati ìfarahàn Oluwa.
Kọnisọnna Igbasan fikun ọrọ rẹ wi pe ipinlẹ Ondo ni ibudokọ okun to jin julọ ni ilẹ Afirika(largest sea port) to le gba awọn ọkọ nla nla , eyi ti o le pese ibudokọ fun awọn oko oju omi ti wọn ba n kẹru bọ lati oke okun wa si Naijiria.
O ni ohun to buru julọ ni pe ko si ohun kan lati fi ṣe afihan pe awọn ero ti san N42,500 fun ayẹwo naa.
Ó sọ fún iranṣẹ rẹ̀ pé kí ó lọ wo apá ìhà òkun.
Fadaka rẹ ti di ìdàrọ́ mọ́ ọ lọ́wọ́.
Ìrètí àwọn ènìyàn lórí Russia 2018 Àwọn ololufẹ ere bọọlu gba pe iwadii yii ti n bi eso rere to yẹ fun àfọ̀mọ́ awọn oṣiṣe ere bọọlu lagbaye.
Obinrin náà wí pé, “Kí ló dé tí o fi ṣe ohun tí ó burú yìí sí àwọn eniyan Ọlọrun?
Wo àwọn àsọtẹ́lẹ̀ ìgbà tó yẹ kí ayé parẹ́ àtàwọn tó sọ àsọtẹ́lẹ̀ náà Ọkúnrin kan gún àfẹ́sọ́nà rẹ̀ pa tán ló bá tún pa ara rẹ̀ náà Ọ̀dàlẹ̀ ni Igbákejì Gómìnà, kìí ṣe pé a dẹ́yẹ si - ìjọba Ondo Gbọ́yì-sọ̀yí àti ìròyìn èké láti ọ̀dọ̀ àwọn olólùfẹ́ wa ló ṣáábà ma ń da ìgbéyàwó àwọn òṣèré rú- Ọpẹ Ayeola Lẹyin-o-rẹyin, Ajimọbio dagbere faye lọjọ karundinlọgbọn, oṣu kẹfa, ọdun 2020 lẹni ọdun mọkanlelaadọrin nile iwosan kan ni ilu Eko.
Abọ́ tí wọn hú ọ̀hún tohun ti ǹkan to wà nínú ẹ ni wọn rí níbi ti wọn bòó mọ́lẹ̀ sí ní mítà mẹ́ta sí abẹ̀ ilẹ̀ ní Lajia, lágbègbè ti ilẹ̀ rírí tí ṣẹ̀lẹ̀ ní ní ọdun ppẹ́ sẹ́yìn 2.
Ó dìde dúró, ó sì súre fún gbogbo ìjọ ọmọ Israẹli, ó gbadura sókè pé, 
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Barcelona vs Bayern: Koeman di akọ́nimọ̀ọ́gbá Barcelona tuntun lẹ́yìn ìjàmbá Champions League 15 Ògún 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 19 Ògún 2020 Oríṣun àwòrán, PA Media Omi tuntun ti ru lẹgbẹ agbabọọlu Barcelona, Ronald Koeman ti di akọnimọọgba tuntun ikọ naa.
Gbogbo àwọn angẹli tí ó dúró yí ìtẹ́ náà ká, ati àwọn àgbààgbà mẹrinlelogun ati àwọn ẹ̀dá alààyè mẹrin dojúbolẹ̀ níwájú ìtẹ́ náà, wọ́n júbà Ọlọrun.
BBC Africa Eye: Àṣìlò òògùn láàrín àwọn ìgbèríko ti ń dínkù
Chelsea àti Valencia pín gaàrí lọ́gbọọgba nílé Valencia Ronaldo, Messi ẹ yàgò lọnà fagbábọ́ọ̀lù Nàìjíríà tó n gbowò julọ!
Ní ọjọ́ kinni Àjọ̀dún Àìwúkàrà, àwọn ọmọ-ẹ̀yìn wá sọ́dọ̀ Jesu, wọ́n bi í pé, “Níbo ni o fẹ́ kí á tọ́jú fún ọ láti jẹ àsè Ìrékọjá?
Adari ijọ naa ni a gbọ pe o rọ Adeleke pe ki o ran ọmọkunrin naa lọwọ lati gbaa gẹgẹ bii oluranlọwọ inu ile.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ebola Virus: ìdí tí Ebola fi ń tàn kálẹ̀ Egbẹ agbabọọlu Burundi ko jade ṣoju orilẹ-ede wọn ri laarin 1930 si 1990 ti idije ife ẹyẹ agbaye ti bẹrẹ.
O ni ohun ti ijọba n duro de bayii ni 'abajade iwadii awọn ọlọpaa' lori ọrọ naa.
Rutu bá rọra lọ sí ọ̀dọ̀ rẹ̀, ó ṣí aṣọ kúrò ní ẹsẹ̀ rẹ̀, ó sì sùn tì í.
Ẹ̀yà kọ̀ọ̀kan yóo mú ẹgbẹrun eniyan wá fún ogun náà.
Boo ṣe le forukọ silẹ fun N75 Biliọnu owo iranwọ ijọba O kere tan, 1.
je pe, bi ere bi ere ni ifẹsẹwọnsẹ naa bere ti won fi gba ami ayo meta sagbon
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Winne aya Mandela - Ó dìgbà ‘N5000 ni wọ́n ta ìbò Ondó,Edo àti Anambra’ Ìkọlùkọgbà ńrúgbó bọ̀ pẹ̀lú ènìyàn 200m Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí kan sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
Leyin isele ijamba oko ofurufu to waye lojo Abameta , igbakeji aare
Ọmọ ẹni ire a má a tọrọ jẹ
George Floyd: Ẹ̀rọ ayàwòrán ara ọlọ́pàá ṣàfihàn bí George Floyd ṣe ni òun kò le mí mọ́
Bákan náà ni àwọn ọlọ́pàá tó wà ní àgọ́ náà fórí ara wọn pamọ́ kọ́wọ́ má bàà tẹ̀ wọ́n.
Sowore ṣèpàdé pẹ̀lú Nnamdi Kanu láti dojú ìjọba Nàíjíríà bolẹ̀ - Àjọ DSS Sowore àti àwọn ọmọ ẹgbẹ Revolution Now kò ṣẹ̀ ṣófin lórí ìwọ́de, ẹ tú wọn sílẹ̀ - NLC Gbígba onídùròó Zakzaky ṣàfihàn àṣeyọrí ìfaradà wa lásìkò ìfìyajẹni - Shiite Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, RevolutionNow: Ẹ̀rù ò bàwá, a ṣetan láti wà ní àtì mọ́lé- olùfẹ̀hónúhàn Ezeife to bu ẹnu atẹ lu igbesẹ Sowore to pe fun iyipada isejọba lorilẹede Naijiria, ni Sowore ati awọn ẹgbẹ lẹyin rẹ ti mu itiju ba ẹgbẹ oselu naa.
Chukwuocha kẹkọọ nipa itan ni fasiti ipinlẹ Deleware, o si ni iriri nipa eto oṣe abẹle ipinlẹ ọhun.
Funmilayo Ogunsola Ijewuru ni adape orukọ Funmilayo Ogunsola ninu iṣẹ tiata, to si ti silẹ bora lọdun 2019 lati ipasẹ aisan ẹjẹ ruru to ba fínra.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Alaafin Ọyọ Queens: Ǹjẹ́ o mọ àwọn olorì àkọ́fẹ́ Aláàfin Adeyẹmi?
asoju naa lati  maa ba awon ti oro kan
"Gbogbo ifẹhonuhan yii ti n waye saaju ki wọn to bura fun mi bii gomina, ki ijọba ipinlẹ ni ọlọpaa tiẹ si lo le yanju ọrọ yii nitori wọn yoo jẹ ọlọpaa agbegbe.
Nígbà tí ó ṣe, ó já sí gbangba ìta, èmi sì tẹ̀lé e, lẹ́hìn èyí ó kúrò ni ààrin ìlú pátápátá èmi náà tún ń bá a lọ, nígbà tí ó pẹ́ ó yà sí ọ̀nà kan báyìí, èmi náà sì yà tì í, nígbà tí ó rìn ọ̀nà yìí jínnà ó dé gbangbakan níbi tí ó tẹ́jú púpọ̀.
Lorileede South Africa ni idije fawọn ọjẹwẹwẹ ti ọjọ ori wọn ko ju ọdun mọkandilogun lọ naa ti o ti gbera sọ lọjọ kọkanlelogun oṣu kini ti n waye.
Idi ni pe wọn tun dede ri oku ọmọbinrin ẹni ọdun mẹrindinlogun mii ninu igbo kan ni agbegbe Akinyẹle, lẹyin ti ileeṣẹ ọlọpaa ipinlẹ Ọyọ kede pe awọn ti mu awọn afurasi ọdaran naa to n paayan ni Akinyele.
Àwọn ọmọ Israẹli kó gbogbo dúkìá ìlú náà ati àwọn ẹran ọ̀sìn wọn ní ìkógun, ṣugbọn wọ́n fi idà pa gbogbo àwọn eniyan ibẹ̀ run patapata, wọn kò dá ẹyọ ẹnìkan sí.
Abajade iwadii lori wahala ounjẹ ẹlẹẹkẹrin iru ẹ, 'Global Report on Food Crises' tọka si orilẹede Yemen, Democratic Republic of Congo, Afghanistan, Venezuela, Ethiopia, South Sudan, Sudan, Syria, Nigeria ati Haiti.
Sanusi ni wọn gbe lọ si ilu Awe ni ipinlẹ Nasarawa ni ibi ti wọn ti fi si inu ahamọ lẹyin ti ijọba ipinlẹ Kano yọ ọ ni ipo ni Ọjọ Aje.
Ò ń fi ọpọlọpọ ọrọ̀ rẹ ati ọjà rẹsọ àwọn ọba ayé di ọlọ́rọ̀.
Nígbà tí àwọn ọmọ ogun Israẹli rí Goliati, ẹ̀rù bà wọ́n; wọ́n sì sá lọ.
Bio tile jepe, A ti jo fenuko lati pinya fun akoko yii, bee sini anfani nla lo je fun mi lati sise papo pelu re fun odun merin-in gbako,” .
Ninu ẹ̀yà Gadi, àwọn tí wọ́n tó ẹni ogún ọdún, tí wọ́n tó lọ sójú ogun, gẹ́gẹ́ bí àkọsílẹ̀ wọn ní ìdílé-ìdílé 
Aare so pe : “ope ni fun Olorun ati imo ero igbalode lori kaadi eto idibo ati eyi to n se ayewo kaadi naa, iyalenu gbaa lo jẹ.
Ara ògiri ilé ìsìn náà níta ni wọ́n kọ́ ilé alágbèékà mẹta yìí mọ́, àgbékà kọ̀ọ̀kan ga ní igbọnwọ marun-un, wọ́n sì fi pákó igi kedari so wọ́n pọ̀ mọ́ ara ilé ìsìn náà.
Bi awọn ipinlẹ to ni Coronavirus ṣe lọ ni yii: Eko-123 Kaduna-50 Rivers-40 Edo-37 Adamawa-25 Oyo-20 Nasarawa-16 Osun-15 Enugu-15 FCT-14 Ekiti-13 Ondo-13 Ebonyi-11 Katsina-10 Abia-9 Delta-8 Kwara-4 Ogun-3 Cross River-3 Kano-3 Bauchi-3 Yobe-2 Sokoto-1 Niger-1 Èèyàn 591 míràn tún kó COVID-19 ní Nàìjíríà l'Ọ́jọ́ Ẹtì Eeyan 591 ni wọn tun kede pe ayẹwo tun ti fihan pe o laarun COVID-19 lorilẹede Naijiria bayii.
Oríṣun àwòrán, @AsoRock Jikan Sabo, @Usmern_ssg, o ni se ẹgbẹ NANs to n dun mahuru-mahuru laipẹ yii lati tẹsẹ bọ sokoto kanna pẹ́lu Buhari, lo wa n pada fun ni kaadi ọjọ ibi yii?
Anjola, Femi Bamishele, Benjamin Mzondu ati eni owo Samuel Onuigbo.
Orilẹ-ede yii lo ni akọsilẹ iṣekupaniyan to pọju ni gbogbo agbaye.
Ìjọba àpapọ̀ - BBC News Yorùbá BBC News, YorùbáFò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Lockdown school feeding programme: To bá ní ọmọ ni kíláàsì Kínní dé ìkẹta nílé ẹ̀kọ́ alákọ̀ọ́bẹ̀rẹ̀ tìjọba, lọ gba oúnjẹ fún ọmọ rẹ - Ìjọba àpapọ̀ 6 Ẹrẹ̀nà 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 14 Èbibi 2020 Oríṣun àwòrán, Federal Ministry of Humanitarian Affairs Ijọba apapọ ti kede pe Ọjọbọ ọla ni eto ipese ounjẹ fawọn akẹkọọ jakejado Naijiria yoo bẹrẹ nilu Abuja, Eko ati Ogun.
Akọsilẹ fidi rẹ mulẹ pe Ọgbẹni Colston ko awọn eeyan alawọdudu bii ẹgbẹrun un lọna ọgọrin lati ilẹ Afirika lẹru lọ si Amẹrika nigba owo ẹru.
Mo tún rí angẹli kan tí ó dúró ninu oòrùn, ó kígbe sí àwọn ẹyẹ tí ń fò lágbedeméjì ọ̀run pé, “Ẹ wá péjọ sí ibi àsè ńlá Ọlọrun, 
Àwọn ọ̀dọ́ ilẹ̀ Yoruba kò gbọdọ̀ gbàgbé àṣà ati ohun àdàyébá wọn - Ooni Ile Ife Wo àwọn olorì àgbà mẹ́rin tí Aláàfin ń wárí fún Ègún ọ̀dá owó yóò jà yín, tẹ́ ẹ̀ bá san ìdá mẹ́wàá - Oyedepo Ǹjẹ o yẹ kí èèyàn máa sùn lẹ́nu iṣẹ́?
Lẹ́yìn náà, o fún mi ni ẹyọ obì kan báyìí, o tún fún mi ni àwọn èso igi, o sì fún mi ni ẹyọ àgbàdo púpọ̀, o ni obi ìgbéraga, àgbàdo ìgberaga àti eso igberaga ni òun fún mi wọ̀n-ọnnì, ìgbà tí a bá jí, kí a fi obi ìgbéraga fún àwọn iwin jẹ, kí a fi àgbàdo ìgbéraga fún àwọn ẹyẹ, kí a sì fi èso ìgbéraga fún àwọn ẹranko.
Ajọ to n gbogun ti ajakalẹ aarun lorilẹede Naijiria, NCDC ko ṣai fi da awọn eeyan loju pe akitiyan n lọ bayii lati ṣawari gbogbo awọn eeyan ti wsn ti ni ajọṣepọ pẹlu awọn eeyan mẹta yii.
Solomoni ti gúnwà lórí ìtẹ́ ọba.
 Àwon ará ìlú Òbà gba àwon Ègbìrà láàti bá won gbé ekùú ti won náà .
Ẹ̀rù bà wọ́n gidigidi, wọ́n ní, “Ǹjẹ́ àwa lè bá Jehu, ẹni tí ó ṣẹgun ọba meji jà?
Atiku wa gbadura fun Naijiria, lẹyin naa lo tun pe gbogbo ọmọ Naijiria lati gbagbọ pe Naijiria yoo dara.
Bí ó tilẹ̀ mú kí ìbànújẹ́ dé bá wa,yóo ṣàánú wa, yóo tù wá ninu,gẹ́gẹ́ bí ọpọlọpọ ìfẹ́ rẹ̀ tí kì í yẹ̀.
Nigba ti awọn miran gba pe ojukokoro lo n fa irinajo ti ko dara lọ silẹ okeere yii.
OLUWA yóo dojú ogun kọ wọ́n.
Bakan naa lo ṣalaye pe baba oun kò fi iwe akọsilẹ ogún pinpin silẹ.
PDP ni ki Buhari o dẹkun ẹkun abosi Ẹgbẹ Afẹnifẹre ṣe ipade pẹlu Aarẹ Muhammadu Buhari ni ọjọ Iṣẹgun, ọrọ aabo wa lara ohun ti wọn ba aarẹ naa sọ.
Ona ti o le gba se eleyi kii sẹ ki o gbana ṣugbọn ti eeyan ba fin in si imu, Dokita Anthony wi pe ''o le fa iku ti eeyan ko ba tete ri atẹgun aafin simu lasiko.
Oluranlọwọ fun Aarẹ Buhari lori ọrọ ilẹ okeere, Abike Dabiri-Erewa ni oun ibanujẹ lo jẹ fun oun bi awọn alawọdudu, paapaa awọn ọmọ Naijiria se n padanu ẹmi wọn ninu ikọlu ni ilẹ Geesi kọ oun lominu.
Ṣugbọn wọn kàn ń fi ẹnu wọn pọ́n ọn ni;irọ́ ni wọ́n sì ń pa fún un.
Bí ilẹ̀ ọjọ́ keji ti mọ́, wọ́n ní kí àwọn arakunrin Josẹfu máa lọ ati àwọn ati kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ wọn.
#Revolution March: Ìjọba Buhari ń wùwà bíi ìjọba Abacha lórí ọ̀rọ̀ Ṣoworẹ- Ṣoyinka
Wo odò tí wọ́n ti rí Aishat tí àgbárá òjò gbé lọ ní Eko Iṣẹ́ márùn ún tí àwọn adarí ẹgbẹ́ APC gbọ́dọ̀ ṣe kíákíá kí omi má tẹ̀yìn wọ ìgbín lẹ́nu Ẹbí Abiola Ajimobi kéde bí ètò ìsìnkú rẹ̀ yóò ṣe rí pé.
iba, paapaa julo lati ri i pe opin de ba aarun naa ni orile ede Naijiria.
Milionu mẹtadinlogun ati aabọ eniyan lo wo ifẹsẹwọnsẹ naa lori ẹrọ mohun-maworan Atamatase Cristiano Ronaldo lo kọkọ ṣide eto nigba to gba bọọlu si àwọ̀n ni iṣẹju mẹrindinlọgbọn nigba ti Wes Brown fori gbe bọọlu naa si i.
Eyi ni igbesẹ igbimọ ti ijọba fi lọlẹ lori itankalẹ arun Covid-19 lẹyin ipade idankọkọ ti wọn ṣe niluu Abuja lọjọ Iṣẹgun.
” OLUWA dáhùn pé, “Bí mo bá rí olódodo marundinlaadọta n kò ní pa ìlú náà run.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù CAF President: Wọ́n ti fòfin ọdún márùn ún de Aàrẹ̀ CAF, Ahmad Ahmad 23 Bélú 2020 Oríṣun àwòrán, Getty Images Ajọ to n mojuto ọrọ ere bọọlu ni agbaye ti fofin ọdun marun un de aarẹ ajọ to n ri si ọrọ ere bọọlu nilẹ Adulawọ.
Ó sàn láti sá di OLUWA,ju ati gbẹ́kẹ̀lé eniyan lọ.
” Hẹrọdu bá ń wá ọ̀nà láti fojú kàn án.
Bo tilẹ jẹ pe o le to aadọta iṣẹju lati pese Ọjọjọ, ṣugbọn ko ṣoro lati pese rara.
N óo mú kí ìpọ́njú dé bá wọn,kí wọ́n lè mọ̀ pé nǹkan ṣe àwọn.
Ajo to n mojuto isele pajawiri lo fi isele yii mule lojo Aje ni Maiduguri pe Isele yii waye, ni ojo karun un osu keje ni Kaleri ni ipinle  Maiduguri.
Nípa lílò rẹ̀ Baba-onírùngbọ̀n wí báyìí fún wa, ó ní, Nígbà tí ẹ bá ń lo omi yìí, ẹ kò gbọdọ̀ jẹ epo, ẹ kò gbọddọ̀ jẹ iyọ̀, ẹ kò gbọdọ̀ jẹ ata, ẹ sì níláti wà ní ìhòhò gidigbi bí ẹ ti ṣe wá sí òde ayé àti bí ẹ ó ti ṣe sí òde ọ̀run.
joba ni tibu- toro ekun naa.
Lasiko ariya alaalẹ Satide to tun waye lana ati asiko ounjẹ ni aarọ ọjọ isinmi oni, ara miran tun ti sẹlẹ.
Eleasari ọmọ Aaroni alufaa ni yóo máa ṣe alákòóso àwọn olórí àwọn ọmọ Lefi, òun ni yóo sì máa ṣe àkóso àwọn tí ń ṣe ìtọ́jú ibi mímọ́.
Nígbà tí ò ń ṣe àgbèrè ati gbogbo nǹkan ìríra rẹ, o kò ranti ìgbà èwe rẹ, nígbà tí o wà ní ìhòòhò goloto, tí ò ń ta ẹsẹ̀ ninu ẹ̀jẹ̀!
Àsìkò tó láti fi ìwọ́de gba ara wa sílẹ̀ lọ́wọ́ ebi àti oko ẹrú - Sowore Ìjọba Ọyọ ti ọjà Ṣáṣá pa ní Ibadan torí ìjà láàrin ẹ̀yà Hausa Àwọn Pásítọ́ ijọ Redeem márùn ún bọ́ sọ́wọ́ ajínigbé ní Ijebu Ode Alhaja Abẹni fikun ọrọ rẹ pe lootọọ l'oun n kọ orin Waka, ṣugbọn oun kọ l'oun da orin Waka silẹ.
Ó bá bèèrè lọ́wọ́ Amasa pé, “Ṣé alaafia ni, arakunrin mi?
Asiko ti wọn si n lọ lọna ni wọn ja ọkọ gba, wọn bọ aṣọ ọmọ ogun kuro lọrun un wọn, wọn si salọ.
Adebayo Adelabu - Ọmọ ẹgbẹ́ 8.
Nígbà tí Lea rí i pé òun kò bímọ mọ́, ó fún Jakọbu ní Silipa, iranṣẹbinrin rẹ̀, kí ó fi ṣe aya.
Orilẹede Naijiria si jẹ orilẹede to n san fun wara ati oyin, ti ọba oke si fi ọpọ ohun alumọọni jinki rẹ.
Awọn ti o fi ehonu han yii lọ si iwaju lle lgbimọ Aṣofin Ipinlẹ Eko lati fariga lori iyansipo rẹ gẹgẹ bi alaga ẹgbẹ.
Ọ̀nà márún-ún láti mú àdínkù bá dátà (Data) lílò rẹ Gbìyànjú àwọn òwé Yòrúbà yìí wò Ṣé ìwọ mọ irúfẹ́ ọmọ ti Yorùbá ń pè ní Àìná?
Isikiẹli Gbé Òfin Jáde lórí Ìwà Ìbàjẹ́ ní Jerusalẹmu.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Akọ́mọlédè àti Àṣà lórí BBC Yorùbá: Kọ̀ síi nípa iṣẹ́ tí oúnjẹ ń ṣe lára níbí Ẹwẹ lọjọ Iṣẹgun yi, igbẹjọ tẹsiwaju lori ẹsun ti wọn fi kan Maina tawọn eeyan mẹta si wa jẹri lori ẹsun ti wọn fi kan an yi.
O sọ siwaju pe  Bi mo ṣe duro niwaju yin yii, mo jẹ ẹni ti o de ipo gomina lai ni baba isalẹ, afi Ọlọrun nikan ṣoṣo."
Ninu ọrọ minisita fun ọrọ epo bẹntirol naa, o ni oun to ba ni ninu jẹ ni wi pe, ti awọn ba yọ owo iranwọ, gbogbo awọn osisẹ ni yoo da isẹ silẹ , eleyii ti yoo ni ipa buburu lori ọrọ aje orilẹede Naijiria.
"Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ìtàn ayé Ọba Seriki Abass ti Badagry, tó ní aya 128, ọmọ 144 Mo fẹ́ kí Ọlọ́run fún wa ní ọmọ olójú búlúù si lẹ́yìn yìgì - Ọkọ olójú búlúù Wo bí o ṣe le fi orúkọ sílẹ̀ fún ìgbani ṣíṣẹ́ ológun Nàìjíríà tó bẹ̀rẹ̀ Kò sí ọ̀nà láti jáde tàbí wọlé sí Mali, ikọ̀ ológun ọlọ́tẹ̀ kéde ìṣédeWo ibùdó arẹwà tí ọ̀pọ̀ èrò ń ya lọ ní Abuja Ọmọdé 5 àti àgbà 40 bómi òkun lọ, 37 mórí bọ́ lásìkò tí ẹ́ńgínì ọkọ̀ ojú omi gbiná ""Mo ti ka ofin naa, wọn ko gbe kalẹ lọna to dara nitori ijọba to ba n san na bi eto idalesẹ silẹ yoo se rọrun, ko ni gbe ofin mẹrinlelẹgbẹta kalẹ lori agbekalẹ ileesẹ aje."
mi dun si  Imam yii fun iru eto lati fi
Lẹyin eyi lo lọ sile ẹkọ aṣalẹ ti Igbobi College nigba ti o n ṣiṣẹ lojumọmọ.
"6bn ohun ìní Nàìjíríà Àwọn ọmọ Naijiria kóju ija sí àwọn South Africa wọ́n ní ""Ó tó gẹ́"" Àtúnṣe òpópónà Lagos-Ibadan àwọn ọ̀ná míràn ti e lè gba Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Port harcourt Bole: Mi kò mọ́ pé bọ̀ọ̀lì títà lè gbé mi dé ipò yìí láyé mi!"
Á máa jókòó lẹ́nu ọ̀nà ilé rẹ̀,á jókòó ní ibi tí ó ga láàrin ìlú.
Ninu iwe abadofin ti won fenuko le lori, apapo ijoko naa pinnu lati ni ibasepo to donmonron lojuna ati fopin si ikolu iko olote boko haram patapata.
Ẹni tí ó wá láti ọ̀run ju gbogbo eniyan lọ.
Tsehaytu Beraki to je gbajugbaja onkorin ni ile Eritrea to sa asala kuro ni ilu re lo si ile okeere ti ku si Netherland lomo odun mokandinlogorin.
INEC ni APC ni ìbò 255, 505 nigba ti PDP ni ìbò 255, 023, eyi to fihan pé Alhaji Oyetola bori Senato Ademọla Adeleke ti ẹgbẹ oṣelu PDP ti wọn jọ na atundi ìbò toni tan bi owó ati awọn oludije to ku.
"Tẹ́lẹ̀-tẹ́lẹ̀, mo máa ń mu tó mẹ́ta tàbí mẹ́rin nígbà tí mo bẹ̀rẹ̀ sí ní muú.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ẹ̀mí ogójì ṣòfò, ọgọ́ta míràn farapa nínú ìjàmbá ọkọ̀ epo tó jóná 'Èèyàn mi mẹ́ta ló wà nínú ọkọ̀ ojú omi tó dà nù l'Eko!
Bí a bá po wàrà pọ̀ títí, yóo di òrí àmọ́,bí ó bá pẹ́ tí a ti ń tẹ imú, imú yóo ṣẹ̀jẹ̀,bẹ́ẹ̀ ni ríru ibinu sókè, a máa mú ìjà wá!
Sẹnẹtọ tẹlẹ ri sọ pe ti Yoruba ati Igbo ko ba fẹnu ko lori ẹni ti yoo apa guusu orilẹede Naijiria, afai mọ ki ipo aarẹ maa bọ mọ wọn lọwọ lọdun 2023.
Oríṣìíríṣìí orílẹ̀-èdè ni wọ́n, wọ́n sì ń sọ oríṣìíríṣìí èdè.
 wọ ́ n bí benito ní 1883 .
Nítorí irú ẹjọ́ tí ẹ bá dá eniyan ni Ọlọrun yóo dá ẹ̀yin náà.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Kemi Dairo: Iṣẹ́ abẹ nínú ọpọlọ àti ẹ̀rọ ni mo fi ń gbọ́ ọ̀rọ̀ báyìí O fikun wi pe, awọn fi oku naa silẹ lẹyin ti Ọba ilu naa dasi iṣẹlẹ naa, ti wọn si fun awọn ni owo, ki awọn to fun awọn Musulumi laaye lati lọ sin.
Kọjá lọ láàrin ọgbà àjàrà rẹ̀ ní poro ní poro, kí o sì pa á run,ṣugbọn má ṣe pa gbogbo rẹ̀ run tán.
A ni eyi to n mu inu ẹni dun ki iṣẹ le ya lori ibusun, a tun ni eyi to n jẹ ki àtọ̀ pọ sii lara ati eyi to n mu ni gbadun ifẹ ẹni.
Ibanujẹ nile Oloye Ọpẹ Bademọsi Ibanujẹ nla gbaa ni iku Oloye Ọpẹ Bademọsi jẹ fun ẹbi ati ara bi wọn ṣe peju-pesẹ si ile olóògbé naa.
Nigba ti akori ti ọdun yìí jẹ́ ṣiṣiṣẹ pọ lati dena iwa pipa ara ẹni, eeyan 264 gbẹmi ara wọn laarin oṣu kinni ọdun 2017 sí oṣu kẹjọ ọdun 2020 yii.
Mo ti yan ọ̀nà òtítọ́,mo ti fi ọkàn sí òfin rẹ.
“OLUWA, ò máa ṣe olóòótọ́ sí gbogbo àwọn tí wọ́n bá hu ìwà òtítọ́ sí ọ;ò sì máa fi ara rẹ hàn bí aláìlẹ́bi, fún gbogbo àwọn tí kò ní ẹ̀bi.
Bẹ́ẹ̀ ni Dafidi, ọmọ Jese, ṣe jọba lórí gbogbo Israẹli.
Oloye Obsanjo woye ọrọ yii ninu isẹ to fi ransẹ fun ibẹrẹ ọdun tuntun, to si wa n sekilọ pe kawọn asaaju Naijiria dẹkun didi ẹbi isẹlẹ aisi eto aabo to peye, ọrọ aje ti ko dara, osi atawọn ipenija miran to n ba ilẹ yii finra, ru Ọlọrun.
Mohammed lo soro yii nile –aare to wa niluu Abujalasiko to n ba awon akoroyin
Makinde júwe ilé fún Kọmíṣọ́ná iṣẹ́ òde, ó ṣe pàsípàrọ̀ àwọn kọmíṣọ́nà méjì míì Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Samuẹli kò mọ̀ pé OLUWA ni, nítorí OLUWA kò tíì bá a sọ̀rọ̀ rí.
Ọ̀nà kan ò wọjà fáwọn òṣèré tíátà, bí wọn ṣe ń ta ìpara ìbóra ni wọ́n ń ta aṣọ ẹbí Uganda kó rọ́bà ìdáàbòbò mílíọ̀nù kan kúrò ní ìlú Iléẹjọ́, ẹ sọ fùn ọ̀gá DSS kó fún wa ní ₦1bn torí àhámọ́ lọ́nà àìtọ́ - Sowore àti Bakare Ìtọ́jú ara di ìrọ̀rùn!
Ninu ọrọ rẹ nibi ipejọpọ naa, alakoso fun iroyin, aṣa ati irinajo igbafẹ nipinlẹ Ọyọ, Toye Arulogun ṣalaye wi pe ẹbun lati ọrun wa ni ilu IgboỌra jẹ fun ipinlẹ Ọyọ ati orilẹede Naijiria l'apapọ, gẹgẹ bi ilu ti ibeji ati awọn ọmọ to ju meji lọ ti pọ julọ ni agbaye.
Saraki pe fun ajọṣepọ Ghana ati Naijiria Eeyan 35 miran ko aarun iba Lassa Nkan ti mo ti n gba lero ni inu mi si dun wi pe, ẹ mu ẹnu baa nitori wi pe funmi, nkan manigbagbe ni yoo jẹ."
Ni bayii, Alyona n jẹjọ lọwọ lori ẹsun naa, ti ọkọ rẹ maa n gbiyanju lati tu u ninu nigba kuugba ti wọn ba lọ si ileẹjọ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Cardiac Attack: Wo ọ̀nà méje bí o ṣe lè dẹ́kun ikú òjijì 8 Sẹ́rẹ́ 2020 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Alága ẹgbẹ́ òṣèlú PDP ní ìpínlẹ̀ Kogi, Taiwo Kola-Ojo papòdà lẹ́yìn tí ó fò sánlẹ̀ kú níbí tó tí ń gbá bọ́ọ̀lù ẹ́lẹyin.
Dokita àti Nọ́ọ̀sì fìyà jẹ mí lásìkò tí mò ń rọbí- Alaboyún Sugbọn ọgbẹni Uwem Okon ni tire tako ọrọ yii, o ni oun ko fara mọ ki ijọba tẹ awọn afurasi lọdaa nitori ẹsun ifipabanilopọ.
Àwọn ìròyìn kan sọ pé wọ́n ti sún ọjọ́ ìdìbò nàá síwájú nígbà tí àwọn kan tún sọ pé irọ́ ni.
Folagbade Olateru Olagbeji ni Alaga Tẹlẹ̀ri fun Ajọ Lọbalọba ni ipinlẹ Ondo.
Wọn ni igba to dara julọ lati loogun naa ni keeyan to sun lori ibusun rẹ lalẹ.
 A o mọle aseyọri ti ile igbimo asoju kẹjọ ti se .
Gbogbo àwọn tí ó jókòó ní ìgbìmọ̀ tẹjú mọ́ ọn, wọ́n rí ojú rẹ̀ tí ó dàbí ojú angẹli.
Roshan royin ifẹ ti Gauri ni si oun koda nigba ti oun gba isinmi, ni ṣe ni o n sunkun.
Nígbà tí Ahasi pada dé, o rí i pé Uraya ti mọ pẹpẹ ìrúbọ náà; ó lọ sí ìdí rẹ̀, 
“Lai pe igbimo amusese fun ijoba apapo yoo jabo ise re, bee si ni lara ohun ti o si n dawa duro ni lati kan si ile-igbimo naa lati mo ona kookan ti won yoo gba lati tele ofin ati ilana igbimo ohun ki a o to wa sagbekale iwe isuna ohun.
Jehoaṣi kú, wọ́n sì sin ín sinu ibojì àwọn ọba Israẹli ní Samaria.
Ṣugbọn awọn olufẹhonuhan kan to ko ara wọn jọ nibi ere ti wọn fi n ṣe iranti ogun ni Whitehall ti wọn si gun ere Winston Churchill ni Parliament Square.
Leyin ìkéde adarí àjọ CAN ẹni ọwọ Olasupo Ayokunle lọ́jọ́ru pé kí gbogbo onigbagbọ ṣe ìwọde lágbègbè wọn láti pé àkíyèsí ijoba fún ífòpin sí Ipànìyàn láti ọwọ àwọn darandaran, pàápàá jùlo àwọn Kristẹni tí wọn pá ni Ìpínlẹ̀ Benue.
Wọ́n ran Dafidi lọ́wọ́ láti gbógun ti àwọn ìgárá ọlọ́ṣà kan, nítorí pé gbogbo wọn ni wọ́n jẹ́ akọni jagunjagun, wọ́n sì jẹ́ ọ̀gágun.
O sọ ọrọ yii lẹyin ti iroyin kan jade sori ayelujara pe wahala wa laarin oun ati baba ọmọ rẹ, Olanrewaju saheed 'Jago'.
"Ifarakinra ati pipari ija yii ni yoo bẹrẹ ayẹyẹ iranti ọdun mẹwaa ti Barrister ti papoda.
báyìí , àwọn ìtàn mìíràn tí àwọn baba ńlá wa kò pa rí ti ń dìde .
” Peteru dáhùn pé, “Mesaya Ọlọrun ni ọ́.
Wọ́n ń wí pé, ‘àkókò ilé kíkọ́ kò tíì tó.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, AFCON 2019: Inú mi dùn pé mo jẹ́ ẹni àkọ́kọ́ tó ṣojú Nàíjíríà fún ìgbà 100 Ẹẹmeji ọtọọtọ ni awọn agbabọọlu obinrin, Super Falcons naa fi ẹhonu han nile itura ni South Africa ati Abuja lati beere fun owo ti wọn jẹ wọn.
 Mo seleri pe ijoba mi ko ni dekun sise atileyin to ye fawon gomina ipinle kookan lati rii pe alaafia joba paapaa fawon gomina ipinle ti rukerudo ti n sele lasiko yii bii ti ipinle Plateau.
Instrument Rated"" Oríṣun àwòrán, others Mercy Eke: Oloriire tọdun 2019 Apa kẹrin BBNaija ni akọle rẹ n jẹ ""Pepper Dem"" bẹrẹ ni ọgbọn ọjọ, oṣu keje, ọdun 2019."
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ajisebutu ti o kọ lati fi idi rẹ mulẹ wipe laasigbo naa waye laarin awọn ẹgbẹ OPC Wọn wipe awọn ẹgbẹ mejeeji naa n ja fun isakoso agbegbe Oke-Ado, eyi to sokunfa bi wọn se bẹrẹ si nii kọlu ile itaja ati awọn ile-isẹ to wa lagbegbe naa.
Ìjọba Ààrẹ Buhari kò yàtọ̀ sí ti Abacha Aarẹ tẹlẹri Olusegun Obasanjo, ti fi ijọba Aarẹ Muhammadu Buhari we ti ijọba ologun ti ọgagun Sani Abacha to fi aye ni awọn eniyan nigba aye rẹ.
Nigeria swearing in 2019: Babajide Sanwoolu gba ọpa àṣẹ láti tukọ̀ Eko
‘Irọ́ ni pé Ọmọ ọdọ̀ Ọpẹ Bademosi kú’ Àwọn òṣìṣẹ́ gbọ́dọ̀ jẹ aáyán fún ìjìyà ẹ̀ṣẹ̀ wọn Ipò ètò ààbò ń já àwa gómìnà láyà, ó ń kọ wá lóminú - Àwọn gómìnà Olúbàdàn, ẹ bá wa bẹ́ Seyi Makinde kó tú wa sílẹ̀ - Oyo NURTW Ti a ko ba gbagbe, awọn ọlọpaa ri ọmọọdọ naa mu ni Osu kọkanla, ọdun to kọja ni ilu Ondo, lẹyin to fẹsẹ fẹ.
Ẹ̀rù kò bà wá rárá nítorí Ọlọ́run n bẹ lẹ́hin wa.
Àwọn òbí rẹ̀ kò mọ̀ pé ó ti ra rọ́bà tuntun, àmọ́ àwọn ẹ̀gbọ́n rẹ̀mọ̀.
Bí òṣìṣẹ́ Amotekun bá fi orúkọ sílẹ̀ lórí ayélujára, àwọn ọ̀daràn yóò tètè fojú hàn - Oludari Amotekun l'Oyo Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Ẹlẹ́ẹ̀kẹjọ t'óyún máà bàjẹ́ lára mi ni mo tó rí àànú gbà' Abajade ipinlẹ kọọkan ninu esi tuntun naa re e: Eko-156 Oyo-141 FCT-99 Edo-47 Kaduna-27 Ondo-22 Rivers-20 Osun-17 Imo-13 Plateau-10 Nasarawa-8 Anambra-8 Kano-5 Benue-5 Borno-5 Ogun-4 Taraba-3 Gombe-3 Kebbi-1 Cross Rivers-1 Àpapọ̀ àwọn tuntun to ṣẹṣẹ lugbadi ààrùn Coronavirus ní Nàìjíríà jẹ 571 ní 12/07/2020 Ninu ikede ti ajọ NCDC fi sita ni Ọjọ Aiku lo ti fojuhan pe , awọn to ti ni aarun naa ti pe 32,558 bayii.
Adajọ Danalami Senchi to fi idajọ yii mulẹ ni ki Oshiomole fi ipo alaga silẹ fun igba diẹ, titi ti awọn yoo fi yanju ẹjọ tawọn kan pe lati yọ ni ipo alaga ẹgbẹ naa.
The supporters are standing in groups according to their LGAs, waiting for the accreditation to begin.
Nigba to ya, ninu oṣu kẹrin ni Ọgbẹni El-Rufai tun fi sita ipo ti o ṣi wa koda o tun ṣepade pẹlu awọn lọga ninu iṣejọba rẹ.
Ó ní ilé ìwòsàn tí àwọn èèyàn ń kú sí wa ni ṣíṣí silẹ àmọ́ wọn ti ilẹ̀kùn ilé Ọlọ́run nítorí ìwà ìjẹgàba Èṣù, èyí tí kò ní ìwòsàn.
Messi kọ́ ni agbábọ́ọ̀lù tó dára jùlọ nínú ìtàn, Ronaldinho yarí #Russia2018: Super Eagles ti koju Argentina rí Maradona je okan lara agbabọọlu to lamilaka julọ lagbaye.
Kakaki 1: Àwọn òbí mi rí iṣẹ́ orin bí iṣẹ́ alágbe
Ṣugbọn, ẹ wó gbogbo pẹpẹ wọn, kí ẹ sì fọ́ gbogbo àwọn ère wọn, kí ẹ sì gé gbogbo igbó oriṣa wọn lulẹ̀.
Opolopo emi ni o ti sonu ti awon eniyan kan si ti di alainilelori.
Igbimo Isreal kan ti Tzachi Hanegbi to je minista yoo saaju fun ni won yoo jo duna-dura pelu awon olori ijo naa ki won le mo odiwon iye owo ori ti won yoo maa san.
Bẹẹ ba gbagbe, ileesẹ BBC Yoruba naa ti pe akiyesi ijọba ipinlẹ Ọyọ si obitibiti ẹgbin to n se ilu Ibadan lọsọ, ti kọmisana fọrọ ayika naa si fi da wa loju pe laipẹ ni isoro ẹgbin ayika ọhun yoo di ohun igbagbe.
Láti ibẹ̀ lọ dé ẹnu ibodè Hamati, títí dé Sedadi, 
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù BBNaija 2020: Terry Waya ní torí ìfẹ́ tí Erica ní sọ́mọ òun ló fi ní ọ̀pọ̀ ìṣòro 6 Owewe 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 9 Owewe 2020 Yàtọ̀ sí owó ti àwọn ọmọ Nàìjíríà ń kó jọ fún Erica nítorí pé wọ́n lé e kúrò nilé ẹlẹ́gbọ̀n àgbà, bàbá Kiddwaya náà ti ṣe ilérí tuntun.
Ajafẹtọ ọmọniyan, Kayode Ajulo ti ni Ile Igbimọ Asofin Agba ni asẹ labẹ ofin orilẹede Naijiria lati buwọlu abadofin kan, bi aarẹ orilẹede ti lẹ kọ lati buwolu abadofin naa.
Aworan wa lati ọwọ Reuters, AFP, Getty Images ati EPA.
#Zamfarakillings: Ààrẹ Buhari bínú sí àwọn afẹ̀họ́nú hàn Dokita Abraham rọ awọn awakọ ni Naijiria lati maa rii daju pe ẹnjinni ọkọ ọ̀pá to n gbe eefin jade lara ọkọ̀ wọn n ṣiṣẹ daada.
Pẹlu ọkàn wúwo, ó túbọ̀ gbadura gidigidi.
Ọmọ ilẹ Gẹẹsi ni Iya rẹ, baba rẹ Ali Balógun Sarumi si jẹ ọmọ ile Oluyọle.
Ọpọlọpọ wọn da aṣọ ọ̀fọ̀ bora, wọ́n sì da eérú sára.
Ẹ ta àsíá sókè, fún àwọn eniyan náà.
O sọ siwaju pe, ẹgbẹ APC ko ni fi eru gba ibukun lasiko ibo to n bọ, ti awn ko si sa kiri l ba awọn orilẹede miran gẹg bi ẹgbẹ oselu PDP ti n se kiri.
àwọn ọmọ Lebana, àwọn ọmọ Hagaba, ati àwọn ọmọ Ṣalimai, 
Àwọn òṣèré, olórin Yorùbá gbàdúrà fún MC Oluomo Ta ló leè rò pé ọmọ mẹ̀kúnnù bí èmi leè dé ipò alága NURTW?
" O fikun un pe bi aye ti laju to yii, a si n gbe ni awujọ ti aibara dọgba laarin akọ ati abo ti n waye, ti ojuti si maa n wa fawọn obinrin ta ba n sọrọ ẹya ara ati isẹda wọn.
Erongba awọn eeyan lori ọrọ si ṣe ọtọọtọ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ìran kan si ìkejì ló n gbèrò láti ṣe ìrú ìgbéyàwo àjùmọ̀ṣe 'Shao' fọ́mọ wọn Ilẹ Yoruba nikan kọ ni o ti n ṣẹlẹ: Ni oke ọya Naijria to ṣe pe wọn ko faramọ ki obinrin maa ṣe afihan ara rẹ si awọn ọkunrin, aṣa wiwa ọkọ loju ayelujara yii naa ti n gbalẹ nibẹ.
Àkójọ àwọn àtúnṣe tuntun nínú wiki.
Adedayo Festus lo ṣe idanwo lati di oluranlọwọ pataki fun aarẹ Ahmed Lawan ki wọn to jaa ju silẹ.
 odùduwà gbé ọmọ náà lé ẹsẹ ̀ .
Ara wa fu mi pe ọjọ ti pẹ to ti mọọmọ n ko aarun naa ran awọn obinrin.
Òmùgọ̀ kò ní inú dídùn sí ìmọ̀,àfi kí ó ṣá máa sọ èrò ọkàn rẹ̀.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù FIFA Football Awards: Messi la Ronaldo, Van Dijk láti gba àmì ẹ̀yẹ agbábọ́ọ̀lù tó pegedé jùlọ lágbayé 23 Owewe 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Ìròyìn tó ń tẹ̀ wa lọ́wọ́lọ́wọ́ ní wí pé wọn ti kede Lionel Messi gẹgẹ bii agbabọọlu FIFA to pegede julọ lagbaye.
 Ó gba onírúurú ẹ ̀ bùn fún àṣeyọrí àti àṣeyege ní òpin ẹ ̀ kọ ́ náà .
Francesca Ordega ló jẹ́ goolu akọ́kọ́ fun Nàìjíríà ní ìṣẹ́jú mẹ́wàá (10) sí ìgbà tí wọ́n bẹ̀rẹ̀ eré.
“Nígbà náà ni àwọn olódodo yóo dáhùn pé, ‘Oluwa, nígbà wo ni a rí ọ tí ebi ń pa ọ́, tí a fún ọ ní oúnjẹ, tabi tí òùngbẹ ń gbẹ ọ́ tí a fún ọ ní omi mu?
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Covid-19 Wedding: Ọkọ àti Ìyàwó yìí ti dájọ́ sọ́ná ṣáájú Coronavirus 21 Agẹmo 2020 Oríṣun àwòrán, Courtesy of the couple Maa fẹ lati maa ranti ọjọ oni tii ṣe ọjọ ayẹyẹ wa titi di ogun ọdun si isinsinyii."
Ao ma a mu wa fun yin bi nkan ba tun ṣe n lọ.
Ibi mímọ́ OLUWA yóo wà ní ààrin rẹ̀.
Winter Olympics: Saraki kan saara si awọn ọmọ Naijiria mẹta to ndije
Oríṣun àwòrán, Twitter/tonaishere ''A kan tu awọn oluwọde ka nigba ti wọn fẹ yabo ileeṣẹ ọlọpaa ni Ogbomosho ni.
"Dogara ní ""a kò leè torí pé a fẹ́ gbé èèyàn kan lọ síwájú ilé ẹjọ́, ká gba ẹ̀mí lẹ́nu ẹni bẹ́ẹ̀."
" Nigba to n sọrọ lori ipese owona fun ikọ Amotekun, Adedoyin ni ipinlẹ kọọkan lo ni apo asunwọn owo ti wọn ya sọtọ fun eto aabo, taa mọ si Security Fund, ipinlẹ kọọkan ti ikọ Amotekun ba si wa ni yoo maa pese owona wọn, kii si se ipese owona alajumọse rara.
” Wọ́n bá bẹ̀rẹ̀ pẹlu àwọn àgbààgbà tí wọ́n wà níwájú ilé OLUWA.
N óo fún Dedani mu, ati Tema, ati Busi ati gbogbo àwọn tí wọn ń gé ẹsẹ̀ irun wọn.
O ni awọn mejeji ko ṣafihan apẹẹrẹ aarun naa, ṣugbọn wọn lọ fun ayẹwo gẹgẹ bi agbekalẹ ajọ to n dena ajakalẹ arun, NCDC, ti esi ayẹwo naa si fi han pe Chioma ti ni arun naa.
OLUWA ṣe bí ọ̀tá,ó ti pa Israẹli run.
O sọ ninu atẹjade naa pe Ọjọgbọn Abayomi lugbadi aarun naa lẹyin ifarakinra pẹlu awọn to ti laarun ọhun.
O tun tesiwaju pe, awon ijamba to maa n waye loju opopona naa ti dinku, bee si ni o tun je ki eto aabo tubo fese mule si .
Loṣu to kọja awọn alatilẹyin rẹ ninu ẹgbẹ Republican kọọkan ti n fi han pe awọn ko fi taratara gba tiẹ mọ.
Wọ́n dára ju kí wọ́n wà ninu ayé lọ.
Eyi ni wọn fi n mọ pe omi lo fẹ.
Eyi le waye lasiko ti obinrin ba n ni ibalopọ tabi ti wọn ba n fi ọwọ́ pá à lara.
Iroyin naa sọ pe gígún ni awọn janduku gún Oluọmọ to jẹ oloye ẹgbẹ awọn awakọ lasiko ti wahala naa waye.
Mayegun lo sọ ọrọ yii nigba to gbalejo BBC Yoruba lori eto ifọrọwerọ loju opo Facebook wa.
Nítorípé ó ún yírapo kíákíá, àwòrán Júpítérì jẹ́ bíi òbìrìkìtì afẹ̀lẹ́ẹ̀gbẹ́ (ó wú díẹ̀ síta ní agedeméjì rẹ̀).
gomina ipinle jigawa, Abubakar Badaru naa ko gbeyin, leni ti o tuko igbimo ohun
Nígbà tí mo wà ninu ìpọ́njú; wọ́n gbógun tì mí,ṣugbọn OLUWA dáàbò bò mí.
Ẹni tí ó bá juni lọ ni a fi í búra.
Ẹgbẹ́ ọ̀dọ́ méjì fìjà pẹẹ́ta, ẹ̀mí kan bọ́, ọ̀pọ̀ farapa Ìjà kan to waye laarin awọn ọmọ ẹgbẹ meji nilu Ejigbo ti ṣokunfa iku arakunrin kan, Abeeb Abifarin ti agboole Oke Dada nilu Ejigbo nipinlẹ Osun.
Isẹ alagbẹdẹ ti baba rẹ n se ni Ayinla Ọmọwura kọkọ kọ bii isẹ oojọ nigba aye rẹ, nigba to ya lo tun kọ isẹ ọkọ wiwa, to si se isẹ awakọ fun igba kan.
Awari tuntun yii tayọ ọ̀kan to waye lọdun 2006 to ṣafihan iho iyọ Cave of the Three Nudes to wa ni Erekusu Qeshm lorilẹede Iran.
Ṣugbọn nígbà tí ó ṣì wà ní ọ̀nà jíjìn sí ilé ọ̀gágun náà, ọ̀gágun náà rán àwọn ọ̀rẹ́ rẹ̀ sí Jesu kí wọ́n sọ pé, “Alàgbà, má ṣe ìyọnu.
Ó ní kí á dìde, kí á bẹ̀rẹ̀ sí lọ sí agbègbè olókè ti àwọn ará Amori, ati gbogbo agbègbè tí ó yí wọn ká ní Araba, ní àwọn agbègbè olókè ati ní pẹ̀tẹ́lẹ̀, ati ilẹ̀ Nẹgẹbu, ati èyí tí ó wà létí òkun tí wọn ń pè ní Mẹditarenia, ilẹ̀ àwọn ará Kenaani ati Lẹbanoni, títí dé odò ńlá nnì, àní odò Yufurate.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Nigeria Debt: Gbèsè Nàíjíríà yóò pòórá, tí ìkọ̀ọ̀kan ọmọ Naijiria bá san ₦121,000 28 Ògún 2019 Oríṣun àwòrán, PIUS UTOMI EKPEI Minisita feto isuna ati aato, Udoma Udo Udoma, lasiko ipade awọn ọmọ igbimọ alasẹ apapọ ni, ko si orilẹede ti kii jẹ gbese, ti aayan si n lọ lati se afikun owo ori araalu.
Itan igbe aye Lisabi Agbongbo Akala: Bi o tilẹ jẹ pe ko si akọsilẹ fun akoko ti Lisabi Agbongbo Akala de ile aye, tabi orukọ awọn obi rẹ, amọ a ri i ka pe ọmọ bibi adugbo Itoku ni, to si n gbe adugbo Igbẹhin nigba to dagba tan.
Igbesẹ yii ko dun mọ igbimọ oluwadii naa ninu, eyi si ti mu ki wọn paṣe pe ki awọn agbofinro fi panpẹ ofin mu wọn, ki wọn lee wa sọ tẹnu wọn fun awọn ọmọ Naijiria lori bi ọrọ owo naa ṣe jẹ.
Wón sì fi irin ṣe àmì sí ojú ike yìí kan.
Josẹfu kú nígbà tí ó di ẹni aadọfa (110) ọdún.
- Iya Rainbow Kemi Olunloyo dá sí ìjà Toyin Abraham àti Lizzy Anjorin Lizzy Anjorin: Mi ò bẹ Toyin o!
Nígbà tí ó yọ ọ́ jáde, ọwọ́ rẹ̀ dẹ́tẹ̀, ó sì funfun bí ẹ̀gbọ̀n òwú.
Oríṣun àwòrán, others Àkọlé àwòrán, Itọju lasiko ni kete too ba ti kẹfin arun yii ṣe koko Imọtoto lo le ṣegun awọn arun gbogbo ati pe ki onikaluku tọju ayika rẹ.
Ọwọ́ ba ọlọ́pàá mẹ́rin tó pa ọmọ Nàíjììrà ní S.
10 Aifọkanbalẹ tabi gbigbẹ ọkan ara ẹni gbóná lai nidi.
“Ẹ dúró jẹ́ẹ́, kí ẹ sì mọ̀ pé èmi ni Ọlọrun.
Tí iléèṣẹ́ ológun Nàìjíríà sì sọ̀ pé l'óòtọ́ ni àwọn ọmọ ogun yìnbọn pa ọmọ̀ ẹgbẹ́ Shiite mẹ́ta ní agbègbè Zuba, tó wà ní ìlú Abuja.
Agbẹnusọ fun awọn ọlọpaa ni ipinlẹ Oyo, Olugbenga Fadeyi, ṣalaye pe oun gan an ko gbọ iru nkan to jó bẹẹ ri.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Jeremiah Addo: Ọmọ ọdún méjì tó ṣeeṣe kò mọ̀wé jù l'ágbàáyé Baba rẹ̀ tilẹ̀ mọ pé ọpọlọ ọmọ náà ti kọja ẹkọ ti ẹgbẹ́ rẹ̀ le kọ, nítori náà ilé ni wọn ti ń kọọ niwe, àti pé kìí fẹ́ báwọ́n ọmọde ẹgbẹ rẹ̀ ṣe bí ko ṣe àwọn àgbá tabi àwọn toi jùú lọ.
Ọpọlọpọ ariyanjiyan lo n lọ lori awọn nkan ti o ma n fa aisan iba si ara awọn eniyan, paapaa ni ilẹ adulawọ.
Ganduje ni ko si meni meji fun oun bi oun ba fidirẹmi ninu idibo naa ju pe ki oun ki ẹni to ba bori ku oriire.
 Àwọn ti wọ ́ n ń sọ èdè yìí jẹ ́ àádọ ́ jọ ẹgbẹ ̀ rún .
Rene sọ wipe: ''An gbe ni abule wa l'alafia ki awọn soja Cameroon to ja wọ aarin wa.
Kete lẹyin eyi la kan si ileeṣẹ to n ri si ọrọ awọn obinrin.
EFCC fẹ́ bẹ̀rẹ̀ ìwádìí Fayoṣe Ekiti!
Irú aṣọ kan náà tí wọ́n ṣe iṣẹ́ ọnà sí lára ni kí wọ́n fi ṣe àmùrè rẹ̀.
O fikun pe ni aago mẹjọ si mẹsan owurọ oni to de ibẹ, ko si ẹnikẹni to yọju lati se ipalẹmọ fun eto isinku naa.
Bí a bá wí pé àwa kò dẹ́ṣẹ̀ rí, a mú Ọlọrun lékèé, ọ̀rọ̀ rẹ̀ kò sì sí ninu wa.
Lẹyin naa ni wọn fi panpẹ ofin mu Kingsley, to si foju bale ẹjọ labẹ ofin to rọ mọ iwa ọdaran ti wọn gbe kalẹ lọdun 2006.
O Fagunwa ni wọn ti gbọ nipa Igbo Olodumare.
Amọ Mark Zuckerberg ti ja wa sẹyin ninu awọn ọlọla agbaye ni ọdun to kọja, ti oludasilẹ ile isẹ Amazon, Jeff Bezos, si di ọkunrin to lowo julọ lagbaye.
Àwọn ọmọ Haṣumu jẹ́ ọọdunrun ó lé mejidinlọgbọn (328).
Awọn kan ni kii ṣe ọrọ ibọn yiyin nikan bikoṣe yiyẹ foonu eeyan wo ati ifiyajẹni.
Amọ, awọn oniwadii imọ ijinlẹ ni Brazil naa fikun wi pe, aayan ti awọn fi se burẹdi yii kii se iru aayan ti wọn n rin kaakiri nilẹ n lẹ, sugbọn eleyii ti wọn didi tọju lati se ara loore ni ayika Ariwa Ilẹ Afirika ni.
Nígbà tí wọ́n bá mú ọ̀rá ẹran wá fún ẹbọ sísun, tí wọ́n mú itan ẹran tí wọ́n fi rúbọ, ati igẹ̀ àyà rẹ̀ fún ẹbọ fífì níwájú OLUWA, yóo máa jẹ́ tìrẹ, ati ti àwọn ọmọ rẹ, gẹ́gẹ́ bí ìpín yín títí ayé, gẹ́gẹ́ bí OLUWA ti pa á láṣẹ.
A o ranti pe o ti to obinrin mẹrin ati ọkunrin kan, Mujeeb Tirimisiyu, Barakat Bello, Grace Oshiagwu, Azeezat Shomuyiwa ati Olusayo Fagbemi, ti wọn ti pa ni Akinyele naa, ti awọn ọlọpaa ko si ti mọ awọn eeyan to pa wọn.
n ò mọ ìgbà tí oorun tún rá mi lọ pàfe .
A ó ṣèrànwọ́ fáwọn ẹbí ọlọ́pàá tó bá rògbòdìyàn EndSARS lọ láti inú N500m tí a yà sọ́tọ̀- Makinde Ọpọ awọn ololufẹ ẹgbẹ agbabọọlu Gimnasia y Esgrima lo wa nita ile iwosan ti wọn ti ṣiṣẹ abẹ fun Maradona lati fihan pe gbọin-gbọin lawọn wa lẹyin rẹ.
Sugbọn ileesẹ ologun ilẹ wa ti fesi lori ẹsun naa, to si ni oun ko mọ ohunkohun nipa rẹ.
Ó wí fún mi pé àwọn alufaa tí ń mójútó tẹmpili ni wọ́n ni yàrá tí ó kọjú sí ìhà gúsù.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Wòólì Alfred kú lọ́dún 1964, ó tún padà wà sí ìlú Agelu f'ọ́jọ́ mẹ́rìnlá!
Mò ń ṣe àárò ìwé yìí gidigidi ní óò.
Ẹ̀mí èṣù ni Coronavirus, kò leè ran ọmọ Ọlọrun - Ààrẹ Tanzania Òní ni ìgbẹ́jọ́ Oyo-Ita àti EFCC nílé ẹjọ́ gíga Abuja Èyí làwọn ayẹyẹ nlá tí kò ní wáyé nítorí coronavirus Ìgbésẹ̀ ìjọba láti kojú àrùn coronavirus ń pani lẹ́rìn ín- Pásítọ̀ Adeboye O ní àwọn ti fi ara àwọnnkalẹ fun àyẹwò báyìí ti àwọn si ni ìgbàgbọ́ pé akan ni èsì rẹ yóò jásí.
Ngendera Albert: Mi ò fẹ́ kí wọ́n máa pa ọ̀ọ̀nì ni mo ṣe ń rà wọ̀n
Irufẹ igba yii si lee to meji, mẹta tabi ju bẹẹ lọ niwaju awọn ayaba to n tigba.
Èmi gan ṣẹ̀ṣẹ̀ gbé eégún tè mi ni àná ni ààrín agboolé sì ni mó ti gbée, nítori náà gbogbo ẹlẹsìn ìbílẹ̀ ló n gbàdúrà kí ààrùn yìí kúrò nilùú, sùgbọ́n lásìkò yìí, kí gbogbo elégún sàdúrà nígbàlẹ̀ wọ́n."
Iroyin tun so pe awon dokita ati olutoju eyin nikan lo wa nile-iwosan lati pese itoju fun awon alaisan sugbon awon osise eleto ilera JOHESU  nikan ni won gunle iyanselodi.
epo robi lorile ede Naijiria, (Independent Petroleum Marketers Association of
Obinrin onisowo naa ati afẹsọna rẹ ni wọn wa ninu ọkọ Toyota Highlander lasiko ti wọn ji obinrin naa gbe.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, World Diabetes Day: Ọdún kọkandinlogun ti mo ti wà lẹ́nu itọ ṣúgà nìyí Ìròyìn òfégà Márùn-ún to ti fẹ́ẹ̀ pín Naijiria yẹ́lẹyẹ̀lẹ sẹ́yìn Ẹ fí omí iyọ wẹ̀ nítorí Ebola: Ní ọdún ọdún 2014 tí àìsàn ẹbola wọ orílẹ̀-èdè Naijiríà ní ìròyìn kan gba ìgbòrò kan pé báàlẹ Igala, ilú kan ipinlẹ Kogi ni ki àwọn ènìyàn máa fi omí iyọ wẹ̀ kí wọ́n máa ba ni àìsàn ebola.
O ni nibi ipade yii ni wọn yoo ti gbe ofin kalẹ fun Naijiria eyi ti yoo foju sun idagbasoke awọn ọmọ orilẹede yii.
Alábòyun ṣe iṣẹ́ abẹ pẹ̀lú abẹfẹ́lẹ́, ó gbé ọmọ jádé nínú ara a rẹ̀ Awọn ọmọ ile igbimọ yii rọ gbogbo awọn alaga ijọba ibilẹ lati ko gbogbo ẹru ijọba to ba wa lọwọ koowa silẹ.
E̩nì kò̩ò̩kan ló ní è̩tó̩ sí òmì nira láti ní ìmò̩ràn tí ó wù ú, kí ó sì so̩ irú ìmò̩ràn bé̩è̩ jáde; è̩tó̩yìí gbani láàyè láti ní ìmò̩ràn yòówù láìsí àtakò láti ò̩dò̩ e̩nìké̩ni láti wádìí ò̩rò̩, láti gba ìmò̩ràn ló̩dò̩ e̩lòmíràn tàbí láti gbani níyànjú ló̩nàkó̩nà láìka ààlà orílè̩‐èdè kankan kún.
fenuko le lori, eyi si ni ki aare gbe lo siwaju ile igbimo asoju-sofin.
Ẹ wo fidio naa ni ẹkunrẹrẹ ninu fọ́nrán tó wà lókè yìí.
Ẹ̀rù ba gbogbo àwọn tí wọ́n lọ bá Adonija jẹ àsè, gbogbo wọ́n bá dìde, olukuluku bá tirẹ̀ lọ.
Ìpìlẹ̀ kinni, òkúta iyebíye oríṣìí kan, ekeji oríṣìí mìíràn, ẹkẹta oríṣìí mìíràn, ẹkẹrin, bẹ́ẹ̀; 
Ẹkunrẹrẹ iwadii nipa iroyin naa laa mu wa fun yin laipẹ.
Forúkọ sílẹ̀ nínú ìròyìn yìí Ilé ẹjọ́ yá lórí òfin CAMA tó fẹ́ gba àkóso ilé ìjọsìn, tẹ ẹ̀tọ́ aráàlú mọ́lẹ̀ - SERAP Kí ló ń ṣẹlẹ̀ lọ́wọ́ sí Mamman Daura àti ìlera rẹ̀?
Agbábọ́ọ̀lù Manchester United tẹ́lẹ̀, Marouane Fellaini lùgbàdì àrun coronavirus Nítorí coronavirus, Mikel Obi sá kúrò ní ikọ̀ Trabzonspor Ààrẹ Buhari sún eré ìdárayá àpapọ̀ Edo 2020 síwájú Ọmọkùnrin mi ti kó coronavirus, ẹ bá mi fi sínú àdúrà yín- Atiku Ẹlòmíràn tún ti lùgbàdì àrùn Corona Virus nílùú Abuja àti Eko Ijọba ìpínlẹ̀ Eko àti Kwara ti kéde konile o gbélé Ìgbésẹ̀ ìjọba láti kojú àrùn coronavirus ń pani lẹ́rìn ín- Pásítọ̀ Adeboye Ojo ṣoju ẹgbẹ agbabọọlu Sunshine ilu Akure fun igba pipẹ ko to darapọ mọ Enyimba lọdun 2019.
Mo ti buwọ́lu àdínkù owó orí nítorí ìrọ̀rùn àwọn èèyàn ìpínlẹ̀ Ogun lásìkò Covid 19- Dapo Abiodun Iná sọ nínú ilé Big Brother tó ń lọ lọ́wọ́ ní Cameroon Buruji Kashamu jẹ́ ènìyàn tó nífẹ̀ aráàlú- Gómínà Dapo Abiodun Iná jó àwọn ènìyàn 10 tó ń gbà ìwòsàn arùn Coronavirus níbùdó ìtọ́jú Baba Obasanjọ kò ní àrùn Coronavirus- NCDC Bakan naa lo sọ pe ijọba ti gbaradi lati tẹle gbogbo ilana ti ijọba apapọ la kalẹ lori ṣiṣi ileewe pada lasiko idanwo naa.
“OLUWA fún mi ní èrè òdodo mi,ó san ẹ̀san fún mi, nítorí pé mo jẹ́ aláìlẹ́bi.
Bakan naa ni Alaga fun ẹgbẹ awọn Awọnlẹ ati awọn Onimọ owo ori nnkan ini ni Ipinlẹ Eko, Ogbẹni Olurogba Orimolade rọ ijọba pe ko yẹ ki wọn gbe iṣiro owo-ori naa le nnkan ini, iṣiro owo ori ẹni kọọkan lọdọọdun lo yẹ ki wọn gbe e le.
O ni gẹgẹ bo ṣe wa ninu ofin orilẹede Naijiria ti ọdun 1999, awọn yoo maa da abo bo ẹtọ gbogbo ara ipinlẹ Oyo.
eyi ti a si n gbiyanju lati yanju rẹ.
Igba akọkọ si ree ti orilẹede Ireland yoo da owo Abacha pada eyi to gbẹsẹle lọdun 2014.
O óo wá mọ̀ pé èmi ni OLUWA.
 yorúbà a máa pòwe pe : bí óunjẹ bá ti kúrò nínú ìṣẹ ́ , ìṣẹ ́ bùṣe .
Yari ni awọn gomina setan lati se atilẹyin fun fifi owo kun owo osisẹ, amọ ko si owo tabi ohun alumọni ti wọn yoo fi san afikun owo osu naa.
Igbimọ olugbẹjọ naa wa pasẹ fun ajọ Inec lati tun eto idibo gomina mii se nipinlẹ Bayelsa laarin aadọsan ọjọ pere.
Igba kan n lọ, igba kan n bọ, ẹnikan ko lo ilé aye gbo ni awọn Yorùbá n wi.
Má ṣe gba ọ̀nà ẹni ibi,má sì ṣe rin ọ̀nà eniyan burúkú.
O fẹ́ràn gbogbo ọ̀rọ̀ ìbàjẹ́,Ìwọ ẹlẹ́tàn!
Ṣugbọn Kristi ti dé, òun sì ni Olórí Alufaa àwọn ohun rere tí ó wà.
 Ó yọ àkọlé àwo nàá jáde làti inú ìwé ìtàn ( chinua achebe tí ìwé náà sì fi òye inú orin náà hàn .
Oríṣun àwòrán, Facebook/Seyi Makinde Àkọlé àwòrán, Seyi Makinde: Gómìnà ìpínlẹ̀ Oyo kéde dúkìá tó tó #48bn Gómìnà Makinde ìpínlẹ̀ Oyo kéde dúkìá tó tó #48bn Gomina Seyi Makinde ti ipinlẹ Oyo ti kede dukia to to biliọnu mejidinlaadọta naira gẹgẹ bi ohun ini rẹ.
Leung Hoi Ching ni ó kọ́kọ́ kọ ìròyìn yìí tí a sì tẹ̀jáde ní èdèe Chinese lórí ilé ìgbéròyìn jáde ará ìlú Hong Kong, Stand News ní ọjọ́ karùn-ún-dínlógún, Oṣù Èrèlé, ọdún-un 2019.
Àwọn mààlúù meje tí wọ́n rù, tí wọ́n sì rí jàpàlà jàpàlà tí wọ́n jáde lẹ́yìn àwọn ti àkọ́kọ́, ati àwọn ṣiiri ọkà meje tí kò yọmọ, tí afẹ́fẹ́ ìhà ìlà oòrùn ti pa ọlá mọ́ lára, àwọn náà dúró fún ìyàn ọdún meje.
ohun tí n óo ṣe sí yín nìyí: n óo rán ìbẹ̀rù si yín lójijì, àìsàn burúkú ati ibà tí ń bani lójú jẹ́ yóo bẹ́ sílẹ̀ láàrin yín, ẹ óo sì bẹ̀rẹ̀ sí kú sára.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ilé aṣòfin Èkìtì lé aṣofin Akinniyi fún ẹ̀sùn oorun sísùn 14 Òkùdu 2018 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Wọ́n tún fi ẹ̀sùn kan aṣòfin náà pé ó ń dún mọ̀huru-mọ̀huru mọ́ àwọn akẹgbẹ́ rẹ̀ Awọn aṣofin ipinlẹ Ekiti ti ke si ọkan ninu wọn pe ko lọ rọọkun nile fun igba diẹ Wọn fi ẹsun igbesumọmi ati oorun àsùnjù kan an pe oorun rẹ pọju laarin ọdun mẹta to ti wa nile igbimọ aṣofin naa.
 nípa ìdí èyí , àwon ìlú tí ó yi ká bí : ede , Ìbàdàn , àti Ègbá bèé , wón ròó kí ó mú àrokò àláfíà kí ó má se bá Òyó jagun , kúrunmí gégé bí ológun ti tafà ogun ná ó sì n retí ìjà Òyó .
 babalawo tì wọn ni ko wo aya onikoromebi ko ni ètọ ́ lati ṣe èyí .
Eyi si le waye bi lọkọlaya ba n wa ọmọ, ti wọn si ni ki ọkọ wa fi atọ silẹ, ki wọn le fi ilana IVF gbe sinu iyawo rẹ.
Ẹ júbà ẹni tí ó dá ọ̀run ati ayé, òkun ati gbogbo orísun omi.
Láti ìgbà ti ààrùn náà ti bẹ̀rẹ̀ ní ọjọ kẹtàdílọ́gbọ̀n oṣù keji ẹdún 2020, ni o tí tàn kálẹ̀ si ìpínlẹ̀ mẹ́rìnlélọ́gbọ̀n àti Abuja báyìí.
nínú ẹ ̀ kọ ́ nípa àwùjọ-ẹ ̀ dá , a tún máa ń sọ ̀ rọ ̀ nípa ìsòro tó ń kojú ìbágbépọ ̀ ẹ ̀ dá .
Ni bayii mo ti di ẹlomiran tori ẹkọ ti mo kọ lọdọ gbogbo wọn.
Bí wọ́n ti dúró tí wọ́n tún ń bi í, ó gbé ojú sókè ní ìjókòó tí ó wà, ó wí fún wọn pé, “Ẹni tí kò bá ní ẹ̀ṣẹ̀ ninu yín ni kí ó kọ́ sọ ọ́ ní òkúta.
Saraki ni, ó fihan pe, Naijiria ni lati fọwọ́ líle mu ọrọ aṣilo oògùn bayii.
Shogunlẹ ko sai fi kun pe ti ẹnikẹni ba dun ikoko m ọmọ Naijiria kankan lori igbesẹ naa lẹyin ti wọn ba ti tle awọn ilana ofin to rọ mọ sise bẹẹ, ki wọn yara kan si ohun kia-kia.
Se bi iya nla ba gbe ni sanlẹ, ke ke ke mii tun maa n gori rẹ ni.
Wò ó bí Alaafin àti aya àkọ́fẹ́ rẹ̀, Olorì Abibat ṣe pàdé ní èwe Bí Gómìnà Makinde bá ṣẹ̀ mí, lẹ́tà lásán ló jẹ mí- Aláàfin Ọ̀yọ́ Àwọn onílù mí ló ń tú àṣírí ìkà èèyàn tó bá wọ ààfin mi - Aláàfin Wo ọ̀nà tí àwọn ‘ẹ̀lẹ̀ Daddy’ gbà dé ààfin Ọyọ Ọba Adeyemi ni ko yẹ ki ijọba ma a dukoko mọ wọn, o yẹ ki ijọba fawọn mọra lati gbọ ẹdun ọkan awọn ọdọ ni.
Àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ dá a lóhùn pé, “Níbo ni a óo ti rí ohun tí a óo fún gbogbo àwọn wọnyi jẹ ní aṣálẹ̀ yìí?
Ó sọ fún wọn pé, “Ní òtítọ́ ẹ lè pa òwe yìí fún mi pé, ‘Oníṣègùn, wo ara rẹ sàn!
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Mo fẹ́ di ẹni gíga' Ọgbẹni Nwajiuba sọ pe ileeṣẹ eto ẹkọ yoo gbe ilana jade lori bi nkan yoo ṣe lọ, ti awọn akẹkọọ ba pada sileewe.
Oríṣun àwòrán, Getty Images O ṣalaye pe iru arun yii wọ pọ lapa ariwa orilẹede Naijiria, nibi ti iru igbeyawo bẹẹ ti wọpọ.
Ẹni tí ó bá fi Tẹmpili búra, ohun tí ó wà ninu rẹ̀ ati Ọlọrun tí ó ń gbé inú rẹ̀ ni ó fi búra pẹlu.
Nígbà tí Elija parí ọ̀rọ̀ rẹ̀, Ahabu fa aṣọ rẹ̀ ya láti fi ìbànújẹ́ rẹ̀ hàn, ó bọ́ wọn kúrò, ó sì wọ aṣọ ọ̀fọ̀.
Wọn ni kete ti ọdun Ileya ba ti pari ni ki awọn akẹkọọ onidanwo pada sile iwe koowa wọn.
 gbogbo ìwà àti ìṣe yorùbá ló ní orin tí ó bá wọn mu rẹ ́ gí yálà nígbà ayọ ̀ , nígbà ìbànújẹ ́ lẹ ́ nu iṣẹ ́ tàbí nígbà tí ọwọ ́ bá dilẹ ̀ .
Kí n tóó máa bá ọ̀rọ̀ mi lọ mo níláti kọ́ dúpẹ́ lọ́wọ́ rẹ̀ fún aájò mi tí o ṣe nígbà tí mo wà lọ́dọ̀ rẹ.
Cute Abiola: Agbẹjọ́rò ni bàbá mi fẹ́ kí n ṣe àmọ́ àyànmọ́ mi ni àwàdà
O tún wí pẹ̀lú pé a níláti wá oúnjẹ ti òun fún òun, ìgbà tí mo sì bèèrè ounjẹ rẹ̀, o ní ẹ̀jẹ̀ ni oun ń mu.
" Mo fòpin sí àjẹbánu lórí owó ìrànwọ́ epo àti iná ọba, ní èlé ṣe wáyé - Buhari Ọlọ́pàá tó dá dókítà oníṣẹ́ abẹ dúró lásìkò ìséde, fa ikú alaboyún kan Ènìyàn 100 ló kó àrùn Coronavirus ní Nàìjíríà ní Ọjọ́ Aiku Wo ìdí tí wọ́n ṣe lé Erica dànù kúrò nílé BBNaija l'ọ́sẹ̀ yìí Ni ti fidio kan to n tan kalẹ lori ayelujara, nibi ti tọkọ-taya ti n jo ti awọn eeyan kan si n na wọn lowo, Aliyu ni kii ṣe ile ijọba ni Abuja ni wọn ti ya fidio ọhun, ṣugbọn iṣẹlẹ naa waye lẹyin ti iyawo dele ọkọ rẹ tan ni Kaduna.
ipade ti igbimo osise ba se lọjọ Ẹti.
Police Killing: Iléeṣẹ́ ní àṣìta ìbọn ló pa obìnrin nílùú Eko lọ́jọ́ Satide
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Coronavirus in Nigeria: Ẹ wo àǹfààní tó wà nínú àrùn Coronavirus Ẹnikẹni ko gbọdọ jade Mo n lọ ki ẹnikan ni ibikan ko si nigba ti ofin konile o gbele ba wa nita Ijọ ko ni fi aye gba ki awọn eeyan maa lọ ki ara wọn.
Wọn figbe yii ta si ijọba latari bi wọn ṣe ni awọn daran daran n dun mọhuru mọhuru mọ wọn ninu ilu wọn.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Alápinni: Kò sí ẹni to fẹ́ kọ́kọ́ kọ́ iṣẹ́ òṣèré bíi ti àtẹ̀yìnwá Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Aafin ọba naa si ni wọn ti kun ọmọde naa bii ẹni kun ẹran, lati fi se etutu fun Ọba Alaaye.
Awọn aye to ṣi silẹ ni kilaasi awọn akẹkọọ ti ijọba ko tii fun ni aye lati wọle pada, lo mu ki itakete si ara ẹni di irọrun fun awọn akẹkọọ to wọle pada lonii.
Jehoṣafati jọba lórí Juda, ẹni ọdún marundinlogoji ni nígbà tí ó gorí oyè.
Oun paapa sọ pe, inu okunkun birimu ni oun wa lasiko ti o n la nkan naa kọja.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Eyi joo jẹ idije alakọkọ fun Olivier Giroud fun Chelsea ninu idije Champions League Awọn ẹgbẹ mejeeji ti pade ni igba mejila - lati ọdun 2000.
pe egbe PDP ni yoo jawe olubori ninu eto idibo ti yoo waye ni ila Ariwa ohun.
13 Lõtọ́, lõtọ́, ni mo wí fún ọ, èmi yíò fún ọ lára Ẹ̀mí mi, èyí tí yíò fi òye fun iyè inú rẹ, tí yíò sì fi ayọ̀ kún ọkàn rẹ.
Bí èéfín tií pòórá,bẹ́ẹ̀ ni kí wọn parẹ́;bí ìda tií yọ́ níwájú iná,bẹ́ẹ̀ ni kí àwọn eniyan burúkú parun níwájú Ọlọrun.
Ihoho ni wọn ba oku Uwa ninu ile ijọsin kan ni Benin eyi to mu ki ọpọ bẹrẹ si ni ṣe iwọde kaakiri Naijiria.
Nínú èyí Olúwa sọ fún Joseph nípa àwọn àtúnṣe tí àwọn ènìyàn búburú ṣe nínú àwọn ojú ewé ìwé àfọwọ́kọ mẹ́rìndínlọ́gọ́fà lati ínú ìtumọ̀ ìwé ti Léhì, nínú Ìwé Ti Mọ́mọ́nì.
Láti ibẹ̀ ni ó ti kó egungun Saulu, ati ti Jonatani, ọmọ rẹ̀.
Lọjọ Ẹti ni Sujith ko si kanga nigba ti o n ba awọn ọrẹ rẹ ṣere.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Next Level"" Ààrẹ Buhari àti APC ló gbòde báyìí 25 Èrèlè 2018 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 21 Bélú 2018 Oríṣun àwòrán, TWITTER Àkọlé àwòrán, Reno Omokri ní ọjọgbọ́n kan ní Winthrop University ló ni àsíà 'Next Level' tí Buhari lò fún ìpolongo sáà kejí rẹ̀."
Oluwo Divorce: Ìdí tí Oluwo fi kọ Olorì rẹ̀ sílẹ̀ rèé.
Banki/ẹrọ ilewọ ipọowo(POS) Lati igba ti ipagọ naa ti n fẹ sii titi to ti di ilu nlaa Redemption City ni awọn alaṣẹ ijọ ti faaye gba ki awọn ileeṣ kọọkan wa maa ṣiṣẹ nib eyi ti yoo maye rọrun fun awọn olugbe ibẹ to bẹẹ ti wn ko ni nilo ati jade maa wa ohun ti wọn ba nilo kiri.
Nígbà náà ni mo wí lọ́kàn ara mi pé, Ǹjẹ́ àwọn ọkunrin wọnyi kò tún ń ṣe àgbèrè, pẹlu àwọn obinrin panṣaga burúkú yìí?
”Aare Buhari wa gbosuba fun asoju orile ede Britan fun gudu-gudu, meje yaya mefa ti o se lasiko igba ti o je asoju orile ede yii.
Bill Gates sọ pe irọ nla gbaa ni iroyin ọhun.
Báyìí ni a ṣe títí a fi la àfonífojì náà já, ṣùgbọ́n nígbà tì a là á já tán tí a wo ààrin wa a kò rí ọ̀kan nínú wa mọ́, ọkùnrin náà ni orúkọ rẹ̀ ń jẹ Ìbànújẹ́-ìsàlẹ̀ tí ó jẹ́ ẹnì kan tí ojú rẹ̀ kì í fa ni mọ́ra lọ́jọ́ kan, a máa di ẹnu ká duduudu.
Jẹ́ kí a wò bí Elija yóo wá gbà á là.
O ni ọrẹ timọtimọ ni awọn.
1 148453 Orilẹede Armenia 2344 79.
”Eto Awon OsiseAare so pe ijoba oun ti n se itopinpin ni gbogbo awon ipinle to wa lorile ede Naijiria nipa bi won se lo  owo orile ede Paris ati owo miiran ti won fun awon ipinle kan lati fi  san oso osu awon osise won.
Wọ́n bá bẹ̀rẹ̀ sí bẹ̀bẹ̀, wọ́n ní, “Ọkunrin mejila ni àwa iranṣẹ rẹ, tí a jẹ́ ọmọ baba kan náà ní ilẹ̀ Kenaani, èyí tí ó jẹ́ àbíkẹ́yìn wa wà lọ́dọ̀ baba wa nílé, ọ̀kan yòókù ti kú.
Bí ẹnikẹ́ni bá tọrọ nǹkan lọ́wọ́ yín, ẹ fún un.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Kaduna, Zamfara àti àwọn ìpínlẹ̀ tó ti ilé ìwé nítorií wahala Boko Haram àti ìdí míràn.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, OsunDecides: Adeleke kò jáwọn olólùfẹ́ tó fẹ́ wòran ijó rẹ̀ kulẹ̀ Agbẹnusọ ọlọpaa ni orilẹede Naijiria Jimoh Moshood Wọn ti wa rọọ bayi lati farahan niwaju ọlọpaa fun anfani ara rẹ.
Man U f'aṣọ iyì ya mọ́ Man City lára pẹ̀lú àmì ayò 2-0 Wo àwọn ìwà to le è ṣe àfarawé lára ọ̀rẹ́, èyí tó le ṣekú pa ọ́ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Fadeyi Oloro: Ọfọ̀, àyájọ́ kò ràn án lọ́jọ́ tí 'ṣó o láyà' bá a lálejò Nitori na, sisun ni ihoho yoo fun agọ ara rẹ ni anfaani lati ma gbona, eyi yoo si ran ọ lọwọ lati sun daada.
Wọ́n kò pa ẹnikẹ́ni sí ààfin Ṣọun Ogbomosọ, òkú tí àwọn ọdọ́ gbé wa ni ọlọ́pàá wọ́ jáde- Agbẹnusọ Ṣọ̀un Àwọn aṣòfín ní ìpínlẹ̀ Edo ti yọ Abẹnugan Ilé, Francis Okiye bí jìgá Mọ̀ sí i nípa díẹ̀ lára àwọn èèyàn tí ikú wọn 'láti ọwọ́ ọlọ́pàá' milẹ̀ tìtì ní Nàìjíríà Ènìyàn 17 kú nínú ìjàmbá ọkọ̀ mẹ́ta tó ṣẹlẹ̀ ní Osun, òpópónà Ibadan sí Eko àti Delta Ẹ bá mi tú gbogbo àwọn Olùwọ́de #End SARS tí ẹ mu ní ìpínlẹ̀ Eko sílẹ̀- Gomina Sanwo Olu Kò gbọdọ̀ sí ìfẹ̀họ́núhàn EndSARS ní ìpínlẹ̀ Rivers - Gomina Wike Oríṣun àwòrán, Empics Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, EndSARS protest in Nigeria: Mr Macaroni, Falz, Wizkid, Tiwa Savage àtàwọn míì ṣe ìwọde Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí EndSars protests: Fọ́tò àti ìtàn èèyàn tí ikú wọ́n ní ọ́wọ́ ọlọ́pàá Nàìjíría nínú16 Ọ̀wàrà 2020 ENDSARS: Wo ìgbà mẹ́rin tí ìjọba ti tú ikọ̀ ọlọ́pàá SARS ká sẹ́yìn ṣùgbọ́n.
Osinbajo ní ó jẹ́ ohun ìdunnu lati ni iru arabinrin Folu Adeboye lawujọ àwọn obínrin gẹgẹ bíi oniwàásù àti àwokose fawọn obinrin.
"Eniola sọ pe ""Eẹyin eeyan ẹ ma ran mi lọ si iboji ọsan gangan, ni ṣe ni sanran o, mi o ji yin lẹran jẹ."
Wọ́n fi abẹ́rẹ́ ṣe iṣẹ́ ọnà sára aṣọ títa ẹnu ọ̀nà àgbàlá náà, pẹlu aṣọ aláwọ̀ aró, ati aṣọ elése àlùkò, ati aṣọ pupa, ati aṣọ funfun onílà tẹ́ẹ́rẹ́tẹ́ẹ́rẹ́, ó gùn ní ogún igbọnwọ, ó sì ga ní igbọnwọ marun-un gẹ́gẹ́ bí àwọn aṣọ títa ti àgbàlá náà.
 O ni, ope pupo lowo eledumare fun ebun emi gigun ti o fi ta aare Buhari lore.
Lẹ́yìn ọ̀pọ̀lọpọ̀ wákàtí tí a fi ọ̀rọ̀ wá Wakabi lẹ́nu wò, tí wọn kò sì jẹ́ kí ó rí agbẹjọ́rò, a dá a padà sí Uganda.
Ogunlọgọ awọn eeyan lo peju si Hagley Park, lẹgbẹ Mọsalaṣi Al-Noor mosque, lati kopa ninu irun Jimọ iranti fun awọn to ba iṣẹlẹ naa lọ.
pé wọn kò gbọdọ̀ gbàgbé láti máa pa àwọn ọjọ́ Purimu mọ́ ní àkókò wọn, gẹ́gẹ́ bí àṣẹ tí Modekai ati Ẹsita Ayaba pa fún àwọn Juu, ati irú ìlànà tí wọ́n là sílẹ̀ fún ara wọn ati arọmọdọmọ wọn, nípa ààwẹ̀ ati ẹkún wọn.
Nígbà tí ó tán di ọjọ́ kẹta wọ́n mú ẹnì kan nínú wa, ọ̀kan nínú àwọn tí a bá ní ibẹ̀ ni, wọ́n tún pa eléyìínì fún ọba wọn jẹ.
40 Àti láti ṣe àkóso àkàrà àti wáìnì—àwọn àpẹrẹ ẹran ara àti ẹ̀jẹ̀ ti Krístì—
Alakoso ilu Paris Anne Hidalgo wa lara awon eniyan ti won gboriyin fun akoni omo odun mejilelogun naa, ni eyi ti o so pe, oun tip e ero alagbe ka re lati dupe lowo re.
Wo àpẹẹrẹ, àti ǹkan tó ń fa 'colon cancer' tó pa Chadwick Boseman 'Black Panther' Aarun Colon cancer lo ṣokunfa iku to pa gbajugbaja oṣere Chadwick Aaron Boseman 'Black Panther'.
Pliskova ni olukopa ti o koko pegede sinu ipele keji idije ohun.
Èwo ni ó ṣe pataki jù, ọrẹ ni, tabi pẹpẹ ìrúbọ tí ó sọ ọ́ di ohun ìyàsọ́tọ̀?
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ijede Lagos Boat Mishap: Mi ò rí irí ìṣẹ̀lẹ̀ yìí rí láyé mi!
Ó bá sọ fún àwọn eniyan pé, “Ọjọ́ mẹfa wà tí a níláti fi ṣiṣẹ́.
O ṣalaye siwaju si pe awọn kọlọnbiti ẹda kan ni wọn lẹdi apo pọ pẹlu awọn kan nilẹ okere lati maa da eto alaafia ru ni Naijiria.
Bí èmi bá fẹ́ràn yín pupọ, ṣé díẹ̀ ni ó yẹ kí ẹ̀yin fẹ́ràn mi?
“Ṣugbọn ẹ̀yin ṣe oríire tí ojú yín ríran, tí etí yín sì gbọ́ràn.
Aṣẹ naa n fẹ ki wọn o ko gbogbo awọn ọkọ akẹru ti wọn wa gunlẹ si awọn ojupopo ati ori afara to wa ni Apapa ati awọn agbegbe to wa nitosi rẹ kuro.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Eefin to n jade ni ori ile nikan ni apẹrẹ pe idibo n lọ lọwọ ninu ile Lẹyin eyi ni wọn yoo dana sun awọn iwe naa - eefin rẹ yoo si han si awọn to n woran ni ita.
Wọ́n bá ranṣẹ lọ pe àwọn ọba Filistini jọ, wọ́n sì bi wọ́n pé, “Báwo ni kí á ti ṣe àpótí Ọlọrun Israẹli yìí?
yii lati mu eto idagbasoke to mọnyan lori ba orile ede Naijiria.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ọrọ lori Brexit O ni nibayii, awọn oyinbo alawọ funfun lati orilẹ-ede miran ni wọn kọkọ maa n riṣẹ ki awọn alawọdudu to ri, ṣugbọn o sọ pe ko si ẹni to le sọ pato bi gbogbo nnkan ṣe maa ri ti Ilẹ Gẹeṣi ba fi ajọ EU silẹ.
Iná Ibadan: Àwọn olùgbé inú ilé ń rawọ́ ẹ̀bẹ̀ fún ìrànwọ́
Èmi, èmi ni mo pa ẹ̀ṣẹ̀ yín rẹ́,nítorí ti ara mi;n kò sì ní ranti àwọn ẹ̀ṣẹ̀ yín mọ́.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Awọn ọdọ Ondo fẹ̀họ́nù hàn lórí ìṣekúpani Funke Olakunrin Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Awọn ọdọ Ondo fẹ̀họ́nù hàn lórí ìṣekúpani Funke Olakunrin 15 Agẹmo 2019 Awọn ọdọ ipinlẹ Ondo n fẹhọnu han pe ki awon Fulani o kuro lagbeegbe wọn, leyin ti awọn agbebọn pa Funke Olakunri to jẹ ọmọ adari ẹgbẹ Afẹnifẹrẹ lorilẹ-ede Naijiria.
“Ègún ni fún ọkà rẹ ati oúnjẹ rẹ.
Yeye Omolara Fashola to tun jẹ amofin nipa ọrọ oju omi ṣalaye bo ṣe yan lati di yeye Olokun leti okun eyi ti ọpọlọpọ maa n pe ni Yemoja nilẹ Yoruba.
Ọba ati àwọn ìjòyè pàṣẹ fún àwọn ọmọ Lefi pé kí wọ́n kọ orin ìyìn Dafidi ati ti Asafu, aríran.
 Èyí sí lo fa to fi ṣeṣe fún ifá láti mọ ìwà wọn ó wú oniruuru ìwà yìí jáde torí àjọsepọ ̀ rẹ ̀ pẹ ̀ lú àwọn obìnrin .
Kí ló dé tí ìjọba kò ṣe lọ nọ́mbà àsùnwọ̀n owó ni banki láti fi pín owó náà àti pé ọna wo ni wọn gba mọ àwọn aláìní.
Ẹlẹgan an nikan ni yoo sọ pe ẹlẹsẹ ayo Odion Ighalo n fakọyọ lọwọlọwọ fun ẹgbẹ agbabọọlu rẹ, Manchester United.
bí ó bá dá nǹkan tí ẹni tí ó jẹ ẹ́ ní gbèsè fi ṣe ìdúró pada, tí ó sì dá gbogbo nǹkan tí ó jí pada, tí ó ń rìn ní ọ̀nà ìyè láì dẹ́ṣẹ̀, dájúdájú yóo yè; kò ní kú.
Won ni gbogbo osise ijoba patapata to wa lorile
O kọ ile ẹkọ girama mẹtalelọgọta, Mọsalasi ati Sọọsi mọkanlelọgọfa, ibudo iyawekawe mọkanlelogun, ipese ibudo omi mimu mẹrinlelogun yika naijiria, to si tun jẹ baba isalẹ fun ẹlẹgbẹjẹgbẹ mọkandinlaadọjọ MKO Abiọla jẹ alagbo nla, o ni ọpọ iyawo, to si bi ọmọ pupọ.
Àwọn obinrin bá sọ fún Naomi pé, “Ìyìn ni fún OLUWA, tí kò ṣe ọ́ ní aláìní ìbátan, kí OLUWA ṣe ọmọ náà ní olókìkí ní Israẹli.
Ọlọrun tún fi kún un fún Mose pé kí ó sọ fún àwọn eniyan Israẹli pé OLUWA Ọlọrun àwọn baba wọn, Ọlọrun Abrahamu, Ọlọrun Isaaki, ati Ọlọrun Jakọbu, ni ó rán òun sí wọn.
Díẹ̀ lára àwọn ǹkan ti wọ́n ń sọ lójú òpó Twitter rèé Big Brother Naija season 5 eviction: Nengi, Kaisha, Laycon, Praise àbí ta ni ilé ń pè?
Kábíyèsí, mo mọ oore tí ẹ ṣe fún mi, ki Olódùmarè jẹ́ kí n lè fi hàn yín nípa ìwà mi pé ipò pàtàkì ni ẹ wà ní góńgó orí ọkàn mi.
gomina ati igbimo asofin ipinle ,yoo waye ni 
Awọn yoku ni Osi Balogun Tajudeen Ajibola; Asipa Olubadan, Eddy Oyewole; Ekarun Olubadan Amidu Ajibade ati Ekarun Balogun Kola Adegbola.
Ṣugbọn láti ọjọ́ náà ni Joṣua ti sọ wọ́n di ẹni tí ó ń ṣẹ́ igi, tí ó sì ń pọn omi fún àwọn eniyan Israẹli, ati fún pẹpẹ OLUWA.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ọjọ́ ìdájọ́ déé!
Kanu ni wọn ti fi ọkunrin kan, to pe orukọ rẹ ni Jubril lati orilẹede Sudan, rọpo aarẹ Naijiria to ni o ti di oloogbe ọhun.
Nígbà tí àwọn òbí ọmọ yìí retí rè tí wọn kò ríi ni àwọn náà bá gbéra ó di oko.
 hóró dna le jẹ ́ olóbìírípo tàbí onígbọọrọ , bẹ ́ sì ni inú rẹ ̀ le ní núkléótídì tó pọ ̀ tó 100,000 dé 10,000,000,000 lórí èwọ ̀ n gígún kan .
ẹnikẹ́ni ninu wọn kò ní dé ilẹ̀ tí mo ti ṣe ìlérí fún àwọn baba wọn.
Ẹ Dárí Ji Ẹni Tí Ó Ṣe Àìdára.
8 % je elesin kristi ( 27.
Òun ló dífá fún Alákọ̀wé ní ìlú Bath, tó ju pọ́ùn méjì sínú omi.
Brazil vs Nigeria: Super Eagles ṣetán láti gbéná wojú Brazil Ẹgbẹ agbabọọlu Naijiria, Super Eagles ti ṣetan lati gbena woju ikọ agbabọọlu ilẹ Brazil lọjọ Aiku lorilẹede Singapore.
“Bí ọkunrin kan bá ní ọgọrun-un aguntan tí ọ̀kan sọnù ninu wọn, ṣé kò ní fi mọkandinlọgọrun-un yòókù sílẹ̀ ní pápá, kí ó wá èyí tí ó sọnù lọ títí yóo fi rí i?
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Funmi Adewara: Tele Medicine' ní a fi ń ṣàyẹ̀wò èèyàn ìdá ọgọtá láti dènà ìtànkálẹ̀ Covid Ohun ti wọn n beere fun ni idi ti awọn ọlọpaa ṣe yin ibọn pa Precious.
Mo bá rí àwọn ẹranko ẹlẹ́sẹ̀ mẹrin ati àwọn ẹranko ìgbẹ́ ati àwọn ẹranko tí ń fi àyà wọ́, ati àwọn ẹyẹ ojú ọ̀run.
Nibayii, Arakunrin Jeremy n koju ẹsun ifipabanilopọ ati fifi ọwọ kan ni lọna aitọ oniga-ogun laarin obinrin mẹtalelogun.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Danfo Driver: Mad Melon' ọ̀kan lára àwọn akọrin Danfo Driver 27 Owewe 2019 Oríṣun àwòrán, Danfo Drivers, Mountain Black & Mad Melon Ni ọpọ igba, wọn lee ma fi orukọ ranti eniyan ṣugbọn iṣẹ ti ẹni bẹẹ ṣe le maa fọhun koda bi ẹni na ko ba si ni sakani ibi to ti ṣe iṣẹ naa.
Àwọn ọmọ ogun náà yọ́ wọ ìlú jẹ́ẹ́, bí ẹni pé wọ́n sá lójú ogun, tí ìtìjú sì mú wọn.
O ti ati ipo Emir bọ si ipo Emir Oríṣun àwòrán, Aminu Ado Bayero/Instagram Ṣaaju ki wọn to fi Aminu Ado Bayero jẹ Emir ilu Kano,oun ni Emir ilu Bichi to jẹ ọkan lara awọn ilu to wa labẹ Emirate ilu Kano.
Wọn ko gba bọọlu bo se yẹ amọ wọn koju wa bo se yẹ.
14 Agẹmo 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 15 Agẹmo 2019 Oríṣun àwòrán, Google Àkọlé àwòrán, Ìwádìì Oxfam fihàn pé owó àwọn olówó yìí tó 29.
"Aaye taa sì n ko awọn ti ilẹ ẹjọ ti dajọ ẹwọn fun ni aaye yi jẹ"" Buhari, máṣe gbá ìpànìyàn Lekki sórí ààtàn, kò yẹ́ kí ológun yin ọ̀dọ́ níbọn - Bode George 2015 ni mo ti ń kígbe pé gudugbẹ̀ máa já ní Nàíjíríà - Oyedepo Àwọn oníjàgídíjàgan kọlu aàfin Oba ìlú Eko àti iléesẹ́ ìròyìn LTV Mọ̀ nípa DJ Switch, akíkanjú obìrin tó sàfihàn fídíò ìpànìyàn Lekki bó ṣe ń wáyé Ooni Ogunwusi àti Wole Soyinka kòrò ojú sí ìṣẹ̀lẹ̀ Lekki Tollgate Oríṣun àwòrán, Getty Images ""Ẹ ràn wá lọ́wọ́ láti rí àwọn ẹlẹ́wọ̀n tó sálọ ní Oko àti Benin padà"" Ileesẹ to n sakoso ọgba ẹwọn ni oun ti n gbe igbesẹ lati da nnkan pada sipo lawọn ọgba ẹwọn mejeeji."
Àwọn akópa tó ti jáwé olúborí ní BBNaija sẹ́yìn àti ibi tí wọ́n wà báyìí Kí ìjọ mi ní Sagamu le gbòòrò ni mo fi ń ṣiṣẹ́ ajínigbé pawó - Pásítọ̀ Ológun kan tí ọpọlọ rẹ̀ kò pé, ló pa akẹẹgbẹ́ rẹ̀ tó ṣẹ̀ṣẹ̀ ṣègbéyàwó - Iléeṣẹ́ ológun jẹ́wọ́ Ìjọba Oyo fẹ́ mọ ikú tó pa akẹ́kọ̀ọ́ UI níléeṣẹ́ tó ń ṣe ọṣẹ Ẹ̀rí diẹ wa lara ibeere Aare Trump lasiko yii nitori pe Orilẹ-ede America ti fẹ́ safikun si ọna idibo nipa fifi ransẹ nitori Covid 19 ninu idibo osu kọkanla naa.
Ile igbimo asojusofin lorilẹede Naijiria ti buwọlu abadofin to fi le le pe ẹni to ba lo nylon yoo fi ẹwọn ọdun mẹta jura.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Rape cases in Nigeria: Ọmọ ọdun 5 àti 14 ni Kalu wà nígbà tí obìnrin fipá ba lòpọ̀ Bakan naa lo ni wọn ba ẹgbẹrun lọna mejilelogun ati aabọ lọwọ wọn, owo naa si wa lara owo itusilẹ ti wọn gba lori onisowo naa ti wọn ji gbe.
Àwọn amòfin ati àwọn Farisi mú obinrin kan wá, tí wọ́n ká mọ́ ibi tí ó ti ń ṣe àgbèrè.
jẹ́ ẹgbẹtala ó lé ọgbọ̀n (2,630).
Nígbà náà wọ́n mú ẹnìkan wá sọ́dọ̀ Jesu tí ó ní ẹ̀mí èṣù; ẹ̀mí èṣù yìí ti fọ́ ọ lójú, ó sì mú kí ó yadi.
Bẹẹni awọn ilana ijọba gbogbo ko se koriya fun idokoowo.
Awọn ejo to le aarẹ kuro lọfisi la gbọ pe wọn jade lati inu ilẹ ti wọn si sa wle pada nigba ti awọn eeyanfẹ pa wọn.
"Iya ọmọ naa, Sonia Okome, sọ fun BBC bi inu rẹ ṣe dun to, ṣugbọn o salaye pe ibanujẹ ati ayọ ni iṣẹlẹ naa jẹ fun oun: ""Inu mi i dun lati gba ọmọ mi pada."
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Arsenal fi Newcastle sẹ̀sín, o dà òkùtà sí wan nígbá Nicholas Pepe àti Dani Ceballos o wulẹ̀ le ta pútu bótilẹ̀ jẹ pé Emery fún wọ́n ni ààyé láti fí orúkọ wan hàn níle aláró.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ohun ti awọn osisẹ n sọ ni wi pe adehun AfCFTA yoo se ijamba fun a wọn ileesẹ to sẹsẹ fẹ gberu labẹle Agbẹnusọ fun aarẹ, Fẹmi Adesina, ni ipinnu yii ko pẹ ju sugbọn o tọ ki aarẹ jawọ ni ọrọ naa bayii nitori aifọwọ sii awọn alẹnulọrọ ju ko tẹsiwaju laisi atilẹyin wọn.
Awọn ọlọpaa sọ pe akọsilẹ rogbodiyan 61 ni akojọpọ awọn ileeṣẹ alaabo to mojuto idibo naa ni, laarin aago meje owurọ ọjọ keje, si aago mẹwa owurọ ọjọ kẹsan, oṣu Kejila.
Ohun tí ojú wa ń rí nìyí níbi ìbò abẹ́nú fún olùdíje gómìnà lẹ́gbẹ́ òṣèlú APC ní Edo Fayose dá sí àáwọ̀ igbákejì gómìnà àtí gómìnà Akeredolu l'Ondo Àwọn tó ní Covid-19 ní Nàìjíríà ti tayọ ẹgbẹrun lọ́nà ogún Wọ́n ti pàṣẹ lọ rọọ́kún nílé fún òṣìṣẹ́ káńsù tó lú obìnrin kan ní ìpínlẹ̀ Ogun O gba pe lootọ, oun atawọn awakọ mii loju popo ru ofin irinna nipa gbigba ọna ti ko tọ ọ, ṣugbọn o ni wọn ṣe bẹ ẹ nitori pe abala na ti wọn n gba tẹlẹ di pa fun sunkẹrẹ-fakẹrẹ ọkọ.
Rọbọọti ọhun ni ẹrọ ayaworan lara, o si maa n lọ si yara itọju awọn alaarun Covid-19, Koda, o maa n fun wọn ni ounjẹ ati oogun pẹlu ti awọn oṣiṣẹ eto ilera ko sin ni yọju rara.
Èmi ni ìyè àti ìmọ́lẹ̀ ayé.
Oun ti gba ìṣípayá àtọ̀runwá tẹ́lẹ̀ nípa jíjẹ́ òtítọ́ ẹ̀rí ti Wòlíì, nípa àwọn àwo-àkọsílẹ̀ lórí èyí tí a fín àkọsílẹ̀ Ìwé Ti Mọ́mọ́nì sí.
Ṣé ó ṣeéṣe kò jẹ́ àṣírí ìbejì Aláàfin nìyíì?
Ọ̀pọ̀ èèyàn bẹnu ẹ̀tẹ́ lu Mercy Aigbe lórí bó ṣe ki Adeniyi Johnson Òyìnbó sísọ di èèwọ̀ ní ìpínlẹ̀ Ekiti Yàtọ̀ sí Ọ̀ṣun Òṣogbo, Ṣàǹgó pẹ̀lú a máa ní arugbá lóde Ọ̀yọ̀ Falana àtàwọn míì péjú síbi àpérò #RevolutionNow l'Eko SSANU, NASU gbé fásitì Ibadan tì pa Ayédèrú Ọ̀ṣun ni wọ́n ń bọ lónìí, kìí ṣe ojúlówó - Bàbá Ọlọ́ṣun tún figbe ta Nibayii, ijọba ipinlẹ Ọṣun ti gbe igbesẹ akọ lori rẹ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù NNPC: Buhari yan Kyari ní olùdarí tuntun fún àjọ NNPC 20 Òkùdu 2019 Oríṣun àwòrán, NNPC Àkọlé àwòrán, Buhari yan Kyari ní olùdarí tuntun fún àjọ NNPC Ile iṣẹ to n risi ọrọ epo rọbi ni Naijiria, NNPC ti gba adari tuntun.
Àwọn olórí ní ìdílé kọ̀ọ̀kan kópa ninu iṣẹ́ náà.
 ní sẹ ́ ńtúrì ogún ( 20th century ) , ìgbìyànjú tó ga wáyé láti sọ àwọn èdè yìí di èdè òde òní .
Èpè tí Jotamu ọmọ Gideoni ṣẹ́ sì ṣẹ mọ́ wọn lára.
"Àkọlé àwòrán, ""Idamẹwa ko wa fun gbogbo eniyan"" Àkọlé àwòrán, Ẹ o waasu ọrun mọ ni?"
Mo bá sọ fún wọn pé, “Ó yá, ẹ máa mu ọtí waini.
Awọn eeyan a ma fi oju apọnlẹ wo oloṣelu gẹgẹ bi ẹni ọwọ, ati olori to mọ iwe daadaa.
Yóo ṣe ètùtù fún ìwẹ̀nùmọ́ ọkunrin náà, níwájú OLUWA.
Saraki ni iwe rere ti Yar'Adua wu nigba to jẹ aarẹ Naijiria ti di ohun manigbagbe, bẹẹ lo gbadura pe ki aanu Eleduwa maa baa nibi kibi to ba wa.
Chanchai Lahiri jẹ gbajugbaja ọlọwọ idán ọmọ India to ti n pidan lati ọdun to ti pẹ.
 O yẹ ki a mọ ohun idagbasoke ilu ṣe pataki ni ipinlẹ yii, ipo
Ofin Naijiria Sections 25-28 sọrọ nipa ofin to de ki eniyan jẹ ọmọ orilẹede meji.
Lójú mi, àwọn baba ńlá yín dàbí èso tí igi ọ̀pọ̀tọ́ kọ́ so ní àkókò àkọ́so rẹ̀.
” Wọ́n rú ẹbọ sísun ati ẹbọ alaafia sí OLUWA lórí rẹ̀.
Angẹli kinni lọ, ó bá da ohun tí ó wà ninu àwo rẹ̀ sinu ayé.
Jesu ati àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ jáde lọ sí àwọn abúlé tí ó wà lẹ́bàá ìlú Kesaria ti Filipi.
agbofinro lo si ibi ti awon ro pe wahala lee waye nibẹ , ni ijoba ibile Madagali.
“Gege bi mo se n so tele, ti awon eniyan ba ni ona abayo, e je ki won wa, awo o nipinle Benue, eyi ti o je ona kan gboogi lagbaye, Naijiria ko le gbeyin, ni paapaa julo, nigba ti ile n kere si, ti awon eniyan si n po si.
BBC tun de oju oori Orlando Owoh.
O si tun yẹ ka kọ ẹkọ pe, aisi baba abi iya ko ni ki ọmọ ma mọ ohun to fẹ se lati di eeyan nla lọjọ ọla.
Everton: À ní se ìwádìí lóri ìgbẹ́sẹ̀ ti Moise Kean gbé lásìkò yìí Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Moise Kean: Everton koro oju sí agbabọọlu wọn tó lọ sí òde ijó lásìkò isede ẹ́gbẹ agbabọọlu Everton tí bẹnu àtẹ lù bí ọkan lára àwọn agbabọọlu wọn Moise Kean ṣe yọ lọ sí apejẹ kan lásìkò tí òfin konile o gbélé wà níta.
Afi ki ọlọrun ma jẹ ki abiyamọ fojú sunkun ọmọ.
Bí òkúta adamanti ṣe le ju òkúta akọ lọ ni mo ṣe mú kí orí rẹ le ju orí wọn lọ.
Ileesẹ ọlọpaa orilẹede naa ni awọn mẹrinlelogun ni ọwọ ti ba bayii lori ikọlu naa, ṣugbọn ko tii ye awọn alaṣẹ nipa awọn eeyan to ṣe agbatẹru ikọlu naa.
Àkọlé àwòrán, Kíni ẹyin rànti nínú nkan ti o ti ṣẹlẹ lọ́dun díẹ̀ sẹ́yìn àti nísìnyìí Ní ọjọ oni, ǹkan tí àwọn ọmọ Nàìjíríà ń sọ ni mímú ìránti wọ́n pàda si ìgbà àtẹyin wá.
Ó wa ihò ìfúntí sí ibẹ̀, ó kọ́ ilé-ìṣọ́, ó gba àwọn alágbàro tí yóo máa mú ninu èso àjàrà fi ṣe owó ọ̀yà wọn.
Eto yii ni a fi n kọ awọn eniyan sii nipa ede ati aṣa Yoruba ki o ma baa parun.
Kání òṣèré Amẹ́ríkà kan ló yọjú sí agbègbè náà báun, ọgbà náà ò bá kún dẹ́mú-dẹ́mú ni.
Ńṣe ni yóo gbé e ka orí ọ̀pá fìtílà kí àwọn tí ó bá ń wọlé lè ríran.
Ó dá wọn lóhùn pé, “Ẹ kò mọ̀ pé ẹni tí ó dá wọn ní ìbẹ̀rẹ̀, takọ-tabo ni ó dá wọn, 
Bẹ́ẹ̀ ni àwọn alufaa ṣe bẹ̀rẹ̀ sí gbé àwọn ìlú Juda, pẹlu àwọn ọmọ Lefi, ati àwọn aṣọ́bodè, ati àwọn akọrin, ati díẹ̀ lára àwọn eniyan náà, pẹlu àwọn iranṣẹ tẹmpili, ati gbogbo àwọn ọmọ Israẹli, kaluku ń gbé ìlú rẹ̀.
Bí í ti wí báyìí tán ó mú àwọn ejò méjèéjì ó nà wọ́n mọ́ ilẹ̀, lẹ́hìn eyí ó gbé igi ó nà án mọ́ wọn lórí, ó pa wọ́n, nǹkan dé!
Jonatani dáhùn pé, “Ó gbààyè lọ́wọ́ mi láti lọ sí Bẹtilẹhẹmu.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ọ̀pọ̀ ìgbà ní Hushpuppi àtàwọn èèkàn PDP ti ya fọ́tò ní Dubai, EFCC ẹ wádìí wọn - APC ń lọgun Bí àdúrà Fìdáù ọjọ́ mẹ́jọ fún Abiola Ajimobi yóò ṣe lọ lónìí rèé Obìnrin kan wọ gàù lẹ́yìn tó kan ìṣó mọ́ ọmọ ọ̀dọ̀ rẹ̀ ẹni ọdún mẹ́wàá lórí Bàbá Aláàfin ìlú Ọ̀yọ́, Elérúwà àti àwọn Ọba Ilẹ̀ Yorùbá míràn tí wọ́n rọ̀ lóyè Ìjọba Nàìjíríà ti mú Dókítà Anu tí àwọn kan f'ẹ̀sùn kàn pé ayédèrú iṣẹ́ abẹ ìdí ló n ṣe Ninu atẹjade kan ti akọwe iroyin igbakeji gomina ọhun, Allen Sowore fisita, Ajayi tọkasi abala ofin ilẹ wa tọdun 1999, ori ọgọsan, ẹsẹ keji, eyi to laa kalẹ pe, o yẹ ki Akeredolu fa akoso ipinlẹ naa le oun lọwọ ni.
Bi ilu Eko se kere to yẹn, ọba mẹtalelaadọta lo wa nibẹ, amọ ọba kansoso lo wanilẹ Ibadan bo se tobi to.
Àwọn ọmọbinrin náà dá wọn lóhùn pé, “Ó wà ní ìlú.
Bí wọ́n ti ń lọ, Naomi yíjú pada sí àwọn mejeeji, ó ní, “Ẹ̀yin mejeeji, ẹ pada sí ilé ìyá yín.
O ṣe pàtàkì kí ènìyàn yọ gbogbo ibi ti ẹjẹ le di si, àwọn ẹyà ara bii ọpọlọ, awọ, ojú àti ikùn rẹ̀ ki ènìyàn to bẹ̀rẹ si ni jẹ ẹ.
Lẹyin naa lo kede ni ọjọ Ẹti pe isede naa ti yi pada si aago mẹfa irọle si mẹjọ owurọ.
Ileewe ka eyi si ọna ati fi ilọkulọ ibalopọ lọ eeyan.
Ile riri ti wiwon odiwon re le ni ida kan le ni mefa ti mi Kabul to je olu-ilu Afghanistan nibiti iroyin ti ni ko seni to gbemi mi ninu isele naa rara.
ko orukọ awọn to gbara gba ninu ikọlu naa jọ, ki wọn si fun wọn ni owo
E̩nì kò̩ò̩kan ló ní è̩tó̩ láti kópa nínú ìs̩àkóso orílè̩‐èdè rè̩, yálà fúnra rè̩ tàbí nípasè̩ àwo̩n as̩ojú tí a kò fi ipá yàn.
Iranlọwọ fun araalu Gomina Oyetola tun ṣalaye pe, ijọba ipinlẹ Oṣun labẹ ijọba oun laarin ọdun kan sẹyin ti ṣeranwọ owo fawọn ọdọ lati lati rii wi pe airiṣẹ ṣe dinku nipinlẹ naa.
Àpótí ìkẹ́rùsí jálu ọkọ̀ méjì lórí l'Eko 'Tàpá sófin ojú pópó kóo ṣọdún lẹ́wọ̀n' Ẹnikẹni to ba wa laye yẹ ko dupẹ ni lai nii fi ṣe nkan ti o n la kọja, ki onikaluku to ṣi wa lori oke eepẹ sa ipa rẹ lati mu alaafia jọba ni agbaye, bẹrẹ lati agbegbe rẹ ti o wa.
OLUWA ti ṣẹ́ ọ̀pá àṣẹ àwọn ẹni ibi,ati ọ̀pá àṣẹ àwọn olórí
O ni awọn ikọ Boko Haram to ti fẹhinti lo tu asiri naa si oun lọwọ.
Ṣugbọn ó yẹ kí á máa dúpẹ́ lọ́wọ́ Ọlọrun nítorí yín, ẹ̀yin ará, àyànfẹ́ Oluwa, nítorí Ọlọrun ti yàn yín láti ìbẹ̀rẹ̀ wá láti gbà yín là nípa Ẹ̀mí tí ó sọ yín di mímọ́, ati nípa gbígba òtítọ́ gbọ́.
"Àwọn ọbá aláye ilẹ̀ Yorùbá márùn-ún pẹ̀lú ọ̀pá àṣẹ wọn Àwọn ọ̀nà láti dẹ́kun ìwọ́de ọ̀dọ́ lọ́jọ́ iwájú nìyí ""Ati Ọba ati gbogbo idile rẹ ni ileeṣẹ ogun Naijiria fi ọkọ oju omi Ferry gbe lọ si ibi kan to ni aabo to daju""."
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Coronavirus: updates: ìlú kan rèé l'Abuja tí kò mọ̀ rárá nípa Covid-19 22 Òkùdu 2020 Pẹlu bi ijọba orilẹede Naijiria ṣe ko owo lorii fifi awọn ileeṣẹ iroyin polongo nipa bi ajakalẹ arun Coronavirus ṣe n ran to, awọn ilu kereje kereje kan ṣi wa to wa lokunkun nipa arun aṣekupani naa.
Ṣé o lè tẹ́ ojú ọ̀run bí ó ti tẹ́ ẹ,kí ó le, kí ó sì dàbí dígí tí ń dán?
Bí ẹnikẹ́ni bá kọ̀ tí kò lọ sí ìlú Jerusalẹmu lọ sin Ọba, OLUWA àwọn ọmọ ogun, òjò kò ní rọ̀ sí ilẹ̀ rẹ̀.
Ile igbimo asofin ti ranse si aare lati wa salaye niwaju won lori eeto aabo to n wole, lawon apa ibikan lorile ede Naijiria.
Lẹyin osu mẹsan ti Ọmọyẹ ti fi inu se oyun lai ri ẹni gba lọwọ rẹ, o papa fi ẹyin gbe ọmọ pọn, o ru re, to si tun sọ re.
Premier League kìí ṣegbẹ́ La Liga!
Má gbẹ̀san ẹ̀ṣẹ̀ àwọn baba ńlá wa lára wa;yára, kí o ṣàánú wa,nítorí pé a ti rẹ̀ wá sílẹ̀ patapata.
Ó ti tán fún mí lọ́dún 2023- Ààrẹ Muhammadu Buhari Odunlade àti Femi Adebayọ: Wo ohun tó yà wá sọ́tọ̀ nínú àwọn arẹwà ọkùnrin Àfàìmọ̀ kí Naira Marley má fi ẹ̀wọ̀n bẹ̀rẹ̀ ọdún 2020 Idi ti EFCC ṣe mu Sheu Sani S'ahamọ.
Africa, Zimbabwe, Zambia, ti ọsẹ to kọja yii buru jai gẹgẹ bi wọn ṣe n
“Ní ọjọ́ kinni oṣù keje, ẹ óo máa ní àpèjọ mímọ́, ẹ kò sì gbọdọ̀ ṣe iṣẹ́ líle kankan.
Gege bi osise ijoba to n ri si isele pajawiri,“A n sa gbogbo ipa wa lati ri daju pe, a ye iyara kookan wo, lati wa awon miiran ti won lanfaani lati jade.
Lára àwọn agbọ́másọ wọ̀nyí, bóyá la lè rí ìkankan nínú wọn tó mọn èdè Yorùbá kà dáradára, ká tilẹ̀ má sọ̀rọ̀ ọ kíkọ.
Oyedepo tun rọ ojo epe sori awọn eeyan to n ti awọn apaniyan lẹyin pe, egun ati ibi to n bẹ lori awọn apaniyan naa ni yoo jẹ ipin tiwọn naa.
Ọpọ awọn afurasi tọwọ ba lori ẹsun yii, ni wọn ti n naju ni agọ ọlọpaa.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Èré Ọṣun: Àtáója ní wọn kò jí ère Ọṣun, ó sì wà níbi tó wà Gẹgẹ bi ohun ti iroyin kan lati ọwọ AFP sọ, ''ibọn ati ada'' ni wọn fi pa awọn eeyan ni Ogossagou lagbegbe Mopti.
Kí n máa bá ọ̀rọ̀ mi lọ, nígbà tí ó pẹ́ díẹ̀ tí a ti dé ilé Ikú ni Baba-onírùngbọ̀n fi mí hàn án, ó ní, ‘Ìwọ ọ̀rẹ́ mi ọ̀wọ́n, Ikú ẹni tí ilé rẹ̀ ń bẹ́ lágbedeméjì ayé òun ọ̀run, láì-ṣe-àníàní, ìwọ kò ní ṣáì ṣe àkíyèsí ẹni tí ó tẹ̀lé mi, bí a kò bá sì ní í purọ̀, ìwọ kò ní ṣaìfẹ́ẹ́ mọ irú ènìyàn tí òun jẹ́ pẹ̀lú – òótọ́ ni: ọkǹuirn tí ìwọ ń wò lẹ́hìn mi nìm ọ̀rẹ́ mi ni; ọ̀kan nínú àwọn ọmọ ènìyàn sí ni pẹ̀lú.
Orúkọ rẹ̀ ni kí ẹ máa fi búra.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ado Ekiti Blind Couple: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú Amọ, ikọ Amọtẹkun naa fikun wi pe, o da awọn loju wi pe awọn baalẹ ati awọn olori ilu kereje-kereje lo n pe awọn Fulani darandaran yii wa si agbegbe wọn.
Nínú gbogbo onírúirú nkan mímu tí wọ́n ntà níbẹ̀, frapuccinno ni mo yàn nítorí ooru mú díẹ̀ lọ́jọ́ náà.
Mò ń sọ èyí kí ẹnikẹ́ni má baà fi ọ̀rọ̀ dídùn tàn yín jẹ.
UNICEF: Ìyàn ń bọ̀ nílẹ̀ Áfíríkà Ọmọdé ológun bíi 900 ti gba ìtúsílẹ̀ - UNICEF Nàìjíríà á bí ọmọ 25, 685 lọjọ́ kínni, oṣù kinni, ọdún 2019.
Idi si ree ti ọpọ eeyan tun fi n beere pe 'Nibo ni Olori Badrat Ajoke wa lasiko ọdun Ileya?
Aisan Cancer pa ọkunrin kan lẹ̀yin ọjọ̀ díẹ̀ to jẹ milionu kan dọ́là
“Nítorí pé ìrètí ń bẹ fún igi tí wọn gé,yóo tún pada rúwé,ẹ̀ka rẹ̀ kò sì ní ṣe aláìsọ.
“Sebuluni yóo máa gbé etí òkun,ọkọ̀ ojú omi rẹ̀ kò ní níye,Sidoni ni yóo jẹ́ ààlà rẹ̀.
Bi i ká díbọ́n bí olólùfẹ́ lórí ẹ̀rọ ayélújára, ká fi lu ni ní jìbìtì, tàbí ká ṣe bí olókoòwò láti lu ẹni tí kò bá fura ní jíbìtì.
Mú ìdààmú ọkàn mi kúrò;kí o sì yọ mí ninu gbogbo ìpọ́njú mi.
Mímọ̀ ohun tó jọjú yìí ti wá dá oríṣiríṣi àti iye owó ọ̀tọ̀tọ̀ kalẹ̀.
 O si tun tenumo pe ki gbogbo won duro nipo oba ti won je, ki won si
3b fún àkanṣe iṣẹ́ márùn ún 3 Owewe 2018 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, 'Buhari yoo si tẹsiwaju lati pari awọn apati akanṣe iṣẹ gbogbo dipo bibẹrẹ awọn miran' Ijọba apapọ ti buwọlu owo to le ni biliọnu kan dọla owo ilẹ Amẹrika fun nina lori awọn akanṣe iṣẹ to loorin kan.
Asán ni igbẹkẹle agbára ẹṣin ogun;kìí ṣe agbára tí ẹṣin ní, ló lè gbani là.
” Nítorí ó wí ninu ara rẹ̀ pé, alaafia ati ìfọ̀kànbalẹ̀ yóo sá wà ní àkókò tòun.
Àwọn ọ̀dọ́ ilẹ̀ Yoruba kò gbọdọ̀ gbàgbé àṣà ati ohun àdàyébá wọn - Ooni Ile Ife Ooni Ile Ife, Ọba Adeyeye Enitan Ogunwusi ti rọ awọn ọdọ ilẹ Yoruba lati ma gbagbe aṣa, iṣe atawọn ohun adayeba ilẹ wọn.
Dokita John Jesuwale lasiko to n ba BBC Yoruba sọrọ ni, wọn ko ti i gba abẹrẹ oogun lukuluku (vaccine) fun aisan lukuluku laaye lorilẹede Naijiria, ati wi pe, ẹnikẹni to ba ko wọle, yoo finmu kata ofin.
 Àwọn ìjọba ìbílẹ ̀ náà ni Ìfẹlodun , Ìrẹ ́ pọdun , Òkè-Ẹ ̀ rọ ́ àti isis .
ti oludari ile-ise oloopa orile ede Naijiria, Abubakar Adamu se agbateru re, ni
Gege bi agbenusoro ajo to n ri si oro ile okeere ni Naijiira, Tiwatope Elias-Fatile se so lasiko to n ba ile ise akoroyin AFP soro, “A ni lati duro de iko wa to n se iwadii lowo lori oro naa lati wa jabo bi isele naa se sele,”“O je isele ti o bani ninu je pupo.
Ọmowé Olugbenga wà lára àwọn tó n ṣíṣe nípa ọgbin àgbàdo ní ilé iṣẹ iwadi ijinlẹ IAR and T to wa ni agbegbe Àpáta Ibadan.
Bí ẹnikẹ́ni bá bá aya ọmọ rẹ̀ lòpọ̀, pípa ni kí wọ́n pa àwọn mejeeji; wọ́n ti hùwà ìbàjẹ́ láàrin ẹbí, ẹ̀jẹ̀ wọn yóo wà lórí ara wọn.
Oríṣun àwòrán, Arakunrin Rotimi Akeredolu Gomina Akeredolu ni o ṣenmi laanu pe pẹlu gbogbo igbesẹ ti ijọba n gbe lati dena ajakalẹ arun naa nibẹ, eeyan kan ṣi lee rapala gbe arun naa wọle.
Kí OLUWA tí ó dá ọ̀run ati ayé bukun yín!
Carrington jẹ aṣoju ilẹ America ni Naijiria ati Senegal, nigba aye rẹ.
Ọmọ́táyọ̀ Olútóyè: Àwọn ǹkan tó yẹ kí ẹ mọ̀ nípa Ọ̀jọ̀gbọ́n obìnrin àkọ́kọ́ nínú ẹ̀kọ́ èdè Yorùbá lágbàyé
“Ẹ kò gbọdọ̀ dán OLUWA Ọlọrun yín wò, gẹ́gẹ́ bí ẹ ti ṣe ní Masa.
Oríṣun àwòrán, Other O ni ẹri ọkan oun ko ba ti jẹ ki oun gbadun, to ba jẹ pe ijapa naa ko ru u la ni.
Ẹ lọ fi òfin gbe ìdásílẹ̀ Amotekun lẹ́yìn - Ìjọba àpapọ̀ sọ fáwọn gómìnà Yorùbá Amotekun: Kí ni iṣẹ́ tí Amotekun yóò máa ṣe gangan?
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ẹ̀mí 86 ṣ'òfò ni ìkọlù Plateau Buhari, Lalong gbanájẹ lórí ìkọ̀lù Plateau Sé Nàìjíríà yóò gba lílo igbó láàyè?
27 Ìgbé 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 28 Ìgbé 2019 Ajọdun ilu nilẹ Afrika ti ẹlẹ́ẹ̀kẹrin waye ni ipinlẹ Ogun lorilẹede Naijria jẹ afihan ati ṣiṣe ajọyọ ipa ti ilu n ko nilẹ Afrika.
Gẹ́gẹ́ bí ìfẹ́ rẹ̀, ó fi ọ̀rọ̀ òtítọ́ bí wa, kí á lè jẹ́ àkọ́kọ́ ninu àwọn ẹ̀dá rẹ̀.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù BB Naija: Yàtọ̀ sí Lecon, àwọn olóríire yòkúù ni Katung Aduwak, Efe Ejeba, Miracle Igbokwe, Mercy Eke 30 Agẹmo 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 28 Owewe 2020 Oríṣun àwòrán, others Eruku sọ nigba ti wọn kede Olamilekan Agbelesebioba,'Laycon' gẹgẹ bi ẹni to jawe olubori ninu eto igbe aye aladani lori amounmaworan ta mọ si BB Naijia.
Ọjọ́ ńlá ni ọjọ́ náà nínú igbó ńlá yìí, àwọn ẹranko àti ẹyẹ ń ké kábíyèsí, àwọn igi gbogbo bẹ̀rẹ̀ sí tẹ orí wọn ba, àwọn ìtàkùn bẹ̀rẹ̀ sí kí Olówó-ayé bí òun àti ìyàwó rẹ̀ ti ń ṣe fáàrí nínú ọlá ńlá wọn.
Ó tún sọ̀ pe Adebisi máa ń fún ẹgbẹ́ kan tó jẹ́ ọ̀tá ti òun ní owó déédéé.
Oríṣun àwòrán, Others Boju Boju: Ere boju boju jẹ ere ti awọn ọmọde ma n ṣe lati wa ara wọn ni ibi ti wọn ba ti lọ sa pamọ si.
Láti Alimoni Dibilataimu wọ́n lọ sí Òkè Abarimu níwájú Nebo.
‘Ẹ gba ọrẹ jọ fún OLUWA láàrin ara yín, ẹnikẹ́ni tí ó bá fẹ́, lè mú ọrẹ wá fún OLUWA.
Bakan naa ni kikuro to kuro lati APC lọ si PDP lọ si ZLP ko le e ni ipa buburu ninu irinajo naa.
Wọ́n ti yọ igbákejì olórí ilé aṣòfin Òǹdò Bí èsì ìdìbò gómìnà ìpínlẹ̀ Ondo se ń jáde rèé.
Andrews College ni nilu Oyo, nibi to ti kawe gboye gẹgẹ bi olukọ.
Ó da òrùka wúrà meji meji, ó jó wọn mọ́ abẹ́ ìgbátí pẹpẹ náà lẹ́gbẹ̀ẹ́ kinni-keji, òrùka wọnyi ni wọn yóo máa ti ọ̀pá bọ̀ láti fi gbé pẹpẹ náà.
 Nagy, Jr, so pe, erongba eto aare Trump ni lati faaye sile fun awon olokoowo lati ile okere wo ile Afrika lati da olokan-o-jokan ile-ise sile, eleyi ti yoo tun pese ise fun awon odo lawujo, paapaa julo lati tun se amulo ofin ati ilana ile okere fun amugberu eto oro aje orile-ede Naijiria.
Nígbà tí ó ti fọ ẹsẹ̀ wọn tán, ó wọ agbádá rẹ̀, ó bá tún jókòó.
Eyi to mu ki Obaseki kọwe fi ẹgbẹ silẹ lawọn kan sọ pe o fihan pe ẹnu Aarẹ Buhari ko ka ọrọ bo ti se le wu ko kere mọ ninu ẹgbẹ oselu rẹ.
 O ni Ile Igbimọ Aṣofin Ipinlẹ naa ṣe tan lati gba abadofin
Àwọn orílẹ̀-èdè yóo wá sọ́dọ̀ rẹ,láti gbogbo òpin ayé,wọn yóo máa wí pé:“Irọ́ patapata ni àwọn baba wa jogún,ère lásánlàsàn tí kò ní èrè kankan.
Awọn kan ni ẹgbẹ oṣelu PDP tilẹ̀ ni Sanwo-Olu n fi owo awọn araalu ṣofo ni pẹlu igbesẹ naa.
Àwọn iranṣẹ Akiṣi sì sọ fún un pé, “Ǹjẹ́ Dafidi, ọba ilẹ̀ rẹ̀ kọ́ nìyí, tí àwọn obinrin ń kọrin nípa rẹ̀ pé:‘Saulu pa ẹgbẹrun tirẹ̀,Dafidi sì pa ẹgbẹẹgbaarun tirẹ̀?
Yoruba wo ló fẹ́ gbé Oduduwa Republic tẹ́ n pariwo - Lizzy Anjorin Ohun tójú àwọn èèyàn tún rí tí wọ́n figbé ENDSARS bọnu Àwọn olùpolongo ìdìbò Aketi àti Jegede ń forígbárí l'Ondo, bí wọ́n ṣe n yìnbọn ni wọn n sun táyà Pásítọ̀ CAC àti afurasí 'Yahoo boy' Olawale tó lu Hayatou ní jìbìtì N12.
Idi ti wọn fi ni ka ma muti lasiko ta ba n wakọ ni pe o le ṣe okunfa ijamba ọkọ ti ẹmi si le ba lọ.
Davido sọ̀kò ọ̀rọ̀ sí Oyetola lẹ́yìn rògbòdìyàn tó wáyé níbi ìwọ́de End SARS Osogbo Olorin takasufe, David Adeleke ti ọpọ awọn ololufẹ rẹ mọ si Davido ti sọ oko ọrọ si gomina ipinlẹ Osun, Gboyega Oyetola lẹyin ti eeyan meji padanu ẹmi wọn nibi iwọde End SARS to waye ni ilu Osogbo.
Nigba ti MKO Abiọla jẹ olootu iwe iroyin atigbadegba kan 'The Trumpeter' nileewe, Olusẹgun Ọbasanjọ ni igbakeji rẹ Ọdun 1956 ni MKO Abiọla bẹrẹ isẹ bii akọwe nile ifowopamọ Barclays nilu Ibadan amọ lọdun 1960 lo ri ẹkọ ọfẹ gba lati lọ kawe loke okun ni fasiti Glasgow, nibi to ti gba oye imọ ijinlẹ akọkọ ninu imọ nipa isiro owo, to si tun kawe di akọsẹmọsẹ olusiro owo Ni kete to pada de si Naijiria, ni Moshood bẹrẹ isẹ pẹlu ile iwosan ẹkọsẹ isegun fasiti Eko gẹgẹ bii olusiro owo agba, ko to tun lọ sile isẹ apoogun Pfizer, lẹyin naa lo tun dara pọ mọ ileesẹ to wa fun eto ibaraẹnisọrọ, ITT, nibi to ti di igbakeji aarẹ fun ẹkun Afirika ati aarin gbungbun agbaye, Middle East Nigba to se diẹ, MKO Abiọla di olokoowo aladani, to si n da ileesẹ ara rẹ silẹ ni oniruuru ẹka.
Nígbà tí ilẹ̀ ọjọ́ kejì mọ́, tí àwọn ìjòyè pé sí inú ààfin tí wọ́n múra àti lọ sí odò náà ọkùnrin náà kò gbogbo wọn, ó ń kó wọn lọ.
awon to farapa nibi ikolu ti awon iko olote se si won kẹdun  ni gbogbo agbaye.
Gomina ọhun ṣabẹwo sile iwe naa toun pẹlu igbakeji rẹ, Mannir Yakubu, ti wọn si ṣeleri fun awọn eeyan Kankara nibi ti iṣẹlẹ naa ti waye pe ijọba apapọ yoo sa gbogbo ipa rẹ lati ṣawari awọn akẹkọọ to poora.
Deeper Life: Ni ti ijọ Deeper, awọn sọ pe ago mẹwa alẹ lawọn yoo bẹrẹ isin aisun ọdun tuntun.
Máákì fún ìbálópọ̀: Ọ̀jọ̀gbọ́n Richard Akindele rẹ́wọ̀n ọdún méjì he
Oríṣun àwòrán, Getty Images Bi o tilẹ jẹ pe Ileesẹ ọlọpaa ko ti i daba ohun to le sokunfa ikọlu yii amọ iṣẹlẹ naa lo tẹle ẹhonu to waye lawọn orileede to jẹ ti musulumi.
Atiku dije fun ipo aarẹ labẹ asia ẹgbẹ oṣelu PDP eleyi to ti fidi rẹmi ti Aarẹ Muhammadu Buhari ti jawe olubori.
Èèyàn mọ́kànléláádọta ló wá láti ìpínlẹ̀ Eko nínú èèyàn 72 tó kó ààrùn covid-19 lọ́jọ́ Ajé 'Ṣọ́ọ́ṣì ni mọ ti ń bọ̀ kí n tó pàdé àwọn sójà tó fi abẹ gẹ irun fún mi' EndSARS, EndSWAT Protests: Òbí agbábọ́ọ̀lù Kazim Tiamiyu Kaka àtàwọn míì tí ọlọ́pàá pa sọ̀rọ̀, omijé bọ́ lójú Gomina ipinlẹ Oyo rọ awọn ọlọpaa lati gbagbe ohun gbogbo to ṣẹlẹ ki wọn ṣiṣẹ pọ pẹlu ijọba lati rii wi pe alaafia jọba pada kaakiri ipinlẹ Oyo.
Ẹnìkan wà tíí máa ṣe ìtọrẹ àánú káàkiri,sibẹsibẹ àníkún ni ó ń ní,ẹnìkan sì wà tí ó háwọ́,sibẹsibẹ aláìní ni.
- Ijebu Darasimi tun jẹ afi ewi sọrọ ati bẹẹ bẹẹ lọ.
"Ẹgbẹ́ PDP sọ wí pé ""a fún ẹgbẹ́ wa àti olùdíje wa, Ọ̀jọ̀gbọ́n Kọlapọ Oluṣọla Ẹlẹka ní gbogbo àtìlẹ́yìn tó yẹ láti jáwé olúborí nínú ìdìbò Ekiti sùgbọ́n ó ṣe ni láànú pé a fìdí rẹmi."
Bẹẹ ni ti awọn ọmọ Oodua mẹwaa kan ṣe jẹ, ti wọn n dabira nilẹ Amẹrika ati Yuroopu, paapaa ni ẹka amuludun wọn.
Alawe ni ''asiko ajẹlẹ ti kọja, ati wi pe Ooni Ile Ife ni a gba si baba nilẹ Yoruba, oun ni kokari.
"Itẹdo darandaran RUGA ti ijọba n gbero rẹ bayii kii ṣe atọwọda iṣejọba Jonathan.
Gbogbo àwọn ọmọ Israẹli bá parapọ̀, wọ́n wá sọ́dọ̀ Dafidi ní Heburoni, wọ́n ní, “Wò ó, ẹ̀jẹ̀ kan náà ni gbogbo wa pẹlu rẹ.
O ni ki wọn fi Omah Lay si ẹwọn to wa ni Kitalya, nigba ti Tems yoo wa ni ẹwọn Kigo.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Rasheed Tijani: Ìpèníjà ojú kìí ṣe ìdènà sí ọ̀nà àtijẹ mi Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Rasheed Tijani: Ìpèníjà ojú kìí ṣe ìdènà sí ọ̀nà àtijẹ mi 20 Ẹrẹ̀nà 2018 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 17 Èbibi 2020 Rasheed ni ipenija oju ṣugbọn ko jẹ k'o fa idiwọ fun oun lati ṣiṣẹ oojọ rẹ nibi ti o ti nlọ ata.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù EndSARS Protest Update: DJ Switch ṣàlàyé ohun tójú rẹ̀ rí níbi ìfẹ̀míṣòfò àwọn olùwọde EndSARS ní Lekki 21 Ọ̀wàrà 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 24 Ọ̀wàrà 2020 Oríṣun àwòrán, @djswitch_ Gbajugbaja aseto orin to wa nibi iṣẹlẹ iṣekupani tawọn oluwọde to waye ni Lekki Toll Gate ni ilu Eko, DJ Switch, ti ṣalaye ohun toju rẹ ri lọjọ naa.
Oríṣun àwòrán, Others Baruwa, to n fi isẹ olukọ se idabọ ni ẹka imọ nipa isiro owo lo si gba lati seranwọ fun baba naa, to si gbe ọmọ ọhun ls sile ẹkọ fasiti naa lọjọ kẹtalelogun osu keje ọdun 2015.
A gbọ pe ẹgbẹ awọn akẹkọọ nile ẹkọ giga nilẹ wa ti n figbe bọnu pe ki ìjọba tan ina wadii iku to pa omidan naa to jẹ ọkan lara wọn.
Ó dá wọn lóhùn, ó ní, “Ẹ fọkàn yín balẹ̀, ẹ má bẹ̀rù, ó níláti jẹ́ pé Ọlọrun yín ati ti baba yín ni ó fi owó náà sinu àpò yín fun yín, mo gba owó lọ́wọ́ yín.
’Jẹ́ kí ó dà á lé wọn lórí, kí wọ́n baà lè mọ ohun tí wọ́n ṣe.
Ní 31 oṣù Ọpẹ, Igbá-kejì Alákòóso Ìgbìmọ̀ Ìjọba àti Ààrẹ Àjọ-tí-ó-ń-fètò-sí Ìmúdọ́gba Akọ-àtabo ní àwùjọ, Zorana Mihajlović náà sọ̀rọ̀ tako àwọn òṣìṣẹ́ ilé ìtajà Maxi pé “ìwà ìbanilórúkọjẹ́ ni wọ́n hù àti pé wọ́n jẹ̀bi”.
Nígbà tí Serubabeli, ọmọ Ṣealitieli ati Jeṣua, ọmọ Josadaki gbọ́ ọ̀rọ̀ wọn, wọ́n bẹ̀rẹ̀ sí ṣiṣẹ́ lórí àtikọ́ ilé Ọlọrun ní Jerusalẹmu, àwọn wolii Ọlọrun mejeeji sì ń ràn wọ́n lọ́wọ́.
Onimọ nipa eto oṣelu, Dokita Abubakar Kari sọ wi pe awọn eniyan wa ti yoo rọpọ aye ti Abba Kyari fi silẹ.
 Nigba to n sọrọ lori ija lorisirisi to n waye laarin rẹ ati awọn eeyan miran lori Facebook, eyi to mu ki wọn maa sọrọ kobakungbe ṣi ara wọn, ti ẹnu si saaba maa n kun-un, Esabod ni ọpọ awọn eeyan to n bu oun ni oun kii da lohun afi awọn ti aseju wọn ba pọ ju."
AI ni Naijiria gbọdọ fidi ofin mulẹ lẹka epo rọbi lati dẹkun aibikita awọn ileesẹ apọnpo bii Shell ati Eni.
Wọn tun fí ẹsun kan awọn ọlọ́pàá pe wọn yin awọn ni ibọn lẹsẹ.
Amọ nigba ti awọn agbabọọlu wọn yoo fi ṣara giri, wọn fi goolu meji si ookan ti Brighton fi ẹsẹ rinlẹ lori afara liigi Premiership.
Lara awọn orukọ ọmọ ilẹ Kaarọ Oojiire ti a ko si lee gbagbe ni Afọnja wa, ta ba si se n ranti Afọnja, naa la ma ranti ilu Ilọrin nibi ti Afọnja tẹdo si dọjọ alẹ.
Ó lé ní ogójì ènìyàn tó farapa nínú ìbúgbàmù náà báyìí èyí tó wáyé lálẹ́ ọjọ́ àbámẹ́ta.
Ìsọ̀kan àwọn Oníròyìn náà fẹ ọ̀rọ̀ náà lójú:
Magu wa kede pe egungun si n bọ lẹyin rẹ ninu ọdun 2019, tori ọpọ eeyan to jẹ oniwa ibajẹ si lawọn yoo ri daju pe o da asọ ẹwọn bora.
Ọjọ Isẹgun lawọn iwe iroyin kan gbe sita pe, adajọ ile ẹjọ giga kan nilu Ibadan, Aderonke Aderemi ti kede pe ki wọn gbe iwe ofin to se igbega fawọn ọba mọkanlelogun nilẹ Ibadan ti sẹgbẹ kan naa, eyi to fun wọn lasẹ lati maa de ade bii ọba nilẹ Ibadan.
nítorí aláìgbọràn eniyan ni wọ́n,Òpùrọ́ ọmọ tí kìí fẹ́ gbọ́ ìtọ́ni OLUWA.
Ẹni ti gbogbo ọkunrin fẹ ba dọrẹ ni bẹẹ si ni bi obinrin ko o lọna, wọn a ni beleyi o jẹ ọkọ ẹni ṣebi a ṣi jẹ ale ẹni.
Wọ́n kó àwọn ẹran ọ̀sìn wọn ati gbogbo ohun tí wọ́n ní ní ilẹ̀ Kenaani, wọ́n lọ sí Ijipti.
Bẹẹ lawọn ẹgbẹ oṣelu alako bu ẹnu atẹ lu igbesẹ ọhun, wọn ni oṣelu ni ijọba Aarẹ Buhari fi ọrọ naa ṣe.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Èmi gan máa ń béèrè lọ́wọ́ ara mi pé ta ni Wole Soyinka gangan' Ọrọ bẹyin yọ pẹlu bi wọn ṣe gbe iṣẹ agbase naa fun ileeṣẹ SAGEM S.
Aṣiṣe ẹlẹẹkeji ni ti aṣọle Chelsea Kepa Arizzabalaga to jẹ ki Sane gba goolu keji wọle.
Jeremaya wolii bá sọ gbogbo ọ̀rọ̀ náà fún Sedekaya ọba Juda, ní Jerusalẹmu, 
Lẹ́yìn náà, ó tún fẹ́ Maaka, ọmọ Absalomu; òun bí ọmọkunrin mẹrin fún un; wọ́n ń jẹ́ Abija, Atai, Sisa ati Ṣelomiti.
</p>&mdash; Bukola Saraki (@bukolasaraki) <a hrẹf=”https://twitter.
O ni ọjọ yii kan naa ni ogun ati idarudapọ yoo bẹrẹ laye.
Ẹ óo ka aadọta ọjọ́ títí dé ọjọ́ keji ọjọ́ ìsinmi keje, lẹ́yìn náà, ẹ óo mú ẹbọ ohun jíjẹ tí ẹ fi ọkà titun ṣe wá fún OLUWA.
gbigbogun ti iwa ibaje ti ajo naa n se lorile ede Naijiria.
Yóo jẹ́ ibi mímọ́ lára ilẹ̀ náà, yóo wà fún àwọn alufaa, tí ń ṣe iṣẹ́ ìsìn ní ibi mímọ́, tí wọ́n sì ń dúró níwájú OLUWA láti ṣe iṣẹ́ iranṣẹ.
 Àwọn ohun líle kan tí kìí dun ni , tó tó bíi sẹntimita kan sí méjì , lè wú sórí awọ ara àti ẹran ara ẹni , tàbí kí ènìyàn ní àwọn ààmì àìsàn ètò iṣan nínú ara bí àrùn náà bá kan ọpọlọ ẹni .
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Akomolede ati Aṣa: Mọ̀ síi nípa ìró afárànma àti agbárànmọ́ fáwẹ́ẹ̀lì Yorùbá Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Akomolede ati Aṣa: Mọ̀ síi nípa ìró afárànma àti agbárànmọ́ fáwẹ́ẹ̀lì Yorùbá 15 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Òfin mélòó ní o mọ̀ tí Àrànmọ́ Fáwẹ́ẹ̀lì Yorùbá gbọ́dọ̀ ní?
Nigba ti BBC Yoruba kan si ileesẹ aarẹ lori ẹsun iha kokanmi ti gomina Fayose fi kan Aarẹ Buhari, agbẹnusọ fun ileesẹ aarẹ Shehu Garba ni ko 's'ọ̀rọ!
@pharm_dezzz sọ pe, awọn ile iṣẹ ti wọn n ṣe oogun Codine kọ ni iṣoro, bi koṣe awọn alagbata ti wọn n ko kaakiri @purrples woye pe, igbesẹ NAFDAC le se okunfa ọwọn gogo oogun nilẹ Naijiria.
Lilo rọbọọti ni gbogbo papakọ ofurufu ti wọn n gba rinrinajo lọ ilẹ okere ni Naijiria ni wọn n sọ tori naa bi awọn eeyan o ba lee kan sara si ijọba Naijiria fun iṣẹ takun takun, ki wọn ma fa ibọn yọ o tọrọ ba ti kan ohun daradara nipa Naijiria.
Nítorí èmi OLUWA àwọn ọmọ ogun ni ó rán ni sí àwọn orílẹ̀-èdè tí wọ́n ti ko yín lẹ́rú, nítorí ẹni tí ó bá fọwọ́ kàn yín, fọwọ́ kan ẹyinjú èmi OLUWA.
Sheraton-Opebi Bridge, Ijọba ibilẹ Ikeja Ikeja 28.
Wọn ti mi lẹyin, wọn si mu mi lọ ọ ri onímọ̀ nipa ilera ọpọlọ.
anfani ti oun yoo jẹ loun ṣe dara pọ mo egbe PDP, bi ko se fun idagbasoke
Ẹgbẹ́ òṣèlú PDP ní ìpínlẹ̀ Bayelsa jáwé olúbori nínú ìdìbò ìjọba ìbílẹ̀ Jesu orí ayélujára kan rèé tó wa fun isoji ni Afirika Drone àti CCTV ni yóò máa ṣọ́ ọ̀pọ̀ igbó tó wà nílẹ̀ Yorùbá - Ooni Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Hasori yóo di ibùgbé ajáko,yóo di ahoro títí laelae.
Ṣugbọn Peteru ati Johanu dá wọn lóhùn pé, “Èwo ni ó tọ́ níwájú Ọlọrun: kí á gbọ́ràn si yín lẹ́nu ni, tabi kí á gbọ́ràn sí Ọlọrun lẹ́nu?
"Alesinloye ni ""tẹ bá wà gbọ pé wọn ń jà ní gareji láti oṣù keje ọdún tó kọjá táwa ti kúrò níbẹ, kii se àwa."
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Olusegun Obasanjo: Ọmú ìyá mi ti mo fi ń mùkọ ni kekere ló jẹ ki ń lókun Obasanjo ni awọn ara ilu le bẹrẹ si ni maa ṣe ohun to wu wọn ti ijọba ko ba tete fi wọrọkọ ṣada lori eto aabo ni Naijiria.
Ẹgbẹ agbabọọlu Argentinos Juniors ti fi orukọ Maradona sọ papa iṣere wọn, Estadio Diego Armando Maradona ni papa isẹre naa n jẹ bayii.
Ile ise to n mojuto tita ati rirra epo robi lorile ede Naijiria NNPC ti so pe ohun n san N774 milionu owo iranwo ori epo robi lojumo .
Ki oníkálùkù lọ gba káàdì ìdìbò rẹ ni gẹ́gẹ́ bii agbára láti yan ẹni tó wùú sípò.
"Tani fikun pe ""Ayo Chess maa n jẹ ki eeyan lee ronu jinlẹ, tẹ ba ta bo se yẹ kẹ ta, idi niyi ti mo se fẹran rẹ."
Oríṣun àwòrán, @Saifullahi_Abas Àkọlé àwòrán, Gomina Badaru Abubakar Apapọ ibo ẹgbẹrun mẹta le mẹtalelọgọfa, 3123 lati fẹyin Ubale Hashin to ni ibo mẹrinlelaadọta, 54.
'Ìdí tí kámẹ́rà táa rí ní Lekki Tollgate kò fi ká gbogbo ìṣẹ̀lẹ̀ tó wáyé rè é' Iya Orlando Owoh ti pe ẹni ọdun aadọfa bayii.
orílẹ ̀ -èdè [ germany ] , [ austria-hungary ] ati [ italy ] wà ní ẹgbẹ ́ kan , nígbà tí orílẹ ̀ -èdè [ britain ] , [ france ] àti [ pussia ] wà nínú ẹgbẹ ́ kejì , ní ọjọ ́ kejìdínlógún osù kẹfà ọdún 1914 [ 18 / 6 / 1914 ] ni okùnrin kan tó ń jẹ ́ gavrilo princip tí ó jẹ ́ ọmọ ilẹ ̀ serbia sekú pa ọmọ Ọba orílẹ ̀ -èdè astria-hungary tí orúkọ rẹ ̀ ń jẹ ́ francis ferdinand ẹni tó yẹ kó di ọba ní orílẹ ̀ -èdè náà .
Lábẹ́ kinní bí awọsanma yìí ni àwọn ìyẹ́ wọn ti nà jáde, wọ́n kan ara wọn, àwọn ẹ̀dá alààyè náà ní ìyẹ́ meji meji tí wọ́n fi bora.
Bakan naa lo sọrọ lori ahesọ ọrọ to n wi pe ọjọṣepọ ifẹ n bẹ laarin oun ati gbajumọ oṣere tiata, Jaiye Kuti.
Nibamu pẹlu akoko yii, awọn olujẹjọ naa fọ ọwọ wọn pẹlu ọṣẹ ati omi ti wọn gbe siwaju abawọle ile ẹjọ, ti wọn si tun fi ibomu-bonu bo imu ati ẹnu wọn.
igbakeji aare ojogbon Yemi Osinbajo banuje pupo nigba ti o gbo iku awon agunbaniro, National Youth Service Corps members (NYSC)  mesan an ti won padanu emi won sinu odo Mayo-Selbe ti o wa nijoba ibilẹ Gashaka Local Government nipinle Taraba lojo abameta(Saturday).
”Nígbà tí ó ti sọ báyìí tán, ó tún jáde lọ sọ́dọ̀ àwọn Juu, ó sọ fún wọn pé, “Èmi kò rí ẹ̀bi kankan tí ó jẹ.
Ile igbimọ aṣoju-ṣofiun tun rọ ijọba lati fi idanilẹkọọ lori aarun arunmọleegun sinu eto ẹkọ ile iwe alakọbẹrẹ ati ti girama ni Naijiria.
Lodun to koja, Orile-ede America so pe, ohun ti seku pa ogunlogo afunra si ninu ikolu oju ofurufu kan ti o waye ni agbegbe asale gusu Sirte, ni iyanju ati dekun awon omo-ogun olote ohun lati kora won jo.
Ẹ̀mí Mímọ́ ati iná ni yóo fi wẹ̀ yín mọ́.
Samuẹli bá sọ gbogbo ohun tí OLUWA bá a sọ fún àwọn tí wọ́n ní kí ó fi ẹnìkan jọba lórí àwọn.
láti Aroeri tí ó wà ní etí àfonífojì Anoni títí dé òkè Sirioni (tí à ń pè ní òkè Herimoni), 
O gba oye ọmọwe ti wọn fi daa lọla lati Livingstone College ni North Carolina Orukọ Walter Carrington ni wọn fi sọri adugbo ti ileeṣẹ ijọba America wa ni ipinlẹ Eko nibi ti wọn ti n gba fisa.
Ọlọrun dá a lóhùn, pé, “Rárá o, àní, Sara, aya rẹ, yóo bí ọmọkunrin kan fún ọ, o óo sọ ọmọ náà ní Isaaki.
Ninu ọrọ ti rẹ, Makinde ni abẹwo naa wa lati dupẹ lọdọ Obasanjo ki ohun si beere amọran lọdọ agba oṣelu naa.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Awọn wole wole kii mojuto ibi ti awọn eeyan ti n se ounjẹ lopọ awọn agegbe ni Naijiria Dokita Olanrewaju ni, o di dandan ki ijọba pese ohun eelo to yẹ fun awọn oṣise ilera yii lati ṣe iṣẹ wọn.
“Bí ẹ bá gba irú ẹran bẹ́ẹ̀ lọ́wọ́ àlejò, ẹ kò gbọdọ̀ fi rú ẹbọ ohun jíjẹ sí èmi Ọlọrun yín.
Ẹ máa ṣàánú àwọn tí ó ń ṣiyèméjì.
Lojo kerindinlogun ni aare orile ede Naijiria  Muhammadu Buhari ti pase fun minisita to n ri si ile okeere Geoffrey Onyeama ati akegbe re ,to n ri si ọrọ to je mọ ọkọ  ofurufu Hadi Sirika, lati ko gbogbo  awọn  omo orile ede Naijiria pada wa si ilu Abuja  ni kiakia.
Amọ, Agbẹnusọ ọlọpaa ni ipinlẹ Ogun, Abimbola Oyeyemi ni ko si ẹni to gbe ọrọ naa wa si ile iṣẹ ọlọpaa ni agbegbe naa.
Kí ni ìtumọ̀ gbolohun tí o wí pé, ‘Ẹ̀yin yóo di òmìnira’?
Irú ilú ti ó bá ńná iná-kuna, agbójúlógún àti ọ̀le wọnyi yio ráhùn ni ikẹhin.
Ǹjẹ́ o ni aṣọ tí àwọn òṣìṣẹ́ ìlera ń lò láti dáàbò bo ara wọn?
to kere julọ nile igbimo asofin di abẹbugan.
Angẹli tí ó wọ aṣọ funfun náà ní, “Ní àkókò náà Mikaeli, aláṣẹ ńlá, tí ń dáàbò bo àwọn eniyan rẹ, yóo dìde.
Fatai Rolling Dollar gba ọna ojú omi sa lọ pelu ọkọ ojú omi kan nigba to wa lọmọ ọdun mokandinlogun eyi to mu ki iya rẹ ni ki wọn ti i mọ ile ẹ̀kọ́ṣe kan nitori iwa ipanle rẹ.
Oríṣun àwòrán, Twitter/RotimiAkeredolu Bi iyawo Gomina Rotomi Akeredolu ba ni Covid-19, wọn yoo kede gẹgẹ bi ọkọ wọn naa se sọ faraye.
O tẹsiwaju wi pe, awọn afurasi mẹsan ọtọọtọ ni awọn ọlọpaa ti nawọ gan, wọn si ti gbe mẹta ninu wọn lọ si ile ẹjọ.
O wa gboriyin fun awon ara-ilu lataari iroyin lolokan-o-jokan ti o won fi to awon leti, eleyi ti o seranwo pupo fun aseyori idojuko naa.
Kí o lè gbọ́ adura tí iranṣẹ rẹ ń gbà sí ibí yìí.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ko si ofin to de yiya Tatuu si ara rẹ ṣugbọn o ni gbendeke asiko ti o gbọdọ fi duro koo to le fi ẹjẹ silẹ.
Ọwọn ọkunrin yii lo n fa agbere papa laarin awọn obinrin, iroyin naa ni Aarẹ lo sọ bẹẹ.
Wo ọ̀nà tí àwọn ‘ẹ̀lẹ̀ Daddy’ gbà dé ààfin Ọyọ Èyí ni àwọn arẹwà ‘ẹ̀lẹ̀ Daddy’, àfẹ́fẹ́ tí Aláàfin fi ń mí Kí ló wà ní ìdí igbá tí àwọn olorì Aláàfin máa ń tí lóde Ọ̀yọ̀ Wo àwọn olorì àgbà mẹ́rin tí Aláàfin ń wárí fún Amọ ko si bi awọn ayaba naa ti pọ to ti ayaba akọkọ ko ni da yatọ, idi si niyi to fi se pataki lati mọ nipa aya akọkọ ti ọba Adeyemi gbe sile.
”Nigba ti o n fi pataki ọdun Ileya mulẹ gẹgẹ bi eyi to ṣafihan èrè ifarajin, Aṣofin Ọbasa wa rọ awọn ara ilu lati fi tọkantọkan ṣiṣẹ ilu ati pe pẹlu eyi a o le mu ayipada rere ti a n fẹ ba orilẹ-ede yii.
Idi ti awọn kan ninu wọn fi siwaju ni pe Ruga fẹ gba ilẹ awọn eeyan wọn ni.
 lásìkò tí ó wà níbẹ ̀ , ikọ ̀ nạ ́ à gba ife ẹ ̀ yẹ ' all-ireland championships ' ní tẹ ̀ lé-ǹ- tẹ ̀ lé ní ọdún 2011 àti 2012 .
E ya awọn to ba ti ni arun yi sọtọ Oríṣun àwòrán, Getty Images Lara nkan ti South Korea fi se aseyọri nipa mimu adinku ba iye eeyanto ni arun yi ni pe wọn ya awọn to ba ni arun yi sọtọ.
Eto oselu lorilẹ-ede Naijiria jẹ ọkan gboogi ninu awọn ohun ti o ni i se pẹlu igbe aye awọn eniyan lawujọ.
” Ó fi Dafidi bú ní orúkọ oriṣa rẹ̀, 
Oríṣun àwòrán, @Atiku Àkọlé àwòrán, Ọbasanjọ ti sọ tẹlẹ pe oun le fi Atiku yangan pe yoo sisẹ pẹlu ọ̀wọ̀ àti ìrẹ̀lẹ̀ Aarẹ nigba kan ri ọhun sọ pe, oun rọ awọn ọmọ Naijiria to ti ṣe sababi ohun to n bẹ nita lasiko yii, lati bọ sita, ki wọn si wa ayipada ti yoo ṣe wọn loore.
2 11443 Orilẹede Madagascar 255 1.
Makinde ni nitori naa ni oun ṣe bẹrẹ si ni gbe e yẹwọ asiko ti ile ijọsin le pada bẹrẹ ijọsin nitori awọn ile ijọsin ti kọwe si oun, ti wọn si n bere aṣẹ lati ma a ṣe ẹsin pada ninu ijọ wọn.
1 Ọ̀wàrà 2019 Ẹ wo àkójọpọ̀ orúko àti àwòrán àwọn òsèré àti olórin lórílẹ̀-èdè Naijiria tí wọ́n ti sàtìmọ̀lélórí ẹ̀sùn kan àbí òmíràn.
"Gbogbo rẹ̀ ló hàn sí àjọ yìí.
com/4QsDk7LIJH— ITV Football (@itvfootball) June 26, 2018Bakan naa, Egypt fun omo odun márùndínláàdọ́ta asole iko ohun,  Essam El-Hadary lanfani lati dile mu, eleyi ti o so di asole ti o dagbajulo ninu itan boolu agbaye.
Coronavirus ti di ara wa, kò le è kúrò mọ láéláé - WHO Iwa nabi tu igbeyawo ọgbọn ọdun ka Oró ò!
Ẹ̀ṣẹ̀ wo ni mo ṣẹ̀ tí o fi ń tọpa mi kíkankíkan bẹ́ẹ̀?
Oúnjẹ a máa múni rẹ́rìn-ín,waini a sì máa mú inú ẹni dùn,ṣugbọn owó ni ìdáhùn ohun gbogbo.
“♫ òkúta òde, gbòngbò òde, ♪ ẹ bùnwa lóde lò ò.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Emiliano Sala: Wón ti rí bààlú agbábọ́ọ́lù tó pòórá nínú òkun 4 Èrèlè 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images/David Ibbotson Àkọlé àwòrán, Emiliano Sala (apá òsì) wà nínú ọkọ́ òfúrufú náà tí David Ibbotson wà Eyi to ku ninu ọkọ̀ ofurufu to gbe agbabọọlu Cardiff City, Emiliano Sala to poora ni wọn ti ri ninu okun to wa laarin Ilẹ Gẹẹsi ati orilẹ-ede Faranse.
Oríṣun àwòrán, FACEBOOK Àkọlé àwòrán, Lara awọn ileri Aarẹ Muhammadu Buhari ni lati ya ida márùndínlógójì ninu ida ọgọ́rùn ún ipo ijọba silẹ fawọn obinrin Lara awọn ileri Aarẹ Muhammadu Buhari ni lati ya ida márùndínlógójì ninu ida ọgọ́rùn ún ipo ijọba silẹ fawọn obinrin.
Ṣugbọn ní tiyín, ẹ ó kú ninu aṣálẹ̀ níhìn-ín.
Gbogbo ohun tó bá gbà lá máa fún un láti wa àwọn agbébọn náà- Ọlọ́pàá Ganduje fi ọwọ́ òsì da ìdájọ́ ilé ẹjọ̀ nù lórí Emir tuntun mẹ́rin!
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Iléẹ́jọ́ fún EFCC l’ásẹ láti gbégi lé owó Ayodele Fayose 19 Ìgbé 2018 Oríṣun àwòrán, Facebook/Lere Olayinka Àkọlé àwòrán, Ayo Fayose je alatako to foju han si ijọba orilẹẹde Naijiria Ileẹjọ kotẹmilọrun kan to fikalẹ si ilu Ado Ekiti ni ipinlẹ Ekiti ti paṣẹ pe ki wọn gbẹsẹle asuwọn ifowopamọsi Gomina ipinlẹ Ekiti, Ọgbẹni Ayọdele Fayoṣe.
Loore koore sì ni ìjọba àpapọ̀ máa ń kéde pé owó tuntun wọlé láti ara owó Naijiria ti Abacha kò pamọ sókè òkun, tí àwọn ọmọ Nàìjíríà kò sì leè sọ iye tí àpapọ̀ owó náà jẹ́ báyìí.
 Ìkẹrin nínú àwọn ọmọ méjọ , ọ ̀ mọ ̀ wé ni àwọn òbí rẹ ̀ .
O wa dúpẹ́ lọ́wọ́ gbogbo àwọn èèyàn ti wọn dúró tíì lásìkò ìṣòro náà, àti àwọn tó ṣe iranlọwọ láti tètè rí àwọn ọmọ naa gba padà, tó fi mọ gbogbo àwùjọ agbaye.
Nigba ti ara ni awọn ọmọ eeyan, wọn lọ ọ fi ẹjọ sun olodumare, ṣugbọn o sọ fun wọn pe ko si nkan ti oun le ṣe si, nitori awọn lo kọkọ dalẹ, to yẹ adehun.
Kẹ́kẹ́ bá pamọ́ gbogbo àwọn eniyan lẹ́nu tóbẹ́ẹ̀ tí wọn ń wí láàrin ara wọn pé, “Kí ni èyí?
Arẹwà wundia ni Rebeka, kò sì tíì mọ ọkunrin.
Wọ́n ti ṣìnà ninu èrò wọn nípa ẹ̀ṣẹ̀ nítorí pé wọn kò gbà mí gbọ́.
O ṣalaye pe ọmọkunrin kan ni adugbo ti wọn n gbe ti fi ipa ba ọmọ rẹ akọbi lo ri, ti Basirat ko si sọ fun oun.
Elihorefi ati Ahija, meji ninu àwọn ọmọ Ṣiṣa ni akọ̀wé ní ààfin ọba.
 ní ilẹ ̀ amẹ ́ ríkà , iye owó rẹ ̀ kúsí us $ 50-100 .
N óo sì ta ọfà mẹta sí ìhà ibẹ̀ bí ẹni pé mo ta wọ́n sí àmì kan.
Ki ato wi, ki a to fọ, eeyan mẹsan ati ọkọ mẹrinlelaadọta lo ti jona ninu ijamba naa.
Lasiko ti wọn bẹrẹ si ni ro wipe o yẹ ki awọn oluwọde ni aṣoju, o wa lara awọn ti wọn dibo yan lori ayelujara ki o to wa pada laanfaani ati jẹ ọmọ igbimọ iwadii.
Yà wọ́n sọ́tọ̀ kúrò lára àwọn ọmọ Israẹli, kí wọ́n sì jẹ́ alufaa mi.
Nigba ti o n salaue nipa alaafia ati idagbasoke, Ajimobi
Nígbà tí ó bá dé, yóo fi han aráyé pé wọ́n ti ṣìnà ninu èrò wọn nípa ẹ̀ṣẹ̀, ati nípa òdodo, ati nípa ìdájọ́ Ọlọrun.
Lori wiwa ojutu si isoro to n koju eto aabo ile Amerika lori asilo ibon yinyin kaakiri lasiko yii ni Aare Trump fi gbe ise atunto ofin ibon lilo le awon omo ile igbimo Asofin lowo nibi ipade ti won se pelu amohunmaworan leyin isele ibi to sele nile iwe kan ni Florida laipe.
Oòrùn kò ní ṣe ọ́ léṣe lọ́sàn-án,bẹ́ẹ̀ ni òṣùpá kò ní pa ọ́ lára lóru.
O kò mọ̀ pé mo ní àṣẹ láti dá ọ sílẹ̀, mo sì ní àṣẹ láti kàn ọ́ mọ́ agbelebu?
Idi keji tun ni pe iranlọwọ ati atilẹyin wa lati ọdọ awọn ara ilu: Ninu iwadii kan nipa orilẹ-ede mejidinlogun ti ajọ PERC ṣe loṣu kẹjọ ọdun yii lo ṣafihan pe ida marundinlaadọrun ninu ọgọrun eniyan lo wọ ibomu lọsẹ naa.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ikọ̀ Special Eagles padà s'ílé láti ife ẹ̀yẹ àgbáyé Fọ́tò àǹkóò oyún ọmọ ìyá mẹ́ta gbòde kan Kí ló fà á tí àwọn ọmọ Obasanjo ń ta kò ó ní gbangba?
Gómìnà ìpińlẹ̀ Eko Babajide Sanwol-Olu bákan náà tún fún àwọn ẹbí wọ́n ni míl''iọ̀nù mẹ́wàá náírà pẹ̀lú ìlérí pé àwọn ọmọ wan yóò lánfàní ìwé ẹ̀kọ́ ọ̀fẹ́ títí dé fásitì.
Ajọ to n mojuto irinajo Hajj ni Naijiria, National Hajj Commission of Nigeria, NAHCON, ti fidi rẹ mulẹ pe ọmọ orilẹ-ede Naijiria marun un lo ti ku lara awọn to rinrinajo lọ silẹ mimọ Mecca.
Aago mọkanla aarọ ọjọ Aiku ni baalu to gbe wọn lati New Jersey balẹ si olu-ilu Naijiria, Abuja.
O máa ń gba ààrọ̀ rẹ̀ lọ́wọ́ mi, ìbáà jẹ́ ní òru ni ó sọnù tabi ní ọ̀sán.
Ijọba yoo tun pese garawa irọmi si eyi ti wọn n pe ni Veronica bucket"", galọọnu ọṣẹ ifọwọ, beba inuwọ, ẹrọ to n yẹ igbona ara wo ati mili-lita igba oogun apakokoro sanitaisa."
Huṣai dáhùn pé, “Ẹ̀yìn ẹnikẹ́ni tí OLUWA, ati àwọn eniyan wọnyi, ati gbogbo Israẹli bá yàn ni mo wà.
Ileeṣẹ ọlọpaa wa rọ awọn eeyan pe ki wọn kọ eti ikun si awọn to n sọ pe fọto ayederu lohun fi sí oju opo ayelujara ohun.
Bi o ti le je pe, Mikel ko kopa ninu ifesewonse naa lataari ifarapa ti o ni, sugbon to n tele ifesewonse ohun bi o se n lo.
"Àtẹjáde náà lọ báyìí: ""A ti wòye lóri bi àwọn alábara wà ṣe fi ẹdùn ọkàn wọ́n hàn lori àwọn ìkànnì orí ayélujara lóríṣiríṣi lọ́jọ́ sátide àti ọjọ́ Àìkú nípa owó tí a ń yọ ""Stamp Duty""."
O ni iṣoro ọmọ bibi yii lo bi orukọ pa ẹgan rẹ ti wọn sọ oun pe: Ọmọ tan ibajẹ - Omọtanbajẹ Ìdí márùn ún tí agbára Covid 19 ní ilẹ̀ Adúláwọ̀ kò fi tó tí àwọn ilẹ̀ àgbáyé míràn A máa ná N10.
Ṣugbọn mo kìlọ̀ fún wọn, mo sì sọ fún wọn pé, “Kí ló dé tí ẹ fi ń dúró lẹ́gbẹ̀ẹ́ odi?
a lè rí Ìdomà ní ààrin gùngùn orílẹ ̀ èdè náígíríà .
Awọn iroyin ti ẹ lee nifẹẹ si: HIV ni èrè tó rí lẹ́yìn tí wọ́n tàn án sisẹ́ aṣẹ́wó 'Obìnrin tórí ẹ̀ pé lè tọ́ ọmọ láì nílò ọkọ rẹ̀' Ẹfunsetan Aniwura, obìnrin tó ju ọkùnrin lọ Ìbúgbàmù àdó olóró pá èèyàn 27 nílé ìjọsìn Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí 2 sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 2:23 Fídíò, Water Generator: Ó leè ṣiṣẹ fún wákàtí mẹfà, kó tó sinmi, Duration 2,2310 Òkùdu 2020 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
Oliver ni a kìlọ̀ fún láti ní sùúrù a sì rọ̀ ọ́ láti ní ìtẹ́lọ́rùn lati kọ̀wé, fún ìgbà kan ná, sí àpèkọ ẹnití ó ńtúmọ̀, dípò pé kí ó gbìdánwò láti túmọ̀.
Ṣugbọn ó sọ fún mi pé, “Èèwọ̀!
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ọwọ́ àwọn ọlọ́pàá ti tẹ ọkùnrin kan pẹ̀lú orí ọmọdé nílé aṣòfin àpapọ̀ 14 Owewe 2020 Oríṣun àwòrán, Getty Images Awọn ọlọpaa ti ko mamugarri si ọwọ arakunrin kan ni ẹnu iloro ileegbimọ aṣofin orilẹede naa.
O ni: “Awon agbe elewebe ati ohun jije nikan ni won fun ni oore ofe lati kopa ninu eto ise akanse FADAMA sugbon die ninu awon agbe olohun osin naa nilo re.
Ọjọ Aje, ọjọ kẹta oṣu Kẹjọ ọdun 2020 ni iroyin gbode pe ile itaja Shoperite n mura lati fi orilẹ-ede Naijiria silẹ lẹyin ọdun marundinlogun ti wọn ti n ṣowo.
Kí OLUWA jẹ́ kí o lè mú ìlérí rẹ ṣẹ.
Ṣugbọn Oluwa sọ fún mi pé, ‘Bọ́ sọ́nà, nítorí n óo rán ọ lọ sí ọ̀nà jíjìn, sí ọ̀dọ̀ àwọn tí kì í ṣe Juu.
Ajínigbé jí èèyàn méjì gbé l'Ekiti, Amotekun gba ọ̀kan sílẹ̀ Oríṣun àwòrán, @PoliceNG Awọn gende agbegbọn ti wọn furasi bii darandaran ti ji eeyan meji gbe loju ọna Isan-Iludun nipinlẹ Ekiti lọjọ ọdun keresimesi.
Oríṣun àwòrán, @AlaafinofOyo Awọn gomina ti Alaafin Adeyemiri ibẹrẹ ati opin saa wọn nipo: Ajagunfẹyinti Adeyinka Adebayo (August 1966 - April 1971) Ajagunfẹyinti Christopher Oluwole Rotimi (April 1, 1971 - July 1975) Ajagunfẹyinti Akintunde Akinyooye Aduwo (July 1975 - August 1975) Ajagunfẹyinti David Medayese Jemibewon (March 1976 - July 1978) Ajagunfẹyinti Paul Tarfa (July 1978 -October 1979) Oloye Bola Ige (October 1, 1979 - October 1, 1983) Ọmọwe Victor Omololu Olunloyo (October 1, 1983 - December 31, 1983) Ajagunfẹyinti Oladayo Popoola (January 4, 1984 - September 1985) Ajagunfẹyinti Adetunji Idowu Olurin (September 1985 - July 1988) Ajagunfẹyinti Sasaenia Oresanya (July 27, 1988 - August 1990) Ajagunfẹyinti Abdulkareem Adisa (September 1990 - January 1992) Oloye Kolapo Olawuyi Ishola (January 2, 1992 - November 17, 1993) Ajagunfẹyinti Adetoye Oyetola Sode (December 9, 1993 - September 14, 1994) Ajagunfẹyinti Chinyere Ike Nwosu (September 14, 1994 - August 22, 1996) Ajagunfẹyinti Ahmed Usman (August 22, 1996 - August 1998) Ajagunfẹyinti Amen Edore Oyakhire (August 16, 1998 - May 28, 1999) Alhaji Lamidi Onaolapo Adesina (May 29, 1999 - May 28, 2003) Alhaji Rashidi Adewolu Ladoja (May 29, 2003 - May 28, 2007) Otunba Christopher Alao-Akala (May 29, 2007 - May 29, 2011) Sẹnetọ Abiola Ajimobi (May 29, 2011 - May 29, 2019) Onimọ ẹrọ Oluseyi Abiodun Makinde (May 29, 2019 - titi di akoko yii ).
mi dun pe ajo isokan agbaye ti  tọwọbọ  iwe adehunti yoo je ki ibasepọ to dan mọnran
Ọmọ Ibadan mesiọgọ, Omo Ibadan Maja Maja ti o fina ara waju leru.
"Wọ́n ti fa Ààrẹ Amẹrika, Donald Trump kalẹ̀ fún àmì ẹ̀yẹ Nobel Peace Prize Ààwẹ̀ gbẹ̀mí ọmọ Naijiria ní orílẹ̀èdè Amẹ́ríkà Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ìtàn ọ̀rẹ́ tó fi ògùn gba ọkọ ọ̀rẹ́ rẹ̀ ni Akomolede BBC Yorùbá fẹ́ kọ́ wa lònìí Gẹgẹ bi wọn se ko atẹjade naa: ""Ni ọjọ kọkandinlọgbọn, oṣu keje, ọdun 2019, a kede pe a fi ofin de gbigba fisa awọn ọmọ Naijiria kan ti wọn lọwọ si magomago idibo ni inu oṣu keji ati ikẹ̀ta ọdun 2019."
Ọpẹ́ ni fún Ọlọrun nítorí ẹ̀bùn rẹ̀ tí kò ní òǹkà.
Iléeṣẹ́ ológun: Àbájáde ìwádìí wa lórí ìṣẹ̀lẹ̀ náà yóò hàn síta láìpẹ́
Biodun Fatoyinbo Alufaa to gbafẹ yii ni adari ijọ COZA to fi Abuja ṣe ibudo.
Wọn ní kete to wọ ile ẹkọ Gbogbo Nse tan, lo dara pọ mọ awọn ọmọ ẹgbẹ okunkun, to si tun n mu oogun oloro.
Fagoe sọ pe, awọn ọkunrin kan ti ẹ le ma damira lẹyin ibalopọ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ogun Cholera: Ọdọọdún ni àrùn onígbá-méjì máa n ṣọṣẹ́ ní Nàìjíríà-NCDC Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 3 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 5 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Ọdún 21 tí mo fí sun inú mótò- Ọmọ Naijiria ní Ilẹ̀ Gẹ̀ẹ́sì Ìjọba Canada kò gbó nípa ìgbéṣẹ̀ Harry àti Meghan láti wá sí ilẹ̀ wọn Aláàfin Ọyọ: Ọba tó bá n mú ọtí ní ìta kò yẹ ní ẹni tàá bọ̀wọ̀ fún Naira Marley ti tèṣù mọ́lẹ̀ nílé ẹjọ́ májísíréètì lórí ẹ̀sùn ìjọ́kọ̀gbé Ọdún mọ́kànlá sẹ́yìn ni K1 ti ń béèrè fún oyè Mayegun lọ́wọ́ mi - Alaafin A moye yii jẹ na, iwo nna!
Ọkàn pàtàkì nínú irufẹ ogun bẹẹ ni ogún ìjàyè tó wáyé láàárín Ààrẹ Ọ̀nà Kakanfo ìgbà náà, tí wọn pé ní Kurunmi àti Balogun Ibikunle pẹ̀lú Basorun Ogunmola tí ilẹ̀ Ibadan, to fi mọ àwọn ìlú miran ni ilẹ̀ Yorùbá.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, ijọba ti n fi awọn ọmọ ogun ṣọ diẹ lara awọn ileewosan ti wọn ti wọn ṣẹṣẹ da silẹ.
Makinde júwe ilé fún Kọmíṣọ́ná iṣẹ́ òde, ó ṣe pàsípàrọ̀ àwọn kọmíṣọ́nà méjì míì O ni awọn eniyan lo paṣẹ fun oun lati lọ si ẹgbẹ miran lati lọ dije dupo fun gomina nitori oun ni awọn fẹ.
Ṣugbọn ó ṣeéṣe kí á rí ẹni tí yóo ní ìgboyà láti kú fún eniyan rere.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Lockdown updates: Naira Marley gbóríyìn fún Jude Chukwuka pẹ̀lú #1 míliọnù Akpabio ni lati igba ti oun ti de ori alefa, iṣẹ kọngila mẹta pere ni wọn gba.
Aarẹ Muhammadu Buhari ti sekilọ gidi-gidi
Ṣugbọn ṣa, o dabi ẹni pe 'masturbation' ni awọn anfaani kan to n ṣe fun ilera ẹda.
Ṣugbọn àwọn Juu kan láti Esia wà níbẹ̀.
Ṣaaju iyansipo rẹ, Gani Adams ni olori ẹgbẹ ọmọ Yoruba ti wọn n pe ni Oodua Peoples Congress, OPC.
Ki wọn o si ri pe awọn gomina, ati awọn miran ti wọn dibo yan ninu ẹgbẹ naa n ṣe daada fun araalu.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Daily Trust: A kò mọ̀ ohùn tó mú Iléeṣẹ́ ológun tí ọọfisi wà ní Maiduguri àti Abuja 6 Sẹ́rẹ́ 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 7 Sẹ́rẹ́ 2019 Oríṣun àwòrán, @nigeriaarmy Àkọlé àwòrán, Ileeṣẹ ologun orileede Naijiria ti ti ile iroyin Daily Trust pa ni ilu Maiduguri ati ilu Abuja.
O wa fi ọwọ gbaya pe owo wa ni idi rẹ, ti oun si n ri taje se nibẹ nitori isẹ amọ pe ju lilo ike abi irin lati fi rọ ohunkohun lọ.
“Bí ẹnìkan bá ní iyawo meji, tí ó fẹ́ràn ọ̀kan, tí kò sì fẹ́ràn ekeji, tí àwọn mejeeji bímọ fún un, tí ó bá jẹ́ pé iyawo tí kò fẹ́ràn ni ó bí àkọ́bí ọmọkunrin rẹ̀ fún un, 
Keyamo ni koda ti oludije ba ti di ipo oṣelu mu fun igba pipẹ, ko nilo iwe ẹri girama mọ lati dije fun ipo kan tabi omiran.
Sallah: Ẹyin ará Ondo, Eko, Ogun, Osun, Ọyo, ẹ gbàdúrà ò!
Oshiomhole so pe egbe naa yoo tele ofin orile ede Naijiria ati ilana ajo eleto idibo (Independent National Electoral Commission, INEC) lati le je ki eto idibo naa lo ni irowo-irose.
Oun ni yoo ri ọkunrin to mukun, eyi ti oju rẹ da, eyi ti ẹnu rẹ n run ati eyi to burẹwa, ti ko si si ọkunrin kankan to tẹ Wuraọla lọrun laarin ilu Iwo.
Àwọn ni yóo máa ru àwọn aṣọ ìkélé tí a fi ṣe ibi mímọ́, ati Àgọ́ Àjọ pẹlu àwọn ìbòrí rẹ̀, ati awọ ewúrẹ́ tí ń dán tí wọn fi bò ó, ati aṣọ títa fún ẹnu ọ̀nà Àgọ́ Àjọ.
Àwọn ìròyin mìíràn tí ẹ lè nífẹ̀ẹ́ sí: Kéré o!
Rántí pé ẹni tí ó dá erùpẹ̀ ilẹ̀, tí ó dá omi, tí ó dá igi, eeléyìínì lè lo àwọn ẹlòmíràn fún ìràpadà àwọn aráyé.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Blind Couples: Pẹ̀lú ìpèníjà ojú, tọkọtaya bímọ mẹ́ta, tí wọn sì tún ń ṣiṣẹ́ olùkọ́ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Blind Couples: Pẹ̀lú ìpèníjà ojú, tọkọtaya bímọ mẹ́ta, tí wọn sì tún ń ṣiṣẹ́ olùkọ́ 19 Ọ̀wàrà 2020 Ọrọ Oluwa ẹdẹ ni, bẹẹ si ni ni awamaridi ni pẹlu nitori ero rẹ kọja ti ẹda.
Ohun eelo bii, Irẹsi, garri, suga, indomie to to ọna ọgọrun un lọna ẹgbẹrun o le ni awọn fẹ fun awọn ara Eko gba ọwọ ajọ CACOVID.
Yoruba ni ka ku ni ọmọde ko yẹ ni san ju ka dagba lai ni adiẹ irana lọ.
Mo sọ fún ọ, níwájú Ọlọrun ati Kristi Jesu, ati àwọn angẹli tí Kristi ti yàn, pé kí o pa ọ̀rọ̀ yìí mọ́; má ṣe ojuṣaaju.
Ronke Oshodi Oke ni ọrẹ timọtimọ ni awọn mejeeji jẹ si oun, ti ko si si nnkan ikọkọ laarin awọn, bẹẹ ni awọn ẹbi ati iyawo MC Oluomo mọ oun daadaa ninu ile rẹ.
Ọwọ́ tẹ́ àwọn ọkùnrin Fulani mẹ́ta tí wọ́n jí Màálù méjì kó ní Ogbomọṣọ- Àjọ NSCDC Ọmọ́ Yorùbá korò ojú sí Buhari bí kò ṣe fi orúkọ Obasanjo sọ ibùdókọ̀ ojú'rin Ọ̀nà tó fi le è mọ gbájúẹ̀ babaláwo - Ẹlẹ́buìbọn Ayokunle ni iṣekupani olojoojumọ yii gbọdọ dopin, lai jẹ bẹẹ awọn eniyan yoo bẹrẹ si ni da aabo bo ara wọn.
Omojuwa ni tirẹ sọ pe, aisowo nilu ko sọ pe owo ti awọn kan fọna eru ko jọ ko si niluu, ṣugbọn anfani lati ri owo fun gbogbo eeyan ni ko si.
Bekeri bí ọmọ mẹsan-an: Semira, Joaṣi, ati Elieseri; Elioenai, Omiri, ati Jeremotu; Abija, Anatoti, ati Alemeti.
Mama Rainbow: iṣẹ́ tíátà kò ta sánsán mọ́ bíi ti ayé àtijọ́
Oríṣun àwòrán, @mbuhari Àkọlé àwòrán, Supreme Court: Eré àsá sòfò ní ẹgbẹ́ PDP sá lọ sílé ẹjọ́ Agbẹnusọ APC wá rọ wọn pé kí wọ́n ni sùúrù fún bí ọdún mẹta àti oṣù díẹ̀ láti tun gbe igbá ìdìbò míràn lọdun 2023, kí wan fi ẹgbk APC lọ́run sílẹ̀ láti le rójú ṣe ìjọba.
Mọ̀ sí i nípa díẹ̀ lára àwọn èèyàn tí ikú wọn 'láti ọwọ́ ọlọ́pàá' milẹ̀ tìtì ní Nàìjíríà Àwọn aṣòfín ní ìpínlẹ̀ Edo ti yọ Abẹnugan Ilé, Francis Okiye bí jìgá Inú mi dùn sí iwọ́de EndSARS tàwọn ọdọ́ Nàìjíríà ń ṣè - Ooni Ogunwusi Àìbìkítà yíì gbọ́dọ̀ dópin, ìjọba gbọdọ̀ mú ẹ̀dùn ọkàn àwọn aráàlú lọ́kùnkúndùn- Agbẹjọ́rò Àgbà Àwọn aṣòfín ní ìpínlẹ̀ Edo ti yọ Abẹnugan Ilé, Francis Okiye bí jìgá Adari ijọ Daystar Christian Centre, Pasitọ Sam Adeyemi fikun wi pe awọn ọlọpaa ni alakọja ti wọn dojukọ nitori aisan owo oṣu wọn deede lo mu ki awọn naa ma a ṣe aṣiṣe.
Ọpọlọpọ àwọn mìíràn ni wọ́n bá wọn lọ, pẹlu ọpọlọpọ ẹran ọ̀sìn ati agbo aguntan ati agbo mààlúù.
N óo fún wọn ní ọpọlọpọ nǹkan kórè ninu ohun tí wọ́n bá gbìn, ìyàn kò ní run wọ́n mọ́ ní ilẹ̀ náà, àwọn orílẹ̀-èdè yòókù kò sì ní fi wọ́n ṣẹ̀sín mọ́.
Oríṣun àwòrán, Abiola Ajimobi Pọ eeyan ni ara ta pe akikanju ọmọ ibadan naa ti dara ilẹ, ti onikaluku si n sọ ohun to mọ nipa rẹ.
Awọn mii gbaa paapaa awọn ọkunrin si iyalẹnu ọpọ ero nigba ti awọn miran ko gba ami ori ọrọ naa.
O ni ọkan awọn eniyan mẹta yii gba ipinlẹ Eko wọ Naijiria lọjọ Aje lẹyin ti wọn de lati orilẹ-ede France.
Tillerson ti wa ninu irinajo abewo olose kan ni ile AfrikaO ti se abewo si orile-ede ni ile Africa, leyin ojo die ti o kede akotun iranlowo owo ti iye re din ledegbeta milionu owo dollars$533 m fun ile Afrika ni eyi ti $128m yo je ti orile-ede Nigeria, ati awon orile-ede ti o wa ni ekun Lake Chad.
Ṣùgbọ́n ìgbà tí ó dé orí àpáta tí kò tún rí mi mọ́, o fura pé abẹ́ ìtàkùn náà ni mo wà, ó ju kùmọ̀ rẹ̀ síbẹ̀, èyí tí o kọ́ jù bá mi ní ìpàkọ́ ṣùgbọ́n n kò mira.
Kí a sá ní òun ni mo fi gbogbo àsìkò ṣọ́ láti wò ó bí ó bá wá sí ilé-ìsìn l’ọ́jọ́ náà lọ́hǔ.
Awọn afẹhọnuhan naa n beere opin si ifiyajẹni awọn ọlọpaa lagbegbe John Kennedy nibi ti wọn ti n wọde ni ayika Ile aarẹ.
Yóo rí èrè àníyàn ọkàn rẹ̀,yóo sì tẹ́ ẹ lọ́rùn;nípa ìmọ̀ rẹ̀ ni iranṣẹ mi, olódodo,yóo dá ọpọlọpọ eniyan láre,yóo sì ru ẹ̀ṣẹ̀ wọn.
Nàìjíríà n kẹdun Justice Mustapha Akanbi Kí ló le fà á kí ìyàwó pa ọkọ rẹ̀?
Báwo ni ẹ ti ṣe lè gbàgbọ́ nígbà tí ó jẹ́ pé láàrin ara yín ni ẹ ti ń gba ọlá, tí ẹ kò wá ọlá ti ọ̀dọ̀ Ọlọrun nìkan ṣoṣo?
Ẹ máa fi ìfẹ́ yẹ́ wọn sí gidigidi nítorí iṣẹ́ wọn.
Ninu iwe apileko kan ni oruko re, ijoba ati awon omo orile-ede Naijiria, Aare oun so pe, jijawe olubori Aare Putin fun saa elekerin je, “ eri to daju pe, awon omo orile-ede naa ni igbekele ninu isakoso ijoba re”.
Ìwé ìròyìn iwacu jábọ̀ pé àwọn ìdílé tí ọ̀rọ̀ náà kàn wà nínú ìdààmú gidi.
Wolii àgbàlagbà yìí bá wí fún un pé, “Bá mi kálọ sílé, kí o lọ jẹun.
Ipa aidaa to wa ninu bi gomina ọhun ba wa gba nkan ti wọn sọ gbọ, ti ara rẹ ya sii, to si ti n fi huwa, o lee ṣi ẹni to n ṣe daadaa ọhun gan lọna.
Gbogbo ẹlẹwọn to ba si gba itusilẹ lati ipasẹ oju aanu yii, ni ko tun ni pada lọ sọgba ẹwọn mọ.
Jehu gun kẹ̀kẹ́ ogun rẹ̀, ó lọ sí Jesireeli nítorí ibẹ̀ ni Joramu ọba wà, Ahasaya, ọba Juda sì wá bẹ̀ ẹ́ wò níbẹ̀.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Àwọn agbòfinro Ghana gbé Kwesi Nyantakyi 23 Èbibi 2018 Oríṣun àwòrán, FIFA.
Garba Shehu to jẹ oluranlọwọ pataki fun aarẹ Buhari sọ fun BBC pe awọn adari orilẹede lajọ ECOWAS fẹ lọ ni ọrọ pẹlu iha ti Mali ninu aawọ naa lẹyin ti ikọ ti aarẹ ana, Goodluck Jonathan ran lọ ko ri ojutuu si aawọ naa.
Alaga ajọ INEC naa ni ajọ ọhun ko naani ọrọ yoowu ti aarẹ Buhari lee sọ si nitori aṣẹ ati ilana ajọ naa wa lọwọ ajọ naa gẹgẹ bii ajọ to da duro ni ominira.
Lẹ́yìn náà, ó pada lẹ́yìn Nebukadinesari, ó sì ṣọ̀tẹ̀ sí i.
Àwọn ọmọ Israẹli ní anfaani láti wà láàyè, ṣugbọn ìwà òmùgọ̀ wọn kò jẹ́ kí wọ́n lo anfaani náà.
Ìkáwọ́ rẹ̀ ni ọ̀gbun ilẹ̀ wà;gíga àwọn òkè ńlá wà ní ìkáwọ́ rẹ̀ pẹlu.
Bí ó ti kúrò níbẹ̀ tí ó lọ siwaju díẹ̀ sí i, ó rí àwọn arakunrin meji mìíràn, Jakọbu ọmọ Sebede ati Johanu arakunrin rẹ̀.
" Oríṣun àwòrán, @Official3SC Iya ọmọ naa sọ siwaju sii pe Kazeem ni afojusun lati di araba nidi iṣẹ bọọlu gbigba to n ṣe ki awọn oṣiṣẹ SARS ọhun to ge ẹmi rẹ kuru.
Nígbà náà ni ó wí pé, “Gbé oúnjẹ náà súnmọ́ mi, kí n jẹ ninu ẹran tí ọmọ mi pa, kí n sì súre fún ọ.
Oríṣun àwòrán, LASEMA Àkọlé àwòrán, Awon to farakaaṣa ti ngbawosan bayi O fi kun un wipe wọn ti wo oun ni ile-iwosan ti wọn gbe oun lọ.
Hesekaya náà ló dí ẹnu odò Gihoni ní apá òkè, ó ya omi rẹ̀ wọ ìhà ìwọ̀ oòrùn ìlú Dafidi.
Ninu fọnran agbohunsilẹ kan ti olori ẹgbẹ naa, Abubakar Shekau fi sita, lẹyin ọjọ mẹta ti wọn ji awọn ọmọ naa gbe.
Ibikibi ni afẹfẹ ifẹ ti le fẹ lu ẹda, bẹẹ si ni ọrọ ifẹ kọja agbara ẹda.
Ojú Shagbada Erigga rèé lẹ́yìn tó pa ọ̀rẹ́bìnrin rẹ̀ l'Akinyele ní Ibadan Ìdí tí lílọ Yúrópùù fi di èèwọ̀ fún Nàìjíríà àti àwọn orílẹ̀-èdè adúláwọ̀ míì Arúfin ni Seyi Makinde pẹ̀lú bó ṣe gbà kí wọ́n sin Ajimobi sí GRA - Amòfin IRCC ni ootọ ni pe awọn kan ko tii le lọ si Canada lọwọ yii nitori arun Coronavirus, ṣugbọn aye wa fun awọn mọlẹbi ti yoo lo ju ọjọ marundinlogun lọ nilẹ naa, atawọn ti iṣẹ wọn ṣe koko lati wọ Canada lasiko yii.
Ó so ọba Ai kọ́ sórí igi kan títí di ìrọ̀lẹ́, nígbà tí oòrùn ń lọ wọ̀, Joṣua pàṣẹ pé kí wọn já òkú rẹ̀ lulẹ̀, wọ́n sì wọ́ ọ sí ẹnu ọ̀nà bodè ìlú náà, wọ́n kó òkúta jọ lé e lórí, òkúta náà wà níbẹ̀ títí di òní olónìí.
Ẹni to bori: Egypt Ìpele to kangun si aṣakagba South Africa vs Mali.
Ede aiyede laarin awọn oṣere mejeeji yii bẹrẹ nigba ti iroyin jade sita pe Toyin Abraham to ṣẹṣẹ bimọ laipẹ yii kọ lẹta ipẹjọ si Lizzy eleyi to mu ki Lizzy pẹlu gbana jẹ.
Yin OLUWA, ìwọ ọkàn mi,má sì ṣe gbàgbé gbogbo oore rẹ̀,
Ọlọrun, kí ló dé tí o fi ta wá nù títí ayé?
 Ṣugbọn ọpọ ọmọ Naijiria to ka ọrọ yii lo faraya, ti wọn si ni irufẹ ọrọ bayii ko dara rara."
Ẹ jẹ́ kí ó máa bá yín gbé, kí ó wà láàrin yín ninu èyíkéyìí tí ó bá yàn ninu àwọn ìlú yín.
O wa ro ile igbimo asofin lati tete gbe igbese, nitori pe” eto idibo ti ku ọjọ mọ́kànléláàdọ́wàá si oni yii”.
Yóo máa gba ìmọ̀ràn lọ́wọ́ Eleasari alufaa.
Oríṣun àwòrán, Nasir El-Rufai/Facebook Adekeye ṣalaye pe Gomina El-Rufai fun Sanusi ni ipo ọhun nitori ipa to ti ko lori eto ẹkọ lorilẹede Naijiria.
Àwọn èèyàn Yahaya Bello ló da ìbò abẹ́nú wa ní Kogi rú- PDP Awọn eeyan Gomina Yahaya Bello lo wa fibọn da eto ibo abẹnu ẹgbẹ oṣelu PDP niluu Lokoja ru.
Aṣofin Ọbasa ti igbakeji rẹ, Aṣofin Wasiu Ẹshilokun Sanni ṣoju fun, sọ pe Ile Igbimọ Aṣofin naa ti ṣetan lati mu igberu ba irọrun ni awọn ile gbogbo ti awọn oṣiṣẹ bayii wa.
Idi eyi ni ile iṣẹ naa ṣe gbe iru ero bayii kalẹ lati ṣadinku si gbogbo sunkẹrẹ fakẹrẹ igboke gbodo ọkọ.
ẹjọ ti o wa nile ejo to ga julo lorile ede yii.
BBC Africa Eye: Akọroyin fẹ ìdí àwọn oníṣẹ́ ibi ọmọ ogun síta
Inu mi dun lati lee ba iru agbejọro , onimo bẹẹ
Olootu ijọba UK yóò ṣèpàdé láti dóòlà ‘Brexit’ Àwọn ọmọ Nàìjíríà tahùn sí SERAP lórí ẹjọ́ Onnoghen Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Oduduwa Alphabet: òmìnira èdè ti dé fún Port Novo báyìí Ki lo maa ṣẹlẹ bayii?
 Àwon yorùbá gbàgbó wí pé olódùmarè ló rán ifá wá láti òde òrun latí wá fi ogbón rè tún ilé ayé se .
Awọn ohun to sẹlẹ niwaju ile lasiko to aarẹ n gbe aba isuna kalẹ: Deede aago mọkanla aarọ ọjọbọ ni aarẹ bẹrẹ kika eto isuna naa niwaju awọn asofin apapọ ilẹ wa.
Ṣe awọn agba si bọ wọn ni to ba runi loju, aa bi ilẹ leere.
Use of hijab: Ìjọba ti buwọ́lu lílo hijab láwọn iléèwé ní ìpínlẹ̀ Osun
Ẹnikẹ́ni kò gbọdọ̀ jẹ ẹran rẹ̀; ṣugbọn kí ẹnikẹ́ni má ṣe jẹ ẹni tí ó ni mààlúù náà níyà.
Ajọ naa tun rọ ileẹjọ ICC lati kan si awọn aarẹ ati gomina ti to ṣe ijọba Naijiria tẹlẹ ri lati ọdun 1999, ati awọn to wa lori aleefa lọwọlọwọ lori ọrọ ọhun.
Lẹyin awọn goolu to kọkọ gba sawọn ni kete to darapọ ẹgbẹ agbabọọlu Man U, Ighalo lo gba goolu akọkọ wọle fun Man U ninu abala kinni ''round of 16'' idije Europa ti wọn gba pẹlu ẹgbẹ agbabọọlu LASK.
    Ibi yìí ni mo wà títí ilẹ̀ fi mọ́.
O se e se ki awọn ọmọ ilẹ naa ti wọn ba n gba owo osu ti o to ẹdẹgbẹta lẹ ọgọta dọla losu padanu owo osu kan ninu owo osu wọn laarin ọdun kan.
Nigba to ya, wọn gbe ẹhonu wọn lọ soke Mapo, níbi ti Ileesẹ ijọba wa nigba naa, tí wọn si da gbogbo ọọfisi ijọba ru.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù ICC pari iwadi lori iparun awọn Shiites, IPOB 12 Èrèlè 2018 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, ICC sọ pe awọn ti pari isẹ iwadi nipa ipakupa awọn ọmọ ẹgbẹ Shiites ati IPOB Ile ẹjọ tohun gbẹjọ iwa ọdanran lagbaye (ICC) sọ pe awọn ti pari isẹ alakọkọ lori iwadi nipa ipakupa awọn ọmọ ẹgbẹ Shiites ati IPOB ti awọn si ti fi sọwọ si Abubakar Malami, eyi ti o jẹ minisita fun ọrọ igbẹjọ loriede Naijiria.
Bakan naa, egbe oselu “All Progressives Congress (APC) tun gboriyin fun awon osise alaabo ati awon ajo miiran ti o tun kopa fun aseyori eto idibo akoko ohun.
Nigba to n ba awọn akọroyin sọrọ lori iṣẹlẹ ọhun, igbakeji kọmiṣona ọlọpaa ipinlẹ Delta, Faleye Olayele gboṣuba kare fun awọn agbofinro fun iṣẹ takuntakun ti wọn lori iṣẹlẹ naa.
Àpẹrẹ rere ni èyí jẹ́ fún gbogbo àgbáyé.
 nínú ọdún iléyá ti àwọn mùsùlùmí tàbí ọdún un kérésìmesì tí àwọn onígbàgbọ ́ , àwọn onírárà a máa káàkiri ilé àwọn ẹlẹ ́ sìn wọ ̀ nyi , láti kí wọn kú ọdún nípa rárà sisun .
Ademola Ogunbanjọ ní Inssuance o kìí ṣe ojuutu, ò ni ètò amuludun ló 'se pataki, kin àwọn oogun to wa nibẹ, àwọn osiṣẹ́ ǹkọ kíni àwọn ṣe mọ iṣẹ́ sí.
O soro lori nini oja kan lapapo ati ninu ajosepo to dan moran lati gbogun tiwa ibaje to n sele kaakiri ile Afrika.
Ó kọlà abẹ́ fún ọmọ náà nígbà tí ó di ọmọ ọjọ́ kẹjọ gẹ́gẹ́ bí Ọlọrun ti pàṣẹ fún un.
"Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìgbìmọ̀ ìgbẹ́jọ́ ìdìbò ààrẹ kọ ẹ̀bẹ̀ ẹgbẹ́ PDP láti yẹ ojú òpó ayélujára INEC wò 24 Òkùdu 2019 Oríṣun àwòrán, @Atiku Igbimọ to n gbọ ẹsun to su yọ lori eto idibo aarẹ ti kọ ẹbẹ oludije ẹgbẹ oṣelu Peoples Democratic Party, PDP, lati ṣayẹwo oju opo ayelujara ajọ INEC eyi ti wọn pe ni ""Server""."
Ṣé o dé láti wá dà wá láàmú ṣáájú àkókò wa ni?
Eje kí Ìṣsọ̀kan jọba láàrin wa,
Koda, wakati mẹrinlelogun si igba ti wọn kede pe wọn n wa awọn eeyan naa ni ijọba Eko ṣawari wọn, ti wọn si fi wọn pamọ fun ayẹwo ati itọju.
Ṣugbọn èyí yóo jẹ́ anfaani fun yín láti máa fi wá ṣògo, kí ẹ lè máa rí ohun wí fún àwọn tí wọn ń ṣògo nípa nǹkan ti òde ara, tí kì í ṣe nípa nǹkan ti inú ọkàn.
”      Bakan naa, ni anfani lati ja niwaju ogunlogo awon eniyan tun je ohun iwuri.
Ọga agba ẹgbẹ awọn olukọ fasiti, ni fasiti ọlọgba ẹranko ni Ibadan, Deji Omọle ti ṣalaye fawọn eniyan pe iyanṣelodi n tẹsiwaju.
Ẹ óo sì wí fún wọn pé, “Ẹ pòórá!
Tí géndé ọkùnrin mẹ́wàá bá wọn ẹsẹ̀, mẹ́jọ tàbí mẹ́sàn-án nínu wọn ni wọ́n á bọ́sí láti 7 dé 10.
Ṣé lóòtọ́ ni Aláàfin lé Olorì rẹ̀ tàbí àhesọ ọ̀rọ̀?
Bakan naa ni wọn tete palẹ awọn tẹnti ati aga ọdun mọ nilẹ.
Adajo Agba Akanbi so wi pe oruko awon ti iwa ibaje si mo lori je eyi ti o pe lati gbe jadeEyi yoo si fi okan awon omo orile-ede yi bale pe ijoba to wa lori aleefa se tan lati gboogun ti iwa ibaje.
Ọta oogun orun meji ni wọn yin si i lara lati ọọkan lati le gbe e kuro ninu ile naa wọn si gbe e kanmọkanmọ lọ si ọgba awọn ẹranko inu igbo ni Bogijẹ Omu Zoo ni Lekki, ipinlẹ Eko.
Anthony Joshua na Joseph Parker Ibanuje d'orí agbà k'odò, Ruiz fi ẹ̀ṣẹ́ sọ Anthony Joshua di ọmọ ológo àná Anthony Joshua gba àmì ẹ̀yẹ kejì lọdọ Ọbabìnrin Elizabeth Naijiria gbe ile-ẹkọ giga okeere lọ ile-ẹjọ Ni kete ti wọn lu aago yii ni wọn ti gbe Maxim lọ sile iwosan nitori ẹjẹ ti n dà ni agbari rẹ nibi ti wọn ti sare ṣiṣẹ abẹ fun un.
Ijipti ni baba àwọn ará Lidia ati ti Anamu, ti Lehabu, ati ti Nafitu; 
Ilu Ẹdẹ ni Adeleke ti sọrọ yii lasiko to n fesi nipa iwe ẹri rẹ, ti meji ninu awọn akẹẹgbẹ rẹ ni ile ẹkọ girama Ẹdẹ Muslim Grammar School, si rọgba yii ka.
Zikirullah Hassan to jẹ alaga ajọ to n risi ọrọ to niiṣẹ pẹlu awọn ẹlẹsin musulumi lorilẹede Naijiria, NAHCON ni ijọba Saudi gbe igbesẹ naa lati da abo bo awọn eniyan ilu naa nitori wọn ko i tii rojutu aisan naa.
“Bi o ti le je pe, o pe wa ki a to de bi, lataari idaduro ti a ni, koda awon eru wa miiran si wa lona.
Kò ní di mímọ́ bí kò bá wẹ ara rẹ̀ ní ọjọ́ kẹta ati ọjọ́ keje.
Ita Enang,to je oludamoran si Aare lori oro awon omo ile igbimo lo soro yii fawon oniroyin nile ijoba lojo Eti.
"Ariwo ""ẹ gba wa o, ko sina ni gbogbo adugbo wa o!"
Èyí ni ìpín àwọn iranṣẹ OLUWA,ati ìdáláre wọn lọ́dọ̀ mi.
Koda, awọn aawọ miran ninu ẹgbẹ APC di eyi ti awọn ọmọ ẹgbẹ miran binu kuro fi ẹgbẹ oṣelu APC silẹ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Cancer: Àṣe ara mi ni iso ti n run gbogbo bí mo ṣe n ṣèrànwọ́ lórí jẹjẹrẹ Ọkan lara awọn akanda ẹda naa to bawọn akọroyin sọrọ, Adegbuyi Adekunle ṣalaye pe ida marun un ninu ọgọrun tii ṣe 350 lo yẹ ki wọn fawọn.
Yóo ṣẹgun gbogbo ayé, yóo tẹ̀ ẹ́ mọ́lẹ̀, yóo sì fọ́ ọ túútúú.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Òṣìṣẹ́ Bánkì ni mí l'Amẹ́ríkà kí n tó bẹ̀rẹ̀ Tíátà' Oríṣun àwòrán, EPA Àkọlé àwòrán, Arabinrin ọmọ Somali yii, Iman lo n ṣafihan aṣọ yii ninu irin oge rẹ ni Italy.
Nitori pe iku ọwọọwọ lo ma n tẹle iku iru eeyan bẹ ẹ.
Ilé iṣẹ́ BBC bá agbẹjọ́rò Tayo Fatogun sọ̀rọ̀ láti mọ ẹni to le ṣe àdéhùn idunadura lasiko ẹsẹ ikowojẹ.
Anthony Joshua ka batani ẹṣẹ fun Ruiz daradara.
Oríṣun àwòrán, EPA Àkọlé àwòrán, Hazard ló ran Chelsea lọ́wọ́ níbi àṣeyọrí wọn Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
0 43 Orilẹede Laos 0 0.
Nisinsinyii ẹ gbọ́ èrò ọkàn mi,kí ẹ sì fetísí àròyé mi.
“Nítorí àìdára wa pọ̀ níwájú rẹ,ẹ̀ṣẹ̀ wa sì ń jẹ́rìí lòdì sí wa;nítorí àwọn àìdára wa wà pẹlu wa,a sì mọ àwọn ẹ̀ṣẹ̀ wa:
O fi kun un pe igbesẹ alaafia yoo bẹrẹ ni ọsẹ ti o nbọ lati pa ina aawọ laarin wọn.
EPL: Watford lu Chelsea la'lubolẹ pẹlu amin ayo mẹrin
Ninu ilẹ̀ ẹ̀yà Sebuluni, wọ́n fún wọn ní: Jokineamu, Kata, 
Igbakeji oga olopaa , Habilal Joshak lo soro yii  nigba ti o n ba awọn  akoroyin soro lojoRu ni Ado-Ekiti,to je  olu ilu ipinle Ekiti.
Nítorí láti inú ọkàn ni èrò burúkú ti ń jáde wá: ìpànìyàn, àgbèrè, ìṣekúṣe, olè jíjà, ìjẹ́rìí èké, ìsọkúsọ.
Nígbà náà ni àwọn eniyan bẹ̀rẹ̀ sí jọ́sìn ní orúkọ mímọ́ OLUWA.
Mo ti múra ẹ̀wọ̀n ati ikú pàápàá ní Jerusalẹmu nítorí orúkọ Oluwa Jesu.
Lawọn orileede mii,wọn le fi wọn dari ọkọ lalai ni ẹni to n wa.
Bẹẹni ọrọ ifẹ laarin ilumọọka osere tiata lobinrin kan, Nkechi Blessing Sunday, to jẹ ọmọ ẹya Ibo, amọ to n sere ere Yoruba jẹ.
Ó wí fún wa pé àwọn ọlọ́pàá ejò wọ̀nyí tí wọ́n ń ṣọ́ ojú ọ̀nà ló butú jùlọ nítorí bí a bá ti lè kọjá wọn ìyọnu wa bùṣe àfi bí a kò bá tẹ̀lé ohun gbogbo tí òun bá ṣo fún wa.
Àwọn tí ń dá ọ lóró ni yóo rí ibinu mi,àwọn tí ó wí fún ọ pé,‘Bẹ̀rẹ̀ mọ́lẹ̀ kí á gba orí rẹ kọjá;’tí wọ́n sọ ẹ̀yìn rẹ di ilẹ̀ẹ́lẹ̀,tí wọ́n sọ ọ́ di ojú ọ̀nà wọn, tí wọn óo máa gbà kọjá.
Ajo WHO ni laisi pe won fun ida marundinlogorun un ninunu ida ogorun un awon eniayn ekun yii labere ajesara bayii, itankale igbona ko ni dopin.
O wa na ika aleebu si alagba Sam Agbede gẹgẹ bi ẹni to lọ ko awọn kan jọ pe, wọn ti ju ọgọrin ọdun lọ, to si ni ''a ko mọ wọn nitori wọn ko si ninu iwe ofin ẹgbẹ'' Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, International Day Against Drug Abuse and Trafficking: ìdí ti mo fi ń mu oògùn olóró Olajide ni o da oun loju pe, awọn agbagba ẹgbẹ ni ipinlẹ mejeje ko ni pẹ fesi si ọrọ yii.
6 253121 Orilẹede Bosnia ati Herzegovnia 3199 96.
Amọ iwadii awọn onimọ sayẹnsi naa fi lede pe oogun naa ti ko wọn ju, ti o si wọpọ kaakiri n doola ẹmi awọn eniyan to n koju arun Coronavirus.
naa ni: Alaga egbe oselu APC, Adams Oshiomhole, Minisita to n mojuto oro awon
- Trump Amọṣa, lẹyin to gba idije Australian open ni ọdun 2017, eyi to mu ki iye ife ẹyẹ grandslam to ti gba o jẹ mẹtalelogun lo ti n lepa ati gba ẹyọkan sii ko lee jẹ mẹrinlelogun ti yoo si sọ ọ di elere idaraya Lawn tennis to da gba ami ẹyẹ Lawn tennis to pọ julọ ninu itan lagbaye.
Bí èmi náà bá sì rí i pé àwọn ará Amoni fẹ́ ṣẹgun rẹ, n óo wá ràn ọ́ lọ́wọ́.
Àwọn ọmọ-ogun ṣe bí a ti pàṣẹ fún wọn.
Aarẹ Buhari ti kọkọ fọwọ si ẹgbẹrun mẹtadinlọgbọn naira tẹlẹ
Ṣe Ọlọrun ko sọrọ mọ ni?
Aisha Buhari: Ẹni tí wọ́n ní ọkọ mi fẹ́ fẹ́ kò mọ̀ pé ìgbéyàwó kò ní wáyé
Oríṣun àwòrán, Ogun State Governor's office Àkọlé àwòrán, Oriṣiriṣi ọrọ aṣiri si ni awọn eniyan maa n lo ilu lati sọ, ẹni to ba si ni eti ilu nikan ni ọrọ naa le ye.
Ọjọgbọn Wole Soyinka ni ṣe loun jẹ ọkan lara awọn to n da ile iwosan silẹ lati ran eeyan lọwọ fun itọju iru aisan bayii, lalai mọ pe iso n run lara tirẹ gan - O ni arun jẹjẹrẹ gbẹdun abẹ.
Nigba ti alaga egbe APC, Adams Oshiomhole n tewogba abajade iwe naa, o dupe lowo awon igbimo fun gudu gudu, meje ,yaya mefa ti won se lori akanse ise ti won gbe fun won.
"O ni ""Ko si aṣiri kankan, Ọlọrun lo da mi si, igbakugba ni mo le ku ṣugbọn Ọlọrun lo gbemiro."
Ondo: Àwọn afurasí mẹ́rin ti wà ní àhámọ́ lórí ikú ọkùnrin kan ní Igbokoda
Ijọba àpapọ̀ fòfin de oògùn ikọ́ olómi co Ile igbimo aṣofin agba ni Abuja naa ti sọ̀rọ̀ lori koko yii.
Olojede ni awọn tubọ ni ki ileeṣẹ naa se eto iranwọ fawọn mọlẹbi Richard ati pe, awọn ọlọpaa ti bẹrẹ iwaadi lori ohun to ṣokunfa iku Richard.
Ẹ wá sí àjọyọ̀ ogunlọ́gọ̀ eniyan, 
Gẹgẹ bi awọn onimọ ti ṣe sọ, ko din ni ọgọrin aisan gbẹmigbẹmi ati baraku ti wọn lee fi awọn eroja aṣaralore to wa ninu iwọ ati olubi ọmọ tuntun wo.
Àgbékalẹ̀ rẹ̀ rèé: Ní ọjọ́ Ajé ni Mínísítà fún Ètò Ọ̀gbin, Audu Ogbeh ké gbàjarè pé orílẹ̀èdè kan ń pèsè ìrẹsì olóró.
Nítorí bí ẹnìkan tí ẹ̀rí-ọkàn rẹ̀ kò bá lágbára bá rí ìwọ tí o ní ìmọ̀ tí ò ń jẹun ní ilé oriṣa, ǹjẹ́ òun náà kò ní fi ìgboyà wọ inú ilé oriṣa lọ jẹun?
Aare Muhammadu Buhari, ti o lo
Ile-igbimo ohun tun so fun awon alase lati maa pese owo ti o towo fun eka naa, ninu eto isuna owo odun 2018, o kere tan ile-iwosan ijoba kan ni awon ekun mefeefa kaakiri orile-ede Naijira lodoodunEyi waye lori aba kan ti o dale, “Idi Pataki fun kikede pajawiri ni eka ile-iwosan lori awon ohun elo ti o ti baje tan”.
Àwọn òpó ìlẹ̀kùn gbọ̀ngàn ti òde ibi mímọ́ jùlọ ní igun mẹrin, òòró ati ìbú ìlẹ̀kùn wọn sì dọ́gba.
"Ọga ọlọpaa ni ipinlẹ Ondo, Undie Adie ṣalaye ṣaaju pe, ""mo ti paṣẹ fun wọn pe ki wọn wa fun ayẹwo ni ilu Akurẹ, a ni lati ṣọra gidigidi ki a maa baa ri ajakalẹ arun nileeṣẹ ọlọpaa ni ipinlẹ yii""."
Agbẹnusọ fun ẹgbẹ oselu PDP ti ni igbesẹ Gomina Ajimobi lori bi o se yan olori osisẹ tuntun ko di awọn lọwọ ninu eto ti awọn ni silẹ.
Ọga patapata ileeṣẹ ọlọpaa Naijiria, Mohammed Adamu lo kede ọrọ yi nigba to n ba awọn akọroyin sọrọ lọjọ Aiku.
Ṣugbọn ọrọ ko ri bẹ fun awọn ibeji yii Taiwo ati Kẹhinde Fagbọlagun lẹyin ti ọjọ igbeyawo fori sọ ọjọ ti ajọ eleto idibo INEC sun ibo aarẹ ati ile igbimọ aṣofin agba l'Abuja si, eyi ni ọjọ kẹtalelogun, oṣu keji, ọdun yii.
Kíni àwọn olólùfẹ́Arsenal rí sọ síèyí?
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Blind DJ: Etu Omotayo kò ríran àmọ́ ó le to irinṣẹ́ eléré pọ̀ láti kọrin láì sí ìrànwọ́ Jonathan ni lai ṣe ani ani, Babangida ko ipa ribiribi ninu idagbasoke orilẹede Naijiria.
Báyìí ni ọkùunrin náà sa ipá rẹ̀ fún wa, gbogbo wa sì dúpẹ́ lọ́wọ́ rẹ̀ gidigidi.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Baby abandoned on dunmpsite: Mo ti bímọ mẹ́rin tẹ́lẹ̀ fún bàbá méjì nínú òṣí- Dupe Ogbomos Insipẹkitọ ọlọpaa to wa nidi ọrọ naa, Rosemary Samson sọ fun ile ẹjọ pe ẹni a fẹsun kan yii ati awọn miran to ti salọ lo jọ ṣe ẹsẹ naa ni ọjọ kẹrindinlọgbọn, oṣu kẹjọ, ọdun 2020 ni Obasanjo Farm Ltd Ota.
Ètò náà yóò gbà ènìyàn ẹgbẹ̀rún kọ̀ọ̀kan láti ìjọba ìbílẹ̀ ẹẹ́dẹ́gbẹ̀rin ó lé mẹ́rìnléláàdọ́rin jákejádò òrílẹ̀-èdè Nàìjíríà.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Leprosy Day: Ìgbé ayé arákùnrin tó di alábàágbé pẹ̀lú àwọn adẹ́tẹ̀ 137 Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Leprosy Day: Ìgbé ayé arákùnrin tó di alábàágbé pẹ̀lú àwọn adẹ́tẹ̀ 137 20 Èrèlè 2018 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 28 Sẹ́rẹ́ 2019 Ni ọjọ Aiku, ọjọ kẹtadinlogun, oṣu kinni, ọdun 2019 to jẹ ayajọ ọjọ awọn to ti lugbadi aisan ẹté, BBC fọrọ wa Ogbẹni Tunji Oluwatimilehin, to jẹ ọkan lara awọn akanda ẹda yii lẹnu wo.
Nítorí pé, OLUWA fúnra rẹ̀ ni ó mú kí ọkàn wọn le, kí wọ́n sì gbógun ti Israẹli, kí àwọn ọmọ Israẹli lè pa wọ́n run, kí wọ́n má baà ṣàánú wọn, ṣugbọn kí wọ́n pa wọ́n run gẹ́gẹ́ bí OLUWA ti pàṣẹ fún Mose.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Kaakiri gbogbo agbaye ni wọn ti n gboriyin fun ijọba rẹ fun igbesẹ rẹ lati gbogun ti pipa awọn ẹranko lọna ti ko ba ofin mu.
Oríṣun àwòrán, @T_Bakare Tunde Bakare tun sọrọ lori eto atrunto il yii ati ileri awn oludije aar kọọkan lati mu Naijiria de ebute ogo.
Buhari sọ ọrọ yìí ní ọdun mẹ́ta ṣaaju idibo 2015, Oun to sọ rèé: Àarẹ ana Olusegun Obasanjo, ti o ṣe olori Naijiria laarin ọdun 1999 si 2007 naa ko gbẹyin ninu ọrọ kanka to mu awuyewuye dani.
Oba-birin Elizabeti keeji ti rawo ebe si awon omo egbe Ajo Commonwealth lati gbe ipo adari egbe naa fun omo re Omo-oba kunrin CharlesO so eyi di mimo bi o se n si ipade awon olori orile-ede ti won je omo egbe Ajo naa,ti o waye nilu London lorile-ede Britiko.
Àwọn ará Amori ń lé àwọn ọmọ Dani sẹ́yìn sí àwọn agbègbè olókè, nítorí pé wọn kò fẹ́ gba àwọn ọmọ Dani láàyè rárá láti sọ̀kalẹ̀ sí pẹ̀tẹ́lẹ̀.
Tallen rọ gbogbo ọmọ Naijiria gẹgẹ bi ẹnikankan lati mu ọrọ ẹkọ awọn ọmọ obinrin ni ọkunkundun.
Ronaldo lo ran Juventus lọwọ ti wọn fi bori ni Seria A nigba ti Messsi ran Barcelona lọwọ lati gba Liga.
Batiṣeba wí fún Solomoni pé, “Nǹkan kékeré kan ni mo fẹ́ tọrọ lọ́wọ́ rẹ, jọ̀wọ́, má fi ohun náà dù mi.
Lai pẹ, Ìjàpá ni Ọ̀bọ kọ́kọ́ ri, ó ṣe àlàyé fún ọ̀rẹ́ rẹ ohun ti ojú rẹ ri lọ́wọ́ Ẹkùn lai funra pé Ìjàpá ló fa àkóbá yi fún òhun.
Amọ, o ni bi iwọde naa se yiwọ buru jai, toun si koro oju si pẹlu.
Dájúdájú, ninu àìdára ni a bí mi,ninu ẹ̀ṣẹ̀ ni ìyá mi sì lóyún mi.
A sì máa fi turari rúbọ sí àwọ̀n rẹ̀ ńlá; nítorí a máa rò lọ́kàn rẹ̀ pé, àwọ̀n òun ni ó ń jẹ́ kí òun gbádùn ayé tí òun sì fi ń rí oúnjẹ aládùn jẹ.
Ile-ise aare ti so pe lai pe oun yoo mu ojo lati lo sagbekale iwa isuna odun 2019 fun ile-igbimo asofin.
Nibayii, gomina ipinlẹ Zamfara Alhaji Abdulaziz Yari Abubakar ti bu ẹnu atẹ lu ikọlu ati ipaniyan ọhun pẹlu asẹ fun awọn agbofinro ni ipinlẹ naa lati se awari awọn apaniyan naa.
Igbó sambisa kò ní pe di ibi ìgbàfẹ́ Siasia kọ̀wè fún ipò akọ́nimọ̀ọ́gbá Cameroon Messi ni gbajúgbajà agbábọ́ọ̀lù tó ń gbowó jùlọ làgbáyé.
Ìlú Aṣikeloni yóo rí i, ẹ̀rù yóo sì bà á, ìlú Gasa yóo rí i, yóo sì máa joró nítorí ìrora.
Ìdí rèé tí Donald Trump ṣe fìdí rẹmi nínú ìbò ààrẹ Amẹrika Donald Trump sọrọ pẹlu igboya ṣaaju ibo aarẹ orilẹede Amẹrika ọdun 2020 pe oun yoo wọle lẹẹkeji gẹgẹ bi aarẹ ilẹ Amẹrika.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Bí aya bá kọ ọkọ rẹ̀ silẹ̀, kó wà láì lọ́kọ̀' Ẹsun ti wọn ni Yewande fi kan ọkọ rẹ ni pe o ni ololufẹ ikọkọ, eyi to fa ede aiyede laarin awọn mejeeji, ko to o di pe Yewande fi ọbẹ gun ọkọ rẹ,eyi to pada yọri si iku.
Àwọn eniyan bá bẹ̀rẹ̀ sí bẹ Jesu pé kí ó kúrò ní agbègbè wọn.
Ọlọrun sọ fún Balaamu pé, “Má bá wọn lọ, má sì ṣépè lé àwọn eniyan náà nítorí ẹni ibukun ni wọ́n.
tí kò ni ẹnikẹ́ni lára, ṣugbọn tí ó dá ohun tí onígbèsè fi ṣe ìdúró pada fún un; tí kò fi ipá jalè, tí ó ń fún ẹni tí ebi ń pa ní oúnjẹ, tí ó sì ń da aṣọ bo ẹni tí ó wà ní ìhòòhò, 
O wa pàrọwà sáwọn èèyàn ìpínlẹ̀ Ondo láti fọkàn balẹ torí ohun rere sí ń bọ̀ nipinlẹ náà, tó sì rọ wọn láti jẹ ki itẹsiwaju wá nínú iṣejọba.
Mo dá ṣaṣa àgbẹ̀, ọ̀bùn ará ìlú ni.
Ṣugbọn ọrọ rẹ tako eyi niwaju ile ẹjọ, to si sọ pe ile oun ni oun wa lasiko ti wọn ni oun ṣẹ ẹṣẹ naa.
" Baba naa ni nigba ti iṣẹlẹ ọhun ṣẹlẹ, ọmọdebinrin naa ko le da pa itọ mọra afigba to dero ileewosan lori eyi, ṣugbọn Alhadulilah o lee gbe itọ duro fun ọpọ akoko bayii.
Ati wi pe awọn Fulani nikan kọ lo n pa eniyan ni Naijiria pẹlu ibeere pe se Fulani ni Evans ni ti o wa ni atimole fun ẹsun ajinigbe?
Omohtee tu pẹrẹpẹrẹ ọrọ naa ninu ifọrọwerọ kan pẹlu BBC pe oun kabamọ igbeṣẹ naa, koda, o ni diẹ lo ku ki oun gba ẹmi ara oun.
Àní, kí ó wó mi mọ́lẹ̀,kí ó mú mi, kí ó pa mí dànù.
Ní ọjọ́ náà gan-an ni Noa wọ inú ọkọ̀ lọ, òun ati àwọn ọmọ rẹ̀ mẹtẹẹta, Ṣemu, Hamu, ati Jafẹti ati aya rẹ̀ ati àwọn aya àwọn ọmọ rẹ̀ mẹtẹẹta; 
O le ni ọdun kan tawọn agbofinro ti n tọ pinpin wọn ti wọn si ti ri eeyan ẹgbẹrun lọna aadọta ti wọn ti ko si ọwọ awọn aṣebi yi.
bakan naa, o n jẹ Amala, Irẹsi, Dodo ati Ẹwa ati bẹẹ bẹẹ lọ.
 nígbà tí wọn kò lo gìtá alápòótí mọ ní wọ ́ n bẹ ̀ rẹ ̀ síí lo báńjò .
maa dari wa ninu awon ipo oselu, yala fun ijoba apapo ati ni ipinle.
Nigba ti BBC News Yoruba ṣe ayẹwo nipa ileeṣẹ ọlọpaa ti awọn naa ti n ṣiṣẹ, awọn aladugbo ni awọn ọlọpaa ṣi n ṣiṣẹ ni ibẹ.
ti o kun Mallam Mele Kyari lese lo sile igbimo naa lati ri oludari ile-ise NNPC
Bẹ́ẹ̀ ni kí á má ṣe dán Oluwa wò, bí àwọn mìíràn ninu wọn ti dán an wò, tí ejò fi ṣán wọn pa.
Eyi ri bẹ lẹyin ti ajọ NCDC tun kede eniyan 436 to tun ṣẹṣẹ ni i lọjọ Aiku.
Fulani kò leè dúró, táa bá lo ohun ta jogún lọ́dọ̀ àwọn bàbá wa - Sunday Igboho Dangote, jọ̀ọ́ nawọ́ ìrànwọ́ láti dá iléeṣé sílẹ̀ fún wa ní Ọyọ - Aláàfin rawọ́ ẹ̀bẹ̀ Láti orí 'Our Mumu don do' sí 'Revolution Now' Bí ọdún Ọ̀ṣun Oṣogbo ṣe bẹ̀rẹ̀ rèé àti pàtàkì rẹ̀ fún Nàíjíríà Saudi ṣàtúnṣe lílẹ òkò mọ́ Asitani láti dẹ́kun títẹra-ẹni-pa Sowore takú, kò jẹun ní àgọ́ ọlọ́pàá torí májèlé - Deji Adeyanju A ti n sisẹ kara lati mọ awọn eeyan naa, laipẹ laijinna si ni ọwọ wa yoo tẹ wọn ninu igbo ti wọn sa lọ."
Ó ti di ogún èèyàn tó kú ní ilé alájà tó wó l'Eko Wọ́n dóòlà ẹ̀mí èèyàn mẹ́rin níbi ilé mííràn tó wó l'Eko Ilé wo pà 'yàn meji l'Èkó Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Àlàyé rèé lórí ilé kẹ̀ta tó wó l'Eko Iṣẹlẹ ile wiwo yii ni yoo jẹ ẹlẹkẹtaa ti yoo waye nilu Eko laarin ọsu kan.
Ninu ọrọ rẹ, o ni nitori ọmọ oun kọ lati fi ẹsin Kristẹni silẹ ni wọn ko se fisilẹ lahamọ.
Akọwe UNWTO naa ni: “A wa sibi wa ṣe igbedide fun awọn ibudo igbafẹ tuntun lagbaye ni.
Awọn eniyan Ikenne kan ṣafiwe awọn ọmọ Ogun to ti goke ọla sẹyin ṣugbọn ti wọn ko ṣe nkankan fún ìlú, ipinlẹ ati iran wọn lapapọ.
Bi eto atundi ibo ti yoo waye
Ọkọ lé aya rẹ jáde nílé nítorí ìrísí ojú àwọn ọmọ rẹ méjì ní Ilorin Afẹ́fẹ́ Gáàsì tó ń yọ́ọ́ jò pa Ajibola lẹ́nu iṣẹ́ jórin-jórin Amọṣa igbe 'awọn eeyan ẹkun gusu ipinlẹ Ondo atawọn majẹobajẹ kan ni ipinlẹ naa ni o mu ki O bẹrẹ ijiroro ati igbesẹ lati kuro ni ẹgbẹ oṣelu PDP' Gẹgẹ bi o ṣe sọ, igbakeji gomina ipinlẹ Ondo naa ko tii kuro ni ẹgbẹ oṣelu PDP ṣugbọn yoo ṣi kuro titi opin ọsẹ yii.
8 1139 Orilẹede New Zealand 25 0.
A gbọdọ̀ sọ ọjọ́ ìbíi rẹ̀ di Kérésìmesì China.
Gẹgẹ bi ileesẹ ọlọpaa ti kede rẹ, ọwọ sinkun awọn ọlọpaa kogberegbe SARS lo mu awọn afurasi ajinigbe mẹrẹẹrin naa, lasiko ti wọn n ji olokoowo kan, Chekwas Daniel, gbe.
Agbẹnusọ ilé iṣẹ ọlọ́pàá ló fidi ọ̀rọ̀ yìí múlẹ̀ lásìkò tó n ba BBC News Yoruba sọ̀rọ̀ lóri ibi ti wọ́n bá iṣẹ́ dé lójúnà ati ri Sunday Shodipe, agbénipa to sá lọ lágọọ ọlọ́pàá nípìnlẹ̀ Oyo.
Ẹ̀yin akẹ́kọ̀ọ́, àjọ WAEC ti kéde ọjọ́ tí èsì ìdánwò WAEC 2020 yóò jáde Àwọn èrò yarí lórí sísan owó àyẹwò covid-19 bí bàálù ilẹ̀ òkèèrè ti ba s'Abuja lẹyìn oṣù márùn ún Kọmíṣọ́nà mẹ́ta lùgbàdì àrùn Coronavirus l'Ọyọ Ọkùnrin tí wọ́n fẹ̀sùn kàn pé ó jí ǹkan nílé ìjọsìn rí ẹ̀wọ̀n he!
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Àwọn akẹ́kọ̀ọ́-bìnrin Naijiria fẹyin US ati China gbolẹ nidije ìmọ ẹrọ Ọsẹ́ tí òògùn Tramadol ń se nínú ara Sé ó yẹ kàwọn pásítọ̀ máa bèèrè èso owó ńlá-ńlá ?
Iwakusa ohun ti ba awon omi agbegbe kan je, nigba miiran o tun je idiwo fun awon osise iwakusa ohun.
Iroyin ni ṣe ni awọn ọlọpaa le ọrẹkunrin ati ọrẹbinrin naa nigba ti wọn n bọ lati ile igbafẹ kan ni agbegbe Ajegunlẹ ni ipinlẹ Eko.
Igbimo naa tun ti gba ọkọ ayọkẹlẹ meji ti iko SARS  gba lona aito lowo won, ti won si daa pada si
naa, ni a si n wa ojutuu si awon ile-ise to n pese ero ibanisọrọ ati ipe ti won
Ẹ̀ ń pè mí ní Olùkọ́ni ati Oluwa.
Cute Abiola fikun pe, igba ti nnkan dagun lori awada ṣíṣe lori ayelujara ni oun ṣe lọ gba iṣẹ ologun amọ ko pẹ naa lẹyin eyi, ti ohun gbogbo pada bọ sipo.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ǹkan tí ẹ̀mí mímọ́ fi hàn mí kí n tó bẹ̀rẹ̀ orin ìfèdèfọ̀ rèé- Testimony Jaga Bi eto idibo keji yoo ba waye, wọn yoo ko awọn iwe idibo akọkọ si ẹgbẹ kan, wọn yoo si dana sun wọn papọ mọ ti idibo keji.
Oun toju rẹ ri ko mu'nu rẹ dun rara'' Oríṣun àwòrán, Reuters Àkọlé àwòrán, Ogbontarigi agbabọọlu ẹgbẹ Real Madrid, Cristiano Ronaldo O ti pẹ ti Ronaldo ti'n naani ẹwa ara rẹ Lootọ nipe awọn oniroyin ati ololufe ere idaraya dẹgun le Ronaldo pẹlu yiyẹ apa ara rẹ wo, sugbọn lotitọ, Ronaldo o sẹsẹ maa wu iru iwa bayi.
Auxiliary sọ pe ara lo n ta awọn ọmọ ẹgbẹ NURTW ti wọn n pariwo ohun kaakiri.
Ayẹyẹ naa ti wọn pe ni AMVCA7 lo waye lọjọ Abamẹta nilu Eko, ti ọpọ awọn ilumọọka osere tiata nilẹ Adulawọ ati loke okun peju si.
Bí baba rẹ bá bèèrè mi, sọ fún un pé mo ti gbààyè lọ́wọ́ rẹ láti lọ sí ìlú mi, ní Bẹtilẹhẹmu, nítorí pé àkókò yìí jẹ́ àkókò fún àjọ̀dún ẹbọ ọdọọdún ìdílé wa.
Ọba Amoni bá rán àwọn oníṣẹ́ pada sí Jẹfuta pé, “Nígbà tí ẹ̀ ń bọ̀ láti ilẹ̀ Ijipti, ẹ gba ilẹ̀ mi, láti Anoni títí dé odò Jaboku, títí lọ kan odò Jọdani.
Pilatu wá bi wọ́n pé, “Kí ni ẹ fẹ́ kí n ṣe sí Jesu tí ó ń jẹ́ Mesaya?
Wọn óo jẹ́ eniyan mi, èmi náà óo sì jẹ́ Ọlọrun wọn.
Nigba to n fidi ọrọ naa mulẹ fun awọn akọroyin, alukoro ileeṣẹ ọlọpaa ni ipinlẹ Anambra, Haruna Mohammed ṣalaye pe ọwọ ti ba afurasi naa, Ati pe wọn si ti gba irinṣẹ to fi ṣiṣẹ buruku naa lọwọ rẹ gẹgẹ bi ẹri lati lo nile ẹjọ́ Ènìyàn 213 ló kó arùn Coronavirus ní Nàìjíríà ní Ọjọ́ Ẹti A ti ja aráàlú kulẹ̀, ta bá pè wọ́n fún ìwọ́de, wọn kò ní jẹ́ wa mọ́ - NLC Eko Ẹ gbà mí, Nàíjíríà gbá mi lórí àyẹ̀wò Covid-19 - Iyabo Ojo figbe ta Àwọn afọbajẹ wọ́ Oluwo relé ẹjọ́, ìjọba Osun kò tíì fọùn Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Obateru Akinruntan: Wíwá ohun tá jẹ títí láé ló gbé wa kúrò nílé Ife Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Petrol Price Hike: Ilé aṣojú-ṣòfin dúró ìṣẹ́jú kan fún Buruji Kashamu àti Rose Okoh30 Owewe 2020 Fídíò, Wole Soyinka sọ ìdí tó fi ni òun a fi màálù Fulani ṣe súyà fáwọn èèyàn abúlé23 Owewe 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 3 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 5 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
7 5499 Orilẹede San Marino 49 145.
Lẹ́hìn èyí bàbá mi wí pé, Njẹ́ bí ó bá ṣe ìwọ ni oníbodè, ṣí ‘lẹ́kùn fún mi, mo ń fẹ́ẹ́ lọ ṣe ọdẹ, ṣe wéré, ojú ń kán mi.
tí ẹ bá rí arẹwà obinrin kan láàrin àwọn ẹrú náà tí ó wù yín láti fi ṣe aya fún ara yín.
Ọgbẹni Kareem sọ pe ọrọ naa ko nii ṣe pẹlu Saraki nikan, gbogbo ọmọ ile ti ko pada sile lo kan.
Coronavirus symptoms: Èèyàn mẹ́ta míràn ti ní àrùn Coronavirus ní Nàìjíríà Oríṣun àwòrán, Seyi makinde Eeyan mẹta miran tun ti ko arun Coronavirus lorilẹede Naijiria bayii.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ere bọọlu nla 4) Ibẹrẹ kii ṣe oniṣẹ.
Inu ile Aarẹ Buhari ati Aisha Buhari ni Abuja ni ayẹyẹ igbeyawo naa ti waye, ti iyawo aarẹ Buhari si fi si oju opo Instagram rẹ wi pe oun dupẹ lọwọ Olọrun pe o yọri si rere.
Oríṣun àwòrán, AFP Àkọlé àwòrán, Awọn eniyan marundinlaadọta ti salaisi latari arun iba-pọnju, pọntọ.
ẹ sì níláti kọ́ àwọn eniyan Israẹli ní gbogbo ìlànà tí OLUWA ti là sílẹ̀, tí ó ní kí Mose sọ fun yín.
asofin ipinle Eko mu wa lori bi  ina
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ronaldo ati awn akegbe re jijo ye papa iṣere Old Trafford wo saaju Ifẹsẹwọnsẹ wọn pẹlu Manchester United lọjọ isẹgun Ipade manigbagbe laarin Manchester United ati Juventus kan waye nigba ti wọn koju ninu ipele to pọwọ le asekagba idije Champions League lọdun 1999.
Oríṣun àwòrán, Instagram/dayoamusa Andrew wa gba Dayọ nimọran pe yoo dara ko lọ jo diẹ.
Sheffield faṣọ iyì ya mọ́ Chelsea lára lọ́nà ìrìnàjò sí Champions League Iléeṣẹ́ Ọlọ́pàá ṣetán láti bẹ̀rẹ̀ ètò ìgbanisíṣẹ́ lákọ̀tun Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Ó ṣe pàtàkì kí obìnrin gbádùn ìbálòpọ̀ nítorí.
Ó sì mú akọ mààlúù meji, àgbò marun-un, òbúkọ marun-un ati akọ ọ̀dọ́ aguntan marun-un ọlọ́dún kan wá fún ẹbọ alaafia.
''Mo maa n bẹ awọn Fulani to wa ninu ilu mi wo.
Ẹ ní ìfaradà láàrin ara yín.
Niṣẹ lo tọju to si tọ ẹnu, koda o tun fijo bẹẹ ninu fọnran to fi lede lori oju opo Instagram rẹ.
Ramaphosa, the de-facto president-in-waiting, had been in negotiations with Zuma who rejected an earlier request from party leaders to step down more than a week ago.
Àní, yóo ti pẹ́ tó tí àwọn eniyan burúkú yóo máa ṣe jàgínní?
Arisekola Alao ko ida kan, Adedibu ko ikeji ,Olubadan lo ko mejeji to ku pọ.
Egbe oselu APC ni apapo ibo òjìlénígba dín mẹ́sàn án le  ẹ̀gbẹ̀rún okòólénígba dín kàn(219,231 votes), ti egbe oselu PDP si ni, apapo ibo méjílélọ́gbọ̀n le  ẹ̀gbẹ̀rún mẹ́rìnléláàdọ́jọ(154,032 votes)O kede abajade esi idibo naa
Alaafin lo sọ ọrọ naa ninu ifọrọwerọ pẹlu ileeṣẹ iroyin abẹle ede Yoruba kan.
Abilekọ Madikizela-Mandela duro lẹnu iloro lati ki kaabọ.
“Ṣugbọn ẹ̀yin ọmọ Jeṣuruni, ẹ yó tán,ẹ wá tàpá sí àṣẹ;ẹ rí jẹ, ẹ rí mu, ẹ sì lókun lára;ẹ wá gbàgbé Ọlọrun tí ó da yín,ẹ sì ń pẹ̀gàn àpáta ìgbàlà yín!
Lẹ́yìn náà, àwọn ọmọ Lefi yóo gbé ọwọ́ wọn lé àwọn akọ mààlúù náà lórí.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù NIMC registration portal: Ìjọba Nàìjíríà fọjọ́ mọ́kànlélógún gbako kun ọjọ́ láti so NIN rẹ̀ mọ́ síìmù 21 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Oríṣun àwòrán, Twitter Ijọba apapọ ti fi kun iye ọjọ ti ara ilu yoo fi forukọsilẹ lati so nọmba idanimọ NIN wọn mọ siimu wọn.
Meji ninu awọn ibudo wọnyii ni a o mẹnuba ninu akọsilẹ yii; awọn meji naa si ni Orisun omi orioke Olumirin ti ọpọ mọ si Ẹrin Ijẹṣa Water falls ni ilu Ẹrin Ijẹṣa ati Ojubọ Ọṣun Oṣogbo ni ilu Oṣogbo, ipinlẹ Ọṣun kan naa.
" Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Akure Kidnap: E túbọ̀ ní sùúrù, a máa wá ọmọ náà rí- Alukoro ọlọ́pàá Wọ́n mú u sùgbọ́n wọ́n gba oniduro rẹ̀ lẹ́yìn ti wọ́n ri ẹgbẹ̀rún mẹ́wàá dọla gbà pada, wọ́n ni ko maa yọju si akata wọn loorekoore sùgbọ́n kaka bẹẹ ko jẹ́ ki ẹnikẹni ri òun.
Awọn akọnimọọgba yii mọ ara wọn, padi-padi ni wọn.
Oko ofururfu Bangladeshi ti o gbe ero mẹ́tàdínláàdọ́rin, ati awon atuko merin-in ja lule lojoAje(Monday) lasiko to fe bale si papako ofurufu ni olu ilu Nepa, Kathmandu, bee sini eniyan metadinlogun si farapa yanayana.
Ẹni to bori: Congo DR Ìpele to ṣaaju eyi to kangun si aṣekagba Tanzania vs Benin.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ìwòsàn Somalia: Pàsán àti ‘Harmala’ la fi ń se ìwòsàn òògùn olóró Lẹyin eyi lo sọọ diṣẹ iranlọwọ to fi n gbe awọn to farapa ninu ijamba ado oloro ati ninu iṣẹlẹ miran.
 mark mẹnuba akoko ti òkunkun ni ọsan lakoko ti a kàn mọ agbelebu jésù , ati tẹmpili ibori ti a ya ni meji nigbati jésù ku .
Lati owurọ ni ariwo ibọn ti n dun ni kikan kikan ni agbegbe Iwo road lọ si Abayọmi-Idi-Apẹ.
8 Bélú 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 20 Bélú 2020 Oríṣun àwòrán, CNN Ileesẹ iroyin agbaye ni,CNN, ti fesi si ọrọ Minisita feto iroyin Naijiria Lai Mohammed to ni ijọba yoo fofin de ileesẹ iroyin naa lori ayederu iroyin to gbe jade nipa isẹlẹ iyinbọn paniyan to waye ni Lekki.
Nibayii orilẹede Sudan tabi Kenya ni ẹgbẹ agbabọọlu Naijiria yoo koju bayii ninu ipele to kan.
Awọn idile ti oye kan yoo da'fa, bẹẹ ni awọn afọbajẹ naa yoo da'fa."
Oloye Olusegun Obasanjọ pe ipe atunse yii nilu Eko lasiko akanse eto idanilẹkọ kan ti wọn se niranti asaaju ẹgbẹ agbarijọpọ ọmọ bibi Oodua, Oloye Frederick Fasheun.
Messi gọ̀ láti sọ fun akọ́nimọ̀ọ́gbá Brazil pé kó gbẹ́nu dákẹ́- Thiago Silva FUTA pàṣẹ lọ rọọ́kún nílé f'ákẹ́ẹ̀kọ́ méje tó lu akẹgbẹ́ wọ́n Afunrasí jàǹdùkú 22 lọ́wọ́ ọlọ́pàá ti tẹ̀ lórí wàhálà ìdìbò ní Kogi-Iléeṣẹ́ Ọlọ́pàá Irọ́ ni pé wọ́n sèkọlù sí Gómìnà Seyi Makinde - Ọlọ́pàá Kogi Àgbẹdọ̀!
Idiagbon tiraka nigba aye rẹ, to si sa ipa rẹ lati jẹ ka ni orile-ede Naijiria to duro rẹ, amọ ọpọ ọmọ Naijiria ta ko o.
Akọ mààlúù kékeré kan, àgbò kan, ọ̀dọ́ àgbò kan, ọlọ́dún kan, fún ẹbọ sísun, 
N óo bá ọ dá majẹmu kan, tí yóo wà láàrin èmi pẹlu rẹ, n óo sì bukun ọ lọpọlọpọ.
Fọto Dino ati obinrin naa lo wa lara iwe ipe igbeyawo ọdun, ti wọn ni yoo waye ni ọjọ Satide, ọjọ keji ọdun Keresimesi, eyiun ọjọ kẹrindinlọgbọn osu Kejila ọdun 2020.
Mo dúpẹ́ lọ́wọ́ Olódùmarè lónìí, mo dúpẹ́ lọ́wọ́ irúnmalẹ̀ gbogbo lónìí, mo dúpẹ́ lọ́wọ́ àwọn àǹjànnú ayé, mo dúpẹ́ lọ́wọ́ oògùn àwúre inú àpò mi, bẹ́ẹ̀ ni mo dúpẹ̀ lọ́wọ́ iwin pàtàkì ńlá nì, Aládé-igbó, ẹbọra tí í ṣe alákòoso òkìtì ọ̀gán, tí ó jẹ́ ìbátan mi.
ife ipinle Ọyọ jọba lookan aya rẹ.
Ní kété tí Atalaya, ìyá ọba Ahasaya gbọ́ nípa ikú ọmọ rẹ̀, ó pa gbogbo ìdílé ọba run.
Oríṣun àwòrán, other Ajọ EFCC gbe Olisah Metuh lọ sile ẹjọ giga kan nilu Abuja fun gbigba irinwo miliọnu naira lọwọ ọfiisi alamojuto abo lorilẹede Naijiria lọdun 2014.
Israel Adebajo: Ìlúmọ̀ọ́ká oníṣòwò tó fi òkò Stationery Stores pa ẹyẹ púpọ̀ Ìtàn tó wà nídi òwe ‘Sebótimọ Ẹlẹ́wà Sàpọ́n’ Ìtàn tó rọ̀ mọ́ òwe ‘aṣọ kò bá Ọ́mọ́yẹ mọ́.
Ṣe wọn ni iku o dọjọ, arun o doṣu.
Ẹ tú wọn, kí ẹ mú wọn wá fún mi.
Ṣugbọn gbogbo awọn orilẹede apa iwọ oorun Afririka yii ni ko ni awọn eeyan to laarun coronavirus to Naijiria.
Àkàndá ẹ̀dá Nàíjíríà mókè nínú irin gbígbé OAU fẹ́ wádìí olùkọ́ tó fẹ́ bá akẹ́kọ̀ọ́ lò fún máákì Gẹgẹbi ọrọ ajọ naa, iye eniyan to ku naa ni wọn fi lede lẹyin iwadii lori iye ẹmi to ti sọnu, dukia, ile ati ọna to ti bajẹ nitori aigbọraeniye laarin awọn agbẹ ati darandaran lẹkun gbungun ariwa orilẹede Naijiria to fi mọ Benue, Taraba, Plateau, Kogi ati ipinle Nasarawa.
Gbogbo orílẹ̀-èdè ni yóo máa ṣe ẹrú òun ati ọmọ rẹ̀, ati ọmọ ọmọ rẹ̀, títí àkókò tí ilẹ̀ òun pàápàá yóo fi tó, tí ọpọlọpọ orílẹ̀-èdè ati àwọn ọba ńláńlá yóo sì kó o lẹ́rú.
Oríṣun àwòrán, Instagram/abiolaajimobi Ajimọbi rọ gbogbo ọmọ ẹgbẹ APC nipinlẹ Oyo lati dariji ara wọn nitori akoko niyii lati ṣe atunṣe ẹgbẹ naa ṣaaju ipenija to le wa lọjọ iwaju.
Igbese ipinlẹ ỌṣunỌjọ kọkanlelọgbọn, oṣu Kẹta ni isede kọkọ bẹ̀rẹ̀ ni ipinlẹ Ogun ni eyi ti ko yọ awọn ileewe ati ile ijọsin silẹ.
Ẹ yé fi ilé, mọ́tò bùga lórí ayélujára - Oshodi-Oke Lizzy Anjorin: Mi ò bẹ Toyin o!
A fẹ́ tẹ̀ ẹ́ mọ́ ọba létí pé bí àwọn eniyan wọnyi bá kọ́ ìlú yìí tí wọ́n sì mọ odi rẹ̀, kò ní ku ilẹ̀ kankan mọ́ fún ọba ní agbègbè òdìkejì odò.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, jkkkkk Kini o ti ṣẹlẹ sẹyin?
Nítorí owú jíjẹ a máa mú kí inú ọkọ ru,kò sì ní jẹ́ ṣàánú àlè bó bá di pé à ń gbẹ̀san.
Ebun Oloyede, ti ọpọ mọ si Olaiya Igwe lo kọkọ fidi iroyin naa mulẹ fun BBC Yoruba pe Baba Legba ti papoda.
Oríṣun àwòrán, Muyiwa Ademola Àkọlé àwòrán, Muyiwa Ademọla Muyiwa Ademọla.
Abala keji ko yatọ si ikini ti Wolves ko si dawọ kikan ilẹkun Arsenal duro.
Gjedde sọ fun ileeṣẹ iroyin Fox pe Aarẹ Trump yẹ lẹni to n gba ami ẹyẹ naa fun iṣẹ ribiribi to ti ṣe lati jẹ ki alaafia wa laarin awọn orilẹ-ede kan lagbaye.
 Won ti tile iwe naa pa fun ose yii.
“Acronym” ni wọ́n npe gígé ọ̀rọ̀ kúrú báyìí ní Gẹ̀ẹ́sì.
Coronavirus: Ijọba ìpínlẹ̀ gbé òfin jáde fún àwọn tó n padà sẹ́nú iṣẹ́ lẹ́yìn k'ónílé o gbélé Oni ọjọ Aje ni orilẹ-ede Naijiria bẹrẹ si ni dẹ okun ofin konile-o-gbele to fi sita nitori coronavirus nilu Abuja, ipinlẹ Ogun, ati ipinlẹ Eko lati le din ipa buruku ti aarun naa le ni lara ọrọ aje ku.
Àkọlé àwòrán, Oludije keji Hope Uzodinma to jẹ ọmọ wọọdu kan naa pẹlu Nwodu lo gba gbogbo ibo aadọrun naa.
Bí ajá tíí pada sídìí èébì rẹ̀ bẹ́ẹ̀ ni òmùgọ̀ tó pada sí ìwà agọ̀ rẹ̀.
Ọrọ naa si tun ti mu ki ẹnu tubọ maa kun awọn ayederu pasitọ ni South Afrika.
Oríṣun àwòrán, Yemi Akintunde Àkọlé àwòrán, Adugbo Alagbado nilu Ilorin lawọn janduku da firiiji nla yi pada si lẹyin ihalẹ ọlọpaa Oríṣun àwòrán, onogwuMuha Àkọlé àwòrán, Ni ilu Lokoja, awọn janduku ko tilẹ ṣaanu awọn ile iwosan nibi ti wọn ti gbe ẹrọ ayẹwo ara yi.
O sọ pe Funmi Martins jẹ abiyamọ tootọ ti o si jẹ ẹni to fẹran gbogbo eniyan sugbọn to jẹ pe, iku se emi rẹ legbodo lai pe ọjọ.
Ìdí nìyí tí wọ́n fi ṣẹgun wa.
Bẹẹ ba gbagbe, a ti n mu iroyin wa fun yin tẹlẹ pe nnkan ko fararọ nile asofin ipinlẹ Ondo nitori eto idibo gomina to sunmọ etile.
Àwọn ọmọ-ẹ̀yìn náà bá lọ sọ́dọ̀ Johanu, wọ́n wí fún un pé, “Olùkọ́ni, ọkunrin tí ó wà pẹlu rẹ ní òdìkejì odò Jọdani, tí o jẹ́rìí nípa rẹ̀, ń ṣe ìrìbọmi, gbogbo eniyan sì ń tọ̀ ọ́ lọ.
A o gbe abajade iwadi ati ero wa siwaju Aarẹ lati ṣe ipinnu lori aba igbimọ amusẹṣe, nkan to ba sẹlẹ ni ọṣẹ mẹta si asiko yii ni yoo sakawe igbesẹ ti ijọba yoo gbe.
    Ṣùgbọ́n Ìbẹ̀ǹbẹ̀-olókùnrùn sàn nínú àìsàn rẹ̀ lọ́nà kín-ín-ní òun pàápàá ti ronú pìwàdà ẹ̀sẹ̀ rẹ̀ àtijọ́ gbogbo níto’ri ó ba ẹni rere rìn.
Angẹli OLUWA sì dáhùn pé, “Máa bá àwọn ọkunrin náà lọ, ṣugbọn ohun tí mo bá sọ fún ọ ni kí o sọ.
Nítorí náà, OLUWA Ọlọrun ní, “Nítorí ọ̀rọ̀ asán tí ẹ̀ ń sọ, ati ìran èké tí ẹ̀ ń rí, mo lòdì si yín.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Ninu idahun rẹ, Femi Adesina ninu atẹjade sọ wi pe isọkusọ gba ni ọrọ ti awọn igbimọ ti Ango Abdullahi ṣe adari fun un sọ.
Inu ifẹsẹwọnsẹ to waye lalẹ ọjọ Isinmi ni ẹkọ ti foju mimu han lẹyin ti Chelsea bo Manschester United lẹgba ami ayo mẹta si ọkan ṣoṣo.
ni ibamu pelu iwe ofin Ipinle Oyo, (order on Page 389 Cap 28 section 1,2, and 3
Ó dára kí eniyan máa dúpẹ́ lọ́wọ́ rẹ, OLUWA;kí ó sì máa kọ orin ìyìn sí orúkọ rẹ, ìwọ Ọ̀gá Ògo;
Awuyewuye tun pada ruwe nigba ti o han gbangban pe onimọ ẹrọ Huawei mii lọwọ ninu mimu robot arm yi ati pe awọn ọga rẹ lati China ni wọn ran niṣẹ naa.
"Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Akomolede àti Asa lórí BBC Yorùbá: Mọ̀ síi nípa ẹ̀kún ìyàwó níbí Awọn to lẹtọ si owo iranwọ N75 biliọna naa lasiko yii ni awọn ti iṣẹ wọn nii ṣe pẹlu: - Awọn agbẹ olohun ọsin ati oko ounjẹ - Awọn ti iṣẹ wọn nii sẹ pẹlu imọ ẹrọ ati tikinọlọji Wo àfiwé owó oṣù Ọlọ́pàá Nàìjíríà pẹ̀lú akẹgbẹ́ wọn lókè òkun Wo awọn iroyin manigbagbe to waye ni ọsẹ yii Wo ojú àwọn òṣèré yìí láì lo ""Make-up"" orí ìtàgé bó ṣe rí gẹ́lẹ́ England kéde ìséde ọ̀sẹ́ mẹ́rin míràn láti dẹ́kun ìtànkálẹ̀ Covid 19 Sanwo Olu àti Okowa dẹwọ́ ìséde ní Eko àti Delta pẹ̀lú àlàyé tuntun Wọn ni awọn ti iṣẹ wọn ni i ṣe pẹlu irin ajo afẹ, ile kikọ, ati eto ilera laiyọ karakata silẹ."
A ti tu yín sílẹ̀ ninu ọgbà ẹ̀wọ̀n ẹ̀ṣẹ̀, ẹ ti di ẹrú iṣẹ́ rere.
Oba ọ̀hun sọ pe oun ṣe bẹ́ẹ̀ ni nitori èdè-àìyedè to wà láàárin àwọn oba aladé nilẹ Yorùbá.
" Lori nkan ti aisan naa gba lọwọ rẹ, Arabinrin Fola sọ pe ki oun ṣa dupẹ lọwọ Ọlọrun ti ko fi aaye iyẹn silẹ.
Musa jẹ aarẹ apaṣẹ waa ni ẹkun Gusu ilẹ Afirika laye ọjọ-un ti o fi orilẹede Mali ṣe ibujoko ijọba rẹ.
Ọjọ́ mẹjọ ni wọ́n fi ya ilé OLUWA sí mímọ́, wọ́n parí ní ọjọ́ kẹrindinlogun oṣù náà.
 lori bi awon ipele awon agbe se ri , o da bi pe awon abule na je adurotitisi .
Lọjọru, ọwọ tẹ ọkan lara awọn alakoso idanwo ọdalẹ ọhun nipinlẹ Nassarawa, wọn ko mọ pe awa gan ni ọna ta fi kẹẹfin wọn.
Wọnyi ni awọn iroyin to fi lede, to si sọ pe lati ọdọ Ọgbẹni Quest lo ti wa: ''Kosi ohun to dabi ile iṣẹ itura ni Kenya.
ede Naijiria lati ni ifojusun rere nipa orile ede Naijiria.
 Dẹjọ ti kopa ninu awọn sinima bii Tori ife, Aya rere, Owo o mo agọ, Born boy, Ẹrọ ibanisọrọ, Ejide, Itọ, adigun ati bẹẹbẹẹ lọ."
Ojú kò ní tì ọ́, bẹ́ẹ̀ ni o kò ní dààmú, títí lae.
Wọ́n gbógun tì mí ní ọjọ́ ìpọ́njú mi,ṣugbọn OLUWA ni aláfẹ̀yìntì mi.
Kó ègé ẹran sí i,gbogbo ibi tí ó dára jùlọ lára ẹran,ẹran itan ati ti èjìká,kó egungun tí ó dára náà sí i kí ó kún.
Nígbà tí ó tún di àkókò òjò mo gbin gbogbo ẹyọ àgbàdo tí mo ní sí oko títóbi kan báyìí tí mo ṣe; nígbà tí àwọn àgbàdo mi si wáá gbó, mo bẹ̀rẹ̀ sí jẹun.
Oríṣun àwòrán, AFP Àkọlé àwòrán, Gominọ pe awọn Fulani lati Benue ati Taraba nitori Kano ni ilẹ-ọsin pupọ lati gba wọn ati awọn ẹran wọn Gomina naa tun sọ pe gẹgẹ bi ipinnu rẹ, ijọba setan lati ṣe atilẹyin fun dida ẹranko ni ipinlẹ Kano, atipe ijọba yoo tẹsiwaju lati maa pese awọn ile-iṣẹ ati awọn ohun amulo fun wọn ati awọn ẹranko wọn.
Leyin ti iko ohun gbo ewuro soju iko agbaboolu Bayern pelu ami ayo kan si meji (1-2), lojoRu(Wednesday)Esi ifesewonse ohun lo farahan pe, iko Real Madrid ti gbenu le asekagba idije naa, latari ofin ti o ro mo iye ami ayo ti iko kookan ba gba wole.
Ṣiṣe aṣọ iṣẹ awọn ọlọpaa ni oju kan naa.
Mo ní ìtara rékọjá ààlà ninu àṣà ìbílẹ̀ àwọn baba-ńlá mi.
Ẹ̀ni ọgọ́ta ọdún gbẹ̀mí ara rẹ̀ ní UCH Ibadan Bàbá pokùnso ní àhámọ́ lórí ẹ̀ṣùn pé ó bá ọmọ rẹ̀ lòpọ̀ ‘DJXgee lọ sòde eré lọ́jọ́ ọdún tuntun láìmọ̀ pé yóò gbẹ̀mí ara rẹ̀’ Àwọn mọ̀lẹ́bí ajínigbé tó pàdánù ẹ̀mí l'Ondo kò tí ì yọjú Bàbá ọlọ́mọ márùn-ún pokùn so ní Ekiti Oladejo ni lootọ ni aaye ibugbe Zubair jona ṣugbọn nigba ti awọn panapana yoo fi pa ina na ko si apẹrẹ pe ina jo Othman Zubair mọ ori ibusun rẹ ti wọn ti ba.
Àdúrà mi ni kò jẹ́ kí ìyà Manchester United ó pọ̀ jù lọ́wọ́ Barcelona- Wòlíì Àrólé Arsenal fẹ́ ṣe bíi Barcelona Awọn alatilẹyin ẹgbẹ Arsenal ko tilẹ jẹ ki o pẹ rara ti wọn fi bẹrẹ si ni yọnu eebu si awọn alatilẹyin Napoli lori ẹrọ ayelujara.
Wọn ti kuna wọn si ti mu ofo.
Alaafin Oyo kò dàgbà jù fún mi, ohun tó wù mí ní mo ṣe pẹ̀lú ayé mi- Olori Aanu Ìjọba Nàìjíríà ti parí ìwádìí lórí àgbo Covid-Organics ti Madagascar kó ránṣẹ́ sí i Kùdìẹ̀kudiẹ wà nínú ìbò abẹ́nú APC tó yan Akeredolu, ṣùgbọ́n.
ISWAP vs Muric: À kò ni ìbáṣepọ̀ kankan pẹ̀lú àwón agbésùmọ̀mí- Ishaq Akintola
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Michelle Obama: Ààrẹ Trump kò yẹ nípò ààrẹ fún Amẹ́ríkà 1 Èrèlè 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 18 Ògún 2020 Iyawo aarẹ Amẹrika ana, Michelle Obama, ti sọko ọrọ si aarẹ Donald Trump, bi ẹgbẹ oṣelu Democrat ti se n palẹmọ lati fontẹ lu Joe Biden gẹgẹ bi oludije wọn fun ipo aarẹ.
Nitori naa, nkan ayọ ni bi ajọ WHO, ṣe kede pe aarun polio ko si ni Naijiria mọ, ati gbogbo Africa.
Oríṣun àwòrán, Others O ṣalaye pe, ootọ ni pe awọn eeyan kan n lo ẹrọ ibanisọro lati wu iwa ibajẹ, ṣugbọn ko digba ti ijọba ba gbe gbendeke le oye sim kaadi ti eyan n lo ki eto abo to ṣe dede.
Ti ọkọ obinrin ba ku, iyawo rẹ ni wọn ma a kọkọ fun ra si pe o pa ọkọ rẹ, ti yoo si ṣe awọn ibura to fihan wi pe ko ni ọwọ ninu iku ọkọ rẹ.
Ṣùgbọ́n bí mo ti rí ọ nísisìyí, ọkàn mi balẹ̀, nítorí ta ni ẹranko náà nínú igbó tí yóò wí pé òun kò mọ ìwọ, ọ̀gbẹ́ni ehoro?
Lẹ́yìn náà ni Jonatani sọ fún Dafidi pé, “Kí Ọlọrun wà pẹlu rẹ.
Alaga ẹgbẹ osisẹ ni ipinlẹ Osun, Komreedi Babatunde Adekomi to sọ eyi lasiko to n ba BBC Yoruba sọrọ lori idi ti wọn fi kọ gbedeke owo osu osisẹ, ni awọn osisẹ Naijiria lo n gba owo osu to kere ju lọ ni Afirika.
Tí igi náà bá dá, yóo gún un lọ́wọ́.
O fikun pe owo ti awọn eniyan ba fi ta wọn lọrẹ ni awọn fi n ṣakoso mọsalasi kaakiri Naijiria.
Gbàgbé ẹ̀sọ́ ara $40m rẹ pátápátá - Ilé ẹjọ́ sí Dienzani Ẹ wo márùn ún lára àwọn tí ilé ẹjọ́ ti yọ kúrò nípò lẹ́yìn ìdìbò ọdún 2019 Àrà ni mí; èmi kìí ṣe Àrá -Àyánbìnrin Aralola Olamuyiwa Wo ọ̀nà láti gbógun ti àìsàn Ibà lásìkò yìí Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí kan sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
Botilẹjẹ wi pe ileeṣẹ BBC ko ti le fọwọ sọya pe Kanu lo wa ninu fidio naa, awọn kan to sunmọ ọ ti a ba sọrọ fidirẹ mulẹ fun wa pe oun lo wa ninu rẹ.
Ọmọ ọdún meje ni Joaṣi nígbà tí ó jọba.
A bá àwọn ọmọ-ẹ̀yìn Jesu kan níbẹ̀, a bá dúró tì wọ́n níbẹ̀ fún ọjọ́ meje.
kí ẹ lè yin orúkọ Oluwa wa Jesu lógo, kí òun náà sì yìn yín, gẹ́gẹ́ bí oore-ọ̀fẹ́ Ọlọrun wa ati ti Oluwa Jesu Kristi.
Bèèrè lọ́wọ́ mi, èmi ó sì fún ọ ní àwọn orílẹ̀-èdè,gbogbo ayé yóo sì di tìrẹ.
Ile ẹjọ ko tẹ mi lọrun ti kọkọ ni ko san owo itanran dipo ẹwọn, ṣugbọn igbimọ ẹni maarun to da ẹjọ naa, ti Onidajọ Mary Odili jẹ olori fun, wọgi le e.
Eyi lo mu ki ọpọ obinrin ti ko kawe lati maa gbe igbesẹ to l'ewu fun ilera ati aye wọn.
"Tí ẹ bá rò pé ìrọ́ ni ọ̀rọ̀ coronavirus, tóri pé kò ti mú èèyàn kankan to súnmọ́ yín ni.
Wọ́n sọ fún Ọlọrun pé,‘Fi wá sílẹ̀, kí ni ìwọ Olodumare lè fi wá ṣe?
Buruji Kashamu: Gómínà Dapo Abiodun tí lọ ṣàbẹ̀wò ìbánikẹ́dùn sí àwọn ẹbí Kashamu
N óo fi ẹ̀mí mi si yín ninu, n óo mú kí ẹ máa rìn ní ìlànà mi, kí ẹ sì máa fi tọkàntọkàn pa òfin mi mọ́.
Awon omo egbe ti o je anfaani
Seyi Makinde: Gbogbo ẹ̀yin tí ipò kò tíì kàn, ẹ fọkàn balẹ̀, yóò kàn yín láìpẹ́
Àwọn akẹ́kọ̀ọ́ náà, to gbé ìwé ilewọ ati patako to ni akọle oríṣiríṣi lọ́wọ́, ni wọn n béèrè fún owó iranwọ náà, gẹgẹ bii ẹtọ wọn.
Mo tun n war o awon eniyna lati fun wa ni aaye lati du ẹmi awon
6 163057 Orilẹede Paraguay 2466 35.
Oríṣun àwòrán, Facebook/Oluwatoyin Ogundipe O ni ẹsun aṣilo ọfiisi ni ẹsun mii ti wọn fi kan Ọjọgbọn Ogundipe eyi to jẹ ki wọn da a duro.
Oríṣun àwòrán, Presidency Àkọlé àwòrán, Kunle Afolayan pẹlu awọn adanilaraya miran lọdọ Aarẹ Buhari Bẹẹni ko yanilẹnu nigba ti orukọ rẹ jẹyọ ninu awọn adanilaraya kaakiri orilẹede Naijiria ti aarẹ Muhammadu Buhari gba lalejo ni ọdun 2018.
Ìwọ ni o fi awọ ati ẹran bò mí,tí o rán egungun ati iṣan mi pọ̀.
Ilé ẹjọ́ kòtẹ́mílọ́rùn yọ alága ẹgbẹ́ òṣèlú APC Adams Oshiomhole nípò Agbẹjọ́rò ni n kò bá jẹ́, tí n kò bá bá bàbá mi ṣe tíátà - Sola Kosoko Iléeṣé tó ní bàálù tí Naira Marley lo lọ Abuja tọrọ àforíjìn lówó Mínístà Eeyan 6,307 lo ti ri iwosan gba, nigba ti awọn 475 ti dero ọrun nitori arun ọhun.
Kí wọn máa fi ohùn wọn yin Ọlọrun;kí idà olójú meji sì wà ní ọwọ́ wọn,
Wo àwọn Gómìnà Naijiria tí àrùn Covid-19 ti bá fínra Lọjọ aje, aarẹ Naijiria tẹlẹ ri, Goodluck Jonathan ṣe abẹwo si aarẹ Buhari ni ile rẹ ni Abuja nibi ti wọn ti ṣe ipade idakọnkọ.
Ogun yóo kó àwọn ìlú Moabu,wọn óo sì gba àwọn ibi ààbò rẹ̀.
NCDC fikun un pe awọn yoo fi esi ayẹwo wọn lede lẹyin ti wọn ba ti pari rẹ.
bí ẹ bá sá ti gbọ́ ti OLUWA Ọlọrun yín, tí ẹ sì farabalẹ̀, ti ẹ tẹ̀lé gbogbo òfin rẹ̀ tí mo fun yín lónìí.
Ninu alaye rẹ lo ti mẹnu baa wi pe, ọpọ ọkọ ni abẹbẹ oju gilaasi [wiper] wọn ko dara to lasiko ojo ti wọn ko de riran ri ọkọ to n bọ daada.
2 1645 Orilẹede Maldives 47 9.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Kumuyi Bible: Ọdún mẹ́ẹ̀dógún ni òun àtàwọn onímọ̀ Yorùbá fi ṣe ìwádìí nípa Bíbélì náà 3 Òkùdu 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 29 Agẹmo 2020 Oríṣun àwòrán, W.
Ọjọgbọn Heino Falcke, ti ile iwe giga fasiti Radboud University orilẹede Netherlands, to gbe imọ yii kalẹ sọ fun Ile Isẹ Iroyin BBC pe ibi ti wọn ti ri ihọ rabata yii ni ọrun galaxy ti wọn n pe ni M87.
'Àwọn ọmọ 5 kọ́ ló sọnù, ọmọ 28 ló sálọ síléeṣẹ́ foyúngbowó nípinlẹ̀ Ogun' Ìdí tí mi ò fi lè parí ìjà pẹ̀lú Ààrẹ Ọ̀nà kakanfò, Gani Adams - Obasanjo Ìdí tí ààrẹ Buhari ṣe padà gbà láti yọjú si ilé ìgbìmọ̀ aṣójú-ṣòfin tórí ọ̀sẹ́ Boko Haram Àyà mi já nígbà tí Ganduje rọ Sanusi lóyè Emir Kano tó fi Bayero síi, ṣùgbọ́n.
Lẹ́yìn náà, lọ sí òkè Ọlọrun ní Gibea Elohimu, ní ibi tí ibùdó àwọn ọmọ ogun Filistini kan wà.
Bakan naa ni wọn sọ pe awọn afurasi naa ma n dibọn bi ololufẹ awọn ọmọ ilẹ Amẹrika lati lu wọn ni jibiti.
Jọkẹ Silva ni orukọ rẹ lasiko to ba n sere tiata, sugbọn aya Jacobs lo n jẹ ninu ile, nítoripe iyawo ni lọọdẹ Olu Jacobs, toun naa jẹ gbajugbaja oṣèré tíátà pẹ̀lú.
”Mose sọ ohun tí àwọn eniyan náà wí fún OLUWA.
Oríṣun àwòrán, Nigerian Presidency Pataki ninu ọrọ rẹ ti kii ṣalai ma mu ikunsinu wa ni eyi to niṣe pẹlu fifi ofin de ọrọ kobakungbe lori ayelujara ta mọ si 'hate-speech.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Al-Qaeda, ISIS: Amẹ́ríkà ké gbàjarè pé ẹgbẹ́ agbésùmọ̀mí n palẹ̀mọ́ láti wọ Nàìjíríà 22 Sẹ́rẹ́ 2018 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 6 Ògún 2020 Oríṣun àwòrán, YouTube/Boko Haram Orileede Amẹrika ti figbe ta pe ikọ ẹgbẹ agbesunmọmi Al-Qaeda n gbero lati kogun ja iwọ ila oorun Ariwa Naijiria.
Nítorí kò sí ohun tí ó ṣòro fún Ọlọrun.
2 477545 Orilẹede Egypt 6771 6.
Gomina Glover tun fun Oshodi Tapa ni ami ẹyẹ lorisirisi fun aimọye ipa takuntakun to tun n ko si idagbasoke ilu Eko.
Nígbà tí Peteru kan ìlẹ̀kùn tí ó wà lójúde, ọdọmọbinrin kan tí ń jẹ́ Roda wá láti ṣí i.
Ajọ EFCC ti beere pe ko wa s'iwaju adajọ nibamu pẹlu ilana ofin to de igbesẹ idunadura nipa owo to wa lapo asunwọn rẹ.
Leah Sharibu ni wọn ṣi gba pe o wa ni akata wọn.
23 Ọ̀wàrà 2019 Oríṣun àwòrán, Instagram Àkọlé àwòrán, Seun Egbegbe lo ọdún méjì àti oṣù méje lẹ́wọ̀n láì tìí san béèlì rẹ̀ Olootu ere laarin awọn oṣere Yoruba, Olajide Kareem ti gbogbo eeyan mọ si Seun Egbegbe ti lo o le lọdun meji ati abọ lọgba ẹwọn bayii.
Ikọ alagbelebu pupa tilu Beirut ni ko sẹni to fara pa tabi ku ninu ijamba ina naa amọ awọn eeyan kan, to sun mọ ina naa, ko le mi daadaa.
Awọn onimọto ko ti ẹ ri aaye kọja lagbegbe olu ile iṣẹ ijọba apapọ lẹyin tawọn oluwọde di ọna to wọ inu ibẹ lọ.
Gbogbo òru ọjọ́ náà ni Abineri ati àwọn eniyan rẹ̀ fi ń rìn pada lọ ní àfonífojì Jọdani, wọ́n kọjá sí òdìkejì odò Jọdani.
Nítorí nígbà tí àwọn òkú bá jinde, kò sí pé à ń gbé iyawo tabi à ń fa obinrin fún ọkọ, ṣugbọn bí àwọn angẹli ọ̀run ni wọn yóo rí.
Ninu oro Alhaji Lai Mohammed ti o tesita lojo Aje(Monday), niluu Abuja, O sapejuwe ologbe ohun gege bi eni ti o ni lakai, okan gbogi ni o je laarin awon emewa re ti won jo da ere itage, ero amohunmaworan elefe sile lorile-ede Naijria, ki o to di ohun ti awon eniyan wa tewogba bayii.
omo orile-ede Naijiria lati tuyaya-tuyaya jade lojo idibo lati lo yan gomina
Oríṣun àwòrán, Instagram/Vincent Enyeama Àkọlé àwòrán, Enyeama n gbaradi lati darapọ mọ ikọ agbabọọlu tuntun Enyeama ṣoju ẹgbẹ agbabọọlu Naijiria ninu ifẹsẹwọnsẹ ọgọrun o le kan.
English Premier League: Arsenal jẹ́ọ́ àgbò tó tàdí mẹ́yìn fún Aston villapẹ̀lú àmì ayò mẹ́ta sí méjì
Ìwọ ni o dá ara rẹ lẹ́bi, nípa jíjẹ́wọ́ pé, ìwọ ni o pa ọba, ẹni tí OLUWA fi àmì òróró yàn.
Èmi, OLUWA Ọlọrun, ni mo sọ bẹ́ẹ̀.
Nítorí ìwọ ni o gbọdọ̀ yan ohun tí ó bá wù ọ́, kì í ṣe èmi,nítorí náà, sọ èrò ọkàn rẹ fún wa.
Ẹni ọgbọ̀n ọdún ni, nígbà tí ó gorí oyè, ó sì jọba fún ogoji ọdún.
Ẹ óo fún alufaa ní itan ọ̀tún rẹ̀ gẹ́gẹ́ bí ọrẹ lára ẹbọ alaafia yín.
O fidi oludije fun ẹgbẹ oṣelu PDP, Oluṣọla Ẹlẹka to ni ibo 178,121 janlẹ.
Ọba pàṣẹ pé, “Ẹ lọ pe Hamani wá kíákíá, kí á lè lọ ṣe ohun tí Ẹsita bèèrè.
Ǹkan to wà níbẹ ni pé o ni májèlé ni wan n pè ni Oxalic acid, ti ènìyàn ba wá n fi gbogbo igbe jẹ, a maa ṣeni bi èèbi osí le fá okúta ninú kídìnrín.
 Àwọn ohun díẹ ̀ péréte ni a ó ṣọ ̀ rọ ̀ lé lorí nínú orin yìí .
 Lori igbesẹ gomina Akeredolu pe ki awọn agbofinro gbe sahamọ lori ẹsun sise magomago ibo to fi kan oun, Abegunde ni ẹni to ba jẹ gbi, ni yoo ku gbi."
Àwọn ìfihàn mímọ́ wọ̀nyí ni a gbà ní ìdáhùn sí àdúrà, ní àwọn àkókò àìní, wọ́n sì jade wá láti inú àwọn ìṣẹ̀lẹ̀ tòótọ́ ní ìgbé ayé àwọn ènìyàn gidi.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ẹ̀mí 15 bọ́, èèyàn 38 farapa nígbà tí ọkọ̀ akẹ́rù kan bọ́ sínú odò Ogun Ọmọ ìgboro ní mí, ọdún 13 ní wọ́n fipá bámi lòpọ̀ àmọ́ mo fẹ́ dà bíi Muhammed Alli - Kọńgílá Aṣẹ́wó Malami, IGP àti alága APC Oyo ni yóò káwọ pọ̀'yìn rojọ nítori àwọn alaga Kansu tẹlẹri Ọ̀gọ́rún sọ́ọ̀bù, àìmọye dúkìá ni iná tún jó lọ́jà Sabo nílùú Sagamu Ẹ ta kété sí àjọṣepọ̀ tí kò bá fún yín láyọ̀ torí ẹ̀mí kò ní ààrọ̀ - Àwọn òṣèré tíátà gbarata lórí ìdájọ́ ikú Ninu ọrọ wọn, ẹgbẹ oṣelu PDP fidi ẹ mulẹ pe, iṣekupani ni ipinlẹ Plateau ti peleke si, ti wọn si fẹsun kan ijọba apapọ pe wọn ko ṣiṣẹ wọn bi iṣẹ ni iṣẹkupani to n waye ohun.
Àkọlé àwòrán, Croatia gbo ewúro sójú Nàìjíríà Ìdíje FIFA 2018 ti gbé ojú àwọn agbabọọlu tuntun síta gbàgede.
Oríṣun àwòrán, Mesut Ozil/instagram Ni tiẹ, Rashford sọ pe oun n fi adura ati ero ọkan oun ṣe atilẹyin fun awọn ti iṣẹlẹ iwakiwa ọlọpaa kan ni Naijiria.
Ohun ti a tun gbọ ni pe alase ti o n ba oloogbe naa ṣiṣẹ tẹlẹ lo ṣe eto bi alase tuntun naa ṣe darapọ mọ awọn oṣiṣẹ abẹle fun oloogbe Ọpẹ Bademọsi.
Nítorí náà mo kórìíra ayé, nítorí gbogbo nǹkan tí ń ṣẹlẹ̀ láyé ń bà mí ninu jẹ́, nítorí pé asán ati ìmúlẹ̀mófo ni gbogbo wọn.
igbimo asoju yoo se awon atunse , ni eyi ti yoo wa ojutuu si isoro to n dojukọ
Ajọ EFCC lori Twitter ni wọn ti salaye pe, ẹsun gbajuẹ, ole jija lori ẹrọ ayelujara ni wọn fi kan ọdọmọkunrin naa.
Bakan naa ni awọn miran sọ wi pe oun ti aarẹ Buhari yoo ṣe ni lati fi ọsẹ meji kun ọjọ ti ofin konile-o-gbele yoo dopin ni Naijiria.
Bakan naa, Fadairo ni ẹgbẹ oṣelu PDP naa ko i tii na ọwọ ẹnikẹni soke pe oun ni yoo dije dupo gomina labẹ asia ẹgbẹ oṣelu PDP, Eleyii to ni o fihan pe ile ti wọn naa ko tooro rara.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Afcon 2019: Àwọn olólùfẹ́ Super Eagles fẹ́ kí Rohr tún wọn tò Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Mo máa n forin mi kìlọ̀ ìwà ìbàjẹ́ láwùjọ ni -Hameen Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Ni bayii, o di igba marun un otooto ti won ti dibo yan Ogbeni Dogara gege bi asoju won fun ekun naa.
Ó ní, “Àwọn ọ̀tá wa lágbára jù wá lọ, wọ́n sì jáde láti inú ìlú wọn láti bá wa jà ninu pápá, ṣugbọn a lé wọn pada títí dé ẹnubodè ìlú wọn.
‘Àkókò kan ń bọ̀ tí wọn yóo kó gbogbo ohun tí ó wà ninu ààfin rẹ lọ sí Babiloni, gbogbo ohun tí àwọn baba ńlá rẹ ti kó jọ látẹ̀yìnwá títí di òní ni wọn óo kó lọ, wọn kò ní fi nǹkankan sílẹ̀.
Àwòrán àti ọ̀rọ̀ abẹ́-àwòrán láti ọwọ́ọ Myo Min Soe / Irrawaddy náà ń bá Ohùn Àgbáyé ṣiṣẹ́ ìròyìn.
Ati pe, ohun to ṣe pataki julọ ni pe: à ń reti ki ileeṣẹ ijọba apapọ eto ẹkọ ati ẹgbẹ fasiti Naijiria (NUC) sọrọ lori ohun to n kan laiṣegbe fẹnikan bikoṣe pẹlu ootọ inu.
Aarẹ ni oun ko le sọ bo ya awọn minisita kan yoo si di ipo wọn mu, tabi oun yoo dagbere fun awọn kan lara wọn.
Nígbà tí Ọlọrun rí i pé ó súnmọ́ ọn láti wo ohun ìyanu náà, Ọlọrun pè é láti inú igbó náà, ó ní, “Mose!
Olubadan sugbon ti Olori Olubadan ko je ko se e se.
Toju tiyẹ laparo awọn ilẹ yi fi n se ayẹwo bẹẹ si ni wọn n tọpinpin awọn to ba ti niarun yi.
“Nígbà tí ọkunrin yìí jọba tán, tí ó pada dé, ó bá ranṣẹ pe àwọn ọmọ-ọ̀dọ̀ rẹ̀ tí ó ti fún lówó, kí ó baà mọ èrè tí wọ́n ti jẹ.
Àwọn aládùúgbò talaka pàápàá kórìíra rẹ̀,ṣugbọn ọlọ́rọ̀ a máa ní ọpọlọpọ ọ̀rẹ́.
"Florence Ajimobi tahùn sí igbákeji gómìnà Oyo lórí ikú ọkọ rẹ̀, ""Gbogbo wa làó kú"" Àwọn aṣòfin Naijiria ṣọ̀rọ̀ ìwúrí nípa Ajimobi Ìgbé ayé Abiola Ajimobi nínú àwòràn pẹ̀lú àwọn ǹkan tó ṣẹlẹ̀ Ẹ dá àwọn ẹ̀ṣọ́ aláàbò igbákejì gómìnà ìpínlẹ̀ Ondo padà ní kíá - ọ̀gá àgbà iléeṣẹ́ ọlọ́pàá Soladoye ṣapejuwe iku Oloye Bode Akindele gẹgẹ bi eyi to fọwọ kan ni lẹmi nitori o jẹ ọkan lara awọn ogo ilẹ Ibadan ti awọn n foju sun."
Adebayo Shittu: Ìyàlẹ́nu ló jẹ́ pé ń kò jẹ mínísítà lẹ́ẹ̀kejì
N óo máa fi ọ̀rọ̀ rẹ ṣe orin kọ,nítorí pé gbogbo òfin rẹ ni ó tọ̀nà.
 yunifásítì kalifóníà ní los angeles ( ucla ) ló ti parí ẹ ̀ kọ ́ rẹ ̀ .
À ń bẹ̀bẹ̀ pé kí Ọlọrun lè jẹ́ kí ẹ mọ ìfẹ́ rẹ̀ lẹ́kùn-únrẹ́rẹ́ pẹlu gbogbo ọgbọ́n, kí ó sì fun yín ní òye nípa nǹkan ti ẹ̀mí.
Incentive and Guarantees Bill, Nigerian Film Commission Bill and Proceeds of
Wọn óo ní àṣẹ láti dé ibi igi ìyè, wọn óo sì gba ẹnu ọ̀nà wọ inú ìlú mímọ́ náà.
Ọpọ lo ti'n kan sara sii fun iṣẹ ọwọ rẹ.
Ó pa gbogbo àwọn tí wọn ń gbé àwọn ìlú náà run, ati gbogbo ohun tí ó hù lórí ilẹ̀.
Gbogbo nǹkan ṣípayá kedere níwájú Ọlọrun, ẹni tí a óo jíyìn iṣẹ́ wa fún.
Àwa náà sì kórìíra ọmọnikeji wa.
Gbogbo àwọn pidánpidán, ati àwọn aláfọ̀ṣẹ, àwọn ará Kalidea, ati àwọn awòràwọ̀ bá péjọ siwaju mi; mo rọ́ àlá náà fún wọn, ṣugbọn wọn kò lè túmọ̀ rẹ̀ fún mi.
O fi ọrọ yii lede ni idahun si ibeere lati ọwọ akọroyin wa nipa akẹkọọ ọmọ Naijiria kan to gbiyanju lati gba ẹmi ara rẹ pẹlu bi o ṣe mu oogun apakokoro nitori ko ṣe daadaa ninu idanwo aṣewọle iwe giga JAMB.
Baṣọ̀run Gáà, tó yan ọba mẹ́rin, pa ọba mẹ́rin àmọ́ ọba karùn-ún ló pa á Gómìnà Ganduje wọlé fún sáà kejì ní ìpínlẹ̀ Kano Supplementary election: Ọlọpàá gbé ikọ kògbérégbè díde lọ si wọ́ọ̀dù ìdìbò Gama A kẹ̀yìn sí Atiku torí àtúntò Nàíjíríà tó fẹ́ ṣe - Árẹ̀wá O ni ẹgbẹ́ ti sááju ké si àjọ INEC nígbà ti ẹgbẹ́ òṣèlú PDP ń ṣe èrú ibò lọ́jọ́ sátide.
Super Falcons: Wọn nfi ilọkulọ ibalopọ lọ wa Àráàlú yarí fún fásitì Babcock fún bo ṣe lé akẹ́kọ̀ọ́ tí wọn bá lòpọ̀ nínú fídíò Ọlọ́pàá Eko ní kí olùkọ́ UNILAG Boniface wá sọ tẹnu rẹ̀ lórí ẹ̀sùn ìfipábánilòpọ̀ Àwọn àmì tó fi mọ̀ pé wọn ń fipá bá ọmọdébìnrin rẹ lòpọ̀ Ileeṣẹ ọlọpaa sọ pe Adanlawo ti kọkọ kọ ọ silẹ ni agọ ọlọpaa to wa nilu Iju-Itaogbolu ti wọn gbe e lọ pe ọmọdebinrin naa sọ fun oun pe ki oun sun le e lori, lẹyin to beere fun aadọta Naira ati nkan ipanu.
Ile-ise olopaa lorile-ede Philippine ti fi omo orile-ede Egypt, Fehmi Lassoued  ati arabinrin re Anabel Salipada ti won fesunkan pe, won n ko awon omo-ogun Islamic olote jo lorile-ede naa.
Lati koju iwa adigunjale ati awon iwa odaran miiran ko rọrun rara, iye awon ọlọpaa
Ọmọ isaac Adewọle gba ìdáǹdè lọ́wọ́ ajínigbé Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí kan sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Bayelsa Attack: Ọ̀gá ọlápàá fọnmú pé kí wọn ṣàwárí àwọn ọ̀daràn tó pa ọlọ́pàá 2 Agẹmo 2019 Oríṣun àwòrán, @newsbookng Gọngọ sọ ni aarọ oni nigba ti awọn gende agbebọn kan ya bo agọ ọlọpa to wa ladugbo Ekpetiama to wa ni ilu Yenegoa, tii se olu ilu Bayelsa, ti wọn si gba ẹmi ọga ọlọpa DPO to wa nibẹ, Ọla Rosanla ati awọn ọlọpa mẹta miran, tawọn meji mii si farapa.
Oniruuru igbimọ si ni Dapọ ti ṣiṣẹ lasiko to wa ni aṣofin agba naa.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Palm Wine drinking: Àǹfààní tí ẹmu ń ṣe fún àgọ́ ara 13 Bélú 2020 Gbogbo ilẹ̀ káàrọ̀ -ò-òjííre àti ọ̀ps ibi ni ilẹ̀ Afirika ní àwọn ènìyàn tí máa n rí ẹmu gẹ́gẹ́ bí ǹkan pàtàkì láti fi ṣe àlejò Èyí nìkàn kọ́, ní ilẹ̀ Igbò, ẹnikẹ́ni tí kò bá fi ẹmu ṣe àlejò yàlá lásìkò àyẹyẹ ìgbéyàwó tàbí ìkómọ jáde kò tíì ṣe ǹkan kan.
Grace Taku to sọ ọrọ yii ko sọ pato boya Leah Sharibu tabi Leah mii lo n sọ ṣugbọn kete ni awọn eeyan bẹrẹ si ni tan an kalẹ pe Leah Sharibu lo n sọ.
Èyí ló ti ilẹ̀ gẹ̀ẹ́sì sí ipò ti wan wà yìí ńitori kò fi kátàkára fún oṣù mẹ́fa láti ọdún 2009.
Ṣugbọn ojú ọkunrin náà fàro nígbà tí ó gbọ́ bẹ́ẹ̀, ó bá jáde lọ pẹlu ìbànújẹ́, nítorí pé ọrọ̀ tí ó ní pọ̀.
Egúngún kan rèé tí kò bìkíáfù, ó kọjú ìjà sí ọlọ́pàá pẹ̀lú ohun ìjà olóró Àwọn ògo Ibadan márùn ún tí ikú mú lọ lọ́dún 2020 Mo ti lùgbàdì àrùn Coronavirus - Akeredolu figbe ta Bẹ́ ẹ fẹ́, bẹ́ ẹ kọ̀, July ni ẹjọ́ Sotitobire yóò parí - Adájọ́ gbọmú Wọn fikun wi pe ọpọlọpọ onile lo ti ṣofo ohun ini wọn, ti wọn si ti fi agbegbe naa silẹ lẹyin igbiyanju wọn.
O ni bii agogo mọkanla alẹ ni Linda pari iṣẹ ni Outsource Global Company Mabushi to n ba ṣiṣẹ ni ọjọ Iṣẹgun.
Àwọn àlejò yóo darapọ̀ mọ́ wọn, wọn yóo sì di ọ̀kan náà pẹlu ilé Jakọbu.
O wa lara awọn ti Baba Awolowo jọ sisẹ papọ nigba aye Baba iran Yoruba ninu oselu Naijiria.
Ọmọkunrin naa fi kun ọrọ rẹ pe, ara oun ko ya, nitori pe awọn jẹ iya pupọ ninu igbo ti wọn ko wọn si.
rara, nitori pe tẹgbọn –taburo ni wa.
Ileeṣẹ ọlọpaa ni Nurnberg ni orilẹ-ede Germany ti fidi iṣẹlẹ naa mulẹ fun BBC.
Kíni ẹ mọ̀ nípa Ọmọ́táyọ̀ Olútóyè, Ọ̀jọ̀gbọ́n obìnrin àkọ́kọ́ nínú ẹkọ́ èdè Yorùbá lágbàyé À ti fi àwọ̀n ọlọ́kadà 123 láti Jigawa sílẹ̀ -Ọlọpaa Àwọn jàǹdùkú pa fadá ní Taraba-Iléeṣẹ́ ọlọ́pàá Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Cancer: àpọ̀jù ṣúgà nínú ẹ̀jẹ̀ ń ṣàkóbá fún àgọ́ ara èèyàn Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Nigba to n jẹwọ pẹlu wa, Kọmiṣọna fun ileesẹ to n ri si ọrọ ijọba ibilẹ ati oye jijẹ ni ipinlẹ naa, Adeleke Yekini Adebayo ni ijọba ipinlẹ Osun si n ṣagbeyẹwo ọrọ naa.
Mo fẹ́ kí ẹ mọ̀ pé Kristi ni orí fún olukuluku ọkunrin, ọkunrin ni orí fún obinrin, Ọlọrun wá ni orí Kristi.
Awọn ọmọ ẹgbẹ Shiite n sọ pe o pe ogoji ọjọ bayii ti awọn ọmọ ileeṣẹ ológun Naijiria ṣekupa àwọn ọmọ ẹgbẹ àwọn to le ni aadọta lasiko ti n fi ẹhonu han lọjọ kẹtadinlọgbọn, to fi mọ ọjọ kọkandinlọgbọn si ọgbọnjọ, oṣu Kẹwa, lori olórí wọn, Ibrahim El Zakzaky ti ijọba fi sahamọ lati ọdun 2015.
Ojú ti gbogbo àwọn tí ń bọ oriṣa,àwọn tí ń fi ère lásánlàsàn yangàn;gbogbo oriṣa ní ń foríbalẹ̀ níwájú rẹ̀.
Bí wọ́n ti ń lọ lọ́nà, ẹnìkan wá sọ́dọ̀ rẹ̀, ó ní, “N óo máa bá ọ lọ sí ibikíbi tí o bá ń lọ.
Owo itọju naa to jẹ ẹgbẹrun mẹta le ojilelẹgbẹta dọla di sisan lẹyin eto ipolongo to waye fun idile naa.
Lẹyin ti wọn fa ọrọ naa titi ti wọn ko ri ẹri kankan, ni wọn ba fi Darlington silẹ o lẹyin ọjọ marun ni ahamọ.
- Ọọ̀ni Ife Ìgbẹ́jọ́ aṣaájú ìjọ Sotitobire kúrò nílé ẹjọ́ Mágísíréètì lọ sílé ẹjọ́ gíga l‘Akure Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'N500 dé fún gbogbo ọmọ tuntun lóṣooṣù bí mo bá di gómìnà Ondo - Adeleye AAC Adajọ ni se ni ijọ naa n tẹ siwaju lati maa ba isin ọjọ isinmi wọn lọ titi di aago marun irọlẹ lẹyin ti wọn ti ji ọmọdekunrin, ọmọ ọdun kan naa lọ lati ọwọ ọsan.
awọn aṣiwaju wa lati le tọ wọn sọna to yẹ, ti a o le fi bori awọn
Kì í ṣe ohun tí ó ń wọ ẹnu ẹni lọ ni ó ń sọni di aláìmọ́, bíkòṣe ohun tí ó ń jáde láti ẹnu wá ni ó ń sọ eniyan di aláìmọ́.
Ero ọ̀pọ̀ eeyan yatọ lori lẹta Alaafin Oyo si gomina Fayemi l‘Ekiti nipa iyọnipo ọba Saaju la ti mu wa fun yin pe awọn ọmọ Naijiria lori oju opo ikansiraẹni Twitter ti dasi ọrọ laarin Gomina ipinlẹ Ekiti, Kayode Fayemi ati awọn ọba ni ipinlẹ naa.
Jesu dá wọn lóhùn pé, “Mo ṣe iṣẹ́ kan, ẹnu ya gbogbo yín.
Ṣaaju akoko yii, awọn oṣiṣẹ lati ipele kẹrinla soke lo ti pada sei ẹnu iṣẹ, igbesẹ naa wa ni nibamu pẹlu akitiyan ijọba lati dena itankalẹ aarun coronavirus.
"Wọn ni ""ẹni ti ko mu ọti lile ko ni ba ọmọ ọdun mẹrin si mẹjọ sun""."
Ó mú mi dùbúlẹ̀ ninu pápá koríko tútù,ó mú mi lọ sí ibi tí omi ti dákẹ́ rọ́rọ́;
Ṣugbọn bí a ti ń ṣe bọ̀ nípa ìwà ati ìṣe, bẹ́ẹ̀ ni kí á ṣe máa tẹ̀síwájú.
Nítorí náà, ìdájọ́ tí mo ti pinnu sórí Jerusalẹmu kò ní ṣẹlẹ̀ ní ìgbà ayé rẹ̀, ikú wọ́ọ́rọ́ ni yóo sì kú.
Òfin àtijọ́ tí ẹ ti níláti ìbẹ̀rẹ̀ ni.
Wo ọ̀nà márùn ún tí o lè gbà dáàbò bò ara rẹ lọ́wọ́ ìjàmbá láì gbé ìbọn!
“Èmi ni àjàrà, ẹ̀yin ni ẹ̀ka.
Orúkọ wọn yóo máa jẹ́ ẹnubodè Gadi, ẹnubodè Aṣeri ati ẹnubodè Nafutali.
Democratic Party PDP , ku ori-ire  aseyọri
O tun wa ni 'ṣugbọn ara aburo mi yoo ya emi naa yoo si dagba.
Agbabọọlu Naijiria ni ikejidinlogoji to dara julọ ni agbaye.
Yàtọ̀ fún ìwàkuwà, kò sí ìlànà àtì ètò kankan fún awákẹ̀kẹ́ lójú ọ̀nà.
Nnamdi Kanu to jẹ olori awọn ajajangbara fun ominira iran Igbo ni Naijiria ti a mọ si IPOB ṣalaye ijọra ati iyatọ to wa lara Buhari ati Jubril ti ilẹ Sudan.
Èrò àwọn ènìyàn sọ̀tọ̀ọ̀tọ̀ lórí ẹ̀sùn Onnoghen Agbẹnusọ ileeṣẹ ọlọpaa Frank Mba ko ti i sọrọ lori igbeṣẹ yii, ṣugbọn agbẹnusọ fun Onnghen, Awusam Bassey ni ootọ ni pe wọn ti ti ofiisi naa pa.
Ṣùgbọ́ọ́n a fi Ewédayépọ̀ ṣe yẹ̀yẹ́ sí ìdí ọ̀ràn yìí, ọ̀rọ̀ náà kò kúrò lẹ́nu wa títí a fi kúrò ní ìklú àwọn ejò tí a sì fi padà dé ìlú wa: nígbà tí Olóhùn-ún-dùùrù bá díde a kọjú sí wa, a ní, Ẹ̀yin ọ̀rẹ́ mi, ìgbà tí Òjòlá-ìbínú ké igbe ńlá, Ewédayépọ̀ ṣe kí ni o?
Gege bi ile-ise akoroyin Interfax news agency nilu Syria, O ni, ẹgbàata eniyan lo ti filu Ghouta sile latari ikolu oniruuru eyi ti o n ti n waye lati gbogun ti awon omo-ogun olote islam lorile-ede naa.
Nigba ti kongila ile-ise Reynolds Construction Company (RCC) onimo ero Noar Narkisis to n sise loju opopona Shagamu-Ibadan so fun minisita ati awon emewaa re pe ise ko ni pe pari loju opopona naa.
Bẹ́ẹ̀ ni mo bẹ ìwọ náà, ẹlẹgbẹ́ mi tòótọ́, ran àwọn obinrin wọnyi lọ́wọ́, nítorí wọ́n ti bá mi ṣiṣẹ́ pọ̀ ninu iṣẹ́ ìtànkálẹ̀ ìyìn rere pẹlu Kilẹmẹnti ati gbogbo olùbáṣiṣẹ́ mi yòókù, àwọn tí orúkọ wọn wà ninu ìwé ìyè.
Ajo to n mojuto ero ibanisọrọ lorile ede Naijiria (Nigerian
Jonatani ati Ahimaasi dúró sí ibi orísun Enrogeli, ní ìgbèríko ati máa lọ sí Jerusalẹmu, nítorí pé ẹnikẹ́ni kò gbọdọ̀ fojú kàn wọ́n, pé wọ́n wọ ìlú rárá.
Wọ́n sì kó egungun àwọn mejeeje tí wọ́n so kọ́ pẹlu.
Diẹ-diẹ si ni owe naa gbilẹ, to si di itẹwọgba titi di oni.
Eeru ni Biden fi wọlẹ,'' Trump lo sọko ọrọ yii.
SW Security: Ìpàdé ààbò wáyé nílẹ̀ Yorùbá, wọ́n fẹnu ọ̀rọ̀ jóná pẹ̀lú ilééṣẹ́ ọlọ́pàá
Kí ìpòyì kan máa jẹ́ ọjọ́ kan.
"Newcastle run Manchester United mọ́lẹ̀ jégéjégé ""Ọmọ Daura ti tàpá sí òfin ààbò Nàíjíríà, ó sì yẹ kí Buhari le è to ilé rẹ̀"" Ọmọ Nàìjíríà, ẹ forijì mí!"
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Akomolede ati Aṣa lori BBC:Wo ìrúfẹ́ ìgbeyàwó méje tó wà nílẹ̀ Yorùbá àti ojúṣe Alárinà Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí 0:59 Fídíò, Ǹjẹ́ oòrùn tàbí oru leè pa àrùn Coronavirus bí?
Ọrọ tawọn eeyan yoo sọ lawujọ ko gbami laaye lati ṣalaye ohun to ṣẹlẹ si mi ni pato.
Bẹẹ lọrọ ri pẹlu awọn oṣere tiata lasiko igbele Coronavirus yii, ti ọpọ wọn ko ri oko ere tiata lọ.
” Àwọn eniyan náà bá ki gbogbo wọn mọ́lẹ̀, Elija kó wọn lọ sí ibi odò Kiṣoni, ó sì pa wọ́n sibẹ.
EFCC: Ọmọ Nàíjíríà ń bèèrè pé báwo ní àjọ náà ṣé mọ èké babaláwo?
Àgékúrò àwòrán adarí iléeṣẹ́ náà, Irina Reyder ní ọ́fíìsì iléeṣẹ́ BlaBlaCar ti Russia.
 Àjẹsára àrùn rọpárọsẹ ̀ tí à ń gba ẹnu lò a má a ṣe òkùnfa àrùn rọpárọsẹ ̀ tó níí ṣe pẹ ̀ lú ìmúlò àjẹsára náà nínú ìwọ ̀ n egbògi náà tó tó mẹ ́ ẹ ̀ ta nínú mílíọ ̀ nù kan .
Ọrọ oju alawọ omi aro buluu ti Risikat ni ti di ọrọ to kan gbogbo eeyan bayii lẹyin ti iroyin fọn sigboro pe ọkọ rẹ kọ ọ tọmọ tọmọ tori awọ oju wọn.
Lẹ́yìn náà, àwọn ará ìlú Beti Ṣemeṣi rú ẹbọ sísun, ati oríṣìíríṣìí ẹbọ mìíràn sí OLUWA ní ọjọ́ náà.
Luka Modric lo yọ lara Ronaldo ati Messi lati gba ami ẹyẹ Ballon d'Or lọdun to kọja.
Opo eniyan ni o ti padanu
Ronaldinho ni idunnu lo jẹ fun oun pe Messi gbami ẹyẹ Ballon fun igba kẹfa loṣu yii amọ agbabọọlu bi Pele, Maradona, ati Ronaldo ko le jẹ ki sọ wi pe Messi lo dara julọ ninu itan.
Ksmisana ọlọpa fikun pe wọn ti gbe awọn afurasi ọhun lọ sile ẹjọ lori ẹsun ipaniyan, idigunjale ati sise ẹgbẹ okunkun.
muhammad yunus ( , pipe ) ( ojoibi 28 june 1940 ) je omo ilè bangladesh .
 Ìwà ìrẹ ̀ lẹ ̀ tí wikipedia fẹ ́ níṣe pẹ ̀ lú gbogbo àwọn olóòtú nígbà tí wọ ́ n bá ń bá ara wọn sọ ̀ rọ ̀ ní wikipedia , pẹ ̀ lú ọ ̀ rọ ̀ ní ojú ewé ọ ̀ rọ ̀ oníṣẹ ́ àtí ojú ewé ọ ̀ rọ ̀ àyọkà àti gbogbo ìjíròrò pèlú tàbí nípa àwọn ẹlẹgbẹ ́ rẹ tí ó jẹ ́ olùkọ wikipedia .
Oríṣun àwòrán, Abdulmumin Rabiu Ijọba gbọdọ fi awọn eeyan jofin daadaa lori iwa aburu yii, lati jẹ ki araalu mọ pe iyatọ wa laarin kiko ara jọ pọ, ja fun ẹtọ labẹ ofin ati kiko ara jọ pọ hu iwa ọdaran.
tí ó ń bá àwọn aṣebi kẹ́gbẹ́,tí ó sì ń bá àwọn eniyan burúkú rìn?
Oriṣi ẹyan meje to wa ni olukọ Bunmi Femi Amao kọ wa loni.
Ọba aláde o gbọdọ kọ iyàwó rẹ̀ sílẹ̀ Eyí ni Ọba aláde keji ti yóò kọ ìyàwo sílẹ̀ lori oye ní ilẹ̀ Yoruba.
Eto idibo orilẹede Somalia: Orilẹede Somalia yoo dibo aarẹ miran l'ọdun yii.
Ọlọpaa mu Fagbemi Waheed lẹyin ti àwọn kan kọwe ẹsun ranṣẹ́ si ilé iṣẹ́ ọlọpàá pe ayédèrú ìwé ẹ̀rí ìwé mẹwàá WAEC wà lọ́wọ́ rẹ̀.
 “Nitori naa, a ti pinnu lati se ipade olojo kan ti a o fi pariwo sita , ni eyi ti a o fi maa je ki awon omo orile ede Naijiria mo nipa isele yii.
Wilder to fakọyọ ninu ija naa,ti gbe igba oroke ni igba mọkanlelogoji ninu fi fi ẹsẹkubiojo.
Ọmọ Nàìjíríà kan gbé Fásitì Oxford lọ sílé ẹjọ́ tàko oríkí ọrọ 'Mortgage' nínú ìwé àtúmọ̀ ọrọ Ọwọ́ ọlọ́pàá tẹ àwọn olè tó kó góòlù àti ẹgbẹ̀lẹ́gbẹ̀ mílíọ̀nù lọ nílé MKO Abiola l'Eko Ó sàn kí ẹ pa mí ju kí ẹ ba oko tí mo gbin igbó sí jẹ́ lọ- Afurasi Clement sí NDLEA A kú oríire!
Ẹ̀wẹ̀, akọ́nimọ̀ọ́gbá ikọ Real Madrid, Zinedine Zidane ti sọ pé, títẹ̀ síwájú òun pẹ̀lú ikọ̀ náà, kò nìí se pẹ̀lú pé kí òun gba ife ẹ̀yẹ Champions League.
” Mose sì ti ọwọ́ bọ abíyá.
oun ni Olori ile aṣofin ipinlẹ Ọyọ lasiko iṣejọba Lam Adesina gẹgẹ bi gomina ipinlẹ Ọyọ Bi a ba n wa ọna atijẹ kiri, afi kaa yara maa gbadura ki a maa pade ohun ti yoo jẹ wa o.
Ńjẹ́ bí Ẹlẹ́gbára bá ti pa mi ni ijọ́ náà, ta ni ìbá máa jẹ́ Ìrìnkèrindò lónìí!
Bakan naa ni wọn o tun ma a ṣe ayẹwo bi ara awọn eeyan ṣe gbona si, lo sanitaisa, ati titakete sira ẹni.
"O sọ pe ""Wọn le ni agbara lori yin, ṣugbọn wọn ko lagbara lori mi."
Awọn afẹhonu han ti tu sigboro fun odidi ọjọ meji bayii lai simi nitori ibugbamu naa.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Oando bọ́ si abẹ́ ìwádìí àjọ eto aàbò okòwò àti pàṣípààrọ̀ Naijiria-SEC 1 Òkùdu 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 2 Òkùdu 2019 Àkọlé àwòrán, Oando bọ́ si abẹ́ ìwádìí àjọ eto aàbò okòwò àti pàṣípààrọ̀ Naijiria A ṣi máa gbe ọrọ lọ si ọdọ FIRS, NSE ati CAC -SEC Àjọ eto aàbò okòwò àti pàṣípààrọ̀ okòwò ní Naijiria (SEC) ti kede pe Wale Tinubu to jẹ oludari ileeṣẹ epo OANDO kò gbọdọ ṣe oludari ileeṣe ijọba kankan fun ọdun marun un.
Ọba igbó Olódùmarè ni ó wáá ṣe ìgbéyàwó fún wọn nígbẹ̀hìn.
Àwọn òṣèré tíátà jákèjádò ni wan ti n ki ìyá àbúrò tuntun ku ewu.
Lẹyin to gba igbega si ipo adari ọwọ ogun (Captain) lọdun 1962, o lọ kawe kun iwe ni Royal College of Military Engineering, Chattam ni England.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ìyàwó mi fẹ́ràn ìrìnàjò òfurufú ni mo ṣe kọ́ ilé Bàálù yìí fún un Omi ìṣẹ̀ńbáyé tó ń dà ní Ówù rèé, èyí tó ga jùlọ ní Afirika 'Ǹkan tó jẹ́ kí iṣẹ́ ọ̀nà tèmi yàtọ̀ lágbàáyé ni ǹkan tí mò ń lò' Mo ti sọ ìran nípa ọkọ aképo tó gbiná ní Onitsha kó tó ṣẹlẹ̀ - Primate Ayodele Lasiko to n ba BBC Yoruba sọrọ, Jolaade ni kakuletọ to jẹ eeyan (Human Calculator) ni wọn maa n pe oun, oun lee pin, yọ kuro tabi sọ di pupọ nisẹju aaya.
“Bí ilẹ̀ mi bá kígbe ẹ̀san lé mi lórí,tí àwọn poro oko mi sì ń sọkún;
Oluwo sọ pe oun ni aṣoju Olodumare ni aafin ilẹ Iwo, nitori naa oun ko le maa bọ oriṣa tabi fi ori balẹ fun oriṣa ni aafin.
Nítorí ilẹ̀ tí ó gbẹ,nítorí òjò tí kò rọ̀ ní ilẹ̀ náà,ojú ti àwọn àgbẹ̀, wọ́n káwọ́ lérí.
Agbẹnusọ fun Gomina Kano,Muhammad Garba salaye pe ayederu ni fọnran fidio naa a ti wi pe ẹni to gbe fidio naa jade ko ṣẹṣẹ ma wu iri iwa bẹ.
Awọn ibudo mẹfa ni anfani yii sọkalẹ si nipinlẹ Eko, eleyi ti ko ni na ọ lowo ti ko si si gbede fun; iye to ba wu ọ, tabi ohun to ba wu ọ lo si lee fi gba lori ikanni ayelujara.
Atẹjade kan tijọba fisita ni awọn eroja ounjẹ naa, to pọ babi, kii se ti ipinlẹ Eko nikan, gbogbo ẹkun iwọ oorun Guusu Naijiria lo ni.
Bí Akiṣi bá bèèrè pé, “Àwọn wo ni ẹ kógun lọ bá lónìí?
Wọn si le e jẹ ọkan ejo naa pẹlu ẹjẹ ejo tabi oti waini Vodka.
Nítorí ti Dafidi, iranṣẹ rẹ,má jẹ́ kí ẹni tí a fi òróró rẹ yàn yíjú kúrò lára rẹ.
 o ni “opolopo awon agbe lo ti je anfaani eyawo
Bakan naa lo tun tọka si ilera rẹ to ni ko ṣe deede gẹgẹ bii ara oun ti ko ni lee mu oun lagbara ati duro igbe aye ọgba ẹwọn.
N kò ní di opó,bẹ́ẹ̀ ni n kò ní ṣòfò ọmọ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'N500 dé fún gbogbo ọmọ tuntun lóṣooṣù bí mo bá di gómìnà Ondo - Adeleye AAC Ilé iṣẹ́ ọlọ́pàá fi han pé àwọn ti ṣetan láti bá àwọn ti ọ̀rọ̀ kan láti ri dájú pé, àwọn ọlọ́pàá bọ̀wọ̀ fún ẹtọ́ àrá ìlú àti la'ti ni ìbáṣepọ tó dán mọ́ràn láàrín ọlọ́pàá àti àrá ìlú.
Tó bá wá jẹ́ òòtọ́, a óò gbé ìgbésẹ tí òfin ilé ìwé yìí là kalẹ̀.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Sani Abacha Loots: $6.
"Ati pe àwọn ilé iṣẹ́ tó ń pèsè òunjé àti òhun mímu fún àwọn tó ní ipín ìdókòwò pẹ̀lú wọ́n ní bílíọ̀nù méjìdínlógun nínú oṣù kíní ọdún yìí, Ajọ yii ni pe èyí ju ìlópo mẹwàá iye ti àjọ ìsọ̀kan àgbáye sọ pé àwọn nílò láti kó ẹbi àti òsì kúrò lágbàyé"" Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Kemi Dairo: Iṣẹ́ abẹ nínú ọpọlọ àti ẹ̀rọ ni mo fi ń gbọ́ ọ̀rọ̀ báyìí Chema Vera ni: ""Kódà àwọn orílẹ̀-èdè ti wọ́n ti gbọ́njú dáadaa bi South Africa, India àti Brazil, ló ṣeẹṣe kí orílẹ̀-èdè wọ́n di olú ilú ebi."
Ẹ kẹ́gàn mi ní àìníye ìgbàojú kò tilẹ̀ tì yín láti ṣẹ̀ mí?
ọrọ rẹ, wọn fi lẹta kan ranṣẹ si Ile
fayawo ti won ri gba ni  ekun naa.
Ará ìlú ète, ará ilú eédú
”Saulu mọ̀ pé Samuẹli ni, ó sì tẹríba.
Mo duro pẹlu Allen, ayafi to ba tẹnu ile ẹjọ jade pe o jẹbi.
N kò ṣẹ àwọn Juu, gẹ́gẹ́ bí ẹ̀yin náà ti mọ̀ dájúdájú.
1 Iṣẹ́ títóbi ati yíyanilẹ́nu kan fẹ́ jáde wá sí àwọn ọmọ ènìyàn.
Fayoṣe fi Buhari wé Shina Rambo, Evans ajọmọgbé APC gba ìjòkò tó pọ̀ jùlọ ní ilé aṣòfin àgbà Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Amosun ṣiṣẹ́ l'Ogun ṣùgbọ́n kí Dapo ma yà wá' Ọgbẹni Okoye ni ajọ INEC yoo kede l'Ọjọru ni kikun awọn ẹkun ati ibudo idibo ti afikun idibo yii yoo ti waye.
“Kí ẹ tó pa ẹnikẹ́ni tí ó bá paniyan, ẹlẹ́rìí meji gbọdọ̀ jẹ́rìí sí i pé nítòótọ́ ni olúwarẹ̀ paniyan.
A máa ra ẹṣin wá láti Ijipti ati láti gbogbo orílẹ̀-èdè yòókù.
Awon aseyoriAare ni ijoba apapo ti se aseyori lati mu eto agbe ni okunkundun nipa bayii, o ti je ki idagbasoke de ba  eto oro aje orile ede yii .
Ẹkẹta mú Sakuri, òun ati àwọn ọmọ rẹ̀ ọkunrin, ati àwọn arakunrin rẹ̀ jẹ́ mejila.
Àwọn òṣìṣẹ́ fásitì yóò fi ìyanṣẹ́lódì ṣẹ Nàìjíríà lọ́wọ́ lọ́jọ́ Ajé Òkú sunkún òkú ní ìpínlẹ̀ Benue Wilfred Ndidi, ọmọ Nàìjíríà pa iná ògo Chelsea ní Stamford bridge Wàhálà bẹ́ sílẹ̀ láàrín àwọn ọ̀dọ́ ní Oke Odo ní ìpínlẹ̀ Eko O tun gboriyin fawọn agbabọọlu obinrin ti Naijiria ti o n kọ pe pe wọn fakọyọ daadaa.
Akitiyan nlá ni àwọn onímọ̀ iṣègùn àti oníwàdìí-jinlẹ̀ ilera ti ṣe káàkiri àgbáyé láti wá ògùn tó kápá àrùn yìí.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Bí ìrẹsì tèmi Ayinde bá ń pàkùta, kò tọ́ sẹ́nu aláàrù Barrymaade' Lọdun to kọja nibi ife ẹyẹ ilẹ Afirika, ikọ aṣoju tun wa ri minisita lati ajọ IAAF, ati aarẹ ana AFN ati aarẹ́ tuntun.
Awọn kan tilẹ ni ko yẹ ki ijọba gba awọn to ba ti le ni ọdun marunlelọgọta laaye lati lọ jọsin.
Oníṣẹ́ àdáni 250,000 ni ìjọba ṣe ìlànà yìí fún Ẹ má gbìyànjú láti bo àṣírí ìpànìyàn tó wáyé ní Lekki, á ní ẹ̀rí tó dájú - Amnesty International Àkùkọ dojú ìjà kọ ọlọ́pàá, ikú ló já sí fún agbófinró Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Kété tí wọ́n bá ti báa yín sùn tàn torí pé ẹ tóbi, ẹ gbà pé ìfẹ́ yẹn ti parí - Auntie Remi Ọlọ́yàn ńlá ''Ọkọ naa wa lati fi pa owo si apo ijọba ni nitori awọn ọkọ to wa nilẹ ti n bajẹ, eleyii to n fa inira fun awọn eniyan wa.
PDP, SDP ta ko ìdìbò ipò sẹ́nétọ̀ ẹkùn Ìwọ̀-òòrùn Kogi 'Hèeè!
Wo àwọn ọmọ ẹgbẹ́ 19 tó fọwọ́ sí yíyan Ọ̀jọ̀gbọ́n Banji Akintoye Oríṣun àwòrán, Other Eeyan mọkandinlogun ninu ọmọ ẹgbẹ itẹsiwaju Yoruba jakejado agbaye ti tọwọ bọwe pe irọ ni awuyewuye to n lọ lode pe wọn yọ Ọjọgbọn Akintoye to jẹ aarẹ loye.
Ṣugbọn, Seyitan sọ pe oun kọ jalẹ.
Dadashev Maxim ọmọ Russia ni oun ati Subriel Matias jọ ja du bẹliti abẹṣẹkubiojo IBF light welterwiight.
Aare Muhammadu Buhari ti foruko awon marun un ti yoo je igbimo ti yoo maa sakoso ile ifowopamo ti ijoba apapo(CBN) ranse si ile –igbimo asofin agba lati fonte lu awon oruko naa.
N óo da ẹ̀bi ẹ̀ṣẹ̀ wọn lé wọn lórí.
Yatọ si aarẹ Obasanjo, Makinde tun ṣe abẹwo si alagba Fasoranti ati alagba Olu Falae nipinlẹ Ondo.
Ninu ọrọ rẹ, o fi kun un wi pe o di dandan ki awọn gbe owo le owo ọkọ nitori inira sunkẹrẹ fakẹrẹ ọkọ yoo kọja agbara wọn.
O ka nipa itan ẹda ni University College (Overseas College of the University of London) ni Ibadan to ti wa di fasiti ọlọgba ẹranko ti sanmọnti gbe dun ilẹ lọdun 1956 si 1961.
Oríṣun àwòrán, Tekno/instagram Àkọlé àwòrán, Laipẹ yii ni Tekno kọrin ninu awo orin gbajugbaja akọrin agbaye, Beyonce.
Ẹ kà wọ́n ní ìsọ̀rí-ìsọ̀rí, ati ní ọ̀wọ̀ọ̀wọ́.
Awon to n se lodi si Erdogan fehonuhan lori eto omoniyan ati ohun to n sele lowo ni Turkey Kurd ti won n gbero fun lojo iwaju ni Roomu nibi ti awon agbofinro to le ni egberun meta abo ti wa lenu ise fun.
Gbogbo ìlú tí wọ́n fún àwọn ọmọ Lefi ninu ilẹ̀ àwọn ọmọ Israẹli jẹ́ mejidinlaadọta pẹlu àwọn pápá ìdaran tí ó wà ní àyíká wọn.
Lẹyin wọn lo wa kan orilẹede Naijiria ti a ba ni ki a wo iye awọn ẹmi ti o ti lọ sii.
Ó bi mí pé, “Ǹjẹ́ o mọ ìdí tí mo fi tọ̀ ọ́ wá?
Dayo Amusa gbarata lórí bí agbófinró ṣe ń pa ọ̀dọ́ láì nídìí Àwòrán òkú ọmọ mi ni mo kọ́kọ́ rí lójú òpó ayelujara - Bàbá ọmọ tí SARS lé dójú ikú Àwọn afurasí ajínigbé tó tan oníṣòwò jáde ní ṣọ́ọ́sì wọ gàù Ọlọpaa Ọwọ́ ọlọ́pàá tẹ tọkọ-taya àti èèyàn méjì míì tó gé orí òkú ní Ibojì Awọn ọmọ Naijiria ti fọn sori ayelujara lati bẹrẹ si ni sọ ohun toju wọn n ri lọwọ awọn ọlọpaa SARS pẹlu #ENDSARS.
ti fara kasa isẹ ibi naa.
774,000 Jobs: Muhammadu Buhari ti paá láṣẹ fún mínísítà fún ètò ìgbanisíṣẹ́ láti tẹ̀síwájú lórí ètò ìṣẹ́ 774,000
Ìyàwó igbákejì ààrẹ Zimbabwe dèrò àgọ ọlọ́pàá lórí ẹ̀sùn jẹgúdújẹrá Iná ńlá ṣẹ́yọ nílú Ibadan, ó sọ ọ̀pọ̀ dí onígbèsè Ọmọ Nàìjíríà bu ẹnu ẹ̀tẹ́ lu iléeṣẹ́ Netflix lórí fíìmù tó ní Jesu ní ìbálòpò akọ s'ákọ Bí èèyàn méjì tí ṣé kù nígbà tàwọn jàǹdùkú wọ̀yá ìjà ní ìlú Èkó-Ọlọ́pàá Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Africa Eye: Ohun tí ọ̀rẹ́ mi fí sórí 'Social Media'ló wọ̀ mí lójú- Grace Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Ọ̀pọ́ jàǹdùkú l‘Ọṣun bọ́ sí gbaga ọlọ́pàá lórí ìwà ọ̀daràn Àfikún ọ̀sẹ̀ méjì la tún fun yín láti kúrò l‘Apapa - Ọsinbajo Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Child Labour: Fífi ọmọ ṣòwò wọ́pọ̀ ní Naijiria Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Gomina Glover ni inu rẹ dun si ipa ribiribi ti Oshodi ko si ilọsiwaju alaafia nilu Eko ati iriri rẹ ninu oselu, tó si maa n beere imọran lọwọ rẹ ko to ṣe ohunkohun.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ẹ̀mí kan náà ló n darí ìrìnàjò wa táa fi jọ kọ́lé papọ̀- Ìbejì Awọn oye ati ami ẹyẹ ti wọn fi da Henry Fajemiloku lọla: Awọn eeyan mọ riri ipa ribiribi ti Henry Fajemirokun ko si idagbasoke awujọ ati iran ọmọniyan, ti Jegun Ile Oluji si fi oye Yegbata da a lọla lọdun 1968 Ọdun 1972 ni Fasiti Obafemi Awolowo tilu Ile Ife fi oye Ọmọwe (PHD) ninu imọ nipa akoso okoowo, Business Administration da a lọla, lati mọ riri ipa nla to n ko si eto ẹkọ ati okoowo lawujọ wa Bakan naa ni wọn tun fi jẹ Asiwaju ilu Oke Igbo lọdun 1971, Lijoka ti Ondo ni 1973.
Ìyanṣẹ́lódì òṣìṣẹ́ ilé aṣòfin bẹ̀rẹ̀ ní pẹrẹwu nílé aṣòfin Nàìjíríà Ọ̀tọ̀ọ̀tọ̀ lèrò àwọn èèyàn lórí ìyanṣẹ́lódì SSANU Àwọn àwòrán mánigbàgbé nípa Ààrẹ Muhammadu Buhari Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Tayọ̀tayọ̀ ni mó fẹ́ ṣiṣẹ́ pẹ̀lú INEC ki ìdìbò 2019 lé dára' Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
 a kò le sọ pàtó iye àwọn tó ń gbé agbègbè yìí .
Ní ọjọ́ keji, bí wọ́n ti ń bá ìrìn àjò wọn lọ, tí wọ́n súnmọ́ Jọpa, Peteru gun òkè ilé lọ láti gbadura ní nǹkan agogo mejila ọ̀sán.
 Bakan naa ni yoo tubo je ki ohun jije maa jade pelu imototo ni Naijiria lai tun sese so ti afikun owo ile-okeere to n wole.
Jomanex Kasaye, ẹni tí ó ti bá ẹgbẹ́ náà ṣiṣẹ́ kí àtìmọ́lé ó tó ṣẹlẹ̀ (àmọ́ tí a kò fi àṣẹ mú) náà kò gbẹ́yìn níbi àpérò.
Akeredolu - BBC News Yorùbá BBC News, YorùbáFò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ondo APC Primary: Mo ti bẹ̀rẹ̀ sí ń bá àwọn akẹgbé mi nínú ẹgbẹ́ sọ̀rọ̀ kí àláàfíà léè jọba - Akeredolu 20 Agẹmo 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 21 Agẹmo 2020 Oríṣun àwòrán, Rotimi Akeredolu Aketi Gomina ipinlẹ Ondo, Rotimi Akeredolu ti sọ pe oun ti bẹrẹ igbesẹ alaafia laarin rẹ atawọn akẹgbẹ rẹ ninu ẹgbẹ oṣelu APC ni ipinlẹ naa.
Àjọ NIMC ti fún MTN, Glo, 9mobile àti Airtel ní àṣẹ láti bẹ̀rẹ̀ ìforúkọsílẹ̀ fún NIN Wo iye àwọn ìpínlẹ̀ tó fòfin de ìsìn àìṣùn ọdún ní ṣọ́ọ̀ṣì Ikú Adewole Oniluola, tó ní ẹ̀bùn ìlù lílù jùlọ lágbàyéé, yóò nípa lórí Yorùbá - Tunde Kelani Bẹẹ ba gbagbe, ijọba ipinlẹ Eko ti sọ tẹlẹ pe ẹnikẹni to ba tapa si ofin konile o gbele lati ago mejila oru si ago mẹrin owurọ, yoo sanwo itanran lati ẹgbẹrun lọna ogun naira sí ẹgbẹrun lọna ẹẹdẹgbẹta naira.
"Kalu sọ siwaju si pe ""A ko ni fi ipa mu ẹnikẹni lati gba abẹrẹ ajẹsara, ṣugbọn ẹni to ba mọ pe oun ni arun naa yoo foju wina ofin to ba gbe wọ orilẹede yi."
Ó bá àwọn èèyàn lẹ́nu wàhálà ìpalèmọ́ òkú, òun náà bẹ̀rẹ̀ sí sá síwá, sá sẹ́yìn; lẹ́yìn iṣẹ́ díẹ̀, ó tọrọ ààyè pé kí wọ́n jẹ́ kòun fẹsẹ̀ kan dé ọ̀dọ̀ oníbàráà wọn tó jẹ wọ́n lọ́wó, kí díẹ̀ ó tún lè gun orí owó tí wọn yóò ná ní bi ìsìnkú ọ̀rẹ́ rẹ̀.
Onimọ nipa ihuwasi eeyan, Rhoda Ikumawoyi lo sọ ọrọ naa fun BBC Yoruba ninu ifẹrọwerọ.
Olukọ pa itan adayeba pe korikosun ni Eegun ati Oro nigba alaye ti de aye.
Wọn kó owó iyebíye kalẹ̀ wọ́n npín-in láàrin arawọn.
Iṣẹ́ àgbẹ̀ ló wọ́pọ̀ jù ní ìgbèríko náà, ó sì ṣe kìkì igbó àti oko.
Amọṣa ohun ti wọn ni o ṣeeṣe ko fa ti ọtẹ yii ko fẹẹ ṣẹyin bi pupọ awọn aṣofin ile naa ko ṣe ni anfani ati oreọfẹ pipada dije fun ijoko ile ni ọdun 2019 naa lasiko idibo abẹle ti ẹgbẹ oṣelu APC ṣe kọja.
Ọlọrun Fún Mose ní Agbára Ìyanu.
Jesu bá jáde lọ sórí Òkè Olifi, gẹ́gẹ́ bí ìṣe rẹ̀.
Wọn fikun pe awọn ko mọ ohunkohun nipa bi wọn ṣe gbẹsẹ le apo aṣuwọn oludije fun igbakeji rẹ, Peter Obi, eyi to tako ohun ti ẹgbẹ oṣelu PDP sọ.
 Lara wọn ni Ọba Onikosi, Ọba Ketu, Oloye Oyedele Stephen, Aṣiwaju Ẹgbẹ oṣelu APC, agbegbe Koṣọfẹ, Ọgbẹni S.
Irú ẹni bẹ́ẹ̀ yóo ní ọpọlọpọ ọrọ̀,àwọn ọmọ rẹ̀ ni yóo sì jogún ilẹ̀ náà.
" alákùnrẹ ́ náà ṣàkíyèsí pé , àwọn ará ìlú fẹ ́ ràn Àjàpadá ju òun lọ , ó wa dàbí ẹni pé wọ ́ n rí "" ọkọ ́ tuntun gbé àlòkù èṣí dànù ' ."
"Èèyàn 373 ni ààrùn coronavirus tún ṣẹ̀ṣẹ̀ ràn ní Nàìjíríà - NCDC Ìjọba ìpínlẹ̀ Osun tí búwọlù ìlànà àyẹyẹ Ọṣun-Oṣogboo ọdún 2020 Wo díẹ̀ nípa ohun tí Walter Carrington gbé ṣe nígbà ayé rẹ̀ ""A ti ń sin òkú méjì sínú ibójì kan náà nítorí ọ̀wọ́ngógó ibojì ìsìnkú"" Ẹgbẹgbẹ̀rún ọmọ Nàìjíríà ní yóò má a kú lójoojúmọ́ tí wọn bá gbà wọ́n láàyè láti gbébọn dání- Amofin Onimọ nipa ofin orilẹ-ede Niajiria, Agbẹjọro Monday Ubani ti ni ko si ofin to ṣe agbatẹru pe ki ọmọ Naijiria kọọkan ma a gbe ibọn dani rin ni titi."
Ẹ̀mí wa ni à ń fi wéwu, kí á tó rí oúnjẹ,nítorí ogun tí ó wà ninu aṣálẹ̀.
Wòólì Ajayi kú ní ìlú Àgelú, òkú rẹ pòórá, ìjọ sin pósí lásán!
Ẹ óo mọ̀ pé èmi ni OLUWA nígbà tí mo bá ba yín wí nítorí orúkọ mi, tí kì í ṣe gẹ́gẹ́ bí ìwà burúkú yín tabi gẹ́gẹ́ bí ọ̀nà burúkú yín, ẹ̀yin ọmọ Israẹli, èmi OLUWA Ọlọrun ni mo sọ bẹ́ẹ̀.
Adeleke: Ìjọba Ọ̀sun kò fẹ́ gbọ́ pé ebi ń pa araàlú ni mo se padà sí PDP Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Osun Election 2018: A ti gbaradì de ìdìbò Ọṣun bí ó ti yẹ- Adeoye Bakan naa, Jimoh Moshood fikun wi pe awọn tun ri owo to le ni erinlelaadọfa milliọnu Naira lati ọwọ awọn osisẹ eleto idibo mejila lasiko idibo to waye ni Osu Kejila, ọdun 2016 ni ipinlẹ Rivers.
Oríṣun àwòrán, Instagram/ibidunni_ighodalo Igbakeki aarẹ Liberia ni iba wu oun ki awọn lee fa a pada lẹẹkan sii ṣugbọn o ti di alaarira tori o ni o daju daju, Ọlọrun ti nilo ko wa si ajule ọrun ni.
Àwọn nǹkan tí ó yẹ kí ẹ máa ṣe nìyí: ẹ máa bá ara yín sọ òtítọ́, kí ẹ sì máa ṣe ìdájọ́ òtítọ́ nílé ẹjọ́; èyí ni yóo máa mú alaafia wá.
 nísisìyí ẹ ̀ sìn òmìnira ti wà ṣùgbọ ́ n ojú ọ ̀ nà tí kò dára ń pa ìtànkálẹ ̀ ìhìnrere lára .
Awọn eni jankanjankan ti lu wa lontẹ
Awọn sọja ni ijọba da sita lati le awọn olufẹhonuhan kuro loju titi kaakiri Naijiria.
Orisabunmi: Èyí ni àlàyé lórí àsìkò ìkẹyìn olóògbé Orisabunmi àti ohun tó paá gan láti ẹnu Baba Ijesa
" O ni ileeṣẹ naa pinnu lati ba ọmọdekunrin ọhun dowo pọ nitori o ni igboya, o si mọ bi eeyan ṣe le yọ ara rẹ kuro ninu iṣoro.
Adele Ààrẹ Osinbajo tẹsíwájú pé o di dandan ki àwọn oṣiṣẹ SARS ni àmì idanimo lara wọn ní gbogbo ìgbà tí wọn bá n ṣíṣe wọn.
Wọn mu BBC Yoruba rin agbegbe naa ka ti a si rii wi pe yatọ fun iho to ṣi silẹ yii, gọta ti agbara ojo ti maa n ṣan wọọ wọọ wa nibẹ bẹẹ si ni koto ti omi maa n rọ jọ si wa nibẹ.
O ni ajo eso onibode mu awon fayawo naa, nigbati awon eniyan  kan fi  isele naa to won leti.
Ipinle Ogun ni ekun Gusu orile ede Naijiria ti gbosuba fun atileyin
Adajọ Nnamdi Dimgba to gbe ẹjọ naa kalẹ ni aadọta naira ti wọn pe ni Stamp Duty naa jẹ owo kotọ ti onibara banki kọskan to ba fẹ fi owo pamọ n san.
Ó bi Jesu pé, “Òfin bí irú èwo?
“Igi akasia ni kí o fi ṣe pẹpẹ, kí ó gùn ní ìwọ̀n igbọnwọ marun-un, kí ó sì fẹ̀ ní ìwọ̀n igbọnwọ marun-un; kí òòró ati ìbú pẹpẹ náà rí bákan náà, kí ó sì ga ní ìwọ̀n igbọnwọ mẹta.
Aare orile ede Naijiria Muhammadu Buhari ti ki adari ajo to n mojuto mimu awon eniyan to n se owo ilu kumo-kumo EFCC Malam Nuhu Ribadu ku ori ire ami eye ti ko lopin nipa gbigbogun ti iwa ibajẹ .
Wọ́n bá ṣe bí ó ti wí: wọ́n fi gbogbo wọn jókòó.
Lọ́wọ́lọ́wọ́ báyìí ọ̀ná bi ọgbọ̀n ló wà lójú omi ti ènìyàn le gbà: Ajah - Five Cowries - Marina/C.
Arakunrin Idowu Ọlakunri to jẹ baale ile oloogbe Olufunke Olakunri ti ni wura oniyẹbiye ni iyawo oun ti awọn agbebọn pa.
Ọ̀nà míràn ti a tún lè gbà wò ó ni pé kí a wo iye ènìyàn to ni Covid-19 ti wọn sì bá a lọ.
Lara ohun ti ẹ ko mọ nipa oloogbe ijapa to wa lafin Ṣọun Ogbomoso ree.
 púpò nínú àwon tí ó ń so wón wà ní bolivia ( 1.
Ẹ ṣílẹ̀kùn ọjà àmọ́ ẹ ti ilẹkun ilé Ọlọ́run, ejò lọ́wọ́ nínú - Oyedepo pariwo Àjọ NCDC kéde ènìyàn 195 míràn tó ní ààrùn Covid-19 l'órílẹ̀-èdè Nàìjíríà Ìjọba dín owó epo bẹntiró sí N108 Kòkòrò coronavirus sì wà lára mi títí mo fi kúrò ní ibùdó ìtójú àwọn alárùn covid-19 l'Eko- Motosinoluwa Afolaranmi Ìjà Awolowo, Akintola àti ogun 'Wẹtiẹ', ẹ̀kọ́ wo ló kọ́ wa?
ìwé À-kà-kọ ́ gbọ ́ n aṣàpèjúwe gerald brom ṣe àpèjúwe ohun èlò ìṣeré tó ń jà tako àbíkú , gẹ ́ gẹ ́ pulse ṣe sàpèjúwe rẹ ̀ .
1 Ìgbé 2019 Oriṣii ibudo Kayeefi ló wa lagbaye ni eyi ti Naijiria náà ni awọn ibudo kọọkan to fi agbára Olodumare hàn.
Inu rirò ni àwọn Onimọ-ijinlẹ̀ lò lati ṣe ọkọ̀ òfúrufú tàbi lọ si òṣùpá, oògùn igbàlódé lati wo àisàn, àti fún ipèsè ohun amáyédẹrùn igbàlódé yoku ṣùgbọ́n  àròkàn lo nfa pi-pokùnso, ipàniyàn, olè jijà àti iwà burúkú miran.
Ninu fidio ọhun ni Iyabo ti fi oju awọn ọmọ rẹ lede ninu yara, ti oju wọn si da bi oju Baba Keresi.
Nibi iṣẹ rẹ lo ti ṣalabapade awọn obinrin mii, tawọn naa n koju iru ipenija yii, to si ma n gba wọn niyanju.
Ni Kano, iru nkan bayi naa lo sẹlẹ laarin Gomina Abdullahi Ganduje ati ẹni to gbe ipo le lọwọ, Rabiu Kwankwaso.
Gege bi Oke se sọ,o ni idajo
Yoruba Films: Ireoluwa ṣ'ọjọ́-ìbí, Mide àti ọkọ rẹ̀ lẹ̀pọ̀, Iyabo Ojo f'aṣọ ilẹ̀ Afirika dárà
Ibura Buhari ni Saa iṣejọba keji Lọjọ kọkandinlọgbọn, oṣu karun un, ọdun 2019 ni wọn yoo ṣe ibura fun Aarẹ Buahri to tun jawe olubori lẹẹkeji gẹgẹ bii aarẹ Naijiria.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Twin Festival 2019: Ṣé ọbẹ ìlasa àti àmàlà ló ń ṣokùnfà bíbí ìbejì ní ìlú Igboọrà?
Wọn ke gbajare yii lẹyin iku ọmọbinrin ilẹ Gẹẹsi kan to lọ ṣe iṣe abẹ naa to si gabẹ re ọrun aremabọ.
Lara wọn la ti ri goolu rẹ to jẹ ni ile Barcelona ninu idije komẹsẹoyo Champions league lọdun yii, to mu ki Tottenham tẹsiwaju lọ abala to kan.
Aarẹ ọna kakanfo Yoruba Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ọdalẹ ni Babangida ati Abacha - Ọmọ Abiola Ohun to mu ki ayajọ June 12 ṣe pataki fun Naijiria: Ibo ọjọ Kejila osu Kẹfa ọdun 1993 lo tii lọ ni irọwọ-rọsẹ ju lọ, laisi rogbodiyan lasiko ibo naa, gẹgẹ bo se maa n waye lasiko eto idibo nilẹ wa Naijiria Oludije fun ibo aarẹ fẹgbẹ oselu SDP ti ọpọ eeyan gba pe oun lo bori ninu ibo naa, Oloye MKO Abiọla ati igbakeji rẹ, Babagana Kingibe ni wọn jọ jẹ ẹlẹsin musulumi, eyi ti ko sẹlẹ ri ninu itan oselu Naijiria Ibo ọjọ Kejila osu Kẹfa ọdun 1993 yii lawọn eeyan gba pe ko ni magomago ninu rara, to si jẹ ibo to tii ja gaara julọ ninu itan idibo Naijiria.
wọ́n sì bu ìfọ́jú lu àwọn ọkunrin tí wọ́n ṣù bo ìlẹ̀kùn lóde, àtèwe, àtàgbà wọn, wọ́n wá ojú ọ̀nà títí tí agara fi dá wọn.
A ò ní sàréè ìkọ̀kọ̀ kankan, a ò sì yọ́lẹ̀ sìnkú Sọ́jà 1000 - Ilé iṣẹ́ ológun Nàìjíríà Àwọn obinrin wa lè máa rìrìnàjò lọ orilẹ̀èdè míì báyìí - Ìjọba Saudi Mo rò pé mò ń jà fún Islam ni, ó pẹ́ kó tó yé mi – Boko Haram tẹ́lẹ̀ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Seun Kuti: Fela ló n pọ́n gbogbo òǹkọrin Afrobeat lagbaye O ni oun ti awon ri ka yii ba awọn ninu jẹ pupo, amọ alaafia je awọn logun nitori naa ni awọn se sọ wi pe ipade alaafia n tẹsiwaju laaarin Olubadan ati awọn ọba yii.
Oríṣun àwòrán, Twitter Mo ti lùgbàdì àrùn Coronavirus - Akeredolu figbe ta Gomina Rotimi Akeredolu ti ipinlẹ Ondo ti kede pe oun ti ni arun Coronavirus.
1–6, Àwọn òṣìṣẹ́ nínú oko Olúwa jẹ èrè ìgbàlà; 7–13, Kò sí ẹ̀bùn kan tí ó tóbi ju ẹ̀bùn ìgbàlà lọ; 14–27, Ẹ̀rí ti òtítọ́ máa ńjáde nípa agbára ti Ẹ̀mí; 28–37, Máa wo ọ̀dọ̀ Krísti, kí o sì máa ṣe rere láì dáwọ́ dúró.
Ilẹ̀ Yorùbá pátá ló ni oúnjẹ ìdẹ̀rùn Covid-19 tẹ kó l‘Eko - Ìjọba Eko figbeta Òkú ọ̀dọ́ 15 ni mo kà ní Lekki amọ́ mo kábàámọ̀ pé a gbà kí ológun gbé okù wọn lọ - DJ Switch Májèlé olóró lẹ gbé l‘Ekiti dípò èròjà oúnjẹ Covid-19 - Ariwo sọ lórí ayélujára Apena fẹ́gbẹ́ Oṣugbo, Opa, Akala àtẹ̀yin awo, ẹ wa ọ̀pá àṣẹ Ọ́ba Akiolu jáde"" Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ọwọ́ ọlọ́pàá tẹ àwọn tó lọ kó ọjà ọlajà ní Shoprite Ilorin O ṣalaye pe niṣe ni wọn kọkọ fi iya jẹ ẹṣọ alaabo to wa ninu ile naa, ti wọn fi raaye ṣiṣẹ ibi wọn."
Ní bi tí wọn ti n dáwọ̀ọ̀ ìdùnù ni ìlú Oṣogbo Oyètọla ni òun kò le fi ìdìnú òun pámọ lóri idajọ to wáye náà, ó ni kò lè jẹ ìfòyà fún òun ti oludikje lábẹ òṣèlú PDP ba morile ile ẹjọ to ga jùlọ.
O díje fun ipo aarẹ lọdun 1993 pẹlu Babagana Kingibe gẹgẹ bii igbakeji rẹ níní idibo ti àwọn eniyan Naijiria gba pe o dara julọ.
Awọn 82,555 ti ri iwosan gba, nigba ti eeyan 1,382 jẹ Ọlọrun nipe.
Kàkà bẹ́ẹ̀, ẹ máa bá wọn wí.
s lati 1875 de 1881 beesini ohun ni alagba asofin omo afrika amerika akoko to soju igba re tan .
Nígbà tí àwọn eniyan náà rí i, wọ́n dojúbolẹ̀, wọ́n wí pé, “OLUWA ni Ọlọrun!
James ni ibaṣepọ wa laarin awọn ati ileeṣẹ ifiweranṣẹ ki gbogbo eto naa ba a le lọ deede.
Bi o ṣe le forukọ silẹ jẹ ninu anfaani yi Iforukọsilẹ ọfẹ yi yoo bẹrẹ lati ọjọ kẹtadinlọgbọn oṣu Kẹwa ọdun 2020.
Nítorí náà, o óo kú, wọn kò sì ní sin òkú rẹ sinu ibojì àwọn baba rẹ.
Wike sí Ganduje: 'Èmi kìí ṣe dọ́là tó le kó sápò'
“Fetí sílẹ̀, ìwọ Jobu,dúró kí o sì ronú nípa àwọn iṣẹ́ ìyanu Ọlọrun.
Toyin Abraham ní 'gbogbo wa loníbárà', Ijebu ta sí Odunlade Femi Adebayo Salami ro dẹdẹ ninu asọ oke fun ọjọ ibi ọmọ rẹ Bakan naa ni awọn oṣere wọ si oju opo instagram ọmọ Ọga Bello naa, Femi Adebayo lati ki mọ rẹ to pe ọdun kan lonii ku ayẹyẹ ọjọ ibi.
Àkàra tú s'épò, ICPC dárúkọ àwọn Fásitì tó ń tẹ́ abá isúná wọ́n nídìí Èèmọ̀ rèé o!
Sri Lanka Attacks: Ìbúgbàmù pa èèyàn 207 ní ilé ìjọsìn àti ilé ìtura lọ́jọ́ Àjíǹde
" Ọ̀pọ̀ ìgbà ni àwọn ènìyàn wa yóò ti maa ṣe ìtójú aláìsàn láìmọ̀ pé wọ́n ni ààrùn Corornvirus, kò yẹ ki a maa fi iná sórí òrùlé sùn"" Ní bayii àwọn míràn ti lọ ya arawọn sọ́tọ lẹ́yìn ti wọ́n ti ni nkan ṣe pẹ̀lú alaarun Covid-19 lai lo aṣọ ààbò."
Adilemu fun Man U Ashley Young lo gba bọọlu lẹsẹ rẹ lẹyin naa lo tun ge agbabọọlu Man U meji mii ko to gbayo naa sawọn.
Ṣugbọn bí o bá rí ohun tí ó burú ninu ìwà mi, ìwọ gan-an ni kí o pa mí; má wulẹ̀ fà mí lé baba rẹ lọ́wọ́ láti pa.
Aug 2018 ni ìgbìmọ̀ aláṣẹ APC ti ṣe ìpàdé kẹ́yìn, Oshiomole ti kùnà Ọ̀pọ̀ àwòrán rèé tó ń sàfihàn bí Ibadan se kún fún ẹ̀gbin àti òórùn Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Aeroplane House: Látọdún 1999 ni mo ti bẹ̀rẹ̀ kíkọ́ ilé yìí fún ìyàwó mi ọ̀wọ́n Bẹẹ, loju awọn miran, wọn ni o ṣeeṣe ko jẹ pe NTA ko tete mọ pe awọn maa gbe idije naa ki wọn le pese awọn nkan ti wọn nilo.
Ìdí rèé tí ilẹ̀ Afirika fi gbọdọ̀ kópa nínú dídán abẹ́rẹ́ coronavirus wò Iye epo rọ̀bì tí wọ́n ń kó níbùdó ìpọnpo ti dínkù, ṣé ẹ fẹ́ mọ ìdí i rẹ̀?
O salaye awọn anfaani to wa nibẹ; Isejọba aarẹ gbe gbogbo agbara fun aarẹ (Executive Power), sugbọn ti isejọba igbimọ aṣofin gbe agbara fun gbogbo awọn aṣofin ti wọn dibo yan.
(Eleta Eye Institute) ninu oro ikini kaabo re ti salaye pe awon maa n lọ lati
Igba titi maa n jẹ ki awọn ayaba, paapaa awọn olori kekere to ṣẹṣẹ wọnu aafin, mọ si nipa aṣa ati ise ilẹ Yoruba, to fi mọ oriki Alaafin to wa lori oye ati awọn ọba to ti jẹ siwaju rẹ, eyi ti awọn naa yoo fi kọ iran to n bọ.
Mummy Calm Down di aṣojú iléeṣẹ́ ńlá kan l'Abuja Ọkùnrin tó dàgbà jù lágbàyé jáde láyé lẹ́ni ọdún 116 Ko pẹ si akoko naa ti ijọba ipinlẹ ọhun kede igbele pajawiri, o si rọ awọn to n ṣowo oni wakati mẹrinlelogun lati tilẹkun ṣọọbu wọn nitori awọn kọlọrọsi to n lo iṣẹlẹ naa lati ja ṣọọbu, ti wọn si n ji ọja ko lọ.
Awọn ipinlẹ to ku ni: Plateau-11 Taraba-8 Rivers-7 FCT-6 Enugu-4 Niger-4 Edo-3 Delta-2 Imo-2 Benue-1 Kano-1 Èèyàn méjìlà lé lúgba ló kó àrùn Coronavirus ní Nàìjíríà lọ́jọ́ Ẹtì Eayan mejila le lugba lo lugbadi aarun coronavirus lorilẹede Naijiria lọjọ Ẹti, ọjọ kẹrindinlogunoṣu kẹwaa ọdun 2020 yii.
Ṣugbọn Aarẹ Muhammadu Buhari ti fesi oun ko ni yi ipinu oun pada lori ele owo naa nitori bi nnka ṣe ri lasiko yii.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ìṣẹ̀lẹ̀ Kàyéèfì: Ìpáǹle tú Abass Owonikoko sí ìhòòhò ayé, kó tó gba kéú lọ́gbà ẹ̀wọ̀n Ẹnikan ti iṣẹlẹ ọhun ṣoju rẹ ṣalaye fawọn akọroyin pe, ni bii aago mẹta aabọ ọsan lawọn adigunjale naa de banki ọhun.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, SARS ti bẹ̀rẹ̀ ìgbésẹ̀ láti yọ àwọn ọ̀bàyéjẹ́ kúro Ero awọn eniyan Naijiria lori ọrọ naa Ọgọọrọ ajafẹtọ ọmọniyan ati awọn ile iṣẹ iroyin nile ati loke okun ni wọn ti bu ẹnu ẹ̀tẹ́ lu bi awọn ọlọpaa ti fi akoroyin eto aabo, amuel Ogundipe, fun iwe iroyin Premiun Times s'ahamọ Bakan naa, awọn oṣiṣẹ meji iwe iroyin naa, Musikilu Mojeed to jẹ olootu iroyin ati akọroyin eto ẹkọ, Azeezat Adedigba, naa kọkọ wa latimọle awọn ọlọpaa SARS ki wọn to dawọn silẹ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Àṣìṣe ọlọ́pàá àti Adájọ́ sọ mí di ẹni tí wọ́n dájọ́ ikú fún, ọpẹ́lọpẹ́ Fayoṣe tí ko buwọ́lù ú Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àṣìṣe ọlọ́pàá àti Adájọ́ sọ mí di ẹni tí wọ́n dájọ́ ikú fún, ọpẹ́lọpẹ́ Fayoṣe tí ko buwọ́lù ú 4 Owewe 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 5 Owewe 2020 Bi o ba lo ọdun mẹtadinlogun lọgba ẹwọn lori 'ẹṣẹ aimọdi, Ta ni o maa pe lẹjọ?
Ẹ̀gún ati tàkúté ń bẹ lọ́nà àwọn ẹlẹ́tàn,ẹni tí ó pa ọkàn rẹ̀ mọ́ yóo jìnnà sí wọn.
Iya Waziri sọ ẹdun ọkan rẹ fun akọroyin BBC Yoruba.
Aláìsàn ènìyàn ni obìnrin náà,ojoojúmọ́ ni mo ń ti ilé babaláwo dé ilé babaláwo.
Wọ́n fi ayọ̀ kọ orin ìyìn náà, wọ́n wólẹ̀, wọ́n sì sin OLUWA.
 “A ti n gbe igbese ti o lapere bayii, ni ona lati sagbakale wiwo ero igbalode amohunmawaron ofe, eyi ti a mo si (Free To Air Television platform), pelu ogoro milionu merinlelogun ile ti o n samulo ero amohunmaworan, eyi ti a tun je orile-ede ti ko se yesile ninu eto idanilaraya.
 Eto idagbasoke Aare Muhammadu Buhari ti sapejuwe eto ẹkọ gege bi ona lati mu idagbasoke ba orile ede’’pipese owo lati mu idagbasoke ba eto ẹkọ je dandan’’.
“Kí ló dé tí mo wá àwọn eniyan mi tí n kò rí ẹnìkan;mo pè, ẹnikẹ́ni kò dá mi lóhùn?
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Awọn to n polongo gbigbogun ti HIV n fẹ ki awọn ọmọ Kenya to ni aarun naama tiju lati sọrọ sita Awọn obi maa n kilọ fun awọn ọmọ wọn lati ma ba a awọn to ni aarun HIV ṣere.
Lulu Loius Mnguni, ninu ọrọ rẹ ni awọn iranti rere nipa orilẹede Naijiria kun awọn ohun meremere ti oun n mu pada lọ si orilẹede South Africa.
Angẹ́lì náà ṣe àlàyé pé òun nṣiṣẹ́ lábẹ́ ìdarí Péterù, Jákọ́bù, àti Johannù, àwọn Àpostélì ìgbàanì, tí wọ́n ní àwọn kọ́kọ́rọ́ oyè àlùfáà gíga, èyítí a pè ní Òyè àlùfáà ti Melkizedekì.
bẹ́ẹ̀ gan-an ni gbogbo wa, bí á tilẹ̀ pọ̀, ara kan ni wá ninu Kristi, ẹnìkọ̀ọ̀kan wa sì jẹ́ ẹ̀yà ara ẹnìkejì rẹ̀.
Ṣebí ẹ rí i bí OLUWA Ọlọrun yín ti gbé yín, bí baba tíí gbé ọmọ rẹ̀, ní gbogbo ọ̀nà tí ẹ tọ̀ títí tí ẹ fi dé ibi tí ẹ wà yìí.
Èmi OLUWA, tí mò ń mú kí eniyan máa bímọ,ṣé, mo jẹ́ sé eniyan ninu?
Oríṣun àwòrán, @SenChrisNgige Àkọlé àwòrán, Chris Ngige, Minisita fun ọrọ oṣiṣẹ ni Naijiria Ṣaaju ni iroyin sọ pe Minisita fun ọrọ awọn oṣisẹ ni Naijiria, Chris Ngige sọ pe iyanṣẹlodi naa fi aaye silẹ fun awọn oluwọde End Sars lati ma a lo awọn akẹkọọ fun iwọde naa.
Gege bi gomina Ortom, O gboriyin fun awon odo ohun fun iduro sinsin won lasiko ilakaka ti ipinle naa lakoja, besini, gomina fi dawonloju pe, erongba ifilole eto alafia won yoo wa si imuse.
Nigba ti o jawe olubori ninu idanwo asekagba, o jẹ iyalẹnu fun gbogbo ile ẹkọ naa.
Oduyoye pari ọrọ rẹ pe iṣẹ LASTMA ni lati dari ọkọ ni igboro ilu Eko, ti ala iṣẹ iṣẹ wọn si pin si agbegbe Berger, nitori naa o ṣoro lati mu awọn eeyan to ba n lọ ipinlẹ miran.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Akomolede àti Aṣa: Ọ̀rọ̀ Ẹ̀yán ni Bunmi Femi Amao ń kọ́ wa lórí ètò Akọ́mọlédè àti Àṣà lóri BBC Yoruba Gomina Ipinlẹ Ondo ti kede pe oun ti pari gbogbo iṣẹ akanse ti oun ba nilẹ, lai pa ikankan ti.
Ó ṣeéṣe kí ènìyàn 12,000 máa kú lójoojúmọ́ lẹ́yìn Covid-19 Orílẹ̀-èdè mẹ́wàá tí ẹgbẹ́ alákatakítí Islamic State n fínna mọ́ ní àgbáyé N kò gba ₦4bn lọ́wọ́ Magu, ẹ má ró àjẹbánu mọ́ mi láṣọ - Osinbajo pariwo Mi ò tíì gba ìwé ìfitónilétí pé wọ́n fẹ́ yọ mí nípò igbákejì gómìnà ìpínlẹ̀ Ondo- Agboola Ajayi Bi o tilẹ jẹ pe ẹgbẹrin eeyan to ko arun naa, lo wa nibudo ti wọn ti n tọju awọn alarun Coronavirus nilu Eko, sibẹ ọkunrin kan ni ọgbọn eeyan gbọdọ ku ni ẹgbẹ oun, ki oun to lee gbagbọ pe arun Coronavirus wa.
Síbẹ̀ wọ́n ti fòfin de ìpéjọpọ̀ ẹnikẹni ti kò ní ohun kohun lati ṣe pẹ̀lú ètò ayẹyẹ náà.
Àwọn ọmọ mi ti fi mí sílẹ̀, wọn kò sì sí mọ́.
 ohun ní ó máa kọ ́ kọ ́ ko aṣo léèsì àti àwọn aṣo míràn bẹ ́ è wọ nàìjíríà .
Lasiko ti gomina naa n lọ si ilu Abuja, ti o wa  de
Kong Nonny ṣalaye loju opo twitter tirẹ pe eto foto yiya lasan ni wolii TB Joshua lọ ṣe ni tirẹ.
Ṣugbọn nígbà tí Usaya di alágbára tán, ìgbéraga rẹ̀ tì í ṣubú.
“Sibẹsibẹ, ẹ kò ké pè mí, ẹ̀yin ọmọ Jakọbu,ọ̀rọ̀ mi ti su yín, ẹ̀yin ọmọ Israẹli.
2 bílíọnù fi tún wáyà iná àti inú ilé Aso Rock ṣe- Buhari Mọ̀ sí i nípa díẹ̀ lára àwọn èèyàn tí ikú wọn 'láti ọwọ́ ọlọ́pàá' milẹ̀ tìtì ní Nàìjíríà Ìbò aráàlú pẹ̀lú ẹ̀yà yókù lá fi yanjú àtúntò Nàíjíríà - YCE Ilé alájà mẹ́ta wó pa èèyan méje, èèyàn 20 farapa ní Obalende, Eko Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ondo election 2020: Àwọn ara ìpínlẹ̀ Ondo ránṣẹ́ sí Akeredolu ohun ti wọ́n ń retí ní báyìí Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Akọroyin BBC Yoruba to wa nibi ipade akọroyin naa, Adedayọ Okedare jábọ̀ pe, adari ajọ to n risi aato ati idagbasoke ilu nipinlẹ Ọyọ, Waheed Gbadamọsi lo ṣe alaye ọrọ ọhun, nibi ipade awọn akọroyin to waye nile iṣẹ ijọba ipinlẹ Ọyo l'ọjọ Aje.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ina jo ọja binukonu lọjọta nipinlẹ Eko 23 Ẹrẹ̀nà 2018 Àkọlé àwòrán, Ina jo ọja binukonu lọjọta nipinlẹ Eko Ọpọlọpọ kudia ati ohun ini lo ti ṣegbe ninu ibugbamu ina to ṣẹlẹ ni ọja Binukonu nilu Ojota nipinlẹ Eko lowurọ ọjọ ẹti.
Wọ́n sọ fún un pé ní agbègbè Silisia ni.
Ṣùgbọ́n lẹ́yìn ìṣẹ́jú mẹ́ta sí ìgbà náà ni Asisat Oshoala jẹ góòlù kejì fún Nàìjíríà.
Ní àárín ọdún kan tí a kéde òfin yẹn, ó ti tó bí ọmọ orílẹ̀ èdèe Tanzania 14 tí òfín ti mú tí a sì ti dálẹ́jọ́ lábẹ́ òfin fún pé wọ́n sọ̀rọ̀ mọ́ṣààsí sí ààrẹ lórí ẹ̀rọ alátagbà.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 2020: Oloye Awurela Ifaleke ti wúré ọdún ìgbéga fún kóówá O sálàyé pé: Ní ọjọ kẹ́rinlelogun, oṣù kejila, ọdun 2019, ni déedé àago mẹrin àbọ̀ ní agọ ọlọpàá àgbègbè Bode Thomas gba ipe lati ọdọ oga agba to n ri si ààbò Iganmu Flour Mill pé wọ́n ja ilé ikẹ́ru si ilé iṣẹ́ náà ti wọ́n si jí ajilẹ̀ ọọdunrun apo lọ.
Kí á lè pòkìkí orúkọ OLUWA ní Sioni,kí á sì máa yìn ín lógo ní Jerusalẹmu,
 a má a ńṣe ìdánimọ ̀ oríṣi àìsàn náà nípa wíwá kòkòrò àrùn ajọ ̀ fẹ ́ náà nínú ẹ ̀ jẹ ̀ tí a pèsè fún àbẹ ̀ wò tàbí nínú omi-ara tí a gbà láti àwọn oríìké-ara .
"Wo ojú àwọn òṣèré yìí láì lo ""Make-up"" orí ìtàgé bó ṣe rí gẹ́lẹ́ Wumi Toriọla ti sọ̀rọ̀ sóke láti fi idí rẹ̀ múlẹ̀ pé òun àti ọ̀rẹ́ òun níjà Ẹ gbọ́ ohun tí Desmond Elliot sọ lórí ayélujára tó bí àwọn ọmọ Nàìjíríà nínú Báyìí ni 50kobo ṣe dá ìfẹ̀hónú ""Ali Must go"" sílẹ̀ tó mú ọ̀pọ̀ ẹ̀mí akẹ́kọ̀ọ́ lọ Wo ohun tí Fashola rí níbi ìṣẹ̀lẹ̀ Lekki Tollgate tó ń fa ariwo lórí ayélujara Wo àwọn ayédèrú ìròyìn tó gbà'gboro kan lásìkò ìwọ́de #EndSARS Ẹni tó jí ọ̀pá aṣẹ ń bọ̀ wá túbá fúnrarẹ̀, mo fi dáa yín lójú gẹ́gẹ́ bí ìyá - Erelu Kuti Àwọn olóṣèlú Nàìjíríà márùn ùn tó sọ̀rọ̀ tí ará ìlú fà ìbínú yọ Remilekun Fatolu bú sẹ́kún fún ohun tó ti pàdánù láyé torí ọyàn ńla rẹ̀."
Olori osise ijoba ni ipinle Oyo ,Alhaja Ololade Agboola
Mo dáhùn, mo ní, ‘Oluwa, àwọn gan-an mọ̀ pé èmi ni mo máa ń sọ àwọn tí ó bá gbà ọ́ gbọ́ sẹ́wọ̀n, tí mo sì máa ń nà wọ́n káàkiri láti ilé ìpàdé kan dé ekeji.
Ó sọ fúun wa pẹ̀lú pé omi odò kan tí ó ṣàn la òde ọ̀run já ni, bẹ́ẹ̀ ni kò sí ẹni tí ó lè rí omi náà bù àfi àwọn ara ọ̀run.
Ìyanṣẹ́lódì òṣìṣẹ́ ilé aṣòfin bẹ̀rẹ̀ ní pẹrẹwu nílé aṣòfin Nàìjíríà Ọ̀tọ̀ọ̀tọ̀ lèrò àwọn èèyàn lórí ìyanṣẹ́lódì SSANU Ẹ̀kọ́ mẹ́fà tó jáde nínú ìdíje Premier League òpin ọ̀sẹ̀ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Gbogbo ènìyàn ló wọ agbádá ikú, ẹni tó kàn lẹnìkan kò mọ̀ Gbogbo igbiyanju lati ba alaga ASUU sọrọ lo jasi pabo nitori o ni oun ko ni ohunkohun lati sọ ki Ngige jabọ ohun to ṣẹlẹ.
Òun ni o óo máa jẹ fún irinwo ọjọ́ ó dín mẹ́wàá (390), tí o óo fi fi ẹ̀gbẹ́ lélẹ̀.
Nítorí àwọn kan ninu wọn yóo dènà dè é, wọ́n ju ogoji lọ.
”Aare tun so pe “Iriri wa lorile ede Naijiria ti fihan pe iwa ibajẹ nipa sise owo ilu kumo-kumo maa n je ki awon eniyan je ere nibi ti won ko sise si.
Wọ́n sọ̀rọ̀ ìwọ̀sí sí Ọlọrun, wọ́n ní,“Ṣé Ọlọrun lè gbé oúnjẹ kalẹ̀ fún wa ninu aṣálẹ̀?
Victor ni, ariwo yii lo mu ki oun ati awọn eeyan mii to wa layika sare tete lọ wa ibi ti iṣẹlẹ naa ti ṣẹ lọ, lati le ṣe iranlọwọ fun awọn ti ọrọ naa kan.
N óo fi ẹrù àwọn tí wọn ń jà yín lólè fún àwọn akónilẹ́rù.
Alufaa Uja so pe, “ti won ba pari ise-akanse naa tan, ireti wa pe, awon ara-ilu yoo se amulo re bi o ti to, ati bi o se ye, bakan naa ki won lo anfaani ohun fun eto idokowo.
1 Fetísílẹ̀, ìránṣẹ́ mi Peter, kí o sì tẹ́tísí àwọn ọ̀rọ̀ ti Jésu Krísti, Olúwa rẹ àti Olùràpadà rẹ.
Bí ó bá tilẹ̀ jẹ́ pé ìwọ ni òrùka èdìdì ọwọ́ ọ̀tún mi, 
ọkọ̀ ojú omi tuntun bẹ̀rẹ̀ iṣẹ́ Orílẹ̀-èdè Nàìjíríà ti tójú bọ́ lórí ẹ̀tọ́ obìnrin Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí kan sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
Asoju orile ede Naijria si orile ede Australia ,Amb.
A o fun lasiko lati da ọrọ yi wo ki a to gbe igbesẹ'' Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Gómìnà Rotimi Akeredolu ti ẹgbẹ́ òṣèlú APC tó tún jẹ gómìnà tó wà lórí oye jẹ́ ọmọ ìjọba ìbílẹ̀ náà.
Ṣugbọn mo mọ̀ pé Olùdáǹdè mi ń bẹ láàyè,ati pé, níkẹyìn, yóo dìde dúró lórí ilẹ̀ yóo sì jẹ́rìí mi,
A nilo ọkọ oju irinti yoo maa  ko
Shofiq Ahmed pín Túwíìtì kan nípa ìròyìn àìsàn tuntun:
Ní ọdún tó kọjá, ó lé ni ẹgbẹ̀run lọ́na ìgba tó fẹ́ gba físà H-1B ti ó wà fún ènìyàn ẹgbẹ̀run lọ́na ọgọ́rin lé díẹ̀ péré.
" Nibi ti nkan de duro bayii, sọ pe awọn agbaagba ẹgbẹ awọn nọọi ti n ṣé ipade lori orin ti Olamide kọ, lati mọ igbesẹ to yẹ lati gbe.
Ọ̀sẹ̀ kan ni ìgbìmọ̀ náà ní láti fi jábọ̀ iṣẹ́ rẹ̀.
Wọ́n bá dákẹ́, nítorí ẹnikẹ́ni kò gbọ́ ọ̀rọ̀ tí wọ́n jọ sọ.
Èmi kò forí ṣọta ìjàmbá ọkọ̀ òfúrufú kankan - Obasanjo Obasanjo sí Makinde: yàgò fún òṣèlú sọ ọ́ sápò Ìdààmú ńlá ńbọ̀ fún Nàíjíríà lábẹ́ ìjọba Buhari - Ọbasanjọ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Obasanjo: Buhari ní àìlera lẹ́mìí, lára, àti lọ́kàn.
N óo kọrin, n óo sì máa yìn ọ́.
O wa rọ ijsba ipinlẹ Ọṣun lati dide iranlọwọ fun arakunrin ti adanu naa ṣẹ si nitori pe gbogbo dukia rẹ naa ni ara san pa naa.
Ẹlẹ́wọ̀n 44 kú sọ́gbà ẹ̀wọ̀n nítorí ooru tó mú púpọ̀ Wo àwọn iléèwé gíga tó ti bẹ̀rẹ̀ sí ní ta fọ́ọ̀mù JAMB post UTME screening ní Naijiria Ikú dóró!
O ni awọn ṣi jọ wa pọ ni ọjọ abamẹta.
Atunbọtan itaporogan laarin awọn mejeeji yii gẹgẹ bi igbagbọ ọpọ onwoye ọrs oṣelu ni bi igbimọ ayẹwo fun awọn oludije idibo abẹle lati yan oludije fun ipo gomina labẹ aṣia ẹgbẹ oṣelu APC fi paṣẹ pe ko ni lee kopa nitori ohun ti wọn pe ni aidọgba lori awọn iwe ẹri rẹ.
Agbẹjọrọ Pelumi Olajengbesi to ba ikọ BBC sọrọ sọ wi pe ile ẹjọ kọ lati gbẹ ẹjọ naa yẹwo nitori ọjọ ti lọ lori idajọ naa.
Àkọlé àwòrán, Ní ti Ekiti, ààwọ ẹni tó jáwé olúbori ló di èro ile ẹjọ́ tó ń ri si awuyewuye tó súyọ lẹ́yìn ìdìbò, (Tribunal) Lẹ́yìn àbájáde ìdìbò April 14 ọdún 2007.
Iléeṣẹ́ Twitter tí ojú òpó Ààrẹ Donald Trump lórí ẹ̀rọ rẹ̀ pa Àwọn obìnrin ilé ìgbìmọ̀ aṣòfin Amẹrika fọnmú sí ọ̀rọ̀ Trump Àbẹ́wò ọlọ́jọ́ mẹ́ta Trump sí UK nínú àwòrán Báwo ni Donald Trump ṣè ń rí ọwọ́ mú sí nínú àkójọ èrò àwọn olùdìbò?
Tọkọtaya, ọmọ mẹ́ta àti àlejò kú sínú ilé l'Oshodi Osere tiata naa sọrọ yii nigba to n fesi lori bi eeyan kan to n gbe loke okun, se n bu ẹnu atẹ lu awọn osere tiata ati awọn gbajumọ lawujọ lapapọ pe, ọpọ wọn gbẹnu dani lai koro oju si ọpọ ikọlu tawọn ọmọ orilẹede South Africa n se si awọn ọmọ Naijiria.
 Nobody does it like the #SuperEagles pic.
Mo dáhùn pé, “Mo rí ọ̀pá fìtílà wúrà, àwo kan sì wà lórí rẹ̀.
Ẹ kò tọ́jú àwọn ohun mímọ́ mi, àwọn àlejò ni ẹ ti fi ṣe alákòóso níbẹ̀.
O ni mimu idagbasoke ba ẹsẹpupu ni ibi ti o yẹ ki ijọba gbajumọ nipa ṣiṣe amulo awọn ohun alumọni ti Naijiria ni lọpọyanturu Ọrọ Abo Ahmed Rufai ni idahun si ibere ọrọ abo ni ko si iṣedeede ati idajọ ododo lorileede Naijiria.
Alaga apapọ f'ẹgbẹ oṣelu All Progressives Congress, APC, Adams Oshiomole lo sọ bẹẹ lati fi sapejuwe kikuro ti Aarẹ ile aṣofin agba, Bukọla Saraki kuro ninu ẹgbẹ oṣelu APC lọ si Peoples Democratic Party, PDP.
Lẹyin naa ni wọn lọ si ile ifowopamọsi naa, ti wọn si yin ibọn pa obinrin to n gba owo ninu banki naa.
Àwọn èèkàn ilú tó bẹ̀ wá ni a ò fí dúro de ọjọ́ru kí a tó wọde lọ sọ́dọ̀ Aláàfin A ti ń bimọ ju ǹkan tí apá orílẹ̀èdè lè ká lọ, ẹ má bí ju méjì, mẹ́ta lọ mọ́ o!
Gẹgẹ bi awọn onimọ ijinlẹ ṣe sọ, apẹrẹ arun le bẹrẹ lati ẹyin ọjọ marun un ti eeyan ba ti lugbadi rẹ.
Low Lifes And High Hopes – Nigeria/Austria
Jẹ́ kí wọn ṣubú níwájú rẹ,nígbà tí inú bá ń bí ọ ni kí o bá wọn wí.
Nígbà tí Joṣua ati àwọn ọmọ Israẹli ti pa wọ́n ní ìpakúpa tán, tí wọ́n sì fẹ́rẹ̀ pa gbogbo wọn run, tí àwọn tí wọ́n ṣẹ́kù sì ti sá wọ àwọn ìlú olódi wọn lọ tán, 
Nebo, Baali Meoni (wọ́n yí orúkọ ìlú yìí pada) ati Sibima.
Erongba agbekale ohun ni lati mu alekun agbara ba awon omo-ogun orile-ede Sudan, latari ati le koju ipenija ti o le waye.
Ọpọ lo n tẹ ọ̀pá, ti awọn miran wa lori aga to n gbe alaisan kiri, ti ọpọ ko tilẹ riran mọ.
Ẹ óo jẹ àjẹyó, nítorí pé ó ti gbọ́ gbogbo kíkùn tí ẹ̀ ń kùn sí i; nítorí pé kí ni àwa yìí jẹ́?
Ọdún mẹtadinlogun ni Jakọbu gbé sí i ní ilẹ̀ Ijipti, gbogbo ọdún tí ó gbé láyé sì jẹ́ ọdún mẹtadinlaadọjọ (147).
Minimum Wage: Ààrẹ Buhari ti buwọ́lu #30,000 owó oṣù òsìsẹ́
Aarẹ Buhari ti yan adajọ Ibrahim
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Ohùn gooro ló gbé mi dé ọ̀dọ̀ ààrẹ̀ Bush, Obama, Obasanjo, Goodluck, Buhari' Ọrẹ timọ timọ Zlatan Ibilẹ ni ti wọn mu won papọ ati Rahman Jago, Guccy Branch ati ẹlomiiran.
Ọmọwe Akinreti, ti o sọ pe ọpọ ipenija ni awọn oniroyin maa n koju ni asiko yii, paapaa eto aabo,  wa pe fun aabo to peye fun awọn oniroyin yii.
Nibayii, lẹyin ayẹyẹ yigi ti wọn so lọjọ Satide, aya gomina ti gba ile fun wọn lati maa gbe lọtọ yatọ si ile mọlẹbi.
27 Bẹ́ẹ̀ni, àní àwọn méjìlá; àti pé àwọn Méjìlá náà yíó jẹ́ ọmọ ẹ̀hìn mi, wọn yíò sì gba orúkọ mi sí orí wọn; àti pé àwọn Méjìlá náà ni àwọn tí yíò ní ìfẹ́ láti gba orúkọ mi sí orí wọn pẹ̀lú ẹ̀kúnrẹ́rẹ́ èrò ọkàn.
Oríṣun àwòrán, others Àkọlé àwòrán, Naijiria darapo mo olokowo kan nile Adulawo Pẹlu bi Naijiria ṣe ti wa fi ọwọ si iwe adehun naa, afojusun AfCFTA ni lati mu afikun ba kata-kara laarin awọn orilẹ-ede ilẹ Afrika ti n sun mọ imuṣẹ.
Kí wá ni ìwúlò ọgbọ́n mi?
Ìwọ ọkàn mi, kí ló dé tí o fi ń rẹ̀wẹ̀sì?
Iwon ese Ogorun un  ni awon to n wa gusa sabaa maa fi  n wonu ile lo.
Oyo kọkọ fẹ gbe ilana kalẹ lori iru isori awọn ti o lẹtọ lati wa sọrọ nipa aṣemase SARS."
Ilẹ̀ náà di ìbàjẹ́ tóbẹ́ẹ̀ tí mo fi ń fi ìyà ẹ̀ṣẹ̀ wọn jẹ ẹ́, ilẹ̀ náà sì ń ti àwọn eniyan inú rẹ̀ jáde.
Họwuhọwu laarin Trump ati awọn ileeṣẹ ọhun bẹrẹ lẹyin ti Twitter gbe igbeṣẹ lati ṣe ọfintoto ohun to ba n fi lede loju opo Twitter rẹ lati mọ boya ootọ ni.
A dúpẹ́ lọ́wọ́ ẹ̀yin ènìyàn ìpínlẹ̀ Ekiti pé ẹ tú yáyá láti dìbò fún olùdije ẹgbẹ́ wa''.
Òṣùká kékeré kò rẹrùn àgbà, orílẹ́èdè Nàìjíríà ṣòro púpọ̀ láti darí - Ibrahim Babangida Òyìnbó sísọ di èèwọ̀ ní ìpínlẹ̀ Ekiti Ìpínlẹ̀ Ondo ti ní gómìnà tuntun Ọ̀la ni Arafat, wo iṣẹ́ tó ṣe kókó láti ṣe ní Hajj lásìkò Àràfá àti lẹ́yìn rẹ̀ O ní lẹ́ta tí olórí òṣìṣẹ́ ilé ilé ìjọba Abba Kyari kọ tó sì ń da awuyewuye náà silẹ̀ kàn wà fún ọ̀nà láti pe àkíyèsí ilé iṣẹ́ náà si ìlànà òdì ti wọ́n ń gba láti gba owó orí ni lọ́ọ́lọ́ yìí ni.
Nígbà tí ilẹ̀ ẹ̀yà Dani bọ́ mọ́ wọn lọ́wọ́, wọ́n bá lọ gbógun ti ìlú Leṣemu, wọ́n ṣẹgun wọn, wọ́n pa wọ́n, wọ́n sì gba ilẹ̀ wọn.
O ni iṣẹ ijọba ni lati ṣejọba lọna ti yoo fi rọ ara ilu lọrun.
O ṣiṣẹ aṣojuṣofin lọdun 1979 si 1983 lasiko iṣejọba alagbada keji nigba ti o kopa ribiribi ninu iṣelu Naijiria.
Bákan náà ni ni àwọn tó ń sanwó èlé lórí ilé, ìyẹ náà dínkù dáradára, èyí si fún àwọn ènìyàn ni ànfàni láti lówó lọ́wọ́ ti wọ́n le ná.
''Ati kekere ni mo maa ti n pa awọn agbalagba lẹrin, iwe kẹrin ni girama ni mo ti ko ẹgbẹ osere jọ.
Dino Melaye: Oríṣun àwòrán, Twitter Ọmọ ile aṣofin agba Naijiria nigba kan, Dino Melaye, naa wa lara awọn ti Hush ba ya fọto ri.
Olukayode ni dipo bẹ́ẹ̀, ṣe ni wọn n wọ Naijiria atawọn asare ije wa to lorukọ ninu ẹrẹẹ nitori $130,000.
Ó lè máa wí fún ọ pé, “Jẹ, kí o sì mu!
Jesu Bá Àwọn Amòfin ati Àwọn Farisi Wí.
Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Ooni Ile Ife: Ooni Adeyeye Ogunwusi àti Olòrì Naomi gbé Àrẹ̀mọ tuntun wọ ṣọ́ọ̀ṣì21 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Gómìnà ìpínlẹ̀ Benue, Samuel Ortom ti parí ìjà láàrin akọ̀ròyìn Channels TV, Pius Angbo àti Ifeyinwa Angbo, ìyàwó rẹ̀8 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Borno Zabamari Massare: Àjọ NCC fẹ́ tú ìwé owó àwọn olúpèsè ìtàkùn ìbánisọ̀rọ̀ wo10 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 APC NEC Meeting: Ẹkúnrẹ́rẹ́ ọ̀rọ̀ ìkini PDP sí APC bí àwọn adarí ẹgbẹ́ lápapọ̀ ṣe túká rèé8 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Ọmi ti wọn ta yii tunmọ si pe, ikọ ilẹ Brazil ti kuna lati bori ninu idije mẹrin ti wọn ti gba sẹyin.
Loṣu Kẹwa ọdun ni ileeṣẹ ọlọpaa agbaye, Interpol gba Adoke mu u ni Dubai lori ipa to ko ninu apapin owo epo rọbi ti a mọ si Malabu Oil Deal.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Skin Bleach: Èyí ni ọ̀nà tí àwọn obìnrin n gbà kó ara wọn sí wàhálà nítorí ara bíbó 7 Agẹmo 2019 Oríṣun àwòrán, AFP Àkọlé àwòrán, Ọpọlọpọ miliọnu eniyan, papa awọn obinrin ni Asia ati Africa lo n gba oriṣiriṣi ọna lati di eniyan pupa.
Jesu Oyingbo rèé, pásítọ̀ tó láṣẹ ìbálòpọ̀ lóri ọmọ ìjọ obìnrin Ọlọpa mu afunrasi mẹrinlelaadọta l'ọyọ Ọ̀pọ́ jàǹdùkú l‘Ọṣun bọ́ sí gbaga ọlọ́pàá lórí ìwà ọ̀daràn Ìsìpẹ́kítọ̀ d'àwátì, jàndùkú fara gbọta nínú ìjà ọlọ́pàá ati aráàlú ní Ogun A tun beere lọwọ rẹ boya wọn tilẹ ti mọ ibi ti ọkunrin naa ti wa.
Anthony Joshua: Ajagba akẹ̀ṣẹ́ ọmọ Nàìjíríà lóun ṣetán láti f'ẹ̀ṣẹ́ dín dòdò ìyà fún AJ
O ni ninu ija yii ni ọrẹ oun ti ṣubu lulẹ ki ọrọ to di ranto ni agbegbe Warawa ni ipinlẹ Kano ni ariwa Naijiria.
Iṣẹ́ àṣelàágùn ni o óo máa ṣe, kí o tó rí oúnjẹ jẹ,títí tí o óo fi pada sí ilẹ̀,nítorí inú rẹ̀ ni a ti mú ọ wá.
Gẹ́gẹ́ bí ó ti wà ní àkọsílẹ̀, “Ẹni tí ó kó ọ̀pọ̀ kò ní jù, ẹni tí ó kó díẹ̀ kò ṣe aláìní tó.
 Abdullahi – Nasarawa, Minisita abẹle fun imọ sayẹnsi ati imọ ẹrọ(Science & Tech), State mẹ́tàlélọ́gbọ̀n ) Amb.
Nítorí náà, èmi náà kò lè fi ara dà á mọ́, ni mo bá ranṣẹ láti wá wádìí nípa ìdúró yín, kí ó má baà jẹ́ pé olùdánwò ti dán yín wò, kí akitiyan wa má baà já sí òfo.
Láàrín ọjọ́ mẹ́jọ péré, ibà Lassa kan èèyàn 25 FIFA f'òfin de Chelsea lórí ríra agbábọ́ọ̀lù Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Scrabble: Yorúbà Scrabble ni àkọ́kọ́ ní èdè abínibí nílẹ̀ Afrika Wọn ni Taiwo Adeoluwa fori gba ni ni eyi ti wọn n tọju lọwọ ni ìdí àbá.
Ìwádìí fi han pé ẹni tó bá fẹ le lọ lo àwọn kóòtù míràn ni àwọn agbègbè míràn kí wọ́n wá sọ, sùgbọ́n ẹni náà yóò san bi ẹgbẹ̀rùn lọ́nà ọgbọ̀n náírà sí ẹgbẹ̀rún lọ́nà ààdọ́ta náírà.
Nkankan sọ fun mi pe wọn ti ni ibalopọ, ṣugbọn ko jẹwọ.
Ṣe eto bí ose fẹ́ kí gbogbo nkan ó rí, èyí yóò mú àdínkù bá ẹ̀rù.
Iṣẹ atọkun ariya tabi ayẹyẹ (MC) lo n ṣe tẹlẹ ko to bẹrẹ orin kikọ.
Awọn mẹrindinlọgbọn lo peju sibẹ, ti ẹni to jawe olubori si gba ẹbun to to ọgọta miliọnu Naira.
Nilẹ toni to mọ, awọn to ti ko arun naa ni South Afirika ti kọja ẹgbẹrun lọna ẹẹdẹgbẹta.
Sarri ni lootọ l'oun fẹ ki Hazard duro ni Chelsea, ṣugbọn oun ko ni di i lọna ti o ba fẹ fi ikọ agbabọọlu naa silẹ.
"Oríṣun àwòrán, @Iam_MarkPaul ""Bí ẹ̀bẹ̀ kò bá dẹ́kun ìkọlù South Africa, ẹ gbé iléeṣẹ́ aṣojú rẹ̀ ní Nàíjíríà tìpa"" Ẹnu lasan ko le dẹkun ọrọ bi awọn ọmọ bibi orilẹede South Afrika se n kọlu awọn ajeji, taa mọ si Xenophobia, eyi to ti wa n di lemọ-lemọ bayii, ayafi ki ijọba Naijiria gbe igbeṣẹ to lagbara lori rẹ."
Iranwo owo ohun ni gomina Samuel Ortom bere lati fi pese awon ohun amayederun bi eto ilera, sise atunse si iyara akeko ati awon ohun miiran nipinle Benue.
Kọmisọna fun eto iroyin, Wasiu Olatunbosun lo sọ bẹẹ fun BBC Yoruba lẹyin ti ijọba kede wi pe awọn fẹ ra ọkọ tuntun yii fun idagbasoke eto irinna ni ipinlẹ naa.
Ọjọ Isẹgun ni Gomina ipinlẹ Kwara, Abdulfatah Ahmed polongo lori tẹlifisọn pe ijọba ipinlẹ naa ti fagile iwọde itagbangba gbogbo ẹgbẹ oselu ni ipinlẹ naa lati dẹkun iwa ipa to n ja ni ipinlẹ naa.
kí wọ́n sọ fún àwọn eniyan Israẹli pé, “Àwọn ẹran tí wọ́n lè jẹ lára àwọn ẹran tí wọ́n wà láyé nìwọ̀nyí: 
Àwọn iranṣẹ ọba tí wọ́n súnmọ́ ọn tímọ́tímọ́ bá sọ fún un pé, 
Iléẹjọ́ fún Gómìnà Seyi Makinde láṣẹ láti yan alága tuntun ní ìpínlẹẹ̀ Oyo Inú mi dùn pé ẹni tó gbà ìjọba lọ́wọ́ mi ń san gbèsè tí mo fi kalẹ - Aregbesola Ibadan NURTW: Àwọn ti Auxilliary àtàwọn tí Ajanaku gangan ló ń dàgboro rú Nigba to n ki aarẹ, gomina ipinlẹ Ogun, Dapọ Abiọdun ni awọn eekan ọmọ bibi ipinlẹ Ogun tọ Buhari wa, lati wa dupẹ lọwọ rẹ, fun iyi ati ẹyẹ to fun Abiọla nitori ẹni ta se loore, ti ko dupẹ, bi ọlọsa ko ni lẹru lọ ni.
Gbogbo eeyan ni eto N-Power wa fun •Abala Eto N-Tech ati N- Health wa fawọn to kẹkọ gboye ile ẹkọ giga nikan.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Cancer: Àṣe ara mi ni iso ti n run gbogbo bí mo ṣe n ṣèrànwọ́ lórí jẹjẹrẹ Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Ireti ọpọ onwoye bọọẹu ni pe ikọ Manchester city yoo fi ajuls han ni ifẹsẹwọnsẹ yii.
Ẹni tí ó ju Solomoni lọ wà níhìn-ín.
Ọgbẹni Uwujaren ṣalaaye pe ọwọ tẹ Olawale ati pasitọ rẹ ni Ile Ife lẹyin tawọn ẹbi Hayatou fi ọrọ jibiti naa to ajọ EFCC leti.
Ode iya ni Everton lọ pẹlu bi Chelsea ṣe fi iya ajẹbolori ṣe wọn lalejo ni Stamford Bridge.
Gbogbo àwọn tí a kà ninu ẹ̀yà Bẹnjamini jẹ́ ẹgbaa mejilelogun ó lé ẹgbẹjọ (45,600).
Ètò ọmọ wa ni ẹ jẹ́ kó ṣe é ló ń dá ìdàgbàsókè Nàìjíríà dúró -Osinbajo Kí ló ń sọ ọmọ Nàìjíríà d'èrò ilẹ̀ òkèèrè tí ìjọba kò ronú sí?
Oríṣun àwòrán, Getty Images Pupọ awọn orileede to wa ni Asia toun ti pe wọn sunmọ China nibi ti ajakalẹ yi ti bẹrẹ ni wọn ti n ribi mu adinku ba ajakalẹ arun yi.
Wọ́n óo so ẹran wọn mọ́lẹ̀ títí di ọjọ́ kẹrinla oṣù yìí.
Pẹlu atilẹyin Ọba Oluwọle, tọkọ-taya tuntun yii gbọrẹgẹ-jigẹ ninu okoowo sise lagbegbe Ẹgba Ọba Oluwọle waja lọdun 1841, Tinubu se atilẹyin fun Akitoye, aburo ọkọ rẹ, lati jẹ Ọba ilu Eko, Ọba yii si tun faaye gbaa lati mu ki okoowo rẹ burẹkẹ si Kosọkọ le Akitoye lori itẹ lọdun 1845, ti Ẹfunroye Tinubu ati Akitoye si sa asala fun ẹmi wọn lọ si ilu Badagry, nibi ti okiki obinrin naa nidi ọrọ aje tun ti tan si Losu Kejila ọdun1851 ni awọn eebo Gẹẹsi le Ọba Kosọkọ lori oye, ti Akitoye si tun pada sibẹ, lẹyin to ti tọwọ bọ iwe pe oun ko ni lọwọ ninu owo ẹru sise Adehun yii ko ba Ẹfunroye Tinubu lara mu, to si n dọgbọn se owo ẹru labẹlẹ, to si n fi ẹru paarọ fawọn eebo Pọtugi ati Brazil lati gba ibọn Lara awọn ilẹ ti Ẹfunroye Tinubu gba lọwọ Ọba Akitoye ni gbagede Tinubu (Tinubu Square) ati opopona Kakawa, to wa nilu Eko di oni Aawọ nla bẹ silẹ laarin awọn onisowo ẹru ati Ẹfunroye nitori bi okoowo obinrin naa se n gbinlẹ, ti awọ̀n eebo si gba Ọba Akitoye nimọran lati le Ẹfunroye Tinubu kuro nilu Eko Lẹyin ti Ọba Akitoye jẹ ipe awọn baba nla rẹ, Ọba Dosumu gori itẹ, ti Tinubu si pada silu Eko lati se atilẹyin fun, bẹẹni ọwọja okoowo rẹ ko dinku, o n fẹju si ni Asiko Ọba Dosumu ni Tinubu ko ọpọ ọmọ ogun jọ, ninu eyi ti awọn ẹru wa, to si maa n ta asẹ ọba nipa nigba miran, eyi to mu ki ọrọ rẹ su ọba Dosumu Ẹfunroye Tinubu se agbatẹru ijagboro kan to lagbara lati tako awọn ẹru to ni ominira, ti wọn pada de lati ilẹ Saro, idi si ree ti wọn tun fi le Ẹfunroye kuro ni Eko lọ si Abẹokuta Ẹfunroye Tinubu di onisowo ibọn atawọn ohun ija oloro miran nilu Abẹokuta, to si pese ohun ija lati sẹgun ogun Dahomey, eyi to mu ki wọn fi jẹ Iyalode Ẹgba Ẹfunroye ko gbe jẹ nilu Abẹokuta, to si tun lọwọ si ọrọ ọba jijẹ, to si n se atilẹyin fun Ọmọọba Oyekan lati yẹ aga ọba mọ Ọba Ademọla nidi gẹgẹ bii Alake tilẹ Ẹgba lọdun 1879 Iku pa oju Ẹfunroye Tinubu de lọdun 1887 ni agboole Ojokodo nilu Abẹokuta, ti wọn si fi ita Tinubu sọri rẹ Awaye ku ko si, ọrun ma kanju, gbogbo wa la n bọ, ti ina yoo si dilẹ lẹyin asunsun jẹ.
Gbogbo ọjọ́ wa láyé dàbí òjìji, kò lè wà pẹ́ títí.
Ìtìjú yóo bò yín dípò ẹwà.
O ni ikọ awọn ọmọ ogun lo iwa ipa nigba to di mimọ pe ẹmi ọgbẹni Buratai wa ninu ewu.
Ẹ má ṣe da ara yín pọ̀ mọ́ ayé yìí.
”Akiṣi sì dá wọn lóhùn pé, “Ṣebí Dafidi, iranṣẹ Saulu ọba Israẹli nìyí, ó ti wà lọ́dọ̀ mi láti ìgbà pípẹ́, n kò tíì rí àṣìṣe kan lọ́wọ́ rẹ̀ láti ìgbà tí ó ti dé ọ̀dọ̀ mi títí di òní yìí.
Nisinsinyii ni a óo lé aláṣẹ ayé yìí jáde.
ojo kesan an osu kejo odun 2019.
fun won pe: “Ẹ wa  si orile ede Naijiria , ki ẹ
"APC ṣe afikun saa Oyegun gẹgẹbii alaga 'Naijiria n koju itankalẹ arun iba' O ni ""ijọsin gbọdọ jẹ sise ni ọna to bojumu, to si wa ni tẹle awọn ilana ti wọn lakalẹ."
Kini awọn ohun miran to yẹ ki o mọ nipa Ẹgbẹdokun, ọga ọlọpaa tuntun nipinlẹ Eko?
Wán sì tún bá ibọn tí wọ́n fi ń ṣọsẹ́ lọ́wọ́ wọn.
Okan lara iko agbaboolu orile-ede ti o darajulo lagbaye, ti won si ti gba ife eye idije boolu agbaye fun igba marun un otooto bayii, ti kede agbaboolu metalelogun ti yoo lo soju orile-ede naa fun idije boolu agbaye to n bo lona lorile-ede RussiaApapo iko ogbon agbaboolu ohun ni kikun:  Awon Asole(Goalkeepers): Alisson (Roma, Italy), Ederson (Manchester City, England), Cassio (Corinthians);Awon agbaboolu owo eyin(Defenders): Miranda (Inter Milan, Italy), Marquinhos (Paris Saint-Germain, France), Thiago Silva (Paris Saint-Germain, France), Marcelo (Real Madrid, Spain), Filipe Luis (Atletico Madrid, Spain), Fagner (Corinthians), Pedro Geromel (Gremio), Danilo (Manchester City, England);Awon agbaboolu aarin(Midfielders): Casemiro (Real Madrid, Spain), Fernandinho (Manchester City, England), Paulinho (Barcelona, Spain), Renato Augusto (Beijing Guoan, China PR), Philippe Coutinho (Barcelona, Spain), Willian (Chelsea, England), Fred (Shakhtar Donetsk, Ukraine);Awon agbaboolu owo iwaju(Forwards): Gabriel Jesus (Manchester City, England), Roberto Firmino (Liverpool, England), Douglas Costa (Juventus, Italy), Taison (Shakhtar Donetsk, Ukraine), Neymar (Paris Saint-Germain, France).
Minimum wage: Gbogbo ìpínlẹ̀ tó wà ní Nàíjíríà ní ìwọ́de NLC yóò ti wáyé
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Eld Kabir in Nigeria: Mùṣùlùmí àti Kristiẹni sọ̀rọ̀ nípa àdun oúnjẹ́ àti ẹran ọdún Ileya Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Eld Kabir in Nigeria: Mùṣùlùmí àti Kristiẹni sọ̀rọ̀ nípa àdun oúnjẹ́ àti ẹran ọdún Ileya 31 Agẹmo 2020 Loni ọjọ Ẹti ni ayajọ ọdun Ileya fun tọdun yii taa mọ si Eid Kabril.
Ó ní òun óo sọ wọ́n di ẹni àríbẹ̀rù fún gbogbo ìjọba ayé.
bẹ́ẹ̀ ni a óo ṣe si yín, ẹ̀yin ọmọ Israẹli, nítorí ìwà burúkú yín.
Nibi igbẹjọ, ẹni to pa a gangan to fẹnu ara rẹ jẹwọ, Barnabas Jabila ni oun tẹle aṣẹ latọdọ ọga oun Al-Mustapha ni.
A kí arawa ní èdè wọn.
Eyí ni àwọn ǹkan to maaá n ṣẹlẹ̀ si ara rẹ ti ó ba gba ààwẹ ọgbọ̀n ọjọ́.
Ọba aláde o gbọdọ kọ iyàwó rẹ̀ sílẹ̀- Bakare, Iba àṣà Yorùbá Àwọn afọbajẹ wọ́ Oluwo relé ẹjọ́, ìjọba Osun kò tíì fọùn O ni ojúṣe ọba to mọ iṣẹ rẹ n'isẹ ni eto abo ilu to n jọba lé lórí.
Pẹlu bo ṣe ri yii, ẹgbẹrun mẹtadinlogoji o le igba ati marundinlọgbọn, 37,227.
Fun apẹrẹ, gomina Makinde ṣalaye ninu atẹjade to fi sita pe asiko kan naa ni esi ayẹwo oun ati ti akọwe ijọba ipinlẹ naa, arabinrin Olubamiwo Adeosun de.
Eyi ko ṣẹyin pe ti ijiya to gbopọn ba wa fun wọn, ijọba gan an yoo tubọ ri owo to pọ si i lẹka isẹ tiata.
Ọgbẹ́ni Murby ń ti ìgbéga dé ìgbéga ní ibi iṣẹ́ rrẹ̀.
Ilé ẹjọ gíga India dajọ pé ìbálòpọ̀ ọkunrin sí ọkùnrin b'òfin mú
Aarẹ Buhari tun fikun ọrọ pe ijọba oun yoo tubọ ṣiṣẹ takuntakun si lati rii wi pe eto aabo mọnyan lori, ati pe ijọba tun ọrọ aje Naijiria ṣe sii.
39 Kíyèsíi, ìwọ ha lè ka èyí láì yọ̀ àti láì gbé ọkàn rẹ sókè fún ìdùnnú?
Ṣekeli marun-un gbọdọ̀ pé ṣekeli marun-un.
Orukọ iya iyawo to ti di oloogbe, tii se Yemisi, ni wọn kọ si ara asọ iboju ti wọn ran si ara asọ igbeyawo naa, eyi ti wọn fi diamond kọ.
“Ayọ̀ ń bẹ fún àwọn tí ó jẹ́ òtòṣì ní ẹ̀mí,nítorí tiwọn ni ìjọba ọ̀run.
Ṣugbọn wọ́n ṣọ̀tẹ̀ sí Ọ̀gá Ògo lẹ́bàá òkun pupa.
 wọ ́ n fi alhaji ahmad zaruq joyè bàbá Àdínì àkọ ́ kọ ́ ní mọ ́ sálásí bàbà pupa ní àdúgbò pàkátà ní ìlú ilọrin .
Adajọ Victoria Bob-Manuel to gbọ ẹjọ naa sọ pe ile ẹjọ oun kò lagbara lati gbọ ẹjọ naa.
0 357 Orilẹede Seychelles 0 0.
Awọn eeyan to ba wa sọrọ ni awọn ti wọn ko sile iyasọtọ kan n mu ọti, jo, ti wọn si n se ariya ni.
Bi Afẹnifẹre ṣe n sọ pe Atiku lawọn yoo tẹle ni ẹgbẹ agb Yoruba pẹlu n fi atilẹyin wọn han fun Aarẹ Buhari.
Oríṣun àwòrán, Facebook/UCH UCH si wa lori ẹsẹ rẹ pe, ohun ko gba iranwọ owo kankan lati ọdọ ipinlẹ Oyo fun itọju awọn to ni aarun Coronavirus.
“Awon ajo eleto aabo wa gbodo mu eto aabo le lona ti awon eniyan yoo se ni igbagbo ninu won.
Oríṣun àwòrán, AFP Àkọlé àwòrán, Aworan agbebọn to paniyan ni Texas Aarẹ Amẹrika Donald Trump ti ṣe apejuwe iṣẹlẹ naa gẹgẹ bi iwa to buru O kọ loju opo Twitter rẹ pe'' O dami loju pe emi ati awọn eeyan ilẹ yi jijọ n bẹnu atẹ lu iṣẹlẹ yi.
"Buhari ti buwọ́lu #30,000 owó oṣù òsìsẹ́ ""Gbogbo òṣìṣẹ́ kọ́ ni #30,000 owó oṣù tuntun yóò kan"" Bakan naa ni ẹgbẹ naa rọ awọn olugbanisiṣẹ, paapa ijọba apapọ ati ipinlẹ lati bẹrẹ igbesẹ to yẹ lati le sọ ọ di lilo lasiko."
Nítorí Hẹrọdu yìí ni ó ti pàṣẹ pé kí wọ́n mú Johanu, kí wọ́n dè é, kí wọ́n sì fi í sẹ́wọ̀n nítorí ọ̀rọ̀ Hẹrọdiasi, iyawo Filipi, arakunrin Hẹrọdu.
Gomina naa tun so pe ijọba oun yoo tubo tepele mo gbigbe asa  ati ise laruge , gege bi ko se kaare lati maa pese idagbasoke  lori ohun amayederun, igbaye –gbadun ati eto oro aje  fun awon ara ilu.
Pẹlẹ kutu lọrọ yi gba ni ohun ti ọjọgbọn Bisoye sọ nipa wiwa ọna abayọ si awuyewuye yi ọrọ iayalọja ati babalọja ni Ibadan ati ni ipinlẹ Eko.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Idije FA Cup Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
A bẹ̀rẹ̀ sí í súnmọ́ ọn káa fi lè ríi dáadáa.
O ni Coronavirus ti di ajakalẹ arun yika agbaye, gbogbo aayan si lo yẹ ka sa lati ri pe ko di isoro nla si wa lọrun lorilẹede yii.
Wọn óo la òkun Ijipti kọjá,ìgbì rẹ̀ yóo sì dákẹ́ jẹ́ẹ́.
Nígbà náà ẹ wà ní ipò ẹni tí kò mọ Kristi.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ẹgbọ́n olóògbé Suga: Wọ́n yìnbọn fún Suga lójú mi, n kò sì lè dá wọn dúró Ile iwosan nla UCH ni ilu Ibadan ni Olatoye ku si, ni ọjọ Kẹsan oṣu Kẹta ọdun 2019, lẹyin ti o fara gba ọta ibọn ni agbegbe Lalupọn lasiko idibo sipo gomina to waye nibẹ.
Fun idi eyi, ninu idibo to m bọ ni ọla lati awọn ẹkun yii ni a o ti mọ bi ohun gbogbo yoo ṣe ri fun ẹni ti yoo gba ade aarẹ Ghana.
'Fagunwa Mimọ' si lo yẹ ka maa pe nitori awọn itan ti awọn iwe rẹ kọ wa da bii ti awọn iwe mimọ mi, to si yẹ ka fi se iwe ipari awọn iwe mimọ wa fun awọn ẹlẹsin.
Iwe ipẹjọ yi wa lati ẹka tó n mojuto ọrọ ileẹjo ileesẹ ọlọpaa kan naa.
Nǹkan tí mò wí ni pé bí ó bá jẹ́ pé ó lè fẹ́ mi, kí á tilẹ̀ ní mo wí pé mo fẹ́ fẹ́ ẹ?
"O sọ pe ""ko si nkan to pamọ fun mi nipa nkan to n lọ lori ayelujara onibaraa mi, ṣugbọn, ṣe oun lo n kọ wọn?"
Kábíyèsì fẹnu ara rẹ̀ tú àṣírí àwọn Fulani Daran daran tó ń ṣọṣẹ́ nílùú rẹ̀ Ọ̀nà ọ̀fun, ọ̀nà ọ̀run!
O ni bi bẹẹ kọ, eeyan ko ni le se gbogbo rẹ pọ pẹlu asiko perete to wa nilẹ.
African Drum Festival 2019: Orílẹ̀èdè 23 ló kópa níbi àjọ̀dún ìlù ọdún 2019
Ìdìbò Kano kò fararọ, Atiku fẹ̀sun kan pe ìdúkoko mọ́ni pọ Supplementary election: Ọlọpàá gbé ikọ kògbérégbè díde lọ si wọ́ọ̀dù ìdìbò Gama Èmi ṣì ni Gómìnà ìpínlẹ̀ Ọṣun-Oyetọla Ìdí tí Adeleke kò fi tíì lè kó lọ ilé ìjọba ìpínlẹ̀ Ọṣun Màá gba kádàrá tí mo bá fìdírẹmi - Ganduje Plateau wa lara awọn ipinlẹ marun un ti atundi ibo gomina ti waye.
ọmọ ogun orile ede  Naijiria  ti HARBIN KUNAMA lll ti gbẹmi awon
Israẹli, àwọn wolii rẹ dàbí kọ̀lọ̀kọ̀lọ̀ láàrin òkítì àlàpà.
 Ọ ̀ wọ ́ kejì ni àwọn tó wà lábẹ ́ arisu ìbátan olú-Ìwà .
Wọn tun mu afẹsọna Hajar si atimọle pẹlu awọn oṣiṣẹ ile iwosan naa mẹta.
Iroyin ohun tun kinlo lori awon oro kobakugbe, ti o n sokunfa wahala, iberu-bojo ati laasigbo ni orile-ede naa ti o se se n goke naa.
Ó jókòó nibẹ̀, ó sí pe àwọn tí ó sì jẹ́ olóòótọ́ sí wọ́n múra láti ibé ogun ti ọmọ rẹ̀ náà títí tí wọ́n fi ṣẹ́gun rẹ̀.
Ọ̀pọ̀lọ̀pọ iléeṣẹ́ panápáná ló ń ṣe akitiyan láti pa iná ọjà pákó ní Mushin Amu 'Danfo', 'Okada', 'K-leg' àtàwọn ọ̀rọ̀ Nàìjíríà ti wọ́n fi kún Oxford Dictionary lọ́dun 2020 Tinubu kò ṣékú, kò ṣé ẹyẹ, o n dibọn ní lórí ọ̀rọ̀ ikọ̀ Amotekun - Fani Kayode Diẹ niyi lara awọn oṣere tiata Yoruba to ti pada ls kawe gboye ijinlẹ lẹyin ti wọn bẹrẹ ere sinima ṣiṣe: Ọdunlade Adekọla Oríṣun àwòrán, odunlade adekola/instagram Gbajumọ ni Ọdunlade adekọla ninu ka ṣe ere tiata Yoruba, koda o ti gbiyanju ninu awọn sinima miran to jẹ ti ede oyinbo pẹlu.
Èmi pàápàá bá ọ̀pọ̀lọpọ̀ agbọ̀n ẹ̀kọ ní ilé wọ́n sì lu ìlù fún ọjọ́ púpọ̀ ní ilé wa.
Mekoh salaye pe, akosile aisi ikore to fun awon agbe ipinle naa, da lori aifun won ni eso lasiko, awon agbe agbegbe naa ni iba kore lopo yanturu.
Ẹ máa rìn ní ọ̀nà mi, kí ẹ sì máa pa òfin mi mọ́.
Dá mi lóhùn ninu òtítọ́ ati òdodo rẹ.
Awọn ọmọ Naijiria lori ẹrọ ikansiraeni Diamond Bank lori opo Twitter ti n fesi bi Diamond se darapọ mọ Access Bank.
Oríṣun àwòrán, @tokstarr Ko tan síbẹ̀ o, iroyin naa sọ pe, ọkùnrin olowo tabua kan, Festus Fadeyi, to tun jẹ alaga ileesẹ epo bẹtiro Pan Oceanic Oil Corporation, lo fun Toke ni ile naa lọdun diẹ sẹyin.
Bakan naa, ni won tun  fagi le esi idibo woodu keje ni ijoba Ibile
Ó wá fi òwe bá wọn sọ̀rọ̀ pé:
Ṣe ni Ndume dide ni aaye rẹ to ti fọwọ leran to si lọ ba Lawan bọwọ ni aaye tirẹ lati ki i ku oriire.
Alaga ajọ LASEMA ṣalaye pe kete ti wọn de sibẹ ni wọn ri i pe ọkó akẹru to tobi to iwọn ogoji ẹsẹ bata to kun fun aṣọ oriṣiriṣi to n gbe lọ ni ijanu ọkọ rẹ ja.
Ni ojo kokandinlogbon osu kesan, odun 2018, Makinde jawe olubori
Láàrín ọ̀sẹ̀ àkọ́kọ́ tí ajakale àrùn náà bẹ silẹ, èèyàn mílíọ̀nù mẹẹdọgbọn lọ jáde láyé, èyí tó burú ju iye àwọn èèyàn ti ogun agbaye àkọ́kọ́ gbẹmi wọn lọ.
Bí ọkùnrin náà ti dákẹ́ gan-an ni olúfẹ́ rẹ̀ yìí jáde láti inú ihò ibi tí ó tí ó sá pa mọ́ sí.
nguyễn chánh thi ( Ọjọ ́ kẹtàlélódún oṣù kejì ọdún 1923 - Ọjọ ́ kẹtàlélódún oṣù kẹfà ọdún 2007 ) jẹ ́ ológun ilẹ ̀ vitenam ( arvn ) .
Inú àwọn tí wọn ń pẹ̀gàn ìbẹ̀rẹ̀ iṣẹ́ yìí yóo dùn, wọn yóo sì rí okùn ìwọ̀n lọ́wọ́ Serubabeli.
Orúkọ ìyá rẹ̀ ni Jedida ọmọ Adaya ará Bosikati.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Yorùbá Homograph: Àmì èdè ló mú káwọn ọ̀rọ̀ yìí ní ìtumọ̀ ọ̀tọ̀ọ̀tọ̀ 13 Ẹrẹ̀nà 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 30 Ìgbé 2020 Ede Yoruba rẹwa pupọ, ko si si ohun ti a ko lee fi ede naa da lara nitori pe o rọrun lati fi mu ko ba aye yi, bi aye ba se n yi.
Bi o tilẹ jẹ pe ko ni itan aarẹ kankan, awọn mọlẹbi rẹ sọ pe aisan iba lo paa.
Ẹ bi í pé, ṣé kò mọ̀ pé wíwá tí mo wá láti gbógun ti ìlú yìí ati láti pa á run kò ṣẹ̀yìn OLUWA?
D'banj's rape accusation: Ẹ wo ìṣẹ̀lẹ̀ nípa ẹ̀sùn ìfipábánilòpọ̀ tí wan fi kan D'banj ní sísẹ̀n tẹ̀lé
Offa Descendant Union: A dupẹ́ lọ́wọ́ àwọn agbófinró tó dóòlà àwọn ọmọ Ọffa lọ́wọ́ ajínigbé
Ní ọjọ́ náà, àwọn ọ̀run yóo parun, gbogbo ẹ̀dá ojú ọ̀run yóo yọ́ ninu iná.
Ṣé eniyan lè sọ amọ̀kòkò di amọ̀?
Ẹlẹ́tàn ni wọ́n, tí wọn ń farahàn bí aposteli Kristi.
Ṣugbọn ìwọ ń lé mi kiri láti pa mí, bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé n kò ṣe ọ́ níbi.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: WAEC: Ìwé àfihàn pé Ààrẹ Buhari ṣèdánwò la fún un Fọ́tò àǹkóò oyún ọmọ ìyá mẹ́ta gbòde kan Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Lábẹ́ odò!
Oríṣun àwòrán, Twitter/Sanwo Olu Àkọlé àwòrán, Akojọpọ esi ayẹwo aarun Covid-19 ni orilẹ-ede Naijiria gẹgẹ bi ajọ NCDC ṣe n kede rẹ.
Ẹ óo sì máa yọ̀ níwájú OLUWA Ọlọrun yín, ati ẹ̀yin ati àwọn ọmọ yín lọkunrin ati lobinrin, ati àwọn iranṣẹkunrin yín, ati àwọn iranṣẹbinrin yín, ati àwọn ọmọ Lefi tí wọ́n wà láàrin ìlú yín, nítorí pé wọn kò ní ìpín ninu ilẹ̀ yín.
Ẹ rí ìdààmú mi, ẹ̀rù bà yín.
"Mo jẹ́ ọkan lara awọn ọdọ Naijiria to nsisẹ wọ oru ọganjọ lati se asọ oke lọsọọ fun awọn onibara mi lowo ti ko gun ni lapa mo si n ta a kaakiri Naijiria.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Pistachio Green Puppy: Àwọn ẹgbẹ́ rẹ̀ jẹ́ aláwọ̀ funfun, tí òun sì jẹ́ aláwọ̀ ewé Ko tan sibẹ o, Onisoro tilu Tomaro, Oba Muhammed Adio Yussuf ati Obanikoro tilu Eko, Oloye Adesoji Obembe naa koro oju si isẹlẹ ọhun.
Kí àwọn ẹrú fi ara wọn sí abẹ́ àṣẹ ọ̀gá wọn ninu ohun gbogbo.
Àwọn apani ṣe iṣẹ́ wọn pé, wọn kò sì dáwọ́ dúró lẹ́yìn tí wọ́n yẹgi fún wọn, wọ́n tún wọ́ òkúu wọn nílẹ̀ bẹ́ẹ̀ náà ni wọ́n sì ń jókòó lé wọn lórí.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ogbomsho shooting, End Sars, End SWAT: Isiaka fi ọmọbìnrin kan àti ìyàwó tó lóyún sínú síl Ki lo ti ṣẹlẹ sẹyin?
7 Nítorí, kíyèsíi, ìwọ kò nílati bẹ̀rù ènìyàn ju Ọlọ́run lọ.
Kò sí àyè fún fíìmù eré ìfẹ ṣíṣe ni Kannywood mọ́ Àlùfàá méjì wà lára àwọn mẹ́rin tó fi ipá bámilòpọ̀"" Ẹ̀rù ogun n bà mí fún ìran Yorùbá -Bode George Ọ̀gọ̀rọ̀ èèyàn lórí ayélujára bú Dalung lórí owó IAAF O ni iru awọn ọna ti ko tọ ti awọn kan n lo lati kowo jẹ ko ni ṣi silẹ ni ijọba oun."
 O tẹsiwaju pe A fẹ ki awọn akọroyin ṣe iṣẹ wọn lai si ibẹru, a si fẹ ran awọn alaabọ ara lọwọ.
Afurasi naa ni ọlọpaa ni idaniloju pe o lọwọ ninu iku ọmọ ẹgbẹ awakọ lorilẹede Naijiria, NURTW, Ganiyu Ayinla, ti inagijẹ rẹ n jẹ Piero ni agbegbe Obalende n'ilu Eko ni ọjọ kẹtalelogun osu kini ọdun 2018.
"Ọsanyintolu ni ""Ni kete ta de sibi isẹlẹ naa, a woye pe ọkunrin kan ti ha sabẹ ile awoku naa, taa si ti bẹrẹ isẹ idoola ẹmi rẹ."
Bí ó ti wí báyìí tán ni mo rí i wí pé láti ẹsẹ̀ mi títí dé ìbàdí, kò sí egungun, kò sí ẹran, kò sí iṣan, kò sì sí ẹ̀jẹ̀ mọ́, gbogbo ibẹ̀ ti yípadà ó ti di òkúta n kò sí lágbára lórí rẹ̀ mọ́.
Oró agbọ́n leè wo àìsàn jẹjẹrẹ ọmú sàn, wo ohun tí wàá lò pọ̀ mọ́ra wọn Mo ṣetán láti fi ẹ̀ṣẹ́ dín dòdò ìyà fún Anthony Joshua- Efe Ajagba Daniel Prude: Ìbòjú tí àwọn ọlọ́pàá New York fi bo ọkunrin ọhun ló ṣe ikú pà á Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Ondo Election 2020: Ẹ wo àwọn olùdíje sípò gómìnà nípínlẹ̀ Ondo tó takò bàbá ìsàlẹ̀26 Owewe 2020 Fídíò, Wole Soyinka sọ ìdí tó fi ni òun a fi màálù Fulani ṣe súyà fáwọn èèyàn abúlé23 Owewe 2020 Kano-Niger rail line: PDP ní àìmèyí tó kàn n'ìgbèsẹ̀ ìjọba láti ná $1.
Iwadii si ti fihan pe orilẹede Naijiria lo se ipo keji, lẹyin orilẹede Jamaica, ti isẹlẹ gbigbe ọmọ Ọba fun Ọsun ti maa n waye.
Ọba alaye ni mi, emi kii se oloselu, o si y ki n lee sọ ootọ ọrọ sita.
Àwọn ará Filistia fi oriṣa wọn sílẹ̀ nígbà tí wọn ń sá lọ, Dafidi sì pàṣẹ pé kí wọ́n sun wọ́n níná.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, EndSars, EndSwat Protest: Òbí agbábọ̀ọ̀lù Gbenga Tiamiyu Kaka àtàwọn míì tí ọlapàá pa sọ̀r Awọn ọmọ Naijiria to n dije: Ni ipele ijọba apapọ, 1) Ọgbẹni Oye Owolewa: Ẹni yii ti baba rẹ jẹ ọmọ ipinlẹ Kwara, ati ti iya rẹ wa lati ipinlẹ Oyo, n du ipo (ti ko nilo ibo) sile igbimọ asoju-sofin Onimọ nipa oogun oyinbo ṣíṣe ni Owolewa, o si ni iwe ẹri Ph.
Nigba ti o n ba awọn akoroyin sọrọ, alaga ajọ to n mojuto abo loju popo Robert Sumwalt ni ''iselẹ ọhun jẹ eyi to buru ju lọ nipa iye ẹmi to ku ati wi pe awọn ko ti ri iru ijamba ọkọ bee lati ọdun 2009.
Nígbà tí àwọn ará Jabeṣi Gileadi gbọ́ ohun tí àwọn ará Filistia ṣe sí Saulu, 
Laipẹ yi o si wa si Naijiria nibi to ti ni ohun n wa iyawo.
 lápàpọ ̀ wọn jùmọ ̀ maa ń dẹ ́ kun àwọn wọ ́ nwọ ́ n ojú-ara pẹ ̀ lú àwọn àjẹsára lòdì sí irúfẹ ́ 4 àti 9 hpv tí o ńṣe ìdábòbò ńlá .
Ìwádìí yìí ló gbée dé agbègbè tí agbami ìwà ọ̀daràn ti ń wáyé ní orílẹ̀èdè Nàíjíríà, tó sì se àkọsílẹ̀ ìwà ọ̀daràn tó ń tàn kálẹ̀ bíi ọ̀wàrà òjò, èyí tó ń ba ayé àwọn ọ̀dọ́ jẹ́ jákèjádò ẹkùn ìwọ̀ òòrùn Afrika.
Àkọlé àwòrán, Ibudo ayewo fawọn akẹkọọ imọ iṣegun oyinbo ni Fasiti Pọta.
Yó wá rí ṣàbìlà-sabila gbúgun-gbùngun bíẹnipé wọn kò f’ẹ̀lẹ̀ ṣẹ̀dá rẹ̀ bí àwọn ìyókù.
Ẹ gbọdọ̀ pa ọjọ́ ìsinmi mi mọ́, kí ẹ sì fi ọ̀wọ̀ wọ ilé mímọ́ mi.
Oríṣun àwòrán, OTHER Àkọlé àwòrán, Dammy Krane ti orukọ rẹ n jẹ Johnson Oyindamola ni wọn mu lọdun 2017 fun ẹsun lilo ATM ti kii se ti e lati fi wọ ọkọ baalu.
Gẹ̀ẹ́sì gbẹ́sẹ̀ lé ₦82bn owó Abacha Ọba Adesoji Aderemi, Ọọ̀ni Ifẹ̀ tó gba ipò ọba mọ́ tòṣèlú Àbẹ́wò ọlọ́jọ́ mẹ́ta Trump sí UK nínú àwòrán Ṣugbọn iwadii fidi rẹ mu lẹ pe ile igbimọ aṣofin agba kẹjọ to n ko gba sile lonii lo ṣaṣeyọri julọ ninu itan eto oṣelu orilẹ-ede Naijiria.
Oríṣun àwòrán, Baba wande/aluwe/Elẹṣọ/baba suwe/ suwe/ Inst Àkọlé àwòrán, Ni ọdun 1988 ni sinima agbelewo akọkọ jade lorilẹede Naijiria Ere sinima agbelewo ede Yoruba ti gbẹrẹgẹjigẹ di igi alọye, ti owo rẹ si ti to ẹgbẹlẹgbẹ biliọnu naira bayii.
Ninu abajade esi ibo aarẹ ti
Akowe gbogboogbo fun ẹgbẹ osisẹ naa, Ọmọwe Peter Ozo-Eson lo fi ọrọ yii lede fun awọn oniroyin ni ọjọ Isẹgun ni Abuja to jẹ olu-ilu orilẹ-ede Naijiria.
Bi wọn ṣe n gbiyanju ati na papa bora ni opo ta sinu gọta ti wọn si fẹsun kan pe awọn janduku ọhun sọ ina si epo to ta silẹ lati le awọn agbofinro danu ki wọn ma baa mu wọn.
Ṣugbọn àwọn ọmọ Bẹnjamini kò lé àwọn ará Jebusi tí wọn ń gbé Jerusalẹmu jáde; láti ìgbà náà ni àwọn ará Jebusi ti ń bá àwọn ọmọ Bẹnjamini gbé ní Jerusalẹmu títí di òní olónìí.
Awọn ọdọ ilu Ibadan tu sita lọpọ yanturu ya bo olu ileeṣẹ ọlọpaa ni Ẹlẹyẹle lati fi ẹhonu wọn han lori iṣẹlẹ naa.
Ó sàn fún ọ kí ọ̀kan ninu àwọn ẹ̀yà ara rẹ ó ṣègbé jù kí gbogbo ara rẹ lọ sí ọ̀run àpáàdì lọ.
 Ó fi ojú kan ọmọ rè , obama , ní ìgbàkan péré- ní ìgbà tí oní tòhún pé ọmọ ọdún méwàá .
Àkọlé àwòrán, LASEMA ni eto idoola ẹmi yoo pari ni ibudo naa ni ọjọbọ Bakan naa ni ọga agba LASEMA naa tun ṣalaye pe ajọ naa ko tii lee sọ iye awọn to fara kaaṣa naa lapapọ ṣugbọn ireti wa pe orukọ awọn to wa ninu iṣẹlẹ naa yoo jade laipẹ.
Ẹni to bori: Uganda Ìpele to kangun si aṣakagba South Africa vs Madagascar.
 ilè-ìtayò ni ó wá yí padà sí ilé-ìtayò , ìgbà tí ó yá , wón so ó di ilé-ita .
Àmọ́ àwọn onímọ̀ isegun, lásìkò tí wọn ń rọ ijọba láti mase gbé ẹsẹ kúrò lórí òfin tó fi dé kata-kara ọtí lile, tún tọkasi pé ọtí amuju máa ń mú ki èròjà tó ń dáàbò bo agọ̀ ara di alailagbara ni, tó sì leè ni ipa lórí bí èèyàn ṣe ń mi.
Fulani kò leè dúró, táa bá lo ohun ta jogún lọ́dọ̀ àwọn bàbá wa - Sunday Igboho Fayemi fojú Alufa to fipa bá ọmọde lòpọ̀ síta l'Ekiti 'El-Zakzaky lè má láńfààní láti lọ gba ìtọ́jú mọ́ lókè òkun' Ọ̀pọ̀ èèyàn bẹnu ẹ̀tẹ́ lu Mercy Aigbe lórí bó ṣe ki Adeniyi Johnson Àjẹ́ àti Aṣẹ́wó ní ìyá Rainbow - Òjòpagogo N30,000 ni mo gbà fún orí, ọwọ́ àti ẹran ara wòlíì Bosede - Kayeefi Ṣoyinka ni ọpọ igba lawọn eeyan maa n lo orukọ ati fọto oun fun iroyin lori ayelujara, nigba t'oun o tiẹ sọrọ kankan.
Ẹni ti yoo ba wọ ọkọ oju omi naa ni lati lọ si ori ẹrọ ikanni ayelujara wọn lati beere fun tikẹẹti.
Oriṣiriṣi ọja ni eeyan le ta, eyi ti orí ba ti pe ni ọna ẹni ni aje fi n ba ni gbe ninu ile.
Pasitọ Ẹọlawọle ṣalaye fun ile ẹjs pe oun ko jẹbi ẹsun naa ki ile ẹjs naa to ni gbogbo ẹri to wa niwaju ile ẹjọ naa lati bii ọdun mẹrin ti igbẹjs naa ti bẹrẹ lo fihan pe pasitọ Kọlawọle jẹbi ẹsun pipa Ọlaniyi.
Ijoba apapo ti ni adari orile
Yatọ si pe alatako rẹ lẹgbẹ oṣelu PDP, Eyitayọ Jẹgẹdẹ n pe ẹjọ kotẹmilọrun ta ko o nile ẹjọ bayii lori esi idibo naa, ogun abẹle naa n ba Akeredolu finra pẹlu bii ọkan lara awsn ti wọn jijọ dije fun aṣia ẹgbẹ oṣelu APC fun idibo gomina naa, Ọmọwe Nathaniel Adojutẹlẹgan ti pe e lẹjọ nile ẹjọ giga apapọ kan nilu Abuja pe ọna ti wọn fi yan an lati di aṣia ẹgbẹ naa ko ba ofin mu ati pe o tako ilakalẹ ofin idibo apapọ ilẹẹwa, Electoral Acts tọdun 2010.
"Oríṣun àwòrán, others ""Awọn agbébọn yii n ji eeyan gbe, paapaa awọn ọmọde ati obinrin, ti wọn si n fi tipa ba wọn lopọ."
Wo ohun tó ṣẹlẹ̀ sí àwọn ọba tó kọ ifá sílẹ̀ gbé Bíbélì àti Kùránì O ni kete ti awọn ọkọ bẹrẹ si ni sun siwaju pada naa loun tẹsiwaju.
Kí olukuluku àwọn ọmọ ogun wọ inú ìlú náà lọ tààrà.
    “Ọ̀nà Igbo Irúnmọlẹ̀ ni ọ̀nà Igbó Elégbèje.
7 miliọnu ọmọ Naijiria to jẹ oniṣowo ni yoo lanfani ati gba lara owo yii gẹgẹ bi iroyin ti BBC wadii.
29 Owewe 2020 Olukọ wa lonii ni Niyi Osunlolu, oun si ni yoo maa kọ wa nipa itumọ silebu.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Bayelsa, Kogi Election: APC ní yóò jáwe olúbori 1 Owewe 2019 Oríṣun àwòrán, @tinubu Àkọlé àwòrán, Òṣùsù ọwọ̀ ni a o fi ọ̀rọ̀ náà ṣe láti gbá gbogbo ìdọti àtẹyìn wá dánu láti jáwé olúbori ni Kogi Olóri ẹgbẹ́ òṣèlú All Progressives Congress lórilẹ̀-èdè Nàìjíríà Asiwaju Bola Ahmed Tinubu ní ẹgbẹ́ òṣèlú APC ni yóò fẹ̀yìn gbogbo ẹgb míràn janlẹ̀ nínú ìdìbò gómǹà ti yóò wáyé ni Bayelsa àti Kogi.
Ẹwẹ, o ti gba bọọlu sinu awọn fun Liverpool ni igba mẹrindinlogun lasiko mọkandinlọgbọn to ti kopa ninu idije ni saa yii.
O ní ọjọ́ ìwájú rẹ̀ nínú iṣẹ́ ọmọ ogun dára gidi sùgbọ́n ikú ṣi lọ́wọ́ iṣẹ́.
Mo wí fún ọ, OLUWA, pé, “Ìwọ ni Oluwa mi;ìwọ nìkan ni orísun ire mi.
Òhun tí o sẹlẹ nigba ti Buhari lọ China Èrè ìpàdé Commonwealth fún Nàìjíríà.
Eden Hazard wẹ̀ 'yan kàì-kàin níbi tí Chelsea ti na Brighton ní 1-2
Bi anfaani ara awọn eso ati ewebẹ naa se lọ ree: Carrot: Ti eeyan ba ra Carrot, to fọọ, ko yẹ ki a jẹ bẹẹ, amọ o yẹ ka se lori ina fun igba ranpẹ, ki eroja Vitamin A to wa ninu rẹ lee maa jade si ẹnu wa, ba ba se n jẹẹ.
Ọga ọlọpaa, Badmos Dolapo kede isẹlẹ naa loju opo Twitter rẹ sọ pe, lati igba ti fọnran iwa ika yii ti lu ayelujara pa, eyi to n ṣafihan bi obinrin kan ṣe na ọmọdekunrin yii, lawọn ti bẹrẹ si ni wa a kiri.
Michelle Obama: Ààrẹ Trump kò yẹ nípò ààrẹ fún Amẹ́ríkà
'Ọwọ́ wa tún tẹ ojúkòó tí wọ́n tí ń bá àwọn ọmọdékùnrin lò pọ̀ ní Daura' Lara awọn ere agbelewo ti Iya Rainbow ti kopa ni Back to Africa, lọdun 1997, Lagidigba, to jade lọdun 2000, Kootu Ọlọrun, lọdun 2007, Taiwo Taiwo apa kini ati apa keji to jade lọdun 2008, Oga Bolaji to jade lọdun 2018, ati bẹẹ bẹẹ lọ.
 látàrív ìdí èyí , ó kópa nínú ìdániẹ ́ kọ ̀ ọ ́ tí fásitì madinah , ẹ ̀ ka ti ìpínlẹ ̀ kánò gbé kalẹ ̀ ní àsìkò ọdún1990s .
 awọn akojọ aṣayan ti ounjẹ ounjẹ ni , ṣugbọn kii ṣe opin si hamburgers , faranse fries ati awọn aja gbigbona .
Ọlá àwọn onímọ̀jìnlẹ̀ ọ̀gbìn tí ikọ̀ wọn ń bẹ nínú ọgbà náà ni àwọn òdòdó náà ń jẹ.
Lásìkò ti Wike náà sí orí ilẹ̀ náà, sàlàyé pé àwọn jare bọ ti àwọn Musulumi si ti pe ẹjọ́ kòtẹmilọ́rùn Ǹkan to dáju lóri ọ̀rọ̀ náà ni pé àwọn musulumi maa n lo ill náà láti gbàdúrà , sùgbán nigba kúùgbà ti wan ba ti fi ìpill ilé lélẹ nibẹ̀, ìjọba yóò wa láti tu gbogbo rẹ̀ ká.
Ìwọ tí ò ń pa àwọn wolii, tí ò ń sọ àwọn tí a rán sí ọ ní òkúta pa!
Eyi ti o ba wu wọn ni wọn lee ṣe gẹgẹ bi o ba ṣe dara ninu ọkan wọn.
onigbagbo ni ipinle Eko (Lagos State Christian Association of Nigeria).
  “Egbe oselu PDP ko ni fe mu ebi mo ipolongo idibo lodun 2019.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Iyawo Aarẹ Ilẹ Faranse, Brigitte Macron to jẹ olukọ rẹ Emmanuel Macron nigbati aarẹ naa wa ni ọmọ ọdun marundinlogun (15) , fi ọdun mẹrindinlogun (24) ju ọkọ rẹ lọ.
Moroccan Journalist: Hajar Raissouni de èrò ẹwọn lórí ẹ̀sùn àgbèrè àti oyún ṣíṣẹ́
Obinrin kan tí ń jẹ́ Mata bá gbà á lálejò.
Mo rí àwọn ẹni ibi tí a sin sí ibojì.
" Ilorin gbàlejò Wizkid, àwọn olólùfẹ́ rẹ̀ fẹ́ ẹ̀ gbée lójú agbo Ọkọ̀ agbépo tó da epo nù fa súnkẹrẹ-fàkẹrẹ lòpópónà márosẹ̀ Eko sí Ibadan Ìjọba Buhari kò tíì fi akọ̀ròyìn kankan sátìmọ́lé láti ọdún 2015 - Garba Shehu Èyí ni bí wọ́n ṣe n dìbò yan Póópù tuntun nínú ìjọ Àgùdà Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ǹkan tí ẹ̀mí mímọ́ fi hàn mí kí n tó bẹ̀rẹ̀ orin ìfèdèfọ̀ rèé- Testimony Jaga Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Akor salaye pe emi ni mo ni oko yii."
Ẹ̀wẹ̀, àdińkù nínú súgà inú ẹ̀jẹ̀ yìí lo máá n fa ki ara maa hù Àsìkò yìí ni ebi a maa pa eniyan gan-an Ó ṣeéṣe kí ki ó máa ni ori fifọ, ojú síṣú, kí èbi maa gbe èniyan tabi ki ẹnu eniyan maa rùn.
Òbúkọ náà yóo sì fi orí rẹ̀ ru gbogbo àìṣedéédé wọn, títí tí ẹni náà yóo fi fà á dé ibi tí eniyan kì í gbé, ibẹ̀ ni yóo ti sọ ọ́ sílẹ̀ kí ó lè wọ inú aṣálẹ̀ lọ.
Tọpẹ Adebayọ: Isẹ́ Tíátà tí mò ń se ti tó mi jẹun
Òkú ọmọ tuntun pòórá nílé ìgbókúpamọ́sí nílùú Akurẹ Èyí ni ìdí tí àwọn dókítà fi ń yan iṣẹ́lódì ní ilé ìwòsàn LUTH Aipẹ yii ni Ile Igbimọ Asofin Agba fiwe pe Minisita fun Eto Ilera, Ọjọgbọn Isaac Adewọle, ti wọn si ni ko ṣalaye idi ti nkan ko fi lọ deede ni awọn ile iwosan ijọba apapọ to wa ni orilẹede yii bi ti LUTH.
Nítorí náà Baba-onírùngbọ̀n-yẹ́úkẹ́ mi ọ̀wọ̀n, mo dúpẹ́ lọ́wọ́ rẹ gidigidi.
O jẹwọ pe ko rọrun fun oun nigba ti oun pinnu lati du ipo aarẹ lọdun 2014.
Mo fẹ́ kí tajá tẹran jákèjádò ilẹ̀ yìí lónìí mú u kúrò lọ́kàn wọn bí wọ́n bá ní èrò wí pé nítorí Oyíndayépò kú, iná ìfé wa kú, àti nítorí Oyíndayépọ̀ ṣe aláìsí, òṣùpá ilé wa wọ òòkùn, irọ́ mà ni o, kábíyèsí, irọ́ mà ni o, bí Oyíndayépọ̀ bá kú Oyíndayépọ̀ ma sì ń bẹ o.
Adele aare orile ede Naijiria ojogbon Yemi Osinbajo ti gba ise lowo adari ile-ise otelemuye (State Security Service SSS), Lawal Daura.
Níbẹ̀ ni ọpọlọpọ àwọn aláìsàn ti máa ń jókòó: àwọn afọ́jú, àwọn arọ, ati àwọn tí ó ní àrùn ẹ̀gbà.
O ni ohun ti kilọ fawọn ọmọ Naijiria paapa awọn to kopa ninu iwọde lati tako ijọba PDP nigba ti wọn fi owo kun owo epo bẹntiroo Oríṣun àwòrán, Others Awọn ọmọ Naijiria ti n ke irora lori bi iroyin ṣe gbode pe alekun ti ba iye owo ti wọn yoo maa san lati fi ra jala epo bẹntiroo.
Ṣùgbọ́n tí ìwọ Alákọ̀wé Yoòbá ò bá ṣe bẹ́ẹ̀, ajẹ́pé mo rí oúnjẹ ọ̀fẹ́ jẹ nìyẹn nítorí ìwọ ni wàá tọwọ́ bọ àpò o”.
Ìdí táwọn èèyàn fi gbádún ìtàkurọ̀sọ àwọn ìgbákejì Trump àti Biden ju tiwọn lọ rèé Ènìyàn 8, ilé 25 ilé ìtajà 16 àti àwọn ǹkan mírà lo bá ìṣẹ̀ll iná naa rìn.
Ẹ tẹ̀lé e, ẹ bá a wọ inú ilé tí ó bá wọ̀.
Igba to gbe nkan sori ikansira ẹni facebook gbẹyin ni lọjọ kẹrin, oṣu kẹta, ọdun 2013.
Àwọn eniyan inú rẹ̀ ń sọkún ní ilẹ̀ẹ́lẹ̀,igbe àwọn ará Jerusalẹmu sì ta sókè.
26 Bélú 2020 Fídíò, International Day for Elimination of Violence against Women: Àlùfáà Joel Olugbenga: Bíbélì kò ní kéèyàn dúró títí ọkọ rẹ̀ yóò fi lù ú pa25 Bélú 2020 Covid 19 vacine updates: America kan sárá si Dókítà Ogbuagbu, ọmọ Nàìjíríà tó ṣàwárí abẹ́rẹ́ àjẹsára COVID-19 àkọ́kọ́25 Bélú 2020 Fídíò, Akọ́mọlédè àti Àṣà lórí BBC Yorùbá: Kọ́ síi nípa iṣẹ́ tí oúnjẹ ń ṣe lára níbí24 Bélú 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Àwọn alantakun to tobi pupọ jẹ ohun iṣere fun Phillipe Gillet to jẹ ọmọ ilẹ̀ Faranse.
O kọkọ fi fidio sita bo ṣe sun ẹkun iyawo nibi imana tawọn ọrẹ rẹ si n rọ ọ pe ẹkun ayọ lo n sun ati ọrọ to sọ bii ifọrọwanilẹnuwo nipa ọkọ rẹ.
A ti bẹ̀rẹ̀ ìwádìí lórí ibì tí owó tí àwọn adigunjalẹ̀ gbé ní banki Okeho wọ̀lẹ̀ sí- Ọlọ́pàá Buruji Kashamu jẹ́ ènìyàn tó nífẹ̀ aráàlú- Gómínà Dapo Abiodun Baba Obasanjọ kò ní àrùn Coronavirus- NCDC Ìdí rèé tí igbákejì Gómìnà Ondo Agboola Ajayi tún ṣe fi ẹgbẹ́ òṣèlú PDP sílẹ̀ Kí ló mú Obasanjo ti ilẹ̀kùn mọ́ ẹbí, òṣìṣẹ́, ojúlùmọ̀ ní ibi òkú àna rẹ̀?
Mo mọ àwọn tèmi, àwọn tèmi náà sì mọ̀ mí, 
Ẹwọn ọgbọn ọjọ lo fi jura.
 yàrá irinṣẹ ́ rẹ ̀ gangan tó àlàjá kan nínú 68 cm ( 27in ) tí gígùn ìfojúsí rẹ ̀ sì jẹ ́ 10.
Yoruba Films: Àwọn òṣèré tó bímọ s'Amẹrika lọ́dún 2019 rèé kí Trump tó f'òfin dèé
Tunde Idiagbon, ọ̀gágun kògbagbẹ̀rẹ́ tó ní ẹ̀ẹ̀kan lóṣù ló yẹ kí ológun máa rẹ́rìín Oluwo yí ìpinnu padà,Telu lóun yóò tẹlé àṣẹ lọ rọọ́kún nílé ṣùgbọ́n.
Lẹka awọn oniṣowo aṣọ, to fi mọ tita oogun apakokoro ati bata , awọn ọmọ China ko gbẹyin.
Ọkàn mi kò gbà á,àánú yín a máa ṣe mí.
Rọ òjò sílẹ̀, ìwọ ọ̀run,kí ojú ọ̀run rọ̀jò òdodo sílẹ̀.
Aregbesola: Ó se bẹbẹ ní ọdún mẹ́jọ tó fi sèjọba l‘Ọ́sun
Manchester United lo bori ninu abala yii pẹlu ami ayo mẹfa si marun, ti wọn si gba ife ẹyẹ naa.
Ẹ ní mo ní àwọn mààlúù, àwọn kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́, agbo ẹran, àwọn iranṣẹkunrin ati àwọn iranṣẹbinrin.
Oríṣun àwòrán, The LadyMOTARA Arabinrin Motara to n gbe niluu Ibadan yii fi sita pẹlu alaye pe oun kan n mu ọmọ naa ṣere ni ati pe oun pada fun un lowo.
Ó fi ojúlówó wúrà ṣe ìtẹ́ àánú, gígùn rẹ̀ jẹ́ igbọnwọ meji ààbọ̀, fífẹ̀ rẹ̀ sì jẹ́ igbọnwọ kan ààbọ̀.
Ọpọlọpọ ọdọ lo n darapọ mọ ẹgbẹ naa lati le mọ boya wọn fi orukọ wọn sita.
Kí Ọlọrun sọ ìdílé Jafẹti di pupọ,kí ó máa gbé ninu àgọ́ Ṣemu,ẹrú rẹ̀ ni Kenaani yóo máa ṣe.
Ọkan lara awọn oníbàràá rẹ, lo pariwo sita lori ayelujara l'oṣu Kẹrin pe, iṣẹ abẹ ti Anu ṣe si idi oun ti da aisan si oun lara.
 wọn á pa adìyẹ ìrànà , wọn á sì máa tu ìyẹ ́ rẹ bí wọ ́ n ṣe ń gbé òkú rẹ ̀ lọ .
Nígbà tí ó rí Peteru ati Johanu tí wọ́n fẹ́ wọ inú Tẹmpili, ó ní kí wọ́n ta òun lọ́rẹ.
lẹ́yìn náà mo ko yín wá sí ilẹ̀ àwọn ará Amori tí wọn ń gbé òdìkejì odò Jọdani.
Ajọ to n ri si okowo ati ile iṣẹ nipinlẹ Eko ni tirẹ bu ẹnu ẹtẹ lu bi ijọba ko ṣe wa nnkan ṣe si bi ile iṣẹ mọnamọna ti n bu owo tawọn eeyan n san lai lo ẹrọ mita.
Lẹ́yìn náà, ó mú ninu èso ilẹ̀ náà, ó gbìn ín sí ilẹ̀ kan tí ó lọ́ràá, ní ẹ̀bá odò.
Ṣe ọpa aṣẹ gangan ni wọn ji gba abi gbarọgudu?
Nígbà tí mo wo ààrin àwọn eniyan ati àwọn alufaa, n kò rí ọmọ Lefi kankan níbẹ̀.
Gbogbo ohun tí o bá rí ni o gbọdọ̀ sọ fún àwọn ọmọ Israẹli.
theophilus yakubu danjuma gcon fss psc ( ojoibi 9 december 1938 ) je ogagun to ti feyinti , oloselu ati onisowo ara naijiria lati eya jukun .
Nígbà ti ara mi kò sì gbà á mọ́ mo tọrọ àyè ní òde ọ̀run kí n baà wáá fi ojú gán-ánní rẹ.
ni won wa nidii ikolu naa.
Joṣua yan ẹgbaa mẹẹdogun (30,000) akikanju ọmọ ogun, ó rán wọn jáde ní alẹ́.
Bakan naa ni minisita feto ilera tun kede rẹ pe awọn onimọ ijinlẹ nipa kokoro aifojuri latawọn ileewosan nla LUTH, ibudo iwadi ajakalẹ arun ni fasiti Redeemers ni Ede ati ibudo iwadi nipa iṣegun oyinbo, NIMR to wa nilu Eko ni wọn pawọ pọ lati ṣawari ilana kan fun itọpinpin arun Coronavirus eyi ti oyinbo n pe ni 'genome sequencing' O ni nipasẹiwadii tuntun yii, wọn ti fi idi rẹ mulẹ pe irufẹ kokoro arun Coronavirus to n ja kalẹ ni orilẹede Italy ati ilu Wuhan lorilẹede China.
Nígbà tí Paulu ti sọ báyìí tán, àwọn Juu túká, wọ́n ń bá ara wọn jiyàn kíkankíkan.
10 bn Ileeṣẹ ijọba to n risi eto aabo - N840.
“Ṣugbọn ẹni tí ó bá gbọ́ ọ̀rọ̀ mi yìí, tí kò bá fi ṣe ìwà hù, ó dàbí òmùgọ̀ eniyan kan tí ó kọ́ ilé rẹ̀ sórí iyanrìn.
Wò mi, ọ̀rẹ̀ mi, níwọ̀n ìgbà tí ó sì ti jẹ́ pé bàbá mi nìkan ni ó kù pẹ̀lú ẹbọra kékeré inú ọ̀gán sí igbó burúkú yìí ńkọ́, àtikọjá bàbá mi kò ní ṣàì jẹ́ ìṣporo.
Ọba pàṣẹ pé kí àwọn ọmọ Lefi dúró ninu ilé OLUWA pẹlu ohun èlò orin bíi kimbali, hapu ati dùùrù, gẹ́gẹ́ bí i àṣẹ tí OLUWA pa, láti ẹnu Dafidi ati wolii Gadi tí í ṣe aríran ọba, ati wolii Natani.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Só lè jẹ búrẹ́dì tí wọ́n fi Aáyán se?
- Obasanjo gbarata Ìbẹ̀rù bá olùgbé Eko torí àwọn ọ̀dọ́ Òkè Ọya tó dìhámọ́ra Olùkọ́ mi ń bá mi lòpọ̀ kí ń le yege ìdánwò WAEC - Akẹ́kọ̀ọ́ l‘Ogun Olólùfẹ PDP 18 kú nínú ìjàmbá ọkọ̀ lásìkò tí wọn ń lọ pàdé gómìnà Iyabo Ojo ṣílé, Toyin Abraham fẹ́ ṣílé iṣẹ́ f'ọmọ, àtàwọn nǹkan míràn lágbo òṣéré Wo fọ́tò àrà MC Oluomo, Pasuma àtàwọn òṣèré tíátà míì níbi ìṣílé Iyabo OjoWo ìyá ọlọ́mọ mẹ́ta tó ti pé ọdún 48 tó ń ṣe ìdánwò WAEC, kó le di nọ́ọ́sí Ninu ọrọ to kọ soju opo Instagram rẹ naa ni Lizzy tun ti fi imọran sọwọ sawọn omidan ti ko tii lọkọ pe, eyi ti ko ba lee ṣe wahala ina dida fun ọkọ rẹ, to jẹ pe ọkọ burẹdi ati tii lo fẹ fẹ, ko sare lọ fẹ oyinbo ni o, ko maa da laba lati fẹ ọmọ Ibadan rara.
Agiripa wá sọ fún Fẹstu pé, “À bá dá ọkunrin yìí sílẹ̀ bí kò bá jẹ́ pé ó ti ní kí á gbé ẹjọ́ òun lọ siwaju Kesari.
ohun pàtàkì kan tí ó ya fíìmù yorùbá sọ ́ tọ ̀ ní èdè àmúlò .
Ni aipẹ yii ni okiki kan pe ayederu iwe ẹri agunbanirọ ni minisita feto iṣuna fi wọ iṣẹ minisita; lẹyin o rẹyin ni arabinrin naa kọwe fipo silẹ lẹyin to kọ lẹta si aarẹ pe 'aimọ lo ṣe oun nipa ọrsọiwe ẹri naa nitori awọn ti oun fẹyinti lati ba oun gba iwe ẹri naa ni wọn gbẹyin b'ẹbọ jẹ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ondo Mortuary: Pàǹtí ni òṣìṣẹ́ Mọ́ṣúárì dà sínú pósí dípò òkú ọmọ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Ondo Mortuary: Pàǹtí ni òṣìṣẹ́ Mọ́ṣúárì dà sínú pósí dípò òkú ọmọ 28 Òkùdu 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 29 Òkùdu 2019 Eto Ìròyìn Kàyééfì ti BBC Yorùbá ti oṣù yìí balẹ̀ bàgẹ̀ lónìí.
'Dokita ilé ìwòsàn ló gba ẹsẹ̀ lọ́wọ́ mi' 'Ikàn táa fi ń ṣe pósí, òun náà la fi ń ṣe agbọ̀n fún ìgbéyàwó' Ọgbẹni Omogbolahan Damola to jẹ ọkọ Dorcas ṣalaye fun BBC bi ọrọ ifọju iyawo rẹ ṣe bẹrẹ ko to Bakan naa ni BBC tun kan si oniṣegun oyinbo to jẹ akọṣẹmọṣẹ nipa itọju oju ṣalaye nipa ayẹwo nipa adakẹ-fọju-ẹni Glaucoma.
 O tun sọọ siwaju sii pe, awọn ọmọ orilẹede Naijiria kan a tilẹ tun maa fi ẹrọ ibanisọrọ wọn ra ipapanu pizza lati ilu London.
Abilekọ Obama ninu ọrọ ti ẹ ni aworan rẹ ti Sherald ya yoo jẹ ohun maleegbagbe ati imoriwu fun awọn obinrin to jẹ alawọ dudu.
Ó bínú sí àwọn ọ̀rẹ́ Jobu mẹtẹẹta pẹlu, nítorí pé wọn kò mọ èsì tí wọ́n lè fún Jobu mọ́, bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé wọ́n dá a lẹ́bi.
Shehu Shagari; Àwọn ohun tó yẹ kí o mọ̀ nípa olóògbé
ile -igbimọ asofin agba Bukola Saraki, ti gbosuba fun awon osise orile ede yii fun iwa
Nigba ti o n ba awọn oniroyin lẹyin ilanilọyẹ yii, Aarẹ ẹgbẹ BAI, Ọgbẹni Temitọpẹ Muṣowo, onimọ SDGs, sọ pe ipolongo yii ṣe pataki lati tubọ la awọn ara ilu lọyẹ pe ilanilọyẹ yii ko gbọdọ jẹ ohun ti yoo maa waye lọdọọdun nikan.
Oríṣun àwòrán, Facebook/Olubadan of Ibadan Mogaji ilu Ibadan ṣalaye pe lati ọjọ ti ijoba ti tọwọ bọ ọrọ awọn lọbalọba niluu lbadan lọrọ naa ko ti lojutu mọ.
Nítorí ẹni tí ó bá fẹ́ràn ẹnìkejì ti pa gbogbo òfin mọ́.
O óo fún Eleasari alufaa, yóo mú un lọ sí ẹ̀yìn ibùdó, wọn óo sì pa á níbẹ̀ níṣojú rẹ̀.
Bi eto idibo gomina ati  ile igbimo asofin ni  ipinle Oyo se n lọ pẹrẹu, ti awo osise ajo
Ikinlo ideru baniAwon olopaa yinbo lati fi se ikinlo ni eyi ti o lo taara si aarin awon eniyan ti o si seku pa eniyan meji.
Ọ̀pọ̀ àwọn budo idibo ti BBC ṣe abẹwo si fi han pé àwọn òṣìṣẹ́ elétò ìdìbò kò till yoju tí àwọn janduku àti ẹru ikú àwọn olṣelu si ń le àwọn olùdíbo àti àwọn aṣojú ẹgbẹ́ òṣelú dànù Ojọgbọ́n Sheu Risqua tó jẹ ọga INEC ní ìpínlẹ̀ Kano sàlàyé pé gbogbo ǹkan to ṣẹ̀lẹ̀ páta ni àwọn mọ pàápàá jùlọ bi àwọn janduku ṣe da gbogbo nkan ru, sùgbọ́n àwọn ati ajọ eléto ààbo ń fikulukun láti yanju gbogbo rẹ Baṣọ̀run Gáà, tó yan ọba mẹ́rin, pa ọba mẹ́rin àmọ́ ọba karùn-ún ló pa á Èmi ṣì ni Gómìnà ìpínlẹ̀ Ọṣun-Oyetọla Ní Benue, ọga àjọ INEC Nentawe Yilwatda sàlàye fun BBC pé lẹ́yìn ti wọn pín gbogbo òhun elò ìdìbò tán ni ibudo idibo Ijoba ibilẹ Ukum ní àwọn janduku dé ti wọn bẹ̀rẹ̀ si ni dàbọn bolẹ.
 ní ti oyè tó kù nílùú , o ní agbára tí wọn fún ìlú kọ ̀ ọ ̀ kan láti fi olóyè sílẹ ̀ .
ede Naijiria , ni eyi ti, yoo tun jẹ ki ibasepo to mọnyan lori wa laarin orile ede
Oríṣun àwòrán, Olamide O fikun pe, ni kete ti awọn ọlọpa naa de pẹlu ọga agba ọlọpa to n dari agọ ọlọpa to wa ni Sango nilu Ibadan, ni awọn adigunjale ọhun fẹsẹ fẹ.
Àwọn ọmọ kinniun a máa ṣe aláìní,ebi a sì máa pa wọ́n;ṣugbọn àwọn tí wọ́n bá ń wá OLUWAkò ní ṣe aláìní ohun rere kankan.
"kii ṣe ti ka kan maa ra gbogbo agbaye fun obinrin bikoṣe mimu inu obinrin dun ati fifun un ni ifọkanbalẹ ju ẹni to ni gbogbo nkan laye lọ""."
Kò ní í gbàgbé majẹmu rẹ̀ títí lae,àní àwọn ohun tí ó ti pa láṣẹ láti ṣe fún ẹgbẹẹgbẹrun ìran,
àfi Kalebu ọmọ Jefune ni yóo rí i.
- Sanwoolu Ijọba ipinlẹ Eko ti ni oun ko lọwọ ninu idaru to waye nibi iwọde EndSARS to waye ni agbegbe Alausa ipinlẹ Eko.
Fasiti Abuja to jẹ ti olu ilu Naijiria ni Ebuka ti kọ ẹkọ nipa amofin to si tun lọ sile iwe awọn akọṣẹmọṣẹ lori ofin ni Bwari ni Abuja kan naa.
 kí ó tó di mínísítà , Ó jẹ ́ alàkóso yunifásítì ìlú Ìbàdàn ati Ààrẹ àwọn àjo Áfíríka fún iwadi àti ikẹ ́ kọ ́ àìsàn jẹjẹrẹ .
Bí wọ́n ti ń kúrò ní ààfin ni ọmọ-ọ̀dọ̀ yìí tí wọ ilé ìṣúra lọ tí ó bá wa kó ẹrù wa.
 orúkọ áílándì ní púẹ ́ rtò ríkò , tí orúkọ ìlú s ̀ i jẹ san juań .
Oluwo wá ṣe ikilọ pé arun Coronavirus kò gbọ́dọ̀ gbilẹ ni Nàìjíríà gẹgẹ bo se n pa wọn nílẹ òkèèrè, tó sì rọ àwọn èèyàn láti mase máa yọjú síta kiri àmọ́ kí wọn joko sílè koowa wọn.
sibẹ, tí wọ́n bá ranti, tí wọ́n sì ronupiwada ní ilẹ̀ tí wọ́n kó wọn lẹ́rú lọ, tí wọ́n bá bẹ̀bẹ̀ tí wọ́n sọ pé, ‘àwọn ti ṣẹ̀, àwọn ti hu ìwà tí kò tọ́, àwọn sì ti ṣe burúkú,’ 
Ìbọn ọlọ́pàá ló pa èèyàn, ẹgbẹ́ wa kìí lo ìbọn - Shiite fárígá Iléeṣẹ́ ọmọ ogun dá Bashir tó ri owó he lọ́lá Zaynab ṣalaye ni kikun lori bi ọrọ yii ṣe bẹrẹ nitori ẹṣẹ kii deede ṣẹ lai nidi ni.
Àlàyé rèé lórí bí agbẹjọ́rò tó ń ṣojú Hushpuppi nílé ẹjọ́ ṣe pegedé sí Bí Hushpuppi ṣe tiraka rèé l‘Eko, kí ọlà ‘òjijì’ tó dé Wo bí ọwọ́ orílẹ̀-èdè Dubai ṣe tẹ Ramoni Igbalode tí gbogbo ayé ń pè ní Hushpuppi Hushpuppi di gbajúmọ̀ ẹlẹ́wọ̀n tó ní nọ́ńbà l‘Amẹrika, orúkọ̀ rẹ̀ wà lórí ayélujára Mà á gbẹ̀san bàálù àjọ UN tó já ní Borno - Buhari yarí Gal ni oun ko fi bẹẹ mọ nipa ayelujara asiko yii ṣugbọn oun mọ pe wọn n pa owo to pọ lori ayelujara nitori pe awọn ọmọ oun ni oun ti dagba.
Aare ile-igbimo asofin so lojo-Ru pe, ile-igbimo asofin yoo koko se agbeyewo lori abajade akosile yiyan igbimo ilana lori owo-na ile-ifowopamo ohun  lose to n bo, ni iyanju ati gbe igbese lori didekun awon ipenija to o n koju ipinnu ilana ohun.
Ninu ọrọ rẹ Oba Kabiru Adewale Shotobi, Ayangbunrẹ ti ilu Ikorodu, nigba ti o n sure si awon nnkan eelo naa, o gboriyin fun iru iṣẹ takuntakun bayii, eleyii ti aṣofin yii fi mu inu awọn ara ilu dun.
lowo ami ayo Michael Obafemi ti o gbá sagbon.
Ọládúpọ ̀ - - Ọmọ Àkàngbé orímóògùnjé ni òun náà .
 a kò rí ẹ ̀ rí tó fihàn kedere pé àjẹsára náà ní ohunkóhun ṣe pẹ ̀ lú ìfèsì ara ẹni lọ ́ nà òdì sí ohun tí ènìyàn kòrira .
Bí arakunrin kan tabi arabinrin kan bá wà ní ìhòòhò, tí kò jẹun fún odidi ọjọ́ kan, 
BBC ṣe agbeyẹwo igbeaye arakunrin naa, ohun ti mọ nipa rẹ ree: Wọn bi Yahaya Sharif-Aminu sinu ẹbi Mallam Aminu Sha'aibu Sharifai to jẹ onimọ nipa ẹsin Musulumi lagbegbe Sharifai, ni ilu Kano.
Sophia sọrọ yi lede Twii lori ileeṣẹ redio Hitz FM to wa nilu Accra.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Yollywood: Odunlade Adekola àtàwọn òṣèré sinimá Yorùbá míràn tó padà lọ sí fásiti lọ kàwé 26 Sẹ́rẹ́ 2020 Oríṣun àwòrán, Muyiwa Ademola/mr.
Títí ilẹ̀ ọjọ́ kejì fi ṣú a kò dé ìlú kan rárá ṣùgbọ́n nígbà tí ó di ọ̀sán ọjọ́ kẹta a dé ibi tí àwọn obìnrin méje wọn-ọnnì wà tí wọ́n ń sáré kiri títí ọjọ́ ayé wọn.
Bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé Asa kò wó gbogbo àwọn pẹpẹ ìrúbọ palẹ̀ ní ilẹ̀ Israẹli, sibẹsibẹ kò ní ẹ̀bi ní gbogbo ọjọ́ ayé rẹ̀.
Nítorí pé ìwà ìbàjẹ́ yóo gbilẹ̀, ìfẹ́ ọpọlọpọ yóo rẹ̀wẹ̀sì.
Senakeribu ọba Asiria bá pada sí Ninefe.
Arsenal àti Manchester United kọ́wọ̀ọ́ rìn lọ Europa Bi ala ni ọrọ naa ri loju ọpọ alatilẹyin ẹgbẹ Liverpool nitori pe awọn to jẹ eekan ẹgbẹ wọn meji Mohammed Salah ati Firminho ko kopa ninu ifẹsẹwọnsẹ naa.
 embassy ni Manila, ti n se olu-ilu orile-ede naa.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Wo àwọn ọ̀nà tí o lè gbà láti di ọjọ́ ogbó pẹ̀lú olólùfẹ́ rẹ O ni oun ati àwọn amugba legbe oun ati Komisana ilera sabewo s'awọn ile ìwòsan to wa ni Eko mojumọ, la ti ki awọn to f'arapa.
Nítorí Ọlọrun sọ̀rọ̀ bákan, ó tún tún un sọ bámìíràn,ṣugbọn kò sí ẹni tí ó yé.
Koda, laasigbo to waye lati ipasẹ iwọde to n lọ lọwọ yika Naijiria yii ko yọ awọn osisẹ ọba silẹ pẹlu, nitori wọn ko ri ọkọ wọ tabi gbe lọ sibi isẹ wọn.
Ohun tí a mọ̀ tó lè mú kí ìjọba Nàìjíríà ó dá òfin ìṣéde padà nìyí Àjọ NCDC kéde ènìyàn 381 míràn tó ní ààrùn Covid-19 l'órílẹ̀-èdè Nàìjíríà Owó Abacha sì kú, kò tíì tán, $319m kan sì wà ní UK àti France - Amẹ́ríkà Olateru-Olagbegi II: àkàndá ẹ̀dá tó jọba ní ẹ̀ẹ̀méjì láàrín ọdún márùndínlọ́gbọ̀n síra wọn.
Mo fi ilẹ̀ ati ọ̀run ṣe ẹlẹ́rìí níwájú yín lónìí, pé mo fun yín ní anfaani láti yan ikú tabi ìyè, ati láti yan ibukun tabi ègún.
Ikọ̀lù Darandaran: ìwọ́de pẹ̀lẹ́ kùtù wáyé nípìnlẹ̀ mẹ́ta
19 Ẹrẹ̀nà 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 23 Ẹrẹ̀nà 2020 Oríṣun àwòrán, Getty Images Awọn eeyan ti o n ni awọn apẹrẹ kan ni wọn n gba ikils bayii lati fi ara wọn si isele fun ọjọ mẹrinla gbako lati fi mọ boya arun yii lo n jẹys lara wọn abi oun kọ.
Ta ni yóo kọ́ Oluwa lẹ́kọ̀ọ́?
9th Assembly: Femi Gbajabiamila ni ẹgbẹ́ APC fọwọ́sí sùgbọ́n.
Agbẹnusọ fún àjọ WAEC Damianus Ojijeogu ló sọ èyí ddi mímọ̀ nínú ìfọ̀rọ̀wánilẹ́nuwò kan pé ti ààrẹ ò bá bèrè fún àwọn o lé kùgbùrù gbé e jáde Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Omar Victor Diop: Ipa Áfíríkà nínú àkọsílẹ̀ ìwé kọja ògo tí wọ́n ń fún un lágbáyé Ẹgbẹ́ òṣèlú APC kọ̀jálẹ̀ láti fi ìwé ẹ̀rí Buhari ṣọwọ́ sí INEC Oríṣun àwòrán, APC Àkọlé àwòrán, Aarẹ Buhari ati ami idamọ APC Ẹgbẹ oṣelu All Progressive Congress (APC) ti ni awọn ko ni fi iwe ri mo sedanwo ti ajọ WAEC fun aarẹ Buhari ṣọwọ si ajọ eleto idibo, INEC.
Ẹni to bori: Namibia Algeria vs Benin.
Níwájú Ọlọrun, gẹ́gẹ́ bí onigbagbọ ni à ń sọ̀rọ̀.
Ó ṣe ẹnu mi bí idà mímú, ó fi mí pamọ́ sí ibi òjìji ọwọ́ rẹ̀,ó ṣe mí ní ọfà tí ó mú,ó fi mí pamọ́ sinu apó rẹ̀.
Bí ẹnikẹ́ni bá fẹ́ ra ìdámẹ́wàá rẹ̀ pada, ó níláti fi ìdámárùn-ún ìdámẹ́wàá yìí lé e.
Ninu ifesewonse ipele keji si asekagba idije Ramat Cup  ohun, iko agbaboolu kano fagbahan Kwara pelu ami-ayo kan sodo(1-0), besini ipinle Eko je ore-ofe asemase ti ipinle Kebbi se, leyin ti iko ohun lo agbaboolu ti ko leto lati kopa ninu idije naa, eyi ti o sokunfa bii ipinle Eko se yege sinu asekagba idije ohun.
Akerele gba ijọba ni imọran lati pe ipade apaapọ pẹlu awọn ti ọrọ naa kan, ki owo ori ilẹ o ma ba da gbọmi si omi oto, silẹ laarin ijọba ati awọn ara ilu.
67 biliọnù owó oúnjẹ àwọn akẹ́kọ̀ọ́ tí ICPC ní wọ́n se mọ́kumọ̀ku O ni awọn ṣawari ọgọrin eeyan naa, bi o tilẹ jẹ pe pupọ ninu wọn mu iwe ẹri ayẹwo ti wọn se wa, eyi to ni wọn ko ni arun Coronavirus lara, lọwọ nigba ti wọn dari si Naijiria.
Oríṣun àwòrán, Reuters Àkọlé àwòrán, Lẹyin odi ilu naa ni orilẹede Ijibiti, orilẹede naa n mura ati dibo, gẹgẹ bi awọn aworan yii ṣe fi han ni oluilu orilẹede naa, Cairo.
Èsì tí a gbà dára tó bẹ́ẹ̀ ni ó mú wa tẹ̀síwájú nínú ìrìnàjò alẹ́ nínú oṣù  tí yìnyín bá ń bọ́ tí ojú ọjọ́ bá tútù.
Lati ri aridaju ẹtọ ati sọ̀rọ̀ sita, didaabo bo ẹmi awọn eeyan ati lapapọ, imugbooro ilẹ̀ Yoruba, la fi da ikọ Amotkun silẹ.
Ó tún kọ́ àwọn ilé ìṣọ́ sinu aṣálẹ̀, ó gbẹ́ ọpọlọpọ kànga, nítorí pé ó ní ọpọlọpọ agbo ẹran ọ̀sìn ní àwọn ẹsẹ̀ òkè ati ní pẹ̀tẹ́lẹ̀.
Yatọ si awọn ti a ka kalẹ, awọn obinrin ọmọ Brazil mẹsan kan ti wọn ni ki wọn fi orukọ bo awọn laṣiri naa naka si i pe o fi ọna eburu ba wọn laṣepọ.
Nàìjíríà pòkọ ìyà fún Libya láti wọ ìpele tó kẹ́yìn sí AFCONU23Q Amuneke àti olóògbé Keshi ló gbé orílẹ́èdè míràn lọ sí ìdíje AFCON Orúkọ Amuneke wọ ìwé ìtàn pẹ̀lú ikọ̀ agbábọ́ọ̀lù Tanzania Manchester United wa ni ipo kẹrin bayii ninu idije Premier League, ti wọn yoo si ma a koju Barcelona ni ifẹsẹwọnsẹ keji to kangun si asekagba idije UEFA Champions League, lẹyin ti wọn fagba han PSG pẹlu ayo meji ni Paris.
Solomoni gbé ọmọ Farao, ọba Ijipti níyàwó, ó fi bá ọba Farao dá majẹmu àjọṣepọ̀ láàrin wọn.
 orí kìíní ni ó sọ ̀ rọ ̀ nípa ìlàlà tí a lè tẹ ̀ lé láti pín èdè kan sí ẹbí .
silẹ ni ijoba ibile Kajuru to wa ni ipinle  Kaduna ti rọ ajo to n ri si ipese alaafia ni
Igbakeji abẹnugan  tuntun naa ni Hamisu Ibrahim to wa lati ekun Makoda, ti Baffa Dangundi je adari ti o ni omo egbe oselu to pọ ju, bakan naa ni Ayuba Labran to wa lati ekun Kabo je adari ti o ni omo egbe oselu to kere julọ.
Irú wọn ni Himeneu ati Filetu, 
Ìwọ nìkan kọ́ ló ní wọn Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Igi mimosa kọ̀ nílo òrùn láti mọ̀ àsìkọ̀ tí yóò fẹ àwọn ewé rẹ̀ Wọ́n lérò wí pé gbogbo irú ńkan abẹ̀mí tó máa ń gba agbára láti inú òòrùn ló ní agogo ara (circadian rhythm), látí lè lo iná àti òkùnkùn .
Lẹyin naa ni aarun naa bẹ̀rẹ̀ si tàn de awọn orilẹ-ede yooku, to fi mọ Africa.
Oríṣun àwòrán, Twitter screenshot Ìjọba Naijiria faraya nínú lẹ́tà tó kọ sí CNN lórí ìwádìí rẹ̀ nípa ìṣẹ̀lẹ̀ Lekki Toll Gate Iṣu ata yáan yàan!
Ṣebí nígbà gbogbo ni ò ń dáàbò bo òun ati àwọn ará ilé rẹ̀, ati gbogbo ohun tí ó ní.
Ẹ̀bi ta ni pé àwọn ọ̀dọ́bìnrin Nàìjíríà ń há sí Oman?
”Mo bá dáhùn, mo ní: “Èmi nìyí, rán mi.
Bẹẹ lọrọ ri fun awọn ole meji kan nipinlẹ Eko, nigba ti ọwọ palaba wọn segi, ti akara wọn si tu sepo.
Jeff Okoroaffor sọ pe o yẹ ki Ọjọgbọn Itse Sagay gẹgẹ bi oludamọran pataki fun Aarẹ Muhammadu Buhari kọwe fipo silẹ ni.
Wọn ni, ni awọn ipinlẹ ti wahala yii ti peleke, dida Ruga silẹ lee dẹkun rẹ ṣugbọn ko si ẹni to lee fi ọwọ sọya pe ko ni da wahala silẹ.
Onani ati àwọn ọmọ rẹ̀ ọkunrin mẹrin wà níbi tí wọ́n ti ń pakà.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Sẹ́nétọ̀ Dino Melaye kéde láti dupò gómìnà Kogi 2 Òkùdu 2019 Oríṣun àwòrán, Dino Melaye Àkọlé àwòrán, Dino Melaye Sẹ́nétọ̀ to n ṣoju ẹkun Ila Oorun ipinlẹ Kogi nile igbimọ aṣofin agba, Dino Melaye ti kede pe oun yoo du ipo gomina ipinlẹ Kogi ninu idibo oṣu kọkanla.
Lẹ́hìn èyínì, wo apá ọ̀tún lẹ́bàá igi náà, ìwọ óò rí igi mìíràn tíó kéré díẹ̀, ìwọ yóó sì rí i pé àwọn méjèèjì jọ ara wọn.
Lalẹ oni ni ipele keji ifẹsẹwọnsẹ naa yoo waye ni papa isere Anfield nilẹ Gẹẹsi.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Bolaji Faleke ni Olùkọ́ tó ń kọ́ wa ní àṣà oge ṣiṣe lórí BBC Yorùbá Ni ọjọ ti a n wi yii, wọn lu ẹfanjẹliisi naa debi pe o daku.
Bawọn lawọn ipinlẹ ti ko lee se ẹnubode wọn lasiko ti konile-o-gble- ọlọjọyipo le koko yoo ṣe wa lee se wọn bayii ti konile-o-gbele ti rọlẹ sii?
Oyo labe asia egbe oselu APC .
Awon akekoo fafiti lorile-ede South Africa ti fi ito awon okunrin mo biriki .
Sugbon lonii yii,a ti din ipa awon omo-ogun olote Boko haram ku patapata lorile ede yii, ijoba to wa lori aleefa yii ti gba awon omo Chibok mefalelogorun ati awon omobinrin merinlelogorun ti Dapchi sile, bakan naa ni awon egberun merindinlogun eniyan ni a ti gba sile ni igbekun awon omo-ogun olote Boko Haram.
Iwadii fi han pe agbalumọ kan ṣoṣo ni to ohun amuṣagbara mẹtadinlaadọrin to n ṣe ara loore.
Ẹnikẹni ti ọwọ ba tẹ pe o ru awọn ofin yii loju ni iya nla n duro de e.
Gomina Kano tí ní kí olùrànlọ́wọ́ rẹ̀ lọ rọ́kún nílé nítori o bu Ààrẹ Buhari lórí #EndSars EndSARS: Wo ohun táwọn gbajúgbajà tó n darí ìwọ́de ìfopinsí FSARS n sọ Ààrẹ Buhari kí Akeredolu kú orííré bí ó ṣe jáwé olúborí nínú ìdìbò sípò gómínà Tani Akeredolu tó wọlé láti tukọ̀ ìṣàkóso ípìnlẹ̀ Ondo lẹ́ẹ̀kejì yìí?
Mò ń gbọ́ ìròyìn ìfẹ́ ati igbagbọ tí o ní sí Oluwa Jesu, ati sí gbogbo àwọn onigbagbọ.
Wọn ke pe aarẹ lati fi kun awọn agbofinro to wa ni agbegbe naa.
Aarẹ Buhari fi ẹhonu rẹ han lori iṣẹlẹ ọhun ninu ipade rẹ pẹlu aarẹ Ramphosa, ọjọ mẹta ni Buhari lo nibẹ ko to pada wale.
Oríṣun àwòrán, ECWA Atobi ma see bawi la lee pe awọn darandaran naa, nitori ọwọ ofin kii saba mu wọn, ohun gbogbo ti wọn ba si se, asegbe ni.
Jesu pada láti odò Jọdani, ó kún fún Ẹ̀mí Mímọ́.
OLUWA ni kí ẹ máa tọ̀ lọ fún ìrànlọ́wọ́,Ẹ máa sìn ín nígbà gbogbo.
PDP: Ayé sì wà fún Ambode to bá fẹ tíkẹ̀ẹ̀tì Gómìnà lọ́dọ̀ wà ‘Ó kò lé gba ìwé ìgbéèlú U.
Ekinni gbé iyawo, ó kú láìní ọmọ.
layika won sun ile-ise olopaa, paapaa julo lasiko odun yii.
Ipinlẹ Yobe ni Oyetola ti sin ilẹ baba rẹ ni ọdun 1980 ni agbegbe Potiskum, ki o to bẹrẹ isẹ ti o yan laayo pẹlu ile isẹ adojutofo Leadway Assurance Company.
21 Ògún 2019 Oríṣun àwòrán, @SenAlasoadura Aarẹ Buhari ti bura fawọn minisita tuntun loni Bakan naa lo ya ileeṣẹ ijọba ti wọn yoo mojuto fun wọn.
FRSC dá N443,180 padà fún ẹbí ẹni to ní ìjàmbá mọ́tò Ikú dóró!
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù #HowGodMademechallenge: Ṣe lóòtọ́ bí àwọn olólùfẹ́ BBC Yoruba ṣe rí rè é?
O ní ìṣẹ̀lẹ̀ náà wáyé ni ọjọ́ kẹ́jọ oṣù yìí nígbà ti àwọn erin náà jáde kúrò nínú ọ̀gbà ní àárọ̀ tó sì mórílé ìlú Bajama.
Nítorí pé ẹ ti gbàgbé òfin Ọlọrun yín, èmi náà yóo gbàgbé àwọn ọmọ yín.
"Ọna lati ṣe ayẹsi awọn eeyan to ti ilẹ mimọ de, ka si tun lee da wọn mọ yatọ si awọn eeyan ti ko tii lọ, ni wọn ṣe n pe wọn ni Alhaji abi Alhaja.
Ìwọ ni ọmọ mi, ọmọ bíbí inú mi,ìwọ ni ọmọ tí mo jẹ́jẹ̀ẹ́ bí.
fun ibura fun aare orile ede naa, Macky Sall, fun didibo yan an fun saa keji .
Ẹkunrẹrẹ alaye wa ninu fidio yii.
Igbimọ amusẹya ti ijọba gbe kalẹ fun arun Coronavirus lo sawari isẹlẹ naa, ti wọn ko si kede orukọ ile ẹkọ giga ti aje ọrọ naa si mọ lori sita.
Nǹkan burúkú kò ní ṣẹlẹ̀ sí olódodo,ṣugbọn eniyan burúkú yóo kún fún ìyọnu.
Pupa ni asà àwọn akọni rẹ̀,ẹ̀wù pupa ni àwọn ọmọ ogun rẹ̀ wọ̀Kẹ̀kẹ́ ogun wọn ń kọ mànàbí ọwọ́ iná;nígbà tí wọ́n tò wọ́n jọ,àwọn ẹṣin wọn ń yan.
''Mo ranti wipe lọjọ diẹ sẹyin, wọn pe ipade itagbangba fun ifọrọwanilẹnu wo laarin awọn oludije si ipo gomina ipinlẹ Ọṣun, sugbọn ara ibi kọ lati yọọ ju sibẹ,nitori wipe o ti gba ijo lọ.
Manchester United rii wi pe ipadabọ wa Jose Mourinho si papa iṣere Old Trafford, iya lo ba de.
ni awon ti gbe lati rii daju pe alaafia joba laarin Olubadan ati igbimo
Sọra fun awọn ọkunrin ti inu wọn kii dun si isẹrere obinrin rẹ.
Jona sì wà ninu ẹja náà fún ọjọ́ mẹta.
Ìyànsípò Bichi wáyé lẹ́yìn tí wọ́n yọ Olùdarí Àgbà fún àjọ Ọ̀tẹlẹ̀múyẹ́ DSS tó wà nípò tẹ́lẹ̀, Lawal Daura kúrò nípò rẹ̀.
Davido gba àmì ẹyẹ olórin to gbayii julọ àti orin to gbayii.
Ileeṣẹ ọlọpaa ṣalaye loju opo Twitter rẹ pe, obinrin kan, Talatu Ibrahim ẹni ogoji ọdun lati ipinlẹ Zamfara ni wọn gba ibọn AK49 mẹsan an lọwọ rẹ, ati afurasi ọkunrin kan, Duleji Alhaji Abubakar to n ra ibọn lọwọ obinrin naa lo wa ninu aworan ọhun.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Osinbajo: Ikẹnnẹ yẹ kó jẹ́ Mẹ́kà òṣèlú ni Day 23: Àwọn nkan márùn ún tó gbajúmọ̀ nípa Daura #BBCNigeria2019 Àwọn àwòrán ẹ̀yìn ìtàgé níbi ìpàdé ìfọ̀rọ̀wérọ̀ BBC Yorùbá l'Eko Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
OLUWA wá sọ fún Jeremaya pé, 
Ojú yóo tì wọ́n, nítorí wọn ń wá ìrànlọ́wọ́ lọ sọ́dọ̀ àwọn tí kò lè ràn wọ́n lọ́wọ́.
Ninu atẹjade ti Olori ẹgbẹ Afenifere, Alagba Reuben Fasoranti fi sita lọjọ Satide, ẹgbẹ naa sọ pe oun ko mọ nipa fidio naa rara.
Jonatani ọmọ Saulu wá a lọ sibẹ ó sì fi ọ̀rọ̀ Ọlọrun gbà á níyànjú.
Gbogbo àwọn ọmọ ogun Israẹli bá lọ sí Bẹtẹli, wọ́n jókòó wọ́n sọkún níbẹ̀ níwájú OLUWA, wọ́n gbààwẹ̀ títí di ìrọ̀lẹ́; wọ́n sì rú ẹbọ sísun ati ẹbọ alaafia níwájú OLUWA.
Ó fèsì ó ni, ‘O kò rí i pé ó lẹ́wà ni?
Ninu oṣu Kọkanla, ọdun 2019, kọndọmu to to miliọnu kan niye, ni ijọba gbẹsẹ le, lẹyin ti awuyewuye bẹrẹ si waye lori rẹ lati ọdọ awọn ara ilu.
igbimo naa tun ri i pe, o se
Ẹgbẹ ajafẹtọ ẹni naa wa koro oju si iwa ika naa pẹlu afikun pe iwa kikọju ibọn sawọn oluwọde jẹ ara titẹ ẹtọ wọnsi ipejọpọ, isọrọ sita ati igbe aye loju.
'À ń lọ ilé-ẹjọ́ kòtẹ́milọ́rùn fún ẹ̀kúnwó owó oṣù ẹlẹ́wọ̀n' Akinyele ni aarẹ ana fun ẹgbe awọn agbẹnusọ lorilẹ-ede Naijiria, NIPR.
Minista fun aṣa, Guy Madje Lorenzo ohun to wu ijoba Togo lati sọ iṣẹ fiimu di bii tagbaye.
Kí àwọn ìran tí ń bọ̀ lè mọ̀ ọ́n,àní, àwọn ọmọ tí a kò tíì bí,kí àwọn náà ní ìgbà tiwọnlè sọ ọ́ fún àwọn ọmọ wọn.
Elomiran ti ọbẹ igbogun ti iwa ajẹbanu tun ba nidi ni Umaru Dikko, tii ṣe minisita feto irinna laye ijọba Shagari, ẹni to salọ silu ọba bi ologun ṣe gba ijọba.
Ninu ọrọ to kọ soju opo Instagram rẹ, o ni ọrọ idupe ni mo fẹ fi eyii ṣe!"
Nítorí náà, ẹ gbọ́ ète tí èmi OLUWA pa lórí Babiloni, ati èrò mi lórí àwọn ará Kalidea: A óo kó agbo ẹran wọn lọ tọmọtọmọ; ibùjẹ ẹran wọn yóo sì parun nítorí tiwọn.
Jude, tii se osere tiata salaye pe ilẹ Yoruba ni oun gbe dagba, ede wọn si dun gbọ, bẹẹ naa lo dun lati sọ.
 Ó tún lè ràn nípa ìfarakàn ẹni tí ó ní àkóràn .
“A bá kọjá lọ láàrin àwọn arakunrin wa, àwọn ọmọ Esau tí wọn ń gbé òkè Seiri, a ya ọ̀nà tí ó lọ láti Elati ati Esiongeberi sí Araba sílẹ̀.
5 23266473 Orilẹ́ede Brazil 207095 98.
Iṣẹ̀lẹ̀ náà tó kan ẹlikọ́pítà Bell 206B lll pẹlu nọ́mba ìdánimọ 5N-BQW tí ilé iṣẹ́ ọkọ̀ òfurufú Quorum Aviation Limited ni wọ́n ti sàlàyè gbogbo ǹkan tó fa ìṣẹ̀ll ńlá ibi náà.
" Ikoro pari ọrọ rẹ pe ko nnkan to jọ ija tabi ikọlu tawi ọwọ awọn ọmọ ẹgbẹ okunkun ni ibi ti wọn ti ṣekupa oloogbe naa.
Ẹ wá gbọ́, gbogbo ẹ̀yin tí ó bẹ̀rù Ọlọrun,n óo sì ròyìn ohun tí ó ṣe fún mi.
Amuneke fipò sílẹ̀ gẹ́gẹ́ bí akọ́nimọ̀ọ́gbá Tanzania Kí l'ànfàní àdéhùn okoòwò kan l'Afíríkà, AfCFTA tí Buhari tọ́wọ́ bọ̀?
NEMA: Ìjọba ìbílẹ̀ 102, ní ìpínlẹ̀ 28 ni ẹ̀kún omi ń bọ̀, ẹ múra
Nígbà tí wọ́n gbọ́ gbogbo ọ̀rọ̀ náà, ẹ̀rù bà wọ́n, wọ́n bẹ̀rẹ̀ sí wo ara wọn lójú.
Ní gbogbo ìgbà tí Isaaki ń bá Esau ọmọ rẹ̀ sọ̀rọ̀, Rebeka ń gbọ́ gbogbo ohun tí wọ́n ń sọ.
Oun ati Ngige, to jẹ minista igbode iṣẹ ni wọn jọ winá iyanṣẹlodi awọn olukọ Fasiti, ASUU fun odindin oṣu mẹta.
Ijọ wo gan-an ni 'Church of Satan'?
20 Ṣùgbọ́n nípa ìwà ìrékọjá sí àwọn òfin mímọ́ wọ̀nyí ènìyàn di ti ara àti ti èṣù, àti pé òun sì di ẹni ìṣubú.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Àwa táa jẹ́ alágbàtọ̀ gan, èèyàn ni wá, ẹ ye ṣe wa bí ẹranko' Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Wọ́n sún ìsìnkú Abiola Ajimobi di ọ̀la Satide Ìtàn ìgbésí àyé olóògbé Isiaka Abiola Ajimobi Ìgbé ayé Abiola Ajimobi nínú àwòràn pẹ̀lú àwọn ǹkan tó ṣẹlẹ̀ Ajimobi kìí bá ọ̀lẹ, olè àti ọlọ́pọlọ kúkú ṣe ọ̀rẹ́ - Alaafin Idi si ree ti BBC Yoruba fi se akojọpọ awọn awuyewuye meje to waye, eyi to mu ki ẹnu maa kun Ajimobi lasiko to jẹ gomina nipinlẹ Ọyọ.
lásikò tó ń sọ̀rọ̀ lóri àbájade igbẹjọ Ademola Adeleke tó dije dupo gomina lábẹ ẹgbẹ́ PDP nípinlẹ̀ Osun nibi ìgbẹjọ to waye lánàá odé yìí ààrẹ àná Olusegun Obasanjọ sàlàyé pé ènìyàn buburu àti ẹlẹmi èṣù ní ẹni to ba ni Atiku naa maa ṣẹjọ lóri abajade èsì idibo ààrẹ.
Mo wà lẹ́yìn rẹ, bí ọkàn rẹ ti rí ni tèmi náà rí.
“Nígbà tí OLUWA bá mu yín dé ilẹ̀ àwọn ará Kenaani, gẹ́gẹ́ bí ó ti búra fún ẹ̀yin ati àwọn baba yín, tí ó bá sì fún yín ní ilẹ̀ náà, 
Nígbà tí ó ṣe wọ́n dá ọ̀rọ̀ mi sílẹ̀ ìyàwó mi si bẹ̀rẹ̀ sí tú gbogbo àṣírí tí mo fi lè e lọ́wọ́.
Awọn iwe miran ti oloogbe kọ ni Opa Agbeleka, Oga Ni Bukola, Sango, Iroyin Ayo, Binu Tiri ati, Aajo Aje.
Gbọ́ ìtàn bí ikọ̀ SARS ṣe dà bó ṣe dà láti ẹnu Ọ̀gá ọlọ́pàá tó dá SARS sílẹ̀ Ìjọba kéde ọjọ́ ìwọlé àwọn àgùnbánirọ̀ sí ìpàgọ́ lẹ́yìn Covid 19- Sunday Dare #EndSARS: Àwọn olùwọ́de kọ etí ikún sí àṣẹ ijọba, wọ́n tẹ̀sìwájú ìwọ́de l'Abuja Kanye West, Ozil, Boyega, àti àwọn gbajúmọ̀ ilẹ̀ okèèrè tó ṣàtìlẹyìn fún ìpolongo #ENDSARS Ọba Lamidi Adeyẹmi, òṣìṣẹ́ adójútòfò àti Abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò kó tó jọba Oríṣun àwòrán, @Makinde Lẹyin aisan ranpẹ toripe ọjọ ogbo ni mama wa lọ sinmi.
Bí wọ́n ti ń sọ̀kalẹ̀ láti orí òkè, Jesu pàṣẹ fún wọn pé, “Ẹ má sọ ohun tí ẹ rí fún ẹnikẹ́ni títí a óo fi jí Ọmọ-Eniyan dìde kúrò ninu òkú.
ogun Naijiria pe won sekupa  awon afehonu
Nitori eyi,gbogbo nnkan ti wọn ba ṣe a ma mu iriwisi orisirisi wa.
Sibẹ sibẹ, eyi ṣi wu ni lori jọjọ tori o mu ki awọn akẹgbẹ wọn naa wa da ara wọn lọwẹkẹ eyi si mu inu awọn ololufẹ wọn dun lati ba wọn yọ.
Àsírí ajọ́mọgbé méjì tú ní Kwara Owo ifẹyinti tan fawọn gomina ana ni Kwara Pápá ìṣiré ìpínlẹ̀ Kwara tó wà ní àdúgbò Taiwo Road ló f'ara kááṣá ìjì líle náà jùlọ.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Àjọ INEC sún ìdìbò gómìnà ìpínlẹ̀ Kogi àti Bayelsa síwájú ‘Kò tọ́sí Adeleke láti díje dupò gomina Ọṣun’ Ilé ẹjọ́ kòtẹmilọ́rùn yóò dajọ́ ìdìbò gómìnà Oṣun ọdún 2018 Sugbọn bayii, arakunrin to n jẹ Ajayi Shuaib ọhun lo tun ti wa si gbangba bayii pe wọn parọ mọ ohun ni, ohun kọ lo gbe ẹjọ tako Adeleke lori ẹsun ayederu iwe ẹri naa.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ààrẹ Akufo: Òfin kò fààyè gba ìbálòpọ̀ akọ ṣákọ ni Ghana 30 Ìgbé 2018 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ó ní ìgbéyàwó láàárín akọ àti akọ tàbí abo àti abo si lòdì sí òfin lórílẹ̀-èdè Ghana.
Atẹjade kan loju opo ayelujara rẹ fi sita pe ọdun mẹrin sẹyin ni o ti mọ pe oun laarun naa ṣugbọn o mọọmọ maa fi han sita faraye.
lori owo gọbọi ti awon ile ifowopamo  n
Mo bá bínú gan-an sí àwọn ìlú Juda ati ìgboro Jerusalẹmu; mo sì sọ wọ́n di aṣálẹ̀ ati ahoro bí wọ́n ti wà lónìí.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Xenophophia: Lizzy Anjorin, Yinka Ayefele, Mercy Aigbe sọ̀rọ̀ ìtùnú 4 Owewe 2019 Ọrọ ikọlu ti awọn ọmọ Naijiria to wa lorilẹede South Africa n koju ati iwa igbẹsan to tẹle lati ọdọ awọn ọmọ Naijiria ti n ta ọpọ eeyan lara.
Nígbà tí ó di àfẹ̀mọ́jú Jesu dúró ní èbúté, ṣugbọn àwọn ọmọ-ẹ̀yìn kò mọ̀ pé Jesu ni.
Ramadan: Ramadan tumọ si asiko ti nkan ba gbona.
Wọ́n yá ẹgbaa mẹrindinlogun (32,000) kẹ̀kẹ́ ogun, ati ọba Maaka pẹlu àwọn ọmọ ogun rẹ̀, wọ́n wá, wọ́n sì pàgọ́ ogun wọn sí ẹ̀bá Medeba.
Kogi Lẹyin ti ijọba Kogi sọ pe oun ti pin ounjẹ iranwọ Covid-19 ni awọn ara ilu ri ile to ko ounjẹ naa pamọ si.
Ó ṣe pàtàki gẹ́gẹ́ bi ikan ninú orin (Olóyè Olùdari Ebenezer Obey), pe “Ipò ki pò, ti a lè wà, ká má a dúpẹ́ ló tọ́”.
E̩nì kò̩ò̩kan lórílè̩‐èdè, ló ní è̩tó̩ sí àtúns̩e tó jo̩jú ní ilé‐e̩jó̩ fún ìwà tó lòdì sí è̩tó̩ o̩mo̩nìyàn, tó jé̩ kò‐s̩eé‐má‐nìí gé̩gé̩ bó s̩e wà lábé̩ òfin àti bí òfin‐ìpìlè̩ s̩e là á sílè̩.
Ẹgbẹ eleto ilera - Eyi ni ẹgbẹ awọn onimọ iṣegun oyinbo to ma n tọju awọn alaisan lasiko iṣẹ iranṣẹ ilera ọfẹ, ati ẹnikẹni to ba nilo itọju lasiko ti isin n lọ lọwọ.
Repinoe lo gba ami ẹyẹ ẹlẹsẹ ayo bata goolu, bọọlu goolu àti agbabọọlu to fakọyọ julọ ninu idije ife ẹyẹ agbaye tawọn obinrin to pari ni France yii.
Lẹ́yìn tí a ti kìlọ̀ fún un lójú àlá, ó yẹra níbẹ̀ lọ sí agbègbè Galili.
 27, 2018:Plateau United 1-0 MFM FC.
idile Oloogbe, Pa Olatubosun Makinde ati Mama Abigail Makinde ti agbo-ile
Amọ ẹsun miran lo fi kan iyawo rẹ pe iyawo oun buru ju nkan ti agbara oun ka lọ, ati pe kii ka nkan si""."
Oníṣẹ́ náà bá tọ Dafidi lọ, ó sì ròyìn fún un gẹ́gẹ́ bí Joabu ti rán an pé kí ó sọ.
Oríṣun àwòrán, Oluwo/facebook Àkọlé àwòrán, Ọba tó ṣe fi yangàn láàrín ọba Nàìjíríà ni Ọlọ́fà ìlú Offa-Oluwo Arun Coronavirus sebi ẹni ké ayẹyẹ ọdun kẹwa Ọlọfa kuru sugbọn Ni ọjọ Kẹjọ osu kaarun ọdun 2010 ni Oba Mufutau gun ori itẹ awọn baba rẹ gẹgẹ bi ọlọfa ikẹrinlelogun ilu Offa.
Ẹni to n risi iṣẹlẹ naa, Taiwo Ladipo lo fi ọrọ ọhun lede fun awọn oniroyin lọjọ Iṣẹgun.
Ọlọrun nìkan ni mo fi sùúrù gbẹ́kẹ̀lé;ọ̀dọ̀ rẹ̀ ni ìgbàlà mi ti wá.
Ó ní, “Bí mo ti sùn ní alẹ́, mo rí i lójúran pé afẹ́fẹ́ tí ń fẹ́ láti igun mẹrẹẹrin ayé ń rú omi òkun ńlá sókè.
Ọba Akanbi ṣalaye wi pe koda ilẹ Mẹka nibi ti awọn Musulumi maa n rinrinajo mims lọ pẹlu ti se ilẹkun wọn pa ti wọn si ti ni ko saye lọwọ yii.
Ti ijamba ina ba sẹlẹ, e tete pe ile isẹ panapana lori nọmba wọn: 767 ati 112 ni ipinlẹ Eko.
Àgùnbánirọ̀ gbẹ́mìí mì látàrí 'Snipper' tó fi fọ irun rẹ̀
Aisan iba ọrẹrẹ jẹ aisan to wa lara awọn eku ile, to si le tan ka ara eniyan, nipa ounje tabi ohun elo ile, ti eku naa ba ni ifarakanra pelu.
Kò sí ibi òkùnkùn biribiri kankan,tí àwọn eniyan burúkú lè fi ara pamọ́ sí.
A o ri pe iwadii ẹkunrẹrẹ waye ta o si pe awọn to ba mọ nipa rẹ lẹjọ.
N kò yá ẹnikẹ́ni lówó, bẹ́ẹ̀ n kò yáwó lọ́wọ́ ẹnìkan, sibẹsibẹ gbogbo wọn ni wọ́n ń ṣépè lé mi.
Kí Ọlọ́run dẹ'lẹ̀ fún ẹni ire.
olúwarẹ̀ gbọdọ̀ jẹ́wọ́ ẹ̀ṣẹ̀ rẹ̀, kí ó san ìtanràn ẹ̀ṣẹ̀ rẹ̀, kí ó sì fi ìdámárùn-ún iye owó náà lé e fún ẹni tí ó ṣẹ̀.
Isreal Mobolaji Temitayo, Odunayo, Oluwafemi Owolabi, Adesanya jẹ́ ọmọ Naijiria ti o n gbe Newzealand, ni Auckland, O jẹ́ abẹsẹku bi ojo, lọ́wọ́lọ́wọ́ àbẹ́ àdéhun Utimate Fighting Championship ló wà to si jẹ Middleweight Champions.
Silifat Aboriṣade to jẹ aya oloogbe Adeniyi Aboriṣade to jẹ alaga ẹgbẹ oṣelu PDP fun Apapa nipinlẹ Eko sọ pé titi di àsìkò yìí, ọlọpaa kankan kò tii wa sọ́dọ̀ òun.
Kii ṣe igba akọkọ niyi to dije fun ipo ile aṣofin ni America.
Àwọn olórí á panumọ́,ahọ́n wọn á lẹ̀ mọ́ wọn lẹ́nu.
minisita, awon osise ajo mojuto irinna oko ojurin lorile-ede Naijiria(Management
Ngige ni iṣẹ́ n lọ lọ́wọ́ lórí ǹkan ti ASUU n bèèrè Ilé ẹjọ́ rán ọjọ̀gbọ́n fasiti OAU lọ sẹ́wọ̀n ọdún méjì Ṣé Fulani daran-daran ni àwọn tó n jí ènìyàn gbé ní ìpínlẹ̀ Ondo?
Arlene ni, oun ati ọrẹ oun ọkunrin ti wọn jọ joko papọ ni wọn wọ asọ kan naa, ti wọn si ya aworan lati fi si ori ẹrọ ikansiraẹni Facebook.
Ọba sọ fún àwọn ènìyàn kí wọ́n fi Ọ̀sanyìn ẹlẹ́sẹ̀ kan sílè kí ó gbìyànjú kí ó pa itú ọwọ́ rẹ.
Sibẹ wọ́n ti wa kòtò sílẹ̀ fún mi.
Ohun tí mo rí nìyí, lẹ́yìn tí mo farabalẹ̀ ṣe ìwádìí pẹ̀lẹ́pẹ̀lẹ́, 
31 percent ba eto irinna  oko wiwo laarin ilu.
Kò sí ìfòyà, ọkọ̀ bààlù wà tí ìjọba ba ti afárá 3rd Mainland lósù yìí Wole Soyinka rèé láti kékeré Nise lo pa tọkọtaya ati ọmọ wọn kan, to si ju oku wọn sinu odò adágún kan.
pe ile igbimo asoju se ojuse won lati mu igbaye-gbadun ba awon omo orile ede
Ṣugbọn nígbà tí ìwọ bá ń gbààwẹ̀, bọ́jú kí o sì fi nǹkan pa ara, 
Ninu ìdílé Harimu: Maaseaya, Elija, Ṣemaaya, Jehieli, ati Usaya.
Amòfin kan lọ sí ọ̀dọ̀ Jesu, ó gbọ́ bí wọn tí ń fi ọ̀rọ̀ wé ọ̀rọ̀, ó wòye pé Jesu dá wọn lóhùn dáradára.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù PDP Kogi Primaries: Tá ní àwọn ọmọ ẹgbẹ́ yóò gbé áṣíà gómìnà ìpínlẹ̀ Kogi lè lọ́wọ́?
Àwọn eniyan burúkú yí mi ká bí ajá;àwọn aṣebi dòòyì ká mi;wọ́n fa ọwọ́ ati ẹsẹ̀ mi ya.
Iroyin ti ẹ sọ pe o jíǹde lẹyin ti wọn ṣe àwọn ètùtù kan, ko to o tun pada kú.
Obinrin yìí bá tọ gbogbo àwọn ará ìlú lọ, ó sì fi ọgbọ́n bá wọn sọ̀rọ̀.
Àwòran bí Yorùbá ṣe gbayì ní Austria Kò sí àjòjì darandaran kankan ní Nàìjíríà -NIS Gbìyànjú àwọn òwé Yòrúbà yìí wò Pàtàkì June 12 fún Nàíjíríà Iṣẹ́ Kudirat Abiọla ṣì ń fọhùn síbẹ̀, lẹ́yìn ọdún 23 tó papòdà Ọ̀nà márún-ún láti mú àdínkù bá dátà (Data) lílò rẹ Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Ikọ to n gbogun ti iwa jẹgudujẹra, EFCC lo fi iroyin naa si oju opo rẹ lori Twitter pẹlu aworan ọdaran naa ti ile ẹjọ ni ariwa orilẹ-ede Naijiria ran lọ si ẹwọn naa.
A ri gbọ́ wi pé bi “Ọ̀gá Àgbà Agbẹjọ́rò” bá ni ẹjọ́ ni iwájú Adájọ́ lẹhin ti ẹjọ́  agbejoro ti dé iwájú Adájọ́, wọn yio kọ́kọ́ gbọ́ ẹjọ́ ti “Ọ̀gá Àgbà Agbẹjọ́rò” gbé wá.
Ambọde ti Ipinlẹ Eko ti ṣe agbekalẹ abadofin iṣuna owo ilu onibiliọọnu
Kíákíá ni mo bá tẹsẹ̀ mọ́n’rìn, mo bẹ̀rẹ̀ sí í tọ ilé náà lọ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ọmọ Yoruba di ẹni akọkọ to kawe f'ọgọfa wakati 4 Ẹrẹ̀nà 2018 Oríṣun àwòrán, Twitter/@iread_bayode Ọmọ Naijiria kan, Bayọde Treasure Ọlawunmi ti di ẹni akọkọ to kawe sọke fun ọgọfa wakati lai simi ju wakati meji lọ nijọ kọkan laarin ọjọ maarun.
bí inú kabiyesi bá dùn sí mi láti ṣe ohun tí mò ń fẹ́, ati láti gbọ́ ẹ̀bẹ̀ mi, kí kabiyesi ati Hamani wá síbi àsè tí n óo sè fún wọn ní ọ̀la.
Irinna ipinlẹ yoo wa fun awọn to ba n ko ẹru ti araalu nilo nikan.
Nítorí náà, kò sí ẹnikẹ́ni ninu wọn tí ó fi ẹnu kan nǹkankan.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Amọ bi Pence ba kọ lati ṣe bẹẹ, awọn aṣofin latinu ẹgbẹ oṣelu Democrat yoo dibo lati yọ Aarẹ Trump, nitori bo se sọ fawọn ololufẹ rẹ lati wọde lọ si ile aṣofin apapọ orilẹede naa, ti wọn si kọlu ibẹ lọsẹ to kọja.
Igbeaye irọrun rẹ wa si opin nigbati iya ati baba rẹ kọ ara wọn silẹ.
Ó bọ́ aṣọ rẹ̀, ó sì sọ àsọtẹ́lẹ̀ níwájú Samuẹli.
 Akoko niyi lati ṣawari ara wa
O ni awọn obinrin loriṣiriṣii, ọrẹ, ará, iyekan, ero pupọ ati ojulumọ a maa yabo iru ẹni bẹẹ.
Ó gbin àjàrà dáradára sinu rẹ̀.
Oríṣun àwòrán, Facebook Àkọlé àwòrán, Asọtẹlẹ nipa ẹni ti yoo jawe olubori ninu ibo jẹ nnkan ti awọn arìran kan tẹnumọ saaju idibo; ṣugbọn ṣe wọn jana?
Gẹgẹ bi ikede kan ti ajọ NCDC fi si ori ayelujara Twitter rẹ lọjọ Aiku, wọn ti fi alaisan naa si iyasọtọ, wọn si ti ṣe ayẹwo ara rẹ, esi yoo si jade lọla, ọjọ Aje.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Mo ń retí láti ọ̀dọ̀ bàbá mi nígbà tí mo gbọ́ pé ó bá ìjàmbá bàálù lọ Ogagun agba Saere Mekonnen wa lara awọn ti o di ilu mu ninu iditẹ gbajọba naa to gbẹmi ọpọlọpọ.
OLUWA bá bi í pé “Kí ni o dánwò yìí?
Wọ́n ti ni kí àwọn alága ìjọba ìbílẹ̀ Ogun lọ rọọ́kún nílé Wo àwọn ìlérí tàwọn Gómìnà tuntun ṣe nínú ìbúra wọn Dapọ Abiọdun ree, ẹni tó dépò gómìnà ní àyájọ́ ọjọ́ ìbí rẹ̀ Ará ìlú dájọ́ oró fún ọkùnrin to bẹ́ orí ẹ̀gbọ́n rẹ̀ ní Cross River SEC tun ni ẹsun meji ti awọn ri gba lori ileeṣẹ yii lọdun 2017 lo bi iṣẹ iwadii ti awọn ṣe ni eyi to n bi eso itanran lasiko yii.
"O ni ""Gbogbo wa la mọ ohun to ṣẹlẹ ni Akinyele, a mọ bi awọn ọlọpaa ṣe mu afurasi, bẹẹ la si tun gbọ bo ṣe salọ mọ lọwọ."
Eletricity Tarriff: IKEDC ní sísan owó iná ọba tayọ èèyàn yókù kò lòdì sófin
Awon ojogbon omo Naijiria mejeeji  yii padanu emi won sinu ijamba oko ofurufu EthiopiaỌgunlogo
Ọmọ baba ọhun ti o n tọ baba rẹ lọ naa pade agbako iku lọdọ erin naa.
Nítorí náà ẹ má bẹ̀rù; ẹ níye lórí pupọ ju ológoṣẹ́ lọ.
 O tẹsiwaju pe Inu ọfiisi ni a wa ti a ti gbọ iro ibọn nigba meji, nigba naa ni a sare jade lati wo ohun to n ṣẹlẹ.
Ẹni tí ó ṣe iṣẹ́ yìí lára wa ni Ọlọrun.
Ní alẹ́ ọjọ́ tí mo nsọ yìí, mo tan ẹ̀rọ ayárabíàṣá mi pé kín sáré ṣiṣẹ́ kan kíakiá kí ng tó lọ sùn.
” Nítorí pé ẹ̀mí wọn ni wọ́n fi wéwu kí wọn tó rí omi yìí bù wá; nítorí náà ni ó ṣe kọ̀, tí kò sì mu ún.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ademọla Ogunbanjo: A nílò bàbá ìsàlẹ̀ nínú òsèlú Sẹnetọ Olufẹmi Lanlẹhin ti ẹgbẹ oṣelu ADC ṣalaye pe ireti oun nibi eto yii ni ki ijọba tiwa n tiwa ko lọ deede lai si aawọ tabi ija.
Oríṣun àwòrán, Others Nigba to n sọ nipa ihuwasi awọn ibeji rẹ to bọ lọwọ awọn ajọmọgbe laipẹ yii, Akeugbagold ni ṣe ni awọn ibeji naa n sa si abẹ aga ati tabili ni kete ti wọn ba gburo pe ọkọ wọnu agbala oun, ti wọn si ro pe awọn ajọmọgbe lo tun de.
Aarẹ Buhari ṣ'eleri ati pese iṣẹ fun ọpọlọpọ
Ìwọ ni n óo máa yìn láàrin àwùjọ àwọn eniyan;n óo san ẹ̀jẹ́ mi láàrin àwọn tí ó bẹ̀rù OLUWA.
Èdè tí ó gbòòrò ni èdè adamawa-ubangi .
Mo ní ọpọlọpọ ìrírí tí ó kún fún ọgbọ́n ati ìmọ̀.
Ire owó, ire ọmọ, ire àláfíà tí í ṣe baálẹ̀ ọrọ̀.
Tí ìjọba kó bá dẹ́kun ìpànìyàn ní Gúúṣù Kaduna, aráàlú yóò jà fúnra wọn - CAN Ṣọ́ọ́bù mẹ́sàn-án jóná nínú ìṣẹ̀lẹ̀ ìbúgbàmú míràn l‘Eko Ọwọ́ tẹ́ àwọn ọkùnrin Fulani mẹ́ta tí wọ́n jí Màálù méjì kó ní Ogbomọṣọ- Àjọ NSCDC Bakan naa ni Aarẹ Trump sọ fun awọn akọroyin ni Ọjọ Iṣẹgun pe: ''Ohun ti o ye mi nipa ọrọ yi ni mo le sọ.
OLUWA mú kí á máa ranti iṣẹ́ ìyanu rẹ̀,olóore ọ̀fẹ́ ni OLUWA, àánú rẹ̀ sì pọ̀.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù AFCON 2019: Egypt dá akọ́nimọ̀ọ́gbá Aguirre dúró lẹ̀yìn ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ 7 Agẹmo 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Faraoh kogba wọle, akọnimọọgba Javier kogba sita ni Egypt Bi nkan ko ṣe ṣẹnu re fawọn ẹgbẹ agbabọọlu ilẹ Egypt ninu idije AFCON to n lọ lọwọ naa ni wọn ti da akọnimọọgba wọn duro.
Turari olówó iyebíye tí wọ́n ń pè ní bedeliumu, ati òkúta olówó iyebíye tí wọ́n ń pè ní onikisi wà níbẹ̀ pẹlu.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Àjẹ́, eégún, kí ni wọn ò pè mí tán tórí Vitiligo lára mi' Ami ẹyẹ si lo n mọriri ẹnikẹni to pegede, se aseyọri tabi sisẹ sin fun ileẹkọ naa tabi fun awujọ lapapọ.
OLUWA bá wí fún Mose pé, “Mo ti rí àwọn eniyan wọnyi, wò ó, alágídí ni wọ́n.
Aranmọ Fawẹẹli ni olukọ to dantọ ni o n kọ wa bayii.
 Bakan naa, maa lo anfaani yii fi ki awon elesin igbagbo ku ayeye
Mò ń ronú láti padà sí ẹgbẹ́ agbábọ́ọ̀lù Nàìjíríà, Super Eagles láìpẹ́- Odion Ighalo Ǹjẹ́ o mọ àwọn òṣèré bí Oyin Adejọbi, Funmi Martins àtàwọn míì tó ti dágbére fáyé?
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Child Trafficking: Ọwọ́ ṣìnkún ọlọ́pàá tẹ èèyàn 5 lórí ìṣẹ̀lẹ̀ náà 22 Ìgbé 2019 Oríṣun àwòrán, @PoliceNG Ọkunrin kan, Amanze Anyanwu ati iyawo rẹ Chinonye Oparaocha ẹni ọdun mẹtalelogun, ti ta ọmọ wọn tuntun jojolo, ti ko tii ju ọmọ wakati mẹfa lọ ni owo to to ẹgbẹrun lọna ọtalelẹgbẹrin o din mẹwa naira (₦850,000).
 danjuma ni alaga ile-ise south atlantic petroleum ( sapetro ) .
Yoruba Language: BBC Yoruba ń gbìyànjú kí èdè má parun
Kọ́ mi ní ọ̀nà tí n óo máa rìn,nítorí pé ìwọ ni mo gbójú sókè sí.
23 Ìgbé 2020 Oriṣiiriṣii nnkan lawọn eeyan n sọ pe o le wo aarun coronavirus ti o ba gbogbo aye finra lọwọ.
Bakan naa o ṣe afikun ofin lori awọn to fẹ lati lọ si US fun ilera wọn.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Nigeria 2019 Elections: Ohun mẹ́rin tó jẹyọ nínú ọ̀rọ̀ Atiku níbi ìpàdé PDP 20 Èrèlè 2019 Oríṣun àwòrán, NAIRALAND Lẹyin ti ẹgbẹ oṣelu APC ṣe ipade igbimọ alaṣẹ rẹ, nibi ti Aarẹ Muhammadu Buhari ti sọ ọrọ to mu awuyewuye wa pe, ẹnikẹni to ba ji apoti ibo gbe n fẹmi ara rẹ wewu ni.
A máa lo ìpọ́njú àwọn tí à ń pọ́n lójú láti gbà wọ́n là,a sì máa lo ìdààmú wọn láti ṣí wọn létí.
O ni: “Ankara ti di ohun ti won fi n se eso bii bangulu, yeti eti, ti won fi n se bata, apamowo baagi ati nkan eso ile lorisiirisii to re wa ti won dun lati wo kaakiri ni eyi ti won ti n ko lo sile okeere fun tita bayii .
“Wò ó, mo gbé ikú ati ìyè kalẹ̀ níwájú yín lónìí, bákan náà ni mo sì gbé ire ati ibi kalẹ̀.
Bẹẹ ni o ki ara rẹ ku ọjọ ibi wi pe ẹmi oun yoo ṣe ọpọ rẹ laye ati laaye.
Akọwe Ipolongo ẹgbẹ oṣelu PDP, Kola Ọlọgbọndiyan, ṣalaye fun BBC Yoruba lasiko to n fidi ọrọ naa mu lẹ pe Bukola Saraki lo jẹ ẹni to gajulo pata ninu gbogbo awọn ti wọn dibo yan ninu ẹgbẹ Naa.
Gbé oúnjẹ ati omi kalẹ̀ níwájú wọn, kí wọ́n jẹ, kí wọ́n mu, kí wọ́n sì pada sọ́dọ̀ oluwa wọn.
'Mi o fọ́wọ́ sí bí ọmọ mi, Kiddwaya ṣe lọ fún BBNaija - Terry Waya Mercy Aigbe ṣá ọmọ rẹ̀ sínúu fíìmù tuntun, wo itú tí ọmọ ọdún mẹ́wàá náà pa 'Àgbàrá òjò wọ́ ọmọ méjì lọ ní Ketu l'Eko lálẹ́, a ṣì ń wá wọn di òní' Daddy Freeze túbá!
Ṣugbọn bí wọ́n bá mú ninu ẹ̀jẹ̀ rẹ̀ wá sinu Àgọ́ Àjọ, tí wọ́n bá lò ó fún ètùtù ìmúkúrò ẹ̀ṣẹ̀, ẹnikẹ́ni kò gbọdọ̀ jẹ ẹran náà, sísun ni wọ́n gbọdọ̀ sun ún.
Nígbà náà ni àwọn ọmọ-ẹ̀yìn Johanu wá sọ́dọ̀ rẹ̀, wọ́n bi í pé, “Kí ló dé tí àwa ati àwọn Farisi ń gbààwẹ̀ ní ọ̀pọ̀ ìgbà, ṣugbọn àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ kì í gbààwẹ̀?
Ẹ̀wẹ̀, agbẹnusọ náà ni, bàbá náà ni ẹ̀tọ́ láti lọ sí ilé ẹjọ kòtẹmilọ́run lórí ọ̀rọ̀ náà láàrín ọgbọ̀n ọjọ́.
" tí àwọn ènìyàn bá kọ́ka ri mí ǹkan to máá ń wá si ọkàn wan ni pé: ṣe ó ni ààrun jẹjrẹ ni tàbí o ni sòòbìà?
Ibẹ ni ibujoko Bishoobu agba ijọ Aguda ni Paris.
A Musa lo fi aṣẹ ikilọ yii ranṣẹ ni ilu Abuja.
O ni lai si ore-ọfẹ ti oun n ri jẹ lara Alaafin ni, oun ko le di iru obinrin t'oun da lonii.
Ẹ jẹ́ kí gbogbo wọn pésẹ̀, kí wọ́n jáde wá.
'Mo pada si fasiti' Lẹyin ọpọlọpọ oṣu wiwa iṣẹ ti iwẹ ẹri rẹ ko si so eso rere, o pada si ilu Bahir Dar - lati bẹrẹ iṣẹ ti ko lero pe o le pada si.
O fun ara rẹ ni oye Field Marshal lọdun 1975 pẹlu ami irawọ marun un leti aṣọ rẹ Lẹyin ti wahala bẹ silẹ lọdun 1979 lo salọ ṣe atipo ni ilẹ Saudi Arabia to si ku sibẹ lọdun 2003.
Pius Adesanmi ní kò bá rọ́pò Wole Soyinka tí kò bá kú - ọmọ Naijiríà Ọ̀jọ̀gbọ̀n Pius Adesanmi kú nínú ìjàmbá bàálù Ethiopia!
Mo bá bèèrè pé, “Ta ni ẹni tí ó gbọ́n, tí òye nǹkan yìí yé?
Wọn óo máa gbààwẹ̀ nígbà náà.
Ọkùnrin tó ṣe òfegè fọ́nran àwòrán ìgbéyàwó Buhari pẹ̀lú Mínísítà d'èrò ilé ẹjọ́ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Sickle Cell In Nigeria: Makinde ní ìgbàgbọ́ ninú ìdílé òun ṣèdíwọ́ láti ṣàyẹ̀wò ẹ̀jẹ̀ O ní ìgbésẹ̀ gómìnà láti fòpin si owó ìfẹ̀yìnti fún àwọn gómìnà ànà àti igbákejì wọ̀n, ó jẹ́ ìgbésẹ̀ akin tí òun si fi gbogbo ara dúró ti gómìnà lórí ìgbésẹ̀ náà.
Lọpọ awọn oju opo itakun agbaye wọnyii, awọn obinrin, to fi mọ ọkunrin maa fi iroyin nipa ara wọn, iru ẹsin ti wọn n sin, ati iru ọkọ tabi aya, ti wọn n wa sita.
Ṣugbọn àwọn ẹbọ wọnyi ń mú ẹ̀ṣẹ̀ wá sí ìrántí lọdọọdun, 
Bakan naa ni wọn gbadura fun awọn ẹbi naa lati mu ọkan le, wi pe edua yoo wa pẹlu wọn.
“Ojú wọn ti fọ́,ọkàn wọn sì ti le;kí wọn má baà fi ojú wọn ríran,kí òye má baà yé wọn.
Oríṣun àwòrán, others Àkọlé àwòrán, Oloogbe naa ni Alaga ileeṣẹ Credit Switch Technology.
Yíyọ́ ẹkùn mi, tojo kọ́ o, ẹ jámí lórí ìwọ́de yín lẹ́yẹ́ ò ṣọkà, mo tí gbọ́ ohun tí ẹ ń sọ yékéyéké-Buhari Àwọn ọlọ́jà ń sèdárò Ìyálọ́jà ìpínlẹ̀ Oyo tó dolóògbé, wọ́n yan asojú míràn Tani Oke Obi-Enadhuze: tí orúkọ rẹ̀ gba orí ayélujára kàn lẹ́yìn wàhálà #Lekki tollgate?
 wón sì máa ńki àwon omo bíbí ìlé yìí ní  sagbá mutí sàwo mùko , sa eni -rere bátan sa àgbààgbà bárìn , àwa òní bá enití kò sunwòn tan nílé tiwa ."
Police officer raiding illegal cockfight : Àlàyé rèé bí ọlọ́pàá ṣé kàgbákò ikú gbígbóná lọ́wọ́ àkùkọ
Oríṣun àwòrán, Twitter/FRSC NIgeria Àkọlé àwòrán, Ọrọ ofon oju popo Ọga ajọ FRSC tun rọ awọn awakọ lati ṣiṣẹ pọ pẹlu awọn oṣisẹ eto aabo loju popo bi ọdun ti mbọ wa sopin.
Idẹ ni wọ́n fi ṣe gbogbo àwọn ìtẹ́lẹ̀ òpó rẹ̀; ṣugbọn fadaka ni wọ́n fi ṣe àwọn ìkọ́ ati àwọn ọ̀pá tẹ́ẹ́rẹ́tẹ́ẹ́rẹ́ wọn, fadaka ni wọ́n yọ́ bo àwọn ìbòrí wọn, fadaka ni wọ́n sì fi bo gbogbo àwọn ọ̀pá tẹ́ẹ́rẹ́tẹ́ẹ́rẹ́ fún aṣọ títa wọn.
Ojo arọọroda to rọ ni ọjọ kẹta, oṣu kẹsan an ọdun yii lo n jẹ ki ọkan awọn obinrin yii ma balẹ ni agbegbe Kirkissoye ni Niamey.
Lasiko yii, orin ilẹ alawọ dudu ati ijo wọn lo gbode kan, ti awọn obinrin adulawọ si ti n ri ara wọn bii arẹwa.
UI: Kélé yóò gbé ọkùnrin tó bá ń rin gb;eregbére lágbègbè ibùgbé obìnrin ní fásitì Ibadan
Kìnìhún fa èèyàn kan ya ní Nairobi, àdúgbò dàrú Aisha Buhari figbe ta,o ní pé Garba Sheu tí gbàbọde Ṣé lóòtọ́ ni pé wọ́n fi òfin de Uber àti Bolt ní pápákọ̀ òfurufú?
George Weah: Nàìjírìa fìyà jẹ Ààrẹ Liberia pẹ́lú ikọ̀ rẹ̀
Eyi ko seyin pe wọn maa n tun n da awọn eeyan gbajue bii Taiwo, Gbekuta ati awọn ọmọ ita miran silẹ ni lẹyin ti Tafa ati Lapade ba ti mu wọn tan.
Gomina naa ni iwadii ti bẹrẹ ni pẹrẹwu lati mọ bi awọn janduku ṣe ri aye wọ aarin awọn to n ṣe iwọde alaafia wọn.
Ti asẹ́ idẹ náà bọ abẹ́ etí pẹpẹ, tí yóo fi jẹ́ pé asẹ́ náà yóo dé agbede meji pẹpẹ náà sísàlẹ̀.
Ninu atẹjade lori oju opo Twitter rẹ, Buhari sọ pe oun ba awọn ara ati ẹbi awọn eniyan ti jaguda pa ni Ọjọ Ẹti kẹdun.
 “Ile-igbimo asoju sofin koi ti se agbekale igbimo asewadii lori okooju-omi ti o gbe awon ado-oloro ti o wa lati orile-ede Turkey”.
Davido ninu oro re ni “Inu mi dun lati so fun yin pe Olorun bukun ile Adulawo.
Adari ile-igbimo asofin lorile-ede Libya so pe, Saif Al-Islam Gaddafi, omo olori ijoba orile-ede Liibya teleri Muammar Gaddafi ti pegede lati dije fur ipo aare ninu eto idibo ti yoo waye ninu odun ti a wa yii.
Sugbọn nigba ti a bii pe ṣe wọn ti mọ awọn eniyan rẹ, Joseph ni wọn ko ti i mọ wọn.
Kuṣi ni baba Nimrodu, Nimrodu yìí ni ẹni kinni tí wọ́n mọ̀ ní akọni láyé.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Muhammadu Buhari: Ààrẹ Buhari tìrìn àjò dé lẹ́yìn àbẹ̀wò sílẹ̀ Gẹẹsi 5 Èbibi 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 6 Èbibi 2019 Oríṣun àwòrán, Facebook/Femi Adesina Àkọlé àwòrán, Muhammadu Buhari pada si Naijiria Aarẹ Muhammadu Buhari ti pada si orilẹede Naijiria lẹyin abẹwo ọlọjọ mẹwaa to ṣe silẹ Gẹẹsi.
Mo gbọ́ ohùn kan tí n kò gbọ́ rí: tí ó wí pé,
Ko si ọkọ bọọsi akero to gbọdọ gbe ero kun.
 o teju ofin orile-ede naa mole nipa pipe fun isokan Somaliland ati  SomaliaAwon egbe A-ja-fetomoniyan  ni Somaliland  so pe won  te eto omoniyan ,omidan  Qorane mole nipa esun ti won fi kan an yii, ti won si n pe lati da omidan  Qorane sile.
Kò mọ̀ wi pé ohun ngbẹ́ ikòtò ìṣubú fún ara rẹ́.
“Tó bá jẹ́ bẹ́ẹ̀, oun tó bá yá kìí tún pẹ́ mọ́n, oúnjẹ ọ̀hún dà?
Ọmọdebinrin ẹni ọdun mejila kan lo ṣe igbeyawo tipatipa pẹlu ọkunrin meji laarin oṣu kan ṣoṣo.
Sinimá àwòdamiẹnu, Ẹ̀fáńjẹ́líìsì jìyà àjẹmumi nílé aṣẹ́wó l'Ejigbo ní ìlú Eko Gbajúgbajà òṣèré “Blue film'' wọ gàù ẹ̀sùn fífipá bá obìrin 13 lòpọ̀ Èèyàn 239 míràn ṣẹ̀ṣẹ̀ kó COVID-19 ní Nàìjíríà Ọba Saudi Arabia yọ ọmọ rẹ̀ àti àbúrò rẹ̀ kúrò nípò nítorí ìwà àjẹbánu lórí owó tó yẹ fún ààbò ìlú Ìjàmbá ọkọ̀ tó ṣẹlẹ̀ sí Adams Oshiomole kìí ṣe ojú lásan, àwọn kan ló fẹ́ pa á- APC Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Yoruba World Congress: Mi o fi gbogbo ẹnu sọ pé ẹ̀yà Yorùbá yóò tún èrò rẹ̀ pa ní October 1- Akintoye28 Owewe 2020 6:18 Fídíò, Akomolede: Bolaji Faleke ni Olùkọ́ tó ń kọ́ wa ní àṣà oge ṣiṣe lórí BBC Yorùbá, Duration 6,181 Owewe 2020 Èyí tí a wò jùlọ 5:03 Fídíò, Omolola Arohunmolase Welder: Mo ti fí iṣẹ́ 'Welder' gbayì láwùjọ, tó mo fi tọ́ ọmọ yanjú, Duration 5,039 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 5:39 Fídíò, Akomolede ati Asa lori BBC: Olùkọ́ Kikelomo Ogunboye tan ìmọ́lẹ̀ sí ìwà olè ọ̀gá ọlọ́pàá Audu gẹ́gẹ́ bí àwòkọ́ṣe àsìkò yìí, Duration 5,398 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 4:11 Fídíò, Oba Adeyeye Ogunwusi: Ojú mi ti rí lọ́pọ̀ lọpọ̀, ọ̀pọ̀ èèyàn ni kò tilẹ̀ gbàgbọ́ pé mo lè jọba- Ooni, Duration 4,117 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 4:43 Fídíò, Promise Akinlade: ọmọ ọdún mọ́kànlá tó ń fi ìlù dárà bíi àgbàlagbà sọ̀rọ̀ nípa tálẹ́ǹtì rẹ̀, Duration 4,437 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 0:59 Gbọ́, Ìsẹ̀lẹ̀ jákèjádò orílẹ̀èdè àgbáyé láàárín ìṣẹ́jú kan, Duration 0,59wákàtí 5 sẹ́yìn 7:03 Fídíò, Olumuyiwa Bolade Adedeji Military Bruitality: Bí arákùnrin onípèníjà ara tí sọ́jà lù ṣe dé, Duration 7,035 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 4:45 Fídíò, Yoruba Films: Ẹ̀ẹ́ bẹ̀ mi kúrò láyé ni, mi ò lè kú - Fadeyi Oloro, Duration 4,4526 Èrèlè 2020 2:48 Fídíò, Esther Ajayi: Èmi náà ti borí ìṣòro rí ló ń mu mi ṣojú àánú, Duration 2,481 Ògún 2019 6:08 Fídíò, Adebola Ademilua: Àìrísẹ́ ṣè lẹ́yìn ìwé kíkà ló sọ mi dí ìyá onírú, mo dúpẹ́ tèmi, Duration 6,0827 Bélú 2020 5:55 Fídíò, Soyinka Cancer: Àṣe ara mi ni iso ti n run gbogbo bí mo ṣe n ṣèrànwọ́ lórí jẹjẹrẹ, Duration 5,5527 Bélú 2019 BBC News, Yorùbá Ìdí tí ẹ fi le è nígbàagbọ́ nínú ìròyìn BBC Ìlànà Lílò Nípa BBC Òfin Àṣírí Cookies Kàn sí.
  Wayii o, akowe agba ajo to n mojuto oro abele, Georgina Ehuriah wa ro oga agba naa lasiko to n ki ku oriire itesiwaju lenu ise ohun, lati tesiwaju ninu ise takun-takun re, paapaa julo lati wa ni ibamu pelu afojusun aare Muhammadu Buhari lojuna ati mu idagbasoke alailegbe ba gbogbo eka lolokan-o-jokan lorile-ede Naijiria.
Ko si ina, ko si omi, ko si ile igbọns bẹẹ ni ko si imọtoto kankan.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Kayeefi: Òtítọ́ àti irọ́ wo ló wà nípa oògun owó àtàwọn ìṣẹ̀lẹ̀ kàyééfì míràn Epe ti Alaafin Aole ṣẹ fun iran Yoruba: Gẹgẹ bi iwe itan ti ẹni-ọwọ Samuel Johnson ti sọ ninu iwe Itan Ẹya Yoruba to kọ, o ni ki Aole to si igba wo, o pe oriki ati ipọnri awọn baba nla rẹ ati awọn Alaafin to ti jẹ saaju rẹ.
Ikú tí yóò pamí,kìí ṣe ti Ẹ̀bólà
Bakan naa ni wọn n reti ki awọn gomina ipinlẹ koowa wọn, ki wọn buwọlu ofin naa fun lilo.
Ó tún sọ onírúurúu àwọn nǹkan mìíràn tí yóò jẹ́ ìṣòro fún wa; ó sọ̀rọ̀ nípa àwọn iwin burúkú àti àwọn ẹyẹ àjèjì, àwọn ẹranko ajẹ̀nìyàn àti àwọn kòkòrì olóró.
Oríṣun àwòrán, @pius Àkọlé àwòrán, Aarẹ Buhari kede fifi orukọ MKO Abiola pe papa iṣere Abuja Aarẹ Buhari ni oun ti jagun Boko Haram de ibi to lapẹrẹ lati 2015.
lo anfaani yii lati ki awon omo orile ede Naijiria ku odun keresimesi ati odun
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Àṣìlò òògùn: Ará ìlú sọ oun tó ń sún wọn dé'dí ìwà yí 18 Owewe 2018 Oríṣun àwòrán, Guardian Nigeria Awọn oniṣegun oyinbo ti n bẹnu atẹ lu aṣilo oogun lati ọjọ to ti pẹ, ṣugbon awọn ara ilu to ba ikọ BBC sọrọ ni wahala ti oju awọn n ri ti wọn ba lọ ile iwosan lo faa ti awọn fi di ẹni to n ṣi oogun lo.
Olu Jacobs: Oríṣun àwòrán, Others Ọrọ iku Olu Jacobs lo gba ilẹ kan bayii ti awọn eeyan n gbe kiri loju opo ayelujara amọ to jẹ pe irọ nla to jinna sootọ ni nitori aya rẹ, Joke Jacobs ti kede faraye pe ko ko ko ni ara ọkọ oun le, ko ku rara.
Wolii naa, to maa n sọ asọtẹlẹ lọdọọdun nipa awọn isẹlẹ ti yoo waye ninu ọdun tuntun tun salaye pe awọn agbegbọn yoo tubọ kọlu ilu Abuja lọdun 2021.
Ogun ló ń wáyé ní Kogi, kìí ṣe ìbò dídì - Olùdíje gómìnà Lai Mohammed: A kò ní bojú wẹ̀yìn lórí àbádòfin ìṣàkóso ẹ̀rọ ayélujára Ìbínú ẹlẹ́wọ̀n!
Pẹlu irinajo eniyan meji lọ si ibi to larinrin ti owo rẹ yoo to miliọnu marundinlaadọta Naira.
ASUU ń lérí ìyanṣẹ́lódì lórí ọwọ́jà ìjínigbé lórílẹ̀èdè Nàìjíríà Olùkọ́ fásitì OAU mórí bọ́ lọ́wọ́ àwọn ajínigbé Ta ló ji òṣìṣẹ́ kánsù gbé l'Ekiti?
“Bí ẹnìkan bá gbẹ́ kòtò sílẹ̀, tí kò bá bò ó, tabi tí ó gbẹ́ kòtò tí kò sì dí i, bí kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ tabi mààlúù bá já sinu kòtò yìí, tí ó sì kú, 
O ni ile Franse ni lati sọrọ pọ pẹlu ilẹ Gẹẹsi bayii lori bi ajọṣẹpọ orilẹede mejeeji lati igba asiko lọ yoo ṣe ri.
Awọn olólùfẹ́ wọ́n nínú eré tíàta àti láwùjọ ló ti n bá àwọn gbájúgbajà òṣèré méjèèjì dáwọ idùnú.
Igbagbọ wa pe ilu Daura lo ti bẹrẹ.
Obìnrin Mùsùlùmí ṣe ilé àlúfà ní ọ̀ṣọ́ fún Kérésìmesì Àwọn gómìnà nílẹ̀ Yorùbá ti kùnà láti pèsè ààbò tó péye fún aráàlú - Ẹgbẹ́ Majeobaje Orúkọ Leah Sharibu ló ń léwajú lójú òpó twitter, tí olókúlùkù sì ń gbà ìjọba nimọ̀ràn láti lo àwọn Miyetti Allah ti wọ́n lò láti bá agbegbọn sọ̀rọ̀ fún ìtúsílẹ̀ àwọn ọmọ Kankara náà ni kó yanjú ti Leah Sharibu.
Oríṣun àwòrán, Rotimi Akeredolu Facebook Jàńdùkú olóṣèlú gbàkóso ilé aṣòfin l'Ondo Awọn janduku oloselu ti gba akoso ile asofin nipinlẹ Ondo, ti wọn si n da idarudapọ silẹ nibẹ Iroyin to n tẹ wa lọwọ ni o le ni ọgọfa awọn tọọgi naa ti wọn gbarodan siwaju ile asofin ọhun, pẹlu ogunlọgọ ọkọ ayọkẹlẹ wọn.
Pásítọ̀ gún ìyàwó rẹ̀ lọ́bẹ nínú ṣọ́ọ̀ṣì, ló bá tì í bọ ara rẹ̀ náà níkùn Oríṣun àwòrán, AFP Dokita Micheal Baden to jẹ oṣiṣẹ fẹyin ileeṣẹ ayẹwo oku ni ilu New York, to tun jẹ ọkan lara awọn meji to yẹ oloogbe Floyd wo ṣalaye pe ko ba ti kede pe o laarun naa ti ko ba ṣe pe o di pataki lati lee jẹ ki gbogbo awọn to ti ni ohun kan tabi omiran lati se pẹlu rẹ nigba aye rẹ o mọ igbesẹ to tọ latigbe bayii.
Wolii Lòdì sí Ẹ̀ṣẹ̀ Àwọn Eniyan.
Nítorí ó wà ninu Ìwé Mímọ́ pé,“Mo fi òkúta lélẹ̀ ní Sioni,àṣàyàn òkúta igun ilé tí ó ṣe iyebíye.
" ni ọ̀rọ̀ ikẹyin tí Michael Asiwaju ti àwọn ọmọbirin kan fi ẹsun ifipabanilopọ kan lori Twitter fi si oju opo Twitter tirẹ ni ọjọ Kejila oṣu kinni ọdun yii.
Ilé ẹjọ́ dájọ́ ikú fún àwọn tó pa Tìmílẹ́hìn, akẹ́kọ̀ọ́ fásitì UNIOSUN l'Oṣogbo
OLUWA tún sọ fún Elija pé, 
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Eko: A ti din lara owo-ori ilẹ ati ile ku 15 Ẹrẹ̀nà 2018 Oríṣun àwòrán, @AkinwumiAmbode Àkọlé àwòrán, Gomina se ileri lati se awọn akanse isẹ tuntun mii Ijọba ipinlẹ Eko ti sọ wipe awọn ti din owo ori ilẹ ati ọkọ ku ni ipinlẹ Eko, gẹgẹbi ipinnu wọn lati bẹrẹ si ni gba owo ori naa laipẹ.
APC Ekiti pàṣẹ lọ rọ́ọ́kún nílẹ̀ fún àna Tinubu àti Babafemi Ojudu Ọgbọ̀n ọdún ni mo fi ṣe iṣẹ́ púlọ́mbà kí n tó dí Gomina ìpínlẹ̀ Eko - Babajide Sanwo-Olu Ẹ dín iye ìgbà tẹ n gorí obìnrin kù torí ìdìbò tó n bọ̀, kẹ́ẹ lè lágbára láti ṣe .
Ọpọlọpọ àwọn ọdọlangba agbabọọlu Naijiria lo wu wọn lati maa gba bọọlu fun ẹgbẹ nilẹ okeere ṣugbọn awọn onijibiti kan n fi wọn jẹun lasan ni.
Oríṣun àwòrán, royzkingin / Twitter Ara ọna tawọn ọdọ yii si n gba fi ẹhonu han ree lati tako ipo ti orilẹede Naijiria wa lọwọ lọwọ bayii.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Oronpoto Animation: Akin Alabi ní kò dára bí eré aláwòrán fáwọn ọmọdé ṣe jẹ́ aláwọ̀ funfun Tani Kaisha ọmọbìnrin Hausa yii?
O ni iwaadi ṣi n lọ lori ọrs naa ṣugbọn ko si otitọ ninu ọrọ ti awọn eeyan naa n sọ pe arakunrin ọhun ti poora kuro ni ahamọ ọlọpaa, o si ti yirapada di ẹyẹ igunugun ti n da araalu laamu Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Nitori naa si ni ko sẹ le pa idunnu ati ayọ rẹ mọra, bi awọn ọmọ naa ṣe pe ọdun mejila loke eepẹ, ati ninu aafin baba wọn.
Ni ọdun 2017 ni wọn dibo yan an si ile igbimọ aṣofin ilẹ Gẹẹsi lati ṣoju fun ẹkun Saffron Walden.
Nígbà tí Jesu rí ìyá rẹ̀ ati ọmọ-ẹ̀yìn tí ó fẹ́ràn tí wọ́n dúró, ó wí fún ìyá rẹ̀ pé, “Obinrin, wo ọmọ rẹ.
Ṣugbọn bo ti ṣe aseyọri to lori aleefa, Ajimobi jẹ alawada ọkùnrin, to si maa n fi awada agbekalẹ awọn ọrọ rẹ, eyi ti ọpọlọpọ eeyan maa n si i gbọ, ti ọrọ rẹ si maa n bọ sapo ibinu wọn.
Wọ́n bá dáhùn pé, “Ẹ wá, kí á gbìmọ̀ ibi sí Jeremaya, nítorí pé òfin kò ní parun lọ́dọ̀ àwọn alufaa, ìmọ̀ràn kò ní tán lọ́dọ̀ àwọn ọlọ́gbọ́n, ọ̀rọ̀ Ọlọrun kò sì ní ṣàì máa wà lẹ́nu àwọn wolii.
Àwọn ìgbìmọ̀ wá ń bi ara wọn pé, 
Ṣugbọn kọmiṣọnna sọ pe o yẹ kawọn eeyan mu ọrọ ilera ara wọn lọkunkun lai jẹ wi pe wọn n fipa mu wọn.
 aláàbò ; otùsó bí mo se rìn dé ìtèdó àwon omo ogun náà , àwon olùsó náà dá mi dúró .
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí ‘Irọ́ ni Tinubu ń pa, PDP ló ni ilẹ̀ Yorùbá’ Bàbá ọlọ́mọ márùn-ún pokùn so ní Ekiti Samuel Ladoke Akintọla nìyìí, ọmọ Yorùbá olóṣèlú pàtàkì Owo ti wọn fi n gba fọọmu ati wọ ile iwe giga tẹlẹ JAMB yoo di ẹgbẹrun mẹta aabọ naira lati ẹgbẹrun marun un.
Oríṣun àwòrán, Getty Images 3) Rọ lapa rọ lẹsẹ: Dokita Ibeneme sọ pe ti eeyan ba n ni ibalopọ pupọ paapa ẹni to ba ni ifunpa to ga, o le ṣakoba fun un .
Nítorí èmi OLUWA àwọn ọmọ ogun, Ọlọrun Israẹli sọ pé kí ẹ má jẹ́ kí àwọn wolii ati àwọn tí wọn ń woṣẹ́ láàrin yín tàn yín jẹ, kí ẹ má sì fetí sí àlá tí wọn ń lá; 
O wa rọ awọn eeyan Kano lati fi to ijọba leti, ti wọn ba ṣakiyesi iru ile ọmọ alailobi bẹẹ lagbegbe wọn.
Fayemi ni ọjọ kẹsan an, oṣu kinni, ọdun 2020 ni eto naa tawọn gomina mẹfa apa gusu orilẹ-ede Naijiria iwọ oorun ṣe agbakalẹ rẹ yoo bẹrẹ kaakiri ilẹ Yoruba.
Òun ní kí àwa máa wí pé: ‘Ìjàǹbá’ òun á máa wí pé ‘Forítì’.
Gomina mọ́kàndínlógún  lo ti so pe awon ko dije fun ipo gomina mọ,
Atiwipe ibẹ ni olu-ibugbe wọn, ibẹ ni wọn si ko awọn ọmọ Chibok pamọ si.
Báyìí, Adajo Mayomi Olanipekun ilé ẹjọ́ Magiisirate Kẹta kọ lati gba beeli rẹ, tí o si ni kí o sì lọ ṣeré lọgba ẹ̀wọ̀n fún ìgbà díè.
pẹlu gbogbo àwọn ẹranko, gbogbo àwọn ohun tí ń rìn káàkiri lórí ilẹ̀ ati àwọn ẹyẹ.
 O wa ṣeeṣe ki nkankan ma ṣẹlẹ ni kiakia lẹyin jijẹ tabi lilo nkan ti ọjọ ori rẹ ti kọja."
Ó ní, “Ó sàn kí n kú ju pé kí n wà láàyè lọ.
Jehoaṣi kú, wọ́n sin òkú rẹ̀ sinu ibojì àwọn ọba ní Samaria.
Dafidi jáde, ó pè é, ó ní, “Olúwa mi ọba,” bí Saulu ti wo ẹ̀yìn ni Dafidi dojúbolẹ̀ láti bọ̀wọ̀ fún un.
Ẹ ̀ sìn ìgbàgbọ ́ ló fẹ ́ rẹ ̀ tan kálẹ ̀ jù ní gbogbo àgbáyé .
“Ti e ba ni iru iko to n kopa daradara bayii, ti o tun fagbahan iko agbaboolu Iceland ti o dipo ogun mu lagbaye ninu ipo ate ajo FIFA, ti awa si wa nipo mọ́kàndínláàdọ́ta lori tabili, eleyi ni itumo pupo simi.
Wọ́n wá bi í pé, “Kí ni kí á ṣe kí á lè máa ṣe iṣẹ́ Ọlọrun?
Gbogbo wọn ni yóo ṣègbé papọ̀.
OLUWA sọ fún Mose pé, “Fi idẹ rọ ejò amúbíiná kan, kí o gbé e kọ́ sórí ọ̀pá gígùn kan, ẹnikẹ́ni tí ejò bá bù jẹ, tí ó bá wo ejò idẹ náà yóo yè.
Àti pé, ojú ẹni tí ìyà ń jẹ ni wọ́n máa ń ṣábàá fi wo ẹni tí ń gun kẹ̀kẹ́ ní ilẹ̀ Yorùbá.
Oríṣun àwòrán, Ooni ile ife Àkọlé àwòrán, Ní ọjọ́ kẹrìndínlọ́gbọ̀n oṣù kẹwàá ọdún 2015 ni wọ́n kéde orúkọ rẹ̀ gẹ́gẹ́ bíi ọmọ oyè tí ifá mú Ohun mẹta ni o farahan ninu awọn ohun ti Ọọni Adeyẹye Ogunwusi Ọjaja II gbajumọ julọ ni i.
CJN: Ilé aṣòfin ti buwọ́lu Tanko Muhammad gẹ́gẹ́ bi adájọ́ àgbà Nàìjíríà
Kí olukuluku yín pada sí ilé rẹ̀ nítorí èmi ni mo jẹ́ kí ọ̀rọ̀ yìí ó ṣẹlẹ̀.
papa ofufuru yii fun igbadun awon arinrinajo.
Koda wọn ni oun ati awọn gende to ko so sẹyin wa sibẹ ni, ti meji ninu wọn si ni awọn ri ìbọn lọwọ rẹ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Mr Latin wọlé di ààrẹ ẹgbẹ́ tíátà, TAMPAN 23 Ọ̀pẹ̀̀ 2018 Oríṣun àwòrán, MR LATIN Bọlaji Amuṣan, Mr Latin ti sọ pe afojusun oun gẹgẹ bi aarẹ ẹgbẹ Theatre And Movies Practitioners Association of Nigeria (TAMPAN) ni lati ri daju pe awọn ọmọ ẹgbẹ n ṣe nkan ti awọn araalu fẹ lati ọdọ wọn.
"To ba ti to asiko ti wọn da, oriṣiriṣi ọna ni awọn ẹgbẹ wọn ma n gba yọju si wọn, ti wọn o si ma a sọ fun wọn pe ""asiko ti to, ma a bọ""."
''Ifarabalẹ ati fifi tọkan-tọkan ṣe isẹ pẹlu ifarajin lo ran wa lọwọ lasiko tiwa, gbogbo ohun ti eeyan ba fẹ ṣe, ki o ri wi pe ohun sun mọ Ọlọrun'' Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Kemi Dairo: Iṣẹ́ abẹ nínú ọpọlọ àti ẹ̀rọ ni mo fi ń gbọ́ ọ̀rọ̀ báyìí Nipa iroyin iku Obey rẹ: Ebenezer Obey ni eyi kii ṣe igba akọkọ ti awọn eeyan yoo ma sọ ahesọ ọrọ nipa oun.
BBC Yoruba gbọ pe lati igba ti D.
“Ẹnikẹ́ni tí ó bá jẹ́ ohun ìkọsẹ̀ fún ọ̀kan ninu àwọn kéékèèké wọnyi tí ó gbà mí gbọ́, ó sàn fún un kí á so ọlọ ńlá mọ́ ọn lọ́rùn, kí á sọ ọ́ sinu ibú òkun.
Lizzy vs Toyin: Yomi Fabiyi ní òun fa obì yọ lápò láti bá Toyin sọ̀rọ̀ kó parí ìjà pẹ̀lú Lizzy
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ibà Lassa wọ ìpínlẹ̀ Èkó!
” Wọ́n pín aṣọ rẹ̀ mọ́ ara wọn lọ́wọ́, wọ́n ṣẹ́ gègé láti mọ èyí tí yóo kan ẹnìkọ̀ọ̀kan wọn.
Lẹ́yìn náà, wọ́n lọ sí Dani.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Edo after election: Àwọn aṣòfín ní ìpínlẹ̀ Edo ti yọ Abẹnugan Ilé, Francis Okiye bí jìgá 12 Ọ̀wàrà 2020 Oríṣun àwòrán, Facebook Ile Igbimọ Aṣofin ni ipinlẹ Edo ti yọ Abẹnugan Ile, Francis Okiye kuro ni ipo.
Àjọ NIDCOM rọ àwọn òbí láti má ran ọmọ lọ kàwé ni Northern Cyprus mọ́
Nigba to n fesi lori ẹsun naa, olori ile ni irọ to jinna si ootọ lawọn ẹsun naa, nitori ile asofin fi ọwọ si awọn ọkọ ti wọn ra fawọn asofin ati inawo miran.
Ìtàn ìgbé ayé Bode Thomas rèé, ó kọ́ wa láti máa kó ẹnu wa ní ìjánu Harry àti Meghan kò ní lo orúkọ oyè wọn mọ́, wọn kò sì lẹ́tọ̀ọ́ sí owó ilú mọ́ ní UK Ààfá mẹ́ta réwọ̀n hé nípa ṣíṣe ìrànlọ́wọ́ òjijì fún obìnrin kan pẹ́lù 36 mílíọ̀nù náìrà Wo àwọn krìstíẹ́nì tó n wẹ̀ nínú odò tó ní yìnyín láti ṣàjọyọ̀ ìrìbọmi Jesu Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Super touch: Roller Blader ni mí láti ọdún mẹ́jọ sẹ́yìn Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Abileko Stella Okoh-Esene to je alaga egbe NAWOJ bayii ni: “Ogbon ju agbara lo, eyi ni a se seto idanilekoo yii fun gbigbogunti arun jejere ki awon obinrin le ni ifokanbale lori ilera won”.
Ìgbà tí mo jí tí mo wo ọbẹ̀ mi àwọn ẹja wọn-ọnnì ti yípada wọ́n dúdú pẹrẹpẹrẹ.
Bakan naa lo sọrọ lori yiyan ti Ajimọbi yan awọn eeyan sipo ẹgbẹ ni awọn agbegbe bii Igboho, Kiiṣi, Oke Iho, Isẹyin, Iwere Ile, Tede, Igbẹti ati bẹẹ bẹẹ lọ.
Nígbà náà ni gbogbo àwọn ará ilẹ̀ Midiani ati àwọn ará ilẹ̀ Amaleki ati àwọn ará ilẹ̀ tí ó wà ní ìhà ìlà oòrùn kó ara wọn jọ, wọ́n la odò Jọdani kọjá, wọ́n sì pàgọ́ wọn sí àfonífojì Jesireeli.
OLUWA rán Natani wolii sí Dafidi.
Ìwà burúkú wọn ń jó bí iná,tí ń jó ẹ̀gún wẹ́wẹ́ ati ẹ̀gún ọ̀gàn.
 Gbogbo awon ewe yii n fun mi ni ireti ojo iwaju rere fun Naijiria bi won se po to”.
Peckham jẹ agbegbe kan ti o kun fun ọpọlọpọ ọmọ Naijiria atawọn ọmọ ilẹ adulawọ mii.
Ninu ifọrọwerọ Iya Oṣogbo lori eto ori redio kan, iyawo agba-ọjẹ oṣere Oyin Adejobi ni, nnkan bii ọdun mẹtadinlaadọta loun bẹrẹ ere ori itage.
OLUWA ní, “A óo tún gbọ́ ohùn ayọ̀ ati inú dídùn ninu ìlú Juda ati ìgboro Jerusalẹmu, tí ẹ sọ wí pé ó ti di ahoro, tí kò sí eniyan tabi ẹranko tó ń gbé inú wọn.
O ṣalaye pe àwọn mejeeji ti maa n ja fún ọpọlọpọ igba lataari igbonara Damilọla iyawo rẹ to jẹ ọmọ ọdun mẹtalelogun.
Bakan naa ni wọn rọ awọn asofin tuntun yii ati awọn asaaju wọn lati fọ̀wọ sowọpọ pẹ́lu ẹka alasẹ, nitori awọn ko fẹ ki aawọn to waye lasiko ile asofin kẹjọ, tun gberi mọ.
    Ní alẹ́ ọ̀jọ̀ náà, ni nǹkan bí agogo méje, a tún ránṣẹ́ lọ sí ààfin láti ba wa wò bí ọba bá ti dé, nígbà tí oníṣẹ́ wa padà ó wí fún wa wí pé ọba kòì tíì dé.
Wọn ni awọn Maalu nla meji ti wọn ji ko naa to ẹgbẹrun lọna ẹẹdẹgbẹta ti wọn ba ta wọn (#500, 000) ti wọn ba ta wọn lasiko yii.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Àwòrán Amosun, Adekunle àti Buhari tó n dá awuyewuye sílẹ̀ 6 Sẹ́rẹ́ 2019 Oríṣun àwòrán, @AHMAD BASHIR Àkọlé àwòrán, Aworan yi n kan awọn ọmọ ẹgbẹ APC kan lominu Lọjọ́ Aiku ni Gómìnà ìpínlẹ̀ Ogun, Ibikunle Amosun kọwọrin lọ si ọdọ Aarẹ Buhari pẹlu oludije Gomina ayanfẹ rẹ Adekunle Akinlade.
Sugbọn lọdọ Enefiok Bassey, ko sí ohun tó buru nínú ṣíṣe bẹẹ.
Femi Adesina , oluranlowo aare  lori iroyin ati ikede  fesi lori  oro ti Obasanjo so pe, ijoba Muhammadu Buhari ti kuna nibi isejoba re.
Koda, wọn tun ke si ra lati jọ ya foto pọ.
Láàrin àwọn orílẹ̀-èdè tí wọ́n yí yín ká ni ẹ ti lè ra ẹrukunrin tabi ẹrubinrin.
Bákan náà ni, ẹni òmìnira tí a pè láti di onigbagbọ di ẹrú Kristi.
Ó wá mọ̀ nígbà náà pé OLUWA ni Ọlọrun.
Nibi ikede to ba awọn oniroyin sọ nileejọba ipinlẹ Eko, gomina Sanwo-Olu ni bẹrẹ lati ọjọ Satide, agogo mẹjọ owurọ si mẹfa irọlẹ ni konile o gbele naa yoo maa wa bayii.
Ní ọjọ́ keje, yóo wẹ̀, yóo sì di mímọ́.
Biodun Fatoyinbo fi ipò sílẹ̀ lorí ẹ̀sùn ìfipábánilòpọ̀ Ìlú tí ọ̀daràn bá tí dẹ́ṣẹ̀ ló yẹ kí wọn tí gbẹjọ́ rẹ̀ -Agbẹjọ́rò Ìjọ Satani dá MI lóhùn lórí ọ̀rọ̀ Fatoyinbo Ẹ padà sílé èyin ọmọ wa tó n ṣiṣẹ́ darandaran - NEF ti Fulani O ni pataki idi ti wọn ṣe kọkọ fẹ ṣe iwọde naa ni tori pe awọn gbọ pe awọn olori ajọ CAN ni wọn n ṣatileyin fun pasitọ Biodun Fatoyinbo ni eyi ti wọn gba pe ko yẹ ko ri bẹẹ.
Lẹ́yìn ọdún kan, wọ́n rí Nnamdi Kanu ni Israel Oríṣun àwòrán, Elliot Ugochukwu-Ukoh Fidio kan ti ṣafihan ọkunrin kan ti wọn sọ pe o jọ Nnamdi Kanu, to jẹ olori ẹgbẹ to n polongo fun idasilẹ orilẹede Biafra, IPOB ni orilẹede Israel.
Ṣugbọn lonii, o ti di ibi ti wọn nko awọn ti wọn ran lẹ ẹwọn si to si ti wa n sọ ti ijakulẹ orilẹede naa gẹgẹ bi ile ile nla to niyi ju ni ẹkun Latin America ati ibi ti idarudapọ ti wa n ṣẹlẹ.
Dybala ni agbabọọlu Juventus kẹta ti yoo larun naa lẹyin Daniele Rugani ati Blaise Matuidi ti kọkọ lufgbadi arun ọhun.
Wo ìdí to fi gbọdọ̀ yàgò fún Bobrisky, akọ tó ń ṣe bíi abo Sùgbọ́n Idris Olarewaju okuneye tí gbogbvo ènìyàn mọ si Bobrisky ti jáde síta bayiìí láti sọ ipo to wà fún gbogbo ayé yálà obinrin ni o tàbi ọkunrin.
"cysticercosis jẹ ́ àkóràn àrùn inú ẹran ara , èyítí ọmọ inú ( cysticercus ) aràn mùjẹ ̀ mùjẹ ̀ pẹlẹbẹ inú ẹran ẹlẹ ́ dẹ ̀ ( "" taenia solium "" ) má a nṣe òkùnfà rẹ ̀ ."
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Murtala Muhammed international Airport 2 Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Bí aya bá kọ ọkọ rẹ̀ silẹ̀, kó wà láì lọ́kọ̀' Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
O ni gbogbo ohun tawọn kan n gbe kiri nipa ilera rẹ lati bi ọsẹ diẹ sẹyin kii ṣe ootọ.
” Ajo to n mojuto eto irinna tun so pe  awọn  ti n se isẹ lori ibi ti baalu naa yoo maa gba, ibi ti yoo maa balẹ si, bi wọn  yoo se maa mojuto ati ile-ise ti yoo maa lo o lati fi pawo.
Ayọ̀ ń bẹ fún ẹni tí ó wá ọgbọ́n rí,ati ẹni tí ó ní òye.
Wọ́n pọ́n ahọ́n wọn bí idà,wọ́n ń sọ̀kò ọ̀rọ̀ burúkú bí ẹni ta ọfà;
He called me in Copenhagen and told me categorically that I was going to be arrested on returning home and, therefore, advised me not to return home.
Ipade igbimo ijoba apapo, ti won mojuto eto oro aje isakoso saa keji aare buhari, eleyi ti igbakeji aare ojogbon  Yemi Osinbajo tuko re, waye lonii ti n se ojoRU(Wednesday), ojo kejidinlogbon, osu kejo, odun 2019.
Nígbà tí àwọn iranṣẹ Absalomu dé ọ̀dọ̀ obinrin náà, wọ́n bi í pé, “Níbo ni Ahimaasi ati Jonatani wà?
Ṣugbọn àwa kò sí ninu àwọn tí wọn ń fà sẹ́yìn sí ìparun.
Eruku ọrọ naa ko ti lọ silẹ, ti fidio kan tun jade bayii ninu eyi ti iranṣẹ Ọlọrun miran, ti n beere fun ilaji miliọnu kan naira lọwọ awọn akẹkọ gẹgẹ bii eso fun Ọlọrun.
Àjọ tó ń ṣètò ìdánwò àṣe wọlé sí ilé ẹ̀kọ́ gíga, JAMB ṣẹṣẹ kéde pe awọn ileewe to ba fẹ ṣe idanwo Post UTME ko gbọdọ bẹrẹ titi di Ọjọ Keje, Oṣu Kẹsan an, ọdun yii.
Ẹwẹ, niṣe lawọn ọm Naijiria to fi mọ awọn to n gbe lẹyin awọn ologun yii fun gbogbo ohun ti wọn n la kọja tu sori ayelujara lati wu aworan iwe ti ileeṣ ologun fi sita fun orukọ awn to fẹ fi silẹ.
Jẹ́ kí mànàmáná kọ, kí o sì tú wọn ká,ta ọfà rẹ, kí o tú wọn ká.
Bi awọn ipinlẹ to ni Coronavirus ṣe lọ ree: Lagos-117 FCT-40 Ondo-35 Rivers-28 Osun-24 Benue-21 Abia-19 Ogun-19 Ebonyi-18 Delta-17 Kwara-17 Kaduna-15 Anambra-14 Ekiti-11 Kano-9 Imo-6 Gombe-4 Oyo-3 Taraba-3 Bauchi-1 Edo-1 Nasarawa-1 Àkọlé àwòrán, Bí Coronavirus ṣe n ṣe ni Afrika láti oṣù mẹ́fà sẹ́yìn Èèyàn 290 míràn ló ṣẹ̀ṣẹ̀ fara káásá àrùn Covid-19 ní Nàìjíríà, 160 gbàwòsàn Ajọ to n gbogun ti ajakalẹ arun lorilẹ-ede Naijiria, NCDC ti kede eeyan mẹwaa din ni ọọdunrun lo ṣẹṣẹ lugbadi arun Covid-19 ni Naijiria.
Oríṣun àwòrán, @Chinasanworu Bakan naa ni wọn tun jo ọọfisi awọn VIO ni Ojodu, ile ẹjọ magisireti ni Igbosere, ileeṣẹ iroyin TVC ati The Nation, ati bẹẹ bẹẹ lọ.
Ẹ máṣe gba ààwẹ̀ dójú ikú, ẹ gba iye tí agbára yín gbé - Dókítà Omíyalé àgbàrà ti ya ṣọ́ọ̀bù ní Niger Wọ́n gbé Akọ̀ròyìn ní Morocco lọ sílé ẹjọ́ lórí ẹ̀sùn àgbèrè àti oyún ṣíṣẹ́ Ìdí rèé ti Nàìjíríà fí ń gbé inú òkùnkùn Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Osun elections: Ademọla Adeleke, Fayoṣe, Atiku sọ̀rọ̀ lórí ìdájọ́ ilé ẹjọ́ 22 Ẹrẹ̀nà 2019 Oríṣun àwòrán, Davido Àkọlé àwòrán, Ilé ilé ẹjọ́ tó ń gbọ́ ẹjọ́ ìdìbò gómìnà ìpínlẹ̀ Ọṣun ti kede oludije fun ẹgbẹ oṣelu PDP gẹgẹ bii gomina ti ilu dibo yan ni Ọ̀ṣun Ẹni ti ile ẹjọ ṣẹṣẹ kede pe ilu dibo yan gẹgẹ bii gomina ipinlẹ Ọṣun, Sẹnetọ Ademọla Adeleke ti ṣalaye pe Ọlọrun ni oun fi ọpẹ fun lori idajọ to waye naa.
 Àwọn ìlépa míìràn ni láti dín iye àwọn eṣinṣin kù nípa fífí wọn ogùn apa kokorò .
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Genotype test: Ilé aṣòfin kàn án nípá fáwọn tó fẹ́ ṣèyàwó láti ṣàyẹ̀wò ẹ̀jẹ̀ 15 Bélú 2019 Àkọlé àwòrán, Genotype test: Ilé aṣòfin kàn án nípá fáwọn tó fẹ́ ṣèyàwó láti ṣàyẹ̀wò ẹ̀jẹ̀ Dandan lowo ori; tulaasi laṣọ ibora.
Lẹ́yìn náà, mo rí ọ̀pọ̀ eniyan tí ẹnikẹ́ni kò lè kà láti gbogbo orílẹ̀-èdè ati ẹ̀yà, ati oríṣìíríṣìí èdè, wọ́n dúró níwájú ìtẹ́ náà ati níwájú Ọ̀dọ́ Aguntan.
Àwọn mejidinlogun ni ó gbé ní iyawo, o sì ní ọgọta obinrin mìíràn.
Kí ẹ sọ fún wọn pé, ‘Ìjọba Ọlọrun ti dé àrọ́wọ́tó yín.
Ṣugbọn, Olórí Alufaa nìkan ní ó máa ń wọ inú àgọ́ keji.
Ẹni ọdún mọkanlelogun ni Sedekaya nígbà tí ó jọba.
Eyii ni awọn ohun to yẹ ki o mọ ti o ba fẹ ṣe iforukọsilẹ fun eto ọhun.
Àwọn nǹkan tí obìnrin lè ṣe pẹ̀lú olólùfẹ́ oníwà ipá lásìkò ìgbélé Coronavirus yìí Kí lo mọ̀ nípa fẹntilétọ̀, ohun eèlò aṣèrànwọ́ èémí Coronavirus and OCD: 'Mo fi ogún ọdún gbáradì fún àjàkálẹ̀ ààrùn yìí' Eyi lo mu BBC wo awọn orilẹ-ede to fofin de awọn obinrin lori awọn ohun kan tẹlẹ, sugbọn ti wọn ti gba awọn obinrin laaye lati ṣe awọn ohun naa bayii.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Gbáko!
Wọ́n ti gbé òkú àwọn méjéèjì lọ mọ́ṣúárì jẹ́nẹ́rà tó wá ní Ìjẹ̀bú.
”“Awon itan ilu  ati agbegbe yii  lee maa je tuntutn si wa, sugbon akọsilẹ re yoo ni ipa pataki ti yoo ko fun awon to n kaa nigba akọkọ”.
Orí Yoòbá ti pé tipẹ́ o jàre 🙂
A gbọ pe awọn agbebọn naa wa lati orilẹede DR Congo tan wọn si ya bo ẹkun Cibitoke.
Fidio yi ti wa mu ki awọn eeyan ma beere pe ta ni Dokita yi to sọ pe ni Naijiria loun ti kẹkọ nipa eto iṣegun ilera.
 Ó fi àwọn ẹyẹ kan sígbó .
Ará, kí oore-ọ̀fẹ́ Jesu Kristi Oluwa wa kí ó wà pẹlu yín.
Nibi eto naa, Akeredolu ni oun dupẹ lọwọ ijọba ilẹ Thailand fun igbesẹ yii.
Ẹkùn, ìróra, ìkẹ́dùn gba ayé kan, nǹkan ṣe!
Ninu fidio kan to fi sita lori Instagram lo ti sọ bẹ, to si tun gba awọn ololufẹ rẹ ni imọran lati ṣe bakan naa nitori ebi.
Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Oyinkan Abayomi: Ajàfẹ́tọ̀ọ́ ẹni tó dá ẹgbẹ́ òṣèlú obìnrin àkọ́kọ́ sílẹ̀, tó tún jà fún ètò ẹ̀kọ́, ìṣèlú àti òmìnira obìnrin5 Bélú 2020 Ìtàn Mánigbàgbé: Ìnà ẹgba mẹ́sàn-án ni Jesu Oyingbo fi ń kí ọmọ ìjọ ọ́kùnrin tuntun káàbọ̀31 Èbibi 2020 Ìtàn Mánigbàgbé: Èyí ni àwọn Ọba ilẹ̀ Yorùbá mẹ́jọ tí wọn lé kúrò lórí oyè10 Ọ̀wàrà 2020 Ìtàn Mánigbàgbé: Duro Ladipọ fi òjò àti àrá ńlá sàmì ìpapòdà rẹ̀11 Ọ̀wàrà 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Kódà wọ́n lé òun dànù ni.
Àbíkú ń tọ ́ ka sí ẹ ̀ mí ẹni tókú yálà ọmọdé tàbí ẹni tí ó kú kí ó tó dàgbà .
WAFU: Falcons gbera lo si Abidjan
" ni ọ ̀ rúnmìlà ba ti àṣẹ Èṣù bọnu "" ."
Dokita Stella Nwokeji, gbaju-gbaja dokita oyinbo wa ro ijoba lati da  ile-ise pajawiri, ti yoo maamojuto awon eto ilera pajawiri lorile ede Naijiria sile.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Abiola Ajimobi: Àwòrán rèé nípa ìgbé ayé Abiola Ajimobi 25 Òkùdu 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 26 Òkùdu 2020 Eniyan ti itan igbesi aye rẹ tan kalẹ gẹgẹ bi atapata dide ni Abiola Ajimobi jẹ.
"Olori isoro ileesẹ yii ni ọda owo.
Mo jẹ́ ojú fún afọ́jú,ati ẹsẹ̀ fún arọ.
Gbajugbaja olorin waka naa ṣalaye pe iṣelẹ naa ko tu irun kankan lara oun.
fortify : v ; ( they fortified the building againt the attack of enemies .
INEC, 2023 election: Àjọ eleto ìdìbò kéde ọjọ́ tí ìdìbò ààrẹ Nàìjíríà 2023 yóò wáyé
Sunday Shodipe: Àlàyèé rèé lórí bi wọ́n ṣe ri ọ̀daràn tó n dá ẹ̀mí àwọn ènìyàn légbodò l'Akínyele Oríṣun àwòrán, others Àwọ́n àṣìrí míràn tún ti jẹyọ lórí bi ọwọ́ ṣe tẹ afunrasí ọ̀daràn Sunday Shodipe tí àwọn ọlọpàá ni àwọn gbé ẹgbẹ̀rún lọ́nà ẹ̀ẹ́dẹ́gbẹ̀ta Naira kalẹ̀ fún ẹnikẹ́ni tó ba ri i mú.
Ipade awọn at Burnley lalẹ ọjọ Aje jẹ eleyi ti ọ́pọ ro pe Chelsea yoo fi fẹsẹ rinlẹ lori ipo kẹrin ṣugbọn ko ri bẹ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Sunday Igboho: Bí ń kò bá jẹ́ èèyàn dáadáa, Ọlọ́run kò ní ṣe oun dáadáa fún mi 14 Èrèlè 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 27 Agẹmo 2020 Oríṣun àwòrán, Instagram sunday_igboho Ilumọọka agba awujọ kan, Oloye Sunday Adeyemo, ti ọpọ eeyan mọ si Sunday Igboho ti yari kanlẹ pẹlu awọn eeyan to n sọrọ aidaa nipa rẹ.
Oby Ezekwesili naa bẹnu atẹ lu ààrẹ, o si rọ ọ ko yi ọrọ rẹ pada.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Osun Election Tribunal: Èyí ni òkodoro ìdájọ tí àwọn eniyan ìpínlẹ̀ Ọsun ti ń reti- Oyetola 9 Èbibi 2019 Oríṣun àwòrán, Jamiu Omookose Àkọlé àwòrán, Okan ninu awọn to n ba gomina dawọn idunu wipe o jawe olubori Gómìnà ìpínlẹ̀ Osun Gboyega Oyetola ti sapejuwe ìdájọ ilé ẹjọ́ kòtẹ́milọrun gẹ́gẹ́ bii èyí ti àwọn ènìyàn Ọsun ti n reti tipẹ.
Ẹ̀mí náà bá kígbe, ó mú kí gìrì ki ọmọ náà ní akọ, ó sì jáde.
Ilé kọmíṣọ́nà Oyo tó kú, Kehinde Ayoola kún fọ́fọ́ fáwọn olùkẹ́dùn Ile Oloogbe Kehinde Ayọọla ti o jẹ kọmisana fun ọrọ ayika ni ipinlẹ Ọyọ ti kun fọfọ fun awọn abanikẹdun to pejupesẹ lati ṣe idaro ẹni to papoda.
Oríṣun àwòrán, BBnaija BBNaija tọdún 2020 gbéra sọ, wo ohun tó fi yàtọ̀ sí tọdún tó kù!
Section 104 Abadofin naa yoo fun ijọba lanfani lati mọ ẹni to ba n lo omi laloju ki ijọba le din iye omi ti idile kan yoo maa ri gba si dede iye ti wọn nilo gẹlẹ.
Ọba bá pàṣẹ fún Ebedimeleki ará Etiopia, ó ní, “Mú eniyan mẹta lọ́wọ́, kí ẹ lọ yọ Jeremaya wolii kúrò ninu kànga náà kí ó tó kú.
Akọroyin BBC Andrew Harding jabọ pe, Dokita kan sọ fun oun pe, nkan ko rọgbọ ati pe aisi nkan elo idaabo fawọn dokita, oogun fawọn alaisan ati bi iṣẹ ti ṣe wọ awọn dokita lọrun jẹ ipenija nla.
Awọn ipinlẹ̀ mẹ́tàdinlógun lóyẹ ki ètò ìdìbò ti òni ti wáye, Kano, Benue, Sokoto, Bauchi, Lagos, Rivers Àkọlé àwòrán, Bayi ni idibose lo lapa ibikan ni Kano Àkọlé àwòrán, Alaboyun ni ànfani lati lọ sibi atundi ibo ni Plateau Àkọlé àwòrán, Idibo ni Drass ati Bogoro Ipinlẹ Bauch Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Man U tún ṣubú dàánù bí City ti dìgbájú rù wọ́n
 wọ ́ n pín àwọn èdè wọ ̀ nyí sí ẹgbẹ ́ turkic , mongolian àti manchus-tungus .
Àwọn òwe tí Solomoni, ọmọ Dafidi, ọba Israẹli pa, 
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ado Ekiti Blind Couple: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú Idahun si ibeere naa wa lọwọ iwọ ati emi ati iwa ta ba hu lati fẹsẹ irẹpọ Naijiria mulẹ tabi pagidina rẹ.
Siddharatha Biswas to jẹ ọga agba ile iwosan Rampurthat Government Medical College ti wọn ti ṣe iṣẹ abẹ naa ni owọ ṣile aadọrun un ni awọn yọ sita ninu ikun rẹ.
Ìròyìn sọ pé, ọgbẹ́ni Shu'aibu ṣe àbẹ̀wòsí ilé iṣẹ ọlọ́pàá Hisbah nípìnlẹ̀ Kano lásìkò ti ìṣẹ̀lẹ̀ náà kọ́kọ́ jẹyọ ó ní ọmọ òun Yahaya Shariff Aminu (Baban Gona) kò si nínú ilé òun lásìkò tó hùwà ọdaran.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, jkkkkk Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Kí ló ń jáde bọ̀ láti inú aṣálẹ̀ yìí,tí ó dàbí òpó èéfín,tí ó kún fún òórùn dídùn òjíá ati turari,pẹlu òórùn dídùn àtíkè àwọn oníṣòwò?
“Ọba tí ẹ bèèrè fún náà nìyí, ẹ̀yin ni ẹ bèèrè rẹ̀, OLUWA sì ti fun yín nisinsinyii.
Agbenusoro ajo ohun, ogbeni Afolabi Oni  so pe, won yoo kede apapo iko ti yoo maa kopa fun idije ohun ni kete ti idije boolu agbaye Russia 2018 ba pari.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Nigeria 2019 Elections: Akala ní APC kò tó bẹ́ẹ̀ láti yọ ọmọ òun nípò alága Ni owurọ ọjọru ni gomina tẹlẹ nipinlẹ Ọyọ, Adebayọ Alao Akala ṣi n fi to ileeṣẹ BBC news Yoruba leti pe, iwa kotọ ti ko lee duro niwaju ofin ni yiyọ ti wọn yọ ọmọ oun nipo ati pe, oun ṣi ni alaga ijọba ibilẹ Ogbomọṣọ North.
Lọjọ Ẹti ti ọga agba ọlọpaa n ṣe ibẹwo si awọn ileeṣẹ ọlọpaa to wa kaakiri olu ilu orilẹede yii ni ilu Abuja lo sọ bẹẹ.
33 ninu miliọnu ) , ati iye iku 15 l ' ọdun ni Ọsirelia ( 0.
O le debẹ ni oṣu kejila nigba ti wọn ba n ṣe Ajọdun Omi.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Lagos Senatorial Elections: Abiru ṣ'àbẹ̀wò sí Tinubu lẹ́yìn tó wọlé àtúndi ìbò Sẹnẹtọ ìlà oòrùn ìpínlẹ̀ Eko 4 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 7 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Oríṣun àwòrán, Twitter/RitaAdubaBlog Lẹyin ti ajọ eleto idibo INEC kede rẹ tan gẹgẹ bi oludije to jawe olubori ninu atundi ibo sẹnẹtọ ẹkun ila-oorun ipinlẹ Eko, Tokunbo Abiru ti lọ ṣabẹwo si Asiwaju Bola Tinubu.
Dafidi kó àwọn ọmọ Aaroni ati àwọn ọmọ Lefi jọ: 
Ìwọ́de #RevolutionNow forí ṣánpọ́n ní Ibadan, àgbófinró gbàkóso ojú pópó Bí ọdún Ọ̀ṣun Oṣogbo ṣe bẹ̀rẹ̀ rèé àti pàtàkì rẹ̀ fún Nàíjíríà Saudi ṣàtúnṣe lílẹ òkò mọ́ Asitani láti dẹ́kun títẹra-ẹni-pa Ẹgbẹ́ Akọ́mọlédè àti Àṣà Yorùbá Nàìjíríà pé àádọ́ta ọdún Bakan naa ni Adeyanju ni awọn mọkanlelogun eniyan to fẹhọnu han ni ipinlẹ Eko ni Ọjọ Karun un , Osu Kẹjọ, ọdun 2019 ni o si wa ni atimole ọlọpaa ni agbeegbe Panti to jẹ Olu-ile isẹ ọlọpaa ni ipinlẹ Eko.
Èyí fihàn dájú pé gbogbo ohun tí OLUWA sọ nípa ìdílé Ahabu yóo ṣẹ.
E̩nì kò̩ò̩kan ló ní è̩tó̩ láti dá e̩gbé̩ òs̩ìs̩é̩ sílè̩ àti láti dara pò̩ mó̩ irú e̩gbe̩; bé̩è̩ láti dáàbò bo àwo̩n ohun tí ó je̩ é̩ lógún.
 májẹ ̀ mú láíláí sọ nípa iṣẹ ́ ìgbàlà ti jésù wá ṣe nílé aye .
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù N10m suit: ‌Agbẹjọ́rọ̀ ọmọ Nàìjíríà, Ogedi Ogu gbé Fásitì Oxford lọ sílé ẹjọ́ lórí ìtumọ̀ ọ̀rọ̀ 3 Owewe 2020 Oríṣun àwòrán, others Ile ẹjọ giga kan ni ipinlẹ Eko ti da ẹjọ ti Oxford ti pe tako ipẹjọ oni miliọnu mẹwaa Naira ti agbẹjọro ọmọ Naijiria Ogedi Ogu pe tako wọn nu.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Rape cases in Nigeria: Ọmọ ọdun 5 àti 14 ni Kalu wà nígbà tí obìnrin fipá ba lòpọ̀ Sugbọn ileesẹ ọlọpa ko tii le sọ ohun to sokunfa isẹlẹ naa.
Lẹyin eyi o tun ṣiṣẹ olukọni ni Montgomery County Community College PA ati ni Eastern University St Davids ni Pennsylvania ni America.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Onnoghen: Adájọ́ àgbà ní òun kò jẹ̀bi ẹ̀sùn tí ìjọba fi kan òun 15 Èrèlè 2019 Oríṣun àwòrán, @todayng, @SERAPNigeria Àkọlé àwòrán, Èrò àwọn ènìyàn sọ̀tọ̀ọ̀tọ̀ lórí ẹ̀sùn Onnoghen Ile ẹjọ CCB ti fi gbé Adajọ́ Agba Walter Onnoghen lọ ilé ẹjọ́ CCT níbi tí wọ́n ti fi ẹ̀sùn alábala mẹ́fa, eyí tó dá lórí pe kò jẹ́wọ́ awọn dukia rẹ̀ ati awọn owo kan to ni sile ifowopamọ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Gani Adams: Ẹni ba fe pẹ laye, maa ra aye gbe ni Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Gani Adams: Ẹni ba fe pẹ laye, maa ra aye gbe ni 20 Èrèlè 2018 Aarẹ Ona Kakanfo ilẹ Yoruba, Otunba Gani Adams ni ifọrọwanilẹnuwo pẹlu BBC Yoruba.
Àwọn ìlẹ̀kùn náà ní awẹ́ meji meji.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ondo: Dejí sun ọmọ méje àtagbalagba meji mọ́lé nítorí pé ó ń bínú Arsenal ti fi ibanujẹ wọn han lori iroyin iku Reyes, bẹẹ si ni Thierry Henry ti oun ati Reyes gba bọọlu fun Arsenal laarin ọdun 2004 si 2007 ti gbori yin fun oloogbe naa.
 Bukọla Saraki lo ko eleyii lori ẹrọ twitter rẹ.
Láti Dani, wọ́n lọ sí apá ìwọ̀ oòrùn títí dé Sidoni.
Ewu wà fún wa pé, iṣẹ́ wa yóo di ohun tí eniyan kò ní kà sí mọ́.
OLUWA àwọn ọmọ ogunní ń kó àwọn ọmọ ogun jọ fún ogun.
”Loju agbami ifigagbaga naa, gbagede ti Pete Sampras, eni ti Djokovic n wo awokose re, ti gba ife-eye merinla ati ami-eye lorisirisi.
Gbogbo ebi ara ati ọrẹ oloogbe lo maa fọwọsowọpọ wa ṣe ẹyẹ ikẹyin fun arugbo to re ibi agba n re Oríṣun àwòrán, @abe Àkọlé àwòrán, Ko si ẹni to maa n fẹ ki arugbo to ba wulo ninu ile rẹ o ku, ọpọ igba ni awọn eniyan maa n sunkun lori iru iku to ba pa ẹni kan.
Kí ni àwa yìí jẹ́, tí ẹ óo fi máa kùn sí wa?
Akinlade fi kun un pé, inú ìyanṣẹ́lódi ni àwọn wà nígba ti gómínà Dapo Abiodun gorí oye sùgbọ́n aàwọn ṣẹ́wẹ́le ni láti ṣe àpọ́nlé fún, síbẹ̀ ko si igbéṣẹ̀ kankan to gbe lóri ọ̀rọ̀ náà láti igba to ti gori oye.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Irú ẹ̀dá wo ni Kofi Annan jẹ́?
Macron, aarẹ France ṣèlérí láti tún Notre-Dame kọ́ Yóò nira fún Afrika láti sàtìpó ní Yuroopu’ Ọgọ̀rọ̀ èèyàn s'ayẹyẹ ọjọ́ ìbí ọgọ́rin ọdún fún Fẹla Ǹjẹ́ o mọ̀ pé o le gba owó lára 'ATM' láì lo káàdì?
O ni ọjọru tii ṣe ọjọ kẹtala oṣu keji ọdun 2019 ni igbims naa fi ipade si lati tẹwọ gba abajade iṣẹ igbimọ alabẹ ṣekele ti wọn gbe kalẹ lori rẹ ni ibamu pẹlu abala kẹtadinlogun iwe ofin igbimọ iṣedajọ to ga julọ lorilẹede Naijiria.
OLUWA wí fún Gideoni pé, “Àwọn tí wọ́n wà pẹlu rẹ ti pọ̀jù fún mi, láti fi àwọn ará ilẹ̀ Midiani lé lọ́wọ́, kí àwọn ọmọ Israẹli má baà gbéraga pé agbára wọn ni wọ́n fi ṣẹgun, wọn kò sì ní fi ògo fún mi.
Leyin atunyansipo aare Ibrahim Boubacar Keita gege bi aare orile-ede Mali, ti o si kede lati fi igbe-aye alafia ati eto aabo to muna doko mule lorile-ede Mali, aare ohun ti yan awon minisita tuntun miiran ti yoo maa mojuto eto aabo, iwakusa ati ipese irin ati eni ti yoo maa mojuto oro ile-okere.
Ọjọ Eti lo gbe ẹmi mi lẹyin aisan ọna ọfun rẹ ko ṣiṣẹ daradara mọ.
Akọnimọọgba Arsenal yii yombọ iṣẹ akọni to gba pe Iwobi ṣe ninu idije naa nibi ti o ti fun Nile ni bọọlu to gba sawọn niṣẹju kọkanla ti idije naa bẹrẹ.
Àwọn ìṣẹ̀lẹ̀ tí ẹ kò lè gbàgbé níbi ìfọ̀rọ̀wérọ̀ BBC Yorùbá l'Ọyọ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Báwo ni àwọn olùdíje Oyo ṣe fẹ́ kojú ìṣòro ìlera?
Ara oko wale, ti ẹniti ko lee rin si ni ki wọn gbe oun nitori o le ni ẹgbẹrun lọna ọgbọn oluworan to wa wo oju ole Oyenusi ati bo se fẹ ku iku oro, bẹẹ si lawọn onworan naa n fi se ẹlẹya Ko to di pe Oyenusi gba ọta ibọn sara, lasiko to n ba awọn akọroyin sọrọ ikẹyin, Oyenusi ni abamọ lo gbẹyin ọrọ fun oun ninu isẹ ibi ti oun rawọ le.
Marafa, ẹni to dije dupo gomina nipinlẹ Zamfara tẹlẹ ni, bi igbimọ fidihẹ naa se n fi orukọ awọn ọmọ ẹgbẹ oselu naa silẹ jakejado Naijiria kii se ojuse wọn.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ìtàn tó wà nídi òwe ‘Sebótimọ Ẹlẹ́wà Sàpọ́n’ Ipinlẹ Eko kò sí lóko ẹ̀rú ẹnì kankan - Sanwo-Olu Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Ìyá Tíṣà lòdì sí kí n mutí, fagbó tàbí sìgá' Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Tọkọ-taya Aràrá: Àwọn èèyàn máa ń wò wá, ta bá fa ọwọ́ ara wa ní títì .
Ṣugbọn ẹ kọ́kọ́ máa wá ìjọba Ọlọrun ná ati òdodo rẹ̀, gbogbo nǹkan wọnyi ni a óo fi kún un fún yín.
Eyi to ba kan wọn lo maa n jẹ ki wọn gbe ọ̀pọ̀ fídíò sita fi tako iroyin nipa wọn ní kété ti wọ́n ba ti wo ìròyìn tán.
''Ni se ni awọn ololufẹ Baba n wa ba wa kẹdun ni ile ati ile ijọsin wọn'' Àkọlé àwòrán, Àwọn abánikẹ́dùn ní ilé Bàbá Sala Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Moji Olaiya: Lẹ́yìn ọdun kan Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ọmọge Campus: Lọla Alao ní Aisha ti ni àìsàn jẹjẹrẹ ti pẹ́ Ni igba to wa laye, Baba Sala jẹ ọgunnagbongbo ẹka ere idaraya lorileede Naijiria ti ọpọ awọn olorin ati osere tiata kose lọdọ rẹ́.
Iye awọn eeyan to ṣẹṣẹ ko arun naa ni ipinlẹ kọọkan ree: Eko-155 Edo-75 FCT-67 Rivers-65 Oyo-56 Delta-50 Bayelsa-25 Plateau-18 Kaduna-18 Enugu-17 Borno-12 Ogun-12 Ondo-7 Kwara-4 Kano-2 Gombe-2 Sokoto-1 Kebbi-1 Eeyan 490 tuntun mii lo ṣẹṣẹ lugbadi arun Coronavirus ni Naijiria.
Ará ìlú Abéòkúta ke gbajare lórí Omiyale ‘Omi yale sọ awọn eniyan di alai ni ile’ Ẹ̀kún omi gbé ọmọ oṣù mẹ́ta lọ 324 èèyàn bá ẹ̀kún omi lọ Iwadi BBC Yoruba fi han pe, aadọta naira si ọgọrun naira ni ẹni kọọkan n na lati fi wọ ọkọ oju omi igbalode naa.
Awọn agbẹjọro, Wolii Sọtitobirẹ Oluṣọla Oke n fẹ ki ile ẹjọ wọgile ẹjọ naa.
Ẹ yìn ín, ẹ̀yin iranṣẹ OLUWA.
Iroyin ohun safihan orisirisi ona ifiya-jeni naa, lara eyi a ti ri iseku-pani, fifi owo sinkun ofin muni lona aito, fifi enian si atimole lona aibofin mu, titi awon ile-ise iwe iroyin, didi awon ero ayelujarapa laarin osu keje odun 2016 si osu kejila odun 2017.
Egbe oselu APC ni apapo ibo mẹ́rìnlélọ́gbọ̀n le ẹgbẹ̀ta o le lọ́ọ̀dúnrún(347,634), ti apapo ibo egbe oselu PDP si je(337,377).
Inu awo orin Pansaga ranti ọjọ ọla"", si lo ti tahun si awọn obinrin oninabi."
O lòdì s'ofin ki oga ile iṣẹ aṣobode máa polongo fún Ààrẹ.
Federation (NFF) ti so pe, o seese ki o je pe papa
Nibi oṣu melo kan ni awọn aworan kan jade sori ayelujara, eyi to ṣafihan rẹ pe awọn mejeeji sẹ igbeyawo.
ni lori bi idagbasoke yoo se tubọ maa gbile si lori ibasepọ to wa laarin orile
Ofin konile-o-gbele yoo maa wa laarin agogo mẹjọ alẹ si agogo mẹfa irọlẹ.
Ó ní, “Kó ara rẹ kúrò níwájú mi, ìwọ Satani.
“Mo fẹ́ kí ẹ mọ̀ dájúdájú pé ìran yìí kò ní kọjá lọ kí gbogbo nǹkan wọnyi tó ṣẹ.
Lẹ́hìn èyí wọ́n mú wa lọ sí ẹ̀hìnkùnlé nígbà tí a sì dé ọ̀hún, ènìyàn mẹ́ẹ̀ẹ́dọ́gbọ̀n bí àwa ni a bá, àwọn wọn-ọnnì ti ṣìnà sí igbó ọdẹ wọ́an sì ti bọ́ sí ọwọ́ ọba àwọn ejò náà.
O ni o yẹ kawọn ile ijọsin nla jọwọ lo ohun ini wọn lati ran ijọba lọwọ, dipọ kawọn olori wọn maa tako igbesẹ ijọba lori ofin konle-o-gbele.
Jonathan ni Yar'Adua jẹ olori ti ko ni imọ tara ẹni nikan, bakan naa lo ṣapejuwe rẹ gẹgẹ ẹniti o maa n gbiyanju nigba gbogbo lati ri wi pe ifẹ orilẹede Naijiria siwaju ifẹ ọkan rẹ.
BBC ba alukoro ile iṣẹ ọlọpaa ipinlẹ Eko, DSP Bala Elkanah sọrọ.
Àwọn Olóri Ilú àti Ẹlẹ́sin ni oriṣiriṣi ati gbogbo àgbáyé ṣe ìdárò Muhammad Ali bi wọn ti ṣe ẹ̀yẹ ikẹhin tó yẹ fún Ọba, ni ibi ìtẹ́ ìsìnkú ni oṣù kẹfa, ọjọ́ kẹwa, ọdún Ẹgbàálémẹ́rìndínlógún.
 Àwọn ìtọ ́ jú tí Àjọ Ìlera fún Àgbáyé dámọ ̀ ràn ni àwọn egbògi bíi albendazole , mebendazole , levamisole tàbí pyrantel pamoate .
Ki wọn si pe fun iranwọ awọn onimọiṣegun ni kiakia.
Ile ẹjọ naa ti wa ni ki wsn ls yẹgi fun un.
 Èdè gèésì ni èdè tí wọ ́ n fi ń ṣe ìjọba .
Bakan naa, ni ọdun 2018 ni ilu Georgia, lorilẹede Amẹrika fun Pasuma ni iwe igbelu ọmọ onilẹ ati asoju ilẹ naa.
O si n ran awọn eeyan to ku diẹ kaato fun lọwọ.
 Nitori naa, ẹ ko lee san owo osu
Sùgbọ́n àwọn ìròyìn ti a sà káàkíri awọn ìwé ìròyìn míràn, tàbí ti a ba mú ìwádiìí jáde ní àwon ẹka BBC mírà, tàbi ti akọròyìn kan ti kọkọ ṣiṣé lé lori sáájú tẹ́lẹ̀ kò lé gbé orúkọ kankan lóri.
Ibeere: Ki ni abadofin yii da fun araalu?
Bẹ́ẹ̀ ni ẹ óo ṣe mú nǹkan burúkú kúrò láàrin yín.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, John Amanam: Ìfẹ́ tí mo ní sí àbúrò mi ló sọ mi dí ẹni tó ń ṣe 'Prosthetic' báyìí Boris Johnson ni lati ọjọ keji, oṣu kejila ọdun 2020 ni wọn yoo dẹwọ isede naa O si gbadura pe ki Olorun fi aanu han lagbaye bayii pẹlu imọran pe o san ki ọdun keresimesi yatọ pẹlu igbesẹ akin yii ki ẹbi le pada ṣajọyọ ọdun papọ.
Nígbà tí Jesu kúrò níbẹ̀, ó rí ọkunrin kan tí ó ń jẹ́ Matiu tí ó jókòó níbi tí ó ti ń gba owó-odè.
Eeyan marun un lo lugbadi aarun naa lati Ogun nigba ti eeyan mẹrin-mẹrin ni aarun covid-19 lati Bayelsa ati Kwara.
Atẹjade naa ko sọ boya wọn ti ri wọn, boya wọn ti ku tabi wọn wa laaye ṣugbọn ohun taa gbọ ni pe wọn ko tii ri ara wọn.
Lẹ́yìn èyí mo tún rí Tẹmpili tí ó ṣí sílẹ̀ ní ọ̀run.
“Bí o bá pàdé akọ mààlúù ọ̀tá rẹ tabi kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ rẹ̀ tí ń ṣìnà lọ, o níláti fà á pada wá fún un.
 O ku fowo rori ku ni lori ibusun re lojo Isegun ni aafin ni.
Igbe àwọn Igbo ti pọ si lẹhin ti wọn jagun abẹ́lé, àwọn ẹya miran bi Yorùbá nkun ni abẹ́lẹ̀ pé àwọn ma fẹ dá dúró ki wọn san iṣákọ́lẹ̀ fún Ìjọba àpapọ̀.
Awọn iroyin ti ẹ le nifẹ̀ si: 'Naijiria ko laṣeyọri lori gbigbogun t'iwa ijẹkujẹ' Rufai Imam di adajọ agba ile ẹjọ Sharia ‘A ko mọ ibi ti Nnamdi Kanu wa’ Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Ohunkohun tí òkú wọn bá jábọ́ lé lórí di aláìmọ́, ìbáà jẹ́ ohun èlò igi, tabi aṣọ tabi awọ, tabi àpò, irú ohun èlò yòówù tí ó lè jẹ́, ó níláti di fífọ̀, yóo sì jẹ́ aláìmọ́ títí di ìrọ̀lẹ́, lẹ́yìn náà, yóo di mímọ́.
Arsenal vs Manchester United: Arsenal borí i Manchester United ní Premier league
nígbà tí Mose bá fún wa ní òfin,tí ó jẹ́ ohun ìní gbogbo eniyan Israẹli.
wọn, ,lasiko ti o gba awon
Nibayii gbogbo awọn olugbe agbegbe naa ti rawọ ẹbẹ si gomina ipinlẹ Ọyọ, Onimọẹrọ Ṣeyi Makinde lati dide iranlọwọ lori afara kan to nilo atunṣe ni agbegbe naa lati bi i ọdun mẹwa sẹyin ki iru iṣẹlẹ bẹẹ ma baa waye mọ.
 mẹ́rìnlélógójì lo wa  nibi ipade naa .
Ẹni ìyìn títí lae ni ẹni tí orúkọ rẹ̀ lókìkí,kí òkìkí rẹ̀ gba ayé kan!
Àwọn nìkan ni wọn óo jẹ́ iranṣẹ fún wọn láàrin àwọn ọmọ Israẹli.
Ni ọdun 2007 nigba to n ṣe ipolongo ibo fun Umaru Musa Yar'Adua to rọpo rẹ, Ọbasanjọ sọ ọrọ kan ti ọpọlọpọ eniyan bẹnu atẹ lu.
A gbọ pe ki Aláàfin Atiba to waja, lo tí fi ohùn silẹ pé Adelu, tíì ṣe àkọ́bí òun, ní òun fẹ́ kó jẹ ọba lẹ́yìn òun.
Eleyi lo jẹ ki wọn o koju Milan.
O fi omi ata bọ̀wọ́n lójú
Kí ó sì bukun yín gẹ́gẹ́ bí ó ti ṣe ìlérí fun yín.
Aminat Abiọdun: Ọjọ́ Satide ni Iyalode kí ayé pé ó dìgbóṣe
"O ni ""ẹ o maa gba iwe atẹjiṣẹ latọdọ mi laipẹ""."
Ni ti awọn to n bu ẹnu atẹ lu Obasanjo lori atẹjade ọhun, Akinyemi sọ pe gbogbo eeyan lo lẹtọọ lati sọ erongba inu wọn.
Èyí fún ọpọlọpọ ninu àwọn onigbagbọ tí wọ́n mọ ìdí tí mo fi wà ninu ẹ̀wọ̀n ní ìgboyà gidigidi láti máa waasu ìyìn rere láì bẹ̀rù.
Arabinrin Taiwo naa ni bi o tilẹ je wi pe oun ti bẹrẹ si ni jẹ irọra atirọbi, ni se ni awọn eleto ilera fi oun silẹ fun ọpọlọpọ wakati pẹlu irọra ko to wa di wi pe wọn da oun loun.
Wọ́n bá ń pariwo, wọ́n ń fi aṣọ wọn, wọ́n sì ń da ìyẹ̀pẹ̀ sókè.
Absalomu wà ní Geṣuri níbi tí ó sá lọ fún ọdún mẹta.
Pátá Jíjí : Agbẹnusọ ọlọ́pàá ní àwọn olè ajípátá ń gbìdánwò ìpànìyàn ni
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Rélùwéè Èkó sí Ìbàdàn: tíkẹ́ẹ̀tì ọ̀fẹ́ lẹ ó lò fún oṣù mẹ́rin gbáko- Amaechi 30 Bélú 2019 Oríṣun àwòrán, Rotimi Amaechi Awọn eeyan Naijiria ti n fi ero ọkan wọn han lẹyin ti ijọba kede irinajo ọfẹ loju opo reluwe laarin ilu Eko si Ibadan.
"Wole Soyinka ni ""mo kọ́kọ́ wò ó pé ṣe mo máa tètè fa orí yẹn ni àbí mo fẹ́ kí àrùn yẹn fá a fún mi""."
Oun tun ni igbakeji alaga ẹgbẹ oṣelu AD nigba kan ri.
Ikọ yii ko pegede ri lati kopa ninu idije ife ẹyẹ agbaye.
Ṣugbọn nígbà tí ó bà bímọ tán, kò ní ranti gbogbo ìrora rẹ̀ mọ́, nítorí ayọ̀ pé ó bí ọmọ kan sinu ayé.
Gbogbo awujọ eeyan, ẹlẹgbẹjẹgbẹ ati onwoye ibo labẹle ati loke okun lo panupọ kede ibo ọjọ Kejila osu Kẹfa ọdun 1993 gẹgẹ bii eyi ti wọn faramọ julọ lai si atako kankan bi eyi to n waye lasiko yii.
 Ogbeni opeyemi Agbaje soro yii lasiko ti ile -ise naa se
Ṣugbọn kò lè wo àìsàn Israẹli tabi kí ó wo ọgbẹ́ rẹ̀ sàn.
O ni ọpọ akoba ni oṣelu oni baba isalẹ n ṣe fun iṣejọba lorilẹede Naijiria, idi ti gbogbo awọn minisita ti ọkọ oun, iyẹn Aarẹ Buhari yan gbọdọ fi ji giri dide si iṣẹ to yẹ.
Eyi fi hàn bi Yorùbá ti  fẹ́ràn  lati ma ṣe àlejò tó.
Báwo ni àwọn ọmọ Jakọbu yóo ṣe là, nítorí wọ́n kéré níye?
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Hero Tortoise: Ìjàpá 14 ni wọn yà sọ́tọ̀ láti bí Ìrère 2000, kí ìran wọn má baà parun Obasanjọ wa se kare, mo gba fun yin si awọn gomina to wa nilẹ Yoruba fun agbekalẹ eto alaabo Amotekun, pẹlu afikun pe ko si ẹkun kankan ni Naijiria ti yoo lagbara lati da ẹkun miran to ba fẹ yapa duro, tijọba ko ba tete wa nkan se nidi eto atunto orilẹede yii.
pé kí gbogbo wọn lè jẹ́ ọ̀kan.
" O ni oun ko si lara awọn to gbe iwọde naa kalẹ tabi ṣiwaju rẹ, oun kan lo anfani ti oun ni lati fi ṣe koriya fun awọn ọdọ naa ni.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Grandma Maruwa: Ó yẹ kí obìnrin sisẹ́ láì wojú ọkọ kó tó jẹun Olori Ọlọwọ ti ilu Ọwọ, Adenikẹ Ogunoye la gbọ pe o lewaju ikọ awọn agba oloye ilu Ọwọ gẹgẹ bi awọn to kọkọ ṣe abẹwo si Arẹmọ tuntun ati Iya rẹ, Olori Naomi Silẹkunọla ni ileewosan nla naa.
Ṣugbọn Ogunbiyi táko èsì ìbò náà niwájú ìgbìmò apẹtu-saawọ ẹgbẹ.
Ní tiwa, a ti gbàgbọ́, a sì ti mọ̀ pé ìwọ ni Ẹni Mímọ́ Ọlọrun.
Wọ́n ní, “Bí ó bá rí bẹ́ẹ̀, ta ni yóo rí ìgbàlà?
Ṣe ofin Naijiria faaye gba igbeyawo ori ayelujara?
Ìyàwò lárìnlọọ̀dù mi pè mí ní akálòlò ni mo ṣe paa - Afurasí Buhari, pe ìpàdé àpérò ọmọ Nàíjíríà fún àgbékalẹ̀ òfin tuntun - Afe Babalola ‘Kò sí ohun tó lè yẹ ìfèhọnú ọjọ karun un Oṣu Kẹsan lórí àtìmọ́lé Omoyele Sowore’ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Badagry Historical Wells: Omi inú kànga Wawú ló ń kó ọpọlọ àwọn ẹrú lọ Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
‘Ẹ Yé é Pa Àwọn Òbìnrin’ – ìpolongo tuntun tí ó ń tako ìjìyà inú ìgbéyàwó ní Angola
Awọn oloṣelu ko naani eeyan lo fa ohun to n ṣẹlẹ si Naijiria bayii eyi ti ko si tii ṣẹlẹ ri.
The Church of Beer: Ìnira nlá ni òfin tó dé kátà-kárà ọtí líle lásìkò Covid-19 jẹ́ fún ilé ìjọsìn wà
’ Ìpínlẹ̀ méjìlá nínú ewu àgbárá òjò ní Nàìjíríà Ní báyìí, ilé ìfowópamọ kò ni ẹ̀tọ láti má san owó oníbàrá wọn tó bá há sí ẹnu ẹ̀ro tó ń pọ owó jáde (ATM Machine) láàrin wákàti mẹrìnlélógún.
Lọjọ kerinla, oṣu keje ni irọlẹ bii aago mẹrin abo ni iṣẹlẹ buruku yii ṣẹlẹ.
Owurọ ọjọ Abamẹta ni awọn aladugbo to ri oku arakunrin naa nibi ti agbara ojo naa wọ si.
Eyi ni ṣe pẹlu ṣiṣe afihan ohun ini tabi ohun tuntun ti awọn oniṣẹ tiata, ba dawọ le laye wọn lori ẹrọ ayelujara faraye gbọ.
ni eyi ti o ti fi ọṛọ rẹ ṣatilẹyin fun eto mada-ni-dofo ẹka eto ilera lpinle yii.
 gírámà ti a ó lò : gírámà ìyidà onídàro ti chomsky ni a ó mú lò nínú isé yìí .
 a sọ nípa rẹ ̀ nínu ègbògi Íjíbítì ebers papyrus , láti 1550 bc .
kí ó tó já Àwọn àwòrán ìṣẹ̀lẹ̀ tó làmìlaaka láti ilẹ̀ Áfríkà l'ose tó kọjá #EndSARS lu ayélujára pa lórí ikú Kolade Johnson Awọn aladugbo ti ọrọ naa ṣoju wọn ni idije bọọlu alafẹsẹgba laarin Liverpool ati Tottenham ni oloogbe wa wo nile ijẹun adugbo ki ọlọjọ to de.
Ó ṣe nǹkan burúkú lójú OLUWA, ó tẹ̀lé ìwà ẹ̀ṣẹ̀ Jeroboamu, ọmọ Nebati, tí ó mú Israẹli ṣẹ̀, kò sì fi ẹ̀ṣẹ̀ náà sílẹ̀.
Tọkọtaya, ọmọ mẹ́ta àti àlejò kú sínú ilé l'Oshodi Iṣẹ́ ṣẹ̀ṣẹ̀ bọ́ lọ́wọ́ Seth Ator tó yìnbọn pa ọ̀pọ̀ èèyàn ní Texas ni- ọlọ́pàá Àwọn èèyàn Gómìnà Yahaya Bello ló da ìbò abẹ́nú PDP rú- Ọlọgbọndiyan Àjẹ́ àti Aṣẹ́wó ní ìyá Rainbow - Òjòpagogo Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí 2 sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
Lati oṣu kẹta ni awọn oṣiṣẹ yii ti n ṣiṣẹ lati ile nitori Covid 19.
Arsenal fa Chelsea ya pẹ́rẹpẹ̀rẹ gba ife FA Cup Ebenezer Obey ń wá ìyàwó , wo àmúyẹ tí o gbọdọ̀ ní tí o bá fẹ́ ẹ́ di aya lọ́ọ̀dẹ̀ baba Iwadii fi han pe ọpọlọpọ nkan ti a ṣẹnu ku sọ nipa ibalopọ lo n ko ba ọpọlọpọ igbeyawo to si ti jẹ ọpọlọpọ wọn tuka.
Ohun tí mo kọ si yín ni pé kí ẹ má ṣe darapọ̀ mọ́ ẹnikẹ́ni tí a bá ń pè ní onigbagbọ tí ó ń hùwà àgbèrè, tabi ti ó ní ojúkòkòrò, tabi tí ó jẹ́ abọ̀rìṣà, tabi abanijẹ́, tabi ọ̀mùtí, tabi oníjìbìtì.
Deji ti ilu Akurẹ, to ti wa ni ipinlẹ Ondo bayii, ati Owalobo ti Obo to ti wa ni ipinlẹ Kwara bayii naa wa lara awọn ọba to lọ fun ipade akọkọ.
Obìnrin yìí kò ba tì ṣiṣẹ lábẹ́ C.
ati abanijẹ́; wọn kò sì bọ̀wọ̀ fún Ọlọrun.
BBC Yoruba ko fẹ ki ede ati aṣa Yoruba parun kaakiri agbaye lo jẹ ki a gbe oju ọkan lara awọn ọmọ Oodua to n gbe aṣa ati ede Yoruba larugẹ nilẹ okeere wa fun un yin lonii.
,”Aare Buhari so fun awon alejo re pe, ki aaye ti oun fun awon obinrin ninu isakoso ijoba re maa ba sofo, lataari awon minisita obinrin mejeeji re ti o fipo sile, ni oun fi tete ropo won lai fi fale rara pelu awon obinirn miiran.
orile ede Naijiria nimọran lati fowo iranwọ si ina mona-mona , ki eto
Lẹyin ti Marcel, iyẹn Akukọ ti a n wi naa ku ni olowo rẹ torukọ rẹ n jẹ Sebastian Verney bẹrẹ si nii kọ iwe ifisun fun idajọ ododo fun un.
Àní, bí mo tilẹ̀ ń rìn ninu òkùnkùn létí bèbè ikú, n kò ní bẹ̀rù ibi kankan;nítorí tí o wà pẹlu mi;ọ̀gọ rẹ ati ọ̀pá rẹ ń fi mí lọ́kàn balẹ̀.
Ṣé títí ayé ni o óo máa bínú ni?
Lọdun 2012 si 2013, ijọba ilẹ Saudi gba awọn agbalagba ni imọran pe ki wọn maa wa si Hajj nitori ajakalẹ aarun MERS.
Ní àkókò tí wọ́n dó ti ìlú náà ni Nebukadinesari ọba Babiloni lọ sibẹ.
Ẹ̀wẹ̀, ìròyìn sọ pé, àjọ EU ní orílẹ̀-èdè mọ́kànla nínú orílẹ̀-èdè mẹ́rìnléláàdọ́ta to wà ni Afirika, nìkan ni yóò láàfàni láti maa wọle, ti wọ́n ba ṣi ibodè náà pada.
 ibà pọ ́ njú-pọ ́ ntọ ̀ jẹ ́ àkóràn àrùn kòkòrò àìlèfojúrí afàìsàn tó má a ń sábà wáyé ní afrika àti gúsù amẹ ́ ríkà .
O tesiwaju pe ajo eleto idibo INEC ti
Àwọn àádọ́ta ọ̀dọ́ wọ gàù nítorí ilé ijó ní Ilorin Afurasí tí Ọlọ́pàá ní ó pa Barakat, Grace àtàwọn míì l'Akinyele ti sọ̀rọ̀ pé.
Abieseri, ará Anatoti, ati Mebunai, ará Huṣa; 
Ariwo ẹkún ńlá yóo sọ ní gbogbo ilẹ̀ Ijipti, irú èyí tí kò ṣẹlẹ̀ rí, tí kò sì tún ní sí irú rẹ̀ mọ́.
À ṣé àwọn ẹyẹàwodi kan wà̀ ní ìletò yìí tí wọ́n ti máa ń ṣọ́ bàbá ní ìgbà tí ó bá ń kiri ká inú ìletò náà.
Donald Trump àti ìyàwó rẹ́ ti lùgbàdì àrùn CoronaVirus Oríṣun àwòrán, Reuters Saaju la ti mu iroyin wa fun yin pe aarẹ orileede Amẹrika Donald Trump ati iyawo rẹ Melania Trump ti lugbadi Covid-19.
Nígbà tí OLUWA Ọlọrun yín bá fi ìlú náà le yín lọ́wọ́, kí ẹ fi idà pa gbogbo àwọn ọkunrin tí wọ́n wà níbẹ̀.
O ní àṣẹ̀yìnwá, àṣẹ̀yìn bọ̀ ìjọ̀ba náà ni yóò ṣe ǹkan ti yóò ṣàǹfàní fún gbogbo ènìyàn.
Ọmọ Naijiria miran to bori nin ninu idibo ọdun 2020 ni Nnamdi Chukwuocha ti wọn dibo yan lati ṣoju ẹkun kinni ti ipinlẹ Deleware nile igbimọ aṣoju.
O kò gbọdọ̀ bá ọkunrin lòpọ̀ gẹ́gẹ́ bí obinrin, ohun ìríra ni.
Ogunlọ́gọ̀ eniyan sì ń tẹ̀lé e.
 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Awọn eku maa n ko arun iba orere ran gaari Nipataki julọ, ko si agbara fun awọn ileewosan to wa awọn ipinlẹ Edo, Ondo ati Ebonyi."
 eyi so ebi curie di ebi to ni awon elebun nobel julo titi doni .
Kí ló dé tí àwọn eniyan wọnyi fi yipadakúrò lọ́dọ̀ mi,tí wọn ń lọ láì bojúwẹ̀yìn?
''O ṣeni laanu pe titi di asiko yii aarẹ Trump ṣi kọ lati gba wi pe oun kọ lo wọle gẹgẹ bi aarẹ lorilẹede naa'' Aibikita aarẹ Trump yii yoo jasi iku ọpọlọpọ awọn eniyan to n koju arun Coronavirus lọwọ'' Ti a ko ba gbagbe, aarẹ Donald Trump ti lọ si ileẹjọ lati tako awọn esi idibo to jade ni awọn ipinlẹ jankan-jankan lorilẹede naa.
O ni ohun elo ibugbamu naa ya ọna to wa ni opopona to lọ si papakọ ofurufu ni ipinlẹ naa jẹ ati ile meji to wa ni ẹba ọna ni agbeegbe Eleyowo ni ipinlẹ naa.
Bí ǹkan ṣe wá ń ri ni Afíríkà yìí, ó ti fẹ́ jọ bi ó ṣe rí ni àwọn orílẹ̀-èdè àgbáyé ti aàrùn náà ti ṣe lọ́sẹ́ gidigidi.
Kí le ri si àwòrán yìí Ankara lórí gini 
Bukola Saraki: Ìwà àrékérekè ni ilé mi tí EFCC tì pa
"- Iya Rainbow ""Ẹ gbe ẹni wa lati sun sibi kẹ wa gbọ itan bi ifẹ emi ati ọkọ mi se bẹrẹ nitori diẹ ni mo fi han yin nipa mi, ẹ wa ka nipa igbe aye obinrin to yo ifẹ."
Iya baraka ṣe apejuwe ọmọ rẹ ti di oloogbe gẹgẹ bii eyin ọọkan ati ogo idile ti oun ati baba rẹ n reti wi pe yoo tọju awọn ati aburo rẹ titi dọjọ alẹ.
Ó takò òfin kí àwọn obí jẹ̀yà ti ọmọ ba darapọ̀ mọ́ ẹgbẹ́ òkùnkùn- Ajàfẹ́tọ̀ọ́mónìyàn Ètò ọ̀rọ̀ ajé ilẹ́ Gẹ̀ẹ́sì ti dẹnukọlẹ̀ fún ìgbà akọ́kọ́ láti ọdún 2009, wo bí yóò ṣe nípa lórí rẹ̀.
ninu egbe oselu APC, Hajia Salamatu Baiwa,ati awon eniyan pataki lorile ede yii.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: N11.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Akomolede ati asa Yoruba: Ẹ wá kọ́ nípa àpòtí ìṣura èdè wa lórí BBC Yorùbá Awọn iroyin ikọlu awọn Boko haram yii fihan pe wọn yi n ṣọṣẹ to pọ ni ila oorun ariwa Naijiria lai nii fi ṣe iṣẹ akọni ti wọn ni awon ọmọ ogun ilẹ n ṣe ni ẹjkun naa lati bori awọn oniṣẹ ibi ọhun.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Àkójọpọ̀ àwòrán Òjò òwúrọ̀ Ọjọ Àjé l'Eko Èèmọ̀ rèé o!
” Wọ́n sì túbọ̀ kórìíra rẹ̀ sí i nítorí àlá tí ó lá ati nítorí ọ̀rọ̀ rẹ̀.
Nítorí náà mo tún bẹ̀ yín gidigidi pé kí ẹ máa gbadura fún wa, kí wọ́n baà lè dá mi sílẹ̀ kíákíá láti wá sọ́dọ̀ yín.
Ayeye yii waye lojo Aje, nile
'Naijiria gbọdọ̀ kọ ìrẹ́pọ̀ pẹ̀lú SouthAfrica ' Bakan naa, Igbakeji Aarẹ Ile igbimọ Asofin to kọja, Ike Ikeremadu ti kesi ijọba orilẹede Naijiria lati jawọ ninu gbogbo irẹpọ pẹlu orilẹede South Africa, titi ipaniyan awọn ọmọ Naijiria lorilẹede naa yoo fi dopin.
Àpọ̀jù òògùn ikọ́ olómi Codeine, ìbẹ̀rẹ̀ wèrè Òògùn ikọ́ olómi Codeine dùn àmọ́ ewu ni Egbìnrìn ọ̀tẹ̀ nìkọlù Plateau, èèyàn mẹ́ẹ̀dógún tún dèrò ọ̀run Ẹ̀wọ̀n ọdún méjì fún awọ̀n tó ń lo Codeine Ọ̀rọ̀ ń bọ́ lóríi fídíò Codeine Oògùn olóró, ọmọ ìyá Codeine Orilé-ede Naijiria ti fofin de gbigbe Codeine wọle lẹyin iwadii ile iṣẹ wa (BBC) lori bi àwọn ọdọ ṣe n ṣìí lo.
“Ẹ ti gbọ́ tí a sọ pé, ‘Nígbà tí o bá fẹ́ gbẹ̀san, ojú dípò ojú ati eyín dípò eyín ni.
Ni a bá gba ẹ̀gbẹ́ Kirete níbi tí afẹ́fẹ́ kò ti fẹ́ pupọ.
Ewe, ninu eto agbe bakan naa isejoba aare Buhari ko se fowo ro seyin lati dena gbigbe okan le epo robi lasan.
Jaquelin Adebija to je akoroyin pelu Invicta FM ni won yan gege bi alaga igbimo ipolongo yii.
NAFDAC: Ohun tí wọ́n fi ń se báàgì, bàtà ni wọ́n ń tà bíi ‘pọ̀ǹmọ́
lorile ede Naijiria lati fi kun awon adajo  to wa tẹlẹ ,ki won lee jẹ mọ́kànlélógún
wọn bá bẹ̀rẹ̀ sí sọ ọ̀rọ̀ àfojúdi sí Ọlọrun ọ̀run nítorí ìrora wọn ati nítorí egbò ara wọn, dípò kí wọ́n ronupiwada fún ohun tí wọ́n ti ṣe.
Ṣugbọn nígbà tí èéfín tí àwọn ọmọ ogun Israẹli fi ṣe àmì bẹ̀rẹ̀ sí yọ sókè láàrin ìlú, àwọn ará Bẹnjamini wo ẹ̀yìn, wọ́n rí i pé èéfín ti sọ, ó sì ti gba ìlú kan.
Lati igba ọdọ rẹ lo ti n fi apẹrẹ akinkanju han.
Àwọn tí ń ṣe inúnibíni mi ati àwọn ọ̀tá mi pọ̀,ṣugbọn n kò yapa kúrò ninu ìlànà rẹ.
Hesekaya dáhùn pé, “Ó rọrùn fún òjìji láti lọ siwaju ní ẹsẹ̀ mẹ́wàá, kí ó pada sẹ́yìn ni mo fẹ́.
tí bá ní kí a woo bi ìtàn ìkọ ́ ni sé bẹ ̀ rẹ ̀ , a máa tó ọ ̀ pọ ̀ lọpọ ̀ odún sẹ ́ yìn .
Adari ile-ise oloopa naa wa fi asiko naa pe fun ifowosowopo gbogbo osise olopaa pelu awon ara ilu  ni ekun Gusu ohun , ki won lee se aseyori ninu igbiyanu won lati gbogun ti iwa odaran, ijinigbe-jinipa to maa n waye ni ekun ohun.
"Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Akomolede ati Asa: Mọ̀ si nípa àwọn ọ̀nà tí Yorùbá ń gbà ran ara wọn lọ́wọ́ ""Jàńdùkú gún ẹ̀gbọ́n mi lọ́rùn pa, jó ilé àti mọ́tò wa méjì, kòròfo la wà"" Àbúrò' olóògbé ní kìí ṣe àsìta ìbọn ló pa ẹ̀gbọ́n òun, jàǹdùkú ni A kii gbe inu ile ẹni, ka fọrun rọ, ase irọ patapata ni."
Ni kete to le awọn agbofinro naa jinna lo paṣẹ pe kawọn kọngila wa bẹrẹ atunṣe ileegbimọ naa.
de George - BBC News Yorùbá BBC News, YorùbáFò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù BBC Nigeria 2019: Ọ̀rọ̀ àwọn olóṣèlú, tásìkò bá tó, akólòlò á pe baba - Bode George Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ BBC Nigeria 2019: Ọ̀rọ̀ àwọn olóṣèlú, tásìkò bá tó, akólòlò á pe baba - Bode George 8 Èrèlè 2019 O ti pẹ ti ọrọ ti n jẹyọ si gbangba laarin oloye Oluṣẹgun Ọbasanjọ àti aarẹ Muhammadu Buhari, Ni kete ti ọkan ba sọ ni ẹnikeji yoo ti fesi.
Nígbà tí àkókò bá tó, gẹ́gẹ́ bí mo tí ń ṣọ́ wọn tí mo fi fà wọ́n tu, tí mo wó wọn lulẹ̀, tí mo bì wọ́n wó, tí mo pa wọ́n run, tí mo sì mú kí ibi ó bá wọn; bẹ́ẹ̀ ni n óo ṣọ́ wọn tí n óo fi kọ́ àwọn ìlú wọn tí n óo sì fìdí wọn múlẹ̀.
Ó rọ̀jò yìnyín lé wọn lórí,mànàmáná sì ń kọ káàkiri ilẹ̀ wọn.
Toò, gẹ́gẹ́ bí ìṣe mi Alákọ̀wé yín tòótọ́, àwọn àwòrán tó jọjú ni mo mú wá lónìí o.
"Àgbààgbà Yorùbá kò fara mọ́ àbá gbígbógun ti ojú òpó ayélujára - Seyi Makinde Aṣaájú olùwọ́de EndSARS 50 dèrò iléẹ́jọ́ lórí ìfẹ̀hónúhàn àti ìdàlúrú Ìpínlẹ̀ mọ́kànla ni kò tíì bẹ̀rẹ̀ sí ń ṣàmúlò òfin tó dáàbò bo ẹ̀tọ́ àwọn ọmọdé - Ìjọba àpapọ̀ ""Kii ṣe ifẹ ọkan mi lati da igbeyawo mi ru lainidi, n ko si le tẹsiwaju mọ lati maa gbe ninu igbekun."
Anunobi ni: “leyin ti a ti se ayewo yii tan ni a ri awon alaboyun mewaa ti won ni ito suga ti ati ni ki won maa lo si ibudo itoju aisan yii ti a n pe ni Akinkugbe Renal Centre fun itoju to peye.
Wọn yoo jẹ ki esi naa ma tete jade bayi ti o si ṣeeṣe ki awọn eeyan ma mọ esi ayẹwo laarin wakati mẹrinlelogun Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Bí ẹ bá ti ń rìn kiri nínú ayé, mo fẹ́ kí ẹ máa wo ohun gbogbo fínnífínní, kí ẹ fiyèsí ohun tí o gbé àwọn eni ìṣáájú ṣubú kí ẹ má ba à ṣubú bí wọn, kí ẹ sì wo iṣẹ́ tí ìforitì ń ṣe fún ọmọ ènìyàn, kí ẹ̀yin náà ba forítì ìṣoro yín.
 Mimojuto iwole atiijade awon fiimu agbelewo lati ile okeere je okan lara awon ise ajo yii.
Ọjọgbọn Adebanji gba oye ọmọwe (Ph.
Ati wi pe ile ẹjọ Kotẹmilọrun l'orilẹ-ede Naijiria sọ ọ ni gbangba pe iru igbesẹ bẹ ko ba ofin mu, lasiko ti ijọba ipinlẹ Kebbi rọ Emir ilu Kebbi l'oye.
Mo bá dojúbolẹ̀, mo kígbe sókè, mo ní, “Áà!
"Gbogbo nnkan to ṣẹlẹ yii la fi ọwọ wa tun ṣe, mo ṣe tan lati sisẹ, sugbọn mo nilo iranlọwọ yin.
lẹ́yìn tí ó bá ti ta ara rẹ̀, wọ́n lè rà á pada: ọ̀kan ninu àwọn arakunrin rẹ̀ lè rà á pada.
Lọjọ Kejilelogun Oṣu Kẹrin ọdun 2010 ni Dagrin padanu ẹmi rẹ ninu ijamba ọkọ nilu Eko.
Ẹ máa tẹríba fún ara yín nítorí ọ̀wọ̀ tí ẹ̀ ń bù fún Kristi.
Ogun kó Samaria nítorí pé àwọn ọmọ Israẹli ṣẹ̀ sí OLUWA Ọlọrun wọn ó gbà wọ́n lọ́wọ́ ọba Farao, tí ó sì kó wọn jáde kúrò ní Ijipti.
Ninu àwọn ọmọ Adini, Ebedi, ọmọ Jonatani, ni olórí;orúkọ aadọta eniyan ni wọ́n kọ sílẹ̀ pẹlu rẹ̀.
Oludari Agba fun ajọ naa, Ọjọgbọn Mojisola Adeyeye lo sọ bẹ ẹ ninu ifọrọwanilẹnuwo kan to ṣe nileeṣẹ amohunmaworan ipinlẹ Oyo, BCOS lọjọ Iṣẹgun.
Bí kò bá ṣe bẹ́ẹ̀, ǹjẹ́ n óo sọ fun yín pé mò ń lọ pèsè àyè sílẹ̀ dè yín?
Ìwọ ni o óo máa ṣe olórí àwọn arakunrin rẹ,àwọn ọmọ ìyá rẹ yóo sì máa tẹríba fún ọ.
'Orúkọ pásítọ̀ ni Magu fi ra ilé N573 mílíọ̀nù sì Dubai - PCARA Ajayi fikun un pe igbeṣẹ rẹ gẹgẹ bi Abẹnugan ti ko ẹrẹ ati idọti ba eto ofin ni ipinlẹ Ondo.
Ẹran mẹ́ta ni wọ́n bá ní ilé àwọn olè wọ̀nyí nítorí pé wọ́n ti jí méjì tẹ́lẹ̀.
Gẹgẹ bi ọrọ to sọ fun awọn oniroyin, iṣẹ awakọ lo n ṣe pẹlu ileeṣẹ awakọ Bolt nilu Eko.
N óo dá iná kan ninu àwọn ìlú rẹ,iná náà yóo sì jó gbogbo àyíká rẹ.
Ọrọ lẹta ti wọn kọ yii si ti n fa ariyanjiyan lori ayelujara Twitter.
Adajọ agba lorilẹede Naijiria lagbara lati yanju awuyewuye lori esi idibo.
Nibi táwọn kan ti fẹ́ yọ oyún lọsibitu, ni Judith ti rina pade wọn nigba ti iṣoro rẹ yii kọkọ bẹrẹ to si n bẹ̀ wọ́n fún pàsípàrọ̀ - Bawo ni wọn ṣe fẹ ṣe e?
awon si ti fi won ranse si ile ise olopaa orile ede yii fun iwadii kikun.
Anu, ẹni to ni pẹlu ibanujẹ ni oun fi n kọ ikede naa tun ni ó pọn dandan lati ṣe bẹẹ nitori ẹ̀mí oun atawọn ọmọ oun wa ninu ewu.
ki ilumọọka ajafẹtọmọniyan Sunday Igboho to gbẹna woju wọn.
Awọn ohun to ṣe pataki si awọn igberiko ni a gbaju mọ, gẹgẹ bii awọn ẹgbẹ oṣelu ṣe ṣalaye rẹ.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ayefele sọ ìdí ti gómìnà Ajimobi fi wo ilé rẹ̀ Tinubu: Ọbasanjọ kò lè yan olùdíje fún wa ‘Ojú larí, ọ̀rẹ́ kò dénú ni Tinubu ń se lọ́dọ̀ Buhari’ Èèwọ̀!
Bi a ba ni ki a ka ni meni meji, oju iwe yoo kun koda, yoo tun ṣeku.
Igba yẹn ni a ri awọn ọkunrin meji lori ọkada, ti wọn n gbe owo ati alupupu rẹ salọ."
Nígbà tí ilẹ̀ mọ́, ìdààmú bá Farao, ó bá ranṣẹ lọ pe gbogbo àwọn adáhunṣe ati àwọn amòye ilẹ̀ Ijipti, ó rọ́ àlá náà fún wọn, kò sì sí ẹnìkan ninu wọn tí ó lè túmọ̀ rẹ̀ fún un.
Bukunmi Oluwashina ṣe igbeyawo bonkẹlẹ Iroyin eleyii dabi ole to yọ tọ onile laarin oru fun ọpọ awọn ololufẹ Bukunmi Oluwashina.
 Ó ní àwọn akẹ ́ kọ ẹgbẹ ̀ rún lé ọgọ ́ rún ní ọdún 2011 sí 2012 .
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ẹgbẹ ọmọ Yorùbá kí Gomina Abiola Ajimobi kú oríire ọjọ́ ìbí 16 Ọ̀pẹ̀̀ 2018 Agbarijọpọ ẹgbẹ awọn ọmọ bibi ilẹ Ibadan, Central Council of Ibadan Indigenes (CCII) n ṣe akanṣe eto igbalejo fun ayẹyẹ ọjọ ibi ọdun mọkandinlaadọrin ti gomina ipinlẹ Ọyọ, Sẹnetọ Abiọla Ajimọbi.
Gomina ipinle Kano ni ekun ila
Obìnrin Mùsùlùmí ṣe ilé àlúfà ní ọ̀ṣọ́ fún Kérésìmesì Àwọn gómìnà nílẹ̀ Yorùbá ti kùnà láti pèsè ààbò tó péye fún aráàlú - Ẹgbẹ́ Majeobaje Bakan naa ni wọn lo tun se owo iranwọ eto ẹkọ fawọn ọmọ mẹkunnu nilu Nairobi basubasu.
YWC yọ Ààrẹ Banji Akintoye nípò àbi Akintoye tú ìgbìmọ̀ aláṣẹ YWC ká?
Lizzy Anjorin vs Toyin Abraham: Ẹ wòó ẹ fi wọ́n sílẹ̀, ìgbà ọtun ń bọ láipẹ́ -Toyin
Awọn ọlọpaa ni irọ pọnbele ni Melaye pa lori iṣẹlẹ naa to lo waye loju ọna marosẹ Abuja si Lọkọja.
Nígbà tí wọ́n rí i, wọ́n fẹ́ dá a dúró kí ó má kúrò lọ́dọ̀ wọn.
Igbakeji oludari eto ibanisọrọ fasiti Futa, Adegbenro Adebanjo lo fi ikede yii sita ninu atẹjade kan ti ile ẹkọ naa fi sita.
"Wọn a si sọ ninu ọkan wọn pe: Aye o naani wa, kilode ti ao fi naani rẹ?
 Oríṣun àwòrán, Getty Images Joshua wa gba ladura pe, ki eledua jẹ ki alaafia jọba ni Naijiria tii ṣe orileede abinibi oun."
Pupọ ninu awọn owo naa lo n wa lati ọwọ eeyan to maa n gbe owo kalẹ gẹgẹ agbatẹru oludije.
Ninu awọn ẹgbẹ agbabọọlu mẹfa to maa n du ipo mẹrin akọkọ lori atẹ igbelewọn liigi ilẹ Gẹẹsi, iyẹn Manchester city, Liverpool, Arsenal, Manchester United, Chelsea ati Tottenham, Manchester city pẹlu Liverpool nikan lo bori ninu ifẹsẹwọnsẹ wọn lopin ọsẹ yii, ọmi ni Manchester United ati Chelsea ta ninu ifẹsẹwọnsẹ tiwọn to waye lọjọ satide.
Títí laelae ni òun ati àwọn ọmọ rẹ̀ yóo máa pa ìlànà yìí mọ́.
Èèyàn kàn kú méjì farapa níbi ikọlù ẹ̀ṣọ́ asọ́bodè àtàwọn oní fàyàwọ́ ìlú Ayetoro Àìsàn Muyiwa kò lè la ẹ̀mí lọ - Agbẹnusọ Òṣèré, Muyiwa Ademola Fọnran fidio o to di gbajugbaja lori ayelujara, ṣafihan arakunrin naa nibi ti o ti n fi ọwọ mejeeji tẹ ara erin naa to ṣubu si aarin opopona kan.
"Ẹfunroye Tinubu - Ògbóǹtagí oníṣòwò, olówò ẹrú àti afọbajẹ Samuel Ajayi Crowther, òjíṣẹ́ Ọlọ́run tó gbé èdè Yoruba lárugẹ Mọrèmi Àjàṣorò, akọni obìnrin tó gba Ilé Ifẹ̀ sílẹ̀ lóko ẹrú ""Lati igba ti mo ti gori itẹ awọn baba nla mi, awọn ohun adiitu ti ko wọpọ ni mo ti se awari rẹ, eyi to kọja oye eniyan ati imọ sayẹnsi pẹlu."
* Orilẹede Naijiria kun ara awọn orilẹede to buwọlu adehun ajọṣepọ okoowo ọfẹ laarin awọn orilẹede Afirika, agreed African Continental Free Trade Area (AfCFTA), Wo àwọn oúnjẹ márùn ún tó ń mú kí àtọ̀ ọkùnrin dára síi Kí làwọn nǹkan tó lè rán ọkùnrin sí ọ̀run alákeji lásìkò ìbálòpọ̀ pẹ̀lú obìnrin?
Kò sí àyè fún fíìmù eré ìfẹ ṣíṣe ni Kannywood mọ́ Aisha Buhari ké gbàjare pé ètò ìjọba Buhari kò ṣànfàní f'óbìrin NBC fọwọ́ sí ìdásílẹ̀ ilé iṣẹ́ Fulani Radio Ọ̀rọ̀ Aisha Buhari sí Ramaphosa wú ọ̀rọ̀ síta lẹ́nu àwọn ọmọ Nàìjíríà Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Bode George: òòtọ́ ni ìkìlọ̀ Obasanjọ ati Soyinka Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Agbára Ọlọrun ni ó fi ṣe ohun tí ó ṣe lónìí.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù SERAP: Àwọn èèyàn Oyo gbọdọ̀ dásí àbá àjọ tó ń gbógun tìwà ìbàjẹ́ 11 Agẹmo 2019 Oríṣun àwòrán, Facebook/Seyi makinde Ajọ SERAP ti rọ awọn eeyan ipinlẹ Oyo lati sọ tẹnu wọn lori aba lati da ajọ to n gbogun tiwa ajẹbanu nipinlẹ naa silẹ.
Iku akọroyin kan ni ọdun 2018 to ya gbogbo aye lẹnu ni ti ọmọ Saudi Arabia, Jamal Khashoggi.
Ó wí fún wọn ninu ẹ̀kọ́ rẹ̀ pé:
"Aguero sọ pe"" ẹru n ba pupọ ninu awọn agbabọọlu nitori pe wọn ni ọmọ ati ẹbí."
Ìgbì omi òkun líle ni wọ́n, tí ó ń rú ìwà ìtìjú wọn jáde.
oun ati awon ti o tẹle wa se abewo si Ajimobi lati fihan pe isejoba oun yoo
Bi a ko ba si ni gbagbe, o ṣi ku ifẹsẹwọnsẹ mẹrin ki saa bọọlu liigi ti ọdun yii to pari.
Nígbà tí ó yí ojú pada, tí ó rí wọn, ó ṣépè lé wọn ní orúkọ OLUWA, abo ẹranko beari meji sì jáde láti inú igbó, wọ́n fa mejilelogoji ninu àwọn ọmọ náà ya.
O ti kọ iyawo mta silẹ saaju asiko yi ti o si bi ọmọ meje.
Bi a ko ba gbagbe lọjọ kejioṣu Kẹrin ni ile ẹjọ giga ni Bwari nilu Abuja dajọ pe Ademola Adeleke ko kaju osuwọn lati du ipo Gomina ninu idibo Gomina to waye ldun to kọja nipinl Osun.
 amo apere to dara lawon meji nitoripe awon eya mejeji ngbe papo lalafia laisi wahala .
Ni ọdun 2018 ni ijamba akọkọ to waye ti eeyan 189 si padanu ẹmi wọn nigba ti baalu Lion Air kan ja si okun.
orile ede Naijria se tobi to ati ohun ti o dara nipa orile ede naa,” o
Ninu atẹjade kan ti alukoro ileeṣẹ naa, Joseph Attah fi sita, ileeṣẹ aṣọbode ni ọwọ awọn oṣiṣẹ ikọ ojulalakan fi nṣọri rẹ lo tẹ agba ikọja si kan ti nọmba rẹ jẹ MRSU 3040288 ti wọn fi nko ẹru nnkan ijagun naa lopopona marosẹ Aba si Port Harcourt.
idagbasoke ati ọjọ iwaju rere orile ede Naijiria, ijoba aare Buhari ko ni jaa
Wọn ni o ti fipa ba ọpọlọpọ obinrin lo pọ, koda, a gbọ pe iya arugbo ẹni ọgọrin ọdun kan wa ninu awọn obinrin naa to ti fipa ba lopọ.
 ní ọjọ ́ kẹtàdín-lógún oṣù kéje , ọdún 2004 ( july 23 , 2004 ) nígbà tí ó ń múra láti jábọ ̀ ìṣẹ ̀ lẹ ̀ omíyalé tí ó ṣẹlẹ ̀ ní hackensack , new jersey , ní ọlọ ́ kọ ̀ kán gba tí ó sì sálọ ( hit and run ) .
Ó fi kún pé ní báyìí ìpińlẹ̀ mẹ́rìndílógún nínú mẹ́rìndínlógójì ló ti pari ìpolongo abẹ́rẹ́ àjẹsára ààrún ibà pọ́jú.
Awọn ibi ti wọn ni akọsilẹ iforukọsilẹ to dara ti ko dẹ si oṣiṣẹ INEC ti yoo ṣe atojọ esi ijọba ibilẹ naa ni awọn yoo fi pari ikede naa lẹyin iwadii to yẹ.
A fún ọ láṣẹ lórí ohnu gbogbo nínú ayé, lórí ohun alààyè gbogbo.
  Iroyin to n te wa lọwọ bayii ni wi pe igbakeji oludije fun ipo aarẹ labe asia egbe oṣelu PDP, Peter Obi ti dibo ni ibudo idibo rẹ.
” Labani dáhùn, ó ní, “À ń gbọ́.
Ṣùgbọ́n òjò yìí pọ̀ gidigidi bẹ́ẹ̀ ni ẹ̀fúùfù ń fẹ́ kíkankíkan.
"O ni ""Mo n fẹ awujọ ti awọn eeyan ko ti ni maa ta awọn opo awọn akọni to ti ba ogun lọ sẹyin."
Obinrin náà dá a lóhùn, ó ní: “A lè jẹ ninu èso àwọn igi tí wọ́n wà ninu ọgbà, 
Ọtí líle ń mú wọn ta gbọ̀n-ọ́n-gbọ̀n-ọ́n;wọ́n ń ríran èké, wọ́n ń dájọ́ irọ́.
Mọ̀ sí i nípa àwọn ọmọ Nàìjíríà mẹ́sàn-án tó ń díje nínú ìdìbò ilẹ America lọ́jọ́ Ìṣẹ́gun Inú mi máa ń bàjẹ́ ni tí mo bá ti rí SARS- Fasasi Tiamiyu Èmi kọ́ ló pàṣẹ fún àwọn sọ́jà láti má a pa èèyàn ní Oyigbo - Nyesom Wike US Election 2020: Ṣé èsì ìdìbò Ààrẹ Amẹrika yóò jáde lálẹ́ ọjọ́ ìdìbò?
Meji lara awọn mẹta ninu ẹgbẹ agbabọọlu ti awọn onwoye bọọlu alafẹsẹgba n ro pe yoo gba ife ẹyẹ ti saa ni ikọ Liverpool ati ikọ Manchester City, to jawe olubori ninu idije Premier League.
Ọpọ eeyan ti ko si ni òye kíkún nípa rẹ ti bọ sọwọ gbajuẹ.
Arabinrin Oche Meno, ti o jẹ osiisẹ Amofin ni Ile-iṣẹ ijọba Ẹṣọ Alaabo Labẹle (Nigerian Security and Civil Defence Corps (NSCDC) ṣalaye pe o yẹ ki abadofin naa ṣagbeyẹwo owo ọya awọn oṣiṣẹ olutọju ile bayii.
Bawo ni ijamba naa ni ti ṣe ṣẹlẹ Baalu Boeing 737 ti ile iṣẹ ọkọ ofurufu pọku lowo ẹ 'Lion Air' gbera ni nnkan bi ago mẹfa kọja ogun iṣẹju lowurọ ọjọ aje lati olu ilu Indonesia tii ṣe Jakarta.
Coronavirus Lockdown: Gómìnà Akeredolu fárígá,Ó ṣèlérí àti ti ìpínlẹ̀ Ondo pa bí èèyàn míràn ba kó àrùn Coronavirus níbẹ̀ Oríṣun àwòrán, Arakunrin Akeredolu Gomina ipinlẹ Ondo, Arakunrin Rotimi Akeredolu ti kede ofin konile-o-gbele kaakiri ipinlẹ Ondo.
Nítorí ìkọlù àjòjì ní South Africa, èèyàn 5000 ló padánù iṣẹ́ wọn ní Nàìjíríà Ààbò tó péye wà fún àwọn okòwò ará South Africa ni Eko -Sanwo Olu Ìkọlù sáwọn àjèjì kò tíì tán ní South Africa, ètò ń lọ láti kó ọmọ Nàíjíríà wálé Ìdajì owó iṣẹ́ àgbàṣe ló ń padà sápò gómìnà àná àti aya rẹ̀ l‘Ọyọ - Seyi Makinde Ṣé lóòtọ́ ni PDP fẹ́ kẹ̀yìn sí Gómìnà Seyi Makinde nípínlẹ̀ Oyo?
Ìjọba àpapọ̀, ẹ so ifilọlẹ ẹ̀rọ alatagba 5G rọ na - ilé asofin àgbà Mẹ́rin nínú àwọn mọ́kànlá tó ń bọ̀ láti Sokoto tí wón mú l'Oyo ló ní Coronavirus Wo àwọn to ti rí ìwòsàn lọ́wọ́ àrùn coronavirus àti ibi tí wọ́n ti wá káàkiri Nàìjíríà Iye ìgbà tí Sani Abacha tí fi owó ransẹ si Nàìjíríà láti ọrun Amọṣa o ni ọna kan pataki lati bori wahala to lee waye lori eto ọrọ aje lẹyin ajakalẹ arun naa ni ki olukuluku orilẹede ni ilẹ Afirika o boju wo inu ile rẹ lati lo awọn ohun ti o ba ni fi gbe ara rẹ dide.
Yóo máa ṣẹlẹ̀ láàárọ̀,yóo sì máa ṣẹlẹ̀ tọ̀sán-tòru.
Oríṣun àwòrán, The Nation Àkọlé àwòrán, Aworan iroyin ayederu lori opo ayelujara kan Lẹyin ti awọn eeyan ti pin iroyin yii loju opo Twitter lọjọ kẹrinla osun Kẹwaa, awọn iwe iroyin ayelujara meji ba gbe iroyin ọhun.
"Ṣugbọn bi ọmọ yẹn ṣe sọnu o ye Ọlọrun ọba to jọ ṣẹda emi ati ẹ""."
Kò gbọdọ̀ mu ọtí èso àjàrà, bẹ́ẹ̀ ni kò gbọdọ̀ jẹ èso àjàrà tútù tabi gbígbẹ.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Mọ ẹ̀tọ́ rẹ gẹ́gẹ́ bíi ọmọ Nàìjíríà gidi Ibà yọ Serena Williams ní Madrid open Bàtà àti aṣọ tú àṣírí afurasí adigunjalè Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
"Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Lẹ́yìn ìfẹ̀yìntì ọdún márùn-ún, báágì àti bàtà ló kàn Kloe tó lọ sí BB Naija rèé, ó ní òun fẹ́ràn ọkùnrin tó bá dúdú ""Ìlú mímọ́ nibí, wọn kò gbọdọ̀ bímọ, sin òkú àbí ẹran síbẹ̀"" Ọlọgbọndiyan ni ọpọlọ APC ko mọ ọna odo mọ, lo ba da si awuruju, idi si ree to se n kesi awọn ileesẹ ọtẹlẹmuyẹ DSS ati ọlọpa lati fẹhonu han lori abajade awọn nipa oju opo ajọ INEC naa."
4 Bẹ́ẹ̀ni, ẹnikẹ́ni tí ó bá fi dòjé rẹ̀ tí ó sì kórè, òun kannáà ni Ọlọ́run pè.
Eyi si mu ko ṣe e ṣe fun lati fi ikede ori amohunmaworan bori Trump ni awọn ipinlẹ ti ijakade ti ma n waye.
latari bi won se sun eto idibo to yẹ ko waye lojo Abameta, ojo kerindinlogun
L'oṣu Kinni, ọdun 2020, olori tuntun fun IS, Abu Hamza al-Qurashi, kede pe igun tuntun ẹgbẹ naa yoo kọlu awọn Júù ati Ísírẹ́lì.
Nígbà ti wọ́n tun bèrè pé ṣé o darapọ̀ mọ́ àwọn olùwọ́de #EndSars tẹ́lẹ̀, o ni rárá òun ko si lára wọ̀n rárá.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Eeyan mẹrin ku ninu ijamba afara to wo lulẹ Ẹmi mẹrin sọnu sinu ijamba afara Kara Àìsàn jẹjẹrẹ mú ẹ̀mí Aisha Abimbọla lọ Ṣugbọn Gómìnà Mutua ní ọrọ̀ kò ri bẹẹ.
Nítorí aìsan owó àjẹmọ́nú, àwọn dókítà yóò bẹ̀rẹ̀ ìyanṣẹ́lódí lọ́jọ́ Ajé Oríṣun àwòrán, others Ẹgbẹ awọn dokita nileeẹkọṣẹ iṣegun gbogbo lorilẹede Naijiria, NARD ti kede pe awọn yoo bẹrẹ iyanṣẹlodi ọlọjọgbọọrọ bẹrẹ lati ọjọ Aje, ọjọ keje oṣu kẹsan ọdun 2020.
Awọn onwoye nipa ọrọ oṣelu sọ pe Trump wọle ibo aarẹ lọdun 2016 nitori o sọ ọrisiiriṣii ọrọ ti ko baku gbe.
 o koko bo si ipo kinni lagbaye ni ojo 8 osu kejo 2002 .
Ní ti àwọn arakunrin wa, òjíṣẹ́ àwọn ìjọ ni wọ́n, Ògo Kristi sì ni wọ́n.
Wọ́n lu àbúrò mi ló jẹ́ kí ń fi ìbínú lu òǹtàjà l‘Abuja - Sẹ́nétọ̀ tó lu obìnrin ṣàlàyé Biodun Fatoyinbo fi ipò sílẹ̀ lorí ẹ̀sùn ìfipábánilòpọ̀ Agbébọn yabo àgọ́ ọ́lọ́pàá, wọ́n pa DPO àti ọlọ́pàá mẹ́ta míràn Don Jazzy, MrP, Kate Henshaw àtàwọn èèkàn ìlú míràn sọ̀rọ̀ lórí Sẹ́nétọ̀ tó lu obìnrin l'Abuja Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Widows Day 2019: Mo máa ń sá kiri wá owó ilé ni -Opó Ọpọ lo si ti n koro oju, bu ẹnu ẹtẹ lu ihuwasi sẹnetọ naa.
"O ni ""Ni osẹ meta sẹyin ni orilẹ-ede Amẹrika kọwe siwa lati ranwọn lọwọ lọna lati mu awọn afurasi oni jibiti."
Ọgbẹni Christian Oha to jẹ akọwe ile iṣẹ to n ri si ọrọ olu ilu orilẹede yii, ki aarẹ ku oriire lori eto iburawọle rẹ wọn ṣe adura fun un wọn si jẹjẹ atilẹyin wn fun aarẹ Buhari pe gbọingbọin lawọn ara Abuja wà lẹyin aarẹ ni saa to ti wọle yii.
Ta ló lè gba ìyìn tí a rò gbọ́?
Ohun mẹfa ti ọpọlọpọ eniyan ko mọ nipa Majek Fashek Majẹkodunmi Fasheke to tumọ si pe ifa kii ṣe eke, ni orukọ abisọ oloogbe onkọrin, Majek Fashek.
“O fe e to ilopo meji  esun, ti won fi kan onibara mi , laisi ani-ani  a o beere pe ki won sun esun naa siwaju si I”.
Àwọn àgbà ati àwọn olórí alufaa ati àwọn amòfin yóo ta á nù, wọn yóo sì pa á, ṣugbọn lẹ́yìn ọjọ́ mẹta yóo jí dìde.
Iná sọ láàrin wọn,ó sì jó àwọn eniyan burúkú náà run.
Ọkàn kan ń sọ pé kí n wí pé, ‘Baba, yọ mí kúrò ninu àkókò yìí.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Google searches Nigeria 2020: Hushpuppi, Naira Marley, Rema, ASUU wà lára ohun táwọn èèyàn ń wá 10 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Oríṣun àwòrán, Getty Images Oju opo Google maa n saba ṣagbejade ọrọ ti awọn eeyan n wa julọ lori itakun wọn, ti onikaluku orilẹede n wa lọdọọdun.
Ile igbimo asofin orile ede Naijiria  ti yoo kogba wọle niwọn igba diẹ bayii ti  gba ijoba apapo nimoran lati ya owo kan sọtọ fun awon ti ko nisẹ lọwọ lorile ede Naijiria, lati fi di oro airise ku  lorile ede yii.
Njẹ́ ní òde òni àwa ọmọ Odùduwà ń náání oun tiwa bí?
Aisha Buhari sọ pe nkan ti wọn ni ki ẹlẹmọṣọ Garba Sheu sọ kọ ni o gbaju mọ ti o si yapa adehun to ṣe lati ba aarẹ Naijiria ṣiṣẹ tọkantọkan.
Ọ̀pọ̀lọpọ̀ àwọn ajihinrere lo bẹ̀rẹ̀ sii tẹ̀dó si Ìjàyè nígbà ti yoo fi di ọdún 1854.
Gbogbo ohun tí Igboho sì ń sọ yẹ, kò leè sọ lójú mi torí òun gan lo ń dá gbogbo wàhálà yìí silẹ, bẹ́ẹ̀ ni kò sì ṣiṣẹ fún ìjọba yìí, ìjọba to ṣiṣẹ fún tí parí.
O ni oun ko ni dakẹ lori igbagbọ oun nitori olorin naa gbe Imaamu ga ju anabi Muhammed lọ, o yẹ fun ikú ni.
" Ìtàn ayé Abiola Peller, ọlọ́wọ́ idán tó fi ọ̀bẹ gé ìyàwó rẹ̀ sí méjì Oba Folagbade Olateru-Olagbegi wàjà lẹ́ni ọdún 77 Eji Gbadero, ọmọ Ibadan àti jayé-jayé ọmọ ónílẹ̀ ti wọn yẹgi fun l'Eko Áṣẹyin kìlọ̀ fáwọn adarí olóṣèlú Nàìjíríà láti ṣe ohun tó yẹ nítorí ará ọ̀run ń wò wọ́n!
Bí omi ṣé ń sun jáde ninu kànga,bẹ́ẹ̀ ni ibi ń sun ní Jerusalẹmu.
Wọ́n fi ọjọ́ meje ṣe ìyàsímímọ́ pẹpẹ, wọ́n sì fi ọjọ́ meje ṣe àjọyọ̀.
Olùdarí ọgbà ẹ̀wọ̀n Ìkòyí, Ìbíkúnlé Àbáyọ̀mí Idris ni, ẹlẹ́wọ̀n méjìlá ló yege ìdánwò UTME náà.
Koko ti BBC fidiẹ mulẹ ni pe tootọ ni inu awọn agbabọọlu naa ko dun si aisan owo ajẹmọnu wọn bi o ti yẹ.
Ọba oke si lo mu ki ẹsẹ Naijiria duro re pada, bibẹẹkọ, wahala ibo June 12 ko ba ti ree isọkan ati irẹpọ Naijiria ni ẹfasẹ.
- iléeṣẹ́ ológun kìlọ̀ Àṣé àṣírí wà nínú Hijabu tí Aisha Yesufu ń wọ̀ lọ ìwọ́de Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Eegunjobi Omotanbaje Ajobiewe- Èébú ní wọ́n kọ́kọ́ ń bù mí nígbà tí mo bẹ̀rẹ̀ ẹ̀ṣà pípé ní Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Seyi Makinde: Ọ̀sẹ̀ àkọ́kọ́ ní December ni màá sìnkú ìyá mí20 Ọ̀wàrà 2020 ENDSARS, End SWAT: Ààrẹ Buhari ló pa àṣẹ tó mú kí iléeṣẹ́ ọlọ́pàá ó dá ikọ̀ SARS sílẹ̀, Fulani Kwajafa tó dá SARS sílẹ̀ ṣàlàyé15 Ọ̀wàrà 2020 NYSC Camp, After coronavirus: Ìjọba kéde ọjọ́ ìwọlé àwọn àgùnbánirọ̀ sí ìpàgọ́ lẹ́yìn Covid 19- Minista ọ̀rọ̀ ọ̀dọ́ Nàìjíríà15 Ọ̀wàrà 2020 Fídíò, Soyinka Cancer: Àṣe ara mi ni iso ti n run gbogbo bí mo ṣe n ṣèrànwọ́ lórí jẹjẹrẹ27 Bélú 2019 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Pochettino to jẹ ọga wọn gboriyin fun Skipp pe o fakọyọ bo ti yẹ.
Wọ́n ń jẹ oúnjẹ àgàn tí kò bímọ,wọn kò sì ṣe rere fún opó.
Ilé ẹ̀kọ́ alakọbẹrẹ ni mo ti kọkọ bẹ̀rẹ̀ ere ṣíṣe, kò tó wà di pé mo bẹ̀rẹ̀ si ni rí owó ni ìdí rẹ lọ́dún 1984."
Tani Akeredolu tó ń díje dupò gómìnà fún ìgbàkejì nípìnlẹ̀ Ondo Ikọ̀ Boko Haram àti gbogbò àwọn tó ń sàtìlẹyìn fún wọn kò ní rí ọdún 2021 - Pásítọ̀ Adeboye INEC kéde agbègbè ẹsẹ̀ odò 270 ti èrú ìbò ti le wáyé ní ìpínlẹ̀ Ondo Ayé má níkà o!
Ìkùukùu náà bá dúró ní aṣálẹ̀ Parani.
Iléẹjọ́ ní Elijah Abbo kò lẹ́jọ́ jẹ́ N kò ri ipa ẹ̀jẹ̀ lára ọmọ mi tó kú sí iléeṣẹ́ ọṣẹ, èjò lọ́wọ́ nínú - Òbí àkẹ́kọ̀ọ́ UI Mò máa ń fọ àwọ̀tẹ́lẹ̀ ìyá mi, ni ìṣe àwọn obìnrin fi wù mí - Bobrisky Àlàyé rèé lóríi àjọṣepọ̀ tó wà láàrin èmi àti MC Oluomo - Ronke Oshodi Oke Ẹ bá mi wá nọ́ńbà ìpè òbí ọmọ Mummy Calm Down jáde - Yinka Ayefele Ọlọ́pàá sálọ fún aráàlú l‘Okeho, nígbà tí wọn yari láti ṣun olè méjì tó kù Nibi ipade akọroyin to si tẹle isẹlẹ naa ni Sẹnatọ ọhun ti tọrọ aforijin pupọ lọwọ obinrin to fiya jẹ naa.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Wo bí Sunday Orimola ṣe gba ikú ẹranko kú ní Ifon ni Ondo lórí ọ̀nà àtijẹ Ọ̀pọ̀ ọmọ Naijiria lo tún ti wa n bere bayii pé, ṣe tọkọtaya ni awọn méjeeji lootọ ni?
Àwọn ẹlẹ́wọ̀n yòókù ń dẹtí sí wọn.
‘OLUWA àwọn ọmọ ogun, Ọlọrun Israẹli ní kí o mú ìwé ilẹ̀ yìí, ati èyí tí a fi òǹtẹ̀ tẹ̀ tí a sì ká, ati ẹ̀dà rẹ̀, kí o fi wọ́n sinu ìkòkò amọ̀ kí wọ́n lè wà níbẹ̀ fún ọjọ́ pípẹ́.
Lootọ ni awọn ibeji onibẹmbẹ oru gba pe ede aiyede maa n wa amọ aawọn aarin awọn ko kọja inu ile, tawọn iyawo awọn ko si lee da si.
Ǹkan tí a mọ̀ nípa kọ́lẹ̀jì olùdìbò tó ń fìdì ẹni ti yóò jẹ ààrẹ ilẹ̀ Amérika múlẹ̀ Owatapa ti Itapa Ijesha, Wolii Olapade Agoro jáde láyé Àwọn jàǹdùkú ya bo àfin Ọba ní Alade Idanre, wọ́n lu Adele ní ìlù bàrà Sanwo Olu àti Okowa dẹwọ́ ìséde ní Eko àti Delta pẹ̀lú àlàyé tuntun Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, John Amanam: Ìfẹ́ tí mo ní sí àbúrò mi ló sọ mi dí ẹni tó ń ṣe 'Prosthetic' báyìí Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí US presidential election 2020: Kíni Kọ́lẹ̀jì ìdìbò, àwọn ìpińlẹ̀ tó le gbé olùdíje wọlé àti àwọn ǹkan ti o yé kí o mọ̀ nípa ìdìbò ilẹ̀ Amerika.
Sibẹ, sibẹ, lai naani awọn alaye yii, ẹnu si n kun Mamma Daura loju opo ayelujara nipa ilera rẹ, bo ba si se jẹ, BBC Yoruba yoo maa mu ẹkunrẹrẹ iwadi wa wa fun yin.
Adamu se ileri ohun leyin ti igbimo to n mojuto ile-ise olopaa bowolu iyansipo
Alukoro ile iṣẹ ọlọpaa, Frank Mba lo fi ọrọ yii lede pe wọn gbe sẹnetọ naa si atimọle lori ẹsun to nii ṣe pẹlu lilo ayederu iwe ẹri.
Bẹ́ẹ̀ sì ni bí ẹ bá ṣe oríkunkun sí OLUWA lónìí, gbogbo àwọn ọmọ Israẹli ni yóo bínú sí lọ́la.
láti tọ́jú ọpọlọpọ igi, nítorí pé ilé tí mo fẹ́ kọ́ yóo tóbi, yóo sì jọjú.
orúkọ ìbílẹ ̀ tí a dífá fún láti ọ ̀ dọ babaláwo ń ṣe àfihàn òrìṣà tó ń ṣe atọ ́ nà ọmọ náà wá sáyé , yálà ọmọ náà jẹ ́ àtúnbí oònilẹ ̀ àtipé kádàrá ọmọ àti nípa ti ẹ ̀ mí tí ó lẹ ́ tọ ̀ ọ ́ sí , tí ó máa ran ọmọ.
O ti sọju ninu ile igbimọ naa lati ọdun 2010.
Wọn fikun un pe ti o ba jasi otitọ, ofin ṣiṣe gaaya si ara ẹni yoo yatọ si bi o ṣe wa bayii.
O dìgbà tí mo bá dórí àgá kí ń tó sọ ìpinnu mi - Fatai Owoseni Ọlọ́pàá ti mú ẹni márùn ún lórí ìjà láàrin Hausa àti Yorùbá l'Eko Ọ̀pọ̀ èèyàn bẹnu ẹ̀tẹ́ lu Mercy Aigbe lórí bó ṣe ki Adeniyi Johnson Ọlọ́pàá Ogun gb'ọmọ Ìmáàmù lọ́wọ́ ajínigbé, ṣùgbọ́n wọ́n gbé ọkọ̀ ojú omi ọlọ́pàá lọ O ni iṣẹ iwadii fi idi ẹ mulẹ wi pe irẹjẹ wa ninu iye owo ti wọn fun awọn oṣiṣẹ naa tẹlẹri.
Iléeṣẹ́ ọlọ́pàá ní Kano tí ṣe àyẹ̀wò àwọn 13, 048 tó fẹ́ darapọ̀ mọ́ wọn Facebook mú àyípadà bá àtẹ̀jíṣẹ́ síra ẹni lórí òpó Instagram, wo àwọn ǹkan tó kàn ọ níbẹ̀ Ẹ̀rọ CCTV tú àsírí ọkùnrin ẹni ọgbọ̀n ọdún tó fi ipá bá ọmọ ọdún mọ́kànlá lòpọ̀ Ọkùnrin tí wọ́n fẹ̀sùn kàn pé ó jí ǹkan nílé ìjọsìn rí ẹ̀wọ̀n he!
Jesu bá dá a lóhùn pé, “Ọkunrin kan ń ti Jerusalẹmu lọ sí Jẹriko, ni ó bá bọ́ sí ọwọ́ àwọn ọlọ́ṣà.
Wo àwọn àwòràn tó làmìlaaka nílẹ̀ Adúláwọ̀ lọ́sẹ̀ yìí Ọwọ́ ọlọ́pàá ti tẹ ọkùnrin kan tó pa ọ̀rẹ́ rẹ̀ nítorí N40 ní Kano Ẹ yé gba owó orí níbi ìdána ìyàwó mọ́, sísọmọbìnrin s'óko ẹrú ni- Daddy Freeze Ọmọwe Monckton Smith ti kọ awọn agbẹjọrọ, onimọ nipa ironusi ọpọlọ ẹda, ati awọn agbofinro ni ọpọlọpọ igba lori iṣẹ iwadii yii ni UK.
Ṣugbọn odidi oṣù kan ni ẹ óo fi jẹ ẹ́, títí tí yóo fi fẹ́rẹ̀ hù lórí yín, tí yóo sì sú yín, nítorí pé ẹ ti kọ OLUWA tí ó wà láàrin yín sílẹ̀, ẹ sì ti ráhùn níwájú rẹ̀ pé: ‘Kí ló dé tí a fi kúrò ní Ijipti.
Àwọn ọmọ Israẹlití wọ́n wà ní oko ẹrú ní ilẹ̀ Halawọ́n óo gba ilẹ̀ Fonike títí dé Sarefati;àwọn eniyan Jerusalẹmu tí wọ́n wà ní oko ẹrú ní ilẹ̀ Sefaradiyóo gba àwọn ìlú tí ó wà ní Nẹgẹbu.
Nibayii, orilẹede naa ti kede ọjọ mẹta lati fi ṣ'ọfọ rẹ.
Lẹ́yìn náà, mú ìwọ̀n hini ojúlówó òróró olifi kan.
se atileyin fun ajo to n mojuto ẹtọ ọmọniyan lorile ede Naijiria.
Fidio naa ni imọran to le ni ẹgbẹrun lọna ọgọta laarin wakati melo to fi sita.
O gba awọn obi akanda ẹda nimọran pé ki wọn ma jẹ ki awọn ọmọ bẹẹ ro pe iṣoro ni awọn jẹ ninu ile fun ẹbi.
’Ọba náà sì fèsì ó ni, Bẹ́ẹ̀ ni, mo ṣẹ̀ṣẹ̀ ń mọ ọwọ́ obìnrin náà ni, nítorí mo gbé e lẹ́ẹ̀kan bí ẹni kí n là á mọ́lẹ̀ àfi ìpàǹtí tí ó kọ́ mi lẹ́sẹ̀ ló jẹ́ kí o bọ́ lọ́eọ́ mi’Ẹnìkan tún bèèrè ó ni, ‘ṣé kò ta yín ní ìpá lónìí?
Agbẹnusọ to ba BBC Yoruba sọrọ ni eniyan mejila ni awọn ti doola bayii, wọn ti gbe eniyan mẹjọ ninu wọn lọ si ile iwosan ijọba tó wà ní Gbagada ti wọn si ko awọn mẹrin lọ si ile iwosan ti LASU.
labẹ asia ẹgbẹ oṣelu All Nigeria Peoples Party, ṣugbọn o bọ mọ ọ lọwọ si ọwọ
Ìgbà tí mo dé etí ọdọ rẹ̀ mo pe ògèdè síi kí inú rẹ̀ bà le rọ̀ sí mi, lọ́yìnn náà mo ni:
anfaani naa lati lo sefilole ise akanse ipese ina mona-mona(Aba Power Plant),
Jesu dá wọn lóhùn pé, “Ẹ ṣọ́ra kí ẹnikẹ́ni má baà tàn yín jẹ.
Nigba ti igbimo to n ri si awuye-wuye lori ibo aare , ni eyi ti adajo
Èyí tí mo rí mọ rèé o, Kábíyèsí, mo dìgbò lulẹ̀ mo dákú.
Eyi mu ka gbosuba fun ọrọ ti minista fun eto aabo nigba kan ri, ajaagunfẹyinti Theophilus Danjuma so pe, ki awọn ọmọ orilẹẹde yi wa wọrọkọ fi sada lori pipese aabo fun ara wọn nitori pe ijọba to wa lode yi ko mo odo ti yoo da ọrunla si, nipa didabo bo ara ilu'' Awọn iroyin ti ẹ lee nifẹẹ si: Se APC fẹ yọwọ PDP lawo oselu Naijiria ni?
O ni wọn yoo le lo o lati fi da iṣẹ́ silẹ fun ara wọn, lati le koju iṣoro airi iṣẹ́ ṣe.
igbalode ati ise atinuda ti odun 2019 to waye ohun.
Nigba ti agbasese (West Africa Energy) ti ijoba fowosi
Wúrà ni wọ́n fi ṣe gbogbo ife Solomoni, ati gbogbo ohun èlò tí ó wà ní ilé Igbó Lẹbanoni.
"O ni ""A fẹ sọ pe ko si ootọ ninu ọrọ ti awọn eeyan n sọ pe a fẹ da ida marundinlọgọrin awọn oṣiṣẹ wa duro."
Kò sí ẹ̀dá kan tí ó lè fara pamọ́ níwájú rẹ̀.
“Nígbà tí àwọn eniyan rẹ bá ṣẹ̀ ọ́, (nítorí pé kò sí ẹni tí kì í dẹ́ṣẹ̀), tí o bá bínú sí wọn, tí o sì jẹ́ kí àwọn ọ̀tá ṣẹgun wọn, tí wọ́n sì kó wọn lẹ́rú lọ sí ilẹ̀ mìíràn, kì báà jẹ́ ibi tí ó jìnnà tabi tòsí, 
''Ohun miiran to mu mi sọ iriri mi ni pe ọpọ lo ri ifipa ba awọn ọmọdebinrin lo pọ si ohun ti ko too pọn ọn.
Kaduna killings: Afurasí mẹ́jọ ti wọ gbaga agbófinró nítorí ìpànìyàn Gúúsù Kaduna
tun soro lori wahala to be sile ni ijoba ibile Katsina-Ala ati Gboko, pe awon
Ẹranko Ewèlè yìí ati àwọn angẹli rẹ̀ náà jà títí, 
Ọ̀gbẹ́ni Abíọ́dún Ọláńrewájú ní fásitì OAU Ife kò fààye gba fífi tìpá tìkúùkù fẹ́ tàbí bá ọmọbinrin láṣepọ̀, yálà látọ̀dọ̀ olùkọ́ sí akẹ́kọ̀ọ́ tàbí akẹ́kọ̀ọ́ sí akẹ́kọ̀ọ́.
Oríṣun àwòrán, Ebenezer Obey Fabiyi Imọran fawọn ọdọ ode oni: Nigba to n gba awọn ọdọ nimọran, Obey ni ''Ohun to ba jẹ ẹbun rẹ, ma pa a mọra, tori to ba pa ẹbun rẹ mọra, ko da.
iyanselodi tiwon naa ni ojo kerin,osu kejila odun 2018.
Ohun tí a rí dì mú ninu wọn kò ju nípa jíjẹ ati mímu lọ, ati nípa oríṣìíríṣìí ọ̀nà ìwẹ ọwọ́, wẹ ẹsẹ̀.
Àkọlé àwòrán, Ènìyàn méji ló ti kú lórí àìsàn Ebola ni DRC Ẹni tí ìṣẹ̀lẹ̀ ọhun tún bẹ̀rẹ̀ lóri rẹ̀ báyìí wá láti ìhà ìlà-òòrun arewa Ituri ti wọ́n si gbe e lọ si ilé ìwòsàn Kizba ní àgbègbè Goma lójọ kẹtàlá osù keje.
Sanwoolu ṣe é dáa fún wa níbodè Lekki, Ikoyi - Awakọ̀ ní Lekki Kíló burú nínú kí Sanwo-Olu fún Super Eagles lówó?
 Ilẹ Yuroopu ati India to jẹ ibudo ti awọn ọmọ Naijiria ti maa n lọ gba itọju julọ ni Coronavirus ti n ba finra, o si yẹ ki ẹni to ba gbọn tete joko sile.
Bẹẹ naa lo tọrọ aforijin lọwọ adajọ Okon Abang lori pe oun ko yọju sile ẹjọ lati ọjọ yi ti wọn ti n sun ẹjọ siwaju leralera.
Ijọba ṣe okede ọhun ninu atẹjade kan ti arabinrin C.
Omo-Agege ni iye ibo méjídínláàdọ́rin (68) nigba
Ṣugbọn Dafidi gun gẹ̀rẹ́gẹ̀rẹ́ òkè olifi lọ, láì wọ bàtà, ó ń sọkún bí ó ti ń lọ, ó sì fi aṣọ bo orí rẹ̀ láti fi ìbànújẹ́ rẹ̀ hàn.
Ènìyàn ogún ló tún jẹyọ láti Bauchi, nígbà ti mẹ́tàlá wá láti Abuja, méjìla ni ìpínlẹ̀ Edo, mẹ́wàá ní Sokoto àti méje ni Zamfara.
"Nitori ọpọ asise lo n waye bayi""."
Lati ibẹrẹ ọdun yi to ti gbori afẹfẹ kan, ọrọ ajakalẹ Covid-19 ati bi aarẹ Trump ti ṣe koju rẹ jẹ nkan tawọn eeyan n ran lẹnu.
Kò séwu nínú ìdìbò tó ń bọ̀ l'Ondo àfi gìrì àparò- Akeredolu Ọ̀nà wo ni ìdẹnukọlẹ̀ ètò ọ̀rọ̀ ajé UK yìí yóò gbà láti kan ìwọ náà Iṣẹ́ / Owó Ọ̀pọ̀ ènìyàn le pàdánù iṣẹ́ wọ́n, tàbi kí wan tni kò ní sí ìgbéga tàbi afówókún owó oṣù wọ́n kò ni wayé.
Báálẹ máa ń ṣe ìjọba pẹ̀lú àwọn àwòrò ǹṣàṣà tí wọ́n jẹ́ àgbà láàrín ìlú.
O ṣàlàyé pé lóòótọ́ ni Tinubu kò fẹ́ lórí bí àwọn èèyàn ṣe ń pariwo rẹ pé kò wá díje nítorí ó ti ìgbésẹ ọhun bíi ìwà ọyaju sì aarẹ Buhari to wa lori aleefa, nígbà tí kò tíì parí ṣáá isejọba rẹ.
Lọjọ kẹjọ, oṣu karun un, odun 1996, ile ẹjọ giga ipinlẹ Eko da a lẹjọ ẹsun igbimo idite ti ijọba ati ọpọlọpọ irọ.
Adari àwọn ajínigbé náà tí wọ́n pè ní Umoru na pápábora pẹ̀lú ìbọn , tí àwọn ọmọ ikọ̀ àmọ̀tẹkun náà si farapa.
Awon alase ijoba torokan gbangban naa lowo si isele ohun to n lo lowo.
Ní ìrọ̀lẹ́, Aaroni yóo máa tan àtùpà náà kalẹ̀ níwájú aṣọ ìbòjú tí ó wà níwájú àpótí ẹ̀rí, wọn yóo máa wà ní títàn níwájú OLUWA títí di òwúrọ̀ ọjọ́ keji.
Gómìnà kẹrin – Ọ̀gágun Ori Omi Ebitu Ukiwe – Gómìnà fún ọdún kan – ọdún mọ́kàndinlógóji titi di ọdún méjidinlógóji sẹhin
O ni awọn ẹni to ba jẹ ọmọbibi Ilẹ Gẹẹsi tabi ẹni to ba ni iwe igbelu lọwọ lanfani lati lọ gbe tabi lọ ile iwe lorilẹ-ede alawọfunfun ni wọn igba ti Ilẹ Gẹẹsi si wa pẹlu ajọ EU.
Ṣugbọn iṣoro kan ti wọn ti tu asiri rẹ lati ibẹrẹ ni bi wọn ṣe ń ṣe kara-kata lai bikita.
Ojú rẹ̀ dàbí àwọn àdàbà etí odò,tí a fi wàrà wẹ̀, tí wọ́n tò sí bèbè odò.
A Adamu ti pasẹ pe ki wọn se awari awọn eeyan to ji awọn pasitọ marun ti ijọ Redeem gbe.
Gómìnà ìpínlẹ̀ Bauchi sàlàyépé òun àti ọmọ Atiku 'sun pàde àra àwọn nínú ọkọ bàlú láti ilú Eko lọ si ilú Abuja ti àwọn si bọ ara àwọn lọ́wọ́ Oludári ilé iṣẹ́ radio naijiria nígbà kan ri Ladan Salihu fi idí èyí mull lori àtẹjiṣẹ́ twitter rẹ̀ pé gbogbo àwọn ti àwọn ba ọmọ náà rin irin ajò ni àwọn ti lọ fi ara àwọn pamọ.
Òjò ló lè mú kí ìtànkálẹ̀ àrun ìgbẹ́ ọ̀rìn má tètè dópin ni Eko- Iléeṣẹ́ ìlera Ta ni Ken Saro-Wiwa tí ìjọba ológun sekúpa?
Bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé OLUWA yóo jẹ́ kí ẹ ní ọpọlọpọ ìṣòro, yóo sì jẹ́ kí ẹ ṣe ọpọlọpọ wahala, sibẹsibẹ olùkọ́ yín kò ní farapamọ́ fun yín mọ́, ṣugbọn ẹ óo máa fi ojú yín rí i.
Mo fẹ́ mọ ìdí tí wọ́n ṣe fi ẹ̀sùn kàn án.
Oríṣun àwòrán, @Aminu Bello Masari Ìjọba ní àwọn jàǹdùkú ló jí akẹ́kọ̀ọ́ ní Kankara, Boko Haram tún ti jáde pé àwọn ni, èwo gan an lèwo?
Gẹgẹ bi awọn eeyan to wa ladugbo naa, ti isẹlẹ ọhun si soju wọn ti wi, se ni oorun gaasi kọkọ gba agbegbe naa kan, ti ara si ti n fu awọn pe ewu nbọ, awọn si n wa ọna abayọ lọwọ, ni ina sọ.
 “Bi won se n pa awon eniyan alawo dudu, paapaa julo awon omo orile ede Naijiria niluu London je ohun to n bani-lokanje.
Àwọn kan ninu wọn ń sọ pé, “Ọkunrin yìí tí ó la ojú afọ́jú, ǹjẹ́ kò lè ṣe é kí ọkunrin yìí má fi kú?
Kò gbọdọ̀ fẹnu kan ohunkohun tí ó bá jáde láti inú èso àjàrà, kò gbọdọ̀ mu waini tabi ọtí líle tabi kí ó jẹ ohunkohun tí ó jẹ́ aláìmọ́.
30 Sẹ́rẹ́ 2019 Oríṣun àwòrán, AFP Lasiko eto ipolongo ibo aarẹ lọdun 2014 si 2015 ṣaaju eto idibo gbogboogbo to waye lọdun 2015, Aarẹ Muhammadu Buhari ṣeleri awọn nkan ti iṣakoso rẹ yoo ṣe fun araalu ti wọn ba fi dibo yan an sipo aarẹ Naijiria.
 Èyí lè fa ìrora àti ìpàdánù àwọn ẹ ̀ yà ìkángun nítorí ìfarapa léraléra .
Bakan naa, ilumọọka oniroyin, Dele Momodu gboṣuba fun Agba Oye ilẹ Ibadan ninu ọrọ to fi lede loju opo Twitter rẹ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Sotitobire: Ọkọ mi kò mọ̀ Jegede PDP rí, kódà kò fa ẹnikẹ́ni kalẹ̀ dípò Akeredolu- Bisola Gẹgẹ bi iwe iroyin abẹle Punch ṣe fidi ẹ mulẹ .
Ẹ̀rí náà ti àwọn Ẹlérìí sí Ìwé àwọn Òfin Olúwa, èyítí Ó fifún Ìjọ Rẹ̀ nípasẹ̀ Joseph Smith Kékeré, ẹnití a yàn nípasẹ̀ ohùn Ìjọ fún èrò yìí:
"Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, ""A gbúdọ̀ wẹ̀ ọmọ tuntun pẹ̀lú epo pupa, kàìnkàìn ìbílẹ̀ àti ọṣẹ dúdú' Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?"
O gba ni adura pe lasiko ifẹyinti Tinubu, ohun gbogbo to ti bajẹ lorilẹede Naijiria yoo gba atunṣe.
Awọn iroyin ti ẹ lee nifẹẹ si: Àyẹ̀wò DNA ti fẹ́ bẹ̀rẹ̀ fún àwọn àlùfá Kátólíìkì tó bímọ Ìgbẹ́ ọmọdé ń dènà ààrun jẹjẹrẹ, àìsàn ìtọ̀ súgà Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Ògidì ọmọ Yorùbá ni mí, kò sí ọ̀rọ̀ tí n kò lè túmọ̀' Nathan Sharibu, bàbá Leah Sharibu, sàláyè fún BBC lálẹ́ pé, 'ìnú wá bàjẹ́ gidigidi nínú ìdílé yìí, ìyàwó mi ní ìpòrúru ókàn nigbà tí ó gbọ́ ohùn ọmọ wa, kò rí ọmọ wa.
Nigba ti Adesina  soro nibi iforowanilenuwo lori ero ibanisoro pe, esi ti Lai Mohammed  to je minisita fun iroyin ati asa , so lori oro naa ti yanju ohun  ti aare ana  so.
’ Olu ilu ileeṣẹ ikọ alaabọ lorilẹede Naijiria lo fi lede pe, ikọ Boko Haram to le ni ẹgbẹta lo ti jọwọ ara wọn, ti wọn si ti ṣetan lati darapọ mọ awujọ.
Awa obinrin mẹtala la ri pe a ni aarun naa.
Ninu iṣẹ ikini ọdun to ran si wọn, Fayemi rọ wọn lati maa gbe igbeaye wọn ninu ifẹ, ififunni ati alaafia, to ṣe e farawe.
“Ìran tí èmi Nebukadinesari rí nìyí.
Ni ana ni o fi aworan iya rẹ sori Twitter ninu eyi to fi n ki pe ki o dara le.
Ẹni ọdun marunlelaadọrin ni Sẹnẹtọ Longjan ki iku to mu lọ.
'' ''Ó ní wọ́n borí àwọn ọmọ ogun Nàìjíríà, wọ́n sì tún kó àwọn nkan ìjà kó.
Rwanda ni orile –ede ti won ni o pegede julo ninu eto ogbin lataari pe won gba ida kan le ni mefa lataari atunto ti won se si ona iselu won.
Agbekalẹ agọ ara eniyan nilo ki eniyan tete jẹun, ki ounjẹ naa si da ki iru ẹni bẹ to sun.
Nígbà tí wọ́n bá rí ẹranko náà ẹnu yóo ya àwọn tí ó ń gbé orí ilẹ̀ ayé, tí a kò kọ orúkọ wọn sinu ìwé ìyè láti ìpilẹ̀ṣẹ̀ ayé wá, nítorí ó ti wà láàyè, ṣugbọn kò sí láàyè nisinsinyii, ṣugbọn yóo tún pada yè.
ogún àwo wúrà tí wọ́n tó ẹgbẹrun (1000) ìwọ̀n diramu ati ohun èlò idẹ meji tí ó ń dán, tí ó sì níye lórí bíi wúrà.
Àwọn ogun Siria sá níwájú Israẹli.
NAF: Iléeṣẹ́ ọmọ ogun dá Bashir tó ri owó he lọ́lá
Ariwo Erica ati Kiddwaya ni awọn eeyan tun npa lori ayelujara .
Ilesha Baruba: Ìjọba ìpińlẹ̀ Kwara bá ẹbi àwọn tó sòfò ẹ̀mí kẹ́dùn ni Baruteen
Ayédèrú èsì ibo: Ohun èkejì tí Yar'adua tún ṣe daada ni pé, ó gbà pé èsì ìbò tó gbé òun wọlé kún fún magomago àti ayédèrú esi ibo.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Àwọn ọ̀jọ̀gbọ́n Yorùbá foríkorí gbé ìwé tó lè sọ ẹ̀yà ara yín lédè Yorùbá.
Ẹ fi í sọ́kàn pé ìdí tí Oluwa wa fi mú sùúrù ni pé kí á lè ní ìgbàlà, bí Paulu arakunrin wa àyànfẹ́ ti kọ̀wé si yín, gẹ́gẹ́ bí oore-ọ̀fẹ́ tí Ọlọrun fi fún un.
 nítorí pé kò sí owó lọ ́ wọ ́ àwọn òbí rẹ ̀ láti tọ ́ ọ kọjá ìwé mẹ ́ jọ .
Jẹ́ kí àwọn òpùrọ́ yadi,àní àwọn tí ń fi ìgbéraga ati ẹ̀gàn sọ̀rọ̀ àìdára nípa olódodo.
Ewe, Ronaldo gba ife-eye UEFA champions league nigba marun un otooro ati ife-eye idije La Liga meji fun odun mesan an ti o lo ninu iko agbaboolu Real Madrid.
" Lọwọlọwọ bayii, awọn eeyan to ni arun Coronavirus le ni miliọnu mẹrindinlogun ni orilẹede mejidinlaadọwa.
Agbabọọlu ikọ Manchester United tẹlẹ ri, Patric Evra lo sọrọ yii lẹyin ti Sheffield United ṣina iya fun Arsenal lalẹ ọjọ Aje pẹlu ami ayo kan sodo ninu ifẹsẹwọnsẹ Premier League.
Báwo ni Professor Peller se kú gan?
Gbogbo agbaye lo mọ pe ọrọ idasilẹ ọlọpaa agbegbe ti pẹ lori igba agbeyẹwo lagbo oṣelu lorilẹede Naijiria.
Èso igi ni a fi ń mọ igi.
Amọ ṣa, Dokita Innocent Ujah to jẹ aarẹ ẹgbẹ NMA ṣalaye fun BBC pe kii ṣe dandan ki awọn dokita gba iyọnda lọdọ ẹgbẹ naa lati rin irinajo kuro ni Naijiria.
EFCC fẹ́ gbẹ́sẹ̀ lé ilé tí mo fi owó ìfẹ̀yìntì kọ́ nílùú Ilorin- Saraki Òṣìṣẹ́ LASTMA kan àgbákò ikú lọ́wọ́ àwọn jàǹdùkú méjì nílùú Èkó Missing Child: Òbí àti asọ́nà ṣọ́ọ̀ṣì 14, lọ́ búra nì'dí imọlẹ̀ l'Akure UK ṣetán láti dá Adìyẹ 'Àkùkọ' Nàíjìrìa ti wọ́n gbé padà Sẹnẹtọ Adeyemi ṣalaye pe ''aṣọ alaṣọ ti ko ṣe deedee ti Dino to wọ s'ọrun nigba to wa nile aṣofin agba lo jẹ ko ṣiwawu nibẹ.
Lẹ́yìn ìgbeyàwó ọdún mọ́kànlá àti ọ̀pọ̀ ìjà, Bọsẹ di èrò ọ̀run nílé Saidi Àlejò àpàndodo ni Fayoṣe, a kò fìwé pèé - Afuye Japan ṣèrànwọ́ N149m fún Nàìjíríà lórí ètò ààbò!
Oríṣun àwòrán, Getty Images Bakan naa eniyan le ni aarun to niṣe pẹlu oju ara (UTI).
Àkọlé àwòrán, Obìnrin tí DSS fi ẹ̀sùn kan pé ó ń ọ̀nà alùmọkọ́rọ́yín wọ ilé ààrẹ l'Abuja láti lo gbájúẹ náà rèé Ìròyìn sọ pé obìnrin yìí máà ń lo onírúurú ọ̀nà alùmọkọ́rọ́yín wọ ilé ààrẹ l'Abuja láti lo gbájúẹ pẹ̀lú àwọn ayédèrú òwò ṣíṣe ṣùgbọ́n ó ti kábamọ̀ ìwà rẹ̀ báyìí.
AEDC: Ìdí rèé ti Nàìjíríà fí ń gbé inú òkùnkùn
 Gbogbo NTTF lo n se idaro eni rere to lo.
Ẹẹmeji ọtọọtọ ni wọn tun ibo naa di kile ẹjọ to gbe e fun Fayẹmi.
Ní Asotu ni a tún ti rí Filipi.
Ìtàn Mánigbàgbé: Hubert Ogunde jẹ́ kọ́sítébù ọlọ́pàá àti olùkọ́, kó to bẹ̀rẹ̀ eré síse
Dípò gbogbo wọn, yóo máa bọ oriṣa àwọn ìlú olódi; oriṣa tí àwọn baba rẹ̀ kò mọ̀ rí ni yóo máa sìn, yóo máa fún un ní wúrà ati fadaka, òkúta iyebíye ati àwọn ẹ̀bùn olówó iyebíye.
Kí OLUWA dájọ́ láàrin èmi pẹlu rẹ.
Lara awon gbajugbaja akonimoogba ti o ti tuko kan tabi keji lorile-ede China ni: Luiz Felipe Scolari, Fabio Capello, Manuel Pellegrini ati Andre Villas Boas.
O ni wọn a to rii pé ayé pé meji nitori ominira ti wọn n ri ni PDP ko le tete tẹ wọn lọwọ ni APC ti wọn lọ.
Bí ó ti jẹ́ ìfẹ́ Ọlọrun pé kì í ṣe ipasẹ̀ gbogbo ọgbọ́n ayé yìí ni eniyan yóo fi mọ Ọlọrun, ó wu Ọlọrun láti gba àwọn tí ó gbàgbọ́ là nípa iwaasu tí à ń wà, tí ó dàbí ọ̀rọ̀ òmùgọ̀.
Nigba ti wọn yoo fi pada toro toro ni wọn ba de ti Abubakar Shekau si kede ara rẹ gẹgẹ bi olori ẹgbẹ naa.
Ìkórìíra ni wọn yóo fi máa bá ọ gbé, wọn yóo kó gbogbo èrè iṣẹ́ ọwọ́ rẹ lọ, wọn yóo sì fi ọ́ sílẹ̀ ní ìhòòhò goloto.
Eyi lo mu ki BBC Yoruba fi ara ọtọ ọn la ṣe igbelarugẹ ti ọdun yii nipa ṣiṣe akojọ fidio yii pẹlu awọn alabiyamọ toju wọn ti ri too nipa asiko ifọmọlọyan.
Tolulọpẹ niyi, to n sọ ọrọ funwa lori ohun ti oju oju n ri nibẹ latigbati iṣẹlẹ naa ti ṣẹlẹ.
Ẹwẹ, o ni alaga PDP ọhun tun rawọ ẹbẹ si Ọbasanjọ lati tẹsiwaju ninu wiwa ojuutu si awọn iṣoro to n dojukọ eto ọrọ aje orileede Naijiria.
Ènìà ní láti sọdá afárá yìí kọjá sí ọ̀nà tí ó wọ inú igbó lọ.
Ṣugbọn nígbà tí ó mú àkọ́bí rẹ̀ wọ inú ayé, ohun tí ó sọ ni pé,“Kí gbogbo àwọn angẹliỌlọrun foríbalẹ̀ fún un.
Ṣugbọn àwọn ọmọ Kora kò kú.
Ninu ọrọ ti wọn fi lede, ki o to di Osu Kẹfa, ọdun 2019 ni awọn yoo pari gbogbo eto lati se idarapọ mọ Access Bank.
Ayọ̀ ń bẹ fún gbogbo ẹni tí ó bá ń ṣe bẹ́ẹ̀,ati fún ẹni tí ó bá ń tẹ̀lé e,tí ó ń ṣọ́ra, tí kò rú òfin ọjọ́ ìsinmi,tí kò sì fi ọwọ́ rẹ̀ ṣe nǹkan burúkú.
Ẹ jẹ́ kí àwọn ọmọ Naijiria má a gbebọn bíi AK47 láti fi dáàbò bo ará wọ́n- Gómìnà Benue Gomina ipinlẹ Benue, Samuel Ortom ti rọ ijọba apapọ lati fun awọn ọmọ Naijiria to kunjunwọn ni anfaani lati ma a gbe ibọn ilewo bii AK47.
Ní tèmi n kò rí ohun kan tí ó ṣe tí ó fi jẹ̀bi ikú.
O fi igba kan sa kuro ni CAR lọ ṣatipo ni France lọdun 1980, ṣugbọn o pada si CAR nibi ti wọn ti pada ran an lẹwọn igbere.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Fulani Ilorin l'ọkọ mi' Gomina Samuel Ortum ti ipinlẹ Benue bi apẹrẹ ti ni ero ijọba apapọ yii ni lati tabuku awọn eeyan ipinlẹ oun.
Nítorí náà, kí n má baà ṣe ìgbéraga nípa àwọn ìfihàn tí ó ga pupọ wọnyi, a fi ẹ̀gún kan sí mi lára, ẹ̀gún yìí jẹ́ iranṣẹ Satani, láti máa gún mi, kí n má baà gbéraga.
Bẹ́ẹ̀ ni wọ́n rí sí mi, ṣugbọn nígbà tí wọ́n dé òkè Baali Peori, wọ́n ya ara wọn sọ́tọ̀ fún oriṣa Baali, wọ́n sì di ohun ẹ̀gbin, bí oriṣa tí wọ́n fẹ́ràn.
Jegede ni ki wọn ranti gbogbo iranwọ ti awọn ṣe lẹka eto ẹkọ to fi rọ awọn ọmọ ileewe lọrun ti wọn ko si ri alebu kankan lara rẹ.
Bí ó bá sì jẹ́ pé oriṣa Baali ni ẹ máa bọ ọ́.
Ọmọ ìyá ni ẹlẹ́dẹ̀ àti ìmọ̀dò, bẹ́ẹ̀ náà sì ni inàki àti ọ̀bọ, gbogbo ibi tí a bá ti dárúkọ Ìjẹ̀ṣà ni a á ti máa fi ojú oníṣòwo gidi wò wọ́n.
 ipo yi je didasile leyin greek republic referendum , 1974 , o si je ti ofin ibagbepo ni 1975 .
 Ijọba fi ẹsun kan pe, yatọ si ojupopo ti ile iṣẹ naa bọsi, to si n ṣe fa ijamba ọkọ ni agbegbe naa, ile igbọnsẹ, yara idana, gbọngan igbalejo ati pẹtẹsi to n bẹ lẹyin ile naa, tako aṣẹ ti ijọba buwọlu."
BBC ko tii ri awọn ifitonileti ni ẹkunrẹrẹ lori ohun to n ṣẹlẹ bayii ni agbegbe Kukawa ni ipinlẹ Borno.
Ìgbà tí ọba ti kú ni gbogbo àwọn ìránńṣẹ́, ìjòyè, ìyàwó àti ọmọ rẹ̀ tí ó ń gbé ní àa[fin ti sá jáde.
ti o kun fun egbogi oloro nijoba ibile Odukpani Local Government ni eka iwo
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìmúra málegbàgbé ti Sẹnatọ Dino Melaye ti mú níle aṣòfin àgbà l'Abuja 2 Ọ̀pẹ̀̀ 2019 Ní òpin ọ̀sẹ̀ tó kọja ní àtúndi ibo ilé ìgbìmọ àsọfin àgbà wáye láàrin Sẹnatọ Dino Melaye ti ẹgbẹ òṣèlú PDP àti Sẹnatọ Smart Adeyemi ti APC láti sóju ẹkun ìwọ̀-òòrun ìpínlẹ̀ Kogi.
Ó bá pín àwọn ọmọ rẹ̀ fún Lea ati Rakẹli, ati àwọn iranṣẹbinrin mejeeji.
Oríṣun àwòrán, Twitter/ NIPOST O sọ fun BBC pe, ajọ NIPOST ni lati salaye nnkan ti owo naa wa fun, nitori pe ijọba ipinlẹ Eko ati awọn ijọba ibilẹ, naa n gba owó lọwọ àwọn.
Nítorí náà, àwa bẹ̀ yín, ẹ fún wa ní ilẹ̀ yìí gẹ́gẹ́ bí ìní wa, ẹ má kó wa sọdá odò Jọdani.
Asán ni sísìn tí wọn ń sìn mí, ìlànà eniyan ni wọ́n fi ń kọ́ni bí ẹni pé òfin Ọlọrun ni.
 Ó jẹ ́ àkọkọ ́ àṣeyọrí ìfipá gba ọkọ ̀ ojú omí tí yio ṣelẹ ̀ ́ ̀ lati bíi ọ ̀ kànlélógun ọgọrún ọdún sẹ ́ yìn .
Eyi ni esi ifesewonse idije NPFL, Nigeria Professional Football League ti o waye lojo Aiku(Sunday):Heartland FC 0-1 Lobi StarsNasarawa United 1-0 Wikki TouristsRivers United 1-1 FC IfeanyiUbahAbia Warriors 1-0 Kwara UnitedEl-Kanemi Warriors 0-0 Niger TornadoesKano Pillars 2-0 Go Round FCSunshine Stars 1-1 Rangers International.
Ẹbi Richard Gbadebo, akẹkọọ fasiti Ibadan to ku iku ojiji nileeṣẹ kan to n ṣe ọṣẹ ni Ibadan ti ni irọ ni awọn iwe iroyin kan n gbe jade pe ileeṣẹ ọṣẹ ti ọmọ wọn ku si fun wọn ni ẹbun owo.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Kaduna: Àwọn agbébọn pa ènìyàn 14 níbi ìgbéyàwó ní Ungwan Pa-Gwandara 18 Ọ̀pẹ̀̀ 2018 Oríṣun àwòrán, AFP Àkọlé àwòrán, Ìròyìn ní wí pé àwọn mẹ́rìnlá ló kú lẹ́yìn tí àwọn agbébọn sígun bo agbéégbé Ungwan Pa-Gwandara tí wọ́n tí ń se ìgbéyàwó.
Ọrọ yi si lọju gan ni.
Láti inú ìran rẹ̀ ni Ọlọrun ti gbé Jesu dìde bí Olùgbàlà fún Israẹli gẹ́gẹ́ bí ó ti ṣe ìlérí.
”Mata, arabinrin ẹni tí ó kú, sọ fún un pé, “Oluwa, ó ti ń rùn, nítorí ó ti di òkú ọjọ́ mẹrin!
Ewu n bẹ loko Longẹ Oríṣun àwòrán, AFP Awọn orilẹ-ede mejeji sọ pe ilẹ naa ṣe pataki si wọn nipa ọrọ aje ati eto abo.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Bolaji Faleke ni Olùkọ́ tó ń kọ́ wa ní àṣà oge ṣiṣe lórí BBC Yorùbá Meji ninu awọn ọlọpaa to wa ninu ọkọ naa jade laye ti awọn miran si wa ni ẹsẹ kan aye, ẹsẹ kan ọrun ni ileewosan.
 Opolopo idojuko ni ati dojuko niniu irin –ajo yi sugbon awon omo orile-ede Naijiria duro ti wa lati ri wipe a se aseyori ninu ilana meta to se gboogi labe isakoso yi : Eto abo to pe ye, gbigbogun ti  iwa ibaje ati eto oro aje.
Kop e ti UK gab ami eye o pegede pe won ko ni igbona mo laarin won ti eyi tun be sile leyin isele mejidinlogun din ni oodunrun ti won ri ldoun 2017.
Orúkọ àwọn aposteli mejila náà nìwọ̀nyí: Simoni tí ó tún ń jẹ́ Peteru, ati Anderu arakunrin rẹ̀; lẹ́yìn náà Jakọbu ọmọ Sebede, ati Johanu arakunrin rẹ̀.
OLUWA bá pe Mose, ó ní, “Wọlé tọ Farao lọ, nítorí pé mo tún ti mú ọkàn rẹ̀ le, ati ti àwọn ẹmẹ̀wà rẹ̀, kí n lè ṣe àwọn iṣẹ́ ìyanu mi láàrin wọn.
Aṣiri to fi ara pamọ sinu kókó naa ni pe Biden fi ipilẹ aṣeyọri rẹ lelẹ lori pe ọwọ lile ni Trump fi n ṣe iṣakoso, nkan ti awọn eeyan ilẹ America si n wa ni adari ti yoo ma a ṣe jẹẹjẹ.
Amọ, Ileẹjọ Giga nipinlẹ Rivers tako igbẹsẹ ki gomina pa aṣẹ miran.
aare to wa ni Murtala Muhammed , ni ipinle Eko ni deede aago  10.
Coronavirus gbẹ̀mí èèyàn mẹ́rin lánàá Ọjọ́rú ní Nàìjíríà, èèyàn márùndínlọ́gọ́jọ 155 míì tún kóo Eeyan mẹrin ni coronavirus ṣekupa ni Naijiria l'Ọjọru nigbaa ti eeyan marunlelaadọjọ(155) mii tun lugbadi aarun ọhun lọjọ kẹrin oṣu kọkanla ọdun 2020 yii.
Adájọ́ rán agbẹjọ́rò àgbà lọ sẹ́wọ̀n oṣù kan
N óo rán ẹ̀bùn tí Baba mi ṣe ìlérí sí orí yín.
ASUU ni bi eyi ba waye, yoo fun awọn ni anfaani lati lee joko sọrọ lori awọn nkan to so pọ mọ iyanṣẹlodi to ti bẹrẹ lati ọjọ kẹtalelogun, Oṣu Kẹta, Ọdun yii.
Ayew kuro ni ọdun 2016, nigbati West Ham san owo ti o to bii ogun millọnu pọun fun un.
Ni ọjọ Iṣẹgun ni ile ẹjọ paṣẹ naa nibi itẹsiwaju igbẹjọ ẹsun jiji ọkọ gbe ti wọn fi kan an.
Àwọn ìjòyè rẹ̀ dààmú, wọn kò sì mọ ohun tí wọ́n lè ṣe.
Agbaboolu owo iwaju iko Villereal teleri Cedric Bakambu naa ko gbeyin lara apapo iko ohun.
Ẹni tí ó sọ àpáta di adágún omi,tí ó sì sọ akọ òkúta di orísun omi.
O ni eyi lo mu oun lo anfani ibudo ikẹkọọ fasiti agbelegboye NOUN ti wọn da silẹ lọgba ẹwọn ilu Enugu lati fi kẹkọọ gboye ijinlẹ.
Wọ́n kún fún owú jíjẹ tó bẹ́ẹ̀ ti ó jẹ́ pé bàbá kò jẹ́ fi nǹkan kan ọmọ rẹ̀ ọkùnrin, ìyá kò ni jẹ́ kí ọmọbìnrin rẹ̀ tilẹ̀ wò bí òun ti ń ṣe ọbẹ̀.
 kiwoyo ( bantu ) ni èdè àwọn ẹ ̀ yà yìí .
Oríṣun àwòrán, Alambo Datonye Àkọlé àwòrán, Ikede Esi idibo ijoba ibilẹ Bayelsa Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Wọnyi ni awọn ohun to yẹ ki o mọ nipa arabinrin Joy Nunieh naa: Joy Nunieh ni ẹni akọkọ ti yoo di agbẹjọro ni gbogbo ilẹ Ogoni lagbegbe Niger Delta, ni iha ila-oorun Naijiria.
Toke Makinwa, Banana Island house & Festus Fadeyi: Toke Makinwa fọhùn síta; Jude tí Amcon náà dá a padà pé.
iṣẹlẹ pajawirini ipinle Eko ti sọ  pea
Emi ni mo wa nipo to dara julọ lati tọ ijọba sọna, ki n si gba wọn ni imọran lori awọn ọrọ to nii se pẹlu asa ati isẹse Yoruba nitori Alaafin ni oludaabo bo asa to ga julọ.
Wọ́n sì fi Miriamu sí ẹ̀yìn ibùdó fún ọjọ́ meje, àwọn eniyan náà kò sì kúrò níbẹ̀ títí di ìgbà tí wọ́n mú un pada.
Ọdun 2018 ni Mattis kọ iwe fi ipo silẹ lẹyin ti Aarẹ Trump fi ipinnu rẹ han lati ko awọn ọmọogun ilẹ Amerika kuro ni Syria.
L'ọ́jọ́bọ̀ tó kọjá ni ìjọba apapọ̀ àti àwọn gómìnà fẹnukò láti pé ìpè pájáwìrì lóri ètò ẹkọ́ l'áwọn ilé ìwé ìjọba jákèjádò gbogbo ìpínlẹ̀ ní Nàìjíríà.
Ó rẹ ẹni ọdún 49 tó ri ẹ̀wọ̀n ọgọ́ta ọdún he lẹ̀yìn tó bá ọmọ ọdún méjì lòpọ̀ Mo pàṣẹ pé kí ọ̀gá owó ìfẹ̀yìntì tẹ́lẹ̀, Maina sì wà látìmọ́lé- Adájọ́ Oríṣìíríṣìí ẹ̀bùn tí àwọn olọṣèlú ń pín #BBCNigeria2019 Ṣé irúfẹ́ oúnjẹ tí ò ń jẹ́ lè jẹ́ kí o gbádùn ìbálòpọ̀ rẹ síi?
Lagos Chinese restaurant: Ayorinde ní Ìpínlẹ̀ Eko ń gbé ìgbésẹ̀ nípa ilé oúnjẹ elẹ́yàmẹ̀yà
gbese owo osu ati ajẹmọnu awon osise ti ijọba ana kọ lati san fun awọn osise ni
Àwọn t'órí kóyọ nínú ìkọlù nàá ti n késí iléèṣẹ́ ológun láti pèsè àwọn ọmọ ogun tí yóò maa dáàbò bo àwọn tó n gbé lẹ́nu àálà ìpínlẹ̀ Kaduna àti Zamfara.
Ẹni tí ó ya ara rẹ̀ sọ́tọ̀ fún Ọlọrun, kí ó máa ya ara rẹ̀ sọ́tọ̀ fún Ọlọrun bọ̀.
Idà rẹ̀ yóo pa àpatẹ́rùn, yóo sì mu ẹ̀jẹ̀ wọn ní àmuyó.
Ọpẹlọpẹ isẹ abẹ ninu ọpọlọ ati ẹrọ igbalode kan, to gba Kemi silẹ lọwọ ipenija eti didi, eyi to fi n gbọrọ bayi .
Àwọn eniyan dá a lóhùn pé, “Nǹkan kọ lù ọ́!
 o tún ṣe ẹ ̀ ṣọ ́ fún ilé ìjọsìn carmelite ti faubourg saint-jacques , tí ó jẹ ́ ìkan lara àwọn ilé ìjọsìn tí iyá olorì yàn lààyò .
Nítorí pé a óo pa àwọn eniyan burúkú run;ṣugbọn àwọn tí ó gbẹ́kẹ̀lé OLUWAni yóo jogún ilẹ̀ náà.
Gómìnà Osun ṣàbẹ̀wò síbi ìṣẹ̀lẹ̀ àrá tó sán pa màlúù ní Iba Wo àwọn akọrin Nàìjíríà tó fakọyọ ní àmì ẹ̀yẹ AFRIMA Ofin lodi si ẹgba ọwọ ati tọrun Irufin ni lati wọ yẹrin eti, ti imu, ahọn, idodo, aya ati ẹgba ọrun.
Gègé ogún mú Eliata, òun ati àwọn ọmọ rẹ̀ ọkunrin, ati àwọn arakunrin rẹ̀ jẹ́ mejila.
"Awa naa si ti n ba wọn fikunlukun, a ti ṣalaye ipa ti ijọba Naijiria ko lori iwọde #EndSars naa fun awọn to yẹ ninu ijọba UK pẹlu ohun to ṣẹlẹ ni pato""."
4 Òkùdu 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Ẹ ku oju lọna abala keji ẹṣẹ kikan laarin abẹṣẹkubiojo, Anthony Joshua ati alatako rẹ, Andy Ruiz to fẹṣẹ dara si i lara niluu New York lorilẹede Amẹrika.
Arakunrin naa ririn ajo lọ si Iran nibiti ajakalẹ naa peleke julọ nilẹ larubawa.
Bí a tí ń ti ìlú dé ìlú ti ìletò dé ìletò ni wọ́n ń gbà wá tọwọ́tẹsẹ̀ tó bẹ́ẹ̀ tí a kò fi ẹnu kan oùnjẹ tí a mú lọ tí a fi dé.
Bí ìtàn ayé Toyosi Arigbabuwo ṣe lọ rèé láti ẹnu Musiliu Dasofunjo àti Ogun Majek Àsọtẹ́lẹ̀ Fada Mbaka, tó yẹ àga mọ́ gómìnà Imo nídìí rèè Wo ipa tí Mayegun yóò ma kó ní ilẹ̀ Yoruba!
Funke Akindele fún mi lówó tí mo fi gba ilé, kò ra ilé fún mi o - Ajirebi Nile ọkunrin keji yii to ṣe igbayawo pẹlu rẹ lo wa ko ti wi pe ajọ ajafẹtọ awọn ọmọde kan gba a silẹ pẹlu atilẹyin awọn oṣiṣẹ ijọba kan.
Inú mi dùn sí iwọ́de EndSARS tàwọn ọdọ́ Nàìjíríà ń ṣè - Ooni Ogunwusi Ọ̀ba Eniitan Ogunwusi Ọjaja II, Ooni Ile Ifẹ ti sọ pe wamu wamu loun wa lẹyin awọn ọdọ Naijiria lori iwọde ENDSARS to gbode.
Tí ó bá ṣe bẹ́ẹ̀, aṣọ titun náà yóo súnkì lára ẹ̀wù náà, yóo wá tún fà á ya ju ti àkọ́kọ́ lọ.
A ò tì ilé Saraki pa ní'lú Eko - EFCC Àwọn ọmọge wọ gàù l'Abuja nítorí asọ péńpé Ilé ẹjọ́ kòtẹmilọ́rùn yóò dajọ́ ìdìbò gómìnà Oṣun ọdún 2018 Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, '500 level'' ni mo wà nígbà tí mo di adélé Ọba' Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Helen Paul sọ idi tó fi gba orúkọ ní kékere Amọ, Ọgbẹni Amuwa to ba BBC Yoruba sọrọ ṣalaye pe ko si ibi ti wọn ti n ṣe iru ẹ kaakiri agbaaye.
Wọn yóo gbin àjàrà,wọn yóo sì mu ọtí waini rẹ̀.
Kí ni ìdí tí o fi ń dá arakunrin rẹ lẹ́jọ́?
0 887 Orilẹede Eritrea 0 0.
Ọpọlọpọ gba pé eyi jẹ ọkan lara ikọlu sawọn Juu to buru ju lasiko yii.
Òfin ṣì gbẹ́sẹ̀lé Ẹgbẹ́ awakọ̀ èrò NURTW ní ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́ Iye epo rọ̀bì tí wọ́n ń kó níbùdó ìpọnpo ti dínkù, ṣé ẹ fẹ́ mọ ìdí i rẹ̀?
Samuẹli dáhùn pé, “OLUWA ati ọba, ẹni àmì òróró rẹ̀ ni ẹlẹ́rìí lónìí pé, ẹ gbà pé ọwọ́ mi mọ́ patapata.
Ewe, ohun to sokunfa ijamba oko ofurufu naa ni iwadii ti n lo lori re labele, bee sini iwe idanimo awon omo ogun ti won di oloogbe naa ni won koi ti gbe sita, titi di igba ti won ba fi maa ri awon molebi won.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, UI graduation: Fasiti Ibadan ló fún mi ni ẹ̀bùn ẹ̀kọ́ ọ̀fẹ́ tí mo fi kàwé síi- Habibat 5) Pa awọn ifitonileti iṣẹju iṣẹju to n sọ nipa awọn atẹjiṣẹ to n wọle bi wọn ṣe n wọle.
Ayederu ni orukọ Twitter naa jẹ nitori pe @dino_melaye lorukọ ojulowo Senetọ Dino Melaye loju opo Twitter.
Níbo ni ọba ìlú Sefafaimu ati ọba Hena ati ọba Ifa wà?
Ótì o, èmi ò rò bẹ́ẹ̀ rara.
Ẹlẹ́rìí wo ni a tún ń wá?
O ni isẹ ilu kii se ohun ti eniyan fi n se ibatan, amọ o nii se pẹlu titako igbesẹ ijọba ti ko ba ba awọn eniyan lara mu.
Ṣugbọn George wa lara ẹgbẹlẹgbẹ ọmọ ilẹ Amẹrika to padanu iṣẹ wọn nitori ajakalẹ aarun covid-19.
Ilu Daura ni ipinlẹ Katsina jẹ ilu abinibi Aarẹ orilẹ-ede Naijiria, Muhammadu Buhari.
“Ìjọba ọ̀run dàbí ọba kan, tí ó ń gbeyawo fún ọmọ rẹ̀.
“O mú àwọn ọmọ rẹ ọkunrin ati àwọn ọmọ rẹ obinrin tí o bí fún mi, o fi wọ́n rú ẹbọ ohun jíjẹ fún àwọn oriṣa.
 kuenne ni ilẹ-iwe ni princeton university .
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, È gbọ àlàyé lẹnu àwọn ti ójúẹlẹgba leko irú iṣẹ ti oògùn olóró má n ṣé lara.
Gbajugbaja oṣere Yoruba ni Funkẹ Adesiyan, o si wa lara awọn oṣere ti Eleduwa fun lẹbun ere ṣiṣe lagbo awọn oṣere.
Ìdí abájọ ni pé lọ́jọ́ òní, tí í ṣe ọjọ́dọ́gba, ni ìbẹ̀rẹ̀ ìgbà ìrúwé.
Awọn ile igbimo ti dibo wọn si ti ni ki awọn Họnọrebu mẹta o ko kangara ẹru wọn pada si ile.
Rahman gba igbanu ẹyẹ WBC, IBF ati IBO lọwọ Lewis nibi ija wọn to waye lorilẹede South Africa.
Nibayii ajọ INEC ṣi n kọminu lori iha kokanmi ti awọn eeyan kan n kọ si gbigba kaadi idibo wọn jakejado Naijiria, ni pataki julọ, bi eto idibo 2019 ṣe n kan lẹkun.
ilẹ̀ náà ni OLUWA Ọlọrun yín tẹ́ kalẹ̀ níwájú yín yìí, mo ní kí ẹ gbéra, kí ẹ lọ gbà á, gẹ́gẹ́ bí OLUWA Ọlọrun àwọn baba ńlá yín ti sọ fun yín.
Àwọn olórógun tún ní àwọn ẹgbẹ ́ kejì tó ń tún ìlú tò .
Àwọn tí wọ́n rí oúnjẹ jẹ lájẹyó ríti di ẹni tí ń fi ara wọn ṣọfà nítorí oúnjẹ,ṣugbọn àwọn tí ebi ti ń pa tẹ́lẹ̀ rí tí ń jẹ àjẹyó.
Àdúrà ni mo nílò kìí ṣowó - Pa Kasumu Bóo bá yin báńgà l'Ondo lásìkò ọdún, kélé yóò gbé ọ!
Ayọ̀ ń bẹ fún àwọn tí ó ń mú kí alaafia wà láàrin àwọn eniyan,nítorí Ọlọrun yóo pè wọ́n ní ọmọ rẹ̀.
Amọ, lọwọlọwọ bayii, Jeremy n jẹjọ ẹsun ifipaba obinrin mẹrin mii lọpọ laarin ọdun 2014 si 2019.
NERC ni awọn ti gbọ gbogbo ohun ti ijọba pa laṣẹ, amọ awọn nilo asiko lati gbeyẹwo, lori bi adinku yoo se ba ina ọba laarin ọsẹ meji.
OLUWA pàṣẹ fún mi nígbà náà, láti kọ yín ní ìlànà ati òfin rẹ̀, kí ẹ lè máa tẹ̀lé wọn ní ilẹ̀ tí ẹ̀ ń lọ gbà.
Ìlànà rẹ mú mi gbọ́n ju àwọn ọ̀tá mi lọ,nítorí pé òun ni ó ń darí mi nígbà gbogbo.
Bakan naa ni isẹlẹ yii le waye nipa asise lai jẹ pe awọn olutọju alaisan tabi eleto ilera mọọmọ paarọ ọmọ.
Bakanna ni wọn ko ti mọ awọn to farakasa ninu isẹlẹ ọhun sugbọn iwe iroyin New York Times sọ pe awọn ọmọ iya mẹrin kan wa lara awọn to ko ijamba yi ati awọn tokotaya meji kan naa.
Ìyá àgbà Ọlayinka, arúgbó tó ń ṣoge bí omidan Oshisko twins, àwọn 'ìbejì' tó ń dẹ́rìn ín p'òṣónú Wọ́n ta ère Ọ̀ṣun Osogbo sí Togo - Bàbá Ọṣun figbe ta Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Mí ò ya wèrè, mí ò burú, ọ̀nà àtijẹ là ń wá' Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Oríṣun àwòrán, Oluwo Àkọlé àwòrán, Awọn Ọba alaye ṣabẹwo si ilu Eko Oríṣun àwòrán, oluwo Àkọlé àwòrán, Awọn Ọba alaye ṣabẹwo si ilu Eko Oríṣun àwòrán, Oluwo Àkọlé àwòrán, Awọn Ọba alaye naa ṣepade pẹlu Gomina Babajide Sanwo-Olu ti ipinlẹ Eko Oríṣun àwòrán, oluwo Àkọlé àwòrán, Wọn ni alaafia orilẹ-ede Naijiria lo jẹwọn logun Oríṣun àwòrán, oluwo Àkọlé àwòrán, Oluwo ti ilu Iwo ati Aṣiwaju Bola Ahmed Tinubu Oríṣun àwòrán, oluwo Àkọlé àwòrán, Wọn ba ipinlẹ Eko kẹdun ẹmi ati dukia to sọnu lasiko iwọde EndSARS Oríṣun àwòrán, oluwo Àkọlé àwòrán, Abẹwo àwon Ọba si ilu Eko Oríṣun àwòrán, oluwo Àkọlé àwòrán, Oluwo ati Gomina ipinlẹ Eko, Babajide Sanwo-Olu Oríṣun àwòrán, oluwo Àkọlé àwòrán, Oluwo ati Oba ilu Eko Oríṣun àwòrán, oluwo Àkọlé àwòrán, Awọn Ọba alaye ṣabẹwo si ilu Eko Oríṣun àwòrán, oluwo Àkọlé àwòrán, Gbagede ile itura Eko Oríṣun àwòrán, oluwo Àkọlé àwòrán, Olugbo ilu Ugo ati Oluwo ilu Iwo Oríṣun àwòrán, oluwo Àkọlé àwòrán, Ọba ilu Ejo atawọ ori ade bii tirẹ Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Ned Nwoko: Regina Daniels kàn wù mí ni, mo nàwọ́ sí i ó sì di tèmi3 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Ogun Stolen Mace: Bí wọ́n ṣe rí ọ̀pá àṣẹ ìpínlẹ̀ Ogun ní Eko rèéwákàtí 5 sẹ́yìn Obasanjo: Mo lòdì sí ìgbé ayé tí Gani Adams ń gbé látẹ̀yìnwá, ṣùgbọ́n n kò bá a jà - Obasanjo3 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Borno Zabarmani massacre: Ípànìyàn tó wáyé ní Borno fihàn pé omi n bẹ lámù fún ètò ààbò - Tinubu3 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 BBC News, Yorùbá Ìdí tí ẹ fi le è nígbàagbọ́ nínú ìròyìn BBC Ìlànà Lílò Nípa BBC Òfin Àṣírí Cookies Kàn sí.
Ṣugbọn ẹni tí ó bá ṣàìgbọràn sí Ọmọ kò ní rí ìyè, ṣugbọn ibinu Ọlọrun wà lórí rẹ̀.
Gomina Akeredolu sọ loju opo Twitter rẹ ko si ohun kan to le mu oun sọ fawọn ẹṣọ alaabo lati dena mọ igbakeki oun.
Jesu sọ gbogbo nǹkan wọnyi fún àwọn eniyan ní òwe.
Ọ̀pọ̀ tì orí kó yọ ní bèbè ikú, pàápàá jùlọ àwọn awakọ̀ ṣàlàyé wí pé ǹkan bíi agogo mẹ́fà sí méje alẹ́ ni òjò tó fa ìjì líle náà bẹ̀rẹ̀.
Nígbà tí Saulu gbọ́, ó lépa Dafidi lọ sí aṣálẹ̀ Maoni.
Ilé Ẹjọ́ Àgbà yi Àṣà Ìgbéyàwó Àdáyébá padà ni ilú Àmẹ́ríka.
Ó gbé e lọ sí ilé èrò níbi tí ó ti ṣe ìtọ́jú rẹ̀.
Nígbà tí Jesebẹli bẹ̀rẹ̀ sí pa àwọn wolii OLUWA, Ọbadaya yìí ló kó ọgọrun-un ninu wọn pamọ́ sinu ihò àpáta meji, ó kó aadọta sinu ihò kọ̀ọ̀kan, ó sì ń fún wọn ní oúnjẹ ati omi.
Ọlọ́run níkan ló mọ ẹni tí ó là o.
" Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi O ni eeyan nla ni Ọlọrun gba lọwọ ẹbi naa ati pe Ọlọrun nikan lo lee di aye to fi silẹ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Omotola Jalade Ekeinde: Òjòjò Covid-19 ló mú mi, mò ń gba ìtọ́jú lọ́wọ́ 16 Ògún 2020 Oríṣun àwòrán, Facebook/Omotola Jalade Ekeinde Ọrọ arun coronavirus to n ba gbogbo aye finra ko mọ olowo, bẹẹ ni ko mọ talaka, koda ko mọ ọmọde, ko mọ agba.
Lẹ́yìn náà ó tún fara han àwọn ọmọ-ẹ̀yìn mejila.
Makiri, ọmọ Amieli, náà wá, láti Lodebari; ati Basilai, láti Rogelimu, ní ilẹ̀ Gileadi.
Oun si ni akọkọ akanṣẹ ti yoo gba ogo Akanṣẹ agba, heavyweight nigba mẹta lagbaye.
A ko ti i le sọ nkan to pa oloogbe naa.
Gẹ́gẹ́ bi ìròyìn ṣe sọ, ọ̀rẹ́ rẹ̀ Tonto Dikeh lo gbàá nimọràn pé ki o jẹ́ ki àwọn jẹ àkàrà òyínbo náà tàbi ki àwọn bun èèyàn ló ba gbé àkàrà onipele mẹ́wàá náà si ojú òpó Instagram.
N óo máa tọ́jú rẹ̀ níbẹ̀, nítorí pé ó tún ku ọdún marun-un gbáko kí ìyàn yìí tó kásẹ̀ nílẹ̀, kí òun ati ìdílé rẹ̀ ati gbogbo àwọn eniyan rẹ̀ má baà di aláìní.
Jesu tún bẹ̀rẹ̀ sí kọ́ àwọn eniyan lẹ́bàá òkun.
Ko tan sibẹ, akẹẹgbẹ rẹ lati ipinlẹ Ondo, Alhaji Garuba Bello naa ni awọn ọmọ ẹgbẹ Miyetti Allah yoo bawọn peju sibi ipade gbangba lori Amotekun lọjọ Aje, to si fikun pe oun tijọba ba ni ki awọn se, lawọn yoo se.
A si tun rii pe awọn ileeṣẹ wọnyii gan an lo yẹ ko maa ṣe atọna ati amojuto fun awọn ileeṣẹ yooku.
Sugbọn awọn onwoye kan ti salaye pe, aawọ abẹnu ẹgbẹ oselu APC lo seese ko tẹsiwaju wọnu eto idibo ọdun 2023, ta ba wo iyapa, ati ikunsinu to wa laarin awọn ọmọ ẹgbẹ naa.
Eyi fihan pe, agbọn n ṣe bayii, ikamọdu naa n ṣe, bẹẹ oju oloko ree to wu yii.
Nigba ti awọn aṣojuṣofin jẹ ọtalelọọdunrun nile igbimọ aṣojuṣofin kekere ni Abuja.
Iwadi naa fi han pe awakọ baalu na tẹle gbogbo ilana ti Boeing to ṣe baalu na ni ki wọn tẹle.
Láti Kiburotu Hataafa wọ́n lọ sí Haserotu.
Ko si ile ijo alaalẹ ti mi o mọ ni Kaduna."
Ninu atẹjade kan ti agbẹnusọ Saraki fi sita fawọn oniroyin, o ni igbesẹ EFCC tapa si ofin nitori ile ẹjọ giga lAbuja to ti paṣẹ pe ki wọn ma ṣe gbe igbesẹ lori gbigba ogun Saraki kankan.
Ojú yóo ti gbogbo wọn; eniyan sá ni wọ́n.
Ogun Assembly: Wọ́n ti ni kí àwọn alága ìjọba ìbílẹ̀ Ogun lọ rọọ́kún nílé
Gbogbo awọn tọrọ kan lati ipinlẹ Eko, Oyo, Osun, Ondo, Ekiti ati Ogun yoo pade lati sọrọ lori awọn igbesẹ ti wọn yoo gbe ninu afẹfẹ oṣelu tuntun to ba fẹ.
Sultan Sokoto kéde òpin àwẹ̀ Ramadan Ta ló fẹ́ ki bọwọ́bọwọ́ ọlọ́pàá agbègbè bọ Buhari lọ́wọ́?
adura mi ni pe, baba, gbogbo ẹnu esu ti ko wulo, to fẹ maa tabuku ibukun rẹ ninu aye mi, ki ina ẹmi mimọ lọ kọlu wọn, ki wọn si maa sisẹ lai ni akojọ ni orukọ Jesu.
 luku kọ marku ; gẹgẹbi matteu , ni afikun pe o kan ìṣẹlẹ ati ajinde awọn eniyan mimọ ti o ku .
Ajọ Ecowas ati ajọ iṣọkan ilẹ Afrika, (AU) lo ṣagbatẹru ipade naa eleyi ti aarẹ fidihẹ igba kan ri lorilẹede Liberia, ọjọgbọn Amos Sawyer ṣ'oju Ecowas, ti aarẹ ana lorilẹede South Africa Kgalema Motlanthe si ṣoju AU.
Ìjọba ìpínlẹ̀ Oyo kéde pé kí àwọn òṣìṣẹ́ ìjọba dáwọ́ iṣẹ́ dúró nítorí coronavirus Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Coronavirus: Fífi nkan bó ìmu nìkan kò le dènà kíkó coronavirus Bakan naa ni awọn kan tun n sọ pe ẹsan aitun awọn ileewosan orilẹ-ede yii ṣe lo delẹ yii.
Ìdá bi ogoji pere ni mọlẹbi to lowo lati gba ile tuntun ti owo rẹ kere ju.
O wa n fẹ ki awọn eniyan maa kaanu rẹ nisin yii.
22 Bélú 2020 Fídíò, Akomolede ati Aṣa lori BBC:Wo ìrúfẹ́ ìgbeyàwó méje tó wà nílẹ̀ Yorùbá àti ojúṣe Alárinà10 Bélú 2020 Covid 19 update: Wo ǹkan mẹ́wàá tó yẹ kí o mọ̀ tí o bá fẹ́ lọ fún ìsinmi lẹ́yìn Covid 1923 Bélú 2020 Fídíò, Akomolede Yoruba: Kí ni ìdí tí aṣọ fi máa ń pọ̀ lára Egúngún ju Orò lọ́?
Ẹ̀yin ará, ẹ má gbàgbé pé gbogbo àwọn baba wa ni wọ́n wà lábẹ́ ìkùukùu.
Nigeria Custom: A kò tí ẹnu Bodè pa rárá- iléeṣẹ́ Aṣọ́bodè
Gẹgẹ bi o ṣe sọ, ori ọgọta dọla lori jala epo kan ni wọn gbe eto iṣuna naa pẹlu ireti pe orilẹede Naijiria yoo maa pọn jala epo rọbi ti o le ni miliọnu meji lojumọ.
OLUWA àwọn ọmọ ogun, Ọlọrun Israẹli ní òun ti fi àjàgà irin sí ọrùn gbogbo orílẹ̀-èdè wọnyi kí wọn lè di ẹrú Nebukadinesari ọba Babiloni, kí wọn sì máa sìn ín, nítorí òun ti fi àwọn ẹranko inú igbó pàápàá fún un.
"Amugbalẹgbẹ rẹ feto iroyin naa ni "" Akọwe ijba yoo papa du ipo gomina sugbọn emi ko lee sọ abẹ asia ẹgbẹ ti yoo ti dije fun ipo naa."
Ni bayii, Djoliba  ti pegede sipele ti o kan ninu idije ohun.
Wọ́n dínà mọ́ mi,wọ́n dá kún wahala mi,kò sì sí ẹni tí ó lè dá wọn lẹ́kun.
Jekolaya ará Jerusalẹmu ni ìyá rẹ̀.
"Wo àwọn ìpínlẹ̀ tó ti dẹwọ́ ìséde lẹ́yìn ìwọ́de #EndSars Àwọn kan ní ìpínlẹ̀ Kwara já ilé ìkó-ǹkan-sí wọ́n pín "" CaCovid Palliative"" fáwọn èrò ní Ilorin Wo nǹkan tí yóò ṣẹlẹ̀ sí ọba tí wọ́n bá gbé ọ̀pá àṣẹ rẹ̀ lọ nílẹ̀ Yorùbá Sanwo-Olu kéde ìlànà ìséde tuntun l'Eko Àìsọ̀rọ̀ Buhari lórí ìṣẹ̀lẹ̀ Lekki, ìkọjú ìjà sí Yoruba ni - YWC Ìwọ́de EndSARS ló ń sọ pé inú ń bí àwọn ọ̀dọ́, ìjọba, ẹ náání wọn - Obasanjo Ọ́ba Enitan Ogunwusi ni awọn ọdọ ti gba akoso orilẹede yii, lati ọjọ akọkọ iwọde, si ni wọn ti se afihan pe awọn ni abuda asaaju rere."
Ọkọ rẹ̀ ní àṣẹ láti gbà á láàyè láti san ẹ̀jẹ́ rẹ̀ tabi kí ó kọ̀ fún un láti san án.
A kò ní sin ọ́ gẹ́gẹ́ bí àwọn ọba yòókù,nítorí pé o ti pa ilẹ̀ rẹ run,o sì ti pa àwọn eniyan rẹ.
Ńṣe ni gbogbo àwùjọ dákẹ́ jẹ́ẹ́.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Intersextuality: Dokita ni ká mu èyì tó wù wá nínú jíjẹ́ akọ tàbí abo Akọ̀ròyìn Morocco, Hajar gbà ìdájọ́ ẹ̀wọ̀n lórí ẹ̀sùn àgbèrè àti pé o ṣẹ́yún Ǹ jẹ́ o mọ àwọn èèyaǹ wọ̀nyí tó jà fún òmìnira Nàìjíríà?
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ọmọ méjì ò sọnù nínú àgbàrá òjò o!
Ìbejì Oníbẹ̀mbẹ́ Òru: Owó, ọmọ àbí aya kò leè yà wá
 lára ìwọ ̀ nyí ni ìnira ní ojú ibi abẹ ́ rẹ ́ náà tàbí ibà díẹ ̀ .
Awọn ọlọpaa to wa ni ẹkun Ariwa yoo ṣe ti wọn ni Police Mobile Force Training College, Ende, nipinlẹ Nasarawa.
" Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ondo: Dejí sun ọmọ méje àtagbalagba meji mọ́lé nítorí pé ó ń bínú Oṣu Karun un, ọdun 2018 ni gomina to ṣẹṣẹ fi ipo silẹ nipinlẹ Ọyọ, Abiọla Ajimọbi, ṣeto idibo ijọba ibilẹ.
Ile-ejo yoo gbe aworan awon afunrasi naa sita, fun idanimo won, bakan naa ni a n pe awon eniyan ti won ni iroyin ti o wulo fun iwadii naa.
Nítorí náà, sọ fún wọn pé èmi, OLUWA Ọlọrun ní: ‘N óo fi òpin sí òwe yìí, wọn kò ní pa á ní ilẹ̀ Israẹli mọ́.
Ìbò 341 ni Tambuwal fi ju Aliyu lọ ninu esi atundi ibo ti ajọ INEC ka.
 gbogbo àwọn ìpele wọ ̀ nyí ni ó ní ìbáṣepọ ̀ tí ó ṣòro láti yà sọ ́ tọ ̀ .
Ọmọwe Yemi-Esan tun sọ pe aṣẹ ti ileẹjọ to n ri si ọrọ awọn ile iṣẹ ni Naijiria l'Ọjọbọ ti sọ pe ẹgbẹ oṣiṣẹ ko le gunle iyanṣẹlodi mọ lọjọ Aje.
Ọmọge naa sọ fun BBC Yoruba lori eto naa wipe, ọkọ aburo iya oun naa tun bẹrẹ si ni fipa ba oun lopọ, gẹgẹ bi baba iya oun ti n se.
- Ọọ̀ni Ife Lai tii mọ nipa Tiata, ọmọ Aremu Afolayan gba iyẹsi awọn oṣere Eleyi maa ṣafihan ifẹ ati ibaṣepọ to gun to wa laarin awọn oṣere to fi le mu wọn nawọ ifẹ si idile ara wọn lasiko ti wọn ba n ṣe ayẹyẹ tabi jọ ibi.
Nítorí náà ni àwọn olùdíje ṣe máá n dójúkọ àwọn ìpińlẹ̀ tí ó le fi ìdì ẹni ti yóò wọlé múlẹ̀.
Nigeria 2019 Elections: Ohun mẹ́rin tó jẹyọ nínú ọ̀rọ̀ Atiku níbi ìpàdé PDP
Ta ni ninu yín tí ó ká ẹ̀ṣẹ̀ mọ́ mi lọ́wọ́ rí?
 O tun je alaga ijoba ibile Ijero, bee si ni O tun ti figba kan je amugbalegbe pataki si gomina.
Lojo-Bo, Aare Muhammadu Buhari se ifilole kiko etikun Lekki ni ipinle Eko, ni eyi ti o seleri pe, ijoba apapo yoo satileyin to ba ye lori ise-akanse naa.
Àwọn oníṣòwò a máa ra kẹ̀kẹ́ ogun kan ni ẹgbẹta (600) ìwọ̀n ṣekeli fadaka wá fún Solomoni láti Ijipti, wọn a sì máa ra ẹṣin kan ní aadọjọ (150) ìwọ̀n ṣekeli fadaka.
Orin to kọkọ pokiki Majek Fashek ni awo orin rẹ to fun ni akọle 'Prisoner of conscience' orin kan to si tan bi itanṣan oorun ninu awo naa ni orin Send down the rain"" eleyi to di orin ti tagba-tọmọde n kọ nigba naa; ọdun 1988 lo si gbe e jade."
Lásìkò ìdájọ to yọ Eleruwa nípò, adájọ ni gbogbo ìgbésẹ̀, láti ori yíyàn ọmọ oye to fi mọ bi ìjọba ṣe gbe ọ̀pá àṣẹ fún kò tọ̀na rárá.
Ilú pọ̀ jàǹtirẹrẹ ní ìpínlẹ̀ Èkó bí o ti pọ̀ ní ìpínlẹ̀ mẹ́fà mìíràn tí ó parapọ̀ di Orílẹ̀ Ọmọlúàbí.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Oyè Ibadan: Àwọn ọba 21 ní kí Olubadan yé fẹnu yẹpẹrẹ adé àwọn 4 Ìgbé 2019 Oríṣun àwòrán, Lekan Balogun Awọn ọba nilẹ Ibadan ti koro oju si ilana ti Olubadan ilẹ Ibadan.
Awọn onwoye nfoya wipe isẹlẹ yii le je ki irẹsi ti wọn gbin ni Naijiria ko wọn nitori osẹ t'awọn eku ati kokoro nse ninu ogunlogo oko to wa ni ipinlẹ Kebbi, to jẹ okan lara awọn ipinlẹ ti wọn tin gbin irẹsi ju lọ.
O ni Aarẹ ko sọrọ nipa ohun ti awọn ọmọ Naijiria n reti ko sọ, ṣugbọn ọna miran lo ya si.
Wọn kò lè rí ara wọn, bẹ́ẹ̀ ni ẹnikẹ́ni kò sì dìde kúrò níbi tí ó wà fún ọjọ́ mẹta.
Ẹ tú u, kí ẹ fà á wá.
Hate Speech: Ìjọba àpapọ̀ ṣàlàyé ìdí tó fi ṣàfikún owó ìtanràn ọ̀rọ̀ kòbákùngbé Oríṣun àwòrán, @thebridgenewsng Minisita eto iroyin ati aṣa, Lai Mohammed ti ṣalaye idi ti ijọba apapọ ṣe ṣafikun iye owo itanran fun awọn to ba sọrọ odi si ijọba lati ẹgbẹrun lọna ẹẹdeẹgbẹta naira si miliọnu marun un naira.
Àwọn ọmọ Bani jẹ́ ẹgbẹta ó lé mejilelogoji (642)
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Gbajugbaja Bjorn Ulvaeus ti awọn onirinṣe ori=in Abba Orchestra naa mura bii ti aye atijọ 1977.
Rice Subsidy: Ìjọba àpapọ̀ gbé ₦60bn kalẹ̀ bíi owó ìrànwọ́
Pípín Ilẹ̀ Tí Ó Wà Ní Apá Ìwọ̀ Oòrùn Odò Jọdani.
Iwa aibikita bẹẹ naa lo mi ki Granit Xhaka gba kaadi pupa ti wọn fi le danu ninu ifẹsẹwọnsẹ ọjọ Aiku lẹyin to fẹ fun agbabọọlu Burnley, Ashley Westwood lọrun.
"Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù IAAF World Championships: Abiyamọ kan di lobìnrin tó leè sáré ""100 meters"" jùlọ l'àgbáyé 1 Ọ̀wàrà 2019 Oríṣun àwòrán, @BBCSport Àkọlé àwòrán, IAAF World Championships: Abiyamọ kan di lobìnrin tó leè sáré ""100 meters"" jùlọ l'àgbáyé Obinrin ọmọ ọdun mejilelogun kan lati orilẹ-ede Jamaica ti wọ inu iwe itan gẹgẹ bi obinrin to lee sare ori papa oniwọn ẹsẹ ọgọrun un julọ l'agbaye."
Oríṣun àwòrán, Alaafin Oba Adeyemi III Bakan naa ni Ọba Adeyẹmi tun rọ awọn ọmọ Kaarọ Oojire lati maa fi asa ati ise wa kọ awọn ọmọ wa nitori orisa ti a ko ba fi oju ọmọde mọ, ko ni pẹ parun.
Ó dé sílé Simoni tí ń ṣe òwò awọ, létí òkun.
'Àáfà aríran yóò jìyà ẹ̀ṣẹ̀ ìfipábánilòpọ̀' Tó o bá ṣàdéhùn ìfẹ́ tó ò mú u ṣẹ, ẹ̀wọ̀n lo fi ń ṣeré Olórin Makossa, Koffi Olomidé rẹ́wọ̀n he lórí ẹ̀ṣùn ìfipábánilòpọ̀ Wọ́n ti yọ Donald Trump nípò gẹ́gẹ́ bí ààrẹ orílẹ̀-èdè Amẹ́ríkà Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
" Ẹgbẹ oselu PDP wa ki aarẹ Buhari ku oriire ọjọ ibi ọdun kejidinlọgọrin to ko, ti wsn si dupẹ lọwọ Ọlọrun pe o mu aarẹ se ọjọ ibi ọdun yii.
Eleasari yóo sì máa lo Urimu ati Tumimu láti mọ ohun tí mo fẹ́.
Amẹ́rika dá akẹ́kọ̀ọ́ padá nítori Facebook A ń fikunlukun pẹ̀lú FBI láti mú àwọn Yahoo Boys"" tó kù- EFCC Tí ẹ ò bá gbàgbé olùdári Arts & Culture nínú iwé ìròyìn Vanguard ti bura pé òun yóò fí ojú rẹ̀ hàn mabo bí o ṣe pèé ni ""adoju tini""."
àwọn ará Gebali, àwọn ọmọ Amoni, ati àwọn ọmọ Amaleki,àwọn ará Filistia ati àwọn tí ń gbé Tire.
Onigbodogi ati Alape ni ọlọkọ to wa Temitọpẹ wa sile aye lọdun 1973, ṣe wọn ni ọmọ Ibadan ti ko ba ni agboole ati oko kii ṣe ojulowo ọmọ Ibadan.
Lọjọ Aje yii ni aare orile
Ìbọ̀sẹ̀ àwọn ọdọmọde naa ni wọn lò fun iwadii yii ni eyi ti àwọn aja naa gba meje ninu mẹwaa dàadáa.
Eyi yoo din ikọlu arun nipa eemi ku fun wọn lasiko yii Maa gbe ohun eelo èémí rẹ rin kaakiri nigba gbogbo paapaa ti o ba kẹfin ikọlu ikọ rẹ nitori ti ikọlu yii ba pọ ju, o ṣeeṣe ki o wa ni ewu nini coronavirus Ṣe awọn alaabọ ara wa ni ewu coronavirus pupọ?
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Tunde Idiagbon: Ṣé ìlàkàkà rẹ̀ láti paná ìwà ìbàjẹ́ ní Nàìjíríà sèso rere bí?
Lẹ́yìn tí ó ti wádìí lẹ́nu àwọn ẹ̀ṣọ́ tán, ó ní kí wọ́n pa wọ́n.
Kábíyèsí lóòótọ́ ni bàbá mi kò sí nínú ayé mọ́, kí ọba kí ó pẹ́, mo mọ̀ pé ẹ tó baba fún mi.
Ẹni to bori: Algeria Aṣekagba Mali Algeria Mali vs Algeria.
Dopemu Bridge, Ijọba ibilẹ Agege / Alimosho3.
Lẹyin naa lo pada si ilẹ Afirika ni ọdun 1934 lati bẹrẹ iṣẹ akoroyin.
Ẹ̀yin olùfẹ́, ẹ má máa gbẹ̀san, dípò bẹ́ẹ̀, ẹ máa fún Ọlọrun láàyè láti fi ibinu rẹ̀ hàn.
Oríṣun àwòrán, OTHERS Emmanuel ni ọkọ oju omi naa n lọ lati Makoko pẹlu awọn eniyan mẹje ninu rẹ, awọn marun un jẹ agbalagba nigba ti awọn ọmọde meji wa nibẹ pẹlu awakọ naa.
Inu Minisita fọrọ abo ni ilẹ Amẹrika dun si igbaradi naa eleyi ti wọn fi kasẹ abẹwo ọlọjọ mẹta to se si orilẹede Indonesia nilẹ.
Mo tún ṣe ìlérí níwájú gbogbo yín, pé n ó kìlẹ̀ fún ojú mi, n kò ní jẹ́ kí ojú kòkòrò wọ ibẹ̀, bí ìyàwó mi ti ń wù mí tẹ́lẹ̀, ni yóòo máa wù mí títí láéláé.
Ogun yóo jà ní Ijipti,ìrora yóo sì bá Etiopia.
Nibayii igbimọ olupolongo idibo APC ni ipinlẹ Edo ni awọn ti fi eto ipolongo rọ naa lati yẹ awọn to ku ninu iṣẹlẹ ijamba ọkọ naa sii.
 Ìwàìbàjẹ ́ nínú àwọn òṣìṣẹ ́ ààbò àti àwọn ajàfẹ ́ tọ àwọn ènìyàn jẹ ́ kí ìgbìyànjú àti bẹ ́ gilé àìní ìsinmi yí ṣòro .
Oyo Land Revocation: Ajimobi gbé Makinde lọ ilé ẹjọ́ lórí ilẹ̀ rẹ̀ tí ìjọba gbẹ́sẹ̀ lé
Mo yára jókòó dáradára mo dì mọ́ ìtàkùn kan tí ó fà mọ́ igi tí mo wà lórí rẹ̀ mò ń retí ẹ̀fúùfù líle tí èkúté sọ̀rọ̀ rẹ̀ fún mi.
“Laasigbo to wa lori owon gogo epo-robi , eyi ti o mu ki ajo  DPR gbe igbese oju-lalakan fi-n sori,  lati je ki  awon ibi  igbonpo to n tapa si ofin ati ilana ajo naa fi oju wina ofin ijoba”.
Ìrọ́ ńlá ní o, iléeṣẹ́ ọṣẹ́ kòì ṣèlérí owó kankan fún wa o!
Ní àkókò kan náà ni Merodaki Baladani, ọmọ Baladani, ọba Babiloni, fi ìwé ati ẹ̀bùn ranṣẹ sí Hesekaya nítorí ó gbọ́ pé Hesekaya ń ṣe àìsàn.
Dìde, ìwọ onídàájọ́ ayé;san ẹ̀san èrè iṣẹ́ àwọn agbéraga fún wọn!
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Coronavirus symptoms in Nigeria: Pẹ̀lú èròjà olùgbèjà ara 'Antibodies' ṣé ó ṣeéṣe kí ènìyàn tó ní àrùn coronavirus rí lè níi lẹ́ẹ̀kejì Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Coronavirus symptoms in Nigeria: Pẹ̀lú èròjà olùgbèjà ara 'Antibodies' ṣé ó ṣeéṣe kí ènìyàn tó ní àrùn coronavirus rí lè níi lẹ́ẹ̀kejì 18 Èbibi 2020 Ohun tó yẹ kí o mọ̀ nípa ìbòmú tí ń lò yẹ́n Coronavirus ti di ara wa, kò le è kúrò mọ láéláé - WHO Kí ló ń mú àwọn adarí obìnrin lágbáyé rọwọ mú nípa kíkojú covid 19?
’Àwọn tí wọn ń ṣe àmójútó òfin kò mọ̀ mí,àwọn olórí ń dìtẹ̀ sí mi,àwọn wolii ń sọ àsọtẹ́lẹ̀ ní orúkọ oriṣa Baali,wọ́n sì ń tẹ̀lé àwọn oriṣa lásánlàsàn.
Ile ti sun ijoko lori ọrọ naa siwaju lai lọjọ lẹyin ijoko ọjọ Aje.
O kò béèrè ìdí rẹ̀ tí mo fi sọ bẹ́ẹ̀ ńdán?
Ìyà tí ọpọlọpọ ninu yín ti fi jẹ irú ẹni bẹ́ẹ̀ ti tó.
Ṣugbọn lẹ́yìn ìgbà tí Dafidi ka àwọn eniyan náà tán, ẹ̀rí ọkàn rẹ̀ bẹ̀rẹ̀ sí dà á láàmú.
Bayii la ṣe bẹrẹ irinajo ifẹ wa.
 Àkókó tí wọ ́ n ń ṣe ọdún ìbílẹ ̀ kò yàtọ ̀ sí ara wọn .
Okoye wa salaye pe awọn yoo pawọpọ pẹlu gbogbo awọn ajọ to ba yẹlati ri wi pe eto idibo nipinlẹ naa ni iyanju.
Titi di igba ti awọn ọmọ yi fi pada de, ko si ihalẹ to milẹ lati ọdọ ijọba Katsina tabi ijọba apapọ lori pe awọn yoo fiya jẹ ẹnikẹni to ba mọ si ijingbe awọn akẹkọọ yii.
Aisha Buhari, ìyàwó ààrẹ Gambia Fatoumatta Bah-Barrow ṣe ọjọ ìbí níléèwòsàn l'Ábújá
“Ẹ̀yin ará Juda pàápàá, mo ti dá ọjọ́ ìjìyà yín sọ́nà, fún àwọn ẹ̀ṣẹ̀ tí ẹ̀ ń dá.
Ebi ń pa àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀, ni wọ́n bá bẹ̀rẹ̀ sí já ọkà, wọ́n ń jẹ ẹ́.
Ìbàdàn ni olú-ilú ipinlẹ̀ Yorùbá ni Ìwọ̀-Oorun Nigeria tẹ́lẹ̀ ki Ìjọba Ológun ti Aguiyi Ironsi ti jẹ Olóri tó kó gbogbo ipinlẹ̀ Nigeria pọ si aarin lẹhin ti wọn fi ibọn gba Ìjọba lọ́wọ́ Òṣèlú ni aadọta ọdún sẹhin.
Ní ọdún kẹrinla, Kedorilaomeri ati àwọn ọba tí wọ́n wà lẹ́yìn rẹ̀ wá, wọ́n ṣẹgun Refaimu tí ó wà ní Aṣiterotu Kanaimu.
Ẹkarun-un mú Netanaya, òun ati àwọn ọmọ rẹ̀ ọkunrin, ati àwọn arakunrin rẹ̀ jẹ́ mejila.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Child Abuse: Oyinye Mbadike ní ìbátan òun mu ọti yó ni òun ṣe dín dùǹdú ìyà fun 15 Ògún 2019 Oríṣun àwòrán, InSTAGRAM/@OPETODOLAPO Obinrin kan, Oyinye Mbadike tawọn ọlọpaa mu nitori pe o na ọmọkunrin kan, tii se ibatan rẹ, to si tun ti mọ inu akolo aja ti ṣalaye idi abajọ t'oun fi ṣe bẹẹ.
Àwọn opó 150 gba irinṣẹ́ ọrọ̀ ajé nílú Ìwó
"Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Àwa ọba alayé ń wọ́nà láti ṣẹ́ eegun ẹ̀yin ọ̀daràn Fulani - Ọọ̀ni Àwọn àṣà àti ìse tó yọ obìnrin sílẹ̀ nílẹ̀ Yorùbá Iṣọla Oyenusi rèé, ẹnití ìfẹ́ obìnrin ṣun dé ìwà ìdigunjalè Àwọn àrùn aṣekúpani ti ń yọjú torí àìgba abẹ́rẹ́ àjẹsára Wọn ni ""ẹni to ba se ni idi pẹpẹ, lo yẹ ko jẹ ni idi pẹpẹ, bi ijọba ko ba si gbe igbesẹ to tọ ni idi iyansipo rẹ, ko fi ika to ba tọ si imu, re imu, awọn yoo fi ọwọ ara awọn tun iwa ara awọn se, eyi to lee lẹyin ti ko dara fun ijọba to wa lode bayii."
Ti a ko ba gbagbe, ni Osu Kinni, ọdun 2018 ni wọn se ayẹwo oni wakati mẹta fun Aarẹ Donald Trump lati wo bi ọpọlọ re se pe si.
Wọ́n kò pa ẹnikẹ́ni sí ààfin Ṣọun Ogbomosọ, òkú tí àwọn ọdọ́ gbé wa ni ọlọ́pàá wọ́ jáde- Agbẹnusọ Ṣọ̀un Wo ìdí tí Tẹni, ọ̀dọ́mọdé olórin obìnrin kìí fi ń ṣí ìhòhò rẹ silẹ̀ Ilé alájà mẹ́ta wó pa èèyan méje, èèyàn 20 farapa ní Obalende, Eko A máa ná N10.
Solomoni gbọ́n ju àwọn amòye ìhà ìlà oòrùn ati ti Ijipti lọ.
Nibẹ lo ti kọ iṣẹ ọwọ tuntun nípa orin kiko sugbọn nigba to sú u, o pinnu láti bẹ̀rẹ̀ isẹ orin kíkọ.
Ní apá ìhà àríwá, ilẹ̀ wọn lọ títí kan ilẹ̀ ẹ̀yà Aṣeri, ó sì kan ti ẹ̀yà Isakari ní apá ìlà oòrùn.
Awọn ara ilu naa fi ẹsun kan Udo ati ijọ rẹ pe, apẹẹrẹ buruku ni wọn jẹ fun ilu naa, ti wọn si ba awọn dukia ijọ naa jẹ.
O óo pè wọ́n, ṣugbọn wọn kò ní dá ọ lóhùn.
Coronavirus in Nigeria: Èèyàn mẹ́wàá míì tún ti ní àrùn Coronavirus ní Naijiria Eeyan mẹwa miran ni ayẹwo tun ti fihan pe o ni arun Coronavirus bayii lorilẹede Naijiria.
”Ọba dáhùn, ó ní, “Kò sí ohun kan ninu ilé ìṣúra tí n kò fi hàn wọ́n.
Ọmọ ọdún meje ni Joaṣi nígbà tí ó gorí oyè, ó sì jọba ní Jerusalẹmu fún ogoji ọdún.
Ǹjẹ́, ìwọ mú gbogbo nǹkan wọnyi kúrò wò, o óo rí i pé yóo sọ̀rọ̀ àfojúdi sí ọ lójú ara rẹ.
Iṣẹ́ ọnà kan náà ni kí wọ́n ṣe sí i lára pẹlu wúrà, aṣọ aláwọ̀ aró, aláwọ̀ elése àlùkò, aláwọ̀ pupa, ati aṣọ ọ̀gbọ̀ tí ó ní ìlà tẹ́ẹ́rẹ́tẹ́ẹ́rẹ́.
"Iléẹjọ gíga jùlọ da ẹjọ́ SDP àti PDP nù, wọ́n ní Yahaya Bello ló wọlé ìbò gómìnà Kogi Ààrẹ Buhari buwọ́lu gbígbé ìṣàkoso nọ́mbà ìdánimọ̀ (NIMC) lọ sí ẹ̀ka ìjọba tó ń rí sí ìbáraẹnisọ̀rọ̀ Wọ́n ti sún ìdájọ́ àwọn sójà tó pa ìyá àti ọmọ ní ọdun 2018 sí oṣù tó m bọ̀ Ṣé Nàìjíríà lẹ́mìí nkan tí Ghana ń ṣe fáwọn akẹ́kọ̀ọ́ ""Secondary"" tí yóò wọlé ní October yìí?"
Nítorí pé OLUWA Ọlọrun wà pẹlu mi, mo ṣe ọkàn gírí, mo kó àwọn aṣiwaju àwọn ọmọ Israẹli jọ, mo ní kí wọ́n bá mi kálọ.
Iṣọri karun ni ofin imọtoto ayika: Wọn ṣe ifilọlẹ ofin naa ni ọjọ kọkandinlọgbọn osu keje ọdun 1985.
Ó bá rán àwọn oníṣẹ́ ṣiwaju rẹ̀.
Ẹgbẹẹdogun (3,000) ni òwe tí òun nìkan pa, orin tí òun nìkan kọ sì jẹ́ marunlelẹgbẹrun.
egbe oselu APC Comrade Adams OshiomoleIgbakeji alaga fun ila Ariwa Asofin
Ọkùnrin yìí wáá bẹ̀rẹ̀ mú ìtàn ó sọ bíòun ti ṣe jẹ́ tálákà tí olówó kan ṣàánú òun, àti bí òun àti olówó náà ti ṣe ètò nípa ẹmu àti bí òun ti ṣe bá akèǹgbè ẹmu òun ní fí fọ́ ní ọ̀pọ̀lọpọ̀ ìgbà kí ó tóó di pé òun pinnu àti wá nǹkan tí ó n fọ́ òun ní akèǹgbè ẹmu bẹ́ẹ̀, àti bí òun ti ṣe rí abàmì ẹ̀dé náà tí òun sì níláti lé e títí òun fi dé ọ̀dọ̀ àwọn ẹranko.
''Inu ọkan wọn ni itan ti wọn ba kọ ti maa n wa ati pe ẹkọ ti wọn kọ nipa gbigbe itan silẹ ni wọn n lo.
Wo bí èsì ìdìbò ìpínlẹ̀ Edo ṣe ń jáde Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Fídíò, Akomolede Yoruba: Ìtàn ọ̀rẹ́ tó fi ògùn gba ọkọ ọ̀rẹ́ rẹ̀ nílùú òyìnbó rèé15 Owewe 2020 Fídíò, Akomolede: Bolaji Faleke ni Olùkọ́ tó ń kọ́ wa ní àṣà oge ṣiṣe lórí BBC Yorùbá1 Owewe 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 3 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 5 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Loju opo Twitter iwe Iroyin Daily Trust ni wọn fi ọrọ yi si lọjọ aiku ti wọn si ni ko si ẹni to mọ ibi ti wọn gbe awọn akoroyin naa lọ.
Ohun yòówù tí ẹ lè sọ, àpérò yín yóo di asán.
Ìwà yín yóo mú kí ilẹ̀ tí mo fun yín bọ́ lọ́wọ́ yín; n óo sí sọ yín di ẹrú àwọn ọ̀tá yín ní ilẹ̀ tí ẹ kò mọ̀rí.
Wahala gbigba Visa a maa mu inira ba ọpọ lẹyin odi.
Awọn abawọn tabi ewu to wa nibẹ nkọ?
Má kọ̀wé fipò sílẹ̀, àwọn àgbààgbà Yorùbá sọ fún Osinbajo Ǹjẹ́ o mọ ohun tó ń fa súnkẹrẹ-fàkẹrẹ nílùú Eko Aàrẹ, igbákejì aàrẹ àti aàrẹ ilé ìgbìmọ̀ aṣòfin kọ̀wé fipò sílẹ̀ lọ́jọ́ kan náà Bakan naa ni wọn ni o lo ayederu iwe pe oun fẹ fi owo naa ra ọkọ ofurufu lorilẹ-ede Amẹrika ni.
Bẹ́ẹ̀ ni Dafidi ṣe sí gbogbo àwọn ìlú Amoni.
Agbabọọlu orilẹede Amẹrika, Alex Morgan gba goolu marun un wọle ninu ifẹsẹwọnsẹ naa, Lavelle (meji), Mewis (meji), Horan, Megan Rapinoe, Mallory Pugh ati Carli Lloyd pẹlu naa gba goolu kọọkan wọle ninu ifẹsẹwọnsẹ naa.
orile ede yii yoo sa gbogbo ipa rẹ lati fopin si iwa igbesunmomi,iwa odaran ati
Ẹgbé Awakọ lpińlẹ Èko yan Musiliu Ayìndé Akínsànyà MC Oluọmọ bíi Adarí.
Gbẹ̀san lára rẹ̀ ní ìlọ́po meji ìwà rẹ̀.
Nígbà tí ó yá, Hadadi náà kú.
Wo àwọn èèyaǹ jàǹkàn mérin tí àrùn Coronavirus ti sọ dèrò ọ̀run ní Naijiria Wo bí o ṣe lè di aṣojú tó ṣe pàtàkì nínú àjọ ìṣọ̀kan àgbáyé 'UN Goodwill Ambassador' Ìgbé ayé Abiola Ajimobi nínú àwòràn pẹ̀lú àwọn ǹkan tó ṣẹlẹ̀ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Mobile Wash: iṣẹ́ fífọ́ mọ́tò tà ni mó yàn láààyò- Slay Mama Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 3 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 5 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Won bii nile Faranse lodun 1934, o gbe MArgrethe niyawo lodun 1967, won bi omo meji, iyen omoba alade Frederick ati omobakunrin Joachim.
Ó bá sọ ọ́ ní Seti.
Báwo ni Donald Trump ṣè ń rí ọwọ́ mú sí nínú àkójọ èrò àwọn olùdìbò?
" Kí làwọn ìdàmú tí Coronavirus n mú bá àgọ́ ara?
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ladoja: Àwọn èèyàn Oyo fì ìbò sọ̀rọ̀ pé ìjọba Ajimobi kò dára Saraki ni ọjọ ti awọn janduku wa da ile aṣofin ru ti wọn si ji ọpa aṣẹ ile naa gbe ni o ba oun ninu julọ.
minisita naa bẹrẹ isẹ won  ni ojo  Isegun, ojo  kẹ́rìnlélógún ,
Òun náà sì lè kojúu wàhálà, onípè àjèjì náà léríléka.
Ìpín kan tí Isakari ní yóo wà lẹ́gbẹ̀ẹ́ ti Simeoni, láti ìlà oòrùn títí dé ìwọ̀ oòrùn.
Ṣùgbọ́n Àǹjànnú-ìbẹ̀rù bú sí ẹ̀rín ó sì wí pé: Ìwọ kò mọ nǹkan tí ń bẹ, wíwọlé tàbí kí ni?
Osinbajo de si ibi idibo ni deede aago mọ̀kànlá ku ogún
O ni idi niyi ti wọn fi ni ki iwọn perete ninu awọn oṣiṣẹ to jẹ ipele lọgalọga o pada si ẹnu iṣẹ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìdíje AWCON: Nàìjíríà fi ẹ̀yìn Cameroon janlẹ̀ 24 Bélú 2018 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 27 Bélú 2018 Oríṣun àwòrán, Superfalconsfanspage Àkọlé àwòrán, Ẹgbẹ agbabọọlu obinrin Naijiria, Super Falcons Ẹgbẹ agbabọọlu obinrin Naijiria, Super Falcons ti bori ẹgbẹ agbabọọlu obinrin ti orilede Cameroon ninu ifẹsẹwọnsẹ to kagun si aṣekagba ninu idije AWCON to n lọ lọwọ.
Ni agbegbe Asokoro ni olu ilu orilẹede Naijiria, Abuja ni ile awoyanu nla yii kalẹ si.
 O ni eleyii yoo bọ si sisan owo-ori ju ẹẹkan lọ.
CBN gbé òfin tuntun sílẹ̀ fún àwọn Báǹkì 'A máa bá àwọn èèyàn Ọṣun kọ́ ilé àkọ́tì wọn parí' Èyí ni bí o ṣele dá ayédèrú ìròyìn mọ̀ A kú ewu ọmọ Linda Ikeji ooo Ọ̀rọ̀ LAUTECH gba àpérò f'áwọn Olúdíje Ọṣun Alhaji Fatai Akinbade ni owọ tijọba Ọṣun fi n ṣofo lasiko yii to ìdá ọgọrin ninu ọgọrun un ni eyi ti oun a fopin si ti oun ba wọle.
Gbogbo ipa la o ṣa lati rii pe wọn wa wi tẹnu wọn'' ''Awọn eeyan sọ pe wọn pa ẹbi ati ọrẹ wọn.
Wọn fi orukọ igbakeji Atiku, Peter Obi naa kun ti wọn si n dawọn laṣa pọ pe Atikulated Obi-diently.
Wo kókó mẹ́rìnlá nípa Ààrẹ tó ń du ipò fún sáà kẹfà lẹ́yìn ọdún 35 lóri oyè A kò le gbà kí ASUU gba ₦30bn nínú ₦40bn tíjọba gbé kalẹ̀ - NASU yarí Ìjọba ń ṣapá rẹ̀ lórí ìdènà Covid-19 àmọ́ àwọn awakọ̀ Eko ya aláìgbọràn - Ìjọba Ẹ ṣọ́ra o, àwọn kọ̀lọ̀rọ̀sí kan ń múra láti dá ìjà ẹ̀sìn sílẹ̀ ní Naijiria - DSS figbe ta Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Itaniji: Oluwo sọ ìtàn bí Orunmila ṣe jìyà nílùú Iwo àti ayọ̀ tó gbẹ̀yìn rẹ̀ torí sùúrù Bakan naa ni awọn alaṣẹ Facebook ati Twitter gbegile oju opo aarẹ orilẹede Amerika, Donald Trump lẹyin ti ikanni naa ni o tapa si awọn aṣẹ to de lilo oju opo naa.
Oṣu to lọ ni awọn ole pa dokita ile iwosan naa kan, Stephen Urueye, ninu ọgba ile iwosan naa.
Ó bá pàṣẹ pé kí wọ́n kó àwọn egungun inú wọn jáde, kí wọ́n sì jó wọn lórí pẹpẹ ìrúbọ náà; ó sì fi bẹ́ẹ̀ sọ pẹpẹ ìrúbọ náà di ìbàjẹ́, gẹ́gẹ́ bí àsọtẹ́lẹ̀ tí wolii Ọlọrun ti sọ.
Ẹgbẹ oṣelu keji ni ẹgbẹ National Republican Convention, NRC, eyi ti ami idamọ rẹ jẹ Ẹyẹ, tawọn eeyan si mọ si ẹgbẹ ẹlẹyẹ.
ṣe fi paṣẹ pe ki wọn tu olori ẹsin Islam Shiite silẹỌ̀pọ̀ èèyàn farapa nínú ìwọ́de Shiite.
N óo sọ ọ́ di eniyan pataki, ohunkohun tí o bá sọ, n óo ṣe é.
“ ‘Ẹni ìfibú ni ẹnikẹ́ni tí ó bá bá aya baba rẹ̀ lòpọ̀, nítorí pé ó dójúti baba rẹ̀.
World Radio Day: Àwọn òṣìṣẹ́ rédíò ní àwọn ń pa ìsòro àwọn mọ́ra ni láti mú inú aráàlú dùn
 Ẹtu èyí tẹ ́ ẹ ́ rẹ ́ tẹ ́ sẹrẹ ̀ gùn , springbok gùn tó 71 sí 86 cm ( 28 to 34 in ) ní ìwọ ̀ n èjìká àti ìwúwosí láti 27 sí 42 kg ( 60 sí 93 lb ) .
Awọn ibudokọ ọkọ oju irin to wa ni opopona Eko si Ibadan to fi ya lọ ba ti Lagos Port Complex to wa ni ibudokọ ọkọ oju irin Apapa ni Aare Buhari ni ki wọn fi sọri igbakeji rẹ, Ọjọgbọ Yẹmi Osinbajo.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Liverpool vs Arsenal: Liverpool kun Arsenal wẹ́lẹ́wẹ́lẹ́ bí ẹran àsun 'lójúbọ' Anfield 24 Ògún 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Idije Premier League Ajura wa lọ, ti ijakandi kọ o!
Bakan naa, ninu ikoko keta Brazil, Spain, Ghana ati China yoo jo maa figagbaga.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ọlọ́pàá Germany ń wádìí àfurasí mẹ́rin nínú àwọn tó kọlu Ekweremadu ni Germany 22 Ògún 2019 Oríṣun àwòrán, @Ekweremadu Àkọlé àwòrán, Emi ti dariji awọn to ju ẹyin lu mi ni Germany Awọn ọmọ Naijiria kan foju Ekweremadu han eemọ ni GermanyIke Ekweremadu, igbákejì ààrẹ ilé aṣòfin àgbà tẹ́lẹ́ rí èèmọ̀ he nilùú Germany!
Gege bi ero  alatagba ere idaraya  owngoalnigeria.
ki Hazard darapọ mọ ikọ ọhun lorilẹ-ede Spain.
Woods tun pari sipo méjílélọ́gbọ̀n  ninu idije U.
Ẹnikẹ́ni kò gba ẹ̀mí mi, ṣugbọn èmi fúnra mi ni mo yọ̀ǹda rẹ̀.
Gẹ̀ẹ́sì gbẹ́sẹ̀ lé ₦82bn owó Abacha Aisha, bá ọ̀kọ̀ rẹ sọ̀rọ̀ ní yàrá lórí ìpèníjà ètò ààbò - Obasanjo Nibi ipade igbimọ alaṣẹ ajọ CAF to waye ni ilu Paris lorilẹede France lọjọru ni aṣẹ yii ti jade.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Naira Marley gba ipò mọ́ Atiku lọ́wọ́ gẹ́gẹ́ bí èèyàn tí wọ́n ń wá jùlọ ní Google lọ́dún 2019 Kìí ṣe ìwà ọ̀lẹ ni bàwọn obìnrin ayé òde òní kìí ṣe dàra pọ̀ mọ àwọn olobinrin ilé DSS ti gbé Pasitọ ìjọ tí wọ́n fẹ̀sùn kan pé ó mọ̀ sí Gold Kolawole tó sọnù ni Akurẹ Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí 3 sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 2:23 Fídíò, Water Generator: Ó leè ṣiṣẹ fún wákàtí mẹfà, kó tó sinmi, Duration 2,2310 Òkùdu 2020 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
O wa bu anu ate lu awon toro kan, fun ikuna won, lati yanju aawo naa.
Ileeṣẹ ọlọpaa orilẹede Uganda ka apo kan mọ arakunrin naa lọwọ ninu eyi ti wọn ti ba ori ọmọde kan ti wọn ge nibẹ.
Fi fẹ̀ iyàwó púpọ̀ kò pin si ilẹ̀ Yorùbá tàbi ilẹ̀ Aláwọ̀dúdú nikan, ó wọ́pọ̀ ni ilẹ̀ Aláwọ̀funfun ni ọ̀pọ̀lọpọ̀ ọdún sẹhin ṣùgbọ́n nitori òwò ẹrú àti ẹ̀sin igbàgbọ́ wọn bẹ̀rẹ̀ àṣà fi fẹ iyàwó kan.
Ìdí ni yi ti wọn fi n sọ ọmọ ni orukọ lataari iṣẹlẹ to n ṣẹlẹ lagboole, ninu ẹbi, ninu ilu lasiko ti a ba bi ìkókó.
OLUWA, òtítọ́ rẹ yí ọ ká.
Orowọle Jaaniini Fagunwa ni orukọ akọni onpitan yii, amọ orukọ ti ọpọ eeyan mọ si ni Daniel Ọlọrunfẹmi (D.
Solomoni jọba lórí àwọn ọba gbogbo, láti odò Yufurate títí dé ilẹ̀ àwọn ará Filistia ati títí dé ààlà Ijipti.
Àwọn ìlú ati àwọn ìletò wọnyi ni ìpín tí ó kan ẹ̀yà Dani gẹ́gẹ́ bí iye ìdílé wọn.
  Ènìà láti rìn lórí ọ̀nà nlá yìí nítorípé kò sí ọ̀nà àfẹsẹ̀rìn kankan lẹ́gbẹ̀ẹ́ ọ̀nà nlá yìí bí a ṣe lè ríi lẹ́gbẹ̀ẹ́ àwọn ọ̀nà nlánlá míran.
 a & w jẹ gangan ile-iṣowo franchise akọkọ : awọn franchises bẹrẹ ni california ni ayika 1921 .
Awọn ẹgbẹ osisẹ sọ pe ẹru ba awọn pe ẹmi awọn awakusa to há sinu ihò ọun lee wa ninu ewu.
Ọna lati ba baba laafin se ayẹsi awọn olori naa si lo mu ka fi aworan naa soju opo Facebook wa.
Oríṣun àwòrán, Others Àkọlé àwòrán, O seese kí panpẹ́ ọba ti wọn fi mu oludije sipo aarẹ ni ọdun 2019,Ọmọyele Sowore niise pẹlu ifẹhọnu gbogboogbo ti wọn fẹ sẹ ni Ọjọ Aje.
Risikat Azeez: Aya gómìnà tún fẹ́ gba sọ́ọ́bù, ra ọjà fún obìnrin olójú búlúù
Aare sọrọ yii  lọjọ Isẹgun nile aare to wa  niluu Abuja  fun awon omo egbe  United Kingdom-based Foundation for Good
Ìwà olukuluku ni n óo fi dá a lẹ́jọ́.
Lori pe aarẹ́ Buhari ko sọ̀rọ̀ iburawọle si awọn ọm Naijiria, Omoyele Sowore ni ijọba paṣan ni Naijiria wa yii eyi ti o ta ba ara ile ta ba ara oko."
Awọn iṣẹ akanṣe ti a n dawọle naa yoo tun fa awọn ero pupo mọra ni eyi tijọba yoo ri owó ori to pọ pa sii nile itura ati lẹnu iṣẹ wọn gbogbo.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Kí lo fẹ́ mọ̀ nípa D.
Bẹẹ ni ọrọ ri pẹlu ibasepọ tọkọtaya Saheed ati Fathia Balogun, taa gbọ pe ipinya ti de si aarin wọn tẹlẹ, amọ lẹyin ọdun mẹrinla, wọn pada joko se sinima papọ.
"Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ìtàn tó rọ̀ mọ́ òwe ""Ẹni tí kò ṣe bíi aláàárù l'Oyingbo."
’’ Ogbeni Arkwright naa so pe orile ede oun, nifee si eto ijọba tiwa-n-tiwa lorile ede Naijiria , nitori naa, ni awon yoo se yan awon asoju lasiko eto idibo, ki eto idibo naa lee lo ni irowo-irose.
Níwọ̀n ìgbà tí ẹ̀ ń tiraka láti ní ẹ̀bùn Ẹ̀mí Mímọ́, ẹ máa wá àwọn ẹ̀bùn tí yóo mú ìjọ dàgbà.
Àwọn Ìpínlẹ̀ tí coronavirus kò tíì dé ní Nàìjíríà, àti ìgbésẹ̀ tí wọ́n ń gbé láti dènà rẹ̀ Ìjọba yóò lo BVN àtàwọn ọ̀nà méjì míràn láti pín owó ìrànwọ̀ fún aráàlú Bí Coronavirus kò bá pa wá, ẹ má fi aisun pa wá torí ìbẹ̀rù olè - Àwọn olùgbé Ibadan figbe ta Kí làwọn ìdàmú tí Coronavirus n mú bá àgọ́ ara?
kí OLUWA má baà bínú sí ọ tí ó bá rí ọ,kí ó sì yí ojú ibinu rẹ̀ pada kúrò lára ọ̀tá rẹ.
Nítorí pé kò sí ọ̀nà láti fi yí ọkọ̀, kí ó kọjú sí atẹ́gùn yìí, a fi í sílẹ̀ kí afẹ́fẹ́ máa gbé e lọ.
Aṣọ àlòkù Bàbá, Ìyá àti ẹbi ni wọn nya si wẹ́wẹ́ lati ṣe itẹdi ọmọ nitori kò si itẹdi à lò sọnú bi ti ayé òde òni.
kí wọ́n mú aṣọ ìgúnwà ọba, tí ọba ti wọ̀ rí, ati ẹṣin tí ó ti gùn rí, kí wọ́n sì fi adé ọba dé ẹni náà lórí, 
Oríṣun àwòrán, @OfficialPDPNig Àkọlé àwòrán, Ìdìbò gómìnà nipinlẹ Ekiti yóò wáyé lọ́wọ́ Àbámẹ́ta Fayoṣe figbe ta pé wọ́n fẹ́ gbẹ̀mí òun Akoroyin wa to wa ni ibì ìpolongo náà so pé, lẹyìn tí Fayoṣe bá àwọn akọròyìn sọrọ ní won gbé dìgbà dìgbà sínú ọkọ alarẹ lọ sí ilé ìwòsan.
O ni kò sí ileesẹ ìjọba kankan tó tíì ṣe ìwádìí imọ ìjìnlẹ̀ nípa ẹ̀rọ alatagba 5G náà, kò tó di pé a ń ṣe ifilọlẹ rẹ.
Nígbà tí Tẹra di ẹni aadọrin ọdún ni ó bí Abramu, Nahori, ati Harani.
Ti mo ba kẹfin wi pe ko wu obinrin naa ki ọkọ rẹ fẹyawo keji, mi o ni gba ọkọ naa laaye lati fẹ iyawo miran.
Àwọn eniyan yóo máa wí nípa Israẹli pé,‘Wo ohun tí Ọlọrun ṣe!
Ile iṣẹ ọlọpaa sọ ninu atẹjade naa pe ohun ko ni gba ki ẹnikẹni ko tapa sofin Naijiria bo tilẹ jẹ pe awọn ọmọ Naijiria lẹtọọ labẹ ofin lati fẹhonu han ṣugbọn kii ṣe afipa sẹ bi iru eyi tawọn kan n gbero.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Iléeṣẹ́ ológun: Àbájáde ìwádìí wa lórí ìṣẹ̀lẹ̀ náà yóò hàn síta láìpẹ́ 24 Agẹmo 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Ileeṣẹ ologun Naijiria ti bẹrẹ iwadii aṣiri kan to tu pe, awọn ọmọ ogun kan salọ pẹlu owo naira to le ni miliọnu kan ati aabọ Dọla ($1.
Ọmọ meje ni baba ati iya Nazanin bi - obinrin mẹta ati ọkunrin mẹrin.
Àìmọye àwọn ènìyàn tí ó wà nínú ìrìnàjò afẹ́ náà jẹ́ àgbàlagbà.
Ni Taiwan to se pe orile-ede China ka kun ara ilẹ wọn, Aarẹ Tsai Ing-wen tara sasa se agbekalẹ ibudo kokoro aifojuri ti o si tun se awọn nkan miran lati dena itankalẹ arun yi.
Gbogbo ayé yín, èmi lẹ fi sìn.
O ni ọrọ aje orilẹ-ede Malaysia buru ju ti Naijiria lọ lasiko ta gba ominira lọdun 1960, bẹe naa ni South Korea ati Vietnam, ṣugbọn ni bayii, ọrọ aje awọn orilẹede naa ti ṣenu ire ju ti Naijira lọ, leyi to tumọ si pe, ọpọ nnkan ni Naijiria le kọ lara wọn.
Oríṣun àwòrán, Reuters Nigba to n sọrọ lori ipo ti ilera Trump wa, Dokita rẹ, Sean Conley ni o rẹ aarẹ naa diẹ amọ ọkan rẹ wa nipo to dara, ti oun gan si n se daradara.
Iṣẹ́ alaafia ni mo rán sí i, mo ní, 
Niwọn igba to jẹ pe awaye ku ko si, Ọgagun Tunde Idiagbon dagbere faye ni ọjọ Kẹrindinlogun oṣu karun ọdun 1999, lasiko aisan ranpẹ ni ẹni ọdun mẹrindinlọgọta.
Mẹrindinlogun lo ku nibẹ ni ọdun to kọja.
Ìgbà tí o bá dé ọ̀run Àpáàdì gan-na, máa lọ gan-an ran sí ọ̀dọ̀ Èṣù ní inú ààfin rẹ̀.
 Fún gbogbo àwọn ÌYÁ káàkiri àgbáyé.
Maduagwu ni o ṣeni laanu wi pe iru iwa ẹlẹyamẹya ati idẹyẹsi si ni to n waye ni ilẹ Amẹrika naa n waye ni orilẹede Naijiria, ti oun si ṣẹtan lati fi ofin si iwa buruku yii.
Oni lẹyin irinajo naa ni awọn di ọrẹ, ti ọrẹ si pada di tọkọ-taya.
Alẹ́ ọjọ́ ẹti ni ikéde yìí jáde, tí ìpínlẹ̀ Eko si ní iye èèyàn to pọ̀ jùlọ pẹ̀lúu èèyàn mẹ́ràndín ni ààdọ́san, ]ipínlẹ̀ Kano ṣe ipo keji, pẹ̀lú èèyàn márùndinlọ́gọ́ta.
Ó gbọ́n ju Etani ará Ẹsira lọ, ati Hemani, ati Kakoli, ati Dada, àwọn ọmọ Maholi.
Àwọn ẹ̀yà Juda ati ẹ̀yà Simeoni fi àwọn ìlú náà sílẹ̀ fún àwọn ọmọ Lefi, 
Ẹ ranti iṣẹ́ ribiribi tí ó ti ṣe,ẹ ranti iṣẹ́ ìyanu rẹ̀ ati ìdájọ́ rẹ̀.
Nigba ti Dino Melaye yoo fi gunlẹ sile ẹjọ, kayefi lo ṣe ọpọ nigba ti wọn rii lori kẹkẹ alaarẹ ti oloyinbo n pe ni 'Stretcher' Ènìyàn 653 míràn tún kún iye àwọn tó ní COVID-19 ní Nàìjíríà Báwó ni òògùn dexamethasone ṣe ń ṣiṣẹ́ lára Lẹ́yìn gbogbo sinimá oríta ní Ondo, Akẹti jáwé olúborí ní APC Akanbi mi, má fọ̀ ọ́, mo wà pẹ̀lú ẹ; ẹni tó ṣe ìgbéyàwó olórùka ló l'ọkọ- Lizzy Anjorin Olisah Metuh Ni ọdun 2018 kan naa ni wọn gbe Olisah Metuh to jẹ alukoro tẹlẹ fun gbẹ oṣelu PDP.
O tẹra mọ iṣẹ siso bata ni kete to pari idanwo iwe mẹwaa rẹ ni kilomita ẹgbẹta si abule rẹ.
0 18001 Orilẹede Sri Lanka 255 1.
Èmi Paulu, ẹrú Ọlọrun, ati aposteli Jesu Kristi, ni mò ń kọ ìwé yìí.
Nítorí ẹni tí kò bá fẹ́ràn arakunrin rẹ̀ tí ó ń fojú rí, kò lè fẹ́ràn Ọlọrun tí kò rí.
Seleki, ará Amoni, ati Naharai, ará Beeroti, tí ń ru ihamọra Joabu ọmọ Seruaya.
Ogbẹni Tosin Jemide to jẹ Aarẹ ẹgbẹ PBAN ni Naijiria sọrọ lori iṣoro ti awọn ọmọ ẹgbẹ n koju lẹnu oko owo naa bayii.
Ó tún pàṣẹ pé kí àwọn akọni ninu àwọn ọmọ ogun rẹ̀ di Ṣadiraki, Meṣaki ati Abedinego, kí wọ́n sì sọ wọ́n sinu adágún iná.
 9 ninu idije enimeji , o gba open australia 1996 pelu arantxa sánchez vicario .
À ń gbé inú Ọlọrun, àní inú Ọmọ rẹ̀, Jesu Kristi.
Tú okùn tí a dè mọ́ ọ lọ́rùn kúrò,ìwọ Sioni tí ó wà ninu ìdè.
Oríṣun àwòrán, Press information bureau O ti to nnkan bi ọdun diẹ sẹyin ti fa ki n fa ti n waye laarin orilẹ-ede meji ọhun nitori ilẹ kan ti awọn eeyan ki n gbe.
O kò mọ̀ pé akúṣẹ̀ẹ́ tí eniyan ń káàánú ni ọ́, òtòṣì afọ́jú tí ó wà ní ìhòòhò.
Lẹyin eyi ni wọn fun mi ni iwe kan lati tun lọ se ayẹwo Coronavirus ni adugbo Lekki.
Jibri sọ pe igbesẹ lati ti ibode naa jẹ ọkan gboogi lara aṣeyọri aarẹ Buhari lati ri pe awọn ileeṣẹ to n ṣe aṣọ lorilẹ-ede yii gbera sọ.
Ọọni Ilé-Ifẹ̀ jẹ Atọbatẹlẹ, ko to jẹ Ọba, nitori ọmọ ọba ni.
Nígbà tí ó bá dé, tí ó bá kanlẹ̀kùn, lẹsẹkẹsẹ ni wọn yóo ṣí ìlẹ̀kùn fún un.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ibudo ikepo si bu gbamu nipinlẹ eko 24 Sẹ́rẹ́ 2018 Oríṣun àwòrán, LASEMA Àkọlé àwòrán, Ko si ẹmi ti o padanu ninu iṣẹlẹ naa Ibudo ipamọ epo bẹtiroo kan ti o ni awọn agba ikepopamọsi nlanla marun (PMS) ti gba ina jẹ ni agbegbe Ijegun nilu Eko lọjọọru.
Nigba to n fidi isẹlẹ naa mulẹ, agbẹnusọ fun ileesẹ ọlọpaa ipinlẹ Oyo, Olugbenga Fadeyi salaye pe ẹrọ ilewọ Tecno kan ati ibọn lawọn afurasi lo.
Èèyàn 745 ló lùgbàdì àrùn Coronavirus ní Naijiria ní Ọjọ́bọ̀ Wo àwọn Gómìnà Naijiria tí àrùn Covid-19 ti bá fínra Àwọn akẹgbẹ́ ẹ̀ṣọ́ àjọ FRSC mẹ́ta tí àrá sán pa l'Ogun gbọdọ̀ ṣ'ètùtù- Elebuibọn Gómìnà márùn ún tó fojú winá ìbínú bàbá ìsàlẹ̀ wọ̀n Òjò àrọ̀ọ̀rọ̀dá dá wàhálà sílẹ̀ l'Eko Awọn ọlọṣa naa wọ agọ awọn ọlọpaa naa ti wọn si ko awọn dukia kan to wa nibẹ lọ.
Kí ló dé tí ẹ kò fi bẹ̀rù ati sọ̀rọ̀ òdì sí i?
Emzor gbọnmú lóríi fídíò codeine Àwọn aláṣẹ iléeṣẹ́ Emzor, tó jẹ́ ọ̀kan lára àwọn iléeṣẹ́ tó ń se òògùn ikọ́ olómi tó ní èròjà codeine síta, fi sí orí ìkànnì twitter wọn ní @emzornigeria pé, wọ́n ti fòpin sí pínpín oògùn ikọ́ olómi Codeine síta báyìí títí wọn yóò fi parí ìwádìí abẹ́lé tí wọ́n n ṣe.
3 Bí ó tilẹ̀ rí bẹ́ẹ̀, nísisìyí a ti mú un padà sípò fún ọ lẹ́ẹ̀kansíi; nítorínáà ríi pé o jẹ́ olótĩtọ́ kí o sì tẹ̀síwájú sí píparí ìyókù iṣẹ́ ìtumọ̀ náà gẹ́gẹ́bí o ṣe bẹ̀rẹ̀.
Lori ipo ti Naijira de dúro lonìí, Obesere sàlayhe pe botill jẹ pe ìjọba o ṣe nkan ti ilú n fẹ, o ṣe pataki láti maa fi adura ran wọ́n lọ́wọ́.
Jiti Ogunye ṣalaye fun BBC Yoruba pé Naijiria ti n di ọlá n rẹyin nitori pe ọla wa ko lọ siwaju mọ ni gbogbo ọna.
Association (NAFOWA) fun iwa akin ati ifomoniyanse , ni eyi ti aare won  Hajiya Hafsat Abubakar, gba fun egbe naa.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Mo ń ṣa ike jọ láti san owó ilé iwé ọmọ mẹ́ta' Ṣaaju ki ọkọ afurufu Trump to balẹ lo ti bẹnu ẹ̀tẹ́ lu Sadiq Khan to jẹ olori London lẹyin ìkọlu wọn atẹyinwa.
soju fun aarin gbungbun Kebbi , Muhammad Adamu Aliero, ni alaga igbimo naa.
O sọ pe pẹlu bi Buhari ti ṣe ṣe aṣeyọri to yi, ko jẹ iyalẹnu pe awọn oloṣelu ti ko ni aseyọri lasiko wọn yoo maa jowu aarẹ Buhari.
Ojogbon Adewole soro idaniloju yii ,nigba to n ba awon akoroyin soro niluu Abuja leyin ipade igbimo ijoba apapo.
15 Nísisìyí mo pàṣẹ fún ọ lati ronúpìwàdà—ronúpàwàdà, bí bẹ́ẹ̀kọ́ èmi yíò nà ọ́ pẹ̀lú ọ̀gọ ẹnu mi, àti pẹ̀lù ìrunú mi, àti pẹ̀lú ìbínu mi, àti pé àwọn ìrora rẹ yíò dunni jọjọ—bí yíò ṣe dunni tó ìwọ kò mọ̀, bí yíò ṣe rẹwà tó ìwọ kò mọ̀, bẹ́ẹ̀ni, bí yíò ṣe nira láti faradà tó ìwọ kò mọ̀.
Ẹbí ìyàwó lu ọkọ ìyàwó lẹ́yìn tí ìyàwó rẹ̀ yọjú síbi ìgbéyàwó tó ṣe pẹ̀lú obìnrin mìràn
Àkókò yìí ni àgbàlagbà òyìnbó bá mín kànlẹ̀, ó sọ̀rọ̀ àgbà.
Ọpọlọpọ sọ pe ofin naa n mu wọn o dajọ ẹ̀wọ̀n ọlọjọ pipẹ fun awọn eeyan, to si tun n mu ki awọn ti wọn n ju si ẹ̀wọ̀n o pọ.
Ta ni Alexander Akinyele, minisita ọrọ iroyin rí?
Lasiko to n sọrọ pẹlu awọn akọroyin lọjọbọ ni Minisita Lai Mohammed sọ pe ko si ẹnikankan to ku ninu ikọlu to waye ni Lekki.
Ṣugbọn n óo rúbọ sí ọ pẹlu ohùn ọpẹ́,n óo sì san ẹ̀jẹ́ mi.
 Àwọn tí ó wà ní ẹgbẹ ́ yìí ni àwọn slowworm , alángbá gílásì àti alángbá inú omi , àti bẹ ́ ẹ ̀ bẹ ́ ẹ ̀ lọ .
Abimeleki ọmọ Gideoni lọ sí ọ̀dọ̀ àwọn eniyan ìyá rẹ̀ ní Ṣekemu, ó bá àwọn ati gbogbo ìdílé wọn sọ̀rọ̀, ó ní, 
Nítorí pé kò ronú láti ṣàánú,ṣugbọn ó ṣe inúnibíni talaka ati aláìní,ati sí oníròbìnújẹ́ títí a fi pa wọ́n.
OLUWA àwọn ọmọ ogun tún bá mi sọ̀rọ̀ pé 
N óo fun yín ní ìlera,n óo sì wo àwọn ọgbẹ́ yín sàn,èmi OLUWA ni mo sọ bẹ́ẹ̀.
“Yóo dára fún àwọn tí ó fẹ́ràn rẹ!
Yoòbá bọ̀ ó ni “Ẹni bá máa ga, ẹsẹ̀ rẹ̀ yó tínrín” èyí ló dífá fún igi ọ̀pẹ́ nínú igbó.
wọ́n wá siwaju Mose, ati Eleasari ati àwọn olórí àwọn eniyan, wọ́n ní, 
Ede yoruba ati ede Gẹẹsi dan lẹnu Tolani daadaa.
lati ṣe ohun to yẹ fun idagbasoke ede ati aṣa Yoruba lasiko yii.
Joabu bá ranṣẹ sí Dafidi láti ròyìn ohun tí ó ṣẹlẹ̀ lójú ogun fún un.
Ibeere to gba ọkan awọn eeyan nipinlẹ Ogun ree lẹyin ti awọn janduku ji ọlọpaa mẹrin gbe ti wọn si tun yinbọn lu ọga agọ ọlọpaa, DPO, kan.
Aare egbe naa, Georges Armand Ouegnin ke gbajare lori ohun ti o pe ni, “titapa si ominira awon ara-ilu lati soro”.
Mẹsan an ninu awọn eeyan ọhun wa ni ipinlẹ Eko, meje wa ni Abuja, marun un ni ipinlẹ Akwa Ibom, ẹnikan ni Kaduna ati ẹnikan yoku ni Bauchi.
Minisita fun oro ile abele ajagun –feyinti ,Lt-Gen Abdulrahman Bello Dambazau lo soro yii lori ero ayelujara Twitter re ni ale ojo Aiku.
Agbẹnusọ fun Ọọni, Moses Ọlafare sọ fun BBC Yoruba pe gbogbo awọn nkan to y ki olori tuntun ṣe lo ṣe ni ibamu pẹlu aṣa ilẹ Yoruba, ko to wọ iyẹwu kabiesi.
Olúwo ni gbogbo àwọn ẹgbẹ́ báwọnyìí máa ń sọ wọ́n di ẹrú ni nígbá ti wọ́n ba jẹ́jẹ̀ẹ́ owó àtí àwọn agbára ẹmi àìrí.
Àwọn ni wọ́n pa àwọn ará Ijipti ní ìpakúpa ninu aṣálẹ̀.
Laipe ni won se itebomi fun un laarin awon ebi re.
Iya ọmọ naa, Modupe Kolawole ṣalaye fun BBC Yoruba pe, inu oṣù kẹfa lawọn ṣẹṣẹ bẹ̀rẹ̀ sí ní lọ sí ṣọọṣi naa, ki iṣẹlẹ yii to o waye.
Ó bá sọ fún un pé, “N óo gbọ́ ẹjọ́ rẹ nígbà tí àwọn tí ó fi ẹjọ́ rẹ sùn náà bá dé.
OLUWA sọ fún mi, pé, “Ìwọ Ọmọ eniyan, àwọn tí wọn ń gbèrò ibi nìyí; tí wọn ń fún àwọn eniyan ìlú yìí ní ìmọ̀ràn burúkú.
Fawọn to ba jẹ akẹkọ,awọn ohun ti wọn ma n ṣe ni irọrun tẹlẹ nipa iforukọsilẹ yoo mu wahala lọwọ nitori aisi ileeṣẹ orileede Naijiria nibẹ mọ Awọn olokoowo ati ọlọrọ aje miiran naa yoo koju iṣoro pẹlu awọn iwe idanimọ kan ti o ba yẹ ki wọn gba nirọrun lati ọdọ awọn oṣiṣẹ ọfisi orileede wọn nibẹ.
gẹ́gẹ́ bí ọjọ́ tí àwọn Juu gba ara wọn sílẹ̀ lọ́wọ́ àwọn ọ̀tá wọn, tí ìbànújẹ́ ati ẹ̀rù wọn di ayọ̀, tí ọjọ́ ọ̀fọ̀ wọn sì di ọjọ́ àjọ̀dún.
Ọlọ́gbọ́n a máa gba ìlú àwọn alágbáraa sì wó ibi ààbò tí wọ́n gbẹ́kẹ̀lé lulẹ̀.
Àkọlé àwòrán, Lẹyin ti Baba Obasanjọ pada de latin ọgba ẹwọn ni o jẹ adari orilẹede Naijiria labẹ ijọba tiwantiwa lọdun 1999 lati ẹgbẹ oṣelu PDP.
Nípa igbagbọ ni ó fi kúrò ní Ijipti, kò bẹ̀rù ibinu ọba, ó ṣe bí ẹni tí ó rí Ọlọrun tí a kò lè rí, kò sì yẹ̀ kúrò ní ọ̀nà tí ó ti yàn.
Ẹni ba fẹ ọkọ ni Ibadan bi igba to lọ si igbo Sambisa ni.
Ijọba ipinlẹ Ondo, Ọyọ ati Kwara ti sọ wi pe, awọn ko le e sọ lọwọlọwọ bayii boya awọn yoo san ẹgbẹrun lọna ọgbọn naira (₦30,000) gẹgẹ bi owo osu tuntun fawọn osisẹ eyi tijọba apapọ sẹsẹ fẹnu rẹ jona.
Ọkùnrin tí kò ríran kan rèé tó ń lọ ẹ̀rọ ata Ọọ̀ni obìnrin, Lúwòó Gbàgídà rèé, akọni tó ń gun ọkùnrin ní ẹṣin rìn Ìtàn Ọba Yorùbá tí wọ́n yẹgi fún torí ó jí ọmọ gbé ṣe ètùtù 5:30 p.
Oríṣun àwòrán, Other Ijọba ipinlẹ Ondo sọ pe iṣẹlẹ naa tọka si pe ipenija eto aabo to kọja oju lasan, lo n ba 'wa' finra.
Eyi lo difa fun Bisi Alimi to fẹ ọkunrin ẹgbẹ rẹ, Anthony Davis gẹgẹ bi ọkọ.
Buhari ni saa meji ti iwe ofin ilẹ Naijiria la kalẹ fun ipo aarẹ naa loun yoo ṣe.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù WhatsApp: Ìgbésẹ̀ tó gbé rèé láti mọ̀ bóyá fóònù rẹ̀ kò ní lo áàpù yìí mọ́ 29 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Oríṣun àwòrán, Getty Images Ọ̀pọ̀ ìròyìn lo ti fi ìdí rẹ̀ múlẹ̀ pé ápùù ìfọ̀rọ̀ ránsẹ́ síra ẹni ti a mọ̀ sí WhatsApp, ko ni ṣiṣẹ́ fún ẹgbẹ̀lẹ́gbẹ̀ mílíọnù fóònù ìgbàlódé, láti ọjọ́ kini oṣù kíní, ọdún 2021 Ní ìbẹ̀rẹ̀ ọdún 2020, WhatsApp ko síṣẹ́ mọ lórí àwọn fóònù kan ọdún yìí WhatsApp ko síṣẹ́ mọ lórí àwọn fóònù kan ti wọn n fi Andriod 2.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Celestine ẹlẹ́wọ̀n: Òun àti ọmọ rẹ̀ ló wà lọ́gbà ẹ̀wọ̀n 12 Ọ̀wàrà 2018 Oríṣun àwòrán, GLOBAL SOCIETY FOR ANTI-CORRUPTION Àkọlé àwòrán, Paul àti Celestine Egbuchune ti lo ọdún méjìdínlógún ní ọgbà ẹ̀wọ̀n Celestine Egbunuche ti pé ọgọ́rùn ún ọdún, tí àwọn kan si gbàgbọ́ pé òun ni ẹlẹ́wọ̀n tó dàgbà jù ní Nàìjíríà, èyí sì tí mú kí àwọn ènìyàn maa bẹ ìjọba láti tu u sílẹ̀.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù 2019 Guber election: Adelabu pe Makinde, INEC l'ẹ́jọ́ 2 Ìgbé 2019 Àkọlé àwòrán, 2019 Guber election: Mí ò faramọ èsi ìdìbò tó gbé Makinde wolé Olóye Adebayo Adelabu to jẹ olùdíje lábẹ̀ àsìá ẹgbẹ́ òṣèlú All Progressives Party (APC) ní ìpínlẹ̀ Oyo ti fi ìwé ẹsun sọwọ si ilé ẹjo tó ń gbọ ẹsun ìdìbò láti pe ìjáwe olúbori ọgbẹni Seyi Makinde ti ẹgbẹ́ òṣèlú People's Democratic Party (PDP) lẹ́jọ nibi ìdìbò tọ wáye lọ́jọ́ kẹsàn oṣù kẹta.
babaláwo ( oníyẹ ̀ míwò ) máa ń lo ọ ̀ pẹ ̀ lẹ ̀ láti lè sọ ̀ rọ ̀ pọ ̀ pẹ ̀ lú òòṣà ọgbọ ́ n / ìmọ ̀ ( Ọ ̀ rúnmìlà ) nínú ìsẹ ̀ ṣe yorùbá ẹni tí ó lè ṣe àfihàn okùnfà àti ojútùú sí ìsòri àdáni àti gbogbogbòòtí yóò sì fi mú ìrọ ̀ rùn padà wá sí ayé onítọ ̀ hún nípa títún ìpín àti / tàbí orí ( òòṣà ẹnikọ ̀ ọ ̀ kan ) ẹni ṣe .
Láfikún-un Kérésìmesì, àkàsílẹ̀ àwọn àjọ̀dún Òyìnbó kò yọ Àyájọ́ Ọjọ́ Olólùfẹ́, Àjíǹde àti Halowíìnì, àti bẹ́ẹ̀ bẹ́ẹ̀ lọ sí ẹ̀yìn.
ile igbimo asofin ti ni awon yoo se atunse si yiyan  bi awon  aare orile ede Naijiria se maa n yan awọn alakoso
Ǹkan mẹ́jọ tó máa kọ́kọ́ ṣẹlẹ̀ kí olólùfẹ́ méjì tó pa ara wọn EFCC ti ri mílíọ̀nù 65.
Abubakar Adamu soro lasiko to se abẹwo si olu-ile ise olopaa ni ipinle Oyo to kale si agbegbe Eleyele niluu Ibadan.
Bi wọn ti ṣe n gbe ounjẹ ati omi ni awọn kan n fi nkan eelo itọju alaisan to fi mọ ibomu ṣọwọ si awọn oluwọde.
Bi awọn kan ṣe n sọ pe nitori konile-o-gbele lati dena itankalẹ Coronavirus lo faaa.
Ohun tí ò ń sọ kò yé mi rárá!
Arsenal ti wa ni ipo kẹfa bayii lori tabili idije Premier League.
 “Ọlọrun si pasẹ, pe ki  imọlẹ ki o wa, imọlẹ si wa , Ọlọrunsi ri I pe
Opopona yii lo ja mọ abule Mgwa Magaba, Kompani, Rubo, Nafsira, Shikira, ati Wayam papọ mọ ara wọn.
Awọn to mọ ni a ma riran si awọn eeyan ti a si ma woye nipa iṣẹlẹ orisirisi lawujọ.
ewuro iya soju iko agbaboolu  Manchester
Amọ ọkan lara awọn Ọba mọkalelogun, Lekan Balogun to ba BBC Yoruba sọrọ ṣalaye pe, isọkusọ gbaa ni Olubadan n sọ, ko si si ẹni to dan iru rẹ wo ri.
Arakunrin Bisi Kazeem ni ọga ajọ naa ti wa rọ awọn oṣiṣẹ FRSC lati ma ṣe jẹ ki iṣẹlẹ yi mu irẹwẹsi ọkan ba wọn.
Seyi Makinde bẹrẹ ile-iwe alakọbẹrẹ ni St.
Ibugbamu ado oloro eleyi ti omo okunrin agbesunmomi kan sokunfa re ti seku pa eniyan meje lasiko adura owuro ni Mosalasi kan lagbegbe ijoba ibile Konduga Local Government, nipinle Borno.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: N kò ri ipa ẹ̀jẹ̀ lára ọmọ mi tó kú sí iléeṣẹ́ ọṣẹ, èjò lọ́wọ́ nínú - Òbí àkẹ́kọ̀ọ́ UI Mò máa ń fọ àwọ̀tẹ́lẹ̀ ìyá mi, ni ìṣe àwọn obìnrin fi wù mí - Bobrisky Àlàyé rèé lóríi àjọṣepọ̀ tó wà láàrin èmi àti MC Oluomo - Ronke Oshodi Oke Ẹ bá mi wá nọ́ńbà ìpè òbí ọmọ Mummy Calm Down jáde - Yinka Ayefele Ọlọ́pàá sálọ fún aráàlú l‘Okeho, nígbà tí wọn yari láti ṣun olè méjì tó kù Atẹjade kan ti agbẹnusọ fun ẹgbẹ Afenifere, Yinka Odumakin fisita lo sisọ loju ọrọ yii pẹlu afikun pe ominu n kọ awọn ọmọ Naijiria lori igbesẹ ijọba apapọ naa.
Kò sí ẹni tí ó bá ti mu ọtí tí ó mú, tíí fẹ́ mu ọtí àṣẹ̀ṣẹ̀pọn.
Ọba Adeyẹmi gbafẹ, o gboge, to si rẹwa lọkunrin.
Ìtokò : adágbà je omo ìrówò ìbàràpá òun ní ó kókó dé abéòkúta , ogun lé won dé orí dímo ( Àwon ìbàràpá ) wón bá adágbà tí ó ń se isé ode ní orí olúmo .
Oríṣun àwòrán, Getty Images, Wikipedia Àkọlé àwòrán, IBB tẹ ń pariwo pé ó kú, kò kú o, Ko ko lara ọta ń le- Agbẹnusọ Kassim Ẹwẹ, agbẹnusọ ọgagun Babangida, Ọmọba Kassim Sule sọ fun BBC Yoruba wi pe bẹẹ naa lawọn ṣe ji lowurọ yii ti awọn n gbọ iroyin ẹlẹjẹ ọhun kaakiri.
Àwọn ologun dóòlà akẹ́kọ̀ọ́ mẹ́fà lọ́wọ́ àwọn ajínigbé ní Kaduna Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Chadwick Boseman wife: Simone Ledward ni ìyàwó Chadwick Boseman, wọ́n sì 'sègbéyàwó kó tó jáde láyé31 Ògún 2020 Fídíò, Yoruba Language: Akomolede ati Asa Yoruba tọ̀sẹ̀ yí rèé lẹ́nu olùkọ́ wa30 Ògún 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
OLUWA ló ni ilẹ̀ ati gbogbo ohun tí ó wàninu rẹ̀,òun ló ni ayé, ati gbogbo àwọn tíń gbé inú rẹ̀;
Ẹ lọ sí Jerusalẹmu ní ilẹ̀ Juda, kí ẹ tún ilé OLUWA Ọlọrun Israẹli kọ́, nítorí òun ni Ọlọrun tí wọn ń sìn ní Jerusalẹmu.
Ṣugbọn o ni ninu iwoye oun, pupọ awọn ẹbun wọnyii lo ti de ọwọ awọn elere idaraya bẹẹ.
41 Days Fasting: Akẹ́kọ̀ọ́ kan gba ààwẹ̀ ọlọ́jọ́ 41, ó dèrò ilé ìwòsàn
Agbẹ yoo sọ iye owo ire oko ti maalu naa jẹ, ti darandaran naa ko ba si le sanwo ọhun, wọn yoo ta maalu naa.
 osi tun je oludasile ati alase ile ise redrick public relations .
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù FGM: Èyí ni bí àwọn obìnrin kan ṣe n fi abẹ̀ dídá sọ ara wọn di 'fágìn' lẹ́ẹ̀kejì 20 Ọ̀pẹ̀̀ 2019 Oríṣun àwòrán, María Conejo/BBC Awon obinrin kan ni orilẹede Sudan n lọ fun iṣẹ abẹ lati da abẹ fun'ra wọn ti igbeyawo wọn ba ti ku oṣu kan tabi meji ki wọn o le ro wi pe wundia ti ko ti i ni ibalopọ ri ni wọn.
Wọ́n dojú kọ Mose ati Aaroni, wọ́n ní, “Ẹ ti bẹ̀rẹ̀ sí kọjá ààyè yín, nítorí pé olukuluku àwọn ọmọ Israẹli ni ó jẹ́ ẹni ìyàsọ́tọ̀ fún OLUWA, OLUWA sì ń bẹ láàrin wọn.
Nígbà tí ó di ààrin ọ̀gǹjọ́, ọkùnrin náà rí nǹkan kan tí ó ń bọ̀ ní ibi ọ̀pẹ wọ̀nyí ó sì wó ó dáradára.
Alhaji Abdulfatah Ahmed  ati iyawo rẹ arabinrin,
Èmi, OLUWA Ọlọrun àwọn ọmọ ogun ni mo sọ bẹ́ẹ̀.
nile-igbimo asofin lati sagbakale isuna ati awon abadofin ile-ise ohun sono kan
Bí ó bá sọ òkúta lu arakunrin rẹ̀ tí arakunrin náà sì kú, apànìyàn ni; pípa ni wọn yóo pa òun náà.
ijoba tun n fun awon agbe, kiko ounje wole lati oke okun ko ni pe di ohun
Ṣé ẹ rò pé mò ń parọ́ ni?
Àkọlé àwòrán, Afárá 3rd Mainland: Ìjọba ṣí afárá lẹ́yìn àtúnṣe Kọmisọna fun igbokegbodo ọkọ nipinlẹ Eko, Ọmọwe Taiwo Salaam fidi rẹ mulẹ pe igbesẹ lati ṣi afara naa saaju igba ti wọn fẹẹ ṣi waye lẹyin ti wọn ti pari iṣẹ atunṣe ti wọn se lori afara naa.
 Awon ohun amuyẹ wa l’Ekiti to ti n sọnu ni mo fẹ wqa gba pada bii aṣa itẹriba fagba, aisi iwa ipá ati fif opin si jagidjagan nipinle Ekiti.
Oríṣun àwòrán, INEC Àkọlé àwòrán, Oniruuru iha lawọn eeyan, lẹgbẹlẹgbẹ, ati lajọlajọ ti sọ lori igbesẹ yii Boya ka bi ara wa leere ibeere yii; bawo gan ni Amina Zakari ṣe tan mọ Buhari?
Temilola ri i funra rẹ ṣugbọn Kehinde ko tilẹ ṣakiyesi bi ko ṣe igba ti ọga rẹ kan nile iwe bi i pe ki lo ṣe e nibi to da bii pe eṣo gun un lara.
O ni bi awọn eeyan ṣe n lanfani lati mu ọti wọnyii nigbakugba to ba wu wọn ninu ọra pelebe pelebe ati igo kekeke n ṣe ọpọ akoba fun awujọ paapaa julọ bi iwadii ti ṣe fihan pe awọn eroja yii lo fihan pe ohun lo n ṣokunfa bi awọn eeyan ṣe n mu ọti bi ẹni n mu omi lawujọ.
Mo ti fi ara mi búra, mo sì fi ẹnu mi sọ̀rọ̀ pẹlu òtítọ́ inú,ọ̀rọ̀ tí kò ní yipada:‘Gbogbo orúnkún ni yóo wólẹ̀ fún mi,èmi ni gbogbo eniyan yóo sì búra pé àwọn óo máa sìn.
Baalu ileesẹ ọkọ-ofurufu Saratov Airlines ton lo si igboro Orsk jabo ni abule Argunovo, to to ọgọrin kilomita si guusu ila orun Moscow.
Awọn ileeṣẹ Multi choice to n ṣe BBNaija ti ni ninu ifilọlẹ iṣide eto naa ni wọn yoo ti kede orukó ti BBNaija 2020 yoo jẹ .
 fìlà olófìn-íntótó tilẹ ̀ sí sọ ̀ nù ní ọ ̀ nà .
" Àmọ́ àwọn èèyàn wa kò gbọ́ràn pé, kí wọ́n mase lọ sí ọjà mọ.
Ibinu mi óo jó wọn run bí iná, kò sì ní ṣe é pa.
Ilé iṣẹ́ ọmọogun òfurufú ti bẹ̀rẹ̀ ètò ìgbaníwọlé- Àwọ ìlànà ìforúkọsilẹ̀ rèé Ṣé àbáwọle sójú òpó NPF policerecruitment.
Yau Ma Tei jẹ́ ọ̀kan lára àwọn agbègbè tí èró pọ̀ sí jù lọ ní Hong Kong.
Yoruba wo ló fẹ́ gbé Oduduwa Republic tẹ́ n pariwo?
Ilé aṣòfin Amẹrika gbọnmú lórí ìtìmọ́lé Sowore, ó ní ìjọba Nàíjíríà tako òmìnira aráàlú Mẹ̀kúnnù 80,000 l'Ọṣun ti j'ànfàaní ètò ìlera láìsan kọ́bọ̀ - Oyetola EFCC fẹ́ gbẹ́sẹ̀ lé ilé tí mo fi owó ìfẹ̀yìntì kọ́ nílùú Ilorin- Saraki Ìdájọ́ Dikko bófin mu, kò sẹ́ni tí kò lè bẹ̀bẹ̀ láti dá owó tó jí padà"" Igbakeji aarẹ ile iwosan naa to tun jẹ olori awọn dokita nibẹ, Reginald Blaber sọ pe iru aṣiṣe bayii ko wọ pọ rara."
Aawọ àwọn aṣáájú ẹgbẹ́ méjèèjì yii si wa lara àwọn ohun tó fa rògbòdìyàn àti rukerudo ni ẹkun ìwọ oòrùn gúúsù Nàìjíríà ijọun, èyí tí wọn pe ni 'Wẹtiẹ', nínú èyí tí ọ̀pọ̀ ẹ̀mí ti bọ, tí ọ̀pọ̀ dúkìá bajẹ, tí ẹkùn náà kò sì fararọ.
Ó ṣí ọ̀rọ̀ rẹ̀ payá fún Jakọbu,ó sì fi òfin ati ìlànà rẹ̀ han Israẹli.
Eégún Iwobi jóo re, orí ya Liverpool
"Àwọn èèyàn ń san ìdámẹ́wàá tó ""Heavy"" fún mi ni mo fi ń r'áànú ṣe - Iya Adura Esther Ta ni ó bẹ̀rẹ̀ Fújì?"
Àkọlé àwòrán, Ikọ BBC Yoruba rin kaakiri awọn adugbo bii Ringroad, Mọkọla, Eleyẹlẹ, Iwo Road, Mọnatan ati Iyana Church.
Kónílé-ó-gbélé Covid 19 ló tú àṣírí àwọn àfipábánilòpọ̀ láwùjọ- Mínísítà ọ̀rọ̀ àwọn obìnrin Ọwọ́ ọlọ́pàá tún tẹ afurasí tó fipá bá odi àti adití lòpọ̀ nílùú Ibadan Ẹ fọkàn balẹ̀!
O si ran awọn asofin leti wipe sise ipolongo siga fun awon eniyan tako ofin orillẹede Naijiria lori isakoso taba fifin ti wọn n pe ni (Framework Convention on Tobacco Control (FCTC ) ati ti (National Tobacco Control Act ) tọdun 2015.
Àkókò náà ni ẹni ti ó ṣẹ̀ṣẹ̀ dé yìí sọ fún wa pé ọba ni à ń bá sọ̀rọ̀ àti pé òun ni ẹni tí ń jẹ́ Òmùgọ́diméjì tii ṣe ọba ìlú àwọn Èdìdàrẹ́.
Àyọrísí òdodo yóo sì jẹ́ alaafia,ìgbẹ̀yìn rẹ̀ yóo sì jẹ́ ìbàlẹ̀ àyà wa,ati igbẹkẹle OLUWA títí lae.
Wọn yóo le yín jáde kúrò ninu ilé ìpàdé wọn.
Ẹ̀yin baba, mò ń kọ ìwé si yín, nítorí pé ẹ ti mọ ẹni tí ó wà láti ìṣẹ̀dálẹ̀ ayé.
Bẹẹ ni ko si akọsilẹ fun ẹgbẹ ololufẹ ọkunrin s'ọkunrin.
N óo dárúkọ ẹnìkan fún ọ, ẹni náà ni kí o fi jọba.
Wọn ni o fi ifẹ han lati gba riba ki ẹgbẹ agbabọọlu rẹ le gba bọọlu bi o ti wu wọn ninu idije ni eyi to lodi si ofin FIFA.
Amọ, ijọba ipinlẹ Ọṣun ti ni awọn ko tii gbọ nipa iyanṣẹlodi kankan.
O rọ awọn aṣiwaju ni ilẹ Yoruba lati gbe aṣa ati iṣe Yoruba nitori ibi a gbe laa ṣe.
Wo awọn orile-ede mi tobinrin n dari wọn kan naa ti wọn ko si jajabọ ninu ajakalẹ coronavirus yi.
2019 Prophesies: Kíni ohun tí àwọn ìránṣẹ́ Ọlọ́run sọ nípa ọdún 2019
Biafra at 51: Ikọ̀ Boko Haram, ìbò June 12, ìwọ́de EndSARS wà lára ìṣẹ̀lẹ̀ tí kò bá sọ Nàíjíríà sójú ogun
Bẹẹni awọn osisẹ ti setan lati maa da bi ẹdun, rọ bii owe lori oju opo BBC Yoruba bayi.
Òun ni yóo ṣáájú Oluwa pẹlu ẹ̀mí Elija ati agbára rẹ̀.
Lo ba ri ọkunrin kan lara awọn to n ko ẹru ninu ọkọ ofurufu, to pee pe ko wa ran oun lọwọ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ọ̀dọ́kùnrin tó kọ́kọ́ ṣe ẹ̀rọ tó ń tu ìyẹ́ lára adìyẹ Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
"O ni ""lọna kinni, o yẹ ki ijọba ṣe ohun ti awọn eeyan n bere, lẹyin naa, o yẹ ki a bẹrẹ atunto ilu yii ni kiakia."
Stingy Men Association: Ojú òpó Twitter ń ṣọkutu wọ̀wọ̀ pẹ̀lú ọ̀rọ̀ àwọn ọkùnrin ahun
Ogunsola dagbere faye lọdun 1992 lẹni aadọta ọdun, to si fi ọpọ iyawo ati ọmọ saye lọ.
Eeyan eeyan ọrinlelugba o le ẹyọkan lo ko aarun naa lọjọ Iṣẹgun.
"O ni ""Ọkọ ofurufu akọkọ ti yoo ko ookolelọọdunrun eeyan yoo gbera laago mesan aarọ, nigbati abala keji yoo gbera lọjọbọ."
Bẹẹ naa si lo ka iwe kun iwe sii loke okun.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Zlatan: Ọ̀rẹ́ ni mo sìn lọ ‘studio’ tí mo fi bẹ̀rẹ̀ orin lẹ́yìn tí mo kùnà ìdánwò WAEC Igun mejeeji si lo pada gba pe ko ni dara ki wọn se agbekalẹ isuna fọdun to n bọ ti yoo nira lati se amusẹ rẹ, tile asofin si yọ owo gbese to ni oun fi sori aba isuna ọhun, eyi to mu ko ga soke.
Ifigagbaga lati di olori ile si wa laarin olori ọmọ ẹgbẹ oselu to pọ julọ nile asofin Kẹjọ, Femi Gbajabiamila ati Umar Bago.
Àwọn ẹ̀tọ́ wọnyi kò tọ́ si àlejò, ẹni ti ó fi èrú wọ ilú ti kò ni àṣẹ igbelu, tàbi ẹni tó ni iwé lati ṣe iṣẹ ṣùgbọ́n ko ti i di ará ilú.
Ọkunrin naa, Feyisola Dosumu to ti na papa bora fun ọjọ melo kan naa ni wọn ti n wa kiri.
DR Congo Ebola: Òṣìṣẹ́ ìlera méje kú torí ibínú àwọn èèyàn nípa Ebola
Ariwo Ali Must Go lo gba ilẹ kan, ti ilu ko si fararọ rara lasiko ifẹhonuhan awọn akẹkọọ naa.
 O ni mo kere diẹ laisko Idi Ami ṣugbọn ọpọlọpọ awọn akẹgbẹ mi lo padanu awọn obi wọn nigba naa.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ẹgbọ́n olóògbé Suga: Wọ́n yìnbọn fún Suga lójú mi, n kò sì lè dá wọn dúró @TopsyAshaolu ti iṣẹlẹ ọhun ṣoju rẹ ni awọn oṣiṣẹ ajọ to n ri si iṣẹlẹ pajawiri ko tete debi ti ile naa ti da wo lulẹ.
5 147860 Orilẹede Guatemala 5151 29.
Wọn sọ fun pé Uwa ko ti i da pada, pe ko lọ wo boya o si n kawe lọwọ tabi o ti mu kọkọrọ lọ sile.
Ẹgbẹ agbabọọlu Super Eagles Naijiria lo gba ipo kẹta ninu idije 2019 AFCON ti waye lorilẹede Egypt.
#JusticeFor Chima: Àgbáríjọ àwọn ajàfẹ́tọ̀ọ́ pè fún ìdádujro Kọmisọna ọlọpàá
Ogbeni Clement Oladele to jẹ ọga agba ileeṣẹ ẹ̀ṣọ́ ààbò ojú pópó ti fìdí ẹ múlẹ̀ pé Adesanya, ọ̀rẹ́ gomina Amosun ti jáde láyé nígbà tí Adeoluwa, akọ̀wé ìpínlẹ̀ Ogun wà nílé ìwòsàn.
Àkọsílẹ̀ gbogbo nǹkan yòókù tí Jehoiakimu ṣe ati gbogbo ohun ìríra tí ó ṣe, ati àwọn àìdára rẹ̀ wà ninu Ìwé Ìtàn Àwọn Ọba Israẹli ati ti Juda.
Bí wọn kò bá gba àwọn àmì mejeeji wọnyi gbọ́, tí wọ́n sì kọ̀, tí wọn kò gbọ́ ọ̀rọ̀ rẹ, lọ bu omi díẹ̀ ninu odò Naili kí o sì dà á sí orí ìyàngbẹ ilẹ̀; omi náà yóo di ẹ̀jẹ̀ bí o bá ti dà á sí orí ìyàngbẹ ilẹ̀.
Ọwọ́ rẹ̀ tẹ ọdọmọkunrin ará Sukotu kan, ó sì bèèrè orúkọ àwọn olórí ati àwọn àgbààgbà ìlú Sukotu lọ́wọ́ rẹ̀.
A dúpẹ́ lọ́wọ́ Ọlọrun, Baba Jesu Kristi Oluwa wa, tí ó fi ọ̀pọ̀ àánú rẹ̀ tún wa bí sí ìrètí tí ó wà láàyè nípa ajinde Jesu Kristi kúrò ninu òkú.
Aare soro yii lasiko to n ba
Ṣugbọn bí ó bá jẹ́ ọwọ́ Ọlọrun ni mo fi ń lé ẹ̀mí èṣù jáde, a jẹ́ pé ìjọba Ọlọrun ti dé ba yín.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Coronavirus in Nigeria: Ìwádìí fihàn pé ọ̀pọ̀ aráàlú ni kò gbà pé àrùn Covid-19 wà Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Coronavirus in Nigeria: Ìwádìí fihàn pé ọ̀pọ̀ aráàlú ni kò gbà pé àrùn Covid-19 wà 10 Agẹmo 2020 Arun Coronavirus ti n ba gbogbo agbaye finra lati bii osu meje sẹyin, ti ọpọ eeyan si ti jade laye lati ipasẹ arun naa.
Iru ọdun to yọ awọn obinrin silẹ yii ni ọdun oro jẹ ọkan ninu wọn nitori igbagbọ Yoruba ni pe obinrin kii fi oju kan oro, bibẹẹkọ, oro yoo gbe.
"Oun si lo kẹyin awọn eeyan to n sa lọ naa, ti Sabitu si n pariwo pe ""Eji Gbadero mo ri ẹ o, ara abule, Eji Gbadero ti pa mi lọkọ ó."
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Thanksgiving Trump: Aàrẹ Trump kọ̀ láti jẹ Tọkí ìsìn ìdúpẹ́ 2019 nílé, ó gba Afghanista lọ!
“Ni kete ti mo ba jawe olubori gege bi gomina ipinle Osun, Ma a se agbekale eto lolokan-o-jokan ni erongba lati mu iyipada otun ba eto oro aje ipinle wa yii,”Bakan naa, Ma a koju iwa ibajẹ, bee si ni maa fopin si lilo owo ilu lona aito, eleyi ti o n dena idagbasoke ipinle yii.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Kére o!
 O wa pe fun ironilagbara fun osise olopaa lati le sisẹ wọn bi isẹ, ki awọn eniyan ipinle Oyo le sun fori lejika.
Ní òwúrọ̀ kutukutu ọjọ́ keji, Elikana ati ìdílé rẹ̀ múra, wọ́n sì sin OLUWA.
Èmi tí mo fi iyanrìn pààlà fún omi òkun,tí òkun kò sì gbọdọ̀ rékọjá rẹ̀ títí ayé!
Adepoju Ademola, Geoffrey Onyeama ati minisita fun oro to je mọ ile okeere fun orile ede  Angola , Manuel  Augusto, lọjọRu niluu Abuja.
Ifẹ̀họ̀núhàn ń lọ lọ́wọ́ ní Belarus lẹ́yìn tí ìdìbò tùn gbé Ààrẹ̀ Lukashenko tó ti wà nípò fún ọdún 26 wọlé Dẹ́rẹ́bà kẹ̀kẹ́ Maruwa rí ẹ̀wọ̀n gbére he lẹ̀yìn tó fi ipá bá ọmọ ọdún mẹ́rìnlá lòpọ̀ Àjọ JAMB kéde ìlànà ìgbà ni wọlé tuntun fún àwọn ilé ẹ̀kọ́ gíga Ọwọ́ ikọ̀ aláàbò STF tẹ afurasí mẹ́jọ tó lọ́wọ́ nínú ìpànìyàn lemọ́-lemọ́ọ Gúúsù Kaduna O bẹrẹ ileewẹ alakọbẹrẹ ni Goat Primary School, to wa lagbegbe Koki, lẹyin naa lo ṣe idanwo onipele ikẹta akọkọ ni GATC ni Gwale.
bí ó tilẹ ̀ jẹ ́ wí pé kì í ṣe ipa àtàtà ni ó ń kó nínú orúkọ gidi , oríkì máa ń sáábà jẹ ́ lílò ní ẹ ̀ gbẹ ́ kan , ó máa ń sáábà jẹ ́ ohun tí gbogbogbò mọ ̀ mọ ̀ ọ ̀ yàn ní àkókò kan.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Child Labour: Fífi ọmọ ṣòwò wọ́pọ̀ ní Naijiria Lo Wi-Fi fún àwọn ǹkan to ba gba dátà púpọ to ba fẹ se lori ayelujara, bí àpẹrẹ gbígba máàpù tí kìí jẹ dátà tàbí o fẹ jẹ ki àgbéga bá àwọn 'áàpù' ti ó wà ló ẹ̀rọ alágbeka rẹ Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Data Usage: Ọ̀nà márún-ún láti mú àdín kù bá dátà (Data) rẹ̀ lílò Wíwo fọ́ràn pẹ̀lú dátà rẹ kìí ṣe eyí to le sànfani fún dátà rẹ.
Ọkunrin kan wà ní ìlú Maoni tí ń ṣe òwò ní Kamẹli.
Ọmọ bíbí ìpínlẹ̀ Ekiti ni Odunlade.
" Abiola Ajimọbi, gomina ipinlẹ Ọsun iwọ oorun gusu orilẹede Naijiria.
Eyi lo jẹ ki ọpọ ọmọ Kaarọ Oojire yan orin rẹ ni aayo, paapaa awọn obinrin to n ta ọti bia ni ilu Abẹokuta ati Mushin.
Ó kọ àṣẹ náà sílẹ̀ báyìí pé:
Nítorí náà láàrin ẹgbẹẹgbẹrun àwọn ọmọ Israẹli, ẹgbaafa (12,000) ọkunrin ni wọ́n dájọ láti lọ sójú ogun, ẹgbẹẹgbẹrun láti inú ẹ̀yà kọ̀ọ̀kan.
Ọmọbinrin náà bá gbé e lọ fún ìyá rẹ̀.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ooni: Mo ti fi ọ̀rọ̀ obinrin tó ń parọ́ ìfẹ́ mọ́ mi sun agbófinró Gbogbo wọn pata ni Kabiesi wure ipese fun pe onikaluku a jere iṣẹ ati làálàá wọn lori awọn ọmọ yii.
Wọn da iṣẹ Hajj duro laarin ọdun 1837si 1858 nitori ajakalẹ aarun bakan naa.
Wọnyi ni awọn ohun to ṣẹlẹ lọsẹ yii lagbo awọn oṣere tiata Yoruba lọsẹ yii.
Kingston lọmọ Áfíríkà tó gba ohun tí Hulk Hogan kò rí gbà Òkè òkè ní Barcelona lè téńté lórí àtẹ La liga Kìnìhún joko jẹ ẹran ara afurásí ọdẹ tí kò gbààyè kó tó ṣọdẹ Dangote: Mo ti gbà $10m ri ní bánkì kí n lè mọ bí o tí ṣé rí lójú Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ayekofẹnifọrọ: Ó yá, ẹ fi àmì sórí ọ̀rọ̀ náà.
Bẹrẹ lati ọjọ kini oṣu Kẹfa, ijọba ibilẹ yoo ma gba owo wọn lọtọ ti ijọba ipinlẹ ko si ni le ma la lewọn lọwọ lori owo naa.
 Àwọn ìlú tí wọn tí ń sọ ẹ ̀ ka-èdè Ìgbómìnà ní ìpínlẹ ̀ Ọ ̀ ṣùn ní ìlá Ọ ̀ ràngún Òkè-Ìlá àti Ọ ̀ rà .
Ṣebí òkùnkùn ni ọjọ́ OLUWA, kì í ṣe ìmọ́lẹ̀!
Èṣù-ú pàápàá wà, Ẹlẹ́gbára náà sì wá pẹ̀lú.
Awọn wọnyi lo ni wọn pọ ninu ẹgbẹ National Liberation Front eyi ti o ti n ṣakoso Algeria bọ lati ọdun 1962 ti Algeria ti gba ominira lọwọ ilẹ Faranse.
Nollywood: Bẹbẹ ń lọ ní ibùdó yíya sinimá Àgbésọrísùn
Farao bá fi jẹ gomina lórí gbogbo ilẹ̀ Ijipti ati lórí ààfin ọba.
Ó ti pẹ́ tí Alaa ti ń ṣiṣẹ́ lóríi ìjìnlẹ̀ ìmọ̀-ẹ̀rọ àti òṣèlú pẹ̀lú ìyàwóo rẹ̀, Manal Hassan.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Mínísítà fọ́rọ̀ obìnrin fẹgbẹ́ APC sílẹ̀ pẹ̀lú ìbànújẹ́ Taa ni Jọkẹ Silva, òsèré tíátà tó ń se ọjọ́ ìbí ?
Wo ti Abrahamu, ati Isaaki, ati Israẹli, àwọn iranṣẹ rẹ, àwọn tí o ti fi ara rẹ búra fún pé o ó sọ arọmọdọmọ wọn di pupọ gẹ́gẹ́ bí ìràwọ̀ ojú ọ̀run; o ní gbogbo ilẹ̀ tí o ti ṣèlérí ni o óo fi fún àwọn arọmọdọmọ wọn; ati pé àwọn ni wọn yóo sì jogún rẹ̀ títí lae.
Imọran pataki ni pe ki o ranti fọ ọwọ rẹ daadaa ti o ba ti fi ọwọ kan ata nitori ata kii ṣe ọrẹ oju.
A óò wá àwọn ọmọ ilẹ̀ Turkey mẹ́rin tí wọ́n jígbé rí láàyè- Ọlọ́pàá Kwara Ọlọ́pàá kó àwọn ọmọ ẹgbẹ́ òkùnkùn Ẹiyẹ Confraternity ni Ikorodu Ọlọ́pàá Ogun gb'ọmọ Ìmáàmù lọ́wọ́ ajínigbé, ṣùgbọ́n wọ́n gbé ọkọ̀ ojú omi ọlọ́pàá lọ Gbàgbé ẹ̀sọ́ ara $40m rẹ pátápátá - Ilé ẹjọ́ sí Dienzani Ogbeni Maruf ni: ''Looto la ni erongba lati san owo fawọn ajinigbe naa ṣugbọn ki a to san owo naa lawọn agbofinro tu wọn silẹ'' O ṣalaye pe awọn eeyan meje ni wọn ribi doola ẹmi wọn ti a si ri ọmọ bibi ilu Offa ninu wọn.
 Bush, bee si ni O je iya aare mẹ́tàlélógójì  orile-ede Amerika, George W.
Ilana ofin naa fi lede pe awọn akẹkọọ gbọdọ tẹle ofin ijinasiraẹni pẹlu mita meji ni gbogbo ileewe kaakiri Naijiria.
 Elebuibon tẹsiwaju pe, awọn obi obinrin lo yẹ ki ọkunrin dọbalẹ fun lati beere pe ,oun fẹ fi ọmọ wọn ṣaya, kii ṣe obinrin naa."
Sudan protest in pictures: Bó ṣe ń lọ lórílẹ̀èdè Sudan
ninu eto idibo gomina ati igbimo asofin ti ipinle .
Ninu ikini naa, Buhari sọ pe ki gbogbo ọmọ Naijiria fi awọn nkan rere ti ọdun Keresimesi duro fun han ninu iwa wọn.
Mọ́ngòrò nìkan ni wọ́n fún mi jẹ ní àhámọ́ ajínigbé -Olùdarí eré Kannywood Mo fẹ́ di obinrin to dára júlọ lágbàyé-Bobrisky Ṣé Fulani daran-daran ni àwọn tó n jí ènìyàn gbé ní ìpínlẹ̀ Ondo?
Àwọn alárìíyá máa ń gba títì kan ní ọdọọdún fún Ijó ìta-gbangba Ijó ìta-gbangba Trinidad àti Tobago, tí wọn ń ṣe pẹ̀lú orin.
Opin Zuma: ANC se'pade lori aarẹ ANC fẹ yọ Zuma Lọpọ igba ni aarẹ Zuma ti kọ jalẹ lati kọwe fipo silẹ lori ẹsun iwa ibajẹ ati lilu owo ilu ni ponpo.
Sẹnetọ Ajimobi pẹlu gomina tẹlẹ nipinlẹ Oyo, Alao Akala lasiko ti wọn jọ n ṣe awada Oríṣun àwòrán, Twitter/ajimobi Àkọlé àwòrán, Sẹnetọ Ajimọbi lasiko to n gbe opa aṣẹ fun ọkan lara awọn agba oye mọkanlelogun ilẹ Ibadan to gbe soke di Ọba Oríṣun àwòrán, Twitter/abiola ajimobi Àkọlé àwòrán, Abiola Ajimobi pẹlu aṣiwaju Bola Ahmed Tinubu, agba ẹgbẹ oṣelu APC.
”Obinrin náà dáhùn pé, “Ọkunrin arúgbó kan ló ń bọ̀, ó sì fi aṣọ bora.
Ilé Olukuoye ni Oluyole ti wa, láti ara ọmọba Agbonyin to jẹ ọmọ aláàfin Abiodun, ẹni tii se Alaafin to jẹ́ pé oun níkan lo bori Basorun Gaa lásìkò Oyo atijọ.
Ẹni tí ó bá gbà mí gbọ́, bí ó tilẹ̀ kú, sibẹ yóo yè.
Ìgbésẹ̀ àti yọ Dino: èèyàn péréte ló kópa.
Ó wí fún Sara náà pé, “Mo ti kó ẹgbẹrun (1,000) owó fadaka fún arakunrin rẹ, èyí ni láti wẹ̀ ọ́ mọ́ lójú gbogbo àwọn tí wọ́n wà pẹlu rẹ, nisinsinyii, o ti gba ìdáláre lójú gbogbo eniyan.
Kọ́lá Akínlàdé ní ìyàwó ó sì bí ọmọ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Genotype: Kí làwọn àǹfàni àti ewu tí ẹ̀yà jínótáìpù rẹ le mú bá ìgbé ayé rẹ̀ Gẹgẹ bi Dokita Muhammad Gidado Fari ti wi, wọn ti da ọmọ naa silẹ nile iwosan ṣugbọn wọn yoo tun pada wa lọjọ kọkandinlọgbọn oṣu kẹfa.
Ẹ jẹ́ kí á fẹjọ́ rẹ̀ sùn.
43 Èmi kì yíò fi ààyè sílẹ̀ pé kí wọn ba iṣẹ́ mi jẹ́; Bẹ́ẹ̀ni, èmi yíò fi hàn sí wọn pé ọgbọ́n ti èmi ga ju àrékérekè ti èṣù lọ.
Wọn n beere pe níbo ní Leah Sharibu, ti wọ́n jígbé lásìkò ti àwọn ọmọ Dapchi ti wọ́n sì kọ̀ láti tu sílẹ̀ nítorí, ó kọ̀ láti ju ìgbàgbọ́ rẹ̀ nínú ẹ̀sìn krìstẹ́nì nù.
Lẹyin naa lo tun gbinyanju lati du ipo gomina ipinlẹ Oyo lọdun 2007 labẹ ẹgbẹ oselu ANPP, amọ, to fidi rẹmi, Ṣugbọn wọn ni ẹṣin kii da ni, ka ma tun un gun, Abiola tun gbinyanju lẹẹkan si lati du ipo gomina losu kẹrin, ọdun 2011, to si yege.
Lagos Kidnap: Ọwọ́ ọlọ́pàá tẹ afurasí méjì tó nííṣe pẹ̀lú ìjínígbe Ọgá panápaná l'Eko
 Ẹni èkejì ni john mccain .
Obìnrin k'óbìnrin tó bá yan Abiola Ajimọbi l'álè, ajẹ kù mi ló ń jẹ-Florence Ajimọbi Florence Ajimọbi to jẹ aya gomina ana ni ipinlẹ Ọyọ, Abiọla Ajimọbi ti ṣalaye pe igba meji ọtọọtọ loun ti ka ọkọ oun mọ ale yiyan.
O ni : “omo egbe  APC to ba tapa si ilana ti egbe APC ba la sile
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Chelsea lu West Brom pẹlu ami ayo mẹta s'odo 13 Èrèlè 2018 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Chelsea lu West Brom pẹlu ami ayo mẹta s'odo Ẹgbẹ agbabọọlu Chelsea pada s'oju agbami jija'we olubori ninu idije Premier League pẹlu bi wọn se lu ẹgbẹ agbabọọlu West Bromwich Albion pẹlu ami ayo mẹta si odo ni papa isere Stamford Bridge.
Jehoṣafati kú, wọ́n sin ín pẹlu àwọn baba rẹ̀ ninu ibojì àwọn ọba ní ìlú Dafidi.
Ẹ óo sì mọ̀ pé èmi ni OLUWA.
Ohun marun t'ejo n jẹ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ejo abami to n mu owo ni ajọ Jambu Iru ejo to bu obinrin naa jẹ, 'Carpet pythons', ko ni oró lara, botilẹ jẹ wi pe awọn onimọ iṣegun oyinbo sọ pe ki iru ẹni bẹ ẹ gba abẹrẹ kokoro tetanus.
Bí wọ́n ti ń bá Hamani sọ̀rọ̀ lọ́wọ́ ni àwọn ìwẹ̀fà ọba dé láti yára mú un lọ sí ibi àsè Ẹsita.
” Mose bá ṣe bẹ́ẹ̀ níwájú gbogbo àwọn àgbààgbà Israẹli.
 a mẹ ́ nu bà á pé àwon nnkan wònyí kìí hànde bákan náà , sùgbọ ́ n ó lè gbọ ́ n fara sin sínú àwon kóòdù mofọ ́ lójì nínú ọ ̀ rò náà , ní àwon àyíká tí a kò funra sí .
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Osisẹ Jamb: Ọga mi lo mi 36m, kii se ejo 6 Ẹrẹ̀nà 2018 Àkọlé àwòrán, Ohun abami ni kii ejo o maa jẹ owo Ajọ to n gbogun tiwa jẹgudujẹra lorilẹede Naijiria, EFCC ti sọ wipe osisẹ Jamb to ni ejo gbe owo toto miliọnu mẹrindinlogoji naira to jẹ ti ajọ Jamb, Philomina Chieshe ti nkawọ pọnyin rojọ lori ẹsun irọ pipa ti ajọ Jamb fi kan an.
Ṣugbọn, ó ṣeéṣe pé aadọta tí mo wí lè dín marun-un, ṣé nítorí eniyan marun-un tí ó dín, o óo pa ìlú náà run?
Akoko mẹjọ ti ẹnu kun Abiola Ajimobi lori ipo gomina: Oríṣun àwòrán, Abiola Ajimobi Igba to wo isọ ati ile lulẹ kaakiri ipinlẹ Ọyọ: Ni saa akọkọ gomina Abiola Ajimobi lo wo awọn sọọbu kan to wa lẹba oju popo yika ipinlẹ Ọyọ, paapa nilu Ibadan.
"Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Coronavirus in Nigeria: Báyi ni ẹ ṣe leè ṣe ""hand sanitizer"" nínú ilé yín Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Coronavirus in Nigeria: Báyi ni ẹ ṣe leè ṣe ""hand sanitizer"" nínú ilé yín 29 Ẹrẹ̀nà 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 10 Ìgbé 2020 Lati igba ti arun Coroavirus ti bẹ silẹ lorilẹ-ede China lọdun 2019, arun naa ti rapala wọ ọpọlọpọ orilẹ-ede l’gbaye, ti ilẹ Naijiria ko si gbẹyin."
Awọn ipinlẹ wọnyii ni awọn janduku ti lọ ji ounje iranwọ Covid-19 ko.
Yemi Blaq: Ìyàwó mi lọ́wọ́ sí kí n fẹnuko obìnrin míì lórí ìtàgé
Ọmọ ilẹ̀ Italy tó kó Coronavirus wọ Naijiria kò ní àrùn náà mọ́ Kò tíì sí àrùn Coronavirus ní ìpínlẹ̀ Oyo, a ṣi ń retí èsì àyẹ̀wò - Ijọba Oyo Wo ohun tó mú kí Ṣèyí Makinde ó tẹ̀síwájú pẹ̀lú ìpàdé ìtagbangba níbàdàn láàrín ìṣẹ̀lẹ̀ àrùn Coronavirus Ẹgbẹ CAN tun wa rọ awọn ijọ lati pese ọṣẹ ati omi si ile ijọsin wọn fun imọtoto awọn eeyan, ati pe ki wọn gbiyanju lati jina diẹ si ẹnikẹni to ba n sin, tabi wukọ.
Lọdun 2017 ni wọn di ilumọọka nigba ti wọn gba ami ẹyẹlati lọ kopa ninu idije agbaye kan ni Amẹrika.
''O fihan gbangba pe awọn ọdọ asiko yii ko ni tẹriba fun iwa agidi ti ijọba ma n lo pẹlu awọn eniyan nigbakan ri.
Ni alẹ ọjọ igbeyawo wa, ẹru n ba mi nigba ti mo ri ọkọ mi to n bọ ara silẹ, kia si lo gun ori mi, to n se nkan to fẹ se lai fẹ mọ boya o dun mọ mi ninu.
Awon musulumi lorile ede Naijria ti bẹrẹ awẹ Ramadhan tọdun 2019,lọjọ kẹfa ,Aje (Monday)osu karun un ti a wayii.
Àwọn ìròyìn mìíràn tí ẹ lè nífẹ̀ẹ́ sí: Oun tí ẹ lè má mọ̀ nípa Omar al-Bashir, olórí Sudan ti wọ́n yọ nípò Pápà mímọ́ gbarata lóríi ìpànìyàn Benue Póòpù rán aṣojú lọ́ fún ìsìnkú Benue Àwọn Bísọ̀ọ̀bù Aguda figbeta lóri ìtàjẹ̀ sílẹ̀ Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí kan sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
Ṣugbọn Basilai dáhùn pé, “Ọjọ́ tí ó kù fún mi láyé kò pọ̀ mọ́, kí ni n óo tún máa bá kabiyesi lọ sí Jerusalẹmu fún?
Iyẹn lo mu ki Muyiwa Ademola ṣi wa nile iwosan.
Mo ké pè ọ́, OLUWA,mo ní, “Ìwọ ni ààbò mi,ìwọ ni ìpín mi lórí ilẹ̀ alààyè.
Jerusalẹmu, ìṣekúṣe ti dípẹtà sinu rẹ, mo fọ̀ ọ́ títí, ìdọ̀tí kò kúrò ninu rẹ, kò sì ní kúrò mọ́ títí n óo fi bínú sí ọ tẹ́rùn.
O ni awọn oyinbo amunisin Gẹẹsi, pẹlu ibẹru pe ẹya to kawe gidi ni ẹya Yoruba, wọn si sa gbogbo ipa nigba naa lati tẹri rẹ ba.
O kere tan eniyan mọkanlelogun lo ti gbe ẹmi mi latari otutu ati yinyin arọọrọda, iru eleyi ti wọn ko ti ri ri lati bi ogun ọdun sẹhin to gbalẹ kan ni ilẹ Amerika.
Flying Eagles fàtòrì já ewé bọ̀wọ̀ fágbà 4-0 fún ikọ̀ Qatar
Bakan naa, o mẹnu ba pe ẹtọ ti aarẹ ni lati yan pe oun fẹ farahan niwaju ile aṣofin lati ba wọn sọrọ torinaa ki ile aṣofin maa pe aarẹ lẹjọ tabuku ba ipo aarẹ.
Oríṣun àwòrán, Instagram/EFCC Nigeria Jamiu ni oun fẹ ba eebo Kọraa naa gba aṣẹ lọwọ ajọ elepo rọbi NNPC, lati maa ra epo rọbi ni Naijiria.
Nigba ti o n ka koko ọrọ ipade apero naa fun ti saa yii, ti wọn pe akori rẹ ni: “Nigbaradi fun Eto Idibo ti yoo waye ni irọwọ Irosẹ, ti yoo si jẹ Ojulowo”  Aṣofin Braimoh ṣalaye pe erongba Ile Igbimọ Aṣofin yii ni lati tubọ le jẹ ki awọn ara ilu le mọ riri eto idibo ninu iṣakoso Ijọba Tiwa-n-tiwa, paapaa lojuna ati ṣaṣeyọri ninu eto idibo ọdun 2019.
Wọ́n ti gb’owó ẹ̀yìn lọ́wọ́ àlejò.
Adepero Oduye: Oríṣun àwòrán, Twitter/Adepero Oduye Àkọlé àwòrán, O je ọkan lara awọn ọmọ meje ti awọn obi rẹ bi.
O ni ọpọ ninu awọn dokita ati nọọsi naa ni ẹru n ba lati ṣe ojuṣe wọn lẹnu iṣẹ.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Njẹ́ Naijiria buyì kún D'Tigress tó?
O tun sọ pe awọn ti kii ti ẹ sọ sita, tabi lọ si ileeṣẹ ọlọpaa ti iru nkan bẹ ẹ ba ṣẹlẹ si wọn, pọju awọn to n sọ sita lọ.
7 220707 Orilẹede Honduras 3335 34.
naa  fun ipese eto alaafia ti won gunle
Queen Salawa Abẹni sọ pe ''ẹbun lorin kikọ fun emi, Ọlọrun lo fun mi.
"Wo àwọn nkan tó yẹ́ kí o mọ̀ nípa 'Awawa Boys', ọ̀kan lára ẹgbẹ́ òkùnkùn tó n dá Eko rú Ìjọba Nàìjíríà ti parí ìwádìí lórí àgbo Covid-Organics ti Madagascar kó ránṣẹ́ sí i Wo àwọn òṣìṣẹ́ kólẹ̀-kódọ̀tí tó ń fi ẹ̀mí wọn wéwu kí Abuja leè mọ́ tónítóní Ọkùnrin kan pa ara rẹ̀ sínú ọgbà àjọ TRACE tó n mójútọ ìrìnnà ọkọ̀ nípìnlẹ̀ Ogun ""Ohun gbogbo da bii adapọ aidunu, ireti, ibinu koda to fi mọ igbagbọ pe ohun gbogbo ṣi maa dara"", Reme sọ fun BBC."
 nicholas hospital , lagos àti cathedral of the holy cross , lagos .
Jíjogún ìṣẹ́ Àwọn onímọ̀ ti sàlàyé pé, iṣẹ́ àti òṣì ti ìdẹnukọlẹ̀ ètò ọ̀rọ̀ ajé yìí yóò dá fún ẹbi míràn, ìran wọ́n kò ni lè san tán.
Oríṣun àwòrán, @PoliceNG Wọn fikun pe eyi kun ara ọna ti wọn fẹ gba lati dẹkun gulegule awọn to n da omi alaafia ilu laamu lẹkun yii.
Nítorí náà OLUWA ní, “Bí o bá yipada, n óo mú ọ pada sípò rẹ, o óo sì tún máa ṣe iranṣẹ mi.
Ṣé ó lè máa yọ̀ nígbà náà?
Buhari bowo lu ni : Police Trust Fund Act, Nigeria Natural Medicine
"Oríṣun àwòrán, Doris_Simeon Bí o ṣe lè forúkọ silẹ̀ fún ètò ""N75BN Nigerian Youth Investment Fund"" rèé."
Nítorí ẹ̀ ń di ẹrù bàràkàtà-bàràkàtà lé eniyan lórí nígbà tí ẹ̀yin fúnra yín kò jẹ́ fi ọwọ́ yín kan ẹrù kan.
Fasola so pe gbigbe ọkọ agbepo rẹ soju titi to jẹ maroṣẹ tako ofin irinna ajọ FRSC Naijiria.
Naming of Railway stations in Nigeria: Afenifere, YCE, Akitoye, Fani-Kayode ní ẹ̀tanú Obasanjo ni Buhari ṣe
Gbajabiamila ti ni oun ko lee san gbese ti oun jẹ asiwaju Bola Tinubu tan ,fun
Wọn yóo dàbí irúgbìn tí gbòǹgbò rẹ̀ wọnú ilẹ̀ lọ tí ó sì ń so èso jáde.
24 usd fún ìda ́ kan ní bí ọdún 2014 .
Aarẹ Naijiria fẹ ẹ lo papa iṣere naa, ni wọn n sọ awawi oriṣiriṣi bayii.
Ẹ gbọ́ ohun tí OLUWA sọ nípa àwọn wolii tí wọn ń ṣi àwọn eniyan mi lọ́nà, tí wọn ń kéde “Alaafia” níbi tí wọ́n bá ti ń rí oúnjẹ jẹ, ṣugbọn tí wọn ń kéde ogun níbi tí kò bá ti sí oúnjẹ.
Oríṣun àwòrán, @BashirAhmaad Àkọlé àwòrán, Àjọ WAEC ṣàfihàn ìwé ẹ̀rí girama Ààrẹ Muhammadu Buhari Ohun ti Buhari sọ nigba naa ni pe ọwọ ileeṣẹ ologun ni iwe ẹri oun wa, ti awọn eniyan si n sọ pe to ba jẹ lootọ ni, ki ileeṣẹ ologun fi sita.
tí ń gba owó èlé; ǹjẹ́ irú eniyan bẹ́ẹ̀ lè yè?
Bótilẹ̀ jẹ́ pé kò wọ́pọ̀ ṣùgbọ́n ti ènìyàn ba jẹ Nutmeg púpọ o le ja si ikú.
' 'Mo ti gbà pé lóòtọ́ ni ọmọ mi ní àárùn ọpọlọ Obìnrin míì tún ti kú lórí ìṣẹ́ abẹ ìdí ńlá Orilẹede Naijiria naa darapọ mọ gbogbo eeyan lagbaye lati sayẹyẹ ayajọ ọjọ ọmọbinrin.
Àmọ́ Adájọ́ Akinlade fún àwọn olujẹjọ márùn-ún yòókù tó ń jẹjọ pẹ̀lú Arogundade ni ìdáǹdè lórí ẹ̀sùn onikoko méjì, tí wọn fi kan wọn.
Nígbà tí Jakọbu gbọ́ pé oúnjẹ wà ní Ijipti, ó kọ́kọ́ rán àwọn baba wa lọ.
Ṣugbọn, lasiko ti wọn fi ọrọ wa lẹnuwo ni wọn ni obinrin naa pada yi ọrọ pada, to si ni pe ọmọ ọdọ oun ati obinrin kan, Joan Asen lo lo agbara airi lati ji owo naa gbe ni ibudo ti wọn ko owo naa pamọ si.
“Nitori naa,a n ro ijoba orile ede Britain lati  se iwadii gidigidi lori iku gbigbona ti won fi pa omokunrin orile ede Naijiria yii, ki won si ri I pe won fi iya to to je awon odaran naa gege bi ofin se laa sile”.
(Ìdámẹ́ta yóo máa ṣọ́ ẹnu ọ̀nà Suri; ìdámẹ́ta yòókù yóo máa ṣọ́ ẹnu ọ̀nà tí ó wà lẹ́yìn àwọn tí wọn ń ṣọ́ ààfin), wọn yóo dáàbò bo ààfin.
Nítorí wọ́n ti tọ̀ wọ́n lọ bí àwọn ọkunrin tí ń tọ aṣẹ́wó lọ.
Tamari dáhùn pé, “Rárá, má fi ipá mú mi, nítorí ẹnìkan kò gbọdọ̀ dán irú rẹ̀ wò ní Israẹli, má hùwà òmùgọ̀; 
Ọmọ ọdún mẹ́wàá ń fọn fèrè lágbo àríyá Ìtàn ọmọ Afirika tó ló lówó jùlọ lágbàyéé rèé O ni awọn fọwọsi aarẹ Muhammadu Buhari lasiko eto idibo to kọja lai naani awọn aise deede ẹgbẹ oselu APC to n sejọba lọwọ, nitori ilọsiwaju ilẹ Naijiria ni.
 O tesiwaju pe egbe APC ti pinnu lati pe ipade gbogbogboo, ni eyi ti won yoo dibo lati yan awon igbimo alakoso egbe APC  ni  eka  ijoba apapo, ipinle ati ibile.
Amọ adari ile isẹ naa, Yaroslav Goncharov sọ fun BBC pe awọn ko lo fọto awọn eniyan lati ori ẹrọ ibanisọrọ wọn, wọn ni awọn n lo eyi ti wọn ba fi si ori ẹrọ wọn lati fi pamọ.
Ijoba orile-ede Naijiria ti pase fawon osise eleto ilera lati bere ayewo ni kikun fun gbogbo awon arinrinajo to n wo Naijiria bayii fun arun ebola.
O fikun wi pe ti ko ba fipo rẹ silẹ,a jẹ wi pe wọn fẹ lo o lati yii ibo ati lati tẹ ika lọna ẹburu.
Lẹhin ọ̀pọ̀lọpọ̀ ọdún, Bàbá re ibi àgbà nrè, ó ku.
Awọn ẹsun ti wọn fi kan Fayoṣe ni gbigba oniruuru owo lọna ti ko bofinmu, gbigba owo ẹyin lọwọ awọn ileeṣẹ kan ati fifi owo ilu ra ile kaakiri awọn agbegbe kan lorilẹede Naijiria.
Kii ṣe ani-ani mọ pe awọn eeyan ni ipinlẹ Ọyọ n se gbọnmọgbọnmọ fifi idajọ afurasi sọwọ ara wọn, eleyi to si ti n kọ ọpọlọpọ eeyan ati awọn onwoye lominu.
" Asọ kansoso lo ku fun mi laye lọrun bayii, wọn ti jo gbogbo dukia mi, to fi mọ awọn ọkọ ayọkẹlẹ mi ati eyi ti mo sẹsẹ ra ni osu mẹta sẹyin.
Nítorí náà, ẹ fẹ́ òtítọ́ ati alaafia.
Bí kò bá doríkọ ibẹ̀, a óo mọ̀ pé kì í ṣe òun ló rán àjálù náà sí wa, a jẹ́ pé ó kàn dé bá wa ni.
NIN: Ohùn mẹ́ta pàtàkì tó yẹ kí o mọ nípa nọ́mbà ìdánimọ̀ Nàìjíríà
Oríṣun àwòrán, Getty Images Iwosan fun awọn ti wọn ba ti bẹrẹ si ni lo ẹrọ ventilator lati mi le lo to osu mejila si osu mejidinlogun ni ileewosan, ki ara to bẹrẹ si ni pada si ipo notori ọpọlọpọ eroja ara lo ti sọnu lasiko ti ara n ba arun Coronavirus naa ja.
Wo àwọn ìwà to le è ṣe àfarawé lára ọ̀rẹ́, èyí tó le ṣekú pa ọ́ African Parents: Òbí ayé àtijọ́ ló tọ́ ọ dàgbà tí o bá ṣe àwọn ǹkan wọ̀nyii Òbí tó n fa sìgá n fi ọmọ rẹ̀ sínú ìdè àìsàn l'ọ́jọ́ iwájú Awọn ere idaraya yii ma n jẹ ki ifẹ gbooro si laarin awọn ewe ati ọdọ ni agboole si agboole, ati wi pe, o ma n wu awọn ọmọde naa lati tete dagba ni kiakia, nitori naa ni wọn ṣe n ṣe awọn ere ohun.
Níbẹ̀, wọ́n fi ẹ̀kọ́ kún ẹ̀kọ́ ìmọ̀ ìtàkùrọ̀sọ àti kọ́ nípa ipa àyípadà ojú-ọjọ́.
Dira ogun, kí o sì wà ní ìmúrasílẹ̀, ìwọ ati gbogbo eniyan tí wọ́n pé yí ọ ká, kí o jẹ́ olórí ẹ̀ṣọ́ fún wọn.
Ẹ wo iye ọmọ Yorùbá tó bá Coronavirus lọ lókè òkun Èèyàn 17 mííràn tún ti lùgbàdì ààrùn Coronavirus ní Naijiria Bí ẹni forí ọká họmú ni ti ìjọba bá dẹ́kun òfin koníléógbélé báyìí-WHO Tikútìyè lọ̀rọ̀ Coronavirus, àdúrà lọ̀rọ̀ gbà lásìkò yìí-Ààrẹ Buhari Bákan náà lo tún kesi gómìnà àti àwọn èèyàn jàǹkàn-jàǹkàn láwùjọ nipinlẹ Ọ̀yọ́ láti gba Auxiliary nímọ̀ràn pé, kó ti ọwọ ọmọ rẹ bọ aṣọ nítorí bo se n lo ipò agbára tí wọn gbé lé e lọ́wọ́ nilo-kulo, tó si ń lo agbára apàṣẹ wàá láàárín ìlú.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Almajiri: Kíni ìjọba ń ṣe lórí ewu ẹkọ Almajiri àti covid 19 ní Nàìjíríà?
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ebenezer Obey: Orin ṣì kù tí mo máa kọ, bí ń kò bá parí rẹ̀, ń kò ní kúrò láyé 4 Agẹmo 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 9 Agẹmo 2020 Oríṣun àwòrán, Ebenezer Obey Fabiyi Ilumọọka olorin Juju nni, Oloye Ebenezer Obey Fabiyi ti salaye lẹkunrẹrẹ nipa bo ti se rin irinajo aye rẹ lagbo orin juju.
” Imam agba fun egbe  Al-Habibbya lorile ede Naijiria,Faud Adeyemi so
Àjọ Ìlera Àgbáyé ( who ) gbani nímọ ̀ ràn pé kí àwọn orílẹ ̀ èdè tí àrùn náà ti ṣe rẹ ́ gí tàbị wọ ́ pọ ̀ máa gba àjẹsára yìí lóòrèkóòrè .
Àwọn òkè ńlá yọ́ bí ìda níwájú OLUWA,àní, níwájú OLUWA gbogbo ayé.
”Nígbà tí ó sọ báyìí tán, ó wá tún sọ pé, “Ẹni tí ó bá ní etí láti fi gbọ́ràn, kí ó gbọ́!
Àwọn olóòtú ètò gbìyàjú pé kí ayẹyẹ ọ̀hún ó l'árinrin, àmọ́ àwọn èèyàn wa ò kọbiara sí i.
Ẹ kú-u bí ojú ọjọ́ ti rí.
Ninu ọrọ rẹ, Aarẹ Buhari ni awọn ajọ to n ri si ọrọ oogun lilo yoo ṣayẹwo lori agbo ọhun ki o to le di lilo ni Naijiria.
Awọn akọsẹmọsẹ kan ti wa woye pe pataki isẹlẹ to waye lọdun 1619 naa ko see foju fo nitori wọn ti n lo awọn adulawọ to wọ ni Amẹrika naa lati sisẹ ni oko taba ni agbegbe Bermuda, eyi ti ilẹ Gẹẹsi n dari.
Ṣugbọn Peteru wí fún un pé, “Bí gbogbo eniyan bá pada lẹ́yìn rẹ, èmi kò ní pada.
Ogbeni Agara, oga agba yanyan fun ile-ise oloopa, Yahaya Bello, alaga ijoba ibilẹ Lafia, Aminu Muazu wa sapejuwe isele buruku naa, eleyi ti o waye nile epo Natson, niluu Lafia, gege bi ohun ti o buru ti o si bani ninu je lopolopo.
OLUWA àwọn ọ̀tá rẹ ń fi ẹni tí o fi àmì òróró yàn ṣe yẹ̀yẹ́,wọ́n sì ń kẹ́gàn ìrìn ẹsẹ̀ rẹ̀.
Awọn aṣewadii ti n toju bọ ọrọ yii lati mọ kini kokoro to wa ninu ẹnu nii ṣe pẹlu kokoro to wa ninu oju ara lasiko ti eeyan ba n gba ẹnu ni ajọṣepọ Àwọn ọ̀nà tí obìnrin fi le gbádùn ìbálòpọ̀ Ẹ̀mi arákùnrin yìí kò gbé e, ó bá aláṣẹ́wò lò dórí ìgbà ìkéje ló bá ré sálákeji Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Tóò bá fún ọkùnrinn lóúnjẹ́ tóo tẹ́ kiní yẹn sílẹ̀ fún un dáadáa.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù 2020 Budget Defence: Buhari láwọn mínísítà kò gbọdọ̀ rìnrìn àjò lọ sí ilẹ̀ òkèrè 11 Ọ̀wàrà 2019 Oríṣun àwòrán, Twitter/Bashir Ahamd Aarẹ Muhammadu Buhari f'ofin de awọn minisita atawọn oṣiṣẹ ijọba miiran ti wọn n ṣiṣẹ pẹlu ileeṣẹ aarẹ lati rinrin ajo lọ si oke okun.
N óo ta àwọn ọmọ yín ọkunrin ati àwọn ọmọ yín obinrin lẹ́rú fún àwọn ará Juda.
Fúnra wọn ni wọ́n ṣe òṣùnwọ̀n tí wọ́n fi ń wọn ara wọn, àwọn tìkalára wọn náà ni wọ́n sì ń fi ara wọn wé.
Yinka Quadri: Mo dúpẹ́ pé Ogogo jẹ́ ọ̀rẹ́ mi!
Jesu tí ó farahàn ọ́ ní ojú ọ̀nà tí o gbà wá, ni ó rán mi wá, kí o lè tún ríran, kí o sì kún fún Ẹ̀mí Mímọ́.
Nígbà tí ìyàn náà tàn káàkiri gbogbo ilẹ̀, Josẹfu ṣí àwọn àká tí wọ́n kó oúnjẹ pamọ́ sí, ó ń ta oúnjẹ fún àwọn ará Ijipti, nítorí ìyàn náà mú gidigidi ní ilẹ̀ náà.
Bẹrẹ lati ọjọru aarẹ ni awọn yoo la ọjọ mẹta kalẹ lati se idaro lorileede naa.
 Ki lo gbe Ibrahim Chatta dele iwosan?"
atẹ lu iwa awọn olori ẹlẹsin musulumi kan ti wọn ti kuro lojuna pataki
Orisun: Banki agbaye (IDS), Gbogbo gbese ti wọn jẹ soke okun.
Agbenuso fun ile-igbimo asofin orile-ede Uganda, Rebecca Kadaga, ti so fun igbimo alabe sekele lori oro ofin, ifiyajeni ati anfaani lati sewadii Twinamasiko.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Wasiu Ayinde: Ìrìnàjò ọdún kẹtàlélọ́gọ́ta rẹ̀ rèé, títí tó fi di Máyégún ilẹ̀ Yorùbá 3 Ẹrẹ̀nà 2020 Oríṣun àwòrán, Instagram/K1 the ultimate Àkọlé àwòrán, Alaafin ilu Oyo fi Wasiu Ayinde jẹ Mayegun ilẹ Yoruba lọjọ kẹtala, oṣu Kinni, ọdun 2020.
Ọjọgbọn Fatunde sọ fun BBC Yoruba wi pe, El-Rufai gan to n bẹnu atẹ lu ọrọ baba isalẹ ni oṣelu, baba isalẹ lo ran an lọwọ lati denu oṣelu, ati wi pe, ọrọ naa kii ṣe ti Ipinlẹ Eko nikan.
Bakan naa ni ajọ onidanwo iwe mẹwa, WAEC pẹlu ti ṣalaye pe lootọ ni Ademọla Adeleke joko ṣe idanwo naa.
Ilẹ̀ ìjọba rẹ̀ bẹ̀rẹ̀ láti Aroeri, tí ó wà ní etí àfonífojì Arinoni, ati láti agbede meji àfonífojì náà, títí dé odò Jaboku, tí í ṣe ààlà ilẹ̀ àwọn ará Amoni, ó jẹ́ ìdajì ilẹ̀ Gileadi; 
Ninu ikede ti wọn fi soju opoo wọn bakan naa Ajọ NCDC sọ pe awọn ṣeṣi kede pe eeyan kan ku ni Bayelsa lọjọ Kẹtalelogun oṣu Kẹsan.
ohun di mimo lasiko to n se idanileko nile eko giga fasiti onimo ero Ladoke
Gbogbo yín ni yóo fọ́nká,tí olukuluku yóo sì yà sí ọ̀nà tirẹ̀,kò sì ní sí ẹni tí yóo kó àwọn tí ń sá fún ogun jọ.
towry-coker jẹ ́ olùkọ ́ ni ti institute of architects ( nfia ) àti alábàáṣepọ ̀ ti institute institute of arbitrators ( aci .
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'O yé kí ìbáṣepọ̀ Nàìjíríà àti UK dán mọ́rán síi lẹ́yìn àbẹ̀wò May' Adinku to ba iye ọmọogun to wa ni ilẹ Gẹẹsi ọhun ni eyi to ti i buru ju lati ọdun 2010, gẹgẹ bi ohun ti ileeṣẹ ayẹwo kan, National Audit Office, ṣe sọ.
Níbo sì ni gbogbo àwọn iṣẹ́ ìyanu OLUWA wà, tí àwọn baba wa máa ń sọ fún wa nípa rẹ̀, pé, ‘Ṣebí OLUWA ni ó kó wa jáde láti ilẹ̀ Ijipti?
Ǹjẹ́ ọ̀rọ̀ mi ati ìlànà mi tí àwọn wolii, iranṣẹ mi, sọ kò ṣẹ sí àwọn baba ńlá yín lára?
Nítorí n kò ní máa jà títí ayé,tabi kí n máa bínú nígbà gbogbo:nítorí láti ọ̀dọ̀ mi ni ẹ̀mí ti ń jáde,Èmi ni mo dá èémí ìyè.
Oluranwlowo aare lori iroyin ati ikede Femi Adesina lo soro yii pelu awon akoroyin ile-aare, leyin ipade igbimo to waye niluu Abuja.
 I played a great match against a great player,” said Nadal.
Ẹni tí ń gbé àre fún ẹlẹ́biati ẹni tí ń gbé ẹ̀bi fún aláre,OLUWA kórìíra ekinni-keji wọn.
Òun náà kò sì jẹ́ wọ ibẹ̀ láì mú ẹ̀jẹ̀ lọ́wọ́, tí yóo fi rúbọ fún ara rẹ̀ ati fún ẹ̀ṣẹ̀ tí àwọn eniyan bá ṣèèṣì dá.
” Eliṣa sì dá a lóhùn pé, “O óo fi ojú rẹ rí i, ṣugbọn o kò ní jẹ ninu rẹ̀.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Lizzy Anjorin vs Toyin Abraham: Èrò àwọn olólùfẹ̀ Toyin Abraham ati Lizzy Anjorin lórí ìjà tó bẹ́ sílẹ̀ láàrín wọn 18 Owewe 2019 Oríṣun àwòrán, @trafficwaka Kaka kewe agbọn ija laarin gbajugbaja oṣere sinima ede Yoruba, Toyin Abraham, ati ojugba rẹ Lizzy Anjorin dẹ, pipele lo n pele sii gẹgẹ bi awọn ololufẹ wọn ṣe ti gbe e ru sori tiwọn naa bayii.
Bi a ra oúnjẹ ilẹ̀ wa dipò oúnjẹ òkè-òkun, àgbẹ̀ yi o ri owó, a o si mọ irú oúnjẹ ti a njẹ ju ìrẹsì oníke ti wọn nkó wọ ilú.
Ẹ lọ sọ fún àwọn arakunrin mi pé kí wọ́n lọ sí Galili; níbẹ̀ ni wọn yóo ti rí mi.
Àmì Ọmọ-Eniyan yóo wá yọ ní ọ̀run.
Oríṣun àwòrán, Adesoye Àkọlé àwòrán, Ọ̀ọ̀ni ile ifẹ àti ọmọ rẹ̀ kan soso Ọba Ogunwusi jẹ́ gbajúgbajà onísòwò nínú káràkátà ilé àti ilẹ̀, ó jẹ́ ẹlẹ́yinjú àànu tó maa ń fi owó soore fún àwọn tó ba kù díẹ̀ fún láwùjọ àti àwọn tó ba nílò ìrànlọ́wọ́.
Kí alufaa yẹ̀ ẹ́ wò, bí ojú egbò náà bá ti funfun, nígbà náà ni kí alufaa tó pe abirùn náà ní mímọ́, ó ti di mímọ́.
Awọn ẹgbẹ mẹtẹẹta ni orúkọ wọn ma n jẹ jade lasiko ti wahala bá waye ni awọn adugbo to wa ni aarin gbùngbùn Ibadan.
Máa ṣe bẹ́ẹ̀, ìwọ yóo sì yè.
Leicester City 18:30February 11 Huddersfield Town ?
tesiwaju ninu eko imo ijinle lati tun gba oye miiran  ( post graduate degree) ninu ẹkọ akoroyin  (Mass Communication) lọdun 1986.
Ni bayii, Leon Balogun ko ni kopa latari ifarapa ti o ni, beesini Shehu Abdullahi, Kelechi Iheanacho, ati Odion Ighalo ko ni bere ifesewonse ohun.
kọ ni awọn ibo ti ko ṣafhan eni ti oludibo naa dibo fun daadaa, nitori wọn
Àwọn Èkìtì á bù mẹ́ta-mẹ́ta tí ó gbọọrọ, tàbí ẹyọ kan ṣoṣo tí ó gbọọrọ, tàbí mẹ́ta ọ̀rọ́ lórí mẹ́ta ìbú tí ó gbọọrọ.
Èròjà tí ènìà bá fẹ́ ni ènìàn nfi síi.
Àwọn ni wọ́n fún ní Kiriati Ariba tí wọ́n ń pè ní ìlú Heburoni lónìí, (Ariba yìí ni baba Anaki), ati àwọn pápá ìdaran tí wọ́n wà ní àyíká rẹ̀ ní agbègbè olókè ti Juda.
mimo nibi ifilole ‘iwe Awo’ (ni ede Yoruba) nile igbalejo ,International
Forúkọ sílẹ̀ nínú ìròyìn yìí Access Bank, dá ₦206,000 ìyá mi pádà lónìí, bí bẹ́ẹ̀ kọ́.
2017, amoju ẹrọ Makinde pada si ẹgbẹ oṣelu rẹ tẹlẹ, PDP; o ni kii ṣe tori
Eyi wu mi ti ko wu ọ lo jẹ ki èrò wọn kó dọgba si idahun ibeere naa.
Àwọn tí a fi dá ọmọ ọlọ́mọ lóró sẹ́yìn kò mọ ní ìba.
Lẹyìn tí mo figbe ta, INEC mú PVC mi wá bá mi nílé - Gani Adams El-Rufai, lọ tọwọ́ ọmọ rẹ bọ aṣọ!
Wò ohun mẹ́ta tí a mọ̀ tí yóò mú ìjọba pàṣẹ kónílé-ó-gbélé lẹ́ẹ̀kejì ní ìpínlẹ̀ Èkó Coronavirus: Kíni àwọn àmì tuntun tó n fihàn?
Kogi Commissioner: Àlàyé rèé bí Kọmíṣọ́nnà ìlera Kogi ṣe bù sẹkùn lórí amóhùnmáwòrán
Ó wá yá nígbà tí wọ́n wà ní Bẹtilẹhẹmu, àkókò tó fún Maria láti bímọ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Revolution Now: Àwọn èèyàn tó ń ṣèwọ́de ní ẹ̀rù kò bà àwọn, awọn ṣetan láti wà ní àtìmọ́lé Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Revolution Now: Àwọn èèyàn tó ń ṣèwọ́de ní ẹ̀rù kò bà àwọn, awọn ṣetan láti wà ní àtìmọ́lé 7 Ògún 2019 Ọ̀pọ̀ àwọn alátilẹ̀yìn RevolutionNow ló ti fáríga o pé àwọn ti sẹ́tàn fun gbogbo ìgbẹ́sẹ̀ ti ààrẹ Muhammedu Buhari bá fẹ́ gbé.
Gbogbo akitiyan BBC Yoruba lati ba awọn agbẹnusọ fun aarẹ Buhari s'ọrọ ja si pabo.
Àmọ́ṣá, onírúurú àṣeyọrí ni àwọn ikọ̀ yìí ti ṣe sẹ́yìn, tó fi mọ́: Gbígba ìyáa mínísítà fún ètò ìṣúná orílẹ̀èdè yìí nígbà kan rí, Ọ̀mọ̀wé Okonjo Iweala Oríṣun àwòrán, Facebook/Abba kyari Àkọlé àwòrán, Ibi to ba le la n bọmọ ọ̀kunrin, awọn iṣẹlẹ to ba le lawọn ikọ yii maa n da si Ikọ yìí bákan náà ló mú Godogodo tó ń dá ìlú Ìbàdàn rú Oríṣun àwòrán, Facebook/Abba kyari Àkọlé àwòrán, Awọn adigunjale kii fẹ bọ sọwọ ikọ yii Ọmọ ìyá mẹ́ta tí ọmọ ọ̀dọ̀ jí gbé àwọn iko yìí bákan náà ló mú u Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ọpọ igba ni araalu ti kun lori ijafafa ileeṣẹ ọlọpaa, ṣugbọ̀n ikọ yii ti fẹ maa yi ero yii pada Bákannáà ni wọ́n lọ́wọ́ nínú bí wọ́n ṣe rẹ́yìn ògbójú ajínigbé tó ń jẹ́ Henry Chibueze tí àwọn ènìyàn mọ sí Vampire Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Àwọn akẹgbẹ́ Kyari ń dáwọ̀ ìdùnú léyìn tí wọn mú Evans Àwárí àwọn ọ̀daràn tó bọ́ lọ́wọ́ ọlọ́pàá nipinle Kogi Láìpẹ́ yìí, àwọn ikọ̀ yìí kan náà ni wọ́n ṣe àwárí àwọn ọ̀daràn tó bọ́ lọ́wọ́ ọlọ́pàá nípínlẹ̀ Kogi, tí wọ́n sì ń wá ojútùú sí ìkọlù àwọn adigunjale tó wáyé n'ilu Offa ni ìpínlè Kwara tí wọn sì ti mú àwọn kan tó nisẹ pẹ̀lú ìṣẹ̀lẹ̀ náà.
Àjọ ìsọ̀kan àgbáyé fún ètò ìlera (WHO) sọ pé oníruurú ààrùn ló tí n yọjú láti ìbẹ̀rẹ̀ ajákàll ààrùn Covid-19 ni ìhà àríwá-ìlààoòrùn ilẹ̀ Nàìjíríà.
MMM: Àìsàn ọkàn ló pa Mavrodi lẹ́ni ọdún méjìlélọ́gọ́ta
”Ní àkókò yìí, kò sí ẹnikẹ́ni ninu ìdílé Ahasaya tí ó lágbára tó láti jọba ilẹ̀ Juda.
Ẹlomiran tiẹ n beere pe elo ni owo osu osisẹ ni Naijiria ati ti Saudi, Ghana, Chad, Egypt.
Omowe Jane Monckton Smith to jẹ onimọ ijinlẹ nipa iwa ẹda lo ṣẹṣẹ fi abajade iwadii to ṣe sita lori iwa ipa laarin ololufẹ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Yetunde Bakare dárà lórí ètò Ṣé o láyà, ẹ ràn án lọ́wọ́ nínú ìbéèrè tó ṣì Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Ìjọ́ba ìpínlẹ̀ Ogun náà ti gbóríyín fún Laycon gẹ́gẹ́ bíi ògidì ọmọ Ogun sùgbọ́n dandan ní owó orí sísan Ijoba ipinle Ogun naa ti ki Lekan ku oriire pelu erongba lati jo sise papo sii lodun to m bo.
”Nígbà tí ó dé ilé, Jesu ló ṣáájú rẹ̀ sọ̀rọ̀, ó ní, “Kí ni o rò, Simoni?
Bí ẹ̀mí náà ti bà lé wọn, wọ́n bẹ̀rẹ̀ sí sọ àsọtẹ́lẹ̀, ṣugbọn wọn kò sọ àsọtẹ́lẹ̀ mọ́ lẹ́yìn ọjọ́ náà.
Gbogbo rẹ̀ yóo jẹ́ aadọtaleerugba (250) àwo turari.
Gege bi oro agbejoro  re Abdelrahman Haridy, eyi ti o so pe, Abol Fotouh se awon esun ti won fi kan-an naa pe, “Aheso ati iro funfun balau ni esun naa je”.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Jesu Oyingbo rèé, pásítọ̀ tó láṣẹ ìbálòpọ̀ lóri ọmọ ìjọ obìnrin Igbó mímu lè ṣe kóríyá, kò lé fi kún orín ẹnu òṣèré - 9ice Ìtàn tó wà nídi òwe ‘Sebótimọ Ẹlẹ́wà Sàpọ́n’ Ọba Adesoji Aderemi, Ọọ̀ni Ifẹ̀ tó gba ipò ọba mọ́ tòṣèlú Ahmed Lawan, tii se olori ile asofin agba tuntun yii lo n soju ẹkun idibo ariwa ipinlẹ Yobe, ko to di aarẹ ile tuntun.
Gbogbo àwọn tí wọ́n ní aṣọ aláwọ̀ aró, tabi ti elése àlùkò, tabi aṣọ pupa, tabi aṣọ funfun, tabi irun ewúrẹ́, tabi awọ àgbò tí a ṣe ní pupa, tabi awọ ewúrẹ́, bẹ̀rẹ̀ sí kó wọn wá.
a óo lé ọ kúrò láàrin àwọn eniyan, o óo máa bá àwọn ẹranko gbé, o óo sì máa jẹ koríko bíi mààlúù fún ọdún meje, títí tí o óo fi mọ̀ pé, Ẹni Gíga Jùlọ ní àṣẹ lórí ìjọba eniyan, ati pé ẹni tí ó bá wù ú ní í máa gbé e lé lọ́wọ́.
 Lẹyin naa ni igbimọ miran yoo wo gbogbo kudiẹ kudiẹ to ba wa ninu rẹ, lẹyin naa ni yoo de ile aṣofin agba, ti awọn naa yoo si ṣe iṣẹ le lori.
” Wọ́n bá ń fi í ṣe ẹlẹ́yà.
Kí n lè mọ bí a tií gba àwọn tí ọkàn wọn rẹ̀wẹ̀sì níyànjú.
Wọ́n kó àwọn ìkòkò, àwọn ọ̀kọ̀, àwọn ọ̀pá tí wọ́n fi ń pa iná lẹ́nu àtùpà, àwọn àwo turari ati àwọn ohun èlò bàbà tí wọ́n máa ń lò fún ìsìn ninu ilé OLUWA.
Ṣugbọn Mẹlikisẹdẹki tí kì í ṣe ìran Abrahamu gba ìdámẹ́wàá lọ́wọ́ rẹ̀, ó sì súre fún Abrahamu tí ó rí àwọn ìlérí Ọlọrun gbà.
Bí a bá sẹ́ ẹ,òun náà yóo sẹ́ wa.
Nigba ti BBC beere nipa fidio yii ni iwadii fihan pe Fatima Daura lo ya fidio naa.
gomina labe asia egbe oselu , Peoples Democratic Party, PDP,lo jawe olubori pẹlu
Ọjọ manigbagbe ni alẹ Ọjọru ọjọ keje oṣu kẹwaa, ọdun 2020 jẹ fun Giroud nitori ifẹsẹwọnsẹ to fakọyọ ninu rẹ yii lọ jẹ ifẹsẹwọnsẹ ọgọrun un ti yoo kopa ninu rẹ fun ilu baba rẹ, Faranse.
Ẹ kún fún àdúrà nítorí ìdájọ́ kóòtù àgbà lórí gómìnà l'Ọ́ṣun-APC Ọṣun Ìdí rèé táwọn ọmọ Nàíjíríà kan ṣe ń tako ìdásílẹ̀ ‘Ruga Settlement’ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, A nilo agọ ọlọpa ni Orin Ekiti fún aabo wa -Falua O tun ni oun ko lọ lati lọ ra nkan ibalopọ ninu ṣọọbu naa.
ati àwọn ọmọ Reubẹni wọnyi: Hanoku, Palu, Hesironi, ati Karimi.
Ìgbá tí wọ́n tún ronú títí wọ́n kúkú pa a.
Nibayii, Aisha ti wa se bi ẹni fi idi ahesọ ọrọ yii mulẹ ninu ifọrọwerọ rẹ pẹlu BBC, eyi to ti fi ẹsun kan awọn agbofinro ati ẹsọ rẹ pe wọn n wo gbogbo bi Fatimah ṣe ṣe si oun.
Adamu ni ki wọn lọ yẹ gbogbo opopona marosẹ to wa ni ẹkun Guusu-guusu ati Guusu ila oorun ati iwọ oorun Naijiria wo.
" Awọn ikọlu to ti waye: Awọn ayederu iroyin ti fa awọn ikọlu to l'agbara.
Kaadi idibo mi lemi fi n ja nitemi o.
Mohamed Abdi Faray ati Abdirahman Mohamed Isaq jẹwọ iwa ọdaran yi leyin ti wọn ji ọmọdebinrin yi gbe ni ilu Bosaso ni ibẹrẹ ọdun yi.
Mose yìí ni ó sọ fún àwọn ọmọ Israẹli pé, ‘Ọlọrun yóo gbé wolii kan bí èmi dìde fun yín láàrin àwọn arakunrin yín.
Gẹgẹ bi oun ti Olori Folashade sọ, bi ibẹta ṣe ni ilọpo wahala ni ti tọju, bẹẹ naa ni wọn tun jẹ ilọpo idunnu.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Hydroxychloroquine, Zinc ati Zithromax : Ààrẹ Trump tí sọ̀rọ̀ nípa Dókítà Stella Immanuel,ẹ gbọ́ ohùn tó sọ 27 Agẹmo 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 29 Agẹmo 2020 Oríṣun àwòrán, Getty/Twitter Aarẹ orilẹede Amẹrika, Donald Trump ti fesi lori ọrọ Dokita Stella Immanuel to sọrọ pe Hydroxychloroquine (HCQ), Zinc ati Zithromax jẹ oogun to daju lati wo awọn to ba ni arun Covid-19.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Presidential Debate: Ọ̀rọ̀ bọ́ lórí bí Buhari àti Atiku ṣe kọ̀ láti ṣe ìjírọ̀rọ̀ 20 Sẹ́rẹ́ 2019 Oríṣun àwòrán, Connect Nigeria Àkọlé àwòrán, Ọrọ lori ijiroro fun ipo aarẹ Ero ọkan awọn ọmọ Naijiria ti lu ori opo ikansira ẹni lori ayelujara pa lori bi Aarẹ Muhammadu Buhari ko ṣe yọju sibi ijiroro laarin awọn oludije fun ipo aarẹ.
'Àwọn ọmọ 5 kọ́ ló sọnù, ọmọ 28 ló sálọ síléeṣẹ́ foyúngbowó nípinlẹ̀ Ogun' Soun ilẹ̀ Ogbomoṣo pàdánù ọmọkùnrin rẹ̀ Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí 3:49 Fídíò, Boko Haram: Oluwatobi Adeigba, Ọkọ mi ń lọ siṣẹ́ fún àjọ INEC ló kàgbákò ikú - Opó Adeigba, Duration 3,492 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Soun Ogbomoṣo pàdánù ọmọkùnrin rẹ̀2 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Òun ati ẹ̀wù rẹ̀ yóo di mímọ́, àwọn ọmọ rẹ̀ ati ẹ̀wù wọn yóo sì di mímọ́ pẹlu.
ìjọba Tanzania ko 30 Mílíọ̀nù rẹ̀ wọ̀lú Bàbá ìsàlè ilé ìwé fásitì Nàìjíríà ni Ọba Enitan Ogunwusi!
OLUWA Ọlọrun ní, “Nítorí àwọn ará Edomu gbẹ̀san lára àwọn ará Juda, wọ́n sì ṣẹ̀ nítorí ẹ̀san tí wọ́n gbà.
Nígbà tí ó rí èyí ó mú ọfà nínú apó rẹ̀ ó fi gún ọwọ́ ìjà náà pẹ̀lú agbára, ọfà sì wọlé sinṣin.
Ìjà bẹ́ sílẹ̀ láàrin àwọn ẹ̀yà Israẹli káàkiri.
O tun  ni”Gbigbogun ti aarun kogboogun  jẹ ija ti a gbọdọ sẹgun rẹ, ki i se ojuse ijoba nikan.
Nítorí OLUWA ni ó pàṣẹ bẹ́ẹ̀,ẹ̀mí rẹ̀ ni ó sì kó wọn jọ.
N30,000 ni mo gbà fún orí, ọwọ́ àti ẹran ara wòlíì Bosede - Kayeefi Ẹ kọ́ nípa ohun tí Yorùbá ń pè ní Àrígiṣẹ́gi Wọ́n ta ère Ọ̀ṣun Osogbo sí Togo - Bàbá Ọṣun figbe ta Baṣọ̀run Gáà, tó yan ọba mẹ́rin, pa ọba mẹ́rin àmọ́ ọba karùn-ún ló pa á Bakan naa lo fi idi rẹ mulẹ pe, ootọ ni ọrọ tawọn kan n sọ pe oun lee pasẹ fun ibọn pe ko yọ jade latinu afẹfẹ, kii si se ẹnu lasan ni.
Ó bá kígbe pé, “Ẹ bẹ̀rù Ọlọrun kí ẹ sì fi ògo fún un, nítorí àkókò ìdájọ́ rẹ̀ dé!
Nítorí náà èmi bẹ̀ ọ́, ìwọ ẹ̀dá pàtàkì tí í ṣe Aṣojú-Olódùmarè, bá mi wí fún Ọlọ́run Ọba wí pé kí Ó gba ìyàwó éléyìí kí ó fi fún ẹlòmíràn kí ó bá mi wá ìyàwó tí yóò mọ́ mi lára.
Kì í jẹ àjẹṣẹ́kù,nítorí náà, ọlá rẹ̀ kò le tọ́jọ́.
Nítorí Baba kò ṣe ìdájọ́ ẹnikẹ́ni, ṣugbọn ó ti fi gbogbo ìdájọ́ lé Ọmọ lọ́wọ́, 
Orisun iku aitọjọ lorilẹede naa ni aisan ọkan ati ijamba mọto.
Ami ayo mẹta ọtọọtọ ni wọn Brighton fi ṣagba Tottenham eleyi to jẹ iyanlẹnu fun ọpọlọpọ awọn ololufẹ ere bọọlu.
Ero pejọ si waju ile awọn Sridevi ni igboro Mumbai nigba ti iroyin iku rẹ jade.
Ile Igbimọ Aṣofin kọkọ ṣe agbeyẹwo rẹ.
Orísìírísìí ọ̀nà ló ti wà fún kíkọ èdè Yorùbá sílẹ̀ pẹ̀lú àmì.
bí agbára mi ṣe rí nígbà tí Mose rán wa jáde láti lọ ṣe amí, bẹ́ẹ̀ náà ni ó wà títí di òní olónìí, mo tún lágbára láti jagun ati láti wọlé ati láti jáde.
Wọ́n ní kí ẹ má wá àwọn oriṣa lọ, kí ẹ má bọ wọ́n, kí ẹ má sì sìn wọ́n.
Ìgbà Marún-un ti Aisha Buhari ti tako ìjọba Buhari Aisha Buhari ké gbàjare pé ètò ìjọba Buhari kò ṣànfàní f'óbìrin Èmi kò sí nílé, ọkọ́ mi ló leè sọ bóyá lóòtọ́ọ́ ló fẹ́ gbéyàwó àbí bẹ́ẹ̀ kọ́ - Aisha fèsì Bó tilẹ̀ jẹ́ pé ìròyìn òfegè ni pé Buhari fẹ fẹ́ Sadiya, síbẹ̀ àwọn ọmọ Nàìjíríà ń ṣètò ìyàwò náà lórí ayélujára Daura kò tan mọ́ Buhari àmọ́ òun àti ọmọ rẹ̀ ti fẹ́ ba ẹbí mi jẹ́ - Aisha figbe ta O ya fidio ọhun niwaju awọn ẹṣọ mi ati gbogbo awọn to wa nibẹ to si n fi mi rẹrin"", ohun ti Aisha sọ fun BBC ree."
Ayipada si DNA eeyan Awọn iroyin kan ti n gbode lori ayelujara pe abẹrẹ ajẹsara Covid-19 lagabra lati yi DNA eeyan pada.
Ki awọn ọmọogun to lee se iru ohun ti wọn gbe se, pẹlu bi wọn se se e ni sisẹ n tẹle, o di dandan pe wọn lee gbe nkan ribiribi se.
Lori bi awọn musulumi ṣe maa n fẹ iyawo pupọ, onimọ nipa ẹṣin Islam naa ni ko si ohun to buru ti wọn ko ba fẹ ju iyawo mẹrin lọ, ti wọn si n ṣe deede laarin wọn.
ọmọ Amisi, ọmọ Bani, ọmọ Ṣemeri; 
O ti le lọdun kan ti awọn ibode orilẹede Naijria ti wa ni titi pa ko to wa di pe ijọba pinu lati ṣi wọn pada loṣu yii.
O ti fi mí sinu isà òkú tí ó jìn pupọ,ninu òkùnkùn, àní ninu ọ̀gbun.
Wọn óo sì ròyìn ògo mi láàrin àwọn orílẹ̀-èdè.
Akitiyan wa lati ba alukoro ile ise ọlọpaa Jimoh Moshood sọrọ lori isẹle naa lo ja si pabo pẹlu bi ko se gbe ipe wa.
Awọn Gomina ipinlẹ mẹta,Yahaya Bello Kogi,Abiola Ajimobi ati Gomina Abubakar Badaru Jigawa yoo kọwọ rin pẹlu aarẹ́ Buhari.
'Ẹ fi gbogbo ọrọ emi ati MC Oluomo silẹ fun Ọlọrun.
“Ṣugbọn ṣé ìwọ Ọlọrun yóo máa bá eniyan gbé lórí ilẹ̀ ayé?
Ó bẹrẹ sí í pòṣé títí ó fi dé ọ̀dọ̀ ìyàwó rẹ̀.
Ẹkunrẹrẹ iroyin yii n bọ laipẹ.
Àkọlé àwòrán, Won jo n sin Olorun ninu iṣẹ iranṣẹ pẹlu awọn ọkọ wọn ni Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí kan sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
Emery n gba iṣẹ lọwọ Javi Calleja to fi ẹgbẹ agbabọọlu naa silẹ pẹlupẹlu bi wọn ṣe ṣe ipo karun un lori atẹ liigi Spanish Liga, to si fihan pe wọn yoo lanfani lati kopa ninu idije Liigi Europa ni saa to n bọ.
”Eliṣa dáhùn pé, “Bí OLUWA ti wà láàyè, tí ìwọ náà sì wà láàyè, n kò ní fi ọ́ sílẹ̀.
Oríṣun àwòrán, Alamy Abalọ ababọ nile ẹjọ, lo pada wa ja si idajọ to waye to wọgile iyansipo awọn ọba naa.
Pe bi iye awọn ti wọn n tu silẹ nilu Ibadan atawọn agbegbe rẹ ṣe n pọ sii, o ti n sọ ọ di aarin gbungbun fun ifini ṣ'owo ẹru.
Lara awọn eeyan ọhun ni Falz, Toyin Abraham, Kanyew West, ati bẹẹ bẹẹ lọ.
Mo lá àlá kan tí ó bà mí lẹ́rù.
Ṣugbọn, maa kuku fi eyi ṣiṣẹ ṣe.
Àkọlé àwòrán, Àwọn ọdọ Naijiria ni titasẹ agẹrẹ sinu ẹtọ ẹni lati sọ ohun tọkan ẹni fẹ gẹgẹ bo ṣe wa ninu ofin Naijiria ni igbesẹ ijọba yii.
Lẹ́yìn náà, ó lọ sí ibi odò Enṣemeṣi, ó sì pin sí Enrogeli.
Ní orúkọ rẹ ni a jáde láti wá bá ogun ńlá yìí jà.
Opral Benson, ẹni ti oge ṣíṣe sọ di gbajúmọ̀ àti Yeye Oge ìlú Eko Ǹjẹ́ ó ṣeéṣe kí ìyáwò rẹ gbé ọmọ àlè wá sílé láì mọ̀?
O ni lọdọ toun Sharia ati ipo ti oun dimu gẹgẹ bi adajọ wa láti dáàbò bo àwọn obìnrin ni.
 Àwọn èèyàn tí ó pàpà rí ìyàtọ ̀ lẹ ́ yìn èyi á gba hepatitis b immunoglobulin ( hbig ) tí wọ ́ n bá kó àrùn jẹ ̀ dọ ̀ jẹ ̀ dọ ̀ b lọ ́ jọ ́ wájú .
Eni to ti yi awọn ofin mii pada bii iye owona fun idanilaraya tioti odun 2030 ati fifun awọn obinrin laye lati lọ wo ere idaraya ati orin fun igba akọkọ nita.
" Oríṣun àwòrán, @VoicingNG Iwọde naa di ọna mọ awọn arinrinajo to n bọ lati Ibadan si ilu Eko, bakan naa ni ko si ọpna lati relọja lati Eko si Ibadan.
Kí ó gbé ọwọ́ lórí ẹbọ ìmúkúrò ẹ̀ṣẹ̀ yìí, kí ó sì pa á fún ẹbọ ìmúkúrò ẹ̀ṣẹ̀ níbi tí wọ́n ti ń pa ẹran tí wọ́n bá fẹ́ fi rú ẹbọ sísun.
Àwọn ọ̀tá yí mi ká bí akọ mààlúù,wọ́n yí mi ká bí akọ mààlúù Baṣani tó lágbára.
Akilov,ti won le kuro nile itoju  aarun opolo, lo sa kuro nibi isele naa, ki owo awon agbofinro to o mu, bakan naa, ni o tun  jewo fun awon olopaa lasiko iwadii won.
Ọ̀rẹ́ mi, kíyè  sára, má ṣe bá àwọn elékèé péjọ nínú àwújọ wọn, nítorí aṣiwèrè ni wọ́n, ẹnu wọ́n mú bí idà olójú-méjì, ó lágbára bí àáké tí bàbá mi fi ń bẹ́ igi oko, wọ́n a fi ẹnu pa ènìyàn, wọ́n á fi ẹnu ba iṣẹ́ ènìyàn jẹ́, wọ́n á fi ẹnu ti ọmọnìkejì wọn sí inú ibojì: nítorí kí ni ńkọ́?
Kín ló kan ṣọ́ọ́sì pẹ̀lú ọkọ tí kò leè ta pútú?
Grandpa àti Uncle mi, ń fipá bá mi lòpọ̀ láti ọmọ ọdún mẹ́rin"" Ẹ má bínú, mo kábàmọ́ pé mo na obìnrin -Elisha Abbo Ààrẹ Buhari jámi lórí ètò RUGA ná Sọ àsọtẹ́lẹ̀ orílẹ̀èdè tí yóò borí ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ t'òní Ọpọlọpọ ero lo maa n wa sọkan awọn to ba ri iru ayipada awọ ara yii lara ẹlomiiran ati awọn to ṣẹlẹ lagọ ara wọn gan."
#EndSARS: Pe nọ́mbà wọ̀nyìí láti fẹjọ́ ọlọ́pàá SARS sùn Àṣìta ìbọn pa èèyàn kan lásìkò tí SARS ń kojú adigunjalè l'Eko Kolade Johnson; Iléeṣẹ́ ọlọ́pàá ní ọwọ́ ti tẹ àwọn afurasí ọlọ́pàá tó ṣekúpaá Ofin Naijiria lodi si ifiyajẹni.
Passover Night: Òjíṣẹ́ Ọlọ́run ní o lè gbàdúrà ìparí ọdún nílé rẹ láì lọ sí ṣọ́ọ̀ṣì
Lawan kii ṣe aimọ lagbo oṣelu ti ọpọ awọn Sẹnẹtọ si ti lawọn yoo gbaruku ti lati di aarẹ ile asofin.
Olólùfẹ́ rẹ tí ó dára bí abo egbin.
ki  a dawọ iwa ipaniyan, igbesunmọmi ati
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Yomi Fabiyi: Fíìmù ‘Owó orí ẹlẹ́wọ̀n’ jẹ́ ká mọ̀ pé ìgbà ìpọ́njú làá mọ ọ̀rẹ́ Trump ti fi igi gun eto ipolongo ibo rẹ nibayii ti eto idibo aarẹ Amẹrika, ninu eyi to ti n kopa ku osu kan soso pere.
Nígbà tí wọ́n ko ri ojútùú sì aigbọraẹniye yìí lo bá di ogún, ìṣẹ̀lẹ̀ náà sì ló bi ogún Ìjàyè.
Bí ọ̀rọ̀ Ọlọrun ni ẹ gbà á, kì í ṣe bí ọ̀rọ̀ eniyan.
O nira diẹ lati mọ boya o ni aarun naa, tabi igba to ti ni.
Leyin irin ajo ohun, aare ati awon emewa re yoo tun lo sabewo si awon omo Naijiria ti won fi orile-ede France se ibugbe.
Ojora ti mú wa, nítorí ọ̀rọ̀ tí àwọn arakunrin wa sọ fún wa, tí wọ́n ní àwọn ará ibẹ̀ lágbára jù wá lọ, wọ́n sì ṣígbọnlẹ̀ jù wá lọ.
Litireṣọ akọsilẹ Yoruba de lẹyin ti mọọkọ-mọọka de ba ede Yoruba ni.
Gbogbo ibi tí àwọn orílẹ̀-èdè tí ẹ óo lé kúrò ti ń sin oriṣa wọn ni kí ẹ wó lulẹ̀, ati àwọn tí wọ́n wà lórí òkè ńlá, ati àwọn tí wọ̀n wà lórí àwọn òkè kéékèèké, ati àwọn tí wọ́n wà lábẹ́ igi tútù.
ó ní ‘Ìyìn ni fún OLUWA Ọlọrun Israẹli, tí ó jẹ́ kí ọ̀kan ninu àwọn ọmọ mi jọba lónìí, tí ó sì jẹ́ kí n fi ojú mi rí i.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Rape Castration: Ìpínlẹ̀ Bauchi láwọn náà fẹ máà tẹ àwọn afipábánilopọ̀ lọ́dàá bíi ti Kaduna 26 Owewe 2020 Oríṣun àwòrán, Facebook/Bauchi State Government Gomina ipinlẹ Bauchi, Bala Mohammed ti sọ pe awọn yoo ṣagbeyẹwo ofin to n daabo bo awọn eeyan lọwọ ifipabanilopo nipa fifi ijiya titẹ lọda jẹ awọn ọdaran afipabanilopọ.
Lẹ́yìn náà, Dafidi gbógun ti àwọn Filistini, ó ṣẹgun wọn, ó sì jagun gba ìlú Gati ati àwọn ìletò agbègbè rẹ̀ lọ́wọ́ wọn.
Eeyan 63,328 lo ti lugbadi coronavirus ni Naijiria bayii, ṣugbọn eeyan 59,675 lo ti ri iwosan.
Amasa ni Absalomu fi ṣe olórí ogun rẹ̀, dípò Joabu.
Oríṣun àwòrán, @tokstarr Iroyin naa sọ pe, Makinwa fun ẹnikan ni èsì lórí Twitter pe, o da oun loju pe awọn to n fi oun ṣe yẹyẹ nitori pe Amcon ti ile oun pa, si n pada bọ wa tọrọ owó lọwọ òun.
Bẹ̀ ẹ́ ló bá gbé ike omi tó sì lọ Omi àkọ́kọ́ ló n fà jáde nínú kànga, nígbà tí ìfami fa òun fúnra rẹ̀ sínú kànga nà.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Saa kẹta tọ si Ajimọbi - Olubadan Ẹ̀ni ọgọ́ta ọdún gbẹ̀mí ara rẹ̀ ní UCH Ibadan Ajimobi kéde ọjọ́ mẹta fún ìdàrò Adeyemọ Osi Olubadan ti ilẹ Ibadan, Rashidi Ladoja lo pe ọkan lara awọn ọba alade tuntun naa lẹjọ.
nkan bíì ọsù mẹ́ta-mẹ́ta ni ìgbà kọ̀ọ̀kan ngbà, tí ìgbà mẹ́rẹ̀rin bá kọjá tán ni ó di ọdún kan, tí nṣe oṣù méjìlá.
 A wa rọ awọn ọmọ wa lati gba alaafia laaye ki wọn si dẹkun biba awọn  ile iṣẹ 
Fidio to wa lori ẹrọ ayelujara ṣe afihan bi awọn adigunjale naa ṣe yin ado oloro to pa awọn ọlọpaa naa, ti o si ba agọ ọlọpaa naa jẹ.
Ó sọ fún àwọn ọmọ rẹ̀ pé kí wọ́n di kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ òun ní gàárì, wọ́n di kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ rẹ̀ ní gàárì.
‘Irọ́ ni pé Leah Sharibu ti kú sí àhámọ́ Boko Haram’ Bakan naa ni ijọba apa-pọ ti bu ẹnu atẹ lu iroyin to n ja rain nilẹ pe Leah Sharibu ti ku si ahamọ Boko Haram.
bíbélì fìdí rẹ múlè pé gbogbo ènìyàn ní ó sá ti ṣè tí ó sì ti kùnà ògo Ọlọrun ( romu 3 : 23 ) .
Saaju ki o to di aṣoju nile aṣofin, Femi Gbajabiamila ti a bi ni ọjọ kẹẹdọgbọn oṣu Kẹfa ọdun 1962, bẹrẹ iṣẹ agbẹjọro lọdun 1984 lẹyin to gboye nile Ẹkọ imọ ofin Naijiria.
Ajọ eleto ilera agbaye WHO ti sọ pe ki wọn da iwaadi duro lori lilo oogun yi fun itọju Covid 19 nitori pe ko ṣiṣẹ.
Arifa Sultana, ẹni ogun ọdun bi ọmọ kan ninu oṣu Keji, sugbọn lẹyin ọjọ mẹrindinlọgbọn, ni wọn tun sare gbe digba-digba ls sileewosan nitori pe inu n run un.
Lẹyin ti mo dawọ gbogbo eyi duro ni mo sakiyesi pe egungun mi ti yẹ̀.
Abẹrẹ-ajẹsara máa n ṣiṣẹ bi o ti yẹ 3.
 Èyí tó pọ ̀ jù nínú àwọn ọmọ yorùbá ń gbé ní orílẹ ̀ -èdè nàìjíríà .
"Mo nílò ìrànlọwọ láti kọ mi ní ọ̀nà ti ǹ ko fi ni máá ṣe oore púpọ̀ nítori oore ti mò ń ṣe, ní àwọn eniyan fi ń jámi kulẹ̀ báyìí, ti mò sì ń dárijì wọn ní gbogbo igbà"" Sááju ní King ti ṣe ìfọ̀rọ̀wánílẹ̀núwò pẹ̀lú àwọn obìnrin méjì, Azriel Clary àti Joycelyn Savage, tí wọn n jẹ wọ́le-wọde Kelly lọ́wọ́lọ́wọ́."
Lara wọn ni ọkan ninu awọn oludije fun ipo gomina ipinlẹ Ọyọ l'abẹ ẹgbẹ oselu PDP, Onimọ-ẹrọ Seyi Makinde.
Àpapọ̀ gbogbo àwọn tí wọ́n ti oko ẹrú dé jẹ́ ọ̀kẹ́ meji ó lé ẹgbaa, ó lé ọtalelọọdunrun (42,360).
Ṣé bí ó bá tilẹ̀ jẹ́ oògùn dúdú ni ṣe ìbá bá mi lórí mi; àìròtẹ́lẹ̀ ni mo ń tọrọ ọṣẹ kiri mo sì lò tó oníkọ́bọ̀ kí n tóó kúrò ní olórí funfun.
“Ijọba ti n sa gbogbo ipa lati sin ilu ati lati ri i daju pe awọn ara ilu lẹnikọọkan jere ijọba tiwa-n-tiwa yii.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Army: Ọkọ mẹ́sàn-án tó kún fún àpò ẹja la gbà lọ́wọ́ Boko Haram 20 Ọ̀wàrà 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 21 Ọ̀wàrà 2019 Oríṣun àwòrán, @HQNigerianArmy Ọgbọn kii tan laye, ka wa lọ sọrun ni awọn Boko Haram n fi iwalaaye wọn se, ti wọn si n da ọgbọn orisirisi lati mu ki igbe aye idẹrun wa fun wọn.
Ó yé ẹyin rẹ̀ sórí ilẹ̀,kí ooru ilẹ̀ lè mú wọn,
O tun kede ọna ijiroro ajọsọ lori ọna ti yoo rọrun fawọn to jẹ owo ori tẹlẹ lati tele ọna ti ko ga ju ara lọ.
Gomina ipinlẹ Borno lo tẹwọgba wọn Ọgagun to wa fun eto ironupiwada awọn ọmọ ikọ Boko Haram lẹkun ila oorun ariwa orilẹede yi, lo ko awọn ọmọ ikọ Boko Haram naa kalẹ fun gomina ipinlẹ Borno, tii se ọkan lara awọn ipinlẹ ti Ikọ agbesunmọmi naa ti se ọsẹ julọ lati ọdun mẹjọ sẹyin.
Ewu ni bí a bá fẹ́ máa bá ìrìn àjò wa lọ nítorí ọjọ́ ààwẹ̀ ti kọjá.
Nígbà tí ó dé ọ̀dọ̀ Dafidi, ó wólẹ̀, ó dojúbolẹ̀ níwájú rẹ̀, ó sì kí i tọ̀wọ̀tọ̀wọ̀.
Ọba bi í pé, ‘Arakunrin, báwo ni o ti ṣe wọ ìhín láì ní aṣọ igbeyawo?
Èyí ẹ̀gbọ́n fò ó bà lé orí igi ràbàtà kan tí ń bẹ ní ẹnu ibodè, èyí àbúrò tí ó sì jẹ́ ìyàwó ń fò le orí àwọn igi kékeré ẹ̀bá ọna lọ ó ń tẹ̀lé bàbá mi bi onítọhùn ti ń ba ojú ọ̀nà lọ.
Ìran tí mo rí yìí dàbí èyí tí mo rí nígbà tí Ọlọrun wá pa ìlú Jerusalẹmu run ati bí ìran tí mo rí létí odò Kebari; mo bá dojúbolẹ̀.
Gomina Ambode buwọlu aba isuna ti o le ni trillionu kan naira
atunse lori eto iselu orile ede naa, ni eyi ti yoo tun faaye sile fun
Kọmíṣọ́nà àgbà fún ọ̀rọ̀ ìpolongo àti ìdánilẹ́kọ́ lájọ INEC ni, awọn akẹkọ ati awọn agunbanirọ ni eyi kàn julọ.
”OLUWA dá wọn lóhùn, ó ní, “Ẹ lọ gbógun tì wọ́n, nítorí pé, lọ́la ni n óo fi wọ́n le yín lọ́wọ́.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Dele Momodu : Lẹ́yìn Buhari àti Atiku, èrò ọjà làwọn olùdíje yóòkù ní ìdìbò 2019 O ni lara awọn ileegbe aladani to wa fawọn akẹkọ ileewe naa ni o ti ṣẹlẹ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Zlatan: Ọ̀rẹ́ ni mo sìn lọ ‘studio’ tí mo fi bẹ̀rẹ̀ orin lẹ́yìn tí mo kùnà ìdánwò WAEC Bakan naa ni Sanwo-Olu tun pàṣẹ pé kí gbogbo ilé ẹ̀kọ wà ní títì pa titi di asiko ti ijọba yoo mọ igbesẹ to kan.
Nibo gan ni aaye wọn wà, ṣe loju popo ni tàbí ní ibodè to jade kuro lorilẹede kan?
Joṣua gba gbogbo ìlú àwọn ọba náà, ó kó àwọn ọba wọn, ó fi idà pa wọ́n, gẹ́gẹ́ bí Mose iranṣẹ OLUWA ti pàṣẹ fún un.
Àbí a fẹ́ mú Oluwa jowú ni bí?
Ikinni re ohun waye ni kete ti esi ifesewonse pelu iko agbabooolu Bafana Bafana pari si ami-ayo kookan.
O ṣiṣẹ gẹgẹ bii Amofin ni Masachussetts ni Boston ni America fun igba diẹ, ko to jẹ kọmiṣọnna nibẹ.
Ẹrijiyan Ekiti ni Omi Erin wa
O ni ko si iwe kankan ti adajọ ri gba lati ọdọ rẹ pe ki wọn yọnda oun ninu ẹjọ naa.
Ìmọ́lẹ̀ dára, oòrùn sì dùn-ún wò.
Ile-ise aare soro ohun di mimo pe aare Trump ti yan ogagun teleri ohun, John Abizaid, leni ti o tuko omo ogun ile Amerika lasiko ogun pelu orile-ede IraqNi bayii, ireti wa pe ile igbimo asofin ile Amerika yoo sepade lati bowolu iyansipo tuntun naa.
Akori ipade naa ni:“idagbasoke eto ilera gege bi igi leyin ogba fun idagbasoke ayika lorile ede Naijiria’’.
 x  jé bí àfikún fún òrò-ìse nínú apis .
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù George Weah tí padà sí ọ́fíìsì rẹ̀ tó fí sílẹ nítorí ejò 2 Èbibi 2019 Oríṣun àwòrán, Anadolu Agency Mọjamọsa la fi mọ akinkaju ọkunrin.
Lọjọ kẹẹdogun, oṣu kẹrin, ọdun 2019 ni iná sọ ni Notre Dame Oríṣun àwòrán, SHIV MALIK Àkọlé àwòrán, Ijọ Aguda, Paris Awọn oṣiṣe pajawiri ti pa ina to jo ile ijọsin atayedaye Notre-Dame Cathedral to wa ni ilu Paris, orilẹede France, eyi ti ina bọ si ni ọjọ Aje.
Olupẹjọ ni Tehran Ali Alqasimehr sọ pe ọgbẹni Trump ati awọn marundinlogoji mii n koju ẹsun isekupani ti awọn si ti kan si ileesẹ ọlọpaa lagbaye Interpol lati bawọn mu wọn.
 Gbogbo oun to yẹ ni ṣiṣe ni a maa ṣe ni ibamu pẹlu ilana Covid-19.
Ọmi alayo meji meji ni Manchester United ta pẹlu Aston Villa ninu ere bọọlu ti wọn gba kẹyin lọjọ Aiku.
Agbẹnusọ sẹnatọ náà ni alágàbangebe ni ASD àti pé o ti gba ki wọ́n lo òun fún oṣèlú, sùgbọ́n ni bayii tọ́rọ̀ ti di ti ọlọpàá ilé ẹjọ ni yóò yanju gbogbo rẹ̀ Òṣèrébìnrin tí wọ́n bá fi ìbálòpọ̀ lọ̀ 'torí ìṣẹ́, kó bọ́ síta láti sọ̀rọ̀ - Kunle Afod Wo àwọn èèyàn jáńkán tí yóò ṣe ọdún tuntun ní ọgbà ẹ̀wọ̀n Àwọn fóònù wọ̀nyìí kò ní lè ṣe WhatsApp láti ọdún 2020 Àwọn orílẹ̀-èdè tó ti ṣáájú Nàìjíríà wọ ọdún 2020 Odunlade àti Femi Adebayọ: Wo ohun tó yà wá sọ́tọ̀ nínú àwọn arẹwà ọkùnrin Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Òṣìṣẹ́ Bánkì ni mí l'Amẹ́ríkà kí n tó bẹ̀rẹ̀ Tíátà' Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 3 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 5 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Ṣugbọn mo rò pé ó sàn fún un pupọ jùlọ tí ó bá dá wà.
 Mo si ro gbogbo omo ipinle eko patapata lati gbaruku ti oludjie wa saaju idibo gbogbogbo to n bo lọdun 2019.
Bẹ́ẹ̀ ni iṣẹ́ ìsìn ninu ilé OLUWA ṣe tún bẹ̀rẹ̀.
jabo wipe isele ijamba omiyale agbara ya soobu ti o waye ni eka ila oorun
jẹ́ ẹgbaa mẹrindinlogun ó lé igba (32,200).
Ewe, millionu meji awon olugbe ile naa lo ti fi agbegbe won sile lataari isele omiyale naa.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Security state of Nation: Ọ̀rọ̀ ààbò kìí se èyí tí a lé fí gbèdéké sí- Femi Adesina 21 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Oríṣun àwòrán, Channels Olùbádámọ́ràn pàtàkì fún ààrẹ Muhammadu Buhari, lórí ọ̀rọ̀ tó n lo àti ìpolongo, Femi Adesina tí rọ àwọn ọmọ Nàìjíríà láti tẹ́síwájú nínú sùúrù tí wọ́n ni pẹ̀lú ààrẹ Muhammadu Buhari, pàápaá jùlọ lórí ọ̀rọ̀ àbò tó mẹ́hẹ Adesina sọ ọ̀rọ̀ yìí lásìkò eto kan lórí móhùnmáwòràn Channels lọjọ́ Àìkú.
Ninu esi ayẹwo tuntun naa, ipinlẹ Eko ni apapọ eeyan 64, Abuja si ni 24.
Ẹ wò ó, ogun àsọtẹ́lẹ̀ nìyí.
Ninu atejade kan ti akole re dale, “Fifaake kori awon adari kan lati gbejoba sile” ile-ise ti o ri si oro ile okeere so pe, ipo ti egbe alaaanu wa buru jai lorile-ede DRC, botile pe, olori orile-ede naa, ko faye sile fun eto idibo to ye ko waye, eyi ti o sokunfa bi o se padanu akoso eto aabo orile-ede naa.
39 Àti láti yan àwọn alàgbà míràn, àwọn àlùfáà, àwọn olùkọ́, àti àwọn díákónì.
Eyi to tumọ̀ si pe ọọdunrun ọkọ BRT pere lo fi owo naa ko wọ ilu, tawọn eeyan fi oju ri.
Wo àwọn èèyàn jáńkán tí yóò ṣe ọdún tuntun ní ọgbà ẹ̀wọ̀n Àwọn fóònù wọ̀nyìí kò ní lè ṣe WhatsApp láti ọdún 2020 Àfàìmọ̀ kí Naira Marley má fi ẹ̀wọ̀n bẹ̀rẹ̀ ọdún 2020 Odunlade àti Femi Adebayọ: Wo ohun tó yà wá sọ́tọ̀ nínú àwọn arẹwà ọkùnrin Oríṣun àwòrán, fausat balogun Àkọlé àwòrán, Rafiu Balogun ati Fausat Balogun (Madam Ṣajẹ Rafiu Balogun ati Fausat Balogun (Madam Ṣajẹ) Lara awọn agba lọkọlaya lagbo oṣeere tiata Yoruba ni Fausat Balogun ti ọpọ mọ si 'Madam Ṣajẹ' wa.
Rwanda gbe'lẹkun ṣọọsi 700 ti pa Àwọn 'ẹ̀bùn' tí ikú George Floyd fún àgbáyé Koko iroyin: Àyẹ̀wò di ọ̀ranyàn ni sọọsi, Ẹ̀mí èṣù ni okunfa ipààyàn Benue Ìlànà tí ìjọba Eko gbé kalẹ̀ fún ìjọsìn lásìkò Covid-19 kò bá wa lára mu - Chris Okotie Òfìfo ṣọ́ọ̀ṣì pa aṣọ dà fún àwọn Páṣítọ̀ Nàìjíríà Oríṣun àwòrán, Facebook/Gabola-Church Oludasilẹ ile ijọsin naa Pope Tsietsi Makiti salaye fun akọroyin BBC to ṣabẹwo sile ijọsin naa lati mọ bi nkan ṣe n lọ lasiko yi pe ''awọn ko kọ ki ijọba ti awọn mọle titi di igba ti Jesu yoo fi pada wa.
Lasiko to fi n dahun ibeere lori eto redio kan nilu Ibadan ni Gomina Makinde sọ eyi.
Irúgbìn mìíràn bọ́ sórí ilẹ̀ dáradára, ó dàgbà, ó sì so èso.
Afegbua yoo pada s'ọdọ ajọ DSS Buhari: Ẹ fira yin jin f‘orilẹede Naijiria Tani Ọjọgbọn Mahmood Yakubu ti yóò ṣètò ìdìbò 2019?
Oríṣun àwòrán, others O fi kun pe nigba ti oun wa lori akete aisan ni ilu awon ni iyawo oun ke gbajare pe iya n jẹ oun ati ọmọ ti oun si ni ki wọn ba oun ta mọto ti oun fi n ṣiṣẹ ki wọn si ko owo naa fun Gloria ko fi bẹrẹ okoowo ki o le maa san owo ile iwe ọmọ.
Olukọ̀ni fún ikọ̀ Arsenal náà tí ó jẹ́ ọmọ ọdún méjìdínláàdọ́rin ni òun dúpẹ́ fún iye ọdún to ti lò gẹ́gẹ́bíi olùdari Arsenal.
soro lati gbogun ti iwa ijinigbe-jinipa.
Ṣebí a sọ fún ọ ní Ijipti pé kí o fi wá sílẹ̀ kí á máa sin àwọn ará Ijipti tí à ń sìn, nítorí pé kì bá sàn kí á máa sin àwọn ará Ijipti ju kí á wá kú sinu aṣálẹ̀ lọ.
Mo sì tún ranṣẹ pe Joiaribu ati Elinatani, tí wọ́n jẹ́ amòye.
May yoo tun gbiyanju fun igba kẹta ni ọjọbọ lati tun rọ awọn aṣofin orilẹede naa lati tẹwọ gba aba adehun naa lẹyin to ti jẹ ẹjẹ ati fi ipo silẹ.
Ó bá dá mi lọ́kàn le, ó ní, “Má bẹ̀rù, Daniẹli, nítorí láti ọjọ́ tí o ti pinnu láti mòye, tí o sì rẹ ara rẹ sílẹ̀ níwájú Ọlọrun rẹ, gbogbo ohun tí ò ń bèèrè ni a ti gbọ́, adura rẹ ni mo sì wá dáhùn.
Wọn ti pa aisan olode tabi ṣanpọnna, (Small pox) run, ti o si ti n mu iparun awọn aisan miran bii rọmọlapa-rọmọlẹsẹ sun mọ etile.
Nígbà tí àwọn tí ó wà pẹlu Jesu rí i, wọ́n ní, “Oluwa, ṣé kí á fa idà yọ?
Awọn oniṣowo ti bi bọda ṣe wa ni titi pa ṣe akoba fun yoo bẹrẹ iṣẹ pada.
Ní àkókò kan, agbọ́tí Farao, ọba Ijipti, ati olórí alásè rẹ̀ ṣẹ ọba.
Ṣugbọn bí ọkàn yín bá yipada, tí ẹ kọ̀, tí ẹ kò gbọ́ tirẹ̀, tí ẹ bá jẹ́ kí wọn fà yín lọ bọ àwọn oriṣa, tí ẹ sì ń sìn wọ́n, 
Eniola Badmus kilọ fun awọn to n bu pe o ti sanra ju lati dẹyin lẹyin oun.
Hakeem Otiki Inu aga arọ ti ko lẹsẹ naa ni ọgagun Hakeem Otiki ti wa sile ẹjọ awọn ologun lọdun 2020.
Àwọn obinrin wa lè máa rìrìnàjò lọ orilẹ̀èdè míì báyìí - Ìjọba Saudi Kí ni Oluwo lọ ṣe ní Aso Rock lẹ́yìn lẹ́tà rẹ̀ sí ààrẹ Buhari?
Bi o tilẹ jẹ pe ọpọ ẹbi, ọrẹ, ojulumọ ati alajọse nidi oselu lo ti peju sile rẹ lati daro iku rẹ, amọ ẹtahoro wọn lo bawọn peju sibi ti wọn ti sin oku rẹ.
ifẹsẹwọnsẹ ọhun, sugbon won ni, eegun to koo jo iran niru won ma n pada wo
Sàká: Oun tí orí bá yàn fún ẹ̀dá ni kó ṣe
"Oṣiṣẹ ajọ to n ri si iṣẹlẹ pajawiri ni ipinlẹ naa, usman Kachalla wi fun ile iṣẹ iroyin AFP pe ""iye ẹmi to nu ti to ọgbọn ti o si le ni ogoji to fara pa."
“Nítorí náà, OLUWA Ọlọrun ní, ‘Nítorí pé o ka ara rẹ kún ọlọ́gbọ́n bí àwọn oriṣa, 
Kí ó gbé ìyẹ̀fun náà tọ alufaa wá, kí alufaa bu ẹ̀kúnwọ́ kan ninu rẹ̀ gẹ́gẹ́ bí ẹbọ ìrántí, kí ó sì fi rú ẹbọ sísun lórí pẹpẹ sí OLUWA, ẹbọ ìmúkúrò ẹ̀ṣẹ̀ ni.
Èyí ni a fi mọ̀ pé àkókò ìkẹyìn nìyí.
Ṣíbẹ̀ Àyédèrú=ẹ̀dá ṣe ìtọ́jú wa tó bẹ́ẹ̀ ti n kòì tíí rí ẹni ti ó tọ́jú ènìyàn tó bẹ́ẹ̀ rí.
Àṣẹ yìí gbọdọ̀ múlẹ̀ ní gbogbo ilẹ̀ Pasia, ní ọjọ́ tí wọ́n yàn láti pa gbogbo àwọn Juu, ní ọjọ́ kẹtala oṣù kejila, tíí ṣe oṣù Adari.
Ti ọmọ naa ba jẹ ọmọ okunrin, Babajide, Babatunde, Babawale, Babarinde ni wọn n sọ ọ.
Nínú ọ̀rọ̀ rẹ nígbà tí ó ń bá àwọn akoroyin sọ̀rọ̀, Dókítà, Taiwo Olagbe, tí ó jẹ ọkan lára àwọn dókítà náà ṣàlàyé pé, ijoba ipinle Ondo pá wọn ti nígbà tí ọ̀pọ̀ nínú wọn ń koju bíbá aarun Corona ń fínra nípa titoju àwọn tí ó fara kaasa aarun náà.
Àwọn ni wọn óo ni ín títí lae,wọn óo sì máa gbé ibẹ̀ láti ìrandíran.
Ọlọrun ti sọ̀rọ̀ ninu ilé mímọ́ rẹ̀,ó ní, “Tayọ̀tayọ̀ ni n óo fi pín Ṣekemu,n óo sì pín àfonífojì Sukotu.
Idi ni pe ilana electoral college ti Amẹrika n lo ko tumọ si pe bi eeyan ba ni ibo to pọju lọ yoo jawe olubori.
Iwadi fi han pe to ba n ṣiṣẹ ọmọ ọdọ ile ounjẹ,ọdun miliọnu marun un le diẹ ni yoo fi ṣiṣẹ ki o to le ri iru owo yi .
- Agbẹnusọ Kassim Ó pé mi kí n kú jù kí n darapọ̀ mọ́ ẹgbẹ́ APC - Fani-Kayode China o, Nàìjíríà o, kò s'áyè òwò mọ́ ní Ghana!
Oríṣun àwòrán, Getty Images Awọn alufaa ijọ aguda mẹrin ti wọn lugbadi ajinigbe ni Ìjọba Ibilẹ Ethiope ni Ipinlẹ Delta lọjọru ni awọn ajinigbe ohun ti saaju beere ọgọrun miliọnu Naira lati tu wọn silẹ.
Shiite ni ọlọpaa ti pa mẹta ninu àwọn ni Kaduna lasiko iwọde iranti iku ọmọ ọmọ Anọbi.
"Oríṣun àwòrán, Lizzy Anjọrin ""Ẹ jẹ ki n danu duro diẹ na, ma tun tẹsiwaju nipa itan igbesi aye mi lọjọ miran, ọjọ re."
Chelsea na Brighton mọle pẹlu ami ayo meji sọkan lọjọ Aiku.
Vee Oríṣun àwòrán, BIG BROTHER NAIJA Vee gan-an ko ni i ṣanwọ ofo pada sile lẹyin eto BBNaija.
mo sì fún Isaaki ni Jakọbu ati Esau.
Ọgbẹni Garba ni niwọn igba ti wọn ti paṣẹ ki iwadii bẹrẹ lori iṣẹlẹ to iyalẹnu ti awọn ọlọpaa yii, aarẹ Buhari ti ṣe ni ibamu pẹlu ofin.
Titi laelae si la o maa ranti akọni onkọwe naa fun ipa ribiribi to ko si ede Yoruba, bi o tilẹ jẹ pe J.
Olori Badrat, bẹẹ ba gbagbe, ni ẹnu n kun pe o ti kuro ni aafin Ọba Lamidi Olayiwola Adeyemi Kẹta gẹgẹ bii olori rẹ.
Ẹsun kikowo ilu jẹ ni ajọ EFCC nwa ọga agba DSS ọhun fun.
Ẹ má tilẹ̀ kí i, “Kú ààbọ̀.
Ẹmemanka ni Ikpeazu kọ ni gomina akọkọ ti yoo ni Coronavirus ni Naijiria, ati pe oun naa yoo ru la bi awọn akẹgbẹ rẹ iṣaaju.
 Àwọn ẹka ọnà tí ó fẹ ́ ràn ni yíya ọoṃdébìrin tí ó wà ní ìhòho .
Oríṣun àwòrán, AFP Àkọlé àwòrán, Ni orilẹede Kenya, awọn onijo n gba ẹrọ isọ kọja ki wọn to wọ papa ọkọ ofurufuu Jomo Kenyatta lati ki ife ẹyẹ bọọlu agbaye kaabọ sorilẹede naa.
Ọ̀pọ̀ àwọn to bá si yèé, wọ́n a maa ni àpá lára tàbi ki wọ́n fọ́ lójú.
Awọn miran ti wọn tun jawe lọ gbe ile rẹ fun ni, Adari ile iwosan ẹkọsẹ isegun fasiti naa, KSUTH, Kolawole Ogundipe ati adari ile ẹkọ giga to wa ni Ikẹrẹ-Ekiti, Ọjọgbọn Mojisola Oyaraqua.
Ẹ ṣọ́ra kí ẹnikẹ́ni má jẹ́ oníṣekúṣe tabi alaigbagbọ bíi Esau, tí ó tìtorí oúnjẹ ẹ̀ẹ̀kan péré ta anfaani tí ó ní gẹ́gẹ́ bí àrólé baba rẹ̀.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ejo abami to n mu owo ni ajọ Jambu Ninu ọrọ Lar to nmojuto eto idanilọla fun Bashir Umar lo ti ni ootọ inu ati iwa ọmọluwabi jẹ ọkan gboogi lára abuda adamọ ọmọ ogun ofurufu rere.
Uwa lọtun, Uwa l'osi, bi ẹni pe oun nikan ni ọmọ to wa ninu ṣọọṣi.
Wọn kò gbọdọ̀ farahàn níwájú OLUWA ní ọwọ́ òfo.
Láti ojú ọ̀run ni àwọn ìràwọ̀ ti ń jagun,àní láti ààyè wọn lójú ọ̀nà wọn,ni wọ́n ti bá Sisera jà.
Eyi tumọ si pe kii ṣe awọn ọmọ ẹgbẹ oṣelu Sẹnetọ tabi aṣoju-ṣofin naa nikan lo lẹtọ lati maa wa sibẹ pẹlu ẹdun wọn.
Yóo pada sí ìlú olódi ti ara rẹ̀, ṣugbọn ijamba yóo ṣe é, yóo sì ṣubú lójú ogun; yóo sì fi bẹ́ẹ̀ parẹ́ patapata.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Àsìkò Amojúẹ̀rọ Seyi ni ló fi wọlé l'Oyo, kìí ṣe àsìkò èmi Omobolanle' Fun awọn ti agbara ojo naa ba ka mọ irinajo, ni wọn ni ki wọn yẹra fun ijamba, wọn ni lati wa ọna lati wa ọkọ wọn sibi kan, ki wọn si jade ninu rẹ ni kiakia.
O tesiwaju ninu oro re wi pe awon obirin ati awon odomode ni won sa fi ibugbe won sile nilu Kono ni apa ila – oorun orile-ede naa leyin ti won kolu awon omo egbe oselu Sierra Leone People’s Party (SLPP) eyi ti o je ti Ogbeni Bio.
Igi ìyè yìí ń so èso mejila, ọ̀kan ní oṣooṣù.
Bí wọ́n ti ń gbádùn ara wọn lọ́wọ́ ni àwọn ọkunrin lásánlàsàn kan aláìníláárí, ará ìlú náà, bá yí gbogbo ilé náà po, wọ́n bẹ̀rẹ̀ sí lu ìlẹ̀kùn.
Gbogbo awọn eeyan yii wa ba mọlẹbi Tolulope kẹdun, ti wọn si gbadura pe Ọba oke yoo fun wọn ni ọkan akin lati gba adanu nla naa mọra.
"- Ìwádìí BBC Àwọn òṣèré tíátà kan rèé, tí wọn fẹ́ ara wọn, tí ìgbeyàwó wọn sì pẹ́ 'Èmi àti Toyin Abraham ṣẹ̀ sọ̀rọ̀ fún ìgbà àkọ́kọ́ láti ọdún méjì torí ìjà òun àti Lizzy' Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Funke Akindele jẹ àkàndá ẹ̀dá - Adaku Ibi ti Funke Akindele ti di gbajugbaja ni ninu ere rẹ to ṣe ni ọdun 2008, ""Jennifer"" eyi to tan kari aye kari oko."
"Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Mo ti kó kúrò nílé Olu Jacobs rí lẹ́ẹ̀mejì- Joke Silva ""Mo fẹ́ pa ara mi torí ojú àbùkù tí wọn ń fi wò mí pé mo fi iṣẹ́ abẹ bímọ"" Èmi àti Saheed kìí ṣe ọmọdé, a ti jọ ṣe Sinimá papọ̀, èyí túmọ̀ sí pé ìjà ti parí - Fathia Balogun Yatọ̀ fún orí ìtàgé, wo ohun tí o kò mọ̀ nípà Mr Latin Àrà méèrírí!"
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Seyi Makinde: Ibùdó ìlera tó wà ní Idí Iroko-Adewole tí bàjẹ́ pátápátá Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Seyi Makinde: Ibùdó ìlera tó wà ní Idí Iroko-Adewole tí bàjẹ́ pátápátá 30 Òkùdu 2020 Awọn oṣiṣẹ ile iwosan Idí Iroko-Adewole ni ijọba ibilẹ Oluyole nipinlẹ Oyo ti kesi ijọba Gomina Seyi Makinde, lati ṣe atunṣe si ibudo ilera naa.
 ( ; / ˈnɛsleɪ , ˈnɛsəl , ˈnɛsli / , tì a mó télè si : / ˈnɛsəlz / ) jẹ ́ ilé-iṣẹ ̀ aṣońjẹ ti orílè-èdè swiss , tí olú-iléesé wọn wà ní vevey , vaud , switzerland .
Nigba idibo gomin ato kọja gan, awọn aworan ati fidio ti wọn s'afihan bi wọn ṣe lo owo nibi rira ibo n kakiri lori ẹrọ ayelujara.
Iroyin to tẹ wa lọwọ ni isoro ẹrọ kaadi to n yẹ orukọ awọn oludibo wo, to n se segesege gan tun da kun ọpọ isoro to wa nidi kudiẹkudiẹ to ba eto idibo naa.
Ilé ńlá àràmàndà tó di ọgbà ẹ̀wọ́n
Àwọn igi bá lọ sí ọ̀dọ̀ igi ọ̀pọ̀tọ́, wọ́n sọ fún un pé kí ó wá jọba lórí àwọn.
Oríṣun àwòrán, @Ransome-Kuti Àkọlé àwòrán, Akọni obìnrin Olufunmilayọ Ransome-Kuti Ọjọ kẹta, oṣù kinni, ọdún 1949 jẹ́ ọjọ́ málegbàgbé ni Abẹokuta nipinlẹ Ogun.
dapo ma baa sele ni ilu Ibadan.
Awọn ibi ti àwọn Alaboyun maa n fẹ bimọ si ni Naijiria: Opọlọpọ àwọn Alaboyun Naijiria ni wọn maa n fẹ bimọ sinu ilé wọn tabi lọdọ awọn agbẹbi ladugbo tabi ki iyale wọn gbẹbi fun wọn Nigba ti awọn mii maa n fi oyun inu wọn bí abíọ́nà nibikibi ti ọmọ ba ti mu wọn ni wọn a bii si bii opopona, ọna ọja, oko, tabi loju titi laiyọ lẹnu irin ajo silẹ.
Koda ọpọlọpọ fidio lawọn ọmọ Naijiria fi ranṣẹ si Mama Adeboye gẹgẹ bi ikini ku ọjọ ibi to fi mọ awọn oṣere adẹrinpoṣonu gan atawọn ọmọ ijọ irapada gan.
Ní agbo ọ̀rẹ́ẹ wa, àgọ́ alòdìsí àjọ̀dún Òyìnbó àti alòdìsí alòdìsí àjọ̀dún Òyìnbó ń ṣe àríyànjiyàn.
Kí ibùdó wọn ó di ahoro,kí ẹnikẹ́ni má sì gbé inú àgọ́ wọn.
“Ó bá sọ fún àwọn tí ó dúró níbẹ̀ pé, ‘Ẹ gba owó wúrà náà ní ọwọ́ rẹ̀, kí ẹ fún ẹni tí ó ní owó wúrà mẹ́wàá.
Dele ṣalaye pe idajọ erefee ni ile ẹjọ kotẹmilọrun da, ati pe ile ẹjọ naa ko foju sunnunkun wo ẹjọ ọhun ki o to dajọ.
Makinde sàbẹ̀wò sí LAUTECH, ó gbé owó ₦500m kalẹ̀ láti tán ìyanṣẹ́lódì àwọn olùkọ́ Àṣírí tú!
Nigba tiyẹn ko ṣẹlẹ, Armstrong tun sọtẹlẹ pe yoo ṣẹlẹ laarin ọkan ninu awọn ọdun ọtọọtọ yii - 1943, 1972 ati 1975 pe igbasoke yoo waye ṣugbọn gbogbo rẹ ko ṣẹlẹ.
8 Ṣùgbọ́n, kíyèsíi, mo wí fún ọ, pé o gbọ́dọ̀ kọ́kọ́ ṣe àsàrò rẹ̀ nínú iyè rẹ; lẹ́hìnnáà ìwọ gbọ́dọ̀ bèerè lọ́wọ́ mi bóyá ó tọ́, bí ó bá sì tọ́, èmi yíò mú kí oókan àyà rẹ kí ó gbóná nínú rẹ; nítorínáà, ìwọ yíò mọ̀ lára pé ó tọ́.
Mose bá gbẹ́ wàláà òkúta meji gẹ́gẹ́ bíi ti àkọ́kọ́, ó gbéra ní òwúrọ̀ kutukutu, ó gun òkè Sinai lọ gẹ́gẹ́ bí OLUWA ti pàṣẹ fún un; ó kó àwọn wàláà òkúta mejeeji náà lọ́wọ́.
Bakan naa la tun mọ nipa awọn ọna ta le gba lati san eto yii pada laarin awọn eeyan to ba n kopa ninu rẹ.
Kí ló dé tí eniyan burúkú fi wà láàyè,tí ó di arúgbó, tí ó sì di alágbára?
Bakan naa ni iwadi fihan lati ọdọ awọn akẹkọ faisti naa pe ohun ọjọgbọn Richard Akindele lo wa ninu ohun ti wọn gba silẹ naa.
Ẹ sì lè rà láàrin àwọn àlejò tí wọ́n wà láàrin yín ati àwọn ìdílé wọn tí wọ́n wà pẹlu yín, tí wọ́n bí ní ilẹ̀ yín, wọ́n lè di tiyín.
Ọkunrin kan ninu àwùjọ kígbe pé, “Olùkọ́ni, mo bẹ̀ ọ́, ṣàánú ọmọ mi, nítorí òun nìkan ni mo bí.
ṣe bí o ti mọ, ìwọ ọ̀rẹ́ mi, rí i pé ìyàwó rẹ fẹ́ràn rẹ kí ó tóó wọ ilé rẹ.
lojo Abameta lasiko eto idibo gomina ati ile igbimo asoju El-Rufai  tun wa fi asiko naa dupe pupo lowo awon ara
Aston Villa lo kọkọ gba goolu sawọn Chelsea ninu ifẹsẹwọnsẹ ọhun.
Eyi mu ki BBC Yoruba o kàn si igbakeji akọwe iroyin fun gomina, Ọgbẹni Gboyega Akosile.
Mo bá a tí ó ń mọ ìkòkò kan lórí òkúta tí wọn fi ń mọ ìkòkò.
Gege bi o se sọ: “Eto
Orilẹ̀-èdè South African jk ibùgbé fún sps àwọn àtìpò ni àgbáyé Oríṣun àwòrán, AFP Àkọlé àwòrán, Àwọn tó ń fẹ̀hónú han fọn sí ìgboro lẹ́yìn tí wọn fẹ̀sùn kan pé àwọn to ní iss ń ta àyéderun ọja àti àwọn nkan ti ọjọ ori ti pẹ́ kajá àlà.
Wọ́n ti rí òkú Alága ẹgbẹ́ APC ní Nasarawa tí àwọn agbébọn jí gbé lọ́jọ́ Satide Ṣugbọn asiri awo yi pada tu si ọwọ awọn igbimọ amuṣẹya lọwọ lẹyin ti iwe iroyin kan gbe ọrọ bi Kayode ṣe ni ki Ekanem san owo si akoto ifowopamọ si rẹ.
O ni iwa ti ko boju mu ni lati sọ pe ki agbalagba gbẹnu dakẹ.
Mo sọ fún ẹni tí ó dúró tì mí pé, “Olúwa mi, gbogbo ara ni ó wó mi, nítorí ìran tí mo rí, ó sì ti rẹ̀ mí patapata.
Ní ilẹ̀ Yorùbá ati níbi gbogbo ti ẹ̀dá ènìyàn ń gbé, ìbágbépọ̀ ẹ̀dá ṣe pàtàkì púpọ̀.
” Ó bá pe orúkọ ibẹ̀ ní Baali Perasimu.
O na ọwọ́ ọ̀tún rẹ,ilẹ̀ sì yanu, ó gbé wọn mì.
O ni o di ọjọ kẹrindinlọgbọn oṣu kẹwaa ki ileewe to tun ṣi pada.
O fikun ọrọ rẹ pe bi wọn ti yọ oun kuro ninu awọn oludije ibo abẹle fun idibo gomina ipinlẹ Edo ko sẹyin bi alaga apapọ ẹgbẹ oṣelu APC, Adams Oshiomhole ti sọ pe oun ni ileẹjọ to ga julọ ninu ẹgbẹ naa.
dokita Abubakar Bukola Saraki, gege bi asoju re bayii.
Wò ó, mo ti sọ ọ́ di ìlú tí a mọ odi yíká lónìí, o di òpó irin ati ògiri tí a fi bàbà mọ fún gbogbo ilẹ̀ yìí, ati fún àwọn ọba ilẹ̀ Juda, àwọn ìjòyè, ati àwọn alufaa rẹ̀, ati àwọn eniyan ilẹ̀ náà.
Orin yii gba igboro debi pe awọn ololufẹ n beere ẹbun assurance lọwọ ara wọn bi Davido ṣe fun Chioma ololufẹ ẹ.
Ikọ agbabọọlu ilẹ Gẹẹsi Leicester City ni Musa ti darapọ mọ ẹgbẹ agbabọọlu Al Nassr FC lorilẹede Saudi Arabia Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 3 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 5 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
#EndSARS: Àwọn olùwọ́de kọ etí ikún sí àṣẹ ijọba, wọ́n tẹ̀sìwájú ìwọ́de l'Abuja Pásítọ̀ Enoch Adeboye darapọ̀ mọ̀ #ENDSARS, ó fún ìjọba Nàìjíríà ní ìmọ̀ràn ọ̀nà àbáyọ MC Oluọmọ gbé ara rẹ̀ ṣépè nítorí ìwọ́de #ENDSARS Wo àwọn ojúṣe àti èèwọ̀ fún ikọ̀ ọlọ́pàá SWAT tó gba iṣẹ́ lọ́wọ́ SARS Toyin Abraham tú àṣírí ohun tí ọlọ́pàá Náìjíríà sọ mọ́lẹ́bí rẹ̀ kan dà Oríṣun àwòrán, @Sanwo Olu Yatọ si eyi, Sanwo-Olu tun kede pe ijọba ti ṣeto miliọnu lọna igba Naira, lati fi tu awọn eeyan to kagbako ifiyajẹni lọwọ ọlọpaa, ati igbimọ oluwadii ti yoo ṣe amojuto rẹ.
ṣugbọn ni atunja ija wọn to waye lẹyin oṣu meje, Lewis fọ lẹnu tan yanyan ni Las Vegas.
Eyi waye lẹyin ti iroyin naa jade sita.
Baba toní o ó dà lo dàyìí
Omoyele Sowore ni awọn osisẹ ajọ ọtẹlẹmuyẹ mu si ahamọ wọn lọjọ Satide to kọja saaju iwọde ẹgbẹ Revolution Now to waye lọjọ Aje, ti wọn si tun gba ile ẹjọ lọ pe awọn fẹ gba asẹ lati fi asaaju ikọ oluwọde naa si ahamọ fun aadọrun ọjọ, tii se osu mẹta gbako.
Ọpọlọpọ eniyan bá gbà á gbọ́ níbẹ̀.
igbesẹ ti wa ni sẹpẹ fun ifilọlẹ eto fifun awon omo ile iwe ni ounje ofe.
Kii fun mi ni ounjẹ, emi ko si fẹ tii ku bayi nitori onuruuru ọkunrin lo maa nwa sun ti ninu ile wa.
Fun iru ede to rẹwa, to si yaayi lati sọ, bii ede wa yi, ohun to rọrun lati foju sọna fun ni eyi.
Wọ́n níláti sọ ohun tí ó wà ninu ìwé náà di òfin ní gbogbo ìgbèríko, kí wọ́n sì sọ fún gbogbo eniyan, kí wọ́n lè múra sílẹ̀ de ọjọ́ náà.
- Kemi Afolabi Àwọn ọmọ Nàíjíríà ń bèèrè pé taa ní ààrẹ Nàíjíríà ní Aso Rock?
Òdodo ọ̀rọ̀ nìyí, ó sì yẹ kí eniyan gbà á tọkàntọkàn.
Bẹ́ẹ̀ ni Olówó-ayé sọ tí ó fi orí lé ọ̀nà Igbó Olódùmarè, ojú rẹ̀ si ti yípadà, ó ń pọ́n kankan.
Lẹ́yìn rẹ̀ ni Eseri ọmọ Jeṣua, aláṣẹ Misipa, náà ṣe àtúnṣe apá kan lára ibi ihamọra ní ibi igun odi.
Oríṣun àwòrán, @NGRSenate Àkọlé àwòrán, Osu kẹrin lẹyin ti Aarẹ Buhari gbe aba eto isuna ọdun 2018 kalẹ, ko tii lojuutu niwaju awọn asofin apapọ O sọ ọ̀rọ̀ naa lẹyin ti Aarẹ Muhammadu Buhari ṣe ipade l'Ọ́jọ́rú, pẹlu awọn gomina to kù sinu ẹgbẹ oṣelu APC.
Donald Trump ní àwọn ọmọ ogun IS yi wà lára àwọn tó burù julọ nínú ìkọlù Morenike sàlàyé pé Orílẹ-ede Naijiria ti kọja pe a fẹ ki obinrin di aya ààrẹ tàbi aya gomina nikan, sùgbọn kì àwọn gan an jẹ aarẹ tabi gomina funra wọn.
Ni lọọlọ yii, Zimbabwe jẹ ilu to ṣe pe kii ṣe Coronavirus nikan lo n ba wọn finra, to fi mọ iṣoro ọrọ aje to jinra atọrọ oṣelu pẹlu.
Gege bi iko agbaboolu West Bromwich Albion se so lori ero ayelujara iko naa “West Bromwich Albion ati Alan Pardew ti fenuko lati fopin si ibasepo won,”Bakan naa, ni won so pe Darren Moore yoo maa sakoso iko ohun bayii gege bi adele.
Ko si ẹni lee sọ iye awọn eeyan to fara kaasa ninu idarudapọ naa.
FMW/ twitter Àkọlé àwòrán, Gomina ana ni ipinlẹ Eko, Raji Fasọla n gba owo ifẹyinti leko, o si tun n gba owo osu gẹgẹ bii minisita Ọgbẹni Mumuni tun salaye wipe asiko to lati pe awọn asiwaju ti ko nifẹ araalu sita wa jihin isẹ iriju ti ilu ran wọn dipo ki wọn maa fi ọwọ ọla gba araalu loju.
Nigba to ba ile iṣẹ BBC sọrọ, ọgbẹni Agbakoba oun ko lee gba ohun ti aarẹ Buhari ṣe gbọ.
Oyo state: Ẹ̀mí mẹ́rin bọ́ sọnù, ọ̀pọ̀ èèyàn fara pa nínú ìjàmbá ọkọ̀ l'Ogbomoṣọ Eeyan ẹrin ọtọọtọ lo padanu ẹmi wọn ti ọgọrọ awọn eeyan mii si fi ara pa ninu ijamba ọkọ to waye nilu Ogbomoṣọ lọsan ọjọ ẹti.
Eyi lo difa fun awọn ọmọ orilẹede Naijiria to ti fi ilu kan ni London ṣe ibugbe fun ọjọ pipẹ, Peckham.
Israẹli bá pe Josẹfu, ó ní, “Ǹjẹ́ Ṣekemu kọ́ ni àwọn arakunrin rẹ da ẹran lọ?
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Èrò àwọn ènìyàn lórí ẹ̀rọ àyélujára nípa ìdámẹ́wàá sísan 13 Ìgbé 2018 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Kí la tún gbọ́ nípa ìdámẹ́wàá?
To- lórí tẹlẹ́mù tọ̀kọ̀tùlùú ló pàwọ̀dà di dúdú fún ọ
2 271200 Orilẹede Morrocco 6492 18.
ng, tabi ki wọn kan si oju opo ileeṣẹ ọlọpaa lori ayelujara.
Kí ni n óo ti ṣe yín sí, ẹ̀yin ọmọ Seruaya?
UEFA f'ẹ̀sùn kan Bayern Munich Salah dá iná yá Anfield lára Messi di aláṣẹ lórí ohun eèlò tó gbé orúkọ rẹ̀ Ikọ̀ Real Madrid ń gbìyànjú láti gba Champions League l'ẹ́ẹ́kẹ̀ta lẹ́yìn ìgbàtí wọn ti gbàá lẹ́mèejì léra wọn.
Ṣugbọn nígbà tí ìdánwò dé, wọ́n bọ́hùn.
Sanbalati ati Geṣemu ranṣẹ sí mi, wọ́n ní “Wá, jẹ́ kí á pàdé ní ọ̀kan ninu àwọn ìletò tí ó wà ní pẹ̀tẹ́lẹ̀ Ono.
Kí èyíkéyìí má ní àbùkù nígbà tí Oluwa wa Jesu Kristi bá farahàn.
Ti a ko ba gbagbe, Ajọ Amuṣẹya lori aarun Coronavirus ni ipinlẹ Imo lo ke gbajare pe eniyan mẹẹdọgbọn ti sa kuro ni ile ayẹwo aarun Coronavirus ni ipinlẹ Imo.
Àkọlé àwòrán, Witi witi ni awọn eniyan pe jọ lati gbọ esi idibo ni wọọdu ati ekun idibo wọn.
Eyi tumọ si pe, awọn ọna miran ni awọn to n bọ lati Lagos Island lọ si ọna Iyana Oworo, yoo gba laarin asiko yii.
L'Ọjọru ni ileeṣẹ ijọba to n ri si ere idaraya ati idagbasoke awọn ọdọ kede eto naa lati maa fun awọn mama oloogbe agbabọọlu Naijiria mejeeji tẹlẹ ni ẹgbẹrun mẹwaa naira loṣooṣu gẹgẹ bi owo iranwọ.
Àwọn ọkunrin tí ó ń bá a rìn dúró.
Ẹnikẹ́ni ninu ìdílé rẹ tí ó bá kú láàrin ìlú, ajá ni yóo jẹ òkú rẹ̀, èyíkéyìí ninu wọn tí ó bá sì kú sinu igbó, àwọn ẹyẹ ni yóo jẹ òkú rẹ̀.
Mo lè sọ arúgbó dí ọmọge nígbàkúgbà - Hakeem Effect 'Dokita ilé ìwòsàn ló gba ẹsẹ̀ lọ́wọ́ mi' Eyi lo mu ki BBC News Yoruba gbe ọrọ naa tọ ẹni ti awọn oṣere tiata Yoruba yan gẹgẹ bi aarẹ wọn, iyẹn Ọgbẹni Bọlaji Amuṣan ti ọpọ mọ si Mr.
Lẹyin ti iroyin ni awọn ọlọpaa ṣe ikọlu si wọn, ni a ti gbọ pé ọrẹọkunrin rẹ, Emmanuel Akomafuwa, naa si wa ni ile iwosan lẹsẹ kan aye, ẹsẹ kan ọrun.
Bẹ́ẹ̀ náà sì ni ìwọ̀n àtẹ́rígbà wọn, ní ẹ̀gbẹ́ kinni keji.
Eyín akọ̀ròyìn fò yọ lásìkò tó n ka ìròyìn lọ́wọ́ lórí tẹlifísàn Coro wà Coro ò sí o, èmi á lọ́ sókè òkún bí mo bá ríṣẹ́ - dókítà Oríṣun àwòrán, OTHERS Sinima àgbéléwò Yoruba kan ti wọn pe orúkọ rẹ ni One Million Boyz ti ẹ jade lọdun 2014, eyi to safihan ihuwasi wọn.
" aureus "" ( mrsa ) bá jẹ ́ ìṣòro , wọ ́ n lè júwe doxycycline tàbí trimethoprim / sulfamethoxazole fún wọn ."
Lẹ́yìn náà, Solomoni ọba ranṣẹ sí àwọn àgbààgbà Israẹli: àwọn olórí ẹ̀yà kọ̀ọ̀kan, ati gbogbo àwọn olórí ìdílé kọ̀ọ̀kan, ó pè wọ́n jọ sí Jerusalẹmu láti gbé Àpótí Ẹ̀rí OLUWA láti Sioni, ìlú Dafidi, wá sinu ilé OLÚWA.
Ohùn tí Brexit túmọ sí fún ilẹ̀ Áfríkà rèé Corovavirus: Àjọ WHO tí bẹ̀rẹ̀ ètò láti ran àwọn orílẹ́-èdè Afrika lọ́wọ́ Ìdílé kan gbé ilé iṣẹ́ ọkọ̀ òfurufú lọ ilé ẹjọ́ lẹ́yìn tí wọ́n léwọ̀n dànù nínú ọkọ̀ pé ara wọ́n ń rùn Ìròyìn òfegè lásán ni!
O ṣiṣẹ olukọni to n ṣabẹwo ni ẹka ikọni nipa iṣelu àti ibudo ikọni nipa Aáwọ̀ píparí ni Fasiti ọgba ẹranko ti sánmọ́ntì gbé dunlẹ̀ ni Ibadan.
Lara awọn ere to ti se ni ''Sunday Dagboru, Alani Pamọlekun, Mufu Oloosha oko ati Adebayo Arẹmu Abẹrẹ''.
Ọba ìlú Gasa yóo ṣègbé, ìlú Aṣikeloni yóo sì di ahoro.
O Davies Oun ni Olootu agba fun iwe iroyin Daily Service Newspaper lọdun 1943, to si tun wa lara awọn to da iwe iroyin Iroyin Yoruba silẹ Samuel Ladoke sisẹ bii Agbẹjọro pẹlu Chris Ogunbanjọ, Bọde Thomas ati Michael Ọdẹsanya Oun ati awọn eeyan kan, to fi mọ Oloye Ọbafẹmi Awolọwọ ni wọn dijọ da ẹgbẹ oselu Action Group (AG), eyiun ẹgbẹ ọlọpẹ silẹ Akintọla ati Awolọwọ tako ara wọn lori igbesẹ didapọ mọ ijọba alajumọse ti NPC to n dari orilẹede yii, ti Akintọla si gba pe o yẹ ki Yoruba kopa ninu ijọba naa AAwọ to wa laarin Awolọwọ ati Akintọla lo mu ki laasigbo bẹ silẹ nile igbimọ asofin lẹkun iwọ oorun Naijiria, nigba ti wọn dibo a ko ni igbẹkẹle ninu rẹ mọ fun Akintọla lọdun 1962 Laasigbo yii lo mu ki onigbo dagbo si meji nile asofin naa, eyi to tan yika gbogbo ẹkun iwọ oorun guusu Naijiria Olootu ijọba nigba naa, Ọlọla Abubakar Tafawa Balewa kede pe ẹkun iwọ oorun Naijiria ko fararọ, to si yan Oloye M.
L’áti ìgbà tí mo ti mọ̀ nípa ètò Tiwantiwa ni ng kò lè ṣàì fetísí i lọ́sọ̀ọ̀sẹ̀!
"Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: ""Ọmọ ọdún méje ni mo bẹ̀rẹ̀ òwò nàbì nílé aṣẹ́wó tó tóbi jùlọ lágbàyéé"" Kí ni àyájọ́ ‘Má wọ kọ́mú’ wà fún?"
Toyin Abraham bí ọmọkùnrin jòjòló Saheed àti Fathia Balogun dìjọ ń ṣe ọjọ́ ìbí lónìí, ẹ wo àjọṣepọ̀ tó wà láàrin wọn Ẹ́ wo ojú àwọn òṣèré tíátà tó péjú sí Ibadan fún ìpàdé ọlọ́dọọdún Àwọn ọmọ Iyabọ Ojo rí Bàbá lẹ́yìn ọdún mẹ́fà Mr Latin, Jide Kosọkọ àti Mama Rainbow sọ̀rọ̀ lórí ìjà Toyin ati Lizzy Surutu to wọ aṣọ funfun lasiko ayẹyẹ idana naa, bi eeyan ba gun ẹṣin ninu rẹ, ko lee kọsẹ rara paapaa nigba to n rọ ojo adura le ọmọ naa lori.
Lara oun ti wọn yoo tun jiroro le lori nibi ipade naa ni wahala oṣelu to n waye ni Guinea Bissau.
Asiko ti to ki a ni akosile to ye ki a le mu idagbasoke ba irin ajo afe Naijiria ni eyi ti ko tona tele”Ninu oro Ogbeni Davis Mc Ewen, o tepele mo ifowosopo ati igboraeniye ni eka ijoba kookan ti oro kan ki irin ajo afe Naijiria le bi eso rere.
Ṣugbọn Fatoyinbo sọ ninu atẹjade kan to fisita lọjọ Ẹti wipe, Busola ati awọn ẹbi maa n wa si ijọ oun, nigba to kọkọ bẹrẹ.
 mo fi ọkàn balẹ ̀ jẹun ọ ̀ ún ni .
Orísirísi ènìyàn ló parapọ̀ di àwùjọ-bàbá, ìyá, ará, ọ̀rẹ́, olùbátan ati bẹ́ẹ̀ bẹ́ẹ̀ lọ.
Ṣááju kí abẹ́rẹ́ àjẹsára to dé, àyé yìí jẹ ibi to ni ewu gídigidi ti ọ̀pọ̀ àwọ̀n ènìyàn si n kú lọ́dọ̀dun nítori àìsàn to ṣee dènà.
" Oríṣun àwòrán, queen_aanu Ọrọ yii si lo daju pe o fi n fesi pada fun Olori Badirat, to kọkọ pe ara rẹ ni ẹlẹ Daddy ati oxygen ti ọba Adeyemi fi n mi, eyi to kọ bi akọle sabẹ aworan kan ti oun ati sba naa dijọ ya.
Alfred ni ti wọn ba dibo fun oun gẹgẹ bii gomina ipinlẹ Ọṣun, oun ko ni fọwọ kan owo nina fun eto aabo (security vote) rara.
Ogbeni Gbenga Oluṣẹgun jẹ ọmọ Badagry to n fi agbọn ṣe iṣẹ ọ̀nà to wuu gẹgẹ bii iṣẹ oojọ rẹ.
- Ìwádìí BBC Awọn afurasi ọdaran naa ni awọn ko jẹbi gbogbo ẹsun ti wọn fi kan wọn ṣugbọn wọn ṣi wa latimọle di akoko yii.
Ṣitirai, ará Ṣaroni, ni ó wà fún àwọn agbo mààlúù tí wọ́n wà ní Ṣaroni.
Èrè wo ni ẹ rí gbà lóko ẹrú ẹ̀ṣẹ̀, àfi ohun tí ń tì yín lójú nisinsinyii?
 ní pàtàkì jù lọ , ewì obìnrin ni ewì ayaba .
Orile-ede Amerika ko i ti ni asoju sile Saudi Arabia lati igba ti aare Trump ti gori aleefa lọdun 2017.
Iru iku gbona bayi kọ lo tọ si Richard.
Nítorí náà, wọ́n túká nítorí pé wọn kò ní olùṣọ́, wọ́n sì di ìjẹ fún àwọn ẹranko burúkú.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Esabod: Esther Aboderin tí ọ̀pọ̀ mọ̀ sí Esabod ní ẹ̀sín pọ̀ fún òun lọ́jọ́ tí wọn parọ́ pé mo mu sìgá lórí Facebook 10 Òkùdu 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 11 Òkùdu 2020 Oríṣun àwòrán, others Oloye Esther Aboderin tii ṣe ilumọọka sọrọ-sọrọ lori ayelujara ati elegbogi ibilẹ to n lo ewe ati egbo ti salaye pe ọrọ aje ati ọna atijẹ lo sọ oun di were lori ayelujara.
Mikel Obi: Orílẹ̀èdè Egypt ni mo ti bẹ̀rẹ̀ ayò, ibẹ̀ náà ló parí sí
Ṣugbọn awọn alatako rẹ pada fẹsun kan an pe o lọwọ ninu iku ọmọ gb oṣelu FLN marun un.
” Josẹfu bá dáhùn pé, “Èmi nìyí.
Nigbati iyá wọn kọ̀ wọ́n lọ́mọ, wọn kò lè ṣe ọdẹ inú igbó mọ́, wọn di ẹranko tó ńrágó, ti wọn ńsin ninú ilé, to ńpa eku kiri.
Ṣugbọn àwọn olódodo tí wọ́n jẹ́ tèmiyóo wà láàyè nípa igbagbọ.
Sẹnatọ Saraki ni orilẹede Naijiria lo gbe ipo kini ninu awọn eeyan to n ngba ọna aitọ Agadez route fi ko awọn eeyan lọ soke okun.
Ẹ sọ fún mi, ẹ̀yin tí ẹ fẹ́ wà lábẹ́ òfin: ṣé ẹ gbọ́ ohun tí òfin wí?
Eeyan 41,180 ni apapọ ni arun naa ti fara kan labẹ ayẹwo lorilẹede Naijiria.
Republic of Congo fagba han orile-ede Zimbabwe pelu ami ayo merin sodo(4-0),
opolopo iwe ifesunkan ti awon omo egbe won kọ lori awon to hu iwa atako si egbe
Iṣẹ́ amòfin tí mo kọ́ ni Fáṣítì kò mú owó wọlé fún mi bíi iṣẹ́ tíátà - Femi Adebayo Toyin Abraham jọ̀wọ́ dáríjì mí - Yomi Fabiyi World water day: Ẹrin Ijesa, Ọ̀ṣun Oṣogbo, àwọn ibùdó ìgbafẹ́ omi tí ó yẹ kí o mọ̀ Ǹjẹ́ o mọ àwọn ǹkan èlò ilé tó léwu fún ẹ̀mí?
Ọkọ mi, Alayeluwa Ọba Lamidi Ọlayiwọla Atanda Adeyẹmi kẹta, IKU BABA YEYE."
"- Ilé ẹjọ́ ìpínlẹ̀ Ondo Florence Ajimobi tahùn sí igbákeji gómìnà Oyo lórí ikú ọkọ rẹ̀, ""Gbogbo wa làó kú"" Orúkọ ìnagijẹ mẹ́jọ tí wọ́n fi ń pe Abiola Ajimọbi nígbà ayé rẹ̀ L'Eko, Bàbá ẹni ọdún 61 bá ọmọ rẹ̀ lopọ̀, ó fún un lóyún Ọrọ awọn afipabanilopọ yii lo ti n gab ẹbọ lọwọ gbogbo ipinlẹ lorilẹ-ede Naijiria lasiko yii."
Fun ọpọ ọmọ ilẹ Yoruba to wa loke eepẹ loni, eti lasan ni wọn fi n gbọ orukọ Da Rocha, wọn ko mọ iru eeyan to jẹ, ti awọn miran tiẹ ro pe arosọ lasan ni, ati pe Da Rocha kii ṣe ọmọ ilẹ Yoruba rara.
"Ìgbà tí mo pé ọmọ ọdún mẹ́rìndínlógún ni bàbá mi ti kọ ọ̀rọ̀ tí yóò sọ níbi ayẹyẹ ìgbéyàwó mi'' ''Àdúrà kan ṣoṣo tí màmá mi sì maa n gbà fún mi láti ìgbà tí mo ti di obìnrin, kò ju ọkọ níní lọ Bó tilẹ̀ jẹ́ pé Lulu ti ṣe àṣeyọrí lẹ́nu ẹ̀kọ́ rẹ̀ lẹ́yìn tó gba ẹ̀bùn ẹ̀kọ́ ọ̀fẹ́ láti gba oyè ìmọ̀ ìjìnlẹ̀ àkọ́kọ́ l'órílẹ̀-èdè Australia, tó sì tún ti ṣiṣẹ́ pẹ̀lú iléèṣẹ́ kan nínú àjọ ìṣọ̀kan àgbáyé, ohun kan tó kan ẹbí rẹ̀ ni ìgbà tí yóò mú ọ̀rẹ́kùnrin rẹ̀ wá sílé, tí yóò sì ṣe ìgbéyáwó.
A óo jọ máa gbé pọ̀, ibi tí ó bá wù yín ni ẹ lè gbé, ibi tí ẹ bá fẹ́ ni ẹ ti lè ṣòwò, tí ẹ sì lè ní ohun ìní.
Bàbá obìnrin náà lówó gidigidi àti kékeré ni wọ́n sì ti fi àkẹ́jù ba Àrùn jẹ́ níwọ̀n ìgbà tí kò sì ti sí ẹni tí ó lè fẹ́ ẹ láàárin àwọn ọmọ ènìyàn, iwin kan ni ó fẹ́ ẹ tí ó gbé e lọ sí òde ọ̀run.
Igbó sambisa kò ní pe di ibi ìgbàfẹ́ Nig vs Argentina: Óyá ẹ mú olóngbo àti ẹlẹ́dẹ̀ wọ̀nyẹn wá Ọ̀bọ lé àwọn ènìyàn kúrò nílè Kiniun pa olusọ ọgba ẹranko Erin wọ̀lú, ó pa ènìyàn méjì Ẹran dida lalẹ ati ibọn gbigbe deewọ ni Edo Ijọba Ondo n wa ọdẹ aperin Awọn eniyan Yoruba gbà pe inu igbo ni èranko afayafa n gbé ati pe wọn lewu pupọ.
OLUWA kórìíra òṣùnwọ̀n èké,òṣùnwọ̀n tí ó péye ni inú rẹ̀ dùn sí.
Ìgbẹ́jọ́ Naira Marley sún síwájú bí àwọn agbẹjọ́rò ń jà sí àga ìjókòó Kí ló ń fa ìjàmbá omíyale ní Naijiria?
Akinbade di oludije ẹgbẹ oṣelu ADC lẹyin ọsẹ meji to fi ẹgbẹ PDP silẹ.
  Ó di dandan kí olúwarẹ̀ náà gbìyànjú àti pọ́n-ọn dókè.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Òkú ṣùn nínú ìbúgbàmú tó wáyé l‘Eko Ọọ̀ni Ifẹ̀ la mọ̀ bíi olórí ọba Yorùbá, kí Aláàfin ya ṣo ewé gbéjẹ́ mọ́wọ́ - Ọ́ba Ekiti fárígá Àwọn kókó ohun tó wà nínú lẹ́tà tí Aláàfin kọ sí Fayemi rèé N kò ní ìjà pẹ̀lú Fayemi, ipò mi bíi aláàbò àṣà Yorùbá ní mó ṣe kọ lẹ́tà sí gómìnà Ekiti - Aláàfin Wò ó ọ̀nà láti mú ara rẹ dé ibi tó ga jùlọ nínú ìbálòpọ̀ pẹ̀lú ìlànà Tantra Ọ̀sẹ̀ yìí laá gbàwọn ẹ̀sọ́ Amotekun sísẹ́, ìparí oṣù kẹta ni iṣẹ́ yóò bẹ̀rẹ̀ - Akeredolu Ìpele tuntun ló kàn nínú ìrìnàjò ayé mi, ń kò pe ẹjọ́ lóri ìrọ̀lóyé - Sanusi Nibi ayẹyẹ naa si lawọn ọpọ osere tiata lede oyinbo ati lawọn oniruuru ede miran nilẹ Afirika ti gba ami ẹyẹ, ti awọn osere tiata lede Yoruba naa ko si gbẹyin nibẹ.
Falana (SAN) tun rọ Ile Igbimọ Aṣofin yii lati ni atinuda loriṣiriṣi lati
O tun so pe yato si iroyin eke ti awọn eniyan n gbe jade pe ija to n bẹ silẹ laarin awọn agbe ati adaran,ni i se pelu ija esin, ohun ti o faa ni  oro  ilẹ , ohun alumọọni ilẹ ati omi.
Awon omo orile-ede Sierra Leone seto idibo ninu eyi ti won yoo ti yan Aare tuntun, ati awon omo ile-igbimo asofin.
Orilade ni, Ẹ ranti wipe ẹjọ ti wa nile ẹjọ, ko si idi to fi yẹ ki Fayose maa lọ yọ ẹnu si awọn oniroyin."
Alaga gbogbo-gboo fun ẹgbẹ oselu APC, Adam Oshiomole, ti fẹsun kan Gomina Ipinlẹ Ekiti, Ayọ̀délé Fayose pe, o n lo owo osu to yẹ ko san fun awọn osisẹ fun apo ara rẹ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Kí ló wà nínú Tea tí Abiola mu?
Ekeinde ṣalaye pe ohun ti wa ni iyasọtọ lẹyin ti oun lugbadi aarun naa, ara oun si n ti n pada bọ sipo diẹdiẹ bayii.
Ẹni tí ó bá pa ẹran, yóo san òmíràn pada, ẹni tí ó bá sì pa eniyan, wọn yóo pa òun náà.
Lọjọ ẹti to kọja ni ọrọ naa bẹrẹ si ni ja rayin-rayin lori ayelujara lẹyin ti Jada funrarẹ sọ ẹkunrẹrẹ bi wọn ṣe maa n laṣepọ lori eto kan to maa n ṣe lori Facebook, Red Table talk.
"O ni ""A o tun ile iwe awọn akanda ṣe, ọrẹ araalu ni Senator Lanlẹhin nitori naa a o ni yan ọrẹ ati ojulumọ sipo afi ara ilu."
ẹ óo mú ìdámẹ́wàá lọ́nà mẹta òṣùnwọ̀n efa ìyẹ̀fun kíkúnná tí a fi ìdajì òṣùnwọ̀n hini òróró kan pò wá, 
Oun ni alakoso agba fun ileeṣẹ Hydrocarbon Pollution Remediation Project, (HYPREP) lọdun 2012 ko to darapọ ajọ NDDC.
Mo sọ fun yín pé, kò sí ẹnikẹ́ni jákèjádò ayé yìí tí ó ṣe pataki ju Johanu lọ.
Melaye n j'ẹjọ niwaju adajọ Olasumbo Goodluck nitori pe o purọ mọ olori oṣiṣẹ ni ọfiisi Gomina ipinlẹ Kogi, ọgbẹni Edward Onoja pẹlu ẹsun ipaniyan.
" Lori ohun ti yoo sẹlẹ si iṣẹ tiata lẹyin ti arun Covid-19 ba kasẹ nilẹ, Fabiyi ni adinku gbọdọ ba awọn sinima oyinbo ti wọn n gbe wa si awọn ile sinima ni Naijiria, ki awọn osere tiata si ni orisun ọrọ aje pupọ, kipo iṣẹ sinima nikan, ti wọn gbajumọ.
Jonatani sì fi ibinu dìde kúrò ní ìdí tabili oúnjẹ, kò sì jẹun ní ọjọ́ náà, tíí ṣe ọjọ́ keji oṣù.
Bo tilẹ jẹ pe awọn eeyan ọhun ko mọ ara wọn ri, ṣugbọn ero wọn ṣọkan pe, ko si ibi to dabi ile, ilẹ Afrika si ni ile fun wọn.
Àwọn ọmọ ogun alágbára kan tí yóo joyè, yóo pa Jerusalẹmu ati Tẹmpili run.
Ewe, awon adari ifesewonse merinla miiran ni won tun daduro di akoko ti won yoo fi lo foju ba ile ejo ninu osu kejo odun ti a wayii.
Ó tẹ àwọn orílẹ̀-èdè lórí ba fún wa,ó sì sọ àwọn orílẹ̀-èdè di àtẹ̀mọ́lẹ̀ fún wa.
Mo fi aye gba wọn gaan ṣugbọn laarin bii ọdun mẹrin bayii, arifin wọn ti pọju'' Oba Abdulrasheed nigba ti a beere nipa ẹsun ti wọn fi kan wọn pe wọn da apa si ọba Agbowu lara sọ pe ''Iro balawu ni wọn pa mọ mi'' Kii ṣe oni ni wọn ṣẹṣẹ n na ọpa si mi loju.
Ẹlẹwọn le ma wẹ fun odidi ọsẹ kan.
Kí ló dé tí o fi ń ṣe bí ẹni pé ẹlòmíràn ni ọ́?
Ile-ise ologun so pe, ohun ni eri to fi mule pe, awon omo-ogun IS ti ko awon omo-ogun re lo si Sinai leyin ti won segun re ni orile-ede Iraq ati orile-ede Syria.
ẹrọ igbalode lori eto ọrọ aje.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Ọ̀lọ́wọ́ òsì kọ́ndọ́rọ́' Ṣùgbọ́n, Ààrẹ àná, Goodluck Jonathan nínú ìkède kan lójú òpó Facebook rẹ̀ ní kò ṣeéṣe fún òun sláti ná irú owó bẹ̀ ní ìnákúnàá nítorí wí pé òun làárẹ Nàìjíríà tó sọ ẹ̀ka iná mọ̀nàmọ́ná di ti aládàáni, bẹ̀rẹ̀ láti ọdún 2010, lásìkò tó se ìfilọ́lẹ̀ ètò àtúnṣe sí ẹ̀ka ìná ọba, títí di oṣù Kẹwàá, 2012, nígbà tó kéde títà àwọ̀n iléèsẹ́ tó n pèsè tó sì n pín iná.
Wọn óo tú wọn kalẹ̀ níbẹ̀, wọn óo sì kó wọn fún àwọn iranṣẹ rẹ.
Ìtàn tó wà nídi òwe ‘Sebótimọ Ẹlẹ́wà Sàpọ́n’ Ṣẹ gbọ́ nípa Alájọ Ṣómólú, tó ta mọ́tò ra kẹ̀kẹ́?
Àdùnní: Àdùnní ni ìyàwó tí Orímóògùnjẹ́ kọ́kọ́ fẹ́.
Mí mọ èròngbà tàbí ohun tó n ṣe ìwúrí fún ẹni tó gbé ìròyìn nàá jáde le ràn ọ́ lọ́wọ́ láti pinnu bóyá ayédèrú tàbí òtítọ́ ni ìròyìn nàá.
Èyí jẹ́ àkàwé ìrìbọmi tí ó ń gba eniyan là nisinsinyii.
Ẹ yéé pé ìran Yorùbá ní Abọ̀rìṣà mọ́ -Ooni Ife Kí ni àmì ohùn 'Aguntaṣọọlo'?
leyin ipade ti won se pelu aare niluu Abuja.
Awon omodebinrin ohun ti awon omo-ogun olote da sile lojo-Ru, ni won ko lo silu Abuja, nibi ti won ti pade Aare Muhammadu Buhari lojo-Eti.
Ẹsun awọn ọmọ ilẹ South Africa fi kan awọn ọmọ ilẹ okere ni pe wọn n gbaṣẹ awọn ṣe.
Abikoye ni, iwa ifiyajẹni lọna aitọ ni awọn osisẹ eleto irina ati asọbode ni ilẹ Ghana hu si awọn ọmọ Naijiria.
Iroyin ni ọmọ ọdun mẹrinla naa n bọ lati ile iya-iya rẹ lọjọ kejila, oṣu Keje, ọdun 2018 ni ilu Ondo nigba to pade ọdanran ọhun, Blessing Kingsley, to jẹ alabagbe wọn.
Lẹ́yìn náà, gbogbo àwọn ọmọ Israẹli súnmọ́ ọn, ó sì ṣe gbogbo ohun tí Ọlọrun bá a sọ lórí òkè Sinai lófin fún wọn.
Èèyàn 667 ló lùgbàdì àrùn Coronavirus ní Naijiria ní Ọjọ́ Ẹtì Godwin Obaseki ti darapọ̀ mọ́ ẹgbẹ́ òṣèlú People's Democratic Party Ohun méje tí o kò gbọ́ rí nípa aláìsàn arunmọ-léegun- Dókítà Igbekele Ìlànà ìjìnàsíraẹni 'social distancing' forí ṣánpọ́n bí ìrun Jímọ̀ ṣe bẹ̀rẹ̀ padà ni Ilorin Ni ti Toyin Lawani, o ni ohun to dara ni ki okunrin ṣe atilẹyin fun iyawo rẹ ninu iṣẹ to ba n ṣe nitori ọjọ iwaju.
Buhari wa di gbajumọ ẹgbẹ oṣelu alatako lakọkọ gẹgẹ bi ọmọ ẹgbẹ oṣelu All Nigeria People's Party (ANPP) lẹyin naa, Congress for Progressive Change (CPC) ati All Progressives Congress (APC).
 kẹ ́ místrì tún úndálórí àwọn ìbáraṣepọ ̀ láàrin àwọn átọ ́ mù ( tàbí ọ ̀ pọ ̀ àwọn átọ ́ mù ) àti orísirísi irú okun ( f.
Ni kekere lọwọ rẹ ti ji sowo, koda ọmọ ọdun mọkandinlogun lo wa nigba to kọ ile akọkọ rẹ.
Mo wò ó láti ibi tí ó dàbí ìbàdí rẹ̀ lọ sókè, ó rí bíi bàbà dídán, ó dàbí iná yíká.
Orúkọ Abiku ni Okunnu tí mo ń jẹ nínú eré, inú orin Barrister ni mo sì ti ri - Wale Akorede Wo àwọn èèkàn ìlú Kano tó kú láàrín ọjọ́ mẹ́rin sí ara wọn Ẹ wo àwọn gbajúmọ̀ òṣèré tíátà tó jogún eré ṣíṣe lọ́dọ̀ òbí wọn O kò leè wọ inú ilé mi lẹ́yìn ìrìnàjò láti Eko, lai ṣe àyẹ̀wò Coronavirus - Bàbá yari fún ọmọ O ni gbogbo ohun tí wọn ń béèrè, tí mo bá tá nkan ti mo ní, ko kà, mo sì ń bẹ wọn lọwọ ni, wọn si ti ní ń kó gbọ́dọ̀ kéde síta."
Ẹ óo wá mi, ẹ óo sì rí mi, bí ẹ bá fi tọkàntọkàn wá mi.
Nile ẹjọ nibi ti Gbenga ati iyawo rẹ ti fẹ tu ara wọn ka lo ti fi ẹsun naa kan baba rẹ gẹgẹ bi ẹri l'ọdun 2008.
Wọ́n sọ fún Joṣua pé “Iranṣẹ yín ni wá.
Gomina ìpinlẹ Ondo, Arakunrin Oluwarotimi Akeredolu fi àṣọ ìbílẹ̀ tí wọn ṣe ní ìpínlẹ̀ Ondo ta ààrẹ lọ́rẹ.
Ero awọn miran ni síse ounjẹ ta nitori wi pe, ojumọ kan kò ni mọ́ ki ẹnu má gba ẹbọ ounjẹ.
 Àìsàn-kẹ ̀ kẹ ̀ tí-n-mú-ẹ ̀ dọ ̀ ṣíwọ ́ -iṣẹ ́ kí í sáábà bá ìmọ ̀ lára yìí rìn nítorí tí ó wọ ́ pọ ̀ júlọ láàrin àwọn àgbàlagbà .
Fi orukọ silẹ fun iṣẹ ologun Naijiria nibi.
Agbábọ́ọ̀lù Super Falcons tẹ́lẹ̀, Chiejine jáde láyé lẹ́ni ọdún 36 Bakan naa ni ọjọgbọn Oni Fagbohungbe sọrọ siwaju pe, ijọba ni i ṣe pupọ lati ṣẹ lori igbogunti iwa ibajẹ lorilẹ-ede yi.
"Àwa àti fijilanté pẹ̀lú ọdẹ́ ìbílẹ̀ ló dojú kọ adigunjalè ní First Bank Okeho - Iléeṣẹ́ ọlọ́pàá ""Ọmọ mi kò tíì mọ̀ pé òun ti di ìlúmọ̀ọ́ká, ó ń wádìí bó ṣe ń rí ara rẹ̀ lórí ayélujára"" Ìtàn ọba Yorùbá tí wọn yẹgi fún torí ó jí ọmọ gbé ṣe ètùtù Àwòkọ́ṣe ìwà ìrẹ̀lẹ̀, òtítọ́ àti olùfẹ́ mẹ̀kúnnù ni Ayo Fasanmi - Ìjọba Osun Oríṣun àwòrán, Getty Images Saaju isẹlẹ yii ni Aarẹ Donald Trump ti sọrọ̀ pe."
Iroyin Ofege lasiko aarẹ Donald Trump Laiko aarẹ Donald Trump ni iroyin ofege peleke julọ lagbaye.
Ọga agba to n dari ẹka ede ni Iwọ Oorun ilẹ Afirika fun BBC, Toyosi Ogunseye fi idunnu rẹ han lori igbesẹ akọni yii.
Kí OLUWA wa ṣe èyí tí ó dára lójú rẹ̀.
Oríṣun àwòrán, Instagram/queenola2 Ninu ile itaja naa lo ti n ta aṣọ, ati ohun ẹsọ iṣaraloge, to si tun sọ lọjọ ayẹyẹ ọjọ ibi rẹ to kọja pe, awọn nkan to ṣẹlẹ si oun lọdun 2020 ba oun lọkan jẹ, to si jẹ ki oun mọ pe ohun gbogbo to n dan kọ ni wura.
Ma si ṣe lo oogun ti dokita ko ba kọ fun ọ, o l'ewu.
Olóòótọ́ ni OLUWA ninu gbogbo ọ̀rọ̀ rẹ̀,olóore ọ̀fẹ́ sì ni ninu gbogbo ìṣe rẹ̀.
Ni igbẹjọ to waye lọjọ Iṣẹgun, Adajọ ti ṣaaju ni ki wọn mu ọmọ Maina Faisal ti o kọ lati yọju sile ẹjọ.
N óo jẹ́ kí ẹnìkan ninu ìdílé rẹ ṣe ibi sí ọ.
Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold Wo ìdí tí Oluwo fi ń wọ ìbòmú lẹ́yìn tó ní covid-19 ò lè wọ ìlú Iwo láéláé Covid-19: Ilé aṣojú-ṣòfin l'Abuja dábàá kí ìjọba sún ìwọlé àwọn akẹ́kọ̀ọ́ síwájú pẹ̀lú oṣù mẹ́ta Àwọn ìṣẹ̀lẹ̀ ńlà lọ́sẹ̀ tó kọjá tó fi mọ́ bí Covid-19 ṣe gbẹ̀mí èèyàn 23 lọ́jọ́ kan ṣoṣo Gẹgẹ bi fidio to gba ori ayelujara kan naa ṣe fihan, ti wọ inu awọn Gaa Fulani kan lọ lagbegbe Ibarapa nibi ti o ti fun awọn Fulani to wa nibẹ ni gbede ọjọ meje eleyi ti yoo pari ni ọjọ kejilelogun, oṣu kini ọdun 2021 lati fi ilẹ naa silẹ.
"Ọkọ meji ni mo ti padanu laarin ọdun kan,'' ni arabinrin kan sọ, t'ohun ti omije loju fun awọn araalu to pejọ sibi ipade kan to waye niluu Kayole loṣu Kẹta.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Yoruba Culture: Kò sí nínú àṣà Yorùbá kí wọ́n tú ọfọ fèèyàn lórí fóònù-Gbenga Adeoye 14 Ọ̀wàrà 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 21 Èbibi 2020 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Gbogbo nnkan lo ni ilana ninu aṣa Yoruba ṣugbọn ṣe ẹyin mọ bi Yoruba ti ṣe n tufọ fun eeyan?
Bashir darapọ mọ awọn ọmọ ogunn ofurufu lọjọ kinni, oṣu kẹjọ, ọdun 2016 lẹyin to kẹkọ nipa iṣe ologun yanju ni Kaduna.
5% láti 5% lẹ́yìn tí ààrẹ Buhari buwọ́lu àbá ètò ìnáwó Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
 Èyí tí kò léwu púpọ ̀ di títà ní odún 1986 .
Ko tan sibẹ, awọn araalu naa fara gba ninu isẹlẹ yii, ti awọn eeyan si ku nilu Eko, Ibadan ati Plateau.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Fashọla: Àwọn ọmọ Nàìjíríà sọ̀rọ̀ lórí ìpèsè iná ọba tí mínísítà Fashọla ní ó ti ń ṣe dédé 28 Ẹrẹ̀nà 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 1 Ìgbé 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Kii ṣe iroyin mọ pe ina ọba ko ṣe e mu yangan ni orilẹede Naijiria Ṣe awọn agba bọ, wọn ni ẹyin lohun, bi o ba ti jabọ ko tun ṣee ko mọ.
Ìdí tí wọ́n ṣe sọ ọ́ ní Aquae Sulis ni pé sẹ́lẹ̀ru omi gbígbóná kan wà níbẹ̀ tí wọ́n gbàgbọ́ pé a máa wo aláìsàn sàn, a sì máa múni lára dá.
Ọ̀nà apanilẹ́rìń táwọn ọmọ Nàíjíríà gbà fèsì sí ìṣúnsíwájú ìbò ààrẹ Àwòrán rèé lórí bí ìgboro ṣe rí lẹ́yìn tí ìbò kò wáyé mọ́#NigeriaDecides2019 Yakubu, lasiko to n ba awọn eniyan sọrọ ni gbọngan ti wọn ti maa n ko esi isibo jọ to wa ni ilu Abuja sọ pe ''ijamba ina, oju ọjọ ti ko dara to lati fi baalu gbe eroja idibo, ati idiwọ ninu eto gbigbe awọn eroja idibo lo mu ka sun eto idibo naa siwaju.
Oríṣun àwòrán, Nigerioa Police Force Ìdí tí ìjọba fi tú FSARS ká rèé!
Nítòótọ́ bí OLUWA tí ń bẹ láàyè, tí ẹ̀mí rẹ náà sì ń bẹ láàyè, ìṣísẹ̀ kan ló wà láàrin èmi ati ikú.
Nígbà tí àwọn ọ̀tá wa ti gbọ́ pé a ti mọ àṣírí ète wọn, ati pé Ọlọrun ti da ìmọ̀ wọn rú, gbogbo wa pada sí ibi odi náà, olukuluku sì ń ṣe iṣẹ́ tirẹ̀.
Bakan naa lo kesi ijọba Naijiria lati ṣe iwadii àwọn to wa nidi ipaniyan ọhun, ko si fi oju wọn wina ofin.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ọbẹ Ẹgusi sise ati jijẹ Oríṣun àwòrán, AFeez eniola Àkọlé àwòrán, Ẹniọla Afeez ati Esther Kalẹjaye Ẹniọla Afeez ati Esther Kalẹjaye Ẹniọla Afeez ati Esther Kalẹjaye ti ọpọ mọ si Ọmọ jọ ibo pẹlu kun ara awọn oṣere tiata Yoruba ti wọn n ṣe lọkọlaya.
Ọlọrun bá pada lẹ́yìn wọn, ó fi wọ́n sílẹ̀ láti máa sin ìràwọ̀ ojú ọ̀run, gẹ́gẹ́ bí ó ti wà ní àkọsílẹ̀ ninu ìwé àwọn wolii pé, ‘Ẹ̀yin ọmọ Israẹli,ǹjẹ́ ẹ mú ẹran wá fi rúbọ sí mi fún ogoji ọdún ní aṣálẹ̀?
Ìjọba ìpínlẹ̀ Eko tí kéde ìlànà ìséde tuntun fún ará ìlú Ṣé lóòtọ́ ni Afenifere fún àwọn èèyàn ẹ̀yà Igbo ní wákàtí 48 láti fi ilẹ̀ Yorùbá sílẹ̀?
Gbogbo àwọn ẹ̀dá alààyè patapata ni wọ́n wọ inú ọkọ̀ tọ Noa lọ ní meji meji.
Lọdun 2020 ni ireti wa pe fasiti yi yoo gbera sọ.
 Àwọn ni àwọn òrìṣà atẹ ̀ wọ ̀ nrọ bíi odùduwà , sàngó , Ọya , Èṣù àti bẹ ́ ẹ ̀ bẹ ́ ẹ ̀ lọ .
Anfaani bẹliti yi pọ ti a si ma dena fifi ori gba ti ijamba ọkọ ba ṣẹlẹ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ọ̀ṣọ́ Aṣọ Òkè ti kọjá lílo ìlẹ̀kẹ̀ níkan Awọn olorin bii King Sunny Ade naa gboṣuba kare fun Stationery Stores ninu awo orin oriṣiriṣi ti wọn gbe jade lasiko naa.
Igbimọ ẹlẹni mẹta to n gbọ ẹjọ naa, ti adajọ Abubaka Datti Yahaya ko sọdi wọgile ẹjọ ti ile ẹjọ giga ilu Abuja da ṣaaju, leyi to yọ Oshiomole nipo gẹgẹ alaga ẹgbẹ ọhun.
Jesu tún wí fún wọn pé, “Èmi ni ìmọ́lẹ̀ ayé.
Agbẹnusọ fun awọn ọlọpaa tun fi kun ọrọ rẹ pe mọkanlelọgbọn ninu awọn to dana sun ile iṣẹ awọn ọlọpaa ni ọwọ ofin ti ba bayii.
Nígbàkúùgbà tí ẹnikẹ́ni bá ń mú ẹjọ́ bọ̀ wá sọ́dọ̀ ọba, Absalomu á pe olúwarẹ̀ sọ́dọ̀, á bi í pé, “Níbo ni o ti wá?
- BBC News Yorùbá BBC News, YorùbáFò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Kunle Afod: Òṣèrébìnrin tí wọ́n bá fi ìbálòpọ̀ lọ̀ 'torí ìṣẹ́, kó bọ́ síta láti sọ̀rọ̀ - 27 Ọ̀pẹ̀̀ 2019 Oríṣun àwòrán, KunleAfod/Imstagram Àkọlé àwòrán, Òṣèrébìnrin tí wọ́n bá fi ìbálòpọ̀ lọ̀ 'torí ìṣẹ́, kó bọ́ síta láti sọ̀rọ̀ - Kunle Afod Gbajumọ oṣere, Kunle Afod ba BBC Yoruba lalejo, o ṣi dahun ọpọlọpọ ibeere nipa igbe aye rẹ gẹgẹ bi oṣere lati igba to ti bẹrẹ.
Eyi to mu ki ọkan lara awọn to n du ipo ọba ọhun, Ọmọba Tajudeen Olarewaju, lati idile Aketula pe ẹjọ lodi si ọba tuntun to ṣẹṣẹ gori itẹ lọjọ naa lọhun.
Nígbà tí wọ́n gbé wọn mì tán, eniyan kò lè mọ̀ rárá pé wọ́n jẹ ohunkohun, nítorí pé wọ́n tún rù hangangan bákan náà ni.
Ayẹyẹ ifilọlẹ ileeṣẹ BBC Yoruba MC Oluọmọ, fara gb'ọ̀bẹ níbi ìpolongo ìbò APC l'Eko Wàhálà bẹ́ sílẹ̀ níbi ìpolongo ìbò APC l'Eko Mohammed Salah gba àmì ẹ̀yẹ̀ CAF fún ìgbà kejì Lara awọn eeyan pataki to wa nibi eto naa ni Igbakeji aarẹ orilẹede yii, Ọjọgbọn Yemi Oṣinbajo, Ọjọgbọn Wọle Ṣoyinka, adari agba fun ẹka iroyin ni BBC, Jamie Angus ati bẹẹbẹẹ lọ.
Bí aládùúgbò rẹ bá fi ẹ̀wù rẹ̀ dógò lọ́dọ̀ rẹ, tí o sì gbà á, dá a pada fún un kí oòrùn tó wọ̀; 
mo oro rẹ pe orile ede Amerika  ko
Anthony Enahoro: Oloye Anthony Enahoro jẹ ọkan gboogi lara awọn to ja fun ominira Naijiria.
Iye owo ti ẹni kọọkan n pa wọle ti dikun lati ọdun 2010.
Oga gba ajọ NSCDC ni Ibadan, Kọmandanti Iskilu Akinsanya lo fi iroyin yii to awọn akọroyin leti pe awọn ikọ akanṣe aabo lasiko yii ti wọn pe ni Agro Ranger lo gba awọn oniṣẹ ibi naa mu.
Loju opo Twitter ileeṣẹ naa ni wọn fi ikede yi si lọjọ Aje.
Wọ́n bi í pé, “Níbo ni ọkunrin náà wà?
Lẹyin ọdun marundinlaadọrun un ti wọn ti ti ile iṣẹmbaye yii pa fun awọn Musuilumi lo di ṣiṣi pada.
A ní lati dúró gẹ́gẹ́ bí ọ̀kan ṣoṣo.
Europa League - ìnàkunà ni Arsenal na ojúgbà rẹ ti Frankurt.
Komisona fun eto ilera, Ojogbon Ebitimitulah Etebu ni ibudo naa to lati maa fi se gbogbo ayewo awon eniyan ipinle Bayelsa bii ayewo eje, ayewo egungun ati isele inu eran ara.
Igbakeji Aare  oun so pe, “A dupe pupo lowo ile-ise Nestle fun anfaani yii, ni paapaa julo bi won da ile-ise sile si awon igberiko ati bi won se n ra ohun elo won latodo awon agbe, eyi yoo tun mu idagbasoke ba orile-ede Nigeria”.
Èrò wọ́ tẹ̀lé Seyi Makinde lọ ibi ìbúrawọlé l'Oyo Kẹti kẹti ni ero wọ tẹle amoju ẹrọ Seyi Makinde ati iyawo rẹ lọ si ibi eto iburawọle ni ipinlẹ Oyo BBCCopyright: BBC Seyi Makinde ti OyoImage caption: Seyi Makinde ti Oyo Article share tools Facebook Twitter ṢàpínlòView more share options Share this post Copy this linkKà síwájú síi nípa àwọn ìtọ́kasí wọ̀nyí.
Bí ara rẹ̀ kò bá le, n ó bá a wá òógùn si i, bí n kò bá mọ òògùn àìsàn náà, n ó wí fún àwọn tí ó bà mọ̀ ọ́, kí wọ́n ṣe é fún mi.
Kíkọ́ ẹ̀kọ́ gboyè nínú iṣẹ́ ìṣègùn ìbílẹ̀ yóò pèsè ìtọ́jú tó péye fọ́mọ Nàìjíríà- Ẹgbẹ́ àwọn dókítà Wọ́n mú ọjọ́ ìgbẹ́jọ́ agbésúnmọ́mí 9/11 tó ṣẹlẹ̀ l'Amẹrika Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Pneumonia: Dókítà ní kòkòrò àìfojúrí ló ń fàá òtútù àyà Iléẹjọ́, ẹ sọ fùn ọ̀gá DSS kó fún wa ní ₦1bn torí àhámọ́ lọ́nà àìtọ́ - Sowore àti Bakare Àráàlú yarí fún fásitì Babcock fún bo ṣe lé akẹ́kọ̀ọ́ tí wọn bá lòpọ̀ nínú fídíò Ó gbẹnután!
Ayefele ni iwe wa fun ilẹ oun, ti wọn si pe ọrọ naa lowe, amọ to ni araaro ninu.
Ati pe iṣẹ iwadi ati abẹwo ti awọn asoju ijọba ṣe si ile iṣẹ redio Ayefẹlẹ, lo fi idi ọrọ mulẹ wipe gbajugbaja olorin naa ti tayọ aṣẹ ti ijọba fun un.
Lóòótọ́ ó mọ ìwé dáadáa, a sì máa ṣe ètò daadaa, bẹ́ẹ̀ ni a máa ṣíṣọ́ bí o ti yẹ, ṣùgbọ́n ohun pàtàkì tí ó ti ọkùnrin náà lẹ́yìn jù ni ti Ọlọ́run tí ó gbà gbọ́.
Na okùn àgọ́ rẹ kí ó gùn,kí o sì kan èèkàn rẹ̀ mọ́lẹ̀ kí ó lágbára.
Awa ti a poju ,ni a gba eleyii wole .
Awọn gomina mẹrẹẹrindinlogoji to wa lorilẹede yi pẹlu awọn minisita tọrọ aje kan, ati gomina banki apapọ ilẹ wa lo jẹ ọmọ igbimọ naa.
Tọkàntọkàn ni mo fi ń ké pè ọ́,OLUWA, dá mi lóhùn;n óo sì máa tẹ̀lé ìlànà rẹ.
Infantino ni: Russia ti gbaradi daadaa, iwonba perete ise lo ku fun won lati se ni eyi ti won n sise le lori bayii.
Justin Bayili, ti o je akowe agba ajo ti o n ri si oro enu ibode so pe, “o ye ki ilana kan wa fun gbigba owo ori oja ati eyi ti o je ofe laarin enu-i-bode orile-ede Nigeria ati orile-ede Benin, latari ati maa je orile-ede Naijiria maa padanu awon eru ti o ye ko wo orile-ede naa lo si awon orile-ede miiran ti o je amulegbe re”.
Ninu wọn ni Maria Magidaleni wà, ati Maria ìyá Jakọbu kékeré ati ìyá Josẹfu, ati Salomi.
Bayero ni Emir kẹẹdogun ti yoo jẹ lati igba ti ijọba Fulani ti bẹrẹ niluu Kano.
Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Ondo Election 2020: Ẹ wo àwọn olùdíje sípò gómìnà nípínlẹ̀ Ondo tó takò bàbá ìsàlẹ̀26 Owewe 2020 Fídíò, Wole Soyinka sọ ìdí tó fi ni òun a fi màálù Fulani ṣe súyà fáwọn èèyàn abúlé23 Owewe 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Bi o ti le je pe, O ti so fun aare Ramaphosa lati gba ise lowo re tele, sugbon ti aare ohun ko kobi ara si.
 O parowa pe ki gbogbo awon toro kan fowosopo pelu igbimo Asiwaju Tinubu ti oun ti gbe ise onilaja fun lati pari aawo to ba wa laarin awon omo egbe gbogbo lati ipinle kan si ikeji.
Nígbà tí wọ́n kó wọn jáde tán, wọ́n wí fún wọn pé, “Ẹ sá àsálà fún ẹ̀mí yín; ẹ má ṣe wo ẹ̀yìn rárá, ẹ má sì ṣe dúró níbikíbi ní àfonífojì yìí, ẹ sá gun orí òkè lọ, kí ẹ má baà parun.
Lagbaye, orilẹede yii tun siwaju Italy ati Turkey.
Ó fi igi tí ó fi ṣe àjàgà wọn ṣe igi ìdáná, ó bá se ẹran wọn.
'Ẹ má pè mí ní Kupe; DJ Copy l'orúkọ mi' Obinrin kan rèé tó borí ogun Gẹ̀ẹ́sì Ìgbà méje ti ọ̀fọ̀ ti ṣẹ̀ lágbo eré bọ́ọ̀lù Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí 2 sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 2:23 Fídíò, Water Generator: Ó leè ṣiṣẹ fún wákàtí mẹfà, kó tó sinmi, Duration 2,2310 Òkùdu 2020 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
ko lee toka si igba ti won yoo sekulo.
Mike Edwards lo ṣe ipo lẹyin to ri ibo to pọju lọ sikeji lẹyin Mercy.
Ni ipinlẹ Kano bakan naa, wọn ni oye oluranlọwọ pataki lori ibojì òkú.
Ti kii ba ṣe ti isede yii, ijamba yii ki ba ti waye, nitori pe owo kekere kọ lati padanu bayii."
Eliṣa tọ̀ wọ́n lọ, ó sọ fún wọn pé, “Ẹ ti ṣìnà; èyí kì í ṣe ìlú tí ẹ̀ ń wá, ẹ tẹ̀lé mi n óo fi ẹni tí ẹ̀ ń wá hàn yín.
Àkọlé àwòrán, Gbogbo awọn oludije naa lo pinnu lati san 30,000 gẹgẹ bi owo osu osisẹ to kere julọ.
Nitori o ṣeeṣe ki iru awọn aawọ bẹ ni ipa ti ko tọ lara ẹgbẹ naa ninu idibo gomina ipinlẹ Edo.
Ni Naijiria, ile ẹkọ girama to jẹ ti ijọba apapọ ko ju ọgọrun kan ati meje lọ.
Síbẹ̀ mo lọ ni ọjọ́ kẹrín, ṣùgbọ́n ó fi ogede pe ajá eṣù láti ìsàlẹ̀ ilẹ̀ ni inú òkùnkùn biribiri kí ajá náà bà wá pa mi jẹ, ṣùgbọ́n ọwọ́ ajá náà kò tẹ̀ mi, mo sì tún mu sùurù mo lọ ba Ìbínú-ẹkùn ní ọjọ́ kàárún, ṣùgbọ́n ki n tó dé ọ̀hún o ti mọ̀ pé mo ń bọ̀ o sì ti kó onírúurú ẹ̀dá ọ̀run tí ìwà wọn bá tirẹ̀ mu sílẹ̀ dè mi, bí mo ti yọ lọ́kàn-án kán ni mo rí gbogbo wọn pẹ̀lú ohun ìjà tí i wọ́n fẹ fi ṣe mi ni  ìjàǹbá, ṣùgbọ́n èmi dúró lókéèrè mo sì bẹ Ìbínú-ẹkùn tàánútàánú pé kí ó ṣe àforíjì fún ọmọ rẹ̀, lẹ́yìn èyí nì èmi náà padà lọ sí ilé mi ṣùgbọ́n bí ilẹ̀ ọjọ́ keeje ti ń mọ́ hàì ni mo tún dide, mo bá ilé Ì ínú-ẹkùn lọ, àṣé òun ti ní èrò pé mo lè wá bá òun o sì ti dẹ pàkúté sí ọ̀nà dè mi ni òru.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù PDP: Ilé aṣòfin àti Gómìnà Kwara kùnà pẹlú yíyọ àwọn alága ìjọba ìbílẹ̀ 18 Òkùdu 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 19 Òkùdu 2019 Oríṣun àwòrán, officialpdpnig/RealAARahman Ẹgbẹ́ òṣèlú PDP tí tápà sí ìgbésẹ Gómìnà ìpínlẹ̀ Kwara nípa jíjà ìwé lọ gbélé rẹ fawọn alága ìjọba ìbílẹ̀ ní ìpínlẹ̀ náà.
Ojú yóo wá tì yín,ẹ óo sì di ẹni ẹ̀tẹ́,nítorí gbogbo ibi tí ẹ̀ ń ṣe.
awọn aṣeyori yii lati bii ọdun mẹrin sẹyin ni ṣiṣe ofin to ṣagbekalẹ
Ibi tí ẹranko yìí tún ti ń jà Ìjàǹbáforítì yí lulẹ̀ láti òkè ó sì fi ara pa bẹ́ẹ̀ ni ẹnikẹ́ni kò mọo ìwọ̀nyí ní ilé ó sì tó ijọ́ mẹ́ta kí ó tóó lè dìde.
Osun Strike: Gbèdéke ọjọ́ méje ni àwọn olùkọ́ ilé ẹkọ́ gíga fún ìjọba
3SC ti awon eniyan tun mo si “Oluyole Warriors” jawe olubori pelu ami-ayo kan sodo, eleyi ti ko yato si bi iko ohun se gba irufe asekagba idije ohun lodun 2017 lowo iko kannaa ti n se Crown FC.
O ni yoo tun wa fi awọn ikoko to fi dana silẹ fun oun lati fọ.
Chinonso Eche, tii se ọmọ ọdun mọkanla ree, to jẹ elege ara nilu Warri, ko si si elege to dabi rẹ.
Food Festival: Ìbọn pa èèyàn mẹ́ta níbí ayẹyẹ Oúnjẹ ní Carlifornia
Ọlọrun ni aláṣẹ gbogbo ayé;òun ni ọlọ́lá jùlọ!
Pàṣán ni baba mi fi nà yín, ṣugbọn àkeekèé ni èmi óo fi ta yín.
Ọjọgbọn Bashua ti ṣiṣẹ pẹlu ajọ iṣọkan agbaye gẹgẹ bi oludari ikọ to n ṣoju ajọ naa (UNAMID) ọdun 2015 lo fipo naa silẹ.
Shittu ti tikẹẹti ẹgbẹ ko ja mọ lọwọ, ni iroyin sọ pe o o sọ pe alaafia ko ni i jọba ninu ẹgbẹ APC.
Ṣugbọn Jesu sọ pé, “Ẹ fi wọ́n sílẹ̀.
níwájú Efuraimu ati Bẹnjamini ati Manase.
Ọrẹ Tolu sọ pe, ti a ba sọrọ iwe mimọ, Tolu ko gba ipo mii ri yatọ si ipo kinni.
Lakotan gbogbo awọn nkan ti awọn eeyan n sọ ko ju ere lọ irufẹ eleyi ti o ma n waye laarin awọn alatilẹyin ere boolu jakejado agbaye.
Ni oṣu kejila ọdun 2019 ni Kabiyesi Oluwo, Ọba Abdulrasheed Akanbi kede pe ipinya ti de laarin oun ati Olori oun, Channel ti igbeyawo awọn si ti tuka.
Aarẹ Muhammadu Buhari ti da ẹbi iku awọn eeyan wọnyi le ẹgbẹ Boko Haram.
Solomoni ọba fún ọbabinrin náà ní gbogbo ohun tí ọkàn rẹ̀ ń fẹ́.
“Afunrugbin kan jáde lọ láti fúnrúgbìn.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Baby abandoned on dunmpsite: Mo ti bímọ mẹ́rin tẹ́lẹ̀ fún bàbá méjì nínú òṣí- Dupe Ogbomos Amọṣa bi awọn eeyan ba ri i pe agbara awọn gbe isọri olowo nla, awọn naa lee bọ si isọri awọn to n lo ina ọba daadaa.
Durkwa ni  “Laarin odun mẹ́wàá  sẹyin ni  ile-isẹ ologun pelu ajosepo awon iko omo ogun
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Bí o ṣe lè fí òǹkà, ọ̀mọ̀ ìka tàbí ìkúùkù wọn oúnjẹ́ Isreal to jẹ ọmọ ọdun mọkandinlọgbọn naa ba di agbo to fẹyin rin to lọ mu agbara wa, lo jẹwọ ọmọ ọkọ fun Kelvin nigba to ṣina fun un.
Muhammadu Buhari ti ni ojo iwaju orile ede Naijiria yii dara  lọdun 2019.
“Nígbàkúùgbà tí ìyàn bá mú ní ilẹ̀ yìí, tabi tí àjàkálẹ̀ àrùn bá bẹ́ sílẹ̀, tabi ọ̀gbẹlẹ̀, tabi ìrẹ̀dànù ohun ọ̀gbìn, tabi eṣú, tabi kòkòrò tíí máa jẹ ohun ọ̀gbìn; tabi tí àwọn ọ̀tá bá gbógun ti èyíkéyìí ninu àwọn ìlú wọn, irú ìyọnu tabi àìsàn yòówù tí ó lè jẹ́, 
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Coronavirus lockdown: Àwọn ọ̀nà tí ẹ le fi dun ara yín nínú lásìkò ìgbélé Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Coronavirus lockdown: Àwọn ọ̀nà tí ẹ le fi dun ara yín nínú lásìkò ìgbélé 19 Ìgbé 2020 Ọpọlọpọ orilẹ-ede ati ilu ni ọrọ igbele tipa-tipa kan, nitori itankalẹ aarun coronavirus.
Dokita Abubakar sọ fun BBC pe, ọmọ ẹni to ni ijapa ọhun, Sadiq Sulaiman n fẹyin rin pẹlu ọkọ, lo fi ṣeeṣi gun ijapa naa lori, eyi to mu ki igba ẹyin rẹ fọ.
Ẹni tí ó gbé ọjọ́ kan ga ju ọjọ́ mìíràn lọ, ti Oluwa ni ó ń rò.
"1967 sí 1970, gbọ́ ẹ̀dà ìtàn míì nípa ogun Biafra látẹ́nu ""Ìyá àgbà"" Ǹjẹ́ o mọ ipa tí ẹja Panla kó lásìkò ogun abẹ́lé Biafra?"
Awọn kan ni o ti fẹ maa ni iru ibaṣepọ to wa larin aarẹ ati olori awọn oṣiṣẹ aarẹ tẹlẹ, Abba Kyari.
Dokita àti Nọ́ọ̀sì fìyà jẹ mí lásìkò tí mò ń rọbí- Alaboyún EFCC ti ri mílíọ̀nù 65.
Mo ti jẹ́ kí ẹ̀mí mi bà lé e,yóo máa dá ẹjọ́ ẹ̀tọ́ fún àwọn orílẹ̀-èdè.
Igbe ati agbára rẹ kò lè gbà ọ́ kúrò ninu ìpọ́njú.
Bi iwaadi naa se n tẹsiwaju awọn ọlọpaa ni awọn ti ri afurasi kan to wa ni ahamọ bayi ti awọn ko si ni iroyin kankan lati fi to ara ilu leti lọwọ yi nipa isẹlẹ naa.
Àwọn nǹkan tí Solomoni ṣe pọ̀ tóbẹ́ẹ̀ tí a kò fi mọ ìwọ̀n idẹ tí ó lò.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Pius Adesanmi: Ọ̀gọ̀ọ̀rọ̀ èèyàn ń dárò ọ̀jọ̀gbọ́n ọmọ Nàìjíríà tó kú nínú ìjàmbá bàálù Ethiopia 10 Ẹrẹ̀nà 2019 Oríṣun àwòrán, @pius Àkọlé àwòrán, Ko sẹni ti kò ni ku laye!
Ta ni ẹ óo wá fi mí wé,tí n óo sì dàbí rẹ̀?
Èmi wá jókòó níhìn-ín, ebi ń pa mí kú lọ!
Mo gbóhùn ẹnìkan láàrin bèbè kinni keji odò Ulai tí ó wí pé, “Geburẹli, sọ ìtumọ̀ ìran tí ọkunrin yìí rí fún un.
Wọ́n mọ ìlànà ti Ọlọrun; wọ́n mọ̀ pé ikú ni ó tọ́ sí àwọn tí wọn bá ń hu irú ìwà wọnyi; sibẹ kì í ṣe pé wọ́n ń hu irú ìwà bẹ́ẹ̀ nìkan, wọ́n tún ń kan sáárá sí àwọn tí ń hùwà bẹ́ẹ̀.
Gbogbo aráyé,ẹ̀yin tí ń gbé orí ilẹ̀ ayé,nígbà tí a bá gbé àsíá sókè lórí àwọn òkè,ẹ wò ó, nígbà tí a bá fun fèrè ogun, ẹ gbọ́.
Afcon2019: Egypt ni yóò gbàlejò Afcon 2019
Saraki àgbà ló kọ́ ilé yìí fáwa arúgbó kìí ṣe Bùkọ́lá- Arúgbó Ilọrin Bàbá akẹ́kọ̀ọ́ LASU tí ọ̀rẹ́kùnrin rẹ̀ àti pásítọ̀ fi ṣ'oògùn owó ń bèèrè fún ìdájọ́ òdodo Idi ti EFCC ṣe mu Sheu Sani S'ahamọ.
Ko din ni agbẹ onirẹsi mẹtalelogoji ti Boko Haram bẹ lori nibẹ.
Awọn iroyin, aworan ati fidio eke ti wọn pin kiri lori isẹlẹ Lekki: Aadọrin oluwọde EndSARS ni ologun yinbọn pa ni Lekki: Ni kete ti isẹlẹ ikọlu Lekki waye ni ọjọ Isẹgun, ogunjọ kẹwaa, ni iroyin kan ti gba ori ayelujara pe awọn ologun ti yinbọn pa awọn ọdọ to le ni aadọrin.
alaga igbimo to n sagbekale ami-eye NNMA, ojogbon Shekarau Yakubu gboriyin fun
'Kristẹni lo n fara kaaṣa ikọlu fulani ju' Sé ó yẹ kàwọn pásítọ̀ máa bèèrè èso owó ńlá-ńlá ?
ero Seyi Makinde to gba gbogbo gomina ekun Gusu lalejo fi asiko ohun da adari
Sanusi Lamido Sanusi: Ashraf, ọmọ Lamido Sanusi ní ìṣọ̀kan ṣì wà nínú ẹbi Emir àná náà pẹ̀lú gbogbo ohun tí wọ́n là kọjá
Àtẹṣin, àtẹni tí ń gùn ún ni ó dà sinu Òkun Pupa.
Ogbeni Saleh Hassan to n soju ekun kan nipinle Benue lo te pepe ero yii niwaju awon omo ile lati rii pe aabo to peye wa fun awon asatipo paapaa julo awon obinrin ati awon omode.
 Ó ṣiṣẹ ́ ní Àmẹ ́ ríkà àti ilẹ ̀ gẹ ̀ ẹ ́ sì .
OLUWA, o fi ojurere wo ilẹ̀ rẹ;o dá ire Jakọbu pada.
Kí ló yẹ ká se sí ẹkùn tó pa ènìyàn márùn ún?
"Eyi to ṣe pàtàkì jùlọ ni pé, Ọtunba Kunle Olasope kìí korira ẹnikẹni, kìí ṣe ìgbéraga tàbi ko ma foju pa ẹnikẹni rẹ.
Oga agba kan nile-ise ajo eleto idibo Abdul Tholley, eni to ba awon oniroyin soro so pe, ko si isoro Kankan ninu eto idibo ohun.
Gomina Yahaya Bello ni alaga igbimọ to n ṣe kokari idibo abẹle naa; oun pẹlu si ṣepade pẹlu gbogbo wọn lalẹ ọjọ Aiku kan naa.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Police officer raiding illegal cockfight : Àlàyé rèé bí ọlọ́pàá ṣé kàgbákò ikú gbígbóná lọ́wọ́ àkùkọ 28 Ọ̀wàrà 2020 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Fifi akukọ ja nilẹ Phillipines ko ṣẹṣẹ bẹrẹ Hmmmn.
Bi awọn ipinlẹ to ṣẹṣẹ tun ni arun naa ṣe lọ ree.
Bakan naa ni wọn tun na Super Eagles ni ami ayo meji si ookan ninu idije ẹlẹgbẹjẹgbẹ ti AFCON lọdun 1982.
sibi lati wa gba imoran baba somo.
Ṣugbọn OLUWA tún gbọ́ ẹ̀bẹ̀ mi nígbà náà.
Ṣaaju ni olori igun kan ninu ẹgbẹ oṣelu APC nipinlẹ Zamfara, Sẹnetọ Kabiru Marafa, sọ pe ki Buni mu ọ̀kan ninu ko kọwe fi ipo silẹ, tabi ko ṣe ipagọ l'oṣu Kejila.
Àjẹsára ṣegede jẹ ́ èyítí kò léwu láti lò , àwọn àtúnbọ ̀ tán rẹ ̀ kìí sì ní ipá rárá .
ọba wọn ati àwọn ìjòyè rẹ̀ yóo sì lọ sí ìgbèkùn.
Ṣugbọn nígbà tí ó wu Ọlọrun, tí ó ti yà mí sọ́tọ̀ láti inú ìyá mi, ó fi oore-ọ̀fẹ́ rẹ̀ pè mí, 
88 Ipese ohun eelo amayedẹrun ati isẹ ode - 172,238,545,968.
Wọ́n ní, “Arakunrin wa ni Abimeleki jẹ́.
Ọ̀nà àtigun òkè Heresi ni Gideoni gbà nígbà tí ó ń ti ojú ogun pada bọ̀.
Kì í ṣe oúnjẹ ni yóo mú wa dé iwájú Ọlọrun.
Àwọn àgbà ti pa á lówe pé, bí o ti wù kí ó pẹ́ tó, ẹgbẹ̀rún ọdún ń bọ̀ wá ku ọ̀la, ọ̀la náà pé lónìí a sì dúpẹ́ lọ́wọ́ Ọlọ́run ọba.
Aṣofin Ọbasa ṣalaye pe Ile Igbimọ Aṣofin naa yoo gba gbogbo akiyesi wọn lati ṣayẹwo wọn nitori pe ẹka irinajo-afẹ ti ṣe gudugudu meje ninu ọrọ-aje awọn orilẹ-ede to ti goke agba.
Jesu wí fún un pé, “O wá gbàgbọ́ nítorí o rí mi!
Igbimọ naa ṣalaye pe Azikiwe ṣi lo agbara ati ipo rẹ lati maa fi fa ire lọ sọdọ banki naa (Report of the Foster-Sutton Tribunal of Inquiry, 1956: 42; Sklar, 2004: 185).
Paul sọ pé àwọn kò jẹ̀bi ẹ̀sùn tí wọ́n fi kan àwọn.
Obìnrin akọkọ nipinlẹ Kwara ni oun ti kan si Risikat Azeez atawọn ọmọ rẹ lati ipasẹ ibudo ajọ alaanu to da silẹ, iyen, Ajike People Support Centre.
Atẹjade naa ni wọn ti gbe igbimọ kalẹ lawọn ipinlẹ kan, eyi ti yoo wa ojutu si aawọ aarin wọn, ti eyi si ti n fidi mulẹ nipinlẹ Oyo, Ondo, Ekiti, Edo, Bauchi, Cross River, Enugu ati Zamfara.
‘Wán tú tírí kọ́ lafi ń mọ àgbà
Kí ló dé tí o fi gbé mi dìde?
Gbogbo eniyan ń sọkún tẹ̀dùntẹ̀dùn ní gbogbo orí ilé Moabu, ati àwọn ìta gbangba rẹ̀.
Ẹwẹ, Sẹnẹtọ Adeyemi naa ṣapejuwe Dino gẹgẹ ọmọ ọdọ ọkunrin rẹ.
Manfe-Dove: Àgbà ìlú kan ní ohùn kan ló fọ̀ sáwọn baba ńlá àwọn láti ṣe bẹ́ẹ̀
Sugbọn ṣe ẹyin tilẹ ranti itan Dokita Adadevoh ati oun ti o ṣe ti gbogbo eeyan fi n jaran iku rẹ?
Lẹyin iwadii ile aṣofin agba, pa aṣẹ iwe aṣẹ fun awọn agbofinro lati mu u jade ṣugbọn o na papa bora.
Agbenuso naa, Femi Joseph sọ fun BBC Yoruba wipe ọrọ naa dojuru nigbati Fulani darandaran kan fẹ ẹ wọ oko agbẹ yi, ti agbẹ naa si yari pe ohun ko ni i faaye gba Fulani darandaran na lati wọ inu oko oun.
Lọjọ kejila oṣu keji, akọroyin fun ile iṣẹ iroyin SABC lorilẹede South Africa sọ pe Aarẹ igba na Jacob Zuma ti gba lati kọwe fipo silẹ.
Oríṣun àwòrán, Instagram/officialefcc Magu wọjọgbọn lẹyin ti adajọ agba Naijiria, Abubakar Malami kọwe mọ ọ lori awọn aṣemaṣe kan.
Ṣé o ranti pé ìbátan wa ni Boasi, tí o wà pẹlu àwọn ọmọbinrin rẹ̀?
Aare orile ede Kenya, Uhuru Kenyatta ti darapọ mọ awọn adari kan lorile ede Afirika lojo Aiku, pe ki won  jẹ ki awon omo orile ede Afirika lee maa  rin lati orile ede kan si ekeji laini wahala rara.
Peka, ọmọ Remalaya, olórí ogun rẹ̀, pẹlu aadọta ọmọ ogun Gileadi dìtẹ̀ mọ́ ọn, wọ́n sì pa á ní Samaria, ninu ilé tí a mọ odi tí ó lágbára yíká, tí ó wà ninu ààfin rẹ̀, Peka sì jọba dípò rẹ̀.
Wọn ti gbé òkú ọmọ náà lọ sì ilé ìgbókùúsí kan tó wà ni GRA Ikeja nílu Èkó.
Aare Buhari yo pelu, ebi, ore, ara awon ololufe ati gbogbo awon akegbe re ninu eto idanilaraya.
tesiwaju nipa iwadii lori oro naa, laipe si ni ọrọ naa yoo niyanju.
Iroyin sọ pe  Dahir Mohamoud Gelle ti jẹ ki awon oniroyin mọ
nítorí ìwọ ni ààbò mi,ìwọ ni ilé ìṣọ́ tí ó lágbáraláti dáàbò bò mí lọ́wọ́ ọ̀tá.
Ni ọdun 1963 ni wọn bi alagba Afeez Oyetoro ti ọpọ mọ si Saka ninu ere agbelewo.
Gomina ipinlẹ naa, Onimọẹrọ Ṣeyi Makinde ni oun ti pada lọ ṣe ayẹwo ara oun lẹẹmeji ọtọọtọ lati mọ boyi arun Coronavirus ṣi wa lara oun tabi o ti lọ ati pe ayẹwo mejeeji bayii lo fihan pe ṣaka lara oun le.
Bẹẹ wọn ni wọn ko mu iyipada kankan ba ẹka ina ọba.
Wọ́n gbé òkú rẹ̀ lọ sí ilẹ̀ Kenaani, wọ́n sì sin ín sinu ihò òkúta tí ó wà ninu oko Makipela, ní ìhà ìlà oòrùn Mamure, tí Abrahamu rà mọ́ ilẹ̀ tí ó rà lọ́wọ́ Efuroni ará Hiti láti fi ṣe itẹ́ òkú.
Oúnjẹ àràmọ̀ǹdà mọ́kànlá tí wọ́n ń jẹ lágbààyé rèé, ẹ tẹ́wọ́ gbàá
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Opo omo South Africa mii ni iwa ikọlu sawọn ajoji yii ko tẹ lọrun Bawo ni gbogbo wọn ṣe pade?
Ṣé o wá sọ́dọ̀ mi láti rán Ọlọrun létí àwọn ẹ̀ṣẹ̀ mi, ati láti ṣe ikú pa ọmọ mi ni.
Mo nigbagbọ pe ootọ kọ ni ọrọ yii, Oyedepo yoo nilo lati da orilẹ-ede tirẹ silẹ ti yoo si ma da ibẹ gbe pẹlu awọn ofin tirẹ."
Nítorí náà, ẹ má ṣe àníyàn nípa nǹkan ti ọ̀la; nítorí ọ̀la ni nǹkan ti ọ̀la wà fún; wahala ti òní nìkan ti tó fún òní láì fi ti ọ̀la kún un.
Nitori naa, ẹ jẹ ka ṣe agbeyẹwo diẹ lara awọn aṣọ to ti logba ri.
Ni èyí tí o dẹ padà ri bẹẹ.
‘Ọ̀rẹ́ mi ní kí n fi ‘acid’ sí oúnjẹ ọmọ mi’ 'Ojú mi gún régé nítòótọ́ ṣùgbọ́n ọ̀pọ̀ máa ń sá fún mi ni' Abiyamọ ju abiyamọ lọ ni ọ̀rọ̀ Sima Sarkar 'Mo gba kádàrá lórí àìlera mi láìnáání yẹ̀yẹ́' Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí kan sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
Ó dára kí ẹ dá àkópamọ́ kí ẹ sì ṣe ìtẹ̀jáwọlé, ṣùgbọ́n kò pọn dandan
Ọlọrun mi, Ọlọrun mi, kí ló dé tí o fi kọ̀ mí sílẹ̀,tí o fi jìnnà sí mi, tí o kò gbọ́ igbe mi,kí o sì ràn mí lọ́wọ́?
Ekweremadu ni o pe ipe yii, ninu oro iranse re si awon onigbagbo ododo, nilu Abuja.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Orúkọ ọmọ ni Yorùbá gbà pé ó máa ń ro ọmọ nílẹ̀ Oodua Bi orilẹ-ede Thailand ba gba ki Chile gba ayo to ju meji si awọn rẹ, a jẹ wi pe orilẹ-ede Naijiria yoo ja kuro ni ipele to kan.
àwọn mejeeji ati ti àwọn ẹlẹgbẹ́ wọn tí wọ́n ṣẹ́kù pẹlu àwọn adájọ́, àwọn gomina ati àwọn ará Pasia, àwọn eniyan Ereki, àwọn ará Babiloni ati àwọn eniyan Susa, àwọn ará Elamu, 
Alabojuto náà fi Josẹfu ṣe olùdarí gbogbo àwọn tí wọ́n wà ninu ẹ̀wọ̀n, ohunkohun tí Josẹfu bá sọ, ni wọ́n ń ṣe.
Ìdá 90% nínú àwọn olówó Naijiria lo n lọ ilé babaláwo- Mr Latin Àyẹ̀wò gbogbo irinṣẹ́ ètò ìlera ti di dandan báyìí lẹ́yìn ikú Chineme Martins- NFF Israel Adesanya ti fi ẹ̀ṣẹ́ yanjú Romero Ó ṣe f'ọ́mọ tó n jeérú!
jẹ ́ ohun àìbójúmu tí kò wọ ́ pọ ̀ , leyí tí ọmọ ìkókó maa ní okó méjì .
Bẹ́ẹ̀ ni Solomoni ọba ṣe lọ́rọ̀, tí ó sì gbọ́n ju gbogbo ọba yòókù lọ.
idunnu re han lati kopa ninu ifesewonse naa.
Oun ni igbakeji gomina ipinlẹ Plateau ko to o tun dije dupo gomina ipinlẹ naa lọdun 2011 ki Jonah Jang to jawe olubori.
ní ọjọ ́ kan ẹrú aláwọ ̀ dúdú kan jáde ni ilé olówó rẹ ̀ , ó sì lọ sí ọ ̀ dọ ̀ agbejọ ́ rò aláwọ ̀ dúdú kan pẹ ̀ lú ọwọ ́ tí agbẹ ́ jọ ́ rò yìí yóò lò láti sọọ ́ di òmìnira .
Sùgbọ́n àwọran náà ti n ja lorí ayélujára láti ọdún 2011 tó si jẹ àra àwọn ìṣẹ̀lẹ̀ to wáye ninu ìjà abẹlé láàrin ọkọ ati ìyàwo ni Naijiria.
Kete ti ifẹsẹwọnsẹ naa pari ni ariya ti bẹ sode lorilẹede Egypt laarin awọn ọmọ Naijiria to wa nibẹ.
Ti a ba ri awon odaran to gbe ibọn AK47 lowo lasiko ti eto idibo n  lo  lowo, ti iye awon odaran naa si poju awon olopaa lo, se o maa so pe ki n maa lo iko omo oogun bi?
Ajagba sọ fawọn akọroyin pe ko ba wu oun ki Joshua gba lati ba oun ja lorilẹede Naijiria tawọn mejeeji ti wa.
Ẹ ò jẹ́ ká dánu dúró ń’bẹ̀un bí?
Ọna lati dẹkun rigbodiyan to le ti idi ẹhonu yii suyọ, lo mu ki ijọba lo iwa ipa lati bomi pana rẹ, ti wọn si ti awọn asaaju ẹgbẹ Agbekoya kan mọle.
1865 - 1877 ) je omo afrika oniwofa ati omo agbatoju si henry morton stanley .
“Nítorí èyí mo sọ fun yín pé a gba ìjọba Ọlọrun lọ́wọ́ yín, a fi fún orílẹ̀-èdè tí yóo so èso tí ó yẹ.
 oun ni ẹkẹta ninu idile awọn ọmọ marun ti iya rẹ , ati kẹfa lati inu idile awọn ọmọ mẹwa lati ọdọ baba rẹ .
Ṣugbọn èmi wá ń sọ fún yín pé, ẹ má ṣe gbẹ̀san bí ẹnikẹ́ni bá ṣe yín níbi.
Wọ́n ní o sọ pé kí wọn má kọ ọmọ wọn nílà; àtipé kí wọn má tẹ̀lé àṣà ìbílẹ̀ wọn mọ́.
#SagamuOnFire: Àwọn ẹbí Tiamiyu bèrè fún ìwádìí tòótó lórí ikú ọmọ wọn
Yóo tún fi ẹ̀rín kún ọ ní ẹ̀rẹ̀kẹ́,ẹnu rẹ yóo kún fún ìhó ayọ̀.
Ìtàn Obinrin tí Ó Ṣe Àgbèrè .
Irufẹ baba bẹẹ ti wọn sọ fun pe ojulowo ọmọ ni ọmọ rẹ, ko ni mọ pe ọmọ oun kọ, ọmọ ọlọmọ to jẹ mọlẹbi oun ni.
 wọ ́ n sábà tọ ́ ka sí àdàpọ ̀ yìí bíi ásìdì lewis .
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ọọ̀ni: Àwọ̀ méje bíi pupa, aró, ewéko ni omi àjèjì náà ní 17 Ẹrẹ̀nà 2019 Oríṣun àwòrán, Ooni adeyeye Enitan Ogunwusi Ọọni tilu Ile Ifẹ, Ọba Adeyẹye Ẹnitan Ogunwusi, Ọjaja keji, ti kede faraye pe oun tun ti se awari omi ajeji miran to n da nilu Ile Ifẹ.
Tọkọ-taya yii jọ da ileeṣẹ Lafodo Group silẹ.
Dafidi bá wá sí Baali Perasimu, ó sì ṣẹgun àwọn ará Filistia níbẹ̀.
Bouteflika  yoo fipo aleefa  aarẹ sile fun aare ti won yoo  dibo yan.
bí ó bá jẹ ́ òkú ọ ̀ dọ ́ tàbí ọmọdé , òkú ọ ̀ fọ ̀ àti ìbànújẹ ́ ló jẹ ́ .
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Juventus: Ronaldo gbáyò sáwọ̀n fún ìgbà àkọ́kọ́ 16 Owewe 2018 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ronaldo fakọyọ bí Juventus ti na Sassuolo Ẹlẹsẹ ayo Cristiano Ronaldo fi idunnu rẹ han lẹyin to gba bọọlu sawọn fun igba akọkọ ninu idije Seria A lati gba to ti to fi ikọ Real Madrid silẹ darapọ mọ ẹgbẹ agbabọọlu Juventus.
Syria si ni wọn n ṣe ikọlu si ju lẹyin Iraq.
Ohun ti iwe akọsilẹ ọlọpaa sọ ree.
    Ìgbà tí o kù díẹ̀ kí a wọnú ìlú náà, a bẹ̀rẹ̀ síí gbọ́ ariwo, ìgbà tí a sì dé ibẹ̀ ariwo náà ti pọ̀ tó bẹ́ẹ̀ gẹ́ẹ́ tí àti gbọ́ nǹkan tí enikejì ń sọ ṣòro.
Eyi to mu ki wọn da ile ẹkọ girama Oduduwa College silẹ losu Kinni, ọdun 1932, oun si lo fi owo ara rẹ silẹ fun kikọ ileẹkọ naa.
Arabinrin May Agbamuche-Mbu to jẹ adari ajọ eleto idibo ni ẹkun Bayelsa, Edo, ati ipinlẹ Rivers lo fun awọn mejeeji ni iwe ẹri yii ni Yenagoa Bayelsa loni.
Iroyin idasilẹ Yewande fa awuyewuye lori ayelujara.
Bakan naa lọ ṣiṣẹ gẹgẹ bi adari ni ẹka eto (Administrative Officer) ni ileeṣẹ Katsina Native Authority fun ọdun meje.
"Awa eeyan kan ma n gbiyanju ni, ti Ọlọrun ba sọ pe oun lọkọ mi, ma a sọ pe bẹẹni.
Àkànpọ̀ igi mẹfa ni kí ó wà lẹ́yìn àgọ́ náà ní apá ìwọ̀ oòrùn.
Àrùn náà a má a wáyé láti ìgbà dé ìgbà ní àwọn agbègbè tí ó wà ní gúsù aginjù sahara ní afrika , níbití àwọn ènìyàn tí ó wà lábẹ ́ ewu ti pọ ̀ tó àádọ ́ rin mílíọ ̀ nù ( 70 million ) ní orílẹ ̀ -èdè mẹ ́ rìndílógójì .
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, AbdulQudus Bello ṣàlàyé bí òun ṣe dí aláàbọ̀ ara nítorí pọpọ́ọ̀fù àti ìbínú jàǹdùkù àdúgbò Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Prophet Shepherd Bushiri: Iléẹjọ́ gbẹ́sẹ̀ lé ilé wòlíì tí iye rẹ̀ tó $350,00021 Bélú 2020 NÍ YÀJÓYÀJÓ US Elections: Donald Trump ti n fi àmì hàn pé òun ṣetán láti kúrò ní White House Akomolede Eko round up: Àwọn Olùkọ́ ìpínlẹ̀ Eko dárà lórí Akọ́mọlédè àti Àṣà lórí BBC7 Bélú 2020 Fídíò, Erelu Elemure: Ìyá mi rò pé mi ò lè tibi kíkọrin bíi bàbá mi là21 Bélú 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Eyi lo si mu wa duro ṣinṣin di oni Aisha Yesufu ni tirẹ ni, ""Fun ọdun mẹrin, awọn ọmọbinrin mejilelaadọfa wa ni ahamọ."
ninu isẹ rere ti won ti bẹrẹ.
Ẹ̀yin ará Taṣiṣi,ẹ máa tàn ká orí ilẹ̀ yín títí ẹ ó fi kan odò Naili,kò sí èbúté tí yóo da yín dúró mọ́.
“Gbogbo eniyan lo mo pe opo ninu awon agbaboolu wa lo n toju ifarapa kan tabi keji.
Orukọ awọn mejila ti wọn ko lọ idije naa ni: Jasmine Nwajei, Adaora Elonu, Sarah Imovbioh, Sarah Ogoke, Elo Edema, Nkechi Akashili, Evelyn Akhator, Aisha Mohammed, Ezinne Kalu, Atonye Nyingifa, Cecilia Okoye ati Promise Amukamara Oríṣun àwòrán, @phatill Fun anfani awọn ti ko mọ bii idije naa ṣe waye, awọn oun to ṣẹlẹ nigba idije naa ree.
"Ohun ti inu mi kan dun si ni pe bi o ṣe lo ile aye rẹ.
 Fun idi eyi maa ro awon akegbe mi gbogbo lati ri da ju pe, won ko fayegba ile itaje kankan ni ayika papa isere bi o ti le wu ko mo,”O tenumo pe, awon ise akanse ti a pese bii: eroja igbalode, awon ohun amayederun si awon papa isere wa kookan fun idije agbaye ohun, yoo wulo fun wa lopolopo lojo iwaju fun idagbasoke ere idayara lorile-ede yii.
Lẹ́yìn atótónú lọ́pọ̀lọpọ̀ láti oṣù díẹ̀ sẹ́yìn ni ilé ẹjọ́ ni wọ́n jẹ̀bi ẹsùn ijínígbé àti díde ìwádìí lọ́nà lórí àwọn ẹ̀rí tó wà níwájú ílé ẹjọ́.
Bakan naa ni IGP nigba naa paṣẹ ki awọn ọlọpaa ma a wọ aṣọ iṣẹ wọn pẹlu ami idanimọ lasiko iṣẹ.
Bi a bá ṣè eléyìí tán, kí a gbàdúrà pé kí kòkòrò náà má yà inú okò wà''.
Àkọlé àwòrán, Ajà fẹ́tọ ọmọniyan gbàgboro lAbuja lóri mimu obinrin sátimole nitori iwosọ Ní ti àwọn ajàfẹto, wọn ni mímu wọn si atimọle kìí ṣe ǹkan ti o ba ofin mú àti pé wọn ń fi ọwọ pa ẹtọ àwọn obinrin náà lóju ni Àkọlé àwòrán, Ajà fẹ́tọ ọmọniyan gbàgboro lAbuja lóri mimu obinrin sátimole nitori iwosọ Ọkan nínú àwọn to jáde wa ni ajàfẹtọ obinrin Aisha Yesufu, ó sàlàye pé ìdí ti òun fi jáde wa ni pé o ti tó gẹ  O dà bi ẹni pe ti ènìyàn ba ti jẹ obinrin, ọ̀ràn ní oluwa rẹ̀ dá, wọn kan máà ṣe obinrin báṣubaṣu, obinrin a maa rìn lọ lọ́san gangan, ọlọpàá a si jú ènìyàn si inu ọkọ̀, a wá ń gbọ pe àwọn ènìyàn ti wọn ń mu yìí, àwọn ọlọpàá a maa fi ipá ba wọn lò pọ̀ ki wọn to tú wọn silẹ̀."
N óo máa jẹ́ Ọlọrun rẹ̀, òun náà yóo sì máa jẹ́ ọmọ mi.
Mo fẹ́ kí ẹ mọ̀ dájúdájú pé n kò ní mu ninu èso àjàrà mọ́ títí di ọjọ́ tí n óo mu ún ní ọ̀tun ninu ìjọba Ọlọrun.
Ibudo idibo akọkọ si maa n pari idibo wọn ni aago meje.
naa, lati jẹ ki won lo  atẹ ayluara ti
Ile-isẹ ijọba to n risi ọrọ igbẹjọ lorilẹede Naijiria, sọ wipe ita gbangba ni wọn yoo ti ṣe igbẹjọ awọn afunrasi to le lẹgbẹrun naa, eleyi ti o yatọ si igbẹjọ ikọkọ ti wọn maa n ṣe fun wọn tẹlẹ.
Nítorí náà, bí Baba yín tí ń bẹ ní ọ̀run ti pé ninu ìṣe rẹ̀, bẹ́ẹ̀ gan-an ni kí ẹ̀yin náà pé.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Traffic gridlock: Sanwo-Olu fẹ́ sún ìrìnnà ọkọ̀ àjàgbé kúrò lọ́sàn sí òru l'Eko 26 Bélú 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Njẹ o mọ pe o ṣeeṣe ki irinna loju popo ni ọsan di eewọ fun gbogbo awọn ọkọ ajagbe nlanla ni ipinlẹ Eko?
Wọn wa pe fun agbekalẹ igbimọ kan ti yoo wadi ohun gbogbo to rọ ms iṣẹlẹ ọhun.
Wọn bi mẹta ninu awọn obinrin naa is Amerika nigba ti Omar wa lati Somalia lati kekere.
Wọn kò ní ilé tí wọn ń kó nǹkan pamọ́ sí, bẹ́ẹ̀ ni wọn kò ní abà.
15 Ọ̀wàrà 2020 Fídíò, EndSars, EndSwat: Ọlọ́pàá ti fi ìbọn lù mí láyà rí torí mó ní 'extra tyre' méjì- afẹ́hònúhàn15 Ọ̀wàrà 2020 Fídíò, Soyinka Cancer: Àṣe ara mi ni iso ti n run gbogbo bí mo ṣe n ṣèrànwọ́ lórí jẹjẹrẹ27 Bélú 2019 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Niṣe ni pupọ lara wọn dahun pe ''awọn jẹbi, nigba ti adajọ beere pe ''ṣe ẹgba pe lootọ ni ẹ n ta ara yin, ti ẹ si fi n da alaafia ilu laamu, leyi to tako ofin ilu Abuja.
Oríṣun àwòrán, Oluwo Ọrangun ni Oluwo ti yaju tẹlẹ si Alaafin tilu Ọyọ, Ọba Lamidi Ọlayiwọla Adeyemi Kẹta ati Ọọni tilu Ile Ifẹ, Ọba Adeyẹye Ẹnitan Ogunwusi.
Ìyẹn ló fàá tó fi jẹ́ pé nígbà ooru, ọjúmọ́ máa ngùn ju ilẹ̀ṣú lọ.
Oríṣun àwòrán, Reuters Àwọn orilẹ̀-ède Afirika náà ni Algeria, Angola, Egypt, Ethiopia, Mauritius, Morocco, Mozambique, Namibia, Rwanda, Uganda àti Zambia.
Amọ awọn ero to wa sibẹ sọ wi pe ijọba ko se daato nitori wọn gbegidi sinima awọn.
Bí eniyan bá ké pè é, kò lè gbọ́,kò lè yọ eniyan ninu ìṣòro rẹ̀.
Kí o fi igbagbọ ati ẹ̀rí-ọkàn rere jà.
"Lizzy, ẹni to sọrọ nipa ipenija to n koju ninu iṣẹ to yan laayo naa ni, ""oju obinrin tó wa lagbo amuludun n ri to, nitori ọpọ ilọkulọ ti wọn n fi lọ obinrin, to si jẹ pe obinrin ko le wọ awujọ kan, lai jẹ pe ọkunrin ni yoo mu lọ sibẹ."
Oríṣun àwòrán, Others Nibi ipolongo idibo to waye ni aafin Ọba Benin, Ọba Ewuare 11 ni ija ti bẹ silẹ, ti ọpọlọpọ dukia to fi mọ ọkọ ayọkẹlẹ, awọn asia ipolongo ni wọn bajẹ ni agbegbe naa.
Adeboye: Màá fi ọlọ́pàá gbé ẹni tó bá lo fọ́tò mí sára kàlẹ́ńdà
A máa dárí ẹ̀ṣẹ̀ ati àìṣedéédé ji eniyan, ṣugbọn kì í jẹ́ kí ẹlẹ́bi lọ láìjìyà.
Ninu ọrọ kan to kọ si ori ayelujara Instagram rẹ, Lizzy sọ pe ọkọ oun ko ni agbara lati mojuto iyawo meji, de ibi mẹfa ti awọn eeyan n pariwo kiri.
Òun ni ó ń fún àwọn ẹranko ní oúnjẹ,tí ó sì ń bọ́ ọmọ ẹyẹ ìwò, tí ó ń ké.
Minisita tun ni oko oju irin
Ṣugbọn nígbà tí Farao rí i pé òjò ti dá, ati pé yìnyín ati ààrá ti dáwọ́ dúró, ó tún dẹ́ṣẹ̀, ọkàn rẹ̀ tún le, ati ti àwọn ẹmẹ̀wà rẹ̀.
O ni iwadi si nlọ lọwọ lori ẹsun ti wọn fi kan an ati wipe awọn idahun ti o fesi lori ibeere yoo se iranlọwọ fun ajọ naa lati ni aridaju ẹsun.
Igba keji ree ti Nengi yoo gba ipo olori laarin oṣu meji le diẹ.
Rebeka bímọ meji fún ẹnìkan ṣoṣo, òun náà ni baba wa Isaaki.
Lẹ́hìn èyí, wọ́n wáá fi ọ̀pá ìlẹ̀kẹ́ lé e ní ọwọ́ wọ́n sì mú ìyàwó àfẹ́sọ́nà rẹ̀ wọ́n ṣe é ní ọ̀ṣọ́ láti orí dé àtẹ́lẹsẹ̀, ara eléyìínì mọ́ tónítóní bí òṣùmàrè àwọsánmọ̀, eyín obìnrin náà sì dàbí òòrùn ọ̀án gangan.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ọja Arena Oshodi ni àwọn èèyàn ti ń r'aja Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Àwọn ẹ̀bùn ati ẹbọ tí wọn ń rú nígbà náà kò lè fún àwọn tí ó ń rú wọn ní ìbàlẹ̀ àyà patapata.
Ariwo pe awọn ko fẹ igbesẹ igbọjẹgẹ Boris ni wọn n pa.
 Ó ṣe àwo tí ó ju ogún lọ , tí ó sì jẹ ́ pé gbkogbo wọn ni ó ṣe ní àṣeyọrí.
Gẹgẹ bi a ti kaa ni oju opo Wikipedia lori itakun agbaye, ilana iwaasu iwa irẹlẹ ni Emmanuel Odumosu, ti gbogbo eeyan mọ si 'Jesu Oyingbo' fi bẹrẹ, ko to wa gbajumọ eto okoowo sise.
Ẹwẹ, onimọ kan nipa oogun oyinbo to ba BBC sọrọ ṣalaye pe bo ya oogun Chloroquine le ṣiṣẹ fun aarun coronavirus tabi bẹẹ kọ, ajọ eto ilera lagbaye(WHO) ati ajọ ilẹ Amẹrika to n ṣakoso ounjẹ lo le sọ.
Ṣugbọn nígbà tí wọ́n dé Harani, wọ́n tẹ̀dó sibẹ.
Idris Olawuyi n ṣe'ranti Barrister pẹlu orin to fun ra rẹ kọ pe b'iku ṣe lagbara to ko si oloogun to ri tiku ṣe.
"eré oníṣe "" Ọ ̣ ba kò so "" ( the king did not hang ) , jẹ ́ ọ ̀ kan kàǹkà lára ìtàn akọni ìgbà ìwáṣẹ ̀ tí ó ṣòro nípa bí ọba Ṣàngó ṣe di Òriṣà àkúnlẹ ̀ bọ , loyin-mọmọ àdò láti nàìjíríà títí dé àwùjọ àgbáyé pàá pàá jùlọ àwùjọ ìpéjọ-pò àkọ ́ kọ ́ ' commonwealth arts festival ' ní 1965 àti ní ilẹ ̀ aláwọ ̀ funfun pátá pátá european , níbi tí lámèyítọ ́ ilẹ ̀ berlin kan , ọ ̀ gbẹ ́ ni ulli beier tí ṣe gbémi n gbé ọ wò láàrín ládípọ ̀ sí karajan ."
Nigba ti wọn gbe Sade pada silu Ọba, o yan isẹ orin kíkọ takansufe laayo, to si di gbajumọ akọrin yika agbaye.
bayii,Bakan naa, awon eleto aabo,agbofinro naa duro ni papa isere naa lati mojuto eto aabo.
nígbà náà kí alufaa yẹ olúwarẹ̀ wò, bí àrùn ẹ̀tẹ̀ yìí bá ti bo gbogbo ara rẹ̀ patapata, kí ó pè é ní mímọ́.
Lọjọ Aje ni wọn bura sipo fun aderinposonu ọmọ orileede Ukrain,Volodymyr Zelensky, gẹgẹ bi aarẹ ilẹ naa tuntun.
Awọn ọkunrin naa ni wọn sọ pe wọn wa lara ikọ adigunjale to fi nnkan abugbamu fọ ilẹkun awọn banki mẹta ọhun, ki wọn o to ja wọn lole.
Ohun ni aṣoju agbegbe Saint Ann South East nile asofin ilẹ naa.
 Adamu pasẹ fun komisona awon olopaa to wa ni
Nígbà ti wọ́n bẹ̀rẹ̀ si ni fi ọ̀rọ̀ wáa lẹ́nu wò, ọmọkunrin náà ni òun ko tii fi òunjẹ kan ẹnu fún ọjọ meji pẹ̀lú ìreti pé o yẹ ki oun rí iṣẹ́ gbà sùgbọ̀n ti kò yori.
Mo lọ kúnlẹ̀, mo ké sí Ọlọ́run, mo bẹ ẹ kí o maṣe jẹ́ kí ojú tì mi, mo ké tàánútàánú tó bẹ́ẹ̀ tí omi ń bọ́ lójú mi nígbà ti mo fi máa jáde.
" Wọ́n dájọ́ ikú nípa sísọ̀kò pa ẹni ọdún 61 ní Kano Àwọ̀ ojú pọ̀ bíi àwọ̀ òṣùmàrè, àmọ́ ojú búlúù Risikat kò nílò àtúnṣe- Dókítà Feyi Èmi sì ni Gíwá fásítì UNILAG, kò sẹ́ni tó yọ mí nípò- Ọ̀jọ̀gbọ́n Ogundipe yarí Ó takò òfin kí àwọn obí jẹ̀yà ti ọmọ ba darapọ̀ mọ́ ẹgbẹ́ òkùnkùn- Ajàfẹ́tọ̀ọ́mónìyàn Bakan naa lọrọ ri nile igbokusi Gidan Gona, to wa ni ijọba ibilẹ Tarauni, ti oṣiṣẹ rẹ kan ti ko ba fẹ ki BBC darukọ oun ni, ọku pọ ju iye iboji to wa lọ.
Oríṣun àwòrán, SA MEDIA MINISTRY OF YOUTH AND SPORT DEVELOPMENT Àkọlé àwòrán, Mínísità fún ọ̀dọ́ àti ìdàgbásókè eré ìdáraya, Sunday Dare Ilé iṣẹ́ ọdọ́ àti ìdàgbàsókè eré ìdáraya ti bẹ̀rẹ̀ ètò lórí bi àwọn ilé ìfowópamọ́ ọ̀dọ́ yìí yóò ṣe bẹ̀rẹ̀, Bákan náà ni gbogbo iwé ofin ti yóò gbe e dúró ti n lọ lọ́wọ́.
Gbajumọ awujọ naa ni oun dupẹ lọwọ Ọlọrun Ọba to se oore daadaa fun oun, bi oun ba si jẹ eeyan radarada ni, Ọlọrun ko se nnkan daadaa fun oun.
Lẹ́yìn tí ó ti lé àwọn eniyan jáde, ó wọ inú ilé, ó mú ọmọbinrin náà lọ́wọ́, ọmọbinrin náà bá dìde.
Lẹ́yìn náà, Josaya ọba ranṣẹ pe gbogbo àwọn àgbààgbà Juda ati ti Jerusalẹmu.
Bẹẹ ni wọn wa rọ awọn eniyan lati tẹlẹ imọran ijọba lori ofin yiyagofunraẹni ti o le dẹkun itankalẹ arun Coronavirus.
Ijokodo - Apete road ni wọn pe ni Ambassador Olu Sanu bayii 3.
Iṣẹ́ Kudirat Abiọla ṣì ń fọhùn síbẹ̀, lẹ́yìn ọdún 23 tó papòdà Buhari ṣèlérí tuntun fún Nàìjíríà fún ìtúnu àwẹ̀ Kini Pásítọ̀ Kumuyi fi ṣẹ ọmọ Naijiria?
BBC Yoruba ba gbajugbaja olorin nni to tun jẹ oludaleeṣẹ redio silẹ, Yinka Ayefẹlẹ sọrọ lati fi aridaju rẹ han pe ni bayi, o ti di baba ibẹta lootọ.
 Pupo ninu awon to ku ni won dana sun , ti eefin si pa awon miiran.
Igbákejì gómìnà, olórí òṣìṣẹ́ ọba àtàwọn míì ni wọ́n dá padà níbi àdúrà Saaju la ti kọkọ s fun yin pe ikọ ijọba ipinlẹ Oyo to lọ sibi adura Fidau ọjọ mẹjọ fun Gomina ana, Abiola Ajimobi ni wọn ko jẹ ki wọn wọle sile Ajimobi to wa ni Oluyole nilu Ibadan.
’’ Ìpanu ‘Cheese ball’ ni wọ́n fi jí Ikimot gbé, àmọ́ ó padà sílé lẹ́yìn ọdún márùn-ún Yorùbá, ọmọ ọdún mẹ́jọ tà ọmọ òyìnbò yọ nínú ayò Chess l‘Amẹrika Àwọn àmì tó fi mọ̀ pé wọn ń fipá bá ọmọdébìnrin rẹ lòpọ̀ Akọroyin BBC ṣe idanwo ranpẹ fun lati ọ boya lootọ ni.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Kemi Lala: mo ń gbìyànjú láti mú inú òbí mi dùn Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 3 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 5 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Fayoṣe ní ìbéèrè mẹ́rin fún Buhari lórí ìwé ẹ̀rí rẹ̀ Ààyè sí sílẹ̀ fún ọmọ Nàíjíríà láti di ológun nílẹ̀ Gẹẹsì Ẹgbẹ́ òṣiṣẹ́ Nàìjíríà so ìyanṣẹ́lódì rọ̀ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Lekan Kingkong: Níbikíbi tí mo bá wà, màá gbé àṣà Yorùbá ga Oju opo Twitter INEC ni ikede nipa ibẹrẹ ayẹwo orukọ yii ti waye.
Ó ní ìwádìí tí ń lọ lọ́wọ́ lórí ẹ̀sùn tí wọn fi kan, pélú ìdánilójú pé àwọn yóò kan sí BBC padà lẹ́yìn ìwádìí.
Ajọ LASEMA ati agbẹnusọ ajọ to maa n wadii ọrọ to ni ṣe pẹlu ijamba lorilẹede Naijiria, Accident Investigation Bureau lo fidi ọrọ naa mulẹ.
Bichi lasiko to n sọrọ pẹlu awọn akọroyin ni ti Inec ko ba wọgile esi ibo naa, awọn yoo gbe ọrọ naa lọ si iwaju ile ẹjọ nitori pe awọn eeyan Kano ti fihan pe PDP lawọn yan laayo.
Bí ọkàn mi ti rí gan-an nígbà náà ni mo ṣe ròyìn fún un.
Ó bá lọ sí ilé OLUWA pẹlu gbogbo ará Juda, ati àwọn tí wọn ń gbé Jerusalẹmu; ati àwọn alufaa, ati àwọn ọmọ Lefi ati àwọn eniyan yòókù; ati olówó ati talaka.
World TV Day: Èwo nínú àwọn amóhùnmáwòrán yìí lẹ rántí?
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Mo fòpin sí àjẹbánu lórí owó ìrànwọ́ epo àti iná ọba, ní èlé ṣe wáyé - Buhari Ọlọ́pàá tó dá dókítà oníṣẹ́ abẹ dúró lásìkò ìséde, fa ikú alaboyún kan Wo ìdí tí wọ́n ṣe lé Erica dànù kúrò nílé BBNaija l'ọ́sẹ̀ yìí Kí ló ṣe Ibrahim Chatta tó fi dèrò ilé ìwòsàn?
Apapo iko ogbon agbaboolu ohun ni kikun:  
 Bakan naa  la n sise papo pelu awon omo ogun lati wo awon ekun to ni eru diedie lati ri aaye fun won labere ajesara to ye”Minista fi da awon eniyan loju pe ijoba maa sa ipa re lati rii pe polio ko tun gberi mo ni ekun yii.
Oríṣun àwòrán, Reuters Àkọlé àwòrán, Petr Cech mu bọọlu gbelẹ-ko-gba-sile (Penalty) ti Watford gba Nisẹju kẹrindinlaadọrin (76) ti wọn bẹrẹ ere ni Henrikh Mkhitaryan gba bọọlu ẹlẹkẹta s'awọn Watford.
Alukoro ọlọpaa Fadeyi Olugbenga lo fidi ọrọ naa mulẹ.
Nítorí pé àwọn fèrèsé ojú ọ̀run ti ṣí,àwọn ìpilẹ̀ṣẹ̀ ayé sì mì tìtì.
O ni awọn alakoso eto adojutofo ilera ti amọ si HMO ko ri owo ọfẹ na mọ; wọn ko si gbadun awọn ilana atunto gbogbo ti oun n gbe kalẹ lo faa; eyi lo si n fa wahala lọ rọọ kun nile ti wọn n fun oun.
Baba ọmọ náà mọ̀ pé àkókò náà gan-an ni Jesu sọ fún òun pé, “Ọmọ rẹ yóo yè.
Bí o fẹ́ bí o kọ̀ n ó fà ọ́ dé ‘bẹ̀ bí ó ṣe gbígbé ni n óò gbé ọ.
 Ṣùgbọ ́ n ìsàlẹ ̀ díẹ ̀ ni òun náà bá dúro sí .
“Mo ti sọ nǹkan wọnyi fun yín nígbà tí mo ṣì wà lọ́dọ̀ yín.
Yóo yọ́ gbogbo ọ̀rá rẹ̀, bí wọ́n ti ń yọ́ ọ̀rá ẹran tí wọ́n bá fi rú ẹbọ alaafia.
Ẹja ree lọfẹ-lofo yii, haa, ẹran ku si ilu ailọbẹ.
Ìṣẹ̀lẹ̀ náà jẹ́ ọkan lára àwọn ikọlu to tún buru níní àwọn èyí tó tí ń wáye, èyí to fi han pé ìjọba oríẹ̀-èdè Nàìjíríà.
Fayoṣe iru awọn eeyan ko yẹ ki wọn maa gbe aarin awọn eeyan lawujọ.
Wọ́n bá jókòó lọ́wọ̀ọ̀wọ́, ní ọgọọgọrun-un ati ní aadọtọọta.
Gege bi Rohr se so“A fe awon agbaboolu ti o yara legbe.
awọn aami aiṣan ninu ifun le ni pajapaja ninu [ [ inu rirun ] ] , igbẹ-ọrin , ati eebi bίbὶ .
Ni bayii, Super Eagles yoo maa fojusona lati jawe olubori ninu ifesewonse olorejore keyin to ni, leyin ti iko ohun padanu ifesewonse olorejore meji ti won gba seyin sowo Serbia ati England.
Àwọn tí ó wá ṣiṣẹ́ náà sọ wípé olóríi àwọn, ọmọ ìgbìmọ̀ ìbílẹ̀ (Dhaka-7) Haji Md.
Oríṣun àwòrán, Reuters Àkọlé àwòrán, Awọn eniyan Almoradi ni ẹkun Costa Blanca ree ti wọn duro ti ẹru wọn lẹyin iji lile lasiko arọọrọda ojo to rọ lọsẹ to kọja Oríṣun àwòrán, @folasade Àkọlé àwòrán, Aarẹ Mohammadu Buhari yan Omowe Folasade Esan dipo Winnifred Oyo Ita Giwa.
Àwọn ìpín mejeeji tí wọ́n bá ṣíwọ́ iṣẹ́ ní ọjọ́ ìsinmi, yóo wá dúró ní ilé OLUWA láti dáàbò bo ọba.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù What did Buhari say about the lockdown: Awọn ọmọ Nàìjíríà káàkiri àgbáyé sọ ìrírí lábẹ́ àṣẹ kónílé-ó-gbélé Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ What did Buhari say about the lockdown: Awọn ọmọ Nàìjíríà káàkiri àgbáyé sọ ìrírí lábẹ́ àṣẹ kónílé-ó-gbélé 28 Ìgbé 2020 Kariaye laarun Coronavirus.
Eyi tumọ si pe 'kii ṣe owó ti ofin faaye gba', o ko si le lo o lati san gbèsè.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Coronavirus: Ìjọba ìpínlẹ̀ Eko rọ àwọn tó bá ọmọ Nàìjíríà tó k'árùn COVID-19 wọ bàlúù láti jókó sílé fún ọjọ́ mẹ́rìnlá 17 Ẹrẹ̀nà 2020 Oríṣun àwòrán, Ahmad bashir Aarẹ Muhammadu Buhari ti buwọlu isunsiwaju ere idaraya apapọ Naijiria to yẹ ko waye nipinlẹ Edo lọdun yii.
Ẹni tí ó mọ́, ati ẹni tí kò mọ́ lè jẹ ninu ẹran náà bí ìgbà tí eniyan ń jẹ ẹran ẹtu tabi ti àgbọ̀nrín.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ẹtàn ni àwọn ọ̀rẹ́ fi ń tan èèyàn lọ si Libya pé iṣẹ́ gidi wà níbẹ̀ Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
EndSARS Protest Updates: Feminist Coalition sọ fáwọn ọ̀dọ́ láti fòpin sí ìwọ́de
Jesu bá fi ọwọ́ kàn án lọ́wọ́, ibà náà sì fi í sílẹ̀.
Wéré ọba tọ lé ọ̀kan nínú àwọn màúù wọ̀n-ọnnì, ìgbà tí màlúù ju orí, ẹ̀yìn ọba, ilẹ̀ lo lọ, màlúù ní igi.
Gbogbo awọn mẹwaa to wa nibẹ ni wọn ni ki wọn sanwo itanran to din diẹ ẹgbẹrun lọna ọgọfa.
Ruga Settlement: Osinbajo ta kété sí ọ̀rọ̀ Gàá Fúlàní
(Mirror) Amọ ṣa, o ṣeeṣe ki Pogba o ṣi lo ọdun kan si i ni Old Trafford, eyi to le mu ifasẹyin ba rira ti wọn fẹ ra Milinkovic-Savic.
Atiku ṣalaye pe oun ti sọ fun ajọ to n gbogun ajakalẹ arun ni Naijiria, NCDC, ati pe ọmọ naa ti n gba itọju nile iwosan olukọni fasiti Abuja to wa ni Gwagwalada.
Ẹni ti oríyà rí ni kó gbá àbúlé Ẹ ̀ san lọ .
Ipade naa tun menuba awon oga ologun  ti yoo gba igbega lenu ise .
    Emi àti ìyàwó mi lo sì jọ ròó pé ki ń wá sí ọ̀dọ̀ ọ̀rẹ́ mi yìí ki n sọ ìtàn ìgbésí ayé mi fún un.
Fuji: Èmi àti Adewale Ayuba ò ja, Ọlọ́run ló fún mi lóhùn t'èmi
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Oyo Algon: Agbẹjọ́rò ìjọba Ọyọ ní Makinde kò tí ì rí ìwé ìpẹ̀jọ́ 18 Òkùdu 2019 Oríṣun àwòrán, Seyi@official Àkọlé àwòrán, Local Government Dissolusion: Ọgbọ̀n ọjọ́ oṣù keje ní igbéjọ yóò wáye ló ìjọba ibílẹ̀ Ọyọ.
Obinrin ni mo bi fun-un, ti yoo si pe ọdun mẹsan laipẹ.
Akọ̀ròyìn lóbìnrin á ní láti fọ̀rọ̀wọ́rọ̀ pẹ̀lú alámọ̀dájú ọkùnrin kan nígbà tí Akọ̀ròyìn lọ́kùnrin á ní ìfọ̀rọ̀wọ́rọ̀ pẹ̀lú àwọn obìnrin.
Ajimobi ni ìlérí òun láti mú àwọn tó pa 'Ṣuga' kò yí padà
Agbada yìí wà lórí ère mààlúù mejila tí wọ́n kọjú síta: mẹta kọjú sí ìhà àríwá, mẹta kọjú sí ìwọ̀ oòrùn, mẹta kọjú sí ìhà gúsù, mẹta yòókù sì kọjú sí ìlà oòrùn.
OLUWA tún sọ fún Mose pé kí ó dìde ní òwúrọ̀ kutukutu, kí ó lọ siwaju Farao, kí ó sì sọ fún un pé kí ó gbọ́ ohun tí òun OLUWA Ọlọrun àwọn Heberu wí, kí ó jẹ́ kí àwọn eniyan òun lọ sin òun.
Gẹgẹ bi ileeṣẹ iroyin NAN ṣe sọ, ọdun 2018 ni wọn ti afara ọhun kẹyin fun ọjọ mẹta lọna ati ṣe iwadii awọn iha to ti n dẹnukọlẹ lori rẹ.
Ọkan lara awọn afojusun eto idagbasoke kariaye, SDGs ti ajọ iṣọkan agbaye UN gbe kalẹ ni mimu anfani omi to mọ gaara ati imọtoto waye fun tẹrutọmọ ni ọdun 2030 lati lee dẹkun awọn aisan bayii.
Amọ, Agbẹjọrọ fun Albert Akintoye,Adamson Adeboro ni ẹjọ to yẹ ni adajọ da nitori Gboluga sọ fun ile ẹjọ wi pe oun ti jẹjẹ fun Ilẹ Gẹẹsi(UK) gẹgẹ bi ile oun, ti oun yoo si tẹlẹ gbogbo asẹ wọn.
Minisita fun eto owo-na ati idagbasoke oro aje, abileko Eucharia Offor, so eyi di mimo lasiko ti o  n fo eto isuna owo odun 2018 si wewe.
Ati pe ijà (ikọlu, ogun), àyípada ojú ọjọ́, àìdọ́gbà láwùjọ àti bí ètò òunjẹ ṣe dí èyí ti kò tóó pín naa fẹ apero.
Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Prophet Shepherd Bushiri: Iléẹjọ́ gbẹ́sẹ̀ lé ilé wòlíì tí iye rẹ̀ tó $350,00021 Bélú 2020 4:25 Fídíò, Erelu Elemure: Ìyá mi rò pé mi ò lè tibi kíkọrin bíi bàbá mi là, Duration 4,2521 Bélú 2020 Prophet Israel Oladele: Àwọn ìlúmọ̀ọ́ka tó ti jọ́sìn ní ijọ CCC, Genesis Global rèé21 Bélú 2020 Professor Peller: Ọlọ́wọ́ idán àkọ́kọ́ nílẹ̀ Áfíríkà tó ń pidán fáwọn aṣaájú orílẹ̀èdè19 Bélú 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 3 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 5 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Ìwà burúkú wa pọ̀ pupọ níwájú rẹ, àwọn ẹ̀ṣẹ̀ wa ní ìpele ìpele, sì ga títí kan ọ̀run.
Wọ́n lé wọn jáde kúrò ní agbègbè wọn.
 Oba alaye yii wa gba ijoba apapo nimoran lati palẹ
Ẹ darapọ̀ mọ́ BBC Yorùbá lásìkò ìbò fún ìròyìn yàjóyàjó Obinrin kan rèé tó borí ogun Gẹ̀ẹ́sì Akíkanjú obìnrin Algeria tó kojú ogun Lárúbáwá fáwọn ènìyàn rẹ̀ INEC: Kò sí ìká tí o kò lè fí dìbò, ṣáà tí tẹ̀ ẹ́ sójú ẹ dáadáa Iranlọwọ nla fun ọkọ ni obinrin jẹ lọọdẹ ọkunrin to ba mọ itọju aya.
Ọjọ́ ipè ogun ati ariwo ogun sí àwọn ìlú olódi ati àwọn ilé-ìṣọ́ gíga.
Ṣekemu bá lọ sọ fún Hamori, baba rẹ̀, pé kí ó fẹ́ ọmọbinrin náà fún òun.
Àkọlé àwòrán, Ọ̀rẹ́kùnrin Khadijat Olubọyo gba ọjọ́ ikú Lẹyin ọsẹ kan tí wọn ti ń wá Khadijat tó jẹ́ ọmọ igbákeji gómínà tẹ́lẹ̀rí ní ìpínlẹ̀ Ondo, ni wọ́n bá òkú rẹ̀ ní ilé àfẹ́sọ́nà rẹ̀, Adeyemi Alao.
Ìyẹn ni pé èèyàn lè fi báni sọ̀rọ̀ láì gbé ẹ̀rọ ìbánisọ̀rọ̀ gan-gan sétí.
Bí kò bá ti ẹ̀ jáwé olúborí nínú ìdíje Ìwọ́de Ojúnà (bí ó ti lẹ̀ jé pé ó ní àyè tí ó pọ̀!
Òriṣà ni ò gbọdọ̀ bínú da igbá nù
Èmi fúnra mi ni mo mu yín jáde wá láti ilẹ̀ Ijipti, mo mu yín la aṣálẹ̀ fún ogoji ọdún, kí ẹ lè gba ilẹ̀ àwọn ará Amori.
Ọgagun Ibikunle Daramọla to jẹ alukoro ileeṣẹ ologun ofurufu ni Naijiria ti kede bi wọn ṣe fa awọn mẹtẹẹta to wa ninu ọkọ to pa Tolulope Arotile le agbofinro lọwọ.
Dino fẹ́ fún èèyàn mẹwa ní ₦10m tí Atiku bá wọlé kẹ̀?
Nisinsinyii, n óo fi òtítọ́ hàn ọ́.
Ẹ wá, ẹ yin OLUWA,gbogbo ẹ̀yin iranṣẹ rẹ̀,gbogbo ẹ̀yin tí ń sìn ín ninu ilé rẹ̀ lóru.
O fikun-un pe“Ni pataki inu wa dun pupo fun ipalemo ajo NFF saaju idije boolu agbaye yii, eyi ti o farahan gbangba-gbangba pe iko Super Eagles naa ti setan fun idije naa.
Ninu atẹjade kan ti Alaga igbimọ eto ilera ninu ajọ NACHON, Dokita Ibrahim Kana fi sita, to si tẹ BBC Yoruba lọwọ, ajọ naa sọ pe oriṣiriṣi aisan bii aisan ọkan ati ẹdọforo lo pa awọn eeyan to ku naa.
Oríṣun àwòrán, AFP Àkọlé àwòrán, Ado oloro ba ile igbafẹ Shangri-La jẹ ni Colombo Ado oloro kẹjọ ti o bu ni agbegbe Dematagoda nigba ti ọlọpaa lọ mu awọn kan pa ọlọpaa mẹta.
Èmi Ẹni Mímọ́ ni mo bèèrè bẹ́ẹ̀.
    Nítorí náà bí a ti ń lọ yìí, a ki yín ó dìgbóṣe ẹ wò wá kí ẹ tún wa wò, nítorí bóyá eléyìí ni yóò jẹ́ ìgbẹ̀yìn tí ẹ ó ri ẹlòmíràn ń mú wa.
 O tẹsiwaju pe, ""Nigba miran ẹwẹ, ti a ba ri oku to ti jẹra tan, niṣe ni a maa ko ẹgungun rẹ sapa kan, ti a o si sin oku miran le e lori."
Awọn ọmọ Naijiria ni imọtaraẹni lo n damu Aisha Buhari Kete ti Aisha Buhari fi ọrọ yi sita loju opo Twitter lawọn eeyan yabo oju opo rẹ ti wọn si bẹrẹ si ni fesi.
Ni olukuluku wọn bá lọ sí ilé wọn; ṣugbọn Jesu lọ sí Òkè Olifi.
Bawo ni idán eto 'idokowo yii ṣe n lọ?
Ọrọ owo naa lo da awuyewuye yii silẹ.
‘Epo Rọ̀bì’ ni ‘Awọ’ nitori ó lé ni idá ọgọrin ti owó epo rọ̀bì kó ni owó ọrọ̀ ajé ti ilú tà si Òkè-Òkun.
Auxiliary lo ń jà káàkiri ìlú Ibadan lọ́jọ́ Aje, ẹgbẹ́ ọlọkọ èrò NURTW kọ - Ejiogbe Àwọn ènìyàn ti n dárò Richard Akinjide tó d'olóògbé Ìyàwó mi ṣẹ̀ṣẹ̀ bímọ tuntun, kò si oúnjẹ fún wa torí ìgbélé Coronavirus- Yakubu Iọ ọmọ ogún Ibadan náà sì di ọ̀nà mọ ìjàyè, èyí tí kò jẹ ki wọn kó oúnjẹ wọlé síbẹ̀ àmọ́ àwọn oyinbo fà ojú àwọn Remo tó wà ní ìlú Sagamu ati Ikorodu mọ́ra,.
Ipa tí mo kó lágbègbè mí lásìkò ìwọ́de EndSARS ló dènà làásìgbò - Alaafin Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Eégun àti orò, bí wọ́n ṣe jọ bí Ẹ̀ṣà Egúngún nílẹ̀ Yorùba rèé Wo àwọn òṣèré tíátà Yorùbá mẹ́fà tó bẹ̀rẹ̀ eré ṣíṣe láti kékéré Wo iye obìnrin tó bá Ginimbi ọ̀dọ́mọdé olówó kú àti obìnrin to ṣeéṣe kó jogún rẹ̀ ''Aláàfin kìí ṣe ọkùnrin tí wàá jẹ lásán, tó sì wá sálọ - Aráàlú fèsì fún Olorì Anu Wo ọ̀pọ̀ ìgbà tí Ginimbi ọ̀dọ́mọdé olówó ti ṣe àríyá aláṣọ funfun kó tó kú Gbogbo ìgbésẹ̀ Aláàfin láti jí mi gbé ló já sí pàbó, n kò le panumọ́ - Olori Anu Lady Peller to ti di ẹni ọdún mẹ́tàléláàdọ́rin báyìí dúpẹ́ lọ́wọ́ elédùà tó fún ni okun àti àwọn ọmọ ti Ọlọrun fi jíìkí rẹ̀.
Títí di àsìkò yìí, àjọ WHO ní kò sí àyẹ̀wò sáyẹ́Nsì to fi ìdí rẹ̀ múlẹ̀ pé àgbo náà lé wo àarùn Covid-19 Oríṣun àwòrán, OTHERS Àkọlé àwòrán, Díẹ̀ lára àwọn èròjà to wà nínú àgbo Covid-19 ti Madagascar n lò Wo àwọn ǹkan tí a mọ̀ nípa àgbo tí orílẹ̀-èdè Madagascar ṣe fún Covid-19 Aarẹ orilẹ-ede Madagascar sọ fun awọn onimọ lati ṣe oogun ibilẹ, ko si pẹ ti wọn fi ṣe ọkan jade.
Awọn ọmọ ẹgbẹ Sinai n kọlu awọn ọmọ ogun Egypt, ati awọn Kristẹni nibẹ.
Oríṣun àwòrán, Twitter/Saudi Embassy Laipẹ yii ni wọn pa ọmọ Naijiria kan ni Saudi Arabia, Kudirat Afolabi lori ẹsun pe o gbe oogun oloro wọ orilẹede ọhun.
Tí HIV bá wọnú àgọ́ ara tán, àwọn ẹ̀yà ara tí wọ́n npèsè ọmọ-ogun ara ní í bájà.
O wa rọ awọn ọmọ ilẹ yii lati maa gbe aṣa ilẹ wa larugẹ, nitori ọpọ ohun alumọni wa lo ti sọnu laisi ẹni ti yoo wa.
Awọn ajọ aranilọwọ loriṣiriṣii náà ti wa ni Congo bayii ti wón n pese iranlọwọ fún wọn.
Ẹ múra láti pa àwọn ọmọ rẹ̀ runnítorí ẹ̀ṣẹ̀ àwọn baba wọn,kí wọn má baà tún gbógun dìde,kí wọn gba gbogbo ayé kan,kí wọn sì kọ́ ọpọlọpọ ìlú sórí ilẹ̀ ayé.
Nígbà tí ẹ̀ka tí ó ń ṣe àkópamọ́ sítám̀pù ti wo ògiri àtijọ́ àmọ̀káyée Lalbagh Fort láti fi ṣe àyè ìgbọ́kọ̀sí, báwo ni a ó ṣe dojú ìjà kọ ìwà òmùgọ̀?
Ajọ UN sọ pe Orilẹede Naijiria ru ofin ojuse wọn ninu awọn orilẹede agbaye lati da abo bo awọn atipo.
UEFA tún fẹ̀sùn kàn ikọ̀ agbábọ́ọ̀lù náà pé àwọn olólùfẹ́ wọn ṣ'àfihàn àtẹ tí wọ́n kọ ọ̀rọ̀ àlùfàńṣá sí nínú pápá ìṣeré wọn.
Samuẹli bá bi í pé, “Èwo ni igbe àwọn aguntan ati ti àwọn mààlúù tí mò ń gbọ́ yìí?
Ó sì jẹ ọmọ ẹgbẹ́ àwọn asofin ni ile wa Naijiria ati ni òkè òkun.
Ọba dìgbòlulẹ̀ adé ọba ṣí ó ta fiiri síwájú, ọba dákú, ìyàwó dákú, àwọn ìránńṣẹ́ tí ó tẹ̀lé ọba dákú, ìgbà tí atẹ́gùn sì tóó fẹ́ sí wọn ni wọ́n tóó jí.
O tesiwaju pe  awon awon agbofinro ti n se gudugudu meje ,yaya
Ìdí nìyí tí mo fi ń jìyà báyìí.
Agbẹjọro ati ajafẹtọ, Femi Falana lo sọrọ yii idanilẹkọ ọdọọdun fun iranti Dokita Beko Ransome-Kuti ẹlẹẹkẹrinla rẹ.
Ilé iṣẹ́ ológun Nàìjíríà gbẹ́sẹ̀ kúrò lórí òfin tó de UNICEF Aṣoju UNICEF ni tolowo ti mẹkunnu ni Naijiria lo ni iṣẹ latiṣe ki nkan le yipada lori iku awọn ewe Naijiria.
Nigeria movie industry: Àgbà òṣèré, Lere Paimo ní àìgbọràn ló ń da ọ̀pọ̀lọpọ̀ àwọn òṣèrè sinimá láàmú
Ó ni ohun kan ṣoṣo ni ọmọ ọkùnrin ohun ni ẹ̀tọ́ si lati mu.
Wọ́n ń fún òróró lára èso olifi tí ó wà ní oko ìkà,òùngbẹ sì ń gbẹ wọ́n, bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé ọtí ni wọ́n ń pọn.
Kò sí ohun tí ó jẹ́ tiwọn tí ó sọnù ní gbogbo ìgbà tí wọ́n wà ní Kamẹli.
Oladejo Okediji àti ìgbé ayé ìtàn kíkọ rẹ̀ Àwòrán àjọyọ̀ ìjọba ológun ní Sudan Ọwọ́ tẹ afurasí méjì tó nííṣe pẹ̀lú ìjínígbe Ọgá panápaná l'Eko Dókítà yọ oyin mẹ́rin tó n gbé nínú ẹyinjú arábìnrin kán Awọn ikọ Boko Haram ko lati fi Leah Sharibu silẹ lẹyin ti wọn yọnda awọn iyoku rẹ nitori ọmọ naa kọ lati fi ẹsin Kristẹni silẹ fun ẹsin musulumi ki wọn le tu silẹ lahamọ.
Kí á má dárúkọ àwọn ìran ẹni ibi mọ́ títí lae!
Jọgbọdọ Orunmila ni ''ohun ti a ri nipe ileeṣẹ ifowopamọ Access Bank ti yọ ẹgbẹrun lọna o le mẹfa naira ninu apo ikowosi mama mi lasiko ti wọn fun un ni kaadi ATM mii.
Rárá, ẹnìkan kì í máa pa ọkà títí kí ó má dáwọ́ dúró.
omo egbe oselu All Progressives Congress (APC), Wahab Raheem ati Adam Habeeb,
Jesu Lọ sí Ibi Igbeyawo Kan ní Kana.
Mo sì bẹ̀bẹ̀ pé kí o dárí ẹ̀ṣẹ̀ yìí ji èmi iranṣẹ rẹ, nítorí pé ìwà òmùgọ̀ ni mo hù.
Bakan naa ni wọn kesi Ọga agba ọlọpaa lati ṣe iwadii ẹsun ipaniyan ti wọn ki kan awọn ikọ SARS, eleyii ti wọn ni awọn lọgalọga naa mọ nipa rẹ.
Ninu ọrọ tirẹ, Minisita feto obinrin, Paulen Tallen ṣapejuwe ifipabanilopọ gẹgẹ bi iwa ipaniyan to lagbara.
Ẹ kò sì gbọdọ̀ jáde kúrò ní ẹnu ọ̀nà Àgọ́ Àjọ, kí ẹ má baà kú, nítorí pé òróró ìyàsímímọ́ OLUWA wà lórí yín.
Ohùn ẹ̀dá náà ba ni lẹ́rùn gidigidi, nígbà tí mo sì kọ́ gbọ́ ọ, ó dà bí ìgbà tí àpáàrà ńlá bá sán lójú ọ̀run, ọ̀nà ọ̀fun rẹ̀ si ń kù bí ìgbà tì òjò ńlá bá ń fẹ́ẹ́ rọ̀.
Lara awọn iwadii ti ẹrọ naa ṣe ni lati mọ igba ti nkan oṣu maa n de, ati iru iriri ti awọn to ba n ṣe nkan oṣu n ni.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìjọba àpapọ̀ Nàìjíríà fèsì sí ilẹ̀ gẹ̀ẹ́sì,EU àti Amẹ́ríkà 27 Sẹ́rẹ́ 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Ijọba orileede Naijiria ti fẹsi si orileede Amerika, ajọ iṣọkan ilẹ Yuroopu ati ilẹ Gẹẹsi lori ọrọ adajọ agba Walter Onnoghen ti wọn ni aṣẹ lọ rọọkun nile rẹ ko boju mu.
Plastic for School fees: Àwọn èèyàn rò pé wọ́n fẹ́ máa lò wá ni
a ) ní ọdún 2006 , gboyè ẹlẹ ́ ẹ ̀ kejì ( m.
OLUWA Ọlọrun sọ fún Mose pé, “Àkókò ń tó bọ̀ tí o óo kú, pe Joṣua, kí ẹ̀yin mejeeji wá sinu àgọ́ àjọ kí n lè fi ohun tí yóo ṣe lé e lọ́wọ́.
Yàtọ̀ sí Olúwó, wo àwọn Ọba alayé tó ti kọ ìyàwó rí láìpẹ́ nílẹ̀ Oodua Èyí tí a wò jùlọ 5:03 Fídíò, Omolola Arohunmolase Welder: Mo ti fí iṣẹ́ 'Welder' gbayì láwùjọ, tó mo fi tọ́ ọmọ yanjú, Duration 5,039 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 5:39 Fídíò, Akomolede ati Asa lori BBC: Olùkọ́ Kikelomo Ogunboye tan ìmọ́lẹ̀ sí ìwà olè ọ̀gá ọlọ́pàá Audu gẹ́gẹ́ bí àwòkọ́ṣe àsìkò yìí, Duration 5,398 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 4:11 Fídíò, Oba Adeyeye Ogunwusi: Ojú mi ti rí lọ́pọ̀ lọpọ̀, ọ̀pọ̀ èèyàn ni kò tilẹ̀ gbàgbọ́ pé mo lè jọba- Ooni, Duration 4,117 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 4:43 Fídíò, Promise Akinlade: ọmọ ọdún mọ́kànlá tó ń fi ìlù dárà bíi àgbàlagbà sọ̀rọ̀ nípa tálẹ́ǹtì rẹ̀, Duration 4,437 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 0:59 Gbọ́, Ìsẹ̀lẹ̀ jákèjádò orílẹ̀èdè àgbáyé láàárín ìṣẹ́jú kan, Duration 0,59wákàtí 6 sẹ́yìn 7:03 Fídíò, Olumuyiwa Bolade Adedeji Military Bruitality: Bí arákùnrin onípèníjà ara tí sọ́jà lù ṣe dé, Duration 7,035 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 4:45 Fídíò, Yoruba Films: Ẹ̀ẹ́ bẹ̀ mi kúrò láyé ni, mi ò lè kú - Fadeyi Oloro, Duration 4,4526 Èrèlè 2020 2:48 Fídíò, Esther Ajayi: Èmi náà ti borí ìṣòro rí ló ń mu mi ṣojú àánú, Duration 2,481 Ògún 2019 6:08 Fídíò, Adebola Ademilua: Àìrísẹ́ ṣè lẹ́yìn ìwé kíkà ló sọ mi dí ìyá onírú, mo dúpẹ́ tèmi, Duration 6,0827 Bélú 2020 5:55 Fídíò, Soyinka Cancer: Àṣe ara mi ni iso ti n run gbogbo bí mo ṣe n ṣèrànwọ́ lórí jẹjẹrẹ, Duration 5,5527 Bélú 2019 BBC News, Yorùbá Ìdí tí ẹ fi le è nígbàagbọ́ nínú ìròyìn BBC Ìlànà Lílò Nípa BBC Òfin Àṣírí Cookies Kàn sí.
Ìdí rèé tí Aisha Buhari kò tíì padà sí Nàìjíríà- Iléeṣẹ́ ààrẹ Ẹ ṣé mo dúpẹ́ fún àdúrótì àti ìfẹ tí ẹ ní sí mi - Toyin Abraham Aarẹ Buhari fi aidunnu rẹ si bi awọn ọmọ South Africa ti fiya jẹ awọn ọmọ Naijiria ti wọn n ṣe atipo lorilẹede South Africa.
Wọ́n bá pe àwọn aposteli wọlé, wọ́n nà wọ́n, wọ́n kìlọ̀ fún wọn pé wọn kò gbọdọ̀ fi orúkọ Jesu sọ̀rọ̀ mọ́.
Àrùn Coronavirus fa'lẹ̀ya láwọn ìletò aláwọ̀dúdú ní Amẹ́ríkà Kí lo mọ̀ nípa fẹntilétọ̀, ohun èlò aṣèrànwọ́ èémí Èyí ni ìdí tí coronavirus ṣe n pa àwọn kan, tí kò sì pa àwọn kan ''O lè kó coronavirus nípa ṣíṣe eré ìdárayá, ẹ gbélé yín lásìkò yìí,''- onímọ̀ ètò ìlera Pasitọ Enoch Adeboye - olori ijọ Irapada Kristi, to fẹ ẹ ni sọọsi ni gbogbo adugbo ni Guusu Naijiria ti fun ijọba ipinlẹ Eko ni ẹgbẹrun lọna igba ibọwọ, ẹgbẹrun mẹjọ sanitiser, ati ẹgbẹrun mẹjọ iboju.
“Mo mo ohun ti orile-ede Naijiria le se, awon iko omo ogun ti won ti da soju ogun, ipa ti won ti sa lati ri daju pe igbe-aye irorun fi ese mule lorile-ede Naijiria ati ile Afrika lapapo.
Ìgbà tí ọkùnrin yìí dé, ọdún méjì ni àwọn akẹ́kọ̀ọ́ ń lò, ilé tí ó wà fún ìlò àwọn akẹ́kọ̀ọ́ kò ju ìba díẹ̀ lọ.
Jesu bá sọ fún wọn pé, “Ṣé ẹ̀yin mejila ni mo yàn.
- Atiku bèèrè lọ́wọ́ ọmọ Nàíjíríà Hubert Ogunde rèé, baba àwọn òsèré tíátà Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, World Toilet Day: Aráàlú ní woléwolé yẹ kó bẹ̀rẹ̀ àyẹ̀wò ojúlé dé ojúlé Ajọ ICPC ni, ọjọ ori to fi silẹ ninu ọrọ rẹ yatọ si eyi to wa ninu paali rẹ ti wọn ri ni fasiti OAU.
Gẹgẹ bi atẹjade ti oludamọran pataki si aarẹ, Femi Adesina fi sita, aago meje aarọ ọjọ Ẹti ni Buhari yoo bawọn ọmọ Naijiria sọrọ.
Abumere/BBC Nitirẹ, iyawo Tẹjuoṣo, ti wọn jijọ ni ile orin naa ni Fatai Rolling Dollars no oun ko lee gbagbe.
"Ó ní "" Báwó ni ń o ṣe ṣe ògbẹyàwó nígbà ti kò tíì san owó orí mi"" Bákan náà ló ké gbàjarè pé, ìwà gbajuẹ 419 ni èyí nítorí pé òun kò mọ obìnrin náà rí débi ti àwọn yóò maa sọ̀rọ̀ ìgbéyàwó."
Àsẹ̀yìnwá àṣẹ̀yìnbọ̀, ìnàkí-ìbẹ̀rù túúbá ó ní mo ju òun lọ.
Olukuluku wọn sì mú àwo turari tirẹ̀, wọ́n fi ẹ̀yinná ati turari sí i, wọ́n sì dúró ní ẹnu ọ̀nà Àgọ́ Àjọ pẹlu Mose ati Aaroni.
Ọjọ́ Ìṣẹ́gun yóò ro lásìkò ìwọ́de lórí èlé owó epo - Ẹgbẹ́ òṣìṣẹ́ Yoruba ni awifuni ko to da ni, agba ijakadi ni, bẹẹ si ni ogun awitẹlẹ kii pa arọ, eyiun arọ to ba gbọn.
Ẹ yàgò fún ìwà adìẹ dàmí lóògùn nù, màá fọ lẹ́yin lásìkò ìjà - Buhari Kingston lọmọ Áfíríkà tó gba ohun tí Hulk Hogan kò rí gbà Kìnìhún joko jẹ ẹran ara afurásí ọdẹ tí kò gbààyè kó tó ṣọdẹ Wo bí o ṣe lè kọ́ ọmọ rẹ lẹ́kọ̀ọ́ ìbálòpọ̀ Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Ẹ óo kà wọ́n sí ọmọ onílẹ̀ láàrin àwọn ọmọ Israẹli.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Coronavirus symptoms in Nigeria: Pẹ̀lú èròjà olùgbèjà ara 'Antibodies' O fi ẹsun kan ọkọ rẹ wi pe gbogbo igba lo maa n beere owo ori lọwọ oun.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ilé jóná ní Òkè Àdó Ibadan, ọ̀pọ̀ dúkìá ṣòfò Iṣọla Oyenusi rèé, ẹnití ìfẹ́ obìnrin ṣun dé ìwà ìdigunjalè Ganduje Video - Ìwádìí ilé aṣòfin foríṣánpọ́n Ilé ẹjọ́ Kano: Ganduje kò lẹ́tọ̀ọ́ láti yan Emir Fọnran fidio orin naa ti n ja rainrain loju opo Whatsapp.
lorile ede Naijiria ,Abubakar Malami, lati wa wọrọkọ fi sada nipa gbigbe igbesẹ
 Ọ ̀ rọ ̀ kẹta jẹ ́ nọ ́ mbà adúróṣinṣin .
Ẹ gbé ojú sókè,kí ẹ wo àwọn tí ń bọ̀ láti ìhà àríwá.
 Ẹ ̀ gbọ ́ n fẹ ́ jẹ oyè , àbúrò náà sì ń fẹ ́ jẹ oyè náà .
Kí gómìnà òní yáa múra síṣẹ́ gidi-gaan ni.
Orí àwọn ẹṣin náà dàbí orí kinniun.
rẹ̀, ni, tòun, èrò, tiyín, ìgbésẹ̀, yìí Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Awọn àpẹẹrẹ pe nkan ti n bọ sipo ti n farahan ni China.
 Ọjọ ́ orí àwọn tí ìsẹ ̀ lè yí ṣẹlẹ ̀ sí wà láàrin mẹwa sí méjìléláàdọrin .
Koda ko si ẹnikẹni to tẹle ọrọ ijinna sira ẹni lawọn ibudo ọlọpọ ero naa.
Nigba ti yoo fi di agogo meje alẹ ọjọ Aiku, ọjọ kọkandinlogun, oṣu keje ti Dorathy farahan lori eto agbelewo BBNaija si agogo marun un owurọ Ogunjọ, oṣu keje, iye awọn eeyan to n tẹlee loju opo Instagram rẹ ti le ni ẹgbẹrun mọkandinlogoji.
Wọ́n ń gun odi ìlú,wọ́n ń sáré lórí odi.
Nígbà tí wọ́n dé ibi tí Ọlọrun júwe fún Abrahamu, ó tẹ́ pẹpẹ kan níbẹ̀, ó to igi sórí pẹpẹ náà, ó di Isaaki ọmọ rẹ̀ tọwọ́ tẹsẹ̀, ó bá gbé e ka orí igi lórí pẹpẹ tí ó tẹ́.
Minisita fun oro abele lorile-ede Cameroon Paul Atanga Nji so pe, ijoba orile-ede Cameroon yoo faye gba eto ijiroro, gege bi abala kan lati fipon si laasigbo awon elede Geesi lorile-ede naa.
Óyá fi ààmì sórí 'Bobajiroro' Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Yoruba gbayì!
Igbimo asoju yii ni o je ikẹ́sán án ti won
Iwobi ni omo ile Italy to wa lati Naijiria to jawe olubori ni Brasca ni Italy ni Amofin ni o ti di  awokose rere fun awon odo Naijiria.
Iwadii fihan wi pe daju daju, eniyan marun un ni wọn da ẹmi wọn legbodo ni Abraham Adesanya Estate, ijọba ibilẹ Eti Ọsa ni ilu Eko loru ọganjọ ọjọ aiku to kọja yii.
Isejọba Aarẹ Trump lo sọ lọdun to kọja pe oun yoo bẹrẹ idajọ iku pada lẹyin idaduro ọlọjọ pipẹ.
N óo tún máa jó níwájú OLUWA.
Nínú kó o fi omi fọ ìdi tàbí lo tííṣù fi fá a, Èwo ló rọrùn?
Ta ni kò ní fi ògo fún orúkọ rẹ?
Àkọlé àwòrán, #BBCOGUNDEBATE: Ijọba mi yoo de gbogbo ẹsẹkuku ati igberiko -Akinlade GNI ní ti rẹ̀ sọ̀rọ̀ ni ede ẹgba o si tun salaye pe oun yoo sejoba pelu ogbon imo oye ati ifokansin ati iberu Olorun Paseda ni ki won o maa ran omode nise ki won ran paseda nise.
Mà á gbẹ̀san bàálù àjọ UN tó já ní Borno - Buhari yarí Òṣìṣẹ́ LASTMA gún olólùfẹ́ rẹ̀ l'ọ́bẹ, ó tún gba ẹ̀mí ara rẹ̀ l'Eko Ikọ̀ ìjọba Ọ̀yọ́ dé lásìkò tí kò yẹ ni wọn kò ṣe wọlé - Ẹ̀bí Ajimobi fèsì Wo ohun márùn ún tó yẹ kí o mọ̀ nípa Kanye West tó fẹ́ du ipò ààrẹ Amẹrika When is WAEC 2020 starting: Ajọ onídánwò WAEC ní kété tí wọ́n bá ṣí iléèwé padà ní ìdánwò WASSCE yóò bẹ̀rẹ̀ Oríṣun àwòrán, legit Ajọ to n ṣe kokari idanwo aṣepari ni ileewe girama, WAEC ti ṣalaye wi pe oun ti ṣetan bayii lati ṣeto idanwo fawọn akẹkọs oniwe mẹwaa lorilẹede Naijiria.
Ọlọ́pàá àti àwọn ìkọ̀ #RevolutionNow ń tahùn sí ara wọn.
kare lai fun gomina ipinle Ebonyi, David Umahi fun ise takun-takun re to n
Òun ati àwọn ọmọ rẹ̀ bá kó wọn lọ jìnnà sí Jakọbu, ní ìwọ̀n ìrìn ọjọ́ mẹta.
kí àwọn mejeeji tí wọn ń ṣe àríyànjiyàn yìí wá siwaju OLUWA, níwájú àwọn alufaa ati àwọn tí wọ́n jẹ́ onídàájọ́ nígbà náà.
"Agbẹjọro fun EFCC, Mohammed Abbas sọ nile ẹjọ pe ""akọsilẹ fihan bi owo nlanla ṣe n wọ apo asuwọn ti Adesanya n mojuto lati inu aka-nti ijọba ipinlẹ Eko."
Ó gbé àpò ńlá kan kọ́ èjìká, ó sì kó kùmọ̀ púpọ̀ lọ́wọ́.
Alase ile akede  Naijiria, Voice of Nigeria, ogbeni Osita Okechukwu ti gba awon akekoo,paapaa julo awon odo nimoran lati se gafara fun aawo tabi rogbodiyan bi o se lewu ko mo lasiko idibo gbogbogboo to n bo lọdun 2019.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Àwọn jàǹdùkú sọ Ààrẹ Buhari, Dapọ Abiọdun lókúta nílùú Abẹokuta 11 Èrèlè 2019 Oríṣun àwòrán, Bashir Ahmad Àkọlé àwòrán, Wàhálà ti wà nílẹ̀ láàárín gómìnà Amosun àti àwọn adarí ẹgbẹ́ òṣèlú APC lórí ẹni tí yóò díje fún gọmìnà ní ìpínlẹ̀ Ogun.
Awọn ileewe girama ti ijọba ati aladani yoo di ṣiṣi pada fun awọn akẹkọọ to fẹ ẹ ṣe idanwo aṣejade.
1bn ni wọn yoo fi se eto ilanilọyẹ fawọn oludiboN4.
Bí ó bá fẹ́, ó lè fi amọ̀ rẹ̀ mọ ìkòkò tí ó wà fún èèlò ọ̀ṣọ́.
Naijiria n se ise lori bi yoo se ni  imo
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Malabu Oil Scandal: Iléẹjọ́ ní kí àwọn ọlọ́pàá, Interpol gbé wọn níbikíbi tí wọn bá wà 17 Ìgbé 2019 Oríṣun àwòrán, @Shell Adajọ D.
Iroyin sọ pe wọn gbẹsẹ le iwe irinna rẹ, ati awọn nkan miran.
Ní oṣù keji ọdún keji tí wọ́n dé sí ilé Ọlọrun ní Jerusalẹmu ni wọ́n bẹ̀rẹ̀ iṣẹ́ náà.
Nítorí nígbà tí obinrin yìí da òróró yìí sí mi lára, ó ṣe é fún ìsìnkú mi ni.
Lẹyin ti ileeṣẹ BBC gbe iwadii wọn jade to ṣafihan olukọ fasiti Eko, ati ti fasiti Ghana, to n beere ibalopọ̀ lsna aitọ, ni awọn eniyan ti n fi ero ọkan wọn han lori ayelujara.
Ṣugbọn kí ẹ lè mọ̀ pé Ọmọ-Eniyan ní àṣẹ ní ayé láti dárí ẹ̀ṣẹ̀ ji eniyan ni,” ó bá sọ fún arọ náà pé, “Mo sọ fún ọ, dìde, gbé ibùsùn rẹ, kí o máa lọ sí ilé rẹ.
Lẹ́yìn tí alufaa bá di aláìmọ́, yóo dúró fún ọjọ́ meje, lẹ́yìn náà yóo di mímọ́.
Ohun tó wù kí ileẹjọ́ kòtẹ́milọ́rùn sọ, Adeleke kò lè di gómínà Ọ́ṣun - APC Rochas Okorocha, káàbọ̀ sí àwùjọ àwọn gómìnà tí EFCC ń wá - Fayose Òṣìṣẹ́ Ọ̀yọ́ fi tijó-tìlù kí Ṣeyi Makinde káábọ̀ sí ọọ́fìsì Èrè ńlá ńbẹ fáwọn obìnrin nínú okoòwò ọ̀fẹ́ ní Áfíríkà Pataki igbesẹ iwadii ninu igbeyawo iran Yoruba ni ki obi ọkọ ati iyawo ṣe iwadii lẹyin ifojusode ati iṣẹ alarinna.
Ere náà lo jẹ́ ẹsẹ bàtà mẹ́tadínlógójì.
Ọkunrin yìí ní kànga kan ní àgbàlá ilé rẹ̀.
Gbogbo wọn jọ lọ, nígbà tí wọ́n dé etí odò Jọdani, wọ́n bẹ̀rẹ̀ sí gé igi.
Ṣugbọn o kò gbọdọ̀ jẹ́ kí ó lọ láìjìyà.
26 Agẹmo 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Foniku fọla dide to n ba ẹka ina ọba lorile-ede Naijiria jẹ ọrọ kan to n kọ ara ilu ati ijọba lominu.
Amọ oun ko jẹ ki ipinlẹsẹ oun dina atigoke nitori naa ni oun se tẹra mọsẹ.
Nínú àwọn ìfihàn náà, a ngbọ́ ohùn jẹ́jẹ́ ṣùgbọ́n dídúró ṣinṣin ti Olúwa Jésù Krístì, tí ó nsọ̀rọ̀ lákọ̀tun ní ìgbà kíkún ti àwọn àkókò; àti iṣẹ́ tí a ti bẹ̀rẹ̀ níhĩnyí jẹ́ ìmúrasílẹ̀ fún Bíbọ̀ Rẹ̀ Ẹ̀kejì, ní ìmúṣẹ àti ìbámu pẹ̀lú àwọn ọ̀rọ̀ ti gbogbo àwọn wòlíì mímọ́ láti ìgbà tí ayé ti bẹ̀rẹ̀.
Awọn eeyan to n gbe lagbegbe naa lo ke gbajare sita, lẹyin ti wọn dede ri ọmọ tuntun jojolo lori aatan ni nnkan bii aago mẹsan an aṣalẹ Ọjọru.
Alukoro ọlọpaa ni ipinlẹ naa, Folashade Odoro sọ fun awọn akọroyin ni ipinlẹ naa wi pe awọn ti wa ni digbi.
O maa n sisẹ lati ṣe agbekalẹ ìrísí ọjà 'product design'.
Iṣẹlẹ yi waye nipinlẹ Borno lọsẹ ti o pe ọdun mẹwaa ti Boko Haram bẹrẹ si ni ṣoro ni Naijiria.
"Wo àwọn oúnjẹ tí àṣẹ Buhari leè mú kó gbówó lórí Àjẹ́ àti Aṣẹ́wó ní ìyá Rainbow - Òjòpagogo ""Ẹ̀yin obìnrin, ẹ lọ kọ́ iṣẹ́ káfíńtà torí ó lówó lórí ju iṣẹ́ aránṣọ lọ"" Àwọn ọmọbíbí ìpínlẹ̀ Ọyọ nìkan ni yóò rí iṣẹ́ àgbàṣe gbà lábẹ́ ìjọba mi - Seyi Makinde Bí Khafi ṣe ní ìbálòpọ̀ ojútáyé tako àṣà Yorùbá - Ìjọba Ekiti Nigba to n salaye ayẹyẹ igbalejo naa, agba ọjẹ kan nilu Osogbo salaye pe, ọna lati fi ẹmi imoore han si gbogbo awọn obinrin to ti ru igba Ọṣun sẹyin lo mu ki Kabiyesi gba wọn lalejo."
"Shina ni ""Baba mi duro de mi ni alẹ, o yọ kẹlẹ wọ yara mi, to si fẹ fi ada ge mi lori, mo tiraka lati sa mọ lọwọ sugbọn ada naa ba mi ni ẹsẹ osi, ti apa rẹ si wa lara mi di oni olonii."
Ó jẹ́ aṣiwaju ní ilẹ̀ Israẹli fún ọdún mẹtalelogun, nígbà tí ó ṣaláìsí wọ́n sin ín sí Ṣamiri.
flag : v ; ( the streels were flagged to celebrate the team ' s victory .
"Ìpadà , Àbíkú ọmọ náà wáyé nínú ìwé kíkọ òǹkọ ̀ wé ará sìlìfẹ ́ níáànì gabriela babnik , nínú ìwé rẹ ̀ "" koža is bombaža ."
Ìpínlẹ̀ Osun kéde ọjọ́ táwọn iléèwé yóò ṣí padà YWC yọ Ààrẹ Banji Akintoye nípò àbi Akintoye tú ìgbìmọ̀ aláṣẹ YWC ká?
14 Ògún 2020 Agbekoya War: Ọta ìbọn kan ṣoṣo ló fa ogun tó fi ọ̀pọ̀ ẹ̀mí ṣòfò nínú ìtàn mánigbàgbé lẹ̀ Yorùbá13 Ògún 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Ọlọ́pàá mú èèyan mẹ́ta pé wọ́n so akẹ́kọ̀ọ́ mọ́gi Nàìjíríà ń ṣọ́ pápákọ̀ òfurufú tórí Ebola Gẹ́gẹ́ bó ṣe sọ, àjọ NDLEA kò ní oore ọ̀fẹ́ láti mọ àwọn tó fi òògun òhún ráńṣẹ́, bákan náà kò sí ẹnikẹ́ni tó wá láti gba a kúrò ní pápákọ̀ òfurufú.
O ni o ṣeeṣe o ko jẹ pe wọn ko mọ Ọlọrun ni, abi ko jẹ pe ọrọ wọn ati Ọlọrun ko wọ.
Abidjan ni orilẹ-ede Ivory Caost gablejo awọn ero nibi eto isinku ọmọ ódun mẹtalelọgbọn naa to ku nibi ijamba to ni lori alupupu rẹ.
Nitoripe awọn ọkunrin kan maa n mu ju igo ọti kan lọ nibudo imuti kan, ti wọn ko si ni lero lati se ere idaraya lẹyin mimu ọti yii naa maa n fi kun 'Calorie'ara ni.
Alufa Agba ijọ Redeemed Christian Church of God, Pasitọ Enoch Adejare Adeboye naa ti darapọ mọ awọn ọdọ Naijiria to n polongo fun fifi opin si ọlọpaa SARS.
Aisi ọkunrin mọ to wa lati idile to n jẹ Alaafin lo fa sababi bi Aláàfin Ọ̀rọ̀ǹpọ̀tọ̀niyùn se di ọba lode Ọyọ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ẹni ti ko riran to nlọ'ta ni Mushin Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Wùnmí Toríọlá: Toyin Abraham kìí se ọ̀gá mi nínú tíátà Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
"Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Kayeefi: Facebook ni Wolii Arole Jesu fi tàn an wọ agbo, orí rẹ̀ ni wọ́n fi s'owó Idi ti awọn kan ṣe n sọ pé mo n ṣe akọ: Eeyan kii jẹ Oluwo, ipo ade, ti mo gba ni wọn n pe ni Oluwo ""Awọn kan tilẹ ni wọn ni Gay ni mi, Yahoo yahoo ni mi."
Shehu Shagari darapọ mọ oṣelu lọdun 1951 lasiko to fi di akọwe ẹgbẹ Northern People's Congress ni Sokoto.
Bakan naa niasọfin lati nipinlẹ Ọyọ, to jẹ ọmọ ẹgbẹ oselu APC to n tukọ ijọba ipinlẹ Ọyọ lọwọ, Dapọ Lam-Adesina, naa wa sibi iṣẹlẹ naa, to si ni 'iwa ika bẹ ẹ ko dara rara.
Oríṣun àwòrán, OTHERS Bi Shina Rambo ṣe di ẹru jẹjẹ si ilu lọrun: Lẹyin to gba ọpọ agbara yii, Shina Rambo di ẹru jẹjẹ, ogbontagi adigunjale ati apamọlẹkun jaye, to n ja ilu lole laisi ẹni to to wo o loju.
Koda, nibi ti ẹwa rẹ dun, to si tun jẹ itẹwọgba de, awọn onibara rẹ maa n ra ounjẹ naa ni awin, lai sanwo ti owo ba sa fẹrẹ lapo wọn.
Dokita Ann Lindstrand, to jẹ onimọ agba fun ajọ ilera agbaye, WHO ṣalaye pe, ibi ti ọrọ de duro bayii le pupọ.
Loju opo rẹ o fi aworan kan sita ti o ro wi pe o jẹ aworan awọn ọmọ ogun to n ke irora lori iku awọn akegbe wọn ni.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù 9th Assembly: Saraki kí àwọn adarí aṣòfin tuntun kú oríire 12 Òkùdu 2019 Oríṣun àwòrán, @bukolasaraki Aarẹ ile igbimọ aṣofin agba ana ti gba awọn adari ile aṣofin tuntun ti wọn ṣẹṣẹ yan sípò nimọran.
Ibi ni yóo pa eniyan burúkú;a óo sì dá àwọn tí ó kórìíra olódodo lẹ́bi.
Oríṣun àwòrán, Fedral Govt/ Twitter Àkọlé àwòrán, Eto idibo 2019 ti n kan ilẹkun Agbẹnusọ igbimọ naa, Abdulrazaque Barkindo, lo sọ bẹẹ ni Abuja ni ọjọ Iṣẹgun, nibi to ti ṣalaye pe iwadii ẹka igbimọ naa lo fi ọju iye owo naa lede.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, BIAFRA at 50: Ìhàlẹ̀ ológun ni Gowon ni ká kọ́kọ́ fi bẹ̀rẹ̀- Aladejẹbi Eyi mu ki awọn olori ni Ariwa o sọ pe ki orilẹ-ede Naijiria o wa ni pinpin si ẹkun mẹta nikan lo le mu ki awọn o faramọ ominira, ki Ariwa si ni agbegbe to pọju.
Ọ ̀ nà tí à ń gbà sọ àwọn ìṣòro yìí di pẹ ̀ tẹ ́ lẹ ̀ ni ìyípadà igun ní degree fún ìṣẹ ́ jú kan .
Sex Offenders: NAPTIP ní àwọn aráàlú tó jẹ́ ẹ̀jẹ̀ kannáà kìí fẹ́ kí ẹbí wọn ṣẹ̀wọ̀n ìfipábánilòpọ̀
Atiku: Ọ̀dọ́ yóò gba isẹ́ 40%, obìnrin yóò mú 30%
 Àgbè ọlọ ́ gìn àgbàdo , isu , ati ewébe ni àwọn ará wum .
"A ti ṣe ipade ṣaaju iyanṣelodi yii ti a si ti fun awọn alaṣẹ ni gbedeke ọsẹ meji eyi to pari ni ọjọru, ọjọ kejidinlọgbọn oṣu kọkanla lai si ayipada.
Oríṣun àwòrán, Queen_Aanu/Instagram Bakan naa ni n ko fẹ maa bẹru lori pe ohunkohun to jẹ aburu le sẹlẹ si mi.
Ikeremadu ni o seni laanu pe ijọba orilẹede South Africa fi ọwọ yẹpẹrẹ mu ipaniyan to n waye naa, lo se di ohun to n la ẹmi ọpọlọpọ eniyan lọ.
Oríṣun àwòrán, @NGRPresident Àkọlé àwòrán, Ikọ agbabọọlu Naijiria se pegede lati kopa nibi idije ife ẹyẹ agbaye Aarẹ orilẹede Naijiria, Muhammadu Buhari seleri nibi ayẹyẹ naa lati se iranwọ ati atilẹyin gbogbo to ba yẹ fun ikọ agbabọọlu orilẹede Naijiria, Super Eagles nibi idije naa.
Sajẹnti Regina fi kun un pe, ěni ti wọn fẹsun kan naa fẹnu ara rẹ jẹwọ pe lootọ ni oun ji awọn aga naa amọ oun nikan kọ.
Inú ilẹ̀ ni a ti ń wa irin,a sì ń yọ́ idẹ lára òkúta.
Tọkọ-tayà kọ ara wọn silẹ nitori Buhari nínú ìdìbò 2019 tó m bọ̀
instagram Àkọlé àwòrán, Yewande bi'mọ tuntun jòjòló, Mercy pàdánù èèyàn rẹ, Toyin Abraham fèsì lórí ìi asoju NCDC Mercy Aigbe Oríṣun àwòrán, Mercy/instagram Àkọlé àwòrán, Yewande bi'mọ tuntun jòjòló, Mercy pàdánù èèyàn rẹ, Toyin Abraham fèsì lórí ìi asoju NCDC Nínú ọ̀sẹ̀ yìí bákan náà ni Mercy Aigbe gbe sọ́rí ojú òpó Instagram rẹ pé, ọjọ́ oní ni o burú jùlọ ní ayé mí, mò rò pé mo le gbe àgbélébu gbogbo ǹkan ti aye ba jù si mi ni sùgbọ́n ko si ǹkan ti o ṣẹll si mi yìí mí o múra sílẹ̀ fún"" Mercy Aigbe ni ọṣẹ kan sosọ yìí jẹ́ eyi to buru jù fun irú ìpinyà yìí òjijì."
Ohun mẹ́fà tí àgbáyé kò mọ̀ nípa Majek Fashek tó d'olóògbé nìyí Ṣé ìjọba àpapọ̀ tí ṣí àwọn ìléèwé àti ilé ìjọsìn padà bí?
 títí di òní yìí ni ẹnikẹ ́ ni tí a bá yàn gẹ ́ gẹ ́ bí ọba tuntun gbọ ́ dọ ̀ jáde ní ìlú lọ sí Òdo , kí ó sì wọ ìlú padà gẹ ́ gẹ ́ bí i mọnigbùwà àti Ọbańta kí ó tó ó gbadé .
O ni obinrin ti ko ba tẹriba fun ọkọ rẹ lodi si ofin Ọlọrun ọba, iru obinrin bẹẹ ko baa jẹ ojisẹ Ọlọrun.
Gbogbo oye to yẹ keeyan gba ninu imọ iṣẹ Tiata lo gba nigba aye rẹ- oye Diploma, Degree, Masters, PhD ni ẹka Tiata fasiti ilu Ibadan.
Kabashor Koko to je olubadamoran igbimo egbe oselu to n tuko Sudan ni egbe ko sai deede gba lati satileyin fun Bashir bikose lati ri si atunse ilana ofin ile naa ni.
Wọn ni ki awọn eeyan to ku lọ ni suuru nitori pe eto naa maa kari gbogbo awọn to ba nifẹ sii laipẹ.
Dafidi rò ní ọkàn rẹ̀ pé Saulu yóo pa òun ní ọjọ́ kan, nítorí náà ohun tí ó dára jù ni kí òun sá àsálà lọ sí ilẹ̀ àwọn ará Filistia.
Abiola Ajimobi: Wo àwọn ìwà tó burú ju àlè yíyàn lọ nínú ìgbéyàwó Oríṣun àwòrán, Abiola Ajimobi Nigba ti a fi koko ọrọ yii sita loju opo Facebook wa pe ẹsẹ wo ni ọkọ tabi aya le sẹ ara wọn to le ju agbere lọ, awọn kan lara wọn sọ pe ẹsẹ agbere yii naa ni kọ́kọ́rọ́ to ba eyin aja jẹ lọdọ ti wọn.
Ọjọ́ tí ó pé irinwo ọdún ó lé ọgbọ̀n (430) gééré, tí wọ́n ti dé ilẹ̀ Ijipti; ni àwọn eniyan OLUWA jáde kúrò níbẹ̀.
Oríṣun àwòrán, @NG Yoo gbe ọ lọ si oju ewe to kan lati sọ nipa iwe ẹri ileewe ti o wa lọwọ rẹ.
Tọ̀sán-tòru mo rò pé Ọlọrun ń fi òpin sí ayé mi ni.
Wayii o, El Hadji Diouf, fi
Gẹgẹ bi Yasin ti wi, o ti to ọsẹ kan bayii ti awọn janduku to jẹ ẹya Hausa ati Yoruba ti n san ọna wahala naa ninu ọja ọhun.
'Mo mọ̀ọ́mọ̀ sin ọmọ-ọmọ mi, ìkókó jòjòló láàyè ni, nítorí wọ́n fipá bá ọmọbìnrin mi lòpọ̀ ló fi lóyún rẹ̀'!
Bi onirese Ọgbẹni Rauf Adesọji Arẹgbẹsọla ko ba si wa fingba mọ nipinlẹ Ọsun, awọn eyi to ti fin silẹ ko lee parun, tawọn eeyan ipinlẹ naa yoo si maa ranti rẹ fun awọn ohun to gbe se laarin ọdun mẹjọ to fi se ijọba.
Iṣẹ iwadii naa ṣalaye pe, awọn ọmọ to ba jade lati inu igbeyawo ibatan si ibatan papaa julọ, tawọn obi wọn ba jogun arun kan tabi omiran lara awọn obi tiwọn naa.
Kii ṣe igba akọkọ niyii ti Ọgbẹni Zulum yoo jade lati bu ẹnu atẹ lu ileeṣẹ ologun Naijiria pe wọn ko ṣe to lati da abo bo ẹmi ati dukia ni ipinlẹ oun.
6 153741 Orilẹede Bugaria 8396 119.
Nítorí náà, ẹ̀yin ará, kò sí ohunkohun mọ́ tí ó mú wa ní túlààsì pé kí á máa hùwà gẹ́gẹ́ bí àwọn tí ẹran-ara ń darí.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Kunle Afolayan: èmi kò fẹ́ fi ogún sílẹ̀ fún ọmọ mi BBC Yoruba wa n gbàdúrà fún ọmọwe Victor Omololu Olunloyo to pé ẹni ọdun marundinlaadọrun lókè eepẹ pé Ọba òkè yóò túbọ̀ lọ́ra ẹ̀mí wọn fún ilẹ Yoruba.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Fadele: Dán an wò, lóbí ìyá ọ̀kẹ́rẹ́ ni a fi ọ̀rọ̀ ọ̀kadà náà ṣe Gẹ́gẹ́ bí agbẹnusọ ọlọ́pàá ní ìpílẹ̀ Taraba, David Missal, ṣe sọ, ọ̀pọ̀ àwọn agùnbánirọ̀ ló lọ́ fún ìrìnàjò ìgbáfẹ́ ọ̀hún sí odò náà ti omi ọhun si déédé ru kójá bèbè rẹ̀ tí ó si gbé àwọn agùnbánirọ̀ náá lọ O ní ènìyàn méjìlélógún ló lọ sùgbọ́n méje nínú àwọn tí omi náà gbé lọ ni ó kú ti àwọn méjì sì di àwátì, sùgbọn ìwádìí sì ń lọ lọ́wọ́ lati wa wọn.
Èyí wáyé lásìkò tí àwọn agbébọn ya wọ abúlé kan, tí wọ́n sì dáná sun ọ̀pọ̀lọpọ̀ ilé.
N óo fún ọ ní ìṣúra tí wọ́n fi pamọ́ sinu òkùnkùn,ati àwọn nǹkan tí wọ́n kó pamọ́ síkọ̀kọ̀;kí o lè mọ̀ pé èmi, OLUWA, Ọlọrun Israẹli,ni mo pè ọ́ ní orúkọ rẹ.
Eyi lo si mu ki oun beere pe ta a lo n gbọ bukaata irinajo naa.
Agbabọọlu Arsenal tẹlẹ ri, Thierry Henry nikan lo ti ṣe iru rẹ ri lati igba ti Premier League ti bẹrẹ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Lockdown Extension: Kí ló le mú kí ìjọba Nàìjíríà ó dá òfin ìṣéde padà?
Àwọn pidánpidán náà ṣe bẹ́ẹ̀ pẹlu ọgbọ́n idán wọn, wọ́n mú kí ọ̀pọ̀lọ́ bo ilẹ̀ Ijipti.
Àyẹ̀wò òkú tú àṣírí bí òṣìṣẹ́ NSCDC tí ọlọ́pàá lù ní Abuja ṣe kú Ǹjẹ́ o mọ̀ pé o le gba owó lára 'ATM' láì lo káàdì?
9 38246 Orilẹede Syria 447 2.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ifa Worshippers: Àwọn ẹlẹ́sìn ìbílẹ̀ ń fẹ́ kíjọba pín èrè òṣèlú alágbádá yíká gbogbo ẹ̀sìn ''Bi awọn ile epo ba ti ta epo to wa ni akoto wọn tan, wọn ko ni ri omiran nitori awọn ọlọkọ epo bẹntiroo ati ọja miran ko ni gbe epo labẹ aṣẹ wa.
Ṣugbọn Jesu sọ fún un pé, “Jẹ́ kí àwọn òkú máa sin òkú ara wọn.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Parental Guidance: Ọdún méjì ni kí ẹ ti bẹ̀rẹ̀ kíkọ́ ọmọ nípa ìbálòpọ̀ Oríṣun àwòrán, AFP Àkọlé àwòrán, Òní ni àyájọ́ ọdún karùn ún tí Boko Haram jí àwọn ọmọ náà gbé ní ilẹ́ ìwé wọn, tí 100 nínú wọn sí ti di àwátì.
Ṣugbọn OLUWA sán ààrá lù wọ́n láti ọ̀run wá.
Loju opo Twitter ọkan lara awọn oluranlowo Aarẹ Buhari,Bashir Ahmad ni ikede ibuwọlu owo yi ti jẹyọ ti ọpọ eeyan si n sọ pe yoo tan iṣoro iyanṣelodi ASUUni Naijiria.
Ṣugbọn awọn alaṣẹ ajọ NIPRD tun sọ pe iwadii ko pin si ibi kan.
Sibẹ mo rí i pé, nǹkankan náà ni ó ń ṣẹlẹ̀ sí gbogbo wọn.
ti a n dojuko ni ila oorun Ariwa.
Lẹ́hìn tí wọ́n ti pa púpọ̀ nínú wa tí ó sì jẹ́ pé àwa tí ó kù sílẹ̀ kò pọ̀ mọ́, ẹ̀rù bẹ̀rẹ̀ sí ba ni wí pé nígbẹ̀hìn wọ́n lé wáá mú wa yálà a sanra tàbí a kò sanra.
 Gbogbo ìgbà ni mo máa n ni láti sàlàyé pé mo ní ààrun to ma ń mú ki orí ènìyàn pá ni, kìí ṣe pe mo gba ọjọ ikú kìí sì ran ènìyàn.
Mo ní kí wọ́n ṣílẹ̀kùn fún mi kí n máa gùn’kè lọ.
Didibo lori itakun agbaye BBNaija 2020 lati ori ẹrọ kọmputa lori tabili Didibo lori itakun agbaye BBNaija 2020 lati ori foonu alagbeka Didibo lẹyin ti o ba ti san owo to yẹ lati ma wo eto naa lori aapu MyDSTV ati MyGOTV App Ọmọ Yorùbá mẹ́wàá tó jẹ́ àmúlùúdùn ní Amẹ́ríkà àti Yúróòpù Àwọn alágbára ni mo bá díje ṣùgbọ́n mo ti gbà f'Olọrun- Agboola Ajayi Ta ni Yusuf Satia ti iku mu lọ?
Irú àtúntò wo ni àwọn ọmọ Nàìjíríà fẹ́ kó bá FSARS?
Ṣugbọn igba mẹtadinlogun ni iṣẹlẹ ifipagbajọba ti ṣẹlẹ laarin ọdun mẹwaa sẹyin bayii.
Nígbà tí oòrùn bá wọ̀, yóo di mímọ́, lẹ́yìn náà, ó lè jẹ ninu àwọn ohun mímọ́ náà nítorí oúnjẹ rẹ̀ ni wọ́n jẹ́.
Igba ti wọn ba si to o fa ori ikoko ni Ọọni yoo si tun lee rii.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Coronavirus in Nigeria: Ǹjẹ́ òògùn vitamin C lè pa coronavirus?
Alẹ́ yìí ni alẹ́ gígùnjùlọ lọ́dún.
O ni ajo naa ti ri isoro ti o n dena  awon to n wa ekusa lati maa jeki won ri  anfaani eyawo ohun.
Ètò RUGA wọn kò lè ká Fulani 500,000 tó wà nínú igbó ilẹ̀ Yorùbá - Oluwo Ṣé ẹ̀mí ilé aṣòfin lè gbé ṣíṣe ìwádìí 16 bn owó àgbàṣe iná ọba Nàìjíríà?
Nígbà tí ó bá yá, ẹnìkọ̀ọ̀kan wọn yóo gba èrè tirẹ̀ gẹ́gẹ́ bí iṣẹ́ rẹ̀ bá ti rí.
    Onírúurú ẹ̀dá ni o ń jìyà ní ọ̀run Àpáàdì, a rí bàbá tí ó yìnbọn pa ọmọ rẹ̀ láyé, ìyá tí fún ọmọ ní òogùn jẹ láti fi pa ọmọ, àbúrò tí ó lu ẹ̀gbọ́n pa àti ọ̀kẹ́ àìmọye ìwà burúkú gbogbo tí àwọn ọmọ ènìyàn ń hù.
42 Àti kíyèsíi, ìwọ yíò tẹ̀ẹ́ jade gẹ́gẹ́bí àkọsílẹ̀ ti Néfì; àti báyìí èmi yíò dà àwọn wọ̃nnì láàmú tí wọn yí àwọn ọ̀rọ̀ mi padà.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Bukola Saraki di adarí gbogboògbò PDP Ènìyàn mẹ́ta ti kú ní ìdìbò Zimbabwe Yẹmi Oṣinbajo di 'Ààrẹ̀ Nàìjíríà' Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Irú ẹ̀dá wo ni Fẹla Jẹ́?
Egbọn rẹ, John to n ṣiṣẹ awọn to n ṣe ara loge lẹyin itage ninu ere lo ba a wa ọna abayọ si iṣoro rẹ.
Jẹ́ kí n tọ́jú oúnjẹ fún ọ, kí o jẹ ẹ́, kí o lè lókun nígbà tí o bá ń lọ.
 “Fun idi eyi, a ko ni faye gba awon iwa ibaje yii.
Olorí ogun Ethiopia ti kú sínú ìdìtẹ̀-gbàjọba Ethiopia Ileeṣẹ iroyin Ethiopia ti kede pe olori ọmọ ogun ti gbẹmi mi.
Ọpọ igba yii ni aarẹ Buhari fi wa niluu London nibi to ti n gba itọju lẹyin to ṣaarẹ.
Ẹ máa kíyèsí i bí ó bá ti ń lọ.
 O ni  “A o ni gbagbe awon akoni wa, ti won padanu
Ó súre fún Abramu, ó ní:“Kí Ọlọrun Ọ̀gá Ògo,tí ó dá ọ̀run ati ayé bukun Abramu.
O ni: “A n soro lori awon eto idanilaraya loniruuru to ti dise afijeun fun opo eniyan ni Naijiria ati loke okun.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ìgbátí ìgbámú àná látọwọ́ sọ́jà obìnrin ti bá arákùnrin náà dé iléèwòsàn Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Sanwo-Olu fi ẹ̀gbin dá àrà tuntun l'Eko Kàáyéfì, alárùn ọpọlọ 13 ní ẹbí jù sí ọgbà ẹ̀wọ̀n - Ọ̀gá ọgbà ẹ̀wọ̀n Robert Mugabe, akọni òṣèlú tó lo ọdún mẹ́wàá lẹ́wọ̀n fún ìjìjàgbara Zimbabwe Òògùn olóró tí àwọn ọmọ Naijiria ń tà ló fa ìkọlù - South Africa Ṣugbọn o ṣalaye wi pe, ti ara ko ba ti ni anfani lati tẹsiwaju mọ, o di dandan ki a mu iru aawẹ bẹẹ wa si opin.
Ko si alaye to kuna bi alara lori oloogbe naa.
OLUWA yóo máa bá ìrandíran àwọn ará Amaleki jà títí lae.
Ọlọrun ń dáàbò bò wọ́n, ó ń ràn wọ́n lọ́wọ́,ó sì ń pa wọ́n mọ́ ni ọ̀nà wọn.
Amofin Dorothy Njemanze to ba BBC News Yoruba sọrọ lori ọrọ kan ti wọn ni arabinrin naa kọ loju opo Facebook rẹ ninu eyi to ti ki kọmiṣọna ọhun ku oriire ọjọ ibi rẹ ṣalaye pe ko si idi fun arabinrin yii lati yi pada lori ẹjọ naa ti kii ba ṣe pe awọn alagbara ti n lo agbara wọn lori iṣẹlẹ naa.
Nítorí pé agbára wa kò tó láti dojú kọ ogunlọ́gọ̀ àwọn ọmọ ogun wọn tí wọn ń kó bọ̀ wá bá wa jà.
Orile-ede Amerika ti kede ipese iranlowo owo to to milionu metalelogbon le ni eedegbeta owo dola ile okeere fun iranlowo fun Nigeria, Ethiopia, Somalia, ati South Sudan pelu awon orile-ede ekun Lake Chad.
Bí ẹ bá wá jẹ́ ọmọ, ẹ di ajogún nípasẹ̀ iṣẹ́ Ọlọrun.
"Laipẹ laijinna ni maa kọ ibudo itọju awọn alarun jẹjẹrẹ, ti wọn yoo ti maa gba itọju kímò, maa si pe orukọ ibudo naa ni Wuraola Chemotherapy Cancer Centre, lati ma ṣe jẹ ki orukọ iya mi parẹ.
Ẹ máa yọ̀ nítorí èyí, bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé fún àkókò díẹ̀, ẹ níláti ní ìdààmú nípa oríṣìíríṣìí ìdánwò.
Bye-election (Idibo si ipo asofin) : Eyi ni eto idibo
Ni bayi, ara iṣẹ ti ajọ naa n ṣe ni pipolongo fun ẹtọ awọn ọmọde, eto ilanilọyẹ fun awọn araalu lori ẹtọ awọn ọmọde, to di mọ ipese ibudo ti aabo yoo ti wa fun awọn ọmọde.
' Amọ ṣa ninu ọrọ to ba BBC News Yoruba sọ, alukoro ọlọpaa fun ipinlẹ Adamawa, Othman Abubakar ṣalaye pe lootọ ni awọn eeyan kan lati ijọba ibilẹ Maiha fi ẹjọ sun awọn pe eeyan kan to wa ni ahamọ ọlọpaa ti yirapada di ẹyẹ igunugun eleyii ti o n wa si ile ati ilu wọn lati da wọn laamu.
Amọ, Joe Biden ni awọn ṣẹṣẹ bẹrẹ pẹlu orilẹede Russia, nitori awọn yoo ṣewadii bi wọn ṣe tọwọbọ eto idibo wọn ni ọdun 2016.
Awọn akẹkọọ naa korajọ si oriṣiriṣi ojuko ni olu ilu awọn ipinlẹ naa lati fi aidunun wọn han si ijọba lori ibi ti eto ọrọ aje Naijiria n dori kọ.
Ajọ ọlọpaa ọtẹlẹmuyẹ lorilẹede Naijiria, DSS ti sọ pe iroyin ofege lawọn kan n gbe kaakiri pe ajọ naa ti mu awọn oṣiṣẹ ajọ eleto idibo INEC kan.
Dafidi wí fún ọdọmọkunrin ará Amaleki náà pé, “Ìwọ ni o fa èyí sí orí ara rẹ.
Farao bá ranṣẹ lọ pe Josẹfu, wọ́n sì mú un jáde kúrò ninu ẹ̀wọ̀n kíá.
Bi o tilẹ jẹ wi pe ijọba apapọ paṣẹ konile-o-gbele lawọn ipinlẹ kan bii Eko, Ogun ati Abuja, ohun ti o n farahan bayii paapaa lori ayelujara ni pe ọpọ awọn ọmọ Naijiria ti wọn ko fẹ ki jijoko pa sile o sọ awọn di nnkan miran ti wọn si ti bẹrẹ ere idaraya kaakiri lati fi na eegun ati ara wọn.
“Gbọ́, oluwa wa, olóyè pataki ni o jẹ́ láàrin wa.
Olori awọn oṣiṣẹ gomina nipinlẹ Ọṣun, Họnọrebu Rasaq Salinṣile ṣalaye fun BBC Yoruba pe lootọ ni ijọba ti gba lati san owo oṣu mẹrin ninu mẹtalelọgbọn ti ijọba jẹ awọn oṣiṣẹ ati oṣiṣẹfẹyinti nipinlẹ naa lẹyin ifikuluku pẹlu awọn adari ẹgbẹ oṣiṣẹ.
Tèmi ni ohun gbogbo tí Baba ní.
Awọn ilumọka oniroyin lorilẹede Kenya meji pin iroyin ayederu Kinni iroyin naa?
Wọ́n péjọ láti bá ẹni tí ó gun ẹṣin funfun náà ati àwọn ọmọ-ogun rẹ̀ jagun.
Tọkọtaya lu ọmọ ni gbanjo fun 400k Ta ni yóò borí láàrin Aisha Buhari àti ọkọ rẹ̀ lórí ọ̀rọ̀ ‘First Lady’?
Coronavirus in Nigeria: Ayodeji Osowobi ṣàlàyé bí ó ti jàjà bọ́ lọ́wọ́ àrùn covid-19
N óo wá jẹ́ kí odò wọn ó tòrò, kí wọn máa ṣàn bí òróró.
Won ni awọn ti ri to idaji rẹ gba pada bayii.
Iye awọn eeyan wọnyi ni ajọ to n gbogun ti ajakalẹ arun lorilẹede Naijiria, NCDC ni awọn ṣawari nipa ayẹwo lati awọn ipinlẹ mejidinlọgbọn kun ẹgbẹrun marundinlogoji o le diẹ to wa nilẹ tẹlẹ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Badagry Historical Wells: Omi inú kànga Wawú ló ń kó ọpọlọ àwọn ẹrú lọ Sùgbọ́n ǹkan ti mo fẹ́ ni pé ki n ri ẹni ti yóò fẹ́ràn mi, tí yóò maa pèsè gbogbo ǹkan ti mo nilò.
Ninu awo orin rẹ kẹẹdogun (Vol 15) to pe ni Ọrọ kan jẹ mi logun"", lo ti ba wọn wi."
Má máa yára bínú, nítorí àyà òmùgọ̀ ni ibinu dì sí.
Osaze Uzzi wa rọ awọn oludije ti ọrọ naa kan, lati gunle ipolongo ibo wọn jake jado orilẹede Naijiria, eyi to wa nibamu pẹlu atẹ ilana eto idibo gbogbo-gboo ọdun 2019.
"Gbolohun naa fa awuyewuye ati ariwisi laarin ilu, ọpọlọpọ eeyan fara, ti wọn si n pe gomina Ajimobi ni ""Mr Constituted Authority"" lati igba naa."
kí wọ́n lè máa bẹ̀rù rẹ ní gbogbo ọjọ́ tí wọ́n óo gbé lórí ilẹ̀ tí o fi fún àwọn baba ńlá wọn.
 bàbá rẹ ̀ siṣẹ ́ gẹ ́ gẹ ́ bíi onímọ ̀ iṣẹ ́ -ẹ ̀ rọ ( engineer ) nígbàtí ìyá rẹ ̀ sì jẹ ́ olùkọ ́ .
Akonimoogba ohun wa fi ye iko naa pe, apapo orile-ede Naijiria ati awon ololufe won jake-jado wa leyin won ni digbi.
Àwọn ará láti Itali ki yín.
ogun oju omi naa si ori omi je aseyori nla fun ile-ise ologun oko oju omi
wahala oselu to be sile nile igbimo asoju-sofin lorile ede Guinea Bisau ko ni pẹ
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù NECO: Ààrẹ Buhari ti fi ọwọ́ òsì júwe ilé fún Ọ̀gá Àjọ NECO àti àwọn mẹ́rin míràn lórí ẹ̀sùn ṣíṣe owó báṣubàṣu 21 Èbibi 2020 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ìjọba ààrẹ Buhari ti ní àwọn gbé ìgbésẹ̀ náà lẹ́yín ìwádìí ẹ̀sùn ìwà àjẹbánu tí wọ́n fi kàn wọ́n.
Awọn ti ọ̀rọ̀ naa ka lara ti n fi ọrọ adura sita si Ọlọrun lati dawọ ibi yii duro ki ẹmi si ma nu.
Nígbà tí àwọn tí ó bẹ̀rẹ̀ iṣẹ́ ní agogo marun-un ìrọ̀lẹ́ dé, wọ́n gba owó fadaka kọ̀ọ̀kan.
O fi soju opo twitter rẹ pe gbogbo owo itanran ti wọn beere ni awọn san.
Iwé ìròyìn Punch so pé, EFCC gbe iwadi jade pe Akpan gbé iṣẹ agbaṣe fún Omokore nigba ti ọ jẹ Komisana ètò ìṣúná n'ipinle Akwa Ibom.
eto bi awon eniyan se wole-jade kuro niluu Girdon Kihalegwa lati san owo
Dokita Tomi fikun ọrọ rẹ pe ewu to wa bayii ni wi pe awọn eeyan ko tẹle ilana wiwọ ibomu lati dena itankalẹ coronavirus.
Bí wọ́n ti ṣe ètò wọn kò rí bí awa ti rò.
BBC: Osisẹ ijọba Eko fi tipa gba irinsẹ akọroyin wa
Ó dá wọn lóhùn pé, “Èmi náà yóo bi yín ní ọ̀rọ̀ kan, ẹ dá mi lóhùn.
Alaga tẹlẹri fun eto owo yiya labẹle ati lokeere ni ile igbimọ asofin to kọja, Sẹnatọ Shehu Sani ti bu ẹnu ẹ̀tẹ́ lu igbesẹ Aarẹ Buhari lori bi o ṣe kọwe si Ile Igbimọ Asofin lati buwọlu igbesẹ oun lati ya ọgbọn biliọnu Naira lọwọ ilẹ okeere.
Ẹni rere kanṣoṣo ni ó wà.
 Ki Olorun fi adun keyin isele yii fun won”.
 Ìdí nì yí tí ó fi jí owó rẹ ̀ gbé .
1 18091 Orilẹede Angola 362 1.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Femi Okunronmu: Parliamentary pé wa ju ìṣèjọba presidential lọ 14 Ọ̀pẹ̀̀ 2018 Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fọ́nrán ohùn, Femi Okunronmu: Parliamentary pé wa ju ìsàjọba presidential lọ Gbajugbaja oloselu, Femi Okunronmu ti kan saara si awọn asofin to buwọlu abadofin to fi agbara fun isejọba igbimọ awọn aṣofin (parliamentary) lati rọpọ iṣejọba to fi agbara fun aarẹ.
olopaa meta ati ara ilu kan nipinle naa.
Isin oni ti pari ni COZA nigba ti Pasitọ Biodun Fatoyinbo ba awọn ọmọ ijọ sọrọ.
Awọn adari orilẹede ni Iwọ- Oorun Ilẹ Afirika (West Africa), ni ko naani lati ri wi pe ibaradọgba wa laarin awọn olowo ati awọn mẹkunnu ni agbeegbe naa.
Alaafin Ọyọ Queens: Ǹjẹ́ o mọ àwọn olorì àkọ́fẹ́ Aláàfin Adeyẹmi?
Ẹlomii t'oun naa n ṣe e sọ pe, eto naa ki i ṣe sogun-dogoji rara, ''o da bi àjọ dida ni.
Ilé iṣẹ̀ ọlọpàá sọ pé wọ́n yín àwọn òṣìṣẹ́ àwọn mẹ́jì níbọn lẹ́sẹ̀ tí àwọn mẹ́fà sì farapa nígbà tí àwọn Shia lá ponpo àti òkúta mọ́ wọ́n.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ìtàn ọba Yorùbá tí wọn yẹgi fún torí ó jí ọmọ gbé ṣe ètùtù Ọdẹ ìbílẹ̀ ní Okeho pa adigunjalè mẹ́rin tó fọ́ báńkì, aráàlú dáná ṣun wọ́n Aláwàdà ni ọmọ mi láti kékeré, kò ṣẹ̀ṣẹ̀ máa gbé mi mọ́ra- ìyá ‘Mummy calm down’ (Toluige Olokoobi Babalola) Wo ìyàtọ̀ tó wà láàrin Bíbélì Yorùbá tí Kumuyi kọ sí èyí tó wà ńlẹ̀ Ìkúnlẹ̀ abiyamọ, ìkókó mẹ́jọ kú nílé ìwòsàn lálẹ́ ọjọ́ kàn Dayo Amusa gbarata lórí bí agbófinró ṣe ń pa ọ̀dọ́ láì nídìí Arabinrin naa ni Fasiti Babcock fi ọwọ oṣi juwe ile fun, nitori fọnran kan to lu ayelujara pa, nibi ti ọkunrin kan ti n ba lopọ.
"Ti aaye rẹ ba yọ funmi maa beere owo mi pada nitori ko rọrun lati ri owo yii.
OLUWA ni ó ní kí ó máa ṣépè, nítorí náà, ẹ fi sílẹ̀, ẹ jẹ́ kí ó máa ṣẹ́ ẹ.
o ṣe pataki kí òun yan akanda ẹdá gẹ́gẹ́ bii kọmisọna.
Ó bá mú Paulu lọ siwaju wọn.
  Tọmọdé tàgbà ni wọ́n fẹ́ràn láti máa fi yìnyín gbẹ́ ère.
Ti o ba ti lo ẹrọ alagbeka ri ti oju rẹ si fọ, o mọ bi ko ti ṣe nira ki oju rẹ fọ ṣugbọn wa mọ inira to wa nibi nina owo pupọ lori piparọ rẹ.
Ẹ óo joró nítorí ẹ̀ṣẹ̀ yín, ẹ óo sì máa bá ara yín sọ̀rọ̀ tẹ̀dùntẹ̀dùn.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Parental Guidance: Ọdún méjì ni kí ẹ ti bẹ̀rẹ̀ kíkọ́ ọmọ nípa ìbálòpọ̀ Alaga ẹgbẹ awọn obi awọn ọmọ ile iwe Chibok, Yakubu Nkeki ni ibanujẹ ati ẹdun ọkan lo jẹ fun awọn nitori lẹyin ọdun marun un, ọgọrun un awọn ọmọ naa lo si wa ni panpẹ Ni eyi ti lara awọn mọlẹbi awọn ọmọ wọnyii si ti ku nipase iku ojiji, ijamba ọkọ, aisan ati ikọlu awọn Boko Haram si awọn agbeegbe wọn.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Bangladesh wedding: Khadijah yí àṣà ìgbéyàwó padà ni Bangladesh 3 Ọ̀wàrà 2019 Àkọlé àwòrán, Tọkọ-taya tuntun lẹyin ti wọn yi aṣa atọdunmọdun pada ni Bangladesh Aṣa to ti wa fun ọpọlọpọ ọdun ninu igbeyawo awọn eniyan Bangladesh ni Khadiza Akter Khushi yi pada.
O sọ ninu atẹjade naa pe Aarẹ Buhari gba lati gbe iṣakoso kaadi idanimọ fun ẹka ijọba to n ri si eto ibanisọrọ nitori ipa ribiribi ti ileeṣẹ ijọba naa ti ko ninu ilọṣiwaju ọrọ aje Naijiria.
Eniyan burúkú ṣubú nítorí ìwà ibi rẹ̀,ṣugbọn olódodo rí ààbò nípasẹ̀ òtítọ́ inú rẹ̀.
Bákan lo fikùn pé, oselu kò pá isẹ tíátà tí òun ń ṣe lára nítorí pé, Ọlọ́run fún òun ní aya tó di ilé mú dáadáa, tí Gomina tí òun sì bá ṣíṣẹ náà fún òun ní ààyè láti máa lọ síbi ère tíátà, ni àwọn ọjọ́ kan.
Ó gbé pẹpẹ ẹbọ sísun kalẹ̀ níbi ẹnu ọ̀nà àgọ́ náà, ó sì rú ẹbọ sísun ati ẹbọ ohun jíjẹ gẹ́gẹ́ bí OLUWA ti pàṣẹ fún un.
34 biliọnu ni ijọba fi n bọ awọn ẹlẹwọn 75,789 to wa ni orilẹ-ede yii.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù 2019 Prophesies: Kíni ohun tí àwọn ìránṣẹ́ Ọlọ́run sọ nípa ọdún 2019 1 Sẹ́rẹ́ 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ọdún 2019 ti wọlé, àwọn olórí ẹ̀sìn gbogbo si ti ń sọ àsọtẹ́lẹ̀ wọn fún ọdún tuntun náà.
ASUU strike: Mi ò tíì lè sọ ní pàtó ìgbà tí a ó fòpin sí ìyanṣẹ́lódì wa
Ẹgbẹta (600) ọkunrin ninu ẹ̀yà Dani tí wọ́n dira ogun gbéra láti Sora ati Eṣitaolu.
Tanimọla sun igbẹjọ naa siwaju si ọjọ kẹtadinlogun oṣu yii.
Bi o tilẹ jẹ pe Boko Haram tu awn akẹk yoku silẹ, amọ wọn ko fi Leah silẹ, nitori pe o faake kọri lati di ẹlẹsin Islam, ko si kuro ni ọmọlẹyin Kristi.
Bí ó ṣe fẹ́rẹ́ fún òriṣà
Má máa fetí sí gbogbo nǹkan tí àwọn eniyan bá wí, kí o má baà gbọ́ pé iranṣẹ rẹ kan ń bú ọ.
Ajọ NCDC naa fi lede loju opo ikansiraẹni Twitter wọn ni alẹ Ọjọru.
Àkọlé àwòrán, Ọpọ eeyan guusu Cameroun di atipo lorilẹede Naijiria Agbenusọ ijọba orilẹede Cameroon Issa Tchiroma Bakary, sọ fun BBC wipe awọn soja naa kan ngbiyanju lati daabo bo iyi orilẹede naa lasan ni pelu fifi ẹse alafia rinlẹ l'agbegbe guusu Cameroon niibi ti awọn ajijagbara tin gbiyanju lati da orilẹede ti wọn pẹ ni Ambazonia siilẹ.
Àwọn idẹ tí wọ́n dájọ jẹ́ aadọrin ìwọ̀n talẹnti ati ẹgbaa ó lé irinwo (2,400) ìwọ̀n ṣekeli.
Ní ojúmọmọ, kò jẹ́ kí àwọn ẹyẹ jẹ wọ́n ní ọ̀sán, kò sì jẹ́ kí àwọn ẹranko burúkú fọwọ́ kàn wọ́n lóru.
Ǹjẹ́ o mọ̀ pé ètò ìdìbò kan wà tí erin àti òkúta Dáyámọ́ǹdì leè yí èsì rẹ̀ padà Wo bí ètò ìsìnkú Isa Funtua ṣe wáyé ní ìlú Abuja Ọkùnrin kan pa ara rẹ̀ sínú ọgbà àjọ TRACE tó n mójútọ ìrìnnà ọkọ̀ nípìnlẹ̀ Ogun A yìnbọn lu Precious láti dáa dúró ni, akò mọ̀ pé o máa kú- Ọlọ́pàá Awọn akẹkọọ SS3 yoo bẹrẹ idanwo WAEC wọn ni kete ti Ajọ WAEC ba ti fi ọjọ idanwo naa lede.
Osun 2018: Àwọn aráàlú da ìbéèrè bo àwọn olùdíje ìpínlẹ̀ Ọṣun
Òṣìṣẹ́fẹ̀yìntì, ọmọ ọdún 71 wọ gbaga ọlọ́pàá fún pípe iléeṣẹ́ kan fún ìgbà 24, 000 Wo bí o ṣe le è gba páálí ìrìnnà àti bí ò ṣelè di ọmọ orílẹ́èdè Malta Akọkọ ẹni to daa lohun ni eeyan kan to lo orukọ Bigdaddy terry @terry_abiola lo kọkọ dahun pe 'Sọrọ nipa DSS, ẹgbọn, maa sọrọ nipa AJ Ọgbẹni kan labẹ orukọ @calabar_virgin pẹlu bi Keyamo leere pe ṣe kii ṣe pe o fẹ ka iṣẹgun AJ ku ara aṣeyọri aarẹ Buhari.
National Association of Resident Doctors (NARD) ṣalaye pe lati osu kẹfa ni wọn ti ṣepade pẹlu ijọba apapọ lori igbesẹ yii.
Amọṣa Gomina El Rufai ti salayeidi ti o fi sọ ọrọ naa loju opo Twitter rẹ ni idahun si iriwisi orisirisi to muwa.
Àjọ NAFDAC fọwọ́ sí pípo ògùn chloroquine fún àyẹ̀wò ìtọ́jú coronavirus Èèyàn Ènìyàn márùn ún gba ìwòsàn lọ́wọ́ àrùn Coronavirus Èyí ni àwọn tí òfin kónílé-ó-gbélé tí ààrẹ Buhari pa l'áṣẹ kò kàn ní Eko, Ogun àti Abuja Ààrẹ Buhari: Kò ní sí lilọ bibọ ni Eko,Ogun ati Abuja fọjọ́ mẹ́rìnlá gbako Sẹnetọ Ajimọbi ni inu oun bajẹ gidigidi nigba ti oun gbọ iroyin pe Gomina Seyi Makinde ti ko arun ọhun.
Ede Yoruba dun lọrọ, paapaa julọ pẹlu ami ohun.
Awọn eto to maa n waye lasiko ọdun Ọṣun Oṣogbo: Iwọ Popo: Iwọ Popo ni wọn maa fi n bẹrẹ ọdun Ọṣun Oṣogbo lọdọọdun, asiko yii si ni awọn olujọsin ati awsn oluworan yoo maa yi ilu po lati fọ ilu mọ pẹlu adura ati etutu.
Van Dijk gbadé UEFA mọ́ Messi àti Ronaldo lọ́wọ́ Nigba ti adari eto lori papa pe fun idije ifẹsẹ-wọn- sẹ ojule si ojule ti o mu ki Naijiria gba amin ayo mẹta si meji si ile ojugba wọn.
 orílẹ ̀ èdè tí ó ní jù ni gúúsù sudan .
Bakan naa, nitori pe aarẹ Buhari maa n wa lẹyin ofin, aarẹ yoo ba adele alaga tuntun naa se ipade lati ori ẹrọ ayelujara ni ọsan ọla."
Uztas:Ọjọgbọn ni wọn n pe ni Uztaz.
O ni oun n riran ọjọ iwaju rere to kun fun owó ati iṣẹ lọpọ yanturu fawọn eniyan ipinlẹ Kaduna ni saa iṣejọba keji oun yii.
Ṣugbọn bí wọ́n bá gbà pé kí ẹni tí ó ni ín san owó ìtanràn, ó níláti san iyekíye tí wọ́n bá sọ pé kí ó san, kí ó baà lè ra ẹ̀mí ara rẹ̀ pada.
Ati pe orilẹede oun yoo tun imọ ijinlẹ nipa iṣẹ ọwọ ati imọ ẹrọ pẹlu Naijiria.
Oríṣun àwòrán, 1996 VT Freeze Frame Àkọlé àwòrán, Ọrọ ikorira ti di agbẹdọ ni orilẹede Naijria pẹlu asẹ tuntun lati ọdọ ijọba O ni, ilẹ Amẹrika ti kan-an ni ọranyan fun ilẹ Naijiria lati san owo naa ki o to di ogunjọ osu keji ọdun 2018, bẹẹni ki o to lee di wipe o tẹwọgba awọn baluu ogun naa, yoo di ọdun 2020, iyẹn ọdun mẹrin si asiko yii.
O ni oun ti loogun ipaniyan nitori o san fun oun lati ku ju ki oun wa laaye lọ.
Wọn sin oku rẹ si Odo-Naforija ni Epe, ilu Eko.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Bisi Alimi: Èmi tí mò ń tọrọ ilé gbé ní London, wá di onílé méjì 8 Bélú 2020 Oríṣun àwòrán, Instagram/bisialimi Ọrọ ifẹ bi adanwo ni lawọn Yoruba maa n wi.
Nisinsinyii, kabiyesi, gbogbo àwọn eniyan mi ni wọ́n ti kẹ̀yìn sí mi.
Ẹ̀yin olólùfẹ́ mi àti ẹbí ni mo bẹ̀ Àwọn olólùfẹ̀ Toyin Abraham ati Liz Anjorin ti gbé ọ̀rọ̀ wọn rù sórí, ẹ wo òjò òkò ọ̀rọ̀ Mi ò fẹ́ dá sí ìjà Toyin ati Lizzy!
Lẹ́yìn awuyewuye yìí ni Ààrẹ ilé aṣòfin àgbà, Bukọla Saraki, àti àwọn aṣòfin mìíràn fi ẹgbẹ́ òṣèlú All Progressives Congress sílẹ̀ tí wọ́n sì darapọ̀ mọ́ ẹgbẹ́ òṣèlú alátakò, Peoples Democratic Party, PDP.
ṣamojuto igbega awọn oṣiṣẹ lẹnu iṣẹ, eto idanilẹkọọ fun wọn ati ẹtọ
Wọ́n sì mọ̀ pé ó ti rí ìran ninu iyàrá Tẹmpili ni.
Iwé ìròyìn irọlẹ, gbe jade bi Trudy Alli-Balogun, ti lo ipò rẹ ni ilé iṣẹ́ ti ó nṣe ipèsè ibùgbé fún ọmọ ilú, lati gba àbẹ̀tẹ́lẹ̀ lọ́wọ́ àwọn Yorùbá ti kò ni ẹ̀tọ́ si irú ilé bẹ́ ẹ̀.
Wọn sọ ọ sinu iho naa, ki wọn to gbe oku ẹgbọn rẹ lu u laya, ti wọn si fi yẹpẹ bo o mọlẹ laaye.
Láti ìgbà tí o ti kúrò ní ọ̀dọ̀ mi, n kò yéé ṣe ìdárò rẹ̀, mo sì tànmọ́ọ̀ pé lákòókò tí ìwé yìí yóò bá fi tẹ̀ ọ́ lọ́wọ́ ìwọ yóó tí kúrò ní ìlú àwọn ejò ìwọ yóó sì ti rékọjá àwọn olórí-burúkú obìnrin.
Idi keji fun eewọ yii ni pe kii ṣe gbogbo igba ni wọn n gbe ọmọ ikoko lọ ki Ọba nitori kabiyesi ti le e wa ni ẹgun pẹlu awọn Onnilẹ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Nikesuliat: Ọ̀dọ́mọdébìnrin akéwì tó n fi ẹ̀ṣà kìlọ̀ ìwá lásìkò yìí Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Sunday Adeyemo, ti ọpọ mọ si Sunday Igboho lo sọ ninu fidio BBC Yoruba pe, awọn to ba fẹ darapọ mọ ikọ Amọtẹkun gbọdọ maa fi Ogun bura.
Awọn eeyan naa gba ominira lọwọ awọn ajinigbe naa lẹyin ti awọn ẹbi wọn san owo itanran ti ko din ni miliọnu kan ati ẹgbẹrun lọna igba naira.
Ilya Pam ni ọmọ orilẹede Naijiria to gbegba oroke ni abala ti idije abẹle.
37 Àti nísisìyí, kíyèsíi, èmi fi fún ọ, Oliver Cowdery, àti bákannáà fún David Whitmer, pé ẹ̀yin yíò ṣe àwárí àwọn Méjìlá, tí wọn yíò ní ìfẹ́ inú èyí tí mo ti sọ nípa rẹ̀;
Awọn fidio naa ti Aisha Buhari fi sita fa awuyewuye lori ẹrọ ayelujara, ti ọpọ eniyan si bẹrẹ si ni foju wo o gẹgẹ bi alatako gboogi fun Aarẹ.
Umrah 2019: Ààrẹ̀ Buhari yóò balẹ̀ bìbà sí Saudi Arabia
Nigba ti ọsẹ kan yoo fi pari, awọn ologun tun ti ran akẹkọọ mẹjọ miran sọrun ọsan gangan nilu Zaria, ti bilisi si so.
Ninu atejade kan ti oluranlowo aare lori iroyin ati ikede Garba Shehu,gbe
Àkókò ń bọ̀ tí ó jẹ́ pé, ati ní orí òkè yìí ni, ati ní Jerusalẹmu ni, kò ní sí ibi tí ẹ óo ti máa sin Baba mọ́.
Wèrè tí mò ń ṣe ní Facebook ló pawó fún mi-Esabod Kónílé-ó-gbélé Covid 19 ló tú àṣírí àwọn àfipábánilòpọ̀ láwùjọ- Mínísítà ọ̀rọ̀ àwọn obìnrin 'Soyinka máa ń kó sí wàhálà; ó tún máa ń kó àwọn èèyàn míì sí wàhálà' Ìjìyà ń bẹ fún àwọn ti adé ọ̀rọ̀ náà bá ṣí mọ́ lóri -Ọga àgbà FRSC FRSC dá N443,180 padà fún ẹbí ẹni to ní ìjàmbá mọ́tò 60,000 àwakọ ló ń lo iwé ìrinà ọ̀kọ̀ tí kò k'oju oṣùwọn ní ìpínlẹ̀ Eko - FRSC Fi fọọmu ranṣẹ si ọfiisi iwe aṣẹ iwakọ Igbesẹ to kan ni lati mu fọọmu ti eeyan ba ti fọwọ si lọ si ọfiisi ti ajọ FRSC ti maa n fawọn awakọ Nibi ni ẹni to fẹ gba nọmba adani ti gbọdọ sọ iru nọmba to fẹ gba si ọkọ rẹ gan an ninu fọọmu ti yoo ṣọwọ si ọfiisi ti wọn ti n gba iwe aṣẹ ọkọ wiwa.
Oríṣun àwòrán, Facebook/Ibraheema yakubu Àkọlé àwòrán, Ibraheema Yakubu náà wà lára àwọn oníròyìn tí wọ́n fara káasá ìkolù àwọn ọlọ́pàá Awọn ọlọpaa kọkọ fiya jẹ oniroyin meji, iyẹn, ọgbẹni Daniel Elombah ati ọgbẹni Tim Elombah ti wọn n ba ile iṣẹ iroyin ayelukara kan ṣiṣẹ ki wọn to mu wọn ni ọjọ kinni, oṣu kinni, ọdun 2018 nilu Nnewi, ipinlẹ Anambra.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Olofa ina: ẹ parí òwe yìí pé ìgbà tí ara bá tu ìgbẹ́ láà ri eṣú.
O salaye pe Gomina ipinlẹ Yobe, Mai Mala Buni lẹni to tako ofin yi nipa pe o di ipo alaga ẹgbẹ APC mu to si tun yan Akeredolu lati dije dupo Gomina.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ramadan 2020: Buhari, Ọọni, Sultan Sokoto ní kí àwọn ọmọ Nàìjíríà láti fi ìtúnu àwẹ̀ gbàdúrà fún Nàìjíríà 4 Òkùdu 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 24 Èbibi 2020 Oríṣun àwòrán, others Aarẹ orilẹede Naijiria, Muhammadu Buhari ti kesi awọn ọmọ Naijiria lati gbadura ni ile lasiko ọdun itunu aawẹ Ramadan, lẹyin to kọ fun awọn eniyan lati maṣe wa si Ile Aarẹ ni Abuja.
Ojú ọ̀run ń kéde òdodo rẹ̀ péỌlọrun ni onídàájọ́.
Ilé ìwòsàn l'Àbuja ti ya àwọn ìbejì tí wọ́n sọpọ̀ láyà lọ́fẹ̀ẹ́ Àbọ̀ ìpàdé bòńkẹ́lẹ́ láàrin Tinubu àti Buhari rèé Makinde wa kesi alaga afunsọ ijọba ibilẹ ila oorun Ọyọ, ti ọja Akẹsan wa labẹ rẹ lati se akojọpọ orukọ awọn ontaja ti ajalu naa ba, lọna ti seto iranwọ to yẹ fun wọn.
Wọ́n bá ranṣẹ sí Josẹfu pé, “Baba rẹ ti fi àṣẹ yìí lélẹ̀ kí ó tó kú pé, 
Ohun tó yẹ kóo mọ̀ nípa Fásitì Babcock rèé Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Àfi bí mo bá sunkún mọ́ títọrọ̀ owó, tórí gbobo wa ni ìyà ń jẹ níbí' Ṣe lori ọrọ yii abomii?
Brooklyn, New York ni wọn ti bi Adepero Oduye.
Wọn óo máa wí nisinsinyii pé, “A kò ní ọba, nítorí pé a kò bẹ̀rù OLUWA; kí ni ọba kan fẹ́ ṣe fún wa?
Orilẹede wo lo ni eeyan to pọ julọ?
Lẹsẹkẹsẹ ọ̀kan ninu wọn sáré, ó ti nǹkankan bíi kànìnkànìn bọ inú ọtí kíkan, ó fi sórí ọ̀pá láti fi fún un mu.
" Amòfin Ojo ní ǹkan tí àwọn ọlọ́pàá ń ṣe yìí ló fún àwọn ènìyàn burúkú yìí lágbára láti maa ṣiṣẹ́ ibi lásìkò Coronavirus.
Aláìmọ́ náà yóo fọ aṣọ rẹ̀, yóo sì wẹ̀ ninu omi, yóo sì di mímọ́ ní ìrọ̀lẹ́.
Ẹ kò gbọdọ̀ ṣàánú olúwarẹ̀ rárá, tó bá jẹ́ pé ó fẹ́ kí wọ́n pa arakunrin rẹ̀ ni, pípa ni kí ẹ pa òun náà; bí ó bá jẹ́ ẹyinjú tabi eyín rẹ̀ ni ó fẹ́ kí wọ́n yọ, ẹ yọ ojú tabi eyín ti òun náà; bí ó bá sì jẹ́ pé ọwọ́ tabi ẹsẹ̀ rẹ̀ ni ó fẹ́ kí wọ́n gé, ẹ gé ọwọ́ tabi ẹsẹ̀ ti òun náà.
Wọ́n dá a lóhùn pé, “Láti ọ̀nà jíjìn ni àwa iranṣẹ rẹ ti wá nítorí orúkọ OLUWA Ọlọrun yín, nítorí a ti gbúròó rẹ̀ ati gbogbo ohun tí ó ṣe sí wọn ní ilẹ̀ Ijipti, 
A tun ti fun ile-ise kan nise lati tubo se iwadii lori awon ibi ti awon dukia tabi owo ti awon jekudu-jera ko lo si ilu-okeere.
Ṣugbọn Asaraya, alufaa, wọlé lọ bá a pẹlu àwọn ọgọrin alufaa tí wọ́n jẹ́ akọni.
Àwọn òṣèré tíátà kan rèé, tí wọn fẹ́ ara wọn, tí ìgbeyàwó wọn sì pẹ́ Xenophobic Attack: Àwọn ọmọ Nàìjírìá bínú kọlu Shoprite l'Eko Kí ni ó gbé ọlọ́pàá dé ibi àjọ̀dún ọjọ́ ìbí i Bobrisky?
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Obasanjo: Ìdùnnú ọmọ Nàìjíríà ló jẹ́ mí lógún ní 2019 10 Ọ̀pẹ̀̀ 2018 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ọ̀pọ̀ igbà ni Olúsẹ́gun Ọbásanjọ́ ti sọ̀rọ̀ àbùkù sí ìjọba Muhammadu Bùhárí Aarẹ nigba kan fun Naijiria, Oloye Oluṣẹgun Ọbasanjọ ti sọ pe, ko si ọrọ ko gbona ko tutu lori ibi ti oun fi si lori eto idibo ọdun 2019.
'Kìí ṣe gbogbo ohun tí dókìtà ni kí n má jẹ torí àìsàn jẹjẹrẹ ni mo tẹ̀lé' Wo àwọn ọtí ẹlẹ́rìndòdò tó ń fa àrùn jẹjẹrẹ.
Abdulazeez Sanni to jẹ ọmọ Imaamu ati Adamson Bamidele pẹlu Adam Jelili ti wọn jigbe leti bọda ipinlẹ Ogun ati ipinlẹ Eko ni wọn ti pada sọdọ awọn ẹbi wọn bayii.
Ó tó bí ọjọ́ mẹjọ lẹ́yìn tí ọ̀rọ̀ yìí ṣẹlẹ̀, Jesu mú Peteru, Johanu ati Jakọbu lọ sí orí òkè kan láti gbadura.
Ninu iwe yi, o ni ohun fẹ ki ile ẹjọ kotẹmilọrun fọwọ rọ idajọ ile ẹjọ giga to ni ohun ko yẹ ni ẹni to n du ipo Gomina.
Mo rí Ọ̀dọ́ Aguntan náà nígbà tí ó ń tú ọ̀kan ninu àwọn èdìdì meje náà.
A gbọdọ jẹ́ olóòtọ́ kí a sì yẹra fún ohun ti a kò mọ̀, iroyin kùbá kùgbé.
ati kíndìnrín rẹ̀ mejeeji, pẹlu ọ̀rá tí ó bo ibi ìbàdí ati ẹ̀dọ̀ rẹ̀ 
Wọn kuro ni papakọ ofurufu Nnamdi Azikiwe , Abuja lọ si India fun itọju ara , pẹlu awọn ọtẹlẹmuyẹ ati ẹbi rẹ diẹ.
Ẹni tí à ń sọ̀rọ̀ rẹ̀ yìí wá láti inú ẹ̀yà mìíràn.
Atiku: Igun olùjẹ́jọ́ gan kò fèsì sí àṣìṣe ìṣirò tí ẹlẹ́rìí kan mẹ́nubà pé INEC ṣe
Jẹ́ kí inú rẹ máa dùn ninu OLUWA;yóo sì fún ọ ní ohun tí ọkàn rẹ ń fẹ́.
títí n óo fi sọ àwọn ọ̀tá rẹ di tìmùtìmù ìtìsẹ̀ rẹ.
Ọmọ yìí ni mò ń tọrọ lọ́wọ́ OLUWA, ó sì fún mi ní ohun tí mo bèèrè lọ́wọ́ rẹ̀.
Ilé Aṣòfin Àgbà fòǹtẹ̀ lu N30,000 owó oṣù òṣìṣẹ́ A gba ìwé ìpẹ̀jọ́ ₦200m lọdọ mọlẹbi Sugar - UCH Ìjì líle mú ẹ̀mí èèyàn 1000 lọ, odidi ìlú kan bàjẹ́ Akoroyin BBC, Nadir Djennad jábọ̀ pé, ìtumọ̀ ìdájọ́ tí wọn dá fún gbájugbaju olorin ọmọ bibi Congo ni pe, yóò kóju àtimọ́le ní to ba tún lu òfin.
Aje bu igba jẹ daada lọdọ tirẹ pẹlu bi owo rẹ ṣe tẹ wọn si lati biliọnu maarun le die to wa tẹlẹ lọdun to kọja si biliọnu mẹsan lọdun yii.
O ni ko si ohun to wa ninu Cross-over night"" ju kí eeyan fi ọna ara rẹ le Ọlọrun lọwọ ninu gbadura lọ."
Nípa ojurere rẹ, OLUWA,o ti fi ìdí mi múlẹ̀ bí òkè ńlá;ṣugbọn nígbà tí o fi ojú pamọ́ fún mi,ìdààmú dé bá mi.
Oxford ni gẹ́gẹ́ bi Chimamanda ṣe sọ, ìgbàgbọ́ wà pé yóò fi iyọ si èdè Gẹ̀ẹ́sí gẹ́gẹ́ bi àwọn ṣe n koju mọ sísọ èdè gẹ̀ẹ́si àye òde òní.
“Ẹ kò gbọdọ̀ bọ ọmọ ẹran ninu omi ọmú ìyá rẹ̀.
A máa gbé ẹni tí ó bá fẹ́ ga, a sì máa rẹ ẹni tí ó bá wù ú sílẹ̀.
''Loni, awọn Yoruba a ma lo ''Igbo'' ninu orukọ awọn ilu wọn ti eleyi si jẹ atọka pe ọrọ na jẹ ayalo lati igba ti awọn iran Igbo wa ni ile Ifẹ'' Apẹrẹ kan ti a ri fun alaye to sọ yi ti Ọọni na fidi rẹ mulẹ ni orukọ ilu Olugbo ti olori rẹ́ si n jẹ Akarigbo.
Kaakiri Naijiria si ni iwọde yii ti ṣe idiwọ fun lilọ bíbọ ọkọ ati ero, to si tun mu ki ọrọ aje dẹnu kọlẹ pẹlu.
Ìgbà mélòó ni darandaran ti kọlu wàá?
Bayii Bashir Umar to jẹ Air Craft man ti fo ipele meji (Lance Coporal) bọ si ipo Coporal ni eyi to le gbaa to ọdun meje lẹnu iṣẹ ologun ko to de tẹlẹ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Jose Mourinho: Ayélujára ń hó yaya lórí ọ̀rọ̀ Mourinho pẹ̀lú Arsenal 31 Ọ̀wàrà 2019 Oríṣun àwòrán, Twitter/Express Sport Yoruba bọ wọn ni bi ohun ti a n ba n jẹ ba tan, ohun ti a kii jẹ naa lo ku.
O ni oun gbero pe wọn lo ọna ipa lo nọmba oun ni oun si fura si ijọba orilẹede Senegal.
4 Nítorí ọ̀pọ̀lọpọ̀ ìgbà ni ìwọ ti fẹ́ mọ̀ lati ọ̀dọ̀ mi èyíinì tí yíó ní iye lórí jùlọ sí ọ.
Aare Buhari ni: “Mo fe gboriyin fun Gomina Simon Lalong  ipinle Plateau fun ise rere to n se lati je ki alaafia joba ki isokan awon eniyan ipinel yii tubo jinle sii.
Wọ́n gba ẹnu ọ̀nà tí ó wà láàrin àwọn odi meji tí ó wà lẹ́gbẹ̀ẹ́ ọgbà ọba, bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé àwọn ará Kalidea yí ìlú náà po, wọ́n bá dorí kọ apá ọ̀nà àfonífojì odò Jọdani.
Kọmiṣọnna fun eto ẹkọ naa wa fikun wi pe awọn n ṣe atunṣe awọn ileewe ti ojo arọrọda naa bajẹ ni igbaradi fun awọn akẹkọọ to fẹ wọle pada si ẹnu ẹkọ wọn.
Kete ti Dele Giwa ṣi apo iwe yii ni ado oloro bu gbamu ti o si gbina jẹ.
Lọjọ Aje tii ṣe ọjọ ọdun Ajinde to kọja ni iroyin gbode pe ọwọ tẹ afunrasi naa, Deji Adenuga labẹ afara lẹba ibudoko ni ilu Ijebu Ode.
’ Lóòótọ́ sì ni, ibẹ̀ gan-an ni wọ́n tií rí ìtumọ̀ ọ̀rọ̀.
Ní ọjọ́ keje oṣù karun-un ọdún kọkandinlogun ìjọba Nebukadinesari, ọba Babiloni, Nebusaradani, tí ń ṣiṣẹ́ fún ọba Babiloni, tí ó sì tún jẹ́ olórí àwọn tí ń ṣọ́ Babiloni wá sí Jerusalẹmu.
Ìgbà tí ó ṣe, àwọn mẹ́tẹ́ẹ̀ta padà dé oríta.
Ìwà ni ìfẹ́, ẹ ti fi ìwà yín gbin èso ìfẹ́ sí inú mi, èso náà hù, ó ti ní ẹ̀ka, ó ti ní ewé, o sì ti ní gbòǹgbò, ó gbalẹ̀ kankan nínú mi tó bẹ́ẹ̀ tí n kò lè mu ọkàn kúrò lára yín mọ́.
Wọn wo bi arun naa ṣe kọkọ tankalẹ laarin aadọta ilu lagbaye ni eyi ti wọn ni o tete tankalẹ lawọn ibi to tutu ju ibi to gbona lọ.
Egbe oselu ti o wa lori alefa All Peoples’ Congress (APC) ti mu minisita fun oro ile okere teleri, Samura Kamara gege bi oludije labe asia egbe oselu naa, nigba ti egbe oselu alatako kan gboogi Sierra Leone Peoples’ Party (SLPP) mu olori  ijoba ologun teleri, Julius Maado Bio gege bi oludije labe asia egbe oselu naa, eni ti o fidi remi fun Bai Koroma ninu eto idibo ti o koja.
Àwọn ọmọ ogun rẹ̀ kó ara wọn jọ,wọ́n dó tì mí,wọ́n sì pa àgọ́ tiwọn yí àgọ́ mi ká.
Five G: Ìjọba àpapọ̀, ẹ so ifilọlẹ ẹ̀rọ alatagba 5G rọ na
Yoruba wo ló fẹ́ gbé Oduduwa Republic tẹ́ n pariwo - Lizzy Anjorin Ohun tójú àwọn èèyàn tún rí tí wọ́n figbé ENDSARS bọnu Adìyẹ́ jẹ̀fun ara wọn!
Erin wọ̀lú, ó pa ènìyàn méjì Ọ̀bọ lé àwọn ènìyàn kúrò nílè Kiniun pa olusọ ọgba ẹranko Ijọba Ondo n wa ọdẹ aperin Ẹran dida lalẹ ati ibọn gbigbe deewọ ni Edo Ọpọlọpọ awọn eniyan ni wọn gbiyanju lati wa ẹran ara rẹ to ku ki wọn to ri egungun agbari ọkunrin naa ati ṣokoto to wọ lọjọ Alamisi Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Jawahir Roble:Hijab tí mò n lò kó jẹ́ kọ́kọ́ jẹ́ ìyàlẹ́nu fún àwọn agbábọ́ọ̀lù mi Alakoso igbo igbafẹ naa ṣapejuwe iṣẹlẹ ọhun pé o bani ninujẹ gidi ni ati pe ọpọ igba ni awọn maa n kilọ fawọn ero pé igbo naa lewu fun ẹni ti ko ba gbọn ninu gbọn lode.
Latori ọmọ bibi inu Oba Olayode, to fi mọ gbogbo mọlẹbi lo tan imọlẹ si ẹdun ọkan wọn nipa bi Oba yii ṣe waja.
Oríṣun àwòrán, Funke Oshonaike Ni ọmọ ọdun mẹrinla ni Oshonaike ti bẹrẹ si ni gba tẹniisi ori tabili, lẹyin ọdun meji si igba naa ni o lọ ṣoju Naijiria ninu idije All Africa Games lọdun 1991.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Waste to Wealth: Ẹ̀gbin tìrẹ ni èròjà táwọn èèyàn míràn fi n ṣiṣẹ́ ajé, okoòwò ńlá ni Ohun ti eleti tumọ si ni pe, orileede Ireland ko ni si lara awọn ilẹ yi nitori pe ko si lara awọn orileede ibode Schengen mẹrindinlọgbọn to wa.
Gbajugbaja osere Hollywood, John Boyega ti setan lati dowopo pelu Nollywood ki idagbasoke le ba eka ere sinima.
Bakan naa lo fikun pe o le ni eniyan marundinlọgọfa lo wa ni ahamọ ni ile iwosan to n tọju arun Coronavirus.
Ẹ má fi burúkú gbẹ̀san burúkú, tabi kí ẹ fi àbùkù kan ẹni tí ó bá fi àbùkù kàn yín.
Níkẹyìn, àwọn tí wọ́n wà lẹ́yìn Omiri ṣẹgun àwọn tí wọ́n wà lẹ́yìn Tibini, ọmọ Ginati.
Àwọn orílẹ̀-èdè yóo rí ìdáláre rẹ,gbogbo ọba ni yóo rí ògo rẹ;orúkọ tuntun, tí OLUWA fúnra rẹ̀ yóo sọ ọ́,ni a óo máa pè ọ́.
Àwọn ọmọ Lefi yóo yí ọba ká láti ṣọ́ ọ, olukuluku yóo mú ohun ìjà rẹ̀ lọ́wọ́, wọ́n gbọdọ̀ wà pẹlu ọba níbikíbi tí ó bá ń lọ.
ni gbogbo ìgbà tí àwọn alásẹ bẹ ̀ rẹ ̀ sí fi ara mọ ́ pípa òwò ẹrú rẹ ́ díẹ ̀ díẹ ̀ , luiz gama kò fi ar amọ ́ èyí , ó ń jà fitafita wí pé kí òwò ẹrú parẹ ́ káíkíá ni .
0 87 Orilẹede Dominican 0 0.
3 564200 Orilẹede Romania 12320 63.
Bakan naa ni Ijọba kede pe oun yoo pin owó àti oúnjẹ fun awọn alainiláwùjọ ni eyi ti wọn ni o wa fun miliọnu mẹta aabọ idile.
Kò gbọdọ̀ fi ohunkohun dípò rẹ̀, tabi kí ó pààrọ̀ rẹ̀.
Ni ọdun 2017, Arabinrin Oge Maduagwu gbe ajọ kan kalẹ ti yoo fi opin si idẹyẹsi ni ni agbegbe naa, eleyii ti o pe orukọ rẹ ni 'Eradication of Traditional and Cultural Stigmatisation in our Society (Ifetacsios).
Ibudo to wa di ayawaawo nilu Abuja bayii lo jẹ ibudo ti wọn ti n wa kusa okuta tẹlẹ.
Èmi ati gbogbo àwọn eniyan tí wọ́n wà pẹlu mi nìkan ni a óo wọ ìlú náà.
Nengi Oríṣun àwòrán, BIG BROTHER NAIJA Pupọ ninu awọn idije to waye lori eto naa ni Nengi ti jẹ ẹbun.
Ẹgbẹ́ Shiite lẹgbẹ́ tó kéré jù ní orílẹ̀èdè Nàìjíríà sùgbọ́n se ní wọ́n ń pọ̀ síi Ẹgbẹ́ mùsùlùmí lórílẹ́èdè Nàìjíríà (IMN) tí wọ́n dá sílẹ̀ lọ́dún 1980s ni ẹgbẹ́ Shiite gangan tí Sheikh Zakzaky ń darí Wọ́n dá ní àwọn ilé ìwé àti ilé ìwòsàn ti wọn ní àwọn apá àríwá kọ̀ọ̀kan Wọ́n ní ìtàn ìkọlù pẹ̀lú àwọn òsìsẹ́ aláàbò Ẹgbẹ́ mùsùlùmí lórílẹ́èdè Nàìjíríà ní àtìlẹyìn ilú àwọn Shia, Iran ni bi tí àwọn ọmọ ẹgbẹ́ naa tì máa ń lọ kàwé níbẹ̀ Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ sí: Wọ́n jí ọmọ Germany gbé ní Nàìjíríà Darandaran pa ọlọ́pàá 4 ní Benue Mo sọ̀rọ̀ tako ọkọ mi torí òtítọ́ - aya Bùhárí Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Josẹfu sọ ọmọ rẹ̀ kinni ní Manase, ó ní, “Ọlọ́run ti mú mi gbàgbé gbogbo ìnira mi ati ilé baba mi.
" Akeugbagold wá dúpẹ́ lọ́wọ́ gbogbo aráàlú fún àdúrà àti aduroti wọn láti ìgbà tí ìṣẹ̀lẹ̀ náà tí wáyé, tó sì tún ń rọ wọn láti túbọ̀ máa bá òun bẹ àwọn ajọmọgbe ná Coronavirus: Àwọn ohun tí a kò tíì mọ̀ nípa àrùn Covid-19 Kí lo mọ̀ nípa fẹntilétọ̀, ohun èlò aṣèrànwọ́ èémí Ṣé òògùn Chloroquine lè dènà ààrùn Coronavirus bí?
Aarẹ Donald Trump sọ wipe Naijiria ti ra ọkọ ofurufu mejila lọwọ Amẹrika lati lee mu eto aabo gbooro lorilẹede Niajiria.
Wọ́n dó ti ìlú Samaria, wọ́n sì bá a jagun.
Ìyá Alájé: O wá, èló lẹ fẹ́
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Taiwo Akinkunmi, ọmọ Ibadan tó ya àsìá Nàíjíríà Ìtàn tó wà nídi òwe ‘Sebótimọ Ẹlẹ́wà Sàpọ́n’ Ṣẹ gbọ́ nípa Alájọ Ṣómólú, tó ta mọ́tò ra kẹ̀kẹ́?
Wo ìròyìn tuntun tó tún jáde laááàfin Oòduà nípa Àrẹ̀mọ tuntun Ọọ̀ni Ile Ifẹ̀ Èmi ni mo fẹ́ ṣíwájú ìwọ́de ọ̀dọ̀ tí yóò tún wáyé-Oluwo Amotekun gbàràdá ní ìpínlẹ̀ Oyo Iku gbajumọ Ginimbi mu ki Davido pahun da,o ni asan nile aye jẹ Wọn ni ọta ti wọn yin kii ṣe eyii to le gbẹmi eeyan ati pe inu afẹfẹ lasan ni awọn yin ibọn naa si.
Diẹ lara awọn ipa ti Ọgbẹni Tunde Bello mẹnu ba gẹgẹ bi ipa ti eto isuna naa yoo ko ni: Awọn nkan amayedẹrun ati amuludun bii ọna, ile iwe ati bẹẹ bẹẹ lọ fun awọn ara ipinlẹ Eko eyi ti yoo pese iṣẹ sii fun awọn eniyan.
Kaakiri oju opo ayelujara ni iroyin yii ti gbode, ti awọn eeyan kan si ti n fi ọrọ ikini ranṣẹ si Ọọni ati iyawo rẹ, Olori Naomi Silekunola Ogunwusi.
Idije ohun ni ireti wa tele pe, yoo bere ninu osu keta odun yii, sugbon won sun siwaju latari afikun un awon iko agbaboolu miiran ti o darapo mo idije ohun.
Kí òkun ati ohun gbogbo tó wà ninu rẹ̀ hó yèè,kí pápá oko búsáyọ̀, ati gbogbo ẹ̀dá tó wà ninu rẹ̀.
 lílà tí Ọ ̀ rúnmìlà la inú ẹja lo ba agbára rẹ ̀ nínú ẹja .
Kíákíá mo darapọ̀ mọ́n àwọn èrò níbẹ̀, a bẹ̀rẹ̀ sí í gun àwọn pẹ̀tẹ́ẹ̀sì lọ́kọ̀kan láti àbáwọlé ilé náà títí dé yàrá ńlá kan.
Ẹnìkẹta ní, ‘Mo ṣẹ̀ṣẹ̀ gbé iyawo ni, nítorí náà n kò lè wá.
Olayanju ni kii ṣe ipinlẹ Oyo nikan ni eyi ti n waye sugbọn ilana igbanisisẹ kan ṣoṣo ni gbogbo ipinlẹ to wa nilẹ Yoruba n lo.
Bi o tilẹ jẹ pe Ọgbẹni Quinn wa loke okun ṣugbọn EFCC ti fi Ọgbẹni Nolan satimole titi di igba ti wọn yoo gba iwe beeli rẹ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Russia Covid 19 Vaccine: Nàìjíríà ṣetán àjọṣepọ̀ pẹ̀lú Russia lórí ìpèsè abẹ́rẹ́ àjẹsára 4 Owewe 2020 Oríṣun àwòrán, @Fmohnigeria Ijọba orile-ede Naijiria ti fifẹ han lati ṣe amulo abẹrẹ ajẹsara Sputnik V ti orile-ede Russia n ṣeto lati koju arun Covid -19.
Wọn si gbọdọ ni iwe ẹri owo ori ti wọn san fun ọdun mẹta, ati ilẹ̀ tabi ile to j'oju nigbese.
lati ni ẹmi ifẹ, ifarada ati ifaraji, eleyii ti a n wo mọ Jesu Kristi lara Aṣofin
Bí igi kò bá léṣo lórí, ayé kì í ju òkò fún un!
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Imperial Majesty ni Olubadadan, Royal Majesty làwa, òfin sì tẹ̀lé e - Ọtun Olubadan Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Ọmọ Nàìjíríà kan tó lùgbàdì àrùn coronavirus ti di olóògbé Òní ni ìgbẹ́jọ́ Oyo-Ita àti EFCC nílé ẹjọ́ gíga Abuja Èèyàn márùn ún míì tún ti lùgbàdì àrùn coronavirus ní Nàìjíríà- NCDC Ọmọ ilẹ̀ Italy tó kó Coronavirus wọ Naijiria kò ní àrùn náà mọ́ Bẹẹ ni wọn ke si awọn eniyan lati sa ipa wọn lati fọ ọwọ wọn ni igba de igba.
 wọ ́ n wá dọ ́ gbọ ́ n , wọ ́ n dáṣọ ̣ eégún .
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Celestine fa adá yọ, ó sì gé orí ọmọ mi méjì' Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Aisan yii kii ṣe eyi to lee la ẹmi lọ, o kan jẹ eyi to maan da eeyan lagara ni."
Wọn wipe asiko ti to fun awọn ọdọ lati fa enikan lara wọn kale fun ipo adari ni Naijiria, wọn si wipe awọn agbalagba bi ti wọn yoo gbaruku ti iru ẹni bee leyin.
Saulu ati àwọn eniyan rẹ̀ pada sílé, Dafidi ati àwọn eniyan rẹ̀ sì pada sí ibi tí wọ́n sá pamọ́ sí.
Dogara: Ohunkóhun kò gbọdọ̀ ṣe Dino Melaye
Oríṣun àwòrán, Wikipedia Fun iyalẹnu, ọpọ awọn orukọ ti Fagunwa mẹnuba ninu iwe rẹ lo wa ninu Igbo Olodumare ta n sọrọ rẹ yii bi o tilẹ jẹ pe awọn ohun aramọnda bii iwin, idan, ati ọpọ adiitu ti poora nibẹ.
Naijiria (Independent National Electoral Commission ,INEC) ti salaye bi eto ibo
“Gbọ́ ohun tí èmi Jẹfuta wí, Israẹli kò gba ilẹ̀ kankan lọ́wọ́ àwọn ará Moabu tabi lọ́wọ́ àwọn ará Amoni.
Oríṣun àwòrán, @aishambuhari Àkọlé àwòrán, Awọn oṣere tiatia obinrin naa wa nibi ayẹyẹ naa BBC News, Yorùbá Ìdí tí ẹ fi le è nígbàagbọ́ nínú ìròyìn BBC Ìlànà Lílò Nípa BBC Òfin Àṣírí Cookies Kàn sí.
Won ṣalaye fun akọroyin BBC pe awọn ti yọ oku mọkanla bayii ninu ile alaja mẹta ọhun.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Mohamed Hussein Tantawi ni wọn gba ni igi lẹyin ọgba fun ọpọlọpọ Aarẹ Ofin naa lo ni pe ki wọn fi oye 'Field Marshal' da ààrẹ ilẹ naa, Idrissa Deby Itno lọla lati ipo ọgagun agba julọ, iyẹn 'General'.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Yollywood: Ẹ wo àwọn ohun tí ẹ kò mọ̀ nípa Mama Rainbow tó pé 77 lóniìí 16 Ọ̀wàrà 2019 Oríṣun àwòrán, MAMARAINBOWOFFICIAL Àkọlé àwòrán, Mama Rainbow pe 77 lonii Idowu Philips, ti apele rẹ n jẹ Mama Rainbow, tabi Iya Rainbow jẹ mọlumọọka oṣere tiatia Yoruba.
Òṣùmàrè wá fà kàlákìní lójú ọ̀run.
Aarẹ Buhari parọwa fun awọn ọdọ Naijiria lati farawe ọkunrin yii ki gbogbo wọn maa fi ootọ inu ṣe iṣẹ wọn bi o ti yẹ.
O ni oun tun kọọ lati fi ta awọn oluranlọwọ ji ki wọn le ṣe iranlọwọ to ye fawọn to sun mọ wọn.
awon oludari eka ni,Mohammed Umar,Sunkanmi Akinbohun,Ubong Sunday, Ibrahim Goni
Lara awọn oloṣelu ti wọn ti jajabọ lọgba ẹwọn, amọ ti wọn si n koju ẹsun jẹgudujẹra miran ni Sẹnetọ to n soju ipinlẹ Abia, Uzor Kalu ati agbẹnusọ ẹgbẹ oṣelu PDP, Olisa Metuh.
Ati pe ọna kan ṣoṣo to le mu ki alaafia jọba lawujọ ni ki awọn to n gbe ninu rẹ ni ọkan lati gbe pọ ni alaafia, isọkan, ati yiyanju aawọ ni ilana ofin.
Naboti dáhùn pé, “Ọwọ́ àwọn baba ńlá mi ni mo ti jogún ọgbà àjàrà yìí; OLUWA má jẹ́ kí n rí ohun tí n óo fi gbé e fún ọ.
Àwọn ọba Filistini bá kó awọ tí wọ́n fi ń ṣe ọrun, titun, meje, tí kò tíì gbẹ, fún Delila, ó sì fi so Samsoni.
Ni kete ti o farahan nile ẹjọ ni wọn ti gbe e fii lọ sinu ile lai jẹ ko foju kan awọn eniyan rara.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ekiti APC: Kíkọ ọjà tàbí afárá sí Ekiti kọ́ ni ìdàgbàsókè 16 Ọ̀wàrà 2019 Oríṣun àwòrán, Facebook Àkọlé àwòrán, Kayode Fayemi Ijọba Kayode Fayemi ni ipinlẹ Ekiti pe ọdun kan ni ọjọru ọsẹ yii ṣugbọn ẹgbẹ alatako ni ko si ipe fun ajọyọ.
Bí Edomu bá sọ pé, “Ìlú wa ti di òkítì àlàpà, ṣugbọn a óo tún un kọ́.
"Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Nikesuliat: Ọ̀dọ́mọdébìnrin akéwì tó n fi ẹ̀ṣà kìlọ̀ ìwá lásìkò yìí O ni ""Ohun to yẹ ki ijọba ṣe ni ko fi iya to tọ jẹ gbogbo ile ijọsin to kọti ikun si aṣẹ ọun, nitori ko si iyatọ laarin wọn ati awọn agbesumọmi to n gbẹmi awọn eeyan."
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Damilọla Ajayi: Ọ̀dá owó ló ṣún mi dé ìdí lílo ìyarun bíi fèrè Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Damilọla Ajayi: Ọ̀dá owó ló ṣún mi dé ìdí lílo ìyarun bíi fèrè 20 Èrèlè 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 13 Èbibi 2020 Damilọla Ajayi, to n se ohun ara pẹlu lilo iyarun lati fi fọn fere, salaye fun BBC Yoruba pe, orin Fẹla Anikulapo Kuti lo fun oun niwuri lati maa fọn fere.
FIFA: A fi òfin de ẹ̀yin eléré ìdárayá mẹ́ta wọ̀nyí láti ilẹ̀ Adúláwọ̀ títí ayé
2 Kíyèsíi, mo ti fi hàn fún ọ, nípa Ẹ̀mí mi nínú ọ̀pọ̀lọpọ̀ àpẹrẹ, pé awọn ohun tí ìwọ ti kọ jẹ́ òtítọ́; nítorínáà ìwọ mọ̀ pé wọ́n jẹ́ òtítọ́.
Bẹ́ẹ̀ ni ó ṣe darí àwọn eniyan rẹ̀,kí ó lè gba ògo fún orúkọ rẹ̀.
"Ọrọ naa di yanpọnyanrin fun ọpọ ọdun, ti ori ayelujara si n gbona fun aawọ wọn ọhun.
o se nile akede Naijiria , Voice of Nigeria, lojo Isegun niluu Abuja .
Oríṣun àwòrán, OTHER Ṣugbọn ọrọ iṣẹlẹ ijinigbe to waye ni adugbo Soka, nilu Ibadan lo jẹ ki okiki Abiola Ebila tan nilu Ibadan nitori ọrẹ rẹ Ọlọkada to sọnu, to n wa kiri lo gbe e de agbegbe Soka, níbi ti akara ti tu sepo nipa iṣẹlẹ ijinigbe to n waye nibẹ.
Sáájú ní ó ti gbé si orí àtẹjísẹ́ instagram rẹ pé  ọmọ ọlọjọ́ ìbí, Jesu mo dúpẹ́ fun ifẹ́ rẹ."
Ìbànújẹ́ ńlá dé bá ọba, ó bá gun òkè lọ sinu yàrá tí ó wà lókè ẹnu ọ̀nà ibodè, ó sì sọkún.
 Idi niyi ti mo se wa lati wa ri egbon mi fun imoran.
Ọpọlọpọ ọkọ to n jade kuro ni ilu Eko ni sunkẹrẹ fakẹrẹ ọkọ ti fa wahala fun.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ọlọ́pàá ilẹ̀ Gẹ̀ẹ́sì ti sanwó ìtaràn £2500 fún oníwàásù ọmọ Nàìjíríà tí wọn mú lọnà àìtọ́ 28 Agẹmo 2019 Oríṣun àwòrán, Christian Concern Àkọlé àwòrán, Paitọ Oluwole Ilesanmi yoo fi iwe ẹhonu sọwọ si ileeṣẹ ijọba eleyi ti awọn eeyan fọwọsi lati le daabo bo awọn to n ṣe iwaasu nita gbangba Oniwaasu Kristẹni kan ni awọn ọlọpaa ilẹ Gẹẹsi ko panpẹ si lọwọ ti wọn si fipa gba bibeli lọwọ rẹ.
Ipade naa yoo jẹ eyi ti wọn yoo ti ṣabewo si Eko Atlantic City ni Victoria Island.
Bẹ́ẹ̀ ni ẹ rí sí mi nisinsinyii.
Awakọ̀ agbókùú, ọlọ́pàá, ológun, oníròyìn ló máa ń kọ́kọ́ dìbò ní Ghana, bó ṣe ń lọ rèé Oba Akinruntan ni iṣeeṣe awọn lọbalọba lorilẹede ko di atẹmẹrẹ nitori eto aabo to dẹnukọlẹ lorilẹede Naijiria.
Ajepákó nì kan ló lè mon.
"Mò máa ń fọ àwọ̀tẹ́lẹ̀ ìyá mi, ni ìṣe àwọn obìnrin fi wù mí - Bobrisky Ogundipe gbé fásitì Unilag ló sí iléẹjọ́ nítórí wọn yọ́ ní ipò VC Shina ni: "" Wọn n pa awọn eeyan miran ti ko mọwọ-mẹsẹ ninu iwa idigunjale, wọn ro pe Shina Rambo ni awọn n pa, koda, babalawo mẹsan to ṣe oogun naa fun mi, ọwọ ara mi ni mo fi pa wọn, ki wọn ma baa tu asiri mi."
ori re to Milioni Merin Naira, oko
N óo sọ àwọn ohun tí ó ti wà ní àṣírí láti ìpilẹ̀ṣẹ̀ ayé.
Ẹ bá Jerusalẹmu yọ̀, kí inú yín dùn nítorí rẹ̀,gbogbo ẹ̀yin tí ẹ fẹ́ràn rẹ̀,ẹ bá a yọ̀ ṣẹ̀ṣẹ̀,gbogbo ẹ̀yin tí ẹ̀ ń ṣọ̀fọ̀ nítorí rẹ̀.
"Ọ̀gá àgbà Ọlọ́pàá wọ́ ọ̀rọ̀ Aisha Buhari tì sẹ́gbẹ̀ẹ́ kan Alhaja Kudirat Abiola: Odindi géńdé ọkunrin mẹ́fà ni wọ́n gbé iṣẹ́ ikú rẹ̀ fún Ìròyìn nípa ìyàwó túntún fún ọkọ mi kò mì mí lọ́kàn rárá-Aisha Buhari Ẹ̀wọ̀n gbére ni fún ẹnikẹ́ni tó bá fipá bánilòpọ̀ ní ìpínlẹ̀ Ọ̀ṣun ""Awọn ẹṣọ aarẹ atawọn ti ẹnu ibode gba ẹkọ to yẹ nipa amulo ohun elo ijagun ati bi wọn ṣe n lo o bi wọn ba si ṣe aṣiṣe, awọn adari wọn mọ ohun to yẹ ki wọn ṣe."
Ní ayé àtijó, ìgbín àti Ìjàpá jọ ń ṣe ọ̀rẹ́.
agbegbe Adara silẹ yoo tun jẹ ki eto alaafia  tun tubọ fẹsẹ mulẹ si ni agbegbe naa.
'Rọ́bọ́ọ̀tì ni yóò máa yẹ̀ yìn wò kẹ́ẹ tó rìnrìnàjò òfurufú ní Nàìjíríà' Peter Okoye, ìyàwó àti ọmọ lùgbàdì ààrùn Coronavirus Atẹjade naa sọ pe gbogbo igbiyanju àti igbesẹ oun lati ṣe atilẹyin fun idile Ajimobi, lasiko to fi wa ni i dubulẹ aisan lo jasi pabo.
Bakan ni omiran ṣẹlẹ si ẹnikan to ni ijamba ọkọ, ti wọn si sọ pe o ti ku, ko to di pe wọn rii to n mi l'ọjọ keji.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Nollywood :Àwọn òṣèré Yorùbá márùn ún tí kò sí lójú ìwòran mọ́ ṣùgbọ́n tí wọ́n wà láyé.
osise otelemuye bale si papako ofurufu laago marun un irole, niluu Jalingo lojobo(Thursday)Ogbeni Obiezu, jabo fun awon akoroyin pe, awon wa lati ton imole si ohun ti o sokunkun nidii isekupa ohun.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìfipábánilòpọ̀: ọlọ́pàá ní àáfà aríran yóò jìyà ẹ̀sẹ̀ rẹ̀ 17 Agẹmo 2018 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 18 Agẹmo 2018 Oríṣun àwòrán, Chike Godwin Obi/Facebook Àkọlé àwòrán, Àwọn ọlọ́pàá ìpínlẹ̀ Eko sọ pé àáfà tó fipá bá akẹ́kọ̀ọ́bìnrin lòpọ̀ ní ìlú Ikorodu jẹ́wọ́ pé òun jẹ̀bi ẹ̀sùn náà Ile-iṣẹ Ọlọpaa ipinlẹ Eko ti sọ pe Aafa aríran Mustapha Hammed to fipa ba akẹkọbinrin Ile-Ekọ giga olukọni agba ni Akoka, Eko lo pọ yoo jiya ẹṣẹ rẹ.
O kilọ wiwa òkìkí ti àwọn àsáwò inu ere tiata kọọkan n wa lasiko yii fun wọn.
Kí wọn tó pè mí, n óo ti dá wọn lóhùn,kí wọn tó sọ̀rọ̀ tán, n óo ti gbọ́ ohun tí wọ́n fẹ́ sọ.
Wọn ni awọn oṣiṣẹ ẹnu bode South Africa lo da wọn duro ti wọn ṣẹṣẹ\\tun n bẹrẹ ayẹwo tuntutn fun wọn.
Ọlọrun, mímọ́ ni ọ̀nà rẹ;oriṣa wo ni ó tó Ọlọrun wa?
Gẹgẹ bi o ṣe ṣalaye, lasiko ti awọn aṣoju ileeṣẹ ibaraẹnisọrọ NCC wa ṣe abẹwo si oun ni ọfiisi gomina to wa ni Agodi nilu Ibadan loṣu Kẹjọ ọdun 2019 ni wọn jiroro lori agbekalẹ nọmba naa.
Gẹgẹ bi àṣà Yorùbá, ibi ti ẹbi iyàwó bá ngbé ni ẹbi ọkọ yio lọ lati ṣe igbéyàwó.
Gègé ni kí ẹ ṣẹ́ kí ẹ pín ilẹ̀ náà láàrin àwọn ẹ̀yà tí ó pọ̀ ati àwọn ẹ̀yà kéékèèké.
Ìlú tí ó bèèrè fún ni Timnati Sera ní agbègbè olókè ti Efuraimu, ó tún ìlú náà kọ́, ó sì ń gbé ibẹ̀.
ọlọpaa  ni ipinle Katsina, Gambo Isa ti
Gege bi akowe agba ajo CAF, Amr Fahmy.
Ẹ dìde kí ẹ tẹ àwọn ọ̀tá yín mọ́lẹ̀, ẹ̀yin ará Jerusalẹmu!
Ó sì kó gbogbo àwọn ọmọ ogun rẹ̀ yòókù sábẹ́ ọ̀gágun Abiṣai, tí ó jẹ́ arakunrin rẹ̀, Abiṣai bá fi olukuluku sí ipò rẹ̀, wọ́n dojú kọ àwọn ará Amoni.
Alhaja Kudirat Abiola ba ọpọlọpọ ileeṣẹ iroyin sọrọ kaakiri to si n pe fun itusilẹ ọkọ rẹ ati pe o n fi ẹsun kan ijọba pe wọn n run isuna idile oun.
"Lẹyin eyi, Funke tun ṣe agbejade sinima agbelewo to ṣi n han lọwọ lori ẹrọ amohunmaworan, ""Jennifer's Diary"", eyi jẹ bii amọle ere ""Jennifer""."
Nigeria border closure: Ìdí tí Ààrẹ Buhari kò ṣe tíì ṣí ibodè tó tì pa rèé
O sọ eyi di mimọ leyin ipade ti ẹgbẹ ṣe pelu ikọ̀ ijọba apapọ ni ileeṣe ijọba apapọ to n mojuto eto ẹkọ ni Naijiria, eyi to wa nilu Abuja.
" Oríṣun àwòrán, Instagram/oye4dc Ipinlẹ Kwara ni baba Owolewa ti wa, ti iya rẹ si jẹ ọmọ bibi ipinlẹ Oyo.
Ọ̀pọ̀ èèyàn bẹnu ẹ̀tẹ́ lu Mercy Aigbe lórí bó ṣe ki Adeniyi Johnson 'El-Zakzaky lè má láńfààní láti lọ gba ìtọ́jú mọ́ lókè òkun' Samson Siasia fèsì lórí FIFA tó fòfin dèé Lampard wọ gàu!
OLUWA ní, “Gbogbo ẹni tí òùngbẹ ń gbẹ,ẹ máa bọ̀ níbi tí omi wà;bí ẹ kò tilẹ̀ lówó lọ́wọ́,ẹ wá ra oúnjẹ kí ẹ sì jẹ.
Iroyin ni iṣẹlẹ naa da sunkẹrẹ-fakẹre ọkọ silẹ loju ọna naa nigba ti ina ọhun bẹrẹ si n jo.
Surrogate: Ibi táwọn kan ti fẹ́ yọ oyún, ni Judith ti bẹ̀ wọ́n fún pàsípàrọ̀ Wo iye owó tó wọlé fún ìjọba lórí COVID-19 àti bí wọ́n ṣe ná an Ẹ wo ọ̀nà tí ìjọba Nàìjíríà fẹ́ gbà san owó àwọn olùkọ́ iléèwé aládàni tí kò rówó oṣù gbà Ọkùnrin kan fipá bámi lòpọ̀ lọ́mọ ọdún mọ́kàndínlógún- Funke Oshonaike Minisita fun eto ẹkọ ni Niajiria, Mallam Adamu Adamu lo buwọlu iwe atẹjade naa.
eniyan to n gbe agbegbe naa lati tubo maa se atileyin fun ile-ise ologun lona
Woli Kasali ṣe ọpọlọpọ alaye to si ni kii ṣe wi pe oun mọmọ le iyawo oun jade bii kii ṣe wi pe oun fun ararẹ lo kẹru kuro nile.
NLC: Ìjọba ti gbà láti san owó oṣù mẹ́rin fáwọn òṣìṣẹ́ l'Ọ́ṣun
Ní àkókò náà, àṣẹ kan jáde láti ọ̀dọ̀ Kesari Augustu pé kí gbogbo ayé lọ kọ orúkọ wọn sinu ìwé ìjọba.
Oríṣun àwòrán, Reuters Àkọlé àwòrán, Ẹni akọkọ to pade agbebọn naa re ni Mọṣalaṣi Al Noor Daoudi Nadi Oun ni ẹni ti wọn kọkọ darukọ pe o faragbọta ninu iṣẹlẹ naa.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Tọkọ-tayà kọ ara wọn silẹ nitori Buhari nínú ìdìbò 2019 tó m bọ̀ 24 Sẹ́rẹ́ 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ko yẹ ki igbeyawo tuka nitori idibo 2019 Abdullahi ṣalaye fun BBC pé oun ti kọ iyawo oun silẹ lataari pe ó fe ki Buhari tun wọle ni 2019.
ní èrò tiwa , ìtàn yìí fara pẹ ́ òtítọ ́ ní àwọn ọ ̀ nà kan , ó sì jìnnà sí òtítọ ́ ní àwọn ọna mìíràn .
Ko ṣẹyin fọnran fidio ti Fani Kayode ti n bu pe ko yẹ ki o beere ibere agọ lọwọ ohun ṣe lawọn eeyan bẹnu atẹ lu Fani Kayode pe ko yẹ ko bu akọroyin naa to bẹ.
Ile igbimọ asofin Naijiria da ijiroro lori aabo duro
Níbo ni àwọn olórí yín wà, tí wọn yóo gbèjà yín?
24 Àti nísisìyí, kíyèsíi, ìwọ ti gba ẹ̀rí kan; nítorí bí èmi bá ti sọ àwọn ohun tí ènìyàn kankan kò mọ̀, ìwọ kò ha ti gba ẹ̀rí kan bí?
N óo mú wọn pada,nítorí àánú wọn ń ṣe mí,wọn yóo dàbí ẹni pé n kò kọ̀ wọ́n sílẹ̀ rí;nítorí èmi ni OLUWA Ọlọrun wọn,n óo sì gbọ́ ohùn ẹ̀bẹ̀ wọn.
Bi kò ri ẹni gba a, ó lè jẹ epo na a tàbi ki ẹni tó ni epo ri mú ni wéré.
O tun so pe “A n fowosowopo pelu Ajo Europe ati  awọn  ajọ miiran , pelu  awọn  amuleti wa lati koju isoro to n dojuko  awọn  ekun orilẹ ede  Afirika.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ọmọ 24 bá omi lọ Irú ẹ̀dá wo ni aṣòfin Bukola Saraki jẹ́?
Nígbà tí Jeremaya pada dé láti Tofeti, níbi tí OLUWA rán an lọ pé kí ó lọ sọ àsọtẹ́lẹ̀, ó dúró ní àgbàlá ilé OLUWA, ó sọ fún gbogbo àwọn tí wọ́n péjọ sibẹ pé, 
 ile na ni mosalasi ti won ko yika , mosalasi al haram .
Nítorí ìwọ, Ọlọrun, ti dán wa wò;o ti dán wa wò bíi fadaka tí a dà ninu iná.
Ẹ kò gbọdọ̀ jẹ ajá mọ́' Ajá dóòlà ọmọ tuntun tí ìyá rẹ̀ bò mọ́lẹ̀ láàyè Mary jẹ arugbo ẹni ọdun mẹrindinlọgọrin to n gbe ni Florida ni orilẹ-ede America.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù PDP: Ọ̀tẹ̀ tó pa wọ́n pọ̀ náà ló ń tu wọ́n ka 10 Èbibi 2018 Oríṣun àwòrán, @AbekeOlamide Àkọlé àwòrán, Mo sa ipá mi ni NIMC gẹ́gẹ́ bii ọmọ Nàìjíríà rere ṣùgbọ́n mo fẹ́ tẹ̀siwaju ninu ìran míràn Omọba Olagunsoye Oyinlola ti kọ̀wé fi ipò rẹ̀ silẹ̀ gẹ́gẹ́ bii alaga àjọ NIMC to ń ṣè káàdì ìdánimọ̀ ni Nàìjíríà, tó sì tún kúrò nínú ẹgbẹ́ òsèlú APC Oyinlọla kọwe ìfipòsílẹ̀ náà ránṣẹ́ sí Aarẹ Buhari lọjọ kẹsan an osù karùn-ún.
Agbẹjọ́rò ni n kò bá jẹ́, tí n kò bá bá bàbá mi ṣe tíátà - Sola Kosoko Alága méjì láàrín ọjọ́ kan, sinimá oríta láàrín àwọn adarí APC Ìdílé márùn-ún tó gbajúmọ̀ fún òwò ẹrú nílẹ̀ Yorùbá Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
sapejuwe orile-ede Naijiria gege bi orile-ede ti o tobi lopolopo.
- Ilé ẹjọ́ ìpínlẹ̀ Ondo Ẹ dá àwọn ẹ̀ṣọ́ aláàbò igbákejì gómìnà ìpínlẹ̀ Ondo padà ní kíá - ọ̀gá àgbà iléeṣẹ́ ọlọ́pàá Ògo ilẹ̀ Ibadan míì lọ, Pàràkòyí Olóyè Bode Akindele dágbére fáyé Òpin oṣù kaarun ni ayẹyẹ ọdún eégun máa ń bẹ̀rẹ̀ ní ìlú Ibadan sùgbọ́n ìjọba ti kéde pé kò ni sí ààyè fún ayẹyẹ eégún kankan láti wọde nílùú Ibadan lọ́dún yìí, èyí ni láti dẹ́kun ìpéjọpọ̀ elérò púpọ̀ tí ó si lé mú kí ààrùn coronavirus túbọ̀ tànkalẹ̀ síi.
Àwọn ọkọ̀ agbérò nlá nlá ni wọ́n máa nkó àwọn ẹ̀rọ gboùngboùn sí tí wọ́n a máa fi gbóùn àti orín sáfẹ́fẹ́ fún ìgbádùn gbogbo èrò.
ALGON: 35% la fẹ́ kíjọba àpapọ̀ máa pín bíi owónàá fún ìjọba ìbilẹ̀
” Àwọn eniyan náà bá pada lọ.
Ọba Alakinyẹle ṣalaye pe iwadii to rinlẹ gbọdọ waye o lati mọ awọn ọlọpaa to gbabọde lori iṣẹlẹ naa.
Independence Day Nigeria: Ogun abẹ́lé, Ikọ̀ Boko Haram, ìbò June 12 wà lára ìṣẹ̀lẹ̀ tó fẹ́ pín wa sí yẹ́lẹ-yẹ̀lẹ
Bakan naa ni wọn si ba ẹbi ati ara kẹdun lẹyin ti o dakẹ ni ile iwosan to ti n gba itọju arun Covid 19, ki ọlọjọ to de.
 fagunwa kọ ní ọdún 1938 .
Ṣùgbọ́n n kò tilẹ̀ ni èrò rárá pé ọkùnrin tí mo rí pẹ̀lú rẹ̀ nínú òṣùpá ni ó ń pè ni ẹ̀gbọ́n fún mi.
Lasiko ti eyi ba waye, yoo mu ko nira fun nnkan ọkunrin lati jade kuro loju ara obinrin, paapaa ti nnkan ọmọkunrin naa ba si le gbagidi sibẹ.
tẹlẹ, ti awọn kan si n fẹsun kan Ile Igbimọ Aṣofin naa pe awọn lo kọ
Ṣugbọn ẹni to ba wọ aṣọ ọmọ ogun lati fi tan ara ilu jẹ pe ologunn ni oun ti ko si ri bẹẹ, yoo lọ si ẹwọn oṣu mẹfa.
Àwọn alufaa gbé àpótí majẹmu OLUWA wá sí ààyè rẹ̀ ninu tẹmpili ní ibi mímọ́ jùlọ, wọ́n gbé e sí abẹ́ àwọn ìyẹ́ kerubu.
''Tí ẹ bá bi i ní ìbéèrè kan, ọ̀tọ̀ ni ìdáhùn tí yóò fún yín.
Ìkébé mi tóbí ju ohun tí mo lè dọwọ́ bò lọ, n kìí fí ṣakọ- Nkechi Blessing Kíni 'Ẹ̀lẹ̀ daddy' Olorì Abbey Adeyemi ṣe tí ojú òpó ayélujára Instagram rẹ̀ fi ń yeruku lálá?
'Ojú mi rí tóó, àwọn ìyàwó kìí ṣiṣẹ́, ọkọ àtàwa ọmọ-ọ̀dọ̀ laláṣekú lórílẹ̀èdè Oman' Kí ló le è mú kí ìlú kan ó já ọmọge mẹ́rin sí ìhòhò?
Ẹlomii wọn a maa ni iṣoro to le lasiko nkan oṣu wọn ni ti awọn obinrin.
Oríṣun àwòrán, @MBuhari Àkọlé àwòrán, Ipade ajọ isọkan awọn orilẹede Afrika, AU Ẹwẹ, nibi ipade apero ajọ isọkan awọn orilẹede ilẹ Afrika, awọn adari mejeeji ya gbogbo eniyan lẹnu pẹlu bi wọn se ki'ra wọn bi ọrẹ, wọn di mọra digba ti wọn si nsọrọ tẹrin tọyayaya bi ẹni wipe ko si aawọ kankan laarin awọn mejeeji ko to di wipe aarẹ tẹlẹri, Abdulsalam Abubakar naa dara pọ mọ wọn ninu ẹfẹ.
se jawe olubori gege bi aare orile ede Naijiria, ninu eto idibo to waye ni ọjọ kẹ́tàlélógún  osu keji, odun 2019.
Isọri keji awọn akẹkọọ naa ni yoo bẹrẹ ikẹkọọ ni aago mẹwa abọ aarọ, ti wọn yoo si pari ni aago kan ọsan.
 O tun le mu idagbasoke ba ikoroyin lori ako ati abo fun ilosiwaju ere idaraya lapapo.
Bi ẹ ba lọ si ẹka iṣẹ akanṣe, awọn ọmọ orilẹede China lo gba ibẹ."
Gẹgẹ bi iroyin to tẹwa lọwọ, iṣẹlẹ naa waye lagbegbe Nganzai ni nnkan bi ago mọkanla owurọ ọjọ Abamẹta.
Òní lònìí ń jẹ́ fún ìdìbò Brexit ni London Iyawo Dele Giwa, Funmilayo gẹgẹ bi Kayode ti ṣe sọ gbe akara fun wọn ti wọn si jijọ n ṣaroye nipa bi awọn ọtẹlẹmuye ti ṣe fọrọ wa Dele Giwa lẹnuwo ṣaaju ọjọ naa.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Wo fidio 'ẹwọn idẹra' ''Màá pàárọ̀ aṣọ rẹ̀, màá sì ṣe oúnjẹ rẹ̀ fun un.
Beckham: Èdè mẹ́sàn-án ni Beckham fi gbógun ti àrùn ibà
O benu ate lu egbe PDP wipe won lo d'ogbon lo fina bo'le l'Abia, won pale oko mo ati bee bee lo.
Bi awọn ẹgbẹ oṣiṣẹ ipinlẹ naa ṣe ni ìgbésẹ̀ naa ko daa to, lawọn to wa ni ipinlẹ miran ti n ni awọn ko lodi si.
Ó gba agbára lọ́wọ́ àwọn ẹ̀mí ojú ọ̀run: ati ìjọba ni, ati àwọn alágbára wọ̀n-ọn-nì; ó bọ́ wọn síhòòhò, ó fi wọ́n ṣẹ̀sín ní gbangba, nígbà tí ó ti ṣẹgun wọn lórí agbelebu.
kí ẹ má jẹ́ òpè, ṣugbọn kí ẹ fara wé àwọn tí wọ́n fi igbagbọ ati sùúrù jogún àwọn ìlérí Ọlọrun.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù NLC Strike update: Ìná ẹgbẹ́ òṣìṣẹ́ NLC ati ìjọba kò wọ̀ níbi ìpadé 17 Ọ̀wàrà 2019 Oríṣun àwòrán, @others Àkọlé àwòrán, NLC Strike update: Ìná ẹgbẹ́ òṣìṣẹ́ NLC ati ìjọba kò wọ̀ níbi ìpadé Lẹyin ipade fun ọpọlọpọ wakati ni ọjọru, ni awọn ẹgbẹ oṣiṣẹ ṣì fariga pe ìná ko nii wọ lasiko yii.
Bakan naa lo kede lati ẹnu agbẹjọro rẹ, Mike Ozekhome(SAN) pe ki Seyitan o san ọgọrun miliọnu Naira fun oun lati tu oun ninu.
tu yaaya lati dibo yii, o da mi lojuipe , emi  ni gomina Ajimobi yoo gbe ijoba fun ni ojo
Aworan igba ti Abdulfatah Yahaya Seriki Gambari, n ṣe ipolongo gẹgẹ bi oludije fun ipo Gomina labẹ asia ẹgbẹ APC, ni awọn ọbayejẹ eeyan fi sita'' O ni ọtọ ni aṣọ ti Abdulfatah Yahaya Seriki Gambari w,ọ ko si wa lati ṣe madaru kankan nibi idibo toni.
Ìgboro ilú London dá páro nìtorí àrùn Coronavirus Lásìkò kónílé-ó-gbélé coronavirus yìí, Òbí gbọ́dọ̀ fi àsìkò sílẹ̀ fi tọ́jú àwọn ọmọ wọn Ó ṣe é ṣe kí o ti ní coronavirus kí ó má mọ̀ nítorí pé ó kò rí àpẹẹrẹ Ẹ̀wẹ̀ ọ̀pọ̀ lọ ní àríwísí lórí lílo Fẹntílàtọ̀ onibòjú-bomu nitoripe tí ihò kan bá si sílẹ̀ tí aláìsàn sì wúkọ́ èyí lè tá sì ọ̀sìsẹ́ ìlera lára kí ó sì kó aarun náà.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Guru Maharaji : Aṣòfin Adéyẹmọ kì bá tí kú kání ó mọ mi 28 Ìgbé 2018 Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Èmi kò leè kú láéláé Gbajúgbajà aṣíwájú ẹ̀sìn ni, Sat Guru Maharaji ti sọ wípé òun kò lè kú nítorí òun kìí ṣe ẹlẹ́ṣẹ̀.
Asiko imuṣẹ ala rere yii n sun mọ dẹdẹ ni Alfa Ridwan ba ni ki iyawo rẹ o maa bọ nile wa bimọ sọdọ awọn obi oun lo ba di wi pe iroyin iku aya rẹ ni wọn fi ranṣẹ sii pada ni ilu Kano.
ilu ipinle Oyo, ti n se Ibadan.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Kayode Abiara: Ọmọ Nàíjíríà, ẹ má ba ọkàn jẹ́ lórí ààbò tó mẹ́hẹ, ewu ìgbà ìkẹyìn ló jẹ́ O ni arumọjẹ lasan ni ikede naa, ati pe ko si iyatọ kankan ti adinku yii yoo mu ba aye awọn ara ilu ti ara n ni.
Èèyàn mẹ́tàdínláàdọ́fà ló móríbọ́ lọ́wọ́ Covid-19, àwọn 443 míràn tún lùgbàdì rẹ̀ lọ́jọ́ Ẹtì Èèyàn 16 kú lẹ́yìn tí bàálù Air India já lulẹ̀ , tó sì kán sí méjì ní Kerala Wo àwọn ìgbẹ́sẹ̀ mẹ́wàá tí o nílò láti wò èsì ìdìbò Edo, Ondo bí wọ́n ṣe ń kàá Òwò mẹ́wàá tí yóò pàdánù àìsí ìpéjọpọ̀ ńlá RCCG lọ́dún yìí Oríṣun àwòrán, Getty Images Abiyamọ́ kan taa ba sọ̀rọ̀ ṣalaye bi ọkan oun ṣe maa n bajẹ bi fifun ọmọ lọyan ko ba lọ deede.
Bi o ba maa n tẹ nkan to ni oorun lọfinda si agbegbe oju ara rẹ.
Atiku ninu atẹjade to fi si oju opo Twitter rẹ sọ pe awọn oṣiṣẹ fi ipa wọ oun ati oṣiṣẹ oun.
Àrùn Coronavirus ti tàn dé orílẹ̀-èdè míràn nílẹ̀ Afrika Gómìnà Oyetọla tí yi ìlànà ètò ẹ̀kọ Rauf Aregbesola pada Obìnrin tó ń ṣiṣẹ́ ẹrú ní Oman tó bá fẹ́ òmìnira, yóò bá ọ̀gá rẹ̀ ṣùn - obìnrin méjì tó ti oko ẹrú dé Ọ́lọ́pàá bá aṣọ, bàtà àti fóónù ọkùnrin tó dàwátì nílé Pásítọ̀ etí òkun l‘Eko Ẹ fi ọkàn balẹ̀ lórí àrùn Coronavirus, à ń ṣa ìpa wa láti dènà ìtànkálẹ̀ rẹ̀ - Buhari Ẹ́ fún ọmọ Nàíjíríà ní ẹ̀kọ́ tó yè kooro dípò kẹ rán Boko Haram tó ronúpìwàdà lọ kàwé lókè òkun - Serap Ẹ wo fidio yii lati mọ si nipa arun asekupani Coronavirus ati ba se lee bọ lọwọ rẹ.
Orin yii ni awọn eeyan n kọ bi Buhari se n kọja lọ Àkọlé àwòrán, Bi a ko ba gbagbe ọrọ ana, a kii ri ẹnikan a ba ṣere.
Nígbà tí ó yá, àwọn ọ̀gágun rẹ̀ dìtẹ̀ mọ́ ọn, wọ́n sì pa á ní ààfin rẹ̀.
Cox Àkọlé àwòrán, Musa tun gba ami ẹyẹ fun goolu to fakọyọ lọdun 2018 Ẹlẹsẹ ayo ikọ agbabọọlu Super Eagles orile-ede Naijiria, Ahmed Musa, ti gba ami ẹyẹ agbabọọlu ọkunrin to pegede julọ ni Naijiria f'ọdun 2018.
Oríṣun àwòrán, Olatunji Babatunde Àkọlé àwòrán, Gẹgẹ bi iyalode, ohun ni oloye Obinrin ti o ga julọ ni igbimọ lọbalọba ilẹ Ibadan O bẹrẹ lati ori oye Jagun Iyalode, ko to o di pe o jẹ oye Iyalode lọdun kẹrindinnlọgbọn to bẹrẹ ọrọ oye ìlú.
Nítorí bí mo bá ti sọ ohunkohun nípa yín, tí mo sì ti fi ọwọ́ yín sọ̀yà, ẹ kò dójú tì mí.
Oloye Agẹsin Adimula naa fara kin ohun ti baba Ẹlẹbubọn ṣe ni alaye.
Lọjọ ti wọn pa a, oun ati iya wa lo jọ jade nile, ki o to o ya si sọọsi.
Gbogbo ẹni tí Baba ti fi fún mi yóo wá sọ́dọ̀ mi.
Bí iré bí iré wọ́n mọ ojú ara wọn, bí iré bí iré wọ́n ń jùmọ̀ sọ̀rọ̀ ìkọ̀kọ̀, bí iré bí iré wọ́n ń sọ̀rọ̀ ọkọ òun aya, láìfa ọ̀rọ̀ gùn lọ títí, wọ́n gbé ara wọn ni ìyàwó.
Ṣugbọn mo ti gbadura fún ọ Simoni, pé kí igbagbọ rẹ kí ó má yẹ̀.
Bakan naa ni ileeṣẹ ologun ma n fi aworan ati fidio sita lori ayelujara Twitter rẹ pe, oun n ṣẹgun ikọ naa.
Wọn bẹ minsita ile iṣẹ ijọba apapọ to n mojuto ọrọ ọkọ ofurufu pe ko ma binu pe awọn fi baalu naa gbe onkọrin Naira Marley wa si Abuja lopin ọsẹ to kọja.
Dokita Wilson tun ṣalaye pe ti eeyan ba n ṣe ere idaraya, eemi ẹni naa maa pọ si, bakan naa ni afẹfẹ to n jade lati inu ẹdọ foro naa yoo pọ si.
Pasitọ naa ni, oun ti fi ọrọ naa to awọn agbẹjọro oun leti ati wipe, gbogbo awọn eeyan ti wọn ni nkan ṣe pẹlu ẹsun naa, ni wọn yoo foju ba ile ẹjọ.
''O ti di dandan lati se agbeyewo ibasepọ laarin awọn aladani ati ẹka ijọba ti a mọ si PPP'' Arinrinajo lọ si ilẹ okere fun ẹkọ tabi ilera yoo mọ asiko yi lara Ninu awọn ti Ọjọgbọn Nazifi Abdullahi Darma sọ pe yoo mọ asiko yi lara ju, ni awọn ti wọn maa n na owo dọla, yala lati fi gba itọju nilẹ okere ni tabi fun eto ẹkọ ni oke okun.
Èmi kò wá ògo ti ara mi, ẹnìkan wà tí ó ń wá ògo mi, òun ni ó ń ṣe ìdájọ́.
Àwa fúnra wa gbọ́ ohùn yìí nígbà tí ó wá láti ọ̀run nítorí a wà pẹlu rẹ̀ lórí òkè mímọ́ nígbà náà.
tí ó yàgò fún ẹ̀ṣẹ̀, tí kì í gba owó èlé, tí ń pa òfin mi mọ́, tí sì ń rìn ninu ìlànà mi, kò ní kú nítorí ẹ̀ṣẹ̀ baba rẹ̀, dájúdájú yóo yè.
Lẹ́yìn náà, obinrin náà yóo tọ̀ ọ́ lọ lójú gbogbo àwọn àgbààgbà, yóo bọ́ bàtà ẹsẹ̀ rẹ̀, yóo tutọ́ sí i lójú, yóo sì wí pé, ‘Bẹ́ẹ̀ ni wọ́n ṣe sí ẹni tí ó bá kọ̀ láti kọ́ ilé arakunrin rẹ̀.
13 Nitorí-èyí, mo pàṣẹ fún ọ lati ronúpìwàdà, kí o sì pa àwọn òfin mọ́ èyítí ìwọ ti gbà láti ọwọ́ ìránṣẹ́ mi Joseph Smith, Kekere, ní orúkọ mi.
"Ọranyan ni nnkan oṣu ṣíṣe fawọn obìnrin, o si yẹ ki ijọba ṣe ipese paadi ọfẹ fun wọn gẹgẹ bi wọn ṣe n pin rọba idaabobo ta mọ si condom fawọn ọkunrin.
Ó mú awọ ewúrẹ́ tí ó pa, ó fi bo ọwọ́ Jakọbu ati ibi tí ó ń dán ní ọrùn rẹ̀, 
Afirika:Ona lati mu eto idagbasoke ba awujọ’ nibi ayẹyẹ ikẹkọọ gboye
Nígbà tí Dafidi ọba gbọ́ ohun tí ó ṣẹlẹ̀, inú bí i gidi.
Ṣugbọn Daniẹli tún ta gbogbo àwọn alámòójútó ati gomina náà yọ nítorí ẹ̀mí tí kò lẹ́gbẹ́ tí ó wà ninu rẹ̀.
Oribamiṣe ni ọrọ Moses, nitori pe, ibi to ti n gba bọọlu ni ile iwe rẹ, ni ẹka awọn ọdọ ti ẹgbẹ agbabọọlu Crystal Palace ti wa mu.
Ọpẹ́lọpẹ́ iná tí kìí lọ, tí kìí dákú ní’lẹ̀ yìí.
Wọ́n tú àwọn ọmọ-ogun ilẹ̀ àjèjì ká tóbẹ́ẹ̀ tí wọ́n fi sá pada sẹ́yìn.
Orilẹ-ede Spain ti kede isede alaalẹ, pupọ ninu awọn ẹkùn lo si ti ti ẹnu ibode wọn pa.
Ìtàn Mánigbàgbé: Mọrèmi Àjàṣorò fi ọmọkùnrin rẹ̀ kanṣoṣo rúbọ fún odò nítorí ìlú
Ó bẹ àwọn ará Sukotu, ó ní, “Ẹ jọ̀wọ́, ẹ fún àwọn tí wọ́n tẹ̀lé mi ní oúnjẹ, nítorí pé ó ti rẹ̀ wọ́n, ati pé à ń lé Seba ati Salimuna, àwọn ọba Midiani mejeeji lọ ni.
CCC Genesis Global: Ǹkan mẹ́wàá tí ẹ ò gbọ́ rí nípa Israel Oladele, Woli ìjọ Genesis Global Ẹ̀ṣọ Gbajabiamila yìnbọn pa fẹ́ńdọ̀ kan l'Abuja, àwọn akẹgbẹ́ rẹ̀ fẹ ṣe iwọde Báyìí ni olùwọ́de EndSARS, Eremosele Adene ṣe gba òmìnira lọ́wọ́ ọlọ́pàá Nàìjíríà CCC Genesis Global: Ǹkan mẹ́wàá tí ẹ ò gbọ́ rí nípa Israel Oladele, Woli ìjọ Genesis Global O fi kun ọrọ rẹ pe ẹka to n mojuto iye awọn eeyan to ku nipinlẹ Eko naa ti kesi araalu to ba padanu eeyan wọn kankan lati wa ran awọn lọwọ fun eto idanimọ oku to ba ku laarin ọjọ Kọkandinlogun si ọjọ Kẹtadinlọgbọn Osu Kẹwa.
Ajọ EFCC ko lasẹ lati wadi isuna ipinlẹ Latari ẹbẹ rẹ nile ẹjọ, agbẹjọro rẹ ke si ile ẹjọ lati sun igbẹjọ rẹ siwaju, ki o si wa ni atimọle ajọ EFCC titi ti wọn yoo fi gba ẹjọ beeli rẹ.
Nibayii, gbogbo igbiyanju wa lati ba ijọba ipinlẹ Ondo sọrọ lori igbesẹ ti wọn n gbe lati ri wi pe iru iṣẹlẹ naa ko waye mọ lo jasi pabo.
Oun lo pe fun Biafra Ogun abẹle ni Naijiria, ti a tun mọ si ogun Biafra, waye laarin ijọba orilẹ-ede Naijiria ati awọn ípinlẹ Biafra to yapa laarin ọjọ kẹfa, oṣu Keje, ọdun 1967 si ọjọ kẹẹdogun, oṣu Kinni, ọdun 1970.
Àwọn ọmọ Muṣi jẹ́ mẹta: Mahili, Ederi ati Jeremotu.
Ààrùn onígbáméjì (Cholera) ó maa dá wàhálà silẹ̀ sínú ẹ̀dọ̀fóró tí ara yóò sì máa gbìyànjú láti báa jà.
Ọ̀rọ̀ kẹ́lẹ́kẹ́lẹ́ olófòófó dàbí òkèlè oúnjẹ dídùn,a máa wọni lára ṣinṣin.
Dafidi pàṣẹ pé kí Joabu ati àwọn tí wọ́n wà lọ́dọ̀ rẹ̀ fa aṣọ wọn ya, kí wọ́n wọ aṣọ ọ̀fọ̀, kí wọ́n sì ṣọ̀fọ̀ Abineri.
Ohun ta n beere ni pe ki ijọba o o yẹ owo ori ti wọn n fi si ori epo wo.
Iroyin naa ni wọn fi lede lẹyin ti ijọba Amẹrika ko awọn ọmọ ogun rẹ kuro ni agbegbe ọhun lọsẹ yii.
Wọn yóo kí ọ, wọn yóo sì fún ọ ní meji ninu burẹdi náà, gbà wọ́n lọ́wọ́ wọn.
Ninu esi rẹ, Agbẹnusọ Ile Igbimọ Aṣofin Ipinlẹ Eko, Aṣofin Mudashiru Ọbasa fi idunnu han si ọrọ akin ti Kabiyesi sọ, o wa rọ gbogbo ọmọ Yoruba lati gbaruku ti gbigbe ede ati aṣa Yoruba larugẹ.
‘Àní ìwọ Bẹtilẹhẹmu ilẹ̀ Juda,o kì í ṣe ìlú tí ó rẹ̀yìn jùlọ ninu àwọn olú-ìlú Juda.
Eyi ni anfani lati yan awọn ti ẹ fẹ sinu ẹgbẹ agbabọọlu aayo yin yii.
Nigeria Police: Eko, Oyo, Kwara, Anambra gba Ọ̀gá Ọ̀lọ́pàá tuntun
 máa ń àti a máa ló máa ń tọ ́ ka ibá-ìṣẹ ̀ lẹ ̀ yìí nínu ya .
Amofin Agba to tun jẹ kọmisanna fun eto idajọ nipinlẹ Ondo, Adekola Olawoye sọ pe idajọ na fihan pe ìlú ko ni fi ara rọ fun awọn to n fi ipa ba ọmọde lopọ nipinlẹ naa Iru idajọ yii ni ikeji to waye laarin ọsẹ kan ni ipinlẹ Ondo.
O ni ki iran Yoruba ronu lori nkan to m bọ fun wọn ni 2023 lai naani ipenija to n ṣẹlẹ bayii.
Iléeṣẹ́ ọlọ́pàá ti bẹ̀rẹ̀ ìwádìí lórí fídíò ọkùnrin kan tó ń fi shisha"" ṣagbeji ara Ẹ dín iye ìgbà tẹ n gorí obìnrin kù torí ìdìbò tó n bọ̀, kẹ́ẹ lè lágbára láti ṣe ."
Àkọlé àwòrán, Agbe parawu ni awon eniyan Madaka n se ni eyi ti won kii tete ri awon ire oko won gbe lo ta loja nlanla O ni apo ile ọmọ wọn le ja tabi ki wahala irora wiwẹ tabi gbigbe wọn lori odo to maa n ṣakoba aile tete ṣe iṣẹ abẹ fawọn to nilo rẹ ti wọn ba gbe wọn de ile iwosan.
Ṣugbọn ọ̀nà olódodo dàbí ìmọ́lẹ̀ àfẹ̀mọ́júmọ́,tí ń mọ́lẹ̀ sí i láti ìdájí títí tí ilẹ̀ yóo fi mọ́ kedere.
Ìmísí ọjọ́ ọ̀la mi sí Tibet kan náà ni mo ní sì gbogbo àgbá-ńlá-ayé: Mo fẹ́ jẹ́ kí ẹ̀tọ́ tí àwọn ará Tibet ń jẹ gbádùn máà yàtọ̀ sí ti àwọn Canada, àwọn ni òmìnira láti lè sọ èrò ọkàn ẹni, òmìnira láti ní ìgbàgbọ́, òmìnira láti máà fi òṣèlú pá ẹniẹlẹ́ni lẹ́kún.
Nibayii naa, gomina ipinlẹ Ekiti tẹlẹ naa ti jade pẹlu ibeere mẹta fun aarẹ Muhammadu lori awuyewuye iwe ẹri girama rẹ.
Ogagun Omozoje lo soro yii lasiko ti egbe obinrin akoroyin ni ipinle Oyo
Oríṣun àwòrán, Other O ni ohun to fa sababi ti oun fi n wọ Hijabu lọ sode iwọde EndSARS ni pe ẹsin oun fi aye rẹ silẹ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Lagos-Ibadan Repair: Àwọn ọ̀ná míràn ti e lè gba jáde tàbi wolé si ìpínlẹ̀ Eko 2 Owewe 2019 Oríṣun àwòrán, LASMA Àkọlé àwòrán, Àtúnṣe òpópónà Lagos-Ibadan àwọn ọ̀ná míràn ti e lè gba A ti ṣetan lati tun opopona marosẹ Eko si Ibadan ṣe ṣaaju ọdun.
Iyabo Ojo ṣe ọjọ ibi ọdun mejilelogoji Fun apẹrẹ, bi o til jẹ pe o fẹ sa pẹrẹ diẹ laarin gbajugbaja oṣere Lizzy Anjorin ati akẹgbẹ rẹ Iyabo Ojo lasiko ija to waye laarin Lizzy ati Toyin Abraham, ṣe ni idunu Lizzy anjorin pọ to debi pe ko wa si i lọkan pe oni ọj kọkanlelogun gangan ni ọjọ ibi Iyabo Ojo ṣugbn o ti ṣaaju gbogbo eniyan ki i ku ayẹyẹ ọjọ ibi ni ogunjọ osṣu kejila loju opo instagram rẹ.
O menuba bi Eledaa se pese awon ewe ati egbo to kun fofo nile Asia, Afrika ati guusu Amerika fun lilo awon omo eniyan fun ilera pipe.
Kò sí ohun tí ó fi jù mí lọ ninu ilé yìí, kò sì sí ohun tí kò fi lé mi lọ́wọ́, àfi ìwọ nìkan, nítorí pé aya rẹ̀ ni ọ́.
Ká ni ilú farabalẹ̀ ni àsikò na a, ilú ki bá ti dára si.
Bawo ni wọn ṣe le tẹ okunrin lọdaa?
Gẹ̀ẹ́sì gbẹ́sẹ̀ lé ₦82bn owó Abacha Iṣẹ́ Kudirat Abiọla ṣì ń fọhùn síbẹ̀, lẹ́yìn ọdún 23 tó papòdà Ọba Adesoji Aderemi, Ọọ̀ni Ifẹ̀ tó gba ipò ọba mọ́ tòṣèlú Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ladoja: Àwọn èèyàn Oyo fì ìbò sọ̀rọ̀ pé ìjọba Ajimobi kò dára Sẹnẹtọ Saraki ni oun gbe igbesẹ yii nitori pe ko si igba ti ile ba ṣe apero lori ọṣẹ tawọn agbsumọmi n ṣe papaajulọ lagbegbe ila-oorun ariwa, ti kii ba oun lọkan jẹ.
Amọṣa ileeṣẹ agbofinro DSS ti bọ si gbangba walia lati ṣalaye idi to fi jẹ awọn gan an lo n ṣe kokaari ẹjọ naa.
Nipari, onisegun oyinbo yii ro awon jorinjorin, awon agbe ati awon osise ile ise imo ero nlanla lati daabo to ye bo oju won lenu ise nitori pe oju se pataki pupo yato si lilo fi reran, o tun je ki eda kookan rewa sii ni.
Oríṣun àwòrán, OTHERS Àkọlé àwòrán, Ọmọbìnrin Adeola, ẹni ọdún mẹ́ẹ̀dọ́gbọ̀n sọ ìrírí rẹ̀ lásìkò tí wọ́n fi ṣe òwò ẹrú lọ sí òkè òkún.
22 Òkùdu 2019 Oríṣun àwòrán, Charlotte Wilson/Offside Ami ayo kan si odo ni ikọ agbabọọlu Super Eagles ti orilẹede Naijiria fi ki ikọ agbabọọlu Burundi kaabọ sinu idije ife ilẹ Afrika, Afcon 2019 to n lọ lọwọ ni orilẹede Egypt.
Biu tun salaye pe ile-isẹ omo ologun ti si
 Ó sọ ̀ rọ ̀ nípa ògbójú ọdẹ tí ojú rẹ ̀ ti rí oríṣiríṣi , bí idán , iwin , ẹbọra àti àwọn òòṣà .
Àwọn ọmọ Diṣoni ni Hamirani, Eṣibani, Itirani ati Kerani.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Yoruba Language: Ṣé ẹ mọ ìdí tí ọmọ fi ń jẹ́ orúkọ yìí?
Ilẹ̀ wọn kún fún oriṣa,wọ́n ń bọ iṣẹ́ ọwọ́ ara wọn,wọ́n ń wólẹ̀ fún ohun tí wọ́n fọwọ́ ara wọn ṣe.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Christmas: Jesu ni ọjọ́ ọ̀la àti ibi ìyanu mi- Jaga 3.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ojú mi ti rí lọ́pọ̀ lọpọ̀, àmọ́ mo dúpẹ́ pé mo ti pé ọdún márùn ún lórí oyé- Ooni Eyi waye lẹyin wakati diẹ ti Ifeyinwa fi fidio kan sori ayelujara, pe ọkọ oun fi iya jẹ oun.
Mo dúpẹ́ lọ́wọ́ gbogbo yín o.
A ko ti ri aridaju lati ọdọ awọn ajọ to n risi iṣẹlẹ pajawiri lori iye eeyan to ku ṣugbọn awọn to wa nibẹ ni ko le kere ju mẹẹdogun lọ Àkọlé àwòrán, Ijamba ọkọ naa da sunkẹrẹ fakẹrẹ silẹ loju ọna naa Akọroyin wa jabọ pe nisoju oun, awọn ẹsọ abo oju popo n fi ọkọ alaarẹ gbe awọn eeyan kan to farapa lọ si ile iwosan.
Bayii ni akọnimọọgba Manchester United, Ole Gunnar Solskjaer ṣe fesi si ọrọ ti ẹleṣẹ ayo tẹlẹ ri fun ẹgbẹ agbabọọlu Arsenal ati Man U, Robin van Persie.
Ẹ fun fèrè ati ìwokí ẹ sì hó ìhó ayọ̀ níwájú OLUWA Ọba.
Minisita kan ti dero atimọle ni Indonesia lẹyin ti wọn fẹsun kan pe o gbọna ẹburu ji owo iranwọ Covid-19.
Ǹjẹ́ kò rẹ́rìn-ín nígbà tí o jíṣẹ́ fún un?
Ninu ọlá ńlá rẹ̀ yóo wà ninu àhámọ́,ìbànújẹ́ yóo máa fi tagbára-tagbára bá a jà.
Michael Job ṣeleri wi pe, oun n ṣiṣẹ iyanu ati imularada ninu awọn fọnran iwaasu rẹ lorilẹede Kenya, bo tilẹ jẹ pe ọpọ lo koro oju si ọrọ yii.
Kí ẹ gbadura pé kí n lè ṣe àlàyé bí ó ti yẹ.
Bí ó ti jáde ninu àgọ́ Lea ni ó lọ sí ti Rakẹli.
Ṣùgbọ́n àwọn ìran tàbí ìdílé pàtàkì pàtàkì pàápàá ní ààrin ẹ̀yà Yorùbá Ọ̀yọ́ ní ètò ìsọmọlórúkọ tó yàtọ̀ sí ọjọ́ mẹ́fà.
Ó dúró, ó wọn ayé;Ó wo ayé, ó sì mi àwọn orílẹ̀-èdè tìtì;àwọn òkè ńláńlá ayérayé túká,àwọn òkè àtayébáyé sì wọlẹ̀.
 Ìdí nìyí tí Ọ ̀ rúnmìlà fí gbé ẹ ̀ mí ni ìyàwó ko ba le ṣe rere láyé .
Amọ lasiko idibo gbogboogbo Naijiria ti o ku ọjọ diẹ, ika onikaluku ni ipa ti yoo ko sugbọn kii ṣe wi pe wọn yoo fi re imu.
Police Constable Grade Level 10 - N613, 363.
Wọn yóo jẹ àjẹyó, wọn yóo dùbúlẹ̀, kò sì ní sí ẹni tí yóo dẹ́rùbà wọ́n.
Osinbajo ya lo si aafin Emir tile Kano lati ki Alhaji Muhammadu Sanusi 11 ni aarin gbungbun Kano.
Juda bá sọ fún àwọn arakunrin rẹ̀, ó ní, “Anfaani wo ni yóo jẹ́ fún wa bí a bá pa arakunrin wa, tí a sì bo ẹ̀jẹ̀ rẹ̀ mọ́lẹ̀?
Gómìnà Makinde ìpínlẹ̀ Oyo kéde dúkìá tó tó #48bn Àwọn olówó Naijiria 5 tí owó wọn ju owó ìsúnná Naijiria lọ!
Nítorí náà, ìlú meji tabi mẹta ń wá omi lọ sí ẹyọ ìlú kan wọn kò sì rí tó nǹkan; sibẹsibẹ ẹ kò pada sọ́dọ̀ mi.
Gbé agbára rẹ wọ̀ bí aṣọ,gbé ẹwà rẹ wọ̀ bí ẹ̀wù,ìwọ Jerusalẹmu, ìlú mímọ́;nítorí àwọn aláìkọlà ati aláìmọ́, kò ní wọ inú rẹ mọ́.
Etí rẹ̀ yíká fẹ̀ ní ìka kan (idamẹrin mita kan).
ibajẹ sise owo ilu basu-basu, iru ayeye bayii ko lee waye.
Sugbọn wọn sọ pe awa mejeeji nikan ko le fidi ẹjọ naa mulẹ, ayafi ti obinrin bi i mẹrin tabi maarun ba ṣetan lati jẹri ni wọn to o le ṣi agbẹjọro agbegbe naa lati wo ọrọ wọn.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Àwọn ará ìlú Abiola ní Abẹokuta bá BBC sọ̀rọ̀ Ọpọ wahala to suyọ yii lo mu ki Ọgagun Ibrahim Babangida yẹba lori aleefa, ti Ọgagun Sani Abacha si gba ipo rẹ.
Ọdún iṣu tuntun wáyé ní Ilé Ifẹ̀, Ọọ̀ni rawọ́ ẹ̀bẹ̀ sáwọn àgbẹ̀ àti darandaran Gbígba onídùròó Zakzaky ṣàfihàn àṣeyọrí ìfaradà wa lásìkò ìfìyajẹni - Shiite Ó tó gẹ́ẹ́!
Nítorí náà inú a bí OLUWA sí àwọn ọmọ Israẹli, a sì wí pé, “Àwọn eniyan wọnyi ti da majẹmu tí mo pa láṣẹ fún àwọn baba wọn, wọn kò sì fetí sí òfin mi.
Wolii Aisaya ọmọ Amosi, wá sọ́dọ̀ rẹ̀, ó sọ fún un pé, “OLUWA ní kí o palẹ̀ ilé rẹ mọ́ nítorí pé kíkú ni o óo kú, o kò ní yè.
Olukuluku yóo máa pa aládùúgbò rẹ̀ jẹ nítorí ìdààmú tí àwọn ọ̀tá wọn, ati àwọn tí ń wá ẹ̀mí wọn yóo kó bá wọn, nígbà tí ogun bá dótì wọ́n.
Aṣofin Ipinlẹ naa, ti yoo ṣe agbeyẹwo rẹ.
Ẹ dákun, ẹ má jẹ̀ kí tọwọ́ ó bọ́
Àwọn èrò ẹ̀yìn yóo di ará iwájú; àwọn ará iwájú yóo di èrò ẹ̀yìn.
Afurasi naa, ni wọn sọ pe ilẹ isinku Kristiẹni kan to wa ni adugbo Oke-Eri, nilu Ijebu-Igbo, lo ti ge awọn ẹya ara naa lọjọ Aje, pẹlu iranlọwọ ẹnikan, Lekan Bakare, to ti salọ bayii.
Diẹ ninu aworan naa ree: Lonii ọjọ Ẹti ni Alfa Babatunde to jẹ oludasilẹ ijọ Sọtitobirẹ Miracle Centre yoo foju ba ileẹjọ niluu Akure lori ẹsun to da lori bi ọmọ ọdun kan, Gold ṣe di awati ninu ṣọọṣi rẹ lọjọ kẹwaa oṣu kọkanla ọdun 2019.
Ohun méje tí o kò gbọ́ rí nípa aláìsàn arunmọ-léegun- Dókítà Igbekele Ọ ṣòro fún mi láti foríjin ìbátan mi tó jé ọmọ ikò Boko Haram tó fipá bámi lòpò Wo àwọn àsọtẹ́lẹ̀ ìgbà tó yẹ kí ayé parẹ́ àtàwọn tó sọ àsọtẹ́lẹ̀ náà Ohun tí a rí nílé Ajimobi rèé lẹ́yìn ìròyìn òfégè pé ó jáde láyé Ninu fidio ti Ibukun fi soju opo Instagram to gan an mọ orukọ ajọ LASTMA ati gomina Sanwo-Olu lori ayelujara.
si enikeji, ilu lo so awon eniyan papọ.
Fogoe ṣalaye pe awọn ijamba kan wa ti iwa yii le ṣe fun awọn to ba n ṣe e.
Inú wa yóo máa dùn, a óo sì máa yọ̀ nítorí rẹa óo gbé ìfẹ́ rẹ ga ju ọtí waini lọ;abájọ tí gbogbo àwọn obinrin ṣe fẹ́ràn rẹ!
Ogun Flood: Ọ̀pọ́ Dúkìá ló sọnù ní 2019 lásìkò tí ìjọba ṣí 'dáàmù Ọyan' Tàpá sí ìlànà ìdáàbò bò Coronavirus, ko rí ìdánilẹ́kọ̀ọ́ òjijì he - Ìjọba Osun Ìdí tí lílọ Yúrópùù fi di èèwọ̀ fún Nàìjíríà àti àwọn orílẹ̀-èdè adúláwọ̀ míì Àjọ NCDC kéde ènìyàn 561 tó tún ṣẹ̀ṣẹ̀ ní Coronavirus ní Nàìjíríà O ni ibi ti wọn ti n ṣe ariyanjiyan lori idi ti ko ṣe gba ki o ba a ni ṣe pọ ni oun ti fun un ni ẹṣẹ mẹta pere, to si gba'bẹ dagbere faye.
Williams ti kọkọ fẹyin Wang gbolẹ ni idije US open ni osu kẹsan ọdun to kọja ki Wang to wa gba ẹsan rẹ bayii Oko Oloyun: Ta ló pa Àlhájì Fataì Yusuf?
ẹṣọ abẹle Ipinlẹ Eko, iyẹn “Neighbourhood”, ti wọn ti tipasẹ rẹ gba
 O ni pe, sibẹ, ijọba Ipinlẹ Eko ti n sa ipa lati mu igberu ba amojuto iru awọn idoti bayii, pẹlu awọn ibi ti wọn ti n yi wọn pada fun ipese awọn ohun eelo miiran, eleyii ti yoo le mu awujọ bọ lọwọ idoti, ti yoo si le mu aye rọrun gbe fun awọn ẹda.
Ní ọdún keji tí Nebukadinesari gun orí oyè, ó lá àwọn àlá kan; àlá náà bà á lẹ́rù tóbẹ́ẹ̀ tí kò fi lè sùn mọ́ lóru ọjọ́ náà.
Avengers yii naa tun ni fiimu to ta julọ lagbaye lọdun 2018.
to dara lori ise rere to ti wa nile ni pataki julo oro aabo emi ati dukia.
Oríṣun àwòrán, Others Àkọlé àwòrán, Lassa Fever: Dokíta mẹrin àti àwọn mẹ́tàdinlólogun ti kú ni Kano àti Ondo.
Ipo kẹjọ ni Man City wa bayii lori tabili idije Premier League nigba ti Liverpool si wa loke tente.
O ni ko si akọsilẹ kankan nile iṣẹ wọn to ṣafihan awọn to ti wọ Naijiria lọna itọ tabi pẹlu ibọn lọwọ.
Ṣùgbọ́n nǹkan kan wáá ṣẹlẹ̀ nígbà tí ó di ọdún kẹta gééré tí mo ṣìnà sínú igbó yìí báyìí ni: ṣe ló di ọjọ́ kan tí mo rìn lọ si inú igbó tí mo wá èèso igi lọ.
Irẹsi Awọn eeyan maa n ra baagi ireṣi kan ki ijọba to ti ibode ni bi ẹgbẹrun mẹtala naira si mẹrindinlogun (eyi nii ṣe pẹlu ti irẹsi naa ba ṣe mọ to ati ibi ti wọn ti n ko o wa).
Yóo fi àgbò náà rú ẹbọ alaafia sí OLUWA pẹlu burẹdi agbọ̀n kan tí kò ní ìwúkàrà ninu.
Mo rí ọ̀run titun ati ayé titun, ayé ti àkọ́kọ́ ti kọjá lọ.
Tí ènìà bá ṣeré díè tí ó pọ́n òkè tí ó ya àwòrán tán, ó di ilé!
"''Awa o ni ibẹru kankan nipa eto ti ilẹ Amẹrika fẹ ṣe ṣugbọn awọn to fi agidi gba ipo, awọn ti wọn gun awọn eeyan lada ati lọbẹ ni Kanoni ẹru ma ma ba'' Dalung, Audu Ogbe, Shittu Adebayo àti Isaac Adewole kò wọlé Àwa ò mọ ẹgbẹ́ kankan tó ń jẹ́ fijilanté fulani l'Ondo- Ìjọba ìpínẹ̀ Ondo Àgùnbánirọ̀ akọ̀ròyìn Channels náà ti dágbére fáyé látààrí ìkọlù Shiite l'Abuja Ìtàn tó rọ̀ mọ́ òwe ""Ẹni tí kò ṣe bíi aláàárù l‘Oyingbo."
Ayọ̀ ń bẹ fún ẹni tí ó bá gbọ́ tèmi,tí ó ń ṣọ́nà lojoojumọ ní ẹnu ọ̀nà àgbàlá mi,tí ó dúró sí ẹnu ọ̀nà ilé mi.
 Àwọn egbògi mìíràn tó tún má a nṣiṣẹ ́ ni tribendimidine àti nitazoxanide .
"Awọn Yoruba ni a kii nilee baba ka ma nile iya ni mo ṣe da mejeji pọ si ilu Ijefẹ""."
Bẹ́ẹ̀ ni mo paríu ìjà líle náà.
Ẹ̀dá tí kò bá ní ìforítì, yálà nínú ayé ni tàbí lóde ọ̀run, ẹ̀dá lásán ni.
Kí o má baà kérora nígbẹ̀yìn ayé rẹ,nígbà tí o bá di ìjẹ fún ẹni ẹlẹ́ni
Ìwé Mímọ́ ti sọ tẹ́lẹ̀ pé nípa igbagbọ ni Ọlọrun yóo fi dá àwọn tí kì í ṣe Juu láre, ó waasu ìyìn rere fún Abrahamu pé, “Gbogbo àwọn tí kì í ṣe Juu yóo di ẹni ibukun nípasẹ̀ rẹ.
Àṣẹ tuntun tó kalẹ̀ ní Zamfara Kìnìhún joko jẹ ẹran ara afurásí ọdẹ tí kò gbààyè kó tó ṣọdẹ “Kò sí àgbègbè Nàìjíríà kánkan tó wà lábẹ́ àkóso Boko haram” Elkanah jẹ ko di mimọ pe oju ọna omi Ikorodu ni awọn afurasi janduku gba yọ si wọn ti wọn da wọn lọna.
Ẹlẹ́yà ni ọtí waini,aláriwo ní ọtí líle,ẹnikẹ́ni tí a bá fi tànjẹ kò gbọ́n.
Osun Ilu Ede ni awọn eeyan ti rọlu ile ti ijọba ko ounjẹ iranwọ Covid-19 si ni Cocoa House ti wọn si bẹrẹ si n ji ko.
Oríṣun àwòrán, @EkitiGovt Àkọlé àwòrán, Ẹni to wa lẹgbẹ to n sejọba lọwọ ni 2014, lo jẹ oludije fun ẹgbẹ alatako bayii Oríṣun àwòrán, @EkitiGovt Àkọlé àwòrán, Gaga lara awọn eeyan ya lati dibo Oríṣun àwòrán, @EkitiGovt Àkọlé àwòrán, Ẹni ti aye n fẹ, kii ni abuku kan lara Oríṣun àwòrán, @EkitiGovt Àkọlé àwòrán, Ẹni ti ko lee rin, ni ki wọn wọ oun lasiko ipolongo ibo Oríṣun àwòrán, @InecOfficialNg Àkọlé àwòrán, Oju ri lọjọ ibo Oríṣun àwòrán, @dan-f Àkọlé àwòrán, Ẹbọ gbigbe kan ko gbẹyin lasiko ibo Oríṣun àwòrán, Kolawole Amusat Gbenla Àkọlé àwòrán, Oludije kan n lu ilu fawọn eeyan jo Oríṣun àwòrán, Kolale Amusat Gbenla Àkọlé àwòrán, Ọ́pọ eeyan wọ oorun sori lati dibo Oríṣun àwòrán, Kokoirin layinka Àkọlé àwòrán, Awọn osisẹ ajọ eleto idbo sisẹ kara Oríṣun àwòrán, Kokoirin layinka Àkọlé àwòrán, Kii se igba akọkọ ree tawọn agbofinro yoo peju sibi eto idibo, o ti waye saaju Oríṣun àwòrán, Kolawole Amusat Gbenla Àkọlé àwòrán, Tarugbo-tomidan lo jade lati dibo Oríṣun àwòrán, Jerome Olowoye Àkọlé àwòrán, Oludije kan ami iifẹ ati atilẹyin lọ̀wọ ololufẹ rẹ kan Oríṣun àwòrán, Jerome Olowoyeye Àkọlé àwòrán, Bi awọn olodije gomina se wọ ayẹta ni 2014, naa lawọn oludije goomina ni 2018 tun n wọ ayẹta ni Elkiti Oríṣun àwòrán, Kolawole Amusat Gbenla Àkọlé àwòrán, Bi oludije kan se n gba oriyin, naa ni omiran n gba BBC News, Yorùbá Ìdí tí ẹ fi le è nígbàagbọ́ nínú ìròyìn BBC Ìlànà Lílò Nípa BBC Òfin Àṣírí Cookies Kàn sí.
Ẹ ti jìyà ẹ̀ṣẹ̀ yín ní àjẹpé,ẹ̀yin ará Sioni,OLUWA kò ní fi yín sílẹ̀ ní ìgbèkùn mọ́.
Wọ́n bọ ẹran ẹbọ mímọ́ ninu ìkòkò, ìsaasùn ati apẹ, wọ́n sì pín in fún àwọn eniyan lẹsẹkẹsẹ.
Awọn ere re a ma koni lẹkọ.
O wa koro oju si awọn ọrọ ibajẹ ti ọpọ eeyan maa n sọ nipa rẹ nitori pe irisi rẹ jọ ti ọkunrin.
Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Katsina Child sale: Obìnrin olówònààbì ta ọmọ rẹ̀ tuntun jòjòlò ní N300,0002 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Alaafin Oyo: Olorì Anuoluwapo Adeyemi gba àmì ẹ̀yẹ lórí oge ṣíṣe1 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Barrister - K1 rift: Ìjà parí!
Ẹ máa fi ọ̀rọ̀ ìyìn rere ṣe ìwà hù; ẹ má kàn máa gbọ́ ọ lásán.
Ó kún fún ìfẹ́kúfẹ̀ẹ́ fún àwọn ọkunrin tí ojú ara wọn dàbí ti kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́, nǹkan ọkunrin wọn sì dàbí ti ẹṣin.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Bíi ẹgbẹ̀rún kan àbọ̀ ènìyàn ni ó ti kú ní Benue láti 2013 Amọ ṣa, ajọ naa ni ko si ootọ ninu nnkan ti ileeṣẹ ologun sọ nipa awọn.
Festus Fientes - Ọmọ ẹgbẹ́ 4.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Kini o ṣẹlẹ si Rolling Doller ni ilu Eko?
Níbi ìjòkó ilé ni Dogara ti sọ ọ̀rọ̀ yìí nígbà tí aṣòfin Sunday Karimi, láti ìpínlè Kogi pe àkíyèsí ilé náà sí ìgbésẹ̀ àwọn ọlọ́pàá láti gbé Melaye lọ sí ilé ẹjọ́ lórí kẹ̀kẹ̀ aláìsàn.
” Wọ́n bá jáde lọ, wọ́n wọ ọkọ̀ ojú omi.
Ó wá mú burẹdi meje náà ati àwọn ẹja náà, ó dúpẹ́ lọ́wọ́ Ọlọrun, ó bù wọ́n, ó bá kó wọn fún àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀; àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ wá pín wọn fún àwọn eniyan.
Ẹ bu ọlá fún ẹni tí ọlá bá yẹ.
CBN gbé òfin tuntun sílẹ̀ fún àwọn Báǹkì 'Due Process ni mo fẹ́ tẹ̀lé láti gbọn ìyà Ọṣun nù' Èyí ni bí o ṣele dá ayédèrú ìròyìn mọ̀ A kú ewu ọmọ Linda Ikeji ooo Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí kan sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
O ni nigbakugba ti alaboyun ba ti nilo lati sare lọ fun ilera pipe, ẹgbẹrun meji naira pere ni ọkọ rẹ yoo san, ninu eyi ti won yoo ti yọ ẹgbẹrun kan ati ẹẹdẹgbẹta Naira fi ra epo sinu oko .
Dajudaju, ẹja nla lo lọ laarin awọn elere Tiata pẹlu bi ayelujara awọn olukọni ati akẹkọ, to fi mọ awọn ọjọgbọn fasiti atawọn agba oṣere ṣe kun fọfọ pẹlu aworan ati iṣẹ ire ti Ayo Akinwale ṣe.
Bí kò bá sí ẹni tí yóo ṣe ìtumọ̀, kí ẹni tí ó fẹ́ fi èdè àjèjì sọ̀rọ̀ dákẹ́ ninu ìjọ.
'Mo ya Olamide Badoo, Davido sórí oníbarà mi' 'Wọ́n ní a kò lówó tó láti díje dupò ní Nàìjíríà' ‘Lootọ ni nkan pa emi ati Baba Suwe pọ’ MURIC ní Falz tọ́‘jà Mùsùlùmí nínú orin rẹ̀ School Boy ni ohunkohun ti eti oun ba gbọ, ati nkan ti awọn eeyan n ṣe ni agbegbe oun lo maa n fun oun ni imisi lati kọrin.
Ọkùnrin yìi kún fún àbẹ̀tẹ̀lẹ̀òun ni alága ẹgbẹ́ ríkísí, òuun ni olórí àwọn alarèékérekè, òun ni balógun àwọn tí ń yọ́ kẹ́lẹ́kẹ́lẹ́ káà kiri òde òru.
Wọn kò wọ ẹ̀wù bẹ́ẹ̀ ni wọn kò wọ ṣòkòtò, ṣùgbọ́n wọ́n sán yẹ̀rì mọ ìdí, ẹyọ owó sì bo yẹ̀rì náà pátápátá.
Itakun ayelujara naa ninu iroyin ti wọn fi lede wi pe, ayipada ti awọn se lori ipolongo ọja, ipolongo ẹgbẹ oselu lori itakun agbaye naa, jẹ ọna abayọ lati koju ipalara ti oni lori ọrọ awujọ.
Nibayii na, ileesẹ ọlọpaa ilẹ wa ti kede pe lootọ ni oun fi lẹta sita lati ransẹ pe tọkọtaya Dakolo lori ẹsun ifipabanilopọ ti wọn kede nijooni.
Àwọn ìṣẹ̀lẹ̀ ńlà lọ́sẹ̀ tó kọjá tó fi mọ́ bí Covid-19 ṣe gbẹ̀mí èèyàn 23 lọ́jọ́ kan ṣoṣo Ninu ọrọ rẹ, Alhaji Bello ni lootọ Oloye Sunday Igboho mu ibẹru ba awọn eeyan nibẹ.
Airport reopening in Nigeria: Àwọn ìlànà fún ìrìnàjò bàálù tí pápákọ̀ òfurufú bá sí padà ní Nàìjíríà Oríṣun àwòrán, Getty Images Ajọ to n mojuto igboke-gbodo ọkọ ofurufu ni Naijiria, NCAA, ti gbe ilana ti awọn arinrinajo gbọdọ maa tẹle ti wọn ba ṣi awọn papakọ ofurufu pada Ajọ NCAA sọ pe nibi ti nkan de duro bayii, awọn oṣiṣẹ inu baalu gbọdọ maa wọ aṣọ idaabo bo ara lọwọ aarun, lasiko ti wọn ba wa ninu baalu.
Akowe agba naa ni pupo ninu awon omo orile ede Naijiria lo n
4 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Nkechi Blessing: Gbajúgbajà òṣèré ní ó sàn fún òun láì tíì lọ́kọ báyìí ju kí òun lọ́kọ láì láyọ lọ11 Ọ̀wàrà 2020 Nkechi Blessing: Ọ̀rọ̀ ìfẹ́ wa dàbí ti Romeo àti Juliet9 Sẹ́rẹ́ 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Èyí ni àwọn àjọ̀dún ati àpèjọ tí OLUWA yàn, tí wọ́n gbọdọ̀ kéde, ní àkókò tí OLUWA yàn fún wọn.
Kò lè ṣééṣe kí Ruga wà lápá gúúsù Nàìjíríà fáwọn Fulani- Ganduje Ẹ sọ ìwé kíkà di dandan fún ẹ̀yà Fulani - Oluwo rọ ìjọba àpapọ̀ Wo ohun tó yẹ kí o mọ̀ nípa àwọn obìnrin méje ti Buhari fẹ́ yàn sípò minista Kòsí àṣà tó faramọ́ fífi èmí ènìyàn ṣe ìrúbọ - Olúwó O ni lẹyin eyi ni wọn to ri awọn mẹtẹẹta gba pada lẹyin ọdun Ileya.
Ikubese ni kii ṣe oru nikan ni arun Coronavirus n rin, nitori naa ko yẹ ki ijọba paṣẹ konileogbele laago meje alẹ si meje owuro.
Àwọn akẹ́kọ̀ọ́ náà ni, àwọn tí lọ sí ilé ìṣe tó wà fún eto isuna láti mọ nkan tó se okùnfà idiwo láti sàn owó naa, amọ gbogbo igbinyanju awọn nibẹ lo ja si pabo.
“Baba wa kú sinu aṣálẹ̀ láìní ọmọkunrin kankan.
Wọn yóo máa lé wa lọ títí tí a óo fi tàn wọ́n jáde kúrò ninu ìlú, nítorí wọn yóo ṣe bí à ń sálọ fún wọn bíi ti àkọ́kọ́ ni; nítorí náà ni a óo ṣe sá fún wọn.
Àbí, ṣé ọ̀pọ̀ ọ̀rọ̀ lè mú kí á dá eniyan láre?
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Lizzy Anjorin vs Toyin Abraham: Lizzy Anjorin tún rọ òjò ọ̀rọ̀ tuntun lórí Toyin 19 Owewe 2019 Oríṣun àwòrán, Lizzy Anjorin/Facebook Àkọlé àwòrán, Lizzy Anjorin Bi o tilẹ jẹ pe awọn agba ọjẹ ninu ere sinima Yoruba n wa ọna lati pari aawọ to wa laarin Lizzy Anjorin ati Toyin Abraham, o dabi ẹni pe opin ko tii de ba aawọ naa.
"Ko sẹni to sọrọ lori ọrọ isẹ mi mọ, mo si fẹ ki wọn mojuto ọrọ ile iwe awọn ọmọ mi, isẹ temi naa, bẹẹ ni skọ mi gan ko ni isẹ to duro re.
Manchester United vs Arsenal: Ta ni yóò borí nínú ìjà arọ méjì yìí?
Wọn óo pe àwọn àlejò jọ sórí òkè,wọn óo sì máa rú ẹbọ ní ọ̀nà ẹ̀tọ́ níbẹ̀.
Ẹ̀yin ará, n kò lè ba yín sọ̀rọ̀ bí ẹni ti Ẹ̀mí, bíkòṣe bí ẹlẹ́ran-ara, àní gẹ́gẹ́ bí ọmọ-ọwọ́ ninu Kristi.
Bí eniyan ba wá ni ààrùn náà, àwọn kòkòrò to ń jáde kọjá milionu méjì to sì ni àwọn èròjà ààrùn naa nínú"" ""Nítorí náà, tí o bá n ba ènìyàn sọ̀rọ̀ lọ́wọ́ tí ẹni náà sì sín tàbí wúkọ́ sí ọ lójú, òó ríi bóse rọrùn láti gba kòkòrò bíi ẹgbẹ̀rún kan tí ẹni náà ba tún wa ní ààrùn náà."
Ọmọ agba olorin naa ṣalaye pe lootọ ni awọn ṣina ibọn bolẹ, oun o si sa fun ẹnikẹni o nitori pe adugbo oun loun wa, ẹnikẹni to ba si ṣe aṣemaṣe, awa maa da sẹria to tọ fun un ni.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Israel Adesanya: Romero yóò jìyà bí mo bá gbá a mú 7 Ẹrẹ̀nà 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 8 Ẹrẹ̀nà 2020 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, ǸJẹ́ ẹ̀yín mọ Adesanya tó ní òun yóò dá bàntẹ́ ìyà fún Romero?
Igboho gbosuba fun awọn gomina to wa lẹkun iwọ oorun guusu Naijiria pe wọn se ara wọn ni osusu ọwọ lori eto yii lai fi oniruuru ẹgbẹ oselu ti wọn wa se, eyi to fihan araye pe wọn nifẹ awọn araalu lọkan.
Èyíkéyìí tí ó bá wà láàyè ninu arọmọdọmọ rẹ yóo máa tọ alufaa yìí lọ láti tọrọ owó ati oúnjẹ lọ́wọ́ rẹ̀.
Ni tawọn ile ẹkọ to ni akẹkọọ to n gbe ileewe ,o ni o di dandan ki wọn mu esi ayẹwo yi wa.
Ẹka ilera Ipese eto ilera ọfẹ alabọde Igbelarugẹ eto ilera ati igbayegbadun Adinku iku awọn ọmọde ni rewe-rewe Ipese paadi nkan oṣu fawọn akẹkọọbinrin Ohun amayedẹrun Ipese ohun amayedẹrun pẹlu $10bn ti orukọ rẹ n jẹ ''Big Push.
Ki ni o sun Oluwatobi, sọja ilẹ Amẹrika di alawada ere Yoruba lori ayelujara?
Oríṣun àwòrán, THE BREAKFAST CLUB ON POWER 105.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ileejọ Kenya wọgile ofin to ti ileesẹ tẹlifisan pa 1 Èrèlè 2018 Oríṣun àwòrán, KTN Àkọlé àwòrán, Ajọ akoroyinjọ nilẹ Kenya sọ pe igbese ijọba Kenya naa ko bojumu, ti kosi lẹtọ labẹ ofin to faaye gba ominira awọn akọroyin Ile ẹjọ giga lorilẹede Kenya ti wọgile asẹ ijọba, eyi to fi ti awọn ile isẹ amohunmaworan mẹta to tobi julọ lorilẹede naa pa.
com/Y7cmInTgsd— Сборная России (@TeamRussia) July 1, 2018.
Lẹ́yìn náà, Joṣua ọmọ Nuni rán amí meji láti Akasia, lọ sí Jẹriko, ó ní, “Ẹ lọ wo ilẹ̀ náà, pàápàá jùlọ, ìlú Jẹriko.
Awọn eeyan naa ni wọn sọ pe, lai naani bawọn se n kigbe tako iwa ika latọdọ awọn ọlọpaa, se ni ọlọpa kan tun yinbọn mọ onikẹkẹ Maruwa kan, to si gbẹmi lẹnu rẹ.
Labẹ ijọba Romu, ẹya Giriki, Juu ati Egipti lo korajọ pọ n jẹ ẹlẹsin kristẹni Coptic.
ti o to, eleyi ti o tunmo si pe, orile-ede ti o ba kaju osuwon ni ajere sise
A ni ọpọ ero ti iyawo mi ko lẹyin wa si agboole wa ti wọn duro bi o ṣoju mi fun igbeyawo nikẹyin.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ẹfunroye Tinubu - Ògbóǹtagí oníṣòwò, olówò ẹrú àti afọbajẹ Samuel Ajayi Crowther, òjíṣẹ́ Ọlọ́run tó gbé èdè Yoruba lárugẹ Mọrèmi Àjàṣorò, akọni obìnrin tó gba Ilé Ifẹ̀ sílẹ̀ lóko ẹrú Ọ̀rọ̀ǹpọ̀tọ̀niyùn, Aláàfin obìnrin àkọ́kọ́ rèé, tó ní nǹkan ọkùnrin Iwa aanu rẹ yii si lo mu ki ọpọ eeyan jade lati dibo fun pe ko di aarẹ Naijiria lọjọ Kejila, osu Kẹfa ọdun 1993, bi o tilẹ jẹ pe wọn ko kede rẹ bii aarẹ, eyi to fa rogbodiyan ni Naijiria, to si tun da ẹmi MKO Abiọla legbodo, amọ ti awọn eeyan n seranti rẹ titi di oni oloni.
Fidio: Obinrin to ni ejo mi 36m naira JAMB Eku sé oko ìrẹ́si lọsẹ́ ni Kebbi Coronavirus and OCD: 'Mo fi ogún ọdún gbáradì fún àjàkálẹ̀ ààrùn yìí' Coronavirus: Kíni àwọn àmì tuntun tó n fihàn?
“Wò ó, a gbé OLUWA ga ninu agbára rẹ̀;ta ni olùkọ́ tí ó dàbí rẹ̀?
Ti a ko ba gbagbe, laipẹ yii ni ile ẹjọ da ẹjọ iku fun Abileko Maryam Sanda fun fifi ọbẹ gun ọkọ rẹ lori ẹsun pe o n ṣe pansaga ninu igbeyawo wọn.
Aṣiwaju Ẹgbẹ Oṣelu to pọ ju ninu Ile, Aṣofin Sanai Agunbiade naa ki Oba ku oriire.
Oríṣun àwòrán, Others Ajagun fẹyinti Babangida jẹ aarẹ ologun orilẹede Naijiria laarin ọdun 1985 si 1993.
''Awọn alainikanṣe ẹgbẹ Democrat mọ pe awọn ko le bori rẹ, nitori naa ni wọn fi n dete iyọni-nipo'' Atẹjade wọn tẹsiwaju pe, ọna ati ṣe ipolongo ni 'iṣẹlẹ buruku' yii ati 'iranu' ti wọn ṣe jẹ.
Labani bá dá a lóhùn pé, “Ó dára, ohun tí o wí gan-an ni a óo ṣe.
Àwọn tí ó jẹ pàtàkì tí mo mọ̀ nínú àwọn èrò náà ni mo kà sílẹ̀ yìí.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Kí ni àmì ohùn 'Aguntaṣọọlo'?
“Ṣugbọn ní òkè Sionini àwọn tí wọ́n bá sá àsálà yóo máa gbé,yóo sì jẹ́ òkè mímọ́;àwọn ọmọ Jakọbu yóo gba ohun ìní wọn pada.
Nibayii, ninu aibalẹ ọkan ni ọpọ awọn ololufẹ Liverpool wa bayii lori pe, ki ọrọ rẹ ma si di eyi ti ko ni lee gba bọọlu fun igba pipẹ, paapaa julọ bi idije ife ẹyẹ agbaye ṣe n bọ lọna.
Lori 'App' ileefowopamọ to wa lori ẹrọ ibanisọrọ alagbeka rẹ, tẹ 'Cardless Withdrawal' lara awọn igbesẹ ti o ba gbe wa fun ọ.
Ta ni olori ọmọ ogun Ethiopia, Saere Mekonnen?
Lọ láti ilé rẹ sí ibòmíràn bí ẹni tí ń lọ sí ìgbèkùn.
Naijiria, ti o tun je ajagun feyinti teleri, ogagun Ibrahim Badamasi Babangida,
Ayẹwọ naa ti o tẹ awọn oniroyin lọwọ fi han wi pe ko si aisan kankan lara arakunrin naa ki o to ku lojiji lẹyin iṣẹlẹ pẹlu awọn ọlọpaaa naa.
Nínú ìtàn rẹ̀, Wòlíì náà ṣe àfihàn rẹ̀ bíi “òfin ti Ọlọ́run tí kìí sìí ṣe ti ènìyàn, sí Martin Harris, tí a fi fúnni láti ọ̀dọ̀ ẹni náà tí ó jẹ́ Ayérayé.
Bí o kò bá jí lójú oorun, n óo dé bí olè, o kò sì ní mọ àkókò tí n óo dé bá ọ.
Oríṣun àwòrán, Instagram/Lady Peller Lady Peller fi kun pé, nínú àwọn ìdá ti àwọn máa n ṣe nígbà míran tí ọkọ́ òun yóò gé òun sí méjì nínú pòsí, kò sí èyí tí òun siyè méjì níbẹ̀ rí, nítorí pé òun mọ pé kò ni ṣe aburu fún òun.
Laarin ọdun kan, o wọ ileewe girama.
Iná Edo: Àwọn ọmọ ni àdájọ́ lọ wò ní fásitì, tí ina fi mú wọn
Yika Naijiria ni iku ti n mu awọn eeyan lọ, ti a si ri atọkasi pe arun Covid 19 to n ja rainrain nilẹ bayii, ni ipa to n ko ninu rẹ.
Ṣùgbọ́n bí àwọn Èdìdàrẹ́ ti gọ̀ tó nì, kò sí ẹyọ kan nínú àwọn tí o bá ni kúrò nínú ìlú wọn tí o jẹ́ pé ó kú sínú odò Ẹ̀jẹ̀, gbogbo wọn ni wọ́n dé òdì kejì dáadáa.
Àwọn ọba Yorùbá kan rèé tí wọ́n rọ̀ lóyè, tí ọba míràn jẹ lójú ayé wọn Ọba Lamidi Adeyẹmi, òṣìṣẹ́ adójútòfò àti Abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò kó tó jọba Duro Ladipọ, ìlúmọ̀ọ́ká òṣèré tíátà àti ọmọ àlúfà tí kò gbàgbé àṣà ìbílẹ̀ Wo ìmọràn tó lè jẹ kóo gbádùn ṣíṣe iṣẹ láti ilé lásìkò kónílé-ó-gbélé COVID 19 yìí Ikú Mugabe jẹ́ àdánù fún gbogbo ilẹ̀ Afiríka lápapọ̀ - Ọbasanjọ Irú èpè wo ni Aláàfin Aolẹ ṣẹ́ fún ìran Yorùbá?
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ganiyat tó fi irin gbígbóná àti àdá ya ara ọmọ àbúrò ọkọ rẹ ti dèrò àgọ́ ọlọ́pàá l' Ogun 26 Bélú 2020 Oríṣun àwòrán, others Ileeṣẹ ọlọpaa ipinlẹ Ogun ni iwadii ti bẹrẹ lati fi arabinrin afunrasi naa jofin.
Èkúté t;obi ju òk;et;e, ìgbín si tóbi ju ìjàpá, nínú Igbó Olódùmarè.
Nígbà tí wọ́n dé orílẹ̀-èdè tí mo fọ́n wọn ká sí, wọ́n bà mí lórúkọ jẹ́, nítorí àwọn eniyan ń sọ nípa wọn pé, ‘Eniyan OLUWA ni àwọn wọnyi, sibẹsibẹ wọ́n kúrò lórí ilẹ̀ OLUWA.
O ni jijẹ, mimu, ile ati idagbasoke ọmọ ṣe koko, eleyii ti ijọba kọ lati fi ṣe iranwọ fun awọn obi.
Ninu àwọn tí wọn ń jẹ àpọ̀jẹ tabi tí pátákò ẹsẹ̀ wọ́n yà, ẹ kò gbọdọ̀ jẹ àwọn wọnyi: ràkúnmí, nítorí pé ó ń jẹ àpọ̀jẹ, ṣugbọn pátákò ẹsẹ̀ rẹ̀ kò yà, ó jẹ́ ohun àìmọ́ fun yín.
Aare ajo FIFA, Gianni Infantino soro lori igbese igbaradi ti Russia ti gbe lati gbalejo idije lodun yii.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Amọṣa aarẹ ko ṣai ṣe gafara fun awọn oṣiṣẹ ti iṣẹ wọn jẹ koṣemaani lasiko naa bii awọn oṣiṣẹ eto ilera, akọroyin ati bẹẹbẹl lọ.
Aago mẹ́fà sí mẹ́jọ ni ọ̀gá ọlọ́pàá máa ń rí ènìyàn ṣùgbọ́n ó gbà láti rí Akin àti Ilésanmí lẹ́yìn ìgbà tí ó ti rí káàdì Akin.
Ó yẹ kí ọmọdékùnrin àti ọmọdébìnrin máa la ojú wọn sílẹ̀ dáradára kí wọ́n sì máa bẹ Ọlọ́run Ọba ki ó tọ́ wọn sí ọ̀nà kí ó tóó di pé wọ́n bẹ̀rẹ̀ sí fẹ́ràn ẹnìkan.
Oríṣun àwòrán, AFP Àkọlé àwòrán, Eto aabo to peye ti jẹ ipenija nla fun orilẹede Naijiria Awọn gomina ti o wa nibẹ ni, Atiku Bagudu ti ipinlẹ Kebbi, Udom Emmanuel lati ipinlẹ Akwa Ibom ati Aminu Masari ti ipinle Katsina.
Eyi tumọ si pe awọn oṣiṣẹ ipele kini si ikejila to ti wa nile tẹlẹ latari ọna lati dẹkun itankalẹ ajakalẹ arun coronavirus ni iṣẹ ti bẹrẹ pada fun bayii.
oríṣìíríṣìí ọ ̀ nà ni a le gbà mọ ohun tí à ń pè ní orin ifá .
Yironi, Migidalieli, Horemu, Betanati ati Beti Ṣemeṣi, gbogbo ìlú ati àwọn ìletò wọn jẹ́ mọkandinlogun.
Ondije oluja omo orile-ede Amerika, Deontay Wilder so pe, oun ko lero pe ifigagbaga pelu Anthony Joshua ko ni waye, bi o ti le je pe, oun ko àádọ́ta milionu owo dola sile fun ifigagbaga ohun, eyi ti iko naa ko lati gba.
Trump ni adehun yii yoo lamilaaka ju iru adehun ti wọn ti jọ ṣe tẹlẹ lọ, nigba ti wọn wa ninu ajọ EU.
Ó ti pa àkọsílẹ̀ tí ó lòdì sí wa rẹ́, ó mú un kúrò, ó kàn án mọ́ agbelebu.
FUTA pàṣẹ lọ rọọ́kún nílé f'ákẹ́ẹ̀kọ́ méje tó lu akẹgbẹ́ wọ́n Afunrasí jàǹdùkú 22 lọ́wọ́ ọlọ́pàá ti tẹ̀ lórí wàhálà ìdìbò ní Kogi-Iléeṣẹ́ Ọlọ́pàá Èwo nínú àwọn amóhùnmáwòrán yìí lẹ rántí?
Ṣugbọn ní tèmi, mo kún fún agbára, ati ẹ̀mí OLUWA, ati fún ìdájọ́ òdodo ati ipá, láti kéde ẹ̀ṣẹ̀ Jakọbu, ati láti sọ ẹ̀ṣẹ̀ àwọn ọmọ Israẹli fún wọn.
Ìfihàn tí a fi fúnni nípasẹ̀ Wòlíì Joseph Smith sí Joseph Knight Àgbà, ní Harmony, Pennsylvania, Oṣù Karũn ọdún 1829.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù #EndSARS: Pe nọ́mbà wọ̀nyìí láti fẹjọ́ ọlọ́pàá SARS sùn 15 Òkùdu 2018 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 19 Òkùdu 2018 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Àwọn ọlọ́pàá kògbérègbéè SARS lẹ́nu iṣẹ́ Awọn ọlọpaa Naijiria ti kede awọn nọmba ti awọn eeyan le pe wọn sori ẹ ti awọn ọlọpaa SARS ba n dunkooko mọ wọn Iṣẹ awọn ọlọpaa SARS ni lati gbogun ti iwa ibajẹ lawujọ paapa julọ lati daabo bo awọn ara ilu lọwọ awọn adigunjale.
, ìròyìn sọ pé ǹkan tun buru síi nígbà ti ọmọ Somali kan yìnbọn pa ọdọmọde kan to ń gbìyànjú àti jí ọja rẹ̀.
Oṣu kejila ọdun 2008 ni Burnley fi ẹyin Arsenal gbolẹ kanyin Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Ẹ̀rù ati ìwárìrì dà bò mí,ìpayà sì bò mí mọ́lẹ̀.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Aworan Afrika to rẹwa ju laarin ọsẹ 3 Ẹrẹ̀nà 2018 Ẹsa ninu awọn aworan to rẹwa ju lati Afrika ati tawọn ọmọ Afrika lagbaye ninu ọsẹ yii.
DPO Gwazah eleyii ti ko tii yọju sile ẹjọ lati igba ti igbẹjọ naa ti bẹrẹ pe Adeniyi lẹjọ pe o ba aṣọ ti oun gbe fun lati ran jẹ.
Tètè kúrò níwájú ọba, má sì pẹ́ lọ́dọ̀ rẹ̀ nígbà tí ọ̀rọ̀ bá ń di ibinu, nítorí pé ohun tí ó bá wù ú ló lè ṣe.
Ohun Tí Ó Ṣẹlẹ̀ ní Kadeṣi.
Kunle Afolayan, òṣìṣẹ́ báńkì tẹ́lẹ̀ kó tó di gbajúgbajà òṣèré Òtítọ́ inú òfin ilẹ̀ Nàìjíríà nípa asòfin tó bá jẹ́ ọmọ orílẹ̀èdè méjì?
CP Omololu Bishi - CP Benue Command xxxi.
god : n ; ( christians and muslims believe in one god ; in other religions there are different gods for raim , fire , health e.
O sọ pe awọn obi oun sọ fun pe oun ko ju ọmọ ọdun kan lọ nigba ti iṣẹlẹ naa waye.
Funke Akindele, oníròyìn, agbẹjọrò àti òṣèré; ohun tí ẹ kò lérò nípa rẹ̀ Àwọn Olúkọ ìpínlẹ̀ Oyo fakọyọ lórí ètò Akọ́mọlédè àti Àṣà púpọ̀ Toyin Abraham fi orin yẹ́ Iyabo Ojo sí níbi ìsìnkú ìyá rẹ̀, Falz di ẹni tí wọ́n fí òpópónà ṣọ orí rẹ̀ Látilẹ̀ ni mo ti fẹ́ràn orin ìjọ Kérúbù àmọ́ ẹlẹ́sìn mùsùlùmí àti krìstẹ́nì ni mí- Qdot Èèmọ̀ rèé!
Otubela sọ ninu atẹjade kan to fi ránṣẹ si BBC pe awọn ileewe aladani naa yoo pin ninu 2.
Kí ọmú rẹ dàbí ìdì èso àjàrà,kí èémí ẹnu rẹ rí bí òórùn èso ápù.
Ní òpin ọ̀sẹ̀ tó kọjá, ìyẹn Àbámẹ́ta àti Àìkú ọjọ́ 27 àti 28 oṣù yí, gọngọ sọ ní agbègbè Hackney.
"Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ìdẹ̀ra dé, Gẹnẹrátọ̀ tó ń lo omi dé, a bọ́ lọ́wọ́ òkùnkùn ""Ojú wa rí tó ní Egypt, bí wọ́n ṣe ń tẹ̀ wá lọ́mú, ni wọ́n ń gbá wa ní ìdí"" Ọlọ́wọ̀ tìlú Ọ̀wọ̀ tuntun gorí ìtẹ́, idà àlááfìà ló mú ní Ìpèbí Á máa ṣíjú àánú wo ẹlẹ́wọ̀n láti mú àdínkù bá ọgbà ẹ̀wọ̀n - Ìjọba Ọyọ Toyin Abraham kìí bá èmi náà yọ̀, ni kò jẹ́ kí ń gbé e lárugẹ fún ayọ̀ ọmọ - Lizzy Anjorin Ọjọgbọn Ṣoyinka sọ pe, nigba ku gba ti ijọba ba n fi awọn ologun, ọlọpaa atawọn ọtẹlẹmuyẹ dunkoko mọ ara ilu, o tumọ si pe ijọba n bẹru ni."
Àwọn ni wọn óo kọ́ ọ,tí wọn óo bá ọ sọ̀rọ̀,tí wọn óo sì fún ọ ní ìmọ̀ràn ninu òye wọn.
Coronavirus pandemic: Ẹgbẹ́ àwọn àgbẹ̀ ní Nàìjíríà ní ìyàn ń bọ̀ lẹ́yìn coronavirus àyàfi.
Iyansipo ohun waye lojo Aiku(Sunday) lati ropo Dave Sarachan, eleyi ti yoo so di akonimoogba tojo ori re kere julo ti yoo tuko agbaboolu orile-ede naa lati saa Steve Sampson lọdun 1995.
Òrìṣà ni ìyá mi, kìí ṣe ènìyàn, òun sì ni alátìlẹ́yìn mi - Wòlíì Àrólé Oríṣun àwòrán, Wolii arole Ilumọọka adẹrinposonu lórí ayelujara, Oluwatoyin Bayegun, tí ọ̀pọ̀ èèyàn mọ si Wòlíì Arole, tí ṣàlàyé pé ore-ọ̀fẹ́ àti àánú Ọlọ́run ló gbé òun sókè.
 Ènìyàn le mú irú ìlù yìí le .
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Coronavirus: Kò sí ẹni tí coronavirus kò le mú Ajọ NCDC tun ṣe atupale awọn ipinlẹ ti arun Coronavirus naa ti tan de.
A bi Olóògbé, Olóyè Hannah Ìdòwú Dideolú ni ọjọ́ karundinlọ́gbọ̀n, oṣù kọkanla, ọdún Ẹ̀dẹ́ẹ́gbãlemẹ̃dógún, ó ṣe igbéyàwó pẹ̀lú Olóògbé Olóyè Ọbáfẹ́mi Awólọ́wọ̀ àgbà Òṣèlú ni ọjọ́ kẹrindinlọ́gbọ̀n, oṣù kejila, Ẹ̀dẹ́ẹ́gbãlemẹ̃tadinlọ́gbọ̀n, o jade láyé nigbati ó kú bi oṣú meji ó lé di ẹ ki ó pé ọgọrun ọdún.
APC pàdánù aṣòfin míràn ní'pínlẹ̀ Osun Ninu iroyin miran ẹwẹ, Pẹlu gbogbo gbọnmọgbọnmọ iroyin nipa awọn oloṣelu to n fi ẹgbẹ oṣelu APC silẹ nipinlẹ Ọsun, kaka ki ewe agbọn ọ dẹ fun ẹgbẹ oṣelu naa, lile lo n le ṣii o.
"O ni ""igbagbọ wa ni wipe igbesẹ naa yoo mu opin de ba ija to n waye ni gbogbo igba laarin awọn darandaran ati agbẹ lawọn ipinlẹ kan l'orileede yi."
Ladoja - BBC News Yorùbá BBC News, YorùbáFò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù El-Zakzaky: Arúfin ni ijọba Muhammadu Buhari gan-an - Ladoja 11 Ògún 2019 Àkọlé àwòrán, El-Zakzaky: Arúfin ni ijọba Buhari gan-an - Ladoja Gomina tẹlẹri nipinlẹ Ọyọ, ti o tun jẹ Osi Olubadan ti ilẹ Ibadan, Oloye Rashidi Ladọja ti bẹnu atẹ lu ijọba apapọ lori ẹgbẹ Shiite, gẹgẹ o ti ṣe alaye wi pe ijọba apapọ gan an lo n ru ofin lori aṣẹ ti ile ẹjọ pa wi pe ki wọn da adari ẹgbẹ naa, El-Zakzakky silẹ.
Ọrọ ko pariwo rara nigba ti ọkan lara awọn afurasi to wa ni ahamọ ọlọpaa lori isẹlẹ yii ka boroboro nipa ohun ti wọn se, ti ile fi jona.
Gẹgẹ bi iroyin to tẹwa lọwọ lati ọdọ News Agency of Nigeria, NAN, Adama sọ pe abala ikini ninu awọn eeyan naa yoo gbera kuro ni South Africa laago mesan aarọ Ọjọru.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, AFCON 2019: Àwọn ọmọ Naijiria sọ̀rọ̀ lórí ìdíje Madagascar àná Lẹyin eyi lo pada si ilu Igbara Oke lati tẹdo sibẹ.
Ni ipari, Aare seleri pe eka amusese yoo tubo fowosopo pelu eka asofin nijoba ki ilosiwaju le de ba Naijiria.
Igbọnwọ mẹsan-an ni gígùn pósí náà, ó sì fẹ̀ ní igbọnwọ mẹrin.
Awọn ti ọrọ soju wọn sọ pe ikun ni ibọn ti ba Oloruntoba nigba ti afurasi naa si fẹsẹ fẹẹ.
"Ti gbogbo ọba ba le ṣe, alaafin jẹ ẹni to yẹ ki wọn o ma a lọ si ọdọ rẹ lojoojumọ, lati ma a gbọ itan nipa ilẹ Yoruba.
Àwọn ará Filistia kó ara wọn jọ láti bá Israẹli jagun.
Brazil: Àwọn ọlọ́pàá tí f'òfin mú ẹyẹ tó n tú àṣírí fún àwọn ọ̀daràn
Palmatah Mutah, ẹni ọdun mẹtalelogun, to bẹ silẹ ninu ọkọ lasiko ti wọn n gbe awọn akẹkọbinrin naa lọ, ni akẹkọọbinrin Chibok akọkọ to kẹkọ gboye imọ ijinlẹ akọkọ nilẹ okeere.
Ọ̀kan lára àwọn agbébọn tẹ̀lẹ̀, tíí se ẹni ọdún mọ́kànlélógún, tó wà ní àgọ́ àwọn ológun ilẹ̀ Nàíjíríà, lẹ́yìn tó ti sá ní àgọ́ Boko Haram lósù kínní 2018, sàlàyé pé ọdún mẹ́rin ni òun fi gbé inú igbó níbi tí kò sí omi tó tó tàbí oúnjẹ - sùgbọ́n Tramadol wà.
Pẹlu ìnira ni wọ́n sì ń ṣe gbogbo iṣẹ́ tí wọn ń ṣe.
Bobrisky dárò pé EFCC gbé Mompha, ọ̀dọ́mọdé olówó tó ń lo aago ₦20m Mò ń dókòòwò láti pín ọrọ̀ mi yíká Nàíjíríà kí àdínkù leè bá ìṣẹ́ - Dangote Kí ló dé tí Ilé ẹjọ́ sún ìgbẹ́jọ́ Naira Marley sí ọ̀la?
83ninu ida ogorun si iko 1.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ijamba ọkọ ran eeyan mẹjọ lọ srun lopopona marosẹ Ibadan si Eko 6 Èrèlè 2018 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Awọn eero inu ọkọ akẹru lo ku ninu isẹlẹ naa Ko din ni eeyan mẹjọ to padanu ẹmi wọn ninu ijamba ọkọ ajagbe ejo kan to waye lopopona marosẹ Eko si Ibadan lọjọ isẹgun.
lori ọdun Hijira, ikọkankanla rẹ, ti Ile Igbimọ Aṣofin Ipinlẹ Eko n
Oríṣun àwòrán, Mike bamiloye/facebook Olorin Kristẹni, Lawrence Oyor ni ọkọ iyawo, to si jẹ ọmọ Oluṣọ Agutan Gomba Fortune to di oloogbe laipẹ yii.
Aare orile-ede Nigeria, Muhammadu Buhari ti bale sipinle Borno fun ayeye ayajo iko omo-ogun Naijiria Nigerian Army Day Celebration (NADCEL).
Ó ní “bí iṣu ẹni bá ta àá fọwọ́ bòójẹ ni”!
Jeremaya sọ ọ̀rọ̀ náà fún gbogbo àwọn ará Juda ati àwọn tí wọn ń gbé Jerusalẹmu.
Lẹ́yìn náà, ọkunrin náà wí fún mi pé, “Àwọn yàrá ẹ̀gbẹ́ ìhà àríwá ati àwọn yàrá ìhà gúsù tí wọ́n kọjú sí àgbàlá ni àwọn yàrá mímọ́.
Nǹkan iyì ni pé kí eniyan máa yẹra fún ìjà,ṣugbọn òmùgọ̀ eniyan níí máa ń jà.
Amọ, eyi ko jẹ iṣoro rara, nitori pe inu rere kan naa ni ẹyin mẹtẹẹta ni."
Ko pẹ lẹyin rẹ ni Ọwọ Ọlọ́pàá tẹ afunrasi méjì tó mọ nípa ikú dókítà LUTH naa.
Nitori pe Allah (SAWA) yoo se alekun ati ibukun si irun kọọkan ati bi eekanna naa ba ṣe gun to, titi di asiko ti yoo fi ge irun rẹ tabi eekanna.
Awọn eeyan mii tiẹ n beere pe ta ni ọkunrin ti wọn n sọrọ nipa rẹ gan an.
Ìtàn Mánigbàgbé: Àáró tó yẹ kí Lisabi gbà, ló fi bẹ ọ̀wẹ̀ láti kọlu Ìlàrí Ọlọyọ fún ìdáǹdè Ẹ́gbá
Nọ́mbà ẹ̀rọ ibanisọrọ ti o fi ṣe akọsilẹ NIN rẹ yoo jade pẹlu ibeere meji pe: Mo ṣi n lo nọ́mbà yii Mi o lo nọ́mbà yii mọ Tẹ eyi to ba jẹ ninu mejeeji, ki o si tun tẹ 'Next'.
Ó wólẹ̀, ó dojúbolẹ̀ níwájú rẹ̀, ọba bá fi ẹnu kò ó ní ẹnu.
Láti ìlà oòrùn ni yóo ti pe orúkọ mi;yóo máa gún àwọn ọba mọ́lẹ̀ bì ìgbà tí wọ́n gún nǹkan ninu odó,àní, bí ìgbà tí amọ̀kòkò bá ń gún amọ̀.
Ọjọ́ mẹfa ni kí ẹ máa fi ṣiṣẹ́, ṣugbọn kí ẹ ya ọjọ́ keje sọ́tọ̀ fún OLUWA bí ọjọ́ ìsinmi tí ó lọ́wọ̀; ẹnikẹ́ni tí ó bá ṣe iṣẹ́kíṣẹ́ ní ọjọ́ náà, pípa ni kí ẹ pa á.
Iṣẹlẹ idigunjale naa ṣe ọpọ ni kayefi nitori kii si igba kan ti kii si ọlọpaa to n ṣọ agọ ọlọpaa naa.
Afe mọ ohun ti obinrin yii n wo.
Awọn ẹjẹ kan naa kii fẹ jade wa jẹri tako ara wọn nitori pe inu mọlẹbi kansoso ni wọn ti wa, wọn kii si fẹ ki mọlẹbi wọn lọ sẹwọn, nitori naa ni yoo se nira lati se iru ẹjọ bẹẹ ni aseyanju.
Rivres , Nyesom Wike sọ pe egbe PDP 
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, David Adiatu oníṣẹ́ ọnà pẹ̀lú ìṣó àti òwú Lẹyin eyi ni iroyin ni Femi Adesina to jẹ olubadamọran fun Aarẹ Buhari lori eto ifitonileti ti sọ ni Tribune Online pe awọn kan ni wọn gbe irọ naa kalẹ.
Òrìṣà ni ìyá mi, kii se ènìyàn.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ayo Fasanmi Afenifere: Ta ni Bàbá Fasanmi tí wọ́n ń gbé lọ sí Iye Ekiti padà lẹ́yìn tó papòdà?
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Building Collapsed: O kéré tán, ènìyàn 10 ló ti jáláìsí níbi ìṣẹ̀lẹ̀ ilé tó wó ọ̀hún 16 Agẹmo 2019 Oríṣun àwòrán, other Àkọlé àwòrán, Building Collapsed: O kéré tán, ènìyàn 5 ló ti jáláìsí níbi ìṣẹ̀lẹ̀ ilé tó wó ọ̀hún O kéré tán, ènìyàn 5 ló ti jáláìsí níbi ìṣẹ̀lẹ̀ ilé tó wó ọ̀hún.
Ninu iroyin kan latọdọ ẹka ede Hausa ti ile iṣẹ BBC ni alaga ẹgbẹ oṣelu APC, Adams Oshiomole ati adari kan fun ipolongo Atku, Sẹnetọ Rabiu Kwankwaso ni ofin idibo faaye gba i[polongo ko to di wakati mẹrinlelogun ṣaaju ọjọ idibo.
Wọn yóo fi àmì ńlá hàn, wọn yóo sì ṣe iṣẹ́ ìyanu láti tan eniyan jẹ; bí ó bá ṣeéṣe fún wọn, wọn óo tan àwọn àyànfẹ́ pàápàá jẹ.
Mo ti nawọ́ ìyà si yín, n óo sì fi yín ṣe ìkógun fún àwọn orílẹ̀-èdè mìíràn.
Àwọn ọmọ Harifi jẹ́ aadọfa ó lé meji (112).
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Usman vs Masvidal: Àlùbami ní Kamuru na Jorge Masvidal láti dí Àmí Ẹ̀yẹ rẹ mú!
" Lori bi ẹgbẹ awọn darandaran ni Naijiria, Miyetti Allah, ṣe ni ki wọn fi ofin gbe aarẹ Naijiria nigba kan, Olusegun Obasanjo nitori lẹta to kọ si arẹ Muhammad Buhari lori ọrọ eto aabo ni Naijiria laipẹ yii, ẹgbẹ OPC sọ pe ki ẹgbẹ Miyetti Allah ''ṣọra lati maa wa ẹni ti wọn fẹ fi j'ofin fun awọn iwa ti ko tọ ti wọn n hu.
lorile ede Naijira, ogbeni Rotimi Amaechi lo sọ eyi di mimọ, nile –ise ajọ naa
Nigeria Customs: Àwọn ìgbà tí ẹ̀ṣọ́ aṣọ́bodè ti pànìyàn lọ́nà àìtọ́
Ní orúkọ Jesu Kristi ti Nasarẹti, máa rìn.
Kí ló dé tí wọn bí mi sáyé?
 Ọpọ ̀ lọpọ ̀ ènìyàn ni kò mọ àwọn àmì tí a maa ń rí tí ó bá ṣẹ ̀ ṣẹ ̀ bẹ ̀ rẹ ̀ .
Wọ́n ń jẹ́wọ́ ẹ̀ṣẹ̀ wọn, ó sì ń ṣe ìrìbọmi fún wọn ninu odò Jọdani.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Gbigba bọọlu sáwọ̀n kọja ààwọ̀ dudu tabi pupa Ikú to n pa ojúgbà ẹni, òwe nla lo n pa fun ni.
Ìgbìmọ̀ ìgbẹ́jọ́ ìdìbò ààrẹ kọ ẹ̀bẹ̀ ẹgbẹ́ PDP láti yẹ ojú òpó ayélujára INEC wò
Lójú kan náà, angẹli bá rá mọ́ Peteru lójú.
Oruko afurasi ti won gba pe o ju ado-oloro to dun ni Manchester ni awon olopaa kede ni Salman Abedi.
Nígbà náà ni ẹ óo ranti ìrìnkurìn ati ìwà burúkú yín, ara yín óo sì su yín nítorí ẹ̀ṣẹ̀ yín ati ìwà ìríra yín.
O ni idi ni pe awọn ẹya Yoruba nikan lo n ra fiimu lede Yoruba, nigba ti fiimu oloyinbo jẹ itẹwọgba kari aye.
Àjọ Elétò ìdìbò INEC ti sọ̀rọ̀ lórí iná tó jó àwọn káàdì ìdìbò ní Ondo Adájọ́ ní kí Ahmed Danladi, tó jẹ́ awakọ̀ tó jalè gbálẹ̀ kóòtù f'ọ́jọ́ méjì ní Abuja Ọ̀dọ́ Nàíjíríà fèsì padà fún Buhari lórí ìkéde pé kí wọn padà sóko Wo àmì márùn-un tí o fi le mọ ẹni tó fẹ́ gbẹ̀mí ara rẹ̀ Toyin sọ loju opo Instagram rẹ pe ileeṣẹ naa yoo da lori idilẹ ati eto ẹkọ, eyii ti wọn yoo fi sọri ọmọ naa.
2018: Badeh, Alkali bẹ̀rẹ̀ ọdún 2018 ṣùgbọ́n wọn kò là á já
Nígbà tí àwọn ọmọ ogun kéde pé ènìyàn mẹ́ta nínú ọmọ Shí'ite tún kú, sùgbọ́n àwọn ọmọ Shi'ite sọ pé ó lé ni èèyan ààdọtá tí àwọn ọmọ ogun pa.
Ìdí márùn ún tí agbára Covid 19 ní ilẹ̀ Adúláwọ̀ kò fi tó tí àwọn ilẹ̀ àgbáyé míràn A máa ná N10.
Nígbà tí Jesu gbọ́, ó wọ ọkọ̀ ojú omi kúrò níbẹ̀ lọ sí ibìkan tí eniyan kò sí, kí ó lè dá wà.
Ki wa ni nkan ti wọn se ti wọn fi pegede?
Mo ti bá ọba Olúwò lórí ọmọbinrin ọdún mẹ́tàlá rìí- Olorì chanel Àwọn àràmọ̀ndà ìbomú-bẹnu tó gbòde lásìkò Coronavirus yìí Oríṣun àwòrán, Others Àkọlé àwòrán, Ilé ẹ̀jọ́ tún pàṣẹ pé ẹnikẹ́ni tó bá nífẹ̀ẹ́ láti ra àwọn dúkìá náà gbọ́dọ̀ yọjú láàárín ọ̀sẹ̀ méjì péré Àwọn dúkìá yókù tí Ojerinde yín pàdánù ni, ilé epo àti gaasi Doyin tó wà nilu Ibadan, ilé Tejumola to wá ní Ikeja n'ilu Eko tó fi mọ ilé awodamienu kan tó wà lojule Kẹrìnlá, Yobe close, Maitama n'ilu Abuja pẹ̀lú dúkìá rẹ miran tó wà ní orílẹ̀ èdè South Africa.
ó pàṣẹ pé kí wọ́n la ààyè ọmọ sí meji, kí wọ́n sì fún àwọn obinrin mejeeji ní ìdajì, ìdajì.
Bolaji Abdullahi to jẹ agbẹnusọ fun ẹgbẹ oselu APC teleri wa lara awọn to sẹsọẹ kede erongba lati du ipo naa.
Àjẹjù Ṣúgà ò dára fún Ènìyàn
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Victor Agunbiade ni ojú àlá ni Ọlọrun ti yan iṣẹ́ ọmọ ogun ojú omi fún òun ní America 5) Adewumi Kuforiji: Ni Delaware, Adewumi Kuforiji n dije fun ile igbimọ aṣofin ipinlẹ, lati ṣoju ẹkun idibo kẹrinlelọgbọn.
Lẹ́yìn náà, Joabu fọn fèrè ogun, kí wọ́n dáwọ́ ogun jíjà dúró.
”Jesu wá sọ fún un pé, “Èyí ni pé kò kan àwọn ọmọ onílẹ̀.
Ayé á fi ẹnu rẹ̀ tẹ́ńbẹ́lú òriṣà
Biṣọbu Godwin ṣalaye pe ajọ PFN ti kede ọjọ meji bayii fun akanṣe adura lati rii pe apero naa ko waye.
Àwọn ọmọ Paroṣi jẹ́ ẹgbaa, ó lé mejilelaadọsan-an (2,172).
Awon onkorin Naijiria ti moke nitori pe ise won ti lo kaakiri agbaye, ohun to ku ni ki a fimo sokan ki a maa ko ara wa siwaju.
Gomina fi ṣọwọ si Il-Igbimọ Aṣofin naa.
àwọn ará Sabea rí wọn, wọ́n sì kó gbogbo wọn, wọ́n sì fi idà pa gbogbo àwọn iranṣẹ, èmi nìkan ni mo sá àsálà láti wá ròyìn fún ọ.
Laipẹ ni iroyin jade pe igbimọ alaṣẹ ẹgbẹ oṣelu AAC ti jawe lọ simi fun Omoyele Sowore to jẹ alaga wọn.
Ìyà àti ìṣẹ́ ni fún ọmọ púpọ̀ àti àwon iyàwó ọkùnrin ti kò ni iṣẹ́ tàbi eyi ti ó ni iṣẹ́ ti kò wúlò.
Wọ́n bá bù ninu ẹja díndín fún un.
silẹ paapaa julọ lori awọn wo gan an lo ṣiṣẹ laabi naa.
Eyi ko sẹyin bi o ṣe satilẹyin fun ẹgbẹ oṣelu NCNC to jẹ ti Oloye Nnamdi Azikiwe, dipo Action Group ti Obafemi Awolowo da silẹ.
Èrò ọmọ Nàíjíríà sọ̀tọ̀ọ̀tọ̀ lórí ₦30,000 owó osù òsìsẹ́ Kí lo fẹ́ mọ̀ nípa ‘Ajala Travels’?
Wọn óo kọ́ ilé, wọn óo gbé inú rẹ̀;wọn óo gbin ọgbà àjàrà, wọn óo sì jẹ èso rẹ̀.
Agbébọn pa ẹ̀nìyàn 20 ní Texas l'Amẹrika Wo àwọn àwòrán ìgbà ayé Aretha Franklin George H.
Lẹ́yìn náà ó rí i, ó sì sọ ọ́ jáde,ó fi ìdí rẹ̀ múlẹ̀, ó sì dán an wò.
ni orundun keta kio ( bce ) , opo gbogbo guusu asia je piparapo di ileobaluaye maurya latowo chandragupta maurya o si lokunkun ni asiko ashoka olokiki .
Abiyamọ fi ọmọ sínú ọkọ̀ wọlé lọ, lọ̀rọ̀ yíwọ́
Àwọn tí wọn ń bu ọlá fún un tẹ́lẹ̀ ti ń kẹ́gàn rẹ̀,nítorí pé wọ́n ti rí ìhòòhò rẹ̀.
Kò sí ẹni tí ó tíì gòkè lọ sí ọ̀run rí àfi ẹni tí ó ti ọ̀run sọ̀kalẹ̀ wá, èyí ni Ọmọ-Eniyan.
Ìyá Siasia kúrò lákàtà àwọn ajínigbé lẹ́yìn oṣù méjì ààbọ̀ Ẹ̀yin baálé ilé, ẹ yé sá tẹ̀lé mi kiri mọ́!
Orile-ede America tun fofin de awon adari awon omo-ogun olote meta miiran, latari esun lilo awon omode fun ogun jija, eyi ti o lodi si ofin awon ajafeto omo eniyan.
Gege bi atejade latodo egbe awon osise naa pe, “Awon egbe osise ohun ti sa gbogbo ipa won lati dena eto iyanse-lodi naa”.
Wo àbọ̀ tí ọmọba kan, obìnrin àkọ́kọ́ tó ṣe ìwádìí nípa rẹ̀ gbé jáde 'Ó tẹ́mi lọ́rùn kí n pàdánù ẹsẹ̀ mi, ju kí ǹkan ṣe oyún inú mi' Ẹkọ ti itan aye Tunde Idiagbon kọ wa Oríṣun àwòrán, OTHERS Ẹkọ akọkọ ta ri ninu itan igbe aye Tunde Idiagbon ni pe, ka ni ẹmi ikora ẹni nijanu, iwa ọmọluabi ati ifẹ ilẹ baba ẹni.
Irinajo lọ si ilu Dubai fun eeyan meji Ile filaati oniyara meji (2 bedroom apartment) Irinajo lati lọ wo aṣekagba idije ife ẹyẹ Champions league, gbigba ohun mimu Pepsi fun ọdun kan, ohun amohuntutu Branded Chiller Foonu igbalode OPPO RENO Ọkọ ayọkẹlẹ Innoson G40 Irinajo afẹ lọ si ilu Dublin lorilẹede Germany Ẹrọ mohunmaworan ati amohuntutu Pẹlu omilẹgbẹ ẹbun miran.
Ni kete ti Benjamin Netanyahu to n tuko Isreal fi atejade ranse si odo ijo aguda atawon olori ijo miran ni Isreal lojo Isegun pe won yoo si ile ijosin naa lojo Ru ni idunnu ti subu lu ayo awon onigbagbo nibe.
Mò ń parẹ́ lọ bí òjìji àṣáálẹ́,a ti gbọ̀n mí dànù bí eṣú.
Gẹgẹ ba a ṣe ka a lori awọn oju opo itakun agbaye, orukọ akọni ọkunrin naa ni Balogun Landuji Oshodi Tapa, bi itan igbe aye rẹ si ṣe lọ ree.
Agbára rẹ̀ ti dín kù,ète rẹ̀ sì gbé e ṣubú.
Gbọ́ ìmọ̀ràn kí o sì gba ẹ̀kọ́,kí o lè rí ọgbọ́n lò lẹ́yìn ọ̀la.
Nítorí náà, ọjọ́ ń bọ̀, tí a kò ní pe ibí yìí ní Tofeti tabi àfonífojì ọmọ Hinomu mọ́.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Kunle Fela Anikulapo-Kuti: Olótìítọ́ ni Fẹla Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Kunle Fela Anikulapo-Kuti: Olótìítọ́ ni Fẹla 2 Ògún 2018 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 2 Ògún 2020 Ó pé ọdún méjìlélógún báyìí tí abàmì ẹ̀dá Fẹla Anikulapo Kuti re 'bi àgbà ń re ní ọjọ́ kejì oṣù kẹjọ ọdún 1997.
Ekong gba ami ayo keji sawon ikọ
Kankara Abduction: Àwọn ológun ṣàlàyé ìdí tí wọ́n fi yọ̀nda àwọn tó jí àwọn akẹ́kọ̀ọ́ gbé.
Aláàfin ń se ọgọ́rin ọdún, àwọn àwòrán mánigbàgbé Fayoṣe lọ, kí la maa fi rántí rẹ̀?
Àwọn àṣà àti ìse tó yọ obìnrin sílẹ̀ nílẹ̀ Yorùbá Lẹ́yìn ọlọ́pàá, VIO nìkan ló láṣẹ láti dá ọkọ dúró láìṣẹ̀ - Ọ̀gá VIO Eko Ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ parí, Germany di ẹrù ìyà aláwẹ́ mẹ́ta lé Najiria lórí Ọjọgbọn Yemi Osinbajo yoo ṣe ipade pelu igbimọ ajọṣepọ ile okeere lasiko abẹwo yii.
Ninu wọn la ti ri gbajugbaja akorin juju King Sunny Ade.
Daura kò tan mọ́ Buhari àmọ́ òun àti ọmọ rẹ̀ ti fẹ́ ba ẹbí mi jẹ́ - Aisha figbe ta Yatọ̀ fún orí ìtàgé, wo ohun tí o kò mọ̀ nípà Mr Latin Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí 2 sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 2:23 Fídíò, Water Generator: Ó leè ṣiṣẹ fún wákàtí mẹfà, kó tó sinmi, Duration 2,2310 Òkùdu 2020 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
Ẹ wá, ẹ jẹ́ kí á fi ọ̀rọ̀ ẹnu wa pa á, ẹ má sì jẹ́ kí á fetí sí ọ̀rọ̀ rẹ̀ kankan.
Bó tilẹ̀ jẹ́ pe wọ́n mọ̀ ewu tó wà níní pínpín ìròyìn òfégè, kò yé wọ́n tó pe ìròyìn òfégè lè dojú ìjọba tiwantiwa bolẹ̀ tó sì lè ran àwọn olóṣèlú lọ́wọ́ láti yí ìbò.
Jesu dá a lóhùn pé, “Bí mo bá fẹ́ kí ó wà títí n óo fi dé, èwo ni ó kàn ọ́?
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Akomolede ati Asa: Mọ̀ si nípa àwọn ọ̀nà tí Yorùbá ń gbà ran ara wọn lọ́wọ́ Osun: Agbẹnusọ fun Gomina ipinlẹ Osun, Ismail Omipidan salaye pe erongba lati se agbekalẹ igbimọ yi ko jinna si ọkan Gomina Gboyega Oyetola to n tukọ ipinlẹ̀ Osun.
OLUWA, àwa mọ̀ pé ní òtítọ́ ni ọba Asiria ti pa ọpọlọpọ àwọn orílẹ̀-èdè run, ó sì ti sọ ilẹ̀ wọn di aṣálẹ̀.
Ìtàn tó rọ̀ mọ́ òwe Ẹni tí kò ṣe bíi aláàárù l‘Oyingbo."
"Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: ""Ẹ ràn wá lọ́wọ́ láti rí àwọn ẹlẹ́wọ̀n tó sálọ ní Oko àti Benin padà"" Ìwọ́de EndSARS ló ń sọ pé inú ń bí àwọn ọ̀dọ́, ìjọba, ẹ náání wọn - Obasanjo Ẹni iyì àti akíkanjú tó ṣe gbẹ́kẹ̀lé làwọn èèyàn Akure, ilú ìyá mi - Seyi Makinde Ẹ̀yin ọ̀dọ́ ti rí èrè ìwọ̀de yín lórí EndSARS àmọ́ ẹ ṣọ́ra, kẹ má baà sọ èrè náá nù - Tinubu Owó ìrànwọ́ Covid-19 dé, ìjọba fẹ́ san ₦75bn fún 54,000 olókoòwò Ìjọba ìpínlẹ̀ Eko ti iléèwé pa nítorí ìwọ́de #EndSARS Ìrẹ̀wẹ̀sì ń bá wa torí ìdánwò NECO tẹ ń ṣún síwájú lọ́pọ̀ ìgbà - Akẹ́kọ̀ọ́, ọ̀gá iléèwé Agbára ìgbìmọ̀ ìdájọ tí mo gbé kàlẹ̀ yóò dé ọ̀dọ̀ àwón ólọ́pàá tó ti kúrò lẹ́nu iṣẹ́ tẹ́lẹ̀- Sanwo Olu Wo àwọn orílẹ̀èdè míràn tó ń fojú winá ìwọ́de bíi ti ENDSARS Bakan naa lo ni oun ko ni buwọlu eto isuna ọhun, ti ko ba pese owona fun ẹgbẹ ASUU lati wa idahun si ohun ti wọn n beere fun."
17 Ṣùgbọ́n bí wọ́n kò bá ní ronúpìwàdà wọ́n gbọ́dọ̀ jìyà àní bí ti èmi;
Nitori eyi, o ni Ifeanyi ati awọn akẹgbẹ rẹ rọ yika ọkọ oun nitori wọn mọ pe a maa fun awọn lowo.
Mba sọ nigba naa wi pe ko si ootọ kankan ninu iroyin wi pe awọn ọlọpaa lu u ni alubami.
Ṣugbọn orin ni Naira Marley fi fesi si ọrọ yii lẹyin to sọ pe ''Se bi omo jesu niwo, gbese ko Tesumole .
O ni bi awon eniyan  se po ni ekun ile Afirika, sibe ko ti i mu
Idris ni, ni kete ti isẹlẹ naa waye, nijọba ti pasẹ fawọn eeyan ti aje ọrọ naa si mọ lọwọ, lati lọ rọọ kun nile na, ki wọn maa baa dena iwadi ijọba lori ọrọ naa.
Àsìkò wo ni àwọn akẹ́kọ̀ọ́ yóò wọlé padà?
Agbègbè tí ó jẹ́ ìpín tiwọn lọ títí dé Saridi.
Ọbẹ yọ jẹ orukọ awọn ọbẹ to maa fa tikọ tabi yọ lọwọ .
Bí mo sì ti ń wò ó tí ó dákẹ́ mo ṣe ìbéèrè lọ́wọ́ rẹ̀, mo ní, ‘Baba-onírùngbọ̀n-yẹ́úkẹ́ mi ọ̀wọ́n ò, mo dúpẹ́ lọ́wọ́ rẹ̀ gidigidi – mo dúpẹ́ mo tún ọpẹ́ dá.
Amramu bí ọmọ mẹta: Aaroni, Mose, ati ọmọbinrin kan tí ń jẹ́ Miriamu.
Ondo: Sísá Gààrí síta ń fa àtúnṣẹ̀ àrùn ibàa Lassa
Aaroni gbé ọ̀pá rẹ̀ sókè ó sì fi lu omi tí ó wà ninu odò Naili, gbogbo omi tí ó wà ninu odò náà sì di ẹ̀jẹ̀.
Amọ, o ni ko ṣi ewu fawọn mejeeji nitori ara awọn ti n ya bọ diẹdiẹ.
Àwọn adigunjalè yabo ṣọ́ọ̀ṣì, wọ́n fipá bá obìnrin kan lòpọ̀, wọ́n yìnbọn fún òmíràn Kọ́ sí i nípa àwọn oúnjẹ aṣaralóore tó yẹ kí Aláboyún máa jẹ Ọwọ́ ọlọ́pàá tẹ arábìnrin tó fẹ́ ta alòkù kọ́ńdọ́ọ̀mù 324,000 padà f'áwọn èèyàn Mo ṣetán láti ṣe Paulo Costa bí ọṣẹ sẹ ń ṣojú lọ́la- Israel Adesanya Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Ondo Election 2020: Ẹ wo àwọn olùdíje sípò gómìnà nípínlẹ̀ Ondo tó takò bàbá ìsàlẹ̀26 Owewe 2020 Fídíò, Wole Soyinka sọ ìdí tó fi ni òun a fi màálù Fulani ṣe súyà fáwọn èèyàn abúlé23 Owewe 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 3 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 5 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Oríṣun àwòrán, Instagram/mydemartins O ni nigba ti oun wa ni kekere, gbogbo ọna lati dari ọkan oun kuro nidi ere tiata ni iya oun maa n wa, amọ akọsilẹ ti ko pe ere tiata lọna oun.
Togo, Ghana, Serria leone, Brazil, United Kingdom àti United State.
Èyí ni àkọsílẹ̀ ìran Jesu Kristi, ọmọ Dafidi, ọmọ Abrahamu.
Atọmọde atagba lo gbudọ maa gbe aṣa Yoruba larugẹ nibikibi ti a ba wa yala nile ni tabi lẹyin odi.
Ìkìlò : À n sọ ̀ rò nípa àwọn àbùdá tó wà nínú èdè ènìyàn , kì í kan n se nínú ẹ ̀ dẹ ̀ gẹ ̀ ẹ ́ sì tàbí èdè yorùbá .
Ọtẹlẹ̀múyẹ́ DSS yabo ilé asófin àgbà Kí lẹ ò mọ̀ nípa àwọn obinrin Yollywood yìí?
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Janine Van Wyk: Lẹ́yìn ọdun mẹ́rìnlá ti mó ti gbà bọ́ọ̀lù, mó ń lọ fún ife ẹ̀yẹ àgbáye Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Janine Van Wyk: Lẹ́yìn ọdun mẹ́rìnlá ti mó ti gbà bọ́ọ̀lù, mó ń lọ fún ife ẹ̀yẹ àgbáye 6 Òkùdu 2019 Janine Wyk tó jẹ́ agbábọọlu obìnrin ní orílẹ-èdè South Africa, sọ gbogbo ìr'\\inri rẹ̀ lásìkò tó bẹ̀rẹ̀ sí ni gbá bọ́ọ̀lu gẹ́gẹ́ bi obinrin.
Bo tilẹ jẹ pe lasiko kan oju rẹ ko fi bẹẹ maa jade lori awọn ere agbelewo, bẹẹ naa lo to akoko to gberasọ pada tori naa, Biola Adebayo o ṣee fọwọ rọ sẹyin lagbo awọn awọn oṣere.
Ìjà tó wáyé ọ̀hún sì mú kí àwọn olùgbé ní agbègbè Somolu, Bariga, Onipanu àti àwọn àdúgbò míràn tó súnmọ́ wọn sá àsálà fún ẹ̀mí wọn.
Ẹni tí ó fi í fún àwọn ọ̀tá ti fi àmì fún wọn.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Risikat Moromoke Azeez: Inú èmí àti Òbí mi dùn nígbà ti Risi bí ọmọ olójú búlù- Wasiu Ohun kẹta ni lati kọkọ farapamọ ti o ba bọ sinu ẹwu.
Kò sí ẹni tó lè yọ Saraki - Ademọla Adeleke Tinubu: Ọbasanjọ kò lè yan olùdíje fún wa Akpan wa kesi ile aṣofin pe ko gbe igbesẹ nitori pe 'eto idibo naa dunkooko mọ alaafia ipinlẹ Akwa Ibom’.
Ó bá mú Peteru ó tì í mọ́lé.
" Elkana sọ pe ikọ janduku naa ti ṣe ọpọlọpọ idigunjale ni Ilupeju ati awọn agbegbe to wa ni tosi rẹ.
Ẹ kò gbọdọ̀ gbé adití ṣépè tabi kí ẹ gbé ohun ìdìgbòlù kalẹ̀ níwájú afọ́jú, ṣugbọn ẹ níláti bẹ̀rù Ọlọrun yín.
Ẹ̀gbọ́n ọmọ náà bá bi ọmọbinrin Farao pé, “Ṣé kí n lọ pe olùtọ́jú kan wá lára àwọn obinrin Heberu, kí ó máa bá ọ tọ́jú ọmọ yìí?
Taye Currency ni ''ibukun aṣalẹ leleyi lati ọdọ Gomina ipinlẹ Oyo, Seyi Makinde.
 Busari so pe ifetosomo-bibi ko tumo si
Ó tún lọ títí dé orí òkè náà, tí ó dojú kọ àfonífojì ọmọ Hinomu, ní apá ìwọ̀ oòrùn, ní òpin ìhà àríwá àfonífojì Refaimu.
Imaamu Ọmọ Naijiria Alabi Lateef Imamu yi lo kọkọ ri agbebọn naa ni Mọṣalasi Linwood, ti o si figbe ta si awọn janmọ rẹ lati sapamọ fun agbebọn naa.
 Ọọ ̀ ni Ògúnwúsì , gẹ ́ gé bí a ti júwe rẹ ̀ jẹ ́ ògbóǹtarìgì olùṣòwò tí ó lè ṣe ohun tí ọpọ ̀ lọpọ ̀ kò lè dojúko .
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù President George Weah: Ààrẹ fẹsẹ̀ fẹ́ ẹ ní ọ́fíìsì rẹ̀ tórí ejò 19 Ìgbé 2019 Oríṣun àwòrán, AFP/Getty Àkọlé àwòrán, Aarẹ George Weah Wọn ti ri ejo ninu ọfiisi aarẹ orilede Liberia George Weah, eyi to ti mu ko maa ṣe iṣẹ tipa tipa lati ile, BBC lo ṣe aridaju eyi.
Koda, awọn orilẹ-ede bii Lesotho bẹrẹ igbesẹ laitii ni iṣẹlẹ coronavirus kankan.
Alukoro fun ile iṣẹ ọlọpaa ipinlẹ Ondo to ba BBC Yoruba sọrọ lasiko ti isẹlẹ naa waye sọ wi pe, ṣe ni Adeyemi gbe oku Khadijat sinu ile fun ọjọ mẹfaki ẹnikẹni maa baa fura si.
Bakannaa ẹgbẹ naa si tu awọn iyawo ọlọpa mẹwa to jigbe silẹ leyin igba ti ileese ọtẹlemuyẹ Naijiria ati Igbimọ ICRC ton sẹ iranwọ f'awaọn t'ajalu ba f'ọrọjomitoro ọrọ pẹlu Boko Haram naa .
Amọ, awọn eeyan jankan-jankan ti kii ṣe Yoruba, amọ ti wọn jẹ ilumọọka lorilẹede Naijiria naa ni yii.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Awọn agbofinro duro wamu lẹnu iṣẹ ni Quagadougou.
Olori Abbey ni oun ko le ṣalai dupẹ lọwọ Iku Baba Yeye fun ifẹ ti ko ṣe fẹnu sọ to ni si oun, fun ọrọ ti oun n jẹ anfaani rẹ ati fun idunnu ati ayọ to n ri lara Oba Adeyemi.
Minisita fun eto inawo  lorile  ede Algeria, adari ile-ise ọlọpaa tẹlẹri
Ori ayelujara gbona janjan lori iṣẹlẹ yii, paapa nigba ti iroyin jade pe awọn ọlọpaa ti mu Seyitan.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Suicide: Ẹ wo ọkùnrin tó dáná sún ọ̀rẹ́bìnrin rẹ̀ nítorí kó gbà látí jẹ́ aya rẹ̀ 9 Bélú 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 16 Bélú 2020 Oríṣun àwòrán, Getty Images Iwadii ti fihan pe arakunrin kan ti orukọ rẹ n jẹ, Nicodemus Nomyange ti dana sun ara rẹ ati ọrẹbinrin rẹ, Shininenge Pam nitori o kọ lati jẹ aya afẹsile rẹ.
 oríṣiríṣi àwọn oludàsìlẹ ́ tó ṣe aṣájú iṣẹ ́ idánwò lóri àtagbà ohùn lóri okùn-irin àti àtún-ṣe lóri ìrò ọ ̀ kọ ̀ ọ ̀ kan míiràn .
Ọkọ̀ BRT pẹ̀lú nọmbá LSR-228 XS ọhun to forisọri pẹlu ọkọ simẹnti ní gbogbo èrò inú rẹ̀ ní ifarapa kan tábi òmiràn ti ẹsẹ̀ dẹ́rẹ́bà náà sí gé pátápátá.
Ẹ gbàgbé wa sẹ́yìn, ẹ bẹ̀rẹ̀ sí jọba!
Tí a fiṣọwọ́ ní 10:34 11 Òkùdu 201910:34 11 Òkùdu 2019 Ilé ẹjọ́ gíga lòdì sí lílo ìlànà ìdìbò bòńkẹ́lẹ́ Bi o tilẹ jẹ wi pe Ile ẹjọ giga ti ilu Abuja ti paa laṣẹ fun akọwe ile igbimọ aṣofin Naijiria atawọn tọrọ kan pe wọn ko gbudọ lo ilana idibo bonkẹlẹ eyi ti ile igbimọ aṣofin ṣe atunṣe ofin rẹ lọdun 2015.
”O wa ro awon ajo eleto aabo ati agbofinro lati mu awon to dana isẹ ibi
Nígbà tí Mikaeli, olórí àwọn angẹli pàápàá ń bá Èṣù jiyàn, tí wọ́n ń jìjàdù òkú Mose, kò tó sọ ìsọkúsọ sí i.
tẹlẹ lati mu awon onisẹ ibi agbesunmomi ti won n da omi alaafia ru ni  Ila oorun Gusu ati Ila Gusu ,orile
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ìkọlù Ọ̀ffà: Ọwọ́ tẹ afurasi méjìlá míì OAU: Ohùn ọ̀jọ̀gbọ́n Richard Akindele ni wọ́n ká sílẹ̀ Bùhárí sọ ìdí tó fi ń díje lẹ́ẹ̀kejì Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Aya Buhari ni ''lati igba ti Mariam Babangida ti ku ni ipo yi ti wọmi, ni temi ti ọkọ mi ba wọle gẹgẹ bi aarẹ, mi o ni jẹ oye First Lady, bii kii ṣe ki wọn ma a pe mi ni iyawo aarẹ'' O si dabi ẹni pe ọrọ ọkọ rẹ to ni oun ko ni faye gba ipo First Lady labẹ ijọba oun, ni Aisha Buhari tẹle.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ẹwa Agọnyin jẹ aayo ounjẹ Badagry Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Ẹwa Agọnyin jẹ aayo ounjẹ Badagry 21 Èrèlè 2018 Ẹwa Agọnyin jẹ ounjẹ to gbajugbaja nilu Badagry, amọ o di aayo kaakiri awọn ilu nlanla nilẹ kaarọ oojire.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Awọn ọdọ Ondo fẹ̀họ́nù hàn lórí ìṣekúpani Funke Olakunrin Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Oríṣun àwòrán, TVC Àkọlé àwòrán, Ehi Iden ni ko si oṣiṣẹ kankan to yẹ ko padanu ẹmi rẹ nitori wipe ko fẹ pẹ de ibi iṣẹ ni ọjọ ti ojo ba rọ.
Awọn kan tun sọ pe awọn ologun lọ si ileewe naa lati doola awọn akẹkọọ ṣugbọn wọn pada ji awọn akẹkọọ kan lọ.
ko si ni ijọba, amọ to jẹ awọn lo poju lẹyin ẹgbẹ to wa ni ijọba.
“Lọ sọ fún Dafidi iranṣẹ mi, pé, báyìí ni OLUWA wí, ‘Ṣé o fẹ́ kọ́ ilé fún mi láti máa gbé ni?
“Lónìí, ìráhùn mi tún kún fún ẹ̀dùn,ọwọ́ Ọlọrun ń le lára mi,bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé mò ń kérora.
Ọ̀wọ̀ nlá sì ni wọ́n fi bù fún Elizabeth nítoripé ti àtijọ́ ni wọ́n, àwọn èyí tí wọ́n fi jagun nla kan nígbàtí ọba-bìnrin yìí kọ́kọ́ gorí oyè.
Àwọn ìròyìn tí ẹ lè nífẹ̀ẹ́ sí: Obí ta ọmọ tuntun tí kò ju wákàtí mẹ́fà lọ ní ₦850,000 Àkójọpọ̀ àwòrán ọdún ọdún Àjínde l'Afrika Ọbìnrin Gẹ̀ẹ́sì tó wá fún ìsinmi ní Nàíjíríà ṣàgbákò ikú O fikun pe awọn inaki naa ni wọn n ri awọn olutọju ibudo naa to wa layika wọn bii obi wọn ti wọn sekupa lọdun 2007 Ọdun meji ati osu mẹrin si lawọn inaki mejeeji ọhun lasiko ti wọn padanu obi wọn, idi si ree ti wọn fi ko wọn lọ si ibudo ti wọn n gbe ọhun.
won ninu ijamba omiyale to waye ni orile ede South Africa.
Wọ́n gbọdọ̀ jẹ́ ẹran ẹbọ alaafia tí ó fi ṣe ẹbọ ọpẹ́ tán ní ọjọ́ tí ó bá rú ẹbọ náà, kò gbọdọ̀ ṣẹ́kù di ọjọ́ keji.
Amọṣa ipadabọ naa ko so eso rere ninu ifẹsẹwọnsẹ akọkọ ti wọn gba.
Ẹré tirẹ̀ jẹ́ ìdíje ìgbẹ́rùwíwo sókè.
Oluranlọwọ fun Aarẹ Buhari lori ọrọ Iroyin, Bashir Ahmad naa wa lara awọn to ni ọrọ to dara ni Diezani sọ, ati wi pe ki awọn eniyan fi i silẹ.
Bakan naa, abenugan fun ile igbimo asofin fun ipinle Kwara omowe Ali Ahmad naa sapejuwe adajo agba ana,ninu iwe ikedun ti oun naa gbe sita,  gege bi okan lara awon adajo to dara julo ni ajo eto idajo, lorilede Naijiria.
Lẹ́hìn rẹ̀ ni ó bí Simeoni, Lefi, Juda, Isakari ati Sebuluni.
Yàtọ̀ f'àwọn mẹ́fà tó m bọ̀ láti ìpàgọ̀ àdúrà tó kú, àjọ FRSC Osun sọ ipò táwọn tó fara pa wà báyìí BBC tún gbé e dé!
11 Ìgbé 2019 Oríṣun àwòrán, Google Àkọlé àwòrán, Ogúnjọ́, Osu Kini, ọdún tó kọjá ni ilé ẹjọ́ gíga nípínlẹ̀ Ọyọ ní gomina Ajimobi kó lásẹ láti yan ọba.
2m ọmọdé kò ṣe lọ sílé ẹ̀kọ́ - SERAP ké tọ iléẹjọ́ àgbáyé Ọrọ̀ ajé Nàíjíríà tún leè dagun tí Buhari bá fi ìyànsípò àwọn mínísítà falẹ̀ si - Onímọ̀ 'Kò sí ohun tó burú nínú bí Ajimobi ṣe dá Yewande tó pa ọkọ rẹ̀ sílẹ̀' Ìlú ò rẹ́rìn ín rárá, Alaafin Adeyemi III fárígá fún Buhari nínú lẹ́tà tuntun A si fẹ kẹ yọju si osisẹ ọlọpaa to fọwọsi lẹta yii ni lọjọ Iṣẹgun to n bọ, eyiun ọjọ Kẹtalelogun, osu Keje, ọdun 2019 ni aago mẹwa owurọ ki Ibrahim Agu le e wadi ohun gbogbo daju, ko si fi idi eyi tii se otitọ mulẹ."
Kí ló dé tí nǹkan ń dára fún àwọn eniyan burúkú?
Wọn kì í fúnrúgbìn, wọn kì í kórè, bẹ́ẹ̀ ni wọn kì í kó nǹkan oko jọ sinu abà.
Ẹ kò sì gbọdọ̀ jáde kúrò ní ẹnu ọ̀nà Àgọ́ Àjọ náà fún ọjọ́ meje títí tí ọjọ́ ètò ìyàsímímọ́ yín yóo fi pé; nítorí ọjọ́ meje gbáko ni ètò ìyàsímímọ́ yín yóo gbà.
Kí n má baà máa wá ọ kiri,láàrin agbo ẹran àwọn ẹlẹgbẹ́ rẹ?
O fi kun ọrọ pe Sagay ko yẹ lati maa dari ọfisi ajọ to ri si igbogun ti iwa ajẹbanu lorilẹede Naijiria.
 Àlàyé ìbę ̣ rę ìran ọmọ ènìyàn wa nínù jénésísì ( genesis ) .
Àbí ẹ kò mọ̀ pé ẹ̀yà ara Kristi ni àwọn ẹ̀yà ara yín jẹ́?
Ayédèrú òṣùnwọ̀n jẹ́ ohun ìríra lójú OLUWA,ìwọ̀n èké kò dára.
”O tesiwaju pe” iko omo ogun oju omi tun ti se gudu-meje , yaya mefa lati gba oja fayawọ to le ni egberun mẹ́tàlá  sile lowo awon onifayawọ, ni eyi ti iye rẹ le ni igba milionu ati awon oja ti ko ba ofin mu .
Barrakat Bello: Sábàbí ire ní ikú Barakat padà já sí fún wa- Ẹ̀bí fẹ̀mí ìmoore hàn sí àwọn ọmọ Nàíjíríà
Orukọ ẹgbẹ ẹlẹsin naa ni Hakika.
Mo sọ̀rọ̀ tako ọkọ mi torí òtítọ́ - aya Bùhárí ‘A ó ran àwọn tó lùgbàdì omíyalé ìpínlẹ̀ Kogi lọ́wọ́’ 'À kò ní f'ìlú sílẹ̀ fún jégúdújérá' Ìyàwò ààrẹ ń fi ẹ̀sùn kan pé ṣe ni Sani Baba-Inna tó jẹ́ ọ̀gá ọlọ́pàá gba owó mọ̀dá-mọ̀dá gọbọi lọ́wọ́ àwọn olóṣèlú àtàwọ́n oníṣòwò lórúkọ rẹ̀ tó sì kó o sápò ara rẹ̀.
Èmi OLUWA Ọlọrun yín ni kí ẹ máa sìn.
 À ń fún ni gẹ ́ gẹ ́ bí abẹ ́ rẹ ́ tí a gún sínú ẹran ara ẹni tàbí tí a gún sábẹ ́ awọ ara ẹni .
Lara eyi naa lo mu ki awọn ọdọ ipinlẹ Ondo figbe ta pe o ti to gẹ pe ki awon Fulani kuro lagbegbe awọn, tori awọn kan n sọ wi pe awọn lo wa nidi iku rẹ.
Nítorí náà, mo ní ohun tí mo lè fi ṣògo ninu Kristi Jesu, ninu iṣẹ́ tí mò ń ṣe fún Ọlọrun.
Bákan lọ fikùn pé lọ́nà àti rí dájú pé àlàáfíà túbọ̀ jọba láàárín àwọn tí ọrọ kan, ní òun tún ṣe kọ ìwé ẹ̀sùn nípa ìṣẹ̀lẹ̀ náà sáwọn Aláṣẹ tó yẹ, kí wọn leè dasi ọrọ náà ní kíákíá.
Orúkọ baba rẹ̀ ni Jerohamu, ọmọ Elihu, ọmọ Tohu, láti ìdílé Sufu, ará Efuraimu.
A bí Báálẹ̀ Abúlé Ọjà ní ǹnkan bi ọdú márùn ún dín lọ́gọ́ta sẹ́yìn sí Ẹbí Elétùù Òdìbò.
 Àgbẹ ̀ àti darandaran sì ni wọ ́ n ; wọ ́ n gbajú gbajà fún fínfín àti kíkun ibojì / sàréè .
Idí tí àwọn dókítà ọpọlọ kò fi faramọ́ lílo igbó fún ìtọ́jú àìsàn Èyí ni díẹ̀ lára ìgbà tí Buhari àti àwọn aṣòfin gbéná wojú ara wọn Ọlọ́pàá Sharia Kano mú èèyàn tó lé ní 80 tori oúnjẹ nínú ààwẹ̀ Umrah kii ṣe irinajo ọ̀ranyàn fun awọn musulumi ṣugbọn eyi ti wọn maa n gba wọ́n niyanju gẹgẹ bi irinajo Hajj lọ si Mekahh ti wọn lee lọ nigbakuugba to ba wu wọn ninu ọdun.
Ẹ kíyè sí àwọn ẹyẹ ojú ọ̀run, lékèélékèé ń fò láti ibi kan sí ibi kejì lọ́dọọdún, àparò ń wá oùnjẹ rẹ̀ káàkiri inú oko, àdán ń ffi ẹnu jẹun ó tún ń fi ẹnu yàgbọ́, ara ẹyẹ mìíràn dà bí ara aṣọ funfun, òmíràn dà bí aṣọ àrán, omíràn dà bí aṣọ aláró tí wọ́n ti pa tí ó dúdú kẹlẹkẹlẹ.
Ohun ti yoo si ti idi rẹ yọ ni agbekalẹ awọn iroyin meriiri nipa awọn eeyan, latọwọ awọn eeyan ati fun awọn eeyan e - ẹ ma binu, o ka mi lara ni, o sa yẹ ki ohun ti mo n wi ye yin.
Ipa tí Fathia Balogun kó nínú bí mo ṣe dèèyàn lágbo òṣèré fíìmù Yorùba rèé - Baba Ijesha A ó fún ẹbí akẹ́kọ̀ọ́ Fásitì Ibadan tó dolóògbé ní owóo gbà mábìnú - Ìjọba Oyo Aya gómìnà Kwara fẹ́ ran tìyá- tọmọ olójú búlúù lọ́wọ́ Ìdè jáá!
Òní ni ọjọ́ pé tí ẹ óo jáde kúrò ní Ijipti, ninu oṣù Abibu.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Sogidi Lake: Kòṣẹja-kòṣèèyàn lá bá nínú adágún odò náà -Ojedele Obinrin to ba n se eela, tabi nkan osu lọwọ ko gbọdọ ni ajọsepọ pẹlu ọkunrin.
O tun di odun 2022 ki idije ife ẹyẹ agbaye miran to waye ni orile ede Qatar.
Aisaya dá wọn lóhùn pé, “Ẹ wí fún oluwa yín pé OLUWA ní:‘Má bẹ̀rù nítorí ọ̀rọ̀ tí o gbọ́tí iranṣẹ ọba Asiria sọ tí ó ń fi mí ṣe ẹlẹ́yà.
OLUWA sì wí pé, ‘Àwọn eniyan wọnyi kò ní olórí, kí olukuluku wọn pada lọ sí ilé ní alaafia.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Rẹfirí Nestor Pitana ló darí ifẹsẹ̀wọnsẹ̀ àṣekágbá láàrin France àti Croatia Agbaọjẹ agbabọọlu Luka Modric to jẹ balogun ẹgbẹ agbabọọlu Croatia lo gba ami ẹyẹ agbabọọlu to pegede julọ ninu idije ife ẹyẹ agbaye.
Ìtàn kíkùn lórí Mọ́ṣáláṣí Anabi ní Medina tó bẹ̀rẹ̀ lọ́dún 1440 sẹyin Coronavirus: Ǹjẹ́ àwọn dókítà tó ń tọ́jú eyín ń ṣisẹ́ lásìkò pàjáwìrì?
Ṣugbọn Dafidi ọba dá Onani lóhùn pé, “Rárá o, mo níláti ra gbogbo rẹ̀ ní iye tí ó bá tó gan-an ni.
Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold Àwọn ìṣẹ̀lẹ̀ ńlà lọ́sẹ̀ tó kọjá tó fi mọ́ bí Covid-19 ṣe gbẹ̀mí èèyàn 23 lọ́jọ́ kan ṣoṣo Covid-19: Ilé aṣojú-ṣòfin l'Abuja dábàá kí ìjọba sún ìwọlé àwọn akẹ́kọ̀ọ́ síwájú pẹ̀lú oṣù mẹ́ta Mo ti ní ìyàwó àfẹ́sọ́nà, ayẹyẹ ìgbeyàwó mi ń bọ̀ láìpẹ́ - Lateef Adedimeji Irọ́ ni pé ọba tuntun má a ń jẹ ọkàn ọba tó bá wàjà ní ìpèbí - Elebuibon Èèyàn 1,598 míì tún ti lùgbàdì covid-19 ní Nàijíríà, 1,420 ló ti kú báyìí Mo si tun sọ pe ki arun coronavirus to ba fẹ wọ Iwo pe ki o wa mu mi nitori ọfiisi Ọlọrun ni mo wa, ti coronavirus ba ti mu mi, o ti mu Ọlọrun naa niyẹn.
n óo nà wọ́n lẹ́gba nítorí ẹ̀ṣẹ̀ wọn,n óo sì nà wọ́n ní pàṣán nítorí àìdára wọn.
Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Ìtàn Mánigbàgbé: Bode Thomas ní ọpọlọ pípé, ó jẹ́ aṣaájú àmọ́ ó ní inú fùfù19 Sẹ́rẹ́ 2020 Ìtàn Mánigbàgbé: Mọrèmi Àjàṣorò fi ọmọkùnrin rẹ̀ kanṣoṣo rúbọ fún odò nítorí ìlú20 Èrèlè 2019 Ìtàn Mánigbàgbé: Ọ̀rẹ́ àjèjì ló kóbá Afọnja, tí Ilọrin fi bọ́ lọ́wọ́ Yorùbá24 Ìgbé 2020 Ìtàn Mánigbàgbé: Adebisi Idikan ni olówó tó kọ́kọ́ ra ọkọ̀ nílẹ̀ Ibadan20 Èbibi 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Ní ìhà míràn igbe kò sì iná mọnamọna ni àwọn miran nke, tí wọn sì ni èyí mú kó nira púpọ fún àwọn láti gbé inú ilé fún ọjo mẹ́rìnlá.
Baakan naa ni Gomina Makinde tun pin ileeṣẹ ti onikaluku wọn yoo ti ṣiṣẹ fun wọn lẹyin to bura fun wọn tan.
Nígbà náà ni Peteru wá sọ́dọ̀ Jesu, ó bi í pé, “Oluwa, ìgbà mélòó ni arakunrin mi óo ṣẹ̀ mí tí n óo dáríjì í?
Ẹnìkan tí mo tún ṣe àkíyèsí pé mo mọ̀ nínú àwọn ènìyàn náà ni babaláwo kan tí orúkọ rẹ́ ń jẹ́ Ewédayépọ̀.
Egúngún kan rèé tí kò bìkíáfù, ó kọjú ìjà sí ọlọ́pàá pẹ̀lú ohun ìjà olóró Àwọn ògo Ibadan márùn ún tí ikú mú lọ lọ́dún 2020 Bẹ́ ẹ fẹ́, bẹ́ ẹ kọ̀, July ni ẹjọ́ Sotitobire yóò parí - Adájọ́ gbọmú Arúfin ni Seyi Makinde pẹ̀lú bó ṣe gbà kí wọ́n sin Ajimobi sí GRA - Amòfin Mo ti lùgbàdì àrùn Coronavirus - Akeredolu figbe ta Kọmiṣọna ọlọpaa naa ṣalaye siwaju sii pe iwadii ati iṣẹ takuntakun ileeṣẹ ọlọpaa lo jẹ ki wọn ri afurasi ọhun mu.
OLUWA ní, “Ṣugbọn sibẹ, ní gbogbo àkókò yìí, n kò ní pa yín run patapata, 
Adebajo Àkọlé àwòrán, Ọjọ kọkanlelogun, oṣu kinni, ọdun 1920 ni wọn bi i ni Imobi, Epe, nilu Eko.
Aṣofin agba kan ni ile aṣofin apapọ ilẹ wa, Sẹ́netọ́ Ben Murray Bruce ti kede pe ẹ́bu lasan ni fidio kan to n ja rain-rain pe Gomina ipinlẹ́ Kano, Abdullahi Ganduje gba owo abẹtẹlẹ to to miliọnu marun dọla.
Iru iṣẹlẹ bayii ti n waye kaakiri orilẹede Naijiria lẹnu ọjọ mẹta yii.
Aarun yii ko bikita ipo ti ẹnikẹni wa, sugbọn igbimọ amusẹya ìjọba ko ni sinmi, lati maa ṣe ikilọ ni igba gbogbo.
Kí ló dé tí ẹ̀ ń lu ara yín?
Ẹni tí ó bá rú ẹbọ alaafia fún ìdúpẹ́ yóo mú ẹbọ rẹ̀ wá pẹlu àkàrà tí ó ní ìwúkàrà.
3 triliọnu tawọn ṣadehun ki wọn si san eleyi to ku ni ipele 220 bilọnu naira laarin ọdun 2014,2015,2016 2017 ati 2018.
Sẹnẹtọ Sani sọ pe eebu ti ọpọ n bu Omotola ko yi otitọ ọrọ ti o ti sọ pada.
Saaju si ni Alaafin ti kọ orisirisi lẹta bii mẹta si ọga agba patapata fun Ileesẹ ọlọpaa nilẹ wa, to si n beere pe oun n fẹ ẹka ibudo ọlọpaa kogberegbe (MOP 73) nilu Oyo, eyi ti aarẹ Muhammad Buhari ti fi ontẹ lu.
“Ojuse ile-ise ologun ni lati daabobo agbegbe jake-jado lorile-ede Naijiria, ati lati se ojuse won loore-koore, ni bayii, ijoba ti se agbekale ise-akanse kan ti a pe ni EX AYEM AKPATUMA, eyi ti awon alase so pe, awon omo-ogun gbodo wa ni ekun ariwa ati awon agbegbe miiran lati dekun laasigbo laarin awon daran-daran ati agbe, bakan naa ki won si dekun awon iwa odaran ti o n waye ni ekun naa.
Egypt ni goolu mọkandinlọgọrun, fadaka mẹrindinlọgọrun ati baba mọkandinlaadọrin nigba ti Naijiria ni apapọ mọkanlelọgọfa.
Opó ni mí, ṣùgbọ́n ọ̀pọ̀ ló ń rí opó bíi gbọkọgbọkọ 'A máa ń fí oògùn olóró 'ginger'ká tó ka ẹsẹ bíbélì ni ṣọ́ọ̀ṣì' O gba awọn eeyan niyanju pe, ti a ba bi ẹni, a maa n tun ara ẹni bi ni pẹlu apẹẹrẹ ipa ti Baba rẹ ko ninu igbesi aye rẹ.
Ó tún wí pẹ̀lú pé gbogbo àwọn ohun èlò tí a rí wọ̀n-ọnnì, Ẹlẹ́dàá ló fi wọ́n ránṣẹ́, àwọn ni idá ìṣẹ́gun, àáké ìṣẹ́gun, ọkọ́ ìṣẹ́gun, akeǹgbè ìṣẹ́gun.
Ó yẹ kí á ṣe àkíyèsí pé Oníṣèègùn Ọ̀sanyìnnínbí ni olórí àwọn olè ajẹ́rangbé yìí gẹ́gẹ́ bí a ó ṣe rí i kà ní iwájú.
Aago meji ọsan ni eto idibo naa pari, ti ohun gbogbo si lọ leto-leto bi o tilẹ jẹpe iroyin kan ti a ko lee fidi rẹ mulẹ sọ pe, awọn janduku oloselu kan si ja apoti idibo gba lawọn agọ idibo kan lẹkun idibo ọhun.
    Kò pẹ́ púpọ̀ tí ilẹ̀ ọjọ́ kéjì sì mọ́ tí gbogbo ènìyàn tun fi ń rọ wọ ilé mi, ìgbà tí àwa náà sì jẹun tán, àlejò mi tún bẹ̀rẹ̀ o ń bá ìtàn náà lọ ó ni:
Ile-ise eto ilera lorile-ede Egypt so pe, awon osise agbemila ati awon oko agboku bi ogbon n sise takun-takun nibi isele ohun.
Ṣaaju ni iroyin kan ti tan kalẹ loju opo Twitter ati Facebook pe ile ifowopamọnaa ti bẹrẹ si n da awọn oṣiṣẹ rẹ duro lẹyin to fun ijọba apapọ ni biliọnu kan naira lati fi gbogun ti ajakalẹ arun Coronavirus.
ẹyin kokoro naa ko gbẹyin ninu ounjẹ amaradan.
Ẹ jẹ́ ká wo èrò àwọn ọmọ Nàíjíríà lóríi Twitter ní sísẹ̀ ń tẹ̀lé: Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Dino melaye gba ìdáǹdè lọ́wọ́ ọlọ́pàá Sé wọ́n lè yọ Sẹ́nátọ̀ nípò?
ọ̀jẹ̀wẹ́wẹ́ agbábọ́ọ̀lù orí pákó tó ń gbógo Nàìjíríà yọ lọ́wọ́lọ́wọ́ naa bá Ilé iṣẹ́ BBC Sport Africa sọ̀rọ̀ lórí àfojúsùn rẹ̀ fún ọjọ́ ọla pé yóò dùn púpọ̀.
Kì í ṣe ọ̀rọ̀ ẹ̀ẹ̀kan tabi ẹẹmeji ni èmi Paulu ti fẹ́ wá, ṣugbọn Satani dí wa lọ́wọ́.
- Ẹnu ti ń yà mi láti ìgbà tí o ti ń sọ̀rọ̀ lónìi’tí mo ń gbọ́ ọ̀rọ̀ ńlá tí ń bẹ lẹnu rẹ tí mo sì ń fiyè sí ọ̀rọ̀ pàtàkì tí ń bẹ ní ọ̀nà ọ̀fun rẹ.
O tun so pe“Je ki n sọ eleyii fun un yin
 ohun na tun lo je oludari orin fun radio project lati 1937 de 1941 , ni u.
riri ipa ribiribi ti ẹ ko, gẹgẹ bi aare se seleri pe awọn obinrin ati ọdọ ni
Ijọba ni awọn yoo kede ẹka ọlọpaa miran ti yoo ma gbogun ti awọn adigunjale.
O wa fi oro re mule pe, gege bi ofin ati ilana ajo INEC, nikorita bayii, won gbodo tun idibo naa di ni, eleyi ti eto idibo atundi naa yoo si waye lojoBo(Thursday).
Aarẹ Buhari ni iku Funtua jẹ ibanujẹ nla fun oun, ati pe iroyin iku naa ba oun lojiji.
Oríṣun àwòrán, @GeoffreyOnyeama/twitter Ọjọ Ẹti ni awọn gende agbebọn ni Ghana yabo ile'gbe aṣoju orilẹ-ede Naijiria ni Ghana, ti wọn si fi kata-kata wó awọn ile kan ninu ọgba naa.
aládùígbò ni odùduwà àti alárè jé ni apá ilè lárúbáwá .
Ojogbon Osinbajo tun ro awon omo orile ede Naijiria lati lowo si atunse to n lo lowo, ki won si tun maa gbadura fun awon adari won.
N óo máa kọrin sí ọ, OLUWA,nítorí o ṣeun fún mi lọpọlọpọ.
"Iwé ofin Naijiria ọdun 2019 lóri ìṣúna ti paa lásẹ pé ki ilé ìfowópama máa yọ ààdọ́ta nairia gẹ́gk bi ""Satamp duty lórí gbogbo ẹgbẹ̀run mẹwàá náírà ti ó ba wọ àpò ikówósi nílé ìfowwópamọ́."
Ìgbàwo ni èròjà tó gbógun ti àìsàn lára lè ṣiṣẹ́ dá, àti pé bóyá ó lè ní ààrùn náà ni ẹ́ẹmèjì Oríṣun àwòrán, Getty Images Onírúurú aheso lọ tí wá sugbon peleu ẹri péréte lórí bí èròjà tó gbógun ti àìsàn ṣe lè ṣíṣe pé tolati gbógun ti aarun náà.
Ilé iwé Harvard náà ti sọ pé àwọn ń ba àwọn ẹbí ọmọ náà sọ̀rọ̀ àti pé àwọn ń gbìyànju láti pẹ̀tù sááwọ náà kí ìdánilẹ̀kọ tó bẹ̀rẹ̀ ni ọjọ́ kẹta oṣù kẹsàn Ajọ kan ti kìí ṣe ti ìjọba tí pèsè ìrànwọ láti gbẹjọ rò fún Ismail.
Jesu sọ fún wọn pé, “Àwọn ọba àwọn orílẹ̀-èdè alaigbagbọ a máa jẹ ọlá lórí wọn.
Èmi OLUWA ni mo sọ bẹ́ẹ̀, bẹ́ẹ̀ ni n óo sì ṣe.
“Ẹnikẹ́ni tí ó bá sì jẹ ohunkohun tí ó kú fúnra rẹ̀, tabi tí ẹranko burúkú fà ya, kí ẹni náà fọ aṣọ rẹ̀, kí ó sì wẹ̀, yóo jẹ́ aláìmọ́ títí di ìrọ̀lẹ́, lẹ́yìn ìgbà náà ni yóo tó pada di mímọ́.
N óo dúró sí ibìkan lórí ilé-ìṣọ́, n óo máa wòran.
Alaye aṣiri tu nipa bi Adediwura se di awati ree: Bi ọkan lara awọn afurasi naa se tu asiri yii, ni awọn iwadii miran ati ọpọ asiri miran bẹrẹ si ni tu nipa bi ọmọde naa se di awati.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ilé wo pà 'yàn meji l'Èkó 31 Ẹrẹ̀nà 2018 Oríṣun àwòrán, Agege TV Ile kan ti da wo pa awọn eeyan meji l'agbegbe Agege ni ipinlẹ Eko.
Ayédèrú agbẹjọ́rò tó ṣiṣẹ́ fún ọdún mẹ́ta láì ní'wé ẹ̀rí
Awa gẹgẹ bii osisẹ ko ni gba rara, o din ni ida marun osisẹ to n seto mọda-mọda owo ifẹyinti naa.
Áfíríkà yóò gba ife ẹ̀yẹ UEFA Champions league lónìí Ileẹjọ pasẹ igbejọ ọtọ fun Nnamdi Kanu Minisita fọ́rọ̀ ilẹ̀ òkèèrè kọ̀wẹ́ fipò sílẹ̀ Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
okunrin ati obinrin,ti won ni igboya, iwa akin ati okan lile, lenu ise won.
O ni ko si ẹni to tayọ ofin bi o ti wu ki ipo ti ẹni bẹẹ ba wa ṣe lee ri lawujọ.
Ìfihan tí a fi fúnni nípasẹ Wòlíì Joseph Smith sí Oliver Cowdery, ní Harmony, Pennyslvania, Oṣù Kẹrin 1829.
Orí rẹ dàbí adé lára rẹ, ó rí bí òkè Kamẹli,irun rẹ dàbí aṣọ elése-àlùkò tí ó ṣẹ́ léra, wẹ́lẹ́wẹ́lẹ́irun orí rẹ ń dá ọba lọ́rùn.
Ṣé òótọ́ ni pé Tayo Amusan ni yóò gba ìṣàkóso ilé ìtajà Shoprite?
Ajọ to n gbogun ti iwa ajẹbanu lorilẹ-ede Naijiria EFCC lo gbe Ọgbẹni Obi lọ sile ẹjọ lori ẹsun iṣowo to to miliọnu mẹrindinlogoje (#136m) kumọkumọ.
Gẹgẹ bi ileesẹ asoju ijọba ilẹ Gẹẹsi to wa ni Naijiria ti kede rẹ, ẹlomiran ti wọn tun yinbọn mọ ni Matthew Oguche, ẹni to n sisẹ fun ẹgbẹ alaabo kan ti kii se tijọba, ti wọn pe ni Safety Organisation.
Idi ni pe lọjọ Isẹgun lawọn eeyan kan to n fẹhonu han morile awọn ileesẹ South Africa to wa nilu Ibadan, ti wọn si kọlu wọn, koda, wọn dana sun ileesẹ MTN to wa ni Bodija, ti wọn si ko ọpọ ẹru olowo iyebiye ni ile itaja Shoprite to wa ni Ring Road.
Ọna marun re e lati le mu ṣẹ 'Logo Benz yóò lẹ́yìn fún àwọn ọ̀dọ́ tó bá ṣògùn owó' Àwọn ìpànìyàn mánigbàgbé tó wáyé lọ́dún 2018 Àwọn ìmúra tó làmìlaaka ní Nàìjíríà lọdún 2018 Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Afro Brazilians: ìlú Rio ni a máa kọ ilé ìṣẹmbáyé náà sí Awọn eniyan ni wọn ti n sọ oriṣiiriṣii ọrọ nipa aforiji Shagari paapaa fun aarẹ Buhari.
Ọ̀wọ́ngógó epo bẹntirò: NNPC ni 'ìròyìn ẹlẹ́jẹ̀' ni Kíni ìdí tí àwọn ẹbí àwọn ọmọ Chibok fi ń tọ woli lọ?
"Aarọ Ọjọ Aje, Ọjọ Kọkandilọgbọn, Oṣu Kẹjọ, ọdun 2020 ni awọn soja naa de ileẹjọ awọn ọmọogun, lẹyin ti wọn rii wi pe wọn jẹbi ẹsun iwadii ti ''BBC Africa Eye'' ṣe ni ọdun 2018 ti wọn si pe ni ""2018 Anatomy of a killing"" ."
Ohun tí Baba mi ti fún mi tóbi ju ohun gbogbo lọ.
"Ayẹyẹ Àmì ẹ̀yẹ tó jẹ́ Àwọn ẹgbẹ́ Tijjaniyya ti yọwọ́ kílàńkó Yahaya Sharif kúrò láwo ẹgbẹ́ wọn ní Kano ""Mi ò ní wọ Uber mọ́ tí wọ́n bá leè fi owó lée nítorí àfikún owó orí tí Sanwo Olu ṣe"" Ilé ayé mi ti d'ojú bolẹ̀ pẹ̀lú ikú àfẹ́sọ́nà mi- àfẹ́sọ́nà Immaculate Okochu Ilé aṣòfin orílẹ̀-èdè UK n gbèrò fífí ìyà jẹ àwọn adarí Naijiria tó lọ́wọ́ nínú rògbòdìyàn ENDSARS Èyí ni ohun tí Ọọ̀ni sọ nípa Àrẹ̀mọ rẹ àti ètùtù tó ń ṣe lọ́wọ́ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, jkkkkk Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí ENDSARS Tribunal: ọlọ́pàá àti olùjẹ́rìí tó gbá létí lẹ́ẹ̀mẹrin pàdé níwájú ìgbìmọ̀, ariwo sọ!"
Ninu atẹjade ti akọwe iroyin si gomina, Ọgbẹni Taiwo Adisa fi sita, Gomina Makinde ni owo to le ni igba miliọnu nairia nipamọ ko to gori oye gẹgẹ bii gomina.
Ẹ ṣe oríkunkun sí àṣẹ OLUWA, ẹ sì lọ pẹlu ẹ̀mí ìgbéraga.
Bí mo bá wí pé kí kìkì òkùnkùn bò mí mọ́lẹ̀,kí ọ̀sán di òru fún mi,
Ní ọjọ́ ìkomọjáde, àwọn ẹbí, ọ̀rẹ́ àti ojúlùmọ̀ yóò péjọ síwájú ilé níbi tí ọ̀ṣọ̀ọ̀rọ̀ òjò máa ń dà sílẹ̀ láti orí òrùlé.
Ṣugbọn Ìwé Mímọ́ níláti ṣẹ tí ó sọ pé, ‘Ẹni tí ó ń bá mi jẹun ni ó ń jìn mí lẹ́sẹ̀.
"Oríṣun àwòrán, Seyi Makinde O tun tẹnumọ pe, ""eyi ko tumọ si pe mo fẹ kẹyin si awọn eeyan wa to wa nipinlẹ Ọsun nitori ẹbi kannaa ni wa amọ igbesẹ naa yoo jẹ ọna abayọ ayeraye, nitori ipinlẹ Ọyọ ti gbaradi pẹlu owo lati gbe ẹru sise akoso ileẹkọ fasiti naa gẹgẹ bii eyi to jẹ tirẹ nikan."
Àwọn àbùbá àdámọ ́ ọ ̀ rò wà tí a lè tọ ́ ka sí báyìí .
Ọjọgbọn Mahmood Yakibu ni mìmì kan ko lee mi ipinnu ajọ naa lati rii pe idagbasoke ba iye awọn obinrin to n da si kikopa lagbo ọọrọ oṣelu lorilẹede Naijiria.
Gbajugbaja oṣere tiata naa, tii ṣe ọmọ agba ọjẹ oṣere to ti di oloogbe, Ray Eyiwunmi, tun kede fun araye pe, inu ẹjẹ oun ati awọn ẹgbọn oun ni iṣẹ tiata wa, ogun nla tí baba awọn si fi silẹ fun awọn nìyẹn.
Oríṣun àwòrán, others Kete ti ìdíje yí parí ni gbogbo èèyàn rọ si ori papa ti won ko si fi ti ẹyà ṣe nínú idawọ ìdùnnú lọjọ ta n wí yi.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Awakọ̀ 3rd Mainland Bridge: Ìjọba ko yanjú súnkẹrẹ fàkẹrẹ ọ̀nà Apapa Orukọ afara naa ni afara Hong Kong-Zhuhai, ohun si ni afara to gun julọ ti wọn kọ si ori okun.
Ile ẹkọ Baptist Grammar School, Idi Ishin ni Ibadan ni olukọ yii ti n da bi ẹdun ti n wọn n rọ bi owe.
” Ó ní, “Gbogbo eniyan, ṣé ẹ gbọ́ ohun tí mo wí?
Gomina Makinde ni Alaga fun eto idibo sipo gomina ti yoo waye ni ipinlẹ Kogi ni Ọjọ Kẹrindinlogun, Osu Kokanla, ọdun 2019.
Ṣugbọn àwọn eniyan burúkú yóo ṣègbé;àwọn ọ̀tá OLUWA yóo pòórá bí ẹwà ewékowọn óo parẹ́ bí èéfín tí í parẹ́.
Ìkùukùu tí ó nípọn yí i ká,tóbẹ́ẹ̀ tí kò lè ríran,ó sì ń rìn ní òfuurufú ojú ọ̀run.
Dafidi bá tún lọ bèèrè lọ́wọ́ Ọlọrun.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fọ́nrán ohùn, Inú mi dùn pé ọmọ obinrin nìkan ni mo bi Laide Bakare: Ọjọ Aje, ọjọ keje, oṣu kẹwaa ni ọjọ ibi Laide Bakare, eyi to ṣe ni ilu Atlanta, nipinlẹ Georgia l'Amerika.
Gbajabiamila ni lakọkọ, oun ko ni buwọ lu eto isuna ọdun 2020 lai jẹ pe o pese owo iranwọ fawọn mọlẹbi awọn eeyan to jalaisi lasiko iwọde naa.
Oba Abdulrasheed Akanbi kan saara si Awujale ilu Ijẹbu Ọba Sikiru Adetona pe iru idagbasoke yi n waye lasiko rẹ lori apere.
Má ṣe fi ọkọ̀ rẹ gbé àgùnbánirọ̀ lẹ́yìn aago mẹ́fà ìrọ̀lẹ́- FRSC Ọkùnrin tó yí orúkọ padà sí Muhammadu Buhari ṣ'ayẹyẹ ìsọmọlórúkọ ní Kano Kò burú tí ẹ bá pe Ààrẹ Buhari ni 'Major General'- Ìjọba Nàìjíríà Aisha Buhari figbe ta,o ní pé Garba Sheu tí gbàbọde Iba aṣa Yoruba ṣalaye pe láye atijọ bi Ọba ba fẹ́ ọmọ ogun ọdun ti Ọba gbésẹ̀ kò si ẹnikẹni to láya láti fẹ́ ọmọbinrin náà, sùgbọ́n láye òde oni ọlaju ti de, eyi to ti pa ọ̀pọ àṣà rẹ́.
N óo pa yín run láàrin àwọn eniyan ilẹ̀ ayé, n óo sì pa yín rẹ́ láàrin àwọn orílẹ̀-èdè, ẹ óo wá mọ̀ pé èmi ni OLUWA.
Ibi ti mo ti n ṣiṣẹ nigba naa jina.
Ọpọ ọrọ ni àwọn eniyan ti sọ loju òpó facebook BBC Yoruba lori eyi.
" A ń fikunlukun pẹ̀lú FBI láti mú àwọn Yahoo Boys"" tó kù- EFCC Ẹ yọjú sí FBI bí ẹ kìí bá ṣe ''yahoo boys'' - Abike Dabiri-Erewa A kó dúnkoòkò mọ́ Ambode, isẹ́ wa là ń ṣe - Ilé Aṣòfin Eko A kò tí ì gbọ́ ǹkankan lórí owó ìwé ìrìnnà sí Naijiria - U."
 Pataki si ni ọrọ eto ilera ninu ofin orilẹ-ede Naijiria”Nigba ti wọn n ṣe agbeyẹwo abadofin naa, Aṣofin Sanai Agunbiade, Olori ọmọ ẹgbẹ oṣelu to pọju lọ ninu Ile Ìgbìmọ Aṣofin Ipinlẹ Eko, ẹni ti o ṣe agbeyẹwo abadofin naa, sọ pe abala mẹfa pere ni Ile Ìgbìmọ Aṣofin naa fẹ ṣatunṣe si ninu ofin yii, iyẹn abala keji, ikẹrin, ikẹfa, ikẹtalelogun (ipinrọ keji (b), abala ikẹtalelogun (ipinrọ  kẹrin (b) ati abala kẹtadinlọgbọn.
Ọ̀rọ̀ tí eniyan bá sì ti búra lé lórí, kò sí àríyànjiyàn lórí rẹ̀ mọ́.
Àwọn ọmọ Nàìjíríà kan ń dá ẹ̀bi, òmíràn ń dárò, lórí bí ológun ṣe pa ọlọ́pàá mẹ́ta Ọ̀la ni Arafat, wo iṣẹ́ tó ṣe kókó láti ṣe ní Hajj lásìkò Àràfá àti lẹ́yìn rẹ̀ Ìpànìyàn, ìjínigbé ti gbàkóso ilẹ̀ Yorùbá, Buhari, tètè kéde pé ètò ààbò kò fararọ - Soyinka Èèyàn mẹ́rìnlá tí ọpọlọ wọ́n pé la buwọ́lù bíi kọmísọ́nà l‘Oyo - Olórí ilé aṣòfin kan sáárá Gẹgẹ bẹẹ se mọ pe ọmọ ọla tun ni Wuraọla yatọ si pe o tun jẹ ọlọpọ ẹwa, ọwọ ifẹ ti awọn ọkunrin si n na si omidan naa ko ni itumọ kankan sii, tori ko jẹ hoo fun ọkunrin kankan laarin wọn, to si maa n fi ọpọ wọn se akọ.
Ṣugbọn nígbà náà, a kò ì tíì rí i, pé gbogbo nǹkan ni ó ti wà ní ìkáwọ́ rẹ̀.
Ọmọ to n ko ọmọ alainile kuro lori titi Ọmọdé mẹ́tàdínlọ́gbọ̀n gbòmìnira nílé ayédèrú ọmọ òrukàn tíjọba tì pa 'Ọjọ́ mẹ́fà lọ́sẹ̀ ni mo fi ń gbáradì láti tayọ àwọn ẹlẹgbẹ́ mi táá jọ ń wẹ odò' 'Àwón òbí míì n fi ọmọ wọn ṣe òwò ní Naijiria’ Fayemi fojú Alufa to fipa bá ọmọde lòpọ̀ síta l'Ekiti Fopefoluwa ni nigba ti oun lọ wo ori ayelujara fun fọnran awọn to ti di gbajugbaja ninu iru ohun to yan laayo yii, o pinu lọkan ara rẹ pe oun le ṣe ohun ti wọn n ṣe daadaa.
Nítorí pé ilẹ̀ Yorùbá súnmọ́ ààrin ọ̀bìrìkìtì aiyé, ènìà ò lè rí iyàtọ̀ púpọ̀ láàrin ojúmọ́ àti ilẹ̀ṣú rárá, Bíótilẹ̀jẹ́pé ìyàtọ̀ isẹ́jú mélòókan máa nwà.
Idije naa to waye ni ilu Alexandria l'orilẹede Egypt ni idije akọkọ fun orilẹede mejeeji.
N óo fìdí rẹ̀ múlẹ̀ bí èèkàn tí a kàn mọ́ ilẹ̀ tí ó le, yóo di ìtẹ́ iyì fún ilé baba rẹ̀.
Ó ti kọ́kọ́ sisẹ́ olùkọ́, kó tó lọ fún isẹ́ amòfin.
Lọ si Yidi O ṣe pataki bakan naa ki eniyan lọ fun adua yidi lọjọ ọdun ileya, ki eniyan si wọ asọ tuntun.
Ṣugbọn nisinsinyii, ninu Kristi Jesu, ẹ̀yin tí ẹ wà ní ọ̀nà jíjìn nígbà kan rí, ti súnmọ́ ìtòsí nípa ẹ̀jẹ̀ tí Kristi ta sílẹ̀.
" Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Mo fẹ́ ìdájọ́ òtítọ́ àti òdodo lóríi ikú àìmọ̀dí tí wọ́n fi pa ọmọ mi' Ọ̀jọ́ eérú t'ọdún yìí bẹ̀rẹ̀ pẹ̀lú aṣọ ọ̀fọ̀ Ọmọ oyè wọ gbaga ọlọ́pàá nípìínlẹ̀ Ogun lóríi ayédèrú sabuké WAEC Ẹ jọ̀ọ́, ẹ má jẹ́ kí ikú ọmọ mi lọ lásán - Ìyá Tiamiyu tí ọlọ́páà pa Igbákejì mínísíta fún ìlera ní Iran ti kó Coronavirus Ilé ẹjọ́ gíga jùlọ dúró gbọingbọin lórí ìdájọ́ ìdìbò gómìnà Bayelsa Iyaafin Tiamiyu sọ fun BBC pe ibanujẹ nla ati iṣẹlẹ manigbagbe ni iku ọmọ naa jẹ fun gbogbo ẹbi wọn lapapọ.
Ọba wí fún Sadoku pé, “Gbé Àpótí Ẹ̀rí náà pada sí ìlú.
Ninu ọrọ rẹ aarẹ Akufo ni laipẹ wọn yoo pinu lorii igba ti awọn ere idaraya yoo bẹrẹ ṣugbọn lọwọlọwọ bayii, awọn ibudo itura bii eti okun, ibi igbafẹ, ile sinima ati ile ijo yoo ṣi di titi pa di igba ti alakoko ba ni o to.
Oríṣun àwòrán, @ArewaHistory Àkọlé àwòrán, Ààrẹ Muhammadu Buhari Ni ọdun 1963 nigba to pe ogun ọdun, Buhari gba oye second liutenant wọn si fi jẹ adari ikọ ogun Second Infantry Battalion ni ilu Abeokuta.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Yeye Olokun of Lagos Omolara Fasola Fanimokun: Pásítọ̀ ṣọ́ọ̀ṣì ló sọ ìran pé kí n di Olókun Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Yeye Olokun of Lagos Omolara Fasola Fanimokun: Pásítọ̀ ṣọ́ọ̀ṣì ló sọ ìran pé kí n di Olókun 21 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Ipe mi ni Oloriṣa olokun, iṣẹ ti mo si yan laayo ni iṣẹ Amofin lorilẹede Naijiria""."
Ṣé gbogbo àwọn aṣebi kò gbọ́n ni?
Kete lẹyin aṣẹ naa ni awọn ọmọ ogun gba ọna mẹrin ọtọọtọ lati doju kọ awọn ajinigbe ọhun pẹlu iranlọwọ kaakiri lati ri i pe wọn di gbogbo agbegbe ti wọn wa gbagba.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Sé ìwọ mọ Kayọde Fayẹmi tó ń díje ni APC?
Oríṣun àwòrán, @Oyetọla_Gboyega Awọn ajafẹtọ miiran to sọrọ nibi eto naa ni Dare Ariyo lati ajọ Democracy and Good governance ati Festus Ojewumi lati ibudo to wa fun eto idajọ ododo ati ipẹtu saawọ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, World Diabetes Day: Ọdún kọkandinlogun ti mo ti wà lẹ́nu itọ ṣúgà nìyí Ileeṣẹ FRSC ti gbe oku awọn to ba iṣẹlẹ ọhun lọ si ile igbokusi to wa ni Ipara, ni ipinlẹ Ogun.
Ọ̀kan lára àwọn agbófinró tí ó mú Zelalem Kibret ti fi ìgbà kan rí jẹ́ akẹ́kọ̀ọ́ Kibret ní Ifásitì tí ó ti ń ṣe iṣẹ́ olùkọ́.
 gbogbo awon musulumi kakiri aye unkoju si kaaba ti won baun kirun ibiyowu ti won ba wa .
Wọn fi sọ orukọ Usman dan Fodio to jẹ oludasilẹ agbegbe Sokoto.
Ṣugbọn o ti wa ni oun yoo fẹ lati pada sẹnu iṣe laipe ni kete ti awọn dokita ba ti fun ni aye ati ṣe bẹ.
Siba dáhùn pé, gbogbo ohun tí ọba pa láṣẹ ni òun yóo ṣe.
Ilé iṣẹ náà sàlàyé pé èyí ni láti jẹ kí gbogbo ǹkan rọrùn fún ará ìlú.
"O wa sísọ lójú rẹ pé, ""ẹgbẹ́ àwọn osere tíátà, Tanpan, tí ń gbé igbesẹ láti maa fún àwọn iléèwé náà niwe àṣẹ, kí wọn má bàa yapa kúrò ní ìdí ìlànà tó tọ́."
Fun gbogbo ileeṣẹ ogun ofurufu Naijiria, iku to wọ ni lara, kan ni leegun ni iru iku to mu Ajagun-wakọ ofurufu Tolulope lo.
Magu, ẹni to kede bẹẹ lasiko to n bawọn osisẹ ajọ naa sọrọ nigba to n rin yika inu ọọfisi ajọ EFCC, o tun fi kun pe, ajọ EFCC ti gba idajọ mẹta ninu ọdun tuntun taa bẹrẹ yii, eyi to ni o jẹ ibẹrẹ to dara.
OLUWA, ìwọ ni agbára mi, ati ibi ààbò mi,ìwọ ni ibi ìsápamọ́sí mi, ní ìgbà ìpọ́njú.
yii se n lo to yin leti nikete ti a ba pari,”Bi a ko ba gbagbe, ile-ise
Ayipada to ba fẹ de ba eto idibo gbọdọ wa lati ọdọ awọn ile igbimọ asofin ni pelu ifọwọsi gbogbo awọn asoju ni eyi ti aarẹ Trump ko lasẹ le lori.
Wọn gbe e digba-digba lọ sileewosan, ko to o gbẹmi mi nibẹ.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ìbejì yóò mú àìsàn bá òbí tí kò bá gbé wọn jó kiri - Àwọn ìbejì Oluwo gba Aláàfin nímọ̀ràn pé kí olorì máa dé adé Obìnrin tí kò bá rẹwà ló ń ṣí ara sílẹ̀ - Ṣọla Allyson Ohun tó burú ni ‘Dìbò kó o sebẹ̀’, ìyà ló bá dé - Olùdíje ANRP Ọbasanjọ kọ́ ni yóò sọ ibi tí Yorùbá yóò dìbò sí ní 2019 - Falọmọ Lasiko to n ba BBC Yoruba sọrọ, Okiki ni owo ilana IVF wọn, ko si rọrun rara, bẹẹ ni eeyan nilo adura, ati iranwọ awọn ẹbi rẹ, ko to se aseyọri lori rẹ.
kò tíì sí ohun ọ̀gbìn kankan lórí ilẹ̀, bẹ́ẹ̀ ni ewéko kankan kò tíì hù jáde nítorí pé OLUWA Ọlọrun kò tíì rọ òjò sórí ilẹ̀, kò sì tíì sí eniyan láyé tí yóo máa ro ilẹ̀.
OLUWA ní: OLUWA ní:“Ìwé ìkọ̀sílẹ̀ tí mo fi kọ àwọn eniyan mi sílẹ̀ dà?
Nítorí, kíyèsíi, bí ìwọ bá le mú àwọn ọ̀rọ̀ kannáà jade, wọ́n yíò sọ pé ìwọ ti pa irọ́, àti pé ìwọ ti ṣe bíi ẹnipé o túmọ̀, ṣùgbọ́n pé o ti tako ara rẹ.
Bí eniyan burúkú bá sì yipada kúrò ninu ìwà ibi rẹ̀, tí ó sì ń ṣe rere, yóo gba ẹ̀mí ara rẹ̀ là.
" Koda, igba ti gbogbo igbiyanju mi lati ba Florence sọrọ ja si asán, ni mo pé gomina ipinlẹ Eko, Babajide Sanwo-olu, pe mo fa ohun gbogbo le e lọwọ, ati pe ko ba ipinlẹ Ọyọ tọju Ajimobi daada, ko si jẹ ki n mọ ti wọn ba nilo iranlọwọ mi.
Gẹgẹ bi ẹ ti mọ pe Chelsea kii ṣe ẹran rirọ, Willian gba goolu mii wọle fun Chelsea, ni ere bọọlu ọhun ba di ọmi alayo mejimeji.
Ẹkọ ọfẹ fun oye imọ ijinlẹ keji ati PHD Fun awọn to fẹ ẹ gba oye keji, ọjọ ori wọn ko gbọdọ ju ọdun marundinlogoji, ati ogoji ọdun fun awọn to fẹ ẹ gba PHD.
Kọmiṣọnna ọlọpaa ni ipinlẹ Ogun, Edward Awolọwọ Ajogun ti paṣẹ pe ki wọn fa iwadii ọrọ naa si ọwọ awọn ikọ to n ṣe aayan iwa ọdaran sawọn ọmọde (anti-human trafficking and child labour unit).
N óo fi ìdájọ́ rẹ lé wọn lọ́wọ́, òfin ilẹ̀ wọn ni wọn óo sì tẹ̀lé tí wọn óo fi dá ọ lẹ́jọ́.
Ẹ̀bùn Ọlọ́run ni ọmọ bíbí ni mo ṣe bí ọmọ 17 Wole Soyinka rèé láti kékeré Ikọ agbabọọlu Desert Foxes ti Algeria naa ni awọn ko ni gba a laabọ lalẹ oni fun Super Eagles rara.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Omololu Akinwale: Ọ̀tá ìlú ni àwọn adarí tó ń lọ sèpàdé nílẹ̀ òkèèrè 26 Ìgbé 2019 Oríṣun àwòrán, Google Àkọlé àwòrán, Olùdíje fún ipò adarí Ilẹ̀ Ìgbìmọ̀ Asojúsòfin,Femi Gbajabiamila kó asojúsofín àádọ́ta tí wọn sẹ̀sẹ̀ dìbò yàn lo sí Saudi Arabia láti lọ sèpàdé.
Nǹkan púpọ̀ ni ó jẹ́ nǹkan ìyàlẹnu fún mi l’ọ́jọ́ ìsìnkú yìí.
Ile iwosan ti wọn ti wa sewadi pe ibale Somayya nipọn pupọ, to si ki pẹlu, idi ree to fi nira fun ọkọ rẹ lati jaa lalẹ ọjọ igbeyawo wọn, afi igba ti Somayya ba fẹ bimọ nikan si ni ibale naa to lee ja.
Coronavirus in Nigeria: Èèyàn 1,598 míì tún ti lùgbàdì covid-19 ní Nàijíríà, 85,367 ló ti rí ìwòsàn
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Anthony Joshua: Ta ni yóò borí nínú abala kejì ìjà Ruiz pẹ̀lú AJ?
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ladoja Gbìyànjú àwọn òwé Yòrúbà yìí wò Pàtàkì June 12 fún Nàíjíríà O kọ ọ̀rọ ikilọ pé ki akọwe fi ọwọ mejeeji rẹ gba ọpa aṣẹ mu daadaa o, mi o fọkan tan Omo Agege ole yii o""."
Ajẹ bi idan ni orilẹede Kenya!
"Nigba to n ba awọn akọroyin sọrọ, Aliyu ni ""Mo kabamọ pe mo n ba awọn ọmọ ọwọ lopọ, ọmọ to tu asiri mi yii, tii se ọmọ osu mẹta, si ni ọmọ ọwọ kẹrin ti maa ba lopọ, ko si si eyi to to ọdun meji ninu gbogbo wọn."
Gbogbo àwọn tí wọ́n bá dẹ́ṣẹ̀ láì lófin, láì lófin náà ni wọn yóo kú.
Afurasí Alárun Coronavirus kejì ní Nàíjíríà tún rí ìwòsàn Ọkùnrin tó bẹ́ sì òdò ọ̀sà pa ọ̀rẹ́bìnrin rẹ̀, lòun náà fi fẹ́ kú - Iléeṣẹ́ ọlọ́pàá Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
"Inú ọ̀rẹ́ mi dùn pé, "" lóòtọ́, oò tíì lè mọ níní ìmọ̀lára ìgbádùn ìbálòpọ̀ bí o kò bá tíì fi ojú ara ṣe bíi ẹni tó nílò ìbálòpọ̀ rí tí wàá ṣe bí ẹni ń bá ara rẹ̀ lájọṣepọ̀""."
Láti wá mú èyí kúrò, ẹ̀rọ Fẹntílàtọ̀ yìí ni wón ń lọ láti gbé afẹ́fẹ́ wọ inú ẹ̀dọ̀ fòòró.
Kò sí ẹnìkẹta láàrin àwa mejeeji,tí ó lè dá wa lẹ́kun.
Àwọn ológun dojú ìjà kọ ara wọn ní Khartoum Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Hakeem: Mo lè sọ arúgbó dí ọmọge nígbà tó bá wù mí Ninu ifẹsẹwọnsẹ keji to waye, ọmi alayo kọọkan ni Ajax ati Juventus ta.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Seyi Awolowo: Torí mo fẹ́ j'ólórúkọ ni mo ṣe lọ fún ètò Ẹlẹ́gbọ́n Àgbà 11 Ọ̀wàrà 2019 Oríṣun àwòrán, Yetunde Olugbenga Seyi Awolowo ni oun fẹ ni orukọ toun ni yatọ si orukọ Baba Baba oun ti gbogbo agbaye mọ.
O wa parọwa si awọn aṣoju Amọtẹkun lati ṣiṣẹ wọn pẹlu otitọ inu pẹlu alaye wi pe, ijọba ipinlẹ Ọṣun ti ya ikorita Ọlajokun silẹ ni opopona maroṣẹ Gbọngan, ti yoo maa jẹ olu ileeṣẹ Amọtẹkun nipinlẹ Ọṣun.
Ẹ ko le yan ọba ilẹ Yoruba bii ti ilẹ Gẹẹsi, bẹẹ naa ni wọn ko le yan ọba ilẹ Gẹẹsi bii ọba ilẹ Yoruba, nitori ọtọọtọ ni Ọlọrun da wa.
Ọmọ kẹjọ ti obinrin naa yoo bi niyii.
Oríṣun àwòrán, Others Ijọba ni ohun ti ko kan awọn asaaju ẹgbẹ awakọ ero naa ni wọn n dasi, bẹẹ si ni igbesẹ ijọba Ọyọ lati maa gba owo ni ẹẹkan lojumọ lo dun mọ awọn awakọ yika ipinlẹ naa ninu, lodi si ohun to n waye tẹlẹ.
" Owoseni wa gba awọn ọmọ Yoruba nimọran lati mase maa pe maalu ni buọda, tori pe wọn fẹ jẹran, tabi fi ohun ti wọn fẹ jẹ loni ba ọjọ ọla wọn jẹ.
Wọn parọwa si ijọba lati wa ojutu si ọrọ iyanṣẹlodi naa, ki o ma baa ṣe akoba fun okoowo wọn.
Ilu kan ti wọn n pe ni Jabata si ni Afọnja ti wa Lasiko ti Alaafin Abiọdun wa lori itẹ awọn baba nla rẹ, ni Afọnja jẹ Aarẹ Ọna Kakanfo, titi ti Alaafin Aolẹ, tii se ọmọ bibi Alaafin Abiọdun fi gori itẹ lẹyin to seku pa baba rẹ Ni kete to jẹ oye akọni yii tan, ni Afọnja lọ tẹdo silu Ilọrin nitori pe Aarẹ Ọna Kakanfo kankan kii gbe ni ilu kannaa pẹlu Alaafin, ọga meji kii sa gbe ninu ọkọ kan, agbo meji ko si lee mu omi ninu koto kan soso Afọnja ni Aarẹ Ọna Kakanfo kẹfa, amọ ko pẹ rara ti ija de, ti orin si di owe laarin rẹ ati Alaafin Aolẹ, eyi ta lee ni o se okunfa bi awọn ẹya Fulani se gba Ilọrin mọ ilẹ Yoruba lọwọ.
 ""Àwọn ọmọ kò lè sọ èdè abínibí wọn mọ́."
Wọn yọ Alake kuro nipo, wọn si lu ilu iyọkuro nipo fun un leyin ikede.
A bá wọ ọkọ̀ ojú omi kan tí ó ń ti Adiramitu bọ̀ tí ó fẹ́ lọ sí ibi mélòó kan ní Esia.
Amẹ́rika dá akẹ́kọ̀ọ́ padá nítori Facebook Nínú gbèsè Nàíjíríà, ₦121,000 ló kàn ẹnìkọ̀ọ̀kan, ṣó o ṣetán láti san tìẹ?
Ile asofin apapọ nilẹ Amẹrika ti se agbekalẹ ajọ kan ti yoo ri si akoso awọn eto to n sami irinwo ọdun itan awọn ọmọ Amẹrika to jẹ adulawọ ( African-American) ti yoo waye lọdun yii.
Ọ̀wọ́ àwọn ọmọ ogun Filistini kan sì lọ sí ọ̀nà Mikimaṣi.
Ó ní òun óo jẹ arọmọdọmọ Dafidi níyà nítorí ẹ̀ṣẹ̀ Solomoni, ṣugbọn kò ní jẹ́ títí ayé.
Ta ni òpùrọ́ bí ẹni tí ó bá kọ̀ láti gbà pé Jesu ni Mesaya?
Àwọn ọmọ ogun Farao ti jáde, wọ́n ń bọ̀ láti Ijipti; nígbà tí àwọn ará Kalidea tí wọn dóti Jerusalẹmu gbọ́ pé wọ́n ń bọ̀, wọ́n kúrò ní Jerusalẹmu.
’ rèé Duro Ladipọ, ìlúmọ̀ọ́ká òṣèré tíátà àti ọmọ àlúfà tí kò gbàgbé àṣà ìbílẹ̀ Gẹgẹ bi itan atẹnudẹnu ti jẹ ko ye wa, to fi mọ oju opo Wikipedia ati Facebook , a ko lee pe ori aja, ka ma peri ikoko ta fi se e, ni ọrọ Afọnja, ilu Ilọrin ati Ọyọ ile jẹ, nitori pe wọn tan mọ ara wọn.
Asaheli wó lulẹ̀, ó sì kú síbi tí ó ṣubú sí.
Ṣugbọn Abineri kò sí lọ́dọ̀ Dafidi, ní Heburoni, nígbà tí wọ́n dé, nítorí pé Dafidi ti ní kí ó máa pada lọ, ó sì ti lọ ní alaafia.
Nitori ọpọlọ pipe to ni lo jẹ ki aarẹ Umaru Musa Yar'Adua faa kalẹ lọdun naa lọhun gẹgẹ bi ọga agbaile ifowopamọ apapọ Naijira.
Ẹnìkan ka ọjọ́ kan sí ọjọ́ pataki ju ọjọ́ mìíràn lọ, ẹlòmíràn ka gbogbo ọjọ́ sí bákan náà.
are  Muhammadu Buhari ti soro nigba akoko lati tako aheso oro  pe ohun ki I se eniyan, pe eda ni oun.
Wọ́n á lọ̀ọ́ kúnná, wọ́n á wá da Kọfí lùú, wọ́n a wá pòó pọ̀ dáadáa nínu ẹ̀rọ ọlọ.
Ẹni tí ń kórè a máa rí èrè gbà, ó ń kó irè jọ sí ìyè ainipẹkun, kí inú ẹni tí ń fúnrúgbìn ati ti ẹni tí ń kórè lè jọ máa dùn pọ̀.
”Jehoṣafati dáhùn pé, “Bẹ́ẹ̀ ni, n óo lọ, ìwọ ni o ni mí, ìwọ ni o sì ni àwọn ọmọ ogun mi ati àwọn ẹṣin mi pẹlu.
Oríṣun àwòrán, Tony Ezimakor Àkọlé àwòrán, Ibẹru bojo ti ba ọpọ awọn oniroyin lorilẹede Naijiria nitori ọkan o jọkan awọn ikọlu agbofinro nibẹ O fẹ jọ bi ẹni wi pe iroyin naa fi awọn alagbara kan lorilẹede Nbaijiria siba-sibo, paapaa julọ bi o se jẹ wi pe ko pẹ pupọ ti awọn kọlọransi agbebọn Boko Haram yii tun ji awọn akẹkọ kan gbe ni ilu Dapchi ni ipinlẹ Yobe lẹkun ila oorun ariwa orilẹede Naijiria.
Oríṣun àwòrán, Others Ọmọdé méjì àtàgbà kan ló kú nílé alájà mẹ́ta tó wó l'Eko pátápátá - LASEMA Kí ló mú Obasanjo ti ilẹ̀kùn mọ́ ẹbí, òṣìṣẹ́, ojúlùmọ̀ ní ibi òkú àna rẹ̀?
Ìsàlẹ ̀ Èkó ( lagos island ) jẹ ́ àárín gbùngbùn agbègbè ìjọba ìbílẹ ̀ ( local government area ní lagos ) , ìpínlẹ Èkó ( lagos state ) .
 Eyi tako ipinnu lati gbajumo eto ilera wa ki a mu idagbasoke to ye de ba eto ilera wa ki awon olopolo pipe Naijiria to n sise isegun le duro sile sise lai lo sile okeere mo.
Lara wọn ni: 1980: Iba 1981: Esi Oro 1982: Igbalaye 1984: Talazo System 1984: Talazo '84 1984: Ise L'Ogun Ise 1984: Ijo olomo 1985: Talazo Disco 85 1985: Alhaji Chief Wasiu Ayinde Barrister and His Talazo Fuji Commanders Organisation Oloriki Metta / Ki De Se 1985: Elo-Sora 1985: Pomposity 1986: Ori 1986: Tiwa Dayo 1986: Erin Goke - Lecture 1986: Baby Je Kajo 1987: Talazo In London 1987: Aiyé 1987: Adieu Awolowo Oríṣun àwòrán, Instagram/kwam1_official 1988: Sun - Splash 1988: Fuji Headline 1988: My Dear Mother 1989: Fuji Rapping 1989: Achievement 1990: Jo Fun Mi (Dance For Me) 1991: American Trips 1991: Fuji Collections 1993: The Ultimate 1995: Consolidation 1995: Reflection 1995: Talazo Fuji Party Music Compact Disk 1996: Legacy 1996: Faze 2 Global Tour '96 1997: History 1997: Berlin Compact Disk 1999: Fuji Fusion (Okofaji Carnival) 2000: New Era 2000: Faze 3 2001: Message 2001: Statement 2001: New Lagos 2002: Gourd 2003: Big Deal 2006: Flavour 2011: Tribute To My Mentor 2012: Instinct 2012: Fuji Time 2017: 22 Dec Fuji Ep Let Music Flow Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Oun ni oludasilẹ ati ọga agba ile iṣẹ amojuẹrọ Hydropec Engineering Company Ltd.
N óo ròyìn orúkọ rẹ fún àwọn ará mi;láàrin àwùjọ àwọn eniyan ni n óo sì ti máa yìn ọ́:
New Minimum wage: Ẹgbẹ́ òṣìṣẹ̀ yóò bẹ̀rẹ̀ ìyanṣẹ́lódì ní Jan.
Ninu òkùnkùn, ati ìbànújẹ́ ni a ti ń lo ìgbésí ayé wa, pẹlu ọpọlọpọ ìyọnu, àìsàn ati ibinu.
Dájú dájú a wà pẹ̀lú NLC.
Dájúdájú OLUWA yóo jẹ́ kí o jọba ati àwọn ọmọ rẹ pẹlu.
Ikú tún ti wọ agboolé òṣèré Yorùbá.
Saaju, alamojuto agba ile-ise naa dokita Nteranya Sanginga se akiyesi wi pe ile-ise re ni ojuse lati se atungbekale ati igbeeru ise agbe ni ile Afirika.
Agbaboolu owo iwaju fun iko Super Eagles tele, Emmanuel Amuneke wa lara awon ti o sekilo ohun pe, bi iko Super Eagles ko ba fe jade kuro ninu idije agbaye naa lai ro ti tele, iko ohun gbodo ni afojusun, ki wo si tun tepa mo ise won si, ki won o to koju Croatia ninu ifigagbaga kinni in won.
Ninu atẹjade kan ti alukoro ileeṣẹ ọlọpaa ni ipinlẹ Eko fi sita, ọwọ awọn ọtọlẹmuyẹ tẹ ọgbẹni Hassan Maiwake ni ilu Kano ṣugbọn awakọ ajagbe elepo naa ṣi na papa bora.
"Lotọ, awọn kan gbimọ abosi lodi si mi lasiko idibo komẹsẹ̀-o-yọọ́ fun ipo gomina lẹgbẹ oṣelu APC, ṣugbọn emi ko lee tori eyi ṣiṣẹ tako ẹgbẹ tabi fi ẹgbẹ oṣelu yii silẹ"" Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Onídájọ́ Fọlahanmi Oloyede léwájú ìwọ́de òṣìṣẹ́fẹ̀yìntì fún ọjọ́ mẹ́ta l'Ọ́ṣun Yusuf Lasun jẹ́ ọkan nínú àwọn akópa mẹ́tàdínlógún tó dìde láti gbégba ipò gómìnà lábẹ́ àsíà ẹgbẹ́ òṣèlú APC nípìnlẹ̀ Ọsun lóṣù kede ọdun 2018."
"Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Kayeefi: 'Ọkọ mi ṣẹ̀ṣẹ̀ ní kí n lọ se mọ́í-mọ́í, tó ṣẹ̀ bá mi ṣeré tán ni mo gbọ́ pé ""Mopol"" yìnbọn pa á' Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Fídíò, Coronavirus: Àwọn ìpèníjà márùn ún tó wà lórí pínpín abẹ́rẹ́ ajẹ́sara àrún Coronavirus3 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Adeyeye Ile Ife: Kílódé tí Ọọni Ife, Oba Ogunwusi kò fi gbọdọ̀ rí ọmọ rẹ̀ tuntun títí di ẹ̀yìn oṣù mẹ́fà?"
Ni ti Zarka, o ni ọmọ oun ṣi wa lọdọ awọn ẹbi ọkọ oun, ojojumọ si ni oun maa n ronu nipa alaafi rẹ.
O ni ko yẹ ki o si ifoya kankan nipa awọn onwoye idibo nitori pe INEC yoo ti saaju ṣe agbeyẹwọ wọn ki wọn to gba iyọnda lati wa kopa ninu eto idibo.
Ọlọrun kì í ṣe Ọlọrun àwọn òkú, ti àwọn alààyè ni; nítorí pé gbogbo wọn ni ó wà láàyè fún Ọlọrun.
Ohun ati Chiwetel Ejiofor jọ kopa ninu ere Steve McQueen, 12 Years a Slave, to gba ami ẹyẹ Oscars fun aworan to dara ju lọdun 2014.
Ọpọlọpọ iṣẹlẹ lo ti ṣẹlẹ lori eto aabo Naijiria lapapọ.
Yìnyín àti òtútù ti pa ènìyàn 21 ní America Ètò ìlera alábọ́dé la ó ṣe fún àwọn ènìyàn Ọyọ Àwọn ìṣẹ̀lẹ̀ tí ẹ kò lè gbàgbé níbi ìfọ̀rọ̀wérọ̀ BBC Yorùbá l'Ọyọ Bakan naa, Ọmọ Naijiria to kọkọ kọja ori ila, Gideon Goyet yoo gba miliọnu mẹta naira lọ si ile, nigba ti ẹni keji ati ẹni kẹta to jẹ ọmọ Naijiria to kọkọ de ori ila naa yoo gba miliọnu meji ati miliọnu kan lọ sile.
Nígbà ti BBC ba ọgá àgbà lọgba eranko náà sọ̀rọ̀, ó kọ̀ láti fí ìdí ọ̀rọ̀ yii múlẹ̀ yálà pé ó ṣẹlẹ̀ tàbí kò ṣẹlẹ̀, ó ni ìwádìí ń lọ lọ́wọ́ lórí ọ̀rọ̀ náà, òun kò si ní ẹ̀tọ́ láti sọ̀rọ̀ le lóri.
Wọn a maa lọ si ọdọ Aafaa tabi Mallam ti yoo kọ wọn ni kewu fun bi ọdun marun un si mẹwaa.
Kí ẹ lè pẹ́ lórí ilẹ̀ tí OLUWA ti búra fún àwọn baba yín pé òun yóo fún wọn ati àwọn arọmọdọmọ wọn.
A óo máa kọrin, a óo sì máa yin agbára rẹ.
Jẹtiro sì bá wọn yọ̀ nítorí gbogbo oore tí OLUWA ti ṣe fún àwọn ọmọ Israẹli, nítorí gbígbà tí ó gbà wọ́n kalẹ̀ lọ́wọ́ àwọn ará Ijipti.
Ogun ti kó Esau,gbogbo ìṣúra rẹ̀ ni wọ́n ti kó tán!
"ó fún Nàìjíríà l'èsì àwọn ẹ̀sùn tó fi kàn-án Ọ̀fẹ́ ni China yóò kọ́ fásítì $50M ètò ìrìnnà sí Daura ìlú Ààrẹ Buhari- Amaechi ""Wọn gbe Stanley lọ sile iwosan General Hospital to wa ni Ikorodu, sugbọn ẹpa ko boro mọ."
Oríṣun àwòrán, Abiru/ Twitter Àjọ INEC kéde ní òwúrọ̀ ọjọ́ ìsìnmi pé Abiru ní ìbò 89, 204 nígbà tí Babatunde ti ẹgbẹ́ òṣèlú People's Democratic Party (PDP) ní ìbò 11, 257 Àlàfo tó pọ ni Abiru fi ẹyin alátako rẹ̀ janlẹ̀ ní àwọn ìjọba ìbílẹ̀ márun tó gbé ẹkùn náà ró Oríṣun àwòrán, Getty Images Lonii, ipinlẹ Eko, Kogi, Bayelsa, Borno, Cross River, Plateau ati Zamfara n ṣe atundi ibo lọjọ Satide ọjọ karun un oṣu kejila ọdun 2020.
Dokita Ola Bukola to tun jẹ oluranlọwọ rẹ ni Niajiria, lo kede bẹẹ loju opo Twitter rẹ pẹlu afikun bukata ẹkọ rẹ naa ni oke okun ti gbe.
Máṣe bẹ̀rù ìṣòro, ọkùnrin kkì bẹ̀rù ìṣòro, oníṣòwò tí ó pàdánù lẹ́ẹ̀kan tí ó ti ìtorí bẹ́ẹ̀ wí pé òun kò ṣòwò mọ́ ti ba ayé jẹ́, àgbẹ̀ tí ohun ọ̀gbìn rẹ̀ bàjẹ́ ọ́dún kan tí ó wí pé òun kò ṣe àgbẹ̀ mọ́ ti ba orúkọ ara rẹ̀ jẹ́, bẹ́ẹ̀ ni ẹni tí ń ṣe ìmẹ́lẹ́ ni ibi iṣẹ́ rẹ̀ kò ṣe ibi sí ẹlìmíràn bí kò ṣe sí ara rẹ̀, nítorí onímẹ̀ẹ́lẹ́ ènìyàn kò ní lè dúró ní àwújọ àwọn èrò iwájú, wọ́n ó máa wà láàrin àwọn èrò ẹ̀hìn láéláé.
"Wọn ni ""eto aabo to mọyan lori nilẹ Yoruba san ju erongba ẹnikan lati dije fun ipo aarẹ lọ""."
Bótilẹ̀ jẹ pe báku à ó jẹ ẹran to ju eerin lọ, oore ofẹ si wa pé àwọn mejeeji yóò tun pada foju rinju Pẹ̀lú bi ǹkan ṣe ri yìí, iṣẹ́ nla lorin kewu lo wa niwaju Liverpool ninu abala Keji to yóò wáye ni Anifield Igba akọkọ rèé ti Liverpool yóò fìdírẹmi pẹ̀lú àmi ayo mẹ́ta nínú ìdíje Champions League ọdun yìí.
“Nítorí pé ìran irọ́ tabi àfọ̀ṣẹ ẹ̀tàn yóo dópin láàrin àwọn ọmọ Israẹli.
Ó dàbí àwọn ọmọde tí wọ́n jókòó ní ọjà, tí wọn ń ké sí àwọn ẹlẹgbẹ́ wọn pé.
Iroyin naa ni aisan owo oṣu wọn deede ati aisi ohun ijagun fun awọn ọmọ ọmọgun naa wa lara idi ti wọn fi fẹ fi iṣẹ silẹ.
Ti a o ba gbagbe, lasiko to n ba BBC sọrọ lori Facebook Live, Pasuma sọ pe orilẹede Canada ni oun yoo ti se ayẹyẹ ọjọ ibi oun ti ọdun 2018.
Coronavirus Updates: UCH ní èròjà Covid-19 tíjọba fún òun kò tó ₦1m
Olólùfẹ́ mi kò bínú sí ǹkan ìṣeré ìbálòpọ̀ mi, a ma ń lò ó nínú eré tó ṣáájú ìbálòpọ̀.
Ni bayii, awọn alakoso idije Premier League yoo ṣepade pajawiri lọjọ Ẹti lati jiroro lori ọjọ iwaju idije naa ni saa yi.
Kì í ṣe àwọn àgbà nìkan ni wọ́n gbọ́n,tabi pé arúgbó nìkan ni ó mọ òye ohun tó tọ́, tó yẹ.
Agbára wọn ju tèmi lọ, nítorí náà, wá bá mi ṣépè lé wọn, bóyá bí mo bá bá wọn jagun, n óo lè ṣẹgun wọn, kí n sì lé wọn kúrò lórí ilẹ̀ mi.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ibadan Airport: Ìdí rèé tí pápákọ̀ ofurufú Ibadan ṣe n dá paroparo ní gbogbo ìgbà 1 Ògún 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 7 Ògún 2019 Ko fi bẹẹ si ilu kan ti eeyan n lọ loriẹede Naijiria ti ko ni ri ọkọ ibẹ wọ nilu Ibadan.
Awon alase lorile-ede Egypt naa ko sai foju wina awon alakatakiti elesin Islam naa, eyi ti won gbogun ti awon eniyan ti o wa ni agbegbe Sinai Peninsula, Ronke Osundiya.
Ajo isokan ile-Europe (EU) ti gboriyin fun ijoba orile-ede Naijiria fun akitiyan re, latari bi won se fi awon omo ile-iwe Dapchi ti o wa ni ipinle Yobe sile.
 indonesia jẹ ́ ọmọ ẹgbẹ ́ olùdásílẹ ̀ asean àti ọmọ egbẹ ́ Àwọn òkòwò únlá g-20 .
Lẹyin ọrẹyin ni akọwe agba nileesẹ ọrọ ayika, Abiọdun Bamgboye, wa da ẹrọ ibanisọrọ naa pada sugbọn gbogbo aworan ati ohun mẹtadinlogun to wa ninu rẹ, ni wọn ti parẹ patapata.
Wo àwọn ojúṣe àti èèwọ̀ fún ikọ̀ ọlọ́pàá SWAT tó gba iṣẹ́ lọ́wọ́ SARS Ọlọ́pàá mẹ́sàn án tó farapa nínú ìjàmbá ọkọ̀ Akure t'éèyàn méjì ti kú sì wà nílé ìwòsàn Àwọn ìṣẹ̀lẹ̀ mánigbàgbé tó wáyé nibi ìwọ́de ENDSARS Nàìjíríà Ọlọ́pàá mú afurasí 31 tó ń dúnkokò máwọn ọmọdé lórí ayélujára Bàbá ọlọ́mọ méjì fi ipá bá ọmọ ọdún mẹ́rin lò pọ̀; Adájọ́ rán an ní ẹ̀wọ̀n gbére 5.
Nítorí pé Kristi kò fi iṣẹ́ ṣíṣe ìrìbọmi rán mi, iṣẹ́ iwaasu ìyìn rere ni ó fi rán mi, kì í sìí ṣe nípa ọ̀rọ̀ ọgbọ́n, kí agbelebu Kristi má baà di òfo.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Borno Zabarmani Rice Farmer Massacre: Àwọn àgbàgbà Òkè Ọya ní ẹ̀mí èèyàn kò níyì mọ́ lábẹ́ ìṣèjọba Buhari 30 Bélú 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 5 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àwọn àgbàgbà Òkè Ọya ń fẹ́ kí Ààrẹ Muhammadu Buhari kọ̀wé fipò sílẹ̀ nítorí ẹ̀mí èèyàn kò níyì mọ́ lábẹ́ ìṣèjọba rẹ.
Ṣugbọn to ba jẹ okun gbọọrọ lo ni, so o mọ ẹyin ori rẹ.
Wọ́n kúrò ní Elimu, wọ́n lọ pàgọ́ sí etí Òkun Pupa.
Agbẹjọro fun olupẹjọ ni niwọn igba ti agbẹjọro rẹ ti fi idi rẹ mulẹ pe ilumọọka ni Naira Marley, iwa ati iṣe rẹ yoo jẹ awokọṣe fun ọpọ awọn ọdọ lorilẹ-ede Naijiria eyii to lee ni ipa ti ko kere laarin wọn.
Ajo to n mojuto asa ati igbafe lorile ede Naijiria ti so pe awon ko ni pe gbe iwe akosile ti yoo safihan gbogbo awon asa to wa jake-jado orile ede Naijiria sita lati le mu idagbasoke ba asa ati igbafe lorile ede yii.
Bí ẹ bá gbọ́ ohùn rẹ̀ lónìí,
Báwo ni ojú mi kò ṣe ní fàro, nígbà tí ìlú tí ibojì àwọn baba mi wà, ti di ahoro, tí iná sì ti jó àwọn ẹnubodè rẹ̀?
Trump picture: ọjọ́ tí Trump kí mi kú iṣẹ́ lórí 'twitter' ní inú mi dùn jù- Oyedele Ọkọ̀ òfurufú Boeing 737 jábọ́ ni kété tó gbéra ní pápákọ̀ òfurufú ni orílẹ̀-èdè Iran Gómìnà mẹ́ta àtí ènìyàn 1,242 ló kó sí panpẹ EFCC ni ọdún 2019 Ẹ́ gba fóónù, ẹ pe ẹbí yín pé a fẹ́ dáná ṣun yín - Aráàlú sọ fún adigunjalè méji Dokita Ameh fikun un wi pe o gba awọn dokita naa ni wakati mejila lati fi ṣe iṣẹ abẹ naa, ti awọn dokita mejidinlọgọrin naa si pin ara wọn si ọna meji lati ṣiṣẹ abẹ naa.
Wo àwọn agbábọ̀ọ́lù obìnrin ti wọ́n jọ máa figagbága ni France 2019 Òbí tó n fa sìgá n fi ọmọ rẹ̀ sínú ìdè àìsàn l'ọ́jọ́ iwájú Ọjọ kẹfa, oṣu kẹfa ni idije naa bẹrẹ lọdun 2019.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Kayeefi: Facebook ni Wolii Arole Jesu fi tàn an wọ agbo, orí rẹ̀ ni wọ́n fi s'owó Kii ṣe igba akọkọ niyi ti iru iṣẹlẹ bayii ti waye ni ipinlẹ Rivers.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Daddy Freeze s'alaye n to faa ti oun fi n tako idamẹwa Ile iṣẹ ọlọpaa ilẹ Gẹẹsi ni ẹtọ awọn ni lati ṣe iwadii ọrọ tawọn fura si pe o nii ṣe pẹlu idunkooko mọ awọn eeyan ẹya kan tabi ẹlẹsin miran.
Olukuluku orílẹ̀-èdè a máa rìn ní ọ̀nà tí oriṣa rẹ̀ là sílẹ̀, ṣugbọn ọ̀nà OLUWA tí Ọlọrun wa là sílẹ̀ ni àwa yóo máa tọ̀ títí laelae.
Mo bẹ̀ ọ́, jẹ́ kí n kọjá sí òdìkejì Jọdani kí n sì rí ilẹ̀ dáradára náà, agbègbè olókè dáradára nnì ati Lẹbanoni.
Ka sọ ootọ, awọn akojọ ero ara ilu kọọkan laahẹ pẹlu bi wọn ko ti ṣe ṣẹkunrẹrẹ akojọ ero ara ilu lawọn aaye kọọkan paapa awọn ti ko kẹkọ gboye fasiti.
“Ile Igbimọ Aṣofin ni ẹka to ṣe pataki fun ijọba tiwantiwa, a ko ni ṣalai sa gbogbo ipa lati daabo bo fun ifẹsẹmulẹ pataki ijọba naa”.
Chike bẹ ile ẹjọ lati tu wọn ka ko to o di wi pe 'iyawo oun yoo pa oun'.
Joseph Nanven Garba ni ẹni akọkọ lati Naijiria, to wa nipo naa laaarin ọdun 1989 si 1990.
“Bí ẹnìkan bá bí ọmọkunrin kan, tí ó jẹ́ aláìgbọràn ati olórí kunkun ọmọ, tí kì í gbọ́, tí kì í sì í gba ti àwọn òbí rẹ̀, tí wọ́n bá a wí títí, ṣugbọn tí kò gbọ́, 
Ọmọde mẹfa wa ninu awọn to farapa ọhun.
    Nítorí èyí, a ránṣẹ́ lọ sọ fún ọba pé à ń bọ̀ wá ri i nípa ọ̀rọ̀ kan àti pé kí ó sọ ìgbà tí òun lè rí àyè rí wa.
Lati igba naa ni ọpọ eeyan ti n pe Aderibigbe ni 'Tisa Seyi', to si ko ipa to jọju si aseyọri akẹkọọ rẹ naa ninu ibo gomina to gbe wọle lọdun 2019.
Kolawọle ni iye ti wọn ba ra a ni yoo ma a sọ iye ti wọn yoo ma a ta, nitori naa iye owo epo bẹntirlo yoo lọ soke si.
Sibẹ kò sí ẹnìkan ninu yín tí ó ń ṣe ohun tí òfin wí.
Sugbọn ninu idile aarẹ tẹlẹ fun Naijiria, Olusẹgun Ọbasanjọ, kiiṣe ẹẹkan tabi ẹẹmeji ni awọn ọmọ rẹ ti tako o tabi gbena woju rẹ ni gbangba.
Koda ọkan ninu awọn oniwahala naa kọlu akọroyin ti wọn si ba ẹrọ ibanisọrọ rẹ jẹ.
Fi mí ṣe ọ̀kan ninu àwọn alágbàṣe rẹ.
Eyín rẹ dàbí ọ̀wọ́ aguntan tí wọn ṣẹ̀ṣẹ̀ gé irun wọn,tí wọn wá fọ̀;gbogbo wọn gún régé,Kò sí ọ̀kan kan tí ó yọ ninu wọn.
Bẹẹ ba si gbagbe, yoo to osu mẹfa tawọn ileewe fi wa ni titipa nitori arun Coronavirus, tawọn akẹkọọ si fidi mọle wọn.
Cassidy Nurse ni ọdọbinrin naa to woye pe ẹni ti oun ṣẹṣẹ pade yii ti jọ oun ju.
Toyin Abraham ní òun lo àgbo ni ipo iloyun
Ati pe: ko si ẹni to ni ki ẹnikẹni ma sin Shia to ba fẹ sin rara.
Bótilẹ̀ jẹ́ pe àgbéjọro ń fẹ́ ki wọn fi si ẹ̀wọn ọdun méje síbẹ̀ adájọ dá gbogbo atotonu agbẹjọrà nù ni to fi mọ ẹsun ìjíní gbé.
 Àwọn méjèjìbsì fẹ ́ ràn ilẹ ̀ baba wọn .
“Ìwọ kò gbọdọ̀ lọ́wọ́ sí ọ̀tẹ̀ tí àwọn eniyan yìí ń dì.
Kí ìtàn náà wọ inú–un wa lọ, kí ó wọ inú ẹ̀jẹ̀-ẹ wa lọ kό ṣe wá ní àṅfàní; kí a sì jọ kọ́ ẹ̀kọ́ ti yóò ṣe ọmọ aráyé lόore.
Ile-ise omo ogun oju ofurufu Naijiria, ti bere eto idanileko olojo marun un fun awon akosemose onisegun oyinbo mẹ́tàdínlógójì lori ona ati gba emi awon eyan la jake-jado ile iwosan awon omo ogun ohun lorile-ede Naijiria.
Bẹ́ẹ̀ ni àwọn eniyan Israẹli ṣe ṣẹgun àwọn ará Filistia, wọn kò sì gbógun ti àwọn ọmọ Israẹli mọ́.
Nupeng àti Pengassan gùnlé ìyanṣẹ́lódì Ààrẹ Mali tẹ́lẹ̀, Amadou Toumani Toure jáde láyé Afurasí afipábánilópọ̀ kàgbákò, obìnrin tó jà lólè fi eyín gé nǹkan ọkùnrin rẹ̀ jábọ́ lásìkò ‘Blow Job’ Àwọn tó pè lẹ́jọ́ náà ni, Damini Ogulu ti àwọn ènìyàn mọ̀ sí Burna Boy, David Adeleke (Davido) Folarin Falana (Falz); Debo Adebayo (Mr Macaroni), àti Maryam Akpaokagi (Taoma).
Alaga yii wa fi idi ọrọ rẹ mulẹ wi pe kii ṣe pe ajọ naa yoo fi panpẹ ọba mu wọn lasan ṣugbọn wọn tun maa ṣe alakalẹ ọna ti wọn yoo fi wulo lawujọ ti wọn yoo si sọ wọn di ọtun.
Ó ní ìfẹ́ sí Israẹli, ó fẹ́ fi ìdí wọn múlẹ̀ títí lae; nítorí náà, ó fi ọ́ jọba lórí wọn, láti máa ṣe ìdájọ́ òtítọ́ ati òdodo.
Nítorí náà, Dafidi pe gbogbo àwọn ọmọ Israẹli sí Jerusalẹmu, kí wọ́n baà lè gbé Àpótí Majẹmu OLUWA wá sí ibi tí ó pèsè sílẹ̀ fún un.
Nígbà tí a dé Sirakusi, a dúró níbẹ̀ fún ọjọ́ mẹta.
 a pa ìlu wọn àkọ ́ kọ ́ run nígbà tí Ọba kikongo tó jẹ ́ olùbágbè wọn kógun jàwọ ́ n .
Kengbe Ilorin: Àṣà ẹ̀yà Fulani, Bariba àti Gambari tó dàpọ̀ mọ́ ti Yoruba
Imọ pe awọn alakatakiti Islam Al-Shabab maa n beere fun owó ìtanràn ati owo ipese aabo lọwọ awọn olokowo koda ni Mogadishu ti wọn ti lé wọn ni 2011 kò dá Aamin duro.
N óo kó gbogbo àwọn olólùfẹ́ rẹ, tí inú rẹ dùn sí jọ, ati àwọn tí o fẹ́ràn ati àwọn tí o kórìíra, ni n óo kó wá láti dojú kọ ọ́ ní gbogbo ọ̀nà.
Ǹjẹ́ mo tọrọ ẹ̀bùn lọ́wọ́ yín?
    Inú àwọn apànìyàn méjì yìí dun dé inú egungun, wọ́n jókòó jẹ àkàṣù ẹkọ tí Ọ̀kánjúwàfẹ̀yìntì rà tán, wọ́n bẹ̀rẹ̀ ẹmu mímu.
Gege bi Kemanci ti sọ, “A ṣe akiyesi awọn iwa rere
Iléeṣẹ́ ọlọ́pàá dóòlà ẹ̀mí ọmọ ogun orí omi tí wọ́n jígbé ní ìpínlẹ̀ Ondo Óṣeéṣe kí ìjọba yí ètò ẹ̀kọ́ sí ẹ̀kọ́ àárọ̀ àti ìrọ̀lẹ́ láti ṣí iléèwé padà ní Nàìjíríà Àjọ NCDC kéde pé ààrùn coronavirus ti pàpà wọ ìpínlẹ̀ Kogi Ìjọba kéde àwọn ìlànà tuntun fún òkú sínsín ní ìpínlẹ̀ Ọ̀ṣun Oríṣun àwòrán, @gods_psych O ni Twitter ki ṣe ileeṣẹ ijọba, nitori naa ileeṣẹ aladani lee ṣakoso ohun ti awọn eeyan le fi lede loju opo rẹ lai si họwuhọwu.
láti mú àwọn eniyan mọ agbára rẹ,ati ẹwà ògo ìjọba rẹ.
LCC - BBC News Yorùbá BBC News, YorùbáFò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Lekki Tollgate shooting: Fídíò táa ní lọ́wọ́ kò ṣàfihàn gbogbo ohun tó ṣẹlẹ̀ nírọ̀lẹ́ ọjọ́ náà - LCC 26 Ọ̀wàrà 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 3 Bélú 2020 Oludari ileeṣẹ to n ṣakoso Lekki Tollgate, Lekki Concession Company ni fọnran ti awọn ni lọwọ nipa ohun gbogbo to ṣẹlẹ nigba ti wọn fẹsun kan pe awọn sọja yinbọn lu awọn afẹhonuhan to n ṣewọde EndSARS ni ogunjọ oṣu kẹwa ọdun 2020 ko ka gbogbo nkan to ṣẹlẹ nirọlẹ ọjọ naa silẹ.
Nigba ti o fi maa di ipari akoko ija naa ni gbogbo awọn to n woran ni Atlanta ti bẹrẹ si ni kigbe orukọ ọmọ Naijiria olugbe New Zealand naa.
Iwe akọsilẹ orukọ awọn eeyan to jẹbi ẹsun ibalopọ lọna aitọ yii nii se akọkọ iru rẹ ti ajọ to n gbogun ti iwa ifinisowoẹrun NAPTIP, se agbekalẹ rẹ nifọwọkọwọ pẹlu awọn ileesẹ alaabo ati awọn ajafẹtọẹni lorilẹede Naijiria.
49 million, eyi ti o je N 61.
“a ri i bi igbe aye awon eniyan se n yi pada si rere, ope pataki lowo banki agbaye fun iranlowo won,” o so pe , a gbo pe eto pataki n lo lowo lori atunse fun idagbasoke lorile ede yii, a si wa lati wa satileyin  fun awon eto rere naa.
Tí a fiṣọwọ́ ní 11:20 11 Òkùdu 201911:20 11 Òkùdu 2019 KókóAhmed Lawan jáwé olúborí gẹ́gẹ́ bí ààrẹ ilé aṣòfin àgbà Ahmed Lawan ti ẹgbẹ oṣelu APC to n ṣoju ẹkun idibo ariwa Yobe ti gbe igba oroke gẹgẹ bii aarẹ ile igbimọ aṣofin agba Naijiria.
Ní ọjọ́ kẹjọ ni Gamalieli ọmọ Pedasuri, olórí àwọn ẹ̀yà Manase mú ọrẹ ẹbọ tirẹ̀ wá.
Talàwọn ọmọlẹ́yìn Saraki tó ń du ipò Gómìnà ní Kwara?
Ati wi pe mo ti naa ọpọlọpọ owo sori ibaṣepọ naa.
Àwọn ẹ̀yà Aṣeri jókòó létí òkun,wọ́n wà ní ẹsẹ̀ odò.
Lọwọlọwọ ni awọn to ni ojulowo ohun eelo idibo ti bẹrẹ ayẹwo kaadi awọn ọmọ ẹgbẹ ati aṣoju bo ṣe yẹ Eto ididbo yii ni yoo yan ẹni ti yoo ṣoju ẹgbẹ PDP ti yoo si koju APC ati awọn oludije ẹgbẹ to ku ninu eto idibo fun ipo gomina to m bọ lọna Gómìnà ìpínlẹ̀ Ekiti, Kayode Fayemi nàá ti ni aàrùn Coronavirus A yìnbọn lu Precious láti dáa dúró ni, akò mọ̀ pé o máa kú- Ọlọ́pàá Wo bí PDP ṣe fẹ́ yàn olùdíje fún ipò gómìnà l'Ondo Ta ni yóò kojú Akeredolu fún ipò gómìnà Ondo?
 sugbon , orile-ede na tuka si czech republic ati slovakia ni 1993 , awon orile-ede mejeji yi si gba cctlds ti won otooto : .
Àwọn ìròyìn mìíràn tí ẹ lè nífẹ̀ sí: APC pàdánù aṣòfin míràn ní'pínlẹ̀ Osun Ọmọ ẹgbẹ́ òsèlú APC tako Oshiomole Ni ọjọ Aje ni gomina Ambọde gba fọọmu iferongba han lati dije fun ipo gomina lolu ileeṣẹ ẹgbẹ oṣelu APC nilu Abuja.
Ǹjẹ́ ẹ rántí ní nǹkan bí ọdún mẹ́ta sẹ́hìn, mo ṣe àgbéyẹ̀wò àwọn ọ̀nà tí a lè gbà kọ èdè Yorùbá pẹ̀lú àmì lórí àwọn ẹ̀rọ wa.
Nibi ipade naa Obasanjo sọ pé òhún gùn lé ìrìnàjò ọ̀hún láti gba orílẹ̀-èdè Nàìjíríà kúrò lọ́wọ́ ẹgbẹ́ òṣèlú All Progress Congress (APC) lọdún 2019.
Òkè ló yí ìlú Ìgbẹ́tì po.
Ìwọ kò fi ebi pa mí ní bàbá, ìwọ kò tú àṣírí rẹ̀ níwájú àlejò, ìwọ kò ro ẹjọ́ bàbá mi ní ilé ìyá rẹ kí o sì mú ìtìjú bá a ní ilé àna, n kò gbọ èébú bàbá mi lẹ́nu rẹ rí, bẹ́ẹ̀ ni ìwọ kò ṣẹ́ èpè fún un lẹ́ẹ̀kan ṣoṣo, bẹ́ẹ̀ ni ìwọ kò sì dàbí àwọn olórí-burúkú obìnrin ti wọ́n máa ń wí tìgbéraga tìgbéraga wí pé kò sí nǹkan tí ọkọ àwọn lè fi àwọn ṣe.
Adajọ ile ẹjọ giga ipinlẹ Eko ni gbogbo ẹri fihan wi pe lootọọ ni Lekan Shonde pa iyawo rẹ Ronke.
Bí mo bá wà láàyè ninu ẹran-ara, iṣẹ́ tí ó lérè ni ó jẹ́ fún mi.
Oríṣun àwòrán, Reuters Àkọlé àwòrán, Bouteflika, ẹni ikeji lati apa ọtun pade Saddam Hussein Ṣugbọn nigba to maa fi di ọdun 1965, ẹgbẹ oṣelu FLN ti wa ninu idamu.
Àmọ́ pàápàá jùlọ, nkan tó fàá nipé bí àsìkò àti ìgbà ṣe nlọ síwájú ni iṣẹ́ tí a nfún ẹ̀rọ yìí ṣe nsòro síi tí ó sì nwúwo síi.
Idibo ti ọdun 2015 jẹ eyi to laami laaka gẹgẹ bi Aarẹ Muhammadu Buhari ati igbakeji rẹ Ọjọgbọn Yemi Oṣinbajo ṣe polongo pẹlu ileri 'ayipada' ni ibo to le ni miliọnu mẹẹdogun lati jawe olubori ninu idibo naa.
Scott McTominay lo kọkọ gba goolu sawọn fun Manchester United lẹyin iṣẹju mẹjọ ti wọn bẹrẹ ifẹsẹwọnsẹ naa.
 dákun máà saájú mọ - risà o .
Amọṣa ki lo n fa afikun epo loorekoore lẹnu ọjọ mẹta yii na?
Ẹ̀yin ọmọ kéèkèèké tẹ́ ẹ ṣẹ̀ lẹ́yìn wa
Ní àkókò yìí, ogunlọ́gọ̀ eniyan péjọ; wọ́n pọ̀ tóbẹ́ẹ̀ tí wọn fi ń tẹ ara wọn mọ́lẹ̀.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Yorùbá tone mark: Fífi àmì ohùn sí orí ọ̀rọ̀ Yorùbá ṣe pàtàkì Saraki loun ṣetan lati pade ajọ EFCC nile ẹjọ, nitori oun gbagbọ pe nibẹ loun ti le ri idajọ ododo gba.
O ni ko si apẹlrẹ aisan kankan lara gomina Makinde ti yoo lo ogun kankan fun, arun naa wa ni o si lọ lai fa wahala kankan si ni agọ ara.
Èmi Ọba tí wọ́n ń kó jẹ nígboro- Oluwo ti ilú Iwo Nǹkan mẹ́sàn án tí Mùsùlùmí gbọdọ̀ ṣe nínú oṣù Dhual- Hijjah Wo bí ètò ìsìnkú Tolulope Arotile ṣe lọ nílùú Abuja Donald Trump ti gbà pé Coronavirus yóò burú jáì kí ǹkan tó dára fún Amẹ́ríkà Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí kan sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
 Ọkọ mi kilọ fun mi pe n ko gbọdọ sọ fun ẹnikẹni nipa iṣẹ abẹ naa.
O ni ta la ba gbẹkẹle nigba ti wọn tun n na ika afurasi i ẹni ti wọn fipa ba lo pọ.
Loorọ kutukutu ni igun kan ninu ẹgbẹ awọn ọlọkada to n ṣatilẹyin fun ẹgbẹ oṣelu All Progressives Congress, APC, yabo ọpọlọpọ ẹka ile ẹgbẹ wọn lati le awọn alaga ẹgbẹ to wa ni iṣakoso, to fi mọ awọn alatilẹyin wọn, ti wọn fi ẹsun kan pe wọn n ṣe ti iṣakoso Fayose, kuro.
Ohun ìríra ni lójú OLUWA, pé kí àwọn gbẹ́nàgbẹ́nà fi ọwọ́ gbẹ́ nǹkan, kí ẹnìkan wá gbé e kalẹ̀ níkọ̀kọ̀, kí ó máa bọ ọ́.
Mo ti bẹ̀rẹ̀ sí ń bá àwọn tí a jọ díje nínú ìdìbó abẹ́lé sọ̀rọ̀ kí àláàfíà léè jọba - Akeredolu Wo àwọn nkan tó yẹ́ kí o mọ̀ nípa 'Awawa Boys', ọ̀kan lára ẹgbẹ́ òkùnkùn tó n dá Eko rú Adarí àjọ NDDC, Pondei ṣetán láti sọ ohun tó mọ̀ nípa ìwàdíì tó bá ti gbádùn- NDDC Ọkùnrin kan pa ara rẹ̀ sínú ọgbà àjọ TRACE tó n mójútọ ìrìnnà ọkọ̀ nípìnlẹ̀ Ogun O le lẹgbẹrun meji awọn ọmọ oṣelu PDP to n kopa ninu idibo abéle naa.
wọ ́ n bí adams ní 1819 .
Iko alabarapa agbaboolu ori tabili orile-ede Naijiira ti teko leti lo siluu Beijing ti n se olu ilu orile-ede China, lati lo kopa ninu idije agbaye ifigagbaga boolu ori tabili awon abarapa naa ti yoo waye niluu Beijing (2018 World Para Table Tennis Championships).
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ifọrọwanilẹnuwo pẹlu Ọmọ Baba Sala Diẹ lara awọn nkan ti o da yatọ nipa oloogbe Oladejo ree.
Òdodo ni o fi pa àṣẹ rẹ,òtítọ́ patapata ni.
Kano Pillars 16:00Yobe Desert Stars ?
Tí ó sì bani lẹ́rù,bí àwọn ọmọ ogun tí wọn dira ogun?
'Digbi ni mo wa lẹyin ki a se idibo to yanranti, inu mi dun pe ẹgbẹ oselu mi n se daadaa'' O tẹsiwaju pe ''Idibo to waye lai pẹ yi ni Katsina Bauchi ati Kogi je oun iwuri fun wa'' Oríṣun àwòrán, @NGRPresident Àkọlé àwòrán, Orilẹ-ede South Africa, Nigeria ati Kenya ni olootu ijọba ilẹ Gẹẹsi n bẹwo pẹlu ireti ati tubọ fi idi iṣakoso rẹ mulẹ gẹgẹ bii olootu ijọba Buhari tun dupẹ lọwọ Thersesa fun ìfọwọ́sowọ́pọ̀ láti kojú ìpeníjà Boko Haram.
Ṣugbọn oun naa ni alebu tirẹ.
Harani kú ṣáájú Tẹra, baba rẹ̀, Uri ìlú rẹ̀, tí ó wà ní ilẹ̀ Kalidea ni ó kú sí.
Àwọn ẹ̀ka rẹ̀ yóo tàn kálẹ̀;ẹwà rẹ̀ yóo yọ bíi ti igi olifi,òórùn rẹ̀ yóo sì dàbí ti igi Lẹbanoni.
30 Àní bí wọn bá sì ṣe síi yín aní bí wọn ti ṣe sí mi, alábùkúnfún ni ẹ̀yin, nítorí ẹ̀yin yíò gbé pẹ̀lú mi nínú ògo.
Ọ̀rẹ́ gbogbo àwọn tí ó bẹ̀rù rẹ ni mí,àní, àwọn tí wọn ń pa òfin rẹ mọ́.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Period party: Àwọn obìnrin kan ṣe ayẹyẹ nkan oṣù l'órí ayélujára Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 3 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 5 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Bí OLUWA ti pàṣẹ fún Mose pé kí àwọn ọmọ Israẹli ṣe fun àwọn ọmọ Lefi, ni wọ́n ṣe.
Jose Mourinho - BBC News Yorùbá BBC News, YorùbáFò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Manchester United ko ri anfani to tọ lara Alexis Sanchez - Jose Mourinho 10 Ẹrẹ̀nà 2018 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Alexis Sanchez jẹ ọgọrin bọọlu fun ẹgbẹ agbabọọlu Arsenal saaju ko to darapọ mọ Manchester United lori adehun ọlọdun mẹ̀rin abọ Akọnimọgba ẹgbẹ agbabọọlu Manchester United, Jose Mourinho, ti sọ wipe ẹgbẹ na ko ti bẹrẹ si ni ri anfani to tọ lori Alexis Sanchez.
Bayii, iwadii ti bere lori oro naa ni eka Motshekga pelu erongba pe ko sohun to buru ninu ipolongo asa iran Kankan sugbon kii se ki a maa foju egbo tele rin kiri lai mo eto awon akekoo.
Àwọn ǹkan ti a rí lára wọn ni aago ọwọ́, ẹ̀rọ ìbánisọ̀rọ̀ ìgbàlóde àti àwọn ǹkan míran.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù BBC Africa Eye: Àṣìlò òògùn láàrín àwọn ìgbèríko ti ń dínkù Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ BBC Africa Eye: Àṣìlò òògùn láàrín àwọn ìgbèríko ti ń dínkù 9 Òkùdu 2019 Ohun tẹ́ẹ̀ mọ̀ àti tí ẹ tí wá mọ̀ báyìí nípa ìjàmbá Codeine, báyìí ló ṣe bẹ̀rẹ̀.
(Kì í ṣe àwọn ọmọ yín tí kò mọ̀ nípa àwọn ohun tí mò ń sọ ni mò ń bá sọ̀rọ̀); nítorí náà, ẹ máa ṣe akiyesi ìtọ́ni OLUWA Ọlọrun yín, ati títóbi rẹ̀, ati agbára rẹ̀, ati ipá rẹ̀.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Islamic State: Ilẹ̀ Amẹrika ń kó àwọn ọmọ ogun IS tó burù kúrò ní Syria- Trump 11 Ọ̀wàrà 2019 Oríṣun àwòrán, Reuters Àkọlé àwòrán, Aarẹ Trump ni awọn afurasi ọhun ni wọn ma n bẹ ori eeyan ni Syria Meji lara awọn ọmọ ẹgbẹ ogun Islamic State, IS, ni wọn ti gbe kuro ni Syria lọ si agbegbe kan ti ijọba ilẹ Amẹrika n ṣakoso rẹ bayii.
Nítorí ti orúkọ rẹ, OLUWA, dá mi sí;ninu òtítọ́ rẹ, yọ mí ninu ìpọ́njú.
Wọ́n sì gbé àpótí Ọlọrun lọ.
wọ ́ n kọkọ gba lílò àjẹsára rubella láàyè ní ọdún 1969 .
Awọn eeyan miran tí ó bá iko BBC Yoruba sọrọ, Ogbeni Jephrey Abidoye ṣàlàyé pé, àsìkò ti to láti mú eto ààbò ilé Yoruba gbòòrò sì.
Nisinsinyii, ọba ni yóo máa ṣe olórí yín.
Dá mi dá wọn, inú ń bí mi sí wọn gidigidi, píparẹ́ ni n óo sì pa wọ́n rẹ́, ṣugbọn n óo sọ ìwọ di orílẹ̀-èdè ńlá.
Bola Ahmed Tinubu  naa wa nile aare lojoRu
Bí àlàyé yìí ba wá rí bẹ́ẹ̀, o túmọ̀ sí pé, èèyàn yóò mi èémí naa fún ìṣẹ́jú àádọ́ta láti gba ẹgbẹ̀rún kan kòkòrò náà ti yóò fi ní ààrùn Covid-19 (Atọ́ka ni àlàyé èyí jẹ́).
OLUWA bá mú kí afẹ́fẹ́ kan fẹ́ wá láti ìlà oòrùn, afẹ́fẹ́ náà fẹ́ sórí gbogbo ilẹ̀ náà, ní gbogbo ọ̀sán ati ní gbogbo òru ọjọ́ náà.
Orìlẹ-èdè mẹrindínlọgbọn tí ọmọ Nàìjíríá lè wọ̀ láì ní àṣe ìwé ìgbélùú Àwọn ọmọ Naijiria yarí lórí ọ̀rọ̀ owó 'tollgate' tí ìjọba kéde rẹ̀ Ronaldo, Messi ẹ yàgò lọnà fagbábọ́ọ̀lù Nàìjíríà tó n gbowò julọ!
Bẹẹ lawọn miran gboriyin fun gomina Sanwo Olu pe awọn agbagbọ ninu rẹ pe yoo yan awọn to yẹ sipo.
Lẹyin oṣu mẹta ni ileewosan mi i na pe mi pe ki n wa fun ayẹwo.
Alfa Babatunde Sotitobire tún fojú balé ẹjọ́ lọ́nìí, bàbá ọmọ jẹri níwájú adájọ́ Ohun mẹ́fà tí àgbáyé kò mọ̀ nípa Majek Fashek tó d'olóògbé nìyí Èsì àyẹ̀wò òkú George Floyd tí ẹbí rẹ̀ ṣe fihàn pé ó kú lẹ́yìn tí wọ́n fẹsẹ̀ fún un lọ́rùn Iye awọn to ti ri iwosan ti jẹ 3239, ti awọn to si ti ku nitori arun naa lorileede Naijiria ti jẹ 314.
Kii se pe àwọn ibùdó iyasọtọ wa ti kún àmọ́ a kàn fẹ́ máa palẹ mọ báyìí ka leè pèsè ohun èlò tó yẹ síbẹ̀.
OLUWA tún wí fún un pé, “Ti ọwọ́ rẹ bọ abíyá.
”Ẹni tí ó gbọ́ níláti sọ pé, “Máa bọ̀.
Nígbà tí ọba pàṣẹ, tí wọ́n kéde rẹ̀, tí wọ́n sì mú ọpọlọpọ wundia wá sí ààfin, ní Susa, ní abẹ́ ìtọ́jú Hegai, tí ń tọ́jú àwọn ayaba, Ẹsita wà pẹlu wọn ní ààfin ní abẹ́ ìtọ́jú rẹ̀.
Bí Jesu ti ń kọ́ àwọn eniyan ninu Tẹmpili, ó bèèrè pé, “Báwo ni àwọn amòfin ṣe wí pé ọmọ Dafidi ni Kristi?
Fi ibinu lépa wọn, OLUWA,sì pa wọ́n run láyé yìí.
Nígbà tí ó di àkókò àtilọ gan-an, ó pe gbogbo ilé jọm ó sọ̀rọ̀ fún wọn ó wí pé:
Laipẹ yii ni Pasitọ Omashola sọrọ loju opo Twitter rẹ, nibi ti o ti kọ orukọ awọn eeyan to ro pe wọn ko le wọ ijọba ọrun ninu eyi ti Naira Marley wa loke tente.
A gbọ pe ni agbegbe Ori-Oke Olorunkole ni iṣẹlẹ naa ti waye ni Ọjọbọ, ti awọn kan si gbagbọ pe awọn to n fi eeyan sẹ oogun owo lo ṣa obinrin naa.
Ogún ọmọdé ni wọ́n kú ikú oró lọ́wọ́ ìkà ọkùnrin lọ́jọ́ náà.
Bakan naa ni wọn ti naka aleebu si ni ọpọ igba lori idarudapọ to n waye ni Yemen, nibi ti ijọba Saudi ti ran ijọba Yemen lọwọ lati maa tẹ ẹtọ awọn obinrin mọlẹ.
Mose sọ fún Aaroni pé, “Mú àwo turari rẹ, fi ẹ̀yinná sinu rẹ̀ láti orí pẹpẹ kí o sì fi turari sí i.
5 546833 Orilẹede Phillippines 8572 8.
Olukọ agba ile ẹkọ Eton, Simon Henderson ni awọn ti gbe igbesẹ lati dẹkun iru iwa yi sugbọn o ni oun gba pe lootọ ''isẹ si ku tawọn yoo se'' Ogbẹni Henderson tọrọ aforijin yii gẹgẹ bi idahun si ọrọ ti BBC beere lọwọ rẹ, nipa apilẹkọ kan ti akọroyin Adaobi Tricia Nwaubani kọ, lori nnkan ti oju Onyeama ri lori iwa ẹlẹyamẹya ati nipa iwọde Black Lives Matter to n ja rain.
Àwọn ẹni tí ẹ kò bá dárí ẹ̀ṣẹ̀ jì, Ọlọrun kò dáríjì wọ́n.
Ní ìrọ̀lẹ́, kí o fi ọ̀dọ́ aguntan keji rúbọ bíi ti ẹbọ ohun jíjẹ òwúrọ̀ pẹlu ẹbọ ohun mímu rẹ̀.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Reluwé Abuja: Amaechi ní èrò pọ̀ ní ojú ìrìn Abuja si Kaduna nítori ìjínigbé lójú pópó 9 Ìgbé 2019 Oríṣun àwòrán, Amaechiofficial Àkọlé àwòrán, Ìjọba tí yòó ṣe àfikun yàrá ikérò si ọkọ ojú irin Ìjọba àpapọ ti pinu lati ra iyara ikero méjì míràn láti fi kún ọkọ oju irin to n ná Abuja si Kaduna, eyi ti yoo mu àdínku ba èrò àpọjú to fẹ wọ ọkọ oju irin.
Àbádárìgì, Ẹ̀pẹ́, Ìsàlẹ̀ Èkó jẹ́ pàtàkì lárá àwọn ìlú pàtàkì tí wọ́n jọ tẹ̀dó tí wọ́n sì jẹ iyèkan.
 Eto idanileko ohun lori didawole ohun osin fun awon osise ati awon omo-ogun, eleyi ti o waye ni gbagede olu ile-ise iko omo-ogun naa lojo Isegun(Tuesday), ojo keje osu kejo odun ti a wayii, ni ogunlogo awon eniyan jankan-jankan kopa ninu re, ti o fi mo awon agunbaniro  National Youth Service Corps members (NYSC), ati awon osise ile-ise alaabo Ministry of Defence (MOD) ti won sise niluu Ibadan,”Ogbeni Babatunde Onileola ti o je onmo ijinle nipa ohun osin ti o wa lati iluu Ede nipinle Osun, lo se idanileko ohun.
Arabinrin yi to ti pada si Ile ẹkọ girama ni o wu oun lati di ọmọ ogun lọjọ iwaju ki oun ba a le dojú ija kọ awọn ọmọ ikọ Boko Haram.
Ìgbẹ̀yìn ewéko inú igbó, ikú ni; ìgbẹ̀yìn ejò afàyàfà, ikú ni; ìgbẹ̀yìn ẹyẹ ojú ọ̀run, ikú ni; ìgbẹ̀yìn àwọn ẹranko ẹlẹ́sẹ̀ mẹ́rin, ikú sì ni pẹ̀lú.
Naira Marley ti de ile ẹjọ lati ibẹ wọn tun ti gbe si ahamọ ọlọpaa nigba naa.
Nígbà tí Ọjọ́ Ìsinmi ti kọjá, tí ilẹ̀ fẹ́rẹ̀ mọ́ ní ọjọ́ kinni ọ̀sẹ̀, Maria Magidaleni ati Maria keji wá wo ibojì Jesu.
Mamman Daura lọ sọ ọrọ yii lasiko to n kopa lori ifọrọwanilẹnuwo kan pẹlu ileeṣẹ iroyin BBC.
Seng sapejuwe Naijiria gege bi orile ede to je egbon fawon orile ede ile Adulawo to ku.
Ẹwẹ, nitori isede to wa lode bayii, iye awọn onibara to n lọ si Shoprite dinku pẹlu nkan bii ida meje abọ.
Nítorí náà, inú bí ọba gidigidi, inú rẹ̀ sì bẹ̀rẹ̀ sí ru.
Bó tilẹ̀ jẹ́ pé ọ̀pọ̀ ló rò pé kìí ṣe àsìkò to tọ̀nà rèé fún yansẹlódì ti ilé ìwòsàn ìkọ́ni yìí gùnlé.
Níbẹ̀ ni ó ti ń ṣọ́ ohun tí yóo pa,ojú rẹ̀ a sì rí i láti òkèèrè réré.
Bí eniyan bá kọlu òkúta yìí, olúwarẹ̀ yóo rún wómúwómú.
Ara ọtọ ni Solade fi ayẹyẹ ọjọ ibi r ti ọdun yii da gẹgẹ bi o ṣe fọ si ori ayelujara pẹlu oriṣiriṣi fọto rẹ.
Ninu ọrọ kan to fi si ori ayelujara Instagram rẹ, Mercy sọ pe isẹ́ loun n se, ki oun to ri taje se.
Jesu wí fún un pé, “Arakunrin rẹ yóo jí dìde.
ọfada ayamase ati oriṣi irẹsi miran ni Yoruba n se lode.
fun ijọba ipinlẹ Ogun lasiko iṣejọba Ọtunba Gbenga Daniel.
Dalung ni oun ko le sọ pato boya ajọ IAAF ṣi owo san ni tootọọ tabi Naijiria tilẹ ṣe aṣiṣe kankan lori owo naa.
Loju opo rẹ ni Instagram, o tun sọ nipa ọjọ ori rẹ pe, oun ti gun oke agba bọ diẹ diẹ wọ ọmọ ọgbọn ọdun.
Bí ó ti ń wọ ọkọ̀ ojú omi pada, ọkunrin tí ó ti jẹ́ wèrè rí yìí bẹ̀ ẹ́ pé kí ó jẹ́ kí òun máa bá a lọ.
E̩nì kò̩ò̩kan gé̩gé̩ bí è̩yà nínú àwùjo̩ ló ní è̩tó̩ sí ìdáàbò bò láti o̩wó̩ ìjo̩ba àti láti jé̩ àn fà ní àwo̩n è̩tó̩ tí ó bá o̩rò̩‐ajé, ìwà láwùjo̩ àti às̩à àbínibí mu; àwo̩n è̩tó̩ tí ó jé̩ kò‐s̩eé‐má‐nìí fún iyì àti ìdàgbàsókè è̩dá ènìyàn, nípa akitiyan nínú orílè̩‐èdè àti ìfo̩wó̩s̩owó̩ pò̩ láàrin àwo̩n orílè̩‐èdè ní ìbámu pè̩lú ètò àti ohun àlùmó̩nì orílè̩‐èdè kò̩ò̩kan.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Àwòràn ọdún egúngún ilu Ìwó jẹ́ àwòpadà-sẹ́yìn 12 Ògún 2018 Àwọn àwòrán yìí ló jẹ ojú ní gbèsè nípa ọdún egúngún 2018 tó wáyé ní ìlú Ìwó.
Margaret Read ni ọ̀gá Ilé Ẹ̀kọ́ ńlá tí ọ̀pọ̀lọpọ̀ àwọn tí ó bá lọ sí ìlú Gẹ̀ẹ́sì láti kọ bí a ti ṣe ń ṣiṣẹ́ Olùkọ́ tí ń kọ́ ìwé wọn, ogunlọ́gọ̀ ènìyàn láti orígun mẹ́tẹ́ẹ̀rin ayé lo ń wá, a kò sì lè ka iye àwọn ọkùnrin tí o ń ṣiṣẹ́ lábẹ́ obìnrin yìí ni bí a ti ń sọ̀rọ̀ yìí.
Kò sí ọmọ-ogun tí ó wà lẹ́nu iṣẹ́ tí ó gbọdọ̀ tún tojú bọ àwọn nǹkan ayé yòókù.
Mose na ọwọ́ rẹ̀ sórí Òkun Pupa; OLUWA bá mú kí afẹ́fẹ́ líle kan fẹ́ wá láti ìhà ìlà oòrùn ní gbogbo òru náà, afẹ́fẹ́ náà bi omi òkun sẹ́yìn, ó sì mú kí ààrin òkun náà di ìyàngbẹ ilẹ̀, omi rẹ̀ sì pín sí ọ̀nà meji.
”Fun idi eyi, ki Oshuntokun ati awon emewa re lo towo won boso, ki won si lo jawo ninu apon ti o yo, nitori pe ko seese ki eniyan je majele, ki o si ma reti pe, ki majele ohun sise lara elomiran.
Ànábì Ọlọ́run ni àwọn ẹlẹ́sìn Islam kàá kún.
Ẹ̀yin náà wá ń fara wé wa, ẹ sì ń fara wé Oluwa.
Ẹni to bori: Senegal Morocco vs Mali.
Baka naa ni ariyanjiran tun be sile nile igbimo asofin boya ile igbimo asofin lagbara lati pe aare Muhammadu Buhari lati wa salaye lori eto aabo.
Buhari dasi ipaniyan Benue Awọn olori ileesẹ aabo tẹdo si Dapchi CAN pe fun atunto ileeṣẹ alaabo ni Naijiria Rwanda gbe'lẹkun ṣọọsi 700 ti pa Iwadii naa to da lori iṣẹ ẹka ajọ lori ọ̀rọ̀ aabo ni Naijiria (Nigeria Security Tracker) ni awọn wọnyii ni Boko Haram ati awọn daradaran pa pẹlu awọn ti ikọ ologun Naijiria pa laitọ nigba ti wọn n koju igbesunmọmi.
“Mo ri isoro to wa nibi ise agbe, mo si se ohun to ye ki n se, lonii yii, inu awon eniyan n dun , ni ti eto airisẹ, awon eniyan to lagbara lati se ise sugbon ti won ko ri ise se nitori pe won ko  ni imọ ẹkọ ti pada lo si oko , ni bayii ko si enikankan ninu won to n ke abamọ lori rẹ.
Mo ka leta ti Abiola ko ,pelu awon ebi MKO lati fi dupe lowo aare.
Elioenai, Jaakoba, ati Jeṣohaya; Asaya, Adieli, Jesimieli ati Bẹnaya; 
Ayo Adebanjo: Màá túbọ̀ parí aáwọ̀ Obasanjo àti Gani Adams torí ilẹ̀ Yorùbá kò gbọdọ̀ bàjẹ́
Wo àwọn tó ń jí owó Covid-19 tí Ìjọba ní wọ́n yóò káwọ́ pọ̀nyìn rojọ́ Ọ̀kọ̀ ojú omi dànù, ènìyàn méjì kù, ẹnìkan di àwátì Alaga kansu, Adeyinka Rẹmi Oluwaseun ni Ogbomọṣo ati aya rẹ ba BBC sọrọ lori bi wọn ṣe pada ri ọmọ naa ti wọn si n tọju iya ati ikoko bayii.
Ìyá rẹ̀ ni Jehoadini ará Jerusalẹmu.
Ruggedy Baba to je ilumoka olorin takasufe wa lara awọn to fi ikini ransẹ.
Ẹ má bẹ̀rù, ẹ níye lórí pupọ ju ológoṣẹ́ lọ.
O ni lọpọ igba ni wọn ti ma n dunkoko mọ oun nitori oun ma n ṣe igbeyawo fun awọn iru ololufẹ bayii.
Kia ni ijọba ologun Obasanjo kede pe oun ti gbe ilẹkun awọn ile ẹkọ fasiti gbogbo nilẹ wa tipa, to si paṣẹ fáwọn akẹkọọ lati gba ile obi wọn lọ.
Nígbà tí fèrè bá dún, tí dídún rẹ̀ pẹ́, kí wọn wá sí ẹ̀bá òkè náà.
Wọ́n ń sin OLUWA, ṣugbọn wọ́n tún ń bọ àwọn oriṣa tí wọn ń bọ tẹ́lẹ̀ ní orílẹ̀-èdè tí olukuluku wọ́n ti wá.
“Ile-ise to n ri si isakoso eru ati pasipaaro yoo da ogo ateyinwa ipinle yii pada si boti wa tele.
 Ise ko duro soju kan, o gbodo tesiwaju, mo ti se temi, ki awon yooku se ti won, ti o ba se tire, ise yoo lo siwaju.
Ọmọbìnrin ọdún 25 gún ọ̀rẹ́kùnrin rẹ̀ pa nítorí ó ní ko lọ ṣẹ́ oyún Èsì ìdánwò òhun tí a ṣé síwájú là n bá fínra báyìí ní Nàìjíríà- Yemi Shodimu Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Baby abandoned on dunmpsite: Mo ti bímọ mẹ́rin tẹ́lẹ̀ fún bàbá méjì nínú òṣí- Dupe Ogbomos Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí 2:52 Fídíò, Nítorí owú jíjẹ, ọkọ Zarka gé imú aya rẹ̀ dànú!
Governorship Election Results: Àgbùnbánirọ̀ tó bá INEC ṣiṣẹ́ kú nínú ìjàmbà ọkọ̀ ojú omi l'Ondo Ta ni Ọjọgbọn Pius Adesanmi gan an?
Nígbà tí wọ́n bá di ẹni aadọta ọdún, iṣẹ́ wọn ninu Àgọ́ Àjọ yóo dópin.
Gbogbo àwọn oníṣòwò ati àwọn tí wọn ń ta oríṣìíríṣìí nǹkan sùn sí ẹ̀yìn odi Jerusalẹmu bíi ẹ̀ẹ̀kan tabi ẹẹmeji.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, World Radio Day: Àwọn òṣìṣẹ́ rédíò ní àwọn ń pa ìsòro àwọn mọ́ra ni láti mú inú aráàlú dùn Nigba to n sọrọ, Ọọni tilu Ile Ifẹ, Ọba Ẹnitan Adeyeye Ogunwusi, Ọjaja Keji ni nitori pe awọn ọba alaye lọwọ si eto aabo Amotekun, ni yoo se fidi mulẹ, to si rọ ijọba lati maa jẹ kawọn ọba alaye lọwọ ninu agbekalẹ eto aabo lagbegbe wọn.
Àwọn mẹ́rin t'íjọba Buhari k'etí ikún s'àṣẹ òmìnira iléẹjọ́ lórí wọn rèé Kí ni pàtàkì nọ́mbà 615 láàrín àwọn èèyàn ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ̀ Ọwọ́ tẹ babaláwo àti adigunjalè márùń ni Imo - Olọpàá Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
N kò rò pé mo kéré sí àwọn tí wọn ń pe ara wọn ní “aposteli” pataki wọnyi!
" Ìbáṣepọ ̀ òun àti cobhams , ni ó jẹ ́ kí ó mọ ọ ̀ gbẹ ́ ni christophe dupouy àti benjamin constant , ní ó so èso rere tí ó fi gbé àwo orin rẹ ̀ "" "" Àṣá "" jáde."
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Lagos Building Collapse: Èèyàn méjì tó há sábẹ́ ilé tó wó ní Ebute Meta ti ń gba ìtọ́jú, LASEMA ń ṣàyẹ̀wò ilé náà ló̩wọ́ 24 Agẹmo 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 25 Agẹmo 2020 Oríṣun àwòrán, Said Ile kan to wa ni ọgangan Ileewosan Comprehensive Health Centre ni agbegbe Ebute Meta nipinlẹ Eko la gbọ pe o ti ṣaa dede wo lulẹ funrarẹ ti eeyan meji si ha sabẹ ile naa.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Ìgbà tí mo máa fi lajú sáyé padà, ọ̀fọ̀ ikú mi ní wọ́n ń kígbe' Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Ó sì jẹ́ olókìkí láàrin wọn.
O ni ọna kan gbogii niyii lati pawo sí apo ijọba ki wọn le pèse ohun amayedẹrun fun araalu Ibadan NURTW: Àwọn ti Auxilliary àtàwọn tí Ajanaku gangan ló ń dàgboro rú Wọ́n ti dáwọ́ ìdánwò àbẹ́rẹ̀ àjẹsára Oxford dúró lẹ́yìn ti olùkopa kan ṣàìsàn Kí ló le è mú kí agbábọ́ọ̀lù subú, kó sì kú lásìkò ìfẹsẹ̀wọ̀nsẹ̀?
Nítorí náà OLUWA ni a óo máa sìn nítorí pé òun ni Ọlọrun wa.
Nigba to tun pada sidi oselu lọdun 1980, lo di alaga ẹgbẹ oselu NPN, ti ireti si wa pe yoo dije fun ipo aarẹ lorilẹede Naijiria lẹyin saa keji aarẹ to wa nipo, ko to di pe awọn ologun ditẹ gba ijọba lọdun 1983 Lẹyin ọdun mẹwa tawọn ologun ti n dari Naijiria, wọn se agbekalẹ ẹgbẹ oselu alagbada meji fun ipadapọ ijọba tiwantiwa, ti MKO Abiọla si darapọ mọ ẹgbẹ oselu Ẹlẹsin taa mọ si Social Democratic Party, SDP, nibi to ti gbe apoti fun ibo aarẹ lọdun 1993 Gbogbo eeyan lo tu yaya jade lati di bio MKO Abiọla lọjọ Kejila, osu Kẹfa ọdun 1993, eyi ta mọ si June 12, ti ireti si wa pe oun lo moke ninu ibo naa bi o tilẹ jẹ pe idaji esi ibo naa ni wọn ka, ki wọn to dawọ duro, eyi to mu laasigbo ba orilẹede yii Lasiko ti MKO Abiọla wa lọgba ẹwọn yii, ni wọn yinbọn pa ọkan lara iyawo rẹ, Kudirat Abiọla nilu Eko lọdun 1996 nitori pe o n se atilẹyin fun ọkọ rẹ to ti lo kọja ọdun marun ninu ahamọ MKO Abiọla kede ara rẹ bii aarẹ Naijiria lẹyin ọdun kan ti eto idibo June 12 waye, ti ijọba ologun Sani Abacha si sọ si ahamọ, nibi to wa to fi jalaisi lọjọ Keje osu Keje ọdun 1998 Yooba ni baa ku laa dere, eeyan ko sunwọn ni aaye, wọn fi oye igbẹyin da MKO Abiọla lọla lẹyin ogun ọdun to ti tẹri gbasọ, nigba ti aarẹ Muhammadu Buhari fi oye GCFR da lọla lọdun 2018, oye yii si ni wọn maa n fun ọwọ awọn eeyan to jẹ adari lorilẹede Naijiria.
Orisirisi ni nkan to waye nibẹ ṣugbọn a ni ki a ṣe akojọpọ diẹ lara awọn ohun manigbagbe to waye nibẹ.
"O ni owo ori ti yoo san da lori awọn ohun ti ko ṣiṣẹ fun, iyẹn ""unearned tax"" lede oyinbo."
Ẹnikẹ́ni kò gbọdọ̀ fìyà jẹ opó tabi aláìníbaba.
Parveena Ahanger - Ajafẹtọ ẹni nipa agbegbe Kashmir ti orilẹede India n dari Parveena ni wọn n pe ni obinrin alagbara lagbegbe Kashimir, Kashimir Iron lady, ti ọmọkunrin rẹ si poora lọdun 1990 nigba ti wahala naa de oju ẹ.
Boya bo se ta ayo naa lo wu wọn lori.
Àjọ ICPC sọ èyí di mímọ̀ ní kété tí àjọ tó ń ri sí ètò ìsinrú ìlú baba ẹni sọ pé òun ti pari ìwádìí lórí ọ̀rọ̀ náà tí ó si ti fi àbájáde rẹ̀ sọwọ́ sí ilé iṣẹ́ tó ń ri sí ìdàgbàsokè ọ̀dọ́ àti eré ìdárayá.
Àwọn òfin yìí nìkan ni ó fun yín, kò sí òmíràn lẹ́yìn wọn, ó kọ wọ́n sára tabili òkúta meji, ó sì kó wọn fún mi.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Pásítọ̀ ló sọ fún mi pé Ọlọ́run pè mí láti di Olokun tó ń bọ omi' Gẹgẹ bi ẹgbẹ awọn onimọ sayẹnsi ilẹ Amerika ṣe sọ (U.
” Nítorí náà, gbogbo wọn kó mààlúù wọn lọ sí ọ̀dọ̀ Saulu ní alẹ́ ọjọ́ náà, wọ́n sì pa wọ́n níbẹ̀.
Níbi tí a ti sọ fún wọn pé, “Kì í ṣe eniyan mi”, níbẹ̀ ni a óo ti pè wọ́n ní, “ọmọ Ọlọrun Alààyè.
Mo bá mú un lọ sí iwájú ìgbìmọ̀ wọn.
Kemi Afolabi joyè ìmọ́lẹ̀ Adinni Ìjà Toyin àti Lizzy kìí ṣe àkọ́kọ́, àwọn òṣèré t'ọ́rọ̀ ìjà kàn rí rèé Òṣèrébìnrin tí wọ́n bá fi ìbálòpọ̀ lọ̀ 'torí ìṣẹ́, kó bọ́ síta láti sọ̀rọ̀ - Kunle Afod Jumọkẹ Odetola ṣe ọjọ́ ìbí, Wumi Toriola bímọ, Ṣé ẹ fẹ́ tẹ̀lẹ́ Funkẹ Akindele lọ si Dubai?
Ògúndélé bínú nítorí pé Jìnádù kò tètè san múrí méjì tí ó kì.
Nígbà tí Jesu yipada sí wọn, ó ní, “Ẹ̀yin ọmọbinrin Jerusalẹmu, ẹ má sunkún nítorí tèmi mọ́; ẹkún ara yín ati ti àwọn ọmọ yín ni kí ẹ máa sun.
Nítorí náà, ìgbà tí mo déédéé gbọ́ ariwo láàrin aginju yìí, ẹ̀rù bà mi gidigidi.
Maria yìí ni obinrin tí ó tú òróró olóòórùn dídùn sára Oluwa ní ọjọ́ kan, tí ó fi irun orí rẹ̀ nu ẹsẹ̀ Jesu.
Weinstein, to je omo odun merindinlaadota ni iro ni won n pa mo oun nitori ko si eni toun fipa ba lopo.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Fun apẹẹrẹ, ni ipinlẹ Michigan, nnkan bii miliọnu mẹta eeyan lo ṣeṣe ko dibo nipasẹ ileeṣẹ ifiweranṣẹ, ṣugbọn wọn ko ni bẹrẹ si ni ka ibo naa titi di ọjọ ibo gangan, to n tumọ si pe yoo to ọjọ diẹ si akoko naa ki wọ to ka ibo ọhun tan.
Iyaafin Buhari ni “O se pataki ki a ro awon obinrin lagabara, nitori owo ti won nilo lati fi bẹrẹ isẹ wọn ko pọ rara, iru ironilagbara bẹẹ  yoo tun ko ipa pataki ninu igbesi aye  ebi won ati ara ilu lapapọ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Lai, wá wi tẹnu rẹ lóri bílíọnu mẹ́jì àbọ owó DSO 28 Òkùdu 2019 Oríṣun àwòrán, @Laiofficial Àkọlé àwòrán, Lai Muhammed yóò foju balé ẹjọ lori màgàgòmágó owó-ICCP Àjọ tó ń ri sí ìwà jẹ́gudujẹra ní orílẹ̀-èdè Nàìjíríà (ICPC) ní mínísítà fún ọ̀rọ̀ tó ń lọ àti àṣà Lai Muhammed yóò fóju han nile ẹjọ́ giga ní Abuja lati jẹ́ri lóri ẹsun síṣé bílíọnù méjì lé ọwọ́ márun tí eto igbọhun sáféfé fí sún si ẹrọ ìgbàlóde (DSO) níọ̀n[s ti ko yẹ.
Ojulowo ati fọtokọpi iwe ẹri ile iwe girama, iwe ẹri ilu abinibi, iwe ẹri to n ṣafihan ọjọ ori, faili funfun meji ati aworan pelebe.
Jẹ́ kí ó mú kí òdodo yọ jáde pẹlu,èmi OLUWA ni mo ṣẹ̀dá rẹ̀ bẹ́ẹ̀.
"Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ọbasanjọ: PDP bẹ̀bẹ̀ lórí ìwà àìda wọn sí mi 14 Agẹmo 2018 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, ""Ọbasanjọ ti foriji PDP ni ibamu pẹlu ohun ti Bibeli sọ."
ninu igbesi aye awon olugbe ipinle naa.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Wo tuntun tó ṣẹlẹ̀ lágbo àwọn òṣèré Yollywood bíi Femi Adebayo, Odunlade Adekola, Toyin Abraham, Funke Akindele lọ́sè̩ yìí 21 Ògún 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 5 Owewe 2020 Oríṣun àwòrán, others Lọsẹ yii, o da bii pe awọn oṣere Yoruba naa ti n wọle pada sẹnu iṣẹ tiata wọn ni pẹrẹwu gẹgẹ bi ijọba naa ṣe bẹrẹ si ni ṣi awọn ibi kọọkan pada lẹyin isede oṣu gbọọrọ torii arun COVID-19.
 yàtọ ̀ sí orí méje yìí , ìwé náà ní index to language classification , key to language classification àti index of languages .
Oluranlọwọ pataki fun gomina ipinlẹ Eko, Gboyega Akosile fi lede ni ori opo ikansiraẹni Twitter wọn.
Bí iranṣẹ náà bá dé, ẹ ti ìlẹ̀kùn ẹnu ọ̀nà kí ó má lè wọlé.
O ni ki iru ẹni bẹẹ ma jẹ ounjẹ aṣaraloore.
Iyààrá kan pàtàkì ni mo fi fún òògùn nínú ilé wa, ọmọkọ́mọ kò gbọdọ̀ ta firi lágbègbè ibẹ̀, àfi ọmọ tí ó bá ro ọkàn tán láyé tí ó fẹ́ lọ fi ọbẹ jẹ ẹ ni ọrun.
Ọkọ iyawo, Chike Aroh to jẹ ẹni ọdun marundinlaadọta sọ fun ile ẹjọ wi pe iyawo oun, Chioma Aroh maa n gbe awọn aale wa si ile ti awọn n gbe, ti wọn si jọ maa n ni ibalopọ lori ibusun awọn.
Gẹgẹ bii ẹgbẹ oṣelu naa ṣe sọ, 'idajọ ọhun ko lee duro labẹ itanna ofin.
odùduwà àti àwọn ẹmẹ ̀ wá rẹ ̀ rọ ̀ sí ni wọ ́ n ń pè ní òkè Ọ ̀ ràmfẹ ̀ lónìí .
Awon to ku ni Abdulrasheed Abolarin, AbdulRauf Mahmud, Adewale Biokoto, Oguniran Samuel (Cricket), Jimoh Rofiat, Falana Iyanuoluwa, Aiyelabegan Shukrat (Table Tennis), Saidat Yekeen, Idogbe Deola (Wushu Kung Fu), Jimoh Sulyman Adisa, Jamiu  Ibrahim Muhammed ati AbdulRazaq Yusuf Olatunji (Rugby).
Nigba to n salaye bi ifọrọwerọ Tinubu ati awọn ọdọ kan lori aago, amugbalẹgbẹ Tinubu feto iroyin, Tunde Rahman kede loju opo Twitter rẹ pe igbesẹ naa safihan pe oloselu to dantọ ni.
O ni o ṣe ni laanu pẹ okan ninu awọn osiṣẹ to n sisẹ nibẹ ba iṣẹlẹ nla ibi naa rin.
Ọrọ ti Trump sọ fawọn ololufẹ rẹ níwájú ilé aṣofin, k'awọn ero naa to kọlu ile aṣoju-ṣofin lo mu ki wọn fẹ yọ ọ nipo.
UN gbé mílíọ́nù méjì dọ́là kalẹ̀ fún ìtọ́jú onígbáméjì
Ṣugbọn àwọn tí ó bá gbin ọkà, ni yóo máa jẹ ẹ́,wọn óo sì máa fìyìn fún OLUWA;àwọn tí ó bá sì kórè àjàrà ni yóo mu ọtí rẹ̀,ninu àgbàlá ilé mímọ́ mi.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Ikọ Liverpool ni afojusun lati ṣe oun tẹnikan o ṣe ri lati igba ti idije naa ti pawọda si Champions League lọdun 1992, eyi ni lati gba ife idije naa lẹkan sii.
Gbajugbaja akanṣẹ lagbaye, Anthony Joshua bẹ ile wo lọjọru.
' Lati ọmọ kekere si ni Shina ti n laju ri owo tuulu bayii lọwọ baba rẹ, eyi to maa n wọ ọ loju.
 Ajo ile-ẹjọ agbaye to n ri si
Awọn mejeeji sọrọ lori itako ti wọn jọ ni lati ẹkun onikaluku.
Buhari tún ti yan òkú sípò alàyè Wo àwọn tí yóò leè jáde l'Eko lọ́jọ́ ajé tó ń bọ̀ Se lootọ ni pe eniyan le ko Coronavirus lara ẹni to ti kú?
Ọrẹ tirẹ̀ ni àwo fadaka kan tí ìwọ̀n rẹ̀ jẹ́ aadoje (130) ṣekeli ati abọ́ fadaka kan tí ìwọ̀n rẹ̀ jẹ́ aadọrin ṣekeli.
"Bí ó tilẹ̀ jẹ́ wí pé mẹ́fà nínú wọn kópa nínú àwọn ìdíje kan kí wọ́n tó júbà ehoro, méjì nínú wọn kò tilẹ̀ kópa rárá.
Oríṣun àwòrán, EPA Dj Switch tun tan imọlẹ si awọn ọrọ kan to ti n tan ka lori ayelujara nipa awọn ohun to ti sọ ṣaaju.
Ẹgbẹ awọn akẹkọ to jẹ ọmọ bibi ipinlẹ Kwara wa n rọ awọn alasẹ ipinlẹ naa lati wa nkan se si ọrọ yii nitori iwọde awọn ko mu ija lọwọ.
Nitori eyi, mọsalasiDar Assalamni agbegbe Neukölln ko gba gbogbo awọn to wa jọsin nibẹ.
Èyí ni yóo jẹ́ àmì fun yín pé n óo jẹ yín níyà ní ilẹ̀ yìí, kí ẹ lè mọ̀ pé ọ̀rọ̀ ibi tí mo sọ si yín yóo ṣẹ mọ yín lára, 
Mourinho di akọ́nimọ̀ọ́gbá tuntun fún ikọ̀ Tothenham Àkàra tú s'épò, ICPC dárúkọ àwọn Fásitì tó ń tẹ́ abá isúná wọ́n nídìí Àwọn jàndùkú dáná sun Aṣáájú obìnrìn ẹgbẹ́ òṣèlú PDP mọlé ní Kogi Kìnìhún tí wọ́n mú l'Eko kìí ṣe ti orílẹ́èdè Nàíjíríà Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
World Food Day 2020, Yollywood; Dayọ̀ Amúsà jẹ́wọ́ ara rẹ̀ lórí ètò Àjẹpọ́nulá
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Kílò fa èdè àìyedè láàrin ìjọba àti àwọn ọmọ lẹ́yìn El-Zakzaky?
Mo wa ninu ogun Liberia ni 1989."
Oríṣun àwòrán, Twitter/Nigeria Railway Corporation Yatọ si eyi, Amaechi tun sọ pe igbimọ naa tun buwọlu isẹ agba ṣe ti owo rẹ le ni biliọnu mẹta Naira ₦3.
Ninu fidio kan ti BBC Pidgin gbe sita ni Jonathan ti kede ọrọ yii pẹlu afikun pe, to ba jẹ pe ẹgbẹ oselu PDP ko pegede lori aleefa ni, ebi ati iyan ni ko ba ti lu gbogbo ọmọ Naijiria pa tan.
jawe olubori gege bi aare orile ede Naijiria lodun 1993, ni eyi ti ijoba ogagun
Losu kerin pdun yii ni awon omo ile igbimo Asofin yoo dibo yan Aare ti yoo dipo Raul Castro to je eni odun merindinlaadorun lojo kokandinlogun.
Bàbá akẹ́kọ̀ọ́ LASU tí ọ̀rẹ́kùnrin rẹ̀ àti pásítọ̀ fi ṣ'oògùn owó ń bèèrè fún ìdájọ́ òdodo Ọlọ́pàá bẹ̀rẹ̀ ìwadìí lórí ikú olùṣirò owo táwọn agbénipa pa ní Ikorodu Ọwọ́ ọlọ́pàá tẹ afurasí ọkùnrin tó gé akẹ́kọ̀ọ́ ọ̀rẹ́bìnrin rẹ̀ wẹ́lẹ́ wẹ́lẹ́ fún òògùn owó ní Ikorodu Ṣé òtítọ́ ni pé nǹkan oṣù obìnrin le ba òògùn ìbílẹ̀ jẹ́?
“Lẹhin ọkùnrin tàbi obinrin (ni ayé òde òni) ti ó bá ṣe ori-ire, obinrin tàbi ọkunrin rere wa lẹhin tabi ẹ̀gbẹ rẹ”.
” Ó bá lọ sórí òkè kan.
Eyi to tumọ si pe ohun lo so agbegbe ọrọ aje ilu Eko mọ ti Mainland.
Mo dupe lowo Olorun to ti n ba wa rin irinajo yii.
Pasitọ Adeboye ni gẹgẹ bi aarun Ebola, covid-19 naa ti di aarun ti yoo ba gbogbo aye gbe laelae.
Wọn sọ ninu iroyin naa pe ẹgbẹ awọn ololufẹ ọkunrin s'ọkunrin kan ti orukọ rẹ n jẹ ''Diverse'' n ṣatilẹyin fun Atiku Abubakar fun ipo aarẹ.
Nítorí pé ó ṣíwọ́ sókè sí Ọlọrun,o sì ṣe oríkunkun sí Olodumare,
” Mo bá rí i tí ó wọlé lọ.
Nítorí èyí mo ní inú dídùn ninu àìlera mi, ati ninu àwọn ìwọ̀sí, ìṣòro, inúnibíni ati ìpọ́njú tí mo ti rí nítorí ti Kristi.
naa, tun wa n fi anfaani naa ran awon oludibo leti ipinnu ajọ INEC  lati lo ẹrọ a-yẹ-kaadi –wo ati awon ilana eto
Nibẹ ni wọn ni arakunrin yii atawọn ẹbi rẹ n gbe ki ọlọjọ to de.
Arsenal vs Valencia: Arsenal gbẹ̀san fún Liverpool, Tottenham
Ẹ sọ ìwé kíkà di dandan fún ẹ̀yà Fulani - Oluwo rọ ìjọba àpapọ̀ Ìtàn tó rọ̀ mọ́ òwe ‘aṣọ kò bá Ọ́mọ́yẹ mọ́.
Ileeṣẹ naa ṣalaye pe, idi ti wọn fi gbe sita ko yẹ lẹyin bi awọn ọrọ kan kii ṣe n duro bi awọn to kọ wọn ṣe fẹ loju opo twitter, ṣugbọn bi wọn ba fi ẹnu wọn sọ ọ yoo tubs gbe pẹẹli sii.
Ọlọrun pàṣẹ pé kí omi kún fún oríṣìíríṣìí ẹ̀dá alààyè, kí ojú ọ̀run sì kún fún àwọn ẹyẹ.
Ẹni tí ó ṣìnà ilé rẹ̀,dàbí ẹyẹ tí ó ṣìnà ìtẹ́ rẹ̀.
baba mi mú mi búra nígbà tí àtikú rẹ̀ kù sí dẹ̀dẹ̀, pé, ‘Nígbà tí mo bá kú, ninu ibojì tí mo gbẹ́ fún ara mi ní ilẹ̀ Kenaani, ni kí ẹ sin mí sí.
27 Bẹ́ẹ̀ gẹ́gẹ́ ni fún àwọn wọ̃nnì tí wọn yío wá lẹ́hìnáà, tí àwon náà yíò ní ìgbàgbọ́ nínú àwọn ẹ̀bùn àti àwọn ìpè ti Ọlọ́run láti ọwọ́ Ẹ̀mí Mímọ́, èyí tí ó nṣe ìjẹ́rìí nípa Bàbá àti Ọmọ.
Baba Suwe bọ́ lọ́wọ́ àìsàn, ó bẹ̀rẹ̀ tíátà padà Ìjọba ilẹ̀ Canada bẹ̀rẹ̀ iṣẹ́ lórí fọ́ọ̀mù àwọn tó fẹ lọ sí orílẹ̀-èdè náà Pásítọ̀ tó bá Ọlọ́run jiyàn kó tó di Ààrẹ Oríṣun àwòrán, Rotimi Akeredolu Bakan naa, ọjọ kan sira wọn lo wa laarin ikede tirẹ ati ti gomina ipinlẹ Ondo, Rotimi Akeredolu.
 Ki odun yii to pari ni a o se ifilọlẹ baalu orilẹ ede  yii.
Oríṣìíríṣìí pẹpẹ ìrúbọ ni àwọn eniyan tẹ́ káàkiri, tí wọ́n sì ń rúbọ lórí wọn, nítorí wọn kò tí ì kọ́ ilé OLUWA nígbà náà.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Eko bridge: Ìjọba ń ṣe afárá Eko Bridge l'Eko, àwọn ọ̀nà àbùdá tí ẹ lèè gbà nìyí 11 Ẹrẹ̀nà 2020 Oríṣun àwòrán, @jidesanwoolu Ijọba ipinlẹ Eko ti bẹrẹ atunṣe opoopona afara Eko.
Ẹ̀rù bà á, ó sì wí pé, “Ààrin yìí mà tilẹ̀ bani lẹ́rù pupọ o!
 O tun so pe gbogbo awọn  to ba fe se ipolongo egbe wọn  gbodo gba iwe ase lati odo awọn agbofinro.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Tí mo ba ti múra bí ọkùnrin fi kọrin, kò sí ọ̀dọ̀ ààrẹ́ tí mi ò lè wọ̀- Erelu, ọmọ Elemure Ekiti Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Femi Gbajabiamila: DSS ti fi ẹ̀sọ́ àbò Gbajabiamila tó pa fẹ́ndọ̀ l'Abuja sátìmọ́lé23 Bélú 2020 Fídíò, The New Pandemic: Kíni àwọn onímọ̀ sáyẹ́ńsì ń sọ nípa rẹ̀?
"Ó ní ìwòsàn àkọ́ka ti wọ́n lo sítẹ́mú sẹẹ̀lì fún wáye ni ọdún 1988 tí ó sì ni àṣeyọri, ó ni ẹni ti wọ́n ṣe fún ni ọmọkunrin kékere kan to ni ààrun ti wọ́n ń pè ni ""Fanconi's Anemia, ó sì niṣe pẹ̀lú ẹ̀jẹ̀ ti ko já geere."
, ti awon eniyan si n kii ni measn-mewass, ti oun naa si n ki won pelu, o jẹ
Oríṣun àwòrán, Reuters Àkọlé àwòrán, Àwọn agbébọn náà gbìyànjú làti dojúkọ ìlú Maiduguri gangan ṣùgbọ́n àwọ̀n ọmọogun kò gbà wọ́n láàyè Òṣìṣẹ́ iléeṣẹ́ ọmọogun kan ni àwọn eṣinṣin-ò-kọ kú méje ni wọ́n dira ogun kọ̀lu ìletò méjì kan níbẹ̀ tí àwọ̀n míràn sì tún kọlu ibùdó ọmọ ogun tó wà níbẹ̀.
Èmi pibà sì ti wọlé kí o tó rí mi ṣùgbọ́n n kò fẹ́ wọlé láàrin òru, bẹ́ẹ̀ ni ààrin òru ni mo dé ilé rẹ.
    Ẹni ti ó dórú tẹ̀lé mi ni Ayédèrú-ẹ̀dá ti mo tì sọ ìtàn rẹ̀ sáájú.
Iwadi fihan pe sisọ awọn sẹẹli ara di titun ṣeese ki adinku ba bi ara se n fihan pe oun ti n dagba.
Ayo Fasanmi, aṣaájú ẹgbẹ́ Afenifere jáde láyé Oríṣun àwòrán, Others Iroyin to n tẹ wa lọwọ ni yajoyajo ti kede pe Oloye Ayọ Fasanmi, tii se ọkan lara awọn asaaju ẹgbẹ Afenifere ti jade laye.
Bayii won ti n ko awon osise kuro ni agbegbe Exxon mobil kuro lati fi doola emi won ati dukia.
Bẹẹ ni ọrọ ri pẹlu ìgbé ayé ọba Ọlọ́lá James Titus Olateru-Olagbegi kejì, Ọlọwọ tilu Ọwọ tó ti di olóògbé.
Agbejoro fun  Kusa ,Solomon Umoh ati Raji naa  faramo pe , ki won sun esun naa siwaju.
Èyí ni yóo jẹ́ ìṣògo fún mi ní ọjọ́ tí Kristi bá dé, nítorí yóo hàn pé iré-ìje tí mò ń sá kì í ṣe lásán, ati pé aápọn tí mo ti ṣe kò já sí òfo.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Africa Eye: Ìrírí àwọn ọ̀dọ́bìnrin tó dágbà sójú pópó àti ìrètí wọn fún ọjọ́ ọ̀la O ní o yẹ ki awọn eniyan ma a dupẹ lọwọ aarẹ nitori iṣẹ to ṣe lati fi opin si iṣekupani ni Naijiria.
 O gba pe eyi ko seyin enu bode wa ti o si sile to gba ole to gba ole.
SWAT Police: Wo bí ikọ̀ ọlọ́pàá Special Weapons and Tactics yóò ṣe má a ṣiṣẹ́ wọn Ileeṣẹ ọlọpaa ti kede pe ko ni si ẹnikẹni lara awọn ọlọpaa SARS ti wọn ṣẹṣẹ tuka ninu awọn ti yoo wa ninu SWAT ti wọn ṣe ifilọlẹ rẹ lọjọ kẹtala, oṣu Kẹwa.
disposal : n ; ( bomb disposal is not common .
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Zamfara INEC ti kéde pé àwọn ọmọ ẹgbẹ́ òṣèlú PDP ló jáwé olúbori nínú ìdìbò 2019 25 Èbibi 2019 Oríṣun àwòrán, INEC Àkọlé àwòrán, Zamfara INEC ti kéde pé àwọn ọmọ ẹgbẹ́ òṣèlú PDP ló jáwé olúbori nínú ìdìbò 2019 Ilé iṣẹ́ àjọ elétò ìdìbò órílẹ̀-èdè Nàijirià lọ́jọ́ sátide ti kédé àwọn olùdíje ọmọ ẹgbẹ̀ alatako ni Nàijiria PDP gẹ́gẹ̀ bi ẹni to jáweé olúbori nínú ìdìbò gómìnà àti ile ìgbìmọ̀ aṣòfin ní Zamfara ti ọdun 2019 to wáye.
“Ògo ati títóbi ta ni a lè fi wé tìrẹ láàrin àwọn igi tí ó wà ní Edẹni?
Bawo ni iyansipo ọga fasiti ti ṣe maa n waye?
Oríṣun àwòrán, Others O fi iye owo ti wọn n ta a ni awọn orilẹede yii lede bayii; Nigeria -N162 Ghana -N332 Benin -N359 Togo - N300 Niger - N346 Chad -N366 Cameroon -N449 Burkina Faso -N433 Mali -N476 Liberia - N257 Sierra Leone -N281 Guinea -N363 Senegal - N549 Minisita naa fikun wi pe, ti a ba kuro ni ẹkun iwọ oorun Afrika lọ si awọn orilẹede bii Egypt ati Saudi Arabia, oye ti wọn n ta a ni N211 ati N168.
Gbogbo ìjọ ní Judia, ati Galili, ati Samaria wà ní alaafia, wọ́n sì fìdí múlẹ̀.
Nítorí náà, gẹ́gẹ́ bí àyànfẹ́ ọmọ, ẹ fi ìwà jọ Ọlọrun.
N óo jẹ́ kí ogun dó tì yín yíkán óo fi àwọn ilé ìṣọ́ ka yín mọ́;n óo sì mọ òkítì sára odi yín.
Sugbọn adajọ to n gbẹsun naa, Ijeoma Ojukwu kọ lati da Sowore ati ojugba rẹ Bakare silẹ.
12 Kíyèsíi, èmi ni Ẹnití Ó ti sọ ọ́; àti pé èmi kan náà ni ó ti bá ọ sọ̀rọ̀ láti àtètèkọ́ṣe.
Sugbon ni temi, ni ipinle Niger eto idibo naa  lọ ni irọwọ ati irọsẹ .
Aarẹ Muhammadu Buhari ti sọrọ nipa igbimọ yi to si ni ''oun wa lẹyin igbimọ naa bi ike'' Aarẹ sọ pe oun ni gbagbọ pe igbimọ yi yoo jẹ ki awọn oluwọde ati ọlọpaa to padanu ẹmi wọn ri idajọ ododo gba.
Laipẹ, arun yi tan kaakiri de agbaye, koda ilẹ Afrika naa ba wọn nipin ninu rẹ.
Ipa tí ìyànsípò Olóòtú ìjọba Gẹ̀ẹ́sì tuntun yóò mú bá ‘Brexit’ Lati igba ti Naijiria ti fẹ dibo tọdun 2015 ni ilẹ Amerika ti n kilọ fawọn oloṣelu lati ṣọra fun iwa aitọ.
Kàyéèfì ni bí àwọn agbébọn ṣe pa akápò ìjọ Anglican l'Akurẹ nítorí owó ṣọ́ọ́ṣì Dangote: Mo ti gbà $10m ri ní bánkì kí n lè mọ bí o tí ṣé rí lójú Beckham, àgbábọ́ọ́lù tẹ́lẹ̀ rèé tó ń sọ èdè Yorùbá Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Colorado ni Amẹrika àti odò Awaye ní Naijiria nikeji àdágún órí àpáta ní gbogbo àgbáyé!
Ile igbimo asofin kekere ati agba ti ranse si adajo agba ati minisita fun eto idajo, lorile ede Naijiria ati alaga ajo to n ri si atunse ofin  lati farahan niwaju ile igbimo asoju-sofin, lati wa salaye lori ase ijoba muhammadu Buhari naa.
Òkìkí ìwọ pàápà’ti kàn jákèjádò ayé, ṣùgbọ́n ayọ̀ kún ọkàn mi lónìí wí pé a ojú rí ara wa.
Leyin ti aare Buhari gba egbe naa pada sinu egbe oselu APC, aare fikun un oro re pe, aye si wa pupo fun enikeni ti o ba tun fe darapo mo egbe APC, bee si ni O seleri lati ba awon adari egbe APC nipinle Kano soro lati tewo gba awon eniyan naa.
Má yọ̀ nígbà tí ọ̀tá rẹ bá ṣubú,má sì jẹ́ kí inú rẹ dùn bí ó bá kọsẹ̀,
Gbogbo àwọn ọba yóo máa wólẹ̀ fún un;gbogbo àwọn orílẹ̀-èdè yóo sì máa sìn ín.
FG Covid Palliatives: Àjọ SERAP ń wá ìdájọ́ tó tọ́ lórí rògbòdìyàn jíjí ǹkan ìrànwọ́ Covid-19
Daura kò tan mọ́ Buhari àmọ́ òun àti ọmọ rẹ̀ ti fẹ́ ba ẹbí mi jẹ́ - Aisha figbe ta Ni ọjọ Aje ni iroyin ifọrọwanilẹnuwo kan ti iyawo aarẹ, Aisha Buhari ati Fatimah, ọmọ Daura to jẹ bi ẹgbọn fun Buhari ṣe pẹlu ileeṣẹ iroyin BBC gbode kan lori ayelujara.
Ẹ̀ka PCRRU fi àtẹ̀jáde tó sàfihàn ìdádúró Charles Omotosho sójú òpó Twitter wọn.
Ikọ ọmọ ogun orilẹ-ede Iran ṣalaye pe awọn fi ikọlu naa fa awọn orilẹ-ede to n lẹdi apo pọ pẹlu Amẹrika, ti wọn n fun Amẹrika laaye lati kọ ibudo sori ilẹ wọn leti ni.
Àwo̩n òbí ló ní è̩tó̩ tó ga jù lo̩ láti yan è̩kó̩ tí wó̩n bá fé̩ fún àwo̩n o̩mo̩ wo̩n.
Agbada náà gbà tó ẹgbẹẹdogun ìwọ̀n bati omi.
Nígbà tí wọ́n dé inu ilé oúnjẹ, ọba rí i pé lóòótọ́ ni àwọn ẹja wọn-ọnnì ti yípadà tí wọn dúdí bí ìdí ikòkò ọbẹ̀, ìyàlẹ́nu sì ni eléyìí jẹ́ fún ẹnikẹ́ni tí ó bá rí wọn.
Ajọ UNO tun ya ọjọ naa sọtọ lati fihan wi pe ẹtọ awọn eeyan ti wọn ko ri ile ni lati lati ni igbegbe ti wọn naa.
Abhay Thakur  tun so pe “
A bi àwọn eniyan burúkú lulẹ̀, wọ́n sì parun,ṣugbọn ìdílé olódodo yóo dúró gbọningbọnin.
Ni ile iwosan kan nilẹ Gẹẹṣi ni arabinrin Oko dakẹ si.
Ẹ gbọ ohun to sọ ninu fidio yii.
“Nítorí náà, OLUWA àwọn ọmọ ogun, Ọlọrun Israẹli ní, ‘Ẹ wò ó, n óo dójúlé yín, n óo sì pa gbogbo ọmọ Juda run.
 onímọ ̀ ìwòràwọ ̀ ọmọ faransé , henri joseph perrotin ṣàwárí rẹ ̀ ní Ọjọ ́ ọ ̀ kàndínlógún oṣù karún Ọdún 1874 tí ó sì sọó ní orúkọ ní èdè latin àti occitan orúkọ fún toulouse , france .
Ejò Sebe, Ọká, òjòlá àti àkeèké jẹ́ alábagbé Phillipe
Adajọ to lewaju igbimọ ẹlẹnu mẹta naa, Emmanuel Agim, tọkasi kudiẹ-kudiẹ to wa ninu idajọ akọkọ naa, paapa lori bi ileẹjọ giga ọhun se gba pe oun ni aṣẹ lati gbọ ẹjọ naa, lẹyin ọjọ mẹrinla ti ofin la kalẹ lati pe ẹjọ saaju idibo.
àfi àwọn ohun ọ̀sìn tí a kó bí ìkógun, pẹlu àwọn ìkógun tí a kó ninu àwọn ìlú tí a gbà.
Ṣugbọn ẹnu ya Pilatu pé Jesu ti yára kú!
Wọn ni eyi ṣẹlẹ lasiko ti ọkọ naa morile agbegbe Berger ni ijanu rẹ naa ja.
 o je fififun ni odun 1997 .
 iru ona iselu lowolowo bayi bere ni 1990 pelu ofinigbepo ile benin ati iyipada si ti oloselu ti o tele ni odun 1991 .
Miller fikún ọ̀rọ̀ rẹ̀ pé olóògbé náà jẹ́ onísòwó asọ àga ìjókò nígbà tí ó wà láyé.
O tona ki won koko fi awon fiimu yii ranse si ajo wa ki a woo wo ati ki a le so irufe awon to ye ki won woo ki a to fun won ni iwe ase bi o ti ye.
Àkọlé àwòrán, Ibadan Rape: Àjọ ọlọ́pàá, Ìjọba ìpínlẹ̀ Ọyọ jẹ́jẹ̀ẹ́ láti ṣàwárí òòsà tó ń mu ẹ̀jẹ̀ nílùú Ìbàdàn Wọn tún ti gbẹ̀mí ọmọbìnrin kan lẹ́yìn tí wọn fipá balòpọ̀ n'Ibadan Ibadan Rape: Wọn tún ti gbẹ̀mí ọmọbìnrin kan lẹ́yìn tí wọn fipá balòpọ̀ n'Ibadan Oríṣun àwòrán, Others Àkọlé àwòrán, Ni ile rẹ to wa ni Ori Sasa Ojoo agbegbe Akinyele ni iṣẹlẹ naa ti ṣẹlẹ lọjọ Abamẹta.
 ni ajọ ọdun 2019 ni lati ṣe ifojusi iwoye lgbtqi ni kikun , ati ki o ni idojukọ aifọwọyi lori abo .
Yan àwọn tí o fẹ̀ fún ẹgbẹ agbábọ́ọ́lù ààyò rẹ Ọ̀pọ̀ ẹ̀mí sọnù sínú Ọkọ̀ ojú omi to dànù l'Eko A kò fipá mú ẹnikẹ́ni láti dá Ruga, aàgọ́ Fulani sílẹ̀ -Iléeṣẹ́ aàrẹ Àwọn orílẹ̀èdè àjọ ECOWAS yóò máa ná owó kan nàá l'ọ́dún 2020 Opo ninu awọn to ṣe iwọde na ni awọn jade ki ọrọ ifipabanilopọ le di ohun igbagbe ni Naijiria ni.
Nígbà kan rí àwọn oníṣòwò rẹ ni àwọn gbajúmọ̀ ninu ayé.
Ìkérora dá mi lágara:ní òròòru ni mò ń fi omijé rẹ ẹní mi;tí mò ń sunkún tí gbogbo ibùsùn mi ń tutù.
Oríṣun àwòrán, @GreatIfeNG Àkọlé àwòrán, OAU ni ìwádìí fi hàn pe ọ̀jọ̀gbọ̀n náà lo ipò àgbára láti dún-koko mọ́ akẹkọọ náà ni.
Ohun tí ń ṣẹlẹ̀ nisinsinyii ni pé: ó ń dára fún àwọn agbéraga; kì í sì í ṣe pé ó ń dára fún àwọn eniyan burúkú nìkan, ṣugbọn nígbà tí wọ́n bá fi ìwà burúkú wọn dán Ọlọrun wò, kò sí nǹkankan tí ń ṣẹlẹ̀ sí wọn.
Òwìwí yóo pa ìtẹ́ sibẹ, tí yóo máa yé sí.
Ọpọ ni bí onirese wọn kò bá fín igba mọ, èyí tí wọn fín silẹ, kò leè parun láéláé ati pe ariṣe larika; arika ni baba iregun, ohunkohun ti oloṣelu kọọkan ba ṣe laraye a royin lọjọ iku rẹ.
Ṣugbọn ó fi díẹ̀ ninu àwọn talaka sílẹ̀ láti máa tọ́jú ọgbà àjàrà ati láti máa dáko.
Wọ́n sọ fún ara wọn pé, “Ẹ wá, ẹ jẹ́ kí á kọ́ ìlú ńlá kan, kí á sì kọ́ ilé ìṣọ́ gíga kan tí orí rẹ̀ yóo kan ojú ọ̀run gbọ̀ngbọ̀n, kí á baà lè di olókìkí, kí á má baà fọ́n káàkiri orí ilẹ̀ ayé.
àwọn ọ̀pá fìtílà tí wọ́n fi ojúlówó wúrà ṣe: marun-un ní ìhà àríwá, ati marun-un ní ìhà gúsù níwájú Ibi-Mímọ́-Jùlọ; àwọn òdòdó, àwọn fìtílà, ati àwọn ẹ̀mú wúrà, 
Iroyin naa ni ọmọdebinrin naa, tii ṣe ẹni ọdun mejidinlogun, to maa n da aṣọ hijab bori bii musulumi ododo, ni baba rẹ ba oku rẹ ni ayika ile wọn, ti wọn si sawari rẹ pe awọn ọkunrin kan lo fi tipa baa lopọ.
Amòfin kan wá sọ́dọ̀ rẹ̀, ó sọ fún un pé, “Olùkọ́ni, mo fẹ́ máa tẹ̀lé ọ níbikíbi tí o bá ń lọ.
Nígbà tí Dafidi gbọ́ ọ̀rọ̀ yìí, inú bí i gidigidi sí ọkunrin ọlọ́rọ̀ náà tóbẹ́ẹ̀ tí ó fi OLUWA Alààyè búra pé ẹni tí ó dán irú rẹ̀ wò, kíkú ni yóo kú.
Josaya ọba lé gbogbo àwọn abókùúsọ̀rọ̀ ati àwọn oṣó jáde kúrò ní Jerusalẹmu, ó sì kó àwọn ère, àwọn oriṣa, ati gbogbo ohun ìbọ̀rìṣà kúrò ní Jerusalẹmu ati ilẹ̀ Juda, gẹ́gẹ́ bí ó ti wà ninu òfin tí ó wà ninu ìwé tí Hilikaya olórí alufaa rí ninu ilé OLUWA.
7m) to gba lọwọ Hayatou wa ninu apo ikowosi Olawale ni banaki kan to n lo.
OLUWA ní: “Ṣugbọn ẹ dìde sí àwọn eniyan mi gẹ́gẹ́ bí ọ̀tá, ẹ gba ẹ̀wù lọ́rùn àwọn tí wọn ń lọ lalaafia, àwọn tí wọn ń rékọjá lọ láìronú ogun.
”Ó sọ fún wọn pé, “Èmi gan-an nìyí.
 wọ ́ n á ta ọtí sí òòṣà , wọ ́ n á jó yíká ojúbọ wọ ́ n á sì wúre .
xxxxxxxxxxxxxxxxxxxxxxxxxxxxxxxxxxxxxxxxxxxxxxxxxxxxxxxxxxxxx Oríṣun àwòrán, realmercyaigbe Àkọlé àwòrán, Ilé náà tó kùn ní àwọ̀ búlùù ojú sánmọ̀ àti ti ọtí wáìnì ló ní gbàgede ìgbafẹ́ ní òkè àti ìsàlẹ̀ Gbajú-gbajà òsèré tíátà ni óbìnrin, Mercy Aigbe ti ra ilé alájà kan tó jẹ́ àwòsí-fìlá.
Ọga ọlọpaa lorilẹ-ede Naijiria, Mohammed Adamu ti sọ fun awọn ọmọ Naijiria pe ki wọn ma foya.
Patrick Youssef ti o je igbakeji oloriise-akanse naa so fun awon oniroyin pe, “nigba ti o ba fi awon ohun ija ogun kun, o n fi iya ati inira kun”.
O ni lai si ìrànlọ́wọ́ ará ilú, ijọba Naijiria ko le ri ilú tò, iranwọ ara ilú ni àwọn oyinbo fi n rọ́wọ́ mú, tori pe to ba jẹ ti ẹsẹ ni, àwọn oyinbo n dẹsẹ ju Naijiria lọ.
Òmíràn jẹ́ òkú ọmọ-ọwọ́ kan tí ìwọ́ọ rẹ̀ ṣì wà ní a ara rẹ̀, tí obìrin kan tí ó ń ṣe ìmọ́tótó ìbùdókọ̀ abẹ́-ilẹ̀ ní Yau Ma Tei bá nínú àpò kan.
Yatọ si aarẹ NFF, Amaju Pinnick, awọn mẹrin ti wọn tun n jẹjọ niwaju ile ẹjọ naa ni igbakeji aarẹ akọkọ Ṣeyi Akinwunmi, igbakeji aarẹ keji Shehu Dikko, Sanusi Mohammed to jẹ akọwe agba ajọ naa pẹlu Yusuff Fresh to jẹ ọkan lara awọn ọmọ igbimọ alakoso ajọ naa.
Ìdí abájọ ni pé nítorí kòsí ètò ìtanná tó péye ní Naija, nṣe ni olúkálukú nlo ẹ̀rọ amúnáwá fi ṣe ìtanná fúnrarẹ̀.
Àwọn ìran Simeoni ní ń gbé àwọn ìlú wọnyi títí di àkókò ọba Dafidi: Beeriṣeba, Molada, ati Hasariṣuali.
Ọjọ kejila, oṣu Kẹta, ọdun 2020 ni iṣẹlẹ naa waye nilu Akungba-Akoko.
O fún mi ní ìyè,o sì fi ìfẹ́ ńlá rẹ tí kì í yẹ̀ hàn sí mi,ìtọ́jú rẹ sì ti gbé ẹ̀mí mi ró.
"Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Buhari kọ́ ni ìṣòro wa, bó ṣe wà láti láéláé rèé - Fr Mbaka Àwọn ọ̀dọ́ fi ọ̀nà àrífín pe Tinubu lórí aago àmọ́ ó ní òun kò mọwọ́-mẹsẹ̀ nípa ìpànìyàn Lekki Á ràgà bo CCTV Lekki bí i ẹ̀rí tó dájú fún ìwádìí ìpànìyàn - Sanwo-Olu SERAP gbé ìjọba àpapọ̀ lọ ilé ẹjọ́ àgbáyé ICC lọrí ẹ̀sùn ìpànìyàn ""Jàǹdùkú gún ẹ̀gbọ́n mi lọ́rùn, jó ilé àti mọ́tò wa méjì, kòròfò la wà"" Olùwọ́de 12 kú ni Lekki, 38 lapapọ kú lọ́jọ́ Isẹ́gun, 56 ni àròpọ̀ àwọn tó bá ìwọ́de lọ - Amnesty International Osinbajo gbarata lórí ìṣẹ̀lẹ̀ Lekki, ó ní ìdájọ́ òdodo yóò wà Ooni Ogunwusi àti Wole Soyinka kòrò ojú sí ìṣẹ̀lẹ̀ Lekki Tollgate O ni ""awa ko fi ọwọ si pe ija ti awọn eeyan n ja jẹ ti ẹlẹyamẹya, ṣugbọn ara n ni awọn eeyan naa, ni wọn fi ṣe ohun ti wọn n ṣe."
Saaju ni minista ti fofin de ile isẹ naa ni kete ti ọrọ irinajo Naira Marley yii ti n bi Ige ati Adubni lori ayelujara ni Naijiria.
"Ilumọka olorin ""Ọmọ Iya Tiṣa, Small Doctor"" ti orukọ rẹ n jẹ Adekunle Temitope naa ti n gbaradi fun ifẹhonuhan to fẹ dari lonii, ọjọ Ẹti jọ kẹsan oṣu kẹwa ọdun 2020."
N óo jẹ yín níyà gẹ́gẹ́ bí ìwà yín, níwọ̀n ìgbà tí ohun ìríra ṣì wà láàrin yín.
Èyí yóo wà bí ìlànà, títí lae, fún arọmọdọmọ yín.
Ṣugbọn iyalẹnu nla lo jẹ nigba ti awọn obinrin kan to ti de lati ilẹ mimọ yari loju opo Twitter pe, ki ẹnikẹni mase pe awọn ni Alhaja.
Awọn ipinlẹ ti ọwọja arun iba lassa ti wọpọ ju lọ ni Edo, Ondo ati Ebonyi.
Wo iye ìgbà mẹ́rin tí ìtàkùn ìpínná ní Nàìjíríà ti dákú lọ́dún 2020 nìkan Olorì Aláàfín tẹ́lẹ̀, Anuoluwapo Adeyemi gba àmì ẹ̀yẹ lórí ipa tó kó nínú oge ṣíṣe Kàyééfì!
Bakan naa lo ni níní tabi gbigbe kọmputa agbeletan (laptop) dani, ati wiwọ aṣọ to ba igba mu, ti di ọ̀ran nla bayii nilẹ wa.
Ó bá mú un lọ sórí òkè Pisiga ní pápá Sofimu.
Bi kii ba se wipe adọgbọnsi ati ọgbọn ori ti wọn fi bọọ, ọrọ naa ko ba da yanpanyanri silẹ ni loju gbogbo eniyan.
Awọn ọmọlanke naa si lo fi n haya fun awọn alabaru miran lati maa sisẹ.
Wọ́n gbé oúnjẹ tirẹ̀ kalẹ̀ lọ́tọ̀, ti àwọn arakunrin rẹ̀ lọ́tọ̀, ati ti àwọn ará Ijipti tí wọn ń bá a jẹun lọ́tọ̀, nítorí pé ìríra ni ó jẹ́ fún àwọn ará Ijipti láti bá àwọn Heberu jẹun pọ̀.
Ta ni ó wá tọ́ àwọn wọnyi dàgbà?
Nítorí èyí àwọn Juu túbọ̀ ń wá ọ̀nà láti pa á, nítorí kì í ṣe pé ó ba Ọjọ́ Ìsinmi jẹ́ nìkan ni, ṣugbọn ó pe Ọlọrun ní Baba rẹ̀, ó sọ ara rẹ̀ di ọ̀kan náà pẹlu Ọlọrun.
Ṣugbọn nibayii, ẹsẹ Harris ti baba wa lori afara idije naa.
Oríṣun àwòrán, @seyimakinde Àkọlé àwòrán, Oluwaseyi Makinde Ni ti Oṣelu, Seyi Makinde ti du ipo aṣoju nile aṣofin fun ẹkun idibo Guusu ipinlẹ Oyo labẹ asia ẹgbẹ oṣelu All Nigeria Peoples Party, ṣugbọn o bọ mọ ọ lọwọ si ọwọ oludije ẹgbẹ oṣelu PDP nigba naa lọhun, Kamoru Adedibu.
Election Update 2019: Onímọ̀ kan ní Obasanjọ ni ko jẹ ki Atiku wọlé ààrẹ
"Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ẹ̀sùn ìfipábánilòpọ̀: Wọ́n bá òkú afẹ̀sùnkan nínú ilé ìgbáfẹ́ 19 Sẹ́rẹ́ 2019 Oríṣun àwòrán, @Asiwaju_limited/Twitter ""Ó digbere, mo maa ku laipẹ."
Aare wa kẹdun pelu ebi, ore ati awon eniyan agbegbe naa, bee si ni O ro ijoba ipinle Nassarawa, ijoba apapo ati awon eniyan ti o niwa daradara nipinle naa lati ri daju pe won pese itoju ti to fun awon ti o fara kaasa isele ibi ohun.
láti gbẹ̀san lára àwọn orílẹ̀-èdè mìíràn,ati láti jẹ àwọn eniyan wọn níyà;
Ó dáhùn pé, “Ohun tí kò ṣeéṣe fún eniyan, ó ṣeéṣe fún Ọlọrun.
Lọjọ kẹẹẹdogun oṣu kẹrin, Bouteflika fara han lori ẹrọ mohunmaworan to ti n ṣeleri lati ṣatunṣe iwe ofin ati itẹsiwaju ijọba awa ara wa ni Algeria.
Mo ní ohun pupọ láti sọ nípa yín ati láti fi ṣe ìdájọ́ yín.
Gbogbo àwọn eniyan rẹ̀ ń kérorabí wọ́n ti ń wá oúnjẹ;wọ́n ń fi ìṣúra wọn ṣe pàṣípààrọ̀ fún oúnjẹkí wọ́n baà lè lágbára.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, #Sweetsweetcodeine: Ẹ wo bí ìròyìn BBC nípa oògùn ikọ́ Codeine ṣe ń tún ayé tó ti bàjẹ́ ṣe Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Buhari ti gba fọ́ọ̀mù láti dupò ààrẹ ọdún 2019 Ẹgbẹ́ ọmọ Nàìjíríà ra fọ́ọ̀mù fún Buhari APC pàdánù aṣòfin míràn ní'pínlẹ̀ Osun Fasure sọ pé àwọn ọmọ ìgbìmọ aláṣẹ ìjọba ló fọwọ́ sí i lásìkò ìpádé wọn, o fí kún-un pé wọn ti búra wọlé fún olóri òṣìṣẹ́ túntun náà ní wàràńṣeṣà.
Nítorí náà kí Olódùmarè gbà ọ́ lọ́wọ́ ọ̀tá ilé àti ọ̀tá òde.
O ní ọrọ tí ààrẹ sọ pé àwọn aṣòfin kan joko sile fún ọpọ ọdún, láì fi aba kánkan ṣòwò ku diẹ kaato.
Kí àwọn ọmọ rẹ̀ di alárìnká,kí wọn máa ṣagbe kiri;kí á lé wọn jáde kúrò ninu ahoro tí wọn ń gbé.
amugbalegbe aare Buhari pataki lori sise agbekale orisirisi eto, Mariam Uwais, ro
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, afin pupa Bi ẹ ko ba gbagbe, laipẹ ni ọmọ oloṣelu kan yinbọn fi tu awọn to n ṣajọyọ pe ẹgbẹ wọn bori ninu eto idibo to kọja ka.
“Heṣiboni ati Eleale kígbe sókè, igbe wọn sì dé Jahasi láti Soari, ó dé Horonaimu ati Egilati Ṣeliṣiya.
Ṣugbọn wọn yóo jáde kúrò ninu ilẹ̀ náà, ilẹ̀ náà yóo sì ní ìsinmi nígbà ti ó bá wà ní ahoro, nígbà tí wọn kò bá sí níbẹ̀.
ati pé, “Hilikaya, alufaa, fún mi ní ìwé kan.
O ti di ohun to wọpọ ki awọn arinrinajo to lọ si orilẹede italy maa gba idọti awọn adugbo orilẹede naa.
Ẹ wo fidio bi oṣiṣẹ Jamb ṣe sọ wipe ejo gbe 36m naira mi
" olú ìlú wọn sì ni "" ÌddÓ "" tí ó wà níbi tí Ọ ̀ yọ ́ wà báyìí ."
Oṣere-binrin yii ti kopa ninu fiimu agbelewo to le ni aadọjọ sẹyin.
Atẹjade kan ti agbẹnusọ fun Ibikunle Amosun, Rotimi Durojaye fọwọsi kede pe, ti ko ba si ẹsẹ, ẹsẹ kii dede sẹ.
O ni awọn ileewe ti wọn ba fi orukọ silẹ pẹlu ipinlẹ Eko nikan ni yoo jẹ anfaani iranwọ owo ọhun.
Oòrùn rẹ kò ní wọ̀ mọ́,bẹ́ẹ̀ ni òṣùpá rẹ kò ní wọ òkùnkùn.
Buhari ransẹ ikini ku ọdun si orilẹede China Aarẹ lailai bẹrẹ ni China Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ile igbimọ asofin Chin ati panupọ yan Xi Jinping l'aarẹ ni saa keji ọlọdun maarun Buhari ni oun ni ireti wi pe ajọsepọ laaarin Naijiria ati China yoo ma pọ gẹgẹ bi oun ti lero wi pe ajọpọ China pẹlu Afrika yoo tun m agbopọn si.
Ọkan pataki ninu ẹgbẹ ẹlẹ́sìn Shiite, Abdullahi Mohammed Musa sọ pe wọn ti kọwe pe awọn ajafẹtọ ọmọniyan, to fi mọ awọn kristẹni ati pasitọ, lati darapọ mọ iwọde ti ẹgbẹ naa fẹ ẹ ṣe.
Bẹ́ẹ̀ ni a kò ní mu omi inú kànga yín.
'God support stealing' fídíò ọlọ́pàá tó n da orí ayélujára rú'?
Òkúta ńláńlá ni wọ́n fi ń kọ́ ọ, wọ́n sì ń tẹ́ pákó sára ògiri rẹ̀.
Dino to fi ọrọ naa lede lori ikani Twitter rẹ sọ pe awọn ti wọn n hu iru iwa bayii fẹ ba oun jẹ niwaju ile isẹ aarẹ ni.
To fi mọ oju ewe akọsilẹ nipa wọn lori iwe irinna wọn, akọsilẹ nipa ilera ara wọn lati ileewosan ijọba, nọmba idanimọ NIN, iwe iyọnda lati ileeṣẹ ọlọpaa, Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 3 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 5 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
2 mílíọ́nù owó ìtanràn Àjẹ́ àti Aṣẹ́wó ní ìyá Rainbow - Òjòpagogo Ìjọba Nàìjíríà ti gbà láti san N30b owó àjẹmọ́nú fún ASUU Ọkọ̀ agbépo méjì gbiná ní orí afárá Otedola ní ìpínlẹ̀ Eko!
EFCC ṣlaaye pe afurasi keji, pasitọ Adesoju naa gba ẹbun ọkọ BMW kan, ilẹ ati ọpọ tabua ninu owo ti Olawale gba lọwọ Hayatou.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ikọlu mẹfa ti o ti waye lawọn ileewe girama lorilẹede Naijiria 22 Èrèlè 2018 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ọpọ igba ni ijọba ti ti ileewe pa nitori ikọlu awọn agbebọn lorilẹede NAijiria Ikọlu alẹ ọjọ aje nibi ti awọn agbebọn ikọ adukukulaja Boko Haram ji awọn ọmọ ileewe kan ko ni ileewe girama Government Girls Secondary School, ni ilu Dapchi, ipinlẹ Yobe kii ṣe akọkọ iru rẹ.
Oludije sipo gomina ninu ẹgbẹ oṣelu PDP ni ipinlẹ Ondo, Eyitayo Jegede ti kede Gboluga Ikengboju gẹgẹ bi igbakeji rẹ ti wọn yoo jọ dije.
"Mo rọ ẹyin ajẹ ati oṣo ki ẹ maa gbe igbe aye ododo, eyi ti wọn mọ awọn oniṣegun ibilẹ fun, ki ẹ si jẹ ki ẹsin awọn baba nla baba wa ṣe atunṣe ọna yin pada tori ohun nikan lo lee daabo bo iru eeyan ti ẹ jẹ lagbaye""."
Ninu ìran náà Oluwa sọ fún un pé, “Má bẹ̀rù, máa waasu, má dákẹ́.
Heburoni bí ọmọ mẹrin: Jeraya, tí ó jẹ́ olórí, lẹ́yìn rẹ̀ ni Amaraya, Jahasieli, Jekameamu.
O mú aṣọ rẹ tí a ṣe ọnà sí lára, o dà á bò wọ́n.
Ó kọ́ àká fún ọkà, ọtí waini, ati òróró; ó ṣe ibùjẹ fún oríṣìíríṣìí mààlúù, ó sì ṣe ọgbà fún àwọn aguntan ati ewúrẹ́.
Lẹ́yìn náà, Ṣalimaneseri, ọba Asiria, gbógun ti ilẹ̀ Israẹli, ó dó ti Samaria fún ọdún mẹta.
Má máa mu omi nìkan, ṣugbọn máa lo waini díẹ̀, nítorí inú tí ń yọ ọ́ lẹ́nu ati nítorí àìsàn tí ó máa ń ṣe ọ́ nígbà gbogbo.
Àwọn ìròyìn mìíràn tí ẹ lè nífẹ̀ẹ́ sí: Kíni igbimọ NJC fẹ́ jíròrò lè nípa Onnoghen Àjọ NEMA fèsì ẹ̀sùn táwọn aṣòfin fi kan Ọṣinbajo Awọn asofin koro oju s'afikun owo ori Ẹ sọra fun Bitcoin - Ile Asofin Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Saraki dúpẹ́ lọ́wọ́ àwọn alátìlẹ́yìn rẹ̀ Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
’ Hajj: Ǹjẹ́ o mọ pàtàkì Ọjọ́ Àràfá fún àwọn mùsùlùmí?
Lizzy Anjorin, ti dáhùn ìbéérè yín lórí ìdí tó fi ṣe ìgbéyàwó lẹ́yìn ọdún mẹ́rìnlá tó ti pàdé ọkọ rẹ̀.
“Ni eyi ti o gbadura pe, ki ayeye odun ajinde odun yii mu akotun ireti ati igbekele wa si orile-ede Naijiria, ki ajinde ara je fun gbogbo wa”.
Nítorí bí obinrin kò bá bo orí, kí ó kúkú gé irun rẹ̀ mọ́lẹ̀.
O ni aini afojusun ati iran to kuna awọn oloṣelu Naijiria n ṣakoba fun orilẹede yii, bẹẹ lo rọ wọn pe bi wọn ko ba ni afojusun lori bi wọn yoo ṣe gbe orilẹede Naijiria goke agba, ki wọn yago fun ipo oṣelu.
Ninu ifọrọwerọ rẹ pẹlu BBC News Yoruba, Agẹṣin Adimula ti ilu Ila Ọrangun, Oloye Fagbenle Adedayọ to tun jẹ alukoro fun ẹgbẹ awọn oniṣẹṣe ni ipinlẹ Ọsun sọrọ ilẹ kun.
Wọ́n sọ èyí láti fi ká ọ̀rọ̀ mọ́ ọn lẹ́nu ni kí wọ́n lè fi ẹ̀sùn kàn án.
“Èmi ni OLUWA,kò sí olùgbàlà kan, yàtọ̀ sí mi.
Kí bàbá mi tóó kúrò ní ilé ó pa itú ọdẹ: nítorí ogunlọ́gọ̀ onńdé ni òun sán mọ́ ìbàdí, ọmo ìka ọwọ́ rẹ sì kún fún òrùka àwọn àgbàlagbà bẹ́ẹ̀ ni mààlúù mẹ́fà ni ó fi ṣe sàráà nínú ilé wa.
 13 : 12 ] wiwọle si awọn olutọju-nipasẹ [ mt .
Bakare sọ eyi lasiko to n ba ebi ati ara Abileko Funke Olakunrin to jẹ ọmọ baba pa Reuben Fasọnranti, ti wọn ni awọn agbebọn pa ni ọna Ọrẹ si Benin ni opin ọsẹ.
Titi di bi a ṣe n sọrọ yii, Tobilọba ti foju ba ile ẹjọ o, koda o ti kawọpọnyin wi fun adajọ pe oun ko jẹbi ẹsun ti wọn fi kan oun rara.
Ẹyin naa ni haa, baba Ebenezer Obey ṣalaye ọrọ yii ninu ifọrọwerọ rẹ pẹlu iwe iroyin abẹle kan lorilẹede Naijiria.
Mo ṣebí àwọn agbowó-odè náà a máa ṣe bẹ́ẹ̀.
Ọpọlọpọ lo ti n reti asiko ti Kabiyesi, Ọọni Ogunwusi yoo gbe Arẹmọ rẹ dani ninu fọto fun gbogbo mutumuwa, ki araye fun oju lounjẹ aworan arẹmọ Ọba.
Yorùbá dùn lédè, ẹ máa sọọ́ Ẹfunroye Tinubu - Ògbóǹtagí oníṣòwò, olówò ẹrú àti afọbajẹ Samuel Ajayi Crowther, òjíṣẹ́ Ọlọ́run tó gbé èdè Yoruba lárugẹ Mọrèmi Àjàṣorò, akọni obìnrin tó gba Ilé Ifẹ̀ sílẹ̀ lóko ẹrú Ọ̀rọ̀ǹpọ̀tọ̀niyùn, Aláàfin obìnrin àkọ́kọ́ rèé, tó ní nǹkan ọkùnrin Ṣé ìwọ mọ odò adágún Adó Àwáyè tí kò ní òpin ní ìsàlẹ̀?
Awọn eeyan to lorukọ yika Naijiria si ni wọn peju pesẹ sibi ayẹyẹ igbeyawo naa, eyi to kasiara.
Lasiko to n ba awọn ara adugbo kẹdun, Hamzat fi ifarajin ijọba han nipa mimu atunṣe ba agbegbe naa ati pipese aabo to peye.
ilosiwaju ara ilu ko seyin alaafia ati aabo to joba ni tibu- tooro Ipinle Oyo.
Ẹlẹ́dàá fi ọmọ jínkí wa, abí ọmọ méjì, ọ̀kan ọkùnrin, ọkan ọbìnrin.
Oluwo gbá Ọba Ọ̀gbàágbàá lójú níbí ìpàdé àláfíà, ẹ̀jẹ̀ tọ Sunday Igboho gba àwọn èèyàn Soka n‘Ibadan sílẹ̀ lọ́wọ́ àwọn ọmọ onílẹ̀ tó wá ṣọṣẹ́ Inec kéde pé olùdíje gómìnà fẹ́gbẹ́ PDP ní Bayelsa làwọn gbà pé ó yege ìbò Arisekola ló fún mi ní ilẹ̀ tí ìjọba Ọyọ gbẹ́sẹ̀ lé, ń kò ní gbà - Ajimobi Ó ṣeéṣe kó má sí ẹ̀ṣọ́ aláàbò Amotekun l‘Eko - Ìjọba Eko Ìpínlẹ̀ Oyo, Ogun, Ondo buwọ́lu àbádòfin Àmọ̀tẹ́kùn Awọn olugbe agbegbe naa to ba wa sọrọ labẹ aṣọ ṣalaye pe, pupọ ninu awọn abulẹṣowo to ta ilẹ fun awọn lo ti di oloogbe.
Iwọde 'Black Lives Matter' to n mi igboro titi, lo mu ki gbogbo wọn ma tọrọ aforijin lọdọ awọn alawọdudu.
Kí ló dé tí ìlú yìí yóo fi di ahoro?
O salaye laarin bi inu awon eniyan se n dun pe, “Awon obinrin ni amulu-dun, sugbon nipa idi aimokan, esin awujo deye si awon obinrin”.
Ó pa á láṣẹ fún àwọn ọmọ Josẹfu,nígbà tí ó kọlu ilẹ̀ Ijipti.
Adams; Asoju egbe Afenifere, Yinka Odumakin; Asoju eya igbo, onimo ero Ndubuisi
Orúkọ náà ni wọ́n ń pe ìlú náà títí di òní olónìí.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Mo fẹ́ ọkọ mi torí bó se ń kọrin, kìí se torí owó - Ìyàwó Aràrá Mo fẹ́ kí àyẹyẹ ìgbeyàwó mi dùn ni mo se bú sẹ́kún - Ọkọ ìyàwó ẹlẹ́kún Samuel Ladoke Akintọla jẹ́ Agbẹjọ́rò àti Akọ̀ròyìn tí ọ̀rọ̀ dá lẹ́nu rẹ̀ Hubert Ogunde rèé, baba àwọn òsèré tíátà Ìyàtọ̀ wà nínú ìlépa àwọn òṣèré tíátà ayé àtijọ́ àti ìsisìnyí-Papalolo ‘Èmi kò leè gbà kí Ọba Ìbàdàn di 48 Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Adebisi Idikan: Òun ló gba Ìbàdàn sílẹ̀ lọ́wọ́ ìyà owó orí sísan Awọn kan ti ẹ maa n pe Iyalode Aminat Abiọdun ni Ọbabinrin ilẹ Ibadan.
Ṣugbọn Jehu kò kíyèsára kí ó fi gbogbo ọkàn rẹ̀ tẹ̀lé Òfin OLUWA Ọlọrun Israẹli; ìwà ẹ̀ṣẹ̀ Jeroboamu tí ó mú kí Israẹli hù ni ó tẹ̀lé.
Obinrin Níláti Bo Orí ninu Ìsìn.
Bí ó bá jẹ́ pé OLUWA ni Ọlọrun, ẹ máa sìn ín.
Ṣugbọn Ọlọrun tí ń tu àwọn tí ọkàn wọn bá rẹ̀wẹ̀sì ninu, ti tù wá ninu nígbà tí Titu dé.
 Àwọn àtúnbọ ̀ tán kò ní ipá , wọn kìí sì pẹ ́ rárá .
O ni ''Awẹ ti Ọlọrun mọ, ti yoo si tẹwọgba ni eleyi ti gbogbo eeyan jijọ gba ni ilana pẹlu aṣẹ olri wọn.
Emi le maa ro o bayii pe ko si wahala, mi o le gba ẹnu rẹ sọrọ pe ko si wahala.
to si nifẹẹ omo orile ede Naijiria ni oun yoo mu lati baa se ise papo.
Osogbo Gbé àwọn ìgbésẹ̀ yìí láti ṣàfikún ìròyìn nípa ará rẹ lójú òpó ìgbanisíṣẹ́ ọlọ́pàá Oríṣun àwòrán, PoliceNG Ileeṣẹ ọlọpaa lorilẹede Naijiria ti kesi gbogbo awọn to n wa isẹ to forukọ silẹ loju opo wọn, lati ṣe afikun iroyin nipa ara wọn ti wọn ti kọ silẹ ṣaaju.
Wọ́n bá gbé e dìde, wọ́n gbé e pada sí ààyè rẹ̀.
“Nígbà tí ìjọba wọn bá ń lọ sópin, tí ẹ̀ṣẹ̀ wọn bá kún ojú ìwọ̀n, ọba kan tí ojú rẹ̀ le, tí ó ní àrékérekè, tí ó sì lágbára yóo gorí oyè.
Kò sì sí ọmọbinrin tí ó lẹ́wà bí àwọn ọmọbinrin Jobu ní gbogbo ayé.
Èmi kii lọ rọba idaboobo ṣáájú asiko yii, njẹ mo lè bẹ̀rẹ̀ báyìí?
Kí á fi alaafia jẹun, láìsí ọbẹ̀,ó sàn ju kí á máa fi ẹran jẹun pẹlu ìyọnu lọ.
"Itura lo wa jẹ lasiko Trump pe ko ṣẹlẹ"", Richard Chogo, pasitọ ni ijọ onitusilẹ kan ni Nairobi lorilẹede Kenya sọ fun Akọroyin BBC."
Ṣugbọn èyí tí a fún sórí ilẹ̀ rere ni ẹni tí ó gbọ́ ọ̀rọ̀ náà, tí ọ̀rọ̀ náà yé, tí ó wá ń so èso, nígbà mìíràn, ọgọrun-un; nígbà mìíràn, ọgọta; nígbà mìíràn, ọgbọ̀n.
Minisita feto ọgbin, Audu sọ de ori wi pe awọn eeyan kan wa lorilẹede Naijiria to jẹ wi pe ipapanu Pizza ti wọn n jẹ, ilẹ Gẹẹsi ni wọn yoo ti raa ti wọn yoo si fi baalu gbe e wa si orilẹede Naijiria ni kutu hai ọjọ keji.
bẹrẹ si ni san ẹgbẹrun lọna ọgbọn naira gẹgẹ bi owo oṣu tuntun fun awon oṣiṣẹ.
Atawẹwẹ tun fikun ọrọ rẹ pe, iṣẹ Fuji lo yọ oun ninu iṣẹ alabaru lọja Ketu ati Mile 12.
Wọ́n kọjú sí ọ̀nà mẹrẹẹrin tí afẹ́fẹ́ ti ń fẹ́ wá.
Àwọn tó jẹ́ olólùfẹ́ àwọn eré rẹ̀ náà kò sími láti sọ ipa pàtàkì tí àwọn àwàdà Bàbá Sala ń kó láti mú àwọn ènìyàn fùrù ara.
Mo sọ fun yín, ó tilẹ̀ ju wolii lọ!
Bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé ó fẹ́ràn Hana, sibẹ ìdá kan ní í máa ń fún un, nítorí pé OLUWA kò fún un ní ọmọ bí.
Kí ni kí á wí nípa Abrahamu baba-ńlá wa nípa ti ara?
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ṣé ó leè jẹ́ ilẹ̀ tí Makinde kò jẹ́ kí Florence Ajimobi gbà ló ń bi nínú?
Wọn ni ayẹyẹ ọdún iléya tó ń bọ̀ àti ti ìpàdé àpapọ ìjọ RCCG tí yóò wáyé ní àṣẹ́ ṣe lọ pé kí kọngila tó ń siṣẹ́ ọ̀nà náà dẹwọ́ gbogbo àwọn ojú pópó ti wọ́n dí.
Bákan nàá ni àwọn tó bá ní àìsàn ọlọ́jọ́ pípí lára.
Ṣugbọn obinrin náà ti kó àwọn ọkunrin mejeeji pamọ́, ó dáhùn pé, “Lóòótọ́ ni àwọn ọkunrin meji kan wá sọ́dọ̀ mi, ṣugbọn n kò mọ ibi tí wọn ti wá.
Lonii ọjọ Aje, ọjọ keji, oṣu kẹsan an ni ileẹjọ to ga julọ ni Naijiria yoo gbẹjọ kotẹmilọrun tawọn kan pe wi pe Aarẹ Muhammadu Buhari ko koju oṣuwọn to lati dije ninu ibo aarẹ oṣu keji, ọdun 2019.
Èyí ni ìdí tí coronavirus ṣe n pa àwọn kan, tí kò sì pa àwọn kan Coronavirus- Atọ́nà bí nkàn ṣe ń lọ ní Afirika Amọṣa, ohun to wa n ṣe ọpọ ni haahinin bayii ni bi awọn eeyan ko ṣe karamasiki ilana yii.
D lati Fasiti Northeastern, ni Boston.
Àwọn ìjọba ìbílẹ̀ tó wà ni ìpínlẹ̀ náà ni Akoko North East, Akoko North West, Akoko South East, Akoko South West, Akure North, Akure South, Ifedore, Ile Oluji/Okeigbo, Ondo East, Ondo West, Owo, Ilaje, Okitipupa, Ose, Odigbo, Ese Odo, Idanre àti Irele.
”Oludari ẹka Ijiyinrere Ijọ Methodist ti Ipinlẹ Eko, Ẹni-ọwọ Samuel Ajayi so pe Ajọdun Orin Iyin ati Orin Imisi Ẹmi yii ti bẹrẹ lati ọdun 2000 pẹlu erongba lati da ẹmi imisi orin kikọ pada si inu Ijọ Methodist, eleyii to dabii pe awọn orin igbalode ti fẹẹ maa bori wọn bayii, ati pe ajọdun naa jẹ ayẹyẹ ati ṣafihan ojulowo orin aladun ẹmi ti o jẹ aṣa idanimọ Ijọ Methodist.
“Kí ọkunrin tí nǹkan ọkunrin rẹ̀ bá dà sí lára, kí ó wẹ gbogbo ara rẹ̀ láti òkè dé ilẹ̀, yóo jẹ́ aláìmọ́ títí di ìrọ̀lẹ́.
19 Bélú 2019 Oríṣun àwòrán, OTHER Awọn afunrasi janduku kan ti dana sun aṣaju awọn obinrin ẹgbẹ oṣelu PDP kan mọ inu ile nipinlẹ Kogi.
Nígbà tí alufaa bá fẹ́ sọ ilé náà di mímọ́, yóo mú ẹyẹ kéékèèké meji ati igi kedari ati aṣọ pupa tẹ́ẹ́rẹ́ kan, ati ewé hisopu, 
O fikùn pé, Alhaji Kazeem Afolayan, tíì ṣe olùdarí ileesẹ asesinima kan lo gba òun níyànjú, láti máa ṣe awada nínú eré tíátà, èyí to wá di ohun tí ayé mọ òun mọ báyìí.
Lẹyin naa lo darapọ mọ ileeṣẹ ijọba ipinlẹ Eko to wa fun eto iroyin, nibi to ti di amugbalẹgbẹ fun igbakeji ọga agba.
ti ijoba fi sinu iwe abadofin lori ekunwo  awon osise orile ede yii, o ni igbese yii je
Ọ̀pọ̀lọpọ̀ òkú ẹyẹ igún ré bọ́ lọ́jà Eke-Ihe Ẹ padà sílé èyin ọmọ wa tó n ṣiṣẹ́ darandaran - NEF ti Fulani Àwa ò mọ ẹgbẹ́ kankan tó ń jẹ́ fijilanté fulani l'Ondo- Ìjọba ìpínẹ̀ Ondo 'Kò sí ohun tó burú nínú bí Ajimobi ṣe dá Yewande tó pa ọkọ rẹ̀ sílẹ̀' Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
OLUWA bá Aaroni sọ̀rọ̀, ó ní, 
Ni ọdun yii, iroyin iwa ijẹkujẹ gba ode kan lori ajọṣepọ to wa laarin ijọba orilẹede naa ati De Beers, ileeṣe kan to n wa kusa okuta Dayamọndi lagbaye.
Ṣugbọn bí bẹ́ẹ̀ bá kọ́, iná yóo yọ jáde láti ara ẹ̀gún mi, yóo sì jó igi kedari tí ó wà ní Lẹbanoni run.
Marina-Eko Bridge: Ìjọba gbóṣùbà fún àtìlẹyìn aráàlú lásìkò tí wọn ti afárá méjèèjì pa
Nígbà tí mo bọ́ wọn ní àbọ́yó tán,wọ́n ṣe àgbèrè,wọ́n dà lọ sí ilé àwọn alágbèrè.
Won ro awon adajọ lorile-ede Naijiria lati ko eti ikun si iwa-ibaje, bee si ni ki won mu igberu ba isejoba rere lorile-ede yii.
Nígbà tí àwọn olùṣọ́-aguntan dé, wọ́n lé àwọn ọmọbinrin meje náà sẹ́yìn; ṣugbọn Mose dìde, ó ran àwọn ọmọbinrin náà lọ́wọ́, ó sì fún àwọn ẹran wọn ní omi mu.
Owurọ ọjọ Isẹgun ana niroyin gba igboro Ibadan kan, tawọn eeyan si n pe sori redio gbogbo nilu naa pe ẹmi awọn eeyan to n gbe ladugbo naa ko de tori awọn gende agbebọn to ya bo wọn.
Orilẹ-ede Germany ati USA lo ti jawe olubori julọ, lẹẹmẹta ẹnikọọkan wọn.
" Sugbọn nigba ti amugbalẹgbẹ aarẹ Onochie yoo fesi lori ọrọ yii loju opo Twitter rẹ, o fa ibinu yọ.
ni ile-ise olopaa yoo tun tẹpẹlẹ  mọ
Oríṣiríṣi ẹ̀bùn ni wọ́n sì fi ta tọkọtaya yìí lọ́rẹ.
” Ojogbon Osinbajo tun ni ijoba
Lasiko ọdun Ojude Ọba, faaji maa n pin silẹ Ijẹbu ni, ti awọn Ijẹbu kii si fi ọdun Ileya sere boya ẹlẹsin Kristiẹni ni, Musulumi abi abọrisa, ti wọn yoo si wọ asọ ẹgbẹjọda lọkan o jọkan, ti gbogbo ilu yoo si maa gba yin-in lasiko ọdun Ojude Ọba.
Ó ní àpọ̀ nínú tó nfa gbogbo ìdọ̀tí sí.
Gbogbo àwọn nnkan wọ̀nyí ló ti wà tí ó sì tún wà síbè di òní.
 Akinyele tún gbàlejò àwọn mùjẹ̀mùjẹ̀, tìyá-tọmọ̀ fara gbọgbẹ́ Isẹlẹ ikọlu miran tun ti waye ni agbegbe Akinyele nilu Ibadan ni idaji ọjọ Aiku."
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ondo election 2020: Àwọn ara ìpínlẹ̀ Ondo ránṣẹ́ sí Akeredolu ohun ti wọ́n ń retí ní báyìí Wike ni ikede akanṣe owo oṣu tuntun fawọn olukọ yo fikun ẹru to wa lori awọn ijọba ipinlẹ.
zɔ ] ) jẹ ́ ìgbàjá ìsọ ̀ gbé oòrùn kékeré aláwọ ̀ títàn àti olókúta .
BBC Yoruba tun foju ganni ileẹ́kọ alakọbẹrẹ akọkọ nilu naa ti wọn kọ lọdun 1896, ile ijọsin ọmọlẹyin Kristi kinni, aafin ọba akọkọ atawọn ile alarabara ti wọn ti kọ laye atijọ, amọ to si duro di oni.
“Bẹ́ẹ̀ náà ni ẹni tí ó gba àpò meji wá, ó ní ‘Alàgbà, àpò meji ni o fún mi.
Wọn gba Lagos State Challenge Cup ni 1974 ati 1976; FA Cup ni 1982 ati 1990; Ife ẹyẹ Liigi ni 1992; ti wọn si kuna lati gba ife ẹyẹ African Cup Winners' Cup lọdun 1981 lẹyin ti wọn fidi rẹmi lọwọ Union Douala Cameroon.
Bàbá rẹ̀ iwin ni, ṣùgbọ́n ìyá rẹ̀ ènìyàn ni.
Oríṣun àwòrán, Corbis Royalty free Ipinlẹ Ondo pẹlu eeyan marun, ipinlẹ Bauchi pẹlu eeyan kan, ipinlẹ Ebonyi pẹlu eeyan mẹsan, ti eeyan kan si tun ti ni aarun iba lassa naa ni ipinlẹ Plateau pẹlu.
MC Oluomo, lasiko to n kopa lori eto kan ni ikanni BBC Yoruba salaye pe, ọmọ ọdun meje ni baba oun jade laye, atijẹ atimu di ọran, iṣẹ agbalẹ oju popo ni iya oun si n ṣe.
Kini Kurt Zouma n ro naa?
"Oríṣun àwòrán, Abiola Ajimobi Arabinrin Ajimọbi ni, ""Igba kan si meji ni mo ti ba ọkọ mi to n yan ale, yoo si tọrọ aforiji lọwọ mi, ni kete to ba si ti bẹ mi, o tan niyẹn mi o kii ro arokan lori rẹ tabi fi sọrọ sii mọ."
Yálà lórí ẹ̀rọ ojútáyé nì tí a mọ̀n sí Facebook, tàbí àwùjọ ẹjọ́wẹ́wẹ́ nì tí orúkọ rẹ̀ ń jẹ́ Twitter.
Odion Ighalo: Ole Gunnar Solskjaer gbóṣùbà káre fún Ighalo lẹ́yìn tó sọ góòlò méjì sáwọ̀n Derby County
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Aisha Buhari: Aya ààrẹ tọrọ àforíjìn lórí fídìo tó ti fi ìbínú sọ̀rọ̀ 17 Ọ̀wàrà 2019 Oríṣun àwòrán, Faceboo/Aisha Buhari Àkọlé àwòrán, Aisha Buhari: Aya ààrẹ tọrọ àforíjì lórí fídìo tó ti fi ìbínú sọ̀rọ̀ Aisha Buhari ti tọrọ aforijin lori fọnran ti Fatima to jẹ ọmọ ibatan Aarẹ Muhammadu Buhari, Mamman Daura fi sita.
O ni ẹgbọn obinrin ati aburo obinrin.
Bí ọtí kíkan ti rí sí eyín,ati bí èéfín ti rí sí ojú,bẹ́ẹ̀ ni ọ̀lẹ rí sí ẹni tí ó bẹ̀ ẹ́ níṣẹ́.
O sọ fun BBC pe ọmọ oun ọdun mẹẹdogun wa nile kewu alimajiri ni Kano.
N óo rọ òjò iná lé Magogu lórí, ati àwọn tí wọn ń gbé láìléwu ní etí òkun, wọn yóo sì mọ̀ pé èmi ni OLUWA.
Akosilẹ naa ni ile ẹjọ ti paṣẹ fun minista fun eto igbẹjọ ni Naijria lati kede aṣẹ ijọba ati tawọn ile iṣẹ iroyin mejeeji.
Bakan naa, akonimoogba ohun, Thomas Dennerby ti seleri lati sa gbogbo ipa ati akitiyan re lati gbe iko Super-Falcons de bi ti o lapere.
Atẹjade naa wa rọ awọn olugbe ilu Abuja lati maa ba isẹ oojọ wọn lọ, ti alaafia si ti n pada jọba ni agbegbe naa.
Ilà Abẹ́ Kíkọ, Àmì Majẹmu Ọlọrun.
Nítorí náà, mo bẹ̀ ọ́, bí inú rẹ bá dùn sí mi, fi ọ̀nà rẹ hàn mí, kí n lè mọ̀ ọ́, kí ǹ sì lè bá ojurere rẹ pàdé.
Mourinho wòye pé òun àti Wenger sì lè pàdé nńú ìdíje mìíràn yàtọ̀ sí Premier League nílẹ̀ Gẹ̀ẹ́sì.
Mose sọ fún Aaroni ati àwọn ọmọ rẹ̀ mejeeji tí wọ́n ṣẹ́kù, Eleasari ati Itamari, ó ní, “Ẹ gbé ohun ìrúbọ tí ó kù ninu ẹbọ ohun jíjẹ tí a fi iná sun sí OLUWA, kí ẹ sì jẹ ẹ́ lẹ́bàá pẹpẹ, láì fi ìwúkàrà sí i, nítorí pé mímọ́ jùlọ ni.
Awọn adan nla ,okuta ati igbo ti o pọ jantii rẹrẹ.
Mo lè pa eniyan,mo sì lè sọ ọ́ di ààyè.
Iwe abadofin mẹ́tàdínlógún (17) ti aare Buhari kọ  lati
Fún àpẹẹrẹ, ọ̀kan tí ó ràn ká bí ìgbà tí iná bá ń jó pápá inú ọyẹ́ sọ wípé:
" a ton rí ewì wọlé sóyínká "" Àbíkú "" tẹpẹlẹ gidi lórí i ìṣèlẹ ̀ yìí ."
ohun ti oju rẹ ri lọna nigba to n lọ, a ti mu wa fun iran yin ni abala akọkọ, abala ekeji ree nibi ti arabinrin Yetunde Abrahams ti sọ ohun ti oju rẹ ri ni Libya ati bi irinajo rẹ lati pada si orilẹede NAijiria ṣe jẹ.
Èèyàn 5 farapa, ọ̀pọ̀ ọkọ̀ jóná nínú ìjàmbá iná márosẹ̀ Ibadan sí Eko Aarẹ Buhari yoo tun sọrọ lori anfaani to wa nibi idokowo awọn orilẹ-ede ilẹ okere ni Naijiria.
 Bẹ́ẹ̀náàni gbogbo ọ̀nàfun á máa ta àwọn bí ẹní máa kú ni.
Olori Adedayo ati iyale rẹ, Olori Nihinlola ni iyawo meji ti Olayiwola Adeyemi ni lọọdẹ, ko to di Alaafin tilu Ọyọ, awọn mejeeji si ni wọn wa pẹlu rẹ lasiko to n jẹ ọba.
Bo tile je pe ijoba Ologun koti ikun lati fagile ibo naa, leyin ijiroro , ni ijoba gbe igbese pe ojo kejila osu kefa, ni ajodun eto ijoba tiwa-n-tiwa yoo maa waye lorile ede Naijiria.
Níwọ̀n ìgbà tí àwọn àkọ́bí Israẹli fi igba ó lé mẹtalelaadọrin (273) pọ̀ ju àwọn ọmọ Lefi lọ, wọ́n níláti rà wọ́n pada.
'Ìṣòro àìrílégbé ló burú jùlọ nínú ìṣòro ẹ̀dá láyé' Wo ìdí to fi gbọdọ̀ yàgò fún Bobrisky, akọ tó ń ṣe bíi abo Sanusi Adebisi Idikan rèé, olówó tó ń san owó orí fún gbogbo ọkunrin ilẹ̀ Ibadan Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí kan sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
Pipẹ de rẹ laanfaani nitori pe awọn to ba ọkọ ofurufu Lion Air padanu ẹmi wọn ninu ijamba ọkọ ofurufu to waye lowurọ ọjọ aje lagbegbe ariwa Jakarta.
Ija bẹrẹ nigba ti aye sun Zarka nile ọkọ rẹ, to si fi ile naa silẹ lati pada sile baba rẹ.
Nítorí OLUWA wí fún mi pé:“Lọ fi aṣọ́nà ṣọ́ ojú ọ̀nà,kí ó máa kéde ohun tí ó bá rí.
"ICC pari iwadi lori pipa Shiites, IPOB CAN pe fun atunto ileeṣẹ alaabo ni Naijiria ""Arakunrin naa yoo de ile ẹjọ."
Ǹjẹ́ ẹ mọ ohun tí igbákejì ààrẹ Yemi Osinbajo sọ nílé bàbá Fasoranti Kí ló mú àwọn adarí Nàìjíríà tako ra wọn lórí ikú ọmọ alága ẹgbẹ́ Afenifere?
Ìfihàn tí a fi fún Wòlíì Joseph Smith, ní Harmony, Pennsylvania, ní oṣù Keje ọdún 1828, tí ó níí ṣe pẹ̀lú sísọnù ojú ewé ìwé mẹ́rindinlọgọ́fà tí a fi ọwọ́ kọ ìtumọ̀ rẹ̀ láti inú abala àkọ́kọ́ Ìwé Ti Mọ́mọ́nì, èyí tí a pè ní ìwé ti Lehi.
Ǹjẹ́ bí ọ̀kan ninu àwọn eniyan wọnyi bá ti bá aya rẹ lòpọ̀ ńkọ́?
iṣẹ́ olukuluku yóo farahàn kedere ní ọjọ́ ìdájọ́, nítorí iná ni yóo fi í hàn.
Ondo Election 2020: Ẹgbẹ́ òṣèlú PDP ní ó dá àwọn lójú pé àwọn yóò jáwé olúborí
Ìdí nìyí tí ìrì kò fi sẹ̀ láti òkè ọ̀run wá, tí ilẹ̀ kò sì fi so èso bí ó ti yẹ.
wọ́n wọ̀ ọ́ ní aṣọ àlàárì, wọ́n wá fi ẹ̀gún hun adé, wọ́n fi dé e lórí.
tí ẹ bá yipada sí OLUWA Ọlọrun yín, ẹ̀yin ati àwọn ọmọ yín; tí ẹ bá tún ń gbọ́ tirẹ̀, tí ẹ sì ń fi tọkàntọkàn tẹ̀lé gbogbo òfin tí mo ṣe fun yín lónìí, 
E kú ìfé Àsà àti Èdè Yorùbá lára mi o.
Iha ti awọn onimọ nipa eto abo ni Naijiria kọ si ohun ti gomina ipinlẹ Borno, Babagana Zulum sọ ree.
A pàṣẹ fún irú àwọn bẹ́ẹ̀, a tún ń rọ̀ wọ́n ninu Oluwa Jesu Kristi pé kí wọ́n máa ṣiṣẹ́ wẹ́rẹ́wẹ́rẹ́ fún oúnjẹ ti ara wọn.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Manchester City: De Bruyne gba àmì ẹ̀yẹ Premier League mọ́ Henderson lọ́wọ́ lẹ́yìn tí Lyon fi City ṣ'ẹ̀sín 17 Òkùdu 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 16 Ògún 2020 Oríṣun àwòrán, Getty Images Lẹyin ti wọn kan abuku oloronbo ninu idije UEFA Champions League lalẹ ọjọ kẹẹdogun oṣu kẹjọ ọdun 2020, ẹlẹsẹ-ayo, Kevin de Bruyne gba ami ẹyẹ agbabọọlu to pegede julọ ninu idije Premier League fun saa bọọlu to ṣẹṣẹ pari.
Naijiria yoo tun ko awon omo ogun lopo lo si ipinle Zamfara lati fopin si
Barrister ló sọ mí di èèyàn ńlá - Ayinla Kollington Afọnja, ẹni tó finú wénú ní Ilọrin, àmọ́ tó jẹ iwọ Ọjọ Kejila, Osu Keje, ọdun 2019 ni awọn agbebọn da ibọn bo arabinrin naa ni ọna Benin/Ore, eleyii ti o si jasi iku Olufunke Olakunri.
Aláàfin Ọyọ: Mí o ní kí Wasiu Ayinde má bọ̀wọ̀ fàwọn ọba ilẹ̀ Yorùbá ayafi.
odaran ti won farapamọ sinu igbo to wa ni awon  ipinle Kebbi, Katsina, Sokoto ati Zamafara.
26 Agẹmo 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Akọnimọọgba ẹgbẹ agbabọọlu Liverpool, Jurgen Klopp ti ni ko si n to o jọ rara pe oun fẹ ẹ ra Gareth Bale Manchester United ti n gbaradi de lilọ Paul Pogba kuro lọdọ wọn.
O ni oun ko lero pe oun yoo jawe olubori rara.
Wo odò tí wọ́n ti rí Aishat tí àgbárá òjò gbé lọ ní Eko Kọmíṣọ́nà mẹ́ta lùgbàdì àrùn Coronavirus l'Ọyọ Àjọ NCDC kéde ènìyàn 649 tó tún ṣẹ̀ṣẹ̀ ní Coronavirus ní Nàìjíríà Ọkùnrin kan bá ọmọ oṣù mẹ́ta lòpọ̀, ìfun ọmọ tú jáde!
Ìpínlẹ̀ Kaduna Ní àgbègbè yìí ẹ̀wẹ̀, ìdí ti wọ́n fi gbé ilé-ẹ̀kọ́ ti ni nítorí ààrun coronavirus tó tún padà dé.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ọọ̀ni ilé Ifẹ̀, Ọba Adeyeye Ẹnitan Ogunwusi, Ọ̀jájá Kejì ń ṣe ayẹyẹ ọjọ́ ìbi ọdúnKẹrinlelo Tìlù-tìfọn sì ni wọ́n fi ṣe ayẹyẹ ọjọ́ ìbí ọ̀hún tó wáyé nílùú ilé Ifẹ̀.
Mo deedee ń lọ ni ẹni náà yìnbọn sí ojú ọ̀nà tí à ń bá lọ, díẹ̀ báyìí lo kù kí ìbọn náà bà mi, o sì dá ẹnikẹ́ni lójú pé ẹni tí ó yìnbọn náà fẹ́ pa ọ̀kan nínú wa ni, mo tilẹ̀ ṣebí àwọn ọ̀tá kan ni wọ́n ba sínú igbó tí wọ́n ń fẹ́ bá ni jagun ni, mo bá da ojú ìbọn kọ ibi tí ìbọn tí dún, ìgbà tí a sì lọ wo ibi tí mo yìnbọn sí, Ojúayédùn, ènìyàn ayédèrú-ẹ̀dá ni a bá, tí ìbọn ti bà tí ó ti kú pátápátá.
 o ti je tele bi alagba ile igbimo asofin amerika fun ipinle new york lati 2001 de 2009 .
Gomina ipinle kano, ogbeni Abdullahi Umar Ganduje, yoo je alejo pataki ninu asekagba merindinlogoji idije Ramat Cup, eyi ti ijoba ipinle kano ati ajo to n ri si boolu afesegba ati idagbasoke awon odo lorile-ede Naijria sagbeteru re.
O ni irọ patapata ni iroyin ti ileeṣẹ CNN gbe jade pe awọn ọmọ ogun pa awọn oluwọde ni Lekki lalẹ ọjọ naa.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ishaq Oloyede: Jamb ko ni fi esi idanwo silẹ lẹsẹkẹsẹ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Ishaq Oloyede: Jamb ko ni fi esi idanwo silẹ lẹsẹkẹsẹ 6 Ẹrẹ̀nà 2018 Adari ajọ Jamb, Ọjọgbọn Ishaq Oloyede sọ wipe esi idanwo ti ọdun yii ko nii jade ni kia kia bi ti ọdun to kọja.
Ninu atẹjade naa, Minisita feto ilera ṣalaye pe mẹsan ninu awọn eeyan mẹwaa tuntun to ni arun naa lo jẹ ọmọ Naijiria ti wọn ṣẹṣẹ de lati orilẹede Canada, France, Netherlands, Spain ati ilẹ Gẹẹsi.
Eyi lo mu ko gbe imọ ijinlẹ kan jade pe: bi alaafo to wa laarin idọ ati oju ara obinrin ba ṣe kere to, ni yoo sọ bi obinrin naa yoo ṣe ni itura si lasiko ibalopọ pẹlu nkan ọmọkunrin.
Alaafin Oyo Oríṣun àwòrán, Oba Lamidi/Premium Times Oba Lamidi Adeyemi keji lo gba ọpa aṣẹ lọwọ Alaafin Gbadegesin Ladigbolu II lọdun 1970 lẹyin ogun abẹle igba naa.
Ó tọ́jú wọn pẹlu òdodo,ó sì tọ́ wọn pẹlu ìmọ̀.
Ní ibi Àpérò Òmìnira Ẹ̀rọ-ayélujára ní Ilẹ̀-Adúláwọ̀ (FIFA) tí ó wáyé ní Accra, Ghana, ikọ̀ akópa láti àwọn ìlú ilẹ̀ Adúláwọ̀ pátá sọ wípé kò ní ṣe ẹnu rere bí ìjọba bá fi òfin de ọmọ-ìlú tí ó ń lo ẹ̀rọ-ayárabíaṣá.
Láti ọdún 2025 lọ, to bá ṣe ìgbọ̀nsẹ̀ sigboro, o rugi oyin - Buhari INEC mo ko dé, ẹ̀rí rè é to ṣàfihàn èrú ìbò ní Kogi - Dino Melaye Èèmọ̀ rèé o!
’ rèé Afọnja, ẹni tó finú wénú ní Ilọrin, àmọ́ tó jẹ iwọ Bakan naa lo salaye pe, oun mọ pe awọn eeyan yoo maa beere idi ti wọn se yan oun ni olootu ijọba ilẹ Gẹẹsi, to si dahun pe ko si ẹnikẹni tabi ẹgbẹ oselu kankan to da nikan ni ọgbọn tara rẹ.
Yẹ̀kínì kan kò lè yẹ ipinnu wa láti ṣí iléèwé pàda lóṣù yí - ìjọba ìpínlẹ̀ Oyo Ann Grace Aguti, Obìnrin kan to fẹ́ ọkọ mẹ́ta lẹ́ẹkàn ṣoṣo Ìlànà ìjìnàsíraẹni 'social distancing' forí ṣánpọ́n bí ìrun Jímọ̀ ṣe bẹ̀rẹ̀ padà ni Ilorin Yẹ̀kínì kan kò lè yẹ ipinnu wa láti ṣí iléèwé pàda lóṣù yí - ìjọba ìpínlẹ̀ Oyo Arabinrin yi ni iṣẹlẹ aburu yi ṣẹlẹ sí òun lẹyin ti awọn ọmọ ikọ boko haram ṣigun bo ilu wọn.
Eyi ni abajade iyikoto ifigagbaga idije UEFA Champions League ni kikun:  Tobi Sangotola.
Wọn ni tori awọn Gomina ipinlẹ mẹfẹfa ti n ṣe akitiyan lati rii pe abo to daju wa fun gbogbo eniyan lẹkun wọn nitori naa ki wn ma gb ohun ti ẹgbẹ awọn agba ẹkun Ariwa n sọ.
Nítori àwọn àtúgbẹ́yẹ̀wò, o níra láti ṣe àkójọpọ fún àwọn ọkọ́ naa Orisun: Johns Hopkins University atawọn ajọ eto ilera ilu Iye akọsilẹ to waye gbẹyin 15 Oṣù Ṣẹ́rẹ́ 2021 20:44 WAT+3 Kabiyesi Oluwo fi kun un pe, gbogbo awọn oloye, ọmọọba atawọn oṣiṣẹ laafin ni wọn gbọdọ maa lo ibomu atipe eyikeyi ninu awọn oṣiṣẹ laafin ti oun ba ri nigboro tabi to wa laafin lai wọ ibomu facemask yoo dagbere fun iṣẹ rẹ.
Aare ajo to n mojuto boolu afesegba lorile-ede Naijiria, ogbeni Amaju Pinnick ti gboriyin banta-banta fun ile ifowopamo Zenith lataari atileyin won fun iko agbaboolu Super Eagles eleyi ti o seranwo fun iko naa lati pegede fun idije (AFCON) ti yoo waye lorile-ede Cameroon.
àwọn tí wọ́n ti kọ ọ̀nà òdodo sílẹ̀tí wọn sì ń rìn ninu òkùnkùn;
"Alága ètò nàá, Ọ̀jọ̀gbọ́n Ayọ Bámgbóṣé nínú ọ̀rọ̀ rẹ̀ sọ pé ó ṣe pàtàkì láti náàní ""nkan tí a ná, ṣùgbọ́n nítorí pé ó jẹ́ èdè wa, a kó kọbi ara sii."
Awọn idile to n gun ẹsin yoo maa le ara wọn lare ni, ti wọn yoo si wọ oniruuru asọ ti wọn fi n se idije ẹsin gigun laarin awọn ọkunrin, tawọn obvinrin naa yoo si maa tadi reke lati pa ara wọn layo lasiko ọdun Ojude Ọba.
Wọ́n ń fi burúkú san ire fún wa, wọ́n ń bọ̀ wá lé wa kúrò lórí ilẹ̀ rẹ, tí o fún wa bí ìní.
Oríṣun àwòrán, Oba Lamidi Olayiwola Adeyemi kẹta Nibẹ si ni Olori agba yii ti kọ isẹ aransọ taa mọ si Telọ, ilu Eko yii si ni wọn bi ọmọ mẹta si.
Wọn gbe ẹjọ naa lọ sile ẹjọ giga tilu Akure labẹ adajọ NS Pollard, ti awọn ẹlẹrii mọkanlelogun si yọju siwaju rẹ.
Osinusi ni odun naa kii se fun  aso wiwo tabi iwode afihan goolu ati bata nikan tabi afihan asa nikan bikose ona lati mu idagbaoske ba ile Ijebu lapapo.
O sọrọ kikun lori awọn eewọ odo naa ati abami ẹja ko ṣẹja-ko ṣeeyan to finu adagun odo naa ṣe ibugbe.
Oríṣun àwòrán, @AIT Àkọlé àwòrán, NBC: AIT kọ̀ láti tẹ̀le ìlànà òfin ìgbóhùnsáfẹ́fẹ́ Naijiria Àjọ National Broadcasting Commission to n mójútó ọ̀rọ̀ ìgbóhùnsáfẹ́fẹ́ ní Naijiria ti gba àṣẹ̀ ìgbóhùnsáfẹ́fẹ́ lọ́wọ́ iléeṣẹ́ AIT àti Ray Power lọjọbọ.
Ọkan ninu wọn ṣe afiwe onimọ Sayẹnsi, Michael Farraday gẹgẹ bi eeyan nla to si jẹ apari.
Ó fi igi akasia kan tabili kan; gígùn rẹ̀ jẹ́ igbọnwọ meji, fífẹ̀ rẹ̀ jẹ́ igbọnwọ kan, gíga rẹ̀ sì jẹ́ igbọnwọ kan ààbọ̀.
Amọ, gbogbo igbiyanju wa lati ba ẹka Rural Electrification Agency sọrọ lori awọn agbegbe ti yoo kọkọ jẹ anfaani yii ni ko i tii kẹsẹjari nitori a ko ri ẹka naa basọrọ lori ẹrọ iabnisọrọ wọn.
ọkọ̀ ojú omi tuntun bẹ̀rẹ̀ iṣẹ́ Buhari ti fòfin de àwọn mínísítà láti rìnrìn àjò lọ sí ilẹ̀ òkèrè Elizabeth ni: ''Mo gbe igbesẹ lati sọrọ yii lasiko yii nitori mo ti gbe ile aye ṣerere, gẹgẹ bi oniroyin ati minisita tẹlẹri lorilẹ-ede Ghana.
kí ẹ lè bá mi jẹ, kí ẹ sì bá mi mu ninu ìjọba mi, kí ẹ sì jókòó lórí ìtẹ́ láti máa ṣe ìdájọ́ ẹ̀yà Israẹli mejila.
Oríṣun àwòrán, @NGRSenate Àkọlé àwòrán, Ireti awọn eeyan ni pe ki apero ọrọ abo to n lọ lọwọ o so eso rere pẹlu gulegule ikọlu ati ipaniyan to n waye lorilẹede Naijiria Bi iwa ikọlu ati ipaniyan se wa di tọrọ-fọnkale kaakiri orilẹede Naijiria bayii n se afihan aisi abo fun ẹmi ati dukia awọn eeyan lorilẹede lo ji wa kuro ninu orun aibikita ti gbogbo wa n sun tẹlẹ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù FIFA U-20 World Cup: Senegal sin Nàìjíríà lọ'lé pẹ̀lù ìgbájú ìgbámú 3 Òkùdu 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 4 Òkùdu 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Ajẹtun iya ni ẹgbẹ agbabọọlu Flying Eagles ti Naijiria jẹ lọwọ Senegal ninu idije ife ẹyẹ agbaye FIFA U-20 to n lọ lọwọ lorilẹ-ede Poland.
1 9370 Orilẹede Uganda 206 0.
Pe arakunrin rẹ ní “Eniyan mi” kí o sì pe arabinrin rẹ ní “Ẹni tí ó rí àánú gbà.
, Duration 8,0016 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 2:23 Fídíò, Water Generator: Ó leè ṣiṣẹ fún wákàtí mẹfà, kó tó sinmi, Duration 2,2310 Òkùdu 2020 5:57 Fídíò, LASTMA Yesufa: Àwọn dókítà gbìyànjú lórí ojú mi ṣùgbọ́n.
lati rọ awon eniyan pe ki won daabo bo ibo won, ki won si tun pese ina
Arabinrin kan to ni ki a fi orukọ bo oun laṣiri ṣalaye pe ni agbegbe ti oun n gbe ni ilu Eko ni oun ti maa n ṣe ere idaraya lati na eegun ati ara oun.
Kíkọ́ ẹ̀kọ́ gboyè nínú iṣẹ́ ìṣègùn ìbílẹ̀ yóò pèsè ìtọ́jú tó péye fọ́mọ Nàìjíríà- Ẹgbẹ́ àwọn dókítà Ṣaaju ninu ọsẹ yii, bi ẹ ko ba gbagbe, ni Bobrisky ati alaga ajọ agbaṣaga lorilẹ-ede Naijiria, National Council for Arts and Culture, Ọtunba Oluṣẹgun Runṣewe ti ta ohùn si ara wọn.
Kí ó rí fún mi gẹ́gẹ́ bí ọ̀rọ̀ rẹ.
N óo jẹ́ baba fún un, yóo sì jẹ́ ọmọ mi.
Pinnick ní irọ́ ni, òun kò ní ẹ̀sùn ajẹbánu lọ́rùn ASUU pahùndà, ó fẹ́ kópa nínú àkóso ìbò 2019 Yorùbá dùn lédè, ẹ máa sọọ́ Jí pátá obìnrin ko jẹ́jọ́ ìpànìyàn - Dolapo Badmos Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí kan sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
Mo dúpẹ́ lọ́wọ́ Kristi Jesu Oluwa wa, ẹni tí ń fún mi ní agbára.
Gbogbo ìtàn ìjọba Solomoni, láti ìbẹ̀rẹ̀ títí dé òpin, wà ninu ìwé ìtàn wolii Natani, ati ninu ìwé àsọtẹ́lẹ̀ Ahija ará Ṣilo, ati ninu ìwé ìran tí Ido rí nípa Jeroboamu ọba Israẹli, ọmọ Nebati.
Ọgbẹni Jerro polowo Busari Peace pẹlu iwe irina rẹ loju opo Facebook rẹ.
Oloye Bode Akindele lasiko aye rẹ jẹ ilumọọka oniṣowo ti o si tun jẹ Parakoyi ti ilu Ibadan.
Iye awon oludibo to yẹge lati dibo
'Adarí àjọ NDDC, Pondei ń ṣe àìsàn ló ṣe dákú lásìkó ìfọ̀rọ̀wánilẹ́nuwò' Wo àwọn nkan tó yẹ́ kí o mọ̀ nípa 'Awawa Boys', ọ̀kan lára ẹgbẹ́ òkùnkùn tó n dá Eko rú Kùdìẹ̀kudiẹ wà nínú ìbò abẹ́nú APC tó yan Akeredolu, ṣùgbọ́n.
ọmọ ipinlẹ Kwara naa ni o jẹ.
Wo bí ọwọ́ orílẹ̀-èdè Dubai ṣe tẹ Ramoni Igbalode tí gbogbo ayé ń pè ní Hushpuppi Oríṣun àwòrán, Screenshot/DUBAI MEDIA OFFIC Àkọlé àwòrán, Invictus Obi, Hushpuppi, àwọn ọ̀dọ́ Nàìjíríà méjì tí ẹ̀sùn gbájúẹ̀ wà lọ́rùn wọn Ramoni Igbalode ti ọpọ eeyan mọ si Hushpuppi to fi orilẹ-ede Dubai ṣe ibujoko lasiko yii ni ọwọ awọn agbofinro ilẹ Dubai ti tẹ.
Bí mo bá tilẹ̀ wá ṣòfò àwọn ọmọ mi nígbà náà, n óo gbà pé mo ṣòfò wọn.
    Èyí tí ó burú púpọ̀ ní ìlú yìí ni ìwà wọn sí ara wọn.
Ida mẹwaa apapọ owo iye ẹbun to jẹ lapapọ ni yoo san gẹgẹ bi owo ori bayii.
Ti a o ba gbagbe pe alaga
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Cancer: àpọ̀jù ṣúgà nínú ẹ̀jẹ̀ ń ṣàkóbá fún àgọ́ ara èèyàn Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Cancer: àpọ̀jù ṣúgà nínú ẹ̀jẹ̀ ń ṣàkóbá fún àgọ́ ara èèyàn 1 Owewe 2019 Abajade iwadii naa ni kikun fihan pe ṣuga ko dara - Emma.
Wọ́n ń yẹ àdéhùn, wọ́n ń paniyan léraléra.
’’Ile naa ko wa ni ibamu ilana ile kikọGomina ni oun gbọ pe awon eniyan n gbe inu ile naa, ti won tun n lo  ile naa fun ile ẹkọ lọna aitọ , o ni aja mji
Awọn gomina ipinlẹ ni Naijiria to ti ni arun Coronavirus ree: Seyi Makinde, Oyo Ọgbọn ọjọ, ọṣi Kẹta ọdun 2020 ni gomina ipinlẹ Oyo, Seyi Makinde kede loju opo Twitter rẹ pe oun ti ni arun Covid-19.
Ẹwẹ, awọn leekan leekan ninu ẹgbẹ oṣelu APC ni Ipinlẹ yii bii Aṣiwaju ẹgbẹ oṣelu naa, Aṣiwaju Bọla Ahmed Tinubu ati gomina ana ni Ipinlẹ Eko, ti o jẹ Minisita fun ọrọ Ina monamona, Iṣẹ-ode at Ile kikọ, Amofin Babatunde Faṣola ko si nibi ipade naa.
Ọwọ́ ọlọ́pàá ti tẹ ọkùnrin kan tó pa ọ̀rẹ́ rẹ̀ nítorí N40 ní Kano Ọkọ̀ òfúrufú ọlọ́pàá yóò bẹ̀rẹ̀ sí ní káàkiri Naijiria - Ọgá Ọlọ́pàá Wo àwọn àwòràn tó làmìlaaka nílẹ̀ Adúláwọ̀ lọ́sẹ̀ yìí ‘Àti fi àwọ̀n ọlọ́kadà 123 láti Jigawa sílẹ̀’ Ileeṣẹ ọlọpaa ti kọkọ fi ikilọ sita ṣaaju ni ibẹrẹ ọdun 2019 pe ki gbogbo awọn abẹya ara kan lo tete wa ibi gba.
Gẹgẹ bi iroyin ṣe sọ ọ, o ayẹyẹ ọdun mẹwaa lori oye ninu oṣu kọkanla ọdun 2016.
Mo ti fi agbára ṣiṣẹ́ jù wọ́n lọ.
Bẹẹ ni ọrọ ri pẹlu tọkọ-taya kan, Tash ati Simon Young, ti wọn se igbeyawo nile iwosan nigba ti dokita ni arun jẹjẹrẹ to n se iyawo, ko ni pẹ mu ẹmi rẹ lọ.
Ó fi ẹ̀kọ́ òtítọ́ kọ́ni, kìí sọ̀rọ̀ àìtọ́.
Nisinsinyii, nítorí gbogbo ohun tí ẹ̀ ń ṣe wọnyi, tí mo sì ń ba yín sọ̀rọ̀ lemọ́lemọ́, tí ẹ kò gbọ́, tí mo pè yín, tí ẹ kò dáhùn, 
64Owona fun isẹ gbogbo - 136,278,189,622.
Oríṣun àwòrán, other Àkọlé àwòrán, Toju-toju ni ọkunrin yii fi ibomu-bẹnu bo.
 Àwọn ẹbí pàápàá ń sọ ̀ rọ ̀ òdì .
Asa atijọ si ni ilana Pẹlupẹlu to jẹ asa awọn ọba alaye ni Ekiti.
Pabanbari lasiko yii ni ti sunkẹrẹ fakẹrẹ ọkọ to maa n waye paapaa lọjọ ti eto naa yoo pari tii ṣe ọjọ ẹti.
Jẹfuta ṣe aṣiwaju ní ilẹ̀ Israẹli fún ọdún mẹfa.
Lọ́jọ́ kan àná lo gbé ikú jẹ; o gbé ikú mì
Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Abiola Ajimobi: Iku Ajimọbi jẹ́ ǹkan ìjayà nítori kò só sí ẹnìkan tó ń reti irúẹ̀ lásìkò yii28 Òkùdu 2020 Àtẹ Àwòrán, Abiola Ajimobi: Àwòrán rèé nípa ìgbé ayé Abiola Ajimobi26 Òkùdu 2020 Abiola Ajimobi: Oríkì mẹ́jọ tí wọ́n fi ń pe Ajimọbi nígbà ayé rẹ̀28 Òkùdu 2020 Abiola Ajimobi: Ìtùnú tí mo ní nípa ikú ọkọ mi, ni pé Sẹ́nétọ̀ Abiola Ajimobi rí ọ̀run rere wọ̀- Florence Ajimobi3 Ògún 2020 2019 Election: Ta ni olùdíje gómìnà l‘Ogun, Kashamu àbí Adebutu?
Ó ṣe dáradára gẹ́gẹ́ bí Asa, baba rẹ̀, ó sì ṣe ohun tí ó tọ́ lójú OLUWA.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Rwanda Genocide: Ó fẹ́ gba ẹ̀san ṣùgbọ́n ó padà dáríjì í Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Rwanda Genocide: Ó fẹ́ gba ẹ̀san ṣùgbọ́n ó padà dáríjì í 8 Ìgbé 2019 Ọjọ buruku eṣu gbomimu lọjọ naa lorílẹ̀-èdè èdè Rwanda.
Atẹjade ti Amnesty International fi sita ni ọjọ kẹẹdọgbọn, oṣu kẹfa ló sọ eyi di mimọ.
“Nítorí náà, dìde kí o pada sílé, ṣugbọn bí o bá ti ń wọ ìlú, bẹ́ẹ̀ ni ọmọ náà yóo kú.
Ó pe ọkùnrin yìí ó sì bá a ṣe ètò wí pé kí ó máa dá ẹmu lórí ọ̀pẹ wọ̀nyí, nígbà tì í bá dá ẹmu náà tán tí ó tà á, kí àwọn jọ máa pín owó tí ó bá ti ibẹ̀ jáde ní dọ́gbadọ́gba.
Ọdọ kan sọrọ lori ipalara aibuwọlu abadofin Peace corps
3 trillion ni CBN gbé jáde fún ọdun 2020 Kìnìhún nìkan kọ́ ló burú, àwọn ajá mẹ́wàá yìí náà kò fararọ!
Bí ó bá jẹ́ pé ọlọrun ni Baali nítòótọ́, kí ó gbèjà ara rẹ̀, nítorí pẹpẹ rẹ̀ tí wọ́n wó lulẹ̀.
Ayẹyẹ ami ẹyẹ Caf ọlọdọọdun yoo tẹle ikede naa lonIi.
Ikú kò náání ẹbọ,  kò bìkítà fún ṣìgìdì, bẹ́ẹ̀ ni ońdè àti òrùka kò ṣe é ní nǹkan.
Igbesẹ wo ni ijọ Four Square ti gbe lori iṣẹlẹ yii?
Awon egbe oselualatako ohun ni won fe atunse si iwe ofin orile-ede naa lati faye saa meji gbaaare lori aleefa.
Adari orile ede yii  tun so pe ijoba ko ni kaare lati gbogun ti iwa ibaje , ni ona ti igbe aye iderun yoo se de ba awon omo orile ede yii,labe bo ti wu ko ri.
N óo pèsè ọpọlọpọ nǹkan jíjẹ ati nǹkan mímu fún yín, n óo sì mú àìsàn kúrò láàrin yín.
Gomina Ali Yerlikaya to n tukọ Istanbul ni gbogbo eeyan lo fẹ lọ kirun Jimọ akọkọ nile iṣembaye naa.
 Ìgbà tí ọmọ-ilé kan ọkùnrin tàbí ọmọ-osu , tàbí ọ ̀ kan nínú àwọn ìyàwó ilé bá ń ṣe ìnáwó ni wọn tóó sun ti wọn .
Mẹẹta ninu ọkunrin atobinrin mẹwaa ti wọn ri iwosan l'Eko yii ni wọn jẹ ọmọ ilẹ okeere.
Mo ṣe ètùtù títí mo pa ẹsin mẹ́fà, mo pa àgùntàn mẹ́fà ní àgbàlá, ọgọ́ta ewúrẹ́ ni mo sì fi ṣe sàáráa[sí ìkòríta.
Ọmọ ọdún mẹrin yìnbon pá ọmọ ọdún méjì ní California
"Ọlọ́pàá tún yìnbọn pa awakọ̀ Márúwá, ìwọ́de gba Portharcourt kan Amotekun yóò gba owó oṣù kẹtàlá ní ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́ - Seyi Makinde Maina dákú fún ọ̀pọ̀ ìṣẹ́jú, iléejọ́ sáré so ìjókòó rọ̀ Wo ìròyìn tó pọ̀ jùlọ táwọn èèyàn ń wá ní Google lọ́dún 2020 Obasanjo àti Gani Adams tẹ́ mi pẹ̀lú bí wọn ṣe tahùn síra wọn - Adebanjo Gẹgẹ bo ṣe sọ, o ni ""ọdaran naa maa n dibọn pe oun ni ọgagun Larry Pham, lati lu awọn ololufẹ rẹ ni jibiti lori ayelujara, paapaa awọn obinrin."
Ọba náà fi idà pa àwọn ọdọmọkunrin Juda ninu tẹmpili, kò ṣàánú àwọn ọdọmọkunrin tabi wundia, tabi àwọn àgbà tabi arúgbó; gbogbo wọn ni Ọlọrun fi lé e lọ́wọ́.
Dayọ ni oun fẹ gbe ni alaafia, ki wọn si ye wa eekanna mọ oun lọrun nitori pe oun ko tii ni ọkọ tabi di oyun sinu.
Ọgbẹni Rekpene Bassey to jẹ onimọ lori eto aabo sọ pe owo kereje lowo ti ijọba ya sọtọ fun eto ti wọn ba parọ rẹ lati naira si owo dọlaÒpópónà àti afárá 19 níjọba fẹ́ ṣe nínú àbá ìṣúná ọdún 2020.
Ni awọn ipinlẹ bi Kano awọn alaṣẹ ti fofin de ṣiṣe awọn eto kan to maa n tẹle Sallah bi Durbar tawọn eeyan ti maa n gun ẹṣin ati awọn faaji miran.
OLUWA ní,“Wò ó, ẹnìkan yóo fò wá bí ẹyẹ idì,yóo sì na ìyẹ́ apá rẹ̀ lé Moabu lórí.
wọ ́ n bíi ní Ọjọ ́ kejìlá oṣù kínín Ọdún 1954 ní ìlú èkó sí ìdílé ọlọ ́ ba kosoko ti erékùṣù èkó .
Obaseki la Ize-Iyamu mọ́lẹ̀ wọlé ìbò gómìnà lẹ́ẹ̀kejì ní ìpínlẹ̀ Edo Wo bí Sunday Shodipe ṣe pa Funmilayo tó pa kẹ́yìn l' Akinyele Ẹ̀yin òṣìṣẹ́ elétò ìlera, ẹ padà sẹ́nu iṣẹ́- JOHESU Bí PDP ṣe na APC lálùbami ní Edo, bẹ́ẹ̀ ni yóò ṣẹlẹ̀ ní Ondo- PDP Wo ìdí tí ètò ìdìbò gómìnà ìpínlẹ̀ Edo ṣe lọ ní ìrọwọ́-rọsẹ̀ Fi orukọ silẹ nibi lati jẹ anfaani owo yii.
Gbogbo wọn bá péjọ sí Misipa, wọ́n pọn omi, wọ́n dà á sílẹ̀, wọ́n sì ṣe ètùtù níwájú OLUWA.
Èkó – Aginjù laarin àwọn Olú Ilú Àgbáyé
Neko, ọba Ijipti fi Eliakimu, arakunrin Joahasi jọba lórí Jerusalẹmu ati Juda, ó yí orúkọ rẹ̀ pada sí Jehoiakimu, ó sì mú Joahasi lọ sí Ijipti.
Gẹgẹ bi iwadii ti BBC Reality Check ṣe, ninu idibo ọdun 2000, 2004, 2008 ati 2016, awọn oludije owo ti iye rẹ ko din ni biliọnu meji dọla lori eto idibo Aarẹ.
Yoruba Films: Mr Latin ní òṣèré tó bá ya sinimá lásìkò Coronavirus yìí, òun ò lọ́wọ́ ń bẹ
Trikytee àti Ozo ní wọ́n di ẹrù ilé lé lórí nilé bbnaija lọ́sẹ̀ yìí Iléeṣẹ́ ọlọ́pàá sọ afurasí ọlọ́pàá tó yìnbọn fún ọ̀dọ́kùnrin tó fún èèyàn lóyún lẹ́sẹ̀ s'átìmọ́lé Njẹ awọn orilẹ-ede mii yo janfani nibẹ?
Ó ṣe ohun tí ó burú lójú OLUWA, ó tẹ̀lé ìwà ẹ̀ṣẹ̀ Jehoiakimu baba rẹ̀.
Èèyàn méjì farapa nínú ilé tó jóná ní Tejuoso l‘Eko Ọlọ́pàá kan jáde láyé, èèyàn méjì fara gbọta lásìkò ìdigunjalè ní Falomo l‘Eko Busola Dakolo, lọ san N1m owó gbà má bínú fun Biodun Fatoyinbo - Ileẹjọ Ìbò gómìná Bayelsa ku ọjọ́ méjì, Iléejọ́ yẹ àga mọ́ olùdíje APC ńídìí, Àwọn ọmọ Nàìjíríà bu ẹnu ẹ̀tẹ́ lu NTA lórí ìgbóhùnsáfẹ́fẹ́ ìdíje bọ́ọ̀lù Koda o se afihan ọpọ ohun ti ọta ibọn ba ninu ile aburo rẹ to ni awọn janduku wa ka mọle amọ ori lo ko yọ ti ko ba ibẹ lọ.
Agbọ́ yìí sọ̀ yìí; Asọ̀lú kọ̀lú
O wa pe nọmba to wa lara apo owo naa ki o fi ba ẹni to ni owo naa sọrọ lati wa gba owo rẹ pada.
Olè gbé òrùka ìgbéyàwó mì ní Eko Bíbéèrè fún ìbálòpọ̀ gbogbo ìgbà sọ ìyàwó ilé dèrò ilé ìwòsàn Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Kayeefi: Facebook ni Wolii Arole Jesu fi tàn an wọ agbo, orí rẹ̀ ni wọ́n fi s'owó Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
 Bẹẹ ni wọn tun woye pe o yẹ ki ami ẹyẹ fun ẹka eto ẹkọ ṣe pataki ninu Ofin naa.
Ọgbẹni Sodipo sọ pe ninu ewu nla ni awọn dokita tọju awọn to laarun coronavirus wa, notori naa, o yẹ ki ijọba wa nkan ṣe si ọrọ aabo wọn lẹnu iṣẹ.
ṣalaye pe ko si aabo to peye ni orilẹ-ede yii, ijọba ipinlẹ kan si ni ẹtọ
Ajo naa tun so pe opolopo iwa ibaje lo ti gbile ni orile ede naa bi I jiji awon ohun ini to je ti  orile ede naa ati fifun awon molebi ati ore won ni ise akanse lona ti ko tọọ.
Eyi ko dun mọ Naira Marley ninu, o si fi esi ọrọ kobakungbe ranṣẹ sii lori ayelujara.
Wọn n fi ẹsun kan wolii Sọtitobirẹ ati awọn oṣiṣẹ ijọ naa mẹfa pe wọn lọwọ si bi ọmọ ọdun kan, Kọlawọle Gold ṣe poora ni ileejọsin naa ni oṣu kọkanla ọdun 2019.
Lagos-123 FCT-100 Delta-58 Edo-52 Ogun-42 Katsina-24 Bayelsa-23 Rivers-22 Borno-19 Plateau-18 Ondo-18 Oyo-17 Kwara-15 Osun-13 Enugu-9 Nasarawa-7 Abia-6 Cross River-5 Kaduna-3 Ekiti-1 Lọwọlọwọ, eniyan 29,286 lo ti ni aarun naa, 11828 ti ri iwosan, 654 si ti ku.
Wo ìdí tí wọ́n fi dá Alága àjọ EFCC Ibrahim Magu sílẹ̀ Tolulope Arotile: Ọ̀rẹ́ Tolu ṣàlàyé bí ìjàmbá ọkọ̀ tó ṣekúpa á ní Kaduna ti ṣẹlẹ̀ Bí ẹgbẹ́ One Million Boys ṣe bẹ̀rẹ̀ rèé àti ọṣẹ́ tó ṣe n'Ibadan Sotitobire: Kò sí èléyìí tó kàn mí nípa ìjínígbé Gold Kolawole!
Obaseki la Ize-Iyamu mọ́lẹ̀ wọlé ìbò gómìnà lẹ́ẹ̀kejì ní ìpínlẹ̀ Edo ''Operation Burst'' ti mú Eji, tó gba ipò Ebila olórí ''One Million Boys'' ní ìpínlẹ̀ Oyo Lẹ́yìn olóògbé Barrister àti Kollington, èmi làgbà kàn nínú iṣẹ́ orin Fuji- Obesere yarí Ọ̀tọ̀ lórìn bi wọ́n ṣe yan àwọn ti yóò kúrò nílé ẹlẹ́gbọ̀n ọ́n àgbà BB Naija lónìí Ó fí kún-un pé èyi tọka si àrídáju pé ìjọba ààrẹ Buhari nígbàgbọ́ nínú ètò ìdìbò ti kò ni kọ́nukọ́họ nínú.
Lara awọn ile itaja to jona ni, ibi ti wọn ti n ta bata, aṣọ, kapẹẹti ati ẹya ara ọkọ.
O ni nitori pe itankalẹ arun Covid-19 ti wa n peleke si ti Naijiria ṣi n gbiyanju lati ri abẹrẹ ajẹsara, o di dandan ki igbimọ yi si wa nibẹ di oṣu Kẹta ọdun 2021.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ọọni Ogunwusi Adeyẹye pe fun itọju awọn ọdọ Ọpọlọpọ obi, alagbatọ ati awọn olukọ awọn akẹkọọ wọnyii ni wọn kọwọrin wa pẹlu awọn ọmọ wọn.
Aare muhammadu Buhari ti ki igbakeji rẹ , osinbajo  ati awon mẹ́sán án miiran ku ori-ire ewu ijamba
Irú ara wo ni wọn óo ní?
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Sunday Igboho yarí, ó fohùn ránsẹ́ sáwọn èèyàn tó ń pẹ̀gàn rẹ̀ Ìkúnlẹ̀ ló bá dé fún Oshiomole, Ize-Iyamu láti bẹ̀bẹ̀ fún ìbò aráàlú ní Edo Sunday Igboho yari, o fohun ransẹ sawọn eeyan to n pẹgan rẹ Ikú Barakat Bello ní Akinyele gbé aláàánú pàdé ẹ́bí rẹ̀ A ṣe ọdún Ọ̀ṣun lásìkò yìí láti kó Coronavirus lọ ni - Ooni ṣàlàyé Wo àwọn nǹkan tí o kò mọ̀ nípa 'Church of Satan' Àwọn afurasí ajínigbé tó tan oníṣòwò jáde ní ṣọ́ọ́sì wọ gàù Ọlọpaa Diẹ lara awọn ileesẹ naa to fi ikede si oju opo ayelujara Instagram wọn sọ pe, iyansẹlodi naa tun jẹ ọna ti awọn fẹ ẹ fi tako bi awọn oṣiṣẹ ajọ amusẹya 'task force' atawọn oṣiṣẹ ijọba ibilẹ, ṣe n gba owó ti ko tọ ọ lọwọ wọn.
Fẹmi Anikulapo-Kuti naa ki Fẹla ku ọjọ ibi, o ni kosi ẹni to le gbagbe Fẹla laelae pẹlu ọpọ ohun to gbe ile aye ṣe.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Omolola Arohunmolase Welder: Mo ti fí iṣẹ́ 'Welder' gbayì láwùjọ, tó mo fi tọ́ ọmọ yanjú Agbẹnusọ ajọ naa tun ni minisita eto ibanisọrọ ati ọrọ aje igbalode, Ọmọwe Isa Pantami lo fun awọn laṣẹ ṣiṣe ayẹwo iwe owo naa ni kiakia.
Iṣẹlẹ naa waye ni nnkan bi aago kan abọ ọsan ọjọ Aje.
Tinubu to ni idi abẹwo oun gan ni lati mọ hulẹhulẹ iṣẹlẹ naa ni lara awọn ibeere ti oun wa bi gomina Sanwo-Olu nipa iṣẹlẹ naa ni pe 'ṣe oun lo paṣẹ ki awọn ṣọja yinbọn sawọn oluwọde naa?
" Bákan náà ló tako ẹsùn ti wọn fi kàn nínú fónrán ti wọn pè ni Surviving R Kelly pé, ó kó àwọn obinrin pamọ lòdi sí ìpinu wọn, tó sì ń gba fóònù wọn, sàmójútó ounjẹ wọn, kò sì fún wọn láànfàní láti rí àwọn ẹbi wọn.
Ṣelomiti láti inú ìdílé Iṣari, Jahati láti inú ìdílé Ṣelomiti.
 fún ìdí èyí ọmọ ènìyàn nílò ìdáríjì ẹ ̀ ṣẹ ̀ láti ọ ̀ dọ ́ olódùmarè , torí rè ni jésù ṣe wá sílé aye láti wàásù ìgbàlà àtì láti kú fún ọmọ aráyé fún ìwènùwọ ́ àti ìràpadà ẹ ̀ sẹ ̀ wọn ( john 3 : 16 , matthew 1 : 21 ).
Idi ni pe awọn janduku to ti ja iwọde naa gba, ti dana sun agọ ọlọpaa to wa lagbegbe yii ni deede aago mẹwa ku isẹju mẹẹdogun laarọ yii.
Awọ́n akinkanju obinrin to n wa ọkada ni ilu Eko ní isẹ́ náà pé ju kí èèyàn máa se òwò nàbì lọ.
Is̀irò ni èdè Yorùbá ti fẹ́ di ohun ìgbàgbé, nitori àwọn ọmọ ayé òde òní kò rí ẹni kọ́ wọn ni ilé tàbi ilé-ìwé, nitorina ni a ṣe ṣe àkọọ́lẹ̀ ìṣirò yi si ojú ewé yi.
Ṣugbọn Jesu wí fún un pé, “Kí ló dé tí o fi pè mí ní ẹni rere?
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Christmas & Border Closure: ìrẹsì dí góòlù fún Kérésì 2019 Buhari ni ti awọn oniwakiwa ko ba jawọ, wọn yoo gba ko ẹsan iwa wọn, nitori pe awọn oṣiṣẹ alaabo ti ṣetan lati gbogun ti wọn, ti wọn yoo si ṣẹgun wọn.
Lọdun ti Naijiria gba ominira ni wọn bii si ile iwosan ikọṣẹ iṣegun, UITH nilu Ibadan.
 Àwọn olùsifá gbàgbọ ́ nínú ẹ ̀ mí takọ-tabo nítorí wípé akọ ń ṣẹ ̀ mí nítorí abo ; bákan náà ni abo ń ṣẹ ̀ mi nítorí akọ ni .
APC tú ilé ká ní ìpele ìpínlẹ̀ àti ti ìjọba àpapọ́ Igbìmọ̀ aláṣẹ ẹgbẹ́ òṣèlú APC tú ilé ká!
Nítorí o sọ pé ẹ̀kọ́ rẹ tọ̀nà,ati pé ẹni mímọ́ ni ọ́ lójú Ọlọrun.
N óo da èrè ìṣekúṣe yín le yín lórí, ẹ óo sì jìyà ẹ̀ṣẹ̀ ìbọ̀rìṣà yín.
Paulu bá dìde dúró láàrin ìgbìmọ̀ tí ó wà ní Òkè Areopagu, ó ní, “Ẹ̀yin ará Atẹni, ó hàn lọ́tùn-ún lósì sí ẹni tí ó bá wò ó pé ẹ kò fi ọ̀rọ̀ oriṣa ṣeré.
Wọn fi aridaju han fun awọn ololufẹ eto naa wipe wọn o kan ni gbadun rẹ lasan sugbọn se ni wọn ko ni le yin in kuro loju opo ti wọn ti n wo o titi ipari rẹ ti wọn yoo kede ẹni to jawe olubori.
Ilé fi kún un pe ìwà yìí jẹ́ ọ̀yájú sí ẹ̀ka asòfin, àwọn asáájú ilé sì ti dúró láti tako ìwà burúkú yìí."
Ènìyàn 416 ló ti lùgbàdì àrùn Coronavirus ní Ọjọ́ Ajé ní Naijiria Coronavirus recovery cases: Ìrírí ọkùnrin kan tó ní àrùn coronavirus ní ilẹ̀ Gẹ̀ẹ́sì rèé Bẹẹ ni Oloyede ni awọn kii gba iranwọ lati ile okeere tabi abẹle lati fi se akoso awọn mọsalasi kaakiri orilẹede Naijiria nitori naa ni awọn ṣe n rọ ijọba lati ran awn lọwọ pẹlu oogun apakokoro.
Nígbà tí ògo mi bá ń kọjá lọ, n óo pa ọ́ mọ́ ninu ihò òkúta yìí, n óo sì fi ọwọ́ mi bò ọ́ lójú nígbà tí mo bá ń rékọjá.
 Ọpọ ́ n ifá tún lè jẹ ́ onígun mẹ ́ rin tí kò dọ ́ gba , èyí tí kò rí roboto tán tàbí kí á sọ pé onígun mẹ ́ rin tí ó dọ ́ gba .
Ọjọ Aje ọjọ kejidinlọgbọn ni ti awọn oniṣowo mii lee lọ soju opo naa.
Nítorí náà ni èmi ó ṣe máa yìn ọ́ láàrin àwọn orílẹ̀-èdè, OLUWA,èmi ó sì máa kọrin ìyìn sí orúkọ rẹ.
"Òkú ọmọ ọdún mẹ́ta tó kó sí kàǹga ní Ipaja ni wọ́n yọ' Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Ìgbà tí mo máa fi lajú sáyé padà, ọ̀fọ̀ ikú mi ní wọ́n ń kígbe' O ni ""bo tilẹ jẹ pe ọpọ eeyan lo wo fido naa ti wọn si n rẹrin, ṣugbọn ọgbọn ti mo kọ ninu rẹ ko kere rara."
Ó sàn kí ẹ pa mí ju kí ẹ ba oko tí mo gbin igbó sí jẹ́ lọ- Afurasi Clement sí NDLEA Isiaka Busari, Mighty Joe tó jẹ́ adigunjalè tó rọ́pò Ọyenusi lẹ́yìn tí wọ́n pa á Ọkùnrin kan da ṣọ́ọ̀ṣì rú lásìkò ìgbéyàwó, Ó ní òun lọkọ àárọ̀ ìyàwó tuntun Àṣà Oge Ṣíṣe ní Akọ́mọlédè BBC Yorùbá ń gbé yẹ̀wò lónìí, Ó yá, iṣẹ́ ti bẹ̀rẹ̀.
Iroyin sọ pe lojumọ ọjọ Ẹti lawọn eeyaEde gbàlejò jàńdùkú tó fọ́ ilé ẹrù ìjọba n kan tun ya bo ibudo iko nnkan awọn ohun elo iranwọ lasiko ajakalẹ arun COVID-19 pamọ si nilu Ẹdẹ, ni ipinle Oríṣun àwòrán, Screen shot Jàǹdùkú ya bo ilé ẹrù ìjọba Osun, wọ́n kó èròjà ìdẹ̀rùn Covid-19 lọ Ni ile kan ti wọn n pe ni Hocoa house ni ilu Ẹdẹ ni wọn ko awọn ohun irọrun COVID-19 naa si.
Bi a ko ba gbagbe, lai pẹ yi ni Gomina Amosun lewaju awọn ọmọ ẹgbẹ APM la ti lọ fun Aarẹ Buhari ni iwe atilẹyin lati ọdọ ẹgbẹ naa gẹgẹ bi oludije ipo Aarẹ ti wọn yan laayo.
Ọwọ́ mi óo tẹ̀ wọ́n; n óo sọ ilẹ̀ wọn di ahoro ati òkítì àlàpà, ní gbogbo ibùgbé wọn, láti ibi aṣálẹ̀ títí dé Ribila.
Nítorí náà, nígbà tí àwọn òbi wa bá wà láyé, ẹ jẹ́ kí á máa tẹ́jú wọn, kí wọn kí ó gbó, kí wọn ki ó tọ́ fún wa.
Eyi ni esi ifesewonse idije boolu afesegba torile-ede Niajiria NPFL ti o waye lopin ose:Abia Warriors 0 – 0 Enugu RangersAkwa United 4 – 0 Wikki TouristEl Kanemi Warriors 0 – 0 EnyimbaKano Pillars 2 – 0 MFM FCKatsina United 2 – 0 Niger TornadoesPlateau United 5 – 0 Sunshine StarsRivers United FC 1 – 0 Go RoundHeartland Owerri 2 – 0 Kwara UnitedLobi Stars 1 – 0 Ifeanyi Ubah UnitedEwe, ifesewonse meji yooku yoo waye laarin iko agbaboolu Nasarawa United ?
Ṣugbọn yóo túbọ̀ máa burú sí i ni fún àwọn eniyan burúkú ati àwọn ẹlẹ́tàn: wọn yóo máa tan eniyan jẹ, eniyan yóo sì máa tan àwọn náà jẹ.
Rohr so pe,“Mi o lero pe, isoro asole ni iko Super Eagles ni ”“Lati igba ti Carl Ikeme ti wa nipo aisan, a lero pe isoro asole ni a ni, sugbon Ikechukwu Ezenwa se daradara ninu awon ifesewonse ipegede ti a gba, papa sibe a si n wa asole miran.
El-Zakzaky: Ṣé lóòtọ́ ni ìjọba ń ná N3.
Lasiko ayewo ohun, oga agba Sadiq Abubakar se ayewo lofintoto awon ohun elo igbaradi ati oko ofurufu iko naa lojuna ati ri daju pe gbogbo ohun elo ohun wa ni sepe papaajulo nipo ti o dara.
Fayemi to jẹ minisita tẹlẹ fun ẹka iwakusa ati irin ni ibo to le ni ida aadọrin lati jawe olubori ninu ibo ọhun.
"Ko yọ Yinka Ayanda ti ọpọlọpọ mọ si ""Yinka TNT"" silẹ pẹlu bo ṣe tẹnu mọ ọ pe ""bi ẹ ṣe n pe oju ara yẹn o maa n bi mi ninu, ẹ wa orukọ mii to dun fun un""."
Ní ìgbẹ̀yìn ó wá rán ọmọ rẹ̀ sí wọn, ó ní, ‘Wọn óo bu ọlá fún ọmọ mi.
Apẹ̀rẹ̀ ti a pin àwọn èso oriṣiriṣi wọnyi si
"haile gebrselassie ( , "" haylē gebre silassē "" ; ojoibi , 1973 ) je ara ethiopia asareidaraya ona jijina ati isare ojuona ."
- Ọọ̀ni Ife Olè yabo báńkì.
O óo lágbára ju àwọn ọ̀tá rẹ lọ, a óo sì pa wọ́n run.
Ohun kan ni pe, mo mọ bi mo ṣe n jẹ ki obinrin o pẹ lọwọ mi, paapa obinrin to rẹwa.
O ṣeeṣe ki o jẹ wahala idibo ile asofin agba to n kopa ninu rẹ eleyi ti Inec sun siwaju lo n ba po o.
Nígbà tí àsìkò tó fún Adéláyò láti mú òkan péré nínú ògòòrò dúkìá tí baba rè fi sílè, ó kúnlè kí gbogbo àgbà tí wón wà níkàlè ó sì tóka sí olórí erú baba rè gégé bí dúkìá baba òun tí òun mú.
O fẹrẹẹ ma si ìpínlẹ̀ Nàìjíríà tí wọ́n o kii n mu oogun yii to bẹẹ ti a lee bẹrẹ si ni gbe e lẹgbẹ kẹgbẹ pe ipinlẹ bayii lo gba ipo ikinni ninu mimu oògùn Codeine jù.
Aare ni ’’ Awon iran mi mo egbe Rotary International .
OLUWA yóo sì bá Mose sọ̀rọ̀.
Lẹ́yìn náà, ó kú, wọ́n sì sin ín.
Lakoko to n ba awon ti won n kopa nibi ipade naa soro ,awon omo-oba ati olori ijoba orile-ede naa, Oba –birin Elisabeti   so wi pe,ireti oun  ni wi pe Ajo naa yoo tesiwaju fun iran ojo iwaju,nigba ti Omo –oba  kunrin naa yoo si tesiwaju ninu ojuse baba re eyi ti o beere l;odun 1949.
Wọn fikun un pe ọkọ ayọkẹlẹ kan n gbe eniyan mẹta lori afara naa nigba ti o ja, ti wọn si ni awakọ ati awọn eniyan naa ja si koto, ti wọn ko si le doola ẹmi wọn.
Oríṣun àwòrán, University of Ibadan O ni ko si awijare fun igbesẹ ti awọn alaṣẹ ileewe girama ISI ni fasiti ilu Ibadan n gbe, labẹ ofin nipa fifofin de elo ibori Hijab ni ileewe naa.
Ọjọgbọn Adewọle ni, ajọṣepọ ti waye pẹlu awọn ajọ eleto ilera lagbaye lati kani ọwọja arun naa nilẹ.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Wo àwọn òṣèré tíátà Yorùbá mẹ́fà tó bẹ̀rẹ̀ eré ṣíṣe láti kékéré Wo iye obìnrin tó bá Ginimbi ọ̀dọ́mọdé olówó kú àti obìnrin to ṣeéṣe kó jogún rẹ̀ ''Aláàfin kìí ṣe ọkùnrin tí wàá jẹ lásán, tó sì wá sálọ - Aráàlú fèsì fún Olorì Anu Wo ọ̀pọ̀ ìgbà tí Ginimbi ọ̀dọ́mọdé olówó ti ṣe àríyá aláṣọ funfun kó tó kú Ilé ẹjọ́ tú ìgbéyàwó ọdún mọ́kànlá ká nítórí pé ìyàwó fí ìbálòpọ̀ dun ọkọ rẹ̀ Ta ni olóògbé Jerry Rawlings, tí wọ́n fún ní àlàjẹ́ 'Junior Jesus' Gbogbo ìgbésẹ̀ Aláàfin láti jí mi gbé ló já sí pàbó, n kò le panumọ́ - Olori Anu Sé ọlọ́pàá tasẹ̀ àgẹ̀rẹ̀ tàbí fìyà jẹ ọ́ láìtọ́, wo bó ṣe fi ẹjọ́ rẹ̀ ṣùn l‘Eko Ọjọ Isẹgun ni ọwọ sinkun ọlọpaa tẹ baba akumọmojudi naa, nigba ti ẹgbọn ọmọ ọhun mu ẹjọ tọ ileesẹ ọlapaa lọ.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Sunday Igboho kàn ń gbé ‘Camera’ lẹ́yìn kiri, kí wọ̀n lè rò pé ó ń jà fún Yorùbá - Gani Adams Ẹgbẹ́ tó ń fẹ́ Oduduwa Republic kọ̀wé ẹ̀hónú sí UN, EU, AU àti ìjọba Gẹ̀ẹ́sì Àjọ EFCC ti mú ọ̀dọ́kùnrin mẹ́wàá lórí ẹ̀sùn jìbìtì lílù lórí ayélujára ní Oyo Kíni ó lè mú kí ọmọbìnrin sá kúrò nílé láti ìpínlẹ̀ Plateau lọ sí Ekiti?
Atẹjade kan lo lu ayelujara pa ninu eyi to fẹsun kan Tinubu pe o ṣapejuwe Buhari bi alakati ẹsun, ẹlẹyemẹta ati daaru daapọ lọdun 2013.
Ẹni ọdun mẹrinlelogun ni arabinrin Okochu, oun si ni oju arẹwa to wa ninu ikede gbajugbaja ohun mimu amunututu Cold Stone Creamery ko to ṣalabapade iku ojiji ninu ijamba ọkọ to waye ninu sunkẹrẹ fakẹrẹ ọkọ ni agbegbe Lagos Island nipinlẹ Eko lọjọ kejila, oṣu Kẹjọ.
Aarẹ naa wa fikun pe awọn ko ni kawọ gbera ti awọn ba wọle ẹlẹẹkeji, ati pe oju rere ti awọn ara oke fi n wo orilẹ-ede Naijiria bayiii yoo tẹsiwaju.
“Pàṣẹ fún àwọn ọmọ Israẹli pé ninu ilẹ̀ ìní wọn, kí wọ́n fún àwọn ọmọ Lefi ní àwọn ìlú tí wọn yóo máa gbé, kí wọ́n sì fún wọn ní ilẹ̀ pápá yíká àwọn ìlú wọnyi.
Ọ̀dọ̀ ta ni yóo fẹ́ lọ, tí yóo fi kúrò lọ́dọ̀ wa?
Ó bá kìlọ̀ fún wọn pé, “Ẹ sá lọ sí orí òkè, kí àwọn tí wọ́n ń lépa yín má baà pàdé yín lójú ọ̀nà.
Ṣugbọn ọrọ bẹyin yọ nigba ti Brighton fi pọnmọ kun pọnmọ pọnmọ ete awọn Gunners pẹlu ayo meji si ẹyọkan.
Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú
Àwọn ọdọ àti àwọn ọdẹ náà kò gbeyin nínú iwode naa.
Mo ti rù láàrin ọ̀sẹ̀ kan, iṣẹ́ Eko kò dẹ́rùn - Sanwo-Olu Mi ò m'àwọn ẹgbẹ́ tó ń gbé ''Tinubu 2023'' kiri- Bola Tinubu Bakan naa ni BBC kan si alaga igbimọ fidihẹ lori eto iroyin ati ifitonileti gbogbo fun ile igbimọ aṣofin ipinlẹ Eko, Oloye Tunde Braimoh lati Alimoṣọ II sọrọ lori koko yii nibi to ti ni oun ko faramọ ero Gbadamọsi rara.
 Ó di alákòso ológun orílè èdè nàígíríà ní 1975 títí di odún feb 13 , 1976 murtala mohammed jé elésìn mùsùlùmí , hausa ni pèlú láti ( òkè oya apá gúúsù .
ṣùgbọ́n lónìí yìí tí mo déédéé ri ọ láìròtẹ́lẹ̀, mo dúpẹ́, orí mi gbé ǹkan pàdé mi, nítorí ọjọ pẹ́ díẹ̀ tí mo ti ri ẹran ènìyàn jẹ mọ.
" Gbogbo nkan yii ni Regina ati awọn iyawo mi yooku mọ.
Fetí sí igbe mi,Ọba mi ati Ọlọrun mi,nítorí ìwọ ni mò ń gbadura sí.
Bí mo ti yọ sii, ti mo ní ki n gbé àdá sókè, àdá wúwo o ju àkúta lọ, n kò sí lè gbé ọwọ́ sókè rárá.
Bi iṣẹlẹ naa ṣe lọ niyi: Mo maa n ro wi pe igbeyawo mi ko ni abuku kankan, nitori pe emi ati ọkọ mi ti mọ ara wa fun ọpọlọpọ ọdun, ka to gbe ara wa ni iyawo."
Jesu dá wọn lóhùn pé, “Ṣé ẹ kò ì tíì ka ohun tí Dafidi ṣe nígbà tí ebi ń pa òun ati àwọn tí ó wà pẹlu rẹ̀?
"Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: A kò fẹ́ 23% tẹ fẹ́ yà sọ́tọ̀ bíí owónàá fáwọn ìjọba ìbílẹ̀ - ALGON Ọlọ́wọ̀ tìlú Ọ̀wọ̀ tuntun gorí ìtẹ́, idà àlááfìà ló mú ní Ìpèbí ""Ojú wa rí tó ní Egypt, bí wọ́n ṣe ń tẹ̀ wá lọ́mú, ni wọ́n ń gbá wa ní ìdí"" Ẹ wo adúrú ẹnu tí mó n bọ́ - Jaiye Kuti Oyewọ salaye pe bakan naa ni ijọba Ọyọ ti setan lati se atunto awọn ọgba ẹwọn wa, ti aparo kan ko fi ni ga ju ọkan lọ, ti idajọ yoo si maa waye lai fi igba kan bo ọkan ninu tabi se oju saaju."
ni ile igbimo asofi kekere , ti ile igbimo asofin agba si je ogoji din ni
ile-ise akoroyin ti orile ede Amerika so pe aare Trump ti n gbero lati se atunse si baalu naa.
Nítorí náà, ẹ̀yin ará ninu Oluwa, tí a jọ ní ìpín ninu ìpè tí ó ti ọ̀run wá, ẹ ṣe akiyesi Jesu, tíí ṣe òjíṣẹ́ ati Olórí Alufaa ìjẹ́wọ́ igbagbọ wa.
Àrà ọ̀tọ̀ inú orin tó jáde lọ́dún 2018 ní Nàìjíríà 'EFCC mo dé' àti àwọn àṣà míì táwọn olóṣèlú fi dagbo rú ní 2018 Àkójọpọ̀ àwòrán ọdún Kérésìmesì lágbáyé Àwọn orílẹ̀-èdè tó ti ṣáájú Nàìjíríà wọ ọdún 2020 Oríṣun àwòrán, Ninalowo bolanle Àkọlé àwòrán, Bolanle Ninalowo Bolanle Ninalowo.
Lati igba to si ti bẹrẹ iṣẹ ni awuyewuye loriṣiriṣi ti n jẹyọ lori ihuwasi rẹ.
Nigba to n ba ileeṣẹ iroyin CNN sọrọ, Abdukareem ni Oore nla ni ọmọ Ọba Dubai ṣe oun atawọn mọlẹbi oun.
”Eliṣa dáhùn pé, “Nítorí pé mo mọ oríṣìíríṣìí nǹkan burúkú tí o óo ṣe sí àwọn ọmọ Israẹli: O óo jó ibi ààbò wọn, o óo fi idà pa àwọn ọmọkunrin wọn, o óo tú àwọn ọmọ wẹ́wẹ́ wọn ká, o óo sì la inú àwọn aboyún wọn.
Nítorí pé ẹnikẹ́ni tí ó bá ń ṣe aiṣootọ, ìríra ni lójú OLUWA Ọlọrun yín.
“Ninu gbogbo àwọn abẹ̀mí tí ó wà ninu omi, àwọn wọnyi ni kí ẹ máa jẹ: gbogbo àwọn ohun tí ó bá ní lẹbẹ ati ìpẹ́ ni ẹ lè jẹ.
Ẹgbẹ agbabọọlu Arsenal ya agbado ha sawọn ololufẹ ere bọọlu lẹnu lẹyin ti wọn ra agbabọọlu aaringbungbun Thomas Partey lati Atletico Madrid.
DBanj: Ikú ọmọ mi kò leè paná ìfẹ́ láàrín èmi àti ìyàwó mi
22 Bélú 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Yagboyaju tun tẹsiwaju pe, ijọba tun gbọdọ ri si bi wọn se n bawọn to n se imẹlẹ lẹnu isẹ wi, eyi ti yoo mu ki ayipada orukọ naa ni ipa gidi lori awọn ọgba ẹwọn wa.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ahmed Musa ló fakọyọ jùlọ láàrín àwọn agbábọ́ọ̀lù Nàìjírìa lọdún 2018 2 Ìgbé 2019 Oríṣun àwòrán, Kevin C.
Bo tilẹ jẹ pe oun funra rẹ ko tii fesi, ṣugbọn o fẹ da bii pe aiṣootọ wa ninu ipolongo rẹ ti wọn n sọ pe ko tii si ewu kankan tabi boya o wa.
Nígbà náà ni inú bí OLUWA sí àwọn eniyan rẹ̀,ó sì kórìíra àwọn ẹni ìní rẹ̀.
Oríṣun àwòrán, kwange Àkọlé àwòrán, Asòfin yóò ṣe ìpàdé pàjáwìrì l'Abuja Èso wo ni àìpadà àwọn sílé àwọn aṣòfin lé bí?
Won gba aya aarẹ nimọran lati ba aarẹ Buhari sọ ootọ ọrọ.
Kí ló dé tí gbogbo yín fajúro?
Ṣugbọn àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ bá àwọn tí wọn gbé wọn wá wí.
Ó tún wọn ẹgbẹrun igbọnwọ (mita 450) mìíràn sí ìsàlẹ̀, ó sì mú mi la odò náà kọjá: odò yìí sì mù mí dé orúnkún.
fun aaye lowo ijoba ipinle Akwa Ibom lati lo papa isere Akpabio International
Sanusi beere ki ile ẹjọ da ẹtọ oun pada gẹgẹ bi ọmọ orilẹede Naijiria.
Gbogbo ìlú dá wáí ní Israẹli, ó dá,gbogbo ìlú di àkọ̀tì,títí tí ìwọ Debora fi dìde,bí ìyá, ní Israẹli.
Oríṣun àwòrán, omoyele sowore Àkọlé àwòrán, Ṣòwòrẹ́ tó jẹ́ olùdíje AAC ní ìdí tí òun kò fi leè kí ààrẹ Buhari kú oríire ni pé ọ̀na èrú ló fi wọlé Àfikún ìdìbò ààrẹ yóò wáyé lọ́jọ́ kẹsàn án oṣù kẹ̀ta Ohun márùn-ún tí Atiku ń bèrè lọ́wọ́ Buhari níbi ìpàdé rẹ̀ pẹlú Abdulsalam, Kukah Àwọn ohùn tó ṣé kókó tó yẹ ká mọ ṣáájú ìdìbò 2019 #BBC Nigeria Decides: Akala darapọ̀ mọ́ APC fún ìbò gómìnà Oludije fun ipo aarẹ labẹ aṣia ẹgbẹ oṣelu AAC naa ni omi ṣi n bẹ lamu fun eto idibo lorilẹ-ede Naijiria.
igbalejo aare ni ile-ise  aare niluu
Bakan naa ni Dokpesi sọrọ lori eto Kakaki ti NBC fi ẹsun kan pe, eto naa wa fun ero inu awọn ara ilu.
"Awọn eeyan n patẹwọ fun mi, tawọn obinrin yoo maa ni ki n bọ awọn lọwọ, ọpọ ni yoo pe ọkọ rẹ lori aago, tori kii se ojoojumọ ni wọn n ri iru aworan bayii, bi o tilẹ jẹ pe o nira lati ya irufẹ aworan yii.
N óo mu yín gẹ́gẹ́ bí eniyan mi, n óo jẹ́ Ọlọrun yín; ẹ óo sì mọ̀ pé èmi ni OLUWA Ọlọrun yín, tí ó fà yín yọ kúrò lábẹ́ ẹrù wúwo tí àwọn ará Ijipti dì rù yín.
''Ni ọpọlọpọ agbegbe ni Naijiria, awọn eniyan giga ati ọlọla n jọba lori ofin, ti ko si si ẹni ti yoo mu wọn si.
n se ayẹwo kaadi naa bẹrẹ si n se mọna -mọna 
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Natalia Mufuta ìyá Yakub, Kamil àti Adam sọ̀rọ̀ lórí bí wọ́n ń sọ èdè mẹ́rin pàpọ Nitori naa lo ṣe ro pe awọn mejeeji n fẹ ara wọn."
Èèyàn 110 tún ti ní COVID-19 ní Nàìjíríà Eeyan aadọfa lo tun kun iye awọn eeyan to laarun COVID-19 lorilẹede Naijiria bayii.
Ohun to n ṣẹlẹ yii niiṣe pẹlu awọn iṣẹlẹ mii.
Lẹyin eyi, o dara pọ mọ ikọ afara jọ ologun CADET lati ṣaa fihan pe gbogbo ọkan oun, ọdọ awọn ologun lo wa.
Ṣugbọn lọ fi ara rẹ han alufaa, kí o sì rúbọ ìwòsàn rẹ bí Mose ti pàṣẹ, gẹ́gẹ́ bí ẹ̀rí fún wọn pé ara rẹ ti dá.
“Ìwọ ọmọ eniyan, ohun tí èmi OLUWA Ọlọrun sọ nípa ilẹ̀ Israẹli ni pé: òpin ti dé.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Fulani Kidnapping: Owó púpọ̀ la san kí wọ́n tó fi mi sílẹ̀ Awọn agba ọjẹ mejjeji mẹnuba wahala to maa n jade lati ara ẹlẹyamẹya ati aini irẹpọ lorilẹ-ede ati ni agbegbe kọọkan.
Ní ọjọ́ keji a kúrò níbẹ̀, a dé òdìkejì erékùṣù Kiosi.
Aṣofin Ọbasa wa gbadura pe ki Ọlọrun tẹ aṣofin naa safẹfẹ ire, ki o si tu awọn ẹbi, ọrẹ, Ile Igbimọ Aṣofin Ipinlẹ Oyọ, Ijọba Ipinlẹ Ọyọ ati awọn ọmọ ẹgbẹ oṣelu APC ninu.
Igbesoke alaafia laaarin awọn lọbalọba ati gbogbo Yoruba lapapọ iii.
Adari ifesewonse omo ile Kenya ti o ye ko kopa ninu idije boolu agbaye to n lowo lorile-ede Russia ni ajo FIFA ti fofin de bayii lataari esun iwa ibaje ti won fi kan pe, O gba owo abetele, eleyi ti o si jebi esun ohun.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Bí o ṣe lè fí òǹkà, ọ̀mọ̀ ìka tàbí ìkúùkù wọn oúnjẹ́ Oriṣiriṣi iwadii lo ti fihan pe iru ounjẹ ti obinrin ba n jẹ ko to o loyun ṣeeṣe ko ni ipa ninu bi ọmọ rẹ yoo sẹ tobi si, tabi ko bi ọmọ lai pe ọjọ.
Ẹnu rẹ ni ó dá ọ lẹ́bi, kì í ṣe èmi;ẹ̀rí tí ò ń jẹ́ nípa rẹ ní ń ta kò ọ́.
Wọn ni, iwadii fi han pe awọn onigbọwọ owo nabi yi maa n fi oogun halẹ mọ awọn ọmọbinrin naa lọri ẹro ibanisọrọ ni lati se ifẹ ti wọn.
gbọ́ adura ati ẹ̀bẹ̀ ẹnìkọ̀ọ̀kan, tabi ti gbogbo Israẹli, eniyan rẹ, lẹ́yìn tí olukuluku ti mọ ìṣòro ati ìbànújẹ́ rẹ̀, bí wọ́n bá gbé ọwọ́ adura wọn sókè sí ìhà ilé yìí, 
"Nítori náà àwọn ti ""T Cell bá wà nínú àgọ́ àra wọ́n ko ni ni ààrun coronavirus, tàbí kí wọ́n ni i, ko si ma farahàn tàbí dáwọn dùbúlẹ̀."
" Adeboye fikun pe oun ko f ri ibinu Ọlọrun, yoo si dara kawọn eeyan naa ma mu oun kọsẹ niwaju Ọlọrun pẹlu aworan oun ti wọn fi n pe Ọlọrun yii.
Bíbéèrè fún ìbálòpọ̀ gbogbo ìgbà sọ ìyàwó ilé dèrò ilé ìwòsàn Ó ṣeéṣe kó jẹ́ pé àwọn alágbara ló ń fi agbára hàn lórí arábìnrin tó fẹ̀sùn ìfipábánilòpọ̀ kan kọmíṣọ́nà Kogi -Agbẹjọ́rò Ààrẹ fi nǹkan ọkùnrin rẹ̀ pa mí lójú, kó tó fipá bámi lòpọ̀ - Ọmọge Arẹwà O ni lẹyin ti ayẹyẹ naa pari, oun lọ si yaara ti oun gba ni ile itura Glee, to wa ni Victoria Island.
Mo rí ìyá arúgbó òyìnbó kan tó nsọ̀rọ̀ kan sí mi, ṣùgbọ́n tí ng kò gbọ́ nkan tó nsọ nítorí kiní orin tí mo tì bọ'tí.
O fèsì lori ìròyìn kan to jade tó sọ pé oṣù mẹ́ta ni gbèndéke ti àwọn fún àjoji ni orilẹ̀-èdè Nàìjíríà láti wá gba ìwé ìgbélùú tàbí ki wọn fi wọ́n ránṣẹ́ padà si orilẹ̀-èdè wọn.
Nítorí èyí, níwọ̀n ìgbà tí ó wu Ọlọrun ninu àánú rẹ̀ láti fi iṣẹ́ yìí fún wa ṣe, ọkàn wa kò rẹ̀wẹ̀sì.
Àkọlé àwòrán, Adams Oshiomọle ni Gomina Ayo Fayose ń lo owó osù àwọn òsìsẹ́ fún ara rẹ̀ Aarẹ Muhammadu Buhari, Bola Tinubu ati awọn adari ẹgbẹ oselu APC pẹlu ọgọọrọ awọn ololufẹ wọn wa ni asekagba ipolongo idibo naa.
Awọn oun to wa lori ẹrọ alagbeka to n ka igba ti obirin ba n ṣe nkan oṣu yii lee mọ oun ti eniyan jẹ, ohun ti wọn mu, alaye nipa ibalopọ ati iru ohun ti won n lo lati ṣe nkan oṣu naa.
Akure: Deji Akure, Oba Aladelusi Ogunlade ti pàṣẹ kí gbogbo ọjà wà ní títì pa fún ọjọ́ méjì nítorí àjọ̀dún ìṣẹ̀mbáyé méjì
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ilé jóná ní Òkè Àdó Ibadan, ọ̀pọ̀ dúkìá ṣòfò Àwọn alága ìbílẹ̀ tún wọ́ Seyi Makinde relé ẹjọ́ Iṣọla Oyenusi rèé, ẹnití ìfẹ́ obìnrin ṣun dé ìwà ìdigunjalè Orí mi wú, ọmọ Nàíjíríà 16 gbàmì ẹ̀yẹ nínu akẹ́kọ̀ọ́ fásitì 27 l‘òkè òkun Adebisi ni  A maa tẹsiwaju lati wa ajọsepọ pẹlu ẹlẹgbẹjẹgbẹ, ẹnikẹni tabi ileesẹ kileesẹ to ba setan lati mu agbega ba eto irinajo afẹ ni ipinlẹ Ọsun, a si n fi oju sọna fun ajọsepọ to loorin pẹlu ẹka aladani."
Ó jẹ́ àkójọpọ̀ àwọn ọmọ Israẹli tí a kà, gẹ́gẹ́ bí ìdílé baba wọn.
Nígbà tí Mose bá àwọn ọmọ Israẹli sọ gbogbo ọ̀rọ̀ wọnyi tán, 
Iwadi ijinlẹ gan si fidi rẹ mulẹ pe ẹja ni ẹranko kansoso ti nnkan osu rẹ naa maa n dawọ duro gẹgẹ bii tawọn obinrin.
Atamatase omo odun merindinlaadorin ohun, gba ifesewonse ogorun-un fun iko Barcelona pelu ami-ayo merinlelogoji, besini O gbaa ife-eye Copa del Rey meji ni saa  (1981, 1983), ati ife-eye idije UEFA Cup ni saa (1982).
Miliọnu kan dọla o le ni ilumọọka, Kylie Jenner n gba lati ile -iṣẹ Instagram nigbakigba ti o ba kọ nkan si oju opo rẹ.
Àwọn ọmọ Ṣutela nìwọ̀nyí, ìdílé Erani.
Gbogbo wa la mọ̀ pé ọ̀pọ̀ ọmọ Naija ni wọ́n bí sí UK, ọ̀pọ̀ náà ló sì ti di ọmọ ìlú náà nípasẹ̀ ìwé-ìgbélùú gbígbà.
Iyàlẹnu ńlánlà lọ́ jẹ́ fún Agígírì láti rí Lúmọ̀ogun pẹ̀lù àwọn ọdẹ mélòó kan, Ó ti para pọ̀ pẹ̀lú àwọn ọdẹ wọ̀nyí ó sì ti gbàgbé iṣẹ́ tí wọ́n rán an nítorí ti ibẹ̀ dùn mọ́ on fún ọwọ́ ìfẹ́ tí àwọn ọdẹ náà fi gbà á.
Lati igba naa, ni won ti n ikolu, ti won si ti seku pa awon omo-ogun ijoba bi: olopaa ati oloogun , bakan naa ni won ti ji awon osise ijoba meji gbe, ologun kan nigba ti won jo oko ayokele re tan ati osise ijoba kan ti o o n bebe ninu awonran kan pe ki won gba oun kale.
Gbigba nọmba aladani ọkọ rẹ Lẹyin ti o ba ti tẹ le gbogbo igbesẹ yii ni ajọ ẹṣọ oju popo yoo fun ọ ni nọmba ọkọ rẹ.
82 Pẹ̀lú títò lẹ́sẹẹsẹ àwọn orúkọ ti onírúurú àwọn ọmọ ìjọ tí wọ́n ti ṣe ara wọn ní ọ̀kan pẹ̀lú ìjọ lẹ́hìn àpéjọpọ̀ tí ó kẹ́hìn; tàbí fífi ránṣẹ́ láti ọwọ́ àwọn àlùfáà kan; kí títò lẹ́sẹẹsẹ dáradára kan ti gbogbo awọn orúkọ inú ìjọ pátápátá baà le wà ní pípamọ́ ńinú ìwé kan lati ọwọ́ ọ̀kan nínú àwọn alàgbà, ẹnikẹ́ni tí àwọn alàgbà yókù lè yàn láti àkókò dé àkókò;
Ninu ifọrọwerọ pẹlu BBC News Yoruba, agbẹnusọ fun Agboọla Ajayi, ọgbẹni Ọkẹowo ni lẹyin ti esi ibo abẹle ẹgbẹ oṣelu ni ipinlẹ Ondo ti waye ti Jẹgẹdẹ si ti wọle lo ti gba fun Ọlọrun to si ti kii ku orire.
Bẹ́ẹ̀ náà sì ni àgbàlá ti inú ilé OLUWA ati yàrá àbáwọlé.
Laasigbo laarin awon olopaa, awon oloja ati awon awako ti n fi igba pupo waye nilu naa, amo isele je eyi ti o buru jai.
nítorí bí mo bá pẹ́ kí n tó wá, kí o lè mọ̀ bí ó ti yẹ láti darí ètò ilé Ọlọrun, èyí tíí ṣe ìjọ Ọlọrun alààyè, òpó ati ààbò òtítọ́.
Àmó oba fi èpè lé e pé yàjóyàjó nikú eni tí ó bá yí òrò òun padà yóòjé.
Lasiko ti ikọ iroyin BBC Yoruba ṣe abẹwo si ọgba ile ẹkọ giga naa lowurọ ọjọ aje, ẹnu ọna abawọle ile ẹkọ naa wa ni ṣiṣi silẹ, bẹẹ si ni ọgọrọ awọn akẹkọ n rin sokesodo, bo tilẹ jẹ wipe ko si olukọ kankan ninu awọn yara ikẹkọ to n bẹ ninu ọgba ile ẹkọ naa.
Ará, mo fẹ́ kí ẹ mọ ohun àṣírí yìí, kí ẹ má baà ro ara yín jù bí ó ti yẹ lọ.
Láti ìgbà náà, kò tíì sí wolii mìíràn ní ilẹ̀ Israẹli tí ó dàbí Mose, ẹni tí Ọlọrun bá sọ̀rọ̀ lojukooju.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Iraq, Palestine wà nínú orílẹ̀-èdè mẹ́wàá tí ìwádìí BBC ti wáyé Atẹjade ti ijọba fi sita bayii ti yanana ọrọ naa pé ipinlẹ mejila pere lo tii fi ifẹ han pe awọn faramọ igbesẹ ijọba naa.
N óo rán àwọn agbọ́n ńlá ṣáájú yín, tí yóo lé àwọn ará Hifi ati àwọn ará Kenaani ati àwọn ará Hiti jáde fún yín.
56k Ẹgbẹ alagbata epo aladani lorileede Naijiria IPMAN ti paṣẹ ki awọn ọmọ ẹgbẹ wọn jakejado Naijiria maa ta jala epo kan ni naira mejilelọgọjọ.
Mo rò pé kò bójú mu kí á fi ẹlẹ́wọ̀n ranṣẹ láìsọ ẹ̀sùn tí a fi kàn án.
Iwe iroyin ilu naa sọ pe arakunrin naa fẹ lọ fẹ ẹlomiran ni o ṣe paa.
Ọkan lara awọn iroyin to mi ilu titi ni ọsẹ yii ni Minisita fun ọrọ iṣẹ ati ibugbe, Babajide Fashola sọ wi pe oun ri fọnran to safihan ikọlu to ṣẹlẹ ni Lekki nigba ti awọn n kaakiri ibi iṣẹlẹ naa.
Ayaba Faṣiti pàápàá se àsè fún àwọn obinrin ní ààfin ọba Ahasu-erusi.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ọ̀rọ̀ Oduduwa Republic gbọgbọ́n, kìí ṣe ọ́rọ̀ Igboho nìkan - Gani Adams Ìfẹ́ Yorùbá ló mú mi fi ẹ̀mí wéwu láti kojú ajínigbé ní Kishi - Sunday Igboho Kò bójúmu kí owó epo ní Nàíjíríà dínwó ju ti Saudi lọ - Buhari Ẹ gbà mí o!
ni egbe won gba lati dibo fun gege bi aare orile ede Naijiria lasiko eto idibo
Bákan náà, e ṣọ́ra fún fífẹ́ àtẹ̀gùn láti paná àbẹ́là lórí àkàrà oyinbo (cakes) ọjọ́ ìbí.
- Amina Zakari Dino Melaye ṣubú lulẹ̀, ó d'èrò ilé ìwòsàn Pásítọ̀ wọ gàù lórí ìran ikú, ọ̀dọ́ musulumi ya wọ ṣọ́ọ̀ṣì Ọ̀sẹ̀ méjì péré la fẹ́ kí iṣẹ́ reluwe Eko sí Ibadan parí - Amaechi Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Mọrèmi: Ọọ̀ni ní láìsi Mọrèmi, kò leè sí ilẹ̀ Yorùbá Buhari, Atiku, Ezekwesili, Sowore àti àwọn méjìléláàdọ́rin míràqn ló ń dije dupò ààrẹ Nàìjíríà.
Bakan naa ni wọn pe ijọba apapọ lati tete muṣẹ ṣe lori atunṣe si iwe-ofin fun idasilẹ ile-iṣẹ ọlọpaa ipinlẹ fun aabo ilu ni kikun.
Aṣọle iko agbabọọlu Arsenal Petr Cech
Ǹjẹ́ Titu rẹ yín jẹ bí?
SSANU, NASU yóò bẹ̀rẹ̀ ìyanṣẹ́lódì lọ́jọ́ Ajé láti fa ìjọba létí
Ẹka ẹkunrẹrẹ rẹ nibi Ọjọ 25, Osu Keji Ile-ise omoogun ofurufu lorilẹede Naijiria sọwipe awọn ti ran ikọ awọn lati lọ wa awọn ọmọ naa lawari.
Ọwọ́ rẹ̀ dàbí ọ̀pá wúrà,tí a to ohun ọ̀ṣọ́ sí lára.
Afenifere: Ìgbà wo ni Bola Tinubu di ọmọ ẹgbẹ Afenifere?
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Fayẹmi bá BBC sọ̀rọ̀ ní kété tó di gómìnà Ekiti Gomina Fayemi yoo gbajọba lọwọ Gomina ipinlẹ Zamfara Abdul-aziz Yari Abubakar ti ijọba rẹ tan lalẹ Ọjọru.
Àwọn ìbejì mi kò le rìn dáadáa nítorí ọgbẹ́ tí wọ́n dá sí wọn lára ní ìgbèkùn - Akeugbagold Àfi ìgbà tí mo bọ́ sọ́wọ́ ọ̀tá mí nínú ìrìnàjò ìfẹ́- Roshan Mú N22.
Funke, toun naa n kopa ninu sinima oloyinbo ati Yoruba si ni wọn gbe ami ẹyẹ oserebinrin to danagajia julọ, ninu ere apanilẹrin fun.
kí ó sì mú ẹbọ ìmúkúrò ẹ̀ṣẹ̀ rẹ̀ wá sọ́dọ̀ OLUWA fún ẹ̀ṣẹ̀ tí ó dá.
Ọmọ ilẹ kaarọ oojire ni ọkunrin to da ara yii, orukọ rẹ a si maa jẹ Moshood Ọlabisi Adisa Ajala, ti gbogbo eeyan mọ si Ajala Travels.
Ninu gbogbo orílẹ̀-èdè, ẹ̀yin ni ẹ kéré jùlọ.
Àwọn ẹlẹ́ṣin kan ń bọ̀, wọ́n fẹ̀gbẹ́kẹ̀gbẹ́ ní meji-meji!
Àlàyé tó fí síta rèé O ní àwọn isòrò ẹṣẹ̀ tó ń yojú yìí ń kan òun lóminú lásìkò tí ó yẹ ki òun maa gbádún ayé òun nínú eré bọ́ọ̀lù Mó n gbá bọ́ọ̀lù fún Manchester United, mo sì ń sojú ẹgbẹ́ agbábọ́ọ̀lù England gẹ́gẹ́ bíi balọ́gun ikọ̀ agbábọ́ọ̀lù náà, mo sì ti mọ ijọ synagogue láti kékeré.
fun ipinle naa, ọjọgbọn Sebastian Maimako kede abajade esi idibo naa pe, gomina
’ Ṣugbọn ẹranko burúkú kan tí ó wà ní Lẹbanoni ń kọjá lọ, ó sì tẹ ẹ̀gún náà mọ́lẹ̀.
E̩nì kò̩ò̩kan ló ní è̩tó̩ láti gba iye owó tí ó dó̩gba fún irú is̩é̩ kan náà, láìsí ìyàsó̩tò̩ kankan.
Sugbọn bayii, inu fẹ́lẹ́ ti ti ebi kọ ni awọn eeyan n fẹ ninu eyi ti ọpọ ọkunrin si maa n gba ibudo ere idaraya lọ lati mọ bi wọn se ri, ki wọn si din ọra ikun wọn ku.
O wa yan pe, lootọ ni oun n sun ita tabi inu ọkọ mọju, sugbọn oun ko huwa ọmọ buruku ri, oun kii jale, mu igbo, mu siga tabi ọti, ti oun kii si ṣe ipanle.
Igbimó naa yoo mojuto ọrọ naa ki wọn si gbe lọ siwaju ileeṣẹ eto idajọ fun eto to tọ labẹ ofin.
Pín gbogbo ìkógun náà sí meji, kí apákan jẹ́ ti àwọn tí wọ́n lọ sójú ogun, kí apá keji sì jẹ́ ti àwọn ọmọ Israẹli yòókù.
Pẹlu iye awọn eeyan tuntun yii, o ti pe 61,440 eeyan ti arun ọhun ti kọlu ni Naijiria, awọn 1,125 ti dagbere faye, nigba ti awọn 56,611 ti moribọ.
Ijọba gbe igbesẹ ọhun lẹyin idarudapọ to waye laarin awọn obi to ni ọmọ nile ẹkọ girama ati ijọba ipinlẹ Ogun lọjọ Aiku.
"Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ààbọ̀ ìpàdé Bùhárí rèé pẹ̀lú Trump Ìpinnu Buhari lóri lẹ́tà Ọbásanjó Àjọ CAN bẹ̀rẹ̀ ìwọ́de L'òndó Oloye Ayo Adebanjo so pé, ""Ka to gb'ominira, awọn Ọba kíi lọwọ ninu ọrọ̀ idibo."
Bakan naa lo niBuhari gbọdọ wa nnkan ṣe si aṣa gbigbe owo ina ti araalu ko lo wa ka wọn mọle fun sisan.
Ṣugbọn ọlọ́rọ̀ náà ní, ‘Ó tì, Abrahamu, Baba!
Ó sọ fún Adamu, pé,“Nítorí pé o gba ohun tí aya rẹ wí fún ọ,o sì jẹ ninu èso igi tí mo pàṣẹ fún ọ pé o kò gbọdọ̀ jẹ,mo fi ilẹ̀ gégùn-ún títí lae nítorí rẹ.
A ó ṣe àkíyèsí pé èyí yàtọ̀ sí pípòòyì, ijó ọlọ́bọ̀ùnbọ̀un, dídún tàbí fífò tata tàbí jíjuwó alákàn sí ara wọn.
6: Ori Mi Ewo Ninse / Majority Boy (1975) Vol.
Ó kó gbogbo ọ̀rá náà lé orí igẹ̀ ẹran náà; ó sun ún lórí pẹpẹ.
Rìn káàkiri kí o wo bí gbogbo ilẹ̀ ti di ahoro,wo bí ọ̀tá ti ba gbogbo nǹkan jẹ́ ninu ibi mímọ́ rẹ.
Ẹyin ọ rẹyin ni wọn ri oku wọn, ti wọn si ti sin wọn.
Aarẹ orilẹede Ghana ni igbesẹ to loorin ti n lọ lati wa ojuutu ẹlẹkunjẹkun si iwa ipa ati ikọlu awọn darandaran nibẹ Bakannaa ni aarẹ orilẹede Ghana tun kede wipe ayipada ti n de ba ọrọ aje oril€de naa pẹlu afikun pe ni opin ọdun yii ni owo iranwọ ti orilẹede naa gba lọwọ ajọ isuna agbaye, IMF yoo pari ti o si ni igbesẹ to yanranti ti wa nikalẹ lati rii daju wipe orilẹede naa ko maa sa tọ awọn orilẹede ati ajọ okeere mọ fun iranwọ.
Ninu ifọrọwanilẹnuwo pẹlu BBC Yoruba, agbẹnusọ ileeṣẹ naa, Sunday James sọ pe awọn ko ṣẹṣẹ maa ṣe bẹẹ amọ awọn eeyan ni ko lo anfani naa.
Ẹgbẹ́ Al-Qaeda fẹ́ da ìbò Mali rú Lagbaja da ìlù bolẹ̀ nílú Abuja Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí 2 sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 2:23 Fídíò, Water Generator: Ó leè ṣiṣẹ fún wákàtí mẹfà, kó tó sinmi, Duration 2,2310 Òkùdu 2020 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Tantra: Ìlànà yìí ló ń kọ́ wa láti fi èémí àti ìṣẹ́po ara gbádùn ìbálòpọ̀ 15 Ẹrẹ̀nà 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 24 Ẹrẹ̀nà 2020 Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Tantra: Ìlànà yìí ló ń kọ́ wa láti fi èémí àti ìṣẹ́po ara gbádùn ìbálòpọ̀ Christiana, tii se oludanilẹkọ nipa ibalopọ lorilẹede Singapore, to jẹ ẹni ọgbọn ọdun, ni pẹlu ilana idanilẹkọ Tantra, a lee mu ara wa debi to ga julọ ninu ibalopọ.
Bakan naa ni iyawo babalawo yii, Owomobi jẹrii pe inu ile awọn ni ọmọde naa wa titi di aajin, ti ọkọ oun kan an nipa fun oun lati pọn ọmọ naa sẹyin lọ sile afurasi keji, Gabriel Olabirinjo.
Ó tún wí fún mi pé, “Àwọn omi tí o rí níbi tí aṣẹ́wó náà ti jókòó ni àwọn eniyan ati gbogbo orílẹ̀-èdè.
Won fi mule pe, ipinnu erongba ohun ni lati fikun  saa aare Pierre Nkurunziza lati wa lori aleefa fun saa odun meji miiran si.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Delta Building Colapse: Ilé wó lu ọ̀gọ̀ọ̀rọ̀ èèyàn ní Abraka 20 Agẹmo 2019 Oríṣun àwòrán, EPA Àkọlé àwòrán, Ile wiwo Iroyin to n tẹ wa lọwọ ni wi pe ile alaja mẹta kan ti wọn n kọ lọwọ ni ijọba ibilẹ Ethiope East, ipinlẹ Delta ti wo lulẹ.
Ọrọ ti maa n pẹju ti awọn eniyan buruku laarin ilu ba gba agbara.
Nínú oṣù kíní alákoso àgbà ilé iṣẹ́ náà Vikas Kapoor sọ fun BBC pé níwọn ǹkan ti òun mọ, kò si Melecine nínú rẹ̀ Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Gbà mí lọ́wọ́ idà ìkà,gbà mí lọ́wọ́ àwọn àjèjì,tí ẹnu wọ́n kún fún irọ́,tí ọwọ́ ọ̀tún wọn sì kún fún èké.
Àkọlé àwòrán, O gbẹnu tan fun egungun to n lo irukẹrẹ bii ọba Àkọlé àwòrán, Ibadi egungun yii dara nijo Àkọlé àwòrán, Ọdọ lo n gbe egungun ni abi agba ?
Aṣọ ọ̀fọ̀ ni wọn yóo wọ̀ ní gbogbo àkókò náà.
Ohun to se pataki ni pe kẹ sisẹ, isẹ sise ati adura gbigba gbọdọ lọ papọ ni.
Nígbà tí Jesu gbọ́, ó wí fún wọn pé, “Àwọn tí ara wọn le kò nílò oníṣègùn bíkòṣe àwọn tí ara wọn kò dá: èmi kò wá láti pe àwọn olódodo bíkòṣe àwọn ẹlẹ́ṣẹ̀.
SERAP: Ọjọ́ méje la fún UI, AAUA lati dá owó iléẹ̀kọ́ padà
Nǹkankan tí ó burú, ninu àwọn nǹkan tí ń ṣẹlẹ̀ nílé ayé ni pé, ìpín kan náà ni gbogbo ọmọ aráyé ní, ọkàn gbogbo eniyan kún fún ibi, ìwà wèrè sì wà lọ́kàn wọn; lẹ́yìn náà, wọn a sì kú.
O ni aṣeyege pọ, kudiẹkudiẹ naa pọ to fi mọ awọn nkan aṣa wa to pọ ti a ko ti fi han fun araye ninu sinima.
Àkọ́bí Kenaani ni Sidoni, òun náà ni ó bí Heti.
Oshonaike sọ pe ''iriri naa ṣakoba fun igbeyawo mi, o si pami lara nipa nini ibalopọ, ṣugbọn mo ti n bori rẹ diẹdiẹ bayii.
Àwọn igi míì tí wọ́n bá ti gbẹ á wọ́ lulẹ̀ tí ìjì kan bá jà, tàbí tí atẹ́gùn òjò tí ó lágbára bá fẹ́ lù wọ́n.
O ni Glaucoma je arun to n ba isan oju je lagbari ni eyi to maa n di ifoju ti ko ba tete ri itoju to ye lasiko.
Nígbà tí ojú rẹ̀ wálẹ̀, ó ní, ‘Àwọn alágbàṣe baba mi tí wọn ń jẹ oúnjẹ ní àjẹṣẹ́kù kò níye.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ramadan: Sultan pàṣẹ fún àwọn mùsùlùmí láti ṣ'ọdẹ òṣùpá lónìí 3 Òkùdu 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ìtúnu àwẹ̀ leè wáyé ní ọjọ́ ìṣẹ́gun tàbí ọjọ́rú ọ̀sẹ̀ yìí Sultan ti ilu Sokoto, Alhaji Muhammad Saád Abubakar ti ni ki awọn musulumi lorilẹede Naijiria bẹrẹ si ni ṣọ oṣupa tuntun.
219 biliọnu ni ọjọ kẹtadinlogun oṣu kẹfa ọdun 2014, lati fi ṣeto ipolongo ibo gomina rẹ lọdun 2014 nipinlẹ Ekiti.
Ogagun  Benson Akinroluyo, to jẹ oga  agba fun ikọ Lafiya Dole,naaa tun gbosuba fun
Ǹjẹ́ o mọ́ pé àwọn igi máa ń bá ara wọn sọ̀rọ̀ nínú igbó?
Nitori naa, Ọjọgbọn Campbell sọ pe awọn olori to jẹ ọkunrin ti ko hu iwa bayii naa wa tawọn naa ko si ni eeyan pupọ to ti ku nipasẹ arun coronavirus yii lawọn orilẹ-ede wọn.
APC kéde ìkànì ẹ̀rọ ayélujára tuntun
Elebuibon lo sọ ọrọ yii ninu ifọrọwerọ rẹ pẹlu BBC Yoruba, lori ọrọ ti ọkan lara awọn agba ọjẹ oṣere tiata lorilẹ-ede yii, Pete Edoche sọ pe, oponu ati ọdẹ ni ọkunrin to ba n kunlẹ fun obinrin lati beere pe, ko gba ki oun lee fi ṣaya.
Kódà, àbọ ìwádìí àjọ WHO tuntun sọ pé àwọn orílẹ̀-èdè Afíríkà mẹwàá ló ni ìdá ọgọ́rún un àwọn to ni aàrun náà ni Afíríkà.
Ilana fun awọn ile sinima Oríṣun àwòrán, OTHERS Fun awọn ile sinima, wọn gbọdọ ri i daju pe eero iworan ko ju ìdá aadọta lọ lẹẹkan naa, ti wọn si gbọdọ fi ọwọ si iwe akọsilẹ nipa Covid-19.
Ẹni tí ó bá jẹ́ aláìlẹ́gàn, tí ó ní ẹyọ iyawo kan, tí àwọn ọmọ rẹ̀ jẹ́ onigbagbọ, tí ẹnìkan kò lè fi ẹ̀sùn kàn pé ó ń hùwà wọ̀bìà tabi pé ó jẹ́ alágídí.
Muyiwa Fafowora: Ìlú Eko lówó, àwọn ẹ̀gbọ́n wa ló ya ìkà Onnoghen: PDP so ìpolongo ìbò rọ̀ Mọ̀ nípa adelé adájọ́ àgbà tuntun, Ibrahim Tanko Muhammed Garba Sheu tẹsiwaju pe ijọba Naijiria lẹtọ lati gba tabi kọ amọran lori akoso ilu ti o si tọ ki awọn orileede agbaye to ku naa bọwọ fun ẹtọ yi.
Spaghetti, mílíìkì, Chivita àti Àǹkàrá sọ Rabiu dèrò ẹ̀wọn ni Eko Gomina ipinlẹ Ọyọ naa fikun un wi pe idi ti oun fi jẹ ki awọn eniyan mọ iye owo ti oun gba gẹgẹ bi owo oṣu ni lati mu ileri ti oun ṣe wi pe awọn eniyan yoo ma a mọ bi oun ṣe n na owo ijọba ipinlẹ naa.
O le pẹ titi ṣugbọn lọjọ kan asiri yoo pada tu Yago fun ifẹkufẹ oju gẹgẹ bi ọdọ.
5M El-Zakzaky Ni bayii, wọn ti yan Ọlamide George lati ẹkun idibo ti ariwa Akurẹ North gẹgẹ bii olori ile aṣofin naa nigba ti Abimbọla Fajolu lati ẹkun idibo Oluji / Okeigbo si ipo igba keji.
naa, ni won ko  tun jẹ ki awon eniyan kọja
Kódà kí n tó sọ ọ̀rọ̀ jáde lẹ́nu,OLUWA, o ti mọ gbogbo nǹkan tí mo fẹ́ sọ patapata.
Gomina Ganduje ran kọmisọna fun ọrọ to jẹ mọ iroyin ni ipinlẹ naa, Muhammad Garba lati lọ soju rẹ pẹlu lẹta ti ọga rẹ Ganduje kọ.
OLUWA ní,“Ẹ gbọ́ igbe kan láti Babiloni!
Nigba ti awọn ọmọ ogun wa gbiyanju lati kọja,niṣe ni wọn kagidi bori ti wọn si bẹrẹ si ni sọ oko ati awọn nkan ija oloro lu wa.
Ọpẹ́lọpẹ́ irin tí wọ́n fi dì í pọ̀, kò bá fọ́n ká pátápátá ni.
" Oluwo wá ṣe sadankata si ìjọba Ìpínlẹ̀ Osun fun bo ṣe kogiri mọ igbogun tí àrùn Covid-19, ó si tún woye pe, ẹsẹ̀ lo fà ajakalẹ àrùn yìí.
' Amọsa alamojuto ASUU ni ẹkun iwọ oorun gusu Naijiria, Ọmọwe Alex Odili se apejuwe awọn olukọni to wa ni ẹgbẹ tuntun naa gẹgẹbii awọn ti ko ni ẹkọ tio rọ mọ ẹka imọ iwe.
Wọ́n bá fi okùn fa Jeremaya jáde kúrò ninu kànga.
Buhari kìí ṣe adùn-ń-bárìn"" Wo àwòrán ayẹyẹ ọjọ́ ìbí Olúbàdàn tilẹ̀ Ibàdàn Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Wọ́n rò pé mo ya wèrè ni Saudi lẹ́yìn ikú ọkọ mi Bó tilẹ̀ jẹ́ pé àwọn míràn ní ìgbàgbọ pé ènìyàn kò lè mú ki òjò rọ tàbí dí òjò lọ́wọ́ tí àwọn àjọ tó ń ri sí bí ojú ọjọ́ ṣe rí (NIMET) pẹ̀lú sọ pé kò sí eni tó lè dán irú ẹ wò."
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Àwọn ọmọ Nàíjíríà ló ṣiṣẹ́ takò mí ní Ireland kí ń má baà wọlé ìbò Káńsélọ̀ - Yemi Adenuga Láti January lọ, gbogbo ẹni tó bá ra ọjà lórí ayélujára yóò máa sanwó orí - FIRS Owó dé!
Oríṣun àwòrán, PIUS UTOMI EKPEI Oun nikan ṣi lo ti i raaye wọ ileewe giga Community College lai pe ọdun akọkọ to de Amẹrika, laarin awọn akẹkọbinrin Chibok mẹwaa ti agbẹjọro kan to jẹ ajafẹtọ ọmọniyan l'agbaye, Emaanuel Ogebe, ran lọ sileewe nilẹ okeere.
Gege bi atejade kan to wa lati ile-ise abenugan ile igbimo asofin  pe awon igbimo asofin ko ni lee pada wọle wa jokoo
Ni Russia: Ko buruju ti wọn ba fi omi ara ẹja to n sere ibalopọ se ọbẹ ti wọn yoo jẹ.
Awon ara South Korea ni ipade naa ye ko bi eso rere nitori pe iko mejeeji ti fenuko lori awon ohun ti yoo bi ijiroro lojo iwaju.
Nítorí gbogbo ìwà ìríra yín, n óo ṣe ohun tí n kò ṣe rí si yín, tí n kò sì ní ṣe irú rẹ̀ mọ́ lae.
Ó yí wọn ká, ó sì ń tọ́jú wọn,Ó sì dáàbò bò wọ́n bí ẹyin ojú rẹ̀.
Lẹ́yìn náà, ààlà náà yípo lọ sí Rama; ó dé ìlú olódi ti Tire, lẹ́yìn náà, ó yípo lọ sí Hosa, ó sì pin sí etíkun.
OLUWA Ọlọrun tìkalárarẹ̀ ni yóo máa ṣiwaju rẹ lọ, yóo sì máa wà pẹlu rẹ.
Igi Lẹbanoni ni Solomoni fi ṣe ìtẹ́ rẹ̀.
" Bakan naa lo tun rọ awọn obi lati fọwọsowọpọ pẹlu awọn olukọ, nipa sise afihan ifẹ wọn si ede abinibi, aṣa ati iṣe ilẹ Kaarọ Oojire lasiko ti awọn ọmọ wọn ba wa nile tabi nile ẹkọ laisi ifiyajẹni.
Ibà náà sì fi í sílẹ̀, ó bá bẹ̀rẹ̀ sí tọ́jú oúnjẹ fún wọn.
Ẹni to bori: Nigeria Morocco vs Kenya.
Oríṣun àwòrán, others A fí ara mọ́ ìdájọ́ ikú Sharia tó tọ́ sí Olórin Yahaya- ẹgbẹ́ Amòfin Mùsùlùmí ẹ̀ka ìpínlẹ̀ Kano Ẹgbẹ́ musulumi ti wọn jẹ amofin, ẹ́ka ti ipinlẹ̀ Kano ti ọ̀rọ̀ olorin Yahaya Sharif Aminu ti sele ti sọ̀rọ̀ lori idajọ iku naa.
 Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Baruwa Gas Explosion: Àwọn tó forí sọta ìjàmbá iná ń bẹ ìjọba láti dìde ìrànwọ́ Ẹgbẹ Majeobaje wa rọ awọn gomina nilẹ Yoruba lati gbe owo kalẹ fun ikọ Amotekun, ki wọn si gba osisẹ to to sibẹ, ki wọn lee wa laarin ilu ati igberiko gbogbo."
O sọ pe ọmọ Naijiria lẹtọọ labẹ ofin lati fẹhonu wọn han lori ohun ti ko ba tẹ wọn lọrun.
m ni ojú mi déédé fọ́ níbi tí mo ti ń darí ọkọ̀ ni Ọrẹgun Ikẹja -LASTMA Yesufa Inú mi dùn pé ẹni tó gbà ìjọba lọ́wọ́ mi ń san gbèsè tí mo fi kalẹ - Aregbesola Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Abuja ti yan asofin Ovie Omo-Agege gege bi igbakeji abenugan ile igbimo asofin
Oríṣun àwòrán, Lizzy anjorin/instagram screenshot Sugbọn ṣa, iyawo ẹlẹsẹ osun ọhun ti fun awọn to n gbe iroyin naa jade ni esi.
Ọpọlọpọ àwọn Alaboyin Naijiria maa n fẹ bimọ sile ijọsin tabi ibudo adura wọn nitori awọn miran gbagbọ pe ogun ti inu ẹmi a di ṣíṣẹ́ lataari adura ti wọn ba gba si Olorun wọn.
"Ẹka ẹkunrẹrẹ rẹ nibi Ọjọ 23, Osu Keji Aarẹ Muhammadu Buhari pe ijinigbe awọn ọmọbinrin Dapchi ni ""isẹlẹ pajawiri gbogboogbo""."
Dokita fi ye eto BBC ''La a han mi'' pé abẹrẹ ajẹsara maa n dena Hepatitis A ati B ṣugbọn ko si eyi to le dena C Bakan naa ni Dokita ṣalaye awọn ọna ti eeyan fi le ko arun jẹdọjẹdọ yii lawujọ.
Aworan kan ti ile-ise Television Uganda safihan omo ile-igbimo kan Onesmus Twinamasiko, ti o n soju fun ekun Bugangaiz ti o wa ni apa ila-orun, iwo-orun orile-ede Uganda so pe, awon obinrin nilo ibawi egba latodo oko won, ni iyanju ati ko won lekoo.
kani wipe o ti bẹrẹ isẹ lati Odun 1933, o ba ti maa gba iye owo wọn bayii iye owo sẹnatọ kan losu le ra apo irẹsi toto 866, nigbati iye owo osu rẹ yoo ra apo irẹsi mẹwa To o ba n gba ₦200,000: Yoo gba sẹnatọ ni wakati 11 ati isẹju 14 lati pa iye owo to n pa losu.
Lára ilẹ̀ mímọ́ náà, ẹ óo wọn apá kan tí òòró rẹ̀ yóo jẹ́ ọ̀kẹ́ kan ati ẹẹdẹgbaata (25,000) igbọnwọ (kilomita 12½), tí ìbú rẹ̀ yóo sì jẹ́ ẹgbaarun (10,000) igbọnwọ (kilomita 10), níbẹ̀ ni ilé mímọ́ yóo wà, yóo jẹ́ ibi mímọ́ jùlọ.
Ẹ wo báwọn òṣèré tíátà kan yóò ṣe rí lọ́jọ́ ogbó Mercy Aigbe bu èpè jó àwọn tó ní gómìnà kan ló ra ilé fún-un Ẹ padà sílé èyin ọmọ wa tó n ṣiṣẹ́ darandaran - NEF ti Fulani Ẹyẹ j’ẹyẹ lọ!
Oríṣun àwòrán, Getty Images Ajalu inu idile O ṣe ni laanu fun Biden pe ọkan lara ohun to fi jk ko da bii pe o fẹ jina diẹ si ọpọ oloṣelu ni pe ohun kan to kan gbogbo eeyan ti sun gbọngbọn kan oun naa ri - iku.
Ikọ̀ aláàbò Nàìjìríà dojú kọ Shiite ICC pari iwadi lori pipa Shiites, IPOB Lọjọ ajé ni ikọlu wáyé láàrin àwọn ọmọ ẹgbẹ́ Shi'ite àti ọlọ́paa, ti ọpọ èèyàn sí farapa nínú ìṣẹlẹ náà.
Ilé ẹjọ́ fún Elzakzaky àti ìyàwó ní ẹ̀tọ́ sí ètò ìwòsàn Èmi kò ní kí Shiite má ṣe ẹ̀sìn won o -Muhammadu Buhari Ẹ ṣọ́ra fún ìròyìn ẹlẹ́jẹ̀ lórí ètò ààbò - Ọlọ́pàá Àgùnbánirọ̀ akọ̀ròyìn Channels náà ti dágbére fáyé látààrí ìkọlù Shiite l'Abuja Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Shiite: Ẹ̀mí àti ara wa kọ ohun tí ìjọba ń ṣe sìwa láti 2015 Ọrọ aabo ti peleke sii ni olu ilu ipinlẹ naa ṣaaju igbẹjọ naa ninu eyi to si ti mu ẹmi ọlọpaa kan ati akọroyin lọ.
Nítorí náà, ẹ jẹ́ kí á sa gbogbo ipá wa láti wọ inú ìsinmi náà, kí ẹnikẹ́ni má tẹ̀lé àpẹẹrẹ burúkú ati àìgbọràn bíi ti àwọn tí à ń sọ̀rọ̀ wọn.
” Ọkunrin yìí lù ú, lílù náà pọ̀ tóbẹ́ẹ̀ tí ó fi pa á lára.
Ijinigbe/Ipaniyan Pẹlu pẹlu ilọsiwaju to waye lka abo ni ipinlẹ Eko, ọdun 2016 jẹ ọdun manigbagbe nipa ijinigbe.
Ṣugbọn bí ọkọ rẹ̀ kò bá lòdì sí ẹ̀jẹ́ náà ní ọjọ́ tí ó gbọ́, ó níláti san gbogbo ẹ̀jẹ́ rẹ̀ nítorí pé ọkọ rẹ̀ kò lòdì sí i.
Pẹlu iye awọn eeyan tuntun yii, o ti le ni ẹgbẹrun mẹrinlelaadọta ati ojilelugba ati meje, 54,463 eeyan to ti larun naa lorilẹede Naijiria bayii.
Ohunkohun tí ó bá kù ninu ẹran ati burẹdi náà, ẹ dáná sun ún.
Gẹgẹ bi Ebenezer Obey ti ṣalaye, lẹyin ọpọ ẹbẹ ni ọkunrin oyinbo to ni ileeṣẹ rẹkọọdi naa pada gba oun laaye, lati wa kọrin.
Coronavirus ti di ara wa, kò le è kúrò mọ láéláé - WHO Àfi ìgbà tí mo bọ́ sọ́wọ́ ọ̀tá mí nínú ìrìnàjò ìfẹ́- Roshan Kínni ife ẹ̀yẹ ti Tiger Woods gbà ní Augusta fi yàtọ́?
" MC Oluomo, ẹni to ni ẹgbẹ awakọ ero kii lọwọ ninu eto iselu, wa rọ awọn ọmọ ita lati mase ro ara wọn pin, kí wọn mase jale amọ ki wọn lo ọpọlọ wọn lati ṣíṣẹ, ki wọn si fi igbe aye toun ṣe arikọgbọn.
N óo sọ ọ́ di ibùgbé òòrẹ̀, adágún omi yóo wà káàkiri inú rẹ, n óo sì fi ọwọ̀ ìparun gbá a.
Sunday Igboho yarí, ó fohùn ránsẹ́ sáwọn èèyàn tó ń pẹ̀gàn rẹ̀ Ọwọ́ tẹ́ àwọn ọkùnrin Fulani mẹ́ta tí wọ́n jí Màálù méjì kó ní Ogbomọṣọ- Àjọ NSCDC Irọ́ ni o, kò sí ẹ̀rí pé Hydroxychloroquine leè kojú àrùn Coronavirus- Ẹgbẹ́ àwọn adarí ilé ìwòsàn ní Naijiria Oríṣun àwòrán, @tokstarr Ṣé lóòótọ́ ni Amcon gba ilé Toke Makinwa ti wọn ní bàbá olówó rà á fun?
bódìjà ni àdúgbò kan ní ìlú Ìbàdàn , ní ìpínlẹ ̀ Ọ ̀ yọ ́ .
Ní òru, òun ati àwọn olórí ogun rẹ̀ kọlu àwọn ará Edomu tí wọ́n yí wọn ká, wọ́n sì sá àsálà, ṣugbọn àwọn ọmọ ogun rẹ̀ sá pada sí ilé wọn.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Risikat, ìyá àwọn ọmọ olójú búlù tí bẹ̀rẹ̀ sí ní kọ́sẹ́ aṣojú lóge Àwọn ọ̀daràn tó jí ìbejì ọmọ Akeugbagold kó ti fojú ba ilé ẹjọ́ lòníì Àjọ ECOWAS yan Aàrẹ Ghana, Nana Akufo-Addo gẹgẹ bíi aàrẹ tuntun Àrà mánigbàgbé tí Baba Legba dá lágbo tíátà rèé Ẹgbẹ́ akọ̀ròyìn NUJ ìpínlẹ Oyo bà àwọn ọmọ ẹgbẹ́ tó lọ ìpàdé tí Femi Fani Kayode pè ní Ibadan wí Fìdíhẹẹ́ ní Banji Akintoye nínú YWC, lílọ ni yóò lọ - Tola Adeniyi Nigba to n fidi isẹlẹ naa mulẹ, akọwe iroyin si aya gomina, Yinka Adeniyi sisọ loju rẹ fawọn akọroyin pe, lati ipasẹ ẹgbẹ alaanu ti aya Abdulrazak da silẹ, ni eyi ti see se.
Nítorí náà OLUWA Ọlọrun sọ pé, “Wò ó!
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Helen Paul sọ idi tó fi gba orúkọ ní kékere Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Hakeem: Mo lè sọ arúgbó dí ọmọge nígbà tó bá wù mí Manchester City lo wa loke Liverpool bayii ninu idije Premier League.
Oríṣun àwòrán, Instagram/oluwoofiwoland Wo ìdí tí àwọn afọbajẹ ìlú Iwo ṣe fẹ́ kí ìjọba ìpínlẹ̀ Osun rọ Oluwo l'óyè Igbimọ ijoye mejila nilu Iwo, ipinlẹ Osun, ti kọwe si ijọba ipinlẹ naa, lati rọ Oluwo ti Iwo, Oba Abdulrasheed Akanbi, loye, fun 'awọn iwa adojutini to hu gẹgẹ bi ọba.
ni eyi ti o wa ni isinmi ranpẹ.
Ó ń tọ́ wa sọ́nà pé kí á kọ ìwà aibikita fún Ọlọrun ati ìfẹ́kúfẹ̀ẹ́ ayé sílẹ̀, kí á máa farabalẹ̀.
O yẹ ko pe ọkọ rẹ tẹ si yara ni, lati baa jiroro lori aifaraọ eto aabo naa.
Yoruba Movie Actors On Set vs Off Stage: Bí àwọn òṣèré fíìmù ṣe rí láì mura gegege
Igbakeji Aarẹ ṣalaye nibi isin naa pe Ọlọrun ti ṣetan lati mu orilẹ-ede Naijiria de ilẹ ileri.
Loju opo Instagram rẹ, ni olori Aanu ti sọrọ sita pe, ti nkankan ba ṣẹlẹ si oun lẹyin toun fi aafin silẹ, Alaafin ni ki awọn eeyan mu.
Orilẹede Amẹrika lo ni awọn ọlọla to pọju lọ pẹlu awọn olowo toto ẹgbẹta le meje (607), nigba ti orilẹede China tele won pelu olola to to okoolelọọdurun ati mẹrin (324), nigba ti Ilẹ Gẹẹsi si ni ọlọla mejilelaadọrun.
Philomina nikan kọ lo ṣe magomago owo JAMB Ajọ JAMB fun osisẹ n'iwe lọ gbe'le ẹ Ẹlẹ́wọ̀n gba máákì 248 ni ìdánwò Jamb JAMB: Ẹ̀dínwó míràn ṣì leè wáyé lórí owó fọ́ọ̀mù ìdánwò Ọgbà ẹ̀wọ̀n ni mo ti s‘orí re - Ẹlẹ́wọ̀n Bakan naa ni adari ajọ JAMB fun Naijiria ni ko si ikọlura ninu ọjọ idanwo UTME ati idanwo iwe mẹwaa lọdun 2019 rara.
Idibo gboogbo ọdun 2011 lorilẹ-ede Naijiria ni Shekarau ti dije fun ipo aarẹ, bakan naa lo si ti jẹ gomina ipinlẹ Kano ri.
Makinde júwe ilé fún Kọmíṣọ́ná iṣẹ́ òde, ó ṣe pàsípàrọ̀ àwọn kọmíṣọ́nà méjì míì Ẹgbẹ́ àwọn awakọ̀ epo rọ̀bì NUPENG so ìyanṣẹ́lódì tí wọ́n gùnlé l'Eko rọ̀ Ìdí rèé tí igbákejì Gómìnà Ondo Agboola Ajayi tún ṣe fi ẹgbẹ́ òṣèlú PDP sílẹ̀ Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Gun control in Nigeria: Wo ọ̀nà márùn ún tí o lè gbà dábòbò ara rẹ lọ́wọ́ ìjàmbá!
Ọmọ Naijiria hú ẹ̀sùn ìfipá bánilòpọ̀ tí wọ́n fi kan Fatoyinbo síta lẹ́yìn tó lọ sí Shiloh Ìwọ́de ńlá yóò bẹ́rẹ̀ lọ́jọ́ táwọn gómìnà bá yá ₦17trn nínú owó ìfẹ̀yìntì òṣìṣẹ́ - NLC Ìdí rèé tí mo fi yan ikọ̀ PMS rọ́pò NURTW nípìnlẹ̀ Oyo - Seyi Makinde Buhari, Olóṣèlú àtàwọn òjíṣẹ́ Ọlọ́run ló mú àjẹbánu gogò ní Nàíjíríà"" Ero maa n wọ ni nibi iworan ti wọn ti maa n wo ija Anthony Joshua ni Sagamu, koda Joshua tun ni ẹgbẹ awọn alatilẹyi n tirẹ ni Sagamu."
Nibayii, ọwọ ti tẹ baba rẹ gẹgẹ bi atẹjade ọhun ṣe sọ.
A ṣi n ṣe akojọpọ iroyin naa, ẹ ma tele wa kalọ lori ikanni yi fun ẹkunrẹrẹ.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ sí: NYSC ko awọn agunbanirọ kuro nileewe l'Ọsun Kílódé tíleeṣẹ ààrẹ ń fẹ́ káwọn aṣòfin pada sile?
Giadom ni ileejọ to kọkọ yọ Adam Oshiomole kuro nipo, fi lede wi pe oun gẹgẹ bi Akọwe ẹgbẹ ni ki o jẹ adele alaga titi wọn yoo fi yan alaga miran.
N kò sọ èyí nítorí mo ṣe aláìní, nítorí mo ti kọ́ láti máa ní ìtẹ́lọ́rùn ní ipòkípò tí mo bá wà.
” Lẹ́yìn náà odò pín sí meji, Eliṣa bá kọjá sí òdìkejì.
Odunlade Adekola Gbajugbaja oṣere Odunlade Adekola fi fọto ara rẹ ati ti olootu rẹ, Mercy Aigbe sori oju opo Instagram nibi tawọn mejeeji ti rẹrin muṣẹ.
A ti ri i pe ohun to n se ọmọ ẹgbẹ  kọọkan yato si ara wọn, sugbon wọn ti setan lati jiroro lori ohun to n dun wọn lokan , ki isoro naa si yanju.
” Wọ́n lọ pàdé rẹ̀, wọ́n wólẹ̀ níwájú rẹ̀, 
Ewe, gbogbo apapo omo ile igbimo ohun lo fọwọ si pe ki ijọba
Obey padà fi ẹgbẹ́ Fatai silẹ pẹlu awọn ọmọ ẹgbẹ́ mẹfa míì lọdun 1963.
Wo bí bàbá ẹni ọdún 67 yóò ṣe tún lo ọdún 25 ayé rẹ̀ lẹ́wọ̀n O bere fun idajọ ododo ati iya to tọ fun awọn to pa ọmọ rẹ, nitori olu ọmọ ni ọmọ naa, ati wi pe iya naa ko gbọdọ jẹ oun gbe.
Fásitì Ghana lé olùkọ́ méjì tí àṣírí wọ́n tú lórí ẹ̀sùn ìbálòpọ̀ lọlé Ṣé lóòtọ́ ni Lateef Adedimeji àti Adebimpe Oyebade ṣe ìgbéyàwó?
PDP: Ẹní ṣe nǹkan ètùfù ní kíyèsí ẹ̀hìnkùlé, ọmọ ẹgbẹ́ wà kò hùwà àìtọ́ lásìkò ìdìbò Agbẹnusọ fun ajọ EFCC, Tony Orilade, fi idi iroyin naa mulẹ fun BBC News Yoruba.
"'Ìbọn dún láàfin Ọ̀ọ̀ni ilé ifẹ̀ lóòtọ́, ṣùgbọ́n kò séwù' Àwọn ìbejì Akeugbagold kò le rìn dáadáa mọ́ lẹ́yìn tí wọ́n dáwọn padà Arákùnrin tó jí Ese Oruru gbé ti rí ẹ̀wọ̀n ọdún 26 he Àfi ìgbà tí mo bọ́ sọ́wọ́ ọ̀tá mí nínú ìrìnàjò ìfẹ́- Roshan O fi kun pe ""Awọn eeyan na n kuro ni ilu Eko ni, a ko mọ ibi gan ti wọn lọ, boya ipinlẹ Ogun ni wọn lọ tabi Oyo, a ko lee sọ, ṣugbọn ohun ti a mọ ni pe wọn n rinrin ajo kuro ni Eko ni."
Ìṣẹ̀lẹ̀ Èkó: Aáwọ̀ Ọbàkan sọ ilé di áláwọ̀ méjì Ìfẹ̀hónúhàn àwọn aláboyún ní ìpínlẹ̀ Òǹdó Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí kan sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
Wọn óo máa sáré, agara kò ní dá wọn;wọn óo máa rìn, kò sì ní rẹ̀ wọ́n.
Nígbà tí àwọn eniyan kẹ́gàn rẹ̀, kò désì pada; wọ́n jẹ ẹ́ níyà, kò ṣe ìlérí ẹ̀san, ṣugbọn ó fi ọ̀ràn rẹ̀ lé Onídàájọ́ òdodo lọ́wọ́.
A óo lé àwọn ọ̀tá mi padaní ọjọ́ tí mo bá ké pè ọ́.
N óo fi ojurere wò wọ́n, n óo kó wọn pada wá sí ilẹ̀ yìí.
Ẹrú, ẹlẹgbẹ́ rẹ̀ bá dọ̀bálẹ̀, ó ń bẹ̀ ẹ́ pé, ‘Ṣe sùúrù fún mi, n óo san án fún ọ.
Oríṣun àwòrán, Private via Amnesty International Àkọlé àwòrán, Aworan Zeinab ti wọn pa ni Iran Zeinab Sekaanvan, ọmọ ọdun mẹrinlelogun lati orileede Iran Awọn alaṣẹ Iran lopa Zeinab Sekaanvan lori ẹsun pe o pa ọkọ rẹ.
Nigba to n salaye bi isẹlẹ naa se waye, ẹnikan ti isẹlẹ naa soju rẹ ni o to awọn agbegbọn bii aadọta lo ya bo abule Zikpak, ti wọn si n yinbọn laibikita.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Mo fọ́ lójú ṣùgbọ́n mo mọ gbogbo irinṣẹ́ tí mo fi ń ṣe mọkalíìkì' Fun apẹẹrẹ, eeyan to n ṣiṣẹ laarin ẹgbẹ Peace Corpse, OPC, ẹgbẹ Fijilante tẹlẹ lo dara pọ mọ Amotẹkun kii ṣe awọn ti ko ni gbongbo kankan ninu iṣẹ aabo tẹlẹ.
Facebook: Naijiria wà lára àwọn orílẹ̀èdè tó ní ojú òpó ayédèrú
"Ìdí rèé ti Nàìjíríà fí ń gbé inú òkùnkùn Omíyalé àgbàrà ti ya ṣọ́ọ̀bù ní Niger Láìpẹ́, ará ìlú rẹ ni ọlọ́pàá tí yóò máa ṣọ́ ìlú rẹ Bianca júwe ilé fún Serena Williams nínú ìdíje l'America Bakan naa lo bu ẹnu ẹ̀tẹ́ lu iwa ki awọn ọmọ Naijiria naa maa fi oro ya oro nipa biba nkan awọn ara South Africa jẹ ni NaijiriaÀwọn ọmọ Naijiria kóju ija sí àwọn South Africa wọ́n ní ""Ó tó gẹ́""."
Coronavirus tún ti ṣe ọṣẹ́ lórí iṣẹ́ líla ojú ọ̀nà relùwe láti Eko sí Ibadan - Ìjọba àpapọ̀ Àrùn Coronavirus fa'lẹ̀ya láwọn ìletò aláwọ̀dúdú ní Amẹ́ríkà Aworan atọnisọna Iye awọn to ti ni arun naa lagbaye Sunmọ aworan Àgbáyé Orilẹede Afrika Ariwa Amẹrika Apa Latin Amẹrika ati Caribbean Ilẹ Asia Ilẹ Yuroopu Agbegbe Middle East Erekusu Oceania Fihan 69609761 iye iṣẹlẹ arun naa 1583112 Iye awọn to ku Group 4 Jọwọ ṣe atunṣe ilana ikansi ayelujara rẹ lati ri ẹkunrẹrẹ rẹ Aworan n ṣafihan awọn ti ayẹwo ti fi han lorilẹede kọọkan Orisun: Johns Hopkins University atawọn ajọ eto ilera ilu Igba ti wọn kede iṣiro awọn to nii kẹyin 11 Oṣù Ọ̀pẹ̀ 2020 13:00 WAT+3 Ẹkunrẹrẹ data Sun atẹ wa silẹ tabi oke lati ri ẹkunrẹrẹ akọsilẹ *Iye awọn to tọwọ aisan ku ni isọri eeyan ẹgbẹrun lọna ọgọrun Gbe e yẹwo: Àgbáyé Orilẹede Afrika Ariwa Amẹrika Apa Latin Amẹrika ati Caribbean Ilẹ Asia Ilẹ Yuroopu Agbegbe Middle East Erekusu Oceania Iye to ti ku Iye awọn to ku %* Apapọ awọn iṣẹlẹ arun Akọtun arun yii 0 10 100 1000 10000 ** Orilẹede Amẹrika 280985 85.
Wàhálà tí àwọn ẹgbẹ́ òkùnkùn àt'àwọn ẹgbẹ́ ìjayà míràn ń dá sílẹ̀ láwọn ọgbà fásitì Nàìjíríà Akẹkọọ ọlọdun kini fasiti Naijiria kan ni Roland jẹ nigba to darapọ mọ ẹgbẹ okunkun Buccaneers.
Ohunkohun tí ó wà, ó ti wà tẹ́lẹ̀, èyí tí yóo sì tún wà, òun pàápàá ti wà rí; Ọlọrun yóo ṣe ìwádìí gbogbo ohun tí ó ti kọjá.
Ìlú-u Gẹ̀ ẹ́ sì ni òkúta náà wà ní ẹ̀ bá igbó nlá kan.
Osinbajo, ti o se abẹwo ọgba ẹwọn naa ni ọjọru, sọ oju abẹ n'iko nibi ifilọlẹ iwe kan nipa awọn ipo ẹwọn jakejado orilẹ-ede.
Ìpínlẹ̀ Eko, Ọṣun àti Ondo yóò bẹ̀rẹ̀ sí ní lo ‘Drone’ fún ààbò Láti orí 'Our Mumu don do' sí 'Revolution Now' Bí ọdún Ọ̀ṣun Oṣogbo ṣe bẹ̀rẹ̀ rèé àti pàtàkì rẹ̀ fún Nàíjíríà Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Bẹ́ẹ̀ náà ni aṣọ títa ti àgbàlá náà, àwọn òpó rẹ̀ ati àwọn ìtẹ́lẹ̀ wọn, ati aṣọ fún ẹnu ọ̀nà àgọ́ náà, okùn rẹ̀ ati àwọn èèkàn rẹ̀, ati gbogbo ohun èlò fún ìsìn ninu àgọ́ mímọ́ náà, ati fún àgọ́ àjọ náà.
 booth ń gbé ní ilé ìtura yìí , tí ó sìlè ní ànfàní lati pa lincoln tí booth kò bá lọ sí ilé ìwòsàn .
Ojú alágbe ni wọ́n fi ń wo alága ìdúró- Ayo Oladokun Itan bi wọn si se mu Samuel Ajayi Crowther lẹru yii lo n kọ wa pe bi a ko ba jiya to to agbọ̀n, a ko lee jẹ aye to to aha.
Nítorí náà, ronupiwada kúrò ninu ohun burúkú yìí, kí o tún bẹ Oluwa kí ó dárí èrò ọkàn rẹ yìí jì ọ́.
Mo ti rò pé n óo kú lọ́jọ́ àìpé,ati pé a óo sé mi mọ́ inú ibojì,níbẹ̀ ni n óo sì ti lo ìyókù ọjọ́ ayé mi.
- Ilé ẹjọ́ ìpínlẹ̀ Ondo Ilé ìwòsàn kan rèé tó ń fi àtùpà gbẹ̀bí aláboyún Awọn eekan ilu miran naa si ti lọ ki o to kan gbajugbaja olokoowo yii.
Ẹni tí ó fi turari ṣe ẹbọ ìrántí,kò sì yàtọ̀ sí ẹni tí ó súre níwájú oriṣa.
“Bakan naa, alekun tun de ba isuna eto eko lataari ile-iwe giga fafiti mejila ti won sese se ifilole re ati owo ounje awon akeeko ile-iwe ijoba apapo, eleyi ti o le ni bilionu màrúndínlógún naira.
A si tun  fi n da awon omo orile
Jobu kàn ń la ẹnu,ó sì ń sọ̀rọ̀ lásán ni.
Wọ́n rí ninu àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ tí wọn ń fi ọwọ́ àìmọ́ jẹun, èyí ni pé, wọn kò wẹ ọwọ́ wọn gẹ́gẹ́ bí ìlànà òfin.
Ẹ wo márùn ún lára àwọn tí ilé ẹjọ́ ti yọ kúrò nípò lẹ́yìn ìdìbò ọdún 2019 Atiku kùnà!
Ẹ̀bùn ọdún tuntun tó yááyì ni ikọ̀ Amotekun - Soyinka Amotekun dé!
O ni irọ ni pẹpẹ awọn alatako n pa, àjà lo lẹrù ni ọrọ ipolongo Buhari fún idibo 2019.
OLUWA ní, “Nígbà tí ẹ bá fẹ́ ṣí lọ siwaju, kí àwọn ọmọ Lefi tú Àgọ́ Ẹ̀rí palẹ̀ kí wọ́n rù ú.
Ara awọn alabaṣiṣẹ pasitọ naa ni Walter ni asiko naa.
Aarẹ Nana Akufo-Addo n dije fun ipo naa fun igba keji, ṣugbọn o ni iṣẹ pupọ lati ṣe lati mu ki awọn eniyan o wo ọdọ̀ rẹ, bakan naa ni yoo maa fi iga-gbaga pẹlu aarẹ tẹlẹ, John Mahama t'oun naa n ṣẹju si ipo naa.
" Iwa omugọ ni ki obinrin sọ ara rẹ di ẹru ọkunrin fun Ibalopọ,"" Genevieve lo sọ bẹẹ."
Àkọlé àwòrán, Liliya ni ioṣẹ́ oun lati maa ran àwọn ọmọ yìí lọ́wọ́ tí mu iwuri ba oun la'ti ma sisẹ iranwo amuludun.
Lẹ́yìn èyí ni wọn ri àwọn àmì Ebola bii ki ẹ̀jẹ̀ máa ya, wọ́n ṣe àyẹwò àbájade àyẹwo yii ló fìdí rẹ̀ múlẹ̀ pé Ebola ni .
ati àwọn ilé tí ó kún fún àwọn nǹkan dáradára, tí kìí ṣe ẹ̀yin ni ẹ kó wọn sibẹ, ati kànga omi, tí kìí ṣe ẹ̀yin ni ẹ gbẹ́ ẹ, ati àwọn ọgbà àjàrà ati igi olifi tí kìí ṣe ẹ̀yin ni ẹ gbìn ín.
Kọmisona ìpínlẹ̀ Eko, Hakeem Odumosu sàlàyé pé ni kété ti ọ̀rọ̀ náà ti jẹyọ nínú oṣù kẹrin tí wọ́n mú ẹ̀sùn wá pé ẹnìkan fẹ́ bá Salawa Abeni lórúkọ jẹ́ ní òun ti pàṣẹ fún ẹka RRS láti ṣe ìwádìí irú ẹni bẹ́ẹ̀.
Ọmi ti wọn ta naa mu ki Athletico Madrid ṣi ni igberaga lati sọrọ pe ko si ẹgbẹ agbabọọlu to tii fi ẹyin wọn balẹ ninu ifẹsẹwọnsẹ mẹwaa ti wọn ti gba sẹyin nile wọn ni papa iṣire Blaise Matuidi.
Ó sì rí bẹ́ẹ̀ fún un, nítorí àwọn eniyan tẹ ọ̀gágun náà pa ní ẹnubodè ìlú.
Awọn balogun ẹgbẹ agbabọọlu ogun to wa ni Premier atawọn onimọ nipa ere bọọlu lo dibo lati yan de Bruyne gẹgẹ bi agbabọọlu to dantọ julọ.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ikọ̀ ìjọba Ọ̀yọ́ dé lásìkò tí kò yẹ ni wọn kò ṣe wọlé - Ẹ̀bí Ajimobi fèsì Ọ̀pọ̀ èèyàn tí kò yin Ajimobi lojú ayé, tó ń yìn-ín lẹ́yìn ikú, yóò jẹ ìyà - Oníwáàsí Ọ̀pọ̀ ìgbà ní Hushpuppi àtàwọn èèkàn PDP ti ya fọ́tò ní Dubai, EFCC ẹ wádìí wọn - APC ń lọgun Àwòrán rèé nípa àwọn gbajúmọ̀ tó ti bá Hushpuppi ṣe Mo ti bá ọmọ ọwọ́ mẹ́ta lòpọ̀ sẹ́yìn, ọmọ oṣù mẹ́ta ló ṣìkẹrin - Afurasí jẹ́wọ́ Atẹjade naa, to bọ sita ni ọjọ Keji osu Keje ọdun 2020 tun kede pe, kikida awọn ile ẹkọ tijọba fi ọwọsi, to si ni iwe ẹri pe o peju sibi idanilẹkọ nipa arun Coronavirus nikan ni yoo jẹ sisi lonii.
faa ti won fi sun atunse ofin naa siwaju.
Wọn fi igi sipirẹsi ṣe ìlẹ̀kùn meji, ekinni keji ní awẹ́ meji, awẹ́ ekinni keji sì ṣe é pàdé mọ́ ara wọn.
Adájọ gbà ìdájọ ikú lọ́wọ́ ejò Awọn agbofinro ti fọn afẹfẹ tajutaju kaakiri pẹlu ayederu ọta ibọn ki wọn le fopin si ia alo-ki-olohun-kigbe to n ṣẹlẹ lọwọ ni South Africa bayii.
Awọn ọmọ Naijiria naa ni; Esther Agbaje, Oye Owolewa ati Nnamdi Chukwuocha.
Lóòtọ́ ni ọkọ mi lù mí bí àṣọ òfì, àmọ́ gómìnà ti bá wa parí ẹ̀, ẹ máa gbàdúrà fún ìdílé mi- Dokita Ifeyinwa Mi ò kí n ṣe afẹfẹ-yẹ̀yẹ̀ lórí ayélujára nítorí pé mí ò ní dúkìá tí mó le fihàn- Ronke Oshodi-Oke Àwọn èèyàn tí bẹ̀rẹ̀ sì ní gba abẹ́rẹ́ àjẹsára fún ìdènà àrùn Coronavirus ni ilẹ̀ Gẹ̀ẹ́sì Bakan naa ni wọn tun ni ko san ọọdunrun owo Euro, lẹyin naa ni wọn tun fofin de e pe ko gbọdọ gbe ibọn fun ọdun mẹta gbako.
 wọ ́ n dáa síle \ ̣ ní ọjọ ́ ogún oṣù kẹsán ọdún 1909 pẹ ̀ lú àwọn akẹ ́ kọ ́ mẹ ́ wá ní erékùṣù Èkó , lẹ ́ gbẹ ́ tafawa balewa square .
Oríṣun àwòrán, NGSuper_Falcons Àkọlé àwòrán, Naijiria ati Cameroon koju ara wọn lorilẹede Ghana Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 3 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 5 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Ṣugbọn, ajọ INEC sọ fun BBC l'ọjọ Ẹti pe awọn ko jẹbi ẹsun ṣiṣe mago-mago lasiko eto idibo gomina to waye ni ipinlẹ Ọṣun ti ẹgbẹ oṣelu PDP fi kan awọn.
Ṣugbọn ilẹkẹ ọwọ la fi ma n da ẹni to ba ni ooṣa ẹgbẹ sile.
O soro yii nibi ipade kefa ti igbimo egbe naa se ni olu-ilu egbe won to wa niluu Abuja.
Ajafẹtọmọniyan kan ninu awọn akopa naa, Alaaji Tokunbọ Korodo gboriyin fun iṣẹ akinkanju Ile Igbimọ Aṣofin naa, paapaa akitiyan wọn lati wa ojutu si awọn aawọ ni ipinlẹ yii nigbakigba to ba waye.
Ṣugbọn wọn ti bẹ Chidozie ati arabinrin rẹ lati maa binu lẹyin ti wọn jẹwọ pe lootọ ni ọjọ ti lọ lori awọn omi ti awọn fa si lara.
O ni ọrọ oṣelu ati okoowo to gbilẹ ni saa awọn aarẹ mejeeji to jẹ ki oun to jẹ lo faa ti ọpọ lode oni fi woo pe ko si ninu itan pe aarẹ yan igbimọ oloye laikii ṣe ọba.
Ko i tii pẹ l titi ti orilẹede Naijiria tun ya owo aadọjọ miliọnu dollar lati fi san owo akanṣe iṣẹ ipese ina lorilẹede yii.
Wúrà ni tabi Tẹmpili tí a fi sọ wúrà di ohun ìyàsọ́tọ̀?
ipinle naa sugbon ti won ko lee ka nitori wahala ati bi awon ikọ ologun orile
"Oríṣun àwòrán, Getty Images Somayya ni""lootọ lo n ba mi sun lẹyin alẹ ọjọ igbeyawo wa amọ se ni mo n lera tori pe ọkan mi ko nifẹ rẹ mọ lati alẹ ọjọ to ti safihan ikorira si mi."
Ṣugbọn Oluwa dúró tì mí, ó fún mi lágbára tí mo fi waasu ìyìn rere lẹ́kùn-únrẹ́rẹ́, tí gbogbo àwọn tí kì í ṣe Juu fi gbọ́.
yoo si bẹrẹ si maa se  amulo abajade apero
Ken NnamaniAlakoso eto  Rotimi AmaechiIgbakeji Alakoso eto  ( Akanse isẹ)Asofin A.
Sugbọn tawọn obinrin ba wa ni ipo olori, wọn maa n mu iyatọ ba isakoso''.
Dida ile orin Ayefele wo: Oríṣun àwòrán, Yinka Ayefele Instagram Pabambari awuyewuye to waye lasiko isejọba gomina Abiola Ajimobi ni bo se da ile orin Yinka Ayefele wo, ladugbo Challenge, nilu Ibadan.
Ọjọ kọkanlelogun, oṣu kẹjọ ni ọjọ ibi Kelvin ni tirẹ.
Oríṣun àwòrán, Others Ẹnikan ti isẹlẹ naa soju rẹ sọ fun akọroyin naa pe isẹlẹ naa waye ni deede aago mẹwa kọja isẹju mẹẹdogun lalẹ.
Láti ọ̀dọ̀ rẹ wá ni ọrọ̀ ati ọlá ti ń wá, o sì ń jọba lórí ohun gbogbo.
Ọlọrun mi, gbà mí lọ́wọ́ àwọn eniyan burúkú,àwọn alaiṣootọ ati ìkà.
Nípa igbagbọ, wọ́n ṣẹgun ilẹ̀ àwọn ọba, wọn ṣiṣẹ́ tí òdodo fi gbilẹ̀, wọ́n rí ìlérí Ọlọrun gbà.
Makarau ni won ri gege bi alatileyin kan pata ki fun omo odun metaleladorun aare tele ri Robert Mugabe, eni ti o ti wa lori alefa lati bi odun metadinlogoji lorile-ede naa, amo arabirin Makarau ko so idi kan pato ti o fi kowe fise sile, leyin osu kan ti Mugabe kuro lori alefa nigba ti egbe oselu ZANU-PF ati ile-ise ologun orile-ede naa keyin si.
Gbogbo igbiyanju ile iṣẹ BBC lati ba ijọba sọrọ lori koko yii ni ko tii bi eso to yẹ.
Àwọn ọmọ Israẹli sì ṣe gbogbo ohun tí OLUWA pa láṣẹ fún Mose.
Eyi jẹyọ ninu esi ayẹwo ti ajọ naa fi sita l'Ọjọbọ, fun ipinlẹ mẹtalelogun, ati ilu Abuja.
Awọn to yapa lori rọ yi ko ni awijare tofẹsẹ mulẹ.
Ni bayii, eeyan mejidinlọgọn lo wa lati ipinlẹ Eko ninu ogoji to larun naa ni Naijiria, meje lati Abuja.
Ibú sọ pé, ‘Kò sí ninu mi,’òkun sì ní, ‘Kò sí lọ́dọ̀ mi.
Ẹ sọ fún un pé kí ó má ṣe àgbèrè mọ́, kí ó sì fi ìṣekúṣe rẹ̀ sílẹ̀.
Ki ni iṣoro yii gan ati pe ki ni ohun to ṣokunfa iku Iya rẹ, bi baba rẹ ṣe sa kuro nile ati ọgbẹ ọkan to wa lọkan iya iya rẹ bayii?
Sibẹsibẹ ẹ kò gba OLUWA Ọlọrun yín gbọ́, 
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, America yóò tutù ju bó ti yẹ lọ Laarin ọjọ iṣgun si ọjọbọ si ni ni awọn alasọtẹlẹ oju ọjọ ni yoo waye ti wọn si ni pe Chicago yoo tutu ju ẹkun Antarctica.
”OLUWA dáhùn pé, “Gbógun tì wọ́n kí o sì gba àwọn ará Keila sílẹ̀.
OLUWA sì ti búra pé, òun kò ní jẹ́ kí wọ́n rí ilẹ̀ tí òun ti búra láti fún àwọn baba wọn, ilẹ̀ tí ó kún fún wàrà ati oyin.
- Mike Bamiloye Ọkùnrin kan da ṣọ́ọ̀ṣì rú lásìkò ìgbéyàwó, Ó ní òun lọkọ àárọ̀ ìyàwó tuntun Mi ò fẹ́ ìrànwọ́ ẹgbẹ́ òṣèré, àwọn kọ́ ló kóbá mi- Chief Kanran Èèyàn mẹ́jọ jónà ráúráú nínú ìjàmbá ọkọ̀ akérò tó ṣẹlẹ̀ ní mọ́rosẹ̀ Eko sí Ibadan Ninu atẹjade to fi lede naa sọ wi pe Gomina Sanwo Olu gbe igbesẹ naa lẹyin wakati mejidinlaadọta to jẹjẹ lati tun agbegbe Opebi ti baalu naa jabọ ṣe pada.
” Wọ́n ní, “Ẹnikẹ́ni tí ó bá kọ́kọ́ kò wọ́n lójú ni yóo jẹ́ olórí fún gbogbo àwa ará Gileadi.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Kí ni ìtumọ̀ àwọn alárùn covid-19 tí wọ́n ń pè ní ''Asymptomatic'' ?
Irọ́ ni, mi ò sọ pé mọ fẹ di Ààrẹ ní 2023- Tunde Bakare Osinbajọ: Ọlọrun ṣetán láti mú Nàìjíríà d'élẹ̀ ìlérí, TUC ní Nàìjíríà ti kùnà lẹ́ni ọdún 59 Ìjí idágbére ti wọ́ Elozonam àti Ike kúrò nílé ẹlẹ́gbọ̀n àgbà BBNaija Orí kó aboyún 19 yọ lọ́wọ́ àwọn tó ń tá ọmọ ní gbàǹjo ₦300,000 Bakan naa, kii se arabinrin yii nikan lo ti se iru aseyọri yii.
Nigeria Election Update: 'Ilé iṣẹ́ DSS kò mú òṣìṣẹ́ INEC kankan lórí ẹ̀sùn Atiku'
Ahabu dá a lóhùn pé, “Ẹnìkan tí ó kù, tí ó tún lè bá wa wádìí lọ́dọ̀ OLUWA ni Mikaaya ọmọ Imila, ṣugbọn mo kórìíra rẹ̀; nítorí pé kò sọ àsọtẹ́lẹ̀ rere nípa mi rí, àfi burúkú.
O ni Àrá ni orukọ ọmọ Igbo naa n jẹ ati pe ọna ilu lilu awọn yatọ sira wọn.
Victor Moses, Oshoala gba ami ẹyẹ CAF kéde orúkọ àwọn olùdíje àmì ẹ̀yẹ agbábọ́ọ̀lù Áfíríkà Super Falcons pegedé fún àṣekágbá AWCON Pinnick ní irọ́ ni, òun kò ní ẹ̀sùn ajẹbánu lọ́rùn Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, ọkan gboogi ninu papa iṣere ti wọn ti maa figagbaga ni France Papa iṣere mẹsan an ni ilu mẹsan an ọtọọtọ ni wọn a ti gba bọọlu naa.
9 Àti pé èmi, Jésu Krísti, Olúwa yín àti Ọlọ́run yín ti sọ ọ́ fún yín, kí èmi baà lè mú àwọn èrò òdodo mi ṣẹ sí àwọn ọmọ ènìyàn.
Jakko wa gborin fun awon ologun ohun fun iwa omoluabi won ati emi ifokan jin lori ise ti won yan laayo naa.
President George Weah: Ààrẹ fẹsẹ̀ fẹ́ ẹ ní ọ́fíìsì rẹ̀ tórí ejò
Ṣugbọn ninu oṣu Keje ọdun 2017, ajọ CAF pinnu lati sun idije ti ọdun yii si oṣu Kẹfa ati ikeje.
Ó kún fún ọpọlọpọ adágún omi, ati orísun omi tí ó ń tú jáde ninu àwọn àfonífojì ati lára àwọn òkè.
Ẹ̀mí OLUWA bà lé Jahasieli, ọmọ Sakaraya, ọmọ Bẹnaya, ọmọ Jeieli, ọmọ Matanaya; ọmọ Lefi ni, láti inú ìran Asafu.
com Àkọlé àwòrán, Àwọn ọlọpàá sọ wípé ọmọ̀ ọ̀dọ̀ Sunday Adefonou Anani ti jẹ́wọ́ pé òun ló pa ọ̀ga rẹ̀, Ọpẹ Bademọsi, tó wà nínú àwọran yìí Ọgbà ẹ̀wọ̀n ti ilu Eko sọ pé irọ gbáà ni pe Sunday Anani tó jẹ́ ọmọ ọ̀dọ̀ tó ń dáná fún Oloye Ọpẹ Bademọsi ti gbẹ́mìí mì.
Ajọ naa ni gbogbo awọn eeyan to ni ajọṣepọ kan abi omiran pẹlu arakunrin ọmọ orilẹede Italy naa ni ipinlẹ Eko ati Ogun ni yoo ṣi wa labẹ ahamọ ayẹwo ajọ naa ati ileeṣẹ eto ilera pajawiri lawọn ipinlẹ mejeeji.
‘Ọdún Ojúde Ọba kìí se gbàgede olósèlú’ Yàtọ̀ sí Ọ̀ṣun Òṣogbo, Ṣàǹgó pẹ̀lú a máa ní arugbá lóde Ọ̀yọ̀ Baṣọ̀run Gáà: Ó yan ọba mẹ́rin, tó sì pa ọba mẹ́rẹ̀ẹ̀rin àmọ́ ọba karùn-ún ló pa á Ọba Adesoji Aderemi, Ọọ̀ni Ifẹ̀ tó gba ipò ọba mọ́ tòṣèlú Ofin yi ti wọn pe orukọ rẹ ni 'Ogun State Traditional Rulers (Installation and Burial Rites) Bill 2020' ṣebi ẹni ri atẹwọgba lọdọ awọn aṣofin naa.
Jesu gbé ojú sókè, ó ní, “Baba, mo dúpẹ́ lọ́wọ́ rẹ nítorí ò ń gbọ́ tèmi.
ipinle Oyo nipa wiwa ojutu si opolopo isoro to n doju ko ipinle naa.
BÍ O BÁ JALÈ RÍ, JỌ̀WỌ́ JẸ́WỌ́ Ẹ̀ṢẸ̀; BÍ O BÁ PÀNÌYÀN JỌ̀WỌ́ JẸ́WỌ́ Ẹ̀ṢẸ̀; BÍ O SOJÚKÒKÒRÒ, JỌ̀WỌ́ JẸ́WỌ́ Ẹ̀ṢẸ̀; BÍ O FẸ́ OBÌNRIN OLÓBÌNRIN, JỌ̀WỌ́ JẸ́WỌ́ Ẹ̀ṢẸ̀, ẸNI TÍ KÒ JẸ́WỌ́ Ẹ̀SẸ̀ RẸ̀ KÍ Ó TÓ KỌJÁ ODÒ Ẹ̀JẸ̀ Á KÀNJÀNGBỌ̀N, JỌ̀WỌ́ JẸ́WỌ́ Ẹ̀ṢẸ̀ RẸ KÍ O TÓ KỌjÁ ODÒ Ẹ̀JẸ̀.
Ó ṣe èmi Alákọ̀wé gan-an ní kàyéfì ní ìgbá tí mo f’ojú mi kòró-kòró kàn án.
Ó ń bọ̀ láti ọ̀dọ̀ Ọlọrun.
Tí ó bá jẹ́ pé ninu ayé yìí nìkan ni a ní ìrètí ninu Kristi, àwa ni ẹni tí àwọn eniyan ìbá máa káàánú jùlọ!
Bẹ́ẹ̀ ni wọn kò mọ ìyá rẹ̀.
Ọ̀nà tí Ọlọrun fi fi ìfẹ́ tí ó ní sí wa hàn ni pé ó ti rán ààyò ọmọ rẹ̀ wá sáyé kí á lè ní ìgbàlà nípasẹ̀ rẹ̀.
Yọllywood yoo ma fun un yin niroyin nipa awọn osere to jẹ Yoruba lori itakun agbaye BBC Yoruba loorekoore.
Ọjọgbọn Adesanmi lọ sile iwe Titcombe College niluu Egbe, bẹẹ lo tun kawe ni ile iwe giga fasiti ti ilu ijọba apapọ ni Ilorin, nipinlẹ Kwara nibi to ti gboye ninu ẹkọ ede Faranse.
Kí ni anfaani tí ọlọ́gbọ́n ní tí ó fi ju òmùgọ̀ lọ?
ORÚKỌ TÍ Ó JẸ MỌ ÀSÌKÒ
Ọlọ́gbọ́n ọmọ a máa gba ẹ̀kọ́ baba rẹ̀,ṣugbọn ẹlẹ́yà kì í gbọ́ ìbáwí.
Ìjọba, ẹ yé fi ọlọ́pàá àtàwọn ológun dúnkokò máwọn èèyàn- Ṣoyinka Irọ́ ló pa, a kò mọ̀ ọ́ rí tàbí fún ọ ní ₦13m - APC tako afurasí ajínigbé Aṣírí ìdí ti El-Zakzaky fi padà si Nàìjíríà láti India Momodu wa gba gbogbo ọmọ Naijiria nimọran pe, ohun to ja ju bayii ni lati fọwọ sowọpọ fi gbe orilẹede Naijiria de ibi giga nitori ohun atijọ ti kọja lọ.
"Niwọn igba ti a mọ pe ijọba ti wa lẹyin wa, a n gba yin niyanju lati maa ṣe iṣẹ yin lọna to tọ.
Èrò àwọn ọmọ Naijiria ṣọ̀tọ̀ọ̀tọ̀ lórí àwọn ti Sanwo Olu yàn sípò Ko pẹ lẹyin iṣẹlẹ yii ni Senetọ Ike Ekweremadu ti raaye pada si Naijiria ti iroyin si n tan kiri pe o ti dariji awọn to gbena woju rẹ ni Germany.
Coronavirus symptoms: Ó ti di Ọgbọ̀n èeyàn báyìí tó ti ní àrùn Coronavirus ní Nàìjíríà
Ẹ̀wẹ̀ àjọ tó ń rí sí erébóòlù lágbàáyé, Fifa ti sọ fún ilé iṣẹ BBC pé àwọn n fi ọkàn bá ọrọ náà ló.
Ìwádìí náà tún pe àkíyèsí síi pé, àwọn orílẹèdè tí òfin kò fààyè gbà láti máa sẹ́yùn ni ó pọ̀jù, nínú àwọn tó ń ṣe ìwádìí òògùn oyún ṣíṣẹ́ lórí ìtàkùn àgbáyé.
Òfo ni ọ̀rọ̀ mi látoṣù-dóṣù,ìbànújẹ́ ní sì ń dé bá mi láti ọjọ́ dé ọjọ́
Ladoja: Àwọn èèyàn Oyo fì ìbò sọ̀rọ̀ pé ìjọba Ajimobi kò dára
Oríṣun àwòrán, Bashir ahmad Eyi ni awọn ohun miran ti Buhari ko mẹnuba ninu ọrọ rẹ.
 Mo rín ẹ̀rín àrínbomilójú nígbà tí wọ́n sọ ọ̀rọ̀ yìí tán.
Bi bẹẹ kọ, o yẹ ki Naijiria ti di irinwo miliọnu bayii."
Ta ló lè rí ìrètí mi?
Olúbàdàn: Ìgbésẹ̀ Ajimọbi tako ìsèjọba ìsẹ̀ǹbáyé
Awọn ti BBC ba sọrọ sapejuwe re gẹgẹ bi ọmọ to mọwe ati pe o ti n kọle fun iya rẹ, Josepine ni Naijiria, ti iya rẹ naa si ti pinnu lati pada wa si orilẹ-ede Naijiria.
Dájúdájú ibinu eniyan yóo pada di ìyìn fún ọ;àwọn tí wọ́n bá sì bọ́ lọ́wọ́ ibinu rẹyóo ṣe àjọ̀dún rẹ.
"Igbé ayé aláfia ni à n gbé pẹ̀lú gbogbo àwọn ajoji to wà ni inú ìlú wa tó fi ma àwọn Fulani"" Osun cow death: Gómìnà Oyetola ṣèlérí àtìlẹyìn ìjọba fáwọn Fúlàní tó pàdánù màlúù l'Osun Oríṣun àwòrán, Premium times Gomina ipinlẹ Ọṣun Gboyega Oyetọla ti ba awọn eeyan ilu Iba kẹdun lori iṣẹlẹ ara to san pa awọn maluu ti ko din ni mẹtadinlogun to jẹ tawọn darandaran Fulani nibẹ."
Dokita Omowumi lo sọ ọrọ naa lẹyin ti awọn ọdọ kan dana sun ọkọ akero lẹyin ti awakọ rẹ pa ọlokada kan ninu ijamba ọkọ to waye lagbegbe Idi Ape, ni ilu Ibadan.
Reno Omokri to jẹ oluranlọwọ pataki Aarẹ ana, Goodluck Jonathan, ni ti aarẹ ba ṣe daradara, oun maa n gboriyin fun un, ṣugbọn to ba ṣe nkan abuku, oun yoo tun bẹnu ẹtẹ lu u.
lodun 2006, leyin ti iko Super Eagles gbo igi ewuro soju won pelu ami ayo meji
“Ni paapaa julọ mo fẹ dupẹ lọwọ , Asiwaju Bola Tinubu fun iwa asiwaju rẹ
Ṣùgbọ́n èmi ń wò ó láti òkè, ó ń rọ̀ nísàlẹ̀ lé àwọn tó wà nílẹ̀ lórí.
Nibayii, Ọmọwe Oby Ezekwesili ni oludije ipo arẹ fun ẹgbẹ oṣelu Allied Congress Party of Nigeria, ACPN fun idibo apapọ ọdun 2019 lorilẹede Naijiria.
Ọjọ kẹtalelogun osu kẹta ọdun 2018 ni Super Eagles yoo wọ asọ naa fun igba akọkọ nigbati wọn ba n waako pẹlu akẹẹgbẹ wọn lati orilẹede Poland ninu ifẹsẹwọnsẹ ọlọrẹsọrẹnilu Warsaw Ẹgbẹ agbabọọlu orilẹede Croatia, Iceland ati Argentina ni Super Eagles yoo maa ba figa-gbaga ni igun kẹrin nibi idije ife ẹyẹ agbaye naa.
Ni kete tie to idibo ohun pari ni apapo awon alamoju to eto idibo ti gbe aworan asekagba eto idibo ohun sori ero aseyewo igbalode won.
Ọkùnrin kan gbé ‘búrọ́ọ̀ṣì ìfọyín’ mì Coronavirus ti di ara wa, kò le è kúrò mọ láéláé - WHO Àfi ìgbà tí mo bọ́ sọ́wọ́ ọ̀tá mí nínú ìrìnàjò ìfẹ́- Roshan Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Coronavirus tips: Kìí ṣe gbogbo ìbòmù ló ń dá coronavirus dúró Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Àwọn tó ní ààrùn Coronavirus ní Nàìjíríà ti pé 29,789 Olórí òṣìṣẹ́ ìjọba ìpínlẹ̀ Kwara, Adisa Logun ti dágbére fáyé lẹ́yìn tó lùgbàdì àrùn Covid-19 Wọ̀nyí ni àwọn ẹjọ́ tó làmìlaaka ti EFCC ṣe lásìkò Ibrahim Magu Ki lo ti ṣẹlẹ ṣeyin?
”Asofin Uwajumogu ni lati fi ipo re sile gege bi akowe agba egbe nitori idi kan .
Ose kan gbako ni won fi se ayeye naa , ni eyi to waye niluu Calabar, ni ipinle Cross RiverIyaafin Winifred Oyo-Ita, adari awon osise ijọba apapo lorile ede Naijiria  lo soro yii, nigba ti o n soju aare Buhari nibi ipade naa.
N óo kẹ̀yìn sí yín, àwọn ọ̀tá yín yóo sì ṣẹgun yín.
"Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ọjà Àgbáláta ní Badagry rèé, níbití ẹran ejò ti dùn ju ẹran adìẹ lọ Àwọn èèyàn ń san ìdámẹ́wàá tó ""Heavy"" fún mi ni mo fi ń r'áànú ṣe - Iya Adura Esther Ta ni ó bẹ̀rẹ̀ Fújì?"
Lati ọwọ Graham Wright ni London Iroyin BBC Ikọ eleto ilera Ti o ba n ba ẹni to n danikanwa gbe, o yẹ ki o din ajọṣepọ ifarakan ara yin ku, koda, to ba ṣeeṣe ki ẹ ma jọ wa ninu iyara kan naa O yẹ ki ẹni to danikanwa yii wa ni iyara to ni afẹfẹ to pọ pẹlu ferese to ṣeeṣi sita , ki ẹlomiran ma si wọnu iyara naa pẹlu rẹ End of Didaabo bo ara mi ati awọn elomiran Emi ati ẹbi mi Ibeere yin Skip Emi ati ẹbi mi Mo wa ninu oyun oṣu marun un, mo fẹ mọ ewu to wa fun emi ati oyun inu mi ti mo ba nii?
Ìwọ̀n tí wọn ń lò ní ibi mímọ́ ni wọ́n fi wọ̀n ọ́n.
Shehu Abdullahi darapọ mọ Bursaspor Tottenham vs Ajax: Láti òní lọ,Lucas 'Miracle' lòó má jẹ!
Eyi ko mu irẹwẹsi ba Bonaparte o, nitori pe o ni idaniloju pe imọ ijinlẹ rẹ kii ṣe otubantẹ, debi i pe ẹẹmẹta ọtọọtọ ni oun fun'ra rẹ ṣe iṣẹ abẹ naa.
Oríṣun àwòrán, Other Wọn ni iwa bi arakunrin naa ṣe bọ aṣọ idaabobo to wọ lasiko to n gbe oku Abba Kyari sọnu silẹ naa ku diẹ kaato.
Ṣugbọn, mú ọkàn le, ìwọ Serubabeli, má sì fòyà, ìwọ Joṣua, ọmọ Jehosadaki, olórí alufaa; ẹ ṣe ara gírí kí ẹ sì ṣe iṣẹ́ náà ẹ̀yin eniyan; nítorí mo wà pẹlu yín.
aṣiwaju Ile Igbimọ Aṣofin naa lati kọ ile ijọsin to joju n gbese bayii fun
Ọgá àgbà náà sí ní láti bi osù mẹ́wàá ṣẹ́yìn ni ajọ náà ti gba àwọn ǹkan iní ti à fojuri ti owo rẹ̀ to Bílíọnù mejilélọgbọ̀n, yála ki ijọba gbẹsẹ le e pátápáta tàbi ki wọn gba fun igba diẹ̀ ki igbẹjọ to pari.
Eleyii ti ko ṣẹyin iwọde to n waye kaakiri orilẹ-ede Naijiria bayii nibi ti awọn eeyan ti n gbe ohun soke lati tako idasilẹ ikọ naa.
Eyín akọ̀ròyìn fò yọ lásìkò tó n ka ìròyìn lọ́wọ́ lórí tẹlifísàn ‘DJXgee lọ sòde eré lọ́jọ́ ọdún tuntun láìmọ̀ pé yóò gbẹ̀mí ara rẹ̀’ Amọ Olatunde ni aisi owo lo mu ki msto naa pẹ, ko to dide amọ ti owo ba wa, ko gba oun ju osu mẹta lọ.
October 30, 2018 Irínwó àwọ́n ọmọ òògun IMN ní wọ́n tì mọ́le fún dídamú àláfíà àrá ìlú ní ìlú Abuja.
Awọn ọmọ Naijiria mii ko náání pé wọn ti lé laadọrin ọdun nitori ibanujẹ lọjọ ori, ipo lagba.
Amọ o ni o da oun loju pe ẹ̀mí oun wa ninu ewu, idi si ree ti oun fi kuro ninu igbeyawo oun, amọ oun ko ni panumọ nipa rẹ.
Ninu ọrọ rẹ, Buhari gboriyin fun Dokita Adadevoh fun ifaraẹnijin ati iwa akọni to hu lati gbogun ti itankalẹ aarun Ebola ni Naijiria l'ọdun 2014.
Ṣugbọn ẹ̀yin òkè Israẹli, igi óo hù lórí yín, wọn óo sì so èso fún Israẹli, àwọn eniyan mi, nítorí pé wọn kò ní pẹ́ pada wálé.
Ifẹsẹwọnsẹ naa ku iṣẹju mẹjọ ko pari ni ẹlẹsẹ ayo Alexandre Lacazette gbayo sawọn ti ere bọọlu naa fi di omi.
Nígbà tó yá, òun gan-an kò mọ ìwọ̀n ọkà náà mọ́, nítorí pé ó ti pọ̀ kọjá wíwọ̀n.
Lẹ́yìn tó rúfin, àjọ NBC ṣí iléèṣẹ́ ìgbóhùnsáfẹ́fẹ́ Ekiti padà Afurasi tó fa ìpayà nílé ìwé Port Harcourt ti wọ gàù Ọjọ́ tí inú mi bàjẹ́ jùlọ gẹ́gẹ́ bíi ààrẹ ilé aṣòfin àgbà-Saraki Ẹ dákẹ́ àhesọ ọ̀rọ̀, n kò bí ìbẹta - Yinka Ayefẹlẹ Oga agba fun ajọ NBC ni ọpọ igba ni awọn ti ri ẹsun gab lati ọdọ awọn ara ilu lori akoonu eto tile iṣẹ AIT ati Ray Power n gbe jade.
Ṣugbọn gba ìjìyà tìrẹ ninu iṣẹ́ ìyìn rere pẹlu agbára Ọlọrun, 
Awon asofin agba lorile-ede Naijiria ti fi dandan sii pe ki ise to n lo lowo lori ipese oko-oju-irin lorile–ede yii wa kaakiri ekun kookan ni.
“O ni ile ise RCC ti n se ise gidi-gidi loju opopona naa lati ko awon oju ibi ti agbara yoo maa gba koja ,nigba ti ojo ba n ro ati lati se atunse si awon afárá irinna  ese.
 Isẹ wa ni lati daabo bo awọn  irinse ibo ati awọn  eniyan.
 o jẹ alabaṣepọ ti institute of chartered accountants , england ati wales 1977 , ican nigeria 1976 , awọn ile-iṣẹ ti ilu awọn alakoso british chartered ( acis 1964 ) .
Wọ́n lọ títí dé àfonífojì Eṣikolu, wọ́n wo ilẹ̀ náà.
Ìṣẹ̀lẹ̀ kan ní agbègbèe Ajmer ní Rajasthan lọ́dún-un 2017 jábọ̀ ìlọ́wọ́sí panchayat ipò-ìsàlẹ̀ tí ó ṣ’okùnfa ikú obìnrin ogójì ọdún kan.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, #BBCGovDebate: Olùdíje 5 ni yóò kópa nínú ìpàdé ìtagbangba l‘Ogun Gẹgẹ bi alaye agbẹjọro fun olujẹjọ ori ọkada alupupu ni oloogbe wa ti awọn mẹrin kan ti ke e lọna, bi awọn mta ṣe di i mọlẹ ni olujẹjọ, Arogundade gun un lọbẹ lọpọlọpọ igba.
Ọjọgbọn Adesanmi tun kẹkọọ ni fasiti British Columbia niluu Vancouver lorilẹ-ede Canada.
Àkọlé àwòrán, Fayemi saaju ikede Nínú ọrọ tirẹ, gómìnà Ibikunle Amosun ti ìpínlẹ̀ Ògùn ní ìdìbò yìí ṣe àfihàn ìgbàgbọ́ tí àwọn ará ìlú ní nínú ẹgbẹ́ APC.
Oga agba ajo ohun so fun ile-ise akoroyin BBC pe, o ya won lenu bi  won se da ejo lati fi Nacima Qorane si ewon.
Koda, o sọ fun mi pe awọn waasi ọhun dara to bẹẹ, ti oun maa n fi ṣe waasi ni sọọsi lọjọ ìsinmi.
Oríṣun àwòrán, Instagram/Neo Neo ni olukopa keji to ja kuro lori eto naa l'alẹ aṣekagba.
 “Eemi ati ebi mi patapata dupe pupo,”Pelu idojuko ohun, Mikel si kopa ninu ifesewonse ohun lai so fun enikeni ibi ti bata ti n ta lese.
Bí mo ti dé ibi ti mo kọ́ dúró mo tún rí i pé ògiri yìí bìlà sẹ́yìn, ìlẹ̀kùn ìyààrá ìyàwó mi tú sí, mo múra ó di ibẹ̀ pẹ̀lú àdá mi.
”Pilatu sọ fún wọn pé, “Kí n kan ọba yín mọ́ agbelebu?
Ìwọ ni o mọ mí, ìwọ ni o dá mi,fún mi ní òye kí n lè kọ́ òfin rẹ.
Wọ́n yára ju àṣá lọ,wọ́n sì lágbára ju kinniun lọ.
Ate bi won se gba ami eye naa niyi nisale fun gbogbo awon to gba ebun:Onkorin tuntun fodunTENIAdako Raapu to dara juYou Rappers Should Fix up your Life – M.
“Eniyan á dá ọwọ́ rẹ̀ lé òkúta akọ, á gbẹ́ ẹ,á sì hú òkè ńlá tìdítìdí.
Lẹ́hìn èyí ni bàbá mi bẹ̀rẹ̀ tí ó gbé oníbodé lé èjìká tí ó sì ń gbé e lọ ní ìrètí àti na ẹ̀hìn rẹ̀ mọ́ òkúta kọ̀bìtì kan tí ń bẹ ní ẹ̀bá ibẹ̀ ṣùgbọ́n kí òun tóó dé ibi òkúta yìí, onítọ̀hún ti tàkítí ọ̀bọ láti èjìká ó sí bọ́ sí ilẹ̀ ó dùró gbọnin - awọn iwin sì lu ìlù ayọ̀ láti fi bá oníbodè yọ̀ wí pé ó kú oríire.
Ati pe a le fi kun akoko ti telomeres yoo lo lara, eyi ti yoo si fi kun ọjọ aye wa - wọn ti dan an wo lara ekute.
Kí Ọlọrun tó dá ayé, ati pápá oko,kí ó tó dá erùpẹ̀ ilẹ̀.
Nitori eyi àwọn Ológun gbe pẹ̀lú àlejò rẹ wọn si pa wọ́n pọ ni Ìbàdàn.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Boko Haram titu awọn olukọni mẹta Unifasiti Maiduguri silẹ 10 Èrèlè 2018 Oríṣun àwòrán, .
Wọn ni ileesẹ ọlọpaa kọ lati fesi ti atẹjade kan lati ọdọ ijọba ipinlẹ Eko si ni awọn ko ni nkankan sọ lasiko ti igbimọ iwadii si n joko lori ọrọ naa.
Abrahamu tún dáhùn pé, “OLUWA, jọ̀wọ́ má bínú sí mi, ẹ̀ẹ̀kan ṣoṣo péré yìí ni ó kù tí n óo sọ̀rọ̀.
Eyi ni akojọpọ aworan ere itage itan Baba Oluṣegun Obasanjọ: Àkọlé àwòrán, Ọbasanjọ jẹ adari Naijiria labẹ ijọba ologun ni ọdun 1976 si 1979 ati ijọba tiwantiwa ni ọdun 1999 si ọdun 20007 Àkọlé àwòrán, Ìdílé Owu ni agbeegbe Ibogun-Olaogun ni ipinlẹ Ogun ni wọn ti bi Baba Obasanjo,ti o si lọ ile iwe ni Abẹokuta.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Chelsea vs Manchester City: Man City gba fújà lọ́wọ́ Chelsea n'íbẹ̀rẹ̀ ọdún tuntun 3 Sẹ́rẹ́ 2021 Oríṣun àwòrán, Getty Images Awọn Yoruba maa n gbadura kan wi pe ''aye ko ni gba fuja lọwọ rẹ.
Èèyàn 216 míràn ṣẹ̀ṣẹ̀ kó COVID-19 ní Nàìjíríà Ajọ to n gbogun ti ajakalẹ aarun lorilẹ-ede Naijiria, NCDC ti kede pe eeyan okoolelugba o din mẹrin miran ti kun iye awọn to ti ni aarun COVID-19 lorilẹ-ede Naijiria.
O ni akọkọ iṣẹ oun ni lati se koriya fawon oṣiṣẹ eto ilera.
Gideoni ati ọgọrun-un eniyan tí wọ́n wà pẹlu rẹ̀ bá lọ sí ìkangun àgọ́ náà ní òru, nígbà tí àwọn olùṣọ́ mìíràn ṣẹ̀ṣẹ̀ gba ipò àwọn tí wọ́n wà níbẹ̀ tẹ́lẹ̀.
Bakan naa ni Rohr sọ pe oun yoo mu ayipada ba awọn ti oun yoo lo fun idije ti yoo waye pẹlu Madagascar l'ọjọ Aiku.
Iṣẹ́ Ẹ̀mí Mímọ́ ń farahàn ninu olukuluku wa fún ire gbogbo wa.
Sugbọn ohun ti IMN n fẹ ni ki ijọba fi olori awọn sile ati aya rẹ fun itọju nilẹ okeere.
Oríṣun àwòrán, I_am-shai/Instagram Bákan náà ni Seyi ko ki Wumi Toriola lọ́jọ́ ibi rẹ̀ gẹ́gẹ́ bi wọ́n ṣe máa n ṣe lojú òpó ìkàsíraẹni Instagram.
lọdun 2003 ni ijọba dariji oku rẹ nigba ti wón n sami ayẹyẹ ominira aadọta ọdun nibẹ.
Oríṣun àwòrán, Others Koda, ẹgbẹ APC ti kọkọ yan gomina ana nipinlẹ Oyo, Abiola Ajimobi gẹ́gẹ bii adele Alaga ẹgbẹ, amọ Ọjọru ni wọn tun yan Geidom rọpo rẹ.
Wọ́n ṣe òkú náà dáadáa, nítorí bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé n kò fi ojú rí òkú náà kí wọ́n tó sin ín, síbẹ̀ àwọn àbúrò mi tí ó wà ní ilá wi fún mi pé àwọn ọmọlẹ́bí mú aṣọ wá ni oríṣìíríṣìí láti fi dìí, àti wí pé wọ́n pa ọ̀pọ̀lọpọ̀ ẹran.
Ọgbọ́n dára bí ogún, a máa ṣe gbogbo eniyan ní anfaani.
Ipinlẹ Ondo: Bakan naa ni ọmọ sori nilu Akure tori se ni awọn oluwọde ọhun gbe idi dana lawọn opopona nlanla nipinlẹ Ondo, ti ko si si lilọ bibọ ọkọ ati ero.
Ta ba si ni ka maa darukọ awọn to jẹ sawawu oloogbe Odunjọ, a o mẹnuba Daniel Olorunfẹmi Fagunwa, taa mọ si D.
Amọṣa, olori smọ ẹgbẹ to kere julọ nile naa, Ehinaya Abaribe pẹlu olori ẹgbẹ to pọ julọ nibẹ, Abdullahi Yahaya ko awọn akẹgbẹ wọn ni ijanu lati maṣe da ẹjs lai kọkọ jẹ wi pe wọn tan ina si idi ọrọ naa.
Wọn ni ko ṣeku ko ṣẹyẹ ni Ọjọgbọn Akintoye wi pe bi o ṣe n ṣe ẹgbẹ Afẹnifere, lo n ṣe awọn ẹgbẹ mii nigba ti o si jẹ aarẹ YWC.
NLC pẹ̀lú ẹ̀bùn ọ̀dún tuntun fún Nàìjíríà Dangote, Otedola di olùdámọ̀ràn ìgbìmọ̀ ìpolongo APC Dino: Olúwa, ṣe sí àwọn ọ̀tá mi bí o ṣe ṣe sí Egypti Àáyá bẹ́ sílẹ̀ ó bẹ́ áré, lọ́gán ní wọn ti fori kori láti yan àwọn ti wọn yóò jumọ sisẹ́ pọ̀.
Ọkan lara awọn asofin agba naa parọwa si ijọba apapọ lati daabobo ẹtọ awọn ọmọ Naijiria, lori yiyọ owo aitọ ni apo asuwọn wọn.
Michelle Dede ati Olisa Adibua, lo ṣe atọkun eto naa.
Alaawẹ, ninu lẹta naa, lo tun ni ko si aniani pe Alaafin maa n mọọmọ da awuyewuye ati rogbodiyan silẹ ni nibi ti ko si, to si n dasi ọrọ ti ko kan, to n gbe wahala to da silẹ fun igbimọ lọbalọba ni ipinlẹ Ọyọ ijọun wa, eyi to da ija agba meji silẹ laarin Alaafin ati Ọọni, ti wọn ko si lee se ipade mọ titi ti wọn fi yọ ipinlẹ Ọsun lara Ọyọ.
Ọlọrun ni ààbò ati agbára wa,olùrànlọ́wọ́ tí ó wà nítòsí nígbà gbogbo, ní ìgbà ìpọ́njú.
 Osise ile akede Naijiria ,VON naa wa nibẹ lati se ifọrọwanilẹnuwo
Wọ́n yan àwọn arakunrin wọn wọnyi kí wọ́n wà ní ipò keji sí wọn: Sakaraya, Jaasieli, Ṣemiramotu, Jehieli, Uni, Eliabu, Bẹnaya, Maaseaya, Matitaya, Elifelehu ati Mikineiya, pẹlu àwọn aṣọ́nà: Obedi Edomu ati Jeieli.
Kọmiṣọnna eto ibaraẹnisọrọMurtala Olarenwaju ni kọmiṣọnna tuntun fun ile iṣẹ ijọba to n ṣamojuto ibaraẹnisọrọ.
 eré ìtàgé tí ó ti ṣe bíi vincent price , lewis black , orson welles , jesse ventura , paul giamatti , michael caine , philip seymour hoffman àti comedy bang !
Ẹ juwọ́, kí àwọn ológun gba ẹnu ibodè àwọn ọlọ́lá wọlé.
 Ẹsìn Ìjọ páàdi àti ti lárúbáwá ni a gbọ ́ pé wọ ́ n gbárùkù mọ ́ jù .
ojutuu sii ti won ba dibo yan egbe oselu  ANC ninu eto idibo yii.
 nípa ṣíṣe èyí , wọn óò ni àǹfààní láti mọ ̀ bọ ́ yá Ọláńrewájú ni iṣẹ ́ wọn tàbí Ọláńrẹ ̀ yìn .
9/11 Baby: Aramanda ọmọ, wọ́n bi ní ọjọ́ 9/11, láago 9/11 tó si wọn 9/11
" Omijé bọ́ níbi ìsìnkú Ogun Majek Eji Gbadero, ọmọ Ibadan àti jayé-jayé ọmọ ónílẹ̀ ti wọn yẹgi fun l'Eko Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí 3 sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 2:23 Fídíò, Water Generator: Ó leè ṣiṣẹ fún wákàtí mẹfà, kó tó sinmi, Duration 2,2310 Òkùdu 2020 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
Ọba Awujalẹ sọ eyi ni ibi ti o ti n sọrọ lori akọtan ọrọ isejọba abẹle lorilẹede Naijiria, ni Ile Iwe giga Ọlabisi Ọnabanjo, to kalẹ si Ijebu Ode, ni ipinlẹ Ogun.
Wọ́n bẹ̀rẹ̀ sí bú oníbodè nì káà kiri pé òun ń ba àwọn èrò ọ̀nà jẹ́, òun kò fi ìyà jẹ wan tó bí ó ti yẹ kí ó ṣe, òun ń jẹ́ kí àwọn èrò rí oníbodè Igbó Olódùmarè fín, wọ́n sí wáá bẹ̀rẹ̀ sí yin Àǹjànnú-ìbẹ̀rù fún ìyà ńlá gboggbo tí ó ti fi ń jẹ wọ́n.
Òhun tí o sẹlẹ nigba ti Buhari lọ China Mo Salah bínú sí àjọ agbábọ̀ọ́lù Egypt Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ọ̀rọ̀ Trump àti Russia kò yàtọ̀ pé àhesọ lásán ni èyí jẹ́ Ẹ o ranti wipe, ifẹhonuhan bẹ silẹ ni orita Rabaa al-Adawiya to wa ni olu ilu orilẹede naa, Cairo, ni 2013, ti awọn agbofinro si pa ọgọrọ awọn eniyan.
Àwọn iròyin tì ẹ leè nífẹ̀ síí: SERAP fẹ́ pe UI, AAUA lẹ́jọ́ lórí àfikún owó iléẹ̀kọ́ Ní Àwòrán: Ìsìnkú Winnie Mandela Bùhárí sọ ìdí tó fi ń díje lẹ́ẹ̀kejì Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Àṣẹ tí Ẹsita pa fi ìdí àjọ̀dún Purimu múlẹ̀, wọ́n sì kọ ọ́ sílẹ̀.
Trump kò yẹ láti jẹ́ ààrẹ lásìkò yìí, èèyàn kò le fi mọ̀kàrúrù ṣe ààrẹ - Michelle Obama Ṣé ìrànwọ̀ ni Kamala, ìgbákejì tí Biden yàn yóò jẹ́ fún un tàbí ìpalára?
Ẹnìkínní ń bá aya ẹnìkejì rẹ̀ lòpọ̀; àwọn kan ń bá aya ọmọ wọn lòpọ̀; ẹ̀gbọ́n ń bá àbúrò rẹ̀ lòpọ̀, àwọn mìíràn sì ń bá ọbàkan wọn lòpọ̀ ninu rẹ, Jerusalẹmu.
Ileeṣẹ iroyin BBC bere lọwọ awọn onimọ sayẹnsi nipa ibẹru awọn eeyan lori ọrọ yii, awọn onimọ naa si sọ pe ko si ohun to jọ bẹ.
Ko daju idi tawọn to fi fidio yi sita ti ṣe pe ni oludije ipo aarẹ ṣugbọn ohun ti fọnran wa fun ni pe wọn fi ṣe igbelaruge iṣẹ rẹ gẹgẹ bi aṣofin nilẹ Jamaica ati iṣẹ ribiribi to n ṣe.
Shuaibu ni Iya jẹ ọkunrin naa fun ọpọlọpọ ọdun, ti wsn so so mọ ara igi pẹlu irin ninu yara kan ti ko ni ilẹkun tabi ferese."
Wọn ni fifun awọn ọmọ ileewe alakọbẹrẹ bi miiọnu mẹẹdogun ni ounjẹ ọfẹ yoo mu idagbasoke ba ipese ounjẹ, ti yoo si tun pese iṣẹ.
Oríṣun àwòrán, Others Erica ń kígbe pé, Laycon ko si lára ẹni to wu òun rárá, òun ko sì fi ìgbà kankan gbìyànjú lati fẹnu kòó lẹ́nu ri.
JAMB, àwọn òbí fún Ààrẹ Buhari lésì lórí àdínkù owó ìdánwò tó kéde
”Ni Jesu bá dìde, ó bá afẹ́fẹ́ ati ìgbì omi wí, ni ìgbì bá rọlẹ̀, gbogbo nǹkan bá dákẹ́ jẹ́.
Nígbà tí ó kú, wọ́n sin ín sí ààfin rẹ̀.
"Ẹ gbọdọ kesi gbogbo awn asaaju ẹgbẹ wọn lati le fi ọrọ wawọn lnu wo,wọn gbodo foju ba ile ẹjọ ẹ si gbọdọ ri pe awọn to ba lọwọ ninuiwa yi jẹ iyan wọn niṣu'' Keyamo kasẹ ọrọ rẹ nilẹ pe lootọ ni pe ẹgbv alatako jẹ ohun to da fun ijọba arawa ṣugbọn eleyi ko gbọdo wa jẹ anfaani lati ma fi wu iwa ojoro.
Nítorí náà, ẹ kì í ṣe ẹrú mọ́ bíkòṣe ọmọ.
Àfojúsùn ìpàdé náà ni láti kó àwọn alásẹ ní Nàíjíríà àti ní Amẹ́ríkà sábẹ́ òrùlé kan pẹ̀lú àwọn oníléesẹ́ aládàáni, olùdókòwò, àtàwọn ọ̀gá àgbà iléesẹ́ ńláńlá.
Ọba ti ko ba ti wa ṣe e, baba Araba ni kii ṣe Ọba, eeyan lasan ni.
Bakan naa ni wọn ni o yẹ ki ileeṣẹ naa ri wi pe, iru awọn ẹrọ to le paniyan bẹẹ wa ni ibi ti eto aabo to peye wa fun awọn oṣiṣẹ lati le da abo bo wọn.
Eyi tumọ si pe awọn minisita yoo lanfaani lati maa rinrinajo pada silẹ okere lẹyin ti Aarẹ Buhari ba ti gbe eto iṣuna lọ siwaju ile aṣofin tan, ti wọn si gba a wọle.
Bí àrùn Coronavirus ṣe dá gbogbo àgbáyé gúnlẹ̀ sójú kan náà nìyí Kí lo mọ̀ nípa fẹntilétọ̀, ohun èlò aṣèrànwọ́ èémí Kí làwọn ìdàmú tí Coronavirus n mú bá àgọ́ ara?
Ó pada sí ìlú Jesireeli, ó lọ wo ọgbẹ́ náà sàn.
Gaali tún dáhùn, ó ní, “Tún wò ó, àwọn eniyan kan ń bọ̀ láti agbede meji ilẹ̀ náà, àwọn kan sì ń bọ̀ láti apá ibi igi Oaku àwọn tíí máa ń wo iṣẹ́.
O ni pataki kikọ marosẹ naa ni lati mu idagbasoke ba okowo ariwa si guusu Naijiria lapapọ.
Wọ́n pàgọ́ wọn sí òdìkejì ilẹ̀ Anoni.
 Ọmọ Ibadan ni awada ori ayelujara naa ti gbe oun de awọn orilẹ ede lorisirisi loke okun, to si gba awọn eeyan nimọran pe ki wọn tẹra mọ ohunkohun tí wọn ba da wọle daadaa lai rẹwẹsi."
Morocco ti n gbero lati sagbateru idije boolu agbaye fun igba karun-un bayii, bakan naa won tun gbiyanju lati sagbateru idije naa lodun 1994, 1998, 2006 ati odun 2010.
CAN faraya lórí ìdáwò ọlọ́pàá Akọwe ẹgbẹ ọmọlẹyin Kristi, CAN jade laye CAN pe fun atunto ileeṣẹ alaabo ni Naijiria 'Kí ni alága NFF, Amaju Pinnick ń wá ní Egypt fún AFCON?
”Ṣugbọn onítọ̀hún dáhùn pé, “Alàgbà, jẹ́ kí n kọ́ lọ sìnkú baba mi ná.
    Ṣùgbọ́n fún odidi oṣu kan, ni a fi ń ja ìjà yìí tí kò sí ẹni tí ó ṣẹ́gun ẹnì kejì, ọ̀ràn náà sì ń fẹ́ wá bọ́ sí ìtìjú fún àwọn ọdẹ.
Ọmọ-Eniyan ń lọ gẹ́gẹ́ bí ó ti yan ìpín tirẹ̀.
Àwọn olórí ogun Filistini bèèrè pé, “Kí ni àwọn Heberu wọnyi ń ṣe níbí?
"Wọ́n ti ní kí Jolaosho ""TBlak"" wá káwọ́ pọ̀nyìn r'ojọ́ ìdí tó fi ya ""Blue Film"" nínú igbó Osun Osogbo 'Níbo lo ti gbé ọmọ aràrá wa ni bàbá mi kò bá bi ìyá mi' - Aràrá adájọ́ Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí 6:10 Fídíò, Yoruba Language: Akomolede ati Asa Yoruba tọ̀sẹ̀ yí rèé lẹ́nu olùkọ́ wa, Duration 6,1030 Ògún 2020 6:18 Fídíò, Akomolede: Bolaji Faleke ni Olùkọ́ tó ń kọ́ wa ní àṣà oge ṣiṣe lórí BBC Yorùbá, Duration 6,181 Owewe 2020 Èyí tí a wò jùlọ 5:03 Fídíò, Omolola Arohunmolase Welder: Mo ti fí iṣẹ́ 'Welder' gbayì láwùjọ, tó mo fi tọ́ ọmọ yanjú, Duration 5,039 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 5:39 Fídíò, Akomolede ati Asa lori BBC: Olùkọ́ Kikelomo Ogunboye tan ìmọ́lẹ̀ sí ìwà olè ọ̀gá ọlọ́pàá Audu gẹ́gẹ́ bí àwòkọ́ṣe àsìkò yìí, Duration 5,398 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 4:11 Fídíò, Oba Adeyeye Ogunwusi: Ojú mi ti rí lọ́pọ̀ lọpọ̀, ọ̀pọ̀ èèyàn ni kò tilẹ̀ gbàgbọ́ pé mo lè jọba- Ooni, Duration 4,117 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 4:43 Fídíò, Promise Akinlade: ọmọ ọdún mọ́kànlá tó ń fi ìlù dárà bíi àgbàlagbà sọ̀rọ̀ nípa tálẹ́ǹtì rẹ̀, Duration 4,437 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 0:59 Gbọ́, Ìsẹ̀lẹ̀ jákèjádò orílẹ̀èdè àgbáyé láàárín ìṣẹ́jú kan, Duration 0,59wákàtí 5 sẹ́yìn 7:03 Fídíò, Olumuyiwa Bolade Adedeji Military Bruitality: Bí arákùnrin onípèníjà ara tí sọ́jà lù ṣe dé, Duration 7,035 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 4:45 Fídíò, Yoruba Films: Ẹ̀ẹ́ bẹ̀ mi kúrò láyé ni, mi ò lè kú - Fadeyi Oloro, Duration 4,4526 Èrèlè 2020 2:48 Fídíò, Esther Ajayi: Èmi náà ti borí ìṣòro rí ló ń mu mi ṣojú àánú, Duration 2,481 Ògún 2019 6:08 Fídíò, Adebola Ademilua: Àìrísẹ́ ṣè lẹ́yìn ìwé kíkà ló sọ mi dí ìyá onírú, mo dúpẹ́ tèmi, Duration 6,0827 Bélú 2020 2:36 Fídíò, Sotitobire: Ìdájọ́ òdòdò ló fẹsẹ̀ múlẹ̀ lórí ọ̀rọ̀ Pásítọ̀ Sotitobire - Agbẹjọ́rò fún ìjọba, Duration 2,367 Ọ̀wàrà 2020 BBC News, Yorùbá Ìdí tí ẹ fi le è nígbàagbọ́ nínú ìròyìn BBC Ìlànà Lílò Nípa BBC Òfin Àṣírí Cookies Kàn sí."
" wọ ́ n fàá sí ojú ọ ̀ nà sufism ní ìl ̀ anà qadiriyya , lábẹ ́ ìkọ ́ àti ìtọ ́ sheu ahmad roufai "" nda salati "" ní ọdún ( 1897-1966 ) , ẹni tí ó jẹ ́ ọ ̀ kan lára àwọn ògbó-ǹ-tagì onímọ ̀ nípa sufi nílùú Ìlọrin lásìkò náà ."
Àpótí Majẹmu OLUWA sì wà níwájú wọn láti bá wọn wá ibi ìsinmi tí wọn yóo pàgọ́ sí.
Itankalẹ aarun coronavirus ko da ayẹyẹ ọjọ ibi awọn oṣere kan duro l'ọsẹ yii.
Dájúdájú wúrà àti fàdákà dára púpọ̀, wọ́n sì níye lórí gan- an.
Wọn dibo ijọba ibilẹ ni Kano Ganduje pe awọn darandaran si Kano Wọn maa yẹẹ wo lati yọ orukọ awọn ọmọde to ba fi orukọ silẹ ninu iwe naa.
A dàbí omi tí ó dà sílẹ̀, tí ẹnikẹ́ni kò sì lè kójọ mọ́.
8 147157 Orilẹede Naijiria 1180 0.
Agboke salaye pe olusakojopo eesi idibo ijoba Ibile naa ni lati tun eesi idibo
"Irọ́ ni, abẹ́rẹ́ àjẹsára Covid-19 kò lè ṣàyípadà DNA rẹ Àwọn agbègbè tí àtùndi ìbò yóò kàn lọ́jọ́ Àbámẹ́ta nípìnlẹ̀ Eko rèé Wo ọ̀nà tóo lé tọ̀ láti gba físà tóo bá fẹ́ ṣiṣẹ́ ní UK lábẹ́ ìlànà tuntun Ilé-ẹjọ́ kòtẹ́milọ́rùn fòntẹ̀ lu ìdájọ́ ikú fún Maryam Sanda tó gún ọkọ rẹ̀ pa Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Kayeefi: 'Ọkọ mi ṣẹ̀ṣẹ̀ ní kí n lọ se mọ́í-mọ́í, tó ṣẹ̀ bá mi ṣeré tán ni mo gbọ́ pé ""Mopol"" yìnbọn pa á' Adolf Hitler Uunona jawe olubori labẹ asia ẹgbẹ Swapo to jẹ ẹgbẹ to wa lori oye níbẹ."
"Ìkọlù agbébọn tó ṣékú pá ọmọ ogún Niger 89, iṣẹ́ bọ lọ́wọ́ Ọgágun àgbà Fọ́fọ́ ní ilé ẹjọ́ kún fún ìdájọ gomina ìpínlẹ̀ Kano, Imo, Sokoto, Benue, Plateau àti Bauchi Ọdún mọ́kànlá sẹ́yìn ni K1 ti ń béèrè fún oyè Mayegun lọ́wọ́ mi - Alaafin Àwọn ọjọ́ ìsìnmi tó máa wà nínú ọdún 2020 ní Nàìjíríà O wa salaye pe ""eto Amotekun ko ni ohunkohun se pẹlu ẹgbẹ oselu kankan, bẹẹ lo si kọja agbara ẹda kankan, idi si ree ti gbogbo ọmọ Yoruba fi gbọdọ ri eto naa gẹgẹ bii ipe lati sin ilẹ abinibi wa."
Akọwe eto iroyin fun gomina Kayode Fayemi, Olayinka Oyebode lo fi lede bẹẹ ninu atẹjade kan.
niluu Abuja nibi ayeye to waye , ti won pe akori re ni’Eri iyipada’ lati fi salaye
Aya Aare orile-ede Naijiria, Aisha Buhari ti gba ipo, gege bi asoju pataki tuntun fun ajo UNAIDS, lori ipolongo didekun atagba aarun HIV/AIDS latara iya si omo inu re, ati pipolongo sise itoju awon omode ti won gbe pelu aarun HIV lorile-ede Naijiria.
 Àkọsílẹ ̀ lórí ìbẹ ̀ rẹ ̀ ìdàgbàsókè àwọn èdè yìí kò pọ ̀ .
Davido omo Adeleke, to je gbajugbaja onkorin takasufe ni Naijiria ti fi agbon nla ko ami eye lo sile pelu onkorin Simi nibi ifamieye o pegede ti Headies lojo Abameta, eyi to je eekejila re.
'Àwọn agbébọn tó pá Olufon ti Ifon ti ṣe ohun èèwọ̀ ní ilẹ̀ Yoruba' Àwọn onímọ̀ ṣàlàyé àǹfàní tó wà nínú gbígba ajaguntà láti kojú Boko Haram Awakọ̀ agbókùú, ọlọ́pàá, ológun, oníròyìn ló máa ń kọ́kọ́ dìbò ní Ghana, bó ṣe ń lọ rèé Olorì Aláàfín tẹ́lẹ̀, Anuoluwapo Adeyemi gba àmì ẹ̀yẹ lórí ipa tó kó nínú oge ṣíṣe Ṣaaju ni ariyanjiyan ti kọkọ waye laarin awọn ọmọ ile igbimọ aṣoju lori boya ki wọn ke si Aarẹ tabi ki wọn ma ṣe bẹẹ.
Laye atijọ olukọ dabi obi ati alagbatọ fawọn akẹkọọ, ṣugbọn nkan ti yipada lasiko yii nile ẹkọ giga gbogbo.
Ajọ to n si sami ayẹyẹ aadọta ọdun ti eniyan wọ inu osupa naa NASA, pẹlu sise afihan fidio bi wọn se wọ inu osupa ọhun, eyi to fun iran tuntun to le ni idaji biliọnu kan lanfaani, lati ri ohun to sẹlẹ ni aadọta ọdun sẹyin.
“Ààwẹ̀ tí ẹ̀ ń gbà ní oṣù kẹrin, oṣù karun-un, oṣù keje, ati oṣù kẹwaa yóo di àkókò ayọ̀ ati inú dídùn ati àkókò àríyá fun yín.
Lọwọlọwọ bayi o wa ni ahamọ ọlọpaa nibi ti wọn ti fẹsun ipaniyan kan an.
Ni adajọ agba ba pa a laṣẹ pe ki wọn wa ni atimọle titi di igba ti wọ́n ba lee san beeli wọn.
Oríṣun àwòrán, State House Bi wọn ṣe n sọko ọrọ lori ikanni ayelujara Twitter naa, ni wọn bu ẹnu ẹtẹ lu Aarẹ loju opo Facebook.
Ile iwosan Jinyintan Hospital ni Wuhan, China, ni awọn meji kan ti kọkọ ku gẹgẹ bi alaye to wa ninuiwe igbadegba nipa isegun Lancet Medical journal.
Ta ni ń já ọ láyà,tí ẹ̀rù rẹ̀ bà ọ́, tí o fi purọ́;tí o kò ranti mi, tí o kò sì ronú nípa mi?
Ninu asọ ọgba ẹwọn alawọ omi ọsan lowa to ti n sọrọ bi iṣẹlẹ naa ṣe waye lowurọ kutu ọjọ kẹwa oṣu kẹrin ọdun 1994.
"Oríṣun àwòrán, Olusegun Obasanjo ""O yẹ ka da silẹ, ka tun ṣa ni lasiko yii, ka lee wa ojutu sawọn isoro to n mi ẹka eto aabo Naijira logbo-logbo, o si yẹ ka ba ara wa sọ ootọ ọrọ lori rẹ, lai fi epo bọyọ."
Super Eagles fẹyin Angola gbo'lẹ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Super Eagles: Akojọpọ aworan asọ fun ife ẹyẹ agbaye Saaju ni olukọni ikọ agbabọọlu Super eagles, Gernot Rohr ti fiwe pe awọn agbabọọlu mejidinlọgbọn ti yoo kopa ninu ifẹsẹwọnsẹ ọlọrẹsọrẹ ti yoo waye naa.
Ẹ bá mi wá nọ́ńbà ìpè òbí ọmọ Mummy Calm Down jáde - Yinka Ayefele Ìpalẹ̀mọ́ ọdún Ileya kò rọgbọ ní Maiduguri, ojo ado oloro n rọ leralera N kò ri ipa ẹ̀jẹ̀ lára ọmọ mi tó kú sí iléeṣẹ́ ọṣẹ, èjò lọ́wọ́ nínú - Òbí àkẹ́kọ̀ọ́ UI Akpata di aàrẹ àjọ àwọn agbẹjọ́rò ní Nàìjíríà, ọ̀pọ̀ èèyàn kíi kú oríire Ipinle Oyo lo kọkọ́ bẹrẹ bayii: Ìpínlẹ̀ Oyo kéde àdínkù owó orí nítorí Covid 19 Coronavirus Updates in Oyo: Seyi Makinde kéde àdínkù owó orí nítorí Covid 19- Akinola Ojo Oríṣun àwòrán, Seyi Makinde/Dreamstime Komisọnna eto ẹnawo ni ipinẹ Oyo lo kede bẹ́ẹ̀ lorukọ Gomina Seyi MAkinde.
Ó bá bẹ baba rẹ̀, ó ní, “Kinní kan ni mo fẹ́ kí o ṣe fún mi, fi mí sílẹ̀ fún oṣù meji, kí èmi ati àwọn ẹlẹgbẹ́ mi lọ sí orí òkè kí á máa káàkiri, kí á sì máa sọkún, nítorí pé mo níláti kú láì mọ ọkunrin.
Jahati ni ó jẹ́ olórí, Sisa ni igbákejì rẹ̀, ṣugbọn Jeuṣi ati Beraya kò bí ọmọ pupọ, nítorí náà ni wọ́n fi kà wọ́n sí ìdílé kan ninu ọ̀kan ninu àwọn àkọsílẹ̀.
Ó dìgbà o, ó dìgbà o.
O ni ijamba naa waye ni ọjọ mẹta ṣaaju ọjọ ibi rẹ, lasiko ti oun n jade.
Akin ni ó sọ pé, Ajímutí kìí tí’ Akin náà ni ó sọ pé, ‘Ẹni fojú di Pópó á gba póńpó lórí…’.
Oríṣun àwòrán, Ojude Oba Facebook Aṣa sise Kade pẹ lori, ki bata pẹ lẹsẹ fun ọba: Lara awọn ohun pataki ti kii gbẹyin lasiko ọdun Ojude Ọba ni asa lilọ ki ọba pe ki ade pẹ lori, ki bata pẹ lẹsẹ, ki ẹsin ọba si jẹ oko pẹ.
Bakan naa ni ọjọgbọn naa tun yin wọn fun atilẹyin wọn fun Ile-ẹkọ Fafiti Ipinlẹ Eko (LASU) ati bi wọn ṣe ṣalekun ọdun ti awọn to ṣẹṣẹ bimọ yoo maa lo nile, gẹgẹ bI ọiṣẹ ijọba ki wọn to pada sẹnu iṣẹ, eleyii ti o ti di oṣu mẹfa bayii, lati oṣu mẹrin to wa tẹlẹ.
O ni iwa ẹlẹya mẹya ti ti oju oun ri ni ilẹ South Afrika ko kere ni pataki laarin awọn eniyan alawọ dudu ilẹ naa.
”Omo odun méjídínláàdọ́rin ohun, bere si ni n tuko agbaboolu Arsenal lati odun 1996, ti O si tuko ohun gba ife eye idije ile geesi meta (EPL), ife eye idije FA meje.
Ṣebí OLUWA yí ibi tí ó ti pinnu láti ṣe sí wọn pada, nítorí pé Hesekaya bẹ̀rù OLUWA ó sì wá ojurere rẹ̀.
Gbajugbaja atamatase ikọ naa ti o jẹ Balogun Kaafata Black Stars Asamoah Gyan ko tilẹ mọ boya oun yoo tun kopa ninu idije AFCON mi mọ lẹyin ijakulẹ yi.
“Bí o bá sọ ọ̀rọ̀ yìí fún àwọn eniyan náà tán, bí wọn bá bi ọ́ pé, ‘Kí ló dé tí OLUWA fi sọ gbogbo ọ̀rọ̀ burúkú yìí nípa wa?
Nítorí, àfi Ọlọ́run Ọba ló lè san oore tí o ṣe fún mi.
Dino Melaye -Kogi Lara awọn ti ile ẹjọ to n gbẹsun idibo da pada sile ni Sẹnetọ Dino Melaye to n soju ẹkun idibo iwọ oorun ipinlẹ Kogi.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Adebola Ademilua: Àìrísẹ́ ṣè lẹ́yìn ìwé kíkà ló sọ mi dí ìyá onírú, mo dúpẹ́ tèmi Bibi akanda ọmọ: Ajọ eleto ilera NHS sọ pe, iṣoro arun ajogunba wa kaakiri ni gbogbo awujọ lagbaaye.
Ilé ẹjọ́ tí sún igbejọ lori ẹsun ijọmọgbe ti wọn fi kan gbajugbaja wolii kan ni ilu Akurẹ, Alfa Babatunde ti p eeyan m si Sọtitobirẹ siwaju di ọjọ́ kẹjọ oṣù kẹfà ọdún yìí láti jẹ ki igbejo náà yà kíákíá.
Aṣiri nla ti maa gbe wọ koto ni.
Nípa igbagbọ ni Rahabu aṣẹ́wó kò fi kú pẹlu àwọn alaigbagbọ, nígbà tí ó ti fi ọ̀yàyà gba àwọn amí.
O wa fi da awọn ọmọ orilẹede Naijiria loju pe eera kan ko ni rin ibo wọn nitori ajọ naa ṣetan lati rii pe eto idibo apapọ ọdun 2019 kẹsẹjari.
Judasi bá mú àwọn ọmọ-ogun ati àwọn ẹ̀ṣọ́ láti ọ̀dọ̀ àwọn olórí alufaa ati àwọn Farisi, wọ́n wá sibẹ pẹlu ògùṣọ̀ ati àtùpà ati àwọn ohun ìjà.
Nídà kejì, bí ọ̀rọ̀ àwùjọ-ẹ̀dá ba jẹ́ kónkó-jabele, ẹ̀tẹ́ àti wàhálà ni ojú ọmọ ènìyàn yóó máa rí.
"A ṣi n ba wọn duna-dura lati yọnda papa iṣere naa fun wa lati gbalejo aarẹ.
Bẹ́ẹ̀ ni bàbá mi máa ń sọ fún wa ígbà tí a wà ní èwe, nígbà tí a bá jókòó sí ibi ẹsẹ̀ rẹ̀ tí a ba ń bá ṣiré, bi mo sì ti n ssọ̀rọ̀ yìí, ìwọ ọ̀rẹ́ mi, diẹ ló kù ki omi bọ́ lójú mi nítorí mo rántí bàbá mi Olówó-ayé, arẹwà kọ́kùnrin.
“N kò gbadura fún àwọn wọnyi nìkan.
Ṣé o dá ara rẹ lójú?
O tun tesiwaju pe “Inu mi dun bo tile je pe eto idibo odun 2019 ti n sun mo etile.
Moshood Jimoh ni ọga olopaa ti ṣaaju paṣẹ fun ikọ apapọ ọtẹlẹmuyẹ eleyi ti ọga agba ọlọpaa fun ikọ ọtẹlẹmuyẹ ko sọdi lati lọ si Zamfara ki wọn si bẹrẹ iwadi lori isẹlẹ ipaniyan to waye nibẹ.
Adewale ni wọn ni o jẹbi ẹsun ipaniyan pẹlu ẹnikeji rẹ, Lateef Balogun to jẹ oṣiṣṣẹ ninu ile arabinrin ọhun.
Bí ẹnìkan bá bi yín ní nǹkankan, ẹ dá a lóhùn pé, ‘Oluwa nílò wọn.
 Epe yii si ni ọpọlọpọ eeyan maa n tọkasi lasiko ti idaluru, aawọ, iyapa ati aigbọraẹniye ba wa laarin awọn olori, araalu, paapaa awọn oloselu ati ẹya Yoruba lapapọ."
Aarẹ Buhari ko se gbọkanle pe o ni baba ni igbẹjọ Ẹkọ pataki yii la ri kọ lati ara aawọ to waye laarin Adams Oshiomole ati Godwin Obaseki.
Ibi to si ti n ṣe ọmọọdọ olounjẹ lo ti pade ọkunrin keji, to bi ọmọ meji fun.
“Nítorí náà, mo pàṣẹ pé, ẹnikẹ́ni, tabi orílẹ̀-èdè ati ẹ̀yà tí ó bá sọ̀rọ̀ àbùkù sí Ọlọrun Ṣadiraki, Meṣaki ati ti Abedinego, fífà ni a ó fa irú ẹni bẹ́ẹ̀ ya ní tapá-titan, a ó sì sọ ilé rẹ̀ di ahoro; nítorí kò sí ọlọrun mìíràn tí ó lè gbani là bẹ́ẹ̀.
Wọn gbiyanju lọdun 1982, 1994, 1998, 2002, 2006, 2010, 2014, ati 2018 ṣugbọn wọn ko jawe olubori lati le kopa ninu ife ẹyẹ agbaye.
nítorí mo mọ̀ pé ọlọ̀tẹ̀ ati olóríkunkun ni yín; nígbà tí mo wà láàyè pẹlu yín lónìí, ẹ̀ ń ṣọ̀tẹ̀ sí OLUWA, kí á má ṣẹ̀ṣẹ̀ wá sọ ìgbà tí mo bá kú tán.
Orukọ baba rẹ ni Yusuff Gbogbolowo, tii se alagbẹdẹ ati orukọ iya rẹ ni Wuramọtu Morẹnikẹ, gẹgẹ bo se maa n ki ara rẹ.
Ọrọ yi mu ibinu wa lọdọ awọn ọmọ Naijira.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Khadijat ni awakọ̀ Bàálù àkọ́kọ́ láti Ọffa Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Khadijat ni awakọ̀ Bàálù àkọ́kọ́ láti Ọffa 3 Owewe 2018 Bi eeyan ba kọkọ ri Khadijat Olabanke Adigun o seese ki o lero wi pe ko ni nnkankan se pẹlu ọkọ baalu wiwa.
Má bẹ̀rù, má sì jẹ́ kí ọkàn rẹ rẹ̀wẹ̀sì; nítorí OLUWA Ọlọrun, àní Ọlọrun mi, wà pẹlu rẹ.
Mo le ri nnkan loju, ki n si sọ dorin.
 nneka gba ìmọ ̀ orin kíkọ ́ lóòórọ ̀ ayé ẹ ̀ nílé ìwé ẹ ̀ àti nínú ẹgbẹ ́ akọrin ti ilé ìjọsìn .
Alaafin Oyo: Olorì Anuoluwapo Adeyemi gba àmì ẹ̀yẹ lórí oge ṣíṣe
" Ó pè é ní "" osuofia in london "" ."
Àwọn ìgbà tí jándùkú òṣèlú tí wáyé ní Nàìjíríà
Laarin idije ija naa, bi Colby ṣe n ta a ni Kamaru n gbakuru mọ ọ koda o tun fi ẹṣẹ fọ Colby leyin isalẹ ti gbogbo oju rẹ si kun fun ẹjẹ.
Pọtifari yìí jẹ́ ọ̀kan ninu àwọn ìjòyè Farao, òun sì tún ni olórí àwọn tí wọn ń ṣọ́ ààfin ọba.
 Ṣùgbọ ́ n ìgbẹ ́ ayé gama gẹ ́ gẹ ́ bí amòfin , òǹkọ ̀ wé àti olóṣèlú fi hàn gbangba pé ẹni tí ó nífẹ ̀ ẹ ́ sí òmìnira tẹrú-tọmọ ni .
Ajọ agbabọọlu lagbaye, FIFA ti ni ki Nyantakyi to jé ọmọ igbimọ FIFA lọ rọọkun sile fun aadọrun ọjọ.
Mo ti ṣí ìlẹ̀kùn ilé ìṣúra àwọn nǹkan ìjà yín,mo sì kó àwọn ohun ìjà ibinu yín jáde,nítorí èmi OLUWA Ọlọrun àwọn ọmọ ogun ní iṣẹ́ kan láti ṣe ní ilẹ̀ àwọn ará Kalidea.
Onimọ ijinlẹ kan nipa bi eeyan ṣe n ronu nilẹ South Africa, Nthabiseng Ramothwala ni o yẹ ki awọn ara adugbo jẹ oluranwọ aladugbo wọn ti wọn lero pe o le ma la igbeyawo to ni iwa ipa kọja.
Ọmọ eniyan á sì jáde lọ síbi iṣẹ́ rẹ̀,á lọ síbi làálàá rẹ̀ títí di àṣáálẹ́.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Morocco Journalist: Wọ́n gbé Akọ̀ròyìn ní Morocco lọ sílé ẹjọ́ lórí ẹ̀sùn àgbèrè àti oyún ṣíṣẹ́ 8 Owewe 2019 Oríṣun àwòrán, @others Àkọlé àwòrán, Ẹṣẹ ni agbere ati oyun ṣiṣẹ ni orilẹ-ede Morocco bayii nitori ẹsin Islam wọn Ọpọ awọn ajafẹtọ ọmọniyan ti dide iranlọwọ lati gbeja obinrin akọroyin yii.
“Pàṣẹ fún àwọn eniyan Israẹli pé kí wọn mú ojúlówó òróró olifi wá fún títan iná, kí wọ́n lè gbé fìtílà kan kalẹ̀ tí yóo máa wà ní títàn nígbà gbogbo.
Ṣé igbagbọ yìí lè gbà á là?
Wọ́n bá gbadura sí OLUWA, wọ́n ní, “A bẹ̀ ọ́, OLUWA, má jẹ́ kí á ṣègbé nítorí ti ọkunrin yìí, má sì ka ẹ̀jẹ̀ aláìṣẹ̀ yìí sí wa lọ́rùn; nítorí bí o ti fẹ́ ni ò ń ṣe.
Iwa jẹgudu-jẹra gbayi l'orilẹede naa Oríṣun àwòrán, MARCO LONGARI Cameroon ti gba ami ẹ̀yẹ fun iwa ibajẹ lẹẹmeji, kekere kọ si ni kiko owo ìlú jẹ lati igba ti Aarẹ Biya ti wa nipo fun ọdun marundinlogoji bayii.
Bakan naa lo tun gbe obitibiti owo kalẹ fun igbimọ naa lati fun gbogbo awọn ti ẹri wọn ba dantọ lori ẹjọ ti wọn ba fi kan agbofinro to ba tasẹ agẹrẹ.
) Obinrin yìí jẹ́ ẹnìkan tíí máa ṣe ọpọlọpọ iṣẹ́ rere, ó sì láàánú pupọ.
Lọwọlọwọ, eniyan 19,808 lo ti ni, 6,718 ti ri iwosan, awọn 506 si ti ku.
Wọn ni Bagudu, tii se korikosun Buhari ati eekan kan ninu ẹgbẹ oselu APC, nijọba ilẹ Amẹrika ti fẹsun kan saaju pe oun lo seranwọ fun Abacha lati fẹyin pọn aimọye biliọnu dọla jade kuro ni Naijiria nidaji saa ọdun 90s.
Kí ẹnikẹ́ni tí ó bá ru èyíkéyìí ninu àwọn nǹkan tí ẹni náà fi jókòó, fọ aṣọ rẹ̀, kí ó sì wẹ̀; olúwarẹ̀ yóo jẹ́ aláìmọ́ títí di ìrọ̀lẹ́.
 lati san owo gba –maa-binu fun awon
oun ati awon eniyan  re se koworin wa pe,
Ajo to n mojuto eto Ilaniloye lorile-ede Naijiria (National Orientation Agency, NOA)  so pe, eto liana lenu ise se pataki fun idagbasoke orile-ede.
''Iwe iroyin mi kii gbe ayederu iroyin tabi eyi to le ba orukọ ẹnikẹni jẹ, jade .
Kò sí òògùn kankan tó ń mú mi bí ìbejì bíkòṣe oúnjẹ ìbílẹ̀ - Aláàfin Ọyọ Ṣé ìpèsè iná ọba yóò wà lọ̀dún 2020 torí ₦9bn nìjọba fẹ́ ná fún ẹ̀rọ amúnáwá?
Púpọ̀ nínú àwọn wọn-ọnnì ni ó dà bí ènìyàn gan-an bẹ́ẹ̀ ni ọba Igbó Olódùmarè pàápàá kò yàtọ̀ sí ìwọ àti èmi.
Ó di àwọn nǹkan dáradára ilẹ̀ Ijipti ru kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ mẹ́wàá, ó di ọkà ati oúnjẹ ru abo kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ mẹ́wàá, ó kó wọn ranṣẹ sí baba rẹ̀ pé kí ó rí ohun máa jẹ bọ̀ lọ́nà.
Ẹ̀ẹ̀kan láàrin ọjọ́ méjì là ń jẹun ní ìgbèkùn, ìyà jẹ wá - Akẹ́kọ̀ọ́ Kankara ṣàlàyé Sé Boko Haram ń pẹ̀ka kiri Nàíjíríà ní ìjínigbé ṣe burú báyìí?
Òṣùṣùerékùṣù indonesia ti jẹ ́ agbègbè òwò pàtàkì láti ọ ̀ rúndún keje , nígbàtí srivijaya àti majapahit ṣòwò pẹ ̀ lú Ṣáínà àti india .
Ṣina Peters bú sẹ́kún lórí ikú Ras Kimono, pé ẹni rere lọ
Nidi ATM wayi, tẹ 'Enter' lara awọn bọtinni to wa lara ATM naa.
Oyerinde ṣe akiyesi wi pe ọlaju lo ṣe okunfa ina iṣegun ibilẹ ilẹ adulawo to n jo ajorẹyin.
Ibi tí mo ti ń sá kiri yìí ni mo ti rí abẹ̀ ìtàkùn ńlá kan tí ó kún fún ewé, tí ó ní oríṣiríṣi ìpàǹtí, tí ó dà bí awùsá tí ó si rí rẹ̀gẹ̀jìrẹ̀gẹ̀jì.
Ẹkunrẹrẹ data Sun atẹ wa silẹ tabi oke lati ri ẹkunrẹrẹ akọsilẹ *Iye awọn to tọwọ aisan ku ni isọri eeyan ẹgbẹrun lọna ọgọrun Gbe e yẹwo: Àgbáyé Orilẹede Afrika Ariwa Amẹrika Apa Latin Amẹrika ati Caribbean Ilẹ Asia Ilẹ Yuroopu Agbegbe Middle East Erekusu Oceania Iye to ti ku Iye awọn to ku %* Apapọ awọn iṣẹlẹ arun Akọtun arun yii 0 10 100 1000 10000 ** Orilẹede Amẹrika 280985 85.
"Funke Akindele ti di ìyábejì Àwọn sinimá tó pegedé ni 2018 lágbàyé Njẹ o mọ oju yi ni ""Yollywood""?"
Ẹni tí ó ń sálọ nítorí ìpayà,yóo jìn sinu ọ̀gbun,ẹni tí ó bá sì jáde ninu ọ̀gbunyóo kó sinu tàkúté.
wọn naa dabi awọn ọlọpaa ilu.
Sẹnẹtọ Shehu Sani kin ọrọ ti Omotola sọ lẹyin, o ni ohun ti ọpọ eeyan ti ko rọwọ họri n la kọ ja ni Omotola sọ jade.
Awon ile ise Condé Nast International, to n gbe iwe iroyin yii jade ko tii soro lori koko yii.
Afunrasí jàǹdùkú 22 lọ́wọ́ ọlọ́pàá ti tẹ̀ lórí wàhálà ìdìbò ní Kogi-Iléeṣẹ́ Ọlọ́pàá 'Àwọn olósèlú rán aṣọ ọlọ́pàá f'àwọn ayédèrú ọlọ́pàá ní Kogi ati Bayelsa' Ogun ló ń wáyé ní Kogi, kìí ṣe ìbò dídì - Olùdíje gómìnà Àwọn jàndùkú dáná sun Aṣáájú obìnrìn ẹgbẹ́ òṣèlú PDP mọlé ní Kogi Ẹ̀yin ẹ̀ṣọ́, ẹ kò gbọdọ̀ fààyè gba jíjí àpótí ìdìbò ní Kogi àti Bayelsa- Buhari Idibo ọjọ kẹrindinlogun, Osu Kọkanla, ọdun 2019 ni wọn fẹ tundi nitori wahala ati rogbodiyan to bẹ silẹ ni ọjọ idibo Àjọ Ìsọ̀kan Yúròòpù àti Amẹ́ríkà bẹnu ẹ̀tẹ́ lu ìdìbò Kogi àti Bayelsa.
Fún ji jade ojoojúmọ́, a lè lo ipèlé aṣọ àdirẹ àti àwọn aṣọ igbàlódé  lati fi wé gèlè, ṣùgbọ́n fún òde gidi, gèlè igbàlódé tàbi Aṣọ Òfì ti wọn npe ni Aṣọ Òkè ni Yorùbá ma nwe.
Lára ǹkan ti wọn ń mú gbọ́ náà ni kíní ìdi gan ti ó mú Atiku fìdírẹ̀mi?
#EndSARS: Oṣinbajo ní Ìjọba àpapọ̀ ti ń wáàdí àṣemáṣe ikọ̀ SARS
"Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Oluwaremilekun Fatolu: Mo máa ń wọ kọ́mú “size 50H"", ẹyọkan leè tó N15,000, Okrika N9,000 Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Oluwaremilekun Fatolu: Mo máa ń wọ kọ́mú “size 50H"", ẹyọkan leè tó N15,000, Okrika N9,000 28 Ọ̀wàrà 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 2 Bélú 2020 ""Ti wọn ba ti debẹ tan."
Bakan naa lo ni ọrọ ri fun inawo lori iwe alakọle ti wọn na miliọnu mẹrindinlaadọta le lori, eyi to ni wọn pin fun ileeṣẹ agbaṣẹṣe mọkanla ti ọkọọkan wọn si gba miliọnu marun naira.
Tinubu sọ pe pipa ti wọn pa awọn agbẹ naa, to n tiraka lati pese fun ẹbí wọn ati oúnjẹ fun orile-ede Naijiria, ko yatọ si iwa ika ati ti Satani.
Ẹ wo ohun tí wọn yóò máa ṣe ní ìpínlẹ̀ - DAWN Commission Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 3 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 5 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Ọkan gboogi ninu ẹgbẹ oṣelu APC, Sogbogbe Eli lo kọkọ fi idi ẹ mulẹ pe awọn ipo adari ninu ẹgbẹ oṣelu APC ṣofo ni Giadom ṣe di adele alagba.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ìtàn rèé nípa bí Ogbomoso ṣe pa ọba, yọ nǹkan ọkùnrin rẹ jó kiri ìlú Ẹ fi dókítà àgùnbánirọ̀ rọ́pò àwọn dókítà tó ń yanṣẹ́ lódì - Ìjọba àpapọ̀ pàṣẹ Afenifere fara ya lórí bí Tinubu ṣe jókòó kí Ooni Háà ilẹ̀ wẹ!
Nígbà náà ni yóo kúrò lọ́dọ̀ rẹ, òun ati àwọn ọmọ rẹ̀, yóo pada sí ọ̀dọ̀ àwọn eniyan rẹ̀, ati sórí ilẹ̀ ìní àwọn baba rẹ̀.
"Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Akomolede ati Asa lori BBC: Olùkọ́ Kikelomo Ogunboye tan ìmalẹ̀ sí ìwà olè ọ̀gá ọlọ́pàá Mike Pompeo ni, ""loni, Amẹrika ti tọka si Burma, China, Eritrea, Iran, Nigeria, North Korea, Myanmar, Pakistan, Saudi Arabia, Tajikistan, ati Turkmenistan gẹgẹ bi awọn orilẹ-ede to n kọ agbaye lominu labẹ ofin ominira ẹsin lagbaye tọdun 1998 fun titẹ oju ofin ominira ẹsin mọlẹ."
omo egbe All Progressives Congress APC.
Àyipadà ni Ìjọba pẹ̀lú pe Olóri Òṣèlú Muhammadu Buhari/Yẹmi Osinbajo ti ó gbógun ti iwà ibàjẹ́, ló jẹ ki àṣiri iṣẹ́ ibi wọnyi jade si ará ilú bi àwọn ti ó  wà ni ipò giga ti nlo ipò lati fi hu iwà ibàjẹ́ nitori àti kó ọrọ̀ jọ ni ọ̀nà ẹ̀bùrú.
Ọgbọ́n inú níí mú kí ọ̀rọ̀ ọlọ́gbọ́n tọ̀nà,ọ̀rọ̀ ẹnu rẹ̀ a sì máa yíni lọ́kàn pada.
Ohun ti o sọ re e: Aisan kokoro oju ara Aisan kokoro oju ara, Urinary Track Infections ma n fa ki agbalagba ma a tọ sile ti wọn ko ba moju to o ni kiakia.
“Ẹ̀yin obinrin Israẹli,ẹ sọkún nítorí Saulu,ẹni tí ó ro yín ní aṣọ elése àlùkò,tí ó sì fi ohun ọ̀ṣọ́ wúrà ṣe yín lọ́ṣọ̀ọ́.
Dákẹ́ jẹ́ẹ́ níwájú OLUWA; fi sùúrù gbẹ́kẹ̀lé e.
Wọ́n dé ibi tí odò wà tẹ́lẹ̀,ṣugbọn òfo ni wọ́n bá.
Bi o tilẹ jẹ pe Duro Ladipọ ko si laye mọ, ọpọ awọn agba iwoyi ni ko lee gbagbe ere Ọba Koso, Sango, Ajagun Nla, Ẹda, Bode Wasinmi, ati bẹẹ bẹẹ lọ.
Ó ní àwọn tí wọ́n ń ṣe àkóso àtúnṣe ilé náà kò ní nílò láti ṣe ìṣirò owó tí wọn ń ná, nítorí pé gbogbo wọn ni wọ́n jẹ́ olóòótọ́.
Àwọn ọmọ Nàìjíríà la ohùn Aeroplane House: Látọdún 1999 ni mo ti bẹ̀rẹ̀ kíkọ́ ilé yìí fún ìyàwó mi ọ̀wọ́n Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Awọn afurasi naa ni ọwọ awọn ọmọ ikọ pataki ti ileeṣẹ ọlọpaa gbe kalẹ lati gbogun ti ijinigbe, Operation Puff Adder tẹ ni ẹkùn Ariwa Naijiria.
”Fayẹmi dupe lowo gbogbo awọn agba ẹgbe APC ati aarẹ Muhaamadu Buhari atawọn to ku laiyọ ẹbi, ara ati iyawo rẹ, Bisi silẹ fun atileyin wọn.
Mercy Aigbe : Oríṣun àwòrán, Mercy Aigbe Odu ni Mercy Aigbe ninu awọn sinima ede Yoruba, kii si ṣe aimọ fun oloko rara nitori ẹwa ati ede Yoruba ẹnu rẹ to dantọ.
milionu mesan an ti won  n je anfaani ounje
Ọgbẹni Makama o wa ba afurasi kan ninu wọn ti ibọn wa lọwọ rẹ.
96bn Bí èèyàn méjì tí ṣé kù nígbà tàwọn jàǹdùkú wọ̀yá ìjà ní ìlú Èkó-Ọlọ́pàá Mo ti gba pé ológun ni ọkọ mí- Aisha Buhari Mo ṣẹ̀ṣẹ̀ já ọjà 10 mílíọ̀nù ní iná jó, ẹ dákún é gbà wá-Ọlọ́jà Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí kan sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
O ni iṣẹ ti awọn alalẹ gbe le oun lọwọ ni lati lọ igi alaafia ni alọye laaarin awọn lọbalọba ati ọmọ bibi ilẹ Yoruba lagbaye.
Aṣọ funfun ati siliki tí wọ́n ṣe iṣẹ́ ọnà sí lára ni mo dá fún ọ.
Àwọn olùsìn ẹ ̀ sìn ìbílẹ ̀ pọ ̀ ni Ìrèlè .
O tun mẹnu idi ti o fi n gbaruku ti Laycom nile Ẹlẹgbọn Agba iyẹn Big Brother Naija.
Bakan naa ni ero awọn ọmọ Naijiria lori ẹrọ ikansiraẹni Facebook se ọtọọtọ lasiko ti wọn n fesi si iwe ipolongo tuntun naa.
"Oun to rẹwa ni lati ri bi ero ọkan wa ti se ri si ara wa""."
OLUWA sì dá Mose lóhùn pé, “N óo mú kí ẹwà mi kọjá níwájú rẹ; n óo sì pe orúkọ mímọ́ mi lójú rẹ, èmi ni OLUWA, èmi a máa yọ́nú sí àwọn tí ó bá wù mí, èmi a sì máa ṣàánú fún àwọn tí mo bá fẹ́.
Olori Ọmọ ẹgbẹ oṣelu to pọ ju lọ ninu Ile naa, Aṣofin Sanai Agunbiade fi mulẹ pe ọrọ naa ju oro pe wọn ji ọpa aṣẹ nikan gbe lọ, o tumọ si pe awọn ọmọ ẹgbẹ Ile Igbimọ Aṣofin Agba naa wa ninu ewu aisaabo fun wọn.
Alufaa yóo ṣe ètùtù fún un, OLUWA yóo sì dáríjì í.
Kí ló mú ọlọ́pàá wú òkú géńdé nínú sàréè l'Ondo Ìjọba Amẹrika fi ojú àwọn ọmọ Yahoo mẹ́fà léde, wọ́n gbẹ́sẹ̀ lé dúkìá wọn Ìwadìí ti bẹ̀rẹ̀ lórí àrá tó sán pa òṣìṣẹ́ FRSC mẹ́ta nípínlẹ̀ Ogun- Ọ̀gá àjọ FRSC Ohun tí a mọ̀ nìyí nípa ìròyìn Ajimobi kú, kò kú, táyé ń gbé kiri Ni Mosalasi Jimọ Government Girls Day Sec school ni Pakata, mosalasi naa kun fọfọ ni ti ko si si apẹrẹ pe awon eeyan n tẹle ilana ijinasiraẹn lasiko ti arun Covid-19 n ja kalẹ.
Ó bá kọjú sí òkú náà, ó ní, “Tabita, dìde.
O jẹyọ nigba ti Gomina Ajimobi ti ipinlẹ Oyo n fesi si ẹsun wi pe o paṣẹ ki wọn wo ile iṣẹ rẹdio gbajugbaja akọrin, Yinka Ayefẹlẹ niluu Ibadan.
ninu eyi ti o ti n yọ ara rẹ kuro ninu iroyin kan ti awọn kan n pin kaakiri ikanni ibanisọrọ Whatsapp pe ẹgbẹ oṣelu PDP ati Saraki ti gba ijakulẹ wọn, wọn si ti ki ẹgbẹ oṣelu APC atawọn oludije rẹ ku oriire.
Ilé yìí dára púpọ̀, ó dárá ju ààfin ọba pàápàá lọ.
marundinlaadọta-lerinwo (739, 445) esi ibo fakọyọ mọ akẹgbẹ wọn lati ẹgbẹ oṣelu
Ise akanse ohun ni ireti wa tele pe, won yoo pari re laarin osu mejidinlogun, sugbon ti o wa si ipari laarin odun marun un.
Wọ́n bá bẹ̀rẹ̀ sí bá ara wọn sọ̀rọ̀ pé, “Dájúdájú, a jẹ̀bi arakunrin wa, nítorí pé a rí ìdààmú ọkàn rẹ̀ nígbà tí ó ń bẹ̀ wá, ṣugbọn a kò dá a lóhùn, ohun tí ó fà á nìyí tí ìdààmú yìí fi dé bá wa.
ÌLÀNÀ TÓ DÁRA JÙLỌ Ó ti pẹ́ tí BBC tí ní àwọn ìlànà tó ń gba kọ ìròyìn tí yóò sí wà ní ìbámu pẹ̀lú àwọn àlàklẹ tí ó yẹ nínú ètò ìròyìn kíkọ.
Oríṣun àwòrán, others Lẹyin naa lo ni oun ti ni ki igbakeji oun ma a tukọ ilu lọ, ti oun yoo si ma a ṣiṣẹ lati iyẹwu.
Ó dàbí ọmọ tí ó kọ̀, tí kò jáde kúrò ninu ìyá rẹ̀ ní àkókò ìrọbí.
    Ìyàwó mi bú sẹ́rìn-ín, ó na ọwọ́ o ní ki n mú àdá náà fún òun, mo mú u fún un.
BBC News Yoruba fi idi rẹ mulẹ pe oludije fun ipo gomina ipinlẹ Kwara labẹ aṣia ẹgbẹ oṣelu APC, Abdulrazaq Abdulrahman ko si ninu eyikeyi ninu awọn ọkọ ti wọn kọlu lasiko naa gẹgẹ bii awọn iroyin kan ti n gbe e kiri.
"Tí a fiṣọwọ́ ní 17:01 4 Ọ̀pẹ̀ 202017:01 4 Ọ̀pẹ̀ 2020 Díẹ̀ ló kù kí ọjọ́ ìkúnlẹ̀ di ọjọ́ ikú fún ìyá mi lọ́jọ́ tó bí mi - Seyi Makinde Isin idagbere naa ti Gomina Seyi Makinde 'se fun iya rẹ waye ni gbagede ""Arcade"" ile ijọba ipinlẹ Ọyọ."
Koríko a máa rọ, òdòdó a sì máa rẹ̀nígbà tí OLUWA bá fẹ́ afẹ́fẹ́ lù ú.
”Michael  fikun oro re pe, laipe laijina awon odo orile-ede Najiria yoo tun ni anfani si awon ohun elo miran lorisirisi, ni ona lati mu idagbasoke ba ere-idaraya afigigba lorile-ede yii.
Ó ní ǹjẹ́ wọ́n mọ ohun tí òun ati baba òun ti ṣe sí àwọn orílẹ̀-èdè mìíràn?
Àwọn ìròyìn mìíràn tí ẹ lè nífẹ̀ sí: ''Modric kọ́ ni àmì ẹ̀yẹ FIFA tọ́ sí'' Ile Gẹ̀ẹ́sì, Amerika, EU dá sí ìdìbò Osun Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Adeleke fọhùn, 'èmi ni gómìnà tí wọ́n dìbò yàn' Ikọ D'Tigress ni agbabọọlu afọwọgba akọkọ bayii ti wọn yoo jawe olubori ninu ifẹsẹwọnsẹ meji ti wọn kọ gba ninu idije ife ẹyẹ agbaye.
 Ọdún 1938 ni ó di majísíréètì yìí .
" O wa beere pe ki ni ijọba yoo ṣe si awọn ibudo bii ọgba ẹwọn?
Ẹru n ba wọn lori eto ọrọ aje ilẹ Britiko ati ọwọngogo nkan ti erongba wọn ko ba ṣẹ.
Ọgagun yii ni ọpọ eeyan mọ si ẹni ti ko gba gbẹrẹ, onigboya, akikanju ati olotitọ ologun, to korira abẹtẹlẹ, ifiyajẹni ati iwa ibajẹ lorisirisi, eyi to yẹ ki ọpọ ọdọ iwoyi fi ṣe awokọse rere.
N óo sì jẹ́ kí àwọn eniyan wọnyi dàbí igi,iná yóo sì jó wọn run.
England); Samuel Kalu (Girondins Bordeaux, France); Paul Onuachu (FC
Oríṣun àwòrán, Twitter Ninu ọrọ tiẹ, Komisona fun eto iroyin ni ipinlẹ Oyo, Wasiu Olatunbosun ni, ijọba ko le e sọ pato igba ti awọn yoo bẹrẹ si ni san owo osu osisẹ tuntun.
Tolulope Arotile: Lọ́sẹ̀ tó ń bọ̀ ni awakọ̀-òfurufú jagun yóò wọ káà ilẹ̀ lọ l'Abuja Oríṣun àwòrán, Facebook/Nigeria Airforce Ileeṣẹ ologun ofurufu ti kede pe Ọjọbọ ọsẹ to n bọ tii ṣe ọjọ kẹtalelogun oṣu keje ni awakọ-ofurufu jagun, Tolulope Arotile yoo wọ kaa ilẹ lọ.
Wọ́n ni í lára, wọ́n pọ́n ọn lójú, sibẹsibẹ kò lanu sọ̀rọ̀,wọ́n fà á lọ bí ọ̀dọ́ aguntan tí wọn ń lọ pa,ati bí aguntan tíí yadi níwájú àwọn tí ń rẹ́ irun rẹ̀,bẹ́ẹ̀ ni kò lanu sọ̀rọ̀.
Yára dìde, kí o lọ tu àwọn ọmọ ogun ninu; nítorí pé mo fi OLUWA búra pé, bí o kò bá ṣe bẹ́ẹ̀, kò ní ku ẹnìkan ninu wọn pẹlu rẹ ní òwúrọ̀ ọ̀la.
Idẹnukọlẹ ìṣèjọba Amẹrika: Ọ́fíìsì Amẹrika ni Nàìjíríà ṣi ń pín ìwé ìrìnna
Àṣaálẹ́ ni kí o fi ọ̀dọ́ aguntan keji rúbọ, pẹlu ẹbọ ohun jíjẹ ati ọtí waini fún ìtasílẹ̀ gẹ́gẹ́ bíi ti òwúrọ̀.
Ọpọ wọn si ni ko dara fun ara eniyan.
Bí ó bá jẹ́ pé ohun tí ó wu eniyan ni mò ń ṣe sibẹ, èmi kì í ṣe iranṣẹ Kristi.
Ọba Afolabi jẹ ọkan lara awọn ọba ti igbagbọ wa pe o dagba ju ni ipinlẹ Oyo.
Ninu ọrọ tirẹ, aṣoju Balogun Akeem Agbolade to jẹ agbatẹru aba naa ni ofin ọhun ṣe pataki lati dena awọn aṣa ti koba igba mu nipa sisin awọn ọba tabi nipa awọn eto ifinijoye wọn.
Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí 5:47 Fídíò, Akomolede ati Asa: Mọ̀ si nípa àwọn ọ̀nà tí Yorùbá ń gbà ran ara wọn lọ́wọ́, Duration 5,4722 Ọ̀wàrà 2020 End SARS Protest: Babangida ní ejò lọ́wọ́ nínú lórí ìsẹ̀lẹ̀ rògbòdìyàn tó ń wáyé káàkiri Nàìjíríà22 Ọ̀wàrà 2020 Fídíò, Akinwumi Isola: Wo ohun tí Abeni fi ojú ọkọ rẹ rí tórí iṣẹ́ bọ́ lọ́wọ́ rẹ̀ nínú ìwé Nitori Owo""27 Ọ̀wàrà 2020 Iyaloja Oyo state: Àwọn ọlọ́jà ń sèdárò Ìyálọ́jà ìpínlẹ̀ Oyo, Wuraola aya Kola Daisi tó dolóògbé, wọ́n yan asojú míràn22 Ọ̀wàrà 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?"
Bí ẹnikẹ́ni bá wá, tí ó sì bi ọ́ léèrè pé, ‘Ǹjẹ́ ẹnikẹ́ni wà níbí?
Fídíò codeine: Iléesẹ́ Emzor gba‘sẹ́ lọ́wọ́ òsìsẹ́
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù NCS: Òǹwòye kan ní kí ìjọba ṣe àtúnṣe ọgbà ẹ̀wọ̀n àti ìtọ́jú ẹlẹ́wọ̀n 15 Ògún 2019 Oríṣun àwòrán, @NLCtoday Onwoye ohun to n lọ lawujọ kan ti sọ wi pe, bi aare Muhammadu Buhari se yi orukọ ileesẹ to n mojuto ọgba ẹwọn lorilẹede yii pada, si ileeṣẹ to n tọ ẹda sọna, jẹ ohun ti o dara pupọ, ati ohun itẹsiwaju.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Peters Ijagbemi dá àrá lórí ètò 'Ṣé o láyà' ti BBC Yorùbá lọ̀sẹ̀ yìí Wo awọn ọna abuja miran ti o le gba lai gba afara Third Mainland Ijọba ti ṣeto awọn ọna miran ti awakọ le gab lasiko ti iṣẹ atunṣe ṣi n lọ lọwọ lori afara yii Oríṣun àwòrán, LASG Fun apẹẹrẹ, o ni opopona Addo/Oyingbo/Adekunle/Ebutte Metta ti wa ni sẹpẹ ti awọn eeyan le maa gba.
Lebanon: Peace Busari àti àwọn 28 míràn ló padà sí Naijiria
Oríṣun àwòrán, @gift_sotonye Lasiko ayẹyẹ ikẹkọjade lawọn ẹgbẹ akẹkọjade ileewe naa gbe ami ẹyẹ ọhun fun Sotonye, to sẹsẹ gba oye ọmọwe, PHD nile ẹkọ ọhun, ami ẹyẹ naa si ni ikọkanlelogun iru rẹ, pẹlu atilẹyin ile ifowopamọ kan.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Jesu Oyingbo rèé, pásítọ̀ tó láṣẹ ìbálòpọ̀ lóri ọmọ ìjọ obìnrin Igbó mímu lè ṣe kóríyá, kò lé fi kún orín ẹnu òṣèré - 9ice Ìtàn tó wà nídi òwe ‘Sebótimọ Ẹlẹ́wà Sàpọ́n’ Ọba Adesoji Aderemi, Ọọ̀ni Ifẹ̀ tó gba ipò ọba mọ́ tòṣèlú Ayefẹlẹ wa rawọ ẹbẹ sawọn ololufẹ rẹ pe ki wọn kẹyin si iroyin eke naa ati aworan ofege to n gbe kiri.
O sì fún wọn ní ilẹ̀ yìí, ilẹ̀ tí o búra fún àwọn baba ńlá wọn pé o óo fún wọn, ilẹ̀ tí ó kún fún wàrà ati oyin.
Wọn ni eyi ko ba din inawo ijọba orilẹede Naijiria ku lori awọn irinajo yii ku.
Oríṣun àwòrán, Bunkunmi Oluwasina Ọrọ pọ ninu iwe kọbọ ti iyawo ọsingin kọ ṣugbọn lẹyin ọdun mọkanla ti wọn ti n fẹrawọn sọna, ọrọ naa di ohun.
Ìtàn ìgbésí àyé olóògbé Isiaka Abiola Ajimobi Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
"O sàlaye pe òbi ni láti ma á farabalẹ̀ fun wọn gidigidi nítori ki àwọn náà le di èèyàn lẹ́yìn wá ọ́la, ""àwọn ọmọ náà máà ń ni ìfẹ ènìyàn, ojú ti wọn fi ń wo aye si yàtọ si ti àwọn ènìyàn tóku."
Amọ, bi intanẹti naa se yara to yii, eyi ko tumọ si pe wọn n lo intanẹti naa bo se yẹ.
7 38085 Orilẹede Malawi 285 1.
Okon tun salaye siwaju pe, awon olopaa to nimo nipa ado oloro ti wa nibi isele naa.
Gẹgẹ bi ajọ to n moju to n ajakalẹ aarun ni Naijiria (NCDC) se sọ loju opo twitter rẹ lọjọ Ẹti, ipinlẹ mẹrindinlọgbọn pẹlu olu ilu ilẹẹwa lawọn eeyan tuntun naa ti ṣẹyọ pẹlu arun naa.
Ẹ níláti mú gbogbo inú burúkú, ìrúnú, ibinu, ariwo ati ìsọkúsọ kúrò láàrin yín ati gbogbo nǹkan burúkú.
Oríṣun àwòrán, Sajetiologa Bakan naa lo gba awọn akẹẹgbẹ rẹ ninu isẹ tiata nimọran pe ki wọn mase kanju lati di ohunkohun laye, amọ ki wọn se suuru de asiko Ọlọrun.
N óo fún ọ ní ìṣẹ́gun lórí wọn lónìí, o óo sì mọ̀ pé èmi ni OLUWA.
Ile-ise Etisalat ti won yi oruko re pada si 9mobile bayii ni won ti ta, latari isoro gbese ti o koju ile-ise naa lodun to koja, ile-ifowopamo n sakoso iko marundinladota ninu ida ogorun ile-ise naa, leyin ti o je gbese eyawo ti o le ni bilionu kan owo dollarsIle-ifowopamo agba lorile-ede Nigeria ati ajo NCC gbiyanju lati maa je ki ile-ise Etisalat ti o ni awon osise bi egberun lona merin, pelu awon onibara bi milionu metadinlogun subu, nipa sise atileyin owo bi o ba fi maa di ipari osu keta odun 2018.
Pupọ awọn olugbe agbegbe naa ni wọn si ti n kan saara si Alaafin Adeyẹmi fun igbesẹ naa eyi ti wọn ni yoo mu ki ọkan awọn balẹ lọjọyipo ninu ile awọn.
Ẹ jọ máa kọrin pọ̀,gbogbo ilẹ̀ Jerusalẹmu tí a sọ di aṣálẹ̀,nítorí OLUWA yóo tu àwọn eniyan rẹ̀ ninu,yóo ra Jerusalẹmu pada.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ìgbẹ́tì: Òkè Ìyámàpó ló gba wàá sílẹ̀ lọ́wọ́ ogun Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
 ní àwon orílẹ ̀ èdè tí ó ní anfààní jùlọ lati ní àrùn jẹ ̀ dọ ̀ jẹ ̀ dọ ̀ b , gbígba abẹ ́ rẹ ́ àjẹsára yí fún ọmọ tuntun ti dínkù àrùn jẹ ̀ dọ ̀ jẹ ̀ dọ ̀ b àti àrùn jẹjẹrẹ inú ẹ ̀ dọ ̀ .
Bakan naa, ọkan lara awọn ọdọ to ti dagba bayii ṣugbọn to jẹ ọmọde nileewe girama nigba June 12 ṣugbọn to nifẹ si ọrọ oṣelu ati kika iwe iroyin, Kini Kehinde Oyetunji só?
Kò pẹ́ pupọ lẹ́yìn náà, ni Joabu ati àwọn ọmọ ogun Dafidi pada dé láti ibi tí wọ́n ti lọ ja ogun kan, wọ́n sì kó ọpọlọpọ ìkógun bọ̀.
Amoju ẹrọ Wada jawe olubori ninu eto idibo ọhun pẹlu ibo aadọta le ni ẹẹdẹgbẹrin o din meji.
Agbenuso fun ile igbimo asofin ipinle Eko, Asojusofin Mudashiru Obasa ti parowa fun ijoba ipinle Eko lati wo lilo irinajo afe lati fi mu idagbasoke ba eto oro aje ipinle naa.
Lara awọn eeyan jankan to ba oloye Obasanjo ṣayẹyẹ ọjọ ibi rẹ naa ni, gomina ipinlẹ Ogun, Dapo Abiodun, gomina ana nipinlẹ Osun, Olagunsoye Oyinlola, Sẹnatọ ana, Florence Ita Giwa, onimọ nipa ọrọ aje, Nike Akande, atawọn eeyan nla miran.
Bakan naa lo sọ pe awọn tun ti bẹrẹ si ni fi ami si ilẹ'lẹ papakọ ọkọ ofurufu, lati ṣaami aaye ti eero kọọkan yoo duro si lori ila.
Alokoro ọlọpaa ipinlẹ naa, Ikeokwu Godson Orland fi idi ọrọ naa mulẹ fun BBC.
Lagos state lockdown relaxation: Ọ̀sẹ̀ mẹ́fà ni ìlànà tuntun fún Covid-19 yóò fi ṣiṣẹ́ Oríṣun àwòrán, Babajide Sanwo-Olu/Twitter Ijọba ipinlẹ Eko ti n gbeero lati fi opin si isede coronavirus patapata, ṣugbọn diẹdiẹ ni yoo bẹrẹ.
Ohun tí ó ṣe onígbèsè ni yóo ṣe ẹni tí a jẹ lówó.
Lẹ́yìn ò rẹyìn, Wasiu Ayinde sọ̀rọ̀ nípa Ayinde Barrister Èdè àìyedè láàrin Seyi Makinde àtàwọn aṣòfin yanjú, àbá ọdún 2021 dòhun Ojúlówó ọmọ Oluyole gan ni Adedibu, ìpasẹ̀ akọni náà ló tọ̀ nígbà ayé rẹ̀ Ẹ má bínú pé mo kọ́kọ́ ní akẹ́kọ̀ọ́ mẹ́wàá péré ni wọn kó nílé ìwé Kankara - Garba Shehu O fi kun pe akoko ti to fun ijọba Naijiria lati ṣe atunto eto abo rẹ to dẹnu kọlẹ.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Amọ ọmi odo si odo ni wọn jọ gba ni abala akọkọ ere bọọlu ọhun lẹyin ti awọn mejeeji gbiyanju lati gba goolu sawọn ara wọn.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Fọ́tò ló ṣàfihàn ibi tí ọmọ ti Nọọsi jígbé lódún 1997 wà 28 Ọ̀wàrà 2019 Àkọlé àwòrán, Aworan fọto àdáyà to kọkọ ṣafihan awọn mejeeji papọ Osu Kini, ọdun 2015 ni ọmọbinrin ọdun mẹtadinlogun to n lọ ile iwe girama Zwaanswyk High School ni ilu Cape Town ri ohun iyanu!
Gẹ́gẹ́ bí àwọn orílẹ̀-èdè tí OLUWA parun fun yín, bẹ́ẹ̀ ni ẹ̀yin náà yóo parun, nítorí pé ẹ kọ̀, ẹ kò gbọ́ ti OLUWA Ọlọrun yín.
Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí 11:51 Fídíò, EndSARS, EndSWAT Protests: Òbí agbábọ́ọ̀lù Kazim Tiamiyu Kaka àtàwọn míì tí ọlọ́pàá pa sọ̀rọ̀, omijé bọ́ lójú, Duration 11,513 Bélú 2020 US presidential election 2020: Ta a ni Joe Biden tó ń díje fún ipò aárẹ America4 Bélú 2020 Fídíò, Soyinka Cancer: Àṣe ara mi ni iso ti n run gbogbo bí mo ṣe n ṣèrànwọ́ lórí jẹjẹrẹ27 Bélú 2019 Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Bóò bá ní nọ́mbà ìdánimọ̀ NIN, à tí kọ ìdánwò rẹ yóò ṣòro Ọmọ Nàìjíríà, ẹ forijìn mí!
Alága ìjọba ìbílẹ̀ Iganna, Jacod Adeleke ti gba òmìnira lọ́wọ́ àwọn ajínígbé - Ọlọ́pàá ìpínlẹ̀ Oyo Ileeṣẹ ọlọpaa ipinlẹ Ọyọ ti fidi rẹ mulẹ pe alaga fidihẹ ijọba ibilẹ Iganna, Jacob Adeleke ati awakọ rẹ ti gba ominira lọwọ awọn ajinigbe.
Ọkan waye l'oṣu Keje ọdun 2018 lasiko ti ọkọ oju'rin kan kọlu ọkọ elero mẹrinla kan ni agbegbe Agege-Pen Cinema.
Ta ni kí a wí pé wọ́n jọ?
Hate Speech: Àwọn ọ̀dọ́ Nàìjíríà kẹ̀yìn sí ìjọba lórí ofin sísọ̀rọ̀ àlùfànsá
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Cyril Ramaphosa, aarẹ tuntun fun orilẹede South Africa?
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Maina N2bn Fraud: Agbẹjọ́rò Maina yọ ọwọ́ nínú ìgbẹ́jọ́, Ó lóun kò ṣé mọ̀ 23 Bélú 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 25 Bélú 2020 Oríṣun àwòrán, Google Ojumọ kan ara kan ni o n ṣẹlẹ lori igbẹjọ Abdulrasheed Maina ti ijọba ni oun ati ọmọ rẹ sa mọ ile ẹjọ lọwọ lori sun lilu owo ijọba ni ponpo.
Ìbejì ní wá ṣùgbọ́n àyẹwò fí hàn pé baba ọtọ́ọ̀tọ̀ ló bí wà Àyẹ̀wò DNA ti fẹ́ bẹ̀rẹ̀ fún àwọn àlùfá Kátólíìkì tó bímọ Àwọn àpẹẹrẹ pé o ti ń darúgbó Irọ́ ni, abẹ́rẹ́ àjẹsára Covid-19 kò lè ṣàyípadà DNA rẹ Pipaarọ atọ ọkunrin kan si ti ẹlomiran: Ni awọn ile iwosan ti wọn ti n fi atọ pamọ, o see se ki pasipaarọ atọ ọkunrin kan si ti ẹlomiran waye.
Egbe Eko Edum, to jẹ oludari to wa ni No.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Jose Mourinho: 3-2 ni Tottenham fi se àgbà fún West Ham 23 Bélú 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Bí ẹ̀nìyàn bá gẹsin nínù Jose Monrinho kò lé è kọ̀sẹ̀ pẹ̀lú bí ikọ̀ Tottenham se fakọyọ.
‘OLUWA ní, “Wò ó n óo jẹ Jerusalẹmu ati àwọn eniyan inú rẹ̀ níyà bí a ti kọ ọ́ sinu ìwé tí ọba Juda kà.
"Bí ẹ ṣe mọ̀wé tó, ẹ wá dánrawò níbí pẹ̀lú ""Àpólà Ọ̀rọ̀ Orúkọ - Noun Phrase Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí kan sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn."
Oríṣun àwòrán, @MBuahri Ààrẹ Buhari wọ́gilé kí àwọn òṣìṣẹ́ ìjọba máa wọ ọkọ̀ bàálù olówó gọbọi Aarẹ Buhari ti fagile ki awọn oṣiṣẹ ijọba maa wọ ọkọ baalu olowo gọbọi tabi ipele ẹlẹ́yẹ̀ẹ, eleyi ti oloyinbo n pe ni 'Business Class'.
Ibinu ti n suyọ laarin awọn obi awọn ọmọde wọnyi pẹlu awọn iroyin ti o jade sita wipe awọn ọmọ-ogun kuro ni awọn agbegbe Dapchi ni oṣu to kọja.
 iwádìí fi hàn wá pé , Àjàpadá yìí jẹ ́ ọmọ Ẹkùn , Ẹkùn sì jẹ ́ ọmọ Òdùduwà1 .
Láti ìgbà yìí ni ọmọ náà tí di ènìyàn ǹlá tí iṣẹ́ ọwọ rẹ̀ si ti dí èyí ti wọ́n ń rà káàkírí.
“Tabi bí iná bá jó eniyan lára, tí ó sì di egbò, tí ọ̀gangan ibẹ̀ bá pọ́n tabi tí ó funfun, 
Jesu dáhùn pé, “Ẹ̀yin ìran alaigbagbọ ati ìran tí ó bàjẹ́ yìí, ìgbà wo ni n óo wà lọ́dọ̀ yín dà?
“Ẹ gbọ́rọ̀ mi, ẹ̀yin ọlọ́gbọ́n,ẹ tẹ́tí sí mi, ẹ̀yin tí ẹ ní ìmọ̀,
Ṣugbọn ki lẹ tun mọ nipa Belarus?
Pápáa Queen's Park Savannah, ibi tí ó ní ewéko bíi kàá-sí-nǹkan ní àárín gbùngbùn olú ìlú Trinidad, ni ibi tí ayẹyẹ Ijó ìta-gbangba àti ilé ìtàgé àjọ̀dún náà.
Ọ ̀ rọ ̀ ni àárín , inú , àti àwọn ìbẹ ̀ rè ọ ̀ rọ ̣ ̣ ̣ ̀ .
O sọ ọrọ lẹyin ti gomina ipinlẹ Benue, Samuel Ortom, ba wọn pari ija ni ile ijọba to wa ni Makurdi.
Bákan náà ni: inú yín bàjẹ́ nisinsinyii, ṣugbọn n óo tún ri yín, inú yín yóo wá dùn, ẹnikẹ́ni kò ní lè mú ayọ̀ yín kúrò lọ́kàn yín.
Wo aláànú tó n wa ọkọ̀ tí wọ́n fi n gbé aláìsàn lọ́fẹ̀ẹ́ Buhari bá àwọn èèyàn ìpínlẹ̀ Sokoto kẹ́dùn lẹ́yìn tí àwọn agbégbọn f'ọ̀pọ̀ ẹ̀mí ṣòfò níbẹ̀ Ẹ wo àwọn òfin tí àjọ NCAA gbé jáde fún síṣí pápákọ̀ òfurufú padà ní Nàìjíríà Ó ṣeéṣe kó jẹ́ pé àwọn alágbara ló ń fi agbára hàn lórí arábìnrin tó fẹ̀sùn ìfipábánilòpọ̀ kan kọmíṣọ́nà Kogi -Agbẹjọ́rò Oríṣun àwòrán, Getty Images O ni awọn arun mii wa to n pa awọn eeyan kaakiri Naijiria ju ti Coronavirus lọ bii aisan iba, ṣugbọn Coronavirus ni NCDC joko ti.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù ASSU Strike: Ìpàdé ASUU àti ìjọba tún forí sánpọ́n 17 Ọ̀pẹ̀̀ 2018 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 18 Ọ̀pẹ̀̀ 2018 Oríṣun àwòrán, other Àkọlé àwòrán, ijọba kò ṣetan lati wọn ọn kun, ASUU naa ko fẹ gbaa ni aabọ lori ọrọ iyanṣelodi olukọ fasiti Ipade to n waye laarin ẹgbẹ olukọni ile ẹkọ giga fasiti lorile-ede Naijiria Asuu ati ijọba Naijiria tun ti fori sanpọn.
" Ẹnu tí ìgbín sì fib ú òrìṣà yóò fi lọlẹ ̀ dandan ni "" Ọmọ náà tẹríba fún bàbá rẹ ́ ó sì mọ ̀ àgbà légbọ ̀ n-ọ ́ n ."
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Fraud Allegations: Abike Dabiri-Erewa rọ àwọn tọ́rọ̀ kàn láti yọjú sí FBI 23 Ògún 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Awọn gbajuẹ ma n lo ẹro ayara bi aṣa lati lu awọn eniyan ni jibiti Ijọba apapọ ti fi ọrọ lede pe iwa awọn ọmọ Naijiria ti ajọ FBI ṣatẹjade orukọ wọn gẹgẹ bi afurasi oni gbajuẹ, jẹ eyi ti o ti doju ti orilẹ-ede wa.
Ti ko ba si ṣe gbogbo nkan to yẹ, yoo tun pada si ẹsẹ aarọ ni.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Bobrisky: Ẹ má ṣe ìdájọ́ mi, mo ṣún mọ́ Ọ́lọ́run, máà sì lọ sí Mecca láìpẹ́ 3 Owewe 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 31 Agẹmo 2020 Oríṣun àwòrán, Bobrisky Ilumọọka ọkunrin kan to lee mura bii obinrin tabi ọkunrin, Idris Okunneye ti ọpọ eeyan mọ si Bobrisky, ti sọrọ kikun nipa igbe aye rẹ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Google ati awọn ọmọ Naijiria ṣe ìrántí ọjọ ibi Dokita Stella Adadevoh pẹlu àwòrán 27 Ọ̀wàrà 2018 ''Eeehya!
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ọ̀ọ̀ni Ilé Ifẹ̀: Ọ̀rúnmìlà ni ó kọ́kọ́ lo 'Google' láàgbáyé 6 Ọ̀pẹ̀̀ 2018 Àkọlé àwòrán, Kabiyesi ni Yoruba gbọdọ ranti mọ ipo wọn gẹgẹ bii ẹya ti ko ṣee fi ọwọ rọ sẹyin ni agbaye Ọọni ile ifẹ, Adeyẹye Ogunwusi ti ṣalaye pe ilẹ Yoruba ni ipa nla ti o ko lori idagbasoke imọ ẹrọ ati imọ sayẹnsi lagbaye.
" Ni ti Titilope Oyewusi, epe lo fi ranṣẹ si Aarẹ nigba to n ba awọn ọmọ Naijiria sọrọ lọwọ.
Kwara: Fọ́fọ́fọ́ ni mọ́ṣáláṣí kún tí ìlànà ìjìnàsíraẹni sí forí ṣánpọ́n lẹ́yìn tí ìrun Jímọ̀ bẹ̀rẹ̀ padà ni Ilorin
Ṣugbọn ninu gbogbo ìrírí wọnyi, a ti borí gbogbo ìṣòro nípa agbára ẹni tí ó fẹ́ràn wa.
Ìgbà kan mo ń fẹ́ fi ọwọ́ gbá ìyàwó rẹ̀ ní ìdí, bí mo sì ti ní ki ń ṣe bẹ́ẹ̀, ṣe ni ọwọ́ mi rọ, àti ọjọ́ náà ni ọwọ mi ti dí rírọ di òní abbl.
Ènìyàn ti yóò péjú nínú kọ́lẹ̀jì náà ní yóò jẹ́ aṣojú ìpińlẹ̀ tó ti wá.
Ẹ jẹ ka sootọ pẹlu ara wa, ka ṣe ipade ba ti pin èrè, iya ko ni jẹ wa, tori isẹ ọwọ wa to wa jẹ.
Dán Yorùbá rẹ wò pẹ̀lú ààmì lórí 'Bobajiroro' Kí ni Yorùbá ń pe ọmọ tí wọ́n bí lẹ́yìn Àlàbá?
Bóò bá ta Ọba rẹ lọ́pọ̀, òó lè rí i ní gbànjo""."
’’Aare Buhari tun ni:“Pelu ifowosowopo awon agbe ati iranwo ti
Fikun iṣẹ oore ṣiṣe O ṣe pataki lati maa ṣe saara nigbagbogbo ni oṣu Dhu al-Hijjah Bi apẹrẹ, ti o ba n sẹ ọrẹ ẹgbẹrun kan Naira, o ni lati fi kun un tabi ki o ṣe ni ilopo Nkan miran tun ni pe ẹni ti ko ba lọsi Hajj ọdun yii, o yẹ ko fi ilaji owo rẹ ra ounjẹ ati aṣọ fun awọn alaini, iṣẹ oore naa ni.
Eyi maa n jẹ ki apa ọpọlọ wọn to n mu ki ifẹ gbooro ji pepe sii.
Ninu atejade ti oludamoran gomina lori eto iroyin ko loruko gomina,
"Mimu omi niṣẹju mẹẹdogun mẹẹdogun Iroyin kan ti ogunlọgọ eniyan ti pin kiri lori ayelujara Facebook ni pe ""Dokita kan ni Japan'' sọ pe mimu omi laarin iṣẹju mẹẹdogun sira wọn dara lati fọ arun karun to ba gba ẹnu wọle jade."
Nítorí pé láti ọ̀dọ̀ àwọn wolii Jerusalẹmuni ìwà burúkú ti tàn ká gbogbo ilẹ̀ yìí.
Ó sọ pé àìníṣẹ́ ló fàá tí àwọn fi wọ ẹgbẹ́ náà láti ìbẹ̀rẹ̀ .
Ọjọ Aje si ni Atiku morile ile ẹjọ lati gbe atako r kalẹ, nigba to ku wakati mẹrinlelogun pere ki iye ọjọ ti ofin la kalẹ fun oludije kan lati pe ẹjọ tako esi ibo pe.
'Ojú mi rí tóó, àwọn ìyàwó kìí ṣiṣẹ́, ọkọ àtàwa ọmọ-ọ̀dọ̀ laláṣekú lórílẹ̀èdè Oman' 'Iṣẹ aṣẹwo ni wọn fi mi ṣe ni Moscow' Òwò ẹrú pé irinwó ọdún tó bẹ̀rẹ̀, àwọn Amẹrika tó jẹ́ dúdú wá sí Afirika láti bẹ ilé wò Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí 3 sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 2:23 Fídíò, Water Generator: Ó leè ṣiṣẹ fún wákàtí mẹfà, kó tó sinmi, Duration 2,2310 Òkùdu 2020 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
N óo dá wọn lẹ́jọ́ nítorí gbogbo ibi tí wọ́n ti ṣe, tí wọ́n kọ̀ mí sílẹ̀, tí wọn ń sun turari fún àwọn oriṣa, tí wọ́n sì ń bọ ohun tí wọ́n fi ọwọ́ ara wọn ṣe.
Alao-Akala ni oun ati Ajimọbi sọ ọpọlọpọ ọrọ ninu eyi tawọn ti fẹnu ko pe ki oun pari aawọ to wa laarin gbogbo ọmọ ẹgbẹ to n binu lẹyin idibo gbogbogbo to lọ.
“Ninu àwọn mẹta yìí, ta ni o rò pé ó jẹ́ ọmọnikeji ẹni tí ó bọ́ sọ́wọ́ àwọn ọlọ́ṣà?
Ẹni bá sì ń lọ si ilé Ẹ̀kọ́ fáfitì Èkó ti ìjọba àpapọ̀ kò lè yẹ Abúlé Ọjà sílẹ̀ láì má gbà á kọjá.
Ohun ti Dokita Rafiq Raji ati Ajibade Adegbitẹ fi ṣakawe rẹ ni tiwọn ni pe '.
Oríṣun àwòrán, Instagram/olori_omoh_one Awọn idagbasoke to ba ilu Oyo ati ipa manigbagbe ti Ọba Adeyemi ko ni Naijiria: Kii se pe a sọ asọdun ta ba ni idagbasoke alailẹgbẹ ba ilu Ọyọ lati aadọta ọdun ti Lamidi Adeyemi ti wa lori itẹ bii Alaafin Ọyọ.
Victoria ya agbado ha sawọn eeyan lẹnu nigba to fesi si ibeere ti ẹnikan beere pe kilode to maa fi n ṣi ara silẹ.
" Nigba ti ileesẹ BBC pe Fada Mbaka lati oju opo Facebook rẹ, o ti pa aago rẹ.
RCCG Congress 2020: Pásítọ̀ ní owó Naira yóò sì tún gbé pẹ́ẹ́lí lẹ́ẹ̀kàn síi
Nkechi Blessing vs Toyin Abraham: Nkechi tí tọrọ ìdáríjí ẹ̀ṣẹ̀ lọ́wọ́ akẹgbẹ́ rẹ̀, Toyin Abraham Díẹ̀ ló kù kí ọjọ́ ìkúnlẹ̀ di ọjọ́ ikú fún ìyá mi lọ́jọ́ tó bí mi - Seyi Makinde Adolf Hitler gbé àpótí ìbò, aráàlú yàn án sípò gẹ́gẹ́ bíi Káńsílọ̀ Sójà obìnrin lù mí lálù bami nílùú Ibadan Àwọn agbègbè tí àtùndi ìbò yóò kàn lọ́jọ́ Àbámẹ́ta nípìnlẹ̀ Eko rèé Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ìgbátí ìgbámú àná látọwọ́ sọ́jà obìnrin ti bá arákùnrin náà dé iléèwòsàn Bótilẹ̀ jẹ́ pé ìpèníjà oníruuru ló maa ń wà nínú eré títa síbẹ̀, ẹbùn ló ṣe pàtàkà kí ẹnìyàn ni ẹbún"" ""Àgbà òṣèré náà ní lásìkò tí òun fẹ́ ṣe eré ọmọ tó niṣe pẹ̀lú àsà Yoruba, ni ọ̀pọ̀ àwọn akẹ́gbẹ́ òún díde pé, ọmọ Igbo ni òun nítori naa ipa náà kò ta sí òún, èyí náà tún wáyé lásìkò eré Efunṣetan Aniwura"" Bákan náà ni Clarion sàlàye pé, ó yẹ ki Nollywood fòpin si àwọn eré tó níṣe pèlú lílọ sí ilé bábá aláwo tàbí fífí ọmọlakejì rẹ̀ ṣe òògún owó."
Bẹẹ lo fikun pe iwadii fihan pe arun Coronavirus ni agbara lati tankalẹ ju bo ṣe lọ nibi ti awọn eniyan ba fun pọ si.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Tramadol: Ọwọ́ tẹ afurasí méjì tó kó òògùn olóró N60m wọlé l'Apapa 17 Agẹmo 2019 Ọwọ awọn oṣiṣẹ aṣobode lebute ọkọ oju-omi to wa l'Apapa nipinlẹ Eko, ti tẹ awọn afurasi meji kan ti wọn ko oogun Tramadol wọ Naijiria lọna aitọ.
Ẹ̀yin ọmọ mi, ẹ má jáfara, nítorí pé OLUWA ti yàn yín láti dúró níwájú rẹ̀, ati láti sìn ín; láti jẹ́ iranṣẹ rẹ̀ ati láti máa sun turari sí i.
Mo fẹ́ kí ẹ mọ̀ dájúdájú pé, yóo sàn fún ilẹ̀ Sodomu ati ti Gomora ní ọjọ́ ìdájọ́, ju ìlú náà lọ!
Nítorí Ọmọ-Eniyan yóo wá ninu ògo Baba rẹ̀ pẹlu àwọn angẹli rẹ̀, yóo wá fi èrè fún ẹnìkọ̀ọ̀kan gẹ́gẹ́ bí iṣẹ́ rẹ̀.
Ẹlẹsẹ ayo, Mohammed Salah lo gbayo akọkọ sawọn fun ikọ Liverpool lẹyin iṣẹju meji pere ti wọn bẹrẹ ere bọọlu ọhun.
Àwọn ènìyàn le padà sí bí wan ṣe n ṣe tẹ́lẹ̀ bí eré ìdáraya, tí ìdá márùndílọ́gọ́rin èèyàn sì ni yóò máa péjú sí ibiṣẹ́ kí àlàfo to péye baa lè wà.
boya won yoo tun ija won ja.
CAN: Darandaran ti ran ida aadọrun ninu ọgọrun ọmọlẹyin Kristi s'ọrun
Carrington to execute his duties with panache and grace as he addressed the most complicated international crises.
Ó kọ ́ kọ ́ ṣe àfihàn iṣẹ ́ rẹ ̀ ní salon ní ọdún 1890 .
Coronavirus : Idris Elba ti lùgbàdì àrùn Coronavirus
Wón ni ko sẹni tó lè tọ́ka ibi tí awọn Yoruba yoo fì sí ni idibo 2019 nitori pe kò si ìkókó mọ́ nínú oludibo.
O óo jẹ́ adé ẹwà lọ́wọ́ OLUWA,ati fìlà oyè lọ́wọ́ Ọlọrun rẹ.
Ogbeni  Akpata ni o tako iwa omoniyan lati fiya je eni
Nígbà tí Ebedimeleki ará Etiopia tí ó jẹ́ ìwẹ̀fà ní ààfin ọba gbọ́ pé wọ́n ti ju Jeremaya sinu kànga.
Ni Mose bá gba ẹ̀jẹ̀ ẹran yòókù tí ó wà ninu àwo, ó wọ́n ọn sí àwọn eniyan náà lára, ó ní, “Èyí ni ẹ̀jẹ̀ majẹmu tí OLUWA bá yín dá, gẹ́gẹ́ bí ọ̀rọ̀ tí mo sọ.
Àwọn Juu kan tí wọ́n ti ń kiri láti ìlú dé ìlú, tí wọn ń lé ẹ̀mí burúkú jáde kúrò ninu àwọn eniyan, fẹ́ máa ṣe bíi Paulu nípa pípe orúkọ Oluwa Jesu lé àwọn tí ó ní ẹ̀mí burúkú lórí.
Ní oṣù kinni, ọdún keji tí àwọn ọmọ Israẹli jáde kúrò ní Ijipti, OLUWA sọ fún Mose ninu aṣálẹ̀ Sinai pé, 
Ni ti awọn eeyan ilu Akure, adura ni wọn fi iwọse wọn ṣe ni bi wọn pe ipade adura lati fi ifẹhonuhan.
Bakan naa ni ijọba Naijiria fi ẹsun kan Biafra pe oun lo awọn ọmọ ogun ilẹ okeere lati le fa ogun naa gun.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Kílò fa èdè àìyedè láàrin ìjọba àti àwọn ọmọ lẹ́yìn El-Zakzaky?
Awọn to n ba dokita naa ṣiṣẹ ati nọọsi to wa nibẹ naa ko lọ lai jiya.
Ẹ dákun, e má jẹ́ ki tẹ sẹ̀ ó gbọ̀n dànù
Àwọn Olóyè Ilé-Ifẹ̀ sẹ́ ọ̀rọ̀ ikú Ọba yi, nitori ni ayé àtijọ́, àwọn àgbà Oyè ló ni àṣẹ lati tú ọ̀fọ̀ pé Ọba wàjà fún ará ilú, nitori gẹ́gẹ́ bi àṣà Yorùbá Ọba ki kú.
Gẹgẹ bi a se ka a loju opo itakun agbaye Wikipedia, ọmọ bibi ilu Ibadan ni Akinkunmi, amọ ti ẹkọ funfun rẹ ti inu ikoko dudu jade.
 Àwọn àtẹ lè ní àlékún àwòrán ère Èṣù , a sì ti rí àtẹ tí ó ní ojú méjì , mẹ ́ rin , mẹ ́ jọ àti mẹ ́ rìndínlógún rí .
"O ni ki wọn to lee fa irun ọmọ miran, ""o le e pe oṣu mẹta, o le jẹ oṣu mẹfa, o le e pe osu meje."
Ni bayi, Super Eagles dipo keje mu nile-Afrika, ti orile-ede Tunisia, Senegal, DR Congo, Morocco, Egypt ati Cameroon si tele ra-won.
Alhaji AbdulRasaq AbdulRahman naa tun sapejuwe eto idibo naa pe o  lọ ni irọwọ ati irọsẹ .
Gẹg bi ohun ti ajọ WHO sọ, pupọ awọn ti iba n pa wa l'Afrika nibi ti ọmọde to le ni ẹgbẹrun lọna òjìlénígba lé mewaa ma n ku.
O ni kii ṣe wi pe o fẹ ba awọn ara ipinlẹ naa kẹdun bi kii ṣe lati wa ibo wọn.
8 8787 Orilẹede Cameroon 443 1.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Torí ₦300, awakọ̀ ojú omi ṣokùnfà ikú èèyàn méjìlá l‘Eko - Ọlọ́pàá Láì san owó oṣù tẹ jẹ wá, kò sọ́rọ̀ kankan - ASUU sọ fún ìjọba Ìjọ́ mí ní Italy ni mo fi ń ṣèrànwọ́ fáwọn aṣẹ́wó ọmọ Nàíjíríà tó há - Taribo West Ààrẹ orílẹ̀èdè Mali, Boubacar Keita kọ̀wé fipò sílẹ̀ Àwọn òṣèré tíátà Yorùbá kọjú ìjà síra wọn lórí ìdárò akẹẹgbẹ́ wọn tó kú Ìpàkọ́ kò gbọ́ sùtì ní ọ̀rọ̀ ẹ̀yin tí ẹ̀ ń bú mi- Oyedepo Mo kọ̀ láti pín ọkọ mi pẹ̀lú ẹnikẹ́ni, nítorí náà ẹ tú wa ká- Abílékọ Idowu faraya ní kóòtù kọkọ-kọkọ Arabinrin Adejobi wa bẹnu atẹ lu bi awọn oṣere tiata kan paapa awọn obinrin, ti ṣe maa n mura ihoho.
bí mo bá ṣẹ̀, o óo dójú lé mi,o kò ní jẹ́ kí n lọ láìjìyà.
Ko arokọ rẹ daadaa ni ede PIDGIN.
Oríṣun àwòrán, Facebook/Mike Bamiloye Mo dupẹ pe a di tọkọtaya ni ọdun mejilelọgbọn sẹyin; mo dupẹ pe iṣẹ iranṣẹ wa ri bo ṣe ri; mo dupẹ fun igbe aye rẹ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ọ̀dọ́kùnrin tó kọ́kọ́ ṣe ẹ̀rọ tó ń tu ìyẹ́ lára adìyẹ Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
lásìkò tí ó wọ ilé-ifẹ ̀ wá , àjọṣepọ ̀ tó lọ ́ ọ ̀ rìn wà láàrín àwọn olùgbé ìran mẹ ́ tàlá ( 13 ) ifẹ ̀ , tí ìlú kọọ ̀ kan sì ní Ọba tirẹ ̀ bí Ọba Ìjùgbé , Ìwínrín , ijió , Ìwínrín àti bẹ ́ ẹ ̀ bẹ ́ ẹ ̀ lọ .
Nítorí náà níwọ̀n ìgbà tì ìlérí àtiwọ inú ìsinmi rẹ̀ tún wà, ẹ jẹ́ kí á ṣọ́ra gidigidi kí ẹnikẹ́ni ninu yín má baà kùnà láti wọ̀ ọ́.
Wọ́n pa àṣẹ náà ní Susa tíí ṣe olú-ìlú.
Kí enítọ̀hún sì dì-káká dì-kuku bíi Baba Sùwé kó má baà ganpa nínú òtútù!
“Tabi, ‘Ta ni yóo wọ inú ọ̀gbun ilẹ̀ lọ?
 @MBuhari signs, on behalf of Nigeria, the Agreement Establishing the African Continental Free Trade Area (#AfCFTA), at the opening of the 12th Extraordinary Session of the Assembly of African Union Heads of State and Govt, in Niamey, Niger Republic, July 7, 2019 #AUSummit pic.
Mo bá dáhùn pé, “Háà, OLUWA Ọlọrun, àṣé ò ń tan àwọn eniyan wọnyi, ati àwọn ará Jerusalẹmu ni, nígbà tí o sọ fún wọn pé, yóo dára fún wọn; àṣé idà ti dé ọrùn wọn!
Bakan naa ni wọn gboriyin fun pe o fi ipa manigbagbe silẹ ni ẹka iṣẹ aladani, to si tun jẹ ẹni to sin awọn eniyan rẹ tọkan-tọkan.
Ó wí fún un pé, “Máa tẹ̀lé mi.
Èyí ni ọ̀rọ̀ Lemueli, ọba Masa, tí ìyá rẹ̀ kọ́ ọ:
Wọ́n tẹ́ ẹ sórí àkéte, tí ó kún fún oniruuru turari tí àwọn tí wọ́n ń ṣe turari ṣe.
 Àpólà méjì tí ó kù tí a ó menu bà sí i ni àpólà atókùn àti àpólà àpónlé .
Àṣepọ̀ ni wọ́n ṣe é mọ́ efodu yìí láti máa fi so ó gẹ́gẹ́ bí OLUWA ti pàṣẹ fún Mose.
Bakan naa ni ikede yi sọ pe ki awọn ile ẹkọ gbogbo ti wọn yoo ti gba isinmi lati ọjọ Kejidinlogun oṣu Kejila wa ni titi pa fun ọsẹ marun lati asiko yi lọ.
Ó sì fún wa ní Ẹ̀mí Mímọ́, ó fi ṣe onídùúró gẹ́gẹ́ bí ẹ̀rí ohun tí yóo tún fún wa.
"Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Àǹfàní ńlá ni àṣẹ ìgbélé jẹ́ fún àyíká ọmọnìyàn pàápàá nílùú Eko Wọn ní ""wọn tí mú ọkàn lára wa, Alfa Coach Kehinde lọ sí agọ ọlọ́pàá Mapo, tí wọn si sọ si ahamọ pé, àwọn yóò fi jofin fún àwa yoku"" "" Nígbà tá tún lọ sí agọ ọlọ́pàá láti gba Kehinde silẹ, ẹgbẹ̀rún lọ́nà àádọ́ta náírà ni wọn ní ká mú wá ní ìbẹ̀rẹ̀ ṣùgbọ́n ní báyìí, wọn ti ní ká san ẹgbẹ̀rún mẹ́wàá náírà."
Sibẹsibẹ, n óo yàn wọ́n láti máa tọ́jú tẹmpili ati láti máa ṣe àwọn iṣẹ́ tí ó yẹ ní ṣíṣe ninu rẹ̀.
 ju bílíọ ́ nù 3 àwọn ènìyàn ni o ń gbé ní ẹkùn lágbàyé níbi tí dìgbòlugi ti ń ṣẹlẹ ̀ .
Ninu ẹjọ naa ti adajọ Okon Abang ti ile ẹjọ giga ni ilu Abuja da, wọn ni Ọgbẹni Olisa Metuh jẹbi ẹsun ti ajọ EFCC fi kan an.
Ǹjẹ́ o mọ ǹkan wọ̀nyìí nípa Kanu Nnwankwo?
Onnoghen n koju iwadi nitori ẹsun ti wọ̀n fi kan an pe o parọ́ ninu dukia to kede pe oun ni gẹgẹ bi adajọ agba orilẹede Naijiria.
Oríṣun àwòrán, Others Ninu ọrọ kan to ba BBC News sọ, Aishaa Yesufu ni aburo oun gan an lo kọkọ pe oun pe oun dabi eṣin o kọ'ku janduku ninu aworan oun ti wọn kọkọ ya nibi iwode naa ninu aṣọ yii.
Ijoba orile-ede Naijiria ati egbe awon oluko nile eko giga fafiti, Academic Staff Union of Universities (ASUU) ti panupo lati tun joko sepade lose to n bo lati fopin si iyanselodi awon oluko fafiti to n lo lowo.
"O ni ""bi a ṣe n sọrọ yi, minisita ko tii fọ ohunkohun""."
Mo dákẹ́, n kò ya ẹnu mi;nítorí pé ìwọ ni o ṣe é.
Tẹ iwe awọn ti yoo ṣe oniduro fun ọ jade.
’’“Ohun ti o se koko ni lati mu inu awon ebi won dun, lati gbe igbe aye ti o dara, bee si ni ki won si tun mu orile-ede wo yangan lawujo,”Tesiwaju si, Afolayan wa ro ijọba ipinle, ijọba apapo lati pese ayika ti yoo ro awon ara ilu lorun, ki won ko si ro awon odo lagbara nipase ipese ise, ipese awon ohun amayederun abbl.
 Ìdí ni wí pé ọ ̀ pọ ̀ lọpọ ̀ ènìyàn ni ó kọ ̀ ọ ́ sílẹ ̀ nítorí pé ìlú bahama tí rògbòdìyàn pọ ̀ sí jùlọ láti tako òwò ẹrú ni gama ti wá , èyí ni ó sì fàá tí ọ ̀ pọ ̀ lọpọ ̀ ènìyàn fi ń rà á ní àràtúntà .
Ẹni-ọwọ Ajayi sọ pe Ajọdun Orin Iyin ati Orin Imisi Ẹmi ti ọdun 2018 yii, pẹlu akori, “Orin Kikọ ninu Imisi Ẹmi Mimọ” ni wọn gbe kalẹ lati fi pe awọn ẹgbẹ akọrin kaakiri Ijọ Methodist ẹka Ipinlẹ Eko lapapọ jọ, lati tubọ kọ wọn ni pataki orin ẹmi ati orin imisi ninu Ijọ Eleto (Methodist Church), ki wọn si pada lọ ṣe amulo imọ naa ni awọn ile ijọsin wọn gbogbo, nitori “Ijọ Eleto jẹ eyi ti wọn bẹrẹ pẹlu orin imisi ẹmi.
 Ó bùdó sí apá ìwọ ̀ òrùn afrika .
oríṣìíríṣìí oyè ni wọ ́ n máa ń jẹ ní iléṣà tí wọn sìń jẹ ́ ní Ìjẹ ̀ bú jẹ ̀ ṣà .
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Kengbe Ilorin: Àṣà ẹ̀yà Fulani, Bariba àti Gambari tó dàpọ̀ mọ́ ti Yoruba Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Kengbe Ilorin: Àṣà ẹ̀yà Fulani, Bariba àti Gambari tó dàpọ̀ mọ́ ti Yoruba 22 Ọ̀wàrà 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 31 Èbibi 2020 Orisirisi orin ati ilu ni ẹya Yoruba fi maa n da ara wọn laraya laye atijọ bii Bọlọjọ, Sakara, Sẹnwẹlẹ, Apala, Were, Waka, Kengbe lilu ati bẹẹ bẹẹ lọ.
Lọwọlọwọ, apapọ awọn to ti ni aarun naa ti pe 80,922, eyan 69,274ti ri iwosan, 1,236 si ti ku.
Ọrẹ timọtimọ Ogun Majek ti wọn tun jọ jẹ oṣere tiata, Musiliu Dasofunjo, ti ọpọ eeyan mọ si Esu laalu, lo fi idi isẹlẹ naa mulẹ fun BBC Yoruba.
Toò, ẹ jẹ́ ká fi man báhun lónìí nítorí pé “ṣókí l’ọbẹ̀ oge”.
"Ẹ̀fọn Arsenal já bàálù Liverpool lulẹ̀ ní Wembley ní ìrìn-àjò sí Community Shield Wo ohun tó ṣẹlẹ̀ sí Saka, Sunkanmi Omobolanle àtàwọn òṣèré sinimá míràn lọ́sẹ̀ yìí Wọ́n tún ti pa omidan ẹni ọdún 18 míràn l'Akinyele ní ìlú Ibadan Olorì tí yóò nífẹ̀ẹ́ àwọn ará Iwo ni mo fẹ́ fẹ́- Oluwo ti Iwo Wo àpẹẹrẹ, àti ǹkan tó ń fa 'colon cancer' tó pa Chadwick Boseman 'Black Panther' Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Bí ẹ ṣe mọ̀wé tó, ẹ wá dánrawò níbí pẹ̀lú ""Àpólà Ọ̀rọ̀ Orúkọ - Noun Phrase Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Arsenal vs Liverpool: Arsenal fìyà bẹ̀rẹ̀ sáà bọ́ọ̀lù tuntun fún Liverpool pẹ̀lú Community Shield30 Ògún 2020 6:10 Fídíò, Yoruba Language: Akomolede ati Asa Yoruba tọ̀sẹ̀ yí rèé lẹ́nu olùkọ́ wa, Duration 6,1030 Ògún 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!"
Atiku to tun dije dupo aarẹ ninu idibo ọdun 2019 sọ pe aitete gbe igbesẹ ijọba nigba ti ajakalẹ akọkọ waye lo jẹ ki ọrọ di bo ti ṣe ri loni.
Nítorí náà, ìbáà ṣe èmi ni, tabi àwọn aposteli yòókù, bákan náà ni iwaasu wa, bẹ́ẹ̀ sì ni ohun tí ẹ gbàgbọ́.
Ìpínlẹ̀ Ọ̀ṣun kò le è sanwó o ọmọ́gọ̀ lórí LAUTECH- Gómìnà Oyetola Ẹ jọ̀ọ́, òógùn ojú mi kò gbọdọ̀ já sásán lórí sinimá tí mo yà pẹ̀lú oyún oṣù mẹ́fà - Toyin Abraham Èmi kò sí nílé, ọkọ́ mi ló leè sọ bóyá lóòtọ́ọ́ ló fẹ́ gbéyàwó àbí bẹ́ẹ̀ kọ́ - Aisha fèsì Ìjọba àpapọ̀ kò leè ṣùn torí ìyanṣẹ́lódì òṣìṣẹ́ tó ń bọ̀ Ìdùnnú ni yóò jẹ fún wa ti wọn bá ṣe àwọn ọnà tí kò dára wọnyíì- Bosun Aguda Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Twin Festival 2019: Ṣé ọbẹ ìlasa àti àmàlà ló ń ṣokùnfà bíbí ìbejì ní ìlú Igboọrà?
’ N óo mú wọn pada sórí ilẹ̀ wọn, ilẹ̀ tí mo fún àwọn baba wọn.
Bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé onirese Baba rẹ kò fín igbá mọ, tó sì ti jáde láyé, síbẹ̀, Segun kò jẹ ki igbá tí bàbá rẹ̀ fín silẹ parun, to sì ń ba ere tíátà lọ ní pẹrẹu.
Bakan naa, Ojọgbọn omo orile-ede Naijiria miiran naa tun ba isele ijamba buruku ọkọ ofurufu ọhun loỌjọgbọn Abiọbun Bashua wa lara awọn to lugbadi iku ojiji ninu
Àkọlé àwòrán, BBC Yoruba bẹrẹ iṣẹ ni pẹrẹwu Amọ, wọn ni Ọba mẹwa, igba mẹwa, bi aye ba nyi, o yẹ ka maa ba aye yi ni.
Ẹ tètè máa lọ, ẹ óo bá a.
''Àjọ NERC ti fún Disco láṣẹ láti padà sí owó tàríìfù tuntun iná mọ̀nàmọ́ná'' EFCC bẹ̀rẹ̀ ìwádìí lórí ẹ̀sùn ìwà jẹgúdújẹrá tí wọ́n fi kan Fowler tó jẹ́ Alága iléeṣẹ́ FIRS tẹ́lẹ̀ Wo ǹkan tó yẹ kí o mọ̀ nípa Joe Biden, tó ń kojú Trump nínú ìbò America Kíní ọ̀nà àbáyọ sí ìjàmbá ọkọ̀ tó ń wáyé lemọ́lemọ́ ní Ọjà Akungba,ní Ondo?
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Dambe fight: ìdíje ìjà láàrin àwọn akóni tó n ja ẹ̀ṣẹ̀ Ẹsun ti wọn fi kan Maina nigba naa ni pe ọwọ rẹ ko mọ lori bi wọn ṣe lu biliọnu meji naira, owo ifẹyinti awọn oṣiṣẹ ọlọpaa ni ponpo.
Ọkàn kan ati ẹ̀mí kan ni gbogbo àwùjọ àwọn onigbagbọ ní.
Ṣugbọn majẹmu tí n óo bá ilé Israẹli dá nígbà tó bá yá nìyí: N óo fi òfin mi sí inú wọn, n óo sì kọ wọ́n sí ọkàn wọn.
Ó bá sọ fún mi pé, “Ọmọ eniyan, gbẹ́ ara ògiri yìí.
" Nígbà tó ń ṣàlàyé ìdí tó fi ń fi arákùnrin si ìbẹ̀rẹ̀ orúkọ rẹ dípò ọlọ́lá jùlo, Akeredolu ni orúkọ tí bàbá òun ń pè òun láti kékeré ni òun padà sí, òun kò si fẹ́ òye kankan.
O ni awọn to wa nidi ọrọ naa gbọdọ foju wina ofin.
Bẹẹ, arugbo ṣe oge ri, akisa lo igba ri, oṣiṣẹ to ja fafa lẹnu iṣẹ loni ni yoo di oṣiṣẹ-fẹyinti lọla.
Olùràpadà wa, tí ń jẹ́ OLUWA àwọn ọmọ ogun, ni Ẹni Mímọ́ Israẹli.
Arafat ní ayé kan ti won n pé ni Jamrah.
Oríṣun àwòrán, Olori Memunat Adeyemi Facebook Ọrẹ awọn olori mejeeji yii wọ debi pe wọn maa n ki ara wọn ni mẹsan-mẹwa ni lori ayelujara, ti wọn si tun dijọ n ta asọ ni.
Àwọn ọmọ Satu jẹ́ ẹẹdẹgbẹrun ó lé marundinlaadọta (945)
December 7 Ogúnlọ́gọ̀ àwọn olùfẹ́honúhan, gba gbogbo ìlú Abuja tí wọ́n ń pè fún ìtúsílẹ̀ olórí wọ́n January 22, 2019 Adájọ́ Gideon Kurada, pàsẹ́ fún El-Zakzaky àti ìyáwó rẹ̀ Zeenat, kí wọ́n wà nínú àtìmọ́lé àwọ́n ọtẹ̀lẹ̀múyẹ́ June 29, 2019 Adájọ Kurada sún ìgbẹ́jọ síwájú láìsí gbèdéke nítori ó nílo lati jòkó fún ìgbìmọ tó ń gbọ́ ẹ́jọ tó súyọ lẹ̀yìn ìdíbo ààrẹ ní Yobe July 9, 2019 Ọlọ́pàá àti Shi'ite tún kọlu ara wọ́n níwájú ilé ìgbìmọ̀ aṣòfin Abuja.
Òun óo mú Jehoiakini ọba Juda, ọmọ Jehoiakimu, ati gbogbo àwọn tí a kó lẹ́rú láti Juda lọ sí Babiloni pada sí ibí yìí, nítorí òun óo ṣẹ́ àjàgà ọba Babiloni.
Awọn Orilẹ ede miran ti ko nilo iwe aṣẹ igbelu fun awọn ọmọ Nigeria ni ; 8.
 Àwọn tí ó ń lọ ́ wọ ́ sí ìwà Ìjalèlókun ni wọ ́ n ń pè ní àwọn ajalèlókun .
Ohun tí ó ń tù mí ninu ní àkókò ìpọ́njú ni pé:ìlérí rẹ mú mi wà láàyè.
Orile-ede Egypt fofin de egbe Brotherhood ni odun 2013, leyin ti won fipa le Aare Mohamed Mursi kuro lori alefa, eyi ti o sokufa ifehonu-han iwode awon alatileyin re tako igbese ohun, latigba naa, ni ijoba ti pe egbe naa ni egbe omo-ogun olote.
Aṣagbeyẹwo iṣuna owo si abẹ akoso kan, eleyii ti Igbimọ Aṣakoso Iṣẹ Agbeyẹwo
Ó sì fi ògúnná náà kàn mí lẹ́nu, ó ní: “Wò ó, èyí ti kàn ọ́ ní ètè: A ti mú ẹ̀bi rẹ kúrò, a sì ti dárí ẹ̀ṣẹ̀ rẹ jì ọ́.
Kunle Olasope ní ifẹ si isẹ iroyin lo jẹ ko lọ si ileesẹ agbohunsafẹfẹ BBC lati lọ gba imọ kun imọ nipa isẹ igbohunsafẹfẹ lọdun 1962.
Baba Ijesha mẹnu ba a pe Alagbe ni Yoruba oni Tiata ka ma fi nkankan bo o loju o si ṣalaye idi to fi sọ bẹẹ pe iṣẹ awọn jẹ iṣẹ igba tori naa ẹni to ba pe eeyan si ere naa ni eeyan le ba ṣere.
“Nítorí náà, bí wọn bá sọ fun yín pé, ‘Ẹ wá wò ó ní aṣálẹ̀,’ ẹ má lọ.
ti won yoo gba lati mojuto eto iselu, eto isejoba , gbigbogun ti ikọ ọlọtẹ ,eto
Aarẹ Buhari dẹbi ru awọn musulumi lori ọrọ agbesunmọmi Boko Haram nitori wọn o tete dẹkun iwaasu odi tawọn Boko haram n gbe kiri ki wọn to di nla.
Tortoise surgery: Àwọn dókítà fi wákàtí mẹ́fà ṣiṣẹ́ abẹ dóòlà ẹ̀mí ìjàpá tí ọkọ̀ gbá
Lẹ́yìn naáà ni Bobrisky bá gbe sojú òpó Instagram rẹ̀ pé àkàrà òyìnbó yìí yẹ ki o jẹ́ tí ọjọ́ ìbí mi ki wan to wọ́gile láì nídìí."
Àjẹsára ọ ̀ fìnkì , tí a tún mọ ̀ sí àbẹ ́ rẹ ́ ọ ̀ fìnkì , jẹ ́ àjẹsára tí ń dáàbò bo ni lọ ́ wọ ́ ọ ̀ fìnkì .
Àwọn oníṣẹ́ Dafidi bá lọ sọ́dọ̀ Hanuni ní ilẹ̀ Amoni láti bá a kẹ́dùn.
Bí ó ti wù kí ẹ bínú tó, ẹ má dẹ́ṣẹ̀;ẹ bá ọkàn yín sọ̀rọ̀ lórí ibùsùn yín,kí ẹ sì dákẹ́ jẹ́ẹ́.
odù ifá pín sí ojú odù igba ó lé mẹ ́ rìndínlọ ́ gọ ́ ta ( 256 ) nígbà tì àwọn ojú odù wọ ̀ nyí náà pín sí ọ ̀ nà ẹgbẹgbẹ ̀ rún tí wọ ́ n ń sọ ̀ rọ ̀ nípa ìmọ ̀ oríṣiríṣi bíi : ìmọ ̀ ẹ ̀ rọ , ìmọ ̀ ní bí ayé ṣe wà , ìmọ ̀ ìṣègùn , ìmọ ̀ ìjìnlẹ ̀ àti bẹ ́ ẹ ̀ bẹ ́ ẹ ̀ lọ .
Oríṣun àwòrán, NAF Ogagaun agba naa ṣalaye pe awọn mẹtẹẹta ti wọn fa le agbofinro lọwọ yii jẹ awọn ti Tolulope lọ sile iwe girama pẹlu wọn ni Air Force Secondary School ni Kaduna.
Lágbára Oluwa, mò ń gbèrò ati rán Timoti si yín láì pẹ́, kí n lè ní ìwúrí nígbà tí mo bá gbúròó yín.
"O ni pe ""Aarẹ Buhari ko mọ eniyan marundinlogoji ninu aadọta to yan sipo nigba naa, ati pe emi paapa ti mo ti jẹ iyawo rẹ fun ọdun mẹtadinlọgbọn ko mọ wọn."
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé 12 Sẹ́rẹ́ 2021 Yoruba ni ọmọ ti yoo ba jẹ asamu, kekere ni yoo ti maa jẹnu samu-samu.
Akọroyin BBC to wọ inu ile itaja naa ni, ṣe ni awọn janduku ba ọpọ dukia jẹ nibẹ.
Togo ti fontẹ lu ipinnu pe ki ipo aare orile ede naa  ko gbọdọ ju saa meji lọ mọ.
Oríṣun àwòrán, View Press IYATỌ OJU ỌJỌ: Joe Biden ni oun yoo pada si adehun ti orilẹede Amẹrika ni pẹlu agbaye lori idẹkun oju ọjọ gbigbona, eleyii ti wọn pe ni 'Paris Climate Change.
Iṣé perfume tita kí ṣé nkán tí Adéwálé Aladejana yan láàyò ṣùgbọ́n nígbàtí anfààní rẹ sì sílẹ lati bere owo naa,n'isẹ ní o sọ di ilumọka.
Wo ohun táwọn jàǹdùkú ṣe sí ilé ẹjọ́ Igboṣere l'Eko Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, #EndSARS: Wo ohun táwọn jàǹdùkú ṣe sí ilé ẹjọ́ Igboṣere l'Eko Kò sáyè iwọ́de mọ́ l'Eko ẹ lọ tọwọ́ yín bọṣọ - Ọlọ́pàá Ileeṣẹ ọlọpaa ti fi ikilọ sita pe ko saye iwọde mọ ni ipinlẹ Eko bẹrẹ lati agogo mẹrin ọjọ Iṣẹgun Ogunjọ oṣu kẹwaa ọdun 2020.
Ó kéré tán, è̩kó̩ gbo̩dò̩ jé̩ ò̩fé̩ ní àwo̩n ilé‐è̩kó̩ alákò̩ó̩bè̩rè̩.
Osa Iwo ni, nitori iwa abuku Oluwo yii ni wọn se ni ko lọ rọọkun nile ninu ipade igbimọ awọn lọbalọba nipinlẹ Osun.
awon janduku gege bi omo –ise ti won fẹ lo ni jake –jado orile ede yii lati lọ
 Abiyamọ ni mi , mo si pa obi awọn ọmọ kan, bẹẹ lo sọ.
"Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Nollywood: Funmilayo Ogunsola mí kanlẹ̀ lásìkò àìsàn ráńpẹ́ 5 Èrèlè 2019 Oríṣun àwòrán, FACEBOOK Àkọlé àwòrán, Funmilayo Ogunsola tí ọ̀pọ̀ ènìyàn mọ̀ sí ""Mama Ijẹwuru"" ti fi ayé sílẹ̀ ní ilé rẹ̀ ní Ibadan."
Ó dìde, ó sì dúró níwájú ọba, ó ní, “Bí inú kabiyesi bá dùn sí mi, tí mo sì rí ojurere rẹ̀, bí ó bá fẹ́ràn mi, tí ọ̀rọ̀ náà bá tọ́ lójú rẹ̀, jẹ́ kí ìwé àṣẹ kan ti ọ̀dọ̀ ọba jáde, láti yí ète burúkú tí Hamani, ọmọ Hamedata, ará Agagi, pa pada, àní ète tí ó pa láti run gbogbo àwọn Juu tí wọ́n wà ní ìjọba rẹ̀.
 Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Mayowa Omoniyi: Kò sí orin Obey, Sunny Ade abí tàkasúfèé tí ń kò le ta gìtá sí Nitori naa, darandaran to ba fun maalu rẹ laaye lati lọ sinu oko oloko ni ijọba yoo gbe lọ sile ẹjọ.
Nígbà tí ó bá yá, a óo fìdí òkè ilé OLUWA múlẹ̀bí òkè tí ó ga jùlọ,a óo gbé e ga ju àwọn òkè yòókù lọ,àwọn eniyan yóo sì máa wọ́ wá sibẹ.
Kàkà bẹ́ẹ̀ à ń fara da ohun gbogbo kí á má baà fa ìdínà fún ìyìn rere Kristi.
Premier League yóò bẹ̀rẹ̀ padà lóṣù kẹfà NFF fi #30,000 kún #10,000 owó ìrànwọ́ oṣooṣù fún ìyá Rashidi Yekini àti Samuel Okwaraji Mo kábàámọ̀ pé n kò kàwé, kí n tó bẹ̀rẹ̀ iṣẹ́ tíátà - Sanyeri Aláàfin gbé àṣẹ kalẹ̀ láti dènà àtúnṣẹ̀ ìṣẹ̀lẹ̀ 'Soka'nílùú Ọ̀yọ̀ Nínú ìṣèjọba yìí, Èmi àti Ààrẹ Buhari lọlọ́rọ̀, kìí ṣe ọmọ Nàìjíríà-Ibrahim Gambari, olórí òṣìṣẹ́ lọ́fíìsì ààrẹ Àwọn alárùn coronavirus ṣe ìwọ́de ní Gombe, wọ́n ní ìjọba n febi pa wọ́nAmọ, Klopp ṣalaye pe lootọọ ni Ronaldo jẹ agbabọọlu to lamilaaka, o ga, o le fo, o le sare, gbogbo amuyẹ agbaọjẹ agbabọọlu pata lo ni.
Ẹ fi pẹ̀lẹ́pẹ̀lẹ́ wádìí ọ̀rọ̀ náà.
Ni agogo mẹsan aarọ ọjọ Ẹti ni eto naa yoo bẹrẹ ni gbangan Ọjọgbọn Theophilus Ogunlesi nidojukọ ọgba UCH.
Àwọn kókó ohun tó wà nínú lẹ́tà tí Aláàfin kọ sí Fayemi rèé Ọmọ ti lọ kí baba, Fayemi bẹ Aláàfin wo l‘Ọyọ, wọ́n jírórò lórí lẹ́tà Ìlú ò rẹ́rìn ín rárá, Alaafin Adeyemi III fárígá fún Buhari nínú lẹ́tà tuntun Àwọn alálẹ̀ kò ní forí jìn mí tí ń kò bá ṣe ọdún Ṣàngó - Alaafin Fatomilọla ní Ọ̀ọ̀ni Ifẹ ní olórí aládé nílẹ̀ Yorùbá, òun ló lẹ́tọ̀ọ́ láti dá sí ọ̀rọ̀ ọba l'Ekiti Ogbontagi olukọ ede ati Aṣa Yoruba, Peter Fatomilọla ti sọ pe, bi Alaafin ilu Ọyọ, Ọba Lamidi Adeyẹmi Kẹta, ṣe dasi ọrọ awọn lọba-lọba ipinlẹ Ekiti ko bojumu to.
Ẹlẹka jẹ igbakeji gomina to wa lori alefa lọwọlọwọ, Peter Ayodele Fayoṣe ẹni to fidi Kayode Fayemi rẹmi ninu idibo ọdun 2014 ni ipinlẹ naa.
Àwọn oluwọde #EndSARS yii n ṣé iwọde lati pe fun iwogile ikọ ọlọpaa SARS ati pe ki ijọba fi iya to tọ jẹ awọn to ti ṣọṣẹ ibi fun ara ilu sẹyin.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Àlàyé rèé lórí ìdí tí ìyá mi fi sọ fáráyé pé mo ti kú Supreme Court : Oyetola fẹ̀yìn Adeleke janlẹ̀ nílé ẹjọ́ tó ga jù lọ!
Iha kokanmi ti Aarẹ Buhari n kọ si gbigbe igbesẹ to tọ lati dẹkun awọn isẹlẹ ipaniyan to n waye ni ipinlẹ Benue ati awọn ipinlẹ miran latọwọ awọn darandarn Fulani lewu pupọ fun ibagbepọ alaafia awọn ọmọ orilẹede Naijria.
A máa hun aṣọ ọlọ́nà a sì fi bo ibùsùn rẹ̀,òun náà á wọ aṣọ funfun dáradára ati ti elése àlùkò.
"Oríṣun àwòrán, Facebook/Adoration Ministry Enugu Nigeria Obianinwa ni ""Mbaka sọ pe ka duro titi di ipari isin ti oun n se fun ifọrọwanilẹnuwo naa."
Nítorí ẹ ti ìlẹ̀kùn ìjọba ọ̀run mọ́ àwọn eniyan, ẹ̀yin fúnra yín kò wọlé, bẹ́ẹ̀ ni àwọn tí wọ́n fẹ́ wọlé, ẹ kò jẹ́ kí wọ́n wọlé.
Oríṣun àwòrán, Others O wa jẹjẹ lati san gbogbo owo itọju awọn ọmọ to lugbadi ibalopọ aitọjọ naa nile iwosan, ti yoo si tun seto iranwọ fun awọn obi wọn lati mu adinku ba isoro ti wọn koju.
00) Níní orí yìí, a ó rí òwe, ‘Àfàgò kẹ́yin àparò…’ Ohun tí ó fa òwe yìí ni ẹran tí Ọ̀sanyìnnínbí jí gbé àti ẹ̀wọ̀n tí wọ́n ní yóò lọ tí ìyàwó rẹ̀ yóò sì ti bímọ kí ó tó dé.
USOpen: Tání Naomi Osaka to gbewúro sójú Serena Williams?
Ajogun sọ pe, awọn kọlu agbegbe ti awọn afurasi naa n farapamọ si nile itura Mayas to wa ladugbo Lafenwa, niluu Abeokuta, lẹyin ti awọn kan ta awọn lolobo.
Àwọn jàǹdùkú pa fadá ní Taraba-Iléeṣẹ́ ọlọ́pàá Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
 ní ọdún 2010 , ó ṣe òkùnfà ikú àwọn ènìyàn tó tó 2,700 , èyítí ó wálẹ ̀ láti ènìyàn 3,400 tó kú ní ọdún 1990 .
Koda ọrẹbinrin rẹ ọhun sọ pe ọmọbinrin ti George bi fihan pe eeyan ti ko ṣe fi ọwọ rọ sẹyin lawujọ ni.
Àwọn tí wọ́n hu ewú lórí wà láàrin wa, ati àwọn àgbàlagbà,àwọn tí wọ́n dàgbà ju baba rẹ lọ.
 bákan náà , ewì ayaba a tún máa wáyé nínú ayẹyẹ ìlú ; tí ọba bá ti wà níbè .
Ìdin di ibùsùn tí ẹ sùn lé lóríàwọn kòkòrò ni ẹ sì fi bora bí aṣọ.
Inu atẹjade kan ti Oluwo fi ranṣẹ si BBC Yoruba ni ọrọ yi ti jade.
Osinbajo salaye pe, erongba awon egbe ohun ni lati ko awon ti oro kan ni eka aladani ati ile-ise ijoba ati awon oludokowo papo, lati fori kori, fikunlukun lati se amulo awon agbegbe meta naa.
Ti ẹ ko ba gbagbe, lọjọ ti eto idibo naa waye, ọtọ ni awọn ti ẹgbẹ oṣelu All Progressives Congress to jẹ ẹgbẹ to wa ni iṣakoso, ati ẹgbẹ to ni aṣofin ju n ile fi ọwọ si.
Amotekun: Àwọn ọdẹ nìkan kọ́ ni àmọ̀tẹ́kùn wà fún, a gba àwọn ọ̀dọ́ tó sán eegun pẹ̀lú
Nigba ti o n ba BBC Yoruba sọrọ, Ọgbẹni James Fanope to jẹ ọkan lara awọn alakoso eto owo iranwọ ijọba apapọ sọ pe oun ko le sọ ni pato iye awọn eeyan to ti fi orukọ silẹ ni ipinlẹ Eko.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: D.
Iléesẹ́ asojú Amẹ́ríkà ní Nàíjíríà sèfilọ́lẹ̀ ojú òpó tí yóò sọ gbogbo ẹ̀tọ́ tóo ní fún ọ̀ lóríí fóónù àti kọ̀ńpútà rẹ.
Koda, a lee ni ko si ohun to jọ ede ti wọn n pe ni iyawo lode oni ninu ede Yoruba, bi kii ba se isẹlẹ kan to waye lasiko kan, eyi to mu ki Iyawo wọ inu ede Yoruba, ti wọn si tun n pe awọn aya ni ọọdẹ ọkọ ni iyawo.
Premier League: Tottenham yọ ṣọ́ọ̀kì lẹ́sẹ̀ , ọ̀mì ni wọ́n ta lọ ní pápá ìṣiré Etihad
 o soju fun mississippi ni 1870 ati 1871 nigba itunko .
Jibirin ṣalaye pe bo tilẹ jẹ ko si ikankan ninu awọn ọmọ wọn ba agbara ọpọlọpọ awọn ọdaran naa jẹ.
Iṣẹ́ òkòwò ni wọ́n jọ ń ṣe.
Mo lépa àwọn ọ̀tá mi,mo sì ṣẹgun wọnn kò pada lẹ́yìn wọn títí tí mo fi pa wọ́n run.
O ṣafiwe ohun tawọn ologun ṣe nigba yẹn pe bii igba ti obinrin bi ọmọ tan ti wọn si bẹ ori ọmọ to ṣẹṣẹ yọri sita ni.
Jospeh Yobo ti di igbákejì akọ́nimọ̀ọ́gbá Super Eagles tuntun Ìpínlẹ̀ Oyo, Ogun, Ondo buwọ́lu àbádòfin Àmọ̀tẹ́kùn Ẹ wo àwọn ìlérí tí Buhari ṣe láti ọdún 2015 àmọ́ tí kò tíì mú ṣẹ Sultan parọwa yii nilu Osogbo lọjọbọ lasiko to n sọrọnibi ipade apero lori eto aabo ati aifararọ ni Naijiria eyi ti ibudo kan to wa fun agbelarugẹ asa ilẹ adulawọ seto.
Ohun mẹ́wàá tó yẹ kóo mọ̀ nípa Kunle Afod Ìgbà tí òògùn ẹ̀jẹ̀ ríru lè ṣiṣẹ́ jù rèé- Onímọ̀ Wọ́n ti rí Kìnìún tó sá lọ́gbà ẹrankò lẹ́yìn tó pa gbogbo ewúrẹ́ jẹ tán Ìdí tí mo ṣe fẹ́ yọ ayédèrú ìdí ńlá tí mo ní- Sophie Àṣẹ àwọn gómìnà là ń retí, àwa ti ṣetán láti dáàbò bo ilè Yorùbá- Gani Adams Kini awọn ọmọ Naijirria n sọ nipa Ken Saro-Wiwa?
Ogbontarigi oṣere yii ni ayika oun ati iṣẹ ti Babab oun ṣe silẹ maa n fun oun ni iwuri lati tẹsiwaju ninu iṣẹ ti oun yan laayo.
Irú wọn ni wọ́n ń sọ pé kí eniyan má ṣe gbeyawo.
Oríṣun àwòrán, @DAWNCommission Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Nítorí èyí ni mo ṣe di iranṣẹ láti mú ọ̀rọ̀ Ọlọrun ṣẹ, gẹ́gẹ́ bí iṣẹ́ tí Ọlọrun ti fún mi láti ṣe nítorí yín.
OLUWA yóo ṣàánú yín nígbà tí ẹ bá ké pè é, yóo sì da yín lóhùn nígbà tí ó bá gbọ́ igbe yín.
" Àwọn irú ìfarakọ ̀ àti / tábí àìgbọràn aráàlú ní bọikọ ́ tì bíi ti bọikọ ́ tì Ọkọ ̀ -akérò montgomery ( 1955-1956 ) tó yọrí sí rere ní alabama ; "" ìjókòódè "" bíi ti ìjọ ́ kòó greensboro ( 1960 ) ni north carolina ; ìwọ ́ de , bíi ti àwọn ìwọ ́ de láti selma lọ sí montgomery ( 1965 ) ni alabama ; àti orísirísi ọ ̀ pọ ̀ akitiyan aláìníjàgídíjàgan ."
Ọpa epo bẹntiroo naa to gba ina ni agbegbe Ijegun/Isheri nipinlẹ Eko bẹrẹ ni owurọ kutu ni nkan bii ago marun.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ọ̀ṣun Oṣogbo 2018: Ulrich Salazar wálé ọdún láti New York Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Ọ̀ṣun Oṣogbo 2018: Ulrich Salazar wálé ọdún láti New York 16 Ògún 2018 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 17 Ògún 2018 Arugbá ti ṣetan láti gbé ìgbà fún ọdún 2018 kí àláàfìà lè jọba ní Ọṣun.
Lẹyin o rẹyin, baba ati ọmọ foju kan ara wọn fun igba akọkọ, wọn bu sẹkun, ọjọ yii si ni Karoline ri ara rẹ bii ọmọ eeyan kan, ti inu mi si dun pe mo jẹ alawọ dudu.
ó bá fi àrùn burúkú pa wọ́n.
Timi Frank to fi atẹjade sita wa kesi orilẹede Amẹrika(US), Ilẹ Gẹẹsi(UK), Ajọ Isọkan Agbaye(UN) ati Ajọ Isọkan Europe(EU) lati kilo fun Aarẹ Buhari ko dẹkun iwa ifiyajẹ awọn ẹgbẹ alatako.
Ajalu nla nii ba jẹ fun ipinlẹ wa ka ni ọna miran lọrọ yii ba yọ ni.
Mo láyọ̀ pupọ nítorí mo ti rí àwọn tí wọn ń gbé ìgbé-ayé òtítọ́ ninu àwọn ọmọ rẹ, gẹ́gẹ́ bí a ti gba òfin lọ́dọ̀ Baba.
Fifi owo sinkun ofin mu awon alufaa yii waye leyin ti Aare Paul Kagama so ni gbangba  pe, opolopo awon ile-ijosin ni won da sile lona aibofin mu lorile-ede naa.
“Mo wí fun yín nígbà náà pé kí ẹ má ṣojo, kí ẹ má sì jẹ́ kí ẹ̀rù wọn bà yín.
 Òdùduwà tí ó jẹ ́ bàba Ẹkùn ni ó tọ ́ jú Àjàpadá dàgbà nítorí Ẹkùn tètè kú .
Kunle, Aremu Gabriel àti Mojisola Afolayan: Oríṣun àwòrán, others Àwọn akínkanjú osere tíátà yìí, Kunle Afolayan, Aremu Afolayan, Gabriel Afolayan àti Mojisola Afolayan ni wọn jẹ ọmọ bibi inú gbajumọ àgbà ọjẹ osere tíátà kan tó ti di olóògbé, Adeyemi Afolayan, tí àwọn èèyàn tún ń pe ni Ade Love.
 O ni: “Won yoo bere sini san owo osu awon
Lóòótọ́ à ń fi ẹwìrì fẹ́ iná,òjé sì ń yọ́ lórí iná;ṣugbọn alágbẹ̀dẹ ń yọ́ irin lásán ni,kò mú ìbàjẹ́ ara rẹ̀ kúrò.
“Ní ọjọ́ ìsinmi, ẹ fi ọ̀dọ́ aguntan meji ọlọ́dún kan tí kò ní àbààwọ́n rú ẹbọ pẹlu idamẹrin ìyẹ̀fun òṣùnwọ̀n efa tí a fi òróró pò fún ẹbọ ohun jíjẹ pẹlu ẹbọ ohun mímu.
Minisita to n ri si oro ere idaraya ati idagbasoke awon odo ni Naijiria, ogbeni Solomon Dalung ti pe fun atileyin ti o lelegbe latowo awon omo orile-ede yii ati ajo NFF fun aseyori iko agbaboolu Super Eagles saaju idije agbaye to n bo lona lorile-ede Russia.
Lọna rẹ pada sile pẹlu awọn akẹgbẹ rẹ lati ile iwe ni awn sọja yii ti fipa mu u.
"Abamiẹda leleyi o, ti o si jẹ eyi ti o tobi julọ ni gbogbo aye ati orun"" Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!"
Oríṣun àwòrán, PHILIP OJISUA Àkọlé àwòrán, Àyájọ́ ọjọ́ àwọn èwe lónìí Ní ọjọ́ ọ̀tọ̀ọ̀tọ̀ ni oníkálùkù orílẹ̀-èdè àgbáyé máa ń se ayẹyẹ àyájọ́ ọjọ́ àwọn èwe káàkiri àgbáyé.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Àwọn dókítà ya ìbejì tó lẹ̀pọ̀ l'Abuja PDP: Ayé sì wà fún Ambode to bá fẹ tíkẹ̀ẹ̀tì Gómìnà lọ́dọ̀ wà Buhari: Àwọn tó lọ́wọ́ nínú ìṣekúpani Kaduna yóò fojú winá Ni kete ti wọn ti sọ niwaju ileẹjọ naa pe awọn ko jẹbi ẹsun ni adajọ ti gba oniduro awọn mẹta pẹlu Sẹnetọ Adeleke.
Nígbà tí Rehoboamu dé Jerusalẹmu, ó kó ọ̀kẹ́ mẹsan-an (180,000) àwọn akọni ọmọ ogun jọ láti inú ẹ̀yà Juda ati Bẹnjamini, láti bá àwọn ọmọ Israẹli jagun, kí ó lè fi ipá gba ìjọba rẹ̀ pada.
"Mo máa ń rí wọn pẹ̀lú ojú ẹ̀mí.
Gbogbo àfonífojì ni a óo ru sókè,a óo sì sọ àwọn òkè ńlá ati òkè kéékèèké di pẹ̀tẹ́lẹ̀:Gbogbo ọ̀nà tí ó wọ́ ni yóo di títọ́,ọ̀nà gbágun-gbàgun yóo sì di títẹ́jú.
Ọkọ akero ẹlẹni mẹrinla to n rinrin ajo lati ilu Eko lọ si Enugu ni a gbọ pe o lọ fori sọ ọkọ tirela laarọ ọjọ Iṣẹgun.
Police vs Shiite: Ẹ̀mí sùn níbi ìkọlù Shiite àti àwọn ọlọ́pàá l'Abuja
Oru ọjọ Iṣẹgun ni iroyin jade pe amofin ati agbẹjọrọ, Oloye Abimbọla Oṣuọlale Richard Akinjide ti ju awa silẹ.
Lẹ́yìn náà, Jesu wọ inú ilé lọ, àwọn eniyan tún pé jọ tóbẹ́ẹ̀ tí òun ati àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ kò fi lè jẹun.
Chelsea tún ṣubú dàánù lẹ́ẹ̀kan si
Ènìyàn méjìdínlọ́gbọ̀n lo ṣe pẹ̀kí ọlọ́jọ́ wọn ni Mubi
Ẹ gbé ọwọ́ yín sókè, kí ẹ gbadura ninu ilé mímọ́ rẹ̀,kí ẹ sì yin OLUWA.
to jẹ oniṣegun oyinbo lori atunṣe ẹwà sọ pe ohun ni iṣẹ abẹ to lewu jú, nítorí àwọn àbẹ́rẹ́ tí wọn máà ń lò lati fa ọ̀rá sí inú iṣan tó wà nínú ìkébè a máa rìnrìn àjò lọ sí inú ọkàn tàbí inú ọpọlọ.
 Ẹni tí ó gbé eégún náà ń pe ẹni tí ó wà láàyè pé :.
Oju ọjọ ilẹ naa dara ti ayika orilẹ ede naa si rẹwa.
Akitiyan aarẹ ile, Bukọla Saraki lati dawọn lẹkun si lo ja si pabo.
Eni to ba jale lo ba ọmọ jẹ nilẹ Yoruba.
Adamu ti ni awon ko ni fi ojo pe Aina lati fiya jẹ ọlọpaa ti o ba ru ofin tabi
Mr Latin, Jide Kosọkọ àti Mama Rainbow sọ̀rọ̀ lórí ìjà Toyin ati Lizzy Àwọn olólùfẹ̀ Toyin Abraham ati Liz Anjorin ti gbé ọ̀rọ̀ wọn rù sórí, ẹ wo òjò òkò ọ̀rọ̀ Ronke Oshodi Oke ati Liz Anjorin Oríṣun àwòrán, Ronke Oshodi Oke Àkọlé àwòrán, Ronke Oshodi Oke Ija bóóde nitori pe gbajugbaja oṣere, Ronke Oshodi Oke bu ẹnu atẹ lu ki awọn oṣere maa gbe aye ati aṣeyori wọn si ori ẹrọ ayelujara.
Public Holiday: Ìjọba Nàìjíríà ya ọjọ́ méjì sọtọ̀ fún ìsinmi ọdún Iléyá
ọ̀kan fún ẹbọ ìmúkúrò ẹ̀ṣẹ̀, ekeji fún ẹbọ sísun, pẹlu ẹbọ ohun jíjẹ.
yorùbá gbágbọ ̀ pé , iṣẹ ́ àgbẹ ̀ jé iṣẹ ́ ilẹ ̀ wa .
, ẹgbẹ́ òṣèré tíátà pàṣẹ fún Lizzy àti Toyin Àwa kìí jà lásìkò tiwa, ta ló bí ẹ tí wàa máa jà?
A ti rí ohun tí à ń wá!
Obinrin kansoso to jẹ oludije fun ibo gomina ti yoo waye lọjs Satide nipinlẹ Kogi, to tun n soju ẹgbẹ oselu SDP, Natasha Akpoti ti ke gbajare fun araye pe oun n bẹru ẹmi oun.
Oluwaremilekun Fatolu: Mo máa ń wọ kọ́mú “size 50H, ẹyọkan leè tó N15,000, Okrika N9,000"
 síbẹ ̀ , Ìfá tabi adábigbá ń gbé láàrin wọn .
Dogara fikun ọrọ rẹ pe, awọn alaṣẹ ẹgbẹ oṣelu gbọdọ rii pe wọn ko da ile aṣofin mejeeji pada sẹyin nipa fifa olori kalẹ fun wọn.
Ní igun mẹrẹẹrin ni àwọn gbọ̀ngàn kéékèèké yìí wà.
Ori mọto wọn ni wọn tun gun lọ yii Àkọlé àwòrán, Ki la ti fẹ se awọn ijamba ina epo pẹtiroolu to maa n waye ladugbo Ijẹgun, nipinlẹ Eko yii si Àkọlé àwòrán, A ba awọn mọlẹbi awọn eeyan to fori sọta ijamba ina to waye ni Ijẹgun yii kẹdun pẹlu awọn eeyan ti ọkọ ati isọ wọn jona BBC News, Yorùbá Ìdí tí ẹ fi le è nígbàagbọ́ nínú ìròyìn BBC Ìlànà Lílò Nípa BBC Òfin Àṣírí Cookies Kàn sí.
Mínísítà, fún ètò ìrìnnà orí afẹ́fẹ́ tẹ́lẹ̀ ri, Femi Fani-Kayode, ló fa ìbínú wọn yọ nígbà tó ń bú adelé ààrẹ ọjọgbọn Yemi Osinbajo pé ọmọ iṣẹ́ Sàtánì ni.
Eyi mu ki awọn ọdọ beere ṣe iwọde fún iwọgile ikọ yi ati idasilẹ igbimọ iwadii ti yoo gbẹjọ lori aṣemase wọn.
Fani Kayode ni ifura pe awọn ọlọtẹ ọta oun ninu oṣelu lo lee ṣe agbatẹru iru ibeere yii ti wn si fẹ lo arakunrin naa lati doju ti oun ati lati ba daadaa oun jẹ.
Sudan Protest: Ìkọlùkọgbà bẹ́ sílẹ̀ láàrín àwọn ológún
Nitori naa, ni a ṣe ṣe akojọpọ diẹ lara awọn iṣẹlẹ ti ẹ le fojusọna fun l'ọdun 2020.
AFRIMA: Davido, Falz, Ambọde gba àmì ẹ̀yẹ olórin Afíríkà
Ni igbà ti ó yá, èrò bẹ̀rẹ̀ si kúrò lati ilú kan si ekeji, pàtàki nitori ọ̀gbẹlẹ̀, iyàn, ogun tàbi ẹni ti wọn lé kúrò ni ilú nitori iwà burúkú.
Ó kó aṣọ ranṣẹ sí i, kí ó lè pààrọ̀ àkísà rẹ̀, ṣugbọn Modekai kọ̀ wọ́n.
Jesu dáhùn, ó wí fún wọn pé, “Ẹ ní igbagbọ ninu Ọlọrun; 
Eyi lawọn eeyan kan ni o mu ki awọn ọlọpaa o ṣina ibọn bolẹ sawọn oluwọde naa ti meji si ku.
O ni , “ki a tẹ siwaju lati maa jẹ oluranlọwọ fun awọn arakunrin ati arabinrin wa, ki a si maa fi ifẹ han sira wa”.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Akomolede ati Aṣa: Mọ̀ síi nípa ìró afárànma àti agbárànmọ́ fáwẹ́ẹ̀lì Yorùbá Bakan naa ni wọn tun fi kun un pe awọn ileeṣẹ redio ati tẹlifiṣan ipinlẹ naa yoo tẹsiwaju lati maa ṣe eto ẹkọ lori ikanni wọn gẹgẹ bi wọn ti ṣe n ṣe tẹlẹ.
Amọ eyi to ku awọn yoo se loju opo ayelujara lati ago mọkanla alẹ di ago kan owurọ.
Bakan naa ni Asoya ti Ile Isoya, Oba Muraina Adedini mẹnuba awọn iṣe akanṣe ti Ọọni n ṣe fawon to ku diẹ kaato fun lawujọ.
Ilé aṣòfin ìpínlẹ̀ Oyo jáwée lọ sinmi nílé fún alága ìgbìmọ̀ mẹ́tàlá káàkiri ìjọba ìpínlẹ̀ 'Ìdí tí kámẹ́rà táa rí ní Lekki Tollgate kò fi ká gbogbo ìṣẹ̀lẹ̀ tó wáyé rè é' Wo àfipábánilòpọ̀ ẹni ọdún 51 tí ìjọba ìpínlẹ̀ Ekiti tú làṣirí ní gbangba Adeniyi ṣalaye pe DPO ọhun ni ki oun wa gba owo lọjọ Abamaẹta ọjọ kinni oṣu kọkanla ni o fi o ju oun si atimọle.
Báyìí ni ọ̀rọ̀ yìí ṣe rí ní òwúrọ̀ Ọjọ́bọ, ọjọ́ kínní oṣù kẹẹ̀rin , ọdún 2020.
Ẹ maṣe lo awọn ohun elo ile to mu bi abẹ tabi ohunkohun rara lati fi yọọ.
Ìgbà mẹ́rin tí ọ̀rọ̀ Oluwo dá awuyewuye sílẹ̀ Ìjọba Ọṣun ti dásí ìjà láàrin Oluwo àti Agbowu Oluwo yí ìpinnu padà,Telu lóun yóò tẹlé àṣẹ lọ rọọ́kún nílé ṣùgbọ́n.
Nítorí náà, èmi OLUWA Ọlọrun àwọn ọmọ ogun, Ọlọrun Israẹli, ni mo sọ pé n óo jẹ́ kí ibi bá àwọn ará Juda ati àwọn tí wọn ń gbé Jerusalẹmu, nítorí pé mo bá wọn sọ̀rọ̀, wọn kò gbọ́; mo pè wọ́n, wọn kò dáhùn.
Oríṣun àwòrán, Twitter/Ministry of Humanitarian Affairs Koda, ki ajakalẹ arun yii to wọle de, apa kan ẹkun ila oorun Afirika ati gusu Aṣia lo ti n ba ọwọngogo ounjẹ finra eleyii to waye nipasẹ ọda ojo ati ajalu awọn kokoro ajẹkorun fun ọpọlọpọ ọdun.
Bí wọ́n ti ń jẹ àsáró náà, wọ́n kígbe pé “Eniyan Ọlọrun, májèlé wà ninu ìkòkò yìí!
    Pẹ̀lú ìbànújẹ́ ni ọmọ náà fi kúrò lọ́dọ̀ bàbá rẹ̀ tí ó lọ sí ààfin isalẹ ilẹ̀, nítorí nní ọjọ́ tí ẹnikẹta bá ti bọ́ sí ààrin olùfẹ́ méjì, ayọ̀ a ki iré mọ́lẹ̀ a sáré bí ẹranko tí ó gbúròó ajá ọdẹ, ìbànújẹ́ a gbé àga Òyìnbó, á fẹ̀yìntì dípò ayọ̀, ayé a yí, nǹkan a di rúdurúdu.
Wọ́n pọ́n ahọ́n wọn, ó mú bí ahọ́n ejò;oró paramọ́lẹ̀ sì ń bẹ ninu eyín wọn.
Pilatu bá gbà láti ṣe bí wọ́n ti fẹ́.
Pupọ ninu wọn ko ni ribi kọ kewu ọhun ti wọn a si maa tọrọ bara loju titi kaakiri.
asaaju nile igbimo asofin mọ, oun se eleyii lati fi aaye silẹ fun awon eniyan
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Mama Rainbow: Toyin Adegbola àti Razak Olayiwola ní ìyá rere àti àwòkọ́ṣe gidi ní Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
"Bi Seyi Edun si ṣe fẹ Adeniyi Johnson lo da aawọ silẹ laarin emi ati Toyin Abraham, nitori o gbagbọ pe lati ipasẹ mi ni Adeniyi Johnson fi fẹ Seyi Edun.
Ifẹsẹwọnsẹ naa ti o mu iriwisi orisirisi wa gbona janjan lati ibẹrẹ titi di ipari.
 eniyan ki i ko àìsàn hcv nipa ara-kan-ara lasan , bi i didi mọ ni , fifi-ẹnu-ko-ẹnu , tàbí nipa ajọlo ohun-elo ijẹun tàbí ohun-elo sise-ounje .
for Peace Studies and Practice) ti ile eko giga 
Gbọ́ tiwa, Ọlọrun mi, ṣíjú wò wá, bí àwa ati ìlú tí à ń pe orúkọ rẹ mọ́, ti wà ninu ìsọdahoro.
    Ẹ̀yin aláìmoye, ẹ̀yin aláìgbọ́n, jíjókòó tí mo jókòó, n kò jókòó ní ìjókòó ọba ni, tàbí aṣọ tí aṣọ tí mo wọ̀ ni kò tó ti ọba?
Gege bi akoroyin ile-igbimo naa, Edwin Akwueh se so, o salaye pe ninu oro ikinni kaabo abenugan ile-igbimo asofin, dokita Ahmad Lawan, o lo menu ba eto ilana Isuna owo ina, MTEF, eleyi ti ile-igbimo ohun si ti tewo gba.
eto idibo aare ,ti ajo INEC kede rẹ, mo ba ọ yọ, inu mi si dun pẹlu, Nitori naa,mo
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Kòkòrò ajokorun n ṣé ọsẹ fún ọpọ àgbẹ lorílè-èdè Naijirià Ebola tiwá ni kòkòrò ajokorun"" Tope Amujo n ṣíṣe pẹlú àwọn àgbẹ̀ ní ìpínlè Kwara Osun ati Oyo."
''Lasiko konle o gbele coronavirus ni mo bẹrẹ iṣẹ lori awo naa tori mo mọ pe awọn eeyan yoo mujo jo lẹyin ti covid-19 ba kasẹ nilẹ,'' Obesere lo sọ bẹẹ.
Nǹkan mẹ́wàá tó yẹ kí o mọ̀ nipa George Floyd tí ọlọ́pàá fún lọ́rùn pa rèé Oyún oṣù méje ló ń bẹ nínú Azeezat, kí wọ́n tó f'òkúta fọ́ ọ lórí Ṣé lóòtọ́ ni òjòjò dá Abiola Ajimobi wólẹ̀?
”Ó sì dáhùn pé: “Títí tí àwọn ìlú yóo fi di ahoro, láìsí ẹni tí yóo máa gbé inú wọn; títí tí ilé yóo fi tú láì ku ẹnìkan, títí tí ilẹ̀ náà yóo fi di ahoro patapata.
"Ibeere naa bi Fani-Kayode ninu, eyi to mu ko pe akọroyin naa ni ""ọdẹ''."
Idriss ni olori miran ti gbaṣẹ lọwọ Shekau nitori opin ti de baa.
Nítorí eléyìí ńkọ́, nígbà tí ó di ọjọ́ kan báyìí, nítorí ọkùnrin náà kò wo iwájú, mọ́tò ńlá kan kọlù ú, ó ṣubú lulẹ̀, ọkàn rẹ̀ kò sì lù kìkì mọ́, bẹ́ẹ̀ ni Olódùmarè ti pa á láṣẹ fún mi pé, ẹni tí ọkàn rẹ̀ kò bá lù kìkì mọ́, kí n mú olúwaarẹ̀ wá síwájú òun.
Ṣugbọn wọn kò rí, bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé ọpọlọpọ ni àwọn ẹlẹ́rìí-èké tí wọ́n yọjú.
''Maa fọwọ rọri ku, ti iriri mi yii ba le jẹ ki ọpọ bẹrẹ si sọrọ lori iwa ifipabanilopọ ati ọna abayọ si iṣoro yii.
Bí mo sì tẹ́ ibùsùn mi sí isà òkú, n óo bá ọ níbẹ̀.
 Ìfèsì ara ẹni lọ ́ nà òdì sí ohun tí ènìyàn kòrira a má a wáyé lára àwọn ènìyàn tó kéré sí ìwọ ̀ n kan nínú 100,000 lára àwọn tó gba àjẹsára náà .
Ó fi orin titun sí mi lẹ́nu,àní, orin ìyìn sí Ọlọrun wa.
Àjọ NAFDAC fọwọ́ sí pípo ògùn chloroquine fún àyẹ̀wò ìtọ́jú coronavirus Ifá ti sọ̀rọ̀ lórí àrùn Coronavirus-Ọọ̀ni Ilé Ifẹ̀ Coronavirus: Wo ohun tí o ní láti ṣe láti dáàbò bo ara rẹ Ẹ gbọ́ ìròyìn ayọ̀ lórí àrùn Coronavirus Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí 2 sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
Ìgbẹ́jọ́ Naira Marley sún síwájú bí àwọn agbẹjọ́rò ṣe ń jà sí àga ìjókòó Kí ló dé tí Ilé ẹjọ́ sún ìgbẹ́jọ́ Naira Marley sí ọ̀la?
Lẹ́yìn tí o bá ti wẹ̀ wọ́n mọ́, tí o sì ti yà wọ́n sọ́tọ̀ bí ẹbọ fífì sí OLUWA, ni àwọn ọmọ Lefi tó lè ṣiṣẹ́ ninu Àgọ́ Àjọ.
O si kede l'oṣu Kọkanla, ọdun 2014, pe oun ti ri atilẹyin gba ni Philippines.
Oríṣun àwòrán, Others Àkọlé àwòrán, Àwọn ti ọrọ naa ṣe oju wọn ni ojo arọrọda lo fa bi afara naa ṣe ja ni Ọjọ Abamẹta.
Awọn ará ìlú ti rọ ìjọba láti fi àwọn ọmọogun sí ìlú to sún mọ wọn Gudumbali kí ìkolù yìí tó wáyé sùgbọn ti wọn kò kọ bi ara sí ẹ̀bẹ̀ náà.
Bí o bá lọ sí apá òsì, èmi á lọ sí apá ọ̀tún, bí o bá sì lọ sí apá ọ̀tún, èmi á lọ sí apá òsì.
ohun, Juan Guaidó ti pe lati sawari awon ti o ba wa nidi iku omobinrin omo odun
Ilé Aṣòfin yóò pe Godswill Akpabio l'ẹ́jọ́ fún ìbanilórúkọ jẹ́ Ọmọ Yorùbá mẹ́wàá tó jẹ́ àmúlùúdùn ní Amẹ́ríkà àti Yúróòpù Àwọn alágbára ni mo bá díje ṣùgbọ́n mo ti gbà f'Olọrun- Agboola Ajayi Bàbá mi Aláàfin, ẹ ṣeun ẹ̀bùn owó tí ẹ fún èmí àti ọkọ mi- Lizzy Anjọrin Ta ni Yusuf Satia ti iku mu lọ?
Ayobami fi ayo rẹ han lori yiyan iṣẹ yii laayo pe o n mu iwuri ba oun nigba gbogbo.
Ó fún ọba ní àwọn ẹ̀bùn wọnyi tí ó mú wá: ọgọfa (120) ìwọ̀n talẹnti wúrà, ọpọlọpọ turari olóòórùn dídùn ati ohun ọ̀ṣọ́ òkúta olówó iyebíye.
OLUWA ja àjàṣẹ́gun ńlá ní ọjọ́ náà.
Nítorí náà, iye eniyan tí ó pa nígbà tí òun náà yóo fi kú, ju àwọn tí ó pa nígbà tí ó wà láàyè lọ.
”Josẹfu dáhùn, ó ní, “Mo gbọ́, n óo ṣe bí o ti wí.
4 13527 Orilẹede Bahrain 341 21.
Arabinrin Díaz wa lati agbegbe Tarahumara nibi ti ọpọlọpọ eniyan ko ni imọ kika ati kikọ ninu Ede Ilẹ Spain (Spanish) ati ede abinibi wọn ni Ariwa orilẹ-ede Mexico.
Ní ọjọ́ mẹ́wàá sẹ́yìn Ọdọmọkunrin tó lówó jùlọ ní Afrika ti di awati ni olu ilu orileede Tanzania, Dar es Salaam.
Rehoboamu bá ṣe apata idẹ dípò wọn.
Oun ni ẹleṣẹ ayo keji to gbabọọlu sawọn julọ fun orilẹede Faranse, agbaọjẹ agbabọọlu Arsenal tẹlẹ ri, Thierry Henry lo wa ni ipo kinni.
O ṣeeṣe ki wọn dibo gbogboogbo loṣu kẹwaa ti awọn ọmọ ile ba dibo jẹwọ ara rẹ ni oṣu késan an ọdun.
Aṣọ funfun onílà tẹ́ẹ́rẹ́tẹ́ẹ́rẹ́ ati aṣọ ẹlẹ́pa ati elése àlùkò ati aṣọ pupa fòò ni wọ́n fi ṣe àwọn aṣọ títa náà, wọ́n sì ya àwòrán kerubu sára rẹ̀; wọn fi dárà sí i.
Ṣugbọn mo dáhùn pé,“Mo ti ṣiṣẹ́ àṣedànù.
La ẹnu rẹ kí o sì jẹ ohun tí n óo fún ọ.
Bí èmi Oluwa ati Olùkọ́ni yín bá fọ ẹsẹ̀ yín, ó yẹ kí ẹ máa fọ ẹsẹ̀ ẹnìkejì yín.
Gẹgẹ bi iroyin to jade lati aafin Emir, o ti ṣe diẹ ti Mama Nma ti n ba aisan ọjọ ogbo fa a ko to wa di pe o jẹ Ọlọhun nipe ni ile iwosan Fasiti Ilorin.
“Lonii labe isakoso ile-ise asoju orile-ede China ati ajo ti o n ri si oro-aje, awon ile-ise orile-ede China lorile-ede Nigweria ti to igba (200)”.
Awọn itan adiitu ti Fagunwa kọ yoo jẹ ki eeyan ro pe Iwin, ti eeyan n sa fun ni: Ọpọ awọn itan adiitu ti Orowọle kọ silẹ, lo n mu ki ọpọ eeyan maa ro pe Iwin tabi ẹmi airi kan ni, nitori se ni awọn ajẹ gan n sẹju pako-pako nigba ti Orowọle kọ itan nipa awọn ajẹ Koda awọn ọdẹ gan pe sibi ayẹyẹ Ijala wọn fun ọsẹ meji nigba ti Fagunwa tun sọ nipa bi awọn ọdẹ se n lo egbe lati poora kuro ninu ewu, pada sile Tun wẹ, ọpọ awọn eeyan lo n duro si awọn opopona to da lọna oko, to si wa ninu igbo lati pade Egbere ti yoo gbe ọrọ ojiji wa fun wọn nigba ti wọn ka itan ti Jaaniini kọ lori Iwin kan to pe ni Omi-loju-Egbere, ẹni to maa n gbe ẹni kiri pẹlu omije loju, ams to lee sọ eeyan di olowo lojiji Ọpọ eeyan lo tun yan ile Fagunwa lodi, ti wọn ko si debẹ wa kii mọ, nigba ti wọn ka bo se se apejuwe igbe aye awọn ara ọrun, ati ibugbe awọn eeyan mimọ, to fi mọ Esu ati oritamẹta tawọn orisa maa n gba kọja ati ile Iku, ti ọpọ eeyan si ro pe Orowọle gan ni ọrẹ iku Koda, awọn mọlẹbi Jaaniini paa ti, lai ba se pọ mọ fun ọpọ ọjọ nitori ohun to kọ nipa ọna to de ibode Arun, ti abule kan ko si na ọja fun ọpọ osu nitori eyi pẹlu Iyawo rẹ gan fẹ sa kuro nile, ti mọlẹbi rẹ kankan ko si ba sọrọ fun odidi ọdun kan nitori ohun ti Jaaniini kọ pe oun de ọrun Apaadi.
Akonimoogba agba iko Super Eagles, Gernot Rohr ti ro apapo orile-ede Russia lati satileyin fun iko re, papaajulo balogun iko ohun, John Obi Mikel ti iyawo re wa lati orile-ede Russia.
Awọn adari méèjì ssrs papọ bí wọn ṣe rọ àwọn musulumi láti túbọ máa[tèlé àwọn ẹ̀kọ́ ti wọn kọ ninu ààwẹ Ramadan, bákan náà ni Emir fi asìkò náà kí gómìnà kú ori ire ìwọle fún sáà keji.
Gomina ipinlẹ kano, Abdullahi Ganduje ti ṣalaye ohun ti yoo ṣe bi okete ba padi ọrẹ da fun ninu idibo gomina ọjọ satide.
s to soju fun ipinle mississippi gege bi republikani ni ile alagba asofin u.
 A o ni sinmi titi ti a o fi ri I pe a mu gbogbo awon odaran yii, ki a si fiya je won labe ofin.
OLUWA ní kí n sọ fún wọn pé,“Ṣé bí eniyan bá ṣubúkì í tún dìde mọ́?
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù SERAP: Àwọn olósèlu ń fojú ará ìlú gbolẹ̀ pẹlu owó tí wọ́n bù fún ara wọn 15 Èbibi 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 16 Èbibi 2019 Lẹyin ti ajọ ajafẹtọ ti a mọ si SERAP pinnu lati gbe ile igbimọ aṣofin Naijiria lọ ile ẹjọ lori biliọnu mẹrin ati aabọ ti wọn ni awọn ọmọ ile igbimọ aṣofin tuntun (9th National Assembly) yoo gba, ajọ naa ni awọn ko ni dawọ duro nibẹ; wọn ni o ṣeeṣe ki wọn tun gbe ileeṣẹ aarẹ lọ ile ẹjọ naa.
Ọtun Olubadan ilẹ Ibadan, Agba oye Lekan Balogun, ẹni to sọrọ lorukọ awọn ọba yoku salaye pe bi Olubadan se n fi ẹnu yẹpẹrẹ ade ori awọn ko jẹ itẹwọgba rara.
Nigba ti awọn ọmọde to le lẹgbẹgbẹrun miliọnu ni aisan naa mu ẹmi wọn lọ ni awọn orilẹede ti ọrọ aje wọn ko kẹsẹjari lagbaye.
Joshua so lasiko to n ba BBC soro pe, “O gbami ni igba di e lati le ja niwaju ero ti o po to yii, fun idi eyi anfani naa ni maa lo lati fi fagbahan Parker,”Ni bayii, eni ti o ba pegede ninu ifigagbaga ohun, ni yoo lanfani lati gbe beliti igbadi meta loole.
"Ṣugbọn Ọjọgbọn Trudie Lang ni Fasiti Oxford sọ pe ""ko si ilana kankan"" to faramọ fifi omi ṣan arun lọ sinu ikun rẹ lati pa a."
Aare ni odun merindinlogun ti  ijobe egbe  People’s Democratic Party (PDP)  ti lo lori aleefa ti ba opolopo nnkan je ,
Shiite: Ẹ̀mí àti ara wa kọ ohun tí ìjọba ń ṣe sìwa láti 2015
Oríṣun àwòrán, Twitter Ní kété tí mo bá ti bímọ kí ló yẹ kí n ṣe láti dáàbò bo ọmọ mi?
Moesha Boduong: Gbogbo obìnrin nílò ọkùnrin tí yóò máa tọ́jú wọn
Nigba ti idanwo 'Competitive Entrance Examination' ni awọn ileewe imọ sayẹnsi yoo waye ni Ọjọ Kọkandinlogun, Oṣu Kẹjọ.
Ayefele fi orin ẹ ṣeun sẹ́nu kí Ajimobi Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Orangun: Èdè àti àṣà Yorùba ní láti jọ wá lójú Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Toyosi Adesanya: Iléeṣẹ́ ọlọ́pàá ní Kwara ní àwọn àti Fijilanté wà nínú igbó láti ṣàwárí ọ̀daràn tó ṣèkọlù náà
Nítorí pé ní àkókò ajinde kò ní sí pé à ń gbé iyawo, tabi pé à ń fi ọmọ fún ọkọ; nítorí bí àwọn angẹli ti rí ní ọ̀run ni wọn yóo rí.
" Sanches, ẹni to darapọ mọ Man Utd latinu ikọ Arsenal losu to kọja, ni iroyin kan nsọ kiri pe oun ni agbabọọlu to n gba owo julọ ninu idije liigi Premier , lẹyin ti wọn ti taa, to si n gba miliọnu mẹrinla Euro fun ọdun kan lẹyin ti wọn ba ti yọ owo ori.
N óo dá ọ̀tá sí ààrin ìwọ ati obinrin náà, ati sí ààrin atọmọdọmọ rẹ ati atọmọdọmọ rẹ̀.
Ninu àlá, lójú ìran ní ààrin òru,nígbà tí eniyan bá sun oorun àsùnwọra, lórí ibùsùn wọn,
Ọdun marun un ni ijọba fun awọn ile isẹ nigboro tabi nkan irina bii ọkọ ati baalu gbudọ tun ọna wọn ṣe ki awọn akanda le maa ri aye wọle.
com/rhdH5v5na6— The NFF 🇳🇬 (@thenff) June 28, 2018Ewe, Rohr ti tuko Super Eagles gba ifesewonse ogun niye, O jawe olubori ninu ifesewonse mesan, O padanu ifesewonse mefa, O si gba ami dogba-dogba marun un.
Oyèyẹmí sọ wípé, Olóògbé tí ó gbẹ̀mí ara rẹ̀ náà jẹ́ ọ̀gá fún àwọn ọlọpàá pàtàki tí ó ńkọjú ìjà sí àwọn ọlọ́ṣà ní ìpínlẹ̀ Enugu nígbà kan rí."
Aburo oloogbe oun Chukwuemeka Odili salaye fun oniroyin lorukọ gbogbo ẹbi ni ejo lọwọ ninu lori ọrọ naa.
Èyí ni bí èèyàn 538 ṣe ń yan ààrẹ lé èèyàn mílíọ̀nù 331 ní Amẹ́ríkà Kóníléógbélé ọlọ́sẹ̀ márùn ún gbáko ni ìjọba Nàíjíríà gbé kalẹ̀ fàwọn oṣìṣẹ́ lábẹ́ ìlànà Covid-19 tuntun Ìwádìí tú àṣírí Dókítà tó pa ìyàwó rẹ̀, ó fẹ́ pa ọmọ wọn méjì, òun fúnrarẹ̀ tún pokùnso Kí ló tún ṣe Òṣèré fíìmù Yorùbá míì tó ń gba ẹ̀jẹ̀ àtomi níléèwòsàn?
Awon agbofinro orile-ede Germany ti kede pe won ti lo mu awon kan ni awon ibudo afurasi kookan kaakiri orile-ede naa ninu ise akanse fo-o-tuutu ti won n se lori awon onise ibi ajinigbe.
Iranṣẹ náà lọ, ó sì pada wá, ó ní, òun kò rí nǹkankan.
Eyi lo mu ki awọn oṣiṣẹ ileewosan naa ṣe ifẹhonu han ni Ọjọbọ, lati fi ẹdun ọkan wọn han si ohun ti wọn ṣapejuwe gẹgẹ bi 'aibikita ijọba ipinlẹ naa si alaafia wọn.
Ọgbẹni Biden lo n lewaju lati di oludije ti wọn yoo gbe aṣia ẹgbẹ Democrat fun lati kopa ninu idibo aarẹ lọdun to n bọ.
Kini awọn igbesẹ to ṣeeṣe ki Ajọ Amuṣẹya lori arun Coronavirus,,PTF gbe loni?
Coding Kids: Ẹ wo àrà t'àwọn ọmọ kékeré ń fi ẹ̀kọ́ kọ̀mpútà dá
Wọ́n ń kígbe pé,“Ọ̀dọ́ Aguntan tí a ti pa ni ó tọ́ síláti gba agbára, ọrọ̀, ọgbọ́n, ipá, ọlá, ògo ati ìyìn.
Oludari agba awon omo ogun ohun ni to n mojuto ipese ina monamona ati mekaniki, ogagun Johnson Olawumi ti o lo soju oga agba yanyan ohun safihan ipa ati akinkanju awon omo ogun naa gege bi ohun ti o te lorun.
 Ijoba ti seto adojutofo fawon agbe sisele pajawiri ti enikeni ko fokan si lasiko yii”.
Nigba to n gbe idajọ ọhun kalẹ, Adajọ Abdullahi Ilelah ni oun gba ẹbẹ Abbo to ni oun ko lẹjọ jẹ lori awọn ẹsun ti wọn fi kan.
Ọjà Àgbáláta ní Badagry rèé, níbití ẹran ejò ti dùn ju ẹran adìẹ lọ Ìròyìn ayọ̀!
Wọ́n bẹ̀rẹ̀ sí pẹ̀gàn mi, wọ́n ń fi mí ṣe ẹlẹ́yà;wọ́n sì ń wò mí bíi pé kí n kú.
Labani sọ fún un pé, “Jẹ́ kí á lọ sí ilé, ìwọ ẹni tí OLUWA bukun.
Ọgba ọlọpa Israel sọ wipe olukọni ere boolu kan wa ninu awọn ti wọn ku, sugbọn wọn ko ti gbe orukọ kankan jade.
Kò sì ṣe ohun tí ó tọ́ lójú OLUWA bíi Dafidi baba ńlá rẹ̀.
Akin Olúṣínà àti Ilésanmí lọ sí ilé Ọ̀sanyìnnínbí.
Ilẹ̀ Gẹ̀ẹ́sì yóò kúrò pátápátá lára àjọ EU ní Jan 31 ọdún 2020 Lẹ́yìn ìpàdé òní l‘Abuja, ṣé ASUU yóò yanṣẹ́ lódì àbí bẹ́ẹ̀kọ́?
Kí àwọn tí ń wá ìdáláre mimáa hó ìhó ayọ̀, kí inú wọn sì máa dùn,kí wọ́n máa wí títí ayé pé,“OLUWA tóbi,inú rẹ̀ dùn sí alaafia àwọn iranṣẹ rẹ̀.
Bí a bá fi í sílẹ̀ báyìí, gbogbo eniyan ni yóo gbà á gbọ́, àwọn ará Romu yóo bá wá, wọn yóo wo Tẹmpili yìí, bẹ́ẹ̀ ni wọn yóo pa orílẹ̀-èdè wa run.
Chief of staff Ibrahim Gambari: Ohun tí a mọ̀ nìyí nípa Ọ̀jọ̀gbọ́n Ibrahim Gambari tó ṣeéṣe kó rọ́pò olóògbé Abba Kyari gẹ́gẹ́ bíi olórí àwọn òṣìṣẹ́ lọ́fíìsì Ààrẹ Buhari Oríṣun àwòrán, Presidency Ààrẹ Muhammadu Buhari ti yan Ọ̀jọ̀gbọ́n Ibrahim Gambari gẹ́gẹ́ bíi olórí àwọn òṣìṣẹ́ tuntun nílé iṣẹ́ ààrẹ.
Gbogbo eniyan níláti fi ara wọn sí abẹ́ àwọn aláṣẹ ìlú, nítorí kò sí àṣẹ kan àfi èyí tí Ọlọrun bá lọ́wọ́ sí.
Gẹgẹ bi itan ṣe sọ, asọtẹlẹ ti wa nipa ibi rẹ ni wọn fi sọọ ni Ẹnitan, baba baba rẹ ni o si sọọ ni Adeyẹye.
Ayédèrú Ọ̀ṣun ni wọ́n ń bọ lónìí, kìí ṣe ojúlówó - Bàbá Ọlọ́ṣun tún figbe ta Wá gbàkàrà, gba dùǹdù ni Tottenham fi gba ọ̀mì lọ́wọ́ Manchester city Awọn janduku kan lo lanfani yii lati ja ole, koda wọn tun di opopona mọrosẹ ilu Eko si Abeokuta pa.
Ipinlẹ Ọṣun ati Ekiti ti gbe igbimọ kalẹ gẹgẹ bi itẹsiwaju igbesẹlẹyin ti gbogbo awọn ipinlẹ naa ti kọkọ buwọlu ofin Amọtẹkun ki wahala ajakalẹ arun coronavirus to wọle de Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Ìdàkejì rẹ̀ sì làá rí nígbà ọ̀gìnìntìn tí nṣe ìgbà òtútù.
Nítorí èyí, kò sí ẹni tí ó yẹ ki ń fún ni Ẹwadapọ̀ nítorí ohun tí ẹ mú bọ̀, ìdánwò mìíràn ni mo máa ṣe fún yín, ẹni tí ó bá ṣe dáadáa jùlọ nínú èyí nì ní yóò fẹ́ Ẹwadapọ̀, ìwọ̀ntunwọ̀nsì lobìnrin.
“Wọn yóo da aṣọ aláwọ̀ aró bo tabili tí burẹdi ìfihàn máa ń wà lórí rẹ̀.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ìbúgbàmù ńlá ati iro ibọn gbalẹ ni ile itura Nairobi Awọn ti ọrọ naa ṣoju wọn sọ fun awọn akọroyin pe niṣe ni awọn eeyan n sa asala fun ẹmi wọn ti ẹjẹ si kun ara awọn eeyan kan niwaju mọṣalaṣi Al Noor.
Bakan naa ni ranpẹ, Buhari ṣe Gomina ipinlẹ Borno lati ọjọ Kẹta Oṣu keji ọdun 1976 si ọjọ ikẹẹdogun oṣu Kẹta ọdun 1976.
Ninu ọrọ to kọ sori ayelujara Twitter rẹ ni owurọ Ọjọru, o ni oun koro oju si awọn iroyin ipaniyan to n waye nipinlẹ Eko, ati awọn ibomiran ni Naijiria.
Alakoso igbo ti wọn ko àwọn eranko ìgbẹ́ sí yìí, Habu Mamman, lo fìdí ọ̀rọ̀ náà múlẹ̀ nínú àtẹ̀jáde tó fi léde fún àwọn akọ̀ròyìn ní Bauch lónìí.
Inu mi ko dun si bi ero ṣe n pọ lawọn ibudo iforukọsilẹ fun NIN, o dabi ọna ti arun le gba maa ran bi ina inu ọyẹ, eleyi ti a ko fẹ ko ṣẹlẹ, Dokita Mamora lo woye bẹẹ.
Àyọrísí rẹ̀ ni ògo tí ó pọ̀ pupọ, tí yóo wà títí, tí ó sì pọ̀ ju ìyà tí à ń jẹ lọ.
Ladodo ni lọjọ Kẹjọ osu Keji ọdun 2019 ti obinrin naa bimọ nile iwosan kan lopopona Nekede nilu Owerri, ni wọn gbe ọmọ wakati mẹfa ọhun lọ si ilu Portharcourt nipinlẹ Rivers, ti wọn si ta fun Duru Christian, ẹni to ti mura silẹ lati gba ọmọ naa, to si gbe fun ọkunrin kan ti wọn pe ni George Iyowuna.
Abẹnugan ile naa, Funminiyi Afuye lo sọrọ yi nigba to n fọrọjomitoro ọrọ pelu ile iṣẹ BBC.
Eliṣa sọ fún obinrin ará Ṣunemu, ẹni tí Eliṣa jí ọmọ rẹ̀ tí ó kú pé, “OLUWA yóo rán ìyàn sí ilẹ̀ yìí fún ọdún meje, nítorí náà, kí ìwọ ati ẹbí rẹ lọ máa gbé ní ilẹ̀ mìíràn.
“Nígbà tí ẹ̀mí èṣù jáde kúrò ninu ẹnìkan, ó bẹ̀rẹ̀ sí wá ilẹ̀ gbígbẹ láti sinmi.
Mose da eérú náà sókè sí ojú ọ̀run, eérú náà bá di oówo tí ń di egbò lára eniyan ati ẹranko.
Gẹgẹ bii aṣiwaju, a tun gbe awọn agbegbe ti o yẹ ki awọn mejeeji o ti bu omi suuru mu.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ex Boko Haram: Àwa ọmọ ẹgbẹ́ Boko Haram kan kìí kírun, à ń mu ìmukúmu, a sì ń ṣe ṣìná 1 Ògún 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ọ̀pọ̀ ọ̀dọ́ ló ni wọ́n darapọ̀ mọ́ ẹgbẹ́ Boko Haram, nítorí ọ̀pọ̀lọpọ̀ ìdí Ní àsìkò tí ìjà Boko Haram pé ọdún mẹ́wàá ní àríwá Nàìjíríà, ọmọ ẹgbẹ́ náà tẹ́lẹ̀rí ti ṣàlàyé fún BBC pé, àwọn kan nínú àwọn ọmọ ẹgbẹ́ náà kìí kí ìrun rara.
eniyan márùndínláàdọ́ta, ki won si tọrọ
Bóò ṣe lè yẹra fún ikú nígbà òjò- Onímọ̀ Ehi Iden Ará ìlú Abéòkúta ke gbajare lórí Omiyale ‘Omi yale sọ awọn eniyan di alai ni ile’Omiyalé ní Ghana, èèyàn 28 dolóògbé!
ile-ise VON ti o wa ni agbegbe Ikoyi-Obalende, nipinle eko.
 igbakeji re ni ergash shoismatov .
"O ni ""asiko ti de fun wa lati ṣe tayọ àlá wa nikan."
Kí ló dà wá pọ̀ pẹlu ọmọ Jese?
 Àwọn odù idá wọ ̀ nyí dà bí ojúpọ ̀ nà tí ọmọ ènìyàn lè gbà láti rí àyànmọ ́ wọn lò ní kíkún , nípa bì àwọn babaláwo tí wọ ́ n jẹ ́ olùkọ ́ ifá bá ṣe ṣàlàyé rẹ ̀ níbàámu pẹ ̀ lú odù tì ó bá yọ fún ẹni abdífá fún gẹ ́ gẹ ́ bí Ọ ̀ rúnmìlà tí ó jẹ ́ babaláwo àkọọ ́ kọ ́ ṣe làá kalẹ ̀ .
"(Winter Olympics)"" Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?"
Ẹ dìde, ẹ máa lọ, nítorí pé ìhín yìí kì í ṣe ibi ìsinmi; nítorí pé ẹ ti hùwà ìríra tí ń mú ìparun ńlá báni.
Oríṣun àwòrán, @tvnigerian Adeyẹmọ lo ti sisẹ saaju gẹgẹ bii oludamọran fun ijọba aarẹ Obama lori eto ọrọ aje lọdun 2015, ti ojuse rẹ nigba naa si jẹ sise akoso awọn ilana to jẹ mọ eto ẹnawo, okoowo ati idokowo, ohun amusagbara ati ọrọ to jẹ mọ ayika.
Wòlíì Genesis kan yẹra díẹ̀ ni, ó máa tó wọlé padà bí olè lóru- Adelé pásítọ̀ Oladele Òtítọ́ làwọn sọ́jà gbé ìbọn tó lọ́ta gidi nínú lọ sí Lekki Toll Gate lásìkò ìwọ́de EndSARS- Ọ̀gágun Taiwo Ìjọba àpapọ̀ pàṣẹ pé kí gbogbo ọkọ̀ agbépo kúrò ní márosẹ̀ Lagos-Ibadan Seyi Makinde fún olórin Fuji Taye Currency lẹ́bùn ọkọ̀ bọ̀kìnnì Toyota Prado 2020 Wo orúkọ ẹ̀ṣọ́ Gbajabiamila tó yìnbọn pa fẹ́ńdọ̀ nílùú Abuja, pẹ̀lú ibi tó ti ń ṣiṣẹ́ Olori ileegbimọ aṣoju-ṣofin lorilẹede Naijiria, Họnọrebu Fẹmi Gbajabiamila ti ṣiṣọ loju ẹṣọ alaabo rẹ to yinbọn pa fẹndọ kan ni ilu Abuja l'Ọjọbọ Họnọrebu Gbajabiamila darukọ ẹṣọ alaabo naa gẹgẹ bii Abdulahi Hassan.
”“Mo lo anfaani yi lati tun ki adari agba egbe APC, Asiwaju Bola Ahmed Tinubu, ati awon toro kan gbongbon ninu egbe oselu yii nipinle eko ati lapapo, ti o fi mo awon eniyan ipinle Eko.
 lowolowo ohun ni alakoso oro okere orile-ede amerika 67th labe ijoba aare barack obama .
Bí ó bá fẹ́ pààrọ̀ rẹ̀, ati èyí tí ó fi pààrọ̀ ati èyí tí ó pààrọ̀, mejeeji jẹ́ mímọ́ fún OLUWA, ẹnikẹ́ni kò sì gbọdọ̀ rà á pada.
Igba akọkọ ree ti Arsenal yoo fidi rẹmi ninu ifẹsẹwọnsẹ mẹrin lera lera nile wọn lati bii ọdun mọkanlelọgọta.
Áṣẹyin kìlọ̀ fáwọn adarí olóṣèlú Nàìjíríà láti ṣe ohun tó yẹ nítorí ará ọ̀run ń wò wọ́n!
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Coronavirus: Mọ ọ̀nà láti tóju fóònu rẹ kí o ma ba ko àrùn Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Coronavirus: Mọ ọ̀nà láti tóju fóònu rẹ kí o ma ba ko àrùn 18 Ẹrẹ̀nà 2020 O ṣe pàtàkì ki a ma mó ṣe imótótó fóònu ìléwọ bi aṣe n ṣe itọjú ọwọ ni ìgbà gbogbo.
Ninu esi awọn akopa, Arabinrin Lola Animasahun, ti o n pese iru iṣẹ iranlọwọ itọju ile bayii, gboriyin fun abadofin naa, o wa fi kun ọrọ rẹ pe o yẹ ki wọn maa ṣe idanilẹkọọ awọn oṣiṣẹ itoju ile lati le mọ iṣẹ ti wọn fẹ ṣe ni pato ni awọn ile ti wọn ba gba wọn si.
 Ìṣẹ ́ jú ọwọ ́ yí má a ń yípo nípasẹ ̀ 360 ° ní àwọn ìṣẹ ́ jú 60 tàbí 6 ° fún ìṣẹ ́ jú kan .
Ní ọjọ́ ìrúbọ OLUWA, “N óo fi ìyà jẹ àwọn alákòóso ati àwọn ọmọ ọba, ati àwọn tí ń fi aṣọ orílẹ̀-èdè mìíràn ṣe ara wọn lọ́ṣọ̀ọ́.
Ṣugbọn nígbà tó yá, wọ́n yí ọ̀rọ̀ pada, wọ́n tún mú àwọn ẹrú tí wọ́n ti dá sílẹ̀, lọkunrin ati lobinrin, wọ́n tún fi ipá sọ wọ́n di ẹrú.
Hesiro, ará Kamẹli, Paarai, ará Abiti; 
O Fagunwa, ẹni ti oun naa se gudugudu meje ati ya ya ya mẹfa ninu isẹ iwe itan arokọ.
"Ẹ wo bí Isa Funtua, amúgbálẹ́gbẹ̀ẹ́ Aàrẹ Buhari ṣe lo ìgbé ayé rẹ Wo àwọn nkan tó yẹ́ kí o mọ̀ nípa 'Awawa Boys', ọ̀kan lára ẹgbẹ́ òkùnkùn tó n dá Eko rú Lẹ́yìn gbogbo sinimá oríta ní Ondo, Akẹti jáwé olúborí ní APC Èèyàn 562 tuntun ló tún ti lùgbàdì COVID-19 ní Nàìjíríà ní àná Idan orita ṣẹlẹ niwaju igbimọ naa nigba ti Akpabio sọ pe awọn ọmọ ile aṣojo-ṣofin ""lo n jẹ mudun-mudun iṣẹ agbaṣẹ to n jade lati NDDC."
Ọ̀kan ninu àwọn ọmọ òmìrán ni òun náà.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: 'NLC, ẹ máa retí ìdádúró lẹ́nu iṣẹ́ 'tórí N30,000' Aṣòfin 18 sá àsálà kúrò nípínlẹ̀ Ondo Surety- Ṣọ́ra kí o tó ṣe onídùróò ẹnikẹ́ni Iroyin naa tun ṣalaye pe ibi ipolongo idibo kan ni Tunji Ajulo Opin ati ikọ rẹ ti n bọ ki awọn agbebọn naa to kọlu wọn.
Oríṣun àwòrán, Screenshot/instagram/jago000007 Ṣugbọn, o n fi owe sọ awọn ọrọ kan pe: O ṣoro lati gbagbe ẹdun ọkan yii, ṣugbọn ohun to nira ju ni iranti adun.
Bí o bá ti kìlọ̀ fún adíjàsílẹ̀ lẹ́ẹ̀kan tabi lẹẹmeji, tí kò gbọ́, yẹra fún un.
"Ọrọ naa wa lọwọ awọn alagbata sinima, awọn Olootu ere atawọn ololufẹ wa, nitori ọmọ pupa ni wọn n wá ninu fiimu ki wọn to wo o, a si maa n fi wọn ta ọja ni amọ awọn ọmọ dudu naa si wa ninu fiimu wa.
Nibi ipolongo naa, alaga ẹgbẹ oṣelu APC Adams Oshiomhole fi ẹsun kan oludije fun ipo aarẹ labẹ PDP, Atiku Abubakar pe ti o ba wọle, oun ati PDP yoo ta ile iṣẹ epo rọbi Naijria, NNPC.
Bakan naa, ijoba orile-ede India ti kede owo ti o to ẹ̀gbẹ̀rún lona irinwó rupees ($6,000; £4,400) fun ebi awon oloogbe kookan ti o ba isele ohun lo gege bi owo gba mabinu.
“Nígbà tí àrùn ẹ̀tẹ̀ bá wà lára aṣọ kan, kì báà jẹ́ pé òwú tabi irun tí wọ́n fi hun aṣọ náà, 
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ọbásanjọ́: Àwọn ọ̀dọ́ kò gbọdọ̀ dìbò fún Bùhárí Ìwé 'Things Fall Apart' pé ọgọ́ta ọdún Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí 2 sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 2:23 Fídíò, Water Generator: Ó leè ṣiṣẹ fún wákàtí mẹfà, kó tó sinmi, Duration 2,2310 Òkùdu 2020 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Èmi ni afunfèrè àkọ́kọ́ lágbo eré KWAM 1 ní 1983' O sàlàyé pe, gómìnà ń gbé ìgbéṣẹ̀ láti yan àwọn ọmọ ìgbìmọ̀ alámojuto fún àwọn ìjọba ibilẹ.
ÀJọ UN bu ẹnu àtẹ́ lu bí Nigeria se kó àwọn ọmọ Cameroon pada silu wọn
Ó sì ṣe ọgọrun-un àwo kòtò wúrà.
 o gbajumo fun iwadi re ninu igbegbin onihaanu and cloning .
Inu mi ko dun pe emi ni obirin akọkọ to kọkọ bi ibeji to lẹpọ ni ilu wa ati ni ipinlẹ wa""."
Kí ni kí n sọ fun yín?
A ti fi ìdí ìjọba rẹ múlẹ̀ láti ìgbà laelae;láti ayérayé ni o ti wà.
Amọ, awọn ẹlomiran nitori ibinu ma n ba elomiran jijakadi nipa ọrọ ẹnu, tabi ifiyajeniyan tabi isọrọ odi si eniyan lori ẹrọ ayelujara bii Twitter ati bẹẹ bẹẹ lọ.
Ami ayo mẹta si meji ni Palace fi ṣagba fun awọn Gunners nile wọ.
ayeye igbami-eye ti o ti farahan 
Láti Rimoni Peresi wọ́n lọ sí Libina.
NCDC lo kede bẹẹ loju opo Twitter rẹ ni Ọjọ́bọ̀.
Nigerian Youth Investment Fund: Ijọba àpapọ̀ yóò kó bílíọnù 75 owó ẹyá fún àwọn ilé ìfowópamọ́ kéékèké fún ìṣòwò àwọn ọ̀dọ́
Minista fun eto iroyin, ifitonileti ati asa, Ogbeni Lai Mohammed lo se ikilo yii nibi apero apapo awon akoroyin ni Naijiria to je eleekeji re to n lo lowo nipinle Kano pelu akori: Oro ikorira: titete pa ina ote re ko too di nla ti apa ko ni ka mo.
Eti-Osa Lekki Coastal Road Àwọn nkan tó yẹ kí o mọ̀ nípa ìgbẹ́jọ Trump tí yóò bẹ̀rẹ̀ l'ọ́dọ̀ àwọn Sẹ́nétọ̀ Makinde, dá àwọn alága ìjọba ìbilẹ̀ padà sípò- Abubakar Malami Mí ò le nífẹ̀ẹ́ obìnrin Nàìjíríà kankan mọ lẹ́yìn ti mo ti tọ́ obìnrin òyìnbó wò- Issa Ìríwísí àwọn aráàlú bí EFCC ṣe kó afurasí ọmọ yahoo 49 ní Ibadan Wo awọn afara ti okada ati marwa ko nile rin nibẹ mọ1.
Ẹyin ti Saudi, ẹyin ti Jedah ẹ gbagba nnkan to n jẹ pe a wa kọrin o.
O si tun n kọlu awọn Kristẹni.
Oríṣun àwòrán, Nigeria Bar Association Ṣe wọn ni ki sobiya to di egbo, oluganbẹ laa kọ ke si.
Oríṣun àwòrán, BB Naija Neo, wa sọ fun Nengi, Kiddwaya, Trikytee ati Vee bi inu oun se dun to lati bawọn kopa ninu eto BB Naija tọdun yii.
Kọ orukọ rẹ, nọmba rẹ, adirẹsi ilé rẹ, koko arokọ ti o n kọ, àti gbolohun diẹ nipa ara rẹ ni eyi ti BBC yoo lo fun idije yii nikan ṣoṣo.
Jesu ti mọ ohun tí wọ́n ń bá ara wọn sọ, ó bá dá wọn lóhùn pé, “Kí ló dé tí ẹ fi ń ro irú èrò báyìí ní ọkàn yín?
Bakan naa naa ni Everton naa Brighton ni ami ayo mẹrin si meji , nibi ti Rodriguez ti gba ami ayo meji wọ ni awọn, ti CalverLewin ati Mina naa gba bọọlu wọ inu awọn.
Ìfẹ́kúfẹ̀ẹ́ ọkàn olukuluku ni ó ń tàn án, tí ó ń fa ìdánwò.
Máfọ́ya, mo wà pẹ̀lú ẹ, Ajimọbi kàn sí Makinde lóri Coronavirus to ni Coronavirus: Àwọn ohun tí a kò tíì mọ̀ nípa àrùn Covid-19 Ibi gbogbo là ń dáná alẹ́, ìwà jẹgúdújẹrá pa iléeṣẹ́ Spencom run ní Uganda Iṣẹ́ bẹ̀rẹ̀!
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Coronavirus: Àwíjàre ọlọ́pàá ni pé dókítà múra bíi onínàbì láago mẹ́wàá alẹ́ 18 Ẹrẹ̀nà 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 7 Owewe 2020 Oríṣun àwòrán, Others Oniruuru ẹmi ni arun Coronavirus ti gba, boya lati ipasẹ kiko arun naa ni abi ni ọna miran.
Malaga:Brown Ideye di aayo agbabọọlu tuntun
Ṣùgbọ́n nígbà tí a wo ilẹ̀ ṣe ni a rí òkú ejò ní ilẹ̀ lọ bẹẹrẹ ṣùgbọ́n bí wọ́n ti kú lọ tóó nì, àwọn tí ó kú kò já mọ́ nǹkan kan lára àwọn tí kò kú.
Idí tí mo fi faramọ́ ìpinnu NEC- Oshiomole A wà nínú igbó tí a ti ń wá àwọn arinrìnàjò mẹ́jọ láti Abuja sí Eko tí wọ́n jígbé lọ- Ọlọ́pàá Ondo Yàtọ̀ sí coronavirus, wo ìgbà mẹ́wàá míì táwọn mùsùlùmí kò lè ṣiṣẹ́ Hajj Ọwọ́ NDLEA tẹ àádọ́jọ èèyàn tó gbé oògùn olóró l‘Ondo Wọn ti ọwọ bọ iwe lati ṣe idagbere ikẹyin fun goimina Ọyọ tẹlẹri bẹẹ sini wọn ba awọn ẹbi rẹ kẹdun.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, International Day Against Drug Abuse and Trafficking: ìdí ti mo fi ń mu oògùn olóró Amosun wa rọ awọn araalu lati kẹyin si iroyin eke to n lọ kiri naa pe ohun ko ohun ijagun pamọ nitori pe ko si awo kankan ninu awo ẹwa nipa awọn ohun ija oloro naa.
Ó súre tí ó tọ́ sí olukuluku fún un.
Àwọn ìdílé akọrin bá kó ara wọn jọ láti gbogbo agbègbè Jerusalẹmu ati láti àwọn ìletò tí ó wà ní àyíká Netofati, 
Pasuma kìí ṣe ọkọ mi o!
” Ó sì yára gbé ìkòkò rẹ̀ lé ọwọ́ rẹ̀ láti fún un ní omi mu.
Inú mí dùn bí ìpínlẹ̀ Ọyọ se setán láti bẹ̀rẹ̀ ilé-ìwé tí àwọn akẹkọ̀ọ́ ń gbé- Òbí Ọkùnrin kan di èrò ọ̀run nítorí pé o fi ẹ̀sùn kan alájọgbélé rẹ̀ pé o n yan ìyàwó ẹnìkan lálè Àṣà Oge Ṣíṣe ní Akọ́mọlédè BBC Yorùbá ń gbé yẹ̀wò lónìí, Ó yá, iṣẹ́ ti bẹ̀rẹ̀.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fọ́nrán ohùn, Oyinlọla kọ̀wé fipò rẹ̀ sílẹ̀ ni NIMC Odẹyẹmi sọ̀rọ̀ lori àìsí agbára òfin lòdì sí ki àwọn ènìyàn maa ṣe aṣẹ́wó òṣèlú lati égbẹ́ òṣèlú kan si ìkejì.
Lọ́jọ́ nàá, ọmọ wọn obìnrin, tó jẹ́ ọmọ ọdún mẹ́jọ, Zulaiha Bashir, lọ pọn omi ní inú kànga kan tó wà nítòsí ilé wọn, láti fi wẹ̀, ṣùgbọ́n tí kò padà sílé nítorí pé ó jábọ́ sínú kànga.
"Oludamọran Pataki fun aarẹ lori eto iroyin, Femi Adesina to fi ikede ibanikẹdun naa sita lorukọ aarẹ sọ pe: ""Ajimọbi kú lasiko ti ẹgbẹ APC, ati orilẹ-ede rẹ nilo imọran tẹ lati gba iwosan ati idagbasoke."
Lọwọ-lọwọ, o ti to miliọnu meji eniyan to ti ni aarun naa.
O ni: Kelvin fi ara re han ni ọmọ ogun ilẹ Mexico to jẹ akinkanju lẹnu ija ni bẹẹ mo ti pinnu lati ibẹrẹ pe ohun to ba gba ni mo maa fun un.
Ile-igbimo asofin kekere lorile-ede Liberia ti lo ipo ati ase won lati fi ti minisita satimole ojo meji.
Buhari kàn ń kọwọ́ bọ̀wé nílẹ̀ òkèèrè kiri ni, a ò rí ipa ní Nàijíríà- Onímọ̀ ọrọ̀-ajé Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Nitori naa ni orilẹede China ati Amerika ṣe gbe owo ori to lagbara le ori ọja to n wọ orilẹede mejeji lati ọdọ ara wọn.
Ajẹ́pé t'òjò t'ọ̀gbẹlẹ̀ ni àwọn òdòdó ń tanná káàkiiri ọgbà náà.
OLUWA bá mi sọ̀rọ̀; ó ní, 
dandan ki awọn wadii lọfintoto lẹyin ibo idi ti Inec ṣe sun ibo naa siwaju.
Ṣebí Filistini kan ni èmi, ẹ̀yin náà sì jẹ́ ẹrú Saulu?
Zeyar Lwin ń tọ́ka sí ìwé òfin ọdún-un 2008 tí ọ̀pọ̀lọpọ̀ àwọn atúnǹkanká gbàgbọ́ wípé a ṣe é to láti fi agbára fún ìṣèjọba ikọ̀ ajagun pàápàá lẹ́yìn tí alágbáda gba ìjọba.
Bala Mohammed to bori ti fi igba kan jẹ Minisita fun olu ilu orilẹede Naijiria, Abuja.
Fọwọ́ kan obìnrin lọ́nà àìtọ́, kí o rẹ́wọ̀n ọdún mẹ́rìnlá he- Àwọn aṣòfin yarí Wọ̀nyí ni àwọn ẹjọ́ tó làmìlaaka ti EFCC ṣe lásìkò Ibrahim Magu Kò ní sí ayẹyẹ ọdún Ojúde Oba lọ́dún yìí- Awujale ilẹ̀ Ijebu O tẹsiwaju pe ijọba atawọn eeyan ipinlẹ Kwara ti padanu ẹni iyi to sin ijọba ipinlẹ ọhun pẹlu gbogbo ọkan rẹ ki ọlọjọ to de.
OLUWA a máa jẹ́ kí ohun gbogbo yọrí sí bí ó bá ti fẹ́,ó dá eniyan burúkú fún ọjọ́ ìyọnu.
ni orile ede Congo ni ,aarun yii ti pa awon eniyan to le ni egberun mokanla.
 bitcoin jẹ ́ dídá sílẹ ̀ látọwọ ́ ẹnìkan tàbí ọ ̀ pọ ̀ àwọn ẹníkan tí orúkọ wọn únjẹ ́ satoshi nakamoto tó sì jẹ ́ fífi s ' óde gẹ ́ gẹ ́ bíi ìlànà ìṣiṣé kọ ̀ mpútà atúdìísílẹ ̀ ní ọdún 2009 .
Ọpọlọpọ ọmọ ni awọn ọmọ olooku fi sori ayelujara ti wọn si fi n daro ẹni wọn to lọ.
Adari ileeṣẹ to n ri si ọrọ iṣẹ agbegbe, Olukayode Popoola lo fi ọrọ naa lede lọjọ Aje.
 gbólóhùn yìí máa ń ní olùwà kan sùgbón àwon òrò-ìse yìí mó ara won .
Lákọ̀kọ́, ó run mí nínú kí afẹ́fẹ́ ìgbádùn tó fẹ́, ara mi wá ṣẹ̀'sẹ̀ balẹ̀, ọkàn mí wá tutù wẹ̀ẹ̀.
Bakan naa ni alaga ẹgbẹ awọn olukọ fasiti ti ipinlẹ Eko, Dokita Dele Ashiru ni awọn tako bi wọn ṣe yọ Ọjọgbọn Ogundipe nipo, ti awọn si fi igboya tẹle gẹgẹ bi adari wọn.
Angola fi ìdí òfin tí ó ń de ìfìyàjẹni tí wọ́n mọ̀ sí  múlẹ̀ ní ọdún 2011 tí ó ń sọ onírúurú ìfìyàjẹni abẹ́lé di ìwà ọ̀daràn ní gbangba.
”Yara okuAare tun lo si yara keji lati lo bowo fun awon akoni naa, nibi “Yara Iku”Gege bi won se ko o sinu iwe iku naa:’’Awon elewon  okunrin ati obinrin ti won ko sinu yaya kan lati gbogbo ibi ti won  ti fi se ipago….
Kò tọ́ sí Ọlọ́pàá láti ti ọmọ mi mọ́lé tórí ore tó ṣe lásìkò ìwọ́de EndSARS - Iya Eremosele Akomolede Yoruba: Kí ni ìdí tí aṣọ fi máa ń pọ̀ lára Egúngún ju Orò lọ́?
Ọbasanjọ, to sọ eyi lasiko ifọrọwanilẹnuwo pẹlu ile isẹ iroyin Premium Times ni, eto ọrọ aje orilẹede Naijiria ti dẹnu kọlẹ labẹ isejọba to wa lode.
"Àjọ Ètò owó káríayé ( aeok ; "" international monetary fund "" , imf ) je agbajo kariaye to n mojuto sistemu inawo lagbaye nipa titele awon ipinu makroekonomi awon orile-ede omo egbe re , agaga awon ipinu to nipa lori osuwon pasiparo owo ati ibamu awon isanwo ."
Covid-19 60seconds: Ṣé ìjìnà síra-ẹni ṣe paàtàkì lẹ́yìn lílo ìbòmú?
Wo àwòrán ńkan tó ń ṣẹlẹ̀ ní ìpádé ìran Yorùbá ní Ibadan báyìí Ọmọ onílẹ̀ wọ gàù, ó kó sí gbaga ọlọ́pàá Ẹ̀ṣọ́ tó pa Ọ̀gágun Ethiopia tí a sọ pé ó kú, kò kú mọ́!
Koda ẹmi ti bọ latara lilo awọn nnkan wọnyii.
Gege bi oludari agba iko omo ogun naa to n mojuto oro ifitonileti ati igbodegba, ogagun Ibikunle Daramola, O ni, ise akanse naa bere lojo aje(Monday), ojo keta osu kesan odun ti a wayii.
Awọn eniyan pataki bi igbakeji aarẹ, Yemi Osinbajo ati Alhaji Aliko Dangote wa lara awọn to ti gbiyanju lati pari ija laarin gomina ati Emir.
Lára ilẹ̀ ẹ̀yà Nafutali, wọ́n fún wọn ní Kedeṣi ní ilẹ̀ Galili, Hamoni, ati Kiriataimu, pẹlu àwọn pápá oko àyíká wọn.
Leah Sharibu: Mo gbàgbọ́ pé ọmọ mi ṣì wà láàyè
''Mi o mọmọ sa fun ile ẹjọ.
Ìpínlẹ̀ Oyo àti Eko kò nífẹ̀ẹ́ láti gba 'Ruga Settlement' láyè Biodun Fatoyinbo fi ipò sílẹ̀ lorí ẹ̀sùn ìfipábánilòpọ̀ 'Èèyàn mi mẹ́ta ló wà nínú ọkọ̀ ojú omi tó dà nù l'Eko!
Eniyan to din diẹ ni ẹgbẹrun mejidinlaadọrin (67,301) lo wo ifẹsẹwọnṣe naa ni papa iṣere Luzhniki to wa ni Moscow, orilẹede Russia.
Àìsàn Muyiwa kò lè la ẹ̀mí lọ - Agbẹnusọ Òṣèré, Muyiwa Ademola Joe Biden náà ti gba abẹ́rẹ́ àjẹsara Covid-19 New Variant: Kí ni ìbẹ̀rù tó gbọkàn àwọn èèyàn lágbàáyé nítorí ẹ̀yà ààrùn Covid-19 tuntun?
Àwọn eniyan sì tẹ ọ̀gágun náà pa, gẹ́gẹ́ bí Eliṣa ti sọtẹ́lẹ̀ nígbà tí ọba lọ sọ́dọ̀ rẹ̀.
Ní ọjọ́ kinni àjọ̀dún náà ẹ óo máa ní àpèjọ mímọ́, ẹ kò gbọdọ̀ ṣe iṣẹ́ líle kankan.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ọmọ igboro to di ayaworan pataki lawujọ 22 Sẹ́rẹ́ 2018 Oríṣun àwòrán, MARIO MACILAU/WATER AID Àkọlé àwòrán, Mario Macilau Ọmọ ọdun metalelogun kan, Mario Macilau lọdun 2007 fi ẹrọ ibanisọrọ alagbeka iya rẹ se pasiparọpẹlu ẹro iyaworan Nikon.
Ṣugbọn bí ìkùukùu yìí kò bá tíì gbéra, àwọn náà kò ní tíì tẹ̀síwájú títí tí yóo fi gbéra.
Nítorí náà, ni mo ṣe sọ pé,“Ẹ ṣíjú kúrò lára miẹ jẹ́ kí n sọkún, kí n dami lójú pòròpòrò,ẹ má ṣòpò pé ẹ óo rẹ̀ mí lẹ́kún,nítorí ìparun àwọn ará Jerusalẹmu, àwọn eniyan mi.
OLUWA tún bi mí pé: “Ọmọ eniyan, ṣé o rí ohun tí àwọn àgbààgbà ilé Israẹli ń ṣe ninu òkùnkùn?
"Premier League yóò bẹ̀rẹ̀ padà lóṣù kẹfà Ẹ̀rù n ba àwọn agbábọ́ọ̀lù Premier League láti padà sórí pápá nítorí coronavirus Arsenal rántí ""Invincibles,"" ó pé ọdún mẹ́rìndínlógún tí Arsenal gba ife Premier League Awọn ẹsẹ bata buutu ti ko bara dọgba ni Jordan n wọ, ẹsẹ osi rẹ n wọ iwọn bata mẹtala nigba ti ẹsẹ ọtun rẹ n wọ iwọn ẹsẹ bata mẹtala ati aabọ."
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Premier League: Southampton dáná sun Stamford Bridge pẹ̀lú àmì ayò 2-0 26 Ọ̀pẹ̀̀ 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 27 Ọ̀pẹ̀̀ 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Southampton dáná sun Stamford Bridge pẹ̀lú àmì ayò 2-0 Ikọ Southampton fẹyin Chelsea gbolẹ nile wọn ninu idije Premier League to waye lonii.
O tẹ siwaju pe, “a gbọdọ maa tẹ siwaju lati maa ṣatilẹyin ati lati maa gbadura fun ijọba ni gbogbo ipele.
Bakan naa, ni won tun fun igbakeji aare ni iwe kan , ni eyi ti won fi
Eni to n ṣee yii jẹ akọṣẹmọṣẹ nipa ara lílọ́pọ̀ ni.
Awọn to n fi ẹrọ wọn lede lara awọn ololufẹ ile iṣẹ BBC lori ẹrọ ibanisọrọ Facebook sọ wi pe ki Aarẹ Muhammadu Buhari fi opin si ofin konile-o-gbele lorilẹẹde naa.
Àjọ tó ń mójútó àyíká l'Eko mú 123 ọlọ́kadà tó ń bọ̀ láti Jigawa Ọkọ̀ òfúrufú ọlọ́pàá yóò bẹ̀rẹ̀ sí ní káàkiri Naijiria - Ọgá Ọlọ́pàá ‘Àwọn jàǹdùkú pa fadá ní Taraba’ Bàbà ọmọ ọdún 75 kó HIV ran ọmọ ọdún 14 lẹ́yìn tó fi ipá báa lò Dokita Faduyile tun fikun ọrọ rẹ pe kikọ iṣegun ibilẹ ni ileewe giga fasiti yoo jẹ ki gbedeke wa lori odiwọn lilo ogun ibilẹ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Nigeria Army: Ọmọ ológun gún awakọ̀ lọ́bẹ pa 29 Agẹmo 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Kini awakọ le ṣe fún ọmọ ológun to fi rí ikú he?
Wọ́n bá bẹ̀rẹ̀ sí kígbe sókè, wọ́n ń fi idà ati ọ̀kọ̀ ya ara wọn lára, gẹ́gẹ́ bí ìṣe wọn, títí tí ẹ̀jẹ̀ fi bò wọ́n.
Àwọn ohun tí ẹ ti kọ́ lọ́dọ̀ mi, tí ẹ bá lọ́wọ́ mi, tí ẹ ti gbọ́ lẹ́nu mi, tí ẹ ti rí ninu ìwà mi, àwọn ni kí ẹ máa ṣe.
O si jẹ ẹni to tako iṣelu awọn ilẹ Gẹẹsi.
Se bi ohun ti o kowaju sini, eyin lo ko si elomiran, pelu gbogbo awuye-wuye iwe ateranse ti are ana oloye Olusegun Obasanjo fi ranse sile ise aare, oro ohun tun gba ibo mi yo bayii.
Ní tòótọ́ ni ó kópa nínú ìyíde kiri tí ó ń tako ẹjọ́ tí àwọn ológun dá mẹ́kúnnú ní ọjọ́ 26 oṣù Belu ọdún 2013, Alaa kò kó ipa nínú àgbékalẹ̀ẹ rẹ̀.
Ikú mú Olanrewaju tó jẹ́ bàbá ọmọ Bisola lọ Ọ̀ọ̀ni ilé Ifẹ̀, Buhari ṣèpàdé nílú Abuja Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ilu Ubang, jẹ ilu kan nibiti ede ti awọn ọkunrin wọn n sọ yatọ si ti awọn obinrin wọn.
"Ìwé à-kà-kọ ́ gbọ ́ n ti ben okri tí ó pè ní "" the famished road "" ọ ̀ nà tókú fún ebi "" dá lé lórí àbíkú."
Ṣugbọn iṣeju marun lẹyin rẹ, wọn tun fun wọn ni wo-mi-n-gba-si-ọ, to sọ ami ayo naa di meji.
Ẹ̀rù yín ń bà mí pé kí gbogbo làálàá mi lórí yín má wá jẹ́ lásán!
Gbogbo igbesẹ yii ni ireti wa pe yoo fi opin si iyanṣẹlodi oṣu meje ti ẹgbẹ ASUU wa lori rẹ.
O ṣe pataki ki a fun awọn ọmọ ni Abẹrẹ-ajẹsara O ṣeeṣe ki àròpọ̀ rẹ má tó ìdá ọgọrun un (100 %) Iwadii yii beere ero awọn eeyan lori awọn iṣẹ kilaasi to jẹ nioa sayẹnsi.
Awọn onwoye ni idanwo ni idibo aarẹ ile asofin yi yoo jẹ lati mọ boya awọn ọmọ ẹgbẹ APC yoo tẹle aṣẹ ẹgbẹ.
O ni oun ti fọrọ aṣẹ lọ́wọ́ Ọlọ́run ọba kí òun tó máa bọ̀, Ọlọ́run sì ti wí pé òun wà lẹ́yìn mi.
Ẹ tún bèèrè pé, ‘Ọ̀nà wo ni a fi sọ pẹpẹ rẹ di àìmọ́?
Eka Ami Ẹyẹ onimọ ẹrọ ni wọn fi orukọ wọn si.
Sugbọn bawo ni wọn yoo se mọ wi pe ohun ti wọn sọ jẹ otitọ?
- kí ni ayé ọmọ ènìyàn já mọ́?
Nígbà tí ilẹ̀ Ilèṣà dàrú nígbà kan láyé ọjọ́ún, àrìmọ-kùnrin Ọwá àti àrìmọ-bìnrin Ọba Ìjẹ̀bù-Jẹ̀ṣà ni wọ́n fi ṣe ètùtù kí ilẹ̀ Ìjẹ̀ṣà tó rójù ráyè, kí ó tó tùbà tùṣẹ.
Ọ̀kan nínú àwọn ìtàn náà sọ pé: Ọwà Iléṣà kìíní Ajíbógun àti Ọba Ìjẹ̀bú-Jẹ̀ṣà kìíni, Agírgírì jẹ́ tẹ̀gbọ́n tábúrò.
Ọpọ awọn ẹgbẹ ajijangbara fobinrin lo ti n dide ni ẹkun Bangladesh bayii.
Lọjó Iṣẹgun ni awọn agbebọn darandaran ji awọn oṣiṣẹ mẹjọ ile iwe naa gbe, ṣugbọn wọn da mẹrin ninu wọn silẹ L'Ọjọru.
Ilu Eko ni Kyari ku sii lẹyin ti wọn gbe e wa si ipinlẹ naa fun itọju nigba to lugbadi aarun covid-19 l'Abuja.
Ìfẹ́ yín kò gbọdọ̀ ní ẹ̀tàn ninu.
Ninu ọrọ rẹ, gomina ipinlẹ Ekiti, to tun jẹ alaga apapọ fun igbimọ awọn gomina to n bẹ lorilẹede yii, Ọmọwe Kayọde Fayemi ṣe alaye wi pe, gbogbo orilẹede yii lo n koju ipenija eto aabo.
Ìdíje Madrid, Juventus: Àwọn àwòràn mánigbàgbè
A fi n da yin loju ,gege bi  alamojuto ati iko iriju ijoba pe, a o ni kaare nipa gbigbayin niyanju  lori  awon eto ilana lona ti igberu yoo fi de ba akitiyan yin ati mimu  iwuri ba eto  idokoowo .
Ajọ SERAP naa ni awọn ni asẹ lati ri iwe naa nitori asẹ ti awọn gba lati ile ẹjọ giga ni ilu Eko ni Osu Keji, ọdun 2019.
Ó dá wọn lóhùn pé, “Nígbà tí ọjọ́ bá rọ̀, ẹ máa ń sọ pé, ‘Ojú ọjọ́ dára, nítorí ojú ọ̀run pupa.
A kẹ́gàn rẹ̀, a kò sì kà á kún.
Ìgbá tí a dí mọ́ra tán tí a jáde, o ń wu àwọn ti kò fẹ́ lọ tẹ́lẹ̀ ki wọ́n bá ni lọ.
Bí ó ti fẹ́ kúrò lọ́dọ̀ wọn, ó ní, “N óo tún pada wá sí ọ̀dọ̀ yín bí Ọlọrun bá fẹ́.
Kí ẹnikẹ́ni tí ó bá ní ìdánwò má ṣe sọ pé, “Láti ọ̀dọ̀ Ọlọrun ni ìdánwò yìí ti wá.
O fikun pe awọn minisita oun yoo bẹrẹ si ni tọpinpin bi wsn se n gba owo ori wọle lati ri daju pe ohun gbogbo n sisẹ bo se yẹ.
fowosowopo pelu awon loba-loba jakejado ilẹ kaarọ- o-jiire, nitori awon ọba wonyi
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Tone marks: Ṣé ẹ̀yin lè ṣe jú àwọn tó f'àmì sí Awọlumatẹẹ?
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Xenophobia: Àbọ̀ ààrẹ Muhammadu Buhari rèé láti ilẹ̀ South Africa 4 Ọ̀wàrà 2019 Oríṣun àwòrán, Twitter/Bashir Ahmad Aarẹ Muhammadu Buhari ti pada si olu ilu orilẹede Naijiria, Abuja lọjọ Ẹti lẹyin abẹwo ọlọjọ meji si orilẹede South Africa.
lorile ede Naijiria , Boss Mustapha lo soro yii lasiko ti adari iko osise awon  ile –ise naa, Usman Mohammed  saaju iko naa wa si ile-ise rẹ niluu Abuja.
Ipinlẹ Eko ni guusu Iwọ Oorun Naijiria ni Yusuf gbe dagba.
A kó púpọ̀ nínú àwọn oògùn wa fún Ewédayépọ̀ kí ó máa tọ́jú wọn nítorí òun pàápàá jẹ́ babaláwo tí ó fẹ́ràn fáàrí: bí a ba fi ọwọ́ kan àwọn oògùn rẹ̀ a máa halẹ̀ mọ́ wa, ìgbà gbogbo ni òun sì máa ń jẹ ataare lẹ́nu tí ó máa ń dárúkọ Odùduwà, tí ó máa ń sọ̀rọ̀ Àgbọnnìrègún tí ó sì máa ń já ewé inú igbó kiri.
Ileeṣẹ eto idajọ nilẹ Amẹrika si sọ lọjọ Ẹti pe oun yoo taari ọmọ orilẹ-ede Naijiria naa silu Los Angeles, lati lọ jẹjọ nibẹ.
Jesu bá sọ fún Peteru pé, “Ti idà rẹ bọ inú àkọ̀.
OLUWA sọ fún Mose pé, “Ka iye àwọn ọmọ Merari ní ìdílé-ìdílé, gẹ́gẹ́ bí ilé baba wọn.
Ọ̀nà kan ò wọjà fáwọn òṣèré tíátà, bí wọn ṣe ń ta ìpara ìbóra ni wọ́n ń ta aṣọ ẹbí O wa n parọwa sawọn eeyan to ni ipenija kan abi omiran lati mase ro ara wọn pin nitori bi ẹmi ba si wa, ireti n bẹ.
Wọ́n bi í pé, “Olùkọ́ni, nígbà wo ni gbogbo nǹkan wọnyi yóo ṣẹ.
Dangote to jẹ ẹni to lọrọ julọ nilẹ Afirika ti n sọ tipẹ pe oun nifẹ lati ra ẹgbẹ agbabọọlu Arsenal.
Gègé ni wọ́n ṣẹ́ fún ìdílé kọ̀ọ̀kan, láti mọ ẹnu ọ̀nà tí wọn yóo máa ṣọ́, wọn ìbáà jẹ́ eniyan yẹpẹrẹ, wọn ìbáà sì jẹ́ eniyan pataki.
 Àmọ ́ ètò ìkọ ́ ni bí a sè mọ ̀ ti di àtọwọ ́ dọ ́ wọ ́ débi wípé olúkúlùkù lóti gbàá ti wọ ́ n sì ti fi tún orílẹ ̀ èdè wọn tò .
Angẹli OLUWA náà pada wa, ó jí i, ó sì wí fún un pé, “Dìde kí o jẹun, kí ìrìn àjò náà má baà pọ̀jù fún ọ.
Bíbú wọn dàbí ti kinniun,wọn a bú ramúramù bí ọmọ kinniun,wọn a kígbe, wọn a sì ki ohun ọdẹ wọn mọ́lẹ̀,wọn a gbé e lọ, láìsí ẹni tí ó lè gbà á lọ́wọ́ wọn.
O gba wọn nimọran lati ṣiṣẹ laini ibẹru ẹnikẹni ati lai ṣegbe fun ẹnikẹni.
Koda, gbogbo ẹka agbofinro, awọn adajọ ati awọn Agbẹjọro ni ọrẹ Eji Gbadero nitori ojoojumọ ni wọn n gbe lọ sile ẹjọ, to si mọ ẹsẹ ofin ti yoo sọ fun Agbẹjọro rẹ pe ko fi daabo bo oun nile ẹjọ lai lọ sile ẹkọ nipa ofin.
Ìjọba Ọ̀yọ́: Kò sí ilé kan tí wọn kò tíì bí ìbejì ní Igbó Ọrà
Awọn agbẹjọro Sanusi, ti Lateef Fagbemi (SAN) n ṣaaju wọn pe ẹjọ ọhun lodi si bi wọn ko ṣe jẹ ko kuro ni ilu Awe to wa ni, ni ipinlẹ Nasarawa.
Bayii ni atẹjade ileeṣẹ ọlọpaa sọ pe ọkunrin naa fipa ba iyawo rẹ lopọ lati le tan ifẹ inu ara rẹ.
Ijoba apapo ti sepinnu lati na owo iranwo si awon eniyan agbegbe ijoba ibile Jibia Local Government Area (LGA) nipinle Katsina, ti o fara kaasa isele omiyale agbara ya soobu lojo isegun(Tuesday).
Ileeṣẹ ọkọ-ofurufu Dana d'awọn ero lẹbi ilẹkun to yọ
Gbajugbaja adari ere ni, ati wipe Adeyemi Josiah Afolayan (Ade Love) ni baba rẹ, to si jẹ tẹgbọn taburo loun ati Moji Afolayan, Gabriel Afolayan ati Aremu Afolayan.
 gbe awo re ‘Super star’ jade.
Pọtifera ni babalóòṣà oriṣa Oni, ní Ijipti.
Ìbọn àti afẹ́fẹ́ aláta ní DSS fi tú wa ká lásìkò ìwọ́de fún ìdásílẹ̀ Sowore Òfin ọ̀dájú ni àṣọ́bodè ṣe pé epo kò gbọdọ̀ dé ẹnu bodè Nàíjíríà - Ilé aṣojú-ṣòfin Ẹ wo àwọn ààrẹ tí ikọ̀ ọmọ ogun ti gba ìjọba lọ̀wọ̀ wọn O ni ''alawada lawọn to gbe iru igbesẹ yii'' nitori pe wọn ko laṣẹ lati paṣẹ lọ fidimọle fun alaga ẹgbẹ lapapọ.
Ọkan lara awọn to ja ninu ogun Agbekoya, Alhaji Lalekan Lasisi Akekaka, ninu ifọrọwerọ rẹ pẹlu awọn akọroyin salaye pe, bi iroyin ṣe kan Tafa Adeoye ni Akanran lo sare wa si Olorunda lati Akanran, lati mọ ohun to n sẹlẹ.
Tinubu,oun ko lee depo ti oun wa bayii.
Helebu, ọmọ Baana, tí òun náà jẹ́ ará Netofa, ati Itai, ọmọ Ribai, ará Gibea, láti inú ẹ̀yà Bẹnjamini; 
Alaga igbimọ ijọba apappọ lori igbogun ti iwa ibajẹ, Ọjọgbọn Itse Sagay ti bu ẹnu ẹ̀tẹ́ lu agbẹjọro ijọba apapọ, Abubakar Malami, lẹyin to sọ pe ikọ Amọtẹkun ko ba ofin mu.
Mo ti rà wọ́n pada,nítorí náà wọn yóo tún pọ̀ bíi ti àtẹ̀yìnwá.
Nibi yi ni atẹgun taa n mi sinu,oxygen, ti ma n lọ si inu ẹjẹ ti eleyi ti a si n mi sita,Carbon monoxide si ma n gba jade.
Human Rights Watch sọ wípé lábẹ́ ìṣàkóso ìjọba Ààrẹ John Magufuli Tanzania ti rí “ìrésílẹ̀ ìbọ̀wọ̀ fún òmìnira ọ̀rọ̀ sísọ, ìkẹ́gbẹ́ àti àpéjọ dé ojú àmì”
ofurufu naa ti gba lati din owo oko ofurufu ku lara won ni, Aero contractors ati Arik Air .
Iná run àwọn ọdọmọkunrin wọn;àwọn ọdọmọbinrin wọn kò sì rójú kọrin igbeyawo.
“Nígbà tí ìyàn bá mú ní ilẹ̀ yìí, tabi tí àjàkálẹ̀ àrùn wà, tabi ìrẹ̀dànù èso, tabi tí ọ̀wọ́ eṣú, tabi tí àwọn kòkòrò bá jẹ ohun ọ̀gbìn oko run, tabi tí àwọn ọ̀tá bá dó ti èyíkéyìí ninu ìlú àwọn eniyan rẹ, tabi tí àìsàn, tabi àrùnkárùn kan bá wà láàrin wọn, 
Koda akọsilẹ ibanisọrọ lori oju opo Whatsapp ati akasilẹ ohun ajọsọ ọrọ awọn mejeeji lori ẹrọ ibanisọrọ wa lara awọn ẹri maajẹmi niṣo ti wọn ni akẹkọọ naa fi sita.
Biṣọọbu agba, ayọ Ladigbolu lo waasu nibẹ, oun naa jẹekan ninu igbagbọ to wa lati ile Oba Ladigbolu ni Oyo.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Barister lo bi gbogbo oníṣẹ́ fújì -Oṣupa Igba ti wọn gbiyanju lati mu Ojemba, ṣe ni arakunrin naa ti ara rẹ mọ inu ile ti o si n kilọ pe ẹnikẹni to ba sun mọ oun, yoo fara gbọgbẹ́ bí i ti ẹgbọn oun.
Kò yé wa bí afurasí ṣe sálọ ní àhámọ́ àmọ́ ẹ ràn wá lọ́wọ́ lári ri mú padà - Ọlọ́pàá Oyo Ile ișẹ ọlọpaa ipinlẹ Oyo ko ti le e salaye titi asiko yii, ọna ti Sunday Shodipe, ẹni ọdun mọkandinlogun gba sa kuro ni ahamọ ọlọpaa ti wọn fi si, titi di asiko ti yoo tun pada foju ba ile ẹjọ.
Kọ́misọnà ọlọpàá ní ìpínlẹ̀ Edo, Muhammed DanMallam tó fìdí ọ̀rọ̀ náà múlẹ̀.
’ Àwọn tí ò ń gàn ni wọ́n dé yìí, yára jáde kí o lọ gbógun tì wọ́n.
Serena ti sọ tẹlẹ l'ọjọbọ ọṣẹ to kọja wipe, oun nilo akoko diẹ si ki oun to le ṣetan fun idije tẹniisi ori amọ.
Ìmọ̀ yi kò ni jẹ́ ki èniyàn ṣi iwà hù, tàbi binú ẹni keji.
Agbẹnusọ gomina Aminu Masari fi aridaju han pe lootọ ni awọn ọmọ naa ti darapọ mọ ẹbi wọn pada lalafia lẹyin ayẹwo ilera fihan pe ara wọn pe.
Ó fi kún pé, irú òṣèlú ti Awolowo ṣe nígbà ayé rẹ̀ ni òun náà ń ṣe, láti fún gbogbo ènìyàn lánfàni kí wọ́n sọ èrò wọ́n fún ìgbéga ìràn Yoruba.
Gideoni dáhùn, ó ní, “Sọ fún mi OLUWA, báwo ni mo ṣe lè gba Israẹli sílẹ̀?
Adajọ sún ìgbẹ́jọ́ naa siwaju di ọjọ kẹẹdọgbọn, oṣu kẹfa ọdun.
Oríṣun àwòrán, Facebook/Saheed Abdullahi Ilé aṣòfin Ondo bẹ̀rẹ̀ ìgbésẹ̀ láti yọ igbákejì gómìnà nípò Kòṣẹlẹ̀rí ni Hajj ọdún 2020, wo ìyàtọ̀ tó wà nínú rẹ̀ sí ti tẹ́lẹ̀ Ìjọba Akeredolu kò ní omi àánú lójú, a kò tọ́jú alárùn Coronavirus mọ́ - Dókítá Ondo Ẹ̀yin ẹlẹ́gbẹ́ òkùnkùn tẹ fẹ́ ṣe àjọ̀dún lónìí, lákọ la ń dúró dè yín - Iléeṣẹ́ ọlọ́pàá Lẹyin naa lo ni gomina ọhun ba ẹbi olori oṣiṣẹ ijọba tẹlẹri naa ati gbogbo awọn olugbe ilu Ilorin kẹdun iku rẹ.
O dárí àìdára àwọn eniyan rẹ jì wọ́n;o sì bo gbogbo ẹ̀ṣẹ̀ wọn mọ́lẹ̀.
Kí ó má gbẹ́kẹ̀lé òfo,kí ó má máa tan ara rẹ̀ jẹ,nítorí òfo ni yóo jẹ́ èrè rẹ̀.
ati agbegbe ti ijamba omiyale ati ilẹ riri ti waye , ni eyi ti awon eniyan mọ́kànléláàdọ́ta padanu
Afurasí Boko Haram pa ogójì ọmọ ogun ilẹ̀ Nàìjíríà ní Borno Ilééṣẹ́ Facebook leè mọ ìgbà tí àwọn tó wà lójú òpó wọn ń ní ìbálòpọ̀ E yé ṣíra yín s'íhòhò nínú fíìmù, àṣà burúkú ni- Efusetan kìlọ̀ fáwọn òṣèré Ẹ wo ohun tí òfin kónílé-ó-gbélé ti bí ní London báyìí Ẹlomiran le mi iru afẹfẹ bẹ simu, tabi to ba fọwọ kan ibi (ori aga ijoko tabi ori tabili) ti arun naa ti bale, ti iru ẹni bẹ si fi ọwọ naa si oju, imu tabi ẹnu rẹ.
Alaga ajọ naa ọmọwe Nureni Adeniran to ṣalaye ọrọ yi fun ileeṣẹ iroyin BBC sọ pe nigba kigba to ba de,awọn ṣetan lati gba tọwọ tẹsẹ.
Bi wọn si de n de ibẹ, naa ni Gbadero yọ lẹyin wọn, ti oun naa wa fi ẹjọ sun ọlọpaa.
“Ẹ̀yìn Paulu ni èmi wà,” ni ẹlòmíràn ń wí pé.
Dame Tallen,okan lara igbimo to n mojuto aarun kogboogun lorile ede Naijiria, (National
Bi a ba sọ pe Hushpuppi nikan lo ri ara rẹ lasiko yii ati pe awọn mọlẹbi ko foju han pe, eeyan awọn nii ṣe, a ko kuna rara lati sọ bẹẹ.
Àwọn igi OLUWA ń mu omi ní àmutẹ́rùn,àní àwọn igi kedari Lẹbanoni tí ó gbìn.
Nígbà tí Modekai gbọ́ gbogbo ohun tí ó ṣẹlẹ̀, ó fa aṣọ rẹ̀ ya.
 nítrójìn jẹ ́ wíwárí gẹ ́ gẹ ́ bí ohun inú afẹ ́ fẹ ́ yíyàtọ ̀ , látọwọ ́ oníṣègùn ará skọ ́ tlàndì daniel rutherford , ní 1772 .
" Idi niyi ti BBC News Yoruba fi wa gbe gege le lati mọ iye gan ni o lee na eniyan lati ra ipapanu Pizza wa lati oke okun ti ko fẹ fi raa lorilẹede Naijiria.
Òtítọ́ rẹ wà láti ìrandíran;o ti fi ìdí ayé múlẹ̀, ó sì dúró.
Ṣugbọn, nítèmi, n kò ṣe bẹ́ẹ̀, nítorí pé mo bẹ̀rù Ọlọrun.
Ṣemu ati Jafẹti bá mú aṣọ kan, wọ́n fà á kọ́ èjìká wọn, wọ́n fi ẹ̀yìn rìn lọ sí ibi tí baba wọn sùn sí, wọ́n sì dà á bò ó, wọ́n kọ ojú sí ẹ̀gbẹ́ kan, wọn kò sì rí ìhòòhò baba wọn.
Maimouna Alpha Sy, akọ̀wé gbogboògbò fún Ẹgbẹ́ Ọ̀ràn Opó àti Aṣàánù ọmọ-ènìyàn, ti fi ìgbà kan rí jẹ́ aya Ba Baïdy Alassane, tí ó jẹ́ adarí àwọn ẹ̀ṣọ́ ibodè tẹ́lẹ̀.
Ejò bu ìdí obìnrin kan jẹ nínú ilé ìgbọ̀nsẹ
Ikede ilu o fara-ro olosu mewaa to wa sopin lodun to koja ko le fopin si ifehonu-han to n waye lorile-ede ohun, bi won se  fi ogoro awon alatileyin ti won fi si atimole sile ninu osu to koja.
Ìre àwọn tí ń kú lọ mọ́ mi,mo sì mú kí opó kọrin ayọ̀.
Ninu iwe ipẹjọ naa ti wọn kọ l'ọjọ kẹtadinlọgbọn, oṣu Keji, ọdun 2020, lati ọwọ agbẹjọro rẹ, Soji Oyetayo, ni wọn ti kọ ọ pe, Agbowu tun n beere pe ki ile ẹjọ fi ofin de Oluwo ati awọn iranṣẹ tabi aṣoju rẹ, lati mase tun fi iya jẹ Agbowu mọ.
Èmi ni OLUWA, Ọlọrun gbogbo eniyan, ǹjẹ́ nǹkankan wà tí ó ṣòro fún mi láti ṣe?
Iṣẹ kekere kọ ni awọn obi ọmọ ti aisan naa ba mu n ṣe.
 Àgbe ni àwon obìnrin yaka , wón si ma ń gbìn ègé , ànànmó , èwà àti erèé míràn .
Abineri bá sọ fún Dafidi pé, “N óo lọ, n óo wá ọ̀nà tí gbogbo Israẹli yóo fi wà lẹ́yìn rẹ, oluwa mi, (ọba), tí wọn yóo bá ọ dá majẹmu tí o óo sì jọba lórí gbogbo ibi tí ọkàn rẹ bá fẹ́.
Pabanbari rẹ wa ni ti Aawọ to waye ninu ẹgbẹ oselu All Progressive Congress (APC) laarin Gomina ipinlẹ Edo, Godwin Obaseki ati alaga ẹgbẹ Adams Oshiomole ni ipinlẹ Edo blọwọlọwọ.
Gomina Akinwunmi Ambọde ati igbakeji rẹ, Ọmọwe Idiat Adebule ati awọn alẹnulọṛọ ẹgbẹ oṣelu APC miiran ni Ipinlẹ Eko wa nibẹ.
Àwọn angẹli ọ̀run kò mọ̀ ọ́n; ọmọ pàápàá kò mọ̀ ọ́n, àfi Baba nìkan ni ó mọ̀ ọ́n.
Adajọ ni ki arakunrin naa lọ gba ẹkọ ninu bi obi rere ṣe maa n ṣe.
Ní oṣù Ọ̀wàrà ọdún 2018, nínú àwọn adarí ipò ìjọba 24, márùn-ún péré ni àwọn tí ó jẹ́ aláwọ̀ dúdú àti elẹ́yà-méjì, tí wọ́n ń ṣojú ìdá 70 àwọn mẹ̀kúnù.
Ninu atẹjade ti Frank Mba alukoro ọlọpaa fi sita lorukọ oga agba ọlọpaa Naijiria Muhamed Adamu, wọn ni iwadii yoo bẹrẹ lori bi iwe ipẹjọ yi ṣe waye.
“Ìwọ ọmọ eniyan, kí ló dé tí wọ́n máa ń pòwe ní ilẹ̀ Israẹli pé, ‘Ọjọ́ ń pẹ́ sí i, gbogbo ìran tí àwọn aríran rí sì já sí òfo.
Jesu dáhùn pé, “Ati òun ni, ati àwọn òbí rẹ̀ ni, kò sí ẹni tí ó dẹ́ṣẹ̀, ṣugbọn kí iṣẹ́ Ọlọrun lè hàn nípa ìwòsàn rẹ̀ ni.
Mo ti fi Jẹriko lé ọ lọ́wọ́ ati ọba wọn ati àwọn akikanju wọn.
Nínú àtẹ̀jáde ọ̀hún, ìpínlẹ̀ Eko ni 338 nígbà ti Abuja ni 77, Kwara náà tun ni 39 nígbà ti Katsina ni 35.
'Nínú ọmọ mẹ́rìndínlógún tí mo bí, ààyò ibẹ̀ gan ni Boko Haram pa' Oríṣun àwòrán, BELLO ZABARMARI Ninu ọmọ mẹrindinlogun ti mo bí, Musfau jẹ pataki, nitori pe akikanju ni."
20 Ọ̀wàrà 2019 Oríṣun àwòrán, ANI Àkọlé àwòrán, Àwọn ènìyàn lórí ẹ̀rọ ayélujára ti bu ẹnu àtẹ́ lu ìgbésẹ̀ ilé ìwé gíga fásitì ní Havari, lorilẹede india.
ANC ni yoo tun jawe olubori ninu eto idibo yii , ti won ba ni asofin irinwó (400) nile igbimo asoju-sofin orile ede naa.
Awọn alasẹ ileesẹ Facebook nifọwọkọwọ pẹlu igbimọ to n wadi ọfintoto iroyin nilẹ Afirika, Africa Check, ti gunle isẹ sise awari awọn oju opo ikanni eke ni ede abinibi to lu oju opo Facebook pa.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Cancer: Àṣe ara mi ni iso ti n run gbogbo bí mo ṣe n ṣèrànwọ́ lórí jẹjẹrẹ Eso Oríṣun àwòrán, Getty Images Jijẹ eso ṣe pataki fun ọkunrin ki atọ rẹ le dara si.
the Allied Peoples Movement (APM) ni won pade nibe , ni eyi ti o da wahala sile
Ewe, Bello so eyi di mimo lori ero ayelujara Instagram re “#Melaninpopping #mavin records”  , eleyi ti ogoro milionu meji abo awon ololufe re n tele lojo aiku (Sunday).
''Ọkan ninu wọn mu ibọn dani ti mo si ri wi pe ẹni keji mu iwe kan lọwọ.
Ọjọ́rú to kọjá ni ìròyìn ti fi tó ni létí pe awọn ènìyàn wọ̀nyí há sínú ihò níbùdó ìwakùsà náà.
Gígùn aṣọ títa fún apá ìwọ̀ oòrùn jẹ́ aadọta igbọnwọ, òpó rẹ̀ jẹ́ mẹ́wàá, àwọn àtẹ̀bọ̀ rẹ̀ náà jẹ́ mẹ́wàá; fadaka ni wọ́n fi ṣe àwọn ìkọ́ ati àwọn ọ̀pá tẹ́ẹ́rẹ́tẹ́ẹ́rẹ́ wọn.
Ẹjọ́ to bá pa mùsùlùmí àti ẹni ti kìí ṣe musulumi pọ̀, mùsùlùmí náà ni àṣẹ láti sọ ibi ti ó fẹ́ ki ìgbẹ́jọ́ náà ti wáyé.
Ati pe ohun ti wọn ba ni akoko ipenija ati wahala to de ba orilẹ-ede yii ko kere rara.
Iṣu àti epo tàbí kẹ̀tẹ́ Oríṣun àwòrán, Youtube/Nigerian Food Recipes Àkọlé àwòrán, Iṣu ati epo Bo tilẹ jẹ pe awọn eeyan lero pe talaka nikan lo n fi epo jẹ iṣu, ṣugbọn ko ri bẹẹ rara tori ounjẹ to da yatọ ni.
Swearing in 2019: Àga, àsìá, àtìbàbà àti ẹní àtẹ́ẹ̀ká ti wà nílẹ̀ fún ìbúra
, lati ilẹ France nigba ti ileeṣẹ itẹwe abo lorilẹede Naijiria (Nigerian Security Printing and Minting Company, NSPMC), naa fifẹ han lati gba iṣẹ naa ni owo to dinwo ju ti ileeṣẹ Faranse naa lọ.
Laipẹ niroyin gbode kan pe Muyiwa Ademola wa lori akete aisan ti agbẹnusọ rẹ si pada jade wa sọ oju abẹ niko gan lori ohun to ṣẹlẹ.
Pẹlu ọwọ lile ni baba rẹ fi dari orilẹede Oman.
Kò fi aigbagbọ ṣiyèméjì sí ìlérí Ọlọrun.
Toyin Abraham bí ọmọkùnrin jòjòló Òṣèré tíátà Toyin Abraham daya Kolawole Ajeyemi Wo àgbáríjọpọ̀ àwọn Arugbá Ọ̀ṣun Òṣogbo látìgbà tó ti bẹ̀rẹ̀ Àjẹ́ àti Aṣẹ́wó ní ìyá Rainbow - Òjòpagogo Amọ nigba to n fesi, Kabiyesi naa dahun pe lati igba iwasẹ ti wọn ti n bọ Ọsun, ere naa ko see ji gbe, nitori naa, ohun ti Baba Ọlọsun n sọ kii se ododo ọrọ.
Ṣugbọn ọpẹ́ ni fún Ọlọrun tí ó fún wa ní ìṣẹ́gun nípasẹ̀ Oluwa wa Jesu Kristi.
"jesse king gbé àwo orin rẹ ̀ àkọ ́ kọ ́ tí ó sọọ ́ di ìlúmọ ̀ ọọ ́ ká jáde ní ọdún 2006 tí ó porúkọ rẹ ̀ ní "" buga "" ."
Bakan naa ni wọn yoo fun ọ ni gbogbo iwe to ṣe pataki fun lati ni nipa nọmba aladini rẹ.
Ṣé ìrànwọ̀ ni Kamala, ìgbákejì tí Biden yàn yóò jẹ́ fún un tàbí ìpalára?
omo ogun ọlọtẹ Boko Haram run lasiko  ti ikọlu
Àìríṣẹ́ṣe kọ́kọ́ sọ mi di olè ṣùgbọ́n mo di alásè ńlá lẹ́yìn ti mo ti ẹ̀wọ̀n dé- Eduardo Ǹjẹ́ ọmọ Buhari lásẹ láti wọ Ọkọ̀ òfúrufú Nigeria Air force 1 lọ sí òde?
20 Bélú 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ikọ ẹṣinokọku Boko Haram ti bẹrẹ idukuku mọni lọdun 2009 Akọroyin BBC naa jabọ pe ẹgbẹgbẹrun awọn afunrasi ikọ Boko Haram ti wọn ṣi wa latimọle awọn ile-iṣẹ ologun kaakiri orilẹede Naijiria, ni o ṣeeṣe ki igbẹjọ wọn naa o waye laipẹ.
Ìdí rèé tí mi ò fi yọjú sí ìgbìmọ̀ àjọ PFN- Fatoyinbo ‘Ilé ẹjọ́ kò gbé ẹ̀sùn ìfipánílòpọ̀ yẹ̀wò, à ń lọ sí ilé ẹjọ́ - Busola Dakolo CAN kò rán ẹnikẹ́ni lọ ṣọ́ọ̀ṣì COZA, iṣẹ́ ara wọn ní wọ́n lọ jẹ́ -Samson Ayokunle Agbejọ́rò Dakolo:Mílíọ́nù mẹ́wàá náírà tí a béèrè kì í ṣe owó gbà má-bínú PFN: Fatoyinbo kọ̀ láti yọjú ni ìwádìí wa kò ṣe parí Biodun Fatoyinbo fi ipò sílẹ̀ lorí ẹ̀sùn ìfipábánilòpọ̀ Iroyin sọ pe Pasitọ Oyedepo lo kede lasiko eto isin kan ni Ọjọbọ, pe Biodun Fatoyinbo yoo farahan ninu isin Shiloh, gẹgẹ bi alejo pataki.
Oríṣun àwòrán, Iamnino_b Àkọlé àwòrán, Gbaajúgbaja oṣèré Ninalowo Bolanle náà ò gbẹyìn nínu àwọn okúnrin ti ìmúra wọn fakọyọ lọdún 2018 Èyí o wa jojú ní gbèsè bí Bolanle Ninalowo, oṣèrè fíìmù Yoruba àti lédè Òyìnbo ṣe dúró déédé l'ọ́mọkùnrin níbi àmì ẹ̀yẹ náà.
” Ó bá mú Simeoni jáde sí wọn.
Ayinla Ọmọwura ko lọ sile iwe rara, amọ o se iwọn to lee se lati ko ipa tiẹ si idagbasoke awujọ to wa lati ipasẹ orin kikọ ati gbolohun ede Yoruba.
Ní ọ̀nà àbáwọ  igbó náà, àwọn arúgbó igi tò síbẹ̀ wàlàhìhì.
Amọ ṣa, lọjọ kẹsan an, to jẹ ọjọ̀ keji, ni akọwe ipolongo fun ẹgbẹ oṣelu All Progressives Congress, APC, to jẹ ẹgbẹ gomina, Joe Igbokwe fi ikede kan sita pe ko si n to buru ti gomina ba ṣe bẹẹ.
Tamari bá bọ́ aṣọ ọ̀fọ̀ kúrò lára, ó fi ìbòjú bo ojú rẹ̀, ó wọ aṣọ tí ó dára, ó bá jókòó lẹ́nu bodè Enaimu tí ó wà lọ́nà Timna; nítorí ó mọ̀ pé Ṣela ti dàgbà, wọn kò sì ṣú òun lópó fún un.
Oríṣun àwòrán, @GovAyoFayose Àkọlé àwòrán, Asọ oyinbo ni gomina wọ lati fa ọmọ rẹ fun ọkọ ni kootu Oríṣun àwòrán, @GovAyoFayose Àkọlé àwòrán, Baba ati iya iyawo ni wọn se bii oloyinbo nibi igbeyawo oloruka ti Tomi Fayose ati Arẹwa Ọdunlade se Oríṣun àwòrán, @GovAyoFayose Àkọlé àwòrán, Awọn ẹbi tọkọ-taya tuntun ti parada si asọ ibilẹ wa Oríṣun àwòrán, @GovAyoFayose Àkọlé àwòrán, So bẹbẹ fẹ, abi o ko bẹbẹ fẹẹ ?
Iroyin sọ pe Adanlawọ lọ si ile awọn obi ọmọ naa, lasiko ti awọn ẹgbọn rẹ ati obi rẹ ti lọ si oko, to si fi tipatipa ba a lopọ.
Bola Ahmed TinubuAwon igbakeji alaga miiran1.
Wọ́n dán an wò léraléra,wọ́n sì mú Ẹni Mímọ́ Israẹli bínú.
Ijamba ọkọ tirela meji ti ran eeyan mẹfa lọ si ọrun ọsan gan gan niluu Ikare-Akoko nipinlẹ Ondo.
Lẹ́yìn náà ni a rí obìnrin mẹ́ta àti ọkùnrin mẹ́ta tí wọ́n dúró ni apá ọ̀tún àti apá òsì tí wọn ọmọ ìyà ìyàwó mi.
O ni to ba da yin loju, ẹ sọ ọrọ sita, kẹ si duro lori rẹ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Afeez Agoro: O ṣòro fún mi láti wọ Danfo jáde Onimọ naa ni, fun apẹẹrẹ, bi agbara ojo ṣe n ṣọsẹ ni adugbo kọọkan ni Ipinlẹ Eko lagbara ju'ra wọn lọ.
Bí iré bí iré ilẹ̀ ń ṣú lọ síbẹ̀ n kò rí òye ọ̀nà rárá.
Ẹ ran Wikipedia lọ́wọ́ láti fẹ̀ẹ́ jù báyìí lọ
Oga agba fun ile-ise olopaa Ibrahim Idris soro naa di mimo lasiko ipade re pelu awon komisona olopaa ti o waye ni olu-ile ise olopaa, niluu Abuja.
 pratt , lẹ ́ yìn tí ó kọjá sí england ní ọdún 1946 , ó kọ ́ ẹ ̀ kọ ́ nípa ìtọ ́ jú aláìsàn ní nightingale school tí ó wà ní st thomas ' hospital , ní london , ó sì yege gẹ ́ gẹ ́ bí state registered nurse ní ọdún 1950 .
Wọn yóo sì mọ̀ pé èmi ni OLUWA.
Àkọlé àwòrán, Papa isere Abiola tuntun Ọpọlọpọ ọmọ Naijiria lo n parọwa fun ijọba apapọ lati ṣe gbogbo atunṣe si papa yii ko le ba ẹgbẹ pé.
Ọmọbinrin naa farapa, ki wọn o to gbe lọ sileewosan, to ku si.
Oríṣun àwòrán, Others Àkọlé àwòrán, Obinrin ti to gabngba sun lọyẹ ninu iṣelu Naijiria Lẹyin ti ile igbimọ aṣofin ba ti pari ayẹwo ti wọn bẹrẹ loni ni a maa mọ awọn to ba wọle gẹgẹ bii minista ati ipo ti wọn maa di mu.
0 1787783 Orilẹede Italy 62626 103.
Alaga igbimo ohun, ogbeni Ali Isa JC so lasiko to n ba awon akoroyin soro niluu Abuja so pe, abo igbimo ohun ko niise pelu igbakeji aare, ojogbon Yemi Osibanjo bi o se le wu ko mo.
" Gani Adams lo sọ bẹẹ.
Wọ́n bá gbé Jona jù sinu òkun, òkun sì dákẹ́rọ́rọ́.
Amofin Fẹmi Falana (Amofin Agba Lorilẹ-ede Naijiria (SAN), gbajugbaja onimọ ofin gbe oṣuba sadankata fun abadofin naa, o ni o yẹ ki wọn ṣagbeyẹwo ofin to wa nilẹ fun awọn ẹtọ to nii ṣe pẹlu awọn ọmọde ati laasigbo inu ile to wa ni ipinlẹ yii ki wọn to fi ẹnu ofin naa ko.
Àwọn Òṣèlú àti Olóri ilú kò ti kọ́ ọgbọ́n, nitori wọn nṣe àṣiṣe si nipa li lo iṣẹ ti wọn gbà lai ṣe kó owó ilú jẹ, àbẹ̀tẹ́lẹ̀ gbigbà àti iwà ibàjẹ́ ló fa ibàjẹ́ ohun amáyédẹrùn àti ìṣẹ́ laarin ọrọ̀ ni orilẹ̀ èdè Nigeria.
“Àwọn alufaa gbọdọ̀ pa àwọn òfin mi mọ́, kí wọ́n má baà dẹ́ṣẹ̀ nítorí rẹ̀, kí wọ́n sì kú nítorí àwọn òfin mi tí wọ́n bá rú.
Àkọlé àwòrán, Akinyele Murder: Iléeṣẹ́ ọlọ́pàá ní aago márùn-ún ìdájí ni wọ́n pa obìnrin náà níwájú ilé rẹ̀ Mùjẹ̀-mùjẹ̀ ní Akinyele tún ti mu ẹ̀jẹ̀ obìnrin míràn lónìí Kaka ki ewe agbọn dẹ ni adugbo Akinyele nilu Ibadan ti wọn ti n pa awọn eeyan lẹnu ọjọ mẹta yii, ko ko ko lo n le si i.
Ẹ̀gbọ́n ké pẹ̀lú omijé lójú pé “Bi ó bá jẹ ìwọ ni Ọlọrun, ma ṣe iwà burúkú yi lọ, ṣùgbọ́n bi ó bá jẹ́ enia bi ti òhun, wà á ká ohun ti o gbin yi”.
Ìjọba ìpínlẹ̀ Osun tí búwọlù ìlànà àyẹyẹ Ọṣun-Oṣogboo ọdún 2020 Wo ọ̀nà márùn ún tí o lè gbà dáàbò bò ara rẹ lọ́wọ́ ìjàmbá láì gbé ìbọn!
Yatọ si nkan ti ọjọgbọn Nyenswah sọ pe a ko le mọ bi arun ba se nipa lara awọn eeyan to lalai se ayẹwọ lati mọ iye eeyan to mu, awọn onimọ mi to fi mọ ọga agba ajọ ilera lagbaye Tedros Ghebreyesus ni sise ayẹwo fun ẹnikẹni to ba ni apẹrẹ arun naa ni ọna ati mu adinku ba itankalẹ kokoro aifojuri yi.
Ẹgbẹ́ IPOB ò tako Ààrẹ Buhari ní Japan- Iléeṣẹ́ Ààrẹ Òfin nìkan ló lè gbadé lórí àwa Ọba ìlú lbadan- Oba Lekan Balogun Irọ́ ló pa, a kò mọ̀ ọ́ rí tàbí fún ọ ní ₦13m - APC tako afurasí ajínigbé Afikun iye owo ti wọn n pe ni (Reciprocity Fee) re e: B1$110 B2$110 B1/B2$110 F1 $110 F2$110 H1B $180 H4$180 I$210 L1 $303 L2$303 R1 $80 R2$80 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
 lóni , quincy herbals tí gbà ọpọ ̀ lọpọ ẹ ̀ bùn nítorì ipa ribiri tí àwọn ojà rẹ ́ ńse .
Lati igba naa, ko si ọmọde kankan ti awọn ọlọde to n koju awọn agbesunmọmi pelu awọn ologun tun ti gba mọra wọn mọ.
Jesu Kristi, nípasẹ̀ ẹni tí a dá gbogbo nǹkan, nípasẹ̀ rẹ̀ ni a sì ti dá àwa náà.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù MMM ti kógbá wọlé 8 Ìgbé 2018 Oríṣun àwòrán, https://nigeria-mmm.
Mose sì wà pẹlu OLUWA fún ogoji ọjọ́ tọ̀sán-tòru, kò jẹ, bẹ́ẹ̀ ni kò mu, ó sì kọ ọ̀rọ̀ majẹmu náà, tíí ṣe òfin mẹ́wàá, sára àwọn wàláà òkúta náà.
Boya yoo fọọre tabi fọbi, boya iwaju ni ọlọkọ idije Yuroopu n gbe wọn lọ tabi ẹyin.
Hazard pegedé nígbà tí Chelsea na Brighton Bí Hazard bá fẹ́ lọ kó máa lọ - Sarri Ó ṣe f'ọ́mọ tó ń jeérú!
Ìtàn ayé Ọba Seriki Abass ti Badagry, tó ní aya 128, ọmọ 144 Mọ̀ síi nípa Shina Rambo tó pàdé Jesu lọ́gbà ẹ̀wọn lẹ́yìn tó ti jalè Afọnja, ẹni tó finú wénú ní Ilọrin, àmọ́ tó jẹ iwọ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Oyenusi ló mú mi wọ ẹgbẹ́ adigunjalè kó tó di pé mo b'Ólúwa pàdé' Àwọn òṣèré Nollywood tí wọn ò sí lóri amóhùmáwòrán mọ́ 'A ní àrídájú, a rí àwọn ẹgbẹ́ ISIS pẹ̀lú àlùpùpù olówó ńlá, ọmọ Yoruba ẹ funra -Gani Adams Ìdí tí mo fi gbàdúrà ìyàwó bíi Chanel Chin fáwọn tó d'ẹ̀bi ìkọ̀sílẹ̀ rẹ̀ rù mí rèé - Oluwo Oral Sex: Bóo bá ń gba ẹnu ní ìbálòpọ̀, wo àìsàn tóo lè kó lójú ara rẹ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Tíátà ọ́mọdé tí wọ́n ń kọ́ wa ní Bariga ti mú mi lọ Germany, Switzerland, Amsterdam.
Bẹẹ ba gbagbe, ipinya ti wa ninu igbeyawo iyawo Iyabọ Ojo lati ọjọ pipẹ, to si jẹ pe oun lo n da awọn ọmọ mejeeji naa tọ ni Naijiria.
Àbùṣọrọ̀ lu lé uṣu, mọ́ m’ẹ́ùrà kàn kàn dé bẹ̀
 Àwọn bú mílíọ ̀ nù márùn-ún ni ó ń sọ èdè yìí ní agbègbè ethiopia nígbà tí ̣ àwọn ọ ̀ pọ ̀ lọpò mílíọ ̀ nù mìíràn ń sọ èdè yìí gẹ ́ gẹ ́ bí èdè kejì àkọ ́ kúntẹnu ní ethiopia àti sudan ( sùdáànù ) .
Ikechukwu Wilson ló gba Àmì Ẹ̀yẹ 2019 BBC Pidgin Essay Competition Ọmọ ogun Nàìjíríà mẹ́wàá dèrò ọ̀run lẹ́yìn ìkọlù ẹgbẹ́ Boko Haram A gbọ́dọ̀ ṣewàdìí ìròyìn ayélujára kí a tó pin in- OloriSuperGal Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Illegal Rehab Centre: A le ni ogójì tí wan n kó 'sinú ìyará kékeré kan níle Ọlọrẹ Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 3 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 5 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Idà mímú yọ jáde ní ẹnu rẹ̀, tí yóo fi ṣẹgun àwọn orílẹ̀-èdè, nítorí òun ni yóo jọba lórí wọn pẹlu ọ̀pá irin.
Ibi tí mo ti ń ronu báyìí ni ọkùnrin náà ti kígbe láìròtẹ́lẹ̀, ohùn rẹ̀ sí dà bí ìgbà tí jàgídíjàgan ìranńṣẹ́ bá da ǹkan lulẹ̀ láti ibi gíga; ẹrù bá mi bí ìyàwó ẹni tí ó lọ sí ojúu ogun, mo sì ń wárìrì bi ìgbà tí alùpùpù tí ó bàjẹ́ bá ń gun orí òkè, níotrí igbe ọkùnrin náà lágbára bi ti kìnnìún, ó rin ilẹ̀ dòdò bi ti àjànàkú ó gba igbó kankan bí ìgbà tí rélùwéè bá ń súnmọ́ etí ìlú tí ó ń fún fèèrèkikankikan.
Ó fi kún pé ọ̀tẹ̀ tó pa wọ́n pọ̀ náà ló ń tu wọ́n ka.
Ìbànújẹ́ yóo bá eniyan burúkú nígbà tí ó bá rí i.
O ni idi ti iru eyi fi n ṣẹlẹ ni wi pe, awọn obi ko ni imọran to to lori ewu to wa ninu ki awọn ọmọ wọn jade nigba ti agbara ojo ba wa lori popo.
Ẹ̀mí ogójì ṣòfò, ọgọ́ta míràn farapa nínú ìjàmbá ọkọ̀ epo tó jóná Fayẹmi: Kò tí ì sí òṣìṣẹ́ ìjọba kankan l'Ekiti tó tíì gba owó oṣú ní 2018 Ẹ̀mí ogójì ṣòfò, ọgọ́ta míràn farapa nínú ìjàmbá ọkọ̀ epo tó jóná Òkú èèyàn mẹ́jọ ni wọ́n yọ níbi ìṣẹ̀lẹ̀ ìjàmbá ọkọ̀ nílùú Eko lọ́jọ́ Aje Buhari yan Mohammad Sambo, olùdarí NHIS tuntun Alagba Joseph Falua to jẹ olori ilu yii ni aìsi agọ ọlọpaa ni ẹkun Ekiti yii lo n jẹ ki wọn maa ṣagbako awọn oniṣẹ ibi yii Ni kete ti wọn gba ipe pe ole n ja ni igbo ọba ni Alagba Emmanuel Ilori ti pe awọn ọdẹ ẹgbẹ rẹ to ku ti wọn si jọ lọ gbiyanju lati daabo bo ọrọ ijọba ni agbegbe wọn.
Egbe to n ri si boolu afigigba lorile-ede Naijiria(NAN), ti ni idije ohun yoo pari ni ojo abameta ni arin gungun papa isere ni ilu Abuja.
Lasiko ifilole ohun ti o waye lojoBo(Thursday),  aare so wipe lati koju eto aabo to mehe lorile-ede Naijiria, a niloo ibasepo ti o donmonron laarin ijoba apapo ati laawon ipinle wa kookan.
Toju tiyẹ laparo fi n riran, ki awọn eeyan ma fi taratara duro nibi kibi ti wọn ba wa.
6 miliọnu ju Buhari lọ jẹ eleyi to panilẹrin julọ.
Mo ti rí gbogbo ìrora tí àwọn eniyan mi ń jẹ ní Ijipti.
Awon oludibo ti dibo won tan  ni deede aago méjìlá  osan oni, ni eyi to jẹ pe bi awon oludibo
Ọgbẹni Kehinde Oyetunji sọ iriri tirẹ nigba naa lori eto BBC Yoruba pe koda lọjọ naa gbogbo oju popo ni wọn dana si.
O tun wa ninu adehun pe Everton yoo pada fi miliọnu meje kun owo naa to ba ya.
Agbaboolu orile-ede France, ti o tun kopa fun iko agbaboolu Atletico Madrid, Antoine Griezmann ti kede fun awon oludari iko re lati fi iko naa sile ti idije La liga saa odun yii ba pari.
Bo tile je pe , eyi ko dunmọ awon
O ka ẹkọ nipa iṣẹ imọ ẹ̀rọ ni fasiti Cairo ko to lọ gba oye ọmọwe (Ph.
Nígbà tí ó ṣe ni Òjòlà-ìbínú kígbe ńlá tó bẹ́ẹ̀ tí gbogbo àwọn ará ìlú náà jí lójú oorun tí ilẹ̀ sì mì tìtì.
Ọgbọ́n ati òye tí Ọlọrun fún Solomoni kọjá sísọ, ìmọ̀ rẹ̀ sì kọjá ìwọ̀n.
Ọwá gba Òdùdu lọ, Ọna Ìjẹ̀bú-Jẹ̀ṣà sì gba Ilékéte lọ.
Gbèsè Nàìjíríà ti lé ní 18 tírílíọ́ọ́nù lábẹ́ ìṣèjọba Ààrẹ Buhari- DMO Àìsí iṣẹ́ nígboro lọ̀pọ̀ ọ̀dọ́ fi fẹ́ gba iṣẹ́ Amotekun - Toogun Wo bí iṣẹ́ abẹ wákàtí mẹ́fà, tí wọ́n fi dóòlà ẹ̀mí ìjàpá tí ọkọ̀ tẹ̀, ṣe lọ Alámì ẹ̀yẹ Scrabble Paul Sodje àti ọ̀rẹ́ rẹ́ kú lásìkò tó fẹ́ lọ́ sanwó ìdóòlà ẹ̀mí àbúrò rẹ̀, tí afurasí darandaran jí gbé Bàbálọ́jà márùn ún la ó ò ní l'Oyo tí Makinde bá lè buwọ́lu ìyànsípò YK Abass Akọsilẹ fihan pe eleyii yatọ si awọn eeyan mii to pa ara wọn ṣugbọn ti awọn akọroyin ko gbe sita.
Lẹ́yìn tí òun kú ni Ahasaya ọmọ rẹ̀ gun orí oyè.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Nollywood stars: Àwọn èèkàn òṣèré sinimá ní Nàìjíríà jẹ́wọ́ ara wọn lórí fífi ohùn àmì Gẹ́gẹ́ bi Yomi Fabiyi to jẹ ọ̀kan gbòógi lara awọn òṣere Nollywood Yoruba ṣe sọ, ó ni láìpẹ́ yii àwọn yoo ṣe àtẹjáde àti èrèdí ti àwọn fi darapọ̀ síta ninu fọto.
Wàyí ò, ó já sí pé kì í ṣe èmi alára ni mò ń hùwà bẹ́ẹ̀, bíkòṣe ẹ̀ṣẹ̀ tí ń gbé inú mi.
Kò sí ẹni tí yóo tọ́ ọ sọ́nà,ninu gbogbo àwọn ọmọ tí o ti bí,kò sí ẹni tí yóo fà ọ́ lọ́wọ́,ninu gbogbo ọmọ tí o tọ́ dàgbà.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ramadan: Àwọn mùsùlùmí tí kò bẹ̀rẹ̀ àwẹ̀ títí d'ìgbà tí wọ́n tó fojú r'óṣù 7 Èbibi 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 8 Èbibi 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Olori Musulumi ni Naijiria ni o ma n saba paṣẹ bibẹrẹ awẹ Ramdan ni Naijiria Ninu oṣu Ramadan ọdun yi,gẹgẹ bi iṣe rẹ Sultan Sokoto kede pe ki awọn musulumi bẹrẹ awẹ lọjọ Aje lẹyin ti wọn ri oṣu lawọn ilu kọọkan.
Lẹta Ọbasanjọ si Buhari Irọ́ ni o!
lasiko ti igbimo tẹẹkotọ to n mojuto eto idagbasoke inawo ni ipinle Katsina se
Àwọn ẹran ọ̀sìn tí wọ́n kó lójú ogun nìwọ̀nyí: ẹgbaa mẹẹdọgbọn (50,000) ràkúnmí, ọ̀kẹ́ mejila lé ẹgbaarun (250,000) aguntan, ati ẹgbaa (2,000) kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́; wọ́n sì kó ọ̀kẹ́ marun-un (100,000) ọkunrin lẹ́rú.
Nítorí náà ẹ má ṣe yẹ̀yẹ́,kí á má baà so ẹ̀wọ̀n yín le.
Minisita feto ilera ṣalaye pe, mẹrin ninu awọn eeyan marun un naa ni wọn jẹ ọmọ Naijiria ti ọmọ ikoko naa si jẹ ọkan lara wọn.
Wọ́n ní, “Oluwa, àwọn ẹ̀mí èṣù pàápàá gbọ́ràn sí wa lẹ́nu ní orúkọ rẹ.
Ẹ ní ìtẹ́lọ́rùn pẹlu ohun tí ẹ ní.
Lori awọn sinima to nii se pẹlu afihan ihooho ati iwa jagidi jagan abi lilo ibọn, Gbajugbaja osere tiata naa ni asa alasa ni a n kọ pẹlu sise fiimu onijagidijagan.
Lati lee koju awọn iwa aidaa si awọn araalu, awọn yoo ṣe agbekalẹ ikọ aṣewadii ti awọn ẹgbẹ araalu ti awọn yoo si maa fi awọn ti igba iwa yii ba ṣi mọ lori jofin.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù The 27th Anniversary: Ò ti pé ọdún 27 tí Shah Rukh Khan ti ń se fíìmù India 26 Òkùdu 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ọ̀pọ̀lọpọ̀ ènìyàn ló mọ Shah Rukh Khan gẹ̀gẹ̀ bi gbajúgbajà òsèrè tó ma ń se fíìmù ìfẹ́ ní Bollywood.
Bí Israẹli tilẹ̀ rúwé bí ewéko etí odò, atẹ́gùn OLUWA láti ìlà oòrùn yóo fẹ́ wá, yóo wá láti inú aṣálẹ̀; orísun rẹ̀ yóo gbẹ, ojú odò rẹ̀ yóo sì gbẹ pẹlu; a óo kó ìṣúra ati ohun èlò olówó iyebíye rẹ̀ kúrò.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Wo imọran Fọlọrunṣọ Alakija fun awọn ọdọ adulawọ Ni oṣu Kẹfa, ọdun 1969, Biafra yawọ Naijiria pẹlu agbara lati le kọlu wọn lojiji.
Ninu àwọn ẹranko tí wọ́n ń fi ẹsẹ̀ mẹrin rìn, gbogbo àwọn tí wọ́n bá ti ń fi ẹsẹ̀ mẹrẹẹrin rìn tí wọ́n sì ní èékánná jẹ́ aláìmọ́ fun yín; ẹnikẹ́ni tí ó bá fi ọwọ́ kan òkú wọn yóo di aláìmọ́ títí di ìrọ̀lẹ́.
Atiku ni  Orilẹede wa ko tii pinya bii eyi ri, ohun gbogbo lo ti dẹnu kọlẹ, ọpọ eeyan lo ti padanu is wọn, eyi to n sọ awọn ọmọ orilede yii sinu agbami isẹ ati osi."
Ṣùgbọ́n bí ẹ kò bá ṣe èyí, wọ́n ni ogun yóò bẹ́ sílẹ̀ láàrin àwọn àti ẹ̀yin ni agogo mẹ́sàn-án òwúrọ̀ ọ̀la.
Àkọlé àwòrán, ìfọ̀rọ̀wérọ̀ BBC Yorùbá Ni ti Ọtunba Alao Akala, o gboriyin fun BBC fun akitiyan yii lati gbe ede ati aṣa Yoruba larugẹ.
O tun dupẹ lọwọ awọn ti wọn jọ dije dupo labẹle pe wọn ba oun ṣiṣẹ.
Amọ ibi to yiwọ ọkọ si, agbegbọn miran naa wa nibẹ, to na ibọn si wa amọ awakọ tiwa jafafa pupọ nidi ọkọ wiwa, to si salọ.
Bẹẹ lọrọ ri lọdọ ọgbẹni Jonathan Wareham lati Italy ti isede ka oun, iyawo rẹ ati awọn ọmọ mẹta mọle.
Commonwealth: Ànfàní wo ni Nàìjíríà rí?
Rehoboamu ń gbé Jerusalẹmu, ó kọ́ àwọn ìlú ààbò wọnyi sí Juda: 
Nítorí pé, a ti fi ìdí ìfẹ́ rẹ tí kì í yẹ̀ múlẹ̀ títí lae;o sì ti fi ìdí òtítọ́ rẹ múlẹ̀ bí ojú ọ̀run.
Ile ni awọn aṣofin ko ni gbe igbesẹ ti yoo ṣe ipalara fun awọn ọmọ Naijiria lẹyin tawọn ba ṣe agbeyẹwo erongba wọn tan.
Ileeṣẹ ọlọpaa sọ pe, awọn mọ pe Kareem n kopa ninu eto agbelewo naa lọwọlọwọ lai gba iyọnda lọwọ awọn alaṣẹ ileeṣẹ ọlọpaa.
Yóo di èrò ẹ̀yìn láàrin àwọn orílẹ̀-èdè,yóo di aṣálẹ̀ tí ó gbẹ.
Ko si ẹni to le sọ ibi ti ọrọ yoo fi si lọjọ iwaju.
Falana ni ọrọ ti Aarẹ Buhari sọ nipa owo epo nigba to n ba awọn ọmọ Naijiria sọrọ ko bojumu to, ati pe ko lẹtọọ ki Aarẹ maa ṣafiwe igbe aye awọn ọmọ naijiria si ti awọn eeyan Saudi Arabia.
Atẹjade kan tijọba fisita lo sisọ loju ọrọ yii pẹlu afikun pe wọn ti fi owo to to irinwo miliọnu naira (₦400m) ṣọwọ si awọn ile iwe girama, nigba ti ile iwe alakọbẹrẹ naa si ti tẹwọ gba aadoje miliọnu naira o din mẹrin ( ₦126m) bakan naa.
Bayii, adan ti gba awọn oṣiṣẹ to to marundinlogoji sẹnu iṣẹ yii ti ọpọ ninu wọn jẹ oluranlọwọ ati akẹkọọ.
Eyi lo mu ki awọn ololufẹ Gomina Ganduje o wọ gbọngan kan ni ọfiisi ijọba ipinlẹ Kano, ti wọn si yọ aworan Emir Sanusi kuro lẹyin ti Ganduje wọle saa keji sipo gomina.
Júpítérì jẹ́ ṣíṣàjọsínú pẹ̀lú háídrójìn tí ìkan-nínú-ìdámẹ́rin ìsúpọ̀ sì jẹ́ hélíọ̀m; bákannáà ó tún ṣe é ṣe kó ní inúàrin oníàpáta apilẹ̀sè wíwúwo.
Nipa awọn ọmọ rẹ, o ni ihoho ọmọluabi loun maa n ba awọn ọmọ oun wi, o ni gende ọkunrin marun un loun bi.
 Ṣùgbọ ́ n orílẹ ̀ ẹ ̀ dẹ ̀ bíi gíríìsì ( greece ) tí ìsirò ti bẹ ̀ rẹ ̀ , ilẹ lárúbáwá ( arabia ) , ile isrẹẹli ati bẹ ́ ẹ ̀ bẹ ́ ẹ ̀ lọ , wa nínú àwọn irú ènìyàn tí ó tayọ nínú ètò ìkọ ́ ni .
Mose súre fún ẹ̀yà Reubẹni, ó ní:“Ẹ̀yà Reubẹni yóo máa wà ni, kò ní parun,àwọn eniyan rẹ̀ kò ní dínkù.
 Ó jẹ ́ ìkan lára àwọn tí ó ń gbé oge ìbílẹ ̀ larugẹ .
‘Ilé ẹjọ́ kò gbé ẹ̀sùn ìfipánílòpọ̀ yẹ̀wò, à ń lọ sí ilé ẹjọ́ - Busola Dakolo Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
 fómilúsì tí ó sọ ìtàn bí eré àpíìrì ṣe bẹ ̀ rẹ ̀ ní Ìjerò-Èkìtì .
Òtítọ́ ni pé èrè ńlá wà ninu jíjẹ́ olùfọkànsìn, tí eniyan bá ní ìtẹ́lọ́rùn.
Eboseremene, bẹbẹ pe ki Onidajọ O.
Gbogbo igi yín ati gbogbo èso ilẹ̀ yín ni yóo di ti àwọn eṣú.
Ní ọjọ́ kan ṣoṣo, Peka, ọmọ Remalaya, ọba Israẹli, pa ọ̀kẹ́ mẹfa (120,000) ninu àwọn ọmọ ogun Juda; tí gbogbo wọn sì jẹ́ akọni.
Oríṣun àwòrán, @Worldstagegroup Alaga ikọ Amọtẹkun ni iha Iwọ Oorun Naijiria, Kunle Togun lo fi lede pe awọn Fulani darandaran yii kii ṣe ọmọ Naijiria.
Nítorí Ọlọrun ni Ọba gbogbo ayé;Ẹ fi gbogbo ohun èlò ìkọrin kọ orin ìyìn!
Olówó yalumọ àkọ́kọ́ nílẹ̀ Yorùbá Wo iye ìgbà tí ẹgbẹ́ òṣìṣẹ́ àtàwọn ọmọ Nàìjíríà ti ṣèwọ́de lórí àfikún owó epo bẹntírò Lọjọ yi, ọkọ nla to n gbe afẹfẹ gaasi gbina to si jo ile mẹtalelogun, ọja, ọkọ marundinlogun, ti eniyan ọgbọn si farapa ninu iṣẹlẹ naa.
Oríṣun àwòrán, @APCUKingdom Bayo Osinowo: Sẹ́nétọ̀ tó ń ṣojú ẹkùn ìdìbò ìlà-oòrùn ìpínlẹ̀ Eko, Adebayo Osinowo ti d'olóògbé Sẹnetọ to n ṣoju ẹkun idibo ila-oorun ipinlẹ Eko, Adebayo Osinowo ti jade laye.
Àwọn ọmọ Magibiṣi jẹ́ mẹrindinlọgọjọ (156)
Gẹgẹ bi awọn agba awo to ba BBC News Yoruba sọrọ ṣe sọ, ọdun iṣẹṣẹ jẹ ọdun iranti ipilẹ, ori, ati Olodumare.
N óo fọ́ ìlẹ̀kùn odi ìlú Damasku.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ohun ti oju awọn alufa ijọ aguda ni Naijiria ri lọwọ awọn ajinigbe kọja afẹnusọ Alukoro ọlọpaa Andrew Aniamaka sọ pe lẹyin ọsẹ meji ni wọn to tun wn silẹ ti ọwọ awn si ti tẹ afunrasi kan.
"Wo bí odò Nile tó gùn jù l'Áfíríkà, ṣe ń fójúu ilẹ̀ Egypt, Ethiopia àti Sudan han màbo Àlàyé rèé lórí bí wọ́n ṣe pa Ebila, olórí àwọn ""One million boys"" n'Ibadan Ohun tí o kò mọ̀ nípa Ebila ""One Million Boys"" àti Ekugbemi, olórí ẹgbẹ́ òkùnkùn méjì tó da ìlú Ibadan rú Áṣẹyin kìlọ̀ fáwọn adarí olóṣèlú Nàìjíríà láti ṣe ohun tó yẹ nítorí ará ọ̀run ń wò wọ́n!"
ara ipinle naa pe, oun ko ni kaare lati mu ipinle naa de ebute ogo.
Ile isẹ amohunmaworan akọkọ lorilẹede Naijiria, Western Nigeria Television (WNTV) lo se iranwọ fun Baba Sala to fi da ilumọọka gbajugbaja amuludun.
Wọn á máa ké pé, “Yàgò lọ́nà.
SERAP gbé ìjọba àpapọ̀ lọ ilé ẹjọ́ àgbáyé ICC lọrí ẹ̀sùn ìpànìyàn Ajọ ajafẹtọ ọmọniyan, SERAP ti kọwe mọ ijọba ati ileeṣẹ ologun Naijiria lọdọ ile ẹjọ agbaye to n gbọ ẹsun iwa ọdaran, ICC.
Tọ alufaa tí ó wà lẹ́nu iṣẹ́ ní àkókò náà lọ, kí o sì wí fún un pé, ‘Mò ń wí fún OLUWA Ọlọrun mi lónìí pé, mo ti dé ilẹ̀ tí ó ti búra fún àwọn baba wa láti fún wa.
Pa mí mọ́ ninu ewu tàkúté,ati ti okùn tí àwọn aṣebi dẹ sílẹ̀ dè mí.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Aarẹ ọna kakanfo Yoruba marun to jẹ kẹyin 1 Ẹrẹ̀nà 2018 Oríṣun àwòrán, facebook/Aare Gani Abiodun Adams Àkọlé àwòrán, Aarẹ Gani Adams ni Aana kakanfo karundinlogun Oju eeyan pataki ni Yoruba fii wo awọn ologun laye atijọ.
 Ó máa n saaba ṣẹlẹ ní awọn orilẹ-ede 53 lati ìhà afirika , aṣia , Ààrin-gbùngbùn àti gúúsù amẹrika pẹlu awọn eniyan bí i miliọnu 230 tó wà ninu ewu àìsàn náà .
Ṣugbọn ẹ mọ pe nnkan ti awa ontaja epo aladani ba ra naa ni a maa ta.
mo wá rí gbogbo iṣẹ́ Ọlọrun pé, kò sí ẹni tí ó lè rí ìdí iṣẹ́ tí ó ń ṣe láyé.
Arisitakọsi, ẹlẹ́wọ̀n, ẹlẹgbẹ́ mi ki yín, ati Maku, ìbátan Banaba.
Gbé e sílẹ̀ lóde aṣọ títa tí ó wà lẹ́bàá àpótí ẹ̀rí, lọ́gangan iwájú ìtẹ́ àánú tí ó wà lókè àpótí ẹ̀rí náà, níbi tí n óo ti máa ba yín pàdé.
Lasaru tí ó ń ṣàìsàn jẹ́ arakunrin Maria yìí.
n óo fún ọ ní ọgbọ́n ati ìmọ̀; n óo sì fún ọ ní ọrọ̀, nǹkan ìní, ati ọlá, irú èyí tí ọba kankan ninu àwọn tí wọ́n ti jẹ ṣiwaju rẹ kò tíì ní rí, bẹ́ẹ̀ sì ni kò ní sí èyí tí yóo jẹ lẹ́yìn rẹ tí yóo ní irú rẹ̀.
Wọ́n ń sọ nípa rẹ pé ò ń kọ́ gbogbo àwọn Juu tí ń gbé ààrin àwọn orílẹ̀-èdè mìíràn pé kí wọ́n yapa kúrò ninu ìlànà Mose.
Afẹsun kan Taofeek Adebayo ẹni ọdun mọkandinlogun ati ojugba rẹ Toheeb Tijani ọmọ ogun ọdun ni a gbọ wi pe wọn ja obinrin meji ni ole ni Oshodi ti wọn si gba yẹti ati oruka oni goolu lọwọ wọn.
fine : adj ; ( that is a fine performance .
Igbesẹ Karun: Ti ida meji ninu mẹta awọn aṣofin ko ba buwọlu igbesẹ Kẹrin, wọn yoo da igbesẹ lati yọ Igbakeji Gomina naa duro lẹsẹkẹsẹ Amọ, ti ida meji ninu mẹta awọn aṣofin ba buwọlu igbesẹ Kẹrin naa, olori ile Aṣofin, laarin ọjọ meje, yoo kọ lẹta si Adajọ agba nipinlẹ Ondo lati gbe igbimọ kalẹ, ti yoo ṣe iwadii ẹsun ti wọn fi kan Igbakeji Gomina naa Amọ, awọn Igbimọ naa ko gbọdọ jẹ oloṣelu, oṣiṣẹ ijọba tabi aṣofin.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Mama Rainbow: iṣẹ́ tíátà kò ta sánsán mọ́ bíi ti ayé àtijọ́ O jẹ ọkan lara awọn oṣere tiata to kọkọ ṣe ere itage lori amohumaworan pẹlu awọn gbajumọ oṣere tiata miran bii Hubert Ogunde, Baba Sala, Baba Mero, Kola Ogunmola, Oyin Adejobi, ati Adeyemi Afolayan.
Baba rẹ Oloye Daniel Adekoya Awojobi,ọmọ bibi ilu Ikorodu, jẹ oga agba ni ile iṣẹ ọkọ oju irin Nigerian Railway Corporation.
Nítorí náà, OLUWA Ọlọrun ní: “Wò ó, n óo fi ogun jà yín, n óo sì pa yín run, ati eniyan ati ẹranko.
Bí wọ́n ti ń sọ̀kalẹ̀ láti orí òkè náà, Jesu pàṣẹ fún wọn pé wọn kò gbọdọ̀ ròyìn ohun tí wọ́n ti rí fún ẹnikẹ́ni títí òun, Ọmọ-Eniyan, yóo fi jí dìde kúrò ninu òkú.
OSCOTECH: Òṣìṣẹ́ mẹ́rin ilé ìwé gíga l'Oṣun gb'òmìnira lọ́wọ́ ajínigbé darandaran Fulani
N óo dúró ní gbogbo ọjọ́ làálàá mi,n óo máa retí, títí ọjọ́ ìdáǹdè mi yóo fi dé.
Ojú yóo ti gbogbo ilẹ̀ rẹ̀,òkú àwọn eniyan rẹ̀ tí ogun yóo pa,yóo wà nílẹ̀ káàkiri ìgboro.
Coronavirus: Wo ohun tí o ní láti ṣe láti dáàbò bo ara rẹ Wọ́n ti fi ọmọ orílẹ̀-èdè Italy tó kó coronavirus sílẹ̀ nílèéwòsàn Ṣé ẹ̀yin mọ idí ti Abass Akande fi n jẹ Obesere?
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Obasanjo àti Gani Adams tẹ́ mi pẹ̀lú bí wọn ṣe tahùn síra wọn - Adebanjo Buhari le sọ ipò ààrẹ́ nù tí kò bá yọjú sáwọn aṣòfin - Amòfin Ẹgbẹ́ òṣèlú alátakò takú láti gba èsì ìbò ààrẹ ní Ghana Ọ̀pọ̀ nkan tó n ṣẹlẹ̀ kò jẹ́ kí n gbàgbọ́ pé Naijiria wà ní abẹ́ ìdarí ẹnikẹ́ni - Wole Soyinka Ọmọ ẹgbẹ́ òkùnkùn ṣoro ní Ijebu Ode, ọ̀pọ̀ ẹ̀mí sọnù Ẹni akọkọ lorii ila awọn ti wọn n wa ju lori google ni aarẹ tuntun ti wọn dibo yan l'Amẹrika, Joe Biden, lẹyin naa ni Rema ati Naira Marley tẹle e.
Australia: Igbe ayekòótọ́ sàànfàní, ó kó olówó rẹ̀ yọ lọ́wọ́ ikú gbígbóná
Ile Asofin ni ipinlẹ Kwara ti pasẹ pe ki wọn gba ilẹ ti wọn n pe ni 'Ile Arugbo' pada lọwọ Aarẹ Ile Igbimọ Asofin tẹlẹri, Bukola Saraki.
Bakan naa lo jẹ ẹbun Pepsi Fresh your mix, to si pese miliọnu kan naira ati irinajo lọ si Dubai fun ayẹyẹ Africa Music Fest, ati ipese Pepsi ati Aquafina fun odindin ọdun kan.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ballon D'or 2018: Modric jáwé olú borí, Ronaldo, Messi fìdí r'ẹmi 3 Ọ̀pẹ̀̀ 2018 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 4 Ọ̀pẹ̀̀ 2018 Oríṣun àwòrán, FRANCK FIFE Agbabọọlu aarin gbungbun papa Luka Modric to jẹ ọmọ orilẹede Croatia ló gba àmì ẹ̀yẹ Ballon D'or fun ọdun 2018 lẹ́yìn tí Lionel Messi àti Cristiano Ronaldo.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ẹ̀yin ọ̀dọ́ ti rí èrè ìwọ̀de yín lórí EndSARS àmọ́ ẹ ṣọ́ra, kẹ má baà sọ èrè náá nù - Tinubu Owó ìrànwọ́ Covid-19 dé, ìjọba fẹ́ san ₦75bn fún 54,000 olókoòwò Ìjọba ìpínlẹ̀ Eko ti iléèwé pa nítorí ìwọ́de #EndSARS Ìrẹ̀wẹ̀sì ń bá wa torí ìdánwò NECO tẹ ń ṣún síwájú lọ́pọ̀ ìgbà - Akẹ́kọ̀ọ́, ọ̀gá iléèwé Agbára ìgbìmọ̀ ìdájọ tí mo gbé kàlẹ̀ yóò dé ọ̀dọ̀ àwón ólọ́pàá tó ti kúrò lẹ́nu iṣẹ́ tẹ́lẹ̀- Sanwo Olu Wo àwọn orílẹ̀èdè míràn tó ń fojú winá ìwọ́de bíi ti ENDSARS Mo fura pé ẹ fẹ́ da Nàíjíríà rú, ń kò ṣe ìwọ́de mọ́ - Segalink, agbátẹrù ìwọ́de yọwọ́ Aarẹ ana ni Naijiria naa ni o le ni ida ọgọta ninu ọgọrun awọn eeyan Naijiria ti ọjọ ori wọn ko to ọdun marundinlogoji, ti wọn si n fi oju sọna fun igbe aye to dara amọ ti wọn n jijagudu pẹlu eto ẹkọ lọwọ.
“Sí Dariusi ọba, kí ọba ó pẹ́.
Seyi Makinde ati Adari Ile Asofin Ipinlẹ Ọyọ, Adebo Ogundoyin lo fi tọwọtọwọ ki Abdusalami Abubakar kaabọ si ipinlẹ naa.
Nígbà tí o bá parí iye ọjọ́ yìí, o óo fi ẹ̀gbẹ́ rẹ ọ̀tún lélẹ̀, o óo sì fi ogoji ọjọ́ ru ìjìyà ẹ̀ṣẹ̀ ilé Juda; ọjọ́ kọ̀ọ̀kan tí o óo fi dùbúlẹ̀ dúró fún ọdún kọ̀ọ̀kan tí wọ́n fi dẹ́ṣẹ̀.
O fidi rẹ mulẹ pe, ko din ni ọlọpaa meji toun lee fidi rẹ mulẹ pe wọn dagbere faye lati ipasẹ awọn ikọlu to waye yika ilu Eko naa.
Baba náà bá mú wọn lọ sí ilé rẹ̀, ó fún àwọn kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ wọn ní koríko.
O wa ni ẹka NADC to jẹ ti Mobile Air Defence Team (MADT) ni MAKIA nipinlẹ Kano.
Nigeria Swearing in 2019:Olókoòwò tó dáńtọ́ ni gómìnà Ogun tuntun
Ọkàn mi ń ṣe hílàhílo bí ẹyẹ aláàpáǹdẹ̀dẹ̀ ati ẹyẹ àkọ̀,mò ń ké igbe arò bí àdàbà.
Ẹ wò ó, n óo pàṣẹ, n óo sì kó wọn pada sí ìlú yìí, wọn yóo gbógun tì í, wọn yóo gbà á; wọn yóo sì dáná sun ún.
ti bẹrẹ ni pẹrẹu ni awon ibudo idibo kan ni Oturkpo  ni ipinle Benue  ni arin gbungbun orile ede Naijiria.
Yomi darukọ pe Iyabo Ojo akẹgbẹ wọn naa ti da si ọrọ naa ṣaaju to ba wọn sọrọ.
 ni pe gbogbo olori orile ede kookan ni lati ji dide si ise to ye ni sise, nipa gbigbe awon igbese akoni laifigbakan bokan ninu ki ile Afrika le ba egbe pe lagbaye.
Mo mọ pe o tan mọ Watford amọ ọmọ ilu wa ni baba ati baba baba rẹ ati babaa babaa babaa rẹ.
Bawọn kan ti ṣe n ba aarẹ Trump daro lawọn miran n sọrọ kobakungbe si.
"Bẹẹ wọn jẹ ko di mimọ pe oṣuṣu ọwọ kan ṣoṣo ni ẹgbẹ YWC labẹ idari Ọjọgbọn Banji Akintoye ati pe ""a gboriyin fun igboya ati ọkan ire ti Akintoye ni si mimu ayipada ba iran Yoruba lagbaye""."
Eniyan burúkú kò ní ní àṣẹlórí ilẹ̀ àwọn olódodo,kí àwọn olódodo má baà dáwọ́ lé ibi.
Yohanna Saidu to jẹ́ osisẹ́ ileesẹ́ to n rì sí ọ̀rọ̀ awọn igbó ẹran ati olusó agba nigbo ẹran Gashaka Gumti sọ pe ibi ta le fi safiwe ẹwà igbo ẹran ọhun nilẹ̀ Afrika ko to nnkan.
Ọjọ́ meje ni mo fi wà pẹlu wọn, tí mo jókòó tì wọ́n, tí mò ń wò wọ́n tìyanu-tìyanu.
O ni deede aago mejila oru ni wọn gunlẹ si aafin oun lati kọlu oun, ori ogiri aafin si ni oun ati olori oun meji gba salọ.
dari rẹ lọ si ile-ise to n mojuto eto ijoba , ni eyi ti o wa ni ofisi akọwe
Àwọn yìí kò mutí yó bí ẹ ti rò, nítorí ó ṣẹ̀ṣẹ̀ di agogo mẹsan-an òwúrọ̀ ni.
Ní ọjọ́ kan, ní nǹkan agogo mẹta ọ̀sán, ó rí ìran kan.
Ó ti ṣe ohun ìtìjú ní Israẹli.
Ó rọ gbogbo ará ìlú láti fọkàn bálẹ̀ àti pé ìjọba yóò ṣe ìwádìí ọ̀rọ̀ náà lẹ́kùnrẹ́rẹ́.
Lati ibe ni wọ́n ti se ifilọ́ọ́lẹ̀ ọsẹ́ sise to fi mọ́ jiju ado oloro ni orilẹ̀ede Niger, Chad ati Cameroon.
Àwọn àṣá yóo péjọ sibẹ,olukuluku wọn, pẹlu ekeji rẹ̀.
O dàbi pé ìdániloju to pọju fún Liverpool ninu ifẹsẹwọnsẹ yìí lo fa ìdí ti wọn fi fid rẹmi pátápata.
Lara awọn to kọkọ ki ẹbi naa ku oriire ni baba iya ọmọ, alagba Thomas Markle.
Amọ Ajagbo ti ge ègún pe aarẹ ọna Kakanfo kankan ko gbọdọ ko ogun ja ilu naa laelae.
Òun náà ṣe ohun tí ó burú lójú OLUWA, ó tẹ̀lé ìwà ẹ̀ṣẹ̀ àwọn baba ńlá rẹ̀.
Oríṣun àwòrán, @GovKaduna Bakan naa ni wọn tun ni awọn se akiyesi awọn alẹnulọrọ lati ilẹ okeere, ti wọn n lọwọ ninu isẹlẹ yii, ti wọn si kesi gbogbo ọmọ Naijiria lati foju sọri, paapaa awọn ọdọ.
June 12: Ìtàn bí Alhaja Kudirat Abiola ṣe dojúkọ ohun t'ọ́kùnrin kò leè dojúkọ fún ìjọba àwaarawa
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ibadan expressway: Àwọn olè Fulani ló ń jí ènìyàn, pànìyàn ní òpópópónà!
Abayomi Semako Koroto Hunye -O yege Ipinlẹ Kwara1) Mal.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, The seed: Àwa sì wá láti mú ẹ̀bùn fún Ọba tí a bí lónìí Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ọdọọdun ni gbogbo ẹlẹsin Kristẹni lagbaye ma n parapọ lati se ayẹyẹ Ọjọ ibi Jesu Kristi.
Ẹní ọmọ ọdún Mẹ́tàdínláàdọ́run ní ààrẹ Shagari wọ ilú Abuja lọjọ́ Iṣegun lẹ́yìn ti ilera rẹ̀ bẹ̀rẹ̀ sí ní mẹ́hẹ, sùgbọn to jẹ́ Ọlọ́run nípè lálẹ́ ọ́jọ́ Jimoh Gomina Aminu Tambuwal ló gba òkú ààrẹ nígbàkan rí ní pápákọ̀ òfurufú Sultan Abubakar láti gbe lọ ilú rẹ̀ Shagari níbi tó ti wọ káà ilẹ̀ sùn.
Fayemi fojú Alufa to fipa bá ọmọde lòpọ̀ síta l'Ekiti El-Zakzaky: Arúfin ni ijọba Muhammadu Buhari gan-an - Ladoja Àwọn òṣìṣẹ́ fásitì yóò fi ìyanṣẹ́lódì ṣẹ Nàìjíríà lọ́wọ́ lọ́jọ́ Ajé Wàhálà bẹ́ sílẹ̀ láàrín àwọn ọ̀dọ́ ní Oke Odo ní ìpínlẹ̀ Eko Alukoro ileeṣẹ ọlọpaa ni ipinlẹ Eko, Bala Elkana to ba ikọ BBC news sọrọ ṣalaye pe wọn ti da ikọ ọlọpaa kogberegbe kan si agbegbe naa to pana wahala ọhun.
Ní òru náà, ó mú wọn, ó wẹ ọgbẹ́ wọn.
Nítorí oriṣa lásánlàsàn, wọn sọ èmi Ọlọrun di òjòwú;wọn sì ti fi àwọn ère wọn mú mi bínú.
Wilder ti inagijẹ rẹ n jẹ Bronze Bomber sọ pe oun yoo bẹrẹ igbaradi kete ti oun ba ti gbadun tan.
Bo tilẹ jẹ pe o kọ lati da ẹbi naa le iṣẹlẹ ọjọ Abamẹta ti wn ti dumbu awọn agbẹ onirẹsi ni Koshebe lori.
Gomina fi kun ọrọ rẹ pe laipẹ ni wọn yoo tun ti eyi to wa ni Agidingbi, ti wọn o si ko awọn alaarun naa lọ si ibudo nla tuntun IndoCentre, ti wọn ṣẹṣẹ kọ si adugbo Anthony.
Ń ko roo ní ẹẹmeji tí mo fi sọ fun pé owó ìṣẹ wa wọ́n pupọ.
Lassa: Ẹnikan ku,ogoji mii wa labẹ ayẹwo l'Ọsun
O kere tan, akọroyin marundinlọgọrun lo padanu ẹmi wọn lẹnu iṣẹ lọdun to kọja lẹnu, gẹgẹ bii ajọ awọn akọroyin lagbayee (IFJ) ṣe sọ.
Egbe naa tun pinnu pe awon yoo so fun awon osise eleto ilera to wa ni ipinle ati ijoba ibile lati darapo mo iyanselodi  naa, ti ijoba ba ko lati da won lohun leyin ose meji .
Fani Kayode ninu lẹta naa ni bi oun ṣe fẹran tilẹ jẹ iwa rẹ lo mu ki oun sa fun un nitori imọtara ẹni nikan n ba ja.
Yóo sì ti ìka bọ inú ẹ̀jẹ̀ náà, yóo wọ́n ọn sílẹ̀ nígbà meje níwájú OLUWA, níwájú aṣọ ìbòjú tí ó wà níbi mímọ́.
Oríṣun àwòrán, others Àkọlé àwòrán, Toyin poora lẹyin to figbe ta nipa ifipabanilopo loju opo Twitter - ka ohun ta mọ nipa iku rẹ Oríṣun àwòrán, @virgingrltoyin/twitter Àkọlé àwòrán, Toyin poora lẹyin to figbe ta nipa ifipabanilopo loju opo Twitter - ka ohun ta mọ nipa iku rẹ Ijọba Naijiria ti pe fun iwaadi ẹkunrẹrẹ lori iku Toyin Awọn alasẹ Naijiria ko foju kere isẹlẹ iku Toyin yi.
Wọn jare wa,'' Osinbajo lo sọ bẹẹ.
Iheanacho ẹlẹ́sẹ̀ ayò tún ti dábírà Èmi kò ní kí Shiite má ṣe ẹ̀sìn won o -Muhammadu Buhari 'Nàìjíríà, ṣọ́ra, ogun ń sọ ilé ọlá di ahoro!
Wọ́n jáde kúrò ninu ibojì lẹ́yìn tí Jesu ti jí dìde, wọ́n wọ Jerusalẹmu lọ, ọpọlọpọ eniyan ni ó rí wọn.
Ṣé ìwọ mọ odò adágún Adó Àwáyè tí kò ní òpin ní ìsàlẹ̀?
Nítorí àwọn ohun tí wọn ń ṣe níkọ̀kọ̀ tilẹ̀ ti eniyan lójú láti sọ.
Good luck fish: Ààrẹ Zambia ṣ'èdárò Ẹja akóredé tó papòdà
pẹlu gbogbo àwọn ìletò tí ó yí àwọn ìlú ńláńlá wọnyi ká títí dé Baalati Beeri, (tí wọ́n ń pè ní Rama) tí ó wà ní Nẹgẹbu ní ìhà gúsù.
Igbó Olódùmarè jìnnà gidigidi, ó to ìrìn ọjọ́ méjì gbáko sí ìlú wa.
Mose kó ìpín ti OLUWA fún Eleasari alufaa gẹ́gẹ́ bí OLUWA ti pàṣẹ fún un.
Ààrẹ Muhammadu Buhari sọ ọ̀rọ̀ yìí lẹ́yìn ìkéde ikú arábìnrin Winnie Mandela ní ọjọ́ ajé.
Ola Aina, àwọn akẹgbẹ́ rẹ̀ bá BBC sọ̀rọ̀ lórí owó àjẹmọ́nú wọn Ààrẹ fi nǹkan ọkùnrin rẹ̀ pa mí lójú, kó tó fipá bámi lòpọ̀ - Ọmọge Arẹwà Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Kayefi BBC Yorùba: Bàbá ọmọ, Mọ́ṣúárì, Ọlọ́pàá kẹ́jọ́ rò nípa òkú ọmọ tó pòórá Baru fi kun pe alága tuntun yóò bẹ̀rẹ̀ iṣẹ́ ni wàrànsesà.
Daura varsity: Amaechi ní ọ̀fẹ́ ni China yóò kọ́ fásítì $50M ètò ìrìnnà sí Daura ìlú Ààrẹ Buhari
Lara awọn ọmọ ilẹ Yoruba to tun sọrọ ni Ọjọgbọn Banji Akintoye.
” Ó mú kí ìdámẹ́ta omi korò, ọ̀pọ̀ eniyan ni ó sì kú nítorí oró tí ó wà ninu omi.
Oríṣun àwòrán, Toye Arulogun Snr/Facebook Àkọlé àwòrán, Ayefẹlẹ ko sọ fun ijọba ipinlẹ Ọyọ̀ pe oun yoo lo 'Music House' fun ileeṣẹ redio nigba to fẹ gba iwe aṣẹ lati kọ ọ Ati pe ki i se nkan ti Yinka Ayefẹlẹ sọ pe oun fẹ fi ile naa ṣe nigba to fẹ ẹ gba iwe aṣẹ lo fi ṣe.
Ajọ NERC ni ipin meji lawọn onibara ileeṣẹ mọna-mọna bayii: awọn to lo ina gan an ati awọn ti ko lo ina pupọ.
Ní ọdún kinni ìjọba Kirusi, ọba Pasia, OLUWA mú ohun tí ó ti sọ láti ẹnu wolii Jeremaya ṣẹ.
” Èmi OLUWA àwọn ọmọ ogun yóo wá dáhùn pé, “Wọ́n lè máa kọ́ ọ, ṣugbọn n óo tún máa wó o lulẹ̀ títí tí àwọn eniyan yóo fi máa pè wọ́n ní orílẹ̀-èdè burúkú, àwọn ẹni tí OLUWA bínú sí títí lae.
Wọn nná owó ti ọgọrun enia lè ná ni ọdún kan ni alẹ́ ọjọ́ kan lai ronú ọ̀pọ̀ aláìní ni orílẹ̀ èdè wọn, ti Bàbá wọn ti fa ijiyà fún lati kó ọrọ̀ ti wọn nná dànù jọ.
Ghana ní kò gbọdọ̀ sí ìsìn mọ́ láwọn ṣọ́ọ́ṣì àti mọ́ṣálásí fún ọ̀sẹ̀ mẹ́rin Oríṣun àwòrán, Others Ijọba Ghana gbe ilẹkun gbogbo ileẹkọ tipa lati dekun itankalẹ Coronavirus Kaka ki ewe agbọn arun asekupani Coronavirus dẹ, ko ko ko lo n le si jakejado agbaye, to si ti n kan si ilẹ Afirika pẹlu.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù June 12: Àwọn tó ṣojú wọn kòró sọ irírí ọjọ́ náà 16 Òkùdu 2020 Àkọlé àwòrán, Ọlọ́run ló ní kí Abacha kú, àwọn àgbà Yorùbá púpò kò bá ṣòfò- Dele Momodu Awọn ti iṣẹlẹ June 12 ṣoju wọn ti bu ẹnu atẹ lu bi ijọba ologun to wa nigba naa lọhun ṣe fi ẹtọ ọpọ ọmọ Naijiria dun wọn.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Àgbà ni Obasanjo, oun tó ń sọ yé e, ìjọba ni kó tají - Wale oke Awọn Iroyin ti ẹ le nifẹ si Ìtàn tó wà nídi òwe ‘Sebótimọ Ẹlẹ́wà Sàpọ́n’ Ìtàn tó rọ̀ mọ́ òwe ‘aṣọ kò bá Ọ́mọ́yẹ mọ́.
jo kopa ninu iko kan naa seyin.
Amọ ṣaa, ọwọ pada tẹ ọkan lara awọn adigunjale naa nibi ti iṣẹlẹ naa ti waye.
Nígbà tí àwọn ọmọ onílẹ̀ bá fẹ́ rú ẹbọ sísun, tí ó jẹ́ òórùn dídùn sí OLUWA, wọn óo tẹ̀lé ìlànà yìí.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Coronavirus ti di ara wa, kò le è kúrò mọ láéláé - WHO Coronavirus ti di ara wa, kò le è kúrò mọ láéláé - WHO Ṣé ìwọ leè wa kẹ̀kẹ́ lórí ìgò?
Oun lo si rọ ọ loye lẹyin ti igbimọ oluwadii sọ pe o jẹbi ẹsun naa.
Mo ti búra pé n óo fún àwọn baba yín, ilẹ̀ náà yóo sì di ohun ìní yín.
"Oríṣun àwòrán, @SegunAde88 Nigba to n salaye idi ti eyi fi ri bẹẹ, Garba Shehu tii se oludamọran agba si aarẹ lori eto iroyin ni ""ko si idi fun aarẹ lati lọ si Auno, abẹwo aarẹ si ni lati bawọn eeyan ipinlẹ Borno lapapọ kẹdun nipa ajalu to ba wọn."
Ó ṣe é ṣe kí o ti ní coronavirus kí ó má mọ̀ nítorí pé ó kò rí àpẹẹrẹ Èyí ni àwọn tí òfin kónílé-ó-gbélé tí ààrẹ Buhari pa l'áṣẹ kò kàn ní Eko, Ogun àti Abuja Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Sogidi Lake: Kòṣẹja-kòṣèèyàn lá bá nínú adágún odò náà -Ojedele Bẹ ẹ ni awọn kan n sọ pe nkankan lo jabọ lati oju ofurufu to si fa a.
 Ó dé ẹnu iṣẹ ́ ní ọjọ ́ kẹwá oṣù kárùnún ọdún 2019 ( june 10 , 2019 ) .
Nígbà tí Jesu gbọ́, ẹnu yà á, ó sọ fún àwọn tí ó ń tẹ̀lé e pé, “Mo fẹ́ kí ẹ mọ̀ dájúdájú pé, n kò rí irú igbagbọ báyìí ní Israẹli pàápàá!
S Abdulsalm gba pe ki wọn gba oniduro fun ọkun rin naa pẹlu ẹgbrun lọna ẹẹdẹgbẹta naira gẹgẹ bi owo itanran, pẹlu oniduro meji.
 Awon meta ni won ti doloogbe ni Ebonyin ti eni kan ti Kogi.
"Sunday Igboho yarí, ó fohùn ránsẹ́ sáwọn èèyàn tó ń pẹ̀gàn rẹ̀ ""Ni kete ti wọn ta awọn ọlọpaa SARS lolobo ni wọn ya bo adugbo naa, ti ọwọ si tẹ afurasi adigunjale mẹrin."
Bẹ́ẹ̀ ni àwọn eniyan Israẹli ṣe, tí wọ́n sì fi kó ohun ọ̀ṣọ́ àwọn ará Ijipti lọ.
sun ijiroro lori eto isuna odun 2019 siwaju sii ni igba keji .
Ikọlu Dapchi: Awọn akẹkọ pada sile lẹyin ipade pẹlu Buhari
Ṣugbọn ìwọ, OLUWA Ọlọrun mi,o mú ẹ̀mí mi jáde láti inú ibú náà.
Ki ifẹsẹwọnsẹ naa to wọ isinmi fun saa akọkọ ni Lacazette, atamatase Arsenal da ọka pada ninu rẹ.
Ibeere: Njẹ eyi ti ṣe anfani fun awọn araalu?
Oríṣun àwòrán, Aisha buhari ''A ko mọ ẹni ti yoo bori lọtẹ yi nipa ipo First Lady, nitori nnkan ti Aisha loun fẹ ree'' O salaye pe, ọrọ ọọfisi 'First Lady' ohun gan tẹlẹ dabi arumọjẹ nitori ''kii ṣe wi pe nnkan ti Aisha n ṣe gẹgẹ bi Iyawo aarẹ, Wife of the President, yatọ si nkan ti ẹni to jẹ 'First Lady' n ṣe'' Abdulaziz pari ọrọ rẹ pe ''orukọ lasan ni wọn fẹ yii pada, ko si iyatọ'' Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Àbẹ̀wò ààrẹ Buhari sí ìpínlẹ̀ náà láti fi dá àwọn ará ìlú lójú pé àbò wà kò sì tíì dáwọ́ ìkọlù yìí dúró.
Aarẹ Morsi Mohammed wa ni atimọle lati igba ti ẹjọ naa ti bẹrẹ .
Ifẹsẹwọnsẹ naa waye laisi ero iworan.
Mo bẹrẹ si ni pe wọn lọkọọkan.
Ọkọ̀ ẹrù mẹfa ati akọ mààlúù mejila.
Ó gbé ẹbọ sísun ojoojumọ kúrò lọ́dọ̀ rẹ̀, ó sì gba ibi mímọ́ rẹ̀.
Àwọn arakunrin Jesu sọ fún un pé, “Kúrò níhìn-ín kí o lọ sí Judia, kí àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ lè rí iṣẹ́ tí ò ń ṣe, 
"Ki lo de to jẹ pe ẹya ni ""Federal Character n gbajumọ, lai fi ti awọn to mọ iṣẹ naa ṣe si."
Bi ẹ ko ba gbagbe, Sunday Shodipẹ ti kọkọ jẹwọ pe oun loun pa Barakat, Grace, Azeezat atawọn meji miran ki ọwọ ọlọpaa to tẹẹ to si tun sa lahamọ.
 Gomina wa fi asiko naa ro gomina tuntun ohun lati meti
Bi awọn ipinlẹ to ni Coronavirus ni Ọjọ Abamẹta ṣe lọ ree: Eko-39 FCT-22 Kaduna-19 Oyo-7 Ebonyi-6 Edo-3 Katsina-1 Ekiti-1 Bauchi-1 Nasarawa-1 Ajọ to n gbogun ti ajakalẹ arun lorilẹede Naijiria, NCDC ti kede pe eeyan 162 miran ti lugbadi arun Covid-19 ni Naijiria.
Paulu tún bi wọ́n pé, “Ìrìbọmi ti ta ni ẹ ṣe?
Adìẹ díndín ni wọ́n ń tà níbẹ̀.
Bẹ́ẹ̀ ló ṣe fọ Jerusalẹmu ati Juda mọ́ tónítóní.
Ewu to wa ninu igbẹ yiya nita gbangba A na ọwọ ibeere yi si onimo isegun ilera ayika ẹni, Dokita Olajire Olanrewaju, to si salaye fun ileese BBC Yoruba wi pe, ewu nla lo wa ninu ki awọn ara ilu ma yagbẹ sita gbangba.
Ìbá sàn fún un bí a kò bá bí i.
Awọn iṣẹẹ rẹ bii October 1, CEO ati bẹẹ bẹẹ lọ ti gba amiẹyẹ lorilẹ-ede Naijiria ati loke okun.
Ninu oṣu kọkanla ni gomina ipinlẹ naa, Abubakar Bello naa gba esi to fihan pe o lugbadi arun naa ṣugbọn ti ara rẹ ya lẹyin ọsẹ kan.
Wíwọ̀n ni o óo máa wọn omi tí o óo máa mu pẹlu; ìdá mẹfa òṣùnwọ̀n hini ni omi tí o óo máa mu ní ọjọ́ kan, ẹ̀ẹ̀kan lojumọ ni o óo sì máa mu ún.
Oríṣun àwòrán, Reuters Àkọlé àwòrán, Donald Trump, aarẹ Amẹrika ree lasiko to n wọ baalu Air Force tawọn ọmọ ogun lasiko irinajo rẹ.
Iṣẹ́ ọwọ́ rẹ̀ tọ́, ó sì tọ̀nà,gbogbo ìlànà rẹ̀ sì dájú.
Shodimu yabara labẹ akori ọrọ yi lati sọ nipa oselu to n lọ lọwọ ni Naijiria O sọ pe awọn to dantọ lati se oselu pọ ni Naijiria,bẹẹ lawọn ti ko yẹ ki wọn sunmọ oṣelu naa wa nibẹ.
Ooni Ifẹ bu ẹnu ẹ̀tẹ́ lú ètò BBNaija nítorí ó tàbùkù àsà Yoruba Ogun Àgbẹ́kọ̀yà, ẹ̀kọ́ wo ló yẹ́ kí àwá ọ̀dọ́ kọ́ níbẹ̀?
Ẹni tí kò mọ Ọlọrun a máafi ẹnu ba ti aládùúgbò rẹ̀ jẹ́,ṣugbọn nípa ìmọ̀ a máa gba olódodo sílẹ̀.
Nítorí náà, ẹ jẹ́ kí á fi ìgboyà súnmọ́ ìtẹ́ oore-ọ̀fẹ́, kí á lè rí àánú gbà, ati nípa oore-ọ̀fẹ́ rẹ̀, kí á lè rí ìrànlọ́wọ́ ní àkókò tí ó wọ̀.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Taiwo Akinkunmi, ọmọ Ibadan tó ya àsìá Naijiria Ayinla Ọmọwura, orin èébú àti oríyìn lo fi di ọ̀rẹ́ àwọ̀n obìnrin ''Wàhálà Ikẹja ló sọ mí di oníṣẹ́ ọwọ́ àgbọn ní Badagry'' Ìtàn tó rọ̀ mọ́ òwe ‘aṣọ kò bá Ọ́mọ́yẹ mọ́.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù National Grid: Ìgbà mẹ́rin ọ̀tọ̀ọ̀tọ̀ tí ìtàkùn ìpínná ní Nàìjíríà ti dákú lọ́dún 2020 30 Bélú 2020 Oríṣun àwòrán, Twitter/tcn Ọrọ idakureku itakun ina ọba pinpin lorilẹede Naijiria ti n kọ ọpọ awọn ọmọ Naijiria atawọn alẹnulọrọ lẹka naa lominu.
5 Èmi sọ fún ọ, Pétérù, èyí jẹ́ ìfẹ́-inú rere; ṣùgbọ́n àyànfẹ́ mi nfẹ́ pé kí òun lè ṣe púpọ̀ síi, tàbí iṣẹ́ tí ó tóbi síbẹ̀ lààrin àwọn ènìyàn ju èyí tí ó ti ṣe ṣíwájú.
Ǹkan pàtàkì ni oyún, ayọ̀ púpọ̀ sì ni ó ń fún ni tí ènìyàn bá ní oyún ní àsìkò tí ò tọ́, àti àsìkò tí ó yẹ, èyí sí ni lẹ́hìn ìgbéyàwó.
Ibadan Tailor: Ilé-ẹjọ́ dá ẹjọ́ lòdì sí ìwà ọ̀gá ọlọ́pàá sí télọ̀ rẹ̀
Ibi gbogbo là n kádìyẹ alẹ,èkúté jẹ ìdì oògùn olóró lagọ ọlọpaa ni Kenya
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ọrọ lori owo epo rọbi Orilẹede Naijiria lo ni ọrọ aje to lowo lori ju nilẹ Afirika, ṣugbọn ọpọ ọmọ orilẹede naa si n ba osi ati iṣẹ finra.
 Ohun ti o wa nile kosi ni ibamu pelu ohun ti o so rara.
Turkey ya 10,000 eeyan sọtọ: Idi ni pe ko din ni ẹgbẹrun mẹwa arinrinajo ẹsin to de lati orilẹ-ede Saudi Arabia l'opin ọsẹ ti wọn ti ya sọtọ bayii ni Turkey, eniyan mẹjọ lo si ti ni arun Coronavirus lorilẹede naa bayii.
Fadele Adu: Kwara la gbà wọlé láti Germany
Orile-ede Canada lo gbalejo idije akọkọ, sugbọn USA lo gba ife ẹyẹ naa l'ọdun 2002.
Nítorí náà ni wọ́n ṣe ń pe ibẹ̀ ní Bama títí di òní.
baba tún fa mọ ́ lúbi mìíràn yọ .
Kì í ṣe èmi nìkan ni mo fẹ́ràn rẹ̀, ati gbogbo àwọn tí wọ́n mọ òtítọ́ ni; 
Bí kò bárí ẹmọ́, ó máa ń ta rọ́bà rẹ̀ lu aláǹgbá bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé kò sí ẹbọ tó fẹ́ fi í rú.
Lónìí, àwọn akẹ́kọ̀ọ́ ń lo ọdún mẹ́rin, ilé pọ̀ lọ bẹẹrẹ fún iló wọn.
”Gbogbo àwọn ọmọ Israẹli bá pada lọ sí ilé wọn, 
Ìgbà míràn niyi lẹ́yìn èyí tó ṣẹ́lẹ̀ lọ́dun 2002, tí Kelly yoo kojú ẹsùn mọ́kànlélógùn tó fi mọ sísàfihan àworàn ìhòhò àwọn ọmọ kéèkéé, ti ọmọ kan nínú wọn si jẹ́ ọmọ kékeré Sùgbọ́n àṣẹ̀yìn wá àṣẹ̀yìn bọ, adájọ nígbà náà sọ pé, kò si àrídájú pé ọmọ tó wà nínú fọ́nran ti wọn gbé yọjú sílẹ̀ ẹjọ jẹ ọmọ kékéré.
Ami ayo mẹta lo jẹ ninu marun un ti Chelsea gba wọ ile Dynamo.
Lara awon loba-loba, ti o kopa nibi ipade apero naa ni: Sultan ilu Sokoto,  Alhaji Yahaya Abubakar, ti o oun naa wa lara alaga igbimo loba-loba, Obi ilu Onitsha, Igwe Nnaemeka Achebe ati Emir ilu Kano, Muhammadu Sanusi II.
Ẹ óo ká ọwọ́ lérí ninígbà tí ẹ óo bá jáde níbẹ̀.
Dokita Mamora rọ ajọ NIMC lati ronu ọna miiran ti wọn fi le maa ṣe iforukọsilẹ fawọn eeyan lọna ti ero ko fi ni maa pọ to bi wọn ṣe n pọ bayii.
Ati alẹ ọjọ Abamẹta lo ti dabi pe nnkan ko ni ṣenu ire fun Erica lẹyin iwa to wu ninu ile naa, eyii to jẹ igba kẹta rẹ.
Bi o tilẹ jẹ wi pe ijọba ipinlẹ Ogun ninu atẹjade kan ti olubadamọran fun gomina ipinlẹ Ogun lori ọrọ Ẹkọ alakọbẹrẹ ati girama, arabinrin Ronkẹ Soyọmbọ ṣalaye pe o di dandan fun awọn akẹkọ lati pese iwe ẹri ayẹwo COVID-19 wọn ki wọn to gbawọn si ileewe paapaajulọ awọn to ba wa ni ileegbe lawọn ileewe naa.
Oríṣun àwòrán, @CREVO360_NG Àkọlé àwòrán, Adajọ agba Naijiria, Walter Onnoghen Igbimọ iṣedajọ yi labẹ ofin ni Naijiria lo lagbara lati jiroro tabi paṣẹ, lẹyin agbeyẹwọ ẹri, yiyọ adajọ kankan kuro nipo titi to fi de ori adajọ agba orile-ede Naijiria.
Lọdun 2017,a lo ọdọ awọn ẹbi rẹ a si san ẹgbẹrun lọna ọọdunrun din diẹ gẹgẹ bi owo ori ati awọn nkan miran ti wọn gba.
Oríṣun àwòrán, veeQtor Kaakiri ibi iwọde ni awọn ọdọ ti ṣe ohun iyalẹnu kan pẹlu bi wọn ti ṣe n ko panti lẹyin ti wọn ṣe iwọde tan.
tele, ipinle Cross River ko ni fayegba karakata egbogi oloro ati awon olupese
O ni ibẹru rẹ naa kuku ye oun, nitori pe ibaṣepọ to wa laarin Alaafin ilu Oyo ati awọn eniyan Isalẹ Oyo nilu naa, ko dan mọran lasiko naa.
”Àwọn nǹkan pupọ wà tí kì í ní ìtẹ́lọ́rùn,wọ́n pọ̀ tí nǹkan kìí tó:
5% láti 5% lẹ́yìn tí ààrẹ Buhari buwọ́lu àbá ètò ìnáwó Amotekun: Kí ni iṣẹ́ tí Amotekun yóò máa ṣe gangan?
Simoni ni baba Aminoni, Rina, Benhanani ati Tiloni.
Àkọlé àwòrán, Aarẹ Buhari Pataki rẹ julọ fun iran Yoruba ati awọn ọmọ Naijiria lapapọ to ṣi ranti iṣẹlẹ ọjọ kejila oṣu kẹfa ọdun 1993 ni pe ọjọ naa lọhun ni ti ibo waye ni NAijiria.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Fayẹmi bá BBC sọ̀rọ̀ ní kété tó di gómìnà Ekiti Ṣugbọn awọn aṣofin ọmọ ẹgbẹ oṣelu PDP to wa ni ijoko naa bẹnu atẹ lu igbesẹ yii, bo tilẹ jẹ pe abẹnugan ile , Adeniran Agbada fi ontẹ lu ipinnu ile naa, bo ṣe sọ wipe awọn alaga ọhun ṣe aṣeju ni owo nina wọn.
Ẹ jẹ́ kí á sin Ọlọrun bí ó ti yẹ pẹlu ọ̀wọ̀ ati ẹ̀rù; 
Gege bi akonimoogba agba Chelsea, Antonio Conte: “Ninu ifigagbaga mejeeji, a n so nipa agbaboolu ti o darajulo lagbaye, Lionel Messi ni o ta yo julo, tio si mu iyanto wa ninu ifesewonse ohun.
Mo fẹ́ kí ẹ mọ̀ pé wọ́n ti dá Timoti, arakunrin wa, sílẹ̀: ó ti jáde lẹ́wọ̀n.
Ọ̀kan lára ẹni tí a fi ẹ̀sùn kàn, Zeyar Lwin, sọ pé:
Ọlọrun bá sọ fún Noa pé, “Mo ti pinnu láti pa gbogbo ẹ̀dá alààyè run, nítorí ìwà ipá wọn ti gba gbogbo ayé, àtàwọn àtayé ni n óo parun.
MManifesto (Iwe ipolongo) : Eyi ni iwe to kun fun
Aare Nana Akufo-Addo, eni ti o gori alefa lodun to koja , ti so pe, o n lo bi bilionu marun-un owo dollars ni o wole sapo ijoba nipa tita goolu si United Arab Emirates.
Khadijat ni awakọ̀ Bàálù àkọ́kọ́ láti Ọffa
Oríṣun àwòrán, others Oríṣun àwòrán, others Oríṣun àwòrán, others Deji Akure pàṣẹ kí wọ́n ti gbogbo ọjà pa fún ọjọ́ méjì, ohun tó fàá nìyí Làásìgbò òṣèlú wáyé nílùú Ondo, ọ̀pọ̀ èèyàn fara pa Kí ni ọkùnrin yìí ṣe tí bàbá rẹ̀ fi só mọ́lẹ̀ fún ọgbọ̀n ọdún?
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù CBN: owó oníbara tó ha si ATM kò gbọdọ kója wákàtí 24 31 Sẹ́rẹ́ 2018 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 18 Owewe 2018 Oríṣun àwòrán, AFP Àkọlé àwòrán, CBN: owó oníbara tó ha si ATM ò gbọdọ kója wákàtí 24 Ilé ìfowópamọ ìjọba àpapọ (CBN) tí gbé ofin tuntun jáde lóri ìfówórànṣẹ́ láti ilé ìfowópamọ kan sí ìkejì.
"Lai si ile igbọnsẹ, ọranyan ni fun awọn eeyan lati wa ibi ti wọn yoo tura si; ita gbangba si ni ọna abayọ niru ipenija bẹẹ, eleyi si lee fa ọpọ arun bii igbẹ gbuuru, ọnigbameji tabi iba pọnju-pọntọ Ọga agba UNICEF naa ṣalaye pe, ""ẹgbẹrun mejilelọgọfa awọn ọmọ orilẹ-ede Naijiria, ninu eyi ti ẹgbẹ mẹtadinlaadọrun ti jẹ ọmọ wẹwẹ, ni aisan igbẹ gbuuru n ran lọ sọrun lọdọọdun; bẹẹ ni biliọnu marundinlẹẹdẹgbẹta naira ni orilẹ-ede Naijiria n padanu lọdun nitori aisi imọtoto to yẹ""."
Laipẹ yii ni iyawo gomina ipinlẹ Ọyọ nigba kan, Florence Ajimobi sọ ninu fidio kan pe ọpọ igba ni oun ti dari ji ọkọ oun, Abiola Ajimobi, fun ẹsẹ agbere.
O wa gboriyin fun àjọ eleto idibo lori isẹ takuntakun to ṣe lori eto idibo ni Edo.
Ṣùgbọ ́ n láyé òde òní , tíátà ṣíṣe ti gba ìgbà ọ ̀ tun , tí à ń se sínú fánrán fún àgbéléwò àwọn ènìyàn fún ìgbádùn .
Fayoṣe tí lahùn, ó dá APC lóhùn pé.
nítorí tèmi ni gbogbo àwọn àkọ́bí.
 augustine the blessed ) , je amoye ati onimo oro-olorun omo beriberi to gbe aye re ni igberiko afrika ile romu .
O sọ eyi nigba ti ọrọ Boko Haram ti n gbẹbọ lọwọ Orilẹ-ede Naijiria, Chad, Niger ati Cameroon.
Ewe, omobinrin afesona re ohun je omo oloogbe Shadrack Rwakairu ati iyaafin Peace Ruhindi, eleyi ti ogbeni Mbabazi gba to lati igba ti awon obi re mejeeji ti je olorun ni pe.
Mohammad Hussain, to n gbe ni ilẹ Canada pinu lati ṣe ọdun Keresi pẹlu awọn akẹgbẹ rẹ meji kan nitori isede to de wọn mọle.
Iṣẹlẹ yii mu ki awọn agbofinro mu Pasitọ ijọ Sotitobire, Alfa Babatunde, ti wọn si fi ẹsun kan oun ati awọn ọmọ ijọ rẹ bi i mẹrin, pe wọn mọ nipa bi ọmọ naa ṣe sọnu.
Mugabe kò le rìn mọ́ Àwọn àwòrán ìṣẹ̀lẹ̀ tó làmìlaaka láti ilẹ̀ Áfríkà l'ose tó kọjá Ohun ti iroyin yi tumọ si ni pe o ti jawọ ninu erongba rẹ lati du ipo fun saa karun un.
2010 (ipo kẹta) Benguela Nigeria 1-0 Algeria Algeria ni ko jẹ ki Naijiria pegede lati lọ fun idije ifẹ ẹyẹ agbaye lọdun 1982 nigba ti wọn na Super Eagles mọle.
Àwọn ará Bẹnjamini wí fún ara wọn pé, “A tún ti tú wọn ká bíi ti iṣaaju.
Wọ́n bá jáde sí ojú ọ̀nà kan.
Isho Pepper: Isola Ogunsola pẹ̀lú àfihàn àwọn ìyàwó tó jẹ́ igi lẹ́yìn ọgbà fun un nínú iṣẹ́ tíátà
Bẹ́ẹ̀ ni ó ṣe parí kíkọ́ ilé náà.
Oríṣun àwòrán, AFP Ọrọ di iṣu ata yan an yan an ni alẹ Ọjọru pẹlu ibọn yinyin ati ile fifọ Eyi ni aṣalẹ keji ti awọn eeyan to n fi ẹhonu han lori bi awọn ọlọpaa kan ṣe ṣekupa George Floyd.
Ja'afar Mahmud Adam: Gbaju-gbaja onimọ ẹsin Islam ni, o si lo pupọ ninu igbesi aye rẹ ni ilu Kano.
Wọn kì í sinmi tọ̀sán-tòru, wọ́n ń wí pé,“Mímọ́!
Ẹ̀ ń rú àwọn ẹbọ yín, ẹ sì ń fi àwọn ọmọkunrin yín rú ẹbọ sísun, ẹ sì ti fi oriṣa bíbọ ba ara yín jẹ́ títí di òní.
Ṣugbọn àwọn aguntan kò gbọ́ ti wọn.
Olóbó ti ta wá wípé oníròyìn fún Unionradionet Luis Carlos Díaz, ti wà nínú àtìmọ́lé agbófinró Ìlú.
Igbimọ to n ṣe konkaari aṣuwọn ilu ni ile aṣofin naa lo ranṣẹ pe Fayoṣe o.
Kọ́ ilé lọ́nà àìtọ́, ko rẹ́wọ̀n he - Buhari Ilé ẹjọ́ dajọ ikú fun ọkunrin tó pa olólùfẹ́ rẹ̀ Kíni ìdí ti wọn fi ń lọ ọmú obinrin Oluwadare fí kún pé ẹka eto ìdajọ náà tún jẹ ohun to yani lẹnu bí wọn ṣe ri pé ìdá ti ohun náà ko kìí ṣe kèrèmí rárá.
Bẹ́ẹ̀ ni ìwà ènìyàn ni ìgbẹ̀yìn rẹ̀, ẹni tí ó bá soore fún ọmọnikejì rẹ̀ ń gbin eso ìwà sílẹ̀ bẹ́ẹ̀ ni ọjọ́ tí ó bá máa ká èso ìwà, ojú ìkà ènìyàn yóò máa pọ́n kankan.
bíbélì jé ọ ̀ rọ ̀ olọ ́ run tí a ti ọwọ ̣ ́ awọn ènìyàn mímọ ́ kọ .
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Sport Betting: Idí rèé tí àwọn ọ̀dọ́ kan fi n ta tẹ́tẹ́.
Àwọn kan ninu àwọn baálé baálé fi ọ̀kẹ́ kan (20,000) òṣùnwọ̀n diramu wúrà sí ilé ìṣúra ati ẹgbọkanla (2,200) òṣùnwọ̀n mina fadaka.
Iru asiri to tu sita yii mi ilu titi, to si le pin orile-ede si yẹlẹ yẹlẹ, amọ ohun ti ijọba lee ṣe ni ko ṣẹ pe irọ ni ọrọ naa pẹlu ẹri to daju, tabi ko ṣe eto atunto.
Sẹnatọ Ekwunife ni, òun gbé àbá ọhun wá síwájú ilé, láti rọ ìjọba àpapọ̀ pé kò sún ifilọlẹ ẹ̀rọ alatagba 5G ọhun síwájú títí tí yóò fi parí ìwádìí rẹ, lọ́nà àti fi dá àwọn ọmọ Nàìjíríà lójú pé, ààbò tó péye wà fún wọn.
Nígbà tí wọ́n ti waasu ìyìn rere ní Pega, wọ́n lọ sébùúté ní Atalia.
ile-ise naa lati fowowewo pelu ajo to n mojuto papako ofurufu ijoba apapo lorile-ede
   Babangida wa ro iko Super Eagles lati ri daju pe, won jawe olubori ninu ifesewonse kinni in won pelu orile-ede Croatia, ti won ba fe tesiwaju ninu idije naa.
N lo si ibi ikolu naa saaju abewo ajo ohun ti n se Organisation for the Prohibition of Chemical Weapons (OPCW) international watchdog, lati lo foju finle ki igbimo ohun o to de.
Iwe iroyin New Zealand Herald ti saaju ni ọkan lara awọn to yinbọn naa jẹ ọmọ orileede Australia ti o si kọ apilẹkọ eleyi ti o fi erongba rẹ si.
Ile ẹjọ ti ni ki ọkùnrin kan, Chibuzor Eleke tí ó sọ wí pé ọwọ òun ni ọmọ tí wọn jì gbé ní ilé ìjọsìn Sotitobire ni ilu Àkúré.
Oríṣun àwòrán, @queenola2/Instagram Àkọlé àwòrán, Olori Badirat Ọlaitan Adeyẹmi tó bí ìbejì ọkùnrin nínú oṣù Kẹta.
Nigba ti owo ṣi ni iyi lo ti bẹrẹ to jẹ wi pe ati san aadọta naira pere gun awọn eniyan lara ṣugbọn o jẹ ki awọn eeyan mọ iyi owo ti wọn n san nigba naa lati wa fi wo awọn ẹfẹ rẹ.
Nígbà tí OLUWA bá dá ire àwọn eniyan rẹ̀ pada,Jakọbu yóo yọ̀, inú Israẹli yóo sì dùn.
Àwọn kan ń sọ pé, “Eniyan rere ni.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ayinla Kollington: ọ̀rẹ́ ni èmí àti Barrister kó tó jáde láyé Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Àìsàn jẹ́ kí àwọ̀ ara Amida dàbí ara ẹja Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Ajọ to n mojuto ajakalẹ aarun ni Naijiria, NCDC, ti kede pe awọn to ti ni aarun coronavirus ni Naijiria ti pe 9,302 bayii.
” Ó bá sọ ibẹ̀ ní Mahanaimu.
Nítorí pé Nebukadinesari, ọba Babiloni ń pète ibi si yín,ó ti pinnu ibi si yín.
Gomina Fayose ni ohun to ku ti awọn ọms orilẹede Naijiria fẹ mọ bayii ni ẹkunrẹrẹ iroyin nipa awọn dukia ti ajọ EFCC ti gba dipo ariwo gee nitori gẹgẹbi o se sọ, 'pupọ awọn dukia yii ni wọn ti ta ti wọn ṣi tun ti tun ta.
4 25368 Orilẹede Congo 628 0.
Awọn ẹgbẹ Muslim Brotherhood ni wọn fa Morsi kalẹ gẹgẹ bii oludije fun ipo aarẹ ninu idibo ọdun 2012 ni Egypt.
Àìmọ̀kan ló mú mi hu ìwà tí mo hù kọjá sẹ́yìn, Jonathan dárí jì mí - Dino Melaye Ìdí tí àwọn ìpińlẹ̀ se ń ti ilé ẹ̀kọ́ ni ìhà ìríwá-ìwọ̀-oòrun Nàìjíríà Ìròyìn ayọ̀!
Jesu wọ ọkọ̀ ojú omi kan, àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ sì tẹ̀lé e.
Ibinu àwọn aninilára kò ní dé ọ̀dọ̀ rẹ mọ́.
Rohr so pe, erongba oun ni lati mo bi won se n kopa si, bi okan won se n mi si loorekoore, bi won se n sare lotun losi si abbl.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Iran ti jáwọ nínú ìlù ogun tó n lù -Trump 8 Sẹ́rẹ́ 2020 Àkọlé àwòrán, Iran ti jáwọ nínú ìlù ogun tó n lù -Trump Ààrẹ orílẹ̀-èdè Amẹrika ni o jọ bi ẹni pe Iran ti jáwọ nínú ìlù ogun tó n lu lẹ́yin ti o ju àdá olóro si ibudo ikọ ọmọ ogun ilẹ Amẹrika ni Iraq.
Alaye ti ile isẹ iroyin orileede Rwanda kan sọ wi pe ọrilẹẹde mẹtadinlọgbọn lo fọwọ si karakata lai si idiwọ laarin awọn orilẹẹde.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Wòlíì Àrólé sọ àsọtẹ́lẹ̀ s'áyé BBC ní London 12) Mr Real - Legbẹgbẹ Eyi jẹ ọkan lara awọn orin to sọ ipede ṣakuṣaku di gbajugbaja ni Naijri alọdun 2018.
"Àbájáde ìwádìí náà lọ báyìí, pé  Wọ́n rọ epo kúnú ọkọ òfurufú náà lọ́jọ́ kẹtàdínlógún, oṣù kẹjọ, ọdún, 2020, wọ́n ẹnjínì rẹ̀ ṣiṣẹ́ fún ìṣẹ́jú mẹ́wàá fún àyẹ̀wò, bákan náà ni wọ́n tún wàá wò fún ogún ìṣẹ́jú ní ìlú Port Harcourt"" Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Abule Ado explosion: Irọ́ ńlá ní NNPC pa lórí ìbúghbàmù Abule Ado níbí tí ẹ̀mí èèyàn 23 Wákàtí mẹ́tà àti ìṣẹ́ju mẹ́ẹ̀dógún ni ẹlikapítà náà le farada iṣẹ́ mọ, sùgbọ́n ó ìrìnàjò wákàti méjì àti iṣẹ́jú mọ́runlélógójì ni wọn rán."
Alága àjọ tó n rísí àwọn ọmọ Nàìjíríà lókè òkun Abike Dabiri-Erewa ló fìdí ọ̀rọ̀ náà múlẹ̀ lórí àtẹ̀jíṣẹ́ twitter rẹ̀ @abikedabiri Ohun mẹ́fà tí àgbáyé kò mọ̀ nípa Majek Fashek tó d'olóògbé nìyí Wo àwọn ìjọba ìbílẹ̀ 20 tí àrùn coronavirus pọ̀ sí jùlọ ní Nàìjíríà Ọwọ́ bàtá Auxiliary tó ń ró ní àrójù, leè ya láìpẹ́ - Ìjọba Oyo dúnkookò Èsì àyẹ̀wò òkú George Floyd tí ẹbí rẹ̀ ṣe fihàn pé ó kú lẹ́yìn tí wọ́n fẹsẹ̀ fún un lọ́rùn Ẹ̀wẹ̀ ọ̀pọ̀ àwọn ọmọ Nàìjíríà ló ti ń fèrò wọ́n hàn lórí ìgbẹ́sẹ̀ ilé iṣẹ́ ọlọ́pàáb ní àsìkò yìí Mo sunkún nígbà tí mo rí ẹ̀jẹ̀ nílẹ̀ ní sọ́ọ̀ṣì tí wọ́n pa ọ̀mọ mi sí- Bàbá Uwa, akẹ́kọ̀ọ́ fásitì tí wọ́n fipábálòpọ̀ Justice for Uwa: Bàbá Uwa, akẹ́kọ̀ọ́ fásitì tí wọ́n fipábálòpọ̀ ní Benin bá BBC sọ̀rọ̀ lórí bí wọ́n ṣe pa mọ rẹ̀ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Justice for Uwa: Bàbá Uwa, akẹ́kọ̀ọ́ fásitì tí wọ́n fipábálòpọ̀ ní Benin bá BBC sọ̀rọ̀ Baba arabinrin akẹkọọ ti awọn eeyan kan fipabalop ti wn si tun ṣekupa ni ilu Benin ti ṣalaye fun BBC News pe ibanuj ti ko lẹlgbẹ ni o ba oun pẹlu iku mbinrin naa.
"Sinima naa ti akọle rẹ n jẹ ""No time to Die"" ni wọn sun si Oṣu Kọkanla ọdun 2020 dipo Oṣu Kẹrin."
Ẹ̀yin ọkunrin nìkan ni kí ẹ lọ sin OLUWA; nítorí pé bẹ́ẹ̀ gan-an ni ẹ fẹ́ àbí?
Àwọn ọmọ Lefi wẹ ara wọn mọ́ kúrò ninu ẹ̀ṣẹ̀, wọ́n sì fọ aṣọ wọn.
Oríṣun àwòrán, PoliceNG Oyeyemi sọ pe, ni kete ti awọn ri iwe ehonu yii ni awọn ọtẹlẹmuyẹ ileesẹ ọlọpaa Ajuwon, labẹ ọga wọn DPO Andrew Akinseye, bẹrẹ iwadii nipa ayederu agbẹjọro naa.
Arákùnrin tó 'jíǹde' ní mọ́ṣúárì tí kú Amẹrika ti yọ àfikún owó Físà kúrò fún arìnrìnàjò Nàìjíríà Iyawo gomina ipinlẹ Ekiti, to tun jẹ alejo pataki nibi idanilẹkọ naa, Erelu Bisi Fayemi mẹnuba ojuṣe awọn aya gomina nipa idagbasoke awujọ.
Wo gbèsè tí Nàìjíríà ti jẹ láàrin ọdún 2015 sí 2019 EFCC ti ri mílíọ̀nù 65.
 Iwa-ipa Fulani darandaran: ọlọpa fi panpẹ ọba mu eniyan meji Fayose: Awọn darandaran to pa Tunde ko ni lọ lai jẹjọ Nigbati o n gba awọn agbẹ ati awọn olori igberiko ni imọran lati daabobo ara wọn kuro lọwọ ipaniyan awọn darandaran, Soyinka sọ pe ijafara lewu, ati pe awọn eniyan ko gbọdọ duro ki awọn darandaran gb'ẹmi wọn ki Naijiria to bẹrẹ iṣẹ lati dena ipaniyan bayi.
Ṣugbọn ẹ̀yin ọmọ Israẹli ti hu ìwà aiṣododo sí i,ẹ kò sì yẹ ní ẹni tí à bá máa pè ní ọmọ rẹ̀ mọ́,nítorí àbùkù yín;ẹ̀yin ìran ọlọ̀tẹ̀ ati ẹlẹ́ṣẹ̀ yìí.
"W) sọ pé: ""Kò sí ijọ tí Ọlọrun máa ń yọ àwọn eeyan kúrò nínú ọmọ iná bíi ọjọ Arafa"" Aawẹ ọjọ Arafa maa n pa ẹsẹ rẹ: Gbígba ààwẹ lọjọ Arafa máa ń pa ẹṣẹ oṣù méjì rẹ, gẹgẹ bí Anabi (S."
Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Fídíò, Akomolede àti Asa lórí BBC Yorùbá: Mọ̀ síi nípa ẹ̀kún ìyàwó níbí3 Bélú 2020 US presidential election 2020: Ta a ni Joe Biden tó ń díje fún ipò aárẹ America4 Bélú 2020 Electricity new tariff: ''Àjọ NERC ti fún Disco láṣẹ láti padà sí owó tàríìfù tuntun iná mọ̀nàmọ́ná''2 Bélú 2020 Fídíò, Soyinka Cancer: Àṣe ara mi ni iso ti n run gbogbo bí mo ṣe n ṣèrànwọ́ lórí jẹjẹrẹ27 Bélú 2019 Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Banki agbaye ni Ọjọgbọn Ngozi Okonjo-Iweala ti n ṣiṣẹ ki aarẹ Oluṣẹgun Ọbasanjọ to pe e wa sile wa ṣe minisita fun eto iṣuna lorilẹede Naijiriaoun ni obinrin akskọ ti yoo ṣe minisita fun eto iṣuna ati minisita fun ọrọ ilẹ okeere lorilẹede Naijiria.
Ogun yii ṣe pataki nitori pe ohun ni ogun akọkọ yika Naijiria ninu eyi tawọn mẹkunnu to jẹ agbẹ, ti kọju oro sijọba.
Saulu dáhùn pé, “OLUWA yóo bukun yín nítorí pé ẹ káàánú mi.
Joseph Knight gba àwọn ohun tí Joseph Smith kéde gbọ́ nípa níní àwọn àwo Ìwé Ti Mómónì ní ìkáwọ́ rẹ̀, àti ìṣẹ́ ìtumọ́ tí ó nlọ lọ́wọ́ nígbànáà, òun sì ti fi ọ̀pọ̀ ìgbà ṣe àtìlẹ́hìn fún Joseph Smith àti akọ̀wé rẹ̀, èyí tí ó mú kí ó ṣẽṣe fún wọn láti tẹ̀ síwájú nínú ìtumọ̀.
Àwọn òpópónà àti títì kékeré nìkan ni òfin gba kẹ̀kẹ́ Marwa láàyè àti rìn.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ekiti: Àwọn ọmọ ilé ìgbìmọ̀ aṣòfin yọ abẹnugan ilé 11 Ọ̀wàrà 2018 Àkọlé àwòrán, Ilé ìgbìmọ̀ aṣòfin Ekiti yọ Abenugan rẹ̀ Àwọn ọmọ ilé ìgbìmọ aṣòfin ìpínlẹ̀ Ekiti tí yẹ àga nídìí abẹnugan ilé ìgbìmọ Aṣofin ìpínlẹ̀ Ekiti, Kolawole Oluwawole àti igbákejì rẹ Ṣina Animasahun.
Orúkọ ìyá rẹ̀ ni Jeruṣa, ọmọ Sadoku.
Àwọn mìíràn ninu wọn ré odò Jọdani kọjá sí agbègbè Gadi ati Gileadi.
Àkókò fífọ́n òkúta ká wà, àkókò kíkó òkúta jọ sì wà;àkókò ìkónimọ́ra wà, àkókò àìkónimọ́ra sì wà.
houses) ni abule Korok, ti o si sekupa egberun lona mewa maluu.
Foreign Secretary: Gboingboin ni a wà lẹ́yìn Nàìjíríà lórí ìgbógun ti Boko Haram
Nigeria 2019 budget: Ààrẹ Muhammadu Buhari buwọ́lu owó ìṣúná ọdún 2019
Ajọ tó ń gbógun ti ìwá àjẹbánu àti gbigbọ́ ẹ̀sun ara ìlú ní ìpínlẹ̀ Kano, ló fẹ̀sún kan Emir tí wọn si dábàá pé kí Emir lo rọ́kun nílé.
Tinubu ni ti atunto ba de ba bi wọn se n pin owo to n wọle nilẹ yii, nipa ṣiṣe amulo awọn ohun alumọọni wa bo se yẹ, ọrọ aje wa yoo tubọ gbooro si.
Oga agba ile eko giga Fafiti ilu Ibadan, Ojogbon Idowu
Ajo to n mojuto boolu afesegba lorile-ede Spain ti yan akonimoogba iko agbaboolu Barcelona tele ri, Luis Enrique gege bi akonimoogba agba iko agbaboolu orile-ede naa.
Ilé ẹjọ́ - BBC News Yorùbá BBC News, YorùbáFò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Buhari vs Atiku: Ẹni tó bá kàwé leè di Ààrẹ, dandan kọ́ ni ìwé ẹ̀rí - Ilé ẹjọ́ 15 Bélú 2019 Oríṣun àwòrán, @ogbetakome Ile ẹjọ to ga julọ lorilẹ-ede Naijiria ti sọ pe, Aarẹ Muhammadu Buhari yẹ lati dije sipo Aarẹ orilẹ-ede yii, lo jẹ ki oun da ẹjọ Atiku Abubakar nu.
Ìyàwò lárìnlọọ̀dù mi pè mí ní akálòlò ni mo ṣe paa - Afurasí Nínú gbèsè Nàíjíríà, ₦121,000 ló kàn ẹnìkọ̀ọ̀kan, ṣó o ṣetán láti san tìẹ?
Ni bayii, ajo WHO ti n gbero lati pin abere ajesara eyi ti yoo dena arun asekupani ohun ki o to tan kakaakiri, bakan naa si ni, o hun ti o tun le je ipenija ni, ibi ti o tutu ti won yoo ko abere ajesara naa pamo si, eleyi ti ina monamona ko se deede ninu ilu naa.
Ọ̀rọ̀ kékeré lẹ pè é, díẹ̀ ló kù kí obìnrin náà fọ́ mi lórí, ṣe lorí ń ta mí fòò bí mo ti ń sọ̀rọ̀ yìí, ṣùgbọ́n kò yà mí lẹ́nu, bẹ́ẹ̀ ni ìyá rẹ̀ ń fọ̀ bàbá rẹ̀ lórí tí wọ́n fi sí ẹ̀wọ̀n, ìdílé fọ́rífọ́rí ni ìdílé wọn.
Ayekofẹnifọrọ: Ó yá, ẹ fi àmì sórí ọ̀rọ̀ náà.
Ó fi ìrù gbá ìdámẹ́ta àwọn ìràwọ̀ ojú ọ̀run, wọ́n bá jábọ́ sórí ilẹ̀ ayé.
Ìròyìn sọ́ di mímọ̀ pé, àwọn márùndínláàdọ́fà ọmọ egbẹ́ náà ni àwọn ọlọ́pàá mú ní ọjọ́ kérìndínlógún osù kẹrin.
Bí ẹnikẹ́ni bá gbé òkú wọn, kí ó fọ aṣọ rẹ̀, yóo sì jẹ́ aláìmọ́ títí di ìrọ̀lẹ́; ohun àìmọ́ ni wọ́n jẹ́ fun yín.
" Ọ ̀ rọ ̀ wa dàbíi "" ẹni tí ófi àdá pa ìkún , ikún sálọ àda tún sọnù "" ."
Àwọn kan ń káàkiri ninu aṣálẹ̀,wọn kò sì rí ọ̀nà dé ìlú tí wọ́n lè máa gbé.
Alufaa yóo tún yẹ ohun èlò tí àrùn náà ràn mọ́ wò lẹ́yìn tí wọ́n bá ti fọ̀ ọ́.
Ìgbà tí ó ṣe ṣa, ó ki  kùkùté lọ̀rùn mọ̀lẹ̀ ó gbe e sókè ni reti pé kí ọwọ́ òun rí àyè ba kùkùté lẹ́sẹ̀, kí ó da orí rẹ̀ kodò, kí ó na orí rẹ̀ mọ́ òkúta kàbitì kan, ṣùgbọ́n nígbà tí o ń gbé kùkùté lọ sí òkè, kí ó tó kọja ibi abẹ́yá rẹ̀, kùkùté lọ ẹsẹ̀ mọ́ ọ ni ibi ẹ̀yìn, o fa ẹbọra náà létì, ó lọ́ ọ dáadáa, ẹbòra yìí bá ke bí màlúù, ṣùgbọ́n Oníbodè pàtẹ́wa pé kí wọ́n ddáwọ́ dúd’ro, o sì bá kùkùté wí pé tí ó ba tún ṣe bẹ́ẹ̀ lẹ́ẹ̀kan sí òun ó wí pé ẹbọra ṣẹ́gun, n;itor;i pé ìjàkadì láṣán ni a wí pé kí kùkùté jà.
Atamatase omo orile-ede Egypt, ti o tun n kopa fun iko agbaboolu Liverpool ninu idije ile geesi, EPL, Mohamed Salah ti ta yo laarin awon akegbe re yooku lati gba ami eye agbaboolu nnu idije ile geesi ti o darajulo ti a mo si, PFA player of the year lojo Aiku(Sunday).
Nígbà tí Usaya kú, wọ́n sin ín sí itẹ́ àwọn ọba, wọn kò sin ín sinu ibojì àwọn ọba, nítorí wọ́n ní, “Adẹ́tẹ̀ ni.
Wúrà yín ati fadaka yín ti dógùn-ún.
Wo ohun tí Adájọ́ ṣe sí àṣùwọ̀n ìfowópamọ́sí Wòlíì Sotitobire Iléẹjọ́ mú ọjọ́ kejìdínlógún, oṣù kọkànlá fún ìgbẹ́jọ́ àwọn tó jí ìbejì Àáfà Akeugbagold ní Ibadan Ajínigbé kọlu òṣìṣẹ́ FRSC, èèyàn méjì kú, mẹ́rin farapa, mẹ́wàá di àwátì Àwọn tó jí mi gbé ti fẹ́ẹ̀ pa mí, kí àwọn ọlọ́pàá tó dóòlà mi - Agbẹjọ́rò Bisola Ajayi RCCG: Pásítọ̀ Adeboye ṣáájú ìwọ́de àdúrà CAN lòdí sí ìpànìyàn ní Nàìjíríà Awọn ọlọpaa sọ pe ni nkan bi aago mọkanla, alẹ Satide ni wọn wọ inu ile rẹ, ti wọn si gbe e salọ.
Ẹ máa takété sí ohunkohun tí ó bá burú.
Igbimọ naa ni awọn orilẹede bi China, Iran, South Korea, Germany, Italy, United States, United Kingdom, Switzerland, Norway, Netherlands, Spain, France ati Japan ko ṣee rinrin ajo lọ lasiko yii nitori coronavirus.
Dafidi fi àwọn wọnyi ṣe alákòóso ẹgbẹ́ akọrin ninu ilé OLUWA lẹ́yìn tí wọn ti gbé Àpótí Majẹmu OLUWA sibẹ; 
 wọ ́ n ń gbádùn láyé ; wọn ń gbádùn lọ ́ run .
Yala ni Ọwọ ni, Akurẹ ni, opopona ilIfẹ/ Ijẹsa ni titi lọ de agbegbe Ibrapa ati Ijẹbu ni ipinlẹ ogun ni ọrọ ko ti yatọ 'Aláàfin mọ̀ sí àwọn olóyè tí mo yàn' Orílẹ́-èdè 5 tí takọ-tabo kò gbọdọ̀ fẹnu ko ara wọn lẹ́nu Falz f'ohùn lẹ̀ fún PDP, APC, MURIC, àwọn ọmọ Yahoo Alaafin ni lẹyin ifikuluku ati ijiroro pẹlawọn agbaagba ati majẹobajẹ ilẹ Yoruba, o han gbangba pe inu hilahilo lawọn eeyan n gbe bayii nitori awọn kọlọransi yii ti wọn n fipa ba aya lo niwaju ọkọ, ti wọn si tun n ba nnkan ọgbin jẹ pẹlu oniruru iwa familete n tutọ miran.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ondo: Dejí sun ọmọ méje àtagbalagba meji mọ́lé nítorí pé ó ń bínú Ẹhonu awọn akẹkọọ naa ni pe aikun oju iwọn awọn oṣiṣẹ to wa ni ileewosan ileewe naa lo ṣokunfa iku akẹgbẹ wọn ọhun.
O ni: Mo maa n fi imu gboorun iso Naira Marley nitori mo fẹran rẹ gan an.
Ilé aṣòfin àgbà ní ìyàtọ̀ wà láàrín gbèsè ti Buhari àti Jonathan jẹ Atẹjade kan ti alukoro ẹgbẹ oṣelu PDP ni ipinlẹ Ọyọ, Akeem Ọlatunji fi sita ṣalaye pe irọ ni gbogbo awọn to ba n sọ pe gomina Makinde n fi oju tẹmbẹlu ipo aarẹ n pa.
Lójú òpó Twitter, iriwisi loriṣiiriṣii ní wọn tí n sọ ti ọpọ sí dá lórí pe ki ọkọ epo ma rìn lójú ọsán mọ.
Amofin Adebayọsọ pe wọn ni agbara lati yọ ọ ni ipo aarẹ, to ba kuna lati farahan niwaju wọn, pẹlu ibo ìdá meji ninu mẹta apapọ wọn.
Àwọn eniyan náà ṣe gẹ́gẹ́ bí OLUWA ti pa á láṣẹ fun wọn.
Èmi a máa ṣe gbogbo nǹkan wọnyi nítorí ti ìyìn rere, kí n lè ní ìpín ninu ibukun rẹ̀.
26 Nítorínáà, fi pamọ́ sí inú ọkàn rẹ títí di ìgbà náà tí, nínú ọgbọ́n mi, ìwọ yíò fi jáde lọ.
Ngige ni iṣẹ́ n lọ lọ́wọ́ lórí ǹkan ti ASUU n bèèrè Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Yorùbá gbà pé òrìṣà bí ìyá kò sí!
Mohammed Gomina Bala Mohammed ti ipinlẹ Bauchi ni iha ila oorun ariwa orilẹede naa ti gba esi ayẹwo to fi han pe o lugbadi Covid-19 ninu oṣu kẹta ọdun 2020.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Sunday Igboho: Mo fẹ́ jẹ́ ọ̀kan lára àwọn tó jà fún ilẹ̀ Yoruba 12 Sẹ́rẹ́ 2021 Oríṣun àwòrán, Instagram/sunday_igboho1 Oloye Sunday Adeyemo, ti ọpọ eeyan mọ si Sunday Igboho ti ke si awọn ọmọ Yoruba lati ṣe sisẹ fun isọkan ilẹ Yoruba Igboho lo kede bẹẹ ninu fidio kan to ṣẹyọ nibi ayẹyẹ ti wọn ti ṣe ami ẹyẹ ami ẹyẹ fawọn ogo ọmọ Yoruba, to waye niluu Ibadan.
Ṣugbon o fidi rẹmi, lẹyin naa lo gba ile ẹjọ lọ pe, oun ni o yẹ ki INEC kede gẹgẹ bi ẹni to jawe olubori, ni eyi ti ile ẹjọ to n ṣegbẹjọ ọrọ naa ni bẹẹkọAjímọ̀bí lè pe Ọlọ́run lẹ́jọ́ bí ìdájó kò bá tẹ́ ẹ lọ́rùn -Kọla Balogun .
A ṣe àkọsílẹ̀ àwọn ìtàn wọ̀nyí, dà á kọ sílẹ̀ sínú ìwé, àti ìtúmọ̀ ìtàn sí àwọn èdè orílẹ̀ Thailand, Laos, àti Cambodia kí ó tó kan ẹ̀da ti èdè Gẹ̀ẹ́sì.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Premier League: Man City fìyà jẹ Cardiff láti padà sókè téńté 4 Ìgbé 2019 Oríṣun àwòrán, Twitter/Man City FC Àkọlé àwòrán, Idije Premier League Manchester CIty ti pade sipo kinni ninu idije Premier League lẹyin ti wọn fiya jẹ Cardiff City pẹlu ami ayo meji sodo.
O ni awọn ileesẹ to ba tun tete san owo ori wọn saaju ọgbọn ọjọ, osu kẹsan an a tun ri ẹdinwo ida mẹẹdọgbọn gba sii.
Amọ ninu gbogbo awọn ọlọla ti iwe atẹjade Forbes Billionaire gbe jade, awọn obinrin mejilelaadọrin lo ti di ọlọla ni pase isẹ ọwọ wọn, eleyii ti ko waye lati bi ọdun mẹrindinlọgọta sẹhin.
Ni Port Moresby ni won ti n pese afefe gaasi ti won n ko ranse si oke okun lati inu oko oju omi nlanla.
Lásìkò tí Ezuruke tó jẹ́ olóri ìlú náà ń ṣàlàyè ìṣẹ̀lẹ̀ abúrú ọ̀hún o ní ó hàn gbangba pé èèfí gẹnẹretọ̀ tó ń ṣiṣẹ́ títí di ààrọ ọjọ ajé ní nígbà ti wọ́n fi tipátipá ṣí ìlẹ̀kùn, àwọn kan ti jẹ́ ọlọrun nípè.
 A o le rin a ò lé rimu mi, a o le wọṣọ, a lé lọ si ilé ijo, ọlọpaáà to yẹ ko dáàbò bò wá àwọn gan-an ló ń fipá báwa lòpọ, a fẹ ki àwọn ọmọ Naijiria mọ pe ẹ̀tọ́ obinrin náà ni ẹ̀tọ́ ọmọniyan, kò sí ìyàtọ ninu gbogbo ẹni to ń rin ni títì Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Ọrọ yii jẹ jade nigba ti gomina naa pe ipade awọn lọba lọba, igbimọ awọn alaga ijọba ibilẹ, ati awọn igbimọ idagbasoke ilu to fi mọ awọn alufaa.
Kebbi àti Taraba ko ti ẹ gba ki ẹnikẹni wọle si tabi jade kuro ni ipinlẹ naa.
Ó mú ọ̀kan ninu àwọn ìdílé ọba, ó bá a dá majẹmu, ó sì mú kí ó búra.
Ọ̀pọ̀ àwọn ìlú ni ẹ̀kún omi ti dé ba pẹ̀lú, tó sì tí ṣí ọ̀pọ̀ nídìí kúrò ní ìbùgbé wọn pẹ̀lú gbogbo èrè oko wọn, bákan náà ní àjọ náà ni kí àwọn ènìyàn ṣì máa reti ẹkún omi ní Nàìjíríà ní àwọn ọ̀sẹ̀ tó ń bọ̀ Awọn ìpínlẹ̀ méjìlá ti ọ̀rọ̀ náà kàn ní Niger, Kwara, Benue, Kogi, Adamawa, Taraba, Kebbi Bayelsa, Edo, Anambra, Rivers àti Delta.
Agba Amofin lorilẹede Naijiria(SAN ) ni Ọba Ọlagbẹgi darapọ mọ awọn baba nla rẹ ni Ọjọ kẹtadinlogun, Osu Kẹrin, ọdun 2019.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Wọ́n fi ikú Tunde Braimoh dá wa lóró ni o - Ẹbí pariwo Ẹ̀yin ọmọ ìta tó ní Funke Akindele ra ilé fún mi, irọ́ ni o - Ajirebi Ìtàn ayé Henry Fajemirokun, olówó tó fi owó mọ Olúwa àti ènìyàn Báwo ni Coronavirus ṣe n tànkálẹ̀ l'Afrika?
Awọn eeyan naa n ṣe iṣẹ takuntakun lati ri pe ko si idọti Kankan lojuko ti iwọde ti n waye.
ti Jonathan ko, ni eyi ti awon opolopo eniyan lorile ede yii ati ni oke-okun wa nibe.
Àwọn tí wọ́n wà lẹ́yìn ìdílé Saulu, ati àwọn tí wọ́n wà lẹ́yìn ìdílé Dafidi bá ara wọn jagun fún ìgbà pípẹ́.
Orilẹ-ede Ghana lo maa gbalejo ti ọdun 2023.
Kí ló dé tí o fi ń wo ẹ̀ẹ́rún igi tí ó wà lójú arakunrin rẹ, nígbà tí o kò ṣe akiyesi ìtì igi tí ó wà lójú ìwọ alára?
Ṣé bí ó ti yẹ kí ó fi ibi san ire fún mi nìyí.
" Oyemade ni iyi ati ẹyẹ ti awọn eeyan fi n ki ohun ni agọ naa lo jẹ ki oun tete ri iyawo oun yọ ninu ahamọ ti wọn fi si.
Lẹ́yìn ọdún mẹta, OLUWA dáhùn pé, “Bí Aisaya, iranṣẹ mi, ti rìn ní ìhòòhò tí kò sì wọ bàtà fún ọdún mẹta yìí, jẹ́ àmì ohun tí yóo ṣẹlẹ̀ sí ilẹ̀ Ijipti ati ilẹ̀ Kuṣi: 
Ó ra páànù ìgàn méjìlá ní ọ̀dọ̀ kékeréowó.
Ìdí rẹ̀ ni pé ara yín kò lè gba ọ̀rọ̀ mi.
6 Ìgbé 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 7 Ìgbé 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Onimọ kan nipa ayipada oju ọjọ, Ọmọwe Adepẹlumi Abraham sọ pe ooru to ju boṣeyẹ lọ ni awọn ọmọ Naijiria n koju lasiko yii.
Sugbon ose meji seyin ti o ye ki igbimo naa sepade po lati fenuko jabo ipade naa fun ijoba apapo, minisita to n mojuto oro awon osise ati ipese ise, dokita Chris Ngige, so pe ijoba tun nilo asiko die lati jo jiroro si ki won o fenuko lori owo ti yoo gun owo osu ohun.
Wo ibùdó arẹwà tí ọ̀pọ̀ èrò ń ya lọ ní Abuja Olólùfẹ́ mi ṣèèsì fi ọkọ́ gbá mi sí gọ́tà, mo rò pé ọlọ́jọ́ dé ni - Iya Osogbo Ẹgbẹ́ akẹ́kọ̀ọ́ gíga n‘Ibadan ṣèwọ́de lọ iléeṣẹ́ ọlọ́pàá lórí afurasí tó dàwátì Bí ìrìnàjó ààrẹ ọlọ́dún méje nílẹ̀ Mali, Keita, ṣe lọ rèé Oríṣun àwòrán, Emmanuel oloye Àkọlé àwòrán, Ìjọba orílẹẹède Niajiria ti pàṣẹ kí ẹ̀ka ìṣúná má san owó oṣù fún àwọn òṣìṣẹ́ tí kò bá gba ètò IPPIS.
Lara awọn to wa ni agbegbe naa ni awọn janduku ja ile igbe nkan pamo si naa, ti wọn si ko gbogbo awọn ohun eelo amayederun Covid-19 to wa nibẹ.
Awọn eniyan ẹ̀yà Igbo n fi sun kan ijọba orilẹede Naijiria pe wọn n dẹ́yẹ si awọn, eyi to mu ki wọn o maa ja fun idasilẹ orilẹede olominira Biafra.
Ọjọ kẹtalelogun, oṣu Kẹjọ, ọdun 2011, ni iyawo Ebenezer Obey, Ajinhinrere Juliana Obey-Fabiyi kú lẹni ọdun mẹtadinlaadọrin.
Ẹ ̀ tẹ ̀ ti ń ran àwọn ènìyàn fún àwọn ẹgbẹ ̀ rún ọdún sẹ ́ yìn .
 Kọ́ńdọ̀mù tó bẹ́ gbé iléèṣẹ́ ìjọba àti aládáni kan dé ilé ẹjọ́ Èèyàn 16 kú lẹ́yìn tí bàálù Air India já lulẹ̀ , tó sì kán sí méjì ní Kerala Àgbáríjọ àwọn nọ́ọ̀sì fẹ́ gbé Olamide Baddo lọ sílé ẹjọ́ fún ìbanilórúkọjẹ́ Inú odò ni wọ́n ti rí òkú ọmọ ọdún méjì tó sọnù l'ọ́jọ́ ọdún Eid nílùú Ibadan Iléeṣẹ́ ìjọba méjì NIPOST àti FIRS, fẹ̀dí ara wọn síta lórí Twitter Kí ló mú Olorì Badrat Ajoke kúrò ní ààfin Oyo lọ́jọ́ Iléyá?"
Nítorí èyí ni àwọn onísọ̀ ibọ̀sẹ̀ dín iye bàtà tó ju 10 lọ kù.
Àgbáríjọ àwọn nọ́ọ̀sì fẹ́ gbé Olamide Baddo lọ sílé ẹjọ́ fún ìbanilórúkọjẹ́ Ariwo ayọ̀ sọ nílé Remi Surutu, ọmọ rẹ̀ mú ọkọ wale Àgbáríjọ àwọn nọ́ọ̀sì fẹ́ gbé Olamide Baddo lọ sílé ẹjọ́ fún ìbanilórúkọjẹ́ Ọkọ kọ àwọn ọmọ méjì lé ìyàwó lọ́wọ́ nítorí ìrísí ojú wọn ní Ilorin Ka3na àti Lilo ló kọ́kọ́ dágbére fún ètò Big Brother Naija 2020 Ni nkan bi aago mẹjọ alẹ ọgbọnjọ, oṣu Keje, ọdun 2020 ni ọmọ naa di awati, ni ile wọn to wa ni adugbo Ahoyaya ni agbegbe Olodo niluu Ibadan.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Mo fara da ìsòro gan láwùjọ́ torí àwọn òbí mi di létí' Olukọni naa ti lo ọpọ ọdun ninu ẹwọn ti oun nikan wa, lẹyin ti awọn ẹlẹwọn yooku kọlu leralera.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Linda Ikeji: Gbájugbaja àkọ̀ròyìn ẹ̀rọ alátagbà bímọ tuntun 17 Owewe 2018 Oríṣun àwòrán, @official Lindaikeji Àkọlé àwòrán, Linda Ikeji: Gbájugbaja àkọ̀ròyìn ẹ̀rọ alátagbà bímọ Gbajúgbajà akọròyìn, àkọ̀wé, to tun jẹ onísowò nígbà kan rí, Linda Ikeji ti bímọ ọkunrin làntì-lanti.
o tun je ti iyaafin Aisha Buhari ( AIisha Buhari Foundation)pelu ajosepo ajo to
o ni atọkunri ati obinrin lo y ko ni suuru.
Ẹfunroye Tinubu - Ògbóǹtagí oníṣòwò, olówò ẹrú àti afọbajẹ Samuel Ajayi Crowther, òjíṣẹ́ Ọlọ́run tó gbé èdè Yoruba lárugẹ Mọrèmi Àjàṣorò, akọni obìnrin tó gba Ilé Ifẹ̀ sílẹ̀ lóko ẹrú Ọ̀rọ̀ǹpọ̀tọ̀niyùn, Aláàfin obìnrin àkọ́kọ́ rèé, tó ní nǹkan ọkùnrin Lara anfaani ti ọpọ eeyan n jẹri si pe o wa ninu bibọ Ọṣun Oṣogbo ni pe o jẹ orisa ọlọmọ, to si maa n pese ọmọ fun awsn agan tabi dahun awọn adura miran.
Ó ṣeéṣe pé ahọ́n ọ̀n mi ló ti yí padà, nítorí lóòótọ́ ni kiní ọ̀hún dùn sí mi nígbà kan rí.
Aworan atọnisọna Iye awọn to ti ni arun naa lagbaye Sunmọ aworan Àgbáyé Orilẹede Afrika Ariwa Amẹrika Apa Latin Amẹrika ati Caribbean Ilẹ Asia Ilẹ Yuroopu Agbegbe Middle East Erekusu Oceania Fihan 93418283 iye iṣẹlẹ arun naa 2000905 Iye awọn to ku Group 4 Jọwọ ṣe atunṣe ilana ikansi ayelujara rẹ lati ri ẹkunrẹrẹ rẹ Aworan n ṣafihan awọn ti ayẹwo ti fi han lorilẹede kọọkan Orisun: Johns Hopkins University atawọn ajọ eto ilera ilu Igba ti wọn kede iṣiro awọn to nii kẹyin 15 Oṣù Ṣẹ́rẹ́ 2021 20:44 WAT+3 Ẹkunrẹrẹ data Sun atẹ wa silẹ tabi oke lati ri ẹkunrẹrẹ akọsilẹ *Iye awọn to tọwọ aisan ku ni isọri eeyan ẹgbẹrun lọna ọgọrun Gbe e yẹwo: Àgbáyé Orilẹede Afrika Ariwa Amẹrika Apa Latin Amẹrika ati Caribbean Ilẹ Asia Ilẹ Yuroopu Agbegbe Middle East Erekusu Oceania Iye to ti ku Iye awọn to ku %* Apapọ awọn iṣẹlẹ arun Akọtun arun yii 0 10 100 1000 10000 ** Orilẹede Amẹrika 387741 118.
Ati pe wọn yoo ṣi iwe ọtọ silẹ fun wọn ni papakọ ofurufu ki awọn arinrinajo lati orilẹede mejeeji fi orukọ wọn silẹ ti wọ́n ba ṣe n de ki wọn lee maa foju to wọn lẹyin ayẹwo ẹlẹẹkeji.
Bí ọkunrin kan bá wà ninu yín tí ó di aláìmọ́ nítorí ohun tí ó ṣẹlẹ̀ sí i láàrin òru, kí irú ẹni bẹ́ẹ̀ jáde kúrò ninu àgọ́.
Àwòrán àwọn afurasí tí a fi léde kìí ṣe òfegè, ṣùgbọn a dọ́gbọ́n síi - Iléeṣẹ́ ọlọ́pàá Ọmọ ààrẹ Donald Trump ti kó Coronavirus Àwọn afurasí ṣá ìgbákejì kọmísọ́nà ọ̀gá ọlọ́pàá láàké dójú ikú Ṣe lóòtọ́ ní ọmọ Nàíjíríà mílíọ́nù 25 yóò má ló ìná Solar látí Dec 1, 2020?
Báwo ni ẹ ṣe lè wí pé,‘Ọlọ́gbọ́n ni wá,a sì mọ òfin OLUWA?
Ọmọbinrin náà yára lọ sí ọ̀dọ̀ ọba, ó wí pé, “Mo fẹ́ kí o fún mi ní orí Johanu Onítẹ̀bọmi kíákíá, kí wọ́n fi àwo pẹrẹsẹ gbé e wá.
Èyí mú kí ọ̀pọ̀lọpọ̀ búlọ́ọ̀gù aládàádúró ó wọ òkùnkùn.
Nipa iwadi mi, wọn wipe ko si aaye fun ẹlẹwọn nibẹ mọ, ẹnikẹni ti ba o lọ sibẹ yoo pada wale bi ẹranko.
Igbagbọ awọn ọmọ ijọ Satani ni pe eniyan, nipa ọgbọn inu rẹ, lo da gbogbo awọn ọlọrun ke ke ke.
Nítorí ó hàn gbangba pé láti inú ẹ̀yà Juda ni Oluwa wa ti wá.
Remi Oladoye, ẹni to salaye bii isẹlẹ naa se waye fun BBC Yoruba ni, ti kii ba se ọpẹ Ọlọrun ati ti awakọ to wa ọkọ ti oun wa, boya isẹlẹ buruku ko ba waye tabi ki oun se ọdun tuntun ni akata awọn ajinigbe.
ti won yoo si foju wina ẹjọ.
Ambode so pe, a o tewaju lati maa se ijoba ti yoo faye gba awon eniyan lati ko ipa tiwon fun idagbasoke ipinle Eko ati orile-ede Naijiria lapapo.
Ẹgbẹrun lọna irinwo owo pọun ni yoo maa gba nigba ti o ba bẹrẹ sii ṣoju ikọ Juventus.
Wo àwọn ohun tí a mọ̀ lọ́wọ́ yìí nípa ìṣẹ̀lẹ̀ ikú Barakat Bello Bamidele Olumilua fi òsèlú tiẹ̀ sin Ọlọ́run àti ènìyàn - Mimiko Ọ̀pọ̀ ọmọ ẹgbẹ́ wa ló n tẹpo níye tó kéré sí iye ti PPPRA fi síta- IPMAN Ẹ̀wọ̀n gbére ni fún ẹnikẹ́ni tó bá fipá bánilòpọ̀ ní ìpínlẹ̀ Ọ̀ṣun Kanye West ṣèrànwọ́ $2m fún ẹbí George Floyd, yóò tún rán ọmọ rẹ̀ nílé ìwé Gbajugbaja olorin taka sufe ilẹ Amẹrika, Kanye West ti ṣeranwọ miliọnu meji dọla fun idile George Floyd to ku lẹyin ti ọlọpaa tẹ lọrun mọle ni Minesota.
9th Assembly: PDP ní láìpẹ́ làwọn aráàlú yóò mọ ìyàtọ̀ lórí àkóso ilé aṣòfin
Iko agbaboolu mẹ́rìnlélọ́gọ́ta  ni won ti bowolu bayii pe won yoo kopa ninu ere idije boolu Bishop Mike Okonkwo Football Championship, eyi ti yoo waye ni papa isere National Stadium tilu Eko, bere lojo karun-un osu karun-un odun ti a wa yii,Gege bi awon ti o sagbateru idije naa, idije ohun ni iko agbaboolu obinrin otooto mejo yoo kopa ninu re fun igba akoko.
Àwọn ọmọ ẹgbẹ́ PDP tó sápamọ́ kọlù mí lásìkò tí mò ń lọ sí ibi iṣẹ́, ló fa rògbòdìyàn - Olamiju Akala Alukoro ileeṣẹ ọlọpaa nipinlẹ Ogun, Abimbola Oyeyemi, sọ ninu ikede kan pe, aṣiri ti tu pe awọn kan n gbero lati ṣeto igbani wọle ṣẹgbẹ okunkun lọjọ keje, oṣu Keje.
Lẹ́yìn àwọn onílù wọ̀n-ọnnì ni àwọn onífèrè dé tí wọ́n wọ aṣọ kan náà, tí wọ́n tò ní méjì méjì bí wọ́n ti ń gbé ẹsẹ pọ̀ lẹ́ẹ̀kan ṣoṣo.
 siem reap , to je ilu to sunmo angkor wat ni enu bode si agbegbe angkor nibi to je ibi ibewo .
Aare Macron soro nipa oloogbe Kuti pe:“Fela ki ise onkorin lasan, O tun je oloselu ti o n ja feto omoniyan, O je eni ti ife ara ilu mu omu laya re abbl.
Gbogbo àwọn àgbààgbà wa ati gbogbo àwọn ará ilẹ̀ wa bá wí fún wa pé, “Ẹ wá lọ bá àwọn eniyan wọnyi, ẹ sì mú oúnjẹ lọ́wọ́ fún ìrìn àjò náà, ẹ wí fún wọn pé iranṣẹ yín ni wá, ẹ jọ̀wọ́, ẹ jẹ́ kí á jọ dá majẹmu.
Sugbọn ni aarin ọgọta ọdun ti Naijiria ti n tukọ ara rẹ, lai si ọwọ awọn eebo amunisin nibẹ, oju ti ri.
Eyi to jẹ igba ikẹta yii si ni igba ikéyin ti wọn a jọ pade jọ dije dupo ni igbesi aye wọn.
Òun ni ó fi ọ̀kọ̀ rẹ̀ pa ọọdunrun (300) eniyan ninu ogun kan ṣoṣo.
Ìjọba àpapọ̀ ti gba 800 bílíọ̀nù padà lọ́wọ́ àwọn tó jí owó ìlú kó, àwọn 1,400 ti wà nínú ẹ̀wọ̀n -Lai Mohammed Ọwọ́ tẹ́ àwọn ọkùnrin Fulani mẹ́ta tí wọ́n jí Màálù méjì kó ní Ogbomọṣọ- Àjọ NSCDC Ọmọ́ Yorùbá korò ojú sí Buhari bí kò ṣe fi orúkọ Obasanjo sọ ibùdókọ̀ ojú'rin Irọ́ ni o, kò sí ẹ̀rí pé Hydroxychloroquine leè kojú àrùn Coronavirus- Ẹgbẹ́ àwọn adarí ilé ìwòsàn ní Naijiria Aarẹ ẹgbẹ ọmọlẹyin Kristi, Samson Ayokunle naa ni, ọpọlọpọ igba ni oun ti kọ iwe si Gomina ipinlẹ Kaduna, Nasir El-Rufai, to si fi da oun loju pe awọn yoo pese aabo fun awọn eniyan.
Àwọn ọmọ Merari ni yóo máa ru àwọn igi férémù Àgọ́, àwọn ọ̀pá ìdábùú rẹ̀, àwọn òpó rẹ̀ ati àwọn ìtẹ́lẹ̀ rẹ̀.
Nígbà tí wọ́n péjọ ní Galili Jesu sọ fún wọn pé, “A óo fi Ọmọ-Eniyan lé àwọn eniyan lọ́wọ́, 
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, CAN: Samson ni ọrọ awọn ajinigbe ti gba àpérò ní Naijiria Ni ọsan Ọjọru ni iroyin kan jade lati inu ọkan lara awọn iwe iroyin ori ayelujara lorilẹede Naijiria pe Aarẹ Muhammadu Buhari ti gba lati da eto naa duro.
Mo ṣẹ̀ṣẹ̀ ṣe òrùka góòlù kan, mo fii sí ọwọ́ òsì mi sí ọmọ ìka tí ó dúrò sí ipò kerín sí àtàǹpàkò mi.
Lojoojumọ ni n óo máa yìn ọ́,tí n óo máa yin orúkọ rẹ lae ati laelae.
"O jẹ olùdije dupo àarẹ lábẹ̀ àsìá African Action Congress lasiko ìdìbò ọdun 2019 ní Nàìjíríà Ìwọ́de #RevolutionNow forí ṣánpọ́n ní Ibadan, àgbófinró gbàkóso ojú pópó Gbígba onídùròó Zakzaky ṣàfihàn àṣeyọrí ìfaradà wa lásìkò ìfìyajẹni - Shiite Sowore, AAC ti yọ Leonard Ezenwa tó kéde ìyọnípò Ṣòwòrẹ́ Sowore jẹ́ ọmọ Naijiria tó ti lo ọdun marundinlogun láti maa gbaruku ti ẹ̀tọ́ ọmọniyan àti ètò ìṣèjọba awa arawa ní Naojiria, bákan náà lo dá isejọba ologun dúro àti gbogbo ìwà àitọ ti àwọn ilé epo rọọbi pẹ̀lú gbogbo ǹkan ti wọ́n se Ní ọdun 1989, Sowore wode pe ""a o ni gbà"" láti bẹnu àtẹ lu ìwà àìtọ to wáye ninu ẹyáwo IMF kan to to ọgọfà miliọnu dọla ti ìjọba fẹ lò fún kíkọ ojú ọpá epo, sùgbọ́n àsírí to wà nibẹ ni pé ẹyáwo náà yóò mú àwọn fasiti Nàìjíríà dín láti mẹ́jidinlọgbọ̀n sí marun pere."
Bakan naa ni ki o se iwadii nipa awon ohun idabobo ara ẹni ti wọn gbekalẹ lasiko arun Coronavirus yii.
Ọjọgbọn Soyinka ni o dabi igba tawọn agbesunmọmi mu yan lọganjọ oru nile rẹ.
Fayose tun sọrọ lori opo twitter rẹ pe, ki awọn alagabagebe ti wọn n ru awọn oṣiṣẹ laya soke lati tako oun pe, oun n ya baalu lati rinrin ajo lọ silu Abuj, maa gun kẹtẹkẹtẹ tabi alupupu lọ si Abuja ti wọn ba ti dori oye losu kẹwa to nbọ.
Democratic Party, PDP se fi ranse si won.
Ǹ bá sọ fún Abimeleki pé kí ó lọ wá kún àwọn ọmọ ogun rẹ̀ kí ó jáde wá bá mi jà.
ng/ Kọ nọmba idanimọ NIN rẹ si oju aaye ti wọn la kalẹ.
Rọbọọti ọhun maa n bere iwe idanimọ awọn eeyan to ba n rin gberegbere ni igboro lasiko igbele lati mọ idi ti wọn fi wa ni igboro lasiko igbele.
“Ẹ lè jẹ gbogbo àwọn ẹyẹ tí wọ́n bá mọ́.
Ọrọ ti Minisita tẹlẹ fun irinna ofurufu, Femi Fani-Kayode sọ, ko yatọ si ti Ọjọgbọn Akintoye.
Lori ọrọ pe boya gomina Seyi Makinde fun Kabiyesi ni ẹbun owo ọgọrun miliọnu naira, Toyin Ajamu ni oun ko le sọ boya wọn fun Kabiyesi ni owo tori ko ṣe oju oun.
níyì adéolókun tí wọ ́ n bí ní ọjọ ́ kẹ ́ ta oṣù kọkànlá ọdún 1990 ( 3 november 1990 ) jẹ ́ agbá bọ ́ ọ ̀ lù rugby fún ( irish rugby union ) .
Challenge - Efunsetan Road ni yoo maa jẹ Lam Adesina road latoni lọ.
 Adajọ Tanko Muhammed di adajọ agba ile-ẹjọ giga ilu Abuja ni ọdun 1989
O fidunnu rẹ han lori bi wọn ṣe yan an fun ami ẹyẹ naa nitori ohun ti oju oun ri pọ lẹnu iṣẹ orin kikọ.
N óo sọ gbogbo ọrọ̀ yín ati gbogbo ohun ìṣúra yín di ìkógun fún àwọn ọ̀tá yín; n óo fi gbẹ̀san ẹ̀ṣẹ̀ yín ní gbogbo ilẹ̀ yín.
''A ti gba ìwé ẹ̀sún náà, ìjọba si ti bèèrè fún èsì láàrin wákàtí mẹ́rinlélógún.
Magu ati Keyamo ri'binu ijọba Ijọba apapọ Naijiria ti fẹsun kan alaga ajọ EFCC ton gb'ogun ti iwa'bajẹ, Ibrahim Magu, ati gbajugbaja agbẹjọrọ ton ja f'ẹto ọmọniyan, Festus Keyamo.
Ṣugbọn a óo gba obinrin là nípa ọmọ-bíbí, bí àwọn obinrin bá dúró láì yẹsẹ̀ ninu igbagbọ ati ìfẹ́ ati ìwà mímọ́ pẹlu ìwà ìkóra-ẹni-níjàánu.
Bí ó sì ti nà lé ọmọ náà, ara ọmọ náà bẹ̀rẹ̀ sí lọ́ wọ́ọ́rọ́.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Elebuibon: Àwọn asòfin Ogun yóò ṣe àkóbá fún ilẹ̀ Yoruba pẹ̀lú òfín tó fágilé àsà 6 Ẹrẹ̀nà 2020 Oríṣun àwòrán, @followlasg Onimọ nipa eto ati asa ilẹ Yoruba, Baba Fayemi Elebuibon ti bu ẹnu atẹ lu igbesẹ awọn asofin ipinlẹ Ogun, ti wọn pe fun ọna igbalode nipa yiyan ọba ati ṣise isinku ọba ni ilẹ Yoruba.
Festus Keyamo lo  fiwe ẹsun naa ransẹ si adele adari ile-isẹ
Lẹ́yìn náà, yóo bá àwọn orílẹ̀-èdè ati àwọn ilẹ̀ tí ó wà ní etíkun jà, yóo sì ṣẹgun ọpọlọpọ wọn.
Wọ́n fi ẹ̀sùn kan akópa náà wí pe, ó huwà àìtọ tí kò si bá ìlànà iṣẹ́ rẹ̀ gẹ́gẹ́ bii ọlọ́pàá ní ilẹ̀ Gẹ̀ẹ́sí (MET Police) mu.
OLUWA Ọlọrun Israẹli ní kí òun Jeremaya sọ fún ọba pé, àwọn ọmọ ogun Farao tí wọn wá ràn wọ́n lọ́wọ́ ti ń múra láti pada sí Ijipti, ilẹ̀ wọn.
aye iderun ba awon omo orile ede Najiria.
"Igbọra ẹni ye wà pé èdè gẹ̀ẹ́sì nìkan ní kí wọn dahun sí"" Ìgbìyànjú wa láti bá ileesẹ ọlọ́pàá sọ̀rọ̀ ló já sí pàbó nitori agbẹnusọ fun ileesẹ ọlọ́pàá, Moshood Jimoh, kò gbé ẹrọ ibara ẹni sọrọ ti a fi pee."
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Nàìjíríà ni orílẹ̀-èdè kẹta tí ìkọlù ìgbésùnmọ̀mí pọ̀ sí jùlọ láàgbáyé 21 Bélú 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Nàìjíríà ni orílẹ̀-èdè kẹta tí ìkọlù ìgbésùnmọ̀mí pọ̀ sí jùlọ láàgbáyé Abajade iwadii kan lori iwa igbesunmọmi ti kede rẹ pe Naijiria ni orilẹ-ede kẹta ti iwa igbesunmọmi ti wọpọ ju lọ lagbaye lọdun 2018.
Ìmúra obinrin Yorùbá kò pé lai wé gèlè, ṣùgbọ́n òwe Yorùbá ti ó ni “Gele ko dun bi ka mo we, ka mo we, ko to ko yeni”, fihan pe ki ṣe owó ti enia ná lati ra gèlè ni ó ni kó yẹni.
Eliṣa tẹjú mọ́ Hasaeli títí ojú fi tì í.
" ní ìlẹ ̀ nàìjíríà náà , a rí irú fíìmù bíi "" elébòlò "" ( charlot ) àti "" wheel of change "" ( kẹ ̀ kẹ ́ ìyípadà ) tí ó níí ṣe pẹ ̀ lú àrùn kògbóògùn éèdì ."
Gẹgẹ bi mimọ ede Yoruba ṣe ti wa n lọ sokun igbagbe paapaa laarin awọn ọdọ ode oni, awọn ọrọ to jẹ wi pe itumọ wọn ko to nkankan ti wa di ohun to n kọ awọn ọmọ Yoruba leyin.
Ó dá àwọn ohun èlò wúrà ati ti fadaka pada, tí Nebukadinesari kó ninu ilé OLUWA ní Jerusalẹmu, lọ sí ilé oriṣa rẹ̀ ní Babiloni tẹ́lẹ̀.
Ijọba Eko ni awọn ọlọpaa ipinlẹ Eko naa yoo ma fi panpẹ mu ẹnikẹni ti wọn ba ri ni ile igbafẹ, ibi ayẹyẹ tabi ibikibi ti ẹro pọsi lati ri wi pe arun coronavirus naa dẹkun.
Oriṣiriṣi ounjẹ ni Yoruba n jẹ fun idagbasoke ara wọn.
O tó gẹ́; A kò fẹ́ ìwòkuwò mọ́ ní Nàijíríà- Runsewe (NCAC) Falana àtàwọn míì péjú síbi àpérò #RevolutionNow l'Eko O dìgbà tí mo bá dórí àgá kí ń tó sọ ìpinnu mi - Fatai Owoseni SSANU, NASU gbé fásitì Ibadan tì pa 7) Ramatu Tijjani: Ramatu Tijjani jẹ ọmọ ọdun mọkandinlaadọta.
Mo pá a láṣẹ fún ọ níwájú Ọlọrun tí ó fi ẹ̀mí sinu gbogbo ohun alààyè, ati níwájú Kristi Jesu tí òun náà jẹ́rìí rere níwájú Pọntiu Pilatu, 
Georgina Rodríguez to je omo odun merinlelogun to maa n jo ni ololufẹ Cristiana Ronaldo to je omo ile Portuguese.
Nígbà tí ó yá, àkókò tó fún Elikana ati ìdílé rẹ̀ láti lọ sí Ṣilo, láti lọ rú ẹbọ ọdọọdún, kí Elikana sì san ẹ̀jẹ́ tí ó jẹ́ fún OLUWA.
Ibudo sinima ọhun si lo jẹ ti ilumọọka sẹnetọ kan ati oludasilẹ ileesẹ amohunmaworan Silverbrds nilu Eko, Ben Murray Bruce.
Ibadan Drivers Clash: Àjọ OYRTMA sọ ohun tó fa wàhálà láàrín àwọn awakọ̀
Òun náà ni baba ńlá gbogbo àwọn ìdílé tí ń gbé Kiriati Jearimu, àwọn ìdílé bíi Itiri, Puti, Ṣumati, ati Miṣirai; lára wọn ni àwọn tí wọn ń gbé ìlú Sora ati Eṣitaolu ti ṣẹ̀.
“OLUWA Ọlọrun ti sọ̀rọ̀, ta ló gbọdọ̀ má sọ àsọtẹ́lẹ̀?
Ó wù mí kí o ro ọ̀rọ̀ yìí wò, nítorí kò yẹ kí ọmọdé kọ ìmọ̀ràn àgbàlagbà àfi bí ìmọ̀ràn náà bá jẹ́ èyí tí ó lè mú ìṣìnà bá ni.
Nípa ìfẹ́ Ọlọrun náà ni a fi yà wá sọ́tọ̀ nítorí ẹbọ tí Jesu fi ara rẹ̀ rú lẹ́ẹ̀kan ṣoṣo.
Wọn a máa fi ọ̀rọ̀ dídùn ati kí á máa pọ́n eniyan tan àwọn tí kò bá fura jẹ.
Gbogbo nkan sì ni mò nlò ó fún.
Ó bá rán meji ninu àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀, ó wí fún wọn pé, “Ẹ lọ sí inú ìlú, ọkunrin kan tí ó ru ìkòkò omi yóo pàdé yín, ẹ tẹ̀lé e.
Ó sọ fún un nígbà náà pé, “Gba àwọn ohun èèlò wọnyi, kó wọn lọ sinu tẹmpili tí ó wà ní Jerusalẹmu, kí ẹ sì tún tẹmpili náà kọ́ sí ojú ibi tí ó wà tẹ́lẹ̀.
Adari awon asoju onijo ti won n je Xoriginal Soca lati Trinidad ati Tobago, Kyle Lequay ni iko onijo naa yoo ko nipa asa ati ise awon iran Yoruba ni Naijiria.
Nítorí èmi tí mo kéré jùlọ ninu gbogbo àwọn onigbagbọ ni Ọlọrun fi oore-ọ̀fẹ́ yìí fún, pé kí n máa waasu fún àwọn tí kì í ṣe Juu nípa àwámárìídìí ọrọ̀ Kristi.
FRSC dá N443,180 padà fún ẹbí ẹni to ní ìjàmbá mọ́tò Leon van Biljon dí èrò ọrun nípasẹ̀ Kìnìún rẹ̀ Ta ni Ọjọgbọn Adebanji Akintoye tó borí Tinubu láti di olórí àwọn Yoruba?
Ni inú oríkì ti a ó bẹ̀rẹ̀ si i kọ, a ó ri àpẹrẹ ohun ti Yorùbá ṣe ma a nsọ oríkì pàtàki fún iwuri nigbati ọkùnrin, obinrin, ọmọdé àti ẹbí ẹni bá ṣe ohun rere bi ìṣílé, ìgbéyàwó, àṣeyorí ni ilé-iwé, oyè jijẹ tàbi ni ayé òde òni, àjọyọ̀ ọjọ́ ìbí.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ẹgbọ́n olóògbé Suga: Wọ́n yìnbọn fún Suga lójú mi, n kò sì lè dá wọn dúró ''Oloye Akindele jẹ akikanju ti a le fi we awọn jagunjagun aye atijọ bi Ogunmọla, Ibikunle, Odẹrinlọ.
Ó sì tún wí fún wọn pé, “Elija ti dé, wọ́n ti ṣe ohun tí wọ́n fẹ́ sí i, gẹ́gẹ́ bí a ti kọ nípa rẹ̀.
Oríṣun àwòrán, Alambo Datonye Àkọlé àwòrán, Ikede Esi idibo ijoba ibilẹ Bayelsa Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Bakan naa ni awọn kan naa n sọ pe, adiye Buhari kuku n laagun ṣugbọn iyẹ ara rẹ ni ko jẹ ka mọ.
, Duration 5,5712 Òkùdu 2020 BBC News, Yorùbá Ìdí tí ẹ fi le è nígbàagbọ́ nínú ìròyìn BBC Ìlànà Lílò Nípa BBC Òfin Àṣírí Cookies Kàn sí.
Eyi yóò fún ẹni to gbà ọ lálejo ní ìdánilóju pé o gbádùn ounjé to pèsè fún ọ 6.
"Leah Sharibu ṣì wà láàyè - Iléeṣẹ́ Aarẹ Buhari Ilé ẹjọ́ Kano: Ganduje kò lẹ́tọ̀ọ́ láti yan Emir Ganduje Video - Ìwádìí ilé aṣòfin foríṣánpọ́n Nwakaudu nínú àtẹjáde rẹ̀ sọ pé Ganduje ò mọ̀ pé gòmìnà Wike kìí ṣe ""dọ́là tí Ganduje lé kò sápò bó ṣe wùú."
Bẹ́ẹ̀ ni Baba-onírùngbọ̀n ka gbogbo nǹkan búburú wọn-ọnnì sílẹ̀ tí wọ́n lè jẹ́ ìdíwọ́ lójú ọ̀nà bì a bá wí pé dandan à ń lọ.
Oríṣun àwòrán, Ahmad Bashir Àkọlé àwòrán, Diẹ lara awọn to ti ba irufẹ itiju ati ariwo idẹyẹsi bayii pade ni Donald Trump, Theresa May, Jacob Zuma ati George Bush Bi aarẹ Buhari ṣe n ṣe alaye awọn ohun to wa ninu aba owo iṣuna naa, ati awọn aṣeyọri ti iṣakoso rẹ ti ṣe, ni awọn aṣofin kan n da ọrọ mọ ọ lẹnu, ti wọn si n ho le lori.
Bí ènìyàn bá pàdé Bádérù ní ibi fàájì, yóò rò pé ọlọ́lá kan ni.
Iwe iroyin Thisday lo kọkọ gbe iroyin naa pe olu ile iṣẹ ilẹ Amẹrika ni Naijiria kọ lati fun Bisọbu ni fisa.
Amosa, awon eniyan lee maa lọ lati dibo won ni irọwọ ati irọsẹ.
Naijiria  ko kaarẹ lati tun maa pa ikọ
Ninu awọn orileede taa n sọ yi ni Italy, Belgium ati Netherlands wa.
Lọsẹ to n bs ni ajọ UEFA yoo pade lati tubọ jiroro lori rẹ ninu eyi ti wọn fi n gbero ati lo aṣekagba idije Champions league fi pari saa ere bọọlu tọdun yii ni ọjs kọkandinlọgbọn oṣu kẹjọ.
Ilana ti wọn lo lati se isẹ yii Awọn orilẹede to n kopa ninu idije ife ẹyẹ ilẹ Afirika, AFCON, ni wọn se igbelewọn wọn nibamu pẹlu bi wọn ti pegede si ni ilana odiwọn mejila, ti wọn si ri orilẹede to pegede julọ laarin wọn bii orilẹede to gbegba oroke.
Muideen fihan pe oun gbọ ede Yoruba daadaa gẹgẹ bi oṣere ere tiata Yoruba.
Wọn ko sọ boya wọn ko awọn ara ilu mọ awọn ti wọn ko nibẹ.
8 wọlé lójúmọ́ lẹ́yìn tíjọba ti ẹnu bodè -Ali Tokọtaya Tariqul ati Khadijah ti gba pe igbesẹ ti wọn gbe ninu igbeyawo wọn yii yoo mu itẹsiwaju ba ominira awọn eniyan Bangladesh.
Ó na ọwọ́ mú èèkàn àgọ́,ó na ọwọ́ ọ̀tún rẹ̀, ó he òòlù àwọn alágbẹ̀dẹ,ó kan Sisera mọ́lẹ̀ lẹ́ẹ̀kan ṣoṣo;ó fọ́ ọ lórí,ó lù ú ní ẹ̀bá etí,ó sì fọ́ yángá-yángá.
Ní ọjọ́ náà, ìyókù Israẹli ati àwọn tí yóo yè ní agbo ilé Jakọbu, kò ní gbé ara lé ẹni tí ó ṣá wọn lọ́gbẹ́ mọ́, ṣugbọn OLUWA, Ẹni Mímọ́ Israẹli ni wọn óo fẹ̀yìn tì ní òtítọ́.
Joabu ati àwọn ọmọ ogun rẹ̀ tẹ̀síwájú láti gbógun ti àwọn ará Siria, àwọn ará Siria sì sá.
Nítorí náà, n óo rán iná sí ìlú Temani, yóo sì jó ibi ààbò Bosira ní àjórun.
Ọlọrun mi ti rán angẹli rẹ̀, ó ti dí àwọn kinniun lẹ́nu, wọn kò sì pa mí lára.
O ni ọkan imoore loun ni fun ẹgbẹ naa atawọn alaṣẹ rẹ fun bi wọn ko ṣe da oun da wahala naa.
Ìtàn àkọ ́ kọ ́ yìí wà nínú odù Èjì ogbè , Ẹsẹ ̀ Èkejì .
Ní òwúrọ̀, OLUWA bá mi sọ̀rọ̀, 
Bakan naa, gbogbo awọn ile igbimọ aṣofin to wa ni ilẹ Yoruba ni wọn ti buwọlu abadofin naa, ti wọn si ti fi ṣọwọ si gomina ipinlẹ naa lati buwọ lu u.
Kò sí bí a ti le ṣe ifa kí ó má hùwà èkùrọ́, kò sí bí a ti le ṣe ẹni ti o ń ká[kiri ẹ̀yìn odi kí ọgbọ́n rẹ̀ má ta ẹni tí kò kúrò lójú kan yọ.
Ní'hà ibòmíì, ilẹ̀ ṣú fún wákàtí mọ́kànlélógún.
Oríṣìí òkúta mejila ni ó wà níbẹ̀; orúkọ ọ̀kọ̀ọ̀kan wọn dúró fún orúkọ ẹ̀yà àwọn ọmọ Israẹli kọ̀ọ̀kan, wọ́n dàbí èdìdì, wọn sì kọ orúkọ àwọn ẹ̀yà Israẹli mejeejila sí wọn lára, òkúta kan fún ẹ̀yà kan.
 a má a wá bíi iyẹ ̀ fun gbígbẹ tí a gbọ ́ dọ ̀ pò kí á tó fúnni yálà sábẹ ́ awọ ara tàbí sínú ẹran-ara .
Bakan naa l'oṣu Kinni ọdun 2018, ọmọ orilẹede America meji, ati Canada meji ni wọ̀n jigbe lasiko ti wọn n rinrinajo lati ilu Kafanchan nipinlẹ Kaduna lọ si ilu Abuja.
idibo alakọkọ ba ni magomago ninu, tabi ti awọn eleto idibo ko ba tẹlẹ alakalẹ
Àwọn alufaa ati àwọn ọmọ Lefi wà fún ẹbọ sísun, ati ẹbọ alaafia.
"Aṣedanwo yoo nilo lati fi orukọ ""[Surname FirstName MiddleName]"" pẹlu ifọrọranṣẹ lati ajọ JAMB ranṣẹ si 55019."
Àwọn arakunrin rẹ̀ ní ìdílé wọn, nígbà tí a kọ àkọsílẹ̀, ìran wọn nìyí: olórí wọn ni Jeieli, ati Sakaraya, ati 
Àìsàn ìtọ̀ súgà kò túmọ̀ sí pé èèyàn ti gba ọjọ́ ikú- Dókítà
Lójú àwọn eniyan Israẹli, ìrísí ògo OLUWA lórí òkè náà dàbí iná ńlá tí ń jóni ní àjórun.
Ẹjọ naa da lori ẹsun ti wọn fi kan Buhari pe o parọ lori awọn iwe ẹri rẹ to fi ṣọwọ si ajọ eleto idibo, INEC ṣaaju idibo gbogboogbo to lọ.
Corornavirus: Kini Gómìnà ìpínlẹ̀ Ekiti ṣe fun baba tọ ni ọmọ òun ko gbọdọ tèlé oun déle nitori o ṣẹ̀ṣẹ̀ de lati Eko?
Gutterres sọ eyi lasiko to n fi iroyin bi nkan se n lọ lagbaye to Igbimọ Ajọ Agbaye to n risi ẹtọ ọmọniyan lagbaye leti.
Mose gbà láti máa gbé ọ̀dọ̀ ọkunrin náà, ó bá fún un ní Sipora, ọ̀kan ninu àwọn ọmọbinrin rẹ̀ láti fi ṣe aya.
Abayomi tẹsiwaju pe wọn yoo ṣe ayẹwo mii fun ọkunrin naa, ti esi rẹ ba wa bakan naa, wọn yoo da silẹ ko ma lọ ile rẹ layọ ati alafia.
”Ẹni tí òùngbẹ bá ń gbẹ kí ó wá, ẹni tí ó bá fẹ́ kí ó mu omi ìyè lọ́fẹ̀ẹ́.
Osu Keje, ọdun 2020 yii si ni oloogbe naa ko ba pe ẹni ọdun mẹrinlelaadọrun.
Ojú wọn bá là; wọ́n wá mọ̀ pé Jesu ni.
Nígbà tí BBC kàn sí olórin Afro-Juju ni, Sir Shina Peters, tí ó jẹ́ ọ̀rẹ́ rẹ̀ tímọ́tímọ́, ṣe ni ó bú sẹ́kún tí kò sì lè sọ̀rọ̀.
Seba ati Salimuna náà nìyí o.
Àwọn tí Wọ́n Kọ́kọ́ Jẹ́ Ọmọlẹ́yìn Dafidi Ọba láti Inú Ẹ̀yà Bẹnjamini.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Awọn ti apẹẹrẹ wọn ko ba le ju yoo tete ri iwosan gba laarin ọsẹ meji.
Awọn ti wọn jọ kawọ pọnyin rojọ nileẹjọ Majisireeti ni pẹlu Jolaosho ni Ladiva Aije, Juliet Semion, Ahmed Olasunkanmi, Eritosin ati Tunde Jimoh ti wọn si fi ẹsun mẹjọ kan wọn to rọ mọ yiya fiimu ibalopọ ninu igbo Osun Osogbo.
Ṣé kí n wá siwaju rẹ̀ pẹlu ẹbọ sísun ni tabi pẹlu ọ̀dọ́ mààlúù ọlọ́dún kan?
Ìjọba Burundi fi òfin de BBC Burundi da eto idibo bi ọgbọn Ìkọlù abúlé Burundi gb'ẹ̀mí èèyàn 26 Isẹlẹ arigbarimu lori owo to poora waye ni Burundi Wọn yọ ara wọn kuro ninu idije lọdun 1980 ati lọdun 1998.
Ilé aṣòfin fèsì sí ẹ̀sùn tí Jega fi kàn án Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Obìnrin tí kó ba fẹ́ òṣìṣẹ́ Mọ́ṣúárì, ìpinu rẹ̀ mẹ́hẹ' Alhaji Aminu Kura tún ni òbí míì tó pàdánù ọmọ rẹ̀ Farook, tó jẹ́ ọmọ ọdún mẹ́ta lọ́dún márùn ún sẹ́yìn.
Oríṣun àwòrán, Instagram/hushpuppi Ọkan ninu iṣẹ ti wọn lo ṣe ni pe, o jẹ olootu orin ti a mọ si Music Producer, ti o si ba awọn olorin Naijiria kọọkan ṣiṣẹ pọ.
Ọmọ rẹ ọkunrin to jẹ ẹgbọn Indimi lo fẹ ọmọbinrin aarẹ Buhari, Zarah.
Elija dá a lóhùn pé, “Ní orúkọ OLUWA àwọn ọmọ ogun, tí mò ń sìn, mo ṣèlérí fún ọ pé, n óo fara han ọba lónìí.
”Ó dáhùn pé, “Ará Ijipti ni mí, ẹrú ará Amaleki kan.
Tinubu ti ń gba orí ayélujára kan, àwọn aráàlú ń fèsì
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Coronavirus in Nigeria: Wòlíì 'Sọtítóbirẹ̀' fójú ba ilé ẹjọ́, fídíò ohun tójú rẹ̀ rí nílé ẹjọ́ nìyí 6 Ìgbé 2020 Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ilé ẹjọ́ kànán nípá fún Wòlíì Sọtítóbirẹ̀ kó tó wọ ilé ẹjọ́ Awọn agba bọ wọn ni, ohun to n ṣe ilemboye kọ lo n ṣe ọmọ rẹ.
Lásìkò tí wọ́n pè ìpàdé akọ̀ròyìn lónìí, ní ọ̀gá àgbà ilé-ìwé náà, ọ̀jọ̀gbọ́n Eyitọpẹ Ogunbọdẹde sọ pé, lẹ́yìn ìpàdé ìgbìmọ̀ alasẹ ilé ẹ̀kọ́ náà, wọn rí okodoro ọ̀rọ̀ pe ọ́jọ́gbọ̀n Richard Akindele fẹ́ bá akẹkọ-binrin Monica Osagie dọ́ọ̀rẹ́, tí òun náà sì fi ìdí rẹ̀ múlẹ̀.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Alaafin: Wo arẹwà mẹ́jọ̀ tó ń ṣìkẹ́ Ọba Adeyemi 24 Òkùdu 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 13 Ògún 2020 Oríṣun àwòrán, Alaafin Oba Lamidi Adeyemi III Alaafin tilu Ọyọ, ọba Lamidi Ọlayiwola Adeyemi kẹta ni awọn ọpọ ayaba ni iyẹwu, ti wọn rẹwa pupọ, ti wọn si wu oju ri.
Ẹlòmíì, Bani Jackreece sọ pe ni nkan bi aago mẹrin idaji ni oun raaye salọ lọjọ Aiku, ọjọ kinni, oṣu Kọkanla, nitori ibẹru ẹ̀mí oun, ati bi oun ko ṣe raaye ra oúnjẹ tabi gba owo ni banki.
Ọpọ gba pe o yẹ ki Naijiria le ṣina fun Algeria ninu idije ti alẹ oni nitori pe wọn ti ri asiko isinmi to pọ diẹ.
MKO ku ni ọjọ keje, oṣu keje, ọdun 1998 satimọle.
Wọ́n Gba Àpótí Ẹ̀rí Lọ́wọ́ Àwọn Ọmọ Israẹli.
Bi o tilẹ jẹ pe eyi bi Ọrunmila ninu amọ ko gbe soju rara,ti ko si tori rẹ sa kuro nilu Iwo.
Ó bẹ̀rẹ̀ sí kó gbogbo àwọn ará ìlú náà ṣiṣẹ́.
Oríṣun àwòrán, others Olaitan Shittu to jẹ aṣoju minisita ere idaraya lo fọrọ naa lede l'Ọjọru nigba to ṣabẹwo si Alhaja Yekini niluu Ijagbo nipinlẹ Kwara.
Ènìyàn 653 míràn tún kún iye àwọn tó ní COVID-19 ní Nàìjíríà Àwọn àádọ́ta ọ̀dọ́ wọ gàù nítorí ilé ijó ní Ilorin Báwó ni òògùn dexamethasone ṣe ń ṣiṣẹ́ lára Òògùn ìtura dé fún Coronavirus!
ede Naijiria,bo tile jẹ pe eto oro aje naa n se seke-seke bi ẹsẹ telọ.
Ni ọjọ kẹrinlelogun oṣu kẹfa ọdun 2020 ni agbẹjọro fun Wolii Sọtitobirẹ, Amofin Oluṣọla Oke lo pẹjọ fun gbigba beeli wolii naa atawọn mẹfa miran ti wọn jijọ n jẹjọ lori ẹsun naa ti Onidajọ Oduṣọla si sun igbẹjọ lori boya ki wọn gba beeli rẹ tabi rara siwaju.
Ṣọra fun ile ounjẹ ati ibi ase ti ko ba bọwọ fun ofin idadobo ara ẹni: Iwadii fihan wi pe o ṣe koko ki eniyan jẹun tabi gbafẹ ni awọn agbegbe to bọwọ fun ofin Coronavirus.
Ẹ wo aláwàdà kan tí mo rí ní ìgboro London ní ìrọ̀lẹ́ àná.
Àwọn ọmọ Harimu jẹ́ ọọdunrun ó lé ogún (320).
Oríṣun àwòrán, Instagram/Super Falconspage Àkọlé àwòrán, Idije Awcon Ikọ Super Falcons lo jawe olubori pẹlu ami ayo meji sodo nigba ti wọn pade ninu idije ti ọdun 2000 nilu Johannesburg lorilẹede South Africa.
Ọ̀tẹ̀ ṣá ni ti eniyan burúkú ní gbogbo ìgbà,ìkà òjíṣẹ́ ni a óo sì rán sí i.
Ẹgbẹ JOHESU paṣẹ pe ki awọn oṣiṣẹ eleto ilera da iṣẹ silẹ laago mejila oru ọjọ Aiku ọjọ kẹtala oṣu kẹsan an ọdun 2020.
Girl Child Day 2019: Inú mi dùn pé ọmọ obinrin nìkan ni mo bi -Tawakalitu Olawale
Ẹ le ka nipa rẹ si nibi Ati nibi Akuoma Omeoga Ọjọ ori: Mẹẹdọgbọn Orilẹẹde: Nigeria Ere idaraya: Kẹkẹ ori yiyin ‘Bobsleigh’ Akuoma ni wọn npe ni “brakewoman” fun ikọ kẹkẹ ori yiyin ‘Bobsleigh’  akọkọ fun orilẹẹde Nigeria.
Labani bá sọ fún Jakọbu pé, “Wo òkítì ati ọ̀wọ̀n yìí, tí mo ti gbé kalẹ̀ láàrin àwa mejeeji.
Igbọran gẹgẹ bi o ti ṣe wi, san ju ẹbọ ruru lọ.
”Awon niran ti won kopa nibi eto naa ro awon eniyan lati wa aaye lo gba kaadi idbo won ki won le ni agbara lati yan enikeni ti okna won ba fe sipo to wu won fun idagbaoske Naijiria.
Eyi lo si yẹ ki ọpọlọpọ orilẹede wo awokọṣe rẹ.
Àsìkò tó láti fi ìwọ́de gba ara wa sílẹ̀ lọ́wọ́ ebi àti oko ẹrú - Sowore Ìjọba Buhari ń wùwà bíi ìjọba Abacha lórí ọ̀rọ̀ Ṣoworẹ- Ṣoyinka Ẹ o ranti pe El-Zakzaky ati iyawo rẹ beere fun beeli nitori wọn ṣaisan latimọle ti wọn wa nitori ijiya tawọn ologun fi jẹ awọn mejeeji.
"Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Gbọ̀ngàn Mapo, ọ̀kan lára ibi àmúyangàn n'Ibadan rèé ""Kashamu ṣì ni olùdíje PDP fún ipò gómìnà l'Ogun"" Kò sọ́wọ́ mi nínú ẹdáwó orí ayélujára - Atiku figbe bọnu Adelabu yóò sọ ìpínlẹ̀ Oyo jí tó bá di gómìnà - Akala Ọ̀rẹ́ la mọ ṣe!"
3 ni ó wà lọ ́ wọ ́ , ìkọ oníbiṣẹ ́ rẹ ̀ ṣe é rí ní àdírẹ ́ sì http : / / www.
 Nigba ti o n fesi, Ajimobi fi da minisita loju pe
Oríṣun àwòrán, @Shuleman El-zakzaky Ọpọ ẹmi lo ti sun tawọn miiran si farapa ninu ikọlu to waye laarin awọn ọlọpaa ati ẹgbẹ Shiite.
Eyi si ṣẹlẹ ni asiko ofin konile-o-gbele nitori arun Coronavirus.
Má jẹ́ kí wọn rú ọ lójú,fi wọ́n sọ́kàn.
Oríṣun àwòrán, @mko_abiola Oniruuru iporogan, ifẹhonu han, wahala, rogbodiyan ati jagidi-jagan si lo tẹle bi wọn se wọgile esi ibo aarẹ ọjọ Kejila osu Kẹfa ọdun 1993 naa.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Arsenal na Watford ni 3-0 11 Ẹrẹ̀nà 2018 Oríṣun àwòrán, Getty Images Ẹgbe agbabọọlu Arsenal ti fẹsẹ wọn rinlẹ nipo kefa ninu atẹ igbelewọn liigi ilẹ Gẹẹsi pẹlu ami ayo 48 lẹyin igba ti wọn naa Watford pẹlu ami ayo mẹta s'odo.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ọ̀rọ̀ ti yanjú dé ibì kan lórí owó àjẹmọ́nú àwọn Super Falcons Colin Udoh to jẹ agbẹnusọ Super Eagles tẹlẹ ni ọkan lara awọn agbabọọlu naa ṣo fun oun pe awọn owo ajẹmọnu mii ti pẹ.
Wọ́n ní àṣẹ láti ti ojú ọ̀run pa, tí òjò kò fi ní rọ̀ ní gbogbo àkókò tí wọn bá ń kéde.
A o maa mu ẹkunrẹrẹ wa fun yin bi a ba ti ri aridaju ohun gbogbo.
Ọ̀gá iléeṣẹ́ gbé £10 mílíọ̀nù ẹ̀bùn owó fún òṣìṣẹ́, èyí lohun tó pawọ́n pọ̀ Ọ̀rọ̀ Soyinka àti Obasanjo papọ̀ lórí pé Buhari n ṣe ìpínyà Nàìjíríà O ni ọrọ naa tun kan ẹnikan to n wa oye lati ọpọ ọdun sẹyin ti ko ri.
Ninu iwe kan 'Muhammadu Buhari: The Challengesof Leadership in nigeria.
Dino gba àgọ́ Ọlọ́pàá ré sílé ìwòsàn
George Weah tí padà sí ọ́fíìsì rẹ̀ tó fí sílẹ nítorí ejò
Bakan naa, Ọba Samuel Adeniran Asusumasa Atewogboye keji, Alaaye tilu Efon Alaaye lasiko naa, tun gbe awọn gende dide lati wa Adediwura, sugbọn ẹja ni ọrọ naa, kii se akan rara.
Ayọ̀ọlá: Lẹ́yìn ẹ̀wà, kínni ẹ tún ní
Arabinrin Nnenna Anyim sọ wi pe o sọrọ fun awọn lati ri omi pọn, ti awọn tilẹ le rin irin wakati meji ki awọn to le ri omi ti awọn yoo lo nitori ko si omi mimọ ni agbeegbe naa.
Bẹ́ẹ̀ ló ṣe sí òpó keji pẹlu.
3 Àti sí Oliver Cowdery, ẹnití Ọlọ́run pè bákannáà, àpóstélì kan ti Jésù Krístì, láti jẹ́ alàgbà ìkejì ti ìjọ yìí, tí a sì yàn ní abẹ́ ọwọ́ rẹ̀;
Gẹgẹ bi ohun ti awọn oniroyin to wa lagbegbe naa sọ, agbẹnusọ fun ileeṣẹ ọlọpaa Femi Joseph ni awọn yoo ṣafihan afunrasi ọ̀hún faraye.
O tun tesiwaju pe opolopo aseyori ni ajọ NiBUCAA ti se lati dekun itankale aarun kogboogun lorile ede Naijiria.
 kaa siwaju si ni ede geesi kan si>.
Lẹyin to bẹbẹ pe oun gba pe oun jẹbi ẹsun ti wọn fi kan an ni olupẹjọ, Franklyn Ofoma, rọ ile ẹjọ naa lati ṣe idajọ bo ṣe tọ labẹ ofin.
Jẹ́ kí ìkérora àwọn ìgbèkùn wá sí ọ̀dọ̀ rẹ;gẹ́gẹ́ bí agbára ńlá rẹ,dá àwọn tí a dájọ́ ikú fún sí.
Ó sọ kànga náà ní Ṣeba.
Bakan naa, papanbari be ni pe, aare Buhari tun ti surẹ fun oludije wa.
Sekinat Quadri ọmọ ọdún méje ajẹ̀sẹ́ to fẹ dabi Anthony Joshua
Bakan naa ni alukoro ẹgbẹ oṣelu nipinlẹ Ondo, ni awọn ṣi n gba alaye lori esi idibo naa lọwọ nitorinaa awọn ko tii le fesi.
Èmi náà sì dáhùn, mo ní, Ọgbà ẹ̀yin mélòó?
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Saheed-Fathia Balogun: Ọjọ́ Karùn-ún oṣù kejì ni wọ̀n bí wọn, tí wọn sì bí ọmọ méjì fúnra wọn 5 Èrèlè 2020 Oríṣun àwòrán, Fathia Balogun Ọjọ ibi se pataki, o se koko, bẹẹ si ni inu ẹni kii dun ka pa mọra ni ọjọ ibi ẹni.
Eniyan burúkú a máa gba àbẹ̀tẹ́lẹ̀ níkọ̀kọ̀,láti yí ìdájọ́ po.
Carrington lived well and successfully by making unique contributions to make the world a better place than he met it.
Lẹyin ti o gba abajade iwadii ti igbimọ naa gbe kalẹ ni Aarẹ Buhari ti paṣẹ fun ileeṣẹ eto idajọ nijọba apapọ, ajọ to n risi ibọwọ fun ẹtọ ọmọniyan lorilẹede Naijiria, NHRC pẹlu ọga agba ileeṣẹ ọlọpaa lorilẹede Naijiria lati lọ tan imọlẹ si ọna ti wọn yoo gba lati ṣe amulo awọn aba ti igbimọ naa gbe kalẹ ninu iwadi rẹ.
BBC 100 Women: Obìnrin tí o lasẹ lórí kí ọkùnrin fẹ ìyàwó kejì
Lagos-60 Katsina-37 Kaduna-35 FCT-6 Ogun-4 Edo-3 Kwara-3 Rivers-2 Kano-2 Jigawa-1 Oyo-1 Taraba-1 Èèyàn 246 tún kó Covid-19 ní Nàìjíríà ní 21/11/2020 Esi ayẹwo ti ajọ to n mojuto ajakalẹ aarun ni Naijiria, NCDC fi sita lọjọ Abamẹta fihan pe eeyan ojilerugba ati mẹfa, 246, eeyan lo ṣẹṣẹ ni Covid-19 ni Naijiria.
 Ma so fun yin pe gbogbo ogbon ti a ti kojo lateyin wa, a ko ni gba lati je kan re yin je.
Yìnyín ti inú èémí Ọlọrun wá,gbogbo omi inú odò sì dì.
Risikat Moromoke Azeez: Inú èmí àti Òbí mi dùn nígbà ti Risi bí ọmọ olójú búlù- Wasiu
O jẹ ọmọ ipinlẹ Osun (Ile Ife ati Ede) o si gbe ni ilu Ibadan dagba.
Wọn tun sọ fun un pe orukọ rẹ ti wọn sọ ọ ni Zephany Nurse.
 Ó ye kí á tètè se àlàyé síwájú sí i nípa ìgbàgbò tàbí àìgbàbò òrò-ìse .
Wọn ju s'ẹwọn, o si lo ẹẹdẹgbẹta ọjọ din mẹsan latimọle.
''A ri wi pe o ti mu oti yo nigba ta de ọdọ rẹ.
Onídàájọ́ yóo bá fi ọ́ lé ọlọ́pàá lọ́wọ́, ni ọlọ́pàá yóo bá tì ọ́ mọ́lé.
O ṣe àpèjúwe pé igi náà kò jìnà sí igi ti mo ti gùn.
"Opayinka sọ pe ""Ẹmi eṣu to n kaakiri ninu afẹfẹ ni Coronavirus, ti ẹni to ba ni arun ọhun ba ti n wọle sinu ile ijọsin, ẹmi naa ko ni ba wọle."
”O je abere ajesara omo oojo ni igba akoko 
yii pe, laisi ajo yin to n gbogun ti iwa sise owo ilu basu-basu , ile akede
Ẹni kan wá sí ọ̀dọ̀ Aṣojú-Olódùmarè, nígbà tí ó sí bẹ̀rẹ̀ si ọ̀rọ̀ í sọ, ó ni, ìwọ ìránṣẹ́ Ẹlẹ́dàá ayé, ìwọ iranṣẹ́ Ẹlẹ́dàá ọ̀run, bá mi wí fún Ọlọ́run Ọba pé, ìyàwó tí mo ní kò fún mi ní ìtẹ́lọ́rùn kan ṣoṣo, ìyàwó náà ló tilẹ̀ kọ́ ń wá ojú mi mọ́ra, n kò kọ́ ní èrò àti fẹ́ ẹ.
tun pegede sipele ti o kan ni Anastasija Sevastova, Petra Kvitova, Anett
Fun idi eyi la ṣe da wọn pada'' O ni o jẹ ohun to tabuku ba awọn pe ko si iwe kankan tawọn ile iṣẹ ilera tabi ẹgbẹ awọn onimọ iṣẹgun kọ lati fi han pe wọn mọ si irinajo awọn dokita wọnyi.
nítorí pé apanirun ti dé sí i,àní ó ti dé sí Babiloni.
Ohun to tun ba ni lọkan jẹ nipe ko ni aworan ọmọ naa, nitori aworan kan ṣoṣo to ya wa lori ẹrọ ibanisọrọ t'omi gbe lọ.
Àwọn ọmọ Àbẹ̀ní, ọmọ Oótù Ifẹ̀
Wọ́n sáré kọjá lọ bíi koríko ojú omi,bí ẹyẹ idì tí ń fò fẹ̀ẹ̀ lọ bá ohun tí ó fẹ́ pa.
"Ọrọ ti akọwe agba gomina, Ọgbẹni Taiwo Adisa sọ fihan pẹlu akọlee ""Idaduro lẹnu iṣẹ"" pe oun n ṣe ifitonileti aṣẹ to wa latọdọ gomina, Seyi Makinde pe iṣẹ rẹ gẹgẹ bi kọmiṣana ti wa sopin ki eyi si waye kiakia."
Bí inú bá ń bí òmùgọ̀, kíá ni gbogbo eniyan yóo mọ̀,ṣugbọn ọlọ́gbọ́n kìí ka ọ̀rọ̀ àbùkù sí.
Koda, gbogbo aworan to wa nibẹ ko sẹni ti ko ni rii pe Olori laafin nla niyi, afi ẹni ti oju ba n dun.
Ileeṣẹ ọlọpaa doola ẹmi ọmọ imaamu atawọn meji mii ti wọn jigbe lọjọ Ileya lagbegbe Ọde Omi nipinlẹ Ogun.
Kingston to jẹ ọmọbibi orilẹ-ede Ghana lo foju ọmọ Amẹrika, Daniel Bryan gbo lẹ to fi gba ami ẹyẹ ijakadi WrestleMania.
Godswill Akpabio lati Udom Gabriel Emmanuel Ọpọlọ̀pọ eniyan lo gbagbọ wi pe Godswill Akpabio ni baba isalẹ fun wọn ni ipinlẹ Akwa Ibom.
Jìnnìjìnnì bo gbogbo àwọn ará Moabu nítorí àwọn ọmọ Israẹli.
FRSC: èyí kọ́ ni ìgbà àkọ́kọ́ tí èyí máa ṣẹlẹ̀
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Seyi Makinde ṣèlérí owó oṣù kẹtàlá fáwọn òṣìṣẹ́ Amotekun l' Oyo 4 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 10 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Oríṣun àwòrán, dawn commission Alaga ikọ Amọtẹkun ni ipinlẹ Ọyọ, Ajagunfẹyinti Olayinka Olayanju ti ṣalaye pe, awọn osisẹ ikọ Amọtẹkun ni ipinlẹ Õyọ yoo gba owo oṣu.
Ninalowo jẹwọ pe ẹkan ṣoṣo lohun fẹsẹ tẹ inu sọọṣi laye Arẹwa ọkunrin oṣere Yoruba, Bolanle Ninalowo lo jẹwọ ọrọ yii to si tun sọ awọn nkan mii to ni ṣe pẹlu ibagbepọ lọkọ laya.
Ọlọ́run fẹ́ràn ènìyàn, A máá ṣe ènìyàn gẹ́gẹ́ bí ọmọ.
A ní àfí ká ṣe ìwádìí nkan tó fa adùn inú àwọn nkan wọ̀nyí, kí a lè ṣe wọ́n ní ìlànà tiwa.
    Báyìí ni ọkùnrin náà sọ, àwọn àlejò wọ̀n-ọn nì sì dúpẹ́ lọ́wọ́ mi, lẹ́yìn náà o tún ń bá ọ̀rọ̀ rẹ̀ lọ ó ni:
Oríṣun àwòrán, @AAAjimobi/Twitter Seyi Makinde Gomina ipinlẹ Oyo, Seyi Makinde, ti ranṣẹ ibanikẹdun si ẹbí Abiola Ajimobi to d'oloogbe l'Ọjọbọ.
Amọ wọn ni bi ọmọ ko ba ba itan, yoo ba arọba, tii se baba itan.
Fun ọpọ ọmọ Kaarọ oo jiire, o lee dabi ọrọ rirun tori owe kan to ni, ‘obinrin ko le e laya laya, ko fi ale rẹ han ọkọ rẹ.
Baba Legba Bo tilẹ jẹ pe o ti ṣe die ti o ti kopa ninu ere agbelewo, aarin oṣẹ yii ni Alhaji Yekini Omobolanle, ti ọpọ mọ si Baba Legba jade laye.
Bo tilẹ jẹ pe Badirat tabi aafin ilu Ọyọ ko fi idi iroyin naa mulẹ titi di asiko yii, awọn akiyesi kan nipa nkan ti Badirat n fi sori ayelujara Instagram rẹ n fihan pe, o ṣe e ṣe ko jẹ ootọ ni iroyin naa.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Kii ṣe tuntun mọ pe ifigagbaga wa laarin Ronaldo ati Messi toun pẹlu jẹ odu agbabọọlu lagbaye.
Awon obinrin ko ni o seda ara won .
Yobo bọ si ipo yii lẹyin ti wọn fi ọwọ osi juwe ile fun Imama Amapakabo to di ipo na mu tẹlẹ.
Nítorí gbogbo eniyan ló ti dẹ́ṣẹ̀, tí wọ́n sì kùnà ògo Ọlọrun.
" Osa ilu iwo fikun pe, ọpọ eeyan lo n kọwe ẹhonu nipa Oluwo ati awọn iwa to n hu, koda, ohun tawọn eeyan maa n sọ nipa rẹ lawọn oju opo ibanidọrẹ lori ayelujara ko bojumu rara.
O ni ileeṣẹ Galaxy Backbone Limited, National Information Technology Development Agency, National Identity Management Commission, Nigeria Communication Commission, ati Nigeria Data Protection Regulation gbọdọ fọwọsowọpọ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Fídíò BBC yọ àwọn èèyàn FIFA níṣẹ́ ṣááju Russia 2018 Wọn tun ni ki Fatma ṣi maa ṣe iṣẹ akọwe ajọ FIFA lọ ṣugbọn o lè ya diẹ ninu iṣẹ rẹ fawọn oluranlọwọ.
Yemi Osinbajo: 'Orilẹede Naijiria n sọ ẹlẹwọn di ẹranko' Metuh ni lati yọju sile ẹjọ ni osu to n bọ Awọn asofin agba lorilẹede Naijiria n se agbeyẹwo awọn ofin to rọ amojuto ọgba ẹwọn lorilẹede Naijiria.
Okan lara ọmọ ile igbimọ asofin ti sọ pe  ibasepo ti ko dan monran wa  laarin awọn agbofinro  ati awọn ijọba ipinlẹ lo fa ijakulẹ ati eto aabo ti  ko monyan lori.
Ilẹ poyi ni ilu Iwo lọjọ Ẹti lẹyin ti awọn afọbajẹ kan dide pẹlu iwe ẹhonu si ijọba ipinlẹ ṣun lati rọ Oluwo loye nitori ohun ti wọn pe ni awọn iwa aṣemaṣe rẹ lori oye.
James Manager, Kemebradikumo Pondei Àwọn èèkàn nínú òṣèlú Nàìjíríà ti mínísítà fún ọ̀rọ̀ Niger Delta Godswill Akpabio nànka sí pé àwọn ni wọ́n ń gba kọngilá iṣẹ́ NDDC ti fèsì pé àhesọ ọ̀rọ̀ lásán ni ọ̀rọ̀ Akpabio, ati pe ko ni ẹ̀ri kankan.
Eniyan lè wà láàyè ní òwúrọ̀kí ó kú kí ó tó di ọjọ́ alẹ́,wọn a parun títí laeláìsí ẹni tí yóo bìkítà.
Dokita Igbekele jẹ ko di mimọ pe ni ilana iṣegun oyinbo, ko ṣee ṣe rara ki ẹya ẹjẹ eeyan yi pada O ni o ri bẹẹ nitori pe awọn onimọ iṣegun oyinbo ko gbagbọ ninu eyi rara lodi si bi awọn kan ṣe maa n ti ẹsin igbagbọ bọ ọ pe adura maa n yi ẹya ẹjẹ pada.
Aarẹ orilẹede Naijiria, Muhammadu Buhari ti fagile irinajo rẹ lọ si ilu Kigali tii se olu ilu orilẹede Rwanda fun bibuwọlu eto adehun fun idasilẹ ẹkun karakata ọfẹ laarin orilẹede gbogbo ni ilẹ Afirika (AfCFTA).
 Jordan, Lupita Nyong’o, Danai Gurira, Martin Freeman, Daniel Kaluuya, Letitia Wright, Winston Duke, Angela Bassett, Forest Whitaker, ati Andy Serkis.
Gbogbo àwọn ẹni tí ó wà lọ́dọ̀ mi ní kí n kí ọ.
4m òògùn ikọ́ codeine Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Fídíò òògùn ikọ́ Codeine: Ó dùn lóòtọ́ àmọ́ ewu ni O ní bótilẹ̀ jé pé ó yẹ kí o tàá fún àwọn tó tí gba ìwé àṣẹ láti ta irú ǹkan bẹ́ẹ̀ tí wọn sì ní ilé ìtajà òògùn ló yẹ kí ó máà tàá fún, sùgbọn ó bẹ̀rẹ̀ sí ní tàá fún àwọn ti wọn o ma ṣìí òògùn náà lò.
Bakan naa, ẹwu tabi sikẹẹti to ba soke lori orokun kii ṣe ohun ti wọn gba laye ayafi ki sikẹẹti skale si abẹ orokun daadaa.
Lati iwaju ita ijọ Peteru Mimọ (St Peter's Basilica) ni wọn yoo ti kede pe: Annutntio vobis gaudium magnum."
Ní ọjọ Arafat láwọn Alalaaji máa n tọrọ aforijin ẹsẹ, ti wọn sì máa n wà ìyọnu Allah.
A óo sọ gbogbo ilẹ̀ náà di pẹ̀tẹ́lẹ̀, láti Geba ní ìhà àríwá, títí dé Rimoni ní ìhà gúsù.
Ko da awọn obi awọn mejeeji jẹri wi pe iwuwasi awọn naa yatọ nile lati igba ti wọn ti bẹrẹ ẹkọ ''coding'' lori lori ẹrọ kọmputa.
Ikolu ti o waye laarin iko omo-ogun Somali ti won n daabobo agbegbe abule kan ati iko omo-ogun olote  al-Shabab ti sokunfa iku eniyan metala.
Àwọn òbí Jesu a máa lọ sí Àjọ̀dún Ìrékọjá ní Jerusalẹmu ní ọdọọdún.
Wo ọ̀nà tí o fi lè dáàbò bo ọmọ rẹ lọ́wọ́ COVID-19 níléèwé Kia ti iroyin gbode pe awọn ọmọ ẹgbẹ kan yọ Gomina Kayode Fayemi lẹgbẹ ni akọwe agba rẹ, Ọgbẹni Yinka Oyebode ti fesi si iroyin yi.
Ìyàtọ̀ wo ló wà láàrin Amotekun àtàwọn àjọ aláábò mìíràn Hope Uzodinma: Mo ti dárí ji àwọn tó jámi lólè ẹ́tọ̀ọ́ mí Ọdún 21 tí mo fí sun inú mótò- Ọmọ Naijiria ní Ilẹ̀ Gẹ̀ẹ́sì Gabriel sọ nipa awọn igbesẹ ati aṣẹ ti Ọgagun Yakubu Gowon pa lasiko ogun yii titi di ọjọ ti Phillip fi kede pe iran Igbo ko ja ogun Biafra mọ lọdun 1970 Ṣé lóòtọ́ ni pé ẹ̀wà jíjẹ máa ń jẹ́ kí èèyàn ga?
- Obasanjo gbarata Yoruba ni agba kii wa lọja ki ori ọmọ tuntun wọ, bẹẹ si ni agba ti ko ba kẹhun sọrọ, afaimọ ko ma kẹ itan sare to ba ya.
Paapaa julọ nipa awọn ile ti wọn ba gba lọwọ awọn to lu owo ilu ni ponpo.
 Ki a si maa gbadura fun itọni sọna Rẹ fun
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ilé ìtura Amazonia ní wọn kó àwọn ọmọ òhun pamọ́ si Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí NUJ ìpínlẹ Oyo bà àwọn ọmọ ẹgbẹ́ tó lọ ìpàdé tí Femi Fani Kayode pè ní Ibadan wí7 Owewe 2020 Fídíò, Natalia Mufutau ìyá Yakub, Kamil àti Adam sọ̀rọ̀ lórí bí wọ́n ń sọ èdè mẹ́rin pàpọ31 Ògún 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Àwọn ìgba mẹ́rin t'áwọn èèkàn tí dùbúlẹ̀ àìsàn lásìkò tí wọ́n ń jẹ́jọ́ níwájú adájọ́ 11 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Oríṣun àwòrán, other Ọga agba ile isẹ to n risi owo awọn osisẹfẹyinti tẹlẹri, Abdurasheed Maina, ti darapọ mọ awọn eeyan to daku nile ẹjọ lẹyin ti wọn fi ẹsun ikowojẹ kan wọn.
Ododo kuku ni iṣẹlẹ yii to si waye lagbegbe ariwa Samar.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, EndSars, EndSwat Protest: Òbí agbábọ̀ọ̀lù Gbenga Tiamiyu Kaka àtàwọn míì tí ọlapàá pa sọ̀r Fadeyi pari ọrọ rẹ pe ai kii fi ọrọ ijamba ọkọ to ọlọpaa leti ni kii jẹ ki awọn eeyan ri idajọ ododo gba lẹyin iru iṣẹlẹ bẹẹ.
Ó wúlò láti wo ara ríro sùgbọ́n ó leè jẹ́ kí inú rẹ máa dùn ládùnjù.
Ṣe ẹ mọ pe lọsẹ to kọja lawọn aṣofin ipinlẹ Eko paṣẹ pe ki Ambọde wa farahan niwaju ile naa ni Ọjọru ọgbọn ọjọ oṣu kẹwa lati wa wi tẹnu rẹ lori bi o ṣe na owo ti wọn ya sọtọ fun rira bọọsi bọgini akero BRT atawọn inawo akanṣe iṣẹ miran.
Èmi náà wá pinnu láti kọ ìwé sí ọ lẹ́sẹẹsẹ, ọlọ́lá jùlọ, Tiofilu, 
Ẹni tí ó bá jẹ ẹran ara mi, yóo yè nítorí tèmi.
Ewe, lara awon ti o lo kopa ninu ipade ohun ni: asofin Ben Bruce, ti o je igbakeji alaga igbimo to n mojuto eto iroyin ati igbodegba, asofin Monsurat Sunmonu, ti o je alaga igbimo to n mojuto oro ile okere ; ati eni owo Nnenna Ukeje, ti oun je alaga igbimo to n mojuto oro ile okere nile igbimo asoju-sofin.
OLUWA fi ara hàn wọ́n ninu ọ̀wọ̀n ìkùukùu ninu àgọ́ náà.
Kí ẹ fẹsẹ̀ múlẹ̀, kí ẹ máa dàgbà ninu rẹ̀, kí ẹ sì jẹ́ kí igbagbọ yín dúró ṣinṣin bí ẹ ti kọ́ láti ṣe, kí ẹ máa dúpẹ́ nígbà gbogbo.
Àkọlé àwòrán, Àwọn kan sọ pé oúńjẹ náà dùn lénu BBC News, Yorùbá Ìdí tí ẹ fi le è nígbàagbọ́ nínú ìròyìn BBC Ìlànà Lílò Nípa BBC Òfin Àṣírí Cookies Kàn sí.
Ọmọ ipinlẹ Ekiti ni, sugbọn ilu Ibadan ni wọn bi i si.
"Ni kia naa lo pada sinu ọkọ rẹ to si salọ"" Aladugbo miran Seyifunmi Akinola, salaye pe baba alawo kan tilẹ gbiyanju lati yọ ọta ibọn naa kuro lara Ọlọruntoba, ṣugbọn o ku nigba ti wọn n gbe e lọ fun itọju nile iwosan."
Won bura fun Fayemi gege bi gomina ipinle Ekiti lojo Isegun.
Day 19: Wo ohun àràmàndà tí àwọn olósèlú máa ń ṣe lásìkò ìbò #BBCNigeria2019 Ìgbìmọ̀ NJC sún ìgbẹ́jọ́ Onnoghen síwájú Kí ni àwọn olùdíje ìpínlẹ̀ Eko fẹ́ ṣe nípa ètò ìlera?
 báyìí ni ẹrú yìí ṣe gba ìtúsílẹ ̀ .
   Iwe abadofin odun 2019 , ni yoo se atunse si iwe ofin to ti wa tẹlẹ
Igbagbọ Idiagbon ni pe Naijiria yẹ ko le e da duro lati pese awọn eroja ta nilo fun awọn Ileesẹ nla nla wa labẹle.
    Ìgbà tí ọba gbọ́ bí gbogbo rẹ ti rí, ó pè àwọn ọmọ rẹ̀ mẹ́tẹ́ẹ̀ta, ó bá wọn sọ̀rọ̀ ó ní:
Áfíríkà yóò gba ife ẹ̀yẹ UEFA Champions league lónìí Akẹ́kọ̀ọ́ Poly Iree jáde láyé lẹ́yìn tó ṣubú ní gbọ̀ngàn iṣèdánwò SEC: Tinubu kò gbọdọ̀ ṣe olúdarí iléeṣẹ kankan fódùn márùn ún Iléeṣé MTN ti san bíliọnù N55 owó ìtanràn wọn tó kù -MTN Agbabọọlu ọmọ orilẹ-ede Spain naa darapọ mọ ẹgbẹ agbabọọlu Arsenal ni oṣu kinni, ọdun 2004 to si wa lara ikọ ti o ṣegun awọn agbọọlu to ku lati gba ife ẹyẹ Premier League ni ọdun 2003 si 2004.
Ó di olókìkí láàrin àwọn ọgbọ̀n ọ̀gágun; ṣugbọn òkìkí tirẹ̀ kò tó ti àwọn akọni mẹta náà.
Póópù Francis kúnlẹ fí ẹnu ko ẹsẹ̀ àwọn adarí orílẹ̀ède South Sudan
5 Kíyèsíi, a ti fa àwọn ohun wọ̀nyí lé ọ lọ́wọ́, ṣùgbọ́n báwo ni àwọn òfin rẹ ṣe le tó; kí o sì rántí bákannáà àwọn ìlérí tí a ṣe fún ọ, bí ìwọ kò bá ré wọn kọjá.
Àwọn àṣà àti ìse tó yọ obìnrin sílẹ̀ nílẹ̀ Yorùbá Lekan kingkong lọmọ Yorùbá tó ń fi òwe dárà lẹ́yìn odi Àwọn ọmọ Yoruba kẹ́dùn Sophie Oluwole tó kú lẹ́ni ọdún 83 Ìran Yorùbá: Àṣà ju àṣà lọ!
Bí wọ́n ti ń sọ àwọn nǹkan wọnyi lọ́wọ́, Jesu alára bá dúró láàrin wọn.
- Amina Zakari Àwọn òṣèré tíátà Yorùbá tó bá 2018 lọ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ìwà ipá nínú ìdílé máa ń bí ìgè àti àdùbí ni tó lè já sí ikú Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Àwọn gómìnà Ìwọ̀-Òòrùn Nàìjíríà ṣe ìpàdé láti gbógun ti ààbò Loni ni ipade ọhun n bẹrẹ.
Má ṣe jẹ́ kí àyà rẹ já rárá nítorí ibinu gbígbóná Resini ati Siria, ati ti ọmọ Remalaya, nítorí wọn kò yàtọ̀ sí àjókù igi iná meji tí ń rú èéfín.
Ó bá bèèrè, pé, “Ìwọ ta ni?
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù May 29, 2019: Láti 1999 títí di 2019, wo àwọn ààrẹ tó jẹ ní Nàìjíríà 27 Èbibi 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 28 Èbibi 2019 Laarin ọdun 1999 si ọdun 2019, aarẹ mẹrin ọtọọtọ lo ti dari orilẹede Naijiria latigba ijọba awa ara wa.
tí ó ní kí n sọ fún ẹ̀yin ọmọ Israẹli pé òun OLUWA sọ pé òun óo sọ ibi mímọ́ òun di aláìmọ́: ibi mímọ́ òun tí ẹ fi ń ṣògo, tí ó jẹ́ agbára yín, tí ẹ fẹ́ràn láti máa wò, tí ọkàn yín sì fẹ́.
Ó ṣeéṣe kí a pàṣẹ òfin Kónílé-ó-gbélé tuntun láìpẹ́ - Ìjọba ìpínlẹ́ Ekiti Iṣẹ́ ọpọlọ ló yẹ ká ṣe nínú tíátà, kìí ṣe àfihàn ara bíbó àbí ìhòòhò wa - Binta Mọgaji Wo àwọn ohun tó yẹ kí o mọ̀ nípa Pierre Nkurunziza, ààrẹ orílẹ̀-èdè Burundi tó dolóògbé Igbakejì ààrẹ ṣèpàdé pẹ̀lu àwọn gómìnà ilẹ̀ Yorùbá Oríṣun àwòrán, @toluogunlesi Ijọba apapọ lorilẹede Naijiria ati awọn Gomina ipinlẹ lẹkun iwọ oorun guusu Naijiria, to fi mọ agbẹjọro agba ati ọga agba ọlọpa ni Naijiria, ti fẹnuko lori ọrọ idasilẹ ikọ Amotekun.
Ẹ kò rí i pé ó sàn kí ẹnìkan kú fún àwọn eniyan jù pé kí gbogbo orílẹ̀-èdè ṣègbé!
Àjọ onísirò ní Nàíjíríà NBS kéde lọ́jọ́bọ pé àdínkù ti bá owó ọjà lábẹ́lé sí ìdá mẹ́tàlá lósù kẹta ọdún 2018.
Bẹẹ ni wọn fikun un pe, iye owo to le ni biliọnu, N8.
Bakan naa lo rọ gbogbo eeyan lati darapọ mọ eto ikede 'wọ ibomu rẹ l'Eko' iyẹn '#MaskUpLagos campaign' Nàìjíríà tún ní àkọsílẹ̀ ènìyàn 108 tó ní ààrùn coronavirus Oríṣun àwòrán, Getty Images Ajọ to n mojuto ajakalẹ aarun ni Naijiria, NCDC tun ti kede pe esi ayẹwo fihan pe eniyan mejidinlaadọfa lo tun ti ni coronavirus ni Naijiria.
Ní àkókò kan, kò sí ọba ní ilẹ̀ Israẹli, ati pé, ní àkókò náà, àwọn ẹ̀yà Dani ń wá ilẹ̀ tí wọn yóo gbà, tí wọn yóo sì máa gbé, nítorí pé, títí di àkókò yìí wọn kò tíì fún wọn ní ilẹ̀ kankan láàrin àwọn ẹ̀yà Israẹli.
Ṣugbọn nígbà tí Ọlọrun fi inú rere ati ìfẹ́ rẹ̀ sí àwa eniyan hàn, ó gbà wá là; 
Wọ́n fi iṣẹ́ tàn án wá sí Eko, kí wọ́n tó fún un ní HIV Ilé ẹjọ́ fún Elzakzaky àti ìyàwó ní ẹ̀tọ́ sí ètò ìwòsàn Lẹ́yìn òkò ọ̀rọ̀, Buhari àti Ọbasanjọ fẹ̀rín pàdé ara wọn l‘Abuja Wo ohun márùn-ún tó ń fa ìjàmbá iná nínú ilé Gbogbo ìran Yoruba lo gbà pé aríṣe ni aríkà; bẹẹ aríkà ni baba ìrègún ni ọrọ ile aye jẹ.
Snake bite: Ejò sàn adájọ South Africa tó lọ gbàfẹ ni Zambia pá
Gẹgẹ bi ọrọ ti amofin kan ni fasiti Havard, Laurence Tribe ṣe sọ, Twitter kii fi ẹtọ awọn eeyan dun wọn lati sọ ohunkohun to ba wa lọkan wọn.
Lara wọn niyii to kan ọmọ Yoruba yala nipa ipinlẹ ti wọn n ṣoju tabi pe wọn jẹ ọmọ Yoruba: iii.
Ni ipari, Dokita Adan sọ fun BBC pe: Awa ki ṣe ẹgbẹ oṣelu kankan, a ko da ile iṣẹ yii silẹ lati fi jèrè bẹẹ a ko mọ ohun ti ẹgbẹ́ Al-Shabab le maa wa lọwọ wa.
Kíkú tí ó kú jẹ́ pé ó ti kú ikú tí ó níláti kú lẹ́ẹ̀kan; yíyè tí ó yè, ó yè fún ògo Ọlọrun.
 ibi ti àwọn kan ti ń gbá adùn ní ikọ ̀ lé ọ ̀ run ni a tún ti rí àwọn kan tí ń gbá ìyà .
Ẹ̀jẹ̀ àwọn tí ó pa yóo wà lórí rẹ̀ ati lórí àwọn arọmọdọmọ rẹ̀ títí lae, ṣugbọn OLUWA yóo fún Dafidi ati àwọn arọmọdọmọ rẹ̀ ati ilé rẹ̀ ati ìjọba rẹ̀ ní alaafia títí lae.
Nígbà tí ó yá, ó kúrò ní Nẹgẹbu, ó ń lọ sí Bẹtẹli, ó dé ibi tí ó kọ́kọ́ pàgọ́ sí 
ipo aare sile , leyin ti o ti kuna lati jawe olubori ninu eto idibo to waye
Fi àmì ojurere rẹ hàn mí,kí àwọn tí ó kórìíra mi lè rí i,kí ojú sì tì wọ́n;nítorí pé ìwọ, OLUWA, ni o ràn mí lọ́wọ́,tí o sì tù mí ninu.
igbimo asoju  asofin to yẹ ko waye lonii
Ó lóyún, ó bí ọmọkunrin kan, Juda sọ ọmọ náà ní Eri.
Yà wá sọ́dọ̀ mi, má bẹ̀rù.
Ọmọ orileede Chile naa darapọ mọ Inter Milan fun saa ọdun kan lẹyin to lo oṣu mọkandilogun ni Old Trafford.
Ẹ̀yin ni ẹ̀ ń ṣòwò káàkiri àgbáyé.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Iberemi Osadebe da Gospel Salvation Christian Church rú lásìkò ìgbéyàwó ní Father's Church ni Eko 1 Owewe 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 5 Owewe 2020 Oríṣun àwòrán, others Ọkunrin kan da sọọsi ru lasiko isin igbeyawo, o ni oun lo n kọkọ fẹ tẹlẹ Darudapọ lo bẹ silẹ ninu ijọ Great Salvation Christian Church ti gbogbo eniyan mọ si Father's Church ni agbegbe Ako Aro, Ifako-Ijaye nipinlẹ Eko lọjọ Satide.
Bakan naa ni nkan ṣe ri fun awọn to n rin lojupopo.
Nígbà tí ó dé òdìkejì òkun, ní ilẹ̀ àwọn ará Gadara, àwọn ọkunrin meji tí wọn ní ẹ̀mí èṣù jáde láti inú itẹ́ òkú, wọ́n wá pàdé rẹ̀.
Nigba to n ba BBC Yoruba sọrọ, Ọrangun ile Ila, Ọba Wahab Kayode Oyedọtun, Bibire Kinni salaye pe, ko si ẹni to kanro Oluwo sinu tabi korira rẹ tori pe o n se akọ, asa ilẹ wa naa lo n gbe ga, eyi si kọ lo jẹ kawọn juwe ọna ile fun.
Nítorí náà inú mi dùn, mo bú sẹ́rìn-ín.
Bi awọn ipinlẹ to ku ṣe lọ ree: FCT-79 Lagos-59 Kaduna-56 Katsina-37 Nasarawa-30 Kano-25 Edo-18 Gombe-14 Kebbi-12 Akwa Ibom-7 Rivers-7 Sokoto-7 Abia-3 Ogun-1 Cross River -1 Èèyàn mẹ́ta jẹ́ Ọlọrun nípè, 501 míràn tún fara kásá Coronavirus ní Naijiria Oríṣun àwòrán, @NCDCgov Ajọ NCDC tun ti kede esi ayẹwo ọkanlelẹẹdẹgbẹta eeyan to tun ṣẹṣẹ ni Coronavirus ni Naijiria.
Ni bayii, ile igbinmo  asoju tun fenu adehun ko lati tun sagbeyewo iwe
Ṣugbọn Onani mọ̀ pé ọmọ tí opó náà bá bí kò ní jẹ́ ti òun, nítorí náà, nígbàkúùgbà tí ó bá ń bá opó yìí lòpọ̀, yóo sì da nǹkan ọkunrin rẹ̀ sílẹ̀, kí ó má baà bí ọmọ tí yóo rọ́pò arakunrin rẹ̀.
Iwọde naa to ti n gbẹnule ọjọ kẹjọ bayii ni awọn ọdọ Naijiria fi n bere fun fifopin si iwa Baṣọrun Gaa ti awọn oṣiṣẹ ẹka ileeṣẹ ọlọpaa, SARS, n wu si awọn ọdọ ti wọn n fẹsun iwa jibiti kan lọna aitọ.
Iwe mẹwaa pere ni won yoo tẹ sita ni apapo fun sisami ayẹyẹ ọdun mẹwaa PEN ni ṣiṣe atilẹyin fun ominira awọn onkowe ninu ewu.
Má ṣé tọrọ aforijin lọ́wọ́ Buhari lásìkò àbẹwò rẹ- South Africa Díẹ̀ lára àwọn òṣèré Nollywood ti wọ́n ti ṣe ìgbéyàwó lẹ́ẹ̀kejì Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Adeniyi ni, lẹsẹkẹsẹ ni oun rii pe Baba ko mi daadaa mọ ti wọn si sare gbe baba lọ sile iwosan UCH to jẹ ti Fasiti Ibadan nibi ti wọn ti fidiẹ mulẹ pe baba ti re ibi ti awọn agba maa n re.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Manchester United: Gunnar Solskjaer di akónimọ̀ọ́gbá tuntun 28 Ẹrẹ̀nà 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Gunnar Solskjaer ti jáwé olúborí ìfẹsẹ́wọnsẹ̀ eré bọ́ọ̀lù márìnlá nínú mọ́kàndínlógún láti ìgbà tí ó ti jẹ́ adelé fún osù mẹ́rin.
Ó wí fún wa pẹ̀lú pé nígbà tí a bá dé ọ̀dọ̀ wọn gan-an, àyà wá yóò já, irun orí wa yóó sì dìde.
Tabi pé bí o bá ń ṣe ẹlẹ́yà ẹnikẹ́ni kò lè dójútì ọ́?
Ọbasa, ẹni ti Olori Ọmọ ẹg̣bẹ Ọṣelu to pọ julọ ninu Ile, Aṣofin
Aare Muhammadu Buhari ti pase fawon osise eleto aabo gbogbo lati lo sawari awon akekoobinrin tile iwe Government Girls Technical College, Dapchi, nipinle Yobe bi obinrin se n wa nkan obe lawari.
Ileesẹ okeere orile-ẹde Naijiria ati awọn ọfisi to rọ mọ wa labẹ aabo ofin yi.
Bakan naa lo gba bọọlu loke okun fun awọn orilẹ-ede bii Ivory Coast (African Sports0 , Korea (Anyang LG Cheetahs), Austria (SK Sturm Graz) ati ẹgbẹ agbabọlu Mohun Bagan AC ni orilẹ-ede India.
O tẹsiwaju pẹlu ọrọ rẹ pe, ọrọ Naijiria ti kọja afarada bayii, o ni ibẹru bojo wa nibi gbogbo.
Lẹyin ti gbogbo nkan walẹ tan, ọpọ ọkọ ni wọn bajẹ ti awọn ẹgbẹ mejeeji si n naka si ara wọn pe ẹnikeji lo kọkọ da wahala silẹ.
Ìmọ́lẹ̀ olódodo a máa fi ayọ̀ tàn,ṣugbọn fìtílà eniyan burúkú yóo kú.
O sọ eyi nitori ailera rẹ.
Ará àdúgbò á dá owó ki àwọn òṣiṣẹ́ ilé-iṣẹ́ mọ̀nàmọ́ná tó wá tú ohun ti ó bàjẹ́ tàbi ohun ti wọn yọ ṣe.
Dino Melaye to jẹ Sẹnẹto to n ṣoju ẹkun idibo iwọ oorun Kogi ni oludije kẹta labẹ asia PDP ti yoo gba fọọmu.
 Àfikún yìí lè dúró fún ìsòrí òrò kan tàbí àpólà .
Minisita fun eto ilera naa wa rọ awọn orilẹede to ku lagbaye lati mura sii ki wọn ma a ṣe ayẹwo awọn eniyan wọn ti o ba n jade kuro ni orilẹede wọn lọ si ibomiran.
Toò, ó tún dìgbà kan ná o ẹ̀yin ẹ̀dá pàtàkì mi.
Gabon: Àlááfíà ti padà, a ti mú àwọn ológun tó fẹ́ gba ìjọba
"Ohun tí a mọ̀ nìyí nípa gbọ́nmi síi omi ò tó lórí ọ̀rọ̀ oyè Babaloja-General ní ìpínlẹ̀ Oyo Iléẹjọ gíga jùlọ da ẹjọ́ SDP àti PDP nù, wọ́n ní Yahaya Bello ló wọlé ìbò gómìnà Kogi Ààrẹ Buhari buwọ́lu gbígbé ìṣàkoso nọ́mbà ìdánimọ̀ (NIMC) lọ sí ẹ̀ka ìjọba tó ń rí sí ìbáraẹnisọ̀rọ̀ Wọ́n ti sún ìdájọ́ àwọn sójà tó pa ìyá àti ọmọ ní ọdun 2018 sí oṣù tó m bọ̀ Kanrani ni: ""Lẹyin nkan bu oṣu diẹ ti mọ de lati Canada, ile iṣe ipolowo ọja ati yiya ere amohunmaworan mi jona raurau, ti irinṣe to le ni miliọnu lọna ọgbọn Naira si jọna patapata."
O tun sọ fun mi pe oun yoo maa sun oorun ni ile emi ati iyawo tuntun to fẹ Àṣírí ńlá tó ń bẹ láàrín Alaafin àtàwọn onílù rẹ̀ rèé Oyedepo àti ìjọba ń tahùn síra lórí bí ìjọba ṣe ń gba àkóso àwọn ilé ìjọsìn EFCC tún gbé Mompha lórí ẹ̀ṣùn lílu jìbìtì lórí ayélujára Ọlọ́pàá méjì wọ gàù lóri bí afurasí apanìyàn l‘Akinyele ṣe sá lọ Abilekọ Idowu faraya pe: Inu bi mi gidigidi nitori eyi ko si ninu adehun ti a jijọ ṣe, itiju nla leyi mu ba mi ladugbo ati ninu ẹbi.
Lẹ́yìn ìgbà tí Hesironi kú, Kalebu ṣú Efurata, iyawo baba rẹ̀ lópó, ó sì bí Aṣuri, tíí ṣe baba Tekoa.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Akin Oyebode: ohun tí wọ́n fẹ́ jẹ ni wọ́n ń wá Onimọ nipa ofin ilẹ okeere ati abẹle, Ọjọgbọn Akin Oyebọde ti sọ wipe awọn adari ilẹ Europe n wa si orilẹede Naijiria nitori oun ti wọn o jẹ.
Ninu idahun tirẹ, Ademola Adeleke to jẹ oludije ninu idibo naa to waye nin 2019 ni yatọ fun gbogbo ikunsinu ti oun ni ati gbogbo ohun ti inu oun ko dun si, ohunkohun ti ile ẹjọ giga ju l ba sọ ni abẹ ge.
Lisa Li jẹ ọkan lara awọn to ni ẹka iroyin blog ti ara rẹ lori ayelujara to dẹ ni awọn to le ni Idakeji bi o ṣẹ n ṣe loju opo ẹrọ ayelujara ni arẹwa ọmọ obinrin naa gẹgẹ bi fidio ti iya onile rẹ fihan sita ṣe ri.
''Ṣùgbọ́n tí o bá ri i pé iléèṣẹ́ ìròyìn bi i méjì sí mẹ́ta ló gbé ìròyìn nàá, ó le finilọ́kàn balẹ̀ díẹ̀.
Se Aare Donald Trump yóò sọ iru ọrọ yi sile asofin ile Amerika?
alaga igbimọ alabẹ-sekele ọhun lo sọ eyi  di mimọ lasiko to n baa won akoroyin soro ni
" Bakan naa lo fi kun pe ilana tuntun naa yoo mu ki eto aabo ko fẹsẹ mulẹ daada nile aṣofin.
Àwọn oriṣa ayé yìí ni wọ́n fọ́ irú àwọn ẹni bẹ́ẹ̀ lójú, tí ọkàn wọn kò fi lè gbàgbọ́.
A tun mọ wipe awọn ologun wa, to n sọ ọna to lọ si ilu naa, nitori gomina ipinlẹ Yobe, sọwipe awọn agbebọn naa, sọsẹ lẹyin wakati diẹ tawọn ọmọogun kuro loju popo ti won n sọ.
Falana ni ti Aarẹ Buhari ba fẹ ṣe afiwe, ni ṣe lo yẹ ko bẹrẹ lati owo oṣu to kere ju ti awọn ọmọ orilẹ-ede Saudi Arabia n gba si ti Naijiria ko to sọrọ nipa iye ti wọn n san fun owo epo.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Akomolede ati Aṣa lori BBC:Wo ìrúfẹ́ ìgbeyàwó méje tó wà nílẹ̀ Yorùbá àti ojúṣe Alárinà 4) Oriṣi Igbeyawo meje to wa ni ilẹ Yoruba ni olukọ wa, Aya Adetunji fi ara balẹ kọ wa lọsẹ naa.
 Awọn obi ti wa n jade wa lati sọ nipa bi ọkunrin naa se n ba awọn ọmọ tuntun wọn lo lati ẹyin wa."
Ann Grace Aguti, Obìnrin kan to fẹ́ ọkọ mẹ́ta lẹ́ẹkàn ṣoṣo A kò tíì rí ọmọ ọdún méjì tó kó sí kànga- Olootu India Ebi ló ń pami ti mo fi já sọọbu láti jí bisikitì- Afurasi Asuquo Ilẹ̀ Gẹ̀ẹ́sì yóò kúrò pátápátá lára àjọ EU ní Jan 31 ọdún 2020 Lẹ́yìn ìpàdé òní l‘Abuja, ṣé ASUU yóò yanṣẹ́ lódì àbí bẹ́ẹ̀kọ́?
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Fayose: Dídarapọ̀ mọ́ APC dàbí bíbá adigunjàlè ṣ'ọ̀rẹ́ ni 6 Ògún 2018 Oríṣun àwòrán, @GovAyoFayose Àkọlé àwòrán, Fayose jẹ alatako ẹgbẹ oṣelu All Progressives Congress 'Irọ́ ni pé èmi àti Oluṣọla Ẹlẹka wa Tinubu lọ' Gomina ipinlẹ Ekiti, Ayodele Fayose ti ni ko si ootọ kankan ninu iroyin to gba igboro pe, oun ni nkan 'ṣe pẹlu Asiwaju ẹgbẹ oṣelu All Progressives Congress, APC, Asiwaju Bola Tinubu.
Awon asofin ohun wa ninu isinmi olodoodun won, eleyi ti o bere ninu osu keje odun ti a wayii, sugbon won ranse pe won lati wa jiroro lori asaaro eto isuna.
#Democracy Day: Pápá ìṣeré Abuja di MKO Abiola Stadium BBC Yorùba balẹ̀ bàgẹ̀ s'ílée MKO Abiola l'Eko Ofin ti f'àyè gba ìbálòpọ̀ Akọs'akọ, Abos'abo ní Botswana Ti a ko ba gbagbe, Atiku Abubakar to jẹ oludije fun ipo aarẹ labẹ ẹgbẹ oselu PDP ni Ọbasanjo se atilẹyin fun, ninu idibo gbogbo-gboo to waye lọdun 2019.
"Yakubu ni '' Eyi wa láti wa ojúùtú sí ọ̀rọ̀ ìyànṣẹ́lódì tó ń lọwọ́, sùgbọ́n ìpàdé náà kò ní kọjáa ọ̀rọ̀ nípa ìmúrasílẹ̀ fún ìdìbò gbogboogbo tó n bọ̀ nínú oṣù kejì ọdún"" "" Ǹkan tó kàn wá jùlọ ní àwọn ipa pàtàkì tí àwọn olukọ tí INEC ti yan ní àwọn Fasiti láti kopa nínú ètò ìdìbò yoo ni."
Oríṣun àwòrán, NCDC Àkọlé àwòrán, Àjọ NCDC kéde èèyàn 248 míràn tó ni ààrùn Covid-19 lórílẹ̀-èdè Naijíríà Coronavirus ṣekúpa èèyàn mẹrin l'Abuja, méjì ní Kebbi, ẹni márùnlélógójì jàjàbọ́- NCDC NCDC update on coronavirus: Covid-19 ṣekúpa èèyàn mẹrin l'Abuja, méjì ní Kebbi, ẹni márùnlélógójì jàjàbọ Oríṣun àwòrán, Twitter/todayng Aarun coronavirus ti ṣekupa eeyan mẹrin ni olu ilu orilẹede Naijiria, Abuja.
Pẹ̀lẹ́ o, èkúté, bá mi kí àwọn ará ilé rẹ; nìgbà tí mo bá sọ̀kalẹ̀ tán, n ó wáá mọ ihò rẹ, ṣùgbọ́n bí n kò bá sì lè sọ̀kalẹ̀ mọ́, a jẹ́ pé a lè ṣàìtáun rí ara wa mọ́ o.
O so pe,, “Nigbati Mo bere si ni n gba boolu afigigba, orisirisi idojuko ni Mo la koja; Mi o ni awon ohun elo kankan.
Bí mààlúù náà bá kan ẹrú ẹnìkan pa, kì báà ṣe ẹrukunrin tabi ẹrubinrin, ẹni tí ó ni mààlúù náà níláti san ọgbọ̀n ṣekeli fadaka fún ẹni tí ó ni ẹrú tí mààlúù pa, kí wọ́n sì sọ mààlúù náà ní òkúta pa.
“Ṣugbọn nígbà tí ẹ bá rí ẹ̀gbin burúkú náà tí ó dúró níbi tí kò yẹ– (kí ó yé ẹni tí ń ka ìwé yìí)– nígbà náà, kí àwọn tí ó wà ní ilẹ̀ Judia sálọ sí orí òkè.
Nítorí Sioni, ń kò ní dákẹ́,nítorí Jerusalẹmu, ń kò ní sinmi,títí ìdáláre rẹ̀ yóo fi yọ bí ìmọ́lẹ̀,tí ìgbàlà rẹ̀ yóo sì tàn bí àtùpà.
Arabinrin Ogunbadejo wa sọ pe bi o ti wu ki igbyawo ori ayelujara tẹ ọpọlọpọ lọrun to, o ṣi ṣe pataki ki wọn lọ ṣegbeyawo ni ile ẹjọ nitori bi ọlọjọ ba de tabi atubọtan ohun ti wọn ṣe lọjọ iwaju.
Ẹlẹ́tàn kankan kò ní gbé inú ilé mi;bẹ́ẹ̀ ni òpùrọ́ kankan kò ní dúró níwájú mi.
"Ọkan lara awọn owe to n parọwa fun wa ni ""Ṣebotimọ Ẹlẹwa Sapọn"", awọn ohun to si yẹ ka mọ nipa owe naa ree: Itan nipa owe ‘Sebótimọ Ẹlẹwa Ṣàpọ́n Obinrin kan wa nilu Abẹokuta to n ta ẹwa sise ni adugbo Sàpọ́n nilu Abẹokuta, tii se olu ilu nipinlẹ Ogun bayii."
a tún múra, à ń bá iṣẹ́ náà lọ.
Ohun gbogbo tí mò ń rí ní ààfin tẹ́ mi lọ́rùn, èmí ní mo ní ayé mi- Olori Aanu Àwọn ǹkan tí ó yẹ kí o mọ̀ nípa 'Sharia Law' ní Nàìjíríà Ọwọ́ ọlọ́pàá ìpínlẹ̀ Kebbi tẹ bàbá àti ìyàwó rẹ̀ méjì fún pé wọn so ọmọ pọ̀ mọ́ ewúrẹ́ fún ọdún méjì Diezani gan an ní Hushmummy tó ń bú àwọn Yahoo boys- Àwọn Ọmọ Naijiria lórí Twitter Nítorí pé mo gba ẹ̀há kò ní kí ń ṣọlẹ̀ tàbí ṣagbe- Ẹ̀lẹ́hàá Amina Èdè Yorùbá dùn lẹ́nu àwọn ọmọ òyìnbó yìí ní Michigan!
Oríṣun àwòrán, Getty Images Ènìyàn 721 fi ayédèrú ìwé ẹ̀rí gba iṣẹ́ ìjọba àpapọ̀ - ICPC Iṣọla Oyenusi rèé, ẹnití ìfẹ́ obìnrin ṣun dé ìwà ìdigunjalè Buhari yan Kyari ní olùdarí tuntun fún àjọ NNPC À fẹ́ àjọṣepọ̀ aládàníi láti sọ ọdún Ọṣun Oṣogbo di káríayé - Ìjọba Ọṣun Ọdún Odùduwa lórílẹ̀èdè AustriaBáwo ni abẹ́rẹ́ àjẹsára ṣe bẹ̀rẹ̀?
Nítorí èyí ẹsẹ̀ kan náà nì wọ́n pa àgbọ̀nrin olè tí ó ń gun orí ọ̀pẹ kiri.
Wo orúkọ àwọn ẹ̀yà ara rẹ̀ ní èdé Yorùbá Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
7 Nítorínáà, ẹ̀yin ti gba agbára kan náà, àti ìgbàgbọ́ kan náà, àti ẹ̀bùn kan náà gẹ́gẹ́bí ti òun.
Ní nǹkan bíi ọdún kan ó lé díẹ̀ sí iẹ̀yin obinrin tí ẹ wà ninu ìdẹ̀ra; ẹ ó rí ìdààmúnítorí pé àkókò ìkórè yóo kọjá,èso àjàrà kò sì ní sí lórí igi mọ́.
I Language Centre: Yorùbá ló làṣà àti èdè Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ U.
Nibayii, Orilẹede Naijiria ti ni eniyan mejidinlogojilelẹlọọdurun(5,959) lo ti ni arun Coronavirus ni Naijiria.
Ẹ mọ gbogbo ibi tíí máa ń sá pamọ́ sí dájúdájú, kí ẹ sì wá ròyìn fún mi.
Iroyin yii ka gbogbo aye laya to si mu ki ọpọ o maa ṣe haa hin, ki ree?
Ni ti ọga agba ajọ NCDC, Chikwe Ihekweazu, o ni oun mọ pe erongba rere ni awọn aṣofin ni, ti wọn ṣe n gbero lati gbe ofin ọhun kalẹ, ṣugbọn kii ṣẹ asiko lo yẹ ki wọn daba rẹ.
Lọdun 2002 nigba ti irufẹ iṣẹlẹ waye lorilẹede Venezuela nigba ti awọn ologun fẹ ditẹ gbajọba aarẹ Hugo Chavez ṣugbọn wọn kuna.
Ikorajọpọ wọn ni lati ma a kọ awọn obinrin lati dagba ninu ẹmi.
Baba Alatika wa kede pe oun n fẹ ọjọ ọla rere fun orin Fuji, ti oun ko si fẹ ki olorin Fuji kankan ja mọ nitori orogun owo, bakan naa lo si gba awọn olorin iwoyi nimọran lati mase maa fi ede ajeji kọ orin Fuji nitori tiwa n tiwa, akisa ni ti aatan.
Eyi ni ọrọ iwuri to ti ẹnu tọkọtaya Omoniyi ati Elizabeth Oke, ti wọn ni ipenija oju jade lasiko ti wọn n ba BBC Yoruba sọrọ nilu Ado Ekiti.
0 13 Agbegbe Guusu Sahara 1 0.
2bn fún Obanikoro Lori ẹrọ ayelujara, awọn ololufẹ rẹ ti n ki i pẹlu #27GoldenYearsOfSRK (Shah Rukh Khan Guide at 27 years) lati ki ku oriire.
Yóo sì fi ògo rẹ̀ hànníwájú àwọn àgbààgbà wọn.
Bi o ti le je pe, orile-ede Russia ohun lo sagbateru idije agbaye naa, sugbon, “bi irin ba kan rin, okan yoo te fun kan” ni oro ohun ri, leyin ti iko agbaboolu Uruguay fagbahan iko naa pelu ami-ayo meta sodo(3-0).
Ó jẹ́ ẹni tí ó sanra púpọ̀ ó sì yà mi lẹ́nu bí òun ti ṣe lọ ni orí ire bẹ́ẹ̀, ìgbà tí Ẹlẹ́gbára ti tú wa ká tí òun sì ti rọra fi ara pamọ́ sínú igbó ṣúúrú kan, Ẹlẹ́gbára kò rii títí gbogbo wa fi ń sá gun òkè sá gun gègéle.
Oríṣun àwòrán, others Àkọlé àwòrán, Ewu ni ẹgbẹ́ ajijagbara IS jẹ fun gbogbo agbaye Yemen: Oṣu Kọkanla, ọdun 2014 lo kede pe oun ti da ẹka silẹ ni Yemen.
Má ṣe yẹsẹ̀ kúrò ninu rẹ̀ sí ọ̀tún, tabi sí òsì, kí gbogbo ohun tí o bá dáwọ́ lé níbikíbi tí o bá lọ lè máa yọrí sí rere.
Nigba to n dahun ibeere lori iye eeyan to ku lasiko idibo ni ipinlẹ Kogi, lẹyin ti iroyin fi idi rẹ mulẹ pe eeyan mẹta lawọn afunrasi janduku kan ti wọn wọ aṣọ ọlọpaa yinbọn pa lasiko idibo naa, alukoro ileeṣẹ ọlọpaa lorilẹede Naijiria naa ni oun ko tii le sọ ni pato iye awọn eeyan to padanu ẹmi wọn lasiko idibo naa.
Kódà, ọmọ Ibrahim tí orúkọ rẹ̀ ń jẹ́ Isaac ni babańlá àwọn ẹ̀yà Isreal àti Juda.
Wọn á gbẹ́ kòtò ninu àfonífojì,níbi tí ó jìnnà sí ibi tí eniyan ń gbé,àwọn arìnrìnàjò á gbàgbé wọn,wọn á takété sí àwọn eniyan, wọn á sì máa rọ̀ dirodiro sọ́tùn-ún sósì.
Gẹgẹ bi àsọtẹ́lẹ̀, wọn pe Olóri Ẹrú jade, wọn si ko gbogbo ohun ini Bàbá ti o di Oloogbe fún.
 Mamood wa ni ajo eleto idibo wa ni ki gbogbo awon omo orile ede Naijiria
Diẹ lara awọn oluṣeto ni a ti ri olorin takasufe, oṣere tiata ati awọn gbajumọ kaakiri agbaye.
Ki ni a o sọ lẹyin ti ọlọjọ ba de fun ẹyin naa?
Igun igbakeji gomina Ondo, Agboọla Ajayi ṣalaye pe eyi ko ṣokunkun si awọn nitoripe ọbẹ to dun ni Agboọla Ajayi gbogbo awọn ẹgbẹ oṣelu lo si fẹ bula nibẹ.
Nigeria swearing-in: Ètò ìbúrawọlé káàkiri Nàìjíríà Sẹ́nétọ̀ Dino Melaye kéde láti dupò gómìnà Kogi Ibanuje d'orí agbà k'odò, Ruiz fi ẹ̀ṣẹ́ sọ Anthony Joshua di ọmọ ológo àná Kí ló ṣe ikú pa Adewura Latifat Bello lẹ́yìn ọ̀sẹ̀ méjì tí wọ́n ń wá a?
Bẹ́ẹ̀ ni a ṣe tí a sọ ọ̀kan nínú àwọn ènìyàn wa nù, Ọ̀gbẹ́ni Àgùntàn-ìnàkí, dọ̀ǹgíṣọlá ọkùnrin; nígbà tí gbogbo wa sì ń sọkún Ìjàǹbáforítì kò sọkùn rárá, dípò bẹ́ẹ̀ ó bẹ̀rẹ̀ sí súfèé ó ń kọrin òwe wí pé, ‘Afọ́jú tí ó di ojú tí ó wí pé òun kò ríran, ìgbà tí kò sùn kí ló rí, aṣeni ṣe ara rẹ̀.
kí OLUWA lè lé àwọn ọ̀tá yín jáde fun yín, bí ó ti ṣèlérí.
Ọjọgbọn Banji ni o ṣe pataki lati wo awọn ipenija to n doju kọ ilẹ Yoruba paapa julọ eleyi to ni ṣe pẹlu aabo.
Kani wipe o ti bẹrẹ isẹ lati ọdun 1931, o ba ti maa gba iye owo wọn bayii.
Labour Congress ,NLC) ni ipinle Ondo ti ro ile igbimo asoju to n sẹsẹ wọle
Bí ó bá ṣe bẹ́ẹ̀, inú kòtò ni àwọn mejeeji yóo bá ara wọn.
Ìròyìn fi kún pé òfin náà wáye nítori pé àwọn agbásùmọmi tí n dúnkokó mọ́ ìjọba.
Ní àkọkọ, o gbọ̀dọ kó àwọn aran náà nítori o le fo ibuso mẹẹdogun lẹ́ẹ̀kan náà.
Iléẹjọ́ gba onídùròó El-Zakzaky, ó ní kó lọ gba ìtọ́jú lókè òkun Ìròyìn tó ń tẹ̀ wa lọ́wọ́lọ́wọ́ ní sọ pé ileẹjọ giga ilu Kaduna, ti gba oniduro olori ẹsin Shiite, Ibrahim El-Zakzaky ati iyawo rẹ.
Aṣofin Braimoh fi kun ọrọ rẹ, pe ofin naa yoo tun le mojuto iwa awọn oniṣegun ibilẹ kan ti wọn maa n lu awọn alarun ọpọlọ bayii ni ilukulu.
com Ti o ba ti wọ ọ tan, ri i daju pe o bo imu ati ẹnu rẹ daada titi de abẹ àgbọ̀n rẹ.
" Ó ní ní kété ti àwọn ba ti mọ àsìkò tí tí ilé ìwé yóò wọlé padà làwọn yoo ti fi àwọn ìlànà tí àwọn ilé ẹ̀kọ́ yóò maa tẹ̀lé síta.
Lẹyin naa ni wọn kede ẹnikan to ni nkan ṣe pẹlu ọmọ orilẹ-ede Italy naa nipinlẹ Ogun.
Nítorí bí àwọn tí kì í ṣe Juu ti pín ninu àwọn nǹkan ti ẹ̀mí ti àwọn onigbagbọ láti Jerusalẹmu, ó yẹ kí wọ́n kà á sí iṣẹ́ ìsìn láti ràn wọ́n lọ́wọ́ pẹlu ohun ìní wọn.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Shiite: Ẹ̀mí àti ara wa kọ ohun tí ìjọba ń ṣe sìwa láti 2015 Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Shiite: Ẹ̀mí àti ara wa kọ ohun tí ìjọba ń ṣe sìwa láti 2015 29 Agẹmo 2019 O lé ni ẹgbẹrun kan ninu wa ni Islamic Movement of Nigeria.
Nítorí náà, ààbò Farao yóo di ìtìjú fún wọn,ibi ìpamọ́ abẹ́ Ijipti yóo di ìrẹ̀sílẹ̀ fún wọn.
lorile ede naa, Abdelghani Hamel  ti aare
Jesu dá wọn lóhùn pé, “Mo fẹ́ kí ẹ mọ̀ dájúdájú pé, bí ẹ bá ní igbagbọ, láì ṣiyèméjì, ohun tí ó ṣẹlẹ̀ sí igi ọ̀pọ̀tọ́ yìí nìkan kọ́ ni ẹ óo ṣe, ṣugbọn bí ẹ bá sọ fún òkè yìí pé, ‘Dìde, kí o lọ rì sinu òkun,’ bẹ́ẹ̀ ni yóo rí.
Bí ọwọ́ ọlọ́pàá Sharia Kano ṣé tẹ ọkùnrin 26 tó mura bi obìnrin Àkọlé àwòrán, Yan Daudu lorukọ ti wọn p e awọn ọkunrin to n mura bi ọkunrin ni ilẹ Hausa Ọwọ ọlọpaa Ṣẹria ti wọn pe ni 'Hisbah Police' ti tẹ awọn ọkunrin mẹrindinlọgbọn kan ti wọn mura bi obinrin ni ilu Kano.
Wúrà ni wọ́n fi ṣe ìgbàyà wọn.
Ó sọ òfin ati àwọn ìlànà ati àṣẹ di nǹkan yẹpẹrẹ, kí ó lè sọ àwọn mejeeji di ẹ̀dá titun kan náà ninu ara rẹ̀.
Mali pa Argentina lẹ́kún kúrò ni FIFA U-20 Ìgbájú ìgbámú ni Senegal fi lé Nàìjíríà kùrò ní ìdíje ife àgbáyé FIFA U-20 Buhari: Ẹni ibi tí kò ṣeé má ní làwọn ará Abuja Trump ti gbé òdòdó ìrántí sójú oórì akọni lójú ìjà Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Pẹ̀lú gbogbo bùkátà, Bàbá 80 gboyè Masters Ọdun mẹtadinlogun ni aarẹ tẹlẹ, Blatter fi wa lori alefa ti wọn fi gbọn ọn yọ latari ẹsun iwa jẹgudujẹra lọdun 2015 ti Infantino si bẹrẹ iṣẹ lọdun 2016.
Ṣaaju ni ijọba United Arab Emirates kede pe oun ti fi afurasi gbajuẹ naa, ranṣẹ si ileesẹ ọtẹlẹmuyẹ ilẹ Amẹrika, FBI.
Ọkan lara awọn onilu Alafin Ọyọ loun bẹ ninu aworan yi.
O ni Bibeli ti Kumuyi ti yan ọrọ rẹ naa ni oun n tẹle lati ba wọn sọrọ atunṣe s'awọn adari ti kọ ba ṣe daradara.
Ǹ bá ti dùbúlẹ̀,ǹ bá ti dákẹ́ jẹ́ẹ́;ǹ bá ti sùn,ǹ bá sì ti máa sinmi
Bi awọn kan n ṣe n sọ pé kò yẹ kó rí bẹ, láwọn mìí ní bo ṣe yẹ kó rí gán niyẹn.
Ajọ NCDC ṣalaye pe awọn mejeeji ṣẹṣẹ rinrin ajo de lati ilẹ okeere si Naijiria ni bi ọjọ meje sẹyin ni.
Ìgbà tí àṣádì bá sì fi ibi tí ó jókòó sí sílè òun a wá sí ọ̀dọ̀ àwọn àlejò mẹ́fà yìí a bẹ̀rẹ̀ sí fi ọwọ́ pa àgbébọ̀ mẹ́fà lára a wí pé òun ń bá wọn ṣiré.
Bi èniyàn bẹ̀rù á kú, bi kò bẹ̀rù á kú, nitori gẹ́gẹ́ bi itàn àdáyébá, gbogbo ohun ti ó nṣẹlẹ̀ láyé òde òni ló ti ṣẹlẹ̀ ri.
Èyí rán ọ̀pọ̀ ọmọ South Africa léti ìpanìyan nípakúpa tó wáyé nínú oṣù karun-ún ọdun 2008, ìròyin BBC fi han nígbà náà pé ènìyàn méjìlélọgọta ló pàdánù ẹmi wọn, mọkanlélógójì jẹ́ àjòjì nígbati àwọn mọkànlélógún jẹ ará South Africa.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Tinubu ki Buhari nílọ̀ lórí àwọn ohun tó leè ṣàkóbá fún sáà kejì rẹ̀ Fintiri fi ìdí gómìnà ìpínlẹ̀ Adamawa janlẹ̀ nínú ìdìbò gómìnà Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Oluwakaponeski ní iṣẹ́ ọmọogun ilẹ̀ Amẹ́ríkà ni òun tẹ́lẹ̀ kí òun tó di aláwàdà Lati igun ẹgbẹ oṣelu APC to faramọWolii Jones Erue ni Omo-Agege ati Waive ti jade lati jawe olubori ninu idibo sile aṣofin apapọ lọdun 2019 lẹyin ti ile ẹjọ giga apapọ ti kọkọ le Wolii Erue gẹgẹ bii alaga ti ofin mọ.
Bí ó bá di òwúrọ̀ ọ̀la, n óo jẹ́ kí ẹ lọ, n óo sì sọ gbogbo ohun tí ẹ fẹ́ mọ̀ fun yín.
Àwọn adigunjalè yabo ṣọ́ọ̀ṣì, fipá bá obìnrin kan lòpọ̀, yìnbọn fún òmííràn Amọ, ninu ohun to kọ sori awọn to fi sori awọn fọto, Olori Abbey kọkọ gboṣuba rabandẹ fun Eleduwa fun ore-ọfe to fun oun.
Ó ní, “Gbé àsíá OLUWA sókè!
Ẹgbẹ agbabọọlu Manchester United ti fi ontẹ lu Ole Gunnar Solskjaer gẹgẹ bi akọnimọọgba tuntun fun ọdun mẹta.
Ó jẹ́ ọ̀kan lára olùdásílẹ̀ Ìpolongo BringBackOurGirls .
Owolabi tun fidi rẹ mulẹ pe, okoowo naa ti n ni agbega lati ọdun mẹrin ti oun ti daa silẹ.
Ọmọ Nàíjíríà 218 padà dé láti Libya Ayinla Ọmọwura, orin èébú àti oríyìn lo fi di ọ̀rẹ́ àwọ̀n obìnrin Auxiliary ń ní wá lára pẹ̀lú gbígba owó aitọ, a ń ko ọkọ̀ wa kúrò lójú pópó - Awakọ èrò Ọwọ́jà coronavirus yóò ṣì wà pẹ̀lú àgbáyé fún ìgbà pípẹ́- Ngozi Okonjo-Iweala Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ẹsẹ̀ bàtà, èso kukumba ni wọ́n fi ń já àbálé àwọn ọmọ Nàìjíríà ní Libya Nitori naa, ofin yii ko sọ pe wọn gbọdọ ri ọmọ ti wọn bi sinu baalu orilẹ-ede kan, gẹgẹ bi pe orilẹ-ede naa ni wọn bi i si nitori a ti di ọmọ oniluu.
Ó bi í pé, “Ṣé kò sí, tí oluwa mi, ọba, fi wá sọ́dọ̀ èmi, iranṣẹ rẹ̀?
Nítorí náà àwọn ará Róòmù kọ́ ilé-ìwẹ̀ ńlá kàbìtì yí àwọn sẹ́lẹ̀ru náà po.
Ẹni to bori: Benin Egypt vs Tanzania.
Ile riri ohun de orile-ede Pakistan nibi to ti sele de iwon kilomita ogbon din ni oodunrun ni ariwa ila oorun Kabul ni ori oke Hindu Kush.
Ọjọ Iṣẹgun ọsẹ ni ilu Ibadan tii ṣe olu ilu ipìnlẹ Oyo, lawọn eekan tọrọ kan ni iha Guusu-Iwọ Oorun Naijiria yoo ti korajọ lati jiroro lorii ohun to wa niwaju fun il Yoruba ṣaaju idibo ọdun 2023.
Ní ọjọ́ karun-un oṣù kẹwaa ọdún kejila tí a ti wà ní ìgbèkùn, ẹnìkan tí ó sá àsálà kúrò ní Jerusalẹmu wá sọ́dọ̀ mi, ó ní, “Ogun ti kó Jerusalẹmu.
Oni lo pe ọdun mẹwaa geerege ti ilumọọka olorin Fuji, Alhaji Sikiru Ololade Ayinde Balogun Barrister jade laye.
Má fi ẹ̀mí àwa àdàbà rẹ lé àwọn ẹranko lọ́wọ́;má sì gbàgbé àwa eniyan rẹ tí ìyà ń jẹ títí lae.
Oríṣun àwòrán, others Ka iroyin nipa ibi ti on rin irinajo lo: Aarun Covid-19 ko i tii ni iwosan nitori naa ni ipinlẹ kọọkan ati orilẹede n gbe akọsilẹ jade lori ọna ati dẹkun ajakalẹ arun naa.
lati mu ki won le e se ise won bo ti tọ ati bi o ti yẹ.
Ìdí nìyí tí ó fi jẹ́ pé títí di òní olónìí, àwọn babalóòṣà oriṣa Dagoni ati gbogbo àwọn tí wọ́n máa ń bọ ọ́ kò jẹ́ tẹ ẹnu ọ̀nà ilé oriṣa Dagoni tí ó wà ní ìlú Aṣidodu, dídá ni wọ́n máa ń dá a kọjá.
Ṣùgbọ́n ebí dé, ó pẹ́ tí wọ́n ti ń yí inú igbó kiri wọ́n bá rán ọ̀kan nínú wọn kí ó lọ ra oúnjẹ wá bí o bá ra oúnjẹ tán kí ó ra agbè ẹmu kékeré kan pẹ̀lú, kí àwọn bà mu ú lée orí ounjẹ àwọn.
Nipa iroyin to n tan kalẹ, mo ro pe irọ ni gbogbo wọn n pa."
Ilé gogoro kan mà ni o.
Yoòbá ní “Kùtù-kùtù kìí jóni lẹ́sẹ̀ bí ọ̀sán”.
Ètò kíní // Ìgbésí ayé Alákọ̀wé – Ààrin gbùngbùn Lọndọn // Ẹ bámi kálọ sí Piccadilly Circus, Leicester Square àti China Town.
Ọ̀rẹ́ mi ni Kẹ́hìndé Ayọ̀ọlá tó kú, olùfọkànsìn ńlá ni-Ṣeyi Makinde Gomina Seyi makinde ti ṣe apejuwe skan lara awọn ksmiṣọna rẹ, Kẹhinde Ayọọla to jade laye ni Ọjọbọ, ọjọ kẹrinla oṣu karun ọdun 2020 ni Kẹhinde Ayọọla ku lẹyin aisan ranpẹ.
Jesu Fara Han Àwọn Ọmọ-Ẹ̀yìn Meje.
Awọn obinrin tun maa n sami ọjọ ‘Ma lo Kọmu’ yii nitori ọpọ wọn to ti lugbadi jẹjẹrẹ ọyan, lo nilo lati wọ kọmu lọna ati fi asọ bo oju egbo itọju ti wọn ti la kọja.
Tottenham ati Ajax ni yoo koju ninu ifẹsẹwọnsẹ keji lati mọ ẹni ti yoo pade Liverpool ninu aṣekagba idije naa ti yoo waye ni Madrid.
Ọkọ rẹ̀ ni Ṣalumu ọmọ Tikifa, ọmọ Harihasi tíí máa ń ṣe ìtọ́jú yàrá tí wọn ń kó aṣọ pamọ́ sí.
bí ìtàn ìwáṣẹ ̀ yìí ìbá ṣe rọrún tó láti gbàgbọ ́ awọn àskìyèsí kan ní a rí tọ ́ ka sí tí ó jẹ ́ kí ìtàn náà rú ènìyàn lójú .
-Big Brother sọ fún Dorathy Ìwé èsì àyẹ̀wò arùn Covid-19 lè di kòṣeémàní fáwọn tí o bá fẹ́ rìnrìn àjò sí ilẹ̀ òkèèrè Wo oríṣìí ìlù Yorùbá, ìwúlò wọn àti ba ṣe ń lò wọ́n Àwọn òṣèré tíátà Yorùbá kọjú ìjà síra wọn lórí ìdárò akẹẹgbẹ́ wọn tó kú Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Olusegun Obasanjo sọ̀rọ̀ síta pé ọpẹ́lọpẹ́ Walter Carrington láyé òun nígbà tí Sani Abacha ń lé òun kíri18 Ògún 2020 BBNaija: Terry Waya sọ oun tó fojú Kiddwaya rí nílé nígbà tó ń bẹ̀bẹ̀ láti lọ BBNaija28 Ògún 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Alufaa yóo sun ọ̀rá ẹran náà lórí pẹpẹ, ṣugbọn àyà rẹ̀ yóo jẹ́ ti Aaroni ati ti àwọn ọmọ rẹ̀.
Kò sí ẹnikẹ́ni tó kú níbi rògbòdìyàn tó wáyé lánàá - Deji ilu Akure Ọlọ́pàá, sójà yabo Lekki Toll Plaza láti dènà ìfẹ̀hónúhàn míràn Gbọ́yì-sọ̀yí àti ìròyìn èké láti ọ̀dọ̀ àwọn olólùfẹ́ wa ló ṣáábà ma ń da ìgbéyàwó àwọn òṣèré rú- Ọpẹ Ayeola Idi ti Odili fi gba ibi ìbálòpọ̀ lọ sí ọ̀run alákeji nílùú Port Harcourt Makinde, Dele Momodu ń ṣèdárò Àgbà Oyè Ilẹ̀ Ibadan, Harry Akande tó jáde láyé Laipẹ yii ni Gomina Seyi Makinde sọ pe ki ajọ to n ri si ọrọ awọn olukọ gba ẹgbẹrun un meje olukọ, ati ẹgbẹrun un meji awọn ti kii ṣe olukọ nipinlẹ Oyo.
Nítorí náà, nígbà tí ó sùn, Delila mú ìdì irun mejeeje tí ó wà lórí rẹ̀, ó lọ́ ọ mọ́ igi òfì, ó sì fi èèkàn kàn án mọ́lẹ̀, ó bá pè é, ó ní, “Samsoni!
Lootọ ilu mọọka ni igbeyawo naa yoo jẹ, ṣugbọn awọn ohun kan wa ti o yẹ ki o mọ nipa igbeyawo yii.
Year 2020: Iléri Àarẹ Buhari fún ọdún 2020 rèé
Eléyìí yàtò sí Àlàó tí ó tójú àwọn Olófìn-íntótó tí a ti ṣe àkíyèsí rẹ̀ ṣáájú.
Bakan naa, ijoba apapo ti kan si gomina ipinle Adamawa Bindow Jibrilla lati foju lameeto wo isele naa.
Ti ẹ ba ranti, ile ẹjọ to n gbọ ẹjọ esi idibo kọkọ dajọ ni oṣu Kẹta ọdun yii wi pe, Adeleke lo jawe olubori ṣugbọn Oyetola gba ile ẹjọ kotẹmilọrun lọ lori ọrọ naa.
A kò bí wọn bí eniyan ṣe ń bímọ nípa ìfẹ́ ara tabi ìfẹ́ eniyan, ṣugbọn nípa ìfẹ́ Ọlọrun ni a bí wọn.
Oríṣun àwòrán, @bankyw Àkọlé àwòrán, Ifẹ ara agbegbe ti mo n lọ ṣoju fun ló jẹ mi logun O ni oun mọ pe oun kò ni baba isalẹ ti ọpọ gbà pé o ṣe pataki sí oṣelu Naijiria ṣugbọn oun gbagbọ ninu Ọlọrun.
"Á ràgà bo CCTV Lekki bí i ẹ̀rí tó dájú fún ìwádìí ìpànìyàn - Sanwo-Olu SERAP gbé ìjọba àpapọ̀ lọ ilé ẹjọ́ àgbáyé ICC lọrí ẹ̀sùn ìpànìyàn ""Jàǹdùkú gún ẹ̀gbọ́n mi lọ́rùn, jó ilé àti mọ́tò wa méjì, kòròfò la wà"" Olùwọ́de 12 kú ni Lekki, 38 lapapọ kú lọ́jọ́ Isẹ́gun, 56 ni àròpọ̀ àwọn tó bá ìwọ́de lọ - Amnesty International Osinbajo gbarata lórí ìṣẹ̀lẹ̀ Lekki, ó ní ìdájọ́ òdodo yóò wà Sanwo Olu búra fún ìgbìmọ̀ tí yóò má a ṣe ìdájọ́ àwọn ọlọ́pàá tó bá hùwà kò tọ́ sáwọn ará ìlú ní Eko Oríṣun àwòrán, Babajide sanwo-olu Gomina ipinlẹ Eko, Babajide Sanwo Olu ti ṣagbekalẹ igbimọ ti yoo maa ri si idajọ awọn ti awọn agbofinro ba fiya jẹ ni ipinlẹ Eko."
Bakan naa náà lo rọ gbogbo àwọn arinrinajo láti ṣeto ìrìn wọ́n ki wọ́n tó gun le.
Lẹ́hìn eléyìí, a tún kí ara wa dáadáa a sì ṣe ọ̀pọ̀lọpọ̀ àwàdà.
Ní ìlú Susa nìkan, àwọn Juu pa ẹẹdẹgbẹta (500) eniyan.
Ó ń ṣe iṣẹ́ rẹ̀ ninu àgọ́ tí ó pé tí ó sì tóbi ju ti àtijọ́ lọ, àgọ́ tí a kò fi ọwọ́ kọ́, tí kì í sì í ṣe ti ẹ̀dá ayé yìí.
Sugbọn Freeze yi ohun pada lẹyin ti ọwọ ọlọpaa tẹ Hushpuppi laipẹ yii.
Ilé ẹjọ sún ìgbéjọ Maina síwájú lati fi okodoro àìlera rẹ hàn Mo pàṣẹ pé kí ọ̀gá owó ìfẹ̀yìntì tẹ́lẹ̀, Maina sì wà látìmọ́lé- Adájọ́ Ìyàwó wọ sòkòtò fún ayẹyẹ ìgbéyéwò rẹ̀, ní wáhálà bá bẹ́ sílẹ̀ Scotland ti di orílẹ̀-èdè àkọ́kọ́ tó bẹ́rẹ̀ si pínpín páàdì ǹkan osu fún gbogbo obìnrin lọ́fẹ̀ẹ́ Agbẹjọro naa ni idi ti oun fi fiwe ranṣẹ ni pe Maina ko san owo fun oun nitorinaa oun ko ni le ṣoju rẹ nile ẹjọ mọ.
” Ó bọ́ bàtà ẹsẹ̀ rẹ̀ fún Boasi, 
“Nítorí náà, ohun tí èmi OLUWA Ọlọrun, ń sọ fun yín ni pé: mo ṣetán tí n óo ṣe ìdájọ́ fún àwọn aguntan tí ó sanra ati àwọn aguntan tí kò lókun ninu.
Yinka Ayefele ti eto isinku iya Sẹnetọ Dino Melaye ṣoju rẹ koro gẹgẹ elere to kọrin nibi eto naa dahun si ọrọ to n tan kalẹ pe ṣe ni Dino n nawo bi ọmọ Darosa koda ti ile iṣẹ ọlọpaa ti ni awọn yoo ṣewadi rẹ.
Ẹ óo sọ ní ọjọ́ náà pé,“Ẹ fọpẹ́ fún OLUWA,ẹ ké pe orúkọ rẹ̀,ẹ kéde iṣẹ́ rere rẹ̀ láàrin àwọn orílẹ̀-èdè;ẹ kéde pé a gbé orúkọ rẹ̀ ga.
ko iye awon eniyan ti iye won jẹ mẹ́tàlélógóje de si orile ede Naijiria ni deede aago mẹ́wàá kọja
Idi ni pe ti eeyan ko ba tẹ ika rẹ bi o ti ṣe yẹ s'aye ti INEC pese lori iwe idibo, irufẹ ibo bẹẹ ko ni jẹ itẹwọgba, eyi to ja si pe eni naa sọ ibo naa danu.
Sani Abacha tún gbé owó míì dé láti Ireland Ibùdó ìyàsọ́tọ̀ ni mo wà, ló fi pẹ́ kí ń tó sọ̀rọ̀ lórí tírélà tó já l‘Eko - Omotola Jalade Ekeinde Ire ṣ'ọjọ́-ìbí, Mide àti ọkọ rẹ̀ lẹ̀pọ̀, Iyabo Ojo f'aṣọ ilẹ̀ Afirika dárà Funke Akindele fún mi lówó tí mo fi gba ilé, kò ra ilé fún mi o - Ajirebi Èèkàn ẹgbẹ́ òṣèlú APC mií Lanre Razak jáde láyé lẹ́yìn àìsàn ráńpẹ́ Ìpànìyàn tún wáyé ní Akinyele, àwọn ará àdúgbò ṣe ìwọ́de O ni ki wọn ṣe eyi ki ibinu Ọlọrun to sọkalẹ sori orilẹede yii.
    Báyìí ni gbogbo wọ́n ṣe ti wọn da ẹ̀yìn kọ ẹ̀yìn.
 awon ohun alumoni mali ni wura , uraniomu , ati iyo .
Àmùrè ẹnìkankan kò tú,bẹ́ẹ̀ ni okùn bàtà ẹnìkankan kò já.
Karakata yii kii ṣe ohun to ba ofin mu nitori o fi aaye silẹ fun ṣiṣe ọmọde atawọn obinrin baṣubaṣu.
Ẹwẹ, saaju ni amofin Farintọ ati ikọ rẹ ti wọn n ṣoju ipinlẹ Oyo, ti kọkọ rọ ileẹjọ lati fofin de awọn alaga naa, ki wọn ma baa le gbe igbesẹ kankan titi di igba ti ileẹjọ kotẹmilọrun yoo fi dajọ.
Oga agba Gabriels-Gorsolke to wa ni Fourth Office ni Nurnberg-Furth sọ fun BBC pe awọn n ṣe iwadii naa bii ti ọdaran ati pe ọwọ ofin yoo tẹ ẹni ti ade ba ṣi mọ lori.
Akọwe agba ileeṣẹ ijọba to n ri si ọrọ ayika ati ohun alumọni, Bashir Olanrewaju lo kede bẹẹ nigba to ṣabẹwo si ẹbi oloogbe ọhun.
Ó pe iyawo rẹ, sugbọn ko gbe ipe.
Àwọn ọmọ Jerohamu ni: Ṣamṣerai, Ṣeharaya, ati Atalaya; 
Kà nípa ìròyìn mánigbàgbé tí BBC News Yorùbá ṣe láàárín ọdún kan Jí àpótí ìbò, ko fi ikú ṣe ìfà jẹ - Iléeṣé ológun laago ìkìlọ̀ Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí kan sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
Nígbà tí ilẹ̀ mọ́, ìdààmú ńlá bá àwọn ọmọ-ogun.
Ó wọn ibẹ̀, láti ẹnu ọ̀nà náà sí ẹnu ọ̀nà tí ó wà ní ìhà gúsù, jẹ́ ọgọrun-un (100) igbọnwọ (mita 45).
Ipade naa lo ko ọpọlọpọ ọdọ ati awọn agbaagba oṣere Yoruba jọ lati jiroro lori ọna ti ẹgbẹ naa yoo fi tẹsiwaju.
Mo ríbà ‘i’ ríbá, mo ríbà dagbaro
Ṣugbọn ẹni tí ó wá rúbọ yóo fi omi fọ àwọn nǹkan inú ẹran náà ati ẹsẹ̀ rẹ̀, alufaa yóo sì sun gbogbo rẹ̀ níná lórí pẹpẹ, gẹ́gẹ́ bí ẹbọ sísun, ẹbọ tí a fi iná sun, tí ó jẹ́ ẹbọ olóòórùn dídùn sí OLUWA.
Nítorí bí ó bá jẹ́ pé àwọn ohun tí mo ti wó lulẹ̀ ni mo tún ń kọ́, èmi náà di ẹlẹ́ṣẹ̀.
Arsenal fiya jẹ Fulham Aaron Ramsey fakọyọ bi Arsenal ṣe lu Fulham la lu bolẹ lati jawe olu bori ni ifẹsẹwọnsẹ wọn ni Premier League to n lọ lọwọ pẹlu ami ayo marun si ẹyọkan.
O ni: “Bi a se n soro yii, a n pese oromodie egberun mewaa lojumo ni eyi to n safikun si idagbasoke ise agbe wa”.
Ní ibẹ̀ ni odò náà ti kọjú sí ibòmíràn.
OLUWA bínú gidigidi,ó tú ibinu gbígbóná rẹ̀ jáde.
" Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ìṣẹ̀lẹ̀ Kàyéèfì: Ìpáǹle tú Abass Owonikoko sí ìhòòhò ayé, kó tó gba kéú lọ́gbà ẹ̀wọ̀n O wa rọ awọn akọroyin atawọn adari eto, ta mọ si MC pe, ki wọn maa bọwọ fun ara wọn, ki wọn ma si toju bọ ayẹyẹ ti wọn ko ba pe wọn si, tori awọn abuku bii eleyi.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Buhari at 76: Àwọn àwòrán tó làmì-laaka nípa Buhari 17 Ọ̀pẹ̀̀ 2018 Ọdun 1942 ni Hando Adamu ati Hajia Zulhatu Musa bi Aarẹ Muhammadu Buhari sinu idile Baalẹ Fulani, l'abule Dumurkol nitosi Daura.
O gbe igbesẹ yii pẹlu gbigba fọọmu idije lolu ile iṣẹ ẹgbẹ oṣelu PDP l'Abuja.
Angẹli mìíràn wá ti ẹ̀gbẹ́ pẹpẹ ìrúbọ wá, òun ni ó ní àṣẹ lórí iná.
Asiri ibudo igbafẹ ẹranko ni Naijiria Ẹran dida lalẹ ati ibọn gbigbe deewọ ni Edo Kiniun pa olusọ ọgba ẹranko Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí 2 sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 2:23 Fídíò, Water Generator: Ó leè ṣiṣẹ fún wákàtí mẹfà, kó tó sinmi, Duration 2,2310 Òkùdu 2020 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
 Òfin sì wà wí pé tí orílẹ ̀ -èdè méjì bá ń jà , àwọn ọmọ ogun ara wọn nìkan ní wọ ́ n dojú ìjà kọ .
Ijọba ni biliọnu mẹrinla ni iṣẹ naa yoo gba.
kí ẹ lè fi ẹsẹ̀ wọ́ àgbàrá ẹ̀jẹ̀ àwọn ọ̀tá yín,kí àwọn ajá yín lè lá ẹ̀jẹ̀ wọn bí ó ti wù wọ́n.
Ibadan VC Appointment: Ẹgbẹ́ ọmọ Ibadan fẹ́ kí ààrẹ Buhari yan ọmọ wọ́n gẹ́gẹ́ bí ọgá fásitì Ibadan
 bákan náà ni ó jẹ ́ ìgbàgbọ ́ pé apá agbègbè yìí nìkan ni ọdún Ẹ ̀ yọ ̀ ti lè wáyé ní ìpínlẹ ̀ Èkó .
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, T'obìnrin àti t'ọmọde ni wọn ń jigbe kaakiri bayii Titi di bi mo ti ṣe n ba yin sọrọ yi, a ko tii ri ibi doola wọn, amọ, a ni ireti pe wọn yoo pada wale layọ ati alaafia'' Lalẹ ọjọ Abamẹta ni iroyin ijinigbe naa kan gẹgẹ bi alaye ti Olaboye ṣe.
Eleyi maa n jẹ iyalẹnu fun Ogungbile wipe, kinni aise igbeyawo oun ni i ṣe pẹlu ile ti oun n wa.
Ile Itura yii ni Ijọra Badia ni opopona Gasikiya, ni ilu Eko ni iṣẹlẹ naa ti ṣẹlẹ ni nkan bi aago mẹjọ owurọ nibi ti Raji ti sanwo iyara kan fun igba diẹ.
Lẹsẹkẹsẹ ó dìde, ó bá tọ́jú oúnjẹ fún wọn.
Toun ti igbiyanju ikọ Mauricio Sarri, wọn ko ribi bori Burnley amọ wọn ti bọ si ipo kẹrin lori afara liigi bayi.
O ti han gbangba bayii wi pe ootọ ni ohun ti ile n sọ lọpọ igba wi pe a o ni itẹsiwaju kankan lori ọrọ gbigbogun ti iwa ibajẹ ati iṣowo ilu baṣubaṣu nitori awọn ipilẹ gbogbo to yẹ lati mojuto lo si mẹhẹ ti wọn si tun wọ."
Mo ké pe OLUWA,ó sì dá mi lóhùn láti òkè mímọ́ rẹ̀ wá.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Buhari ba osinbajo sayẹyẹ igbeyawo ọmọ rẹ.
Asẹ yii waye lẹyin ti asofin agba kan, Sẹnatọ Sabo Mohammed ti pe akiyesi awọn asofin agba si ọrọ naa.
Ninu fidio orin ọhun to fi bintin ninu rẹ sori ayelujara lọjọ Iṣẹgun, a ri awọn obinrin to wọ aṣọ nọọsi, wọn n jo ninu yara itọju awọn alaisan, ti awọn kan si n fi ọwọ pa awọn alaisan to jẹ ọkunrin lara lọna ati ni ibalopọ pẹlu wọn.
Ṣugbọn ninu ọrọ ti Arabinrin naa tun sọ ninu fidio mii to fi sita ni ọjọ kẹrinlologun, oṣu Kejila, o ni diẹ lo ku ki wọn o lu oun ni ọfiisi Kọmisanna fun eto ẹkọ nipinlẹ naa, lasiko to ni ki oun wa sibẹ.
Ẹ̀bùn ni ó yẹ kí ọbẹ̀ náà jẹ́ fún ẹ̀gbọ́n náà.
Bí ó ti rí wọn, ó dìde lọ pàdé wọn, ó wólẹ̀, ó sì dojúbolẹ̀ láti kí wọn.
Ilé ìwòsàn New Jersey ṣ'àṣìṣe ṣiṣẹ́ abẹ kìndìrín fún aláìṣàn l'Amẹrika Eku gba ìjọba ní Estonia, ìjọba pàdánù owó gọbọi EFCC fẹ́ gbẹ́sẹ̀ lé ilé tí mo fi owó ìfẹ̀yìntì kọ́ nílùú Ilorin- Saraki Akẹ́kọ̀ọ́ mẹ́fà tó lu akẹẹgbẹ́ wọn ní fásitì FUTA dèrò ilé Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ọmọ Yahoo tú àṣírí ara rẹ̀ fún, bí wọ́n ṣe ń ṣe é BBC Yorùbá Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Leah Sharibu ṣì wà láàyè - Iléeṣẹ́ Aarẹ Buhari Kí ni ó gbé ọlọ́pàá dé ibi àjọ̀dún ọjọ́ ìbí i Bobrisky?
Ní ọdún kẹta ìjọba Jehoiakimu ọba Juda, Nebukadinesari ọba Babiloni wá gbógun ti Jerusalẹmu, ó sì dótì í.
" Baba Araba ni ohun to n da awọn ọba ya sọtọ naa ni awọn oro, ati nnkan ibilẹ ati iṣẹdalẹ ilu rẹ to jẹ ọba le lori.
A bẹ̀rẹ̀ síí kọ̀wé sí ara wa à ń fi nǹkan ránṣẹ́ sí ara wa pẹ̀lú, bí mo bá pa ẹran èmi a fi ránṣẹ́ sí i, bí òun náà bá ṣe ọbẹ̀ á bú ránṣẹ́ sí mi.
Tottenham tẹ̀yìn gbéru Ajax Abala Ikeji ti bẹrẹ Nigba ti a ba fi ri iṣẹju márùndínláàdọ́ta tabi ju bẹ lọ diẹ a o mọ ẹgbẹ agbabọọlu ti yoo gba ife ẹyẹ Premiership ti ọdun yi.
Bakannaa ni ileẹjọ to ga julọ lorilẹede Naijiria, tun pasẹ pe ki Akeredolu san ẹgbẹrun lọna ẹẹdẹgbẹta naira (N500, 000) gẹgẹbii owo 'gba maa binu' fun Abraham.
Ẹkunrẹrẹ alaye nipa bi wọn ti ṣe gbe owo naa lati papakọ ofurufu ilu Eko ti wọn si gbe e fun Obanikoro ni eleri miran Damola Otuyalo ṣe fun ile ẹjọ.
Iko agbaboolu Juventus fagbahan iko akegbe wo pelu ami-ayo merin sodo(4-0), lati so apapo ife eye ohun ti iko naa ti gba di metala bayii.
wa gbiyanju lati  mọ Olorun, bo tile jẹ
Ilé yìí jẹ́ ilé Ẹlẹ́dàá ti ń fẹ́ kí ọ̀pọ̀lọpọ̀ nínú àwọn ará òde ọ̀run kọ́ àti pé nítorí tí ọ̀pọ̀lọpọ̀ ti gbìyànjú tí wọn kò lè kọ́ ọ o òun ti sọ fún Olódùmarè pé òun fẹ́ kọ́ ilé náà Olódùmarè sì gbà fún òun o sì ti fi ilẹ̀ ibi ti òun lè kọ́ ilé náà sí han òun, nítorí náà òun fẹ́ lọ bẹ̀rẹ̀ síi máa ṣánko kí òun ṣe díẹ̀ nínú iṣẹ́ náà lówùúrọ ọjọ́ kejì, inú òun ó sì dùn bbí a bá lè bá òun ṣan díẹ̀ nínú oko yìí.
È yìí ló mú àwọn àgbà Yorùbá wípé; Àṣẹyẹ̀ ni ti Alákàn àmúbó ni ti ọmọ Ẹja"" Ìdí nìyí tí àwọn Yorùbá ṣe máa ń ṣe àsamọ̀ pé; Ẹja N ' B'Ákàn"
Àti fún àwọn aríwá orílẹ̀ Nàìjíríà lókè Ọya lọ́hùn-ún.
Wọ́n sọ gbogbo ohun tí ojú wọn rí, wọ́n sì fi èso tí wọ́n mú wá hàn wọ́n.
20 bn Ajọ ajafẹtọ ọmọniyan - N3.
O óo fara pa bí o bá ta igi ẹlẹ́gùn-ún nípàá.
WASSCE: Ìpínlẹ̀ Delta fòfin de olùkọ́ 41 tó ṣe màgòmágó nínú ìdánwò Wọ́n ti yìnbọn pa ọkùnrin ẹni ọgbọ̀n ọdún tó ń jà sí ogún ilẹ̀ bàbá rẹ̀ Ẹgbẹ́ NULGE Oyo dìbò yan olóyè ẹgbẹ́ tuntun èyí tó tako àṣẹ iléẹjọ́ Ilé iṣẹ́ ọmọogun òfurufú sọ orúkọ Tolulope Arotile di mánigbàgbé lórílẹ̀-èdè Nàìjíríà Daniel ń bọ̀ wá wò mí nítori mo ṣàìsàn ló dàwátì- Baba Daniel Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Ondo Election 2020: Ẹ wo àwọn olùdíje sípò gómìnà nípínlẹ̀ Ondo tó takò bàbá ìsàlẹ̀26 Owewe 2020 Fídíò, Akomolede àti Aṣa: Ọ̀rọ̀ Ẹ̀yán ni Bunmi Femi Amao ń kọ́ wa lórí ètò Akọ́mọlédè àti Àṣà lórí BBC Yorùbá24 Owewe 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Ti o ba n sise fun orile ede , o ko gbodo maa se owo ilu kumo-kumo , bi awon obayeje eniyan  se maa n se.
Mo ṣakiyesi pe, kọmputa agbeletan rẹ wa ni ṣiṣi silẹ, mi o kọkọ fẹ ẹ wo, nitori kii ṣe aṣa mi lati maa sọ ọkọ mi.
Ilẹ iṣẹ ijọba ṣalaye ninu atẹjade naa pe atunṣẹ yoo waye lori awọn ibi ti wọn ti so afara naa pọ ti wọn mẹnu ba ninu fidio ti awọn kan fihan loju opo Facebook.
ohun ti eka ipinle Borno to n mojuto ise akanse “Operation Lafiya Dole”, ogagun
Asuquo ní èyí lo tí oun láti já sọọbu náà láti rí ǹkan jẹ láti dóòlà ẹ̀mí oun nítori oun ní ọgbẹ́ inú tí o si ti n dàá láàmu fú odindi ọjọ́ meji.
Jide Kosoko forin sẹ́nu sọ pé òun ni igi lẹ́yìn ọgbà Mr Latin lórí ipò ààrẹ TAMPAN tó wà Ìyàwó mi fi mí sílẹ̀ kó lọ sílé ọkùnrin míì nínú báráàkì kan náà, àmọ́ mò sí tún fẹ́ràn rẹ̀- Sọ́jà Wo àwọn ìṣesí ojoojúmọ́ mẹ́wàá tó le ṣàkóbá fún ọpọlọ rẹ Coronavirus: ''Ìjọba kò tíì pàṣẹ ìlànà ìtakété-síra-ẹni padà nínú BRT la ò ṣe máa tẹ̀le'' Ìjọba gbé ilé ijó oníhòhò tì pa lórí ẹ̀sùn títàpá sí ìlànà àti dẹ́kun coronavirus Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Akomolede ati Aṣa: Mọ̀ síi nípa ìró afárànma àti agbárànmọ́ fáwẹ́ẹ̀lì Yorùbá Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Coronavirus in Lagos: Sanwo-Olu ti ilé ẹ̀kọ́ pa, fòfin de ayẹyẹ àdúgbò àti òde fàájì torí ọwọ́jà àrùn19 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Ganduje: Gòmìna Ganduje ni yíyọ Sanusi nípò Emir Kano wà fún àtúnṣe ètò oyè jíjẹ ní ìlú Kano16 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 New Covid 19 update: Ẹ̀yà kòkòrò Covid-19 míràn jáde ní ọgọ́ta agbègbè nílẹ̀ Gẹẹsi, àjọ elétò ìlera fọkàn ará ìlú balẹ̀15 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Ede Poly Rector suspension: Wọ́n ní kí ọ̀gá àgbà Pólì Ede lọ rọ́kún ńlé lórí ẹ̀sùn pé 'ó kan bẹ́ẹ̀dì sí ọ́fíìsì'15 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 New Covid-19 Strain UK : Atiku ní kí ìjọba dì ìrìnnà ọkọ̀ òfurufú láàrin ilẹ̀ Gẹ̀ẹ́sì sí Nàìjíríà kú nítorí Covid-1921 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
ó pàdé àwọn ìbátan Ahasaya, ọba Juda, ó bèèrè lọ́wọ́ wọn pé, “Ta ni yín?
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Akomolede ati Aṣa: Mọ̀ síi nípa ìró afárànma àti agbárànmọ́ fáwẹ́ẹ̀lì Yorùbá Bẹẹ lọrọ ri fun awọn adigunjale meji kan lọjọru nilu Ibadan nigba ti wọn ja ọkunrin kan lole amọ ti ọwọ palaba wọn segi.
Gbogbo àwọn tí ó jẹ́ pàtàkì nínú wa ni inú wọn dùn sí ìmọ̀rà  mi.
2019 Election: Bí Buhari ba le lọ Kóòtù ní ẹ̀ẹ̀mẹ́ta- Obasanjo Gbogbo ayé ń dúró dé ìkéde INEC lórí ìdìbò Ọṣun Secondus pẹtu saawọ nínú PDP Ọ̀sun Osun Election Tribunal: Èyí ni òkodoro ìdájọ tí àwọn eniyan ìpínlẹ̀ Ọsun ti ń reti- Oyetola Ademọla Adeleke ni yóò sojú PDP nínú ìbò gómìnà Ọ̀sun Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ìbànújẹ́ ló pọ̀ nínú òṣèlú Nàìjíríà tórí a ti lo Pásítọ̀, Wòlìí, Ọ̀jọ̀gbọ́n Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Mo bá mú àwọn tabili mejeeji, mo là wọ́n mọ́lẹ̀, mo sì fọ́ wọn lójú yín.
Ẹ wo Sioni, ìlú tí a yà sọ́tọ̀ fún àjọ̀dún.
Siasia: Ọlọ́pàá Bayelsa ṣalàye ibi tí wọ́n bá ìyá Siasia tó bọ́ sọ́wọ́ ajínigbé
Nítorí àwọn aláṣẹ kò wà láti máa dẹ́rù ba àwọn tí ó ń ṣe rere.
amọ eyi wa lọwọ ọmọ naa boya o wuu lati kọ ila to ba dagba.
olori ti won nifee si, ni eyi ti yoo je ki isagbasoke ba eto ijjoba tinwa
N óo yìn ọ́ pẹlu inú mímọ́,bí mo ṣe ń kọ́ ìlànà òdodo rẹ.
Lẹyin iwaaadi naa ni ijọba ipinlẹ Kano, labẹ iṣakoso Abdullahi Umar Ganduje yọ nipo gẹgẹ bi Emir lu ọhun.
Láìṣe àní àní, n óo mú ojú kúrò lára wọn ní ọjọ́ náà, nítorí gbogbo ibi tí wọ́n ti ṣe, nítorí pé wọ́n ti yipada, wọ́n sì ń bọ oriṣa.
Ni iwaju bareke awọn ologun ni adugbo Mile 2 ni iṣẹlẹ yi ti waye lọjọ Ẹti.
O wa fi asiko ohun tenumo pe laisi atileyin ati ifowosowopo akoroyin, ile ise ọlọpaa
 Ẹmu tó mu yìí mú ki ó sùn lójú ọ ̀ nà , kò le è lọ mọ ́ .
Nítorí àwọn eniyan yóo máa sá síhìn-ín, sá sọ́hùn-ún, ìmọ̀ yóo sì pọ̀ sí i.
Àwọn eniyan Anatoti jẹ́ mejidinlaadoje (128)
Ikú tí yóò pamí, kìí ṣe t’ọfà
"Akomolede ati Asa Yoruba: Kí ni \""Future tense\"" lédè Yorùbá?"
Bakan naa ni ileesẹ ologun ti ṣẹ́ lori iroyin to sọ pe awọn sọja n lọ lati ojule si ojule, lati pa eeyan.
"Trump nínú àtẹ̀jíṣẹ́ twitter rẹ̀ ""Ara mí yá gágá jú tí ogún ọdún sẹ́yìn lọ"" Bákan náà ló sọ pé "" òun kò ni pẹ́ pada fún ìpolongo ìdìbò"" Donald Trump: Ó lé ní ọjọ́ méjì tí Ààrẹ ilẹ́ Amerika ń lò ní ilé ìwòsàn Oríṣun àwòrán, Twitter/Donald Trump Aarẹ orilẹede Amerika, Donlad Trump to ti lo ọjọ keji ni ile iwosan lẹyin to lugbadi arun Coronavirus, ti dupe lọwọ awọn ololufẹ rẹ, to si sọ wi pe oun wa ni alaafia."
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Mo máa n forin mi kìlọ̀ ìwà ìbàjẹ́ láwùjọ ni -Hameen A ṣee lati ya awọn ipinlẹ lẹkun oke ọya Naijiria ti wọn nifẹ ati kọ oko ijẹko maluu fun pipese ẹran maluu lọna igbalode eyi ti wọn yoo maa gbe ninu rẹ dipo dida ẹran maluu kaakiri.
Ẹ yan balogun tí yóo gbógun tì í;ẹ kó ẹṣin wá, kí wọn pọ̀ bí eṣú.
Bakan naa wọn fi si oju opo Twitter wọn pe ki awọn eeyan ma kọ lati fi ẹjọ oṣiṣẹ LASTMA ti wọn ba ri to n ṣe aṣemaṣe sun awọn.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù South Africa: Iṣẹ́ bọ lọ́wọ́ adarí ile-ẹ̀kọ́ ìmọ̀ ìkọ́lé 17 Èrèlè 2018 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 7 Owewe 2018 Oríṣun àwòrán, SAICE Àkọlé àwòrán, Iṣẹ́ bọ́ lọ́wa ọ̀gá ilé iṣẹ́ tó bẹ́nu àtk lu Obinrin Manglin Pillay tó jé ọgá àgbà ìmọ̀ ẹ̀rọ ìkọ́lé lórílẹ̀-èdè South Africa ti gba ìwé ìdádúró lẹ́yìn tó bu ẹnu àtẹ́ lu ìgbìyanjú obìnrin láwùjọ.
Clement mẹnuba ba pe, yiya ọkọ silẹ lojiji naa maa n ṣe okunfa ijamba ti o si le mu ẹmi dani.
won yoo ko won lo soju ogun lati kun awon omo ogun lowo si.
ati gbogbo ọkọ̀ ojú omi láti ìlú Taṣiṣi,ati gbogbo ọkọ̀ tí ó dára.
Zainab ti jẹ akọwe agba fun Nigeria Extractive Industries Transparency Initiative tẹlẹ.
Liverpool lu Chelsea lálùmọ́lẹ́ bíi bẹ̀m̀bẹ́ Góòlu mẹfa ọtọtọ ni United fi gba pada lọwọ Tottenham.
O ni atunto ni lati de ba agbekalẹ isẹ ọlọpa lorilẹede Naijiria ki wọn si sọ iye ọlọpa orilẹede yii di ilẹpo mẹta iye rẹ bayii fun amojuto aabo tẹru-tọmọ.
Ronaldo gba ayo 450 sawọn ninu ifẹsẹwọnsẹ 438 nigbati o wa pẹlu Real Madrid O si gba ami ẹyẹ Idije Champions League pẹlu Real Madrid ni igba mẹrin.
Bí ó bá sá wọ inú ìlú kan, àwọn ọmọ Israẹli yóo fi okùn fa ìlú náà lulẹ̀ sinu àfonífojì tí ó wà ní ìsàlẹ̀.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù CBN pàṣẹ kí MTN àti àwọn ilé ìfowópamọ́ da $8bn pada 29 Ògún 2018 Oríṣun àwòrán, Central Bank of Nigeria Àkọlé àwòrán, Banki apapọ orilẹede Naijiria lo n se isakoso eto ọrọ owo Naijiria Ile ifowopamọ apapọ l'orileede Naijiria (CBN) ti paṣẹ ki awọn ile ifowopamo mẹrin kan san owo itanra to le ni biliọnu marun naira.
ni lati pese ise fun awon odo jakejado orile-ede yii nitori ọwọ to ba dilẹ ni
Tí a fiṣọwọ́ ní 6:23 4 Ọ̀pẹ̀ 20206:23 4 Ọ̀pẹ̀ 2020 Ọ̀dọ́bìnrin, ẹ ṣọ́ra!
Ọjọ kẹrinla, oṣu Kejila, ọdun 2018 ni ẹgbẹ TAMPAN ṣe eto idibo lati yan awọn oloye ẹgbẹ tuntun.
Coronavirus: Báyìí ni àwọn ṣọ́ọ̀ṣì ńlá nlá ní Nàìjíríà ṣe ń bá ìgbà coronavirus yí
Ó tún gbadura, òjò sì rọ̀ sórí ilẹ̀ láti òkè, ilẹ̀ sì hu ohun ọ̀gbìn jáde.
26 Bélú 2020 Amos Dauda, Iphone: Ilé ẹjọ́ dájọ́ ẹgba mẹ́ẹ̀dóògún fún ọ̀daràn tó jí Iphone ní Kaduna25 Bélú 2020 Fídíò, Akọ́mọlédè àti Àṣà lórí BBC Yorùbá: Kọ́ síi nípa iṣẹ́ tí oúnjẹ ń ṣe lára níbí24 Bélú 2020 Grammy awards 2021 - Burna Boy, Beyoncé, àti Dua Lipa, wà lára àwọn ti wọ́n fi orúkọ wọn sílẹ̀25 Bélú 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Kò ṣe é ṣe kó máa sì wàhálà láwùjọ ènìyàn.
ijọba, awon egbe to n se iranwọ, awon ẹbi,awon ijọ ẹlẹsin, ile-isẹ aladaani ati
Lootọ ni awọn eyin naa tobi ju ara wọn lọ, amọ gbogbo wọn lo jọ eyin, ti wọn si ni ki ọmọ naa maa lọ sile lẹyin ọjọ kẹta to se isẹ abẹ naa.
Ó ṣeéṣe kí ènìyàn 12,000 máa kú lójoojúmọ́ lẹ́yìn Covid-19 Orílẹ̀-èdè mẹ́wàá tí ẹgbẹ́ alákatakítí Islamic State n fínna mọ́ ní àgbáyé N kò gba ₦4bn lọ́wọ́ Magu, ẹ má ró àjẹbánu mọ́ mi láṣọ - Osinbajo pariwo Mi ò tíì gba ìwé ìfitónilétí pé wọ́n fẹ́ yọ mí nípò igbákejì gómìnà ìpínlẹ̀ Ondo- Agboola Ajayi Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí 3 sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 2:23 Fídíò, Water Generator: Ó leè ṣiṣẹ fún wákàtí mẹfà, kó tó sinmi, Duration 2,2310 Òkùdu 2020 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Osinbajo: Ọmọ Nàìjíríà, nǹkan kò ní pé ṣẹnure fún mẹ̀kúnù 19 Òkùdu 2019 Oríṣun àwòrán, yemi osinbajo Àkọlé àwòrán, Ìgbákejì ààrẹ Yemi Osinbajo rọ ọmọ Nàìjíríà pé ǹkan ò ni pé ṣẹnure fún mẹ̀kúnù Ààrẹ orílẹ̀-èdè Nàìjíríà ọ̀jọ̀gbọ́n Yemi Osinbajo ní òsí àti ìṣẹ́ tó ba orilẹ̀-èdè Nàìjíríà jà kìí jẹ ki òun ri òòrun sùn lóru.
Ó fi idẹ ṣe ayanran ààrò kan fún pẹpẹ náà, ó ṣe é mọ́ abẹ́ ìgbátí rẹ̀, ayanran náà sì bò ó dé agbede meji sí ìsàlẹ̀.
 Ó tún ṣeéṣe láti ràn nípa ìbálòpọ ̀ àti ìfa ẹjẹ ̀ sára .
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Fasiti OAU: À wádìí olùkọ́ tó fẹ́ bá akẹ́kọ̀ọ́ lò fún máákì 10 Ìgbé 2018 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 12 Ìgbé 2018 Oríṣun àwòrán, @OfficialOAU Àkọlé àwòrán, Fásitì OAU ní ààbò àṣírí wà fún akẹ́kọ̀ọ́ yóówù tó bá ta àwọn aláṣẹ fásitì náà lólobó ìwà ìbàjẹ́ Fásitì Ọbafẹ́mi Awólọ́wọ̀ ní Ìlú Ilé ifẹ̀, OAU, ti gbé ìgbìmọ̀ kan kalẹ̀ lórí ìròyìn aṣemáṣe tó dá lóríi ẹ̀sùn bíbéèrè fún ìbálòpọ̀ láti gba máàkì ìdánwò lọ́wọ́ akẹ́kọ́bìnrin kan, èyítí wọ́n fi kan ọ̀kan lára àwọn olùkọ́ fásitì náà.
Ṣebí àwọn tí ń jẹ ẹbọ ń jẹ ninu anfaani lílo pẹpẹ ìrúbọ fún ìsìn Ọlọrun?
Wọn n fi ẹtan gbe awọn obinrin naa kuro nilu Benin wi pẹ igbe aye to rọsọmu n duro de wọn nile Yuroopu.
A kò lọwọ́ sí ìwé ìpẹ̀jọ́ tó tako ìdásílẹ̀ ìgbìmò ìwádìí aṣemáṣe ikọ̀ SARS- ọlọ́pàá Nàìjíríà Ṣé ẹ rántí àkọ́lé àwọn ìwé àkàgbádùn yìí?
Orilẹede China a ma a fi ekute ile se ọti waini ẹlẹrin dodo.
Akíkanjú obìnrin Algeria tó kojú ogun Lárúbáwá fáwọn ènìyàn rẹ̀ ‘Ile-ise kolẹkodọti ko sisẹ to l’Eko’ Derin gba awọn ọdọ Naijiria ti wọn ṣi n wa iṣẹ kiri pe ki wọn wo nkan ti awọn le maa ta tabi ṣe ni ọna igbalode.
Mike Bamiloye, adarí Mount Zion bèrè bóyá àpaàyàn kọ́ ní ẹni tó ń ṣí ara sílẹ̀ lọ ṣọ́ọ̀ṣì, ṣé apàyàn kọ́ ni ẹ́ báyìí?
Bakan naa ni idaro yii ko yọ Sanyẹri silẹ.
Kí ló dé tí o fi fẹ́ mú àwọn ọmọ Israẹli jẹ̀bi?
com tun ṣalaye pe, Akufa le waye ti ẹlẹda oku to ku ko ba ni isinmi tabi to ba n binu si awọn alaaye.
Small Doctor: Mi ò fi igbò tàbí sìgá kọrin rí
Ni kete ti iroyin naa balẹ ni ọgọọrọ awọn osere tiata lede Yoruba ti dide si ọrọ naa, ti wọn si n bẹbẹ fun awọn ẹlẹyinju aanu ati awọn akẹẹgbẹ wọn to rijẹ sẹku, lati gba ọrọ agba osere naa ro.
n ri si ironilagbara ati isẹ ọwọ lorile ede Naijiria , to wa ni Yola ni ipinle
A ti ń sin òkú méjì sínú ibójì kan náà nítorí ọ̀wọ́ngógó ibojì ìsìnkú Ẹgbẹgbẹ̀rún ọmọ Nàìjíríà ní yóò má a kú lójoojúmọ́ tí wọn bá gbà wọ́n láàyè láti gbébọn dání- Amofin Ohun rere ti Victor Agunbiade n ṣe nilẹ okeere yii jẹ iwuri fun iran Yoruba ati Naijiria lapapọ paapaa lasiko yii ti awọn bii Hushpuppi ati awọn miran n ba orukọ Naijiria jẹ.
Ẹni tí OLUWA kò ṣépè lé,báwo ni mo ṣe lè gbé e ṣépè?
Jean Baptiste Antoniew Lassus ati Eugene Emmanuel Viollet-le Duc lawọn ayaworan ile ti wọn siṣẹ naa.
@Hermosa_Reinaa ni tiẹ sọ pe bi Fatoyinbo ṣe jẹ alejo pataki ni Shiloh jẹ ara idi ti oun ko ṣe fẹ ẹ ni nkankan ṣe pẹlu ẹsin Kristiẹni ni Naijiria.
Ọọni Ile-Ife, Ọba ẹnitan Ogunwusi, ati Alaafin Ọyọ, Ọba Lamidi Adeyẹmi naa n bẹ lara awọn alejo pataki ti wọn n reti nibi ipejọpọ naa.
O ní òun ri àra òun bi omi sùgbọ́n ìna ni Nengi, eni ti àwọn si lé jọ gbé ìdílé ró ni Nígbà ti Ebuka bèrè lọ́wọ́ Dorathy bóya ó ti ṣetán láti lọ ilé, o ni rárá nítori ko si ibi ti oun fẹ́ lọ bí òun bá kúrò nilé ẹlẹ́gbọ̀n àgbà.
Èyí mú kí inú mi dùn pupọ.
“Láìpẹ́ ẹ kò ní rí mi mọ́.
Kìnìhún Manchester City tó bú ramúramù, ó fẹ́ pa Chelsea jẹ ni?
O ni ile awọn ṣofo lai si ọkọ oun.
Ẹja ńlá ní í fòkun ṣelé
Àlàyé rèé lórí bí agbẹjọ́rò tó ń ṣojú Hushpuppi nílé ẹjọ́ ṣe pegedé sí Ẹ wo àwọn àmúyẹ ti gbajúmọ̀ agbẹjọ́rò tó fẹ́ ṣojú Hushpuppi nile ẹjọ ní Onileeṣẹ adani ni Hushpuppi, ọmọ Naijriia ti wọn fi si ọgba ẹwọn nilẹ Amẹrika, nitori ẹsun jibiti.
Angelique kidjo pe fun anfani f'awọn obinrin Kíni ìdí ti wọn fi ń lọ ọmú obinrin Ọlọpa kan yinbọn mọ ọga rẹ nitori obinrin Kí ló dé tí obinrin tó ní HIV/AIDS fi pọ̀ ju ọkunrin lọ ní Nàìjíríà?
Ohun to gbẹyẹ lasiko iyikoto naa ni bi wọn ṣe mu ẹgbẹ agbabọọlu Juventus ati Barcelona pọ si ipin kan naa.
Àkọlé àwòrán, Awọn oludije gomina l‘Ekiti Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí 2 sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
Ó da òrùka wúrà mẹrin, ó jó ọ̀kọ̀ọ̀kan mọ́ ẹsẹ̀ mẹrẹẹrin tabili náà lábẹ́ ìgbátí rẹ̀, 
Ọ̀rẹ́ tí ènìyàn lè gbẹ́kẹ̀lé ni, kì í ṣe ọ̀rẹ́ tí ojú rẹ̀ dùn bí oyin ṣùgbọ́n tí inú rẹ̀ dà bí oró paramọ́lẹ̀, kì í ṣe ọ̀rẹ́ tí ń dé ilé ẹni tí ó ń kí ni ní ìgbà àádọ́ta lóòjọ́ tí ó sì jẹ alága ní ìdí rìkíṣí ẹni.
“Bí o bá tẹ̀lé ọ̀nà mi, tí o sì pa òfin mi mọ́, o óo di alákòóso ilé mi ati àwọn àgbàlá rẹ̀.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Canada yóò bẹ̀rẹ̀ àyẹ̀wò f'áwọn ọmọ Nàìjíríà tó fẹ́ wọ Amẹrika 6 Èbibi 2018 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Wọn ni awọn yoo maa wo awọn ti o ba fẹ gba iwe irinna Amerika fínífíní Canada ti n ṣiṣẹ pọ pẹlu orilẹ ede Amẹrika bayi, lati dẹkun iye awọm ọmọ Naijiria to n sa wọ Canada nigba ti wọn ba ti de Amerika, The Canada Press lo sọ bẹ .
Gẹg bi a ṣe gbọ, o to ọdun mẹtala ti ija wọn ti bẹrẹ.
Ọkan lara awọn arinrinajo naa, to ṣẹṣẹ de lati Saudi Arabia l'ọsẹ to kọja ni aarun naa lara.
Lonii ni Oloogbe Oladẹjọ Okediji to jẹ ogbontarigi agba onkọwe lede Yoruba ko ba pe ẹni aadọrun un ọdun loke eepẹ.
O wa fi ọwọ ìdánilójú sọya pé, aáyán tí ń lọ láti ṣe àwárí àwọn ìbejì náà, tó sì ń rọ àwọn èèyàn tọrọ náà kan láti fi ọwọ sowọpọ pẹ̀lú ileesẹ ọlọ́pàá.
Botilẹjẹ pe awọn onimọ nipa eto ilera sọ pe ko ti i si iwadii kankan to sọ pe sisun ni ihoho lalẹ dara ju sisun pẹlu aṣọ lọ.
 Àwọn mọ ̀ lẹ ́ bí èdè koin ni niger-congo , atlántic-congo , volta-congo àti bẹ ́ ẹ ̀ bẹ ́ ẹ ̀ lọ .
 wón ní bàbá yìí ma ń fi àyíká ilé e rè gbin orisirisi nǹkan lódodún sùgbón wón wí pé , àwon eran òsìn bíi ewúré ma ń yo ó lénu púpò .
rẹ fun ayẹwo finni-finni ko to di ipari ọsẹ yii.
ohun lo mu ki Wilder bori ninu ifigagbaga  naa.
Èmi ọ̀jọ̀gbọ́n yìí ti jẹ ọba lórí Israẹli, ní Jerusalẹmu.
àwọn ọmọ Basiluti, àwọn ọmọ Mehida, ati àwọn ọmọ Hariṣa, 
Asuba ọmọ Ṣilihi ni ìyá rẹ̀.
"Ẹnikan tilẹ fesi wipe ""njẹ o yẹ ki iru nkan bayii tilẹjẹ koko iroyin ti gbogbo eniyan wa npin kiri?"
Ohun ta gbọ ni wi pe ṣadede lawọn agbebọn yọ si awọn obinrin naa ti wọn yinbọn lu ọkọ wọn ti si jin wọn gbe.
Lonii, ọjọbọ, ọjọ keje oṣu keji ni èyí wáyé.
Ara awọn iwa ipa ni ki ọkọ maa foro ẹmi iyawo ni ile, ki ọkọ maa fi orun adidun jẹ iyawo rẹ niya ati bẹẹbẹẹ lọ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Man United bọ́ si ìpele àsekágbá ninu ìdíje FA 21 Ìgbé 2018 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Àwọn ọmọ ẹgbẹ́ agbabọọlu Manchester United fi ìdùnú wọn hàn Egbẹ́ agbábọ́ọ́lù Manchester United ti bọ́ sí ìpele àsekágbá ninu ìdíje FA lẹ́yìn ti wọ́n na ẹgbẹ́ agbabọọlu Tottenham ni àmì ayò meji si ẹyọkan.
Bàtà àti aṣọ tú àṣírí afurasí adigunjalè Ọdún Ọlọ́jọ́ dùn ní Ilé Ifẹ̀, ó lárinrin Ìtàn tó rọ̀ mọ́ òwe ‘aṣọ kò bá Ọ́mọ́yẹ mọ́.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Akure fire: Àwọn tó fara káásá ìjàmbá iná nílùú Akure d'ẹ̀bi ru panápaná 15 Òkùdu 2020 Awọn aladugbo ni agbegbe Ọbanla ni ilu Akurẹ ti di ẹbi bi ọṣẹ ti ijamba ina to waye lagbegbe naa ṣe se pọ ru bi awọn oṣiṣẹ panapana ṣe pẹ de ibi ti ijamba ina naa ti waye lalẹ ọjọ Aiku.
" "" ipò tí jìjì sì ń fẹ ́ gẹ ́ gẹ ́ bí arẹwà obìnrin ni ipò ayaba , kí ó jẹ ́ olorì àgbà pátápátá ."
Gawat Àkọlé àwòrán, Ọpọ onwoye gbagbọ pe omi n bẹ lamu fun Oshiomole lori iṣọkan ẹgbẹ oṣelu naa Nigba ti akọroyin wa beere lọwọ Giadom nipa iroyin to n ja rain pe awọn agbofinro ti wa ọkọ gunlẹ niwaju oluileeṣẹ ẹgbẹ naa ni Abuja, o ni ko si ohun to jọ bẹ.
Awọn ti iṣẹlẹ naa ṣ'oju wọn sọ pe tẹlifisan ni awọn kọkọ ri to fo jade lati oju ferese ibugbe naa, lẹyin naa ni obinrin ọhun ati ololufẹ rẹ to jẹ ẹni ọdun mọkandinlọgbọnfo jade lati oju ferese bọ si isalẹ ile.
"Ni ti olorin Falz, o fi ye awọn ọdọ Naijiria pe ""eyi ni agbara ti ẹ ni."
Titi di asiko yii, ko sẹni to tii le sọ nipato boya awọn oniṣẹibi alakatakiti ẹsin Islam, Boko Haram lo ṣiṣẹ naa tabi bẹẹkọ, ṣugbọn awọn ni wọn fura si.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ààrẹ Buhari gúnlẹ̀ pádà sí Nàìjíríà Olórí alátakò ìjọba ní Mozambique kú Bioraj dá òṣìṣẹ́ dúró torí fídíò BBC Ibà yọ Serena Williams ní Madrid open Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Sunday Igboho: Bí ń kò bá jẹ́ èèyàn dáadáa, Ọlọ́run kò ní ṣe oun dáadáa fún mi
Ẹ kò gbọdọ̀ bá ẹnikẹ́ni dá majẹmu ninu gbogbo àwọn eniyan tí ń gbé ilẹ̀ náà, kí ẹ má baà bá wọn dá majẹmu tán, kí ó wá di pé, nígbà tí wọn bá ń rúbọ sí oriṣa wọn, tí wọn sì ń ṣe ìṣekúṣe nídìí oriṣa wọn, wọn óo máa pè yín, pé kí ẹ máa lọ bá wọn jẹ ninu ẹbọ wọn.
Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí 2021 Budget: Wo ìgbà márùnn ún tí Buhari ti rìnrin àjò lọ sókè òkun fún ìtọ́jú ara rẹ̀6 Bélú 2020 Florence Ajimobi: Àwọn Káfíńtà ti kó igi dé láti tún òrùlé ilé ìtajà tó jóná ṣe9 Bélú 2020 Fídíò, Orlando Owoh: Ayé ti sú mi, àdúrà ikú ìrọ̀rùn ló wù mí- Christiana, Ìyá Orlando Owoh tó ti pé ọdún 1105 Bélú 2020 Fídíò, Fire accident victim: AbdulQudus Bello ṣàlàyé bí òun ṣe dí aláàbọ̀ ara nítorí pọpọ́ọ̀fù àti ìbínú jàǹdùkù àdúgbò7 Bélú 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
“Ìdájọ́ ti dé sórí àwọn ìlú tí ó wà ní ilẹ̀ tí ó tẹ́jú: Holoni, Jahisai, ati Mefaati; 
Báwo wá ni eniyan ṣe lè jẹ́ olódodo níwájú Ọlọrun?
Oloye Ogundokun lo rọ ileẹjọ lati paṣẹ naa fun Oluwo, o si tun pa awọn aṣoju moṣalaṣi aringbungbun ilu Iwo sọrọ naa nileẹjọ.
Ni oju opo ikansiraẹni Twitter wọn, PDP ni aṣiwaju n fi awọn kọ eebu pẹlu bi o ṣe gbẹra lati orilẹede Naijiria lọ si Mecca lati lọ ba Aarẹ Buhari sọrọ kubakungbe.
Tani gbajugbaja òṣèré ''Toromagbe'' nínú fíìmù ''Arelu'' tí jáde láyé Gbajugbaja òṣèré ''Toromagbe'' nínú fíìmù ''Arelu'' to jáde láyé jẹ akanda ẹda ti gbogbo eniyan mọ si 'arara'' nitori eniyan kukuru ni.
Igi gigun meji ni ọkan ninu awọn ayaba yoo fi maa na igba kekere to wa ninu omi yii.
Alufaa Bakare lu awọn oṣiṣẹ eleto ilera lọgọ ẹnu lori iṣẹ takun takun ti wọn n ṣe lasiko ajakalẹ coronavirus yii, o gbadura fun aabo Ọlọrun lori wọn.
Losu kẹta ọdun yi ni wọn kede ẹni akọkọ to safihan arun yi.
Múra ní àárọ̀ ọ̀la, kí o gun òkè Sinai wá, kí o wá farahàn mí lórí òkè náà.
Ikú tí yóò pamí, kìí ṣe ti ‘HIV’
PDP ati Atiku ni, to ba jẹ pe wọn ka awọn esi ibo naa bo se yẹ ni, awọn ko ba fi ibo to to 222,332 na aarẹ Muhammadu Buhari, tii se alatako latinu ẹgbẹ oselu APC, ti wọn kede pe o jawe olubori.
 ojú abẹ ́ titani lè wáyé .
Ṣugbọn, igbe aye ode oni, ko fi aaye silẹ fun ọpọlọpọ lati tete maa jẹun Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Yorùbá dùn lédè, ẹ máa sọọ́ Ìgunnukó nìyí, òrìsà Tápà, òrìsà olówó àti tọlọ́mọ Eré Mọrèmi rèé, obìnrin tó gba Ilé-Ifẹ̀ là lọ́wọ́ ìparun Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Woli Kasali: Angẹli mi ni orékelẹ́wà Dọlapo Awoṣika Mama Oloye tuntun naa, Lizzy Anjọrin, si fi awọn aworan ayẹyẹ iwuye rẹ lu oju opo Twitter rẹ kan, diẹ lara rẹ ni iwọnyi.
Àwọn ẹ̀rọ wọnyi kò lágbára tó lati dipò iná mọ̀nàmọ́ná ti ó yẹ ki Ìjọba pèsè.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Afenifere: Ọlọ́pàá kò le sọ bóyá Fulani darandaran ló pa Funke Olakunrin 13 Agẹmo 2019 Oríṣun àwòrán, Google Àkọlé àwòrán, Alagbà Fasoranti àti ọmọ rẹ̀, Funke Ọlakunrin Agbẹnusọ ileeṣẹ ọlọpaa nipinlẹ Ondo, Ọgbẹni Femi Joseph ti fidirẹmulẹ fun BBC Yoruba pe lootọ ni awọn kan ṣekupa ọmọ Alaga fun ẹgbẹ Afẹnifẹre, Oloye Reuben Fasoranti, Funke Olakunrin loju ọna Ore si Benin.
"Ṣe awọn agba maa n sọ pe ""Ọmọ tí yóò bá ti ṣe ṣámú ṣámú, àti kékére la ti ń mọ̀"", Favour Adebayo wa ni ipele keji ileewe girama (JSS 2) ṣugbọn ọgbọn to wa lori rẹ ju ti kilaasi to wa lọ."
omoluabi to fihan nipa ibewo to se, o wa se afikun pe ibewo re fihan gbangba pe
Ẹ wo ohun tawọn ọmọ Naijiria mii n sọ loju opo Twitter.
Pípè fún ìfẹ̀hónú hàn túmọ̀ sí ìdìtẹ̀ gbàjọba àti ìgbésùnmọ̀mí - Ọlọ́pàá Dandan ni láti kéde dùkìá ṣáájú ìbúra wọlẹ́ sípò Mínísítà Ọlọkọ tó ṣàfihàn ìhòòhò obìnrin ní Lekki n fí ẹwọn ọdún mẹ́ta runmú- Ìjọba Èkó Ó tó gẹ́ẹ́!
OLUWA, ranti bí èmi, iranṣẹ rẹ, ti di ẹni yẹ̀yẹ́;ati bí mo ti ń farada ẹ̀gàn àwọn eniyan,
Nígbà tí ó dé ilé, ó rẹ́ wọn sinu ìkòkò àsáró náà láìmọ̀ ohun tí wọ́n jẹ́.
nì májísíréètì kìíní ní ilẹ ̀ nàìjíríà tí ó jẹ ́ ọmọ nàìjíríà ni sir olumuyiwa jibalaru .
"Amọ ko sai yan ọrọ rẹ pe, ""igbakeji aarẹ, ni orukọ ijọba apapọ, ti tọrọ aforijin lọwọ baba mi lori iṣẹlẹ naa, ti a si ti fi ija fun Ọlọrun ja, fọwọ lẹran."
Nítorí ohun tí ó bá wà ninu ọkàn ẹni ni ẹnu ẹni ń sọ jáde.
O fi kun le pe, bi wọn ba ṣe n tẹle adehun yii ko gbọdọ pa gbogbo akitiyan ijọba lara, lati ṣe gbogbo eto amuludun ti wọn ti n pinu lati ṣe tẹlẹ tabi eyi ti wọn n ṣe lọwọ.
Ọdun kan ati oṣu mẹjọ si ni Idiagbon lo lori aga aleefa bii igbakeji adari Naijiria, ki wọn to yẹ aga akoso nidi rẹ.
Ko si ilẹ riri, iji lile tabi ikun omi to lee bi afara naa wo.
"Atẹjade kan ti olubadamọran fun aarẹ lori ọrọ iroyin, Fẹmi Adesina fi sita salaye rẹ pe, lootọ ni aarẹ sọrọ lori awọn ọdọ Naijiria, sugbọn ohun to sọ ni wi pe: ""Awọn ọdọ pọ lorilẹede Naijiria, wọn si ko ida ọgọta ninu ọgọrun awọn eeyan orilẹede wa to to ọgọsan miliọnu eniyan."
Èèyàn 78 míràn tún ti ní àrùn Coronavirus ní Nàíjírìa Eeyan mejidinlọgọrin miran ni ayẹwo tun ti fihan pe o ni arun Coronavirus bayii lorilẹede Naijiria.
"Lọjọ naa lo si ti bẹrẹ si ni fipa bamilopọ"" ""Leyin igba diẹ ti ede aiyede waye laarin oun ati awọn ọmọ ẹgbẹ naa miran ti won si pa a, wọn fi mí fun ẹlomiran gẹgẹ bi iyawo."
Wọ́n sun ọ̀dọ́ aguntan Ìrékọjá gẹ́gẹ́ bí ìlànà.
Saaju, nigba ti ,adari egbe  awon
 gbogbo àwọn orílẹ ̀ -èdè tí awọn orílẹ ̀ -èdè alágbára wọ ̀ nyí ń ṣe àkóso lé lórí tí wọ ́ n ń mú sìn pàápàá jùlọ ní ilẹ ̀ adúláwọ ̀ [ africa ] àti ilẹ ̀ lárúbáwá ni gbogbo wọn náà múra láti gbè sẹ ́ yìn àwọn ọ ̀ gá wọn láti bá àwọn orílẹ ̀ -èdè yòókù jà tí èyí sì di isu atayán-an yàn-an káàkiri orílẹ ̀ -èdè àgbáyé .
dúró ládipọ ̀ ( 1931-1978 ) jẹ ́ ọ ̀ kan lára àwon ògúná gbòngbò olùkọ ̀ tàn eléré oníṣe yorùbá tí ń dátó lẹ ́ nu ìgbín ní ilẹ ̀ adúláwọ ̀ lẹ ́ yìn ìmúnisìn àwọn òyìnbó .
Agbara Ajo NFVCBNFVCB je ajo labe ijoba apapo Naijiria to wa fun amojuto awon fiimu, orin ati fonran fidio to n jade ni Naijiria.
Jesu Kristi ni ó fihàn mí.
 Àwon elékọ ̀ ọ ́ bíbélì tí à ń pè ni ( theologians ) gbà pe májẹ ̀ mú láíláí wà ní ìṣọ ̀ kan pẹ ̀ lu májèmú títun .
Ẹ sanwo ẹ gba turọli yin o.
O ni ọkunrin to ba fi ipa ọmọde tabi agbalagba to jẹ obinrin lopọ ti ṣe ohun buruku.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Florida: Ọọ̀nì àléégbà dé ba Mary lálejò lọ́gànjọ́ òru Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Florida: Ọọ̀nì àléégbà dé ba Mary lálejò lọ́gànjọ́ òru 21 Òkùdu 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 8 Èbibi 2020 To ba jẹ iwọ, kini o maa ṣe?
Se wọn ni, iborun ti ko ba sunwọn, abẹ abiya lo n gbe, eyi to ba sunwọn, ejika ni yoo wa, bi kaadi idamọ wa yi se sunwọn, lo mu kawa naa maa gbee kọrun kiri bii ami ẹyẹ goolu .
Fi òkúta Urimu ati òkúta Tumimu sí ara ìgbàyà ìdájọ́, kí wọn kí ó sì máa wà ní oókan àyà Aaroni, nígbà tí ó bá lọ siwaju OLUWA.
Ọmọ ọdun mejidinlọgbọn naa tako ẹsun ti wọn fi kan an, ti o si ṣalaye pe niṣe ni oun gba itọju fun bi ẹjẹ ti ṣe n ya lara oun.
Nitori naa ni mo ṣe duro sile, tori boya mo ni aarun naa ti mi o mọ.
"Gomina Ambode se afikun ọrọ wipe akọle aba isuna ọdun 2018 ni, ""aba isuna itẹsiwaju ati idagbasoke""."
O ní ọ̀pọ̀ awọn tó n lo ìwà ipá sábà máa fi àwọn àmìn yìí hàn: Wọ́n maa n fẹ ki obìnrin tàbí ọkùnrin náà jẹ tíwọn nìkan Wọ́n máà ń ṣọ ẹnìkejì wọ́n lọ́wọ́ lẹ́ṣẹ̀, yàlá, fóònù rẹ̀ àti ibi to n rì sí Irú ẹni bẹ́ẹ̀ yóò ti le ẹbí kúrò lára ẹni náà, òun ni yóò maa sọ irú ọ̀rẹ́ tí ó gbọdọ ni fún pẹ̀lú O ní lẹ́yìn tí o bá ti ṣe àṣeyọri lórí àwọn ǹkan wọ́nyìí ni yóò ṣẹ̀ṣẹ̀ wá yọ́wọ́ ìwà.
Ẹwẹ, awọn asofin to jẹ ọmọ ẹgbẹ oselu to kere julọ nile asofin naa, ti kọ lati fi ọwọ si iwe iyọnipo igbakeji gomina.
Elifasi ará Temani bá dáhùn pé,
Díẹ̀ lára àwọn ìṣẹ̀lẹ̀ tí yóò mi ìgboro tìtì l'ọ́dún 2020 rèé Gómìnà mẹ́ta àtí ènìyàn 1,242 ló kó sí panpẹ EFCC ni ọdún 2019 Iran ti jáwọ nínú ìlù ogun tó n lù -Trump Ilé ìwòsàn l'Àbuja ti ya àwọn ìbejì tí wọ́n sọpọ̀ láyà lọ́fẹ̀ẹ́ Lakotan, o ni ki awọn ara ẹkun mii to n sọrọ lodi si agbekalẹ ikọ Amọtẹkun lọ jokoo tori oye ko ye wọn to ni.
Ìran mi já Nàìjíríà kulẹ̀ 24 Ìgbé 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Onimọ nipa iwe kikọ ati Litiresọ, Ọjọgbọn Wọle Ṣoyinka ti sọ pe, iran oun ti ja orilẹede Naijiria kulẹ patapata.
Ọ ̀ kọrin lè fi orin mú iwúrí àti ìdùnu bá ara rẹ ̀ tàbí ẹlòmìíràn .
Oyo Police:: A ti rí ọkọ̀ méjì tí àwọn ajínigbé lò láti jí Dayọ Adewọle Ile isẹ ọlọpaa ni ipinlẹ Ọyọ ti mu afurasi mẹta to jẹ osisẹ ni oko ti wọn ti ji Dayo Adewole, to jẹ ọmọ minisita fun eto ilera tẹlẹri Isaac Adewole naa gbe.
Bo ti tilẹ jẹ pe ipo Aarẹ ni oju Kamala wa tẹlẹ oun ni aṣayan awọn agba ẹgbẹ ninu oṣelu naa yan gẹgẹ bi i igbakeji.
Kí ó mú abo ọ̀dọ́ aguntan, tabi ti ewúrẹ́ wá fún ẹbọ ìmúkúrò ẹ̀ṣẹ̀, alufaa yóo sì ṣe ètùtù fún un nítorí ẹ̀ṣẹ̀ rẹ̀.
Bẹ́ẹ̀ ni olóríburúkú parí tirẹ̀ láyé, òṣùpá ènìyàn búburú wọ òkùnkùn, àṣírí aláìníláàárí tú sí ìta.
“Inu mi dun pe, ipade ojukoju yii waye, eyi ti o fihan pe, akotun ajosepo to muna doko laarin eka aladani ati ile-ise ijoba le yori si rere, fun idi eyi a niloo awon ile-ise eka aladani”.
Arsenal ṣẹ́ṣó ìyà, búlálà ẹlẹ́nu mẹ́ta ni Leicester City fi lù wọ́n lálù bami Duro Ladipọ, ìlúmọ̀ọ́ká òṣèré tíátà àti ọmọ àlúfà tí kò gbàgbé àṣà ìbílẹ̀ Lati mọ iya ilu nikan gan gẹgẹ bi ọba ilu, kii ṣe iṣẹ kekere ṣugbọn ni ti Ayanfunke pẹlu ekeji rẹ, oriṣiriṣi ilu ni wọn lee dawọ le lai foya eyi ko si sẹyin baba wọn, Ọgbẹni Ganiyu ẹni to ti wa di alamojuto wọn ni gbogbo ode tabi eto ti wọn ba n lọ.
Ògogó òkú kò gb'orí, Onígborí mi l'Ọ́yọ mọ̀kọ.
2,bilionu, ati eka elekun-jekun je eji-le-logoje milionu  Naira N152 Bakan naa ni alakoso na tun so pe, bilionu mokanleladota N51.
Eero awọn wọnyi ko yatọ rara si nkan ti ọpọ sọ loju opo náà, ati ni awọn oju opo ayelujara bi twitter.
"A ní ìfarajì láti mú ìròyìn tó gún reége láì gbé ọmọ ọbà fún ọ̀ṣun, bákan náà ni a maa ń yàgò gédégédé fún ǹkan to ba lé ṣi àwọn olólùlùfẹ́ wa lọ́nà ""Ìfarajì wa fún àìfigbákan bọ̀kan nínú jẹ gbùngbùn ọkọ̀ ìgbákẹ̀le àwọn ènìyàn nínú wa."
Ọpọ wọn lo si ti da awọn ọmọ almajiri pada si ipinlẹ ti wọn ti wa, lasiko coronavirus.
US presidential election 2020: Iye owó tí ìjọba Amẹrika ń ná sí ìdìbò Ààrẹ rèé
Mo ti rawọ́ ẹ̀bẹ̀ sí àwọn aláṣẹ fún ogójì ọdún tí ó kọjá láti gba àwọn ilé àjogúnbá bíi Bara Katra àti Choto Katra sílẹ̀ lọ́wọ́ àwọn tí ó fẹ́ pa ìtàn àtẹ̀yìnwá rẹ́.
Ṣugbọn titi di oni, alufaa naa ko fesi si ẹsun naa.
ọ̀pọ̀lọpọ̀ nǹkan rere gbogbo sì ni ìforítì tì mú bá mi.
 fún ìdí èyí yó şànfàní nígbà tí a bá n sọ nípa èsìn ìgbàgbọ ́ lati máa mẹ ́ nu ba àwon èsìn míran .
Pẹ̀lú agbára àti àjọṣe wa, ẹ̀rọ-ayélujára yóò di ibi òmìnira fún ìtẹ̀síwájú ìjọba àwa-arawa.
Wòlíì kọ pé, “A gbà lati ọ̀dọ̀ Rẹ̀ [Jésu Krístì] àwọn àtẹ̀lé wọ̀nyí, nípa ẹ̀mí ìsọtẹ́lẹ̀ àti ìfihàn; èyí tí kò fún wa ní ọ̀pọ̀lọpọ̀ ọ̀rọ̀ nìkan, ṣugbọ́n bákannáà ó tọ́kasí ọjọ́ náà gan an fún wa nígbàtí, ní ìbámu pẹ̀lú ìfẹ́ àti òfin Rẹ̀, a nílati tẹ̀síwájú lati ṣe àkójọ Ìjọ Rẹ̀ lẹ́ẹ̀kan síi níhĩn ní orí ilẹ̀ ayé.
Àkókò ẹ̀rín wà lọ́tọ̀ pẹ̀lú, bẹ́ẹ̀ ṣá ni gbogbo ètò wọn.
Ẹ má gbàgbé pé àwa ni a dábàá ati mú ọba pada sílé.
Ìwà kan náà ni ó wà lọ́wọ́ ìwọ ati àwọn arabinrin rẹ, àwọn náà kò ka ọkọ ati àwọn ọmọ wọn sí.
“Bí ó bá jẹ́ pé, aguntan ni ó mú wá fún ẹbọ ìmúkúrò ẹ̀ṣẹ̀, ó níláti jẹ́ abo aguntan tí kò ní àbààwọ́n.
Gbẹgẹdẹ fẹ́ gbiná l‘Ọṣun, àwọn olùkọ́ iléẹ̀kọ́ gíga fẹ́ gba àjẹẹ́lẹ̀ owó oṣù ìdajì Agbébọn yabo àgọ́ ọ́lọ́pàá, wọ́n pa DPO àti ọlọ́pàá mẹ́ta míràn Frank Lampard fi igba kan ri jẹ agbabọọlu ikọ naa ti orukọ rẹ ko lee parẹ laelae, oun si ni agbabọọlu to gba goolu wọle julọ fun ikọ ọhun ki o to fi ibẹ silẹ.
O ni dipo bẹẹ, se ni aarẹ Buhari se atilẹyin fun ikede konile o gbele to wa lawọn ipinlẹ kan lorilẹede yii, to si rọ awọn eeyan lati dẹkun iwọde fun aabo ẹmi wọn.
Lónìí ni Ajimobi yóò mọ bó ṣe ń lọ pẹ̀lú ẹjọ́ kòtẹ́milọ́rùn tó pè Irọ́ ni pe a ti pa mẹ́ta nínú àwọn Shiite -Ileeṣẹ ọlọ́pàá Naijiria Òní ni Shi'ite fẹ́ ṣe ìwọ́de ikú ọmọ ọmọ Anọ́bì ní èyí tí ó lòdí sí àṣẹ agbófinró Irọ funfun báláwú ni, Boko Haram kò dawa lọnà rárá -Ọmọ ogun Naijiria Ni kete ti Aarẹ Muhammadu Buhari pari ipade pẹlu awọn ikọ to lọ ṣabéwo si South Africa tan to si gbọ abọ wọn lo fi ikede yii sita.
Adebayo Faleti tun kọ awọn iwe miran bii Basorun Gaa to je iwe ere onitan ati ọ̀pọ̀lọpọ̀ ewi to dun bii Onibode Lalupọn, Alagbara ile ati Alagbara Oko, Adebimpe Ojedokun, Erelu omo ati bẹ́ẹ̀ bẹẹ̀ lọ Iwe Omo Olokun Ẹṣin, yii n ran onkawe leti pataki ominira, pẹlu ẹkọ loriṣiiriṣi nipa igbe aye alaafia ati ọna ijijangbara kuro loko ẹru.
Oluwo wi pe awọn alaabo Ọọni lo tipa-ti-ikuku pẹlu ohun, eleyi ti Ọọni sọ wipe irọ patapata gbaa ni.
Igbesẹ Boris yii ṣeeṣẹ ko tẹ awọn ololufẹ ẹ lọrun ṣugbọn o nii ṣe pẹlu ileri rẹ lati yọ kuro ni Brexit titi oṣu kẹwaa ọdun.
Olusola kuro lọdọ ọga rẹ lọdun 1965 lati da ẹgbẹ tiata tara rẹ silẹ, to si n kọrin, lu ilu, jo ati sere.
Igba ti yoo si fi di alẹ ọjọ keji, wọn ti fun Chidozie ni ọpọlọpọ abẹrẹ pẹlu omi mẹjọ, ki esi ayẹwo to ṣe to o jade.
Iru awọn iroyin ti ẹ le nifẹ si: Buhari ṣ'abẹwo si Tabara, Benue 'Akonimu BBC' Jamb padanu owo s'ikun ejo Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
O tesiwaju pe, o se ni laanu wi pe, aseyori akitiyan ijoba lori awon ikolu naa koi ti gbode to bi o se ye lataari iha ti  awon akoroyin ko si aseyori naa.
Ko yẹ ki n le sare jo bayii laarin ọjọ perete.
Ipo kẹta ni PSG lori tabili idije Lique 1, ati pe Barcelona ni wọn yoo koju ni ipele ẹlẹni mẹrindinlogun(round of 16) ninu idije Champions League loṣu keji ati ikẹta ọdun 2021 yii.
Gbajabiamila sọ ninu ikede kan to fi sita loju opo Twitter rẹ ni ọsan Ọjọbọ, pe oun ti paṣẹ fun akọwe ile aṣofin naa lati lai gba awọn agbẹjọro ti yoo bẹrẹ ẹjọ lori ẹsun iwa ọdaran lori Akpabio.
Iroyin ofege nipa oludije fun ipo aarẹ to n ṣatilẹyin fun ololufẹ ọkunrin s'ọkunrin le fa wọn ṣeyin.
Mikel Obi se ikinni ku oriire nas lori ero ayelujara re.
Wọn gba pe ki awọn eniyan awujọ dẹkun ìdẹ́yẹsí awọn to n lo oogun oloro ti wọn ba n gbiyanju lati yi pada.
‘Tapátẹsẹ̀ ni wọ́n ń dín in.
mo sì fún Baruku ọmọ Neraya ọmọ Mahiseaya ní èyí tí a fi òǹtẹ̀ tẹ̀, níṣojú Hanameli, ọmọ arakunrin baba mi ati níṣojú àwọn ẹlẹ́rìí tí wọn fọwọ́ sí ìwé ilẹ̀ náà, ati níṣojú gbogbo àwọn ará Juda tí wọn jókòó ní àgbàlá àwọn olùṣọ́ náà.
Ṣugbọn gudugbẹ ja nigba ti Andriy Yarmolenko gba goolu ẹlẹkẹta sawọn fun West Ham, nigba ti o ki iṣẹju kan pere ki ifẹsẹwọnsẹ naa pari, lọrọ ba di wo mi n wo ọ.
mo fẹ́ kí ẹ mọ̀ dájúdájú pé, bí ẹnikẹ́ni bá wí fún òkè yìí pé, ‘ṣídìí kúrò níbi tí o wà, kí o bọ́ sí inú òkun,’ tí kò bá ṣiyèméjì, ṣugbọn tí ó gbàgbọ́ pé, ohun tí òun wí yóo rí bẹ́ẹ̀, bẹ́ẹ̀ ni yóo rí fún un.
Bukola Saraki kò kọjá òfin - EFCC Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Bakannaa ni Igbakeji aarẹ, Yemi Osinbajo pẹlu wa nibẹ.
Ẹ̀rù ba Dafidi nítorí pé Saulu ń wá ọ̀nà láti pa á.
Aarẹ Ramaphosa tọrọ aforiji lọwọ Aarẹ Buhari lori bi awọn ọmọ South Africa ti ba ọpọ dukia awọn ọmọ Naijiria jẹ ninu ikọlu ọhun.
Buhari kopa ninu ipolongo idibo koda o tun dije dupo aarẹ.
    Báyìí ni olórí-ogun àwọn ẹ̀dá alaàyè wọ̀n-ọnnì sọ, ọ̀gbẹ́ni Ìnàkí-ìbẹ̀rù.
ipade yii , lara awon to wa nibi ipade ọhun ni, minisita fun eto aabo lorile
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ọyọ: Olubadan ni saa kẹta tọ si Ajimọbi 1 Ẹrẹ̀nà 2018 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Olubadan ati gomina Ajimọbi woju ara wọn lori ilana oye jijẹ nilu Ibadan Olubadan tilu Ibadan, Ọba Saliu Akanmu Adetunji ti ni ọpọ aseyọri Gomina Abiọla Ajimọbi ti ko lẹgbẹ lo mu ko yẹ lẹni ti yoo se saa min gẹgẹbii gomina.
Oríṣun àwòrán, Twitter/DefenceInfoNG Iṣoro kan to wa nibẹ ni pe araalu ko fi inu tan awọn ọmọ ologun.
BB Naija: Kí ló pa Elisha Abbo, Leycon àti Naira Marley pọ̀, tí àríyá yóò fi wáyé?
Lẹ́yìn rẹ̀, Hananaya, ọmọ Ṣelemaya, ati Hanuni, ọmọkunrin kẹfa ti Salafu bí ṣe àtúnṣe apá ibòmíràn.
"Koda, aṣa "" Dibo koo sebẹ"" to di gbajugbaja ọrọ lawujọ oṣelu Naijiria bayii, ko ṣẹyin BBC NEWS Yoruba, nitori awa gan an lara."
 Nibiti ile-ise iwe iroyin naa ti n sayeye odun marundinlogun ti won sagbekele re.
Jallow sọ pe, igba ti oun wa ni ẹni ọdun mejidinlogun ni oun pade Ọgbẹni Jammeh, lẹyin ti oun jawe olubori gẹgẹ bi ọmọbinrin to rẹwa ju ni olu ilu orilẹede naa, Banjul l'ọdun 2014.
 A ko ti ri otito oro dimu sinsin.
8bn owó àìtọ́ lọ́wọ́ mi ní tipá - Ẹlẹ́rìí Ìyá òòṣà fẹ̀sùn àjẹ́ kan ìyá ẹni ọdún 90, aráàlú bá sọ ọ́ lókò pa Sábàbí ire ní ikú Barakat padà já sí - Ẹ̀bí fẹ̀mí ìmoore hàn sọ́mọ Nàíjíríà Ọlọ́pàá ìpínlẹ̀ Kwara lé ọlọ́pàá mẹ́rin kúrò lẹ́nu iṣẹ́ fún ẹ̀sùn ìwà ìbàjẹ́ Gbogbo wọn ló fẹenuko pẹlu ijọba pe awọn yoo pese ohun to yẹ ki awọn akẹkọọ le wa ni alaafia nile iwe lasiko idanwo naa pẹlu iranlọwọ wọn ile iwe.
Imọran ati itọni Ọbasanjọ se koko lori imurasilẹ PDP fun idibo 2019.
Arabinrin Siddiqi sọ pe ọkọ oun ko kọkọ jẹwọ pe o ti ni iyawo tẹlẹ, ko to o pada sọ pe oun ti fẹyawo.
Yóo fi nǹkan ọ̀ṣọ́ tí ó lẹ́wà bò ọ́ lórí,yóo sì dé ọ ní adé dáradára.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Coronavirus: Afurasí aláàrùn coronavirus ní ìpínlẹ̀ Enugu ti wà ní ìyàsọ́tọ̀ 15 Ẹrẹ̀nà 2020 Oríṣun àwòrán, Getty Images Ajọ to n risi idena ajakalẹ aarun ni Naijiria, NCDC, ti sọ pe alaisan kan wa ni ipinlẹ Enugu, ni apa ila oorun orilẹ-ede Naijiria ti wọn fura si pe o ni aarun coronavirus.
Ogagun agba Poaw Kagbo so pe, awon omo-ogun eleto-abo to wa nibi ipago idiboohun ni, lati ri daju awon eniyan n dibo won pelu alaafia, amo leyi aroye yii, ogagun naa gba lati ko awon olopaa ati awon ologun naa siwaju ita.
Fatai Rolling Dollar, Ọmọ ìdílé oyè tó gbé igbá orin tí Ebenezer Obey ń ṣiṣẹ́ lábẹ́ rẹ̀!
A jẹ́ pé àsìkò kò dúró de ẹnìkan.
Ọdun 2012, 2016 àti 2020 ni John Mahama àti Nana Akufo-Addo ti jọ ń figagbága dupò aàrẹ Ghana Wo ohun tó yẹ kí o mọ̀ nípa akínkanjú obìnrin alága àjọ elétò ìdìbò Ghana 2020 Ẹ dín iye ìgbà tẹ n gorí obìnrin kù torí ìdìbò tó n bọ̀, kẹ́ẹ lè lágbára láti ṣe .
“Lẹ́yìn èyí, wọn óo da aṣọ aláwọ̀ aró bo pẹpẹ wúrà, wọn óo fi awọ ewúrẹ́ tí ń dán bò ó, wọn óo sì ti igi tí a fi ń gbé e bọ̀ ọ́.
O ni oun yoo ṣepade pẹlawọn alatilẹyin ohun lati mọ ibi ti awọn yoo gbe ka.
O sọ pe nitori naa, ti awọn alaṣẹ ẹgbẹ APC ba lero pe oun ni ipo naa yẹ, ko si alatako to le e yi pada.
 ibọdòrìṣà ni ó wà ní ìpín kẹ ́ ta .
Yóo ní ayọ̀ ní ilẹ̀ náà;OLUWA kò ní fi í lé àwọn ọ̀tá rẹ̀ lọ́wọ́.
Wọ́n bá tọ Ahabu ọba lọ, wọ́n ní, “Benhadadi, iranṣẹ rẹ, ní kí á jíṣẹ́ fún ọ pé kí o jọ̀wọ́ kí o dá ẹ̀mí òun sí.
Gẹgẹ bi Armando, New Kim di tita lẹyin ti awọn onibara meji lati orilẹ-ede China fi obibiti duna dura lori rẹ.
Moses ni ọmọ meji - ọkunrin kan ati obinrin kan.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Arsenal àti Athletico yóò wáákò Marseile lati orilẹede France yoo si maa koju Salzburg ti orilẹede Austria.
Gbogbo àwọn tí a kà ninu ẹ̀yà Isakari jẹ́ ẹgbaa mejilelọgbọn ó lé ọọdunrun (64,300).
Ẹ̀yin olólùfẹ́ mi àti ẹbí ni mo bẹ̀ Kemi Olunloyo dá sí ìjà Toyin Abraham àti Lizzy Anjorin Ọkọ Toyin Abraham pẹ́ ọ̀rọ̀ sọ lórí aáwọ̀ láàrin ìyàwó rẹ̀ àti Lizzy Anjorin Ẹ lọ́ jáwé gbé jẹ́ẹ́ sọ́wọ́ bí bẹ́ẹ̀ kọ́.
Lori ọrọ iye ti awọn orile-ede miran to ni epo rọbi n ta epo bẹtiro fun ara ilu aarẹ ni Egypt ₦211 Saudi Arabia ₦168 Chad ₦362 Niger ₦346 Ghana si n ta ni ₦326, ti Naijiria si ti n taa ni ₦161 báyìí.
Ṣugbọn nígbà tí ẹ kò mọ Ọlọrun, ẹ di ẹrú àwọn ẹ̀dá tí kì í ṣe Ọlọrun.
 oun ni omo african-american ojogbon akoko ni new york university .
Lati igba ti awọn ikọ ẹṣinokọku Boko Haram ti bẹrẹ idukuku mọni lọdun 2009, eniyan ti o le lẹgbẹrun lọna ogun ni wọn ti ran lọ s'ọrun ọsan gangan, ti ọgọọrọ eniyan si ti di alairilegbe nipasẹ awọn igbesunmọmi ati isekupani awọn ikọ Boko Haram lorilẹede Naijiria ati lagbegbe Lake Chad.
Gẹgẹ bi ohun ti a ri ka,wọn fin oogun kẹmika to lagabara si ọfisi rẹ daada ki wọn to ni pe ko pada sibẹ l'Ọjọru Weah se ibura wọle gẹgẹ bi aarẹ Liberia Ejò bu ìdí obìnrin kan jẹ nínú ilé ìgbọ̀nsẹ Oga mi lo gba 36m Jamb Ejò lé ààrẹ Liberia kúrò ní ọ́fíìsì Koda a gbọ pe o gab alejo lọjọ to ko wọ ofisi rẹpada ti ṣe ọjọru.
Dibu Ojerinde, akọ̀wé JAMB tẹ́lẹ̀ pàdánù ọ̀pọ̀ dúkìá sọwọ àjọ ICPC Èèyàn 78 míràn tún ti ní àrùn Coronavirus ní Nàíjírìa Alakoso igbimọ to n ri si ọrọ covid-19 nipinlẹ Kano, Dokita Tijani Hussaini lo fidi ọrọ yii mulẹ.
Ṣaaju ni ẹgbẹ ti kọkọ kede Ajimobi gẹgẹ bii adele alaga kuro nipo igbakeji alaga to wa tẹlẹ.
Wọ́n bá fi iyawo rẹ̀ fún ẹni tí ó jẹ́ ọ̀rẹ́ rẹ̀ tímọ́tímọ́ ninu àwọn ẹlẹgbẹ́ rẹ̀ ní àkókò igbeyawo.
Ọgbẹni Nwoko ṣalaye pe oun ko faramọ ki ọkunrin ati obinrin fẹ ara wọn fun igba pipẹ, ki wọn o to ṣe igbeyawo.
Ilé Ìgbìmọ̀ Aṣòfin gba àbá owó ìṣuná 2019 wọlé pẹ̀lú àfikún N10bn
Mo ti rù láàrin ọ̀sẹ̀ kan, iṣẹ́ Eko kò dẹ́rùn - Sanwo-Olu Ẹni tí ó wà láti Gúúsù ìlà oòrùn ni Ogbeni Sam Egube.
Ilẹ̀ ló lọ jaburata níwájú rẹ yìí, jọ̀wọ́, jẹ́ kí á takété sí ara wa.
Agbẹnusọ ileeṣẹ ọlọpaa Ipinlẹ Ondo ni awọn ṣi n wa awọn afunrasi to ku.
When Babies Don’t Come – South Africa
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Nígbà tí kò ṣeéṣe fún wa láti fò, a ó lọ́ wọkọ̀' Àwọn arẹwà obinrin Yollywood, tá ló mọ iṣẹ́ rẹ̀ jù?
Binta Mọgaji ni imura eeyan kan nigboro nii ohun se pẹlu idile to ti jade wa ati iwa ọmọluabi to ni, ti yoo si lee ronu jinlẹ pe iru oju wo ni aye fi n wo oun.
Alufaa yóo mú díẹ̀ ninu òróró tí ó wà ni ọwọ́ òsì rẹ̀, yóo fi kan ṣóńṣó etí ọ̀tún ẹni tí wọ́n fẹ́ sọ di mímọ́ ati àtàǹpàkò ọwọ́ ọ̀tún rẹ̀, ati àtàǹpàkò ẹsẹ̀ ọ̀tún rẹ̀ tí ó ti kọ́ fi ẹ̀jẹ̀ ẹbọ ìmúkúrò ẹ̀bi kàn.
Ẹni ti itan ko ba si ye, to ba tọ Alaafin lọ, oye yoo ye kedere nipa ohun to ba fẹ mọ, ti ọba alaye naa si jẹ iwuri fun ọpọ ọmọ Yoruba, paapaa lasiko to ba n hu awọn itan manigbagbe jade.
Nígbà náà ni Joṣua, ọmọ Nuni, iranṣẹ Mose, ọ̀kan ninu àwọn olùrànlọ́wọ́ rẹ̀ wí fún Mose pé, “Pa wọ́n lẹ́nu mọ́.
Wọn yii pada labẹ iṣejọba Aarẹ Buhari si ọjọ kejila, oṣu kẹfa lati fi sami igbiyanju, ijiya ati iku Moshood Kashimaawo Olawale Abiola to dije dupo aarẹ Naijiria.
Wọn pin awọn oludibo yii si ipinlẹ kọọkan gẹgẹ bi awọn eeyan ipinlẹ kọọkan ṣe pọ si.
ti won fi ẹsun kan ko tọna rara.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Mayowa Omoniyi: Kò sí orin Obey, Sunny Ade abí tàkasúfèé tí ń kò le ta gìtá sí Bakan naa ni Aarẹ tun paṣẹ fun igbimnọ naa lati gbe awọn eto ti yoo rọrun lati tẹlẹ kalẹ, paapaa lasiko ti awọn eeyan to wa ninu igbimọ ọhun ba pari saa wọn tan.
Ẹ pada sinu àgọ́ yín, ẹ̀yin ọmọ IsraẹliDafidi, fọwọ́ mú ilé rẹ.
Afurasi ọmọ ẹgbẹ Boko Haram lọwọ ti te ni ilẹ Germany
Orin apilẹkọ ẹgbẹ awọn ọkunrin alahun ti @coolehizy1 fi lede loju opo Twitter rẹ.
Ohun mii ti awọn eeyan tun un sọ ni wi pe o ṣeeṣe ki ileeṣẹ aarẹ maa bẹru wi pe, ilẹ Yoruba ti fẹ ya ara wọn kuro ni Naijiria nipasẹ agbekalẹ naa.
Aarẹ Buhari ni tiku tiye lọrọ Coronavirus, gbogbo eeyan orilẹ-ede Naijiria lo si gbọdọ farada awọn igbesẹ gbogbo lati da alaafia ati abo pada sorilẹ-ede Naijiria.
Àwọn gomina yòókù tí wọ́n jẹ ṣiwaju mi a máa ni àwọn eniyan lára, wọn a máa gba oúnjẹ mìíràn ati ọtí waini lọ́wọ́ wọn, yàtọ̀ sí ogoji ìwọ̀n Ṣekeli fadaka tí wọn ń gbà.
Seyi: Ọmọde lo n ṣe mi nigba naa.
Ọpọ eeyan lo tun maa n pe olori Folasade ni Iya Mẹta abi yeye Iṣẹṣe, to si mọ oriki awọn Alaafin to ti jẹ sẹyin ati ti ọkọ rẹ pẹlu.
Naijiria si gbọdọ  wa ni isọkan.
Gbajabiamila kéde èróńgbà rẹ̀ láti jẹ adarí ilé aṣojú ṣòfin l'Abuja Ìjọba South Africa pèpàdé lórí ìkórìíra àlejò Egbọn oloogbe ni idojukọ ikorira Xenophobia to ṣẹlẹ ni South Africa lo jẹ ki Kolade wale lati ibujoko rẹ.
A sì máa fún ẹni tí kò lágbára ní agbára.
Àwọn ẹja inú omi, àwọn ẹyẹ ojú ọ̀run, àwọn ẹranko inú igbó, gbogbo ohun tí ń rìn lórí ilẹ̀, ati gbogbo eniyan tí ó wà láyé yóo wárìrì.
“Lara awon ofin yii ni; ‘Ṣiṣe agbekalẹ fun ile-iṣẹ aṣewadii aisan Jẹjẹrẹ, Ofin Ṣiṣe Igbelarugẹ ede Yoruba, Ofin to nii ṣe pẹlu ile-ẹjọ kekere, Ofin Ṣiṣe atunṣe si ofin to jẹ mọ iṣẹ ina mọnamọna ni Ipinlẹ Eko ti ọdun 2018; Ṣiṣe atunṣe si ofin to jẹ mọ Irinna Ọkọ ni Ipinlẹ Eko ti ọdun 2018, Ofin to ṣe agbekalẹ Igbimọ Aṣakoso Iṣẹ Olukọ, eleyii to nii ṣe pẹlu awọn oṣiṣẹfẹyinti ati aabo ilu labẹle ti wọn pe ni ‘Neighbouhood Safety Corps’ ati awọn miiran.
karun un odun 2015 , ni eyi ti o ran an lowo lati jawe olubori ninu eto idibo
Iyanrìn làwọn ẹbí olóògbé bàálù Ethiopia rí gbà dípò òkú 'Súnkẹrẹ-fàkẹrẹ ọkọ̀ ló kó mí yọ lọ́wọ́ ìjàmbá ọkọ̀ òfurufú' Ẹrọ igbalode ti ko ni jẹ ki ọkọ ofurufu o duro lojiji loju ọrun Boeing 737 Max ni awọn oniwadii sọ wi pe o seese ko se okunfa iku awọn to wa ninu ọkọ baalu wọn.
Iyalẹnu ni ọrọ yii jẹ nitori Bouake ta n wí yii dàbí ilé agbára àwọn ọmọ ogun ọlọtẹ.
Oríṣun àwòrán, Trace Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Ko pẹ lẹyin igba to kawe dari nipa imọ ofurufu ni o gba iṣẹ labẹ ile isẹ ọkọ ofurufu Kabo Air gẹgẹ bi alukoro.
Lara ẹsun ti wọn fi kan an nigba naa ni pe o sa lẹnu iṣẹ.
Eliṣa bá dáhùn pé, “Bí OLUWA àwọn ọmọ ogun, ẹni tí mò ń sìn ṣe wà láàyè, n kì bá tí dá ọ lóhùn bí kò bá sí ti Jehoṣafati, ọba Juda, tí ó bá ọ wá.
Òpin burúkú dé bá ọ, o kò ní sí mọ́ títí lae.
Ẹ máa gbọ́ ti OLUWA Ọlọrun yín, kí ẹ sì máa pa gbogbo òfin rẹ̀, tí mo fun yín lónìí mọ́, kí ẹ sì máa ṣe ohun tí ó tọ́ lójú OLUWA Ọlọrun yín.
ká ọwọ́ ibinu rẹ kúrò lára mi,má sì ṣe jẹ́ kí jìnnìjìnnì rẹ dà bò mí.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Buhari ń bọ̀ l'Eko: Àwọn ọ̀nà láti yàgò fún àyàfi tí ẹ ba gbé ibùsùn dání Ǹjẹ́ irú irun ti ò ń ṣe ń fa orí pípá fún ọ?
"Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Èmi àti Saheed kìí ṣe ọmọdé, a ti jọ ṣe Sinimá papọ̀, èyí túmọ̀ sí pé ìjà ti parí - Fathia Balogun ""Mo fẹ́ pa ara mi torí ojú àbùkù tí wọn ń fi wò mí pé mo fi iṣẹ́ abẹ bímọ"" Fulani kò leè dúró, táa bá lo ohun ta jogún lọ́dọ̀ àwọn bàbá wa - Sunday Igboho Ọjà Àgbáláta ní Badagry rèé, níbití ẹran ejò ti dùn ju ẹran adìẹ lọ Ọlọ́run yóò ṣe ìdájọ́ nkan tó wà láàrin èmi àti Ireti Ajanaku - Tope Alabi O ṣalaye pe, gbogbo ohun to n ṣẹlẹ ni Naijiria ni oun n fi ọkan ba lọ, to si gbe oṣuba kare fawọn alaṣẹ ile igbimọ aṣoju ṣofin l'Abuja, adari ile ati gbogbo ile lapapọ."
Onimọ ẹ̀rọ lo jẹ, ni ileesẹ eto irinna ipinlẹ naa.
Mo ri pe, e tin fojusona lati bere sini n kopa, leyi ti o farahan pe, e ti gbaradi lopolopo fun idije yii.
Ẹ se idanilẹkọ ati itankalẹ iroyin yii, ki awọn ti ko mọ ẹtọ wọn lee mọ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, È gbọ òun ti ojú awọn ara ipinle Ogun rí lọwọ ìṣẹlẹ omiyale Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Nígbà tí àwọn olórí ilẹ̀ Babiloni ranṣẹ sí i láti mọ̀ nípa ohun ìyanu tí ó ṣẹlẹ̀ ní ilẹ̀ náà, Ọlọrun fi sílẹ̀ láti dán an wò, kí Ọlọrun lè mọ gbogbo ohun tí ó wà lọ́kàn rẹ̀.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Àwọn adarí ìjọ olókìkí tó ti f'ara ko imí ẹ̀sùn àgbèrè ní Naijiria 5 Ẹrẹ̀nà 2019 Ẹsun agbere ko jẹ ajoji si awọn ile ijọsin kakakiri agbaye.
‘Ẹ sọkún tẹ̀dùntẹ̀dùn nítorí ọjọ́ burúkú tí ń bọ̀,nítorí ọjọ́ náà súnmọ́lé,ọjọ́ OLUWA ti dé tán,yóo jẹ́ ọjọ́ ìṣúduduati ìparun fún àwọn orílẹ̀-èdè.
O rán oníṣẹ́ rẹ láti fi OLUWA ṣe ẹlẹ́yà,o ní, ‘N óo fi ọpọlọpọ kẹ̀kẹ́ ogun mi ṣẹgun àwọn òkè,títí dé òkè tí ó ga jùlọ ní Lẹbanoni;mo gé àwọn igi Kedari gíga rẹ̀ lulẹ̀,ati àwọn igi sipirẹsi rẹ̀ tí ó dára jùlọ,Mo wọ inú igbó rẹ̀ tí ó jìnnà ju lọ,mo sì wọ inú aṣálẹ̀ rẹ̀ tí ó dí jùlọ.
Oluranlọwọ pataki fun aarẹ Muhammadu Buhari, Garba Shehu lo fi ọrọ yii lede ninu atẹjade ti aarẹ fi sita.
Bakan naa lo fi kun un pe ọrẹ lasan loun ati gbajugbaja oṣere tiata, Ronkẹ Ididowo ti ko si si ohun ifẹ ikọkọ kankan to pa wọn pọ.
Minimum Wage: Ẹgbẹ́ àwọn òṣìṣẹ́ TUC fárígá sí ìjọba Naijiria lórí owó oṣù tuntun
Ní Tofeti ni wọn yóo máa sin òkú sí nígbà tí wọn kò bá rí ààyè sin òkú sí mọ́.
 Àǹtí rẹ ̀ yìí náà mọ orin-ín kọ gan-an ni .
O tún fẹ́ láti máa ṣe ìṣekúṣe tí o ṣe nígbà èwe rẹ, tí àwọn ọkunrin Ijipti ń dì mọ́ ọ lẹ́gbẹ̀ẹ́, tí wọ́n sì ń fi ọwọ́ fún ọ ní ọmú ọmọge.
Títí kan àwọn tí wọ́n máa ń yọ̀ kí wa, lásán ni wọ́n kí wa.
Ṣugbọn wọn kò gbọ́, wọ́n jẹ́ ọlọ́kàn líle bí àwọn baba ńlá wọn, tí wọn kò gba OLUWA Ọlọrun wọn gbọ́.
Bí mo ti ń lọ, mò ń wo àwọn ògiri Jerusalẹmu tí wọ́n ti wó lulẹ̀ ati àwọn ẹnu ọ̀nà tí wọ́n ti jó níná.
O sọ itan igbesi aye rẹ bi baba rẹ sẹ fẹ iyawo mẹtala to si jẹ pe oun nikan ni ọmọ lọwọ wọn.
OLUWA tún fi ara hàn án lẹẹkeji, bí ó ti fara hàn án ní Gibeoni, 
Ajafẹtọ ọmọde naa wa rọ ijọba lati ri i wi pe wọn la awọn obi loyẹ nigba ijiya to wa ninu ifiyajẹ ọmọ wọn, ati wi pe ki wọn pese nọmba ti kọ gunju ti awọn ọmọ naa le pe, ti wọn ba n la ifiyajẹni kọja.
Ẹ padà sílé èyin ọmọ wa tó n ṣiṣẹ́ darandaran - NEF ti Fulani Buhari ti buwọ́lu ẹ̀kúnwó sísan owó oṣù tuntun fáwọn òṣìṣẹ́ àpapọ̀ Ẹgbẹ́ àwọn òṣìṣẹ́ TUC fárígá sí ìjọba Naijiria lórí owó oṣù tuntun Super Eagles gba iṣẹ́ lọ́wọ́ Seedorf olùkọ́ni Indomitable Lions Cameroun Ṣaaju asiko yii ni ajọ PFN ti kede pe awọn ko ni fọwọ bo iwa ibajẹ kankan lainii fi ṣe ẹni ti ade naa ba ṣi mọ lori.
O gba imọran yi ti wọn si ko owo jọ fun awọn ẹlẹyinju aanu meji to n pese ounjẹ, Milton Halal Foodbank ati Parkdale Food Centre.
Lóòótọ́ ó di ọmọ ìlú mìíràn ṣùgbọ́n láàárin ọdún mẹ́ta ni gbogbo ọmọ rẹ̀ kú tán, atẹ́gùn ìlú náà kò bá a lára mu.
Àwọn ará Filistia bá kógun wá sí Juda, wọ́n sì kọlu ìlú Lehi.
Àwọn eniyan náà dúró lókèèrè, bí Mose tí ń súnmọ́ òkùnkùn biribiri tí ó ṣú bo ibi tí Ọlọrun wà.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ọdun marun un ni McCain fi jẹ ẹlẹwọn ogun Vietnam, ti o si jẹ orisirisi iya ni ọwọ awọn ti o mu u pamọ.
Bó tilẹ̀ jẹ́ pe ó dàbí ẹni pé òun já kulẹ̀ nínu ìdìbò naa, a gbé igbá orókẹ̀ nínú ìpè fún ìjọba tó tọ́.
Asòfin PDP Ondo fìdírẹmi torí ó jẹ́ ọmọ orílẹ̀èdè méjì Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Iya Adura Esther Ajayi sọ àṣírí owó rẹ̀ tó fi ń ṣàánú Ipade yii waye ni Aso Rock, ile aarẹ niluu Abuja.
Ẹgbẹ oselu PDP ti ni ibi ipade awọn igbimọ amusẹya ẹgbẹ oṣelu PDP ti yoo waye lọla ni awọn yoo ti se agbeyẹwo bi eto idibo ṣe lọ ni ipinlẹ Kogi ati Bayelsa.
A ti wi pe gbogbo awọn ti wọn j n ṣiṣẹ ni awọn n wa bayii lati ri wi pe ọwọ tẹ wọn ni kiakia.
Opolopo lo ti kedun iku re ninu ero ibanisoro ayelujara lorisiirisii ti won si ti n ki ebi, ara ati ore re ku ara feraku lai yo awon ololufe re sile lagbaye.
Yoruba film: Ipò wo ni Seun Egbegbe, Olóòtú eré wà báyìí lẹ́wọ̀n?
ijoba ibile Tsafe (Local Government ), nibi ti awon afehonu han ti ba orisirisi
Ijọba ibilẹ Fagge ni Ọjọgbọn Maikaba ti ṣẹ.
Itan sọ pe, ọkan lara awọn ọmọbinrin Oduduwa lo tẹdo si ibẹ lẹyin ti o ko awọn eeyan rẹ lẹyin kuro ni ile ifẹ Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: 'Ìwádìí ńlọ lórí àwọn alákatakítí agbébọ̀n tuntun tó wọ Nàìjíríà’ Ǹjẹ́ o mọ àwọn ǹkan èlò ilé tó léwu fún ẹ̀mí?
Yatọ si ọrọ ọjọgbọn Soyinka, pupọ awọn to jẹ olori ẹgbẹ, yala ti Yoruba ati awọn agbẹjọro to fi mọ awọn amofin, lo ti da si ọrọ yii.
Eyi kii ṣe igba akọkọ ti ajọ Amnesty International ati ileeṣẹ ologun Naijiri ayoo ma gbena woju ara wọn.
Ẹnu ya àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀, ẹ̀rù sì ba àwọn eniyan tí wọ́n tẹ̀lé e.
Oluwo ti ìlú Iwó kìí ṣe ẹgbẹ́ Àtaọjà Osogbo - Alaafin ìlú Ọ̀yọ́ Ẹ̀ gbọ́ ọ̀rọ̀ lẹ́nu Adelé Ọba Alade Idanre ló rí ohun tó ṣẹlẹ̀ láàárín òun àti Ọba Aroloye Ẹ̀yin ọlọ́pàá, ẹnikẹ́ni tó bá fi ọwọ́ kàn yín, ẹ dojú ìjà kọ ọ́ padà- Ọ̀gá Àgbá Ọlọ́pàá Owatapa ti Itapa Ijesha, Wolii Olapade Agoro jáde láyé LASEMA ni ibanujẹ ọkan lo jẹ fun awọn wi pe ẹmi meji lọ si iṣẹlẹ naa, ti awọn si ti ko oku wọn lọ si ile igbokusi ni ilu Eko.
Bakan naa lo fi kun un pe igbesẹ ti bẹrẹ lori wiwadii bi iṣẹlẹ naa ṣe ṣẹ ati ohun gan to sokunfa rẹ.
Oríṣun àwòrán, Genesis global Awọn ọkunrin ọlọla Eyi ni ẹgbẹ awọn ọkunrin to n jọsin ninu ijọ CCC Genesis Global.
Akin àti Ilésanmí sun ọ̀dọ Fìlísíà mọ́jú.
(1/4) NAF AIRCRAFT DECIMATES TERRORISTS’ CAMP WHILE PROVIDING CLOSE AIR SUPPORT TO TROOPS IN BORNO The Air Task Force (ATF) of Operation LAFIYA DOLE has decimated a Boko Haram Terrorist (BHT) camp and neutralized some of their fighters at Arboko settlement  in Borno State.
Ọjọ́ tí inú mi bàjẹ́ jùlọ gẹ́gẹ́ bíi ààrẹ ilé aṣòfin àgbà-Saraki Ọba Adesoji Aderemi, Ọọ̀ni Ifẹ̀ tó gba ipò ọba mọ́ tòṣèlú Dangote, Fayemi pari ìjà láàrin Ganduje àti Emir Sanusi Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, BBC Africa Eye: Akọroyin fẹ ìdí àwọn oníṣẹ́ ibi ọmọ ogun síta Gomina ipinlẹ Oṣun ṣalaye pe ijọba oun yoo tẹsiwaju lati maa fun awọn oṣiṣẹ ọba lanfaani lati maa lọ fun idanilẹkọọ loorekoore bi agbara rẹ ba ti mọ.
Ajo naa tun jẹ ko di mimọ pe Agbanah Toba ni tire ti jẹwọ
Kore, ọmọ Imina, ọmọ Lefi kan tí ń ṣọ́ ẹnu ọ̀nà ìlà oòrùn tẹmpili ni ó ń ṣe alákòóso ọrẹ àtinúwá tí wọ́n mú wá fún Ọlọrun.
O ni ko si ẹni to n tele awọn ilana lati dena aarun coronavirus bi wọn ti n ṣe ifẹhonuhan #EndSARS.
idibo re saaju idibo gbogbogbo-o odun 2019, “Gege bi asofin se so, ipolongo naa
"O ni "" A ko sọ pe a ko ni paṣẹ konileogbele o, ṣugbọn a n gbadura ki ọrọ naa ma de ipele yẹn ni."
"Akọsilẹ fihan pe ogunlọgọ awọn eeyan yii lo mu kẹmika ""sniper"" rọrun nigba t'awọn miiran pokun so."
Ẹwẹ, gbajugbaja agbabọọlu AC Milan tẹlẹ, Paolo Maldini ati ọmọ rẹ Daniel naa ti ko coronavirus.
NCDC lo kede bẹẹ loju opo Twitter rẹ ni Ọjọ Aiku.
Oríṣun àwòrán, AFP Ṣugbọn ajọ naa pada sọ pe ko si eto igbani sisẹ kankan.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ìdíje ata tútù: Jẹ ata 50, ko gba góólù gírámù mẹ́ta Alaboyun, abiyamọ to n fọmọ lọyan lọwọ, tabi to ṣẹṣẹ ṣẹyun gbọdọ sinmi daadaa ko to le fẹjẹ silẹ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ighalo Transfer Fee: Ilé aṣòfin Osun ní òun kẹ́ẹ́fín pé àpò àdáni ní owó náà wà 30 Owewe 2020 Oríṣun àwòrán, Getty Images Ile Igbimo Asofin ipinlẹ Osun ti bẹrẹ iwadii lori ẹgbẹrun mẹwaa pọnun, to kan ẹgbẹ agbabọọlu Osun United, lara owo adehun to gbe Odion Ighalo lọ si Manchester United.
"Nigba to n kede ami ẹyẹ naa, o ni ""mo ki gbogbo wa ku oriire o, ami ẹyẹ yii wa fun gbogbo awọn ẹbi mi loju opo Instagram yii nitori mi o jẹ ohun kankan laisi Ọlọrun ati ẹyin ololufẹ mi."
 Ọpọ awọn oniṣẹ ọwọ, awọn oniṣowo ati awọn ara ilu ni arugbo ati ọdọ ni wọn janfani ninu eto ironilagbara ọlọpọ miliọọnu naira yii.
 Opolopo ebi Castro lo ti tuko Cuba bere pelu egbon Raul, iyen Fidel lo baa won miran fun bii ogota odun lapapo.
Ẹgbẹrun meji ati mẹrinlelaadọsan (2174), ti ri iwosan, okoolerugba le ẹyọkan (221) si ti ku.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Niyi Akinmolayan tó ṣe fíìmu àwòrán-dèèyàn Cartoon nípa COVID-19 tó la ayé já ní N Kọmiṣọna ọlọpaa naa tun paṣẹ ki wọn ko awọn mọlẹbi wọn ati gbogbo awọn eeyan ti wọn ti ba pade lẹnu ọjọ mẹta yii dani pẹlu.
Owó ìtanràn N40,000 ni mo san nítorí pé mí ò wọ ìbòmú- Vincent Oloyun ko gbọdọ ba ọkunrin ti kii se ọkọ rẹ lopọ rara.
pupo lowo igbimo ajo FIFA ti o wa fun iwode ohun fun atileyin won.
O ni ati oun ati Joshua lawọn jọ lagbara ṣugbọn o ni ọgbọn ju ọgbọn lọ.
Àwọn òbí yóo ra àwọn ọmọ wọn pada nígbà tí wọ́n bá pé ọmọ oṣù kan.
“Ní ìwòyí ọ̀la, n óo rán ọkunrin kan sí ọ láti inú ẹ̀yà Bẹnjamini.
Awọn ẹni tuntun naa wá lati ìpínlẹ̀ mọkandinlogun, ati olu ilu Naijiria, Abuja.
Ṣebí ìwọ ni o dà mí bí omi wàrà,tí o sì ṣù mí pọ̀ bíi wàrà sísè?
Ìgbésẹ̀ yìí kò ṣeyin bí àwọn ọmọ Nàìjíríà ṣe bẹnu ẹ̀tẹ́ lu ìpínnú àwọn kọngila láti dí àpá ibikan pa fún iṣẹ́ àkanse lóju pópó náà bẹ̀rẹ̀ láti ọjọ kẹta, oṣù kẹjọ ọdun.
Ẹni to bori: Guinea Mali vs Senegal.
Ẹgbẹ naa wa kilọ pe o ṣeeṣe ki iyan mu laipẹ yii nitori bi awọn agbẹ ko ṣe ri aye lọ kere oko nitori eto abo to mẹhẹ lagbegbe ọhun.
Ipa pataki to ko ninu ilana alafia ilẹ Palestine ati Isreal fẹsẹ ibaṣepọ rẹ mulẹ pẹlu awn aarẹ to jẹ lorilẹede America ti wọn si n fun un ọpọlọpọ biliọnu dollar owo iranwọ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Osun 2018: Àwọn olùdíje ADC, ADP, APC, SDP bá aráàlú sọ̀rọ̀ lórí èròǹgbà wọn Eto ipade itagbangba naa waye ni gbongan Olagunsoye Oyinlọla ni fasiti ipinlẹ Ọṣun lọjọ Ẹti, ọjọ kẹrinla, oṣu kẹsan an.
fun idi eyi, o je ohun buru pupo ki enikan o maa gbe iroyin eleje, ti ko si
Ẹwẹ, Naira Marly gan gan fun ra rẹ ti sọ pe aburo oun ni Babatunde Fashola to wa lori iwe akọsilẹ arinrin-ajo ninu baalu Executive Jet.
Ọpọlọpọ owo bii owo to wa fun itọju Covid 19 ni Amẹrika ati awọn owo to le ni biliọnu dọla mẹrinlelogun ni wọn ti fi gbajuẹ gba.
Huṣai dáhùn pé, “Ìmọ̀ràn tí Ahitofeli fún Kabiyesi ní àkókò yìí, kò dára.
Ilé ẹjọ́ pàṣẹ kí Sẹ́nétọ̀ Elisha Abbo san N50m fún obìnrin tó fìyà jẹ Mi o fi ìgbà kankan sọ pé Buhari ni yóò jẹ ààrẹ kẹ́yìn ní Nàìjíríà- Akintoye Ikọlu yii n waye lẹyin ọjọ meji ti wọn kọlu kẹyin, lasiko abẹwo rẹ si agbegbe kan lẹba adagun omi Lake Chad.
Ẹ ṣọ́ra, kí èròkerò má baà gba ọkàn yín, kí ẹ wí pé, ọdún keje tíí ṣe ọdún ìdásílẹ̀ ti súnmọ́ tòsí, kí ojú yín sì le sí arakunrin yín tí ó jẹ́ talaka, kí ẹ má sì fún un ní ohunkohun.
0 12428 Orilẹede Equatorial Guinea 85 6.
"Ṣáájú ìdìbò Sátidé nípínlẹ̀ Ọyọ, ọwọ́ ọlọ́pàá tẹ àwọn afurasí pẹ̀lú ìbọn ""Àwa Mọ́gàjí ilẹ̀ Ibadan kò dásí ọ̀rọ̀ òṣèlú"" Màá ṣiṣẹ́ kára."
Ẹ kọ ipakọ si ẹnikẹni ti yoo fa ọwọ agogo ilẹ Ijẹbu si ẹyin.
Ni ó bá ń waasu ní gbogbo àwọn ilé ìpàdé ní Judia.
premier league: Liverpool to ọrẹ́ sí ẹ̀yìn Manchester United pẹ̀lú àmì ayò méjì sí òdo
Ẹ kò gbọdọ̀ jẹ ninu ẹran yìí ní tútù, tabi bíbọ̀; sísun ni kí ẹ sun ún; ati orí rẹ̀ ati ẹsẹ̀ rẹ̀, ati àwọn nǹkan inú rẹ̀.
Railway Corporation ,NRC) lorile ede yii, lati lee mu ipinnu ile –ise
Ó tú gbogbo ẹṣin tí àwọn ọba Juda ti yà sọ́tọ̀ fún ìsìn oòrùn, ní ẹnu ọ̀nà ilé OLUWA, lẹ́bàá yàrá Natani Meleki, ìwẹ̀fà tí ó wà ní agbègbè ilé OLUWA; ó sì dáná sun àwọn kẹ̀kẹ́ ogun tí wọ́n yà sọ́tọ̀ fún ìsìn oòrùn.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Nàíjíríà ti pín yẹlẹyẹlẹ láyé Buhari, ìjákulẹ̀ dé!
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ondo Killing: Dejí sun ọmọ méje àtagbalagba meji mọ́lé nítorí pé ó ń bínú Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Ondo Killing: Dejí sun ọmọ méje àtagbalagba meji mọ́lé nítorí pé ó ń bínú 31 Èbibi 2019 Ọrọ ìfẹ́ bí àdánwò ni ohun to ṣẹlẹ pẹlu Titi àti Deji ni Okiti pupa.
Ninu lẹta kan ti Tinubu kọ si gomina ipinlẹ Borno, Zulum, lati ba kẹdun iṣẹlẹ naa to waye ni Zabarmani, lo ti sọ eyi.
tun fenuko le lori ni atunse si awon gbogbo awon ile-eko  gbogbonse ati ile -eko  ti awon oluko(colleges of education) to wa
A óo wí nípa Sioni pé,“Ibẹ̀ ni a ti bí eléyìí ati onítọ̀hún,”nítorí pé Ọ̀gá Ògo yóo fi ìdí rẹ̀ múlẹ̀.
N óo yára láti pa òfin rẹ mọ́,nígbà tí o bá mú òye mi jinlẹ̀ sí i.
"Ẹ wá dánrawò níbí pẹ̀lú Àpólà Ọ̀rọ̀ Orúkọ, ""Noun Phrase"" Ẹ̀yin tí ẹ kò gbọ́ Yorùbá, ẹ ṣúnmọ́ bí láti kọ́ lítíréṣọ̀ èdè Yorùbá lórí BBC Ẹ ṣúnmọ́ bí láti kọ́ ẹ̀kọ́ nípa ìsọ̀rí ọ̀rọ̀ nínú gbólóhùn Yorùbá Eto Akomolede ati Asa yii n waye lati ọwọ BBC Yoruba pẹlu ajọṣepọ ẹgbẹ Onimọ Yoruba YSAN ati apapọ ẹgbẹ Akomolede Naijiria."
Pasitọ Osagie Eze-Iyamu ni APC fun lanfaani lati dije fun ipo gomina, labẹ asia ẹgbẹ oṣelu naa dipo Obaseki.
tun gboriyin fun orile-ede Naijiria lataari lilo awon obinrin ati odo ninu
Ẹni to jẹ Baba Ọṣun tẹlẹ, Alagba Ọlayiwla Adigun ṣalaye pe kabiyesi Ataọja ti ilu Oṣogbo ti ta oriṣa ọṣun fun awọn are kan ati pe igba ti wọn fẹ gbee jade kuro lorilẹede Naijiria ni Ọṣun wa wuwo ti ko ṣe e gbe mọ ti o fi wa yọ si ọkan lara wọn pe ki wọn da oun pada sọdọ awọn to ni oun bi wọn ko ba fẹ ri pipọn oju oun.
-Olugbo Obateru Akinruntan Ìgbín, iṣu, epo, àádùn, obì, iyọ àti oyin wa lára ohun ti a fi sọ ọmọ tuntun Ọọni Ifẹ lórúkọ!
Nigba to n salaye lori ohun to faa, ti oun fi tẹ iwe kan sita, Jonathan ni ọpọ eeyan ni ko mọ ohun to n sẹlẹ́= nijọba, paapa awọn ọmọ, ti oun si fẹ ki ọpọ wọn mọ nipa isejọba ti oun se kọja, O fi kun pe awọn ọdọ nilo iwe itan lati ka, ki wọn lee mọ awọn aseyọri ti oun se lori oye, ti wọn yoo si maa fi tọ awọn adari sọna lọjọ iwaju, paapa bo se kan eto idibo ọdun 2015.
Agbẹnússọ ọlọ́pàá ní ìpínlẹ̀ náà, Bala Elkana, tó fi ìdí ọ̀rs náà múlẹ̀ , sọ pé lóríi ẹ̀sùn ìtàpá sí òfin kí onílé gbé ilé àti lílo ẹfgbò igi olóró ni wọ́n fi mú àwọn afurasí náà.
Ọlọ́pàá rí òkú ọ̀gá àgbà iléèṣẹ́ ńlá kan tí wọn ń wá, lójú omi l‘Eko A gbé òfin 1960 jáde, màálù tó bá jẹ oko àgbẹ̀, tí olówo rẹ̀ kò sanwó, títà ni - Buhari Ìjọba fẹ́ kọ́lé 300,000, pẹ̀lú ìrànwọ́ fún àgbẹ̀ 4m láti mú àdínkù bá ìṣẹ́ - Osinbajo Wò ó bí Alaafin àti aya àkọ́fẹ́ rẹ̀, Olorì Abibat ṣe pàdé ní èwe Coronavirus ti fa ọ̀wọ́ngógó oúnjẹ ní ìpínlẹ̀ Eko, Kano, Rivers àti Abuja- NBS Àwọn èrò yarí lórí sísan owó àyẹwò covid-19 bí bàálù ilẹ̀ òkèèrè ti ba s'Abuja lẹyìn oṣù márùn ún Nítorí ìdí èyí, Terrywaya ní bi ọmọ òun bá gbégbá orókè nínú idíjẹ to n lọ lọ́wọ́ yìí, òun yóò ri dájú pé ìdajì nínú rẹ̀ lọ sí ọ̀dọ̀ Erica, nígbà ti èyí tó kù yóò padà lọ sí ilé àwọn aláìní.
Lootọ, ẹka alaṣe lo bẹrẹ irinajo aba yii ṣugbọn lọdọ awọn aṣofin ni o yi wa bayi lẹyin ti wọn ti ka a fun igba ekeji ti wọn si ti gbe e fun awọn igbimọ lati tubọ ṣe ayẹwo finifini aba naa.
Nígbà tí ó bú báyìí tán, ààrá meje sán.
Sẹnetọ Osinọwọ to ni akoko to fun olukuluku o maa gbaradi fun ọjọ afiyesi ni: 'ọpọ la bi ti ko duro ṣe ọdun kan lori oke erupẹ, Melo la fẹ ka ninu oore Ọlọrun, ọpọ ni ko ri ọdun kẹwaa loke erupẹ.
Awọn ologun tun ka awọn ohun ija oloro lorisirisi mọ awọn darandaran Fulani ọhun lọwọ.
Ọ̀kan ninu àwọn àlejò náà wí pé, “Dájúdájú, n óo pada tọ̀ ọ́ wá ní ìwòyí ọdún tí ń bọ̀, Sara, aya rẹ yóo bí ọmọkunrin kan.
*Minisita iṣuna ati ato ọrọ aje, Zainab Ahmed ṣalaye loṣu to koja pe igbimọ ti aarẹ gbe kalẹ ti pari iṣẹ rẹ o si ti buwọlu ki wọn ṣi awọn ẹnubode naa pada.
Gíga àwọn ọpọ́n náà jẹ́ igbọnwọ marun-un marun-un.
Ninu ọrọ rẹ, Sẹnatọ Bala Na'allah ni 'o yẹ ka mọ boya ohun ti wọn ṣe yii ba ofin mu.
A máa pa gbogbo egungun rẹ̀ mọ́;kì í jẹ́ kí ọ̀kankan fọ́ ninu wọn.
Báwo ni ilẹ̀ náà yóo ti dára tó, yóo sì ti lẹ́wà tó?
N óo sì bá ọ dá majẹmu tí kò ní yẹ̀ títí lae.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù 'Àwọ̀ ara Nisha wà ní ipò tó ba ni lẹ́rù gan' Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ 'Àwọ̀ ara Nisha wà ní ipò tó ba ni lẹ́rù gan' 4 Sẹ́rẹ́ 2020 Nisha Lobo jẹ ọmọ ti a bi pẹlu ipenija awọ ara kan to le ba ni lẹru gidi gan.
Ṣugbọn àwọn kan ninu wọn ń sọ pé, “Agbára Beelisebulu, olórí àwọn ẹ̀mí èṣù, ni ó fi ń lé àwọn ẹ̀mí èṣù jáde.
Nitori naa, Victor ni abọ iwadii igbimọ ni yoo ṣi aṣọ loju ohun gbogbo to ṣẹlẹ.
38 Ojúṣe àwọn alàgbà, àwọn àlùfáà, àwọn olùkọ́, àwọn deakoni, àti àwọn ọmọ ìjọ ti Krístì—àpóstélì jẹ́ alàgbà, àti pé ó jẹ́ ìpè rẹ̀ lati ṣe ìrìbọmi;
Okeho Robbery: Ó tó 60 mílíọ̀nù tí àwọn olè jí ṣùgbọ́n a kò rí kọ́bọ̀ gbà padà- Òṣìṣẹ́ banki
Wón se eyi lati fi ẹhonu han tako iwa ipa si awọn obinrin lẹyin ti awọn ọlọpaa ri oku arabinrin kan, Shannon Wasserfall lẹyin oṣu mẹfa ti wọn ti n wa a.
lati Omdurman, lo si ekun Nile
Iru awọn orukọ bayi si jẹ iranti fawọn eeyan pe wọn ni nkan ṣe pẹlu Germany.
OLUWA tún wí fún Mose pé, 
Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Oyinkan Abayomi: Ajàfẹ́tọ̀ọ́ ẹni tó dá ẹgbẹ́ òṣèlú obìnrin àkọ́kọ́ sílẹ̀, tó tún jà fún ètò ẹ̀kọ́, ìṣèlú àti òmìnira obìnrin5 Bélú 2020 Professor Wole Soyinka láti kékeré13 Agẹmo 2020 Professor Peller: Ọlọ́wọ́ idán àkọ́kọ́ nílẹ̀ Áfíríkà tó ń pidán fáwọn aṣaájú orílẹ̀èdè19 Bélú 2020 Alajo Somolu: Ọdún mẹ́ta ló fi gba àjọ láì kọ ọ́ sílẹ̀, kò sì si owó àjọ san16 Ògún 2020 Ayinla Ọmọwura kò kàwé, àmọ́ ó kópa sí àgbéga orin àti èdè Yorùbá19 Òkùdu 2019 Seriki Williams Abass: Ọba Badagry tó jẹ́ ẹrú, tó tún padà di olówò ẹrú20 Ògún 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Ẹ̀wẹ̀, akọwé ìjọba ìpínlẹ̀ Kano tó kọ ìwé ẹsun náà Usman Alhaji sàlàye pe èsì Sanusi yoo fún ìjọba láàfàní láti gbé ìgbésẹ̀ to tọ àti èyí to yẹ Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
 ilé-iṣẹ ́ wọn wà ní adẹ ́ ọ ̀ yọ ́ .
Izeowayi gb'ẹ̀bùn ẹ̀kọ́ ọ̀fẹ́ lórí ìdíje àròkọ BBC Pidgin:
Hesekaya jọba ní Juda nígbà tí ó di ẹni ọdún mẹẹdọgbọn; ó sì wà lórí oyè fún ọdún mọkandinlọgbọn.
Ó sì tún jẹ́ pé àwọn baba- ńlá wa ní ìmọ̀ ẹ̀sìn Krístì kí wọ́n tó wá tẹ̀dó sí Ilẹ̀- Ifẹ̀.
Ọba bá bí i pé, “Ṣé Joabu ni ó rán ọ ní gbogbo iṣẹ́ tí o wá jẹ́ yìí, àbí òun kọ?
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Aarẹ Buhari ni ifọwọsowọpọ lo le mu alaafia j'ọba 6 Ẹrẹ̀nà 2018 Oríṣun àwòrán, @MBuhari Àkọlé àwòrán, Aare Buhari pe fun ibagbepo lalafia ni Taraba Aarẹ orilẹẹde Naijiria Muhammadu Buhari ti kesi awọn ọmọ orilẹẹde yi lati fọwọsowọpọ pẹlu awọn eleto aabo ki wọn baa le dẹkun ọwọja iwa ọdaran to gbalẹ kan.
Má máa lọ sílé aládùúgbò rẹ lemọ́lemọ́,kí ọ̀rọ̀ rẹ má baà sú u, kí ó sì kórìíra rẹ.
Àwọn alufaa ati àwọn ọmọ Lefi gba fadaka, wúrà ati àwọn ohun èlò náà, wọ́n kó wọn wá sinu ilé Ọlọrun wa ní Jerusalẹmu.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Obin n sukun, ijọba ko mọ ibi tawọn akẹkọbirin Dapchi wa 23 Èrèlè 2018 Oríṣun àwòrán, Getty Images Ikọlu to ba ile-iwe girama to wa ni abule Dapchi nipinlẹ Yobe ti fẹ fi ara jọ bi awọn ikọ Boko Haram ti kọlu ileewe girama Chibok ti wọn si ji awọn akẹkọbirin ọdurun din ni mẹrinlelogun lọ ni ọdun 2014.
"Orukọ ti kabiyesi fun arẹmọ ni 'Aderiye""."
Atupalẹ yii yoo jẹ otitọ, ti ko si ni fi si apa kan ju ti omiran lọ pẹlu akiyesi si awọn ohun ti ẹgbẹ oṣelu yii yoo ṣe fun awọn ara ilu.
Bí a bá rí eniyan mẹ́wàá ńkọ́?
 Bi ẹ se n gbiyanju lati sa kuro lorile ede yii, ni awon
Oríṣun àwòrán, Others Atẹjade ti oluranlọwọ pataki feto iroyin fun aarẹ Buhari, Mallam Garba Shehu fi lede lo ti salaye idi ti Aarẹ Buhari fi gbe igbesẹ naa.
Nigeria: Afunrasí ẹ̀sùn jìbìtì ló ni iléeṣẹ́ tó ń ṣe ìwé àṣẹ wọléwọ̀de ní Nàìjíríà
Gẹgẹ bi ohun ti o sọ, o ni Olorun sọfun oun pe saa kan ṣoṣo ni Buhari yoo ṣe ati wi pe ti o ba ṣesi polongo idibo yoo ku ni.
’ ” Wọ́n gbọ́ràn sí OLUWA lẹ́nu, wọ́n pada, wọn kò sì lọ bá Jeroboamu jagun mọ́.
Ifẹsẹwọnsẹ naa waye ni papa isere ni ilu Uyo, ni ipinlẹ Akwa Ibom.
Nígbà gbogbo ni Asa ọba Juda, ati Baaṣa, ọba Israẹli ń gbógun ti ara wọn, ní gbogbo ìgbà tí wọ́n wà lórí oyè.
Wọn fi ẹsun kan awọn alaṣẹ pe wọn kofun awọn ni oogun tabi itọju, ati pe ounjẹ paapa ko si ka'nu.
Ó ní, “Ẹ sọ fún àwọn ará Jerusalẹmu pé,‘Wò ó, olùgbàlà yín ti dé,èrè rẹ wà pẹlu rẹ̀,ẹ̀san rẹ sì wà níwájú rẹ̀.
O ni oun ko ni ki oṣiṣẹ kankan ko biliọnu mẹwaa naira wa.
“Ó mú kí àwọn arakunrin mi jìnnà sí mi,àwọn ojúlùmọ̀ mi sì di àjèjì sí mi.
”OLUWA ní:“N óo mú ibi kúrò lórí yín,kí ojú má baà tì yín.
yii ni iwa ibajẹ , mo ti salaye eleyii lẹkununrẹrẹ , ti mo si mo pe ẹyin naa mo
Bawo ni EFCC ṣe mọ pe ayederu babalawo ni?
Yóo wulẹ̀ pa yín run patapata ni;kò sì sí ẹni tí OLUWA yóo gbẹ̀san lára rẹ̀ lẹ́ẹ̀kantí yóo lè ṣẹ̀ ẹ́ lẹẹkeji.
Awọn iṣẹ gbogbo ti o si ti ṣe ni wọn maa n gbayi lorilẹ-ede yii ati loke okun.
"Góòlù pọ̀ ní ìlú Madaka ṣùgbọ́n wọn kò ní ọ̀nà fún ọgọ́rùn ún ọdún ""$2,600 àǹtí mi ni mo jí láti lọ sókè òkun àmọ́ àbámọ̀ ló gbẹ̀yìn ọ̀rọ̀ mi"" Òbítíbitì ẹ̀gbin ti sọ ìlú Ibadan di ààtàn - Aráàlú figbe bọnu A ti gba aṣẹ ilé ẹjọ míì to tako àṣẹ́ ilé ẹjọ to wọ́gile olùdije APC ni Bayelsa Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, World Diabetes Day: Ọdún kọkandinlogun ti mo ti wà lẹ́nu itọ ṣúgà nìyí Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!"
Ọlọ́pàá Eko ní kí olùkọ́ UNILAG Boniface wá sọ tẹnu rẹ̀ lórí ẹ̀sùn ìfipábánilòpọ̀ Kíni ìdí ti àwọn ọmọ ogun fi n ṣọ́ àwọn Imaam ni Mecca?
Oríṣun àwòrán, Getty Images Nibayii, aarẹ Mokgweetsi Masisi ti gbe ofin to de pipa erin lọna ti ko tọ kuro eyi si wa da oniruuru awuyewuye silẹ.
Kò dín ní ogún àwọn obìnrin àti ọmọdé lára mẹ́rìnléláàdọ́fà tí àwọn ọlọ́pàá kó sí àhámọ́ láti ọjọ́ ajé.
Ṣugbọn o ni ṣe ko wa ti ya ju lati yaa fopin si ayẹsi, ayẹyẹ ati ajọyọ ta n ṣe lori ẹmi awọn to fi ọkọ baalu rẹ gbe wale laaye.
Baba Obasanjo ninu atẹjade to fi lede sọ wi pe, nitori arun Coronavirus ni oun ṣe gbe igbesẹ naa.
Simoni Peteru bi í pé, “Oluwa, níbo ni ò ń lọ?
" Oríṣun àwòrán, Nigeria Presidency Àkọlé àwòrán, Osinbajo ń lọgunìkówójẹ lábẹ́ ìṣèjọba Jonathan ẹgbẹ́ òṣèlú PDP pẹ̀lú ń pariwo pé ọ̀rọ̀ òṣèlú lásán ni wọ́n ń fi ṣe Bákannáà ló ní ààrẹ Mùhámádù Bùhárí kò lè fọwọ́ sọ̀yà pé òun kógoja pẹ̀lu bi o ṣe jẹ pé àwọn to ba ni ẹ̀sùn ìkówòjẹ lọ́rùn wọn kìí jẹ́jọ́ mọ́ ní kété tí wọ́n bá ti darapọ̀ mọ́ ẹgbẹ́ òṣèlú APC.
lọdun 2018, sibẹ ki awon eniyan tun nigbagbọ ninu orile ede yii.
14 ní orí ìwé àkọsílẹ̀ àjogúnbá ti di wíwó.
Ọwọ́ tẹ ayédèrú agbẹjọ́rò ní Eko Àlàyé rèé lórí ìdí tí Sẹnẹtọ Ishaku Abbo fi kọ̀wé fi PDP sílẹ̀ Ọlọ́pàá tó dúró yìí gbá mi létí lẹ́ẹ̀mẹrin-Ajẹ́rìí ìwà ipá níwájú ìgbìmọ̀ SARS Ọwọ awọn ologun tẹ afunrasi to pa ṣọja Ọwọ́ tẹ àwọn pásítọ̀ oniíṣẹ́ ìyanu èké méji nílùú Eko Ọwọ́ tẹ awakọ̀ tó ń ra ọjà olè Ninu ọrọ rẹ, adajọ Abang ni Adedipe mọmọ lati ma ṣe yọju sile ẹjọ lọjọ iṣẹgunni.
Kete ti goolu naa wọle ni gbogbo agbo daru ti awọn alatilẹyin City si bẹrẹ si ni jojo ayọ.
Koda, ọpọ ọmọ Naijiria lo sọ nigba naa pe, ile aṣofin n fi oro ya oro lara Lamorde ni, fun bo ṣe n wadii awọn aṣofin kan.
Abi ki ni ka ti sọ ti aarẹ Muhammadu Buhari bayii to ni oun n ṣọfọ alase oun.
Èrò ọmọ Nàíjíríà yapa lóríi mímú Mélayé Khafi wọ gàu lẹ́nu iṣẹ́ lórí ẹ̀sùn ìbálòpọ̀ ní BB Naija Ọlọ́pàá ti mú ẹni márùn ún lórí ìjà láàrin Hausa àti Yorùbá l'Eko Ọ̀pọ̀ èèyàn bẹnu ẹ̀tẹ́ lu Mercy Aigbe lórí bó ṣe ki Adeniyi Johnson O tẹ siwaju wi pe, iwa ibaraẹni lopọ lori afẹfẹ je ohun ti emi ko faramọ rara, o si tun jẹ nkan ti o leè ni ipa buburu lara awon ojẹ wẹwẹ to n bọ leyin."
Awon ile ise nlanla di titipa lataari ile riri oni odiwon ida meje ati abo to tun sele lojo Aje ni eyi to ba awon ile nlanla je ti awon miran si wo lule.
Ṣugbọn ńṣe ni wọ́n túbọ̀ ń kígbe pé, “Oluwa ṣàánú wa, ọmọ Dafidi.
Saraki vs Abdulrazaq: Àwọn arúgbó ní kí ìjọba máà ṣe wó ilé arúgbó m'áwọn lórí
Obasanjo: Eré ìtàn nípa ìbí, àti jéèyàn pẹ̀lú ìpèníjà Olusegun Aremu Obasanjo Atiwipe awọn ti ṣetan lati ri daju pe awọn ṣe oun gbogbo ti awọn nilo lati ri wi pe eto aabo to gbooro wa ni ipinlẹ naa.
Ohun to si fa gẹgẹ bi awọn kan ti ṣe sọ ni pe kii saba sọ odod ọrọ fara ilu.
Wayi o, Nadal yoo lo koju akegbe re ti won
Àwọn kan n ṣe onídùró gẹ́gẹ́ bi okòówò - BBC News Yorùbá BBC News, YorùbáFò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Surety - Àwọn kan n ṣe onídùró gẹ́gẹ́ bi okòówò 15 Bélú 2018 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 24 Ìgbé 2020 Oríṣun àwòrán, Getty Images Kini o gbọdọ mọ ki o to ṣe oniduro ẹnikẹni?
Yemi Alade: Bí a bá ní ìdí nlá bàa ní, kó sí ẹni tí kò rẹ́wà
Kò ní sí ẹni tí yóo lè borí rẹ ní gbogbo ọjọ́ ayé rẹ.
Ọjọbọ ni Onidajọ Oweibo gbe idajọ naa kalẹ lẹyin ti ajọ to n gbogun ti iwa ibajẹ ni Naijiria, EFCC kọ iwe ẹbẹ kan pe ki ile ẹjọ o ṣe bẹ ki igbẹjọ ẹsun iwa ibajẹ ti wọn fi kan Madueke o to maa tẹsiwaju.
o ni lakọkọ, wọn fẹsun kan oun pe oun lo ṣagbatẹru ifẹhonuhan ọhun, nigba to ya wọn tun ni oun lo ran awọn lati yinbọn lu awọn oluwọde ni ibode Lekki lọjọ Iṣẹgun ọsẹ to kọja lati tu wọn ka.
Bi Táyélolú ti nló ni iwájú, Bééni, Kehinde ń tó lẹ́yìn, Táyélolú ni àbúrò, Kehinde ni ẹ̀gbọ́n, Táyélolú ni a rán pé kí o ló tó ayé wò, B'ayé dára , bi ko dára O tọ́ ayé wò, Ayé dun bi oyin Táyélolú, Kehinde, ni mo ki Ejìwọ̀rọ̀ lojú ìyá ẹ̀ O dé ilé ọba tẹ̀rín-tẹ̀rín, Jẹ́ kí nrí jẹ, kí n rí mú.
 Julius Maada Bio, ti se agbekale iko oluwadi eyi ti gbogbo awon omo egbe oloselu lorile-ede naa wa , lati se iwadi laasigbo to be sile laarin awon alatileyin re ati  alatako re Samura Kamara.
Dandan ní kí a mú Dino sí àhámọ wa- Ọlọ́pàá Àwọn sinimá tó pegedé ni 2018 lágbàyé 'EFCC mo dé' àti àwọn àṣà míì táwọn olóṣèlú fi dagbo rú ní 2018 Àrà ọ̀tọ̀ inú orin tó jáde lọ́dún 2018 ní Nàìjíríà Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Asisat Oshoala: ìbẹ̀rẹ̀ mi kò rọrùn rárá nínú eré bọ́ọ̀lù Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Saba Gul: Ọmọbìnrin aláìlápa tí o fẹ̀ dì agbẹjọro Saifura Hussaini Khorsa.
N óo mi gbogbo orílẹ̀-èdè, wọn óo kó ìṣúra wọn wá, n óo sì ṣe ilé yìí lọ́ṣọ̀ọ́.
Agbẹnusọ ileeṣẹ ọlọpaa ipinlẹ Benue, DSP Catherine Anene fidi iṣẹlẹ naa mulẹ fawọn akọroyin.
bi igbimo isipo-ropo, ti osu kan ohun si ti bere lati oni lọ.
Ẹ kò gbọdọ̀ sun turari tí ó jẹ́ aláìmọ́ lórí pẹpẹ náà, ẹ kò sì gbọdọ̀ sun ẹbọ sísun lórí rẹ̀; tabi ẹbọ oúnjẹ, bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò gbọdọ̀ ta ohun mímu sílẹ̀ fún ètùtù lórí rẹ̀.
Òkú ọ̀dọ́ 15 ni mo kà ní Lekki amọ́ mo kábàámọ̀ pé a gbà kí ológun gbé okù wọn lọ - DJ Switch Awọn jàndúkù yabo ilé Sẹ́nétọ̀ Teslim Folarin, wọ́n kó ẹ̀rọ ata, ọ̀kadà, fírìíjì àti àwọn nkan tí owó rẹ̀ tó N200m ₦147m la rí kójọ fún ìwọ́de, a kò fẹ́ owó mọ́, ìwọ́de ti parí - Feminist Coalition Májèlé olóró lẹ gbé l‘Ekiti dípò èròjà oúnjẹ Covid-19 - Ariwo sọ lórí ayélujára Lara awọn olori orilẹede Naijiria to kopa ninu ipade naa eleyii ti wọn ṣe lori ayelujara ni Ọgagunagba Yakubu Gowon, Oloye Oluṣẹgun Ọbasanjọ, Ọgagun Ibrahim Babangida, Oloye Ernest Shonekan, Ọgagun Abdusalami Abubakar pẹlu aarẹ ana, Goodluck Jonathan.
Awọn eeyan ilu Eko si faraya nigba ti wọn ri fidio naa to ya ninu ọkọ rẹ to n fi ọti ẹlẹrindodo la ọmọde naa loju.
A kò lọwọ́ sí ìwé ìpẹ̀jọ́ tó tako ìdásílẹ̀ ìgbìmò ìwádìí aṣemáṣe ikọ̀ SARS- ọlọ́pàá Nàìjíríà Àwọn Ọba alayé ní Naijiria ṣàbẹ̀wò sí Ọba Eko, Gómìnà Eko àti Bola Tinubu lẹyin ìwọ́de EndSARS Lara wọn ni gomina tẹlẹri nipinlẹ Ọyọ, Oloye Rasheed Ladoja, Gomina Rotimi Akeredolu ti ipinlẹ Ondo, aṣoju orilẹede yii tẹlẹri, Taofeek Arapaja, aarẹ ẹgbẹ awọn ọmọ lẹyin Kristi, Dr Olasupo Ayokunle, Alufa Femi Emmanuel, Biṣọọbu agba Segun Okubadejo ati awọn ẹẹkan mii.
Yoruba bo won ni kosi iku ti yoo pagba ta ni ba polo ori re ni be, orisirisi isele ailero lo n waye lenu ijo meta seyin ninu idije ile geesi, ti awon miiran mosi idije EPL(English Premier League).
OLUWA jìnnà sí eniyan burúkú,ṣugbọn a máa gbọ́ adura olódodo.
Baba Fatima, Ọgbẹni Abubakar sọ fun BBC pe, iṣẹlẹ buruku naa waye lasiko ti ọmọbinrin naa ati awọn ọrẹ rẹ nlọ fun ayẹyẹ alẹ omidan nile anti rẹ kan l'ọjọru.
Ipinlẹ Edo, Bauchi ati Osun naa ni eeyan kọọkan to ni arun coronavirus bayii.
Má bẹ̀rù, ìwọ ilẹ̀,jẹ́ kí inú rẹ máa dùn,kí o sì máa yọ̀,nítorí OLUWA ti ṣe nǹkan ńlá.
Bakan naa ni awọ̀n oriade nilẹ́ Yoruba bii Ọ́ọni tilu Ile Ifẹ, Ọba Adeyẹye Ẹnitan Ogunwusi, Olugbọn tile Igbọn ti peju sibi ayẹyẹ naa.
Gege bi minisita ipinle Rajasthan, Vasundhara Raje, so pe, awon osise ti jade lo bere ise bayii ni awon ibi ti ikolu ohun ti waye.
Dokita John Nkengasong, to n dari ajọ to n mojuto itankalẹ ajakalẹ arun Africa Centres for Disease Control and Prevention (Africa CDC) ni iku covid ko ṣe e gbe pamọ rara.
 Oríṣun àwòrán, @Bulamacartoons Igbeyawo ọmọ Aarẹ Buhari jẹ ọkan gboogi lara awọn igbeyawo onirẹlẹ julọ ti awọn to n tukọ ijọba yoo ṣe ninu itan orilẹ-ede Naijiria.
Messi kan ṣadeede lọ sẹgbẹ kan lori papa nibi ti Tite wa, nibẹ lo ti fi ika sẹnu to si ni ''fẹẹmu'' fun akọnimọọgba ẹgbẹ agbabọọlu Brazil.
Nítori àwọn àtúgbẹ́yẹ̀wò, o níra láti ṣe àkójọpọ fún àwọn ọkọ́ naa Orisun: Johns Hopkins University atawọn ajọ eto ilera ilu Iye akọsilẹ to waye gbẹyin 11 Oṣù Ọ̀pẹ̀ 2020 13:00 WAT+3 O fikùn pé, àwọn yóò ṣe iranwọ fún àwọn osere tíátà lobinrin àti àwọn aláìní pẹ̀lú nítorí ohun tó máa ń mú inú bàbá òun dùn nìyẹn, èyí tíì ṣe fífún àwọn aláìní ni oúnjẹ.
Ọlọ́pàá, sójà yabo Lekki Toll Plaza láti dènà ìfẹ̀hónúhàn míràn Ìjọba àpapọ̀ ti kéde àdínkù owó epo bẹntiróòlù sí N162.
Bakan naa si ni ọmọ sori pẹlu ilana ati imọ ẹrọ ti wọn n gba se ayẹwo DNA.
Benjamin Kalu, to ṣoju ile naa so fun BBC pe, irọ ni iroyin ti a wọn eeyan kan n gbe kiri pe, ile aṣofin ọhun yara sọ abadofin naa di ofin laarin ọjọ diẹ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Yorùbá gbà pé òrìṣà bí ìyá kò sí!
OLUWA, san ẹ̀san ẹ̀gàn tí àwọn aládùúgbò wa gàn ọ́,san án fún wọn ní ìlọ́po meje,
Ìbànújẹ́ ti dé bá Gasa, Aṣikeloni ti parun.
Eyi si lo mu ki Senetọ Bassey Akpan fi pe akiyesi awọn akẹẹgbẹ rẹ lasiko ijoko ile naa pe, isẹlẹ ọhun se apakan jamọ, nitori pe awọn asofin naa yoo lọ fun isinmi olosu meji laipẹ.
Ninu ọrọ rẹ, Oloye Bademosi jẹ ọkan googi lara awọn to kọkọ bẹrẹ ọdun naa ni ọgbọn ọdun sẹyin.
' Ja'afar Ja'afar sọ pe, awọn oṣiṣẹ ijọba kan fi to oun leti pe, awọn akẹẹgbẹ wọn kan, lai ni ọwọ gomina Ganduje ninu, n gbeero lati kọlu oun.
Ẹni tí ó bá ń fọ́ òkúta, ni òkúta í pa lára;ẹni tí ó bá ń la igi, ni igi í ṣe ní jamba.
Ni kete to de iwaju sọọbu naa, ko ri awọn onibara naa, o pe wọn pe oun ti de, to si n silẹkun ẹnu ọna sọọbu rẹ naa.
Gomina Fayẹmi ni ede oyinbo sibo ko gbọdọ jẹyọ nibi eto gbogbo to ba jẹ ti aṣa tabi ibilẹ.
Àwọn ọmọ tó jáwé olúborí ní 'Headies' 2018 Ọ̀kẹ́ àìmọye olórin lo kópa níbi igbami ẹyẹ headies elekeejila tí ọdún 2018.
OLUWA a máa tọ́jú àwọn aláìlẹ́bi;ilẹ̀ ìní wọn yóo jẹ́ tiwọn títí lae.
Eyitayo ni lootọ ni oun wa lara ikọ aṣofin Mimoko nigba naa lọhun ti iṣẹ ire awọn ko si parẹ.
Kò sí ẹlòmíràn, nítorí náà ààrẹ ló bèrè fún-un.
Ó ju ọ̀kọ̀ náà, ó ní kí òun fi gún Dafidi ní àgúnmọ́ ògiri.
Lẹ́yìn ọdún mẹta, àwọn ẹrú Ṣimei meji kan sá lọ sí ọ̀dọ̀ Akiṣi, ọmọ Maaka, ọba ìlú Gati.
Oríṣun àwòrán, BBC Àkọlé àwòrán, Agbabọọlu naa di awati lẹyin to buwọlu adehun Cardiff Gbọ̀ngàn Mapo, ọ̀kan lára ibi àmúyangàn n'Ibadan rèé Àgbálùmọ̀, ohun mẹ́fà tó ń ṣe lára tí o kò mọ̀ Ààrẹ Gani Adams sọ ẹni tí Yorùbá yóò dìbò fún ní ọdun 2019 #BBCNigeria2019 Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ọ̀nà tí àwọn olùdíje ipò gómínà ní Ìpínlẹ̀ Ọyọ fẹ̀ gbà yànjú ọ̀rọ̀ ààbò rèé Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ademọla Ogunbanjo: A nílò bàbá ìsàlẹ̀ nínú òsèlú Ọpọlọpọ ọrọ ibanikẹdun lo wọle lo ti n wọle lati igba ti ọkọ naa poora.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Badagry: Erékùṣù tí àwọn ọmọdé ti ń wọ odò ńlá láti lọ sílé ìwé Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Badagry: Erékùṣù tí àwọn ọmọdé ti ń wọ odò ńlá láti lọ sílé ìwé 20 Ògún 2019 Ko si ẹwu idaabobo fawọn ọmọ wa lori odo nla yii.
- Nkechi Blessing Duro Ladipọ, ìlúmọ̀ọ́ká òṣèré tíátà àti ọmọ àlúfà tí kò gbàgbé àṣà ìbílẹ̀ Akeredolu ti mókè nínú ìbò gómìnà níjọba ìbílẹ̀ méjìlá l‘Ondo, PDP gba mẹ́ta Ijọba ni ko si ohun to n jẹ FSARS mọ ni gbogbo ipinlẹ mẹrindinlọgbọn to wa ni Naijiria ati ni Abuja Ijọba ni awọn yoo pin awọn agbofinro ẹka FSARS yii kaakiri ẹka ileeṣẹ ọlọpaa miran.
Wo ìdí tó fi tọrọ àforíjì fún ọ̀rọ̀ ẹ̀gbin tó sọ sí Pásítọ̀ David Oyedepo Lọjọ Aiku Eniyan 160 lo tun ṣẹṣẹ ni aarun Covid-19 ni orilẹ-ede Naijiria.
Ati pé ju gbogbo rẹ̀ lọ, ọjọ́ kẹta nìyí tí gbogbo rẹ̀ ti ṣẹlẹ̀.
Wọ́n bá kígbe pé, “Kí ni ó pa tàwa-tìrẹ pọ̀, ìwọ Ọmọ Ọlọrun?
Won pari ejo naa pe o seesi ku nigba ti o daku lasiko ti o n we lowo ni baluwe ni.
Nítorí Ọ̀dọ́ Aguntan tí ó wà láàrin ìtẹ́ náà ni yóo máa ṣe olùtọ́jú wọn, yóo máa dà wọ́n lọ síbi ìsun omi ìyè.
Ọrọ̀ ti Igbokwe sọ yii mu ki BBC Yoruba o tun pada kàn sí Gboyega Akosile to ti kọkọ sọ̀ pe Gomina Sanwo-Olu ko fun Super Eagles ni owo kankan.
Iwaju ile rẹ lo wa pẹlu awọn eniyan nigba ti awọn agbebọn yii de.
Ó pé ọdún kẹrin tí àwọn ọmọbìnrìn Chibok nù 'Mẹ́ẹ̀dógún lókù láàyè nínú àwọn ọmọ Chibok' Àmọ́ṣá, Aisha Buhari ní, níwọ̀n ìgbà tí ọmọ ẹni ò ní ṣèdí bẹ̀bẹ̀rẹ̀, ká fi ìlẹ̀kẹ̀ sídí ọmọ ẹlòmíràn, digbí lòun wà lẹyìn ọkọ òun nínú ìpinnu rẹ̀ láti tẹ̀síwájú pẹ̀lú ìṣèjọba rẹ̀ fún sáà kejì.
Nínú ìdájọ́ Adájọ́ Okon Abang lo sàlàyé pé, títí di àsìkò tó yóò fi le ṣe àmúṣẹ òníduro rẹ̀, yóò sán mílíọ̀nù 500 si àpò ìjọba Bákan náà ni ilé ẹjọ́ tún fún ìjọba àpapọ̀ láṣẹ láti ta ilé rẹ̀ tó wà ni Asokoro lati rí mílíọ̀nù ẹ̀ẹ́dẹ́gbẹ̀ta náírà kójọ.
Àwọn eniyan ayé gbọ́ nípa rẹ̀,wọ́n tàn án sinu kòtò wọn.
Ìbá ṣe pe mo mọ eléyìí tẹ́lẹ̀ ni, emi ìbá ti tètè kọ orí sí ọ̀nà ibòmíràn, kí n jókòó sí ibi tí ẹnikẹ́ni kò lè rí mi.
lori eto oro aje wa laarin orile ede Afirika.
Ọ̀rọ̀ nípa ìwẹ̀mọ́ di àríyànjiyàn láàrin àwọn ọmọ-ẹ̀yìn Johanu ati ọkunrin Juu kan.
Ó bá dá wọn lóhùn pé, “Ẹ̀yin ni a fi àṣírí ìmọ̀ ìjọba ọ̀run hàn, a kò fihan àwọn yòókù wọnyi.
Agbẹnusọ awọn ọlọpaa ni ipinlẹ Ondo, Tee-Leo Ikoro lo fidi ọrọ naa mulẹ fun BBC Yoruba pẹlu alaye lori ibi ti ọrọ dee duro.
Inú gbogbo àwọn eniyan dùn, ìlú sì rọ̀ wọ̀ọ̀, nítorí pé wọ́n ti pa Atalaya.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Akomolede àti Aṣa: Ọ̀rọ̀ Ẹ̀yán ni Bunmi Femi Amao ń kọ́ wa lórí ètò Akọ́mọlédè àti Àṣà lóri BBC Yoruba Ka ìròyìn yìí láti fi orúkọ sílẹ̀ fún owó ìrànwọ́ ìjọba àpapọ̀ Nàìjíríà!
Ọpọ awọn idile to n gbe agbegbe naa ti lọ si ile ijọsin lakoko naa, bẹẹ naa ni awọn akẹkọ ile iwe Bethlehem College naa ti wa ni ibi adura owurọ nigb ti iṣẹlẹ ọhun waye.
O ni ko si ohun ti ẹnikan le ṣe mọ bayii ju ki wọn maa adupẹ lọwọ Ọlọrun lọ nitori igbe aye ti Tolu gbe.
Bákan naa ni wọn tun kesi ile asofin apapọ lati dìde si ọrọ naa, ko to bọ̀wọ sori.
Eyi ni oun ti ile ẹjọ ti ṣe lori idibo gomina Osun ninu idajọ to waye ni Abuja ni ọjọ Ẹti.
Ẹ máa gbé pọ̀ ní alaafia.
Nítorí náà, ẹ óo jèrè iṣẹ́ yín,ìwà burúkú yín yóo sì di àìsàn si yín lára.
Gnassingbé, nitori naa, yoo lẹtọọ lati tun dupo lojo iwaju lodun 2020 ati odun
Obìnrin náà dáhùn ó si wi pé: 
àwọn tí ó ń pète ibi lọ́kàn wọn,tí wọ́n sì ń dá ogun sílẹ̀ nígbàkúùgbà,
Yóo ké pè mí pé, ‘Ìwọ ni Baba mi,Ọlọrun mi, ati Àpáta ìgbàlà mi.
ẹnikẹ́ni tí ó bá pa Kaini, a óo gbẹ̀san lára rẹ̀ nígbà meje.
Lásán ni gbogbo aáyan mi láti rí i pé ọkàn mi mọ́,tí mo sì yọwọ́-yọsẹ̀ ninu ibi.
Ó dàbí ẹni pé wọ́n ti ṣá ọ̀kan ninu àwọn orí ẹranko náà lọ́gbẹ́.
5m ni owo ajẹmọnu osoosu awọn sẹnatọ.
Òun fúnrarẹ̀ tilẹ̀ ní àníyàn láti wá sọ́dọ̀ yín tẹ́lẹ̀.
Abdulrasheed ni gbogbo ohun to wulo fun oniṣẹ Tiata ni rere lawọn atawọn akẹkọ kọ lọdọ Ayo Akinwale.
Ọga Agba ọlọpaa tun paṣẹ fun gbogbo awọn ọlọpaa SARS ti wọn tuka, lati wa si olu ileeṣẹ ọlọpaa nilu Abuja, fun ayẹwo ilera ara ati ọpọlọ wọn.
Ẹ̀wẹ̀, lọ́wọ́lọ́wọ́ báyìí, ọkùnrin náà wà ni àga ọlọ́pàá agbègbè Sango.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Bakan naa nijọba ilẹ Ghana tun ti kede pe, ọmọbibi ilẹ naa to ba ti lọ si awọn orilẹede tawọn alarun Coronavirus ibẹ ju igba lọ, laarin ọjọ mẹrinla sẹyin ko ni ni anfaani lati wọle pada si orilẹede naa.
“Ohun tí ó bá wu ọba náà ni yóo máa ṣe; yóo gbé ara rẹ̀ ga ju gbogbo oriṣa lọ, tóbẹ́ẹ̀ tí yóo máa sọ̀rọ̀ tó lòdì sí Ọlọrun àwọn ọlọrun, yóo sì bẹ̀rẹ̀ sí lágbára sí i títí ọjọ́ ibinu tí a dá fún un yóo fi pé; nítorí pé ohun tí Ọlọrun ti pinnu yóo ṣẹ.
    Lóòótọ́ ìgbà tí ilẹ̀ tún mọ́ ẹnikeni kò wá.
 Ìkan nínú ọkọ ̀ yíi gba ènìyàn mẹ ́ rìndínlọ ́ gọrin , gbé èrò òkànlélọ ́ gọ ́ ta lati midlands tàbí liverpool , tí ọjó orí wọn wà láàrín mẹsan sí mẹ ́ rìndínlọ ́ gọrin , ẹ ̀ ṣó mẹ ́ fà àti awakọ ̀ , ń padà bọ ̀ sí birmingham lati nîmes , àwọn kan sọpé ó ń padà bọ ̀ lati costa brava , spain .
6 8345 Orilẹ́ẹede Boswana 37 1.
Curruption Scandal: Ọ̀gá NIMASA tẹ́lẹ̀ r'ẹ́wọ̀n ọdún méjìlélógójì he
Mose bá ka gbogbo àwọn àkọ́bí ninu àwọn ọmọ Israẹli gẹ́gẹ́ bí OLUWA ti pàṣẹ fún un.
 Ìrírí wa nip é àti akẹ ́ kọ ̀ ọ ́ àti olùkọ ́ ni ó máa ń ni ìṣòro lórí iṣẹ ́ tí ó bá èdè yàtọ ̀ sí lítíréṣọ ̀ .
Stanley Olisa ṣalaye pe awọn kọkọ ṣe agbeyẹwo adinku owo oṣu ni ida oodo is ogoji ṣugbọn nigba ti nkan koi rọgbọ lawọn ba fi da awọn oṣiṣẹ silẹ.
Ẹ kí Asinkiritu, Filegọnta, Herime, Patiroba, Herima ati àwọn arakunrin tí ó wá pẹlu wọn.
Ni oṣu kọkanla ọdun 2014 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ọkan pataki ninu ohun ti an eeyan fi se odinwọn eeyan ti wọn dibo fun lasiko idbo apapọ orilẹede Naijiria lọdun 2015 Ko din ni eeyan mẹrindinlaadọta to ku ti awọn mọkandinlọgọrin miran si fi ara ṣeṣe yanayana nigba ti awọn ọmọ ikọ Boko Haram kan to so ado oloro mọra lọ pa ara rẹ lasiko ti awọn akẹkọ ko ara jọ si ileewe Government Science Secondary School.
ẹran ọ̀sìn bo pápá oko bí aṣọ,ọkà bo gbogbo àfonífojì, ó sì so jìngbìnnì,wọ́n ń hó, wọ́n sì ń kọrin ayọ̀.
Ǹjẹ́ eléyìí lè rí ìran kankan?
Ọsányìn ẹlẹ́sẹ̀-kan kò gbàgbé ẹsẹ̀ kan náà, nítorí ó wọ bàtá dáyámọ́ǹdì sí i.
Cynthia Obianodo ti Ebuka gbe sile ni iyawo lo sọ ọ di ana gbajugbaja oniṣowo oloko owo nla naa.
Ọgbà tí ó ní orísun omi ni ọ́,kànga omi tútù,àní, odò tí ń ṣàn, láti òkè Lẹbanoni.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Lagos/Ibadan Expressway: Èèyàn mẹ́jọ ló kù nínú ìjàmbá ọkọ̀ kìí ṣé mẹ́ẹ̀dógún 13 Òkùdu 2019 Àkọlé àwòrán, Lagos/Ibadan Expressway: Ọpọ̀ èrò ló farapa tí mọ́tò ṣòfò Ọkunrin mẹfa,obinrin kan ati ọmọdekunrin kan lo ku ninu ijamba ọkọ to waye lopopona marose Eko si Ibadan.
Ile asofin agba si ọmọ Naijiria: Ẹ sọra fun owo bitcoin
”“A ni awon irinse  ati osise ti yoo maa da awon eniyan lohun.
O sọ nipa irinajo rẹ láti ilé ẹ̀kọ́ Fáṣítì ti òun ti bẹ̀rẹ̀ awada lórí ayelujara.
Ohun ti wọn fẹ ṣe ni pe oju ila itagbangba (public forum) wọn nikan ni ohun ti araalu ba ka yoo maa wa.
lori awon osise eleto ilera, awon apoogun oyinbo, awakọ, akọroyin , awon
Mo fẹ́ kí o mọ̀ pé Ọlọrun ti fi ẹ̀mí gbogbo àwọn ẹni tí ó wọkọ̀ pẹlu rẹ jíǹkí rẹ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Food Poison: Oúnjẹ márùn-ún tó lè ṣekú pa'ni kíákíá 24 Bélú 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Gẹ́gẹ́ bí àwọn mìíran ṣe máa n dáṣà pé gbogbo ejò jíjẹ ni, ṣùgbọ́n ìwádìí ti fi hàn pé ọ̀rọ̀ kò rí bẹ́ẹ̀, àti pé kò si òunjẹ ti kò léwu ti à o bá ṣètò rẹ̀ dáradára.
Ijọba apapọ orile ede Naijiria ti pinnu lati gbe  awọn  onibara  ọkọ  ofurufu to ko  awọn  ololufe lo si orile ede Russia  sugbon  ti wọn  kuna lati ko wọn  pada si orile ede Naijiria , ni eyi ti o jẹ ki  awọn  eniyan naa di alarinka lẹyin ife ẹyẹ bọọlu 2018 to waye lorile ede Russia.
Bo tilẹjẹ pe ikọlu Biafra naa ba Naijiria lojiji, ko pẹ pupọ ti wọn fi gbẹsan.
” Gege bi ojogbon Muhammad-Bande,“Inu mi dun lopolopo, o si je ohun iwuri fun mi lati gba aare orile-ede
Ninu osu kokanla odun to koja, awon oluko ile-eko giga fafiti ijoba bere iyanse-lodi, latari bi ijoba se kuna lati se amulo adehun ifenuko ti won se ninu osu keta odun, lati mu alekun ba ajemonu owo osu ati ile-gbigbe awon osise.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Beautiful Nubia: Kò sí wàhálà tó ń ṣẹlẹ̀ láàgbáyé tí kò ní ọwọ́ ẹ̀sìn lábẹ́nú Dokita Ọba to jẹ aarẹ ẹgbẹ awọn dokita nileewosan nla LUTH ṣalaye pe ninu biliọnu mẹjọ o din igba ẹgbẹrun naira, N7.
Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Fídíò, Akomolede àti Asa lórí BBC Yorùbá: Mọ̀ síi nípa ẹ̀kún ìyàwó níbí3 Bélú 2020 US presidential election 2020: Ta a ni Joe Biden tó ń díje fún ipò aárẹ America4 Bélú 2020 Electricity new tariff: ''Àjọ NERC ti fún Disco láṣẹ láti padà sí owó tàríìfù tuntun iná mọ̀nàmọ́ná''2 Bélú 2020 Fídíò, Soyinka Cancer: Àṣe ara mi ni iso ti n run gbogbo bí mo ṣe n ṣèrànwọ́ lórí jẹjẹrẹ27 Bélú 2019 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 3 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 5 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Oríṣun àwòrán, Getty Images Yoo ya ọ lẹnu pe iyatọ gedegbe wa laarin iye awọn ọkunrin ati obinrin to n ku nipasẹ arun yii?
Nígbà tí Jesu mọ ohun tí wọn ń sọ, ó bi wọ́n pé, “Kí ló dé tí ẹ̀ ń sọ láàrin ara yín pé nítorí ẹ kò ní burẹdi lọ́wọ́ ni?
Oríṣun àwòrán, @aishambuhari Kii ṣe iroyin mọ pe, ọpọ onwoye lo ti n fi ẹsun kan Mamman Daura, to jẹ baba Fatimah pe oun atawọn eeyan kan lo ti joye alagbara, to ti gba agbara lọwọ aarẹ Buhari, ti wọn si n tukọ Naijiria labẹ aṣọ.
3 Ògún 2019 Oríṣun àwòrán, Facebook/Pastor Enoch Adeboye Àkọlé àwòrán, Awọn ọmọ Redeem mori bọ Ìròyìn tó ń tẹ̀ wa lọ́wọ́lọ́wọ́ ní wí pé gbogbo awọn ọmọ ijọ Redeem maraarun tawọn ajinigbe ji gbe ni Ijebu Ode ti gba itusilẹ lonii.
4 4927 Orilẹede Gabon 62 2.
“Ijipti yóo di aṣálẹ̀;Edomu yóo sì di ẹgàn,nítorí ìwà ipá tí wọ́n hù sí àwọn ará Juda,nítorí wọ́n ti pa àwọn aláìṣẹ̀ ní ilẹ̀ wọn.
Herbert Macaulay: Olayinka Herbert Samuel Macaulay jẹ oloṣelu, onimọ-ẹrọ, ayaworan ile ati akọroyin.
Bakan naa, ero igbalode ohun ni Low lo lati safihan Mario Gotze, eleyi ti o si ran an lowo lati gba ife eye idije agbaye lowo Argentina.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Corornavirus:A o gbé pápákọ̀ ofurufu Eko ati Abuja ti laipẹ- Hadi Sirika 20 Ẹrẹ̀nà 2020 Oríṣun àwòrán, Hadi Àkọlé àwòrán, A o gbé pápákọ̀ ofurufu Eko ati Abuja ti laipẹ- Hadi Sirika Mínísita fun ọ̀rọ̀ irinajo ofurufu Hadi Sirika, sọ pé ìjọba yóò gbé papakọ ofurufu meji to ṣe gbòógi ti pa laipẹ yìí ju bi awọn ṣe ro tẹ́lẹ̀ lọ.
Wọ́n bá dá a lóhùn pé, “A kò mọ ibi tí ó ti wá.
O ni ijoba ti fowosi kiko oopona kilomita mejo ataabo ni Ndue Otong- Ibiaku- Ekritam to je ibudo ile ise redio aladani akoko nipinle naa ti won pe ni Planet FM.
Oríṣun àwòrán, Twitter Ninu alaye to ṣe sinu iwe ipẹjọ, Oluyide ni iṣẹ ọpọlọ oun, ti oun ṣe akọsilẹ rẹ fun agbeyẹwo niwaju ijọba ipinlẹ Oyo gẹgẹ bii Agbaṣẹṣe, ni ilana akoso tuntun fawọn gareeji ọkọ nipinlẹ Oyo.
"Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Omolola Arohunmolase Welder: Mo ti fí iṣẹ́ 'Welder' gbayì láwùjọ, tó mo fi tọ́ ọmọ yanjú Nigba ti wọn tun bi i pe ẹkọ wo lo mu kuro ni aafin, o ṣalaye pe ẹkọ ti oun kọ kuro ni aafin ni pe ""ma ṣe finu tan ẹnikẹni."
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Baby abandoned on dunmpsite: Mo ti bímọ mẹ́rin tẹ́lẹ̀ fún bàbá méjì nínú òṣí- Dupe Ogbomọṣọ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Baby abandoned on dunmpsite: Mo ti bímọ mẹ́rin tẹ́lẹ̀ fún bàbá méjì nínú òṣí- Dupe Ogbomọṣọ 2 Owewe 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 4 Owewe 2020 Mo parọ fawọn eeyan pe mi ò loyun ni titi mo fi bimọ- Dupẹ BBC Yoruba ṣawari obinrin kan, dupe ti ọpọ n pe ni Iya Muiz sọrọ ilẹ kun lori bi o ṣe bi awọn ọmọ rẹ mẹrin fun baba meji ki o to tun loyun ọmọ karun un.
Àwọn ọmọ ogun rẹ̀ kò ní kó apata wọ inú rẹ̀.
7 581550 Orilẹede Belgium 17320 150.
Dokita àti Nọ́ọ̀sì fìyà jẹ mí lásìkò tí mò ń rọbí- Alaboyún Ó wá rọ àwọn obinrin lọ́mọde àti lágbà níyànju láti maa gbárùkù ti obinrin ẹgbẹ́ wọ́n ní gbogbo igba.
5m), tó bá ti ṣiṣẹ́ láàrin ọdún mẹ́rìn sí méje, to si wa ni ipò tí Khapilat wa gẹ́gẹ́ bii kọ́bùrù ọlọ́pàá, Police Constable (PC).
Ninu atejade ti iko agbaboolu Real Madrid fi sita lojo isegun(Tuesday), won ni awon ta Ronaldo fun iko agbaboolu Juventus ni ibamu pelu ohun ti o nikan lati se.
O dìgbà tí mo bá dórí àgá kí ń tó sọ ìpinnu mi - Fatai Owoseni Ìpínlẹ̀ Ondo ti ní gómìnà tuntun Òyìnbó sísọ di èèwọ̀ ní ìpínlẹ̀ Ekiti Ìpínlẹ̀ Ọ̀ṣun kéde ìsinmi lẹ́nú iṣẹ́ nítorí ọdún Ìṣẹ̀ṣe Oya, ẹyin naa ẹ gbiyanju ẹ wo, ẹ fi ami si gbolohun yii ki a gbọ idahun yin o.
Àwọn ọmọ wọ̀nyí a máa farahàn ní ìgbésí-ayé ẹ̀dá ní oríṣìíríṣìí ọ̀nà àrà, wọn a sì máa da ọmọ-ènìyàn l’áàmú.
Ó ti wọ́ ògo Israẹli luláti òkè ọ̀run sórí ilẹ̀ ayé;kò tilẹ̀ ranti àpótí ìtìsẹ̀ rẹ̀ ní ọjọ́ ibinu rẹ̀.
Gbogbo wọn jẹ́ irinwo (400) ọkunrin, ó sì jẹ́ olórí wọn.
“OLUWA, ìwọ ni ìmọ́lẹ̀ mi,ìwọ ni o sọ òkùnkùn mi di ìmọ́lẹ̀.
Ọrọ yii tun di ohun a n tana wo loni to jẹ ayajọ ọjọ ayika ti wọn ṣi n mẹnu ba ọrọ atẹgun buburu tabi atẹgun ti ko mọ ni ayika eniyan.
Kí aṣálẹ̀ ati àwọn ìlú inú rẹ̀ kọ orin ìyìn sókè,ati àwọn abúlé agbègbè Kedari;kí àwọn ará ìlú Sela kọrin ayọ̀,kí wọn máa kọrin lórí àwọn òkè.
Bakan naa ni aarẹ Ghana tun fapa janu lori bi orilẹ-ede Naijiria ṣe ti ẹnu ibode rẹ nitori fayawọ irẹsi.
OLUWA ti fi ara rẹ̀ hàn, ó ti ṣe ìdájọ́,àwọn eniyan burúkú sì ti kó sinu tàkúté ara wọn.
Akonimoogba omo orile-ede Holland ohun, ti sise papo pelu orisirisi olukopa ninu ere-idaraya yii bii: Monica Seles, Arantxa Sanchez Vicario, Ana Ivanovic, Caroline Wozniacki ati Greg Rusedski.
(Bí mo ṣe gba ṣúgà àti ẹ̀pà lọ́wọ́ Ìyá Aláje rè é, tí mo sì fùn- un ni ogójì náìrà/ múrí méjì)
"Koda, a jọ ki ara wa pe o dabọ ni ko to o lọ si oko irẹsi to ti n ba wọn sisẹ.
Iji lile naa ba n kan je lopolopo ni agbegbe meta otooto nipinle Rajasthan – Alwar, Bharatpur ati Dholpur – nibiti eniyan mokanlelogbon ti je olorun un ni pe.
awon ohun ti o le pa awon eniyan lara ni ikawọ rẹ, ni eyi ti ijoba ipinle naa
Aró ni wọn n lo bayii.
Mo ronú nípa Ọlọrun títí, mò ń kérora;mo ṣe àṣàrò títí, ọkàn mi rẹ̀wẹ̀sì.
Emir ni ki o to jẹ Emir Kano.
com àti òntẹ̀lé  ni màá bẹ̀ sọ́rọ̀ yí o.
Nítorí náà, àwọn ọmọ Israẹli ń gbé ààrin àwọn ará Kenaani ati àwọn ará Hiti, àwọn ará Amori ati àwọn ará Perisi, àwọn ará Hifi, ati àwọn ará Jebusi.
Oríṣun àwòrán, gospelfilmsng Àkọlé àwòrán, Ijo ati ayọ ni baba ati iya iyawo, Mike ati Gloria Bamiloye fi sin Darasimi lọ sile ọkọ.
Ilẹ̀ iyanrìn gbígbóná yóo di adágún omiilẹ̀ gbígbẹ yóo di orísun omi,ibi tí ọ̀fàfà fi ṣe ilé tẹ́lẹ̀ yóo di àbàtà,èèsún ati ìyè yóo máa dàgbà níbẹ̀.
Àjọ ICPC ni yóò sì máa ṣe àkóso àwọn dúkìá náà Ogbeni David Igbodo, tíì ṣe igbá-kejì ọga agba ọlọ́pàá, ẹni tí wọ́n yàn bíi alákòóso fidihẹ lórí àwọn dúkìá náà, títí tilè ẹjọ́ yóò fi gbé àṣẹ míràn kalẹ lórí àwọn dúkìá náà.
Ó pa àwọn agbẹnusọ lẹ́nu mọ́,ó gba ìmọ̀ àwọn àgbààgbà.
Àwọn Juu tí ó ń gbé Damasku kò mọ ohun tí wọ́n le wí mọ́, nítorí ó fi ẹ̀rí hàn pé Jesu ni Mesaya.
Coronavirus: Irọ́ ńlá ni pé ewé dongoyaro lè wo aàrùn coronavirus
Bẹ́ẹ̀ ni wọ́n jùmọ̀ pète pèrò;wọ́n dá majẹmu láti dojú kọ ọ́.
Anfaani ko si fun obinrin to ba wa ninu oyun lati forúkọ silẹ.
 ""Wọn gbe olóògbé tó fara gba ọgbẹ náà lọ sílè ìwòsàn àmọ́ ẹpa kò boro mọ, Ọlọpaa náà jáde láyé."
    Èṣù tún mu adéforítì lọ sí ibi tí ó pè ni òpópó Ìyà-ẹ̀sẹ̀.
a & w restaurants jẹ akojọpọ awọn ounjẹ ounjẹ ounjẹ ounjẹ ti o ṣe iyatọ nipasẹ awọn ẹọti ati awọn ọti oyinbo .
Òun ni yóo máa bá ọ bá àwọn eniyan sọ̀rọ̀, yóo jẹ́ ẹnu fún ọ, o óo sì dàbí Ọlọrun fún un.
Ní ọjọ́ ìṣẹ́gun ọjọ́ kẹta oṣù kẹ́sàán ọdún 2018 ní ẹgbẹ òṣèlú All Progressive Congress (APC) gbé owó tí àwọn tó bá nífẹ láti dupò níbi ìdìbò gbogboogbo ọdún 2019 yóò san jade.
Nígbà náà ni ara bẹ̀rẹ̀ sí ta OLUWA nítorí ilẹ̀ rẹ̀,ó sì ṣàánú fún àwọn eniyan rẹ̀.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ifọrọwanilẹnuwo pẹlu Ọjogbọn Wọle Soyinka Ẹ wo Daniel tí wọ́n fẹ́ yẹgi fún lẹ́yìn tí US kò ṣe irú ẹ̀ fún odidi ọdún 17 Kò sí ìfòyà, ọkọ̀ bààlù wà tí ìjọba ba ti afárá 3rd Mainland lósù yìí Nigeria Police recruitment 2020: Bàyìí ni o ṣe leè di ọlọ́pàá Nàìjíríà Sọ́ọ́bù irun tí ọmọ àarẹ ṣí sílẹ̀ Amerika fa awuyewuye Igi araba ni Akinwande Oluwole Babatunde Soyinka nile ati lẹyin odi gẹgẹ bi ọmọ kaaro o jiire ati ọmọ Naijiria ṣugbọn Wole Soyinka sọọ ni awọn eeyan mọ ọ si.
Aare soro yii lojo Aje , gege bi alaga ajo ECOWAS nibi ipade to waye laarin awon omo orile ede China ati awon adari orile ede Afirika ni China.
Akintola University of Technology (LAUTECH) niluu Ogbomoso, ipinle Oyo, eka
7 688270 Orilẹede Ecuador 14246 83.
Ikorodu Bois: Ko si ẹni ti a kò lè sín jẹ!
Ninu ifọrọwanilẹnuwo lori ẹrọ alagbeka, ọkan lara awọn ọmọ igbimọ ipolongo Ademola Adeleke, Niyi Owolade sọ fun BBC Yoruba pe lootọ ni idajọ naa yoo waye nilu Abuja.
Ó fẹ ̀ rẹ ̀ tó miliọnu 7 sí 8 ènìyàn , pàápáá ní ilẹ meksiko , Ààrin-gbùngbùn amẹrika àti ilẹ gúsù amẹrika ti wọn ní àrùn chagas .
Muhammadu Buhari, fun atileyin re lati tubo maa se atileyin fun ile-ise ologun ofurufu
O tun wa ro won pe” ki won maa toju awon ise akanse ti ijoba pese yii.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Ki lo fa ọta laarin Manchester United ati Liverpool ?
fun awon orile ede ti o wa larọọwoto won.
oniroyin pe ile ise yii ri oniruuru eru fayawo bii iresi,  aloku oko
Tabi kí ni mo fi sàn ju ẹni tí ó dẹ́ṣẹ̀ lọ?
Ẹni tí ó ṣe alábàápín pẹlu olè kò fẹ́ràn ẹ̀mí ara rẹ̀,ó gbọ́ ọ̀rọ̀ ègún, ṣugbọn kò sọ fún ẹnikẹ́ni.
Wo ohun àràmàndà tí àwọn olósèlú máa ń ṣe lásìkò ìbò #BBCNigeria2019 Fela Durotoye, olùdíje ipò ààrẹ ẹgbẹ́ òṣèlù ANN #BBCNigeria2019 Tani Kingsley Moghalu tó ń duipò ààrẹ?
Ileẹjọ f'ofin de ọdun oro nipinlẹ Ogun Àwọn àṣà àti ìse tó yọ obìnrin sílẹ̀ nílẹ̀ Yorùbá Sanwo-Olu kò lè tori ìjà Ọjọta fòfin de NURTW ní Eko - Agbẹnusọ gómínà Buhari yan Kyari ní olùdarí tuntun fún àjọ NNPC Idris lo binu yinbọn lu eeyan meje lori ẹṣin lataari pe o ni oun ko fẹ ki wọn sare ije ẹṣin kọja ni adugbo oun.
"Gbogbo awọ̀n obinrin ni wọn kọlu "" Awọn ọmọ ẹgbẹ wa ti wọn kọlu pọ."
Kò sí ààye fún ènìyàn to bá ti lé ni ogún ènìyàn lẹyìn ibiṣẹ́ Kò ní sí kóníléógbéle òní láyípo ní ìpínlẹ̀ Kano mọ́, sùgbọ́n ìpele tí àwọn ìpínlẹ̀ tókù fi sill ni wọ́n yóóò wà báyìí, eyí túmọ̀ sí pé,aago mẹ́fà ààrọ sí aago mẹ́jọ alẹ́ ni wọ́n yóò maa fi jáde.
Ose oge todun 2018 yii ni eleekesan an iru re.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Nenadi Usman ni mínísítà fún ètò ìnáwó Nàìjíríà láàrin 2006 sí 2007 Sáàjú ló ti sọ fún ilé ẹjọ́ pé àìsàn jẹjẹrẹ n bá òun fínra.
OLUWA sọ fún mi pé, “Lọ dúró ní ẹnubodè Bẹnjamini níbí, tí àwọn ọba Juda máa ń gbà wọlé, tí wọn sìí gbà jáde; ati ní gbogbo ẹnubodè Jerusalẹmu, 
Odò ti ó bá gbàgbé orisun gbi gbẹ ló ngbẹ
Lara ohun ti wọn ka mọ awọn afurasi naa lọwọ ni awọn Garawa to kun fun oriṣiriṣi ayederu oogun, awọn paali ayederu oogun ti wọn fẹ ẹ lọ ta, to fi mọ awọn kẹmika loriṣiriṣi ti wọn fi n ṣe awọn oogun naa.
" rògbòdìyàn , Ìṣòro , ogun àti àìfọkànbalẹ ̀ kọ lu ìgbé - ayé Àjàpadá pẹ ̀ lú ara ìlú "" Òyè ' náà ."
 O ye ki won maa dupe pe won ni Messi lara won ni.
 Ewe, lasiko ifilole ohun, Dokita Adebayo Shittu ro awon omo egbe naa lati se ojuse won bi o  se to ati bo se ye, besini ki won lo oye ijinle won ninu eto ibanisoro lati mu igberu ba ajo ohun.
Amọṣa, nibayii Gomina Rochas Okorocha ti ni aigba imọran igbakeji aarẹ orilẹede Naijiria, Yẹmi Oṣinbajo lo fa wahala ti o n n koju ni ipinlẹ naa.
ilé asofin àgbà - BBC News Yorùbá BBC News, YorùbáFò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Five G: Ìjọba àpapọ̀, ẹ so ifilọlẹ ẹ̀rọ alatagba 5G rọ na - ilé asofin àgbà 6 Èbibi 2020 Oríṣun àwòrán, others Ilé asofin àgbà ilẹ̀ wa ti rọ ìjọba àpapọ̀ láti so ifilọlẹ ẹ̀rọ alatagba itakun àgbáyé 5G rọ̀ ná.
Nítorí náà, àwọn eniyan á yipada, wọn á fara mọ́ wọn,wọn á máa yìn wọ́n, láìbìkítà fún ibi tí wọn ń ṣe.
Oríṣun àwòrán, Facebook/hrmobaolofa Àkọlé àwòrán, Oloffa Ilu Offa ''Ẹni to n ba wa dunadura pẹlu awọn ajinigbe ko ti i pe wa pada lati sọ iye ti wọn fẹ gba ṣugbọn ohunkohun to ba gba la ṣetan lati ṣe ki wọn ba le e doola ẹmi wọn'' O lè ní ẹ́gbẹ́ta àwọn ọmọ Naijiria tí wọ́n ti ṣetàn láti padà sílé!
“Jọ̀wọ́, gbà wá láàyè láti gba orí ilẹ̀ rẹ kọjá.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Rashidat Fawẹhinmi: Sísọ èdè Yorùbá kò leè ba Gẹ̀ẹ́sì jẹ́ lẹ́yìn odi Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Rashidat Fawẹhinmi: Sísọ èdè Yorùbá kò leè ba Gẹ̀ẹ́sì jẹ́ lẹ́yìn odi 5 Sẹ́rẹ́ 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 6 Sẹ́rẹ́ 2019 Rashidat Fawẹhinmi, ninu imọran rẹ fawọn ọmọ ilẹ Kaarọ Oojire to fi oke okun se ibujoko, rọ wọn lati mase ri ede Yoruba sisọ bii ohun itiju nla.
Nǹkan ọ̀ṣọ́ mú kí ẹ̀rẹ̀kẹ́ rẹ lẹ́wà,ẹ̀gbà ọrùn sì mú kí ọrùn rẹ lẹ́wà.
Yoruba film: Irú ẹ̀ṣẹ̀ wo ni gbajugbaja òṣèré, Nkechi Blessing ṣẹ Toyin Abraham tó fi ní kó jèbùrẹ́?
”O ni iwa ti ko boju mu rara ni iwa yii ati pe Ijọba
Nibi ayẹyẹ naa ti ọpọ ẹbi, ọrẹ ati ojulumọ Barrister peju si ni Kwam 1 ti sọ pe orin fuji ni Barrister duro fun ni igba aye rẹ.
Kí ẹ pa ọ̀dọ́ aguntan Ìrékọjá, kí ẹ ya ara yín sí mímọ́, kí ẹ múra sílẹ̀ fún àwọn arakunrin yín láti ṣe ohun tí OLUWA sọ láti ẹnu Mose.
Gbogbo ohun tí Rehoboamu ṣe, láti ìbẹ̀rẹ̀ dé òpin, ni a kọ sinu ìwé ìtàn wolii Ṣemaaya, ati sinu ìwé Ido aríran.
" Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Coronavirus: BBC News Yorùbá ní kí ẹ dúró nílé bí ẹ kò bá ní ìdí láti jáde Nigba to n sọrọ lori eto iranwọ ti ijọba rẹ n ṣe, Fayemi ni oun maa n fun awọn arugbo ni ẹgbẹrun marun naira losoosu, ọdọ bii ẹgbẹrun marun si lawọn fun ni ẹgbẹrun lọna ogun ẹni kọọkan, ti oun si tun fun awon akẹkọọ nile ẹkọ giga ni ẹgbẹrun mẹwa owo iranwo eto ẹkọ.
ana Bouteflika yọ kuro nipo bii jiga, fun idi kan ti won ko sọ nipato ati omo
Nigba to di ọgbọnjọ osu Karun ọdun 1967, Ọgagun Chukwuemeka Ojukwu ya ẹya Igbo kuro lara orilẹede Naijiria, to si kede orilẹede Biafra fun wọn, eyi to jẹ ibẹrẹ ogun abẹle ni Naijiria.
Tribunal: Olujimi ló wọlé ní ìdìbò Ekiti kìí ṣe Adeyeye Oríṣun àwòrán, others Àkọlé àwòrán, Sẹ́nátọ̀ Biodun Olujimi ló gba ilé ẹjọ́ tó ń gbẹ́jọ́ ẹ̀sùn ìdìbò lọ, lẹ́yìn ìdìbò sílé Asòfin Àgbà ti ọdún 2019.
 Aare Buhari  wa rọ awon musulumi lati tubọ maa gbadura fun
 iye àwọn ènìyàn tí ó ń sọ èdè yìí jé 455 , 88 .
A rí i pé wọn kò lè wọ inú ìsinmi yìí nítorí wọn kò gbàgbọ́.
Àsọtẹ́lẹ̀ nípa Edomu nìyí:Ẹnìkan ń pè mí láti SeiriÓ ní: “Aṣọ́nà, Òru ti rí o?
Josẹfu bá wọlé lọ sọ fún Farao pé, “Baba mi ati àwọn arakunrin mi ti dé láti ilẹ̀ Kenaani, pẹlu gbogbo agbo ẹran ati agbo mààlúù wọn, ati ohun gbogbo tí wọ́n ní, wọ́n sì wà ní ilẹ̀ Goṣeni báyìí.
Àkọlé àwòrán, Igba akọkọ ti a maa ṣe eyi niyi Ọna wo ni o le fi yege?
N kò kí ọkùnrin náà dáadáa nítorí láti ọjọ́ tí mo ti mọ̀ ọ́n n kò rí ẹ̀rín lẹ́nu rẹ̀ rí.
Joabu sì parí èyí tí ó kù.
Asofin naa tun ni :“A ni aarẹ to jẹ bii baba wa, to n ba
Minisita ọpọ ọmọ Naijiria to ni arun coronavirus ni wọn n deju mọle, dipo ki wọn jade fun itọju ki arun naa maa ba ran awọn mii.
Amọ o fikun un pe, o seese ki awọn alaboyun naa ma tẹle asẹ awọn nọọsi tabi dokita ki ibimọ naa le rọrun fun wọn.
Obìnrin tó lówó jùlọ ní Africa 'ja orílẹ̀-èdè rẹ̀, Angola lólè' fi kó ọ̀rọ̀ jọ ni Àǹfààní wo ló wà nínú Brexit fún Nàìjíríà àtàwọn orílẹ́-èdè Afíríkà?
3 trillion ni CBN gbé jáde fún ọdun 2020 Fásítì Babcock lé akẹ́kọ̀ọ́bìnrin tó hàn nínú fídíò ìbálòpọ̀ lọ sílé Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
“Lẹ́yìn náà, fi ẹ̀gbẹ́ rẹ òsì dùbúlẹ̀, kí o sì di ìjìyà àwọn ọmọ ilé Israẹli lé ara rẹ lórí.
'Operation Rewire' EFCC / FBI sèso owó tó lè ní mílíọ̀nù N153 Ẹ ṣèwádìí ikú Ọ̀jọ̀gbọ́n Gideon Okedayọ - ASUU Ninu atẹjade kan ti ileeṣẹ aarẹ orilẹ-ede Naijiria gbe jade eyi ti amugbalẹgbẹ fun aarẹ lori ọrọ iroyin ati ipolongo, Garba Shehu fọwọ si, aarẹ Buhari ni mo ti padanu olutọju mi to dara to si lootọ."
Bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé wọ́n lo agbára wọn láti dẹ́rù bani, wọ́n sùn láìkọlà, pẹlu ìtìjú, pẹlu àwọn tí wọ́n kú lójú ogun.
Paulu wá tún sọ gbolohun kan, ó ní, “Òtítọ́ ni Ẹ̀mí Mímọ́ sọ láti ẹnu wolii Aisaya sí àwọn baba-ńlá yín.
Ẹ gbo oun ti wọn so ninu fidio yi: Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Ijọba fẹ le wa kuro ni Ọjọta' Iroyin miran tẹ ni fẹsi Ijọba Eko din owo-ori ilẹ ati ile ku Owo ori ilẹ nipinlẹ Ondo fa ariyanjiyan Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Iṣiboṣẹti bá ranṣẹ lọ gba Mikali lọ́wọ́ Palitieli, ọmọ Laiṣi, ọkọ rẹ̀.
 bí ò ki ifá , yóò máa sun Ìyẹ ̀ rẹ ̀ -ifá .
Nígbà tí wọ́n wọ inú igbó náà, wọ́n rí i tí oyin ń kán sílẹ̀, ṣugbọn kò sí ẹnikẹ́ni tí ó lè fi ọwọ́ kàn án nítorí pé wọ́n bẹ̀rù ìbúra Saulu.
Idajọ ti wọn yoo kede lọla yi da lori pe Oyetola tako idajọ ti Adeleke saaju ri gba lọdọ igbimọ to n gbọ ẹjọ lori idibo naa.
Gẹgẹ bii kọmiṣọna feto iroyin nipinlẹ Ondo, Donald Ojo ṣe sọ, ijọba ko mọ pe iru ẹgbẹ bẹẹ wa nikalẹ ni ipinlẹ ọhun ki ogbontagi amofin kan ti orukọ rẹ n jẹ Kayode Ajulọ to ṣi aṣọ loju wọn.
 o je yiyesi pelu iwe kan , o je yiyalaworan ni madame tussauds bee sini o je alejo nigba isinku dr livingstone .
Atẹjade ti ileeṣẹ igbohun safẹfẹ Double A Media fi lede lo fi idi ọrọ mulẹ pe arọda ojo lo ṣokunfa iṣẹlẹ laabi naa.
Tinubu sọ wipe ọrọ bi ẹgbẹ APC yoo se tẹsiwaju ni oun jiroro lori pẹlu awọn ọmọ ẹgbẹ naa.
"Uganda gbówó orí lé Whatsapp, Facebook Ọkùnrin mẹrin wọ gàù torí ìgbéyàwó orí Facebook ""Mo pàdánù ọkọ méjì láàrin ọdún kan lórí Facebook"" Laipẹ́, ọmọ tí kò bá pé ọdún méjìdínlógún kò ní leè jáde girama l’Ọṣun Facebook fi kọ́kọ́rọ́ ti àwọn ojú òpó ayédèrú ìròyìn léde Yorùbá àti Igbo Bakan naa lo ti hande pe ida mẹtalelogoji ninu awọn ọdọmọde akẹkọọ wọnyi ni wọn n lo ẹya ẹrọ alagbeka ti igbalode t awọn obi wọn ko ni lọwọ."
Ẹ̀rù ba Jakọbu gidigidi, ó sì dààmú, ó bá dá àwọn eniyan tí wọn wà pẹlu rẹ̀ ati agbo mààlúù, ati agbo aguntan ati àwọn ràkúnmí rẹ̀ sí ọ̀nà meji meji.
Efuraimu ni àkẹtẹ̀ àṣíborí mi,Juda sì ni ọ̀pá àṣẹ mi.
Wọ́n ṣe aadọta ojóbó sára èyí tí ó kángun síta lára àránpọ̀ aṣọ kinni, ati èyí tí ó kángun síta lára àránpọ̀ aṣọ keji.
Wọn kò sí ṣàlàyé kankan lórí iye ọmọ ogun tó kú níbi ìṣẹ̀lẹ̀ nàá.
Iléeṣẹ́ Aarẹ Buhari - BBC News Yorùbá BBC News, YorùbáFò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Leah Sharibu ṣì wà láàyè - Iléeṣẹ́ Aarẹ Buhari 1 Owewe 2019 Oríṣun àwòrán, @others Àkọlé àwòrán, Ori Leah ko ni sun lakata awọn boko haram nigbagbọ awọn obi ẹ.
Awọn mejeeji naa panu pọ lati bẹ ijọba pe ko ṣi ileewe pada nitori ọjọ iwaju awọn niyẹn.
Níbòmíràn, ó tún wí pé, “Oluwa mọ̀ pé asán ni èrò-inú àwọn ọlọ́gbọ́n.
Jesu tún wọ inú ilé ìpàdé lọ.
Bakan naa ni Ọga Agba ile isẹ irinna Naijiria naa fikun wi pe ipa rere ni ibode Naijiria ti wọn ti ko lori ọrọ aje orilẹ-ede Naijiria ati wiwọle-wọde awọn eniyan lati orilẹ-ede miran wa si Naijiria.
2 Sẹ́rẹ́ 2021 Saka àti Xhaka Arsenal ṣe Chelsea ṣákaṣàka,3-1 ló bá de lọjọ Boxing Day26 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Ọlọ́pàá kò fẹ́ yìnbọn, kó má ba à ba aráàlú, l‘àwọn afurasí olóògùn olóró ba sá mọ́ wọn lọ́wọ́15 Sẹ́rẹ́ 2021 Covid-19 pa Ọlọ́lá Akin Olugbade, ẹ wo dúkìá jaburata tó fisílẹ̀14 Sẹ́rẹ́ 2021 Ẹ̀yin oríadé, tẹ bá fẹ́ mọ ìtàn Yorùbá, ẹ lọ kọ́ lọ́dọ̀ Alaafin - Oluwo14 Sẹ́rẹ́ 2021 Ẹ wo àwọn èèyàn tó ń da ààrin Seyi Makinde àti igbákejì rẹ̀ rú14 Sẹ́rẹ́ 2021 Irú ẹ̀dá wo ni Lamidi Adeyemi?
tí ó bá tẹ ́ ẹ lọ ́ rùn á tẹ ́ wọ ́ gba ìkejí rẹ ̀ kẹ ́ hìndé ( nígbà mííràn á dá kẹ ́ hìndé padà ) kó ní kó má a bọ ̀ .
Aṣọ aláwọ̀ aró, ati ti elése àlùkò, ati aṣọ pupa ati aṣọ funfun onílà tẹ́ẹ́rẹ́tẹ́ẹ́rẹ́ ni wọ́n fi ṣe aṣọ àgọ́ náà, wọ́n sì ya àwòrán Kerubu sí i lára.
Àkókò tí àwọn ọmọ Israẹli gbé ní ilẹ̀ Ijipti jẹ́ irinwo ọdún ó lé ọgbọ̀n (430).
“A gbọ́ nígbà tí ó ń wí pé, ‘Èmi yóo wó Tẹmpili tí eniyan kọ́ yìí, láàrin ọjọ́ mẹta, èmi óo gbé òmíràn dìde tí eniyan kò kọ́.
Yára nisinsinyii kí o ranṣẹ lọ mú un wá; dandan ni kí ó kú.
àwọn àgbèrè, àwọn ọkunrin tí ó ń bá ọkunrin lòpọ̀, àwọn gbọ́mọgbọ́mọ, àwọn onírọ́, àwọn tí ó ń búra èké, ati àwọn tí ń ṣe àwọn nǹkan mìíràn tí ó lòdì sí ẹ̀kọ́ tí ó dára, 
aadota lenirinwo baalẹ ni o ti sepinnu lati satileyin fun aare  lati pada lẹẹkeji, nitori iwa akin ati otito
Abdullahi Usman Kantago to jẹ oloye pataki ni abule yii ṣalaye fun Dooshima Abu, akọroyin BBC pe awọn ologun ni wọn gbiyanju ọna naa ṣugbọn wọn ko da ọda sii.
Kí àwọn fúnra wọn wá kó wa jáde.
Bí ọmọdé ọlọ́jọ́ orí bá fẹ́ dàgbà onílàákàyè
Facebook to ni Instagram ti fofin de owo ẹru lori Instagram, wọn si ti yọ oju opo eniyan 703 lẹyin iwadii.
Àwọn Ẹ̀yà Juda ati ti Simeoni Ṣẹgun Adonibeseki.
Orúkọ aya Abiṣuri ni Abihaili, ó sì bí Ahibani ati Molidi fún un.
Ijọba apapọ gan ti wa funpe si awọn ijọba ipinlẹ pe ki wọn ṣọra lori bi wọn ṣe fẹ ṣi awọn ileewe tori pe ewu ṣi wa loko longẹ.
Ìkookò yóo máa bá ọ̀dọ́ aguntan gbé,àmọ̀tẹ́kùn yóo sùn sílẹ̀ pẹlu ọmọ ewúrẹ́,ọmọ mààlúù, ati kinniun, ati ẹgbọ̀rọ̀ ẹran àbọ́pa yóo jọ máa gbé pọ̀,ọmọ kékeré yóo sì máa kó wọn jẹ.
Nítorí náà, wí fún wọn pé: mo ní n kò ní fi ọ̀rọ̀ mi falẹ̀ mọ́, ṣugbọn ohun tí mo bá sọ yóo ṣẹ.
Ìwà ìbàjé yìí, mú kí inú bí onígbèsè, ó pinu pé òhun kò ní gbèsè kan san.
Ugbochukwu Michael: Ààrùn kòkòrò HIV kìí ṣe ìdájọ ikú Òṣìṣẹ́ LASTMA kan àgbákò ikú lọ́wọ́ àwọn jàǹdùkú méjì nílùú Èkó 'A kò ní w'ojú olóṣèlú kankan lóríi ìwádìí àpapín owó N5bn ní Kwara' Èrò ọmọ Nàìjíríà ṣé ọ̀tọ̀ọ̀tọ̀ lóríi ìkéde Rélùwéè ọ́fẹ́ Èkó sí Ìbàdàn Dino Melaye lori oju opo ikansiraẹni Twitter ni ohun gbe ẹjọ naa lọ si ile ẹjọ to n gbẹsun ọrọ to jọmọ eto idibo lati tako esi idibo naa.
Naira Marley: Pásítọ̀ Omatsola tún kìlọ̀ fáwọn ọ̀dọ́ láti yé pe ara wọn ní Marlians
25 Agẹmo 2019 Oríṣun àwòrán, TWITTER@GOOGLEAFRICA Ohun yẹn niyen!
Iroyin naa tun fikun pe ṣe ni Dosumu maa n fọnnu kiri pe oun setan lati pa ọpọlọpọ eeyan lagbegbe naa, eyi to n ko ibẹru-bojo ba ọpọ eeyan nibẹ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Oladapo Adu: Nàíjíríà já mi kulẹ̀ torí wọn kò wá gbé mi O farahan niwaju igbimọ tileeṣẹ aarẹ gbekalẹ lati ṣewadi ẹsun mẹrinlelogun ti wọn fi kan larin ọdun maarun to fi jẹ adele alaga ajọ EFCC.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ọba Adesoji Aderemi, Ọọ̀ni Ifẹ̀ tó gba ipò ọba mọ́ tòṣèlú Iṣẹ́ Kudirat Abiọla ṣì ń fọhùn síbẹ̀, lẹ́yìn ọdún 23 tó papòdà Èmi kò leè kú láéláé Yàtọ̀ si èyí, Guru Maharaji ní ó yẹ ki ìjọba àpapọ fí kún owó oṣù òṣìṣẹ́, kí wọ̀n si mú kí ìgbáyégbádùn àwọn adájọ lọkunkundun, kí wọ́n ma ba máá ṣe ojúkokoro láti gba àbẹ̀tẹ́lẹ̀.
Idibo naa waye lẹyin ọdun bi i mẹwa ti iru rẹ ti waye kẹhin nipinlẹ naa.
lojoRu(Wednesday) leyin ipade igbimo ijoba apapo, eleyi ti aare Muhammadu
Oríṣun àwòrán, others Lórí ìwé ìfitóniléti ọ̀hún tó jáde ni ogúnjọ́ oṣù kẹjọ, ọdún 2020, lo ti sọ pé, àwọn ikọ̀ Boko Haram náà ṣètò láti ṣe ìkọ̀lù si àwọn ibì kan nílùú Abuja àti agbàgbè rẹ̀.
Ẹnikẹ́ni tí ó bá sì jẹ ẹ́ yóo jìyà ẹ̀ṣẹ̀ rẹ̀, nítorí pé, ó ti ba ohun mímọ́ OLUWA jẹ́, a óo yọ ọ́ kúrò láàrin àwọn eniyan rẹ̀.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ìgbẹ́ yiyá síta gbángba n fún Nàìjíríà lórúkọ tí kò dá Ǹjẹ́ ó seése kí Buhari se àtúnse ilé-ìwé 10,000 lọ́dọọdún?
ati bí ẹ ti ń retí Jesu, Ọmọ rẹ̀, láti ọ̀run wá, ẹni tí a jí dìde ninu òkú, tí ó yọ wá kúrò ninu ibinu tí ń bọ̀.
Sadoku ọdọmọkunrin akikanju jagunjagun wá, pẹlu ọ̀gágun mejilelogun ninu àwọn ará ilé baba rẹ̀.
O ni ki gbogbo obi ati alagbatọ maa mojuto awọn ọmọ wọn, ki wọn ma jé ki wọn rin irin oru ati ki wọn ma lọ si ibi toju ko ni le to wọn.
Yobe ni 1, Sokoto ni 10, Kebbi ni 8 nígbà tí Enugu ni 6, Edo ní 5 nígbà ti Ondo ni 3 Niger ni 2 sùgbọ́n Kano àti Oyo ni ẹyọ kan péré.
ati osu keta odun yii, lasiko ti aare orile ede naa Rahila Odinga kọ lati fi
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, World Radio Day: Àwọn òṣìṣẹ́ rédíò ní àwọn ń pa ìsòro àwọn mọ́ra ni láti mú inú aráàlú dùn Buhari ni oun ti setan lati se agbekalẹ awọn ilana to gbopọn lati sẹ eegun ẹyin ikọ Boko Haram, to si tẹnumọ pe sise alabapin iroyin laarin awọn araalu atawọn agbofinro si ni ọna abayọ si aseyọri.
O ti jẹ́ kí àwọn eniyan rẹ ní ọpọlọpọ ìnira,o ti fún wa ní ọtí mu tóbẹ́ẹ̀ tí à ń ta gbọ̀n-ọ́n-gbọ̀n-ọ́n.
Ọmọ náà dá a lóhùn pé, ‘Ó dára, mo gbọ́, Baba!
Iléẹjọ gíga jùlọ da ẹjọ́ SDP àti PDP nù, wọ́n ní Yahaya Bello ló wọlé ìbò gómìnà Kogi Wọ́n ti sún ìdájọ́ àwọn sójà tó pa ìyá àti ọmọ ní ọdun 2018 sí oṣù tó m bọ̀ Ìjà d'ópin, fún ìgbà àkọ́kọ́, bàálù gbéra láti Israel lọ sí UAE Ààrẹ Buhari buwọ́lu gbígbé ìṣàkoso nọ́mbà ìdánimọ̀ (NIMC) lọ sí ẹ̀ka ìjọba tó ń rí sí ìbáraẹnisọ̀rọ̀ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Wo bí Sunday Orimola ṣe gba ikú ẹranko kú ní Ifon ni Ondo lórí ọ̀nà àtijẹ Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Oluwo: Èmi l'ọba lórí òrìṣà, oṣó àti ajẹ́, Olorì tuntun tó ń bọ̀ lẹ́tikẹ31 Ògún 2020 6:18 Fídíò, Natalia Mufutau ìyá Yakub, Kamil àti Adam sọ̀rọ̀ lórí bí wọ́n ń sọ èdè mẹ́rin pàpọ, Duration 6,1831 Ògún 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 3 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 5 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Oríṣun àwòrán, Olori Abibat Adeyemi Ọjọ Kẹtalelogun osu Kejila 1939 ni wọn bi Iya Adodo, ti o si ti ri ọmọ-ọmọ ati arọmọdọmọ rẹ, to si ti pe ọgọta ọdun ti oun ati Ọba Adeyemi ti fẹ ara wọn.
 wọn pe ibẹ ̀ ni Ọba-òkè .
Idi ni pe ti obinrin ba sẹsẹ bimọ, ẹmi ati itọju ara rẹ ni yoo kọkọ du, ọmọ tawọn agbẹbi ba si gbe fun pe o bi naa si ni yoo gbe wale.
Seyi Makinde fojú hàn n'íta lẹ́yìn tó ṣẹ́gun Coronavirus Ilé ẹjọ́ kàn-án nípá fún Wòlíì Sọtítóbirẹ̀ kó tó wọ ilé ẹjọ́ Bí ilumọọka agbabọọlu Drogba ṣe dáwọ ogun dúró ní Ivory Coast Màmá Guardiola d'olóògbé lẹ́yìn tó lùgbàdì Coronavirus Ni aipẹ yii ni awọn olujọsin ni mọṣalaṣi kan ni ilu Eko kọlu awọn oṣiṣẹ ikọ amuṣẹya ti ijọba gbe kalẹ ti wọn wa kan si wọn pe ki wọn pa ofin naa mọ nitori nṣe ni ileejọsin naa kun bamubamu fun awọn to wa kirun.
BBC kan si Adedayọ lati gbọ iha ti ẹ latari ọrọ iyansipo rẹ to gba ori ayelujara kan.
Dọla mọkandinlọgbọn ni wọn n ta agba eporọbi kan bayii, dipo ọgọta Dọla to jẹ l'oṣu Kejila.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Xenophobia: Ọ̀sẹ̀ tó ń bọ̀ ni bàálù yóò lọ kó ọmọ Nàíjíríà wálé 7 Owewe 2019 Oríṣun àwòrán, @FriendsofKashm2 Bi wọn se n ge awọn ọmọ orilẹede South Africa lọwọ ni wọn tun n bọ oruka nitori pe wọn ko dẹkun ikọlu ti wọn n se sawọn ọmọ Naijiria.
Ile ẹjo giga kan nilu Abuja ti gbe lẹyin ile asofin agba lori ipinnu rẹ lati lodi si iyansipo ọgbẹni Magu gẹgẹ bi alaga ajọ to n gbogun ti iwa ibajẹ (EFCC) Ẹẹmeji ni Aarẹ Muhammadu Buhari ti fi orukọ Magu sọwọ si ile asofin agba ti wọn si ti daa pada pe ko yẹ fun ipo alaga ajọ naa.
báyìí ni àrá ọ ̀ run náà ṣe ṣe káàkiri ìlú tí ó sì ń súre fún àwọn ènìyàn .
Tèmi tí n óo dì rù yín yóo tilẹ̀ tún wúwo jù bẹ́ẹ̀ lọ; ati pé ẹgba ni baba mi fi ń nà yín, ṣugbọn àkeekèé ni n óo máa fi ta yín.
Ki lo ṣẹlẹ lọjọ Aje, ọjọ kẹrinla, oṣu kejila, ọdun 2020?
Nígbà tí ó yá, Abrahamu dìde níwájú òkú Sara, ó lọ bá àwọn ará Hiti, ó ní, 
Hasaeli ọba Siria gba gbogbo àwọn agbègbè Israẹli, 
    Èyí obìnrin dára tó bẹ́ẹ̀ gẹ́ẹ́, ó ró aṣọ ìlẹ̀kẹ̀ wẹẹrẹ kò sí ìyàtọ́ láàrin obìnrin yìí àti àwọn ọmọ aráyé bí ko ṣe ahọ́n rẹ̀ tí ó gùn láàrin rékọjá tí ó tayọ ẹnu tí ó sàn sí igbá àyà rẹ̀ títí ó fi kàn án ni ìdodo.
"O) Fagunwa, gẹgẹ bii Diipọ ti se alaye, awọn ohun ti awọn eeyan ko mọ̀ nipa oloogbe naa ree: Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Òkè Idanre rèé tí odidi ìlú kan ló ń gbé lórí ẹ̀ Wo àwọn ìṣẹ̀lẹ̀ tó mú Naira Marley di òrìṣà àkúnlẹ̀bọ ní 2019 Ìdí rèé tí kò ṣe sí iná mọ̀nàmọ́ná láwọn agbègbè kan ní Nàìjíríà Ìgbà Marún-un ti Aisha Buhari ti tako ìjọba Buhari Bi Fagunwa ba sọrọ ifẹ fun obinrin, ko si obinrin to lee kọ lati se tiẹ: Jaaniini dantọ ninu ọrọ sisọ, to ba si kọ ẹnu ifẹ kọ obinrin, ori obinrin naa yoo wu, ti ko si ni lee kọ jalẹ pe oun ko se, bi eyi ko ba ye yin, ẹ wa bi iya to bi mi Bi o ba si foju sun obinrin kan fun ifẹ, ẹ ro pe oun gan wa pẹlu ọba Solomoni ni, lasiko to kọ awọn orin ifẹ rẹ ninu bibeli, ti Fagunwa si maa n waasu ifẹ bii ẹni pe inu aye miran lo n gbe Obinrin kan to lo ẹda lẹta ifẹ ti Iyunade kọ si Ireke Onibudo, to si fi ransẹ si ololufẹ rẹ ni ọkunrin naa fi mọto ayọkẹlẹ ta lọrẹ nitori bi ori rẹ se wu to, isẹ ọwọ Jaaniini naa leyi Ko tan sibẹ o, ọkunrin kan to tun lo ọrọ ifẹ ti Irinkerindo sọ fun Ifẹpataki, lọjọ idana rẹ, ni baba iyawo rẹ tun fun ni obinrin mẹta miran si lati mu ki igbeyawo rẹ tọ suna pẹlu iyawo mẹrin ni ọọdẹ rẹ Bi Fagunwa se se apejuwe ẹwa Ifẹpataki, ko si aniani pe iru obinrin bẹẹ ko si lode aye yii, bẹẹ si ni nigba ti ọkunrin kan ka bi Ifẹpade ti ri ninu iwe Ireke Onibudo, se ni ọkunrin naa yi orukọ rẹ pada si Ireke Onibudo, ki afẹsọna rẹ lee gbagbọ pe oun naa dun ju oyin lọ ""To ba jẹ pe D."
Iwe akosile ti won fi fun Chigumba nise, eyi ti akowe agba fun  aare Mnangagwa ati awon igbimo amusese ko fihan pe, Chigumba yoo bere ise tuntun naa ni kiakia, eyi ti ireti wa pe, won yoo se ibura fun lojo-Bo.
Buhari mórí lé Saudi lẹ́yìn ìbúrawọlé fún sáà kejì Lẹyin iburawọle fun saa keji l'Ọjọru, Aarẹ Muhammadu Buhari mo ri le orilẹ-ede Saudi Arabia lonii Ọjọbọ.
sepanu fun  ikọ agbabọọlu  Burundi lati fi ki iko naa kaabọ sinu idije
N óo rán wolii Elija si yín kí ọjọ́ ńlá OLUWA, tí ó bani lẹ́rù náà tó dé.
9) Fi ara balẹ ṣakiyesi bi batiiri foonu rẹ ṣe n lọ, eyi yoo jẹ ki o maa kiyesi ti o ba ti fẹ ku lainii fi ṣe odiwọn nọmba to gbe soju.
Bi ọrọ naa ba ṣe n lọ ni BBC Yoruba a maa fi too yin leti ni ikannni yii.
 n jé o lè dá àwon omo náà lára yá fún wàkàtí kan.
Wọ́n pe gbogbo àwọn ọmọ-ogun yòókù, 
Ẹ wo ọ̀nà àbáyọ sí ọ̀rọ̀ àgbàlagbà tò ń tọ̀ sílé Obìnrin bíi Ruth Bader ni yóò gba ipò rẹ́ ní iléẹjọ́ tó gajùlọ nílẹ̀ Amerika- Donald Trump Wo bí èsì ìdìbò ìpínlẹ̀ Edo ṣe ń jáde Iléeṣẹ́ ọlọ́pàá ní Kano tí ṣe àyẹ̀wò àwọn 13, 048 tó fẹ́ darapọ̀ mọ́ wọn Wakil ni ileeṣẹ ọlọpaa ati ajọ ajafẹtọ ọmọniyan kan lo lọ wu oku ọmọ naa jade nibi ti o sin si, ti ayẹwo nile iwosan si fihan pe ọmọ naa ti ku.
Jesu pàṣẹ kí àwọn eniyan jókòó nílẹ̀.
Neighbours clash: Ọkùnrin kan kú nítorí pé o fi ẹ̀sùn kan alájọgbélé rẹ̀ pé o n yan ìyàwó ẹnìkan lálè
Bi wọn ṣe gba ife ẹyẹ si lati ibẹrẹ Aaya ti bẹ silẹ ninu idije naa.
Texas shooting: Ọlapàá ní Seth Ator tó pa ọ̀pọ̀ èèyàn ní Texas ṣẹ̀ṣẹ̀ pàdánù iṣẹ́ rẹ̀ ni
Ojú wa lara rẹ pe ko ṣe daada ju isejọba àná lọ, awọn kan si ti n wo o boya yoo le se bẹ ẹ.
Nígbà tí wọ́n lọ sí ibi tí ó fún wọn tán èmi náà dìde mo lọ kí wọn.
Nínú ìfọrọ̀wánilẹ̀núwò kan tí Folarin Falana (Falz) àti Laila Johnson Salami ṣe fún-un, lóri òhun ti yóò ṣe láti mú ǹkan dáradara se tó bna dé ipò ààrẹ.
Ṣugbọn nígbà tí a ṣílẹ̀kùn, tí a wọ inú ilé, a kò rí ẹnìkan.
•Segesege ni eto irinna ofurufu yoo maa se biotilẹjẹpe o wa labẹ isẹ koseemase.
O wa pase fun asofin Azeez Sanni ti o je akowe ile
Ati pé bí àwọn ọmọ Israẹli bá júbà àṣẹ mi, tí wọ́n pa òfin mi, tí Mose, iranṣẹ mi, fún wọn mọ́, n kò ní jẹ́ kí á lé wọn kúrò lórí ilẹ̀ tí mo fún àwọn baba ńlá wọn.
Lẹ́yìn tí àwọn ará ilẹ̀ Juda, ati ìdajì àwọn ọmọ Israẹli ti sin ọba kọjá odò, ọba lọ sí Giligali, Kimhamu sì bá a lọ.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Ilé isẹ́ tó n rí sí ètò ẹ̀kọ́ ni Nàìjíríà ni àwọn kò tíì dá ọjọ́ kankan fún ìwọlé ilé ẹ̀kọ́ jákèjádò orílẹ̀-èdè Nàìjíríà.
Bring back our girls: Obi àwọn ọmọ Chibok 34 ló kú ní ọdún márùn ún
INEC: Èsì ìdìbò Ekiti lẹ́kùnrẹ́rẹ́ Atọmọde ati agba jade fun idibo ni Ekiti Russia 2018: Níbo ni ife ẹ̀yẹ ń doríkọ?
"Ọ̀pọ̀ àwọn ènìyàn ní ìhà àríwa ni ko ri owó yìí gbà, kò yé mí oo bóyà àwọn ènìyàn ìpínlẹ̀ tiyín ri owó náà gbà"" O ní lóòtọ́ ó ṣiṣẹ́ dáada ní àwon ìpínlẹ̀ mìíràn, nítorí oriṣiriṣi ọ̀nà ni wọn gbé e gbà."
Nataniẹli wí fún un pé, “Olùkọ́ni, ìwọ ni ọmọ Ọlọrun, ìwọ ni ọba Israẹli.
Wọn ko gba ọmọ ẹgbẹ tuntun kankan sí ẹgbẹ naa mọ.
Oríṣun àwòrán, Efcc/Facebook Àkọlé àwòrán, Awọn asofin kọ lati yan Magu si ipo Alaga EFCC Ninu alaye wọn, wọn ni iroyin ti awọn ileeṣẹ ọtẹlẹmuye fun awọn nipa Magu lo mu ki awọn ṣe lodi sí iyansipo rẹ.
Arakunrin naa lo n tẹle to si n ka nnkan to n ṣẹlẹ silẹ ki o to di wi pe arakunrin Peter naa ṣa dede yii lojiji to si di igbaju ati igbamu fun un.
Ó ní ìpinu òun láti padà sí ẹgbẹ́ oṣèlú LP jẹyọ látàrí èrèdí láti ṣe àgbéǹde àfojúsùn ńla fún gbàgede òṣèlú Nàìjíríà.
'Ẹ fun mi ni oku abi aaye Shekau' Olori ọmọogun oriilẹ l'orilẹede Naijiria, Tukur Buratai ti rawọ ẹbẹ s'awọn ọmọ ogun orilẹede yi lati gbe Abubakar Shekau, tii se olori igun kan ninu ikọ adunkoko mọni Boko Haram, wa fun oun ni aaye abi ni oku.
Idajọ naa ati ofin Anti-Piracy ti ọdun 2019 tun ti mu ki o rọrun lati fi oju awọn ole ori omi wina ofin ni Naijiria.
Kí ẹ tó bẹ̀rẹ̀ sí fẹsẹ̀ kọ lórí òkè,níbi tí kò sí ìmọ́lẹ̀.
Nítorí náà, ìwọ ọmọ mi, jẹ́ kí oore-ọ̀fẹ́ tí ó wà ninu ìdàpọ̀ pẹlu Kristi Jesu sọ ọ́ di alágbára.
Ọmọ Otedola bú sẹ́kún lẹ́yìn tí Brighton tún d'ẹrù ìyà lé Arsenal lórí Chelsea dun DJ Cuppy nínú lẹ̀yìn tí Arsenal gba omijé lójú rẹ̀ Ògbóǹtarìgì agbábọ́ọ̀lù tẹníísìì Novak Djokovic ti lùgbàdì coronavirus A kò ní fara mọ́ fífi àkókò ṣòfò lórí ẹjọ́ Sotitobire - Ìjọba Ondo Àjọ NCDC kéde ènìyàn 790 tó tún ṣẹ̀ṣẹ̀ ní Coronavirus ní Nàìjíríà Àwọn èèkàn òṣèré Nollywood nìyí pẹ̀lú àmì ohùn èdè Yorùbá Ojú Shagbada Erigga rèé lẹ́yìn tó pa ọ̀rẹ́bìnrin rẹ̀ l'Akinyele ní Ibadan Amọ West Ham ko bẹṣu bẹgba nipele keji ere bọọlu ọhun, lẹyin iṣẹju mẹfa ti ipele keji gberasọ ni Michail Antonio dayo ti Chelsea gba wọle pada.
 Ìlédè agígírì kọjá sí láti lọ múlẹ ̀ tuntun tí ó sì kọ ̀ lé sí ilédè náà ní ibi tí aàfin Ọba ijẹ ̀ bú-jẹ ̀ ṣà wà títí di òní yìí .
Ọmọ ogun Nàìjíríà bẹ̀rẹ̀ lílo 'Drone' láti gbógun tàwọn ajínigbé ni Ondo àti Ekiti Jẹ́ kí a jọ sọ àǹfàní US fún Nàìjíríà -Osinbajo Ta ni olórí ogun Ethiopia, Saere Mekonnen to kú sínú ìdìtẹ̀-gbàjọba?
Muftau ni awọn naa gbọ awuyewuye iroyin naa pe ile ẹjọ giga l'Abuja ti paṣẹ pe ẹgbẹ musulumi Shiite ti di agbesumọmi lati igba yii lọ.
Lero tawọn eeyan yii, wọn ni owo yii ko pọ rara fun ikọọkan ọmọ Naijiria lati san, ka lee fagile gbese ti ilẹ wa jẹ, ka si wa lai ni gbese lọrun, eyi ti yoo fun wa ni anfaani ọtun lati mu ki ọrọ aje wa ru gọgọ si.
Amọ, o fikun wi pe ikọ awọn ọmọ ogun ofurufu, ikọ ọmọogun ilẹ ati ti oju omi gbọdọ fọwọsowọpọ lati koju ikọ Boko Haram to n pa awọn ọmọogun ni agbeegbe Borno.
Ó sì tọrọ ààyè lọ́wọ́ mi pé òun fẹ́ wà pẹlu àwọn ìdílé òun ní àkókò àjọ̀dún náà.
Ijọ naa wa ni agbegbe Azikiwe, opopona Mile 2 Diobu niluu Port Harcourt.
ni eyi  ti ajo  EFCC si ka aworan opolopo omo ile Amerika to
Irú kí ni o ṣe sí wa yìí, tí o kó wa kúrò ní Ijipti?
Alamojuto ileeṣẹ rẹ, lo fi ọrọ naa sita faraye gbọ.
tun tepele mo awon aseyori ti ijoba aare Buhari ti gbe se fun ogunlogo awon omo
Ilé ẹjọ́ kòtẹ́milọ́rùn yá lórí ọ̀rọ̀ Adeleke- PDP Oyè Mọ́gàjí àti Báálẹ̀ ti di owó rèé, ọjà rèé ní Ibadan - Lekan Balogun Orúkọ ọmọ ìgbìmọ̀ ẹlẹ́ni mẹ́wàá rèé tí yóò rí sí ìgbàjọba Seyi Makinde Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ayekofẹnifọrọ: Ó yá, ẹ fi àmì sórí ọ̀rọ̀ náà.
Àwọn ìyókù ki àwọn ẹrú mọ́lẹ̀, wọ́n lù wọ́n pa.
Àkọlé àwòrán, Ibudo ayẹwo fun ikọni nipa itọju ẹranko ni Fasiti Pọta nipinlẹ Rivers Awọn nkan wọnyii ni àwọn olukọ ASUU gba pé o fa iyanṣẹlodi ti awọn gunle, yatọ si ti owo ajẹmọnu ti wọn.
O pe ẹni ọdun mọkandinlọgọrun bayii.
Ìyá àti ọmọ méji tí ọkọ wọ́n dà síta nítórí ǹkan ti kìí ṣe ẹ̀bi wọ́n.
O ṣalaye loju opo Instagram rẹ pe oun yoo pin irẹsi, o ni kawọn eeyan maa pe lori eto Gelede to waye lori ile iṣẹ redio Parrot.
kí àwọn àgbààgbà ati àwọn adájọ́ yín jáde wá, kí wọ́n wọn ilẹ̀ láti ibi tí wọ́n pa ẹni náà sí títí dé gbogbo àwọn ìlú tí ó wà ní àyíká ibẹ̀.
Ẹgbẹ agbabọọlu Amerika ko roo pe awọn ti gbe ife ẹyẹ naa lọ ri lọdun 1991, 1999 ati 2015.
Nígbà tí ó gbọ́ pé wọ́n ti gbé àpótí Ọlọrun lọ, ati pé baba ọkọ rẹ̀ ati ọkọ rẹ̀ ti kú, lẹsẹkẹsẹ ni ó bẹ̀rẹ̀ sí rọbí, tí ó sì bímọ.
Lẹ́yìn ọrọ tí oludári àgbà fun ile iṣẹ to n ri si ọrọ aṣa ati iṣe lorilẹ-ede Naijiria, National Council for Arts and Culture (NCAC), Otunba Olusegun Runsewe ṣe sí Okuneye Idris Olarewaju ti gbogbo ènìyàn mọ si Bobrisky pé òun yóò fi imú rẹ̀ dárin.
0 41 New Caledonia 0 0.
Aye ọmọ wa ko lalafia a si wa ninu ibanujẹ.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Anton Szandor LaVey, lasiko to n sẹ iribọmi fun ọmọ rẹ, ọmọ ọdun mẹta, Zeena Galatea LaVey Dipo riri ọmọ naa sinu omi, ẹnu ọna pẹpẹ ijọ ni ọmọ naa joko si, pẹlu oriṣiriṣi nkan ti ẹnu n jẹ.
''Obinrin naa ni ifẹ ọkọ rẹ to bẹẹ gẹẹ ti o si ni oun gba ki ọkọ oun fẹ iyawo keji.
Amọ, ipinlẹ Cross river nikan ni ko i tii kede pe awọn ni arun Coronavirus ninu gbogbo awọn ipinlẹ to wa lorilẹ-ede Naijiria.
Bakan naa ni fasiti yii ṣeleri lati rii pe ọkan awọn akẹkọọ wọn balẹ pẹlu fifi iya to tọ jẹ awọn ti akẹkọọ ba fẹsun kan ti iwadii si fidiẹ mulẹ.
Ìtọrẹ àánú ni mo mú wá fún àwọn orílẹ̀-èdè mi, kí n sì rúbọ.
Ọ̀rọ̀ tí ó dájú ni ọ̀rọ̀ yìí.
 – I’ve Got To Be Me (USA)
Oríṣun àwòrán, Olu Alebiosu Àkọlé àwòrán, Ọmọbinrin Oduduwa lo tẹdo sibi orisun omi orioke olumirin Ko si ẹni to de ibudo igbafẹ yii ti ko ni fi ara gba afẹfẹ tutu minijọjọ Ẹbun ayika to wuyi jọjọ ni oriosun omi orioke ẹrin Ijẹṣa naa jẹ.
Àwọn kan ninu èrò ń sọ nǹkankan; àwọn mìíràn ń sọ nǹkan mìíràn.
Àkọlé àwòrán, Kàyéèfì ni ilá maa n jẹ́ fún àwọn tí kì í sẹ ọmọ Yorùbá Njẹ ofin faaye gba?
Bakan naa lo kilọ iwa ibajẹ fawọn oṣiṣẹ pe oju gbogbo n wa lara àwọn oṣiṣẹ ti ọwọ wọn ko ba mọ to.
Ó fún ọ̀kọ̀ọ̀kan wọn bí agbára rẹ̀ ti tó; ó bá lọ sí ìdálẹ̀.
N óo wí fun yín pé, odi kò sí mọ́, àwọn tí wọn ń kùn ún lẹ́fun náà kò sì sí mọ́; 
Wọ́n ti ìlẹ̀kùn yàrá àbáwọlé tẹmpili, wọ́n pa fìtílà tí ó wà ní ibi mímọ́, wọn kò sun turari, bẹ́ẹ̀ ni wọn kò rú ẹbọ sísun ní ibi mímọ́ sí Ọlọrun Israẹli.
Ìwẹ̀fà náà sọ fún Filipi pé, “Mo bẹ̀ ọ́, ọ̀rọ̀ ta ni wolii Ọlọrun yìí ń sọ, ọ̀rọ̀ ara rẹ̀ ni tabi ọ̀rọ̀ ẹlòmíràn?
“ ‘O kò gbọdọ̀ yá èrekére kankan fún ara rẹ, kì báà jẹ́ ní àwòrán ohunkohun tí ó wà ní ojú ọ̀run tabi ti ohun tí ó wà lórí ilẹ̀, tabi èyí tí ó wà ninu omi ní abẹ́ ilẹ̀.
Àwọn ni wọ́n kó ilẹ̀ Yorùbá pọ̀ mọ́ àwọn ẹ̀yà míràn bíi àwọn Igbo àti Hausa sí orílẹ̀ kannáà, tí wọ́n sì sọ wá lórúkọ “Nigeria”.
Peter Adeeko helping military widows: Wo bí ọkùnrin ọmọ òrukàn yìí ṣe ń ran àwọn opó tí ọkọ wọn kú sójú ogun lọ́wọ́
Oríṣun àwòrán, others Agbẹjoro naa ni ẹnikẹni to ba gbe ibọn bẹẹ dani yoo foju ba agọ ọlọpaa labẹ ofin Naijiria.
O so pe, ile-ise alabo ati awon akoroyin ni ibasepo ti o gboorin, leyi  ti o sise gege bi eri okan ilu.
Àṣe olè àti apànìyàn wà láàrin wa tó bẹ́ẹ̀!
Tinubu kò ṣékú, kò ṣé ẹyẹ, o n dibọn ní lórí ọ̀rọ̀ ikọ̀ Amotekun - Fani Kayode Ohun tó ti yá kan kìí pẹ́ mọ́, fọ́ọ̀mù ìgbaniṣíṣẹ́ fún Àmọ̀tẹ́kùn dé!
Ọjọ Aje ni iroyin iku agba ọjẹ ninu isẹ tiata naa gbalẹ kan, ẹni ti ọpọ eeyan mọ si Baba Legba.
Amọ ṣa, agbẹnusọ ọlọpaa nilu Kano, DSP Abdullahi Haruna sọ fun BBC pe, awọn ti wọ Sanusi lọ si iwaju adajọ nibi ti yoo ti wi tẹnu rẹ.
Ijoba ipinle Zamfara ti da ile-itoju awon omode ti won ba fipa balopo nipinle naa sile.
Awọn onibara gbudọ ni rọba idaabobo tiwọn bayii tori a o lagbara ati maa pin in lọfẹ mọ, oṣiṣẹ ile itura kan sọ fun BBC Swahili.
Nigba 1980s, ijọba bẹrẹ si ni gbe awọn ajọ kan lọ si El Helicoide.
Orukọ tuntun ti wọn yi opopona naa pada si ni ti olori ẹgbẹ Nation of Islam, Louis Farrakhan.
O leè má mọ̀ bóyá o ní àrùn HIV/AIDS o!
Iwadii naa si lo tan imọlẹ si bi Floyd ṣe ja fitafita fun ẹmi rẹ.
"Mo fẹ rọ awọn eniyan lati lọ ka, iwe ofin Naijiria.
ní ọdún 1922 pinnock ṣa àwọn akẹ ́ kọ ́ tí ó ti ní ìmọ ̀ díẹ ̀ láti ago-owu , ago-ijaye àti oke-saje , tí wọ ́ n sì jẹ ́ àkẹ ́ kọ ́ àkọ ́ kọ ́ ní gírama yìí .
Keyamo sọ̀rọ̀ ọ̀hún nínú ìfọ̀rọ̀wánilẹ́nu wò kan ní ìlú Abuja.
Lara awọn ẹsun ti wọn fi kan Lamorde ni pe, o kọ lati ko owo to to triliọnu meji aabọ, ti ajọ naa gba lọwọ awọn olori to ji i ko, si apo ijọba.
 nínú wọn , the magic flute ni ó gbajúmọ ̀ jù .
Ọrọ bi ijọba ipinlẹ Eko se fofin de ọkada ti n bọna miran yọ pẹlu oniruuru ifẹhonu han to n waye lati tako igbesẹ naa.
Wọ́n ní, “Bí ìwọ bá ni ọba àwọn Juu, gba ara rẹ là.
Ṣaaju asiko lo ti sọ orisirisi ọrọ eyi to tako ohun tawọn akọṣẹmọṣẹ oniṣegun sọ nipa aarun naa.
Bush, ààrẹ Amerika tẹ́lẹ̀ jáde láyé A kò tí ì gbọ́ ǹkankan lórí owó ìwé ìrìnnà sí Naijiria - U.
Nígbà tí Aaroni bá ń rú ẹbọ mímọ́, tí àwọn ọmọ Israẹli ti yà sọ́tọ̀ fún èmi OLUWA, kinní bí àwo pẹrẹsẹ yìí yóo máa wà níwájú orí rẹ̀, kí wọ́n lè jẹ́ ìtẹ́wọ́gbà lọ́dọ̀ mi.
Won dupe lowo Olorun  fun aanu re,won tun gbadura fun itesiwaju orile ede Naijiria.
 O tun kọ “Rasta get jail” ati “Rum-Bar Stylee”.
Ìnáwó rẹpẹtẹ ni ìsìnkú arúgbó jẹ́ ni ilé Yorùbá.
’ Ṣugbọn àyọrísí iṣẹ́ Ọlọrun fihàn pé ọgbọ́n rẹ̀ tọ̀nà.
Muhammadu Buhari ti seleri fun gbogbo omo orile ede Naijria ati awon alabojuto
Kíni ẹ mọ̀ nípa Ọmọ́táyọ̀ Olútóyè, Ọ̀jọ̀gbọ́n obìnrin àkọ́kọ́ nínú ẹkọ́ èdè Yorùbá lágbàyé Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí 2 sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 2:23 Fídíò, Water Generator: Ó leè ṣiṣẹ fún wákàtí mẹfà, kó tó sinmi, Duration 2,2310 Òkùdu 2020 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
Níbo ni olùfẹ́ rẹ lọ,ìwọ, arẹwà jùlọ láàrin àwọn obinrin?
Àwọn ni ó ń lò gẹ́gẹ́ bí ọmọ ogun, ati olórí àwọn òṣìṣẹ́ rẹ̀; àwọn ni balogun rẹ̀, ati àwọn ọ̀gágun rẹ̀; àwọn ni ọ̀gá àwọn tí ń darí kẹ̀kẹ́ ogun rẹ̀ ati àwọn ẹlẹ́ṣin rẹ̀.
Kì í ṣe ẹ̀jẹ̀ ewúrẹ́ tabi ti mààlúù bíkòṣe ẹ̀jẹ̀ ara rẹ̀, ni ó fi rúbọ, nígbà tí ó wọ inú Ibi Mímọ́ jùlọ lọ lẹ́ẹ̀kan ṣoṣo láti ṣe ìràpadà ayérayé fún wa.
Ọba Eshinlokun wa pinnu pe, oun ko ni ko awọn ọmọkunrin oun meji silẹ, to si mu awọn ọmọkunrin meji to wa ni aafin rẹ, eyi-un Oshodi Tapa ati Dada Antonio silẹ fun oyinbo, Oríṣun àwòrán, others O ṣe eyi nitori ọmọ ọlọmọ la n ran nisẹ de toru-toru.
Bí ó ba ń sọ̀rọ̀, ojú rẹ a máa pupa wẹ̀ẹ̀, díẹ̀ díẹ̀ ni ọ̀rọ̀ ẹnu rẹ̀ sì máa ń jáde.
Ninu ohun gbogbo ẹ máa hùwà kí ògo lè jẹ́ ti Ọlọrun nípasẹ̀ Jesu Kristi: òun ni ògo ati agbára jẹ́ tirẹ̀ lae ati laelae.
“Ǹjẹ́ o lè wádìí àwọn ohun ìjìnlẹ̀ nípa Ọlọrun?
,Ẹyin omo orile ede Naijiria tootọ,Ni bayii, asiko ti to fun eto idibo ipele akọkọ ti ajo INEC sun siwaju  di ojo Abameta(Satide), ojo ketalelogun osu
Àwọn ọmọ Lefi nìwọ̀nyí: àwọn ọmọ Jeṣua, tí wọn ń jẹ́ Kadimieli, ní ìdílé Hodefa, jẹ́ mẹrinlelaadọrin.
Ṣe ko si b'ọmọ ṣe dara to ti ko ni ni ọta.
Gbogbo ohun tí ó ní lọ́kàn láti ṣe sí ilé OLUWA ati sí ilé ti ara rẹ̀, ni ó ṣe ní àṣeyọrí.
ati kọ́kàndínlọ́gbọ̀n, osu keta odun yii.
Gombe-54 FCT-35 Lagos-26 Ogun-12 Plateau-10 Rivers-10 Kaduna-4 Ekiti-3 Edo-2 Osun-2 Bayelsa-1 Imo-1 Ondo-1 Oyo-1 Èèyàn 118 ló kó àrùn Coronavirus ní Nàìjíríà lọ́jọ́ Ajé Eniyan 118 lo tun ṣẹṣẹ lugbadi aarun Covid-19 ni Naijiria.
Adewale Akinnuoye-Agbaje: Oríṣun àwòrán, Twitter/Adewale Àkọlé àwòrán, O le so ede Yoruba, Geesi, Italian ati Swahili.
Mercy Aigbe, tii se osere tiata lobinrin naa kesi awọn alawọ dudu lati yee kọju ija si ara wọn nitori iwa ailaju gbaa ni eyi.
Iwé ẹ̀sun mẹ́rìn ló wọlé fun ti ilé ìgbìmọ aṣòfin àgbà, mẹ́jìla ní ti ilé ìgbìmọ àsṣojú sòfin nígbà ti mẹ́ẹ̀dógún jẹ ti ilé ìgbìmọ aṣòfin ti ìpínlẹ̀ Lẹ́yìn ọjọ mọkanlélógun tí wọn ba ti kédé ẹni to jáwe olúbori ni òfin fi lélẹ pe kí ẹni ti èsì ìdìbò kò ba tẹ́lọ́run kó kọ ìwé ẹsun rànṣẹ́, ìròyìn fi yé ni pe ọjọ kọkanlélọgbọ̀n oṣù kẹta ni ó pe ni ọjọ pé.
Gbogbo ibi tí ẹsẹ̀ yín bá tẹ̀ ni mo ti fun yín, gẹ́gẹ́ bí mo ti ṣèlérí fún Mose.
Ninú ilé ìjọsìn lásìkò tó lọ kàwé níbẹ̀ ni iṣẹlẹ yii ṣẹlẹ ti wọ́n sì tún pa á sibẹ̀.
Wọ́n gbé àwọn ère wọn, tí ó jẹ́ ohun ìríra fun mi sinu ilé tí à ń fi orúkọ mi pè, kí wọ́n lè sọ ọ́ di ibi àìmọ́.
Ẹkọ ti itan igbe aye Ọrẹdẹin kọ wa: Ẹkọ akọkọ ni pe ka maa jẹ ki ohun ti a ni tẹ wa lọrun, a ko gbọdọ ru ẹran erin sori, ka tun maa fi ẹsẹ wa irẹ Itan yii tun kọ wa lati sọra se nitori ilẹ n yọ, bi aye ba n yẹ wa loni, ka maa huwa ibajẹ A tun ri kọ pe ipokipo taa ba wa, paapa awọn ọlspa, ka maa sọra, tori asegbe kankan ko si, asepamọ lo wa A tun ri kọ pe ko si ẹni ti Ọlọrun ọba ko lee mu afi eyi ti ko ba setan lati mu.
Ìwọ ni Ọlọrun mi,n óo máa gbé ọ ga.
Nígbàkúùgbà tí ọba bá ń lọ sinu ilé OLUWA, àwọn ẹ̀ṣọ́ á gbé apata náà tẹ̀lé e, wọn á sì dá wọn pada sinu ilé ìṣúra lọ́dọ̀ àwọn ẹ̀ṣọ́.
N kò ní buwọ́ lu ìṣúná tí kò pèsè owó fún ẹ̀bí àwọn tó kú nínú ìwọ́de EndSARS - Gbajabiamila Tẹ́ bá fẹ́ lo ìwọ́de láti gba àkóso ìjọba, wọn yóò dá yín lẹ́kun - Tinubu Ẹ ràn wá lọ́wọ́ láti rí àwọn ẹlẹ́wọ̀n tó sálọ ní Oko àti Benin padà"" Ọ̀pọ̀ aráàlú ló ti pàdánù ọwọ́ àti ẹsẹ wọn sọ́wọ́ jàǹdùkú - Sanwo-Olu Iroyin sọ pe iwọde naa n lọ wọọrọwọ ki awọn janduku kan to jaagba ti wọn si bẹrẹ si nii ju okuta ati igo si agọ ọlọpaa naa."
Awon toro kan gbongbon miiran tun ni, minisita to n ri si oro ile okere, Geoffrey Onyeama, minisita to n ri si ohun ipese omi, Suleiman Adamu, ati minisita to n mojuto oro ayika nipinle, Ibrahim Jibrin.
Àwọtẹ́lẹ̀ ọkùnrin àti Ìdọ̀tí Kilo méje ṣekú pa Ìgalà Ẹ wo iye t'óúnjẹ dà báyìí lọ́jà lẹ́yìn tí ìjọba ti ibodè Ajọ INEC wa rọ awọn eniyan lati jade wa dibo fun ẹni ti wọn fẹ lai si ifoya tabi ipaya.
Bakan naa ni Aṣofin Abiodun Tobun dabaa pe itọju awọn alarun ọpọlọ yẹ ko jẹ ọfẹ nitori  ko sẹni to gbadura fun iru aisan bẹẹ, “yoo dara bi wọn ba le ṣeranwọ fun awọn ẹbi wọn lati gbe bukata yii.
Oríṣun àwòrán, Tribune Newspaper Bakan naa lo sọ pe awọn eeyan yoo maa ṣe iranti mama Oyediran gẹgẹ bi ẹnikan to tẹ le awọn ilana ti Oloye Awolowo la kalẹ titi to fi ku.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Boko Haram gbọ̀nà àrà yọ, kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ ló so àdó olóró mọ̀ láti kọlu Gómìnà Borno Ìṣòro jíjẹ́ ìyá n dáàgbé ló sọ mí di àtúnbí krístíẹ́nì - Remi Tinubu Kí ló ń fa wàhálà láàrín Kunle Afolayan àti Mike Ezuruonye lórí ayélujára?
Ooni ile Ifẹ, Oba Adeyeye Enitan Ogunwusi ti muleri ṣẹ lori adehun to ṣe pe oun yoo sọ ọmọ rẹ tuntun lorukọ Ooni to ṣaaju rẹ .
Bí àwọn ọmọ rẹ bá pa majẹmu mi mọ́,tí wọ́n sì tẹ̀lé ìlànà tí n óo fi lélẹ̀ fún wọn,àwọn ọmọ tiwọn náà óo jókòó lórí ìtẹ́ rẹ títí lae.
lorile ede Naijiria, Alhaji Lai Muhammed ti ni igbimo ijoba apapo si duro ni
Agbẹnusọ naa ṣalaye pe Ile Igbimọ Aṣofin yii ti sapa ni gidi fun idagbasoke ipinlẹ yii ati lati wà ni irẹpọ awọn ara ilu.
Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí 6:48 Fídíò, Akomolede ati Aṣa lori BBC:Wo ìrúfẹ́ ìgbeyàwó méje tó wà nílẹ̀ Yorùbá àti ojúṣe Alárinà, Duration 6,4810 Bélú 2020 5:55 Fídíò, Soyinka Cancer: Àṣe ara mi ni iso ti n run gbogbo bí mo ṣe n ṣèrànwọ́ lórí jẹjẹrẹ, Duration 5,5527 Bélú 2019 Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí 2 sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 2:23 Fídíò, Water Generator: Ó leè ṣiṣẹ fún wákàtí mẹfà, kó tó sinmi, Duration 2,2310 Òkùdu 2020 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
Agbábọ́ọ̀lù Super Falcons tẹ́lẹ̀, Chiejine jáde láyé lẹ́ni ọdún 36 Leon van Biljon dí èrò ọrun nípasẹ̀ Kìnìún rẹ̀ Ta ni Ọjọgbọn Adebanji Akintoye tó borí Tinubu láti di olórí àwọn Yoruba?
Wọn fi kun un pe ọdọmọde to mu eroja ado oloro naa dani nigba to bu ku lẹsẹkẹsẹ, ṣugbọn wọn ti gbe wọn lọ si ileewosan ijọba ni Mubi.
O ni awọn fi aaye gbawọn lati da duro,bakan naa ni awọn fayegba ibaṣepo to dan mọran laarin ẹka naa ati ẹka eleto aabo to ku ni ipinlẹ mẹfa ni iwọ oorun Naijiria.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù #EndViolenceAgainstWomen: Àwọn àmì mẹ́fà tó ń sàfihàn ọkùnrin tó ń hùwà ipá!
Ni àsikò ọdún, ọ̀pọ̀lọpọ̀ ma nfi oúnjẹ  àjẹ jù àti ọti à mu para yọ ayọ̀ ọdún.
Ìlérí tí Ọlọrun ti ṣe kò lè torí rẹ̀ di òfo.
Àwọn igi igbó yóo kọrin ayọ̀níwájú OLUWA, nítorí ó wá láti ṣe ìdájọ́ ayé.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Àǹfàní ńlá ni àṣẹ ìgbélé jẹ́ fún àyíká ọmọnìyàn pàápàá nílùú Eko Eeyan bi ọgọrun lo ni aarun naa lọwọlọwọ ni Gombe.
OAU fẹ́ wádìí olùkọ́ tó fẹ́ bá akẹ́kọ̀ọ́ lò fún máákì Ìjọba Ọ̀sun ti OAU pa nítorí owó orí òsìsẹ́ Igbimọ to n mojuto awọn ileeṣẹ iroyin ninu ọgba ileewe naa, jabọ loju opo ayelujara rẹ pe wọn fi nkan gun akẹkọọ kan to jẹ oludari ere idaraya fun awọn akẹkọọ imọ ẹrọ, Oyeniyi Tobi.
Akintola kọkọ di ipo oludamọran lori ọrọ ofin ẹgbẹ naa mu ko to di igbakeji adari ẹgbẹ oṣelu AG lọdun 1953 lẹyin iku Bode Thomas.
Ni ọpọlọpọ awọn ipinlẹ, oludije to ba ti ni ibo araalu to pọ julọ ni ọpọ awọn ipinlẹ ni yoo ko gbogbo ibo awọn ọmọ igbimọ agbaọjẹ oludibo alaṣẹ nibẹ.
Àwọn ìròyìn mìíràn tí ẹ lè nífẹ̀ẹ́ sí: Mọ̀ nípa adelé adájọ́ àgbà tuntun, Ibrahim Tanko Muhammed Ṣé INEC yóò tún ìwé ìdìbò tẹ̀ nítorí Banky W?
Amọ awọn alaṣẹ ajọ CAF ti jẹ ko di mimọ pe ikede orilẹede tuntun ti yoo gbalejo idije naa yoo waye titi ọjọ kọkanlelọgbọn oṣu kejila ọdun 2018.
Àwọn iranṣẹ rẹ̀ yóo máa sìn ín.
Awon ibomiran tun ni ibudo ọkọ
N óo jẹ òun, ati àwọn ọmọ rẹ̀, ati àwọn ẹmẹ̀wà rẹ̀ níyà, nítorí ẹ̀ṣẹ̀ wọn.
Èèyàn mẹ́fà míràn tún ti ní àrùn Coronavirus ní Naijiria Iṣẹ́ bẹ̀rẹ̀!
Ṣugbọn n óo bá Olodumare sọ̀rọ̀,Ọlọrun ni mo sì fẹ́ bá rojọ́.
Ọlọrun ní, “Máa gbé ilẹ̀ yìí, n óo wà pẹlu rẹ, n óo sì bukun ọ, nítorí ìwọ ati àwọn ọmọ rẹ ni n óo fún ní ilẹ̀ wọnyi, n óo sì mú ìlérí mi fún Abrahamu, baba rẹ ṣẹ.
Nigerian Senators deaths: Àwọn sẹ́nẹ́tọ̀ mẹ́rin tó jáde láyé ní Nàìjíríà láàrin oṣù mẹ́fà sẹ́yìn rèé
Ninu atejade kan ti oluranlowo pataki si aare lori eto iroyin , ogbeni Shehu Garba, gbe jade O so pe “Aare se ipade ranpe pelu dokita re lasiko idaduro fun atunse baalu oko ofurufu nilu London lakoko to n bo lati ilu Washinton, eleyi ti dokita si so fun aare lati pada wa fun itoju ilera ara re”Shehu fikun un oro re pe, Aare yoo  pada wa si orile ede Naijiria  ni Ojo kejila osu karun un odun ti a wa yii.
Egbe oselu to n sejoba lorile-ede naa ti yan minisita  teleri fun oro ile okere, omowe Samura Camara lati dije labe egbe oselu naa.
Nígbà tí àwọn Juu pésẹ̀, Pilatu bi wọ́n pé, “Ta ni kí n dá sílẹ̀ fun yín, Jesu Baraba ni tabi Jesu tí ó ń jẹ́ Mesaya?
Gẹ́gẹ́ bí Ìwé Mímọ́ ti sọ nípa Mose, “Nígbàkúùgbà tí ó bá yipada sí Oluwa, a mú aṣọ kúrò lójú.
O ni, “mo ki Ọba ku oriire, Kabiyesi, Olowo Eko, ẹni ti o ti kopa ribiribi fun idagbasoke ati aabo ipinlẹ yii, ẹni ti o jẹ akinkanju Ọba, ti kii fi igba kan bọkan ninu”.
je ki eto idibo waye ni gbogbo ipinle jake-jado lorile ede Naijiria.
Atẹjade Basir Ahmad lori ẹrọ Twitta wi bayi pe: Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ọwọ ọlọpa ti tẹ 'were' to sa ọmọ meji pa nipinlẹ Ogun 15 Ẹrẹ̀nà 2018 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Afunrasi alangana naa na papa bora lẹyin to pa awọn ọmọde meji ki ọwọ awọn ọlọpa to tẹẹ Ọwọ ọlọpa ti tẹ ọkunrin alangana kan to pa ọmọ meji nileewe alakọbẹrẹ kan ni ipinlẹ Ogun.
Ẹ̀rù ń bà mí pẹ̀lú àwọn ìròyìn tí mò ń gbọ́ nípa lílé tí wọ́n ń lé àwọn ọmọ ní ilé-ẹ̀kọ́ àti bí wọ́n ṣe ń tì wọ́n mọ́lé nítorí ìkọkúkọ tí wọ́n kọ sórí àwòrán Ààrẹ nínú àwọn ìwé ìkọ́ni.
Agege keji, ti o ni ni ẹgbẹrun mọkandinlogun-le-ọrinlenirinwo ati mẹsan-an
Ọba gbé adé lé e lórí, ó sì fi ṣe ayaba dípò Faṣiti.
Ẹ̀yin Marlians, ṣẹ mọ̀ pé Naira Marley kìí ṣe aláàbọ̀ ẹ̀kọ́, ó kàwé jáde ní fásitì?
Ohun ti a gbọ ni pe awọn kan ni wọn fi oogun oloro naa sinu ẹru rẹ ati pe ko si mọ nipa rẹ titi ti wọn fi mu u ni Saudi.
Lọjọ ti Baraka ku naa ni wọn sinku rẹ ni ilana ẹsin Islam.
"Ọgbẹni Kampondeni tun sọ pe"" O gbagbọ pe isejọba ti wo lulẹ ni Malawi, ti ko si ṣe ojuse yii, lati ọdun mẹẹdọgbọn sẹyin."
Nígbà tí ó tó bíi wakati mẹta lẹ́yìn náà, iyawo Anania wọlé dé.
Ọmọ Oba Adeleke, ọkan ninu awọn ọmọ ti Kabiesi to waja fi silẹ lọ naa ṣalaye iru eeyan ti baba rẹ jẹ fun BBC Yoruba pe oninuure to fẹran ara ilu to n jọba le lori ni.
Aláapọn ni bàbá mi í ṣe, ọkùnrin ju ọkùnrin lọ, Olówó-ayé pọ̀ lọ́kùnrin, ni ọjọ́ tí bàbá mi múra igbó ọdẹ yìí tán, tí o di àti pínyà pẹ̀lú àwọn ìbátan gbogbo, gọngọ sọ ní ilé wa: àwọn oníṣègùn péjọ sí yàrá àwwọn ọdẹ aperin péjọ sí ọ̀ọ̀dẹ̀m àwọn ọmọdé sá gun òkè àjà lọ, onírúurú ènìyàn ni ń bẹ lẹ́hìn kùlé, ewúrẹ́ sáré ewúrẹ́ kọjá ìloro, obìnrin ń sọkún, ọkùnrin ń sọkún, gbájúmọ̀ kò le sọ̀rọ̀, bọ̀ọ̀kìnní fajúro.
Nígbà tí a bá ṣẹgun wọn, wọn yóo rí ìrànlọ́wọ́ díẹ̀ gbà, ọpọlọpọ yóo sì faramọ́ wọn pẹlu ẹ̀tàn.
Àwọn agbébọn tún gbìyànjú láti gbé akẹ́kọ̀ọ́ ilé Keu 80 ní Katsina Buhari, pàṣẹ fún Pantami kó lọ tọwọ́ ọmọ rẹ̀ bọ aṣọ lórí ìforúkọsílẹ̀ NIN-SERAP Báwo ni mo ṣe fẹ́ fi ìyàwó àfẹ́sọ́nà mi akáta hàn fáwọn òbí mi?
O ni aare Muhammadu Buhari seleri lati ma wu iwa aparo kan .
yii, ni eyi to jẹ pe aabo to peye ko si nibẹ.
"Awọn iroyin ti ẹ lee nifẹẹ si: Eku ba oko ìrẹ́sì jẹ́ ni Kebbi Buhari: Ẹ fira yin jin fun idagbasoke orilẹede Naijiria ""O yẹ kawọn agbẹ maa lo akoko yi lati fi palẹ oko mọ silẹ fun ọgbin ni, kii se lati maa gbin ire oko lakoko yi."
"Awọn asaaju awujọ wa ti ebi n pa gan wa, ni kete ti wọn ba ni inawo kan lati se, wọn yoo maa tọrọ maalu lọwọ awọn darandaran yii, ti wọn yoo si fi ọpọ eeka ilẹ wọn jirọ fun maalu kan.
6 Àti nísisìyí, kíyèsíi, mo wí fún ọ, pé ohun kan tí yíó níye lórí jùlọ fún ọ ni lati kéde ìrònúpìwàdà fún àwọn ènìyàn yìí, kí ìwọ baà lè mú àwọn ọkàn wá sí ọ̀dọ̀ mi, kí ìwọ ó lè sínmi pẹ̀lú wọn ní ìjọba Bàbá mi.
28 Àti pé nísisìyí, àyàfi bí òun bá rẹ ara rẹ̀ sílẹ̀, tí òun sì jẹ́wọ́ fún mi àwọn ohun tí ó ti ṣe tí kò dára, àti kí ó dá májẹ̀mú pẹ̀lú mi pé òun yíò pa àwọn òfin mi mọ́, àti pé òun yíò lo ìgbàgbọ́ nínú mi, kíyèsíi, mo wí fún un, òun kì yíò ní irú ìran bẹ́ẹ̀, nítorí èmi kì yíò fi fún un lati wo awọn ohun náà nipa èyítí mo ti sọ̀rọ̀.
àwọn tí ń wí pé,“Ẹnu wa yìí ni a óo fi ṣẹgun,àwa la ni ẹnu wa; ta ni ó lè mú wa?
Ní alẹ́ ọjọ́ náà, Saulu rán àwọn iranṣẹ kan láti máa ṣọ́ ilé Dafidi kí wọ́n lè pa á ní òwúrọ̀ ọjọ́ keji.
“Bí ẹnìkan bá ta ọmọ rẹ̀ obinrin lẹ́rú, ẹrubinrin yìí kò ní jáde bí ẹrukunrin.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Amosun ṣọ̀fọ̀ Adesanya ọ̀rẹ́ tímọ́tímọ́ rẹ̀ l'Abẹokuta 23 Èrèlè 2019 Àkọlé àwòrán, Ọfọ nla ṣe nipinlẹ Ogun lọna Kọbapẹ Akọwe àgba fún ipinlẹ Ogun, Taiwo Adeoluwa àti Ogbeni Adesanya ti gbogbo eniyan mọ si 'ọrẹ gomina' ni ijamba ọkọ loju ọna Kọbapẹ nitosi Abẹokuta nipinlẹ Ogun.
Gideoni dá a lóhùn, ó ní “Jọ̀wọ́, oluwa mi, bí OLUWA bá wà pẹlu wa, kí ló dé tí gbogbo nǹkan wọnyi fi ń ṣẹlẹ̀ sí wa?
Wọ́n to àwọn òpó, tí wọ́n kọ́ ilé yìí lé lórí, ní ìlà mẹta.
 fáfitì odùduwà ń kọ ́ àwọn akẹ ́ kọ ̀ ọ ́ wọn ní ẹ ̀ kọ ́ ìmọ ̀ ìjìnlẹ ̀ jákè-jádò àgbọ ́ ọ ̀ n-gbẹ ìmọ ̀ lóeíṣiríṣi.
Ènìyàn mẹ́jọ kú lẹ́yìn tí Ọkùnrin kan dáná sun ẹbí ọ̀rẹ́bìnrin rẹ̀ tó l'óun kò ṣe mọ́ Iṣẹ́ àkànṣe tí kò parí ni Buhari ń bọ̀ wá ṣí l‘Eko - Aráàlú figbe ta ‘Ẹbu ‘Sim Card’ ti jẹ́ kí ìjínigbé pọ̀si ní Naijiria’ Faduyile ni owo ni awọn oloselu mọ ni wọn se n faramọ ki awọn dokita ma a lọ si oke okun, amọ o ni ohun to buru ni ki awọn eniyan ma ni eto ẹkọ to peye lorilẹede naa.
“Mo ké pe àwọn alajọṣepọ mi,ṣugbọn títàn ni wọ́n tàn mí;àwọn alufaa ati àwọn àgbààgbà mi ṣègbé láàrin ìlú,níbi tí wọn ti ń wá oúnjẹ kiri,tí wọn óo jẹ, kí wọn lè lágbára
Nigba to n sọ ọna to gba pade ọkọ rẹ ati iha to kọ si iṣẹ tiata to n ṣe, gbajumọ oṣere tiata naa ni, inu sinima kan ni ọkọ oun ti ri oun.
Oríṣun àwòrán, @IsaacFAdewole Àkọlé àwòrán, Inu awọn oṣiṣẹ NHIS ko dun si bi ọga agba ajọ naa ko ṣe tẹle aṣẹ lọ rọọ kun nile ti wọn fun un Ọjọgbọn Usman Yusuf ni ko si ohun ikọkọ kan laarin ohun ati aarẹ ati pe ilana ofin ni aarẹ n tẹlẹ eleyi to fidi rẹ mulẹ wi pe igbimọ tabi minisita ko lee yọ oun bi ko ṣe aarẹ.
Wọ́n sọ fún mi pé, “Dìde!
AfricanDrumFestival: Abẹ́òkúta gbàlejò èrò fún àjọ̀dùn ìlù
Nítorí a kò gbọdọ̀ da ara wa mọ́ àwọn kan tí wọn ń yin ara wọn, tabi kí á fara wé wọn.
Oríṣun àwòrán, thesolaallyson Àkọlé àwòrán, Ẹ o rii pe ẹrin gbajugbaja olorin Sola Allyson lekan sii lọjọ ogbo?
pé, abẹ́rẹ́ lásán, n kò ní fọwọ́ mi kàn ninu ohun tí ó jẹ́ tìrẹ, kí o má baà sọ pé ìwọ ni o sọ mí di ọlọ́rọ̀.
lati fi bọ awon eniyan naa fun osu kan gbako.
Bakan naa, ni won yoo tun fi oye da enikeji ti oun ati  MKO Abiola jo  n  dije papo lasiko igba naa , iyen Babagana Kingibe ni oye igbakeji olori iko awon omo ologun orile ede Naijiria( the second highest honour of the Grand Commander of the Niger, GCON).
Bí ó bá bá àwọn Juu jiyàn níwájú gbogbo àwùjọ, a máa borí wọn, kedere ni ó ń fihàn láti inú Ìwé Mímọ́ pé Jesu ni Mesaya.
O ni eyi yoo ṣeeṣe fun awọn nitori pe 'akọṣẹmọṣẹ ninu imọ nipa igbokegbodo ọkọ ofurufu ni gbogbo awọn.
A lè sọ pé nígbà tí Abrahamu san ìdámẹ́wàá, Lefi tí ń gba ìdámẹ́wàá náà san ìdámẹ́wàá, 
Ìwádìí ni ní kété tí àdán bá ti rii pé òun ṣe àìsàn ní yóò ti ya ara rẹ̀ sọ́tọ̀ kúrò láàrín àwọn tó kù kìí àìsàn náà má ba tànkálẹ̀.
Bayern Munich gbo ewuro si iko agbaboolu Besiktas loju ninu ifigagbaga idije UEFA Champions League, pelu am-ayo meta sookan(3-1).
Femi Adebayo ni ará ìta ti fẹnu kò mí lẹ́nu rí lójú ìyàwó mi láti mọ rírì àwọn fíìmù mi ti mo n ṣe""."
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Kwara Commissioners: Àgùnbánirọ̀ obìnrin, ẹni ọdún mẹ́rìndínlọ́gbọ̀n di kọmíṣọ́nnà ní Kwara 13 Ọ̀pẹ̀̀ 2019 Oríṣun àwòrán, Facebook/Abdulrahaman Abdulrasaq Gomina ipinlẹ Kwara, Alhaji Adulrahman Abdulrazaq kede awọn kọmiṣọnna tuntun lẹyin oṣu mẹfa ati aabọ ti wọn ṣe ibura fun un gẹgẹ bi gomina ipinlẹ naa.
Calabar Prison: Ẹlẹ́wọ̀n bí ìbejì làǹtì lànti!
O ni ẹ̀wọ̀n gbere ni oun n fẹ ki wọn o ju Lee ati ẹnikeji rẹ si i.
Koda, àwọn oloṣelu nla bi i oloogbe Adelabu Adegoke 'Penkelemesi' fi ṣe ibugbe nigba aye rẹ, ile rẹ ṣi wa nibẹ titi di oni.
Nígbà tí àwọn eniyan náà rí i pé Mose ń pẹ́ jù lórí òkè, wọ́n kó ara wọn jọ, wọ́n tọ Aaroni lọ; wọ́n sọ fún un pé, “Ṣe oriṣa kan fún wa, tí yóo máa ṣáájú wa lọ; nítorí pé, a kò mọ ohun tí ó ṣẹlẹ̀ sí Mose tí ó kó wa wá láti ilẹ̀ Ijipti.
Ṣugbọn OLUWA wà pẹlu Josẹfu, ó sì fi ìfẹ́ rẹ̀ tí kìí yẹ̀ hàn sí i, ó jẹ́ kí ó bá ojurere alabojuto ọgbà ẹ̀wọ̀n náà pàdé.
Ààrùn Coronavirus tún ti ran ènìyàn 571 l'órílẹ̀-èdè Nàìjíríà Nigeria Police recruitment 2020: Bàyìí ni o ṣe leè di ọlọ́pàá Nàìjíríà Ipinlẹ Eko ni aarun coronavirus ti pọ ju lorilẹede Naijiria, eeyan to le lẹgbẹrun mejila lo laarun naa nipinlẹ nikan ninu ẹgbẹrun mejilelọgbọn eeyan to ni covid-19 ni Naijiria.
Charlie: La Vie Magnifique Charlie (USA)
Aso Rock: Idi ti eku fi wa ni ile ijọba apapọ Kíni ọ̀nà àbáyọ sí àìsàn Lassa Fever?
Oríṣun àwòrán, twitter/ Gombe PHEOC Gẹgẹ bi atẹjade kan ti ijọba ipinlẹ Gombe fi sita loju opo twitter rẹ, akẹkọo naa ti wọn ko darukọ rẹ joko ṣe idanwo iṣiro ti alamojuto rẹ si duro ninu aṣọ idaabobo lọwọ arun naa.
'Oúnjẹ tí Tinubu àti Ọṣinbajo n jẹ ni wọ́n ṣe n ṣe ti Buhari' Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí 2 sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 2:23 Fídíò, Water Generator: Ó leè ṣiṣẹ fún wákàtí mẹfà, kó tó sinmi, Duration 2,2310 Òkùdu 2020 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
"Oríṣun àwòrán, Seyi Makinde ""O ti pe ọdun kan ti mo gba akoso ipinlẹ Oyo, asiko ka sere yatọ, asiko ijiyin iṣẹ iriju ẹni si yatọ pẹlu, ọdun 2023 si ni maa jiyin iṣẹ iriju mi ni ẹkunrẹrẹ, sugbọn ko to di igba naa, o yẹ ka mọ ibi ti a ti n bọ, ka lee mọ baa ṣe ṣe aseyọri si."
Osise ile-ejo kan lorile-ede Egypt so pe, awon alatileyin metalelogbon egbe Muslim Brotherhood ti won fofin de lorile-ede Egypt  ni won ti da olokan-o-jokan ewon fun lojo-Aiku, bere latori ewon odun meje si ewon gbere, latari laasigbo ti o be sile nibi ifehonu-han ti o waye nilu Cairo lodun 2014.
O ni idi naa jẹ lati kapa awọn kọlọrọsi ti yoo lo ọrọ ikorira lati da orilẹ-ede Naijiria ru.
O ni eyi yoo fi aaye gba kata-kara.
Wọn wa lara awọn to kọkọ ṣe abẹwo si Arẹmọ tuntun ati Iya rẹ, Olori Naomi Silẹkunọla ni ileewosan nla naa.
Wọn yóo máa jọba ní ayé.
Aarọ kutu ọjọ Aje ni a gbọ pe awọn ọlọpaa ya bo ofiisi adajọ agba naa, lẹyin ọjọ mẹta ti Aarẹ Muhammadu Buhari ni ko lo fidi mọ 'le.
O si yẹ ki wọn maa lo agbara wọn fi mu ilọsiwaju alailẹgbẹ ba agbegbe wọn.
Eniyan kò lè máa gbé inú ọlá rẹ̀ títí ayé;bí ẹranko tíí kú, ni òun náà óo ku.
O se pataki lati kọ awon saare oku ti wọn o kọ akọle bii Allahu Akbar, Allahu Akbar, La'ilaha illalLah Allahu Akbar, Allahu Akbar walillahil hamdu sii Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Saudi Arabia Hajj 2020: Alaga Hajj ni Naijiria ni inú wọn kò dùn sí bí Hajj kò ṣe ní wáyé.
''Ọdun keji re to n lo lọwọ.
Mo sì ti mọ̀ lọ́kàn ara mi pé, ọ̀rọ̀ tí kabiyesi bá sọ fún mi yóo fi mí lọ́kàn balẹ̀ nítorí pé, ọba dàbí angẹli Ọlọrun tí ó mọ ìyàtọ̀ láàrin ire ati ibi.
Ọmọ ilé-ìwé tí kò ṣe dáadáa nínú ìdánwò lónìí, bí ó bá múra ọjọ́ ń bọ̀ tí yóò tún ṣe dáadáa tí ayọ̀ yóó bo ìbànújẹ́ mọ́lẹ̀ batakun.
Yubulọsi kí ọ, ati Pudẹsi, Linọsi, Kilaudia ati gbogbo àwọn arakunrin.
Ọjọ yii ni pẹpẹyẹ pọnmọ, ti Oba Samuel Ladapọ Ademọla kejì kọwe fipo rẹ silẹ ni Ẹ̀gbá.
2019 Supplementary election:PDP ní kí INEC wọ́gi lé àtúndì ìbó Kano nítorí ìwà jàǹdùkú Àkọlé àwòrán, Iṣẹ̀lẹ̀ tó wáyé ni ìjọba ìbílẹ̀ Dala Alága ẹgbẹ oṣèlú PDP ní ìpínlẹ̀ Kano, Rabiu Bichi ti ni ó ṣe pàtàkì kí àjọ elétò ìdìbò wọ́gilé àtúndi ìbò tó wáye lọjọ́ sátide, ọjọ kẹtàlélógun, ọdun 2019 nítori àwọn àwọn jàndùkú to fọ́nka ìgbòro ti kò si fún ọ̀pọ̀ láàyè láti dìbò.
Ikede yi n waye lẹyin ti eeyan ẹlẹkẹfa gba ti ọwọ aisan yi ku ta si gbọ pe baba agbalagba ẹni ọdun ọgọrin lẹni to ku kẹyin.
Ǹjẹ́ mo lè ni Coronavirus nípa fífi owó kan nkan obinrjn/ọkùnrin enikeji mi.
 Àwọn orílẹ ̀ èdè kan fọwọ ́ si níwọ ̀ nba fún àwọn ọmọdé àti fún àwọn tí ó wà léwu gidi tí akòití fún ní oogùn rẹ .
Bakan naa o tun ti ṣiṣẹ ni Banki apapọ ilẹ Afirika o si tun ṣi ile iṣ kan ti wọn ti n ṣe oriṣiriṣi iṣẹ Pako ni ilu Kaduna.
Lẹ́yìn ikú Mose, iranṣẹ OLUWA, OLUWA sọ fún Joṣua, ọmọ Nuni, olùrànlọ́wọ́ Mose pé, 
Pupo ninu awon omo Igbimo asoju-asofin ti orile ede South Afrika lo ti  sagbateru iwe abadofin ekunwo fun awon osise ijoba orile ede naa, ni eyi to je pe aare Cyril Ramaphosa gbe lo sile igbimo asofin.
egbe oselu All Progressives Congress, APC ti o waye niluu Abakaliki, ti n se
Ninu iwe to kọ si agbẹjọro agba ICC, Fatou Bensouda, o ni ki ile ẹjọ naa pe aṣoju ijọba Naijiria lati wa jẹjọ lori ẹsun ifẹmi awọn oluwọde ṣofo.
Obasanjo ko si aare Muhammadu Buhari je iru eyi ti awon oloselu ,ti won ko mọ
OLUWA sì jẹ́ kí wọ́n bá ojurere àwọn ará Ijipti pàdé, gbogbo ohun tí wọ́n tọrọ pátá ni àwọn ará Ijipti fún wọn.
Oríṣun àwòrán, Alaafin_oyo O ni o ṣeeṣe ko jẹ lasiko irinajo naa ni Alaafin ti n yofẹ fun oun, nitori pe oun fakọyọ nibẹ nipaṣẹ awọn ibeere ti oun n beere lọwọ baba.
Nígbà tí OLUWA Ọlọrun yín bá mú yín dé ilẹ̀ tí ẹ̀ ń wọ̀ lọ, tí ẹ óo sì gbà, ẹ kéde ibukun náà lórí òkè Gerisimu, kí ẹ sì kéde ègún náà lórí òkè Ebali.
Bí mo ti jí lọ́jọ́ kejì mo ti yára ké sí Inúlayéwà mo ní, ‘Mo ti lá àlá mìíràn, a ti jà, a ti jà, lójú àlá’.
Saraki pín owó ìyọ̀nda rẹ̀ fún ẹbí Leah Sharibu àtàwọn míì Onnoghen k'ọ̀wé ìfẹ́yìntì, Buhari tẹ́wọ́ gbà á Ọjọ́ tí inú mi bàjẹ́ jùlọ gẹ́gẹ́ bíi ààrẹ ilé aṣòfin àgbà-Saraki Gómìnà ìpínlẹ̀ Osun wọgilé ìrìnàjò àwọn alága sí UAE Dokita Jibrin Abdulmumini to jẹ oludari ipolongo ibo fun Gbajabianmila lo fọrọ naa lede lẹyin ipade to waye laarin awọn alatilẹyin Gbajabiamila ati oun funra rẹ l'Abuja.
Iroyin ni, ikọlu aadọrun (90) ni awọn gende agbebọn se nigbati ikọlu awọn aso ado iku mọra jẹ mọkandinlọgọta (59).
” Nipa ohun ti eeyan le ṣe lati gbadun ọjọ rẹ titi dalẹ, mama agba naa ni ohun kinni ni ki eeyan ma ṣe atojubọ, ko si gba ọlọrun gbọ.
Àìsàn Hesekaya Ọba, ati Ìwòsàn Rẹ̀.
Àwọn akọrin, àwọn aṣọ́nà ati àwọn òṣìṣẹ́ tẹmpili ń gbé àwọn ìlú tí ó wà nítòsí wọn, àwọn ọmọ Israẹli yòókù sì ń gbé àwọn ìlú wọn.
Lara wọn ni Gomina ipinlẹ Kano to wa ninu ẹgbẹ oselu APC to ni awọn mọ riri eto Almajiri ti aarẹ Jonathan gbe kalẹ lati koju ipenija awọn ọmọ Almajiri ti ko ri ẹkọ to peye gba.
Mile 2 Bridge Loop, Amuwo-Odofin, Ijọba ibilẹ Amuwo-Odofin 14.
“Ìwọ ọmọ eniyan, bá àwọn eniyan rẹ sọ̀rọ̀.
Asán ni gbogbo ohun tí ó wà níwájú wọn.
Aloku Ọlọ́pàá ni mí nítorínáà mo mọ̀ nípa àbò dáadáa.
Agboole Ajimobi ni adugbo Ọja Ọba nilu Ibadan, tii ṣe olu ilu ipinlẹ Oyo, ni Abiola ti jade wá.
 o tun ipo kinni gba fun igba karun ni ojo 2 osu kokanla 2009 .
Kódà, àwọn agbófinró ń yẹ ara àwọn èrò àti ọlọkada wo pẹ̀lú ẹ̀rọ, kí wọ́n tó kọjá, tí wọn sì n da àwọn ọlọkọ tó bá lòdì sí òfin pada.
Fún àpẹrẹ, Femi Fani Kayode ni aṣiṣe nla ni Ọbasanjọ ṣe ti kò sọ Buhari sẹwọn lori kiko owo PTF jẹ.
Minisita fun oro ise ati ipese ise lorile ede Naijiria, Chris Nigige ti ni ojo Aiku yii ni ijiroro yoo tun tesiwaju nipa  ekunwo owo osu awon osise lorile ede Naijiria, ni ofiisi  akowe agba fun ijoba apapo.
PDP: Ọ̀tẹ̀ tó pa wọ́n pọ̀ náà ló ń tu wọ́n ka
"Mo ti kawe kawe, o ti ṣu mi.
fesun kan orile-ede Amerika fun dida oro naa lona ti o to.
Coro wà Coro ò sí o, èmi á lọ́ sókè òkún bí mo bá ríṣẹ́ - dókítà A fura pé ejò lọ́wọ́ nínú ikú Tolu Arotile, ẹ ṣe ìwádìí ikú rẹ̀ - Afenifere, Gani Adams, Huriwa Ohun tí o kò mọ̀ nípa Ebila One Million Boys"" àti Ekugbemi, olórí ẹgbẹ́ òkùnkùn méjì tó da ìlú Ibadan rú Kò tán síbẹ̀ o, àwọn òṣèrè tíátà míràn tún ṣe ayẹyẹ ọjọ́ ìbí wọn l'ọ́sẹ̀ yìí."
O maa n waye lẹyin ti awọn onigbagbọ ba pari aawẹ ogoji ọjọ ti wọn n pe ni 'Lenth' Kaakiri agbaye ni awọn eniyan ti maa n gba isinmi ọdun Ajinde Jesu yii.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Lagos-Ibadan road: Ọkọ̀ agbépo tó gbiná ní Ibafo dá súnkẹrẹ fàkẹrẹ sílẹ̀ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Lagos-Ibadan road: Ọkọ̀ agbépo tó gbiná ní Ibafo dá súnkẹrẹ fàkẹrẹ sílẹ̀ 4 Owewe 2019 Ọkọ agbepo tun to gbina ni Ibafo loju popo ilu Eko si Ibadan ti da sunkẹrẹ fakẹrẹ ọkọ silẹ loju titi naa.
 ni ojo 3 osu keje 2010 , o di eni kefa lori akojo awon oludijeakoko olokikijulo gbogbo igba lailai .
Rí ẹni tí ó gbé owó ṣùgbọ́n òun kò rí ojú rẹ̀ tí òun fi ta jí.
” Mohammed  ni ijoba apapo ti n sa gbogbo ipa re lati rii pe
Rehoboamu fi ìdí ìjọba rẹ̀ múlẹ̀ ní Jerusalẹmu, agbára rẹ̀ sì pọ̀ sí i.
Ṣugbọn ara rẹ̀ ni ó ń sọ̀rọ̀ bá, tí ó pè ní Tẹmpili.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Idi kẹta tun ni ti iye eeyan to wa nilẹ̀ Adulawọ ti wọ́n ki i fi bẹẹ ko arugbo wọn sile itọju lọtọ: Ọ̀pọ awọn arugbo nilẹ Adulawọ ni awọn ẹbi wọn maa n tọju wọn ninu ile wọn lai gbe wọn sile itọju arugbo.
Alukoro ọlọpàá ipinlẹ Cross Rivers, DSP Irene Ugbo, fìdi ọ̀rọ̀ náà múlẹ̀ pé lootọ ni isẹlẹ naa waye, bi ko tilẹ̀ sọ ọ̀rọ̀ míràn kún alaye rẹ mọ.
Ó bá fi wọ́n sílẹ̀, ó pada lọ gbadura ní ẹẹkẹta; ó tún sọ nǹkankan náà.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Pneumonia in Nigeria: Ó kéré tán ọmọdé 142,000 sí 160,000 ní àìsàn otútú àyà ń pa lọ́dọọdún ní Nàìjíríà 12 Bélú 2020 Oríṣun àwòrán, Getty Images Ileeṣẹ ẹka ijọba to n risi ọrọ eto ilera lorilẹede Naijiria ti ni o kere tan ọmọde ti ọjọ ori wọn ko i ti pe ọdun marun un ni aisan otutu aya n mulọ ni ọgọọro.
Àì ní àkọsílẹ̀ tó pójú owó lórí òdinwọ̀n èròjà codeine tí wọ́n n lò.
Ọba bá bèèrè lọ́wọ́ mi pé, “Kí ni ohun tí o wá fẹ́?
kaasa ninu isele ijamba ile riri ti o gba emi eniyan marun un, leyin  irufe isele naa ti o waye lodun kan seyin.
Alaga Ajọ Hajj ni Naijiria, Alhaji Zikrullah Hassan ti ni ọpọlọpọ awọn to yẹ ki wọn lọ fun Hajj lọdun yii ni inu wọn kodun lẹyin ti ijọba ilẹ Saudi gbegile Hajj ọdun 2020.
" nítorí náà "" aéré eó "" yóò dípò "" ahéré owó ""."
O ni asiko ti to ki ijọba Naijiria wagbo dẹkun fun iru ikọlu yii lori awọn eniyan rẹ kaakiri agabye paapaa ni south Africa.
It Rains on Ouga – Burkina Faso
Oludamọran pataki si Aarẹ Buhari, Femi Adesina lo fi ọrọ naa lede loju opo Twitter lọjọ Ẹti.
NURTW l‘Abuja yóò kàn sí Makinde láìpẹ́ lórí bó ṣe fòfin dè wá l‘Ọyọ - Ejiogbe Lẹ́yìn ọdún mẹ́wàá, Tokyo àti Auxillary ṣèpàdé bòńkẹ́lẹ́ Kíni N11trn owó ìrànwọ́ epo tí ìjọba àpapọ̀ san fún àwọn agbépo lè rà?
'Tattoo’ ara mi kò tí ì pọ̀ tó, mà á sì se si’ Ẹgbẹ òsèlú alátakò gba ilé asojú-sòfin lọ́wọ́ Trump Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, ASUU Strike: Bí àwọn kan se dunnú, làwọn kan fajúro Ninu atẹjade naa Aarẹ Buhari ko sọ pato boya oun yoo buwọlu ẹgbẹrun lọna ọgbọn Naira ti awọn oṣiṣẹ n bere fun.
O ni iran Yoruba kii ṣe ẹṣin inu iwe ti ko lee ta o, o kan n fẹ ki agbaye mọ awọn to tẹ ọka rẹ niru naa ni ki ọka to ja pada.
Ajọ alaanu to npese iranwọ omi sọ wipe ọkan ninu awọn ọmọ mẹsan lagbaye ni ko ni anfaani lati ri omi t'o see mu lagbegbe wọn ati pe ọkan ninu eeyan mẹta ni ko ni ile igbọnsẹ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Sotitobire: Ọkọ mi kò mọ̀ Jegede PDP rí, kódà kò fa ẹnikẹ́ni kalẹ̀ dípò Akeredolu- Bisola Ṣugbọn agbẹjọro Mallet sọ fun ileẹjọ pe onibara oun kii ṣe onijagidijagan.
Nítorí ó wà ní àkọsílẹ̀ pé, “Ègbé ni fún gbogbo ẹni tí kò bá máa ṣe ohun gbogbo tí a kọ sinu ìwé òfin.
Gẹgẹ bi wọn ṣe sọ, awọn foonu to ni eroja iOS nikan lanfani naa ṣi silẹ fun.
Olori Mujidat naa kii pariwo amọ ojuse rẹ ni aafin Ọyọ ko se fi sere rara.
Sùgbọ́n kò wúlò fún àwọn tí wan bá ti wà ni ẹsẹ̀ kan ayé ẹsẹ̀ kan ọ̀ọ̀rún, mímú àdínku bá ara sísàn kò wúlò mọ Òògùn Dexamethasone máá n fa gbogbo kòkòrò tó bá wà nínú àra jáde tí yóò sì fún ara lókun A kò tíì fi ìdí ẹ̀ múlẹ̀ pé ògùn Dexamethsaone ń ṣiṣẹ́ fún àrùn coronavirus- WHO Dexamethsaone tablets: Àjọ NCDC ní kò tíì sí ìfìdímúlẹ̀ pé Dexamethsaone ń ṣiṣẹ́ fún coronavirus Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Awọn onimọ sayẹnsi ni Ilẹ Gẹẹsi ti fi lede pe oogun Dexamethasone n ṣiṣẹ koju ajakalẹ arun Coronavirus.
Ọmọbinrin náà dáhùn pé, “Omi nìyí, oluwa mi.
Gígùn ìyẹ́ mejeeji Kerubu keji náà jẹ́ igbọnwọ mẹ́wàá.
ṣe àwa ti rò pé àwọn ẹranko bii kìnìhúnm ẹkun, ìkookò, erin àti àwọn alágbára gbogbo ni yóò wà níwájú ogun, ṣùgbọ̀n kò rí bẹ́ẹ̀ rárá.
Abineri tọ àwọn àgbààgbà Israẹli lọ, ó ní, “Ó pẹ́ tí ẹ ti fẹ́ kí Dafidi jẹ́ ọba yín.
Iru iyansipo yii kii ṣe nkan ti oju ko riri ni Ariwa orilẹ-ede Naijiria, nitori pe wọn ni i ni ipinlẹ Kano.
Guinea-Bissau, Madagascar, Burundi, Benin, South Africa, Kenya, DR Congo,
Ìwọ ni gbogbo àwọn tí ó wà lórí ilẹ̀ ayé gbẹ́kẹ̀lé,ati àwọn tí wọn wà lórí omi òkun ní ọ̀nà jíjìn réré.
Agọ̀ ni ìbẹ̀rẹ̀ ọ̀rọ̀ ẹnu rẹ̀,wèrè sì ni ìparí rẹ̀.
Ẹ̀yin yìí ni ẹ gba òfin Ọlọrun láti ọwọ́ àwọn angẹli, ṣugbọn ẹ kò pa òfin náà mọ́.
isaac folorunsho adewole ( bíi may 5 , 1954 ) jẹ ́ Ọ ̀ jògbọ ́ dókítà olóyún ọmọ orílẹ ̀ èdè nàìjíríà lati ẹ ̀ yà yorùbá .
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Naira Marley: Ilé ẹjọ́ sún ìgbẹ́jọ́ Naira Marley lórí ẹ̀sún jìbìtì 22 Ọ̀wàrà 2019 Oríṣun àwòrán, @officialEFCC Àkọlé àwòrán, Naira Marley sọ fun ile ẹjọ pe oun ko jẹbi gbogbo ẹsunti EFCC fi kan oun Ile ẹjọ giga kan nilu Eko ti sun igbejọ Azzez Fashola, ti apele rẹ n jẹ Naira Maley, si ọla ode yii.
Idi si ree to fi rọrun fun wa lati maa gbe aye wa lonii lai ranti ohun to sẹlẹ lanaa.
Bẹ́ẹ̀náàni àwọn àgbẹ̀ míràn ṣẹ ọ̀nà tí ó gba ọkọ̀ ṣùgbọ́ n wọ́ n ṣẹ ìlèkùn-ẹranòjẹ sí ẹnu àwọn ọ̀ nà wọ̀ nyìí tí wọ́n wà ní títì ní gbogboògbà tí wọn kò sí ní lílò.
Olori Channel ni awijare ti Kabiyesi Oluwo fun oun ni pe Ọbalaye loun, gẹgẹ bi aṣa ati iṣẹṣe, oun lanfani lati fẹ iye obinrin to ba wu oun.
Wọn gba pe ẹgbẹ oṣelu Democrats to ni ibo miliọnu mọkanlelọgọrin o le ẹgbẹrun lọna ọọdunrun, (81.
Akanse adura naa yoo waye saaju eto isinku nile oloogbe to kalẹ si Oluwo Nla ni agbegbe Baṣọrun nilu Ibadan.
Ẹgbẹ oselu APC ni apapọ ibo to jẹ 197,459 nigbati PDP ni 178,115.
Coronavirus: Kí ni àwọn àpẹrẹ àrùn náà?
Iwọde ọhun ti wọn pe akọle rẹ ni #DaysOfRage abi #Revolution now ni awọn ẹlẹgbẹjẹgbẹ ajafẹtọ ẹni n lewaju rẹ, labẹ akoso oludije fun ipo aarẹ tẹlẹ, Ọmọyẹle Soworẹ, ti yoo si gbera ni aago mẹsan aarọ.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Buhari wa ẹnu si àwọn ọdọ Nàìjíríà Barbara Bush jáde láyé INEC dá òsìsẹ́ lẹ́kọ̀ọ́ láti yọ Melaye Àwọn ọmọ Nàíjíríà kò kà mìí kún mọ́ - IBB Amọ, ipò adari naa kii ṣe oye idile ti wọn ma n gbe fun ẹni ti oye idile kan, iyẹn Ọmọọba Ilẹ Wales, lẹyin iku Ọbabinrin naa.
bí mo bá fi ẹ̀ṣẹ̀ mi pamọ́ fún eniyan,tí mo sì dé àìdára mi mọ́ra,
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Sogidi Lake: Ṣọ́jà tó dẹ́jàá láti pa ẹja odò Sogidi pàdánù ọmọ mẹ́ta láàrín ọ̀sẹ̀ kan -Ojedele Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Sogidi Lake: Ṣọ́jà tó dẹ́jàá láti pa ẹja odò Sogidi pàdánù ọmọ mẹ́ta láàrín ọ̀sẹ̀ kan -Ojedele 14 Òkùdu 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 30 Ẹrẹ̀nà 2020 Ilu Aáwẹ́ ni ìpínlẹ̀ Oyo ni guusu Naijiria ni irinajo gbe BBC Yoruba de bayii.
Èyí tí ń jẹ́ Ohola ni Samaria, èyí tí ń jẹ́ Oholiba ni Jerusalẹmu.
Ilé oníròyìn orí-ayélujára kan ti ṣe àtẹ̀jáde àbájáde ìwádìí tí ó jinlẹ̀ nípa àìkáràmáìsìkí ìjọba lóríi àwọn ilé àjogúnbá àti àwọn alẹ́nulọ́rọ̀ tí ó ń gbìyànjú láti da àwọn ilé tí ó kù wó:
Ireti wa pe, bi ifehonu-han onile-gbele  waye, bi ajafeto omo eniyan ori ero ayelujara Jawar Mohammed, se pe fun igbese naa lori ero ayelujara re.
Àkọlé àwòrán, Awọn ọlọpa meji tun fara gbọta ninu ijamba ipaniyan yi Isẹlẹ yi sokunfa bi awọn onisowo asọ ni agbegbe naa ati awọn eleto ọrọ aje gbogbo se palẹmọ mọ lọgan ti wọn si tilẹkun ṣọọbu wọn.
Egbe oselu APC ni apapo ibo (308,984 votes), ti egbe oselu PDP si ni, apapo ibo (138,184 votes)Ajo INEC so di mimo wipe, won fagile awon ibo miran lataari aisamulo ero idibo ti ajo ohun pese fun lilo.
Ẹwẹ, Dokita Chinedu ti fasiti Nsukka ni lilọ ile igbọnsẹ ṣe koko lati fun lẹẹkan tabi ẹẹmeji loojọ.
Òfin lè má mọ ògùn ṣùgbọ́n èmí gbàgbọ́ pé ǹkan wà nídìí bí wọ́n ṣe pa ọmọ mi - Baba Favour N30,000 ni mo gbà fún orí, ọwọ́ àti ẹran ara wòlíì Bosede - Kayeefi Oyinlọla Olalere, iya Danafojura sọrọ lori itan eegun naa ati igbagbọ awọn eniyan nipa eegun naa pe o n gbọ adura awọn eniyan.
DOLE 121 ati 192 pelu ajọsepọ awon to farajin lati gbogun ti iko Boko
Ẹ jọ̀wọ́, ẹ dárí ẹ̀ṣẹ̀ mi jì mí, ẹ bá mi bẹ OLUWA Ọlọrun yín ní ẹ̀ẹ̀kan ṣoṣo péré yìí, kí ó jọ̀wọ́ mú ikú yìí kúrò lọ́dọ̀ mi.
Oríṣun àwòrán, Instagram Àkọlé àwòrán, Lola Margeret to kopa ribiribi ninu ere ‘Bisola Aremu’ ni wọn fi panpẹ ọba mu ni orilẹ-ede Amerika wi pe o lu jibiti owo, amọ wọn fi i silẹ ni ọdun 2018, ti wọn si da a pada wa si Naijiria.
Aare Buhari so pe ; “o je iyalenu fun mi nigba ti mo gbo pe
Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Ganduje: No be me release dis third video - Jaafar Jaafar31 Ọ̀wàrà 2018 Ganduje Video: Jafaar Jafaar don ready to help Kano lawmakers19 Ọ̀wàrà 2018 Trans Amadi Mosque: Wike say Rivers goment no demolish anything26 Ògún 2019 Ganduje videos make oda senators dey yab me - Rabiu Kwankwaso28 Bélú 2018 Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Nítorí náà, dandan ni kí òun alára jọ àwọn arakunrin rẹ̀ ní gbogbo ọ̀nà, kí ó lè jẹ́ Olórí Alufaa tí ó láàánú, tí ó sì ṣe é gbójú lé nígbà tí ó bá ń ṣe iṣẹ́ rẹ̀ níwájú Ọlọrun fún ìdáríjì ẹ̀ṣẹ̀ àwọn eniyan.
Mika fi ọdọmọkunrin náà jẹ alufaa, ó sì ń gbé ilé Mika.
” Ó fi idà rẹ̀ pa ọọdunrun eniyan, nípa bẹ́ẹ̀, ó di olókìkí láàrin wọn.
O tó gẹ́; A kò fẹ́ ìwòkuwò mọ́ ní Nàijíríà- Runsewe (NCAC) Òṣùká kékeré kò rẹrùn àgbà, orílẹ́èdè Nàìjíríà ṣòro púpọ̀ láti darí - Ibrahim Babangida Ijọba tí júwọlẹ̀ fún Amẹrika lóri iwé ìrìna!
Ọwọ́ ọlọ́pàá tún tẹ afurasí tó fipá bá odi àti adití lòpọ̀ nílùú Ibadan Saaju la ti mu iroyin wa fun yin pe ileesẹ ọlọpaa nipinlẹ Oyo ti kede pe oun ko sinmi nidi ṣíṣe awari awọn to pa Barakat Bello ati Azeezat Somuyiwa.
Oríṣun àwòrán, @DeeOneAyekooto Àkọlé àwòrán, Ààrẹ Muhammadu Buhari Gẹgẹ bi Colonel, Buhari lọ si ile iwe girama US Army ni Carlisle ni Pennyslvania nibi ti o ti gba oye oni ipele keji Masters Degree ninu ẹkọ Stategic Studies.
Koda wọn ni iya kan ati ọmọbinrin rẹ, ti wọn wa ninu kẹkẹ Maruwa ni ọta ibọn seesi ba, ti wọn si jẹ Ọlọrun nipe.
 o ni odun marun ati orinle ruigba ojo lati yipo kilomita 34.
O ò fi mí lé ọ̀tá lọ́wọ́,o sì ti fi ẹsẹ̀ mi lé ilẹ̀ tí ó tẹ́jú.
Ìgbín ní èmi àti ìyá mi máa ń he kiri, ká tó lee jẹun - Lizzy Anjọrin Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí 2 sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 2:23 Fídíò, Water Generator: Ó leè ṣiṣẹ fún wákàtí mẹfà, kó tó sinmi, Duration 2,2310 Òkùdu 2020 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
2 106280 Orilẹede Denmark 918 16.
Oxford English Dictionary: Ọ̀rọ̀ 28 túntun ti wọ́n fi kún-un lọ́dun 2020 Inú ìbànújẹ́ ni mo wà lórí ikú alága CAN tí àwọn Boko Haram pa- Buhari Ọ̀gá ọlọ́pàá tó wà ní 'Check Point' kàgbákò ikú òjijì lọ́wọ́ awakọ̀ l'Eko Ara gbígbóná, èébì, ara ríro, àti àwọn àpẹẹrẹ mìrán tí ibà Lassa máá n fihàn Apẹẹrẹ ti aisan Lassa maa n fihan lara ẹni to ba ni i Ara gbígbóná, èébì, ara ríro, àti àwọn àpẹẹrẹ mìrán tí ibà Lassa máá n fihàn Ninu atẹjade kan ti BBC Yoruba ni anfaani si lori itakun agbaye ajọ naa, fihan pe: Awọn apẹẹrẹ ati ami ti aisan naa kọkọ maa n fihan kọkọ maa n ri bi ti awọn aisan bi iba.
Ișẹ́ tó wù mí bí ișẹ́ à ń mẹ́fun ò sí.
Nigba to n salaye fawọn ọlọpaa lori ohun to ri lọbẹ, to fi waru sọwọ, Taiwo ni wọn ni ki oun lọ pa iya oun ki oun lee ni owo sii ni.
Oríṣun àwòrán, Alaafin of Oyo Lẹta Alaafin naa, to jẹ oju ewe mẹta, ti oun gan funra rẹ buwọlu, lo salaye nipa aawọ to n jẹ laarin igbimọ lọbslọba nipinlẹ Ekiti ati gomina gan funra.
Nítorí náà, orúkọ wa la fi máa dá ara ẹni mọ̀.
Judasi Iskariotu, ọ̀kan ninu àwọn ọmọ-ẹ̀yìn mejila, bá lọ sí ọ̀dọ̀ àwọn olórí alufaa, ó lọ fi Jesu lé wọn lọ́wọ́.
Ighalo soro saaju ifigagbaga olorejore ti won yoo gba pelu England, ”England ni awon agbaboolu ti o dara pupo, bee si ni,  a ni i foju tenbelu won rara .
'Ikọwe-fiposilẹ' Aarẹ South Africa acob Zuma Kinni iroyin naa?
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Sugar: Ilé ìwòsàn UCH ló dákẹ́ sí torí ọgbẹ́ ọta ìbọn 10 Ẹrẹ̀nà 2019 Oríṣun àwòrán, Temitope Sugar Ọmọ agboole Efungade-Onigbodogi, Alafara Oje ni ijọba ibilẹ Ibadan North East ni ipinlẹ Ọyọ, ni Ọlatoye Temitọpẹ ti ọpọ mọ si Sugar.
Haralds Gabrans, a to wa lati orile-ede Latvia ni o nira fun oun lati gba pe bi nkan yoo ti se maa ri ree ati pe yoo to ọsẹ meloo kan ti o to dopin.
mojuto eto aabo lorile-ede Naijiria, Tukur Gusau “O je ohun ti o yanilenu, ti o si buru
8 5774 Orilẹede ajikistan 87 1.
Iyawo Aarẹ Ilẹ Faranse, Brigitte Macron to jẹ olukọ rẹ Emmanuel Macron nigbati aarẹ naa wa ni ọmọ ọdun marundinlogun (15) , fi ọdun mẹrindinlogun (24) ju ọkọ rẹ lọ.
Saulu dáhùn pé, “Mo ti ṣe ibi, máa bọ̀ Dafidi, ọmọ mi.
Ilẹ̀ yìí yóo sì máa jẹ́ ìní yín pẹlu àṣẹ OLUWA.
Bi awọn eroja yii ba n jẹ iṣẹ kọja ala, wọn le ṣe akoba fun awọn eroja ara yoku, ara idi si niyi ti awọn arun coronavirus lee mu iku dani.
lori rẹ lẹyin ti wọn ti baba ṣepade ori ayelujara.
Ilésanmí àti Ọlọ́fin-íntótó sọ nípa ara wọn pé àwọn mọ ilẹ̀ tẹ̀ múyẹ́ (Ẹ rántí pé iṣẹ́ ọ̀tẹlẹ̀lmúyẹ́ ni wọ́n ń ṣe).
áyìí nim ọkùnrin náà wí, mo sì ń fẹ́ bá a sọ̀rọ̀ ki n túbọ̀ wádìí nípa nǹkan tí o sọ, ṣùgbọ́n, wéré ló kọjú kò dúró mọ.
N óo fa idà mi yọ,ọwọ́ mi ni n óo sì fi pa wọ́n run.
O ni ki wọn lepa ifẹ, alaafia àti iṣokan fun ogo Naijiria lapapọ.
Lóru ìjẹta mọ́jú àná ni mo dé si ìhín, àti ìgbà tí mo ti dé ni a sì ti bẹ̀rẹ̀ iṣẹ́, iṣẹ́ la fi gbogbo àná ṣe, a ṣiṣẹ́ títí ilẹ̀ fi ṣu ni èyí kò sì fún ni láyè àti jáde rárá, bí kò bá sí bẹ́ẹ̀ ni, a bá ti fi ẹsẹ̀ ba púpọ̀ nínú ilé yín.
Ṣaaju ni NCDC ti sọ pe arun Covid-19 ti rapala wọ ipinlẹ Kogi, ṣugbọn ijọba ipinlẹ naa ni ko si ohun to jọ bẹẹ, eyi si ti n fa họwuhọwu laarin ajọ naa ati ijọba ipinlẹ ọhun.
Gẹ́gẹ́ bi ó ṣe sọ yíyàn àwọn ọlọpaa lọ si bẹ̀ jẹ àfikun àwọn to ti wà níbẹ̀ tẹ́lẹ̀ lójúnà àti mú ki ètò aabo dájú le wa fún ẹmi àti ohun ìní àwọn ènìyàn nibi ìdìbò tó ń lọ lọ́wọ́ Lóri awuyewuye pé wọn mú kọmisọ́na fun iṣẹ́ àkanṣe Muktar Ishiaq, agbẹnusọ ọlọpàá sọ pé irá to jìnà sí òòtọ́ ni àti pé òun kò ti gbọ́ ǹkan to jọ bẹ́ẹ̀.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Online Slave Market: Wo ìlú tí wọ́n tí ta ọmọdé àti obìnrin ṣe káràtátà lórí ayélujára Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Online Slave Market: Wo ìlú tí wọ́n tí ta ọmọdé àti obìnrin ṣe káràtátà lórí ayélujára 10 Bélú 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 9 Òkùdu 2020 Ara mee riri, mo rori ologbo latẹ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Kid boxer: Ọmọọba 'The Buzz' Larbie rèé, ọmọ ọdún méje tó ń fi ẹ̀ṣẹ́ dá bírà Ọgbẹni Akinrinola fikun ọrọ rẹ pe, gbogbo awọn ileeṣẹ ati eeyan ti wọn ṣeranwọ kan ta bi omiiran fun ile iwosan UCH, ni ile iwosan naa maa n fi lede lori ayelujara.
"Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Kí ìjọ mi ní Sagamu le gbòòrò ni mo fi ń ṣiṣẹ́ ajínigbé pawó - Pásítọ̀ Àwa àti fijilanté pẹ̀lú ọdẹ́ ìbílẹ̀ ló dojú kọ adigunjalè ní First Bank Okeho - Iléeṣẹ́ ọlọ́pàá Ìtàn ọba Yorùbá tí wọn yẹgi fún torí ó jí ọmọ gbé ṣe ètùtù Ẹ káàbọ̀ sọ́jọ́ Arafat, tí Ọlọ́run yóò fi ààwẹ̀ Mùsùlùmí pa ẹ̀ṣẹ̀ wọn rẹ́ ""Ọmọ mi kò tíì mọ̀ pé òun ti di ìlúmọ̀ọ́ká, ó ń wádìí bó ṣe ń rí ara rẹ̀ lórí ayélujára"" Boko Haram da ìbọn bo ọkọ̀ gómìnà Borno, ẹ̀ṣọ́ àláàbò rẹ̀ farapa Lara ohun ti wọn mẹnuba ni ẹran dindin, ounjẹ ọdun, owo ọdun ati asọ ọdun."
Saulu ba sọ fún ọdọmọkunrin tí ń ru ihamọra rẹ̀ pé, “Fa idà rẹ yọ, kí o sì gún mi pa, kí àwọn aláìkọlà ará Filistia má baà fi mi ṣẹ̀sín.
Ipo ti àwọn ohun eelo ikẹkọọ wa ni wọn gba pe ko dara tó.
Ni ọjọ ti wọn ba gbe oro naa, awọn obinrin kii jade titi oorun yoo fi wọ ni awọn ọjọ wọnyii.
Ọ̀wọ́ngógó epo bẹntirò: NNPC ni 'ìròyìn ẹlẹ́jẹ̀' ni
Gomina ipinle Ekiti ti won sese bura fun, Kayode Fayemi wa lara awon gomina ti won jo se ipade po pelu igbakeji aare orile ede Naijiria ojogbon Yemi Osinbajo, ti o je alaga ipade igbimo to n ri si eto oro aje , (National Economic Council ,NEC) ni eyi to waye ni ojoBo.
"òòsà bóò le gbè mi fimi sí bóo se bámi, bí ààrẹ o bá le wá ojúùtú sí ìpànìyàn láti ọwọ́ àwọn darandaran tí wọn ń fẹ̀mi àwọn eniyan sòfò láì rí ìdíwọ kankan'' Bí ààrẹ ò bá le dáàbò ẹmi àwọn ará ìlú, ó túmọ̀ sí pe kò yẹ lẹ́ni to yẹ ko máa darí orílẹ̀-èdè"" Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Àwọn Bísọ̀ọ̀bù ìjọ Kátólíìkì ṣe ìwọ́de Nínú ọ̀rọ̀ rẹ akọwé ẹgbẹ ọhún Fada Evaristus Bassey tó bá BBC sọ̀rọ̀ sàlàyé pé ojúṣe ìjọba ní lati sààbò bo ará ìlú bótilẹ̀ jẹ́ pé ìjọba ń gbìyàjú síbẹ̀, kò sí ojúùtú sí ìsòrò."
Dárúkọ àwọn tọ ń gbaṣẹ́ lọ́wọ́ NDDC tàbí kí o fojú winá òfin- Gbajabiamila sọ̀kò ọ̀rọ̀ sí Akpabio Isa Funtua, Abba Kyari àti Zulaihat Buhari jẹ́ àwọn tó súnmọ́ Aàrẹ tó papòdà láìpẹ́ Ọkùnrin kan pa ara rẹ̀ sínú ọgbà àjọ TRACE tó n mójútọ ìrìnnà ọkọ̀ nípìnlẹ̀ Ogun Wo àwọn tí Pondei fara jọ pẹ̀lú ààrẹ̀ níwájú ijẹ́jọ́ Ṣé lootọ ni àwọn Agba ẹgbẹ ṣe atilẹyin fún oludije kan?
O fi ẹsun kan ijọba pe, awọn gan an lo ko awọn tọọgi wọ inu iwọde naa, bi o tilẹ jẹ wi pe ijọba ti ṣalape lọpọ igba pe, ko sootọ kan ninu ọrọ bẹẹ.
Bákan náa ní òfin gbá ilé ìgbìmọ asofin láàye láti wádìí àwọn alaga ijoba ibilé tí ìwà jégujdujẹra ba wáye láàrin wọ́n.
Ẹgbẹgbẹ̀rún ọmọ Nàìjíríà ní yóò má a kú lójoojúmọ́ tí wọn bá gbà wọ́n láàyè láti gbébọn dání- Amofin Ogun Àgbẹ́kọ̀yà, ẹ̀kọ́ wo ló yẹ́ kí àwá ọ̀dọ́ kọ́ níbẹ̀?
 Èyí bi a mọ ̀ sí ọdún ìsinlẹ ̀ baba ẹni .
gbígba àjẹsára fún ààbò lọ ́ wọ ́ ọ ̀ fìnkì bẹ ̀ rẹ ̀ ní àwọn ọdún 1930 , nígbàtí wíwà fún lílò gbogbogbò ní ilẹ ̀ amẹ ́ ríkà bẹ ̀ rẹ ̀ ní ọdún 1945 .
"Ta ba wo iriri to ni lẹnu isẹ ọba ati ti aladani, ati bo se fi tọkan tara sisẹ fun aarẹ tẹlẹ, Barrack Obama, Adeyẹmọ nikan lo kunju osunwọn lati se amusẹ awọn afojusun ajọ yii, ti yoo fi de ibi giga.
Bí a bá wà láàyè, Oluwa ni a wà láàyè fún.
Ṣugbọn Remilekun ni ko si eyi to kan pada si oun ri.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó Gomina ko ṣai rọ awọn eeyan ipinlẹ Oyo lati maa tẹle Ilana idaabo bo ara ẹni lọwọ covid-19 nípa wíwọ ibomu, fifọwọ deede ati itakete sí ara ẹni.
Atẹjade ti wọn fi s'ita wi pe, nitori eto isinku igbakeji aarẹ Naijiria tẹlẹri, Alẹx Ekwuẹmẹ ti wọn fẹ ẹ se lopin ọsẹ, lofa isunsiwaju ipade gbogboogbo naa.
Ní oṣù Ògún ọdún 2018, nínú ọkọ̀ òfuurufú ìlú apá Gúúsù Ilẹ̀-Adúláwọ̀ SAA,  ìrìnàjò ìlú dé ìlú pẹ̀lú ikọ̀ olóbìrin fò ní ojú sánmà wọ́n sì kó èrò láti Johannesburg sí Sao Paulo, Brazil.
Ẹni náà pè mí, ó ní, “Daniẹli, ẹni tí Ọlọrun fẹ́ràn!
ọkan akin ninu idojukọ yooku , aare tun wa fi ikọ agbabọọlu  naa lọkan balẹ pe orile ede Naijiria yoo maa
1 38161 Orilẹede montenegro 533 84.
< Muhammadu Buhari Anfani omi ẹrọ to jẹ ida mejilelọgbọn ni ọdun 1990 ti lọ si ida meje ninu ọgọrun lọdun 2015; anfani imọtoto ti dinku lati ida mejidinlogoji lọdun 1990 si ida mọkandinlọgbọn lọdun 2015.
Simoni Peteru dá a lóhùn pé, “Ìwọ ni Mesaya, Ọmọ Ọlọrun Alààyè.
Wọ́n bẹ̀rù kí ilẹ̀ má baà gbé àwọn náà mì.
Isọri kọọkan awọn akẹkọọ ọhun ni yoo wa nile ẹkọ fun wakati meji aabọ pere.
  Ni bayii, ireti wa pe iko agbaboolu Barca yoo
Iroyin ni sibẹ awọn olujọsin n wọ lọ sile ijọsin COZA ni nitori igbagbọ wọn.
Ọ̀dẹ̀ ènìyàn pàápàá á ti mọ̀ pé ǹkan ḿ bẹ, bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé a kò mọ nkan náà.
Bo tilẹ jẹ pẹ ileeṣẹ to ma n ṣafihan awọn ohun to lamilaaka lagbaye, Guinness World Records, ko fi ontẹ lu ọjọ ori rẹ, wọn bi Fredie Blom ni agbegbe Ila Oorun Cape, lọdun 1904.
Amọṣa, ki a maa deena pẹnu, kaka ki wọn bu ẹyẹ fun un gẹgẹ bi alejo pataki, nṣe ni wọn yẹyẹ aṣofin agba naa.
Ni ipari, o ro awon akanda eda ati awon odo ki won tete lo gba kaadi idibo won ki won si ko lati ma wo aabo ara won rara sugbon ki won tu jade wa dibo fun eni to wu won ti yoo se oselu daadaa fun idagbasoke terutomo to ba di 2019.
 Ti o ba le ṣaṣeyọri ninu eyi fun nnkan bi oṣu meji tabi mẹta titi di igba ti ofi konile-o-gbele yoo fi kasẹ nilẹ, o ti n bopri diẹ diẹ niyẹn."
pelu awon asoju egbe  oselu YES , ogbeni  Clinton Womoh,lori bi awon eniyan kekere se wa
Bí mo bá ní kí n tún máa sọ ohun tí ojú mi rí nígbà tí mo ń padà bọ yìí èyínì yóó gbà ìwé mìíràn gidigbi.
Igbakeji gomina ipinle naa teleri, ba awon akoroyin ati awon omo egbe naa soro pe, ki won lo fokan bale, o da oun loju pe oun yoo jawe olubori ninu eto idibo gomina to n bo lona.
Agbẹnusọ fun JAMB, Fabian Benjamen sọ fun BBC Yoruba pe igbimọ naa ti pari iwadi rẹ, o si ti gbe abọ iwadi naa lọ si iwaju minisita fun eto ẹkọ ni Naijiria fun ayẹwo.
Oríṣun àwòrán, royzkingin / Twitter Igbesẹ wọn naa fa sunkẹrẹ fakẹrẹ ọkọ ni opopona marosẹ Benin si Ore, tawọn ọlọkọ ko si le tẹsiwaju lẹnu irin ajo wọn naa.
ipinle Kaduna je ‘iwa ọlẹ’ , o wa fi da awon eniyan loju pe awon agbofinro yoo
Sibẹ ọpọlọpọ gba pe amulumala agbara ọdọ ati awọn to ti ni iriri ni akọnimọọgba Amerika lo to fi gba ife ẹyẹ tọdun 2019.
Àwọn ọmọkunrin rẹ ni yóo rọ́pò àwọn baba rẹ;o óo fi wọ́n jọba káàkiri gbogbo ayé.
"Àwọn èèyàn fi ìtara ba ilé ìjọsìn jẹ́ Ejò tí a gé lórí tó ń jẹ aporó ní APC - Seyi Makinde O ni ""lati ọmọ ọdun mejila ni mo ti gbanju ba baba mi to n kọ ile ọkọ baalu yii titi ti mo fi dagba bayii""."
OLUWA bá mi sọ̀rọ̀, ó ní, 
 ilẹ ́ náà wà níbẹ ̀ ní àkókò tí mo ń kọ ìwé yìí .
Nítorí Ọlọrun ti ka gbogbo eniyan sí ẹlẹ́bi nítorí àìgbọràn wọn, kí ó lè ṣàánú fún gbogbo wọn papọ̀.
Ihunbo, Ilase, ajegunle, Idiroko ati Agosasa nijọba ibilẹ Ipokia lawọn ilu ti ọwọn gogo epo ti gbode kan nipinlẹ Ogun.
Àwọn tí ìwọ rí nínú ilé mi wọ̀nyí, Ọlọ́run Ọba ni Ó fi wọ́n fún mi; ọ̀kan nínú wọn kì í gbé ilé mi, òun wá láti wáá bẹ̀ mí wò lónìí ni nítorí òde ọ̀run ni ilé rẹ̀.
Mẹfiboṣẹti tún wólẹ̀ tọ̀wọ̀tọ̀wọ̀, ó ní, “Kí ni èmi iranṣẹ rẹ fi sàn ju òkú ajá lọ, kí ló dé tí o fi ṣe mí ní oore tí ó tó báyìí?
Bí iye ọdún tí ó kù bá pọ̀, yóo ṣírò iye tí owó ìràpadà rẹ̀ kù ninu iye tí wọ́n san lórí rẹ̀, yóo sì san án pada.
Nígbà tí Saulu ati iranṣẹ rẹ̀ dé Gibea, ọ̀wọ́ àwọn wolii kan pàdé rẹ̀.
Ànfààní ńlá wà nínú ètò Amọtẹkun, àwọn agbẹjọ́rò ló lè sọ bó yá kò bá òfin mu- Olu Falae Ninu awọn to fi esi sita la ti ri Femi Fani Kayode ti ko pẹ ọrọ sọ rara lati bẹnu atẹ lu Tinubu.
Lẹyin ti o jẹwo pe oun ji biliọnu meji, ile ẹjo giga dajọ ẹwọn ọdun meji fun tabi owo itanran ọtalelẹẹdẹgbẹrin o din mẹwa naira.
Orin ẹ ku oriire ati eyi wuwa lawọn ololufẹ awọn gbajugbaja olorin takasufe Adekunle Gold ati Simi n kọ si orin tuntun ti awọn mejeeji gbe jade lati fi ṣami igbeyawo wọn to waye laipẹ yii.
Oga ọlọpaa na to bu ẹnu atẹ lu iṣẹlẹ naa, wa ba awọn ẹbi ati ara obinrin naa kẹdun pẹlu ileri pe awọn aṣeka naa ko ni lọ lai jẹya.
Ṣugbọn ọ̀nà tí a fi gba iyì ninu ẹ̀rí-ọkàn eniyan ati níwájú Ọlọrun ni pé à ń fi òtítọ́ hàn kedere.
89 Aabo fun awujọ - 9,156,091,555.
Tohun ti pe awọn ọmọ iya wa lawọn ti Hisbah mu yi, ofin Kano lodi si iwa ti wọn hu yi.
Nígbà tí wọ́n gbà á tán, wọ́n bẹ̀rẹ̀ sí kùn sí ọlọ́gbà àjàrà náà.
Ṣugbọn ní ọjọ́ kan nígbà tí Josẹfu wọ inú ilé lọ láti ṣe iṣẹ́ rẹ̀, kò sí ẹnikẹ́ni nílé ninu àwọn ọkunrin tí wọn ń ṣiṣẹ́ níbẹ̀.
  A maa se isin idagbere lọjọRu ọjọ
Mo fẹ́ ìdájọ́ òdodo lórí ikú tó pa ọmọ mi- Baba ọmọ ti SARS pa Àwọn aṣòfín ní ìpínlẹ̀ Edo ti yọ Abẹnugan Ilé, Francis Okiye bí jìgá Inú mi dùn sí iwọ́de EndSARS tàwọn ọdọ́ Nàìjíríà ń ṣè - Ooni Ogunwusi EndSARS protest in Nigeria: Mr Macaroni, Falz, Wizkid, Tiwa Savage àtàwọn míì ṣe ìwọde Ìfẹ́hònúhàn 'End SARS' ń tẹ́síwájú láì jẹ́ pé Buhari ṣe.
Aarẹ Buhari ni aarẹ akọkọ ti aarẹ ilẹ Amerika, Donald Trump yoo gbalejo rẹ lati iha isalẹ asalẹ Sahara ni ilẹ Afirika.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Láàrin wákàtí mẹ́ta, wọ́n dá ₦4m fún àkàndá ẹ̀dá tó kópa nínú ìwọ́de Aisha Buhari polongo àwo orin tó ní Nàíjíríà ń ṣun ẹ̀jẹ̀ lásìkò ìwọ́de 2015 ni mo ti ń kígbe pé gudugbẹ̀ máa já ní Nàíjíríà - Oyedepo Lizzy anjorin ń kiri àgọ́ ọlọ́pàá láti gba àwọn ọ̀dọ́ afẹ̀hónúhàn, tó wà láhàámọ́ sílẹ̀ Àwọn ọ̀dọ́ se ìrẹsì jọ̀lọ̀ọ́fù ní márosẹ̀ Benin sí Ore láti fẹ̀hónú hàn Afárá Marina àti Eko yóò di ṣíṣí padà lọ́la Wo àwọn Ṣọ́ọ̀ṣì Nàìjíríà àti l'Áfíríkà tó ń wólẹ̀ àdúrà kí Trump lè wọlé ìbò ààrẹ America Iléeṣẹ́ ológun bẹ̀rẹ̀ 'Operation Crocodile Smile' yíká Naijiria fún oṣù méjì Amugbalẹgbẹ fun aarẹ Buhari lori ọrọ ibanisọrọ ori ayelujara, Bashir Ahmad lo fi eyi sita loju opo Twitter rẹ, @BashirAhmad.
Ṣé áńgẹ́lì ọmọdé ni kò jẹ́ ka pàdé èyí tó máa pa wá lára.
“Lẹ́yìn náà, ẹ súnmọ́ òkè náà, nígbà tí ó ń jóná, tóbẹ́ẹ̀ tí ahọ́n iná náà fẹ́rẹ̀ kan ojú ọ̀run, tí òkùnkùn ati ìkùukùu bo òkè náà.
ifinix; oko ayokele Toyota Venza meji; Toyota Camry kan; ati awon irinse miiran
Ìdáhùn Ọbasanjọ Ẹwẹ, nkan bi ọdun kan lẹyin ti Iyabo kọ lẹta atẹjade rẹ si Ọbasanjọ, Aarẹ tẹlẹ ri, Olusgun Ọbasanjọ da esi pada si i to si fi ẹsun kan an pe ijọba Aarẹ Goodluck Jonathan lo kọ ọ si oun lati kọ lẹta naa.
pé OLUWA bojú wo ilẹ̀ láti òkè mímọ́ rẹ̀,láti ọ̀run ni ó ti bojú wo ayé;
Idi ni pe rogbodiyan nla miran tun ti bẹ silẹ nilu Portharcourt lowurọ ọjọbọ nitori bawọn araalu, paapaa awọn onikẹkẹ Maruwa se n sewọde.
" Awọn oníwàádìí ọhun ni, o jẹ iyalẹnu fun awọn pe akika to jẹ ẹranko ti ko wọ́pọ̀, ti ọ̀pọ̀ eniyan si maa n wa kaakiri nitori ìpẹ́ to ni lati fi se oogun ibil,ẹ lawọn tun sàwárí ninu igbo ọhun.
Wọn yóo ṣe inúnibíni sí gbogbo ẹni tí ó bá fẹ́ gbé ìgbé-ayé olùfọkànsìn gẹ́gẹ́ bí onigbagbọ.
Iroyin eke nipa awakọ taxi kan: Iroyin kan nipa awakọ tasi kan ni Naijiria ti wọn lo ko arun Coronavirus lo wa loju opo ayelujara amọ ẹbu ni iroyin naa.
Sugbọn lẹyin rogbodiyan to gba ilu kan nipa olori Badra ọhun, BBC Yoruba lee fidi rẹ mulẹ pe, olori naa ti n dabira pada, to si n ba igbe aye rẹ lọ ni wẹlẹmu.
Èyí ni orúkọ àwọn sẹnatọ tó fi APC sílẹ̀ lọ sí PDP àti ADC Lanre Tejuosho (Ogun) - ANPP - CPC - APC - PDP - APC Dino Melaye (Kogi) Barnabas Gemade (Benue) Ibrahim Danbaba (Sokoto) Shaaba Lafiaji (Kwara) Ubali Shitu (Jigawa) Rafiu Ibrahim (Kwara) Suleiman Hunkuyi (Kaduna) Isa Misau (Bauchi) Monsurat Sunmonu (Oyo) APC-ADC Soji Akanbi (Oyo) SDP - AD - APC Usman Nafada (Gombe) Musa Kwankwaso (Kano) Suleiman Nazif (Bauchi) Abdulaziz Murtala Nyako (Adamawa) ADC.
Ṣugbọn awọn onimọ ni bi awọn ara Amẹrika ṣe dibo yan aarẹ lonii, o ṣeeṣe ki ọrọ covid-19 ṣe akoba lọna mii.
Oni ọjọ Aje ni igbẹjọ laarin Shiite ati ijọba yẹ ko tẹsiwaju ni Kaduna.
”Ṣugbọn wọ́n kọ̀, wọ́n ní,“A kò ní tọ ọ̀nà náà.
Egbe APC si n se akoso awọn ipinle márùndínlọ́gbọ̀n ninu ipinle mẹ́rìndínlógójì to wa lorile ede Naijiria, bakan naa ni wọn si ni ọmọ ẹgbẹ  to po ju nile igbimo asoju-sofin ilu Abuja.
Ṣugbọn Josẹfu wí fún wọn pé, “Ẹ má bẹ̀rù, èmi kì í ṣe Ọlọrun.
Nkem Ejelonu, to jẹ ọlọpaa to ṣe iwadi ọrọ naa, nigba ti ọmọbinrin naa lọ fẹjọ sun ni agọ ọlọpaa, tun salaye pe, John Otema, tii se olujẹjọ, tilẹ tun ji pata ọmọbinrin naa lọ.
Òkè Gerisimu ati òkè Ebali wà ní òdìkejì Jọdani, ní ojú ọ̀nà ní ìhà ìwọ̀ oòrùn, ní ilẹ̀ àwọn ará Kenaani tí wọn ń gbé Araba, ní òdìkejì Giligali, lẹ́bàá igi Oaku More.
Wọn yóo jẹ yín ní oúnjẹ,wọn yóo sì kó gbogbo ìkórè oko yín lọ,wọn yóo run àwọn ọmọ yín lọkunrin ati lobinrin.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Christmas: Ẹni ti ọdun ba ti bá láyé yẹ kó dúpẹ́ Oludije sipo igbakeji aarẹ lẹgbẹ PDP, Senetọ Peter Obi pe fun ajọdun keresi to ni ironupiwada.
Ajọ LASWA fi lede wi pe awọn doola ẹmi awọn eniyan mẹrin, amọ awọn ṣi n wa ẹnikan to ku nigba ti iṣẹlẹ ọkọ oju omi naa waye.
Awon nnkan meji ni a ni ,lati tele ilana eto idibo ati ofin egbe APC, gbogbo nnkan ti a nilo lo wa ninu ofin.
Awọn akẹkọ naa to wa lati ipinlẹ Anambra, ni ila oorun guusu orileede Naijiria sọ pe, awọn fẹ pawọpọ pẹlu ajo to n moju to isakoso ounje ati ogun lorileede Naijiria NAFDAC, ki wọn ba le koju ipenija ayederu ogun.
Ṣugbọn mo rowọ́, mo sì ro ti orúkọ mi, tí n kò fẹ́ kí wọ́n bàjẹ́ lójú àwọn orílẹ̀-èdè tí mo ti kó wọn jáde.
Akeredolu, Okowa, àtàwọn gómìnà Nàìjíríà míì tó ti kó àrùn Coronavirus
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ṣé lóòtọ́ ni olorì méjì míì tún ti kúrò láàfin Oyo?
Kì í ṣe òun ni ìmọ́lẹ̀ náà, ṣugbọn ó wá láti jẹ́rìí ìmọ́lẹ̀ náà.
Bi wọn ba gbegi dina irinajo lọ si orilẹede wọn, yoo ṣe akoba fun orileede wa paapa ju lọ, awọn to ba nilo itọju.
Ètò àdúrà Fìdáù yóò wáyé fún olóògbé nílùú Ibadan Ọjọ karun-un, oṣu Keje, ni adura ọjọ kẹjọ yoo waye fun gomina ipinlẹ Oyo tẹlẹ to di oloogbe, Sẹnetọ Isiaka Abiola Ajimobi.
Bẹ́ẹ̀náàni ààrẹ orílẹ̀ Síríà kò dáwọ́ pípa àwọm ọmọ ìlú rẹ̀ dúró.
Oríṣìí ìparun mẹrin ni n óo jẹ́ kí ó dé bá wọn: idà óo pa wọ́n, ajá óo fà wọ́n ya, àwọn ẹyẹ ati àwọn ẹranko óo jẹ wọ́n ní àjẹrun.
Ó darapọ̀ mọ́ ẹgbẹ́ Awada Kẹríkẹrì lábẹ́ àṣẹ àgba òṣèré, Adebayo Salami.
Oríṣun àwòrán, Mark Metcalfe Àkọlé àwòrán, Orilẹede South Africa lo moke julọ laarin awọn orilẹede to wa lati ilẹ Afrika Orilẹede Kenya lo ṣe ipo kẹta laarin awọn orilẹede Afrika nibẹ pẹlu ami goolu mẹrin.
 Oríṣun àwòrán, @realfemiadebayo Fẹmi Adebayọ tun fi kun pe ko seese ki osere tiata lede Yoruba maa gba owo ju awọn akẹ́ẹgbẹ́ rẹ to n sọ oyinbo lọ."
Wọn lero wi pẹ isẹ ọna naa yoo mu ẹgbẹrun lona ọọdunrun poun wa, ti wọn ba lu ni gbanjo.
Èyí ni òfin tuntun kan tí wọn sẹ̀sẹ̀ gbé jáde èyí tó wà láti dáábò bo ìwà ọmọlúwàbí àti tara ẹni.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Wo àwọn àkókò tó yẹ ko sàìsàn, tí ara rẹ yóò fì tètè dá Ọdún mẹ́rin kò tó láti parí ẹ̀kọ́ ọ̀fẹ́ ní Ọ̀yọ́ - Seyi Makinde Wọ́n ti rí Kìnìún tó sá lọ́gbà ẹrankò lẹ́yìn tó pa gbogbo ewúrẹ́ jẹ tán Ipò aṣaájú ni Yorùbá yóò wà ní Nàíjíríà lásìkò tí mo jẹ Odole - Adebutu Awọn ọmọ Naijiria naa tun salaye pe owo ori tawọn n san ti pọ ju, ti ko si si ẹni to mọ ohun ti wọn n fi se.
Nígbà tí mo sì wo ìsàlẹ̀ orúkọ wọn-ọnnì mo rí ọ̀rọ̀ wọ̀nyí tí wọ́n kọ tí ó sí tóbi gàdàgbàgadagba.
Adesina wa fi oro re mule pe, kikoju iwa ibajẹ, mumu igberu ba eto aabo ati idagbasoke eto oro aje orile-ede yii lo je isajoba aare Buhari logun.
Ṣugbọn Dele ni o da oun loju t'ada pe ile ẹjọ to ga julọ naa yoo da idajọ ile ẹjọ kotẹmilọrun nu.
Awọn arinrinajo ni anfaani lati lo papakọ ofurufu naa, lẹyin to ti wa ni titi pa fun oṣu mẹta lati dẹkun itankalẹ arun Coronavirus.
Ọlọ́pàá kó àwọn ọmọ ẹgbẹ́ òkùnkùn Ẹiyẹ Confraternity ni Ikorodu Wike kò wó Mọṣáláṣi rárá o -Fayẹmi lórúkọ gbogbo Gómìnà Nítoríi fóònù ìbánisọ̀rọ̀, géńdé méjì kú sínú u kọ̀ǹga l'Ékìtì Òfin ṣì gbẹ́sẹ̀lé Ẹgbẹ́ awakọ̀ èrò NURTW ní ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́ O tẹnumọ pe ile ẹjọ giga lAbuja ko ti fiwe pe Busola Dakolo ati Pasito Biodun Fatoyinbo titi di bi a ti ṣe n sọrọ yi.
Lẹsẹkẹsẹ ni àwọn tí wọ́n fẹ́ wádìí ọ̀rọ̀ lẹ́nu rẹ̀ bá bìlà.
Oríṣun àwòrán, @uk Àkọlé àwòrán, Ti a bá so ijokoo ile rọ̀ ki lo lè ṣẹlẹ?
Oríṣun àwòrán, NCDC Gẹ́gẹ́ bi àtẹ́jáde àjọ tó n gbógun ti àjàkálẹ̀ ààrùn ni Nàìjíríà (NCDC) ṣe fi síta lójú òpó twitter rẹ̀, ìpínlẹ̀ ìpínlẹ̀ Eko, Abuja àti Kaduna lo lé ténté tábìlì.
Gómìnà mẹ́ta àtí ènìyàn 1,242 ló kó sí panpẹ EFCC ni ọdún 2019 Mọ̀ síi nípa Oyedele Adedokun tó ya àwòràn Donald Trump tó lu ayélujára pa Pásítọ̀ pe Naira Marley ní ẹlẹ́mìí èṣù, Marley fèsì padà pé kí pásítọ̀ gan tẹ èṣù mọ́lẹ̀ Díẹ̀ lára àwọn ìṣẹ̀lẹ̀ tí yóò mi ìgboro tìtì l'ọ́dún 2020 rèé Ajọ Red Crescent Organisation ni ti wọn ti ni o maa nira pupọ lati ri ẹnikankan to maa jade laaye ninu ijamba ọkọ ofurufu naa.
Tori naa lo ṣe jẹ wi pe aṣe eeyan bi ka gbọnsẹ bi a ba ti mu omi kọọbu kan tabi tii gbigbona.
Alhaji Birgi Rafini lo tẹwọgba aare Buhari nigba ti o de si orile ede Niger
àwọn tí wọ́n rí i mú un wá sọ́dọ̀ Mose ati Aaroni ati gbogbo ìjọ eniyan.
“Wọ́n ń fi ọba jẹ, láìsí àṣẹ mi.
ọpọ igba ni gbọmi sii-omi-ko too ko ba ti waye laarin ijọba ati Dokita Adan ṣugbọn wọn fi suuru sii.
Oríṣun àwòrán, Twitter/NFF Àkọlé àwòrán, Idije FIFA U-20 Balogun Flying Eagles ni awọn yoo lo iriri tawọn ti ni fi ṣẹgun Senegal ninu ifẹsẹwọnsẹ naa.
Saulu náà bá pada lọ sí ilé rẹ̀ ní Gibea.
Ṣugbọn lati igba ti aarẹ Muhammadu Buhari ti dẹ okun lọrun ofin konile o gbele, ni awọn oṣere tiata kan ti n gbero lati pada si idi isẹ wọn, ti wọn si n reti igbimọ alakoso ẹgbẹ lati gbe ẹsẹ kuro lori ofin 'ẹ jokoo sile yin' to pa.
Wọ́n bá wọ inú ìletò àwọn ará Samaria kan láti ṣe ètò sílẹ̀ dè é.
Àkọlé àwòrán, Awọn oludibo pejọ lati wo orukọ wọn saaju ayẹwo orukọ rẹ.
Pupo awon ti won kagbako isele ohun ni won gbemi mi lojukan naa, nigba ti ara san paaraapa nile-ijosin ti o wa ni ekun gudu Nyaruguru.
Ọgbẹ́ni Salkida kò sàfihàn orukọ awọn ọmọ mẹ́ẹ̀dógún tó sọ pe wọ́n sẹ́kù yii, ó sọ pe ojúse ìjọba ni èyí.
Feyikemi Abudu, Olorunrinu Oduala, Pamilerin Adegoke, Japhet Omojuwa, Ayo Sogunro àti Deji Adeyanju náà kò gbẹ́yìn.
O sọ iyatọ to wa laarin Bororo ati Fulani.
Safety Commission), awon osisẹ asọbode naa tun wa  ni awon gbogbo ibi ti won ti n dibo lati pese
Wọn ni àwọn ọdọ lo maa n kopa julọ ninu ẹgba nínà náà.
Ó pe gbogbo àwọn ọmọ ọba lọkunrin, ati Joabu balogun, ati Abiatari, alufaa.
Ṣé ẹ mọ̀n tẹ́lẹ̀ pé ará oko ni èmi jẹ́.
Awọn agba ọjẹ agbẹjọro ti yoo tun ṣoju rẹ ni Niyi Owolade, L.
Eleyii yatọ si bi wọn ṣe n ṣe si awọn ọkunrin.
Ati ọmọ ogun ofurufu ati t'oriilẹ, wọn ti pẹ nibẹ ti eleyi si n ṣe ifasẹyin fun wọ.
O ni ipa ribiribi si ni Naijiria ko ninu iduna dura adehun ọhun.
Bí o bá kọ̀, tí o kò jẹ́ kí ó lọ, pípa ni n óo pa àkọ́bí rẹ ọkunrin.
Buhari ní òun kò gbàgbé àwọn ọmọ Chibok Kíni ìdí tí àwọn ẹbí àwọn ọmọ Chibok fi ń tọ woli lọ?
Màgòmágó nínú àwọn ìwé àkọsílẹ̀ fún bí wọ́n ṣe n kó ọjà wọn láti ibìkan sí òmí.
Ṣé lóòtọ́ ni gómìnà Seyi Makinde fún Soun Ogbomoso ní N100 Miliọ̀nù láti tún ààfin ṣe?
Níbo ni owó Crowd 1 ń lọ?
Akọ mààlúù kékeré kan, àgbò kan, ati ọ̀dọ́ àgbò ọlọ́dún kan fún ẹbọ sísun, 
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Sowore: Ìdí tí mi ò fi lè ṣiṣẹ́ pẹ̀lú Mogbalu 25 Sẹ́rẹ́ 2019 Oríṣun àwòrán, Sahara Reporters Àkọlé àwòrán, Mo kọ lati ṣiṣẹ pẹlu Moghalu - Sowore Oludije fun ipo aarẹ labẹ aṣia ẹgbẹ oṣelu AAC, Ọmọyẹle Ṣoworẹ ba BBC sọrọ lori ìṣẹlẹ to mu Ezekwesili yọwọ ninu idije dupo aarẹ Naijiria.
 kò pẹ ́ tí wọ ́ n dé glasgow tí bí babá , ìyá àti àwọn ẹ ̀ gbọ ́ n rẹ ̀ méjì kú .
Wo àwọn àwòràn tó làmìlaaka nílẹ̀ Adúláwọ̀ lọ́sẹ̀ yìí ‘Àti fi àwọ̀n ọlọ́kadà 123 láti Jigawa sílẹ̀’ Irú ọmọ wo ní Yorùbá ń pè ní Olúgbódi?
Wuraọla dagba, o si di ẹni to to lọ sile ọkọ.
Tomomewo Favour: olóṣèlú kìí ṣe ọ̀daràn tàbí alágbèrè
Ó máa ń wá kòkòrò nínú koríko ilẹ̀, ẹ̀kànànkan ni a sì máa ń rí i.
 Elebuibon ni ejo ọrọ naa lọwọ ninu, nitori pe olè ile lo n ṣilẹkun fun ti ode, bakan naa lo sọ pe eyi fihan pe awọn ọta ti wa ni ayika ọba.
’’lai se iye meji awon omo ipinle Zamfara le keri si eyi nipase sise adiku laasigbo awon daran-daran nipinle naa.
O ṣalaye pe awọn irè oko oun ṣi wa ninu oko, nitori pe ibẹru ko jẹ ki awọn o lọ.
lati san fun awon  osise to kere ju.
O tun tesiwaju pe ajo INEC yoo
N óo fún ọ ní agbára, n óo sì ràn ọ́ lọ́wọ́;ọwọ́ ọ̀tún mi, ọwọ́ ìṣẹ́gun, ni n óo fi gbé ọ ró.
Bí wọ́n bá ti mú ọ̀kan láti inú ìran Eleasari, wọn á sì tún mú ọ̀kan láti ìran Itamari.
Lójijì ni ilẹ̀ mì tìtì, tóbẹ́ẹ̀ tí ìpìlẹ̀ ilé ẹ̀wọ̀n mì.
3 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Kí làwọn nǹkan tó lè rán ọkùnrin sí ọ̀run alákeji lásìkò ìbálòpọ̀ pẹ̀lú obìnrin?
Mo ti fi ibinu dá iná kan, ó ti ràn, yóo máa jó ọ, kò sì ní kú laelae.
Gbogbo ara mi kún fún kòkòrò, ati ìdọ̀tí,gbogbo ara mi yi, ó sì di egbò.
Walter Carrington ràn mí lọ́wọ́ kí ń lè sá àsálà lásìkò tí Abacha ń wá mí kiri- Obasanjo Kíákíá lọ daṣọ bo igbá àyà rẹ to ṣí kalẹ̀!
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Menopause: Ẹja nìkan ni ẹranko tí nǹkan oṣù rẹ̀ ń dáwọ́ dúró, yàtọ̀ sí èèyàn Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Menopause: Ẹja nìkan ni ẹranko tí nǹkan oṣù rẹ̀ ń dáwọ́ dúró, yàtọ̀ sí èèyàn 27 Ọ̀wàrà 2019 Kii se ohun ajeji ki nnkan obinrin dawọ duro eyi ti ko nii se pẹlu ọjọ ori rara, bẹẹ si ni ara maa n yatọ si ara lasiko ti nkan osu ba fẹ dawọ duro.
Ó sọ àwọn ìlú náà ní orúkọ ara rẹ̀; ó pè wọ́n ní Hafoti Jairi.
Awọn ọmọ ile igbimọ asoju sofin l'Abuja sọ eyi di mimọ, lẹyin ti wọn wọle pada lẹyin isinmi oloṣu meji ti wọn gunle, fun isinmi ọdọdun ti wọn maa n ṣe.
ni awon ipinle ti o kogun si eka ila oorun orile-ede Naijriia sapejuwe, eleyi
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Atipo Naijiria 50 rigbala kuro ninu odo Libya 11 Ẹrẹ̀nà 2018 Oríṣun àwòrán, Twitter/@nicolacois Àkọlé àwòrán, Ọpọ ninu awọn atipo naa jẹ ọmọ Naijiria Wọn ti gba adọta atipo Naijiria laa ninu odo Libya.
O gba ami eye yii nibi eto akanse to kun fun awon gbajugbaja agbaye eyi ti won se ni Microsoft Theater ni Los Angeles, California.
"nígbà ti eré jùjú bẹ ̀ rẹ ̀ , àwọn ohun èlò tí àwọn òṣèré n lò ni : báńjò , ṣẹ ̀ kẹ ̀ rẹ ̀ , samba àti "" jùjú ' ( àsìkò ) ."
OLUWA yóo fi ọ́ ṣe orí, o kò ní di ìrù; òkè ni o óo máa lọ, o kò ní di ẹni ilẹ̀; bí o bá pa òfin OLUWA Ọlọrun rẹ, tí mo pa láṣẹ fún ọ lónìí mọ́, tí o mú gbogbo wọn ṣẹ lẹ́sẹẹsẹ, 
Ta ni Afẹ́nifẹ́re yóò mú láàrin Atiku àti Buhari?
BBC 100 Women 2019: Wo ọmọ Nàíjíríà kan tó wà nínú wọn
Gwandu to n tukọ ajọ ọlọpaa kogberegbe ni Naijiria ṣalaye kíkun lori iṣẹ tijọba gbe fun un lati bẹrẹ atunṣe si ajọ SARS.
Bí ó ti wí báyìí tán ẹ̀dá burúkú náà bú sí ẹ̀rín àwọn ìjòyè rẹ̀ sì fi ohùn ka ké Kábíyèsí, aláṣẹ, èkejì òrìṣà.
Sarkozy, ti o je aare ile France fun saa 2007 si 2012, ni won ni okan lara akoroyin ayaworan kan ri ti o jade nile re ti o n gbe ni Paris, lati lo tesiwaju ninu iforowanilenuwo ohun lojo Isegun(Tuesday).
Àwọn Angẹli tí Ó Mú Àjàkálẹ̀ Àrùn Ìkẹyìn Wá.
"O ni ""Eeyan mẹwaa lo ti n gba itọju lọwọ nile iwosan ijọba, ọdọ mọkanla si wa nile iwosan adani Reddington, awọn mẹrin wa ni Vedic, nigba ti awọn meji miran wa ni nibi ti wọn ti n doola ẹmi wọn lọwọ."
"Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ikú Bademosi- Ọwọ́ ọlọ́pàá tẹ afurasí alásè Ganduje: Mi Ò gba rìbá lọ́wọ́ ẹnikẹ́ni rí láyé mi Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Bi eeyan se ẹja yii tabi koo pamọ sinu ẹrọ amohuntutu, kaka ki majele ara rẹ parẹ, n ṣe ni yoo maa rin kaakiri agọ ara rẹ ""Ẹja yii ni majele kan ni ara rẹ eleyi to lee ṣakoba fun ẹnikẹni to ba jẹ ẹ."
Salawa Abẹni: ₦50 péré làwọn èèyàn fí ń pè mí fún ayẹyẹ nígbà tí mó bẹ̀rẹ̀ orin kíkọ̀
Ẹnikẹ́ni kò gbọdọ̀ gba ẹnu ọ̀nà tó gbà wọlé jáde.
Ojogbon Osinbajo soro idaniloju yii nile Ijoba l’Abuja lasiko ti won n se ifilole awon iko osise fun erongba riri oro aje ati idagbasoke gba pada, ERGP ni gbongan Banquet.
Osise ajo naa so fun awon oniroyin lojo-Aje nilu Jos, ti n se olu ilu ipinle naa ni kete ti won se abewo si awon ise-akanse ti won pese naa, ti eka ti o n ri si ipese omi-mimu ati imo-toto ayika ninu ajo isokan ile-Europe sagbateru re, eyi ti o je ipele keta ise-akanse ajo naa.
Bí mo ṣe ń dàgbà ni ǹkan ọmọkùnrin mi ń tóbi síi àmọ́ obìnrin ni mi' Ó ti pẹ́ tí Fayose ti máa ń sọ̀sọkúsọ, ṣé ó mutí yó ni àbí ó mugbó?
Ẹwẹ, ni ipinlẹ Kano eeyan mẹwaa ni iroyin sọ pe ọlọpaa ti ko si ahamọ bayii, fun ẹsun iwa jaduku lasiko idibo naa.
Ọrọ yii kii ṣe ajoji si ẹnikẹni to ba mọ fiimu to gbe Funke Akindele saye gẹgẹ bi ẹni gbogbo eniyan wa mọ lagbaye bayii kaakiri ede ati ẹya.
Akọroyin BBC to wa nibẹ n ṣalalye nsiyi pe, onile naa ti bẹrẹ igbeṣẹ lati tun ile naa ṣe ki o too da wo lulẹ.
Coronavirus: Ewu wo làwọn òṣìṣẹ́ elétò ìlèra ń kojú ní Nàìjíríà?
Ní tèmi o, mo ti jẹ adìẹ díndín níbòmíràn tọ́n dùn yùngbà dé’bi pé, ti KFC gangan ò dùn lẹ́nu mi mọ́n!
 Ọ ̀ nà tí wọ ́ n sì lè fi ṣe bẹ ́ ẹ ̀ ni kí wọn lo ìwé tí yó mú kí ẹ ̀ kọ ́ yorùbá rọrùn fún wọn láti kọ ́ .
Ijọba kede iye ọmọ to sọnu ni Dapchi ‘ Awọn ọmọ Yobe’ Kini yoo pada jasi?
Mo bèèrè pé, “Kí ni àwọn wọnyi ń bọ̀ wá ṣe?
Minisita feto ilera, Osagie Ehanire salaye pe gbogbo awọn ibudo itọju arun Coronavirus tijọba ti gbe tipa tẹlẹ, ni oun ti pasẹ pe ki wsn si pada.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Aretha Franklin: Gbajúgbaja olorin Amerika jáde láyé 16 Ògún 2018 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Aretha Franklin nibi to ti n kọrin ni Chicago ni 1992 Gbajugbaja olorin atọkanwa (soul), Aretha Franklin, ti orile-ẹde Amerika dagbere faye.
Ìwà burúkú wọn yí wọn ká, ẹ̀ṣẹ̀ wọn sì wà níwájú mi.
1 1145 Erekusu Barbados 7 2.
4) Wọn gbọdọ ni omi to mọ, ọṣẹ ifọwọ sanitaisa, imọtoto nigba gbogbo fun akẹkọọ ati awọn Olukọ.
Nígbà náà ni a óo tó máa fi ọmọ wa fun yín tí àwa náà yóo máa fẹ́ ọmọ yín, a óo máa gbé pọ̀ pẹlu yín, a óo sì di ọ̀kan.
Ami ayo kan si odo ti Adamu Alhassan gba wọle lo mu wọn le tente sori afara isori kini ninu idije Total AfconU20.
South Africa:Ọpọ àlejò ló fara káása nínú wàhálà túntun
“NI paapaa julo, erongba ise akanse ohun ni lati pese omi lopo yanturu fun igbaye-gbadun ara ilu ati lati se itoju awon ogbin ati osin won lapapo.
Ẹ pa àwọn afunrugbin run ní Babiloni, ati àwọn tí ń lo dòjé ní ìgbà ìkórè.
Gbogbo igba ati asiko ni iran Yoruba ni ikini fun ati pe gbogbo iṣẹlẹ naa ni wọn ni ikini fun ẹni ti ọrọ kan.
Aadọrun atipo ri s'omi ni Libya 'Iṣẹ aṣẹwo ni wọn fi mi ṣe ni Moscow' Ọpọlọpọ awọn aṣatipo naa lo n wa igbeaye 'idẹrun' lọ silẹ Yuroopu, amọ to bọ si ọwọ awọn ajijagbara ni Libya.
Nítorí náà, gbogbo àwọn tí wọ́n bá jẹ́ tirẹ̀ lára yín, kí wọ́n lọ sibẹ, kí OLUWA Ọlọrun wọn wà pẹlu wọn.
Komisona fun iroyin ati ikede ni ipinle Nasarrawa , Jameel
Ṣe arun yii kii mu obirn ati ọmọde ni pupọ ni?
Nítorí Ọlọrun sọ pé, ‘Bọ̀wọ̀ fún baba ati ìyá rẹ’; ati pé, ‘Ẹni tí ó bá sọ̀rọ̀ burúkú sí baba tabi ìyá rẹ̀, pípa ni kí wọ́n pa á.
Ẹ́ gba fóónù, ẹ pe ẹbí yín pé a fẹ́ dáná ṣun yín - Aráàlú sọ fún adigunjalè méji Pásítọ̀ pe Naira Marley ní ẹlẹ́mìí èṣù, Marley fèsì padà pé kí pásítọ̀ gan tẹ èṣù mọ́lẹ̀ Díẹ̀ lára àwọn ìṣẹ̀lẹ̀ tí yóò mi ìgboro tìtì l'ọ́dún 2020 rèé Mọ̀ síi nípa Oyedele Adedokun tó ya àwòràn Donald Trump tó lu ayélujára pa Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, LASU Ritual: Àwọn akẹẹgbẹ́ akẹ́kọ̀ọ́ LASU tí wọn fi ṣowó sọ̀rọ̀ lórí ìgbé ayé olóògbé Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Alapinni Oosa ṣàdúrà fún gogbo ọmọ kúoótù, oò jíire bí?
Ṣugbọn Ahabu bi í pé, “Ìgbà mélòó ni mo níláti mú ọ búra pé kí o máa sọ òtítọ́ fún mi ní orúkọ OLUWA?
Agbabọọlu Borusia Dortmund Jadon Sancho ni Man United kọkọ le lati ra ṣugbọ ko ri ra nitori owo gọbọi ni Dortmund gbe le lori.
Àwọn Eniyan náà Ní kí Jeremaya Gbadura fún Àwọn.
Kòkòrò oyin sọ ọ̀pọ̀ èèyàn di aláìrílégbé, àwọn míràn tún farapa Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Yoruba Taboo: Èèwọ̀ ni fún ọba láti gbé Bibeli tabi Kurani dání dípò ifá- Elebuibon, Agẹṣin Àdìmúlà29 Bélú 2020 Obateru Akinruntan: Olugbo Obateru akinruntan ṣalaye ìdí ohun tó ń ṣẹlẹ̀ láàrín òhun àti Ooni Ile Ife30 Bélú 2020 Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí 2 sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
Nítorí tí o máa ń gba àwọn onírẹ̀lẹ̀ là,ṣugbọn o máa ń rẹ àwọn onigbeeraga sílẹ̀.
Kí OLUWA pa gbogbo àwọn tí ń fi èké pọ́nni run, ati àwọn tí ń fọ́nnu,
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Awọn eniyan to ba wa si ile India naa ma n lo se abẹwo si awọn elesin Agoris yii Iwadii fihan wi pe awọn ko gbagbo nipa ikorira ọmọlakeji.
"Arakunrin Uunona so fun ileesẹ iroyin Bild pe ""Baba mi kan sọ mi lorukọ Hitler ni."
O ni Alao-Akala ti jẹ oye lemọmu bayii, ko tun le maa du oye Ṣeriki mọ, nitori oun ni alaga apẹtu si aawọ ninu ẹgbẹ oṣelu APC ipinlẹ, ko le maa du ipo gomina mọ to jẹ Ṣeriki.
Gbogbo ero ti sọ kalẹ, ko si eeyan kankan mọ ninu baalu.
lati tubo maa se ipade apero pelu gbogbo awon to ni nnkan se pelu eto
Mo tún wí: ẹ máa yọ̀.
ati Paulu ni, ati Apolo, ati Peteru, ati ayé yìí, ati ìyè, ati ikú, ati àwọn nǹkan ìsinsìnyìí ati àwọn nǹkan àkókò tí ń bọ̀, tiyín ni ohun gbogbo.
Ẹ̀tẹ̀ tó mbá ilú jà ni ‘iwà-ibàjẹ́’.
o je iranse ti ododo titi fiwasile lati pe si ipo ninu kerin 2009 .
 ti yan abenugan ile-igbimo asofin orile-ede Naijiria,
Ìyàwó Bukola Saraki fún tìyá-tọmọ olójú búlúù ní N250, 000!
Ondo Cow Death- Mùsùlùmí òdodo ni emi, mi ò kìí pa irọ́- Olu Ikare
Loni irubọ naa ti kọja irubọ lasan, o ti di ajọyọ gbogbo agbaye.
OLUWA ni ìpín tiwọn, gẹ́gẹ́ bí ó ti ṣèlérí fún wọn.
Awọn nkan miran ti ẹ ni lati mọ loni Davido fi mọ́tò #45 milionu dá Chioma lọ́lá Akọ̀ròyìn BBC bá ìkọlù Afghanistan lọ Òǹyẹ̀ kò leè yẹ èlé owó osù - Ẹgbẹ́ òsìsẹ́ Gbọ iroyin iṣẹju kan BBC Fidio wa fun toni NURTW da ayẹyẹ àyájọ́ ọjọ́ òṣìṣẹ́ rú l'Ékó.
Ile ẹjọ ọhun ti Danladi Umar jẹ adari fun, ko lee joko ni Ọjọ Aje, nibi ti Adajọ Agba Onnoghen ti tako igbẹjọ rẹ ni ile ẹjọ to n gbẹjọ iwa ibajẹ, CCT.
Tambuwal so pe “A nigbagbo ninu eni ti egbe wa fa kale ati ipo pataki to dimu lawujo, a si mo pe yoo mu ipinnu rere rẹ sẹ lorile ede Naijiria.
OLUWA, kò sí èyí tí ó dàbí rẹ ninu àwọn oriṣa;kò sì sí iṣẹ́ ẹni tí ó dàbí iṣẹ́ rẹ.
Àwọn ará Iṣimaeli sì mú Josẹfu lọ sí Ijipti.
Awọn ọlọpaa ni ayẹwọ pẹlu irinṣẹ ṣe afihan wi pe Dokita naa ti mu ọti yo.
Ibeere yii ni ibeere to jẹ awọn onwoye logun lẹnu igba ti awuyewuye Ruga yii ti bẹrẹ.
Ẹni tí ó bá ṣe olóòótọ́ ninu nǹkan kékeré yóo ṣe olóòótọ́ ninu nǹkan ńlá.
Bakan naa, agbenuso fun egbe Alliance 
fun sise owo ilu kumọ-kumọ nile ẹjọ.
Yóo pè mí, n óo sì dá a lóhùn;n óo wà pẹlu rẹ̀ ninu ìṣòro,n óo yọ ọ́ ninu rẹ̀, n óo dá a lọ́lá.
Ọmọ Yorùbá mẹ́wàá tó jẹ́ àmúlùúdùn ní Amẹ́ríkà àti Yúróòpù Àṣẹ yìí kan àwọn tó n gba físà H-1B, èyí ni wọ́n sábà máá n fún àwọn òṣìṣẹ́ onímọ̀ ẹ̀rọ láti ilẹ̀ India.
Apo oogun oloro to to ogoji n gba orilẹede Mozambique ni ọdọọdun, Onimọ Joseph Hanlon lo sọ bẹẹ.
Kíní ìtumọ̀ ''Sọ̀rọ̀ Sókè'' tí àwọn afẹ̀họ́núhàn EndSars ń lò káàkiri Kò sáyè iwọ́de mọ́ l'Eko ẹ lọ tọwọ́ yín bọṣọ - Ọlọ́pàá N kò ní buwọ́ lu ìṣúná tí kò pèsè owó fún ẹ̀bí àwọn tó kú nínú ìwọ́de EndSARS - Gbajabiamila Àwọn ọlọ́jà ń sèdárò Ìyálọ́jà ìpínlẹ̀ Oyo tó dolóògbé, wọ́n yan asojú míràn Bakan naa ni aarẹ Buhari tun bu ẹnu atẹ lu ohun to pe ni iroyin ofege kaakiri awọn iroyin ori ayelujara gbogbo eleyi to ni o ti kun orilẹede Naijiria ni awọ ti ko tọ lawujọ agbaye.
"O tun jẹ ẹni to ni ọgbọn lori, o si tun ni afojusun.
Yàtọ̀ sí ògùn tí a nlò láti mú ara wa dá tí ó bá rẹ̀wá, àgọ́ ara wa gan-an kún fún àwọn ọmọ-ogun tí wọ́n ndáàbò bo ara wa.
iderun ba awon eniyan to n gbe agbegbe naa.
Aaroni alufaa gun Òkè Hori lọ bí OLUWA ti pa á láṣẹ fún un, níbẹ̀ ni ó sì kú sí ní ọjọ́ kinni oṣù karun-un, ogoji ọdún lẹ́yìn tí àwọn ọmọ Israẹli kúrò ní Ijipti.
Masedonia ni n óo kọ́ gbà kọjá, n óo wá wá sọ́dọ̀ yín.
Ojuṣe mi ni lati rii daju pe ibudo kika wa ni ipo to dara fun ohun ti yoo waye nibẹ""."
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Blind DJ: Etu Omotayo kò ríran àmọ́ ó le to irinṣẹ́ eléré pọ̀ láti kọrin láì sí ìrànwọ́ Bakan naa lo rọ awọn ọdọ ilu lati maa ni suuru, ki wọn maa si ja fun ara wọn nitori pe gbogbo akitiyan ni ọlọpaa n sa, lati fọ ilu mọ kuro lọwọ awọn onisẹ ibi gbogbo.
Ìmọ́lẹ̀ ni à ń retí, ṣugbọn òkùnkùn ló ṣú,ìtànṣán oòrùn ni à ń retí, ṣugbọn ìkùukùu ni ó bolẹ̀.
saaju ifesewonse keyin ipegede fun idije 2019 Africa Cup of Nations (AFCON) ti
A wa ọkọ fun igba pipẹ ko to o duro.
awon adari orile ede ti mo n sakoso fun  ,a tako iwa ifipagbajoba to waye ni ekun Amhara
Àwọn tó ń fi ojú ààtò wo lítírésọ ̀ sọ pé kò sí ohun tó dára tí kò ní ààtò tó dára .
Coronavirus Drugs: Àjọ NAFDAC ti bẹ̀rẹ̀ àyẹ̀wò àgbò mẹ́rin tí wọ́n ṣe ní Nàìjíríà fún Covid-19
* Gbogbo òṣìṣẹ́ tí yóò ba kójú àláàrùn Covid-19 gbọdọ̀ wọ aṣọ ìdáàbò (PPE), ìbòmú, ìbọ̀wọ́, awòojú àti fìlà * Ní kété ti òṣìṣẹ́ ìlera bá ti gbé aláàrùn coronavirus tan, o ṣe pàtàkì láti fi àwọn kẹmika apakòkòrò tọ́jú gbogbo ǹkan ti ẹni náà wọ̀ kí o to kúrò ní ilé ìwòsàn.
Bakan naa ni o fidi rẹ mulẹ pe awọn oluwọde naa kọ lo kọlu gomina Oyetọla ati iks rẹ bi ko ṣe awọn janduku.
Awọn ọrẹ rẹ ati ojulumọ rẹ, Joe Biden ati Aarẹ tẹlẹri George W Bush se apejuwe McCain gẹgẹbi olufẹ ara ilu ati asa ati ise to mu ilosiwaju dani.
Agency for The Control of AIDS),agbejoro  Festus Keyamo, (Senior Advocate of Nigeria and
Ọgbà àjàrà yóo so,tóbẹ́ẹ̀ tí a kò ní lè fi ṣe waini tánkí àkókò ati gbin òmíràn tó dé.
Spaghetti, mílíìkì, Chivita àti Àǹkàrá sọ Rabiu dèrò ẹ̀wọn ni Eko Ìyàwò lárìnlọọ̀dù mi pè mí ní akálòlò ni mo ṣe paa - Afurasí Imam Fuad Adeyemi ti mọṣalaṣi Al-Islabiyah sọrọ ni kikun lori ohun ti Islam faaye gba fun alaafia lati jọba ninu ile.
Agbẹnusọ fún àjọ náà, Mallam Adamu Yahaya tó ba BBC sọ̀rọ́ sàlàyé pé, ó jẹ́ ọkan lára ojúṣẹ́ àwọn láti máa mú àwọn ọmọbinrin tó bá ń rìnrìn àrè kákìri ìlú, ó si ṣeéṣe kí wọn jẹ́ aṣẹ́wo.
Gege bi baale ohun, Dokita Galadima,”O gbosuba kare lai fun balogun Takur fun ikanikun un re.
Mohammed, ọmọ Abubakar Atiku sọ̀rọ̀ lórí àrùn Coronavirus tó ń báa finra Ìròyìn ayọ̀!
Ó fi ọ̀wọ̀ gba iṣẹ́ tí Ọlọrun rán sí i, ó sì kan ọkọ̀ fún ìgbàlà ìdílé rẹ̀.
" Igbẹjọ Alfa Babtunde si n lọ lọwọ, a mu ẹkunrẹrẹ iroyin naa wa fun yin laipẹ.
Wọ́n kọ́ pẹpẹ oriṣa Baali, wọ́n sì ń fi àwọn ọmọkunrin wọn rú ẹbọ sísun sí i.
Ẹ wo ibi Alákọ̀wé rìn dé tó fi rí abuké erin.
idibo ti ba ise miiran lọ, ki isẹlẹ naa to waye.
Gbẹ́kẹ̀lé OLUWA; kí o sì máa ṣe rere.
Modekai ń tọ́ ọmọbinrin kan, tí orúkọ rẹ̀ ń jẹ́ Hadasa tabi Ẹsita.
Saaju ni awọn ẹgbẹ ASUU ti gba lati se agbe dìde UTAS ti o fi ara pẹ IPPIS ti wọn si rọ ijọba lati gba wọle fun sisan owo awọn olukọ fasiti.
Bẹẹ naa ni Manchester City na Everton pẹlu ami ayo mẹta sọkan lọjọ Abamẹta.
Àlárùn Coronavirus di 7000 lágbàyéé, ìjọba Nàíjíríà kọjú oro sí ọjà China tó jẹ́ ẹbu Àrùn Coronavirus ti tàn dé orílẹ̀-èdè míràn nílẹ̀ Afrika Ninu alaye rẹ, o ni awọn ti gba ẹjẹ arakunrin naa to lo ọjọ meje ni ilẹ Faranse ti o si pada si Eko ni nkan bi ọjọ mẹta sẹyin.
Irúgbìn mìíràn bọ́ sí orí ilẹ̀ ẹlẹ́gùn-ún.
Saulu dá a lóhùn pé, “Bí a bá tọ eniyan Ọlọrun yìí lọ nisinsinyii, kí ni a óo mú lọ́wọ́ lọ fún un?
Abimeleki gbógun ti ìlú náà ní gbogbo ọjọ́ náà, ó gbà á, ó sì pa àwọn eniyan inú rẹ̀; ó wó gbogbo ìlú náà palẹ̀, ó sì da iyọ̀ sí i.
Nígbà tí Mose rí i pé Aaroni ti dá rúdurùdu sílẹ̀, láàrin àwọn eniyan náà, ati pé apá kò ká wọn mọ́, ọ̀rọ̀ náà sì sọ wọ́n di ẹni ìtìjú níwájú àwọn ọ̀tá wọn, 
Nítorí náà, jẹ́ kí á bá Ọlọrun wa dá majẹmu pé a óo lé àwọn obinrin àjèjì wọnyi lọ pẹlu àwọn ọmọ wọn gẹ́gẹ́ bí ohun tí ìwọ, oluwa mi, ati àwọn tí wọ́n bẹ̀rù òfin Ọlọrun wa wí, kí á ṣe é bí òfin ti wí.
Ireti ọpọ ọmọ ẹgb oselu naa si ni pe ẹkun guusu Naijiria ni wọn yoo pada ti yan alaga afunsọ fun ẹgbẹ oselu naa.
Ẹwẹ ni tiwọn naa, amofin Deji ni lootọ ki ale gba iwa jẹgudujẹra tabi ṣiṣe owo ilu danu lawujọ, o dara ki ijọba ibilẹ da wa kuro labẹ akoso ijọba ipinlẹ patapata.
Malami, IGP àti alága APC Oyo ni yóò káwọ pọ̀'yìn rojọ nítori àwọn alaga Kansu tẹlẹri Ilé ẹjọ gíga kan nípìnlẹ Oyọ to fi Ibadan ṣe ibùjóko ti dá àwọn alága ìjọba ìbílẹ̀ àti àwọn ìgbìmọ ìdàgbasoke agbegbe méjìdínláàdọrin lẹkun láti maa fi tipa àti ọ̀nà ti kò ba òfin mu pada si ọọfiisi wọ́n.
3 Àti pé èmi yíò sọ àwọn ohun kan fún ọ èyítí èniyàn kankan kò mọ̀ àfi èmi àti ìwọ nìkan—
Aṣòfin Tunde Braimoh wọ káà ilẹ̀ sún ní Eko ‘Ko wu wa lati dasi ija to wa laarin Gomina Seyi Makinde ati ẹbi Abiola Ajimobi, amọ ohun to buru ni lati ma pa irọ mọ ẹbi oloogbe Kolapo pe wọn gba owo.
Àwọn ni OLUWA fi dán àwọn ọmọ Israẹli wò, láti wò ó bóyá wọn óo mú àṣẹ tí òun pa fún àwọn baba wọn láti ọwọ́ Mose ṣẹ, tabi wọn kò ní mú un ṣẹ.
Nítorí pé, mo dàbí ìgbà tí wọn ti kórè èso àkókò ẹ̀ẹ̀rùn tán, tí wọ́n ti ká èso àjàrà tán; tí kò sí èso àjàrà mọ́ fún jíjẹ, tí kò sì sí àkọ́so èso ọ̀pọ̀tọ́ tí mo fẹ́ràn mọ́.
O fikun wi pe awọn onijibiti naa le e mu nọmba ẹrọ ilewọ wọn lati fi gba owo lọwọ wọn pẹlu adehun pe wọn yoo fun wọn ni esi idanwo to dara ninu idanwo JAMB.
Saraki san owó oṣù òṣìṣẹ́ ní Kwara
Ewe, Simona gba irufe ife-eye idije ohun ti o waye lodun 2015.
Mò ń gbadura pé kí Ọlọrun, Baba Oluwa wa Jesu Kristi, Baba ológo, lè fun yín ní ẹ̀mí ọgbọ́n, kí ó sì jẹ́ kí ẹ ní ìmọ̀ tí ó kún nípa òun alára.
Láti èdè Latin ni Computer"" ti jáde gẹ́gẹ́ bí ọ̀rọ̀."
Kayode sọ pe orukọ Obasanjo lo yẹ ko siwaju gbogbo orukọ yoku.
Bẹẹ ba gbagbe, afurasi yii ni awọn ọlọpa fẹ gbe nipinlẹ Taraba, amọ ti awọn ologun gbaa silẹ, ti wọn si gbẹmi ọlọpa mẹta ati araalu kan lasiko isẹlẹ naa.
Awọn onimọ sayẹnsi parọwa pe ki awọn eeyan gbe owo silẹ fun iṣẹ iwadii ki ajakalẹ arun naa to di nkan miran ni agbaye, Àwọn Olùkọ́ ìpínlẹ̀ Eko dárà lórí Akọ́mọlédè àti Àṣà lórí BBC Shomolu gbajúmọ̀ fún ìwé títẹ̀ ní gbogbo Nàìjíríà!
alaafia laye , ki won si jawo lati hu iwa ti o le  dojuti aare.
A Okunlola lati ileewe girama Community High School Asewele Korede, ni agbegbe Odigbo ilu Ore, ipinlẹ Ondo ṣe atupalẹ lẹkunrẹrẹ bo ṣe yẹ ki a maa lo awọn ọrọ asiko ninu ede Yoruba.
Ẹ máa lọ sí ibi tí wọ́n ti ń rú ẹbọ, nítorí ẹ óo bá mi jẹun lónìí.
"A le se agbekalẹ igbimọ igbimọ oluwadii aladani lopin ọsẹ, to si seese ki wọn bẹrẹ isẹ lọjọ Aje.
Aare soro lasiko ẹkọ imọ Tafsir (Quranic interpretations) to waye ni mosalasi
Bakan naa, awon asofin naa fi mule pe, ko si n ti yoo ye ojo kọ́kàndínlọ́gbọ̀n inu osu karun un kuro gege bi ojo sise ifilole oludupo aare ati awon oludupo gomina patapata.
Ṣugbọn eyi ko ri bẹẹ pẹlu ọrọ ti Igbakeji aarẹ Yemi Osinbajo kọ soju opo Twitter rẹ lati ki Ọjọgbọn Wole Soyinka ku ọjọ ibi ọdun kẹrindinlaadọrun loke eepẹ.
Mo ti gbọ́ ìkérora wọn, mo sì ṣetán láti yọ wọ́n.
Balogun iko agbaboolu Super Eagles, John Mikel Obi ti fi idunnu re han ti o si dupe pupo lowo awon oloopa orile-ede Naijiria fun ise takun-takun ti won gbese lati gba baba re kuro nipo ahamo.
Ile-isẹ ifowopamọ apapọ n yọ owo ayọju - Magnus Abe Oríṣun àwòrán, @cenbankng Àkọlé àwòrán, Ile igbimọ asofin nwa ọnọ abayo si idojukọ awọn oludokowo Ile igbimọ asofin agba ti gba lati se iwadi lori bi Ile-isẹ ifowopamọ apapọ lorilẹede Naijiria, (CBN) se n yọ owo lọnọ aitọ ni apo asuwọn awọn onibara ni ẹka banki ifowopamọsi.
wọ ́ n dá ilé-ẹ ̀ kọ ́ yìí sílẹ ̀ ní ọdún 1979 pẹ ̀ lú àṣẹ látẹnu gómìnà lásìkò ìjọba ológun sunday tuoyo wípé kí ó ma jẹ ́ the polytechnic owo .
Àwọn ọkunrin náà sì sọ ohun tí ọba sọ pé òun yóo ṣe fún ẹni tí ó bá pa ọkunrin náà fún Dafidi.
jésù kírísítì , ni bíbélì tún sọ fún wa pe o jẹ ọmọ ọlọ ́ run ( john 3 : 16 ) .
”O sakeyesi pe iye awon agbejoro ti won ti kekoo pari lorile ede Naijiria ti tesiwaju si I, bo tile je pe iye awon ti o ti goke agba ninu ise eto ofin si kere jọjọ.
Ara kan ni ó wà, ati Ẹ̀mí kan, gẹ́gẹ́ bí ìpè tí a ti pè yín ti jẹ́ ti ìrètí kan.
 Òródùdùjoyè ni orùkọ àbúrò olúbákin tí wọ ́ n jọ du oyè náà .
Ẹ kò gbọdọ̀ bẹ̀rù wọn rárá, nítorí pé OLUWA Ọlọrun yín ni ó ń jà fun yín.
Ẹ nlẹ́ o ẹ̀yin èèyàn mi.
Ọkan lara awọn akopa yii, Ọjọgbọn Ishaq Akintọla, ti wọn jẹ olukọni ati Oludari Ẹgbẹ to n ja fun ẹtọ to nii ṣe pẹlu awọn musulumi (Muslim Rights Concern) gboriyin fun aṣeyọri Ile Igbimọ Aṣofin naa lati bi ọdun mẹta ti wọn ti dori aleefa.
Bí àwọn ilé ìgbéròyìn sáfẹ́fẹ́ àgbàńlá-ayé gbogbo ṣe tán ìròyìn-in rẹ̀ ká, àwọn akẹ́kọ̀ọ́ tí ó wà láti Hong Kong àti Taiwan gbìnnàyá láti gbéjàa Lhamo.
Ogoji ọdún ni Eli fi ṣe adájọ́ ní ilẹ̀ Israẹli.
IVF ni obìnrin yìí se lẹ́ẹ̀mẹrin tó fi bí ìbejì Oluwo gba Aláàfin nímọ̀ràn pé kí olorì máa dé adé Ọpẹmipọ ní ọkùnrin kò jẹ́ kí òun sinmi nínú tíátà Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí 2 sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 2:23 Fídíò, Water Generator: Ó leè ṣiṣẹ fún wákàtí mẹfà, kó tó sinmi, Duration 2,2310 Òkùdu 2020 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
Wọn kò gun ibi tí odi ti lanu lọ, kí wọn tún un mọ yípo agbo ilé Israẹli, kí ó má baà wó lulẹ̀ lọ́jọ́ ìdájọ́ OLUWA.
 AITEO ti o je onigbowo iko agbaboolu Super Eagles yoo wa ni digbi lorile-ede Russia fun atileyin ti o legbe ati igbani-niyanju.
Jakọbu súre fún Farao ó sì jáde kúrò lọ́dọ̀ rẹ̀.
Ikọ Chelsea ti wa ni ipele to kangun si aṣekagba ninu idije Europa bayii ninu eyi ti wọn ta ọmi pẹlu ikọ Frankfurt lati orilẹede Germany.
Bàbá Wande, ẹni tó koro ojú sì àṣà aṣọ iwọkuwọ àti fífi ara sílẹ̀ nínú eré, ní àṣà tí kò dára ní, àwọn sí ti ń ṣe idanilẹkọọ fún awọn obìnrin oṣere tó máa ń ṣe bẹ́ẹ̀, láti pinwọ ṣíṣe àṣà burúkú náà .
Mohammaed Salah orileede Egypt n lero lati gba ami ẹyẹ agbabọọlu to pegede fun igba ẹkẹta.
Ọmọ bibi Ẹgba Gbagura ni Ayinde Soaga jẹ nipinlẹ Ogun.
 ni ó bí ọ ̀ gbẹ ́ ni jòdià akínyẹlé tí ó jẹ ́ àkọ ́ bí rẹ ̀ , tí jòdià sìjẹ ́ ọ ̀ kan lára àwọn tí ó wà lábẹ ́ àkóso ọ ̀ gbẹ ́ ni david hinderer , tí ó jẹ ́ ọmọ ilẹ ̀ jamaní , tí ó sì tún jẹ ́ olùṣọ ́ onigbagbọ ( cms ) , tí ọ ̀ gbẹ ́ ni jòsià sì jẹẹ ́ ọ ̀ kan lára àwọn mẹ ́ fà tí ó mú ẹ ̀ sìn kìrìsìtẹ ́ ni wọ ìlú Ìbàdàn ní ọdún 1851 .
Igbesẹ yii to ba di mimuṣẹ tumọ si pe gbendeke ti awọn ọmọ ile igbimọ aṣofin a ni lati fi jiroro lori bi UK a ṣe yọ kuro ni Brexit a tun dinku sii ni.
Wọn fidiẹ mulẹ pe o le ni ida aadọrun awọn to n lo abẹrẹ ajẹsara naa to n ri iwosan gba lọwọ arun COVID-19 ni America.
 Bákan náà ni Dele Momoodu koro ojú sì bí ìjọba ṣe kó owó sórí tabili, tí wọn sì ń pín bíi ìgbà tí wọn ń pín àkàrà, èmi kò sì tíì rí èèyàn tó ní òun ti rí owó náà gbà."
Díẹ̀ lárá àwọn ìmọ̀ràn tí ilé ọlọ́pàá gbé sílẹ̀ rèé gẹ́gẹ́ bi ohun to le mú ki lílọ́ bíbọ̀ rọrun fún àwọn awakọ, pàápàá jùlọ ti àwọn ọlọpàá ba di ọ̀nà ní orilẹ̀-èdè Nàìjíríà.
Ìyàwó gbà sí ọkọ lẹ́nu láti ṣègbéyàwó abẹ́ odò Kí lo fẹ́ mọ̀ nípa ‘Ajala Travels’?
George Weah ge owo osu rẹ gẹgẹbi aarẹ Liberia
Agbejoro kan ni o pokunso nile itura to wa ni abule Kaysersberg ni.
Bẹ́ẹ̀ sì ni ìlú Sodomu ati ìlú Gomora ati àwọn ìlú tí ó yí wọn ká.
Ọgagun Taiwo fidi ọrọ yii mulẹ niwaju igbimọ to n ṣe iwadii ipaniyan to waye ni Lekki Toll Gate nipinlẹ Eko.
O tenumo oro re wi pe oruko awon ti won ba wu iwa ibaje gbodo wa lati gbogbo awon egbe oselu pata lati le gboriyin fun ise akanse gbigbogun ti iwa ibaje ti isakoso ijoba Aare Muhhamadu Buhari.
Ọdọmọkunrin náà dá a lóhùn pé, “Orí òkè Giliboa ni mo wà, ni mo déédé rí Saulu tí ó fara ti ọ̀kọ̀ rẹ̀.
Leicester best player award: Iheanacho, Ndidi yóò jọ du àmì ẹ̀yẹ Leicester City
O ni ''ajakalẹ aarun yii ti mu ki gbogbo wa di ọkan naa.
Kabiyesi Oluwo ni oun ni lati fi orilẹede Naijiria silẹ lọpọlọpọ ọdun sẹyin lati wa papa oko tutu fun ọjọ ọla oun nitori iwa ijẹkujẹ ati ajẹbanu to n waye laarin awsn atuks ijọba orilẹede Naijiria nigba naa.
Lọgan ti Taiwo Akinkunmi ni iwe ẹri girama, lo gba isẹ labẹ ijọba ẹkun iwọ oorun guusu ilẹ yii ijọun, gẹgẹ bii osisẹ ijọba eleto ọgbin lọgba Secretariat Taiwo sisẹ fun ọdun diẹ, ko to tẹkọ leti lọ silu London lati kọ ẹkọ nipa imọ ẹrọ to nii se pẹlu ina ọba, taa mọ si Electrical Engineering, nile ẹkọ ẹkọsẹ ọwọ ti Norwood Technical College Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ṣé ẹ̀yin lè ṣe jú àwọn tó f'àmì sí Awọlumatẹ?
Lara awọn miran to peju sibẹ ni aṣoju ijọba ipinlẹ Ọyọ, Kọmiṣọna ọlọpaa nipinlẹ Ọyọ, awọn agba ẹgbẹ awakọ ero nipinlẹ ati ni apapọ orilẹede Naijiria.
Nigba kigba ti Stationery Stores ba fẹ koju awọn akẹgbẹ wọn, awọn alatilẹyin ẹgbẹ naa yoo gba ọkọ lati Ibadan wa si Eko tori pe wọn fẹ wo ifẹsẹwọnsẹ wọn.
Bakan naa loṣu to kọja, Saramento ti California, ọpọlọpọ ibo lo bajẹ lẹyin ti awọn eeyan fin iwe itẹka wọn pẹlu ogun apakokoro eyi to si jẹ ki ọda rọ mọ ọ lara ti ko si ṣee ka mọ afi igba ti wọn ko iwe itẹka miran fun wọn.
tiwa-n-tiwa je ona kan ti o lanfaani pupo lati yan adari orile-ede, o je ohun
Bi awọn eeyan si ti ṣe pọ to nibẹ naa ni iye awọn ọkọ ti wọn n lo fun irinna pẹlu n pọ sii.
NBC fọwọ́ sí ìdásílẹ̀ ilé iṣẹ́ Fulani Radio 'Kristẹni lo n fara kaaṣa ikọlu fulani ju' Ṣé Fulani daran-daran ni àwọn tó n jí ènìyàn gbé ní ìpínlẹ̀ Ondo?
Gẹgẹ bi ele owo oju iworan DSTV ati GOTV tuntun yoo ṣe lọ, DSTV Premium yoo kuro ni náírà merindinlogun ati igba (N16,200) bọ si naira mejidinlogun o le irinwo naira (N18, 400) ati bẹẹ bẹẹ lọ.
Wòlíì Kasali ní Dolapo Awosika kò lé ìyàwó òun jáde Iya Rainbow, ẹni to dupẹ lọwọ Ọlọrun pe ileesẹ naa n se ẹyẹ fun oun lasiko ti oun si wa loke eepẹ.
Nítorí pé n óo sọ ọ́ di kékeréláàrin àwọn orílẹ̀-èdè,o óo sì di yẹpẹrẹ,láàrin àwọn ọmọ eniyan.
Bakan naa, orilẹede yii n koju Coronavirus eyi ti aṣaju rẹ foju kere.
Ọ̀pọ̀lọpọ̀ ǹkan ni àwọn ènìyan ń bèèrè lọ́wọ́ Buhari lásìkò yí
Ọ̀gágun bá súnmọ́ Paulu, ó mú un, ó bá pàṣẹ pé kí wọ́n fi ẹ̀wọ̀n meji dè é.
Juwọn Ọbasanjọ ṣatilẹyin fun Aarẹ Buhari ti baba rẹ tako Oríṣun àwòrán, @BashirAhmaad Eyi to tun n waye laipẹ yii ni ọmọ rẹ ọkunrin mii, Juwọn Ọbasanjọ, to n ṣatilẹyin fun Aarẹ Muhammadu Buhari lati dije fun saa keji.
Sàká: Oun tí orí bá yàn fún ẹ̀dá ni kó ṣe Bakan naa lo ni ọkan oun da oun láre pé oun ko ṣe Liz Anjọrin rara.
Awọn ọkunrin meji kan lo n dari ijọba ọkọ mi Laipẹ yii ni fidio kan tun jade to ṣafihan Aisha Buhari to sọ pe awọn ọkunrin alagbara meji kan lo n dari iṣakoso ọkọ oun.
Akọroyin BBC, Yasini Inayatulhaq ba idile yii sọ̀rọ̀ lori ipinu wọn lati ta ọmọ wọn.
Awon olootu ere Bond, Michael G Wilson ati Barbara Broccoli ni: Ä kedun iku ogbontarigi adari ere yii.
Ìgbéraga ń gbílẹ̀ lórí ilẹ̀ ayé lójoojúmọ́, bẹ́ẹ̀ ni ìgbéraga ni gbòǹgbò ìparun.
awon eniyan ko se jade pupọ, to ti ọsẹ meji sẹyin  lati dibo.
Implementation Committee on Financial Autonomy of State Legislature and
Àwọn ará Babiloni bá tọ̀ ọ́ wá, wọ́n bá a ṣeré ìfẹ́ lórí ibùsùn rẹ̀, wọ́n sì fi ìfẹ́kúfẹ̀ẹ́ wọn bà á jẹ́.
Ọ̀rọ̀ tí Ààrẹ Muhammadu Buhari kà sétí ìgbọ́ ọmọ Nàìjíríà ni ọjọ́ kejìdínlọ́gbọ̀n oṣù kẹrin lórí ààrùn Covid19 ti ṣáájú Ààrẹ dé orí ayélujára wákàtí díẹ̀ kí Ààrẹ tó dórí afẹ́fẹ́.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ajọ JAMB sun opin ọjọ iforukosilẹ idanwo s'iwaju 7 Èrèlè 2018 Oríṣun àwòrán, @JAMB Àkọlé àwòrán, Ajọ JAMB sun opin ọjọ iforukosilẹ idanwo s'iwaju Ajọ to n risi eto idanwo aṣewọle s'ile ẹkọ giga, JAMB ti kede isunsiwaju opin ọjọ iforukọsilẹ fun idanwo ti ọdun yii si ọjọ kọkanla, osu keji, ọdun yii.
Helen Paul: Bí o kò bá fẹ́ kí wọ́n mọ ìrírí rẹ, òun pa ẹlòmíì lára
"O sọ fun gomina Abiodun pe ko ""fọwọ si pipese oriṣiriṣi owo ajẹmọnu ti wọn n jẹ awọn aṣofin ati awọn oṣiṣẹ wọn to fi mọ owo fun aga, owo asiko isinmi lẹnu iṣẹ ati owo aṣọ""."
Ó kẹkọọ gboyè nínú ìmọ̀ ìlera, ni ile iwe olododo Fasiti Ọbafẹmi Awolọwọ, Ile Ifẹ, nibi ti o si tún ti kẹkọọ siwaju síi ni nipa iṣẹ abẹ siṣe.
Sugbọn lẹyin ọse kan awọn alasẹ gba wipe lootọ ni awọn Boko Haram ji awọn ọmọ naa gbe.
Iroyin fi han wi pe ọkọ ajagbe elepo kan lo ja ti o si fori sọ ọkọ akero kan to n bọ ni iwaju ni nkan bi aago mẹta aabọ oru.
To si di gbajumo janduku lẹyin to pada silu Ibadan lẹyin irinajo rẹ si Eko.
Bi ọkan ninu wọn ba si ni ajọsepọ pẹlu iyawo ẹnikeji ninu ẹbi naa, boya ẹgbọn ba iyawo aburo sun, abi baba ba iyawo ọmọ rẹ sun, to si di oyun.
Nítorí gbogbo yín ti di ọ̀kan ninu Kristi Jesu.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Olusegun Obasanjo: Ọmú ìyá mi ti mo fi ń mùkọ ni kekere ló jẹ ki ń lókun Aarẹ ana naa ko lọ ibi iburawọle fun aarẹ Muhammadu Buhari to waye ni Ọjọru ni Abuja.
Arole Oodua to jẹ Ọọni ti Ifẹ iyẹn Oba Adeyeye Ẹnitan Ogunwusi, Ọjaja II nipaseẹ ile iṣẹ aranilọwọ rẹ̀ ti kii ṣe tijọba, iyẹn, Hopes Alive Initiatives (HAI) ti nawọ iranlọwọ si awọn Aṣatipo ti ogun Boko Haram le nile ni agbegbe Wasa nilu Abuja.
 Ẹ jẹ́ kí á tepá mọ́ṣẹ́.
Láti orí wolii títí kan alufaa, èké ni gbogbo wọn.
Wọ́n gbọdọ̀ wọ aṣọ mìíràn kí wọ́n tó súnmọ́ àwọn ohun tí ó jẹ́ ti gbogbo eniyan.
Ọlọ́run bá mi sọ̀rọ̀ púpọ̀ lórí ìṣẹ̀lẹ̀ naa ni àná, àbí ọ̀nà wo ni wọn tún fẹ́ gbà láti dá sọọsi lọwọkọ kò má baa gbòòrò, oyè èyí kò ye àwọn èèyàn ti ọ̀rọ̀ yìí kan.
Oriṣiiriṣii ẹsun to le ni ẹẹdẹgbẹta ni ajọ FBI fi kan awọn eeyan yii to to bi ọgọrin.
Isley sọ pé lẹ́yìn tí òun gba ìtọ́jú náà ló ríi pé wọ́n ò ṣe iṣẹ́ pé èyí kò sì lè tán ìṣòro àìnídùnú rẹ̀ ọlọ́jọ́ pípẹ́.
Bí àwọn èèrà tí ń gé àwọn ejò jẹ bẹ́ẹ̀ náà ni àwọn ejò ń fẹ́ẹ́ gé wọn jẹ, ibi ti wọ́n bá sì ti ṣe bẹ́ẹ̀, ara àwọn pàápàá ni wọ́n ń bù jẹ, nípa bẹ́ẹ̀, olúkúlùkù àwọn ejò wọn-ọnnì bẹ̀rẹ̀ sì pa ara weọn, oró àwọn tìkara wọ́n ń mú ara wọn.
Ayenakin lo sọ ọrọ naa fun BBC Yoruba lẹyin iku Tiamiyu Kazeem to ṣagbako iku lati ọwọ ẹka ileeṣẹ ọlọpaa SARS, ti wọn ni wọn fofin mu latari pe o wọ aṣọ ologun lai jẹ ọmọ ogun.
Gẹgẹ bi o ti ṣe sọ, Zlatan ni oju oun ti ri to ti oun si bori gbogbo ipenija to koju oun.
Ṣela, ọ̀kan ninu àwọn ọmọ Juda, ni baba Eri, baba Leka.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Sogidi Lake: Kòṣẹja-kòṣèèyàn lá bá nínú adágún odò náà -Ojedele Ẹgbẹ ọhun si ni Oyinkan lo lati kan sawọn eekanlu lawujọ fun ikowojọ, eyi to fi da ile ẹkọ girama Queen's College silẹ lọdun 1927 nilu Eko.
Ẹ fọn fèrè ogun ní Tekoa,kí ẹ ṣe ìkìlọ̀ fún wọn ní Beti Hakikeremu,nítorí pé nǹkan burúkúati ìparun ńlá ń bọ̀ láti ìhà àríwá.
Dájúdájú, ọjọ́ ọ̀la rẹ yóo dára,ìrètí rẹ náà kò sì ní já sí òfo.
abdullah gül , gcb , gcolih , ph.
Bakan naa ni olukọ ko gbọdọ fi aworan ihoho rẹ tabi ti ẹlomiran ranṣẹ si akẹkọọ rẹ lori ayelujara tabi nipa ọna miran.
Kajola, ijoba Ibile Irepo nibi ti awon janduku  ti dana sun iwe idibo, woodu kejo ni ijoba
137 obìnrin ni ikú ń pa lójúmọ́ lágbàáyé Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Mo n wayawo - Falz ti kigbe fun awọn ololufẹ rẹ Botilẹjẹ wi pe ile ẹjọ din ẹwọn ọdun mẹwa ti ofin la kalẹ ku si meje fun n, awọn adajọ ni 'dandan ni fun dokita naa lati jiya awọn iwa ọdaran to hu.
Awọn iye wọnyi da lori ẹnikẹni to n ṣiṣẹ pẹlu ile iroyin.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù FUOYE: Fayemi ní ìṣẹ̀lẹ̀ bí àwọn ìrètí ọ̀la náà ṣe kú ba òun nínú jẹ́ 14 Owewe 2019 Oríṣun àwòrán, Ekiti state government Gomina Kayọde Fayẹmi ti ipinlẹ Ekiti ti ranṣẹ ibanikẹdun lọ ki awọn ẹbi akẹkọọ meji ti ọlọpaa yinbọn pa.
Ṣimei bí ọmọkunrin mẹrindinlogun ati ọmọbinrin mẹfa.
Àkọlé àwòrán, Ile iya egbe APC ni Rivers nibiti awon eka Amaechi ti n pejo fun idibo won Ipinlẹ Kwara: Iroyin to tẹ wa lọwọ sọ pe ẹgbẹ oṣelu APC ti sọ pe ki igbimọ alaṣẹ ẹgbẹ naa ni ipinlẹ Kwara labẹ alaga Ishola Balogun-Fulani lọ rọ kun nile.
Mò ń fagi lé ètò náà.
fiya jẹ awon eniyan  lọna aitọ.
Nítorí náà, ẹ má ṣe jẹ́ aṣiwèrè, ṣugbọn kí ẹ máa fi òye gbé ohun tíí ṣe ìfẹ́ Oluwa.
    Mo rí ọgbọ́n díẹ̀ kọ́ nibi tí a jókòó sí yìí nítorí kò pé tí a dé tí àwọn mẹ́ta kan fi dé wá bá ni, mo sì fetí sí ohun tí wọn ń sọ nípa ọba wọn.
Menopause: Ẹja nìkan ni ẹranko tí nǹkan oṣù rẹ̀ ń dáwọ́ dúró, yàtọ̀ sí èèyàn
Ọ̀dàlẹ̀ ni Igbákejì Gómìnà, kìí ṣe pé a dẹ́yẹ si - ìjọba Ondo Ìgbésẹ̀ míràn ṣúyọ lórí ọ̀rọ̀ Abiola Ajimobi Ohun tí a mọ̀ nìyí nípa àwọn tí yóò láǹfàní àti lọ sí Hajj lọ́dún yìí Èyí ni àwọn arẹwà ‘ẹ̀lẹ̀ Daddy’, àfẹ́fẹ́ tí Aláàfin fi ń mí APC: Àlààyé rèé lórí ìdí ta fi gbé ìlẹ̀kùn olú iléeṣẹ́ APC tì pa l'Abuja Oríṣun àwòrán, APCng Ilé iṣẹ́ ọlọ́pàá tí gbé olú ilé ẹgbẹ́ òṣèlú All Progressive Congress (APC) tì pa nílùú Abuja nibamu pẹlu àṣẹ ọgá àgbá ọlọ́pàá ní Naijiria, Mohammed Adamu.
Nisinsinyii OLUWA Ọlọrun wa, jọ̀wọ́ gbà wá lọ́wọ́ Asiria kí gbogbo àwọn orílẹ̀-èdè ayé lè mọ̀ pé ìwọ OLUWA nìkan ni ỌLỌRUN.
ekun ariwa iwo oorun orile-ede yii nibi ti oun ati awon gomina ekun naa ti fenu
Àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ sọ fún un pé, “Bí ọ̀ràn láàrin ọkunrin ati obinrin bá rí bẹ́ẹ̀, kò ṣe anfaani láti gbeyawo.
Kò ní agbára kan lórí mi.
Eto idanileko naa n lo lowo nile iwosan awon omo ogun ohun nipinle Bauchi.
Ta ni ò ń kígbe mọ́,tí o sì ń wò ní ìwò ìgbéraga?
Ṣugbọn nisinsinyii, nítorí pé inú kì í bí i kí ó jẹ eniyan níyà,bẹ́ẹ̀ ni kò ka ẹ̀ṣẹ̀ kún lọ títí.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Afeez Agoro: O ṣòro fún mi láti wọ Danfo jáde Bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé àwọn ìlú yòókù nilẹ Yorùbá fara mọ èyí, aarẹ Kurunmi nìkan ló yari pé kò leè rí bẹ́ẹ̀ rárá, àṣà adayeba ìlú Ọ̀yọ́ kò sì gbọ́dọ̀ parun.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Awọn ẹbi kan ree lọdun 1935 ti wọn n jẹ ounjẹ alẹ idupẹ oṣu kọkanla ọdun naa Awọn kan ni laye atijọ arinrinajo Edward Winslow kọ lẹta nipa ounjẹ adidun ti a fi tọkí ti oun ṣọdẹ sè.
Ẹ̀kọ́ Fásitì Eko (UNILAG) ló ti kọ́kọ́ kẹ́kọ̀ọ́ gboyè wọnlẹ̀wọnlẹ̀ (Surveying) nígba tó wà ní ẹni ọdún mẹ́tàlélógún ní ọdún 1988.
    Lórí gbogbo èyí, ìwọ ọmọ ènìyàn, jọ̀wọ́ mo bẹ̀ ọ́ gidigidi bá mi bọ ẹ̀wù ìgbéraga ọrùn mi, nítorí kò jẹ́ kí inú mi dùn ráá.
 Àwọn babalàwo máa ńsábàá lo ikin ifá ( èkùrọ ́ ifá ) nígbà tí wọ ́ n bá mbọ ifá ní ọọ ̀ dẹ ̀ ẹ ̀ wọn , wọ ́ n a sì lo ọ ̀ pẹ ̀ lẹ ̀ fun ará òdé tí ó wáá da ifá lọ ́ dọ ̀ ọ wọn láti ibi èso igi ọ ̀ pẹ ̀ lẹ ̀ ni a ti ń mú ọ ̀ pẹ ̀ lẹ ̀ ifá .
Ìdí rèé tí ilẹ̀ Afirika fi gbọdọ̀ kópa nínú dídán abẹ́rẹ́ coronavirus wò Ìbúgbàmù ńlá mi olú ìlú Somalia jìgìjìgì Ko si aaye bọọlu gbigba mọ ni Somalia Ọwọ́ tẹ afurasí méjì tó nííṣe pẹ̀lú ìjínígbe Ọgá panápaná l'Eko Àwọn agbébọn jí nọ́ọ̀sì gbé ní Mogadishu Adan ni oun woye pé ọmọlanke ni awọn eeyan ilẹ Somalia fi n gbe alaisan wọn lọ sile iwosan ni eyi ti ko boju mu rara fun ilera alaisan ni pato.
#EndSARS lu ayélujára pa lórí ikú Kolade Johnson ‘Ọ̀rọ ẹnu lásán ni wàhálà tí Nnamdi Kanu ní òun lè dásílẹ̀ ní Nàíjíríà’ 'Fashọla, o ò sì bẹ̀rù Ọlọ́run!
Àwọn ọmọ ogun Israẹli bá sá níwájú àwọn ọmọ ogun Juda, Ọlọrun sì fi wọ́n lé àwọn ọmọ ogun Juda lọ́wọ́.
Ó bá pe àwọn ẹrú rẹ̀, ó fi àwọn dúkìá rẹ̀ lé wọn lọ́wọ́.
" Amọ sa, Neo, tii se ẹya Urhobo wa n fi ika hanu pe o seese ki oun sọ awọn ọrẹ oun naa nu, to fi mọ ololufẹ oun, Vee, ti wọn ba le oun lọ sile lonii.
Yẹra fún un,má tilẹ̀ kọjú sí ọ̀nà ibẹ̀,ṣugbọn gba ibòmíràn, kí o máa bá tìrẹ lọ.
Ki wọn o wọgile saa yii, pẹlu bi agbaye ṣe n dojukọ asiko ewu bi eyi.
Aarẹ Cameroon naa ṣeleri lati koju awọn to ya ara wọn kuro ni Cameroon, to si kọ lati yọnda nkan ijagun wọn.
Ṣugbọn bí Ọlọrun ti ṣe yìí kò dùn mọ́ Jona ninu rárá, inú bí i.
Gomina Hassan ni ko si ninu asa Naijiria lati ka awon eniyan mo rara soju kan bikose pe ki gomina kookan tu won sile ki won si rogun si won lapa fun idagba soke awujo.
Ileesẹ aarẹ ni, ibi gbogbo lati n kadiyẹ alẹ, ko si ibi ti awọn ọlẹ afàjò ko si, ṣugbọn ojuṣe ijọba lẹka gbogbo ni lati pese aye to tọna silẹ fun olukuluku lati mu ala rere wọn ṣẹ.
Ni asiko ti a fi n ko iroyin yii jọ, o din diẹ lẹgbẹrun kan eeyan ti ayẹwo ti fihan pe o laarun naa ni ipinlẹ Eko nikan Coronavirus Cases in Africa: Sanwo-Olu kéde ìgbésẹ̀ fún pípadà sẹ́nu iṣẹ́ ní ìpínlẹ̀ Eko Oríṣun àwòrán, Babajide sanwo-olu Ijọba ipinlẹ eko ti gbe ilana aa tẹẹle kalẹ fun bi wọn yoo ṣe bẹrẹ si ni ka eto kanile o gbele kuro nilẹ ni ṣiṣẹ n tẹle ni ipinlẹ Eko.
Ọgbọn eeyan ninu awọn mẹrindinlaadọta to ni arun covid-19 ni Naijiria lo wa lati ipinlẹ Eko, nigba ti meji wa lati Abuja.
Iyawo Jobu bá sọ fún un pé, “Orí òtítọ́ inú rẹ ni o tún wà sibẹ?
Soworẹ salaye ọrọ yi wa nigba to n ba BBC Yoruba sọrọ lori akanṣe eto nipa idibo aarẹ Naijiria.
Nigeria Pensioners: Wàhálà àyẹ̀wò iwé ìfẹyinti yì ti pọ̀jù
Wọn ni lẹyin ti awọn de Oman ni awọn fi wa di alarinkiri ni orilẹede naa.
Dokita Geeta Rao Gupta to jẹ oludari ajọ 3D Programme for Girl and Women sọ pe ''mi o ro pe o ni ọna tawọn obinrin fi n dari ilu to yatọ si tawọn ọkunrin.
Àwọn èèyàn fi ìtara ba ilé ìjọsìn jẹ́ Ìya lọ ṣọ́ọ̀ṣì, ló bá pàdánù ọmọ!
Rape: Oríṣí ìjìyà ní àwọn bíi Gómìnà El Rufai àti Fayemi ń bèèrè f'àwọn afipábánilòpọ̀
Oríṣun àwòrán, Instagram/acupofkhafi Àkọlé àwòrán, Eto BB Naija Agbẹnusọ fun Khafi sọ pe Khafi yoo sọrọ si ẹsun yii nigba to ba to asiko.
N óo fun yín ní ẹgbaa (2,000) ẹṣin bí ẹ bá lè rí ẹgbaa (2,000) eniyan tí yóo gùn wọ́n.
Oúnjẹ Tí A Fi Rúbọ fún Oriṣa.
Sibẹsibẹ ninu àwọn kòkòrò tí wọn ní ìyẹ́, tí wọn ń fi ẹsẹ̀ mẹrẹẹrin rìn, ẹ lè jẹ àwọn tí wọn bá ní tete tí wọ́n fi ń ta káàkiri lórí ilẹ̀.
Iko omo-ogun oju ofurufu Naijiria ti sefilole ise akanse ara oto lati koju iko omo ogun olote boko haram ni eka ila oorun orile-ede Naijiria, eleyi ti won pe ni Operation Thunder Strike 2.
Ìtumọ̀ ìwo tí ó ṣẹ́, tí mẹrin mìíràn sì hù dípò rẹ̀, ni pé lẹ́yìn ikú rẹ̀ ni ìjọba rẹ̀ yóo pín sí mẹrin, ṣugbọn kò ní jẹ́ láti ọwọ́ rẹ̀.
Bẹ́ẹ̀ ni wọ́n ṣe fi Joaṣi jọba, Jehoiada alufaa ati àwọn ọmọ rẹ̀ sì fi àmì òróró yàn án lọ́ba.
Ẹ wá dánrawò níbí pẹ̀lú Àpólà Ọ̀rọ̀ Orúkọ, Noun Phrase"" Ta ni ìyàwó Chadwick Boseman, tó jẹ́ àwòkọ́ṣe rere f'áwọn ọ̀dọ́ Adúláwọ̀?"
Igbimọ to ga ju nile iwe EKSU ti fi ọwọ si igbesẹ naa.
 kò si ẹni to tíì sọ èyí fún mi  ‘A kò ní ìgbékẹ̀lé mọ́ nínú ọ̀gá ọ́lọ́pàá’ Nàìjíríà yóò ní iná, kò ní ní, di ìtahùn síra láàrin TCN, TUC Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Àwọn onímọ̀ ọpọlọ ní to bá gbé ìgésẹ̀ yí, aṣeyege dájú ní ìdánwò Ilé ìgbé Saraki to wà ní Ikoyi ní wọn fẹ̀sún kàn pé àwọn ajọ tó ń gbógun ti ìwá jẹgudujẹra tìí pa ní ìlú Eko.
Ṣugbọn ó wí fún wọn pé, “Èmi ni.
Àwọn pẹ̀gànpẹ̀gàn yóo ti ní inú dídùn pẹ́ tó ninu ẹ̀gàn pípa wọn,tí àwọn òmùgọ̀ yóo sì kórìíra ìmọ̀?
"Atẹjade naa ni ""Awọn ti a ri mu ninu abala keji iforukọsile ipagọ lọdun ọdun yii jẹ marundinlaadọrin, a si ti fi wọn le awọn agbofinro lọwọ."
"Ọpẹ bàbà mi lára mi, ti ìṣẹ̀lẹ̀ kan bá wáyé, tàbí táwọn oniroyin bá kọ nkan ti kii se òótọ́ nípa mi, ní máa béèrè ìmọ̀ràn lọ́wọ́ wọn, bí kii bá sì ṣe ìtọ́sọ́nà bàbà mi, afaimọ kí n má tí kọsẹ̀ nínú isẹ tíátà.
Fani-Kayode: Iwà Dino dójútini gẹ́gẹ́ bí olóṣèlú
Ìwà àìṣẹ̀tọ́ ń pọ̀ sí i, bẹ́ẹ̀ ni ìgbéraga ń rúwé.
” Bí wọ́n ti gbé ojú sókè, wọ́n rí i pé ẹnìkan ti yí òkúta náà kúrò, bẹ́ẹ̀ ni òkúta ọ̀hún sì tóbi gan-an.
Chelsea vs Leicester city: Lẹ́yìn àjẹranjú ìyà lọ́wọ́ Man United àti Liverpool, Wilfred Ndidi tún pa fìtílà Chelsea ní Stamford bridge
Tí a fiṣọwọ́ ní 12:21 11 Òkùdu 201912:21 11 Òkùdu 2019 Ìdìbò bẹ̀rẹ̀ padà!
'Orúkọ pásítọ̀ ni Magu fi ra ilé N573 mílíọ̀nù sì Dubai - PCARA Ọmọdé méjì àtàgbà kan ló kú nílé alájà mẹ́ta tó wó l'Eko pátápátá - LASEMA August Alsina ti fèsì sí ọ̀rọ̀ ìyàwó oníyàwó tó ń bálòpọ̀ Lójú òpó Instagram bákan náà ni ọmọ ti kéde tirẹ̀ pé òun àti bàbá òun ni àwọn jọ ni ààrùn náà tí àwọn si ti lọ fún ìyàsọ́tọ̀.
Kí ni o sọ nípa ara rẹ?
Fidio ọhun to tan kalẹ lori ayelujara ru ibinu awọn araalu soke, nigba ti wọn ri bi obinrin yii ṣe n fi bẹliiti na ọmọ naa, to si tun sọ si ile aja.
mẹrin-le-ojileọọdurun ati ookan (4,341), pẹlu awọn miiran bẹẹ.
Ìbànújẹ́ mi pọ̀ kọjá ohun tí ó ṣe é wòsàn,àárẹ̀ mú ọkàn mi.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Sunday Igboho: N kò gba kọ́bọ̀ lọ́wọ́ ẹnikẹ́ni láti wá ọ̀daràn jáde nínú igbó Kishi 30 Owewe 2020 Oríṣun àwòrán, Sunday Adeyemo Ọjọ nla ati manigbagbe ni ọjọ ti ilumọọka ajafẹtọ ẹni kan, Oloye Sunday Adeyemo, ti ọpọ eeyan n pe ni Sunday Igboho yabo igbo Kishi.
Felix Dumeh bẹrẹ si ka orukọ awọn eeyan jankajankan, awọn eekan ilu tawọn eeyan n ka orukọ wọn lawọn oju ewe iwe iroyin lojoojumọ, ọga agba kan lẹka ileesẹ ọlọpaa ọtẹlẹmuyẹ nipa iwa ọdaran CID, to wa nilu Ibadan, Patrick Njovens si lo kọkọ darukọ gẹgẹ bii baba isalẹ fun ikọ adigunjale oun Lẹyin eyi lo wa n ka orukọ awọn igi lẹyin ọgba rẹ yoku, to si tun darukọ igbakeji ọga agba lẹka ileesẹ ọlọpaa ọtẹlẹmuyẹ CID yii kan naa, Yesufu Bello nigba ti baba isalẹ rẹ kẹta jẹ Ọga agba ọlọpa miran nilu Ibadan, Amusa Abidogun Gbogbo orukọ ti ogbontagi adigunjale yii n da lo n se awọn ọlọpaa atọpinpin ni haa-hii, amọ ko pẹ lo tun darukọ Oloye Taiwo Ọrẹdẹin pe oun naa wa lara awọn igi lẹyin ọgba fun oun Kọmiṣọnna ọlọpaa nipinlẹ Kwara nigba naa, Sunday Adewusi bẹrẹ si finmufinlẹ nipa awọn eeyan ti Felix ka orukọ wọn yii, to si gbe olori tọọgi oloselu kan nilu Ibadan to n sisẹ fun Ọrẹdẹin, ẹni ti wọn n pe orukọ rẹ ni Mustapha Adigun, ti gbogbo eeyan mọ si Balewa abi Tafa Igiripa Balewa yii si lo jẹwọ pe nirọlẹ ọjọ ti wọn digunjale lọna Bacita naa ni oun tẹle ọga oun, Ọrẹdẹin, lọ sile Felix Dumeh, tawọn ọga ọlọpaa ti wọn n se iwadii wọn naa si wa pẹlu Dumeh lasiko yii Balewa ni Felix gbe ọti ogogoro kan ati ataare jade eyi ti wọn mu lati fi mulẹ pe ohun tawọn se ko ni hun awọn, o ni lẹyin eyi lo gbe apo owo kan jade, ti Ọrẹdẹin kọkọ gba lọwọ oun ki Amusa Abidogun to ja a gba mọ lọwọ, to si gbee fun ọga rẹ lẹnu isẹ ọlọpaa, Njovens, igba to si si apo iwe naa, ni Balewa ss pe oun foju kan owo kọrẹnsi to pọ pupọ O ni Njovens beere pe eelo ni owo naa lọwọ Felix, ti onitọun si dahun pe marun amọ ti ọga ọlọpaa naa mi ori rẹ pe sebi adehun meje lawọn dijọ sọ, amọ Felix ni awọn eeyan pọ lori owo naa, ko ba oun gbaa bẹẹ, ti ọga ọlọpaa naa si ni akọsapo ni a kọ owo, to si gbaa Ni kete ti Adewusi gbọ awọn ọrọ ẹri yii lo si pasẹ pe ki wọn gbe awọn ọga ọlọpaa kan lọ silu Ibadan lati finmu-finlẹ nipa isẹlẹ naa, ki wọn si mu abọ wa fun oun, amọ fun iyalẹnu rẹ, se ni awọn eeyan ti wọn lọ finmu-finlẹ naa bọ si ahamọ awọn eeyan mẹtẹẹta ti wọn lọ se iwadii wọn Lẹyin o rẹyin, wọn tu awọn ọlọpaa Adewusi to wa lahamọ nilu Ibadan silẹ, ti wọn si fewe ọmọ mọ wọn leti pe wọn ko gbọdọ wa silu Ibadan mọ amọ eyi bi Adewusi ninu pupọ, ti oun gangan si wa silu Ibadan funra rẹ, o gbe awọn ọga ọlọpaa mẹtẹẹta naa lọ silu Ilọrin, to si tun kesi Ọrẹdẹin pe oun fẹ fi ọrọ wa lẹnu wo Ẹnu ya Ọrẹdẹin lati foju kan Balewa, Adigun ati Felix ni ahamọ awọn ọlọpaa nilu Ilọrin, ti Adewusi si pasẹ fun wọn pe gbogbo ọrọ ti wọn jẹwọ lẹyin Ọrẹdẹin, ni ki wọn sọ loju rẹ, ti awọn onitọhun naa si se bẹẹ, ni jẹbẹtẹ ba gbe ọmọ le agba oselu naa lọwọ Ariwo sọ, ilu mi titi lori iroyin naa, ti ọpọ si n beere pe ki lo lee sun eeyan nla bayii de idi iwa idigunjale, a se ẹni taa gboju okun le, ko jọ ẹni agba Paapa nigba to jẹ pe Ọrẹdẹin kii ṣe akusẹ, o lowo, o lọla, o ni ọpọ ile, ọkọ ayọkẹlẹ ati dukia loniran nran Lasiko igbẹjọ rẹ nile ẹjọ fun ẹsun ṣiṣe onigbọwọ ati gbigba ere idigunjale, Ọrẹdẹin ati awọn ọga ọlọpaa mẹta yoku kawọ pọnyin rojọ, to si sẹ kanlẹ pe oun ko jẹbi awọn ẹsun ti wọn fi kan oun tori ilu abinibi oun, Ogere ni oun wa lọjọ ti isẹlẹ idigunjale naa waye, to si tun sẹ lori awọn ẹsun ti Felix fi kan an Adajọ Moradeyọ Adesiyun lo gbọ ẹjọ naa, ti Oloye Rotimi Williams si jẹ agbẹjọro fun Ọrẹdẹin ati Patrick Njovens, Richard Akinjide si lo duro bii agbẹjọro fun Bello ati Abidogun.
Okan lara awọn ayalegbe to n gbe nile naa, ọgbẹni Kabiru ni opo ile naa kan lo kọkọ da wo ni ijẹta ni eyi ti onile fẹ tun ṣe.
Idi pataki ti awọn eniyan fi nilo lati ls sileewosan ni ti eemi wọn ko ba ja gaara.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Aláàfin: Àìrí iṣẹ́ ṣe ọ̀dọ́ lágbègbè mi ń peléke, ó sì nílò àmójútó 5 Ògún 2019 Oríṣun àwòrán, Alaafin Oba Adeyemi III Alaafin tilu Ọyọ, Ọba Lamidi Ọlayiwọla Adeyeme Kẹta ti rawọ ẹbẹ si gbajugbaja olokoowo nii, Aliko Dangote lati nawọ iranwọ rẹ fi da ile iṣẹ silẹ ni agbegbe rẹ.
orile ede Naijiria tile-toko lati jawọ ninu awon aheso ọrọ , ki won si gba ẹmi
25 Ẹrẹ̀nà 2019 Oríṣun àwòrán, Alamy Aarẹ orileede Mali Boubacar Keita ti parọ olori awọn oṣiṣẹ ile iṣẹ ologun ati olori awọn ọmọ ileeṣẹ ologun lori ikọlu to mu ẹmi awọn eeyan ẹya Fulani to le ni aadoje lọ.
 Diẹ lara iriri John fi ara jọ nkan ti awọn ọkunrin yooku ti Dokita Weare fi ọrọ wa l'ẹnuwo."
O wulo fun ẹni to ba fẹ jo.
Ìjọba ilẹ̀ Gẹ̀ẹ́sì sì dá ọjọ́ Ìṣẹ́gun gẹ́gẹ́ bíi ọjọ́ ìsimin fún gbogbo àwọn òṣìṣẹ́ kí wọ́n ó le r’áàyè lọ wòran níbi ayẹyẹ nlá yìí.
Bakan naa, ni aare yoo tun maa foju gan an  ni ile ise to n ri si eto irinna ati awon ile-ise miiran.
Ọjọ Aiku ni eto naa yoo wa sopin.
Yí ojú mi kúrò ninu wíwo nǹkan asán,sọ mí di alààyè ní ọ̀nà rẹ.
Jẹ́ kí ojú ó ti àwọn onigbeeraga,nítorí wọ́n ṣe àrékérekè sí mi láìnídìí;ní tèmi, n óo máa ṣe àṣàrò lórí òfin rẹ.
Saaju iku rẹ lo ti n sọrọ rere nipa iyansipo Asiwaju Bola Tinubu gẹgẹ bii aarẹ labẹ APC ni 2023.
Lati igba yii ni orisirisi ẹjọ ti n waye lori iṣe si ati ihuwasi rẹ, to fi mọ kikọ olu ile iṣẹ ajọ EFCC naa.
Fún odidi ọdún mẹ́rìnlá tí ẹ̀dá náà ffi wà ní òde ọ̀run wọn kò yí ọkùnrin náà ní ipò padà.
Ati irinajo Senegal ati eyi to ṣẹsẹ n lọ yi, ko si eleyi to dun mọ awọn ara ilu kan ninu.
Oriṣabunmi jade laye ni ọjọ Iṣẹgun, ọjọ karun un oṣu kini ọdun 2021.
Gomina Makinde, àgbọ́gbọn'tí ni kẹ́ẹ gbọ́ àwọn ará Oyo o lórí sáà kejì 'torí.
Ibi tí wọn ń ti àwọn tí ọba bá sọ sí ẹ̀wọ̀n mọ́ ni wọ́n tì í mọ́.
Ọ̀rọ̀ di bóòlọ-o-yà fún mi lónìí, ní ibi ayẹyẹ àyájọ́ àwọn òṣìṣẹ́ tó wáyé ní pápá ìṣeré Agége nilú Èkó nígbàtí àwọn ọmọ ẹgbẹ́ ọlọ́kọ̀-èrò NURTW kan bẹ̀rẹ̀ sí ní gún àwọn òṣìṣẹ́ kan lọ́bẹ.
Buhari, pe ìpàdé àpérò ọmọ Nàíjíríà fún àgbékalẹ̀ òfin tuntun - Afe Babalola Van Dijk gbadé UEFA mọ́ Messi àti Ronaldo lọ́wọ́ Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
O ni oniruuru idunkoko mọ ni, ifiyajẹni ati ibẹru lo gba ilẹ yi kan lasiko yi, to si dabi ẹnipe oju ọrun su dẹdẹ lai rọ ojo, nitori naa, isẹ nla lo n bẹ niwaju Aarẹ Ọna Kakanfo tuntun lati ri daju pe aabo to peye wa lawọn ẹnu bode to wọ ilẹ Yoruba.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Uganda faulty condom: Uganda kó rọ́bà ìdáàbòbò mílíọ̀nù kan kúrò ní ìlú 23 Bélú 2019 Oríṣun àwòrán, Marie stopes Uganda Àkọlé àwòrán, Marie Stopes salaye pe wọn ti bẹrẹ iwadii lori ohun to ṣokunfa abuku ninu ọra idaabobo wọnyii Ile iṣẹ arannilọwọ kan ti kii ṣe ti ijọba ni orilẹ-ede Uganda ti palẹmọ awọn rọba idaabobo wọn kuro nilẹ.
Orile ede mejeeji naa jo forikori lori ona
 Ìṣẹ ́ gun yìí fún napoleon ní agbara láti máa darí ilẹ ̀ ìlú Òyìnbó .
Military Bruitality: Sójà obìnrin lù mí lálù bami nílùú Ibadan
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Fifi ẹjẹ silẹ maa n jẹ ohun ayọ pe o le gba ẹlomii silẹ Ni ipari: Bi o ṣe lagbara naa ni o ni ilera lati fi ẹjẹ silẹ.
Isola ni Hajjum tumọ si adisọkan irinajo, Alhajjum si tumọ ẹni to gbero lati rinrin ajo sugbọn lẹyin to ba de tan, Visito abi Sahel, to túmọ̀ si olubẹwo ni wọn yoo pe.
Femi Adebayo Salami Aṣọ to gbajugbaja ni oṣere Femi Adebayo Salami fi dawọ idunnu opin ọsẹ.
Kò sí ẹni tí ó lè de wèrè náà mọ́lẹ̀; ẹ̀wọ̀n kò tilẹ̀ ṣe é fi dè é.
Coronavirus lè tara òkú Abba Kyari ran àwọn tó péjú síbi ìsìnkú rẹ̀- Ààrẹ ẹgbẹ́ dókítà ní Nàìjíríà Awọn orilẹede mẹwaa ni ajakalẹ ebi yii yoo ṣe ọṣẹ fun julọ, gẹgẹ bi ajọ to n ri si eto ounjẹ lagbaye ṣe sọ.
Gẹ́gẹ́ bi àṣà àdáyébá, ẹ͂kan ni ọdún nigba ọdún  Ọlọ́jọ́ ti wọn ma nṣe ni oṣù kẹwa ọdún ni Ọba lè dé Adé Aàrẹ Oduduwa.
Wọ̀n á sí máa fi ọmọ wọn tí ó bá jẹ́ akíkanjú tàbí alágbára yangàn láwùjọ.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Kunle Olajide ni Baba Obasanjọ ni ọgbọn to bẹẹ gẹ ti ko jẹ ijọba ologun tun gba ijọba lẹyin ti o ṣẹ ijọba alagbada fun ọdun mẹjọ lati ọdun 1999 si 2007.
Ọlọpaa ti mu George Floyd lọpọ igba Lọpọ igba lawọn ọlọpaa ti mu George Floyd fun ẹsun kan tabi omiiran lorilẹede Amẹrika.
Awọn oludije ẹgbẹrun mẹjọ lo n dije fun ipo oriṣiiriṣi ninu ẹgbẹ oṣelu aadọrin le ni ẹgbẹta ni orile-ede India.
Mo fẹran amin tuntun ti wọn fun un bayii.
Aisha Buhari sọ èyí di mímọ̀ lásiko tó ń ba BBC sọ̀rọ̀, ó ni ọ̀pọ̀ àwọn mínísítà tó n ba ọ̀kọ òun ṣiṣẹ́ ni kò damọ.
DSTV ati GOTv ni wọn yoo maa gbee sita.
Ṣé bó ti wu Elédùà ló ń ṣ’ọlá ẹ̀?
A ko ti i le fidi ọrọ mulẹ awọn to ṣe ikọlu naa ṣugbọn awọn ọmọ ikọ Boko Haram a maa ṣoro lagbegbe yi loorekoore.
" Ó ní oun n pè fun ìpàdé pàjáwìrì ninu àjọ ìsọ̀kan àgbáyé.
Osu keji ọdun 2020 si ni olori Damilola bi ọmọkunrin tuntun fun Alaafin Ọyọ.
Lẹ́yìn nǹkan wọnyi, àwọn olórí àwọn ọmọ Israẹli wá sọ́dọ̀ mi, wọ́n ní: “Àwọn ọmọ Israẹli pẹlu àwọn alufaa ati àwọn ọmọ Lefi kò ya ara wọn sọ́tọ̀ kúrò ninu ìwà ìríra àwọn ará Kenaani ati àwọn ará Hiti, ti àwọn ará Perisi ati àwọn ará Jebusi, ti àwọn ará Amoni ati àwọn ará Moabu, àwọn ará Ijipti, ati àwọn ará Amori.
Lẹyin eyi ni gomina ipinlẹ Ondo ti o tun jẹ alaga awọn gomina ilẹ Yoruba, Rotimi Akeredolu ti ṣiṣọ loju awọn ọkọ iwọde fun Amọtẹkun.
Àwọn ọmọ ìwòyì kò dára o, ẹ má ṣe fi ara sílẹ̀, nítorí bí mo ti ń wòye yìí, bí ẹ kò bá sọ̀ra, ọjọ́ ń bọ̀ tí ọmọ náà yóò kó àwọn ọmọ ogun wá, ti wọn yóò ba a yín jà, ti wọn yóò le e yín kúrrò lórí ìtẹ́.
Gẹgẹ bi ohun ti awọn ileeṣẹ iroyin abẹle kan sọ, ohun ti awọn eeyan n sọ ni pe awọn ọẹọpaa lo ṣeeṣe ki wọn ṣina ibọn bolẹ fawọn eeyan naa.
N óo yan ẹnìkọ̀ọ̀kan ninu yín láti inú ìlú kọ̀ọ̀kan, n óo mú meji meji láti inú agbo ilé kọ̀ọ̀kan, n óo sì ko yín wá sí Sioni.
Báyìí ni Johanu bẹ̀rẹ̀ sí ṣe ìrìbọmi ninu aṣálẹ̀, tí ó ń waasu pé kí àwọn eniyan ronupiwada, kí wọ́n ṣe ìrìbọmi, kí Ọlọrun lè dárí ẹ̀ṣẹ̀ jì wọ́n.
Wọn ṣe akojọpọ iye awọn obinrin ti wọn pa pẹlu agbelewọn pe awọn iku yi wa l;ati owo ẹni to jẹ ololufẹ tabi mọlẹbi.
Ní tiwa, àwa mọ̀ pé ẹlẹ́ṣẹ̀ ni ọkunrin yìí.
CAF Awards: Ahmed Musa, Alex Iwobi, Asisat Oshoala wà lára olùdíje àmì ẹ̀yẹ CAF
Nígbà tí ó bá jọba, àkókò díẹ̀ ni yóo ṣe lórí oyè.
Oríṣun àwòrán, osun state government/ twitter O ni bi orilẹede ṣe n pinu lati ṣi awọn ibi ipejọpọ itagbangba, wọn gbudọ rii pe wọn ṣi n ṣe ohun gbogbo lati bori.
Gbogbo ìran Jeroboamu pátá ni Baaṣa pa láìku ẹyọ ẹnìkan, gẹ́gẹ́ bí ọ̀rọ̀ tí OLUWA ti sọ láti ẹnu iranṣẹ rẹ̀, wolii Ahija, ará Ṣilo.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ìjàmbá reluwe ní Agége pa èèyàn mẹ́jọ Olùdíje méta yẹ̀bá nínú ìbò abẹ́lé APC l‘Ọ́sun Ọwọ́ tẹ Dókítà tó ṣe iṣẹ́ abẹ ìdí ńlá f'óbìnrin tó kú Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Gbajúgbajà òsèré tó tún mọ́ ọbẹ̀ sè Awọn onimọ ijinlẹ to se iwadi naa, ṣe agbeyẹwo idahun ti awọn eniyan okoo le lẹgbẹta o le ẹyọ kan (621) to ni jẹjẹrẹ ile itọ ọkunrin, ati ẹgbẹrun le nigba ati marun-un (1,205) awọn to ni jẹrẹrẹ ọyan, to fi mọ ọrin le lẹgbẹrin o din mẹjọ (872) ọkunrin, ati ẹgbẹrun kan le ni ọọdunrun (1,205) obinrin ti ko ni jẹjẹrẹ.
Kí Olódùmarè dá ẹ̀mí sí, rírí tí mo rí ọ yìí ti fi hàn mi pé ọ̀rẹ́ pàtàkì na a máa jẹ́ fún ara wa.
Aarẹ Buhari kẹ́dùn ọ̀pọ̀ ẹ̀mí àti dúkìá tó jóná ni ọjà Onitsha Ọmọ Nàìjíríà, ẹ forijìn mí!
nikan ni won  gba laaye ni awọn agbegbe ihamọ ti awọn ọkọ
Aye olori ijoba si sile, leyin ti olori ijoba Hailemariam Desalegn kowe fi ipo naa sile, egbe oselu to wa lori alefa lorile-ede Ethiopia, Ethiopia Peoples Democratic Front (EPRDF) ni ireti wa pe, won yoo se ipade gbogbogbo lati yan eni ti yoo dipo Desalegn, amo, Ahmed yoo maa se ojuse re titi ti egbe oselu naa yoo fi mo ohun ti won yoo se.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìbálé ìyàwó: Àwọn onímọ̀ sọ ìdí tí àwọn obìnrin kan kìí ṣe sẹ̀jẹ̀ lẹ́yìn ìbálòpọ̀ àkọ́kọ́ 29 Ọ̀wàrà 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Ibi gbogbo ni wọn ti nko adiẹ alẹ, akoko lo kan yatọ bẹẹ si ni bo se n bẹ ni liki naa lo wa ni gbanja.
Sara Jayne mọ pe oun ko fi awọ jọ awọn toun n pe ni obi oun, amọ ko wa si ero rẹ rara pe alawọ dudu ni, afi igba ti awọn eeyan ilu Surrey jẹ ki eyi ye, tawọn akẹẹgbẹ rẹ nile iwe si maa n fi irun ori rẹ we waya olowu, oun nikan si ni alawọ dudu to foju ganni ri, lọpọ igba si ni wọn maa n sọ fun pe o da yatọ.
Kódà nígbà ti mo mu ú tán, wéré ni mo tún rà’míì mu.
Nígbà tí ọba gbọ́ ohun tí ó wà ninu ìwé òfin náà, ó fa aṣọ rẹ̀ ya láti fi ìbẹ̀rù ati ìbànújẹ́ rẹ̀ hàn.
O mú un jọba lórí àwọn iṣẹ́ ọwọ́ rẹ,o sì fi gbogbo nǹkan sí abẹ́ ẹsẹ̀ rẹ̀: 
Iṣẹ́ tí Natani Jẹ́ ati Ìrònúpìwàdà Dafidi.
”Akitiyan ti a ko lee gbagbe Aare Buhari tun lo anfaani naa lati gboroyin fun awon oludari eka orile-ede ti o kogun si Chad ati apapo awon omo ogun ile ohun fun akitiyan won lojuna ati tun fese igbe aye alafia mule sinisn nile Afrika.
Ohun tó yẹ kí o mọ̀ nípa ìbòmú tí ń lò yẹ́n Coronavirus ti di ara wa, kò le è kúrò mọ láéláé - WHO Ọrọ kan ṣoṣo maa n tumọ si nkan mẹrin nigba mii tabi ju bẹẹ lọ ni eyi ti ami ori wọn maa n fi iyatọ han bii ìgbà, igbà, ìgbá, àti igba.
Afurasi naa, ni iroyin sọ pe oun ati awọn miran, to ti ṣa lọ bayii, tun ṣe ẹlomiran, Chigbo Ugbala leṣe, nipa fifi igi lu u, ti wọn si tun fi àdá ṣa, nibi eto igbani wọle naa.
kwara state polytechnic jẹ ́ ọ ̀ kan lára àwọn ilé-ẹ ̀ kọ ́ gbogbo-nìṣe ilẹ ̀ nàìjíríà tí olórí ìjọba ológun ìpínlẹ ̀ kwara tẹ ́ lẹ ̀ Ọ ̀ gágun col.
Samuẹli sì ń dàgbà níbi tí ó ti ń ṣe iṣẹ́ iranṣẹ sin OLUWA.
Eto naa, eyi ti wọn sefilọlẹ rẹ lagbegbe Sahara nilẹ Afirika, ni yoo tun fi aan ede adulawọ miran bii Yoruba, Igbo Swahili, Wolof, Afrikaans, Zulu, Setswana ati Sotho sinu iwadi rẹ.
Mẹfiboṣẹti bá bẹ̀rẹ̀ sí jẹun lórí tabili ọba, gẹ́gẹ́ bí ọ̀kan ninu àwọn ọmọ ọba.
Mustpaha ni ile-iwe alakọbẹrẹ unit 008 Bako to wa ni  ẹkun ijọba ibilẹ  Gusu ni Yola.
Yorùbá dùn lédè, ẹ máa sọọ́ Ẹfunroye Tinubu - Ògbóǹtagí oníṣòwò, olówò ẹrú àti afọbajẹ Samuel Ajayi Crowther, òjíṣẹ́ Ọlọ́run tó gbé èdè Yoruba lárugẹ Mọrèmi Àjàṣorò, akọni obìnrin tó gba Ilé Ifẹ̀ sílẹ̀ lóko ẹrú Ikọ BBC Yoruba ṣe abẹwo si ibudo ise nkan isembaye lọjọ si naa, ti oludari ibudo naa, alagba Yusufu Amuda Adepeju ti ṣe alaye nipa awọn nkan ti o wa ni ile naa.
Igbesẹ naa lo si waye lẹyin ti aarẹ to wa nipo, Allassane Quatara ni oun ko ni lọ fun saa kẹta lori oye.
 Ṣé ẹ rántí àkọ́lé àwọn ìwé àkàgbádùn yìí?"
OLUWA ní, “Ẹ̀yin ọmọ Israẹli, bí ẹ bá fẹ́ yipada, ọ̀dọ̀ mi ni kí ẹ pada sí.
Inú ọmọdé ma ndùn nitori asiko yi ni wọn nse irẹsi àti pa adiẹ fún ọdún.
Mo tún rí àpẹẹrẹ ọgbọ́n kan nílé ayé, ó sì jẹ́ ohun ribiribi lójú mi.
Ọpọ awọn to ti jẹ ṣeku lo ti n woye lati gbakoso ileeṣẹ naa, ṣugbọn orukọ ẹni ti awọn eeyan n jẹ lẹnu ju ni Tayo Amusan.
Peteru pẹlu àwọn aposteli dáhùn pé, “A níláti gbọ́ ti Ọlọrun ju ti eniyan lọ.
"Ṣugbọn o ni ""wọn ri gba ju oun ti wọn gbe wa lọ""."
Ìwọ̀nba ẹ̀yin tí ẹ bá ṣẹ́kù, kíkú ni ẹ óo máa kú sára lórí ilẹ̀ àwọn ọ̀tá yín, nítorí àìdára yín ati ti àwọn baba yín.
"Gómìnà Makinde ní "" Ààrùn náà sì wà pẹ̀lú wa dájúdájú, pé à n gbìyajú láti dá ọrọ̀ ajé padà bọ̀ sípò kò túnmọ̀ si pé ààrùn náà ti di oun ìgbàgbé"" "" Ó ṣe pàtàkì kí a máa mójú tó ara wa nípa wfífọ ọwọ́ wa déédé pẹ̀lú omi aàti ọṣẹ , kí a sì maa wọ ìbòmú ti a bá ti wà pẹ̀lú àwọn eníyà, ìjìnà síra ẹni náà si ṣe pàtàkì pẹ̀lú."
Ìkọlù UK: Agbébọn pa ọmọ asòfin àpapọ̀ Nàíjíríà kan
 Ọ ̀ rányàn kò sí nílé , àwọn ẹ ̀ gbọ ́ n rẹ ̀ sì pín gbogbo dúkìá bábá wọn mọ ́ ọwọ ́ , ilẹ ̀ nìkan ni wọ ́ n fún un .
Ilu Ado Ekiti ni Afẹ Babalọla ti woye ọrọ yii lasiko ti ajọ isọkan ilẹ Afirika n fi oye Awokọse rere nilẹ Afirika da lọla.
Gẹgẹ bi akọsilẹ to wa ni ori ayelujara ileeṣẹ eto ilera ilẹ United Kingdom, inu ifun to tobi ju ninu ara, ni jẹjẹrẹ naa ti ma n bẹrẹ.
Nígbà tí a jẹun alẹ́ tán tí gbogbo wa jókòó sí orí ẹní lọ bẹẹrẹ tí a ń sọ̀rọ̀ nínú òṣùpápẹ̀lú Baba-onírùngbọ̀n, mo dá ọ̀rọ̀ lílọ wa sílẹ̀, mo béèrè lọ́wọ́ Baba-onírùngbọ̀n bóyá ó lè mọ ọ̀nà tí a lè gbà padà dé ilé wa.
O lootọ awọn ko ni ikapa kankan lati mu aarẹ ni dandan ṣugbọn o ti wa fẹ di lemọlemọ pe wọn yoo fi ọmọ Ibadan to kaju oṣunwọn silẹ ti wọn yoo si yan ọmọ Ilu mi sipo ọga fasiti Ibadan.
Omotara pàdánù isẹ́ olówó ńlá nítorí ó fi ọtí ẹlẹ́rìndòdò sódà lá ọmọ alágbe lójú Ilé aṣòfin orílẹ̀-èdè UK ti faramọ́ fífí ìyà jẹ àwọn adarí Naijiria tọ lọ́wọ́ nínú rògbòdìyàn ENDSARS Jemila dáná sún ilé ọ̀rẹ́kùnrin rẹ̀ àti ọ̀rẹ́bìnrin tó bá nílé Èyí ni ohun tí Ọọ̀ni sọ nípa Àrẹ̀mọ rẹ àti ètùtù tó ń ṣe lọ́wọ́ Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Fídíò, Akọ́mọlédè àti Àṣà lórí BBC Yorùbá: Kọ́ síi nípa iṣẹ́ tí oúnjẹ ń ṣe lára níbí24 Bélú 2020 Lagos State Task Force: Lóòótọ́, a tí mú Ọlọ́páà to f'ọ̀nà ẹ̀bùrú gba owó ẹ̀yìn N100k lọ́wọ́ awakọ̀24 Bélú 2020 Omotara: Mo kábámọ̀ ìwà tí mo hù sí ọmọ alágbe, mo wá a títí ṣùgbọ́n mi ò mọ ibi tó wà26 Bélú 2020 Nigeria government - Lekki Toll Gate - Kí ló wà ninú lẹ́tà tí ìjọba Naijiria kọ sí CNN24 Bélú 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
(Àwọn ni ọmọ tí Lea bí fún Jakọbu ní Padani-aramu ati Dina, ọmọ rẹ̀ obinrin.
A ti rí ọ, Ọlọrun, bí o tí ń yan lọ,pẹlu ọ̀wọ́ èrò tí ń tẹ̀lé ọ lẹ́yìn.
Africa  Cyril Ramaphosa lọ si awon ileto
Ẹ ya ara yín sí mímọ́ kí ẹ bá mi lọ síbi ìrúbọ náà.
Bi wọn ko ba si sọra, orukọ ti wọn kọ si ọwọ iru ọmọ tuntun bẹẹ le jabọ laimọ, ti yoo si nira lati mọ iru ọmọ ẹni tii se.
Igbimọ oluwadi naa ri wipe ọpọlọpọ awọn ọmọ ogun Naijiria to fi mọ Ọgagun Niyi Oyebade to jẹ olori ikọ ọmọogun Naijiria kinni lasiko igba naa lọwọ si iṣekupani naa, o si tun daba rẹ wipe ki wọn o fi oju wọn wina ofin Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, ICC bere fun itusile olori ẹgbẹ Shiite, Ibrahim El-Zakzaky to wa lahamọ ajọ ọtẹlẹmuyẹ DSS Ẹgbẹ Shiite ni awọn ọmọ ẹgbẹ rẹ to le ni ẹgbẹrun kan lo j'ọlọrun nipe lasiko ikọlu naa to waye laarin ọjọ kejila si ikẹrinla osu kejila lolu ile ẹgbẹ rẹ to wa ni Zaria.
Ipinlẹ Enugu, Katsina, Bauchi, Gombe pẹlu ni awọn ko tii lee ṣe ohun to js bẹẹ lọwọ yii.
Se ni agbegbe yaba nilu eko n ro gbarọ gbudu lasiko ayẹyẹ iwuye naa eyi ti ẹbi, ọrẹ, ololuf ati awọn alajọsepọ rẹ peju si.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Yinka Ayefele fi orin ẹ ṣeun sẹ́nu lórí ilé orin tuntun rẹ̀ 8 Sẹ́rẹ́ 2019 Oríṣun àwòrán, yinkaayefele Àkọlé àwòrán, Yinka Ayefele Gbajúgbajà olórin tó tún jẹ́ alága ilé iṣẹ́ rẹ́díò Fresh FM nílùú Ibadan, yinka Ayefẹlẹ gbóríyìn fún Gómìnà Abiọla Ajimọbi pé ó tún ilé orin rẹ̀ kọ̀.
tun jẹ agbenuso fun gbogbo egbe oloselu lorile ede Naijiria, fi aidunnu re han
Lati ileto Bordo de ileto to sun mọ ọ ju jẹ kilomita mọkandilọgbọn, yatọ si pe ileto naa da wa, ọna to so o pọ mọ ibi ti ileewosan naa wa ko dara rara.
5 mílíọ ́ nù ìṣẹlẹ ̀ ní 1986 .
Ìjọba Èkó figbé ìkìlọ̀ ta Nítorí Sẹ́nétọ̀ Adeleke, ìyá àti ọmọ gbé iléeṣẹ́ ọlọ́pàá lọ sílé ẹjọ́ Baale Apese d'àwátì, ó bọ́ sọ́wọ́ ajínigbé!
Farao ati ogunlọ́gọ̀ àwọn eniyan rẹ̀ ni mò ń sọ nípa wọn.
Ó lọ títí dé Jẹriko, ó sì pin sí odò Jọdani.
Precious Owolabi to n sinru ìlú pẹlu ileeṣẹ amohunmaworan Channels TV ti gbẹmi mi nibi ikọlu Shiite.
Ṣugbọn àwọn arakunrin rẹ̀ kò bí ọmọ pupọ, bẹ́ẹ̀ ni ẹ̀yà rẹ̀ kò pọ̀ bí ẹ̀yà Juda.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Risikat Azeez: Ìyá àti bàbá ọmọ olójú búlù tí parí ìjà- wọ́n fẹ́ tún yìgì so Nitori pe oṣu oju ọrun ni wọn maa n tẹle, ko si kankan ninu awọn oṣu yii ta le sọ pe gerege iye ọjọ bayii lo jẹ.
iyawo rẹ Ranti  naa ti dibo is wife,
OLUWA ní, “Sọ fún àwọn eniyan yìí pé èmi OLUWA ni mo la ọ̀nà meji níwájú wọn: ọ̀nà ìyè ati ọ̀nà ikú.
Alufaa yóo fi ohun jíjẹ ati ohun mímu rẹ̀ rúbọ pẹlu.
Oríṣun àwòrán, @justempower Àkọlé àwòrán, Osu Kejila ọdun 2019, paapa lati ọjọ aisun ọdun Keresi ni awọn ologun ti ya bo agbegbe Tarkwa Bay, ti wọn si n le awọn eeyan tipa tikuuku.
Ó kú, a sì sin ín sí ìlú Dafidi, baba rẹ̀.
Ó ń wí pé, “Àkókò tó; ìjọba Ọlọrun súnmọ́ ìtòsí.
Awọn obinrin mejeeji naa ni ọkan meji, apa ọtọọtọ, sugbọn wọn so papọ lati idodo titi de isalẹ, pẹlu ẹdọ ati ẹdọfooro Osu Kejila ọdun to kọja ni wọn fi wọn si ile iwọsan, lẹyin ti wọn ni aisan ọkan, sugbọn wọn ku ni Ọjọ Abamẹta ọsẹ to kọja.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ooni Ile Ife: Màmá tó bí ìyá Ọọ̀ni ilé Ifẹ̀ ju awà sílẹ̀ lẹ́ni ọdún 103 8 Òkùdu 2020 Oríṣun àwòrán, MOses olafare Ọọni ile Ifẹ, Ọba Adeyẹye Ogunwusi, Ọjaja keji ti padanu Iya-iya rẹ, iyaafin Comfort Faramọbi Ajọkẹ Ọlasọji Sọji-Ọpa.
Bẹ́ẹ̀ ni mo múra tí mo ṣán oko tí mo gbin àgbàdo mi kan yìí sí i.
Ogbontarigi akorin omo orile ede Tanzania, Diamond Platnumz, ti toro aforijin lori fifi fidio ti oun ati obinrin kan ti n fenu ko ara won lenu sita lori ikanni Instagram ayelujara re.
Àwọn ọbá aláye ilẹ̀ Yorùbá márùn-ún pẹ̀lú ọ̀pá àṣẹ wọn Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Egbò tó ti fẹ́ẹ̀ jiná ni ìtàn bí wọ́n ṣe pa Soun Ogbomoso, Ọba Olayode tẹ ń bèrè' Eko, Kwara, Osun àtàwọn ìpínlẹ̀ míì tí àwọn èèyàn ti jí oúnjẹ ìrànwọ́ Covid-19 kó Lẹyin ti ọpọ awọn ipinlẹ ti kede ofin konile-o-gbele nitori iwọde EndSARS, awọn janduku bẹrẹ si nii kọlu awọn ile ti ijọba ko ounjẹ iranwọ Covid-19 si, ti wọn si bẹrẹ si n ji i ko.
Lara awon eniyan ti o wa sibi eto idibo ohun lati ri: igbakeji alaga egbe oselu APC ti o n soju fun ekun gusu iwo oorun, ogbeni Emma Eneukwu ati adele adari awon obinrin, iyaafin Oby Nwofor.
Níbẹ̀ ni pẹpẹ wúrà wà fún sísun turari, ati àpótí majẹmu tí a fi wúrà bò yíká.
Gẹgẹ bii ileri ti wọn ṣe, awọn ọmọlẹyin Ibrahim Elzakzakky to jẹ aṣiwaju ijọ ẹsin Shiite ni Naijiria fọn si igboro lọjọ Iṣẹgun lati ṣeto irin idaro Ashura eleyi ti gbogbo awọn ẹlẹsin Shia kaakiri agbaye maa n ṣe ni ọjọọjọ kẹwaa, oṣu kẹsan an, ọdun.
À ṣé àwòdì méjì ti rí bàbá láti ìgbà tó ti wọ inú ìletò.
 Nitori ko lọ sibi adura naa lorukọ ara rẹ, ṣugbọn o lọ lorukọ ijọba ipinlẹ Oyo.
    Wọ́n ní ki n jíṣẹ́ báyìí fún yín, pé bí ẹ kò bá fẹ́ ìjà, kí ẹ ko àwọn ìbọn ọwọ yín jọ kí ẹ kó wọn fún oníbodè Elégbèje kí ó tó di agogo mẹ́jọ àbọ̀ òwúrọ̀ ọla, bí ẹ bá ṣe ijàǹbá, wọn ni àwọn ó jẹ́ kí ẹ lọ sí òkè Ìrònù láìsí ìjà láìsí ìpalára.
OAU lé ọ̀jọ̀gbọ́n tó bèèrè ìbálòpọ̀ fún máàkì Oríṣun àwòrán, @OfficialOAU Àkọlé àwòrán, Ohùn un ọ̀jọ̀gbọ́n Akindele tí o ń bèèrè fún ìbálòpọ̀ ìgbà lọ́wọ́ akẹ́kọ́bìnrin kan bọ́ sójú agbami ayélujára lọ́sẹ̀ tó kọja Àwọn aláṣẹ fásitì Ọbáfẹ́mi Awólọ́wọ̀, OAU nílu ilé ifẹ̀ ti pàṣẹ lọ rọọ́kún nílé fún ọ̀jọ̀gbọ́n Richard Akindele tí ẹ̀ka ìmọ̀ nípa ìṣirò owó tí wọ́n ní, o ń bèèrè fún ìbálòpọ̀ ìgbà máàrún ọ̀tọ̀ọ̀tọ̀ nítoríi máàkì.
alayeluwa Dr Ibrahim Bello, ti n se Emir ilu Gusau.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Obinrin Akansẹ: Ẹsẹ kiku bi ojo kọ mi lati di alagbara Ki ni 100 Women?
Ẹwẹ, alukoro ọlọpaa Ogun jẹ ko di mimọ pe awọn ti n ko awọn ti n ko wọn lọ si olu ile iṣẹ awọn bayii fun abo to daju ati lati fi ẹkunrẹrẹ ọrọ fun awọn oniroyin.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: 'A máa ń fí oògùn olóró 'ginger'ká tó ka ẹsẹ bíbélì ni ṣọ́ọ̀ṣì' Àwòrán apanilẹ́rìn-ín fún ọ̀sẹ̀ yìí, ìtọ́wò rèé Seyi Makinde yan obìnrin míràn sípò akọ̀wé ìjọba SSG Ìgbà mẹ́rin tí ẹ̀sùn àgbèrè ta bá adarí ìjọ olókìkí ní Naijiria Ninu fidio ifọrọwanilẹnuwo naa, Busola ni igba ti oun wa ni ileewe girama, ni oun kọkọ pade Fatoyinbo ni Ilorin, Ipinlẹ Kwara, nigba to ṣẹṣẹ bẹrẹ ijọ COZA.
Ewe, latari sise amulo ero igbalode ohun ninu idije African Nations Championship ti o waye lorile-ede Morocco, ajo Caf, igbimo to n ri si boolu afesegba nile-okere, International Football Association Board (IFAB)  ati ajo to n ri si boolu afesegba lagbaye FIFA, ti fenuko papo lati tun samulo ero VAR ohun ninu idije 2018 Caf Super Cup to n bo lona.
Àmọ́n èyí tó kanni lóminú jù ni ti àwọn alákatakítí Boko Haram, tí wọ́n ndúnbú ọmọ ènìyan bí eran lásán.
Ìfihàn yìí jẹ́ èyí tí a gbà nípa lílo Urimù àti Tummimù ní ìdáhùn sí àdúrà àti ìbéèrè Joseph.
Alaafin Oyo ṣalaye siwaju sii pe oun ko le ṣe nnkan to tako aṣa ati iṣe Yoruba laelae, o ni oye Mayegun wa ni ibamu pẹlu aṣa Yoruba.
"Emi la ò ní yọ̀ sí!
Ọpọ igba ni ijọba ipinlẹ Eko funrarẹ ti jẹwọ pe bi ọrọ ṣe ri gẹlẹ niyi.
Fun ẹnikẹni to ba wọle ninu Trump tabi Biden, iru akọle iroyin to lee jade ree: US Election 2020: Nígbà wo laó mọ èsì ìdìbò àti pé ṣé ó ṣeé figagbága?
Oríṣun àwòrán, @Daily Trust Lẹnu ọjọ mẹta yi, ileeṣẹ ologun Naijiria n ba awọn to ba sọrọ nipa ija rẹ pẹlu Boko Haram fa wahala.
Obinrin mejeeji yìí jẹ́ majẹmu meji, ọ̀kan láti òkè Sinai, tí ọmọ rẹ̀ jẹ́ ẹrú; èyí ni Hagari.
Ọ̀rọ̀ rẹ̀ sì ti sú wọn.
Ṣugbọn ẹ̀yin sọ pé, bí ẹnikẹ́ni bá sọ fún baba tabi ìyá rẹ̀ pé, ‘Mo ti fi ohun tí ò bá fi jẹ anfaani lára mi tọrẹ fún Ọlọrun,’ 
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ọ̀do mẹ́rin rẹ́wọ̀n he lórí ikú ọmọ Naijiria n'ílẹ̀ Gẹ̀ẹ́sì 14 Ògún 2018 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 15 Ògún 2018 Oríṣun àwòrán, Harry Uzoka Àkọlé àwòrán, Ọbe ni wọn fi gun Harry Uzoka pa Ile ẹjọ Old Bailey, Ilẹ Gẹẹṣi ti ran ọmọkunrin kan l'ẹwọn fun pe o pa ọmọ Naijiria kan, Harry Uzoka ni oṣu kinni, ọdun yii ni ilu London.
Ọjọ Ajẹ, ọsẹ yii lo pe ọṣẹ kẹrin ti irọlẹ ofin konile o gbele bẹrẹ ni Naijiria, amọ ofin naa si de irinna lati ipinlẹ kan si omiran.
Lọ́dún 1998 bákan náà, Hamzat Al-Mustapha fara hàn nílé ẹjọ́ pẹ̀lú ọmọ ààrẹ ológun àna Abacha, Mohammed ti wọn fi ẹsùn ikú Kudirat Abiola kan.
(Nítorí Jesu tí ń sọ pé kí ẹ̀mí èṣù náà jáde kúrò ninu ọkunrin náà.
22 Bélú 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 3 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 5 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Alaye bi wọn si se na owo naa ree: Itọju awọn oluwọde to farapa - N20,114,087.
 Sùgbọ́n ǹkan nla ni fún àwọn ènìyàn Cambodia àti gbogbo àwọn ènìyàn tó n kojú ọ̀rọ̀ imó-ilẹ lágbáyé"" Lónìí ni PDSA yóò kéde ètò àmìẹ̀yẹ Magawa lori ẹ̀rọ Ayelujara wọn Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, SS3 ní mo wà báyìí, mo sì ti gba àmì ẹ̀yẹ̀ púpò nílé-lóko gẹ́gẹ́ bí onílù - Ayansike Gẹ́gẹ́ bi Apopo ṣe sọ Ìlú Tanzania ni wọ́n ti bi Magawa ti o sì wà ni ìwọ̀n kílò 1."
nígbà tí Oluwa bá dé ní ọjọ́ náà láti gba ògo lọ́dọ̀ àwọn ẹni mímọ́ rẹ̀, nígbà tí gbogbo àwọn tí ó gbàgbọ́ yóo máa yẹ́ ẹ sí, nítorí wọ́n gba ẹ̀rí tí a jẹ́ fún wọn gbọ́.
Àwa ò mọ ẹgbẹ́ kankan tó ń jẹ́ fijilanté fulani l'Ondo- Ìjọba ìpínẹ̀ Ondo Àgùnbánirọ̀ akọ̀ròyìn Channels náà ti dágbére fáyé látààrí ìkọlù Shiite l'Abuja Ipa tí ìyànsípò Olóòtú ìjọba Gẹ̀ẹ́sì tuntun yóò mú bá ‘Brexit’ Ọrọ ọhun fẹrẹẹ da omi alaafia ilu ru nilu Oṣogbo lọjọbọ pẹlu bi awọn akẹkọ ileewe naa ṣe fọn ka si igboro lati fi ẹhonu han lori awọn akẹgbẹ wọn ti wọn mu naa.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Wasiu Alabi Pasuma: Àjàkálẹ̀ àrùn Covid-19 kọ́ mi láti má a ṣọ́wó ná 8 Bélú 2020 Oríṣun àwòrán, Instagram/@officialpasuma Gbajugbaja akọrin Fuji nni, Wasiu Alabi Pasuma, sọ pe ẹkọ ti ko ni akawe ni ajakalẹ aarun Covid-19 kọ oun.
A kó gbogbo wọn pọ̀ mọ́ àwọn tí wọ́n kú sójú ogun.
OLUWA àwọn ọmọ ogun yóo fi àwọn ẹran ọlọ́ràá se àsè kan fún gbogbo orílẹ̀-èdè; yóo pa àwọn ẹran àbọ́pa, pẹlu ọtí waini, ẹran àbọ́pa tí ó sanra, tí ó kún fún mùdùnmúdùn, ati ọtí waini tí ó dára.
Iroyin ni minisita naa sọ pe awọn asofin n se segesege nitori wọn kọ lati fun ile isẹ ijọba ni ọjọ ti wọn yoo wa sọ nipa eto isuna fun ọdun 2019.
34 Bẹ́ẹ̀ni, àní ẹ sì jẹ́ kí àwọn tí a yà sí mímọ́ náà ó kíyèsára bakannáà.
    Ẹnì kẹrin ni ẹni ti orúkọ rẹ ń jẹ́ Ewé-ẹ̀yẹ tí ó jẹ́ babaláwo pàtàkì ní apá ìlá oòrùn.
US Election 2020: Biden jẹ́jẹ̀ẹ́ láti gbé ìgbìmọ̀ amúṣẹ́yá kalẹ̀ fún ìtọ́jú Coronavirus
Afẹ̀sunkan náà ni àwọn ọlọpàá gba ibọn méjì ati ọta mọ́kànlélàádọ́ta l'ọwọ rẹ̀ nígba tí wọn ràa mú ni ọ̀san ọjọ́ Àìkú ní Maraban Yakawada, Ipínlẹ̀ Kaduna.
Ààrẹ Buhari ti mú ayé dẹrun fún àwọn ọmọ Nàìjíríà - Lai Mohammed Àwọn aṣòfin mẹ́ta takò lílo N37b f'àtúnṣe Ilé Aṣòfin Àpapọ Nàìjíríà Mu pàrágá wakọ̀ l'Oyo, kóo kó sí gbaga ìjọba ‘Ìjọba àpàpọ̀ gbọdọ̀ tọrọ ìdárìjì lọ́wọ́ Sowore, Dasuki’ To n tumọ si pe, inu ọgba ẹwọn ni gomina ana ọhun yoo ṣe ọdun tuntun.
dupe lopolopo lowo gbogbo oludibo ni Ipinle Oyo fun igbagbo won ninu isedeede
Bakan naa, Takur tun fi ese kan ya ki baale ilu Kachia, Agom Adara, dokita Maiwada Galadima.
Awọn iroyin ti ẹ lee nifẹẹ si: Asepati marosẹ Ibadan si Eko lewu - Fasọla Gani Adams gb'oriyin fun'pinlẹ Eko Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Ni bayii, won koi ti kede oruko awon ti o fara kaasa ijamba naa, di igba ti won ba to fojuri awon ebi won, bi o ti le je pe awon miiran ti n sedaro lori ero ayelujara idije ohun.
Kókó Òfin ati ọ̀rọ̀ àwọn wolii nìyí.
Iroyin to kọkọ wọle fi han wipe, ado oloro kan bu ni bii aago mẹsan ku iṣeju marundinlogun ti awọn mẹfa miiran si tẹle.
Buhari ni alaafia ni ki wọn maa lepa nitori ẹsin alaafia lẹsin musulumi bo tilẹ jẹ pe awọn alajagbinla kan ti fun ẹsin naa lorukọ buruku pẹlu iwa ipa wọn.
Oríṣun àwòrán, NIGERIA POLICE Àkọlé àwòrán, Awọn afurasí náà gbẹ̀mi ogunlọ́gọ̀ ènìyàn pẹ̀lú ọlọ́pàá mẹsan Alukoro ọlọpaa ni iwadii ṣi n lọ lọwọ lori idigunjale Ọffa.
9 miliọnu Ọkọ ayọkẹlẹ bọginni mẹtala Ẹrọ ayara bi aṣa mọkanlelogun Ẹrọ ibanisọrọ alagbeka mẹtadinlaadọta, ati awọn nkan miran Iye eeyan ti wọn lo ti lu ni jibiti ku diẹ ko pe miliọnu meji (1,926,400).
''Iyalẹnu lo jẹ fun wa lati ri ki awọn ọmọ ẹgbẹ APC ya de niwaju aafin Oba Akoko ti wọn si bẹrẹ si ni ṣe ikọlu awọn eeyan wa'' Eyitayo sọ pe oun wa ni ọdọ Kọmisana ọlọpaa lati lọ fi ẹjọ suin nitori pe awọn janduku ẹgbẹ APC ba ọkọ awọn to to ogun jẹ ninu ikọlu naa.
Oun ni ohun akọkọ to dun ni ori amohunmaworan akọkọ nilẹ Adulawọ iyẹn WNTV, (Western Nigeria Television) to ti di NTA bayii.
Atamatase iko agbaboolu Liverpool, ti o tun je omo orile-ede Egypt, Mohamed Salah ti sun ibasisepo re siwaju ninu iko agbaboolu Liverpool.
Agbẹnusọ awọn ọlọpaa ni ipinlẹ Ondo, Tee-Leo Ikoro naa parọwa si awọn eniyan lati tẹle ofin ijọba pe ki awọn eniyan ma rin irinajo lati ilu kan si ọmiran nitori itankalẹ arun Coronavirus lasiko yii.
 Bakan naa, ni Ekweremadu tun wi
O so pe, ijoba n gbero lati mu igberu ba ona ti won n gba pese ina mona-mona si gigawati mewaa bi o ba fi maa di odun 2020,bi o tile je pe, o ku bi odun meji ki gbedeke odun ti won da naa pe,  amo ni bayii, aseyori gigawati merin pere ni won ni.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù 'Yorùbá yóò gba ìjọba ni 2023 ti wọ́n bá gbé Buhari wọlé ni 2019' 23 Ọ̀pẹ̀̀ 2018 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ọṣinbajọ n ṣe ipolongo ojule si ojule ki awọn eniyan le dibo fun Buhari Ọṣinbajo ṣabẹwo si aafin iku baba yeye ti Ọyọ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Fulani Kidnapping: Owó púpọ̀ la san kí wọ́n tó fi mi sílẹ̀ Orilẹ-ede France lo gba alejo idije tọdun 2019 naa.
Ni ti awọn ile ijọsin, o ni ki awọn adari ẹsin ri daju pe awọn eeyan to peju si ṣọọṣi àti mọ́sálásì kò kọ́ja ààdọ́tà lọ, ìsìn kò sì gbọdọ̀ kọ́ja wákàtí méjì pere.
Muhammed Idris dájọ pé kí Nwaoboshi wà látìmọ́lé di ọjọ́ Jimo tí ilé ẹjọ́ yóò fi ṣe àgbéyèwò gbígba oniduro rè.
Ijọba Naijiria ni yoo tun pese iṣẹ fun awọn ti yoo ma fi si awọn ile wọnyii lati ri wi pe o ṣiṣẹ doju ami.
ni di i lọna ti o ba fẹ fi ikọ agbabọọlu naa silẹ.
Oríṣun àwòrán, @NGRPresident Wahala bẹ silẹ lọjọ Iṣẹgun ni nnkan bii aago meje ku iṣẹju marundinlogun, nigba ti awọn ọmọ ologun dana ibọn ya awọn oluwọde ni Lekki Toll Gate, to wa ni ilu Eko.
Bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé igbó ni, ẹ gbà á, kí ẹ sì ṣán an láti òkè dé ilẹ̀ títí dé òpin ààlà rẹ̀.
O fi kun oro re pe, “eyi ko so pe ki a so eka eto ilera wa di ti aladani, amo ki a wa ona lati le mu igberu ba eka eto ilera naa”.
BBC Africa Eye tú àṣírí ìfiyàjẹni àwọn Ológun, SARS káàkiri Nàìjíríà
Orí aṣọ wíwọ̀ wa pàtàkì kò ní ilé epo, níto rí náà, fífọ̀ dànù ni a ó fọ̀ ọ́ dànù.
Ọkan lara awọn alatilẹyin rẹ si fi ẹjọ sun ọlọpaa.
Ijọba sọ pe iroyin naa ko tẹle ilana to gbe iṣẹ iroyin duro - aiṣegbe ati fifun igun kọọkan ni anfaani kan naa lati sọrọ Ijọba tun fi ẹsun kan CNN pe o sare gbe iru iroyin bẹ ẹ jade, lai gbọ ọrọ lẹnu ijsba nipa rẹ.
”Samuẹli dá a lóhùn pé, “Èmi nìyí.
O ṣalaye fun BBC Yorùbá lori idaamu ọkan rẹ lori bi awọn akẹgbẹ oun ṣe maa n yẹra fun oun nile iwe.
Ijoba ipinle Eko Oríṣun àwòrán, Instagram/Sanwo-Olu Ijọba ipinlẹ Eko lo kọkọ kede pe ki awọn ọjà nlanla nipinlẹ naa ko wa ni titi pa.
Aṣiri ọrọ yi ti tu si wa lọwọ tori naa la ṣe fẹ sọ fun yin laisiyemeji pe arabinrin yi kii ṣe oludije ipo aarẹ Ki lo wa mu atotonu wa?
 “Ikeji ni pe, a o ni ọrọ
O ni ọkan iru ẹ ni eleyii lati ọdun pipẹ, awọn si n ṣe iṣẹ awọn lati boju wo ohun to ṣi alafo silẹ ati ọna ati di alafo naa pẹlu.
Yóo gbà ọ́ lọ́wọ́ ìnira lọpọlọpọ ìgbà,bí ibi ń ṣubú lu ara wọn,kò ní dé ọ̀dọ̀ rẹ.
ó sọ fún wọn pé, “Ẹ fa ọkunrin yìí wá sọ́dọ̀ mi bí ẹni tí ó ń ba ìlú jẹ́.
Wọn ni awọn pa awọn eeyan naa lati gbẹsan bi orilẹ-ede Amẹrika ṣe pa olori wọn, Abu Bakr al-Baghdadi ni Syria loṣu kẹwaa ọdun yii.
Prince Malik Ado Ibrahim: Wo bí Adama Indimi àti Prince Malik Ado ọmọ Ọba Ohinoyi ilẹ Ebira ṣe fa ayélujára ya
Ó ṣe pàtàkì láti sọ orúkọ àwọn orílẹ̀-èdè tí wọ́n kò fi bẹ́ẹ̀ ni àwọn aláàrùn Covid-19, pàápàá jùlọ láwọ́n ilẹ̀ Afirika tó wà ni ìlà-oorùn.
Bí èyí ọmọbìnrin wọn bá gbé etí sí ẹnu ihò ní iyàrá tiẹ̀ ọmọkùnrin a máa sọ̀rọ̀ sí i lódì kejì, bí ọmọkùnrin bá gbé èti sí ẹnu ihò ni yàrá tirẹ̀ ọmọbìnrin a máa sọ̀rọ̀ sí i láti ọ̀hún wá.
Kò sáyè iwọ́de mọ́ l'Eko ẹ lọ tọwọ́ yín bọṣọ - Ọlọ́pàá Ìwọ́de #EndSARS rán èèyàn méjì sọ́run n‘Ibadan, Seyi Makinde da ikọ̀ Operation Burst sígboro Tẹ́ bá fẹ́ lo ìwọ́de láti gba àkóso ìjọba, wọn yóò dá yín lẹ́kun - Tinubu Ọ̀pọ̀ aráàlú ló ti pàdánù ọwọ́ àti ẹsẹ wọn sọ́wọ́ jàǹdùkú - Sanwo-Olu Bakan naa ni ọjọ aje kan naa awọn janduku miran ṣọṣẹ ni ipinlẹ Eko ti wọn si tun tẹsiwaju lowurọ ọjọ Iṣẹgun nibi ti wọn ti dana sun awọn agọ ọlọpaa ti iroyin si tun kede rẹ pe ẹmi awọn eeyan kan lọ sii ti awọn miran si tun farapa.
Wọ́n dé ibojì, wọ́n ṣe gbogbo ètò tó jẹ́ ti ìsìnkú, àwọn ọmọ olóògbé kò gbàgbé ètò ìṣẹ̀mbáyé, wọ́n da yẹ̀pè sí ara òkú, bí wọ́n ṣe ń ṣe èyí náà ni gbogbo èrò àti àwọn ìbátan òkú ń bá wọn da yẹ̀pẹ bo pósí.
N óo dìde nisinsinyii, n óo sì lọ káàkiri ìlú,n óo wá ẹni tí ọkàn mi fẹ́,ní gbogbo òpópónà ati ní gbogbo gbàgede.
odun merin ni aare Buhariti se gudu gudu meje yaya mefa lati mu idagbasoke  ba orile ede yii.
1 9,819 San Marino 65 192.
3 10884 Erekusu Bahamas 163 42.
Ọ̀rọ́ tán lẹ́nu sùgbọ́n ó pọ̀ níkùn
Ìlú tí a ó gbé yẹ̀wò lọ́sẹ̀ yìí ni Abúlé Ọjà.
Mo mọ̀ pé o kò gbóná, bẹ́ẹ̀ ni o kò tutù.
Lara awon to tele gomina naa
Ẹni to bori: Tunisia Aṣekagba Morocco Tunisia Morocco vs Tunisia.
Oríṣun àwòrán, Instagram/queenola2 Ko si si ẹni to sọrọ taara lori iroyin naa ni gbangba ninu Badirat, K1 ati aafin ilu Ọyọ.
''Bi eeyan ṣe ni maaki to kọ ni yoo ṣe atọna iru orire ti yoo ṣe laye.
Ṣé ìtì igi lásán ló yẹ kí n máa foríbalẹ̀ fún, kí n máa bọ?
Josẹfu bá bẹ̀rẹ̀ sí rọ̀ wọ́n, ó ní kí wọ́n jọ̀wọ́, kí wọ́n súnmọ́ òun.
Pa mí mọ́ bí ẹyin ojú,dáàbò bò mí lábẹ́ òjìji ìyẹ́ rẹ;
Ko rorun fun mi lati mo ohun ti ma se tabi ibi ti ma lo bayii”.
" Bakan naa, ko yẹ ko jẹ NIPOST ni yoo ma a mojuto bi awọn ileesẹ yii ṣe n sisẹ, nitori pe oun fúnra rẹ jẹbi.
Sibẹ, o jàre gbogbo ohun tí ó dé bá wa yìí, nítorí pé o ṣe olóòótọ́ sí wa, àwa ni a hùwà burúkú sí ọ.
Níbẹ̀ ni àwọn ìran Josẹfu, ọmọ Jakọbu ń gbé.
Oríṣun àwòrán, AFP Àkọlé àwòrán, Sokoto ni awọn to toṣi pọ ju si ni Naijiria Awọn ipinlẹ to wa ni Ariwa Naijiria ni òṣì pọ si ju awọ̀n to wa ni Gusu lọ.
Ipo opo: Awọn agbeegbe kan lorilẹede Naijiria ri awọn obinrin gẹgẹ bi ẹru ọkọ rẹ nitori naa ni ọkunrin fi le e ṣe iyawo rẹ bi o ba ti ṣe wu u.
Egbe oselu merin ti won wa labe egbe oselu Ethiopia Peoples Democratic Front (EPRDF), eyi ti  Oromo People Democratic Organization naa wa labe re, Amhara National Democratic Movement (ANDM), Tigrayan People’s Liberation Front (TPLF) ati egbe oselu Southern Ethiopian People’s Democratic Movement (SEPDM).
Kọmisọnna ọlọpaa ipinlẹ Eko naa wa parọwa si awọn araalu ni ipinlẹ Eko lati se akiyesi ofin wọnyii, ki wọn ma ba A lu ofin ibalopo ni gbangba ni ọjọ iwaju.
Ọpọ awọn ẹgbẹ yi lo ti ni ẹka laarin awọn ti ko si ni ọgba fasiti ti awọn wọn yi a si ma gbe igbe aye ole jija ati iwa janduku.
Awọn eniyan ni awọn gba pe o tọrọ aforiji o ṣugbọn bi ofin ba ti tọwọ bọ ọrọ, ko si pẹlẹ ma binu labẹ ofin.
Bẹ́ẹ̀ gan-an ni OLUWA Ọlọrun yín yóo ṣe sí gbogbo àwọn eniyan tí ẹ̀ ń bẹ̀rù.
Àkọlé àwòrán, Aarẹ Buhari Aarẹ Buhari ni ipa ti Abiola ati igbakeji rẹ, Baba Gana Kinjibe ti wọn jọ gbegba ibo lọdun 1993 kii ṣe kekere ninu eto oṣelu orilẹede Naijiria.
Mo ti fi okùn ìwọ̀n àwọn mọlémọlé sí ààrin àwọn ọmọ Israẹli, eniyan mi; n kò ní fojú fo ẹ̀ṣẹ̀ wọn mọ́.
Ademola AdepojuLai Mohammed ni’’Inu mi dun pe ijoba orile ede Naijiria
Mo ti sọ fún àwọn tí ó fi ẹ̀sùn kàn án pé kí wọ́n wá sọ ohun tí wọ́n ní sí i níwájú yín.
00 owo Abacha ti a gba pada o!
Akẹkòó Obìnrin Chibok 57 tí lọkọ ní Cameroon Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 67 year old mother: Mo kojú ọ̀pọ̀lọpọ̀ àìsàn fún ọdún 35 lẹ̀yín ìgbéyàwò Aarẹ Trump fikun wipe orilẹede Amerika nikan ni ọmọ ti wọn bi si ilu ti n gba iwe igbele nitori wọn bii sibẹ nikan.
BBC Yoruba ko le fidirẹ mulẹ boya igbeyawo waye laarin awọn mejeeji.
Oríṣun àwòrán, Instagram/abiola ajimobi Ni nnkan bii ọsẹ diẹ ni iroyin bẹrẹ si ni tan kalẹ pe sẹnetọ ajimọbi n ṣojojo ati pe ara rẹ ko le.
Nígbà wo sì ni ọjọ́ ìsinmi yóo kọjá, kí á lè rí ààyè ta alikama, kí á lè gbówó lé ọjà wa, kí á sì lo òṣùnwọ̀n èké, láti rẹ́ àwọn oníbàárà wa jẹ; 
Wọn fikun pe lẹyin tawọn se iwọde lọsẹ to kọja, ijọba ipinlẹ Kwara gbe ogun miliọnu naira kalẹ fun sisan owo iranwọ eto ẹkọ naa amọ titi di asiko yii, awọn ko mọ ibi ti owo naa wọlẹ si mọ.
Lara awon to wa pade adari ijoba orile ede Britain  nigba to de si papa oko ofurufu ni deede aago merin aabọ osan , ni gomina ati igbakeji gomina, Dr.
O ni awọn gomina naa nilo ifọwọsowọpọ lai fi ti ẹgbẹ oṣelu kankan ṣe lori eto aabo ilẹ Yoruba.
Ṣaaju ni ijọba apapọ fòfin de irinajo si ilẹ okeere nitori arun Covid-19 to n mi gbogbo agbaye titi.
Aṣoju ọga ọlọpaa naa sọ fun ileẹjọ pe DPO naa ko le yọju sile ẹjọ nitori o wa igbimọ to n ṣewadi iwadii ifẹhonuhan EndSARS.
Akitiyan ọmọ'ṣẹ́ mi tó wà lára àwọn tó jí ìbejì mi gbé kò kéré níg Ẹsun marun un ni wọn fi kan meji lara awọn afurasi naa, eyiun, Rafiu Mutiu ati Rafiu Modinat, ti wọn gba pe kawọn afurasi ọhun fi awọn ibeji ọhun pamọ sinu ile wọn.
Ǹjẹ́ Hesekaya ati gbogbo eniyan Juda pa Mika bí?
Ẹ ṣe àyẹ̀wò ìwé akéwì-orin ni èdè Yorùbá ti àwọn ọmọ ilé-ìwé n kọ́ sórí ni ilé-ìwé ilẹ̀ Yorùbá ni ayé àtijọ:
Ilé ẹjọ́ Cassation ti Íjípìtì fi ẹsẹ ẹ̀wọ̀n-ọn rẹ̀ múlẹ̀ nínú oṣù Belu ọdún 2017.
Kí àwọn eniyan rẹ lè máa bẹ̀rù rẹ, kí wọ́n sì máa rìn ní ọ̀nà rẹ ní gbogbo ọjọ́ ayé wọn lórí ilẹ̀ tí o fún àwọn baba wa.
“Bí mo ti ń wo ọ̀kánkán,mo rí àwọn ìtẹ́ kan tí a tẹ́.
Saulu tún bẹ̀rù Dafidi sí i nítorí àwọn àṣeyọrí rẹ̀.
Adebola Ademilua: Àìrísẹ́ ṣè lẹ́yìn ìwé kíkà ló sọ mi dí ìyá onírú, mo dúpẹ́ tèmi
Ìwọ ni o dára jùlọ láàrin àwọn ọkunrin;ọ̀rọ̀ dùn lẹ́nu rẹ,nítorí náà Ọlọrun ti bukun ọ títí ayé.
Bí oníṣẹ́ ọnà wúrà ti máa ń kọ orúkọ sí ara òrùka èdìdì, ni kí o kọ orúkọ àwọn ọmọ Israẹli sí ara òkúta mejeeji, kí o sì fi wúrà ṣe ìtẹ́lẹ̀ wọn.
Ko si ohun to jọ bẹẹ raa!
Oríṣun àwòrán, @Ooni Agba oye ninu iṣẹṣe naa ni ohun akọkọ ni pe Ọba kii ri irun ọrun ori ọmọ tuntun nitori naa wọn gbọdọ kọkọ rii pe wọn fa irun ori ọmọ bẹẹ ki o to lee fi oju kan an.
Ẹnikẹ́ni tí ó bá kọ́kọ́ bọ́ sinu adágún náà lẹ́yìn tí omi náà bá ti rú pọ̀, àìsànkáìsàn tí ó lè máa ṣe é tẹ́lẹ̀, yóo san.
Nibẹ lo ti wa sọ pe ọna abayọ lati di sunkẹrẹ fakẹrẹ Apapa ku ni ki wọn mu adinku ba igbokegbodo to n waye ni Apapa.
Bi o tile jẹ pe Aarẹ orilẹ-ede Madagascar, Andry Rajoelina n lọgun pe agbo awọn n koju arun Coronavirus, Ajo Eto Ilera Lagbaye (WHO) ti ṣekilọ lori lilo agbo naa nitori ko gba ontẹ ayẹwo finifini.
Atẹjade lati ọdọ ẹgbẹ oṣelu PDP nipinlẹ Ọṣun eleyi ti alaga ẹgbẹ oṣelu naa, Sọji Adagunodo fi ọwọ si ni nṣe ni awọn ọlọpaa n fẹ halẹ mọ Sẹnetọ Adeleke nitori ẹjọ to n pe lati gba aga gomina ipinlẹ Ọṣun pada ni ile ẹjọ.
O ni, ẹni ti ko kopa ninu eto ibo abẹle, ko ni aṣẹ lati tako ibo abẹle ẹgbẹ oṣelu kọọkan.
Ami ayo mejidinlọgọta lo ti gba wọle fun awọn ẹgbẹ agbabọọlu to ti ba ṣiṣẹ ati Super Eagles.
Eliasafu ọmọ Deueli ni yóo jẹ́ olórí láti inú ẹ̀yà Gadi.
 ""Naira Marley yii ko lọpọlọ rara, ẹni to n kọrin lodi si aidaa ijọba, lori iṣoro awọn eeyan, aidaa awnọ ọlọpaa, laasigbo, o tilẹ n ṣe bii pe o ni iru ẹmi orin Bob Marley diẹ ṣugbọn Soapy lo n kọ."
2b rẹ tori o ti bọ sọwọ ijọba.
Oríṣun àwòrán, Screenshot Kilo le fa a ti awọn araalu ko fi le daabo bo ọba tabi ma a wo debi pe awọn janduku n wọ ààfin gbe ọ̀pá?
55 Nítorínáà, ẹnikẹ́ni tí ó bá jẹ́ ti ìjọ mi kí ó máṣe bẹ̀rù, nítorí irú wọn yíò jogún ìjọba ọ̀run.
Ìyàwó Ọ̀ọ̀ni Ogunwusi kò bímọ tuntun Wọn ti gun Trump ni abẹrẹ ati oogun Remdesivir, lati wo kokoro arun naa san lara rẹ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Oshodi Tapa: ìgbésí ayé Oshodi, ọmọ Tápà léǹpe tó di akọni ní ìlú Eko rèé 13 Èbibi 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 20 Èbibi 2020 Oríṣun àwòrán, others Ilu Eko ni iwọ oorun guusu Naijiria jẹ ilu nla, ilu olowo ati ọlọla, ilu to gbajumọ, ti ọpọ eeyan si n gbe inu rẹ ṣe oriire.
Dandan ni pé kí gbogbo eniyan kú lẹ́ẹ̀kan, lẹ́yìn ikú ìdájọ́ ló kàn.
Màá ra Arsenal ní 2021 tí mo bá kọ́ iléeṣẹ́ ìfọ́po rọ̀bì tán - Dangote Serena Williams gba ife ẹ̀yẹ àkọ́kọ́ láàrin ọdún mẹ́ta sẹ́yìn Siasia bẹ̀bẹ̀ ìrànwọ́ N100m lọ́wọ́ ọmọ Nàìjíríà láti ṣejọ́ jìbìtì tí FIFA fi kàn án Ayipada yii tun tumọ si pe idije naa ko ni i waye ni asiko kan na pẹlu idije Club World Cup ti yoo waye ni China l'oṣu Kẹfa, ọdun 2021.
 Àwọn ọba mọ ́ kaǹlélógún ló sì ti jẹ lẹ ́ yìn rẹ ̀ .
Awọn eeyan kan tiẹ n gbarata lori inira ti abẹwo naa yoo mu bawọn nitori awọn opopona kan ti ijọba yoo ti pa lasiko abẹwo aarẹ Buhari naa.
Eyi lo mu ki wọn so okun mọ igi kan, ti wọn si ju okun naa si lati lo fi gun igi, sugbọn agbara omi naa mu ki o ṣoro fun lati fa ogun naa.
Ṣé Yoòbá ti wí tẹ́lẹ̀ pé òwe lẹṣin ọ̀rọ̀.
Ni ti ọrọ aje, awọn okoowo yii n mu ki awọn ọmọ ijọ rẹ ri isẹ oojọ se, ti wọn si n gba owo ọya wọn, bi o tilẹ jẹpe ọpọ awọn ọmọ ijọ rẹ ya lọ lọdun 1960 nitori ẹkọ tuntun ti wọn gbọ.
Bello ni isẹ awọn ni awọn n se, ifẹ tawọn araalu ni sawọn, si n lo n jẹ ki wọn maa se aanu awọn.
asofin ajo isokan agbaye, UNGA, ojogbon Tijjani Muhammad-Bande niluu New York, lati fida
Yorùbá ni “Ẹnu Ayé Lẹbo”, Moṣétán fi ẹnu kó bá ara rẹ̀.
Sọ àsọtẹ́lẹ̀ orílẹ̀èdè tí yóò borí ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ t'òní Orin kíkọ kò dí ìwé mi lọ́wọ́ rárá -Hameen School Boy Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí kan sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
Ó bá pàṣẹ fún Seraaya pé nígbà tí ó bá dé Babiloni, kí ó rí i dájú pé ó ka gbogbo ohun tí òun kọ sinu ìwé náà sókè.
A gbọdọ̀ máa ṣe ìdá padà Àìjẹ, àìmu ààrin ààwẹ náà nítori pe líla òògun le mú ki omi ara ó gbẹ Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Omi mimu ṣe patàkì lásiko ààwẹ páàjùlọ lásiko òòrun Awọn ounje ti e gbodo maa je gbodo je ounje afaralokun ati eyi to ni ọ̀rá O ṣe pàtàkì láti maa jẹ ounjẹ to ni gbogbo èròja aṣara lóore.
Ṣe lo ni igbakuugba ti awọn ologun ba tun ti wa gbe baba Gani Fawehinmi nile inu awọn kii dun ṣugbọn kia iya oun yoo ti gba ọdọ awọn agbẹjọro lọ ti yoo ran oun naa lọ gbe igbesẹ mii.
 Bi o ba lo sile okeere opo igba ni waa maa gbo orin awon eniyan Naijiria loju popona won ni eyi to n munu wa dun nitori pe eyi je okan lara ona to n mu isokan joba ni Naijiria.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Nanny: Èèyàn làwa náà, ẹ yé ṣe wá bí ẹranko Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Nanny: Èèyàn làwa náà, ẹ yé ṣe wá bí ẹranko 12 Agẹmo 2019 Ọna lo jin, ẹru naa kuku ni baba.
ati àwọn iranṣẹ tẹmpili tí wọn ń gbé Ofeli ṣe àtúnṣe tiwọn dé ibi tí ó kọjú sí Ẹnubodè Omi, ní ìhà ìlà oòrùn ati ilé ìṣọ́ tí ó yọgun jáde títí dé ibi odi Ofeli.
7 miliọnu awọn ọmọde labẹ ọdun marun ni 2011 ati 250 miliọnu padanu lilọ ile ẹkọ .
Ẹgbẹ alaanu Red Crescent ton se iranlọwọ pajawiri ti tari awọn adoola ẹmi lọ sibi ti isẹlẹ naa ti waye lẹba igboro Semirom nipinlẹ Isfahan.
N óo kọrin ìyìn sí OLUWAníwọ̀n ìgbà tí mo bá wà láàyè.
Oríṣun àwòrán, Faceboo/Babcock University Àkọlé àwòrán, Agbẹnusọ fun ile iwe Babcock to ba BBC sọrọ ṣalaye pe oṣu kẹrin ọdun yii awọn mejeeji ni ibalopọ ṣugbọn kii ṣe ninu ọgba ile iwe naa.
Ṣaaju ni minisita eto ẹkọ, Chuwuemeka Nwajiuba ti sọ pe ijọba ti ṣepade pẹlu ajọ WAEC.
Mo fẹ́ kí ẹ mọ̀ dájúdájú pé ẹ óo sunkún, ẹ óo ṣọ̀fọ̀, ṣugbọn inú aráyé yóo dùn.
Laye iṣejọba Ogagun Ibrahim Babangida ati Ọgagun Raji - Rasaki to n tukọ ipinlẹ Eko nigba naa ni wọn kọọ laarin ọdun 1976 si ọdun 1980 ni apa akọkọ ti apa keji si jẹ 1988 si 1990.
O ni ijọba yoo gbe igbesẹ to laapọn sii lati dẹkun itankalẹ arun Coronavirus ni ipinlẹ Ondo.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù FIFA U-20 World Cup: Amẹrika dá sẹ̀ríà fún Nàìjíríà nínú ààwẹ̀ 28 Èbibi 2019 Oríṣun àwòrán, FIFA Àkọlé àwòrán, Ikọ Flying Eagles fidi rẹmi Abuku oloronbo ni ẹgbẹ agbabọọlu Amẹrika fi kan ikọ agbabọọlu Naijiria, Flying Eagles ninu idije ife ẹyẹ agbaye FIFA U-20 lorilẹede Poland.
    ‘Báyìí ni bàbá mi sọ lójú àlá fún mi, oyíndayépọ̀ Ọkùnrin, bí ó sì ti wí bẹ́ẹ̀ tán ni mo tajì.
Ṣe bi ẹyin naa mọ pe ko ṣẹni ti yoo ṣe, ti ko ni dun.
Akori todun 2018 ni: “Siso asa ilu lilu wa ji gege bi orison isokan fun idagbasoke Naijiria, Afrika ati agbaye”Apero, idanilekoo, afihan awon ilu ati awejewemu lorisiirisii ni yoo wa ye nibi eto naa labe ile ise ijoba ipinle Ogun to n risi ifitonileti ati asa lose keta osu kerin lodoodun.
Bi wọn se pa ọga SARS 'Àwọn SARS ló yìnbọn pa ìyá mi' 'Àwọn SARS ló yìnbọn pa ìyá mi' Kíni iyatọ tó wà láàrin FSARS àti SARS?
Wọn ri iwadi pe nkan bii ago mẹjọ alẹ ni iṣẹlẹ naa waye ti ọmọ awọn ọmọde meji si ti ba agbara ojo ti ọwọ rẹ le ọhun lọ.
Super Eagles f'ìyẹ́ bo Carthage Eagles Tunisia mọ́ 'lẹ̀ Àjọ CAF gba iṣẹ́ lọ́wọ́ Amaju Pinnick Afọnja, ẹni tó finú wénú ní Ilọrin, àmọ́ tó jẹ iwọ OPC kò láṣẹ láti fipa lé ẹ̀yà kan nílẹ̀ Yorùbá lórí ọ̀rọ̀ ikú Olakunrin- Ọlọ́pàá Tí kìí bá ṣe ti Barrister, iṣẹ́ ‘Gateman’ ni ń bá máa ṣe - Ayinla Kollington Ilumọọka agbabọọlu Liverpool, Sadio Mane ati awọn akẹgbẹ gbiyanju agbara wọn lori papa, ṣugbọn awọn agbabọọlu Algeria duro wamuwamu bi ologun ti wọn.
Olufilole ero ogbalode ayara bi asa Microsoft, Bill Gates, ati olokoowo ti o gbooro julo nile Afrika omo orile-ede Naijiria, Aliko Dangote, kopa ninu ipade apero ajo to n ri si eto oro aje no Naijiria, National Economic Council,  NEC, eyi ti o waye ni gbagede Banquet Hall nilu Abuja lojoRu(Thursday).
Ajínigbé kọlu òṣìṣẹ́ FRSC, èèyàn méjì kú, mẹ́rin farapa, mẹ́wàá di àwátì Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Aràrá bíi tèmi, kó má rò pé kò sì ǹkan tó lè ṣe láyé ju iṣẹ́ agbe lọ' Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 3 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 5 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Jesu yìí ni Ọlọrun jí dìde.
Wọn yio pe ẹbi àti ọ̀rẹ́ ti ó bá ni owó lati bá wọn lọ si irú igbéyàwó bẹ́ ẹ̀.
Kí oore-ọ̀fẹ́ Oluwa wa Jesu kí ó wà pẹlu gbogbo yín.
Yusuf lo kede yii lasiko to n dari ile igbimo asoju pe won ti sun ijiroro lori
Oríṣun àwòrán, Getty Images Onimọ isegun naa ni agọ ara ẹnikọọkan lo ni banki to n fi suga ati ounjẹ afaralokun pamọ si, ti ko si gbọdọ dinku abi ko tan rara.
Ọjọgbọn Dora Akunyili Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Akunyili ku ni ọjọ keje oṣu kẹfa ọdun 2014 lẹyin to ba aisan jẹjẹrẹ finra fun ọpọlọpọ igba Ọjọgbọn Dora Akunyili jẹ ọmọ ipinlẹ Anambra, ṣugbọn ilu Markurdi ni ipinlẹ Benue ni wọn bii si ni ọjọ kẹrinla oṣu keje, ọdun 1954.
Ṣugbọn kò sí ẹni tí ó bèèrè pé,‘Níbo ni Ọlọrun Ẹlẹ́dàá mi wà,tíí fún ni ní orin ayọ̀ lóru,
Baba pari atupàlẹ owe toni pe ki onikaluku ṣe pẹlẹ lasiko to ba n yẹ wọn.
" Oríṣun àwòrán, AFP Àkọlé àwòrán, Ọpọlọpọ awọn olugbe ipinlẹ Kano jẹ Fulani darandaran Alakoso fun eto ọrọ nipinlẹ Kano, Mahd Garba sọ fun BBC Yoruba pe Gomina n pe awọn darandaran gẹgẹ bi ọna lati pese ọnọ abayọ si wahala ati apaniyan awọn Fulani pẹlu awọn agbẹ.
Ekiti: Alágá ìjọba ìbílẹ̀ 16 gbàwé ìdádúró Awọn aṣofin gbe igbesẹ naa nibi ijoko aṣekagba saa awọn aṣofin to wa nibẹ lọwọ.
Ileeṣẹ ọlọpaa ni awọn mẹtalelogun ni wọn wa ninu ọkọ oju omi naa, ti wọn si ti doola ẹmi awọn meji ninu wọn.
Wọn wa yi orukọ rẹ pada si fasiti Ọbafẹmi Awolọwọ ni ọdun 1987 lẹyin iku Oloye Ọbafẹmi Awolọwọ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Kayeefi: Facebook ni Wolii Arole Jesu fi tàn an wọ agbo, orí rẹ̀ ni wọ́n fi s'owó Ọọni Ogunwusi ni bi Boris Johnson ba joun gbe, ko maa johun gbe o nitori gbogbo agbaye lo n reti ipa rere ti o nii ko ninu idagbasoke ọmọniyan.
COVID-19 ni yoo pa ẹnikẹni to ba ṣe eru ibo"" Ọjọ kọkandinlogun, oṣu kẹsan an, ọdun 2020 ni ibo sipo gomina ni ipinlẹ Edo yoo waye."
Ṣugbọn kì í ṣe èmi tìkara mi, oore-ọ̀fẹ́ Ọlọrun tí ó wà pẹlu mi ni.
Ó ra májèlé burúkú kan, kò sí ẹni tí o le gbé májèlé yìí mì tí olúwarẹ̀ lè gba ìṣẹ́jú méjì kí ó tó kú, ó fi èyí sínú ẹmu.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Senegal Artist: Ojojúmọ́ ni mo ń gbé àwòrán bàbá tó pọnmọ sẹ́yìn sójú pópó 16 Ìgbé 2019 Oríṣun àwòrán, Marta Moreiras Sugbọn ni orilẹede Senegal, ayaworan kan, Marta Moreiras, ti kede pe aworan oun ti n fa oju awọn baba si isẹ ọmọ pipọn.
Lọdun 2017 ni Naijiria na Algeria pẹlu ami ayo mẹta si ookan ni papa iṣerẹ Uyo ni ipinlẹ Akwa Ibom ni Naijiria.
Ohunkohun tí a bá ti fi fún OLUWA, ó di mímọ́ jùlọ fún OLUWA.
Angẹli OLUWA rí i lẹ́bàá orísun omi kan tí ó wà láàrin aṣálẹ̀ lọ́nà Ṣuri.
Rànwọ́n lọ́wọ́ láti rí ìràwọ́ O kìí ṣe akọ́ṣẹ́mọ́ṣẹ́, Nítori náà, ràn wọ́n lọ́wọ́ láti rí akọ́ṣẹ́mọ́ṣẹ̀ onimọ nipa arun ọpọlọ ati ihuwasi ẹda, eyi tí yóò mú ọ̀rọ̀ wọ́n gbọ́.
láti kọ́ onírẹ̀lẹ̀ lọ́gbọ́n,kí á sì fi ìmọ̀ ati làákàyè fún ọ̀dọ́,
Ti gomina si ko agbofinro tẹle wọn.
Noa bá jáde kúrò ninu ọkọ̀, òun ati aya rẹ̀, ati àwọn ọmọ rẹ̀, ati àwọn aya wọn, 
Oríṣun àwòrán, INSTAGRAM / USMAN DALHATU 4.
Egbe oselu ti o wa lori aleefa lowo bayii, All Progressives Congress, APC, ti benu ate lu esun ti won fi kan egbe naa pe abajade eto idibo gomina ipinle Osun waye lati fi ran egbe APC lowo ni.
Ọ̀pọ̀lọpọ̀ nínú ẹgbẹ́ yìí ti bá Ohùn Àgbáyé ṣe pọ̀ láti kọ àti ṣe ìtúmọ̀ ìròyìn sí èdè Amharic.
Bàbá rẹ̀, Alhaji Habib Aliyu tó ba BBC sọ̀rọ̀ sàlàyhe pe ọkàn Zainab wúwo báyìí yóò s]i gbà wọn lásikò diẹ̀ ki ọkan rẹ̀ to le balẹ̀ ti yóò si bs sípò.
ti egbe osise fenuko le lori, nitori pe awon osise orile ede Naijiria ko ni gba
Etí rẹ̀ là sílẹ̀,ṣugbọn kò gbọ́ràn.
Ọna ni ojuna ti eeyan n gba tabi tọ.
ile-ise naa to wa ni ipinle Kano.
Lẹ́yìn náà, Èṣù mú un lọ sí Jerusalẹmu, ìlú mímọ́ nì, ó gbé e lé góńgó orí Tẹmpili.
    Mo sì fẹ́ kí gbogbo yín mọ̀ pé bí a ti ń lọ yìí, a mọ nǹkan ti ń bẹ níwájú wa, a mọ̀ pé ẹranko búburú wà lójú ọ̀nà, a mọ̀ pé ejò olóró ń ddúró dè wá, a mọ̀ pé à ń ti ilé ọla lọ̀ bá ebi, à ń ti ilé lọ ba òùǹgbe, a sì ń ti ilé lọ bá ẹgbẹ̀rún ìyà tí yóò jẹ ni.
Ọ̀fọ̀ ṣẹ̀ Donald Trump, àbúrò rẹ̀ Robert, dèrò ọrun Robert Trump, aburo aarẹ orilẹede Amẹrika, Donald Trump ti dagbere faye lẹni ọdun mọkalelaadọrin.
Ó dun ọba, ṣugbọn nítorí pé ó ti búra, ati nítorí àwọn tí ó wà níbi àsè, ó gbà láti fi fún un.
ẹni tí ó ń kọ́ wa lẹ́kọ̀ọ́ ju àwọn ẹranko lọ,Ó sì fún wa ní ọgbọ́n ju àwọn ẹyẹ lọ?
Pupọ ninu awọn ọmọ Naijiria lo ti n sọ pe oun ti Main ṣe kii ṣe tuntun nitori awọn eeyan kan ti wọn fi iru ẹsun bẹẹ kan ti daku bẹẹ ṣaaju akoko yii.
"Bí àwọn ará ìlú ṣe pé àkíyèsì wa sí bi àwọn òsìsẹ wá ṣe yìbọn pa àwọn afúrasi méjì kan ti kò ní ǹkan ìjà lọ́wọ́, èyí lòdì sí ìlànà iṣẹ́ wa kò sì bá òfin mu rárá.
Nibayii, Aarẹ Buhari ti tu Igbimọ Amuṣẹya ẹgbẹ oselu APC ka ni bi ipade to waye ni ile Aarẹ ni Abuja.
“Barbara Bush je olokiki, ilumoka, gbajugbaja obinrin ti ilu ni ife si lopolopo, ,” George W.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, È gbọ òun ti ojú awọn ara ipinle Ogun rí lọwọ ìṣẹlẹ omiyale Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Ìwọ ògiri tí wọ́n kùn lẹ́fun lásán yìí!
 nítorí àwọn àtúnbọ ̀ tán , àwọn àgbéjáde titun àjẹsára náà ni a gbani níyànjú láti lò .
O ni: Ojiji ni a deede ri wọn, ti wọn si bẹrẹ si ni i ko gbogbo wa."
Ṣugbọn, yẹ̀yẹ́ ni wọ́n ń fi àwọn iranṣẹ Ọlọrun ṣe.
 o si tun je alakoso oro abo labe ijoba olusegun obasanjo .
Oludije fun ipo aare fun egbe People’s
Imọ ẹkọ nipa ẹda ede (Linguistics) ni Wumi kọ jade lati fasiti ilu Ilorin bẹẹ si lo gboye Diploma ninu imọ ẹkọ Tiata.
 Àwọn tí wọ ́ n ń sọ èdè yìí jẹ ́ ẹgbẹ ̀ rún lọ ́ nà àádọ ́ rin ènìyàn .
Ko si sọ ohunkohun nipa iṣẹlẹ naa.
Kò pẹ́ lẹ́hìn èyí nígbà tí ó padà dé iwájú ọba tí ó ń mí hẹlẹhẹlẹ tí ó bẹ̀rẹ̀ sí ọ̀rọ̀ í sọ tí ó wí pé: Kábíyèsí, mo rí èèmọ̀ lónìí.
Èèyàn 38,344 ló ti ní COVID-19 ní Nàìjíríà lẹ́yìn tí 543 kún un lọ́jọ̀rú Ninu ọrọ kan to kọ soju opo Instagram rẹ, Oluwo ti ilu Iwo ni ohun to ba wu ẹlẹnu ni ko fi ẹnu rẹ sọ ati pe o da oun loju bi ada pe Ọkunrin to dara loju, dara lẹwa loun jẹ.
'Ifiyajẹni, ọrọ kubakugbe ati ikorira ti pọju lorilẹede Naijiria.
Gbogbo àwọn nǹkan yòókù tí Ahabu ọba ṣe, ati àkọsílẹ̀ bí ó ṣe fi eyín erin ṣe iṣẹ́ ọnà sí ààfin rẹ̀, ati ti gbogbo ìlú tí ó tẹ̀dó, wà ninu Ìwé Ìtàn Àwọn Ọba Israẹli.
Wọ́n ń sọ pé, ‘Egungun wa ti gbẹ; kò sí ìrètí fún wa mọ́, a ti pa wá run patapata.
Wo ibi tí ayédèrú ìròyìn bá Áfíríkà dé láàrin ọdún kan 324 èèyàn bá ẹ̀kún omi lọ Kò sí àjòjì darandaran kankan ní Nàìjíríà -NIS 'Ọkọ mi yọ kindinrin mi lati rọpo owo ori' Gbogbo àwọn oluworan ti wọn wa wo idan naa rii nigba ti o bẹ sinu odo naa ṣugbọn wọn ko rii ko jade.
Lẹ́yìn tí Ẹ̀mí Mímọ́ ti fi iṣẹ́ lé àwọn mejeeji lọ́wọ́, wọ́n lọ sí Selesia.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Iléèṣẹ́ ọlọ́pàá mú ọkùnrin ẹni ọdún 55 tó gé ẹ̀yà ara èèyàn nílẹ̀ ìsìnkú ṣọ́ọ̀ṣì l'Ogun 25 Bélú 2020 Oríṣun àwòrán, The Punch Àkọlé àwòrán, Ọwọ ọlọpaa tẹ Yesiru Salisi, amọ ẹni ti wọn jọ ge awọn ẹya ara naa salọ Awọn ọlọpaa nipinlẹ Ogun ti mu ọkunrin ẹni ọdun marundinlọgọta kan, Yesiru Salisu, ti wọn ba ẹya ara eeyan lọwọ rẹ ni Ijebu-Igbo.
Lọjọ Aje ọsẹ ni ile igbimọ aṣojuṣofin Naijiria kọwe pe aarẹ Buhari lati wa wi tẹnu rẹ nipa iṣoro aabo to n koju orilẹede yii.
Ọmọ Nàìjíríà sọ òkò ọ̀rọ̀ sí Osinbajo lórí ìkíni rẹ sí Wole Soyinka Oríṣun àwòrán, @ProfOshinbajo Yoruba ni pẹlẹ ni akọ, to si tun labo, Ọlọrun ma si jẹ ka si ọrọ sọ.
Ogun Police: Àwọn jàǹdùkú kọlu ọlọ́pàá, DPO faragbọta, ọlọ́pàá mẹ́rin di àwátì
Nígbà tí wọ́n ti fi ṣe ẹlẹ́yà tán, wọ́n bọ́ aṣọ àlàárì kúrò ní ara rẹ̀, wọ́n fi aṣọ tirẹ̀ wọ̀ ọ́, wọ́n bá fà á jáde láti lọ kàn án mọ́ agbelebu.
Liz Anjorin ko fara mọ iha ti Ronke Oshodi Oke kọ si ọrọ yii rara o si wọn esi fun rẹpẹtẹ lọrọ ọhun ba di rẹpẹtẹ mọ wọn lọwọ titi to fi pada rọlẹ.
Ekwo nibi ti awọn mẹrẹẹrin ti ni awọn ko jẹbi ẹsun mẹrẹẹrin ti wọn fi kan awọn.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, EndSars, EndSwat: Ọlọ́pàá ti fi ìbọn lù mí láyà rí torí mó ní 'extra tyre' méjì- afẹ́hònúh Ṣaaju nijọba orile-ede Naijiria ti juwọle fawọn afẹhonuhan ENDSARS nipa gbigba lati mu awọn ẹdun nkan marun un ti wọn lawọn fẹ lọkunkundun.
Wilson Uwujaren to jẹ agbẹnusọ EFCC ni o di dandan ki Maina ri aaye wi tẹnu rẹ lori awọn ẹsun wọnyii.
Ijọba orilẹede Naijiria fẹsun kan olori ijọ IMN naa pe o ni erongba ọtọ si ilana ti wọn la silẹ fun irinajo fun itọju rẹ.
Ṣugbọn Benhadadi, ọba Siria, ti gun ẹṣin sá lọ, pẹlu àwọn jagunjagun tí wọ́n gun ẹṣin.
Buhari, Trump yóò ṣèpàdé l'Ámẹ́ríkà Atunse ofin naa, ti wọn pe ni 25th amendment lo kede pe aarẹ ko si ni ipo ilera to tọ lati maa tukọ orilẹede naa.
Oni ọjọ kọkanla oṣu kẹwa ọdun 2018 ni ayajọ ọjọ ọmọbinrin lagbaye.
Josẹfu bá kó wọn kúrò lẹ́sẹ̀ baba rẹ̀, òun gan-an náà wá dojúbolẹ̀ níwájú baba rẹ̀.
Bí ó bá ṣe pé àwọn ará Ijipti ni wọ́n kọ̀ tí wọn kò wá síbi Àjọ̀dún Àgọ́ náà, irú àrùn tí OLUWA fi bá àwọn orílẹ̀-èdè tí wọn kò wá sí ibi Àjọ Àgọ́ jà, ni yóo dà lé wọn lórí.
- Òǹwòye ìdìbò YIAGA Akinlade ni bi oun ba di gomina, gbogbo nnkan ti oun ti ko ninu oṣelu ni oun yoo lo lati rii pe ipinle ogun lo siwaju.
Òfin tí yóò mú àtúnṣe bá ìlànà ìsìnkú ọba ní ìpínlẹ̀ Ògùn ń bọ̀ lọ́nà
Jẹ́ kí àwọn ọmọ ẹran rẹ máa jẹkolẹ́bàá àgọ́ àwọn olùṣọ́-aguntan.
Iṣẹlẹ yi waye lasiko ti wọn n dana sun ile ijọsin naa ni owurọ Ọjọru.
8 million ) ó dín díè ní mílíònù méjì .
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù AFCON 2019: Wo àwọn ẹranko tí wọ́n máa figagbaga ni Egypt 21 Òkùdu 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 25 Òkùdu 2019 Àkọlé àwòrán, Erin àti Ẹkun a gbéná wojú ara wọn ni Egypt Ọpọlọpọ ẹranko nlanla lo maa pade ni idije AFCON to n bẹrẹ ni Egypt loni.
O ni lati oun jogun ba awada ṣiṣe lati ọwọ mama oun ni, bakan naa lo sọ pe iwe ere awada lo ṣoro kọ ju laye.
Iye awọn eeyan to ṣẹṣẹ ko arun naa ni ipinlẹ kọọkan ree: Eko-216 Rivers-103 Oyo-68 Edo-40 Kano-21 Gombe-20 FCT-17 Delta-13 Plateau-12 Bauchi-12 Niger-10 Kebbi-9 Ogun-8 Ondo-8 Abia-7 Nasarawa-5 Borno-1 Kwara-1 Benue-1 Anambra-1 Èèyàn 403 ló lùgbàdì àrùn Coronavirus ní Naijiria ní Ọjọ́ Isinmi Oríṣun àwòrán, Others Àkọlé àwòrán, Akojọpọ esi ayẹwo aarun Covid-19 ni orilẹ-ede Naijiria gẹgẹ bi ajọ NCDC ṣe n kede rẹ.
olú ilé iṣẹ ́ náà fìdí kalẹ ̀ sí Ìbarà ní ìlú abẹ ́ òkútatí ó jẹ ́ olú ìl7 ìpínlẹ ̀ Ògun ní apá ìwọ ̀ oòrùn orílẹ ̀ èdè nàìjíríà .
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Olusegun Obasanjo: Màá fi ìyókù ayé mi sin Ọlọ́run áti ènìyàn Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Olusegun Obasanjo: Màá fi ìyókù ayé mi sin Ọlọ́run áti ènìyàn 5 Ẹrẹ̀nà 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 28 Agẹmo 2020 Ààrẹ tẹ́lẹ̀ ní orílẹ̀èdè Nàíjíríà, Matthew Okikíola Arẹmu Olusegun Obasanjo, ti salaye pe koko ni ara ọta le fun oun, tori pe oun jẹ ọmọ oko.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Johesu: A so ìyansẹ́lódì rọ̀ kí ìjíròrò leè já gaara 31 Èbibi 2018 Oríṣun àwòrán, AFP Àkọlé àwòrán, Iyansẹlodi lẹka ilera orileede Naijiria ki se ohun tuntun mọ Àwọn òṣìṣẹ́ elétò ìlera lórílẹ̀èdè Naijiria, labẹ àsìá ẹgbẹ́ àpapọ̀ àwọn òṣiṣẹ́ ìlera JOHESU fòpin sí iyansẹlodi wọn lónìí.
" Ibọn gigun kan ati ọta ibọn ni wọn ba lọwọ awọn eeyan naa ninu eyi ti wọn ni olorin naa, Small Doctor wa.
Awon igbimo asofin naa ti koko se iforowanilenuwo pelu awon olopaa ati adari otelemuye ana, lati dahun bi won se n wa okuta iye-biye ni papa Chiadzwa.
‘Ohùn-un Jamaica fún Àyípadà Ojú-ọjọ́’ fi orin jíṣẹ́ẹ wọn
Shehu sọ pe Buhari n tun Naijiria ṣe ni ati pe Obasanjo lo n mu ipinya ba orilẹede naa.
Báwo ni ọ̀rọ̀ nàá ṣe wáyé gan an?
Baba ọmọbinrin naa, Alhaji Habibi Aliyu sọ fun BBC pe awọn oṣiṣẹ ijọba apapọ ti pe oun lori ẹrọ ibanisọrọ pe ọmọ oun ti gba ominira.
OLUWA wí pé, “Èyí yóo mú kí wọ́n gbàgbọ́ pé OLUWA, Ọlọrun àwọn baba wọn, Ọlọrun Abrahamu, Ọlọrun Isaaki ati Ọlọrun Jakọbu ni ó farahàn ọ́.
Ìgbà kẹta re e ti igbakeji Aarẹ ilẹ America nigba kan, Joe Biden, n dije fun ipo aarẹ, labẹ ẹgbẹ oṣelu Democrat.
Lasiko arun Covid-19 yi ti awọn ile ọti wa ni titi pa, pupọ lo bẹrẹ si ni mu awọn ọti ayederu yi lati fi rọpọ ọti gidi.
Kò sí Ọlọrun mìíràn lẹ́yìn rẹ.
Okere tan olopaa mejilelogun lo padanu emi won ninu ikolu iko omo ogun olote Taliban sile-ise olopaa Afghan lagbegbe Farah lojo Aiku(Sunday).
O so pe “Mo lero pe ti awọn ijọba ipinlẹ  ba ni oloopa tiwọn, yoo ran wọn lowo , ayafi ti wọn ba n lo wọn lati fi dun ikooko mọ awọn alatako wọn.
82% ọkùnrin ní kó mọ̀ pé òun ní àìsàn jẹjẹrẹ asẹtọ ní Naijiria Dánáfojúrà nìyí, abàmì eégún tí ń gbé inú iná ṣọlá Awọn Fulani gbógun ti ilu Ọ̀yọ́ , tí ìjọba Ọ̀yọ́ si dojú dé lọ́dún 1831, àmọ́ tí ikọ ọmọ ogun Ibadan gba ominira Ọ̀yọ́ padà lọ́wọ́ Fulani lọdun 1840.
N kò gba owó rí lọ́wọ́ olùdíje kó tó dé ipò - Oyedepo Kini awọn ohun ti ile ẹjọ n beere fun beeli Fayose?
Ọwọ́ mi mọ́ lórí eto Gàá darandaran, RUGA- Goodluck Jonathan Wọ́n lu àbúrò mi ló jẹ́ kí ń fi ìbínú lu òǹtàjà l‘Abuja - Sẹ́nétọ̀ tó lu obìnrin ṣàlàyé 'Èèyàn mi mẹ́ta ló wà nínú ọkọ̀ ojú omi tó dà nù l'Eko!
GMT: Osise ajo INEC nipinle Osun, ojogbon  Olusegun Agbaje
Patience Jonathan pàdánù ọ̀pọ̀lọ̀lọpọ̀ mílíọ̀nù dọ́là sọ́wọ́ ìjọba àpapọ̀ Ileeṣẹ LASEMA ṣàlàyé pè ìjàmbá náà wáyé lálẹ́ ọjọ́ Abamẹta nígbà tí ọkọ̀ ojú omi ọ̀hún kọsẹ̀.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Tiger Woods ló borí ní ami ẹ̀yẹ Masters ti 2019 ní Augusta 15 Ìgbé 2019 Oríṣun àwòrán, Reuters Àkọlé àwòrán, Bo tilẹ̀ jẹ́ pe ami ẹ̀yẹ yìí ni ikarùn un irú rẹ̀ tí Tiger Woods yóó gbà, bí ó ṣe gbáà kọjá àfẹnusọ Awọn Yoruba ni, bi ẹsin ba da ni, a maa n tun gùn ni.
Anfani pọ fun abo to ba ni itẹriba, ifẹ àti iwa tutu bii adaba ninu ile ati lawujọ.
Ati lati ri i daju pe awọn ọlọpaa n jiyin iṣẹ fun araalu.
Oríṣun àwòrán, MrLekan Adigun Àkọlé àwòrán, Awon eekan ninu PDP naa de bẹ Láìpẹ́ yìí ìròyìn kan déedé bẹ̀rẹ̀ si ni ja rainrain lójú opó twitter pe ààrẹ orilẹ̀-èdè Nàijíríà Muhammadu Buhari yóò fẹ́ ìyàwó tuntun sáàfin.
 O wa fi asiko naa rọ
Agbẹnusọ kan sọ pe awọn ọmọ ilu Pakistani n ṣe igbiyanju lati ṣe irinajo ti o lewu lati k'ọja si orilẹede Italy.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Kidnapping: BBC ṣe ìwádìí bí ikọ̀ IRT ṣe ń gbéjà ko awọn ajinigbe lójú Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Kidnapping: BBC ṣe ìwádìí bí ikọ̀ IRT ṣe ń gbéjà ko awọn ajinigbe lójú 1 Agẹmo 2019 Ọ̀pọ̀ ọmọ Naijiria lo ti ń kan sáárá sí ẹ̀ka ilééṣẹ́ ọlọpaa to n koju ijinigbe ni Naijiria (IRT) ati oludari rẹ Abba Kyari.
Omiri ati gbogbo àwọn ọmọ ogun Israẹli bá kúrò ní ìlú Gibetoni, wọ́n lọ dó ti ìlú Tirisa.
 O ni, “ojuṣe wa ni gẹgẹ bi obi ati alagbatọ lati moju to awọn igbesẹ ati iwa awọn ọmọ; ka mọ iru awọn ọrẹ ti wọn n ba rin ati ẹgbẹ ti wọn ko”“Lorukọ awọn ẹgbẹ mi yooku ninu Ile Igbimọ Aṣofin Ipinlẹ Eko, mo ki awọn ọmọde ati awọn ọdọ-langba lorilẹ-ede Naijiria ku ajọdun awọn ewe tọdun 2018 yii, a ṣeyii sọpọ rẹ laye o.
Ẹ̀rẹ̀kẹ́ rẹ dàbí ìlàjì èso pomegiranate lábẹ́ ìbòjú rẹ.
fẹ lo ona ẹburu lati ran wọn lọwọ fun esi idanwo ti won se.
Adeleke ni ìbò 1569 ṣáájú Akin Ogunbiyi tó ní ìbò 1562.
Awọn ajafẹtọ tilẹ sọ pe awọn dokita oniwa ibajẹ maa n gba awọn obinrin naa ni imọran lati ṣe iṣẹ abẹ, koda ko jẹ pe aisan kekere ti oogun le wosan ni awọn obinrin naa gbe lọ sileewosan.
Wọn óo gbé igi tí wọ́n fi ń fọ́ ìlẹ̀kùn ti ìlẹ̀kùn bodè rẹ̀, wọn yóo mọ òkítì sí ara odi rẹ̀, wọn yóo sì mọ ilé ìṣọ́ tì í.
Njẹ ẹ mọ pe laarin ọdun mej,i igbakeji niyi ti ariwo kotọ yoo maa sọ eleyi ti yoo rọ mọ ojubọ Ọṣun tabi oriṣa naa funrarẹ.
Àwọn janduku tú àwọn ẹlẹ́wọ̀n sílẹ̀ ní ìlú Benin lásìkò ìfẹ̀họ́núhàn EndSars Amọ, iroyin to n tẹlẹ lọwọ sọ wi pe awọn janduku ti tu awọn ẹlẹwn silẹ ni ọgba ẹwọn ni ilu Benin.
Paulu bá sọ̀kalẹ̀, ó gbá a mú, ó dùbúlẹ̀ lé e lórí.
Àwọn ọ̀dọ́ Akure faraya lẹ́yìn tí ọkọ̀ agbówórìn 'Bullion van' pa ẹnìkan Bakan naa lo salaye pe yatọ sawọn alakoso ibudokọ, ijọba tun ti yan awọn igbakeji alakoso ibudokọ, akọwe ati akapo.
Ambode gbé ilé aṣòfin Eko relé ẹjọ́ Ọ̀pọ̀ ewébẹ̀ àti èso aṣaralóore tó wà ní àyíká àmọ́ tí ẹ kò kà kún rèé Amọ Rashford tun fọba lee fun Manchester United lẹyin to gbayo keji ti wọn fi jawe olubori wọle fun Man U.
Mo ki ijọba atawọn asofin ku oriire lori bi wọn se tete fọwọsi ofin to wa fun agbekalẹ ọọfisi ti yoo maa ri si akanse igbẹjọ."
Ijọba Eko din owo-ori ilẹ ati ile ku Buhari fagile irinajo s'orilẹede Rwanda Ninu ọrọ tirẹ, aarẹ awọn ajọ onimọ ijinlẹ ni ipinlẹ Ondo, Ọgbẹni Gboyega Akerele to jẹ onimọ nipa ile kikọ sọwipe ijọba nilo awọn onimọ lati gbe iru igbese yii, nitori ika o dọgba, atiwipe asọ nla kọ ni eniyan nla.
Ile asofin agba buwọlu aba to fofin de tita siga leyọ ẹyọ Adari ipolongo fun ajọ Environmental Rights Action ati ti Friends of the Earth Nigeria (ERA/FoEN) Philip Jakpor, nigba to n ba BBC sọrọ, wipe idunnu lo jẹ fun awọn nigba tawọn asofin agba fọwọsi aba lati fopin si tita siga layika ile-ẹko, ti ko si si eni to tako aba ofin naa.
Bí mo ṣe dájọ́ àwọn baba ńlá yín ní aṣálẹ̀ ilẹ̀ Ijipti ni n óo dájọ́ yín.
Àwòrán rèé nípa bí 'Hand of God' ṣé dí inagijẹ Diego Maradona Ohun mẹ́wàá pàtàkì nípa Maradona àti ìbáṣepọ̀ rẹ̀ pẹ̀lú ẹlẹ́sẹ̀ ayò Diego Costa rèé Ilé-ẹjọ́ kòtẹ́milọ́rùn fòntẹ̀ lu ìdájọ́ ikú fún Maryam Sanda tó gún ọkọ rẹ̀ pa Sójà obìnrin lù mí lálù bami nílùú Ibadan Èyí sì ló mú kí àwọn ọlọ́pàá máa kìlọ̀ fún ará ilú láti ma gbìyànjú rẹ̀.
Nígbà tí ó sọ̀rọ̀ nípa majẹmu titun, ohun tí ó ń sọ ni pé ti àtijọ́ ti di ògbólógbòó.
Ó ti sùn lọ níbi tí Paulu gbé ń sọ̀rọ̀ lọ títí.
Wéré ni Ayédèrú-ẹ̀dá kígbe pe gbogbo àwọn ènìyàn wa ti ń lọ kí wọ́n dúró, mo ti yìnbọn pa ènìyàn.
“Ìṣòro ti Agbalésanwó n ri ni Ilú Nlá lati ri Ibùgbé”
" Laide fikun pe oun ranti pe oun loyun ni ẹẹmẹta ọtọọtọ, amọ wọn maa n fun oun ni oogun ti ko ni jẹ ki oyun naa duro lara oun.
Nítorí èyí, ẹ má ṣe jẹ́ kí ẹ̀ṣẹ̀ tún rí ààyè jọba ninu ara yín tí ẹ óo fi máa fààyè fún ìfẹ́kúfẹ̀ẹ́ ara.
Akọnimọọgba Napoli, Carlo Ancelotti ni ọkan oun balẹ bi omi inu amu pe ẹgbẹ agbabọọlu oun ni yoo ra James Rodriguez lati ọwọ Real Madrid.
Ìdí nìyí tí mo fi ranṣẹ pè yín láti ri yín kí n sì ba yín sọ̀rọ̀; nítorí ohun tí Israẹli ń retí ni wọ́n ṣe fi ẹ̀wọ̀n so mí báyìí.
Link Kí lo mọ̀ nípa fẹntilétọ̀, ohun èlò aṣèrànwọ́ èémíSam tun tesiwaju pe: Ní ọjọ́ to ra ilé rẹ nílùú Ibadan, owó beba lo fi san gbogbo àìmọye mílíọ̀nù owó ilé naa lẹẹkan ṣoṣo."
Atirobẹ́lẹ́ṣindọ́gba ni ọ̀pọ̀ ọ̀dọ́ ní ìsin yìí-Ọlọ́fàiná Àwọn ọmọ Nàìjíríà yarí lórí àfikún ọjọ ìséde tí Ààrẹ Buhari kéde Gómìnà Akeredolu kede kónílégbélé ní ìpínlẹ̀ Ondo Ni ẹnu ọjọ mẹta yii ni iroyin aawọ laarin awọn mejeeji yii bẹrẹ si ni lu si igboro pe ọrọ emi ni mo ju ọ, iwọ lo jumi laarin awọn mejeeji yii.
Nigeria swearing-in 2019: Wo àwòrán tó jẹ ojú ní gbèsè nípa ìbúra ààrẹ àtàwọn gómìnà
Alakoso ajo aabo ara, aabo ilu (Nigeria Security and Civil Defence Corps), Tajudeen Balogun fun ipinle Eko , ti won wa pese eto aabo ni ipinle Osun, naa gboosuba fun awon ara ilu, bi won se n  dibo won ni irowo-irose.
Ṣé lọ́òtọ́ ni ọlọ́pàá dàwátì torí àti dóòlà aráa India méjì tí wọ́n jígbé?
Hesekaya kú, wọ́n sì sin ín sinu ibojì àwọn baba rẹ̀; Manase ọmọ rẹ̀ sì jọba lẹ́yìn rẹ̀.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Fayose: Mí ò ní èsìí fọ̀ f'áwọn tó ní mo dánìkàn ta ilẹ̀ ẹgbẹ́ PDP ní Ekiti 20 Ọ̀pẹ̀̀ 2019 Oríṣun àwòrán, Facebook/Lere Olayinka Gomina ana nipinlẹ Ekiti Ayodele Fayose ti fesi si ẹsun ti alaga ẹgbẹ nipinlẹ naa fi kan an pe o danikan ta ilẹ̀ ẹgbẹ fọkan lara awọn wọlewọde rẹ.
Ṣalumu bí Jekamaya, Jekamaya sì bí Eliṣama.
Ẹ tún sọ pé, ‘Bí eniyan bá fi pẹpẹ ìrúbọ búra, kò ṣe nǹkankan.
Wọ́n sì pa Paṣandata, Dalifoni, Asipata, 
Kí wọ́n kó gbogbo oúnjẹ wọnyi jọ ninu ọdún tí oúnjẹ yóo pọ̀, kí wọ́n sì kó wọn pamọ́ sinu àwọn ìlú ńláńlá, pẹlu àṣẹ kabiyesi, kí wọ́n sì máa ṣọ́ ọ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, World Diabetes Day: Ọdún kọkandinlogun ti mo ti wà lẹ́nu itọ ṣúgà nìyí Ojọ karun un, oṣu kejila, ọdun 2015 ni wọn ṣatundi ibo naa kaakiri ijọba ibile mejidinlogun kaakiri ipinle Kogi.
Ọgbẹni Okasanmi sọ pe laipẹ laijina, ọwọ awọn ọlọpaa yoo tẹ awọn agbebọn mẹfa ọun.
Ọ̀pọ̀ ni àwọn tí ó ti sọ di ẹni ilẹ̀,ọpọlọpọ àwọn alágbára ni ó ti ṣe ikú pa.
“Kí ló dé tí n kò kúnígbà tí ìyá mi ń rọbí lọ́wọ́, tí ó fẹ́ bí mi,tabi kí n kú, lẹsẹkẹsẹ tí wọ́n bí mi?
Peter Cech de ibi aami ifẹsẹwọnsẹ igba Aarẹ PAOK Salonika yọ'bọn si adari ayo lori papa Oríṣun àwòrán, STATE HOUSE Àkọlé àwòrán, Ọgbẹni Rex Tillerson n pada si America lojo isegun Ileeṣẹ iroyin Reuters wi pe ọgbẹni Rex Tillerson nge abẹwo rẹ kuru si ilẹ Africa ti yoo si pada si Washington DC ni ọjọ iṣẹgun.
O tun salaye pe, ile eko
Seyi Edun ni ki alayọnusọ kọju mọ tiẹ, Nainalowo jẹwọ pe ẹkan ṣoṣo lohun de sọọsi ri laye Oríṣun àwòrán, Instagram/bukunmioluwasina/iamnino_b/ Awọn iroyin to jẹyọ lagbo oṣere Yoruba taa mọ si Yollywood lọsẹ yii ṣebi ẹni pe amulumala ni.
“Bí ẹ bá dẹ́kun láti máa ba ọjọ́ ìsinmi jẹ́,tí ẹ kò sì máa ṣe ìfẹ́ inú yín lọ́jọ́ mímọ́ mi;bí ẹ bá pe ọjọ́ ìsinmi ní ọjọ́ ìdùnnú,tí ẹ pe ọjọ́ mímọ́ OLUWA ní ọjọ́ ológo;bí ẹ bá yẹ́ ẹ sí, tí ẹ kò yà sí ọ̀nà tiyín,tí ẹ kò máa ṣe ìfẹ́ inú ara yín,tabi kí ẹ máa sọ̀rọ̀ àhesọ;
Mo si tun fẹ ẹ ri daju pe, Yahaya Jammeh mọ nkan to ṣe.
Àwọn arakunrin rẹ̀ ṣe àtúnṣe agbègbè tiwọn náà: Bafai ọmọ Henadadi, aláṣẹ ìdajì agbègbè Keila ṣe ti agbègbè rẹ̀.
Oríṣun àwòrán, PIUS UTOMI EKPEI Àkọlé àwòrán, Pẹlu ọpọlọpọ ife ẹyẹ ti wọn ti gba, oju wọn si nri mabo Eyi jẹ ohun kan ti osisẹ ẹka iroyin fun awọn agbabọọlu obinrin Port Harcourt, Rivers Angels naa gba wipe kii se pe awọn oniroyin ko fẹ safihan iru isẹlẹ bayii.
Nítorí nǹkankan náà ni ó ń ṣẹlẹ̀ sí gbogbo wọn: ati olódodo ati ẹlẹ́ṣẹ̀, ati eniyan rere ati eniyan burúkú, ati ẹni mímọ́, ati ẹni tí kò mọ́, ati ẹni tí ń rúbọ ati ẹni tí kì í rú.
08trn kalẹ̀, ó ń wá owó tí yóò fi gbọ́ bùkátà rẹ̀ Aarẹ orilẹede Naijira, Muhammadu Buhari ti gbe aba isuna oni triliọnu mẹtala naira (₦13.
Ó ń ti ibi ìtẹ́ Ọlọrun ati Ọ̀dọ́ Aguntan ṣàn wá.
lorile ede Naijiria ati isejoba tun fẹsẹ mulẹ sii lorile ede yii.
Ohunkohun tí ẹ bá bèèrè ninu adura, bí ẹ bá gbàgbọ́, ẹ óo rí i gbà.
A fura pé ejò lọ́wọ́ nínú ikú Tolu Arotile, ẹ ṣe ìwádìí ikú rẹ̀ - Afenifere, Gani Adams, Huriwa Yahaya Bello ni alága ìgbìmọ ìdìbò abẹ́lé gómìnà ìpińlẹ̀ Ondo Buhari pari ọrọ rẹ pe ijọba oun ko ni bojuwẹyin ninu afojusun rẹ lati ri pe ajọ NDDC atawọn ileeṣe ijooba apapọ miran kun oju oṣuwọn lẹnu iṣẹ wọn, ati pe ki gbogbo ohun ti wọn ba n ṣe nibẹ han si gbogbo ọmọ Naijiria.
 Adura wa ni pe, eso rere ni
 Ọ̀RỌ̀ ìṣítí fún gbogbo òbí sí ọmọ.
Ẹ ̀ wẹ ̀ , àwọn oníṣègùn ìbílẹ ̀ yàtọ ̀ sí àwọ ́ n babaláwo tàbí àwọn onífá , nítorí ifá nìkan ni àwọn babaláwo ma ń dá tí wọn yóò sì ka ǹkan ètùtù nígbà tí ifá náà bá yan ǹkan ètùtù fún ẹni tí wọ ́ n dífá fún .
Eyi lo mu ki Honorebu Adeniyi Adebisi to jẹ kọmiṣọna fun ọrọ okowo nipinlẹ Oyo ni o to gẹẹ lorukọ Gomina Seyi Makinde.
Manchester United fọ́ Manchester City lẹ́nu pẹ́tẹpẹ̀tẹ mọ́lé DJ Cuppy gbóṣùbà ràbàndẹ̀ fún Anthony Joshua ṣáájú ìjà rẹ̀ pẹ̀lú Andy Ruiz Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí 2 sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
Lọjọ keje oṣu kẹfa ọdun 2020 ni gomina Babajide Sanwo-Olu gbe ọpa aṣẹ le e lọwọ gẹgẹ bii Oniru kẹẹdogun ti ilu Iru nipinlẹ Eko.
Adé á pẹ́ lóri, bàtà á pẹ́ lọ́sẹ̀ o
Ni ipari Oloye Tolulaṣẹ sọrọ lori ayipada to ti de ba ede Yoruba lẹnu awọn ọmọ ni Port Novo.
Ní ọjọ́ kẹtala oṣù Adari tíí ṣe oṣù kejila, nígbà tí wọ́n ń múra láti ṣe ohun tí òfin ọba wí, ní ọjọ́ tí àwọn ọ̀tá rò pé ọwọ́ wọn yóo tẹ àwọn Juu, ṣugbọn, tí ó jẹ́ ọjọ́ tí àwọn Juu ṣẹgun àwọn ọ̀tá wọn; 
Dariusi, ará Mede, ẹni ọdún mejilelọgọta sì jọba lẹ́yìn rẹ̀.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Lagos: Ohun mẹ́fà tó yẹ́ kí o rántí nípa Gómìnà Ambode 25 Ìgbé 2019 Àkọlé àwòrán, Gomina Ambode Ọjọ perete lo ku fun gomina Akinwumi Ambode gẹgẹ bii gomina ipinl Eko to jẹ bii olu ilu ibudo katakara ati ọrọ aje orilẹede Naijiria.
Ní òjijì ni gbogbo wọn bá dúró, wọ́n gbójú sókè.
"'Street Gospel' tí mò ń kọ, Ọlọ́run ń fi tún ayé àwọn 'Boys' ṣe gan - Testimony Jaga Òkété bórù mọ afurasí tó gbé àdó olóró wọ ilé ìjọsìn Winners ní Kaduna Ọmọ ìjọ 20 kú bí wọ́n ṣe tẹ̀ wọ́n pa níbi ìsọjí ìtagbangba RCCG: Pásítọ̀ Adeboye ṣáájú ìwọ́de àdúrà CAN lòdí sí ìpànìyàn ní Nàìjíríà O ni ""Ti eeyan ba ti ni nọmba idanimọ lo ṣe koko ju."
4 , wí pé tí a bá fẹ ́ yí ẹ ̀ yán sódì , nínu gbólóhùn àkíyèsí alátẹnumọ ́ , a máa ń sọ ẹ ̀ yán náà di awẹ ́ gbólóhùn asàpèjúwe .
Nígbà tí wọ́n bá tún un gbìn ǹjẹ́ yóo yè?
gbenu le ibo APC ninu idibo naa ko ropo awon oludije labe asia egbe oselu APC.
Àwọn ìjọba ìbílẹ̀ náà ni Epe, Ibeju Lekki, Kosofe, Somolu àti Ikorodu.
Iléeṣẹ́ ààrẹ: Buhari kò bú ọdọ, àwọn ọ̀bàyéjẹ́ ń pa irọ́
Fabiyi ni ọrọ iku lagbara pupọ, to si wuwo, pẹlu afikun pe tawọn akẹẹgbẹ oun ko ba lee mọ ẹni to nifẹ wọn denu loju aye, bawo ni wọn se fẹ sedamọ rẹ ninu saare.
Bí olówó ẹrubinrin yìí bá kọ̀, tí kò ṣe àwọn nǹkan mẹtẹẹta náà fún ẹrubinrin rẹ̀, ẹrubinrin náà lẹ́tọ̀ọ́ láti jáde ní ilé rẹ̀ lọ́fẹ̀ẹ́ láìsan ohunkohun.
’ Ara mi máa ń kótì láti dáhùn – Ìgbà mìíràn mà á pé India ni mo ti wá, ṣùgbọ́n wọn kò fún mi ní ìwé ìgbèlùú; nígbà mìíràn ẹ̀wẹ̀ mà á dáhùn pé Tibet ni mo ti wá, ṣùgbọ́n tí wọ́n bá béèrè pé báwo ni Tibet ṣe rí, n ò mọ bí n ó ṣe dáhùn-un rẹ̀, ìdí ni pé China ò fún mi ní ìwé ìgbèlùú lọ sí Tibet.
Bí bẹ́ẹ̀ kọ́, ó lè gba àwọn ìlú olódi bíi mélòó kan kí ó sì dá wahala sílẹ̀ fún wa.
" Arakunrin naa ni oun ko pe ki ẹnikẹni o lo orukọ oun lati pe ẹjọ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Baby abandoned on dunmpsite: Mo ti bímọ mẹ́rin tẹ́lẹ̀ fún bàbá méjì nínú òṣí- Dupe Ogbomos Ki lo ti kọkọ ṣẹlẹ ni Eko gẹgẹ bii ijamba?
”Aare fi aidunnu re han bi awon kan se
Amọ, laarọ Ọjọbọ lawọn eeyan ri fidio kan ninu eyi ti Nengi ti gbagbe irọri rẹ to fi ṣami aye rẹ lori ibusun pẹlu Ozo.
A láyọ̀ ninu rẹ̀,nítorí pé a gbẹ́kẹ̀lé orúkọ mímọ́ rẹ̀.
Ọgbọ́n ni OLUWA fi fi ìdí ayé sọlẹ̀,òye ni ó sì fi dá ọ̀run.
Ẹ̀ṣùn méje gbòógì tí ìjọba àpapọ̀ fi kan Ibrahim Magu rèé Ṣé lóòtọ́ ni Lateef Adedimeji àti Adebimpe Oyebade ṣe ìgbéyàwó?
Ajọ to n bojuto ọrọ igbo lorilẹ-ede naa ti lo orisirisi ẹrọ igbalode lati wa ẹkun to n sa kiri yii.
Wọ́n bá fi Sebede baba wọn sílẹ̀ ninu ọkọ̀ pẹlu àwọn alágbàṣe, wọ́n ń tẹ̀lé e.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Har yanzu akwai ragowar 'yan matan Chibok kusan 100 da ba a gano ba Ko si ti si ẹri kan to muna doko to le fi han wipe awọn ikọ Boko Haram ni wọn gbe awọn ọmọ ile iwe naa lọ.
Ṣùgbọ́n lẹ́yìn ọjọ́ mẹ́fà, Dáúdà tún bọ́ sọ́jà láti ra rọ́bà mìíràn.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Ọwọ́ tó bá dilẹ̀ ni èṣù ń bl ní iṣẹ́kíṣẹ́' Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Fídíò, Natalia Mufutau ìyá Yakub, Kamil àti Adam sọ̀rọ̀ lórí bí wọ́n ń sọ èdè mẹ́rin pàpọ31 Ògún 2020 Fídíò, Yoruba Language: Akomolede ati Asa Yoruba tọ̀sẹ̀ yí rèé lẹ́nu olùkọ́ wa30 Ògún 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Bí mo ṣe ń dàgbà ni ǹkan ọmọkùnrin mi ń tóbi síi àmọ́ obìnrin ni mi' Ìdí tí Gúúsù Akure, Owo àti ìwọ̀orun Ondo yóò fi sọ ẹni tí yóò jáwé olúborí nínú ìbò gómìnà Ondo Kẹ̀rẹ̀ kẹ̀rẹ̀ Okonjo-Iweala ń súnmọ́ ipò olórí WTO bọ̀ Bode George ní Fayose gọ̀, ó fẹnu họra, Fayose ní ''ẹ ò lè pa mí bí ẹ ṣe pa Bola Ige Ènìyàn 5, ilé 25 ilé ìtajà 16 àti àwọn ǹkan mírà lo bá ìṣẹ̀lẹ̀ iná náà rìn.
Awọn ileesẹ ijọba to to mejile lọgọrun-un ni igbimọ Orosanye dabaa pe ki ijọba parẹ ninu ojilelẹẹdẹgbẹta, 541, awọn ileesẹ ti ijọba ni.
Josẹfu bi wọ́n léèrè, ó ní, “Irú kí ni ẹ dánwò yìí?
Àwọn kan kópa nítorí wọ́n fẹ́ rí àrídájú; àwọn mìíràn rí i bí ọ̀nà láti fi ìmọ̀ kún ìmọ̀.
Ẹni tí ó bí ọmọ meje ṣe àárẹ̀, ó sì dákú,oòrùn rẹ̀ wọ̀ lọ́sàn-án gangan.
  Ó dìgbà tí ènìà bá súnmọ́n-ọn tán kí ó tó ríi pẹ́ àwọn òkúta
Ọlọrun, dákun, gbà mí,yára, OLUWA, ràn mí lọ́wọ́.
Wolves bu Arsenal jẹ bí ajá Iná mọ̀nàmọ́ná lọ fún wákàtí 24 ní Ghana, lariwo bá sọ!
 ""Kí ni ijo ayé nínú ijo tí mo jo táwọn èèyàn fi ń pariwo, bẹ́ẹ̀ ni n kò ṣẹ̀ṣẹ̀ máa wọ ṣòkòtò, kí wa lo jẹ́ nkan tuntun nínú ohun tí mo ṣe, ṣùgbọ́n mo bẹ gbogbo wọn, kí wọn má bínú si mi"" Orúkọ Abiku ni Okunnu tí mo ń jẹ nínú eré, inú orin Barrister ni mo sì ti ri - Wale Akorede Oríṣun àwòrán, Wale Akorede Àkọlé àwòrán, Orúkọ Abiku ni Okunnu tí mo ń jẹ nínú eré, inú orin Barrister ni mo sì ti ri - Wale Akorede Gbajugbaja osere tíátà, Adewale Akorede, tí ọ̀pọ̀ èèyàn mọ si Okunnu, tí sàlàyé pé lásìkò igbele Covid-19 yìí, àwọn amuludun tí ń gba onírúurú ọna lórí ayélujára láti mú inú àwọn olólùfẹ́ wọn dùn."
"O jẹ aṣiṣe buburu lati [gbiyanju lati] pa eniyan dudu.
Líìgì ilẹ Gẹẹsì: Salah ni agbábọọlù tó pegedé jùlọ
A gbọ pe awọn ẹrun naa ni awọn oyinbo yoo fun ni omi mu tẹrun, ki ori wọn ma baa pe, lati kọlu wọn loju omi.
Òfin tuntun náà yóò ra àwọn aláìsàn tí wọn kò ni tó oṣù mẹ́fà lọ mọ́ láyé láti gbé ayé láti gba ìrànwọ́ kíkú láì jẹ ìrora níwọ̀n ìgbà tí àwọn dókítà méjì bá ti fọ́wọ́ sí i.
Donald Trump has announced plans to tackle the opioid crisis.
Orúkọ àwọn ọmọ ati arọmọdọmọ Efuraimu yòókù ni Refa, baba Reṣefu, baba Tela, baba Tahani; 
Lara awọn Baalẹ to wa nilu Iwo, lasiko ti wọn n ba BBC Yoruba sọrọ ni, awọn eeyan kan to n se ilara Oluwo, Ọba Abdulrasheed Adewale Akanbi, Telu Kinni, lo n pariwo pe awọn fẹ rọ loye.
Oun ni aarẹ Naijiria akọkọ to kede dukia rẹ ni kete to de ipo lọdun 2007.
Bí irun orí ẹnìkan bá re, ní gbogbo iwájú títí dé ẹ̀bá etí rẹ̀, orí rẹ̀ pá ni; ó mọ́.
Sugbọn loju Jessica, ọmọdebinrin ti Chris bi, baba si ni ọkunrin naa jẹ, amọ loju awọn ara ita, oju Iwin"" tabi ""o lee jẹ́ ọdaran"" ni wọn fi n wo."
Èmi gan-an nìyí, n kò tíì mọ ibi tí mò ń lọ.
Afurasi ajinigbe naa nikan ni ko ku ninu ikọlu naa eleyi ti awọn ọmọ ogun ọhun ni awọn ro pe awọn ajinigbe lawọn ọlapaa to gbe Wadume nigba naa.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Kidnapping: Ọwọ́ ọlọ́pàá ba Pásítọ̀ olórí ikọ̀ ajínigbé tó pa èèyàn márùn ún 5 Ọ̀wàrà 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 30 Agẹmo 2020 Oríṣun àwòrán, Facebook/Policeng Afurasi ọmọ ikọ ajinigbe kan Musa Umar, ti tu kẹkẹ ọrọ lori bi o ti ṣe maa n gbẹmi awọn eeyan ti wọn ba jigbe.
Àwọn orin wọ̀nyìí kò yé Lhamo, bó ṣe jẹ́ pé kò mọ èdèe Mandarin Ilẹ̀ China sọ.
Ọmọ meji ni oloogbe Ọlayẹmi bi, oun pẹlu ẹnikan ni wọn lọ si oko ẹgẹ to gbin si igbo ọba to wa nilu naa.
Gbogbo àwọn tí wọ́n jẹ ninu àkọ́so èso yìí di ẹlẹ́bi;ibi sì dé bá wọn.
"Àwọn ìròyìn tì ẹ lè nífẹ̀ẹ́ sí: Ààrẹ Buhari yóò sàbẹ̀wò sí ìlú Eko Ológun tó ń ṣùn ni Buhari, kò gbogun ti Boko Haram - Fadá Mamza Aarẹ ọna kakanfo Yoruba ""Gbogbo òṣìṣẹ́ kọ́ ni #30,000 owó oṣù tuntun yóò kan"" Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Wo ohun tí ọkùnrin yìí ń sọ táyà ọkọ̀ dà Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!"
Bákan náà ni àwọn fótò míràn tó jẹ́ ti ọmọbinrin ọ̀hún àti Dino Melaye tún súyọ lórí ayélujara.
Joṣua ati gbogbo àwọn ọmọ Israẹli bá mú Akani, ọmọ Sera, ati fadaka, ati ẹ̀wù àwọ̀lékè, ati ọ̀pá wúrà, ati àwọn ọmọ rẹ̀ lọkunrin ati lobinrin, àwọn akọ mààlúù rẹ̀ ati àwọn kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ rẹ̀, àwọn aguntan rẹ̀ ati àgọ́ rẹ̀, ati ohun gbogbo tí ó ní, wọ́n kó wọn lọ sí àfonífojì Akori.
Atupalẹ awọn ipinlẹ ti wọn ti ri ikọọkan awọn to ṣẹṣẹ ni re e.
" Gbogbo igba ti John ba gbiyanju lati sọ fun awọn eniyan, wọn kii gbagbọ.
ki won ri awon to  sọnu ,bakan naa, ni ki
Awọn orukọ ti wọn yọ kuro 
Awon agbaboolu teleri fun iko Super Eagles ti sekilo fun iko Super Eagles lataari pipadanu ifesewonse olorejore kan ti o ku sowo iko agbaboolu orile-ede Czech republic pelu ami-ayo kan sodo(1-0), ninu ifigagbaga ti o waye ni papa isere Rudolf-Tonn-Stadion lorile-ede Austria.
7 Èrèlè 2020 Oríṣun àwòrán, @DAWNCommission Ohun to ba ti ya kan, kii pẹ mọ, fọọmu igbaniṣiṣẹ fun ẹṣọ alaabo lawọn ipinlẹ Yoruba, Amọtẹkun yoo jade lọsẹ to n bọ.
idibo ati ise akanse – Babatunde Raji Fashola, SANIgbakeji oludari
Ni igba iwasẹ, awọn eniyan ma n binu fun ọpọlọpọ idi, eleyii ti o ma n mu ki wọn gbiyanju lati jẹ gaba lori ara wọn.
Eleyi a ma mu ki awọn ọmọ ogun ara to ku naa gbaradi ti eyi a si ma fa ara riro ati ara gbigbona fun ẹni naa.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Nicolas Otamendi dayo kan pada, amọ ẹpa ko boro mọ fun Man City.
4bn si wa fun asepari awọn oju ọna atijọ ati lila awọn oju ọna tuntun Ijọba Ọyọ si ẹka ileesẹ to n se atunse awọn oju popo nipinlẹ Ọyọ OYSTROMA si ẹkun kọọkan lọna ti ri daju pe atunse n ba awọn oju popo to wa nipnilẹ Ọyọ loore koore Tunwẹ, isẹ riri awọn ina oju popo yika ipinlẹ Ọyọ naa wa ninu eto isuna ọdun 2020.
Alábàárù ni mò ń ṣe lọ́jà Ketu àti Mile 12, kí ń tó bẹ̀rẹ̀ Fuji - Atawẹ́wẹ́ Seyi Makinde fún olórin Fuji Taye Currency lẹ́bùn ọkọ̀ bọ̀kìnnì Toyota Prado 2020 Wasiu Ayinde ti ẹrọ̀fọ̀ dé ibi gíga, bí ikú bàbá rẹ̀ tiẹ̀ ṣèdíwọ́ láti lọ sílé ẹ̀kọ́ Èmi àti Kolington kò fẹ́ra padà o, ọba Wákà kò fẹ́ ọba Fuji mọ́ - Salawa Abeni Mo lóbìnrin tó bímọ fún mi, ṣùgbọ́n ọ̀rọ̀ ìyàwó kò tíì yọ fún mi báyìí-Pasuma Onínúfùfù ni Saheed Oṣupa, ṣùgbọ́n èèyàn dáradára ni-Taye Currency Nigba to pada de lati oju ogun, wọn gbe e lọ si olu ileeṣẹ ologun to n ṣe ifimufinlẹ, ni Apapa nilu Eko, ko to o tun lọ si Army Resettlement Centre ni Oshodi.
O ni iṣẹ ọlọpaa ko faaye gba iwọde kotẹmilọrun rara, koda nigba ti iya owo oṣù ati ajẹmọnu ba n jẹ wọn.
4 10520 Orilẹede Guadeloupe 149 37.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Nigeria's Under-19:Ẹ wo bí Ikọ̀ Cricket Naijiria ṣe mi àgbáyé titi Fagbemi ni Mẹ́rìnlelogun nínú àwọn ènìyàn to ko àìsàn náà ti kú nítori pé ọ̀rọ̀ wọ́n ti de ipele tó lágbara ki wọ́n to gbe wá sí ilé ìwòsàn, èníyàn mẹtadínláàdọta lo ti wa ni ìdádúro bayìí ti wọ́n si n gba ìtọjú nígbà ti àwọn mọkanlelógun ti ni ìmúlárada ti wọ́n si ti lọ ilé wọn.
CP Mu'azu Zubairu - CP Lagos State Command xx.
Mo ní, “oriṣa ni yín,gbogbo yín ni ọmọ Ọ̀gá Ògo.
Jegede gbe ẹjọ lọ siwaju igbimọ to n gbọ awuyewuye to ba ṣuyọ lẹyin eto idibo, nitori awọn mago-mago, ihalẹ mọ ni ati rogbodiyan to waye lasiko idibo naa""."
Àyà rẹ ni o óo máa fi wọ́ káàkiri,erùpẹ̀ ni o óo sì máa jẹ ní gbogbo ọjọ́ ayé rẹ.
"A si fẹ ki o ye e yin pe awọn ọlọpaa Hisbah yoo ma a tọ pinpin lati le dena lilo ede naa, ati lati le jẹ ki alaafia ati irẹpọ wa nipinlẹ Kano.
Joint Security: Ọdẹ ìbílẹ̀, OPC, Aṣọ́gbó, ọlọ́pàá, ológun yóò máa pèsè ààbò nílẹ̀ Yorùbá
 Iṣẹlẹ kan ti mo ranti ni pe ""mo ji l'oju orun ni mo ri i pe ololufẹ mi ti fi mamu gaari (handcuff) so ọwọ ọtun mi mọ ibusun wa."
Ìwọ ọkùnrin alágbára, nígbà ti èmi àti ẹ̀gbọ́n mi di àjẹ́ tán a fi ojú ènìyàn rí ǹkan, nítorí a pa kékeré jẹ, a pa àgbàlagbà jẹ, a sipa ènìyàn pàtàkì ni àwùjọ.
'Kò sí ìrètí pé wọn yóò rí agbábọ́ọ̀lù Cardiff tó pòórá' Lẹ́yìn òkò ọ̀rọ̀, Buhari àti Ọbasanjọ fẹ̀rín pàdé ara wọn l‘Abuja Wo ohun márùn-ún tó ń fa ìjàmbá iná nínú ilé Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Obasanjo: Atiku kìí se Áńgẹ́lì, àmọ́ yóò se dáadáa ní ìlọ́po méjì ju Buhari lọ Ibatan rẹ, Ibrahim Suleiman ti BBC ri ba sọrọ ṣalaye pé ọkọ iyawo ti fẹsẹ fẹẹ lẹyin iṣẹlẹ yii ati pe, o ti ni oun kò ni pada sile mọ.
ede Naijiria, ti won n jabọ fun aare lori ipo ti eto aabo de duro lorile ede yii
Adajọ Kikẹlọmọ tile ẹjọ Abẹ́lé ni Yaba ni ipinlẹ Eko ti ni ki Udeme Odibi, ti wọn fẹ̀sùn kàn pé ó pa ọkọ rẹ̀ Otike Odibi l'ọjọ Bọ to kója ṣi wà látìmọ́lé ná.
Ẹwẹ, kọmiṣọna ọlọpaa ipinlẹ Ondo ti sọ pe afurasi ọhun yoo foju bale ẹjọ laipẹ.
"Ṣugbọn o, baba rẹ fọwọ si igbeyawo naa pe ""to ba jẹ pe fifẹ Alaafin yoo mu Alaafin wọ Isalẹ Oyo, a jẹ pe ko b'ewu de""."
Oba Adeyemi fi kun ọrọ pe, Ajimobi jẹ ọlọkan akin ati olori daada ti kii bẹru lati gbe igbesẹ akinkanju, to si setan lati koju ohunkohun to ba tẹyin igbesẹ naa yọ.
”Aare tun wa ,fi da gbogbo omo
Ṣugbọn Johanu fẹ́ kọ̀ fún un, ó ní, “Èmi gan-an ni mo nílò pé kí o ṣe ìrìbọmi fún mi; ìwọ ni ó tún tọ̀ mí wá?
pelu awon adari ile-ise okoowo lagbaaye nibi ti yoo ti tun ti ri oba Hussein
Ó sì tún kópa nínú kíkọ Àsàyàn Ìtàn.
Ewéko gbígbẹ Cannabis ni o di ewé Marijuana.
Abajade ipade naa si ni pe ijọba yoo san ajẹẹlẹ owo oṣu mẹrin to ku ninu ọdun 2015 fawọn oṣiṣẹ, pẹlu ajẹẹlẹ ajẹmọnu owo isinmi ọdọọdun (leave bonus) fawọn oṣiṣẹ ijọba ipinlẹ ati ibilẹ nipinlẹ naa.
Àkọlé àwòrán, Ojọ̀gbọ́n Samuel Otubusin Ojogbon Samuel to je omo aadorin odun ati iyawo rẹ lasiko ti won n ba BBC Yoruba sọrọ ni ọmọ ọgọrun ọdun le di ọlọmọ ti wọn ba ti ni ipinnu to daju lai bẹru.
" o so nigbana pe "" harlem gbajumo "" ."
" Gomina ipinlẹ Ondo, Rotimi Akeredolu ti jajabọ lọwọ arun Coronavirus.
Ó ní òun pàápàá yóo bá wọn lọ.
Jokitani ni baba Alimodadi, Ṣelefu, Hasamafeti, Jera, 
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Minimum Wage: Apá àwọn gómìnà ò ká ọgbọ̀n ẹgbẹ̀rún Naira owó oṣù-Yari 14 Ọ̀pẹ̀̀ 2018 Oríṣun àwòrán, @BashirAhmad Àkọlé àwòrán, Buhari wa fi ẹmi imoore rẹ han si awọn akẹẹgbẹ rẹ ninu ajọ Ecowas Aarẹ Buhari sọ fun wa pe eto ọrọ aje orilẹede Naijiria ko dara lasiko yii.
Oshiomole tun fikun ọrọ pe, ẹgbẹ oṣelu APC ko ṣeleri lati tun orilẹede Naijiria ṣe laarin ọdun mẹrin, nitori ko rọrun lati tun ohun ti ẹgbẹ PDP ti bajẹ fun ọdun mẹrindinlogun ṣe laarin ọdun mẹta ati aabọ.
Ilu Kano ati isejọba Emir ẹyọkan ti pe igba ọdun ki ijọba to gbe igbesẹ yii, labẹ Emir Muhammadu Sanusi Keji.
Ó dáhùn pé, “Kí ìwọ fẹ́ràn Oluwa Ọlọrun rẹ pẹlu gbogbo ọkàn rẹ, ati pẹlu gbogbo ẹ̀mí rẹ, ati pẹlu gbogbo agbára rẹ ati pẹlu gbogbo òye rẹ; sì fẹ́ràn ọmọnikeji rẹ bí ara rẹ.
Ni isọri isọri, ni wọn ṣe agbekalẹ yi ṣugbọn eleyi to kan wa ni Naijiria la ni ki a ṣe atupalẹ rẹ fun ara wa.
Olugbenga Fadeyi, tii se agbẹnusọ fun ileesẹ ọlọpaa ipinlẹ Oyo fidi ọrọ yii mulẹ, to si ni awọn ti ko awọn afurasi agbebọn naa lọ si ileesẹ ọtẹlẹmuye ọlọpaa to wa ni Iyaganku fun iwadii to munadoko.
Angẹli OLUWA náà dáhùn pé, “Kí ló dé tí o fi ń bèèrè orúkọ mi nígbà tí ó jẹ́ pé ìyanu ni?
Ní ti àwọn arabinrin rẹ: Sodomu ati àwọn ọmọ rẹ̀ obinrin yóo pada sí ibùgbé wọn, Samaria ati àwọn ọmọ rẹ obinrin yóo pada sí ibùgbé wọn, ìwọ ati àwọn ọmọ rẹ̀ obinrin náà yóo pada sí ibùgbé yín.
20 Owewe 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 21 Owewe 2020 Oríṣun àwòrán, Getty Images Nkan ti baba fi ju ọmọ lọ ni ẹgbẹ agbabọọlU liverpool fi ọrọ ṣe pẹlu bi wọn ṣe din dundun iya goolu meji si odo fun Chelsea.
Ọga agba ile iṣẹ ọlọpaa lorilẹede Naijiria Ibrahim Idris lo paṣẹ pe ki wọn wa ọdaran naa ni kiakia.
O si tun ni itakun agbaye ti awọn eeyan ti ma n san owo lati wo awọn fidio naa.
Lara awon ile-ise nla ti yoo
Bí ó bá dìde, ẹ̀rù á ba àwọn alágbára,wọn á bì sẹ́yìn, wọn á ṣubú lé ara wọn lórí.
AFCON 2019: Àwọn olólùfẹ́ Super Eagles fẹ́ kí Rohr tún wọn tò
Lai Mohammed, Ayo Fayose, Afẹnifẹre, Ndigbo, Arewa dá sí ọ̀rọ̀ Buhari àti Obasanjo Ìbẹ̀rù-bojo l'Ado Ekiti lẹ́yìn táwọn agbébọn pa ọ̀gá àjọ tó ń rí sí ọ̀rọ̀ ìjọba ìbílẹ̀ Ó yẹ kí Sotitobire gbọ́ ìdájọ́ lónìí ṣùgbọ́n ẹ wo bí ilé ẹjọ́ ṣe tún ṣe é Ọmọkùnrin tó ya 'Blue film' nínú igbó Osun Osogbo ti bayé ara rẹ̀ jẹ́ - Yemi Elebuibon Kí ló fà á tí àwọn ọmọ Obasanjo ń ta kò ó ní gbangba?
Ajọ Global Witness ti n ṣe iwadi fun ọpọlọpọ ọdun, lati mọ ẹni to fun ile iṣẹ epo Eni ati Shell lasẹ, lati maa wa epo ti wọn pe ni OPL 245 lagbegbe Niger Delta.
Abang ni, ìṣẹ̀lẹ̀ náà ti wáye láti ọjọ kẹtàdínlógún, oṣu kèje ọdún 2020 lásìkò tí wọ́n yan gómìnà ìpinlẹ̀ Kogi Yahaya Bello gẹ́gẹ́ bii alága ètò ìdìbò abẹ́lé náà, tí wọ́n sì gbà láti dìbò ní ọ̀nà tí kìí ṣe ìdìbò olójúkorojú, ọjọ́ kéta, oṣù kéjó, ọdún 2020 ni Adojutelegan ṣẹ̀ṣẹ̀ pe ẹjọ́.
Ìdí tí Gúúsù Akure, Owo àti ìwọ̀orun Ondo yóò fi sọ ẹni tí yóò jáwé olúborí nínú ìbò gómìnà Ondo Kanu Ejike fipá bá ọmọ ọdún méje lò pọ̀ nínú sọ́ọ̀bù ìyàwó rẹ̀ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ondo Elections 2020: Ọgọ́rùn-ún ọdún tí a máa lò lórí oyè l'Ondo, ẹ ó rí àrà - Ojon YPP Ta ni Ngozi Okonjo-Iweala to dupo olori ajọ okowo agbaye WTO?
Lẹ́yìn ọdún méjìlá, mo gun òkè fún ọjọ́ márùn-ún kí ń tó rí ìyá mi"" Àwa obìnrin, ẹ jẹ́ ká di fijilanté kí ọmọbìnrin wa má baà ya pòkíì - Aya Osinbajo Samuel Ajayi Crowther, òjíṣẹ́ Ọlọ́run tó gbé èdè Yoruba lárugẹ Mọrèmi Àjàṣorò, akọni obìnrin tó gba Ilé Ifẹ̀ sílẹ̀ lóko ẹrú Nigba to n kede eyi loju opo ikansira ẹni Twitter ẹgbẹ akẹkọ naa, akọwe apapọ fun ẹgbẹ NANS, Farouk Umar salaye pe nibẹ lawọn yoo ti sepade pọ pẹlu awọn alasẹ ẹgbẹ akẹkọọ ni fasiti Fuoye ati awọn eeyan miran to ni ohun se pẹlu isẹlẹ yii."
Nígbà náà ni Jesu sọ báyìí pé, “Mo dúpẹ́ lọ́wọ́ rẹ, Baba, Oluwa ọ̀run ati ayé, nítorí o ti pa nǹkan wọnyi mọ́ fún àwọn ọlọ́gbọ́n ati àwọn olóye, ṣugbọn o fi wọ́n han àwọn òpè.
" O wa gbe imọran kalẹ pe ti yoo ba se rere, o gbọdọ kọkọ wa ojutu sawọn isoro to nii se pẹlu irẹpọ to sọnu laarin ẹya kọọkan.
Igbimọ ile ẹjọ kotẹmilọrun ti adajọ Tinuade Akomolafe-Wilson dari wọn naa tu ẹjọ kotẹmilọrun ti wọn pe ka lọjọ kejila, oṣu keje.
Kabiyesi ko ṣai mẹnubaa wi pe, gẹgẹ bi Musulumi ododo, ẹsin ko faaye gba wi pe ki awọn maa lọ ile oro tabi ṣe oro to le pa awọn maalu ọhun nibi kan ṣugbọn pe iwadii n lọ lọwọ lori ọrọ naa.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù NigeriaRoadAccident- Ọkọ àjàgbé kọlu obìnrin kan lórí ọkadá ó sì kú 14 Ọ̀wàrà 2019 Oríṣun àwòrán, @LAM Àkọlé àwòrán, Ijamba oko Ajagbe Ọmọbinrin kan ni o ti gbekuru jẹ lọwọ ẹbọra lataari ijamba ọkọ Ajagbe ti o rọlu ọkada rẹ ni Abẹokuta.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Rashidat Fawẹhinmi: Sísọ èdè Yorùbá kò leè ba Gẹ̀ẹ́sì jẹ́ lẹ́yìn odi Akpan tun gbadura fun Buhari pe, aseye ni yoo se ninu eto idibo aarẹ ti yoo waye losu keji ọdun yii.
Gẹgẹ bi òwe Yorùbá ti sọ pé “Ẹni gbé epo lájà, kò jalè̀ tó ẹni gba a”, bi àwọn ti ó n fi ọna èrú àti iwà ibàjẹ́ ja ilú lólè, kò bá ri àwọn Ilú Ọba gba owó iwà ibàjẹ́  lọ́wọ́ wọn, iwá burúkú á din kù.
kí ó lè gba ọkàn wọn lọ́wọ́ ikú,kí ó sì mú wọn wà láàyè lákòókò ìyàn.
Aye tun sọrọ fiimu naa sii nigba ti wọn ni Netfilx ti ra ẹ̀tọ́ fiimu naa.
A fi ayùn rẹ́ àwọn mìíràn sí meji.
Bẹ́ẹ̀ ni Esau ṣe fi ojú tẹmbẹlu ipò àgbà rẹ̀.
Nípa ti oúnjẹ ti ìwọ sì sọ̀rọ̀ rẹ̀ pẹ̀lú, mo dúpẹ̀ lọ́wọ́ rẹ gidigidi, o kú àlejò mi.
Adelé Olúbọ̀rọ̀pa woye ọrọ yii lasiko to n kopa lori eto kan ni ikanni BBC Yoruba.
Awọn aṣofin méta ti wọn ni ki wọn lọ rọọkun nile ni Họnorebu Irọju Ogundeji to jẹ igbakeji adari ile, Họnọrebu Adewale Williams ati Họnọrebu Favour Tomomewo.
Gbogbo awọn nkan wọn yi lo wa lara ẹdun ọkan marun un ti awọn oluwde ENDSARS ni awọn fẹ ki ijọba mojuto.
Ni Gbongan The Dome, awọn apoti idibo gbogbo ti wa ni ato ni isọri ijọba ibilẹ kọọkan.
Ẹ jẹ́ kí omi máa dà lójú yín pòròpòrò tọ̀sán-tòru;ẹ má sinmi,ẹ má sì jẹ́ kí oorun kùn yín.
Wọn n pada si Abeokuta ni awọn akẹgbẹ awọn afurasi mejeeji ba ṣe ikọlu si wọn lọna."
Kete ti o jẹ goolu rẹ keji lo sare lọ mu awọ oju iru eleyi ti wọn wọ ninu fiimu ''Black Panther'' ti o si dawọọ idunnu ''Wakanda Forever'' Chelsea pòkọ ìyà fún Dynamo Kiev pẹ̀lú 5-0 'Mo fẹ́ kí agbábọ́ọ̀lù tí kò fakọyọ bínú' Arsenal fẹ́ tọwọ́ bọ àdéhùn pẹlu Aubameyang Oríṣun àwòrán, Getty Images Ko ye wa si ẹni to fi awọ naa si ibi to ti mu ṣugbọn idawọọ idunnu yi lo gba ẹnu awọn eeyan loju opo Twitter.
Lekan Kingkong, lasiko to n ba BBC Yoruba sọrọ wa rọ gbogbo ọmọ Kaarọ oojire, paapa awọn to wa lajo lati maa gbe asa Yoruba larugẹ nitori ọmọ to ba sọ ile nu, o so apo iya kọ ni.
Ile iṣẹ ọlọpaa ni ipinlẹ Ondo ti fi idi ẹ mulẹ pe lootọ ni awọn ajinigbe ti ji Alaga Ẹgbe Oselu ADC ni ipinlẹ Ondo, Bisi Ogungbemi ati awọn mẹrin miran lọ.
Kin lo mu Saraki dagbere fun APC, to si gba PDP lọ Ni ọjọ kọkanlelọgbọn, oṣu keje, ọdun 2018 ni Saraki kede lori opo Twitter rẹ pe, oun ti fi ẹgbẹ oṣelu APC silẹ lọ si PDP to ti wa tẹlẹ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù 2019 in Retrospect: Wo àwọn èèyàn jáńkán tí yóò rékọjá sí 2020 nínú ọgbà ẹ̀wọ̀n 31 Ọ̀pẹ̀̀ 2019 Oríṣun àwòrán, @others Oriṣiriṣi ohun lo ṣẹlẹ lọdun 2019, ọpọ lo ṣe igbeyawo, awọn kan kọle, awọn mii ra ilẹ, awọn kan dero oke okun, bẹẹ lawọn miran dero ẹwọn.
Ifa lo si le sọ itumọ bi awọn obi yoo ṣe ba adehun tabi ipin awọn naa jẹ.
Kí oore-ọ̀fẹ́ ati alaafia Ọlọrun, Baba wa, wà pẹlu yín ati ti Oluwa Jesu Kristi, 
A lè sọ èyí nítorí a ní igbẹkẹle ninu Ọlọrun nípa Kristi.
Ọlọ́pàá yọ Yomi Shogunle kúrò ní adarí ẹ̀ka PCCRU Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, '500 level'' ni mo wà nígbà tí mo di adélé Ọba' Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Helen Paul sọ idi tó fi gba orúkọ ní kékere Ṣaaju abẹwo rẹ si ilu Maiduguri, Aarẹ Buhari kọkọ wa si ipinlẹ Eko nibi ti o ti ṣi awọn akanṣe iṣẹ kan ti ijọba ipinlẹ naa ṣe.
"Wàhálà bẹ́ sílẹ̀ láàrín àwọn ọ̀dọ́ ní Oke Odo ní ìpínlẹ̀ Eko Wàhálà tí àwọn ẹgbẹ́ òkùnkùn àt'àwọn ẹgbẹ́ ìjayà míràn ń dá sílẹ̀ láwọn ọgbà fásitì Nàìjíríà Ohun tí o kò mọ̀ nípa Ebila ""One Million Boys"" àti Ekugbemi, olórí ẹgbẹ́ òkùnkùn méjì tó da ìlú Ibadan rú Àlàyé rèé lórí bí wọ́n ṣe pa Ebila, olórí àwọn ""One million boys"" n'Ibadan Eyi ko ṣẹyin bi awọn ọmọ ẹgbẹ okunkun Awawa ṣe n ka awọn eeyan mọle lọganjọ oru ati ọsan gangan lasiko ti ijọba kede konile-o-gbele nitori itankalẹ coronavirus l'oṣu Kẹrin, ọdun 2020."
Ninu sin Islam, wọn a ma fi yiyọ oṣu tuntun mọ igba ti awọn ọdun pataki bi ọdun awẹ ati ileya yoo waye.
Bi inu awon osise orile ede
INEC sọ wi pe, ẹgbẹ oselu mọ́kàndínláàdọ́rùn ún lo ti fi orukọ oludije bii ẹgbẹrun kan ati mẹtalelẹgbẹrin (1,803) sọwọ fun ipo asofin agba, nigba ti wọn si ti fọwọ si orukọ awọn 4,548 fun ipo asoju-sofin.
fọ́n owó ká fáwọn èrò lẹ́yìn tó pariwo 'Merry Christmas' Dokita meji pere, awọn to n tun ile ṣe ati awọn alufaa to ni ẹtọ lati gbọ ijẹwọ ẹṣẹ awọn eniyan ni oriṣiriṣi èdè nikan ni anfaani wa fun lati wọ inu ibi ti wọn wa.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Lagos Explosion: Sanwo-Olu rọ olùgbé Eko láti mú ààbò ẹ̀mí ní pàtàkì 15 Ẹrẹ̀nà 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 16 Ẹrẹ̀nà 2020 Oríṣun àwòrán, Others Ajọ to n ri si isẹlẹ pajawiri nipinlẹ Eko, Lasema ti kede pe eeyan mẹtadinlogun, to fi mọ ọga agba ileẹkọ kan lo ti jalaisi ninu isẹlẹ naa, nigba ti awọn mẹẹdọgbọn miran n gba itọju nile iwosan, eyi ti iroyin rẹ gbalẹ kan ni aarọ ọjọ Aiku.
Ní òwúrọ̀ ọjọ́ kẹta, ààrá bẹ̀rẹ̀ sí sán, bẹ́ẹ̀ ni mànàmáná ń kọ, ìkùukùu sì bo òkè náà mọ́lẹ̀, fèrè kan dún tóbẹ́ẹ̀ tí gbogbo eniyan tí wọ́n wà ninu àgọ́ wárìrì.
Bẹẹ gẹgẹ lọrọ ri pẹlu oṣere tiata, Tayo Odueke ti ọpọ mọ si Sikiratu Sindodo, to n ṣopẹ fun Eleduwa to mu ri ọjọ ibi rẹ mii.
ó sọ̀rọ̀ sí wọn gẹ́gẹ́ bí ìmọ̀ràn tí àwọn ọ̀dọ́ fún un, ó ní, “Àjàgà wúwo ni baba mi gbé bọ̀ yín lọ́rùn, ṣugbọn èmi óo tún fi kún àjàgà náà.
Kí ẹ wá gbé ẹni titun nnì tí Ọlọrun dá wọ̀, kí ẹ lè máa ṣe òdodo, kí ẹ sì máa hu ìwà mímọ́ ninu òtítọ́.
O ni lasiko ti Naijiria gbona janjan nigba ti Ogagun Sani Abacha n se awọn eeyan basubasu bo se wu u nigba naa.
Iwadi kan lorilẹede Amẹrika fihan pe, laarin ọdun 1976 si 1997, eyiun ọdun laarin ọdun mọkanlelogun, awọn ọmọde tawọn obi wọn ti pa to ẹgbẹrun mọkanla.
Ìgbà tí o dì í tán, ó pè mi, lẹ́yìn náà ó pe àbúrò rẹ̀, ó bi i léèrè lójú mi ibi tí onítọ̀hún lọ ní alẹ́ ìgbà tí èmi ṣebi mo rí òun, onítọ̀hún sí ssọ ibẹ̀ fún un lójú mi.
Tunde Owokoniran Oṣere tiata Tunde Owokoniran ati iyawo rẹ ki ọmọjojolo kaabọ si ẹbi wọn lọjọ kejidinlogun oṣu kẹjọ ọdun 2019 lorilẹede Amẹrika.
Wọ́n kó àwọn ọmọ ogun Israẹli náà jọ, wọ́n sì wá àwọn ohun ìjà ogun fún wọn.
“Mo fi aṣọ ọ̀fọ̀ bo ara,mo sùn gbalaja sinu erùpẹ̀.
Níbẹ̀ ni àwọn alufaa tí ń rú ẹbọ sí OLUWA yóo ti máa jẹ ẹbọ mímọ́ jùlọ.
Awọn kan pẹlu ni boya o fẹ lọ du ipo gomina ni ipinlẹ rẹ, iyẹn ipinlẹ Ogun lati gba ọpa aṣẹ lọwọ Gomina Amosun ti yoo pari saa keji rẹ ni ọdun to n bọ ni.
Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí 6:18 Fídíò, Natalia Mufutau ìyá Yakub, Kamil àti Adam sọ̀rọ̀ lórí bí wọ́n ń sọ èdè mẹ́rin pàpọ, Duration 6,1831 Ògún 2020 Fídíò, Yoruba Language: Akomolede ati Asa Yoruba tọ̀sẹ̀ yí rèé lẹ́nu olùkọ́ wa30 Ògún 2020 Coronavirus in Nigeria: Èèyàn mẹ́jọ kú, 1,024 míràn tún lùgbàdì ààrùn náà ní Nàìjíria11 Sẹ́rẹ́ 2021 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 3 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 5 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Kò sí nǹkankan ti baba mi ń ṣe, bóyá ńlá tabi kékeré, tí kì í sọ fún mi; kò sì tíì sọ èyí fún mi, nítorí náà ọ̀rọ̀ náà kò rí bẹ́ẹ̀.
Ṣaaju iṣẹ tuntun ti wọn ṣẹṣẹ gba yii, ileeṣẹ igbohunsafẹfẹ ipinlẹ Ọṣun to wa nilu Oṣogbo lawọn oniroyin mejeeji yi ti n ṣiṣẹ fun ọpọlọpọ ọdun.
Lọdun 2012 ni Usman darapọ mọ ajọ ẹṣẹ kikan MMA, bẹẹ lo si bẹrẹ sii ja ni UFC lọdun 2015.
Ìjàmbá iná ọ̀pá epo tó wáyé l'Abule Egba kò leè fa ọ̀wọ́ngógó epo-NNPC Oríṣun àwòrán, @trafficbutter Àkọlé àwòrán, Ọpọlọpọ mọto, ọjà ati nkan amuludun lo jona ni Abule Egba nidaji ọjọru Saaju la ti fi to yin leti ni osu kejila lọdun 2018 pe, ajọ elepo rọbi lorilẹede Naijiria, NNPC ti bẹrẹ iwadii lori iṣẹlẹ ijamba ina to ṣẹyọ ni ori ọpa epo rẹ kan lagbegbe abule ẹgba ni Eko.
"Olóògbé náà ń wà ọkada lọ láti ṣe abẹwo si màmá rẹ, Arábìnrin Mojisola Martins ni ile rẹ to wá ní òpópónà Olayinka ni Ajegunle, nígbà tí àwọn gende mẹ́rin ṣẹburu rẹ nikorita Gbàrà, àwọn mẹta nínú wọn mú Ọlọpaa náà mọ́lẹ̀, tí Arogundade sì ń gùn olóògbé náà laimọye ìgbà, kí gbogbo wọn to salọ.
Agbaboolu mokanla ohun: Uzoho, Shehu, Troost-Ekong, Balogun, Idowu, Ogu, Ndidi, Iwobi, Mikel, Moses, Ighalo.
Oxfam wa salaye pe, ireti si wa ti ijọba orilẹede kọọkan to wa nilẹ Afirika ba lee se awọn atunse ni agbọn kọọkan ti ọrọ yii kan.
Yemi Osinbajo: Igbákejì ààrẹ ní ìṣẹ́ àti òsí tí Covid-19 kó bá wa, kò ṣe dúró wò
Gbogbo ounjẹ ti eniyan n jẹ loun naa n jẹ to fi mọ eso bii Ọpọ Oyinbo, Ibẹpẹ,Ọgẹdẹ.
Eyi si mu ipakiyesi wa fun aṣa ila kikọ ni ilẹ Yoruba ati ohun tawọn eeyan n koju nipa rẹ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Akomolede ati Aṣa lori BBC: Mọ̀ si nípa oríṣìí ẹ̀ka ìsọ̀rí ọ̀rọ̀ àti ìwúlò wọn Tí mo bá kú lónìí, Pásítọ̀ Ibiyeomie ló pa mi - Daddy Freeze kébòòsí Àwọn afurasí lórí ẹ̀ṣùn jíjí ìbejì Akeugbagold gbé yọnú sílé ẹjọ́ láì ní agbẹjọ́rò Tí òṣèré tíátà yóò fi kú, eré ni wọn yóò ló ń ṣe - Ibrahim Chatta Aṣòfin méje yarí mọ́ Akeredolu lọ́wọ́ torí ọkọ̀ ayọ́kẹ́lẹ́ tí kò pín fún wọn Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Udeh ni lọpọ igba, awọn obi kii mọ ohun ti awọn ọmọ wọn n ṣe ni ileewe giga nitori naa wọn ko le e pin ninu iya ẹṣẹ ti ọmọ ba ṣẹ.
Gómìnà Ondo Akeredolu ṣí ilẹ̀kùn ṣọ́ọ̀ṣì àti mọ́ṣáláṣí sílẹ̀ fún ìjọ́sìn Ṣé olorì ṣì ni Badirat Ọla láàfin ikú bàbá yèyé?
Gẹ́gẹ́ bí àtẹjáde náà ṣe sọ, ìwé ìfitónilétí ti ó tẹ ilé ẹgbẹ́ lọ́wọ́ ní ọjọ́ kejìdínlógún oṣù kẹfà ọdún yìí kò ni àbuwọ́lù àlága àpapọ̀ ẹgbẹ́ náà.
Yóo dojú kọ gbogbo igi Kedari ti Lẹbanoni,tí ó ga fíofío, ati gbogbo igi oaku ilẹ̀ Baṣani;
Awọn alatilẹyin Tottenham ko gbagbe ọrọ yi wọn si ti bẹrẹ si ni fi naka abuku si Unai Emery ti o n dari ẹgbẹ alatako wọn Arsenal.
Adeleke to je okan lara omo
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ọ̀pọ̀ ìgbà ní Hushpuppi àtàwọn èèkàn PDP ti ya fọ́tò ní Dubai, EFCC ẹ wádìí wọn - APC ń lọgun Lẹ́yìn ọ̀ rẹyìn, Seyi Makinde ránṣẹ́ ìbánikẹ́dùn sí ẹbí Ajimobi Akeredolu, tó ò bá fa àkóso Ondo lé mi lọ́wọ́ láàrin ọjọ́ 21, o tàpá sófin - Igbákejì gómìnà Obìnrin kan wọ gàù lẹ́yìn tó kan ìṣó mọ́ ọmọ ọ̀dọ̀ rẹ̀ ẹni ọdún mẹ́wàá lórí Bàbá Aláàfin ìlú Ọ̀yọ́, Elérúwà àti àwọn Ọba Ilẹ̀ Yorùbá míràn tí wọ́n rọ̀ lóyè Ìjọba Nàìjíríà ti mú Dókítà Anu tí àwọn kan f'ẹ̀sùn kàn pé ayédèrú iṣẹ́ abẹ ìdí ló n ṣe Isẹlẹ naa to waye lọjọ kẹtadinlọgbọn osu Karun ọdun 2020, si lo n kọ ọpọ eeyan lominu pe ki lo lee se okunfa iwa ailaanu naa.
Àwọn agbébọn pa olóyè ẹgbẹ́ òṣèlú APC ní ìpínlẹ̀ Oyo sínu ilé 'Danfo', 'Okada', 'K-leg' àtàwọn ọ̀rọ̀ Nàìjíríà ti wọ́n fi kún Oxford Dictionary lọ́dun 2020 Àwọ́n kan ń ràgà bo Diezani nílẹ̀ Gẹ̀ẹ́sì láti jẹ́jọ́ ní Nàíjíríà àmọ́ á gbe wá - EFCC Ọkunrin mẹta ni wọn kọkọ fi bẹrẹ owo naabi fun mi, ti maa si lọ kowo fun ọga lẹyin ti mo ba ti ṣiṣẹ tan."
ayalejuara ati gbigbogun ti iwa ibaje ni ajo naa.
O ti le ni ẹẹdẹgbẹta eeyan to ti dero ọrun ni Naijiria nitori arun naa, lara awọnn eeyan ọhun ni: Abba Kyari Ajimobi kìí bá ọ̀lẹ, olè àti ọlọ́pọlọ kúkú ṣe ọ̀rẹ́ - Alaafin Tinubu, ojú tì ẹ́, o ta Yorùbá fún ọ̀tá torí àdánìkànjẹ - Fani-Kayode Àwọn èèyàn ìpínlẹ́ Ondo kò gbàgbọ́ pé Coronavirus wà lọ jẹ́ kó máa pọ̀ síi - ìjọba Iṣẹ́ márùn ún tí àwọn adarí ẹgbẹ́ APC gbọ́dọ̀ ṣe kíákíá kí omi má tẹ̀yìn wọ ìgbín lẹ́nu Ọjọ kẹtadinlogun, oṣu kẹrin ọdun 2020 ni iroyin gbode pe Abba Kyari to jẹ olori oṣiṣẹ aarẹ Muhammadu Buhari, ti doloogbe.
Bí àwọn ọmọ wolii ti jókòó níwájú rẹ̀, ó sọ fún àwọn iranṣẹ rẹ̀, ó ní, “Ẹ gbé ìkòkò ńlá léná kí ẹ sì se àsáró fún àwọn ọmọ wolii.
Bakan naa ni Aare ranse ibanikedun si ebi Baba Ahmed atijoba ipinle Kaduna lori iku ogbontarigi akoroyin Mahmoon to doloogbe.
O ni o yẹ ka jẹ ki awọn araalu mọ pe Isẹse lagba, ayajọ Isẹse yii si ni wọn yoo lo lati gbakanse adura si Ọlọrun ati awọn Alalẹ, bẹẹ si ni Orunmila lo kọkọ fi ipilẹ ilana isẹse yii lelẹ saaju ẹsin Musulumi ati ti Kristiẹni, nitori gbogbo ẹlẹsin lo n tọpasẹ ara wọn de idi ẹsin isẹse.
Ní'lùú Ilọrin, èèyàn méjì fara gbọta ìbọn Ìbọn ọlọ́pàá ló pa èèyàn, ẹgbẹ́ wa kìí lo ìbọn - Shiite fárígá #EndSARS lu ayélujára pa lórí ikú Kolade Johnson Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Shiite: Ẹ̀mí àti ara wa kọ ohun tí ìjọba ń ṣe sìwa láti 2015 Ayẹyẹ Ọdun Gilroy Garlic ti n sun mọ bebe ipari lopin ọsẹ naa lọjọ aiku nigba ti wọn da ibọn bolẹ nibi eto naa.
OLUWA Ọlọrun ti ṣí mi létí,n kò sì ṣe oríkunkun,tabi kí n pada sẹ́yìn.
''Ofin konile-o-gbele oḷọjọyipo ti wa ni ileewe naa, ti awọn Ajọ to n risi ajakalẹ arun nipinlẹ Eko si ti wa ni ileewe naa lati bojuto awọn to lugbadi arun ọhun.
Wo ilẹ̀ Ijipti láti òkè dé ilẹ̀, ibikíbi tí o bá rí i pé ó dára jùlọ ninu gbogbo ilẹ̀ náà ni kí o fi baba rẹ ati àwọn arakunrin rẹ sí.
Iroyin so pe, awon adari igbimo apapo ijoba ti a mo si Ethiopian People’s Revolutionary Democratic Front (EPRDF) se ipade pajawiri leyin ikede ifipo sile naa.
Ọwọ́ rẹ̀ gùn, nítorí baba rẹ̀ nì o ti ọwọ́ jọ ṣùgbọ́n yyíyára ìyá rẹ̀ ló mú lóòótọ́ ẹni tí ó bí ni là á jọ, Kùmọ́dìran jọ àwọn òbí rẹ̀ gan-an.
OLUWA sọ fún Mose ní pẹ̀tẹ́lẹ̀ Moabu lẹ́bàá odò Jọdani létí Jẹriko pé 
Lẹ́yìn tí Wasiu Ayinde bá wá ti gbé ìgbésẹ̀ tí ẹgbẹ̀ náà bèrè fún ni àwọn yoo tó mọ̀ boya àwọn yóò dá owó náà padà bi bẹ́ẹ̀ kọ́, owó ọhun kò tí tó ǹkan ti àwọn fi ṣe ìtọ́jú MC Murphy.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ìran kan si ìkejì ló n gbèrò láti ṣe ìrú ìgbéyàwo àjùmọ̀ṣe 'Shao' fọ́mọ wọn Kini o wa ṣokunfa okùn ifẹ wọn tuntun?
Ọ̀rọ̀ tí OLUWA sọ fún Hosia, ọmọ Beeri nìyí, ní àkókò tí Usaya ati Jotamu, ati Ahasi, ati Hesekaya jọba ní ilẹ̀ Juda; tí Jeroboamu, ọmọ Joaṣi, sì jọba ní ilẹ̀ Israẹli.
Lati igba ti wọn ti kede iku Sẹnẹtọ Abiola Ajimọbi lọjọbọ, ni awọn tolori tẹlẹmu ti n sọ ọrọ nipa iku rẹ.
Lara awọn eeyan ti ọwọ awọn osisẹ ajọ EFCC naa tẹ ni ẹnikan ti wọn furasi bii oludasilẹ ileẹkọ naa, Frank Chinedu, tii se ẹni ọdun mejilelogun.
Ni ipari o ni oun a ṣatilẹyin to yẹ fún ọmọ oun to ba ti dagba to dẹ fi dandan lee pe orin kikọ lo wu oun.
Yollywood: E wo bí àwón òṣèré tíátà Yoruba ṣe ṣàjọyọ̀ ọdún Kérésìmesì
Omobibi orile-ede Serbia, Djokovic fi idunnu re han, “Mo lero pe, ‘Pete yoo wa lati wa wo ifigagbaga yii tele ni, Mo nife re pupo, eni ti mo n wo awokose re.
won yoo se fopin iwa odaran ati ipaniyan ni ipinle naa .
Eyi lo mu igbiyanju BBC Yoruba waye lati maa ṣe ohun to lee mu gbigbe ede ati aṣa Yoruba larugẹ waye.
Naijiria ko ọmọogun ati ọkọ ogun ofurufu lati wa awọn ọmọ Dapchi
Awọn kan lara awọn ti wọn jọ du oye lo gbe e lọ sile ẹjọ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù EFCC: Ọmọ Nàíjíríà ń bèèrè pé báwo ní àjọ náà ṣé mọ èké babaláwo?
Ẹrọ ayaworan inu lori ayelujara Awọn onimọ ẹrọ kan ni Tunisia lo korajọ lati da oju opo kan silẹ lori ayelujara eyii to lagbara lati ya aworan inu ẹdọforo eeyan, ti yoo mọ boya iru ẹni bẹẹ wa ninu ewu Covid-19.
Abiola Ajimobi: Ìtùnú tí mo ní nípa ikú ọkọ mi, ni pé Sẹ́nétọ̀ Abiola Ajimobi rí ọ̀run rere wọ̀- Florence Ajimobi
Ìràwọ̀ kan yóo jáde wá láàrin àwọn ọmọ Jakọbu,ọ̀pá àṣẹ yóo ti ààrin àwọn ọmọ Israẹli jáde wá;yóo run àwọn àgbààgbà Moabu,yóo sì wó àwọn ará Seti palẹ̀.
"Salami ni ""ẹníkẹni to ba lé wá ojúutu si ẹkọ ìṣìrò lé wá ojúutu si ìsòrò tó bá ń ṣẹlẹ̀ láwujọ rẹ̀."
Bi awọn kan ṣe gbagbọ pe ko si ohun to buru ninu ki obi kọ ila sọmọ loju, ni awọn kan gbagbọ pe aye ti laju kọja ki a maa kọ ọmọ nila.
Ǹjẹ́ o mọ Olorì Moremi tó jà fún òmìnira àwọn ẹrú nílẹ̀ Ifẹ̀?
Babaláwo rèé pẹ̀lú afurasí adigunjalè mẹ́rin láhàmọ́ọ́ ọlọ́pàá Agolo gáásì kéeké tó ń jò bú gbàmù l‘Eko, ẹ̀mí kan bọ́, mẹ́ta fara pa Ìyá òòṣà fẹ̀sùn àjẹ́ kan ìyá ẹni ọdún 90, aráàlú bá sọ ọ́ lókò pa Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Olusegun Obasanjo: Ọmú ìyá mi ti mo fi ń mùkọ ni kekere ló jẹ ki ń lókun Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Wo ohun tó yẹ kóo mọ̀ nípa òfin tuntun tó de ọ̀rọ̀ kòbákùngbé Oríṣun àwòrán, Getty Images Laipẹ yii ni ijọba orilẹede Naijiria ti ni ẹnikẹni ti ọwọ ba tẹ pe oun sọrọ kubakugbe yoo san owo itanran miliọnu marun Naira.
Iroyin sọ pe iṣẹ agbẹ ni ọba naa n ṣe, ni ijọba ibilẹ Itesiwaju, ko to o gun ori itẹ lẹyin Ọba Majaro.
"Oríṣun àwòrán, Seyi Makinde ""A ri daju pe a fi ofin to de dida ilẹ kiri laibikita mulẹ nipinlẹ Ọyọ, ta si tun wa ọna abayọ si isoro ẹgbin laarin ọsẹ mẹrin pere si asiko yii."
PDP wa n kesi awujọ agbaye ati awọn ololufẹ ijọba tiwa n tiwa lati gba aarẹ Muhammadu Buahri ni imọran pẹlu ọga agba ọlọpaa, ọtẹlẹmuyẹ, olori ile isẹ ọmọ ogun atawọn ile isẹ agbofinro yoku, ti yoo kopa ninu eto idibo ni ipinlẹ Ekiti, lati ri pe wọn ka ojulowo ibo tawọn eeyan ba di ni ọjọ Satide.
Ààlà ilẹ̀ tí wọ́n pín fún àwọn ọmọ Josẹfu bẹ̀rẹ̀ láti odò Jọdani lẹ́bàá Jẹriko, ní apá ìlà oòrùn àwọn odò Jẹriko, ó lọ títí dé apá aṣálẹ̀.
Coronavirus update: Àwọn ẹgbẹ́ agbábọ́ọ̀lù ìlẹ̀ Gẹ̀ẹ́sì fẹnukò láti parí líìgì ọdún yìí
Gbogbo àwọn iranṣẹ rẹ̀ sì ń tò kọjá níwájú rẹ̀; àwọn ẹgbẹta (600) ọmọ ogun tí wọ́n tẹ̀lé e láti Gati náà tò kọjá níwájú rẹ̀.
Sowore ni olùdásílẹ̀ àti atẹ̀wéjáde SaharaReporters , ilé-iṣẹ́ oníròyìn aṣèwádìí orí-ayélujára.
Òfin yìí ni ó jẹmọ́ ti ọkunrin tí nǹkankan tabi nǹkan ọkunrin bá dà lára rẹ̀, tí ó sì ti ipa bẹ́ẹ̀ di aláìmọ́; 
Ni bayii, won ti fesun kan awon omo-ogun olote Islamic ti won farapamo si agbegbe Nangarhar, leyin ti awon omo-ogun alabo ni won ni owo kolofin, ninu isele ti o waye niluKabul ati awon bi miran.
 king bá ọkọ rẹ ̀ pàdé nkgbà tí wọ ́ n jọ wà ní ilé-ẹ ̀ kọ ́ yunifásítì ní boston .
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ọlọ́pàá Ondo: Dírẹ́bà ọkọ̀ nìkan ni wọ́n jígbé kìí se àwọn 18 28 Òkùdu 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ọlọpaa Ipinlẹ Ondo ti ni awọn ko mọ si pe awọn ajinigbe ti beere fun owo miliọnu marun un lati fi ẹni ti wọn jigbe silẹ.
Sẹ́nétọ̀ Dino Melaye kéde láti dupò gómìnà Kogi
"Òòtọ́ ní pé owó sọnu ní ilé ti wọ́n ń ko eranko si ní Kano, èyí to jẹ owó ti wọn pa ní ọ̀jọ́ márùn ti wọ́n fi ṣe ayẹyẹ ọdún ìtúnu ààwẹ.
Ọgbọn ọjọ oṣu kẹfa ọdun yii ni adehun ti Ramsey ṣe pẹlu Arsenal yoo pari, eleyi ti ko ni jẹ ki ikọ Arsenal gba owo kankan lori rẹ.
Nígbà tí Joabu kúrò lọ́dọ̀ Dafidi, ó ranṣẹ lọ pe Abineri, wọ́n sì dá a pada láti ibi kànga Sira, ṣugbọn Dafidi kò mọ nǹkankan nípa rẹ̀.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Samson Siasia: Ẹ rànmí ìrànwọ́ pẹ̀lú N100m láti ṣejọ́ jìbìtì tí FIFA fi kàn mi 8 Sẹ́rẹ́ 2020 Oríṣun àwòrán, Twitter/Samson Siasia Àkọlé àwòrán, Ẹ rànmí ìrànwọ́ pẹ̀lú N100m láti ṣejọ́ jìbìtì tí FIFA fi kàn mi Akọnimọọgba ẹgbẹ agbabọọlu Naijiria, Super Eagles, Samson Siasia ti bẹ bẹ iranwo to to ọgọrun un miliọnu naira lati fi ṣe ẹjọ lori ẹsun riba ti ajọ FIFA fi kan an.
Toyin Abraham: Egboogi fun onibisi ni oun yan laayo Oju to pawo ni Toyin Abraham ninu awọ̀n fiimu oloyinbo ati ni ede Yoruba, to si jẹ aayo ọpọ eeyan .
awon ebi ati awon eniyan  orile ede
se ajọyọ won, ni ibamu ati ilana ofin.
Bí olówó rẹ̀ bá fẹ́ aya fún un, tí aya náà sì bímọ fún un, lọkunrin ati lobinrin, olówó rẹ̀ ni ó ni aya ati àwọn ọmọ patapata, òun nìkan ni òfin dá sílẹ̀.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ohun ti ọjọ ọla ni fun awọn ọdọ ni orilẹede South Africa ko tii daju Lọwọ ti a n sọrọ yii, ida mẹẹdọgbọn ninu ọgọrun awọn ọdọ orilẹede South Africa ni airisẹ n ba finra.
Bakan naa lo kesi awọn agbofinro lati ri wi pe ifofinde naa fi ẹsẹ mulẹ lọkunkundun.
Bamigbetan ní èyí yóò fún àwọn òsísẹ́ ní ànfààní láti jáde lọ́gọ̀ọ̀rọ̀ láti pàdé Ààrẹ Buhari tí yóò se àgbékalẹ̀ àwọn isẹ́ tó làmìlàaka ní ìpínlẹ̀ náà.
Wọn a máa tan àwọn tí kò lágbára.
Lọjọ keje osu yi ni orilẹẹde Sierra Leone yoo dibo lati yan Aarẹ tuntun,awọn asoju ile igbimo asofin ati ibo ijọba ibile.
Lẹyin iku rẹ ni ọpọ iwadii n fihan pe obitibiti owo ni o ko lọ pamọ si oke okun.
Wọ́n ń fẹ́ ọmọ lọ́wọ́ wọn fún ara wọn ati fún àwọn ọmọ wọn; àwọn ẹ̀yà mímọ́ sì ti darapọ̀ mọ́ àwọn orílẹ̀-èdè tí ó yí wọn ká.
Minisita soro naa di mimo fun awon akoroyin leyin ipade apero igbimo ijoba torokan gbangban Federal Executive Council (FEC) ti won se pelu aare Muhammadu Buhari.
Wọ́n bá mú un gba ẹnu ọ̀nà tí àwọn ẹṣin máa ń gbà wọ ààfin, wọ́n sì pa á.
Naijiria silẹ fun ipade apero lori eto ọrọ aje fun ti aarin gbungbun ati Ariwa
Bakan naa ni ifẹsẹwọnjsẹ to lamilaaka akọkọ ti yoo waye ni papa iṣẹre naa lati igba ti wọn ti ṣatunṣe rẹ.
 tẹ ́ lẹ ̀ tẹ ́ lẹ ̀ ọ ̀ rọ ̀ kò rí bẹ ́ ẹ ̀ , kọ ́ lọ ́ mú dọ ́ mú Ìyá rẹ gbé ni .
Bi awọn kan ṣe n wi pe o yẹ ki awon mejeeji o ṣọra pẹlu ọrọ wọn gẹgẹ bíi opomulero ni ipinlẹ naa l'awọn kan n jiyan lori ọrọ mejeeji.
Kí ló ṣe Ibrahim Chatta tó fi dèrò ilé ìwòsàn?
Akeredolu ò ṣe ǹkan àrítọ́ka si ni Ondo- Komísọnà ọ̀rọ̀ to n lọ tẹ́lẹ̀rí Enìyàn mẹ́ta pàdá ọlọ́jọ́ wọ́n ní'lù Abuja Omíyalé àgbàrà ti ya ṣọ́ọ̀bù ní Niger Díẹ̀ ló kù kí bàlúù arìnrìnàjò sílẹ̀ mímọ́ Hajj gbaná Usman ní : O yẹ ki ìjọba pàsẹ fún àwọn tó n ṣòwò iná mọ̀nàmọ́nà láti fi kún owó ti wọn fi n ṣòwò lójùnà àti wọn le ṣe àtunṣe si àwọn ẹka ti kò jẹ́ ki iṣẹ́ wọ́n yọ"" ""Sùgbọ́n tí èyí bá lọ o túmọ si pé gbogbo àwọn to kù yóò bàjẹ́, kò sì ni sí ọ̀nà abáyọ fún àtunṣe, nitori náà a o maa wa nínú ìṣòrò nigbogbò ìgbà"" Láìpẹ́, ará ìlú rẹ ni ọlọ́pàá tí yóò máa ṣọ́ ìlú rẹ Àwọn ọmọ Naijiria kóju ija sí àwọn South Africa wọ́n ní ""Ó tó gẹ́"" Àtúnṣe òpópónà Lagos-Ibadan àwọn ọ̀ná míràn ti e lè gba Díẹ̀ ló kù kí bàlúù arìnrìnàjò sílẹ̀ mímọ́ Hajj gbaná Àwọn onímọ ní ìsòrò ìna ti a ni Naijiria kò sẹ̀yìn ọ̀nà bí awọn ilé ìṣẹ́ to wà nidi ọ̀rọ iǹá ṣe ń se ipòlowó wọ́n láti mú àwọn ènìyàn dókoowò ìná mọ̀námọ́nà àti pínpín rẹ̀."
O soro idaniloju yii pe, ọwọ ti te awon adigunjale kan , ti awon agbofinro si n sise takun-takun lati mu awon adigunjale tό kὺ, ki won si fi won jiya labe ofin.
Bawo ni igbesẹ gomina Ọyọ ati gomina Kano se jọ ara wọn?
 Bee si ni, ede faranse yoo seranwo pupo fun awon akeeko naa leyin wa ola.
" "" Ẹni "" ni ifẹ ̀ ń pè ni "" Ọni "" ."
Elija wolii kọ ìwé kan sí Jehoramu, ohun tí ó kọ sinu ìwé náà nìyí: “Gbọ́ bí OLUWA Ọlọrun Dafidi, baba rẹ, ti wí; ó ní, nítorí pé o kò tọ ọ̀nà tí Jehoṣafati baba rẹ tọ̀, tabi ti Asa, baba baba rẹ.
A gbọ pe o jẹ arẹwa obinrin, ti ori rẹ si maa n wu nipa ẹwa rẹ eyi to maa n da ọpọ ọkunrin lọrun Luwooo Gbagida mọ riri imọtoto pupọ, to si mu imọtoto aarin ilu lọkunkundun to si mu ki ọpọ araalu, ko si bi wọn se kanka to, maa sisẹ asekara fun imọtoto ayika lai yọ awọn ọkunrin silẹ Luwooo Gbagida lo n lo ọwọ agbara ati oju agan sawọn eeyan to ba lọ tikọ lati se ohunkohun to ba ni ki wọn se O maa n gun awọn ọlẹ ọkunrin bi ẹsin ni, ti wọn ba fi sẹ si ofin rẹ, ti kii si fi oju aanu wo ẹnikẹni to ba n se imẹlẹ Luwooo Gbagida kii se obinrin kan to jẹ ẹran rirọ rara, ti ko si mọ iyatọ laarin ẹru ati ọmọ ilu to ba n se ọlẹ, bakan naa ni yoo se se wọn Nitori pe Luwooo Gbagida ko fẹran lati maa fi ẹsẹ rin, ti ko si si bata ni aye igba naa, lo mu ko da okuta alaranbara sori awọn ilẹ to n rin kọja ati gbagede to ti maa n naju Ọọni Luwoo bi ọmọkunrin kan to pe orukọ rẹ ni Adekọla Telu, to si se iranwọ fun ọmọ naa lati tẹ ilu Iwo do, to si tun jẹ Oluwo akọkọ Nitori ọwọ lile to fi se akoso ilu lasiko to wa lori itẹ, ni awọn ijoye Ile Ifẹ se pinnu pe obinrin ko ni jẹ Ọọni mọ laelae.
6 174568 Orilẹede Portugal 5278 51.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Huawei: Àwọn ohun márun un ti o n ja ilẹ Amẹrika laya nipa ile iṣẹ China yi 21 Èbibi 2019 Oríṣun àwòrán, AFP Àkọlé àwòrán, Odu ni ileeṣẹ Huawei jẹ lagbaye kii ṣe aimọ foloko Loni ni ile iṣẹ to n pese ẹrọ ibanisọrọ alagbeka Huawei yoo ṣe afihan awọn ẹrọ alagbeka rẹ tuntun ti o si ti fiwe pe awọn akọroyin lati wa foju ba ayẹyẹ naa.
Oríṣun àwòrán, @realyomifabiyi Sibẹ, awọn akẹgbẹ wọn to ṣi n fi ọrọ ranṣẹ si wọn fi han pe ija ọhun ko tii tan nilẹ gẹgẹ bi wọn ṣi ṣe n lo oniruuru ọna lati pẹtu si aawọ yii.
Ohun naa sọ ninu fọnran fidio to jade loju opo Twitter pe oun ko fẹ da si ọrọ yii nitori pe abẹ aṣẹ awọn adari ẹgbẹ ijọ onigbagbọ ni oun wa.
 Adedayo Okedare: Ala to wa si imusẹ ni bi mo se darapọ mọ ileesẹ agbohunsafẹfẹ BBC, koda gan, o tete wa si imusẹ ju bi mo se seto rẹ lọ.
Ìkùukùu da omi òjò sílẹ̀,ojú ọ̀run sán ààrá;mànàmáná ń kọ yẹ̀rì káàkiri.
OLUWA ní, “Láti orí àwọn mẹ̀kúnnù títí dé orí àwọn eniyan pataki pataki,gbogbo wọn ni wọ́n fẹ́ràn èrè àjẹjù;láti orí àwọn wolii títí dé orí àwọn alufaa,èké ni gbogbo wọn.
Itan naa sọ fun wa pe, Timi Agbale jẹ ọrẹ timọ-timọ fun Gbọnka Ebiri, ti awọn mejeeji si jẹ jagunjagun laye igba ti Alaafin Sango n jọba.
Ẹwẹ, ajọ FCTA to n ṣakoso ijọba olu ilu Naijiria, Abuja ti kọkọ fofin de iwọde ki wọde kaakiri ilu Abuja.
Messi ge awọn agbabọọlu Athletico meji ati aṣọle wọn Oblak ki o to gba bọọlu wọ awọn lati jẹ goolu ikẹtalelọgbọn rẹ ni saa bọọlu ọdun yi.
OLUWA bá yín sọ̀rọ̀ nígbà tí nǹkan ń dára fun yín,ṣugbọn ẹ sọ pé ẹ kò ní gbọ́.
Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Kenya country profile31 Sẹ́rẹ́ 2018 Viewpoint: Is Kenya serious about tackling corruption?
Inú Ẹrú dùn púpọ̀ nigbati inú ọmọ Bàbá bàjẹ́.
Igberu ti ba ajosepo eto kata-kara laarin orile-ede Nigeria ati orile-ede China, lati gba ti orile-ede China ti se idasile ile-ise ti o n ri si eto oro-aje ti a mo si China Chamber of Commerce in Nigeria, CCCN si orile-ede Nigeria ni odun 2011.
Ṣugbọn ní alẹ́ ọjọ́ kan, àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ gbé e sinu apẹ̀rẹ̀, wọ́n sì sọ̀ ọ́ kalẹ̀ láti orí odi ìlú.
Fún nǹkan bí ọọdunrun (300) ọdún tí Israẹli fi ń gbé Heṣiboni ati Aroeri, ati àwọn ìletò tí ó wà ní agbègbè wọn, ati àwọn ìlú ńláńlá tí ó wà ní etí odò Anoni, kí ló dé tí o kò fi gba ilẹ̀ rẹ láàrin àkókò náà?
Agbẹnusọ fun ajọ WAEC, Demianus Ojijeogu lo fidi ọrọ yii mulẹ fun BBC.
Ayédèrú òògùn ààrùn onígbáméjì tó wà ní ta rèé Àjọ INEC ti bẹ̀rẹ̀ ìkéde èsì ìdìbò gómìnà ìpínlẹ̀ Rivers Ahmed Musa gbàmì ẹ̀yẹ agbábọ́ọ̀lù tó pegede ní ọdún 2018 Ẹ̀ wo bí àwọn ẹ̀ṣọ́ ojú etí òkun ṣe ń ṣiṣẹ́ l'Eko Aba isuna 2019.
Obìnrin Kwara tí wọ́n tà sóko ẹrú ní Lebanon figbe ta, ọwọ́ tẹ èèbó kọ̀ráà tó ṣiṣẹ́ náà Wọ́n ti mu aṣojú ọmọ Britikó ní orílẹ̀-èdè Iran Díẹ̀ lára àwọn ìṣẹ̀lẹ̀ tí yóò mi ìgboro tìtì l'ọ́dún 2020 rèé Amotekun kò ní gbé ìbọn o!
Oríṣun àwòrán, Facebook/KamalaHarris Ninu ọrọ rẹ arabinrin Harris sọ pe oun ko ni wahala kankan pẹlu ibi toun ti wa ati pe oun a ma juwe ara oun gẹgẹ bi ''ọmọ ilẹ Amẹrika.
idaraya boolu afesegba je idaraya ti o n mu ife ohun ibasepo ati ifowosopo jeyo
9 13649 Orilẹede Burkina Faso 69 0.
    Lóòótọ́, ni ọjọ́ọ́ kéjì, àwọn ọ̀rẹ́ wọ̀n-ọnnì kò wá, ẹnikẹ́ni kò sí ya àgbàdo.
Ẹni tí ó fẹ́ ọkàn mímọ́,tí ó sì ní ọ̀rọ̀ rere lẹ́nu yóo bá ọba ṣọ̀rẹ́.
Nibi eto ti wn ti pade ni ilu Eko ti ọrọ naa si jẹyọ ṣe gẹgẹ ero ọkan Gani Adams, o ni anfani nla lo jẹ fun ohun lati ba aarẹ sọrọ nipasẹ agbẹnusọ rẹ.
Lẹ́yìn ikú Abrahamu, Ọlọrun bukun Isaaki ọmọ rẹ̀.
Afurasí ikú ọ̀wọọ̀wọ́ l'Akinyele jápa mọ́ ọlọ́pàá lọ́wọ́ Ṣe ẹ ranti, Sunday Shodipe, afurasi ti ọwọ awọn ọlọpaa tẹ lori awọn iṣekupani to waye lagbegbe Akinyẹle ni ilu Ibadan?
ki o di mimo pe gbogbo awon igbese ti Olubadan n gbe, pe fun ikiyesara ki daru-
Ni bayii, awọn ololufẹ awọn oṣere wọnyi lo ti n sọ erongba tiwọn lori ẹrọ ayelujara.
Àmọ́ ṣá o, ṣé bí a bá gbìyànjú títí, tí a kò rí kókó tú, a ó fi kókó ọ̀hún sílẹ̀, a ó wàá okùn míì lọ?
 Bakan naa, iko yii tun seleri lati soju orile-ede Niaijiria daradara ninu irufe idije ohun tagbaye to n bo lona(2019 Women’s World Cup).
Nígbà tí Delila rí i pé ó ti tú gbogbo ọkàn rẹ̀ palẹ̀ fún òun, ó ranṣẹ pe àwọn ọba Filistini, ó ní, “Ẹ tún wá lẹ́ẹ̀kan sí i, nítorí pé ó ti sọ gbogbo inú rẹ̀ fún mi.
Ṣugbọn ẹnikẹ́ni kò dá wọn lóhùn.
Wọ́n tún lọ láti rú ẹbọ gẹ́gẹ́ bí ó ṣe wà ninu òfin Oluwa: pẹlu àdàbà meji, tabi ọmọ ẹyẹlé meji.
Ẹlòmíràn á tún dé, a ní ṣe irú rẹ̀ ní tiyín mọ́.
 bákan náà ni ó tún jẹ ́ ọmọ ẹgbẹ ́ olùkọ ́ orílẹ ̀ èdè nàìjíríà ( nigeria union of teachers ) fún àìmọye ọdún .
Kí ni ìbá dé tí a óo fi jí fadaka tabi wúrà ní ilé ọ̀gá rẹ?
Láti ǹkan bii ọgbọn ọdun ni Toma tí ń ba àìsàn to jẹ mọ ọpọlọ yí nítori pe bẹ́ẹ̀ ni wọn se bii.
Jọ̀wọ́ ro ọ̀rọ̀ náà dáradára, kí o sì pinnu ohun tí o bá fẹ́ ṣe; nítorí pé wọ́n ti gbèrò ibi sí oluwa wa ati ìdílé rẹ̀, ọlọ́kàn líle sì ni oluwa wa, ẹnikẹ́ni kò lè bá a sọ̀rọ̀.
Fausat Balogun àti Laide Bakare Nínú ọ̀ṣẹ̀ yìí ìṣẹ̀lẹ̀ mánigbàgbé ni bi Fausat Balogun ti gbogbo ènìyàn mọ si Madam Ṣajẹ náà sé tọwabọ iwé àdéhun pẹ̀lú ilé iṣẹ́ kan.
Roberto Mancini ti fenuko pelu ajo to n ri si boolu afesegba orile-ede Italy lati je akonimoogba agba iko agbaboolu orile-ede ohun.
Idi ni pe aya gomina ipinlẹ Kwara, Olufolake Abdulrazaq, to ti tẹwọgba ọrọ wọn lati ilẹ ko tii jawọ nibẹ, to si tun n se wsn loore siwaju lọ.
Awọn ajijagbara ọhun ti orukọ wọn n jẹ Orange Movement wa ni gbọngan Oramiyan ninu ile itura ọhun nibi ti iroyin ni wọn ti n gbero lati ta ko erongba Tinubu ninu idibo gomina to n bọ ni ipinlẹ Eko.
Bí ó bá ṣẹ̀ ọ́ ní ẹẹmeje ní ọjọ́ kan, tí ó yipada sí ọ lẹẹmeje, tí ó bẹ̀ ọ́ pé, ‘Jọ̀ọ́ má bínú,’ dáríjì í.
"Báyìí ni àgbàọ̀jẹ̀ agbábọ́ọ̀lù Diego Maradona ṣe wọ káà ilẹ̀ lọ lólú ìlú Argentina Bí mo bá leè rí ọmọ alágbe t'áyé fẹnu sí pé mo fi ẹlẹ́rìndòdò lá lójú, máa kúnlẹ bẹ ẹ - Motara ""Mi o le ṣalaye nkan to ṣẹlẹ lalẹ oni."
Mo mọ̀ pé, nígbà tí mo bá dé ọ̀dọ̀ yín, n óo wá pẹlu ẹ̀kúnrẹ́rẹ́ ibukun ti Kristi.
Ó ti ṣáájú yín lọ sí Galili; níbẹ̀ ni ẹ óo ti rí i.
Sex for marks: Ilé aṣọ̀fin àgbà ń gbèrò ẹ̀wọ̀n ọdún mẹ́rìnlá fún olùkọ̀ tó bá dẹnu ìfẹ́ kọ akẹ́kọ́
Yẹra fún àwọn ọ̀rọ̀ asán ati ọ̀rọ̀ ìsọkúsọ, nítorí àwọn tí wọ́n fẹ́ràn irú ọ̀rọ̀ wọnyi túbọ̀ ń jìnnà sí ẹ̀sìn Ọlọrun ni.
aleefa gege bi aare orile ede Sudan  lati
Òjò ò ṣẹ̀ṣẹ̀ máa rọ̀ báyìí.
Ènìyàn kò lè fi ẹnu sọ ìbànújẹ́ náà tí tó nígbà tí ó rí òkú olúfẹ́ rẹ̀.
"O ni, ""Inu ile mi ti mo n gbe ni mo wa, mo n wẹ lọwọ ni gbogbo inu ile bẹrẹ sini mi gbugbugbu."
Amọ Olusegun Ajiboye ni iroyin naa ko ri bẹẹ rara.
Oríṣun àwòrán, @NLCHQ_ABUJA Nibayii, Comrade Funmi -Sessi ni awọn ko i tii mọ ohun to kan gẹgẹ bi oṣiṣẹ, amọ awọn n duro de aṣẹ ẹgbẹ NLC, lori ohun to kan lẹyin ti wọn ti wọgile iyanṣẹlodi naa.
Ijinigbe Dapchi: Awọn olori ileesẹ aabo tẹdo si Dapchi
rẹ ojogbon Yemi Osinbajo fun saa keji fun odun merin miiran lorile ede
Ruga Settlement: Iléeṣẹ́ ààrẹ ní àgbékalẹ̀ àgọ́ Fulani lọ̀nà àbáyọ sí wàhálà àgbẹ̀ àti Fulani
Àwọn tí ó ṣẹ̀ láti ọ̀dọ̀ Kohati nìwọ̀nyí: Aminadabu ni baba Kora, Kora ló bí Asiri; 
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Akomolede ati Asa: Mọ̀ si nípa àwọn ọ̀nà tí Yorùbá ń gbà ran ara wọn lọ́wọ́ O ṣalaye pe iwọde ọhun n lọ ni ẹrọ pẹlẹ ṣaaju akoko yii ni ipinlẹ Ondo, ṣugbọn o dabi pe nnkan ti n yiwọ bayii.
Ma sọ pe ẹni ami ororo ni ọ, beere lọwọ Samsoni ninu Bibeli.
"Emi na ri ""doodle"" naa ni owuro oni, ni igba ti mo si oju-iwe google lori ayelujara itakun agbaye."
Nítorí pé, irú ẹni bẹ́ẹ̀ yóo dàbí igi tí ń so èso tí ó korò, tí ó sì ní májèlé ninu.
Wo àwọn oúnjẹ márùn ún tó ń mú kí àtọ̀ ọkùnrin dára síi Ojú mi ti rí lọ́pọ̀ lọpọ̀, ọ̀pọ̀ èèyàn ni kò tilẹ̀ gbàgbọ́ pé mo lè jọba- Ooni Ìwà ìbàjẹ̀ bíi olé jíjà, ìjínigbé àti rìbá gbígbà ní Okediji fi ṣàpèjúwe ǹkan tó ń ṣẹlẹ̀ ní Nàìjíríà Wọn n ṣafihan awọn ikọ naa ati ọna ti wọn n gba ṣe iṣẹ ibi ọwọ wọn.
O ni awọn orileede ti wọn ko jafara ti n gbe igbesẹ to yẹ nitori naa ki Naijiria di lilọ bibọ ọkọ ofurufu lati ilẹ Gẹẹsi si Naijiria ku.
lagos city hall tí a mọ ̀ sí gbọ ̀ gán ìlú Èkó di dídásílẹ ̀ ní ọdún 1900 .
Kachikwu ó ṣeun, wá lọ simi- Ààrẹ Muhammadu Buhari
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Olori Badra sọ̀rọ̀ nípa ayé rẹ̀, ó ní ẹ́ bá òun sọkún Akọ tó fẹ́ akọ ṣayẹyẹ ìgbéyàwó ọdún kẹrin, wọ́n ra ilé kejì Jàndùkú ṣọṣẹ́ lọ́jà Agbeni, àwọn àti agbófinró kọjú ìbọn síra wọn Díẹ̀ ló kú kí owó tán l‘ápò mi torí ìrànwọ́ Coronavirus - Pasuma Mo ṣèlérí láti rí sí ìrẹ́pọ̀ àti ìwòsàn Amẹ́ríkà - Joe Biden Ìjọba Oyo gbé ilé ẹ̀kọ́ gíga kan tìpa torí àrùn Coronavirus Igba akọkọ kọ niyii ti Primate Ayodele sọ asọtẹlẹ nipa awọn oloṣelu.
Ile igbimo asofin tun ti fenuko  lati maa jokoo fun ojo meta gbako lati fehonuhan lori eto aabo to n se seke-seke lorile ede yii.
Oriṣiriṣi ariyanjiyan lo ti n waye lori iru eniyan ti awọn to ṣe ikọlu naa jẹ.
"Igbesẹ pinpin iwe ẹtọ si ounjẹ naa, ta pe ni Voucher ti n waye lọwọ nilu Abuja ati Eko, ti ijọba si ti n pese owo fun awọn ijọba ipinlẹ lati seto ipese ounjẹ fun akẹkọọ nipinlẹ koowa wọn.
Ọmọ bíbí inú ìyá rẹ ni ọ́, tí kò bìkítà fún ọkọ ati àwọn ọmọ rẹ̀.
Amodi ní ìjọ́sí ń kọ́:- ọ̀nà wo ni n bá fi wà lóde ayé lónìí bí kò bá sí ẹ̀yín?
Rejected ballot (Awọn ibo ti wọn kọ) : Awọn ibo ti wọn
Nítorí náà, OLUWA Ọlọrun ní: “Ọ̀tá yóo yí ilẹ̀ náà po, wọn yóo wó ibi ààbò yín, wọn yóo sì kó ìṣúra tí ó wà ní àwọn ilé ìṣúra rẹ̀.
Ninu osu kewa odun ti o koja ni egbe ajafetomoniyan Afriforum so wi pe awon yoo funrara awon pe omo Aare ana naa lejo ti Ajo NPA ba ko lati se eleyi,eyi lo si sokunfa igbese ti Ajo NPA naa gbe bayi,Nibayi, Ogbeni Mfaku so wi pe awon ko mo ojo tabi akoko ti Ogbeni Duduzane  Jacob Zuma yoo fojuba ile-ejo.
Oríṣun àwòrán, @nassnigeria Awọn ohun to yẹ kẹ mọ nipa Ahmed Lawan: Ọdun 1959, eyiun ọgọta ọdun sẹyin ni Lawan de ile aye, to si gba oye imọ ijinlẹ akọkọ nile ẹkọ fasiti Maiduguri, ko to tun lọ gba oye kun oye nile ẹkọ fasiti Ahmadu Bello, to wa nilu Zaria.
Ko daju wi pe APC ri atẹjade PDP nitori atẹjade ti wọn ko mẹnu ba ohun ti wọn sọ nipa Aarẹ Buhari ati erongba rẹ lati fi ọmọ ogun ṣe bojuboju lati dunkoko mọ oludibo.
Kí ló ṣe ikú pa Adediwura Lateefat Bello lẹ́yìn ọ̀sẹ̀ méjì tí wọ́n ń wá a Ọ̀rọ̀ Aisha Buhari sí Ramaphosa wú ọ̀rọ̀ síta lẹ́nu àwọn ọmọ Nàìjíríà Ààrẹ Muhammadu Buhari buwọ́lu owó ìṣúná ọdún 2019 Bóò ṣe lè yẹra fún ikú nígbà òjò - Onímọ̀ Ehi Iden Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Megabite: Ilé-ìwé ni mo ti bẹ̀rẹ̀ orin kíkọ Lọdun 2019 yìí, UNICEF ṣe àfilọ́lẹ̀ ìwé pélébé ti wọ́n pe àkọlé rẹ̀ ni Passport to Your Right"" tí yóò wà ni èdè Hausa, Igbo àti Yorùbá pẹ̀lú ìléri pé ọmọ kọ̀ọ̀kan yóò ni ẹ̀tọ́ sii ni ọdún 2030."
Minisita so pe “A o dake ise duro lati yanju oro iyanselodi yii.
Baba awo fi kun un pe ohun ti wọn ba le fi pilẹ Magun bẹẹ, ni yoo maa wu ọkunrin bẹẹ lati jẹ tabi se.
Oríṣun àwòrán, Others Melee, ẹni to ke gbajare yii asiko to n sọrọ lori ipa ti ebu ẹyin to ba owo epo rọbi yoo ni lori ọrọ aje Naijiria, wa n fi ika hanu pe orilẹede yii ko ni ọrọ aje miran to ju epo rọbi lọ, eyi ti ko ta mọ bayii.
    Lẹ́yìn èyí, ìyàwó mi kọjú sí mi ó ni, ‘ṣe o gbọ́ bí ó ti sọ?
Pẹlu jijawe olubori yii, O tunmọ si pe ami mẹfa lo n dabu ẹgbẹ agbabọọẹu Liverpool bayii lojuna ati gba ife ẹyẹ Premiership ti saa yii.
Ninu ọrọ to ba BBC Igbo sọ, Ayalogu sọ pe ko si otitọ kankan ninu iroyin naa, ati pe ko ṣeeṣe fun tomato alagolo kankan lati wọ Naijiria lati ilẹ okeere nitori pe ofin ko faaye gba a.
Lára àwọn àtẹ̀bọ̀ ni kí o fi àwọn aṣọ títa náà kọ́, kí o sì gbé àpótí ẹ̀rí náà wọ inú ibi tí aṣọ títa náà wà, aṣọ títa yìí ni yóo ya ibi mímọ́ sọ́tọ̀ kúrò lára ibi mímọ́ jùlọ.
Bakan naa ni atejade ohun tun seleri ati satileyin ni kikun fun awon ile-ise ti o n samojuto eto idokowo, ati kikopa ni awon eto ipate orile-ede mejeeji.
Oríṣun àwòrán, others Yàtọ̀ sí Eko, wo ohun t'áwọn ìpínlẹ̀ meje míràn ń sọ nípa ìwọlé àwọn akẹ́kọ̀ọ́ Ni bayii ti awọn eeyan lorilẹ-ede Naijiria, paapaa julọ awọn obi, alagbatọ ati akẹkọọ n ko aya soke lori ibeere ati mọ igba wo gan an lawọn iloro ileewe yoo di ṣiṣi pada fun ẹkọ lorilẹ-ede Naijiria.
Ipo ate ATP ni kikun un:Rafael Nadal (ESP) 8770 pts (+1)Roger Federer (SUI) 8720 (-1)Alexander Zverev (GER) 5755Juan Martín Del Potro (ARG) 5080Marin Cilic (CRO) 5060 (+1)Grigor Dimitrov (BUL) 4780 (-1)Dominic Thiem (AUT) 3835Anderson (RSA) 3635David Goffin (BEL) 3110John Isner (USA) 3070Diego Schwartzman (ARG) 2435Pablo Carreno (ESP) 2145Sam Querrey (USA) 2130Roberto Bautista (ESP) 2120 (+2)Jack Sock (USA) 2110 (-1)Fabio Fognini (ITA) 2030 (-1)Novak Djokovic (SRB) 1965 (+5)Kyle Edmund (GBR) 1950 (-1)Nick Kyrgios (AUS) 1855 (+2)Lucas Pouille (FRA) 1835 (-2).
Ghana elections 2020 winner: Nana Akufo-Àddo àti John Dramani ló jọ ń díje lọ́là
Sugbọn, ni ọjọ Abamẹta, ọjọ kọkanleọgbọn oṣu kerin, asẹwo di olùpẹ́jọ́ ti wọn fi fa Darlington de agọ ọlọpaa to wa ni Utako, Abuja.
Ọlọpaa náà, Gbenga Oladipupo nii ṣe ẹni ọdún méjìlélọ́gbọ̀n, nígbà tó ṣe alabapade ikú òjìji náà.
Ṣowore fesi si ọrọ kan tawọn eeyan kan n gbe kiri lori ayelujara pe Ṣowore wa lara awọn to n ṣagbatẹru ifẹhonu han nitori pe o fidi rẹmi ninu idibo aarẹ to lọ.
”Aare  Buhari wa fi n da gbogbo omo orile ede
Nígbà náà ni Jesu jáde pẹlu adé ẹ̀gún ati ẹ̀wù àlàárì.
Oluwa sọ fún un pé, “Lọ sọ́dọ̀ rẹ̀, nítorí mo ti yàn án láti mú orúkọ mi lọ siwaju àwọn orílẹ̀-èdè yòókù ati àwọn ọba wọn ati àwọn ọmọ Israẹli.
Gbogbo àwọn ará Ai tí wọ́n pa ní ọjọ́ náà, ati ọkunrin, ati obinrin, gbogbo wọn jẹ́ ẹgbaafa (12,000).
Ọrọ owó yii n kọ awọn orilẹ-ede bi i China ati South Korea lomiinu, debi i pe wọn ti fofin de idasilẹ owó tuntun lórí ayelujara.
” Ati pé, “Owó oṣù òṣìṣẹ́ tọ́ sí i.
00 bn Ajọ to n risi ẹto ilera alabode - N35.
Gomina Kano tí ní kí olùrànlọ́wọ́ rẹ̀ lọ rọ́kún nílé nítori o bu Ààrẹ Buhari lórí #EndSars Gomina ipinlẹ Kano, Abdullahi Ganduje ti fi ọwọ osi juwe ile fun oluranlọwọ rẹ lori ọrọ iroyin, Salihu Yakassai lẹyin to bu aarẹ Buhari.
Ohun taa gbọ ni pe igbaradi ti awọn ọlọpaa SWAT gan le ju toripe ati ti imọ ẹkọ ati ti iṣẹ ni wọn n ṣe papọ.
Ni eyi to fi jẹ ki Boseman fi iyawo ati ẹbi silẹ lọ.
Kí ló dé tí ẹ fi dójú lé mi,tí mo di ẹrù lọ́rùn yín?
Ìdààmú bá àwọn orílẹ̀-èdè tí ó bá ti fojú kàn wọ́n,gbogbo ọkàn á rẹ̀wẹ̀sì.
Ẹni tí ó jí ní kutukutu òwúrọ̀,tí ó ń fi ariwo kí aládùúgbò rẹ̀,kò yàtọ̀ sí ẹni tí ń ṣépè.
"A ń fikunlukun pẹ̀lú FBI láti mú àwọn ""Yahoo Boys"" tó kù- EFCC Amẹ́rika dá akẹ́kọ̀ọ́ padá nítori Facebook A kó dúnkoòkò mọ́ Ambode, isẹ́ wa là ń ṣe - Ilé Aṣòfin Eko Ki ni o wa ṣe awa ọmọ Yoruba gangan ti a ko kọ ọmọ wa sii nipa ede ati aṣa Yoruba?"
Ṣebí òun ni ẹ̀gbọ́n mi, ẹ̀yìn rẹ̀ sì ni Abiatari alufaa ati Joabu ọmọ Seruaya wà.
Ẹ̀yin náà yóo sì jẹ́rìí mi nítorí ẹ ti wà pẹlu mi láti ìbẹ̀rẹ̀ iṣẹ́ mi.
"Ó bí alakọbi oju rẹ ri buluu, o bi ẹlẹkeji oju ri buluu, ṣe iru oju yii ni iwọ o maa bi lọ ni?
Ileeṣe BBC wadii lẹnu awọn to n ṣiṣẹ lori ọrọ naa, wọn si sọ pe, ileeṣẹ ọlọpaa ti gbe Peters si atimọle bayii.
Amọ ṣa, igba to pe ọmọ ọdun mẹrinla, lẹyin ti iya rẹ ti ku, lo to o mọ aisan ti awọn oogun naa wa fun.
O ka ẹkọ nipa imọ ẹda ni fasiti Jos.
Ṣugbọn Iṣimaeli, ọmọ Netanaya, pẹlu àwọn mẹjọ sá àsálà lọ sí ilẹ̀ àwọn ará Amoni.
Ọ̀rọ̀ tí o sọ tán nisinsinyii, ara rẹ gan-an ni o fi dá lẹ́bi, nítorí pé, o kò jẹ́ kí ọmọ rẹ pada wá sílé láti ibi tí ó sá lọ?
Òun ni ó ń gbéni ga,òun náà ni ó sì ń rẹ eniyan sílẹ̀.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Dino Melaye: Ilé iṣẹ́ ọlọ́pàá yóò ṣèwádìí fídíò tí Dino ti ń náwó fún olórin kan 16 Agẹmo 2019 Oríṣun àwòrán, Instagram/dinomelaye Àkọlé àwòrán, A ó gbé'gbésẹ̀ lẹ́yìn ìwádìí fídíò tí Dino ti ń náwó fún Ayefẹlẹ- Ọlọ́pàá Ile iṣẹ ọlọpaa sọ pe awọn yoo ṣe iwadii fọnran kan to ṣafihan bi Sẹnẹtọ Dino Melaye ti n fi owo mọ olorin gbajugbaja kan lori loju agbo.
Ọkunrin tí wọn ṣe iṣẹ́ abàmì ìmúláradá yìí lára rẹ̀ ju ẹni ogoji ọdún lọ.
Ọmọ-Eniyan ń lọ gẹ́gẹ́ bí àkọsílẹ̀ nípa rẹ̀.
Àwọn ọlọ́gbọ́n dá wọn lóhùn pé, ‘Rárá o!
 Adari ile igbimo asofin ti koko pe fun ipade pajawiri lati jiroro lori bi
Ilé ẹjọ́ pàṣẹ kí EFCC gbẹ̀sẹ̀ lé àpò àsùwọ̀n kan tó ní nkan ṣe pẹ̀lú Akinwumi Ambode
Pẹlu bi wọn ti bori ninu ifẹsẹwọnsẹ mẹrin ninu mejila ti wọn ti gba a, o ti pe ọdun marunlelogoji bayii ti ibẹrẹ saa bọọlu tuntun ti buru jai fun Arsenal bayii.
Mose bá mu ọ̀pá rẹ̀ ó fi lu àpáta náà nígbà meji, omi sì bẹ̀rẹ̀ sí tú jáde lọpọlọpọ; àwọn eniyan náà ati àwọn ẹran ọ̀sìn wọn sì rí omi mu.
Ile-isẹ̀ iroyin Premium Times lo fi ọ̀rọ̀ naa lẹ́de pe, Adebayo Shittu kùnà lati lọ fun ìsìnrú ilu ọlọ́dún kan to pọn dandan fun gbogbo awọn ti wọn ba pari ni ile ẹ̀kọ́ gíga, yala ni orilẹede Naijiria tabi loke òkun, lẹ́yìn to kẹ́kọ̀ọ́ gboye gẹ́gẹ́ bi agbẹjọ́rò ni Fásítì Ife ti a mọ̀ si Fasiti Obafemi Awolọwọ.
Pupọ ninu awọn ti ile wọn ti wo ni wọn ti ko lọ sile ijọsin lawọn ṣọọṣi wọn ati awọn ile iwe kọọkan.
Bakan naa ni awọn miran ni bi o ti ṣe yẹ ko ri naa lo rii yẹn, nitori nigba ti ebi n pa igun aarẹ Buhari, awodi Mamman Daura ba ra.
Ile-ise aare so oro yii lataari orisirisi ikunsinu, oye ati oju ti awon eniyan ati awon egbe oselu atatako fi n wo igbese tuntun naa.
 Àwọn eléré àpíìrì máa ń ronú láti lè mú kí wọn mú oríṣìíríṣìí ìrírí wọn lò nínú orin wọn .
fowosowopo pelu ijoba to sese de ori ipo, ki Ipinle Oyo ba lee goke agba.
Onkorin omo orile-ede Naijiria, Korede Bello ti o wa labe isakoso Mavin Records, nibayii orin re tuntun ti o sese ko jade ‘Melanin Popping’ ti gba ipo akoko ninu ipo ate orin Boomplay, leyin ose melo kan ti o sese korin ohun jade.
 kòsí ìtọjú kan pàtó , pẹ ̀ lú ìsinmi àti àwọn oogùn fún ìṣu tàbí ṣíṣunú ni a fọwọsí bí o ti yẹ lóòrekoorè .
Kevin De Bruyne (Manchester City), 9.
Ṣugbọn ẹ̀wù tabi aṣọ, tabi ohun èlò awọ, tí àrùn yìí bá lọ kúrò lára rẹ̀ lẹ́yìn tí wọ́n ti fọ̀ ọ́, kí olúwarẹ̀ tún un fọ̀ lẹẹkeji, yóo sì di mímọ́.
O ṣalaye pe niwọn igba ti iwadii awọn ba ti jẹ ootọ pe eeyan kan nilo iranwọ, awọn maa n tete ṣe e fun wọn.
Báyìí ni ẹ fi àṣà ìbílẹ̀ yín yí ọ̀rọ̀ Ọlọrun po.
 wọ ́ n máa ń pe aberdeen ní  granite city ' ."
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Akọ́mọlédè àti Àṣà lórí BBC Yorùbá: Kọ̀ síi nípa iṣẹ́ tí oúnjẹ ń ṣe lára níbí Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí India Wedding: Ìyàwó kan ní India wọ sòkòtò fún ayẹyẹ ìgbéyàwó rẹ̀- Wo ìdí tó fi ṣe bẹ́ẹ̀25 Bélú 2020 Senator Ishaku Abbo: ìdí rèé tí mò fi fi kọ̀wé fi PDP sílẹ̀ darapọ̀ mọ́ ẹgbẹ́ òṣèlú APC25 Bélú 2020 Maina N2bn Fraud: Agbẹjọ́rò Maina yọ ọwọ́ nínú ìgbẹ́jọ́, Ó lóun kò ṣé mọ̀25 Bélú 2020 Free Pad: Scotland ti di orílẹ̀-èdè àkọ́kọ́ tó bẹ́rẹ̀ pínpín páàdì ǹkan osu fún gbogbo obìnrin lọ́fẹ̀ẹ́25 Bélú 2020 Fídíò, International Day for Elimination of Violence against Women: Àlùfáà Joel Olugbenga: Bíbélì kò ní kéèyàn dúró títí ọkọ rẹ̀ yóò fi lù ú pa25 Bélú 2020 Elon Musk, Ọ̀gá àgbà iléeṣẹ́ SpaceX, Tesla CEO ń bá Bill Gates du ipò ẹni tó lówó jùlọ ṣèkejì lágbayé26 Bélú 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
 Ati pe Ijoba orilẹ-ede South Africa ni lati san
Ẹ jẹ́ kí á yẹ ara wa wò,kí á tún ọ̀nà wa ṣe,kí á sì yipada sí ọ̀dọ̀ OLUWA.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ikorodu Festival: Àwọn olórò ní ọdún Màgbó ló ń gbá ibi lọ, kó ire wọlé ní Ikorodu Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Ikorodu Festival: Àwọn olórò ní ọdún Màgbó ló ń gbá ibi lọ, kó ire wọlé ní Ikorodu 9 Ògún 2019 Awọn ọdun kan wa to so tọkunrin-tobinrin papọ nilẹ Yoruba, amọ omiran wa ti obinrin ko gbọdọ foju ri.
Lati igba ti wọn ti da a silẹ si ni ISWAP ti n ṣe ikọlu si awọn ọmọ ogun Naijiria.
Ninu idije ọdun 1999 ni Super Falcons ti rin jina julọ nigba ti wọn de ipele komẹsẹoyọ ẹlẹni mẹjọ.
 Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Orangun ṣàlàyé ìdádúró Oluwo ní ìgbìmọ̀ lọ́balọ́ba Mo ti gbe lọ sile ẹjọ, mo si fẹ ko san owo ti mo n beere lọwọ rẹ, tii se miliọnu lọna ọgọrun naira, lẹyin naa, ohun to ba wu ileẹjọ ko se fun.
Mo n lọ si China, mo fẹ lọ pa Coronavirus run.
Koda, o ni wọn fi tipátipá mu oun san owo ti oun ko gba si apo àsùnwọ̀n ajọ naa.
Ààrẹ Buhari yan Ibrahim Gambari gẹ́gẹ́ bíi olórí àwọn òṣìṣẹ́ lọ́fíìsì Ààrẹ Oríṣun àwòrán, Other Ìròyìn tó ń tẹ̀ wa lọ́wọ́lọ́wọ́ ní wí pé Aarẹ Muhammadu Buhari ti yan Ọjọgbọn Agboọla Ibrahim Gambari gẹgẹbii olori tuntun fawọn oṣiṣẹ lọfiisi aarẹ.
Ninu ariwo ogun ati ti fèrè ni Moabu yóo parun sí, 
Ekiti Election: Ǹkan méwàá tó yẹ kí o mọ̀ nípa Oluṣọla Eleka
Alaga Igbimọ tẹẹkoto fun ọrọ iṣẹ pataki kan laarin ilu ati Ibaṣepọ Ẹka Ijọba ninu Ile Igbimọ Aṣofin Ipinlẹ Eko, ti wọn ṣagbateru ipade itagbangba naa, Aṣofin Hakeem Shokunle ninu ọrọ rẹ fi mulẹ pe igbesẹ yii yoo le jẹ ki ijoba Ipinlẹ Eko ṣe kori-o-ya fun ṣiṣe iṣẹ aṣeyọri ni ipinlẹ yii.
Ọmọ tuntun a ma ya ìgbẹ́ àti ìtọ̀ tó igbà mẹwa tàbi jù bẹ́ ẹ̀ lọ ni ojúmọ́.
 dipo esun ti awon igbimo fi n kan oun, o  yẹ ki won toro aforijin lowo ile Ibadan ati
Yóo rọ̀jò ẹ̀yinná ati imí ọjọ́ gbígbóná sórí àwọn eniyan burúkú;ìjì gbígbóná ni yóo sì jẹ́ ìpín wọn.
Nítorí ẹnìkan náà tí ó wí pé, “Ìwọ kò gbọdọ̀ ṣe àgbèrè,” òun náà ni ó wí pé, “Ìwọ kò gbọdọ̀ paniyan.
Iru eto ẹkọ ti awọn ọmọ yii n gba ni ile iwe naa ṣe pataki.
Darasimi ṣe agunbanirọ ni ipinlẹ Kebbi.
Ọkan lara awọn ọmọ orilẹede China naa to le sọ ede Oyinbo ṣalaye pe nitoun, oun ko mọ pe wọn n ji kusa wa ni nitori pe ireti oun ni pe wọn ni iwe aṣẹ iwakusa latọdọ ijọba.
Mo ní, “OLUWA, ṣàánú mi kí o sì wò mí sàn;mo ti ṣẹ̀ ọ́.
O forin kiko ja ijajangbara ominira ninu oselu ati ife nigba ti Eritrea n ja fun ominira.
Iyawo aare ile Amerika teleri Barbara Bush, ti o si tun je obinrin kan soso ti gigun alefa ipo aare orile-ede Amerika, oko re ati omo re soju re, jade laye lojo Isegun(Tuesday).
14 Lõtọ́, ni mo wí fún ọ, pé èmi kì yíò fi ààyè gbà pé kí Sátánì ṣe àṣeyọrí ète ibi rẹ̀ nínú ohun yìí.
“Ẹ̀yin eniyan mi, ṣé àkókò nìyí láti máa gbé inú ilé tiyín tí ẹ ṣe lọ́ṣọ̀ọ́, nígbà tí Tẹmpili wà ní àlàpà?
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ọmọ ọdún mẹrin yìnbon pá ọmọ ọdún méjì ní California 21 Agẹmo 2018 Oríṣun àwòrán, Yegor Aleyev Báwo ló ṣe yín?
Ṣé ọpọlọpọ ẹ̀jẹ́ ati ẹran tí a fi rúbọ lè mú kí ibi rékọjá rẹ̀?
Ìgbà tí wọ́n sì ṣí àpótí yìí wọ́n kó ẹ̀wù púpọ̀ jádè ẹ̀wù iṣẹ́ ni, wọ́n sì pin in fún gbogbo wa.
Akọsilẹ miran tun niyi - bi ìdá ọgọta ni awọn to n gbe ninu òṣì tó pọ̀ - ohun ti wọn fi ṣe odiwọn rẹ ni iye awọn to jẹ pe ile gbigbe, ounjẹ ati aṣọ nikan ni agbara wọn ka.
Àwọn ọmọ ogun tí ó fi owó bẹ̀ lọ́wẹ̀,dàbí akọ mààlúù àbọ́pa láàrin rẹ̀;àwọn náà pẹ̀yìndà, wọ́n ti jọ sálọ,wọn kò lè dúró;nítorí ọjọ́ ìdààmú wọn ti dé bá wọn,ọjọ́ ìjìyà wọn ti pé.
Kete ti wọn ba ti ṣe igbejọ yii tan ni wọn maa ṣe idajọ to yẹ fun wọn.
5% ninu owo oṣu awọn oṣiṣẹ naa fun eto adojutofo ilera NHIS, ṣi n ṣe ajoji si wọn.
Oríṣun àwòrán, @FRSC Àkọlé àwòrán, Suuru ati ikanju ọgbaagba ni loju popo Abayọmi ni o tọna ki wọn maa ṣe akọsilẹ ohun gbogbo ti wọn ba ri nibi ijamba ọkọ loju popo ki wọn si maa koo fun awọn ẹbi awọn ti ọrọ kan lasiko.
Bí mo ti wà pẹlu Mose ni n óo wà pẹlu rẹ.
O óo bèèrè lọ́kàn ara rẹ nígbà náà pé,‘Ta ni ó bí àwọn ọmọ wọnyi fún mi?
NCC Sim Registeration: Bi o ṣe lè mọ̀ tí káádì inú ẹ̀rọ ìléwọ rẹ kò bá sí nínú àkọsílẹ̀
Omi adidun to maa n jade latara agbalumọ wulo fun bii eyin didun, inu kikun, ọna ọfun ati erigi didun ati bẹẹ lọ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Kidney Transplant: Ilé ìwòsàn ṣ'àṣìṣe ṣiṣẹ́ abẹ kìndìrín fún aláìṣàn ní New Jersey 28 Bélú 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Kidney Transplant: Ilé ìwòsàn ṣ'àṣìṣe ṣiṣẹ́ abẹ kìndìrín fún aláìṣàn ní New Jersey Eleyi maa gbẹnutan!
Àlàyé rèé lórí bí wọ́n ṣe mú mi lẹ́rú ní 1837 - Ajayi Crowther Jesu Oyingbo rèé, pásítọ̀ tó láṣẹ ìbálòpọ̀ lóri ọmọ ìjọ obìnrin Ayinla Ọmọwura, orin èébú àti oríyìn lo fi di ọ̀rẹ́ àwọ̀n obìnrin Irú èpè wo ni Aláàfin Aolẹ ṣẹ́ fún ìran Yorùbá?
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Igbejọ Ipob: Ileẹjọ yoo gbọ ẹjọ Nnamdi Kanu lọtọ 20 Èrèlè 2018 Oríṣun àwòrán, AFP Àkọlé àwòrán, O ti to osu mẹfa ti wọn ti gburo Nnamdi Kanu sẹhin Nnamdi Kanu ni wọn ko tii gburo rẹ lati igba tawọn ọmọ ogun orilẹede Naijiria yabo ile rẹ nibi osu mẹfa sẹhin.
Nkan marun-un lo mu ki Biden, ọmọ alagbata ọkọ, lati Delaware, papa jawe olubori si ipo aarẹ 1.
 Iya Halimat ni gbogbo igba ti mo ba ri awọn ọmọ wẹwẹ ti wọn ba n ṣere ni adugbo ni mo maa n ronu nipa ọmọ mi to sọnu, koda, mi o gbọ ohun taye n sọ mọ nitori ironu ọmọ naa.
oro re mule ti o si tun pase fun awon osise eleto aabo lorile-ede Naijiria lati
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Àṣírí tú!
Ṣugbọn ọba Jehoiakimu rán Elinatani, ọmọ Akibori, ati àwọn ọkunrin kan lọ sí Ijipti, 
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Child Labour: Fífi ọmọ ṣòwò wọ́pọ̀ ní Naijiria Imọran ti Hannah Allyse Kim ati awọn mi mu wa ni pe ,ma se ju ara rẹ lọ.
Titit di oni ni awọn eniyan ṣi n ri gẹgẹ bi oṣere to datọ julọ lati se bii oṣere 007.
Báwo ni ó wá yẹ kí á bọ̀wọ̀ fún Baba wa nípa ti ẹ̀mí tó, kí á sì ní ìyè?
Èyí ti dá wàhálà ìsásàálà sílẹ̀, a ti rí àwọn ará Burundi tí wọ́n sá lọ sí Tanzania, Rwanda, Congo àti Uganda.
Ọlọrun ti kó ìrẹ̀wẹ̀sì bá ọkàn mi,Olodumare ti dẹ́rùbà mí.
Ibi igbafẹ ti Assinie , Parc National de Tai, Ori Oke Artsy jẹ ọkan lara awọn ibi igbafẹ.
Ìbalòpọ̀ jẹ́ ohun tó ti pẹ́ tí ọ̀pọ̀ sì máa ń se lágbàyé.
Ṣùgbọ́n ẹ máṣe rò pé èmi ni ẹ̀ ń ṣe ìwọ̀nyí fún, mo fẹ́ kí ẹ mọ̀ pé ẹ ń ṣe é fún ìran ìran ọmọ wa.
Adebanji Akintoye fí ẹ̀yin Bola Tinubu janlẹ̀ láti jẹ́ Aṣíwáju gbogbo ilẹ̀ Yorùbá
Kí alufaa yẹ àrùn náà wò, kí ó sì ti aṣọ tí àrùn náà ràn mọ́ mọ́lé fún ọjọ́ meje.
Idi ti Ethiopia ṣaa fi fẹ adagun odo yii?
Iko D’Tigress wa ni ipo mẹ́tàdínlógójì  lagbaye, ti won si di ipo karun un mu nile Afrika.
Chukwuka Abiola ní ọ̀pọ̀ àwọn tó fí ọ̀nà àlùmọ́kọ́rọ́yin wọ eré tíátà ló lọ ma ń ṣe àfíkun sí ara.
tí ó ń yọ jáde bí ọkọ iyawo tí ń jáde láti inú yàrá rẹ̀,ati bí akọni tí ara ń wá láti fi tayọ̀tayọ̀ sáré ìje.
Ni aṣọ iyi ba bọ patapata lara Man City, nitori igba kẹta niyii ti Man U na wọn ni saa yii.
Àwọn ọmọ Lefi bá gbé àpótí OLUWA náà, ati àpótí tí àwọn ohun tí wọ́n fi wúrà ṣe wà, wọ́n gbé wọn ka orí àpáta ńlá náà.
"Jazz àtàwọn orin àtijọ́ tẹ́ ò mọ̀ pé ẹ ṣì lè rí gbọ́ Iléeṣẹ́ BBC fi ètò ""Aim High"" lọ́lẹ̀ fún àwọn àkàndá ẹ̀dá Fasiti Eko ti ""Cold Room"" ni Staff Club wọn pa látàri ìwádìí BBC lórí àwọn olùkọ́ kan Ìṣesí Kunle Ọlasọpe ni mo ṣe yan iṣẹ́ akọ̀ròyìn láàyò - Lekan Alabi Àkọlé àwòrán, Lilo èedu láti kun patako ikowe 'Ìṣòro àìrílégbé ló burú jùlọ nínú ìṣòro ẹ̀dá láyé' Kí ló dé táwọn ọ̀dọ́ dìbò 140m fún BBNaija àmọ́ tí ìbò ààrẹ Nàíjíríà jẹ́ 28m?"
O ṣe apejuwe pe ọlọpaa lo maa n gbe ibọn, ikọ Amọtẹkun ko ni lo ibọn tabi nkan ijagun.
Àwọb ìtàn ìbílẹ ̀ kam di múlẹ ̀ wípé odùduqà jẹ ́ ọkan lára àwọn orisa tí elédùmarè dẹẹ ́ ràn jùlọ nígbà ìwáṣẹ ̀ .
Abrahamu fún un ní ìdámẹ́wàá gbogbo ìkógun.
Fun apẹẹrẹ, obinrin to fẹ ọkunrin ibatan rẹ, o ṣeeṣe ki awọn ọmọ to ba bi ni iru arun to wa lara awọn obi ọkunrin naa.
Lọ́nà kejì, mo ri pé ìfẹ́ kìí ṣe ọ̀ràn ẹnikan, ọ̀ràn ẹniméjì ni.
 “ Mo maa n ri o ni gbogbo awon ipinle orile ede yii.
Matitaya dúró ní ẹ̀gbẹ́ rẹ̀, Ṣema, Anaaya, Uraya, Hilikaya ati Maaseaya dúró ní ẹ̀gbẹ́ ọ̀tún rẹ̀, Pedaaya, Miṣaeli, Malikija, ati Haṣumu, Haṣibadana, Sakaraya ati Meṣulamu sì dúró ní ẹ̀gbẹ́ òsì rẹ̀.
"Mo fẹ lọ si ile iṣẹ ajọ eleto idibo bayii fun ibanikẹdun ati lati sọ fun wọ́n pé, ki wọn tete wa ojutu si gbogbo nkan to jona lasiko iṣẹlẹ naa.
Mo kà á sí pé ó di dandan pé kí n rán Epafiroditu pada si yín.
Jeroboamu wí fún aya rẹ̀ pé, “Dìde, kí o yíra pada, kí ẹnikẹ́ni má lè dá ọ mọ̀ pé aya ọba ni ọ́.
Bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé ìwọ kọ́ ni o ṣe iṣẹ́-ibi tí ó kó àbààwọ́n ba gbogbo ọjọ́ 28 oṣù Belu jẹ́, ìwọ ni ó yẹ kí o wá ojútùú sí ẹ̀tọ́ àwọn olùfarapa sí òtítọ́ àti òdodo… Àwọn orílẹ̀-èdè olókìkí àti àwọn èèyàn ńlá kì í gbìyànjú láti pa ìṣẹ̀lẹ̀ aburú inú ìtàn-an wọn rẹ́, dípò èyí wọ́n máa ń fi han ayé kí gbogbo ènìyàn lè rántí kí wọ́n sì sọ pé “KÒ TÚN GBỌDỌ̀ ṢẸLẸ̀ MỌ́’.
Ni saa kini, Liverpool ta ayo gidigidi, ṣugbọn laifọta pe, Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Nígbà tí ó bá wà ní ìdùbúlẹ̀ àìsàn,OLUWA yóo fún un lókun;ní àkókò àìlera OLUWA yóo wo gbogbo àrùn rẹ̀ sàn.
EFCC tẹsiwaju ninu alaye rẹ pe, idaji ọjọ Abamẹta to kọja ni ọwọ wọn tẹ ọkan lara awọn ọmọ naa, Ogbonna Orji ati ọrẹ rẹ kan, lasiko ti wọn lọ fun igbadun opin ọsẹ nile igbafẹ kan l'Abuja.
Nígbàtí Ọba gbọ́ báyìí, ó pàṣẹ pé kí wọ́n tú ìgbín ṣílẹ̀.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Nigerian Fraudsters: Ìwádìí BBC fihàn pé ìdajì àwọn gbájúẹ̀ lágbàyéé wá láti Nàíjíríà Komolafẹ wa rọ awọn araalu lati mase foya nitori ikọ rẹ atawọn agbofinro n sisẹ papọ lati pese aabo to peye lasiko ọdun, ti wọn yoo si tun doola ẹmi ẹni ti wọn jigbe naa.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ladoja Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Ọmọ orilẹede Naijiria kan, Kayode Ogundamisi lo fi fọnran fidio naa si oju opo Twitter rẹ .
” Gbogbo àwọn ọmọ Israẹli bá sọ wọ́n ní òkúta pa, wọ́n sì dáná sun wọ́n.
Nígbà tí àwọn eniyan sùn, ọ̀tá rẹ̀ wá, ó gbin èpò sáàrin ọkà, ó bá lọ.
Lafup: Kò sí ẹni kankan tó ń ṣe ẹ̀fẹ̀ ní Ibadan nígbà táwa bẹ̀rẹ̀
Bí mo bá sì jẹ́ oluwa yín, ṣé ẹ bẹ̀rù mi ni èmi OLUWA àwọn ọmọ ogun ń bi ẹ̀yin alufaa tí ẹ̀ ń tàbùkù orúkọ mi?
Nítorí ẹnikẹ́ni tí ó bá ṣe ìfẹ́ Baba mi tí ń bẹ ní ọ̀run, òun ni arakunrin mi ati arabinrin mi ati ìyá mi.
Ajo to n mojuto sise owo ilu kumo-kumo fi  esun kan won pe, won ji owo to le ni bilionu mẹ́tàlá, ati pe won tun da orile ede Naijiria.
Kíni itunmọ ọrọ 'body bag' tí Gómìnà El-Rufai sọ?
Ọpọ lo tilẹ n wi pe o ṣeeṣe ki o jẹ pe aisan rẹ fẹ le diẹ lo jẹ ki baba Abimbọla o lọ fidimọle sibi kan.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ọdun mẹta lẹyin iku Arisekọla: Kin lo ranti nipa rẹ 22 Èrèlè 2018 Oríṣun àwòrán, Tribune Àkọlé àwòrán, Awọn to mọ Arisekola Alao ni o nifẹ ilu Ibadan lọkan pupọ 'Ida mẹta ni Ibadan pin si.
O sọ siwaju sii pe ọpọlọpọ ẹmi lo nu lọdun to kọja ti ijọba ko si se ohunkohun to to lati da abo bo awọn ilu to ri ikọlu nitori ohun to buru ni pe awọn to nse ikọlu yii kan nlọ lọwọ ofo ni."
 Ó yẹ kí á mò pé nítorí ìdàgbàsókè ni ẹ ̀ dá fi ń gbé papọ ̀ .
Oríṣun àwòrán, Getty Images Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
ọmọ Serugi, ọmọ Reu, ọmọ Pelegi, ọmọ Eberi, ọmọ Sela, 
8 23706 Orilẹede Jamaica 270 9.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Sudan Protest: Ìkọlùkọgbà bẹ́ sílẹ̀ láàrín àwọn ológún 8 Ìgbé 2019 Oríṣun àwòrán, AFP Àkọlé àwòrán, Orilẹede Sudan Awọn ọmọ ogun lọ da aabo bo awọn ẹgbẹ kan to n fẹhonu han ni Khartoum eyi to ja si iṣẹlẹ aburu laarin awọn ọmọ ogun atawọn afẹhonu han.
Tani ikú ò bá faragbá tí kò mú lọ?
Jẹ́ kí àwọn olórí wa dúró fún gbogbo àwùjọ yìí, kí wọ́n dá ọjọ́ tí àwọn tí wọ́n fẹ́ iyawo àjèjì ninu àwọn ìlú wa yóo wá, pẹlu àwọn àgbààgbà, ati àwọn adájọ́ ìlú kọ̀ọ̀kan, títí ibinu Ọlọrun lórí ọ̀rọ̀ yìí yóo fi kúrò lórí wa.
Gege bi alaga ipolongo eto idibo fun egbe naa nipinle Osun, ti o je gomina ipinle Kano, Abdullahi Ganduje,“Gege bi ti ipade yii se lo, a ti setan bee si ni, o da wa loju pe, a o jawe olubori ninu eto idibo to n bo yii, nitori pe gbogbo awon ti o dije dupo labe asia egbe ohun fun ipo gomina naa lo wa n kale bayii, ti won si ti jeje lati se atileyin ti o legbe lojuna lati gbe igba oroke ninu eto idibo naa.
Oṣù mẹsan-an ati ogúnjọ́ ni ó gbà wọ́n láti lọ káàkiri gbogbo ilẹ̀ Israẹli, lẹ́yìn náà, wọ́n pada sí Jerusalẹmu.
” Ìdí rẹ̀ ni pé, OLUWA ni ẹlẹ́rìí majẹmu tí ẹ dá pẹlu aya tí ẹ fẹ́ nígbà èwe yín, tí ẹ sì ṣe aiṣootọ sí, bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé olùrànlọ́wọ́ yín ni, òun sì ni aya tí ẹ bá dá majẹmu.
Bí ó bá sì kọjú ìjà sí mi, n óo di ọ̀fun rẹ̀ mú, n óo sì pa á.
Àwọn ìlú náà ati pápá oko wọn ni àwọn ọmọ Israẹli fún àwọn ọmọ Lefi, lẹ́yìn tí wọ́n ti ṣẹ́ gègé lé wọn lórí, gẹ́gẹ́ bí OLUWA ti pa á láṣẹ láti ẹnu Mose.
Àwọn ọmọ Iyabọ Ojo rí Bàbá lẹ́yìn ọdún mẹ́fà Ẹ yé fi ilé, mọ́tò bùga lórí ayélujára - Oshodi-Oke Mo ti fọ́ bàbá mi, Ọ̀gá Bello létí rí - Fẹmi Adebayọ̀ Àwọn arẹwà obinrin Yollywood, tá ló mọ iṣẹ́ rẹ̀ jù?
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Wọ́n ní kí n máa jẹ ewébẹ̀ láti dín ìtọ̀ súgà kù' Aburo oloogbe naa to wa sile lati beere rẹ ni o ri eyin rẹ ninu ẹrọ ilọta igbalode ti o si lọ agọ ọlọpaa lati fi ẹjọ sun pe ẹgbọn oun ti di awati.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ofada Rice: kíni ẹ̀yin gbádùn nínú ìrẹsì ọ̀fadà?
Nígbà tí mo ronú nípa ìṣe mi,mo yipada sí ìlànà rẹ;
Ta a ni yóò rọ́pò Abba Kyari gẹ́gẹ́ bi olórí òṣìṣẹ́ Buhari?
Nítorí asán ni àwùjọ àwọn tí wọn kò mọ Ọlọ́run,iná yóo sì jó ilé àwọn tí ń gba owó àbẹ̀tẹ́lẹ̀.
"Olori ijọ Gabola ni ""a o ko da ẹṣẹ kankan ni ijọ Gabola, a si korira lilodi si ofin ijọba""."
Mo kọ̀ láti yí ọ̀rọ̀ mi padà lórí ètò ẹ̀kọ́ ọ̀fẹ́ - Gómìnà Dapo Abiọdun 'Operation Rewire' EFCC / FBI sèso owó tó lè ní mílíọ̀nù N153 Báwo ni mo ṣe lè sọ̀rọ̀ ìtùnú fún ẹni tó fẹ́ pa ara rẹ̀?
Wọ́n jí òsìsẹ́ ẹgbẹ́ alágbèlébù pupa gbé ní ìlú Mogadishu
Nítorí a óo fi í lé àwọn tí kì í ṣe Juu lọ́wọ́.
Atupalẹ awọn to ku niyii: Nàìjíríà tún ní àkọsílẹ̀ ènìyàn 108 tó ní ààrùn coronavirus Ó ti pé ènìyàn 981 tó ní Coronavirus ní Nàìjíríà báyìí Wọn tun ti ri eniyan mọkanlelaadọrun to ni aarun coronavirus ni Naijiria.
Bayi ni ọrọ ri pẹlu baba ọmọkunrin to gbe ado oloro wọ baalu to n lọ silu oyinbo lọjọ keresi lọdun 2009, ti orukọ rẹ n jẹ Umar Farouk Abdulmutallab.
Nípa iṣẹ́ ọwọ́ wọn ni ẹ óo fi mọ̀ wọ́n.
Ní alaalẹ́ wọn á pada wáwọn á máa hu bí ajá, wọn á sì máa kiri ìlú.
Wọ́n yà á sí mímọ́ wọn sì ṣe àwọn ìlẹ̀kùn rẹ̀, wọ́n yà á sí mímọ́ títí dé Ilé Ìṣọ́ Ọgọrun-un, ati títí dé Ilé Ìṣọ́ Hananeli.
Eero kun ile ẹjọ debi wi pe awọn kan ko raaye joko, ti adajọ to n gbọ ẹjọ naa de awọn ti ko raaye joko, eyi ti ko yọ awọn akọroyin silẹ.
Bẹẹ ba gbagbe, ijọba ana ti aarẹ Goodluck Jonathan dari, lo gbe igbimọ naa kalẹ lati ṣe atunto ẹka isẹ ọba ni Naijiria, tí abọ igbimọ naa si foju han sita ni oṣu kẹrin ọdun 2012, eyi ti ìjọba Buhari ti tẹwọ gba bayii.
Amọ Eric Lamela to wọle da ayo kan pada eyi to jẹ ki ere bọọlu pari si ayọ meji si ẹyọkan.
"Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Lẹ́yìn ìfẹ̀yìntì ọdún márùn-ún, báágì àti bàtà ló kàn ""Ìlú mímọ́ nibí, wọn kò gbọdọ̀ bímọ, sin òkú àbí ẹran síbẹ̀"" Àràmọ̀ǹdà!"
Nitori eyi ijọba ipinlẹ Eko ti wa kede awọn ọna abuja lati yago fun sunkẹrẹ fakẹrẹ ọkọ lagbegbe to yii ka.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Iléeṣẹ́ ọlọ́pàá: Irọ́ ni kìí ṣe èèsì, ẹ mọ̀ pé ọlọ́pàá ni wọ́n, kẹ tó yìnbọn 8 Ògún 2019 Oríṣun àwòrán, Alamy Àkọlé àwòrán, Ileesẹ ologun ati ọlọpaa ti n tako ra lori idi tawọ̀n ologun se yinbọn pa ọlọpa mẹta ati araalu kan lasiko ti wọn gbe gbajumọ ajinigbe kan.
Tí ó jẹ́ pé kìkì ìjòyè ni àwọn oníṣòwò rẹ̀;gbogbo àwọn tí ń ta ọjà níbẹ̀ ni wọ́n jẹ́ ọlọ́lá ní gbogbo ayé.
Kí orúkọ rẹ di mímọ̀ fún àwọn ọ̀tá rẹ,kí àwọn orílẹ̀-èdè lè máa gbọ̀n níwájú rẹ!
Eniola Badmus fara gbọgbẹ ọta ibọn lọwọ ologun ni Lekki, o wa lẹsẹkan aye, ẹsẹ kan ọrun: Bakan naa ni ẹnikan gbe soju opo Twitter rẹ pe gbajumọ osere tiata kan, Eniola Badmus ti fara gba ọta ibọn latọwọ awọn ologun ni Lekki.
Gbogbo nǹkan tí Asa ọba ṣe láti ìbẹ̀rẹ̀ dé òpin, ni a kọ sinu ìwé ìtàn àwọn ọba Juda ati Israẹli.
- Ọọ̀ni Ife Ṣé ẹ ti gbọ́ ọ̀rọ̀ lẹ́nu Wolii Sotitobire fúnra rẹ̀?
Ó ṣe alábàápàdé ọ̀pọ̀lọpọ̀ ewé kátabá níbẹ̀ ó sì ṣẹ́ wọ́n.
Èèyàn 111 ní àrùn Coronavirus ràn ní Nàìjíríà ní 10/10/2020 Awọn eeyan ti aarun Covid-19 ti ran l'orilẹ-ede Naijiria ti pe ẹgbẹrun lọna ọgọta ati mẹtalelọgọrun (60,103) bayii.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Wasiu Ayinde: Èmi àti Aláàfin sọ fún Gani Adams nípa oyè Mayegun, a kò jà rárá Wasiu Ayinde ko pari ileewe girama ti ko fi lọ sileewe mọ nitori iku baba rẹ.
Nígbà tí wọ́n sọ fún Mose pé Jẹtiro, baba iyawo rẹ̀, ń bọ̀ wá sọ́dọ̀ rẹ̀ pẹlu iyawo rẹ̀ ati àwọn ọmọ rẹ̀ mejeeji, 
Ìfipá gba maersk alabama jẹ ́ àtẹ ̀ léra ìṣẹ ̀ lẹ ̀ orí omi tì ó bẹ ̀ rẹ ̀ pẹ ̀ lú àwọn ajalèlókun mẹrin tí wọ ́ n fi ipá gba ọkọ ̀ ojú omi ẹ ̀ lẹ ́ rù , mv maersk alabama igbalélógójì máìlí ( 440 km ; 280 mi ) gúúsù-ìlàoòrùn eyl , somalia .
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Flood: Ọ̀pọ́ Dúkìá ló sọnù ní 2019 lásìkò tí ìjọba ṣí ’dáàmù Ọyan’ Asẹyinwa, asẹyinbọ, ile ẹjọ da Baba Suwe lare, to si ni ki ileesẹ asọbode ilẹ wa lọ san owo gba, ma binu fun.
Òmùgọ̀ ọmọ jẹ́ ìbànújẹ́ baba rẹ̀,ati ọgbẹ́ ọkàn fún ìyá tí ó bí i.
Oríṣun àwòrán, iyaboojofespris Àkọlé àwòrán, Ṣaaju ni ọkan lara awọn ọmọ oṣere naa, Priscilla, ti kọkọ kede lori ayelujara pe iya oun ti di onile niluu Eko.
 Arun Cataract ko see dapada, arun Glucoma yii lo tele e ninu arun to n bu ifoju lu awon eniyan.
wọ́n ranṣẹ lọ mú Jeremaya jáde kúrò ní ìgbèkùn.
Ìtàn ayé Henry Fajemirokun, olówó tó fi owó mọ Olúwa àti ènìyàn Kí ló ṣẹlẹ̀ tí àwọn ọmọogun Nàìjíríà tó lé ní 350 fẹ́ kọ̀we fi iṣẹ́ sílẹ̀?
Awọn olosere Nollywood naa gbadura fun iwosan rẹ lori ero ikansiraẹni Instagram wọn.
Akowe egbe awon obi awon akekoo obinrin Dapchi ti won ji gbe, Kachalla Bukar ti fi mule pe, ogorun awon akekoo obinrin ile-eko imo ijinle, ti won ji gbe ni Dapchi ti o wa ni ijoba ibile Busari nipinle Yobe, ti pada sile layo ati alaafia.
Wọn ni ti wọn ko ba tẹle ikils naa, omi le tẹyin wọ igbin lẹnu fun wọn.
Inú obìnrin yìí dùn sí ọ̀rọ̀ tí ó gbọ́ yìí, ó mú aṣọ rẹ̀, ó ró o dáadáa, ó fún gèlè rẹ̀ mọ́ ẹ̀gbẹ́, ó ń lọ sí inú ihò látti lọ pàdé ẹni tí ó ṣe bí í ṣe olùfẹ́ òun.
Akowe ipolongo ẹgbẹ oselu PDP naa fikun ọrọ rẹ pe awọn ti ṣetan lati mu igba daadaa pada wa fun awọn eniyan ni ọdun 2019, pẹlu ileri pe awọn ọdọ yoo laaye lati dije dupo fun Ile Igbimo Asofin labẹ asia PDP ninu idibo gbogboogbo to n bọ.
Wabba tun so pe “Boya iwe akosile kankan wa ti gbogbo awon ti oro kan, naa bowolu?
Ìjọba mi ṣetán láti mú àgbéga bá ètò ààbò l‘Ọyọ - Seyi Makinde Èrò àwọn ọmọ Naijiria yàtọ̀ lórí ohun ìní Seyi Makinde Ìtàn ayé Seyi Makinde, gómìnà tuntun ní Ọ̀yọ́ Lẹ́yìn ò rẹyìn Seyi Makinde búra fún ìgbìmọ̀ olùgbaninímọ̀ràn Gege bí ikede tí akọ̀wé agba gómìnà náà Ogbeni Taiwo Adisa fi ṣòwò si awon akoroyin, ní ọjọ́ Kínní, oṣù tí a wà yìí to fidiẹ mulẹ.
Bakannaa lo ni Aarẹ Donald Trum ti kọwe si alaga ajọ isọkan ilẹ Afrika lori ọrọ ọhun.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Lawuyi Ogunniran, àgbà ọ̀jẹ̀ òǹkọ̀wé Eégún Aláré dágbére fáyé!
Iyabo Ojo Aṣa ilẹ Afirika ni Iyabo Ojo gbe larugẹ lọsẹ yii loju opo Instagram rẹ.
Ọjọ kẹrinla, oṣu kẹta ni ọjọ ibi oṣere Funke Adesiyan, ọmọ ilu Ibadan nipinlẹ Oyo nii ṣe.
Oríṣun àwòrán, @sumner_sambo Amọṣa, ṣe igba akọkọ irufẹ iṣẹlẹ bayii niyi lorilẹ-ede Naijiria?
“Ẹ óo di ẹni ẹ̀sín ati ẹni ẹ̀gàn, ẹni àríkọ́gbọ́n ati ẹni àríbẹ̀rù fún àwọn orílẹ̀-èdè tí wọ́n yi yín ká; nígbà tí mo bá fi ibinu ati ìrúnú dájọ́ fun yín, tí mo sì jẹ yín níyà pẹlu ibinu.
O ni awọn ẹsun ti ko bofinmu ni wọn fi kan adajọ agba naa.
Ṣé o óo jẹ́ kí n ṣẹgun wọn?
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Natalia Mufuta ìyá Yakub, Kamil àti Adam sọ̀rọ̀ lórí bí wọ́n ń sọ èdè mẹ́rin pàpọ Wọ́n tún ti pa omidan ẹni ọdún 18 míràn l'Akinyele ní ìlú Ibadan Irọ́ ni, kò sí olóyún nínú àwọn tí Tírélà pa ní Ondo ṣùgbọ́n awakọ̀ ti sá lọ- Ọlọ́pàá Ondo Ta ni ìyàwó Chadwick Boseman, tó jẹ́ àwòkọ́ṣe rere f'áwọn ọ̀dọ́ Adúláwọ̀?
Sedekaya ọba ranṣẹ lọ mú Jeremaya wolii wá sọ́dọ̀ rẹ̀ ní ẹnu ọ̀nà kẹta tí ó wà ní Tẹmpili OLUWA, ó wí fún Jeremaya pé, “Ọ̀rọ̀ kan ni mo fẹ́ bèèrè lọ́wọ́ rẹ, má sì fi ohunkohun pamọ́ fún mi.
naa ni Adamawa, Anambra, Beyelsa, Benue, Delta, Edo, Jigawa, Kebbi, Kogi, Kwara,
-Kollington fésí sí ìbéèrè ńlá Mo ti kó kúrò nílé Olu Jacobs rí lẹ́ẹ̀mejì- Joke Silva Àṣírí mẹ́wàá tí mo mọ̀ nípa Boko Haram-Naomi Adamu Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí 3:54 Fídíò, Zoom Wedding: Àwọn ọkọ àti ìyàwò ló ní àwọn kò leè sún ọjọ́ ayọ̀ wọn síwájú.
Ẹgbẹ CAN ko laṣẹ lati ba ẹnikẹni wi tabi gbee soke.
Ayọ̀ ń bẹ fún àwọn onírẹ̀lẹ̀,nítorí wọn yóo jogún ayé.
Bakan naa la gbo pe Zakari Mohammed to jẹ asoju fun Baruten Kaima ni ẹkun ariwa ipinlẹ Kwara naa fi iwe iferongba rẹ sowo si ile ẹgbẹ PDP, iyẹn Wadata House, labuja lọjọru.
Orileede Italy ni aisan Coronavirus ti gbogo julọ ni ilẹ Yuroopu.
Èyí ni àwọn arẹwà ‘ẹ̀lẹ̀ Daddy’, àfẹ́fẹ́ tí Aláàfin fi ń mí Mùjẹ̀-mùjẹ̀ ní Akinyele tún ti mu ẹ̀jẹ̀ obìnrin míràn lónìí Ọkùnrin kan bá ọmọ oṣù mẹ́ta lòpọ̀, ìfun ọmọ tú jáde!
" Ṣugbọn, iru ori pipa bẹẹ, fun igba diẹ ni.
Mo ti rù láàrin ọ̀sẹ̀ kan, iṣẹ́ Eko kò dẹ́rùn - Sanwo-Olu Ìdílé Pius Adesanmi ti gbé Boeing lọ sílé ẹjọ́ Igbiyanju rẹ nibi ti ikọ Super Eagles ti n bẹrẹ igbaradi wọn niluu Asaba naa ko tun wu olukọ Super Eagles, Rohr lori, eyi to jẹ ko ja a ju silẹ.
Oríṣun àwòrán, others Àkọlé àwòrán, Awon janduku miran lo ọrọ naa fi jale Ileeṣẹ ọlọpaa ni rogbodiyan naa ko ba di ti ẹlẹyamẹya tawọn ko ba tete kọwọ ọmọ bọ aṣọ.
Ó ṣe àpèjúwe àwọn ìfìyàorójẹni tí òun pẹ̀lú àwọn ológun mìíràn rí:
) Ète búburú náà ni láti dúró de àtúnṣe tí wọ́n retí sí ìtúmọ̀ àwọn ohun tí ó wà nínú àwọn ojú ewé ìwé tí wọ́n jí gbé lọ, àti lẹ́hìnnáà kí wọn ó le sọ olùtúmọ̀ di aláìmọ̀kan nípa fífi àwọn àìṣedéédé hàn tí àwọn àtúnṣe náà ti múwá.
Àwọn ará Gileadi dúró ní ìlà oòrùn odò Jọdani,kí ló dé tí ẹ̀yà Dani fi dúró ní ìdí ọkọ̀ ojú omi?
Ẹ dákẹ́ àhesọ ọ̀rọ̀, ohun tó pa ẹ̀gbọ́n àti àbúrò Orisabunmi rèé - Mọ̀lẹ́bí gbarata Wo àdánù tó wà nínú gbígba ayédèrú áápù fún ìforúkọsílẹ̀ NIN lórí ayélujára Àmúlò ẹ̀rọ POS fun òwò ṣíṣe, ṣé ó tọ̀nà nínú Islam àbí bẹ́ẹ̀ kọ́?
Bákan náà, mo máa sọ wípé gbogbo wa ní láti darapọ̀ mọ́ iṣẹ́ àtúnṣe sí ìwé òfin ọdún-un 2008 tí ó ń lọ lọ́wọ́ nínú ìgbìmọ̀ ìjọba.
Ile ise olopaa to wa ni ipinle Sokoto ti ni ipolongo to waye ni ipinle Sokoto lo ni irowo-irose.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù No Bra Day: Àyájọ́ ‘Má wọ kọ́mú’ ló ń pe àkíyèsí àwọn obìnrin sí àìsàn jẹjẹrẹ ọyàn 13 Ọ̀wàrà 2019 Oríṣun àwòrán, Geneva_la_jade Ọjọ Kẹtala osu Kẹwa ọdọọdun no ayajọ ọjọ 'Ma wọ kọmu' lorilẹede Naijiria eyi to n sọ fun awọn obinrin lati yan kọmu lodi lọjọ naa.
idajọ ni ile igbimo asoju sofin  ti
Akọroyin BBC Yoruba to wa ni Alexandria, orilẹede Egypt nibi ti idije ife ẹyẹ AFCON 2019 ti n lọ lọwọ, Joshua Adetunji tun ba ọkan lara awọn agbabọọlu Super Eagles sọrọ lori ohun ti yoo jade lara ifẹsẹwọnsẹ tonii.
Nígbà ti BBC Yoruba bá àkọ̀wé gbogbo-gboo fún àgbájọpọ̀ ẹgbẹ́ àwọn to ń ja fun ìjọba awa ara wa (NADECO), Ayo Opadoku nsọ̀rọ̀, o sàlàyé pé, ìgbẹ́ṣẹ̀ ààrẹ ko tíì kún ojú òṣùwọ̀n to ǹkan ti àwọn ń fẹ.
Ṣugbọn ọjọ́ ń bọ̀ tí a óo mú ọkọ iyawo kúrò lọ́dọ̀ wọn.
Ìwọ ati àwọn ìjòyè rẹ, àwọn ayaba ati àwọn obinrin rẹ, ẹ bẹ̀rẹ̀ sí fi wọ́n mu ọtí waini.
Ṣugbọn kò gbọdọ̀ máa kó ẹṣin jọ fún ara rẹ̀ tabi kí ó mú kí àwọn eniyan náà pada lọ sí ilẹ̀ Ijipti láti ra ẹṣin kún ẹṣin, níwọ̀n ìgbà tí OLUWA ti wí fun yín pé, ‘Ẹ kò gbọdọ̀ pada lọ sí ibẹ̀ mọ́.
Ẹsun ti wọn fi kan Ọgbẹni Babalele ni pe wọn gbe owo bi ẹgbẹrun lọna ogoje owo dọla($140,000) rin ṣaaju idibo gbogbogbo ọdun 2019.
A ti gba àwọn òṣìṣẹ́ 15,000 làti ṣètò ìdìbò gómìnà ní ìpínlẹ Ondo lóṣù kẹwàá - INEC INEC ni awọn ẹgbẹrun mẹẹdogun oṣiṣẹ ni yoo jẹ awọn agunbanirọ ti wọn n sinru ilu ilẹ baba wọn nipinlẹ Ondo.
Ṣé wọn kò sọ fun yín láti ìbẹ̀rẹ̀,kò sì ye yín láti ìpilẹ̀ṣẹ̀ ayé, pé:
Nígbà tí Mose dàgbà, ní ọjọ́ kan, ó jáde lọ sí ọ̀dọ̀ àwọn eniyan rẹ̀, ó sì rí i bí ìyà tí ń jẹ wọ́n.
Iroyin tun sọ pe Makinde pe igbakeji gomina ipinlẹ Eko ni, ki o to o ri nọ́mbà dokita to n tọju rẹ.
Ẹ má lọ, ẹ má máa sáré tẹ̀lé wọn kiri.
òjò sì rọ̀ fún ogoji ọjọ́, tọ̀sán-tòru.
Àwọn ọmọ Israẹli tí wọ́n wá ṣe àsè Àjọ Ìrékọjá, wọ́n sì ṣe Àjọ Àìwúkàrà fún ọjọ́ meje.
Donald Trump gbìyànjú nípa ètò àlááfíà ló jẹ́ kí n fàá kalẹ̀ fún àmì ẹ̀yẹ Nobel Peace Prize- Christian Tybring- Gjedde
“Mo ti so eleyii  nibi opolopo awon ibi ti a ti n se ipolongo
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ṣọla Allyson: Obìnrin tí kò bá rẹwà ni yóò máa ṣí ara sílẹ̀ Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Inú mi á máa ru,nígbà tí mo bá rí àwọn eniyan burúkú,tí wọn ń rú òfin rẹ.
Baalu Sriwijaya Air Boeing 737 gẹgẹ bi awọn alaṣẹ se sọ di awati lasiko to n lọ si Pontianak ni iwọ oorun agbegbe Kalimatan.
Àwọn Juu gbà láti máa ṣe bí wọ́n ti bẹ̀rẹ̀ sí ṣe ati bí àṣẹ Modekai.
Ninu ifẹsẹwọnṣe naa to waye ni papa iṣere NSC Olimpiyskiy Stadium nilu Kiev,Ukraine,Olivier Giroud lagbabọọlu ẹgbẹ naa to fakọyọ.
ẹni ba fẹ gbadun iṣu ati epo ni lati se iṣu naa ṣaaju, lẹyin naa ni yoo tọ epo diẹ sori iṣu gbigbona naa, o lee fi iyọ diẹ si i.
Imọran rẹ re e fun yin: Ri wi pe o ka iwe nipa idanwo naa ni ojoojumọ lati le ṣe igbaradi to peye.
Epe rabandẹ lawọn kan tiẹ n fi ranṣẹ si pasitọ Omashola, wọn ni ko mọ ohun to n sọ.
Kubrat Pulev: Ajẹ̀sẹ́ pàdánù ìwé ìdíje nílùu California nítoríi fífẹnu ko ẹnu akọ̀ròyìn obìnrin
Godwin Obaseki ti kọwe fipo silẹ gẹgẹ bi ọmọ ẹgbẹ oṣelu APC lẹyin ipade rẹ pẹlu Aarẹ Muhammadu Buhari ni ilu Abuja ni ọjọ Iṣẹgun.
A kò sì lè wí pé èyí kò rí bẹ́ẹ̀.
Iwulo aapù ọhun ní láti fun àwọn ìyálọ́jà l'áànfàni láti mọ bi ọjà wọn ṣe ń lọ́ sí.
Pilatu wá bi wọ́n pé, “Ẹ fẹ́ kí n dá ọba àwọn Juu sílẹ̀ fun yín bí?
lilo ipo eni tabi ile-ise ijoba fi lu awon ara ilu ni jibiti je ohun ti ko dara
Wọn ni nitootọ ni o bani ninujẹ pe ọdọmọkunrin ẹni ọdun mejilelogun naa gba iru idajọ.
Bi ẹrin ni awọn kan fi ọrọ naa ṣe.
Ọ̀rọ̀ wo ni ó lè dùn lẹ́nu wa?
Ipinlẹ Eko lo ni eniyan to poju pẹlu eniyan 378 ni Ojo Satide nikan soso.
  Mo lọ sí London Aquarium níjọ́sí, ibi tí wọ́n ti ṣe àkójọpọ̀ àwọn ẹja aláràbarà.
Ile ẹjọ to dajọ lori iku ana Yusuf lẹyin igba naa dajọ ẹbi fawọn ọlọpaa ti awọn mọlẹbi rẹ si sọ fun BBC pe inu awọn dun si idajọ naa ati bi ile ẹjọ ti ṣe paṣẹ ki ọlọpaa san owo itanran $665,000.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Coronavirus updates: Wo àwọn oníròyìn méje tó kú láàrin ọjọ́ méje ní Nàìjíríà 21 Òkùdu 2020 Oríṣun àwòrán, Facebook Lootọ ni pe alagbra naa a maa subu, awọn oniroyin lo ṣikeji lẹyin awọn dokita ti wọn si n lewaju lasiko ajakalẹ aarun Covid -19 yii.
ti won fi n lu awon eniyan ni  jibiti.
”Ife-eye ti o gbayi julo lagbaye ninu ife-eye idije ajo FIFA ohun, ni won yoo safihan re fun awon ara ilu, ni papa isere Old Parade Ground, Garki nilu Abuja lojoBo(Thursday).
Ẹni tí ó bá ń pa òfin Ọlọrun mọ́ ń gbé inú Ọlọrun, Ọlọrun náà ń gbé inú irú ẹni bẹ́ẹ̀.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ẹgbẹ ajafẹtọẹni nfẹ iwadi tuntun lori ifọnkalẹ epo rọbi 19 Ẹrẹ̀nà 2018 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ọpọ igba ni wahala ibajẹ ayika ti sẹlẹ lẹkun Niger Delta nitori aibikita awọn ileesẹ apọnpo nibẹ Ajọ to n tọpinpin ẹtọ ọmọniyan lagbaye, Amnesty international (AI) ti ke si awọn alasẹ lorilẹede Naijiria lati tun iwe iwadi si lori isẹlẹ ifọnkalẹ epo rọbi to waye lẹkun Niger delta.
Ní ìgbàanì, o sọ ninu ìran fún olùfọkànsìn rẹ pé,“Mo ti fi adé dé alágbára kan lórí,mo ti gbé ẹnìkan ga tí a yàn láàrin àwọn eniyan.
Oríṣun àwòrán, Instagram/bintaayomogaji Se ẹ ko ro pe 'ẹbun' kọ ni awọn ile ati ọkọ naa, ti kii si se inu isẹ tiata ti wọn n se ni owo ti wọn fi ra awọn ohun meremere yii ti wa?
Kò dájú pé ìdìbò 2019 yóò kẹ́sẹjárí - BBC News Yorùbá BBC News, YorùbáFò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Atiku Abubakar - Kò dájú pé ìdìbò 2019 yóò kẹ́sẹjárí 17 Sẹ́rẹ́ 2019 Oríṣun àwòrán, REUTERS/Temilade Adelaja Àkọlé àwòrán, Atiku Abubakar ko ṣẹṣẹ ma fidirẹmi ninu idibo Aarẹ lorileede Naijiria Bi idibo ọdun 2019 lorileede Naijiria ti ṣe ku osu kan, oludije sipo aarẹ labẹ ẹgbẹ oṣelu Peoples Democratic Party, ti sọ fun BBC pe oun ko ni igbagbọ pe eto ibo naa ko ni ni mago mago ninu.
ISWAP ti ṣekú pa òṣìṣẹ́ ẹgbẹ́ aláànù Action Against Hunger Ọmọ Uganda gba àmi ẹ̀yẹ Komla Dumor BBC tọdun yii Kí wọ́n tún ìbò Kogi dì nígbà 2,000 Dino ló máa wọle- Dino Gbogbo iṣé àṣepatì ni yóò di mìmù ṣe lọgán- Alaṣọadura Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Ko ni i jẹ iyalẹnu, ti aarẹ ba mu ọkan ninu awọn mejeeji."
Jesu bá bi àwọn ọmọ-ẹ̀yìn mejila pé, “Ẹ̀yin náà fẹ́ lọ bí?
Gabriel ti fọjú ba ilé ẹjọ ó si jẹ̀bi ẹ̀sùn ti wọ́n fi kan, nítori ìdí èyí yóò maa ṣẹ̀wsn ọdún márun ní ọgbà ẹwọ̀n ijọba ni Ado Ekiti fún ẹ̀sùn ìfipá bá ọmọ ọdún méje lòpọ̀.
Nígbà náà ni Gbogbo àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ bá fi í sílẹ̀, wọ́n bá sálọ.
David Bello-Monerville ni ọkùnrin kẹta nínú rẹ̀ tí wọn yóò pa ní London
Lalẹ Ọjọru ni awọn eniyan kan n ṣayẹyẹ idije fifi ẹṣin sare ni agbegbe Tudun Maliki nipinlẹ Kano.
' Ariwo ayọ̀ sọ nílé Remi Surutu, ọmọ rẹ̀ mú ọkọ wale Inú odò ni wọ́n ti rí òkú ọmọ ọdún méjì tó sọnù l'ọ́jọ́ ọdún Eid nílùú Ibadan Olamide ati Lil Kesh dá wàhálà sílẹ pẹ̀lú 'Logo Benz' Patoranking,Teni,Burna Boy: tá ní yóò gbà àmì ẹ̀yẹ̀ Headies?
Ọlọ́pàá ń wa Ọrọ awọn darandaran to ti fẹ di ọdaran nilẹ Yoruba jẹ ohun ti o n kọ awọn eeyan lominu.
Ó ní ọpọlọpọ agbo aguntan ati agbo mààlúù, pẹlu ọpọlọpọ iranṣẹ tóbẹ́ẹ̀ tí àwọn ará Filistia bẹ̀rẹ̀ sí jowú rẹ̀.
Àgbo tí mò ń lò láti jò kó bá mi, ìdí mi ti yọ́ tán - Nkechi Blessing figbe ta EFCC gbe afurasi naa lọ ile ẹjọ lọjọ kẹrin, oṣu kejila, ọdun 2020 lẹyin ti ọwọ tẹ ẹ lọjọ kejila, oṣu Kẹjọ ọdun 2020 yii kan naa.
Alukoro ileeṣẹ ọlọpaa fidi rẹ mulẹ fun BBC Yoruba, Ọgbẹni Tee-Leo Ikolo wi pe pẹlu ayọ ati idunnu ni ọlọpaa naa fi kuro nibi iṣẹ rẹ to wa ni Akungba Akoko, oun pẹlu aya ati awọn ọmọ wọn.
Wọn ni igba karun un rẹ ti ijọba maa sọ bẹẹ ṣugbon ti ko mu ootọ dani.
Wọ́n tú àṣírí ìfiyàjẹni àwọn Ológun àti SARS káàkiri Nàìjíríà ’Awọn sọja Cameroun tu mi sihoho' Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, BBC Africa Eye: Akọroyin fẹ ìdí àwọn oníṣẹ́ ibi ọmọ ogun síta Oṣiṣẹ ajọ eleto idibo Cameroon kan lo fi aridaju iroyin yii han fun BBC.
Aare Buhari ti wa rọ awon gomina, ni gbogbo ipele ijoba lati tubo maa se idanilekoo to yanranti fun awon eniyan won, paapaa julo lori eto idibo odun 2019 ti yoo waye lorile ede yii.
” Agbenusoro awon olopaa, Lt Col André Traut naa fikun un oro ohun pe, bi awon se de ibi isele naa, O tu ko lati fi awon ohun ija owo re sile, ti o si tun koju ija si awon olopaa, eleyi ti o sokunfa bi awon olopaa se gbemi re.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Angelique kidjo ni asiko to fun idọgba laarin akọ ati abo 8 Ẹrẹ̀nà 2018 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Angelique Kidjo ni awọn obinrin lee da isẹ silẹ bi awọn ọkunrin ba fi aake kọri lori didọgba laarin an ọmọ ọkunrin ati obinrin Gbajugbaja akọrin agbaye e ni, Angelique kidjo ti sọ wi pe o di igba ti awọn obi ba rii daju pe idọgba wa laarin ọmọ ọkunrin ati obinrin wọn ki wahala aidọgba laarin ẹya akọ ati abo to lee dopin ni ilẹ Afirika.
Ohun kan péré tó gbà ni dídẹwọ́ lórí ìkúnjú-òsùnwọ̀n ètò-ẹ̀kọ́ àti gbígba àwọn akẹ́kọ̀ọ́ láyè láti máa gbéégún nínú ìdánwò.
Wọ́n ri ìlẹ̀kùn meji, alápapọ̀, tí wọ́n fi igi olifi ṣe, mọ́ ẹnu ọ̀nà Ibi-Mímọ́-Jùlọ.
Awọn yoku ni, alaga apapọ fẹgbẹ oṣelu PDP, ọmọọba Uche Secondus, gomina ipinlẹ Kwara, Abdulfatah Ahmed, gomina ipinlẹ Ogun tẹlẹri, Ọtunba Gbenga Daniel ati bẹẹbẹẹ lọ.
Mo bá lọ sí ilé amọ̀kòkò.
Àáyá bẹ sílẹ o bẹ sáré,wábiwọ́sí ìyá ni Flying Eagles fi bẹrẹ fún Qatar Ọ̀gọ̀rọ̀ èèyàn lórí ayélujára bú Dalung lórí owó IAAF Ẹ̀gbẹ́ òṣìṣẹ́ ní ìpínlẹ̀ Oyo so ìyanṣẹ́lódì rọ̀!
Bí Saulu ti ń bá alufaa náà sọ̀rọ̀ lọ́wọ́, ìdàrúdàpọ̀ tí ó wà ninu àgọ́ àwọn ọmọ ogun Filistini ń pọ̀ sí i.
Lasiko to fi n se ifilọlẹ igbimọ naa, alaga apapọ ajọ Inec, Ọjọgbọn Mahmood Yakubu ni ko si ohun to kan igbimọ naa pẹlu sise iwadi abajade idibo sijọba ibilẹ to waye ni ipinlẹ Kano nitori ajọ Inec ko lagbara lori rẹ labẹ ofin orilẹede Naijiria.
Nítorí ó yá mi lára kí ń kúkú kú jù pé kí ẹnikẹ́ni wá sọ ọ̀nà ìṣògo mi di asán lọ.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: ‘Ìkọlù darandaran pa èèyàn 2000’ Darandaran tun gbẹmi mẹẹdọgbọn ni Kogi Ganduje pe awọn darandaran si Kano Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Odumakin sọrọ lori Fulani darandaran Ẹgbẹ̀rún kan ààbọ̀ ènìyàn ni ó ti kú ní Benue láti 2013 Oṣù kejì ọdún yìí ni kọmíṣọ́nnà fún ìbánisọ̀rọ̀ àti ìlanilọ́yẹ ní Benue, Lawrence Onoja, sọ wí pé bíì ẹgbẹ̀rún kan àbọ̀ ènìyàn ni ó ti kú ní Benue láti 2013 nínú àkọlù àwọn afurasí darandaran agbébọn, tí ogunlọ́gọ̀ sì pàdánù dúkìá, ohun ọ̀gbìn àti ilé wọn.
Jesu tún wí fún wọn pé, “Òtítọ́ ni pé ẹ pa àṣẹ Ọlọrun tì, kí ẹ lè mú àṣẹ ìbílẹ̀ yín ṣẹ.
Ko si anihani, ise akanse yii yoo je eyi ti o tobi ju ni ekun awon alawo dudu ati ni ile Afrika lapapoO salaye pe, “eyi safihan pe awon oko oju-omi nlanla yoo maa gunle si etikun naa, eyi ti yoo maa pa owo pupo sapo ijoba, ti yoo si mu igberu ba eto oro aje orile-ede Naijiria.
A à bá gbádùn oùnjẹ náà dáadáa bí kò ṣe àwọn iwin tí ó bá wa jẹun.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Tọkọ-taya Aràrá: Àwọn èèyàn máa ń wò wá, ta bá fa ọwọ́ ara wa ní títì Awọn nkan wo lo wa ninu ilana tuntun naa?
Wọ́n sọ fún ara wọn pé, “Ẹ jẹ́ kí á yan olórí, kí á pada sí Ijipti.
2 mílíọ́nù owó ìtanràn Báwo làwọn agbébọn ṣe rí ASP Ọlọ́pàá méjìlá jígbé?
Noa wọ inú ọkọ̀ lọ, òun ati aya rẹ̀ ati àwọn ọmọ rẹ̀ pẹlu aya wọn, láti sá àsálà kúrò lọ́wọ́ ìkún omi.
Nítorí ọ̀kan ninu wa ni, ó sì ní ìpín ninu iṣẹ́ yìí.
Ipinle Benue ti gbe igbese lati fi kun awon ona eto aabo won sii lataari abewo ti Aare Mohammodu Buhari fe se si ipinle Benue lojo Aje.
Mumini sọrọ yi ninu ifọrọwanilẹnuwo pẹlu BBC Yoruba.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Sogidi Lake: Kòṣẹja-kòṣèèyàn lá bá nínú adágún odò náà -Ojedele Ọjọ keje, osu kejila, ọdun 1963 ni Daniel Ọlọrunfẹmi ri sinu omi ni Bussa, lẹba Lọkọja nipinlẹ Kogi, lasiko to lọ si odo Ọya (River Niger) lati kọwe, ti wọn si sin si ilu abinibi rẹ, Oke Igbo Iwe Igbo Adimula lo n kọ lọwọ nigba to jade laye.
Ninu gbogbo ẹ̀yà tí ó wà ní Israẹli, ìdílé baba rẹ nìkan ni mo yàn láti jẹ́ alufaa mi, pé kí ẹ máa ṣe iṣẹ́ alufaa níbi pẹpẹ, kí ẹ máa sun turari kí ẹ máa wọ ẹ̀wù efodu, kí ẹ sì máa wádìí nǹkan lọ́wọ́ mi.
Itan igbe aye Samuel Taiwo Oredein: Gẹgẹ baa ti ka loju opo itakun agbaye, ọjọ nla ni ọjọ Kẹtala, osu Kẹrin, ọdun 1971 nigba ti isẹlẹ idigunjale alagbara kan waye lopopona Bacita nipinlẹ Kwara nigba tawọn agbebọn kọlu ọkọ banki Barclays, to ti di Union Bank bayii, eyi to gbe owo rin Ọlọpa meji ati osisẹ banki meji ni wọn wa ninu ọkọ tawọn ole yii kọlu, ti wọn si ṣa wọn lọgbẹ yannayanna.
Gbogbo àwọn ọkunrin tí a kà ninu wọn, láti ọmọ oṣù kan sókè jẹ́ ẹgbaarin ó dín ẹẹdẹgbẹta (7,500).
Ẹni tí ó bá fẹ́ mọ̀ bí ọmọ ènìyàn ti burú tó kí Olúwarẹ̀ lọ sí ọ̀run Àpáàdì nítorí ẹ̀ṣẹ̀ tí ẹnikẹ́ni kò lè fi ẹnu ara rẹ̀ sọ, tàbí kí ọwọ́ kọ́wọ́ kọ  sílẹ̀ fun àti kà wà nínú ẹ̀ṣẹ̀ ọmọ ènìyàn.
Mo sọ̀rọ̀ òtítọ́ ati ìgbàlà rẹ;n kò dákẹ́ lẹ́nu nípa òtítọ́ ati ìfẹ́ rẹ tí kì í yẹ̀,ninu àwùjọ ńlá.
irowo –irose, o tun so pe egbe oselu All Progressives Congress APC yoo tun jawe
4 814565 Orilẹede Poland 20181 53.
O ni o da oun loju pe awọn eniyan Kwara a mọ iyatọ iṣejọba mejeeji laipẹ laijinna.
Ẹ yé irọ́ pa, mí o fún Super Eagles ní ẹbùn owó kánkan -Sanwo Olu Super Eagles kò ní já àwọn ọmọ Nàìjíríà kulẹ̀- Musa Awọn ẹgbẹ ọhun ni wọn wọ aṣọ ti wọn kọ ''Tinubu 2023'' si lara.
O ni bakan naa ni wọn fi katakata ro gbogbo igbo to kun di ile naa tẹlẹri, bẹẹ si ni imọlẹ ti yii ile naa ka.
Awọn iroyin miran ti ẹ le nifẹ si: Ibeere mẹfa lori ijinigbe Dapchi Ọwọ ologun tẹ darandaran mẹwa ni Benue Wahala Kaduna: Ọwọ ọlọpaa tẹ eeyan mẹwa Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Taiwo Akinkunmi, ọmọ Ibadan tó ya àsìá Nàíjíríà Ìtàn tó wà nídi òwe ‘Sebótimọ Ẹlẹ́wà Sàpọ́n’ Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí 2 sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 2:23 Fídíò, Water Generator: Ó leè ṣiṣẹ fún wákàtí mẹfà, kó tó sinmi, Duration 2,2310 Òkùdu 2020 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
Ki lo kan Fayose gan pẹlu ipinlẹ Eko, Ekiti to ti wa gan, wahala to da silẹ nibẹ, a sẹsẹ n yanju rẹ ni.
 A ti kesi awọn osisẹ ajọ elepo rọbi NNPC lati wa ti ẹrọ to n pin afẹfẹ gaasi wa sidi ọpa naa, ki ina ọhun lee tete jo tan, tawọn osisẹ panapana, Lasema, ọga ọlọpa ati olori ileesẹ ologun lẹkun yii si ti de sibi isẹlẹ naa.
Nígbà tí ó kà á tán, ó gbéra, ó lọ sí ilé OLUWA, ó bá tẹ́ ìwé náà sílẹ̀ níwájú OLUWA, 
 @OgbeniDipo kọọ soju opo tirẹ pe: Njẹ o lee pe baba to bi ọ lọmọ ni oponu nitori pe o ko fara mọ ohun to sọ?
Victor Agunbiade ni ojú àlá ni Ọlọrun ti yan iṣẹ́ ọmọ ogun ojú omi fún òun ní America Ilé ayé mi ti d'ojú bolẹ̀ pẹ̀lú ikú àfẹ́sọ́nà mi- àfẹ́sọ́nà Immaculate Okochu Àgbo Covid-19 Madagascar kò ṣiṣẹ́, àwọn ènìyàn tí bẹ̀rẹ̀ sí ní kú níbẹ̀ Ilé ẹjọ́ ju ọmọ ìjọ tó fi ìpá bá ọmọ pásítọ̀ rẹ̀ sùn ní ìpínlẹ̀ Ondo sí ẹ̀wọ̀n gbére Wo ọ̀nà márùn ún tí o lè gbà dáàbò bò ara rẹ lọ́wọ́ ìjàmbá láì gbé ìbọn!
Yóo kó ọkà rẹ̀ jọ sinu abà, ṣugbọn sísun ni yóo sun fùlùfúlù ninu iná àjóòkú.
Johnson wa seleri pe oun yoo ji mu ninu awọn ero ọgbọn alatako oun naa, to si kun kan saara si olootu ijọba ilẹ Gẹẹsi ana, Theresa May fun bo se sisẹ sin orilẹ-ede rẹ.
Yakassai ni '' N ko riru ijọba eleyii ri bi ti aarẹ Buhari ti ko ni oju aanu kankan fun awọn araalu ''Ni ọpọlọpọ igba ni awọn araalu n la iṣoro kọja, amọ aarẹ ko tilẹ ni ṣe bi ẹni wi pe oun ri wọn rara, eleyii buru jai.
Kó gbogbo wọn lé Aaroni ati àwọn ọmọ rẹ̀ lọ́wọ́, kí wọ́n sì fì wọ́n gẹ́gẹ́ bí ọrẹ fífì níwájú OLUWA.
"Oríṣun àwòrán, George Wafula/BBC Gbogbo wọn fẹ mọ boya emi ni mo kọ iroyin kan ti akọle rẹ jẹ ""Ipenija lilo awọn nkan alumọni ilẹ Afirika lọna aitọ"" eyi ti wọn gbe jade loju opo ayelujara ileeṣẹ iroyin kan ni Ghana lọjọ kẹsan oṣu kinni ọdun 2019."
augustine ará híppò ( ; ) ( november 13 , 354 - august 28 , 430 ) , bakan naa bi augustine , augustine enimimo ( st.
– Tí òtútù ń pa mí,tí òógùn ń bò mí, igbá àyà mi rí gelete, inú mi ri ringinndin, ẹ̀rẹ̀kẹ́ mi ri jèkètè, eegun àyà mì ri kẹẹrẹ, orí mi ri palagun, egungun ìhà mi hàn ketekete, iṣan ara mi ri wọ́gọwọ̀gọ bí gbòǹgbò ojú ọ̀nà, ojú mi ri kuọkuọ bi eléèku, ẹsẹ téru, irun orí mi dàbí irun ara ajá eléèku, ẹsẹ mi rí tín-ín rín bí ṣaṣara ọwọ̀, ara mi ń wá rìrì bí àlòkù mọ́tò, mò ń mì fúkéfúké bí rọ́bà kẹ̀kẹ́ ara mi sì ń funfun bí ara aláboyún obìnrin : ìbànújẹ́ dé bá àwọn ará ilé wa, wọn ń sá kiri gọ́lọ́gọ́lọ́ bí ẹja inú omi, àwọn ènìyàn wa doríkodò bí ìmọ̀ ọ̀pẹ, ìyá mi ń rìn ká tìrònútìrònú, ilé wa sì dákẹ́ minimini bí ọ̀gànjọ́ òru.
" Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, JAMB 2019: A ó fagi lé ìdànwò ẹni tó bá ṣe aṣemáṣe O wa rawọ ẹbẹ si gbogbo ọmọ Naijiria lati mase maa fi ọwọ yẹpẹrẹ mu awọn ohun to ba jẹ mọ iyansipo awọn asaaju wa nitori idi ilana yii ni ọrọ wa ti wọ.
Ninu idije ohun ti o waye sikeyin, iko obinrin Kada Queens tilu Kaduna lo gba ife-eye ifigagbaga eka awon obinrin, ti iko Niger Flickers si gba ifigagbaga eka ti awon okunrin.
Ofin ile Sudan faaye gba aare lee meji lodun marun marun ni eyi to je odun mewaa lapapo.
(31) lo nifẹẹ si ko ma sewadii awon eniyan lori ero ayelujara lati fi lu won ni
Ìbẹ̀rù OLUWA níí kọ́ni lọ́gbọ́n,ìwà ìrẹ̀lẹ̀ níí ṣáájú iyì.
Oríṣun àwòrán, Twitter/Nasir El Rufai Iṣẹlẹ ọhun jẹ iyalẹnu fawọn araalu ni Kaduna eleyi ti iroyin sọ pe afẹfẹ gaasi to n jo lo ṣe okunfa rẹ.
Ó wí fún ọkunrin náà tí ọwọ́ rẹ̀ rọ pé, “Dìde dúró ní ààrin àwùjọ.
Oríṣun àwòrán, @YeleSowore Bakan naa ni wọn ni bi iwọde yii ba se n lọ yika Naijiria, naa ni yoo waa waye nilẹ United Kingdom, tawọn ọmọ Naijiria to wa nibẹ yoo si pejọ pọ si ileesẹ asoju ijọba Naijiria to wa nilu London fun iwọde.
O fi orin ayajo Sunny Ade kan ba won wi pelu ijo lese.
    Nígbà tí ó ṣe, mo ń Ẹlẹ́gbára tí ó yọ lọ́kàn-án-kán, ó ba ni lẹ́rù gidigidi.
Nítorí gbogbo àwọn orílẹ̀-èdè ti mu àmuyó ninu ọtí àgbèrè rẹ̀, ọtí tí ó fa ibinu Ọlọrun.
Kano Gorilla: Òṣìṣẹ́ 10 wọ gàù lórí ọ̀rọ̀ Ìnàkí tí wọ́n ló gbé owó tí wọn pa lásìkò ìtúnu ààwẹ̀
Coronavirus ti di ara wa, kò le è kúrò mọ láéláé - WHO Fayemi fojú Alufa to fipa bá ọmọde lòpọ̀ síta l'Ekiti Ìdí rèé tí ilẹ̀ Afirika fi gbọdọ̀ kópa nínú dídán abẹ́rẹ́ coronavirus wò 'Àlàyé rèé lórí ìdí ti mo fi na ọmọ òrukàn, tí mo sì tì í mọ́ ilé ajá' Àwọn èèyàn ń san ìdámẹ́wàá tó Heavy"" fún mi ni mo fi ń r'áànú ṣe - Iya Adura Esther Mo ti kó kúrò nílé Olu Jacobs rí lẹ́ẹ̀mejì- Joke Silva Èmi àti Saheed kìí ṣe ọmọdé, a ti jọ ṣe Sinimá papọ̀, èyí túmọ̀ sí pé ìjà ti parí - Fathia Balogun Awọn ọmọ Naijiria to wa ni South Africa tun fikun ọrọ pe awọn ọmọ ilẹ naa kii saaba wọ aṣọ ibilẹ wọn nigba ti wọn ba n ṣe igbeyawo."
Awọn igbesẹ ti a gbe yii, bi ẹyin naa ṣe mọ, ti gba ọrọ kare ọmọ ọdọ rere lati ọdọ ajọ eto ilera l'agbaye, WHO.
Ìlú tí ọ̀daràn bá tí dẹ́ṣẹ̀ ló yẹ kí wọn tí gbẹjọ́ rẹ̀ -Agbẹjọ́rò Àgùnbánirọ̀ gbẹ́mìí mì látàrí 'Snipper' tó fi fọ irun rẹ̀ ''Òsìsẹ́ Custom tó déédé sọ ara rẹ̀ di Ọ̀gá Àgbà CG ní ìdàmú ọpọlọ'' Ati wi pe yoo to ọdun mẹrindinlaadọta ki ẹni to ni owo julọ ni Naijiria fi na owo rẹ tan, bi o tilẹ n na owo to to miliọnu dọla kan ni ojoojumọ.
'' Wọn a fun awọn oṣiṣẹ ijọba ni ọkọ ẹyọkan lati ma a wọ lọfẹ lati ibi iṣẹ ati awọn ọmọ ileewe ni ọfẹ lati ma a fi rin lati ibi kan si omiran.
Pupọ ninu àwọn onigbagbọ ni mo tì mọ́lé, lẹ́yìn tí mo ti gba àṣẹ lọ́wọ́ àwọn olórí alufaa.
Samuel Okwaraji: Kíni ẹ̀yín mọ nípa akọni yìí?
 won koko diboyan wole ni 2004 , o si tun pade yori ninu idiboyan to waye ni 27 ati 28 november , 2009 .
Bo tilẹ jẹ pe awuyewuye waye lori iyansipo naa, ti ọpọ eeyan si n sọ pe oluranlọwọ pataki lori ọrọ awọn ti ko ni ọkọ tabi iyawo ni gomina yan obinrin naa si.
OLUWA bá wí pé, “N kò ní jẹ́ kí eniyan wà láàyè títí lae, nítorí pé ẹlẹ́ran ara ni wọ́n.
Nitori ọpọ awọn eeyan to wa ni awọn ilu nlanla, eyi to n mu ki eeyan kan ninu mẹta nibẹ o maa pin ile igbọnsẹ lo, eyi to si n mu ki ọwọja aisan o wọpọ.
    Gẹ́gẹ́ bí ẹ̀yín náà ti mọ̀, ìlú tí ó kún fún èérí bí irú èyí tí mo ń sọ yìí kò lè ṣai ní àwọn aláì sàn nínú.
bo ba ya ọkan a simi ẹnu lati tun pada fesi, bo ba wu ọkan, a fesi ni tẹle n tẹle.
Ṣugbọn ẹni tí ó bá wo òfin tí ó pé, tíí ṣe orísun òmìnira, tí ó sì dúró lé e lórí, olúwarẹ̀ kì í ṣe ẹni tí ó gbọ́ ọ̀rọ̀ tí ó gbàgbé rẹ̀, ṣugbọn ó ń fi ọ̀rọ̀ náà ṣe ìwà hù.
Nítorí oore-ọ̀fẹ́ Ọlọrun ti farahàn fún ìgbàlà gbogbo eniyan.
Oríṣun àwòrán, @IsiakaAdeleke1 Àkọlé àwòrán, Senator Isiaka Ademola Adeleke Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: PDP pè fún fífi Kemi Adeosun jófin APC àti PDP takora wọn lórí Olùsirò owó àgba Ọsun tó fisẹ́ sílẹ̀ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Bọla Tinubu: Ìpínlẹ̀ Ọ̀ṣun kò ní owó mi lọ́wọ́ Bakan naa ni iroyin sọ pe wọn tun gbẹsẹ le aṣuwọn Deji Adeleke to jẹ baba Davido, to si tun jẹ ilumọọka oniṣowo.
“Òpin ti dé ba yín báyìí, n óo bínú si yín, n óo da yín lẹ́jọ́ gẹ́gẹ́ bí ìwà yín; n óo sì jẹ yín níyà nítorí gbogbo ìwà ìríra yín.
Ọ̀lọ́pàà ìlú ọba ti fi páńpẹ́ ọba mú olùdásílẹ̀ Wikileaks, Julian Assange ní ìlú London.
“ Lẹyin ti o ba ti dibo tan  , rin jinna diẹ siwaju, ki o lee daabo bo ibo rẹ, sugbọn ti o ba ji ibo gbe , a o ge ọwọ rẹ, ti o ba fe salọ pẹlu apoti ibo, a o ge ẹsẹ rẹ.
Wọn kò dì ọ́ lọ́wọ́,bẹ́ẹ̀ ni wọn kò dì ọ́ lẹ́sẹ̀;o ṣubú bí ìgbà tí eniyan ṣubú níwájú ìkà.
Agogo wúrà kan, àwòrán èso Pomegiranate kan, agogo wúrà kan, àwòrán èso Pomegiranate kan, bẹ́ẹ̀ ni wọ́n tò wọ́n yípo etí ẹ̀wù àwọ̀kanlẹ̀ náà, fún ṣíṣe iṣẹ́ alufaa gẹ́gẹ́ bí OLUWA ti pàṣẹ fún Mose.
Ọba dá a lóhùn pé, “Má wulẹ̀ tún sọ nǹkankan mọ́, mo ti pinnu pé ìwọ ati Siba ni yóo pín gbogbo ogun Saulu.
Gomina ipinlẹ Ondo tẹsiwaju wi pe, agbekalẹ Amọtẹkun yoo mu opin de ba wahala awọn adigunjale, darandaran ati ijinigbe.
Ohun tí mò ń wí ni pé olukuluku yín ní ń sọ tirẹ̀.
Iṣẹ́ Tí Jesu Fi Rán Àwọn Ọmọ-Ẹ̀yìn Mejila.
Ariwo ''O TO GẸ'' ni ọpọ eeyan n pa nipinlẹ Kwara eyi to tumọ si pe awọn ko ni dibo fun Saraki ati ẹnikẹni to ba fa silẹ mọ.
Ọkọ iyawo ọhun, Sanusi Abdullahi, jẹwọ pe 'awada' ni oun fi ba ọrẹ oun kan lori Facebook sọrọ pe oun yoo san owo ori rẹ pẹlu Dọla mẹrinlelaadọta lasiko 'eto igbeyawo ori ayelujara' naa.
Ààrẹ Buhari yóò ṣàbẹ̀wò sí Morocco ''Buhari,Zamfara là fẹ kí o lọ, kìí ṣé Jordan'' Buhari sàbẹ̀wò ọlọ́jọ́ méjì sí Jigawa 'Kò dín ní ẹ̀mí 51 tó bọ́ ní ìkọlù Kaduna' O ṣafikun pe ijọba ohun ti doola ẹmi awọn ti Boko Harm ko ni panpẹ mọra.
Ṣugbọn, o di igba ti igbesẹ to kẹhin ba waye, ki ijiroro to o tan.
 Bakan naa ni Aṣofin Gbọlahan Yisawu ninu ọrọ rẹ rọ
Ìlànà nípa Kíkọ Òfin Ọlọrun Sára Òkúta.
Ọgbẹni Zelenskyti ko ni iriri kankan tẹlẹ lagbọ oṣelu lo jawe olu bori ninu idibo aarẹ to waye ni Ukraine loṣu to kọja.
a tají á bẹ̀rẹ̀ sí í gbálẹ̀.
Eyi lo ṣokunfa idanwo ẹjẹ ti wọn kọkọ n ṣe ṣaaju fifi ẹjẹ silẹ ni gbogbo agbaye.
Garga so pe ikolu naa waye nigba ti ado oloro ti awon olote marun un naa ti won je obinrin meji ati okunrin meta de mo ara won, tu mo won lara ni eyi ti o si gbemi won lẹsẹkẹsẹ.
Ninu idibo to kọja ẹgbẹ oṣelu APC lo gbegba oroke ninu idibo gbogboogbo to waye.
O ni adura oun ni pé ki Olorun gbẹsan ikú ọmọ oun alaiṣẹ.
 aràn yó ̀ o jáde lára lẹ ́ hìn oṣù mélòó .
Igba keji ree ti Tottenham yoo lo papa iṣerẹ tuntun wọn fun ere bọọlu lẹyin ti wọn papa isẹre naa pẹlu ifẹsẹwọnsẹ idije Premier League eleyi ti wọn fi na Cystal Palace.
Àkọsílẹ̀ iye àwọn tí wọ́n tó ogun jà ninu wọn, ní ìdílé ìdílé jẹ́ ẹgbaa mẹtala (26,000).
Inú bí Usaya nítorí pé àwo turari ti wà lọ́wọ́ rẹ̀ tí ó fẹ́ fi sun turari.
Bẹẹ si ni iru ọwọ ti awọn ọmọ ogun naa ngbe tun nfa iku sii ni.
Josẹfu bẹ̀rẹ̀ sí kó oúnjẹ jọ fún ọdún meje tí oúnjẹ fi pọ̀ yanturu ní ilẹ̀ Ijipti, ó ń pa wọ́n mọ́ sinu àwọn ìlú ńláńlá.
Nígbà tí ó yá, Elimeleki kú, ó bá ku Naomi, opó rẹ̀, ati àwọn ọmọkunrin rẹ̀ mejeeji.
Isẹ ọna naa, to jẹ aworan Ọmọọba Adetutu Ademiluyi ti Ilẹ Ife, eyi ti Ben Enwonwu ya ni ọdun 1974 di ami iṣọkan orilẹẹde Naijiria lẹyin ogun abẹle Biafra.
Kí ló dé tí ẹnìkọ̀ọ̀kan wa fi gbọ́ tí wọn ń sọ èdè abínibí rẹ̀?
Oríṣun àwòrán, Getty Images Ṣugbọn awọn onwoye naa sọ pe Trump kun a ninu ibo aarẹ ọdun 2020 nitori awọn ọrọ alufansa to n sọ naa.
Ọkan lara wọn ni Saint Nicholas.
"Ọmọ ọdún mẹ́wàá ń fọn fèrè lágbo àríyá ""Ìlú mímọ́ nibí, wọn kò gbọdọ̀ bímọ, sin òkú àbí ẹran síbẹ̀"" Kloe tó lọ sí BB Naija rèé, ó ní òun fẹ́ràn ọkùnrin tó bá dúdú Lẹ́yìn ìfẹ̀yìntì ọdún márùn-ún, báágì àti bàtà ló kàn Ọbasanjọ sọ àsírí sàgbàdèwe rẹ̀ Ìyá àgbà Ọlayinka, arúgbó tó ń ṣoge bí omidan O fikun pe, se ni wọn ya oun sọtọ ninu yara kan, lai darapọ mọ ọkọ, ọmọ ati gbogbo ẹbi rẹ lapapọ."
Ẹ óo máa jẹ èso orí igi ọ̀pọ̀tọ́ yín, ẹ óo sì máa mu omi láti inú kànga yín; 
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Blind Couples: Pẹ̀lú ìpèníjà ojú, tọkọtaya bímọ mẹ́ta, tí wọn sì tún ń ṣiṣẹ́ olùkọ́ Gbajabiamila wa koro oju si iwa ta ni yoo mu mi tawọn ọlọpaa n hu, to si ni wọn ko ga ju ofin lọ lọna kọna, eyi to ba si tapa si ofin, lo yẹ ki ọbẹ ofin ba.
Lati osu kini ọdun 2017 ni alaafia ti jọba ni agbegbe Niger Delta.
Epo tí a ní kò tó fún àwa ati ẹ̀yin.
Àkọlé àwòrán, The Buccaneers have a reputation for living the good life Won mọ awon Bucaneers gẹgẹ bi àwọn to ma n gbegbe aye to dara O fi ọrọ yi to awọn alaṣẹ fasiti leti ṣugbọn awọn ẹṣọ alaabo fasiti ko ri nkankan ṣe si.
Gẹgẹ bi ohun ti Bloomberg sọ,ile iṣẹ ọtẹlẹmuyẹ FBI n ṣe iwaadi ile iṣẹ naa tori pe o tapa sofin to ni ṣe pẹlu kiko nnkan ija,International Traffic in Arms Regulations (ITAR) nitori bi o ti ṣe n lo gilasi rẹ ti nkankan ko le fọ.
Àwọn ìbejì yabo Igbó Ọrà fọ́dún ìbejì lágbàáyé ‘‘Àwọn egúngún ń mu òògún olóró ló ń jẹ́ kí wọ́n sì ìwà hù’ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Mo kẹ́kọ̀ọ́ fásitì sùgbọ́n aṣọ òké ló ń jáwó báyìí' Ọba Jamiu Adedamọla Badmus, JP, Ayelẹsọ III, Olu Aso ti Iberekodo naa ko gbẹyin ninu awọn ọba ati ijoye to darapọ mọ ọdun naa.
Babalakin ati iyaafin Nike Okundaye .
''Lọpọ igba ni awọn ọmọ wa ti yẹ ki wọn de ipo yi ṣugbọn niṣe ni wọn maa n doju ọrọ ru ti wọn yoo si yan ẹlomiran sipo.
Àkọlé àwòrán, #IRememberWhen: Kíni ẹyin rànti nínú àkna ti ẹ n ṣe tẹ́lẹ̀ Bí àwọn kan ṣe ń sọ nípa bi ìmẹẹrọ àti ìbanisọrọ̀ ṣe rí nbẹ́ẹ̀ ni àwọn míràn ń ránti àwọn àjálu to ti wáye sẹ́yìn Oríṣun àwòrán, Huw Evans picture agency Àkọlé àwòrán, #IRememberWhen: Kíni ẹyin rànti nínú àkna ti ẹ n ṣe tẹ́lẹ̀ Ṣe ẹyin naa ba wọn la eekana Gowon tyabi ẹ jẹ iru bisikii yii?
Kí ẹ lè ba kó àwọn ọmọ yín jẹ̀ pẹ́pẹ́pẹ́
Nítorí ẹ wí pé, ‘Níbo ni ilé àwọn eniyan ńlá wà;níbo sì ni àgọ́ àwọn aṣebi wà?
Nítorí Ọlọrun kò rán Ọmọ rẹ̀ wá sí ayé láti dá aráyé lẹ́bi bíkòṣe pé kí aráyé lè ti ipasẹ̀ rẹ̀ ní ìgbàlà.
Ó jẹ́ ẹni ti o ẹni tí ó mọ ọdẹ i ṣe púpọ̀, nítorí bí ó ti n fi ìbọn pa ẹran náà ni o ń fi ọwọ pa, ti ó tún n fi ẹesẹ̀ pa, nítorí ẹsẹ̀ rẹ̀ tóbi díẹ̀, o fi jọ bàbá rẹ̀, bẹ́ẹ̀ ni ọ̀rọ̀ ọkùnrin náà rí.
rogbodiyan niluu, ki won si maa mu igberu ba awon ohun ti yoo fese idagbasoke
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Àwọn agbébọn jí alága ẹgbẹ́ òsèlú PDP gbé ní Kogi 12 Ògún 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Uhuotu ṣàlàyé wí pé, títí di àsìkò tí a ń sọ̀rọ̀ yìí, kò sí eni tí ó mọ, ibi tí alága náà wọlé sí.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Osun State: Gómìnà Oyetola wọ́gilé ìrìnàjò àwọn alága sí UAE 10 Òkùdu 2019 Oríṣun àwòrán, Facebook/Adegboyega Oyetola Àkọlé àwòrán, Ọrọ lori inrinajo awọn alaga ijọba ibilẹ nipinlẹ Osun Gomina Ipinlẹ Oṣun, Adegboyega Oyetola ti wọgile irinajo si ilu okere tawọn alaga mejidinlaadọrin ipinlẹ naa n gbero lati lọ fun ijiroro.
Orúkọ àwọn ọmọ ogun Dafidi tí wọ́n jẹ́ akọni ati akikanju nìwọ̀nyí: Ekinni ni, Joṣebu-Baṣebeti, ará Takimoni, òun ni olórí ninu “Àwọn Akọni Mẹta,” ó fi ọ̀kọ̀ bá ẹgbẹrin (800) eniyan jà, ó sì pa gbogbo wọn ninu ogun kan ṣoṣo.
Nibo la ti fẹ ri bayi ti owo dọla ti dẹnu kọ ilẹ?
Ọ̀dọ̀ wa ni wọ́n ti kúrò ṣugbọn wọn kì í ṣe ara wa.
Aare Muhammadu Buhari so pe isakoso ijoba re yoo tesiwaju lati maa sagbekale eto ati ilana ti yoo foju awon olokoowo mora, bee si ni ti yoo tun sanfaani fun idagbasoke eto oro aje ati ipese ise.
Patrick Dibuah – Banana Island Ghost
Josẹfu bá fi ẹnu ko àwọn arakunrin rẹ̀ lẹ́nu lọ́kọ̀ọ̀kan, ó sì sọkún, lẹ́yìn náà ni àwọn arakunrin rẹ̀ bẹ̀rẹ̀ sí bá a sọ̀rọ̀.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Estonia pàdánù owó gọbọi látàri Eku tó gba ìjọba ní Estonia 28 Bélú 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Estonia pàdánù owó gọbọi látàri Eku tó gba ìjọba ní Estonia Orilẹ-ede Estonia lo wa ni ariwa ilẹ Yuroopu.
Lẹkki: Araalu gbanajẹ lori afikun owo ibode
Má sọ fún aládùúgbò rẹ pé,“Máa lọ ná, n óo fún ọ tí o bá pada wá lọ́la,”nígbà tí ohun tí ó fẹ́ wà lọ́dọ̀ rẹ.
Enikẹni to ba ti kan si MyMTN APP ni anfaani nla yi wa fun.
yoo gbe lo fun aare Muhammadu Buhari lati  tọwọ bọ ọ, leyin igba ti ẹka to n mojuto eto
Wọn óo dojú kọ ilẹ̀ Juda, wọn óo sì dóti ìlú Jerusalẹmu.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Kwesi Nyantakyi ti wà ní ipò alága nàá láti ọdún 2005.
Bí o bá kùnà lọ́jọ́ ìpọ́njú,a jẹ́ pé agbára rẹ kò tó.
Àwọn mààlúù tí wọ́n rù wọnyi gbé àwọn tí wọ́n sanra mì.
sọ fún àwọn eniyan Israẹli pé, bí ẹnikẹ́ni bá ṣèèṣì ṣe ọ̀kankan ninu ohun tí OLUWA pa láṣẹ pé wọn kò gbọdọ̀ ṣe, ohun tí wọn óo ṣe nìyí:
Bakan naa ni olori ile paṣẹ ki wọn fiwe pe adari ile iṣẹ LAMATA to n ṣe eto awọn ọkọ akero to fi mọ awọn miran lati wa wi tẹnu wọn naa.
“Ìwọ ọmọ eniyan, nítorí pé àwọn ará ìlú Tire ń yọ̀ sí ìṣubú ìlú Jerusalẹmu, wọ́n ń sọ wí pé ìlẹ̀kùn ibodè àwọn eniyan yìí ti já, ibodè wọn sì ti ṣí sílẹ̀ fún wa, nisinsinyii tí ó di àlàpà, a óo ní àníkún.
Ìbátan rẹ obinrin lo fi ọrọ naa sita lori Instagram, pẹlu aworan anti rẹ ninu aṣọ ileewe.
Awon agbateru ifami-eye-dani-lola fawon osere nile Adulawo AMAA ti fi oruko awon ti won seese lati gba ami eye sita fun odun 2018.
Ọpọ ni ki wọn ṣetan lati tun igbe aye awọn eniayn ipìnlẹ Eko ṣe lasiko yii ti a ti yan wọn sipo lai huwa awa ko mọ pe ebi n pa ọmọ ẹnikọọkan.
Ẹ̀sùn ìfipábánilòpọ̀: Orí Twitter ló ti bẹ̀rẹ̀, ikú ló já sí Ṣé o lè dárúkọ mẹ́ta péré nínú ẹgbẹ́ òṣèlú 91 tó wà ní Nàìjíríà?
Ó rí i wí pé láti ẹsẹ̀ nǹkan náà sí ìsàlẹ̀ jẹ́ tí ènìyàn, ọwọ́ rẹ̀ jẹ́ ti ènìyàn pẹ̀lú ṣùgbọ́n orí àti ara ìyókù jẹ́ ti àgbọ̀nrín pátápátá.
Oríṣun àwòrán, The Metropolitan Police Àkọlé àwòrán, Ẹsun ifabanilopọ lori BB Naija Khafi jẹ aṣoju ileeṣẹ ọlọpaa Met gẹgẹ bi ọlọpaa alawọdudu nilẹ Gẹeṣi .
OLUWA yóo pa Ijipti run patapata.
Ẹ wo ọ̀nà àbáyọ sí ọ̀rọ̀ àgbàlagbà tò ń tọ̀ sílé Nínú ọ̀rọ̀ rẹ̀ lẹ́yìn ti Trikytee kúrò nínú ilé, lo sàlàye pé, ìyalẹ́nu ló jẹ́ pé , òun di àsìkò yìí nínú ilé Big Brother nítori pé ọ̀sẹ̀-ọ̀sẹ̀ ni oun ti ma n múra sílẹ̀ láti lọ.
Idagbasoke to n de ba wto  Irinna  ofurufu  nile  Afirika
Olórin Reggae, Ras Kimono ti papòdà Alabi Pasuma Ọ̀gáńlá pé ẹni ọdún 51 Wo àwọn ìlérí tàwọn Gómìnà tuntun ṣe nínú ìbúra wọn K1 pa itan pe baba Barrymade gangan ni Nuru ti o jẹ aburo si Alhaji Sikiru Ayinde Barrister ti awọn si jẹ ọ̀rẹ́ tímọ́ tímọ́.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Lagos-Ibadan Express: Ènì mẹ́rin kú, mẹrin míràn farapa nínú ìjàmbá ọkọ̀ 2 Sẹ́rẹ́ 2020 Oríṣun àwòrán, TRACE Àkọlé àwòrán, Lagos-Ibadan Express: Ènìyàn mẹ́rin ti jẹ́ kú nínú ìjàmbá ọkọ̀ O kéré tán ènìyàn mẹ́rin ni wọ́n ti fi ìdí ẹ múlẹ̀ pé o ti jẹ́ Ọlọrun nípè nígbà ti àwọn mẹ́rin míràn fara pa yánayàna.
Arabinrin Obama, ti wọn ti gba ọrọ rẹ silẹ ṣaaju ki ọgbẹni Biden to kede Sẹnẹtọ Kamala Harris, gẹgẹ bi igbakeji rẹ ko ṣẹnu ku ba aarẹ Trump wi.
Ko da itan s pe wọn maa n fi koro inu rẹ tọju aisan oju ara obinrin tabi kokoro ara lawọn ilu kọọkan.
Oríṣun àwòrán, Gidi_Traffic Iwa yi jẹ eleyi to mu inu ọpọ eeyan dun ti wọn si n kan saara sawọn oluwọde naa Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, EndSARS protest in Nigeria: Mr Macaroni, Falz, Wizkid, Tiwa Savage àtàwọn míì ṣe ìwọde Taa lo sọ foonu nuu?
"Ajọ naa ti orukọ wọn n jẹ ""The Coalition on Conflict Resolution and Human Rights in Nigeria"" ninu atejade kan to jade ni Ọjọ Ajẹ, sọ wi pe ọgọọrọ lọ si ti di alairile gbe ni tori isẹlẹ naa."
21 Òkùdu 2019 Àkọlé àwòrán, Awọn oku ti wọn fi ago onirin daabo bo lọwọ igun ajoku Ikilọ: Iroyin ti ẹ fẹ ka yii ni agbara pupọ, aworan ibẹ si lee ma wu oju ri.
Ṣugbọn OLUWA ṣàánú fún wọn, ó sì yipada sí wọn nítorí majẹmu rẹ̀ pẹlu Abrahamu, ati Isaaki ati Jakọbu; kò sì gbàgbé àwọn eniyan rẹ̀.
Ẹ ṣe bẹ́ẹ̀ kí ẹ fi dán mi wò, bí n kò bá ní ṣí fèrèsé ọ̀run sílẹ̀, kí n sì tú ibukun jáde fun yín lọpọlọpọ, tóbẹ́ẹ̀ tí kò ní sí ààyè tó láti gbà á.
Aare wa dahun si ibere oba Ofem Ubana ti o ro ijoba apapo lati seranwo wa ojutu si rogbodiyan, wahala ti o n sele larin awon agbegbe kankan bi Nko, Nyima, Oyadama, Edibe, Usumtong, Adadama ati Ekureku nipinle naa.
Ko si naira kan ti ẹnikẹni san fun un gẹgẹ bii minisita oun ko si gba kọngilaa iṣẹ akanṣe kankan fun ajọ NDDC.
Gẹgẹ bi ohun to sọ, o ni awọn janduku ri iṣẹ ṣe daada lọjọ naa ti wọn si dun koko mọ awọn oludibo kaakiri awọn agọ idibo.
Bẹrẹ lati ọjọ kẹtadinlọgbọn oṣu Kẹwa ni anfani yi yoo fi ṣi silẹ fawọn onileeṣẹ kekeeke ati alabọde(Meduim Small and Micro Entrepreneurs (MSME) to to ẹgbẹrun lọna ojilenigba le mewaa (250,000).
OLUWA sì fọ́ wọn lójú gẹ́gẹ́ bí adura Eliṣa.
fun ipo ni ipinle Zamfara sile.
Electoral Commission ,Inec) ti n fun awon igbimo asofin ati asoju tuntun lorile
Ṣugbọn ìwọ ni mo gbójúlé, OLUWA, Ọlọrun.
com/yoruba/afrika-47703184 Sẹ́gílọlá: Arúgbó awẹ́lẹ́wà tó ń ṣiṣẹ́ omidan Àkọlé àwòrán, Sẹ́gílọlá: Arúgbó awẹ́lẹ́wà tó ń ṣiṣẹ́ omidan Sẹgilọla, jẹ iya agba ti ọjọ ori rẹ ti le ni aadọrin.
Bí ẹ bá wí pé, “Bẹ́ẹ̀ kọ́,” kí ó jẹ́ “Bẹ́ẹ̀ kọ́.
O ti ṣe olóòótọ́ ninu nǹkan kékeré, n óo fi ọ́ ṣe alámòójútó nǹkan pupọ.
Fayose: Abẹwo Buhari kii ṣe lati kẹdun Ewẹ Gomina Ayodele Fayose ti bu ẹnu atẹ lu igbesẹ Aarẹ Buhari lati ṣe abẹwo si ipinlẹ Taraba.
"O kọ sabẹ awọn aworan naa to fi sita lori ayelujara Instagram rẹ pe ""Adedimeji Lateef, mi o nilo alujanna, nitori pe mo ṣawari rẹ."
Awọn eniyan ilẹ Amẹrika, ni Trump maa n mu ootọ diẹ ati irọ diẹ papọ, to ba n sọrọ lori Covid19.
Lojo-Aiku, gomina Akinwunmi Ambode ti ipinle Eko so pe, apapo awon agbaagba ti won ni iriri ati imo nipa eto oselu ati akotun ogbon ori awon odo se pataki, lati ni aseyori ninu eto isejoba ati idagbasoke to fese mule lorile-ede Naijiria.
Gbogbo àwọn ìjọ ni yóo wá mọ̀ pé Èmi ni Èmi máa ń wádìí ọkàn ati èrò ẹ̀dá, n óo sì fi èrè fún olukuluku yín gẹ́gẹ́ bí iṣẹ́ rẹ̀.
Ile itaja naa to wa lati orilẹede South Africa ṣi ṣọọbu rẹ akọkọ si ipinlẹ Eko lọdun 2005, lati ọdun naa lo si ti n gbilẹ sii ni Naijiria.
A kò ní gbọ́ igbe ẹkún ninu rẹ̀ mọ́,ẹnikẹ́ni kò sì ní sọkún tẹ̀dùntẹ̀dùn ninu rẹ̀ mọ́.
“Ẹ wo bí àwọn akikanju tí ń ṣubú,tí àwọn ohun ìjà ogun sì ń ṣègbé!
Ijoba Naijiria ti ki Mo Abudu, Chiamanda Adichie ati Omotola Jalade-Ekeinde, ti won gbami eye agbaye gege bi omo Naijiria rere ku oriire.
5C, 6 àti 6S náà yóò nílò ìgbélárugẹ láti le jẹ́ ki WhatsApp máa ṣiṣẹ́ lórí iphone.
Níbi ètò àgbéléwò AY Open Comedy Mic lọ́dún 2016 ni àṣeyọrí rẹ̀ ti bẹ̀rẹ̀ látìgbà náà ni wọ́n sì ti mọ̀ ọ́ ní mọ̀lúmọ̀ọ́ká apanilẹ́rìín lórílẹ̀èdè Nàìjíríà.
Ohun tí Tatenai ati Ṣetari Bosenai ati àwọn ẹlẹgbẹ́ wọn kọ sinu ìwé sí Dariusi ọba nìyí:
Kábíyèsí, mo fẹ́ kí ẹ mọ̀ láti òní lọ pé kìí ṣe ẹni tí ó bá fẹ́ ìyá ẹni nìkan ni bàbá ẹni, kìí ẹni í ó bá sì jẹ́ ìyàwó bàbá ẹni nìkan níí jẹ́ ìyá, baba ẹni lè jẹ́ ọ̀kan, ìyá ẹni lè jẹ́ ọ̀kan, bàbá ẹni lè jẹ́ méjì, ìyá ẹni sì lè jẹ́ méjì, wọ́n lè ju méjì lọ pẹ̀lú bẹ́ẹ̀ ni a kò ṣàì rí elòmíràn nínú òde ayé tí bàbá rẹ̀ kú ṣùgbọ́n síbẹ̀ tí ó dúró bí aláìní baba, nítorí wí pé, ìbáà ṣe ará ìlà oòrùn, ìbáà ṣe ará ìwọ̀ oòrùn, ẹni tí ó bá fẹ́ràn ẹni ni bàbá ẹni.
FERE OZAKO AMAA 2018 fun ere onise kekere
EFCC: Pàṣípáàrọ̀ owó ni Mompha fi ń bojú láti ṣe gbájúẹ̀ àti 419
"Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ijamba Italy: Awọn arinrinajo fori sọta ni Macerata 12 Èrèlè 2018 Oríṣun àwòrán, EPA Àkọlé àwòrán, Won furasi Luca Traini pe o se eniyan mẹfa lọṣẹ Jennifer Otioto, ọmọ ọdun mọkandinlọgbọn sọrọ lati ile iwosan rẹ wipe ""Mo ṣẹṣẹ de si orilẹede Italy ni"" Ni owurọ ọjọ kẹta osu keji, Otioto duro ni ibudokọ akero ni ilu Macerata."
Ikede Trump yii ni ikede oludari ipolongo to ya julo to ti sele nile Amerika.
"Gẹgẹbii ara igbesẹ to n lọ lọwọ lati tubọ mu ilọsiwaju ba isọkan laarin ẹgbẹ oselu All Progressive party, APC, Aarẹ Buhari ti yan Asiwaju Bola Ahmed Tinubu lati dari awọn eto ijiroro, ifinukonu ati dida igbẹkẹle awọn ọmọ ẹgbẹ naa pada.
Oríṣi ẹbu ìwé ìdánwò ìṣìrò mẹ́ta ló dọ́wọ́ wa, àmọ́ wọn fi ń lu jìbìtì ni - WAEC Ayederu ni iwe idanwo iṣiro WAEC, Mathematics to lu ori ayelujara pa ṣaaju akoko idanwo ọhun lọjọ Aje ọjọ kẹtadinlogun oṣu kẹjọ ọdun yii.
ẹyẹ ti AFCON to n lọ lọwọ- lọwọ bayii.
Agbẹnusọ ileeṣẹ elepo Shell ninu atẹjade kan sọ pe ''Ileeṣẹ Shell kabamọ lati fidirẹmulẹ pe ikọlu waye si awọn oṣiṣẹ rẹ ati awn alaabo ijọba ni Rumuji, loju ọna East/West nipinlẹ Rivers.
Ṣugbọn Peteru tún tẹnu mọ́ ọn pé, “Bí ó bá kan ọ̀ràn pé kí n bá ọ kú, sibẹ n kò ní sẹ́ ọ!
Eyi waye lasiko ti ijọba ipinlẹ Katsina n sọ pe awọn janduku lo ji awọn akẹkọọ ileewe girama Dankara Science Secondary School naa gbe ati pe ijiroro ti n lọ laarin ijọba atawọn janduku naa lori ohun ti wọn fẹ fun itusilẹ awọn ọmọ naa.
Ẹni meji tabi mẹta ni kí ó ṣe ìsọtẹ́lẹ̀, kí àwọn yòókù máa fi òye bá ohun tí wọn ń sọ lọ.
Àwọn òṣìṣẹ́ iléeṣẹ́ NDLEA fi tóònù meji oògùn ikọ́ olómi Codeine ti Bioraj Biolin pharmaceuticals ti wọn gbẹ́sẹ̀lé hàn wá pẹ̀lú ohun eelò ìjà olóró bii ọ̀bẹ, àdá, àkọ̀ àti bẹ́ẹ̀ bẹ́ẹ̀ lọ.
“Bí àwọn olè bá wá bá ọ lóru,tí àwọn ọlọ́ṣà bá wá ká ọ mọ́lé lọ́gànjọ́,ṣé wọn kò ní hàn ọ́ léèmọ̀?
Ọlọrun yóo san ẹ̀san fún olukuluku gẹ́gẹ́ bí iṣẹ́ rẹ̀; 
Aroke ti ile ẹjọ ti dajọ ẹwọn ọdun mejila fun ni ajọ EFCC sọ pe o tun n da ọran mọ ọran ninu ọgba ẹwọn ti wọn fi si.
O lee ṣeese ni ilu wọn lọhun ṣugbọn to ba gbe e lọ si ile aṣofin yoo nira diẹ.
Àwọn iranṣẹ ọba dá a lóhùn pé, “Hamani wà níbẹ̀ tí ó ń duro ní àgbàlá.
Ó ní, “Ẹ ronupiwada, nítorí ìjọba Ọlọrun fẹ́rẹ̀ dé.
Gbigba abẹrẹ ajẹsara ko ni jẹ tipatipa Ọpọ ahesọ ọrọ lo ti n lọ lori itakun agbaye pe ijọba yoo fi tipa tikuku mu awọn eeyan gba abẹrẹ ajẹsara Coronavirus, ṣugbọn agbẹnusọ awọn aṣofin ọhun ni ọrọ ko ri bẹ.
Ẹ̀sùn ìfipábánilòpọ̀: Orí Twitter ló ti bẹ̀rẹ̀, ikú ló já sí Aishat Lola mu pako-pako gba 'bẹ̀ kú - Ọlọ́pàá ‘Emefiele kò jí owó o, ọ̀nà àbáyọ ló ń wa - CBN Iye maaki ti eniyan ni kọ ni yoo ṣe atọna iru orire ti yoo ṣe laye Ninu ifọrọwanilẹnuwo pẹlu BBC Yoruba, onimọ naa ni iwa ki awọn obi ma fi ọmọ we ọmọ tabi maa fi awọn ọmọ ṣe yẹyẹ lori ijakulẹ idanwo ma n mu ki iru awọn ọmọ bẹẹ ba ọkan jẹ.
Fọ́nran tó jẹyọ lójú òpó twitter ẹgbẹ́ òṣèlú PDP ni gómínà tí sọ pé O ní ni ìpínlẹ̀ Edo àti jákèjádò orílẹ̀ -èdè Naijiria ní òún ti dí ọmọ ẹgbẹ́ náà"" Osagie fi kun pé Gómìnà ń pinu láti dupò gómìnà lábẹ́ àsìá ẹgbẹ́ òṣèlú PDP."
Nítorí náà, ẹ gbọ́ ohun tí OLUWA wí, gbogbo ẹ̀yin ará Juda tí ẹ̀ ń gbé ilẹ̀ Ijipti: Ó ní, ‘Ẹ wò ó, mo ti fi orúkọ ńlá mi búra pé àwọn ará Juda tí wọ́n wà ní Ijipti kò ní fi orúkọ mi búra mọ́ pé “Bí OLUWA ti wà láàyè.
Òmìrán kan wà níbẹ̀ tí ó fẹ́ràn ogun jíjà pupọ, ìka mẹfa mẹfa ni ó ní ní ọwọ́ kọ̀ọ̀kan, ati ẹsẹ̀ kọ̀ọ̀kan; ìka ọwọ́ ati ti ẹsẹ̀ rẹ̀ jẹ́ mẹrinlelogun.
Oríṣun àwòrán, Ajimobi Lives on Àkọlé àwòrán, Deede ago mejila ọsan ni wọn yoo ṣe adura idagbere fun un ni Mọṣaaṣi.
alafẹsẹgba ,African Cup of Nations (AFCON 2019), ti yoo waye ni orile Egypt
“Nítorí Oluwa ni ó ni ayé ati gbogbo nǹkan tí ó wà ninu rẹ̀.
Ọjọ́ pẹ́, tí Israẹli ti wà láìní Ọlọrun òtítọ́, wọn kò ní alufaa tí ń kọ́ ni, wọn kò sì ní òfin.
Èèyàn 290 míràn ló ṣẹ̀ṣẹ̀ fara káásá àrùn Covid-19 ní Nàìjíríà, 160 gbàwòsàn Wọ́n ti sún ọjọ́ ìjà Mike Tyson pẹ̀lú Roy Jones Jr síwájú Asojú ìjọba orílẹ̀-èdè Lebanon ti kọ̀wé fipò silẹ̀ nítorí ìbágbàmù tó gbẹ̀mi ènìyàn 200 Olùrànlọ́wọ́ pàtàkì fún ọ̀rọ̀ ibojì òkú, àti àwọn ipò òṣèlú mìíràn tó jẹ́ kàyééfì ní Nàìjíríà Diezani gan an ní Hushmummy tó ń bú àwọn Yahoo boys- Àwọn Ọmọ Naijiria lórí Twitter Ogagun Chukwuemeka Okonkwo ṣalaye pe awọn iroyin ọlọgbọ́n ti awọn ri gba lo jẹ ki wọn ri awọn apaayan mu.
Mo kọ ọ́ sinu ìwé, mo fi òǹtẹ̀ tẹ̀ ẹ́, mo pe àwọn eniyan láti ṣe ẹlẹ́rìí; mo sì fi òṣùnwọ̀n wọn fadaka náà.
OLUWA sọ fún Mose ati Aaroni pé: 
Awon ti won kopa ninu idije itowo ati ina dida ni ile ounje taile itura bii Relais Cafe Restaurants and Catering Services, Zuma Grill ni Transcorp Hilton, Helene’s Food Co ati Le Petit Square, ni Grand Square restaurants.
Eleasari alufaa, Joṣua, ọmọ Nuni, ati àwọn olórí láti inú ìdílé kọ̀ọ̀kan ninu ẹ̀yà àwọn ọmọ Israẹli ni wọ́n ṣe ètò pípín ilẹ̀ náà.
N kò ní fi pamọ́ fún un, nítorí pé mo ti yàn án, kí ó lè pàṣẹ fún àwọn ọmọ rẹ̀, ati gbogbo ará ilé rẹ̀, láti máa pa ìlànà èmi OLUWA mọ́, ati kí wọ́n sì jẹ́ olódodo ati olóòótọ́, kí èmi OLUWA lè mú ìlérí mi ṣẹ fún Abrahamu.
"Ni kete ti Toyin Abram bimọ tan naa ni ọrọ yọju lorii ""maa ki ọ, mi o ni ki ọ ku ewu ọmọ"" to tẹnu Lizzy jade lẹyin eyi si ni ọpọlọpọ ọrọ wiwu sita, titọwọ agbẹjoro bọ ọ ati bẹẹ bẹẹ lọ ti wọ ọ."
Nítorí pé o mọ èmi iranṣẹ rẹ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ààwẹ Ramandan: Àwọn ouńjẹ tí a fi ń sínu àwẹ̀ 15 Èbibi 2018 Àkọlé àwòrán, Àwẹ Ramandan ń bẹ̀rẹ̀, irú ouńjẹ wo la lè jẹ?
Gbogbo ẹ si waye laarin oṣu kan.
Àkọlé àwòrán, Ajọyọ yii ko yọ awọn ara orilede Egypt ti wọn jẹ ọrẹ awọn ọmọ Naijiria to wa lọhun.
Kí gbogbo àwọn àgbààgbà tí wọ́n wà ní ìlú náà wẹ ọwọ́ wọn sórí mààlúù tí wọ́n ti lọ́ lọ́rùn pa yìí.
Amọ, awọn ọlọpaa sọ wipe awọn alatilẹyin Dino Melaye se ikọlu si ọkọ awọn ọlọpaa to n gbe Dino lọ, ti wọn si fayegba sẹnatọ naa lati fo bọọlẹ kuro ninu ọkọ awọn ọlọpaa.
Wayi o, ileesẹ ọlọpa nipinlẹ Kwara ti salaye lori ikọlu tawọn agbebọn kan se si osere ori itage obinrin, Toyosi Adesanya Ileyemi.
Samsoni ati Ọmọbinrin Kan, Ará Timna.
Ṣugbọn ninu àwọn ẹran tí wọn ń jẹ àpọ̀jẹ ati àwọn tí pátákò ẹsẹ̀ wọn là sí meji tabi tí wọ́n ní ìka ẹsẹ̀, àwọn wọnyi ni ẹ kò gbọdọ̀ jẹ: ràkúnmí, ati ehoro ati ẹranko kan tí ó dàbí gara.
Lọjọ Abamẹta ni Fasola paṣẹ pe ki wọn kuro lopopona yii nibi ipade itagbangba to waye nilu Ogere ti o jẹ aarin gbungbunmarosẹ Eko si Ibadan.
Abọ wa niyi, Ẹ gbe e yẹwo.
Òtítọ́ ni, ó ṣàìsàn, ó tilẹ̀ fẹ́rẹ̀ kú!
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Blood Donor Day: Láìsí ẹ̀jẹ̀ kò sí ẹ̀mí Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Blood Donor Day: Láìsí ẹ̀jẹ̀ kò sí ẹ̀mí 15 Òkùdu 2019 O dára láti máa fi ẹjẹ silẹ fún ilera ara rẹ - Idowu Opọlọpọ eniyan ni wọn ko ni oye to kun to lori pataki fifi ẹjẹ silẹ.
Àṣé Ayédèrú-ẹ̀dá ti wí fún àbúrò ìyàwó mi pé kí ó ró aṣọ ìyàwó mi, kí o wwé gèlè rẹ̀, kí o sì mú ìbòrùn rẹ̀ lálẹ́ ọjọ́ tí à ń wí yìí kí o wá pàdé òun, nítorí òun tilẹ̀ fẹ́ wò bí olùfẹ́ òun ti dára tó nínú aṣọ ẹ̀gbọ́n rẹ̀!
fun ipinlẹ Gombe ti fihan pe egbe , All Progressives Congress (APC) lo tun jawe
Oríṣun àwòrán, @Emefiele Ṣugbọn Banki apapọ Naijiria, CBN, ti sọ fun ile ẹjọ giga ijọba apapọ nipinlẹ Eko pe, owo gọbọi ni yoo na orilẹ-ede Naijiria lati tẹ owo tuntun jade.
Coronavirus in Nigeria: Àjọ NBS ní covid-19 ló fa ọ̀wọ́ngógó oúnjẹ ní ìpínlẹ̀ Eko, Kano, Rivers àti Abuja
Ní ọ̀pọ ìgbà, ó má ń hu àwọn ìwà yìí lábẹ̀ àsía pé òun fẹ́ wẹ ìwẹ̀ mímọ fún wọ́n (Holy Birth).
Lẹyin ọjọ mejila ti wọn gbe de lo ku si ile iwosan.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Alaafin: Olori Aanu Adeyemi ṣàlàyé ìdí tó ṣe gẹ́ Oba Lamidi Adeyemi ti ìlú Oyo Kini o wa n ṣẹlẹ bayii ni fasiti Eko UNILAG?
O tun tenumo pe, nipa sise iroyin to nise pelu ilera ati
Jesu dá wọn lóhùn pé, “Àkókò tí ó wọ̀ fún mi kò ì tíì tó, ìgbà gbogbo ni ó wọ̀ fún ẹ̀yin.
Iṣẹ́ bọ́ lọ́wọ́ ọlọ́pàá ọ̀mùtí ní ìlú Eko Wọ́n lu àbúrò mi ló jẹ́ kí ń fi ìbínú lu òǹtàjà l‘Abuja - Sẹ́nétọ̀ tó lu obìnrin ṣàlàyé Ninu atẹjade kan eyi ti ọkan ninu awọn agbẹnusọ rẹ, Reno Omokri, fi sita, Aarẹ Goodluck Jonathan ni ko si igba kan ti iṣejọba oun ya biliọnu mẹwaa naira (N10 billion) sọtọ fun idasilẹ itẹdo darandaran RUGA.
Lanre Kuti ni mo fẹ́ - Jaiye Kuti Darandaran Fúlàní kankan kò ṣí kúrò l'Ọ́ṣun - olórí Fulani Eji Gbadero, ọmọ Ibadan àti jayé-jayé ọmọ ónílẹ̀ ti wọn yẹgi fun l'Eko Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí 2 sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
" orílẹ̀èdè Germany ló ti ṣẹ̀ wá Orúkọ núdùlù (Noodle) ìpilẹ̀ṣẹ̀ rẹ̀ jẹ́ ti German Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Spell it out Sevaiyan, macarrao, onye onyoghonyo, erişte, mi, vermicelli, fideu, soba, spaghetti, arishta, tambi, udon, nouille, mian tiao.
Oga olopaa agbegba naa, Pearl Pasor ni kii se awon agbesunmomi lo jii bikose oloko ofurufu omo odun mokandinlogbon kan ti won gba pe o seese ko ma si wa laaye.
Siasia lè gba iṣẹ́ akọ́nimọ̀ọ́gbá égbẹ́ agbábọ́ọ̀lù Cameroon
Lanre Kuti ni mo fẹ́ - Jaiye Kuti Abala kẹrin aba naa lo sọ pe ẹnikẹni to ba jẹbi ẹsun ikorira yoo lọ sẹwọn gbere, bakan naa iru ẹni bẹẹ tun le gba idajọ iku ti ọrọ ikorira to ba sọ ṣokunfa iku ẹlomiran.
m ni ojú mi déédé fọ́ níbi tí mo ti ń darí ọkọ̀ ni Ọrẹgun Ikẹja -LASTMA Yesufa Lasiko abẹwo BBC sibi idanilẹkọ awọn ọdọ to n se kẹkẹ alajọwa naa, a ri ti wọn n fi kẹkẹ rin lori igo ti wọn to silẹ, eyi to wu ni lori.
Asofin  Mumin Jibrin (APC-Kano),ti o jẹ oludari eto
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Bí pínpín owó ilù ṣe díjà sílẹ̀ láàrin àwa ìjòyè àti Oluwo rèé - Osa Iwo Kí ló mú kí ọkọ̀ kan tó jóná ráùráú lórí afárá Ojuelegba?
Amọ ko pẹ ti mo fi kabamọ ero mi yii, nitori ko pẹ pups ti ounjẹ inu agolo naa fi mu ki ahọn ọmọ mi funfun, to si n run eyi to mu ki n maa ro pe ounjẹ ti ko peye ni mo n fun ọmọ mi mu, dipo omi ọyan iya rẹ to ladun Ìpanu ‘Cheese ball’ ni wọ́n fi jí Ikimot gbé, àmọ́ ó padà sílé lẹ́yìn ọdún márùn-ún ìfipábánilòpọ̀: Má dákẹ́ - Oluwaseun Wọ́n ta ère Ọ̀ṣun Osogbo sí Togo - Bàbá Ọṣun figbe ta Gbogbo igba ti mo ba si ranti eyi ni mo maa n da ara mi lẹbi, ti ẹbi naa kii si tete lọ, o si seese ki eyi maa se ọpọ iyalsmọ nitorei obi to ba mọ isẹ rẹ nisẹ yoo da ara rẹ lẹbi lọpọigba nitori itọju ọmọ.
Adamu ni ki awọn ọlọpaa naa tẹramọṣẹ, ki wọn si huwa to dara fun awọn araalu, amọ ki wọn koju oro si ẹnikẹni to ba kọju ina si wọn.
Ìrẹsì jọ̀lọ́ọ̀fù Ghana la jọ̀lọ́ọ̀fù Nàìjíríà mọ́lẹ̀ nínú ìdíje Àwọn olówó Naijiria 5 tí owó wọn ju owó ìsúnná Naijiria lọ!
Ijọba orilẹ ede  Naijiria yoo satilẹyin fun ifilọlẹ baalu ti orilẹ ede  Naijiria , ni eyi ti ile-ise ijọba ati alaadaani yoo maa sakoso rẹ.
AWCON: Ṣé Falcons yọò tẹ̀síwájú tàbí tẹ̀lé Ghana jáde ní ìdíje AWCON?
Ìró wọn dàbí híhó omi òkun,bí wọ́n ti ń gun ẹṣin bọ̀.
ati ní gẹ̀rẹ́gẹ̀rẹ́ àwọn àfonífojì náàtí ó lọ títí dé ìlú Ari,tí ó lọ dé ààlà Moabu.
Àkọlé àwòrán, Àwọn ọmọ Naijiria fèsì sí gbèǹdéke owó osú tí Ààrẹ buwọ́lù Abubakar Musa nigba to n fesi si igbesẹ naa rọ awọn ọmọ Naijiria lati ri wi pe wọn fọwọsowọpọ pẹlu Aarẹ Buhari lati mu idagbasoke ba orilẹede Naijria.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù #EndSARS: Lẹ́yin àṣẹ́ adelé Ààrẹ Osinbajo, ọgá ọlọ́pàá yan orúkọ tuntun fun SARS 22 Agẹmo 2018 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 15 Ògún 2018 Oríṣun àwòrán, @NG_Police Àkọlé àwòrán, Idris ko ba awọn oniroyin s'ọrọ lẹyin ipade rẹ pẹlu aarẹ Ọga agba ileeṣẹ ọlọpàá Ibrahim Idris ti kede ayipada orukọ, SARS, lẹyin ti adele Ààrẹ orílè-èdè Naijiria,Yemi Osinbajo pàṣẹ ko ṣe àtúnto ẹka naa.
“Nígbà tí mààlúù, aguntan, tabi ewúrẹ́ bá bímọ, ẹ fi ọmọ náà sílẹ̀ pẹlu rẹ̀ fún ọjọ́ meje, láti ọjọ́ kẹjọ lọ ni ó tó lè jẹ́ ìtẹ́wọ́gbà fún ẹbọ sísun sí OLUWA.
Àwọn nǹkan tí wọn mú wá jẹ́ aadọrin akọ mààlúù, ọgọrun-un (100) àgbò, igba (200) ọ̀dọ́ aguntan, gbogbo rẹ̀ wà fún ẹbọ sísun sí OLUWA.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fọ́nrán ohùn, Bí Sanwo-Olu bá fún Super Eagles lówó ńkọ̀?
Ní apá ọ̀tún ọ̀nà nlá yìí ni ibi tí àwọn òṣìṣẹ́ ìjọba ti nfọ́ òkúta nlánlá lára apáta.
JAMB f'ọjọ kun asiko iforukosilẹ Ikọ oluyẹwe owo wo niroyin gbe wipe wọn ran lọ si awọn ọọfisi ajọ naa to n bẹ lawọn ipinlẹ lati lọ ṣe akọsilẹ bi wọn ṣe ta kaadi naa si, ati lati gba owo ti wọn pa.
Nígbà tí ó di ọjọ́ keji, àwọn eniyan náà dìde ní òwúrọ̀ kutukutu, wọ́n tẹ́ pẹpẹ kan, wọ́n sì rú ẹbọ sísun ati ẹbọ alaafia níbẹ̀.
bu cctld ko je lilo ri rara rara .
’ ”Elija sì ṣe gẹ́gẹ́ bí OLUWA ti pàṣẹ fún un.
Ọpọlọpọ àwọn ọlọ́rọ̀ ń dá owó pupọ sinu àpótí owó.
Ọmọ ọdún mẹ́rìnlá kàwé gboyè jáde ni Oxford Bakan naa ni ko ṣai kẹdun pẹlu Ijọ Aguda lapapọ lori iku ojiṣẹ Olọrun naa ti awọn aṣebi dẹmi rẹ legbodo lai ro tẹlẹ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìjọba ìpínlẹ̀ Ondo pàṣẹ fún àwọ̀n agbófinró láti mú àwọn fijilanté fulani l'Ondo 23 Agẹmo 2019 Oríṣun àwòrán, others Ṣe ẹyin ti gbọ nipa fijilante fulani?
Nígbà tí ó tún jáde lọ ní ọjọ́ keji, ó rí i tí àwọn Heberu meji ń jà; ó bá bi ẹni tí ó jẹ̀bi pé, “Kí ló dé tí o fi ń lu ẹnìkejì rẹ?
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù 9th Assembly: Aráàlú ní àwọn ń fẹ́ ìpèsè àwọn ohun èèlò amáyédẹrùn Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ 9th Assembly: Aráàlú ní àwọn ń fẹ́ ìpèsè àwọn ohun èèlò amáyédẹrùn 11 Òkùdu 2019 BBC Yoruba bọ sigboro lati mọ ero araalu nipa awọn asaaju ile asofin apapọ tuntun to bori ibo lati dari ile.
Ní Dhaka, ilé àjogúnbá ọlọ́gọ́rùn-ún ọdún kan di àdàwólulẹ̀ pátá ní alẹ́ ọjọ́ Ìtunu Àwẹ̀ 5, oṣù Òkúdù 2019.
Nígbà tí Dafidi gbọ́, ó rán Joabu ati gbogbo àwọn ọmọ ogun rẹ̀, láti lọ gbógun tì wọ́n.
Gomina tun so pe “orisirisi itan lo wa  nipa itan awon eniyan nitori pe ko si akosile fun won, awon ọdọ ode -oni ,ni won ko mo nipa itan orisun won.
Igbimọ ajọ iṣọkan agbaye to n ri si ọrọ awọn aṣatipo, UNHCR lo fidi ọrọ naa mulẹ.
Ẹ máa kọrin sí Ọlọrun pẹlu ọpẹ́ ninu ọkàn yín.
Ile ẹjọ wa ni pe Ajimọbi ko ni aṣẹ lati sọ wi pe Balogun ko tọna lati dije labẹ aṣia ẹgbẹ oṣelu PDP.
Olympics ni ọkàn mi wà gẹ́gẹ́ bí òmùwẹ̀
Nítorí náà ọwọ́ gbogbo eniyan yóo rọ,ọkàn gbogbo eniyan yóo rẹ̀wẹ̀sì;
Ìrí tí morí, ṣé mo rí atare, Ẹskẹkẹnkẹ
 iṣẹ ́ àgbẹ ̀ tó jẹ ́ pàtàkì iṣẹ ́ àwọn yorùbá ló rí àwọn oríṣìíríṣìí iṣẹ ́ mìíràn .
'Àwa ọmọ Nàìjíríà tó farapa fẹ́ wálé láti Lebanon, ìjọba kó wa pamọ́' Bamiloye ni ''iwọ to sọ pe o n jo lati yin Ọlọrun ni ti o si mọ pe fun ra rẹ pe irọ lo n pa.
Ilésanmí ni ó kọrin pé, ‘Iyán lóunjẹ.
O ni aifararọ eto aabo ti Amosun ba nilẹ lasiko to tẹwọgba ọpa asẹ lati tukọ ipinlẹ Ogun losu Karun un, ọdun 2011, lo fa sababi bo se ra awọn ohun ija oloro naa.
Ohun ti a fẹ lati ọdọ araalu ni pe ki wọn maa ta wa lolobo, gbadura fun wa, ki wọn si mu suuru diẹ fun wa, ao ṣiṣẹ naa bi iṣẹ A ko mọ boya awọn ajinigbe ti kan si awọn mọlẹbi awọn ti wọn ji gbe, nitori ileeṣẹ ọlọpa kii lọwọ si.
O di dandan ki n pariwo sita ni nitori ẹmi mi ko de mọ."
Fún ìyọsọ́tọ̀ tí wọ́n yọ òun nìkan láti yẹ ara rẹ̀ wò ní ilé ìtajà ìgbàlódé kan ní Serbia, gbajúgbajà ìràwọ̀ òṣèré orí-ìtàgé Roma fi ẹ̀sùn ìwà elẹ́yàmẹyà kan ilé ìtajà náà
" Ìpànìyàn Akinyele: Ìgbọ̀nsẹ̀ ni Mujeed lọ ṣe l'Akinyele, ni wọ́n bá ṣáa ní àdá pa Oríṣun àwòrán, others Ọrọ gbogbo kii fẹ si lẹyin ikeemu agbegbe Akinyẹle bayii ni ipinlẹ Ọyọ paapaa julọ to ba n di ọrọ ka da ẹmi ẹni legbodo.
Benhesedi ní Aruboti ni alákòóso fún ìlú Aruboti, ati Soko, ati gbogbo agbègbè Heferi.
Ṣugbọn bí ẹnìkan bá sọ fun yín pé, “A ti fi oúnjẹ yìí ṣe ìrúbọ,” ẹ má jẹ ẹ́, nítorí ẹni tí ó sọ bẹ́ẹ̀ ati nítorí ẹ̀rí-ọkàn.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Wole Soyinka gege bi oluko fasiti Ibadan nigba to kere diẹ ni aye 60's Ninu awọn to buru ninu wọn ni ẹgbẹ Alaake dudu, Black Axe.
Kíló pilẹ̀ ìgbésẹ̀ wíwó ilé nàá?
Gbogbo ìlú ti di ahoro,wọ́n ti wó ẹnu ibodè ìlú wómúwómú.
Nítorí náà, Saulu fa idà rẹ̀ yọ, ó ṣubú lé e lórí, ó sì kú.
won n wa epo yii ni agbegbe ati awujo  won.
Baba mi, wo etí aṣọ rẹ tí mo mú lọ́wọ́ yìí, ǹ bá pa ọ́ bí mo bá fẹ́, ṣugbọn kàkà bẹ́ẹ̀, mo gé etí aṣọ rẹ.
O wa fi nọmba ipe pajawiri 615 sita pe ki ẹnikẹni tawọn eeyan tabi ẹgbẹ ba n da iṣẹ aje rẹ laamu pe fun iranwọ ni kiakia.
Johanu ni a óo máa pè é.
Alaafin si tun kọ lẹta miran ni ọjọ kẹrinla osu keji ọdun 2020 lati dupẹ lọwọ ijọba, ni pe o seun lori bibuwọlu agbekalẹ Ileesẹ ọlọpaa naa.
Lati 2007, o ti dupo to si wọle lẹẹmẹta ọtọọtọ.
'Ọpọlọpọ ohun ija awọn ajoji wọnyii ni a ti gba, to fi mọ olonde, majele ati oogun abẹnugọngo ti wọn ko wọ ilẹ Yoruba.
Orilẹede South Africa lo moke julọ laarin awọn orilẹede to wa lati ilẹ Afrika nibi idije naa pẹlu ami goolu mẹtala ti Naijiria si ṣe ipo keji.
” Ọkunrin náà bá mu irin àáké náà.
Ẹkunrẹrẹ iroyin yii n bọ lọna.
Nítorí pé bí gbogbo ọ̀run ti tóbi tó, kò gbà ọ́; kí á má ṣẹ̀ṣẹ̀ sọ ti ilé ìsìn tí mo kọ́ fún ọ?
Victor Obanor sọ pe oun wa ni nkan bi kilomita meji si ibi ti iṣelẹ naa ti ṣẹ, ṣugbọn iro ibugbamu naa milẹ titi.
Mose gba ọ̀rọ̀ tí baba iyawo rẹ̀ sọ, ó sì ṣe gẹ́gẹ́ bí ìmọ̀ràn tí ó fún un.
pe ile Afirika n wo orile ede Naijiria gege bi asiwaju rere nipa idagbasoke ati
Èmi ni OLUWA tí mo sọ wọ́n di mímọ́.
 Adele aare ti pase pe ki ise bere gidi lori awon ona abawo orile-ede yii gbogbo.
Wọ́n ti kọ́ ahọ́n wọn ní irọ́ pípa;wọ́n dẹ́ṣẹ̀ títí, ó sú wọn,wọn kò sì ronú àtipàwàdà.
kí gbogbo ẹni tí ó bá gbà á gbọ́ lè ní ìyè ainipẹkun.
Àwọn ará àwọn ilú tí wọ́n wà ní ìtòsíi odò náà máa nwá si etí odò náà.
Sugbon akonimoogba omo orile-ede Germany ohun so pe, orile-ede Naijiria kun fun awon odo ti o ni ebun jankan-jankan ninu ere boolu afesegba, papaajulo ibasepo ati ifowosopo to n oun rigba lowo ajo NFF ti to fun oun lati ma fiko Super Eagles sile.
Eyi waye lẹyin ti Sẹnetọ Biodun Olujimi fariga pe Adeyẹye kọ ni ojulowo ẹni to bori idibo naa ni Ekiti, ni eyi ti ile ẹjọ ti faramọ.
Yoruba ni ooṣa ti a ko ba fidi ẹ han ọmọde kii pẹ parun ni BBC ṣe lọ ṣe iwadii nipa eegun yii, kawọn ọdọ Yoruba le mọ pe agbara ṣi wa lọwọ awọn agba Oodua.
Oloogbe Ted Mukoro, bere aye re gege bi nkowe ati osere to n gbe asa Yoruba laruge, ki o to di osere ori itage ati ori amohunmaworan.
Aisaya bá sọ fún Hesekaya, pé, “Gbọ́ ohun tí OLUWA àwọn ọmọ ogun wí: 
Nígbà tí ilẹ̀ ṣú, àwọn onigbagbọ tètè ṣe ètò láti mú Paulu ati Sila lọ sí Beria.
Dókítà Baka ní àwọn to ti le ni ọgọ́ta ọdún tabi jù bẹ́ẹ̀ lọ náà náà le gba ẹmi ara wọn, ti wọn ba ni ìṣòro.
Ìgbà yìí ṣe pàtàkì fún àwọn àgbẹ̀ nítorí àsìkò ìkórè ló jẹ́.
Iwaadi UNODC naa sọ wi pe awọn obinrin to ba pa ọkọ wọn a ti jẹ iya pupọ lọwọ awọn ọlolufẹ wọn saaju.
Bẹ́ẹ̀ ni OLUWA ṣe gba Israẹli lọ́wọ́ àwọn ará Ijipti ní ọjọ́ náà, àwọn ọmọ Israẹli sì rí i bí àwọn ará Ijipti ti kú sí etí bèbè òkun.
Ìjọba àpapọ̀ fi Austria, Sweden kún àwọn orílẹ̀èdè tí kò lè wọ Nàìjíríà Ogun ebi ni Nàìjíríà ń bá fínra lọ́wọ́, ogun coronavirus kò gbọdọ̀ kún un-Oluwo Èyí làwọn ayẹyẹ nlá tí kò ní wáyé nítorí coronavirus Sirika jẹ ọkan lara ọmo igbimọ amúṣẹsẹ lori COVID-19 nigba ti Boss Mustapha to jẹ akọwé ijoba apapọ jẹ́ alaga wọ́n.
Wọ́n ń lọ síhìn-ín, sọ́hùn-ún lórí òkè, wọ́n ń ti orí òkè kéékèèké bọ́ sí orí òkè ńláńlá; wọ́n ti gbàgbé ọ̀nà agbo wọn.
fork : n ; ( we can eat rice with a fork .
jẹ́ ẹgbaarin ó lé ẹgbẹta ó dín ogún (8,580).
Olufunke to sọ eleyii lori oju opo Facebook rẹ, sọ wi pe oun ti sọ ifẹ fun igbeyawo nu, lẹyin ti ọpọlọpọ ọrọ ifẹ oun ti forisanpọn.
    Mo fẹ́ kí ẹ wo bi ìkórìíra náà ti tó, ọba tí wọ́n ní kí ó san kọ́bọ̀ kan tí kò rí, wá sọ pé ẹni tí kò bá fọ èmi ní kùmọ̀ dáadáa nílati san kọ́bọ̀ márùn-ún owó obìnrin márùn-ún ní ìlú Èdìdàrẹ́!
2 1723242 Orilẹede Italy 60078 99.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù US presidential election 2020: Esther Agbaje, Oye Owolewa àti Nnamdi Chukwuocha jáwé olúborí nínú ìdìbò Amẹrika 2 Bélú 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 6 Bélú 2020 Oríṣun àwòrán, owolewa/Chukwuocha/Agbaje Awọn ọmọ Naijiria mẹta, to tun jẹ ọmọ ilẹ Amẹrika ti jaweolubori ninu idibo to n lọ lọwọ lorilẹ-ede ọhun.
Ẹgbẹẹgbẹrun un eeyan dudu ati alawọ funfun lo ti n ṣe iwọde papaa julọ l'Amẹrika ati ilẹ Gẹeṣi lori iku George Floyd Níbo ni Sẹ́nétọ̀ Abiola Ajimobi, gómìnà àná ní ìpínlẹ̀ Oyo wà?
Joaṣi ṣe ohun tí ó dára lójú OLUWA ní gbogbo ọjọ́ ayé Jehoiada alufaa.
Láti òní lọ, nígbà tí o bá dá oko, ilẹ̀ kò ní fi gbogbo agbára rẹ̀ so èso fún ọ mọ́, ìsáǹsá ati alárìnká ni o óo sì jẹ́ lórí ilẹ̀ ayé.
Ọdun 1950 si ọdun 1960 ni awọn alawọdudu dide lati ja fun ẹtọ wọn gẹgẹ bi i ọmọniyan.
“Àwọn ọmọ Juda ti ṣe nǹkan burúkú.
Nítorí àwọn mìíràn wà tí èèwọ̀ nípa ìbọ̀rìṣà ti mọ́ lára tóbẹ́ẹ̀ tí ó jẹ́ pé, bí wọn bá jẹ irú oúnjẹ yìí, bí ìgbà tí wọn ń bọ̀rìṣà ni.
Bí ẹni tí ó wá láti ọ̀run ti rí, bẹ́ẹ̀ ni gbogbo àwọn ti ọ̀run rí.
Àwọn ìlú tí wọ́n wà ní orí òkè nìwọ̀nyí: Ṣamiri, 
Ọ̀nà èrò tí ó wà ní ìlà oòrùn Noba ati Jogibeha ni Gideoni gbà lọ, ó lọ jálu àwọn ọmọ ogun náà láì rò tẹ́lẹ̀.
Bẹẹ ba gbagbe, o ti to ọjọ mẹta bayii ti eruku aawọ ti n waye laarin Oluwo ati awọn afọbajẹ to taku pe lilọ ni Oluwo gbọọdọ lọ fun awọn.
Ní ọjọ kan bí wọ́n se wo ìròyìn BBC Hausa tán ní wọ́n ba pè wá ni ọkọ̀ọkan àwọn míràn kúnlẹ̀ nígbà ti àwọn kan dúró, wọ́n ni ki a maa ka kùrán sita.
Ṣugbọn àwọn ará Moabu yóo di àtẹ̀mọ́lẹ̀ lórí ilẹ̀ wọ́n, bíi koríko tí a tẹ̀ mọ́lẹ̀ lórí ààtàn.
Ẹ fún ojú lóúnjẹ lórí ìdìbò Ekiti 2018 Ẹgbẹ́ awakọ̀ Ado-Ekiti yọ àwọn alaga ẹgbẹ́ tó sé ti ìjọba Fayoṣe Ìkéde yí jé òun ti o mú àriwisi otooto wà láàrin àwọn ará ìlú àti àwọn amòye.
O sọ pe iwe ẹri ko ni itumọ sii nitori wipe o ṣegbe lẹyin Aarẹ Buhari Kayode Ogundamisi loju opo tiẹ sọ pe o ṣeni laanu wipe iru ojọgbọn bi Sagay lo sọ iru ọrọ bayii lẹyin iṣẹ to ti ṣe fun itẹsiwaju eto idajọ lorilẹede Naijiria.
Alfa Babatunde ati awọn ẹmẹwa rẹ ni wọn n jẹjọ iwa ajinigbe onikoko mẹta, to fi mọ ẹsun iditẹmọni ati biba ẹri jẹ.
Àwọn ọmọ Jehoiakini, ọba tí a mú lẹ́rú lọ sí Babiloni nìwọ̀nyí: Ṣealitieli, 
La ojú rẹ, OLUWA, kí o máa wo nǹkan.
O ṣe eyi nipa awọn ọrọ kan to kọ soju opo twitter rẹ pẹlu #ENDSARS.
OLUWA bá Jeremaya sọ̀rọ̀ lẹ́yìn tí Sedekaya ọba ti bá gbogbo àwọn eniyan tí wọ́n wà ní Jerusalẹmu dá majẹmu pé kí wọn kéde ìdásílẹ̀, 
Àwọn àwòrán tó ṣé àfihàn Osinbajo lẹni tí kò mú ayé le
Àwọn ìwàásù akọnilẹ́nu hàà tí Prophet Israel Oladele CCC Genesis Global ti ṣe rèé Báàgì Ghana Must Go pàwọ̀dà, ó di ohun táwọn ránsọ ránsọ fi ń dárà orísirísi Wòlíì míì, tún wọ gàù lẹ́yìn tó tàpá sí ìlànà béèlì tí wọ́n fún un nílé ẹjọ́ Àwọn Olùkọ́ ìpínlẹ̀ Eko dárà lórí Akọ́mọlédè àti Àṣà lórí BBC Ṣe ofintoto awọn ile idaraya ati iṣeraloge Iwadii fihan pe awọn ile idaraya ati isaraloge gbọdọ wa ni imọtọtọ nipa ti tẹle ofin ijinasiraẹni.
O ni A ko le sọ pe ka ti ile ijọsin nitori Coronavirus, nitori ori bibẹ kọ ni ogun ori fifọ."
Nkechi Blessing vs Toyin Abraham: Nkechi tí tọrọ ìdáríjí ẹ̀ṣẹ̀ lọ́wọ́ akẹgbẹ́ rẹ̀, Toyin Abraham Ó ti tó àsìkò kí Nollywood fòpin sí èré ilé babaláwo lílọ - Clarion Chukwura Ọlọ́pàá, sójà yabo Lekki Toll Plaza láti dènà ìfẹ̀hónúhàn míràn Ìdí rèé táwọn àkàndá ẹ̀dá fi dí iwájú iléeṣẹ́ ìjọba ìpínlẹ̀ Oyo pa l'Agodi n'Ibadan Idi ti Odili fi gba ibi ìbálòpọ̀ lọ sí ọ̀run alákeji nílùú Port Harcourt Ti ẹrin ti ọyaya ni Victoria fi ṣalaye pe ti Ọlọrun ba ṣe ore fun eeyan, ko yẹ ki eeyan maa pa a mọ ra.
2020 International day for Rural Women, Garri Ondo: Owó tà ń ná láti ṣe Garri tà kìí ṣe kékeré
Akowe agba egbe oselu All Progressives Congress APC, ogbeni Maimala Buni so pe, aare Muhammadu ni egbe naa bowolu gege bi oludije dupo aare ninu eto idibo gbogbogbo to n bo lona lọdun 2019.
" Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, End SARS, End SWAT: Ó pé mi bí SARS kò ṣe sọ mí dolówọ́- Fulani Kwajafa Bo tilẹ jẹ pe gbogbo akitiyan lati ba awọn ti ọrọ naa ṣelẹ si ati agbẹnusọ ileesẹ ọlọpaa ipinlẹ Katsina sọrọ lo ja si pabo, awọn eeyan to n gbe ni agbegbe naa sọ pe isẹlẹ ọhun waye ni nnkan bii aago mejila abọ oru ọjọ Iṣẹgun.
Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Ganduje: No be me release dis third video - Jaafar Jaafar31 Ọ̀wàrà 2018 Ganduje Video: Jafaar Jafaar don ready to help Kano lawmakers19 Ọ̀wàrà 2018 Trans Amadi Mosque: Wike say Rivers goment no demolish anything26 Ògún 2019 Ganduje videos make oda senators dey yab me - Rabiu Kwankwaso28 Bélú 2018 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
fun ekun Ariwa- Barrister Ismaeel AhmedIgbakeji oludari
Mika bí ọmọkunrin mẹrin: Pitoni, Meleki, Tarea ati Ahasi.
ti setan lati gbe igbese ti yoo fopin si isekupani awon alaise omo orile-ede
 Àwon ekùú tí wón gbé nígbà náà wà níbè di ìsisìyí .
Nítorí bí mànàmáná tíí kọ yànràn, tíí sìí tan ìmọ́lẹ̀ láti òkè délẹ̀, bẹ́ẹ̀ ni Ọmọ-Eniyan yóo rí ní ọjọ́ tí ó bá dé.
Oríṣun àwòrán, Marta Moreiras Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Bi Tabili naa se lo ni kikun:   Iko                P W D L GF GA GD Pts Uganda            6 4 1 1 7 3 +4 13 Tanzania         6 2 2 2 6 5 +1 8 Cape Verde     6 1 3 2 3 7 -4 6 Lesotho           6 1 2 3 4 5 -1 5.
Oríṣun àwòrán, Rich Watson / Geoxyz Àkọlé àwòrán, Ọkọ oju omi Geo Ocean III ko kuro ni agbegbe ti wọn ti ri ajaku ọkọ naa ni Guernsey Àwọn ìròyìn mìíràn tí ẹ lè nífẹ̀ẹ́ si: Kí ló jó Káàdì ìdìbò 15,000 ní iléeṣẹ́ INEC ní Abia?
Ẹran adiẹ Ki ijọba to ti ibode pa fun apẹrẹ niluu Eko, apo mẹfa naira ni wọn maa n ta ẹran adiẹ (chicken) tutu kilo kan.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, SS3 ní mo wà báyìí, mo sì ti gba àmì ẹ̀yẹ̀ púpò nílé-lóko gẹ́gẹ́ bí onílù - Ayansike A gbọ pe eyi ko sẹyin isẹlẹ kan to waye, eyi to mu ẹmi Oloye Olabode Thomas lọ, ẹni to jẹ agba oselu ninu ẹgbẹ oselu naa, ti ọrọ si se bii ọrọ laarin awọn mejeeji nibi ipade kan to waye lọjọ kejilelogun osu kọkanla ọdun 1953 eyi to mu ki wọn so iku agba oselu naa mọ ọrun Alaafin Ọdun 1954 ni wọn yọ ọba Adeyemi keji lori oye, wọn le kuro nilu Ọyọ lọ si Ilesa, ko to pada lọ gba nilu Eko nibi to ti tẹri gbasọ lọdun 1960.
Ẹ má bẹ̀rù ọba Babiloni tí ẹrù rẹ̀ ń bà yín, ẹ má bẹ̀rù rẹ̀; èmi OLUWA ni mo sọ bẹ́ẹ̀, nítorí pé mo wà pẹlu yín.
Oríṣun àwòrán, facebook\\Alhaji Taofeek Oyerinde Àkọlé àwòrán, Alhaji Fẹlẹ dagbere faye lẹyin aisan kindinrin to baa finra Lẹ́yìn ìkú rẹ̀ ní Gómìnà Ọyọ́ Abiola Isiaka Ajimobi tí gbà pẹ̀lú olórí NURTW tí àpàpọ̀ láti fi Abideen Olajide tí gbogbo ènìyàn mọ sí Ejìogbè bọ́ sípò rẹ̀ gẹ́gẹ́ bí adelé alága.
Minisita to nmojuto oro imo sayensi ati imo ero, dokita Ogbonnaya Onu soro naa di mimo lasiko ipade igbimo to n mojuto igbese ohun lorile-ede Naijiria(National Consultative Committee on Competitiveness NCCC), ti o waye niluu Abuja.
Lati bii ọdun mẹrin bayii, ina ko tii wọ laarin Sudan ati Ethiopia lorii bi wọn yoo ṣe maa ṣakoso adagun odo naa.
O gba igbega si ikọ Super Eagles lẹyin to ṣoju orilẹ-ede Naijiria ninu idije ọjẹ wẹwẹ ti ọjọ ori wọn ko ti ju ogun ọdun lọ lọdun 1999.
Kìnìún mẹ́rìnlá bọ́ sígboro Lẹ́yìn àṣẹ ilé ẹjọ́, AIT àti RayPower padà s'afẹ́fẹ́ Lẹ́yìn àṣẹ ilé ẹjọ́, AIT àti RayPower padà s'afẹ́fẹ́ IKILỌ: FIDIO YII NI OUN TO BA NI LẸRU Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí kan sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
Sugbon o kọ jale o wa si orile ede Naijiria, lati wa sẹwọn lorile ede yii, gege bi aare naa se sẹwọn pelu.
Gege bi, olugbani-nimoran pataki si igbakeji aare lori eto ifitonileti, ogbeni Laolu Akande se so,”Ipade apero naa wa ni ibamu pelu afojusun isakoso ijoba aare Buhari, ni ona lati mu igberu de ba eto oro aje orile-ede yii, ti a mo si Economic Recovery and Growth Plan (ERGP).
    Nígbà tí ilẹ̀ mọ́, mo lo àwọn nǹkan tí ìyá mi fún mi bí o ti wí.
Èèyàn 17 mííràn tún ti lùgbàdì ààrùn Coronavirus ní Naijiria Eeyan mẹtadinlogun miran ni ayẹwo tun ti fihan pe o ni arun coronavirus bayii.
O ku Senegal bayii ti gbogbo ojú wà lara wọn boya wọn a yọ ikọ Afrika kuro ninu ẹgan yii.
Aarẹ Buhari rọ awọn ọmọ Naijiria lati fọwọ sowọpọ pẹlu ijọba fun iṣokan Naijiria O ni Naijiria kii ṣe orilẹ-ede fun Aarẹ tabi ẹgbẹ oṣelu to wa lori alefa nikan ṣoṣo, ṣugbọn o wa fun gbogbo wa lapapọ, nitori naa ni a ṣe gbọdọ fi imọ ṣọkan"" O ṣoro lati maa ṣafikun owo epo bẹntiro lasiko yii, koda epo awọn orilẹ-ede to yi wa ka bii Ghana ati Niger wọn ju tiwa lọ Oriṣirisi eto ni a ti gbe kalẹ fun igbeleke eto ọrọ aje wa, bii Tradermoni ati Farmermoni, ounjẹ ọfẹ fun awọn ọmọ ile iwe, ipese iṣẹ ati bẹẹ bẹẹ lọ Gbogbo awọn to ti ba Naijiria jẹ lati ọdun 1999 si 2015, ko yẹ ko lẹnu ọrọ lati bu ẹnu atẹ lu akitiyan wa Nitori pe owo epo ja silẹ ni iwọn ida ogoji, owo ti ijọba n ri loṣooṣu ti dinku ni ida ọgọta Bakan naa ni adinku de ba owo ipamọ Naijiria nilẹ okeere ti a ni, nitori ajakalẹ arun Coronavirus to kọlu gbogbo agbaye Gbogbo ọmọ Naijiria gbọdọ tẹle ofin nipa titapa si awọn iwa ọdaran ati iwa jẹgudujẹra O dara ki orilẹ-ede yii wa ni iṣọkan, ju ki a pin yẹlẹyẹlẹ lọ nitori itan ti fi han wa pe, a jẹ eeyan to lee gbe papọ ni alaafia Mo ni igbagbọ ninu eto idibo ti ko ni oju-ṣaaju ninu, gẹgẹ bi ẹyin naa ṣe ri i ninu isejọba mi bii Aarẹ alagbada Awọn iṣoro ti a n koju ninu idibo wa lati ọwọ wa, nitori naa, a ni lati yii erongba wa pada lori bi eto idibo ṣe yẹ ko lọ Ẹ jẹ ki a pinnu lati jọ maa gbe pọ gẹgẹ bi ọmọ iya kan Ko si ijọba to kọja ṣẹyin, to tii ṣe iru aṣeyọri ti a ṣe yii pẹlu iwọnba owo perete ti a n ri Lọwọ yii, N161 ni a n ta lita epo kan, N362 ni Chad n ta ti ẹ, N211 ni Egypt, ti Niger si n ta tirẹ ni N346 Ireti mi ni pe ti yoo ba fi di iwoyi ọdun to n bọ, inu wa yoo dun pe a pinnu lati jẹ oṣuṣu ọwọ Ki Ọlọrun o bukun Naijiiria."
Alaafin: Olorì Folashade ní òun ni olorì àkọ́kọ́ tó bí ìbẹta nílẹ̀ Yorùbá
Everton ti faaye gba wọn ju.
Lọjọ kọkanlelọgbọn, oṣu kejila, ọdun 2018 ni igbakeji aarẹ daa lọla.
Èrò wìtì-wìtì lọ́jàa Dugbẹ, Bodija, Orita-Challenge láì náání Corona Virus ní Ibadan Àrùn Coronavirus ti gba ẹ̀mí ẹni àkọ̀kọ̀ ní Zimbabwe Eni mẹ́rin míì kó coronavirus ní Nàìjíríà, àfàìmọ̀ kó má dàbi ti China, Italy- Mínísítà kìlọ̀ Ìjọba àpapọ̀ ní kí àwọn òṣìṣẹ́ grade 1 sí 12 jókòó sílé nítorí Coronavirus Ẹ wo ǹkan to sẹlẹ̀ sí ọmọ àti ìyàwó ọmọ Atikú tó lùgbàdì ààrun Coronavirus Ọmọ Nàìjíríà kan tó lùgbàdì àrùn coronavirus ti di olóògbé Àrùn Coronavirus ti gba ẹ̀mí ẹni àkọ̀kọ̀ ní Zimbabwe Kinni ofin konile o gbele tumọ si gan an?
Kì í ṣe bí ayé ti í fúnni ni mo fun yín.
Akinsanya ṣalaye pe ninu ọja Kara to wa ni ilu Ogbomọsọ ni ọwọ ti tẹ wọn.
Bí kò bá yẹ kí á tẹ̀lé e, sọ ohun tí ó yẹ kí á ṣe fún wa.
Àwọn eniyan bẹ̀rẹ̀ sí gé ara wọn láhọ́n jẹ nítorí ìrora wọn, 
    Mo rọra díde lórí ibùnsùn mi, mó ń wo ibi ti mo ti n gbọ́ ariwo yìí.
Awọn naa fẹ gbe ife ẹyẹ AFCON 2019 lọ lẹẹkeji.
Kò sí Ààrẹ tàbí Gómìnà tó lè dá ìfẹ̀họ́núhàn àwọn Nàìjíríà lórí #EndSARS dúró- Monday Ubani Ẹ lo ìfẹ̀họ̀núhàn #EndSARS lati fí tún gbogbo ohun tó bàjẹ́ ṣe ní Naijiria- Pásítọ̀ Sam Adeyemi Mo fẹ́ ìdájọ́ òdodo lórí ikú tó pa ọmọ mi- Baba ọmọ ti SARS pa Ẹ wo èrò bìbà níbi ìwọ́de #EndSARS ní ìlú Ibadan Ajobiewe Eegunjọbi gba awọn ọdọ ni imọran pe aforiti lẹnu iṣẹ ti eeyan ba yan laayo lo ṣe pataki.
Bí wọ́n ti nkọ orin yìí tán ni oríṣìíríṣìí ọkọ̀-òfurufú fò kọ̀já lókè e àfin náà.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Super Falcons: 3-0 ni Norway fi ṣi'de ìyà fún Nàìjíríà 9 Òkùdu 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ọbinrin agbabọọlu Naijiria, Osinachi Ohale gan an lo gba bọọlu si inu awọn Naijiria ti ayo naa fi di mẹta si odo.
O tun sọ pe koda bi obinrin ti wọn fi ilọkulọ lọ ọhun ba kuro to lọ dara pọ mọ ẹgbẹ mii, wọn a tun pe oludari ẹgbẹ to lọ dara pọ mọ lati taa lolobo ki wọn le pawọpọ foju rẹ han mabo.
Aadọrin ọdún ni ọjọ́ ayé wa;pẹlu ipá a lè tó ọgọrin;sibẹ gbogbo rẹ̀ jẹ́ kìkì làálàá ati ìyọnu;kíá, ayé wa á ti dópin, ẹ̀mí wa á sì fò lọ.
Ǹjẹ́ o mọ̀ pé o le gba owó lára 'ATM' láì lo káàdì?
‘Ijọba yẹ ki wọn kọ awọn obi ni ọna ti wọn yoo fi tọ ọmọluwabi lawujọ’ Bakan naa ni AgbẹjọroTaiwo Akinlami naa bu ẹnu atẹ lu igbeṣẹ ile igbimọ aṣofin ipinlẹ Eko naa to n da a laba lati ma a jẹ ki awọn obi pin ninu iya ti o tọsi ọmọ to ba n ṣe ẹgbẹ okunkun.
Oríṣun àwòrán, @ogun_state Àkọlé àwòrán, Ẹ jẹ ki ifarajin ti ẹ ṣe lasiko Ramadan yẹ ko tubọ fa yin sin mọ Ọlọrun Gomina Abiọdun rọ awọn musulumi lati ma ṣe gbagbe ẹkọ ifara ẹni jin ati titẹle ilana, iwa ati ẹkọ Anọbi Mohammed.
Oríṣun àwòrán, others Efunroye Tinubu: Idile miran to tun gbajumọ fun owo ẹrú ṣíṣe ni idile oloye arabinrin Efunporoye Osuntinubu, ti adape rẹ n jẹ Efunroye Tinubu.
Alaga igbimo naa , ti o tun je gomina ipinle  Zamfara, Abdulaziz Yari, ni  o soro idaniloju naa lasiko ipade apero lori
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù BBC Africa Eye: Ìyá mi, bí mo bá rántí ikú rẹ lásìkò ìrọbí, àìbímọ tèmí ń pa mí kú díẹ̀díẹ̀ 24 Èrèlè 2020 Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Akọ ìbẹ́pẹ ni Yorùbá yóò pè é, ẹ wo bí òṣèré yìí ṣe ń ní ọgbẹ́ ọkàn pé kò tíì r'ọ́mọ bí Ìyá mi, lórí pé o fẹ́ pe ọmọ wáyé, o sọ ẹ̀mí tìrẹ nù, torí emi gan ò lè bímọ, mo tí ń kú díẹ̀ díẹ̀ báyìí.
 a túnmọ ̀ pé ó wáyé ni Áfíríkà , Áṣíà , àti ní etíkun .
Ṣugbọn ile iṣẹ ologun Naijiria ni ki awọn eeyan kọ eti ikun si ọrọ yii patapata.
Nítorí ẹ óo fẹsẹ̀ kọ lojumọmọ, ẹ̀yin wolii pàápàá yóo kọsẹ̀ lóru, n óo sì pa Israẹli, ìyá yín run.
Balogun Olufemi Akinjobi, ti o je alaga igbimo to n sakoso awon ohun ija ogun, ba awon akoroyin soro ni papako ofurufu Nnamdi Azikiwe pe, awon ohun ija ogun miiran si tun wa loju ona, eleyi ti awon orile-ede miiran fe fi satileyin fun wa.
kíni wọn yóò máa ṣe ní ìpínlẹ̀ - DAWN Commission Díẹ̀ lára àwọn ìṣẹ̀lẹ̀ tí yóò mi ìgboro tìtì l'ọ́dún 2020 rèé Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí 2 sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 2:23 Fídíò, Water Generator: Ó leè ṣiṣẹ fún wákàtí mẹfà, kó tó sinmi, Duration 2,2310 Òkùdu 2020 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
Ọba nìkan ni ó lè jókòó níbẹ̀ láti jẹun níwájú OLUWA.
O ni awọn orileede ti o sunmọ China to yẹ ki ajakalẹ arun yi pọ lọdọ wọn ribi fi ilana yi lelẹ ti wọn si tẹlẹ.
 Bí APC ba fà Olóye Tinubu silẹ láti díje fún ipò Ààrẹ Naijiria, ó dá mi lójú pé, ó tó gbangba sùn lọyẹ, òun ni yóò mókè laarin awọn oludije yòókù nítorí pé ó kúnjú òṣùwọ̀n, tí yóò sì soro kò tó má di aarẹ Nàìjíríà.
Iyebíye ni ikú àwọn eniyan rẹ̀ mímọ́ lójú OLUWA.
Wọn kọri si ile ẹkọ Government Girls Science and Technical College, ti wọn si kuro lẹyin igba diẹ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Oshisko twins: Ojú wa rí, ṣùgbọ́nÌgbọ́raẹniyé ló ń ràn wá lọ́wọ́ O fikun pe, gbogbo awọn dukia ti wọn ti ta nilẹ Naijiria tẹlẹ ko mu eso rere kan wa, bakan naa si ni eto atunto to n polongo ko nitumọ mọ ni asiko yii, tori pe, atunto ti ba awọn ẹka isejọba wa tẹlẹ bii ẹka eto iselu, ọrọ aje ati ẹkun idibo kọọkan.
Oríṣun àwòrán, Adégbóyèga Adébàjò Àkọlé àwòrán, Gbogbo awọn agbabọọlu Stationery Stores lo jijọ gbe psoi Adebajo Ẹwẹ, Stationery Stores gba ife ẹyẹ Challenge Cup lẹẹmeeji lera lọdun 1967 ati 1968 ti iku Adebajo si di ọna gbigba ife naa ni igba ẹkẹẹta lọdun 1969.
    Báyìí ni ojúukòkòrò owó fa ikú bá àwọn ọkùnrin mẹ́ta wọ̀nyí.
Kíni ẹ̀yin rí sí ọba Ìwó  tí ilè Ìwó tí o yí orúkọ oyè ọba padà sí Emir
Toure ti yoo pe omo odun marunlelogbon ninu osu keje odun ti a wa yii, ti o tun tuko ohun gba ife-eye idije African Nations Cup lodun 2015 .
Ọ̀rọ̀ǹpọ̀tọ̀niyùn, Aláàfin obìnrin àkọ́kọ́ rèé, tó ní nǹkan ọkùnrin Àwọn wo ni Krìstẹ́ní Coptic tó ń ṣe Kérésìmesi ní January 7?
Wo àwọn ohun márùn ún tó yẹ kí o mọ̀ nípa Sanusi Ganduje ń bèèrè bí Emir Sanusi ṣe se owó ìlú mọ́kumọ̀ku Fulani to wa lati agbegbe Sullubawa ni Naijiria ni Aminu n ṣe.
Nítorí náà mo rò pé ọ̀rọ̀ náà yóò ṣe é ṣe.
Aarẹ Mokgweetsi Masisi ko dabi ẹni to fara si ohun ti awujọ agbaje sọ nipa aṣiwaju rẹ.
Idije Man U ati Liverpool Lẹ́yìn náà ni Jesse Lingard bá Manchester United gbá bọ́ọ̀lù sí àwọ̀n Liverpool ní ìṣẹ́jú mẹ́tàlélọ́gbọ̀n (33) sí ìgbà tí wọ́n bẹ̀rẹ̀ eré.
Ìṣòro jíjẹ́ ìyá n dáàgbé ló sọ mí di àtúnbí krístíẹ́nì - Remi Tinubu 'Bí a kò bá fẹ́ ìbínú Ọlọ́run, a gbọ́dọ̀ jẹ́ kí Tinubu du ipò ààrẹ̀ lábẹ́ àsìá ẹgbẹ́ APC ní 2023' Àbọ̀ ìpàdé bòńkẹ́lẹ́ láàrin Tinubu àti Buhari rèé Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Akomolede ati Aṣa: Mọ̀ síi nípa ìró afárànma àti agbárànmọ́ fáwẹ́ẹ̀lì Yorùbá Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Regent female kings: Wo àwọn Adelé-Ọba aládé méje tó jẹ́ obìnrin nílẹ̀ Yorùbá15 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Sex party: Ìjọba gbé ilé ijó oníhòhò tì pa lórí ẹ̀sùn títàpá sí ìlànà àti dẹ́kun coronavirus15 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 NÍ YÀJÓYÀJÓ Konduga Suicide bombing:Ẹ̀mí mẹ́ta bọ́, èèyàn méjì míì farapa nínú ìṣẹ̀lẹ̀ àdó olóró ní Borno 1:15 Fídíò, Fuji Music: Kollington Ayinla sọ ẹni tó dá orin Fuji sílẹ̀ gan an ní Nàiìjíríà, Duration 1,1516 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Ọpọ asise to kun inu ijọba Buhari lo jẹ afọwọfa Soyinka wa mẹnuba igbesẹ bi Buhari se pe akọwe apapọ fun ajọ to nse amojuto eto adojutofo nidi ilera (NHIS), Usman Yusuff pada sẹnu isẹ, lẹyin ti minisita feto ilera, Ọjọgbọn Isaac Adewọle ni ko lọ rọọkun nile na nitoripe o se owo ilu basubasu, gẹgẹ bii apẹrẹ kan to n safihan pe oniruuuru asise afọwọfa lo kun inu isejọba Buhari dẹnu.
Mo bẹ̀rẹ̀ síi rí ǹkan oṣù mi.
Ibi yii ni wọn tẹ oku Robert Mugabe si ṣaaju isinku rẹ ki awọn ololufẹ rẹ le ri.
Insecurity: Ilé aṣojú-ṣòfin ní ìpànìyàn, ìjínigbé, ìdigunjalè, ìgbéṣùnmọ̀ọ́mí ń peléke ni
 Àwọn aláṣeẹ mìíràn tún sọ qípé iṣẹ ́ ka náà ni ilé-ẹ ̀ kọ ́ kaduna college.
Oríṣun àwòrán, @seyiamakinde Àkọlé àwòrán, Mo jẹ ẹni ti o de ipo gomina lai ni baba isalẹ kankan, afi Ọlọrun Ọba O dùn mí pé Buhari kò yàn mí sípò Mínísítà lẹ́ẹ̀kejì àmọ́ mò gbà kádàrá - Adebayo Shittu Makinde, jọ̀ọ́ kéde Aug 20 ọdọọdún bíi ọjọ́ ìsinmi fún ìṣẹ̀ṣe - Àwọn oníṣẹ̀ṣe Ọyọ Wo ipò tí Buhari fún Faṣọla, Lai Mohammed, Saraki àti bẹ́ẹ̀ bẹ́ẹ̀ lọ Ta ni Seun Fakorede, ọmọ ọdún 27 tó fẹ́ di kọmiṣọna?
Lẹ́yìn náà olukuluku pada sí ilé rẹ̀, Dafidi náà pada sí ilé rẹ̀ láti lọ súre fún àwọn ará ilé rẹ̀.
Nítorí ọ̀rọ̀ agbelebu Kristi jẹ́ ọ̀rọ̀ òmùgọ̀ lójú àwọn tí ń ṣègbé.
Nítorí náà, ẹ ṣọ́ra bí ẹ ti ń hùwà.
Olè yabo báńkì,fọ́n owó ká fáwọn èrò lẹ́yìn tó pariwo 'Merry Christmas' Èyí ni bí wọ́n ṣe n dìbò yan Póópù tuntun nínú ìjọ Àgùdà Ọkọ̀ agbépo tó da epo nù fa súnkẹrẹ-fàkẹrẹ lòpópónà márosẹ̀ Eko sí Ibadan Ẹ ronúpìwàdà lásíkò ọdún, àti àwọn ìkíni mìrán tó jẹ yọ fún Kérésì Èyí ni ìdí tí Bàbá Kérésì fi máa n wọ aṣọ pupa àti funfun nígbà gbogbo Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Larisa: Má jẹ́ kí ọjọ́ orí rẹ dí ẹ lọ́wọ́ láti bẹ̀rẹ̀ ohunkóhun to wù ọ Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Ile ẹjọ kotẹmilọrin Stockholm sọ pe Etuhu ati agbabọọlu miran ti wọn ko darukọ ẹ jọ gbiyanju lati jẹ ki adilemu AIK Kyriakos, Kenny Stamatopoulos.
Ati jẹ ati mu soro dun Gloria de bi pe o lọn tọrọ bara ni Ọgba, a ma sọfun awọn eeeyan pe oun nilo owo mọto lọ si ibi ti oun n gbe ni Ekiti, owo yii, wọn salaye pe ọkọ rẹ lo lati mu oniruuru imukjmu ati Siga.
Awọn alaboyun naa yoo jẹ ninu anfaani yi.
Buhari, Minisita f'ọrọ okeere nilẹ Amẹrika, Tillerson n ṣe'pade lọwọ
Chelsea fún Man United lóúnjẹ ẹ̀tẹ́ jẹ, Cuppy bínú yí jọ̀lọ́ọ̀fù dànù Liverpool pègúnrẹ́, wọ́n gbé ife ẹ̀yẹ̀ Premier league lẹ́yìn ọgbọ̀n ọdún Bi Arsenal ba kọ lati fidi Chelsea rẹmi, wọn ko ni le tẹsiwaju lati kopa ninu idije Europa League ọdun yii.
Kia kia lo si gba ile iwosan FMC ti wọn ti n tọju awọn alarun naa lọ, amọ ẹpa ko boro mọ, lẹ yin wakati diẹ to debẹ ni ẹlẹmi gbaa.
Bẹ́ẹ̀ ni àwa náà gbà á.
O sọrọ yii laafin Ọba Adeyẹmi ko to maa lọ sibi ipade itagbangba gbọngan Atiba nilu Ọyọ.
Ni ọdun 2017 ati 2018, iṣẹlẹ ikọlu ado oloro bi mẹtadinlọgọrin ati mẹrindinlọgbọn ni ṣiṣẹ n tẹle nipasẹ awọn ọmọde lo waye.
Dandan ni fún mi kí n ṣe iṣẹ́ ẹni tí ó rán mi ní ojúmọmọ, ilẹ̀ fẹ́rẹ̀ ṣú ná, tí ẹnikẹ́ni kò ní lè ṣiṣẹ́.
 wọ ́ n tún maa ń rí àrùn yìí lára àwọn ajá gẹ ́ gẹ ́ bí àrùn abínibí ní àwọn ẹ ̀ yà kan .
Bàsèjẹ́ ni wọ́n jẹ́ ninu àsè ìfẹ́ ìjọ, wọn kò ní ọ̀wọ̀ nígbà tí ẹ bá jọ ń jẹ, tí ẹ jọ ń mu.
Ìlànà IVF là fi bí ìbejì tẹ gbé lẹ́yìn idaduro ọdún méjìlá, ẹ jọ̀ọ́, ẹ tú wọn ṣílẹ̀ - Akeugbagold, aya rẹ bẹ̀bẹ̀.
Lẹyin naa ni Ramphosa pada sibi ipade idakọnkọ naa.
"Wo àwárí akọ́ṣẹ́mọṣẹ́ yìí ""Koda bi ọlọpaa ba ṣa gbogbo ipa wọn, a ṣi n ni ipenija."
O ni aye igba kan ni awọn adẹẹrinpoṣonu jẹ alagbe, ti wọn si kawe.
Hassan ti ile ẹjọ giga kan nipinlẹ Eko sun igbẹjọ awọn alabaṣiṣẹpọ Mompha yii siwaju di jọ kejidinlgbọn oṣu kẹrinla ọdun 2019.
Ó ní:“Fẹliksi ọlọ́lá jùlọ, à ń jọlá alaafia tí ẹ mú wá lọpọlọpọ, a sì ń gbádùn oríṣìíríṣìí àtúnṣe tí ẹ̀ ń ṣe lọ́tùn-ún lósì fún àwọn ọmọ ilẹ̀ wa.
Beckham, àgbábọ́ọ́lù tẹ́lẹ̀ rèé tó ń sọ èdè Yorùbá Champions League: Ajax f'imú Tottenham fọn fèrè Ṣugbọn Isaac Mbenza dayo naa pada lẹyin iṣẹju mẹẹdogun ti abala keji ere bọọlu ọhun bẹrẹ.
Oríṣun àwòrán, @Ghana police Àkọlé àwòrán, Ghana ti mu àwọn afurasí ajínigbé ọmọ Naijiria À ń wo àtubọ̀tán APC níbáyìí tó gba àkóso ilé aṣòfin - PDP #Democracy Day: Pápá ìṣeré Abuja di MKO Abiola Stadium MKO Abiola, iṣẹ́ aṣẹ́gità ló fi bẹ̀rẹ̀ okoòwò Ìdààmú ńlá ńbọ̀ fún Nàíjíríà lábẹ́ ìjọba Buhari - Ọbasanjọ Nigba ti agbofinro ati awón ajinigbe wọnyii gbena woju ara wọn ni ọkan ninu awọn afurasi ọdaran naa farapa.
Oríṣun àwòrán, Bayo Omoboriowo Àkọlé àwòrán, Guru salayepe ààrẹ Buhari ni yóò jawe olúbori ninu ìdìbò ọdún 2019 Lásìkò tí Gúrú ń bá àwọn àkọ̀ròyìn sọ̀rọ̀ nibi àpérò láti se ayẹyẹ ọdún mọ́kàndínlógojí rẹ̀ lórilẹ̀-èdè Nàìjíríà, ló ti sàlàyé pé òun rí pe Buhari ló jáwé olúbori nínu ìdíje ìdìbò ọdún 2019.
Irú ààwẹ̀ tí ẹ̀ ń gbà yìí kò ní jẹ́ kí Ọlọrun gbọ́ ohùn yín lọ́run.
Ṣugbọn kí ẹ mọ èyí pé ìjọba Ọlọrun wà ní àrọ́wọ́tó yín.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ike Ekweremadu attack: Igbákejì adarí ilé aṣòfìn àgbà tẹ́lẹ̀ dáríjì àwọn IPOB tó nà mí ní Germany 18 Ògún 2019 Oríṣun àwòrán, Facebook/Ike Ekweremadu Ọrọ naa da bi ọrọ ti Jesu Kristi sọ lori igi agbelebu pe ''Baba dariji wọn, nitori pe wọn ko mọ ohun ti wọn n ṣe.
Máa ka ìwé òfin yìí nígbà gbogbo, kí o sì máa ṣe àṣàrò ninu rẹ̀, tọ̀sán-tòru; rí i dájú pé o pa gbogbo ohun tí wọ́n kọ sinu rẹ̀ mọ́.
Ní òwúrọ̀ kutukutu kí ilẹ̀ tó mọ́, Jesu dìde, ó jáde kúrò ní ilé, ó lọ sí ẹ̀yìn odi ìlú láti gbadura níbi tí kò sí ẹnìkankan.
3 1588369 Ilu Ọba 87295 130.
Wo ohun márùn-ún tó ń fa ìjàmbá iná nínú ilé Day 25: Àwọn àkànlò èdè lásìkò ìdìbò #BBCNigeria2019 Tani Ọjọgbọn Mahmood Yakubu ti yóò ṣètò ìdìbò 2019?
Kìí ṣe ẹ̀bi wa pé ètò ìsìnkú Abiola Ajimobi falẹ̀ - ìjọba ìpínlè Oyo Ninu waasi rẹ to se ni ede oyinbo nibi adura naa, Imaamu agba fun mọsalasi Oluyole, Sheik Nafiu Atanda Bada mẹnuba pe ọpọ ẹsin to wa laye lo gbagbọ ninu ka gba dura fun oku, eyi ti awọn n se lonii.
Ọjọ keje lẹyin ti idibo Ọsun waye lọjọ́ Kẹjìlélógún, Osú Kẹ̀sán an, Ọdún 2018 ni Oyetọla yoo pe ọmọ ọdun mẹrinlelọgọta.
Èèyàn mẹ́ta pàdánù ẹ̀mí wọn nínú ìjàmbá ọkọ̀ akérò tó ya wọ ọjà ní Ibadan
Awọn ọlọpaa kan naa ti wa nibi ayẹyẹ ọhun latilẹ nitori naa, lẹsẹkẹsẹ ni wọn doju ija ni kete ti wọn gburo ibọn laarin iṣẹju akan.
Olùdíje mẹ́rin ti Gbajabiamila lẹ́yìn ṣáájú ìbò ilé aṣojú ṣòfin Dangote, Fayemi pari ìjà láàrin Ganduje àti Emir Sanusi Ilé ìgbìmọ̀ aṣòfin ikẹ̀jọ kógbá sílé l'Abuja Iṣẹ́ Kudirat Abiọla ṣì ń fọhùn síbẹ̀, lẹ́yìn ọdún 23 tó papòdà Ní báyìí, awọn ẹgbẹ́ amúṣẹyá ẹgbẹ òṣèlú PDP ní àwọn ti fọ́wọ́ sí láti dibò yan Ali Ndume gẹ́gk bii ààrẹ ilé ìgbìmọ aṣòfin nígbà ti wọ́n fọwọ si Umar Mohammed Bago gẹ́gẹ́ agbẹ́nusọ ilé ìgbìmọ aṣojú-ṣòfin.
''Lẹyin ti a wo eṣun ti oludije PDP pe ẹgbẹ oṣelu APC pe kudiẹkudiẹ wa ninu eto idibo to gbe Yahaya Bello gẹgẹ bi gomina ipinlẹ Kogi, o ti han gbangba pe ko si ẹri to dalu lati fi idi ẹsun naa mulẹ, nitori naa, a tu ipẹjọ PDP ka,'' adajọ Okoro lo sọ bẹẹ.
àní àwọn òfin tí OLUWA tipasẹ̀ Mose fún yín, láti ọjọ́ tí OLUWA ti fún un ní òfin títí lọ, ní ìrandíran yín; 
Se wọn fẹ pa ikọ naa rẹ ni?
"O ni ""Awọn oṣiṣẹ wa lati ileesẹ eto ilera yoo ṣepade pẹlu awọn nọọsi, aawọ naa yoo si di ohun igbagbe titi ọjọ Aje, ọjọ kọkandinjlọgbọn, oṣu kẹfa ọdun yii."
Eyi ni abajade  ipade ti minisita fun oro eto aabo Mansur Muhammad Dan-Ali se pelu awon adari Ologun lojo Aje ni olu-ile ise ajo eto aabo to wa niluu Abuja.
Olè kì í wá lásán, àfi kí ó wá jalè, kí ó wá pa eniyan, kí ó sì wá ba nǹkan jẹ́.
Bakan naa ni igbimọ to n ṣe akoso ẹsin musulumi lorilẹede Naijiria, NSCIA tun ke sawọn mọṣalaṣi gbogbo lati wọgile gbogbo eto taraweeh, iyẹn adura araarọ lasiko awẹ, idanilẹkọọ Tafsir, atawọn eto miran to js ms asiko awẹ Ramadan.
Fun gbogbo ẹyin ti mo ti pa rẹrin ri, ati ẹyin ti mo ti mu binu, ẹ gba pe ẹlẹran ara ni mi.
Níbi ìdánilẹ́kọ̀ọ́ kan, a bi àwọn èwe tí ó kópa: “Irúfẹ́ ẹranko wo ni a bá nínú àlọ́ náà?
Bẹ́ẹ̀ ni alufaa yóo ṣe ètùtù fún un nítorí ẹ̀ṣẹ̀ tí ó dá, nítorí pé ó ṣe ọ̀kan ninu àwọn ohun tí OLUWA pa láṣẹ pé ẹnikẹ́ni kò gbọdọ̀ ṣe, OLUWA yóo sì dáríjì í.
Wọ́n létí, ṣugbọn wọn kò gbọ́ràn,wọ́n nímú, ṣugbọn wọn kò gbóòórùn.
Ẹwẹ, titi di asiko yii iwadii ṣi n lọ lori iye eniyan to ku ninu iṣẹlẹ Lekki ati ohun gangan to mu ki awọn soja da ibọn bo araalu.
Bakan naa lo fikun pe o seese ki oun padanu isẹ oun nitori ikọlu yii, to si n beere pe ki lo de tawọn eeyan naa se n kọlu awọn araalu ti wọn sọ pe awọn n ja fun.
Osinbajo tun tesiwaju pe ijoba aare Muhammadu Buhari ko ni kaare lati
N óo máa mí túpetúpe,n óo máa mí hẹlẹhẹlẹ.
Àwọn kan ninu ẹ̀yà Manase darapọ̀ mọ́ Dafidi nígbà tí òun pẹlu àwọn ará Filistia wá láti bá Saulu jagun.
O fi kun pe gbogbo agbaye ni yoo gba isinmi lẹnu iṣẹ nitori arun coronavirus yii, nitori naa ki gbogbo awọn smọ ijọ naa o maa gbadun isinmui lẹnu iṣẹ ti Ọlọrun fun wọn.
Ọ̀rọ̀ ìkà ati ẹ̀tàn ni ọ̀rọ̀ ẹnu rẹ̀.
Ọjọ́ náà yóo burú tóbẹ́ẹ̀ tí àwọn akikanju ọkunrin yóo kígbe lóhùn rara.
Baalu naa gbera lati Eko lọ si olu ilu Naijiria, Abuja, nibi ti ilẹkun baalu naa ti jabọ nigba ti o balẹ.
Noa jẹ́ ẹni ẹgbẹta (600) ọdún nígbà tí ìkún omi bo ilẹ̀ ayé.
Lẹ́yìn náà, ó wọlé, ó jẹ, ó mu, lẹ́yìn náà, ó ní, “Ẹ lọ sin òkú obinrin ẹni ègún yìí nítorí pé ọmọ ọba ni.
ti egbe   People’s Democratic Party (PDP)  ni iye ibo 218,052.
Ọkan lara awọn oṣiṣẹ ileeṣẹ Disco Ikeja ti ko fẹ ki BBC darukọ rẹ lo fidi ọrọ yii mulẹ fun BBC Yoruba.
Yoruba ni agbara, oogun ati iṣẹṣe lati ọwọ awọn baba nla wa.
ku diẹ ki ikọ agbabọọlu mejeeji naa
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Mayowa Omoniyi: Kò sí orin Obey, Sunny Ade abí tàkasúfèé tí ń kò le ta gìtá sí O fi kun un pe, bi o tilẹ jẹ wi pe ijọba ti mojuto ibeere yii, ti ijiroro lori awọn yooku si ti de ipele to lapẹẹrẹ, suuru ni awọn dokita naa ko ba fi yanju ọrọ naa.
Onnoghen sọ pe oun ko jẹbi.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ipò àgbà ló yẹ́ kí a ti bá olórí - Fani-Kayode Irun gígẹ̀ kọjá orí fífá lásán 'Buhari wá sọ tẹnu ẹ' Awọn alatilẹyin sẹnatọ naa sọwipe awọn ọlọpaa fi panpẹ ọba mu sẹnatọ naa nitori aawọ to wa laarin oun ati Gomina ipinlẹ Kogi, Yahaya Bello, ti wọn jọ wa ninu ẹgbẹ oselu APC kan naa.
Awọn mejeeji fẹnuko pe o dara ki obinrin niṣẹ lọwọ ko ma ba a jẹ ajaga fun ọkọ rẹ.
Aṣọ rẹ̀ funfun bí ẹ̀gbọ̀n òwú.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ẹlẹ́wọ̀n: Ẹ̀sùn ìbálòpọ̀ ọmọdé ló gbé dé mi dé ẹ̀wọ̀n Ẹlẹ́wọ̀n tẹ́lẹ̀ gboyè ìmọ̀ ìjìnlẹ̀ méjì lọ́gbà ẹ̀wọ̀n Òní ni ẹ̀bí akọni Pius Adesanmi n ṣètò ìkẹyìn fún ogbontarigi náà Wo àwòdamiẹnu àwòrán Mọ́ṣáláṣí Ànọ́bì ní Medina!
Hamani to wa ni Niamey ni deede aago 16:45 GMT.
16 Bí ó tilẹ̀ rí bẹ́ẹ̀, iṣẹ́ mi yíò mã tẹ̀ síwájú, níwọ̀nbí ìmọ̀ nípa Olùgbàlà kan ti di mímọ̀ fún ayé, nípasẹ̀ ẹ̀rí láti ẹnu àwọn Júù, àní bẹ́ẹ̀ ni ìmọ̀ nípa Olùgbàlà kan yíò wá sí ọ̀dọ̀ àwọn ènìyàn mi—
Ẹ fi ògo tí ó yẹ orúkọ OLUWA fún un,ẹ mú ọrẹ wá sí iwájú rẹ̀!
Ọmọ Downsydrome ti mo bí ló fún mí láǹfàní láti de ilú Oyinbo Ìdí tí mi ò fi lègbà kí ẹnikẹ́ni fọwọ́ tẹ ara mi gẹ́gẹ́ bí olórin-Sola Allyson Ọlọ́pàá, adájọ́ àtàwọn aṣọ́bodè ló gba rìbá jùlọ ní Nàìjíríà-NBS Ìròyìn nípa ìyàwó túntún fún ọkọ mi kò mì mí lọ́kàn rárá-Aisha Buhari Ka to wi, ka to fọ, Dominic Calvert-Lewin gbayo keji sawọn Chelsea lẹyin iṣẹju mẹrin ti ipele keji ere bọọlu naa bẹrẹ.
Orúkọ àwọn alufaa ati àwọn ọmọ Lefi tí wọ́n bá Serubabeli ọmọ Ṣealitieli ati Jeṣua dé nìwọ̀nyí: Seraaya, Jeremaya ati Ẹsira, 
A ti ní ìrírí ìtọ́ni pẹlu ìjìyà, sibẹ ìjìyà yìí kò pa wá.
Ògo mi yóo ṣe ààbò lẹ́yìn yín.
"Iṣẹ́ fẹ́ bọ́ lọ́wọ́ ọlọ́pàá tó gba N100k lọ́wọ́ awakọ̀ tó gba""One way"" l'Eko Ìjọba Naijiria faraya nínú lẹ́tà tó kọ sí CNN lórí ìwádìí rẹ̀ nípa ìṣẹ̀lẹ̀ Lekki Toll Gate Jemila dáná sún ilé ọ̀rẹ́kùnrin rẹ̀ àti ọ̀rẹ́bìnrin tó bá nílé Èyí ni ohun tí Ọọ̀ni sọ nípa Àrẹ̀mọ rẹ àti ètùtù tó ń ṣe lọ́wọ́ Abdulrasheed Maina: Wo àwọn nkan tó yẹ kó mọ̀ kí o tó ṣe onídùró fún ẹnikẹni Ọjọ Aje ni ile ẹjọ giga ijọba apapọ nilu Abuja, paṣẹ ki wọn o fi Sẹnetọ Ali Ndume , lati ipinlẹ Borno si atimọle."
Òbí tó n fa sìgá n fi ọmọ rẹ̀ sínú ìdè àìsàn l'ọ́jọ́ iwájú Ọlọ́pàá mú 115 ẹlẹ́sìn Shiite Ikọ̀ aláàbò Nàìjìríà dojú kọ Shiite Ọlọ́pàá ló ń fa rúkèrúdò lásìkò ìwọ́de wa-ẹgbẹ́ Shi'ite Gẹgẹ bi awọn ti iṣẹlẹ naa ṣoju rẹ ṣe sọ, okiti iyanrin naa ti wọn ni o fẹrẹ ga to ile alaja meji ṣa deede da wo ni ti o si bo awọn eeyan mẹta ti wọn wa ni isalẹ rẹ mọlẹ.
O sọ ninu ifọrọwanilẹnuwo kan to ṣe pẹlu iwe iroyin abẹle kan pe asiko ti oun jẹ akẹkọọ nileewe olukọni Emmanuel Alayande College of Education, ni oun bẹrẹ irinajo ifẹ pẹlu Alaafin.
Sultan Sokoto kéde òpin àwẹ̀ Ramadan ìjọba Nàìjíríà ti kéde ìsinmi lọ́jọ́ Ìṣẹ́gun àti Ọjọ́rú Awọn eekan lorilẹede Naijiria ati ni ilu Ilorin ti n fi ikini ranṣẹ si Emir Sulu Gambari.
sise ojuse won, ni eyi ti o lodi si ofin orile ede Naijiria.
Oríṣun àwòrán, Reuters Àkọlé àwòrán, L'ọjọ kan naa, awọ eeyan ni orilẹede Tunisia ṣe iwọde lati ja fun ẹtọ awọn obirin nibi didọgba ninu ogun pinpin.
Ile Igbimọ asofin orilẹede China lo ṣe awọn atunṣe (si iwe-ofin China) to fun aarẹ naa lanfani ati ma ṣe ijọba lọ lọjọ Aiku (Sunday).
"Èèyàn mẹ́tàlá dèrò ọ̀run nínú ìjàmbá ọkọ̀ lópòpónà Ìbàdàn s'ÈKó Zlatan: Èyí mo ṣé tó, àsìkò tó láti tèsíwájú nínú ìrìnàjò mi Osinbajo kò gbàdúrà ikú fún Buhari lórí àìsàn, ẹ sinmi ìbàjẹ́- Agbẹnusọ Osinbajo ""Àwọn tó jí ọmọ mi gbé nílé ìjọsìn ní ń kò gbọdọ̀ wa tàbí kí ẹ̀mí mi lọ si"" Ikubese pari ọrọ rẹ pe, ko ti si ogun ibilẹ to le wo aisan itọ ṣuga san patapata."
Igba ti ija wọn naa wọ ipele keje, Joshua tun balẹ gbi nigba ti ẹṣẹ ba a.
Oríṣun àwòrán, @Sadiya Àkọlé àwòrán, Ẹ yee parọ mọ mi o!
Gomina Ambọde ni asiko to lati dide tako iwa kotọ naa lawujọ.
Alaga awọn oṣiṣẹ agba labe aburada SSANU ni ẹka fasiti Ibadan, amofin Wale Akinrẹmi, ṣe alaye fun awọn oniroyin pe eyii ti o jẹ olori ipenija ni ajẹmọnu awọn oṣiṣe ti kii ṣe olukọ.
Ikú bàbá rẹ̀ tí ó gbọ́ ní ilé-ẹ̀kọ́ ni o gbé e wálé.
Kò sí ibi náà ní ode ayé yìí tí aisan pọ̀ to tayọ tí ilú Edidarẹ nibi tí omugodimeji ti ń ṣe ọba wọn.
Balogun ikọ agbabọọlu Liverpool, Jordan Henderson gbe ife ẹyẹ Liigi ilẹ Gẹẹsi lalẹ Ọjọru ni papa iṣere Anfield.
Lẹ́tà Obasanjo: Àjálù ń bọ̀ bíi ti Rwanda, tí Buhari kò bá ṣàtúnṣe ètò ààbò Wá gbọ́ ìmọ̀ràn tí Jonathan fún Buhari lórí ọmọ Fasoranti tó kú!
Nàìjíríà, orílẹ̀-èdè tí ó ní ènìyàn tí ó pọ̀ jù ní Ilẹ̀-Adúláwọ̀, yóò di ìbò ipò ààrẹ ní ọjọ́ 16, oṣù 2019.
Aare Buhari yoo maa gba Jos lo si Calabar ni ipinle Cross River lati le se ifilole awon ise akanse ti gomina naa gbe se .
Ni ti tawọn ọdọ ode oni, o sọ pe awọn paapa julọ ninu ẹgbẹ YPP awọn ko niigbagbọ ninu baba isalẹ.
omo egbe yii, pe isẹ sẹsẹ bẹrẹ  fun eni  ti won ba yan sipo , a ni lati gbaradi nipa
Aafa naa ni Ọba oke to da obinrin sọ pe ''owo ti ẹ n na fawọn obinrin, ọkan lara awọn ọna ti ọkunrin maa n fi ṣe idari obinrin ni gẹgẹ bi ọkọ rẹ, ayafi ti ẹ ko ba lowo lọwọ loku.
O ṣalaye pe wọn ko ri ohunkohun to lee fa họwuhọwu lẹyin ayẹwo wọn.
Ẹ fi etí sílẹ̀, ẹ̀yin ará mi olùfẹ́.
Àwọn ọmọ kò náání baba ati ìyá wọn ninu rẹ; wọ́n sì ń ni àwọn àjèjì ninu rẹ lára; wọ́n sì ń fìyà jẹ àwọn aláìníbaba ati opó.
A, wọ́n ṣe bẹ́ẹ̀ wọ́n lọ.
Apollo 11: Àgbáyé sayẹyẹ ọdún 50 tí ènìyàn kọ́kọ́ wọ inú Osupa
Sẹnetọ Buruji Kashamu: Gbajugbaja oniṣowo ati oloṣelu ni Buruji Kashamu nigba aye rẹ, ki o to di oloogbe ni ọjọ Kẹjọ, oṣu Kẹjọ ọdun 2020.
 a bí nneka bẹ ́ ẹ ̀ la tọ dàgbà nílùú warri tíí ṣe agbègbè del , ta lórílẹ ̀ èdè naìjíríà .
Amarachi ni alainitiju ni Kemi Afolabi o ni oun kaanu ẹni to ṣe e ni abiyamọ.
Kinihun yii ni wọn ta ajọ LASSESSO lolobo pe o wa ni agbegbe Muri Okunola ni Victoria Island l'Eko.
Ṣugbọn ó ti mọ ohun tí wọn ń rò ní ọkàn wọn.
O si seese ki iru iriri nla ti wọn ni lati igba ewe yii nipa lori igbe aye wọn lọjọ iwaju.
Ǹkan tí a mọ̀ nípa kọ́lẹ̀jì olùdìbò tó ń fìdì ẹni ti yóò jẹ ààrẹ ilẹ̀ Amérika múlẹ̀ Aàbò tó péye yóò wà fún àwọn tí yóò kópa nínú ìfẹsẹwọ̀nsẹ̀ Naijiria àti Sierra Leone ní Benin - Obaseki Wo iye owó tí ìjọba Amẹrika ń na sí ìdìbò Ààrẹ àti ibi tí owó náà ti ń wá Oluwo ti ìlú Iwó kìí ṣe ẹgbẹ́ Àtaọjà Osogbo - Alaafin ìlú Ọ̀yọ́ 3) Yinka FaletiNi Missouri: Ọgbẹni Yinka Faleti, to jẹ ọmọ ipinlẹ Eko, naa n dije lati inu ẹgbẹ oṣelu Democrat, bo tilẹ jẹ pe ẹgbẹ oṣelu Republican lo n dari nibẹ.
OLUWA sọ fún mi pé: “Ọmọ eniyan, ṣé o rí ohun tí wọn ń ṣe?
Àwọn gómìnà tẹ́lẹ̀rí tó ti dèrò ẹ̀wọ̀n Àrà kengé!
[Ẹ máa ṣe èyí ní ìrántí mi.
gba ẹkunwo won lati ọjọ tipẹ, nitori  pe ẹ̀gbẹ̀rún
Bi o tilẹ jẹ pe ọjọ ori ti lọ lara iya'ṣugbọn ẹwa iya ko lọ.
Oun naa si wa lara ipinlẹ ti ijọba apapọ kede isede fun, bo tilẹ jẹ pe ko bẹ̀rẹ̀ lọjọ ti Aarẹ Buhari kede.
’ rèé Kí lo mọ̀ nípa fẹntilétọ̀, ohun eèlò aṣèrànwọ́ èémí Ọba Eshinlokun ni ki wọn bi ifa leere lati mọ bi asiko alejo naa yoo tu ilu lara si abi bẹẹkọ, tí ifa si fọ ire nipa Oshodi.
Ninu ọrọ rẹ si awọn ọmọ orileede naa,olootu ijọba Acinda Arden ni awọn ko ti mọ pato nnkan to ṣele, ṣugbọn ọjọ yi jẹ ''ọjọ buruku fun orileede New Zealand'' Àkọlé àwòrán, Aworan ibi ti awọn mọṣalaṣi naa wa Mohan Ibrahim,to wa ni agbegbe mọṣalaṣi Al Noor sọ fun iwe iroyin New Zealand Herald pe ''Mo kọkọ ro wi pe ina ọba lo gbe awọn eeyan nigba ti mo ri ti awọn eeyan n sare kitakita'' ''Awọn ọrẹ mi ṣi yi wa ninu mọṣalaṣi'' Mo ti n pe awọn ọrẹ mi lori ago ṣugbọn mi o ti gburo ọpọ ninu wọn.
Oun to jẹ kayefi ni bi wọn gbe ori awọn ọkunrin mẹta naa, ti wọn si náà duro ni ẹgbẹ awọn oku naa.
OLUWA, ìwọ Ọlọrun ẹ̀san,ìwọ Ọlọrun ẹ̀san, fi agbára rẹ hàn!
Fayose: Àwòrán ìgbeyàwó ọmọ Fayose táwọn èèyàn ń kẹ́kòó nípa òṣèlú lára rẹ̀
Ati pé kò sí Ọlọrun mìíràn àfi ọ̀kan ṣoṣo.
“Ohun tí àwọn ọmọbinrin Selofehadi bèèrè tọ́, fún wọn ní ilẹ̀ ìní baba wọn láàrin àwọn eniyan baba wọn.
Awọn olori ni yoo yanju ọrọ naa lọna to tọ, lai da wahala tabi ọta silẹ laarin awọn eniyan orilẹ-ede mejeeji.
 kìí ṣe Ibrahim nìkan, Kennedy Dede ẹni ọdun mejidinlọgbọn Augustine Ngok, Gabriel Sorewei, Osabanjo Owoyale, Augustine Wallace, Stanley Eteno, Hassan Babatunde, Temitayo Adigun, àti Kubat Abraham jẹ́ díẹ̀ ti a le dárúkọ.
Gẹgẹ bi Kọmisọna ọlọpa nipinlẹ Imo, Rabiu Ladodo ti kede rẹ lasiko to n fi oju awọn afurasi ọhun han, salaye pe,iya ọmọ tuntun naa lo gbimọ pọ pẹlu awọn eeyan miran nibi to ti bi ọmọ tuntun ọhun lati ta ọmọ rẹ fun awọn eeyan kan ni ipinlẹ Rivers.
Ẹ óo máa rú ẹbọ yìí pẹlu ẹbọ ohun jíjẹ ati ẹbọ ohun mímu rẹ̀, gẹ́gẹ́ bí ìlànà ti ọjọ́ kinni, 
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Jeremiah Addo: Ọmọ ọdún méjì tó ṣeeṣe kò mọ̀wé jù l'ágbàáyé Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Jeremiah Addo: Ọmọ ọdún méjì tó ṣeeṣe kò mọ̀wé jù l'ágbàáyé 27 Ẹrẹ̀nà 2019 Botilẹjẹ wi pe ko fẹsẹ kan ileewe ri, o mọ orukọ ogoji orilẹede ati olu ilu wọn.
Yóo rán olùrànlọ́wọ́ sí ọ láti ilé mímọ́ rẹ̀ wá,yóo sì tì ọ́ lẹ́yìn láti Sioni wá.
"Bí Ọlọ́run bá gbọ́ àdúrà mi, tí mo parí iléèwè, tí mo rí iṣẹ́ gidi, .
 Àkámó ni a ń pe àmì yìí .
O ku ki a mọ boya yoo wọle saa keji si 'White House' abi bẹẹ kọ.
Àwọn ọmọ Nàìjíríà ṣe ìwọ́de l'Osogbo lórí àfikún owó epo bẹntiróò Wo ohun tí ilé ẹjọ́ ní kí wọ́n ṣe fún Sunday Shodipe, afurasí ìṣekúpani l'Akinyele Wo àwọn òfin tuntun tíjọba fí síta lórí lílọ ìrìnàjò sílẹ̀ òkèrè Ọwọ́ ọlọ́pàá tẹ afurasí olóògùn owó tó fẹ́ gé ọmú obìnrin kan nílé ìtura Àwọn èèyàn ìpínlẹ̀ Oyo gbarata lórí àlékún owó epo bẹntiróò Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Suspected ritual killer: Ọwọ́ tẹ afurasí olóògùn owó tó fẹ́ gé ọmú obìnrin nílé ìtura4 Owewe 2020 Fídíò, Akomolede: Bolaji Faleke ni Olùkọ́ tó ń kọ́ wa ní àṣà oge ṣiṣe lórí BBC Yorùbá1 Owewe 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Iroyin so pe, osise oko oju ofurufu Emirate gbemi-mi, leyin ti o jabo lati enu ona pajawiri oko ofurufu ohun ti o wa ni papako ofurufu Entebbe lorile-ede Uganda.
ipinle Zamfara sile, wa ni ibamu ofin ati asẹ ajo naa.
Ẹmi mokanlẹladorin s'ofo ninu ajalu baalu ilẹ Russia Bauchi: Ọkan ninu ibeji to lẹpọ ye isẹ abẹ Oju ẹsẹ ni gbogbo awọn to wa ninu ijamba ọkọ naa ti gb'ẹmi mi.
Nígbà tí ó tó déédée agogo márùn-ún alẹ́ àwọn tí ń ṣọ́ ilé náà parí iṣẹ́ wọn wọ́n sì jáde kúrò ní ààfin.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Yemi Elesho, ìlúmọ̀ọ́ká adẹ́rínpòṣónú jẹ́wọ́ pé ẹnu nìkan kọ́ lòun ní lórí 'Ṣé o láyà?
Bi eeyan ba ti n fi ọkan tẹle iṣẹlẹ agbo oṣelu yoo ti ṣe akiyesi pe iyawo aarẹ Naijiria Aisha Buhari ko fi tinufẹdọ dunnu si awọn to n ṣe ijọba pẹlu ọkọ rẹ.
Ṣebí gbogbo yín ni ẹ̀ ń bá mi ṣọ̀tẹ̀!
Mo rẹọ gbogbo àwọn gómìnà APC tó kù láti gbé irú ìgbésẹ̀ bẹ́ẹ̀"" Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Grandma Maruwa: Ó yẹ kí obìnrin sisẹ́ láì wojú ọkọ kó tó jẹun Ìṣúná 2021 yóò ṣíjú ọ̀dọ́ kúrò nínú ìwá Yahoo-Yahoo - Sanwo-Olu Oríṣun àwòrán, Twitter/Mr_JAGss Gomina Babajide Sanwo-Olu ti gbe aba iṣuna oni triliọnu kan Naira le diẹ (₦1."
Ayàwòrán náà gba ìpè àwọn ọlọ́pàá lẹ́yìn-in ọgbọ̀n ìṣẹ́jú lẹ́yìn tí ó túwíìtì àwòrán náà pẹ̀lú wípé lẹ́sẹ̀kẹsẹ̀ ni ó mú un wálẹ̀, bẹ́ẹ̀ ni CHRD ṣe ti sọ.
egbe ati ile-ise igbohun safefe , Nigeria Elections Debate Group ati
Òṣìṣẹ́ OSCOTECH gb'òmìnira lọ́wọ́ ajínigbé darandaran Fulani Fulani darandaran lo iwa ipa ni guusu Akurẹ Ọmọogun pa darandaran mẹwa ni Adamawa 'Iha kokanmi Buhari lewu fun Nigeria' Oṣiṣẹ eleto aabo abẹlẹ kan ṣalaye fun BBC pe, niṣe ni wọn n sun awọn eniyan naa lẹyin ti wọn pa wọn tan.
Oríṣun àwòrán, EPA Atẹjade naa, to fi sita lẹyin ipade ẹgbẹ naa lowurọ ọjọ Ẹti, aarẹ ẹgbẹ YWC ni o kọ ni lominu pe, awọn ikọlu to waye fun wakati mejidinlaadọta laidakẹ, lee waye ni Naijiria yii, lai si pe ijọba ka awọn to n ṣiṣẹ laabi naa lọwọ ko.
6 28011 Orilẹede Lithuania 764 27.
Lẹta rẹ naa waye lẹyin ti Oloye Ọbasanjọ kọ lẹta kan si aarẹ tẹlẹ ni Naijiria, Goodluck Jonathan, lati bu ẹnu ẹtẹ lu iṣakoso rẹ.
Èmi ni ẹbọra kékeré inú ọ̀gán, orúkọ ẹni tí ń jẹ́ Èṣù-kékeré-òde.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, BBC Africa Eye: Akọroyin fẹ ìdí àwọn oníṣẹ́ ibi ọmọ ogun síta RRS ni awọn ti n wa Tijani fun igba pipẹ lori ẹsun pe o ja ẹrọ ilewọ lọwọ eniyan kan loju popo.
Nitori naa, sisa ara rẹ sinu oorun, tabi mu omi gbigbona, ati wiwẹ pẹlu omi gbigbona ko le ran ọ lọwọ.
Wọ́n ni, kínni ìṣẹ́ tí àwọn tún gbà mọ́
Ó sọ fún wọn pé, “OLUWA Ọlọrun Israẹli ní, ‘Mo kó yín jáde wá láti Ijipti, mo gbà yín kalẹ̀ lọ́wọ́ àwọn ará Ijipti, ati gbogbo àwọn eniyan yòókù tí wọn ń ni yín lára.
Igbakeji aarẹ Yẹmi Ọsinbajo, to bawọn peju sibi ayẹyẹ naa to waye nilu Eko, sapejuwe ọlọjọ ibi naa gẹgẹ bii akikanju to maa n mu ayipada rere ba nkan ninu itan eto iselu orilẹede yii.
Òun bá dáhùn pé, ‘Ọgọrun-un garawa epo.
 Òun ni èni àkọ ́ kọ ́ tí ó jẹ ́ ọmọ bíbí ìlú Ìbàdàn tí ó kọ ́ kọ ́ gba oyè b.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ilu Ubang, jẹ ilu kan nibiti ede ti awọn ọkunrin wọn n sọ yatọ si ti awọn obinrin wọn.
Won sin oku olori egbe oselu alatako lorile-ede Zimbabwe Morrgan Tsvangirai si ilu abinibi re ni Buhera, ni eyi ti awon alatileyin re, awon asoju orile-ede lagbaye ati awon agbaagba ninu egbe oselu to wa lori alefa Zanu-PF ni won peju pese sibi isinku ologbe naa.
4 5903 Orilẹede Mayotte 56 21.
Nígbà tí alẹ́ lẹ́, òun nìkan ni ó wà níbẹ̀.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ethiopia: Abiy Ahmed di olóòtú ìjọba 28 Ẹrẹ̀nà 2018 Oríṣun àwòrán, EPA Àkọlé àwòrán, Olori agbarijọpọ ẹgbẹ to wa nijọba lo ma'n saba je olotu ijọba ni Ethiopia Agbarijopo ẹgbẹ to wa nijọba lorilẹẹde Ethiopia, EPRDF, ti yan Abiy Ahmed gẹgẹ bi olori wọn tuntun.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù The New Pandemic: Kíni àwọn onímọ̀ sáyẹ́ńsì ń sọ nípa rẹ̀?
Ṣugbọn nígbà tí mo tún gba ibẹ̀ kọjá,mo wò ó, kò sí níbẹ̀ mọ́;mo wá a, ṣugbọn n kò rí i.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Tunde Kelani: Àwa ọmọ Nàíjíríà kò le è bá òyìnbó mọ́ láéláé nínú sinimá ṣíṣe ''Igbeyawo wa ko tii ju ọjọ mọkanlelaadọta lọ, a ṣẹṣẹ n gbero lati bimọ ni, bẹẹ si ni mo nifẹ ọkọ mi,'' Rabi lo woye bẹẹ.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ta ni Aminat Abiọdun, Ìyálóde ilẹ̀ Ìbàdàn tó d'olóògbé Ìlérí àsan ni Atiku ń se lórí àtúntò Nàíjíríà - APC N kò mọ bí wọ́n ṣe n bá obìnrin sọ̀rọ̀ ìfẹ́ - Aláàfin Èmi kìí se Ọlọ́run, ẹ yé lo fọ́tò mí fún ẹ̀bùn - Adeboye Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Kékeré ni mo ti mọ̀ pé iṣẹ́ apanilẹ́ẹ̀rín l'ọ̀nà mi' Akanṣe adura yoo waye fun oloogbe ni aago mẹrin irọlẹ oni tii ṣe ọjọ Aiku, ninu ọgba ile iṣẹ tẹlifisan ipinlẹ Ọyọ, (BCOS) to n bẹ ni agbegbe Baṣọrun nilu Ibadan.
Ọjọ ti pẹ ti awọn ọmọ ẹgbẹ Awawa ti n ṣoro bi agbọn, ṣugbọn ariwo tun sọ lori wọn laipẹ yii, lasiko isede coronavirus.
Wọ́n dá a lóhùn pé, “Kò sí ohun tí ọkunrin náà kò bi wá tán nípa ará ati ẹbí wa, ó ní, ‘Ǹjẹ́ baba yín wà láàyè?
Idà ni yóo pa àwọn ọkunrin yín,àwọn akikanju yín yóo kú sógun.
Ṣugbọn bí ẹ bá mẹ́nu ba “Ẹrù OLUWA,” lẹ́yìn tí mo ti ranṣẹ si yín pé ẹ kò gbọdọ̀ mẹ́nu bà á mọ́, 
Awọn mọlẹbi oloogbe ni iku iroyin iku rẹ ba awọn lojiji gẹgẹ bi Olumide Akanbi ṣe fi ọrọ sita lorukọ ẹbi.
Àwọn ará Amoni yóo gbọ́ràn sí wọn lẹ́nu.
Oríṣun àwòrán, Martin Keene/PA Orukọ baba rẹ n kọ?
" Nigba to n sọrọ lori ajọṣepọ ti ko dan mọran, to maa n waye laarin awọn ọmọ Naijiria ati awọn ọmọ ilẹ South Africa, agba Inaki ni aimọkan lo n ba awọn ọmọ ilẹ South Africa naa ja, ti wọn ṣe n kọju ija si awọn alejo.
Idije naa yoo waye laarin ọjọ karun si ikẹrinlelogun oṣu kẹjọ ni orilẹede france.
Bi ọpọ ero ṣe n darapọ mọ iwọde naa lojojumọ lawọn miran n gbe igbesẹ ki ifẹhonuhan ọhun dun, ko si larinrin.
Koda o ni anfani miran tun wa.
Aramọnda goolu ni goolu ọhun ti Ighalo fi ṣẹ awọn alatako leegun ẹyin lalẹ Ọjọbọ Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Mò ń fojú sọ́nà láti bá Emir àná, Sanusi kírun lọ́jọ́ Jímọ̀ - Aráàlú Awe Ẹ múra o, epo rọ̀bì di òkùtà lọ́jà torí Coronavirus, ìlú yóò le koko - NNPC figbe ta Ẹ́ gbaradì, to bá lo jẹnẹrátọ̀ àbí tà á, ò ń fi ẹ̀wọ̀n ọdún mẹ́wàá ṣeré - Sẹ́nétọ̀ ń dábàá Agbófinró, tó bá wa ọkada àbí kẹkẹ maruwa l'Eko, o rugi oyin - Sanwo-Olu Ará Yúróòpù ẹ fìdí mọ́lé yín, mo ti gbé ìlẹ̀kùn Amẹ́ríkà tìpa torí Coronavirus - Trump Ìjọba ń ṣe afárá Eko Bridge l'Eko, àwọn ọ̀nà àbùdá tí ẹ lèè gbà nìyí Ayo marun un sodo ni Man fi ṣagba LASK, Daniel James lo gba goolu keji sawọn nigba ti Juan Mata lo gbayo ẹlẹẹkẹta wọle ki Mason Greenwood ati Pereira to fi ọba lee Oríṣun àwòrán, Getty Images Ẹwẹ, ajọ UEFA ko gba ki awọn ololufẹ awọn ẹgbẹ agbabọọlu meejeji wọlẹ lati wo wọn nitori aarun coronavirus to n tan kalẹ kaakiri agbaye.
Igbanu mẹta lẹka ẹṣẹ kikan to lami laaka lo wa lo lọwọ AJ nikan.
Ọlọkan ire ni Immaculate Okochu, eleto igbeyawo rẹ sọ fun BBC."
Àwọn ará Moabu ranṣẹ sí àwọn olórí Midiani pé, “Àwọn eniyan wọnyi yóo run gbogbo ohun tí ó wà ní àyíká wa bí ìgbà tí mààlúù bá jẹ koríko ninu pápá.
''Lasiko ti wọn n wa awọn eniyan ti awọn darandaran naa jigbe lọ si ileewosan to wa ni ilu Ọwọ, ni wọn ri oku Paul Sodje ati ọrẹ rẹ ni ile igbokusi to wa ni Ọwọ.
Nígbà tí wọ́n bá ń wọ àgọ́ àjọ lọ, tabi nígbà tí wọ́n bá súnmọ́ ibi pẹpẹ láti ṣe iṣẹ́ alufaa wọn, láti rú ẹbọ sísun sí OLUWA; omi yìí ni wọ́n gbọdọ̀ fi fọ ọwọ́ ati ẹsẹ̀ wọn kí wọ́n má baà kú.
idibo gbe jade, Independent National Electoral Commission (INEC) lo fihan pe aare
Òhun tó yẹ ko mọ nípa Dókítà Stella Immanuel to ní ohùn dóòlà alàrùn 300 lọ̀wọ̀ ààrùn Covid-19 Jiji ti awọn ọmọ Naijiria ji lowurọ ọjọ Iṣẹgun ni wọn ṣalabapade fọnran fidio kan, ti o ṣe afihan Dokita obinrin alawọdudu kan lorileede Amẹrika to n sọ fawọn eeyan pe arun Covid-19 ni oogun to daju.
Ní ọdún 1976 ni Kọ́lá Akínlàdé fẹ̀yìn tì.
Ìwọ tí yóo wó Tẹmpili, tí yóo tún kọ́ ọ ní ọjọ́ mẹta, 
Ayọ̀ ń bẹ fún àwọn tí ń ṣe ẹ̀tọ́,àwọn tí ń ṣe ohun tí ó tọ̀nà nígbà gbogbo.
Ọjọ́ ńlá sì ni ọjọ́ náà, nígbà tí àwọn méjèèjì fi ojú gán-ánní ara wọn, ìjàǹbá pàdé ìjàngbọ̀n, ṣìgìdì pàdé àǹjànnú, kìnnìún méjì fi ojú rí ara wọn.
 gùn azithromycin ní ó dára jùlọ nítorí ó ṣe e lò gẹ ́ gẹ ́ bí àgbémí lẹ ́ ẹ ̀ kan ṣoṣo .
Aarẹ Buhari yọ Babachir Lawal nipo losu kẹwa ọdun 2017 lẹyin ti igbimọ ti wọn gbe kalẹ lati tan ina wadi ẹsun iwa ibajẹ ti wọn fi kan-an gbe aba tọ aarẹ lọ wi pe ko yọ ọ ni ipo.
Afẹnifẹrẹ ko sẹsẹ maa tẹnu mọ atunto isejọba gẹgẹ bi ohun to le dẹkun wahala to n koju orilẹede Naijiria .
Olorin Emeli Sande ni o si ipade pelu orin orile-ede naa ni gbogan ti asia gbogbo awon omo egbe metalelaadota wa.
    Irú ìbéèrè bá wọ̀nyí ni mo ṣe lọ́wọ́ iwin náà, ibi tí mo sì ti ń ṣe bẹ́ẹ̀ lo ti sọ fún mi pé ó béèrè bí mo bá kọ̀wé sí òun tàbí n kò kọ àti wí pé òun sọ pé n kò rí nǹkan fi kọ̀wé.
Adugbo Ọja Ọba nilu Ibadan, tii ṣe olu ilu ipinlẹ Oyo ni Eji Gbadero, ọdọmọde si lo ti tẹle aburo baba rẹ wa gbe ni Eko, o kọ iṣẹ ọwọ, to si da Ileesẹ tiẹ naa silẹ to n ṣe ésó.
Nígbà gbogbo ni ó ń gbadura kíkankíkan fun yín, pé kí ẹ lè dúró ní pípé ati pé kí ẹ lè kún fún gbogbo ohun tíí ṣe ìfẹ́ Ọlọrun.
Wọ́n bà á lójú jẹ́ yánnayànna,tóbẹ́ẹ̀ tí ìrísí rẹ̀ kò fi jọ ti eniyan mọ́.
Awọn afurasi naa ni Masagi Lawal, Muhammed Usman, Adamu Adamu, ati Abubakar Hawawu.
Ẹbọ ni mo wá rú sí OLUWA.
Ó dàbí kí ọkunrin kan máa lọ sí ìdálẹ̀, kí ó fi ilé rẹ̀ sílẹ̀, kí ó fi àṣẹ fún àwọn iranṣẹ rẹ̀, kí ó fi iṣẹ́ ẹnìkọ̀ọ̀kan fún un, kí ó wá pàṣẹ fún olùṣọ́nà pé kí ó ṣọ́nà.
Àwọn jagunjagun tí ó ti kọjá ìwọ lo mú wọn lọ, àwọn tí ń sọ̀rọ̀ tí ọ̀rọ̀ náà ń múlẹ̀ ìwọ tí mú wọn kúrò lórí ilẹ̀, àwọn ènìyàn pàtàkì nínú ẹgbẹ́ àti àwọn ìjòyè nínú igbìmọ̀ ni ìwọ ti fẹ́ ojú wọn kù, inú mi sì dùn lónìí, tí mo mọ ẹ̀dá tí ó tóbi bí ìwọ.
African Drum Festival 2019: Ẹ wo àwòrán tó làmìlaaka níbi Àjọ̀dún Ìlù Ọdún 2019!
Ẹ̀yin tí ẹ kò tíì rí àánú gbà tẹ́lẹ̀ ṣugbọn nisinsinyii ẹ di ẹni tí Ọlọrun ṣàánú fún.
OLUWA bá sọ fún mi pé kí n sọ ọmọ náà ní Maheriṣalali-haṣi-basi.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsèjẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọ Ṣugbọn ṣa, ẹni to sọ ọrọ naa fun BBC nileeṣẹ aarẹ, ko sọ asiko ti aya aarẹ yoo pada sile.
"Labẹ isejọba mi ni ipinlẹ yii, ko si ẹnikẹni ti yoo pa eniyan ti yoo si lọ bẹẹ lai foju ba ofin.
lojoBo(Thursday), eleyi ti igbakeji aare, ojogbon Yemi Osinbajo tuko re.
 oríṣi àjẹsára náà tí à n gún fún ni bí abẹ ́ rẹ ́ kò léwu fún àwọn tó ní àrùn kògbóògùn hiv / aids láti lò , a sì lè lo oríṣi àjẹsára náà tí à n gba ẹnu fúnni níwọ ̀ n ìgbà tí ènìyàn náà kò bá tíì ní àmì àrùn náà .
Ṣugbọn àwọn ọmọ Lefi lè ra gbogbo àwọn ilé tí wọ́n wà ní ààrin ìlú wọn pada nígbàkúùgbà.
Iléeṣẹ́ ológun, ẹ kú àpọ́nlé mi, èmi náà yóò máa ṣúgbàá yin - Seyi Makinde Ìjọba Ọyọ yàtọ̀ sí ti Ọṣun àbí Ekiti tí APC leè fi àṣẹ iléẹjọ́ lé dànù - Seyi Makinde Makinde vs Adelabu: Ilé ẹjọ́ tó ga jùlọ ní Nàìjíríà ní yóò yanjú ọ́rọ́ ìdìbò Gómìnà Oyo O ni lọwọlọwọ bayii, oun ti gbe ẹhonu oun lori ibo gomina naa lọ sile ẹjọ to ga julọ nilẹ wa lati ba wọn da si lẹyin ti ile ẹjọ Kotẹmilọrun ti kede pe igbimọ olugbẹjọ awuyewuye ibo naa ko fun oun lanfaani to lati sọ tẹnu oun.
A gbọ pe wọn pàdé ara wọn lásìkò àyájọ ọdún ominira Naijiria lọdun 1981, ti Ọlọrun fi ọmọ méjì tawọn lọ́rẹ.
Ilẹ̀ sì gbé Kora mì pẹlu àwọn eniyan rẹ̀ ati gbogbo ohun ìní wọn.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Xenophobic Attack:Àwọn ọmọ Naijiria sọ fun South Africa pé Ó tó gẹ́"" 2 Owewe 2019 Oríṣun àwòrán, Marco Longari Àkọlé àwòrán, ọpọlọpọ miliọnu ọja ati ohun ini ni wọn ti jo nina Oriṣiriṣi iroyin lo ti gba ayelujara kan lori ikọlu to n waye lọwọ lorilẹ-ede South Africa."
Nisinsinyii, mo mọ̀ dájú pé o óo jọba ilẹ̀ Israẹli, ìjọba Israẹli yóo sì tẹ̀síwájú nígbà tìrẹ.
Lọ̀ wọ́n pọ̀ gẹ́gẹ́ bíi ti àwọn tí wọn ń ṣe turari, kí o fi iyọ̀ sí i; yóo sì jẹ́ mímọ́.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Britain: Ọmọ-ogun 8200 la fẹ́ gbà láti orílẹ̀-èdè Commonwealth 5 Bélú 2018 Oríṣun àwòrán, PA Àkọlé àwòrán, Adinku to ba wọn ọhun ni eyi to ti i buru ju lati ọdun 2010, gẹgẹ bi ohun ti ileeṣẹ ayẹwo kan sọ Ijọba ilẹ Gẹẹsi ti ṣetan lati kede fun awọn eniyan pe, wọn fẹ ẹ bẹrẹ si ni fi iwe pe awọn ọmọ orilẹede mi i lati darapọ mọ ileeṣẹ ologun wọn.
Nígbà tí gomina rí ohun tí ó ṣẹlẹ̀, ó gbàgbọ́; nítorí pé ẹ̀kọ́ nípa Oluwa yà á lẹ́nu.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Alahan goolu ni nitori pe o le sọ ọpọlọpọ ede.
Bí o sì rí ọ̀pọ̀ ènìyàn, tí wọn fi ẹ̀kọ́ ṣe ẹ̀rín rín
Nigeria vs Benin: Àwọn ọmọ Nàìjíríà bu ẹnu ẹ̀tẹ́ lu NTA lórí ìgbóhùnsáfẹ́fẹ́ wọn
Wọ́n fún wọn ní ìlú Heburoni ní ilẹ̀ Juda, ati gbogbo ilẹ̀ pápá oko tí ó yí i ká, 
Jẹ́ kí jìnnìjìnnì boàwọn tí ń yọ̀ mí, tí ń ṣe jàgínní mi;kí wọn sì gba èrè ìtìjú.
9bn, to jẹ ti ijọba ipinlẹ Eko.
Sùgbọ́n fún gbogbo àwọn ipele ẹ̀kọ́ tó kù láti ilé iwé alákọ́bẹ̀rẹ̀ titi de àwọn onipele kẹrin nílé iwé girama, ìjọba ni òun yóò kéde lẹ́yìn ti arídáju bá ti wa pé gbogbo ìlàna tó yẹ ló ti wà nílẹ̀.
Aare Buhari ni yoo maa sakoso ajo naa fun odidi ọdun kan gbako.
" Muslim ló gba ọrọ yìí wá bákan náà.
 Ẹni ọgọ ́ fa ọdún ni baba mi olóyè fabiyi Àyàndá Òpó , mọjàlekan , aláànì akẹsìn , nígbà tó tẹ ́ rí gbaṣọ .
Nítorí pé, láti ìgbà tí mo ti lọ sí ọ̀dọ̀ Farao láti bá a sọ̀rọ̀ ní orúkọ rẹ, ni ó ti ń ṣe àwọn eniyan wọnyi níbi, bẹ́ẹ̀ ni o kò sì gba àwọn eniyan rẹ sílẹ̀ rárá!
“Bẹ́ẹ̀ ni ẹ mú OLUWA bínú ní Tabera ati ní Masa, ati ni Kibiroti Hataafa.
Oríṣun àwòrán, Screenshot Amotekun yóò gba owó oṣù kẹtàlá ní ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́ - Seyi Makinde Wo ìròyìn tó pọ̀ jùlọ táwọn èèyàn ń wá ní Google lọ́dún 2020 Àlàyé rèé lórí ìdí tí mo fi lọ sílé Tinubu - Rashidi Ladoja Ẹgbẹ́ òṣèlú alátakò takú láti gba èsì ìbò ààrẹ ní Ghana Niṣe ni gbogbo awọn to wa nibi ijoko naa n sare kijokijo lasiko ti Ọjọgbọn Pondei daku lori aga to joko si.
Oríṣun àwòrán, Halimat Babamale Àkọlé àwòrán, Awọn ijọba ilu ta wa ṣe gbogbo eto bo ti ṣe tọ ati bo ti ṣe yẹ O ni ti awọn to n ṣe ijọba a maa saba rin irinajo lọ si ilu okere ti wọn si ma n ri bi nnkan ti ṣe ri nibẹ.
Àsìkò yí ni ewé titun, ewé tútù ń so lórí igi.
Oríṣun àwòrán, others Àkọlé àwòrán, Ọkan tun re e lara awọn ọkọ ayọkẹlẹ ti ibugbamu fi ọwọ ba, a ko le sọ boya ina tabi ile to wo lo sọ ọkọ yii di rirun jege-jege A gbọ pe awọn akẹkọ ile iwe naa wa ni adura owuro, lasiko ti ibugbamu naa ṣẹlẹ, leyi to mu ẹmi rẹ lọ.
Igbesẹ Kẹjọ: Ki esi Igbimọ naa to le fi ẹsẹ mulẹ, ida meji ninu mẹta awọn aṣofin ni Ile Igbimọ Aṣofin naa gbọdọ buwọlu Ni kete ti wọn ba ti buwọlu naa ni Igbakeji Gomina naa yoo fi ipo rẹ silẹ ni kiakia.
Saaju àsìkò yii ni awọn ile iṣẹ ilẹ Gẹẹsi ti dokowo biliọnu marun poun sí Naijiria ti idokowo laarin Naijiria ati ilẹ Gẹẹsi lọdọọdun si le ni biliọnu mẹta poun.
OLUWA jọba, kí àwọn orílẹ̀-èdè wárìrì;ó gúnwà lórí àwọn kerubu; kí ilẹ̀ mì tìtì.
Ẹ̀yà Simeoni ni yóo pàgọ́ tẹ̀lé ẹ̀yà Reubẹni; Ṣelumieli ọmọ Suriṣadai ni yóo jẹ́ olórí wọn.
Àwọn nǹkan wọn-ọnnì tí ó ti ń ṣe gẹ́gẹ́ bí ọmọ ọ̀dọ̀, ẹlòmíràn ń bọ̀ wáa ṣe é lọ́dọ̀ òun.
Nígbà tí ó gbọ́ nípa Jesu, ó rán àwọn àgbààgbà Juu kan sí i pé kí wọn bá òun bẹ̀ ẹ́ kí ó wá wo ẹrú òun sàn.
Mo wáá ṣe àkíyèsí pé ìwé pẹlẹbẹ kan wà ní oókan-àyà rẹ̀, ohun tí wọ́n sì kọ sí inú ìwé náà ní èyí: ‘Mọ́tò kò ní ìbátan, rélùwé kò ní ìyàwó, bẹ́ẹ̀ ní alùpùpù kò ń tijù ẹnikẹ́ni, ẹni tí ó bá fi ojú di irin á bá irin lọ.
Naomi sàlàye pé ẹni ti kò ba ti fẹ wọ́n yóò fọsọ, pọnmi, yóò si maa bọ̀wọ̀ fún ìyàwó wọ́n Oríṣun àwòrán, AFP Àkọlé àwòrán, ipolongo Bring back our girls"" 7."
Kódà gbọingbọin la wà lẹ́yìn Akintoye gẹ́gẹ́ bíi adarí YWC nílé, lẹ́yìn odi Ìwọ tó ń ṣí ara sílẹ̀ lọ ṣọ́ọ̀ṣì, ṣé apàyàn kọ́ ni ẹ́ báyìí?
Bí ó ti ń rọbí, ọ̀kan ninu àwọn ọmọ náà yọ ọwọ́ jáde, ẹni tí ń bá a gbẹ̀bí bá so òwú pupa mọ́ ọn lọ́wọ́, ó ní “Èyí tí ó kọ́ jáde nìyí.
Iyẹn Otun Olubadan, Lekan Balogun ati Balogun Owolabi Olakulehin.
laarin onile ati ayalegbe, eyi to ni se pelu adehun owo asan-sile, pe onile ko
Meje lati Borno ati Edo, mẹfa lati Rivers ati Ogun,mẹrin ni ilu Abuja, Akwa Ibom ati Bayelsa, mẹta ni ilu Kaduna, meji ni ilu Oyo, meji ni Delta ati Nazarawa, ẹyọkan ni Ondo ati Kebbi.
Ọlọ́run Ọba nìkan ló mọ iye ọmọ Naija to ń lọ àwọn ilé-ìwé gíga ní Orílẹ̀èdè UK lọ́dọọdún.
Láti inú ẹ̀yà Bẹnjamini, a yan Elidadi ọmọ Kisiloni.
Irú kí ni o ṣe sí wa yìí?
Akori ti ọdun yii ni Iṣẹ iroyin ati idibo ni akoko ti iroyin ofege pọ nita.
Adarí iléeṣẹ́ BlaBlaCar, Irina Reyder sọ pé wọ́n fagi lé ìfìwépè òun wá sórí ètò Ojúmọ́ Ire lórí Channel One lẹ́yìn tí olóòtú rí i pé obìnrin ni òún jẹ́.
Nítorí a pa á run kúrò lórí ilẹ̀ alààyè.
Nigba ti won fi owo sinkun ofin mu won, ile-ise olopaa so pe, won n fi oro wa won lenu wo tori pe awon olopaa gbo oro ti won n so, nipa bi won se seku pa awon eniyan, ti won di oku won sinu apo ora nla, ti won si so awon oku naa sinu oku, eyi ti sokunfa ikorira laarin ijoba ati awon ara-ilu.
Gbọ́ OLUWA, kí o sì ṣàánú mi,OLUWA, ràn mí lọ́wọ́.
 erin tí Àjàpadá pa fún àwọn ará ìlú Àkúrẹ ́ fún àwọn aré ìlú ní ìwúrí àti ìbẹ ̀ rù , nítorí pé , ọdẹ tí ó bá pa erin jẹ ́ ọdẹ abàmì àti akíkanjú ọdẹ .
’Wọn óo rí ohun jíjẹ ní gbogbo ọ̀nà,gbogbo orí òkè yóo sì jẹ́ ibùjẹ fún wọn.
”Wabba tun so pe “Ti won ko ba soro tabi ki won panumo lori iru isele yii ko lee se orile ede yii ni oore kankan.
O ṣalaye pe oun ko kọkọ fẹ gba ipo ọba orin Fuji nitori ede-ai-yede to wa laarin awọn olorin ṣugbọn oun gbaa lẹyin ti oun tun ero pa lori rẹ.
Coronavirus in Nigeria: Àfẹ́sọ́nà Davido, Chioma ti ní ààrùn coronavirus Oríṣun àwòrán, davido/instagram Gbajugbaja olorin takasufe, David Adeleke ti ọpọ awọn ololufẹ rẹ mọ si Davido ti sọ pe afẹsọna oun, Chioma ti ni aarun Coronavirus.
Láàrin ọdún márùn,Joshua ti gba àmì ẹ̀yẹ méjì, èyí tó túmọ̀ sí pé wọn yòó maa fi ''Sir'' sí iwájú orúkọ rẹ̀.
Ó ti mú gbogbo ìlérí rere rẹ̀ tí ó ṣe láti ẹnu Mose, iranṣẹ rẹ̀, ṣẹ.
Bí àwọn tí wọn ń kórè àjàrà bá wá sọ́dọ̀ rẹ,ṣebí wọn a máa fi díẹ̀ sílẹ̀?
Ẹ̀mí ni ó kọ́ wa bí a ti ń túmọ̀ nǹkan ti ẹ̀mí, fún àwọn tí wọ́n ní Ẹ̀mí.
Orisun orukọ naa bẹrẹ pẹlu bi awọn ọlọla ṣe maa n di ẹbun sinu apoti, ti wọn si maa n pin fun awọn alaini lọpọlọpọ ọdun sẹyin.
Ààrẹ ẹgbẹ́ òṣìsẹ́ Ayuba Wabba, se àpèjúwe ìṣẹ̀lẹ̀ náà bi èyí ti kò ba oju mu rárá.
Ìdí nìyí tí àwọn Juu tí wọn ń gbé àwọn agbègbè fi ya ọjọ́ kẹrinla oṣù Adari sọ́tọ̀ fún ọjọ́ àsè, tí wọn yóo máa gbé oúnjẹ fún ara wọn.
Yéwándé àti àwọn ọmọ náà máa ń wá tọ́jú Orímóògùnjẹ́ nígbà ti ó ń ṣàìsàn lọ́wọ́ tí àìsàn rẹ̀ bá ń yọnu.
Èémí tí ó ń mí jáde dàbí ògúnná,ahọ́n iná ń yọ ní ẹnu rẹ̀.
"Ìlànà tá ń gba pín owó ìdẹ̀rùn lè pupọ nítorí náà, kò ṣeé ṣe fún ọ̀pọ̀ èèyàn nínú ìdílé kan láti gba owó náà.
Àwọn onímọ̀jìnlẹ̀ ni wọ́n mọn ìdí abájọ, àmọ́ àyípadà sí ètò ìlà àti ìwọ̀ oòrùn kópa nínú ìmúrẹ̀wẹ̀sìbáni yìí.
Nígbà tí wọ́n dé Heburoni, wọ́n gbé orí rẹ̀ tọ Dafidi ọba lọ, wọ́n sì wí fún un pé, “Orí Iṣiboṣẹti, ọmọ Saulu, ọ̀tá rẹ, tí ó ń wá ọ̀nà láti pa ọ́ nìyí; oluwa mi, ọba, OLUWA ti mú kí ó ṣeéṣe láti gbẹ̀san, lára Saulu ati àwọn ọmọ rẹ̀.
 Olootu ijọba Ilẹ Gẹẹsi sọ wi pe, abajade ayẹwo abẹrẹ ajẹsara naa fihan wi pe yoo koju arun Coronavirus, nitori naa awọn ti bẹrẹ igbesẹ lati ri wi pe awọn arugbo ati awọn ti arun Conavirus n tete mu ni awọn kọkọ fun ni abẹrẹ ajẹsara naa."
O ti bèrè pé kí wọ́n sún ìgbẹ́jọ́ náà síwájú láti ríidájú pé gbogbo àwọn tí ẹjọ́ náà kan wá sílé ẹjọ́.
Nígbà tí Joṣua tú àwọn ọmọ Israẹli ká, olukuluku wọn pada lọ sí orí ilẹ̀ wọn, wọ́n sì ń gbé ibẹ̀.
gbogbo ọmọ tí ẹ bí ninu ilé yín, ati ẹrú tí ẹ fi owó yín rà gbọdọ̀ kọlà abẹ́.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, SS3 ní mo wà báyìí, mo sì ti gba àmì ẹ̀yẹ̀ púpò nílé-lóko gẹ́gẹ́ bí onílù - Ayansike Daniel ń bọ̀ wá wò mí nítori mo ṣàìsàn ló dàwátì- Baba Daniel Akọ̀wé-owó wọ gàù ní iléẹjọ́ lórí ẹ̀sùn pé ó jí N500,000 lọ́wọ́ ọ̀gá rẹ̀ Ìdùnnú subú layọ̀ nípìnlẹ̀ Ọyọ́, àwọn tó dé láti Lebanon sọ ọmọ wọn ní Seyi Wo ọ̀nà tí o fi lè dáàbò bo ọmọ rẹ lọ́wọ́ COVID-19 níléèwé Ẹ yé parọ́ kiri!
" Nílé ijó Fẹla Anikulapo, àrùn Coronavirus dá fàájì dúró Wo àwọn irọ́ tí wọ́n ń pa fún ọ nípa àrùn Coronavirus Bí àjálù ìbúgbàmù tó gb'ẹ̀mí ọ̀pọ̀ nìlùú Eko ṣe wáyé nìyí Coronavirus ti ba ìfinimọ̀ jẹ́ fún àwọn àgùnbánirọ̀ Opayinka sọ pe Ọlọrun mọ si gbogbo ohun to n ṣelẹ patapata, ati pe Ọlọrun nikan lo le yanju gbogbgo iṣorọ ati aisan to ba n ba aye finra lọwọ yii.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ọ̀kẹ àìmọye ẹ̀rọ àyẹ̀wò káàdì olùdìbò jóná mọ́lé l' Ondo Wo iye àwọn tó ti gbẹ̀mí ara wọn ní Nàìjíríà láàrin ọdún mẹ́rin ìjọba Buhari Gbèsè Nàìjíríà ti lé ní 18 tírílíọ́ọ́nù lábẹ́ ìṣèjọba Ààrẹ Buhari- DMO Wo bí iṣẹ́ abẹ wákàtí mẹ́fà, tí wọ́n fi dóòlà ẹ̀mí ìjàpá tí ọkọ̀ tẹ̀, ṣe lọ Kò sóhun tó ń jẹ́ ‘Captivus’ nílẹ̀ Oodua, mágùn ni mágùn ńjẹ́ - Babaláwo Wo àwọn obìnrin abúlé kan tó dáwó ra ọkọ̀ láti máa gbé aláboyún lọ ilé ìwòsàn Ìtàn rèé nípa bí Ogbomoso ṣe pa ọba, yọ nǹkan ọkùnrin rẹ jó kiri ìlú Lasiko ipade akọroyin ti wọn fi n fa afurasi ọhun le ajọ EFCC lọwọ, igbakeji ọga agba ajọ asọbode, Abdulmumini Bako ni afurasi naa sọ pe ilu Kano ni oun ti wa.
Síbẹ̀síbẹ̀, fún ìdáààbò àwọn ènìyàn, ṣíṣe ṣì kú.
Ó wà níbẹ̀ fún ogoji ọjọ́ tí Satani ń dán an wò.
Saaju ki wọn to gba ipo yi lọwọ Gyan, oun ni Balogun ikọ Black Stars fọdun meje, ti o si jẹ́ goolu mẹtadinlọgọta fun ikọ Black Stars.
 Fun idi eyi, a ko ni salai ma gbosuba fun awon iko wa lorile-ede Naijiria fun ise takun-takun ati akitiyan lati tun bo fese orile-ede Naijiria mule si, paapaa julo fun ipa ti Saraki ko gege bi abenugan ile igbimo asofin Naijiria, ati ninu eto idibo gbogbogbo-o to koja,”Wayii o, fun ipo tuntun yii, ireti wa pe  Saraki ni yoo bere sini tuko IHRC ninu awon ise akanse won ti won
Ìwé náà sọ nípa ìgbé aye gbajúgbajà olóṣèlú Ibadan náà, ti àwọn ọmọ àti olùgbé Ibadan ko le gbàgbé ipa tó kó nínú ètò òṣèlú.
Kí ni ìjọba ń ṣe lórí ààrùn Coronavirus tó wọ Nàìjíríà?
Orílẹ̀èdè Nàìjíríà jẹ́ ọ̀kan nínú àwọn wọ̀nyí ṣùgbọ́n òmìnira dé fún wa ní ọdún un 1960, a sì kúrò lábẹ́ àkóso ilẹ̀ Gẹ̀ẹ́sì.
Lẹ́yìn náà, pa àgbò náà, sì gba ẹ̀jẹ̀ rẹ̀, kí o dà á sí ara pẹpẹ yíká.
 Bakan naa ni oludari ikọ Amotekun nipinlẹ Oyo fikun pe awọn to ba fi orukọ silẹ yoo mu fọọmu naa tọ Baalẹ ati asofin to wa lati ẹkun idibo wọn lọ, ti awọn mejeeji yoo si buwọlu u."
Oríṣun àwòrán, Lere Olayinka Àkọlé àwòrán, Gomina Wike ati Fani-Kayode kọwọrin pẹlu Fayose lọ si ile iṣẹ ajọ Efcc Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 3 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 5 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Ohun tí ojú opó ń rí láwùjọ kò kéré Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ọbìnrin tó fẹ́ ṣojú àwọn ẹ̀yà Sheedi Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, SMS alert: Wo ọ̀nà láti dẹ́kun jìbìtì lórí àṣùwọ̀n báǹkì rẹ Opó Blankson, Mercy sọ̀rọ̀ lórí Blankson ọkọ rẹ̀ 'Ikú ọkọ mi kò gbọdọ̀ já si asàn ni Nàìjíírà' Mercy, opó arakunrin Joe Blankson ni bi ala lo ṣi n ri l'oju oun.
    “Ìrìnkèrindò, èmi ni mo pè ọ́, o kú ìnáwó òkú bàbá rẹ, o kú àsẹ̀hìndè, kí Ọlọ́run jẹ́ kí ẹ́yìn rẹ̀ dára.
Bayii, wọn ni ajọ NFF ti gba lati san owo ajẹmọnu wọn laiyọ ti kikopa ninu ife ẹyẹ agbaye ti FIFA san silẹ.
Pẹlu abajade yii, Naijiria ti tẹsiwaju lati kopa ninu abala to kangun si aṣekagba idije AFCON 2019.
si igbe awon ti won n dari.
Ẹwẹ ninu iwe ipẹjọ kotẹmilọrun to fi ṣọwọ eyi ti agbẹjọro rẹ, Kola Alapinni kọ, ọdaran naa fi ẹsun kan amofin agba ipinlẹ Kano ati gomina.
"Mo mọ̀ pé ibi tó dára ni Ibidun Ighodalo wà báyìí- Adeboye Àwọn ohun tuntun tí a mọ̀ nípa ìgbẹ́jọ́ Wòlíì Sotitobire Gẹgẹ bi ohun ti a ri ka ninu iwe iroyin Naijiria The Punch,akọwe ipolongo ẹgbẹ naa Kola Ologbondiyan fidi ọrọ yi múlẹ pe"" awọn ti sunjọ idibo naa titi di ọjọ Kẹtalelogun oṣu Kẹfa."
Ṣugbọn kò ní jẹ́ èmi nìkan nítorí Baba wà pẹlu mi.
OLUWA Ọlọrun yín yóo máa tì wọ́n sẹ́yìn fun yín, yóo máa lé wọn kúrò níwájú yín, ẹ óo sì gba ilẹ̀ wọn bí OLUWA Ọlọrun yín ti ṣèlérí fun yín.
Àwọn ọmọ Israẹli yóo pọ̀ sí i bí iyanrìn etí òkun tí kò ṣe é wọ̀n, tí kò sì ṣe é kà.
Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Ooni ile Ife: Iná sọ láàfín Ọọ̀ni Ilé Ifẹ̀, Ọọ̀ni ilé ifẹ̀ ní kò sí ẹ̀mí tó báa lọ19 Ògún 2020 5:58 Fídíò, Akomolede ati asa Yoruba: Ẹ wá kọ́ nípa àpòtí ìṣura èdè wa lórí BBC Yorùbá, Duration 5,5820 Ògún 2020 3:13 Fídíò, Mr Macaroni sọ nípa eré tí Freaky Freaky, Sugar Daddy, You are doing well, Freaky Spicy fẹ́, Duration 3,1315 Ògún 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
‘Ṣé o mọ̀ pé, óúnjẹ ni epo pupa, òhun ni a fi ń se ọbẹ̀, tí a fi ń se óúnjẹ gbogbo.
Ó rọ Jehoṣafati láti bá òun lọ gbógun ti ìlú Ramoti Gileadi.
Are orile ede Naijiria Muhammadu Buhari ti lo si ibi ti n won n ko awon ohun alumooni ati ami idagbere si  ni Auschwitz-Birkenau ati Oświęcim lati lo bowo  fun awon to padanu emi won lasiko ogun.
Chemi Lhamo ti jẹ́ ajàjàǹgbara akẹ́kọ̀ọ́ fún ọdún mélòó kan.
OLUWA sì ṣí wọn lójú, wọ́n rí i pé ààrin Samaria ni àwọn wà.
O ni ẹni naa ṣe afihan awọn apẹrẹ bi ori fifọ ati ofikin ti awọn ko si fẹ jafira boya o le ni Coronavirus nitori ilẹ tawọn eeyan ti n ko aisna naa ran ara wọn lo ti dari de.
Oríṣun àwòrán, @Sadiya Àkọlé àwòrán, O je akapo egbe oselu CPC ti o koko gbe Aare Buhari jade 4) Gbemisola Saraki: Gbemisola Saraki jẹ ọkan pataki lara awọn ti oju gbogbo n wo ninu awọn ti Aarẹ Buhari forukọ wọn ranṣe sile igbimọ aṣofin.
Johanu dàbí fìtílà tí ó ń tàn, tí ó sì mọ́lẹ̀.
A o maa fi to o yin leti bi o se n lọ.
" O tẹsiwaju pe ọpọ lo n wa ọmọ ti wọn ko ri to bẹẹ ti awọn kan fi n ra ọmọ lọna aitọ.
Mẹta ninu àwọn mààlúù náà dojú kọ apá ìhà àríwá, àwọn mẹta dojú kọ apá ìwọ̀ oòrùn, àwọn mẹta dojú kọ apá gúsù, àwọn mẹta sì dojú kọ apá ìlà oòrùn.
O ni owo ti wọn o fi maa tun ṣe nikan, awọn papakọ wọnyii ko le pa iru owo bẹẹ.
Ṣugbọn ara ta àwọn Juu nígbà tí wọ́n rí i pé àwọn eniyan pupọ gba ọ̀rọ̀ Paulu ati Sila.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Seyi Makinde-Olaniyan: Igbákejì Gómìnà Oyo ní kò síjà láàrin òun àti Gómìnà 14 Sẹ́rẹ́ 2021 Oríṣun àwòrán, Facebook/Engr Remi Olaniyan Igbakeji Gomina ipinlẹ Oyo, Amoju-ẹrọ Raufu Olaniyan ti ṣalaye pe iroyin ayederu lawọn kan n gbe kiri pe, ija wa laarin rẹ ati Gomina Seyi Makinde.
O ni ijọba to wa lode bayii ṣi ni iṣẹ lati ṣe lori bibọwọ fun ẹtọ ọmọniyan.
Ọwọ ọlọpa ti tẹ 'were' to sa ọmọ meji pa nipinlẹ Ogun
 wọ ́ n tún ṣe àtúnse sí àwọn àkọsílẹ ̀ tí ó ti wà tẹ ́ lẹ ̀ , bí àpẹẹrẹ turkish.
O fikun pe afurasi ọhun, to pe orukọ rẹ ni Opeyemi Ibraheem Agbenuso Odo, ni awọn dijọ jẹun ninu awo kan ṣoṣo lasiko isinu ni ọjọ mẹta sẹyin, to si jẹ ẹni bii ọkan oun.
Àwọn òbí àti àbúrò mi kò le sọ̀rọ̀, ẹ̀mi nìkan ni mo lè sọ̀rọ̀ nínú ìdílé wa - Ifeoluwa Ẹ pèsè ẹlẹ́rìí púpọ̀ bí bẹ́ẹ̀ kọ́, Sotitobire yóò jẹ́rìí fúnrarẹ̀ o!
 wọ ́ n dé ní Ọ ̀ rùndún keje .
 ìdí nìyí tí àwọn ifẹ ̀ ṣe màa ń ki odùduwà ni :.
Wọn ni eniyan marun un ni ilu Eko, eniyan kan ni ilu Kaduna ati eniyan meji ni olu ilu Naijiria, Abuja.
Ibo diẹ le lẹgbẹrun marun un ni gomina Abdulahi to jẹ oludije fẹgbẹ oṣelu APC ni, ninu esi atundi ibo ti wọn kede rẹ.
ba woo dun 1958 ni oludari ijoba Isreal ti te Naijiria gbeyin.
Ààbò tó péye wà fún àwọn okòwò ará South Africa ni Eko -Sanwo Olu Enìyàn mẹ́ta pàdá ọlọ́jọ́ wọ́n ní'lù Abuja Ṣé lóòtọ́ ni àdó olóró bú níléeṣẹ́ ìjọba South Africa tó wà nílùú Abuja?
Ohun to mu aarẹ nigba kan ri dọbalẹ gbalaja lati ki Ọọni ti Ifẹ, a gbọdọ bọwọ fun asa ati iṣe ilẹ Yoruba, Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?"
Awakọ̀èrò, ọlọ́kadà farakáṣá àṣẹ ìjọba Ekiti láti dẹ́kun Coronavirus Àwọn ìbéèrè tó yẹ kí o bi ara a rẹ̀ kí ó tó gba ìròyìn kankan nípa coronavirus gbọ́ Ọ̀rọ̀ Coronavirus kì ń ṣe ṣeréṣeré o-K1 de Ultimate, Toyin Abraham Coronavirus: Wo ohun tí o ní láti ṣe láti dáàbò bo ara rẹ Eyi ti mu iye awọn to ni arun yii lorilẹede Naijiria bayii di mejilelogun.
Oríṣun àwòrán, @others Àkọlé àwòrán, Buhari gbe ipinnu rẹ fun Naijiria jade loju ọpọ ero ni Eagle Square Awọn olori orilẹ-ede to wa nijoko nibẹ pẹlu Buhari lasiko ayajọ ijọba tiwa n tiwa naa ni aarẹ orilẹ-ede Rwanda, Chad, Niger ati Gambia.
Mo fẹ́ kí ẹ mọ̀ dájúdájú pé, àwọn eniyan ìran yìí kò ní tíì kú tán tí gbogbo nǹkan wọnyi yóo fi ṣẹ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Àwa akódọ̀tí táà ń gba £1,500 lóṣù níbi sàn ju Sẹ́nétọ̀ lọ ní Nàìjíríà' Isa Yunusa ti oun naa jẹ olugbe ilu yii fi idunnu rẹ han si orukọ tuntun naa.
Iyebíye ni Ọlọrun rà yín, nítorí náà, ẹ fi ara yín yin Ọlọrun.
Atiku pín Ounjẹ àti owó fún ìpolongo idibò: Laureetta Onochie to jẹ olùrànlọ́wọ́ pàtàkì fún ààrẹ Buhari lórí ọ̀rọ ayélujara padà tọ́rọ́ àfóríjìn gbàngba lẹyin tó parọ́ pé ààrẹ Buhari kọ òpòpónà túntún si Naijiria.
Oúnjẹ wọn yóo dàbí oúnjẹ àwọn tí ń ṣọ̀fọ̀, àwọn tí wọ́n bá jẹ ninu rẹ̀ yóo di aláìmọ́.
”ipade apero naa yoo tun fi ayesile lati yanana bi won yoo se wa ni ibamu pelu ofin ati ilana ile okere lati koju awon isoro lolokan-o-jokan ti won ba gbe wa sile ejo.
Ọlọ́pàá ní àwọn ṣì ń ṣèwádìí ẹni tó bẹ́rí ní Alasiya l'Eko Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, JAMB 2019: A ó fagi lé ìdànwò ẹni tó bá ṣe aṣemáṣe O le tẹle awọn ilana yii lati bẹrẹ si ni i lo ilana tuntun naa.
Ojo si n rọ lasiko  ti a  n kọ iroyin yii lọwọ, ni eyi ti o mu ki awon oludibo lọ duro si abẹ igi .
"Ẹwẹ nibayii isede ti su awọn eeyan wọn si ti dẹ okun ""ma muti"" diẹ."
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Irú ẹ̀dá wo ni Fẹla Jẹ́?
A ṣi rira ni nkan bii ọgbọn iṣẹju sẹyin.
Gomina ipinlẹ Ogun naa parọwa si awọn eniyan lati jawọ ninu sisọ ohun ti wọn ko mọ nipa arun Coronavirus, amọ ki wọn gbiyanju lati tẹlẹ gbogbo ofin ati ilakalẹ ijọba lọna ati bori ajakalẹ arun Coronavirus naa.
Ó ní, “Ọlọrun ti fi ẹ̀bùn rere fún mi, nígbà yìí ni ọkọ mi yóo tó bu ọlá fún mi, nítorí pé mo bí ọkunrin mẹfa fún un,” nítorí náà ó sọ ọmọ náà ní Sebuluni.
O ni, orile ede re ni lati sun eto idibo ti won koko fe se ni ojo kejidinlogun  osu kokanla odun yii siwaju .
 “Ipinnu yii waye nibi ipade ti igbimo
Kínni ẹ̀yin lè rántí nípa Ààrẹ Nàìjíríà tẹ́lẹ̀ rí, Umaru Musa Yar'Adua?
 Oríṣun àwòrán, Getty Images A ti gba kadara wa ati abajade ifẹsẹwọnsẹ ọhun amọ ko dun mọ wa ninu.
"Agbenusọ fún ajọ JAMB sọ pe ""abajade ipade ti a ṣe ni pe eto igbani wọle kankan ko gbọdọ waye ṣaaju ọjọ keje, oṣu Kẹsàn-án si ọjọ kẹrin, oṣu Kẹwàá."
"A o bori ti ifọwọsowọpọ ba wa láàrin àwọn olùgbé ìpínlẹ̀ Eko, a ti ri irú idojukọ bayiìí tẹlẹ""."
Ẹfunroye Tinubu - Ògbóǹtagí oníṣòwò, olówò ẹrú àti afọbajẹ Samuel Ajayi Crowther, òjíṣẹ́ Ọlọ́run tó gbé èdè Yoruba lárugẹ Fun igba akọkọ ninu itan oṣelu Naijiria, awọn eeyan dibo fun ẹni ti ọkan wọn fẹ lati ṣe aarẹ le wọn lori, lai fi ti ẹsin, ẹya ati ede ti wọn n sọ lẹnu ṣe, ti wọn si kẹyin si aṣa ẹlẹyamẹya, ẹlẹsinjẹsin ati ẹlẹkunjẹkun ti wọn maa n ṣe lasiko ibo, gẹgẹ baa ṣe n ri i lonii.
Ṣugbọn o sẹni laanu pe ole, ajinigbe, ati oriṣiriṣi ọdaran ti n dibọn gẹgẹ bi ọmọ ọdọ tabi abaniṣiṣẹ ile.
Ohun to kọkọ ṣẹlẹ si aba owo iṣuna naa ti Aarẹ Buhari gbe lọ siwaju apapọ ile aṣofin mejeeji lọjọ kejilelogun, oṣu Kejila ọdun 2015 ni pe, ile aṣofin agba sọ pe iwe àbá naa di awati nigba ti wọn pada de lẹnu isinmi ọdun loṣu Kinni ọdun 2017.
 Ọjọ ́ kẹtàdínlógún kẹtàdínlógún ni wọ ́ n ń se àpèjọ wọn .
 O tun wa dupe lowo abenugan ile-igbimo  asoju –sofin fun eto iranlowo yii  pe ki i se fun ipinle re nikan sugbon fun orile ede Naijiria lapapo”.
NLC: A fẹ́ kí ìjọba bẹ̀rẹ̀ sí san owó oṣù tuntun kíákíá 'Ẹ ṣọ́ra ní London' Ile ẹjọ to n gbẹjọ awọn ọdaran eyi to wa ni Sharjay ni UAE lo dajọ iku fawọn mọ Naijiria mẹjọ yii fun ẹsun ti wọn pe ni idigunlejale onipele pupọ (string of armed robbery).
Ajọ ICPC ni iwa ti o hu yii tako abala kẹjọ ofin iwa ibajẹ lorilẹede Naijiria ti o si ni ijiya ti o tọ.
Bi o ti le je pe, iko Super Falcons padanu ifesewonse akoko lojo Aiku(Sunday), sugbon won taraji lati jawe olubori ninu ifigagbaga keji lati bosi oke tente tabili ipele naa.
Ko tan sibẹ o, ajọ NERC tun sọ pe ilana tuntun naa yoo ri i daju pe ileeṣẹ DisCos ko yan awọn onibaara wọn jẹ, ti iye ti wọn ba n gba naa si gbọdọ pe wọn lati ṣe iṣẹ to dara.
Èyí ni ìdí tí ẹnu fi n kun Fashọla lórí ayélujára Ohun ìwòsàn pàjáwìrì ti di dandan Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Sola Kosoko: ọlá bàbá mi ni mò n jẹ́ nínú iṣẹ́ tíátà O fikun wi pe wọn tun ti fẹ fi panpẹ ọba mu alaga ile ifowopamọsi Fidelity Bank, Nnamdi Okonkwo nitori wi pe Peter Obi to n dije dupo igbakeji aarẹ ni PDP jẹ alaga banki naa tẹlẹ.
Oríṣun àwòrán, AFP Àkọlé àwòrán, Ọlọ́pàá ti mú ènìyàn mẹ́tàdínlọgbọn tó lọ́wọ́ nínú ìwà jàgídíjàgan àti olè jíja tó wáyé.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ilé isẹ́ ìgbóhùsáfẹ́fẹ́ SSBC dá ètò Ilé isẹ́ BBC dúró 20 Ìgbé 2018 Àkọlé àwòrán, South Sudan ti ilé isẹ́ BBC pa torí àìsanwó Ilé isẹ́ ìgbóhùsáfẹ́fẹ́ BBC sọ wípé ẹgbẹ̀rún lọ́nà irínwó lawọn tó ńgbọ́ wọn ní orílẹ̀èdè South Sudan.
Ti àwa ati àwọn ọmọ wa ni ohun ìní gbogbo tí Ọlọrun gbà lọ́wọ́ baba wa jẹ́, nítorí náà, gbogbo ohun tí Ọlọrun bá sọ fún ọ láti ṣe, ṣe é.
Adaku inú eré Jẹnifa - BBC News Yorùbá BBC News, YorùbáFò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Dálémoṣú ni mí ṣùgbọ́n ó ní ìdí - Adaku inú eré Jẹnifa Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Dálémoṣú ni mí ṣùgbọ́n ó ní ìdí - Adaku inú eré Jẹnifa 16 Agẹmo 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 11 Ìgbé 2020 Kìí ṣe gbogbo Dalemoṣu lo n ṣe aṣẹwo - Adaku Omotunde Adebowale ni orukọ abisọ ti oṣere to tun jẹ sọrọsọrọ ti igba oju mọ ti wọn n pe ni Adaku ninu eré Jẹnifa.
ipinle Oyo tie kun Gusu lorile ede Naijiria, lasiko ti ajo naa n fimu- file fun
Oríṣun àwòrán, Others Ọba Adeniran Adeyemi Keji, Alaafin tilu Oyo: Itan tun sọ fun wa pe baba to bi Alaafin to wa lori oye bayii, Ọba Lamidi Ọlayiwọla Adeyẹmi Kẹta, ti orukọ rẹ n jẹ Ọba Adeniran Adeyemi keji ni ijọba ẹgbẹ oselu Ọlọpẹ, Action Group, AG le kuro lori oye Ọba Adeyẹmi keji si lo jẹ Alaafin tilu Ọyọ laarin ọdun 1945 si ọdun 1954 ti wọn yẹ itẹ sba mọ nidi.
Kògbérèégbè mẹ́ta nínú òṣèré Yorùbá Àṣìta ìbọn pa èèyàn kan lásìkò tí SARS ń kojú adigunjalè l'Eko Lẹ́tà Obasanjo: Àjálù ń bọ̀ bíi ti Rwanda, tí Buhari kò bá ṣàtúnṣe ètò ààbò O ti lé ni òkú ẹni mẹ́wàá ti wọ́n ti ri yọ nínú ilé to dà wó ni Jos Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Olórí Ọ̀dọ́ l'Ondo ní oníkálùkù yóò bẹ̀rẹ̀ sí ní jà fúnra wọn Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Ṣugbọn ọkan ninu awọn ọlọpaa naa fa ìbọn yọ, to si yin in si meji lara awọn Agbekoya naa, ti awọn yoku si na papa bora nitori wọn ko fẹ ki wahala sẹlẹ ki Tafa Adeoye to de.
Ní ọjọ́ kan, àwọn aṣẹ́wó meji kan kó ara wọn wá siwaju Solomoni ọba.
Opọ ni ẹru maa n ba pe awọn ti ki jẹ ẹran ati ẹja le ma ni ni eroja aṣaraloore yii to ninu ẹjẹ.
"Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ìdílé tí ọkọ da ọmọ síta tóríi ojú Búlùú tí wọ́n ní bá BBC sọ̀rọ̀ Kọ́ńdọ̀mù tó bẹ́ gbé iléèṣẹ́ ìjọba àti aládáni kan dé ilé ẹjọ́ Àgbáríjọ àwọn nọ́ọ̀sì fẹ́ gbé Olamide Baddo lọ sílé ẹjọ́ fún ìbanilórúkọjẹ́ Gbajúgbajà òṣèré tíátà, ""Ijẹwuru"" ti jáde láyé Ọ̀nà kan ò wọjà fáwọn òṣèré tíátà, bí wọn ṣe ń ta ìpara ìbóra ni wọ́n ń ta aṣọ ẹbí Ọkọ̀ wa wọ'gbó lọ lẹ́yìn táwọn dánàdánà dàbọn bò wá- Toyosi Adesanya Iṣẹ́ ọpọlọ ló yẹ ká ṣe nínú tíátà, kìí ṣe àfihàn ara bíbó àbí ìhòòhò wa - Binta Mọgaji Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Mama Rainbow: Toyin Adegbola àti Razak Olayiwola ní ìyá rere àti àwòkọ́ṣe gidi ní Idi ni pe ariwo ayọ tun sọ nile rẹ lọjọ Iṣẹgun nigba ti ọmọ rẹ obìnrin, Abiola Ajike, mu ọkọ wale."
" Owolabi Ajasa fikun pe aisan Baba legba tun peleke si ni ọdun to kọja, sugbọn oun maa n pe oloogbe naa si iṣẹ.
Gẹgẹ bi iwadii ti awọn onimọ sayẹnsi ṣe, Dokita Musa ni wọnyii ni awọn arun ti igbeyawo laarin ibatan le fa.
Aare wa rọ awon eniyan naa lati maa foya sugbon ki won ri
Oluwo ni ninu itan ilẹ Yoruba, o ti le ni irinwo ọdun ti Fulani ti n gbe laarin wa""."
O ni ọmọ orilẹ-ede Naijiria mẹta ati ọmọ bibi Ghana marun un ni wọn jọ ṣiṣẹ naa.
Oriṣiríṣii nkan lo ṣelẹ lágbo oṣere, láàrin àwọn olórin, àwọn arìnrín oge àti agbo eré bọọlu ni Naijiria lọdun 2018 bí àwọn ènìyàn ṣe wọ àwọn aṣọ àwòdami ẹnu.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Baby abandoned on dunmpsite: Mo ti bímọ mẹ́rin tẹ́lẹ̀ fún bàbá méjì nínú òṣí- Dupe Ogbomos Awọn to n ta epo bẹntiroo naa tun ba akọroyin BBC sọrọ pe: Ontaja epo mii to ba wa sọrọ ṣe alaye wi pe ọwọ ijọba ni gbogbo rẹ wa nitori ko si ẹni kan to iredi ti ijọba fi gbe igbesẹ naa.
O fi kun pé Omowe John jẹ adari apaọ nígbà kan ri, ọmọ igbimọ adari ajọ NNPC Sọ àsọtẹ́lẹ̀ orílẹ̀èdè tí yóò borí ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ t'òní Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ṣé ẹ̀yin lè ṣe jú àwọn tó f'àmì sí Awọlumatẹ?
Ta ni Ahmed Murtala àti Funkẹ Salami ti Makinde yan sipò?
Adari ile-ise to n ri si wiwọle
Ìtàn ti stride àti ifeka ( 1982 ) sọ ni a fẹ ́ mú lò nínú iṣẹ ́ yìí .
Àjọ WHO tí kéde pé ìṣẹ̀lẹ̀ pàjáwìrì ni ọ̀rọ̀ Ebola yìí lọ́sẹ̀ tó kọja.
- Olorì Naomi Awọn iroyin ni ipinlẹ naa ṣalaye pe agbegbe It5agunmọdi, Igun ati Ariye ni ijsba ibilẹ Atakunmọsa West ni wọn ti mu awọn eeyan naa.
ti awon omo orile-ede Naijiria n mura lati yan adari tuntun miiran.
 Ni afikun, o menuba ajosepo to dan moran to wa laarin ijoba FCT atawon ijoba ibile abe won ni eyi ti o ti gbe gbogbo owo to ye kale sinu asunwon awon ijoba ibile ti won ni papo.
Aṣiwaju tí ó tún dìde lẹ́yìn Ehudu ni Ṣamgari, ọmọ Anati, ẹni tí ó fi ọ̀pá tí wọ́n fi ń da mààlúù pa ẹgbẹta (600) ninu àwọn ará Filistia; òun náà gba Israẹli kalẹ̀.
Kayafa yìí ni ó fi ìmọ̀ràn fún àwọn Juu pé ó sàn kí ẹnìkan kú fún gbogbo eniyan.
 Àkọlé àwòrán, Àwọn olórí àtàwọn ológun ni wọ́n se Tramadol fún Gẹ́gẹ́ bí Ọ̀gbẹ́ni Àyúbà ti wí, kò sẹ́ni tó leè pa èèyàn lójú lásán, sùgbọ́n òògùn Tramadol wà níbẹ̀ láti tìẹ́ sisẹ́ ibi.
Ọmọ ọdún marun-un ni, nígbà tí wọ́n mú ìròyìn ikú Saulu ati ti Jonatani wá, láti ìlú Jesireeli; ni olùtọ́jú rẹ̀ bá gbé e sá kúrò.
Fun awọn ami ẹyẹ Olympics, wọn to awọn orilẹede nibamu pẹlu iye wura, fadaka ati baba ti wọn gba - wọ̀n si pin okun to de wọn niya gẹgẹ bo se tọ.
Ṣugbọn awọn alakoso LUTH ti fẹsi pe ko si ootọ ninu fidio naa, ati pe o jẹ iyalẹnu fun awọn pe awọn eeyan le gbe iru fidio bẹẹ jade nipa ile iwosan ọhun.
al-hajji sir ahmadu bello ( june 12 , 1910 - january 15 , 1966 ) a bí i ní rabahin ní ọdún 1910.
36 Àti pé bákannáà, Olúwa yíò ní agbára lórí àwọn èniyàn mímọ́ rẹ̀, yíò sì jọba láàrin wọn, yíò sì sọ̀kalẹ̀ wá pẹ̀lú ìdajọ́ sí orí Idumea, tàbi ayé.
Ó dàbí ìṣúra iyebíye kan tí wọ́n fi pamọ́ ninu ilẹ̀.
Wọn a máa lépa ọpọlọpọ nǹkan tí kò mú ọgbọ́n wá ati àwọn nǹkan tí ó lè pa eniyan lára, irú nǹkan tí ó ti mú kí àwọn mìíràn jìn sinu ọ̀fìn ikú ati ìparun.
Amọ ṣa, o ṣe ni laanu pe o ni iṣoro kan to nii ṣse pẹlu ibimọ nitori naa wọn ni lati gbe e lọ si ile iwosan akọṣẹmọṣẹ.
Ẹni to bori: Egypt Ìpele to ṣaaju eyi to kangun si aṣekagba Algeria vs South Africa.
'Àwọn èèyàn ń fi orúkọ mi lu àwọn obinrin ní jìbìtì' Ọọni ile ifẹ ni oun ti fi ọrọ arabinrin ti o n kede pe oun ati aṣiwaju ọbalaye naa ni adehun ifẹ ki o to fẹ Olori rẹ ni aipẹ yii to ọlọpaa leti.
Ìròyìn ìbànújẹ́ rán èèyàn kan sọ́run ní pápákọ̀ òfurufú Eko Èmi kò sí nílé, ọkọ́ mi ló leè sọ bóyá lóòtọ́ọ́ ló fẹ́ gbéyàwó àbí bẹ́ẹ̀ kọ́ - Aisha fèsì Odunlade fijó bẹ́ẹ, Lizzy padà sọ́dún 2012, Toyin Abraham tọ̀ lẹ́ẹ̀mẹwàá Ìpínlẹ̀ Ọ̀ṣun kò le è sanwó o ọmọ́gọ̀ lórí LAUTECH- Gómìnà Oyetola Oladele ni wi pe awọn ọna wọnyii ni wọn n ṣe lọwọ ṣugbọn ti aini suuru pupọ awọn awakọ yii lo n fa ijamba ba awọn ẹlomiran.
O tẹsiwaju wi pe ohun ibanujẹ nla gbaa ni iṣẹlẹ naa gẹgẹ bi o ṣe n mu un wa si iranti wi pe aibikita ijọba naa lo ṣekupa iya oun ni nnkan bi i ọdun mẹwa sẹyin.
Kọmiṣọna fun eto ilera ni ipinlẹ Ondo, Dokita Wahab Adegbenro lo sọ eyi di mimọ fun BBC News Yoruba.
Lóòótọ́ ni wọ́n ń fi orúkọ mi búra pé, “Bí OLUWA tí ń bẹ,”sibẹ èké ni ìbúra wọn.
Gbogbo olólùfẹ́ èdè àti àṣà Yorùbá ti ó tẹ̀lé wa ni àwọn ọdún ti ó kọjá, a ki yin fún ọdún tuntun ti ó wọlé.
Ṣugbọn Amasaya kọ̀, kò gbọ́, nítorí pé Ọlọrun ni ó mú kí ọkàn rẹ̀ le, kí Ọlọrun lè fi Juda lé àwọn ọ̀tá wọn lọ́wọ́ nítorí pé wọ́n ń bọ àwọn oriṣa Edomu.
Wọn ni awọn n ṣe atilẹyin fun igbesẹ̀ ijọba ni.
"Ní bayii, àsìkò ti tó fún mi láti sin àwọn ènìyàn mi lọna miran""."
Ẹ gbọ́ ọ̀rọ̀ tí OLUWA ń ba yín sọ, ẹ̀yin ọmọ Israẹli: 
Alufaa ọhun tun sọ pe ko si ohun ti awọn fẹ ki ọlọrun ṣe fun Woli Genesis ti ko tii ṣe fun tẹlẹ.
Oríṣun àwòrán, AFP Àkọlé àwòrán, Ile wiwo ni Afirika 2.
Abhishek sàlàyé pé, àwọn ń fàmi hàn sùgbọ́n kò nira ju bóṣe yẹ lọ .
Oríṣun àwòrán, others Aago mejila ọsan ló yẹ ki baalu naa ba ni Abuja tẹlẹ, amọ awọn ero kan ti ko tete sanwo fun ayẹwo coronavirus ti wọn ba ti de Naijiria lo da a duro.
Ẹni tí ó ṣí àwọn òkè nídìí, ninu ibinu rẹ̀;tí wọn kò sì mọ ẹni tí ó bì wọ́n ṣubú.
fi pari ise oko ogun oju omi naa.
Ni ọdun 1999 ti Atiku da igbakeji aarẹ ni Naijiria ni ileeṣẹ naa gberasọ, amọ ọdun 2012 ni wọn ri iwadii pe wọn bẹrẹ si ni fi owo gọbọi ranṣẹ si oke okun.
Nigba miran paapa, o le jẹ ẹgbọn, alabagbele, ara adugbo tabi baba ọmọdebinrin naa, lo fi ipa ba a lopọ.
Ọdun kan o le diẹ ni Eleduwa fi ọmọkunrin lanti lanti \\ti orukọ rẹ n jẹ Zion jinki idile wọn ti wọn si di ọlọmọ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Eld Kabir in Nigeria: Mùṣùlùmí àti Kristiẹni sọ̀rọ̀ nípa àdun oúnjẹ́ àti ẹran ọdún Ileya Bakan naa ni Oshodi Oke tun sọrọ lori ajọsepọ rẹ pẹlu gbajugbaja olorin takasufe 'Nice' ati alaga ẹgbẹ ọlọkọ ero nipinlẹ Eko, Alhaji Musiliu Akinsanya, ti ọpọ eeyan mọ si MC Oluomo.
O mẹnuba agbara ti ileeṣẹ oun ni ati igbiyanju wọn lati daabo bo awọn ẹnubode Naijiria ati lati mojuto awọn to n wọle ti wọn n jade.
Bukola Saraki kò kọjá òfin - EFCC Loni ní adájọ ile ẹjọ kòtẹmilọrun lẹ́yìn àyẹwò fínífíní lórí ìdájọ tó sááju wáye nile ẹjọ tó ń gbejọ ìdìbò ni ìpínlẹ̀ Osun to ni Sẹnitọ Ademola Adeleke ẹgbẹ́ òṣèlú People's Democratic Party (PDP) ló jáwe olúbori kéde pe Gboyega Oyetola ló jáwe olúbori.
Kano rape cases: Muhammad, ẹni ọdún mẹjìlélọgbọn jẹwọ bí òun ṣe ń fipábá àwọn obìnrin ogójì lò pọ
Ṣugbọn bí ó bá jẹ́ pé wọ́n jí i gbé mọ́ ọn lọ́wọ́ ni, yóo san ẹ̀san fún ẹni tí ó ni ín.
Nítorí pé, OLUWA ti lé àwọn orílẹ̀-èdè tí wọ́n tóbi tí wọ́n sì ní agbára kúrò níwájú yín, kò sì tíì sí ẹni tí ó lè ṣẹgun yín títí di òní.
Baruku, ọmọ Neraya, sì wá sọ́dọ̀ wọn tòun ti ìwé náà lọ́wọ́ rẹ̀.
Jeroboamu kò sì lè gbérí ní àkókò Abija.
lori eto aabo to mehe ohun ni awon ekun ipinle kookan lorile-ede Naijiria, o
Mẹ́tàlá nínú rẹ̀ jẹ láti ìpiínlẹ̀ Eko, méjì wá láti Edo, méjì láti Kano, meji láti ogun nígbà ti ẹyọkan jẹ lati Ondo.
"Oluwaremilekun Fatolu: Mo máa ń wọ kọ́mú “size 50H\"", ẹyọkan leè tó N15,000, Okrika N9,000"
Omi náà sì ń fà sí i títí di oṣù kẹwaa.
Idibo abẹnu ẹgbẹ PDP ni yoo yanju ọrọ yi sugbọn kko to di igba naa o seese ki awọn oludije ma se idunadura lori ni ti yoo jọwọ ipo naa ati ẹni ti wn yoo gbaruku ti lati jawe olubori ninu idibo to n b lọna.
Lẹ́yìn ọjọ́ meji, yóo sọ wá jí, ní ọjọ́ kẹta, yóo gbé wa dìde, kí á lè wà láàyè níwájú rẹ̀.
 O tun je elesin tooto ati adari rere fun awon agbejoro ati adajo lorile ede Najiria.
Wakati meta gbako ni won fi se
Ìdìbò ti a lé fi ìdí rẹ̀ múlẹ̀ pé ìdá ọgọ́ta nínú àwọn olùdibò jáde wá àànú Ọlọ́run ni a fi ṣe ìdìbò náà ti kò si sí ìjà tàbi kí ẹnikẹ́ni kú, gbogbo àyíká wà ni dídákẹ́ rọ́rọ́, a dupẹ́ lọ́wọ́ Ọlọ́run Ọ̀jọ̀gbọ́n Ogbe sọ pé mẹ́rìnlélógójì nínú mọ́kànléláàdọ́run àwọn ẹgbẹ́ òṣèlú to forukọ sílẹ̀ lókópa nínú ìdìbò náà, sùgbọ́n ẹgbẹ́ òṣèlu tó ń bẹ lóri àléfaà All Progressives Congress (APC) wà lára àwọn ẹgbk òṣèlú tí kò kópa nínú ìdìbò náà Ìgbìyànjú BBC láti bá alága ẹgbẹ́ òṣèlú APC Jotan Amos sọ̀rọ̀ lórí ẹ̀rọ ayélujára, ìdí ti wọn kò fi kópa nínú ìdìbò náà, sùgban kò gbé aago rẹ̀.
Ijoba yo se itoju awon eniyan won,gẹgẹ bi ojuse wọn, nipa sisan
Ẹ ka díẹ̀ lára àwọn ìṣẹlẹ̀ ayọ̀ lágbo òṣèré tíátà Yollywood láàrin ọ̀sẹ̀ yìí
Kí ló ń pa ẹbí Orisabunmi lọkọ́ọ̀kàn, àkúfà ni àbí àmúwá Ọlọ́run?
slowly starting to make strides when it comes to transgender visibility.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, World Diabetes Day: Ọdún kọkandinlogun ti mo ti wà lẹ́nu itọ ṣúgà nìyí Olajuwon sọ pe, oun yoo yan lati wo ifẹsẹwọnṣẹ lori ẹrọ asọrọmagbesi kaka ki oun wo lori ẹrọ NTA.
"Wọ́n pé ọdún méjìlá báyìí Elon Musk, Ọ̀gá àgbà iléeṣẹ́ SpaceX, Tesla CEO ń bá Bill Gates du ipò ẹni tó lówó jùlọ ṣèkejì lágbayé Ohun mẹ́wàá pàtàkì nípa Maradona àti ìbáṣepọ̀ rẹ̀ pẹ̀lú ẹlẹ́sẹ̀ ayò Diego Costa rèé Ninu ọrọ rẹ, @DrOlufunmilayo lori Twitter sọ pe ""Black Friday ma n ran awọn ontaja lọwọ."
Lati igbà ti wọn ti kó ọrọ̀ ajé gbogbo ipinlẹ̀ si abẹ́ Ìjọba-àpapọ̀ ti a lè pè ni “Òbí” ti jinà si ará ilú ti a lè pè ni “Ọmọ” ti rù.
Adeyemi ni ''ti ọmọ ọdọ ba ji aṣọ ọga rẹ gbe, aṣọ naa yoo tobi ju lara rẹ, idunnu wi pe oun n wọ aṣọ ọga rẹ lo maa mu un ṣiwa wu sawọn to yẹ ko ṣapọnle fun.
 Ọ ̀ pọ ̀ lọpọ ̀ fíìmù tí ó níí ṣe pẹ ̀ lú ẹ ̀ fẹ ̀ ni wọ ́ n tí gbé jáde .
Wọ́n sọ ìwọ̀ sí i nímú,wọ́n gbé e jù sinu àhámọ́,wọ́n sì fà á lọ sí ọ̀dọ̀ ọba Babiloni.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Brexit: UK fẹ́ so ìjókòó ilé rọ̀, kíni èyí túmọ̀ sí?
Ní ọjọ́ tí angẹli keje bá fọhùn, nígbà tí ó bá fẹ́ fun kàkàkí tirẹ̀, àṣírí ète Ọlọrun yóo ṣẹlẹ̀ gẹ́gẹ́ bí ó ti sọ fún àwọn wolii, iranṣẹ rẹ̀.
Ọrọ yii ni awọn olujiroro nibi ipade apero naa n yanana.
"Wọn ni mo n binu tori gomina ko fa awọn isẹ kan le mi lọwọ, amọ bi gomina fa isẹ le mi lọwọ, agunla, bi ko si fa a le mi lọwọ, ko si wahala, jẹjẹ mi ni mo n lọ.
Bakan naa ni akẹkọọ mi i naa tun farapa lẹyin ti wọn lu u ni alubami.
Wọ́n ń wí pé:“A ti pa á run!
Ng kò jiyàn rẹ̀ rárá o.
Wo àwọn òfin tuntun tíjọba fí síta lórí lílọ ìrìnàjò sílẹ̀ òkèèrè Wo ohun tí ilé ẹjọ́ ní kí wọ́n ṣe fún Sunday Shodipe, afurasí ìṣekúpani l'Akinyele Ó tó gẹ́ẹ́!
 orúkọ yìí ló wú n tí ó sì sọ ìlú tí òun náà tẹ ̀ dó ní orúkọ náà .
 iye owó rẹ ̀ lójú pálí fún àjẹsára tó ní ojú ibi àsopọ ̀ máàrún , ọ ̀ kan lára èyítí ó jẹ ́ hib , jẹ ́ 15.
Ẹni tó jí ọ̀pá aṣẹ ń bọ̀ wá túbá fúnrarẹ̀, mo fi dáa yín lójú gẹ́gẹ́ bí ìyá - Erelu Kuti Oríṣun àwòrán, LASG AND SCREENSHOT, Seyi Soremekun Erelu Kuti Kẹrin ti ilu Eko, Erelu Abiola Dosumu ti fesi lori ọrọ ọpa aṣẹ Ọba ilu Eko ti awọn janduku kan dede ji gbe kuro laafin lọjọru ọsẹ.
Ohun kan to daju ni pe awọn ọmọ ilẹ Amẹrika ko le gbagbe Trump laelae gẹgẹ bi ilẹ naa.
Akpeyi (Kaizer Chiefs, South Africa)Awon agbaboolu eyin(Defenders):
Amọ, ẹgbẹ awọn ẹya ariwa orilẹede Naijiria, northern socio-political group, the Arewa Consultative Forum, ACF ni ọrọ kubakugba ni Osinbajo sọ, bi o tile jẹ wi pe lootọ ni iṣoro lorisirisi n koju Naijiria.
Àwọn adájọ́ fa aṣọ ya mọ́ wọn lára, wọ́n pàṣẹ pé kí wọ́n nà wọ́n.
eyim(Defenders): Olaoluwa Aina (Torino FC, Italy); Abdullahi Shehu
 Lóòótọ́ obìnrin ló mọ ẹni tó loyún, ṣùgbọ́n tó bá rújú, ohun tí Yorùbá ń ṣe rèé-Elebuibon Ọlọ́pàá Oyo n wa afurasí tó ṣekú pa oníṣòwò àti ọmọ ọdún mẹ́sán án méjì ní Ibarapa Ẹ̀kúnrẹ́rẹ́ àlàyé rèé lórí àyẹ̀wò DNA Wo ìgbà tí àwọn akẹ́kọ̀ọ́ yóò wọlé ní ìpínlẹ̀ Eko Kí ló mú kí Baba Barakat tó fẹ̀sùn ìyọnilẹ́nu torí ìbálòpọ̀ kan kọmísọ́nà àyíká ìpínlẹ̀ Ogun pàlù ẹnu dà?"
Ó jẹ èrè ìròyìn ayọ̀ rẹ̀, tí ó mú wá fún mi.
 Ọwọ ́ -fífọ ̀ pẹ ̀ lú ọṣẹ farahàn bí ààbò tó péye .
Tìrẹ ni ọ̀run, tìrẹ sì ni ayé pẹlu;ìwọ ni o tẹ ayé ati gbogbo ohun tí ó wà ninu rẹ̀ dó.
“Nígbà tí a gba ilẹ̀ náà nígbà náà, àwọn ọmọ Reubẹni ati àwọn ọmọ Gadi ni mo fún, ohun tí ó bẹ̀rẹ̀ láti Aroeri tí ó wà ní etí àfonífojì Anoni ati ìdajì agbègbè olókè ti Gileadi, pẹlu gbogbo àwọn ìlú ńláńlá rẹ̀.
Tí wọ́n sì mú ọgbà náà wuni púpọ̀ púpọ̀.
 Awọn miiran ti wọn ṣayẹwo wọn ni: Ọgbẹni
bẹ́ẹ̀ sì ni pé ohun ìyìn ni ó jẹ́ fún obinrin tí ó bá jẹ́ kí irun rẹ̀ gùn.
Àfàìmọ̀ ká máa dá ìforúkọsílẹ NIN dúró tórí ewu coronavirus- Mamora Bi ẹ ko ba gbagbe, ọpọ ero bẹrẹ si n ya bo ileeṣẹ naa ni kete ti ijọba apapọ paṣẹ fun awọn ileeṣẹ ẹrọ ibaraẹnisọrọ pe ki wọn ja okun ila awọn ti ko ba forukọsilẹ fun nọmba idanimọ NIN lọjọ kẹrinla, oṣu Kejila, ọdun 2020.
Ojú mi ti rí lọ́pọ̀ lọpọ̀, ọ̀pọ̀ èèyàn ni kò tilẹ̀ gbàgbọ́ pé mo lè jọba- Ooni Odunayo, ọmọ iya welder naa sọ pe gbogbo ẹbi lo fọwọ si iṣẹ iya rẹ yii ati pe ko sohun to buru nibẹ.
John Berr to jẹ onímọ nípa oorun sọ pe bó tilẹ̀ jé pé àwọn òṣiṣẹ́ ìjọba tí ń ja ìjà yìí típẹ̀, ṣùgbọ́n ti ìjọba ko kọbíara síi.
Ìtàn ayé Ọba Seriki Abass ti Badagry, tó ní aya 128, ọmọ 144 Ilé ẹjọ́ yá lórí òfin CAMA tó fẹ́ gba àkóso ilé ìjọsìn, tẹ ẹ̀tọ́ aráàlú mọ́lẹ̀ - SERAP Wo bí o ṣe le fi orúkọ sílẹ̀ fún ìgbani ṣíṣẹ́ ológun Nàìjíríà tó bẹ̀rẹ̀ Ọmọdé 5 àti àgbà 40 bómi òkun lọ, 37 mórí bọ́ lásìkò tí ẹ́ńgínì ọkọ̀ ojú omi gbiná Bi oṣu mii ba pe mọkandinlọgbọn, omiran le pe ọgbọn tabi ki o si jẹ mejidinlọgbọn.
Gẹ́gẹ́ bí àṣẹ ọba, Hilikaya ati àwọn tí wọ́n tẹ̀lé e, lọ sọ́dọ̀ Hulida, wolii obinrin, iyawo Ṣalumu, ọmọ Tokihati, ọmọ Hasira tí ó jẹ́ alabojuto ibi tí wọn ń kó aṣọ pamọ́ sí ní ìhà keji Jerusalẹmu tí Hulida ń gbé.
 Ìdẹ ̀ ra ni orúkọ ilé-ẹ ̀ kọ ́ àbúrò túndé atọ ̀ pinpin .
Ó rọ ìjọba láti jókó pọ pẹ̀lú àwọn adarí àwọn ASUU láti tọwọ́bọ̀wé lórí àdéhùn tí wọn pinu láti muṣẹ Lórí ibi ti ètEkó dé lórílẹ̀-èdè Nàìjíríà.
Bakan naa, ninu irufe idije NCAA tawon okunrin, iko agbaboolu Kansas, ti Udoka Azubuike  n kopa fun, padanu ipele keji si asekagba idije ohun sowo Villanova pelu ami-ayo màrúndínlọ́gọ́rùn ún si mọ́kàndínlọ́gọ́rin(95-79).
O óo wí pé, “Wọ́n lù mi, ṣugbọn kò dùn mí;wọ́n nà mí, ṣugbọn ń kò mọ̀.
Èmi Alàgbà ni mo kọ ìwé yìí sí àyànfẹ́ arabinrin ati àwọn ọmọ rẹ̀, àwọn tí mo fẹ́ràn nítòótọ́.
omo orile ede Niajiria nigbagbo ninu Olorun ti 
Òtítọ́ mi ati ìfẹ́ mi tí kì í yẹ̀ yóo wà pẹlu rẹ̀;orúkọ mi ni yóo sì máa fi ṣẹgun.
Idagbasoke ede ati aṣa Yoruba lo jẹ BBC Yoruba logun kaakiri agbaye.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Arìnrìn àjò tó bá ṣẹ̀ṣẹ̀ dé gbé, ábẹ́ ààbò ọjọ́ mẹ́rìnlá ni wọn yóò wà torí Covid19 - Uganda Mò ń fojú sọ́nà láti bá Emir àná, Sanusi kírun lọ́jọ́ Jímọ̀ - Aráàlú Awe Ẹ múra o, epo rọ̀bì di òkùtà lọ́jà torí Coronavirus, ìlú yóò le koko - NNPC figbe ta Ẹ́ gbaradì, to bá lo jẹnẹrátọ̀ àbí tà á, ò ń fi ẹ̀wọ̀n ọdún mẹ́wàá ṣeré - Sẹ́nétọ̀ ń dábàá Bi nkan ṣe ri bayii, ti banki apapọ Naijiria ti ni kawọn eeyan ma mura silẹ de igba ti yoo le diẹ lẹka ọrọ aje, lo mu ki BBC Yoruba fọrọ wa awọn onimọ nipa ọrọ aje lẹnu wo, lati ṣalaye ohun ti awọn ọmọ Naijiria yoo ba pade nigba ti ọrọ aje ba dagun.
OLUWA bá pe Samuẹli, ó ní, “Samuẹli!
Alukoro ileeṣẹ ọlọpaa ni ọkunrin naa, Alasan Audu fipa ba iyawo rẹ lopọ lẹyin ti obinrin naa kọ lati fun un.
Mikel se so lori ero ayelujara re pe,“Modupe pupo lowo awon agbofinro fun ise takun-takun won lati gba baba mi sile lowo awon agbebon,”Bakan naa, O tun dupe lowo awon omo orile-ede Naijiria fun atileyin won pelu adura.
Idi ni pe MKO Abiọla ri taje se, Ọlọrun bẹ igi ọla fun, to si jẹ ilumọọka kaakiri agbaye nitori buruji to ni, to si n ṣe aanu fun awọn mẹkunnu.
Ninu ìran lóru,nígbà tí àwọn eniyan sùn fọnfọn,
Ọkọ mi kò sí nílé,ó ti lọ sí ìrìn àjò, ọ̀nà rẹ̀ sì jìn.
Eyí tó gbà tó ọdún mẹẹdogun gbáko, tó sì gba ẹ̀mí ìdá mẹ́wàá ninu ọgọrun un àwọn èèyàn ilẹ̀ náà, àrùn yìí jé akiri madalesi.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Akomolede àti Aṣa: Ọ̀rọ̀ Ẹ̀yán ni Bunmi Femi Amao ń kọ́ wa lórí ètò Akọ́mọlédè àti Àṣà lóri BBC Yoruba Ọgbẹni Ibe ni lẹyin naa ni Atiku gba fisa Amẹrika ti o si rinrin ajo lọ si orilẹede naa, ''koda ẹgbẹ ọfiisi ẹka eto idajọ ni ile itura ti Atiku de si wa.
O Fagunwa; Ǹkankan máa ń darí wọn lọ ibi tí a kò mọ̀ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ D.
O fikun wi pe nigba ti Obasanjo wa lori oye, ọpọlọpọ nkan ni ko fararọ fun awọn ọmọ orilẹede Naijiria.
Fún ẹbọ ohun jíjẹ yóo pèsè òṣùnwọ̀n eefa ìyẹ̀fun kọ̀ọ̀kan fún akọ mààlúù kọ̀ọ̀kan, òṣùnwọ̀n eefa ìyẹ̀fun kọ̀ọ̀kan fún àgbò kọ̀ọ̀kan ati òṣùnwọ̀n hini òróró kọ̀ọ̀kan fún òṣùnwọ̀n eefa ìyẹ̀fun kọ̀ọ̀kan.
Amọṣa, aworan yii kii ṣe ti isinyi, ti ọjọ pipọ sẹyin ni.
Afara Third manland bridge naa ni afara keji to gun julọ ni ilẹ Afrika, o si di Osu Kini, ọdun 2021 ki wọn to ṣi i pada.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ìtàn tó wà nídi òwe ‘Sebótimọ Ẹlẹ́wà Sàpọ́n’ Taiwo Akinkunmi, ọmọ Ibadan tó ya àsìá Nàíjíríà Ogedengbe Agbógun Gbórò, Akọni tó ń dẹ́rù ba ikú.
Yatọ si ẹgbẹrun mẹta yii, idahun naa sọ pe ẹni ti o ba sọ kaadi rẹ nu gbọdọ san ẹgbẹrun marun naira lati gba omiran.
Mo wárìrì nítorí pé mo bẹ̀rù rẹ,mo sì bẹ̀rù ìdájọ́ rẹ.
Ọgbẹni Oludola Gbadamosi ni itura yoo ba araalu, nitori pe owo yoo pọ si nilu.
Ni ipari won yoo sabewo si  ijoba ibile  Zangon Kataf ati Samaru Kataf, Katsit ati Zonkwa ni ijoba ibile Kauru pelu awon agbegbe bii: Ungwan Magaji, Ungwan Rimi, Kaziti, Kigbeni ati Kigam.
2 51594 Orilẹede Quatar 246 8.
28 Àti pe níwọnbí wọn bá ní ìrẹ̀lẹ̀ kí á lè sọ wọn di alágbára, àti kí a bùkún wọn láti òkè wá, kí wọn sì rí ìmọ̀ gbà láti àkókò dé àkókò.
org Àkọlé àwòrán, Ní ìlú Ibadan ni Àjọ EFCC ti fi pańpẹ́ ọba mú ayédèrú babaláwo pẹ̀lú ọ̀pọ̀lọpọ̀ dúkìá tí wọ́n ti lù ní jìbìtì.
'Ẹ jọwọ ẹ da ibọn yin silẹ; ki ẹ si kópa nínú eto idibo, Ati ọkunrin ati obinrin ilẹ wa, lóni a fihan pe gbogbo wa le jijọ gbe pọ ti a ko ro boya èèyàn kan wà lati goosu tabi Ariwa Ọkan ní gbogbo wa.
9 Ma ṣe sọ ohunkohun ṣùgbọ́n ironúpìwàdà fún ìran yìí.
Nitori naa, orile ede Naijiria gbọdọ lee se eto idibo to lọ
O óo wá mọ̀ nígbà náà pé èmi ni OLUWA.
Awọn eeyan agbegbe naa pe orukọ ọlọkada naa ni Kabiru ṣugbọn wọn ni oluyọle ni ọpọlọọ eeyan mọọ si.
Huriwa ni bii igba ti wọn n pa Aalọ lasan ni wọn ṣe tu ọfọ iku akọni obinrin naa, eyi ti ko tẹ ọpọ ọmọ Naijiria lọrun.
Ni Ọjọbọ lo yẹ ko kọkọ ti gbe awijare rẹ kalẹ ṣugbọn ko lee ṣe bẹẹ nitori gẹgẹ bi awọn ileeṣẹ iroyin abẹle ṣe sọ, awọn ọmọ igbimọ naa ko yọju sii rara.
" Mo gbe ọmọ mi ọmọ ọṣẹ meji meji sẹyin mo darapọ mọ àwọn obinrin to n fun awọn ọkunrin ni okuta lati pa awọn eniyan, eyi ni alaye Mukamushinzimana nitori pe o ni wọn paa lasẹ fun-un ni.
Kí wọ́n lè máa mú àṣẹ rẹ̀ ṣẹ,kí wọ́n sì máa pa òfin rẹ̀ mọ́.
Ìdílé onígbàgbọ́ ni mo ti wá, ni àsìkò náà olólùfẹ́ pásítọ ọ̀un ni maami jẹ́, ó sì fẹ́ ki n lọ nítórí àwọn ìṣòrò ti mo ní.
Èèyàn 281 ló kó covid-19 lọ́jọ́ Ìṣẹ́gun, 123 wá láti ìpínlẹ̀ Eko nìkan O dabi ẹni pe coronavirus tun ti n gbilẹ si diẹ diẹ lorilẹede Naijiria.
Wọ́n ti wọ́gilé ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ Arsenal àti Brighton lẹ́yìn tí Mikel Arteta lùgbàdì àrùn Coronavirus Aṣíwájú ni Nàíjíríà nínú ìdènà Coronavirus, ohun márùn-ún rèé tí àgbáyé ń kọ́ lára wa Arìnrìn àjò tó bá ṣẹ̀ṣẹ̀ dé gbé, ábẹ́ ààbò ọjọ́ mẹ́rìnlá ni wọn yóò wà torí Covid19 - Uganda Oṣu Keji ni Naijiria kọkọ ni akọsilẹ aarun coronavirus.
Lábàlúyẹ̀gẹ̀ pẹ́ l’ẹ́bọ, ó d’alákǐsà aṣọ.
Ṣugbọn kii ṣe pe o fẹ ṣe isakoso Malawi ni ilana ẹ̀kọ́ Bibeli.
Ó níláti jẹ́ ẹni mímọ́ fun yín, nítorí pé èmi OLUWA tí mo yà yín sí mímọ́ jẹ́ mímọ́.
naa, ko si ni pe bo sowo awon agbofinro.
 ó dá ẹgbẹ ́ northern peoples congress sílẹ ́ ní ọdún 1951 .
Ọ̀rọ̀ náà dùn nínú Igbó Olódùmarè, nítorí ẹbọra mu ọtí yó, wọ́n sì ń jó bí wọ́n ti lè jó mọ.
Iru aṣẹ bẹẹ ko si yọ awọn ijoye Alaafin, eyiun Oyomesi silẹ, to fi mọ awọn olori ilu to wa labẹ isejọba ni Oyo ati olori ikọ ologun, tii ṣe Aarẹ Ọna Kakanfo.
Wọn ni bi Sanusi ṣe gba lati joye Emir jẹ ọna abayọ fun un ko ma baa jẹjọ lori ẹsun iṣowo baṣubaṣu ti wọn fi kan an gẹgẹ bi gomina banki apapọ Naijiria.
Ti a o ba gbagbe pe , adajọ Onnoghen ni won fi esun kan pe, o kuna lati
Ogun Kidnap: Ìjàmbá ṣàwọn ajínigbé tó fẹ́ fipá gba akẹgbẹ́ wọn lọ́wọ́ ọlọ́pàá
peso argẹntínà jẹ ́ owóníná ní orílẹ ̀ èdè argẹntínà pẹ ̀ lú àmì ìdánimọ $ tí ó máa n wà lẹ ́ yìn iye owó bí ó ṣe wà fún àwọn ìlú tókù tó ń lo owó dólà .
Ninu ọrọ akọroyin onwoye kan to ba BBC sọrọ, Abdulaziz Abdulaziz, o ni ọrọ yii ko ya oun lẹnu nitori pe, irori Aisha Buhari ati Buhari to jẹ ọkọ rẹ, kii papọ lọpọ igba.
Ó sọ̀kalẹ̀ lọ sí Jọpa, ó sì rí ọkọ̀ ojú omi kan tí ń lọ sí Taṣiṣi níbẹ̀.
Ìdámẹ́wàá àwọn ọkunrin tí wọ́n wà ní Israẹli yóo máa pèsè oúnjẹ fún àwọn ọmọ ogun, àwọn yòókù yóo lọ jẹ àwọn ará Gibea níyà fún ìwà burúkú tí wọ́n hù ní Israẹli yìí.
A kò tí ì gbọ́ ǹkankan lórí owó ìwé ìrìnnà sí Naijiria - U.
Ibadan Oba Crisis: Lekan Balogun ní ìjọba kò pe àwọn sípàdé kó tó gbé ẹjọ́ kúrò nílé ẹjọ́
Bi eeyan ba jẹ oloselu lode toni tabi to n gbero lati darapọ mọ oselu, o ti wa foju han gbangba bayi pe ko le mu aarẹ Naijiria gẹgẹ bi baba isalẹ ti yoo gba a la lọjọ iṣoro.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù CAN: Ìbànújẹ́ ńlá ni iku ọ̀mọ̀wé Musa Asake jẹ 11 Èbibi 2018 Oríṣun àwòrán, Dailypost Àkọlé àwòrán, Owurọ ọjọ ẹti ni akọwe ẹgbẹ CAN naa jade laye nilu Abuja lẹyin aisan ranpẹ Akọwe ẹgbẹ ọmọlẹyin kristi ni orilẹede Naijiria, CAN, Ọmọwe Musa Asake, ni iroyin sọ wi pe o ti jade laye bayii.
Wọn ni wọn ko tii le sọ ibi ti ọkọ ofurufu na ti n bọ tabgi ibi to n lọ, ṣugbọn gbogbo eyii ni yoo di mimọ lẹyin iwadii.
Ó gbé ẹ̀wù náà wọ Aaroni, ó sì dì í ní àmùrè rẹ̀, ó gbé aṣọ àwọ̀kanlẹ̀ wọ̀ ọ́ ati efodu rẹ̀, ó sì fi ọ̀já efodu tí wọ́n ṣe iṣẹ́ ọnà dáradára sí lára dì í lámùrè.
iwa ipaniyan ati pipadanu ohun ini ni awon apa ibikan lorile ede yii, paapaa
Buhari padà sí Nàìjírìa láti ìlú London Ninu iroyin ẹwẹ, Aarẹ Muhammadu Buhari pada s'orilẹede Naijiria lẹyin isinmi ọjọ mẹwa nilu London.
Nengi: Oríṣun àwòrán, Instagram/Nengi Rebecca Nengi'' Hampson lo ṣeeṣe ko gba ipo kẹta lonii bi eto BBNaija ọdun 2020 yoo ti wa si ipari."
Nígbà tí ó di ìrọ̀lẹ́, àwọn ẹyẹ àparò fò dé, wọ́n sì bo gbogbo àgọ́ náà; nígbà tí ilẹ̀ ọjọ́ keji mọ́, ìrì sẹ̀ bo gbogbo àgọ́ náà.
N óo pa àwọn tafàtafà Elamu, tí wọn jẹ́ orísun agbára wọn, 
Wọ́n fi ìyìn fún Ọlọrun Israẹli.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Pakistan new rape law: Ìjọba yóò fààye gba fífi kẹ́míkà tẹ ọkùnrin lọ́dàá 15 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Aarẹ orilẹ-ede Pakistan ti buwọlu ofin tuntun ti yoo ma rii daju pe wọn tete n ṣe idajọ ẹni to ba fi ipa banilopọ.
Adájọ́ ní kí Ahmed Danladi, tó jẹ́ awakọ̀ tó jalè gbálẹ̀ kóòtù f'ọ́jọ́ méjì ní Abuja Wo àmì márùn-un tí o fi le mọ ẹni tó fẹ́ gbẹ̀mí ara rẹ̀ Wo fọ́tò àrà MC Oluomo, Pasuma àtàwọn òṣèré tíátà míì níbi ìṣílé Iyabo Ojo Ọ̀dọ́ Nàíjíríà fèsì padà fún Buhari lórí ìkéde pé kí wọn padà sóko Àjọ Elétò ìdìbò INEC ti sọ̀rọ̀ lórí iná tó jó àwọn káàdì ìdìbò ní Ondo Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Fídíò, Akomolede ati Aṣa lori BBC: Mọ̀ si nípa oríṣìí ẹ̀ka ìsọ̀rí ọ̀rọ̀ àti ìwúlò wọn8 Owewe 2020 Fídíò, Akomolede: Bolaji Faleke ni Olùkọ́ tó ń kọ́ wa ní àṣà oge ṣiṣe lórí BBC Yorùbá1 Owewe 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
" Gomina ipinlẹ Ondo, Arakunrin Rotimi Akeredolu (SAN) ti fi da awọn eniyan ipinlẹ Ondo loju wipe ko ni si aaye fun oniwa ọdaran kankan lati da omi alafia ti wọn n gbadun nipinlẹ naa ru.
Awọn oṣisẹ ni awọn ọrọ kobakungbe ti Ajimobi maa n sọ fun awọn lai san owo oṣu lasiko, to si tun n mu awọn oṣisẹ to ba pẹ de ẹnu iṣẹ lo fa eyi.
Ṣugbọn bí gbogbo yín bá ń sọ àsọtẹ́lẹ̀, bí ẹnìkan tí ó jẹ́ alaigbagbọ tabi ẹnìkan tí ó ṣẹ̀ṣẹ̀ ń kọ́ nǹkan nípa igbagbọ bá wọlé, yóo gbọ́ ohun tí ó jẹ́ ìbáwí ati ohun tí yóo mú un yẹ ara rẹ̀ wò ninu ọ̀rọ̀ tí ẹ̀ ń sọ.
ICPC ní Modibo Kawu náà kò yọ sílẹ̀ nínú awọn ti yóò foju wína òfin nítori àsìlò ipò rẹ̀.
Oríṣun àwòrán, @MBuhari Buhari, lasiko to n gbalejo awọn eeyan yii ni Abiọla ati igbakeji rẹ ti wọn dijọ dije, ni wọn jẹ Musulumi, bẹẹ ni aawọ ẹsin tabi ti ẹyako ba ti waye, nitori Kanuri ni ẹni to dije bii igbakeji Abiọla, ti oun naa si jẹ ilumọọka yika Naijiria.
- Atiku bèèrè lọ́wọ́ ọmọ Nàíjíríà Hubert Ogunde rèé, baba àwọn òsèré tíátà Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ìfipábánilòpọ̀: Abiamọ bú sẹ́kún nígbà tí ọkùnrin kan fi tipá bá ọmọ méjì lòpọ̀ Ilé ìfowópamọ méje ló ni ẹ̀ka ní àdúgbò Lagere yii tàwọn adìgunjalè gúnlẹ̀ sí ní dédé aago mẹ́wàá òwúrọ.
Wọn óo máa pòkìkí bí oore rẹ ti pọ̀ tó,wọn óo sì máa kọrin sókè nípa òdodo rẹ.
Dasọfunjo fikun pe, aago meji ọsan oni ni wọn yoo sin Majek gẹgẹ bi ilana ẹsin musulumi.
ati pé Hilikaya fún òun ní ìwé kan; ó sì kà á sí etígbọ̀ọ́ ọba.
Bakan naa lo tun ma n tẹ akọsilẹ jade lori ayelujara, nipa jijẹ òbí.
Akinyele tún gbàlejò àwọn mùjẹ̀mùjẹ̀, tìyá-tọmọ̀ fara gbọgbẹ́ Gẹgẹ bi a se ka a ninu akọsilẹ oju opo ayelujara Wikipedia, ipa ti Ọba Adesọji Aderẹmi ko lati di alafo to wa laarin olowo ati ọlọrọ kii se keremi.
Lẹ́yìn tí Dafidi ti ṣẹgun Hadadeseri ọba, tí ó sì ti pa àwọn ará Siria tí wọ́n wà lẹ́yìn rẹ̀, Resoni di olórí àwọn ìgárá ọlọ́ṣà kan tí wọ́n kó ara wọn jọ, tí wọn ń gbé Damasku.
Awọn ara orilẹede Iran, Afghanistan ati Iraq ko fi oju abo agbo sere rara ati ọpọlọ rẹ.
Sugbọn iroyin naa ni Azriel ní ààrùn ọpọlọ tó lágbàra, taa ba wo iru ìjìyà to ti rí lọ́wọ́ R Kelly.
yorùbá jẹ ́ ìran tó kónimọ ́ ra .
Ni oju opo @GhanaCuties, ilanilọyẹ nipa arun jẹjẹrẹ ọyan lo wa nibẹ.
O ni Ẹ mọ nọmba pajawiri ti ẹ le pe, ẹ jẹ ki awọn aladugbo yin mọ ohun ti ẹ n la kọja, ẹ sọ awọn apẹrẹ ti wọn le ri lara yin funwọn lọna ati le ran yin lọwọ."
Wọn óo wó odi Tire; wọn óo wó ilé-ìṣọ́ tí ó wà ninu rẹ̀ palẹ̀.
Yéwándé ni ó mú wọn wọlé Kọ́kọ́rọ́ ojú ńlá séèfù yìí kìí ya Orímóògùnjẹ́.
”Ninu oro asoju orile ede Gambai naa, o so pe”inu awon omo orile ede Gambai dun si yin pataki julo aare  ati orile ede yin, fun ipa ribi-ribi ti e ko lori orile ede wa.
Èmi gan ti fojú rí ohun tó ń sọ - ọ̀pọ̀ ọ̀dọ̀ Nàíjíríà ni oògùn ikọ́ olómi tó ní èròjà codeine nínú ti di bárakú fún, èyí tó leè di kòsee-mámu fún wọn.
Baale ijọba ibilẹ Maska, Alhaji Abdullahi Umar, ti o gba iwe eri sise aseyori ise akanse naa gbadura pupo fun isakoso ijọba ti o wa lori alefa lowolowo lati wa gba awon eniyan agbegbe yii sile.
Saaju ninu oṣu kẹrin ọdun yii lo n rọ awọ ololufẹ rẹ lju opo iroyin rẹ pe o ti se diẹ ti oun kọ nkan si oju opo naa nitori pe oun padanu aburo ti wọn bi le oun sọwọ aarun coronavirus.
n óo sì jẹ́ kí ó gbé ọdún mẹẹdogun sí i.
ẹni tí ó pa àwọn ọba ńlá,nítorí pé ìfẹ́ rẹ̀ tí kì í yẹ̀ wà títí lae;
ni kikun:  Jay Jay Okocha, Mutiu Adepoju,
Ni asale odun tuntun, olokan-o-jokan  iyanju ati seku pani waye,  ni eyi ti omo-ogun olote IRSAD  kan ti gbemi mi, ti pupo si fara pa,  ikolu ti won gbagbo pe, awon omo-ogun olote IRSAD lo wa nidi re.
Wọ́n ń sọ ọ̀rọ̀ ìbàjẹ́ káàkiri nípa mi,wọ́n sì ń gbógun tì mí láìnídìí.
Ile iṣẹ yii ni ọpọ n tọka si gẹgẹ bii ọkan lara awọn ileeṣẹ agba oṣelu, aṣiwaju ẹgbẹ oṣelu APC, Bọla Ahmed Tinubu lori ẹsun ṣiṣe owo ni magomago.
Ẹni tí ó bá gba olódodo ní orúkọ olódodo yóo gba èrè olódodo.
ó kígbe sókè pé, ‘Gé igi náà lulẹ̀, gé àwọn ẹ̀ka rẹ̀ kúrò, gbọn gbogbo ewé ati èso rẹ̀ dànù; kí àwọn ẹranko sá kúrò lábẹ́ rẹ̀, kí àwọn ẹyẹ sì fò kúrò lórí ẹ̀ka rẹ̀.
O ni kikọ yara ikawe oloju mẹrin,marun un, ati bẹẹbẹẹ lọ ko ni jẹ iṣoro fun ijọba Oun.
Akojọpọ esi naa re e fun ipinlẹ kọọkan.
“Kí Besaleli, ati Oholiabu ati olukuluku àwọn tí OLUWA fún ní ìmọ̀ ati òye, láti ṣe èyíkéyìí ninu iṣẹ́ tí ó jẹmọ́ kíkọ́ ilé mímọ́ náà, ṣe é bí OLUWA ti pa á láṣẹ gan-an.
Sharibu Nathan sọ fun ikọ̀ BBC pe oun ṣi nigbagbọ pe aaye ni ọmọ oun wa.
Àwọn ìròyìn mìíràn tí ẹ lè nífẹ̀ẹ́ sí: 'Kọ́kọ́ kànsí àlúfà lórí ọ̀rọ̀ ìgbéyàwó' 'Ọdún 2019 pẹ̀lú àwọn àsọtẹ́lẹ̀ tó kó lọ́wọ́ dé' Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
EFCC ju akọwe ijọba Babachir silẹ
Ọna to gba yi ṣokunkun ti o si ṣeeṣe ki o jẹ ọna tawọn ẹlomiran yoo fi ko arun yi.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Lucas Moura: Ọmọ atàpátadìde tó gbé Tottenham wọ àsekágbá ìdíje Champions League 9 Èbibi 2019 Oríṣun àwòrán, BBC Sport Bi eeyan ba ma n ta tẹtẹ lori bọọlu ,nkan to n ṣẹlẹ ninu idije Champions League ọdun yi le mu ki eyan padanu owo tabi ki o di olowo tabua.
O mura bẹẹ laisko eto Mamma Mia ni gbọngan O2 ni London BBC News, Yorùbá Ìdí tí ẹ fi le è nígbàagbọ́ nínú ìròyìn BBC Ìlànà Lílò Nípa BBC Òfin Àṣírí Cookies Kàn sí.
Wọn óo sùn, wọn kò sì ní jí mọ́.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Kayode Abiara: Ọmọ Nàíjíríà, ẹ má ba ọkàn jẹ́ lórí ààbò tó mẹ́hẹ, ewu ìgbà ìkẹyìn ló jẹ́ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Kayode Abiara: Ọmọ Nàíjíríà, ẹ má ba ọkàn jẹ́ lórí ààbò tó mẹ́hẹ, ewu ìgbà ìkẹyìn ló jẹ́ 15 Ọ̀wàrà 2019 Odu ni Wolii Samuel Kayọde Abiara laarin awọn ojisẹ Ọlọrun lorilẹede Naijiria, kii si se aimọ fun oloko awọn ọmọ orilẹede Naijiria.
Àwọn tí ó wà nípò àṣẹ kàn ń gbìyànjú láti ri apá òmìnira tí kò farahàn yìí mọ́lẹ̀, gẹ́gẹ́ bí wọ́n ṣe dìbò yan òfin ìdáríjì ìjọba ní ìkọ̀kọ̀ lọ́dún 1993 tí wọ́n sì fìdí ìgbàgbé ìjọba múlẹ̀ nípa ìpakúpa àwọn ológun náà lọ́gbọ̀n ọdún sẹ́yìn.
Ṣugbọn o ṣalaye pe fidio naa to n wo gbogbo ohun to nṣẹlẹ dede duro ni dede ago mẹjọ alẹ eyi si ni dedee akoko ti iroyin sọ pe ibọn yinyin bẹrẹ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Hepatitis: A kò leè kóo nípa dídìmọ́ ara ẹni Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Nítorí kí ni wọn kò ṣe rí òfin náà?
3b fún àkanṣe iṣẹ́ márùn ún
Ni ọdun 1958 ni Olusegun Obasanjo dara pọ mọ awọn ologun Naijiria lati igba naa lo si ti ni oniruuru imọ ẹkọ ogun.
“Nígbà tí ọba bá pèsè ẹbọ ọrẹ àtinúwá, kì báà ṣe ẹbọ sísun, tabi ẹbọ alaafia, ni ọrẹ àtinúwá fún OLUWA tí ó pèsè, wọn yóo ṣí ẹnubodè tí ó wà ní ìhà ìlà oòrùn fún un, yóo sì rú ẹbọ sísun tabi ẹbọ alaafia rẹ̀ bíi ti ọjọ́ ìsinmi.
Ijọba ilẹ Ghana fikun pe, Nana Akufo yoo ma a ṣiṣẹ lọ gẹgẹ bi aarẹ ni igba ti o ba fi wa ni iyasọtọ.
Kì í ṣe láti wẹ ìdọ̀tí kúrò lára, bíkòṣe ọ̀nà tí ẹ̀bẹ̀ eniyan fi lè jẹ́ ìtẹ́wọ́gbà lọ́dọ̀ Ọlọrun nípa ẹ̀rí ọkàn rere, nípa ajinde Jesu Kristi, 
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Akẹ́kọ̀ọ́ wọlé padà, ìjọba Oyo kò pèsè ìbòmú lòdì sí ìlérí rẹ̀ Ẹ wo bí ọ̀rọ̀ òṣèlú, ẹ̀sìn àti ẹ̀yà ṣe fa ogun abẹ́lé Biafra Kàkà k‘éwé àgbọn dẹ̀ lágbo òṣèlú l‘Ondo, akọ̀wé ìjọba tún kọ̀wé fipò sílẹ̀ Ẹ wo bí ọ̀rọ̀ òṣèlú, ẹ̀sìn àti ẹ̀yà ṣe fa ogun abẹ́lé Biafra Diẹ ree ninu nkan ti a ri ko jọ nipa Hushpuppi Ilu Eko ni wọn bi si Ni pato ọjọ ti wọn bi Hushpuppi ti orukọ rẹ gangan n jẹ Ramoni ''Raymond'' Igbalode ko ye wa ṣugbọn bi a ba fi awọn nkan to sọ nipa ara rẹ wo ọrọ yii, ko le ti to ogoji ọdun.
lorile ede Naijiria Tanko Muhammad,n dari rẹ lo sun igbẹjọ naa siwaju.
kí alufaa tún yẹ̀ ẹ́ wò, bí ẹ̀yi náà bá ti gbilẹ̀ lára rẹ̀, kí alufaa má wulẹ̀ wò bóyá irun rẹ̀ pọ́n tabi kò pọ́n mọ́, aláìmọ́ ni.
”Gege bi ile-eṣẹ akoroyin l’orilẹ-ede Argentina won ni, Sala sọ
Ówá jẹ́ etí kan péré ló ngbé ohùn sí.
Ohun ti wọn lo faa tawọn fi ṣe bẹẹ ni bi awọn agbofinro ti ṣe yinbọn pa awọn ọmọ ẹgbẹ wọn.
Wọ́n ti ni kí àwọn alága ìjọba ìbílẹ̀ Ogun lọ rọọ́kún nílé Àràmọ̀ǹdà àwòràn láti ilẹ̀ àdúláwọ̀ lọ́sẹ̀ yìí Àrà kengé!
ti o wa lati ri aare Muhammadu Buhari tun ni aare ana lorile ede yii, ni  ogagun feyinti  Yakubu Gowon (Rtd.
Wọn yóo máa ta hapu, wọn yóo máa lu aro, wọn yóo máa fọn fèrè, wọn yóo máa tẹ dùùrù, wọn yóo sì máa sọ àsọtẹ́lẹ̀.
Nígbà tí Jesu rí igbagbọ wọn, ó ní, “Arakunrin, a dárí ẹ̀ṣẹ̀ rẹ jì ọ́.
Mi o ni ibalopọ ri; mi o ki n ṣe aṣẹwo, bawo ni mo ṣe wa ni aarun HIV?
Igbimo to n mojuto oro irin-ajo ori-ile nile igbimo asofin pelu apapo awon toro kan gbongbon nile igbimo asofin ohun, ti pe fun sisun aabo ise akanse ojuurin to n lo lowo nilu Eko si Ibadan siwaju.
Alufaa yóo pàṣẹ pé kí wọ́n bá ẹni tí wọ́n fẹ́ ṣe ìwẹ̀nùmọ́ fún mú ẹyẹ mímọ́ meji wá ati igi kedari, pẹlu aṣọ pupa tẹ́ẹ́rẹ́ kan, ati ewé hisopu.
Ṣugbọn èyí nìkan kọ́, ewu tí ó tún wà ni pé, ilé ìsìn oriṣa ńlá wa, Atẹmisi, yóo di ohun tí ẹnikẹ́ni kò ní ṣújá mọ́.
Nigba to n fidi isẹlẹ naa mulẹ, oludari ajọ to n ri si isẹlẹ pajawiri nipinlẹ Eko, Lasema, Oke Ọsanyintolu sọ fun BBC Yoruba pe awọn eeyan to n fọ ọpa epo pẹtiroolu lo se okunfa isẹlẹ naa.
' Alukoro ajọ naa, Tunji Oketunbi, sọ pe awọn ti bẹrẹ iwadii ohun to fa ijamba naa.
awon ara ilu ni ekun Niger Delta.
 Ó tún ya àwọn àwòrán oní bèbí sí orí aṣo .
Eko -542 FCT-131 Oyo-120 Rivers-113 Plateau-111 Kaduna-71 Kwara-71 Akwa Ibom-34 Sokoto-31 Benue-28 Ogun-27 Kano-26 Kebbi-17 Osun-12 Nasarawa-11 Delta-10 Gombe-10 Bayelsa-9 Borno-9 Edo-8 Ekiti-3 Jigawa-2 Katsina-2 Kìí ṣe gbogbo àwọn tó ní Covid-19 ló ń ṣàfihàn àpẹrẹ rẹ̀, ẹ ṣọ́ra ṣe o - NCDC Oríṣun àwòrán, @Chikwe_I Ajọ to n ri si igbogun ti ajakalẹ arun ni Naijiria, NCDC, ti ni kii ṣe gbogbo awọn to ni arun Coronavirus lara lo maa n ṣafihan awọn apẹrẹ rẹ, nitori naa ki awọn ara ilu ṣora ṣẹ.
Bẹẹ ni ọrọ ri pẹlu ẹjọ Eji Gbadero.
27 Àti báyìí ni òun nlọ sí òkè àti sí ilẹ̀, síwá àti sẹ́hìn nínú ilé ayé, ní wíwá lati pa ọkàn àwọn ènìyàn run.
 pe eto idibo yoo lọ ni irowo-irose .
Nítorí yóo sọ pé, ‘Ọtí tí ó mú ni ó dára.
Kí ló fa iná ńlá tó ṣẹ́yọ lọ́jà Ajman lórílẹ̀èdè United Arab Emirates DSS tún ti mú Olawale Bakare tó jẹ́jọ́ pẹ́lúu Sowore nítorí ìwọ́de Revolutionnow A ṣì ń ṣèwádìí lọ́wọ́ lórí àwọn t'ọ́ta ìbọn pa lọ́jọ́ ọdún Eid n'Ibadan - Ọlọ́pàá Aarẹ Michel Aoun sọ pe, tọọnu nkan abugbamu ammonium nitrate to le l'ẹgbẹrun meji (2,750), ti wọn ko pamọ lọna ti ko tọ si ibudo ikẹru si, lati bi ọdun mẹfa, lo fa ibugbamu naa.
N óo kọlu àwọn ilẹ̀ tí ó ti di ahoro nígbà kan rí, ṣugbọn tí àwọn eniyan ń gbé ibẹ̀ nisinsinyii, àwọn eniyan tí a ṣà jọ láti ààrin àwọn orílẹ̀-èdè, ṣugbọn tí wọ́n ní mààlúù ati ohun ìní, tí wọ́n sì ń gbé ìkóríta ilẹ̀ ayé.
Ohun ijamba mẹta yìí tí ó ń yọ jáde lẹ́nu wọn pa ìdá mẹta àwọn eniyan.
Jesu wí fún un pé, “Èmi tí mò ń bá ọ sọ̀rọ̀ yìí ni Mesaya náà.
Ìyá yìí mọ ọ̀nà tí ènìà lè gbà dé ibi àpáta Robin Hood ní kíákíá, ó sì júwèé rẹ̀ fúni tí ènìà bá wí fún-un pé ibẹ̀ ni òun nlọ.
Ògo OLUWA gbéra kúrò láàrin ìlú náà, ó sì dúró sórí òkè tí ó wà ní apá ìhà ìlà oòrùn ìlú náà.
Olori ẹgbẹ akẹkọọ nigba naa, Segun Okeowo, (to ti di oloogbe bayii lẹni aadorin ọdun) pe oniruuru ipade awọn akẹkọọ yika Naijiria lori ọrọ yii, ti wọn si fi ipinnu wọn ransẹ sijọba.
Asoju ajo ilera agbaye WHO fun Naijiria, Alemu Wondimagegnehu, ni awon idagbasoke isegun ibile yoo mu itesiwaju ba erongba ilera kariaye.
Èṣù-kékeré doríkodò bí ewé ọ̀gẹ̀dẹ̀, ẹbọra inu ọ̀gán ń wo ilẹ̀ tirònútìrònú, ẹ̀dá kékeré la ẹnu rẹ̀ ó si wí pé:
Ó ti dáwọ́ ire ṣíṣe dúró;kò sì hu ìwà ọlọ́gbọ́n mọ́.
Afi kẹ̀ẹ̀, nina ba ran pada lọ si orisun ibi ti wọn ti n ji epo to si gbana pẹlu ọwọ ina giga to n jo wi wi wi.
Ile-ejo agba lorile-ede Israel da ijiroro erongba ijoba kan duro lojo-Bo, latari ariynajiyan to jeyo lori dida ogunlogo awon arinrinajo lona aibofinmu lati orile-ede Eritrea ati orile-ede Sudan pada,Ile-ejo ohun so ninu ipinnu re pe, won fun orile-ede Israel ni gbedeke  titi di ojo kerindinlogbo osu keta, lati pese awon eri ti o peye, lori erongba re nipa kiko awon arinrinajo naa lo si orile-ede miiran ni won yoo da duro titi di igba to oro naa yoo fi niyanju.
" Ọmọdé yóò máa sọnù ládùúgbò, arúgbó leè kú láì tọ́jọ́, tí wọn bá jókòó sílé lásìkò ìjọsìn - CAN Oríṣun àwòrán, others Saaju la ti kede pe awọn asaaju ẹgbẹ ọmọlẹyin Kristi (CAN) ti n sọrọ lori aṣẹ ti ìjọba apapọ pa pe, awọn ọmọde ati arugbo ko gbọdọ lọ sile ijọsin.
A tun ti bọ sode lori itankalẹ ede Yoruba ati bi awa ọmọ 'kootu oo jiire' ṣe mọ ami ohun ori ọrọ Yoruba si.
Ní ìbẹ̀rẹ̀ ìjọba Sedekaya, ọba Juda, ọmọ Josaya, OLUWA bá èmi Jeremaya sọ̀rọ̀; ó ní: 
Oríṣun àwòrán, PA Àkọlé àwòrán, Joshua ti di ẹlẹṣẹ agbaye - pẹlu igbanu ẹyẹ mẹta , ati ade IBO , igbanu ẹyẹ WBC nikan lo ku fun Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Bí ẹni tí a fi erùpẹ̀ dá ti rí, bẹ́ẹ̀ ni gbogbo àwọn tí a fi erùpẹ̀ dá rí.
Ati pe ọjọ keje, oṣu keje ni awọn alakoso tuntun wọnyii a bẹrẹ iṣẹ.
Aarẹ Muhammadu Buhari ni ko tọ si ọmọ ole ko maa pariwo ọlọpaa n bọ.
Ìjọba náà ń bínú sí alákòóso tẹ́lẹ̀-rí ẹ̀ka náà, Zeid Ra'ad Al Hussein tí ó ṣàpèjúwe Nkurunziza ti Burundi gẹ́gẹ́ bí ọkàn lára “àwọn apanilẹ́kúnjayé ènìyàn tí ó ń gbèrú sí i láìpẹ́ yìí” ní oṣù Èrèlé 2018.
Wọ́n lọ dó ti Gibeoni, wọ́n sì ń bá a jagun.
Akọkọ naa, nọmba NIN ko le sọnu, wọn ko si le forukọ silẹ lati gbaa lẹẹmeji.
Ẹni ọdún mẹẹdọgbọn ni nígbà tí ó jọba, ó sì wà lórí oyè fún ọdún mẹrindinlogun ní Jerusalẹmu.
18 Agẹmo 2020 Oríṣun àwòrán, Getty Images Oogun apakokoro lọwọ ti oloyinbo n pe ni Hand Sanitizer"" ti di ja pataki lori igba bayii koda o ti di nkan pataki to gbud wa lapo rẹ nibikibi too ba n lọ nitorii arun Coronavirus."
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Adigunjalè méjì ko ìjàmbá ọ̀kadà lẹ́yìn ìṣẹ́ ibi n‘Ibadan, ọ̀kan kú lójijì, aráàlú dáná sun èkejì Àwọn ohun kàyéèfì tó le mú kí ọmọbìnrin ní oyún ìju Ìrẹ̀sì kò gbọdọ̀ wọlé níbáyìí ta ṣí ẹnu bodè padà - Ìjọba àpapọ̀ Ìdí tí àwọn ìpińlẹ̀ se ń ti ilé ẹ̀kọ́ ní ìhà ìwọ̀ Oòrun-Àríwá Nàìjíríà rèé Abẹ́rẹ́ àjẹsára Covid-19 yóò dé sí Nàìjíríà nínú oṣù kíní ọdún 2021 Jide Kosoko forin sẹ́nu pé òun ni igi lẹ́yìn ọgbà Mr Latin lórí ipò ààrẹ TAMPAN tó wà Ó pé ọdún mẹ́wàá tí Barrister kú; wo ǹkan tó yẹ láti mọ̀ nípa rẹ̀ gẹ́gẹ́ bíi olórin, tẹ̀wé-tẹ̀wé, akọ̀wé àti sọ́jà Àìmọ̀kan ló mú mi hu ìwà tí mo hù kọjá sẹ́yìn, Jonathan dárí jì mí - Dino Melaye Bakan naa lo tun pe fun mimu adinku ba agbara to wa ni ijọba apapọ, ki idagbasoke le de ba awọn ipinlẹ atijọba ibilẹ.
Agbo-ilé tí OLUWA bá mú yóo wá ní ìdílé-ìdílé.
Bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé àwọn ọmọ Israẹli ti ṣèlérí pé àwọn kò ní pa wọ́n, sibẹsibẹ Saulu gbìyànjú láti pa wọ́n run, nítorí ìtara rẹ̀ fún àwọn ọmọ Israẹli ati Juda.
Ẹ lọ kọ́ bí eniyan tí ń ṣe rere.
Minisita fun eto ilera lorile ede Naijiria,ojogbon Isaac Adewole ti fokan awon omo orile ede Naijiria bale pe ,ijoba apapo n sa gbogbo ipa won lati wa ojutuu si  iyanselodi ti awon osise eleto ilera  (JOHESU)gunle.
Ọkàn rẹ̀ á súnmọ́ ibojì,ẹ̀mí rẹ̀ a sì súnmọ́ àwọn iranṣẹ ikú.
" Tinubu: Ọbasanjọ kò lè yan olùdíje fún wa Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Ọ̀lọ́wọ́ òsì kọ́ndọ́rọ́' Bale ni yóò rọ́pò Ronaldo nínú Super Cup 'Ẹ fi akọ̀ròyìn Samuel Ogundipe sílẹ̀' Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, INEC yoo sun miliọnu meje kaadi idibo Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Wọn fi ofin dee pe kò gbọdọ wọ àfin mọ, wọn gbiyanju lati da aarin awọn oloye ẹgbẹ rú, ki wọn le rọ Kuti loye, ṣugbọn pàbó ló já sí.
Láàrin ọjọ́ meje tí ẹ óo fi jẹ burẹdi tí kò ní ìwúkàrà, a kò gbọdọ̀ rí burẹdi tí ó ní ìwúkàrà lọ́wọ́ ẹnikẹ́ni ninu yín, kò sì gbọdọ̀ sí ìwúkàrà ní gbogbo agbègbè yín.
Ọjọgbọn Claudia Estcourt to jẹ agbẹnusọ fun ẹgbẹ awọn onimọ ilera oyinbo alawọfunfun to nimọ nipa ibalopọ ati arun HIV sọ pe gbigba ẹnu ni ibalopọ tubọ maa n pin awọn arun ibalopọ kiri ni.
Nígbà tí rògbòdìyàn náà kásẹ̀, Paulu ranṣẹ pe àwọn ọmọ-ẹ̀yìn Jesu.
26 Agẹmo 2019 Oríṣun àwòrán, Prof.
Kọmisọnna fun eto isuna ni ipinlẹ Ondo, Emmanuel Igbasan fi idi ọrọ yii mulẹ, lẹyin ti igbakeji aarẹ orilẹede Naijiria, Yemi Osinbajo sọ pe ipinlẹ Ondo ni ọpọlọpọ ohun alumọni kaakiri ipinlẹ naa.
Yoo rin de bi kan bi ko tilẹ kari gbogbo eniyan 'tori Eko gba ole o gba ọlẹ, gbogbo eniyan lo n sa wa silu Eko.
Ó dájú pé àwọn tí ó jìnnà sí ọ yóo ṣègbé,o óo sì pa àwọn tí ó bá ṣe alaiṣootọ sí ọ run.
Ọmọ China j'oyè fún ìgbà àkọ́kọ́ nílùú Kano Ẹ fójú lóúnjẹ níbi African Drum Festival 2019 Top 4 ta pàù!
Ẹyin eeyan mi l'Ọsun, wọn ko fẹran yin o.
Oun naa si ti bọ si gbangba wa bẹbẹ pe Elisha Abbo ṣàlàyé ìdí tó fi lu obìnrin fún BBCiru rẹ ko ni ṣorọ lọwọ oun lẹyin ti awọn bii Atiku ti baa wi ninu ẹgbe PDP to ti n ṣoju ipinlẹ Adamawa.
Aisha Yesufu sọrọ yii loju opo Twitter rẹ, nigba to n sọrọ lori ọrọ apilẹkọ ti aarẹ Muhammadu Buhari ba awọn ọmọ Naijiria sọ lalẹ Ọjọbọ.
 ""Lẹyin Alaafin Atiba, to jẹ Alaafin akọkọ to bi ibẹta, Ayaba Aishat lo tun ni ọla bọ si ọdọ rẹ, lati jẹ ẹni to tun ṣe aṣeyọri naa."
Nítorí pé ninu gbogbo ẹ̀dá alààyè, ta ni ó tíì gbọ́ ohùn OLUWA Ọlọrun alààyè rí láti inú iná, gẹ́gẹ́ bí àwa ti gbọ́ ọ yìí, tí ó sì wà láàyè?
Kò sí ọba ní ilẹ̀ Israẹli ní gbogbo àkókò náà, nítorí náà ohun tí ó bá tọ́ lójú olukuluku ni olukuluku ń ṣe.
Wọn si ba oku obinrin naa ni ilẹ yaara igbalejo rẹ.
 Ìgè jẹ ́ gómìnà ìpínlẹ ̀ oyo lati osù kẹwàá ọdún 1979 títí dé osù kẹwàá ọdún 1983 .
O ni ti waha ba sẹlẹ lasiko eto idibo, ti awon ti ko yẹ ko wọle
5ti iye re je milionu 8 ti o to N 270.
Oríṣun àwòrán, Others Lẹyin isinku naa ni Baba Obasanjo wa tẹsiwaju lọ ki awọn lọbalọba to wa ni agbegbe naa.
Ọdun 2015 ni wọn yan Kyari gẹgẹ bi Olori awọn oṣiṣẹ fun Aarẹ Muhammadu Buhari.
Àkókò tí ìṣẹ ̀ lẹ ̀ yìí ṣẹ rú ni lójú púpọ ̀ .
Tá láwọn ọba aládé àti olóṣèlú tí EFCC n wà lórí owó ìrànwọ́ N2bn ní Kwara?
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Aràrá bíi tèmi, kó má rò pé kò sì ǹkan tó lè ṣe láyé ju iṣẹ́ agbe lọ' Amọ ninu ọrọ ti wọn, ẹgbẹ Arewa Consultative Forun ni Aarẹ Buhari ni awọn ṣe atilẹyin fun pẹlu ẹgbẹ oselu APC, ati wi pe ọrọ Obasanjo gan an lo n da idarudapọ silẹ lorilẹede Naijiria.
Ta tún ni Ọlọrun, bíkòṣe OLUWA?
awon eniyan ati ijoba ipinle Rivers kẹdun lori iku awon osise ile-ise  afẹfẹ  gaasi
Matanaya ọmọ Mika, ọmọ Sabidi, ọmọ Asafu, ni olórí tí ó kọ́kọ́ bẹ̀rẹ̀ ìdúpẹ́ ninu adura, ati Bakibukaya tí ó jẹ́ igbákejì ninu àwọn arakunrin rẹ̀, Abuda, ọmọ Ṣamua, ọmọ Galali, ọmọ Jedutuni.
lati se, bẹẹ si ni ijọba ko ni kuna lati ri i pe atunse to mọnyan ba ikọ naa.
Ọkan lara awọn ẹlẹgbẹ wa kọlu ASP Chukwuma Onuora pẹlu ọbẹ to fi di a n lọ ọ mọra ẹni lọwọ to si gun ọdọkunrin ọhun.
Ajọ WHO ni o ṣeeṣe ki awọn to n ni ibalopọ pẹlu ẹni pupọ, tabi awọn aṣẹwo tabi awọn to n ni ibalopọ akọ si akọ.
Oríṣun àwòrán, Twitter/Bdayo90 Lori iroyin to n lọ pe eeyan bi mẹjọ ni ọlọpaa fi ibọn pa, Ọgbẹni Ajamu sọ pe wọn o pa ẹnikẹni ninu aafin, ati pe oku ti awọn ọdọ naa gbe wa si aafin ni awọn ọlọpaa n wọ jade pada ninu fidio kan to wa lori ayelujara.
Àwọn gómínà ilẹ̀ Yoruba ní àwọn yòò dojú ijà kọ jàndùku Fulani
3m Monthly To LG Ghost Workers - Report', ni Fayemi ti kọminu lori bi awọn oṣiṣẹ ijọba ibilẹ wa ni ipinlẹ Eko ti wọn si n gba owo oṣu ni ipinlẹ Ekiti.
Awọn ara adugbo naa ti wa rọ ijọba ipinlẹ Ọyọ lati tete da si ọrọ naa tori kii se igba akọkọ ree ti awọn ọmọ onilẹ yoo wa maa dun mahuru-mahuru mọ wọn lori ilẹ ti wọn ti ra lati ọdun gbọọrọ.
Ní ọdún kẹta tí Asa, ọba Juda, gorí oyè, ni Baaṣa, ọmọ Ahija, gorí oyè, ní ìlú Tirisa, ó sì di ọba gbogbo Israẹli.
Keita ti kọkọ se asoju ijọba Mali lati ọdun 1994 si ọdun 2000, to si tun jẹ Adari ile igbimọ asofin agba orílẹ̀-ede Mali laarin ọdun 2002 si 2007, oun ni oludasilẹ ẹgbẹ oṣelu Centre-Left Party Rally (RPM) ni Mali lọdun 2001.
Polio: Bàbá kọ abẹ́rẹ́ àjẹsára kí ọmọ rẹ̀ tó ní àìsàn polio!
Ileesẹ iroyin Russia to gbẹnu sọ fun ileesẹ oloogun ilẹ naa, kede pe ọkọ ofurufu An-26 jabọ nigba to n balẹ ni papako awọn ọmọogun ofurufu to wa ni Latakia, lorilẹede Syria.
Lara asa ounjẹ to tun ti n jẹyọ nibi ayẹyẹ bayii ni pe awọn kan ti n fi Gaari Ijẹbu pẹlu omi tutu ati ẹja tabi ẹran adiyẹ dindin ṣe alejo.
Alukoro fun egbe APC tun so pe, igbimo alakoso egbe ti se ipinnu lati yan igbimo  ise akanse  ti   ile igbimo asofin,ijoba apapo  ati egbe yoo foju lameeto wo iwe eto lori atunse to ro mo eto isakoso ijoba apapo  ti egbe won se, lori isejoba orile ede Naijiria “ lati le je ki aare le gbe lo si siwaju ile igbimo asoju –sofin”.
Ìpayà yóo mú kí àwọn ọ̀gágun rẹ̀ ju àsíá sílẹ̀.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Blind Couples: Pẹ̀lú ìpèníjà ojú, tọkọtaya bímọ mẹ́ta, tí wọn sì tún ń ṣiṣẹ́ olùkọ́ Nítorí iwọde yii, NECO ni awọn ko ribi ko iwe idanwo lọ bá awọn akẹkọọ to fẹ kọ idanwo naa.
" A jẹ pé aṣiwere ni R Kelly, pẹ̀lú gbogbo ǹkan ti ojú mí ti rí, kí ń wá ma mú àwọn ọmọde lòdì si ìfẹ́ wọn, ''lo ọ̀pọ̀lọ ẹ,'' èyí ní Kelly sọ fun àkọròyìn níwájú ayawòràn.
Ẹgbẹ agbabọọlu meji ti muṣemuṣe wọn ko da muṣemuṣe to, Manchester United ati Arsenal lo fẹ koju ara wọn lalẹ ọjọ Aje ni papa iṣere Old Trafford ninu idije English Premier League.
Asa ọba bá kéde ní gbogbo ilẹ̀ Juda, ó ní kí gbogbo eniyan patapata láìku ẹnìkan, lọ kó gbogbo òkúta ati igi ti Baaṣa fi ń mọ odi Rama kúrò ní Rama.
Oríṣun àwòrán, AFP/Getty Images Àkọlé àwòrán, Awọn ololufẹ ẹgbẹ agbabọọlu Arsenal kan n pe fun idaduro Wenger gẹgẹbii olukọni ikọ naa O daju wipe abajade ifẹsẹwọnsẹ yii yoo tubọ mu ki ẹnu o maa kun olukọni ikọ agbabọọlu naa, Arsene Wenger ti pupọ awọn ololufẹ ẹgbẹ agbabọọlu naa n pariwo rẹ wi pe asiko to ko fi ipo silẹ gẹgẹbii olukọni ni ẹgbẹ agbabọọlu Arsenal.
Ṣaaju abẹwo yii, aarẹ ti kọkọ ṣabẹwo si ipinlẹ Taraba, Plateau, Benue ati Zamfara lori wahala ọrọ abo to gbode kan lawọn agbegbe kan lorilẹede Naijiria.
Atẹjade yii ni wọn fi lede ni Ọjọ Ayajọ Aisan otutu-aya lagbaye (World Pneumonia Day).
Wọn yóo dá a lẹ́bi ikú, wọn yóo sì fi lé àwọn tí kì í ṣe Juu lọ́wọ́.
Gẹ́gẹ́ bí àṣà àwọn alufaa, Sakaraya ni ìbò mú láti sun turari ninu iyàrá Tẹmpili Oluwa.
Ileeṣẹ ologun ofurufu Naijiria ti sọ abajade iwadii rẹ lori iku to pa awakọ-ofurufu jagun obinrin akọkọ ni Naijiria, Tolulope Arotile.
Nína afurasí ní àhámọ́ nínú eré tíátà, bí àwọn ọlọ́pàá ti ń ṣe lójú ayé burú jáì"" Tacha tọrọ àforíjí, ó da gbogbo ẹ̀bi lé ara rẹ̀ lórí Kàyééfì rèé!"
Lasiko to n ba BBC Yoruba sọrọ, Ọpẹmipọ sọ pe, ti eeyan yoo ba tiẹ fẹ ẹnikẹni ninu isẹ tiata, ko yẹ ko ni gbedeke kankan ti eeyan fi gbọdọ se bẹẹ.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Àjọ NEMA fèsì ẹ̀sùn táwọn aṣòfin fi kan Ọṣinbajo Àǹfáànì wo ló wà nínú ìtẹ̀síwájú ìsèjọba?
nítorí òtítọ́ tí ó ń gbé inú wa, tí ó sì wà pẹlu wa yóo wà títí lae.
Abdulrahman jẹ́ olùdíje gómìnà Kwara kan sọsọ tí kò ní ìbaṣepọ̀ pẹ̀lú ìdílé Saraki láti ìgbà tí Nààjíríà ti padà sí ìlànà ijọba awa ara wa ní ọdún 1999.
Ọpọlọpọ eto ti yoo ṣe wọn lanfani bii idanilẹkọọ lo yẹ ki ijọba kọkọ ṣe ki wọn wa fi ofin lelẹ.
"Oríṣun àwòrán, other ""Wọ́n ní kí n bọ́ aṣọ mi wọ́n sì bẹ̀rẹ̀ sí ni fi 'Pipe' lù mí"" Lásìkò tí wọ́n ń tú fóònù mi wọ́n ri owó ti mo ni, wọ́n sì ní àwọn yóò gba mílíọ̀nu kan Náírà lọ́wọ́ mí'."
Oríṣun àwòrán, @Haramain Awọn alaṣẹ mọṣalṣi mejeeji ṣalaye pe, lẹyin ti awọn Aafa nla yii ba pari irun ti aabo wọn ti daju ni awọn ọmọ ogun ilẹ to n ṣọ wọn naa a ṣẹṣẹ wa kirun ti wọn lẹyin tawọn ero ba ti pari.
O ni péréte báyìí sì ni àwọn akọsilẹ̀ ti wọ́n n fi síta naa.
Pẹlu esi yi,,ile koko n tagbe ni fun wọn Cameroon ti Naijiria si tẹsiwaju lọ abala to kan ninu idije naa Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ẹ wo bí àwọn olólùfẹ́ Super Eagles ṣe tú lọ sí ibùdo Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Wilfred Ndidi: Mi ò fi dáa yín lójú pé a máà bórí o!
“Ní ọjọ́ kẹjọ, yóo mú ọ̀dọ́ àgbò meji tí kò lábàwọ́n, ati ọ̀dọ́ abo aguntan ọlọ́dún kan tí kò lábàwọ́n, ati ìdámẹ́wàá lọ́nà mẹta ìwọ̀n efa ìyẹ̀fun tí ó kúnná dáradára, tí a fi òróró pò ati ìwọ̀n ìgò òróró kan fún ẹbọ ohun jíjẹ.
Ó lọ sọ́dọ̀ ekinni, ó sọ fún un pé, ‘Ọmọ, lọ ṣiṣẹ́ ninu ọgbà àjàrà mi lónìí.
Lásìkò Ramadan, wo àwọn orílẹ̀èdè tí wákàtí ààwẹ̀ wọn gùn ju ti Nàìjíríà lọ Ikọ̀ ẹlẹ́sìn Hàkíkà rèé, níbití wọn ti ń pààrọ̀ ìyàwó láàrín ara wọn Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, RAMADAN: Onímọ̀ ẹ̀sin sọ nípa isẹ́ láádá àti làádà Adamu ni iye àwọn ènìyàn ti àwọn ti mú ni àsìkò yiìí ti lọ silẹ̀ ju ti atẹyin wa lọ, èyí túmọ si pé ìgbìyànjú àwọn ti n ni ipa rere Ọ̀pọ̀ àwọon ti a gbámu pe wọn ń jẹun, ìgbà àkọkọ rèé ti a o mú wọn fún ẹsun ounjẹ jijẹ, gẹ́gẹ́ bi iṣẹ́ wa ṣe ri àwọn ènìyàn yìí, ẹ̀tọ́ wa ni láti gbàwọn nimọran sùgbọ̀n ti a ba mú wọn ní èèkeji o di ẹ̀wọn tààrà ni Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Bí ìrẹsì tèmi Ayinde bá ń pàkùta, kò tọ́ sẹ́nu aláàrù Barrymaade' Agbẹnusọ náà ní ti ẹnikẹni ba mọ ibi ti musulumi kankan ba ti n jẹun nile ounje ki wọn jẹ ki awọn gbọ ki àwọn ba le gbe ìgbésẹ̀.
Ẹ̀ sì máa ni gbogbo àwọn òṣìṣẹ́ yín lára.
Ẹ̀yin ẹ máà wò ó, ó ṣeéṣe kí APC túká lẹ́yìn ìṣèjọ́ba Buhari!
Afi bii ara ilu oyinbo lo maa n ri loju temi.
Ó bá pada lọ sọ́dọ̀ Benhadadi, ó sì bèèrè ohun tí Eliṣa sọ lọ́wọ́ rẹ̀.
Bí ó tilẹ̀ dàbí ọ̀dọ́, tí ó lágbára,sibẹ yóo lọ sí ibojì, yóo sì di erùpẹ̀.
Ṣugbọn Fayose rọ awọn ọmọ ile igbimọ asofin nipinlẹ Ekiti lati fọwọṣowọpọ pẹlu Fayẹmi fun aseyọri eto naa.
Àwọn ará ìjọ́ Cherubim & Seraphim Movement sọ nípa olóògbe Moses Olaiya Àwọn ọmọ àti ìyàwó olóògbé Moses Ọlaoluwa Adejumọ sọ pé ìwà ire sọ́ọ́ ní àwọn kọ lára ìgbé ayé Baba Sala.
Koda, ọpọ ọdọ lo ti n ki ọdọmọde yii ku oriire ti wọn si n gba imọran awokọṣe rere loju opo BBC Yoruba.
Ọjọ Iṣẹgun lo gba ami ẹyẹ naa nibi eto kan to waye l'orilẹede Senegal.
South Africa: Èrò àwọn èèyàn ṣọ̀tọ̀ọ̀tọ̀ lórí fidio ti Aisha Buhari fi síta
Eleyi ni igba kẹta ti iṣẹlẹ ijinigbe yoo waye nile iwe laarin ọsẹ meji nOlúwaṣeuni Kaduna.
N óo fìyà jẹ àwọn tí wọn ń gbé ilẹ̀ Ijipti, n óo fi ogun, ìyàn, ati àjàkálẹ̀ àrùn pa wọ́n run bí mo ṣe fi pa Jerusalẹmu run.
Ṣugbọn mo jẹ́wọ́ ohun kan fun yín: lóòótọ́ ni mò ń sin Ọlọrun àwọn baba wa ní ọ̀nà tí ó yàtọ̀.
Lẹ́yìn náà ni òpin yóo dé.
bí mo ti dúró nídìí kànga yìí, ọmọbinrin tí ó bá wá pọnmi, tí mo bá sì sọ fún pé, jọ̀wọ́, fún mi lómi mu ninu ìkòkò omi rẹ, 
Ẹ ranti bí Ọlọrun ti fi wọ́n ṣe ẹlẹ́yà títí tí wọ́n fi jẹ́ kí àwọn ọmọ Israẹli lọ.
Èyí [ni ọ̀nà kan] fún ìpèsí àkíyèsí ìjọba João Lourenço, wípé àfilé ìdíyelé kò yẹ nírú àsìkò yìí, nítorí owó náà ti ṣe gegere ju fún àwọn ọmọ ìlú.
Ni Àríwá Ireland, awọn ẹgbẹ to lodi si iyapa naa korajọ si Armagh fun ifẹhonuhan lodi si iyapa naa, ṣugbọn o dabi pe omi ti tẹyin wọgbin lẹnu.
Ṣugbọn ńṣe ni ìròyìn rẹ̀ túbọ̀ ń tàn kálẹ̀.
Ọ̀ràn kí ni àgbò dá tó fi jẹ́ pé ọdọọdún ni ẹgbẹẹgbẹ̀rún mùsùlùmí ń yọ ọ̀bẹ́ sí i lọ́rùn?
Oríṣun àwòrán, Twitter/Screenshot Oríṣun àwòrán, Twitter/Screenshot Oríṣun àwòrán, Twitter/Screenshot Oríṣun àwòrán, Twitter/Screenshot Oríṣun àwòrán, Twitter/Screenshot Oríṣun àwòrán, Twitter/Screenshot Ojuloge ni Lisa' Lisa jẹ eeyan to gbafẹ to si tun maa n ṣoge daada.
Agbẹjọ́rò Maina yọ ọwọ́ kúrò nínú ìgbẹ́jọ́, Ó lóun kò ṣé mọ̀ Taa ni Ọọni àná tí Ọba Ogunwusi forúkọ ọmọ rẹ̀ sọ?
Iboju dudu ni Hajar Raissouni wọ wa si ile ẹjọ ni Rabat, to jẹ olu ilu Morocco.
Mìmì kan kò mì wá, Ẹlẹka yóò jíǹde bí i Lasaru inú Bíbélì -PDP Ekiti 'Fashọla, o ò dẹ̀ bẹ̀rù Ọlọ́run!
Yóo fi idà pa àwọn ará ìlú kéékèèké tí ó wà ní agbègbè tí ó yí ọ ká.
Ti wọn ba fidirẹmi Chelsea yoo bọ si ipo kẹfa ti Aston Villa yoo si lewaju wọn ni ipo kaarun.
 Itakun agbaye ile iwe FIU ni won gab to eedegberun awon eniyan sise labe won bayii.
N kò yẹ ní ẹni tí à bá máa pè ní ọmọ rẹ mọ́.
Ní ojú ìran, ó rí ọkunrin kan tí ń jẹ́ Anania, tí ó wọlé tọ̀ ọ́ lọ, tí ó fi ọwọ́ bà á lójú kí ó lè tún ríran.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù AFCON 2019: Ìdíje ife ẹ̀yẹ láàrin orílẹ̀èdè Áfíríkà 14 Òkùdu 2019 .
Wo àwọn orílẹ́-èdè mẹ́wàá tí kò ní coronavirus lágbàáyé, bá wo ni wọ́n ṣe ṣe é?
Ẹgbẹ oṣelu PDP fikun pe fidio to safihan awọn ọkọ ijọba ti wọn fi n ko awọn madaru fihan pe ijọba lọwọ si rogbodiyan to n ṣẹlẹ kaakiri ipinlẹ Eko ati Naijiria lapapọ.
Ìgbà àkọ́kọ́ kọ́ nìyíì tí irú ìjà bẹ̀ ẹ́ yóò wáyé Afi bi ere ori itage ni nilu Ado ekiti to jẹ olu ilu fun ipinlẹ Ekiti lọjọ Aje, nigba ti ẹgbẹ awọn ọlọkọ eero yan awọn alásẹ tuntun, eyi to ṣeese ko jẹ ni ibamu pẹlu ayipada to ba eto iṣejọba oloṣelu nipinlẹ naa.
Lizzy Anjorin vs Toyin Abraham: Lizzy Anjorin tún rọ òjò ọ̀rọ̀ tuntun lórí Toyin
Messi ṣekú pa Man United pẹ̀lu 3-0 16 Ìgbé 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 17 Ìgbé 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Idije UEFA Champions League Ajẹtun iya ni ikọ Manchester United jẹ lọwọ Barcelona ninu idije UEFA Champions League.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Bí Hushpuppi ṣe tiraka rèé l‘Eko, kí ọlà ‘òjijì’ tó dé Wo bí ọwọ́ orílẹ̀-èdè Dubai ṣe tẹ Ramoni Igbalode tí gbogbo ayé ń pè ní Hushpuppi Ṣé lóòtọ́ ni Lateef Adedimeji àti Adebimpe Oyebade ṣe ìgbéyàwó?
Pẹlu abajade ifẹsẹwọnsẹ yi bayi, Chelsea ti ni ami mejilelgbọn ti wọn si wa ni ipo kẹrin lori afara.
Àwo ati abọ́ náà kún fún ìyẹ̀fun kíkúnná tí a fi òróró pò fún ẹbọ ohun jíjẹ, 
Awọn ifarajin ti ẹ ṣe lasiko Ramadan yẹ ko tubọ fa yin sunmọ Ọlọrun sii Babajide Sanwo-Olu: Ẹ ranti awọn eeyan miiran ninu ajọyọ yin Oríṣun àwòrán, @jidesanwoolu Àkọlé àwòrán, Ẹ ranti awọn eeyan miran ninu ajọyọ yin Adura ni gomina ipinlẹ Eko, Babajide Sanwo-Olu gba fun awọn musulumi ni tirẹ.
BBNaija: Laycon, Nengi, Dorathy, Neo àti Vee ti jẹ ẹ̀bùn rẹpẹtẹ lórí ètò Big Brother Season 5
Èmi nìkan ni mo rí ìran yìí, àwọn tí wọ́n wà pẹlu mi kò rí i, ṣugbọn ẹ̀rù bà wọ́n, wọ́n sì sápamọ́.
Aaroni bá sọ fún wọn pé, “Ẹ gba gbogbo yẹtí wúrà etí àwọn aya yín jọ, ati ti àwọn ọmọkunrin yín, ati ti àwọn ọmọbinrin yín, kí ẹ sì kó wọn wá.
"Kii se ọmọ ẹgbẹ́ awakọ èrò lo ń fa wàhálà, digbi la wá, a kò sì já, kódà, kò sì àwọn mọto wa ninu gareji ọkọ mọ gan àmọ́ àwọn èèyàn ti ìjọba yàn bíi Alakoso gareji lo ń ba ara wọn jà.
Awọn mii gba pe ẹni ti kò ba ni itiju iṣẹ le maa ta èso bii ọsan, ibẹpẹ, ọ̀pẹ̀ oyinbo àti bẹẹ bẹẹ lọ.
Èmi kò rí ìdí kankan tí ó fi jẹ̀bi ikú.
Ọgbẹni Bada wa bu ẹnu atẹ lu iroyin kan to n ja rainrain pe ile ifowopamọ kan ti fun ọmọdebinrin ọjọ naa lẹ́bun owo Ọga ileewe Dele gba awọ́n ọmọ ile to ku ni imọran ki wọn gbiyanju lati maa ṣe gẹgẹ bi Dele ṣe ṣe to lo anfani to ni Ọ̀ọ̀ni kò láṣẹ láti yọ mí nípò, mi ò sì ní ááwọ̀ mọ́ pẹ́lú Aláàfin-Oluwo Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ìlú Eko ló jẹ gbèsè jù ní Nàìjíríà lẹ́yìn ìjọba àpapọ̀ Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
n óo bọ́ ọ kúrò, n óo sì fi ọ́ lé Nebukadinesari ọba Babiloni, ati àwọn ará Kalidea lọ́wọ́, àwọn tí wọn ń wá ẹ̀mí rẹ, tí ẹ̀rù wọn sì ń bà ọ́.
Osinbajo naa dahun pe “ Nigba ti o ba si ilekun ile itaja re fun
Ethiopia: Abiy Ahmed ni olóòtú ìjọba tuntun
Sibẹ iroyin ni àwọn ọlọpaa SARS ṣi n lo ipa ninu iwadii.
Serubabeli tún bí ọmọ marun-un mìíràn: Haṣuba, Oheli, ati Berekaya; Hasadaya ati Juṣabi Hesedi.
A fi àmì òróró yan Absalomu ní ọba, ṣugbọn wọ́n ti pa á lójú ogun, nítorí náà, ó yẹ kí ẹnìkan gbìyànjú láti mú Dafidi ọba pada.
Lawan fi ikedun re han ninu atejade kan to fi ranse si alaga egbe NUJ ni ipinle naa lati owo  adari awon osise re , Alhaji Ahmad Amshi ni Damaturu.
Apanirun yóo wọ gbogbo ìlú,ìlú kankan kò sì ní bọ́ lọ́wọ́ rẹ̀;àwọn àfonífojì yóo pòórá, a óo sì pa àwọn pẹ̀tẹ́lẹ̀ run.
Èmi ni mo wí fún un pé ìyàwó rẹ̀ ń bá ẹlòmíràn jáde ní alaalẹ̀, èmi náà tí mo fi i si ibi kan kí ó máa wo ìyàwó rẹ̀ bí o ti ń ṣe pẹ̀lú ọkùnrin mìíràn ni mo ni kí àbúrò ìyàwó rẹ̀ wọ aṣọ ìyàwó rẹ̀, bẹ́ẹ̀ ni emi ni mo yí aṣọ pada tí mo lọ bá àbúrò yìí.
O tesiwaju ninu ọrọ rẹ wi pe, ijọba apapọ yoo ri i daju pe ijọba ilẹ South Africa dide fun iranlọwọ awọn ọmọ Naijiria ti wọn ba dukia wọn jẹ.
Lalẹ Ọjọru ni gbajugbaja akọnimọọgba Jose Mourinho yoo pada si papa iṣere ẹgbẹ agbabọọlu Manchester United nibi to ti ṣiṣẹ ki wọn to fọwọ oṣi juwe ile fun un lọdun 2018.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, ‘Ara fu mí nígbàtí bàbá gbé Bíbélì ìdílé fúnmi’ Ajani akẹkọọ to wa ni ipele aṣekagba ni fasiti nibiti sanmọnti gbe dun ile to tun jẹ ọlọgba ẹranko ni olu ẹda itan to nifẹ Aṣakẹ, Lóla àti Ṣade.
O wa ro awon eniyan lati ma se jafara  , ki won si maa fi to awon olopaa tabi agbofinro leti , nigba ti won ba kofiri awon eniyan ti irin won ba mu ifura lowo.
Lati igba to ti gba ami ẹyẹ nidi eto ọgbin, lo ti n lo anfaani naa lati fi pe akiyesi awọn obinrin si ẹtọ wọn, to fi mọ aini anfaani si rira ilẹ, ailọ sile ẹkọ ati iwa ipa ninu ile sawọn obinrin.
Ó sì yẹ kí ààyè ó gba esè nínú u bàtà pẹ̀lú.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Bàbá ìyàwó ní ìfẹ́ wà láàrin ọmọ́ òun àti ọkọ rẹ̀, inú àwọn sì dùn sí ìgbeyàwó náà 13 Ọ̀pẹ̀̀ 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Ọdọmọbinrin ọmọ ọdun mẹrindinlogun kan, Fatima Abubakar ti padanu ẹmi rẹ lẹyin to re sinu kanga omi nigba ti igbeyawo rẹ ku ọla.
Yatọ fun awọn ere tirẹ, Funke ti kopa ninu ọpọlọpọ ere mii yala lede Yoruba tabi Gẹẹsi eyi ti ko ṣee darukọ tan.
Petrol Price Hike: Ilé aṣojú-ṣòfin dúró ìṣẹ́jú kan fún Buruji Kashamu àti Rose Okoh
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Lọ́gán tí mo bá di ààrẹ, mo máa bẹ̀rẹ̀ iṣẹ́' Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
GOV Iroyin tuntun ti ileeṣẹ ọgba ẹwọn l'orilẹ-ede Amẹrika, fi sita nipa ọmọ orilẹ-ede Naijiria, Hushpuppi ni pe, o ti wa ni ọgba ẹwọn nilu Chicago, Illinois.
gbogbo ilẹ̀ ọba Ogu ti Baṣani, tí ó jọba ní Aṣitarotu ati Edirei.
Wọ́n lé wọn jáde láàrin àwọn eniyan,wọ́n ń hó lé wọn lórí bí olè.
Ẹ wo ohun tí wọn yóò máa ṣe ní ìpínlẹ̀ - DAWN Commission 'A rí wàhálà táwọn Yorùbá ń kojú la ṣe fi Amotekun"" mú ọkàn wọn balẹ̀' 'Àwọn òyìnbó máa ń fẹ́ tọ́ oúnjẹ mi tí wọ́n rí lórí Instagram wò' Oju inu ni Emeka fi n ṣe gbogbo iṣẹ rẹ̀ to si fi n wo gbogbo awọn irinṣ to yẹ ko lo."
kọkọ fẹ dupẹ lọwọ egbe osise orile ede yii, fun ifọkansin ati ifẹ ti ẹ fihan
Kora kó gbogbo ìjọ eniyan náà jọ sí ẹnu ọ̀nà Àgọ́ Àjọ láti dojú kọ Mose ati Aaroni; Ògo OLUWA sì farahàn, àwọn eniyan náà sì rí i.
Eredi ree ti wọn ṣe fi ofin mu.
tóbẹ́ẹ̀ tí ó fi wí pé, “N óo pa àwọn ẹ̀dá alààyè tí mo dá run lórí ilẹ̀ ayé, ati eniyan ati ẹranko ati àwọn ohun tí ń fàyà fà káàkiri lórí ilẹ̀, ati ẹyẹ, gbogbo wọn ni n óo parun, nítorí ó bà mí ninu jẹ́ pé mo dá wọn.
Ma ṣe haa o, ohun ti iwadii ajọ aṣesiro ode lorilẹ-ede Naijiria, Nigeria Bureau of Statisics, NBS lo fi idi rẹ mulẹ ninu iwadii to ṣe to si gbe abajade rẹ sita fun aye ri lọjọ Ẹti.
Inú ẹ̀yà wo ni o sì ti wá?
10 Nísisìyí, ó jẹ́ dandan fún mi pé kí á yàn án láti ọwọ́ rẹ, Oliver Cowdery àpóstélì mi;
Mo kórìíra àwọn tí ń bọ oriṣa lásánlàsàn,ṣugbọn OLUWA ni èmi gbẹ́kẹ̀lé.
Wọ́n pàgọ́ láti Beeriṣeba títí dé àfonífojì Hinomu.
OLUWA Ọlọrun wa yóo pa wọ́n run.
Ondo Accident: Agbègbè Awoyaya ní gáréjì Ifẹ l‘ondo ní ìjàǹbá náà ti wáyé
Oríṣun àwòrán, Ibrahim Musa Àkọlé àwòrán, Òkú ènìyàn mọ́kànlá ni mo rí níbi tí ìṣẹ̀lẹ̀ nàá ti wáyé, tó fi mọ́ òkú obìnrin kan tó n tọ́mọ lọ́wọ́.
Fayoṣe: Mi ò jẹ̀bi ẹ̀sùn kankan Agbẹjọ́rò: Pe Ayọdele Fayose ati ileeṣẹ kan ti orukọ rẹ n jẹ spotless limited jumọ gba owo kan ti apapọ rẹ jẹ N317 miliọnu laarin ọjọ kẹtadinlogun osu kẹfa si ọjọ kẹrin oṣu kẹjọ ọdun 2014.
Ó purọ́ mọ́ ọkọ rẹ̀ pẹ̀lú pé òun orúkọ òun níbi tí baalé òun àti ìyáálé náà ti ń sọ̀rọ̀ àti pẹ̀lú pé kò sí àníàní wí pé òun ní àwọn méjèèjì ń bú.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Boko Haram: Ikọ̀ afẹ̀jẹ̀wẹ̀ náà kó òògùn òyìnbó, oúnjẹ́ tí wọ́n sì tún pa ọmọogun mẹ́ta 23 Èrèlè 2020 Oríṣun àwòrán, @jorowasinda Ilu Garkida to wa nijọba ibilẹ Gombi nipinlẹ Adamawa gbona jain-jain lalẹ ọjọ Ẹti nigba ti ikọ aṣẹrubalu Boko Haram kọlu ilu naa, to si ti si ti fọwọ gbaya pe oun gan loun wa nidi ikọlu ọhun.
” Mose sì ṣe gẹ́gẹ́ bí àṣẹ tí OLUWA pa fún un.
Ìdí ti gómìnà Ajimobi fi wo ilé mi- Ayefelẹ Oludasilẹ ileesẹ Fresh Fm, Yinka Ayefẹlẹ ti fesi si bi ijọba ipinlẹ Ọyọ se wo ileesẹ redio naa ni kutu hai aarọ ọjọ Aiku.
Ẹ̀yin ọ̀rẹ́-ẹ̀ mi Olùkọ́ Èdè Yorùbá,
BBC News Yoruba lo Moremi gẹgẹ bii apẹrẹ.
Nígbà tí mo rí i, mo dojúbolẹ̀, mo bá gbọ́ ohùn ẹnìkan tí ń sọ̀rọ̀.
Tí o fi ń kìlọ̀ fún wa bẹ́ẹ̀?
Okan lara asoju orile-ede Naijiria ni Sudan, ni ijoba orile-ede Naijiria ati ile-ise olopaa Sudan ti sawari oku re ni agbegbe Khartoum, lojoBo(Thursday).
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ekiti Election: Èyí ni àwọn olóṣèlú Nàìjíríà tó tí 'fọ́gbọ́n ṣàìsàn' 3 Èbibi 2018 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 12 Agẹmo 2018 Oríṣun àwòrán, @ogundamisi Àkọlé àwòrán, Fayose kọ́ ni olóṣèlú Nàìjíríà tí yóò kọ́kọ́ 'kán l'ọ́rùn' Oríṣiríṣi awuyewuye ló tí jẹyọ lórí ìṣẹ́lẹ́ tó wáyé ní ìpínlẹ̀ Ekiti l'Ọ́jọ́rú, níbití Gómìnà Ayọdele Fayose ti 'kán l'ọ́rún' nípasẹ̀ afẹ́fẹ́ tajú-tajú.
of the Chiefs law of Oyo State).
Djokovic, ti o je omo orile-ede Serbia, so eyi di mimo lojo Aiku, nigba ti Alexander Zverev fi eyin re nale  ninu asekagba idije ere idaraya ohun ti o waye lorile-ede Italy.
Nígbà tí wọ́n retí títí, tí wọn kò rí i kí nǹkankan ṣe é, wọ́n yí èrò wọn pada, wọ́n ní, “Irúnmọlẹ̀ ni!
O ni o sàn ki lọkọlaya yago funra wọn fun igba diẹ ju ki wọn maa gun ara wọn pa sinu ilé lọ.
Ìgbẹ́ ọmọdé ń dènà ààrun jẹjẹrẹ, àìsàn ìtọ̀ súgà Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Orileede India naa n ba ipenija igbẹ yiya ni ita gbangba finra Pẹlu bi iṣesi yii ti ṣe gbale, ki ni awọn aburu to wa ninu ki eeyan ma yagbẹ si ita gbangba lalai bikita.
"Ẹ mọ wi pe o ṣeeṣe ko ni awọn ẹgbẹ ọdaran tirẹ to si lee fẹ mu ki wọn wa dojukọ abo lawọn ileewosan wa paapaa julọ awọn oṣiṣẹ wa.
Nítorí náà ẹ gbé ọwọ́ yín tí kò lágbára sókè, ẹ mú kí eékún yín tí ń gbọ̀n di alágbára; 
Ninu ọrọ rẹ, Sulaiman Adeniyi sọ wi pe, ko si ohun ti yoo yẹ ẹ ọjọ ifẹhọnu han lati ma se waye, nitori mani gbagbe ni yoo jẹ.
Yoruba ni bi ẹṣin ba da ni, a mọ tun gun, idi ree ti Bamidele tun fi dara pọ mọ ẹgbẹ oselu PDP lọdun 1998, ti wọn si yan sipo alaga igbimọ to n seto idẹrun fawọn arinrin-ajo silẹ mimọ Jerusalemu.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Neymar: Agbábọ́ọ̀lù Brazil kọ ẹ̀sùn ìfipábanilòpọ 2 Òkùdu 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Neymar Gbajugbaja agbabọọlu orilẹede Brazil, Neymar ti ni irọ ni ẹsun ti wọn fi kan pe oun fipa ba obinrin kan lo in Paris.
Óṣeéṣe kí ìjọba yí ètò ẹ̀kọ́ sí ẹ̀kọ́ àárọ̀ àti ìrọ̀lẹ́ láti ṣí iléèwé padà ní Nàìjíríà Ayálégbé wa tó fi tipá já àbálé mi ṣe àkóbá fún ìgbé ayé mi - Foluke Daramola Ó ṣeéṣe kó jẹ́ pé àwọn alágbara ló ń fi agbára hàn lórí arábìnrin tó fẹ̀sùn ìfipábánilòpọ̀ kan kọmíṣọ́nà Kogi -Agbẹjọ́rò Lara oun ti ajọ NCCA tun sọ ni pe oun ko ni fi awọn oṣiṣẹ inu baalu si iyasọtọ , ṣugbọn wọn gbọdọ maa ṣe ayẹwo Covid-19 ni ọjọ mẹrinla-mẹrinla.
nígbà tí àwọn orílẹ̀-èdè bá péjọ tàwọn tọba wọn,láti sin OLUWA.
Mo ti fi í sí ààrin àwọn orílẹ̀-èdè, mo sì ti fi àwọn agbègbè yí i ká.
O ni ijọba yoo pese gbogbo awọn ohun eelo amayedẹrun ti yoo jẹ ki sinsin ati tita ẹran gbooro si.
Amọ, Lucas Torreira gbiyanju lati dayo kan pada nigba ti ifẹsẹwọnsẹ naa ku iṣẹju marun un ko pari.
Ni ayé òde òni, wọn ti fi owó dipò ipò àgbà, nitori ki wọn tó pe olóri ẹbi ti ó wà ni ìtòsí, wọn yio pe ẹni ti ó ni owó ninú ẹbi ti ó wà ni òkèrè pàtàki ti ó bá wà ni Èkó àti àwọn ilú nla miran tàbi Ilú-Òyinbó/Òkè-Òkun.
Ìjọba àpapọ̀ ti kéde ṣáájú pé àwọn ń retí abẹ́rẹ́ tí yóò tó ogún mílíọ̀nù ni ìbẹ̀rẹ̀ ọdún 2021.
Àṣìpè ni, nítorí pé wọ́n kún fún àwọn ẹ̀kọ́ tí ó lòdì sí ara wọn.
Bí ó ti ń lọ, ọpọlọpọ eniyan ń tẹ̀lé e, wọ́n ń fún un lọ́tùn-ún lósì.
Ninu ifọrọwerọ rẹ pẹlu BBC News Yoruba, Araba awo ti ilu Osogbo, Baba Ifayẹmi Ẹlẹbuibọn ṣalaye ipilẹ ọrọ ati bi o ṣe jẹ titi kan ohun to n fa akudaaya.
Ẹ̀yin olólùfẹ́ mi àti ẹbí ni mo bẹ̀ Àwọn olólùfẹ̀ Toyin Abraham ati Liz Anjorin ti gbé ọ̀rọ̀ wọn rù sórí, ẹ wo òjò òkò ọ̀rọ̀ Ìjà Toyin àti Lizzy kìí ṣe àkọ́kọ́, àwọn òṣèré t'ọ́rọ̀ ìjà kàn rí rèé Èmi àti Saheed kìí ṣe ọmọdé, a ti jọ ṣe Sinimá papọ̀, èyí túmọ̀ sí pé ìjà ti parí - Fathia Balogun O wa ke si awọn eekan ninu isẹ ọna to n lo amọ lati se koriya fun awọn ọdọ ki a lee se agbende isẹ amọ pada bii ti aye atijọ.
Àkọlé àwòrán, Tani yoo rẹyin ara wọn?
Kàyééfì, oyún inú nínú ilé ìgbọ̀nsẹ ọkọ̀ òfurufú Leon van Biljon dí èrò ọrun nípasẹ̀ Kìnìún rẹ̀ Ọ̀rọ̀ Aisha Buhari sí Ramaphosa wú ọ̀rọ̀ síta lẹ́nu àwọn ọmọ Nàìjíríà Oró ò!
”“Mi o lero pe Uzoho yoo ni isoro kankan lati koju iru agbaboolu bi Messi ati awon agbaboolu jankanjakan miran, nitori pe leyin ti o koju Lewandowski, Aguero ati Di Maria, O se daradara, eyi ni o fun mi ni idaniloju pe yoo fakoyo ninu idije naa.
Bi o tilẹ jẹ pe mo ni nkan ba Malami fa lori ikede rẹ naa, amọ maa kọkọ rọ awọn gomina ilẹ Yoruba naa lati tete lọ fi ẹsẹ ofin ti agbekalẹ naa nidi.
Ẹgbẹ́ òṣìṣẹ́ ìpínlẹ̀ Ọyọ bẹ̀rẹ̀ ìyanṣẹ́lódì aláìní gbèdéke Ọlọ́pàá Adamawa ni #30,000 ni wọ́n fi bọ́ igún látìmọ́lé Theresa May bú sẹ́kún, ó ní òun kò ṣe olóòtú ìjọba UK mọ́ Ṣugbọn, adari ile iwosan naa, Ọjọgbọn Chris Bode ti Ọjọgbọn Olufemi Fasanmade ṣe agbẹnusọ fun, ni ẹgbẹ awọn dokita ile iwosan naa pinnu lati daṣẹ silẹ nitori wipe wọn jawe ikilọ fun awọn kan lara wọn nitori iwa to ku diẹ kaato ti wọn hu.
Adamu lo soro yii lasiko ti o n ba awon akoroyin soro niluu Abuja , ni eyi ti o
Oṣere Victoria sọ pe oun ti n ṣere fun bi ọdun mẹwaa bayii.
Nítorí bí ayé yìí ti ń rí yìí, ó ń kọjá lọ.
Ọba Ogunwusi ni o seese ki awọn ọdaran yii ma mọ ijamba ti wọn n se fun ara ilu, nitori naa, ti ọwọ ba tẹ awọn afurasi ọdaran wọn yii, ki wọn se ifọrọwanilẹnuwo fun wọn daadaa.
Dokita naa gba awọn ti aisan itọ ṣuga n ba finra lamọran pe, ki wọn ṣọra fun awọn ounjẹ amunukun ati ọti mimu.
Ṣé ó yẹ kí àwọn obinrin máa jẹ ọmọ wọn?
Awọn agbẹbi lo si maa n ṣe e.
Ìre tí olódodo bá sú fún ìlú a máa gbé orúkọ ìlú ga,ṣugbọn ọ̀rọ̀ ẹnu àwọn eniyan burúkú a máa run ìlú.
“Bí eniyan bá bá ọ sọ̀rọ̀,ṣé kò ní bí ọ ninu?
Igbimọ ile naa wa pinnu lati se agbeyẹwo awọn ilana to wa nidi owoya ti Naijiria ti gba sẹyin lọwọ ilẹ China atawọn orilẹede miran lagbaye.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù A ti gba onírúurú ìgbẹ́ tí a rí lọ́wọ́ Emmanuel Egbu lọ fún àyẹ̀wò -Ọlọ́pàá Oyo 22 Ògún 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 23 Ògún 2020 Oríṣun àwòrán, Police Ilé iṣẹ́ ọlọ́pàá ìpínlẹ̀ Oyo ni ìwádìí ti bẹ̀rẹ̀ ni pẹ̀rẹ̀wu lóri ọkunrin kan ti orukọ́ rẹ̀ ń jẹ́ Emmanuel Egbu ti wọ́n ni o n fi igbẹ jẹ búrẹdi ni ori akintan nilùú Ibadan.
Àwọn ni yóo máa tẹ̀lé ibùdó Juda nígbà tí àwọn ọmọ Israẹli bá fẹ́ kó kúrò ní ibùdó kan lọ sí ibòmíràn.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Akomolede àti Asa lórí BBC Yorùbá: Mọ̀ síi nípa ẹ̀kún ìyàwó níbí Ẹni ti wọn ba gbẹsẹ le esi idanwo rẹ yoo tun IDANWO WAEC ṣe ni, sugbọn lẹyin ọdun meji.
Wọn bẹ̀rẹ̀ sí ni wáa láti ọjọ́ kẹ́ta oṣù kẹ́sàn nígbà tó ń rìnrìn àjò láti Abuja lọ si Bauchi #JosPond: 'Ọkọ̀ mẹ́ta péré la rí nínú odò adágún' Oríṣun àwòrán, Twitter/Nigerian army Àkọlé àwòrán, ọ̀kan lára àwọn ọkọ̀ tí wọ́n rí nínú odò adágún Ile isẹ ologun ori-ilẹ lorilẹede Naijiria ti kede pe ọwọ ti ba ọgbọn afurasi ti wọn mọ nipa ọga ologun to ti fẹyinti Idris Alkali nilu Jos.
 A ni ero apoti kulubu isaworan (TV’s, Decoders) lati ta.
Kano deaths: Kí ló ń fa ikú ọ̀wọọ̀wọ́ ní Kano?
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ta ló ji òṣìṣẹ́ kánsù gbé l'Ekiti?
Ojoojúmọ́ ni ọkọ̀ ofurufú ń kó wọn wọ̀lú lọ́gọọgọ́rùn-ún wọn.
 pẹ ̀ lú àwọn ìhùwàsí ẹ ̀ tí kò fi taratara bójú mu , ijọba maa ń fún ní ọ ̀ wọ ̀ , tí wọ ́ n sì maa ń pèé ní  ọkùnrin ẹlẹ ́ sìn "" ."
Ijọba ipinlẹ Ọyọ ati awọn alakoso fasiti ilẹ Ibadan ti ṣe ipade pẹlu awọn oniṣegun ibilẹ to n bẹ nipinlẹ naa ìpàdé náà dá lori ọna abayọ si aarun aifojuri, Coronavirus to n ba gbogbo agbayhe fira.
Marylove, ọ̀jẹ̀wẹ́wẹ́ agbábọ́ọ̀lù orí pákó gbógo Nàìjíríà yọ
Nítorí èyí, bí ilẹ̀ ti ń mọ́ hàì ni ọjọ́ kejì ni mo ti bẹ̀rẹ̀ sí múra, mo sì ti gbé ohun ìkọ̀wé gbogbo sílẹ̀ kí ó tóó wọlé.
Bí ọmọbinrin alufaa kan bá fẹ́ àjèjì, kò gbọdọ̀ jẹ ninu àwọn ohun mímọ́ tí wọ́n bá fi rúbọ.
Manchester United fọ́ Manchester City lẹ́nu pẹ́tẹpẹ̀tẹ mọ́lé Ọlọ́pàá, adájọ́ àtàwọn aṣọ́bodè ló gba rìbá jùlọ ní Nàìjíríà-NBS Ìròyìn nípa ìyàwó túntún fún ọkọ mi kò mì mí lọ́kàn rárá-Aisha Buhari Bakan naa ni Ruiz ṣalaye fawọn akọroyin peode lilọ lalọju lo koba oun.
 wọ ́ n tún máa ń pe austronesian yìí ní malayo-polynesian .
" Oríṣun àwòrán, @Atiku Atiku fi kun pe gbogbo ileri ti oun n se yii kii se afẹnuse lasan, amọ oun setan lati mu ki awn ileri yii wa si imusẹ laipẹ ti oun ba wọle sipo aarẹ.
A de ibi odo to n san, wọn jẹ ka mu omi, taa si mu bii ẹni pe a ko ni mu omiran mọ, tori omi yii la fi se ounjẹ aarọ ni ọwọ irọlẹ.
NFF àtàwọn olólùfẹ̀ eré bọ́ọ̀lù ń ṣe ìdárò Big Boss: Keshi
Ó ní kí àwọn ọkunrin náà jáde fún ìgbà díẹ̀.
Gẹgẹ bo ṣe sọ pe: O ṣeni laanu pe iṣẹ akin ti awọn ọlọde ati ọmọ ẹgbẹ OPC ṣe ja sofo nitori iwa ọkanjua ti awọn eeyan ilu naa wu lẹyin iṣẹlẹ naa."
Àṣàkẹ́ wọlé bá wọn níbi tí wọn ti ń sọ̀rọ̀ níbi tí wọ́n ti ń ṣe ìwádìí nílé Orímóògùnjẹ́.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù 2019 Elections: Iléeṣé ológun ṣèlérí láti mú àṣẹ Buhari ṣẹ 19 Èrèlè 2019 Oríṣun àwòrán, @HQNigeria Ileesẹ ologun orilẹede Naijiria ti kede pe, o di dandan ki oun tẹle asẹ ‘ji apoti ibo, ko fi iku se ifa jẹ’, to ba jẹ pe aarẹ Muhammadu Buhari lo pa asẹ naa fun oun.
Ìwọ ni mo fi pa olùṣọ́-aguntan ati agbo ẹran rẹ̀ rẹ́,ìwọ ni mo fi run àgbẹ̀ ati àwọn alágbàro rẹ̀,ìwọ ni mo fi ṣẹ́ apá àwọn gomina ati ti àwọn olórí ogun.
Àwọn ọmọ Gileadi nìwọ̀nyí: ìdílé Ieseri, ìdílé Heleki; 
Ekiti Ni ti ipinlẹ Ekiti, ijọba ti sọ pe oogun pakopako ati ajilẹ ni awọn eeyan ji ko dipo ounjẹ iranwọ Covid-19.
Ọba Lamidi Adeyẹmi, òṣìṣẹ́ adójútòfò àti Abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò kó tó jọba Àwọn onílù mí ló ń tú àṣírí ìkà èèyàn tó bá wọ ààfin mi - Aláàfin Eyí ni àwọn arẹwà 'ẹ̀lẹ̀ Daddy', àfẹ́fẹ́ tí Aláàfin fi ń mí Wò ó bí Alaafin àti aya àkọ́fẹ́ rẹ̀, Olorì Abibat ṣe pàdé ní èwe Àwọn alálẹ̀ kò ní forí jìn mí tí ń kò bá ṣe ọdún Ṣàngó - Alaafin Àwọn kókó ohun tó wà nínú lẹ́tà tí Aláàfin kọ sí Fayemi rèé Àwọn olorì Aláàfin fi oríkì awúnilórí yẹ́ ọkọ wọn sí fún àádọ́ta ọdún tó gorí ìtẹ́ Gomina ologun nigba naa to ti di oloogbe, Ajagunfẹyinti Robert Adeyinka Adebayo si lo gbe ọpa asẹ le lọwọ gẹgẹ bii Alaafin Ọyọ.
Ìgbà tí ó sì parí ọ̀rọ̀ rẹ̀ tán, Filásayépọ̀ dìde pọ̀ lẹ́ẹ̀kan ṣoṣo.
Ìwọ ni o fi ọwọ́ ara rẹ lé àwọn orílẹ̀-èdè jáde fún wọn,tí o sì fi ẹsẹ̀ àwọn baba wa múlẹ̀;o fi ìyà jẹ àwọn orílẹ̀-èdè náà,o sì jẹ́ kí ó dára fún àwọn baba wa.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ogundiya: Àṣìṣe Dókítà ló sọ mi di aláàbọ̀ ara lórí kẹ̀kẹ́ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Bimpe: Èèyàn bíi tiyín ni àfín, ẹ dẹ́kun dídẹ́yẹsí àfín Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Orisirisi nkan ni awọn ọmọde ati ọdọ koda agbalagba maa n jẹ nigba miran ti wọn ko si mọ bi o ṣe lewu to.
Ile iṣẹ ọlọpaa fi ẹsun marun ọtọọtọ kan an.
Oni gan ni Toyin Abraham, iya Ire pe ẹni ogoji ọdun laye Toyin Abraham pé 40, wo ohun márùn ún tó mú dá yàtọ̀ láàrín ogójì ọdún Ọpọ eeyan lo ti n kii ku oriire lai yọ baba Ire gan an silẹ to ki Toyin ni oriki to pọ pẹlu adura ọjọ iwaju rere.
Awọn agbesunmọmi naa ni ohun to faa tawọn fi pa awọn agbẹ naa ko ṣẹyin bi awọn ara ilu naa ṣe mu awọn ọms ẹgbẹ rẹ kan ti wọn si fa wọn le awọn ọmọogun Naijiria lọwọ.
Joṣua bá wọn dá majẹmu alaafia, pé, àwọn kò ní pa wọ́n, àwọn àgbààgbà Israẹli sì búra fún wọn.
Ẹ hó ìhó ayọ̀ sí OLUWA, gbogbo ilẹ̀ ayé.
Olùfẹ́, bí ọkàn wa kò bá dá wa lẹ́bi, a ní ìgboyà níwájú Ọlọrun.
Má fi èdè Juda bá wa sọ̀rọ̀ kí àwọn ará wa tí ó wà lórí odi má baà gbọ́.
Eniyan mẹjọ miran tun ti ni aarun coronavirus ni orilẹ-ede Naijiria.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ajao Estate Gas Explosion: Alága ìjọba ìbílẹ̀ Isolo ní àwọn yóò fi òfin dè títà afẹ́fẹ́ gáàsì létílé 29 Agẹmo 2020 Ijọba ipinlẹ Eko ti ni awọn yoo ṣe agbeyẹwo ofin ti yoo dena ki awọn eeyan maa ta afẹfẹ gaasi lẹba ibi ti awọn eeyan n gbe.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Obìnrin tí kó ba fẹ́ òṣìṣẹ́ Mọ́ṣúárì, ìpinu rẹ̀ mẹ́hẹ' Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
’ Kí tún ni ìtumọ̀, ‘Nítorí mò ń lọ sọ́dọ̀ Baba?
Ẹgbẹ́ àwọn òṣìṣẹ́ elétò ìlera, JOHESU bẹ̀rẹ̀ ìyanṣẹ́lódì káàkiri Nàìjíríà Ẹ̀yin tó ń tajà lẹ́gbẹ́ẹ títì, ẹ̀ wá 'bi gbà kọ́jọ́ méje tó pé!
 Orile-ede wa ti  pẹ ju  ni ipele ileri .
Àwọn ati àwọn ọmọ wọn ati àwọn ọmọ ọmọ wọn yóo máa gbé ibẹ̀ títí lae.
Sugbon ko ni se pelu ibo ti awon eniyan
Awọn eniyan ni iduro rẹ ko dan mọnran bakan naa ni idi nla naa ko ba ẹya ara rẹ toku mu.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Benue Fire: Ọkọ̀ akérò 18 àtàwọn tó ń gbọ́n epo ló forí ṣọta ìjàmbá iná 2 Agẹmo 2019 Oríṣun àwòrán, @crimefightersng Bi eeyan ba jẹ ori ahun, yoo bu sẹkun lọjọ Aje nigba ti tanka epo kan gbina, ti ẹmi toto ogoji si baa rin, tawọn eeyan miran ti wọn to ọgọta si farapa.
ni egberun metadinlogojo  gbo ewuro si
" Mà á ṣiṣẹ́ bí i gómìnà tó ní èrò aráàlú lọ́kàn - Seyi Makinde Ìjìyà ń bẹ fún àwọn ti adé ọ̀rọ̀ náà bá ṣí mọ́ lóri -Ọga àgbà FRSC Òyìnbó sísọ di èèwọ̀ ní ìpínlẹ̀ Ekiti EFCC ya bo ìlé Akinwumi Ambode Iru eeyan wo ni Fakorede Oluwaseun Tenidayo?
Nigba ti ariwo pọ lori ayelujara, Elliot tọrọ aforijin ni kiakia Ẹ gbọ́ Ohun tí Desmond Elliot àti Mojisola Alli-Macaulay sọ lórí ayélujára táwọn ọmọ Nàìjíríà fi ìbínú Oríṣun àwòrán, DesmondOElliot Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ìjọba Eko kọ orúkọ sí Palliatives"" tiwọn lára o, mo ní ẹrù tèmi f'ọjọ́ ìbí mi tí wọ́n jí - Họ́nọ́rébù Agunbiade Ẹ má gbìyànjú láti bo àṣírí ìpànìyàn tó wáyé ní Lekki, á ní ẹ̀rí tó dájú - Amnesty International Àkùkọ dojú ìjà kọ ọlọ́pàá, ikú ló já sí fún agbófinró Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!"
Ifẹsẹwọnsẹ akọkọ ree ni ipele ''quarter finals'', ọsẹ to n bọ ni wọn yoo gba ẹlẹẹkeji.
Ẹka Ile iṣẹ EFCC ni Ibadan lo mu awọn afurasi naa ni ile igbafẹ to gbagbajugbaja ni ilu ọhun, iyẹn Club 360 to wa ni opopona Akala ni Oluyole Extension ilu Ibadan, ipinlẹ Oyo.
O fi kun un pe waya ina naa lo ja lori ibusun kan tawọn ẹlẹwọn sun si to fi di pe awọn mẹta jalaisi bo ṣe ṣẹlẹ.
Àwọn olódodo yóo wá máa ràn bí oòrùn ninu ìjọba Baba wọn.
Ninu rẹ ni a ti rí ẹ̀jẹ̀ àwọn wolii ati ẹ̀jẹ̀ àwọn eniyan Ọlọrun, ati gbogbo àwọn ẹni tí wọ́n pa lórí ilẹ̀ ayé.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìtàn mánigbàgbé: Ajayi Crowther ní ọjọ́ ìbànújẹ́ àmọ́ tó di ọjọ́ ayọ̀ ni ọjọ́ tí wọ́n kó òun lẹ́rú 26 Ògún 2019 Oríṣun àwòrán, @ArewaHistory O ti pe irinwo ọdun bayii ti owo ẹru ti bẹrẹ jakejado agbaye, tawọn orilẹede agbaye si ti se ọpọ eto lati se ayẹyẹ naa, ninu eyi ti aarẹ orilẹede Naijiria, Muhammadu Buhari ti kopa.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Zainab Habib: Bí ẹ se gba Zainab sílẹ̀, ẹ gba Leah Sharibu lọ́wọ́ Boko Haram’ 1 Èbibi 2019 Oríṣun àwòrán, Google Àkọlé àwòrán, Aríyànjiyàn ń lọ lórí ipa tí ìjọba kó láti gba ìtúsílẹ̀ Zainab lọ́wọ́ ìjọba Saudi nígbàtí Leah Sharibu sì wà ní pańpẹ́ Boko Haram.
Ẹfunsetan Aniwura, obìnrin tó ju ọkùnrin lọ Ọ̀rọ̀ǹpọ̀tọ̀niyùn, Aláàfin obìnrin àkọ́kọ́ rèé, tó ní nǹkan ọkùnrin Ta ni Ààrẹ orílè-èdè Egypt, Morsi tó kú nílé ẹjọ́?
ipinle Ọyọ, Alhaji Olalekan Alli ni Alaga igbimo, nigba ti awon mẹ́rìnlá  miran to wa lati igun gomina Ajimobi, pelu
Ọlọ́jọ́-òní kò ni jẹ́ kí ebi ẹnu pa ọ́ o; àgbọ̀nrín mi ọ̀wọ́n pàtàkì ni ìwọ jẹ́ láàrin àwọn ẹranko, nítorí ìwọ funfun ìwọ sì pupa bẹ́ẹ̀ ni ẹsẹ̀ rẹ lágbára ìwọ si ní ìwo lórí ṣaraṣara.
Ti a o ba gbagbe pe, lojo Abameta
Man City kanra mọ́ Brighton gba Líìgì mọ́ Liverpool lọ́wọ́ Sàǹgbá fọ́!
Bi wọn ba jọ wọya ija, afi ko fẹyin wọn janlẹ ni gbogbo igba - eyi lo bi orukọ OGEDENGBE ti wọn fun un tori orukọ abisọ rẹ gan ni Saraibi.
o to di pe  egbe awon osise bẹrẹ si maa
5%: Àwọn orílẹ̀-èdè Marun un ti wọ́n ni àwọn ènìyàn tó n kó o ni a ṣe àgbéyẹ̀wò wọ́n sí ara wọn, èyí sì fi han pé o farapẹ bi ǹkan ṣe ri fún ọ̀pọ lágbáye, ni eyi ti ko ju ìdá márun un lọ.
Iwadii fihan pe ọpọlọpọ ẹgbẹrun awọn ọdọmọbinrin lo ti ṣe iṣẹ abẹ lati yọ ile ọmọ wọn kuro ni ipinlẹ Maharashtra laarin ọdun mẹta pere.
Toò, Yoòbá ní oun tó bá yá kìí tún pẹ́ mọ́n.
"Ṣùgbọ́n mo fẹ ki o lọ sọ fun aarẹ pe Naijiria n ṣ'ẹ̀jẹ̀""."
nigba ti ile eko imo sayensi ati ise owo , (Government Science and technical
Ọjọ Keje, oṣu Kinni, ọdun 1983 ni Tosin dele aye, to si ti gbe awo orin mẹrin jade, eyi ti aye tẹwọgba.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Napoli vs Arsenal: Ìdùnú subú lu ayọ̀ lórí itẹsiwaju Arsenal nínú ìdíje Europa 19 Ìgbé 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ati agbagbọọlu ẹgbẹ Arsenal ati alatilẹyin wọn ni ẹrin gba ẹnu wọn Bi eegun ni ba joo re, Yoruba ni niṣe ni ori a ma ya atọkun rẹ.
Awon akekoo FIU wa nisinmi Spring lati ojo kejila si ojo ketadinlogun osu keta odun yii.
Oluwo: Èmi l'ọba lórí òrìṣà, oṣó àti ajẹ́, Olorì tuntun tó ń bọ̀ lẹ́tikẹ
Ti o ba ti wa da a pada ti iru ẹni naa kọ lati gba tabi lati fi ẹjọ sun ajọ to n daabo bo ẹtọ onibara, FCCPC, o le pe sori nọmba 08056002020.
Nítorí pé ẹ kórìíra ìmọ̀,ẹ kò sì bẹ̀rù OLUWA.
Iduro ko si mọ fawọn to n ṣe ijọba bayii Ẹlẹẹkeji ipa to ni adinku iye owo epo yii yoo ni lara awọn eeyan Naijiria ni pe, iye owo gbogbo nkan lọja yoo gbowo lori.
''Ṣugbọn lonii, o ti yemi ni pato ohun ti ọkunrin yii ṣe fun mi ni ọdun mẹtadinlaadọrin sẹyin.
Nítorí à ń sọ ọ̀rọ̀ yìí fun yín gẹ́gẹ́ bí ọ̀rọ̀ Oluwa, pé àwa tí a bá wà láàyè, tí a bá kù lẹ́yìn nígbà tí Oluwa bá farahàn, kò ní ṣiwaju àwọn tí wọ́n ti kú.
kan ba sẹgi lati hu iru iwa buruku yii, yoo jẹya labẹ ofin .
Osun : Ilé ẹjọ́ tó ga jù lọ fi òǹtẹ̀ jan Oyetola gẹ́gẹ́ bíi Gómìnà Osun
Oríṣun àwòrán, Nigeria Army Àkọlé àwòrán, Ó ṣeéṣe kí ọ̀rọ̀ yìí níí ṣe pẹ̀lú ìpè tí àwọn aṣòfin pè fún ìyọkúrònípò àwọn aṣíwájú ẹ̀ka iléeṣẹ́ ológun Mẹ́tàdínláàdọ́ta nínú wọn ló jẹ́ afunrasí darandaran Fúlàní, mẹ́fà jẹ́ ẹlẹ́gbẹ́ òkûnkùn, máàrún jẹ́ ajẹ́rangbé tí mẹ́fà míràn sì jẹ́ agbébọn.
Ibojì àwọn tí wọ́n ti kú yí i ká.
Oríṣun àwòrán, Instagram/toyin abraham Toyin yi orukọ pada Ni igba to wọ agbo ere sinima, Toyin Aimakhu ni gbogbo eeyan mọ ọmọge Alakada si.
OLUWA ń bínú sí wa gidigidi nítorí pé àwọn baba ńlá wa kò ṣe ohun tí ìwé yìí pa láṣẹ fún wa.
Ohun tí ó bá nǹkan mu ni a fi ń ṣe nǹkan, àdá ṣòro láti fi fá ’rùngbọ̀n, ọ̀bẹ ni ó bá ’rùngbọ̀n mu.
Pupọ awọn poll to waye lọdun 2016 lo ni Hilary Clinton lo ṣeeṣe ki o jawe olubori ṣugbọn eyi ko tunmọ si pe wọn gbe gbagi patapata.
Ti eyi ba si n ri bẹ, o le sọ awọn sẹẹli naa di nkan to le fa jẹjẹrẹ.
Pẹlẹ ṣ'okunfa pipada Ayew si Swansea Kò lè ṣééṣe kí Ruga wà lápá gúúsù Nàìjíríà fáwọn Fulani- Ganduje Wo ohun tó yẹ kí o mọ̀ nípa àwọn obìnrin méje ti Buhari forúkọ wọn ránṣẹ Inu awọn agbabọọlu Leicester City dun pupọ ni eyi ti o n fi ọkan wọn balẹ de idije Premier league to maa bẹrẹ lọjọ kẹsan an, oṣu kẹjọ, ọdun yii.
Asoju ajo WHO lorile-ede Naijiria, Dokita Wondimagegnehu Alemu, salaye pe, idanilekoo ohun ni lati gba awon akoroyin eka eto-ilera niyanju lori bi won yoo se maa gbe iroyin ojuse ajo WHO jade, nipa akitiyan ati atileyin won lorile-ede Naijiria.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Fasiti Ọbafẹmi Awolowo University, Ọọni ile ifẹ takorawọn lórí ẹ̀sùn májèlé táwọn kan dà sómi iléèwé náà 11 Ìgbé 2019 Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Kò tíì dájú bóyá ọwọ́ àwọn agbófinró tíì tẹ ẹnikẹ́ni lórí ìṣẹ̀lẹ̀ náà Ile ẹkọ to gbajumọ lagbaye ni ileewe Ọbafẹmi Awolọwọ University, OAU to fi ikalẹ si ilu ile ifẹ ni ipinlẹ Ọṣun ṣugbọn ni aipẹ yii ni okiki kan pe awọn eeyan kan ti lọ da majele si odo omi ti ileewe naa n lo fun mimu ati ọpọlọpọ iṣẹ iwadi imọ ijinlẹ gbogbo.
Bi iwadii naa se lọ ree: Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí 3 sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 2:23 Fídíò, Water Generator: Ó leè ṣiṣẹ fún wákàtí mẹfà, kó tó sinmi, Duration 2,2310 Òkùdu 2020 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
HIV Patients: N kò ní ìbálòpọ̀ rí kí ń tó ní HIV
Ó ranṣẹ sí Jehoṣafati ọba Juda pé, “Ọba Moabu ti ṣọ̀tẹ̀ sí mi, ṣé o óo bá mi lọ láti bá a jagun?
Nitori naa a gbọdọ ko awọn ọdọ wa lati ko ara wọn ni ijanu ati bi o ṣe yẹ ki wọn huwa lawujọ.
Jehoiada bá fún àwọn olórí ogun náà ní àwọn ọ̀kọ̀ ati apata Dafidi, tí wọ́n kó pamọ́ sinu ilé OLUWA.
Àjọ NCDC kéde ènìyàn 195 míràn tó ní ààrùn Covid-19 l'órílẹ̀-èdè Nàìjíríà Ẹ̀dínwó epo bẹntíró tí NNPC kéde kò kan ará ìlú Wo ohun tí òfin àgbáyé sọ nípa ọmọ tí a bí sí inú bàlúù Nígbà tó ń ṣàlàyé nípa ohun tó fi ń pa ọwọ dà lẹ́yìn ere tíátà, Gọlugọ ní òun sì ibùdó kan tí wọn ti ń ta bàbá Ìjẹ̀bú taa mọ si Lotto, àmọ́ ajakalẹ-arun Coronavirus tí mú kí òun gbé ilẹkun ibùdó náà tí pá.
Alaga gbogbo fun ẹgbẹ oṣelu naa Adam Oshiomole lo fi ọrọ lede lọjọ Abamẹta.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ondo Kidnap: Ìyá ọmọ tí wọn jí gbé wà nílé iwòsàn tí wọn ń fa omi sí lára 13 Bélú 2019 Oríṣun àwòrán, Eniola Gold Ninu ẹkun asundakẹ ni ikọ iroyin BBC Yoruba ba Iya Eniola Gold, ọmọ to di awati lojiji ninu ile ijọsin kan ni ilu Akure, ti i se olu Olu Ipinle Ondo lọjọ isinmi.
ohun ọ̀gbìn tí o fi ọwọ́ ọ̀tún rẹ gbìn,àní, ọ̀dọ́ igi tí o fi ọwọ́ ara rẹ tọ́jú.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Tóò bá fún ọkùnrinn lóúnjẹ́ tóo tẹ́ kiní yẹn sílẹ̀ fún un dáadáa.
Ọjọ Aiku to kọja ni awọn ọlọpaa mu awọn ọdọmọkunrin mẹtadinlọgọta nilu Eko, ti wọn si fi ẹsun kan wọn pe wọn n ni ibalopọ ọkunrin s'ọkunrin.
 orile-ede tseki olominira ti je omo egbe nato lati 1999 ati isokan europe lati 2004 .
Eyi ti sọ awọn ọdọ to wa nile ẹjọ fun idajọ naa sinu ayọ ohun idunu pe nigbẹyin gbẹyin Eromosele yoo le lọ ile.
Ati owo, ọrọ ati agbara ni Iyalode ilẹ Ibadan fi ṣ'ọla.
Nítorí náà, nǹkan bí ẹgbẹẹdogun (3,000) ninu àwọn ọmọ Israẹli lọ gbógun tì wọ́n.
 Fatou Sylaani bakanna ni ki Weah o ni arojinlẹ lori ọrọ awọn ara orilẹede Lebanon ti yoo wa gẹgẹ bi ẹni to fẹ kọ orilẹede Liberia, sugbọn wọn fẹ paarun ni.
Eyi gẹlẹ ni ọrọ ti akọwe ẹgbẹ oṣelu PDP, Kola Ologbondiyan fi sita ni kete ti igbimọ alaṣẹ APC pari ipade ti wọn ti tu awọn adari ẹgbẹ ni gbogbo ipele ka lọjọ Iṣẹgun ọsẹ.
Amnoni nìkan ni Absalomu pàṣẹ pé kí wọ́n pa.
Irọ́ ni, abẹ́rẹ́ àjẹsára Covid-19 kò lè ṣàyípadà DNA rẹ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Coronavirus: Báwo ní gbogbo àgbáyé ṣe lè gba abẹ́rẹ́ ajẹ́sara àrún Coronavirus?
Àmọ́, nkan ti yoo sẹlẹ si ìdíyelé Bitcoin to ba ti pé ko ti i di mimọ dáadáa.
iyaafin Abike Dabiri ErewaA  bi  iyaafin Abike Dabiri-Erewa ni Ikorodu to wa niluu
Eyi to mu ki iya rẹ ni ki wọn ti i mọ ile ẹ̀kọ́ṣe kan nitori iwa ipanle rẹ.
Minisita tun tesiwaju pe o le
“OLUWA yóo fi ibukun rẹ̀ sí orí ọkà rẹ, ati oúnjẹ rẹ.
Lori papa ere bọọlu papa julọ, wọn kii fi oju ọrẹ wo ara wọn tabi ọmọ ilẹ adulawọ kanna.
Ṣugbọn bí ẹ kò bá ṣe bẹ́ẹ̀, ẹ dẹ́ṣẹ̀ sí OLUWA.
se ojo towo sinkun awon agbofinro te, Gege bi adajo, Quadri yoo tun
to nii ṣe pẹlu ọrọ Islam ni Ile-iṣẹ ologun ofurufu ti ilu Ikẹja ni
Ṣugbọn bí ẹ bá rò bẹ́ẹ̀, ẹ sá gbà mí bí aṣiwèrè, kí n lè fọ́nnu díẹ̀.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Unai Emery akọnimọọgba Arsenal pẹlu Lucas Moura nigba ti o wa ni PSG Oun tawọn kan sọ nipa iṣẹlẹ yii ni pe wọn ta Moura ki wọn ba le faye silẹ fun Neymar ti wọn n gbe bọwa lati Barcelona.
Orileede naa ti bẹrẹ si ni ṣe ọfọ iku awọn to lọ ti ọpọ eeyan jakejado agbaye naa si ti n bawọn ṣe idaro iṣẹlẹ laabi yi.
" Adelé, ẹni to ṣẹṣẹ jade nile ẹkọ fasiti, to si n sinru ilu lọwọ, wa mọ riri atilẹyin iya rẹ ati awọn ijoye rẹ, o ni itọni wọn lo mu ko rọrun fun oun lati dari ilu.
Láti orí 'Our Mumu don do' sí 'Revolution Now' Bí ọdún Ọ̀ṣun Oṣogbo ṣe bẹ̀rẹ̀ rèé àti pàtàkì rẹ̀ fún Nàíjíríà Saudi ṣàtúnṣe lílẹ òkò mọ́ Asitani láti dẹ́kun títẹra-ẹni-pa Sowore takú, kò jẹun ní àgọ́ ọlọ́pàá torí májèlé - Deji Adeyanju Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí kan sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
baa won akoroyin soro leyi ti o dido rẹ ni deede aago Mewaa owuro yii.
Wọ́n ka ìwé tí ẹ kọ sí wa, wọ́n sì túmọ̀ rẹ̀ níwájú mi.
Àbí àwọn aláṣẹ ti mọ̀ dájú pé òun ni Mesaya ni?
Àwọn èrò nígboro Eko fẹ́ lu obìnrin kan pa, pé ó mú nǹkan ọmọkùnrin pòórá Ẹṣẹ wo ni Ambode ṣẹ̀ tí ilé aṣòfin Eko fẹ́ fí ọlọ́pàá mú u?
Arulogun ni igbimọ alaṣẹ gbe igbesẹ ipinu yii ni ipade ti wọn ṣe lọjọ iṣẹgun ọjọ kẹrinla oṣu karun ọdun 2019.
Wọn óo dàbí ìgbọ̀nsẹ̀ lórí ilẹ̀.
O dupẹ lọwọ ileeṣẹ ologun ati awọn agbofinro to ku, fun bi wọn ṣe ji giri si ojuṣe wọn lasiko ti ipenija eto bẹrẹ ni ẹkun iwọ oorun Naijiria.
Awọn olori ẹka ile aṣofin apapọ mejeeji, ile aoṣofin agba ati ile aṣoju-ṣofin, Sẹnetọ Bukọla Saraki pẹlu aṣofin Yakubu Dogara ti bu ẹnu ẹ̀tẹ́ lu igbesẹ naa.
Ṣugbọn sùúrù tán àwọn eniyan náà lójú ọ̀nà, 
Coronavirus: Ìjọ kò ní tilẹ̀kùn ilé ìjọsìn nítorí Coronavirus
Iranṣẹ Ọlọrun naa ti gbe agbada adura gba orioke lọ.
Ni aafin olubadan ti ilẹ Ibadan lawọn oniṣẹṣe ni ipinlẹ Ọyọ korajọpọ si lati ṣe ayajọ ọdun iṣẹṣe ti ọdun yii ni ipinlẹ Ọyọ.
O ni ahesọ tawọn eeyan n gbe ka paapa lori isẹlẹ to n waye ni Ibarapa jẹ ọna ati da omi tutu sookan aya Gomina Seyi Makinde.
Igbese yii yoo ran awon omo ogun orile ede yii lowo ninu ojuse won  lati le koju ipenija lori eto aabo.
Báyìí ni kí o máa wí fún wọn, kí o máa fi gbà wọ́n níyànjú kí o sì máa bá wọn wí nígbà gbogbo pẹlu àṣẹ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Fire Eater: Azonto ní àfojúṣùn òun ni láti lọ fi idán iná yìí pa owó lókè òkun Iwe naa wa n salaye pe awọn isẹlẹ yii lee sokunfa ede aiyede ti yoo sediwọ fun ifọwọsowọpọ laarin Naijiria ati Amẹrika lati gba owo ti Abacha ko wa soke okun, eyi ti ajọ Transpartency International ni o to biliọnu marun dọla.
Àwọn orílẹ̀-èdè ti jìn sinu kòtò tí wọ́n gbẹ́,wọ́n sì ti kó sinu àwọ̀n tí wọ́n dẹ sílẹ̀.
 Àwọn ará Ọ ̀ y ; ọ ló fi Àjàká jẹ ọba sí Òkò .
 ‘‘Erongba mi ni lati je awako ti yoo gbe aare ati oludari
”O ni iko omo ogun oju omi naa ti ko ipa pataki lati fowosowopo pelu aare lati mu idagbasoke ba eto oro aje lorile ede Naijiria.
Nítorí náà mo fi wọ́n sílẹ̀ sinu agídí ọkàn wọn,kí wọn máa ṣe ohun tó wù wọ́n.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ondo state money: Ìjọba Ondo ṣàwárí N4.
Kí ọ̀tá mi má baà wí pé, “Mo ti rẹ́yìn rẹ̀.
Ninu awọn ijamba ti wọn sọ ni yii: Lilo nylon n ba ayika jẹ nitori ọpọlọpọ eniyan to ba lo o, ni wọn ma n ju u si ilẹ tabi inu omi eleyii ti o ma n di oju ọna ti omi n gba kọja.
O sọrọ yii fún BBC lasiko to n fesi si ibeere wi pe ki lo de ti Aarẹ Muhammadu Buhari ko i tii yan awọn minisita miran lati rọpo awọn minisita to kowe fipo silẹ lasiko isejọba rẹ.
Ohun marun niyi ti ẹ le nifẹ lati mọ nipa rẹ.
A wà níbẹ̀ fún ọjọ́ pupọ.
Osinbajo ati Gowon soro yii ni ile –ijosin to wa nile aare niluu Abuja lasiko idupe ajodun.
Lara awọn eroja ti wọn ma n fi se abari ni agbado, tataṣe, ede, igba, ata gigun, epo pupa, ati bẹẹ bẹẹ lọ.
Ni wọ́n bá mú un jáde kúrò ninu ọgbà náà, wọ́n bá pa á.
O salaye pe, “a dupe pupo lori awon akekoo Dapchi  wa, ti won jaja bo lowo awon ajinigbe leyin ogbonjo ti won ti wa ninu igbekun.
Banaba fẹ́ mú Johanu tí à ń pè ní Maku lọ.
Lára rẹ̀ ni wọ́n ti ṣe ìtẹ́lẹ̀ àwọn òpó àgọ́ náà yípo ati àwọn èèkàn àgọ́ ati àwọn èèkàn àgbàlá inú rẹ̀.
O ni lootọ ni wọn ni bi aye ba n yi , ki a maa ba aye yii, ṣugbọn ayipada to de ba sinima ti mu ki awọn oṣere o mu owo lọkunkundun ju ṣiṣe iṣẹ naa gẹgẹ bii akọṣẹmọṣẹ.
Awọn ẹri kan wà pe awọn to ni aarun coronavirus wọpọ julọ ni awọn agbegbe to ni ọgbẹlẹ tabi ti ko gbona ju.
Ninu gbogbo ìrìn àjò wọn, nígbà tí ìkùukùu yìí bá gbéra kúrò lórí àgọ́ náà, àwọn ọmọ Israẹli á gbéra, wọ́n á sì tẹ̀síwájú.
Jesu wí fún wọn pé, “Mo fẹ́ kí ẹ mọ̀ dájúdájú pé, kí wọ́n tó bí Abrahamu ni èmi ti wà.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Oladapo Adu: Nàíjíríà já mi kulẹ̀ torí wọn kò wá gbé mi Ohun ti mo sọ ni pe ẹgbẹ APC to jawe olubori ninu ibo taa di lọdun 2016 nipinlẹ Ondo pegede, debi pe awọn ọmọ ẹgbẹ PDP to jẹ alatako gan ko lee lọ sile ẹjọ.
Afegbua yọju sileesẹ ọlọpaa Ninu iroyin miran ẹwẹ, Ọgbẹni Kassim Afegbua, to jẹ agbẹnusọ fun aarẹ ologun tẹlẹ ni Naijiria, Ibrahim Babangida ati awon agbejoro rẹ ti yoju sileesẹ ọlọpa nilu Abuja.
4 Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold 5 Ẹ wo ọba kan nílẹ̀ Yorùbá, tí kò ṣe ètùtù tàbí náwó ànájù, kó tó jọba 6 Covid-19 pa Ọlọ́lá Akin Olugbade, ẹ wo dúkìá jaburata tó fisílẹ̀ 7 Ǹjẹ́ ó ṣeéṣe kí ìyáwò rẹ gbé ọmọ àlè wá sílé láì mọ̀?
Ojú yóo ti àwọn ọlọ́gbọ́n:ìdààmú yóo bá wọn,ọwọ́ yóo sì tẹ̀ wọ́n.
Awọn ọrọ ti obinrin yi sọ, tawọn ọjọgbọn ba gbe yẹwo, ejo lọwọ ninu, to si foju han pe ọmọbinrin yẹ sa pamọ sawọn abẹ ika kan, a si ti fala sawọn ọrọ kan ti ọmọbinrin naa sọ, eyi to fihan pe ọrọ rẹ ko rinlẹ to."
bí wọ́n bá ronupiwada ní ilẹ̀ tí wọ́n kó wọn lẹ́rú lọ, tí wọ́n sì rawọ́ ẹ̀bẹ̀ sí ọ, tí wọ́n bá jẹ́wọ́ ẹ̀ṣẹ̀ tí wọ́n dá, ati ìwà burúkú tí wọ́n hù, 
Awọn iwa ẹlẹyamẹya ti Sara foju wina rẹ lati kekere lo jẹ ko gba pe nkan kan wa ti ko dara nipa awọn alawọ dudu.
O ni awọn alaṣẹ Air Canada ti bẹ oun lori ọrọ naa.
Ẹwà yín kò gbọdọ̀ jẹ́ ti òde ara nìkan bíi ti irun-dídì, ati nǹkan ọ̀ṣọ́ wúrà tí ẹ kó sára ati aṣọ-ìgbà.
Bí ó bá dáwọ́ òjò dúró, ọ̀gbẹlẹ̀ a dé,bí ó bá sí rọ òjò, omi a bo ilẹ̀.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, BBC Africa Eye: Akọroyin fẹ ìdí àwọn oníṣẹ́ ibi ọmọ ogun síta Koko pataki to wa nibẹ ni pe ọpọ ninu wọn gba pe oorun to ran loke ṣi to aṣọ lati gbẹ lori ọrọ Brexit ko to di oṣu kẹwaa ọdun yii.
Àwọn ọmọ aráyé wò wọ́n, wọ́n bú sí ẹ̀rín, wọ́n sì kọ́ ọgbọ́n pàtàkì nì láti ara wọn wí pé, ko sí nínú ìwà Olódùmarè pé kí o kọ ìlérí fún àwọn ọmọ ènìyàn àfi bí ohun tí àwọn ọmọ èn[piyàn bá fẹ́ ṣe bá máa jẹ́ fún ìpalára.
Naijiria kọ lati ṣe bi awọn orilẹede Afirika to ku ṣe ṣe nipa pe awọn kọkọ tọwọ bọwe adehun ki wọn to lọ sile lọ ro o.
Hubert Ogunde rèé, baba àwọn òsèré tíátà Samuel Ladoke Akintọla jẹ́ Agbẹjọ́rò àti Akọ̀ròyìn tí ọ̀rọ̀ dá lẹ́nu rẹ̀ Àràbarà pósí rèé, ibùgbé ìkẹyìn tó jẹ ojú ní gbèsè D.
Orin rẹ̀ ni a fi ń mọ ibi tí ó wà, àárín oṣù Ọ̀wẹwẹ̀ àti Ọ̀wàrà.
Nnkan ko ṣ'ẹnu 're fun Iheanacho ni ikọ agbabọọlu rẹ naa nilẹ Geẹṣi, Leicester City ni saa ere bọọlu to kọja, nitori ọpọ igba lo maa n joko wo'ran ti awọn akẹgbẹ rẹ ba n gba bọọlu.
Obinrin náà jẹ́ ọlọ́gbọ́n ati arẹwà, ṣugbọn ọkọ rẹ̀ jẹ́ òǹrorò ati eniyan burúkú.
Kò dára kí o gbà wọ́n láàyè ninu ìjọba rẹ.
Igba ti wọn dele iwosan l'awọn dokita ri i pe oyun ibeji ṣi wa ninu ile ọmọ rẹ keji, eyi si mu ki wọn o ṣiṣẹ abẹ fun.
Lẹ́yìn tí ó bí Seti, ó tún gbé ẹgbẹrin (800) ọdún láyé, ó sì bí àwọn ọmọ mìíràn lọkunrin ati lobinrin.
Kọmiṣọna ọlọpaa nipinlẹ Ọyọ, Shina Olukolu ni marundinlogun ninu awọn afurasi naa ni ọwọ ba lasiko ti wọn fẹ da omi alaafia ilu ru lagbegbe Idi Arẹrẹ, Bẹẹrẹ, Orita Aperin, Iwo road ati ibudokọ ni Eruwa, Ilu Ibadan.
" Gomina Amosun ati awọn adari ẹgbẹ oṣelu APC n forigbari bayii lori tani yoo dije fun ipo gomina ni ipinlẹ Ogun.
24 Òkùdu 2020 Ọpọ eniyan lo n gbe igbe aye wahala nitori aimọkan wọn lori jinitaipu wọn.
Oríṣun àwòrán, @raufaregbesola Lara awọn oju ọna to jẹ manigbagbe ti Arẹgbẹsọla pese ni ti awọn oṣiṣẹ, oju ọna Gbongan ati bẹbẹ lọ.
Mooketsi Kgotlele: Ọjọ kejilelogun, oṣu keje ni ajọ FIFA fofin de ọmọ orilẹ-ede Botswana yii.
(Jesu kò tíì wọ ìlú, ó wà ní ibi tí Mata ti pàdé rẹ̀.
Corporal Punishment: Olùkọ́ fẹgba lu akẹ́kọ́ọ̀bìnrin ọmọ ọdún mẹ́rìnlá pa ní yàrá ìkàwé
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Aloe Vera dara fun itọju ara Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Aloe Vera dara fun itọju ara 7 Ẹrẹ̀nà 2018 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 8 Ẹrẹ̀nà 2018 Ewe Aloe Vera ni iwulo pupọ.
Bakan naa ni aarẹ Trump tun ṣekupa ọgagun to lagbara julọ lorilẹede Iran, Qasem Suleimani to n saaju awọn ogun to n ṣẹlẹ ni orilẹede gbungun lagbaye.
“ohun kan pataki ti  o je orile ede yii logun julo ni bi isoro ina mona-mona yoo se di afiseyin ti eegun n fi aso, se  a mo ipa pataki ti ina mona-mona n ko lawujo, ati ipa ti yoo ko nigbesi aye awon omo orile ede Naijiria.
Ikú sí Ẹ̀ṣẹ̀, Ìyè ninu Kristi.
Kí OLUWA Ọlọrun rẹ bá wa lọ́wọ́ sí i.
Àwọn tí wọ́n kọ́kọ́ pada dé sórí ilẹ̀ wọn, ní ìlú wọn, ni àwọn ọmọ Israẹli, àwọn alufaa, àwọn ọmọ Lefi, ati àwọn òṣìṣẹ́ inú tẹmpili.
Amọ o ni eeyan kan ṣẹṣẹ pe oun ni to sọ fun oun pe iru nkan bẹẹ ṣẹlẹ.
Ki ni Adajọ agba Walter Onnoghen funra rẹ n sọ?
Awọn tọkọtaya yii jọ ṣe ọpọlọpọ iṣẹ papọ ki ipinya to de si wọn gẹgẹ bii lókọ laya.
Oríṣun àwòrán, others Agbẹjọro fun Fani-Kayode kesi ileeṣẹ iroyin naa lati gbẹsẹle iroyin naa laarin ọjọ mẹ̀rinla,, ki wọn si san owo gba ma binu biliọnu mẹfa naira.
Ṣugbọn Atlanta 1996 ni o ti ṣoju Naijiria ninu idije ''Olympics'' fun igba akọkọ- nigba naa gan ni ọkunrin yii bẹrẹ si ni huwa ipa si i.
N óo sọ ọmọ ẹrubinrin náà di orílẹ̀ èdè ńlá pẹlu, nítorí ọmọ rẹ ni òun náà.
Tọpẹ salaye pe ko si ọ̀rọ̀ ifẹ ikọkọ laarin oun ati ojisẹ Oluwa naa, gẹgẹ bi awọn eeyan kan ti n sọ kiri, pẹlu afikun pe ti iru eyi ba wa, Ọlọrun ni yoo se idajọ laarin awọn.
Catholic Church: A kò ní bó àṣírí àlùfáà tó bá bá ọmọdé lòpọ̀ mọ́
 Ó wà ní àríwá àárín gbùngbùn ti a mò sí ìgbánú àárín ìlú .
Itse Sagay wọ gàu lórí ọ̀rọ̀ Adeosun Bi o ṣe kọwe fipo silẹ ni ọpọ gboriyin fun un pe o ṣe ohun to yẹ lori ayelujara nigba ti awọn miran tabuku ijọba Buhari ti wọn ni wọn n gbogun tiwa ibajẹ jẹgudu jẹra ni Naijiria.
61 Onírúurú àwọn alàgbà tí wọ́n jẹ́ ti ìjọ Krístì yìí yíò máa ní ìpádé nínú àpéjọpọ̀ ní ẹ̀ẹ̀kan láàrin oṣù mẹ́ta, tàbí láti àkókò dé àkókò bí àpéjọpọ̀ náà bá ṣe darí tàbí fi ọwọ́ sí;
Ẹ wo fidio yii lati mọ bi orin naa se dun to.
lorile ede Naijiria lati tun tepele mo igbese won lati fi oruko awon oludije
Àwọn eniyan ń retí pé ọwọ́ rẹ̀ yóo wú, tabi pé lójijì yóo ṣubú lulẹ̀, yóo sì kú.
Ileeṣẹ ọlọpaa ni eyi lo jẹ ki ohun lẹ fọto rẹ pọ mọ ti awọn ẹlẹwọn yoku ki iroyin naa le ye awọn ọmọ Naijiria ti wọn ba n ka a.
Kí ẹ fi ọ̀dọ́ akọ mààlúù meji, ati àgbò kan, ati ọ̀dọ́ àgbò meje ọlọ́dún kọ̀ọ̀kan rú ẹbọ sísun olóòórùn dídùn sí OLUWA.
Kò sì jọ mi lójú pé ó rí bẹ́ẹ̀, nítorí bẹ́ẹ̀ ni àwọn ẹlìmíràn wà ní òde ayé tí wọn ń jẹ́ orúikọ mìíràn ṣùgbọ́n tí ìwà wọn bá tí Òmùgọ́dimẹ́ta mu.
Kùkùté kìí ṣe ẹni gíga, kúkúrú báyìí ni, o sì ki, bẹ́ẹ̀ ni igbá àyà rẹ̀ tó fẹ̀rẹ̀gẹ̀dẹ̀ fẹrẹgẹdẹ.
Bo tilẹ jẹ pe wọn ti fi ọrọ naa to ileeṣẹ ọlọpaa leti, ohun kan naa ti wọn n sọ fun gbogbo wọn ni pe, wọn ṣi maa ri awọn ọmọ wọn pada, ṣugbọn ọmọ ẹni ku san ju ọmọ ẹni nu lọ.
15) Ma sọrọ pẹ ju lasiko kan nigba ti o ba n gba ipe lori ẹrọ ibanisọrọ rẹ.
Àwọn tí Lea bí ni: Reubẹni, àkọ́bí Jakọbu.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Èmi sì ní Oluwo tilẹ̀ Iwo, kò sí ìgbìmọ̀ ọba kankan tó lè ní kí ń rọ́ọ́kún nílé - Oluwo Toyin Abraham ọkọ rẹ̀ àti Ire ní London, Odunlade 'kòlábò' pẹ̀lú Mercy Aigbe Èlé owó iná ọba kọ́ ló kàn, ẹ kọ́ ṣàtúnṣe sí ìlànà àdánú tẹ́ ń ṣe fún wa - Iléeṣẹ́ apínná sọ fún ìjọba Àdínkù bá owó ojúmọ́ ọlọ́kadà l‘Ọyọ láti ₦200 si ₦100, owó gbígbà bẹ̀rẹ̀ lónìí A fẹ́ ìtọ́jú fún Boko Haram tó bá ronúpìwàdà, ẹ dá iléeṣẹ́ sílẹ̀ fún ìtọ́jú wọn - Ilé aṣòfin Olùkọ́ tó fi tipá gba ìbálé akẹ́kọ̀ọ́ tó fẹ́ wọ fásitì rí ẹ̀wọ̀n ọdún 21 he Fayose, o kò ní àmúyẹ gidi láti di ọmọ ẹgbẹ́ wa, àyè kò sí fún ọ - APC Ekiti Azonto ni lasiko ti oun n sere itage ni oun kọ isẹ naa nipinlẹ Ogun, ti gbogbo eeyan si maa n pe oun ni Sango lai wa lati idile onisango tabi jẹ ọmọ ilẹ Yoruba.
Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Teni entertainer: Idi ti mi ò kì ń ṣí ìhòhò mi bi àwọn olórin obìnrin míran23 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Fídíò, Ondo election 2020: Àwọn ara ìpínlẹ̀ Ondo ránṣẹ́ sí Akeredolu ohun ti wọ́n ń retí ní báyìí12 Ọ̀wàrà 2020 EndSARS Protest Update: Aisha Yesufu ní Buhari jẹ́wọ́ pé òun kò láànú aráàlú nínú ọ̀rọ̀ rẹ̀23 Ọ̀wàrà 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Gbogbo àwọn ọmọ ogun Kalidea tí wọ́n wà pẹlu olórí àwọn tí ń ṣọ́ Nebukadinesari ọba wó gbogbo odi Jerusalẹmu lulẹ̀ patapata.
Ọdun 1995 lo ti bẹrẹ isẹ osere nigba to kopa ninu ere ''Owo Blow''.
Nibayii, Abdullahi Bashir, ẹni ọdun mejilelogun to tun ti yọju sita lori itakun agbaye, to si ni aise alabapade ọmọ aarẹ nilu Abuja lati fẹ, da irẹwẹsi si oun lara.
Hamori ati Ṣekemu, ọmọ rẹ̀ bá lọ sí ẹnubodè ìlú, wọ́n sọ fún àwọn ọkunrin ìlú náà pé, 
Ilẹ Amẹrika ko gbe orukọ awọn ti ọrọ naa kan sita tabi ki wọn sọ igba ti wọn yoo fi orukọ naa sita.
 nítorí náà , ìyàtọ ̀ tí ó wà láàrin èdè Èkìtì àti ti yorùbá káríayé náà ló wà ní tiwọn .
Nígbà tí oòrùn bá là, wọn á wọ́ lọ;wọn á lọ dùbúlẹ̀ sinu ihò wọn.
Nítorí mo láyọ̀ pupọ, mo sì ní ìwúrí lọpọlọpọ nípa ìfẹ́ rẹ.
Kò gbọdọ̀ jẹ́ ọ̀mùtí, tabi ẹni tí máa ń lu eniyan.
Kò si ọmọ Nigeria rere ti kò mọ̀ wi pé,  ‘’Ẹ̀ṣẹ̀ nlá ijiyà kékeré tàbi ki ó má si ijiyà rara fún Olówó, ṣùgbọ́n ẹ̀ṣẹ̀ kékeré ijiyà nla ni fún tálákà tàbi aláìní’’, nitori iwà burúkú àwọn Adájọ́ ti ó ti gba àbẹ̀tẹ́lẹ̀ lọ́wọ́ àwọn Agbejoro.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ìgbátí ìgbámú àná látọwọ́ sọ́jà obìnrin ti bá arákùnrin náà dé iléèwòsàn Wọn ti ko ọlọpaa ẹgbẹrun marun un sita lati mojuto aabo, ṣaaju, lasiko ati lẹyin idibo yii.
    Mo tàn mọ̀ ọ́ pé kò ni ṣàì dùn mọ́ ọ nínú láti gbọ́ pé oyún oṣù mẹ́fà ni ń bẹ ni inú mi, mo sì ní láti gbọ́ pé láti wí fún ọ pé bí mo ti ń ṣe àkíyèsí oyún mi yìí, ọkùnrin méjì gbààgì gbààgì ni mo ggbé sí ikùn mi, tó bẹ́ẹ̀ ti, bí Ọlọ́run bá sọ̀ mi lérù àǹfààní kalẹ̀ t’qan, a kò ni ṣàì wí nípa ti baálé ni tuntun náà pé: “Bàbá ìbejì ni ọkùnrin yìí ń ṣe”
Fún àpẹẹrẹ, wọ́n gbẹ́ kòtò sínú iyẹ̀pẹ̀, wọ́n sì rì wá mọ́lẹ̀ dé ibi ọrùn, orí wa ò ṣe é yí, ojú wa sì wà ní ìhà oòrùn.
Nítorí ìwọ ni o dá inú mi,ìwọ ni o sọ mí di odidi ní inú ìyá mi.
Ogbeni Raphael Igbokwe lati ipinle Imo lo so eleyinn nile igbimo asofin , lati bu ebu ate lu iwa odaran to n se le ni ipinle naa, nipa bi won se n ji eniyan gbe, ati ikolu ati idunkooko mo awon adari elesin lorile ede Naijiria.
Ẹ kò gbọdọ̀ jẹ́ kí ẹ̀rù wọn bà yín, nítorí pé Ọlọrun tí ó tóbi, tí ó sì ní ẹ̀rù ni OLUWA Ọlọrun yín tí ó wà láàrin yín.
Oríṣun àwòrán, PATRIK STOLLARZ/Getty Images Àkọlé àwòrán, Ilé ẹjọ́ Èkìtì d'ájọ́ ikú f'ọ́kùnrin tó jí ọtí méje áti páálí sìgá Amọ, idajọ iku naa ti fa ọpọlọpọ ariyanjiyan laarin awọn ọmọ orilẹede Naijiria, ti awọn miran si n pe fun idajọ iku fun awọn oselu ti wọn n lu owo ilu ni ponpo ati awọn asebajẹ lawujọ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Oshiomole: Ẹ pe aṣaájú olóṣèlú níjà láti lo ọrọ̀ ìpínlẹ̀ fún àìní òṣìṣẹ́ 2 Ògún 2019 Oríṣun àwòrán, @NLCHeadquaters Alaga apapọ fun ẹgbẹ oselu APC lorilẹede Naijiria, Adams Oshiomole, ti kesi awọn ẹlẹgbẹjẹgbẹ lorilẹede Naijiria lati maa pe awọn asaaju oloselu nija lọna ati ri daju pe wọn lo ọrọ ati ohun alumọni ipinlẹ wọn lati ba aini awọn osisẹ pade.
Ó ti rẹ ìjọba ati àwọn aláṣẹ rẹ̀ sílẹ̀,ó fi àbùkù kàn wọ́n.
O sọ pe awọn ti ajọ to n mojuto aarun ni Naijiria, NCDC n ṣiṣẹ pẹlu ti ṣe idasilẹ ibudo itọju pajawiri kan, wọn o si maa ṣiṣẹ pọ pẹlu ijọba ipinlẹ Eko lati ka a lapa ko.
Nígbà tí ó ń fi ọ̀rọ̀ náà lédè, alága ẹgbẹ́ òṣèlú náà ni ìpínlè Kogi, Sam Uhuotu, sọ wí pé, Ìpínlẹ̀ Kogi, tí di ẹru jeje fún olùgbé ìpínlè náà.
Ṣíṣípòpadà Ìjọ lọ sí ìhà ìwọ̀ oòrùn láti New York àti Pennsylvania sí Ohio, sí Missouri, sí Illinois, àti ní ìkẹ̀hìn sí Great Basin ti ìwọ̀ oòrùn Amẹ́ríkà àti àwọn ìgbìyànjú tí ó ní agbára ti àwọn Ènìyàn Mímọ́ ní gbígbìdánwò láti kọ́ Síónì sí orí ilẹ̀ ayé ní àwọn àkókò òde òní ni a fi hàn bákannáà nínú àwọn ìfihàn wọ̀nyí.
Ènìyàn 653 míràn tún kún iye àwọn tó ní COVID-19 ní Nàìjíríà Wo àwọn òṣìṣẹ́ kólẹ̀-kódọ̀tí tó ń fi ẹ̀mí wọn wéwu kí Abuja leè mọ́ tónítóní Èèyàn 562 tuntun ló tún ti lùgbàdì COVID-19 ní Nàìjíríà ní àná Mo ti bẹ̀rẹ̀ sí ń bá àwọn tí a jọ díje nínú ìdìbó abẹ́lé sọ̀rọ̀ kí àláàfíà léè jọba - Akeredolu Kanye West ti bẹ̀rẹ̀ ìpolongo àti díje dupò aàrẹ ilẹ̀ Amẹrika Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Ọmọ ọdún márùn-ún, àgbà mẹ́rin ló bá ìṣẹ̀lẹ̀ ọ̀pá bẹntiróò tó gbiná ní Abule Egba lọ - LASEMA Ẹ̀yin gómìnà Yorùbá, ẹ gbé òfin kalẹ̀ láti ti Amotekun nídìí, kí àròyé leè dópin - Falana Mọ̀ síi nípa ǹkan tí o lè ṣe láti dènà ibà Lassa Oxford English Dictionary: Ọ̀rọ̀ 28 túntun ti wọ́n fi kún-un lọ́dun 2020 Wọn fikun pe Gomina Sanwo-Olu ti buwọ lu ki wọn fun awọn eniyan to lugbadi iṣẹlẹ naa ni ipagọ to wa ni Igando Relief Camp, Igando ni ipinlẹ Eko, ki wọn maa gbe fun igba diẹ na.
Nítorí náà ohun tí Ọlọrun bá ti so pọ̀, eniyan kò gbọdọ̀ yà á.
Oba orile ede Morocco ti koko wa si orile ede Naijiria lodun 2016 , ti awon orile ede mejeeji si towobo iwe adehun to le ni ogun.
Amọ Aarẹ orilẹede Naijiria, Muhammadu Buhari ti fi lede lati ọdọ ajọ amuṣẹya lorilẹede Niajiria pe iṣede yoo tẹsiwaju fun ọsẹ meji miran lorilẹede Naijiria lati kapa arun Coronavirus.
Ajọ eto ilera ni agbaye, WHO, si sọ pe iye ṣuga ti eniyan yoo jẹ ni ojumọ ko gbọdọ ju aadọta giramu lọ.
“Wọn yóo ṣe efodu wúrà, ati aṣọ aláwọ̀ aró, ati ti aláwọ̀ elése àlùkò, aláwọ̀ pupa ati aṣọ ọ̀gbọ̀ tí ó ní ìlà tẹ́ẹ́rẹ́tẹ́ẹ́rẹ́; wọn yóo sì ṣe iṣẹ́ ọnà sí i lára.
Ọkunrin tí ó wọ aṣọ fẹ́lẹ́fẹ́lẹ́ olówó iyebíye ni bí?
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ọlọ́pàá dóòlà ọkùnrin kan tí wọn so mọ́lẹ̀ fún ọdún mẹ́ẹ̀dógún Oríṣi ẹbu ìwé ìdánwò ìṣìrò mẹ́ta ló dọ́wọ́ wa, àmọ́ wọn fi ń lu jìbìtì ni - WAEC Àwa Emèrè Onítẹ̀síwájú la ṣèpàdé nílé Elebuibon, kìí ṣe Oṣó àti Àjẹ́"" Nǹkan wọ̀lú!"
Eeyan meji wa lati ipinlẹ Ogun, nigba ti ipinlẹ Ekiti, Oyo ati Edo ni ẹyọ kọọkan.
Ó wípé ẹ̀kúnrẹ́rẹ́ ìṣẹ̀lẹ̀ náà kò tíì té òhun lọ́wọ̀.
Ẹgbẹ naa ti wa kede pe oun n ko ibujoko oun lọ si silu Ado Ekiti bayii, bẹrẹ lati oni ọjọ Aiku lọ, lati wa wadii iku to gba akẹẹgbẹ wọn mejeeji naa.
Ọlọ́gbọ́n àti òmùgọ̀ dà bí ọkan náà lákòókò igbádùn ṣùgbọ́n ọlọ́gbọ́n yọ gedegbe lákòókò ìyọnu.
Awọn to fi ero wọn han naa sọ wi pe awọn fẹ ki awọn nkan pada si bi o ti wa tẹlẹ ki arun Coronavirus to bẹ silẹ ni Niajiria.
Daura ti o lo ki aare kabo ni papako ofurufu ni Emir ilu Daura, Alhaji Umar
Asẹ yii waye nipa iwe ẹsun ti ijoba orile ede Naijiria fi kan adajọ ana
"Ohun ti awọn osisẹ n sọ ni wi pe yoo se ijamba fun a wọn ileesẹ to sẹsẹ fẹ gberu labẹle eleyi ti yoo lee mu akoba ba isẹ awọn osisẹ nibẹ"" Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!"
Mo rọ́ àwọn àlá mi fún àwọn adáhunṣe, ṣugbọn kò sí ẹnìkan tí ó lè túmọ̀ wọn fún mi.
Nítorí náà, níwọ̀n ìgbà tí a ní irú ìrètí yìí, a ń fi ìgboyà pupọ sọ̀rọ̀.
SERAP fẹ́ pe UI, AAUA lẹ́jọ́ lórí àfikún owó iléẹ̀kọ́ Ó lòdì s'òfin kí ọlọ́páà fìyà jẹ ẹnikẹ́ni tó bá wọ aṣọ ológun - Amofin Ẹ jọ̀ọ́, ẹ má jẹ́ kí ikú ọmọ mi lọ lásán - Ìyá Tiamiyu tí ọlọ́páà pa Olùkọ́ tó kù nínú ìṣẹlẹ ilé to jo nínú ọgbà UI tí kọ̀wé fipo silẹ̀ tipẹ-Alukoro fásitì Àwọn aláṣẹ kéde ìséde lọ́gbà fásitì Ibadan Olojede ni oun ati oluranlọwọ Gomina lori ọrọ ọdọ ati idaraya, to fi mọ aarẹ awọn akẹkọọ fasiti Ibadan, lawọn kọwọrin lọ ṣabẹwo si mọlẹbi Richard.
Àwọ̀ ara rẹ̀ dàbíi ti ẹja.
Wọ́n wọ́ àwọn àgbàlagbà mẹ́rin wọ̀nyí jáde síta ilée wọn, àwọn ọkùnrin tí ó bòjú sì fi igi lù wọ́n títí tí ẹ̀mí fi bọ́ lára wọn.
 Aare egbe awon osise lorile ede Naijiria,
4) Yọọ kuro ni pe ko maa gbọ̀n rìrì bíi ẹlẹgun Sango.
Lẹyin ti Ka3na ati Lilo to bẹrẹ ikopa pẹlu awọn to ku ti dero ile onikaluku ni ọkaa awọn eeyan naa ti gbe soke.
Akure Death: Ọmọ ọdún mẹ́wàá ṣàlàyé ìdí tó ṣe ti àbúrò rẹ̀ tó jẹ́ ọmọ ọdun kan àbọ̀ sínú kàǹga
Ṣugbọn bi iya nla ba gbeni sanlẹ, kekere a gori ẹni ni Brighton fi ṣe fun Tottenham lẹyin ti wọn fi ọba lee pẹlu goolu meji.
Pasito Enoch Adeboye ti ijọ Redeem lorileede Naijiria ki ṣe aimọ foloko.
Òmùgọ̀ ni gbogbo eniyan jẹ́, wọn kò sì ní ìmọ̀;gbogbo àwọn alágbẹ̀dẹ wúrà ni àwọn oriṣa wọn dójútì,nítorí pé irọ́ ló wà nídìí àwọn ère wọn;kò sí èémí ninu wọn.
Ta ni ó fún ọ ní àṣẹ tí o fi ń ṣe wọ́n?
nítorí gbogbo ibi tí àwọn ọmọ Israẹli ati àwọn ará ilẹ̀ Juda ṣe láti mú mi bínú, àtàwọn ọba wọn, àtàwọn ìjòyè wọn, àtàwọn alufaa wọn, àtàwọn wolii wọn; àtàwọn ará Juda àtàwọn tí ń gbé Jerusalẹmu.
E̩nì kò̩ò̩kan ló ní è̩tó̩ sí òmìnira láti pé jo̩ pò̩ àti láti dara pò̩ mó̩ àwo̩n mìíràn ní àlàáfíà.
Ifẹsẹwọnsẹ bọọlu afẹsẹgba lati sọri ọjọ ibi ọgọta ọdun, Ogogo Oríṣun àwòrán, ogogo/Instagram Lara awọn eekan oṣere tiata Yoruba to ti ta gbongbo kaakiri agbaye ni Alhaji Taiwo Hassan ti ọpọ eeyan mọ si Ogogo ọmọ kulodo jẹ.
Oluwo ko sọ ni pato ohun to fa ikọsilẹ naa lasiko yii ju pe ki awọn eeyan dẹkun bibu ọla fun Channel gẹgẹ bii iyawo oun mọ.
Nígbà tí wọ́n gbọ́, wọ́n gbà fún Paulu, ó sì rì wọ́n bọmi lórúkọ Oluwa Jesu.
siluu Abuja, leyin irin ajo olojo marun un re lo sorile-ede Saudi Arabia fun Umurah
bi aare orile ede yii se kọ lati towobo atunse si ofin eto ilana  idibo.
Mú inú iranṣẹ rẹ dùn,nítorí ìwọ ni mò ń gbadura sí.
Jara bí ọmọ mẹta: Alemeti, Asimafeti ati Simiri, Simiri bí Mosa, 
Nítorí kì í ṣe ẹ̀yà kan ṣoṣo ni ara ní; wọ́n pọ̀.
Wọn ti rọ baba-baba rẹ, Muhammad Sanusi Kini l'oye lasiko ti awọn alaṣẹ ijọba sọ l'ọdun 1963 pe ko bọwọ fun awọn.
Àwọn mejila yìí ni Jesu rán níṣẹ́, ó pàṣẹ fún wọn pé, “Ẹ má gba ọ̀nà ìlú àwọn tí kì í ṣe Juu lọ; bẹ́ẹ̀ ni kí ẹ má wọ ìlú àwọn ará Samaria.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìfipálówó: Bàbá ọmọ tí wọn gé lórí ní òun rán an láti gbowó lẹ́nu ATM ni Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Ìfipálówó: Bàbá ọmọ tí wọn gé lórí ní òun rán an láti gbowó lẹ́nu ATM ni 10 Ọ̀pẹ̀̀ 2018 Ọjọ buruku, esu gbomi mu ni ọjọ kẹtadinlọgbọn osu Kọkanla ọdun 2018, ladugbo Ọbakunle Drive, Sapati, Ibẹju-Lekki nilu Eko, nigba tọwọ ọlọpaa tẹ ọmọ iya meji ti wọn bẹ ori ọmọ aladugbo wọn.
Ènìyàn méjìlélẹ́gbẹ̀rún ni ọwajà ààrùn náà ti le lọ sí ọ̀rún alákeji.
Buhari ní ìdìbò 2019 kìí ṣe tikú-tìyè Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ikorodu Bois: Ko si ẹni ti a kò lè sín jẹ!
Ìgbẹ̀dẹ̀gẹ́dẹ̀ inú ayé ni àwọn wọn-ọnnì jẹ́, kí Olódùmarè gba ọmọ aráyé lọ́wọ́ ọ̀rẹ́ mi, bí ẹnikẹ́ni bá ń yẹ́ ọ sí ìwọ náà máa yẹ́ olúwaarẹ̀ sí, bí ó bá ń gbé ọ ga ìwọ náà túbọ̀ máa gbé e ga, bí ènìyàn ńlá bá ń lò ọ́ bí ẹnìkejì ara rẹ̀ túbọ̀ gbé e ga, tó bẹ́ẹ̀ tí yòó fi mọ̀ pé ìwọ kò rí òun fín.
Mo fi Oluwa bẹ̀ yín, ẹ ka ìwé yìí fún gbogbo ìjọ.
Tí ó bá wá rí bẹ́ẹ̀, a jẹ́ pé àwọn onigbagbọ tí wọ́n ti kú ti ṣègbé!
Wọ́n bẹ̀rẹ̀ sí dá gbogbo àwọn tí wọn ń kọjá lọ́nà; ni ìròyìn bá kan Abimeleki.
O salaye pe wọn mu oun ati ẹgbọn oun obinrin to ni ọmọ meji, amọ se ni Boko Haram fi ọbẹ la ọfun rẹ, nigba to taku lati di ẹlẹsin Islam, ti wn si fi awọn ọmọ rẹ si ahamọ.
Òhun ni alásẹ àti olùdarí ilé isẹ́ fíìmù Odunlade Adekola.
Sowore: olùdíje Ààrẹ tó fẹ gbà Nàìjíríà padà fún àwọn ọdọ Day 13: Àwọn ńkan méje tí ẹ lè má mọ̀ nípa Igbákejì Ààrẹ Osinbajo #BBCNigeria2019 Àgbálùmọ̀, ohun mẹ́fà tó ń ṣe lára tí o kò mọ̀ Gbọ̀ngàn Mapo, ọ̀kan lára ibi àmúyangàn n'Ibadan rèé Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ademọla Ogunbanjo: A nílò bàbá ìsàlẹ̀ nínú òsèlú Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Falana: Awọn to n dije dupo ìdìbò 2019 fẹ́ fa ogun si Naijiria Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Laipe yii ni, orile ede Amerika ti fun orile ede Naijiria ni oko –oju –ogun- ofurufu  ti iye re je merindinlẹ̀ẹ́dẹ́gbẹ̀ta dola, owo ile okeere lati fi koju ogun pelu iko olote Boko haram.
Oun lo mu ki Fayose gbe ọrọ naa lọ ori Twitter nibi to ti fi ẹsun kan ajọ naa pe awọn ile-onile ni EFCC n ti pa.
Nibayii gbogbo eto lo ti wa ni ṣẹpẹ bayi ṣaaju ipade itagbangba BBC Yoruba lọjọ Ẹti, ẹ jẹki a jọ pade nibẹ lọla.
 Godpower Tamunoala Jumbo ni ki aarẹ tuntun o gbe orilẹede Liberia lọ si ipele to kan nipa fifi awọn to ni oye nipa imọ ẹrọ ibalode ati idagbasoke yi ara rẹ ka.
Oniruuru ajafẹtọ ọmọniyan, awọn onimọ nipa oju opo ayelujara ati ọpọ eeyan lo peju pesẹ sile aṣofin lọjọ Aje nibi ijiroro itagbangba naa niluu Abuja.
Awọn ọmọ Naijiria kaakiri agbaye ṣalaye ohun ti oju wọn ri ati boya inu wọn dun pe wọn ko si ni orilẹede Naijiria ni iru asiko yii.
Àsẹ̀hìnwá-àsẹ̀hìnbọ̀ gbogbo ẹgbẹ́ gbọ́, ojú sì ti alábòsí gidigidi, nígbà tí a béèrè ọ̀rọ̀ yìí, alábòsí dáhùn bí akólòló ó dàbí ẹni pé kí gbogbo wa bẹ́ ẹ lórí.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fọ́nrán ohùn, Ilé ẹjọ́ kòmítẹlọ́rùn yá lórí ìbò gómìnà Oṣun- PDP O fikun ọrọ rẹ pe iwe ẹri ti oludije sipo gomina fẹgbẹ PDP nipinlẹ Oṣun lo lati dije fun ipo sẹnẹtọ naa lo lo fun ipo gomina, o ni ofin Naijiria ṣi faye gba eleyi.
Victor Agunbiade tun mẹnuba bo ṣe ṣiṣẹ agbalẹ, ẹni to n fọ abọ ati ni 'factory' ki oun le tọju iya agba ati ẹbi to fi silẹ ni Naijiria ki o to lọ kawe sii to si di ọga agba yii Ìbejì wù mí láti kékeré ṣùgbọ́n mí ò mọ̀ pé ìbẹfà lorí kọ mọ́ mi- Ifeoma Ìyá Ìbẹfà Ẹ̀gbọ́n àti àbúrò wà ní ilé ẹ̀jọ́ lórí ikú Tolulope Arotile Ṣé ìrànwọ̀ ni Kamala, ìgbákejì tí Biden yàn yóò jẹ́ fún un tàbí ìpalára?
"Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Àwọn ọ̀dọ́ fi ọ̀nà àrífín pe Tinubu lórí aago àmọ́ ó ní òun kò mọwọ́-mẹsẹ̀ nípa ìpànìyàn Lekki Wo díẹ̀ lára dúkìá tí jàǹdùkú sun níná l‘Eko torí ìwọ́de EndSARS Á ràgà bo CCTV Lekki bí i ẹ̀rí tó dájú fún ìwádìí ìpànìyàn - Sanwo-Olu SERAP gbé ìjọba àpapọ̀ lọ ilé ẹjọ́ àgbáyé ICC lọrí ẹ̀sùn ìpànìyàn ""Jàǹdùkú gún ẹ̀gbọ́n mi lọ́rùn, jó ilé àti mọ́tò wa méjì, kòròfò la wà"" Olùwọ́de 12 kú ni Lekki, 38 lapapọ kú lọ́jọ́ Isẹ́gun, 56 ni àròpọ̀ àwọn tó bá ìwọ́de lọ - Amnesty International Osinbajo gbarata lórí ìṣẹ̀lẹ̀ Lekki, ó ní ìdájọ́ òdodo yóò wà Ojisẹ Ọlọrun naa ni kii ẹbi Buhari ni awọn isẹlẹ to n waye yii, nitori ko to de ipo ni atako sawọn ọlọpaa SARS ti n waye, paapaa lati aye awọn ijọba to ti kogba wọle."
Igbakeji gomina ipinle Kwara, Alagba Peter Kisira lo soro yii lasiko to n gbalejo Oludari ajo NOA, Omowe Garba Abari n’Ilorin.
Isẹlẹ naa si lo mu ki ile ẹjọ so ijoko rẹ rọ fun igba diẹ, ki wọn le fun awọn osisẹ ọgba ẹwọn laaye lati setọju rẹ.
Ìgbẹ́jọ́ Naira Marley sún síwájú bí àwọn agbẹjọ́rò ṣe ń jà sí àga ìjókòó Ó rẹ ẹni ọdún 49 tó ri ẹ̀wọ̀n ọgọ́ta ọdún he lẹ̀yìn tó bá ọmọ ọdún méjì lòpọ̀ Mo pàṣẹ pé kí ọ̀gá owó ìfẹ̀yìntì tẹ́lẹ̀, Maina sì wà látìmọ́lé- Adájọ́ Bi o tilẹ jẹ pe lara awọn to wa ninu igbekun ti ọlọpaa ti gba silẹ ni lootọ ni awọn ya ọmọ buruku to si jẹ pe latari eyi lawọn obi wọn fi mu wọn lọ si ilbudo atunwaṣe yii, wọn ni Ọlọrun ti jẹ ki aye awọn yi pada ṣugbọn bi ẹni to la ina kọja ni.
Ijipti yóo máa rán wọn létí ẹ̀ṣẹ̀ wọn, pé wọ́n ti wá bèèrè ìrànlọ́wọ́ lọ́dọ̀ àwọn ará Ijipti tẹ́lẹ̀ rí.
Ireti si wa pe gomina Seyi Makinde ni yoo jẹ olugbalejo nibi ayẹyẹ naa.
O ni eyi ṣafihan pe ojulowo osere tiata ni Mide n ṣe ti o si ni ki eledua tete mu lara da.
Mú ojú ìbáwí kúrò lára mi,kí inú mi lè dùn kí n tó kọjá lọ;àní, kí n tó ṣe aláìsí.
7 Àti pé èmi yíò jẹ́ kí ìwọ ó ṣe iṣẹ́ ìránṣẹ fún òun àti fún arákùnrin rẹ Jákọ́bù; àti ẹ̀yin mẹ́tẹ̀ta ni èmi yíò fi agbára yìí àti àwọn kọ́kọ́rọ́ iṣẹ́ ìránṣẹ́ fún títí èmi yíò fi dé.
Agbowu fi ẹsun kan Oluwo ninu iwe ipẹjọ naa pe, o kọlu oun ni ọfiisi Igbakeji Ọga ọlọpaa, niwaju awọn ọba miran, ati awọn aṣoju ijọba ipinlẹ Osun, to si fi egbo si oun lara.
Amọ 'sa, gomina paapa ti kọkọ sọ pe oun ko fun wọn ni aṣẹ nitori pe oun ko ni agbara lati paṣẹ fun ileeṣẹ ologun.
Ó gbé ojú sí òkè ọ̀run, ó kẹ́dùn, ó bá ní, “Efata,” ìtumọ̀ èyí tí i ṣe, “Ìwọ, ṣí.
Nítorí bí mo tí ń sọ̀rọ̀ ibinu sí i tó, sibẹ mò ń ranti rẹ̀,nítorí náà ọkàn rẹ̀ ń fà mí;dájúdájú n óo ṣàánú rẹ̀.
 Òjó àti àwọn ọmọ ẹgbẹ ́ rẹ ̀ bẹ ̀ rẹ ̀ sí ní ṣe àwọn àwo orin ọlọ ́ kan- ò- jọ ̀ kan jáde tí wọ ́ n sì ń pèé ní elére káà kiri ìlú àti ìpínlẹ ̀ orílẹ ̀ èdè nàìjíríà bí : Ìpínlẹ ̀ Èkìtì , Ìpínlẹ ̀ Èkó àti Ìpínlẹ ̀ Òṣun .
"Ilé ẹjọ́ pàṣẹ kí EFCC gbẹ̀sẹ̀ lé àpò àsùwọ̀n kan tó ní nkan ṣe pẹ̀lú Akinwumi Ambode Fowler kò sí lábẹ́ ìwádìí kankan-Garba Sheu Wo àwọn eléré ìdárayá mẹ́ta tí àjọ FIFA ti fòfin dè títí ayé Jesu orí ayélujára kan rèé tó ń ṣèlérí iṣẹ́ ìyanu l‘Afirika Ohun mẹ́fà tí kò yẹ́ kí o gbàgbé nípa Gómìnà Ambode Ìwádìí lásàn ní à ṣe lọ sí ilé Ambode-EFCC Nígbà ti akọròyìn BBC Yoruba bèèrè ìdí tí wọ́n fi wà ní ilé Ambode, Tony Orilade ní ""báwọ ni à ó ṣe ya bo ilé Ambode, ǹjẹ́ ẹ mọ ǹkan ti yabo túmọ̀ sí?"
Olumilua, lasiko to n dahun ibeere BBC Yoruba ni lootọ ni inu ijọba ipinlẹ naa dun lakọkọ pe awọn ni asoju ni BB naija, to si jẹ oriire fun awọn, sugbọn eto ori itakun agbaye naa ko fi bẹẹ kan ijọba ipinlẹ Ekiti gbọngbọn.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Olakunrin murder: Ọlọ́pàá ní OPC kò láṣẹ láti fipa lé ẹ̀yà kan nílẹ̀ Yorùbá 19 Agẹmo 2019 Oríṣun àwòrán, Funke Olakunrin Ile iṣẹ ọlọpaa ti sọ pe, ẹgbẹ apapọ ọmọbibi Oodua, Oodua Peoples Congress (OPC), igun ti New Era, ko laṣẹ labẹ ofin lati fipa le eya kan kuro nilẹ Yoruba.
Bakan naa lo sọ pe ọwọ pada tẹ diẹ lara wọn to sa pamọ sinu ile naa nigba ti awọn ọlọpaa de si ibẹ.
Àwọn ìròyìn tí ẹ lè nífẹ̀ẹ́ sí: Obí ta ọmọ tuntun tí kò ju wákàtí mẹ́fà lọ ní ₦850,000 Àkójọpọ̀ àwòrán ọdún ọdún Àjínde l'Afrika Ọbìnrin Gẹ̀ẹ́sì tó wá fún ìsinmi ní Nàíjíríà ṣàgbákò ikú Orilẹede awọn ajoji to ku ti wọn ti ri rèé: Ilẹ Gẹẹsi - 5 Denmark - 3 Portugal - 1 India - 6 Turkey - 2 China - 2 Netherlands - 1 Japan - 1 Oríṣun àwòrán, Reuters Àkọlé àwòrán, Àwọn alufaa ni ile ijọsin St Anthony to wa ni Kochchikade Ọpọlọpọ oku awọn ajoji to fara kaaṣa iṣẹlẹ naa ni wọn ko ti i ri.
Igbakeji Aarẹ ni ''ọgọọrọ ọmọ Naijiria ni awọn ọlọpaa ti fi iya jẹ lọna aitọ, eyi ko si bofin mu.
Kí ọ̀run kọrin ayọ̀, kí ayé kún fún ayọ̀,ẹ̀yin òkè, ẹ máa kọrin,nítorí, OLUWA ti tu àwọn eniyan rẹ̀ ninu,yóo ṣàánú àwọn eniyan rẹ̀ tí ìyà ń jẹ.
Ẹ wò mí, kí ẹnu yà yín,kí ẹ sì fọwọ́ bo ẹnu.
ninu eto idibo ti yoo waye lọjọ Abameta ọsẹ yii, ti won si ti darapọ mọ ẹgbẹ, All Progressive Congress, APC ni ipinle Gombe  lati satileyin fun Alhaji
Oríṣun àwòrán, @NewsOfNigeria Ondo INEC: Iná ṣọ lọ́fíìsì àjọ INEC, ohun èlò fún ìdìbò Ondo jóná mọ́lé Ọkẹ aimọye awọn ohun elo fun ayẹwo kaadi awon oludibo lo ti jona mọle lolu ileeṣẹ ajọ eleto idibo orilẹede Naijiria, INEC ni ipinlẹ Ondo to wa niluu Akurẹ.
Ninu ọrọ to ba BBC Yoruba sọ, agbẹnusọ fun Ayọ Fayose, Lere layinka, ni idunu nla lo jẹ fun wọn pe ile ẹjọ fi aye silẹ fun gbigba oniduro gomina ana naa.
Ọba Adesoji Aderemi, Ọọ̀ni Ifẹ̀ tó gba ipò ọba mọ́ tòṣèlú Iṣẹ́ Kudirat Abiọla ṣì ń fọhùn síbẹ̀, lẹ́yìn ọdún 23 tó papòdà Oshisko twins, àwọn 'ìbejì' tó ń dẹ́rìn ín p'òṣónú Wọ́n ta ère Ọ̀ṣun Osogbo sí Togo - Bàbá Ọṣun figbe ta Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Badagry: Ojú ọ̀nà àrèmabọ̀ fáwọn ẹrú tó ń lọ sókè òkun Lọdun 2019, ile iṣẹ iroyin NAN fabọ jẹni pe ipinlẹ Edo lo ni iye awọn ti wọn fi n ṣ'owo ẹru ju ati irinajo lọna aitọ.
O fi ibú omi bò ó bí aṣọ,omi sì borí àwọn òkè ńlá.
Ikilọ yii lo waye nibi ipade to waye nile ijọba ipinlẹ naa ni Marina, leyi ti Gomina Babajide Sanwo-Olu sẹ alaga rẹ.
lati fi Mogaji tabi Baale jẹ ni ibamu pelu iwe ofin awon lọba-lọba ti ipinle
Awọn alasẹ ọgba ẹwọn lorilẹede Kenya fi ẹsun kan gomina ti wọn yọ nipo naa pe o sa kuro lọgba ẹwọn logun ọdun sẹyin.
Ẹlẹkẹẹta ti iku Baba Yeye mẹnuba ni fun awọn ọmọ Naijiria lati maṣe gbagbe pe ajakalẹ aarun COVID-19 ṣi wa ni sakani wa.
O ni ileeṣẹ ọlọpaa si n wa awakọ to sa lọ lẹyin ti iṣẹlẹ ọhun ṣẹlẹ tan 'Ní ìjọ wa, ọtí mímú la fi ń pe ẹ̀mí Ọlọ́run sọ̀kalẹ̀' Oyenusi ló mú mi wọ ẹgbẹ́ adigunjalè kó tó di pé mo b'Ólúwa pàdé - Kayode Williams Oral Sex: Bóo bá ń gba ẹnu ní ìbálòpọ̀, wo àìsàn tóo lè kó lójú ara rẹ Tunde Idiagbon, ọ̀gágun kògbagbẹ̀rẹ́ tó ní ẹ̀ẹ̀kan lóṣù ló yẹ kí ológun máa rẹ́rìín Ìdí tí mo fi gbàdúrà ìyàwó bíi Chanel Chin fáwọn tó d'ẹ̀bi ìkọ̀sílẹ̀ rẹ̀ rù mí rèé - Oluwo Adura nla ni Yoruba maa n gba pe Eleduwa ko ni jẹ ka rin arin fẹsẹ ṣi.
EFCC ni lootọ loun tẹwọ gba iwe ifisun kan lori ileeṣẹ Alpha Beta Consulting Limited, 'sugbọn ẹni to kọwe ifisun naa ko fi idi ẹsun rẹ mulẹ to bi o ti yẹ pẹlu awọn ẹri to duro digbi.
Agboke lo sọ ọrọ yii lasiko to n gba ami ẹyẹ ‘Akinkanju ninu eto iselu tiwantiwa ti ile isẹ iroyin kan ni ilu Ibadan fun un.
America: Ẹ má dúró ju ìṣẹ́jú mẹ́wàá lọ níta ìlú yóò tutù kọjá àlà
julọ, nipa isẹlẹ ikọlu to waye ni ipinle Zamfara, ni eyi ti awon eniyan mẹ́rìnlélọ́gbọ̀n padanu emi won ni Tungar Kafau ati Gidan Wawa,to wa ni
Dalung so pe,, “Sise ayeye odun ere-idaraya nipinle se pataki lati mu igberu ba sise deede ninu olokan-o-jokan eto idaraya.
South Korea: Èèwọ̀, ẹ kò gbọdọ̀ jẹ ajá mọ́
Lẹ́yìn náà, òun ati àwọn eniyan rẹ̀ pada sí Jerusalẹmu.
 Sugbon, O so pe, Olorun ko oun yo ninu ilakaka omo bibi it o oun la koja.
Lasiko ọdun Ọsun naa, Ọọni tilu Ile Ife, Ọba Enitan Adeyeye Ogunwusi, Ọjaja Keji gbalejo awọn olorisa Ọsun ni aafin rẹ.
Àwọn ọmọ Israẹli ṣọ̀fọ̀ Mose fún ọgbọ̀n ọjọ́ ní pẹ̀tẹ́lẹ̀ Moabu, wọ́n sì parí ṣíṣe òkú rẹ̀.
Yóo kó gbogbo eniyan Gogu ati Magogu jọ láti jagun, wọn óo pọ̀ bí iyanrìn etí òkun.
Àkọlé àwòrán, Abiọla jẹ́ bàbá fún ọmọ tó tó ogójì, tó sì ní ìyàwó mẹrin.
ni, bo tile je pe oun ati Obasanjo ko si nibi egbe oselu kan naa, sibe oun bu ọla
Seyi Makinde: Akọ̀wé ìjba tuntun ni Olubamiwo Adeọsun.
 ‘‘Lataari imo ati oye iko omo-ogun ile Pakistan, a gboriyin fun atileyin ati ironwo yin lati mu igberu ba iko omo ogun orile-ede Naijiria,’’ Tobi Sangotola.
Rakẹli ń sọkún àwọn ọmọ rẹ̀,wọ́n ṣìpẹ̀ fún un títí, kò gbà,nítorí àwọn ọmọ rẹ̀ tí kò sí mọ́.
Bí èsì ìdìbò gómìnà ìpínlẹ̀ Ondo se ń jáde rèé.
Balogun yanyan fun iko omo ogun orile-ede Naijiria, Tukur Buratai ti fi da awon omo orile-ede yii loju pe, eto aabo to mehe lorile-ede Naijiria wa labe akoso.
Àwọn ọmọ Isaaki meji ni Esau ati Jakọbu.
Èdè Akurẹ àti Ibadan ni wọ́n fi fà mí léti pé ẹni re kìí 'se òṣèlú - Seyi Makinde Ìkúnlẹ̀ àbiyamọ o!
ipejọ naa fẹnuko pe omo Yoruba ko ni faaye gba ile fun awon odaran ati apaniyan
Ẹja  Korí sílé, kò rí gbèsè náà gbà, ó relé pẹ̀lú ọ̀fọ̀; Ọjọ́ kejì ọjà.
"Oríṣun àwòrán, @GovKaduna ""A sakiyesi pe ejo lọwọ ninu iwọde janduku, ẹlẹyamẹya ati ẹlẹsinjẹsin pẹlu ti oselu to gbode, tawọn alainikanse naa si setan lati wo orilẹede yii palẹ, ti wọn si n fẹ ki ayipada isejọba waye."
OLUWA ni àpáta mi, ibi ààbò mi, ati olùgbàlà mi;Ọlọrun mi, àpáta mi, ninu ẹni tí ààbò mi wà.
To ba ṣe ẹni to ti dan ile ọkọ pupọ wo, ipinlẹ ti ọkọ to fẹ gbẹyin ni yoo lo tabi ti baba rẹ.
Ìmọ̀ràn Cardee Aláboyún ni mí, báwo ni n o ṣe dáàbò bo ara mi ni àsìkò Covid-19 yìí.
"Igbimọ oluwadii ti joko sẹ ipade, a si ti ko gbogbo awọn oṣiṣẹ ati akẹkọọ ti wọn darukọ wọn ninu iṣẹlẹ naa lọ siwaju wọn ni gbogbo asiko ti iwadii fi n lọ.
Níbikíbi tí ó bá ti dé sí i, ẹ̀mí èṣù yìí á gbé e ṣánlẹ̀, ọmọ náà yóo máa yọ ìfòòfó lẹ́nu, yóo wa eyín pọ̀, ara rẹ̀ yóo wá le gbandi.
inawo ati ipo adari ile-ise ijoba nitori iwa otito won.
Ṣugbọn wọn ń dágunlá, wọ́n ń ṣe orí kunkun, wọn kò sì gbọ́ràn.
- Ọọ̀ni Ife Ìgbẹ́jọ́ aṣaájú ìjọ Sotitobire kúrò nílé ẹjọ́ Mágísíréètì lọ sílé ẹjọ́ gíga l‘Akure Ilé ẹjọ́ ti sún ìgbẹ́jọ́ pásítọ̀ ìjọ Sotitobire si Ọjọ́bo̩ Ọwọ́ ọlọ́pàá tẹ afurasí tó ní òun ló jí ọmọ gbé láti parọ́ mọ́ pásítọ̀ ìjọ Sotitobire Bayìí ni àwọn ọlọpàá Akure ṣe ko àwọn ará ìlú ti o ji ẹrù ni sọọsi Sotitobirẹ Olawoye ni ijọba Ondo ti setan lati ri idi okodoro ọrọ to wa nidi ẹjọ yii, ti igun olupẹjọ ko si ni gba ki wọn fi akoko sofo lori ẹjọ naa rara.
Eso Oríṣun àwòrán, Getty Images Nọọsi Adanna sọ pe jijẹ oriṣiiriṣii eso bii mọngoro, ọsan oronbo atawọn eso mii dara fun ilera agọ ara.
Ní ọjọ́ kẹjọ, ẹ óo ní ìpéjọpọ̀ mímọ́, ẹ óo sì rú ẹbọ sísun sí OLUWA.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Omolola Arohunmolase Welder: Mo ti fí iṣẹ́ 'Welder' gbayì láwùjọ, tó mo fi tọ́ ọmọ yanjú Wayi o, ileesẹ ọlọpaa ipinlẹ Rivers ni oun ti n sanna bi alaafia yoo se jọba pada ladugbo ti isẹlẹ naa ti waye, ti iwọde to n lọ lọwọ yoo si dawọ duro.
Mo pa wọ́n run, mo bì wọ́n lulẹ̀;wọn kò sì lè dìde mọ́;wọ́n ṣubú lábẹ́ ẹsẹ̀ mi.
Oríṣun àwòrán, Tope alabi O ṣàlàyé pé ó ti pé ọdún mẹrindinlọgbọn tí òun ti ń kọ orin ẹ̀mí, tí òun sì ti gbé àwo orin bíi mẹ́rìnlá jáde.
Igba miran awọn agba ile maa n so okun mọ ika rebete yii titi a si fi re sọnu.
Iṣẹ takuntakun to ṣe ni ẹka orin kikọ ti jẹ ki Babatunde Olatunji jẹ awokọṣe fun Afrika ati awọn ọmọ ilẹ Afrika ti wọn bi tabi ti wọn n gbe ni Amerika.
iroyin tesiwaju pe , o je iyalenu fun ijoba apapo bi ikolu ado oloro se waye ni mosalasi  ati oja to wa ni Mubi, Adamawa.
” Angẹli náà bá fi í sílẹ̀ lọ.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Lọdun 2012 lawọn mejeeji jọ pade kẹyin ninu idije yii, Chelsea lo jawe olubori pẹlu ami ayo marun un si mẹrin nigba ti ere bọọlu naa di womi ki n gba siọ.
Wọ́n ṣe àwọn ọnà róbótó róbótó kan báyìí sí òkè àwọn kinniun ati akọ mààlúù náà ati sí ìsàlẹ̀ wọn.
Lẹ́yìn ìṣẹ̀lẹ̀ wọnyi, Josẹfu ará Arimatia bẹ Pilatu pé kí ó jẹ́ kí òun gbé òkú Jesu lọ.
Kọmísọ́nà ètò ìlera ìpińlẹ̀ Eko ọjọ̀gbọ́n Akin Abayomi ti lùgbàdì ààrùn Covid-19 Nigeria Police Recruitment 2020: Àwọn ohun tí ẹ nílò fún àyẹ̀wò ìgbanisíṣẹ́ ọlọ́pàá tí yóò bẹ̀rẹ̀ ní Mon, Aug 24 Ó ṣéeṣé ká fí owó kún #500,000 owó móríya ti a fi ń wá Sunday Shodipe- Ilé iṣẹ́ ọlọ́pàá Ariwo ló ń mú owó wọlé fún mi, kò wù mí láti gbé ayé tó dákẹ́ rọ́rọ́ - Lizzy Anjorin Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Bí ẹ ṣe mọ̀wé tó, ẹ wá dánrawò níbí pẹ̀lú Àpólà Ọ̀rọ̀ Orúkọ - Noun Phrase Ó ní ní kété ti ó sì tún bọ́ lọ́wọ́ ọlọ́pàá padà ni iṣẹ̀ tún bẹ̀rẹ̀ lórí bi wọ́n yóò ṣe ri mu, Ó ní àwọn bẹ̀rẹ̀ sí ni bọ ogún gbígbóna pé gbogbo ibi ti ó bá wa ki èsù tìí síta."
    Ìyá rẹ̀ wò ó tàánútàánú nínú ilé wọn, ojú obìnrin náà yí sókè sódò o ń kọ bí mọ̀nàmọ́ná ojú ọ̀run, ó dáhùn ó ní, ‘Ọmọ mi, ọmọ mi, máṣe dáwọ́lé àti kọ́ ilé Ìgbéga-ọ̀run, àwọn tí ó jù ọ́ lọ ti gbìyànjú bẹ́ẹ̀ ni wọn kò le ṣee, nítorí Ọlarun ọba níkan ló mọ̀ bí ilé Ìgbéga-ọ̀run yóò ti ṣe di kíkọ́ ṣùgbọ́n nípa ti lébìrà, àwọn wọ̀n-ọnnì kò sí ni ìhín, wọ́n wà ní ọ̀run àpáàdì.
"Wo bí ọwọ́ orílẹ̀-èdè Dubai ṣe tẹ Ramoni Igbalode tí gbogbo ayé ń pè ní Hushpuppi Kí ló mú ọlọ́pàá wú òkú géńdé nínú sàréè l'Ondo Orúkọ ìnagijẹ mẹ́jọ tí wọ́n fi ń pe Abiola Ajimọbi nígbà ayé rẹ̀ Àwọn àwòrán ìrántí tó ń sàmì ogójì ọdún tí Ọba Adesoji Aderemi jáde láyé Wo awọn Aàrẹ nílẹ̀ Áfríkà to ti gba oyè ""Field Marshal"" rí Wọn tun sọ ninu atẹjade naa pe Hushpuppi, ati awọn miran tun ja oníbàráà ileeṣẹ amofin kan nilu New York, lole $922,857 loṣu Kẹwa, ọdun 2019."
Ìyìn, ògo, ọgbọ́n, ọpẹ́, ọlá, agbára ati ipá ni fún Ọlọrun wa lae ati laelae.
Kí Ọlọ́run má kọ, àtúnrí, bí Olódùmarè kò bá kọ àtúnrí, a jẹ́ pé n ó tún ffi ojú mi rí ọ, ṣùgbọ́n ikú kìí dá ọjọ́, bẹ́ẹ̀ ni àrùn kìí dá o ṣù, Ẹlẹ́dàá ló mọ ọjọ́ àtisùn ẹni.
Kò sí ẹja kankan nínú odò yìí rárá ṣùgbọ́n oríṣìíríṣìí ẹiyẹ ojú omi bíi pẹ́pẹ́íyẹ ni wọ́n bà sí ojú omi odò náà.
Ibẹru pe ki wọn ma mu oun lẹru pada ni Eko, si lo gbee Oshodi lọ si aafin Ọba Eko, pe ọdọ ọba ni oun fẹ maa gbe.
Ki arun yii ma baa maa gba ẹbọ lọwọ koowa ni BBC Yoruba ṣe lọ ṣe iwadii ilanilọyẹ ninu fọnran yii ki onikaluku le gbogun ti iwa idọti ni agbegbe wa.
Ọmọ ọdún mẹrindinlogun ni Usaya nígbà tí ó jọba, ó sì wà lórí oyè ní Jerusalẹmu fún ọdún mejilelaadọta.
 “Ni bayii, a ni awon odo agbaboolu ti ojo ori won kere.
Senetọ Dino Melaye ni ajọ INEC kede pe o wọle idibo ti o waye lọṣu keji ọdun yii nibi to ti dije lati ṣoju ẹkun iwọ oorun ipinlẹ Kogi.
Gomina ipinlẹ Oyo, Seyi Makinde lo fi eyi hande nigba to n ba awọn lọga lọga lẹnu iṣẹ ọlọpaa sọrọ ni olu ileeṣẹ wọn to wa ni Eleyele, Ibadan lọjọ Aje.
 Ó jẹ ́ ọkàn gbọ ̀ ọ ́ n lára àwọn olórí nígbà ayé rẹ ̀ .
Ikú yá ju ìwọ̀sí ffún gbajúmọ̀; kò yẹ kí ọmọlúwàbí rin ìrìn wọ̀bìà lẹ́sẹ̀; bí a bá lọ sí ìdálẹ̀ ó yẹ kí á kó èrè oko dé ilé, ọ̀ràn dandan nì kí á lọ.
Ṣugbọn Jesu mọ àgàbàgebè wọn, ó wí fún wọn pé, “Kí ló dé tí ẹ fi ń dẹ mí?
Ṣugbọn Peteru dáhùn pé, “Oluwa, mo ṣetán láti bá ọ wẹ̀wọ̀n, ati láti bá ọ kú.
Fish skin: Kóòmù ni wọ́n fi ń họra fún Amida nítorí bí àwọ̀ rẹ̀ ṣe rí
O ni Alaafin ko le duro si Oyo, ki o maa kọ lẹta ranṣẹ si Ekiti nitori Aguda o jẹ labẹ Gẹeṣi ati wi pe kaka ki kiniun ṣe akapo ẹkun, onikaluku a maa ṣọdẹ tiẹ lọtọọtọọ.
"Bí o ṣe le so NIN rẹ̀ pọ̀ mọ nọ́mbà Glo [Globacom] Tí ó bá fẹ́ fi NIN rẹ sórí nọ́mbà Glo kọ ""Update NIN(fi ààyè sílẹ̀) orúkọ rẹ̀ àkọ́kọ́ (fi ààyè sílẹ̀) fi orúkọ kejì sí kí o sì fi ránsẹ́ sí 109 Bí o ṣe le so NIN mọ nọ́mba Airtel Ìgbẹ́sẹ̀ àkọ́kọ́ ni láti tẹ *121*1# Tẹ́ nọ́mba NIN rẹ oní nọ́mba mọ́kànlá síbẹ̀ Lẹ́yìn èyí ni èsì yóòmwọlé bi àtẹ̀jísẹ́ pé, ó ti ṣe àṣeyege Bí o ṣe le so NIN rẹ mọ́ Nọ́mbà 9mobile rẹ."
Oluwa ní, “Kí ni mo rí yìí?
Àwọn kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ Kiṣi, baba Saulu sọnù.
kí ó lọ sọ fún Ebedimeleki ará Etiopia pé, OLUWA àwọn ọmọ ogun, Ọlọrun Israẹli ní, “Wò ó, n óo mú ìpinnu ibi tí mo ṣe lórí ìlú yìí ṣẹ, lójú rẹ ni yóo sì ṣẹ.
Ẹni tí ó bá ń kó oúnjẹ pamọ́, yóo gba ègún sórí,ṣugbọn ẹni tí ó bá ń ta oúnjẹ, yóo rí ibukun gbà.
Nígbà tí mo gbọ́ bẹ́ẹ̀, mo fi òrùka sí imú rẹ̀, mo sì fi ẹ̀gbà ọwọ́ bọ̀ ọ́ lọ́wọ́.
Oò nílò ìwé ẹ̀rí WAEC láti dí ààrẹ tàbí gómìnà - Keyamo Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Segalink:ìkùnsínú pọ̀ láàrin àwọn agbófinró bẹ́ẹ̀ wọn kò ni agbẹnusọ Ẹwẹ, ọga agba ọlapaa fa gbogbo ọlọpaa leti o si sọ awọn koko ọ̀rọ̀ pataki kan ati awọn ikilọ pataki to fi mọ ijiya fun ẹnikẹni ninu awọn ọlọpaa to ba pa eniyan lai ba ofin mu.
Ẹka ẹkunrẹrẹ rẹ nibi Ti tẹlẹ Eyi to tẹlẹ Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Èyí ẹ̀kẹrin je arẹwà obìnrin nínú ayé ṣùgbọ́n àggàbàgebè ènìyàn ni, nígbà tí ó wà ní wúndíá, ó ń ṣe ìlara àwọn ẹgbẹ́ rẹ̀, ó ń dá ìjà sílẹ̀ láàrin àwọn ọ̀rẹ́ méjì, àwọn ọkùnrin méje ni wọ́n wí pé kí ó fẹ́ àwọn ó sì gbà láti fẹ́ àwọn méjèèje, bẹ́ẹ̀ àsẹ̀hìnwá-àsẹ̀hìnbọ̀ kò fẹ́ enì kan ṣoṣo nínú wọn mọ́.
"Èmi gẹ́gẹ́ bíi gómìnà mo gba gbogbo ọ̀rọ̀ náà gẹ́gẹ́ bi ẹ̀bi mi, pàápàá jùlọ àwọn ǹkan alò ti kò tó, láti ọjọ́bọ, ọjọ́ kọkàndílọ́gbọ̀n, oṣù kẹwàá, gbogbo àwọn ǹkan ti ó wà nínú ìwé ẹbẹ̀ yìí ni àó máa gbé ìgbésẹ̀ lórí ẹ"" "" Pàtàkì jùlọ nínú àwọn ìwé ẹ̀bẹ̀ ọlọ́pàá ní fífún àwọn ọmọ ọlọ́pàá tó d'olóògbé ni ẹ̀kọ́-ọ̀fẹ́, mo si ti dári àjọ tó n mójú tó ètò ẹ̀kọ́-ọ̀fẹ́ nípìnlẹ̀ Eko láti fún gbogbo àwọn ọmọ wọ́n ni ẹ̀kọ́-ọ̀fẹ́."
Ara san p'eeyan mẹrindinlogun ninu ṣọọṣi kan ni Rwanda
Madam Sajẹ: Mò ń rọ àwọn akẹẹgbẹ́ mi nínú tíátà láti máṣe kánjú
 alágbọ ̀ ọ ́ -wá yìí ni ó sì di alágbàá ( baba maríwo ) títí di òní olónìí .
Ninu idajọ ti Adajọ Inyang Okoro ka jade lorukọ igbimọ awọn adajọ mejeeje to ṣapero lori ipẹjọ naa, ileẹjọ fi ontẹ lu idajọ ileẹjọ kotẹmilọrun ati ti igbimọ igbẹjọ to n ri si awuyewuye ibo gomina to dajọ pe Bello lo jawe olubori ninu ibo gomina Kogi.
05 bn Ajọ eleto idibo lorilẹede Naijiria (INEC) - N40.
Iwadii fihan pe babalawo Falayi to n kọja lọ, lo ri Adediwura nibi to ti n sere ninu agbala baba rẹ.
Ó bá mú ife, ó dúpẹ́ lọ́wọ́ Ọlọrun, ó ní, “Ẹ gba èyí, kí ẹ pín in láàrin ara yín.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Fásitì ìpínlẹ̀ Ekiti dá òṣìṣẹ́ 355 padà sẹ́nu iṣẹ́ Gómìnà mẹ́ta àtí ènìyàn 1,242 ló kó sí panpẹ EFCC ni ọdún 2019 Ṣo mọ̀ pé J.
Jẹ́ kí ojú inú wọn fọ́,kí ègún rẹ sì wà lórí wọn.
Òtítọ́ ọ̀rọ̀ rè é lórí ilẹ̀ tó fa awuyewuye láàrin Ghana àti Nàìjíríà Ìpínlẹ̀ Oyo sọ àsìá Nàìjíríà kalẹ̀ láti dárò Abiola Ajimobi Kò sí àníàní, Coronavirus ló mú ẹ̀mí Ajimobi lọ - Ìjọba Eko Oríṣun àwòrán, Bashir Ahmed Awọn mejidinlogun naa, ti Hilliard Eta n dari, jẹ alatilẹyin Adams Oshiomole ti wọn yọ nipo alaga.
Ipinlẹ Eko pada sori oke tente tabili ojoojumọ awọn ipinlẹ tawọn eeyan ti ni coronavirus lorilẹede Naijiria lẹyin ti ipinlẹ Plateau ti n ṣiwaju awọn ipinlẹ tawọn eeyan ti n ko arun naa.
Isẹ́jú mẹ́wàá péré lo kọjá ti àwọn ọlọ́pàá fi dé tìbọn-tìbọn, ṣùgbọ́n eléyìí ti pẹ́ jù.
 omi tí ó ti ní àbàwọ ́ n ni a lè tọ ́ jú nípa lílo kẹ ́ míkà tí a ńpè ní temefos láti pa ọmọ kòkòrò .
“Lẹ́yìn náà ni ọkunrin kan tí ń jẹ́ Anania dé.
Awọn oluwọde naa kọri si agbegbe Jules Park ni Johannesburg nibi ti alagba Buthelezi, to jẹ ọkan lara awọn aṣiwaju ẹya Zulu lasiko ijsba alawọn funfun nibẹ ti fẹ ba awọn eeyan sọrọ.
Kayeefi ọhun ni pe ọkọ ati aya rẹ, Pa Israel Akojede ati Mama Esther jẹ Ọlọrun nipe lọjọ kan naa laarin wakati diẹ si ara wọn lẹyin ti wọn ti jọ gbe gẹgẹ bi lọkọlaya fun ọdun mejilelaadọrin.
Iru eyi ni Mary Wischuhusen gba laarin oru ni iyara idana rẹ ni Florida.
Adajọ tẹsiwaju pe awọn ọlọpaa gan ni ọwọ wọn ko mọ lori isẹlẹ yii, ti a ba wo ọwọ ti wọn fi mu isẹlẹ naa, to si bu ẹnu atẹ lu bi wọn se na iya iya ọmọ ti wọn n wa naa, ti wọn si tun ti mọle, lai jẹ pe wọn gbe wa sile ẹjọ.
 Òpin eré ìje ní láti lo sílé-ìwé gíga .
 bẹ ́ ẹ ̀ ẹ ̀ lá kátakàta ni baba ẹ ̀ là .
Josaya Ọba wó ilé oriṣa Tofeti tí ó wà ní àfonífojì Hinomu, kí ẹnikẹ́ni má baà lè fi ọmọkunrin tabi ọmọbinrin rẹ̀ rúbọ sí oriṣa Moleki mọ́.
Iye owo sẹnatọ kan losu le ra apo irẹsi toto 866, nigbati iye owo osu rẹ yoo ra apo irẹsi mẹtala.
Ti ẹni naa ba sa lọ, ori oniduro ni gbogbo atunbọtan ẹjọ yoo da le lori.
Minisita tun tesiwaju wipe,  egbe awon awakọ lorile ede Naijiria(National Union
Davido, Fani Kayode, Kemi Olunloyo, sọ̀rọ̀ lórí ẹ̀sùn jìbìtì Allen Onyeama Ohun tó yẹ kóo mọ̀ nípa Fásitì Babcock rèé Pasuma kìí ṣe ọkọ mi o!
Ileẹjọ naa tun paṣẹ fun Ọga Agba Ọlọpaa ati adari ẹsọ alaabo lati ri wi pe awọn oṣiṣẹ ni aabo to daju lasiko ti wọn ba n ṣiṣẹ wọn tako aṣẹ NLC.
Ìwà tí ó jẹ́ gbòògì àwọn ìpèníjà wọ̀nyí gẹ́gẹ́ bíi ti òfin ń sọ fún ọmọ-ìlú pé ohùn-un wọn ṣe kókó.
Gagara tẹsiwaju pe lọjọ Ẹti nikan, apo igbo marundinlaadọrin ni wsn ri gba ni agbegbe Agunla-Ogbese.
Loṣu to kója ni ile ẹjọ giga ni Kano ni Adajọ Dije Aboki dajọ pe ki wọn pa Umar Yakubu nipa okun siso lẹyin to pa ọrẹ rẹ Ibrahim Adamu nitori pe wọn n jiyan lori ogun naira (N20:00) ti Umar ya Ibrahim.
arọ yóo máa fò bí ìgalà, odi yóo sì máa kọ orin ayọ̀.
Eyi ni igba akọkọ ti eekan ninu ẹgbẹ oṣelu Republican yoo gbaruku ti ẹgbẹ alatako lati yọ aarẹ to jẹ ọmọ ẹgbẹ oṣelu rẹ nipo, lati aye Aarẹ Richard Nixon.
 Ọmọ ọdún mẹ ́ tàdínlógún ( 17 ) nì dúró .
Kò sí ohun kan ninu ilé ìṣúra rẹ̀ ati ní gbogbo ìjọba rẹ̀ tí kò fihàn wọ́n.
 o di apa apapo toseluarailu yugoslafia ni 1943 .
O fikun pe awọn iṣẹlẹ to n waye lagbegbe naa lẹ́nu lọọlọọ yii, jẹ ewu nla feto aabo ilẹ Yoruba lapapọ.
Lati igba yii wa ni Ọọni Ogunwusi ti bẹrẹ iṣẹ ti gbogbo ọmọ Yoruba ni ilẹ yii ati oke okun si ti n kan saara si.
Oríṣun àwòrán, Instagram/officialqueen_dami Àkọlé àwòrán, Ko si aworan ikini ku ayẹyẹ ọjọ ibi fun Alaafin loju opo Instagram Olori Anu, amọ o wa ni oju opo ti Dami Bakan naa ni iroyin sọ pe, lọgan ti wọn fun ni ominira, lo sa kuro ni aafin pẹlu akẹẹgbẹ rẹ, Olori anu, ti wọn si sa lọ si ipinlẹ Eko.
Ṣaaju ipade adura yii, o pọju rara aa ri iru ẹ ri, kii ju N350 lọ ti wọn maa n gbe e.
5m) ti n bọ, eyi to to biliọnu meji ati aabọ owo Naira ilẹ wa.
Ó kúrò níbẹ̀, ó sì lọ sí Naioti ti Rama, bí ó ti ń lọ, ẹ̀mí Ọlọrun bà lé e, ó sì bẹ̀rẹ̀ sí sọ àsọtẹ́lẹ̀ títí tí ó fi dé Naioti.
Lagelu ni agbegbe ti Asofin Temitope Olatoye Sugar ti padanu ẹmi rẹ.
Wí fún wọn pé èmi OLUWA Ọlọrun ní: ‘N óo mú igi Josẹfu ati àwọn ìdílé Israẹli tí wọ́n wà pẹlu rẹ̀, n óo fi ẹnu rẹ̀ ko ẹnu igi Juda; n óo sọ wọ́n di igi kan, wọn yóo sì di ọ̀kan lọ́wọ́ mi.
Bí ó bá dé lójijì, kí ó má baà ba yín lójú oorun.
Ninu atẹjade to fi si oju opo Twitter rẹ, Wike ni ko si idi ti awọn eniyan yoo fi fi ẹhọnuhan nipinlẹ naa nitori Ọga Agba Ọlọpaa, Mohammed Adamu ti tu ikọ SARS.
Sibẹ, nítorí pé aláàánú ni, ó dárí ẹ̀ṣẹ̀ wọn jì wọ́n,kò sì pa wọ́n run;ní ọ̀pọ̀ ìgbà ni ó dáwọ́ ibinu rẹ̀ dúró,tí kò sì fi gbogbo ara bínú sí wọn.
Bakan naa, a ti  n se ikilọ fun awon ti won ko ni  isẹ nibi agọ  idibo , nile ikabo ati ile iforukọsilẹ lati
Ẹ óo ké pè mí, ẹ óo gbadura sí mi, n óo sì gbọ́ adura yín.
Dandan ní kí a mú Dino sí àhámọ wa- Ọlọ́pàá 'Ọlọ́pàá Nàìjíríà ti dí agbẹnusọ ijọba Buhari' Emery: ògidi ọmọ tó mọ iṣẹ́ ẹ̀ ni Alex Iwobi Àwọn arẹwà obinrin Yollywood, tá ló mọ iṣẹ́ rẹ̀ jù?
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Risikat Azeez: Ilé wa ni mo ṣì wà, èmi kò tíì padà sọ́dọ̀ Bàbá Kaosara Bẹẹ ba gbagbe, a mu iroyin wa fun yin pe ọkọ Risikat Abdulwasiu Azeez ni oun ati aya oun ti pada sọdọ ara awọn, ti awọn si ti jọ n se mukẹẹkẹ.
O sàlàyé pé àgbègbè Kabala West, Kabala Doki, Sabo-Tasha, Narayi àti Maraban Rido tó wà ní ìgboro Kaduna kò ti fararọ nítori àwọn alákatakítí ọ̀hún sí ń gbiyanju lati kógùn já àwọn ènìyàn ní inú sọọsì lásìkò ìṣọ́-òru.
atunse lori iko SARS so ninu abajade igbimo naa pe , ki won yọ ọlọpaa mẹ́tàdínlógójì kuro
" Oríṣun àwòrán, Instagram/adedimejilateef Àkọlé àwòrán, Ìgbà akọkọ kọ niyii ti aworan igbeyawo ti jade nipa awọn mejeeji Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Ọ̀lọ́pàá shátà mi láti Mowe dé Magboro dé Shagamu, wọ́n ní ṣé mi ò mọ̀ pé ìjọ́ba ni mo ṣiṣẹ́ fún' Oṣu diẹ sẹyin ni awọn aworan kan to jọ pe oun ati Lateef ṣe igbeyawo jade sori ayelujara.
Ní ìgbà tí ó sì tó fún-un láti ní obìnrin torí owó ló ṣe fẹ́ ìyàwó-o rẹ̀.
 Èyí kò wolé mó nítorí a ti rí gbólóhùn abode tí ó ní ju òrò-ìse kan lo .
O ṣoro fun ẹnikẹni to mọ Buhari lati ma mọ pe ọmọ bibi ilu Daura ni, nitori pe ibẹ lo ti maa n ṣe ọpọ ayẹyẹ rẹ.
Àn fàní tó dó̩gba ní ilé‐è̩kó̩ gíga gbo̩dò̩ wà ní àró̩wó̩tó gbogbo e̩ni tó bá tó̩ sí.
Àwọn eniyan yóo kó ọrun ati ọfà wá sibẹ, nítorí gbogbo ilẹ̀ náà yóo di igbó ẹ̀gún ẹ̀wọ̀n agogo ati ẹ̀gún ọ̀gàn.
Ilu Abuja ni wọn ti kọkọ n tọju Kyari, ko to o di pe iroyin sọ pe wọn ti gbe e wa si ilu Eko ni ọjọ kọkandinlọgbọn, oṣu Kta, lati maa gba itọju fun aarun naa.
Lagos -Ibadan Express: Súnkẹ́rẹ fakẹrẹ ọkọ òpópónà marosẹ̀ tòní tún kọ sísọ
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Mistura Oseni Akintunde: Ara múmú kìí ṣe oríṣun ìfipábánilòpọ̀, ìran àwòjù ló ń fà á Iroyin ni Baba Legba jade laye lẹyin aisan ranpẹ ni ile rẹ to wa ni Abeokuta.
Bẹẹ ba gbagbe, ọjọ kẹtalelogun osu Keji ọdun 2019 ni wsn ti seto idibo aarẹ, ti wsn si kede Buhari lẹyin ọjọ diẹ, ti eto ibura fun saa keji rẹ si waye lọjọ Kọkandinlọgbọn osu Karun ọdun 2019.
Bákan nàá ló rọ àwọn òbí láti mú ọ̀rọ̀ ẹ̀kọ́ àwọn ọmọ wọn ní ọ̀kúnkúndùn, láà fi igbá kan bọ ọ̀kan nínú.
ọ̀gágun náà dáhùn pé, “Ǹjẹ́ èyí lè ṣẹ, bí OLUWA tilẹ̀ rọ̀jò àwọn nǹkan wọnyi sílẹ̀ láti ojú ọ̀run wá.
Golani yìí jẹ́ ìlú ààbò fún àwọn tí wọ́n bá ṣèèṣì pa eniyan, ati Beeṣitera pẹlu àwọn pápá ìdaran tí ó wà ní àyíká rẹ̀, wọ́n jẹ́ ìlú meji.
O ni, lorilẹede India, gbogbo eniyan lo wa lori itakun to lu ja ara wọn ṣugbọn idakeji rẹ lo wa lorilẹede Naijiria ti ko tilẹ tii kọja ida ọgbọn ninu itakun to lu jara.
Nígbà tí àwọn tí wọ́n rán dé ilé-ẹ̀wọ̀n, wọn kò rí wọn níbẹ̀.
Ìdí tí mo fi ṣàbẹ̀wò sí ilé ìjọ́sìn T.
Iléeṣẹ́ ọlọ́pàá dóòlà ẹ̀mí ọmọ ogun orí omi tí wọ́n jígbé ní ìpínlẹ̀ Ondo Ìjà Awolowo, Akintola àti ogun 'Wẹtiẹ', ẹ̀kọ́ wo ló kọ́ wa?
Arakunrin ọmọ orilẹede Italy naa ṣi n gba itọju ni ileewosan fun awọn awọn ajakalẹ arun to wa ni Yaba nilu Eko.
Arun coronavirus si ni ijọba sọ pe o mu ki wọn o fagile adura Eid l'ọdun yii, lati ri i pe ero ko pọju ki aarun naa ma ba a tun ran si.
Ẹ pada sí ibi ààbò yín,ẹ̀yin tí a kó lẹ́rú lọ tí ẹ sì ní ìrètí;mo ṣèlérí lónìí pé,n óo dá ibukun yín pada ní ìlọ́po meji.
ipenija ti o n waye lori kiko awọn idọti
Lazarus Chakwera: Ààrẹ orílẹ̀-èdè Malawi 'tó bá Ọlọ́run jiyàn'
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù 2019 Guber Polls: Ẹ wo àwọn baba ìsàlẹ̀ òṣèlú tí wọ́n bá ìtìjú bọ̀ nínú ìbò gómìnà 26 Èbibi 2019 Oríṣun àwòrán, Facebook/Ibikunle Amosun Àkọlé àwòrán, Idibo gomina ipinlẹ Ogun Baba isalẹ ni itumọ oriṣirisi si awọn eeyan lorilẹede Naijiria.
Lẹyin eyi ni Ile Igbimọ Aṣofin naa sun ipade si Ọjọbọ, ọjọ kẹrinlelogun oṣu yii , ti wọn yoo ti gba alejo Kabiyesi, Ọba Gabriel Adekunle Aromọlaran ti Ilẹ Ijẹṣa ni Ipinlẹ Ọṣun lapa Iwọ-oorun Gusu orilẹ-ede Naijiria.
Ooni Ile ife, Ààrẹ Gani Adams fárígá lórí ikú ọmọ Fasoranti Wole Soyinka rèé láti kékeré Ẹ̀bùn Ọlọ́run ni ọmọ bíbí ni mo ṣe bí ọmọ 17 Obasanjo ni asọyepọ laarin awọn ẹlẹyamẹya lojutuu si ọrọ eto aabo orilẹ-ede Naijiria to mẹhẹ.
Ninu àkọsílẹ̀ ìdílé, a kò kọ orúkọ rẹ̀ sí ipò àkọ́bí.
Ninu ọrọ ti Eyo Charles sọ, o ni ohun kan ṣoṣo ti oun kabamọ ni pe oun tọrọ aforiji lọwọ rẹ lori gbolohun ti oun lo.
Gbogbo wọn péjọ sọ́dọ̀ ọba ní àkókò àjọ̀dún, ní oṣù keje.
Wọn da a pada sipo, o si jẹ di ọdun 1969 to kú.
Ijọba si ti bẹrẹ iwadii iṣẹlẹ naa.
Arabinri Temidayo ni oju opo Twitter rẹ sọ wi pe ibugbamu naa nkan jẹ ninu ile wọn.
Ní òpin ọdún kẹtakẹta, ẹ níláti kó ìdámẹ́wàá ìkórè gbogbo oko yín ti ọdún náà jọ, kí ẹ kó wọn kalẹ̀ ninu gbogbo àwọn ìlú yín.
Nígbà tí Jeroboamu, ọmọ Nebati, gbọ́, ó pada wá láti Ijipti, níbi tí ó ti sá lọ fún Solomoni.
Koda, wọn yoo si sọ tẹlẹ fawọn aladugbo naa lati pese owo silẹ fun awọn, bi bẹẹ kọ, wọn yoo ge ọwọ wọn.
Ìtàkùn náà ní ẹ̀ka mẹta, bí ewé rẹ̀ ti yọ, lẹsẹkẹsẹ, ni ó tanná, ó so, èso rẹ̀ sì pọ́n.
A Ayokunle si iroyin ati fidio kan lori ayelujara pe ẹgbẹ CAN ran awọn aṣoju lọ sinu ijọ pe awọn ṣatilẹyin fun Pasitọ Agba ijọ naa, Biodun Fatoyinbo, ti wọn fi ẹsun ifipabanilopọ kan.
Ẹnikẹ́ni tí kò bá wólẹ̀, kí ó sin ère náà, lẹsẹkẹsẹ ni a óo gbé e sọ sinu adágún iná.
O tun jẹ ifẹsẹwọnsẹ to lamilaaka ti ikọ Super Eagles yoo gba lati igba ti ajakalẹ arun Coronavirus ti bẹrẹ.
Èmi kìí tètè kàwé lásìkò, màá sì kàá dáa-dáa kí ń tó buwọ́ lùú.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Kashamu àti ìjọba àpapọ̀ ń pète láti fi ọlọ́pàá mú wa - PDP Buhari fèsì sọ̀rọ̀ àwọn aṣòfin tó fi APC silẹ́ ‘Èpè ni Toyin Abraham sẹ́ fún mi nínú ìgbìyánjú mi lórí ìgbeyàwó rẹ̀ tó dàrú’ Wọ́n n gbógun tì mí kí ń leè dúró sínú APC - Saraki Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí 2 sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 2:23 Fídíò, Water Generator: Ó leè ṣiṣẹ fún wákàtí mẹfà, kó tó sinmi, Duration 2,2310 Òkùdu 2020 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
Amọ ṣa loju opo Twitter rẹ, ọrọ to nii ṣe pẹlu iwọde ti awọn obinrin Ebira kan ṣe lati fi ẹhonu han si ijọba ''ọta rẹ'' Gomina Yahaya Bello ni o fi sita.
Afárá 3rd Mainland di ṣíṣí ní ìlú Eko Ọ̀rẹ́kùnrin mi fún mi ní àárùn HIV, mo sì gbẹ̀san Ìgbésẹ̀ wo ní aláboyún lé gbé láti dẹ́kun ìjẹkújẹ nínú oyún?
Olùyẹ̀wé owó wò wa fọ́ lójú lẹnu iṣẹ́, ni a kò ṣe ní àkọsílẹ̀ báa ṣe náwó - Alákoso owó UI Èmí kò leè bá obìnrin kankan jà lórí ọkùnrin, kò leè ye yín - Iyabo Ojo Ìsọkúsọ ni Olúbàdàn ń sọ, àwa la lè yọ́ lóyè.
Ọpọ igbeyawo awọn asaaju ẹsin kan n fara da igbeyawo wọn ni, wọn ko gbadun rẹ, tori pe mo si kuna lẹẹkan ko tumọ si pe n ko ni saseyọri lasiko yii, inu mi dun lasiko yii ju ti tẹlẹ lọ.
Ajewole ni o ṣe pataki fun oun lati ṣe iran fawọn eeyan ilu oun lasiko ajakalẹ aarun coronavirus yii ti ijọba ni kawọn eeyan maa takete si ara wọn.
“Nigba ti a ọ ba wọn fun ifọwọsowọpọ fun ṣiṣe agbatẹru idije yii, lọwọ kan ni wọn fi ifẹ han, ti wọn si fi gbogbo ara kopa ninu ṣiṣe agbateru idije ere idaraya ori papa naa”.
O fi aye silẹ lẹni ọdun mẹrinlelọgọrin lọjọ kẹwa oṣu kẹta ọdun 2020 yi kan naa.
Ninu atẹjade naa, Aarẹ Buhari ni gbogbo ọmọ Naijiria lo ni anfaani ati eto lati rin kaakiri agbeegbe ti o ba wu wọn, tabi ki wọn gbe nibẹ.
Ẹ̀rù àwọn ọmọ Israẹli bẹ̀rẹ̀ sí ba àwọn ará Ijipti.
org / wiki / all _ progressives _ congress all progressives congress ] ti o koju gomina , akinwunmi ambode fun ipo gomina ni egeb progressive .
Ìjọba ń ṣe afárá Eko Bridge l'Eko, àwọn ọ̀nà àbùdá tí ẹ lèè gbà nìyí Coronavirus: Kí ni àwọn àpẹrẹ àrùn náà?
”“A pe orile-ede Iran lati mase se ikolu miiran, kii alafia le joba lorile-ede mejeeji.
Mo fẹ́ kí ẹ mọ̀ dájúdájú pé bí ẹyọ irúgbìn kan kò bá bọ́ sílẹ̀, kí ó kú, òun nìkan ni yóo dá wà.
Sikiri, akikanju jagunjagun kan, ará Efuraimu pa Maaseaya, ọmọ ọba, ati Asirikamu, olórí ogun tí ń ṣọ́ ààfin ọba, ati Elikana, igbákejì ọba.
Èyí tí ó kù lára ilẹ̀ náà tí ìbú rẹ̀ jẹ́ ẹẹdẹgbaata (5,000) igbọnwọ (kilomita 2½), tí òòró rẹ̀ sì jẹ́ ọ̀kẹ́ kan ati ẹẹdẹgbaata (25,000) igbọnwọ (kilomita 12½), yóo wà fún lílò àwọn ará ìlú, fún ibùgbé ati ilẹ̀ tí ó yí ìlú ká.
Ko si ẹmi to ba iṣẹlẹ naa lọ.
Àwọn miran tilẹ ṣalaye pe ni àdúgbò wọn làwọn agbegbe kan n'ilu Èkó, òfin isèdè yìí kò múlẹ nitori pe olokada àti awọn onimaruwa lọ ń ṣiṣẹ oojọ wọn, Ó ní n ṣe ní ìta dabi ọjọ lásán tí àwọn ènìyàn ń lọ tí wọn ń bọ̀.
Nítorí náà ẹ bẹ Oluwa ìkórè kí ó rán àwọn òṣìṣẹ́ sí ibi ìkórè rẹ̀.
Chilwell to jẹ ẹni ọdun mẹtalelogun lo gba bọọlu wọ inu awọn, nigba ti Zouma ṣe iranwọ fun goolu keji, Jorginho gba penariti wọ inu awọn ni igba kẹta ati ikẹrin.
2019 election: Bí wọ́n ṣe ń ta káádì ìdìbò ní Kano
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Man United Vs Chelsea: De Gea d'apẹ̀rẹ̀ àjàṣẹ̀, ó fún Chelsea lẹ́bùn góòlù kan 28 Ìgbé 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Man United Vs Chelsea: De Gea dapẹ̀rẹ̀ àjàṣẹ̀, ó fún Chelsea lẹ́bùn góòlù kan Òde o fi bẹ́ẹ̀ daa fún Man United lóni nínú ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ rẹ̀ pẹ̀lú Chelsea bí asọle wọn David de Gea ṣe se àṣìṣe tó jẹ ki wọn gbá ọ̀mì pẹ̀lú Chelsea ti ó si ti depo sí ààla ireti wọn la'ti kọapa nínú Champions League ni sáà tó ń bọ ni Old Traffolrd.
Wọn ṣe alaye wi pe, awọn aṣoju ijọba nilo ifọwọsowọpọ awọn obi ati awọn adari awujọ ninu igbiyanju wọn, lati wa ojutu si ipenija naa.
orile ede Libya jẹ obinrin méjídínláàdọ́jọ , ti awon odomobinrin
Oríṣun àwòrán, @zakzakysupport Kii ṣe iroyin mọ pe ede aiyede bẹ silẹ laarin ikọ aṣaaju ẹsin Shiite lorilẹede Naijiria, Ibrahim Elzakzaky ati ijọba India, eyi to n pagidina itọju rẹ lẹyin ti ileejọ fun laaye lọsẹ to kọja.
Ileeṣẹ Aarẹ, ninu ọrọ kan ti oluranlọwọ pataki fun Aarẹ Muhammadu Buhari, Garba Shehu fi sita loju opo Twitter rẹ, ni ileeṣẹ ọtẹlẹmuyẹ ti n ṣe itupalẹ oohun naa.
UN ni wọn ti fi awọn ọmọ ogun ranṣẹ si ẹkun yii ki iru ikọlu yii ma tun le waye mọ.
 wọ ́ n sì pe ato kí ó máa tọ ́ jú abàmì ọmọ náà .
O j ko di mimọ pe, oṣiṣẹ eleto ilera kan naa tun ti fara ko o ni ipinlẹ Edo eyi to sọ ọ di mtala oṣiṣẹ eleto ilera to ti fara gba a lati igba to bẹ silẹ.
    Àkọlé yìí yà wá lẹ́nu a sì yà sí ọ̀nà náà kí a ba lọ wò bí ibẹ̀ ti rí.
Akọkọ, Ẹ fi panpẹ ofin gbe Ekeji, Ẹ gba ohun rẹ silẹ."
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Belly Mujinga: Bí iléeṣẹ́ ọlọ́pàá ní UK ṣe parí ẹ̀ṣùn rẹ̀ mú kí àwọn adúláwọ̀ fa ìbínú yọ Awọn obi ọmọdebinrin kan, ọmọ ọdun mẹta, ti wọn wọn pe orukọ rẹ ni Aisha, naa tun ti fi ẹsun kan Aliyu pe o ba ọmọ naa ni ajọsepọ nigba to wa ni ọmọ osu mẹsan.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Shiite: Ẹgbẹ́ Shiite fẹ́ wọ́de ní ìrántì àwọn ọmọ ẹgbẹ́ wọn ti iléèṣẹ́ ológun Nàìjíríà pa 7 Ọ̀pẹ̀̀ 2018 Oríṣun àwòrán, @imnig_org Àkọlé àwòrán, Shiite tún fẹ́ fi ẹ̀hónú hàn lórí 'ọ̀pọ̀' ọmọ ẹgbẹ́ wọn ti iléèṣẹ́ ológun Nàìjíríà pa.
Awon ogbontarigi akorin merinla sere nibi ipari eto ayajo ose Francophone lojo Abameta pelu lilo ohun eelo orin lorisiirisii bii duru, dundun, gangan, ilu agbamole ati gita.
Nigba to n ba awọn oṣiṣẹ ile iṣẹ ọlọpaa ipinlẹ naa sọrọ ni ile iwe awọn ọlọpaa to wa ni Ikeja l'Eko, Mohammed ni bii ipari ọdun lo yẹ ki oun yọju si Eko ṣugbọn oun ni lati wa ni akoko yii nitori bi ipaniyan lai bofin mu ṣe n peleke sii.
Nítorí èmi OLUWA àwọn ọmọ ogun ń tọ́jú agbo mi, àní àwọn eniyan Juda, wọn yóo sì dàbí ẹṣin alágbára lójú ogun.
Ni bayii, igbimọ ti ijọba apapọ gbe dide ti ni ki gbogbo ọmọ igbimọ alakoso NHIS naa maa lọ ile wọn.
Ẹ ti gbọ́ tí ó sọ̀rọ̀ òdì sí Ọlọrun!
"Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Coronavirus: 'Ewu ni tí Covid-19 bá wọ àdúgbò wa bí a ṣe fún pọ̀ yìí' ""Kódà ọkàn nínú wọn ń sọkún ni nígbà tí ojú èkejì tí wú fún omijé."
rẹ ni igba mẹ́rìnlélọ́gọ́fà (124 Caps).
ti o si sọ wi pe lootọ igba naa ni wọn bi oun.
O sọ pe, Leon figbe ta nigba ti ọkan lara awọn kiniun rẹ kọlu u, ki awón eniyan ayika ibẹ to fi ibọn pa meta ninu awọn kiniun naa, sugbon, ẹpa ko gboro mọ.
#NigeriaDecides2019 Loju opo Twitter iyalẹnu ni o kọkọ bẹrẹ iriwisi awọn ọmọ Naijiria nigba ti iroyin naa wọ wọn lara tan, ṣeni ọpọ bẹnu ẹ̀tẹ́ lu INEC Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Femi Falana: kò yé kí ìdájọ́ òfin yàtó síra wọn ni Naijiria Ikanra lawọn miran fi n fẹsi si ikede yi.
Ni kete ti erin kan ti wọn gba pé o ṣẹṣi tẹ ọkunrin ọdẹ naa pa ṣe kọja siwaju ni wọn ni awọn kinihun yabo ẹran ara ọkunrin naa ti wọn dẹ fi jẹ.
Mo ti lọ ra gele igbeyawo mi, bata ati gbogbo nkan mii ti mo nilo fun iyawo.
Bẹẹ lọrọ ri fun Ọgbẹni James Daniel, ọlọkada kan ni ilu Akurẹ to jade lọ ibi iṣẹ ọkada rẹ ṣugbọn to ba ara rẹ ni ileewosan.
Oṣere Wakanda ti gbogbo aye n pe ni Black Panther le sọ ede isiXhosa to jẹ ede South Africa.
Balogun Ibrahim Yahaya so pe, “isakoso awon oro ifitonileti lakoko yii, bi ko ba le kan yoo din kan, leyi ti o si le ni ipa lori aabo ilu yala ni rere tabi ni buburu.
Àwọn olórin Nàìjíríà kẹ́dùn ikú ọmọ DBanj DBanj gbé àwo tuntun jáde lẹ́yìn ikú ọmọ rẹ̀ D'Banj fọhùn lẹ́yìn ọjọ́ mẹ́wàá tó pàdánù ọmọ Awọn ọmọ ọdọ meji ti wọn n tọju awọn ọmọ naa lawọn agbofinro ti mu lati wadi ọrọ lẹnu wọn.
O ni ninu ariwo ni ijọ Olorun ti n dagba sii nitori pe ariwo ọja ni gbogbo ohun to n sẹlẹ yii.
Agbẹnusọ fun CUPP, Imo Ugochinyere, to sọrọ lorikọ ẹgbẹ naa ni iwa ikede nita gbangba to tii buru julọ, to si jẹ ikede iwa ika ni Buhari se yii.
Wọ́n ń lù wá, bẹ́ẹ̀ sì ni àwọn ará Ijipti gan-an ni wọ́n jẹ̀bi ọ̀rọ̀ náà.
Ọpẹlọpẹ pe awọn eeyan da si ọrọ naa ni wọn fi tu wọn silẹ lahamọ.
Kwara: Agbófiró mu àwọn ajọ́mọgbé méjì
Dá ẹ̀mí mi sí gẹ́gẹ́ bí ìfẹ́ rẹ tí kì í yẹ̀,kí n lè máa mú gbogbo àṣẹ rẹ ṣẹ.
Ní tiwa, a óo ti múra sílẹ̀ láti pa á kí ó tó dé ọ̀dọ̀ yín.
Joẹli ni olórí wọn ní ilẹ̀ Baṣani, Safamu ni igbá keji rẹ̀; àwọn olórí yòókù ni Janai ati Ṣafati.
" Oríṣun àwòrán, others Agbẹnusọ ọlọpaa naa pari ọrọ rẹ pe awọn afurasi naa yoo foju ba ile ẹjọ lẹyin iwadii.
“Nígbà tí ẹ bá rú ẹbọ alaafia sí OLUWA, ẹ rú u ní ọ̀nà tí yóo fi jẹ́ ìtẹ́wọ́gbà.
0 1083023 Orilẹede Spain 47344 101.
Aarẹ Buhari sọ eyi nigba to n ṣepade kan pẹlu ẹgbẹ awọn gomina Naijiria ni ile aarẹ ni Abuja.
BBNaija 2020 Winner: Laycon ti gba sọ̀wédowó, ilé fúláàtì àti àwọn nkan míràn
Oríṣun àwòrán, @CryptographyAC_ Obinrin meji pere ni wọn tii fa kalẹ lati dije sipo igbakeji Aarẹ ninu itan ilẹ Amẹrika.
Ó sì mú kí wọ́n máa gbé orí ilẹ̀ yìí.
Ẹ dẹ̀kun lílo Sniper àti Dichlorvos fún ìtọ́jú oúnjẹ- NAFDAC kìlọ̀ Ajọ WAEC gbé èsì ìdánwò ọdun 2020 jáde EFCC bẹ̀rẹ̀ ìwádìí lórí ẹ̀sùn ìwà jẹgúdújẹrá tí wọ́n fi kan Fowler tó jẹ́ Alága iléeṣẹ́ FIRS tẹ́lẹ̀ Wo ǹkan tó yẹ kí o mọ̀ nípa Joe Biden, tó ń kojú Trump nínú ìbò America O ni oun ko ri ibi ti wọn maa n jara wọn niyan ri, ''mama mi maa sọ pe ohun ti ọkọ oun ba ti sọ ni abẹ ge.
 ní àsìkò yìí ìlú kọ ̀ ọ ̀ kan ní a ti ń rí wọn .
Eto idoola ẹmi ti n lọ lọwọ, tawọn oṣiṣẹ pajawiri si ti de ibi iṣẹlẹ naa.
Adebayo Akala ati awon eniyan Pataki  ninu egbe oselu PDP ati lawujo.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ẹ sọ́ra, ọ̀pọ̀ èèyàn ni yóò lọ sẹ́wọ̀n ní 2019 - EFCC Mi ò tan mọ́ ààrẹ Buhari rárá o!
Ṣugbọn lẹ́yìn tí wọ́n ti ní ìsinmi tán, wọ́n tún ṣe nǹkan burúkú níwájú rẹ, o sì tún fi wọ́n lé àwọn ọ̀tá wọn lọ́wọ́, àwọn ọ̀tá wọn ṣẹgun wọn.
Ìlú Ògìrììyàndá jẹ ́ ìlú kan tí a tẹ ̀ dó sí igbó ẹ ̀ lùjù ní ilẹ ̀ ọ ̀ dàn .
Bi awọn ọmọ ilẹ Argentina ti fẹran Aarẹ Peron bi oju, ni wọn ṣe fẹran akọni agbabọọlu Maradona naa.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Sasa Market: Seriki Hausa ní ogún èèyàn ló farapa nínú ìjà Ṣasa 2 Ògún 2019 Oríṣun àwòrán, @seyimakinde Seriki Sasa, tii se olori ẹya Hausa to wa lagbegbe Sasa nilu Ibadan Alhaji Haruna Mai Yasin ti salaye ohun to sokunfa ija to bẹ silẹ lsja Sasa eyi to mu ki ijọba ipinlẹ Ọyọ ti ọja naa pa.
Oore wo ni titi bọda ṣe fun Naijiria?
Bakan naa ni Minisita fun ọrọ awọn ọdọ Naijiria, Sunday Dare, to wa laafin Soun lasiko iṣẹlẹ yi fi han pe tootọ ni iṣẹlẹ yi waye.
Oríṣun àwòrán, @Reuters Abẹrẹ Pfizer ni abẹrẹ to ya julọ lati jade, oṣu mẹwàá pere ni wọn fi poo pọ.
A Abass saaju èyi ti àgbẹjọrò àgbà Akin Onigbinde ti mu iwe idaduro lori igbẹ́sẹ̀ àwọn alága ti wọ́n le kuro lori oye lati ma fi tipátipa pada si ẹnu iṣẹ́ nitori o le da omi àláafi ru ni ìpínlẹ̀ Oyo.
Tinubu sọ eyi di mímọ nínú àtẹ̀jáde kan tó fọwọ́ sí lọ́sàn òní sátide, èyí sì ni ìgbà àkọ́kọ́ tí yóò fọhùn láti ìgbà tí wọ́n ti yọ ọwọ́ Adams Oshiomhole láwọ gẹ́gẹ́ bi alága ẹgbẹ́ náà tí wan sì tú ìgbìmọ amúṣẹ́ṣe ká lọ́jọ́rú ọ̀ṣẹ̀ yìí.
Tani Akeredolu tó wọlé láti tukọ̀ ìṣàkóso ípìnlẹ̀ Ondo lẹ́ẹ̀kejì yìí?
 ayé àwọn ọ ̀ ré méjì yìí bẹ ̀ ẹ ̀ rẹ ̀ sí ní dára , tí wọ ́ n sì ń ní ìlọsíwájú àti ìgbéga nínú iṣẹ ́ àti okùn òwò wọn .
galonu epo moto otaleleedegbeta (620) ati awon nnkan miran.
Ẹwo ni ká má tíì lo nkan fún oṣù kan sí méjì, kóti tètè bàjẹ́?
Ó ya àwòrán àwọn kerubu, ati kinniun ati ti igi ọ̀pẹ sí orí àwọn ìtẹ́lẹ̀ ati ìtẹ́dìí yìí, bí ààyè ti wà fún olukuluku sí; ó sì ṣe òdòdó sí i yípo.
Oku arabinrin naa ni a gbọ pe wọn ti gbe lo si ile igbokupamọsi to wa ni ile ẹko iwosan ẹkọṣẹ Ayingba fun ayẹwo.
Oríṣun àwòrán, Algon Oyo Alaga ẹgbẹ awọn alaga kansu, ALGON naa, Ọmọọba Abass Alẹṣinlọyẹ, to ba BBC News Yoruba sọrọ ṣalaye pe, kii ṣe owo ni awọn n fẹ bikoṣe titẹle ilana ofin nipa pipari saa awọn to ku, gẹgẹ bii alaga kansu nipinlẹ Ọyọ.
Ẹnikẹ́ni kò lè wọlé láì jẹ́ pé olúwaarẹ̀ bá búra nínú ìwé mi, èmi ni Àǹjànnú-ìbbẹ̀rù tí í ṣe oníbodè Igbó Olódùmarè, èmi kì í ṣe ẹbọra ọjọ́ òní, ọjọ́ pẹ́ tí mo ti dé ìhín, ọdùn mi fi díẹ̀ dín ní ẹgbẹ̀wá ni.
'Sanwo-Olu kò ní ṣ'àyẹ̀wò covid-19 míì nítorí kọmíṣọ́nà ètò ìlera ṣẹ̀ṣẹ̀ k'árún náà' Wo àwọn ọmọ ilé ìgbìmọ̀ aṣòfin l'Abuja tó sùn fọnfọn lásìkò ìjókòó ilé 'Ó tẹ́mi lọ́rùn kí n pàdánù ẹsẹ̀ mi, ju kí ǹkan ṣe oyún inú mi' Ọkọ Funke Akindele kó eléré àti òṣìṣẹ́ jọ fi ṣe Surprise Pato"" fún un lọ́jọ́ ìbí rẹ̀ Oríṣun àwòrán, folajokun akinlami/facebook ""Iya mi sọ fun mi pe laarin oru ọjọ kan ni mo deede bẹrẹ aisan, ti oun si gbe mi lọ sileewosan."
Òun ló mọ wá kí wọn tó bí wa.
Ọgaagba kan lajọ INEC, Abubakar Nahuche ni yoo lewaju igbimọ ẹlẹni mẹjọ naa.
Ọba aláde o gbọdọ kọ iyàwó rẹ̀ sílẹ̀- Bakare, Iba àṣà Yorùbá Iná ńlá ṣẹ́yọ nílú Ibadan, ó sọ ọ̀pọ̀ dí onígbèsè Moruff Adenekan ni tirẹ sọ pe Barrister ti sọ asọtẹlẹ nipa awọn ipenija to n dojukọ eto oṣelu ati ọrọ aje Naijiria ninu awo kan to gbe jade ṣaaju idibo gbogbogbo ọdun 1983, bẹẹ lo si ṣalaye ọna abayọ.
Akọ mààlúù kékeré kan, àgbò kan, ọ̀dọ́ àgbò kan ọlọ́dún kan, fún ẹbọ sísun, 
Àkàrà tú sépo, Trump ló kọ èsì ìlera ara rẹ̀ Trump yọ Tillerson kuro nipo Ìpànìyàn gbọdọ̀ dópin ní Nàíjíríà - Trump Amẹrika àti North Korea fi ìtàn àlàáfíà lélẹ̀ Aarẹ Donald Trump to n tukọ Amerika ti sọrọ ni kikun lori ohun to ṣo lori ayelujara pe ko ri bi wọn ṣe n gba a.
"Barrister ló sọ mí di èèyàn ńlá - Ayinla Kollington Ọmọ ọdún mẹ́jọ ni mo ti ń bá Adẹ́rùpọkọ̀ ṣe eré tíátà - Tope Alabi Èmi kò gbé pọ̀ pẹ̀lú Kollington Ayinla àmọ́ ọjà t'ọ́mọ ti wọ̀ lọ̀rọ̀ àwa méjééjì - Salawa Abẹni Èkìtì ṣé àgbéga àwọn Ọba Aládé mẹ́rìndínlógún O si fi awada sọ pe: ""Ẹyin ti ẹ ba fẹ ẹ mọ, ẹ jẹ ki a lọ si ibi saare baba wọn, ta a ba kan ilẹkun, boya wọn maa da wa lohun."
 Àwọn tí ara wọn lòdì sí penicillin , lè lo erythromycin tàbí clindamycin .
Saudi Arabia Lati ọpoọlọpọ ọdun sẹyin ni obinrin Saudi ko ti lanfani lati wa ọkọ, sugbọn lati ọdun 2017 n i nnkan ti bẹrẹ si n yipada.
" Oríṣun àwòrán, others Ni tirẹ, kọmiṣọna ọlọpaa ni ipinlẹ Ọyọ, Nwachukwu Enwonwu ṣalaye pe awọn ọlọpaa kọ lo pa Ebila ati pe lati ọjọ kọkanla oṣu kẹrin ọdun yii ni wọn ti n wa Ebila lori iku Moshood Ọladokun ti ọpọ mọ si Ẹkugbemi to jẹ olori ẹgbẹ okunkun miran nilu Ibadan.
Àfojúsùn àtúntò FSARS ni láti mú àgbéga bá iṣẹ́ ọlọ́pàá- IG Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, SARS: Awọn ará ìlú fi ẹ̀rí síta nípa ìrírí wọn Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
idajọ ile- ẹjọ, ki won si tun  mu oga olopaa
15 Èbibi 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 16 Èbibi 2019 Oríṣun àwòrán, MOhammed El-Shaeed Àkọlé àwòrán, Ènìyàn tó lé ní ọgọ́rin ní ọlapàá Shaira Kano mu nítori Ounjẹ Ọlọpàá Sharia ní ìpínlẹ̀ Kano ti mú ènìyàn tó tó ọgọ́rin nítori pe wọn ń jẹun ní àsìkò ààwẹ látigba ti oṣù Ramadan ti bẹ̀rẹ̀.
Ninu iwe aṣẹ mawobẹ (Executive order) kan to fi sita ni ọjọ Ẹti, gomina Kayọde Fayẹmi ni gbogbo ipesjọpọ to ba ti n ni ọpọ ero to ju ogun eeyan lọ, yala ni ile ijọsin, ile igbafẹ, awujọ oṣelu, ile ijo ati ile ọti ko gbọdọ waye mọ titi di igba ti nnkan ba fi rọgbọ lori arun naa.
Èyí kì í ṣe wípé orin mẹ́ta péré ni ó ń du oyè.
Ọ̀gbẹ́ni Ẹ̀tàn ni ό ńdárin, Èké ló ńlu ìyá ìlú, Irọ́ sì ni ό ńlu omele.
Overweight and pot belly: Wo oríṣìí oúnjẹ márùn ún tó lè dẹ́kun ikùn yíyọ àti ara àsanjù
Nǹkan mẹ́wàá tó yẹ ní mímọ̀ nípa fásitì ẹ̀kọ́ ìrìnnà òní $50m ní Nàìjíríà Ọlọ́pàá South Africa rí ẹ̀wọ̀n ọgbọ̀n ọdún he torí ikú ọmọ Nàìjíríà Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Ernest Okonkwo Bi wọn ba n porukọ akọni ninu awọn kọmẹntatọ ere bọọlu,yoo ṣoro ki a ma fi ida Ernest Okonkwo lalẹ gaara.
Bí ohun tí ẹnikẹ́ni bá kọ́ lé orí ìpìlẹ̀ yìí kò bá jóná, olúwarẹ̀ yóo gba èrè.
O ni wọn kò fún àwọn láṣẹ láti sanwó fáwọn Alakoso gareji nítorí amojuto ọkọ èrò ni ojúṣe wọn, tí ọ̀rọ̀ àwọn ọlọkada àti onimaruwa kò sì kàn wón.
Ṣugbọn OLUWA pa wọ́n run fún àwọn ará Amoni, wọ́n gba ilẹ̀ wọn, wọ́n sì tẹ̀dó sibẹ.
ni yoo ri ijọba Ọlọrun wọ.
Ọpọ igba lawọn ijọba lẹka gbogbo ti maa n fi awọn ohun amayedẹrun ilu sọ orukọ awọn akọni ati akinkanju ọmọ orilẹ-ede Naijiria kan.
Inu ojo ti ọwọ rẹ le kikankikan ni wọn gbe wolii sọtitobirẹ atawọn afunrasi yooku wọ ile ẹjọ lowurọ ọjọbọ.
Láti inú ẹ̀yà Manase, a yan Hanieli ọmọ Efodu.
Ninu aworan ti wọn fi lede ni obinrin naa ti n jẹ irora nilẹ, ko to di wi pe o papoda.
Bọ́ sí ìhà ìhín, wáá búra fún mi.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ìyanṣẹ́lódì ẹgbẹ́ òṣìṣẹ́ kò le fa ọ̀wọ́n epo - NNPC Ẹgbẹ́ ASUU bẹ̀rẹ̀ ìyanṣẹ́lódì aláìnígbèdéke Fayoṣe ní ìbéèrè mẹ́rin fún Buhari lórí ìwé ẹ̀rí rẹ̀ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ireti Yusuf: Ìsòro àti fẹjọ́ sùn ló ń mú kí ìwà ìfipábánilòpọ̀ gbilẹ̀ si Eyi tumọ si pe wọn yoo maa gba awọn eeyan to wa lati orilẹede to jẹ ọmọ ẹgbẹ́ Commonwealth sẹnu isẹ ologun tiwọn.
Igba meje ti ẹsẹ isọkan Naijiria ti mi: Ogun abẹle to waye laarin ọdun 1967 si 1970: Ni kete ti orilẹede Naijiria gba ominira tan lọdun 1960, ni oniruuru rogbodiyan oselu gba ilu kan laarin ọdun 1962 si 1965.
France, Brazil, Croati  ati orile-ede England si tele won.
“Ẹ gbọdọ̀ ṣàkíyèsí òfin mi, kí ẹ sì máa pa wọ́n mọ́.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Wọnyi ni Àkójọpọ̀ àwọn àwòrán mánigbàgbé ọdún Àjínde l'Afrika.
Kà nípa ìròyìn mánigbàgbé tí BBC News Yorùbá ṣe láàárín ọdún kan Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí kan sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
Mo fẹ́ kí ẹ mọ̀ dájúdájú pé ohunkohun tí ẹ bá bèèrè lọ́dọ̀ Baba ní orúkọ mi, yóo fun yín.
Omotosho ni igbimọ amuṣẹya kan ti ijọba apapọ gbe kalẹ lati da si sunkẹrẹ-fakẹrẹ to wa ni Apapa n ṣiṣẹ lọ, ijọba Eko si fọwọsowọpọ pẹlu wọn.
dáàbò bò mí lọ́wọ́ ọ̀tẹ̀ àwọn eniyan burúkú;kó mi yọ lọ́wọ́ ète àwọn aṣebi.
”Joabu bi í pé, “Kí ló dé tí o fi fẹ́ lọ, ọmọ mi?
O ṣalaye pe oun ti pinnu lati dẹkun ọmọ bibi, ṣaaju ki o to loyun eyi ti ijamba ka mọ lara.
Sẹnẹtọ Abiola Ajimobi: Oríṣun àwòrán, @AAAjimobi Àkọlé àwòrán, Gomina Ajimobi Gomina nigba kan ri ni ipinlẹ Oyo, Abiola Ajimobi, jẹ ẹnikan ti iroyin iku rẹ milu titi.
Majẹmu àkọ́kọ́ ni àwọn ètò ìsìn ati ilé ìsìn bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé ti ayé ni.
Olootu ijọba nigba naa lo pada di aarẹ akọkọ, iyẹn, Francois Tombalbaye ni asiko ẹni ti ọpọ ija ṣẹlẹ laarin awọn Mususlumi ni ariwa ati awọn Kristiẹni ni guusu.
“Bí ẹnìkan bá jí akọ mààlúù kan tabi aguntan kan gbé, tí ó bá pa á, tabi tí ó tà á, yóo san akọ mààlúù marun-un dípò ẹyọ kan ati aguntan mẹrin dípò aguntan kan.
Awọn ẹgbẹ agbabọọlu mejeeji kọkọ gbiyanju agbara wọn ṣugbọn ko sẹni to gbayo sawọn ẹnikeji fun iṣẹju mọkandinlogoji.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù NCC Sim Registeration: Bi o ṣe lè mọ̀ tí káádì inú ẹ̀rọ ìléwọ rẹ kò bá sí nínú àkọsílẹ̀ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ NCC Sim Registeration: Bi o ṣe lè mọ̀ tí káádì inú ẹ̀rọ ìléwọ rẹ kò bá sí nínú àkọsílẹ̀ 24 Ìgbé 2019 Ijọba apapọ Naijiria ni awọn kaadi inu ẹrọ ilewọ to ju aadọrun miliọnu lọ ni awọn to ni wọn ko ṣe iforukọ silẹ to kun oju osunwọn.
Bayii ni ijọba apapọ ṣe n parọwa fawọn ọmọ Naijiria pe ki wọn ye kọlu awọn ileesẹ to jẹ ti orilẹde South Africa to wa ni Naijiria lati gbẹsan iṣekupani awọn ọmọ Naijiria lorilẹde naa.
Gbogbo ẹyin ololufẹ Leycon, ẹ sunmọ lonii bi ka dijọ se ariya."
Arabinrin May  so pe orile ede Britain fẹ jẹ orile ede ti o ni okoowo julo laarin awon orile ede to ga julo ,G7 nile Afirika lọdun 2020.
agbegbe Kom Kom ni ijoba ibile  Oyibo
A gbọ pe Fadeyi jẹ ile ifowopamọ Skye Bank ni ojilerugba biliọnu Naira (240 billion) , ti ko si ti i san án.
Kí lẹ mọ̀ nípa àwọn tó ń du àṣíá APC mọ́ gómínà Ekó lọ́wọ́?
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: ìyà ń bẹ fún ẹni tó bá kó àbẹ́rẹ́ tó ń dènà lùkúlùkú wọ Nàíjíríà - Onímọ̀ Aṣẹ́wó, olè, gbájúẹ̀ ni 723 ọmọ Naijiria ta lé padà sílé - Ghana APC fẹ́ fa ìṣọwọ́-ṣiṣẹ́ ẹ̀rọ káàdì ìbò sẹ́yìn - Atiku Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fọ́nrán ohùn, APC ní Atiku parọ́ lórí ẹ̀sùn pé yóò jẹ́ kí ẹ̀rọ káádì ṣe aṣemáṣe N ṣe ni awọn agbofinro pọ babi si ayika ileeṣẹ ijọba ibilẹ naa, gẹgẹ bii awọn tisẹlẹ naa ṣoju wọn ṣe sọ.
Eyi mu ki aarẹ Buhari kọ lati buwọlu u, nitori bi awọn ileeṣẹ ijọba ṣe kọ owo iṣuna wọn pe wọn ti ṣe mago-mago rẹ.
Ṣé lọ́òtọ́ ni ọlọ́pàá dàwátì torí àti dóòlà ọmọ India méjì tí wọ́n jígbé?
1 142187 Orilẹede Kosovo 1161 62.
Nipa ti awọn Gomina, o tẹ bayi pe: Ipade lori ọrọ aabo orilẹede.
Iroyin naa ni ibi ti wọn pejọ si naa ni ikọ Operation Burst ti hu gbọ nipa rẹ, to si ko gbogbo awọn agbegbọn ọhun si ahamọ.
“Bí ẹnìkan bá tan wundia tí kì í ṣe àfẹ́sọ́nà ẹnikẹ́ni, tí ó sì bá wundia náà lòpọ̀, ó gbọdọ̀ san owó orí rẹ̀ kí ó sì gbé e níyàwó.
Ilé ẹjọ́ kòtẹ́mílọ́rùn yọ alága ẹgbẹ́ òṣèlú APC Adams Oshiomhole nípò Agbẹjọ́rò ni n kò bá jẹ́, tí n kò bá bá bàbá mi ṣe tíátà - Sola Kosoko Iléeṣé tó ní bàálù tí Naira Marley lo lọ Abuja tọrọ àforíjìn lówó Mínístà Eeyan 5,967 lo ti ri iwosan gba, nigba ti awọn 469 ti dero ọrun nitori arun ọhun.
Ẹgbàáta náírà (#6,000) ni ó ra ilẹ̀ náà.
À ń ké tantan, ẹ̀yin obìnrin bí ẹ kò bá nífẹ̀ẹ́ wa mọ́, ẹ béèrè fún ìtúká kí ẹ tó máa dà wa, ẹ máa lọ.
Nítorí pé ìwọ kò gba ọ̀rọ̀ mi gbọ́, o óo ya odi, o kò ní lè sọ̀rọ̀ títí ọjọ́ tí gbogbo nǹkan wọnyi yóo fi ṣẹlẹ̀.
Inu atẹjade kan ti ajọ FBI fi sita lori ayelujara wọn lọjọ Ẹti ni wọn ti kede rẹ.
Mo rí àwọn àgọ́ Kuṣani ninu ìyọnu,àwọn aṣọ ìkélé àwọn ará ilẹ̀ Midiani sì ń mì tìtì.
Ṣugbọn o, ju gbogbo rẹ lọ, Joshua ko ni awawi kankan fun ijakulẹ rẹ, bakan naa lo sọ pe, oun ko foju kere Ruiz.
Owó epo rọ̀bì fọ́, awọ kò wá ká ojú ilú mọ́.
Jessica Nabongo ni obìnrin àkọkọ nílẹ Adúláwọ tó rin gbogbo àgbáyé.
Yaakugh sàlàyé pé kò sí ẹ̀ni tó tii mọ àwọn agùbánirọ̀ tí ìṣẹ̀lẹ̀ náà ṣẹ̀lẹ̀ sí tan tí àsìkò yìí sí jẹ́ àsìkò ọ̀fọ̀ fún ilé iṣẹ́ agùnbánirọ̀ ní ìpínlẹ̀ Taraba.
Ẹni tí ń fi tọkàntọkàn ṣiṣẹ́ ni yóo máa jẹ́ olórí,ṣugbọn ọ̀lẹ ni a óo máa mú ṣiṣẹ́ tipátipá.
Wahala oun pẹlu awọn gomina tẹlẹ, Amosun tipinlẹ Ogun ati Rochas Okorocha Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ìjì ńlá ló ń ja alága ẹgbẹ́ òṣèlú APC, Adams Oshiomhole lọ́wọ́; ṣùgbọ́n kí ni ẹ̀ṣẹ̀ rẹ̀ gan Kii ṣe iroyin pe titi ti wọn fi kuro ni ipo gomina ni ipinlẹ koowa wọn, ati Amosun pẹlu Rochas Okorocha, ko si eyi to fojuure wo Adams Oshiomole titi ti wọn fi kuro ni ipo.
Angeliki (Pavlou) Heinz, da ọrọ to wa nilẹ yi bi ọgbọn.
Báwo ni ẹ ṣe tún fẹ́ yipada sí àwọn ẹ̀mí tí a kò fi ojú rí, tí wọ́n jẹ́ aláìlera ati aláìní, tí ẹ tún fẹ́ máa lọ ṣe ẹrú wọn?
Gẹgẹ bi owe Yoruba to sọ pe, owu ti iya ba gbọn, naa ni ọmọ yoo ran, arẹmọ Baba Oloye dara pọ mọ baba rẹ ninu oselu, to si tẹsẹ bọ bata baba rẹ, ọmọ kii kuku ba ipele iya rẹ, ko ṣi aṣọ dá.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù End bad government: Wọn rò pé a maa jà tàbí ba ǹkan jẹ́ ni ṣùgban ọmọlúwàbí ni wa-Afẹ̀hónúhàn Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ End bad government: Wọn rò pé a maa jà tàbí ba ǹkan jẹ́ ni ṣùgban ọmọlúwàbí ni wa-Afẹ̀hónúhàn 17 Ọ̀wàrà 2020 Ile ijọba ni alausa ni Ikeja ni awọn eeyan yii ti ranṣẹ si ijọba lori ohun to n dun wọn nipa ifiyajẹni lọna aitọ.
Inú ọmọ náà ni mo rò títí ilẹ̀ fi ṣu ìgbà tí mo sì máa lá àlá òun ni mo lá a rí, mo rii a jọ ń gbé ibi kan bí tọkọtaya.
Andile, omo odun mẹ́rìndínlógójì ohun ati afesona re Bridget, ti o fi odun kan pere julo, ni iroyin fi mule pe, awon mejeeji ti n ba ere ife won bo ojo ti pe, lati igba ti won ti jo wa ni ile iwe giga fafiti nilu Beijing, bee si ni won tn omo osu meji lowo.
Wọ́n ń parọ́ kún irọ́, bẹ́ẹ̀ ni ìwà ipá wọn ń pọ̀ sí i.
Adajọ Oweibo ni ki wọn dawọn pada si atimọle ajọ EFCC.
Bí wọ́n ti pàgọ́ yí Àgọ́ náà ká, bẹ́ẹ̀ ni wọn yóo ṣe máa ṣí, olukuluku ní ipò rẹ̀, pẹlu àsíá ẹ̀yà rẹ̀.
Gẹ́gẹ́ bí Baba mi ti fi ìjọba fún mi, bẹ́ẹ̀ ni èmi náà fi ìjọba fun yín, 
Wọn si fi ikede sita pe kii ṣe ootọ pe awọn fun D'banj ni kọkọrọ si yaara naa.
Ó bá rán àwọn meji ninu àwọn olùrànlọ́wọ́ rẹ̀, Timoti ati Erastu, lọ sí Masedonia ṣugbọn òun alára dúró fún ìgbà díẹ̀ sí i ní Esia.
Kékeré ni èyí tí mo ṣe yìí, n óo máa ṣe jù bí mo ti ṣe yìí lọ.
Ọkunrin kan wà, ará Sora, láti inú ẹ̀yà Dani, orúkọ rẹ̀ ń jẹ́ Manoa; àgàn ni iyawo rẹ̀, kò bímọ.
Ileẹjọ ibilẹ, magisreti to wa ni ipinlẹ Kaduna ni awọn mejeeji ti n jẹjọ ẹsun onigun-mẹrin to rọ mọ ipaniyan.
" "" ajá ode sì jé ohun ìní pàtàkì láàrin àwon yaka ."
O soro lori igbese ijoba apapo lati rii pe eto idibo naa kese jari pelu arowa pe ki awon Oludije se ooto pelu iwa omoluwabi lasiko ipolongo won.
" Ṣugbọn ṣa, ajọ NAFDAC gba awọn ara ilu ni imọran pe ki wọn o ma lo ogun chloroquine lai gba imọran lọwọ dokita wọn, nitori aṣilo rẹ le fa inu rirun, ki oju o ma a wo baibia, ori fifọ, ati ara yiyun.
Ìwọ ni o fi agbára rẹ pín òkun níyà;o fọ́ orí àwọn ẹranko ńlá inú omi.
Mo fẹ jẹ ọmọde to dantọ julọ ninu Chess lagbaye, ki n si lewaju ninu akọsilẹ fun awọn alaseyọri to lewaju lagbaye Nigba toun naa n salaye bi Tanitoluwa se bẹrẹ ayo Chess, mama rẹ, Oluwatoyin ni ọdun 2018 lo bẹrẹ ayo naa, eyiun bii ọdun kan sẹyin."
 O wa bẹbẹ fun ifowosowopo gbogbo omo ile igbimo asofin  lati mase fi oro  eto isuna falẹ ni kete ti oun ba ti gbee wa  siwaju won.
Ìgbẹ̀yìn Joe, akínkanjú to dóòlà ẹ̀mí èèyàn 13 ni P/Harcourt
Nígbà tí Mika kó owó náà fún ìyá rẹ̀, ìyá rẹ̀ mú igba owó fadaka ninu rẹ̀, ó kó o fún alágbẹ̀dẹ fadaka láti yọ́ ọ sórí ère náà, wọ́n sì gbé ère náà sí ilé Mika.
Olukọlu ni awọn osisẹ ọlọpa to n gbogun ti iwa idigunjale, SARS, ni wọn ta mọra, ni kete ti iroyin iwa ọdaran awọn afurasi ọhun de etigbọ wọn, ti wọn si gba wọn mu.
OLUWA bá sọ fún Mose pé, “Yan aadọrin ninu àwọn àgbààgbà Israẹli, àwọn tí àwọn ọmọ Israẹli mọ̀ ní olórí, kí o sì mú wọn wá sí ẹnu ọ̀nà Àgọ́ Àjọ.
Agbẹnusọ fun àjọ ọlọpaa ní ìpínlẹ̀ Kano, DSP Abdullahi Haruna lásiko tí àwọn oniroyin ń fi ọ̀rọ̀ waa lẹ́nu wò ní ìpínlẹ̀ Kano.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Police Checkpoint: Wo àwọn ìgbésẹ̀ tí ó lè gbé láti bọ lọ́wọ́ ẹ̀sọ́ ọlọpàá lóju pópó 9 Èbibi 2019 Oríṣun àwòrán, AFP Àkọlé àwòrán, Police Checkpoint: Wo àwọn ìgbésẹ̀ tí ó lè gbé láti bọ lọ́wọ́ ẹ̀sọ́ ọlọpàá lóju pópó Ilé iṣẹ́ ọlọ́pàá orilẹ̀-èdè Nàìjíríà ti sàlàyé àwọn àbàyọ láti bọ́yọ lọ́wọ́ ìdàmú nígbà ti ọlọ́pàá ba dá wọn dúro lójú pópó.
Nítorí ẹ̀ ń sọ pé agbára Beelisebulu ni mo fi ń lé àwọn ẹ̀mí èṣù jáde.
ní àwùjọ yorùbá , á ní àwọn ọ ̀ nà ìsèlú tiwa tí ó dá wa yàtọ ̀ sí ẹ ̀ yà tàbí ìran mìíràn .
Laarin ọjọ kan si meji ni ara fi maa n da irufẹ ẹjẹ yii pada si ara lẹyin too ba ti fi ẹjẹ silẹ.
”Dafidi bá gbà wọ́n, ó sì fi wọ́n ṣe olórí àwọn ọmọ ogun rẹ̀.
Ko si ọrọ ti mo ni ,
Ó jẹ́ nǹkan ìbànújẹ́ wípé ilé náà ti ṣe tán, ó lè wó nígbàkigbà látorí àìṣàtúnṣe, àìkáràmáìsìkí ohun àjogúnbá, àti ìbàjẹ́ tí àwọn tí ó gbé ilé láì gba àṣẹ ń fà.
Buhari ní òun kò gbàgbé àwọn ọmọ Chibok 'Ọdún méjì sẹ́yìn ni òbí àwọn ọmọbinrin Chibok gbọ́ láti ọ̀dọ́ ìjọba kẹ́yìn' Ọmọ Naijiiria ni mí, ọ̀rọ APC kò lésì -Atiku Àkọlé àwòrán, Òní ni àyájọ́ ọdún karùn ún tí Boko Haram jí àwọn ọmọ náà gbé ní ilẹ́ ìwé wọn, tí 100 nínú wọn sí ti di àwátì.
jẹ́ ẹgbaa mẹtadinlogoji ó lé ẹgbẹta (74,600).
Kíni àwọn ǹkan ti o lè ṣe láti ran ẹni tó fẹ́ gba ẹmi ara rẹ̀ lọ́wọ́: Ọ̀nà àkọ́kọ́ láti déna rẹ̀ láti inu ilé ni Kọ́kọ́ gbà pé ẹni náà ni ìṣòrò tó ń kojú: Tí o bá ti gbà pé ẹni náà ni ìṣòro, o le ràn lọ́wọ́, ti ó sì súnmọ ju ti tẹ́lẹ̀ lọ.
Nítorí OLUWA, tí ó jẹ́ olódodo,Ẹni Mímọ́ Israẹli, tí ó ti yàn ọ́.
Ó dìde dúró bí abo kinniun,ó sì gbé ara rẹ̀ sókè bíi kinniun.
Ẹ̀rí náà ni pé Ọlọrun ti fún wa ní ìyè ainipẹkun, ìyè yìí sì wà ninu Ọmọ rẹ̀.
Ṣugbọn kí gbogbo wọn fi aṣọ ọ̀fọ̀ bora, kí wọ́n sì fi gbogbo ọkàn wọn gbadura sí Ọlọrun.
O ni: Äkosemose nikan lo ye ki o maa ki nkan bo inu eti fun ayewo ati itoju to ye.
mú ninu àkọ́so èso ilẹ̀ náà sinu agbọ̀n kan, kí o sì gbé e lọ sí ibi tí OLUWA Ọlọrun rẹ yóo yàn pé kí ẹ ti máa sin òun.
Amotekun: Àwọn aṣòfin Yorùbá ní ikọ̀ aláàbò náà yóò bẹ̀rẹ̀ iṣẹ́ lọ́sẹ̀ díẹ̀ s‘ásìkò yìí
Ọgbẹni Ayeni ṣalaye pe ''olode'' lawọn baba wa laye ọjọun maa n pe coronavirus.
Ki n to kuro lorilẹede Naijiria ni wọn ti sọ fun mi pe ẹgbẹrun lọna aadọta dọla owo ilẹ Amẹrika ni mo gbọdọ san pada laarin ọdun kan.
Lọ sinu agbo ẹran rẹ, kí o sì mú ọmọ ewúrẹ́ meji tí ó lọ́ràá wá, kí n fi se irú oúnjẹ aládùn tí baba yín fẹ́ràn fún un, 
" Gomina ipinlẹ Eko tẹlẹ naa tun gboriyin fun gomina ipinlẹ Katsina, Aminu Bello Masari atawọn oṣiṣẹ ileeṣẹ ologun fun ojuṣe wọn lati doola ẹmi awọn akẹkọọ naa.
Wò ó bí àwọn ọ̀tá mi ṣe ń pọ́n mi lójú.
Bakan naa ni ọgbẹni Nabena kede pe ẹgbẹ APC ti sun idibo abẹle to yẹ ko waye ni ipinlẹ Ogun, Zamfara, Bauchi ati Abia si ọjọ Aje.
Èyí tí ó túbọ̀ wáá ba nǹkan jẹ́ ni ìlù ìbẹ̀ǹbẹ́ àti gángna tí àwọnn ẹbọra Igbó Olódùmarè kó wá sí ojú ìjà kí ìjà tóó bẹ̀rẹ̀ lẹ́ẹ̀kejì, àwọn ẹbọra ń lu ìyá ìlù, ìnàkí àti ọ̀bọ ń lu omele, nígbà tí wọ́n sì béèrè orúkọ bàbá mi tí ó sọ fún wọn ni wọ́n ti tẹ gọ̀ǹgọ́ mọ́ ojú ìlú ti wọ́n sì bẹ̀rẹ̀ sí wí pé:
Awon apapo egbe oselu alatako n fe ki ijoba se eto ijiroro lati mu ayipada ba ilana ajo eleto idibo, eyi ti o ni iko eleni mejo ijoba, ti awon alatako si ni merin pere, saaju ki eto idibo miiran to waye.
Covid-19 in Ondo: Dókítá mìí dágbére fáyé lẹ́yìn tó lùgbàdì àrùn Covid-19 ní Ondo
’ Ohun tí ẹ bá sọ yàtọ̀ sí èyí, ọ̀rọ̀ ẹni-ibi nì ni.
Ọkà yóo pọ̀ lóko,yóo máa mì lẹ̀gbẹ̀ lórí òkè;èso rẹ̀ yóo dàbí ti Lẹbanoni,eniyan yóo pọ̀ ní ìlú,bíi koríko ninu pápá.
Ajọ to wa fun iwadii ijinlẹ ati idagbasoke nipa oogun ni Naijiria, National Institute of Pharmaceutical Research and Development (NIPRD) lo fi ikede naa sita lẹyin iwadii to ṣe lori agbo naa.
Ẹni to bori: Algeria Madagascar vs Congo DR.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ojú òpó yìí leè gba Agbẹjọ́rò fún ọ Agbẹjọ́rò àgbà lọ sẹ́wọ̀n nílùú Èkó A ò gba ìbálòpọ̀ akọ ṣákọ tàbí abo sábo Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí 2 sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
Ó ní, “Alàgbà, ẹnìkankan kò dá mi lẹ́bi.
Eyii to n tumọ sipe imọ ẹrọ yoo ko ipa to pọ ninu Ramadan ọdun yii."
Ẹ má ṣe sọ ilẹ̀ tí ẹ̀ ń gbé di aláìmọ́, àní, ilẹ̀ àwọn ọmọ Israẹli láàrin àwọn tí èmi OLUWA ń gbé.
Bayii, ikọ̀ IRT ti ọga ọlọ́pàá gbe lọ si ipinle Ekiti, Kwara, Oṣun, Oyọ àti Ondo ti mu meji ninu àwon ìgárá ọlọ́ṣà náà.
dupe lowo yin, bi ẹ se wa sibi ajoyo  asalẹ
Gẹgẹ bi iroyin to tẹ BBC News Yoruba lọwọ ṣe sọ, ileeṣẹ to n ta afẹfẹ idana gaasi kan to wa lagbegbe naa ni ina ọhun ti sọ ni aṣalẹ ọjọ Aiku.
Ilumọọka osere tiata kan, Binta Ayọ Mogaji Odunẹyẹ lo woye ọrọ yii lasiko to n kopa lori eto ileesẹ tẹlifisan kan ni Naijiria.
Ó mú kí inú bi yín sí ohun tí ó ti ṣẹlẹ̀.
 Awon ipinle naa ni: Katsina, Kebbi, Jigawa, Zamfara, Sokoto, Yobe ati Borno.
Nígbà tí ó rí ọ̀kan tí ó dára pupọ, ó lọ ta ohun gbogbo tí ó ní, ó bá rà á.
A maa pese iranlowo to ye lati rii pe oko alagbeka yii n sise lojoojumo bi o ti ye”.
Ẹ kún fún àdúrà nítorí ìdájọ́ kóòtù àgbà lórí gómìnà l'Ọ́ṣun-APC Ọṣun Ìdí rèé táwọn ọmọ Nàíjíríà kan ṣe ń tako ìdásílẹ̀ ‘Ruga Settlement’ Ikọ ọlọpaa taa mọ si 'Operation Puff Adder' ati ikọ IRT ti Abba Kyari n dari rẹ, lo parapọ pẹlu awọn ọlọpaa to wa ni Ipinlẹ Kano lati gba baba naa silẹ ni Gangan Ruwa, ni ijọba ibilẹ Kumbotso ni Ipinlẹ Kano lọjọ Aje.
Naijiria fun suuru ti onikaluku won ni latari igbese ajo INEC, eleyii ti won gbe
AFCON 2019 final: Kọ̀lọ̀kọ̀lọ̀ Algeria là kìnìún Senegal mọ́ lẹ̀ lẹ́ẹ̀kejì gba ife
Ti eeyan ba n wo oko oku yii lati ọkankan, o dabi ori koriko ti eeyan ti lee rin lati naju, sugbọn awọn koriko ibẹ lọra daada, nitori ara oku ti wọn fi n se ounjẹ lati ọsẹ diẹ sẹyin.
Oríṣun àwòrán, bimbooshin Bakan naa lo fi ohun ransẹ si awọn akẹẹgbẹ rẹ ti wọn dijọ n sisẹ tiata pe ki wọn maa sugba akẹẹgbẹ wọn to ba gbe iru aworan bayii sita, ki wn si wadii boya ere ni ọrọ naa abi otitọ.
Internet Fraud: Iléẹjọ́ ní kí ''Yahoo boy'' lọ darí ọkọ̀ f'óṣù mẹ́ta lẹ́yìn tó tan obìnrin òyìnbó jẹ
"Alukoro ilé isẹ́ ọlọ́pàá ìpínlẹ̀ Zamfara, Shehu Mohammed sọ wípé ""òótọ́ ni pé ìkọlù wáyé ní àwọn ìlú mẹ́ta ní ìjọba ìbílẹ̀ Maru."
Ṣé ilẹ̀ náà kò ní di ìbàjẹ́?
Ta ni ha kù bí aláfẹ̀yìn tì mi!
Àlàyé rèé lóríi ìdí tí wọ́n fi ń pe aya ní ìyàwó Ọ̀rọ̀ ìjókòó ìgbìmọ̀ ìwádìí #EndSARS náà dé ìpínlẹ̀ Ogun Wo iye àwọn tí wọ́n ti gbà sí ikọ̀ SWAT báyìí àti òfin ti wọ́n fún wọn Wo bí àwọn ọmọ Nàìjíríà ṣe n kí fún ìjọba nítorí $1.
Ìdí rè tí a fi ń ko ilà pín sí ọ̀nà méjì.
Stefanu ń ṣe iṣẹ́ ìyanu ati iṣẹ́ abàmì ńlá láàrin àwọn eniyan nítorí pé ẹ̀bùn ati agbára Ọlọrun pọ̀ lọ́wọ́ rẹ̀.
Wọn salaye wi pe gbogbo ọna ni omi naa ma n gba ti awọn eniyan a si maa lo ọkọ oju omi kekere lati kọja loju popo.
Oríṣun àwòrán, Lanre Issa-Onilu Àkọlé àwòrán, Ninu idibo to kọja ẹgbẹ oṣelu APC lo gbegba oroke ninu idibo gbogboogbo to waye.
Oludije fun ipo gomina nipinlẹ Ọsun naa wa sisọ loju rẹ pe, bi oun yoo se lọ si ile ẹkọ giga ni ilẹ Amẹrika lo mumu laya oun nigba naa, ti oun ko si duro ki esi idanwo waec oun jade, ti oun fi lọ O wa foju laifi wo igbesẹ bi wọn se n beere iwe ẹri oun, to si se apejuwe igbesẹ naa gẹgẹ bii ‘iwa agabagebe ati ẹtan Bẹẹ ba gbagbe, Ileẹjọ ti fun Sẹnetọ Adeleke to n dije fun ipo gomina ipinlẹ Ọṣun labẹ aṣia ẹgbẹ oṣelu PDP ni aṣẹ maa niṣo ko sewu lori ẹsun ayederu iwe ẹri ti wọn fi kan an.
Aare Muhammadu Buhari ati Igbakeji aare orile ede Naijiria, Ojogbon Yemi Osinbajo naa ti wa nikaleAare Muhammadu Buhari naa ti de si papa isere Eagles SquareAbenugan ile igbimo asoju -sofin ti ilu Abuja Ahmade Lawal ati Femi Gbajabiamila naa wa nibe pelu.
Wo àwọn ohun tó yẹ kí o mọ̀ nípa DCP Kayọde Ẹgbẹdokun
June 12: Buhari fi orúkọ Abiola sọ pápá ìṣeré l'Abuja
Igbó Ẹlégbèje pàápàá ba ní lẹ́rù, tó ti a ba ń wò ó bọ̀ níwájú.
Agoogo meje alẹ Ọjọru ni NTA Ibadan ma n gbe ere Baba Sala jade lori afẹfẹ, ti ọpọlọpọ eniyan si ma n salọ si ile lati lọ wọ ere naa ti wọn pe akọle rẹ ni Alawada Comedy Show.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Buhari: Mo ní ìrètí pé àwọn ọmọ Chibok yóò padà wálé 13 Ìgbé 2019 Oríṣun àwòrán, @BUHARI Àkọlé àwòrán, Ọjọ́ Kẹrinla, Osu Kẹrin, ọdun 2019 lo pé ọdun márùn ún tí ikọ̀ Boko Haram jí àwọn ọmọ ilé ìwé Chibok gbé.
to iye eniyan ti o le sọ bi esi idibo yoo se ri.
Nígbà tí àkókò bá tó, n óo pada wá sọ́dọ̀ rẹ níwòyí ọdún tí ń bọ̀, Sara yóo bí ọmọkunrin kan.
Nígbà tí wọ́n gbọ́, wọ́n wọ inú Tẹmpili lọ nígbà tí ojúmọ́ mọ́, wọ́n bá ń kọ́ àwọn eniyan lẹ́kọ̀ọ́.
Funke Akindele tọrọ àforíjì, Lateef Adedimeji d'obìnrin, Bàbá Ire kó ìrẹsì lọ Ogbomoṣo Òfìfo ṣọ́ọ̀ṣì pa aṣọ dà fún àwọn Páṣítọ̀ Nàìjíríà Ṣé ìrètí wà pé coronavirus yóò dínkù lásìkò ooru?
Huramu fi àwọn ọkọ̀ ojú omi ati àwọn iranṣẹ rẹ̀ tí wọ́n mọ̀ nípa iṣẹ́ ọkọ̀ ojú omi ranṣẹ, wọ́n lọ sí ilẹ̀ Ofiri pẹlu àwọn iranṣẹ Solomoni, wọ́n sì kó ojilenirinwo ati mẹ́wàá (450) ìwọ̀n talẹnti wúrà wá fún Solomoni ọba.
A rọ wọn lati wa fi ọwọ si iwe lati gba oniduro rẹ sugbọn wọn ko pada wa, boya nitori pe ohun to se ko dun mọ wọn ninu rara ni.
Ó ṣe f'ọ́mọ tó n jeérú!
Ìkọlù agbébọn tó ṣékú pá ọmọ ogún Niger 89, iṣẹ́ bọ lọ́wọ́ Ọgágun àgbà Iroyin to n tẹ wa lọwọ ni pe awọn oṣiṣẹ to n mojuto igbokegbodo ọkọ nipinlẹ Eko, LASTMA ti de sibẹ wọn si ti di ọna naa pa ki wọn le raaye wọ awọn ọkọ akẹru naa kuro.
Tunde Kelani nigba to n ba BBC sọrọ sọ wi pe oun ko yan Baba Wande jẹ, ati wi pe ẹtọ rẹ lohun fun un lẹyin ti won gbe fiimu naa jade, lẹyin to sọ wi pe awọn to n se ayederu filmu naa ko jẹ ki ere ko wa lori rẹ.
Oríṣun àwòrán, Oyo Police Ko tii daju ibi ti wọn ti ri i mu ṣugbọn BBC Yoruba ba alukoro ipinlẹ Oyo, Ọgbẹni Fadeyi Olugbenga sọrọ o si fidi ọrọ yii mulẹ.
" Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo Owó tó kàn mí nínú N4 mílíọ̀nù ìbejì Akeugbagold tí a jí gbé, bàtà ni mo fi rà-Afunrasí Kele ofin ti mu awon ọdaran to ji awọn ibeji Alhaji Taofẹẹq Akewugba Gold gbe.
Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Yoruba Taboo: Èèwọ̀ ni fún ọba láti gbé Bibeli tabi Kurani dání dípò ifá- Elebuibon, Agẹṣin Àdìmúlà29 Bélú 2020 Peers of Heaven: Ààrẹ ẹgbẹ́ Emèrè ní àwọn ti wà tipẹ́, wọn kò pariwo síta ni18 Ògún 2020 Gbọ́, Elebuibon: Lẹ́yìn ọ̀pọ̀lọ́pọ̀ oṣù tí òjò kò rọ̀ ní orílẹ̀èdè Cuba, Ọba ilẹ̀ Yorùbá ló pàṣẹ kí ó rọ̀ tó sì rọ̀1 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo18 Èbibi 2020 DNA Paternity: Tó bá wáyé pé ẹ kò mọ ẹni tó lọmọ, ohun tí àwọn àgbààgbà Yorùbá máa ń ṣe rèé5 Sẹ́rẹ́ 2021 Orisabunmi: Elebuibon ní àfọwọ́fà wà lára nǹkan tó n fa Àkúfà nílẹ̀ Yorùbá11 Sẹ́rẹ́ 2021 Elebuibon: Àwọn asòfin Ogun yóò ṣe àkóbá fún ilẹ̀ Yoruba pẹ̀lú òfín tó fágilé àsà6 Ẹrẹ̀nà 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Àlàyé rèé lórí ìdí tí mo fi lọ sílé Tinubu - Rashidi Ladoja Ààrẹ Akufo-Addo la Mahama mọ́lẹ̀ wọlé ìbò ààrẹ Ghana fún sáà kejì Ẹ̀yin tí ẹ máa ń bú àwon tó sanra ni ẹ ń jẹ́ kí wọ́n ronú pa ara wọn - Eniola Badmus Ilé aṣòfin kò láṣẹ kankan láti pe ààrẹ Buhari wá rojọ́ lórí ọ̀rọ̀ ètò àbò - Malami Ṣé lóòtọ́ ni tírélà ti gba ààrín Ronke Odusanya àti bàbá ọmọ rẹ̀, Jago?
Àgbo ṣiṣẹ́ fún mi l'asìkò tí mò ń wojú Olúwa fún ọmọ- Toyin Abraham Islam kọ́ ló ni kí ọmọ ọdún méjìlá lọ sílé ọkọ- Ààrẹ ilẹ̀ Niger Ọ̀nà ọ̀fun, ọ̀nà ọ̀run!
“Nisinsinyii, mo fi yín lé Ọlọrun lọ́wọ́ ati ọ̀rọ̀ oore-ọ̀fẹ́ rẹ̀ tí ó lè mu yín dàgbà, tí ó sì lè fun yín ní ogún pẹlu gbogbo àwọn tí a ti sọ di mímọ́.
Agbẹnusọ ileeṣẹ ọlọpaa nipinlẹ Ondo, Tee-Leo Ikoro lo sọ bẹẹ fun BBC lori ibeere pe kini ijọba le ṣe lati ri wi pe opin de ba ijamba ọkọ to n fi ẹmi awọn eniyan ṣofo ni awọn ọja to wa ni opopona.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù EFCC: Patience Jonathan gbọdọ foju wina igbẹjọ 20 Èrèlè 2018 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Patience Jonathan ti wa nile ẹjọ pẹlu ajọ EFCC lori oniruuru ẹsun kiko owo ilu sapo ara rẹ Ajọ to n gb'ogun tiwa ṣise owo ilu kumọkumọ lorilẹede Naijiria (EFCC) sọ wipe awọn ti yari fun aya aarẹ tẹlẹri lorilẹede Naijiria, Patience Jonathan pe o gbọdọ yọju s'ile-ẹjọ fun igbẹjọ nipa awọn owo tuulu ti wọn ba ninu awọn apo aṣuwọn rẹ.
'Mi ò mọ̀ pé mo lóyún àfìgbà t'ọ́mọ ń rún'ra' Ìwádìí ìwé ẹ̀rí àwọn olùdíje Ààrẹ lọ́dún 2019 Minimum wage: Kí ló fàá tí owó oṣù tuntun fi ṣòro?
Àbí ẹ rò pé òun ni ó ń ṣe àwọn nǹkan wọnyi?
Aisaya bá dáhùn pé, “Ẹ gbọ́, ẹ̀yin ọmọ Dafidi, ṣé eniyan tí ẹ̀ ń yọ lẹ́nu kò to yín, Ọlọrun mi alára lókù tí ẹ tún ń yọ lẹ́nu?
Adama Indimi ti ọpọlọpọ mọ si presido jẹ oniṣowo nla nipa ṣiṣe ara loge.
àwọn ọmọ Hanani, àwọn ọmọ Gideli, ati àwọn ọmọ Gahari, 
Iko Naijiria n kopa ribiribi ninu idije Commonwealth games to n lo lowo lorile-ede Australia.
Agbẹnusọ ọlọ́pàá sàlàyé pé gbogbo ọ̀nà ni àjọ ọlọ́pàá ń gbà láti ri dájú pé, ìpànìyàn dínkù láàrín àwọn kọ̀lọ̀rọ̀sí láàrín àwọn ọlọ́paàá.
Ní gbogbo ọjọ́ ìsinmi, Aaroni yóo máa tò wọ́n kalẹ̀ níwájú OLUWA nígbà gbogbo, ní orúkọ àwọn ọmọ Israẹli, gẹ́gẹ́ bíi majẹmu títí lae.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù IAAF vs AFN: Ó ṣeé ṣe kí Nàìjíríà má lè kópa nínú eré ìdárayá àgbáyé 16 Èbibi 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Awọn asare ije Esi o dá lori aṣẹ ti ajọ to n ri si ere idaraya lagbaye (IAAF) pa fun ẹka rẹ to wa lorilẹede Naijiria(AFN) gbedeke ọsẹ meji pere ni awọn fun wọn lati san owo ti IAAF ṣeesi san si apo asuwọn owo AFN.
Lagos State: Oníṣòwò mẹ̀ta wọ gàù lórí títa pọ̀nmọ́ olóró
A n se oju ona ọkọ ati oju irin lẹẹkanaa lati mu igberu ba eto ọrọ aje.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Sunday Igboho: A lè kojú Fulani táwọn ọba alayé àti àgbà Yorùbá bá tì wá lẹ́yìn Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Sunday Igboho: A lè kojú Fulani táwọn ọba alayé àti àgbà Yorùbá bá tì wá lẹ́yìn 6 Ògún 2019 Sunday Adeyẹmọ, ti gbogbo eeyan mọ si Sunday Igboho, lasiko to n ba BBC Yoruba fọrọwerọ salaye pe, ti awọn agbaagba ati ọba alaye nilẹ Yoruba ba setan lati fi ọwọ si iwe adehun, lati ran oun ati awọn alagbara miran nilẹ Yoruba, lọ koju awọn Fulani to n da eto aabo wa ru, oun setan lati lọ.
Àní, kí á kọ ọ́ sinu ìwé!
”Bakan naa, akonimoogba agba iko ohun, Gernot Rohr naa bowolu sise amulo ero igbalode ohun pe, yoo satileyin n la fun oludari ifesewonse naa.
Osẹ meji sẹyin ni awọn agbofinro IRT tun mu u ni ipinle Kwara.
0 18,001 Sri Lanka 255 1.
Bí mo bá jẹ́ baba yín, ṣé ẹ̀ ń bọ̀wọ̀ fún mi?
Ṣùgbọ́n kò sí ẹni tí ó dá mi lóhùn.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Jude Chukwuka: Wọ́n yóò fi ojú ọlọgbọ́n wo akúrí tó bá sọ ojúlówó èdè Yorùbá Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Jude Chukwuka: Wọ́n yóò fi ojú ọlọgbọ́n wo akúrí tó bá sọ ojúlówó èdè Yorùbá 22 Ògún 2020 Yoruba ni ọmọ to ba sọ ile nu, o ti so apo iya kọ, idi si ree ti ọmọbibi ẹya Igbo, Jude Chukwuka, fi n rawọ ẹbẹ sawọn ọmọ Yoruba lati maa sọ ede abinibi wọn.
ti lọ dibo tiẹ ni ilu abinibi rẹ, MinnaMaa gba esi idìbo oni wọle to ba ti lọ boṣe yẹ – OsinbajoIbudo ìdìbò ni VGC nipinlẹ Eko ni igbakeji aarẹ, Yemi Osinbajo ti sọrọ
Ọmọ mi tí kò ì ṣe ǹkan láyé’.
Ohun ti akori ipade apero ajo agbaye da le lori  ni, ‘ Igbiyanju lati mu osi kuro, eto ẹkọ to ye kooro ati mimojuto iyipada ọjọ ati eefin inu afẹfẹ.
Cazorla dágbére fún Arsenal Iwobi fakọyọ bí Arsenal ti na Chelsea Lukaku sọ Man Utd ji pada,Tottenham fidirẹmi Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 3 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 5 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Àwọn ọmọ Heburoni jẹ́ mẹrin: Jeraya ni olórí wọn, bí àwọn yòókù wọn ṣe tẹ̀léra nìyí: Amaraya, Jahasieli ati Jekameamu.
Apapo  agbaboolu France ni kikun:     Apapo  agbaboolu Belgium ni kikun:.
Ó ń sun turari ní àfonífojì àwọn ọmọ Hinomu, ó sì ń fi àwọn ọmọkunrin rẹ̀ rú ẹbọ sísun, gẹ́gẹ́ bí ìwà ìríra tí àwọn orílẹ̀-èdè tí OLUWA lé jáde kúrò níwájú Israẹli ń hù.
Lẹyin iṣẹlẹ yii ni ẹgbọn oloogbe naa wa gbe oku aburo rẹ wa si ibi ti wọn ti yinbọn pa lati bere idajọ otitọ.
Jerameeli, àkọ́bí Hesironi, bí ọmọkunrin marun-un: Ramu ni àkọ́bí, lẹ́yìn rẹ̀ ni wọ́n bí Buna, Oreni, Osemu, ati Ahija.
Alhaji Abdullahi Surajo to je olori eka ibanisoro fun ajo naa lo so eyi di mimo fawon akoroyin ni Dutse.
Jeremaya wolii pa àṣẹ kan fún Seraaya, alabojuto ibùdó ogun, ọmọ Neraya, ọmọ Mahiseaya nígbà tí ó ń bá Sedekaya ọba Juda lọ sí Babiloni ní ọdún kẹrin ìjọba Sedekaya.
Ninu ọrọ rẹ, akọwe agba fun ere boolu lorilẹede yii, Dokita Mohammed Sanusi banujẹ lori iku Issac Promise.
Ó ní òun gbọ́ ọ̀rọ̀ inú ìpè olóòtú ètò náà pẹ̀lú aṣojú ilé iṣẹ́ BlaBlaCar fún ìbánisọ̀rọ̀ pẹ̀lú àwùjọ tí òun sì gba ohùn-un wọn sílẹ̀:
Muhammadu Buhari ati igbakeji rẹ ojogbon  Yemi Osinbajo  ni won yoo gba iwe ẹri moyege lati pada wa
wa ni osusu ọwọ, gege bi orile ede kan, a si tun gbọdọ ri i pe a setọju awon
Aguti ti wa fèsì si ǹkan ti bàbá rẹ̀ ṣe láti lé àwọn ọkọ rẹ̀ kúrò nilẹ: Mó lọ́kọ tẹlẹ̀, bí awọn ará ìlú mi ṣe fẹ́."
Mo ti sọ̀rọ̀, n óo sì mú un ṣẹ,mo ti ṣe ìpinnu, n óo sì ṣe é.
"Owó tó kàn mí nínú N4 mílíọ̀nù ìbejì Akeugbagold tí a jí gbé, bàtà ni mo fi rà-Afunrasí ""Ọ̀pọ̀ ènìyàn tó ń gbé ní Eko, Ibadan, Osogbo ló ti kú."
ọpọlọpọ àwọn ọmọ Israẹli ni yóo sì yipada sí Oluwa Ọlọrun wọn.
Nígbà tí OLUWA bá parí bírà tí ó ń dá ní òkè Sioni ati ní Jerusalẹmu,yóo fìyà jẹ ọba Asiria fún ìwà ìgbéraga ati àṣejù rẹ̀.
Ẹ wo àrà tí ''Ayo the Creator'' ń fi sinimá dá Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Ayodeji Amodu Photoshop: Aláráǹbàraà!
Òfin ṣì gbẹ́sẹ̀lé Ẹgbẹ́ awakọ̀ èrò NURTW ní ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́ Nítoríi fóònù ìbánisọ̀rọ̀, géńdé méjì kú sínú u kọ̀ǹga l'Ékìtì Wike kò wó Mọṣáláṣi rárá o -Fayẹmi lórúkọ gbogbo Gómìnà Ọlọ́pàá kó àwọn ọmọ ẹgbẹ́ òkùnkùn Ẹiyẹ Confraternity ni Ikorodu Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Port harcourt Bole: Mi kò mọ́ pé bọ̀ọ̀lì títà lè gbé mi dé ipò yìí láyé mi!
láti ìgbà tí Ìgbìmọ ̀ Ìwádìí Ìjìnlẹ ̀ Ẹ ̀ kọ ́ ( n.
Amọ ohun to daju ni pe lootọ lo pa ọkọ rẹ, boya lati ipasẹ asise ni abi o mọọmọ see.
Dafidi lọ lẹsẹkẹsẹ láti rí ibi tí Saulu ati Abineri, ọmọ Neri, olórí ogun Saulu, dùbúlẹ̀ sí.
Mo mọ̀ pé láàrin yín àwọn ẹlòmíràn yóo dìde tí wọn yóo fi irọ́ yí àwọn ọmọ-ẹ̀yìn Jesu lọ́kàn pada láti tẹ̀lé wọn.
Wo ìdí to fi gbọdọ̀ yàgò fún Bobrisky, akọ tó ń ṣe bíi abo Kí ló dé táwọn ọ̀dọ́ dìbò 140m fún BBNaija àmọ́ tí ìbò ààrẹ Nàíjíríà jẹ́ 28m?
O jẹ oluranlọwọ pataki fun igbakeji gomina ni Ipinlẹ Eko nigba kan ri, Femi Pedro.
 Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ẹsẹ̀ bàtà, èso kukumba ni wọ́n fi ń já àbálé àwọn ọmọ Nàìjíríà ní Libya Femi, ẹni tó ṣe àlàyé lórí ohun tó fa tí òun fi ṣe fíìmù Jelili ní, mo rí pé ìlú kan gógó , táwọn èèyàn ń rìn tikanra-tikanra pẹ̀lú aìdùnnú, lo mú kí n fi ṣe sinima tó jẹ́ awada, láti pa àwọn èèyàn ní ẹrin, tí mo sì gbọ́ nílé ìwòsàn UCH pé, fíìmù náà pá àwọn aláìsàn ni ẹrin púpọ̀, tó sì tètè mú kí ara wọn yà.
Lẹ́yìn oṣù márùn ún, Buhari kọ̀ láti yọ ọga NHIS bí ìgbìmọ̀ ṣe sọ
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Corruption: Ọ̀gá àgbà àṣọbodè ní kíkọ rìbá ṣàfihàn aṣọ́bodè tó ti di àtúnbí 18 Ẹrẹ̀nà 2019 Àkọlé àwòrán, O ní onífàyàwọ́ ọ̀hún tún jẹ́ẹ̀jẹ́ pé òun yóò sàn rìbá tó tún pọ̀ jùbẹ́lọ ti tí àkọ́kọ́ yìí ba ṣe dáradára Ilé iṣẹ́ aṣọ̀bode ti ṣe àgbéga fún ọ̀gá àgbà ilé iṣẹ rẹ̀ ní Apapa, Bashir Abubakar sí ipò igbákejì ọgá agba ileeṣẹ náà.
Aarin awọn mejeeji ti ko tooro si ti n da omi alaafia ru l'agbo oṣelu paapaa ni ẹgbẹ oṣelu APC ti ipinlẹ Ondo, paapa bi Ajayi ṣe ti darapọ mọ ẹgbẹ alatako, PDP.
Modupe Kolawole to jẹ iya ọmọkunrin ọdun kan toun funra rẹ din ni ẹni ọgbọn ọdun figbe ta pe ki ijọba gba oun tori ko lẹni kankan.
Níbà tí mo sọ̀rọ̀ yìí tán ọkùnrin náà wò mi, ó pòṣé kò sì fèsì ọ̀rọ̀ mi ṣùgbọ́n dípò bẹ́ẹ̀, ó yi ojú padà ó ń lọ bí ẹni pé ó ń lọ fi ẹjọ́ mi sun ẹni kan pàtàkì ti yóò wáá jẹ mí i ìyà ohun tí mo ṣe.
Ìgbà tí mo sì tóó wọ inú ilé náà ni mo tóó ṣe àkíyèsí pé pẹ̀tẹ́ẹ̀sì ni, lẹ́hìn tí a ti rìn tó bí ẹsẹ̀ bàtà méjìdínlógún a dé ìdí àkàsọ̀ tí wọ́n fi ń gun òkè pẹ̀tẹ́ẹ̀sì ibẹ̀, ọkùnrin náà sì bẹ̀rẹ̀ sí gùn ún títí ó fi dé òkè lọ́hùn-ún bẹ́ẹ̀ ni èmi náà ń gùn ún tẹ̀lé.
Mose, iranṣẹ OLUWA ati àwọn ọmọ Israẹli ṣẹgun àwọn ọba mejeeji yìí, ó sì pín ilẹ̀ wọn fún ẹ̀yà Reubẹni, ẹ̀yà Gadi ati ìdajì ẹ̀yà Manase, ilẹ̀ náà sì di tiwọn.
Ọwọ palaba Oyenusi ati awọn ẹmẹwa rẹ ninu iwa idigunjale papa segi lọjọ Kẹtadinlọgbọn osu Kẹta ọdun 1971 nigba to yinbọn pa ọlọpa kan, ọgbẹni Nwi, lasiko ti wọn lọ digun jale, to si ji ẹgbẹrun lọna mejidinlọgbọn pọnun nigba naa Kia lawọn ọlọpa wa Oyenusi ni awari, ti wọn si gbe lọ sile ẹjọ lati wa jẹwọ awọn iwa ẹsẹ to ti gbe ile aye hu.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Abiola Ajimobi: Ikọ̀ ìjọba Oyo sọ pé àwọn ẹ̀ṣọ́ ilé Ajimobi ní ọwọ́ aya olóògbé ni kọ́kọ́rọ́ géètì wà 28 Òkùdu 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 5 Agẹmo 2020 Oríṣun àwòrán, Others Ijọba ipinlẹ Oyo ti sọ pe oun ko mọ idi ti wọn ṣe da ikọ asoju oun pada lẹnu ọna ile gomina ana, Abiola Ajimobi, nigba to yọju sibi adura ọjọ kẹjọ lẹyin to papoda.
Osinbajo ta kété sí ọ̀rọ̀ 'Ruga Settlement' Ẹ̀yin tẹ́ẹ tako àgbékalẹ̀ àgọ́ Fulani, ìkórira ló ń yọ yín lẹ́nu - Ìjọba àpapọ̀ Ọwọ́ mi mọ́ lórí eto Gàá darandaran, RUGA- Goodluck Jonathan 'Èèyàn mi mẹ́ta ló wà nínú ọkọ̀ ojú omi tó dà nù l'Eko!
Baṣọ̀run Gáà, tó yan ọba mẹ́rin, pa ọba mẹ́rin àmọ́ ọba karùn-ún ló pa á Ọbasanjọ sọ àsírí sàgbàdèwe rẹ̀ Jesu Oyingbo rèé, pásítọ̀ tó láṣẹ ìbálòpọ̀ lóri ọmọ ìjọ obìnrin Igbó mímu lè ṣe kóríyá, kò lé fi kún orín ẹnu òṣèré - 9ice Ko si ọna abayọ miran yatọ si omi ọyan: O yẹ ko ye wa pe labẹ bo ti wu ko ri, ko si ọna abayọ miran to yẹ ka mu lo lati tọju ọmọ wa ju fifun wọn ni omi ọyan lọ.
Ọwọ́ ọlọ́pàá Eko tẹ ọmọ ọdún 22 tó jẹ́ olórí 'bambam' f'ẹ́gbẹ́ òkùnkùn Berry Boys Agbẹnusọ ileeṣẹ ọlọpaa ipinlẹ Ogun, Abimbola Oyeyẹmi sọ wi pe bi awọn ṣẹ gbọ iroyin naa ni awọn ṣe kiakia lọ si bẹ, ti wọn si fi panpẹ ọlọpaa mu ọkunrin ọhun.
2 Èrèlè 2019 Oríṣun àwòrán, FEDERAL MINISTRY OF LABOUR Àkọlé àwòrán, Láti Ọjọ́ Kẹ́rin, Osù Kọkànlá, ọdún 2018 ni àwọn olùkọ́ fásitì náà tí bẹ̀rẹ̀ ìyansẹ́lódì lórí ìwà àìbíkítà sí ìsòro àwọn.
Owo naa si lo wa lati ọpọ awọn osisẹ ijọba apapọ ati ẹka osisẹ aladani, bawo wa lẹ se kore nibi ti ẹ ko gbin si.
Wọn yóo sì máa jọba lae ati laelae.
 Ó tẹ ọ ̀ pọ ̀ lọpọ ̀ ìwé eré onítàn ọlọ ́ rọ ̀ -geere ( novels ) , ìwé eré oníṣe orí-ìtàgé ( plays ) , ìwé ewì ( poems ) àti àkọsílẹ ̀ ní èdè yorùbá .
Morenike Balogun: Oríṣun àwòrán, Twitter/Morenike Balogun Àkọlé àwòrán, Morenike Balogun pelu awọn osere inu ere alabala ''How to get Away with Murder'' Morenike Balogun kii ṣe oju ti ọpọ ẹniyan mọ sugbọn iṣẹ ọwọ rẹ nipa kikọ itan fun awọn ere ori amohunmaworan jẹki o ta awọn akẹgbẹ rẹ yọ.
Èmi kì í ṣe olórí tí kò bìkítà nípa ọmọlẹ́yìn rè-Ààrẹ Buhari ‘Buhari ti wọnu ẹmi lọ’ Ìdìbò Zimbabwe àkọ́kọ́ lẹ́yìn Mugabe Munagagwa ko sọ pato iru aarẹ to n ba Mugabe finra sugbọn o ni Aarẹ ana naa ranṣẹ si oun pe ara ohun ti n balẹ ati wi pe ko ni pẹ ti ohun yoo fi pada wale.
Mò ń tọ ọ̀nà rẹ tààrà;ẹsẹ̀ mi kò sì yọ̀.
Nítorí kì í ṣe ẹ̀yin ni yóo máa sọ̀rọ̀, ẹ̀mí Baba yín ni yóo máa sọ̀rọ̀ ninu yín.
Nítorí OLUWA ní, “Ọ̀fẹ́ ni a mu yín lẹ́rú, ọ̀fẹ́ náà sì ni a óo rà yín pada.
Nígbà tí ilẹ̀ mọ́, Jesu jáde lọ sí ẹ̀yìn odi ìlú níbi tí kò sí ẹnìkankan.
Imọran wa pe ki a sá fun ewe ti wọn ko tii ṣe iwadii lori rẹ tabi awọn gbogbo niṣe ti ko ni ẹri.
 A o ran awon eniyan yii lati mu ipinnu won se.
” “A fẹ ki idagbasoke ba eto oro aje orile ede Naijiria ati Uk, ki a da opolopo ise sile lorile ede Naijiria, Ise to wa lorile ede Britain yoo wulo lorile ede Naijiria.
00 lọwọ oun fun ayẹwo Covid 19.
Aworan to ya kẹyin nigba to dipo naa mu re e.
Nítorí owú jíjẹ, ọkọ Zarka gé imú aya rẹ̀ dànú!
Baṣọ̀run Gáà, tó yan ọba mẹ́rin, pa ọba mẹ́rin àmọ́ ọba karùn-ún ló pa á Gómìnà Ganduje wọlé fún sáà kejì ní ìpínlẹ̀ Kano Supplementary election: Ọlọpàá gbé ikọ kògbérégbè díde lọ si wọ́ọ̀dù ìdìbò Gama A kẹ̀yìn sí Atiku torí àtúntò Nàíjíríà tó fẹ́ ṣe - Árẹ̀wá Ajimọbi tún gbé iṣẹ́ àgbàṣe ₦30bn jáde lọ́jọ́bọ - Seyi Makinde Iná ṣe ọṣẹ́ ní Mile 12 l‘Eko, ọ̀pọ̀ ilé àti ìsọ̀ jóná PDP ṣe èrú ìbò gómìnà ní Benue àti Sokoto, a kò ní gbà - APC yarí Awọn afurasi ti wọn lo gbe Aisha ni ẹni ọgbọn ọdun kan, Abdullahi Abubakar ati iya rẹ, Jummai Salihu, tii se ẹni ọdun mejilelọgọta, tawọn mejeeji wa latilu Lafia, nipinlẹ Nasarrawa.
'Lati bi ọdun mẹta naa ni o ti n kaakiri awọn ipinlẹ marun to wa ni iha Guusu orilẹede Naijiria lati ṣe idanilẹkọ tabi idẹyẹsi eniyan nitori wọn bi i si idile ẹru.
Covid-19 tún ti ran èèyàn 796 míràn ní Nàìjíríà Oríṣun àwòrán, Ncdc Èèyàn mẹ́ta míràn kú, olú ìlú Nàìjíríà, Eko, Kaduna léwájú ìṣẹ̀lẹ̀ Covid-19 ní Naijiria Eniyàa mẹrindinlẹgbẹrin lo tun ṣẹṣẹ lugbadi aarun Covid-19 ni Naijiria.
Nítorí pé ajinnilẹ́sẹ̀ ni gbogbo arakunrin,a-fọ̀rọ̀-kẹ́lẹ́-ba-tẹni-jẹ́ sì ni gbogbo aládùúgbò.
mona-mona sibẹ, nigba ti ilẹ ba su ni gbogbo awon ile ikabo to wa jake-jado
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Adebola Ademilua: Àìrísẹ́ ṣè lẹ́yìn ìwé kíkà ló sọ mi dí ìyá onírú, mo dúpẹ́ tèmi Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí D.
Ẹ̀rù ń bà wọ́n, wọ́n sì ń pada sẹ́yìn.
Dafidi di idà Saulu mọ́ ihamọra náà, ó sì gbìyànjú láti rìn, ṣugbọn kò lè rìn nítorí pé kò wọ ihamọra ogun rí.
EndSARS protest in Nigeria: Mr Macaroni, Falz, Wizkid, Tiwa Savage àtàwọn míì ṣe ìwọde Owó oṣù tuntun fáwọn olùkọ́ tí Buhari kéde yóò dá aáwọ̀ sílẹ̀- Wike Àfikún owó epo, owó iná àti owó orí VAT ló jẹ́ ká fowó kún tàríìfù DSTV- Ọ̀gá MultiChoice Kò gbọdọ̀ sí ìfẹ̀họ́núhàn EndSARS ní ìpínlẹ̀ Rivers - Gomina Wike Agbejọrọ agba Ubani salaye pe: ''Nitori eto iṣejọba tiwantiwa yii, eto awọn ọmọ Naijiria ni lati sọ wi pe awọn ko fẹ ohun ti ijọba n ṣe, Etọ wọn ni lati sọ ohun ti wọn n fẹ, ki wọn si beere fun nkan tiwu wọn lọna to ba ofin mu.
 Ẹ ̀ kọ ́ sayẹbinsi tí ó rọ ̀ gbàká ìlo àwọn ògùn .
Ẹni tí ó bá ní etí láti gbọ́ràn, kí ó gbọ́.
"Emi yoo tẹsiwaju pẹlu ipolongo tori bi a ko ba polongo, awọn eniyan ko ni jade wa dibo""."
Wo awọn iroyin manigbagbe to waye ni ọsẹ yii Amy Coney Barrett di adajọ́ àgbà nílé ẹjọ́ tó ga jùlọ l'Amẹrika Agbára wa kò ká àrùn Covid-19 mọ́ - Ìjọba ilẹ̀ Amẹrika Gbajúgbajà òṣèré tó ṣe fíìmù James Bond tí jáde láyé lẹ́ní ọdún 90 Awọ́n ti wọn ni iṣẹlẹ naa ṣoju wọn ní ǹkan bi aago méje àbọ̀ alẹ́ ló ṣẹlẹ̀, àti pé 'gbàrà ti ìṣẹ̀lẹ̀ náà ṣẹ, okú ènìyàn mẹ́wàá ni àwọn fàyọ, sùgbọ́n yóò tó ènìyàn ogún tó ba iṣẹ̀lẹ̀ náà rìn.
Lẹ́yìn oṣù márùn ún, Buhari kọ̀ láti yọ ọ̀ga NHIS Ina ọba: Bakan naa ni Aarẹ ni ayipada yoo de ba eto ina nitori pe awọn ti bẹrẹ si ni mu imugbooro ba ina ọba lati 5 Gigawatts si 7 Gigawatts, ati 11 Gigawatts ni odun 2023.
A tiẹ tun gbọ pe ileewe kan ti wo lulẹ nitori ariwo ati ilẹ to mi lasiko ti ibugbamu ọpa epo naa waye.
Báyìí ni Baba-onírùngbọ̀n sọ̀rọ̀ tẹ̀, nígbà tí ó sì parí ọ̀rọ̀ wọn-ọnnì mo dáhùn, mo ní, Ọ̀rẹ́ ni ọ̀wọ́n, ọ̀rọ̀ rẹ ha parí ni èyíni bí?
Wọn si ti fẹ ẹ fi ẹnu ko lori rira agbabọọlu orilẹ-ede Serbia, Sergel Milinkovic-Savic, ni aadọrin miliọnu Pọnun.
Oríṣun àwòrán, @ProfOsinbajo Àkọlé àwòrán, Èkùrọ́ lalá bákú ẹ̀wà; àwọn méjèjì a máa tage ìfẹ lóòrèkóòrè.
musulumi jake-jado orile ede Naijiria ku ori –ire fun osu mimo Ramadan yii.
Ki lo n doola ẹmi awọn obinrin lọwọ arun Coronavirus?
Lati ẹgbẹ oṣelu PDP ni Saraki ti kọkọ yapa lọ si APC ko too di aarẹ ile igbimọ aṣofin.
O ni ijọba ti fun gbogbo awọn alejo lati ilẹ okeere ni oṣu mẹta lati fi ṣeto iwe igbeluu wọn ni Naijiria.
"Ẹwẹ, o yẹ ki awọn olujẹjọ wa sọ pe ""bẹẹ ni a sọ ọrọ ti a sọ ti wọn gba ohun wa kalẹ"" lonii ṣaaju idajọ ti adajọ Olusegun Odusola yoo da ṣugbọn wọn ti ni ko tun ri bẹẹ mọ."
Idi ree ti BBC Yoruba fi ṣe agbeyẹwo awọn koko to wa ninu abọ iwadii Orosanye naa, oloju ewe ẹgbẹrin, eyi to n ko ibẹru si aya awọn oṣiṣẹ.
Yar'adua jogun oye Matawalle (alabojuto ẹṣọ ile oye) eyi ti baba rẹ ti jẹ ṣaaju.
Inú bí Hẹrọdu pupọ sí àwọn ará Tire ati Sidoni.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Sé ó yẹ kàwọn pásítọ̀ máa bèèrè èso owó ńlá-ńlá ?
Alága àkọ́kọ́ Ìlú-tí-kò-fi-ọba-jẹ ti China Mao Zedong ti yọ àwọn ènìyàn nínú ìṣòro.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Buhari jawọ ninu ilana okoowo tuntun fun Afrika 19 Ẹrẹ̀nà 2018 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Igbesẹ yii wa lati fun awọn ti ọrọ kan laaye lati dasi ohun ti Naijiria yoo gbe se lori ilana adehun naa.
Ìlú Agbamu, nipinlẹ Kwara si ní àwọn Afolayan yìí ti wa.
ti Ganduje dije gẹgẹ  bi gomina , ti o si
odun  ti Omar al-Bashir ti wa lori aleefa gẹgẹ bi aare orile ede Sudan ni iko omo
Iroyin naa ni pe Sheikh Mutumba to jẹ Imam ni Mọṣalaṣi ilu Kyampisi ni Kampala, olu ilu orilẹ-ede Uganda ko tii ba iyawo rẹ lajọṣepọ kankan tori pe o ni oun n ṣe nkan oṣu lọwọ.
Èèyàn mẹ́tàdínláàdọ́fà ló móríbọ́ lọ́wọ́ Covid-19, 443 míì tún lùgbàdì rẹ̀ lọ́jọ́ Ẹtì Oríṣun àwòrán, @BOBCyril2 Gẹgẹ bi Tinubu ṣe sọ, Obaseki bẹ awọn janduku lọwẹ lati ba apakan ile igbimọ aṣofin naa jẹ, to si parọ pe ṣe ni oun fẹ ṣatunṣe rẹ.
Ọdọmọkunrin náà dá a lóhùn pé, “Ohunkohun tí ọkàn rẹ bá fẹ́ ni kí o ṣe.
 Ṣalanga oniho jẹ ọna ti owo rẹ ko han lati ya igbẹ sọtọ kuro lọdọ awọn eniyan .
Ti a o ba gbagbe pe,aago meji ọsan
Igbésẹ̀ ti SERAP ń gbe láti ṣe àdínku ba ìwá jegudujẹra Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fọ́nrán ohùn, SERAP ni ẹ̀ka ìdájọ ló gbégba oróke sìkeji Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí 5:38 Fídíò, Kidnapped Girl: Iyá Ikimot ní lẹ́yìn ọ̀pọ̀ ìdààmú àti owó láti wá ọmọ náà, òun sọ ìrètí nù, Duration 5,3827 Ẹrẹ̀nà 2019 Fídíò, Rape: Oluwaseun Osowobi ní Commonwealth fún lámì ẹ̀yẹ ọ̀dọ́ tó pegedé jùlọ ní 201826 Ẹrẹ̀nà 2019 Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Coronavirus: BBC News Yorùbá ní kí ẹ dúró nílé bí ẹ kò bá ní ìdí láti jáde Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Pastor Adeboye: Ariwo lórí ayélujára nítorí ọ̀rọ̀ ìkíni kú ọjọ́ọ́bí tí Pásítọ̀ Adeboye kọ sí ìyàwó rẹ̀, Folu
Oríṣun àwòrán, Twitter/NG_Super Falcons Ikọ Super Falcons nikan lẹgbẹ agbabọọlu ilẹ Afirika ti ko tii pa ikankan jẹ ninu gbogbo idije ife ẹyẹ agbaye to ti waye lati ọdun 1991 ti idije naa ti bẹrẹ.
 bí ogun ṣe máa ń sẹlẹ ̀ láàárin ìlú sí ìlú ló máa ń sẹlẹ ̀ láàárín orílẹ ̀ -èdè sí orílẹ ̀ -èdè .
Lẹyin naa ni yoo ri daju pe ibasẹpọ to dan mọran wa larin agbeegbe tabi ipinlẹ ti asọ tabi ija naa ti waye.
”Igbakeji aare wa gbosuba fun awon mewaa ti won yege ninu ifigagbaga, ni eyi ti o da lori eto isejoba ati iwa ibajẹ nibi eto ofin.
Wọn si ti mu awọn afurasi ti wọn ni o mọ nipa ọrọ naa.
Ó bá nawọ́ sí àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀, ó ní, “Wò ó ìyá mi ati àwọn arakunrin mi nìwọ̀nyí.
gbogbo wọn parapọ̀, wọ́n fi ohùn ṣọ̀kan láti bá Joṣua ati àwọn ọmọ Israẹli jagun.
A ti kó gbogbo wọn siwaju pẹpẹ OLUWA.
Abẹnugan fun eto are bọọlu fún Super Eagles, Ademọla Ọlajiire lo fi iroyin naa lede ni ọjọ lsinmi ọsẹ yii.
Àwọn aláìsàn á máa kú lọ́wọ́ irú àwọn dókítà bẹ́ẹ̀.
Àwọn tí wọ́n fi ọwọ́ bomi, tí wọ́n sì fi ahọ́n lá a bí ajá jẹ́ ọọdunrun (300), gbogbo àwọn yòókù ni wọ́n kúnlẹ̀ kí wọ́n tó mu omi.
Gbogbo àwọn ará Juda, ati àwọn alufaa, ati àwọn ọmọ Lefi, ati àwọn onílé ati àwọn àlejò tí wọ́n wá láti ilẹ̀ Israẹli ati àwọn tí wọn ń gbé ilẹ̀ Juda, gbogbo wọn ni wọ́n kún fún ayọ̀.
Ó wà ní àkọsílẹ̀ pé, “Oluwa fi ara rẹ̀ búra, ó ní,‘Èmi ni gbogbo orúnkún yóo kúnlẹ̀ fún,Èmi ni gbogbo ẹnu yóo pè ní Ọlọrun.
Má bẹ̀rù ohunkohun tí ò ń bọ̀ wá jìyà.
"Ẹfunsetan Aniwura, obìnrin tó ju ọkùnrin lọ Ọ̀rọ̀ǹpọ̀tọ̀niyùn, Aláàfin obìnrin àkọ́kọ́ rèé, tó ní nǹkan ọkùnrin Gẹgẹ bi Mama Nike Davies ṣe ṣi ni loju lori iru iṣẹ yii, o ni ""o lere lori ṣugbọn wahala rẹ pọ""."
Oríṣun àwòrán, Seyi makinde/twitter Nnkan bi wakati kan ni wọn ni iro ibọn fi n dun lakọlakọ ti kaluku si sa asala fun ẹmi wọn.
Ti eniyan ko ba mumi bi o ti yẹ, omi to wa ni ara igbẹ eniyan ni agọ ara yoo mulo, eyi yoo si mu ki igbẹ iru ẹni bẹẹ le koko.
L'akọkọ ijọba Naijiria ti ọdun 2014 ko mọ bi ọrọ naa ti tobi to saaju ki wọn o to ma polongo BringBackOurGirls.
 Àwọn eku kìí sábà ní dìgbòlugi.
Gẹgẹ bi ọrọ agbẹnusọ ileeṣẹ ọlọpaa naa, gbogbo eto ti to lati ri i wi pe awọn to fẹ darapọ mọ iṣẹ ọlọpaa, ti wọn si wa fun ayẹwo naa tẹle ofin ijinasiraẹni ati awọn ofin miran to rọmọ didena itankalẹ arun Covid- 19.
Bakan naa lo gba ijọba ni iyanju lati ri wi pe wọn pese owo ati eto eko fun awọn eleto aabo lati ra ohun ija ti wọn nilo lati koju eto aabo to dẹnukọlẹ ni Naijiria.
Lọ́gán tí mo wọnú igbó náà ni mo ṣàkíyèsí i pé àwọn igi ibẹ̀ ti pàwọ̀dà, wọn kò jẹ́ funfun mọ́n.
Onkọrin, onilu, onijo, Olootu ati oludari ere ni I Show Pepper, to si ṣe awọn ere bii Iyawo Alalubosa, Efunsetan Aniwura, Alaafin Aganju, Fere bi Ekun, Eru Jẹjẹ, Ko see gbe, Ọmọ laja ati bẹẹ bẹẹ lọ.
"Ẹgbẹ́ náà sọ pé ọnà ati fi im'oore hàn ní kí oníkálukú bọwọ fún wọn nípa ṣíṣe ohun tó tọ"" Iye èèyàn tó ti tọwọ àrùn Covid 19 lo tí tó ẹgbẹrun ogun nilẹ gẹẹsi."
"Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Kenya: Ile isẹ amohunmaworan mẹta yoo wa ni titi latari ""iburawọle"" Odinga 1 Èrèlè 2018 Oríṣun àwòrán, AFP Àkọlé àwòrán, Ile isẹ amohunmaworan mẹta yoo wa ni titi latari ""iburawọle"" Odinga Ile-isẹ amohunmaworan mẹta to tobijulọ ni orilẹede Kenya yoo wa ni titi nitori igbiyanju wọn lati safihan eto iburawọle lori afefe fun adari alakato to se ibura fun ara rẹ gẹgẹbi aarẹ orilẹede naa ni Nairobi."
Ó ní nígbà tí Farao bá pè wọ́n, tí ó bá bi wọ́n léèrè pé irú iṣẹ́ wo ni wọ́n ń ṣe, 
Ọbabinrin láti ilẹ̀ gúsù yóo ko ìran yìí lójú ní ìdájọ́ yóo sì dá a lẹ́bi.
com Àkọlé àwòrán, Ayipada ti de ba inawo ṣiṣe bayii Bakan naa ni aye ti n kuro ni fifi odó ibilẹ gun iyan.
Nígbà tí ó yá, ọba titun kan tí kò mọ Josẹfu gorí oyè, ní ilẹ̀ Ijipti.
je ipenija ti ajo agbaye n dojukọ bayii, aare ni  “ A gbodo fopin si osi ati aini , ki
Temilolu fẹsun kan Owa ti ilu Idanre, Frederick Aroloye, pe oun lo ran awọn janduku naa lati ṣakọlu si oun.
Mika bí ọmọkunrin mẹrin: Pitoni, Meleki, Tarea ati Ahasi; 
Nígbà tí ọkùnrin yìí bẹ̀rẹ̀ sí ọ̀rọ̀ í sọ ẹ̀rú ba àwọn ará ìlú gidigidi.
O kò gbọdọ̀ bá arabinrin rẹ lòpọ̀, kì báà jẹ́ ọmọ ìyá rẹ lobinrin, tabi ọmọ baba rẹ lobinrin, kì báà jẹ́ pé ilé ni wọ́n bí i sí tabi ìdálẹ̀.
"Atejade naa ni: ""Nitori naa, gbogbo iwọde, igbesẹ tabi iwa ti Naijiria ba hu nitori awọn iroyin to gbọ, ko bojumu."
Oríṣun àwòrán, The Guardian Àkọlé àwòrán, Oṣu Kẹwaa, ọdun 2017, ni wọn yọ Lawal kuro nipo lẹyin ti wọn fi ẹsun kan pe o na N544m ni inakuna lati fi ge koriko.
Nǹkan burúkú gan-an ni èyí pàápàá jẹ́; pé bí a ṣe wá bẹ́ẹ̀ ni a óo ṣe lọ.
Ó sì tún ṣe ọọdunrun (300) apata wúrà kéékèèké, wúrà tí ó lò fún ọ̀kọ̀ọ̀kan jẹ́ ìwọ̀n mina mẹta mẹta.
Kọmisọna fikun ọrọ rẹ pe ijọba Ipinlẹ naa kọ tẹlẹ lati jẹki wọn lo papa iṣere naa nitori o le ṣakoba fun koriko.
Àkọlé àwòrán, Oke oke lẹyẹ nlọ o ni adura ti awọn ololufẹ Super Eagles ni Egypt fi bọ ẹnu ni idunnu si abajade esi ifẹsẹwọnsẹ tonii.
 O ni awọn ohun jijẹ ati mimu yii yoo le jẹ ki okun ara wọn pada lakọtun bi wọn ba ti n ṣere bayii.
Orí mi wú, Joke Silva kọ ewì ìfẹ́ lọ́jọ́ ìbí Olu Jacobs Kí lo mọ̀ nípa fẹntilétọ̀, ohun eèlò aṣèrànwọ́ èémí Laipẹ yi ni Forbes sapejuwe wọn gẹgẹ bi ''awokọse daadaa laarin awọn asiwaju'' Awọn onwoye ni lara awọn to kẹsẹ jari ninu kikoju arun yi, awọn olori obinrin lo pọ ninu wọn.
Nígbà gbogbo tí Saulu bá sì ti rí ọkunrin tí ó jẹ́ alágbára tabi akikanju, a máa fi kún àwọn ọmọ ogun rẹ̀.
Ní ipari Ṣeun Ogundiya rọ àwọn eniyan ki wọn dẹkun ìdẹ́yẹsí àwọn ti wọn ba ni ipenija ara nitori pe kò wù wọn bẹ́ẹ̀ rara.
Angẹli náà dá a lóhùn pé, “Geburẹli ni orúkọ mi, èmi ni mo máa ń dúró níwájú Ọlọrun.
Àwọn onímọ̀ èdè kan tilẹ̀ ti fi ìdí ọ̀rọ̀ múlẹ̀ pé láti orírun kan náà ni àwọn èdè bí Yorùbá, Kru, Banle, Twi, Ga, Ewe, Fon, Edo, Nupe, Igbo, Idoma, Efik àti Ijaw ti bẹ̀rẹ̀ sí yapa gẹ́gẹ́ èdè ọ̀tọ̀ọ̀tọ̀ tó dúró láti bí ẹgbẹ̀rún mẹ́ta ọ̀dún sẹ́yìn.
Ìró wọn dàbí ìró rírú omi òkun;wọ́n gun ẹṣin,wọ́n tò bí àwọn ọmọ ogun.
O salaye pe awọn to farapa marundinlaadọta ni wọn gbe lọ si awọn ile iwosan kaakiri Eko.
Oríṣun àwòrán, @MBuhari/Twitter Àkọlé àwòrán, Buhari tẹwọgba abọ ipade igbimọ to jiroro lori owo oṣu tuntun fun oṣiṣẹ lọjọ kẹfa, oṣu Kọkanla, ọdun 208 Ọ̀nà wo lowó osù tuntun yóò tọ̀, kó tó dé àpò òsìsẹ́?
Igbimo ijoba apapo ti so pe ipade  ti won maa n se lọsẹẹsẹ (Federal Executive Council FEC) ko ni waye LojoRu oni ti n se ojo keta , osu kewaa.
Abọ iwadi ajọ naa ṣe igbelewọn awọn orilẹede mẹrindinlọgọjọ lẹyin to ṣewadi awọn nkan bi i imọ ẹrọ, ihuwasi lawujọ, to fi mọ aawọ ati ipa ti awọn ilana iṣejọba ni lori bi inu awọn araalu ṣe n dun si.
Atupalẹ ẹbun fun ẹni to ba gbade BBNaija ọdun yii ni ọgbọn miliọnu naira(N30m), ile pẹtẹẹsi oni yara meji, ọkọ SUV kan, irinajo afẹ si ilu Dublin lorilẹede Scotland atawọn ọpọlọpọ ohun elo ninu ile Wo nkan ti awọn olukopa to ti já kuro lori eto naa jẹ: Triky tee O jẹ N3,359,000 Ohun elo inu ile Irinajo silu Dubai fun ayẹyẹ One Africa Music Fest Ọ̀dà Ẹẹdẹgbẹta Dọla owo Bitcoin Ozo O jẹ N2,780,000 gẹgẹ bi ẹbun owo Ọkọ ayọkẹlẹ Irinajo silu Abuja Ẹẹdẹgbẹta Dọla owo Bitcoin Irinajo silu Dubai fun ayẹyẹ One Africa Music Fest Prince Oun naa jẹ N2,570,000 Ohun elo inu ile Irinajo silu Abuja Ẹẹdẹgbẹta Dọla owo Bitcoin Irinajo silu Dubai fun ayẹyẹ One Africa Music Fest Kiddwaya O jẹ ẹbun owo: N1,720,000 Foonu tuntun Ọ̀dà Ẹẹdẹgbẹta Dọla owo Bitcoin Wathoni O jẹ ẹbun owo: N1,250,000 Eroja iṣaraloge Ẹẹdẹgbẹta Dọla owo Bitcoin Brighto O jẹ ẹbun owo: N970,000 Ọ̀dà Ẹẹdẹgbẹta Dọla owo Bitcoin Tolanibaj O jẹ ẹbun owo: N825,000 Irinajo silu Abuja Ẹẹdẹgbẹta Dọla owo Bitcoin Praise O jẹ ẹbun owo: N770,000 Ẹẹdẹgbẹta Dọla owo Bitcoin Lucy O jẹ ẹbun owo: N570,000 Ọ̀dà Ẹẹdẹgbẹta Dọla owo Bitcoin Kaisha O jẹ ẹbun owo: N570,000 Ọ̀dà Ẹẹdẹgbẹta Dọla owo Bitcoin Tochi O jẹ ẹbun owo: N220,000 Ẹẹdẹgbẹta Dọla owo Bitcoin Eric Ẹẹdẹgbẹta Dọla owo Bitcoin Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Ṣugbọn ni Ọjọbọ, Ile Igbimọ Aṣofin Agba Naijiria fi to ọmọ Naijiria lẹti pe ijọba apapọ na triliọnu mọkanla naira gẹgẹ bii owo iranwọ epo rọbi (subsidy) ni ọdun mẹfa.
"Oríṣun àwòrán, Abiola Ajimobi ""Akoko to taa sọ ootọ ọrọ pọnbele fun gomina Seyi Makinde pe ofuutu fẹẹtẹ, aasa ti ko ni kaun ni iwa to rawọ le lati fẹ pa oju ẹsẹ asaaju rẹ, Abiọla Ajimọbi rẹ ninu itan akọọlẹ rere nipinlẹ Ọyọ, nitori ijọba Ajimọbi lo tii pegede julọ lati ọdun 1976 ti wọn ti da ipinlẹ Ọyọ silẹ."
omo egbe asoju APC Gbogbo  awon  to
Oun fun'ra rẹ lo fi ọwọ si atẹjade ikede ipade naa ti yoo waye lori ayelujara.
Bi ọba kan ba wa kọ to ni ilana larubawa tabi Isrẹli loun yoo tẹlẹ, ohun ti wọn fi sọri ilẹ Yoruba yatọ si ohun ti wọn fi sọri ilẹ awọn ilu ti ẹsin okeere wọnyii ti wa.
 Èyé kò ni nǹken kan án se pèlú pé bóyá gbólóhùn méjèèjì bófin mu tàbí won kò bófinmu .
, Abiy Ahmed ati aare Sahle  ti orile ede
Awọn ọlọpaa sọ pe apejẹ ọsan àti alẹ ni awọn awọn to ṣe agbatẹru ariya naa sọ pe awọn n ṣe, sugbọn wọn bẹrẹ si ni pe awọn olorin wọle ni alẹ.
Wọ́n bá bẹ̀rẹ̀ sí tutọ́ sí i lójú, wọ́n ń sọ ọ́ lẹ́ṣẹ̀ẹ́, wọ́n ń gbá a létí.
Àgbo tí mò ń lò láti jò kó bá mi, ìdí mi ti yọ́ tán - Nkechi Blessing figbe ta Nkechi Blessing ti sọ pe oun ko ni lo oogun lati dena ara sisan mọ nitori oun ti jo ju bi oun ṣe fẹ lọ.
Jesu bi wọ́n léèrè pé, “Báwo ni wọ́n ṣe ń pe Mesaya ní ọmọ Dafidi?
Bákan náà ni Jesu Kristi wà lánàá, lónìí ati títí lae.
Ọ̀pọ̀ àwọn mẹ̀kúnù ni wọ́n kò ní aṣojú láàárín àwọn aṣojú tí wọ́n dìbò yàn, láàárín àwọn ẹgbẹ́ àbò àti àwọn adarí ipò ìjọba ìbílẹ̀.
1–4, Nípa ìgbàgbọ́ àwọn Ẹlérìí Mẹ́ta yíò rí àwọn àwo náà ati àwọn ohun mímọ́ mìíràn; 5–9, Krísti jẹ́rìí sí jíjẹ́ àtọ̀runwá Ìwé Ti Mọ́mọ́nì.
Ọdun 1841 ni Ọba Akitoye gori itẹ awọn baba nla rẹ, gẹgẹ bi ọba tilu Eko, asiko yii si ni owo ẹru gbinaya, eyi ti ko dun mọ ọba naa ninu ati awọn oyinbo kan nilẹ Gẹẹsi Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Èmi gan máa ń béèrè lọ́wọ́ ara mi pé ta ni Wole Soyinka gangan' Oba naa gbinyanju lati pa owo ẹru run amọ o ba ibinu awọn olowo ẹru labẹle pade, ninu eyi ta ti ri ipa obinrin takuntakun Ẹfunroye Tinubu, ti wọn si le kuro lori itẹ ati kuro ni ilu Eko, pẹlu atilẹyin awọn oyinbo kan, ti ọba Akitoye si gba ilu ọba lọ Aburo rẹ, Kosọkọ lo jọba lẹyin rẹ amọ lẹyin tilẹ Gẹẹsi fofin de owo ẹru sise patapata lọdun 1807, lawọn eebo ba tun se atilẹyin fun Akitoye lati pada sori itẹ lọdun 1851, ti wọn si le ọba Kosokọ kuro lori oye ati laarin ilu, lọ si Badagry.
Àwọn ọ̀dọ́ ìlú Iwó ti dáná sun àgọ́ ọ́lọ́pàá tó wà ní ìlú náà lówùrọ̀ ọjọ́ ẹtì.
lorile ede Naijiria Mohammed Adamu, wa fi ọkan gbogbo ọmọ orile ede Naijiria balẹ pe
US presidential election 2020: Àwọn àkọ́lé ìròyìn tó leè jáde lẹ́yìn ìdìbò Ààrẹ Amẹrika
Ṣugbọn ọ̀ràn kí ẹ jọ pín in ṣe ní dọ́gba-dọ́gba ni.
Bi awọn kan ti ṣe n bẹnu atẹ lu lawọn miran gboṣuba kare fun gẹgẹ bi oniṣegun to dantọ.
Akinwumi Adesina jáwé olúborí gẹ́gẹ́ bí adarí Báńkì AFDB Pupọ ninu awọn akọle to maa n ko sori ikanni facebook rẹ lo maa n fi bu iyi fun awọn ọlọpaa ti wọn ku ṣenu iṣẹ, o si ti fi igba kan jẹ ara ọmọ ikọ ileeṣẹ ọlọpaa abẹle ti ẹka Grayslake ri.
Ohun to waye ni ifowosowopo ati ifohunsokan laarin wọn, lọna ati lee gbogun ti iwa ibo rira ati eru sise eleyi ti awọn oludije kan pẹlu ti n pete rẹ.
Kì í ṣe àwọn baba wa ni OLUWA bá dá majẹmu yìí, ṣugbọn àwa gan-an tí a wà láàyè níhìn-ín lónìí ni ó bá dá majẹmu náà.
A bi Bourdain ni New York City ṣugbọn Leonia, ni New Jersey ni wọn ti tọọ dagba.
Títí di ọjọ́ òní mo ti dúró láti jẹ́rìí fún àwọn mẹ̀kúnnù ati àwọn eniyan pataki.
Lara awọn oṣiṣẹ naa ni iboji Abbatuwa ati Gidan Gona sọ fun BBC pe awọn ile iboji naa kere to bẹẹ ti wọn fi maa n sin oku meji papọ soju kan ṣoṣo.
Aarẹ Buhari lo se akojọpọ igbimọ naa nibi ipade igbimọ alasẹ ijọba orilẹede Naijiria nilu Abuja.
Ọdún meje ààbọ̀ ni Dafidi fi jọba lórí ẹ̀yà Juda ní ìlú Heburoni.
Yatọ si eyi, agbo ijo aọn obinrin naa ko si fun awọn abo to n fẹ ara wọn, taa mọ si Lesbian, ti ode naa ko si wa fun ẹlẹsin kan pato.
Àwọn ìròyìn mìíràn tí ẹ lè nífẹ̀ẹ́ sí: ‘UK yóò pèsè isẹ́ 100,000 ní Nàìjíríà’ Ààrẹ Buhari yóò ṣèbẹwò sí ìlu Ọba Aláàfin yẹ́ lizzy Anjọrin sí níbi ayẹyẹ ìwúyè rẹ̀ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'O yé kí ìbáṣepọ̀ Nàìjíríà àti UK dán mọ́rán síi lẹ́yìn àbẹ̀wò May' Igbesẹ̀ yii lo tẹ̀le ijakulẹ to ri nigba ti awọn ọmọ ile dibo lati maa ṣe atilẹyin fun adehun to ṣe pẹlu ajọ EU lori Brexit.
Ben Okri, to je akowe ami ẹyẹ Booker ni ''isẹ ọna yi je ọkan gbogi ti wọn se awari rẹ ni bii aadota ọdun sẹyin'' Oríṣun àwòrán, Bonhams Àkọlé àwòrán, Won yoo lu awon ise Ben Enwonu ni gbanjo ni Bonhams lojo kejidinlogbon osu keji ọdun 2018 O fi kun pe awari isẹ ọna naa ''pe fun ayo ati idunnu, igba iyipada lo si muba ise ona ''.
Iroyin ni ori ko David ati Jonathan yọ ninu ewu, ṣugbọn ọta ibọn ba Joseph lori.
Òpin ti dé Tán fún Israẹli.
Ọmọ ilẹ̀ Nàíjììrà kan tí ó fi orílẹ̀èdè náà ṣe ibùgbé, Clement Nwaogu ló ti pàdánù ẹ̀mí rẹ̀ lẹ́yìn tí àwọn ọmọ ilẹ̀ náà jóo níná láàyè.
Ó bá sọ fún gbogbo àwọn eniyan pé, “Bí ẹnikẹ́ni bá fẹ́ máa tẹ̀lé mí, ó níláti sẹ́ ara rẹ̀, kí ó gbé agbelebu rẹ̀ lojoojumọ, kí ó wá máa tọ̀ mí lẹ́yìn.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Supplementary Elections: Ganduje ní ìbò 1,033,695, tí alátakò rẹ̀ sì ní 1,024,713.
Dájúdájú, a óo gbé ère oriṣa náà lọ sí Asiria, a óo fi ṣe owó ìṣákọ́lẹ̀ fún ọba ńlá ibẹ̀.
Minisita fun eto ilẹra lorilẹede Naijiria, Dokita Osagie Ehanire lo kesi awọn ajọ naa lati pese ẹrọ ayẹwo Thermo Scanners ati awọn ohun elo idaabobo ara ẹni fun Naijiria.
Nibẹ ni awọn to n wa iṣẹ pẹlu ọlọpaa yoo fi awọn iroyin nipa ara wọn si .
Ijina sira ẹni yoo ṣe iranlọwọ lati kapa aarun coronavirus.
Àwọn ọmọ Lefi sì kó gbogbo wọn lọ dà sí odò Kidironi lẹ́yìn ìlú.
Oko oju ofurufu akero kan to gbera lojo Aiku ni Moscow ti ja, o ti gba emi awon eniyan mokanlelaadorin to wa ninu oko ofurufu naa.
Nígbà ti oníròyìn bèrè pé se ó lo fóònù náà o ní rárá àti pe irú iṣẹ́ wo ló n ṣe, Afurasi ọ̀hún ni òun kò tilẹ̀ mọ Iphone lò, ṣùgbọ́n òun fi síìmù òun sínú rẹ̀, àwọn ọ̀rẹ òun fi ya fọ́tọ̀, àti pé iṣẹ́ olóṣó ni òun ṣe.
Lọsẹ yii naa ni ileeṣẹ ologun ni Naijiria kede wi pe Gomina Ipinlẹ Eko, Babajide Fashola lo ran awọn lọ si Lekki Toll Gate lati lọ koju awọn afẹhọnuhan to wa nibẹ.
OLUWA ni ó fi agbára rẹ̀ dá ilé ayé,tí ó fi ìdí ayé múlẹ̀ pẹlu ìmọ̀ rẹ̀,ó sì fi òye rẹ̀ ta àwọn ọ̀run bí aṣọ.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ọbasanjọ sọ àsírí sàgbàdèwe rẹ̀ Jesu Oyingbo rèé, pásítọ̀ tó láṣẹ ìbálòpọ̀ lóri ọmọ ìjọ obìnrin Igbó mímu lè ṣe kóríyá, kò lé fi kún orín ẹnu òṣèré - 9ice Ìtàn tó wà nídi òwe ‘Sebótimọ Ẹlẹ́wà Sàpọ́n’ Ó tún tẹ̀ síwájú láti kẹ́kọ̀ọ́ ìmọ̀ okòwò àti ìṣèjọba ní àwọn ilé ẹ̀kọ́ gígá wọ̀nyìí: Kennedy School of Government Lagos Business School London Business School Àwọn ibi tó ti ṣiṣẹ́ Sanwo Olu bẹ̀rẹ̀ iṣẹ́ ṣíṣe ní ilé ìfowópamọ́ Lead Merchant Bank láàrin ọdún 1994 sí 1997 gẹ́gẹ́ bíì akápò.
Ẹgbẹ to n ṣiwaju ifẹhonuhan naa sọ ninu atẹjade kan pe ''ipenija ati wahala nla ni awọn afẹhonuhan to wa niwaju olu ileeṣẹ ologun n koju, nitori bi awọn ologun ṣe n gbiyanju lati le wọn kuro.
Awọn ti ọrọ naa soju wọn ni sadede ni awọn n gbọ igbe ti awọn eeyan si n sa asala ẹmi wọn.
O ni “Komisona awon olopaa ni ipinle Sokoto  ti fi awon olopaa si gbogbo awon ileto ati igberiko ipinle naa , lati ri i pe ipolongo naa lo ni irowo-irose.
Ìdí tí a fi ń ṣe làálàá nìyí, tí a sì ń jìjàkadì, nítorí a gbẹ́kẹ̀lé Ọlọrun alààyè, ẹni tí ó jẹ́ Olùgbàlà gbogbo eniyan, pàápàá jùlọ ti àwọn onigbagbọ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Mobile Wash: iṣẹ́ fífọ́ mọ́tò tà ni mó yàn láààyò- Slay Mama Ilé iṣẹ́ náà ni àwọn lo lárá ọ̀rọ̀ ti onkowe Naijiria kan Chimamanda Ngozi Adichie sàlàye pé àwọn èdè ti òun kọ wà lárá ìrírí to ti ri ni Naijiria.
Awọn ijọ ibilẹ naa niwọnyii: Ìjọba àpapọ̀ kò tíì fi ìlànà ṣíṣí iléèjọ́sìn ránṣẹ́ sí wa-Ẹgbẹ́ Mùsùlùmí tó ga jù ní Nàìjíríà, NSCIA Oríṣun àwòrán, Others Àkọlé àwòrán, Aarẹ orilẹede Naijiria, Muhammadu Buhari ti paṣẹ fun awọn ile ijọsin lati si pada lọna ati jẹ ki ofin konile-o-gbele rọlẹ.
O ni iṣẹ ti ẹgbẹ NURTW n ṣe ni ijọba gbẹsẹ le l'Oyo kii ṣe ẹgbẹ NURTW.
Orile-ede Sudan fesun kan orile-ede Egypt lori bi o se n dasi oro oselu won, bakan naa ni o fofin de gbigbe ohun ogbin orile-ede Egypt wo orile-ede Sudan lodun to koja.
"O tẹsiwaju pe ""Ina Naijiria n jo ajorẹyin ni, nitori ko si olori tuntun kankan to jẹ nilẹ yii ti asiko rẹ ko buru ju ti ẹni to jẹ ṣaaju rẹ lọ."
“Bí ó ti ń bọ̀ ní òkèèrè ni baba rẹ̀ ti rí i.
Wọn ni ki wọn o ma binu fun gbogbo inira ti eto naa le mu wa.
Gomina Ibrahim Gaidam ni isẹlẹ to sẹ lọsẹ to kọja naa waye lẹyin ọsẹ kan ti awọn alasẹ ileesẹ ologun ko awọn ọmọogun kuro ni ilu Dapchi nibi ti ileewe naa wa, lai jẹ wi pe wọn fi to ohun leti.
Ofin naa fi kun aato to ti gbigba awọn eeyan laye lati lọ bimọ lẹyin pe yoo boju to iwa ọdaran labẹle tabi tayọ orilẹede.
Pataki lara awọn ohun ti wọn sọ nibi ipade naa ni pe, awọn yoo fun awọn ara ilu lanfani lati gba ile ẹjọ lọ, ti alaye kankan nipa oludije ipo Aarẹ ati awọn to n du ipo ile asọfin agba ti wọn ba fi sita ninu iwe 'Form CF001' ko ba tẹ wọn lọrun.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Widows Day 2019: Mo máa ń sá kiri wá owó ilé ni -Opó Ṣugbọn, lati igba ti Ahmed ti de ipo ni ija ẹlẹyamẹya ti pada si Ethiopia, O to eniyan bi miliọnu meji aabọ ti wọn ti di alainilelori gẹgẹ bi akọsilẹ ajọ Iṣọkan Agbaye, UN, ṣe sọ.
Ẹ kò gbọ́ ọ rí,bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò mọ̀ ọ́n tẹ́lẹ̀.
Nítorí àwọn Sadusi sọ pé kò sí ajinde, bẹ́ẹ̀ ni kò sí angẹli tabi àwọn ẹ̀mí; ṣugbọn àwọn Farisi gbà pé mẹtẹẹta wà.
Gbà mí láàyè kí n bá àwọn eniyan sọ̀rọ̀.
"Ọmọwe Fayemi beere eyi lọwọ Daniel to si ni ""bẹẹ ni, mo ranti""."
 Ààrùn yìí mà ń fara hàn díè díẹ ̀ ni .
Kí alufaa sun wọ́n lórí pẹpẹ náà gẹ́gẹ́ bí ẹbọ sísun olóòórùn dídùn.
 Aare ati awon to tẹle fi papa
Aare Muhammadu Buhari ti ro igbimo tuntun ti o sese yan sipo lati mojuto awon ipinle ti o kogun si eka ariwa ila oorun orile-ede Naijiria lati bere si ni gbe awon igbese ti yoo mu ilosiwaju ohun idagbasoke ba awon ipinle mefa yii lai fi oro naa fale rara.
Esi idibo lawọn ipinlẹ mẹrin yoku ko tii jade, pẹlu iroyin obitibiti wahala awọn janduku atawọn iṣẹlẹ ipa miran to waye nibẹ.
Won wa pe minisita fun eto irinna Rotimi Amaechi lati kan si igbimo to n ri si eto irinna ati eyi to n ri si owo iya loke okun ati orile ede yii, lati  wa salaye lori awon esun  ti won fi kan an.
Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Border Closure: Ilé aṣòfin àpapọ̀ pàṣẹ fáwọn àṣọbodè láti fààyè gba èpo lẹ́nu bodè12 Bélú 2019 Majeobaje: Gómìnà, ẹ gbé owó ńlá fún Amotekun kó le dábírà lẹ́ka ètò ààbò18 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Kaduna, Zamfara àti àwọn ìpínlẹ̀ tó ti ilé ìwé nítorií wahala Boko Haram àti ìdí míràn.
Fun Norway Ati Denmark: Awọn Olootu ijọba obinrin mejeeji ṣiṣẹ to ya wọn sọtọ kuro pelu awọn akẹgbẹ ọn ọkunrin Wọn n pe ipade pajawiri pẹlu awọn akọroyin loorekoore Wọn n dahun ohun to yẹ to dabo ẹru obi lori awọn ọmọde lasiko Erna Solberg ati Mette Frederiksen tun n ṣepade pẹlu awọn ọmọde nigabgbogbo.
Nígbà tí wọ́n dé Jerusalẹmu, gbogbo ìjọ, ati àwọn aposteli ati àwọn àgbààgbà gbà wọ́n tọwọ́-tẹsẹ̀.
Ẹbọ ohun jíjẹ tí ẹ óo máa rú pẹlu wọn ni ìyẹ̀fun kíkúnná tí a fi òróró pò, ìdámẹ́wàá lọ́nà mẹta òṣùnwọ̀n efa fún akọ mààlúù kan, ìdámárùn-ún òṣùnwọ̀n efa fún àgbò kan; 
nígbà tí àwọn baba-ńlá yín dán mi wò,tí wọ́n fi rí iṣẹ́ mi fún ogoji ọdún.
OLUWA bá sọ fún Mose pé, “Wò ó, n óo rọ̀jò oúnjẹ fún yín láti ọ̀run.
Nitori eyi, awọn obinrin mejeeji sọ pe awọn ko le ṣiṣẹ ni oko ireke mọ.
A ṣi n ṣe akojọpọ iroyin naa ṣugbọn ni kete ti a ba ri aridaju bi nnkan ti ṣe ri, a o fi to yin leti.
Ìlúmọọka Olúsọagutan Simeon Ononogbu ní ẹmi ẹ̀tàn ló bàlé òun lásìkò ti òun n sọ àsọtẹ́lẹ̀ nipa ẹgbẹ agbabọọlu Super Falcons.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Kolawọle Ajeyẹmi: Ó yẹ ká ro ọjọ́ ìkúnlẹ̀ bímọ mọ́ aya lára lásìkò tó bá ṣẹ̀ wá 25 Ògún 2019 Oríṣun àwòrán, Instagram/KolawoleAjeyemi Obiri ti wọn n pe ni obinrin!
AMAA 2018 Ami eye awon onigege ara to dara julo
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, EndSars, EndSwat: Ọlọ́pàá ti fi ìbọn lù mí láyà rí torí mó ní 'extra tyre' méjì- afẹ́hònúh Ti were ba sun kan ogiri, were naa yoo pada, adia fun awakọ Uber to fesi pada pẹlu ẹṣẹ loju Mallet ti o si kan an mọlẹ.
" Ẹgbẹ̀rún lọ́nà mẹ́tàlẹ́láàádóje dọ́là ($133,000) sì ni owó ìtanràn fún ìyàwó tó bá dán àsà yìí wò.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ni ọdun 1968, aworan awọn ọmọde ti ebi n pa, ti awọ wọn si ri rada-rada gba ori awọn amohunmaworan nilẹ alawọ funfun.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Kini ọ̀nà àbáyọ sí ooru tó mú lásìkò yìí ní Nàìjíríà?
Yinusa ṣalaye pe ọkọ naa yọnu lọna, eyi si mu ki awọn (oun ati awọn oṣiṣẹ alaabo to tẹle ẹru) pinnu lati sun mọju si oju ọna.
Ileeṣẹ ọlọpaa ẹka to n gbogun ti awọn ajinigbe(kii ṣe SARS) lo n gbiyanju lati mu awọn afurasi ajininigbe kan lagbegbe Ijegun, lawọn afurasi ba doju ibọn ko awọn ọlọpaa.
Rose, ẹni to wa lati agbegbe Igbo nijọba ibilẹ Aniocha nipinlẹ Delta, lo tun jẹ gomina fun gbogbo awọn onitiata lede Yoruba nipinlẹ Oyo.
Alhaji Hamisu Wadume sálọ lásikò ti ọlapàá àti àwọn ọmọ ogun fija pẹ́ẹta ti ọlọpàá mẹ́ta àti àárá ìlú méji ti gbẹ̀mi mì ní Ibi, ìpiínlẹ̀ Taraba, lọ́jọ́ Iṣẹ́gun tó kọjá.
Jesu dá a lóhùn pé, “O ṣetán láti kú nítorí mi?
'Aarẹ Zuma gbọdọ lọ' Ọna wo ni Wenger ati Mugabe gba jọra?
Nǹkan Tí Ọlọ́gbọ́n Eniyan Ń Ṣe.
àtẹ́rígbà rẹ̀ jẹ́ igbọnwọ meji, mita kan.
Ó dá mi lójú pé kò sí ohun tí ó pamọ́ fún un ninu gbogbo ọ̀rọ̀ yìí.
Ọpọ ninu wọn ni wọn tun fi baalu gbe lọ si ilu Abuja nibi ti wọn yoo ti wa ni igbele fun ọjọ mẹrinla.
Amọṣa fun awọn eeyan bi @Kvngdvnni, @uzoakuchie, @chonsyy, @yinkanubi, ati omilẹgbẹ miran ko si ohun to bajẹ bi ẹgbẹ APC ba ri eniyan miran to mọọ ṣe ju gomina ambọde lọ.
Ọpọlọpọ àwọn eniyan náà, atọkunrin atobinrin, bẹ̀rẹ̀ sí tako àwọn Juu, arakunrin wọn.
Ọjọ́ kẹ́rin tí Orímóògùnjẹ́ mú owó kẹ́yìn nínú séèfù rẹ̀ ni ó kú.
Ìwọ náà kò sì gbọdọ̀ hùwà bí àwọn àgàbàgebè ọkùnrin tí àwọn obìnrin máa ń gbàdúrà rẹ̀ pé kí Ọlọ́run má ṣe jẹ́ kí ó dé sàkání àwọn.
 sítẹríọ ́ dù lè tète fa imúláradá fún àwọn tó ń lo egbògi apàkóràn lọ ́ wọ ́ .
Ọja Alaba nilu Ekọ njona Ọkọ̀ ojú irin pa ènìyàn mẹ́rin ní Eko Ambọde f'agbara fun ede Yoruba Kíni ìwọ mọ̀ nípa Funmilayọ Ransome-Kuti?
Mo ti gbógun tì ọ́, Ninefe,n óo ká aṣọ kúrò lára rẹ, n óo fi bò ọ́ lójú;n óo tú ọ sí ìhòòhò lójú àwọn orílẹ̀-èdè mìíràn.
Ìgbà tí ó bá si ń kọjá nígbà míràn tí ó bá tẹ fìlà náà siwájú kọ̀ǹgọ̀, eléyìínì a dà bí ìdí ọ̀pá ìtìlẹ̀, bẹ́ẹ̀ ni bí ó bá ń ṣe fáàrí nígbà míràn, òun a tẹ fìlà yí sí ẹ̀bá etí, eléyìínì a sì dà bí akèǹgbà orí ọ̀pẹ.
Kàkà bẹ́ẹ̀, ẹyọ ọmọ aguntan kan tí talaka yìí ní, ni olówó yìí gbà, tí ó sì pa ṣe àlejò.
Florence, ẹni to n sọrọ pẹlu ibinu salaye pe oun ko fi igba kankan kan si gomina Seyi Makinde tabi ẹnikẹni ninu awọn alasẹ ijọba l'Ọyọ lati beere iranwọ lasiko ti ọkọ oun wa lori aisan, eyi to ja si iku.
3M lórí ayélujára Ko pẹ ko jina ni elege ara, Samuel Chukwueze fọba lee fun ẹgbẹ agbabọọlu Super Eagles.
Wọn á gé igi ninu igbó,agbẹ́gilére á fi àáké gbẹ́ ẹ.
Ọpọlọpọ igba ni awọn ẹgbẹ okunkun ti ma n ja laarin ara wọn, Ohun ti o si mu ki awọn eniyan bẹru wọn ni wi pe wọn ma n lo ọna abalaye lati mulẹ ati lati ṣe ohun ti ko tọ laarin ara wọn.
Awọn darandaran fulani naa ni wọn ba dukia jẹ ti wọn si tun ti ina ile ni ileto naa ki ọwọ awọn ologun to tẹ wọn.
Kí Olódùmarè fún ọ ní ẹ̀mí gígùn; kí Ọlọ́run fún ọ ní ìbàlẹ̀ ọkàn; kí Ẹlẹ́dàá rẹ má ṣáì fi àlááfíà jíǹkí rẹ.
Nigba ti o n  sọrọ nibi ayẹyẹ naa, aare egbe UfUK , Kamil Kemanci
Ẹ gbọ́ èyí, ẹ̀yin tí ẹ̀ ń rẹ́ àwọn aláìní jẹ, tí ẹ múra láti pa àwọn talaka run lórí ilẹ̀ patapata.
Ọkùnrin náà sì bẹ̀rẹ̀ sí ọ̀rọ̀ rẹ̀, ó wípé:
Bí ọba náà ti ba ni lẹ́rù tó ni ó lẹ́wà tó, gbogbo ara rrẹ̀ ‘dabì ìgbà tí ogunlọ́gọ̀ òkúta olówó iyebíye bá wọ́ jọ pọ̀ sì ọ̀nà kan; nígbà tí Òjòlá-ìbínú kájọ tán, ó dàbí òkè kékeré kan.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ọlọ́pàá yìnbọn pa àgùnbánirọ̀ nígbà tó ku ọjọ́ méjì kó gbàwé ẹ̀rí 5 Agẹmo 2018 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 6 Agẹmo 2018 Oríṣun àwòrán, Igwetu Linda Nkechi/Facebook Àkọlé àwòrán, Linda Igwetu ti ọlọpàá yinbọn pa ni Abuja Òní ló yẹ ki Linda gba ìwé ẹ̀rí pé o parí àgùnbánirọ̀ rẹ.
Ta ló lè gun orí òkè OLUWA lọ?
'Ọdún 2018, àwọn gbajúgbajà tó ti lọ sinmi' 'Mo fẹ́ di àwòkọ́ṣe fáwọn ọ̀dọ́bìnrin tó n jà' Ẹ̀kọ́ mẹ́fà tó jáde nínú ìdíje Premier League òpin ọ̀sẹ̀ Alápinni: Àwọn tí kò kọ́ṣẹ́ tíátà n ṣàkóbá fún iṣẹ́ náà Seun sọrọ nipa bàtà ti Fela Anikulapo Kuti bọ silẹ nipa orin afro beat eyi ti gbogbo onkọrin naa lagbaye ti tẹsẹ bọ bayii.
Ọwọ́ ọlọ́pàá tẹ afurasí ọkùnrin tó gé akẹ́kọ̀ọ́ ọ̀rẹ́bìnrin rẹ̀ wẹ́lẹ́ wẹ́lẹ́ fún òògùn owó ní Ikorodu Áṣẹyin kìlọ̀ fáwọn adarí olóṣèlú Nàìjíríà láti ṣe ohun tó yẹ nítorí ará ọ̀run ń wò wọ́n!
Òkè-Àgbàá : Àdúgbò yìí wà láàárín gùn-gùn ìlú .
Bakan naa, o kọ ẹkọ sii ni Nigeria Military Training College, Kaduna laarin oṣu kọkanla dun 1963 si oṣu kinni ọdun 1964.
 tí wọ ́ n bá ko eré , ìṣẹ ̣ ̀ lẹ ̀ láwùjọ àti ọgbọ ́ n inú rẹ ̀ ní wọn ó kó jọ .
 O tesiwaju pe eto naa wa ni ibamu pẹle eto ti ijoba apapọ gunle.
Ẹ sin OLUWA pẹlu ẹwà mímọ́,
Yorùbá ma ńṣe ọdún Egúngún/Eégún ni ọdọ-dún lati ṣe iranti Bàbánlá/Ìyánlá wọn ti ó ti di olóògbé nitori wọn ni iṣẹ́ lati ṣe laarin alàyè lati rán ará ilú leti pé ki wọn di àjogúnbá ẹ̀kọ́ iwà rere mú.
Awọn ara ilu Mamu-Ijẹbu ni Ipinle Ogun lapa Iwọ-Oorun Gusu ni orilẹede Naijiria ti rọ ijọba ati awọn tọrọ kan gbogbo lati gba wọn lọwọ iya owọngogo omi laarin ilu.
Nigba to n bawọn akọroyin sọrọ, agbẹnusọ fun ikọ ologun oju omi to lewaju igbesẹ lile awọn eeyan agbegbe ọhun, Ọgagun Thomas Otuji salaye pe, awọn ọpa epo to n gbe epo wa silu Eko ati awọn etikun lo gba agbegbe ọhun kọja eyi ti wọn maa n fọ lojoojumọ.
Ẹwẹ, awọn aṣofin pariwo le Aarẹ Muhammadu Buhari lori lasiko to gbe aba owo iṣuna ọdun 2019 lọ siwaju apapọ ile aṣofin mejeeji lọjọ kọkandinlogun, oṣu Kejila ọdun 2018.
apeja ni ko le sise mo lataari oko oju omi won ti isele buruku naa ti baje.
Kọ arokọ ọ̀rọ̀ to to ẹẹdẹgbẹrin si ẹgbẹrun kan (800-1000 words) ranṣe lede Pidgin si bbcpidgin.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Coronavirus: Ọmọ márùn ún ni mo ní, ṣùgbọ́n kò sí oúnjẹ fún wa lásìkò ìgbélé yìí -Olùgbé ìlú Eko Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Coronavirus: Ọmọ márùn ún ni mo ní, ṣùgbọ́n kò sí oúnjẹ fún wa lásìkò ìgbélé yìí -Olùgbé ìlú Eko 4 Ìgbé 2020 Awọn olugbe ipinlẹ Eko ti rawọ ẹbẹ si ijọba ipinlẹ naa lati wa nkan ṣe si ọrọ igbele to wa lode nitori ebi.
Nígbà tí àwọn Lefi bá gbé àpótí náà wá fún àwọn òṣìṣẹ́ ọba, tí wọ́n sì rí i pé owó pọ̀ ninu rẹ̀, akọ̀wé ọba ati aṣojú olórí alufaa yóo da owó kúrò ninu àpótí, wọn yóo sì gbé e pada sí ààyè rẹ̀.
BBC News Yoruba gba lalejo loju opo Facebook Live ti o si yanana ọrọ lori awọn ohun to ni ṣe pẹlu ere sinima ni Naijiria.
 Ọrọ yii lo mu ki awọn eeyan bu sẹrin ayọ, ti wọn si patẹwọ, bẹẹ ni wọn n juwọ si ibi Olubadan ati awọn ijoye rẹ naa joko si."
Lẹyin naa lo tẹwọ gba asia tuntun lati ṣilẹkun fun saa rẹ keji, to si rin kiri ninu ọkọ ni eto iburawọle naa wa si opin.
Wọn 'ti awọn ọmọ orilẹede Somalia inu iboji' ni Ethiopia Kinni iroyin naa?
K’ákú sí ogun ṣàgbà kí wọ́n múni l’ẹ́rú
Bí ẹ ti ní ìmọ̀, bẹ́ẹ̀ ni èmi náà ní,ẹ kò sàn jù mí lọ.
"A ti pariwo títí fún ìjọba, wọn kò gbọ, Nàìjíríà kò sì ní àkọsílẹ̀ gidi.
Owoyaa yii, eyiti ijọba apapọ n pin fun awọn ontaja jake-jado orilẹ-ede yii, ni wọn ko beere ohunkohun lọwọ wọn gẹgẹ iduro ki wọn to fun wọn.
Ìwọ arẹwà jùlọ láàrin àwọn obinrin?
 Ebola sẹ́yọ ní DR Congo 'Àwọn Dókítà fẹ́ kẹ́yin s'awọ̀n alárùn lassa' WHO yoo kapa aisan Lassa Fever Ẹ ó rántí wípé ní ọdún 2014 ni Ebola wọ orílẹ̀èdè Nàìjíríà láti ọwọ́ arákùnrin ọmọ Sierra Leone kan, Patrick Sawyer tí ó gbe àìsàn náà wá láti orílẹ̀èdè rẹ̀."
Ijiroro naa da le owo oṣu awọn oṣiṣẹ oni ipele mejila ni eyi ti wọn ko fẹnuko le lori.
”O wa ro awon omo orile ede Naijiria lati fowosowopo pelu aare Muhammadu Buhari lati gbe orile ede yii lo sibi giga.
Ọpọ awọn oludibo nilẹ Amẹrika ni yoo maa retin esi ibo ti wọn di lọjọ ti idibo naa ba waye, ṣugbọn ibeere ti ọpọ eeyan maa n bereni pe igba wo gan ni esi na yo jade?
Ǹjẹ́ mo hu irú ìwà báyìí sí ọ rí?
67 biliọnù owó òúnjẹ àwọn akẹkọọ tí ICPC ní wọn se mọkumọku Iroyin to n tan kaakiri ni pe alaga àjọ to n gbogún ti iwà ibajẹ ICPC ni awọn osisẹ ijaba kan ti lu owo ounje awọn akẹkọọ ni ponpo.
Iyaafin Ambode se lalaye pe, omi oyan se koko nitori pe, yoo sise gege bi abere ajesara lara omo oojo nigba akoko, yoo si tun ran awon eya inu ara omo naa lowo lopolopo.
Dá mi sí kí n lè máa yìn ọ́,sì jẹ́ kí òfin rẹ ràn mí lọ́wọ́.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, BBC Gov Debates: Ètò ẹ̀kọ́ ọ̀fẹ́ ni àwọn olùdíje yóò ṣe Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Ó fi ọ̀já wúrà gba àyà.
Ìgbà tí ènìyàn bá sì tilẹ̀ dúrósí etí odò Ọ̀jọ̀ pàápàá báyìí tí ó wo inú odò, ohun tí ojú rí kò mọ nìba.
Ọmọdé tó ń ṣeré pẹ̀lú àdò olóró ló fa ìbúgbàmu Borno- Cameroon Wọ́n tẹ àádọ́ta olùdárò pa níbi ìsìnkú Qasem Soleimani tí kò wáyé mọ́ Àbọ̀ ìpàdé bòńkẹ́lẹ́ láàrin Tinubu àti Buhari rèé Ẹ́ gba fóónù, ẹ pe ẹbí yín pé a fẹ́ dáná ṣun yín - Aráàlú sọ fún adigunjalè méji Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ojú mi ti rí lọ́pọ̀ lọpọ̀, àmọ́ mo dúpẹ́ pé mo ti pé ọdún márùn ún lórí oyé- Ooni Awọn mẹtẹẹta ti wa ni ile iwosan bayii nibi ti wọn ti n gba itọju fun ara wọn.
Wọ́n rọ̀ wá kí á dúró lọ́dọ̀ wọn, a bá ṣe ọ̀sẹ̀ kan níbẹ̀.
Bí n kò bá mú un pada, kí n sì fà á lé ọ lọ́wọ́, da ẹ̀bi rẹ̀ lé mi lórí títí lae, 
O kesi ijọba pe kii ṣe atunto ileeṣẹ ọlọpaa nikan ni ko mojuto, o ni o pa dandan lati la oju awọn ọlọpaa si bo ṣe yẹ ki wọn o ma a ṣe iṣẹ wọn ni ilana igbalode.
Aláìlóye ni àwọn tí ń gbẹ́ ère igi lásán kiri,tí wọ́n sì ń gbadurasí oriṣa tí kò lè gbànìyàn là.
Ẹyin naa ẹ wo fidio yi, ori yin yoo wu pupọ nipa awọn ọdọ naa.
" Àkọlé àwòrán, Ẹgbẹ osisẹ fẹ ri i daju pe wọn gbe aba sisan owo osu naa lọ sile asofin apapọ lati buwọlu, ki owo Àkọlé àwòrán, Ẹgbẹ osisẹ fẹ ri i daju pe wọn gbe aba sisan owo osu naa lọ sile asofin apapọ lati buwọlu Àkọlé àwòrán, Awọn ọmọ ẹgbẹ́ kọ̀jálẹ̀ pé àfi kí ìjọba gbọ́ ohun ti awọ́n ń jà fún owó [sṣù Àkọlé àwòrán, Dokita Chris Ngige salaye pe, oun to mumu julọ laya aarẹ Muhammadu Buhari bayii ni sisan owo osu tuntun fawọn osisẹ ilẹ yii BBC News, Yorùbá Ìdí tí ẹ fi le è nígbàagbọ́ nínú ìròyìn BBC Ìlànà Lílò Nípa BBC Òfin Àṣírí Cookies Kàn sí.
Ninu ọdun 2017, ajọ ilera agbaye woye pe o le ni ẹgbrun mẹrinlelaadọrin awọn ọmọde ti ọjọ ori wọn ko ju ọdun marun lọ ti aisan igbẹ gbuuru ti ran lọ sọrun.
 o je onilese okowo ti o to bilionu naira ati aare fun ipinle eko .
Awọn  mẹ́rìndínlọ́gbọ̀n ni yoo maa dije fun ipo gomina lọjọ Abamẹta yii ni
O jẹ ọjọ ti wọn maa n ṣe paṣipaarọ ẹbun laarin awọn Kristiẹni.
Gbọ́ ariwo lórí òkè, bí ohùn ọ̀pọ̀ eniyan,gbọ́ ariwo ìdàrúdàpọ̀ ìjọba àwọn orílẹ̀-èdè tí ó ń péjọ pọ̀!
 alamojuto  ajo INEC ni Ipinle Oyo,
jẹ olu-ilu ipinle  Cross River, ni ekun
Bi o ba wa kẹẹfin pe o ni arun yii, awọn igbesẹ ti o lee gbe wa ninu fọnran fidio yii.
 bákan náà ni ipa ti brazil ko nípa èdè àti àṣà afíríkà kìí se kèrémí .
Sugbọn iyemeji ati ipaya ko le salai maa waye.
O tenumo pe, “inu oun dun lati darapo mo awon onigbagbo lokunrin ati lobinrin fun ayeye odun ajinde ti odun 2018 yii.
 Wayii o, tẹrin-tọyaya ni aarẹ orilẹ-ede
Lara awon ise lorisirisi ti won gbese lojo naa ni: oro iyanju lati enu adari ijoba ati awon toro kan gbongbon lorile-ede naa, bee si ni iwode awon omo ogun naa ko gbeyin kakaakiri agbegbe lorile-ede naa.
Ifesewonse ohun yoo maa waye ni papa isere Municipal, Wroclaw.
Oluọmọ, Aṣofin Adebọ Ogundoyin ti Ipinlẹ Ekiti, Aṣofin
Fidio to lu ayelujara pa fihan pe Blake ko gbe ibọn dani, ṣugbọn awọn ọlọpaa tun yinbọn fún un nigba meje lati ẹyin.
Kò sí ọ̀tá àbí ọ̀rẹ́ nínú òṣèlú.
Ó ní, “Ẹ kọ orúkọ ọkunrin yìí sílẹ̀ gẹ́gẹ́ bí aláìlọ́mọ,ẹni tí kò ní ṣe rere kan ní gbogbo ọjọ́ ayé rẹ̀;nítorí pé kò sí ọ̀kankan ninu àwọn ọmọ rẹ̀tí yóo rọ́pò rẹ̀ lórí ìtẹ́ Dafidi,Ìdílé rẹ̀ kò sì ní jọba mọ ní Juda.
O mẹnuba bi oun ṣe jogunba iṣẹ ẹṣa pipe lati ọdọ baba oun.
Wọn ni ijọba to wa lode nipinlẹ Kwara n fi ibi su oloore pẹlu bi o ṣe wo ile arugbo lulẹ.
Jẹ́ kí inú ọ̀run ó dùn, sì jẹ́ kí ayé ó yọ̀;kí òkun ó hó, ati gbogbo ohun tí ó wà ninu rẹ̀.
Wọn un ní ìdí míràn tún ni pé ọ́wọ́ Atiku kò mọ ti ọ̀pọ̀ ọmọ Nàijiriia si mọ, pàápàá julọ àríwísi pé láti ìgbà to tí ń sisẹ ìjọba gẹ́gẹ́ bii aṣọ́bode ló ni owo tabua, ọ̀ps ló fẹ́ mọ ọ̀nà to gbà ri owo náà sùgbọ́n ti kò le sàlàyé.
Adari agba nile-ise awon agbonfinro ohun, Ronald dela Rosa so pe,“A n se iwadi lowo labele lati tun mo ibasepo tabi awon orile-ede ile-okere miran ti won ti n ko awon omo-ogun olote jo,”Rosa fikun oro re pe,”alabasisepo agbafinro ile-okere kan lo so awon eri kookan fun wa nipa Lassoued ati awon ise re to n gbese.
Ọjọgbọn Abayọmi ni ayẹwo mọkandinlogun ni wọn ṣe lori awọn ti wọn funrasi pe wọn ni aarun naa atawọn eeyan to ni nnkan pọ pẹlu awọn awọn marun ti wọn kede pe wọn ni arun naa lọjọru.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù World No Tobacco Day: Bí sìgá mímu ṣe kúrò ní òògun ìlera di ewu ńlá 31 Èbibi 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Onimọ ilera ọmọ Netherlands kan Everard gbagbọ pe taba lagbara to bẹẹ ti ko ni jẹ ki awọn dokita riṣẹ ṣe Tábà wúlò púpọ̀ fún ìlera ẹ̀dá -Everad.
Abẹ́ ìyẹ́ apá OLUWA Ọlọrun Israẹli ni o wá, fún ààbò, yóo sì fún ọ ní èrè kíkún.
 Ìlú kékeré kan ní awọn orílẹ ̀ -èdè méjèèjì yìí ń jà lé lórí .
Ẹ wo ọ̀nà àbáyọ sí ọ̀rọ̀ àgbàlagbà tò ń tọ̀ sílé Amọ, gomina Sanwo-Olu rọ awọn eniyan lati tẹle ofin ijinasiraẹni ati fifọ ọwọ loore koore, lọna ati dẹkun itankalẹ arun Coronavirus.
 oríṣi mẹta àjàkálẹ ̀ àrùn náà ni ó ti wáyé láìpẹ ́ : ọ ̀ kan láti ọdún 1896 sí 1906 ní orílẹ ̀ -èdè uganda àti adágùn omi kongo nìkan , àti méjì ní ọdún 1920 àti 1970 ní ọ ̀ pọ ̀ lọpọ ̀ àwọn orílẹ ̀ -èdè afrika mìíràn .
Eyi waye lẹyin ti wọn ti fi ẹsẹ mulẹ lorilẹ-ede Iraq àti Syria.
Sanwo-olu gbé ìwé ẹ̀dùn ọkàn olùwọ́de ENDSARS lé Buhari lọ́wọ́ Ọlọ́pàá méjì dèrò ọ̀run nínú ìjàmbá ọkọ̀ l'Akure lẹ́yìn tí wọ́n kúrò níbi tí Akeredolu ti gba ìwé-ẹ̀ri moyege Ìwọ́de 'End SARS' lè tan àjàkálẹ̀ arùn coronavirus lẹ́ẹ̀kejì ní Nàìjíríà- Ọjọ̀gbọ́n Faduyile Èèyàn 225 ló tún ṣẹ̀ṣẹ̀ ní àrùn Coronavirus ní Nàìjíríà Mo ṣèlérí láti ṣe ju ohun tí mo ti ṣe lọ fún ẹbí àwọn tó kú torí EndSARS - Seyi Makinde Adamu ni gbogbo awọn ti yoo ba gba iṣẹ labẹ ikọ yi yoo ni lati ṣe ayẹwo ọpọlọ ti wọn yoo si bẹrẹ igbaradi ni ọṣẹ to n bọ.
Àkókò tí wọ́n kú yìí jẹ́ àkókò ìbẹ̀rẹ̀ ìkórè ọkà baali nígbà tí àkókò ìrúwé fẹ́rẹ̀ kásẹ̀ nílẹ̀.
 Osaka salaye pe,“Mo mo daju pe, opo oluworan lo n patewo fun Williams, sugbon iyalenu lo je ibi ti ifigagbaga naa gba yo si won,”“Mo kan fe so pe, ese pupo fun pe e wa wo ifigagbaga yii.
Oun ni aarẹ akọkọ ti wọn dibo yan lorilẹ-ede Egypt.
Ijọba ipinlẹ Kwara ni awọn ohun iranwọ Covid-19 naa wa nibẹ nitori ijọba apapọ ṣẹṣẹ fi sọwọ si wọn ni ipinlẹ naa ni.
Hajar Raissouni ni akọroyin Morocco ti awọn alaṣẹ ilẹ Morocco fẹsun kan pe o ṣeyun ati pe o ṣe agbere.
Orúkọ aya Amramu ni Jokebedi, ọmọbinrin Lefi tí ìyá rẹ̀ bí fún Lefi ní Ijipti.
Oríṣun àwòrán, @bASIR aHMAD Àkọlé àwòrán, Ọga ọlọpaa tuntun ati Aarẹ Buhari Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Tani DCP Kayọde Ẹgbẹdokun, ọ̀gá ọlọ́pàá tuntun ní ìpínlẹ̀ Eko?
Eto iforuko sile yii ni won ri gege bi igbese pata ki lati seto idibo, amo, a si ni awon idena pepepe bi eto oselu, ile-ise ologun ati ofin ti o le je idiwo fun eto idibo gbogbogbo, ati nipa sise amulo akotun ilana ofin ati ofin eto idibo.
Brexit: Boris Johnson ṣèlérí láti mú UK kúrò ní àjọ̀ ìṣọ̀kan Gẹ̀ẹ́sì tiku-tiye
Pilatu wá sọ fún àwọn olórí alufaa ati àwọn eniyan pé, “Èmi kò rí àìdára kan tí ọkunrin yìí ṣe.
Afojusun rẹ ni lati di oniṣẹ adani, ati olokoowo katakara ile ati ilẹ.
Bakan naa ni awọn eniyan lori ẹrọ ayelujara ti bẹrẹ si ni fesi si aṣọ ilẹ Ghana ti awọn aṣofin naa wọ lọ si ile aṣofin naa.
Mo wá ti di ọ̀tá yín nítorí mo sọ òtítọ́ fun yín!
Okei-Odumakin: Awọn obinrin Naijiria nilo ajọ iranwọ fun oṣelu'
Ṣugbọn àwọn eniyan wọnyi a máa sọ ìsọkúsọ nípa ohunkohun tí kò bá ti yé wọn.
Bakanna nile iṣẹ ọlọpaa tun sọ pe aworan awọn ẹlẹwọn ti wọn sa kuro lọgba ẹwọn Oko niluu Benin lasiko iwọde EndSARS kii ṣe ayederu fọto.
Nípa ti arakunrin wa Apolo, mo gbà á níyànjú gidigidi pé kí ó wá sọ́dọ̀ yín pẹlu àwọn arakunrin yòókù.
 Ó ní túbọ ̀ mu ó sì máa ń fi ọwọ ́ pa á .
Minisita fun eto ilẹra naa ni awọn n ṣe ilanilọyẹ fun awọn eniyan wọn lori ri wi pe wọn koju aarun naa lọkunkundun.
Ó pada wálé wá sọ fún baba ati ìyá rẹ̀, ó ní, “Mo rí ọ̀kan ninu àwọn ọmọbinrin ará Filistia ní Timna, ó wù mí, ẹ jọ̀wọ́, ẹ fẹ́ ẹ fún mi.
Wọn tu u yan spo gẹgẹ bi aarẹ ni ọdun 2001, 2006, 2011 ki o to padanu idibo aarẹ fun Adama Barrow lọdun 2016.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Àyà mi kọ́kọ́ máa ń já nígbà ti mo ṣẹ̀ṣẹ̀ bẹ̀rẹ̀ -Alaga iduro ọkùnrin Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
#67yearoldmother: Mo kojú ọ̀pọ̀lọpọ̀ àìsàn fún ọdún 35 lẹ̀yín ìgbéyàwò
 A fẹ ki gbogbo eniyan mọ pe ohun ti o n fa ikunsinu
OLUWA pa àṣẹ yìí kí àwọn ọmọ Israẹli lè máa mú ẹran ìrúbọ tí wọ́n bá pa ninu pápá wá fún OLUWA, kí wọn mú un tọ alufaa wá lẹ́nu ọ̀nà Àgọ́ Àjọ, kí wọn sì pa á láti fi rú ẹbọ alaafia sí OLUWA.
Ẹfunsetan Aniwura, obìnrin tó ju ọkùnrin lọ Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí EndSARS Protest Update: Aisha Yesufu ní Buhari jẹ́wọ́ pé òun kò láànú aráàlú nínú ọ̀rọ̀ rẹ̀23 Ọ̀wàrà 2020 Fídíò, Wole Soyinka sọ ìdí tó fi ni òun a fi màálù Fulani ṣe súyà fáwọn èèyàn abúlé23 Owewe 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
A ba jẹ obinrin, tabi ọkunrin, o yẹ ka ranti pe isẹ ọwọ wa, yoo maa tọ wa lẹyin ta ba lọ tan.
Yatọ si awọn ere itage ti Ajirebi ti se, eyi to fun ni okiki, awọn isẹlẹ kan to maa n waye nipa rẹ lasiko ojo lọdọọdun gan tun n mu ki Ajirebi wọnu iroyin.
Bakan naa ni iru ẹni bẹẹ yoo ṣafihan ẹẹdẹgbẹta owo dọla tikẹẹti ipada sile.
 Bi adinku se de ba iwon epo robi ti awon orile ede kan n ta si orile ede miiran tun je ki owo ori epo robi  tun goke si i.
Láti ọjọ́ náà ni àwọn ọmọ ogun Siria kò ti gbógun ti ilẹ̀ Israẹli mọ́.
NNPC: Buhari yan Kyari ní olùdarí tuntun fún àjọ NNPC
Owó Òṣúnlékè ni ó ti rà á.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ààrẹ orílẹ̀-èdè Algeria Abdulaziz Bouteflika ti kọ̀wé fipo silẹ̀ 2 Ìgbé 2019 Àkọlé àwòrán, Aàrẹ orill-èdè Algeria to tin wa lori oye lati ọdun 1999 Ààrẹ orilẹ̀-èdè Algeria Abdulaziz Bouteflika ti kowe fipo silẹ lẹ́yin ifẹhonu han ọlọjọ gbọ́ọ́rọ Bouteflika tó ti wa lori ipo gẹ́gẹ́ bii ààrẹ láti ogun ọdun sẹyin ti fi èrongba ati di ààrẹ niẹ̀ẹ̀kaarun kálẹ si ẹgbẹ́ kan lẹ́yin ti àwọn ọdọ orilẹ̀-èdè Algeria dide lódi si ìpinu rẹ.
Amaechi pa asẹ yii ni Ọjọbo lasiko to n wọ ọkọ reluwe lori oju irin Ibadan si Eko ti wọn n se lọwọ, eyi ti yoo gba Abeokuta, Ibadan ati Eko.
Ipò kíní ré sórí ìpínlẹ̀ Plateau!
Ask me Share this Explainer Kí ní ìdi ti Super Tuesday fi ṣe kókó?
Ojogbon Fuwape, leni ti o tun je oga agba ile-iwe giga fafiti onimo-ero, Federal University of Technology, niluu Akure, so pe ibo ti o wa laarin egbe oselu mejeeji ti o n gbe igba oroke lowo kere si apapo ibo ti won fagile.
Bí wọn kò bá yipada, Ọlọrun yóo pọ́n idà rẹ̀;ó ti tẹ ọrun rẹ̀, ó sì ti fi ọfà lé e.
Awọn kan mẹnu ba bi awọn adari ẹsin kan bi David Oyedepo,Sheikh Ahmad Gumi ati Bisọọbu Mathew Kuka ti ṣe kọwọrin lọ ọ ba Atiku pari aawọ laarin oun ati Obasanjọ L'ọjọbọ ni Atiku Abubakar tii ṣe oludije fun ipo aarẹ labẹ asia ẹgbẹ oṣelu Peoples Democratic Party, PDP, Atiku Abubakar, gunlẹ si ile aarẹ ana l'orilẹede yii, Oloye Oluṣẹgun Ọbasanjọ ni nkan bi aago kan ọsan.
Oríṣun àwòrán, ayaba_folashade Àkọlé àwòrán, Alaafin ati awọn 'Ẹlẹ Daddy' ninu aṣọ ankoo Olori Folashade sọ pe, iroyin ko to afojuba ni ọrọ bi Alaafin ṣe mọ ikẹ ati igẹ obinrin ṣe to.
Tọkọ-taya wọ gàù nítorí orúkọ tí wọ́n sọ ọmọ wọn Ilé ẹjọ́ ju ọmọ ọdọ tí wọ́n ló pa Ọpe Bademosi s'ẹ́wọ̀n' Àpanisáyé ni ẹ̀wà tí wọ́n n fi 'sniper' pa Iru ipa wo ni iroyin yii ni?
Níbẹ̀ ni Miriamu kú sí, tí wọn sì sin ín sí.
Lootọọ oke okun ni awọn mẹtẹẹta fi ṣe ibugbe, amọ ko si ẹni to gbagbe orilẹede Naijiria gẹgẹ bi orirun wọn, ninu awọn mẹtẹẹta.
Ijegun Fire: Ẹ̀gbà ọrùn ni wọ́n fi dá òkú ẹnìkan mọ̀ níbi ìṣẹ̀lẹ̀ iná Ijegun
”Saulu ati Samuẹli bá jọ jẹun pọ̀ ní ọjọ́ náà.
Wọn ṣalaye pe o ṣe anfani fun adugbo, fun ile iwe koda, ati fun awọn ile iṣẹ to n ṣe atunlo rẹ.
Aṣoju ajọ to n ri si eto Haji ni Naijiria, Dokita Tanko Aliyu lo fọrọ naa lede niluu Muna.
Wéré gbogbo ẹ̀dá alààyè bẹ̀rẹ̀ si i jó, erin jó titi ó tẹ ọ̀pọ̀lọpọ̀ ẹranko pa, àwọn ọbọ jó wọ́n tàkìtì àti iwin àti ọdẹ bẹ̀rẹ̀ sii gbé onírúurú ẹsẹ̀ ijó lójú oggun.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Fulani Heardsmen: Afenifere ní àṣẹ tó bá wu àwọn àgbààgbà agbègbè àríwá Nàìjíríà kí wọ́n pa Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Fulani Heardsmen: Afenifere ní àṣẹ tó bá wu àwọn àgbààgbà agbègbè àríwá Nàìjíríà kí wọ́n pa 17 Agẹmo 2019 Afenifere ní 'Rakatia' ni ìpè àwọn àgbààgbà agbègbè àríwá Nàìjíríà tó ní kawọn darandaran ó padà wálé Ẹgbẹ awọn agba loke ọya Naijiria, Northern Elders Forum (NEF) atawọn agbarijọpọ ẹgbẹ kan nibẹ paṣẹ fun awọn darandaran fulani ti wọn wa ni apa guusu orilẹ-ede Naijiria lati tete dari pada si oke ọya.
Gẹgẹ bii alaye olukọ, Silebu ni ọrọ tabi ege ọrọ ti eemi le gbe jade lati ẹnu ni ẹẹkan soso laisi isoro kankan.
lorile ede Naijiria, Adamu Mohammed wa si imusẹ.
Oríṣun àwòrán, Getty Images O ni bi wọn ba si rii pe ẹnikẹni ninu wọn kuna ti koju osuwọn, ijọba yoo gba iwe aṣẹ iṣiṣẹ lọwọ wọn.
Ẹ kí ìjọ tí ó wà ní ilé wọn náà.
Ọmọọba ilẹ̀ Gẹ̀ẹ́sì bí ọmọ ọkùnrin Ojú ń tì mí láti rí àwọn ọmọbìnrin Nàìjíríà tó ń ṣe aṣẹ́wó ní Italy"" Ramadan: Béèrè lọ́wọ́ onímọ̀ nípa òunjẹ́ kóo tó ṣínu ààwẹ̀ Ninu ifọrọwerọ rẹ pẹlu BBC news Yoruba, alukoro ileewe fasiti OAU, Abiọdun Olarewaju ṣalaye pe ni nnkan bi agogo mẹjọ abọ si mẹsan alẹ ọjọ aiku ni wọn ji ọjọgbọn naa gbe."
Ondo ni mo ti kọ iṣẹ.
Nigba aye rẹ, o gba bọọlu fún ẹgbẹ agbabọọlu Barcelona àti Napoli ó si gba ife ẹyẹ pelu lẹẹmeji ni Serie A.
Nítorí náà, gbọ́ ohun tí OLUWA sọ: ‘Iyawo rẹ yóo di aṣẹ́wó láàrin ìlú, àwọn ọmọ rẹ lọkunrin ati lobinrin yóo kú sójú ogun, a óo pín ilẹ̀ rẹ fún àwọn ẹlòmíràn; ìwọ pàápàá yóo sì kú sí ilẹ̀ àwọn alaigbagbọ; láìṣe àní àní, a óo kó àwọn ọmọ Israẹli lọ sí ìgbèkùn.
Ṣé Èdùà dá ààtàn isó ni?
Igbesẹ naa bẹrẹ lopin ọsẹ lẹyin ti awọn kan bẹrẹ si n ke pe awọn ọdọ Naijiria lati lọ fopin si idunadura laarin wọn ati ile ifowopamọ naa.
Ní àkótán: ara ò rọ ìjọba!
Amọ fawọn tọkọtaya kan nilẹ Amerika,idunnu ṣebi ẹni dara pọ mọ iyalẹnu nigba ti wọn bi ọmọ wọn lọjọ kẹsan (ayajọ 9/11) osu kọkanla, laago mẹsan kọja iṣẹju mọkanla.
Omololu Olunloyo ni aya, tí sì bí ọpọ ọmọ nínú èyí ta ti ri gbajumọ akọroyin obìnrin kan, Kemi Omololu Olunloyo.
Osu kẹjọ ọdun 2018 ni wọn ti se ipade kẹyin, ti ẹka alasẹ to yẹ ko maa se amusẹ ipinnu ti igbimọ alakoso ba se, ti wa ja agbara gba mọ igbimọ alakoso ẹgbẹ lọwọ.
Sa gbogbo ipá rẹ láti tètè wá sọ́dọ̀ mi.
Awon agbebon kan ti won ko mo, ti sekupa okan lara osise ajo t n ri si eto ilera lagbaye World Health Organization (WHO), lojo isegun(Tuesday).
"@TifeOfficial nitirẹ kọọ pe ""tẹlẹ, o yẹ kawọn obinrin maa tẹriba fun awọn ọkọ wọn."
Ọpọ aseyọri ni Ọba Seriki Abass Williams se lasiko to wa lori loke eepẹ, lara wọn si ree: Aseyọri Ọba Seriki Abass Williams: O pin erekusu Gerefu si wẹwẹẹ lọdun 1882 Oyinbo amunisin, ọgagun J.
(Mò ń sọ̀rọ̀ bí ẹni pé eniyan ni Ọlọrun.
Àwọn alufaa kò gbọdọ̀ jẹ ohunkohun tí ó bá kú fúnrarẹ̀ tabi tí ẹranko burúkú bá pa, kì báà jẹ́ ẹyẹ tabi ẹranko.
Ojú yóo sì tì yín fún àwọn ọgbà oriṣa tí ẹ yàn.
Àyíká rẹ̀ sì jẹ́ ọgbọ̀n igbọnwọ.
Ọdun 1988 ni o kẹkọọ gboye ninu imọ iṣegun oyinbo ati iṣẹ abẹ.
Oju opo ikansiraẹni Twitter gomina naa ni o ti fi lede wi pe oun ti sọ Amọtẹkun di ofin ni ipinlẹ naa.
Láìṣe-àní-àní, ọ̀spọ̀lọpọ̀ ìyọnu ni ìwọ o ti bá pàdé ṣùgbọ́n mo rò pé o kò ní í gbàgbé gbogbo ìmọ̀ràn tí mo tí máa ń fún ọ nígbà tí ìwọ wà lọ́dọ̀ mi wí pé, kí o tóó lè borí ayé àwọn nǹkan méje pàtàkì ni o níláti ṣe.
O fi kun ọrọ rẹ pe o tun ṣe koko lati din iyato to wa laarin owo oṣu ọkunrin ati obinrin ku lagbaye.
Gomina Obaseki sọrọ yii lasiko to n jẹri nibi akanṣe eto ọlọdọọdun ijọ Redeem, RCCG Holy Ghost Congress ti ọdun 2020 yii lọjọ Ẹti.
Wọ́n fi kun pe o ṣe pataki ki wan pada si ìlàna ẹkọ 9-3-4 gẹ́gẹ́ bi àwọn onímọ ètò ẹkọ ṣe gbé kalẹ̀.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Coronavirus symptoms: Kí ni àwọn àpẹẹrẹ àrùn yìí, àti pé báwo ni mo ṣe leè dáàbò bo ara mi?
 Àwọn tí wọ ́ n ń sọ ọ ́ jẹ ́ mílíọ ̀ nù méje ọ ̀ pọ ̀ lọpọ ̀ àwọn tí wọ ́ n kó ní ẹrú ní ilẹ ̀ afíríkà tí wọ ́ n sì tà wọ ́ n fún america ni wọ ́ n ń sọ èdè yìí .
Adehun ti awọn ajẹ ṣe nigba ti wọn n bọ si aye ni pe, gbogbo eeyan yoo ma a gbe pọ ni alaafia, ṣugbọn, ọmọ eeyan lo kọkọ yẹ adehun.
O ti ṣiṣẹ ni ọpọlọpọ ẹka imọ ẹrọ ati awọn ile iṣẹ epo bẹntiroo ati afẹfẹ gaasi lorileede Naijiria ati loke okun.
Lẹ́yìn náà ó fara han àwọn mọkanla bí wọ́n ti ń jẹun.
Àbí ẹ̀yìn àwọn ará Juda ni ẹ rò pé mo wà ni?
Bí Jakọbu ti ń lọ ní ojú ọ̀nà, àwọn angẹli Ọlọrun pàdé rẹ̀.
Ọmọ ilu Daura ni, ibẹ lo si ti lo pupọ ninu igbesi aye rẹ.
A gbọ́ pé gbogbo àwọn èèyàn àti ọkọ̀ náà ló jóná di eérú.
Ko si idi meji lori eyi ju pe sunkẹrẹ fakẹrẹ ọkọ lo n jọba l'Eko.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Urueme Adu: Àìsí àfojúsùn mú eléré ìdárayá sá lọ 12 Ìgbé 2018 Oríṣun àwòrán, ANDREJ ISAKOVIC/GETTY Àkọlé àwòrán, Awọn ikọ eléré ìdárayá ọmọ orílẹ̀èdè Naijiria ni Rio Olympics Laipẹ yi ni iroyin gbálè kàn pe awọn eléré ìdárayá ọmọ orílẹ̀-èdè Cameroon ti won kopa nínú ìdíje Commonwealth salọ nilẹ Australia.
Bí ó bá jẹ́ pé o fẹ́ ẹbọ ni, ǹ bá mú wá fún ọ;ṣugbọn o ò tilẹ̀ fẹ́ ẹbọ sísun.
Ibẹ̀ ni yóo wà fún àwọn ọmọ Lefi tí wọn ń ṣiṣẹ́ ninu tẹmpili, ibẹ̀ ni wọn óo máa gbé.
O ni eleyi mu ki a beere wi pe kini eeyan gbodo ṣe ''ki awọn akoroyin to mu kikọ iroyin nipa obinrin ni pataki.
Ibi tí wọ́n ti ń simi yìí, ìyàwó oníbodè gbé oúnjẹ wá fún ọkọ rẹ̀ ó sì bu omi sí i.
Iroyin ro wipe o le ni egberun meji awon alatileyin egbe oselu re All Peoples Congress (APC) ti won sa fi ibugbe won sile.
Ọ̀pọ̀ àwọn olókoowò kéékèké àti àwọn onílé iṣẹ́ náà yóò din àwọn òṣìṣẹ́ kù la'ti kójú ìṣẹ̀lẹ̀ tuntun yii, èyí ni àlàyé Nairametrics Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Tí mo ba ti múra bí ọkùnrin fi kọrin, kò sí ọ̀dọ̀ ààrẹ́ tí mi ò lè wọ̀- Erelu, ọmọ Elemure Ekiti Idénukọlẹ̀ ọ̀rọ̀ ajé lásìkò ààré Buhari Ìgbà kẹta rèé ti ọ̀rọ̀ ajé Nàìjíríà yóò dẹnukọlẹ̀ lábẹ́ àkósò ààrẹ Muhammadu Buhari Gẹ́gẹ́ bi ìwé ìròyìn Reuters ṣe sọ ọ̀rọ̀ ajẹ́ Nàìjíríà ti dẹ̀núkọlẹ̀ rí láti ọdún 1882 sí 1984, láye ìgbà náà ni ààrẹ Buhari wà ní ààrẹ ológun ní Nàìjíríà láàrí ọdún 1983 si 1985 lẹ́yìn ti wan dìtẹ̀ gbàjọba lọ́wọ́ Shehu Shagari.
Bakan naa lo ṣalaye pe, awọn ọjọgbọn kan ninu imọ ofin ti n jiroro lori idajọ naa ni kete ti ile ẹjọ gbe e kalẹ, ohun ti wọn si sọ n mu ireti wa.
Osun Decides: Adegoke ni òun kò ni lo kọngilá mọ́ nipinlẹ Ọṣun
“Nisinsinyii, ẹ̀mí mi fò lọ ninu mi,ọjọ́ ìjìyà sì dé bá mi.
 iṣẹ ́ àgbẹ ̀ pín sí oríṣirísi ònà bíi : àgbẹ ̀ aroko bọ ́ dúndé , ọlọ ́ sìn , àgbẹ ̀ ẹlẹ ́ ja , àgbẹ ̀ olóyin , àgbẹ ̀ oní-fúláwà àti bẹ ́ ẹ ̀ bẹ ́ ẹ ̀ lọ .
Joshua ti fidirẹmi sọwọ alatako ti gbogbo eniyan ti foju eniyan yẹpẹrẹ wo nitori bo ṣe jẹ ẹni sisanra.
Gomina ipinlẹ Kano, Abdullahi Ganduje ni ijọba apapọ gan an lọwọ si bi wahala arun Coronavirus ṣe n gogo sii ni ipinlẹ naa.
Ẹ bẹ̀rù ẹni tí ó jẹ́ pé nígbà tí ó bá pa ara tán, ó ní àṣẹ láti tún sọ eniyan sinu ọ̀run àpáàdì.
Ni ọdun 2018, wahala bẹ silẹ ni Isalẹ Eko nigba ti wọn pa amugbalẹgbẹ ọkan lara awọn aṣaaju ẹgbẹ naa.
Ọdọmọkunrin náà kò fi ọ̀rọ̀ náà falẹ̀, nítorí pé ó fẹ́ràn ọmọbinrin Jakọbu lọpọlọpọ.
Amọ, awọn miran kesi awọnn afẹhọnuhan naa lati gbọ ọrọ si Sega lẹnu, nitori pe adari wọn ni.
Ó ń ṣiṣẹ́ lórí Windows àti Mac
Awọn mejeeji ni wọn fi imọ ''coding'' ninu ẹkọ kọmputa dara nla.
Ojú kò lè wí fún ọwọ́ pé, “N kò nílò rẹ.
Makinde ni lootọọ ni akọsilẹ NCDC ṣe afihan pe ọwọja coronavirus ẹlẹẹkeji n peleke sii ni Naijiria lojojumọ.
Bí mo bá sọ pé kí n gbàgbé ìráhùn mi,kí n sì tújúká;kí n má ronú mọ́;
Wọ́n ń ké bí wọ́n ti ń lọ.
Sé Dino Melaye ti bọ́ sẹ́gbẹ́ PDP ni ?
 Àjọ ( nuc ) tí ó ń rí sí ìgbòkè-gbodò ìdásílẹ ̀ ilé-ẹ ̀ kọ ́ fásitì nílẹ ̀ nàìjíríà fòntẹ ̀ má báṣẹ ́ rẹ lọ oẹ ̀ lú ẹ ̀ rí tó yanarantí tí wọ ́ n sì to ilé-ẹ ̀ kọ ́ náà sí ipò kẹrìnlélọ ́ gọ ́ rùún ( 104 ) láàrín àwọn ilé-ẹ ̀ kọ ́ fásitì ikẹ ̀ nàìjíríà , nígbà tí ó wà ní ipò ẹgbẹ ̀ rún kan ólé ọgọ ́ rùn mẹ ́ fà àti mẹ ́ tàdínlọ ́ gbọ ̀ n ( 10617 ) ní àwùjọ ilé-ẹ ̀ kọ ́ àgbáyé .
lọdọọdun ti Gomina Ambọde funra rẹ ti ṣe fun igba mẹta.
Lati ọdun 2004, Chelsea ko ti i ni ju saa kan ṣoṣo ninu eyi ti wọn ko jawe olubori tabi gbe ipokeji tabi wara lara awọn mẹrin iwaju ni Yuroopu.
"Ẹ má gbìyànjú láti bo àṣírí ìpànìyàn tó wáyé ní Lekki, á ní ẹ̀rí tó dájú - Amnesty International Báyìí ni 50 Kobo ṣe dá ìfẹ̀hónú ""Ali Must go"" sílẹ̀ tó mú ọ̀pọ̀ ẹ̀mí akẹ́kọ̀ọ́ lọ Ìjọba ìpińlẹ̀ Eko ti kédé ìwọlé àwọn akẹ́kọ̀ọ́ ní gbogbo iléèwé aládàni àti ìjọba Aago mẹ́fà òwúrọ̀ sí mẹ́jọ alẹ́ ni ọ̀kadà yóò láǹfàní láti máa ṣiṣẹ́ ní Osun - Gómìnà Oyetola Àkùkọ dojú ìjà kọ ọlọ́pàá, ikú ló já sí fún agbófinró Oríṣun àwòrán, SOB Agunbiade ""Mo ti pinu lati bii oṣu diẹ ṣaaju ọjọ mi pe mi o ni ṣe ayẹyẹ tabi apejẹ kankan ju ki n pin nkan fawn araalu lọ bii ounjẹ ti wọn o tii ṣe""."
Àpáta ńlá kan wà níbẹ̀, àwọn eniyan náà bá gé igi tí wọ́n fi kan kẹ̀kẹ́ ẹrù náà sí wẹ́wẹ́, wọ́n pa mààlúù mejeeji, wọ́n sì fi rú ẹbọ sísun sí OLUWA.
Wọ́n ba yín jà, mo sì fi wọ́n lé yín lọ́wọ́.
 lára irú àwọn ogun bẹ ́ ẹ ̀ tí àwọn Ìjẹ ̀ sà ja a ni ogun Ìbàdàn , ogun jalumu àti ogun kiriji tàbí ogun ekìtì parapọ ̀ .
A bèèrè orúkọ wọn, kí á baà lè kọ orúkọ olórí wọn sílẹ̀ láti fi ranṣẹ sí kabiyesi.
O tesiwaju pe” Ifẹ awon olugbọ wa lo je wa logun, idi niyi ti awon alase ile akede Naijiria, Voice of Nigeria se bere igbohun safefe lati ilu Abuja.
Akeredolu ni eyi wa ni ibamu pelu ipinnu ijoba lati da ipinle Ondo pada si ogo ateyinwa gege bi ipinle ti o n pese koko julo ni Naijiria.
Damasus, Omotola, Ezekwesili, Funmi Iyanda dá sí ẹ̀sùn ìfipábánilòpọ̀ Fatoyinbo Àwọn orílẹ̀èdè àjọ ECOWAS yóò máa ná owó kan nàá l'ọ́dún 2020 Ìjọ Satani dá MI lóhùn lórí ọ̀rọ̀ Fatoyinbo Donald Trump kéde pé ìpàdé òun pẹ̀lú Kim já si rere LASEMA rọ awọn to ba n wa mọlẹbi wọn ti wọn fura si pe o le wa ninu ijamba naa lati kan si ile iṣẹ ọlọpaa eti odo.
Obinrin kan ará Samaria wá pọn omi.
(Orúkọ gbogbo ibi tí wọ́n pàgọ́ sí ni Mose ń kọ sílẹ̀ gẹ́gẹ́ bí àṣẹ OLUWA.
Ooni of Ife: Àwòrán ọmọ mi kọ́ lẹ ń rí lórí ayélujára o, ọmọ ọ mi ń ṣètùtù lọ́wọ́- Ọba Adeyeye Ogunwusi
 iṣẹ ́ tó múná dóko rẹ ̀ ma ń bẹ ̀ ẹ ̀ rẹ ̀ lẹ ́ yìn ọsẹ ̀ méjì tí a bá gba abẹ ́ rẹ ́ àjẹsára yìí , àti pe ́ bíi aarundinlogorun ( 95 % ) máa ní ìí , jẹsára yìí .
"Ori mi gan lo ti bẹrẹ, mo nilo iranlọwọ lori ipo ti ilera ọpọlọ mi wa nigba naa, amọ ọrọ naa bẹyin yọ, ti mo si bẹrẹ ifẹ pẹlu August.
Ijamba ti arun yii ti ṣe ko ṣee fẹnu sọ, pẹlu iwadii ti Royal Insitute of British Architects ṣe, ọpọlọpọ to n ṣiṣẹ lati ile ni o n fun awọn ni wahala pupọ.
Bakan naa ni awọn ọlọpọlọ pipe ẹda kun orilẹede yii dẹnu ni ẹka eto iselu, ọrọ aje, eto ẹkọ, imọ ẹrọ, eto ilera ati bẹẹ bẹẹ lọ.
Wò ó bí ó ti lágbára tó!
”Ko I ti se oro,  ti ko ba si eri ti o muna doko lati fi otito oro yii mule pe, ijoba san owo bi o ti le wu ko kere mo lati fi gba awon omo ti won jigbe lo ohun sile lowo  awon omo-ogun olote,”Minisita naa so ro yii lati fi koju iroyin kan, eleyi ti ajo isokan gbajade pe, ijoba san owo abetele lati fi gba awon omo naa sile.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'A ò tíì rí omi mu, ẹ ní ká máa fọwọ́ tóríi Coronavirus' Agbẹnusọ fun Oloye Agboọla Ajayi, ọgbẹni Ọkẹowo fi kun un pe kii ṣe ẹgbẹ oṣelu ZLP nikan lo ti ṣe iwe pelebe ipolongo idibo pẹlu aworan rẹ, o ni awọn ẹgbẹ oṣelu miran bii ADC, AA pẹlu fẹ gboriwọle.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Sextuplet: Àdúrà Ìbùkún ló kú lẹ́yìn ọmọ mẹ́fà yìí- Ifeoma Thelma àti Onyemaechi Chiaka Walter Carrington lọ si Havard law school ko to dara p\\p mọ awọn ọmọ ogun ilẹ America lẹyin to jade ile iwe.
Ọjọ Kini, Osu Kẹrin ọdọọdun ni ayajọ ọjọ April Fool ni awọn eniyan ya sọtọ lati maa tan awọn ẹlomiran jẹ.
Ninu atẹjade ti Buhari fi sita lati ọwọ oludamọran rẹ lori ọrọ iroyin, Femi Adeṣina, aarẹ Buhari ni imọran rere ni Jonathan n fun awọn olori Naijiria atawọn olori orilẹ-ede kaakiri ilẹ Afirika, lati igba to ti kuro ni ijọba.
Bee si ni, Super Falcons yoo koju Equatorial Guinea ninu ifigagbaga keyin lojo Abameta(Saturday), ti Shepolopolo yoo si koju South Africa lojo kan naa.
Orúkọ Debiri tẹ́lẹ̀ ni Kiriati Seferi.
Mo fẹ́ dúró ní Efesu níhìn-ín títí di àjọ̀dún Pẹntikọsti.
N kò ní fojú fo ohunkohun, n kò sì ní ṣàánú yín rárá; nítorí ẹ ti fi àwọn nǹkan ẹ̀sìn ìríra ati àṣà burúkú yín sọ ilé mímọ́ mi di aláìmọ́.
Agbẹnusọ fun gomina naa, Mallam Isa Gusau ṣalaye pe, ori ko gomina Zullum yọ lai farapa ṣugbọn diẹ lara awọn to baa rin, to fi kan awọn ẹṣọ alaabo, fara ṣeṣe.
Ibeere ti ọpọ eeyan si n bi ara wọn ni pe iru ajọsepọ wo lo wa laarin Bobrisky ati ayaba nilu Oyo debi pe yoo maa pe wa sinu ibudo itaja rẹ.
Ara adugbo míì, Omotola Aderibigbe, sọ pe ni kia ti Adekunle ri i pe Stanley kú, lo sa kuro ni yara Stanley ti ija ti waye, to si salọ.
Ṣugbọn ọpọlọpọ awọn nkan ni wọn ti ko lọ ki awọn oṣiṣẹ alaabo to o de si ile naa."
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Pigeon: Wo ìdí tí wọ́n fi ta ẹyẹlé kan ṣoṣo ní ₦893,000,000 16 Bélú 2020 Oríṣun àwòrán, Reuters Elo ni ẹyin ro pe ẹ le ri ẹyẹle ra l'ọja?
A kò ní pè ọ́ ní ẹlẹgẹ́ ati aláfẹ́ mọ́.
Tí a fiṣọwọ́ ní 12:47 16 Sẹ́rẹ́ 202112:47 16 Sẹ́rẹ́ 2021 Ìgbà mẹ́jọ tí ọ̀rọ̀ Oluwo di ariwo nígboro láàrín ọdún márùn ún rẹ̀ lóyè Ni ọduyn 2016 ni wwọn fi Ọmọọba Abdulrasheed Akanbi jẹ oye gẹgẹ bi Oluwo ti ilu Iwo.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù CAF Awards: Ahmed Musa, Alex Iwobi, Asisat Oshoala wà lára olùdíje àmì ẹ̀yẹ CAF 30 Bélú 2018 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Àwọn agbábọ́ọ̀lù Nàìjíríà farahàn lára àwọn tí yóò díje fún àmì ẹ̀yẹ̀ agbábọ́ọ̀lù tó pegedé lọ́kùnrin àti lóbìnrin Ajọ elere bọọlu ni ilẹ Afirika, CAF ti gbe orukọ awọn agbabọọlu mẹrinlelọgbọn jade lati dije fun ami ẹyẹ agbabọọlu to pegede julọ lori papa ni saa ere bọọlu ni ọdun 2017 si 2018.
Adeleke ni Sẹ́nétọ̀ tó n sójú ẹkùn ìdìbò iwọ òrun ìpínlẹ̀ Osun ní ilé aṣòfin àgbà.
Ọmọ ọwọ́ tí wọn ń tọ́jú!
Ọlọ́pàá wú òkú akẹ́kọ̀ọ́ fásítì LASU tí ọ̀rẹ́kùnrin rẹ̀ àti pásítọ̀ ṣekúpa Lagos-Ibadan Express: Ènìyàn mẹ́rin ti kú nínú ìjàmbá ọkọ̀ Ṣé ẹ ti rí kí èèyàn ní àwọ̀ ara tó ń ṣí bíi ìpẹ́pẹ́ ẹja rí?
Lalẹ ọjọ Isẹgun ni ikọlu naa waye lẹyìn ti ijọba kede isede ni Eko, tawọn ologun si pa awọn oluwọde kan ni Lekki, bẹẹ ni ọpọ ọdọ bii ọgbọn fara gbọgbẹ.
”Wọ́n bàjẹ́, ohun ìríra ni iṣẹ́ ọwọ́ wọn,kò sì sí ẹnìkan ninu wọn tí ń ṣe rere.
" Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo Bakan naa tun ni onimọ nipa ẹṣin Islam ọhun tun sisọ loju rẹ pe, Modinat yii lo maa n fun awọn ọmọ oun ni oogun mu lasiko ti wọn wa ni igbekun wọn, ti oun si fura pe, o maa n fi ibinu na awọn ibeji naa lasiko ti wọn ko ba fẹ gba oogun lọwọ rẹ ni ẹrọ.
Bí a ti wọ inú Igbó ni a déedée gbọ orin lẹ́yìn wa, orin náà dùn tó bẹ́ẹ̀, o sì gba gbogbo àgbègbè tó bẹ́ẹ̀ ti a ṣebi ogun ń bọ̀ lẹ́ẹ̀yìn wa ni.
Amọṣa boya nitori wahala ẹjọ lori ẹsun ṣiṣe owo ilu baṣubaṣu ti wọn fi kan an, Ayọdele ko tete sọrọ lori rẹ.
Herman - BBC News Yorùbá BBC News, YorùbáFò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù South Africa: Kò pọn dandan fún mi láti tọrọ àforíjì lówọ Nàìjíríà - Herman 19 Owewe 2019 Àkọlé àwòrán, Mashaba of Johannesburg Alakoso ilu Johannesburg ni orilẹ ede South Africa, Herman Mashaba ti sọ wi pe oun ko ni idi kankan lati tọrọ aforiji lọwọ orilẹede Naijiria.
Ó ké pe OLUWA pé kí ó ṣíjú wo ìnira òun,nítorí pé ọ̀tá ti borí rẹ̀.
Kí ní ó wí bẹ́ẹ̀ ṣe?
Mo mọ ọkunrin onigbagbọ kan ní ọdún mẹrinla sẹ́yìn.
 kí ìjàmbá yìí tó ṣẹlẹ ̀ , àwọn èrò sọ ̀ rọ ̀ lórí eré tó ń sá ṣùgbọn obìrin náà kjò dá wọn lóhùn .
 Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ọ̀rọ̀ Imam yìí ṣe kòńgẹ́ bó ti ń rí láàrin lọ́kọ láya Collins ṣalaye pe dida ẹlẹwọn silẹ ṣaaju ọjọ to yẹ ko kuro, ko ni nkan ṣe pẹlu iye ọjọ to ti lo lẹwọn ayafi ti idajọ to gbe e de ẹwọn ba sọ pe iru ẹni bẹ ko ni anfaani si itusilẹ latọwọ ijọba."
Simeoni ni baba Nemueli, Jamini, Jaribu, Sera, ati Ṣaulu.
Lóòótọ́ àwọn irúnmọlẹ̀ wí pé Ọlọ́run ni Ó dá ohun gbogbo ní òde ayé àti òde ọ̀run, ǹjẹ́ bí bẹ́ẹ̀ bá ni, èmi pàápàá ti tóbi nínú ọlá mi, èmi ni olórí àwọn ejò ayé gbogbo.
Pẹ̀lú gbogbo bùkátà, Bàbá 80 gboyè Masters Ilé aṣòfin Ekiti ní kí àwọn alága ìjọba ìbílẹ̀ dá N3.
Mo bẹ̀ yín, ẹ má ṣe jẹ́ kí n wá sọ́dọ̀ yín pẹlu ìgbójú, nítorí ó dá mi lójú pé mo lè ko àwọn kan, tí wọ́n sọ pé à ń hùwà bí ẹni tí ó ń wá ire ara wa lójú.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ikú Arẹwa: Ìdíje omidan to rẹwà jùlọ ló fẹ́ kopa nínú rẹ̀ 17 Ògún 2018 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 18 Ògún 2018 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Arẹ̀wà Fasiti kú léti okun Ikú ogun wọn, ni òhun ló ń pa akíkanju, akopa ìdíje arẹwà kan ló jẹ́ Ọọ́run nípè lásìukò t lọ ya fótò ní eti òkun ti wọn ń pè ni Oasis Beach.
Lẹyin ti dokita kan ni ileewosan aladani sọ wi pe o ti jade ni aye ni ọjọ Aje, ni awọn ẹbi rẹ fi pada wa lati gbe oku rẹ losin.
Ko pẹ ti ajọ INEC kede esi ibo to waye ni ipinlẹ Ekiti lọjọ kẹrinla, oṣu Keje, ninu eyi ti igbakeji Fayose, Olusọla Ẹlẹka, to dije fun ẹgbẹ oṣelu wọn, PDP, ti fidi rẹmi, ni ajọ EFCC fi ikede naa sita.
Àgbálùmọ̀, ohun mẹ́fà tó ń ṣe lára tí o kò mọ̀ Àwọn àwòrán ẹ̀yìn ìtàgé níbi ìpàdé ìfọ̀rọ̀wérọ̀ BBC Yorùbá l'Eko Day 19: Wo ohun àràmàndà tí àwọn olósèlú máa ń ṣe lásìkò ìbò #BBCNigeria2019 Sowore: olùdíje Ààrẹ tó fẹ gbà Nàìjíríà padà fún àwọn ọdọ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ademọla Ogunbanjo: A nílò bàbá ìsàlẹ̀ nínú òsèlú Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Tí kì í bá ṣe pé OLUWA tí ó wà lẹ́yìn wa,ẹ̀yin ọmọ Israẹli, ẹ wí pé,
Awon miran ti yoo wa nibe ni minista fun eto ogbin, minista fun irinna, fun okowo, fun eto inawo, fun ina monamona, ile gbigbe ati oro ise ati minista abele fun eto idajo, oro epo robi ati asoju ile ise aare ati tigbakeji aare.
N óo máa bọ́ wọn lórí àwọn òkè Israẹli, lẹ́bàá orísun omi ati gbogbo ibi tí àwọn eniyan ń gbé ní Israẹli.
ati idajo ododo” eleyii to waye ni papa isere
Olódodo tí ó fi ààyè sílẹ̀ fún eniyan burúkúdàbí odò tí omi rẹ̀ dàrútabi kànga tí a da ìdọ̀tí sí.
Amọ, Mama Taraba na ti gba tikẹẹti lati dije dupo gomina labẹ ẹgbẹ oselu UDP ni ipinlẹ Taraba fun idibo gbogboogbo ti ọdun 2019.
Jẹ́ kí àwọn òdòdó ráàyè ta.
6 Covid-19 pa Ọlọ́lá Akin Olugbade, ẹ wo dúkìá jaburata tó fisílẹ̀ 7 Covid-19: Ilé aṣojú-ṣòfin l'Abuja dábàá kí ìjọba sún ìwọlé àwọn akẹ́kọ̀ọ́ síwájú pẹ̀lú oṣù mẹ́ta 8 Ǹjẹ́ ó ṣeéṣe kí ìyáwò rẹ gbé ọmọ àlè wá sílé láì mọ̀?
Ọjọ kẹsàn-án, oṣu Kẹrin, ni ijọba ipinlẹ Kwara kede konile-o-gbele fun ọjọ mẹrinla.
Kọmisana fun isẹ ode wa tẹnumọ pe, ofin to de ẹgbẹ ọlọkọ ero nipinlẹ Ọyọ si wa nilẹ digbi, ti gbogbo owo tawọn asaaju ẹgbẹ ọlọkọ ero ọhun si n gba ko bofin mu.
- Atiku bèèrè lọ́wọ́ ọmọ Nàíjíríà Tosyn Bucknor ti papòdà Obìnrin tó lágbára láti yan ìyàwó míì fún ọkọ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Car Race: Elizade àti Akeredolu kópa nínú ìdíje eré sísá ni Ondo Festus Keyamọ fèsì lórí ẹ̀sùn naa pe: Nigba ti BBC kàn si Festus Keyamo to jẹ adari ipolongo Buhari fun idibo 2019, ọ̀tọ̀ ni ọmọ ṣori lọdọ rẹ̀.
“A se ifilole ofin tuntun naa lati fi aye sile fun idije boolu agbaye ti yoo waye lorile-ede Russia.
Eyí wáye nítori àsa to wọ́pọ̀ ààrin àwọn Yoruba pé ọmọ ọkunrin ṣe koko nínú ébi.
Awọn ọmọ ti wọn ba bi laipe ọjọ wa ninu ewu iku nigba ti wọn wa ni ìkókó.
International Champions Cup: Kane fi góòlù àràmọ̀ndà kọ ojú Ronaldo s'óòrùn alẹ́
Gbogbo àwọn eniyan ń sunkún, wọ́n ń dárò nítorí ọmọ náà.
"Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Aṣíwájú ẹgbẹ́ òṣèlú APC, Bọla Tinubu kìlọ̀ fáwọn ọ̀dọ́ lórí jíjí àpótí ìbò gbé ""Iro opolopo awon oniroyin po."
beere ọkọ oju irin mẹ́wàá   bayii lati le din wahala ti awon ero to n wọ oko oju irin lati  kaduna-Abuja ku.
Pupọ awọn ileeṣẹ South Afrika lo ti pẹka de Naijiria ti wọn si n ri ere tabua lọdọ awọn eeyan Naijiria.
Oríṣun àwòrán, NASir El-Rufai/Facebook Àkọlé àwòrán, Iṣẹlẹ naa lo mu ki ijọba ipinlẹ Kaduna kede aṣẹ ko nile o gbele fun wakati mẹrinlelogun.
Iyawo kan pere ni oun ni, o si bi ọmọkunrin mẹẹrin fun oun.
0 11120 Orilẹede Latvia 262 13.
3 94025 Orilẹede Guatemala 4345 25.
Itan aye obìnrin yii tun n kọ wa lati jẹ akínkanjú, olufẹ mẹkuunu ati ajafetọọ ọmọniyan ni ipokipo ti a ba wa, boya a jẹ ọkùnrin abi obìnrin.
Bí ó tilẹ̀ jẹ́ wípé ènìyàn kò ka ìmọ̀ràn Ọlọ́run sí, síbẹ̀ wọn kẹ́gàn àwọn ọ̀rọ̀ rẹ̀—
Ó wá kọ ìwé lé wọn lọ́wọ́.
Ṣugbọn, awọn olukopa naa ti n jẹ ẹbun owo ati awọn ẹbun nla miran ṣaaju asiko yii.
" O ko gbọdọ jẹ ọmọ ẹgbẹ okunkun Kankan.
Lara awon igbese yii ni :A ti ri bilionu naira lati inu apo isuna kan, ti owo n wole si,  ni eyi to maa n lo sodo awon ile-ifowopamo teleti .
Ranti ọ̀dọ̀ àwọn ẹni tí o ti kọ́ wọn.
Lọdun yii kan naa ni wọn gbe e ga gẹgẹ bi Ọjọgbọn agba (Professor Emeritus) nile iwe giga fasiti Obafemi Awolowo University to ti jẹ olukọni ninu imọ Litiresọ.
Ọpọlọpọ ninu àwọn eniyan tí wọ́n dúró, tí wọ́n gbọ́, ń sọ pé, “Ààrá sán!
 ""Igba ti a sa jade ni a to ri pe ọkọ ofurufu ẹlikọpita lo ja lulẹ."
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Sola Allyson, olorin Ẹmi ni orin àìmọ ààlà ìfẹ́ àti àṣejù ń mú àwọn olólùfẹ́ kóbá àye àwọn olórin Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Sola Allyson, olorin Ẹmi ni orin àìmọ ààlà ìfẹ́ àti àṣejù ń mú àwọn olólùfẹ́ kóbá àye àwọn olórin 7 Ọ̀pẹ̀̀ 2019 Lati Eji Owurọ, Ọpẹ,Ire, Imoore, Imisi titi de ori Ìrì ti o ṣẹṣẹ gbe jade, Ṣọla Allyson aya Ọbaniyi kii ṣe olorin ti a lee fi ọwọ rọ sẹyin ninu agbo orin ẹmi, imisi tabi idanilaraya lorilẹede Naijiria ati lagbaye.
Ǹjẹ́ ẹnìkan lè ṣẹ́ irin, pàápàá, irin ilẹ̀ àríwá tí wọn fi idẹ lú?
Orin Àwọn Ọ̀kẹ́ Meje Ó Lé Ẹgbaaji (144,000) Eniyan.
Idi ree ti Alhaja Fausat Balogun, ti gbogbo eeyan mọ si Madam Sajẹ ninu ere tiata Yoruba, se n dupẹ lọwọ Ọlọrun fun aanu ati aabo rẹ nibayii to pe ẹni ọgọta ọdun loke eepẹ.
 Ti mo ba n ranti bi mo se pade meta ninu won nigba ti mo lo fun itoju lodun 2017, okan mi maa n bale fun ojo iwaju rere ni.
Ìyàwó yìí fẹ́ràn ọkọ rẹ̀ púpọ̀, títí wọ́n sì fi wà nínú ìpọ̀njú yìí kò fi ọkọ rẹ̀ sílẹ̀ lọ́jọ́ kan.
Alex Badeh: Àwọn agbenipa ojú pópó lásán ló paá
Kí ni ìdí tí ọjọ́ òní fí ṣe pàtàkì nínú ìdìbò ilẹ̀ Amérika?
Duro Ladipọ, ìlúmọ̀ọ́ká òṣèré tíátà àti ọmọ àlúfà tí kò gbàgbé àṣà ìbílẹ̀ Baṣọ̀run Gáà, tó yan ọba mẹ́rin, pa ọba mẹ́rin àmọ́ ọba karùn-ún ló pa á Mọrèmi Àjàṣorò, akọni obìnrin tó gba Ilé Ifẹ̀ sílẹ̀ lóko ẹrú Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Wòlíì Kasali sọrọ nípa awuyewuye pé o lè ìyàwó rẹ̀ jáde nílé Ninu ọrọ tirẹ, akọwe agba ẹgbẹ awọn agba ilẹ Yoruba, YCE, Dokita Kunle Ọlajide ni igbesẹ to dara ni aarẹ gbe ṣugbọn o tun ku ni ibọn n ro.
Ṣe ni gbogbo awọn to wa nibẹ wo o latẹwọ ti agba oṣere mii, Adebayo Salami ti ọpọ mọ si Ọga Bello sọrọ pe yoo sọ itumọ orin to kọ toripe ko ye oun to.
"Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ọmọge Campus: Lọla Alao ní Aisha ti ni àìsàn jẹjẹrẹ ti pẹ́ O si ṣapejuwe ọmọ rẹ, ninu ọrọ idagbere to kọ si oju opo Facebook rẹ pe ""goolu ni wọn fi kọ orukọ rẹ nibi ti o wa bayii""."
Akínkanjú agbaboolu ti awọn ololufẹ rẹ lọri pápá àti lorile-ede rẹ kò ní gbàgbé láyè láyé ni.
A kò ní pè ọ́ ní “Ẹni-tí-a-kọ̀-sílẹ̀” mọ́,bẹ́ẹ̀ ni a kò ní pe ilẹ̀ rẹ ní “Ahoro” mọ́,“Ẹni-OLUWA-fẹ́” ni a óo máa pè ọ́,a óo máa pe ilẹ̀ rẹ ní “Ẹni-a-gbé-níyàwó.
Breastfeeding week 2020: Bí ọyàn ṣe tóbi tàbí kéré sí kò ní ǹkan ṣe pẹ̀lú ìfọ́mọlọ́yàn Aya gómìnà Kwara fẹ́ ran tìyá- tọmọ olójú búlúù lọ́wọ́ Ìdí tí a fi ṣàfikún owó ìtanràn ọ̀rọ̀ kòbákùngbé ní Nàìjíríà sí 5 Mílíọ̀nù rèé - Lai Mahammed Ṣé lóòtọ́ ni aya ààrẹ, Aisha Buhari fò lọ sí Dubai fún ìtọ́jú?
"Ẹni ti a fa kalẹ yi ko kundun ode owanbẹ.
Ìtàn ìgbé ayé Bode Thomas rèé, ó kọ́ wa láti máa kó ẹnu wa ní ìjánu Ọta ìbọn ogun Biafra ṣì wà lọ́rùn mi lẹ́yìn àádọ́ta ọdún tí ogun parí - Umar Gbogbo ọba alayé, tó fi mọ́ Ọọ̀ni àná, Sijuwade ló mọ̀ pé mo fẹ́ jẹ Mayegun - Wasiu Ayinde Ìyàwó gómìnà tọ́jọ́ orí rẹ̀ kéré jù ní Nàìjíríà rèé, ohun tóo lè fẹ́ mọ̀ nípa rẹ̀ Bẹẹ ba gbagbe, ni aarọ oni ọjọ Ẹti oni ni alufa Babatunde, tii se pasitọ ijọ Sotitobirẹ to wa nilu Akure, nibi ti ọmọdekunrin naa ti sọnu, yọju sile ẹjọ, ti adajọ si ni ki wọn da pada sọgba ẹwọn nitẹsiwaju ẹjọ naa.
1 15591 Orilẹede Luxembourg 345 57.
Bakan naa ni wọn si sọ wi pe awọn yoo da lara rẹ pada.
Ìrántí Sani Abacha, apàṣẹ wàá tó tún kó owó Nàìjíríà mì Wo àwọn gómìnà Naijiria tí àrùn Covid-19 ti bá fínra Ìdájọ́ ikú ni a fẹ́ fún àwọn afipábánilòpọ̀ - Ẹgbẹ́ ajàfẹ́tọmọnìyàn Mùsùlùmí tó ń gbèrò láti lọ hajj ni Alhaji, Alhaja - Onímọ̀ Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 3 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 5 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Eyi ko ṣẹyin ọrọ to sọ pe ajọ to n ri si ere-eje lagbaye (IAAF) fẹ ba orilẹ-ede Naijiria lorukọ jẹ lori ọrọ $130,000 ti wọn ni ki Naijiria da pada.
Aare ati iyawo re de ibi idibo ni deede aago meje aarọ oni, niluu  Daura,  ti awon osise eleto idibo si se ayewo oruko won, ko ti di pe won dibo pelu kaadi idibo, leyin eyi ni won fun aare ni iwe pelebe ti yoo tẹka si lati dibo fun ẹni ti o fẹ fun ipo aarẹ ati ile igbimo asoju sofin ti ọdun yii.
Oluwa rẹ ni Alhaji Yekeen Omobolanle ti ọpọ eeyan mọ si Baba Lẹgba.
Amọ sa, aba naa ni awọn eeyan to n se akansẹ isẹ pataki wọnyi gbọdọ gba asẹ lọdọ minisita fọrọ ohun amusagbara, ki wọn to lee lo ẹrọ amunawa naa.
Oṣu kẹwa, 2018 ni saa Fayose yoo pari gẹgẹ bi gomina ipinlẹ Ekiti, ti Kayọde Fayẹmi ti wọn ṣẹṣẹ dibo yan yoo si gba iṣẹ.
“Aare mi gbosuba fun un yii nipase awon aseyori ti e ti se lori eto aabo.
Nígbà tí Akin Olúsínà ṣe ìwádìí nípa rẹ̀, èsì tí ó rí gbọ́ ni ìwọ̀nyí: Wọ́n ní ìhà sáábó ni Fáwọlé máa ń gbe Tinúkẹ́ ni orúkọ ọmọ rẹ̀.
A ko faramọ jijoye baba isalẹ le ẹgbẹ lori, mi ṣi n fi daa yin loju pe púpọ ọmọ ẹgbẹ oṣelu APC lo ṣi n bọ"" Oríṣun àwòrán, @MoshoodAdeoti Àkọlé àwòrán, Adeoti wa lara awọn ọmọ ẹgbẹto kọkọ fi ẹgbẹ oselu APC silẹ nipinlẹ Osun ."
Idi mọkandinlogun ni Falana kọ ti ileẹjọ ni lati fi Ṣowore silẹ lahamọ.
Adura wa ni pe ọjọ iwaju yoo san an.
Kete ti fidio BBC yii n ja nilẹ ni awọn alaṣẹ Fasiti Eko ti pe ipade pajawiri lori ọmọwe Boniface.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Fire Eater: Azonto ní àfojúṣùn òun ni láti lọ fi idán iná yìí pa owó lókè òkun Bẹẹ lo tun rọ wọn lati maa tẹriba fun agba.
 Bush, kii se orile ede Amerika nikan ni yoo dun,sugbon ajo gbaye  ati awon eniyan ti o ti ko ipa rere ni igbese aye won pelu.
Nǹkan yan, àwọn aṣẹ́wó fẹ́ daṣẹ́ sílẹ̀ nítorí ẹ̀kúnwó epo ní Nàìjíríà Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, SS3 ní mo wà báyìí, mo sì ti gba àmì ẹ̀yẹ̀ púpò nílé-lóko gẹ́gẹ́ bí onílù - Ayansike Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Joabu fún ọba ní iye àwọn ọkunrin tí wọ́n tó lọ sójú ogun.
 awọ la fin bòó lójú ọ ̀ nà méjèèjì , okun la si nfi wa awọ ojú rẹ lọ ́ nà méjèèjì ki o le dún .
Ọba Oke nikan si lo mọ idi taa fi wa papọ titi di oni, bi o tilẹ jẹ pe diẹ lo ku, ki iji da omi inu agbọn orilẹede Naijiria nu.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Oniṣegun iwosan: eefin oluṣhosun lewu pupọ fun ilera awọn olugbe Nibayi, awọn ẹdun kan wa pe egbegberun awọn ọmọ ile-iwe ni awọn ile-iwe ijọba ati awọn ile-iwe aladani ti o wa nitosi aaye naa ati awọn to n ṣiṣẹ ni ayika yi ni o ni ewu awọn arun ẹdọfóró.
Oṣelu, Seyi Makinde ti du ipo aṣoju nile aṣofin fun ẹkun idibo Guusu ipinlẹ Oyo
Igbeneghu to jẹ Pasitọ ijọ Foursquare Gospel Church ni fidio naa tu aṣiri rẹ, ni bi o ṣe gbiyanju lati fi ọrọ ibalopọ lọ akọroyin BBC to dibọn bi ẹni to ṣẹṣẹ fẹ wọle si Fasiti Eko.
Ẹ ní báwó ni yóò ṣe rí bẹ́ẹ̀ àbí?
Yóo mú ẹ̀gàn àwọn eniyan rẹ̀ kúrò, ní gbogbo ilẹ̀ ayé.
Ìbànújẹ́ dára ju ẹ̀rín lọ; lóòótọ́ ó lè mú kí ojú fàro, ṣugbọn a máa mú ayọ̀ bá ọkàn.
”“Mo n ro eyin to wa leyin mi,lati tele gbogbo ilana ti mo ti la sile.
Àwọn tí a wí yìí ṣiwaju wa lọ, wọ́n lọ dúró dè wá ní Tiroasi.
Iku olori awọn oṣiṣẹ aarẹ Muhammadu Buhari, Abba Kyari lo ti jẹ ki ọpọ ọmọ Naijiria maa sọrọ lori ayelujara bayii.
Ẹgbẹ agbabọọlu Brighton & Hove Albion lo ṣe Tottenham bi ọṣẹ tii ṣoju ninu ifẹsẹwọnsẹ idije Premier League lọjọ Abamẹta.
Bẹẹ ba ya iru igbẹ yii tan, inu a si dun pẹsẹẹ, ọkan a tutu wẹẹ.
"Aláàfin gbé àṣẹ kalẹ̀ láti dènà àtúnṣẹ̀ ìṣẹ̀lẹ̀ 'Soka'nílùú Ọ̀yọ̀ Èmi àti Sanyeri ti tọrọ oúnjẹ jẹ rí nílé oninawo torí ebi, ká tó di gbajumọ oṣere Ìtàn ìgbésí ayé Oshodi, ọmọ Tápà léǹpe tó di akọni ní ìlú Eko Ìdí táwọn apòògùn Nàìjíríà fi tako oògùn Coronavirus láti Madagascar ""Ọpọ awa ta ni sinima to wa lori YouTube ni a ko ri kọbọ gba lori afihan rẹ."
sibẹ o fọ́ wa túútúú fún ìjẹ àwọn ẹranko,o sì fi òkùnkùn biribiri bò wá mọ́lẹ̀.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Lizzy Anjorin: Kò sí òṣèré tíátà lóbìnrin tó ní dúkìá jù mí lọ 13 Ọ̀pẹ̀̀ 2019 Oríṣun àwòrán, lizzyanjorin_original Ilumọọka osere tiata lobinrin, Lizzy Anjorin, ti kede faraye pe ọpọ eeyan ni ko mọ pe awọn ọkunrin kii fẹ nawo ọfẹ fun iru obinrin bii toun, to n sisẹ kara loju mejeeji Lizzy Anjorin, lasiko to n takurọsọ pẹlu iwe iroyin adanilaraya kan salaye pe, oun ko setan lati gbara le ọkunrin kankan fun owo nina, idi si ree ti oun se n se laala lori okoowo katakara ti oun n se.
eto ẹkọṣẹ ọwọ, idokoowo abọde, eto idanilẹkọọ awọn oṣiṣẹ ati
Ìdílé ọ̀mọ̀wé kò sí ní ipò tálákà, bí wọn kò ní owó ni òní, wọ́n ‘b bọ̀ wáá ní lọ́la.
Ó ní, “Òtítọ́ ni pe ẹ mọ̀ mí, ẹ sì mọ ibi tí mo ti wá.
Oríṣun àwòrán, Ademola Adeleke Àkọlé àwòrán, ilé ilé ẹjọ́ kede oludije fun ẹgbẹ oṣelu PDP gẹgẹ bii gomina ti ilu dibo yan ni Ọ̀ṣun Oludije fun ipo arẹ lẹgbẹ oṣelu PDP, Atiku Abubakar ti ki Adeleke ku oriire idajọ to ṣẹṣẹ gba ni ile ẹjọ.
Kí ni èrò Ẹlẹ́dàá tí o fi ẹrọ yìí fún ni?
Ọdun naa gan-an si ni igba akọkọ ti wọn gba ife ẹyẹ FA Cup.
Ǹjẹ́ kò ti kà wá kún àjèjì?
Igbo Olodumare: Ohun gbogbo tó wà nínú ìwé Fagunwa ló wà nínú igbó náà
awon ti yoo wa nibi ipade ohun ni aare ana Goodluck Jonathan, Olusegun Obasanjo,
won se n lo imo ero igbalode lati se ayeduru eto idibo , ni eyi ti o tako ẹtọ ọmọniyan.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Akomolede ati Aṣa lori BBC:Wo ìrúfẹ́ ìgbeyàwó méje tó wà nílẹ̀ Yorùbá àti ojúṣe Alárinà Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Akomolede ati Aṣa lori BBC:Wo ìrúfẹ́ ìgbeyàwó méje tó wà nílẹ̀ Yorùbá àti ojúṣe Alárinà 10 Bélú 2020 Ninu eto ẹkọ wa lori eto Akomolede ati Asa lori BBC lọsẹ yii, ohun ta a maa gbe yẹwo ni oniruuru asa igbeyawo meje to wa nilẹ Yoruba.
Ẹ wo bí wọ́n ṣe dárà sí i lórí bí ẹni pé ọba kan ló fẹ́ mu ú.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ọlọ́pàá méjì gba ìdáǹdè l'ọ́wọ́ ajínigbé Ìjínigbé Congo: ọmọ ilẹ̀ Gẹ̀ẹ́sì gba òmìnira Gbájúẹ̀ méjìlá bọ́ sí gbaga EFCC ní Èkó Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Oyetola ni oun ṣeleri ni ibẹrẹ ijọba oun pe, oun yoo pese eto ilera to peye fawọn eeyan ipinlẹ naa lọna ti ko ni na wọn lowo pọju.
lọ, yoo je ki awon ile-ise kogba wọle.
Mo dupe lowo ijoba ati awon omo orile ede China fun bi won se gba wa ni alejo nigba ti a de si orile ede China.
OLUWA dáhùn adura Elija, ẹ̀mí ọmọ náà sì tún pada sinu rẹ̀, ó sì sọjí.
62b), ọtalenirinwo o le meji biliọnu naira (N462.
Eleyii waye leyin wahala to n sele
Ati pe awọn ohun to ṣẹlẹ yii jẹ ẹkọ fun awọn ti ọrọ kan.
Ọba bá ní kí wọ́n lọ gbé Hamani kọ́ sí orí rẹ̀.
Gbogbo igbiyanju Okorocha lati rii pe ana rẹ, Uche Nwosu oludigbe ẹgbẹ oṣelu Action Alliance(AA) ni yoo gba ijọba lọwọ rẹ gẹgẹ bi gomina ipinlẹ Imo, pabo lo ja si.
Ò kéré tán N1million là ń ná lórí alárùn Coronavirus kọ̀ọ̀kan; àlàyé rèé- Ìjọba Eko Àwọn ọmọ ogun ilẹ̀ Nàìjíríà dóòlà ẹ̀mí ẹni méjì ní Owena ní Ondo Ilé iṣẹ́ ọlọ́pàá lórí àtẹ̀jíṣẹ́ twitter wọ́n ti sàlàyé pé irú àwọn ènìyàn báyìí lé pé nọmba yìí ) 081 0004507 tàbí kí wọ́n fi àtẹ̀jíṣẹ́ ránṣẹ́ sí: email to e-training@recruitment.
Eyi si yipada nigba ti ikọ naa koju Arsenal ni alẹ ọjọ Abamẹta.
"Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ìwọ́de #EndSARS rán èèyàn méjì sọ́run n‘Ibadan, Seyi Makinde da ikọ̀ Operation Burst sígboro N kò ní buwọ́ lu ìṣúná tí kò pèsè owó fún ẹ̀bí àwọn tó kú nínú ìwọ́de EndSARS - Gbajabiamila ""Ẹ ràn wá lọ́wọ́ láti rí àwọn ẹlẹ́wọ̀n tó sálọ ní Oko àti Benin padà"" Ìwọ́de EndSARS ló ń sọ pé inú ń bí àwọn ọ̀dọ́, ìjọba, ẹ náání wọn - Obasanjo Ẹni iyì àti akíkanjú tó ṣe gbẹ́kẹ̀lé làwọn èèyàn Akure, ilú ìyá mi - Seyi Makinde Ẹ̀yin ọ̀dọ́ ti rí èrè ìwọ̀de yín lórí EndSARS àmọ́ ẹ ṣọ́ra, kẹ má baà sọ èrè náá nù - Tinubu Owó ìrànwọ́ Covid-19 dé, ìjọba fẹ́ san ₦75bn fún 54,000 olókoòwò Ìjọba ìpínlẹ̀ Eko ti iléèwé pa nítorí ìwọ́de #EndSARS Ìrẹ̀wẹ̀sì ń bá wa torí ìdánwò NECO tẹ ń ṣún síwájú lọ́pọ̀ ìgbà - Akẹ́kọ̀ọ́, ọ̀gá iléèwé Adejobi ni awọn ikọlu yii lo nii se pẹlu kikọlu awọn ọlọpaa ati ileeṣẹ ọlọpaa pẹlu awọn araalu."
Ṣaa deede ni wọn gbọ ti eeyan kan n kan ilẹkun ti ọmọ Dele Giwa, Kayode si wa jiṣe apo iwe naa fun Dele Giwa lọjọ naa.
Akara Oogun ati awọn diẹ lo pada wa sile lẹyin ti wọn ri eso naa gba wa sile.
Tijani Bande je ọjọgbọn àti oga agba ile ẹkọ fasiti Usman Danfodiyo ti ìpínlẹ Sokoto nigba kan ri, kò ni enikẹni tí ó ba du ipò náà nínú ìdìbò tó wáyé lónìí ọjọ́ ìṣẹ́gun ní ìbi ìjokò ile ẹlẹkẹrinléni ààdọrin irú rẹ̀.
Awọn aṣofin mẹrinla to ku ko si ni ibi ti wọn ti gbe igbesẹ naa, ti wọn si tako igbesẹ naa ati ẹgbẹ oṣelu APC si kọ igbeṣẹ naa, wọn si kesi gomina Obaseki lati pa aṣẹ miran.
Dafidi wá sọ́dọ̀ Saulu, ó sì ń bá a ṣiṣẹ́.
Ẹni tí ó bá ní etí, kí ó gbọ́!
Bakan naa, ohun ni Chancellor Ile Iwe giga fasiti Jos.
Nígbà tí wọ́n gbọ́, wọ́n jọ ké pe Ọlọrun pé, “Oluwa, ìwọ tí ó dá ọ̀run ati ayé ati òkun ati gbogbo ohun tí ó wà ninu wọn, 
gbọ́n mo pa òbí àwọn ọmọ ọlọ́mọ - BBC News Yorùbá BBC News, YorùbáFò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Rwanda Genocide: Òbí ni mi - sùgbọ́n mo pa òbí àwọn ọmọ ọlọ́mọ 15 Òkùdu 2020 Oríṣun àwòrán, Natalia Ojewska Àkọlé àwòrán, Ruwanda Genocide: Obi ni mi - mo pa obi awọn ọmọ wẹwẹ Ẹgbẹlẹgbẹ awọn obinrin lo kopa ninu ipaniyan abẹle to waye ni Ruwanda lọdun 1994 subgọn ko si ẹni to sọrọ nipa wọn ati bi wọn ṣe n ṣe atunṣe pẹlu ẹbi wọn.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Daura varsity: Amaechi ní ọ̀fẹ́ ni China yóò kọ́ fásítì $50M ètò ìrìnnà sí Daura ìlú Ààrẹ Buhari 30 Ògún 2020 Oríṣun àwòrán, Twitter/Ministry of Transportation Minisita eto irinna ọkọ ni Naijiria, Rotimi Amaechi, ti sọ pe ọfẹ ni ijọba orilẹ-ede China yoo kọ fasiti eto irinna ọkọ ti yoo gberasọ niluu Daura, ipinlẹ Katsina loṣu kẹsan an, ọdun 2021.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, ẹẹmeji ni Mahrez ti gba bọọlu sawọn ni idije AFCON Kini igbagbọ awọn eniyan fun Super Eagles Naijiria?
Oga agba ile-ise omo ogun oju ofurufu,  Balogun Sadiq Abubakar ti oga agba ekaa isakoso eto Chief of Administration, NAF, Balogun Ibrahim Yahaya ropo re, lo soro naa di mimo lasiko ipade iforowero ti o waye nilu Abuja, ti won pe akori re ni “Enlightenment Workshop for Defence Correspondents on Air Power”.
 O ni abadofin naa yoo ni akọsilẹ orukọ awọn oṣiṣẹ olutọju ile kaakiri Ipinlẹ Eko.
Ìfipábánilòpọ̀ kìí ṣe ìwà ọmọlúwàbí, àwọn òṣèré tíátà pariwo síta Ìdájọ́ ikú ni a fẹ́ fún àwọn afipábánilòpọ̀ - Ẹgbẹ́ ajàfẹ́tọmọnìyàn Yatọ si awọn mejeeji yi, ipinlẹ Ekiti naa lọna ati dẹkun iwa ibajẹ yi sọ pe awọn naa yoo tẹ afipabanilopọ lọda ni ipinlẹ ọhun.
Láti Jotibata wọ́n lọ sí Abirona.
Wọn gbọdọ fi akọle ti yoo rọ awọn eero lati fọ ọwọ wọn si ile igbọnsẹ ati ile- iwẹ Ounjẹ ti wọn ti di soju kan naa ṣaaju ki baalu o to gbera ni awọn oṣiṣẹ inu baalu gbọdọ pin To ba ṣe e ṣe, ki awọn oṣiṣẹ inu baalu o ya ile igbọnsẹ kan sọrọ fun ara wọn.
Jeremaya bá wí fún Sedekaya pé, “OLUWA Ọlọrun àwọn ọmọ ogun, Ọlọrun Israẹli ní, bí o bá jọ̀wọ́ ara rẹ fún àwọn ìjòyè ọba Babiloni, wọn ó dá ẹ̀mí rẹ sí, wọn kò sì ní dáná sun ìlú yìí, ìwọ ati àwọn ará ilé rẹ yóo sì yè.
Oríṣun àwòrán, Reuters Yatọ si idibo aarẹ, idibo gomina yoo waye nipinlẹ mọkanla, ati ẹkùn meji.
10041 parkinson jẹ ́ plánẹ ́ tì kékeré ní ibi ìgbàjá ástẹ ́ rọ ́ ìdì .
ó ti rí i tẹ́lẹ̀ pé Mesaya yóo jí dìde kúrò ninu òkú.
Tolulope Arotile death: Afurasí tó wa ọkọ̀ pa Tolulope Arotile ti ń jẹ́jọ́ ẹ̀sùn ìgbìmọ̀pọ̀ ṣekúpani
Banaba mú Maku, wọ́n wọ ọkọ̀ ojú omi lọ sí Kipru.
ohun esun ti won fi kan iko omo ogun Naijriia, nitori pe ko si otito ninu oro
"Ìró ìbọn dún lákọ ní Iwo road n‘Ibadan, Seyi Makinde yọjú síbẹ̀ Àwọn jàndùkú kọlu ọgbà ẹ̀wọ̀n Ikoyi, agbófinró gba àkóso ibẹ̀ ""7000 Jàǹdùkú ló fọ́ ọgbà ẹ̀wọ̀n Okitipupa, jó mọ́tò, tí wọn si se òṣìṣẹ́ léṣe"" Tani Oke Obi-Enadhuze: tí orúkọ rẹ̀ gba orí ayélujára kàn lẹ́yìn wàhálà #Lekki tollgate?"
Gbajugbaja òṣèré ''Toromagbe'' nínú fíìmù ''Arelu'' ti jáde láyé Mi ò ṣe ẹ̀tánú Ọọ̀ni ilé Ifẹ̀, ọmọ ìyá mi ni ṣùgbọ́n.
Ibeere nla ti idahun rẹ jẹ pe Ko si ohun ti Olorun ko le ṣe ni ifọrọwerọ BBC oni gbe dani loju ọpọn wa.
Ṣugbọn bí wọ́n ti ń da àwọn ọmọ Israẹli láàmú tó, bẹ́ẹ̀ ni wọ́n ń pọ̀ sí i, tí wọ́n sì ń tàn kálẹ̀.
Oríṣun àwòrán, others 10) Hakeem Kae-Kazim: Ilu Eko ni wọn bi Hakeem Kae Kazim si lọjọ Kinni, oṣu Kẹwaa, ọdun 1962 nibi to ti bẹrẹ igbe aye rẹ.
Ọjọ́ tí a tí ń retí nìyí;ọwọ́ wa ti tẹ Jerusalẹmu wàyí!
Mo ti ni ijamba ọkọ ri lẹnu iṣẹ nigba ti mo fi wa ni ọdọ Ọga Bello.
Nígbà tí àwọn tí wọ́n ti mọ̀ ọ́n tẹ́lẹ̀ rí i bí ó ti ń sọ àsọtẹ́lẹ̀ pẹlu àwọn wolii, wọ́n bẹ̀rẹ̀ sí bèèrè lọ́wọ́ ara wọn pé, “Kí ló ṣẹlẹ̀ sí ọmọ Kiṣi?
Ibi ọwọ, ibi àṣẹ ni aafin ọba, kii ṣe ile igbafẹ, nitori pe ibi ti wọn n ko awọn nkan isẹnbaye pamọ si ni.
Ẹni to bori: Congo DR Ìpele to kangun si aṣakagba Benin vs Nigeria.
Ẹkú dédé àsìkò yìí ẹ̀yin ọmọ ogun.
Lẹ́yìn náà, wọ́n sọ fún Josẹfu pé ara baba rẹ̀ kò yá, Josẹfu bá mú àwọn ọmọ rẹ̀ mejeeji, Manase ati Efuraimu, lọ́wọ́ lọ bẹ baba rẹ̀ wò.
Nítorí ìdí èyí, Olówó-ayé, òótọ́-inúu ni kí o máa fi bá àwọn ènìyàn lò títí ìwọ yóó fi bọ́ ara ènìyàn sílẹ̀, tí ìwọ yóó pa ojú dé, tí ìwọ yóó ṣe bí èmi, tí ìwọ yóó sì wáá bá mi ní òde ọ̀run.
Awọn ijọba ibilẹ ti wọn kọkọ fi fi bẹrẹ naa ni Ifedore, Ile oluji/oke igbo, Irele ati Akoko North West.
Orílẹ̀-èdè Amẹrika kò ṣọ́ wọlé-wọ̀de mi àti ìdílé mi- Atiku fèsì Ẹ dín iye ìgbà tẹ n gorí obìnrin kù torí ìdìbò tó n bọ̀, kẹ́ẹ lè lágbára láti ṣe .
ibi kankan kò ní dé bá ọ,bẹ́ẹ̀ ni àjálù kankan kò ní súnmọ́ ilé rẹ.
“Lodun to koja iko agbaboolu mejilelogbon lo kopa ninu idije yii, sugbon lodun yii iko agbaboolu ogójì ni yoo kopa ninu idije naa.
O si bẹ ijọba lati tete wa opin si iru iṣẹlẹ naa.
” Mo sì tún pè é lẹ́ẹ̀kejì mo ní, “Àkàrà-oògùn,” òun náà si tún fèsì ó wí pé, “Bẹ́ẹ̀ náà ni, máa bá ọ̀rọ̀ rẹ lọ.
Coronavirus ti na'wọ́ gán Mínísítà fétò ìlera nílẹ̀ẹ Gẹ̀ẹ́sì Nínú ọkùnrin àt'obìnrin, ta ni Coronavirus yóò tètè ṣe lọ́ṣẹ́?
Ó tẹnu bọ̀rọ̀ ó wí pé “Àìrìnjìnnà làìrí abuké ọ̀kẹ́rẹ́, tí a bá rìn jìnnà á ó rí abuké erin.
Ìpín ti Simeoni yóo wà lẹ́gbẹ̀ẹ́ ti Bẹnjamini, láti ìlà oòrùn títí dé ìwọ̀ oòrùn.
Ẹwọn ọdun marun ni wọn fun.
Òun náà la fi ngbọn jànkáríwọ̀ kúro lára ògiri inú ilé.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí Siga tita d‘eewọ lẹba ile ẹkọ Waec f'ofin de ile'we mẹtadinlaadọta Èyí ni àwọn ọ̀nà tí o fi lé mú ọpọlọ ọmọ rẹ̀ jì pépé Raji sọ pé ọ̀rọ̀ ẹ̀kọ́ orílẹ̀èdè yii dà bí ẹni pé a kò mọ ìtumọ̀ ẹ̀kọ́ ní Nàìjíríà.
Àkọlé àwòrán, Eto ẹkọ ọfẹ ti bẹre nipinlẹ Oyo bayii Ìjọba Naijiria ti ṣe ìlérí lóríṣíiríṣi látẹnu àwọn Gomina tuntun ti wọ́n ṣe ìbúra ni àná ni èyí tó lè mú ọsàn so dídùn fáwọn ara ilu.
Uber Boat ṣẹsẹ já ọkọ ojú omi tuntun láti ṣàdínkù súnkẹrẹ fàkẹrẹ ọkọ̀
Ìbéèrè pọ̀ lórí òkú ọkùnrin kan tí ọlọ́pàá bá nínú àgbá ní Oyingbo
Bakan naa, ogagun naa tun so aseyori lori ikolu awon omo ogun olote ohun mo
Ayédèrú òògùn ààrùn onígbáméjì tó wà ní ta rèé Àpanisáyé ni ẹ̀wà tí wọ́n n fí 'sniper' sí NAFDAC: Ojú wa wà lára ìpara Blac Chyna náà NAFDAC: Ẹ ṣọ́ra fún ẹja aṣekúpani Puffer Fish Ohun tí wọ́n fi ń ṣe báàgì, bàtà ni wọ́n ń tà bíi ‘pọ̀ǹmọ́’— NAFDAC Tunbosun salaye pe, agbara ijọba ti n ka itankalẹ arun yii ati pe ki awọn eniyan ipinlẹ Eko lọ fọkan balẹ.
Da aṣọ rẹ bo èmi iranṣẹbinrin rẹ, nítorí pé ìwọ ni ìbátan tí ó súnmọ́ ọkọ mi jùlọ.
Sáájú àsìkò yìí ni ẹ̀ka CAN ti ìpínlẹ̀ Ondo ti ni, kò sí ǹkan tó kan àwọn pẹ̀lú ọ̀rọ̀ ìjọba nítórí náà àwọn yóò ṣe ìsìn òpin ọdún ní tàwọ́n.
Jesebẹli bá rán oníṣẹ́ kan sí Elija pẹlu ìbúra pé, “Kí àwọn oriṣa pa mí, bí n kò bá pa ọ́ ní ìwòyí ọ̀la, bí o ti pa àwọn wolii Baali.
Asiko to lo to fi kawe soke lera-lera ju ti ẹni to wa nipọ yii telẹ, Deepak Sharma, ọmọ orilẹede Nepal, lọ.
Ó mú Simeoni láàrin wọn, ó dè é lókùn.
O ni oye oun ni ipinlẹ Ondo ni lo lasiko yi lati le lọ si ibi giga yatọ si ti tẹlẹ.
Olukuluku ni yóo kú fún ẹ̀ṣẹ̀ rẹ̀.
Ọ̀pọ̀ aráàlú ló ti pàdánù ọwọ́ àti ẹsẹ wọn sọ́wọ́ jàǹdùkú - Sanwo-Olu Oríṣun àwòrán, Babajide SanwoOlu Gomina Babajide Sanwo-Olu tipinlẹ Eko ti kede isede konile o gbele nipinlẹ́ Eko.
Àwọn òṣèré, olórin Yorùbá gbàdúrà fún MC Oluomo Lasiko ayẹyẹ rẹ ni Iba Gani Adams yan igbimọ oloye rẹ ninu eyi to ti yan awọn ọmọ Yoruba kaakiri awọn ipinlẹ to jẹ Yoruba.
Akanbi mi, má fọ̀ ọ́, mo wà pẹ̀lú ẹ; Ẹni tó ṣe ìgbéyàwó olórùka ló l'ọkọ - Lizzy Anjorin Òní ló yẹ kí Ibidunni Ighodalo pé ogójì ọdún, Tope Alabi, Kenolly àtàwọn míì tí yóò kọrin níbẹ̀ rèé Èèmọ̀!
Orílẹ̀èdè Amẹrika kò ṣọ́ wọlé-wọ̀de mi àti ìdílé mi- Atiku fèsì Iléẹjọ́ ní kí Yakubu lọ gé oko àgọ́ ọlọ́pàá fọ́jọ́ méjì lẹ́yìn tó jí fóònù N8,700 Ìdùnnú subú layọ̀ nípìnlẹ̀ Ọyọ́, àwọn tó dé láti Lebanon sọ ọmọ wọn ní Seyi Akọ̀wé-owó wọ gàù ní iléẹjọ́ lórí ẹ̀sùn pé ó jí N500,000 lọ́wọ́ ọ̀gá rẹ̀ Ọ̀rọ̀ Soyinka àti Obasanjo papọ̀ lórí pé Buhari n ṣe ìpínyà Nàìjíríà Bakan naa ni ijọba kede afikun owo ina ọba lọna ilọpo meji eyi ti o mu ki ọpọ araalu ṣi maa ke pe inira nla lo jẹ fawọn.
Ẹ foríjìn wá ọmọ Nàìjíríà, mó mọ̀ pé ẹ̀ ń bínú tórí a kò tètè gbé ìgbésẹ̀ lórí ọ̀rọ̀ EndSARS- Osinbajo Àwọn olùwọ́de ṣetán láti bá mínísítà FCT Abuja wọ̀ ṣòkòtò kan lórí àṣẹ má ṣe ìwọ̀de Tola Oyediran ọmọ Obafemi Awolowo ti jáde láyé Ohun tí ojú ìyàwó mi rí lọ́wọ́ SARS kò ṣe é fẹnusọ- Poju Oyemade Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, End SARS, End SWAT: Ó pé mi bí SARS kò ṣe sọ mí dolówọ́- Fulani Kwajafa Ki lo ti kọkọ ṣẹlẹ sẹyin?
Lẹ́yìn náà, n óo gbọn ọrun rẹ dànù lọ́wọ́ òsì rẹ; n óo sì gbọn ọfà bọ́ sílẹ̀ lọ́wọ́ ọ̀tún rẹ.
"Má kọ̀wé fipò sílẹ̀, àwọn àgbààgbà Yorùbá sọ fún Osinbajo O ṣalaye pe, ""Ọkan lara awọn adigunjale ọhun kọ oju ibọn si mi, bi mo ṣe fẹ fun un ni ẹrọ ibanisọrọ mi lo yin ibọn ọhun si mi loju."
Ojoojúmọ́ láti ọjọ́ tí mo ti wọ ẹ̀wù yìí ni àwọn ẹbọra ọ̀run ń sẹ nǹkan tí kò dára ju tèmi, bẹ́ẹ̀ ni n kò fẹ́ kí nǹkan ẹnikẹ́ní gbé tèmi, eléyìí a sì máa bà mi nínú jẹ́, bí mo bá ti ń rí ìlọsíwájú wọn ni inú ń bí mi, èmi a sì máa sọkún títí lójóòjúmọ́ ọjọ́ ayé mi.
mimu idagbasoke  ba Ipinle Oyo ati
Nibẹ ni wọn ti sọ fun Pasitọ Biodun fatoyinbo pe digbi ni awọn wa lẹyin rẹ lori ẹsun ifipabanilopọ ti wọn fi kan an.
Shehu ni aarẹ Buhari ni asẹ ati ẹtọ ni abẹ ofin ilẹ Naijiria ti ọdun 1999, labẹ ẹka 145 (1), lati lọ fun isinmi ati ayẹwo ara rẹ, atiwipe awọn ti fi iwe ransẹ si Aarẹ Ile Igbimọ Asofin Agba, Agbẹnusọ Ile ati Ile Asojusofin.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ìfipá bani lò pọ̀ ní ibùdó IDP Àwọn òrin tó ń k'ókìkí àwọn ọmọ Yahoo Igbákejì alága kú lẹ́yìn wákàtí díẹ̀ tó se ìbúra Àwọn olùgbé àti òsìsẹ́ tó ń bojù tó ìrìn ojú pópó ní ìlú Birnin-Gwari sọ wí pé, ní ọjọ́ náà, àwọn agbébọn dá ọ̀pọ̀lọpọ̀ ọkọ̀ dúró, wọ́n rọ́ ènìyàn púpọ̀ lọ sínú igbó, wọ́n sì pa àwọn ọkọ̀ tì síbẹ̀.
Ni bayii, Arsenal ti fidi rẹmi ninu meje ninu ifẹsẹwọnsẹ mẹwaa ti wọn ti gba bayii.
Ilu Milan lorilẹ-ede Italy lo wa nibi ti wọn ti fami ẹyẹ agbabọọlu to dara julọ ni idije liigi Serie A fun saa 2018-2019 daa lọla.
Bakan naa, ọpọ ni wọn ko gba pe Messi ni agbabọọlu to dantọ julọ lagbaaye.
Oloye Bola Tinubu to jẹ àgbà egbẹ fun APC ti fun Oloye Oluṣegun Obasanjọ to jẹ aarẹ Naijiria nigba kan ri ni esi lẹta to kọ si Buhari to n tukọ Naijiria.
Ọmọ Yoruba to fẹ Fulani Ilorin Ohun marun t'ejo n jẹ Kini ‘technology’ ni ede Yoruba?
Ilẹ̀ kẹta tí wọ́n ṣẹ́ gègé lé lórí bọ́ sí ọwọ́ ẹ̀yà Sebuluni.
Ọọni salaye pe ọdun mejidinlogoji ni iya oun, Wuraola Ogunwusi fi ṣiṣẹ nile iwosan UCH, ti iṣẹ takuntakun to ṣe nibẹ ko si parẹ titi di oni.
Bakanaa lo ni ko ba san fun orilẹede Naijiria ju bayi lọ, to ba jẹ pe o dokoowo pupọ lẹka eto ẹkọ ati ilera, dipo kijọba maa dojukọ ipese awọn ohun eelo taa lee fojuri, eyi to nsakoba fun idagbasoke ọmọniyan.
Ọjọ aiku ni igba akọkọ lẹyin oṣu pupọ ti arun Covid-19 ti bẹrẹ si ni ja rain ni Naijiria ti adinku ba iye awọn eeyan tuntun to ṣẹṣẹ ko arun naa.
Ọmọ a- fi- òórùn- jagun- m’ẹ́rú- kere;
Ẹ óo máa rú àwọn ẹbọ wọnyi pẹlu ẹbọ ohun mímu wọn, yàtọ̀ sí ẹbọ sísun ati ẹbọ ohun jíjẹ ojoojumọ.
Arsene Wenger tuko agbaboolu Nancy, Monaco ati Nagoya Grampus.
Ọmọ Biritiko to n kọni nipa iwa ọdaran yii sọ nipa ihuwasi awọn ti wọn ni ẹmi ati pa ololufẹ wọn hande.
Ṣugbọn a wí fún un pé, ‘Olóòótọ́ ni wá, a kì í ṣe eniyankeniyan, ati pé a kì í ṣe amí rárá.
" Ami ayo mẹta si odo ni Manchester United fi ṣeya fun Derby County ninu ifẹsẹwọnsẹ wọn to waye lọjọ Ọjọbọ, leyii ti Ighalo ti sọ bọọlu meji wọle ninu rẹ.
Jonathan Pryke, oludari eto Pacific Island sọ pe oun ko le sọ bo ya kii ṣe titi ibode mawọn alejo lati ilẹ okeere nikan lọna abayọ si ọrọ coronavirus.
 yóò ṣe bí ti yábàá tàbí kí ó ṣe jù bẹ ́ ẹ ̀ lọ .
Ìdigunjale Offa: Ọlọ́pàá gbé N5m sílẹ̀ Saraki lọ́rọ̀ láti dáhùn lórí ìdigunjalè Offa Gómìnà tí wọ́n yàn ní Kwara, Abdulrazaq ní òun yóò tún ìdigunjalè Offa yẹ̀wò Gẹgẹ bi ohun ti awọn afunrasi mẹta naa Ayoade Akinnibosun,Ibikunle Ogunleye ati Adeola Abraham sọ, niṣe ni awọn ọlọpaa de awọn ni ọwọ mejeeji pẹlu irin ti wọn si fi iya jẹ awọn lati s ohun ti wọn fẹ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Papalolo ní ìlépa owó ni ìyàtọ̀ tó wà láàárín àwọn òṣèré tíátà àtijọ́ àti ìsisìnyí Igba akọkọ kọ niyii ti awọn ọmọ gbẹ́ naa yoo fẹhonuhan lori bi ijba apapọ ṣe fi olori wn si ahamọ lati ọdun 2015, lẹyin ti ija waye laarin wọn ati awọn ọmọ ologun Naijiria.
Àwọn ẹranko ibẹ̀ ń fọhùn ènìyàn bákan náà sì ni àwọn ẹyẹ.
Ọkùnrin tó yí orúkọ padà sí Muhammadu Buhari ṣ'ayẹyẹ ìsọmọlórúkọ ní Kano Kìnìhún fa èèyàn kan ya ní Nairobi, àdúgbò dàrú Má ṣe fi ọkọ̀ rẹ gbé àgùnbánirọ̀ lẹ́yìn aago mẹ́fà ìrọ̀lẹ́- FRSC Àwọn agbébọn ṣekúpa akẹ́kọ̀ọ́ tó wà nípele àṣekágbá ní fásítì Kogi Bakan naa ni Aisha sọ pe Garba Sheu n mu idojuti ba mọlẹbi aarẹ ati ileeṣẹ aarẹ Naijiria.
Ìwọ̀n gbogbo ọrẹ ẹbọ tí àwọn olórí ogun náà mú wá jẹ́ ẹgbaajọ ó lé ẹẹdẹgbẹrin ó lé aadọta (16,750) ṣekeli.
Hmmm mo lero pe ọba to rẹwa ni mi!
Pẹlu iye awọn eeyan tuntun yii, o ti pe 57, 724 eeyan to ti ni arun naa l'orilẹede Naijiria bayii.
Ṣebí gbogbo ẹran ọ̀sìn wọn, ati gbogbo ohun ìní wọn ni yóo di tiwa?
Ó pé ọdún kẹrin tí àwọn ọmọbìnrìn Chibok nù Ìkọlù Ọ̀ffà: Ọwọ́ tẹ afurasi méjìlá míì Awuyewuye owó tí Àbáchà jí Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ekiti Election: Ẹgbẹ́ awakọ̀ Ekiti pa ìjọba dà lẹ́yìn tí wọ́n kéde Fayẹmi 15 Agẹmo 2018 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 16 Agẹmo 2018 Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ekiti Election: Ẹgbẹ́ awakọ̀ Ekiti pa ìjọba dà lẹ́yìn tí wọ́n kéde Fayẹmi Ẹgbẹ́ awakọ̀ Ado-Ekiti yọ àwọn alaga ẹgbẹ́ tó sé ti ìjọba Fayoṣe Afi bi ere ori itage ni nilu Ado Ekiti to jẹ olu ilu fun ipinlẹ Ekiti lọjọ Aje, nigba ti ẹgbẹ awọn ọlọkọ èrò yan awọn alásẹ tuntun, eyi to ṣeese ko jẹ ni ibamu pẹlu ayipada to ba eto iṣejọba oloṣelu nipinlẹ naa.
Mo pinu lati ran ijọba Naijiria ati awọn eeyan lọwọ nitoripe bi mo ba ku,mi o ni gbe owo lọ si ọrun'' Loju opo Twitter ati kaakiri oju ayelujara lawọn eeyan ti n kan sara si arakunrin yi ti pupọ si kun fun adura ki ọna rẹ ma gbooro si Kini ipa ti ijọba naa ko Abikẹ Dabiri Erewa ti o jẹ Alaga ajọ ti o n ri si ọrọ ọmọ Naijiria loke okun kede iranwọ ijọba Naijiria fawọn to ṣeṣe tajo de naa.
 O wa pada kilọ pe ko gbọdọ si pe ẹnikẹni n ba afipabanilopọ bẹbẹ mọ."
fun akitiyan aare Buhari lati gbogunti iwa ibaje, eto abo to mehe, ti o si tun fowo
Iroyin kan ti ko fidi mulẹ ni ilẹ lo yọ ẹlẹyinju aanu naa ni baluwẹ, to si subu, to ki aye pe o digbo se, oku rẹ si ni wọn ba nile itura to wa.
 Ni won pe fun ifehonu-han tako ajo eleto abo, eyi ti won fesun kan pe, o n soju saaju fun ijoba.
Ẹ̀ ń wí pé, “Ẹ jẹ́ kí á jẹ, kí á mu!
O ni awon  egbe mọ́kàndínlógún ati awon egbe miaran ti iye
Wọn a kó eniyan ní ìgbèkùn, bí ẹni kó yanrìn nílẹ̀.
Ṣé ìwọ ni o pàṣẹ fún idì láti fò lọ sókè,tabi láti tẹ́ ìtẹ́ rẹ̀ sórí òkè gíga?
Lójijì Nebukadinesari ta gìrì, ó sáré dìde, ó sì bèèrè lọ́wọ́ àwọn ẹmẹ̀wà rẹ̀ pé, “Ṣebí eniyan mẹta ni a dì, tí a gbé sọ sinu iná?
Ondo politics: Ilé ẹjọ́ da ìpèjọ́ pé Akeredolu kọ ló wọlé ìdìbò ìpińlẹ̀ Ondo nù
“Ṣé kinniun a máa bú ninu igbó láìjẹ́ pé ó ti pa ẹran?
Ní àkókò náà, àwọn eniyan tí wọ́n ga, tí wọ́n sì ń dán,tí àwọn tí wọ́n súnmọ́ wọn, ati àwọn tí wọ́n jìnnà sí wọn ń bẹ̀rù,orílẹ̀-èdè tí ó lágbára, tíí sì í máa ń ṣẹgun ọ̀tá,tí odò la ilẹ̀ wọn kọjá,wọn óo mú ẹ̀bùn wá fún OLUWA àwọn ọmọ ogun,ní orí òkè Sioni, tí àwọn eniyan ń jọ́sìn ní orúkọ OLUWA àwọn ọmọ ogun.
" ní ilẹ ̀ amerika , a rí fíìmù kan tí wọ ́ n pè ní "" philadephia "" ."
Àkọlé àwòrán, Iyawo Muratado wa lara awọn to lugbadi iṣẹlẹ yii Iyawo Arakunrin kan Murtadọ Kurniawan wa lara awọn to farakasa ninu isẹlẹ naa .
Bí Jesu ti ń kọjá lọ, ó rí ọkunrin kan tí ó fọ́jú láti inú ìyá rẹ̀ wá.
Adoke n koju ẹsun pe e o mọ nipa kiko owo kan to ni i ṣe pẹlu iwe asẹ fun ileeṣẹ epo Shell ati ENI lọdun 2011.
” Alaga ohun tun so pe, ki won o to bowolu iwe isuna naa, adinku owo ti o to igba milionu ni won yo kuro, ti ko si ni fi ibi kankan di eto idibo naa lowo .
Àwọn òfin tí a ti kà sílẹ̀ wọnyi ni òfin tí ó jẹmọ́ oríṣìíríṣìí àrùn ẹ̀tẹ̀ ati ti ẹ̀yi ara; 
Richarlison, agbabọọẹu Everton gba kaadi pupa ti wọn fi lee jade ninu ifẹsẹwọnsẹ naa.
Ní ààjìn ni ọwọ àwọn ọlọdẹ orú tẹ Asuquo ní àgbègbè Rumuodara lẹ́yìn to já sọọbu naa láti jẹ Gala, ẹlẹrindodo àti bisikiti.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Baby abandoned on dunmpsite: Mo ti bímọ mẹ́rin tẹ́lẹ̀ fún bàbá méjì nínú òṣí- Dupe Ogbomos Kí wọ́n to di ààrẹ, wọ́n jọ máa n jírorò nilé Akintoye ni, nítori náà gbogbo ipò ti Tola Adeniyi kìí baa wà ni YWC, kò ni àkósílẹ̀ nínú iwe òfin YWC.
Gbogbo ọmọ Wole Soyinka jẹ marun un, obinrin mẹta (Peyibomi Soyinka Airewele, Moremi Soyinka Onijala, Iyatade Apampa) ati ọkunrin meji (Olaokun Soyinka, Makin Soyinka).
    Wọ́n kì í sìnkú ní ìlú náà.
'Ọṣinbajo jọmí lójú pẹ̀lú ìwà akin tó hù' Kò sáyè ìgbafẹ́ mọ́ fáwọn àgùnbánirọ̀ Ta ni Daura DSS tó ń bi oriṣii awuyewuye yìí?
Àwọn ọmọ ogun Nàìjíríà tú àṣírí ẹni tó rán wọn níṣẹ́ lọ kojú àwọn olùwọ́de EndSARS ní Lekki Tollgate Àgbàrá òjò gbé alága àdúgbò àti èèyàn méjì mìí lọ nílùú Ibadan Bakan naa ni Gomina ipinlẹ Osun naa gboriyin fun awọn to ti wa da oun ini ti wọn jigbe lọ pada si iwaju ile ijọba ni ipinlẹ Osun.
 Èmi àti baba amòye la jẹun tán , mo yó .
Ẹwẹ, o ti n polongo fun iwadii ati ijiya fun awọn to ṣe ikọlu naa.
Nigba ti o n sọrọ nibi apero kan ti ajọ eleto idibo lorileede Naijiria INEC ṣagbatẹru rẹ nilu Abuja, Mohammed sọ pe ipinu ile iṣẹ ọlọpaa lori ọrọ kobakungbe ko yatọ si tẹyin wa.
Bakan naa ni ẹgbẹ oselu PDP yoo tun se ifilọlẹ awọn igbimọ tẹẹkoto bii ogun mii fun eto igbajọba to n bọ lọna naa.
Orin náà dùn tó bẹ́ẹ̀ tí mo fi gbàgbé ibi tí mo wà, n kò rántí ìyà tí ó ti ń jẹ mí mọ́, mo la ẹnu sílẹ̀, díẹ̀ ló sì kù kí itọ́ já sílẹ̀ lẹ́nu mi.
Ìgbẹ́sẹ̀ àwọn ọlọpaa kí o tó kú Igba ti wọn si ṣakiyesi pe ko le gbe apa, ko le gbe ẹsẹ, lasiko ti wọn safihan rẹ fun awọn oniroyin ni wọn gbe e lọ sileewosan.
(Health) màrúndínlógún) Clement Ikanade Agba – Edo, Minisita abẹle fun aato ati eto isuna (Budget and National Planning), State mẹ́rìndínlógún) Otunba Adeniyi Adebayo – Ekiti,  Minisita fun ile-eṣẹ, idokoowo ati karakata (Industry, Trade and Investment) mẹ́tàdínlógún) Geoffrey Onyeama – Enugu, Minisita fun ọrọ ile okeere(Foreign Affair) méjìdínlógún) Dr.
Awọn oṣiṣẹ eleto ilera ti ẹbi oloogbe George bẹ lọwẹ lati ṣe ayẹwo lori oku ọkunrin sọ pe ok u lẹyin ti ọlọpaa Minneapolis fun un lọrun.
Àwọn obinrin kan wà ní òkèèrè tí wọn ń wo gbogbo ohun tí ń ṣẹlẹ̀.
Ni bayii, awon alase ile-ise omo ogun Naijiria koi ti so ni pato awon ti o farapa ati iye omo ogun ti o ba isele buruku ohun lo.
Ohun to mu awọn atipo Cameroon yii wa si Naijiria O le lọdun ti igbesẹ awọn afẹhonu han ni orilẹede Cameroon ti fa ọpọlọpọ wahala Awọn apa ibi ti wọn ti nsọ ede Gẹẹsi nsọ wipe ijọba atawọn elede Faranse ti fọwọ rọ awọn sẹgbẹ kan fun ọdun gbọọrọ Awọn afẹhonu han yii npe fun ki wọn da ijọba alapapọ pada tabi didaduro awọn ara ilẹ Cameroon Ni idakeji, awọn to nsọ ede Gẹẹsi maa nsọ wipe wọn yọ nyọ wọn kuro lara awọn lọgalọga osisẹ ijọba ti wọn si nlo awọn elede Faranse Bi o tilẹ jẹ wipe ofin fun ede mejeeji ni ipo kan naa.
Ìbọn ọlọ́pàá ló pa èèyàn, ẹgbẹ́ wa kìí lo ìbọn - Shiite fárígá Àwa ò mọ ẹgbẹ́ kankan tó ń jẹ́ fijilanté fulani l'Ondo- Ìjọba ìpínẹ̀ Ondo Mo mọ̀ọ́mọ̀ dá €37,000 ti mo rí he padà ni -Ọmọ ogun Bashir Bi iroyin kan sọ pe, owo naa to yẹ ki wọn fi gbọ bukata ileeṣẹ ologun ni, ni omiran sọ pe ,ọga ologun kan nigbakan ri lo ni owo naa.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù LASTMA Yesufa: Àwọn dókítà gbìyànjú lórí ojú mi ṣùgbọ́n.
Ijamba ṣe Man United nile wọn lẹyin ti Tottenham wọ wọn ni aṣọ ẹtẹ pẹlu ami ayo mẹfa si ẹyọkan.
Ó pé ọdún mẹ́rìnlélàádọ̀ta tí Akintola kú, ìdí abájọ ìja rẹ̀ pẹ̀lú Awolowo rè é Ọ̀rọ̀ di kọ̀!
2 Kíyèsíi, èmi ni Ọlọ́run; tẹ́tí sí ọ̀rọ̀ mi, èyí tí ó jẹ́ alààyè ati alágbára, ó mú ju idà olójú méjì lọ, láti pín sí ọ̀tọọ̀tọ̀ oríkèé àti mùndùnmúndùn; nítorínáà tẹ́tí sí ọ̀rọ̀ mi.
Surrogate: Ibi táwọn kan ti fẹ́ yọ oyún, ni Judith ti bẹ̀ wọ́n fún pàsípàrọ̀
Ijọba Aarẹ Buhari ti tako ọrọ ti Bishop Ijọ Aguda Mimọ ti ilu Yola, Ẹniọwọ Fr.
Ipinlẹ Cross river lo kere ju pẹlu eeyan kan ni Ọjọbọ.
Ẹgbẹ kan to n pe fun idapada awọn akẹkọọ naa, ti Bukky Shonibare ko sosdi, lo n se iwọde pe ki ijba seranwọ lati ri awọn akẹkọọbinrin naa pada.
Ninu ọrọ tirẹ, minisita lorilẹ-ede Naijiria nigbakan ri, Oby Ezekwesili pẹlu kọminu lori iroyin ọhun.
Lóòótọ́, nígbà tí ó di àfẹ̀mọ́jú, obìnrin náà dé ó sì kó pàṣán bo ọkọ rẹ̀ ó nà án títí ó fi pé ọgọ́rùn-ún pàṣán.
Nígbà tí gbogbo àwọn ìkòkò náà kún, obinrin náà bèèrè bóyá ìkòkò kù, àwọn ọmọ rẹ̀ sì dáhùn pé ó ti tán, òróró náà sì dá.
Oludije meji ṣoju APC to wọle atundi ibo Ariwa Imo Ọrọ di un-un nigba ti ọga INEC, Hakeem Adikum kede pe ẹgbẹ oṣelu APC lo jawe olubori ninu atundi ibo ile aṣofin agba l'Abuja ti ẹkun ariwa ipinlẹ Imo lai darukọ oludije to bori gan an.
Iku wọn ko si ṣẹyin bi okiti yanrin ti wọn n wà ṣe da wo lu wọn ni ibi ti wọn ti n wa yanrin si ọkọ lagbegbe Ologunẹru ni ilu Ibadan.
EndSARS Protest: Àwọn olùwọ́de Endsars ló já sọ́ọ̀bù kìí ṣe torí ebi
Ní ti ìtara ninu ẹ̀sìn, mo ṣe inúnibíni sí ìjọ Kristi.
Ẹ gbọ́, ẹ̀yin ilẹ̀ etí òkun.
Ọgbẹni Oti ṣalaye pe Alfa Hammed to jẹ ọmọ ọdun mẹtalelogun lo riran si akẹkọọbinrin naa wipe yo jade laye laarin wakati mẹrinlelogun ti ko ba ṣe etutu lati yẹ iku kuro lori ara rẹ.
Honorebu Adebisi ni iṣọkan lo n mu ọja dagba sii ni eyi ti yoo tubọ jẹki onikaluku maa ri taje ṣe.
Njẹ o yẹ ki Ọba Alade maa bọ oriṣa Kabiyesi Oluwo ni àrifin àti abuku ń ba ilé Babanla ilẹ̀ Yoruba jẹ́, eyi ti o fi ilú ilé-Ifẹ se ìbùgbe, nítori àwọn kùdiẹ̀-kudiẹ̀ kan ń ṣẹlẹ.
"Bí mo ṣe ń dàgbà ni ǹkan ọmọkùnrin mi ń tóbi síi àmọ́ obìnrin ni mi' €10,000, ara owó tí wọn fi ra Ighalo pòórá, Ilé aṣòfin Osun bẹ̀rẹ̀ ìwádìí Ìwádìí BBC rèé lórí ẹ̀sùn gbájuẹ̀ $120,000 tí wọ́n fí kàn igbákejì olórí òṣìṣẹ́ ìjọba l‘Osun PDP àti APC fi ìbọn dárà l'Ondo, ọ̀pọ̀ èèyan farapa, àìmọye dúkìá ṣòfò ""Dípò ìnákúnàá lórí ìgbéyàwó ọmọ mi, mo lò owó fún ìgbéyàwó ọmọ òrukàn mẹ́tàlá"" Àwàdà kẹríkẹrì nígbà táwọn olùdíje ààrẹ́ Amerika méjì kọjú ìjà síra wọn Ìjọba àpàpọ̀, jọ̀ọ́ máṣe yẹ̀ lórí àdéhùn rẹ fẹ́gbẹ́ òṣìṣẹ́ - Ile aṣojú-ṣòfin Ọgọ́rin arìnrìnàjò tó padà wá sí Nàìjíríà ló ní Coronavirus - PTF Lara awọn to kọwọ rin pẹlu Igboho ni awọn ọmọ ologun ti Area C, awọn osisẹ aabo ara ẹni laabo ilu ati awọn ẹsọ oju ni alakan fi n sọri, taa mọ si fijilante."
títí di isinyi ti iroyin yii n jade Oríṣun àwòrán, Joshua Adetunji Kini o kọkọ ṣẹlẹ?
A óo sì máa sun egungun eniyan lórí rẹ.
 Awon osise eleto aabo naa se ise won gege bi ise ,nigba ti
67 Ààrẹ kọ̀ọ̀kan nínú oyè àlùfáà gìga (tàbí alàgbà tí ó nṣe olórí), bíṣọ́ọ̀pù, ọmọ àjọ ìgbìmọ̀ gíga, àti àlùfáà gíga, ni a ó yàn lábẹ́ ìdarí àjọ ìgbìmọ̀ gíga tàbí nínú ìpàdé àpéjọpọ̀ gbogbogbòò.
ọ̀dọ́ 47,000 fẹ́ di Amotekun, agbófinró yẹ̀ wọ́n wò yẹ́bẹ́yẹ́bẹ́ Aáwọ̀ oyè PDP gbé Fayose àti Seyi Makinde kọlu ara wọn, ìjà ń bọ̀ Bàbálọ́jà márùn ún la ó ò ní l'Oyo tí Makinde bá lè buwọ́lu ìyànsípò YK Abass Auxiliary gbé èèyàn mẹ́fà tó ń jáwèé ayédèrú fáwọn awakọ̀ lọ sí ilèẹjọ́ ní Ibadan Amọ o ni isan oju ara obinrin lo n se ohun to wu, ifarabalẹ laarin ololufẹ mejeeji si ni ẹrọ rẹ lẹyin akoko diẹ, o ni bi wọn ba ti fun won loogun orun tabi sun, ara yoo tu wọn.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Nitori naa lẹyin ti o ba jẹ akara oyinbo, kaka ti o fi mu ọkan rẹ kuro ki o si tesiwaju, yoo tun jẹ ẹ bi ẹmẹẹta si.
Oríṣun àwòrán, @vickisex Àkọlé àwòrán, Ile ẹjọ kọ lati da Sowore ati Bakare silẹ Sowore ati Olawole Bakare ti wọn n pe ni Mandate ni wọn jọ gbe wa sile ẹjọ laarọ yii.
Buhari ni ipaniyan to gbérí padà ní Plateau jẹ́ òun tó n kọni lominu ati pé ìjọba òun yóò wá wọ̀rọ̀kọ̀ fí ṣada láti dẹkùn rẹ Àwòrán ìkọlù Plateau tí ọ̀pọ̀ ẹ̀mí ti sùn Ìgbà wo ni Buhari yóò simi àwáwí?
Wọ́n gbé asà ati àṣíborí wọn kọ́ sinu rẹ, wọ́n jẹ́ kí o gba ògo.
Ìtìjú ńlá gbáà ló jẹ́ fún ìjọba tiwantiwa, bí ètò ìbò tí o yẹ kí ó lọ ní ìrọwọ́-ìrọsẹ̀ láì fi ti apá kan ṣe, ṣùgbọ́n tí ìṣesíi wọn kò fi ìṣedéédé hàn, àìmúdọ́gba tí ó hàn kedere, ẹ̀tàn àti ìjòye àwòdì máà le è gbẹ́dìẹ.
Ọ̀pọ̀lọpọ̀ ilé oníyàwó  púpọ̀ ma nda ahoro lẹhin ikú Olóri ilé nitori kò si ẹni ti ó ni ìfẹ́ tọ si Bàbá oníyàwó  púpọ̀.
Ilẹ̀ ọ̀hún kìkì òkè ni, ó sì kún fún àwọn igbó aginjù ńlá-ńlá àti adágún odò fífẹ̀ ní ọlọ́kanòjọ̀kan.
Ẹ má jẹ́ kí ẹ̀ṣẹ̀ di ọ̀gá yín, nítorí ẹ kò sí lábẹ́ Òfin; abẹ́ oore-ọ̀fẹ́ ni ẹ wà.
Nigba to n fidi isẹlẹ naa mulẹ, Agbẹnusọ fun ileesẹ ọlọpaa nipinlẹ Oyo, Olugbenga Fadeyi ni lootọ ni.
O óo wí fún un pé, Èmi, OLUWA wí pé, ‘Israẹli ni àkọ́bí mi ọkunrin.
Kọmiṣọnna eto ilera ṣalaye pe ko si ẹni ti o ni apẹẹrẹ pe o ni aarun covid-19 ninu awọn oṣiṣẹ naa ti wọn lugbadi coronavirus.
 Besini, A ki lopolopo fun gbigba re lati farajin fun ajo yii.
 kò sì sí ìgbà tí wọ ́ n bá ń lu ìlù yí tí ogun bá wà tí kò ní ṣẹ ́ gun .
Inú OLUWA dùn sí Abeli, ó sì gba ẹbọ rẹ̀, 
won ba di fun oun ,Bola Tinubu ni won dibo naa fun .
gígùn ọ ̀ sà yìí ju àádọ ́ ta kìlómítà lọ , ó jìnà sí òkun pẹ ̀ lú fífè méjì sí márún , tí ó sì ní irà lẹ ́ bá etí ọ ̀ sà .
Maradona nikan ni balogun ẹgbẹ agbabọọlu to ṣoju orilẹede rẹ fun akoko to pọ julọ.
Marcus Pace sọ pe oun ti maa n ṣabẹwo si Ugandan loorekoore lati ọjọ to ti pẹ, ṣugbọn oun ti wa pinnu lati fidi mọlẹ si Afrika bayii.
’ Oluwa bá dáhùn ó ní, ‘Èmi ni Jesu tí ò ń ṣe inúnibíni sí.
Adájọ́ fi agbẹjọ́rò si àtìmọ́lé 'Ẹ máa bọ wálé wá ṣẹ̀wọn yín' Ọ̀pọ̀ ẹ̀mí sọnù sínú ilẹ̀ rírì Indonesia Àkọlé àwòrán, Oga ọgba ẹwọn l'Eko, Tunde Ladipo ni awọn n sa ipa lati ri i pe awọn ẹlẹwọn naa ṣe daadaa ninu idanwo wọn Ninu awọn mẹtadinlọgọjọ naa, awọn mọkanlelaadorun wa lati ọgba ẹwọn Ikoyi, mejila wa lati ọgba ẹwọn ti obinrin ti mẹrinlelaadọta si wa lati ọgba ẹwọn Kirikiri.
Eto sogun-dogoji Claritta ni tiẹ naa fẹ ẹ fara jọ MMM.
Chris Oyakhilome: Wọn tí fòfin de iléeṣẹ́ ìròyìn Chris Oyakhilome lẹ́yìn tó sọ pé 5G lọ ṣokùnfà Coronavirus
Sugbọn igbimọ ile asofin to wa feto isuna, ninu awijare rẹ ni, ile ti fi aaye silẹ fun ẹka alasẹ lati gba owoya fi gbọ bukata aba isuna ọhun, eyi to mu ki aba isuna naa ga soke.
Ó ní àwọn òṣìṣẹ́ tí wọn ń dá oko fún un ati àwọn tí wọn ń ṣiṣẹ́ ninu àjàrà, lórí òkè ati lórí àwọn ilẹ̀ ọlọ́ràá, nítorí ó fẹ́ràn iṣẹ́ àgbẹ̀.
Ẹwẹ, Akintoye funra rẹ ninu ifọrọwerọ kan ni eeyan mẹrin pere ko lagbara lati yọ oun nipo Aarẹ, ati pe oun mọ pe inu lo n bi wọn.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Makinde: Ẹgbẹ́ òṣìṣẹ́ faramọ́ wíwọ́gilé ₦3000 táwọn akẹ́kọ̀ọ́ girama ń san Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Àwọn aladugbo ibí tí ìjọba Èkó tí n wole sọ èrò ọkàn wọn Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Ninu ẹka asoju mejilelọgbọn Inec ni awọn kede esi dibo to waye ni aaye idibo mọkanlelogun.
ti iji lile naa si ti ran eeyan to le ni ọgọsan si ọrun ọsan gangan, ni ẹkun guusu Afrika.
O bẹnu ẹ̀tẹ́ lu bi Aarẹ Buhari ṣe n fọwọ yẹpẹre mú ọ̀rọ̀ àwọn Fulani darandaran to ti n gbẹbọ lọ́wọ́ tonile-talejo ni Naijiria lasiko yii.
Adebimpe Oyebade àti Lateef Adedimeji Bí ọ̀ṣẹ méjì sẹ́yìn ni òkìkí kan nígbà ti àwòràn kan fẹ́ fa orí ayélujára ya lórí pé bóya Adebimpe àti Adedimeji ṣe ìgbéyàwó.
Kí a má sa fa ọ̀rọ̀ náà gùn lọ títí, Gọ̀ǹgọ̀ṣú- tàkìtì padà, Ìnàkí-gorí-ìtẹ́ náà sì tẹ̀lé e.
Bi o ṣe n jo, bẹẹ naa ni awọn eeyan n na lowo ti o si n sọ pe ''Iya Peju ti fẹ jẹ gbese.
Kò sí ìsinmi ìdajì táàmù fáwọn akẹ́kọ̀ọ́ ìjọba l‘Ọyọ - Seyi Makinde Ìjọba mi ṣetán láti mú àgbéga bá ètò ààbò l‘Ọyọ - Seyi Makinde Lẹ́yìn ò rẹyìn Seyi Makinde búra fún ìgbìmọ̀ olùgbaninímọ̀ràn Awọn orukọ naa ni: Hon Barrister Adeniyi John Farito Mr Adeniyi Adebisi Hon Muyiwa Jacob Ojekunle Prof Oyelowo Oyewo Barrister Olasunkanmi Olaleye Barrister Seun Asamu Mr Rahman Abiodun AbdulRaheem Chief Bayo Lawal Hon Funmilayo Orisadeyi Dr Bashir Bello Hon Wasiu Olatunbosun Prof Daud kehinde Sangodoyin Mr Akinola Ojo Rt Hon Kehinde Ayoola Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Biden fọwọ idaniloju naa sọya ninu ọrọ akọsọ rẹ to bawọn eeyan orilẹede Amẹrika sọ lasiko ti wọn n se ajọyọ bo se bori ibo naa.
Kí gígùn rẹ̀ jẹ́ igbọnwọ kan, fífẹ̀ rẹ̀ yóo sì jẹ́ igbọnwọ kan.
"Oṣiṣẹ tọwọ ba tẹ yoo jiya iṣẹ ọwọ rẹ""."
"Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: 'Ẹnu lásán kò lè sàn owó oṣu oṣiṣẹ l'Ekiti' Ó kù díẹ̀ kí UNN rán akẹ́kọ̀ọ́ kan sọ́run àrèmabọ̀ ""A kò ní jẹ́ kí 'Nigeria Air' ṣiṣẹ́"" Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Lion Chaser: Richard, ọmọ ọdún mẹ́ẹ̀dógún se iná tó ń lé kìnìún Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!"
Ọkàn rẹ kún fún ìgbéraga nítorí pé o lẹ́wà, o ba ọgbọ́n rẹ jẹ́ nítorí ògo rẹ.
" Oríṣun àwòrán, Jidenna/instagram Jidenna Ọmọ Naijiria ati ilẹ America ni Jidenna Theodore Mobisson, to tun jẹ akọrin takasufe naa dasi ọrọ ipolongo ENDSARS.
Ṣé o wá fẹ́ pa ìlú tí ó jẹ́ ìyá ní Israẹli run ni?
Kíni àwọn ìpèníjà ẹtọ ààbò ṣáájú òmìnira Nàìjíríà?
Ọjọ méjìléláàdọ́fà lo ku ki idibo ọdun 2019 fi waye, awọn oludije mọ́kàndínlọ́gọ́rin ( 79) si ni yoo du ipo Aarẹ.
Oríṣun àwòrán, olanrewaju Onigegewura Àkọlé àwòrán, Aarẹ Kakanfo kii saba n ba alaafin gbe ilu Yatọ si wipe o jẹ onisowo, ohun kan ti o tun mu ki araye fẹ Abiọla ni bi o se fẹran lati maa fi owo ṣaanu fun awọn ti ko ni.
Aarẹ apapọ fun ijọ Winners, Bishọọbu David Oyedepo, ti sọ asọtẹlẹ pe gbogbo agbara okunkun to n jọba lori ilẹ Naijiria ati ni Afrika ni yoo kan abuku ki ọdun yii to pari Bishọọbu Oyedepo kede bẹẹ lasiko iwaasu rẹ nibi ipade ajọ nla Shiloh, Ogun iru rẹ, to side rẹ ninu gbọngan nla ijọ naa to wa nilu Ọta, nipinlẹ Ogun.
Nítorí èyí gan-an ni mo fi rán an wá sọ́dọ̀ yín, kí ẹ lè mọ bí gbogbo nǹkan ti ń lọ fún wa, kí ó lè fi ọkàn yín balẹ̀.
Wọ́n gba ilẹ̀ Firigia ati Galatia kọjá.
Ọlọrun bukun wa,kí gbogbo ayé máa bẹ̀rù rẹ̀.
Ọbasanjọ sọ àsírí sàgbàdèwe rẹ̀ Àrà méèrírí , ẹ wo ọkùnrin tí eegun rẹ̀ rọ̀ bíi rọ́bà, tó ń ká bíi ẹja O ni oun gba Ikimot wo lẹyin ti iya rẹ ku ni, bẹẹ ni oun gbinyanju lati wa ọmọ naa, toun si ta awọn goolu oun lati wa a, sugbọn oun sọ ireti nu lẹyin ọdun meji, ko to fi ẹsẹ ara rẹ rin pada wale.
“Bí ẹnikẹ́ni bá wí fun yín pé.
Bẹẹ lo si rọ awọn ara ipinlẹ naa lati ṣe bẹẹ gẹgẹ.
Ènìyàn 238 míràn tún ti ní ààrùn Coronavirus ní Nàíjírìa Ìdí tí Ààrẹ Trump fi dínà mọ́ Nàìjíríà àtí orílẹ̀èdè márùn ún míì láti má wọ Amẹ́ríkà Ọmọ Nàìjíríà, ẹ gbé ilé yín silẹ ká fi ṣe ibùdó iyasọtọ - Minisita rawọ ẹbẹ 'Ọjọ́ lọjọ́ tí mo mọ̀ pé wọ́n bí mi láì ní ojú ara obìnrin àti ilé ọmọ' Àwọn tó jí ìbejì mi gbé ti pè mí ṣùgbọ́n N50 mílíọ̀nù tí wọ́n ń béèrè pọ̀ ju agbára mi lọ-Akeugbagold Laipẹ yii ti wọn dan oogun naa wo fun Covid-19, o ṣe iranlọwọ lati mu ki ara awọn ti aarun naa ṣe ni ijamba pupọ ko tete ya laarin ọjọ mọkanla dipo ọjọ mẹẹdogun to maa n gba wọn lọ tẹlẹ.
Ó ní, “Ẹ gbọ́, ẹ̀yin ọmọ Lefi, ẹ ya ara yín sí mímọ́, kí ẹ sì ya ilé OLUWA, Ọlọrun àwọn baba yín sí mímọ́ pẹlu.
Nígbà tí ìyá mi ṣàdúrà fún mi, tí ó sọ gbogbo èyí tí ó níi sọ tán, ṣe ni mo wọ ìyàrá lọ, tí mo lọ sọkún bí ẹni pé ọ̀fọ̀ ṣe mí.
aré yi wọ ́ pọ ̀ lágbègbẹ ̀ Èkìtì .
Lẹ́yìn náà, Mose ati Aaroni lọ sọ́dọ̀ Farao, wọ́n sọ fún un pé, “OLUWA, Ọlọrun Israẹli sọ pé, ‘Jẹ́ kí àwọn eniyan mi lọ, kí wọ́n lè lọ ṣe àjọ̀dún kan fún mi ninu aṣálẹ̀.
Ko to di oloogbe, Kazeem ni igbakeji balogun ikọ agbabọọlu Remo Stars to wa nipinlẹ Ogun.
Nǹkan kan náà ni gbogbo àwọn wolii yòókù ń wí, gbogbo wọn ní kí Ahabu lọ gbógun ti Ramoti Gileadi, wọ́n ní OLUWA yóo fún un ní ìṣẹ́gun.
Ọdọmọbinrin náà dára gan-an; ó wà lọ́dọ̀ ọba, ó ń tọ́jú rẹ̀, ṣugbọn ọba kò bá a lòpọ̀ rárá.
Francois so fun ile-ise iroyin AFP lojo-Aiku pe, “awon onisegun so pe, awon meta ni won wa nipo elege, amo ara won ti n bale bayii”.
Ifẹsẹwọnsẹ naa to jẹ igabradi idije ife ẹyẹ ilẹ Afrika, AFCON, ti yoo waye lọdun 2021 ni yoo waye ni papa iṣẹre Samuel Ogbemudia ni ilu Benin.
Adari ijoba orile ede Britan, Theresa May , ti ni oun yoo kuro lori ipo gege bi adari ijoba orile
Pasitọ Bakare sọrọ yii ninu fidio kan to wa lori ayelujara eleyi tawọn eeyan ti n sọrọ nipa rẹ.
Ó bá dáhùn gẹ́gẹ́ bí wolii Aisaya ti sọ pé:“Èmi ni ‘ohùn ẹni tí ń kígbe ninu aṣálẹ̀ pé:Ẹ ṣe ọ̀nà tí ó tọ́ fún Oluwa.
Ilé ẹjọ́ tú ìgbéyàwó ọdún mọ́kànlá ká nítórí pé ìyàwó fí ìbálòpọ̀ dun ọkọ rẹ̀ Ṣé irúfẹ́ oúnjẹ tí ò ń jẹ́ lè jẹ́ kí o gbádùn ìbálòpọ̀ rẹ síi?
Ninu ohun to maa n ṣe koriya fun wọn lasiko yi ni bi awọn agbabọọlu ti ṣe maa n tasẹ ati bi ẹni to n ṣalaye bi nnkan ṣe n lọ lori papa naa ba ṣe n pitu tiẹ naa.
Àwọn aláṣẹ fásitì Eko ninu atẹjade ti ti kéde pé ki Omowe Boniface lọ rọọ́kún nílé ná Fasiti Eko kede pe Ọmọwe Boniface ko gbọdọ lọ si agbegbe ikọwe ni fasiti naa lẹyin ipade pajawiri ti wọn ṣe.
Ko si idi meji ju bi awọn olukọni naa ti ṣe faake kọri pe iyanṣẹlodi ọlọjọ gbọọrọ lawọn yoo fi yanju ọrọ ilaji owo osu ọdun meji ati aabọ ti ijọba ipinlẹ Ọṣun jẹ wọn.
Iroyin fi mule pe, okan lara osise ajo NDLEA nipinle Cross River lo sawari agbegbe ibi ipese egbogi oloro yii, ti o si tun je agbegbe kan ti o n pese epo pupa.
CAN kò rán ẹnikẹ́ni lọ ṣọ́ọ̀ṣì COZA, iṣẹ́ ara wọn ní wọ́n lọ jẹ́ -Samson Ayokunle Ìdí rèé tí mi ò fi yọjú sí ìgbìmọ̀ àjọ PFN- Fatoyinbo Bíodun Fatoyinbo ti fojú hàn ní àgọ ọlọpàá Agbẹjọrọ lati ile iṣẹ Pelumi Olajengbesi and Co lo gbe ẹjọ naa lọ sile ẹjọ lorukọ Busola Dakolo.
Jonatani bá dáhùn pé, “N óo ṣe ohunkohun tí o bá fẹ́.
(Mail) Ìjọba ti bẹ̀rẹ̀ sí báwọn tó gbé òṣìṣẹ́ aláàánú mẹ́fà sọ̀rọ̀- Garba Shehu Israel Adebajo: Ìlúmọ̀ọ́ká oníṣòwò tó fi òkò Stationery Stores pa ẹyẹ púpọ̀ Ọlọ́wọ́ idán Houdini kò yè é o, ó bómi lọ!
N óo wá mọ agbára tí àwọn tí wọn ń gbéraga ní nígbà náà, yàtọ̀ sí ọ̀rọ̀ ẹnu wọn lásán.
Yọ mí kúrò ninu ogun tí wọn gbé tì mí,gbà mí kúrò lọ́wọ́ àwọn kinniun!
’’Alaga egbe oselu  APC wa dupe lowo asoju orile ede Britain fun orile ede Naijiria,Paul Arkwright naa fun atileyin  re lori eto ijọba tiwa-n-tiwa lorile ede Naijiria.
Jesu wò yíká pẹlu ibinu, inú rẹ̀ sì bàjẹ́ nítorí pé ọkàn wọn le.
Leyin ti iko agbaboolu Golden Eaglets ti gba ife-eye idije CAF U17 Africa Cup of Nations, aare ajo to n mojuto boolu afesegba lorile-ede Naijiria, Amaju Pinnick so pe, ohun yoo ri daju lati pese awon ohun elo lolokan-o-jokan to peye fun iko naa lojuna lati je ki iko ohun kopa daradara ninu idije U17 AFCON ti yoo waye lorile-ede Tanzania.
‘Operation Positive Identification’ láti kojú Boko Haram ti bẹ̀rẹ̀!
Gbogbo álúfábẹ́ẹ̀tì Yorùbá mẹ́dẹ̀ẹ́dọ́gbọ̀n ni wọ́n péjọ sínú gbólóhùn yìí.
 a kò lè ronú lọ ́ nà kan ṣoṣo , nítorí náà , ìjà àti asọ ̀ máa ń jẹ ́ àwọn nǹkan tí a kò lè ṣàì má rì í níbi ti àwọn ènìyàn bá ń gbé .
Oríṣun àwòrán, Getty Images O fi kun un pe, ida mọkanlelogun awọn obinrin to n gbe ni igberiko lo san owo ẹyin fun oṣiṣẹ ijọba kan ninu gbogbo awọn obinrin igberiko to ni ohun kan tabi omiran lati ṣe pẹlu awọn oṣiṣẹ ijọba laarin oṣu mejila to ṣaaju iwadii ọdun 2019 yii.
Ido-Ani Robbery: Àwọn adigunjalè pa ènìyàn mẹ́fà ní báńkì kan nìpínlẹ̀ Ondo
Ko ti si iroyin nipa ibi ti awọn ẹlẹwọn to ku wa tabi boya ọwọ ti tẹ wọn.
Opọlọpọ lo ni orin yii n fọn rere pe ki awọn eeyan maa mu oogun oloro ni eyi to jẹ ki ajọ to n mojuto ere idanilaraya ti a n gbe sita ni Naijiria, iyẹn, National Broadcasting Commission fi ofin dee.
Akọkọ ni adura fun orilẹede wa, ekeji ni adura fun awọn ọmọ ilẹ yii, ti ẹkẹta si jẹ adura fun awọn idile lorilẹede Naijiria.
N óo máa ṣe àṣàrò ninu òfin rẹ,n óo sì kọjú sí ọ̀nà rẹ.
Oríṣun àwòrán, APC Bẹẹ si ni iroyin kan nigba ti Gomina Ipinlẹ Imo, Rochas Okorocha fa ana rẹ silẹ wipe oun ni oun ti lẹyin.
Ìyáàfin Olúmúyìwáá Mama Tise, Ìyá Àgbà Mama Adébọ́lá
tẹle ofin agbaye to rọ mọ ẹtọ ọmọniyan .
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Josh Posh: Irun mií tó ‘Posh’, làwọn èèyàn se ń pè mí ní Josh Posh Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Josh Posh: Irun mií tó ‘Posh’, làwọn èèyàn se ń pè mí ní Josh Posh 7 Owewe 2018 Joshua Roberts, tawọn eeyan n pe ni Josh Posh jẹ ọdọmọde olorin to gba iwuri orin kikọ lede Yoruba lati ọdọ iya rẹ.
Dafidi ati àwọn ìjòyè àwọn ọmọ Israẹli tí wọ́n wọ aṣọ ọ̀fọ̀ bá dojúbolẹ̀.
Ṣugbọn inu wa dun pe ibeere yii jẹ ki awọn eniyan gbero lati pada lọ sile lọ beere nipa olugbodi lọwọ awọn agbalagba ile wọn.
Asenati, ọmọbinrin Pọtifera bí Manase ati Efuraimu fún Josẹfu ní ilẹ̀ Ijipti.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù OsunDecides: Omisore ní ẹni tó bá fẹ́ ra ìbò, àwọn yóò lọ lásọ mú ni Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ OsunDecides: Omisore ní ẹni tó bá fẹ́ ra ìbò, àwọn yóò lọ lásọ mú ni 19 Owewe 2018 Oludije fun ipo gomina labẹ asia ẹgbẹ oselu Social Democratic Party (SDP) ni ipinlẹ Ọsun, Sẹnetọ Iyiọla Omisore, lasiko to n ba BBC Yoruba sọ̀rọ̀ ni, ẹgbẹ alatako ni yoo bori ibo gomina ni ipinlẹ Ọsun, gẹgẹ bo se waye ni Ekiti, nitori isejọ̀ba ẹgbẹ to wa lori aleefa ti su awọn ara ilu.
fun ekun Ariwa – Binta Mu’azuIgbakeji oludari
Gbogbo ìjọ eniyan yóo sọ ọ́ ní òkúta pa, kì báà jẹ́ àlejò, kì báà jẹ́ onílé; tí ó bá ṣá ti sọ̀rọ̀ òdì sí orúkọ OLUWA, pípa ni wọn yóo pa á.
NIN Registration: Mínísítà ní bó yá n'ìjọba kò ní dá ìforúkọsílẹ NIN dúró tórí ewu Covid-19
Mọlẹbi yii to ni ki wọn fi orukọ bo oun laṣiri ni A gbe owo itanran miliọnu mẹta ati aabọ pẹlu paali Schinaapu kan ati jálá lita epo pupa ọgbọn ati iṣu nlanla mẹwaa ati ororo jala lita marun un lọ fun wọn."
” Kí gbogbo wa káàkiri àgbáyé jáwọ́ nínú ìwa ẹlẹ́sìnmẹ̀sìn tó nkó jambá nlá ba ilé-ayé yìí.
Àwọn ohun tuntun tí a mọ̀ nípa ìgbẹ́jọ́ Wòlíì Sotitobire Yatọ si ọkan o jọkan awọn ẹlẹri to n jẹri lori ẹjọ, fidio wolii Babatunde Alfa ti ọpọ mọ si Sọtitobirẹ ni wọn tẹ pẹpẹ rẹ sita nile ẹjọ lọsẹ yii gẹgẹ bi ara awọn ẹsibiiti ti olupẹjọ fẹ tẹ siwaju ile ẹjọ.
" oríṣiríṣi rúkè-rúdò ló wáyé nígbà tí gbajú-gbajà olórin náà ń gba àwọn ènìyàn níyànjú láti yàgò fún ìwà "" akọ sí akọ "" tí ó sì di ẹ ̀ bi ìwà náà lé ìwà lílò ògùn olóró lórí ."
Lẹ́yìn wọn ni àwọn Melataya, ará Gibeoni, Jadoni, ará Meronoti, ati àwọn ará Gibeoni ati àwọn ará Misipa tí wọ́n wà ní abẹ́ ìjọba Ìkọjá Odò ṣe àtúnṣe abala ọ̀dọ̀ tiwọn.
Ṣe ni yóò maa yọ fẹẹrẹ lọwọ rẹ bí ẹni ń fi nkan ṣeré .
Ó tún wá, ó tún bá àwọn ọmọ-ẹ̀yìn tí wọn ń sùn, nítorí oorun ń kùn wọ́n pupọ.
Ògbórògbánńdá ajogun ( Ọbańta ) gbé winniadé , ọmọ osi níyàwó .
3 trillion ni CBN gbé jáde fún ọdun 2020 Asoju Emir Ibrahim Abubakar sọ wi pe Emir naa gbe igbesẹ naa lati le tẹ awọn eniyan ara ilu naa lorun, ati wi pe o seesẹ ki orukọ omugọ naa ma a da wọn laamu.
Ṣùgbọ́n iwin náà kò le wẹ̀.
'' Ṣé Fulani daran-daran ni àwọn tó n jí ènìyàn gbé ní ìpínlẹ̀ Ondo?
Sc, ati iwe ẹri imọ ijinlẹ keji.
Lootọ ni ọrọ ko ti i de ile ẹjọ, ṣugbọn Ọga Agba ọlọpaa ni Naijiria, Mohammed Adamu, ti paṣẹ pe ki iwadii o bẹrẹ lori rẹ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Kunle Afolayan: Òun àti Mike Ezuruonye ń gbéná wojú ara wọn lórí ayélujára 28 Owewe 2020 Oríṣun àwòrán, Instagram Nnkan ko rọgbọ laarin awọn eekan meji lagbo ere sinima lorilẹede Naijiria, Mike Ezuruonye ati Kunle Afọlayan lasiko yii.
Nínú ọ̀rọ̀ rẹ̀, àgbẹnusọ ààrẹ CAN, Pásítọ̀ Bayo Oladeji tó sọ̀rọ̀ lórúkọ ààrẹ ẹgbẹ́, Dókítà Supo Ayokunle ni, gbogbo àwọn alága ìpínlẹ̀ ni àwọn ti jọ sọ̀rọ̀ yé pọ láti tẹ̀lé òfin ti ìjọba ìpínlẹ̀ ti wọ́n wà bá là sílẹ̀ lori sise aisun ọdun tuntun.
Àkọlé àwòrán, Bakan naa ni awọn agbofinro pẹlu naa jabọ eto abo ti wọn ti gbe kalẹ fun idibo naa faraalu Kọmisọna tuntun fun ajọ ọlọpa nipinlẹ Ọyọ, Shina Tairu Olukolu naa ṣe afihan igbaradi ajọ ọlọpa nibi akanṣe apero naa.
Komisana fun irina nipinlẹ Eko Ladi Lawanson ṣalaye loju opo Twitter ijọba Eko pe iyipada yi waye lẹyin ti awọn ṣe agbeyẹwo eto irina ti wọn ti ṣe tele ti wọn si tẹti si ohun ti ara ilu sọ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Hate Speech: Àwọn ọ̀dọ́ Nàìjíríà kẹ̀yìn sí ìjọba lórí ofin sísọ̀rọ̀ àlùfànsá 27 Bélú 2019 Káákiri ìpínlẹ̀ tó lé ní ogún ni ìwọ́de náà ti ń wáyé lórílẹ̀èdè Nàìjíríà.
"Oríṣun àwòrán, @OfficialPDPNig Àkọlé àwòrán, Àwọn ọmọlẹ́yìn Elzakyzaky ń pè fún ìtúsílẹ̀ aṣíwájú ìjọ náà tí ìjọba fi sí àtìmọ́lé lọ́dún 2015 ""Lójú àwọn ọlọ́pàá yìí, tí o bá ti leè sọ fún wọn pé ọmọ ìjọ Shi'ite ni ẹ́, wàhálà ni wọn yóò gbé dìde."
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù EndSARS Protes Updatet: Aláàfin Ọyọ ní ọ̀dọ́ ìwòyí kò gba gbẹ̀rẹ́, kíjọba yé halẹ̀ mọ́ wọn 5 Bélú 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 14 Bélú 2020 Oríṣun àwòrán, Facebook/Alaafin Oba Adeyemi III Alaafin ilu Oyo, Oba Lamidi Olayiwola Adeyemi ti parọwa si ijọba lati jawọ ninu idukoko mọ awọn ọdọ lẹyin ti wọn ṣe ifẹhọnuhan EndSars ni oṣu to kọja.
CAN kò rán ẹnikẹ́ni lọ ṣọ́ọ̀ṣì COZA, iṣẹ́ ara wọn ní wọ́n lọ jẹ́ -Samson Ayokunle Yinka Ayefele di bàbá ìbẹta Wá gbọ́ ìmọ̀ràn tí Jonathan fún Buhari lórí ọmọ Fasoranti tó kú!
Aare orile-ede Naijiria, Muhammadu Buhari fi edun okan re han, bee si ni O seleri lati fopin si ijiya awon ti o fara kaasa ikolu iko omo ogun olote Boko Haram lorile-ede yii.
Àkọlé àwòrán, Emzor ní òun ti ń se ìwádìí Chukwunonye Madubuike (ọwọ́ ọ̀tún) Àwọn òṣìṣẹ́ iléeṣẹ́ apo-òògùn ikọ́ olómi tó ní èròjà codeine síta mọ̀ nípa ewu tó rọ̀ mọ́ àṣìlò òògùn ikọ́ olómi tó ní èròjà codeine.
Igbimọ naa n wadi awọn ẹsun titẹ ẹtọ ọmọniyan mọlẹ to waye lasiko iṣejọba Jammeh.
Tani Deji Adenuga to dáná sun ènìyàn mẹ́jọ?
Àwọn odò ilẹ̀ Edomu yóo di ọ̀dà,erùpẹ̀ rẹ̀ yóo di imí ọjọ́;ilẹ̀ Edomu yóo di ọ̀dà tí ń jó bùlàbùlà.
Ohun ìní Àwọn ǹkan ìní ilẹ̀ Gẹ̀ẹ́sì yóò wálẹ̀, ọ̀pọ̀ àwọn ènìyàn ló nílò owó, èyí yóò si jẹ́ ànfàni fún àwọn to ṣe idókodòwò ilẹ̀ okeèrè, to fi mọ́ àwọn to wá láti ilẹ̀ Afíríkà.
O wa ro gbogbo omo orile-ede South Africa lati fowosowopo mu igberu ba awon obinrin ni abala eto oro aje, lati le ri daju pe, won se aseyori eto dogba-dogba, “awon obinrin gbodo wa ni awon ile-ise gbogbo, ki won si maa gba iye owo kan naa, ti akegbe won okunrin n gbaBakan naa ni o so pe, awon omo orile-ede South Africa gbodo gbogun ti awon ipenija ti o n dena awon odobinrin lati pari eko won, tabi lati tesiwaju ninu eko won.
Saraki pè fún ìwádìí ikú olórí ikọ̀ adigunjalè tó ṣọsẹ́ ní Offa Obìnrin awakọ̀ Bàálù àkọ́kọ́ láti Ọffa rèé Gómìnà tí wọ́n yàn ní Kwara, Abdulrazaq ní òun yóò tún ìdigunjalè Offa yẹ̀wò Lẹyin ọjọ diẹ ti iṣẹlẹ alagbara naa waye ni ileesẹ ọlọpaa kede pe ọwọ titẹ awọn afurasi meje nipa iranlọwọ fidio ati aworan ti ẹrọ ayaworan to n bẹ ninu ọgba ileefowopamọ ka silẹ.
Dafidi bá bèèrè pé, “Báwo ni n óo ṣe mọ̀ bí baba rẹ bá bínú?
 ilẹ ̀ germany pàsẹ láti tú àwọn ọmọ ogun tí wọ ́ n ti kójọ tẹ ́ lẹ ̀ kọ ́ fún ogun yìí ká .
O ni bawo lo ṣe jẹ́ pé awọn darandaran ti ko pa awọn ọmọ ilẹ̀ Libya ni wọn ń wá pa àwọn èèyàn ní Nàìjíríà.
Àwọn akọni mẹta lagbo tíátà náà, tí wọn wa lati ìjọba ìbílẹ̀ Irepodun nipinlẹ Kwara, ni wọ́n ko leè kọ iyán wọn kéré lagbo osere tíátà ni èdè Yorùbá.
Ní àpapọ̀, àwọn nǹkan ọrẹ tí àwọn olórí mú wá fún yíya pẹpẹ sí mímọ́ ní ọjọ́ tí a fi àmì òróró yà á sí mímọ́ ni: abọ́ fadaka mejila, àwo fadaka mejila, àwo kòtò tí wọ́n fi wúrà ṣe mejila, 
’ ‘Baba wa, Oloye Kolapo jẹ ẹni to ni iwa tutu, to si fẹran awọn ara ipinlẹ Oyo nigba ti o wa laye.
Mi o ṣẹṣẹ ma s pe oun ni ẹgbẹ to ti gba ami ẹyẹ julọ ni ilẹ Gẹẹsi'' O salaye pe nigba ti oun lọ si Arsenal,o dun mọ oun ṣugbọn United n gboro si lasiko naa ti wọn si n ra awọn agbabọọlu tori pe wọn fẹ pegede.
A gba ìkógun lọ́wọ́ àwọn akikanju,wọ́n sun oorun àsùn-ùn-jí;àwọn alágbára kò sì le gbé ọwọ́ láti jà.
Abdullahi sọ pe ọrọ ti awọn to tako aba naa atawọn to fara mọ ọ sọ yoo wulo lati ṣe ofin gidi ti yoo dẹkun ọrọ ikorira lorilẹede Naijiria.
 Àwon tí o bá gbégba oróke nínú eré ìje to to saaju àsekágba oróke n sare nínú asekàgbá eré ìje .
Awọn nkan to yẹ ki a ma bere ree lọjọ oni'' O ṣalaye pe nipa eto abo ati ilera, ijọba Naijiria ni lati ṣe ju bi wọn ti n ṣe lọ ki ilu baa le rọgbọ fara ilu.
Sugbọn kii ṣe ọrọ Obasanjọ nikan lo gboju opo ayelujara.
Lasiko ta n wi yi,o le ma se aarẹ ti awọn eeyan mi ko si ni se afihan apẹrẹ arun yi.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Ọlọpaa ni Umar kan naa lo dari ikọ to ṣe ikọlu si orita-mẹta Galadimawa ni Abuja nibi ti wọn ti pa ọlọpaa meje.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Lush Beauties: Ẹ má jẹ́ k‘ójú tì yín torí pé ẹ sanra, ẹ jáde síta Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Lush Beauties: Ẹ má jẹ́ k‘ójú tì yín torí pé ẹ sanra, ẹ jáde síta 8 Ẹrẹ̀nà 2018 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 19 Ògún 2018 Awọn ọmọ ẹgbẹ́ Lush Beauties, lasiko ti wọn n ba BBC Yoruba sọrọ ni, awọn to sanra maa n ni idojukọ gan ni, nitori pe ọpọ wọn ni kii wọ ọkọ elero abi ọkada nitori itiju, tawọn ọlọkọ yoo si ni ki wọn sanwo eeyan meji.
 Guterres tun so pe iwe ofin ti aare tun towobo “ko kere ju lati dije” ati iwe ofin lori eto idibo yoo tun din ojo ori awon oludije fun ipo oselu ku.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Hijab Crisis: Fásitì Ibadan ní kò sí ohun tó yípadà pẹ̀lú ìwọṣọ akẹ́kọ̀ọ́ ISI 26 Bélú 2018 Àkọlé àwòrán, Wamuwamu ni awọn ẹṣọ aabo duro lẹnu ọna abawọle ẹkọ naa, ti wọn ko si fi aye gba ikọ iroyin BBC Yoruba lati wọle.
Mo wá gbọ́ ohùn líle kan láti orí ìtẹ́ náà wá tí ó wí pé, “Ọlọrun pàgọ́ sí ààrin àwọn eniyan, yóo máa bá wọn gbé, wọn yóo jẹ́ eniyan rẹ̀, Ọlọrun pàápàá yóo wà pẹlu wọn; 
Ẹ má bẹ̀rù àwọn tí wọn ń jẹ yín níyà, kí ẹ má jẹ́ kí ọkàn yín dàrú.
Ṣugbọn Ọlọrun ti fihàn mí pé n kò gbọdọ̀ pe ẹnikẹ́ni ni eniyan lásán tabi aláìmọ́.
 Ọ ̀ gá àwon ajalèlókun yìí , abduwali muse gé ara rẹ ̀ lọ ́ wọ ́ nibi tí ó ti n gbìyànjú lati yọ ọ ̀ bẹ tí perry fi síi lọ ́ rùn .
Latin lórí àìsàn Ogun Majek Iléèwé Chrisland yóò wọlé padà lọ́jọ́ Ajé, wọ́n ní òfin ìgbélé coronavirus kò mú ìgbẹ̀kọ́ orí ayélujára Ìyàn ń bọ̀ ní Nàìjíríà lẹ́yìn coronavirus àyàfi.
Ìtàn náà kún fún ọgbọ́n lọ́pọ̀lọpọ̀.
Ajọ ti kii ṣe ti jọba to dasilẹ kii ṣe lati pawo nitori pe o ni gbagbọ pe iṣoro ti o wa nilẹ niṣe pẹlu iru olori to wa niluu.
Ẹ̀yin ẹlẹ́ṣin, ẹ di ẹṣin yín ní gàárì, kí ẹ sì gùn wọ́n.
Floyd US Protest: Ó ṣe wá ní kàyéfì pé Ààrẹ Trump lọ sí Ṣọ́ọ̀ṣì - Ìjọ Kátólìkì Oríṣun àwòrán, Trump Àkọlé àwòrán, Ṣé ó tọ́ kì Ààrẹ Trump máa fi Bíbélì jẹ́rìí?
- Ilé ẹjọ́ ìpínlẹ̀ Ondo Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Bákan náà, ọkan lára àwọn òṣìṣẹ́ Fagoriola tí ọ̀rọ̀ náà sojú rẹ̀ sàlàyé pé, ọ̀gá àwọn wá ṣe àbèwo iṣẹ́ tí àwọn ńṣe lọ́wọ́ nígbà ti àwọn agbébọn ọ̀hún dé láti jíi gbé.
RRS gbé ẹlẹ́wọ̀n lẹ́yìn ọjọ́ 5 tí wọn tú sílẹ̀ ní ọgbà ẹwọ̀n Ikòyí
Christopher Ayeni, to jẹ akọwe ẹgbẹ APC ti ipinlẹ Kwara ni àwọn oludije mẹtala naa ni wọn ti pegede gba ami o yege lati dije dupò gomina ni Kwara.
" Oun to n da arabinrin yii laamu ni o n jẹ 'alopecia' lede oyinbo.
Ní àkókò kan báyìí, méjìlá ni àwọn ọlọ́ṣà pa nínú wa.
Osisẹ alarena fun ileesẹ to n sakoso ọgba ẹwọn ni Ondo, Ogundare Babatunde, lasiko to n ba BBC Yoruba sọrọ salaye pe aago mẹwa abọ aarọ lawọn janduku naa de si ayika ọgba ẹwọn naa.
Lẹhin ti o tiraka lati pari iwé mẹ́fà, gẹ́gẹ́ bi ọ̀dọ́, ó gbéra lọ si ilú Èkó nibiti ó ti bẹ̀rẹ̀ iṣẹ́ pẹ̀lú ilé-iṣẹ́ Ẹlẹ́ja.
Banki Agbaye sọ pe, botilẹjẹ wi pe owo iṣẹ́ ti lọ soke fun gbogbo ẹya, owo ti awọn ti owo oṣu wọn pọ pupọ n lọ soke si ni bi i ilpo meji ju ti awọn ti owo iṣẹ́ wọn kere lọ Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
naa fẹ maa daabobo awon eso wọn.
Láti inú ìdílé Elisafani: Ṣimiri ati Jeueli; láti inú ìdílé Asafu: Sakaraya ati Matanaya, 
Sugbọn eyi ko tu irun kankan lara Jesu Oyingbo nitori o si n tẹsiwaju pẹlu okoowo rẹ ni Lara awọn akọle lede oyinbo to wa lara awọn ile to wa ninu ọgba Jesu Oyingbo, to wa ni opopona Emmanuel ladugbo Maryland nilu Eko ni Alaanu ati alagbara"", ""baba titi aye"", ""Ọmọ alade Alaafia"" to si tun fi awọn ere Jesu yi wọn ka Oríṣun àwòrán, @AfricaFactsZone Bakan naa ni ilana isin ti Jesu Oyingbo yii yatọ si ti ilana ẹsin ijọ igbagbọ yoku nitori oun ni agbara ati asẹ ibalopọ lori awọn obinrin to ba wa ninu ijọ rẹ Niwọn igba to jẹ pe awaye ku ko si, Jesu Oyingbo dagbere fun aye yii pe o digbose, to si jade laye lọdun 1988 lẹni ọdun mẹtalelaadọrin (73 years) Lẹyin ti Jesu Oyingbo papoda tan, ija nla bẹ silẹ lori ogun laarin ọpọ iyawo to bimọ fun ati ogunlọgọ ọmọ to bi, nitori ko se iwe ilana ogun pinpin rẹ silẹ, lasiko yii si ni ọpọ asiri ti ko han sode tẹlẹ, bẹrẹ si tu sita, ti wọn si gbe ara wọn lọ sile ẹjọ fun ọdun gbọọrọ."
Gbogbo àwọn àṣeyọrí aare Umar Musa Yar'adua yìí lo si wa ni ìrántí àwọn ọmọ Nàìjíríà, tá sì ń gbàdúrà pé kí Ọlọ́run tẹ si afẹ́fẹ́ rere Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Niyi Akinmolayan tó ṣe fíìmu àwòrán-dèèyàn Cartoon nípa COVID-19 tó la ayé já ní N Umaru Musa Yar'Adua: Atiku, Saraki, Jonathan ń ṣè'rántí Ààrẹ tó lọ Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Awọn ọmọ Naijiria n ṣeranti aarẹ ana Iku n pani, ilẹ n jẹ'yan.
Ọ̀pọ̀lọpọ̀ òkú ẹyẹ igún ré bọ́ lọ́jà Eke-Ihe Àwa ò mọ ẹgbẹ́ kankan tó ń jẹ́ fijilanté fulani l'Ondo- Ìjọba ìpínẹ̀ Ondo Mo mọ̀ọ́mọ̀ dá €37,000 ti mo rí he padà ni -Ọmọ ogun Bashir Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Lara awon to ku ni a ti ri Ajo African Caribbean ati Pacific Group pelu Apaapo Ajo igbimo ACP-EU ninu eyi ti orile-ede Canada, Australia, New Zealand, Japan, Cuba ati  India je omo-egbe.
Mo ti ti ìlẹ̀kùn, àwọn ọmọ mi sì wà lórí ẹní pẹlu mi, n kò lè tún dìde kí n fún ọ ní nǹkankan mọ́.
Ó ń lo àṣẹ bíi ti ẹranko àkọ́kọ́, lójú ẹranko àkọ́kọ́ fúnrarẹ̀.
Iko agbaboolu Croatia gbo ewuro siko agbaboolu Spain loju ninu ifesewonse ese keji pelu ami ayo meta si meji(3-2).
Police: Mo réèmọ̀ nígboro ayé, adigunjalè dìhámọ́ra lọ ja àgọ́ ọ́lọ́pàá lólè
Mose bá kó àwọn eniyan náà jáde láti pàdé Ọlọrun, wọ́n sì dúró ní ẹsẹ̀ òkè.
Àwọn tí wọ́n wá láti ilẹ̀ Israẹli jẹ́ ọ̀kẹ́ mẹ́wàá (200,000).
Bakan naa lọdun 2005 ni ajọ UNESCO ti kede pe ọdun Ọṣun Oṣogbo ti di ibudo ajogunba lagbaye.
Ẹ̀mí ẹnikẹ́ni ninu yín kò ní ṣòfò; ọkọ̀ nìkan ni yóo ṣòfò.
Bí ó bá jẹ́ pé òtítọ́ ni, tí ó sì dáa yín lójú pé ohun ìríra bẹ́ẹ̀ ti ṣẹlẹ̀ láàrin yín, 
Ìyìn ni fún orúkọ rẹ̀ tí ó lógo, tí ó ga ju gbogbo ibukun ati ìyìn lọ.
Oríṣun àwòrán, AfricanDrumFestival Àkọlé àwòrán, Ọkan ojọkan awọn gbajugbaja olosere ni wọn yoo kopa nibi ajọdun naa Àkọlé àwòrán, Agba osere Nollywood ko gbẹyin nibi ayẹyẹ naa Àkọlé àwòrán, Awọn onidan naa se bi ọkunrin nibi ayẹyẹ ilu Awọn aworan yii wa lati ọwọ: BBC ati AfricanDrumFestival Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Ajọ to n gbogun ti iwa ibajẹ lorilẹede Naijiria, SERAP ti ri iwe gba lati ọwọ Minisita fun ọrọ isẹ ati ile gbigbe, Babatunde Fashola to fi orukọ awọn ile -ise to gba owo, amọ ti wọn ko lati se isẹ naa.
”“Lara oju iwe akosile ti ojogbon Chales Soludo ka,to so pe “Nidgbo n fe orile ede Naijiria ti yoo maa se ojuse re”.
Kinni Jago sọ lori ọrọ naa?
Gbogbo àwọn tí wọn ń fẹ́ kí àwọn ẹlẹgbẹ́ wọn mọ̀ wọ́n ní ẹni rere ni wọ́n fẹ́ fi ipá mu yín kọlà, kí àwọn ẹlẹgbẹ́ wọn má baà ṣe inúnibíni sí wọn nítorí agbelebu Kristi.
    Lẹ́yìn tí ó parí ọ̀rọ̀ rẹ̀, mo wí fún uun pé àwọn ènìyàn mi yóò lọ ro ohun tí o wí a o sì sọ ohun tí a fẹ́ṣe fún Oníbodè Igbó Elégbèje.
Bi o tilẹ jẹ wi pe ijọba ti gbiyanju fifẹ oju agbara kaakiri ipinlẹ Ọṣun, ko dabi ẹni pe eyi ran wahala ikun omi ni ilu ile ifẹ.
Mo láyọ̀ ninu òfin rẹ,nítorí tí mo fẹ́ràn rẹ̀.
 ilé búoyè : Ìwádìí fi yé mi pé omo oba ni àwon omo ilé búoyè àti wípé àwon ni wón kókó dé ìlú Ìkirè .
Sebulu bá lé Gaali ati àwọn arakunrin rẹ̀ jáde kúrò ní ìlú, kò sì jẹ́ kí wọ́n gbé Ṣekemu mọ́.
Wọ́n tún fi kún pé àwọn yóò pẹjọ lóri ọ̀rọ̀ náà, atẹjade ti wọn fi sita ree nisalẹ: Oríṣun àwòrán, Instagram/acupofkhafi Àkọlé àwòrán, Eto BB Naija Ọ̀rọ̀ Khafi túbọ̀ n da aríwò sílẹ̀ lórí òpó Twitter lóri bóyánǹkan ti Khafi ṣe dára tàbí kò dára.
Abike Dabiri-Erewa gbadura wi pe ọna rẹ a dara.
“Bí ẹ bá ti súnmọ́ ìlú tí ẹ fẹ́ bá jagun, ẹ kọ́ rán iṣẹ́ alaafia sí wọn.
Bí ọba ti ta ọfà ni Eliṣa ń wí pé, “Ọfà ìṣẹ́gun OLUWA, ọfà ìṣẹ́gun lórí Siria!
“Kí ni ẹni tí ó ni ọgbà àjàrà náà yóo ṣe?
Odunlade, Toyin, Ijebu dásí ìwọ́de #EndSARS, Mercy Aigbe gbébọn Wo nọ́mbà tí o le è pè láti gba owó gbà-má-bínú tí ọlọ́pàá bá fìyà jẹ ọ́ lọ́nà àìtọ́ l'Eko Ko pẹ ti ti fọran rogbodiyan naa jade lori ayelujara ti Davido fi ọrọ ranṣẹ si Oyetola.
lo se pinnu lati lo owo ilu fun ara ilu nipasẹ ijọba, eyi gan an ni gbigbe apoti ibo fun ipo aarẹ ṣe wu Abiola.
Bakan naa lawọn ile ẹkọ giga nipinlẹ Eko wọle pada.
Oríṣun àwòrán, Abiola Ajimobi Alaafin sọ pe '' Ajimobi mu ipo ogun laarin awọn Gomina ti mo ti ba sisẹ papọ nipinlẹ Oyo.
"Oríṣun àwòrán, Oluwo's Palace Ìjọba Eko kọ orúkọ sí ""Palliatives"" tiwọn lára o, mo ní ẹrù tèmi f'ọjọ́ ìbí mi tí wọ́n jí - Họ́nọ́rébù Agunbiade Báyìí ni 50 Kobo ṣe dá ìfẹ̀hónú ""Ali Must go"" sílẹ̀ tó mú ọ̀pọ̀ ẹ̀mí akẹ́kọ̀ọ́ lọ Ẹ gbọ́ Ohun tí Desmond Elliot àti Mojisola Alli-Macaulay sọ lórí ayélujára táwọn ọmọ Nàìjíríà fi ìbínú Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Kété tí wọ́n bá ti báa yín sùn tàn torí pé ẹ tóbi, ẹ gbà pé ìfẹ́ yẹn ti parí - Auntie Remi Ọlọ́yàn ńlá Oluwo ti ilu Iwo, Ọba Abdulrosheed Adewale Akanbi ti rọ ìjọba àpapọ ati awọn ìjọba ipinlẹ lati fi awọn Ọba alaye sinu igbimọ oluwadii ti wọn gbé kalẹ lori aṣemáṣe awọn ọlọpaa SARS."
Amọ ṣa, ọga agba ileeṣẹ ọlọpaa Kenya nigba kan sọ pe, ẹni to wa nidi awọn ẹgbẹ naa lori Facebook kii ṣe ọlọpaa, ṣugbọn araalu ti ọrọ aabo ilu ka lara ni.
Xenophobic Attack: 'Nàìjíríà ló máa forí kó kíkọlu iléeṣẹ́ South Africa jùlọ' Àjọ Commomwealth gbọ̀dọ pé ìpáde pàjáwìrì lori ọ̀rọ̀ Brexit- Wole Soyinka Ìdí ti àwọn kọmísọna ṣe to láti kí ìyáwó gómìnà tuntun káàbọ̀ Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Àwọn ọmọ Israẹli nìwọ̀nyí: Reubẹni, Simeoni, ati Lefi; Juda, Isakari, ati Sebuluni; 
Ẹ̀yin ọmọ-ọ̀dọ̀, ẹ máa bọ̀wọ̀ fún àwọn ọ̀gá yín ninu gbogbo nǹkan pẹlu ìbẹ̀rù, kì í ṣe fún àwọn ọ̀gá tí ó ní inú rere, tí wọ́n sì ń ṣe ẹ̀tọ́ si yín nìkan, ṣugbọn fún àwọn tí wọ́n rorò pẹlu.
“Nígbà tí Ọmọ-Eniyan bá yọ ninu ìgúnwà rẹ̀ pẹlu gbogbo àwọn angẹli, nígbà náà ni yóo jókòó lórí ìtẹ́ ògo rẹ̀.
Ṣé òjò ní baba; àbí, baba wo ló sì bí ìrì?
Awon eniyan wa ko ni imo idokowo, won ko ni ogbon atinuda lori eto idokowo, amo,ko si oro ti a le so, ti o le sanfaani fun awon ara-ilu.
Gbogbo àwọn eniyan tí wọ́n kù ní ilẹ̀ náà lára àwọn ará Hiti, ati àwọn ará Amori, àwọn ará Perisi, àwọn ará Hifi ati àwọn ará Jebusi, tí wọn kì í ṣe ọmọ Israẹli, 
China ti dẹ ọwọ l'ara awọn ilana rẹ, lẹyin to la asiko ọpọlọpọ iku ati ibujade aarun naa kọja.
Alaga ajo isokan ile Afrika, African Union Commission, AU, ogbeni Moussa Faki ti seleri lati sowopo pelu ijoba aare Buhari lati koju iwa-ibaje ti o gbode kan lorile-ede Naijiria.
’ ” Samuẹli bá pada lọ sùn.
Ògo Ọlọrun Israẹli ti gbéra kúrò lórí àwọn Kerubu tí ó wà, ó dúró sí àbáwọlé.
Lọ wọn Tẹmpili Ọlọrun ati pẹpẹ ìrúbọ, kí o ka iye àwọn tí wọ́n n jọ́sìn níbẹ̀.
Òkìkí Adédèjì tìí tàn yíká ilẹ̀ yìí àti òkè òkun, tí wọn sì fún un ní àmì ẹ̀yẹ ọlọ́pàá tó pegedé jùlọ ní Nàíjíríà.
Nítòótọ́ Ọlọrun ṣeun fún Israẹli,ó ṣeun fún àwọn tí ọkàn wọn mọ́.
Èmi fúnra mi kọ́ ni mò ń sọ ọ̀rọ̀ tí mò ń sọ fun yín.
Nigbati awọn to wa lakasọ kẹtala soke yoo joko jiroro lori ilana iṣẹ ti wọn yoo fi ṣeto bawọn oṣiṣẹ yooku yoo ṣe maa wa si ẹnu iṣẹ.
Ṣé ẹ̀mí Super Falcons gbé e lálẹ́ òní pẹ̀lú France?
" Iwe iroyin abẹle kan lorilẹ-ede Naijiria lo tẹ iroyin kan sita lọjọ Satide ninu eyi ti o ti darukọ igbakeji aarẹ orilẹ-ede Naijiria, Ọjọgbọn Yẹmi Oṣinbajo pe ọwọ rẹ wa nibẹ.
Hospitality and Tourism Establishment),ti Wukari (Establishment) , Warehouse
Geriṣoni ni baba ńlá àwọn ọmọ Libini ati àwọn ọmọ Ṣimei.
Tunisia ni orilẹ-ede ilẹ Afrika to kọkọ gba ami kan wọle ninu idije ife ẹyẹ agbaye ti Russia 2018.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ìtàn ìgbésí ayé Winnie Madikizela-Mandela Titi di asiko yii ko tii si ẹni to le fidiẹ mulẹ irufẹ awọn eniyan to wa nidi iṣẹlẹ buruku yii laarin awọn olugbe South Africa.
Ọba dá obinrin náà lóhùn pé, “Ọ̀rọ̀ kan ni mo fẹ́ bèèrè lọ́wọ́ rẹ, mo sì fẹ́ kí o sọ òtítọ́ rẹ̀ fún mi.
Súgbọ́n o kọ́kín sùn títí tí agogo ara rẹ yóò fi sọ fún o wípé àsìkò tí to láti sùn.
orin àpàlà jẹ ́ ọ ̀ kan lára àwọn orin yorùbá ti wọ ́ n jẹ ́ gbájúmọ ̀ ni agbègbè ẹ ̀ gbá , Ìjẹ ̀ bú , Ọ ̀ yọ ̀ , Ọ ̀ sun àti Ìgbóminà .
Eid-el Kabir: Aisha Buhari lọ Hajj pẹ̀lú ìyàwó Ààrẹ Niger, Senegal, Gambia
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Hepatitis: A kò leè kóo nípa dídìmọ́ ara ẹni Gẹgẹ bo ti wi Nitori pe orukọ aarẹ tẹlẹ, Olusegun Obasanjo ko si lara orukọ awọn ọmọ Naijiria tijọba fi sọri ibudo reluwe, kii se nnkan pataki."
Pẹlu abẹwo si ‘New Afrika Shrine’, Macron yoo jẹ aarẹ akọkọ ti yoo kọkọ wa si ile igbafẹ ti wọn mọ si agbegbe ti wọn ti n mu ogun oloro bi igbo, ati awọn obinrin ti wọn ki n wọ asọ to bo gbogbo ẹya ara wọn lati jo.
itọju ,ohun ti a nilo lati so fun un ni “ O ku ara ya’’.
Bẹ́ẹ̀ ni yóo rí fún ìlú tí ó jókòó láìléwu, tí ń fọ́nnu wí pé, “Kò sí ẹlòmíràn mọ́, àfi èmi nìkan.
Nígbà tí ó fọ nǹkan inú rẹ̀ ati ẹsẹ̀ rẹ̀, ó fi gbogbo rẹ̀ rú ẹbọ sísun, ẹbọ olóòórùn dídùn tí a fi iná sun sí OLUWA, gẹ́gẹ́ bí OLUWA ti pàṣẹ fún Mose.
Ẹ̀mí OLUWA ni ó gbé mi lọ pẹlu agbára.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù MMM: EFCC ìpínlẹ̀ Enugu fi ìkìlọ síta lórí ètò sogúndogójì 23 Òkùdu 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 25 Òkùdu 2019 Oríṣun àwòrán, other Àkọlé àwòrán, CBN àti EFCC ń pàrọwà fáwọn ọmọ Nàíjíríà lórí sogúndogójì Mo kú, Mo gbé, Mo dáràn' tuntun tó jáde.
 Ó ń gbógun ti ilẹ ̀ Ìjẹ ̀ ṣà nígbà kan .
Gbogbo rẹ̀ yóo ru sókè bí odò Naili, yóo máa lọ sókè sódò, yóo sì fà bí odò Naili ti Ijipti.
Bi ara ba ṣe tobi si - Aisan yii tun wọpọ laarin awọn to ba sanra ju bo ṣe yẹ lọ Ere idaraya - Ẹni ti kii ba ṣe ere idaraya, tabi fi ara ṣiṣẹ daadaa wa ninu ewu lati ni aisan yii Oríṣun àwòrán, CHADWICK BOSEMAN Ọti - mimu ọti le ṣakoba fun ọ, lati ni aisan colon cancer Ẹni to ba n mu siga, igbo, ati awọn nkan miran naa le ni aisan yii Ẹbí - ti o ba ni ibatan to sun mọ ọ (iya, baba, ẹgbọn tabi aburo) to ni aisan yii nigba ti ọjọ ori wọn ṣi wa ni abẹ aadọta ọdun, o ṣe e ṣe ki iwọ naa ni .
Oríṣun àwòrán, Facebook/Omoyele Sowore Àkọlé àwòrán, Ifẹhonu han gbogbogbo Ọga ọlọpaa ni Naijiria lo anfani naa lati maa jẹ ki ẹgbẹ kan ti orukọ rẹ n jẹ 'Global Coalition for Security and Democracy in Nigeria' ti wọn lọ sibi ifẹhonu han lọjọ Aje, bibẹẹ kọ, ọwọ ofin lawọn agbofinro yoo fi mu wọn.
jade to waye ni Fafiti ipinle Eko,ni eyi ti o jẹ ikéjílélọ́gbọ̀n re ni Fafiti naa.
Òkun Mẹditarenia ni ààlà wọn ní apá ìwọ̀ oòrùn.
Nnamdi Kanu sọrọ lórí àwọn oludije PDP àti APC
“Èyí ni yóo jẹ́ òfin fún Nasiri: Nígbà tí ọjọ́ ìyàsọ́tọ̀ rẹ̀ bá pé, yóo wá sí ẹnu ọ̀nà Àgọ́ Àjọ 
 Àjẹsára hib wà gẹ ́ gẹ ́ bí èyí tó dádúró , bí èyí tó jẹ ́ àdàlù pẹ ̀ lú àjẹsára ikọ ́ gbẹ ̀ fun-gbẹ ̀ fun / àwàlù eyín / ikọ ́ ọfe , àti bí èyí tó jẹ ́ àdàlù pẹ ̀ lú àjẹsára ibà jẹ ̀ dọ ̀ jẹ ̀ dọ ̀ oríṣi b , láàárín àwọn oríṣiríṣi mìíràn .
5 895620 Orilẹede Ecuador 13850 81.
Aarẹ Epypt, Abdul Fattah al-Sisi sọ ninu oṣu kẹsan ọdun to kọja pe bii kii ba ṣe wahala oṣelu to ṣẹlẹ lorilẹ-ede oun ni, Ethiopia ko ba ma lee bẹrẹ iṣẹ ọhun rara.
nínú ìtàn mìíran a gbọ ́ pé ààfin odùduwà ni wọ ́ n bí aláayè sí .
Oríṣun àwòrán, FIFA>com Bakan naa, Germany yoo maa gnena woju Spain ninu ere bọọlu miiran to yoo yeruku lala.
Bi a ba buwọlu abadofin yii tan, yoo tun pa kun wahala inawo ni, a o nilo alekun aabo, bawo la se fẹ yanju eleyi?
 Òkó ni olú ìlú wọn .
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Mama Arsenal: Màmá àgbà yìí máa ń lọ sí ìbùdó tí wọ́n ti ń wo bọ́ọ́lù láti wòran Arsenal yoo maa pade ikọ to ba bori ninu idije Manchester United pẹlu Chelsea Ninu ọrọ rẹ, Mikel Arteta, olukọni ikọ Arsenal ni iya jẹ awọn pupọ ni ifẹsẹwọnsẹ naa ṣugbọn aato to gun rege ló ko awọn yọ.
Ajax k'ógun ja Tottenham, àlù mọ́lé ni wọ́n nà wọ́n
Wahala airi ounjẹ jẹ yii di nkan ti awọn orilẹ-ede ilẹ okeere n jiroro le lori laarin ara wọn, eyi si mu ki afikun de ba bi wọn ṣe n nawo fun orilẹ-ede miran.
won, lati le je ki awon akekoo  bere ise
Ewu irinna loju ofurufu Nigba ti aarun naa kọkọ bu jade, ọpọ orilẹ-ede lo fi ofin de baalu lati China, tabi ki wọn o fi awọn to ba rinrinajo de lati orilẹ-ede ti aarun naa pọ si, si ìyà sọtọ.
Ǹkan méje tí o kò gbọdọ̀ ṣe ní ọjọ́ ìdìbò Nàìjíríà, orílẹ̀-èdè tí ǹkan márùn ún yì yà sọ́tọ̀!
Ní àkókò kan nígbàtí 1831 nparí lọ, onírúurú àwọn alàgbà Ìjọ fi tọ̀wọ̀tọ̀wọ̀ jẹ́rìí pé Olúwa ti jẹ́ ẹ̀rí sí ọkàn wọn nípa òtítọ́ àwọn ìfihàn náà.
Nígbà tí mo bá ranti rẹ lórí ibùsùn mi,tí mo bá ń ṣe àṣàrò nípa rẹ ní gbogbo òru;
Àwọn ọmọ Naijiria yarí lórí ọ̀rọ̀ owó 'tollgate' tí ìjọba kéde rẹ̀ Ọkùnrin kan ti ṣekú pa Ọlọpàá mẹrin ní Faransé Ọmọkùnrin kan sin Baba rẹ̀ láàyè torì pé ó gbàgbọ́ pé oṣó ni!
Owó ni a fi ń ra omi tí à ń mu,rírà ni a sì ń ra igi tí a fi ń dáná.
Ileeṣẹ ọlọpaa ni awọn ri ọbẹ nibi ti iṣẹlẹ naa ti ṣẹlẹ.
Àwa ati àwọn ẹran ọ̀sìn wa kò ní yà kúrò ní ojú ọ̀nà sinu oko yín tabi ọgbà àjàrà yín.
Ati pe, INEC gbọdọ faaye gba wọn niwọn igba to ti sun idibo siwaju.
Everton já Manchester United sí ìhòhò lọ́jọ́ Àjíǹde Man Utd Vs Man City: Ọ̀rẹ́ dì ọtá, ọtá dì ọ̀rẹ́ torí ife ẹ̀yẹ Bernado Silva ati Leroy Sane ni wọn jẹ goolu mejeeji ti wọn fi pegede ninu ifẹsẹwọnsẹ naa Ikọ Ole Gunnar Solkjaer ko ribi kuro ni ipo kẹfa ti wọn wa lori afara liigi lati ọjọ yi.
Aare Yoweri Museveni so nigba ti o n soro lori ayeye ayajo ojo awon obinrin naa lori ero amohun-maworan ni ekun Mityana ti o wa laarin gbungbun orile-ede Uganda.
Wọ́n ní, ‘Wakati kan péré ni àwọn yìí tí wọ́n dé kẹ́yìn ṣe; o wá san iye kan náà fún àwa ati àwọn, àwa tí a ṣe iṣẹ́ àṣelàágùn ninu oòrùn gangan!
Ohunkohun tí ó bá ti kan ẹran rẹ̀ di mímọ́; nígbà tí wọ́n bá sì ta lára ẹ̀jẹ̀ rẹ̀ sára aṣọ kan, ibi mímọ́ ni wọ́n ti gbọdọ̀ fọ aṣọ náà.
Wọ́n tẹ àádọ́ta olùdárò pa níbi ìsìnkú Qasem Soleimani tí kò wáyé mọ́ Rárá o, ẹ kò gbọdọ̀ sìnkú akẹ́kọ̀ọ́ LASU tí wọn fi ṣe òògun owó - Ìjọba Eko yarí Ìwà ọ̀dàlẹ̀ ni bí ẹ kò bá gbé iléèwé ìkọ́ṣẹ́ olùkọ́ni kalẹ̀ sí ìlú Ìwó- Oluwo Kí ni Buhari sọ nípa ààrẹ tó kàn lọ́dún 2023?
Ní ayé àtijọ́, ọkan nínú àwọn ìráńṣẹ́ Olódùmarè a máa yí ayé po lọ́dọ́dún, orúkọ rẹ̀ a máa jẹ́ Ìmọ́lẹ̀.
Bi awọn ipinlẹ to ni Coronavirus ni Ọjọbọ ṣe lọ ree: Plateau-83 Eko-48 Kaduna-17 FCT-16 Ogun-11 Katsina-7 Imo-4 Edo-3 Nasarawa-3 Rivers-2 Bayelsa-1 Oyo-1 Osun-1 Ènìyàn mẹ́ta pàdánù ẹ̀mí wọ́n lọ́wọ́ àrùn Coronavirus ní Nàìjíríà ní Ọjọ́ọ̀rú Ajọ to n gbogun ti ajakalẹ arun lorilẹede Naijiria, NCDC ti kede pe eeyan 176 miran ti lugbadi arun Covid-19 ni Naijiria.
Arẹwà Ibidunni Ighodalo wọ káà ilẹ̀ lọ nílùú Eko Oríṣun àwòrán, Instagram/trinityhouseng Iku o dọjọ, aarun ko doṣu.
Ǹjẹ́ kò yẹ kí ilẹ̀ náà mì tìtì nítorí ọ̀rọ̀ yìí kí àwọn eniyan tí ń gbé orí rẹ̀ sì máa ṣọ̀fọ̀?
Eniyan mẹtadínlógun ní lo wà nínú ọkọ ofurufu náà Kìí ṣe ìgbà àkọkọ rèé ti irú ǹkan bayìí yóò ṣẹlẹ̀ ni orílẹ̀-èdè DR Congo ní tori ètò ààbo tó wà nibẹ̀ kò gbópọ̀n tó àti pé ìtójú ti wọ́n ń ṣe fún àwọn ọkọ ofurufú naa kéré jọjọ.
Wọ́n ní, “Ẹ wo ọkunrin yìí, ẹ gbọ́ bí ó ti ń pe Israẹli níjà?
Boya ko yẹ lẹni to n joko sori itẹ yẹn, ki wọn sọ, tori lati igba to ti jọba, ẹjọ rẹ to wa nile ẹjọ kii se ọna mẹrin mọ, ti temi yii tun wa pẹlu rẹ.
Wazo funra rẹ si lo kede ayọ ọmọ tuntun ọhun loju opo Instagram rẹ @wazothefirst, to si fi fọto ọmọ tuntun naa sibẹ pẹlu.
Canada ń ṣọ́ ẹ o Wo bí àwọn fàyàwọ́ ṣe ń kó ìrẹsì wọ Nàìjíríà Gbogbo ojú la fi ń ṣọ́ Nàìjíríà báyìí lórí ọ̀rọ̀ ẹ̀sìn - ilẹ̀ Amẹ́ríkà Ọlọ̀pàá yìnbọn pa akẹgbẹ́ rẹ̀ tán, lo bá pa ara rẹ̀ náà l'Abuja Babandede ṣalaye pe eredi fun ayẹwo yii ni lati jẹ ki awọn oṣiṣẹ ṣ iṣẹ wọn daadaa gẹgẹ bi akọṣẹmọṣẹ.
Àkọlé àwòrán, Eto BB Naija Ileeṣẹ ọlọpaa ni awọn ko lọwọ si bi Kareem ti wa lori eto naa ati pe, kii ṣe ileeṣẹ ọlọpaa ilẹ Gẹẹsi loun n ṣoju fun niwọn igba to wa lori eto naa.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Wike sí Ganduje: 'Èmi kìí ṣe dọ́là tó le kó sápò' Karina Igonikon BBC News Pidgin, Port Harcourt 1 Owewe 2019 Àkọlé àwòrán, Bótilẹ̀ jẹ́ pé ẹgbẹ́ ọtọọtọ ni Wike àti Ganduje wà síbẹ̀ ìpínlẹ̀ àwọn méjèjì lo ṣe pàtàkì ni Nàìjíríà.
” Ṣugbọn ẹ óo wá sọ fún talaka pé, “Dúró níbẹ̀, tabi wá jókòó nílẹ̀ lẹ́bàá ẹsẹ̀ mi níhìn-ín.
Nítorí náà, èmi OLUWA ń sọ nisinsinyii pé,ọjọ́ ń bọ̀, tí n óo ṣe ìdájọ́ lórí àwọn ère rẹ̀;àwọn tí wọ́n fara gbọgbẹ́ yóo máa kérora,ní gbogbo ilẹ̀ rẹ̀.
Àwọn ohun tuntun tí a mọ̀ nípa ìgbẹ́jọ́ Wòlíì Sotitobire Kí ló dé tí Aàrẹ Buhari kìí fí í dá sí aáwò àwọn ọmọ ẹgbé APC?
Heberi bí ọmọkunrin mẹta: Jafileti, Ṣomeri ati Hotamu; ati ọmọbinrin kan tí ń jẹ́ Ṣua.
Àwọn ẹni tí kò bá ṣe ìwọ̀nyí jẹ́ ohun ìkọ̀sẹ̀ fún àwọn tí ń bọ̀ lẹ́hìn, nítorí wọ́n fi oore sú àwọn alágbáraṣe, àwọn alágbára á sì máa ti ìtorí bẹ́lẹ̀ hu ìwàkíwà fún àwọn ọmọ ẹ̀hìn wọn; nítorí ki ni ńkọ́, nítorí wọ́n á wí pé bi àwọn bá hu ìwà dáradára àrífín ni èrè àwọn.
Ọ̀daràn tó wà lẹ́wọ̀n tún wọ́'ke $100miílíọnu - EFCC Ohun mẹ́fà tó yẹ ní mímọ̀ nípa Yahaya Bello Àjọ Ìsọ̀kan Yúròòpù àti Amẹ́ríkà bẹnu ẹ̀tẹ́ lu ìdìbò Kogi àti Bayelsa Dino Melaye kọ ipò olùdarí ìpolongo ìbò gómìnà ẹgbẹ́ PDP ní Kogí Nibe ni wọn ti dana sun ilẹ rẹ pẹlu arabinrin Salome Abuh to wa ninu ile lasiko naa.
Ninu ọrọ rẹ, ''jijẹ ounjẹ lasiko ati deedee le jẹ ki ara asanju, aisan bii ẹjẹ ruru ati arun itọ ṣuga jina si agọ ara eeyan.
" Ẹ̀wẹ̀, àjọ LMC ń wá ọ̀nà láti ni ìbáṣepọ ẹgbẹ́ agbábọọlù olóògbé àti àwọn ẹbi rẹ̀, láti le mọ ọ̀nà ti wọ́n yóò gbà ṣe ìrànwọ́ níru àsìkò aburu yìí Bákan náà ni àjọ NFF fi ẹdun ọkan rẹ̀ han fún ọmọ agbabọọlu ọ̀un lóri àtẹjiṣẹ́ twitter rẹ.
Orisun omi orioke Olumirin ti ọpọ mọ si Ẹrin Ijẹṣa Water falls Oríṣun àwòrán, Olu Alebiosu Àkọlé àwòrán, Ipele meje ni omi orisun apata Olumirin yii ti n jabọ Ko si ẹni ti o ba de orisun omi Olumirin ni Ẹrin Ijẹṣa ti ko ni ya ẹnu si ayika rẹ.
Àràmọ̀ndà agbábọ́ọ̀lù tó ń jẹ Messi, ó ju Ronaldo lọ lórí pápá- Jurgen Klopp Ṣé ẹ lè kí Liverpool kú oríire báyìí?
Jobu sọ pé òun kò jẹ̀bi,ó ní Ọlọrun ni ó kọ̀ tí kò dá òun láre.
Yomi Fabiyi tun koro oju si iwa aibọwọ fofin lati ọdọ awọn alaṣẹ ati agbofinro lasiko igbele Covid-19, ti wọn si n tẹ ẹtọ araalu loju.
A ti sún ìgbẹ́jọ́ Ganduje, Tambuwal àti Ihedioha sí ọ̀la Bakan naa lo gba awọn ọdọ ni imọran lati gbajumọ iṣẹ ọwọ wọn nitori pe atẹlẹwọ ẹni, ni kii tan ẹnii jẹ.
Bí eniyan bá kú, ǹjẹ́ yóo tún jí mọ́?
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Gbogbo ìdíje ló ni ẹ̀kọ́ àti àwòkọ́ṣe to yẹ ni mímọ̀ fún ọjọ́ iwájú 16 Ọ̀pẹ̀̀ 2018 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 23 Ọ̀pẹ̀̀ 2018 Oríṣun àwòrán, Reuters Àkọlé àwòrán, Xherdan Shaqiri ń dunú bọ́ọ̀lù tó gbá s'áwọ̀n Ẹgbẹ́ agbábọ́ọ̀lù Liverpool ti gbo ewúro s'ójú Manchester United pẹ̀lú àmì ayò mẹ́ta sọ́kan (3-1) ní pápá ìṣeré Anfield.
Jesu wí fún un pé, “Máa lọ, ọmọ rẹ yóo yè.
kí ló dé tí ẹ fi sọ pé mò ń sọ ọ̀rọ̀ àfojúdi sí Ọlọrun nítorí mo wí pé, ‘Ọmọ Ọlọrun ni mí,’ èmi tí Baba yà sọ́tọ̀, tí ó rán wá sí ayé?
Oríṣun àwòrán, WHO Ngige, ẹni to sisọ loju ọrọ̀ yii lasiko to n opa lori eto kan lori mohunmaworan tun fikun pe, ko si ohun to buru ninu kawọn dokita yii ko aasa wọn lọ si oke okun niwọn igba ti wọn yoo maa fi owo ilẹ okeere ransẹ sile.
” Ṣugbọn àwọn ọmọ ogun náà kọ̀ láti pa àwọn alufaa OLUWA.
Àrà ọ̀tọ̀ inú orin tó jáde lọ́dún 2018 ní Nàìjíríà Rwanda: Àjẹ́ tó dóòlà ẹmí àwọn ènìyàn rèwàlẹ̀ àsà Amọ ṣa, lẹyin ipade ti gomina ṣe pẹlu awọn alaṣẹ ajọ NBC, ajọ naa gba lati ṣi i, ati pe wọn gbọdọ san owo itanran ti wọn bu fun wọn.
Atupalẹ awọn ipinlẹ to ni coronavirus ni Naijiria Titi di ọjọ kejila osu kini ọdun 2020,orileede China nikan ni o ni eeyan to ni arun coronavirus.
Ẹ kọ orin titun sí OLUWA,ẹ kọrin ìyìn sí i ninu àwùjọ àwọn olóòótọ́.
A óò bẹ̀rẹ̀ sí san 30,000 owó oṣù òṣìṣẹ́ tó kéré jù lóṣù yìí- Fayemi Kiki Osinbajo gbóṣùbà fún Seyi Awolowo, MC Oluomo tọrọ ìbò fún Mike ní BBNaija Nigba to n gbẹnu awọn olukọ sọrọ, aarẹ apapọ fun ẹgbẹ awọn olukọ jakejado orilẹede Naijiria lasiko ayajọ ọjọ olukọ naa, Mohammed Nasir Idris salaye pe yoo dara ki akanse owo osu wa fawọn olukọ ki ijọba lee safihan bi awọn olukọ ti se pataki si taa ba wo ọrọ aje ti ko fara rọ yii.
Joṣua, ọmọ Nuni, iranṣẹ OLUWA, ṣaláìsí nígbà tí ó di ẹni aadọfa (110) ọdún.
Awon eniyan jade lati wa wo ogagun ana ti o fi asọ
O ni oun ko le ṣe aroye nipa ohun ti oun n la kọja lasiko yii, nitori gbogbo agbaye lo n la oriṣiiriṣii nkan kọja bayii fun igba akọkọ.
Adebajo fi ọpọ ọmọ ati iyawo silẹ lọ.
Amọ, inú àwọn èèyàn kò dún rárá lásìkò yii tí Ààrẹ Buhari gbé owó lé owó epo àti iná mọ̀nàmọ́ná nigba kannaa, nitori nnkan nira fun awọn eniyan lasiko arun Coronavirus yii.
Angẹli keje fun kàkàkí rẹ̀, àwọn ohùn líle kan ní ọ̀run bá sọ pé, “Ìjọba ayé di ti Oluwa wa, ati ti Kristi rẹ̀.
Ṣugbọn àwọn ọmọ Israẹli mọ́kàn le, wọ́n tún gbógun tì wọ́n, wọ́n sì tún fi ibi tí wọ́n fi ṣe ojú ogun tẹ́lẹ̀ ṣe ojú ogun wọn.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ondo State: Àwọn aláṣẹ Poly Rufus Giwa di ítì pa di ọjọ́ iwájú 18 Òkùdu 2019 Oríṣun àwòrán, Google Àkọlé àwòrán, Poly Rufus Giwa O ṣeese ki igbesẹ awọn alaṣẹ ile iwe giga gbogboniṣe Rufus Giwa to wa ni ilu Owo, ipinlẹ Ondo pa awọn akẹkọọ lara.
Ayé ń ta gbọ̀n-ọ́n-gbọ̀n-ọ́n bí ọ̀mùtí,ó ń mì bí abà oko.
Nítorí kò sí ọ̀kan ninu àwọn eniyan wọ̀n-ọn-nì tí a ti kọ́kọ́ pè tí yóo tọ́ wò ninu àsè mi!
Oríṣun àwòrán, Twitter/Ridwanullah Ọkan lara awọn ọmọkunrin Pa Kasumu, Bode Odumosu naa sọ pe adura ni baba oun nilo bayii pẹlu ipo to wa.
Ijọba ilẹ Amẹrika ti kede pe ohun ko ni fawọn ara ilẹ okere ni iwe irinna lati wa bimọ si orilẹede naa mọ.
Awọn aṣẹwo ti lu efanjẹliisi daku lÉjigbo nilu Eko o, Wọn ni o kọja aye rẹ nipa wiwaasu ni ile aṣẹwo awọn.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ìlẹ̀kẹ̀ ìdí mi ló kó mi yọ lọ́wọ́ àwọn afipábánilòpọ̀ ní Lebanon Kí ló ṣẹlẹ̀ lágbo tíátà lọ́sẹ̀ yìí?
Ninu oro aare Kagame safihan bi orile-ede Rwanda se n fowosowopo ati bi yoo se tesiwaju lati maa fowosowopo pelu awon ile-ise aladani, ni paappa eka eto ilera.
O Fagunwa kú, dúkìá rẹ̀ sì ń fọhùn síbẹ̀, ilé rẹ̀ rèé Samuel Ladoke Akintọla jẹ́ Agbẹjọ́rò àti Akọ̀ròyìn tí ọ̀rọ̀ dá lẹ́nu rẹ̀ Ayinla Ọmọwura, orin èébú àti oríyìn lo fi di ọ̀rẹ́ àwọ̀n obìnrin Àníyàn ìfẹ́ laarin Deji Williams Adenuga ati Titi Sanumi lo gba ẹ̀mí ọmọ Titi kan, ọmọ Jumọkẹ, to jẹ ẹgbọn Titi mẹfa ati ọkọ Jumọke.
Nítorí OLUWA yóo tún Sioni kọ́,yóo sì fara hàn ninu ògo rẹ̀.
Oríṣun àwòrán, @raufaregbesola Sugbọn bi o tilẹ jẹ pe ijọba Arẹgbẹsọla sa ipa rẹ lati mu ki eto ẹkọ muyanyan lasiko rẹ, sibẹ akọsilẹ fihan pe ajorẹyin si ni ina eto ẹkọ jo nipinlẹ Ọsun.
 awon wonyi ni hausa , Ígbò ati yorùbá .
Baru ni ọga agba fun ileeṣẹ to n risi ọrọ epo rọbi ilẹ Naijiria, NNPC ki ọlọjọ to de.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù COZA: Àdúrà kò le pa ìfipábánilòpọ̀ rẹ́, àtàwọn àkọlé mìí tó jẹyọ lórí ọrọ Fatoyinbo 30 Òkùdu 2019 Awọn eniyan ko ara wọn jọ lati fẹhonu han ni ẹka ijọ COZA ni ilu Abuja ati Eko.
Oludije lẹgbẹ oṣelu PDP, Ṣẹneto Dino Melaye ti tako eto atundi idibo si ipo ṣẹnetọ to n ṣoju ẹkùn iwọ- oorun Kogi.
 Aṣaaju ẹgbẹ oṣelu APC naa tẹsiwaju pe oun ko mọwọ mẹsẹ ninu bi Toll gate ṣe n pa owo wọle, bẹẹ si ni oun ko lọwọ ninu iku awọn oluwọde."
 Àdùnní yìí tí kú ní ọdún mẹ ́ ta ṣáájú bàbá rẹ ̀ .
Nígbà tí Olódùmarè sì rántí ẹ̀sẹ̀ ńlá tí baba ńlá ọkùnrin yìí ṣẹ̀ Ó rán mi kí n lọ mu un wá.
Ile igbimọ aṣoju ṣofin niluu Abuja, ti
Ọmọwe Fayẹmi tun ti ṣiṣẹ gẹgẹ bi oniroyin, oniṣẹ iwadi ati olugbani-nomọran lori ọrọ idagbasoke tẹlẹ ri.
Báyìí ni adìẹ̀ náà sọ fún àwọn ọmọ rẹ̀ láìmọ̀ pé ọwọ́ onílé ni òun sọ̀rọ̀ sì.
Kì í ṣe pé ẹ kò mọ òtítọ́ ni mo ṣe kọ ìwé si yín, ṣugbọn nítorí pé ẹ mọ̀ ọ́n ni, kò sí irọ́ kankan tí ó lè jáde láti inú òtítọ́.
Àwọn alákatakítí pa ènìyàn 19 ní Borno Ibugbamu ado oloro pa eniyan 17 ni Konduga Àwa kìí bá ikọ̀ adúnkookò mọ́ni sọ̀rọ̀ - Red Cross Ayo Olaniyan to fi igba kan jẹ oludari ni ẹka to n risi ọrọ iroyin ni ileese ologun Naijiria so pe oun to bani lọkan jẹ ni ki a ma gbo iroyin pe awọn Boko Haram n sigun ba awọn ọmọ ogun Naijiria '''Ti iru nnkan bayi ba n selẹ, ko si nnkan to tọka si to ju wi pe awọn kan n fun awọn agbesunmọmi yi ni iroyin nipa isesi awọn ọlogun wa ni.
Ṣugbọn OLUWA yipada sí i, ó sì dá a lóhùn pé, “Lọ pẹlu agbára rẹ yìí, kí o sì gba Israẹli kúrò lọ́wọ́ àwọn ará Midiani, ṣebí èmi ni mo rán ọ.
Ọpọ eeyan to wa ladugbo ti awọn iwọde naa ti n waye lo fara gba ninu afẹfẹ tajutaju naa, ti wọn si n nu omije loju.
”Aare so pe :“Opolopo awon eniyan ni won fe  ki n ku lasiko ti mo n saisan.
Àwọn ẹni rere ni yóo jogún ilẹ̀ náà;wọn óo sì máa gbé orí rẹ̀ títí lae.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Omiyale Ile Ife: Dukia sọfọ, awọn eniyan si tun farapa 30 Agẹmo 2018 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 2 Ògún 2018 Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Omiyale Ile Ife: Dukia sọfọ, awọn eniyan si tun farapa Awọn eniyan ti agbara ojo ni ilu Ile Ife sọ oun ti oju wọn ri lasiko omiyale to sẹlẹ laipẹ yii.
Àwọn ọmọ ogun rẹ̀ tí a kà jẹ́ ọ̀kẹ́ mẹta ó lé ẹẹdẹgbẹsan-an (62,700).
- Olukoya ti ìjọ MFM Oludasilẹ ijọ Mountain of Fire and Miracles Ministries, MFM, Daniel Odukoya ti fi ọpọlọpọ aṣọtẹlẹ silẹ fun ọdun 2020.
Adetokunbo to ti ṣisẹ oniroyin ni Naijiria fọdun pipẹ ki o to di ero ilẹ Gẹẹsi ni afiwe ko si laarin bi awọn eeyan ilẹ okere ṣe n dari ilu pẹlu ti Naijiria.
Ó bá pàṣẹ fún balogun ọ̀rún pé kí ó máa ṣọ́ Paulu.
O ni :“lakọkọ, mo wa lati ki aare fun isẹ
Ìtumọ̀ àbàdòfin lórí omi tí ìjọba tẹramọ́ tó n bí àwọn ọmọ Nàìjíríà nínú rèé Mílíọ́nù mẹ́wàá Náírà ni ilé ẹjọ́ ni kí Kábíyèsí san gẹ́gẹ́ bí owó ìtaran ilẹ̀ tí ó gbà lọ́nà àìtọ́ Ilé ẹjọ́ dájọ́ ẹgba mẹ́ẹ̀dóògún fún ọ̀daràn tó jí Iphone ní Kaduna Kílódé tí Ọọni Ife, Oba Ogunwusi kò fi gbọdọ̀ rí ọmọ rẹ̀ tuntun ti Olorì Naomi bí títí di bíi ẹ̀yìn oṣù mẹ́fà?
Mo sọ ninu ara mi pé, “Mo fẹ́ gbọ́n,” ṣugbọn ọgbọ́n jìnnà sí mi.
Ìwọ tí o fi agbára fi ìdí àwọn òkè ńlá múlẹ̀;tí o sì fi agbára di ara rẹ ní àmùrè.
MC Oluọmọ, àtàwọn èèkàn míràn sọ̀rọ̀ lórí ikú Fẹ́lẹ́ MC Oluọmọ gbé ara rẹ̀ ṣépè nítorí ìwọ́de #ENDSARS Sanwo-Olu kò lè tori ìjà Ọjọta fòfin de NURTW ní Eko - Agbẹnusọ gómínà Bí ẹgbẹ́ One Million Boys ṣe bẹ̀rẹ̀ rèé àti ọṣẹ́ tó ṣe n'Ibadan Akọṣẹmọṣẹ kan lo n dari ikọ PMS, lati ri pe wọn n tẹle ilana iṣẹ wọn Oríṣun àwòrán, @seyiamakinde Ijọba Oyo sọ pe PMS ko ni ibaṣepọ pẹlu NURTW.
Ileesẹ BBC ti ẹ gbọ nigba naa pe wọn sare gbe e lọ si ìdí òrìṣà ni agboole wọn ni adugbo Born Photo, lẹyin ti wọn ṣá.
Bí ọmọdé bá ti bẹ̀rẹ̀ gbé ìwà ojúkòkòrò ni ó ti yẹ kí àwọn òbí rẹ̀ máa bá a wí, kì í ṣe òbí nìkan, bí kò ṣe gbogbo ìbátan pẹ̀lú.
Aarẹ Buhari ni abadofin oju awo lawo fi n gbọbẹ lawọn fẹ fi eto iṣuna ọdun 2019 ṣe.
To si fi fun gbajugbaja naa l'esi pe, ọwọ ti ẹ naa ko mọ́.
Àwọn ará Nafutali kò lé àwọn ará ìlú Beti Ṣemeṣi ati àwọn ará Betanati jáde, ṣugbọn wọ́n ń gbé ààrin àwọn tí wọ́n bá ni ilẹ̀ Kenaani.
13 Òkùdu 2020 Ohun ti awọn akọṣẹmọṣẹ sọ nipa boo ṣe le mọ ipo ilera rẹ latara awọ ati bi igbẹ rẹ ṣe le tabi rọ si.
Ewe, O tun yanayana ipa orile-ede Naijiria nipase mimu igbe-aye alaafia ati aabo joba nile Afrika.
Àwọn ará Tire yóo máa fi ẹ̀bùn wá ojurere rẹ,àní, àwọn eniyan tí wọ́n ní ọrọ̀ jùlọ.
Ẹ ranti gbogbo iṣẹ́ ìyanu tí ó ṣe ní ilẹ̀ Ijipti sí ọba Farao, ati gbogbo ilẹ̀ rẹ̀.
Owó kò wúlò lọ́wọ́ òmùgọ̀ pé kí ó fi ra ọgbọ́n,nígbà tí kò ní òye?
Bawo ni ìsìn aisun ọdun lawọn ilẹ kaarọ oojiire?
Ẹgbẹ naa ti kọkọ fun ijọba ni ọjọ mẹẹdogun pe awọn yoo gunle iynaṣẹlodi ki wọn to bẹrẹ lọjọ Aiku.
Èyí mú kí gbogbo àwọn ilé yìí báramu dáadáa kí wọ́n sì gúnrégé.
-Big Brother sọ fún Dorathy Eyi ni wọn lo waye leyin ti awakọ pa ina ọkọ oju omi nibi to ti n se ariyanjiyan pẹlu awọn ero ọkọ lori iye owo ti yoo gba.
to kọja fun saa keji .
Atẹjade kan ti Ọọni fi sita latọwọ Oloye Ọyalami Awoyọde ni ẹnikẹni ko gbọdọ yọju sita nitori bi ẹnikẹni foju ba oro yii, oro naa yoo gbe ni o.
25 Bélú 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 26 Bélú 2019 Oríṣun àwòrán, AFP Àkọlé àwòrán, Ọjọ́ Kẹẹ̀dọ́gbọ̀n, Osù Kọkànlá, ọdọọdún ní Àjọ Isòkan Àgbáyá,UN láti lẹ̀ kéde òpin sí ìwà ipá sí obìnrin.
PDP Osun: A fẹ́ fún Ademola Adeleke ní tíkẹ́ẹ́tì ọ̀fẹ́ láti díje dupò gómìnà ní 2022
Sunday Igboho wa kesi ijọba apapọ lati ri wi pe wọn ṣewadii finifini lati mọ awọn to ṣiṣẹ ibi yii, ki wọn si fi wọn jofin.
Wo àwọn oúnjẹ márùn ún tó ń mú kí àtọ̀ ọkùnrin dára síi Kí làwọn nǹkan tó lè rán ọkùnrin sí ọ̀run alákeji lásìkò ìbálòpọ̀ pẹ̀lú obìnrin?
Dan Na Ambassagou eleyi to tunmọ si awọn ọlọde to fọkan tan Ọlọrun lorukọ ẹgbẹ ọlọde ti ijọba fofin de gẹgẹbiohun ti ajọ to n ja fun ẹtọ ọmniyan Human Rights Watch sọ.
OLUWA pàápàá sì ti sọ lónìí pé, eniyan òun ni ọ́, gẹ́gẹ́ bí ó ti ṣèlérí fún ọ, ati pé kí o pa gbogbo òfin òun mọ́.
Òtítọ́ di ohun àwátì,ẹni tí ó yàgò fún iṣẹ́ ibi fi ara rẹ̀ fún ayé mú.
O ni pe o lera fun oun lati darapọ mọ awọn idile tuntun ti iwadii fihan wi pe awọn gan an lo bi oun, amọ oun n tiraka diẹ diẹ.
Ọja ipin idokowo yoo ja walẹ - O ṣe e ṣe ki ọja ti wọn ti n ta ipin idokoowo ja walẹ, nitori pe èrè to n wọle fun awọn ileeṣẹ ti dinku.
Bakare Mubaraq: ọ̀pọ̀ èèyàn ló máa ń fẹ́ dúró sí ẹgbẹ́ mí tójú si máa n tì mí Ìkọlù agbébọn tó ṣékú pá ọmọ ogún Niger 89, iṣẹ́ bọ lọ́wọ́ Ọgágun àgbà Fọ́fọ́ ní ilé ẹjọ́ kún fún ìdájọ gomina ìpínlẹ̀ Kano, Imo, Sokoto, Benue, Plateau àti Bauchi Ǹjẹ́ o mọ ipa tí ẹja Panla kó lásìkò ogun abẹ́lé Biafra?
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Aarẹ Kenyatta ṣe'pade pẹlu olori alatako, Odinga 9 Ẹrẹ̀nà 2018 Oríṣun àwòrán, AFP/Getty Images Àkọlé àwòrán, Igba akọkọ ni yi ti Kenyatta ati Odinga yoo maa pade lẹyin idibo apapọ lorilẹede Kenya Ọrọ n sebi ẹni fẹ ba ibomiran yọ bayii lorilede Kenya nibiti aarẹ orilẹede naa, Uhuru Kenyatta ti n joko sọrọ bayii pẹlu asaaju alatako rẹ, Raila Odinga.
Ìkùukùu ni lọ́sàn-án, ṣugbọn ní alẹ́, ó dàbí ọ̀wọ̀n iná.
serena jameka williams ( ojoibi september 26 , 1981 ) je agba boolu tenis omo orile-ede amerika lowolowo to wa eniipo kinni lagbaye ninu idije enikan ati eniipo keji ninu idije enimeji pelu egbon re venus williams ( 12 / 8 / 10 ) .
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ibrahim Magu: Ọ̀gá àgbà báńkì tẹ́lẹ̀ rojọ́ tako alága EFCC tẹ́lẹ̀, ó fẹ̀ṣùn ìbàjẹ́ kàn-án 19 Èrèlè 2018 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 27 Agẹmo 2020 Oríṣun àwòrán, EFCC Àkọlé àwòrán, Oniruuru ọmọ Naijiria ni Ibrahim Magu ti yẹ idi wọn wo lori ẹsun iwa ibajẹ Ẹlẹ́rìí miran tun ti rojọ tako adele alaga ajọ EFCC, Ibrahim Magu, to n koju iwadii lori ẹsun iwa ibajẹ.
ana fun ile-ifowopamọ ti ijoba apapo orile ede naa, ti Bouteflika yan si
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Gani Adams: Inú ìpèbí ni Ọ̀yọ́mèsì ti pàṣẹ kí n yan olóyè mi 14 Sẹ́rẹ́ 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 15 Sẹ́rẹ́ 2019 Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Gani Adams: Inú ìpèbí ni Ọ̀yọ́mèsì ti pàṣẹ kí n yan olóyè mi Ni opin ọsẹ, ni ayẹyẹ ọdun kan Iba Gani Adams ni ori oye aarẹ ọna kakanfo ilẹ Yoruba wa sopin.
Sibẹsibẹ, mi o sọ fun ẹnikẹni.
Àwọn ọmọ Jadai nìwọ̀nyí: Regemu, Jotamu, ati Geṣani, Peleti, Efa ati Ṣaafu.
Oríṣun àwòrán, AFP Àkọlé àwòrán, Ikọ Arsenal bi jabọ si ipo kẹfa lori tabili liigi, ti wọn to s'ẹhin ikọ Liverpool ti o wa ni ipo kẹrin Akọni-mọọgba fun ẹgbẹ Arsenal, Arsene Wenger ti salaye wipe awọn asise ti awọn ọmọ ẹgbẹ agbabọọlu Arsenal se lori papa lo se okunfa ijakulẹ ninu idije naa.
Bẹ́ẹ̀ ni kí gbogbo àwọn ọ̀tá rẹ ṣègbé, OLUWA;ṣugbọn bí oòrùn ti máa ń fi agbára rẹ̀ ràn,bẹ́ẹ̀ ni kí àwọn ọ̀rẹ́ rẹ máa tàn.
ogun oju ofurufu ti ise akanse, Operation LAFIYA DOLE ti sekolu sibudo awon omo
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Pottery: Àwọn onímọ̀ nípa amọ̀ wúlò púpọ̀ ju ike àbí irin lọ Ayaworan kọfii naa ni isẹ kekere owo nla ni fifi kọfi ya aworan jẹ nitori owo nla lo n mu wa fun oun.
Nígbà tí Joabu ati àwọn ọmọ ogun tí wọ́n tẹ̀lé e dé, wọ́n sọ fún Joabu pé, “Abineri ti wá sí ọ̀dọ̀ Dafidi ọba, ọba sì ti jẹ́ kí ó lọ ní alaafia.
Oríṣun àwòrán, Olori Ramat Adedayo Adeyemi Ọpọ eeyan lo maa n pe Olori Adedayo ni Iya Ile Koto abi Iya Koto, ojuse rẹ si ni lati maa tọ awọn olori kekeke sọna nipa ise ati ihuwasi to yẹ olori, to fi mọ awọn asa adayeba ilẹ Yoruba.
Ọlọrun yóo ranti àìdára tí wọ́n ṣe, yóo sì jẹ wọ́n níyà nítorí ẹ̀ṣẹ̀ wọn.
O ni ki won ma ta ibo wọn.
Fìtílà meje ni ó ṣe fún ọ̀pá náà, ojúlówó wúrà ni ó fi ṣe ọ̀pá tí a fi ń pa iná ẹnu fìtílà.
naa ni awon osise ajo  EFCC ohun ti se
Ẹlẹẹkeji ni pe ki awọn ti wọn n pawọpọ ba wọn ja naa ma ṣe foju di awọn agbesunmọmi yi'' Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ikú wo ló pa ọmọ ogun Nàìjíríà mẹ́wàá àti ọ̀kan tó ṣẹ̀ṣẹ̀ ṣe ìyàwó?
Tí olúwarẹ̀ ò bá ṣọ́ra, èèyàn á kó gbogbo owó ọwọ́ ẹni fún wọn níbẹ̀.
Ìdá ọgbọn fun ọ ti o ba fẹ ẹ gba owo rẹ ati ele ni owo Naira, nigba ti wa a gba ìdá aadọta ti o ba fẹ ẹ gba ni owo igbalode 'Bitcoin.
 títẹ ̀ dó rẹ ̀ náà kìí ṣe pẹ ̀ lú ìrọ ̀ wọ ́ -rọsẹ ̀ , bí kọ ́ ṣebogun tó gbóná janjan fún bí ọdún oúpọ ̀ kí ó tó borí àwọn ẹ ̀ yà mẹ ́ tàlá kan tí ó bá ní ifẹ ̀ tí Ọbàtálá jẹ ̀ adarí fún wọn , tí ó sì sọ ìlú náà di Ìlú kan ṣoṣo tí ó wà ní abẹ ́ ìṣàkóso Ọba kan ṣoṣo .
Ni kete to si ku oun nikan sinu ile, lo mu bileedi, to la ikun ara rẹ, to si gbe ọmọ tuntun jade.
Oríṣun àwòrán, Ajimobi lives on Adura Fidau naa, ni awọn ọmọ, aya ati ẹbi oloogbe nikan peju si, ti ikede saaju pe ko si fun gbogbo eniyan nitori ofin itakete sira ẹni to wa lode lori arun Coronavirus.
Adari igbimo asofin, Temba Mliswa so pe , Aare orile ede Zimbabwe ana, Roobert Mugabe ko ni wa siwaju igbimo asofin to n sakoso  irin ati  ina mona-mona mo, fun wadii lori  okuta iye-biye ti iye re je bilinonu marundinlogun owo dola  ti won fesun kan an   pe o so pe won se e basu-basu.
Nigba to ya ni iroyin tun jade pe ẹsun rẹ gangan ni to ni ṣe pẹlu ọpọlọpọ kaadi ipe lori ẹrọ ayelujara.
Sunday ni igbiyanju obi oun lati ra ẹya ara atawọda lati Germany ko ba aawọ ara ohun mu ki ẹgbọn rẹ to ṣe eyi to n lo fun un.
Nígbà tí o bá fún wọn, wọn á kó o jọ,nígbà tí o bá la ọwọ́,wọn á jẹ ohun dáradára ní àjẹyó.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, India: Ẹ wo bí àwọn ènìyàn ṣe dóòlà èmí erin tó jálulẹ̀ Bawo ni a ṣe maa mọ ẹni to ba jawe olubori ni Ghana?
Ko si aaye fun obinrin ni suadi lati darapọ mọ ọkunrin ti ko ba tan mọ wọn nita gbangba ni Saudi ArabiaItakun agbaye Ogbeni Mohandis, ni ko tii sọ nkanakn nipa fidio to gaboju opo awọn eniyan kiri yii.
Gabon Pierre-Emerick Aubameyang ti Arsenal Ni ti Aubameyang, àmì ẹyẹ Golden Boot tó gbà yóò dúró gẹ́gẹ́ bi gbà mábinu bi ikọ̀ agbábọ́ọ̀lù rẹ̀ ṣe fidirẹmi ti wọn ko le wọn ikọ̀ agbábọ̀ọ́lù mẹ́rin akọ́kọ́ ti wọn ó fi ni ànfani lati kópa ninu Champions League ni sáà tó ń bọ.
4 Sẹ́rẹ́ 2021 Fídíò, Amotekun Osun: A ò gbé Amotekun kalẹ̀ láti máa yọjú sí ọ̀rọ̀ tí kò sí lábẹ́ òfin5 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Amotekun Recruitment: Ìròyìn ayọ̀ fún gbogbo àwọn tó forúkọ sílẹ̀ fún ikọ̀ Amotekun ní ìpínlẹ̀ Oyo1 Bélú 2020 Amotekun Oyo: Iṣẹ́ ti bẹ̀rẹ̀ ní pẹrẹu fún Àmọ̀tẹ́kùn ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́ lẹ́yìn ìdánilẹ́kọ̀ọ́ ọlọ́sẹ̀méjì gbáko18 Bélú 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Wọ́n ka ati máa ṣe àríyá ní ọ̀sán gangan sí ìgbádùn.
Ninu oṣelu Naijiria, baba isalẹ jẹ ẹnikan to lagbara lati rii wi pe oun funra rẹ wọle ibo tabi ẹni to ba ṣatilẹyin fun wọ le.
Kí ẹ lè mu àmutẹ́rùn, ninu wàrà rẹ̀ tí ń tuni ninu;kí ẹ lè ní ànítẹ́rùn pẹlu ìdùnnú,ninu ọpọlọpọ ògo rẹ̀.
Tí ó bá sọ ìtàn ìjàpá, tí ó fi oyin sí i, tí olúwa rẹ̀ bá ti gbọ́ ìtàn náà ní ogún ìgbà, ń ṣe ni ó màa dàbí ẹni pé ìtàn titun ni!
Oba Abiọdun Aderẹmi Adefẹhinti sọ ohun to ṣokunfa àṣà ẹgba nínà lásìkò ọdún ìjẹṣu.
Baba Sala, ogbontarigi agba apanilẹrin elere ori itage naa re ibi agba n re loṣu kẹwaa ọdun.
APC ní yóò jáwe olúbori ni Bayelsa ati Kogi- Tinubu Wike kìí ṣe dọ́là tí Ganduje leè kó sápò- Agbẹ́nuso ìjọba ìpínlẹ Rivers Kí ni ó gbé ọlọ́pàá dé ibi àjọ̀dún ọjọ́ ìbí i Bobrisky?
Ìbò NFF: Ìbò 34 ni Pinnick fi borí àwọn olùdíje yòkúù
Ọmọ ọdún márùn-ún, àgbà mẹ́rin ló bá ìṣẹ̀lẹ̀ ọ̀pá bẹntiróò tó gbiná ní Abule Egba lọ - LASEMA PDP yóò wọ́de nítorí ìdájọ́ ìdìbò gómìnà ìpínlẹ̀ Imo Kò sí ǹkan tí mo lè ṣe bí kìí ṣe kín yẹra kúrò nílé Ọba-Harry Lalong, Tambuwal, Ganduje ni ilé ẹjọ́ gíga jùlọ kéde bíi gómìnà ìpínlẹ̀ wọn Koda, awọn eniyan n sọrọ si awọn nkan keekeeke bi ka di mọ ara wa diẹ, ati ka di ara wa lọwọ mu, ka to wa sọ pe ka jọ sun papọ.
Bi awọn kan ṣe n yin Remi Tinubu pe ootọ ọrọ lo n sọ ni awọn mii ni ọrọ ko tọ sẹnu ọmọ iya ole ni o: Bẹẹ naa ni awọn miran gba ọdọmọde Senetọ ti ẹnu n kun naa niyanju lati moju to ibinu ko too ma a gba ẹbọ lọwọ rẹ lawujọ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù NAFDAC: Ohun tí wọ́n fi ń se báàgì, bàtà ni wọ́n ń tà bíi ‘pọ̀ǹmọ́ 27 Agẹmo 2019 Oríṣun àwòrán, Google Àkọlé àwòrán, Àjọ NAFDAC ti ní àwọn ọlọ́jà káràkátà kan ń lo awọ ẹran màálù tí wọ́n fi ń ṣe báàgì tàbí bátà látì fi ṣe pọ̀nmọ́.
Ìtànṣán ògo OLUWA jáde kúrò ní àbáwọlé, ó sì dúró sí orí àwọn Kerubu náà.
 Awọn iroyin ti ẹ lee nifẹẹ si: Ohun marun t'ejo n jẹ Ọjọgbọn Wole Soyinka soro si awọn ọdọ Aṣigbe ọmọ ni orilẹede India O tun ni, Ọpọlọpọ awọn ti o fi ara wọn jin fun itọju Street Priests jẹ awọn akẹẹgbẹ mi nileewe nigba kan, wọn si mọ bi iwa mi ṣe buru to nigba naa, ati ayipada rere ti o ti de ba mi.
Wiwa si orile ede Naijiria wa lara irinajo re lo si ilu Afirika.
Ó ń gbógun ti ilẹ̀ Ìjẹ̀ṣà nígbà kan.
Wọn óo na ọwọ́ ní ààrin rẹ̀ bí ìgbà tí ẹni tí ń lúwẹ̀ẹ́ bá nawọ́ ninu omi.
 wikipedia ni iṣẹ ́ ọwọ ́ tótóbijùlọ aṣàlàyé ọ ̀ fẹ ́ tó únlo ìwé àṣẹ yìí .
APC, ẹ gbé òṣèlú tì sẹ́gbẹ̀ẹ́ kan ná, kẹ padà wá lọ́dún 2022 - Ṣèyí Mákindé Lizzy Anjorin fèsì padà, ó ní ìsọ̀ alágbo ni Toyin Abraham bímọ sí, kìí ṣe London À fẹ́ ṣe àṣàrò lórí ìdájọ́ láti mọ̀ bóyá á pe ẹjọ́ kòtẹ́milọ́rùn - Agbẹjọ́rò Adelabu South Africa bẹ Naijiria lórí ìsekúpani nítorí ẹ̀yà!
Sibẹ àwọn baba yín kò gbọ́; wọn kò sì fetí sílẹ̀, wọ́n ṣe oríkunkun, kí wọn má baà gbọ́, kí wọn má baà gba ìtọ́ni.
Ibrahim Chatta fesi sí ẹ̀sùn pé òun na iyawo rẹ̀!
Ijọba apapọ Naijiria ti ṣaaju kede pe ki awọn akẹkọ to wa ni ipele ikẹkọgboye nileewe girama wọle pada sẹnu ẹkọ wọn lọjọ kẹrin oṣu kẹjọ.
Nigba to n ba BBC Yoruba sọrọ, agbẹjọro Naira Marley, Olalekan Ojo salaye pe ọlọpa agbefọba ninu ẹri to sọ nile ẹjọ salaye pe oun ko lee sọ boya Marley lu jibiti pẹlu kaadi ti wọn fi n ra ọja.
Bakan naa ni igbimọ naa gbọdọ fi esi iwadii wọn sọwọ si ijọba laarin oṣu mẹfa si asiko yii.
" Ẹ ̀ yà máàrùn "" kòkòrò àṣòkunfà "" lè ranni kí ènìyàn tán kiri ."
RUGA: Adeboye ní àsìkò tó láti wá nǹkan ṣe sí ọ̀rọ̀ ètò pápá ìjẹko RUGA pátápátá
Wọn ko ni le jẹun daradara.
Gẹgẹ bi itan naa ti sọ, ko pẹ ti wọn jẹ ẹran naa, ti akọbi fi bẹrẹ si ni ṣe aisan, eyi to mu ki iya wọn salọ si ọdọ Ọrunmila fun iwosan ọmọkeji to tun bẹrẹ aisan.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Contortion: Nígbà tí mo rí bí ara Soffie Dossi ṣe rọ̀, mo pinu pé mo lè ṣe bẹ́ẹ̀ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Contortion: Nígbà tí mo rí bí ara Soffie Dossi ṣe rọ̀, mo pinu pé mo lè ṣe bẹ́ẹ̀ 23 Sẹ́rẹ́ 2020 Ọmọde ni ara rẹ rọ to yii.
lati ekun Gusu si ipo ijoba apapo, ipese oju popo,ile-iwe, eto ounjẹ ati idagbasoke
Sọ fún àwọn eniyan Israẹli pé, ‘Òróró yìí ni yóo jẹ́ òróró ìyàsímímọ́ ní ìrandíran yín, 
Bẹ́ẹ̀ ni n óo ṣe fi òpin sí ìṣekúṣe ati àgbèrè tí o kó ti ilẹ̀ Ijipti wá.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, IVF: Ìyá ìbejì se IVF mẹ́ta lókè òkun, ìkẹrin tó se ní Nàíjíríà, ló fi bímọ A gbọ pe lati igba ti Iya Rainbow ti n ṣiṣẹ nọọsi lo ti nifẹ si ere ori itage ṣiṣe, o si bẹrẹ rẹ diẹdiẹ ninu ẹgbẹ oṣere Oṣumare ti ọkọ rẹ, Ayanfẹmi Oroniyi Phillips da silẹ.
Ẹ̀ ń sọ pé, “Èyí sú wa!
Ó sàn kí á máa gbé kọ̀rọ̀ kan lókè àjà,ju pé kí eniyan máa bá oníjàngbọ̀n obinrin gbé ilé lọ.
Ti a ba tẹlẹ ilana ti a fi n ṣiṣẹ, ko si nnkan to jọ bẹẹ.
, to si ri aye gbe ko to jẹ Ọlọrun nipe lọjọ ogbo rẹ.
Irọ̀ ni ìjọba ń pa, Ikọ Amọtẹkun ba ofin Naijiria mu- Ìgbìmọ̀ Yoruba Tinubu kò ṣékú, kò ṣé ẹyẹ, o n dibọn ní lórí ọ̀rọ̀ ikọ̀ Amotekun - Fani Kayode Digbí ni mo wà lẹ́yìn Amotekun, máà ṣèrànwọ́ mílíọ̀nú èèyàn fun - Nnamdi Kanu Ẹ̀bùn ọdún tuntun tó yááyì ni ikọ̀ Amotekun - Soyinka Ìbẹ̀rù nípa Amotekun ló ń mú káwọn èèyàn kan máa wí ìwíkùwí - Soyinka Miyetti Allah ni awọn fẹ lọ sibi ipade ita gbangba ọhun lati fi ero awọn han lori ifilọlẹ ikọ alaabo ọhun lẹkun iwọ oorun guusu Naijiria.
“Ẹ ti gbọ́ tí a ti sọ fún àwọn baba ńlá wa pé, ‘Ìwọ kò gbọdọ̀ ṣe àgbèrè.
Àjàpadá tí à ń pè ní aṣọdẹbóyèdé wá ní iyì gidi tí àwọn ará ìlú sì fẹ ́ ràn rẹ gan-an .
19 Kìlọ̀ fún un nínú àwọn àṣìṣe rẹ̀, àti bákannáà gba ìkìlọ̀ láti ọ̀dọ̀ rẹ̀.
“Mo farabalẹ̀ nígbà tí ẹ̀yin ń sọ̀rọ̀,mo fetí sí ọ̀rọ̀ ọgbọ́n yín,nígbà tí ẹ̀ ń ronú ohun tí ẹ fẹ́ sọ,
Yoòbá ní “Àìrìn jìnnà ni ò jẹ́ ká rí abuké ọ̀kẹ́rẹ́, táa bá rìn jìnnà à ó rí abuké erin”.
Àṣà àti èdè Yorùbá dùn púpọ̀, o ní ìtumọ̀ kíkún
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Olubadan: Àláfíà ni mò ń wá ní ìpínlẹ̀ Ọyọ 2 Ògún 2019 Oríṣun àwòrán, OTHERS Àkọlé àwòrán, Àwọn ọba 27 ti gomina tẹlẹri, Ajimobi yan ti faake kọri pe awọn ko ni gbe ade awọn silẹ lati le sisẹ pọ pẹlu Olubadan ti Ibadan.
"A kò lè gbà kí ìjọba àpapọ̀ ṣ'agbátẹrù Amotekun, ìjọba ilẹ̀ Yorùbá yarí Wo àwọn ọmọ ilé ìgbìmọ̀ aṣòfin l'Abuja tó sùn fọnfọn lásìkò ìjókòó ilé Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Bí ẹ ṣe mọ̀wé tó, ẹ wá dánrawò níbí pẹ̀lú ""Àpólà Ọ̀rọ̀ Orúkọ - Noun Phrase Oríṣun àwòrán, OTHERS Iditẹ gbajọba to yẹ igi mọ Idiagbon nidii Lasiko ti ijọba Buhari-Idiagbon n lakaka lati fi iwa Ọmọluabi ati ifẹ ilẹ baba ẹni sookan aya ọmọ Naijiria kọọkan, ariwo pe ijọba n ni awọn lara ni ọpọ ọmọ ilẹ yii mu bọ ẹnu."
Amẹ́ríkà ni wọ́n ti ngbé ètò náà si afẹ́fẹ́ àmọ́ bí mo ti wí tẹ́lẹ̀, ànfàní wà láti fetísí ètò náà káàkiri àgbáyé nípasẹ̀ ẹ́ ẹ̀ro ìgbàlódé tó ti mú aiyé lujára bí ajere!
Orisun awọn aworan naa ni AFP, Reuters, EPA ati Getty Images Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Òṣìṣẹ́ Bánkì ni mí l'Amẹ́ríkà kí n tó bẹ̀rẹ̀ Tíátà' Kini asọtẹlẹ Fada Mbaka nile Igbo ni Guusu Naijiria?
Tó o bá ṣàdéhùn ìfẹ́ tó ò mú u ṣẹ, ẹ̀wọ̀n lo fi ń ṣeré Èèwọ̀!
Àwọn ìròyìn mìíràn tí ẹ lè nífẹ̀ẹ́ sí: 'Ẹwọn ọdun mẹẹdọgbọn ko pọ ju fun afipabanilopọ' Damasus, Omotola, Ezekwesili, Funmi Iyanda dá sí ẹ̀sùn ìfipábánilòpọ̀ Fatoyinbo Ẹ̀sùn ìfipábánilòpọ̀: Orí Twitter ló ti bẹ̀rẹ̀, ikú ló já sí COZA: Mi ò fípá bá obìrin lò pọ̀ rí láyé mi - Pásítọ̀ Fatoyinbo Ààrẹ fi nǹkan ọkùnrin rẹ̀ pa mí lójú, kó tó fipá bámi lòpọ̀ - Ọmọge Arẹwà O ni nigba ti oun ba gba isinmi ni ile iwe, oun maa n lọ lo isinmi lọdọ aburo iya oun to jẹ obinrin, ki oun le farapamọ sibẹ fun igba diẹ, sugbọn kaka ki ewe agbọn dẹ, lile lo n le si fun oun nibẹ.
“Ẹni tí ó bá gbà yín, èmi ni ó gbà.
Oríṣun àwòrán, Others Omotoso ṣalaye pe, awọn eleto abo lee wa alupupu wọn lawọn ibi ti wọn ti fofin de ti wọn ba wa ninu aṣọ iṣẹ nikan, kii ṣe ki wọn maa lo aṣọ ara lati gbe ero nitori wọn jẹ ọlọpaa tabi ọmọ ologun.
Ajọ náà ní tí Falz bá kọ̀, wọn yóò gbe lọ ilé ẹjọ́.
Nígbà tí o di òru ọjọ́ yìí ni ìyá mi ti isà òkú wá bá mi.
Mudasiru Ajayi Ọbasa ti rọ awọn ọmọ orilẹ-ede Naijira paapaa awọn
Ẹ sọra fun jije ẹran ti wọn ti ṣe sibẹ tabi ti wọn ti fi sinu ike.
Igbimọ oluwadii Coker Commission of Inquiry lo ṣewasii rẹ, wọn si ni o jẹbi ẹsun naa.
Mo yọ̀ gidigidi ninu ọkàn mi pé Ọlọrun ṣe òfin.
Àpérò àwọn àjẹ́ kò gbọdọ̀ wáyé - Àjọ PFN Ènìyàn 27 lo ti bá iṣẹ̀lẹ̀ ọkọ̀ ofúrufú tó já rìnrìn ajò Awọn ileeṣẹ iroyin abẹle kan lorilẹede Naijiria ti kọkọ gbe iroyin yii pe eyi to ti n da ariyanjiyan silẹ laarin ọpọ titi de ori ayelujara.
Ajínigbé ń bèèrè fún epo, iṣu àti ọ̀tí Schinap gẹ́gẹ́ bí owó ìtanràn Kò sí àṣà tó faramọ́ fífi èmí ènìyàn ṣe ìrúbọ - Olúwó Ifeoluwa ni kẹkẹ yii ni oun wa ni ojoojumọ ni ile iwe oun ni France ti o fi n din inawo rẹ ku lori mọto wiwọ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Adebola Ademilua: Àìrísẹ́ ṣè lẹ́yìn ìwé kíkà ló sọ mi dí ìyá onírú, mo dúpẹ́ tèmi Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Wọn ni awọn gbe igbesẹ yii lẹyin ti awọn janduku fa wahala ni agbegbe kọọkan ni Kwara.
Èèyàn 250 míràn lárùn náà Igba o le aadọta eeyan ni ajọ to n gbogun ti ajakalẹ aarun lorilẹede Naijiria, NCDC tun ti kede pe o ko aarun COVID-19 lọjọ Abamẹta.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Black women lives matter: Ọdún 2015 ní àwọn ọlọ́pàá pa India Kager láìní ìdí- Gina Best Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Black women lives matter: Ọdún 2015 ní àwọn ọlọ́pàá pa India Kager láìní ìdí- Gina Best 19 Agẹmo 2020 India Kager n gbiyanju lati daabo bo ikoko to gbe dani ni lasiko ti awọn ọlọpaa yinbọn pa a- Gina Best Lasiko ti awọn ọlọpaa n wa Angelo Perry to jẹ baba ọmọ ikoko to wa lọwọ India Kager ni wọn yinbọn pa obinrin naa.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Asset Declaration: Gbogbo ẹni tí ó máa búra wọlẹ́ gẹ́gẹ̀ bíi Mínísítà gbudọ̀ kéde dùkìá 4 Ògún 2019 Àkọlé àwòrán, Ọ̀kan lára àwọn Mínísítà tuntun Igbimọ eleto idajọ to n gbọ ẹsun iwa aṣemaṣe awọn eeyan to dipo oselu mu ati oṣiṣẹ ọba, CCB ti paṣẹ fun awọn ti aarẹ Buhari fẹ yan sipo minisita lati kede dukia wọn ki wọn to ṣebura wọle tabi ki w n koju ofin.
Eyi mu ko jẹ pe emi nikan ni mo n mojuto awọn ọmọ wa, ṣugbọn o maa n wa si ile ni gbogbo opin ọsẹ.
Ati pe koko ti awọn mọ ni pe ifẹmiṣofo ti awọn agbebọn ti ọpọ fura si pe wọn jẹ darndaran fulani n ṣe nilẹ Yoruba to gẹ.
” Jakọbu dáhùn pé, “Má fún mi ní ohunkohun, bí o bá gbà láti ṣe ohun kan fún mi, n óo tún máa bá ọ tọ́jú àwọn agbo ẹran rẹ.
Ìye àwọn ènìyàn to ti kú gẹ́gẹ́ bi ìròyìn ṣe fi idi ẹ mulẹ kò fi bẹ́ẹ̀ pọ̀.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Iho ti wọ̀n n ko awọn ẹru si ni Ghana ki wọn to wọ ọkọ oju omi Bakan naa, lawọn eebo pọtugi ti n ko awọn ẹru lọ si agbegbe wọn lati saa onka sẹnturi kẹẹdogun (15th century) Bawo ni wọn se fẹ sami irinwo ọdun ti owo ẹru bẹrẹ?
Ṣafani sì mú un lọ sọ́dọ̀ ọba, ó ní, “Àwọn iranṣẹ ń ṣe ohun gbogbo gẹ́gẹ́ bí àṣẹ rẹ.
”Eli bá bi í pé, “Kí ló dé, ọmọ mi?
Olúwarẹ̀ di ẹni ibukun nítorí ó ń fi ọ̀rọ̀ tí ó gbọ́ ṣe ìwà hù.
Ninu owo iranwọ biliọnu mẹfa ti ijọba Naijiria la kalẹ lati si awọn ẹka ọrọ aje pada, awọn to wa ni ẹka ofurufu ko ni ipin ninu rẹ.
Akowe agba fun ile ise to n ri si oro agbegbe ati ipese
’Wọ́n kàn án ní ìṣó,ó le dáradára, kò le mì.
Bakan naa, O tuko agbaboolu Manchester City, Inter Milan, ki o to darapo mo iko agbaboolu Zenit lodun 2017, ti o si ran iko ohun lowo lati pari idije saa yii sipo karun un lori tabili.
Dani ni yóo máa ṣe ìdájọ́ àwọn eniyan rẹ̀,gẹ́gẹ́ bí ọ̀kan ninu àwọn ẹ̀yà Israẹli.
A máa bi wọ́n léèrè pé, “Kí ló dé tí ẹ fi ń ṣe báyìí?
Buhari: Maa ran Ghana lọwọ lati jagun iwa ijẹkujẹ
Dafidi sọ ọmọ yìí ní Solomoni.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Yoruba films: Gbogbo bó ṣe lọ rèé lágbo òṣéré láàrín ọ̀sẹ̀ yìí 11 Owewe 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 13 Owewe 2020 Oríṣun àwòrán, Mercy Aigbe Gbajugbaja oṣere fiimu Yoruba, Mercy Aigbe to ṣẹṣẹ ṣe agbejade fiimu tuntun kan ti fi oju ọmọ rẹ, Juwon han gẹgẹ bi ọkan lara awọn to kopa.
EndSARS: Olatunde Abolarinwa London Tailor ní òun á ṣe baba fún mi, kò tilẹ̀ dúró ṣe bàbá àwọn ọmọ tirẹ̀ tóríi ìwà Ọlọ́pàá Mopol A kò lọwọ́ sí ìwé ìpẹ̀jọ́ tó tako ìdásílẹ̀ ìgbìmò ìwádìí aṣemáṣe ikọ̀ SARS- ọlọ́pàá Nàìjíríà Àwòrán àwọn afurasí tí a fi léde kìí ṣe òfegè, ṣùgbọn a dọ́gbọ́n síi - Iléeṣẹ́ ọlọ́pàá Àwọn Ọba alayé ní Naijiria ṣàbẹ̀wò sí Ọba Eko, Gómìnà Eko àti Bola Tinubu lẹyin ìwọ́de EndSARS Lẹyin ọpọlọpọ igbiyanju ni wọn ri yoo ti o si dide lori ẹsẹ rẹ mejeeji.
"Aláwàdà ni ọmọ mi láti kékeré, kò ṣẹ̀ṣẹ̀ máa gbé mi mọ́ra- ìyá 'Mummy calm down' (Toluige Olokoobi Babalola) Oríṣun àwòrán, Instagram/iya_oreanu Iya ọmọdekunrin to wa ninu fidio kan ti ọpọ eeyan mọ si ""Mummy calm down,"" Toluige Olokoobi Babalola ti sọ pe ọmọ naa maa n pa oun lẹrin ṣaaju iṣẹlẹ to sọ ọmọ rẹ di gbajumọ."
- Mike Bamiloye Ọkùnrin kan da ṣọ́ọ̀ṣì rú lásìkò ìgbéyàwó, Ó ní òun lọkọ àárọ̀ ìyàwó tuntun Mi ò fẹ́ ìrànwọ́ ẹgbẹ́ òṣèré, àwọn kọ́ ló kóbá mi- Chief Kanran Ẹfanjẹliisi naa ti wọn pe orukọ rẹ ni Mathew wa pẹlu ileejọsin kan ti awọn eeyan fẹran pupọ ni ilu Ejigbo ni eyi ti ko mọ pe irinajo iwaasu ọjọ naa lee di wahala.
Ile ẹjọ giga to kalẹ si ipinlẹ Kano ti ni otubantẹ ni igbesẹ Gomina Ipinlẹ Kano, Abdullahi Ganduje pẹlu bo se yan Emir mẹrin miran ni ilu Kano.
Manchester City pàdí ọrẹ dà f'ogun ẹ̀yìn ja Chelsea Ǹjẹ́ o mọ ohun tó ń fa súnkẹrẹ-fàkẹrẹ nílùú Eko?
Gedebe Hailu to jẹ Igbakeji adari eto aabo lorilẹede Ethiopia lo sọ bẹẹ fun Ile Isẹ Iroyin BBC, lẹyin ti rogbodiyan sẹlẹ lorilẹede Ethiopia, ti ọpọlọpọ awọn ologun si farapa.
Dele Ali tilẹ gbiyanju ko gba bọọlu sawọn Ajax , sugbọn pabo lo ja si.
"Ọkọ Funke Akindele kó eléré àti òṣìṣẹ́ jọ fi ṣe ""Surprise Pato"" fún un lọ́jọ́ ìbí rẹ̀ A dúpẹ lọ́wọ́ ará ìlú fún àtìlẹ́yìn wọ́n nígbà táa n wa Sunday Shodipe-iléèṣẹ́ ọlọ́pàá Owó dé!"
“ Ki e si ri i pe ẹ jade lopo janturu , lati dibo fun egbe yin, ki e si daabo bo ibo yin, lai je pe awon kan dun ikooko mọ ọn yin.
fi oro yii mule, lojo aje(Monday ojo kẹ́rìnlélógún, osu
Ìbádọ́gba nínú ìsèlú àti iṣẹ́ láwùjọ ṣe pàtàkì fún ìdàgbàsóké
Oríṣun àwòrán, Temilolu Akinboola Ẹwẹ, ninu atẹjade kan to fi lede, o ni irọ pọnbele ni gbogbo ohun ti Adele sọ, nitori oun ko ran janduku kankan lati fi iya jẹ.
Ofin ẹka igbokegbodo ọkọ fun ọdun 2018 lo n risi idagbasoke ati isakoso igbokegbodo to muna doko ati ipese awọn ohun elo amayedẹrun nipinlẹ Ẹko.
Akẹkọbinrin 111 lo sọnu ni Yobe '‘ Awọn ọmọ Yobe’ Kini yoo pada jasi?
Chelsea (1970)Ki aṣọ o ma ba a tako ara wọn, ni ẹgbẹ́ agbabọọlu Chelsea ṣe pa ààwọ̀ ibọsẹ ati awọn nkan miran to jẹ aawọ funfun, si ààwọ̀ ofeefe (yellow),ni asiko ifẹsẹwọnsẹ asekagba pẹlu Leeds.
Àwọn abala ìfihàn yìí kan le ti jẹ́ fífúnni láti ìbẹ̀rẹ̀ bíi ìgbà ẹ̀ẹ̀rùn 1829.
Baba awọn ibeji naa ni inu oun dun pupọ lati ri wi pe awọn mọ mejeeji wa ni alaafia, ti awọn si n woye lati pada sile lai pẹ.
Lati igba tọwọ ti tẹẹ ni awọn obinrin adugbo yii ti n yọ ayọ ominira ti wọn si n wa yọju lati wa wo ẹni to n dunkooko mọ wọn yi ti wọ́n si ti wa fi ẹsun kan lọdọ awọn ọlọpaa tẹlẹ' Muhammad jẹwọ fun akọroyin BBC to fọrọ wa a lẹnu wo pẹ nitootọ ni awọn iṣẹlẹ naa ṣẹlẹ.
Igbesẹ yi yoo tun fun awọn Yoruba lanfaani lati lẹnu ninu ileesẹ agbohunsafẹfẹ BBC.
Mò ń ba yín sọ̀rọ̀ bí ọmọ.
''Buhari pàṣẹ́ kí ojú ọ̀nà Apapa gba ìdáǹdè ní kíákíá Àfikún ọ̀sẹ̀ méjì la tún fun yín láti kúrò l‘Apapa - Ọsinbajo Háà!
Ile iṣẹ to ṣe e- Valneva Canada Inc.
Orilẹ-ede Germany, Ulli Beier, ẹni to nifẹ si awọn ohun isẹnbaye.
Oríṣun àwòrán, others Àjọ JAMB kéde ìlànà ìgbà ni wọlé tuntun fún àwọn ilé ẹ̀kọ́ gíga Ajọ to ṣe eto idanwo aṣewọle si awọn ile ẹ̀kọ́ giga ni Naijiria, JAMB, ti pàṣẹ pe ki eto igbani wọle o bẹrẹ ni ọjọ keje, oṣu Kẹsàn-án.
Eyi ko ṣẹyin fidio kan ṣe gba ori ayelujara, to si ṣafihan ọmọ naa nibi to ti n bẹ iya rẹ fun idariji.
Ìhà àríwá, lẹ́bàá odò Yufurate, ni wọ́n tí fẹsẹ̀ kọ, tí wọ́n sì ṣubú.
Ní ọdún kejila tí Joramu ọmọ Ahabu ti jọba ní Israẹli ni Ahasaya, ọmọ Jehoramu, jọba ní ilẹ̀ Juda.
Nígbà tí ó ṣe, inú bí ẹbọra yìí ó sì pinnu àti fi ara rẹ̀ hàn bí ẹbọra, ó yí padà ó di kìnnìún.
Amọ yatọ si iforukọsilẹ siimu, awọn nnkan mii wa ti o tun nilo NIN rẹ fun gẹgẹ bii ọmọ Naijiria.
Bi o tilẹ jẹ pe eto idibo naa lọ ni wọọrọ wọ, sibẹ Kọmisana feto idibo nipinlẹ Ekiti fidi rẹ mulẹ pe awọn janduku kan si ja apoti ibo gba ni awọn agọ idibo bii marun si mẹfa lasiko eto idibo naa.
Aare Muhammadu Buhari ti sabewo si
Nígbà tí ó yá lẹ́yìn tí Josaya ti ṣe ètò inú tẹmpili tán, Neko, ọba Ijipti wá jagun ní Kakemiṣi, ní odò Yufurate.
Bí o ti rí i pé ara òkè kan ni òkúta yìí ti là, láìjẹ́ pé eniyan kan ni ó là á, tí o sì rí i pé ó fọ́ irin, idẹ, amọ̀, fadaka ati wúrà túútúú, Ọlọrun tí ó tóbi ni ó fi ohun tí yóo ṣẹlẹ̀ lẹ́yìn ọ̀la han ọba.
Ó kọ OLUWA Ọlọrun àwọn baba ńlá rẹ̀ sílẹ̀, kò sì júbà àṣẹ rẹ̀.
Igbe gbajare yi n gbẹnu Oshokomolẹ latari iṣẹlẹ to waye ni asekagba ipolongo idibo ẹgbẹ PDP ni Ondo t'awọn kan ti si fila lori rẹ.
O kò gbọdọ̀ dá nǹkankan sí, pa gbogbo wọn, atọkunrin, atobinrin; àtàwọn ọmọ kéékèèké; àtàwọn ọmọ ọmú; ati mààlúù, ataguntan, ati ràkúnmí ati kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ wọn, gbogbo wọn pátá ni kí o pa.
 Otunba Niyi Adebayo ni alaga igbimo naa, ti o
Poopu lo maa n yan wọn si ipo, wọn si ṣaba maa n jẹ oye biṣọọpu.
Ayinla Ọmọwura kò kàwé, àmọ́ ó kópa sí àgbéga orin àti èdè Yorùbá
“Ẹ kò gbọdọ̀ wọ aṣọkáṣọ tí wọ́n bá pa irun pọ̀ mọ́ òwú hun.
Nigba ti awọn ọmọ ologun yinbọn lu kẹtẹkẹtẹ naa, n ṣe ni ado oloro ara rẹ bu gbamu ti awọn ikọ agbesunmọmi si jade lati ṣina fun wọn.
Ijamba ina afẹfẹ gaasi to ṣẹlẹ ni agbegbe Sabon Tasha ni Kaduna ni wọn ni o ti mu ẹmi Ojọgbọn Simon Mallam lọ.
Tèmi ni gbogbo fadaka ati wúrà tí ó wà láyé; èmi OLUWA àwọn ọmọ ogun ni mo sọ bẹ́ẹ̀.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ondo 2020: Tani ìgbìmọ̀ tó ń sàyẹ̀wò olùdíjẹ lábẹ́ APC nípínlẹ̀ Ondo yọ kúro gan-an?
Bakan naa ni igbimọ yii tun mẹnuba bi ọdun Ileya se maa n larinrin lasiko igba ti wọn wa ni ewe atawọn ọna ti wsn n gba gbadun rẹ.
Nígbà tí Jesu jókòó lórí Òkè Olifi, àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ tọ̀ ọ́ wá, wọ́n bi í pé, “Sọ fún wa, nígbà wo ni gbogbo èyí yóo ṣẹlẹ̀, kí sì ni àmì àkókò wíwá rẹ ati ti òpin ayé?
" Temilolu sọ pe awọn janduku naa kọlu awọn oloye oun mẹta, bẹẹ ni wọn kan apa ọkan lara wọn.
Èéfín ń jáde ní imú rẹ̀,bíi ti ìkòkò gbígbóná ati ìgbẹ́ tí ń jó.
Kogi elections: Ilé ẹjọ́ ní ẹgbẹ́ AA kùnà ìlànà INEC fún ìbò gómìnà ní Kogi, Bayelsa
Saulu dá a lóhùn pé, “Láì sí àní àní, pípa ni wọn yóo pa ọ́; bí bẹ́ẹ̀ kọ́, kí Ọlọrun lù mí pa.
Ileeṣẹ naa tun ni wọn yoo ṣe ọmọde rẹ jade pẹlu gilaasi oju ti ko ni ju 5.
Ẹ fura o, Boko Haram ti pàgọ́ sí Abuja, yóò ṣe ìkọlù láìpẹ́ - Iléèṣẹ́ Aṣọ́bodè lọgun Ká ní ọmọ Buhari fẹ́ mi, màálù 150 ní màá fi dána - Olólùfẹ́ míì tó tún yọjú Tinubu, yé é sọ̀rọ̀ abẹ́lẹ̀, bọ́ sí gbangba láti bèèrè àtúntò Nàíjíríà lọ́dọ̀ Buhari - Afẹnifẹrẹ Ọjọ́ Ìṣẹ́gun yóò ro lásìkò ìwọ́de lórí èlé owó epo - Ẹgbẹ́ òṣìṣẹ́ Faleye ṣalaye pe afurasi ti wọn gbamu kọkọ sẹ pe oun ko mọ ohunkohun nipa iṣẹlẹ ọhun, ṣugbọn o ko ọrọ rẹ jẹ ni ọjọ kẹta, oṣu Kẹsan an, ọdun 2020.
Ondo Crisis: Ẹ̀ṣùn kan ṣoṣo tí ilé aṣòfin fi le yọ igbákejì gómìnà ní tó bá tàpá ṣófin ilẹ̀ wa Oríṣun àwòrán, Ondo Assembly Ile asofin ipinlẹ Ondo ti bẹrẹ igbesẹ lati yọ igbakeji gomina ipinlẹ naa, Agboola Ajayi nipo rẹ.
Ijọ Sotitobire: Òótọ́ àti irọ́ tó wà nínú iṣẹ̀lẹ̀ náà Ikọ̀ Arsenal kéde Mikel Arteta gẹ́gẹ́ bí akọ́nimọ̀ọ́gbá rẹ̀ tuntun Kìí ṣe olórí ọ̀dọ́ ẹgbẹ́ wa ló kú o, ọkọ̀ gb'ókìtì, ọ̀dọ́ kan gba 'bẹ̀ lọ - PDP Oyo Àkìtàn ni mí, kò sí ohùn tí ara mi kò gbà -Fayose Awọn ọmọ ẹgbẹ oṣelu Republican nile aṣofin naa pọ to de bi pe o ṣeeṣe ki wọn dibo gbe Trump lẹyin.
Ìyá Jesu ati arabinrin ìyá rẹ̀ ati Maria aya Kilopasi ati Maria Magidaleni dúró lẹ́bàá agbelebu Jesu.
Wọn kédé Narendra, oludije ẹgbẹ́ BJP ni India pẹ̀lú ariwo ńla Wọ́n jí ọmọ yìí gbé láti máa fi tọrọ bárà l'Eko ‘Bi Gomina Ajimobi se yan adarí òsìsẹ́ tuntun ní Oyo kò dí wa lọ́wọ́’ Mohammed Adamu ti di Ọ̀gá ọlọ́pàá Nàìjíríà tuntun Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
15 Kíyèsíi, mo pàṣẹ fún ọ pé ìwọ kò níláti rò pé a ti pè ọ́ láti wàásù títí tí a ó fi pè ọ́.
Kí àwa náà lè máa ṣe bẹ́ẹ̀.
Gomina ni oun pada lọ ri alufaa Adeboye nigba ti idibo gomina ọhun ku diẹ, o si tun sọ foun pe gbogbo rẹ maa dara lẹyin ''to gbadura fun mi tan.
 láti inú ẹgbẹ ́ àáró tí ọkùnrin kan ti n jẹ lísàbí dá sẹ ́ lẹ ̀ , ní ẹgbẹ ́ olórógun ti yọ jáde .
Mo fi àpẹẹrẹ ìtara àwọn ẹlòmíràn siwaju yín láti fi dán yín wò ni, bóyá ẹ ní ìfẹ́ tòótọ́ tabi ẹ kò ní.
Wo orúkọ àwọn ẹ̀yà ara rẹ̀ ní èdé Yorùbá Ǹjẹ́ o mọ ohun tó ń fa súnkẹrẹ-fàkẹrẹ nílùú Eko?
Ní àkókò kan nígbà tí Jesu wà ninu ìlú kan, ọkunrin kan tí ẹ̀tẹ̀ bò ní gbogbo ara rí i.
Ẹnikorewa, mo nifẹ rẹ pupọ, Ẹniayọ, orukọ rẹ ti salaye ọrọ, iwọ gan ni orisun ayọ mi.
Ọmọbinrin naa wa gba awọn obinrin ti wọn ba n koju iru isẹlẹ buruku yii nimọran, lati mase dakẹ, amọ ki wọn sọ ọrọ jade, o kere tan, fun ẹnikan.
Gbogbo àwọn ọmọ ogun bá rọ́ wọ ààrin ìlú, wọ́n sì gba ìlú náà.
ati Beti Nimra, Beti Harani, àwọn ìlú olódi ati ilé fún àwọn aguntan.
Ṣé irú ààwẹ̀ tí mo yàn nìyí, ọjọ́ tí eniyan yóo rẹ ara rẹ̀ sílẹ̀ lásán?
Ni igbà àtijọ́, oníyàwó kan kò wọ́pọ̀ nitori iṣẹ́ Àgbẹ̀.
Lọjọ kẹfa oṣu kẹta to lọ ni wọn mu Ronaldinho ati arakunrin rẹ, Roberto Assis lori ẹsun pe wọn lo ayederu iwe irina wọn orilẹede Paraguay.
Sibẹsibẹ ẹ̀ ń bèèrè pé, ‘Ọ̀nà wo ni a fi ń tàbùkù orúkọ rẹ?
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Eko Akete yóò gbàlejò BBC Yoruba Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Oun ni olori awọn obinrin ninu ẹgbẹ oṣelu CPC ti aarẹ Buhari ti kọkọ dije ko too darapọ mo ẹgbẹ oṣelu APC.
Akọwe ipolongo ẹgbẹ naa Kola Ologbọndiyan lo fi ọrọ yi sita loju opo Twitter lọjọru.
Lọ́wọ́lọ́wọ́ kò tíì sí àbáyọ Yaba Left: Àṣírí tú!
Ẹ gbọ́ igbe àwọn olùṣọ́-aguntanati ẹkún ẹ̀dùn ti àwọn oluwa agbo ẹran;nítorí OLUWA ń ba ibùjẹ ẹran wọn jẹ́.
Ni ipinlẹ Kaduna, ninu awọn mọkandinlaadọsan ti wọn yẹwo, maarundinlaadọrin ni arun naa.
Ìròyìn tó ń tẹ̀ wá lọ́wọ́ ni wí pé ó mú ẹ̀mí ènìyàn lọ tí ọ̀pọ̀lọpọ̀ sì jóná.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Oríṣí ìjìyà ní àwọn bíi Gómìnà El Rufai àti Fayemi ń bèèrè f'àwọn afipábánilòpọ̀ Sugbọn o, wọn tun pada yan Ọba Olateru pada sori itẹ lọdun 1993, lẹyin ọdun mẹtadinlọgbọn.
O ni iṣe akanṣe yii jẹ ajọṣepọ pẹlu awọn agbofinro, awọn aṣọbode, awọn to n risi iwọle ati ijade awọn eniyan, atawọn oṣiṣẹ eleto aabo miran.
  Kòtò ọ̀hún tóbi tó bíi abúle kan sí méjì!
Inu awọn orin lo ti kọkọ bẹrẹ si ni fojuhan ko to dara pọ mọ sinima agbelewo lede Gẹẹsi, ko to wa re si ti Yoruba to si n ṣe mejeeji sira wọn.
Bi iṣé abẹ ìdí ńlá ṣé n seku pá àwọn obìnrin Buhari yan Mohammad Sambo, olùdarí NHIS tuntun Òkú èèyàn mẹ́jọ ni wọ́n yọ níbi ìṣẹ̀lẹ̀ ìjàmbá ọkọ̀ nílùú Eko lọ́jọ́ Aje Àwọn ọ̀nà tí obìnrin fi le gbádùn ìbálòpọ̀ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Ìlù Bàtá ló yàn mi, èmi kọ́ ni mo yàn an' Ariwo ẹhonu lori iwa iṣẹlẹ naa ko mọ lori awọn nnkan ẹka amuludun nikan.
Ogbeni Femi Adesina to je oluranlowo Aare lori eto iroyin lo so eyi di mimo sugbon ko so gbendeke asiko ti Aare yoo se abewo yii.
Ọmọkùnrin tí bàbá rẹ̀ tì mọ́lé bíi ẹlẹ́wọ̀n f'ọ́dún méje ní Kano gba ìtúsílẹ̀!
Ìbúgbàmù ńlá ba ìlé méjì jẹ́, la ọ̀nà sí méjì ní ìlú Akure!
Iwadii fihan wipe apapọ ikọlu awọn daran daran ati ti awọn ọmọ ogun oju ofurufu fa ijamba pupọ to bẹẹ to jẹ wipe o kere tan, ilu mẹjọ lo ni adanu nla tabi ka ni ina run awọn ilu naa yaan-yaan.
 Ẹ ̀ kọ ́ nípa  economics ' ni ó kà ."
Nítorí mo jẹ́rìí wọn pé wọ́n ní ìtara láti sin Ọlọrun, ṣugbọn wọn kò ní òye bí ó ti yẹ kí wọ́n sìn ín.
N óo yọ̀, inú mi yóo sì máa dùn nítorí rẹ;n óo kọ orin ìyìn orúkọ rẹ, ìwọ Ọ̀gá-Ògo jùlọ.
1 x Automatic Revolver Galil Rifle.
Ẹ yin OLUWA, gbogbo iṣẹ́ ọwọ́ rẹ̀,níbi gbogbo ninu ìjọba rẹ̀.
Àwọn olè ń gbé ilé wọn ní alaafia,àwọn tí wọn ń mú Ọlọrun bínú wà ní àìléwu,àwọn tí ó jẹ́ pé agbára wọn ni Ọlọrun wọn.
Nàìjíríà yóò dá ṣèríà fún Senegal lónìí- Balógun Flying Eagles Donald Trump ti pàdé Ọbabìnrin Elisabeth tilẹ̀ Gẹ̀ẹ̀sì Bakan naa ni akọwe agba yii parọwa fawọn ẹlẹsin Islam pe ki wọn ma yọ ayọ ti ko yẹ lasiko yii.
Risikat Moromoke Azeez: Mínísítà tí fi ẹ̀bùn owó ránṣẹ́ si ìyá Kausara, ó tún jẹ́jẹ̀ẹ́ ẹ̀kọ́ ọ̀fẹ́ f'áwọn ọmọ rẹ̀
O ni owo ti o wọ apo ijọba pọ ju owo ti wọn kede lọ.
Ninu ọrọ ituba rẹ, o jẹ ko di mimọ pe oun to yẹ ko pari lọna nla fun ohun lo wa pari lojiji tori ori inu oun to tako oun.
Eyi lo mu ki wọn sun igbẹjọ naa siwaju di ọjọbọ ọjọ kẹtadinlogun oṣu kẹsan yii.
Taní Ibidunni Ighodalo tí gbogbo ọmọ Nàìjíríà ń selédè lẹ́yìn rẹ̀ Oríṣun àwòrán, Others Àkọlé àwòrán, Ǹkan tí a mọ̀ nípa Ibidunni Ighodalo tó kú Ọ̀pọ̀ àwọn ènìyàn ló ń bèrè pé taa ni Ibídunni Ighodalo, nítori náà ni aṣe ṣe àkójọpọ̀ àwọn ǹkan ti a ti mọ nígbà ayé rẹ̀ Àrẹwa tí ojú rẹ̀ wà lára èpo oṣẹ Lux ní Ibidunni ti ó sì ti jẹ́ ilúmọ̀ọ̀ká láti ẹni ọdún méjìdílógún.
Wayi o, Fayemi, ti tuko ipinle Ekiti lọdun 2010 si odun 2014, leyin ti o gba ipo naa pada labe asia egbe osleu All Progressives Congress (APC).
'Mo kan sara sawọn ayasọlo' 'Oku ọmọ mi ni wọn gbe wa ba mi lẹnu iṣẹ 'Ki lo buru ninu miliọnu mẹtala abọ naira ti a ngba' Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí 2 sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 2:23 Fídíò, Water Generator: Ó leè ṣiṣẹ fún wákàtí mẹfà, kó tó sinmi, Duration 2,2310 Òkùdu 2020 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
Eyi lo n ṣokunfa ọpọlọpọ iṣẹ ibi lọwọ oniruuru eniyan lawọn ẹkun yii.
Vitiligo: Síkẹ̀ẹ̀tì tó gùn ni mo máa ń wọ̀ bíi eégún tórí yẹ̀yẹ́
O ni awon yoo gba ile-ise aladaani laaye
Nítorí pé ẹni tí óo pa Moabu run ti dojú kọ ọ́,ó sì ti wó àwọn ibi ààbò rẹ̀.
títí tí Ẹni Ayérayé fi dé, tí ó dá àwọn ẹni mímọ́ ti Ẹni Gíga Jùlọ láre; tí ó sì tó àkókò fún àwọn ẹni mímọ́ láti gba ìjọba.
Bí ẹnìkan bá ní dúkìá ayé yìí, tí ó rí arakunrin rẹ̀ tí ó ṣe aláìní, tí kò ṣàánú rẹ̀, a ṣe lè wí pé ìfẹ́ Ọlọrun ń gbé inú irú ẹni bẹ́ẹ̀?
Mínísítà fún òṣìṣẹ́ yí ohùn padà lori ifikun owo osisẹ Ìgbìmọ̀ ẹlẹ́ni mẹ́ta lórí ọ̀rọ̀ owó oṣù àwọn òṣíṣẹ́ ní àwọn ti fi àdàgbá lórí ọ̀rọ̀ owó oṣù òṣìṣẹ́ rọ̀ lòdì sí ohun tí Mínísítà Chris Ngige sọ pé ìjọba ò fọwọ́ sí i.
Ohun si ni ibẹrẹ nkan ti wọn n pe ni Pelupelu.
Àwọn ọmọ-ogun gomina bá mú Jesu lọ sí ibùdó wọn, gbogbo wọn bá péjọ lé e lórí.
Ogbeni Agbaje ni “lati Ojobo ni a ti pin gbogbo irinse ati ohun elo ti won yoo fi n dibo lonii si gbogbo ijoba ibilẹ to wa ni ipinle Osun, ti awon agbofinro si  ri I pe won mojuto gbogbo re.
A kó àwọn ẹ̀yà Juda ní ìgbèkùn lọ sí Babiloni nítorí pé wọ́n ṣe alaiṣootọ sí Ọlọrun.
Ní ọ̀gbun jíjìn ni a óo sọ ọ́ sí!
- Yinka TNT Nigba miran, o ni o seese ki isan oju ara obinrin naa ran ju bo se yẹ lọ, eyi si lee mu ki abawọle oju ara naa kere si.
alatako  PDP, naa ni asofin  Enyinnaya Abaribe, (Abia South) ti o jẹ
Ẹlòmíràn kò ni kùrò láàrín ọ̀rẹ́, sùgban ọ̀rọ̀ ti kò tó ǹkan ni wan yóò máa fa ìbínú yọ gidi ti yóò si di ìjà ńla.
"Bakan naa lo tu ṣalaye pe wọn pin isọri owo naa si ọna marun un eyii to pe ni ""Band A, B, C, D ati E."
"Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Professor Wole Soyinka láti kékeré 13 Agẹmo 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 13 Agẹmo 2020 Oríṣun àwòrán, Getty Images, @IfeePeter Iku Olokun Ẹṣin (Death and the King's Horseman) Kongi's Harvest: A Play (Three Crowns) Myth, Literature and the African World Ake : The Years of Childhood The Lion and the Jewel Mandela's Earth: And Other Poems Ibadan: A Memoir 1945-1967 Isara: A Voyage around ""Essay"" A Dance of The forest Opera Wonyosi Early Poems African Theatre Jero Plays ."
Ọgbẹ ́ -inú buruli a má a sábà wáyé ní ìgbèríko gúsù sahara afirika pàápàá júlọ cote d ' ivoire , ṣùgbọ ́ n ó tún lè wáyé ní eṣia , ìwọ ̀ -oòrùn pasifiki àti ní àwọn amẹrika .
Maradona to ṣagbatẹru bi Argentina ṣe gba ife ẹyẹ agbaye ọdun 1986, dagbere faye lẹni ọgọta ọdun.
Wọ́n ní, “Ọkunrin yìí sọ pé, ‘Mo lè wó Tẹmpili Ọlọrun yìí, kí n sì tún un kọ́ ní ọjọ́ mẹta.
Ṣugbọn Ayefele ni oun ko ba ijọba ja, bẹẹ ni oun ki i ṣe ọta Ajimọbi.
"Pẹlu ayipada oju ọjọ ati ba se n pọ si, ati asa awọn darandaran to jẹ pe to ba ni maalu aadọta, ti wọn jẹ koriko, gbogbo orisun omi ti wọn ba ri ni wọn yoo tọ lai naani ẹni yoowu to ni wọn.
Bí ó bá jẹ́ pé òun nìkan ni ó rà, òun nìkan ni òfin dá sílẹ̀, ṣugbọn bí ẹrú náà bá mú aya rẹ̀ lọ́wọ́ wá, bí ó bá ti ń dá a sílẹ̀, ó gbọdọ̀ dá aya rẹ̀ sílẹ̀ pẹlu.
Ọwọ́ ọlọ́pàá ti tẹ ọkùnrin kan tó pa ọ̀rẹ́ rẹ̀ nítorí N40 ní Kano Wọ́n mú ọjọ́ ìgbẹ́jọ́ agbésúnmọ́mí 9/11 tó ṣẹlẹ̀ l'Amẹrika Kíkọ́ ẹ̀kọ́ gboyè nínú iṣẹ́ ìṣègùn ìbílẹ̀ yóò pèsè ìtọ́jú tó péye fọ́mọ Nàìjíríà- Ẹgbẹ́ àwọn dókítà Bakan naa wọn tẹsiwaju ifẹhonu han wọn lọ si olu ileeṣẹ orilẹ-ede Ireland lagbegbe Maitama l'Abuja.
Pákáleke lórí ìdìbò àti ọrọ̀ ajé Nàíjíríà ń já wa láyà - UN UN: Orilẹ́èdè Nigeria dalẹ̀ Cameroon Buhari, tọwọ́ ọmọ rẹ basọ- Timi Frank Tijjani Bande ni yoo jẹ ọmọ Naijiria keji ti yoo je aarẹ Ajọ UNGA lagbaye.
Issac Promise ni adari ojugba rẹ nigba idije awọn ọjẹwẹwẹ ti ọjọ ori wọn ko ju Ogun ọdun ati mẹtalelogun lọ.
7 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 9 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Wo ibi fún èsì ìdìbò yíyan aàrẹ tuntun ní orílẹ̀-èdè Ghana Oludije mejila lo n dije dupo aarẹ Ghana tuntun nigba ti eto idibo na maa waye ni ẹkun mẹrindinlogun kaakiri orilẹ-ede Ghana.
NPolice recruitment 2020: Bí ó bá fẹ́ dara pọ̀ mọ́ ìṣẹ́ ọlọ́pàá, forúkọ́ sílẹ̀ níbí Bí o ṣe lè forúkọ silẹ̀ fún ètò N75BN Nigerian Youth Investment Fund"" rèé."
Ohun ti awọn aladugbo rẹ sọ ni pe agbara ojo naa gba arakunrin ọhun ti wọn ni orukọ rẹ n jẹ Idowu Kọmọlafẹ ati alupupu rẹ nigba to n gbiyanju ati gba aarin agbara ojo naa kọja lọ si ile rẹ.
Olumuyiwa tẹsiwaju pe niṣe ni Ifesinachi gbe Ujunwa pamọ sibi kan to si pe awọn mọlẹbi rẹ pe ki wọn san ọgbọn miliọnu lati fi doola rẹ.
Ṣugbọn ẹpa ko boro mọ nitori, wọn ti kede pe O ku sinu iditẹ-gbajọba to ṣẹlẹ ni Addis Ababa naa.
Ìjọba ti bẹ̀rẹ̀ sí báwọn tó gbé òṣìṣẹ́ aláàánú mẹ́fà sọ̀rọ̀- Garba Shehu Ìdí tí Bàbá Leah Sharibu fi yarí pé ọmọ òun kò kú Ẹgbẹ́ agbésùmọ̀mí ISWAP ti ní adarí tuntun Kí wọ́n tún ìbò Kogi dì nígbà 2,000 Dino ló máa wọle- Dino Awọn alaṣẹ Naijiria to fi mọ awọn ologun ko ti i ṣọrọ lori iṣẹlẹ yi.
si  Khartoum,ni won ti n ri eefin lati
Tolulope ṣẹṣẹ pari akanṣe ẹkọ to lọ kọ ni Starlite International Training Academy, ni orilẹede South Africa to si jẹ akẹkọ to fakọyọ ju.
Kàkà bẹ́ẹ̀ kí ó kúkú gbìyànjú láti fi ọwọ́ ara rẹ̀ ṣe iṣẹ́ rere, kí òun náà lè ní ohun tí yóo fún àwọn aláìní.
S nítorí wọ́n bí ọ síbẹ̀ mọ́’ Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Bakan naa lo sọ pe awọn sọọbu oúnjẹ le ma a si lọjọ Aje, Ọjọru ati Ẹti, laarin aago mẹjọ àárọ̀ si mejila ọsan.
Wọ́n bá pàṣẹ pé kí wọ́n jáde kúrò lọ́dọ̀ àwọn ìgbìmọ̀.
Fi aṣọ tẹ́ẹ́rẹ́, aláwọ̀ aró dè é mọ́ fìlà alufaa níwájú.
9 14695363 Orilẹ́ede Brazil 176941 84.
Duro Ladipọ, ìlúmọ̀ọ́ká òṣèré tíátà àti ọmọ àlúfà tí kò gbàgbé àṣà ìbílẹ̀ Ọ̀rọ̀ǹpọ̀tọ̀niyùn, Aláàfin obìnrin àkọ́kọ́ rèé, tó ní nǹkan ọkùnrin Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí kan sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
  Tí yìnyín bá rọ̀ sí ojú ọ̀nà yìí wọ́n á fi ọkọ̀ tí wọ́n fi nkó ilẹ̀dú kó yìnyín ojú
Oríṣun àwòrán, TWITTER ENDSARS: Ẹ̀yin ọmọ Nàìjíríà, ẹ ṣè ìrànwọ́ irinṣẹ́ fáwọn ọlọ́pàá- Naira Marley bẹ̀bẹ̀ Saaju la ti mu iroyin wa fun yin pe,akọrin takasufe, Naira Marley ti ṣalaye fun ileeṣẹ ọlọpaa Naijiria pe awọn to ṣe irun dada sori kii ṣe ọdaran o.
ipinle Eko (Lagos State University, LASU, Ojo, Lagos)  lati maa wa awijare kankan fun ikunna wọn lati
66 Ṣùgbọ́n àwọn alàgbà tí wọ́n nṣe olórí, àwọn bíṣọpù tí wọn nrin ìrìnàjò, àwọn ọmọ àjọ ìgbìmọ̀ gíga, àwọn àlùfáà gíga, àti àwọn alàgbà, lè ní ànfàní yíyanni, ní ibití kò bá sí ẹ̀ka ìjọ tí a lè ti pe ìbò.
Nígbà mìíràn wọ́n fi yín ṣẹ̀sín, wọ́n jẹ yín níyà, àwọn eniyan ń fi yín ṣe ìran wò.
Ó fí kun pé iná NEPA ló sokùnfa ikú ọmọbinrin náà àti pé Clarence Peters tó ni ilé iṣk kò mọ ǹkankan nípa ikú ọmọbinrin náà Nkan márùn tí nípa Clarion Chukwura Ọmọ ọdún ọdún mẹ́rìndínlọ́gọ́ta ni Clarion Chukwura Ọmọ Ilesha ati Abeokuta ni láti ìdílé ìyá, sùgbọ́n Delta ati Onisha ni Baba rẹ̀ Ọmọ ọdún mẹ́ẹ̀dógún ni làsìkò tó bẹ̀rẹ̀ eré tíátà Ọdun mẹrin ni ó fi wà l'Amẹrika sùgbọ́n ó ti pada si Nàìjíríà ní ìbẹ̀rẹ̀ ọdún yìí, sùgbọ́n gbogbo àwọn eré àgbéléwò tuntun ti tó ti kópa yóò jáde.
Ẹ wo bí a ti gé òòlù tó ti ń lu gbogbo ayé lulẹ̀,tí a sì fọ́ ọ!
"Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí 5:47 Fídíò, Akomolede ati Asa: Mọ̀ si nípa àwọn ọ̀nà tí Yorùbá ń gbà ran ara wọn lọ́wọ́, Duration 5,4722 Ọ̀wàrà 2020 End SARS Protest: Babangida ní ejò lọ́wọ́ nínú lórí ìsẹ̀lẹ̀ rògbòdìyàn tó ń wáyé káàkiri Nàìjíríà22 Ọ̀wàrà 2020 Fídíò, Akinwumi Isola: Wo ohun tí Abeni fi ojú ọkọ rẹ rí tórí iṣẹ́ bọ́ lọ́wọ́ rẹ̀ nínú ìwé ""Nitori Owo""27 Ọ̀wàrà 2020 Iyaloja Oyo state: Àwọn ọlọ́jà ń sèdárò Ìyálọ́jà ìpínlẹ̀ Oyo, Wuraola aya Kola Daisi tó dolóògbé, wọ́n yan asojú míràn22 Ọ̀wàrà 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!"
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: 'Ìdí tí mo fi fẹ́ dupò ààrẹ nìyìí.
Àwọn iranṣẹbinrin ń pe ìyá rẹ̀ ní olóríire.
Tí ẹ bá wá rí Ọmọ-Eniyan tí ń gòkè lọ sí ibi tí ó wà tẹ́lẹ̀ ńkọ́?
Ẹ óo wá mọ̀ dájú pé OLUWA àwọn ọmọ ogun ni ó rán mi si yín.
OLUWA Ọlọrun ọ̀run, tí ó mú mi jáde láti ilé baba mi, ati ilẹ̀ tí wọ́n bí mi sí, tí ó bá mi sọ̀rọ̀, tí ó sì búra fún mi pé, àwọn ọmọ mi ni òun yóo fi ilẹ̀ yìí fún, yóo rán angẹli rẹ̀ ṣáájú rẹ, o óo sì fẹ́ aya wá fún ọmọ mi láti ibẹ̀.
Mo fi ara mi búra pé, ẹ kò ní rídìí ọ̀rọ̀ kankan lọ́dọ̀ mi.
Àwọ́n ẹgbẹ́ tó dá a sílẹ̀ ni The National Union of Air Transport Employees (NUATE) and Air Transport Services Senior Staff Association of Nigeria (ATSSSAN) àti the National Association of Aircraft Pilots and Engineers (NAAPE) Àkọlé àwòrán, Ẹnu ibodè MMA2 Akọ̀ròyìn BBC Yorùbá tó bá àwọn òṣìṣẹ́ àti arìnrìnàjò sọ̀rọ̀ jábọ̀ wí pé lóòtọ́ ni wọ́n ti ẹnu ibodè pápákọ̀ òfúrufú pa tí wọn kò sì jẹ́ kí àwọn tó ti forúkọ sílẹ̀ láti rìnrìnàjò wọlé.
Ninu atẹjade to wa lati ọdọ awọn agbẹnusọ rẹ, Trump ni ''gbogbo wa la mọ idi ti Biden fi n sare lati kede ara rẹ gẹgẹ bi ẹni to jaweloubor ti awọn eeyan rẹ nileeṣẹ iroyin naa si n ṣapa lati ran lọwọ.
Ni kete to si de silẹ Brazil ni ọga rẹ yii tun yi orukọ rẹ pada si Williams nitori ẹru ko ni idamọ kankan to yatọ si ti olowo rẹ.
Àti wípé ni ọdún 2007, òun yìí kan náà ni ó ti Umaru Musa Yar'Adua tí ó jẹ kí Jónátánì ó tó jẹ lẹ́yìn digbídigbí.
Akowo agba ajo naa Patricia Scotland, alaga igbimo amusese, Norman Hamilton, awon omo-egbe igbimo ati asoju orile-ede Gambia, Francis Blain yoo peju pese sibi ayeye naa.
A bá ju Èṣù tí ó ń tàn wọ́n jẹ sinu adágún iná tí a fi imí-ọjọ́ dá, níbi tí ẹranko náà ati wolii èké náà wà, tí wọn yóo máa joró tọ̀sán-tòru lae ati laelae.
OLUWA sọ pé, “Mo ha gbọdọ̀ fi ohun tí mo fẹ́ ṣe yìí pamọ́ fún Abrahamu, 
Awọn cardinal bi igba le mẹta lati orilẹ-ede mọkandinlaadọrin lo wa.
Àwa kò gbọ́ pé àwọn Fulani Darandaran gbé wa lọ sí ilé ẹjọ́- Ìjọba Ọyọ Olanrewaju tun sọ ninu ọrọ rẹ pe ko si ootọ ninu ọrọ tawọn alatilẹyin Saraki n gbe ka pe ile ẹjọ ti paṣẹ kawọn ma fọwọ kan ile naa ''A ko ri iwe kankan gba lati ọdọ ile ẹjọ ṣaaju asiko ta fi bẹrẹ si ni wo ile naa'' O wa parọwa sawọn ara ilu lati bọwọ fofin ki wọn si ma ṣe gbọ ọrọ ahesọ to le ṣakoba fun alaafia ipinlẹ naa.
Rírí tí yóo tún rí, ó rí àwọn mààlúù meje mìíràn, wọ́n tún ti inú odò náà jáde wá, àwọn wọnyi rù hangangan, wọ́n rí jàpàlà jàpàlà, wọ́n dúró lẹ́gbẹ̀ẹ́ àwọn meje ti àkọ́kọ́.
 O fi ofin todun 2011 fun awon agbesunmomi se apere pe: Lati isinyii lo, enikeni to ba soro alufansa tabi ti o so ohunkohun to mu ikorira dani ni won yoo ba se ejo labe ofin agbesunmomi.
Gita yii ni Cobain ta lasiko to n rin irinajo ipolongo orin ni Nirvana ni Utero tour.
Dokita yọ góòlù àti owó ṣílè nínú obìnrin kan Etí ìjọba Buhari di sí ìmọ̀ràn àwọn ará ìlú -Jiti Ogunye Ẹ ṣọ́ra fún ìròyìn ẹlẹ́jẹ̀ lórí ètò ààbò - Ọlọ́pàá O ni lilo ilana ọmọ onilu ati ọmọ onilẹ, (Quota system) fun yiyan awọn eeyan sipo iṣẹ ọba ati iṣejọba n ṣe ọpọ akoba fun idagbasoke Naijiria.
Eto igbanisiṣẹ ajọ DSS Awuyewuye jẹyọ lori eto igbanisiṣẹ awọn oṣiṣẹ ọrinlenirinwo din ẹyọ kan, 479, tuntun fun ajọ DSS.
O mọ bi awọ ara mi ti ri, o si mọ pe emi ni baba rẹ.
N650,000 péré ni mò ń gbà gẹ́gẹ́ bíi owó oṣù -Gomina Ọyọ A padà san owó ìtanràn fáwọn ajínigbé kí wọ́n to fi àwọn mẹ́tẹ̀ẹ̀ta sílẹ̀- Ẹbí Spaghetti, mílíìkì, Chivita àti Àǹkàrá sọ Rabiu dèrò ẹ̀wọn ni Eko Ṣe ẹ ti gbọ́ ri?
Owurọ ọjọ Ẹti ni awọn akẹkọọ ile ẹkọ GSSS, Kankara, nipinlẹ Katsina, to le ni ọọdunrun ọhun gunlẹ si ilu Katsina.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Suspected ritual killer: Ọwọ́ tẹ afurasí olóògùn owó tó fẹ́ gé ọmú obìnrin nílé ìtura 4 Owewe 2020 Oríṣun àwòrán, Other Ọwọ ileeṣẹ ọlọpaa ipinlẹ Anambra ti tẹ ọkunrin afurasi kan to fẹ ge ọmu obinrin kan nile ituru ni ijọba ibilẹ Orumba nipinlẹ̀ Anambra.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Yoruba language: Ọdún 2020 to wọlẹ́ dé yìí á tu gbogbo wa lára Awọn obi gbọdọ pe akiyesi awọn olukọ si ajeji kankan ti ihuwasi rẹ ba mu ifura dani ni ayika ile iwe awọn ọmọ wọn.
OLUWA bèèrè pé, “Amosi, kí ni ò ń wò yìí?
Kẹti kẹti lawọn ara ipinlẹ Eko tu sita kaakiri ẹkun idibo mtẹta to wa lati maa ra irẹsi yii ti wọn gbe sori igba ni ẹgbẹrun mejila fun 50kg, ẹgbrun meji abọ fun 10kg.
Isà òkú tí ó yanu sílẹ̀ ni ọ̀fun wọn;ẹnu wọn kún fún ìpọ́nni ẹ̀tàn.
Ó wá dá àwọn tí ẹ̀rù ikú ti sọ di ẹrú ninu gbogbo ìgbé-ayé wọn sílẹ̀.
Orukọ amutọrunwa ni orukọ to ṣafihan iru ipo ti a fi bi ọmọ ninu ẹ̀jẹ̀ lọjọ ti a bii.
Ẹni to bori: Nigeria Uganda vs Tanzania.
Fayemi sọ pe igba kẹta ti oun ṣayẹwo arun naa ni esi fi han pe oun naa ti darapọ mọ awọn to ni arun ọhun ni Naijiria.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Zamfara Food Poisoning: Iyọ̀ onímájèlé tí wọn fi se oúnjẹ fa inú rírun fún mọ̀lẹ́bí kan 21 Ìgbé 2018 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 16 Ògún 2020 Oríṣun àwòrán, Others Adura ti ọpọ eeyan maa n gba ni pe ki ọba oke mase jẹ ka jẹ ounjẹ ajẹrọrun.
Nigba to wa n kẹdun lori iku alagbe naa, Oche tun rọ awọn ara ilu lati mase tako awọn ofin to rọ mọ lilo oju irin, ki wọn si dẹkun jijoko sẹba oju ọna reluwe, boya lati se agbe ni tabi fun idi miran.
Wọn a ma bi ni awọn ibeere pe 'Ki lo de ti o fi dudu?
Sẹnetọ Lekan Balogun: Taló yẹ kó yan ọba bí kò ṣe Ajimobi?
- Madam Saje Owó ilé ìwé gbígbà ní ìpínlẹ̀ Ogun ti di ìtàn - Gómìnà Amọṣa lẹyin ọpọlọpọ jija raburabu, Ngolo Kante da ẹyọ kan pada fun Chelsea.
Madagascar Covid 19 Update: Àgbo Covid-19 Madagascar kò ṣiṣẹ́, àwọn ènìyàn tí bẹ̀rẹ̀ sí ní kú níbẹ̀
Unicef-sọ pe mimu omi to gbona, ati diduro sinu oorun, to fi mọ yiyago fun 'ice cream' le pa arun naa.
Ní àkókò kan náà, Tatenai, gomina agbègbè òdìkejì odò ati Ṣetari Bosenai ati gbogbo àwọn ẹlẹgbẹ́ wọn wá sí ọ̀dọ̀ wọn, wọ́n bi wọ́n léèrè pé: “Ta ló fun yín láṣẹ láti kọ́ tẹmpili yìí ati láti dá àwọn nǹkan inú rẹ̀ pada sibẹ?
Kogi Election: Dino Melaye náà pariwo pé àwọn apanìyàn ti gbòde ní ìbò ku ọ̀la
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ẹ̀ka aṣòfin méjèèjì lórílẹ̀èdè Naijiria sọrọ lori bi iṣekupani ni agbeegbe Ila-oorun apa ariwa Niajiria ṣe n peleke si Ile asofin agba wa parọwa lati gbe ọrọ ọlọpaa abẹle wo lati gbogun ti eto aabo to dẹnukọlẹ.
Ipe wa si alukoro ileeṣẹ ọlọpa nipinlẹ Eko, Chike Oti, lati fidi iṣẹẹ naa mulẹ, ko ti i so eso rere, pẹlu bi o ṣe ṣeleri lati kan si akọroyin wa to pe e.
Ẹ̀mí OLUWA bà lé Samsoni tagbára tagbára, okùn tí wọ́n fi dè é sì já bí ìgbà tí iná ràn mọ́ fọ́nrán òwú.
Theresa May: Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Awọn aṣofin kan dẹyẹsi aarẹ, awọn ti o ṣe tirẹ pẹlu si n yin in niwaju ile aṣofin apapọ Olotu ijọba ilẹ Gẹẹsi pẹlu ti ni ipin tirẹ ninu irufẹ idẹyẹsi bayii.
Ninu ọrọ ti aya rẹ, o ni kii se owo ni ọkọ oun fi fa oju oun mọra, tori inu yara kansoso ni o n gbe ti oun fi fẹ, ti ko si ni kẹkẹ.
Ṣugbsn ohun to n kọ ọpọlọpọ lominuu ni fidio kan to ṣafihan awọn eniyan kan to sọ pe olori ẹgbẹ oṣelu APC, Bọla Tinubu, ''ti ta ami ororo le oludije tuntun naa l'ori.
 lópin rẹ ̀ , ó parí ẹ ̀ kọ ̣ ́ girama rẹ ̀ ní ilé Ẹ ̀ kọ ́ girama oríwù , ní ìlú Ìkòròdú ní ìpínlẹ ̀ Èkó ní ọdún 1983 , ó sì gba ọ ̀ pọ ̀ lọpọ ̀ àmì ẹ ̀ yẹ ní ilé-ìwé náà .
Ninu ọrọ rẹ, o ni ijọba apapọ ma n se iranwọ fun ẹni to ba n sisẹ ohun ọsin, to si padanu ẹran ọsin rẹ.
Aare Muhammadu Buhari soro naa di mimo lasiko to tewo gba asoju
Nítorí ìdí èyí, ẹ̀tẹ̀ Naamani yóo lẹ̀ mọ́ ọ lára ati ìdílé rẹ ati ìrandíran rẹ títí lae.
" Ó jẹ ́ ọ ̀ kan nínú tí ó máa ń "" compose ' orin ."
Ta ló mọ bí ó ti tẹ́ ìkùukùu?
Oríṣun àwòrán, Google Gẹgẹ bi ọrọ tó jade lati ọfiisi agbẹjọro agba ipinlẹ EKiti, bi wọn ṣe fi orukọ ati didoju ti ni ni gbangba wa ni itẹsiwaju ipinu ijọba lati ma faye gba iwa ifipabanilopọ mọ ni ipinlẹ naa.
Má bẹ̀rù, má sì jẹ́ kí ìrẹ̀wẹ̀sì bá ọkàn rẹ, nítorí pé èmi, OLUWA Ọlọrun rẹ wà pẹlu rẹ níbikíbi tí o bá ń lọ.
NSCDC/Police Clash: Ìwádìí nípa ikú òṣìṣẹ́ NSCDC tí ọlọ́pàá lù níwájú ìyàwó àti ọmọ ti jáde
Oshiomole ati Osagie Ize-Iyamu naa kunlẹ bẹbẹ fun awọn eniyan lati ṣe agbatẹru fun wọn ni asiko idibo to n bọ nipinlẹ Edo naa.
Wọ́n dé ibìkan tí wọn ń pè ní Gẹtisemani.
Ṣùgbọ́n àwọn aṣiwèrè ènìyàn, a máa tanná ògùṣọ̀ òyìnbó, wọn a máa wá ìjà kààkiri òde.
Àwọn ìtàn mánigbàgbé tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ìtàn ayé Taiwo Oredein rèé, àgbà òṣèlú tó parí ayé rẹ̀ sọ́gbà ẹ̀wọ̀n Ìtàn ìgbé ayé Bode Thomas rèé, ó kọ́ wa láti máa kó ẹnu wa ní ìjánu Ṣo mọ̀ pé J.
Láti Libina wọ́n lọ sí Risa.
Àwọn ẹ̀yà mìíràn sọ ara wọn di Juu, nítorí pé ẹ̀rù àwọn Juu ń bà wọ́n.
idanileoo naa  lati so nipa aseyori re
Lọdun 1440 ni Ọba Henry VI da ileẹkọ Eton silẹ, ti o si di ilumọọka nitori iru ẹkọ to ye kooro ti wọn n kọ awọn akẹkọọ nibẹ.
Saáájú ní àwọn ọmọ égbẹ́ APC ẹka ti ìpínlẹ̀ Ogun ti kéde Adekunle Akinlade ní yóò dupò gómìnà lái fi ariweo ará ìlú àti àwọn olùkopa tókù ṣe.
Akẹ́kọ̀ọ́ méjì tó há sí Bosnia ti gúnlẹ̀ padà sí Nàìjíríà Amẹ́ríkà ń béèrè ìròyìn facebook, email arìnrìnàjò tó f'ẹ́ gbà'wé àṣẹ Àti lọ s'Amẹrika ti yàtọ̀ báàyí Fásitì ìpínlẹ̀ Ekiti dá òṣìṣẹ́ 355 padà sẹ́nu iṣẹ́ Ṣugbọn, ko sọrọ lori boya awọn eniyan yoo ma a san owo fun un tabi iye ti iwe irinna naa yoo jẹ.
Ṣé ojurere eniyan ni mò ń wá nisinsinyii, tabi ti Ọlọrun?
Ondo: Ọ̀rẹ́kùnrin Khadijat Olubọyo gba ọjọ́ ikú!
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Seyi Makinde: Inú mi dùn láti rí àwọn ìjòyè lẹ́yìn Olúbàdàn 3 Owewe 2019 Oríṣun àwòrán, Facebook/Seyi Makinde Yooba ni ka rin, ka pọ, yiyẹ nii yẹ ni, bẹẹ si ni apọnle ko si fun ọba to da lọ sode.
Ni gbogbo wọn, àtọmọdé, àtàgbà, ati àwọn olórí ogun bá gbéra, wọ́n kó lọ sí Ijipti, nítorí ẹ̀rù àwọn ará Kalidea bà wọ́n.
Eyi ti ó burú jù ni owó rẹpẹtẹ miran ti wọn bù lati ra ọkọ ti ìbọn ò lè wọ, olówó nla lati Òkè-Òkun fún Ọgọrun-le-mẹsan Aṣòfin-Àgbà.
O ni: “O le ni eedegberun milionu owo dola ile Amerika ti Naijiria n padanu lodoodun ni eyi ti India n gba to otalenigba milionu owo dola nibe.
Arsene Wenger: Arsenal ja bi ẹlẹṣẹ nidije Europa pẹlu AC Milan
Ijọba sọ pe oun yoo san owo naa diẹdiẹ laarin oṣu Karun-un ọdun 2021 si oṣu Keji, ọdun 2022.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Awon ọmọta to n jà ní ori aafara kan nilu Eko O s'ọwọn ki eeyan to wa ninu ẹgbẹ okunkun ribi já ara rẹ gba kuro ninu ẹgbẹ naa lasiko to wa ni ile ẹkọ.
Ni ọ̀pọ̀lọpọ̀ ọdún sẹhin, àwọn Àgbẹ̀ á dari wálé pẹ̀lú irè oko pàtàki iṣu.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Coronavirus: Báwo ni o ṣe le mọ̀ pé o ní àrùn Coronavirus?
Àkọlé àwòrán, Awọn aga manigbagbe ti Fagunwa lo ree.
Facebook: Gbogbo ojú òpó ìròyìn èké ní èdé Afirika pátá ló ń lọ
Agboola lo kede bẹẹ ninu ifọrọwerọ kan pẹlu BBC lati ẹnu agbẹnusọ rẹ, Babatope Okeowo.
”Obinrin náà dáhùn pé, “Kabiyesi, bèèrè ohunkohun tí o bá fẹ́.
Tabi o óo máa pàṣẹ lé wa lórí?
Bi awọn ipinlẹ to ni Coronavirus ni Ọjọ Iṣẹgun ṣe lọ ree: Plateau-183 Eko-33 FCT-25 Ogun-16 Oyo-7 Ekiti-6 Kwara-5 Ondo-5 Anambra-3 Imo-3 Nasarawa-3 Rivers-2 Gombe-2 Edo-2 Akwa Ibom-1 Ènìyàn 309 ló rí ìwòsàn gbà lọ́wọ́ àrùn Coronavirus ní Nàìjíríà ní Ọjọ́ Ajé Ajọ to n gbogun ti ajakalẹ arun lorilẹede Naijiria, NCDC ti kede pe eeyan 155 miran ti lugbadi arun Covid-19 ni Naijiria.
Wọn maa n sọ pe ki a ṣe musulumi dandan nitori pe ẹni tó ba ti kọ̀ lati di musulumi kò ni kúro lọ́dò àwọn.
    Ẹ máṣe gbàgbé pé lẹ́yìn tí ọba ran awa kí a wá àwọn alágbárta gbogbo lọ sí àgbègbè ìlú wa ó tún rán àwọn mìíràn lọ sí ọ̀nà tí ó jìnà sí ọ̀dọ̀ àwọn ọba ńlá gbogbo.
Oduduwa Alphabet: Òmìnira èdè ti dé fún Port Novo báyìí
Ọdun mẹrin miiranIgbakeji aare to wa niluu re
'À ó sa ipá wa láti gbárùkù ti ẹgbẹ́ lásìkò ìdìbò tí yóò wáyé lójọ́ kejìlélogún, oṣù kẹsan an, nítori pé ó ti dandan pé, nínú ìdìbó tẹnikan bá gbégbá orókè, kí ẹnikan fìdí rẹmi.
"Oríṣun àwòrán, @YeleSowore ""Ẹ panumọ́ lórí bẹ ṣe ń bú Buhari pé ó mú Ṣoworẹ sí àhámọ́"" Ẹgbẹ kan to n se atilẹyin fun aarẹ Muhammadu Buhari nidi eto iroyin, BMO, ti kesi Ọjọgbọn Wọle Soyinka, Fẹmi Falana atawọn ọmọ orilẹede yii miran, to koro oju si bawọn ọtẹlẹmuyẹ se gbe asaaju ẹgbẹ Revolution Now, Omoyele Sowore si ahamọ, pe ki wọn pa ẹnu wọn mọ."
Tí a fiṣọwọ́ ní 16:02 15 Sẹ́rẹ́ 202116:02 15 Sẹ́rẹ́ 2021 Wo àwọn ààrẹ Amẹ́ríkà mẹ́rin tí wọn rọ̀ lóyè àti ẹ̀ṣẹ̀ wọn BBC Yoruba se akojọpọ awọn aarẹ to ti jẹ nilẹ Amẹrika ti wọn yọ nipo.
Agbenuso ileeṣẹ Asset Management Coporatiion of Nigeria, Ogbẹni Jude Uwauzor ti ba ileeṣẹ BBC sọrọ ni kikun bayii.
Ni oṣu diẹ sẹyin ni minisita fun eto ilera lorilẹede Naijiria, Ọjọgbọn Isaac Adewọle pẹlu ti paṣẹ lọ rọọkun nile fun lori oniruuru ẹsun iwa ijẹkujẹ ṣugbọn ti aarẹ Buhari daa pada pe ko lọ bẹrẹ iṣẹ.
 ni o gbe ijoba fun Ogbeni Maada Bio.
Ìdí nìyí tí àwọn ọmọ Israẹli kò fi lè dúró níwájú àwọn ọ̀tá wọn.
Ilé ẹjọ́ ni agbábọ́ọ̀lù ọmọ Nàìjíríà, Dickson Etuhu jẹ́bi ẹ̀sùn títa ìdíje Sweden Òjò ló lè mú kí ìtànkálẹ̀ àrun ìgbẹ́ ọ̀rìn má tètè dópin ni Eko- Iléeṣẹ́ ìlera Ta ni Ken Saro-Wiwa tí ìjọba ológun sekúpa?
Ó dá wọn lóhùn pé, “Ẹ ṣọ́ra kí á má ṣe tàn yín jẹ.
Jesu bá sọ fún wọn pé kí wọn fún un ní oúnjẹ.
Ẹ má fi ọwọ́ kan nǹkankan!
"Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: ""Àlàyé rèé lórí bí mo ṣe fi ọsàn híhó fẹ́ ìyàwó mi"" Wo àmì márùn-un tí o fi le mọ ẹni tó fẹ́ gbẹ̀mí ara rẹ̀ Típà tẹ dẹ́rẹ́bà pa ní Epe Ọwọ́ tẹ ọkùnrin kan ní pápákọ̀ òfurufú l‘Eko tó ń kó ike ATM 2,886 lọ si Dubai Lẹ́yìn ọ̀pọ̀ ọdún, ìjọba Kwara fẹ́ sọ orúkọ Rashidi Yẹkini di mánigbàgbé Ọ̀kẹ àìmọye ẹ̀rọ àyẹ̀wò káàdì olùdìbò jóná mọ́lé l' Ondo Wo iye àwọn tó ti gbẹ̀mí ara wọn ní Nàìjíríà láàrin ọdún mẹ́rin ìjọba Buhari Adelegan ní ètò idìbò ṣe pataki si idagbasoke ara ilu lọdun mẹrin-mẹrin, nitori naa ko yẹ ki iru nkan bayii maa ṣẹlẹ niru asiko ti a wa yìí O yẹ ki wọn ni ore ọfẹ lati yan ẹni to ba wu wọn kii ṣe pe ki awọn oloṣelu nitori ifẹ ara wọn ma a di wọn lọwọ."
Gomina Bala Muhammad yii lo ti figa kan jẹ minista fun olu ilu Naijiria, Abuja ki o= to dije dupo gomina ipinlẹ Bauchi.
Nǹkan gan-an tí ò ń torí rẹ̀ dá ẹlòmíràn lẹ́jọ́ ni o fi ń dá ara rẹ lẹ́bi.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Komla Dumor: Solomon Serwanjja ọmọ Uganda jáwé olúborí nínú Àmì ẹ̀yẹ BBC Ipinlẹ Chihuahua ti setan lati ran awọn eniyan agbegbe naa lọwọ lati ri i wi pe wọn lọ si ile iwe bi wọn tilẹ ti dagba ju bẹẹ lọ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Fuel Price Hike: Ìjọba Nàìjíríà rọ aráàlú láti yí ọkọ̀ àti gẹnẹrétọ̀ wọn sí èyí tó ń lo afẹ́fẹ́ gáàsì lọ́fẹ̀ẹ́ 14 Owewe 2020 Oríṣun àwòrán, Twitter/PPPRA Minisita fun ọrọ epo rọbi, Timipre Sylva ti kede pe lati oṣu Kẹwaa ọdun 2020 lọ, ijọba apapọ yoo bẹrẹ si yi awọn ọkọ ayọkẹlẹ ati gẹnẹretọ awọn araalu pada si eyi to n lo afẹfẹ gaasi.
Àdó okoró búrẹ́kẹ' Ẹka ileeṣẹ ijọba to n ri si eto aabo sọ pe awọn ẹṣọ yoo duro wamu wamu lati ṣọ ibi isinku síi Bella Vista lẹyin olu ilu Argentina, Buenos Aires fun o kere tan fun ọsẹ kan.
Bakan naa ni ojiṣẹ Ọlọrun Omoshola kilọ fawọn ọdọ wi pe, ki wọn ye pe ara wọn ni ''Marlians.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Yoruba Culture: ọjọ́ méje ni wọ́n fí n rẹ ẹ̀kú Danafojura kó tó jáde Oríṣun àwòrán, Yinka Alaya/Facebook Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Àwọn ọmọ Nàíjíríà: Bùhárí gbọdọ̀ sọ́ ẹnu rẹ̀ l‘Ámẹ́ríkà 30 Ìgbé 2018 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Aarẹ mejeeji yoo sọrọ nipa eto aabo, ọrọ ajẹ ati idokowo laarin orilẹede mejeeji Awọn ọmọ Naijiria ti kan si Aarẹ Buhari lati sọ ọrọ ẹnu rẹ lasiko ipade pẹlu Aarẹ orilẹede Amerika, Donald Trump nibi ipade awọn adari mejeeji ti yoo waye nile ijọ̀ba Amẹrika, White House.
Ta ni Ìgè Àdùbí nílẹ̀ Oodua?
Buhari Independence Live Broadcast: Wo àwọn kókó tó wà nínú ọ̀rọ̀ tí ààrẹ bá ọmọ Nàíjíríà sọ Oríṣun àwòrán, Femi Adesina Aarẹ Muhammadu Buhari ti sọ pe, kii ṣe Naijiria ni epo rọbi ti wọn ju lagbaye nitori epo wọn ni awọn orilẹ-ede kan bii Ghana ati Niger ju Naijiria lọ.
Diego Maradona: Báyìí ni àgbàọ̀jẹ̀ agbábọ́ọ̀lù Diego Maradona ṣe wọ káà ilẹ̀ lọ lólú ìlú Argentina
Àkọlé àwòrán, O ti to ọjọ mẹta ti igbẹjọ ẹsun jẹgudujẹra ti wọn fi kan Musiliu Obanikoro ti n waye Otuyalo ti o jẹ adari awọn oṣiṣe eto gbigbe owo to pọ nigba kan ri nile ifowopamọ Diamond Bank ni apo nla marundinlaadọrin lawọn fi gbe owo naa.
Buhari pàṣẹ lórí àdínkù owó bẹntiró, alágbàtà ń ṣe tiwọn Ọmọ ilẹ̀ Italy tó kó Coronavirus wọ Naijiria kò ní àrùn náà mọ́ Wo àwọn irọ́ tí wọ́n ń pa fún ọ nípa àrùn Coronavirus Lati igba ti arun naa ti wọ Naijiria ni ipe ti n jade lati ọdọ awọn ọmọ Naijiria pe o yẹ ki Aarẹ Muhammadu Buhari ba awọn ọmọ Naijiria sọrọ lori arun naa lati fi wọn lọkan balẹ, bi awọn aarl to ku ṣe n ṣe kaakiri agbaye.
Ninu lẹta naa si ni Alaafin ti ni oun kọ iwe ọhun lorukọ awọn ọba ọhun bii Ọọni tilu ile Ifẹ, Awujalẹ tilẹ Ijẹbu, Alake tilẹ Ẹgba, Ọwa Obokun tilẹ Ijẹsa, Ọrangun ti Ila, to si fun pe oruko awọn sba naa si ku.
Òun ló mọ iye àwọn ìràwọ̀,òun ló sì fún gbogbo wọn lórúkọ.
lati fowosowopo ki Iran omo Yoruba le goke agba.
Ninu ẹ̀yà Juda, àwọn tí wọ́n tó ẹni ogún ọdún, tí wọ́n tó lọ sójú ogun, gẹ́gẹ́ bí àkọsílẹ̀ wọn ní ìdílé-ìdílé 
Ìfẹ́kúfẹ̀ẹ́ ti ara wọn ni wọn yóo tẹ̀lé, tí wọn yóo kó àwọn olùkọ́ tira, tí wọn yóo máa sọ ohun tí wọn máa ń fẹ́ gbọ́ fún wọn.
Ọ̀kọ̀ọ̀kan fún ìlú kọ̀ọ̀kan; Aṣidodu, Gasa, Aṣikeloni, Gati ati Ekironi.
Nitori kete ti iwọde tabi ifẹhonu kan han ba bẹ́ si igboro, ọpọlọ araalu lo maa n bẹru ki ọlọpaa ma mu wọn.
Ní àkókò ìjọba Jehoramu ni Edomu ṣọ̀tẹ̀ sí Juda, wọ́n sì yan ọba fún ara wọn.
Sibẹsibẹ Ọlọrun fi ẹ̀mí gígùn fún alágbára nípa agbára rẹ̀;wọn á gbéra nígbà tí ayé bá sú wọn.
Geberi, ọmọ Uri, ni alákòóso agbègbè Gileadi, níbi tí Sihoni ọba àwọn ará Amori ati Ogu ọba Baṣani ti jọba tẹ́lẹ̀ rí.
Ó wọn ibi mímọ́ inú náà: òòró rẹ̀ jẹ́ ogoji igbọnwọ (mita 20), ìbú rẹ̀ sì jẹ́ ogún igbọnwọ (mita 10).
Wò ó, o ti ṣe ọjọ́ mi ní ìwọ̀n ìbú àtẹ́lẹwọ́ mélòó kan,ọjọ́ ayé mi kò sì tó nǹkankan ní ojú rẹ;dájúdájú, ọmọ eniyan dàbí afẹ́fẹ́ lásán.
Hilary Clinton to fun wa larikọgbọn pe kii ṣe iye ibo to ba ri ni yoo ṣe atọna boya o ma jawe olubori.
Ẹ̀wẹ̀, àgbẹnusọ ilé iṣẹ́ tó ọ̀rọ̀ abẹ́lé, Mohammed Manga sàlàyé pé, owó ayípada ibudó tuntun láti ọ̀ds ìjọba kò ju ẹgbẹ̀rún lọ́nà ọ̀gbọ̀n náírà lọ Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Ìdámẹ́ta wọn ṣókùnkùn, kò bá sí ìmọ́lẹ̀ fún ìdámẹ́ta ọ̀sán ati ìdámẹ́ta òru.
Ni ero ti ẹ, Oloye Elebuibon sọ pe aṣẹ lọba ma n pa, ọba kii daba, nitori ọ̀pá to wa lọwọ rẹ, idi si niyii ti wọn fi ma n pe ọba ni alasẹ ikeji òrìṣà.
Ninu ọrọ ti gomina Fayẹmi fi ṣọwọ si ibi ipade kan lori aṣa ati iṣe lo ti kede eyi.
Gbogbo ibeere Gani Adams lati bẹ oloye Oluṣẹgun Ọbasanjọ wo yala nigba to wa nipo gẹgẹ bi aarẹ ati lẹyin to fi ipo silẹ ni oloye Ọbasanjọ kọ.
Ìsọ̀rí awọn eniyan mẹ́rin ni ofin yọ silẹ ninu ètò yii, àkọ́kọ́ ni awọn ti wọn ti le ni ọgbọ̀n ọdún ko to di pe wọn pari ni ile iwe gíga, èkeji ni awọn ti wọn ti sisẹ pẹlu ile isẹ ọlọ́pàá ati ológun fun ìwọ̀n osù mẹ́sàán, ikẹta ni awọn ti wọn n sisẹ níléesẹ́ ọ̀tẹlẹ̀múyẹ́ tabi awọn àjọ miiran to fara pẹ́ẹ.
agbaboolu Paris Saint-Germain, Kylian Mbappe ti gba ami eye  agbaboolu orile-ede France ti o darajulo fun
Ninu ọrọ akọsọ rẹ, Johnson fikun pe inu oun dun lati sisẹ ninu isejọba Theresa May, toun si ri itara rẹ ati ipinnu to ni si ọpọ igbesẹ rẹ naa, eyi to di ogun to fi silẹ bayii.
” (Meriba ni wọ́n ń pe àwọn omi tí ó wà ní Kadeṣi ní aṣálẹ̀ Sini).
Atamatase ninu ere boolu afowogba, Novak Djokovic jawe olubori ninu asekagba idije U.
Kí ni àmì ohùn orí 'Aifagbafẹnikan'
Oríṣun àwòrán, AP Àkọlé àwòrán, Àwọn oṣìṣẹ́ agbófinró ń ṣewadìí ẹni to yìnbọ lágbègbè náà, wọn ni àwọn nílò láti mú sps àwọn ti igbá srs náà bá ṣi mọ lóri.
Àwọn àmi méje tó ń tọ́ka sí pé oò kí ń mu omi bí ó ti tó 'Mo máa tó dìde lórí àìsàn', Muyiwa Ademola sọ̀rọ̀ látorí àkéte àìsàn rẹ̀ 'Kí n máa lọ́ ayẹyẹ kiri 'torí ijó láì ṣe pé wọ́n pe mí ló sọ mí di DJ Kulet olórin Fuji nìkan' Ohun tí a mọ̀ nìyí nípa #IGotSurvivalFund owó ìrànwọ̀ Àwọn ìgbésẹ̀ tóo lè fi so NIN rẹ̀ pọ mọ́ síìmù MTN, Glo, Airtel ati 9Mobile rẹ Nínú kó o fi omi fọ ìdi tàbí lo tííṣù fi fá a, Èwo ló rọrùn?
O jáde lọ láti gba àwọn eniyan rẹ là,láti gba àwọn àyànfẹ́ rẹ là.
" Oríṣun àwòrán, Federal Ministry of Humanitarian Affairs Lara awọn eroja ounjẹ ti ijọba yoo pin fun idile akẹkọọ kọọkan to lẹtọọ si ounjẹ naa ni, apo irẹsi oni kilogiramu marun-un (5kg), apo ẹwa oni kilogiramu marun-un bakan naa, ororo ẹẹdẹgbẹta mililita, 500ml, epo Pupa oni ọtalelẹẹdẹgbẹrin o din mẹwaa mililita, 750ml, iyọ oni ẹẹdẹgbẹta miligiramu, 500mg, ẹyin ẹyọ mẹẹdogun ati tomato lílọ lubu-lubu oni miligiramu ogoje, 140gm.
Wọn kì í ṣiṣẹ́, bẹ́ẹ̀ ni wọn kì í rànwú.
Ni orillẹ-ede Italy, awọn alakoso ere bọọlu nibẹ, Italian Football Federation (FIGC) sọ lẹyin ipade kan pe, o ṣeṣe ki idije Serie A saa yii ma pari nitori arun naa.
Ọpọlọpọ awọn eniyan lo kundun ere agbelewo ‘Game of Thrones’ to sọ nipa igbe aye ala ti ko le sẹ ‘Fantasy World’awọn eniyan ilẹ Westeros ati agbeegbe Essos lori bi wọn se n gba ijọba kan si omiiran, ti o si kun fun awọn abami eniyan.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Trump: FBI ko mọ isẹ wọn bi isẹ 18 Èrèlè 2018 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ikọlu ile-iwe kan ni ọjọru l'agbegbe Parkland ni eleyi to buru ju l'Amerika lati ọdun 2012 Aarẹ orilẹede Amerika, Donald Trump ti bu ẹnu atẹ lu ileese agbofinrọ orilẹede naa (FBI) nitori wipe ileese naa kuna lati dẹkun iyinbọn paniyan to waye ni ile iwe ipinlẹ Florida.
Ohun tí mò ń ṣiṣẹ́ fún nìyí gẹ́gẹ́ bí agbára tí Ọlọrun fún mi, tí ó ń fún mi ní okun.
Kẹmika naa, Dichlorvos dimethyl phosphate, ti gbogbo eniyan mọ si 'sniper' jẹ gbaju-gbaja kẹmika ti ajọ NAFDAC fọwọ si lati maa fi pa kokoro bi ẹfọn.
Fún àwọn aboyún ati fún àwọn tí wọn bá ń tọ́ ọmọ lọ́wọ́ ní ọjọ́ náà.
Bi esi ayẹwo naa ṣe lọ niyii: Ni bayii, ẹgbẹrun meji ati ẹgbẹrin le meji (2802) eniyan lo ti ni aarun naa ni Naijiria.
Iroyin naa ni wọn fa awọn mejeeji le ọlọpaa lọwọ nitori pe oogun abẹnu gọngọ lo mu ki awọn mejeeji lẹpọ.
Ọrọ yii kii ṣe wọn ni-wọn pe o!
Ní ọdún kọkandinlogoji tí Asaraya jọba ní Juda, ni Menahemu, ọmọ Gadi, jọba lórí Israẹli ní Samaria, ó sì wà lórí oyè fún ọdún mẹ́wàá.
Kódà, ní ibùdókọ̀ ọkọ èrò ìjọba, BRT to wá ní Berger, àwọn èrò tó fẹ́ wọnú àwọn ọkọ náà kò bọ̀wọ̀ fún òfin ìtakété síra ẹni lórí ila tí wọn tó sì, láti wọ ọkọ náà.
 Ọpọlọpọ awọn ololufẹ ẹṣẹ jija ti bẹrẹ si ni fi erongba wọn lede lori ija naa, ti wọn si ti n ki Tyson Fury ku ori ire."
" Agunbanirọ mẹsan doloogbe nibi igbafẹ Laipẹ yii ni awọn agunbanirọ mẹsan padanu iku aitọjọ nigba ti ẹkun omi gbe wọn lọ lasiko ti wọn lọ wẹ lodo Moyo Salva fun igbafẹ ní ìjọ̀ba ìbílẹ̀ Gashaka ìpínlẹ̀ Taraba.
Ìrìnàjò yìí ń lépa láti pèsè àyè fún àwọn òjìjí láti sọ ìtàn ara wọn.
Ọjọgbọn Wole Soyinka ṣe iranti asiko ti awọn darandaran pa awọn eniyan lọgọọrọ, sugbon kaka ki aarẹ Buhari gbe igbesẹ lati da abo bo awọn eniyan, ohun ti aarẹ Buhari sọ ni pe ki awọn eniyan naa wa ọna lati gbe ni alaafia.
Àwọn alápìíìrì tí ó ti dolóògbèé ni Ọ ̀ gbẹ ́ ni Àṣàkẹ ́ Ìwénifá , ajórùbú , Àjàlá , olóyè Ọsọ ́ lọ ̀ Òkunlọlá , afọlábí Ọ ̀ jẹ ̀ gẹ ̀ lé .
Adeyanju ni lẹyin ti Sowore kọ lati gba ounjẹ ni ajọ DSS wa gba awọn ẹbi ati ọrẹ rẹ nimọran, lati ma a gbe ounjẹ wa fun un lojoojumọ.
Ko ti daju ohun ti o fa iṣẹlẹ ile wiwo tuntun yii ṣugbọn asoju fun Lagos Island nile asofin ipinlẹ Eko, ọgbẹni Sola Giwa,fidi ọrọ naa mulẹ.
Tí a fiṣọwọ́ ní 13:53 3 Ọ̀pẹ̀ 202013:53 3 Ọ̀pẹ̀ 2020 Wo ọ̀rọ̀ tí Asiwaju Bola Tinubu fi síta lórí ìṣòro ètò àbò Nàìjíríà Tinubu gboriyin fun Gomina Zulum, fun gbogbo akitiyan rẹ lati ri pe awọn ti ogun sọ di alainilelori ri ọna abayọ.
Jaiye ṣalaye pe lati igba ti oun ti ṣe agbejade ere ti akọle rẹ jẹ Jaiye Monje"" to si ni ọpọlpọ aworan igbeyawo laarin oun ati Pasuma ninu ere naa ni ọpọlọpọ ro pe aworan igbeyawo rẹ ni lootọ."
Lakota, Mehitabelle wa n fewe ọmọ mọ awọn ẹgbọn rẹ leti pe gbogbo awọn lo ni aja to wa ninu ile, ojuse apapọ awọn si ni lati tọju rẹ.
Fìdírẹmi O sọ asọtẹlẹ pe Senegal yoo fidirẹmi lọwọ Algeria.
Igbakeji aare fi ilu Abuja sile lasale ojo Aiku , yoo si
Wo ohun mẹ́wàá tó yẹ kí o mọ̀ tí o bá fẹ́ lọ fún ìsinmi lẹ́yìn Covid 19 Wo bi wọ́n ṣe n ṣe àmójútó ilé ìjọsìn Prophet Israel Oladele, CCC Genesis Global Seyi Makinde fún olórin Fuji Taye Currency lẹ́bùn ọkọ̀ bọ̀kìnnì Toyota Prado 2020 Ìjọba àpapọ̀ pàṣẹ pé kí gbogbo ọkọ̀ agbépo kúrò ní márosẹ̀ Lagos-Ibadan Awọn ipa ti ọrọ aje to dẹnu kọle yoo ni lara rẹ: Airi iṣẹ ṣe - Lasiko ti ọrọ aje ba dẹnu kọlẹ, awọn ileeṣẹ yoo din awọn nkan ti wọn ṣe sita ku, eyi to tumọ si pe oṣiṣẹ perete ni wọn yoo nilo.
Wo bí o ṣe leè lo èròjà agbohùnsílẹ̀ tuntun tí Twitter gbé dé Wọ́n tẹ́ pẹpẹ fídíò wòlíì Sotitobire níléẹjọ́ Gómìnà márùn ún tó fojú winá ìbínú bàbá ìsàlẹ̀ wọ̀n Òjò àrọ̀ọ̀rọ̀dá dá wàhálà sílẹ̀ l'Eko Ọgagun Ndayishimiye ṣíṣẹ pọ timọ timọ pẹlu Ọgbẹni Nkurunziza lasiko ipade alaafia to waye nilu Arusha laarin ìjọba Burundi ati igun ọlọtẹ FDD.
Eyi ni awọn kọmiṣọnna ati ile iṣẹ wọn ti Gomina Abdulrazaq kede lonii ọjọ Ẹti.
Ìwà jìbìtì àwọn iléeṣẹ́ ìbáraẹnisọ̀rọ̀ ló yẹ kíjọba mójútó, kìí ṣe iye káàdì ìpè ta bá ní Má jẹ́ kí Whatsapp rẹ gbàbọ̀dè, tètè ‘Update’ Àwọn osisẹ yabo iléesé MTN ní Nàìjíríà Pásítọ̀ CAC àti afurasí 'Yahoo boy' Olawale tó lu Hayatou ní jìbìtì N12.
"Ọlọpaa kan ti wọn mọ bi ẹni n mọ owe to n jẹ Chinedu ba yọ ọbẹ fi gun ọkunrin naa""."
Ni ti Tunde Ednut ni tirẹ igba keji ree ti awọn alaṣẹ Instagram yoo pa oju opo rẹ de.
Akure fire: Ọ̀pọ̀ oníṣòwò ni ṣọ́ọ̀bù wọ́n jóná lọ́jọ́ Àìkú nílùú Akure ṣùgbọ́n tí ìséde kò jẹ́ kí wọ́n mọ̀ Dukia ẹgbẹlẹgbẹ owo lo tun parun lasiko ti ina nla kan tun sọ lagbegbe Ọba nla ni ilu Akurẹ, olu ilu ipinlẹ Ondo.
Ekinni ninu àwọn ìyẹ́ kerubu keji náà jẹ́ igbọnwọ marun-un, ó nà kan ògiri ilé náà lẹ́gbẹ̀ẹ́ keji, ìyẹ́ rẹ̀ keji náà jẹ́ igbọnwọ marun-un, òun náà nà kan ìyẹ́ ti kerubu kinni.
Oríṣun àwòrán, @Nigerialawyers Àkọlé àwòrán, Ọ̀pọ̀ amòfin ló ní ìgbésẹ̀ náà kò bá ìwé òfin Nàìjíríà mu.
pẹlu Obedi Edomu ati àwọn arakunrin rẹ̀ mejidinlaadọrin; ó sì fi Obedi Edomu, ọmọ Jedutuni ati Hosa ṣe aṣọ́nà.
Òkun ti ru bo Babiloni mọ́lẹ̀.
Yin OLUWA, ìwọ ọkàn mi,fi tinútinú yin orúkọ rẹ̀ mímọ́.
Agbẹnusọ fun iileeṣẹ ọlọpaa Ipinlẹ Ondo Femi Joseph sọ wi pe ni kete ti ọkọ mejeeji fori sọ ara ni ina sọ, ṣugbọn awakọ ọkọ ajagbe naa ti ọmọ onimọto rẹ bẹ silẹ wọn si fẹsẹ fẹ.
Pupọ ninu awọn Mallam to gba awọn ọmọ yi sọdọ ni ko rọwọmu lọ si ẹnu funra wọn to jẹ pe ko si owo pupọ lọwọ wọn lati gbe igbeaye to pe.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Premier League: Liverpool fẹ́ gbafe yìí ṣá!
N kò ri ipa ẹ̀jẹ̀ lára ọmọ mi tó kú sí iléeṣẹ́ ọṣẹ, èjò lọ́wọ́ nínú - Òbí àkẹ́kọ̀ọ́ UI Àlàyé rèé lóríi àjọṣepọ̀ tó wà láàrin èmi àti MC Oluomo - Ronke Oshodi Oke Ìpalẹ̀mọ́ ọdún Ileya kò rọgbọ ní Maiduguri, ojo ado oloro n rọ leralera Mò máa ń fọ àwọ̀tẹ́lẹ̀ ìyá mi, ni ìṣe àwọn obìnrin fi wù mí - Bobrisky Iye owo ti Napoli san lori Osimhen pọ ju iye owo ti Arsenal san fun Lille lati ra ọmọ orilẹ-ede Ivory Coast, Nicolas Pepe ni nkan bii ọdun kan sẹyin.
Ijọba ọhun ni, bẹrẹ lati ọdun 2022, ileeṣẹ ti ko ba tẹle ofin naa yoo fojuba ile ẹjọ.
Alaga ajo naa so pe, awon ti se akiyesi awon agbegbe ti o niloo amujuto, ni eyi ti o seleri ati wa iyanju si awon agbegbe ohun.
net/news/ Níbáyìí, àwọn ti wọ́n lọwọ ninú sogúndogójì MMM wọ́n yóò mọ iyé owó ti wọ́n pàdanù nigbà tí àwọn alákósó rẹ̀ ti fi òpin síi.
Aarẹ ko wulẹ sọrọ apilẹkọ kankan gẹgẹ bii ti atẹyinwa fun gbogbo aarẹ tabi gomina tuntun ti wọn ba bura fun.
"Sugbọn awọn ọmọ Naijiria yari pe aṣẹ "" Executive order"" ni a\\won fẹ ko fi ṣe nitori ijọba ti kede ifopin si ati atunṣe ọlọpaa lẹẹmẹrin tẹlẹ ṣugbọn to ja si pabo."
'Ìdùnnù wa kọ́ ni kí á má fún ọmọ Nàìjíríà ní 'Visa' Lẹ́yìn oṣù márùn ún, Buhari kọ̀ láti yọ ọ̀ga NHIS Ìbọn ti kò lo ọ̀ta làwọn ọlọ́pàá a máa kọ́kọ́ yìn- IG Wo aláànú tó n wa ọkọ̀ tí wọ́n fi n gbé aláìsàn lọ́fẹ̀ẹ́ Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí kan sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
"Eyi to si n pe fun igbesẹ to tayọ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Myanmar: kékeré ni wọ́n ti n kọ́ àwọn ọmọ nípa ọ̀nà oge ṣiṣe Iroyin ni ileeṣẹ MTN ti wọn da silẹ lati orilẹ-ede South Africa yii ko tii yọ awọn onibara to le ni miliọnu marun un ti wọn ko kopa ninu iforukọ silẹ naa.
Àwọn eniyan náà lọ, wọ́n sì wo ilẹ̀ náà láti aṣálẹ̀ Sini títí dé Rehobu ati ni ẹ̀bá ibodè Hamati.
Oríṣun àwòrán, NCDC Àkọlé àwòrán, Àjọ NCDC kéde èèyàn 239 míràn tó ni ààrùn Covid-19 lórílẹ̀-èdè Naijíríà Gẹ̀gẹ́ bí àjọ náà ṣe sọ, ẹ̀nìyàn mẹ́tàdínlọ́gọ́rùn-ún (97) lo lùgbàdì àarùn náà ni ìpínlẹ̀ Eko, mẹ́rìnlélógójì (44) ni Bauchi, mọ́kàndínlọ́gbọ̀n (29) ní Kano àti mọ́kàndílógún (19) ni Katsina.
Sodomu ni àbúrò rẹ, òun ati àwọn ọmọ rẹ̀ ń gbé ìhà gúsù.
Oríṣun àwòrán, @justempower Pẹlu ibanujẹ la fi n wo ijọba apapọ lati ipasẹ ileesẹ ologun oju omi, ti wọn n le awọn eeyan to n gbe ni adugbo Abagbo, Abule Ẹlẹpa, Abule Glass, Ajakoji, Akaraba, Bobukoji, Ebute Oko, Fashola, Idi Mango, Ilajẹ, Inangbe/Ilado, Kopiamy, Ogunfẹmi, Oko-Kate, Okun Alfa, Okun Babakati, Okun gbogba, Okun Ilasẹ, Okun Kobena, Sankin, Sapo Okun ati Tokunbọ, titi de Tarkwa Bay."
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Wo Ọ̀jọ̀gbọ́n Ẹlẹka tó ń díje fún ipò gómìnà 'A o ni i lọkan lati kọ ibudo maalu' Chris Ngige ní kí wọn dá Fayose padà sípò Àkọlé àwòrán, Awọn oludije gomina l‘Ekiti Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí kan sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
Nítorí ẹ wí pé: “A ti bá ikú dá majẹmu,a sì ti bá ibojì ṣe àdéhùn.
O ni nipinle Kebbi ni won ti koko bere ni eyi to ti bi eso ile ise iresi nlanla bii WACOM, LAVANIA atawon miran.
le dabi pe o lagbara sugbon ti yoo je anfaani lati mu Ipinle Oyo te siwaju.
Rogbodiyan bẹ silẹ nile igbimọ aṣofin ijọba apa iwọ oorun Naijiria lẹyin tawọn aṣofin kan dibo lati yọ Akintola nipo lọdun 1962.
Ibi tí o kò fi nǹkan pamọ́ sí ni ò ń fojú wá a sí.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Dino: Àwòrán Omo Agege tí Dino fi síta ń fa àríyànjiyàn 16 Òkùdu 2019 Oríṣun àwòrán, @OvieOmoAgege Sẹnetọ Dino Melaye ti n gba ọpọlọpọ idahun si aworan ati ọ̀rọ̀ to fi sita nipa Sẹnetọ Omo Agege.
Lọjọ Kẹtadinlọgbọn osu yi ni Victoria ipinlẹ to tobi sikeji yoo bẹrẹ kilaasi tawọn akẹkọọ ati olukọ yoo jọ foju kan ara wọn.
Akọwe ẹgbẹ awọn dokita onisegun ni Ondo, Dokita Olasakinju fi to BBC leti wi pe, awọn ko ti ribi yanju ọrọ pẹlu ijọba lori iyanṣẹlodi to n waye yi.
Lo ba fi ikede sita loju opo Twitter rẹ pe oun yoo gba ẹmi ara oun.
 Ise awon LAWMA ni lati mojuto ayika ati awon idoti miran
Ọṣun Decides: ADC, ADP, APC àti SDP soju abẹ níkòó lórí ìwà ìbàjẹ́
Nítorí pé nígbà tí àwọn eniyan náà kó ara wọn jọ, ẹnikẹ́ni láti inú àwọn tí ń gbé ìlú Jabeṣi Gileadi kò sí níbẹ̀.
Ohun tí ojú ìyàwó mi rí lọ́wọ́ SARS kò ṣe é fẹnusọ- Poju Oyemade Ìjọba ìpínlẹ̀ Eko ti kéde orúkọ àwọn ọlọ́pàá tó fi ìyà jẹ àwọn olùwọ́de #EndSARS Wo ìsọ̀rí àwọn tó jẹ́ kí ìwọ́de End SARS / end SWAT lárinrin àti ìtumọ̀ Ajínigbé tú ìyá àti ọmọ ọdún mẹ́ta sílẹ̀ lẹ́yìn tí wọ́n gba ₦1.
 mali je ikan ninu awon orile-ede to je talaka julo mi agbaye .
Gomina ipinlẹ Ọyo, Abiola Ajimobi ti parọwa si awọn ọdọ wi pe ibi ti eniyan ti dide ko gbọdọ jẹ idiwọ tabi idena si atigoke agba.
Nígbà tí ilẹ̀ mọ́, àwọn Juu péjọ pọ̀ láti dìtẹ̀ sí Paulu.
Kí wọn fi ògo fún OLUWA,kí wọn kéde ìyìn rẹ̀ ní àwọn erékùṣù.
Lẹ́yìn Jẹfuta, Ibisani ará Bẹtilẹhẹmu ni aṣiwaju ní ilẹ̀ Israẹli.
Ó ti wá ẹni tí ó fẹ́, ó sì ti yàn án láti jẹ́ olórí fún àwọn eniyan rẹ̀, nítorí pé, o kò pa òfin OLUWA rẹ mọ́.
“Jẹ́ kí àjọṣepọ̀ wà láàrin wa gẹ́gẹ́ bí ó ti wà láàrin àwọn baba wa.
Ó ṣọ̀wọ́n ju ohun ọ̀ṣọ́ olówó iyebíye lọ.
Dafidi sọ fún Saulu pé, “N kò lè lo ihamọra yìí, nítorí pé n kò wọ̀ ọ́ rí.
Inu mi dun pe awọn eniyan kọọkan ti n da ohun ti wọn jigbe lọ pada, amọ wọn gbọdọ da gbogbo rẹ pada ni kiakia.
Ninu atẹjade kan ti Adebayo Kehinde, agbẹnusọ LASEMA fi sita salaye pe igbiyanju lati doola ẹmi ṣi n tẹsiwaju nipaṣẹ ajọsepọ awọn pẹjapẹja lagbegbe naa ati awọn ọlọpaa oju omi.
"Àwọn ọ̀dọ́ ilẹ̀ Yoruba kò gbọdọ̀ gbàgbé àṣà ati ohun àdàyébá wọn - Ooni Ile Ife Eruku sọ lálá níbi ayẹyẹ ìgbéyàwó Lizzy Anjorin, àwòrán àti fídíò nìyíì Orin ìsìn ọjọ́ ìbí àṣẹ̀yìndè Ibidunni Ighodalo yóò wáyé, Tope Alabi, Kenolly àtàwọn míì tí yóò kọrin níbẹ̀ rèé Gbọ́ ọ̀rọ̀ lẹ́nu afurasí tí Ọlọ́pàá ní ó pa Barakat Bello, Grace Oshiagwu àtàwọn míì l'Akinyele Ibadan Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Coronavirus in Nigeria: Ẹ wo bí ẹ ṣe lè ṣe ""hand sanitizer"" nínú ilé yín Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!"
Ẹ fi àwọn aṣọ́nà sí ipò wọn;ẹ dira fún àwọn kan, kí wọn sápamọ́,nítorí OLUWA ti pinnu, ó sì ti ṣe ohun tí ó sọ nípa àwọn ará Babiloni.
Ọ̀rọ̀ Nàíjíríà kúrò ní sinimá àwòrẹ́rìn-ìn, Buhari gbé ìgbésẹ̀ bíi òbí àti olórí - Obasanjo gbarata Adejobi ni bi awọn oluwọde ṣe n sọ oko si awọn oṣiṣẹ wọn naa, ni wọn n yinbọn si wọn lati pa wọn tabi se wọn leṣe.
Ṣugbọn ní tìrẹ, bákan náà ni o wà.
Àwọn ìkúùkù-òjò sì ti bo bí ìdajì ilé náà lókè.
 wọ ́ n ṣe é fi ṣe pasípàrọ ̀ fún àwọn owóníná míràn , èso-iṣé àti ìránṣe-iṣẹ ́ .
Agbẹjọro naa ni Woli Sotitobirẹ ti sọ wi pe ohun ko mọ nkankan nipa iijnigbe Gold Kọlawole ti wọn jigbe lọ ni Ile Ijọsin rẹ ni Akure.
Lákotan, ẹ̀rí tí a fifúnni nípa Jésù Krístì—ìwà ọ̀run Rẹ̀, ọlá nlá Rẹ̀, pípé Rẹ̀, ìfẹ́ Rẹ̀, àti agbára ìrànipadà Rẹ̀—mú kí ìwé yìí níye lórí púpọ̀ sí ìran ènìyàn ó sì “níye lórí sí Ìjọ bíi àwọn ọrọ̀ ti gbogbo Ilẹ̀ Ayé” (wo àkọlé sí Ẹ&M 70).
Bakan naa lo fikun un wi pe awọn ti pasẹ fun Ọga Agba Ile -Isẹ to n risi irinna lorilẹ-ede Naijiria (NIS), Muhammad Babandede wi pe ọjọbọ, ọjọ Kọkandinlọgbọn, Osu yii ni asẹ ẹdinku naa yoo bẹrẹ.
"Lara ọrọ to yẹ ki ijọba tun mojuto ni lati sise iwadi orisun ibi ti awọn daran-daran ti n ri awọn nkan ijagun ti wọn n gbe kiri.
o ni ti wọn ba da ọlọpaa ipinlẹ  sile yoo yanju awọn ipenija to n koju awọn ijọba ipinlẹ .
Ìtàn ayé Shina Rambo, adigunjale tó fi oyún 27 gún ọṣẹ Wo atẹ àlàkalẹ̀ ìdánwò WAEC fún ọdún 2020 tí yóò bẹ̀rẹ̀ ní August 17 'Ẹru bami, nitori mo ro wi pe iyawo mi ti farapa tabi ọmọ jojolo naa.
 mo yó , mo ṣekùn wọnle ; mo yó , mo ṣekùn bọnbọ .
6 3337 Agbegbe French Guiana 74 26.
Àwọn orílẹ̀-èdè kan tún ti kéde kó nílé-ó-gbélé nítorí coronavirus Abẹ́rẹ́ àjẹsára Covid-19 tí Pfizer kéde ló fa ọ̀wọ́ngógó epo ní Naijiria - Ìjọba àpapọ̀ Ki lo ṣelẹ sẹyin?
Woods, omo odun méjílélógójì naa, eni ti o ti gba ife eye idije ohun fun igba meta otooto, sugbon ko i ti lanfaani lati kopa ninu idije naa lati odun 2015 lataari ifarapa ti o ni.
Nígbà ti mo wòó dáadáa ni mo wá rí i pé wọ́n lu àwọn ihò wíní-wíní sí gbogbo ojú ìwé náà.
fakere opopona Osodi-Apapa ni Ipinle Eko.
Ọ̀daràn náà tó n gbé agbègbè Barnawa ní ìpińlẹ̀ Kaduna ní wọ́n fi ẹsùn onípele méjì kàn fún olè jíjà , ti òun pẹ̀lú sí gbà pé òun jẹ̀bi ẹ̀sùn.
Igbimo to n se ifilole ilana boolu afesegba nile okere, IFAB nireti wa pe won yoo fenuko sojukan lojo abameta(Saturday) boya lati maa samulo ero ohun.
Ilé iṣẹ́ ọ̀tẹlẹ̀múyẹ́ sọ pé Amina Muhammed tí kọ́kọ́ sọ pé oun ní aya gómìnà ìpínlẹ̀ Kogi lójúnà àti rí ààyè wọ Aso Rock ní ìlú Abuja.
    Oun náà lo ṣe ọ̀nà tí mo fi yọ lọ́wọ́ Ẹlẹ́gbára, níbi tí a ti ń sọ̀rọ̀, ó bèèrè ohun tí mo rò pé òun lè fi ràn mi lọ́wọ́ mo sì ròyìn ìyọnu tí mo ti bá pàdé fun un.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Coffee Painter: Adebukola ní kò sí ìrànwọ́ lẹ́yìn ẹ̀kọ́ girama lòun ṣe ń ya àwòrán Bakan naa lo gba awọn eeyan Eko nimọran lati rin jinna sibi ti isẹlẹ naa ti waye tori ewu, ki wọn si mase mi eefin isẹlẹ naa simu.
Oríṣun àwòrán, Other Isọ ti wọn ti n ta aga ijoko ati nnkan ọgbin lo wa ninu fidio to fi sita lori oju opo Facebook rẹ.
Awọn aṣofin to n gọ si abẹ iṣẹ akanṣe idagbasoke ilu lati ja orilẹ-ede Naijiria lole owo gọbọi 2.
Ó ní, ‘N óo fi ogun, ìyàn ati àjàkálẹ̀ àrùn bá wọn jà, òun óo sì sọ wọ́n di àríbẹ̀rù fún gbogbo orílẹ̀-èdè ayé.
Kaisha yoo maa tẹle, Tochi ati Eric ti wọn yọ bii jiga kuro ni ile naa ni opin ọsẹ kẹta rẹ lọjọ Aiku to kọja ninu awọn mẹjọ torukọ wọn wa ninu iwe ile ya fun ọsẹ naa.
Oríṣun àwòrán, Others Awọn eeyan naa n ṣe iṣẹ takuntakun lati ri pe ko si idọti Kankan lojuko ti iwọde ti n waye.
Lasiko ti Olumilua jẹ gomina, Olusegun Agagu ni igbakeji rẹ, nigbati Dokita Olusegun Mimiko jẹ komisana feto ilera, ohun iwuri si lo jẹ pe Agagu ati Mimiko pada jẹ gomina nipinlẹ Ondo, lẹyin Olumilua.
Nítorí náà ni mo ṣe bukun ọjọ́ ìsinmi náà, tí mo sì yà á sí mímọ́.
 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Wọn fẹ fi opin si bi awọn ọmọ Naijiria ṣe n fi iwe irinna Amerika wọn wọ Canada Wọn ni awọn yoo maa wo awọn ti o ba fẹ gba iwe irinna Amerika fínífíní lati mọ boya iru eniyan ti o le fẹ sa wọ Canada ni wọn."
Eni to jẹ ọmọ ọkan lara awọn agba to lorukọ nilẹ Yoruba, Rueben Faṣọranti.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ekiti rape: Ẹni ọdún 51 fipá bá ọmọ ọdún 12 lòpọ̀, ìjọba ìpínlẹ Ekiti lẹ awòrán rẹ̀ gbangba sí àárín ìlú 3 Bélú 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 4 Bélú 2020 Oríṣun àwòrán, Google Ara aato ti wọn la kalẹ lati fopin si iwa ifipabanilopọ lawujọ, ijọba ipinlẹ Ekiti ti ti lẹ orukọ arakunrin kan si oju gbangba ti wọn gbamu pe o fipa ba eeyan lopọ.
lorile ede Naijiria (National Emergency Management Agency ,NEMA)  ti ni  ọmọ orilẹ ede Naijiria ti iye won le ni mẹ́rìndínlọ́gbọ̀nlelọ́ọ̀dúnrún
Àwọn ènìyàn ìjọba ìbílẹ̀ yìí pẹ̀lú jẹ ọkàn lára àwọn tí yóò sọ ẹni tíò jáwé olúborí.
Kódà wọ́n ní ènìyàn lè sanwó ránpẹ́ kan tí ènìyàn bá fẹ́ dúró síbẹ̀ fún ìgbà díẹ̀ gẹ́gẹ́ bí ibùgbé.
Oríṣun àwòrán, NBC Àkọlé àwòrán, NBC Wọn ni ajọ to n bojuto ikẹkọọ awọn Fulani lorilẹede Naijiria kọwe bo ṣe tọ lati gba iwe aṣẹ igbohunsafẹfẹ fun ilọsiwaju ipolongo ikẹkọọ to fi mọ lori afẹfẹ.
“O bá àwọn ará Asiria ṣe àgbèrè ẹ̀sìn pẹlu, nítorí pé o kò ní ìtẹ́lọ́rùn sibẹ, lẹ́yìn gbogbo àgbèrè tí o ṣe pẹlu wọn, o kò ní ìtẹ́lọ́rùn.
Ipinlẹ KanoIjọba ipinlẹ Kano kede isede ọlọsẹ kan lẹyin to kede pe ẹni akọkọ ti ni aarun naa ni ipinlẹ Kano lati le dena itankalẹ rẹ.
Eyi ni igba akọkọ tawọn to ni covid-19 ni Naijiria lọjọ kan yoo pọ to bayii.
”Jesu bá sọ fún wọn pé, “Mo fẹ́ kí ẹ mọ̀ dájúdájú pé àwọn agbowó-odè ati àwọn aṣẹ́wó yóo ṣáájú yín wọ ìjọba Ọlọrun.
''Wọn pada ṣalaye fun wa pe nigba ti Richard fẹ du apo lẹnu ẹrọ to n ṣe ọṣẹ ni o ko si ẹnu ẹrọ naa.
 urasílì kì í sábà sí nínú dna , ọ ́ únṣẹlẹ ̀ nìkan bíi èso ìfọ ́ wẹ ́ wẹ ́ sitosínì .
ọ̀dọ́ 47,000 fẹ́ di Amotekun, agbófinró yẹ̀ wọ́n wò yẹ́bẹ́yẹ́bẹ́ Aáwọ̀ oyè PDP gbé Fayose àti Seyi Makinde kọlu ara wọn, ìjà ń bọ̀ Ajagunfẹyinti naa ni ifilọ ti wọn ṣe ni pe, ẹnikẹni to ba jẹ ọmọ bibi ipinlẹ Ọyọ lọkunrin ati lobinrin laarin ọmọ ọdun mejilelogun de ọmọ ọgọta ọdun, lo ni anfaani lati gba fọọmu fun Amọtẹkun.
Ni aafin Olu ti ilu Itori ni ipade yi ti waye ti Wasiu Ayinde si sọ pe oun ko paṣẹ ki awọn ọmọ gbẹ oun kankan lu Mc Murphy.
ẹ fi irú ẹni bẹ́ẹ̀ fún Satani, kí Satani lè pa ara rẹ̀ run, kí á lè gba ẹ̀mí rẹ̀ là ní ọjọ́ ìfarahàn Oluwa wa.
Ó sì gbadura sí OLUWA pé, “OLUWA, ó tó gẹ́ẹ́ báyìí!
Awọn akọroyin n sọ pe idarudapọ lo gbalẹ bayii ni America, pẹlu ibẹru pe o ṣeesẹ ki ibusun alaisan o ma to mọ nileewosan, ati itọju awọn ọmọde ti wọn ti le ọpọlọpọ miliọnu wọn wa sile.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ijinigbe Dapchi: Bo ṣe ṣẹlẹ 23 Ẹrẹ̀nà 2018 Awọn akẹẹkọbinrin Dapchi mẹrindinlaadofa ati ọmọdekunrin kan ti ṣepade pọ pẹlu Aarẹ Muhammadu Buhari ni Abuja to jẹ olu-ilu Naijiria.
Kíkọ́ ẹ̀kọ́ gboyè nínú iṣẹ́ ìṣègùn ìbílẹ̀ yóò pèsè ìtọ́jú tó péye fọ́mọ Nàìjíríà- Ẹgbẹ́ àwọn dókítà Wọ́n mú ọjọ́ ìgbẹ́jọ́ agbésúnmọ́mí 9/11 tó ṣẹlẹ̀ l'Amẹrika Ọwọ́ ọlọ́pàá ti tẹ ọkùnrin kan tó pa ọ̀rẹ́ rẹ̀ nítorí N40 ní Kano Ẹ yé gba owó orí níbi ìdána ìyàwó mọ́, sísọmọbìnrin s'óko ẹrú ni- Daddy Freeze Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Fela ni awokọse mi - Kunle Ajayi Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Bakan naa ni awọn ti wọn tako ọrọ ti pasito naa sọ salaye pe, imọran Adeboye lodi si ofin ibi iṣẹ to kọ ki wọn le eniyan lai ni idi.
Ó ṣeéṣe kí wọ́n gbọ́, kí olukuluku wọn sì yipada kúrò ní ọ̀nà ibi rẹ̀; kí n lè yí ọkàn mi pada nípa ibi tí mo fẹ́ ṣe sí wọn nítorí iṣẹ́ burúkú wọn.
Nítorí pé OLUWA ni onídàájọ́ wa,òun ni alákòóso wa;OLUWA ni ọba wa,òun ni yóo gbà wá là.
Ninu ifọrọwanilẹnuwo pẹlu BBC, Sunday ni ''awọn ko jẹ ki awọn dokita naa tẹsiwaju irinajo wọn nitori pe bi wọn ba fi le lọ, niṣe ni awọn alaṣẹ ilẹ Gẹẹsi yoo da wọn pada.
Awon osise ti yoo sanwo ile, ra ounje sile, ran omo lo sile iwe , ti won yoo tun mojuto ilera ara won.
Sasa Market: Seriki Hausa ní ogún èèyàn ló farapa nínú ìjà Ṣasa
Awọn ẹgbẹ naa tun fi ẹsun kan awọn obinrin to n ta oti lile ati paraga wi pe awọn naa lọwọ si ọrọ ifipabanilopọ yii nitori pe gbogbo nnkan buruku ti awọn ọdaran naa n mu lo n fun wọn ni igboya lati ṣiṣẹ ibi.
Bakan naa ni arẹwa obinrin, Lola Margaret naa tun dupẹ pe oju oun ri ọdun miran loke eepẹ.
akegbe wa ti o je okunrin, ni won n fi wa se yẹyẹ pe ,oni yii je ayajọ ifọti .
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Davido, Wizkid, Falz kogoja gẹgẹbi ọ̀dọ́ tó pegedé l'Áfíríkà Ọmọ Prof.
Ọba bá sọ fún un pé: “Má jẹ́ kí àlá yìí ati ìtumọ̀ rẹ̀ bà ọ́ lẹ́rù.
kí o sì sun gbogbo wọn lórí pẹpẹ, ẹbọ sísun olóòórùn dídùn ni sí OLUWA, àní ẹbọ tí a fi iná sun.
O fi kun un pe,“leyin gbogbo iforowero, ipade pelu awon toro kan gbangban ninu iko Arsenal, Mo lero pe asiko ti to lati fi iko yii sile gege bi akonimoogba  ti saa to n lo lowo yii ba pari.
Ileeṣẹ ologun wa rọ ẹnikẹni to ba fẹ da rogbodiyan silẹ tabi ṣe ohun kohun to le dunkoko mọ ijọba awarawa Naijiria pe ki wọn semẹdọ.
Séremé so pe, “ Awon alakata-kiti elesin ohun ko siwaju ori tabi so aso funfun mo apa, eyi ti won ko ni ede Arabic ti won tunmo re pe, ko si Olorun ayafi Allah ati Muhammad ti o je ojise re”.
“Nígbà tí ẹnìkan bá ya ilé rẹ̀ sọ́tọ̀ fún OLUWA, alufaa yóo wò ó bóyá ó dára tabi kò dára; iyekíye tí alufaa bá pè é ni iye rẹ̀.
Abadofin fun Ile iwe giga fasiti eto ọgbin ati imọ ẹrọ ni Funtua - 2019.
Ni ọjọ Iṣẹgun ni ijọba apapọ nipasẹ minisita fun iṣẹ akanṣe, ipese oun amuṣagbara ati ọrọ ileegbe, Babatunde Faṣọla, fun akọnimọọgba ikọ̀ agbabọọlu 'Dream Team' to gba goolu ni idije Olympics l'ọdun 1996, Bonfere Jo, ni kọkọrọ ile ti ijọba ìgbà naa ṣeleri fun un gẹgẹ bii ẹbun nigba naa.
Ami ayo mẹjọ si meji ni Bayern fi ṣagba Barcelona ninu ifẹsẹwọnsẹ to waye lorilẹede Portugal lalẹ ọjọ Ẹti, ọjọ kẹrinla oṣu kẹjọ ọdun 2020.
Iwa ti Will Connoly yii wu, mu ki awọn eeyan kan, kan saara si pe o ṣe e daa.
Wọ́n pín ilẹ̀ fún ẹ̀yà Manase nítorí pé ó jẹ́ àkọ́bí Josẹfu.
Awọn Olukọ to ba ikọ iroyin wa sọrọ naa tun salaye gbogbo awọn igbesẹ ti wọn n gbe, lati ri daju pe awọn akẹkọọ naa tẹle awọn ofin ati ilana to rọ mọ idena arun Coronavirus.
ó dára kí eniyan máa kéde ìfẹ́ rẹ tí kì í yẹ̀ ní òwúrọ̀,kí ó máa kéde òtítọ́ rẹ ní alẹ́,
Nítorí iṣẹ́ Oluwa ni àwọn aṣòfin ń ṣe fún rere rẹ.
Ọdúnjọ tẹ ̀ síwájú nínú iṣé ìkọ ́ ni rẹ ̀ gẹ ́ gẹ ́ bí olùkọ ́ ilé ìwé catholic training college , Ìbàdàn láti ọdún 1924 tí tí di ọdún 1927 , tí ó sì padà di ọ ̀ gá àgbà ilé ẹ ̀ kọ ́ rẹ ̀ tó tí jáde tẹ ́ lẹ ̀ rí ìyẹn st augustine , abéòkúta .
Olùdíje mẹ́rin ti Gbajabiamila lẹ́yìn ṣáájú ìbò ilé aṣojú ṣòfin Òfin má wàásù láì gbàṣẹ nìpínlẹ̀ Kaduna ti ń gba àpérò Ìpínlẹ̀ Oyo gba ipò ìkíní mọ́ Edo lọ́wọ́ nínú fífí ọmọdé ṣ'ẹrú Dangote, Fayemi pari ìjà láàrin Ganduje àti Emir Sanusi Akọroyin BBC to wa nibẹ ni wọn dana sun ilu naa ni ti ọpọ ẹmi ati dukia si ti sọnu.
Oríṣun àwòrán, @official_ka3na/@itz__praise Ọjọ Ẹti kan ni eyi waye lẹyin ariya alẹ ti wọn ṣe.
76 Àti pé alàgbà tàbí àlùfáà yíò ṣe ìpínfúnni rẹ̀; ní ọ̀nà yìí ni òun yíò sì ṣe ìpínfúnni rẹ̀—òun yíò kúnlẹ̀ pẹ̀lú àwọn ìjọ yíò sì ké pe Bàbá nínú àdúrà tọ̀wọ̀tọ̀wọ̀, wipe:
"A o si tẹle gbogbo ilana Covid-19"" Saaju ni ijọba apapọ ti sọ agadagodo si gbogbo aaye akojọ NYSC jakejado Naijiria nitori ajakalẹ Covid-19."
O ti le ni miliọnu kan eeyan to ti forukọ silẹ fun eto igbanisiṣẹ naa.
nítorí pé wọn kò ti ṣe Àjọ̀dún Àjọ Ìrékọjá mọ́ láti àkókò àwọn onídàájọ́ ati ti àwọn ọba Israẹli ati Juda.
 Oun lo saaju iko to lo ran Liberia lowo lasiko ti Ebola n yo won lenu julo.
Nisisiyii to ti wa di igbakeji Biden ti wọn yoo jọ dije, o tun ti di ẹni ti ipo aarẹ tọ si yala lẹyin ọdun mẹrin bi Joe Biden ba fidirẹmi tabi ti ko gbapoti ibo lẹlẹẹkeji ninu oṣu kejila ọdun naa fun atunyan gẹgẹ bii aarẹ tabi lẹyin ọdun mẹjọ bi Biden ba ṣe saa ijọba meji.
Gbogbo awọn alarafa yii, ni ọkọ bọọsi ti fẹẹ ko de si inu agọ ti wọn se fun wọn naa, nigba tawọn miran fẹsẹ rin.
Tí ẹ ò bá gbàgbé, ni ọ̀ṣẹ̀ tó kọja ni àwọn ile ìgbìmọ asofin Bayelsa gbé àbádofin owó ìfẹyinti kálẹ̀ fún àbẹnugan ilé, igbákeji rẹ̀ àti àwọn ọmọ ilé tókù.
Ṣugbọn, a ko le sọ eyi to jẹ ninu ọrọ eto aabo ati ọrọ aje, nitori pe ko si ayipada rere kankan nibẹ.
Iroyin so pe, iye owo ori oja idokowo ohun duro gbari soju kan lati bi ose mejiNi oja ifarawe Bureau De change (BDCs), won ta naira kan ni edegbeta N500 si owo pound, eyi ti o pajude si o din die ni edegbeta N442 owo ile-EuroEwe, owo naira si aown owo ile-okere mejeeji yii ni won ta ni  okanleledegbata N501 owo naira ati ojilenirinwo-o-le marun  N445 ni oja ifaraweBakan naa ninu oja kara-kata ti o n wole ati eyi ti o n jade, owo ori oja naira pajude si irinwo din-die N360.
Ọlọpaa naa ni a gbọ pe o fi ọrẹbinrin rẹ naa silẹ lọ lẹyin to da ọran ọhun tan.
Ó sọ fún wọn pé, “Ẹ má ṣe gbà ju iye tí ó tọ́ lọ.
 orílẹ ̀ èdè angola ni á tí ń sọ èdè yìí .
Ọgbẹni Adamu Makoda, ẹni ọdun mẹrindinlaadọta to n gbe ilu Kano lorilẹ-ede Naijiria jẹ ọkan lara ogunlọgọ awọn eeya ti ko rile gbe ni Naijria.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: 'Buhari sọ fún wa pé ipò tí ọ̀rọ̀ ajé Nàìjíríà wà kò dára' Èrò àwọn ọmọ Nàìjíríà ṣọ̀tọ̀ọ̀tọ̀ lórí ọ̀rọ̀ Obi àti Ọṣinbajo Ẹ sọ́ra fún ayé deru òògun nípìnlẹ̀ Eko O ni awọn oṣiṣẹ ajọ FRSC ti wa ni igbaradi lati rii pe ẹnikẹni to ba tapa si ofin irina ko ni lọ lai jiya ẹsẹ rẹ.
N óo fọ́n yín káàkiri ààrin àwọn orílẹ̀-èdè, idà ni wọn yóo máa fi pa yín ní ìpakúpa, ilẹ̀ yín ati àwọn ìlú yín yóo di ahoro.
Lai Mohammed to di iroyin ofege naa ru iṣẹ ọwọ awọn alatako ṣalaye pe ọgbọn ati da omi alaafia iṣejọba ru ni awọn to gbero fidio naa n da.
Koda, iroyin sọ pe ko pe wakati kan ti wọn ko o sita ti awọn eniyan ti ra a tan lorilẹ-ede Japan BBC News, Yorùbá Ìdí tí ẹ fi le è nígbàagbọ́ nínú ìròyìn BBC Ìlànà Lílò Nípa BBC Òfin Àṣírí Cookies Kàn sí.
WHO ní àwọn ẹbí àwọn aláìsàn nà wá sí ibùdó ìtọ́jú ọ̀hún, tó jẹ́ ti àjọ aláànú, Medecins Sans Frontieres, tí wọ́n sì ní kí wọ́n yọ̀ǹda àwọn ènìyàn wọn fún wọn, kí àwọn le gbé wọn lọ fún ètò àdúrà, tí wọ́n sì gbé wọn lọ lórí ọkàdà.
leyin ayeye iyansipo re gege aare orile-ede Naijiria fun saa keji miiran.
Ijọba dunkoko mawọn ẹgbẹ oṣisẹ pe iyanṣẹlodi tawọn ẹgbẹ oṣiṣẹ gunle lodi si ofin, amọ wọn ni awọn ko ni wọgile iyanṣẹlodi ọhun ayafi ti ijọba ba mu afikun owo epo naa kuro.
Ìjọba ìpínlẹ̀ Oyo: Oṣú mẹ́fà ni òṣìṣẹ́ ìjọba tó bá bímọ yóò máa lò nílé kó tó wọṣẹ́ padà- Seyi Makinde
Mo dá ẹ̀bi lé ara mi lórí ohun tí kì''i ṣe ẹ̀bi mi.
Àwọn ọmọ Nàìjíríà kan fẹ́ kí ilé ẹjọ́ ó fagilé orúkọ Buhari gẹ́gẹ́ bi olùdíje APC
agbegbe n soro, o je ko di mimo pe awon yoo te siwaju lati se ise won bi ise.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ọkùnrin kan bẹ́ orí ẹ̀gbọ́n rẹ̀ ní Cross River, ni ará ìlú bá sin ín láàyè 31 Èbibi 2019 Oríṣun àwòrán, Saharareporters Àkọlé àwòrán, Arákunrin náà ti ara rẹ̀ mọ inu ilé, ó sì ń kìlọ̀ pé ẹnikẹ́ni tó bá sún mọ́ òun, yóò fara gbọgbẹ́ bí i ti ẹ̀gbọ́n òun.
Iṣẹ́ ẹ̀mí ẹ̀tàn ló bàlemi lasiko tí mo sọ àṣọtẹ́lẹ̀-Simeon Ononogbu Mo gbàgbé sùnlọ sìnú ọkọ̀ òfurufú, ẹ̀rù ikú bà mí -Tiff Ìdí tí ilé fi wó lu ènìyàn méjì ní Oshodi -LASEMA Ètò sogúndogójì 'MMM' tún ti padà dé, rọ́bọ́ọ̀tì ni yóò maa ṣàkóso Àwọn òṣèré Yollywood tó ń pàrònú rẹ́ Agbọdẹmu ni nitori ọrọ aabo to mẹhẹ ni agbegbe naa ni oun ṣe ko igbimọ ẹlẹni ogoji kan jọ lati maa boju to awọn nkan to n lọ ni awọn adugbo.
Bí ó bá dùn mọ́ Kabiyesi ninu, jẹ́ kí àṣẹ kan jáde lọ láti pa wọ́n run.
Russia 2018: Super Eagles ati Poland yoo dije ọlọrẹsọrẹ
Ó bi Labani, ó ní, “Irú kí ni o ṣe sí mi yìí?
O ni Makinde jẹ asaaju ẹgbẹ PDP lẹkun yii nitori ipo to wa bii gomina kansoso tẹgbẹ oselu PDP ni lẹkun iwọ oorun guusu ni.
Àwọn eniyan Juda sì fi Asaraya, ọmọ rẹ̀, jọba.
Nigeria Police: Ọ̀gá àgbà dín wákàtí iṣẹ́ ọlọ́pàá kù 'torí wàhálà
Òjò gbogbo l’órí akítì ní í dáá lé.
Wọn yoo kọ awọn nọọsi niṣẹ wọn yeke yeke.
Bi awọn eeyan kan ṣe n kan sara si igbesẹ naa ni awọn eeyan kan n pariwo pe ko ṣeeṣe nitori eto to jẹ mọ ilana iwe ofin orilẹede Naijiria ni ọrọ ọlọpaa agbegbe ti yoo si nilo atunṣe ile igbimọ aṣofin apapọ.
Ó pọ̀ pupọ ní oríṣìíríṣìí ọ̀nà.
Juda bí Peresi ati Sera, ìyá wọn ni Tamari.
Gbogbo ọmọ Israẹli yóo gbọ́, ẹ̀rù yóo sì bà wọ́n, ẹnikẹ́ni kò sì ní hu irú ìwà burúkú bẹ́ẹ̀ mọ́ láàrin yín.
Ilé ẹjọ́ sún ẹjọ́ Sẹ́nétọ̀ Abbo síwájú pẹ̀lú béèlì mílíọ̀nù márùn-ún Kí l'ànfàní àdéhùn okoòwò kan l'Afíríkà, AfCFTA tí Buhari tọ́wọ́ bọ̀?
Orilẹ-ede marun un pere lo mu u ṣẹ ninu orilẹ-ede ilẹ Adulawọ.
O ni koda, ti o ba bu mi, inu mi maa n dun sii ni nitori n ko ni dẹkun lilọ si ibi isẹ nitori pe o bu mi, gbogbo ẹya ara mi ti awọn eeyan le fi se yẹ̀yẹ̀ lo tẹ́ mi lọ́rùn ni mo si n dupẹ́ fun.
Ilé iṣẹ́ márùn ún tí wọ́n dárukọ kìí ṣe túntun- Garba Sheu FRSC dá N443,180 padà fún ẹbí ẹni to ní ìjàmbá mọ́tò Ọwọ́ ti tẹ ọlọpàá mẹ́rìn to pa afurasí Ìjìyà ń bẹ fún àwọn ti adé ọ̀rọ̀ náà bá ṣí mọ́ lóri -Ọga àgbà FRSC Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Ati pe iyawo Ajimobi kò tẹle ilana to yẹ lati fi aisan àti ikú ọkọ rẹ to ijọba ipinlẹ Ọyọ l'eti.
Koda o ni awọn obirin gan lee pada ni irun iwaju to ti fa l sipakọ pada nipa aramanda iṣẹ ọwọ awọn.
Ẹwa Agọnyin jẹ aayo ounjẹ Badagry
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Àwọn òṣìṣẹ́ BBC News Yorùbá sọ̀rọ̀ ìdùnnú lórí ayẹyẹ ọdún kan iléeṣẹ́ náà Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àwọn òṣìṣẹ́ BBC News Yorùbá sọ̀rọ̀ ìdùnnú lórí ayẹyẹ ọdún kan iléeṣẹ́ náà 19 Èrèlè 2019 Ni aarin ọdun kan ti BBC News Yoruba ti bs sori afẹfẹ, oniruuru iroyin manigbagbe ni o ti gbe sita eleyi ti o ti rinlẹ kọja orilẹede Naijiria lọ.
Nígbà tí Eloni ṣaláìsí, wọ́n sin ín sí Aijaloni ní ilẹ̀ Sebuluni.
Oríṣun àwòrán, @konkrumah Awọn ipenija to wa niwaju aarẹ Akufo Addo bayii: Nipi apero naa ni wọn ti sọrọ nipa ipenija to wa niwaju ajọ yii lasiko yii pe: Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Temitope Akinnusi: Ọ̀pọ̀ iléeṣẹ́ ló takú láti gbà mí síṣẹ́ torí mo ní ojú kan Owo ti gbogbo orilẹ-ede yii yoo maa na papọ ti yoo jẹ irufẹ kan naa.
O sọ bi wọn ṣe le koju ẹ̀rù obìnrin ninu iṣelu.
Ohun tí ó dára jù lọ ni wípé àwọn tí ó ń tako ìwà burúkú yìí gbàgbọ́ wípé àyípadà lè dé.
Mo ní, ‘Dájúdájú, wọn óo bẹ̀rù mi, wọn óo gba ìbáwí, wọn óo sì fọkàn sí gbogbo ohun tí mo pa láṣẹ fún wọn.
Mọ síi nípa ohun tó ṣẹlẹ ní àwọn ibi tí wọn ti ṣilẹkùn ilé ìwé padà lẹyìn Covid 19 Aláàfin gbé àṣẹ kalẹ̀ láti dènà àtúnṣẹ̀ ìṣẹ̀lẹ̀ 'Soka'nílùú Ọ̀yọ̀ Lagos Lockdown: Ìgbésẹ̀ ìjọba lórí Twitter tì mí lójú- Jimi Disu Èsì àyẹ̀wò tí àjọ NCDC gbé síta fihàn pé ènìyàn 265 ló tún ti ní ààrùn Covid-19 ní Nàìjíríà Ṣọ́ọ́ṣì kan sí ìlẹ̀kùn rẹ̀ fún àwọn mùsùlùmí láti kírun Jímọ̀ ní Germany Gong ni ojúṣe ilé iṣẹ́ tó ń rí sí ètò ìlera, àjọ tó ń gbógun ti àjà kálẹ̀ ààrùn ni Nàìjíríà (NCDC) àti ìgbìmọ̀ amúṣẹ́ya Covid-19 tí Ààrẹ yàn ni àti pé àwọn ni ọ̀rọ̀ kù sí lọ́wọ́ nítorí àwọn ni wọ́n ń léwéjú lórí ọ̀rọ̀ Coronavirus àwọn sì ló mọ àsìkò tó yẹ láti ṣí àwọn ilé ẹ̀kọ́.
Lẹ́hìn èyí mo rí pọ́nùn mẹ́wàá kan yá lọ́wọ́ ọ̀rẹ́ mi mo si bẹ̀rẹ̀ sí fi i ṣòwò, mo jèrè títí mo fi san owó náà tán mo sì ṣe bẹ́ẹ̀ mo kọ́ ilé, lẹ́hìn èyí mo ra mọ́tò mo sì ń di ẹni tí ń gbádùn ayé mi díẹ̀, ṣùgbọ́n àwọn ará ìlú náà kò dára, wọ́n ki ojú bọ̀ mí lára; nígbà tí ó ṣe mọ́tò mikan bàjẹ́, kò sí pẹ́ lẹ́hìn náà èkejì kọlu igi kan ó sì rún wómúwómú, Ọlọ́run ló tilẹ̀ yọ mí tí ẹnikẹ́ni kò kú sí i.
Àjọ DSS tú gbogbo pátá mi wò pé wọ́n ń wa ọmọ- Bisola aya Woli Alfa Àwọn aṣòfín ní ìpínlẹ̀ Edo ti yọ Abẹnugan Ilé, Francis Okiye bí jìgá Inú mi dùn sí iwọ́de EndSARS tàwọn ọdọ́ Nàìjíríà ń ṣè - Ooni Ogunwusi Oṣiṣẹ ajọ ẹṣọ oju popo, FRSC kan ṣalaye ere a-sa-ju ọkọ akero naa lo ṣokunfa ijamba ọkọ naa.
SERAP rọ ìjọba láti ṣe amúlo ìmọ̀ràn yìí láàrín ọjọ́ mẹ́rìnlá tí wọ́n bá ti rí ìwé ẹ̀bẹ̀ SERAP gbà, àti pé tí ìjọba bá kọ láti 'se bẹ́ẹ̀, gbogbo ǹkan tó ba wà ni ìkáwọ́n rẹ̀ nílànà òfin ni òun yoo fi mú ijọba ṣe e Oríṣun àwòrán, Femi Adesina Iná ètò ọrọ̀ ajé Naijiria jó àjórẹ̀yìn fún ìgbà kejì láàrín ọdun mẹ́rin Ijọba apapọ ti kede pe nnkan ko fararọ lọwọ yii nitori pe ifasẹyin ti de ba eto ọrọ aje Naijiria.
The 27th Anniversary: Ò ti pé ọdún 27 tí Shah Rukh Khan ti ń se fíìmù India
Eyi lo mu ki wọn da fasiti yi silẹ Erongba fasiti naa ni ki wọn sọ agbara awọn to n ṣiṣẹ lẹka irinna Naijiria dọtun ki wọn ba le kun oju oṣunwọn Lọwọlọwọ awọn ọmọ Naijiria kan n kẹkọ nipa eto irinna oju reluwe ni China.
O kò ní ṣíjú wo àwọn ará Ijipti mọ́, o kò sì ní ranti wọn mọ́.
Dino gba òmìnira Dino Melaye f'oju ba'le ẹjọ Dino: Mó tí fàgilè ìfilọ́lẹ̀ àkànṣe iṣẹ Dino Melaye tun k'ọrin miran Dino Melaye lo ti kọkọ ṣoju ẹkun yii pẹlu oriṣiriṣi iṣẹlẹ ṣeyin.
Yollywood: Odunlade Adekola àtàwọn òṣèré sinimá Yorùbá míràn tó padà lọ sí fásiti lọ kàwé
Branda yoo je obinrin akoko ti yoo maa je oludari fun Malawi.
Nigba to n ba BBC sọrọ, Prince Wiro, lati ajọ Centre For Basic Rights And Accountability Campaign sọ pe, ọmọ ọhun ṣi wa laaye nigba ti oun foju gan ni rẹ, ṣugbọn o ti gbẹmi mi nigba ti awọn ọlọpaa yoo de ibẹ.
12 Ògún 2019 Oríṣun àwòrán, NFF Àkọlé àwòrán, Samuel Okwaraji: Ó pé ọgbọ̀n ọdún tí lónìí ti akọni àgbábọ̀ọ̀lù papo dà O ní ló pé ọgbọ̀n ọdún gbáko ti akọni agbábọ́ọ̀lù, olùfẹ́ orílẹ̀-èdè rẹ̀ kú lásìkò tó ń ṣe ojúṣe rẹ̀ fún orílẹ̀-èdè Nàìjíríà.
kọ ́ ngrẹ ́ ẹ ̀ sì orílẹ ̀ -èdè amẹ ́ ríkà ( united states congress ) ni ile-oniyewu meji asofin ti ijoba apapo orile-ede amerika to ni ile asofin meji : ile awon asoju ati ile alagba asofin .
Alaafin sọrọ si mi tori pe n ko jẹ ko gbe ade le Onikoyi lori, amọ ibi to ba kan onikaluku ni ko duro si bii ọba.
APC pàṣẹ lọ rọ́ọ́kún nílé fún Amosun, Okorocha Ǹjẹ́ o mọ̀ pé ọdọ 43m ló wà lára olùdìbò?
tabi omiran tete jawo nitori ile ise oloopa ipinle Oyo, ko ni sun beeni ko ni
Olùkọ́ fásitì méjì ń bèèrè ìbálòpọ̀ lọ́wọ́ akẹ́kọ̀ọ́ fún máákì Inú máa ń bí mí láti gbọ́ pé ẹ̀yà kan kò leè darí Nàíjíríà -Tunde Bakare Ìṣesí Kunle Ọlasọpe ni mo ṣe yan iṣẹ́ akọ̀ròyìn láàyò - Lekan Alabi Wo ìdí to fi gbọdọ̀ yàgò fún Bobrisky, akọ tó ń ṣe bíi abo Gẹgẹ baa se gbọ, miliọnu lọna ogoje ni apapọ ibo tawọn ọdọ di fun oludije kan abi omiran lori eto ọhun, bi o tilẹ jẹ pe awọn miran di ibo ju igba meji tabi mẹta lọ.
Òun fẹ́ràn àwọn ará Sioni; nítorí náà ni inú òun ṣe ru sí àwọn ọ̀tá wọn.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Islamic New Year: Ọdún mùsùlùmí Hijiri tuntun bẹ̀rẹ̀ ní Nàìjíríà 20 Ògún 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 21 Ògún 2020 Oríṣun àwòrán, Others Bi awọn musulumi ni Naijiria ṣe n ki ara wọn ku orire ibẹrẹ ọdun tuntun wọn, igbimọ alakoso ẹsin Islam ni Naijiria, NSCIA ti sọ pe, ọjọ Jimọ, ọjọ Kọkanlelogun oṣu Kẹjọ ni onka ọdun tuntun yoo bẹrẹ.
Jesu dá a lóhùn pé, “Jẹ́ kí á ṣe é bẹ́ẹ̀ ná, nítorí báyìí ni ó yẹ fún wa bí a bá fẹ́ ṣe ẹ̀tọ́ láṣepé.
Àwọn òfin mi ni ẹ gbọdọ̀ pamọ́, àwọn ìlànà mi sì ni ẹ gbọdọ̀ máa tẹ̀lé, tí ẹ sì gbọdọ̀ máa tọ̀.
Ìwọ Ọlọrun ni a fi ń yangàn nígbà gbogbo;a óo sì máa fi ọpẹ́ fún orúkọ rẹ títí lae.
Ti o ba ni oye ipa ti aarun naa n ni ni ara, o ko ni yọ ara rẹ lẹnu pe o fẹ ẹ bimọ.
Lẹyin naa ni wọn bẹrẹ si ni fi ṣẹ́kẹ́-ṣẹké wọ́ obìnrin ọhun nilẹ.
Ẹnikẹ́ni kò wò ọ́ lójú, kí ó ṣàánú rẹ, kí ó ṣe ọ̀kan kan ninu àwọn nǹkan wọ̀n-ọn-nì fún ọ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ọpẹmipọ Bamgbọpa: Obìnrin gbọdọ̀ kó ara rẹ̀ níjànu lórí ọ̀rọ̀ ìfẹ́ nínú tíátà Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Ọpẹmipọ Bamgbọpa: Obìnrin gbọdọ̀ kó ara rẹ̀ níjànu lórí ọ̀rọ̀ ìfẹ́ nínú tíátà 17 Ọ̀wàrà 2018 Ọmọdebinrin osere tiata nigbakan, Ọpẹmipọ Bamgbọpa, nibayii to pada sinu isẹ tiata bii ọlọmọge ni, ọpọ awọn ọkunrin to wa nibẹ lo n sọ fun oun pe ‘sebi ọwọ wa lo dagba si, jẹ ka kuku maa tọju rẹ lọ’.
Nígbà tí àwọn eniyan rí i, gbogbo wọn bẹ̀rẹ̀ sí kùn sí Jesu, wọ́n ní, “Lọ́dọ̀ ẹlẹ́ṣẹ̀ ni ó lọ wọ̀ sí!
Akinwumi Adesina bọ́ lọ́wọ́ ẹ̀ṣùn jẹgúdújẹrá tí wọ́n fi kan - AFDB Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Hepatitis: A kò leè kóo nípa dídìmọ́ ara ẹni Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
”“Gege bi ẹgbẹ  to ni ibowo fun eto ijọba tiwa-n-tiwa ati  ẹtọ omoniyan, awon omo ẹgbẹ  lee yapa sinu egbe  to ba wun won  lorile ede yii.
Ó fi kun pé, ibùdó míràn tún wà ninú igbó Robochi/Gwagwalada, igbó Kwaku ní Kuje àti igbó Unaisha ní ìjọba ìbílẹ̀ Toto ní ìpińlẹ̀ Nasarawa.
Ninu atẹjade naa, kọmisana fun ere idaraya, Monday Uko sọ pe ti wọn ba fi lo papa iṣere naa fun eto ti kii ṣe ere idaraya, wọn ko ni le gbin koriko miran si' ko to o di pe Premier League Naijiria yoo bẹrẹ lọjọ kẹtala, oṣu Kinni, ọdun 2019.
Ẹ̀wẹ̀, kìí ṣe Omotosho nìkan ló jìyà ẹ̀ṣẹ̀, igbákejì ọ̀gá àgbà ọlọ́pàá tún já ipò àwọn òṣìṣẹ́ SARS mẹ́ta míì tí wọ́n jọ ṣe aṣemáṣe náà walẹ̀ láti ipò Seargent sí Corporal tí wọ́n sì ti gba gbogbo ẹ̀wù àti káàdì ìdánimọ̀ lọ́wọ́ Inspector ti wọ́n dá dúró.
Oríṣun àwòrán, Instagram/queen Anu Idahun Olori Anu fun BBC Yoruba lati mọ boya o si wa laafin Oyo abi o ti kuro: Awọn arigbamu yii lo mu ki BBC Yoruba kan si Olori Anu lori ẹrọ ibanisọrọ rẹ, lati fi idi ootọ ọrọ nipa iroyin yii to n lọ lori ayelujara mulẹ, lati mọ boya o si wa ni aafin Oyo abi o ti kuro.
Bí ó ti ṣe ń jẹ ọlá,tí ó ń jẹ ayé tẹ́lẹ̀,bẹ́ẹ̀ ni kí o fún un ní ìrora ati ìbànújẹ́.
Ṣugbọn ikú ti jọba ní tirẹ̀ láti ìgbà Adamu títí dé ìgbà Mose, àwọn tí kò tilẹ̀ dẹ́ṣẹ̀ nípa rírú òfin bíi Adamu, pẹlu àwọn tí ikú pa, Adamu tí ó jẹ́ àpẹẹrẹ irú ẹni tó ń bọ̀.
Oríṣun àwòrán, Twitter/TemiOanu Loju opo rẹ ni Twitter ati Instagram, orisirisi aworan lo wa nibẹ lawọn ibi to ti n kopa ninu iwọde.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Leanne kò gbádùn ìbálòpọ̀ Ìgbẹ̀yìn gbẹ́yín, ó lahun sí ọ̀rẹ́ rẹ̀.
Àwọn tí wọ́n fi ṣe olórí láàrin àwọn ọmọ Israẹli bá ké tọ Farao lọ, wọ́n ní, “Kí ló dé tí o fi ń ṣe báyìí sí àwa iranṣẹ rẹ?
Ẹ̀bẹ̀ la bẹ̀ “Òṣèlú Nigeria” ki wọn ma pe Ajá l’Ọbọ fún ará ilú, ki wọn kó owó ilú ti wọn ji pamọ́ si Òkè-Òkun padà, ki wọn si fi àpẹrẹ rere silẹ̀ fún ará ilú nipa àyipadà kúrò ni iwà ojúkòkòrò àti olè ti wọn nfi ipò jà dúró.
Alukoro ileeṣẹ ọlọpaa ni ipinlẹ Ọyọ, CSP Olugbenga Fadeyi ṣalaye fun BBC News Yoruba pe ọrọ naa ko ṣe ajeji si awọn ọlọpaa.
Orí òkè Nebo yìí ni o óo kú sí, bí Aaroni arakunrin rẹ ṣe kú lórí òkè Hori.
O ni pẹlu bi aye ti ṣe di ti ayelujara ti ọwọ si ti n kan owo nipa okowo, igbeyawo atawọn nnkan miran, sisọ ede Ekiti tabi ede Yoruba nikan yoo fa ọpọlọpọ gbọnmisi omi o to ati ede-ai-yede.
Itumọ owe yii lo si n parọwa si ẹni kọọkan wa pe ka ma se kọja agbara wa, ka maa se ohun gbogbo ni iwọntun wọnsi, iwọn eku ni iwọn itẹ, ka maa baa maa jẹ gbese kiri, eyi to lee mu itiju ati ipaya de ba ni.
Eto ayajọ ọjọ ibi Anọbi Mohammed (SAW) ni a n ṣe to bi wahala ki wọn wa pa awọn eeyan wa ni Mọsalasi.
Àwọn ará Bẹtẹli rán Ṣareseri ati Regemumeleki ati gbogbo àwọn eniyan wọn lọ sí ilé OLUWA; wọ́n lọ wá ojurere OLUWA, 
Àwọn èèkàn àgọ́, ati àwọn èèkàn àgbàlá pẹlu àwọn okùn wọn; 
Lara rẹ́ ni Ẹkun Oniwogbe, Onimọto, Yoruba Ronu O kọ abule sinima kan si ilu rẹ Ọsọsa, eyi to jẹ apewawo.
ÌTÀN DANIẸLI ATI ÀWỌN Ọ̀RẸ́ RẸ̀.
O kere tan moto mẹwaa lo jona nibẹ ti ọpọ dukia si ṣofo ninu awọn ọkọ naa.
Missing Child: Òbí àti asọ́nà ṣọ́ọ̀ṣì 14, lọ́ búra nì'dí imọlẹ̀ l'Akure Ìgbéyàwó mẹfa ní a ti ṣe lọ́dun yìí láàrin awọn oníkòkòrò HIV Koda, awọn alaṣẹ ọgba ẹranko naa daabo bo erin meji miiran ti wọn tun fẹ yọ ṣubu lori oke ti ko jina si ibi tawọn erin mẹfa ti ku.
 O wa rọ Ile Igbimọ Aṣofin naa pe awọn ọmọ ẹgbẹ Igbimọ Alaṣẹ eto
Orile-ede Amerika so pe, ise akanse awon omo ogun orile-ede ni orile-ede Syria ti n wa sopin bayii, sugbon won koi ti kede igba ti won yoo ko awon omo ogun naa kuro pata.
Èmi ni mo wí fún ọ, bí ayé yípadà tó bẹ́ẹ̀ tí àgùntàn ń lóyún ewúrẹ́ tí ológbò sì ń lóyún àkùkọ inú onílara kò ní í dùn láéláé.
O ni igbesẹ yii yoo ran awọn to n ta itakun ibanisọrọ yii lọwọ lati maa tẹlẹ ilana to duro ṣinṣin atipe igbesẹ yii ṣe pataki tori ọna ti wọn n gba ṣe iforukọsilẹ awọn to n ra kaadi ọhun ti wọn si fi n ṣiṣẹ ibi.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ibudo epo aburo ati betiroolu Eyi je igba akọkọ larin ọgbọn ọdun, ti iye agba epo rọbi tilẹ wa n pese yoo ja walẹ si milionu kan.
Aruna Quadri omo bibi orile-ede Naijiria to n kopa ninu ere-idaraya boolu afibaati gba, ti bo sipo ogun lagbaye, ipo kinni nile Afrika ninu ipo ate tuntun ajo to n mojuto boolu afibaati gba lagbaye (International Table Tennis Federation), ti o se e jade saaju akegbe re, Omar Assar omo orile-ede Egypt, ti o wa nipo kinni tele nile Afrika.
Ìran tí Daniẹli Rí ní Odò Tigirisi.
Onímọ: Bo bá ṣe le è ṣùn tó, ni ẹmí rẹ yóò ṣe gùn sí
Ta ba wo awọn esi ti ara ilu fun Trump lori ikede arun Coronavirus to ni, eyi fi han pe igbesẹ tí aarẹ gbe lasiko ti ajakalẹ arun naa bẹ silẹ nilẹ Amẹrika ,ko koju osuwọn to.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìjàmbá bàálú Cuba; Ọ̀pọ̀lọpọ̀ ẹ̀mí sọnú ní Havana 18 Èbibi 2018 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ọkọ òfúrufú 'Boeing 737' naa ló gbé ènìyàn mẹrinlelọgọrun Ọkọ ofurufu kan to gbe eniyan to le ni ẹgbẹrun ti jabọ to si gbana, lẹyin to gbera kuro ni papakọ ofurufu to wa ni Havana, lorilẹede Cuba.
Ohun márùn ún tí o kò mọ̀ nípa òfin tó dáàbò bo àwọn àkàndá Day 19: Wo ohun àràmàndà tí àwọn olósèlú máa ń ṣe lásìkò ìbò #BBCNigeria2019 Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Obìnrin ló ni ilé àti àdúgbò fún ìdí èyí wọ́n lè ṣe ìlú dáadáa' Bakan naa o mẹnu ba pipese oogun, awọn ẹrọ igbalode to tọ si awọn ile iwosan to yẹ.
Ìpín Aaroni ni ati ti àwọn ọmọ rẹ̀, lára ẹbọ sísun tí a rú sí OLUWA, àní ẹbọ tí a yà sọ́tọ̀ fún wọn, ní ọjọ́ tí a mú wọn wá siwaju OLUWA láti máa ṣe iṣẹ́ alufaa.
Ìṣọwọ́ gbá bọ́ọ́lù Atletico kò tọ̀nà àmọ́ a gba ìjákulẹ̀ wa - Liverpool Alakoso fun ikọ agbabọọlu Liverpool, Jurgen Klopp ti n kawọ leri lori ilu bara ti alatako wọn, Atletico Madrid na wọn, to si ni nkan ko jọ ara wọn nipa ilana isọwọ gba bọọlu naa.
Akọwe ẹgbẹ awọn agbẹ Idera, Oloye Oyekola Joseph jẹ ko di mimọ pe gbogbo ohun to n ṣẹlẹ yii n kọ awọn lominu lati bii ọdun mẹjọ sẹyin to si n ke si ijọba pe ki wọn tete da si ọrọ naa ko to di nkan mii.
Kọmiṣọnna fun eto ẹkọ Arabinrin Fatimah Bisola ni kọmiṣọnna tuntun fun ile iṣẹ ijọba to n ri si eto ẹkọ.
Ọkọ iyawo ni ó ni iyawo, ṣugbọn ẹni tí ó jẹ́ ọ̀rẹ́ ọkọ iyawo, tí ó wà lọ́dọ̀ rẹ̀, tí ó ń gbọ́ ọ̀rọ̀ rẹ̀, á máa láyọ̀ láti gbọ́ ohùn ọkọ iyawo.
Covid 19 Update: Àwọn orílẹ̀-èdè kan tún ti kéde kó nílé-ó-gbélé nítorí coronavirus
lorilede yii ko le e se aseyori.
Wo àwọn ìlànà tuntun ti o gbọdọ tẹlèé rèé ki ó to le wọkọ̀ òfurufú lọ sókè òkun Ọmọ Ààrẹ lẹ́tọ̀ọ́ láti ṣe ìgbéyàwó yálà àwọn ará ìlú fẹ́ràn ìjọba bàbá rẹ̀ tàbí bẹ́ẹ̀ kọ́ - Aisha Buhari Ó yẹ kí Buhari dá owó epo padà sí ₦97 tàbí kó kọ̀wé fipò sílẹ̀ - Àwọn akẹ́kọ̀ọ́ Àbá àpérò 2014 CONFAB lojútùú sí àtúnṣe ìwé òfin Nàìjíríà- Afenifere sáwọn sẹ́nẹ́tọ̀ Wo àwọn orilẹ́èdè àgbáyé tó ti sí pápákọ̀ òfurufú wọn fún ìrìnàjò Àwọn orílẹ̀èdè to le wọ bàálù lọ lókè òkun Ọpọlọpọ awọn eniyan lo ti n beere igba ti Naijiria yoo si papakọ ofurufu fun irinajo lati orilẹede Naijiria lọ si oke okun.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Toyin Abraham ní òun lo àgbo ni ipo iloyun 18 Ọ̀wàrà 2019 Oríṣun àwòrán, toyin_abraham Àkọlé àwòrán, Toyin Abraham ní òun lo àgbo ni ipo iloyun Gbajúgbajà òṣèré Yorùbá, Toyin Abraham sọ ìtàn bí ò ṣe di abiyamọ láìpẹ́ yìí lásìkò tó bẹ̀rẹ̀ ìpolówó ọjà rẹ̀ to ṣẹṣẹ dawọ le.
Èyí rí bẹ́ẹ̀ kí àsọtẹ́lẹ̀ nì lè ṣẹ pé, “Láti Ijipti ni mo ti pe ọmọ mi.
Àwòrán àjọyọ̀ ìjọba ológun ní Sudan Oun tí ẹ lè má mọ̀ nípa Omar al-Bashir, olórí Sudan ti wọ́n yọ nípò Àwọn ológun dojú ìjà kọ ara wọn ní Khartoum Lati igba ti awọn ologun ti gbajọba lọwọ Aarẹ Omar al-Bashir ninu oṣu Kẹrin ni awọn ọmọ ogun ti n ṣe iṣakoso orilẹede naa.
Super Falcons fi South Korea ṣ’ẹ̀bùn June 12 fún Nàìjíríà Orúkọ àwọn Super Falcons 23 tó ń lọ France ti jáde Ileri Super Falcons fun awọn ọmọ Naijiria: Nitootọ ni ọpọ gba pe Germany kii ṣe ẹran rirọ fun Naijiria ṣugbọn awọn agbabọọlu Naijiria ni awọn a gbiyanju lati bori.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ìdílé tí ọkọ da ọmọ síta tóríi ojú Búlùú tí wọ́n ní bá BBC sọ̀rọ̀ Ninu atẹjade kan eyi ti ileeṣẹ ọlọpaa ni ipinlẹ Ọyọ fi sita, eleyii ti alukoro rẹ, SP Fadeyi Oluugbenga fi fọwọsi ni alaye naa ti jẹyọ.
Àbí n kò mọ nǹkan burúkú yàtọ̀?
Oluranlowo agba fun aare Muhammadu Buhari lori oro ile-okeeere ati ayika ,iyaafin Abike Dabiri-Erewa  lo soro yii pe .
"Oríṣun àwòrán, Getty Images Bákan náà ni Nick Smith, tíì ṣe ọmọ ilẹ̀ Amẹ́ríkà tó ní ibùdó ipọnti lẹ́yìn odi ìlú Cape Town sọ pé "" isẹ tán fún wa nìyẹn""O fikùn pé "" òfin tó dé oko-owo ọtí náà tí ṣe àkóbá nla fún àwọn oko-owo alabọde""."
Joṣua bá rán wọn ṣiwaju, wọ́n sì lọ sí ibi tí wọn yóo fara pamọ́ sí ní ìwọ̀ oòrùn Ai, láàrin Ai ati Bẹtẹli.
Ẹsun ti wọn tori rẹ dajọ iku fun ni pe o pa ọrẹkunrin rẹ, ọgbẹni Auwalu lọdun 2002.
Chinyere sugbon ti ile- ise olopa si ri okada mewaa ati owo ohun gba.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Sekinat Quadri ọmọ ọdun meje ajẹsẹ to fẹ dabi Anthony Joshua DJ Switch (GHANA) Àkọlé àwòrán, Children's Day: Àwọn ọmọde tó ti bẹ́bẹ́ láwùjọ Afíríkà Ọmọdébìnrin, ọmọ ọdún mẹ́ẹ̀wá tó jẹ́ apo orin tàkasufe pọ yìí 'DJ switch' ní àṣírí márùn-ún fún ẹnì tó bá fẹ́ dà bíi rẹ.
" Bobrisky ni oun pari ile ẹkọ fasiti, ti isẹ ko si ni oun ba pinnu lati maa huwa to yatọ si ohun ti awujọ n fẹ, eyi ti yoo pe akiyesi awọn eeyan sọdọ oun, ti yoo si tun mu owo wọle.
Bẹ́ẹ̀ ni èmi OLUWA Ọlọrun wí.
Lasiko iwọde naa ,wọn kesi ijọba lati pese aabo to peye nitori pe ''eyi ki ṣe igba akọkọ ti awọn janduku yoo kọlu awọn akẹkọọ dokita lagbegbe naa.
 ohùn méjì pàtàkì ni a ń bá pàdé nínú eré àpíìrì .
Ẹnu olódodo kún fún ọ̀rọ̀ ọgbọ́n,ṣugbọn ẹnu alaiṣootọ ni a pamọ́.
Manchester United: Paul Pogba sọ pé òun ti ṣe tán láti padà sórí pápá
Asset Declaration: Gbogbo ẹni tí ó máa búra wọlẹ́ gẹ́gẹ̀ bíi Mínísítà gbudọ̀ kéde dùkìá
4m 3 Mo ti kúrò ní ààfin Oyo, kí ìròyìn tó ò jáde pé èmi àti Wasiu Ayinde n fẹ́ ara wa - Olori Badirat 4 Ìdí rèé tí mo fi yan ikọ̀ PMS rọ́pò NURTW nípìnlẹ̀ Oyo - Seyi Makinde 5 Kílódé tí Ọọni Ife, Oba Ogunwusi kò fi gbọdọ̀ rí ọmọ rẹ̀ tuntun ti Olorì Naomi bí títí di bíi ẹ̀yìn oṣù mẹ́fà?
Kò sí bí ó ṣe lè ṣẹlẹ̀ kí wọn ó máà mọ̀ wípé ẹni tí ó ń ṣiṣẹ́ fún wọn ní ojúmọ́ ní oyún ní inú.
Bakan naa lo mẹnuba awọn nnkan miran laisi pe ọkan tako ọkan ninu rẹ kun ara ohun to ba BBC News Yoruba sọ ninu ifọrọwanilẹnuwo yii.
Aare ranti pe Jos ni oun ti n sise ologun ki won to pe oun wa se adari Naijiria ni osun kinni odun 1984.
Ẹnikan to mọ nipa iṣẹlẹ naa ṣalaye pe, wọn gbe oloṣelu ọhun digba digba lọ si ile iwosan ṣugbọn ẹlẹmi ti gba a.
Ẹ wo àwọn ẹlẹ́sìn Hindu tó ń jẹ ènìyàn Gani Adams ní Ọ̀yọ́mèsì ló fún òun láṣẹ láti yan olóyè Aláàfin Ọyọ pé ọdún 48 lórí àpèrè Orílẹ́-èdè 5 tí takọ-tabo kò gbọdọ̀ fẹnu ko ara wọn lẹ́nu Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Eko Akete yóò gbàlejò BBC Yoruba Oríṣun àwòrán, @bASIR aHMAD Àkọlé àwòrán, Ọga ọlọpaa tuntun ati Aarẹ Buhari Ọjọ kẹsan oṣu kọkanla ni wọn bi ọga ọlọpa, lọdun 1986 lo si wọ iṣẹ ọlọpaa.
Dúró níbẹ̀ fún ọjọ́ meje, títí tí n óo fi dé, n óo sì sọ ohun tí o óo ṣe fún ọ.
Ciaran Clark to jẹ agbabọọlu Newcastle da ayo kan nigbati ifẹsẹwọnsẹ ku die ko pari, ṣugbọn Arsenal pada jawe olubori.
Ibaṣepọ to wa laarin wa kọja ọrọ ounjẹ ati owo, o dalori i itakurọsọ ọ wa."
N óo jẹ́ kí àwọn ìjòyè rẹ̀ ati àwọn ọlọ́gbọ́n rẹ̀ mu ọtí ní àmuyó,pẹlu àwọn gomina rẹ̀, àwọn ọ̀gágun rẹ̀, ati àwọn ọmọ ogun rẹ̀.
Kìí ṣe gbájúẹ̀ nìkan lọmọ Nàìjá ń ṣe lókè òkun!
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ramadan: Kíni ǹkan tó ń ṣẹlẹ̀ si àgọ ara rẹ̀ ti o bá n gbààwẹ By Ahmen Khawaja BBC World Service 7 Èbibi 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Lọ́dọọdún àwọn musulumi jákejado àgbáye a máa gbààwẹ láti ààrọ di alẹ́ fún ọgbọ̀n ọjọ gẹ́gẹ́ bii ètò Ramadan Ní ǹkan bi ọdun diẹ̀ sẹ́yìn àsìkò òòrun ni oṣù ààwẹ máa ń wáyé, èyí yóò si wáye ni ǹkan bíi ọjọ mẹ́rindinlogun inu oṣù káàrún ọdun yìí ni ilẹ̀ Gẹ̀ẹ́sì (UK) èyí túmọ̀ si pé ojú ọjọ yóò maa gùn ju bí o ti yẹ lọ.
Jonatani sọ̀rọ̀ Dafidi ní rere níwájú Saulu, ó wí pé, “Kabiyesi, má ṣe nǹkankan burúkú sí iranṣẹ rẹ, Dafidi, nítorí kò ṣe ibi kan sí ọ.
Nígbà tí wọn kò lè gbé e dé ọ̀dọ̀ rẹ̀ nítorí ọ̀pọ̀ eniyan, wọ́n dá òrùlé lu ní ọ̀kánkán ibi tí Jesu wà.
Àwọn gómìnà sọ fun ẹgbẹ́ òṣìṣẹ́ lábẹ́ àbùradà NLC àti TUC pe àwọn kò lágbára láti san ọgbọ̀n ẹgbẹ̀rún tí wọn ń bèèrè fùn, bẹ́ẹ̀ni ìjọba àpapọ̀ náà ti sọ tẹ́lẹ̀ pé ẹgbẹ̀rún mẹ́ẹ̀dọ́gbọ̀n lohun lè san.
Má ṣe sin òkú mi sí ilẹ̀ Ijipti, 
Àwọn ọmọ oníjó a sì máa jó tẹ̀lé àwọn ọkọ̀ nla wọ̀nyí títí wọ́n á fi tọ ọ̀nà já.
“Bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé wọ́n ti kọ̀ ọ́,wọ́n sì kórìíra rẹ,tí kò sí ẹni tí ń gba ààrin rẹ̀ kọjá mọ́,n óo sọ ọ́ di àmúyangàn títí lae;àní, ohun ayọ̀ láti ìrandíran.
Gbọingbọin lọmọ Nàìjíríà wà lẹ́yìn iléẹjọ́ gíga jùlọ lórí ìdájọ́ ìbò Bayelsa- Atiku Àwọn ọmọ onílẹ̀ lọ ṣe àmúṣẹ àṣẹ iléẹjọ́ ní Soka, làwọn ‘Jàǹdùkú’ fi dá wọn lọ̀nà - Iléeṣẹ́ ọlọ́pàá Ọyọ Káńsélọ̀ Sajid Javid kọ̀wé fipò sílẹ̀ lẹ́yìn tí Boris Johnson ṣàtúntò ìjọba rẹ̀ Omotoso ṣalaye pe, ọga agba fun ileesẹ ọlọpaa ti ṣalaye fun awọn gomina ilẹ Yoruba pe, eto Amotekun kii ṣe eto gbogbo ẹkun iwọ oorun guusu Naijiria, ṣugbọn ki olukuluku ṣe amojuto eto abo wọn lọtọtọ.
Morocco tun sapejuwe aseyori aare Buhari gege bi eni ti awon omo orile ede
''Awọn oṣiṣẹ ijọba ilẹ Amẹrika gan an ki Atiku kaabọ nigba to de si Amẹrika,'' Ibe lo sọ bẹẹ.
Ìjọba ní lẹ́yìn ti àwọn dẹkùn ìgbélé fún ará ilú bí tan, o yáni lẹ́nu pé bi olúkúlùkù ṣe ń hùwà àìbìkítà si àwọn ǹkan ti ìjọba ni kí wọ́n ṣe tàbí kí wọ́n má ṣe kò dára tó, sùgbọ́n àwọ́n fẹ́ mọ ǹkan ti àrá ilú ń fẹ́ bí ọsl méji ìdẹ̀kùn igbẹ́le ṣe fẹ́ parí.
Wo bí ìyàwó ṣe le gbé ọmọ Ọbà fún Ọ̀ṣun láì yan àlè Ìgbà mẹ́jọ tí ọ̀rọ̀ Oluwo di ariwo nígboro láàrín ọdún márùn ún rẹ̀ lóyè Irọ́ ni pé ọba tuntun má a ń jẹ ọkàn ọba tó bá wàjà ní ìpèbí - Elebuibon Ẹ wo ọba kan nílẹ̀ Yorùbá, tí kò ṣe ètùtù tàbí náwó ànájù, kó tó jọba Eleyii lo jẹ ki wọn tẹ pinpin ayederu aṣọ naa, ti ọwọ si tẹ Alhaja Oluwakemi Akehusola ni agbegbe ijọba ibilẹ Ido ni ipinlẹ Oyo.
Olówó náà kú, a sì sin ín.
Ibi tí àwọn ọmọ Israẹli pàgọ́ sí ninu ìrìn àjò wọn láti ìgbà tí wọn ti kúrò ní Ijipti lábẹ́ àṣẹ Mose ati Aaroni nìwọ̀nyí: 
to n tẹwọgba  iwe abajade lori bi awon
Tolulope dagaba ni ilu Kaduna nibi to ti bẹrẹ irinajo rẹ sinu iṣẹ ọmọ ogun ni ileewe alakọbẹrẹ ti awọn ologun ofurufu ni Kaduna to si tẹsiwaju lọ ileewe girama awọn ologun ofurufu bakan naa.
Onidajọ Ijeoma Ojukwu paṣẹ naa lẹyin ti Pinnick atawọn mẹrin naa kunna lati farahan niwaju ileẹjọ lati koju ẹsun ṣiṣe owo ajọ NFF baṣubaṣu eleyii ti wọn fi kan wọn.
O ni akọsilẹ ọmọ mẹrin ni ileeṣẹ ọlọpaa ni pe o sọnu, ṣugbọn iṣẹ n lọ lọwọ lati ṣawari awọn ọmọ naa, ati lati fawọn le awọn obi wọn lọwọ.
Òní ni Shi'ite fẹ́ ṣe ìwọ́de ikú ọmọ ọmọ Anọ́bì ní èyí tí ó lòdí sí àṣẹ agbófinró Akitiyan ìjọba láti mú kí àwọn ọmọ Nàìjíríà san owó orí Ronaldo, Messi ẹ yàgò lọnà fagbábọ́ọ̀lù Nàìjíríà tó n gbowò julọ!
‘Gboingboin ni Ilẹ̀ Gẹ̀ẹ́sì wà lẹ́yìn ìgbógun ti Boko Haram’ Kínni ẹ̀yin lè rántí nípa Ààrẹ Nàìjíríà tẹ́lẹ̀ rí, Umaru Musa Yar'Adua?
Kò gbà pé èmi ni mo fún òun ní oúnjẹ, tí mo fún un ní waini ati òróró, tí mo sì fún un ní ọpọlọpọ fadaka ati wúrà tí ó ń lò fún oriṣa Baali.
Ṣugbọn ẹni tí ó bá jẹ́ opó nítòótọ́, tí kò ní ọmọ tabi ọmọ-ọmọ, Ọlọrun nìkan ni ó ń wò, tí ó ń bẹ̀, tí ó ń gbadura sí tọ̀sán-tòru.
Wọn ni awọn gbe igbesẹ lati wọfile saa eto ẹkọ kẹta to yẹ ki awọn akẹkọọ lo tẹlẹ fun anafani wọn ni.
Rọ́jú mú sùúrù díẹ̀ sí i.
Oṣu Kẹfa ni iyawo gbaju-gbaja akọrin, Timi Dakolo, Busola Dakolo, ninu ifọrọwanilẹnuwo kan fi ẹsun kan Fatoyinbo pe o fi ipa ba oun lo pọ lẹẹmeji ọtọọtọ ki oun to o pe ẹni ogun ọdun.
Èyí ni àkọsílẹ̀ iye àwọn tó kù díẹ̀ káà tó fún lórílẹ̀èdè Nàìjíríà BBC Yorùbá gbalejo Adaku ninu ile iṣẹ wa nibi to ti sọrọ ni kikun lori ikọraẹnisilẹ.
Iṣẹlẹ naa waye ni ilu Kenosha, to wa ni ipinlẹ Wisconsin lẹyin ti ileeṣẹ ọlọpaa ni wọn gba ipe gbajawiri lori wahala to waye ninu ile kan.
Ọ̀pọ̀ àwọn agbowó-odè wà níbẹ̀ pẹlu àwọn ẹlòmíràn, tí wọn ń bá wọn jẹun.
Iko agbaboolu orile-ede Madagascar ya opo eniyan lenu ninu idije Africa Cup of Nations to n lo lowo, leyin ti iko ohun fi egba atori le iko agbaboolu Super Eagles kuro nipo kinni sipo keji lataari esi ifesewonse ohun.
 Ó seré ní agbọn eré àgbéléwò yorùbá ti nàíjíríà .
” Àkókò náà ni Hamani wọ inú àgbàlá ààfin ọba, láti bá ọba sọ̀rọ̀ láti so Modekai rọ̀ sórí igi tí ó rì mọ́lẹ̀.
lori ni orile ede yii, lati je ki gbogbo awon ẹka to wa, se ise won bi ise, ti
Ohun ti wọn fi n se aadun ni; agbado ti wọn ti lọ, epo pupa, iyọ, ati awọn eroja miiran.
Ààrẹ orílẹ̀-èdè Nàìjíríà, Muhammadu Buhari yóò rìnrìn àjò lọ sí Morocco lọ́jọ́ ìsinmi, ọjọ́ kẹwàá, oṣù Kẹfà.
Èkó jẹ́ olú ilú fún gbogbo orilẹ̀ èdè Nigeria tẹ́lẹ̀ ki wọn tó gbe lọ si Abuja.
 Ògúndélé bínú nítorí pé jìnádù kò tètè san múrí méjì tí ó kì .
Wọ́n ti kọ̀ mí sílẹ̀, wọn kò sì pa òfin mi mọ́.
Wo ohun tó yẹ kí o mọ̀ nípa akínkanjú obìnrin alága àjọ elétò ìdìbò Ghana 2020 Wo ibi mẹ́rìnlá tí o kò gbọdọ̀ gbé ọkọ̀ rẹ sí lásìkò yìí.
Nibi tọrọ yi de bayi, awọn eeyan ilẹ Faranse naa ti mu ọrọ Omotara gbọ loju opo Twitter ti wọn si faraya gidi gan an.
Ado-oloro ohun ni won ju sile lodun bi melo kan seyin lasiko ogun agbaye keji World War 2, eyi ti o ko lati bu gbamu.
Wọ́n gbé òkúta mejila láti inú odò Jọdani, gẹ́gẹ́ bí iye ẹ̀yà tí ó wà ninu àwọn ọmọ Israẹli, gẹ́gẹ́ bí OLUWA ti sọ fún Joṣua.
Oríṣun àwòrán, Idowu-Sowunmi Àkọlé àwòrán, Opo igba ni Gomina Ambode ti so pe itẹsiwaju ẹgbẹ APC lo jọ oun loju 'Mi ò mọ̀ pé mo lóyún àfìgbà t'ọ́mọ ń rún'ra' Ìwádìí ìwé ẹ̀rí àwọn olùdíje Ààrẹ lọ́dún 2019 Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Iwode fun Ochanya ti won ba lopo waye nilu Eko Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Lagos APC primaries don turn abracadabra as election committee say e neva hold2 Ọ̀wàrà 2018 Fídíò, APC don declare Sanwo-Olu winner of Lagos Primary3 Ọ̀wàrà 2018 Fídíò, 2019 election: 'Our mumu don do' - Sowore10 Ìgbé 2018 2019 Election: Confam list of APC Govnorship candidates5 Ọ̀wàrà 2018 Peter Obi: Nigerians dey atikulate say dem wan see Osinbajo vs Obi12 Ọ̀wàrà 2018 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Ènìyàn 575 ló tún ní ààrùn Covid-19 ní Nàìjíríà ní 05/07/2020 Orilẹ-ede Naijiria tun ti ni akọsilẹ ojilelẹẹdẹgbẹta ati mẹrin eeyan to tun ti ni Covid-19.
Naijiria , ko ba si wa  nibi yara kan ti
Seyi Makinde: Ẹ ṣe àkójọpọ̀ orúkọ àwọn òǹtàjà tí àjálù bá lọ́jà Akẹ̀sán fétì ìrànwọ́
Àwọn ọdẹ pàápàá bẹ̀rù Igbó Olódùmarè ju Igbó Irúnmọlẹ̀ lọ, òfin gan-an sì ni ní ìlú wa pé odẹ tí kò bá tí dí ọdẹ aperin kò gbọdọ̀ lọ sí ibẹ̀ lọ ṣe ọdẹ, nítorí ibẹ̀ ni ibúgbé ìyanu – ibẹ̀ ni àwọn ẹyẹ ti ń fọhùn ènìyàn, tí àwọn ẹranko ń ta ọjà fún ara wọn; tí ogunlọ́gọ̀ igi kò ni gbòǹgbò síbẹ̀síbẹ̀ tá ara wọn tutù nini tí ewé wọn sì dúdú mirinmirin.
bẹ ́ rílíọ ̀ mù ni ẹ ́ límẹ ̀ ntì kẹ ́ míkà tó ní àmì-ìdámọ ̀ be àti nọ ́ mbà átọ ̀ mù 4 .
Ó ní, “Gbé òkúta ńláńlá lọ́wọ́, kí o bò wọ́n mọ́lẹ̀, níbi pèpéle tí ó wà lẹ́nu ọ̀nà ààfin Farao ní Tapanhesi, lójú àwọn ará Juda, 
Ọkan gboogi lara awọn iranṣẹ Ọlọrun to sọrọ bayii ni Pasitọ Enoch Adeboye ti ijọ RCCG lagbaye.
Awọn oṣiṣẹ n beere fun ida mọkandinlọgbọn ninu ọgọrun un alekun owo oṣu fawọn oṣiṣẹ ti owo oṣu wọn ti ji ẹgbérun lọna ọgbọn lọ tẹlẹ, iyẹn awọn to wa ni ipele kọkanla si ikẹtadinlogun lẹnu iṣẹ ọba.
Oríṣun àwòrán, Facebook/Mike Bamiloye Bamiloye ni ọpọlọpọ igba ni oun ti ṣẹ iyawo oun nipa ai fi aaye silẹ fun bose yẹ.
Akọwe ijọba apapọ to jẹ alaga igbimọ amuṣẹya lori ati gbogun ti ajakalẹ aarun covid-19 ni Naijiria, Boss Mustapha lo fidi ọrọ naa mulẹ fawọn akọroyin niluu Abuja lọjọ Aje.
A mọ̀ pé láti ọ̀dọ̀ Ọlọrun ni a ti wá, ati pé gbogbo ayé patapata wà lábẹ́ Èṣù.
Ileesẹ ologun ati ọlọpaa ti n tako ra lori idi tawọ̀n ologun se yinbọn pa ọlọpa naa ati araalu kan lasiko ti wọn gbe gbajumọ ajinigbe kan.
Ṣugbọn, mi o ti i ṣetan lati ni ibalopọ, mi o si ṣetan lati ṣegbeyawo.
Ibeere re to gba ẹnu awọn eeyan lẹyin ti ọwọ ọlọpaa tẹ tọkọtaya kan nilu Eko ti wọn lawọn ra awọn ọmọkunrin meji kan ni ẹgbẹrun lọna ogoje Naira lọwọ obinrin kan nilu Jos.
Bí mo ti ń gbadura, ni Geburẹli, tí mo rí lójúran ní àkọ́kọ́ bá yára fò wá sọ́dọ̀ mi, ní àkókò ẹbọ àṣáálẹ́.
Iṣẹ́ Paulu láàrin Àwọn Tí Kì í Ṣe Juu.
Alágbèrè ni gbogbo wọn; wọ́n dàbí iná ààrò burẹdi tí ó gbóná, tí ẹni tí ń ṣe burẹdi kò koná mọ́, láti ìgbà tí ó ti po ìyẹ̀fun títí tí ìyẹ̀fun náà fi wú.
OLUWA àwọn ọmọ ogun, Ọlọrun Israẹli ní: “N óo fi ìyà jẹ Amoni, oriṣa Tebesi, ati Farao, ati Ijipti pẹlu àwọn oriṣa rẹ̀, ati àwọn ọba rẹ̀.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Major US Twitter accounts hacked: Ẹ wo bí àwọn gbájúẹ̀ ṣe ṣọṣẹ́ ní Amerika 18 Òkùdu 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 16 Agẹmo 2020 Oríṣun àwòrán, Getty Images Awọn ọlọla lorilẹede Amerika ti lugbadi awọn gbajuẹ lori ẹrọ ikansiraẹni Twitter pẹlu imọ ẹrọ ayederu Bitcoin.
Awọn ijọba ibilẹ ti PDP ti moke ni ijọba ibilẹ Ifedore, Akure North ati Akure South.
Ọdọmọkunrin wolii náà bá lọ sí Ramoti Gileadi.
Ahasaya ọba Israẹli, ọmọ Ahabu, ọba Israẹli sọ fún Jehoṣafati pé kí àwọn eniyan òun bá àwọn eniyan rẹ̀ tu ọkọ̀ lọ, ṣugbọn Jehoṣafati kò gbà.
Nítorí pé ère lásán ni àwọn orílẹ̀-èdè yòókù sọ di ọlọrun,ṣugbọn OLUWA ló dá ọ̀run.
Ẹ yí òkúta ńlá kan wá sọ́dọ̀ mi níhìn-ín.
Awọn oludije mejeji ti baba forigbari lori ọrọ ṣiṣe atilẹyin fun awan afẹhonuhan to n bu ẹnu atk lu awọn ọlọpa nitori awọn alawọdudu ati bi ijọba ṣe n koju ajakalẹ arun Coronavirus.
April 27, 2015: Awọn eniyan 28 ku ni ikọlu si ijọba ibilẹ Guma ni Benue Feb 21-24, 2016: O le ni eniyan 500 to ku, ti ọgọọrọ si di alainile gbe nibi ikọlu si agbeegbe ijọba ibilẹ Agatu ni Benue January 24, 2017: Ko din ni eniyan 15 ti awọn Fulani darandaran ti gba ẹmi wọn ni ibi ikọlu awọn Fulani si agbeegbe naa.
Ìgbáyé-gbádùn ọmọ Nàìjíríà ní South Afrika ló jẹwá lógún- Buhari Akẹ́kọ̀ọ́ mẹ́fa, olúkọ̀ méjì ni wọ́n jígbé ní Kaduna Oríṣun àwòrán, facebook Àkọlé àwòrán, Musiliu Ayinde Akinsanya MC Oluọmọ Tajudeen Agbede ni o jẹ adari ẹgbẹ naa tẹlẹ ṣugbọn ti o ti wa di Igbakeji Aarẹ ẹgbẹ ni Orilẹ ede Naijiria.
Fún àpẹrẹ, nigbati iná ajónirun balẹ̀ ni àgọ́ Ológun ni Ikẹja ni ìlú Èkó ni bi ọdún mẹwa sẹhin.
Ninu orin ti o pe akọle rẹ ni ''Bigger'' ni mama agba Mojisọla Odegbami ti safihan ninu fidio naa, gẹgẹ bi ọbabinrin ilẹ Afrika, to si wọ aṣo alaranbara ilẹ Yoruba, pẹlu gele lori rẹ.
Olódodo ṣàkíyèsí ilé eniyan burúkú,eniyan burúkú sì bọ́ sinu ìparun.
‘Wo Kristi níhìn-ín,’ tabi ‘Wò ó lọ́hùn-ún,’ ẹ má gbàgbọ́.
Imọtoto fun gbogbo ẹni to ba n wọle to si n jade ninu ile iwe kọọkan.
Adonija sọ fún un pé, “Máa wọlé bọ̀; eniyan rere ni ìwọ, ó sì níláti jẹ́ pé ìròyìn rere ni ò ń mú bọ̀.
 ní ìpínlẹ ̀ kwara , àwọn ìlú yìí pọ ̀ jut i Ọ ̀ ṣun lọ .
Fidio tun ṣe afihan bi ọta ibọn ṣe ya obinrin naa ni ẹnu ati ẹrẹkẹ.
Ọkọ̀ aképo dàwó, iná ṣẹ́yọ ní Gowon Estate Ààye wà fún àgunbanirọ láti wọ sòkòtò labúlabú- Ọ̀gá àgbà Ẹ̀nh ẹ́ẹ̀nh!
O ni ijọba n fi akoko yii mura silẹ fun awọn eto lati ran awọn ara ilu lọwọ, ati pe o n fi akoko yii fun wọn laaye lati ra ounjẹ sile.
Wọn yan gomina ipinlẹ Eko, Kebbi, Bauchi, Plateau, Akwa-Ibom, Ebonyi, Enugu ati Kaduna gẹgẹ bi ọmọ igbimọ tuntun ọhun.
Ọlọrun fi wọ́n ṣe àpẹẹrẹ fún gbogbo eniyan nígbà tí wọ́n jìyà iná ajónirun.
Ẹwẹ, nigba ti BBC News Yoruba kan si ijọba ipinlẹ Ọyọ, kọmiṣọna feto iroyin ati aṣa, Ọmọwe Wasiu Ọlatubọsun ṣalaye pe ijọba n gbe igbesẹ lati tubọ mu ki okun ati koriya wa fun awọn agbofinro lati ṣiṣẹ wọn.
Nígbà náà ni ó wí fún mi pé, “Àwọn ilé ìdáná níbi tí àwọn alufaa tí óo wà níbi pẹpẹ yóo ti máa se ẹran ẹbọ àwọn eniyan mi nìyí.
O ni adajọ agba kan lawọn gbọ wi pe o fẹ rin irinajo naa ṣugbọn iyalẹnu lo jẹ nigba ti awọn gbọ pe olorin kan.
Bẹ́ẹ̀ ni ó kọ́ nǹkan rẹ̀ fún ara rẹ̀ ni kò sí ẹni tí ó lè dé ọ̀wọ̀ lónìí ti yóò bojúwo ẹ̀yìn tí àyípadà rere gbogbo tí ó dé lákòókò Ọlagbegi II kò ní yà lẹnu, bẹ́ẹ̀ ni kò sí ọmọ Yorùbá tí yòó gbọ́ kí Ọlọ́wwọ̀ yìí sọ̀rọ̀ láàrin àwọn ìgbìímọ̀ pàtàkì gbogbo tí ó máa ń lọ tí kò ní fi ọba yìí ṣe fọ́rífọ́rí.
O tenumo pe,“A ni lati ni ibasepo ti o yekooro pelu awon ile-ise yii kookan lati mu idagbasoke ba ile-ise ipese bebi ati eka asa lona imo ero igbalode lati mu igberu de ba asa ati oniruuru ise lorile-ede yii.
Àwọn mejeeji yóo sì fi orí ara wọn ru ẹ̀bi ẹ̀ṣẹ̀ wọn.
awon ti ọrọ eto aabo ekun Gusu naa kan.
OLUWA, gbogbo ìfẹ́ ọkàn mi ni o mọ̀,ìmí ẹ̀dùn mi kò sì pamọ́ fún ọ.
Sọ agbára rẹ jí,kí o sì wá gbà wá là.
awon  ile-ise  lati tete bẹrẹ si ni maa san owo ọhun.
Ayé ò fẹ́ kí a tálákà
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Bi ọjọ ṣe n gori ọjọ ni awọn sẹẹli n sọ agbara lati lọ awọn eroja ounjẹ bi i ọ̀rá ati ṣuga nu 5.
Ọrùn rẹ dàbí ilé-ìṣọ́ tí wọn fi eyín erin kọ́.
Ọmọ orilẹ-ede Cameroon kan to jẹ ọmọ ọdọ, Leujoe Koyemen Joel, lo gun ọga rẹ pa, nitori pe wọn jẹ ẹ lowo oṣu.
Àwọn àmì tó fi mọ̀ pé wọn ń fipá bá ọmọdébìnrin rẹ lòpọ̀ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Helen Paul sọ idi tó fi gba orúkọ ní kékere Adajọ L Nageswara Rao ati MR Shar sọ pe obinrin naa gba lati ni ibalopọ pẹlu dokita ọhun nitori pe o gbagbọ pe dokita ni erongba lati fẹ ẹ sile bi iyawo.
Ní ọjọ́ kan, nígbà tí ó bá àwọn ọmọ Israẹli jáde, ìjà bẹ́ sílẹ̀ láàrin òun ati ọkunrin kan, tí ó jẹ́ ọmọ Israẹli, ní ibùdó.
A kò gbọdọ̀ máa tẹ́ ara wa nìkan lọ́rùn.
“Ipade ohun waye laarin awon  toro kan gbangban lorile-ede yii, lati ijoba ipinle ti o fimo ijoba apapo, beesini alaga yan-yan ile-ise Dangote, Alhaji Aliko Dangote,  alaga ile-ise Bill & Melinda Gates,  ogbeni Bill Gates naa ko gbeyin ninu ipade naa.
Ati pé, àwọn ọmọ Lefi tí wọn ń gba ìdámẹ́wàá, ẹni tí yóo kú ni wọ́n.
Ileesẹ ọlọpaa sọ pe ọsẹ mẹfa ni iforúkọ silẹ fun eto igbani sisẹ naa yoo fi waye, laarin ọjọ kẹrinla, oṣu Keje, si ọjọ kẹtalelogun, oṣu Kẹjọ.
Nítorí àwọn ọmọ ayé yìí mọ ọ̀nà ọgbọ́n tí wọ́n fi ń bá ara wọn lò ju àwọn ọmọ ìmọ́lẹ̀ lọ.
Agbára wa kò ká àrùn Covid-19 mọ́ - Ìjọba ilẹ̀ Amẹrika Àwòrán nǹkan aláràmbarà oríṣiríṣi táwọn jàǹdùkú jí gbé lẹ̀yìn ìwọ́de EndSARS Àwọn tó mọ̀ nípa ìpànìyàn Lekki yóò fojú winá òfin - Sanwo-Olu sí Becky Anderson Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Àjẹ́ ké lánàá, ọmọ kú lónìí ni ọ̀rọ̀ Tinubu àti ìṣẹ̀lẹ̀ Lekki Tollgate - Bode George Olori ẹgbẹ Democrat nile igbimọ aṣofin, Chuck Schumer ni tirẹ ni bi eto idibo naa ṣe waye laarin ọjọ perete sí idibo ààrẹ n ṣafihan pe igbẹkẹle àwọn ará ìlú ninu ẹgbẹ Republican to jọ wọn lójú.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Duro Ladipọ, ìlúmọ̀ọ́ká òṣèré tíátà àti ọmọ àlúfà tí kò gbàgbé àṣà ìbílẹ̀ Ọ̀rọ̀ǹpọ̀tọ̀niyùn, Aláàfin obìnrin àkọ́kọ́ rèé, tó ní nǹkan ọkùnrin Baṣọ̀run Gáà, tó yan ọba mẹ́rin, pa ọba mẹ́rin àmọ́ ọba karùn-ún ló pa á Ni ilẹ Afirika agaga, WHO ni ilọpo mẹta ati aabọ (700%) ni ọwọja arun Ẹ̀yi fi le koko si lẹkun naa, pẹlu afikun pe o si seese ki iye ida naa tun lọ soke si, niwọn igba to jẹ pe ida kan ninu ida mẹwa awọn eeyan ti arun yii ba mu ni wọn maa n fi to awọn tọrọ kan leti.
O ni ọpọ awọn eeyan to n gbe lagbegbe ariwa Naijiria ni wọn n sọ ede larubawa bo tilẹ jẹ pe ede Gẹẹsi ni ede tofin Naijiria fontẹ lu gẹgẹ bi ede ajumọsọ.
Oríṣun àwòrán, @justempower Iroyin naa fikun pe awọn ọmọ ologun yii lo n yin ibọn soke soju ofurufu, lati fi dẹru ba awọn olugbe erekusu naa, ki wsn lee tete ko aasa wsn kuro lagbegbe naa.
Ó sọ èyí, ó fi ṣe àkàwé irú ikú tí yóo kú.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Òṣìṣẹ́ ẹka arinrinajo ọkọ̀ òfúrufú Nàìjíríà fẹ́ gún lè iyanṣẹlodi 'Ọdún 2019 pẹ̀lú àwọn àsọtẹ́lẹ̀ tó kó lọ́wọ́ dé' Ngige ni iṣẹ́ n lọ lọ́wọ́ lórí ǹkan ti ASUU n bèèrè Buhari ṣèlérí àti dẹ́kun Boko Haram pátápátá Amọṣa, akọwe agba ẹgbẹ oṣiṣẹ NLC, Peter Ozo-Esan ti ṣalaye pe gbogbo ẹgbẹ oṣiṣẹ ti bẹrẹ igbesẹ lati gbe iwọde ti yoo se ilẹkun mọ gbogbo ohun amuṣọrọ aje orilẹ-ede Naijiria bẹrẹ lati ọjọ kẹjọ, oṣu kinni, ọdun 2019.
“Wọn yóo fi aṣọ aláwọ̀ aró bo ọ̀pá fìtílà ati àwọn fìtílà rẹ̀ ati àwọn ohun tí à ń lò pẹlu rẹ̀ ati gbogbo ohun èlò òróró.
" Ìjọba Somalia gbẹ́sẹ̀ lé ìrìn àjò òkè òkun lẹ́yìn tí Coronavirus báwọn lálejò Ilé ẹjọ́ ti sún ìgbẹ́jọ́ si Ọjọ́-Bo̩ Wọ́n gbé òkú ọgá iléẹ̀kọ́ àti òṣìṣẹ́ méjì míì tó kú nínú ìbúgbàmù lọ sílé ìgbókùsí ológun ojú omi l‘Eko Ajá kìí rorò kó ṣọ́ ojú'lé méjì, kò tọ́ ọ́ sí Alaafin láti dásí ọ̀rọ̀ ọba l‘Ekiti - Peter Fatomilọla Oṣere naa ni ṣaka lara oun da bayii ti ko si si apẹrẹ arun lara oun, ṣugbọn o ni oun ti wa ni ipamọ lati igba ti oun ti woye pe o ṣeṣe ki oun ti ko arun naa.
Ní àkókò rẹ̀, alaafia wà ní ilẹ̀ náà fún ọdún mẹ́wàá.
Ṣùgbọ́n àwa ọmọ ènìyàn a kìí yé kọjá àyè wa.
 Ètò ìmúlò yìí ṣe àlàyé nípa bí a ṣe fẹ ́ kí oníṣẹ ́ ṣe máa dojú kọ ìṣòro tí wọ ́ n bá yọjú .
Nigba naa ni o gbe akori, Nigeria.
Ẹgbẹ awon akoroyin Naijiria ti a mọ si Nigerian Union of Journalists ti paṣẹ pe ki ajọ NBC tun ero wọn pa.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Àtẹlẹwọ ẹni kò le tan ni jẹ Oriṣi iṣẹ ọwọ bii aránṣọ, irun gigẹ, irun dídì, kafinta àti bẹẹ bẹẹ lọ.
Lọdun 1969 ni Oladejọ Okediji gbe iwe aja lo lẹru jade lati ile iṣẹ Longmans of Nigeria ni Ibadan ni ipinlẹ Oyo ni eyi ti wọn tun tẹ ni ọdun, 1981, 1996, ati ni 2000 lati ile iṣe Longman ni Ikeja.
Lọtẹ yii ẹwẹ, oṣere ẹgbẹ rẹ naa lo tun fẹ.
Ni ọjọ kẹtadinlogun oṣu kẹrin ọdun 2019 ni Ọba ana waja eleyi to ṣilẹkun fun awọn idile oye atawọn ọmọ oye lati du ipo naa.
A o maa ẹkunrẹrẹ iroyin yii wa fun yin.
Oríṣun àwòrán, Twitter/TemiOanu Loju opo rẹ ni Twitter, o fi ọrọ idupẹ imoore awọn to yan sipo gẹgẹ bi aṣoju ọdọ.
Kí ni ìwọ sì gbẹ́kẹ̀lé tí ọ̀ràn náà fi ṣeé ṣe?
Photos: Eagles in Training ahead of tomorrow’s clash #Training #SoarSuperEagles #NGA #Team9jaStrong #NGAARG pic.
O ni awọn ọlọkada gbọdọ maa fi suuru rin lasiko ojo yii paapaa ti ọpọ opopona ko dara mọ bayii.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Mother Language Day: Ẹgbẹ́ Akọ́mọlédè l‘Eko ṣe káre sí BBC Yorùbá fún àgbéga àṣà 22 Èrèlè 2020 Yinni Yinni, kẹni lee se omiran ni, bẹẹ si ni ku isẹ lo n mu ki ori onisẹ ya.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ibadan Drivers Clash: Àjọ OYRTMA sọ ohun tó fa wàhálà láàrín àwọn awakọ̀ 23 Ọ̀wàrà 2019 Oríṣun àwòrán, Tajudeen Olajide Àkọlé àwòrán, Awọn awakọ Micra Ajọ to n ri si igbokegbodo oju popo nipinlẹ Oyo, OYRTMA ti sọ pe, aitẹle ofin awọn awakọ lo ṣokunfa rogbodiyan to waye laarin ajọ naa ati awọn awakọ lagbegbe Sango, nilu Ibadan.
Ṣugbọn yóo fi ògo, ọlá ati alaafia fún gbogbo àwọn tí ó ń ṣe rere.
Lẹ́yìn náà, ó bí obinrin kan, ó sọ ọ́ ní Dina.
Ile-ise Ologun orile ede Naijiria ti ri oku ogagun Idris Alkali ti won n wa.
láti dá oríṣìíríṣìí àrà sí ara òkúta ati láti tò ó, láti gbẹ́ igi ati láti fi oríṣìíríṣìí ohun èlò ṣe iṣẹ́ ọnà.
fẹ rọ ọ lati yan awon adajo márùn
Bi o ti le je pe, Marseille kopa ribiribi ni saa akoko ifesewonse naa, sugbon omi poju oka lo, leyin ti won fori bale fun Madrid ki saa ohun o to wa si ipari.
arthur robert ashe , jr .
Amọṣa ko jọ pe eto naa mulẹ rara.
Gbajugbaja akọrin Tungba nni, Yinka Ayefẹlẹ ti kigbe sita faraye pe oun ko bi ibẹta gẹgẹ bi awọn eeyan kan ti n tan iroyin naa kalẹ lawọn oju opo ikansiraẹni lori ayelujara.
Lẹ́yìn tí wọ́n ti di kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ náà ní gàárì tán, ó sọ fún iranṣẹ náà pé, “Jẹ́ kí kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ náà máa sáré dáradára, kí ó má sì dẹ̀rìn, àfi bí mo bá sọ pé kí ó má sáré mọ́.
Angẹli náà wọlé tọ Maria lọ, ó kí i, ó ní “Alaafia ni fún ọ!
Wọ́n lé wọn gba ibi gẹ̀rẹ́gẹ̀rẹ́ Beti Horoni, wọ́n sì pa wọ́n títí dé Aseka ati Makeda.
Tolulope Arotile: Ẹ wo ọgbọ́n tí wọ́n tò pọ̀ láti túfọ̀ ikú Tolu fún bàbá àti ìyá rẹ̀ Bí ẹgbẹ́ One Million Boys ṣe bẹ̀rẹ̀ rèé àti ọṣẹ́ tó ṣe n'Ibadan Gómìnà ìpińlẹ̀ Kogi, Yahaya Bello ni yóò jẹ́ alága ìgbìmọ̀ ìdìbò abẹ́lé, nígbà ti Emperor Chris Baywood Ibe yóò jẹ́ alága ìgbìmọ̀ to ń pètù sí ààwọ̀ ìdìbò abẹ́lé.
4m Àádọ́ta Náírà tí báńkì ń yọ nínú owó ìpamọ́ oníbàárà kò tọ̀nà - Iléejọ́ Ìjọba ìpínlẹ̀ Ondo kéde òfin konile-o-gbele ní Ode ati Ishinigbo lẹ̀yìn rògbòdìyàn tó wáyé níbẹ̀ Wọ́n ti rí Ọ̀pá Àṣẹ ilé aṣòfin ìpínlẹ̀ Ogun tí àwọn jàndùkú jí gbé nípinlẹ̀ Eko o!
ki wọn ma gbe igbesẹ ati yọ Gomina ni ipo, ki wọn ba Gomina naa sọrọ lati
Wọ́n pada sí Jerusalẹmu láti orí òkè tí à ń pè ní Òkè Olifi.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Eduardo: Mo ń jí mọ́tò pẹ̀lú àwọn ọ̀rẹ́ mi nítorí pé mo fẹ́ di 'Big boy' Bẹẹ, lo tun fikun un pe Aarẹ Buhari sọ fun olubadamọran lori eto aabo orilẹ-ede Naijiria lori bi arabinrin naa ti lọ ṣe iṣẹ ayawòrán ni ayẹyẹ Durban to waye ni Bauchi.
“Bí mo bá fi ohunkohun pọ́n talaka lójú rí,tabi kí n fi opó sílẹ̀ ninu àìní,
Wọ́n bá ṣe àmì sí àwọn ẹlẹgbẹ́ wọn tí ó wà ninu ọkọ̀ keji pé kí wọ́n wá ràn wọ́n lọ́wọ́.
Àwọn àjèjì darandaran ń wọ ìpínlẹ̀ Oyo àti Ogun lọ́gọ́ọ̀rọ̀ - Amotekun Covid-19 pa Ọlọ́lá Akin Olugbade, ẹ wo dúkìá jaburata tó fisílẹ̀ NCDC àti NYSC bẹ̀rẹ̀ ìpàdé lórí ṣíṣí ìpàgọ́ àwọn àgùnbánirọ̀ Ìjọba ìpińlẹ̀ Kwara dá owó tí àwọn obìrin 25 fi kọ́ ilé Ẹ̀kọ́ fún àwọn ọmọ wọ́n pada Ìjọba àpapọ̀ pàṣẹ kí ilé-ẹ̀kọ́ wọlé ní ọjọ́ 18, oṣù kíní ọdún.
 orin lè wá fún lílò ara-ẹni tàbí tí àwùjọ lápapọ ̀ .
Ọpẹlọpẹ Oludamọran si gomina feto iroyin, Idowu Ajanaku, to dasi ọrọ naa lo mu ki Akọwe agba fun ileesẹ ọrọ ayika ko awọn irinsẹ akọroyin agba wa silẹ.
21 Sẹ́rẹ́ 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 24 Sẹ́rẹ́ 2020 Àkọlé àwòrán, Àwọn tí ìṣẹ̀lẹ̀ iná náà ṣe ojú rẹ̀ ní ó bẹrẹ ní déédé ago márun un ní Ọjọ́ Eti kí àwọn panapana to dé.
Eyi ti sọ iye awsn eeyan ti wọn ti kede pẹlu arun naa bayii di marundinlogoje, (135) Ààrẹ Buhari: Kò ní sí lilọ bibọ ni Eko,Ogun ati Abuja fọjọ́ mẹ́rìnlá gbako Èṣi àyẹ̀wò jáde, Gómìnà Bauchi ti ní aàrùn coronavirus báyìí Àjọṣepọ̀ wo ló wà láàrín Coronavirus àti Chloroquine?
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Footballers: ìkà láwọn aṣojú agbábọ̀ọ̀lù míì lágbàyé Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Ohun tí ó yẹ yín ni pé kí ẹ ṣí ọkàn yín payá sí wa.
Ṣugbọn àwọn arakunrin mi tí a jọ lọ dáyàjá àwọn ọmọ Israẹli, ṣugbọn èmi fi tọkàntọkàn tẹ̀lé OLUWA Ọlọrun mi.
Bẹ́ẹ̀ ni èmi ọba, tí orúkọ mi ń jẹ́ OLUWA àwọn ọmọ ogun sọ.
Agbẹmusọ ajọ ọlọpaa pari ọrọ rẹ pe, ijọba ti wọgile adehun iṣe naa ṣugbọn Duncan Mighty kọ lati da owo pada.
Super Falcons: Wọn nfi ilọkulọ ibalopọ lọ wa Oral Sex: Bóo bá ń gba ẹnu ní ìbálòpọ̀, wo àìsàn tóo lè kó lójú ara rẹ Àjọ ọlọpàá Eko kédé pé ìbalòpọ̀ nítà kò bójúmu Àwọn àmì tó fi mọ̀ pé wọn ń fipá bá ọmọdébìnrin rẹ lòpọ̀ Wo àànfàní ‘Masturbation’, fífún ara rẹ̀ ní adùn ìbálòpọ̀ O tun le mojuto ki nkan ọmọkunrin o ma ṣiṣẹ.
Jesu mọ ohun tí wọn ń sọ, nítorí náà, ó wí fún wọn pé, “Kí ni ẹ̀ ń da obinrin yìí láàmú sí?
Ọ̀rọ̀ ọ̀hún pa mí ní ẹ̀rin lọ́jọ́ náà kì í ṣe díẹ̀.
Trikytee àti Ozo ní wọ́n di ẹrù ilé lé lórí nilé bbnaija lọ́sẹ̀ yìí A fẹ́ gbé orò láti lé àwọn ajínigbé kùrò ní ìpínlẹ̀ Oyo- Áṣẹyin ti Iṣẹyin Ọwọ́ ọlọ́pàá tẹ afurasí ọkùnrin tó gé akẹ́kọ̀ọ́ ọ̀rẹ́bìnrin rẹ̀ wẹ́lẹ́ wẹ́lẹ́ fún òògùn owó ní Ikorodu Ilé ìjọsìn lè bẹ̀rẹ̀ ìsìn àárín ọ̀sẹ̀ padà, Mọ́sáláṣí àti Ṣọ́ọ̀ṣì lé gba iye èèyàn tó wù wọ́n ṣùgbọ́n.
wo àwọn nọ́mba ọlọ́pàá tí o lé pé láti mọ ọ̀nà àbáyọ Bí o bá ń se N-Power tóo sì ti ríṣẹ́ sí ibòmíràn, olè ni ọ́!
O fi kun un pe ikọlu ti awọn ọdọ ṣe si aafin jẹ ohun to dun ni gan o si jẹ nkan iyalẹnu ṣugbọn ibinu o ṣe nkankan tori pe atawọn ọmọ to ba nkan jẹ, ati gbogbo ọmọ Ogbomoso, ọmọ Kabiyesi ni gbogbo wọn."
Ẹ jẹ́ kí èrò ọkàn yín sí gbogbo eniyan máa jẹ́ rere.
NYSC ní Adeosun kòwé ransẹ́ láti gbààyè 'A sinmi ìwádìí lóri Kemi Adeosun' Gẹ́gẹ́ bi ile isẹ Premium Times ti sọ, ọ̀gbẹ́ni Shittu nígbà ti wọ́n kàn sii lati se ìwádìí ọ̀rs naa sọ pe, ko sí irọ́ ninu oun ti wọn sọ pe oun kọ̀ ni iwe ẹri agunbanirọ.
O kere tan eniyan mẹ́rìndínlọ́gọ́rin lo padanu emi won, ti awon miiran si farapa yanayana ninu ikolu iji lile ti o waye ni ariwa gusuu orile-ede India nipinle Rajasthan ati Uttar Pradesh.
Ṣugbọn àwọn pidánpidán ilẹ̀ Ijipti lo ọgbọ́n idán wọn, àwọn náà ṣe bí Mose ati Aaroni ti ṣe, tí ó fi jẹ́ pé ọkàn Farao túbọ̀ yigbì sí i, kò sì gbọ́ ohun tí Mose ati Aaroni wí, gẹ́gẹ́ bí OLUWA ti sọ tẹ́lẹ̀.
Ó bá fi okùn kan sọ̀ wọ́n kalẹ̀ láti ojú fèrèsé, nítorí pé àkọ́pọ̀ mọ́ odi ìlú ni wọ́n kọ́ ilé rẹ̀, inú odi yìí ni ó sì ń gbé.
Ìgbà tí a míra báyìí tán, a múra ó di ọ̀nà ọ̀run Àpáàdì.
Sugbọn ni aarin ọgọta ọdun ti Naijiria ti n tukọ ara rẹ lai si ọwọ awọn eebo amunisin nibẹ, oju ti ri.
Oludari Ajọ LASEMA ni ipinlẹ Eko, Olufemi Oke-Osanyintolu ninu atẹjade to fi sita ni, ijamba ọkọ oju omi naa waye nitori wọn rin lasiko ti okunkun ti ṣu, eleyii to tako ofin irinna ọkọ loju omi.
Fi nǹkan bò wọ́n lójú,kí wọn má baà ríran,kí wọn má sì gbọ́ràn,kí òye má baà yé wọn,kí wọn má baà yipada,kí wọn sì rí ìwòsàn.
Kò sí ní ilé iṣẹ́ ìgbóhùnsáfẹ́fẹ́ náà
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Temitope Akinnusi: Ọ̀pọ̀ iléeṣẹ́ ló takú láti gbà mí síṣẹ́ torí mo ní ojú kan Asiko yii naa si ni irufẹ ibeere yii n waye nilu Ibadan, eyi to papa di Ogun Agbekoya.
Odion Ighalo bale sipinle Eko lati ilu London lojo isegun(Tuesday), lati darapo mo awon akegbe re fun igbaradi  ifesewonse olorejore eyi ti iko ohun yoo gba pelu iko agbaboolu DR Congo.
g levetis kú ní ọdún 1978 .
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Mo ní àṣírí ìyá tó fẹ́ ọmọ rẹ̀ láya fún Boko Haram torí ẹbí rẹ̀' Awọn ẹyẹle ti wọn n kopa ninu ereeje le bimọ titi ti wọn yoo fi pe ọdun mẹwaa.
A tún mọ̀ pé Ọmọ Ọlọrun ti dé, ó ti fún wa ní làákàyè kí á lè mọ ẹni Òtítọ́.
nítorí ẹ̀jẹ̀ mààlúù ati ti ewúrẹ́ kò lè kó ẹ̀ṣẹ̀ lọ.
Chelsea yoo maa pada si agbami bọọlu Champions league lẹyin ti wọn fi saa ọdun to kọja gba bọọlu ni agbami Europa.
Tínú ẹ̀ mọ́, tó ya wòólì
Ondo Kidnap: Ọlọ́pàá Ondo ní àwọn ti rí ẹníkan padà nínú mẹ́jọ tí wọ́n ń wà nínú ọkọ̀
Bí inú ẹnikẹ́ni ninu yín bá dùn, kí olúwarẹ̀ máa kọ orin ìyìn.
Olè gbé òrùka ìgbéyàwó mì ní Eko Agolo akẹ́rù Apapa kò pa ènìyàn ṣùgbọ́n ó ba ọ̀pọ̀ ọkọ̀ jẹ́- Ọ̀ga RRS Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ladoja Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Wákàtí méje ni Monica lò níwájú ìgbìmọ̀ ọ̀hún pẹ̀lú àwọn agbẹjọ́rò rẹ̀.
kí baba ati ìyá rẹ̀ mú un wá siwaju àwọn àgbààgbà ìlú náà, ní ẹnu bodè ìlú tí ó ń gbé, 
Nigba to n dahun lori iwe akosile kan lori  ipade atunse si egbe Ohaneze to waye lojo Aje,ni Awaka, ni ipinle Anambra.
[àmì náà ń sọ pé: Ẹ̀KA ÌṢÈDÁJỌ́ TI ORÍLẸ̀-ÈDÈE RUSSIA Ò RÍ ÀWỌN AṢE-ÌBÁLÒPỌ̀-AKỌ-ÀTI-AKỌ NÍ CHECHYA.
 orí yìí ni a ti mọ ìdí tí Ọ ̀ sanyìnnínbí fi fẹ ́ ràn orímóògùnjẹ ́ .
Mo jókòó bí ọba, mò ń tọ́ wọn sọ́nà,mo dàbí ọba láàrin àwọn ọmọ ogun rẹ̀,bí olùtùnú fún oníròbìnújẹ́.
A ni igbagbo pe, ki o to di odun 2020 , oke aimoye eniyan , ni yoo maa ri ise se.
” OLUWA tún dáhùn pé, “Nítorí ti ogún eniyan, n kò ní pa á run.
Àwọn ìjòyè Isakari náà bá Debora wá,àwọn ọmọ Isakari jẹ́ olóòótọ́ sí Baraki,wọ́n sì dà tẹ̀lé e lẹ́yìn lọ sí àfonífojì.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, World Diabetes Day: Ọdún kọkandinlogun ti mo ti wà lẹ́nu itọ ṣúgà nìyí Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Àwọn aṣọ tí wọn yóo rán náà nìwọ̀nyí; ọ̀kan fún ìgbàyà, ati ẹ̀wù efodu, ẹ̀wù àwọ̀kanlẹ̀ kan, ati ẹ̀wù àwọ̀lékè kan tí a ṣe iṣẹ́ ọnà sí; fìlà kan, ati àmùrè.
Mo mọ ìjáde ati ìwọlé rẹ,ati inú tí ò ń bá mi bí.
O ni pé ọga àgba patapata lori ètò ààbo ni ilé iṣẹ́ náà lo kan sí àwọn ọlọpàá pé àwọn ajílẹ̀ kan din ní ibi ti wọ́n ń ko ẹ̀ru si ti wọ́n si mú aṣọna tó wà lẹ́nu iṣẹ́ lọjọ ti ìṣẹ̀lẹ̀ náà ṣẹ̀ láti wa wi tẹnu rẹ̀.
Ninu ọrọ to ba Akọroyin BBC, Thomas Naadi sọ, oludari ajọ to n risi katakara epo lorilẹede Ghana, ọgbẹni Duncan Amoah ni wahala wa lori eto okoowo ọrọ epo.
Coronavirus: Ó dá mi lójú pé ìwá ìbàjẹ́ ló fa àrùn yìí - Ọ̀gá àgbá EFCC Àwọn Ìyá àwọn ọmọ Yahoo ti ń kórajọ láti dá ẹgbẹ́ sílẹ̀ - EFCC Àwọ́n kan ń ràgà bo Diezani nílẹ̀ Gẹ̀ẹ́sì láti jẹ́jọ́ ní Nàíjíríà àmọ́ á gbe wá - EFCC Magu ati Keyamo ri‘binu ijọba Lati ọdun 2003 ti ajọ EFCC ti bẹrẹ, Alaga mẹrin lo ti ni.
3 Ẹrẹ̀nà 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 3 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 5 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Ní ọdún kọkandinlogoji tí Asaraya ti jọba ní Juda ni Ṣalumu, ọmọ Jabeṣi, jọba lórí Israẹli, ní Samaria, ó wà lórí oyè fún oṣù kan.
Abimeleki bá wí fún Isaaki pé, “Kúrò lọ́dọ̀ wa, nítorí pé o ti lágbára jù wá lọ.
Awon die ni won je alatako ijoba tiwa-n-tiwa.
m ) pẹ ̀ lú diana williams .
Wọ́n gba ìlú Heburoni, wọ́n sì fi idà pa ọba ìlú náà ati gbogbo àwọn tí wọn ń gbé inú rẹ̀ láìku ẹnìkan, gẹ́gẹ́ bí wọ́n ti ṣe sí ìlú Egiloni tí wọn parun láìku ẹnìkan.
Nitori naa, ẹyin ti Naira Marley, nibo lẹ wa?
Sani Bello ti ipinle Niger ati  akowe
O ni awọn ọmọ olori ilu lẹtọ lati ṣe igbeyawo ni asiko to yẹ, ko si ni nnkan ṣe pẹlu boya awọn eeyan ilu fẹran ijọba awọn obi wọn tabi bẹẹ kọ.
Àwọn wọnyi ni yóo lọ sinu ìyà àìlópin.
 Ìrírí tó jẹ mọ ́ pé kí ojú ibití a ti fún ni ní àbẹ ́ rẹ ́ náà má a pupa yòò , kó sì má a dun ni a má a wáyé lára àwọn ènìyàn tó tó bíi 25 sí 85 % nínú àwọn tó gba àjẹsára náà .
Awọn miran gba pé oju meji ni Buhari fi idajọ iditẹ gbajọba rẹ ṣe laarin oloogbe Ekwueme ati Shehu Shagari.
Zulkiflu lo so oro yii di mimo lasiko ti ile ise naa n se afihan awon eru
Wọn n pe wọn ni telomeres.
"Ileesẹ BBC ni "" ohun to nkọni lominu gbaa ni isẹlẹ yii, ti a si nbeere alaye ni kiakia lọwọ awọn alasẹ idi ti wọn fi se bẹẹ."
Ìwọ a-rí-tẹni-mọ̀-ọ́n-wí, kọ́kọ́ yọ ìtì igi tí ó wà lójú rẹ kúrò; nígbà náà o óo ríran kedere láti lè yọ ẹ̀ẹ́rún igi tí ó wà lójú arakunrin rẹ.
8 617 Erekusu Barbados 7 2.
Ọpolopo ikilọ ni o ti jade fawọn ọmọ Naijiria ti wọn ro pe ti awọn ba tun MMM ṣe, boya awọn a ri owo wọn tẹlẹ to ti rì sinu ẹ gba pada.
Ẹ̀yin ọmọ ìta tó ní Funke Akindele ra ilé fún mi, irọ́ ni o - Ajirebi Ìjọba ilẹ̀ Turkey yí ilé Ìṣẹ̀mbáyé tó ti lo ọdún 1,500 padà sí Mọ́ṣáláṣí Awọn ẹbi Kolapo Ishola, nigba ti wọn n fesi ninu atẹjade ti wọn fi sita ni, irọ patapata ni olori oṣiṣẹ Ajimobi pa.
Ní ìrọ̀lẹ́ ọjọ́ kan, ó lọ ṣe àṣàrò ninu pápá, ojú tí ó gbé sókè, ó rí i tí àwọn ràkúnmí ń bọ̀.
Lẹ́yìn èyí, ni Nahaṣi, ọba Amoni kú, Hanuni, ọmọ rẹ̀ sì gorí oyè.
Nígbà tí ọba Israẹli ka ìwé náà ó fa aṣọ rẹ̀ ya láti fi ìbẹ̀rù rẹ̀ hàn, ó sì wí pé, “Èmi ha í ṣe Ọlọrun tí ó ní agbára ikú ati ìyè bí, tí ọba Siria fi rò wí pé mo lè wo eniyan sàn kúrò ninu ẹ̀tẹ̀?
àwọn olè tabi àwọn olójúkòkòrò, àwọn ọ̀mùtí-para tabi àwọn abanijẹ́, tabi àwọn oníjìbìtì, tí yóo jogún ìjọba Ọlọrun.
Oríṣun àwòrán, LASEMA Ọga LASEMA ni ajọ naa ṣiṣẹ takuntakun lati rii pe ijamba ọkọ ọhun ko da sunkẹrẹ fakẹrẹ silẹ lopopona Eko si Ibadan.
O ni ki won gba awon omo PDP ti won darapo mo egbe APC wole.
 Àwọn àríwísí ọlọ ́ kan-ò-jọ ̀ kan nípa ìṣakọ tàbí ìṣabo nínú ọmọ awo ifá ni ó rọ ̀ mọ ́ ìtàn oríṣiríṣi tí a gbọ ́ nípa ifá fúnra rẹ ̀ .
Oríṣun àwòrán, @others Àkọlé àwòrán, Opọ n ṣe idaro Oladejọ Okediji to lọ Oríṣun àwòrán, @others Àkọlé àwòrán, Didun ni iranti agba ọjẹ onkọwe yii ni ọpọ eeyan n sọ lori ayelujara Onigege wura ni ọgbọn ikọwe Okediji dabi ki a da ti ọpọ agba ọjẹ onkọwe papọ ni Dele Momodu, ọkan lara awọn to kọkọ ṣọfọ agba ọjẹ onkọwe yii lori ayelujara ni o ku diẹ ki baba pe aadọrun pẹlu awọn apẹẹrẹ iwe to ti kọ Die lara awọn aworan lasiko isinku Baba Oladejọ Okediji ni Oyo: Oríṣun àwòrán, @Rebecca Àkọlé àwòrán, Awọn onkọwe ede Yoruba nibi igbalejo lẹyin eto isinku Baba Okediji ni Oyo Wo àwòdamiẹnu àwòrán Mọ́ṣáláṣí Ànọ́bì ní Medina!
Ẹ yìn ín, ọ̀run tí ó ga jùlọ;yìn ín, omi tí ó wà lójú ọ̀run.
Ètò ẹ̀kọ́, ìlera, ètò ààbò àti ìdàgbàsókè, ètò ọrọ̀ ajé.
Gbogbo ènìyàn ló ní è̩tó̩ sí ààbò tó dó̩gba kúrò ló̩wó̩ ìyàsó̩tò̩ yòówù tí ìbáà lòdì sí ìkéde yìí àti è̩tó̩ kúrò ló̩wó̩ gbogbo ohun tó bá lè ti ènìyàn láti s̩e irú ìyàsó̩tò̩ bé̩è̩.
Koda, iroyin sọ pe gomina ipinlẹ Kogi, Yahaya Bello paṣẹ pe ki iwadii o waye lori ẹsun naa, to si ni ki kọmisana lọ ko lọ rọọkun nile naa.
Iji nla to ja lori omi naa lasiko irinajo wọn ni wọn ni o ṣokunfa idojude ọkọ naa.
Mo tún rí ẹranko mìíràn tí ó jáde láti inú ilẹ̀.
ni atunṣe si ofin naa yoo le jẹ ki awọn ijọba ibilẹ naa le maa kopa ninu
Ifẹsẹwọnsẹ naa to jẹ akọkọ awọn mejeeji ni saa bọọlu yi gbona jọin jọin ti VAR si gbe Lampard ju Mourinho lọ.
Ṣugbọn kékeré nìyí ninu agbára rẹ̀,díẹ̀ ni a tíì gbọ́ nípa iṣẹ́ rẹ̀!
Ileeṣẹ ọlọpaa ni ipinlẹ mẹtala ni ẹkọ igbaradi wọn yoo ti waye.
Ìmọ̀ràn níí fìdí ètò múlẹ̀,gba ìtọ́sọ́nà kí o tó lọ jagun.
"2017 kan naa ni iroyin tan kaakiri wipe, Akindele loyun ṣugbọn o ti padanu rẹ, ni ọpọlọpọ ba n daro wipe boya ""iran"" wooli naa ti n wa si imuṣẹ ni."
Ohun ti a fi lee pe e ni oniroyin ni wi pe iṣẹ to fi bẹrẹ ẹkọ kika ni ibẹrẹ ile iwe giga rẹ̀ ni imọ nipa iṣẹ iroyin.
Amosun n fẹ ki Adekunle Akinlade dije ṣugbọn Dapọ Abiọdun ni awọn adari ẹgbẹ oṣelu naa n fẹ.
Amosa, a ko lee sọ nipato ohun
Wo àwọn ọ̀nà míràn tí o leè gbà lẹ́yìn tí wọ́n bá ti afára Third Mainland Kí ló pa Bobrisky àti Olorì Aláàfin Oyo pọ̀?
Eyi lo mu ki ọrọ naa di boolọ o yago.
8 Agẹmo 2019 Oríṣun àwòrán, Google Àkọlé àwòrán, Iroyin gbe e jade wi pe osisẹ to wa ni ipo Assistant Superintendent wa si olu ile isẹ naa pẹlu aso oye Comptroller-General.
Nipa iroyin yii: Matthew Caruana Galizia jẹ akọroyin oluwadii ati ọmọ akọroyin Daphne Caruana Galizia, wi wọn fi ado oloro inu ọkọ pa ni oṣu kẹwaa ọdun 2017.
O Fagunwa, ẹni to jẹ ilumọọka onkọwe silẹ bora nilu Bida nipinlẹ Niger lẹni ọdun ọgọta ọdun.
Nítorí náà ẹ̀yin eniyan, ẹ ṣara gírí, nítorí mo gba Ọlọrun gbọ́ pé bí ó ti sọ fún mi ni yóo rí.
Bayii, ijọba ipinlẹ Ogun ti kede pe o ti bẹ silẹ nibẹ ni eyi to ti mu ẹmi eniyan marun un lọ.
O ni arakunrin naa ni ki oun ma binu lasiko ipade oniroyin ọhun o si tun fi ọrọ ẹbẹ rẹ ranṣẹ lẹyin ipade kan naa mo si ti gba ẹbẹ rẹ pẹlu ọkan kan a si ti n ba igbesi aye lọ pada.
waye lẹyin ti awọn oludibo ba yọ ẹni to wa nipo kuro nitori magomago tabi
Naijiria gbiyanju agbara wọn ṣugbọn aṣọ ko ba Ọmọyẹ mọ, Ọmọyẹ ti rin hoho wọja, ami ayo kan ṣoṣo ni wọn le da pada.
NCDC lo fi ikede naa lede loju opo Twitter rẹ, ti apapọ awọn to ti ni arun naa ni Naijiria ti wa di 13464 bayii.
Mo tún rí ohun tí ó dàbí òkun dígí tí iná wà ninu rẹ̀.
Àwọn òńkọ̀wé ń dárò Okediji tí kò bá pé ẹni ọdún 90 lókè eèpẹ̀ lónìí Kini igbẹyin gbajugbaja onkọrin Cobain?
Wọ́n ń sọ pé,“Bóyá yóo bọ́ sọ́wọ́ ẹlẹ́tàn,ọwọ́ wa yóo sì tẹ̀ ẹ́;a óo sì gbẹ̀san lára rẹ̀.
Champions League – IPELE IKO MERINDINLOGUN February 1320:45 Basel ?
Awọn oluwadii naa sọ siwaju pe orun orin yii maa n ran awọn ọmọ ti wọn bi nigba toṣu wọn ko tii pe lọwọ lati dagba.
2 177577 Orilẹede South Korea 549 1.
 Ó jẹ ́ kí ilẹ ̀ r eẹ ̀ dara pọ ̀ mọ ́ european union àti nato ní 2004 .
Ilé alájà méjì wó lu ọmọ mẹ́rin ni Bariga Ipele kan náà kó ní Yorùbá àti ẹgbẹ́ darandaran Miyetti Allah wà- Afẹnifẹre Ẹni mẹ́ta gbé Buhari lọ sílé ẹjọ́ nítorí pé ó parọ́ ìwé ẹ̀rí rẹ̀ fún àjọ INEC Awọn ẹsun naa ni i ṣe pẹlu pipaniyan lọna aitọ, ipejọpọ ti ko bofin mu ati dida omi alaafia ilu ru ati bẹẹ bẹẹ lọ.
Ẹmi mejila ṣofo ninu ijamba ọkọ l'ondo 'Mo mọ bí Boko Haram ṣe bẹ̀rẹ̀' Ọlọpaa ni awọn ṣi n wa awakọ naa ati ikeji rẹ to sa lọ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ọlọ́pàá Ondo: A bá òkú ọmọ igbákeji gómínà tẹ́lẹ̀rí nílé ọ̀rẹ́kùnrin rẹ̀ Ilu Eko ni a gbọ pe ọkọ akero naa ti n bọ ti ọkọ ajagbe naa si n bọ lati Ọwọ.
O ku nigba ti wọn n gbe lọ si ile iwosan miran.
Ní ọjọ́ kan, Sara rí ọmọ tí Hagari, ará Ijipti bí fún Abrahamu, níbi tí ó ti ń bá Isaaki, ọmọ rẹ̀, ṣeré.
Ṣugbọn bí o kò bá dá a pada, mọ̀ dájú pé o óo kú, àtìwọ ati gbogbo àwọn eniyan rẹ.
Ọrọ iwọde ENDSARS ko yọ awọn agbabọọlu paapa silẹ.
Aráàlú faraya torí èèyàn 63 tó dèrò ọ̀run ní Gúúṣù Kàdúná láàrin ọ̀sẹ̀ kan Saaju la ti mu iroyin wa fun yin pe, ariwo ẹkun tun sọ ni Guusu ipinlẹ Kaduna lopin ọsẹ nigba ti awọn gende agbebọn tun se ọsẹ.
Gbogbo àwọn eniyan ni yóo gbọ́, ẹ̀rù yóo bà wọ́n; ẹnikẹ́ni kò sì ní ṣe bẹ́ẹ̀ mọ́.
Eyi ko ṣẹyin bi Kanu ti wọn duro fun ko ṣe yọju sile ẹjọ l'ọjọ kẹtala, oṣu Kọkanla ti igbẹjọ rẹ yẹ ko waye.
Má kọ̀wé fipò sílẹ̀, àwọn àgbààgbà Yorùbá sọ fún Osinbajo Ajọ FRSC ṣèlérí láti fọwọ́ òfín mu eegun tó bá tasẹ̀ àgẹ̀rẹ̀ lásìkò ọdún Keresi Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Èmi gan máa ń béèrè lọ́wọ́ ara mi pé ta ni Wole Soyinka gangan' Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 3 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 5 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Haruna ni agbegbe Isolo l'oun fẹ gbe, ati pe oun ti san ẹgbẹrun meje naira fun owo ile fun ibi t'oun fẹ de si nibẹ.
Ó bá dìde lójú oorun, ó bá afẹ́fẹ́ wí, ó wí fún òkun pé, “Pa rọ́rọ́.
Fún irú nkan báyìí oríṣiríṣi orílẹ̀-èdè lọ ní àṣà tí wọn.
“Àbí ọmọ kinniun a máa bú ninu ihò rẹ̀ láìṣe pé ọwọ́ rẹ̀ ti ba nǹkan?
Wọn gba imọran pe ki awọn ọdọ maa ni isẹ lapa ki wọn si ma pa ọmọ jọ silẹ lai lagbara ati le pese itọju fun wọn.
6 1413 Orilẹede Vietnam 35 0.
Chukwu so pe won mu Lawan   ni atipo ibi to ti darapo mo awon to wa nibe.
Agba Inaki n ṣe'daro Alagba Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ogbologbo ijapa l'aafin Sọun Ó di agbábóòlù mẹta tí a ti pàdánù láàárín ọjọ meji - NFF Ìjọba máa ní láti dá òsìsẹ́ dúró kí wọ́n tó lè san gbedéke owó osù tí ẹ fẹ́ - Ngige Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Imam tó ṣí Mọ́ṣálásì fáwọn Krístẹ́nì sọ ìdí tí kò fi lè ta wọ́n nù Ijapa Ogbomoso dagba ju gbedeke iye ọjọ ori tawọn onimọ ni o yẹ ki Ijapa kan lo laye lọ.
Wo ohun mẹ́wàá tó yẹ kóo mọ̀ nípá ọmọ ọdún mẹ́wàá Emmanuella tó kọ́ ilé ńlá fún ìyá rẹ̀ Irọ́ ńlá ni pé àwọn sọ́jà ń wá olùwọ́de EndSARS DJ Switch- Ọ̀gágun Ahmed Taiwo Iléeṣẹ́ ológun ní ó bàwọn lọ́kàn jẹ́ bí Sanwo-Olu ṣe ni kìí se òun ló pe sójà si Lekki Àwọn oniròyìn ló tú àṣírí ààbò Prof Peller, tí wọn fi ri pa - Lady Peller Ọ̀pá àṣẹ Ọba Akiolu tẹ gbé, a kò ní fọwọ́ yẹpẹrẹ mu - Ìgbìmọ̀ Ọba l'Eko yarí Bi iku ba n pa ojugba ẹni, owe nla lo n pa fun ni, ojo to ba si pa ikan ọrẹ, gbogbo ọrẹ ni eji n pa.
Alaga ajọ EFCC ni, inu oun bajẹ gidigidi pẹlu bo ṣe nira, to si ṣoro lati jẹ ki awọn to n wu iwa ibajẹ fi oju winna ofin, ki awọn ẹlomiran le kọgbọn nipa rẹ.
Ẹni ọdún mọkanlelogun ni Sedekaya nígbà tí ó wà lórí oyè, ó sì jọba ní Jerusalẹmu fún ọdún mọkanla.
Lẹ́yìn ọjọ́ mẹta tí Fẹstu dé sí agbègbè ibi iṣẹ́ rẹ̀, ó lọ sí Jerusalẹmu láti Kesaria.
Oríṣun àwòrán, @LASEMA Ìjọba kéde ọjọ́ ìwọlé àwọn àgùnbánirọ̀ sí ìpàgọ́ lẹ́yìn Covid 19- Sunday Dare Àjọ elétò ìdìbò kéde ọjọ́ tí ìdìbò aàrẹ Nàìjíríà 2023 yóò wáyé Àbádòfin ìṣúná 2021 ré kọjá ìpele ìkejì nílé aṣòfin àgbà Ìjọba ìpínlẹ̀ Eko ti kéde orúkọ àwọn ọlọ́pàá tó fi ìyà jẹ àwọn olùwọ́de End Sars Wo ìsọ̀rí àwọn tó jẹ́ kí ìwọ́de End SARS / end SWAT lárinrin àti ìtumọ̀ Ṣaaju nibẹrẹ ọsẹ yii: Ìjàmbá ọkọ̀ akérò àti tírélà pa èèyàn mẹ́rin lọ́nà mọ́rosẹ̀ Ore sí Benin Ore-Benin Road accident: Ìjàmbá ọkọ̀ pa èèyàn mẹ́rin lọ́nà mọ́rosẹ̀ Ore sí Benin Ọkọ akero ẹlẹni mẹrinla to n rinrin ajo lati ilu Eko lọ si Enugu ni a gbọ pe o lọ fori sọ ọkọ tirela laarọ ọjọ Iṣẹgun.
À ṣé olóòrùn ni ayálégbé mi tó ń fojóojúmọ́ ṣakọ lórí ayélujára- Onílé Lisa Li Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Nigeria Independence Day: Wo ìlérí tí àwọn ènìyàn ṣe Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Àwọn gomina ipinlẹ Eko, Osun, Oyo, Ondo ati Ekiti ti n fori kori lati wa ọna abayọ si iṣoro yii.
FIFA Football Awards: Messi la Ronaldo, Van Dijk láti gba àmì ẹ̀yẹ agbábọ́ọ̀lù tó pegedé jùlọ lágbayé
Ẹnikẹ́ni tí wọ́n bá yà sọ́tọ̀ pé ó gbọdọ̀ jẹ́ pípa láàrin àwọn eniyan, ẹnìkan kò gbọdọ̀ rà á pada, pípa ni wọ́n gbọdọ̀ pa á.
Lásìkò ti patí alẹ́ ọjọ́ Satíde n lọ lọ́wọ́, ni inú ti bẹ̀rẹ̀ si ni bi Erica nítorí bi Nengi ṣe ń jó pẹ̀lú olólùfẹ́ rẹ̀ Kidwaya.
Àwọn ìkógun yìí jẹ́ ohun ìyàsọ́tọ̀ fún OLUWA, ẹ kò gbọdọ̀ fọwọ́ kan èyíkéyìí ninu wọn kí OLUWA lè yí ibinu gbígbóná rẹ̀ pada, kí ó ṣàánú fun yín, kí ó sì mú kí ẹ pọ̀ sí i, gẹ́gẹ́ bí ó ti búra fún àwọn baba yín.
Àríyànjiyàn Osinbajo àti PDP Omiṣore fi ẹgbẹ́ PDP sílẹ̀ Ẹ má dáríji PDP — Tinubu Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ko sọna ni APC ati PDP Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Kola Ologbodiyan: Jẹgudu jẹra ni ijọba APC Gani ṣo pe àwọn yóò gba ìlú ati ijo tí Ambode ba fí lè dára pọ mọ PDP nitori o ṣíṣe ríbi ríbi nílu Èkó gẹgẹ bí Gómìnà Alága ẹgbẹ PDP náà tún sọ fún BBC pé àwọn olóṣèlú ẹgbẹ́ APC tí ọ n fapajanu kan tí n ṣé ìpàdé bonkẹlẹ pẹlú àwọn.
Ọrọ rẹ yi jẹ esi to fọ ni idahun si iroyin kan to gbode pe awọn agbẹjọro ijọba apapọ ti forukọ rẹ sinu awọn to n gbẹjọ ajẹbanu niwaju ile ẹjọ kan nilu London pe o gba abẹtẹlẹ.
Jehoṣafati dáhùn pé, “Wolii òtítọ́ ni.
Iwọde yii ni wọn fi n beere fun itusilẹ oludari ẹgbẹ Revolution Now, Omoyele Sowore to wa ni ahamọ awọn agbofinro, ati awọn eeyan miran ti ọlọpaa mu lasiko iwọde wọn to kọja.
Awọn oluṣeto: Lara awọn oluṣeto ni awọn gbajumọ lawujọ to fi ẹnu si ọrọ naa, to si n ṣatilẹyin fun awọn olufẹhunuhan.
" Bakan naa lo tun kede ọpọ ipinnu ti ikọ naa ti se bii gbigbe ilẹkun abawọle silẹ Mali lati ori ilẹ ati oju ofurufu ti pa titi di ọjọ miran, ọjọ re.
“Bí irun orí ọkunrin bá re, orí rẹ̀ pá ni, ṣugbọn ó mọ́.
Tinubu figbe ọrọ yii bọ ẹnu nigba to ri i pe ẹjọ nihin lọhun fẹ pọ lori oun.
 yàtọ ̀ sí tí àwọn ẹ ̀ yà bí i ti ìgbò tí ó jẹ ́ wí pé àjọrò ni wọn n fi ìjọba tiwọn ṣe ( acephalous ) tàbí ti hausa níbi tí àsẹ pípa wà lọ ́ wọ ́ ẹnìkan ( centralization ) .
Balaamu bá sọ fún Balaki pé, “Dúró níhìn-ín, lẹ́bàá ẹbọ sísun rẹ, n óo máa lọ bóyá OLUWA yóo wá pàdé mi.
Ẹ máa jẹ́wọ́ ẹ̀ṣẹ̀ yín fún ara yín, ẹ máa gbadura fún ara yín kí ẹ lè ní ìwòsàn.
Wọ́n tún ń sọ pé, “Kí ni ìtumọ̀ ‘Láìpẹ́’ tí ó ń wí yìí?
A óo gba Juda là, Jerusalẹmu yóo sì wà ní àìléwu, orúkọ tí a óo wá máa pè é ni ‘OLÚWA ni Òdodo wa.
Ọjọ ori rẹ gbọdọ jẹ laarin mejidinlogun si mẹrindinlaadọrin (O nii fi ṣe ofin agbegbe kọọkan).
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Buhari padà sí Naijiria lẹ́yìn tó lọ tọ́jú ara rẹ̀ 11 Èbibi 2018 Oríṣun àwòrán, @BashirAhmaad Àkọlé àwòrán, Ni ọjọ iṣẹgun ni Aarẹ Buhari fi orilẹede Naijiria silẹ Aarẹ Muhammadu ti pada si ilu Abuja, lẹyin to lọ si ilu ọba lati gba itọju lọdọ dokita rẹ.
Ẹ ranti gbogbo iṣẹ́ ìyanu rẹ̀,gbogbo nǹkan ìyanu tí ó ṣe, ati gbogbo ìdájọ́ rẹ̀,
Laipẹ yii ni aarẹ Muhammadu Buhari yan Bola Tinubu lati pari ija to wa laarin awọn ọmọ ẹgbẹ oselu naa.
Ní ti ẹ̀fẹ̀, láì wí tó, panchayat náà sábà máa ń lọ́wọ́ sí ìpènìyàn ní àjẹ́ pàápàá bí kò bá pàṣẹ ìjìyà t'ó tọ́.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Sambisa: Yóò di ibi ìgbàfẹ́ láìpẹ́ ọjọ́ 25 Ìgbé 2018 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ìbáṣepọ̀ àjọ ọmọogun pẹ̀lu ìjọba ìpínlẹ̀ Borno yóò ran àtúnṣe sambisa lọ́wọ́ Olórí àwọn ọmọogun orile-ede Naijiria Tukur Buratai sọ pé ibùdó àwọn Boko Haram tẹ́lẹ̀ rí nínú igbó sambisa kò ní pẹ di ibi ìgbàfẹ́.
 Àwọn òkúta iyebíye pàtàkì kan tí wọ ́ n ní bẹ ́ rílíọ ̀ mù nínú ni bẹ ́ rìlì ( òkúta odò , ẹ ́ míràldì ) àti bẹ ́ rìlìoníwúrà .
Awọn ile iṣẹ apoogun naa ni Emzor, Peace Standard ati Bioraj.
O ni ki awọn ti ọrọ kan fi ọwọ so ọwọ pọ pẹlu awọn Ọba alade, ijọba ipinlẹ Ogun, ati awọn agbofinro lori iṣoro yii ki awọn agbaṣẹṣe le tete pari iṣẹ akanṣe atunṣe opopona naa to n lọ lọwọ.
Ẹni to bori: Nigeria Mali vs Algeria.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ọ̀ṣun Oṣogbo 2018: Ulrich Salazar wálé ọdún láti New York Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Irun gígẹ̀ kọjá orí fífá lásán Ọmọ kéékèéké 24 bá omi lọ!
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Wo àwọn ohun tó yẹ kí o mọ̀ nípa DCP Kayọde Ẹgbẹdokun 14 Sẹ́rẹ́ 2019 Oríṣun àwòrán, Ẹgbedokun Àkọlé àwòrán, Ọlọpaa to kawe jinlẹ ni Kayọde Ẹgbẹtokun Awọn alaṣẹ ileeṣẹ ọlọpaa lorilẹ-ede Naijiria ti yan kọmiṣọna ọlọpaa tuntun fun ipinlẹ Eko.
Wo àwọn àwòràn tó làmìlaaka nílẹ̀ Adúláwọ̀ lọ́sẹ̀ yìí Kíkọ́ ẹ̀kọ́ gboyè nínú iṣẹ́ ìṣègùn ìbílẹ̀ yóò pèsè ìtọ́jú tó péye fọ́mọ Nàìjíríà- Ẹgbẹ́ àwọn dókítà Wọ́n mú ọjọ́ ìgbẹ́jọ́ agbésúnmọ́mí 9/11 tó ṣẹlẹ̀ l'Amẹrika Ọwọ́ ọlọ́pàá ti tẹ ọkùnrin kan tó pa ọ̀rẹ́ rẹ̀ nítorí N40 ní Kano Emma ni laarin ọdun marun un ni wọn fi ṣe iwadii yii.
Ìdí tí mo ṣe fẹ́ yọ ayédèrú ìdí ńlá tí mo ní- Sophie Wọ́n ti ṣí ilé oúńjẹ oní ọgbọ̀n náírà (N30) ní Kano Ilé ẹjọ́ rán àwọn mérìndínlógún lẹ́wọ̀n gbére fún dídáná-sun Nusrat Oríṣun àwòrán, facebook Àkọlé àwòrán, Maluu ti ara san pa ni Ondo Ninu alaye Ọba alaye naa ni wọn ti sọrọ wi pe, o ṣeeṣe ko jẹ ohun ti awọn maluu naa jẹ lo ṣe ku pawọn ṣugbọn kii ṣe pe boya ẹnikankan to ṣokunfa iṣẹlẹ naa.
wa ni ipinle Ondo , ni Gusu orile ede Naijiria.
Nígbà tí Abramu gbọ́ pé wọ́n ti mú ìbátan òun lẹ́rú, ó kó ọọdunrun ó lé mejidinlogun (318) ninu àwọn ọkunrin tí wọ́n bí sinu ilé rẹ̀, tí ó sì ti kọ́ ní ogun jíjà, ó lépa àwọn tí wọ́n mú Lọti lẹ́rú lọ títí dé ilẹ̀ Dani.
Ẹ wo bí Hushpuppi ṣe farahàn nílé ẹjọ́ l'Amẹrika fún ìgbà àkọ́kọ́ láti jẹ́jọ́ Ìjọba Nàìjíríà ti mú Dókítà Anu tí àwọn kan f'ẹ̀sùn kàn pé ayédèrú iṣẹ́ abẹ ìdí ló n ṣe Erépá ní bàbá àti ìyá mi ṣe tí wọ́n fi bí mi, wọn kò fẹ́ra wọn- Funsho Adeolu Àjọ NCDC kéde ènìyàn 454 tó tún ṣẹ̀ṣẹ̀ ní Coronavirus ní Nàìjíríà Nigba to n fi erongba rẹ lede lori ọrọ naa, Ọjọgbọn Joy Ezeilo to n ṣoju ẹgbẹ ajafẹtọ obinrin atawọn ọmọde, Women Aid Coellective, WACOL ni iṣẹlẹ naa jẹ eyi to bani ninu jẹ pupọ, ati pe o lodi si ofin to rọmọ ẹtọ awọn ọmọ wẹwẹ.
Nígbà tí Baaṣa gbọ́ ohun tí ó ṣẹlẹ̀, ó dáwọ́ odi tí ó ń mọ yí Rama dúró, ó sì ń gbé Tirisa.
Toyin Abraham: Ọ̀pọ̀ èèyàn ní èké ni Mercy Aigbe ń ṣe lórí bó ṣe ki Adeniyi Johnson
Bí mo ti sọ àsọtẹ́lẹ̀ tán, mo bẹ̀rẹ̀ sí gbọ́ ariwo ati ìrọ́kẹ̀kẹ̀, àwọn egungun náà sì bẹ̀rẹ̀ sí so mọ́ ara wọn; egungun ń so mọ́ egungun.
Àrẹ̀mú ò gbọ́ ìlù bàtá kankan, ló bá rọ̀jò lé kiní ọ̀hún jàre.
Ohun ti wọn n pariwo ninu iwọde wọn ni wipe, bi owo epo se n gbe ẹnu lọ soke ni igbe aye n nira fun araalu nibẹ.
Ajo to n mojuto idanwo fun
Ẹ̀wẹ̀, agbẹjọ́rò Oyedepo tó ń ṣojú àjọ EFCC sọ pé òun tẹ́wọ́ gbà á.
#Democracy Day: Pápá ìṣeré Abuja di MKO Abiola Stadium Ẹ̀yin aṣòfin túntun, ẹ má gbàgbé ẹni gbé'ṣẹ́ fún ni o - Saraki MKO Abiola, iṣẹ́ aṣẹ́gità ló fi bẹ̀rẹ̀ okoòwò Ìdààmú ńlá ńbọ̀ fún Nàíjíríà lábẹ́ ìjọba Buhari - Ọbasanjọ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 9th Assembly: Aráàlú ní àwọn ń fẹ́ ìpèsè àwọn ohun èèlò amáyédẹrùn Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Mo sì fi ẹ̀mí mi búra!
Gomina Aminu Masari to je gomina ipinle Katsina to saaju awon agbaagba  wonyii gboriyin fun ijoba Muhammadu Buhari fun ise tijoba re n se lati fi mu idagbasoke ba Naijiria lapapo lasiko yii.
Fasiti FUTA tun ṣalaye pe awọn ṣi n tẹsiwaju pẹlu iwadi lori iṣẹlẹ naa ati pe awọn yoo fi ijiya to le jẹ awọn ti o ba jẹbi ninu iṣẹlẹ ọhun.
Kì í ṣe àníyàn mi ni láti lọ waasu ìyìn rere níbi tí wọ́n bá ti gbọ́ orúkọ Kristi, kí n má baà kọ́lé lórí ìpìlẹ̀ tí ẹlòmíràn ti fi lélẹ̀.
Àkọlé àwòrán, Ẹni ti ko lee rin ni ki wọn gbe oun lasiko ọdun egungun ilu Iwo.
Ó bá lọ, ó ń waasu ninu àwọn ilé ìpàdé wọn ní gbogbo ilẹ̀ Galili, ó ń lé àwọn ẹ̀mí èṣù jáde.
Ajọ tó n ri si ètò àgunbaniro lórílẹ̀-èdè Nàìjíríà (NYSC) ti fèsì lórí awuywuye tó gbòde lóri ìwé ẹ̀rí ìsinlẹ̀ rú baba ẹni nípa Minisità fún ètò ìsúná Kemi Adeosun.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù El-Zakzaky: Ọ̀pọ̀ ẹ̀sùn aṣemáṣe ni ìjọba àpapọ̀ fi kan Zakzaky ní India 15 Ògún 2019 Oríṣun àwòrán, @imnigeria_org Ni Ọjọru ni okiki kan pe yangi ti n da si gaari eto iwosan ti wọn gbe kalẹ, fun aṣiwaju ijọ ẹsin shiite ni Naijiria, Ibrahim El-Zakzaky to wa lorilẹede India.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ààrẹ Buhari yóò sèbẹ̀wò sí Plateau Àwòrán ìkọlù Plateau tí ọ̀pọ̀ ẹ̀mí ti sùn Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ayédèrú Jẹẹsí Nàìjíríà ń tà wàràwàrà lọ́jà Ijinigbe ti wa di ohun to wọpọ lorilẹede Naijiria, atiwipe ogbontarigi ajinigbe ni, Chukwudumeme Onwuamadike aka Evans, lo yọ̀ju si ileẹjo ni Ọjọru, Osu Kẹfa ọdun yii lẹyin ti ọwọ ọlọpaa tẹ ẹ lọdun to kọja ni ile nla rẹ ni Magodo.
Àjọ ìṣọ̀kan àgbáyé UN ti fọmọ ogun apẹ̀tù-síjà ránṣẹ́ sí Mali Koda laipẹ yii ni wọn ṣi ji ọmọ minista eto ilera, Ojogbon Adewole gbe ki awọn agbofinro to rii padaỌmọ isaac Adewọle gba ìdáǹdè lọ́wọ́ ajínigbé.
Ṣugbọn iwadii awọn onimọ ti n waye lati mọ ohun pato to le ṣokunfa ki eeyan ku lasiko ibalopọ.
ijoba ti o fi mo awon omo egbe oselu kookan lati lodi si lilo ipo won tabi
Nígbà tí OLUWA gbọ́ kíkùn wọn, inú bí i, ó sì fi iná jó wọn; iná náà run gbogbo àwọn tí wọ́n wà ní òpin ibùdó náà.
Àwọn ọ̀pá ati fìtílà tí wọ́n fi ojúlówó wúrà ṣe láti máa jò níwájú ibi mímọ́ jùlọ gẹ́gẹ́ bí a ti pa á láṣẹ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Prophecy 2020: Primate Ayodele, Baba Adeboye àti Father Mbaka sọ àsọtẹ́lẹ̀ nípa 2020!
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: A jọ ṣe ìyàwó pọ̀, a jọ bímọ ní ọjọ́ kan náà, a tún jọ máa ń ṣàìsàn pọ̀ ni Lisabi Agbongbo Akala rèé, ẹni tó fi ìfẹ́, ìṣọ̀kan àti ìrẹ́pọ̀ gba ilẹ̀ Ẹ̀gbá lọ́wọ́ ìmúnisìn Iléẹjọ́, ẹ sọ fùn ọ̀gá DSS kó fún wa ní ₦1bn torí àhámọ́ lọ́nà àìtọ́ - Sowore àti Bakare Ọ̀yẹ̀ yóò là fún abẹ́rẹ́ ìfètòsọ́mọbíbí fáwọn ọkùnrin láìpẹ́ Eyi si ni awọn osere tiata lobinrin to mu okoowo miran mọ isẹ tiata, ati irufẹ okoowo ti wọn n se: Wunmi Toriola: Okoowo ipara to n bora lo mu mọ isẹ tiata Ọdọmọde osere tiata ni Wunmi Toriola to sẹsẹ bi ọmọkunrin kan laipẹ yii, ti orukọ rẹ n jẹ Zion.
Oríṣun àwòrán, Emmanuel oloye Àkọlé àwòrán, ASUU ṣalaye pe o di igba ti ijọba apapọ ba mu adehun to baa ṣe ṣẹ ki awọn to pada si ẹnu iṣẹ Bakan naa ni wọn tun paṣẹ pe eyikeyi akẹkọ to ba lọ sile yoo da ara rẹ lẹbi ni nitori pe, igbimọ alaṣẹ ileewe fasiti yii nikan lo lee paṣẹ pe ki awọn akẹkọ maa lọ sile."
Nitori eyi, ó yẹ ki á bẹ alaisan, ki ó lè lo oògùn ti Oníṣègùn ṣe, ki ó bà lè ri ìwòsàn, ki wọn tó bẹ Oníṣègùn.
" Ọ̀nà láti bọ́ lọ́wọ́ àwọn olè nínú súnkẹrẹ fàkẹrẹ ojú pópó À lòdì sí káádì ìdánimọ aráàlú tawọn Ológun fẹ́ máa yẹ̀wò!
Dafidi tún bèèrè lọ́wọ́ OLUWA lẹ́ẹ̀kan sí i pé, bóyá kí òun lọ tabi kí òun má lọ.
Bio ti le je pe, orisirisi asemase ni Simona fi bere ifigagbaga ohun, kii akonimoogba re, Darren Cahill ko to si niye lati tepamose si, ki o si fopin si asemase naa.
Lẹ́yìn náà, ó fún ọkọ rẹ̀, ọkọ rẹ̀ náà sì jẹ ẹ́.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ilé-ẹjọ́ yí ẹjọ́ DPO ọlọ́pàá tó ju télọ̀ sátìmọ́lé torí ó ba aṣọ rẹ̀ jẹ́ dànù Kò tọ́ sí Ọlọ́pàá láti ti ọmọ mi mọ́lé tórí ore tó ṣe lásìkò ìwọ́de EndSARS - Iya Eremosele Wo ìdí tí wọ́n fi ta ẹyẹlé kan ṣoṣo ní ₦893,000,000 Ààrẹ ti kọ̀wé fipò sílẹ̀ torí èèyàn méjì t'ọ́lọ́pàá pa níbi ìfẹ̀hónúhàn lòdì sí ìjọba Wo ohun mẹ́wàá tó yẹ kóo mọ̀ nípá ọmọ ọdún mẹ́wàá Emmanuella tó kọ́ ilé ńlá fún ìyá rẹ̀ Ṣe lóòtọ́ ni ejò ń pọ owó fún Ginimbi, ọ̀dọ́mọdé olówó kó tó jáde láyé?
Bẹẹ ni ọrọ ri pẹlu iku gomina ana nipinlẹ Oyo, Sẹnatọ Abiola Ajimobi to dagbere faye lọjọru.
Ọdun mẹtadinlaadọrin lo ku funmi lori apere awọn baba mi ."
Ko tan sibẹ o, wọn tun damọran saa kẹta fun, ti ijọba si tun fi ontẹ lu u bakan naa.
Lilọ mọ obi ẹni ti o fẹ fẹ ṣe pataki gẹgẹ bi Yetunde ṣe sọ ọ lodi si bi awn ọmọ aye isnsiyii ṣe n ṣe lai fi to obi wọn leti debi ti wn yoo ṣewadi lẹkunrẹrẹ.
Ajo egbe ajafeto omo eniyan lorile-ede Kenya so ninu atejade kan pe, “dekun ikolu awon obinrin lasiko laasigbo eto idibo”.
Wọn fi ẹsun pe o ni ohun ija oloro lọna aitọ.
Ẹyọ ẹnìkan ṣoṣo ni o fẹ́ pa, àwọn eniyan yòókù yóo sì wà ní alaafia.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Africa in Pictures: Àwọn àwòrán tó jojú ní gbèsè láti Africa 28 Òkùdu 2019 Nibayii ti opin ọsẹ wọle de, ẹ jẹ ka pa ara wa lẹ́rin, ka si kọgbọn nipasẹ awọn ọkanojọkan aworan , eyi to wa lati ilẹ Afirika.
Baba ọmọ tuntun naa jẹ ọmọ orilẹ-ede France kan, to rinrinajo lati ilu Paris gba Singapore kọja lọ si Phnom Pehn.
Àkọlé àwòrán, Ipele ti ìwà jẹgudujẹra dé ni Naijiria O ní nínú ìwádii òhun ní àwọn ti beerè ìwoye àwọn ara ilú lóri àwọn kókó tí o fi han bóya ìwa jégudu jẹra ń lọ silẹ̀ tàbí ò ń lọ sókè sí.
Iroyin gbe e wi pe lasiko idibo sipo gomina ni ọdun 2016 naa ni Gomina Adams Oshiomole gbe ipolongo rẹ kari, Nibe naa lo si ti n logun rẹ fun awọn eniyan nigba naa lati tako Pasito Osagie Ize-Iyamu to n dije dupo gomina lẹgbẹ oṣelu PDP.
Wọn tun fikun wi pe, bii abẹrẹ ajẹsara naa ba ṣe ṣiṣẹ si lara awọn eniyan ni yoo sọ bi wọn yoo ṣe lo si fun awọn eniyan.
Ṣugbọn ko le fidi asiko ti wọn yoo tẹ baba si itẹ mulẹ pe ipade ṣi n lọ pẹlu awọn ti ọrọ kan laafin.
Ó ki ọkùnrin náà ó sì ṣe ìbéèrè, ó ní, pẹ̀lẹ́ o, kí ló kúkú dé tó bẹ́ẹ̀ tí o fi ń sọkùn?
1 125115 Orilẹede Kyrgyzstan 1297 20.
APC àti Buhari, ẹ yé irọ́ pa, kẹ sì múra láti kojú ìgbẹ́jọ́ - PDP fèsì Atiku fẹ́ fa Lauretta Onochie, amúgbálẹ́gbẹ́ Buhari lọ ilé ẹjọ́ Ọkọ adajọ naa, Adamu Bulkachuwa jẹ sẹnetọ ti wọn ṣẹṣẹ yan labẹ ẹgbẹ oṣelu APC, ti ọmọ rẹ naa si jẹ oludije fun ipo gomina labẹ ẹgbẹ oṣelu naa.
Ọna to lọ si ilu Ipele nitosi Ọwọ ni wọn ti ji olukọ naa gbe.
Yoruba to ti fẹ Fulani l'ọkọ fun ọdun metala
Abimeleki jọba lórí Israẹli fún ọdún mẹta.
Ọ̀rọ̀ Sotitobire tí a dá sí, àwọn aṣòfin àtàwọn àjọ kan ló fi lọ̀ wá- DSS Pípe ìpínlẹ̀ Osun ni State of Osun kò bá òfin mu- Adájọ́ Agboola Mùsùlùmí tó ń gbèrò láti lọ hajj ni Alhaji, Alhaja - Onímọ̀ Kónílé-ó-gbélé Covid 19 ló tú àṣírí àwọn àfipábánilòpọ̀ láwùjọ- Mínísítà ọ̀rọ̀ àwọn obìnrin Àkọlé àwòrán, Àjọ ọlọ́pàá, Ìjọba ìpínlẹ̀ Ọyọ jẹ́jẹ̀ẹ́ láti ṣàwárí òòsà tó ń mu ẹ̀jẹ̀ nílùú Ìbàdàn Owoṣeni tẹsiwaju wi pe eero gomina ni lati riidaju wi pe kele ofin gbe awọn to n ṣiṣẹ ibi yii ni kiakia ki wọn si fi wọn jofin.
Oshodi Tapa ń dagba, ọkunrin de, to si di akikanju ati akọni pataki laarin ilu, bẹẹ lo sun mọ ọba Eshinlokun bii isan ọrun.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Ohùn gooro ló gbé mi dé ọ̀dọ̀ ààrẹ̀ Bush, Obama, Obasanjo, Goodluck, Buhari' Wọn ji wọn gbe ni agbegbe Iwaraja ni ijba ibilẹ Oriade lọjọ aje ọsẹ yii.
Ó ní kí àwọn eniyan má san owó-orí.
Nípa rẹ̀ ni Ọlọrun ṣe gbogbo nǹkan lọ́kan pẹlu ara rẹ̀, kí alaafia lè dé nípa ikú rẹ̀ lórí agbelebu.
Gomina Ambode tenumo pe, “ijoba ipinle Eko yoo tesiwaju lati ma satileyin fun ere-idaraya, besini Mo fin da aare FIFA loju pe, nigba-kugba ti yoo ba tun pada wa silu Eko, Eko yoo maa sagbateru idije FIFA,”Ninu oro re, igbakeji alakoso ile-ise AITEO, Francis Peters so pe, o je ohun idunnu lati ri pe,  ile-ise epo robi AITEO wa ni ibasepo ti o donmonron ninu itan boolu afesegba ni Niajria.
Ó ní, kí o jẹ́ kí àwọn eniyan òun lọ kí wọ́n lè sin òun.
Kíló fàdí abájọ ti Ọlọ́pàá fi gbé akọ̀ròyin lọ ilẹ́ ẹjọ́ ni ìkọ̀kọ̀ Ileeṣẹ ọlọpaa ti gbe Samuel Ogundipẹ, akọroyin iwe iroyin Premium Times ti wọn mu lori iroyin kan to kọ lọ ile ẹjọ bayii.
ipolongo ibo aare ti odun 2019 yii.
Online Match Making: Ṣé aburú wà lórí yíyan ọkọ àbí aya lórí ayélujára?
Ogundimu ti o n ṣoju ẹkun Idibo Agege kinni ni Ipinlẹ Eko, to ṣakiyesi
 Ni bayii, awon ipinle mejila ni won ti kowe si ile-ise aare pe awon yoo  pese ilẹ fun didasile ibugbe awon daran-daran ni ipinle won.
David Whitmer di ọ̀kan nínú Àwọn Ẹlẹ́rìí Mẹ́ta Ìwé Ti Mọ́mọ́nì.
" Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Oluwo: Mo lè jẹ Ọba ní Ile Ife Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Wọn bii ni ọjọ kọkanla, oṣu Keji, ọdun 1978 ni ipinlẹ Eko.
Nibẹrẹ ọdun 2019 ijọba Naijiria san biliọnu mọ́kànlélọ́gọ́jọ naira fawọn ile ẹkọ giga lorileede naa gẹgẹ bi owo iranwọ fọdun 2018 eleyi ti TETFUND ṣe eto pinpin rẹ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ondo 2020 Tribunal: Ìgbìmọ̀ olùgbẹ̀jọ́ ìbò gómìnà yóò gbérasọ lọ́jọ́ Iṣẹgun 7 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Àkọlé àwòrán, APC,PDP, ZLP àtawọn ẹgbẹ́ miran ni Ondo Igbimọ igbẹjọ idibo Gomina ipinlẹ Ondo ti n palẹmọ lati bẹrẹ ijoko.
 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!"
Àgọ́ àwọn ọmọ ogun Israẹli ati ti àwọn ọmọ ogun Siria kọjú sí ara wọn, wọn kò sì kúrò ní ààyè wọn fún ọjọ́ meje.
O fikun ọrọ rẹ pe didun lọsan yoo so fun Naijiria ti Super Falcons ba le gba bọọlu bi wọn ṣe ṣe ninu abala keji ere bọọlu ti wọn gba pẹlu Norway.
“Nígbà tí ẹ bá dó ti ìlú kan fún ìgbà pípẹ́, tí ẹ bá ń bá ìlú náà jagun tí ẹ fẹ́ gbà á, ẹ kò gbọdọ̀ bẹ́ àwọn igi eléso wọn lulẹ̀ ní ìbẹ́kúbẹ̀ẹ́.
Bẹẹ si ni oriṣiriṣi ere idaraya wa, ṣugbọn o ni awọn to n ṣanfaani fun ibalopọ laarin takọ-tabo.
nitori pe owo naa ti di meta kọbọ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, afin pupa Lọpọ igba, ti aarẹ ba ni ju iyawo kan lọ, iyale ninu awọn iyawo naa ni wọn ma n pe ni First Lady, ti awọn iyawo yoku yoo si maa jẹ iyawo aarẹ, wife of the President.
Nigba ti ọkunrin ba wa ni ọdọ, wsn ma n ni agbara.
Báyìí ni àgbàọ̀jẹ̀ agbábọ́ọ̀lù Diego Maradona ṣe wọ káà ilẹ̀ lọ lólú ìlú Argentina Ohun mẹ́wàá pàtàkì nípa Maradona àti ìbáṣepọ̀ rẹ̀ pẹ̀lú ẹlẹ́sẹ̀ ayò Diego Costa rèé Àwòrán rèé nípa bí 'Hand of God' ṣé dí inagijẹ Diego Maradona Lẹyin o rẹyin Anthony Joshua lo bori nigba to fi ẹṣẹ ja Pulev bs bi apo irẹsi nigba ti ija wọn wọ ipele kẹsan.
Oṣu Kọkanla ni afikun de ba iye ti wọn n ta lita epo pẹtiroolu, lẹyin ti ileeṣẹ to n mojuto tita eporọbi fi owo kun iye to n ta epo fun awọn alagbata.
Bẹ́ẹ̀ ni mò ń wà ninu oòrùn lọ́sàn-án ati ninu òtútù lóru, oorun kò sì sí lójú mi.
Musa Shuabu , alaga igbimo ajọ NiBUCAA naa so pe ipinnu lati je ki awon ile-ise aladaani lorile ede Naijiria fọwọsowọpọ pẹlu ijoba apapo lati gbogun ti aarun kokoro inu eje ati aarun kogboogun (HIV/AIDS) bere ni odun màrúndínlógún seyin lasiko ijoba  aare ana olusegun Obasanjo.
láti inú ìdílé Merari: igba ó lé ogún (220) ọkunrin, Asaaya ni olórí wọn, 
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Jollof rice: Ṣé lóòtọ́ ni ìrẹsì jọ̀lọ́ọ̀fù Ghana dùn ju ìrẹsì jọ̀lọ́ọ̀fù Nàìjíríà lọ?
" Ha, ṣe mo fọ ọwọ mi daada báyìí?
Oríṣun àwòrán, Getty Images Amọ nigba ti Farouk to ran nisẹ de, lo ri iya wọn ninu agbara ẹjẹ, to si fi igbe ta pe kawọn ara adugbo wa gba iya oun.
Idilé ti ifẹ bá wà laarin ẹbi, iyàwó pàápàá kò ni fẹ́ kúrò ni irú ẹbi bẹ́ ẹ̀ lati lọ fẹ́ ọkọ si idilé miran pàtàki nitori àwọn ọmọ tàbi ó dàgbà jù lati tun lọ fẹ ọkọ miran.
Lara awọn ti ọta ibọn ba ni oniroyin kan lati ileeṣẹ iwe iroyin the Nation, Emmanuel Oladesu, Temitọpẹ Ogunbanke lati iwe iroyin NewsTelegraph pẹlu ayaworan ileeṣẹ mohunmaworan Ibilẹ Television, Abiọdun Yusuf atawọn eeyan miran.
ninu idibo gbogbo gbo ti odun 2019 nipinle Oyo.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Oyo Fire: Dukia ṣófo, ọmọ ọdún mẹ́rìnlá faragbọta níbí iná tó jó ọjà Akesan SERAP ni ni iwoye tiwọn, awọn ọta Naijiria ni 1.
Alfred Aji ni tirẹ sọ pe Yahaya Bello ni gomina ti ko ṣe dáadáa ju ninu itan orilẹ-ede Naijiria.
Ṣílẹ̀kùn fún mi,arabinrin mi, olùfẹ́ mi,àdàbà mi, olùfẹ́ mi tí ó péye,nítorí pé, ìrì ti mú kí orí mi tutù,gbogbo irun mi ti rẹ, fún ìrì alẹ́.
oloye  Segun Osoba; gomina ipinle Oyo
Àwọn ará Bẹnjamini ti pa bí ọgbọ̀n jagunjagun ninu àwọn Israẹli, wọ́n sì ti ń wí ninu ará wọn pé, “Dájúdájú a ti ṣẹgun wọn bíi ti àkọ́kọ́.
Ọmọdekunrin naa, Gold Kọlawọle ni oun ati iya rẹ lọ si ileejọsin naa lọjọ naa ki iṣẹlẹ ọhun to waye.
Bí àwọn ìjọba orílẹ̀-èdè ṣe n sẹ́wélé òfin ìgbélé, tí àwọn ènìyàn si ti ń padà sí àwùjọ fún onírúurú ìbáraeníse pọ̀, ọ̀pọ̀lọpọ̀ ènìyàn ló tí n fòyà lórí bi wọn ò ṣe ni kó ààrùn Coronavirus, èyí to sì lè mú àjàkálẹ̀ ààrùn ẹlẹ́kejì bẹ́ sílẹ̀.
Onírúu’rú oúnjẹ ni wọn fi fún wa jẹ, nítorí onírúúrú ẹ̀dá alààyè ni ó wá sí ibi ìgbéyàwó náà.
Ó ti di ogún èèyàn tó kú ní ilé alájà tó wó l'Eko 'Ìwadìí yòó yàtọ̀ lórí ilé tó wó nítorí ààrẹ ti gbọ́ síi' Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Manfe-Dove: Àgbà ìlú kan ní ohùn kan ló fọ̀ sáwọn baba ńlá àwọn láti ṣe bẹ́ẹ̀ Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Njẹ ọ mọ̀ pé mímí afẹ́fẹ́ tí kò dára lè fa àìsàn?
Ṣe o wa to gbangbaa sun lọyẹ lati yẹ aga mọ aarẹ Trump nidii ni White House?
Sony Setiawan di ẹni apewo nigba ti o n ba awọn akọroyin sọrọ ni papakọ ofurufu Pangkal Pinang lẹyin to bale ninu ọkọ ofurufu miran to ba de.
Ileewosan nla LAUTECHTH fi ikede 'ẹ wa gb'oku yin sita l'Oṣogbo Nibayii, awọn alaṣẹ ileewosan nla LAUTECHTH ni ilu Osogbo ti fun awọn eeyan to ba ni oku ni ileegboku pamọ si rẹ ni gbedeke ọsẹ meji lati wa palẹ oku wọn mọ bibẹẹkọ awọn yoo sin gbogbo wọn pọ ni.
Ìjàpá jẹ́ ki Ẹkùn játọ́ titi kó tó fún ni àkàrà olóyin jẹ.
Gbogbo àwọn tí a kà ninu ẹ̀yà Simeoni jẹ́ ẹgbaa mọkanla ó lé igba (22,200).
Kí ló dé tí ojú yín fi rẹ̀wẹ̀sì bẹ́ẹ̀?
”Lopetegui bere si ni tuko agbaboolu Spain lati odun 2016, bee si ni O ti fi igba kan je akonimoogba iko agbaboolu FC Porto.
Ẹ gbọ́ ohun tí OLUWA, Ọlọrun mi sọ; ó ní, “Fi ara rẹ sí ipò olùṣọ́-aguntan tí ó da àwọn ẹran rẹ̀ lọ sí ibi tí wọ́n ti pa wọ́n.
“Pàṣẹ fún àwọn alufaa tí wọ́n gbé Àpótí Ẹ̀rí pé kí wọ́n jáde kúrò ninu odò Jọdani.
Kò sọ́wọ́ mi nínú ẹdáwó orí ayélujára - Atiku figbe bọnu Atiku náà kéde àtìlẹ́yìn rẹ̀ fún ẹ̀ṣọ́ alábòò Amọtẹkun Ìgbìmọ̀ ìgbẹ́jọ́ fún Atiku láǹfàní láti wo ohun èlò ìdìbò ààrẹ Lori ti pe o banujẹ, awọn kan da a lohun pe ki lo kan pẹlu ti ibanujẹ wi pe ṣe bi Naijiria naa lee ṣe ohun ti Amẹrika ṣe fun awọn ọmọ ibẹ naa ti Naijiria si le da gbe lai ni wọn laarin awọn.
Mo gbéra ní alẹ́ èmi ati àwọn eniyan díẹ̀, ṣugbọn n kò sọ ohun tí Ọlọrun mi fi sí mi lọ́kàn láti ṣe ní Jerusalẹmu fún ẹnikẹ́ni.
Atiku Abubakar sọ níbi ìpàdé ìgbimọ̀ aláṣẹ PDP pe, ẹgbẹ oṣelu APC ti lọ kọ àwọn kan níṣẹ́ ní China,lori bí wọ́n ṣe máà jẹ́ kí ẹ̀rọ káádì ìdìbò ṣe ṣégesège lasìkò ìdìbò.
Àjọ NCDC kéde ènìyàn 566 tó tún ṣẹ̀ṣẹ̀ ní Coronavirus ní Nàìjíríà Oríṣun àwòrán, @BAshirAhmad Alaga igbimọ amuṣẹya aarẹ lori kikoju Covid19, Boss Mustapha fi eyi han lẹyin to dari awọn ọmọ igbimọ to ku lati lọ jabọ fun aarẹ Muhammadu Buhari lori ibi ti ọrọ de duro ni ile aarẹ lọjọ aje.
Bí àpẹẹrẹ, Ọbásanjọ́ jẹ́ alẹ́nulọ́rọ̀ tí ó mọ àludé tòun àpadé bí àwọn Ààrẹ ṣe ń gba ipò láti ọdún 2007 sí 2015.
Ó dàbí ẹni pé, èyí ni ọmọbinrin kan rí tó fi gbà láti di aya lọ́ọ̀dẹ̀ Dino Melaye, tii se gbájúgbaja ṣẹ́nétọ̀ tí àtúndi ìbò Kogi West yọọ kúrò nílé ìgbìmọ̀ asofin l'Abuja laipẹ yii.
Bá olóye wí, yóo sì ní ìmọ̀ sí i.
Awọn akẹgbẹ rẹ to ku ti wẹ yankankan lẹyin ayẹwo Covid-19 ti wọn yoo si kopa ninu ifẹsẹwọnsẹ wọn.
Nibayi, ajọ WHO n ṣiṣẹ pẹlu awọn alaṣẹ eto ilera, to fi mọ ileewosan nlanla ati ajọ Alliance for International Medical Action (ALIMA) lati le tete ṣe afikun si awọn ibudo itọju, ati lati pese awọn irinṣẹ ti wọn nilo fun amojuto awọn alaisan, to fi mọ mimu adinku ba ewu to wa fun awọn oṣiṣẹ eto ilera.
Ó bá gbà bẹ́ẹ̀ fún wọn.
Mo fẹ ki o jawe olubori ko lee ṣamulo owo to ba ri daadaa."
Oríṣun àwòrán, Alaafin Oba Lamidi Adeyemi III ''Mi o mọ bi wọn ṣe n lepa tabi dẹnu ifẹ kọ obinrin.
Josẹfu wá ranti àlá rẹ̀ tí ó lá nípa wọn, ó sì wí fún wọn pé, “Amí ni yín, ibi tí àìlera ilẹ̀ yìí wà ni ẹ wá yọ́ wò.
O ni ko si ọrọ sisan owo fun agbaṣẹṣe kankan lori owo naa nitori ko si agbaṣẹṣe ti wọn gba fun eto gbigba owo naa pada.
Yóo bí ọmọkunrin kan, o óo sì pe orúkọ rẹ̀ ní Jesu nítorí òun ni yóo gba àwọn eniyan rẹ̀ là kúrò ninu ẹ̀ṣẹ̀ wọn.
Eyi jẹ́ ki àlejò rò wipé igbà gbogbo ni Yorùbá fi ńṣọdún.
 O sọrọ lori iṣẹ ti ijọba ipinlẹ Eko ti ṣe de igbelarugẹ irin ajo afẹ nilẹ Afrika.
Ibi tí Wọn sọ ní Tabera.
Ó ṣeéṣe kí ènìyàn 12,000 máa kú lójoojúmọ́ lẹ́yìn Covid-19 Orílẹ̀-èdè mẹ́wàá tí ẹgbẹ́ alákatakítí Islamic State n fínna mọ́ ní àgbáyé N kò gba ₦4bn lọ́wọ́ Magu, ẹ má ró àjẹbánu mọ́ mi láṣọ - Osinbajo pariwo Mi ò tíì gba ìwé ìfitónilétí pé wọ́n fẹ́ yọ mí nípò igbákejì gómìnà ìpínlẹ̀ Ondo- Agboola Ajayi O ni adehun tawọn se ni pe ki eto idanwo WAEC waye, pẹlu sise awọn ilana eto aabo kan.
Nítorí bí mo bá ń waasu ìyìn rere, kì í ṣe ohun tí mo lè máa fi ṣògo.
O ni pé ẹnikẹ́ni lo le bu ẹnu ẹ̀tẹ́ lu ìjọba sùgbọ́n irọ́ pipa kò boju mu.
Lasiko ti wọn n se ifilọlẹ iwe kan ti wọn fi peri Jonathan ni Melaye fi ọrọ yi lede nilu Abuja.
Ajọdun Orin Iyin ati Orin Imisi Ẹmi ti ọdun 2018 (2018 Festival of Hymns and Canticles) yii ni wọn fi sọri Ọlọla, Sir Adekunle Oyedipẹ, to jẹ gbajugba onkọrin ati oniduuru imisi ẹmi.
Wole Soyinka: Kò sí ààyè fún ẹnikẹ́ni láti gba ilẹ̀ ìràn Yorùbá
Kò si ounjẹ gidi tàbi omí, kò sí ilé.
Ṣugbọn ninu ọrọ ti ẹ, Auxiliary sọ fun BBC Yoruba irọ nla lawọn ọmọ ẹgbẹ NURTW n pa mọ oun pe oun n gbe ohun ini ẹgbẹ naa kaakiri ipinlẹ Oyo.
Kíni ìdí tí àwọn ẹbí àwọn ọmọ Chibok fi ń tọ woli lọ?
bermuda ( ; lonibise bi , àwọn bẹ ̀ rmúdà tabi Àwọn erékùṣù somers ) je ile-agbegbe okere britani ni ariwa okun atlantiki .
Wọ́n pé ọdún méjìlá báyìí Ọrọ yii n waye lẹyin ti awọn Asofin UK jiroro lori ijiya to yẹ fun ẹnikẹni ni ijọba tabi ninu awọn agbofinro ti ade iwa ibajẹ ohun ti iwadii ba fihan pe o ṣẹlẹ ninu iwọde #EndSars loṣu kẹwaa, ọdun yii ba ṣi mọ lori ni Naijiria.
Ṣugbọn wọ́n ń sọ pé, “Kí á má ṣe é ní àkókò àjọ̀dún, bí bẹ́ẹ̀ kọ́ ìlú yóo dàrú.
"Àwọn aṣòfin ìpínlẹ̀ Ogun pariwo sí Gómìnà wọn Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ẹ wo adúrú ǹkan tí Softface ma ń tò pọ̀ láti sín àwọn òṣèré, gbajúgbajà jẹ ""Ilana kan naa ni mo fi fẹ gbogbo àwọn iyawo mi."
Wo ipò tí Buhari fún Faṣọla, Lai Mohammed, Saraki àti bẹ́ẹ̀ bẹ́ẹ̀ lọ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Awa Bike wà fún eré ìdárayá àti díndín èéfín agbègbè kù Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Jehoadini, ará Jerusalẹmu, ni ìyá rẹ̀.
Díẹ̀ rèé lára àwọn ohun ayọ tọ ṣẹlẹ̀ lágbo òṣèré tíátà láàrin ọ̀sẹ̀ yìí Bi awọn kan ṣe n ṣajọyọ pe oju wọn ri ọdun ti obi wọn ko pa ọdun 2019 jẹ, ni awọn mii bimọ tuntun, ti awọn miran si goke agba sii lẹnu iṣe pẹlu awọn oloṣelu.
5) Ki ile iwe din iye akẹkọọ to n wa ni kilaasi kọọkan ku ati ni ile igbe awọn akẹkọọ ati awọn ibudo ijọsin.
Nítorí pé ní ọjọ́ náà, olukuluku yóo gbé àwọn ère fadakaati ère wúrà tí ó fi ọwọ́ rẹ̀ ṣe sọnù,àwọn ère tí ó mú wọn dẹ́ṣẹ̀.
Ninu awọn akọle ti wọn gbe dani sọ wi pe orilẹede Naijiria nilo adura, nitori oogun ti ohun n ja Naijiria kii ṣe oju lasan mọ.
Irin Kasuwan Magani si aarin gbungbun Kaduna to kilomita mẹrindinlọgbọn o si jẹ oju ọna ti eeyan le gba lọsi apa guusu Kaduna, Plateau, Nasarawa ati ipinlẹ Benue.
òkè agbada náà dàbí adé tí a yọ sókè ní igbọnwọ kan, wọ́n sì ṣe iṣẹ́ ọnà aláràbarà yí etí rẹ̀ po.
Ami ori ọrọ ṣe pataki ninu ede Yoruba, o si yẹ ka maa kọ ara wa, tabi ran ara wa leti.
Ayédèrú Ọ̀ṣun ni wọ́n ń bọ lónìí, kìí ṣe ojúlówó - Bàbá Ọlọ́ṣun tún figbe ta Wá gbàkàrà, gba dùǹdù ni Tottenham fi gba ọ̀mì lọ́wọ́ Manchester city Fayemi fojú Alufa to fipa bá ọmọde lòpọ̀ síta l'Ekiti El-Zakzaky: Arúfin ni ijọba Muhammadu Buhari gan-an - Ladoja Ohun ti awọn iroyin kan n sọ ni pe awọ̀n ọdọ ẹya Yoruba ati awọn akẹgbẹ wọn lati ẹya Hausa ni wọn fija pẹẹta lọjọ aiku bi o tilẹ jẹ wi pe ko tii si ẹni ti o lee sọ ohun ti o ṣokunfa rogbodiyan naa.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Spartan in Ogun: Èèyàn márùn-ún ní ọlọ́pàá sọ pé afurasí náà pa léraléra 26 Ògún 2020 Oríṣun àwòrán, OTHERS Afurasi apaayan ati amu oogun oloro to n daomi alaafia ilu Ogere ati Iperu ru ti awọn ọlọpaa ipinlẹ Ogun si ti n wa la gbọ pe wọn ti yinbọn pa bayii.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Yemi Osinbajo: Ìpínlẹ̀ Ondo lè bọ́ Naijiria pẹ̀lú ohun àlùmóọ́nì rẹ̀ 9 Bélú 2018 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 22 Bélú 2018 Oríṣun àwòrán, @RotimiAkeredolu Àkọlé àwòrán, Kọmisọnna fún ètò ìsúná nípínlẹ̀ Ondo ní pé òkun tó jìn jùlọ ní ilẹ̀ Afirika àti bitumen wà nì ìpínlẹ̀ Ondo.
Jesu bá mú ọkunrin náà, ó wò ó sàn, ó bá ní kí ó máa lọ.
"Oríṣun àwòrán, EPA Àkọlé àwòrán, Orílẹ̀-èdè Zimbabwe léti bèbè dídàwó lẹ́ẹ̀kan si Minisita fun ọrọ abẹnu, Kazembe Kazembe sọ lọsẹ to kọja pe ""ko sohun to jọ mọ ifipagbajọba."
Àwọn nǹkan mẹrin kan wà tí wọ́n kéré ninu ayé,sibẹsibẹ wọ́n gbọ́n lọpọlọpọ:
Tabi kí ló dé tí ò ń fi ojú tẹmbẹlu arakunrin rẹ?
Ọ̀rọ̀ yìí kìí ṣe ọ̀rọ̀ àríyá;nítorí àwọn eniyan mi kọ̀, wọn kò náání ìkìlọ̀ ati ìbáwí mi.
Alexander Akinyele jẹ ẹni to fẹran lati maa sọrọ lori ẹrọ ayelujara ki ọlọjọ to de.
Uzor Kalu (Abia North), ti o jẹ oludari eto ti asofin  Aliyu Sabi Abdullahi (Niger North) si jẹ
Àwọn ọkunrin Gibea bá dìde lóru, wọ́n yí ilé tí mo wà po, wọ́n fẹ́ pa mí.
Alufaa yóo mú ninu òróró tí ó kù ní ọwọ́ òsì rẹ̀, yóo fi kan ṣóńṣó etí ọ̀tún ẹni tí wọ́n fẹ́ sọ di mímọ́, ati àtàǹpàkò ọwọ́ ọ̀tún rẹ̀, ati àtàǹpàkò ẹsẹ̀ ọ̀tún rẹ̀, tí ó ti kọ́ fi ẹ̀jẹ̀ ẹbọ ìmúkúrò ẹ̀bi kàn.
Akomolede àti Aṣa: Ọ̀rọ̀ Ẹ̀yán ni Bunmi Femi Amao ń kọ́ wa lórí ètò Akọ́mọlédè àti Àṣà Ọ̀gá iléeṣẹ́ gbé £10 mílíọ̀nù ẹ̀bùn owó fún òṣìṣẹ́, èyí lohun tó pawọ́n pọ̀ Orílẹ̀èdè Amẹrika ti bẹ̀rẹ̀ sí ní wo wọlé-wọ̀de Atiku, àwọn ìyàwo rẹ̀ lórí owó tí wọ́n kó lọ sí òkèèrè Hisbah mú ọkùnrin mẹ́ta tó pín fídíò ìfipábánilòpọ̀ ọmọdébìnrin 16 tó fẹ́ ṣèyàwó lórí ayélujára Èèyàn mẹ́jọ jónà ráúráú nínú ìjàmbá ọkọ̀ akérò tó ṣẹlẹ̀ ní mọ́rosẹ̀ Eko sí Ibadan O ni ileewe ko ni ṣi pada ni ipinlẹ Katsina titi di igba ti ijọba apapọ ba fi ilana tuntun lede pẹlu akoko ati igba ti awọn akẹkọọ le pada lai si ewu.
Awon egbe awon osise iwadii n beere fun agbekale ajo kan ti yoo maa mojuto ise gbogbo won lapapo gege bi won ti n beere lati odun 2011.
14% fi apẹrẹ arun naa han - o si ṣoro fun wọn lati mi.
Tí àwọn púpọ̀ bá pé jọ gbálẹ̀, kíá kiá ni wọ́n ngbálẹ̀ tán.
Ninu atẹjade kan to fi sita ni ọjọ Aje, Omisore, ti o ṣe ipo kẹta ninu esi idibo ti ajọ INEC kede ni owurọ ọjọ Aiku, ni ipolongo ibo oun lo mu ki awọn ijọba Ipinlẹ Osun tete san lara owo oṣu ti wọn jẹ.
Ile ise ologun Naijiria ti ni ko si ootọ ninu iroyin naa sugbọn ọpọ ile ise iroyin lo gbe iroyin naa jade pe awọn ikọ Boko Haram lo sigun ba awọn ọmọ ogun Naijiria ni agbegbe Sari ni ipinlẹ Borno.
Ọkùnrin kan tó yasó nínú ọkọ̀ Uber rí ẹ̀wọn he Toyin Abraham tú àṣírí ohun tí ọlọ́pàá Náìjíríà sọ mọ́lẹ́bí rẹ̀ kan dà Ìjọba kéde ọjọ́ ìwọlé àwọn àgùnbánirọ̀ sí ìpàgọ́ lẹ́yìn Covid 19- Sunday Dare Idowu Phillips sọrọ lori iyatọ to ti de ba iṣẹ tiata nisinsinyi ati laye atijo lasiko to n ba akọroyin BBC Yoruba fọrọ jomi tooro ọrọ.
'Penis Fish,' ẹ̀ja tuntun tó rí bí nǹkan ọmọkùnrin lúwẹ̀ẹ́ jáde nínú òkun Ọlọ́pàá fi pampẹ́ òfin mú Duncan Mighty lórí ẹ̀sùn jìbìtì mílíọ̀nù mọ́kànlá Nàìjíríà ṣe bẹ́ẹ̀ padà s'áyé ìjọba ológun t'ọ́pọ̀ wà látìmọ́lé láì sí ìgbẹ́jọ́ - Olubunmi-Okogie Ọ̀jọ̀gbọ́n fásitì OAU pàdánù ẹ̀mí lópoópónà Benin sí Auchi.
Ẹkunrẹrẹ ohun ti awọn mejeji sọ wa ninu fidio yii.
Oríṣun àwòrán, others BBC Yoruba tún kan sì alukoro Ọlọpaa nipinlẹ Ọ̀yọ́, Olugbenga Fadeyi láti fìdí rògbòdìyàn náà múlẹ̀, àmọ́ ó ní kó sì rògbòdìyàn kankan tó wáyé laarọ ọjọ́ Aje ni agbegbe Iwo road.
Twins Festival: Asọ ń pe asọ ránsẹ́ lára àwọn ìbejì lásìkò ọdún wọn
Awọn ikọlu tọtẹ yi yoo buru jai, yoo si dojukọ awọn ibudo iwapo tawọn ile ise elepo ile okeere to wa lori omi.
Ó jẹ́ kí ilé ìṣọ́ ati odi ìlú wó lulẹ̀ pẹlu ìbànújẹ́,wọ́n sì di àlàpà papọ̀.
Gomina Ibikunle Amosun ni odun yii bere ni idunta pelu erongba lati so awon asa wa to ti n di ohun igbagbe ji ni iran yii.
Amọ bi iwa naa ṣe jẹ eewọ laarin iran Yoruba, n ṣe lo n gogo si lasiko yii, paapaa lori ẹrọ itakun agbaye.
O ti dabi awokose fun ọpọ awọn alakoṣe ìjọ Celestial, ti ipinu ọpọ eniyan si ti yipada nipa iṣe ati ihuwasi awọn Celestial, o yi ilana iwaasu aye lailai padà nípa ẹbun ikọni, wooli, ajihinrere ati ẹbun ṣiṣe oju aanu fawọn eeyan to ni.
Ọga agba ajọ aṣọbode ni iwọ oorun gusu Naijiria Muhammad Garba sọ pe awọn ara ilu lo ta wọn lolobo nipa oogun naa ti awọn si lọ dabu awakọ naa ati ẹni to ni ọkọ naa.
Maikanti Baru Ọjọ kọkandinlogun, oṣu karun un ọdun 2020 ni Maikanti Baru dagbere faye lẹyin ailera rẹ nitori arun Coronavirus.
Adari awọn   ọlọpaa teleri Alhaji Musiliu Smith to n soju ila Gusu, oun naa tun ni alaga fun igbimọ  yii.
O ṣe pataki láti fi ṣe awọn ounjẹ bii bisikiti àti wàra, àwọn nkan ti wọn tún fi n se ni láti din ata si oduku, ẹràn tabi láti fi ṣe ọbẹ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Cancer: Àṣe ara mi ni iso ti n run gbogbo bí mo ṣe n ṣèrànwọ́ lórí jẹjẹrẹ Bi ileesẹ Fajemirokun se gbọrẹgẹ-jigẹ: Nigba ti yoo fi di ọdun 1977, ileesẹ Fajemirokun ti n dawọle isẹ kikọ awọn ile itura, ileesẹ to n se mọto nla-nla ati ọkọ akẹru.
Ó sọ fún àwọn iranṣẹ rẹ̀ pé, “Ẹ máa lọ ṣiwaju, èmi náà ń bọ̀ lẹ́yìn,” ṣugbọn kò sọ fún ọkọ rẹ̀.
Bawo wa lawọn ''extra tire'' bi aṣa awọn kan ti ṣe wa na Man City?
Wọn ni kii ṣe ootọ ni ohun ti fidio naa n sọ- pẹlu alaye.
Adia fun ọmọ bibi inu gbajugbaja olorin ilu Ekiti, Elemure Ogunyemi ti gbogbo eeyan mọ si Elemure iyẹn Funmilayo Elemure to fiwa jọ baba ninu gbogbo nkan.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù SWAT: Ìpínlẹ̀ Osun àti Nasarawa ni ẹ̀kọ́ ìgbáradì SWAT ti n wáyé 5 Bélú 2020 Gbagbagba ni ibudo àwọn agbofinro wà ní ní ilé ẹ̀kọ́ Olopaa tó wà ní Egbon, Ìpínlẹ̀ Nasarawa.
Ẹ máa ṣe iṣẹ́ yín bí alabojuto.
Kódà, osere tíátà lọkunrin miran, Afeez Abiodun, tí àwọn èèyàn mọ si Afeez Ọwọ nínú eré tíátà, ní Mide fẹ ni ọkọ, tí àwọn méjèèjì sì jọ jẹ gbajumọ osere ni èdè Yorùbá.
Ile Igbimọ Aṣofin Ipinlẹ Eko, ti o tun jẹ Alaga Igbimọ awọn Agbẹnusọ
95bn sórí reluwé làti Kano sí Niger Republic- PDP Ìkébé mi tóbí ju ohun tí mo lè dọwọ́ bò lọ, n kìí fí ṣakọ- Nkechi Blessing Bi awsn kan ṣe n wọde tako igbesẹ awọn afọbajẹ naa lawọn araalu miran n sọ pe ohun to tọ si kabiyesi oluwo naa.
Obasanjo salaye bẹẹ nigba to n ba awọn eeyan sọrọ nibi ayẹyẹ ọdun kẹtalelọgọrin rẹ nilẹ alaye, eyi to waye nilu Abeokuta.
41 usd fún ìwọ ̀ n egbògi náà kanṣoṣo ní ọdún 2014 .
owo ilu ọlọdọọdun, ki o si gbe e wa ṣiwaju Ile-Igbimọ Aṣofin lati ṣagbeyẹwo
Ṣé ẹ rí i , ẹ jẹ́ kí n sọ fún un yín ní ẹ̀rìnkan sí i, famalay ni famalay ń jẹ́ àti pé ó yàtọ̀ sí ẹbí tí ènìyàn ti wá
ati ogbeni Matthew Oguche,to je omo orile ede Naijiria  lasiko ti won wa si orile ede Naijiria fun
Ṣugbọn ìlúkílùú tí ẹ bá wọ̀ tí wọn kò bá gbà yín, ẹ jáde lọ sí títì ibẹ̀, kí ẹ sọ pé, 
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Arẹgbẹṣọla: Kò sí ìjọba tí kìí jẹ gbèsè Bakan naa ni ọmọ sori ni ile isẹ osisẹ ijọba ibilẹ ni Olorunda ati Oṣogbo.
Bi o tilẹ jẹ wipe ofin ko faaye gba tita tabi mimu ọti bayii ni orilẹede naa, ijọ ọlọtii Gabola ni eyi n pa awọn lara gidi gan lasiko Covid-19 yii.
Nítorí ilé-aiyé dàbí ọ̀bìrìkì, o yẹ́ kí iye wákàtí tí ihà a rẹ̀ kọ̀ọ̀kan fi kọjú sóòrùn jẹ́ méjìlá, kó sì kọ́ju sókùnkùn fú iye wákàtí kannáà.
Ọtí tí wọ́n fi Sanitáísà àti Methanol pò pọ̀ ṣekú pá èèyàn 86 Láti 462 sí 386, àwọn tó ní àrùn Covid-19 já wálẹ̀ ní Nàìjíríà lọ́jọ́ Àbámẹ́ta Dúkìá àti ọjà jóná ráúráú lásìkò tí iná sọ ní ọjà Mushin ní Eko Gbajúgbajà òṣèré India, ọmọ, ìyàwó ọmọ àti ọmọ-ọmọ rẹ̀ lùgbàdì ààrùn Coronavirus Oríṣun àwòrán, Reuters Àkọlé àwòrán, Gbajúgbajà òṣèré India, ọmọ rẹ̀, ìyàwó ọmọ àti ọmọ-ọmọ rẹ̀ lùgbàdì ààrùn Coronavirus Gbajúgbajà òṣèré Bollywood míràn tó jẹ́ aya fún ọmọ Bachchan, Aiswarya Rai àti ọmọ rẹ̀ obìnrin ni àyẹwò ti fi hàn pé àwọn náà ni ààrùn náà.
Ṣùrù lọlá tí ń bọ́ báálé tẹrú tọmọ
Awon igbimo egbe naa ti fowo si atunse ti ojo eto idibo inu egbe naa yoo wayeOjo tuntun ti won mu lo wa nisale yii;25th September, 2018 – Eto idibo aare29th September, 2018 – Eto idibo ti gomina2nd October, 2018 – eto idibo ile igbimo asoju -sofin3rd October, 2018 –Eto idibo ile igbimo asofin, Ilu Abuja4th October, 2018 – Eto idibo ile igbimo asofin ti Ipinle6th October, 2018 – Eto idibo awon oloye egbe(Aare)Ki o to di ojo eto idibo egbe yii,ni egbe yoo bere lati maa se ayewo awon  oludije fun ipo oselu ni osu kẹ́sán án  ,ogúnjọ.
Minisita eto ilẹra lorilẹede naa,Manaouda Malachie sọ wi pe ẹni ọdun mejidinlọgọta lati ilẹ Faranse ni ẹni to gbe arun naa wọ ilẹ Cameroon.
Ó bá dá baba rẹ̀ lóhùn pé, “Ẹ̀bùn kan ni mo fẹ́ tọrọ.
Terseer Kiddwaya ni orukọ rẹ, o si jẹ ẹni ọdun mẹtadinlọgbọn Kiddwaya to wa lati ipinlẹ Benue jẹ oniṣẹ ara rẹ, to si juwe ara rẹ gẹgẹ bi ẹni to ni igboya, to rẹwa lọkunrin, to si n lakaka lati jẹ eniyan laye.
 Amosa, bi won se sun eto idibo naa siwaju , ni eyi ti won
Alagba Tayo Saanuade lati ile iwe Baptist Girl's Grammar School ni Ibadan ni ipinlẹ Oyo ni guusu Iwo oorun Naijiria ni olukọ wa loni.
Ohun akọkọ ti a le fi idi ẹ mulẹ ni pe ọmọde naa ko gbe ọdọ awọn obi rẹ.
Paulu dáhùn ó ní, “Níwájú ìtẹ́ ìdájọ́ ọba Kesari ni mo gbé dúró, níbẹ̀ ni a níláti dá ẹjọ́ mi.
Kódà, àwọn ọlọkada tó wà nibẹ gan tí mú ẹ̀sùn rẹ wà pé, Ó wá ń gba owó oúnjẹ fún Igboho, ẹni tí kìí se ọmọ Ibadan, tó wá ń fi ọwọ la ilẹ̀.
Agbẹnusọ fun Aarẹ Muhammadu Buhari, Garba Shehu lo fi ọrọ naa lede ninu atẹjade kan to fi ṣọwọ si awọn akọroyin lọjọ Abamẹta.
Imuse Ileri ni eyi je Gomina Ambode ninu oro iside re nibi eto agbekale oko ohun ni: “Eyi je okan lara imuse ileri ti a se losu kefa odun 2016 fun gbigbogunti arun jejere lawujo ki a tun le fi mu idagbasoke ba eto ilera wa.
Lai Mohammed: Àtúntò yìí kò wà láti ga àwọn iléeṣẹ́ agbóhùnsẹáfẹ́fẹ́ lọ́rùn
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Oba Adedokun Abolarin ti Oke Ila: Ó ya ọ̀pọ̀ tó súnmọ́ mi lẹ́nu bí mo ṣe ń kọ́ Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Fídíò, The New Pandemic: Kíni àwọn onímọ̀ sáyẹ́ńsì ń sọ nípa rẹ̀?
Lọwọ ti a wa yii, Naira Marley ti fẹẹ di oriṣa akunlẹbọ fun ọpọlọpọ awọn ọdọ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Ohùn gooro ló gbé mi dé ọ̀dọ̀ ààrẹ̀ Bush, Obama, Obasanjo, Goodluck, Buhari' Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Nítorí pé kò fi ojú pa ìjìyà àwọn tí à ń jẹ níyà rẹ́;kò sì ṣá wọn tì,bẹ́ẹ̀ ni kò fi ojú pamọ́ fún wọn,ṣugbọn ó gbọ́ nígbà tí wọ́n ké pè é.
“Ìwọ Solomoni, ọmọ mi, mọ Ọlọrun àwọn baba rẹ, kí o sì fi gbogbo ọkàn rẹ sìn ín tìfẹ́tìfẹ́, nítorí OLUWA a máa wádìí ọkàn, ó sì mọ gbogbo èrò ati ète eniyan.
Agbábọ́ọ̀lù Super Falcons tẹ́lẹ̀, Chiejine jáde láyé lẹ́ni ọdún 36 FRSC dá N443,180 padà fún ẹbí ẹni to ní ìjàmbá mọ́tò Leon van Biljon dí èrò ọrun nípasẹ̀ Kìnìún rẹ̀ Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Ìjọba Akeredolu kò ní omi àánú lójú, a kò tọ́jú alárùn Coronavirus mọ́ - Dókítá Ondo Ẹ̀yin ẹlẹ́gbẹ́ òkùnkùn tẹ fẹ́ ṣe àjọ̀dún lónìí, lákọ la ń dúró dè yín - Iléeṣẹ́ ọlọ́pàá Bí àwọn adarí ìjọba ṣe ń kó Coronavirus, ń kọ wá lóminú - Ìjọba àpapọ̀ Àkójọ́pọ̀ àwòrán rèé lórí bí ìwọlé akẹ́kọ̀ọ́ ṣe lọ sí ní Oyo 4.
Ṣaaju, LASTMA gba awọn awakọ nimọran lati lọ gba awọn ọna abuda mii lọ si ibi ti wọn ba n lọ kawọn oṣiṣẹ le doola awọn to fara gba ati ki ọna le la.
"O ni: ""Nigba ti baba mi rí i pe mo ti loyun, o mu mi lọ si ile itaja òògùn kan."
Mí o lè gbà iṣẹ́ Tottenham torí pé mò nífẹ Chelsea púpọ jù-Mourinho Osimhen jẹ́wọ́ ara rẹ̀ bí Nàìjíríà ṣe lu Lesotho lálùbolẹ̀ mọ́lé wọn Lucas Moura lo gba bọọlu keji wọnu awọn, nigbati Harry Kane si ran Serge Aurier lọwọ lati gba bọọlu naa wọ inu.
Kọmiṣọnna fun iṣẹ ṣiṣe Dokota Raji Abdulrasaq ni yoo maa tukọ ile iṣẹ ijọba to n ri si eto ilera nipinlẹ Kwara.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Árẹ̀wá: Bákan náà ni a kò fẹ́ Atiku torí dúkìá àjọni wà tó fẹ́ tà 24 Ẹrẹ̀nà 2019 Oríṣun àwòrán, @Atiku Akọwe apapọ fun ẹgbẹ apapọ awọn eeyan apa oke ọya, Anthony Sani ti kede idi ti ẹgbẹ naa se kẹyin si oludije fun ipo aarẹ labẹ asia ẹgbẹ oselu PDP, Atiku Abubakar.
Ati pe ara ijọba ipinlẹ Ọyọ kọ otitọ ọrọ ni wọn ṣe fẹ gbe igbesẹ naa.
Digbi n'ijọba Kogi wa - Yahaya Bello Yàjóyàjó: Èsì ìdìbò Kogi tó gbé Yahaya Bello wọlé rèé Darandaran tun gbẹmi mẹẹdọgbọn ni Kogi Èèyàn 2,040 làwọn agbésùnmọ̀mí ti pa ní Nàìjíríà lọ́dún yìí- Ìwádìí Gomina Bello ati Onoja igbakeji rẹ a bẹre iṣẹ fun saa iṣejọba tuntun yii ni ọjọ kẹtadinlọgbọn, oṣu kinni, ọdun 2020.
Baba oloogbe naa ni alaga ẹgbẹ Afẹnifẹre, alagba Reuben Fasoranti.
Geoffrey Onyeama dahun si ibeere lori ọrọ idajọ awọn aṣofin UK lasiko to n ba awọn akọroyin sọrọ nilu Abuja to jẹ olu ilu Naijiria ni ọjọru.
Abimeleki bá pe Isaaki, ó wí pé, “Àṣé iyawo rẹ ni Rebeka!
"O sọ pe: ""Nitorina, wọn ko ni idi kan lati jade kuro ni ipinle."
Ẹni to bori: Nigeria Tanzania vs Egypt.
Agbarijọpọ awọn ọlọpaa ọtẹlẹmuyẹ ati akẹgbẹ wọn lati Interpol ni wọn pawọpọ mu awọn afurasi wọn yi.
Ni kete to pari saa iṣejọba rẹ lo ti lọ jọwọ ara rẹ fun ajọ naa ni ọdun 2018.
Dáúdà á tilẹ̀ máa fi rọ́bà rẹ̀ tú ìtẹ́ ẹyẹ tí yóò sì pa ẹyẹkẹ́yẹ tí ó bá rí níbẹ̀.
Felicia jẹ ko di mimọ wi pe ki wọn to lọ wu ẹgẹ ni oko, ki wọn to bẹẹ, ṣiṣan, lilọ, kiko, titẹ ri ati bẹẹ bẹẹ lọ plu imọtoto, kii ṣe ere ọmọde rara.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ẹ jẹ́ ká dá ìbọn kọjá, tó bá jẹ́ pé Oluwo kò fìyà jẹ́ mí - Agbowu Ilé aṣòfin Oyo àti Ogun buwọ́lu àbádòfin ikọ̀ aláàbò Amotekun Nǹkan yan, kò sí àmì ìfẹ́ mọ́!
Mójú kúrò lára ẹ̀ṣẹ̀ mi,kí o sì pa gbogbo àìdára mi rẹ́.
Wolii àgbàlagbà kan wà ní ìlú Bẹtẹli ní ìgbà náà.
 Bruna Marquezine to jẹ ọmọ ọdun mejilelogun lati ilẹ Brazil.
Lọjọ Aje ni ọga agba ọlọpaa kede pe igbesẹ atunto ti oun kede rẹ jẹ ọna lati mu atunṣe ba ajọ SARS.
Lẹhin ìbànújẹ́ yi, ó gbáradi, ó tọ àwọn àgbà lọ fún ìmọ̀ràn.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù USSD: Ìjọba àpapọ̀ bẹ̀rẹ̀ ìwàdíí lórí owó orí tí MTN fẹ́ yọ̀ 20 Ọ̀wàrà 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 21 Ọ̀wàrà 2019 Oríṣun àwòrán, Others Mínísítà fùn eto ìbárẹnisọ̀rọ̀ Isa Pantami, tí pàsẹ oní wàrànsesà fún ilé iṣẹ́ MTN àti àwọn ilé iṣẹ́ ìbánisọ̀rọ̀ míràn láti dẹ́kun ìpinu rẹ̀, lóri fífi náírà mẹ́rin owó àtẹjisẹ lorí onibara rẹ̀, tó fẹ fi owo rànsẹ́ sí ẹlòmíràn láti orí ẹ̀rọ ìbánisọ̀rọ̀ rẹ̀.
Ìgbẹ́ ọ̀ọ̀nì yì ti di oògùn ara lílé fáwọn èèyàn kan.
O tun fi asiko ohun da awon osise ijoba loju pe, ijoba oun yoo yan
Bẹ́ẹ̀ ni ó ṣe mú alaafia wá sáàrin wọn.
Wọn fẹsun kan aarẹ Trump pe o mura mọ aarẹ Zelensky lati ṣe iwaadi igbakeji aarẹ ana, Biden to n ba du ipo.
Gomina naa ni ọjọ marun ni oun fi gbaawẹ nigba naa, ti ọfọ si ṣe oun nitori wipe ẹkùn naa n mu owo wa si ipinlẹ naa lọpọlọpọ.
Àwọn tí ó ní ilẹ̀ tabi ilé tà wọ́n, wọ́n mú owó tí wọ́n tà wọ́n wá, 
Ṣugbọn ni ti Arabinrin Dupe Alabi, ko ri bẹ o.
Awọn ija abẹle bii ede aiyede pẹlu awọn alejo ni eyi ti wọn ni awọn alejo n gba iṣẹ awọn ṣe.
Wọ́n pe orúkọ ibẹ̀ ní Kiburotu Hataafa, èyí tí ó túmọ̀ sí ibojì ojúkòkòrò, nítorí níbẹ̀ ni wọ́n sin òkú àwọn tí wọ́n ṣe ojúkòkòrò ẹran sí.
Joabu, tí orúkọ ìyá rẹ̀ ń jẹ́ Seruaya, ati àwọn iranṣẹ Dafidi yòókù lọ pàdé wọn níbi adágún Gibeoni.
Àbí ta ló lè wọ inú odi ìlú wa?
Tí ẹ bá wí pé, “Bẹ́ẹ̀ ni,” bẹ́ẹ̀ gan-an ni kí ó jẹ́.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Afunrasí jàǹdùkú 22 lọ́wọ́ ọlọ́pàá ti tẹ̀ lórí wàhálà ìdìbò ní Kogi-Iléeṣẹ́ Ọlọ́pàá Ọlọpàá gba owó ilé ìwé #150,000 lọ́wọ́ akẹ́kọ̀ọ́ DELSU kan Ikú ni fífi oògùn 'Paracetamol' bọ ẹran tàbí se ẹ̀wà- Iléeṣẹ́ ìlera Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
” Nígbà tí àwọn ará Jabeṣi gbọ́ ìròyìn náà, inú wọn dùn gidigidi.
Nígbà tí wọn ń jẹ ẹran náà, ibinu OLUWA ru sí wọn, ó sì mú kí àjàkálẹ̀ àrùn jà láàrin wọn.
Sibẹ ó ń retí pé Paulu yóo fún òun ní owó.
Abenugan ni awon ojuse kan wa nilẹ  nile igbimọ asofin ti won gbodo yanju , ni
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Itan Ilu gangan O tun ni aaye wa lati pe tabi sọrọ ni kikun lori ayelujara pẹlu awọn osisẹ to n risi ọ̀rọ̀ owo ori lai rinrin ajo wa si ilu Ibadan ni olu ileeesẹ wọn bii ti atijọ O pari re pe awọn ti kọwe ransẹ si awẹn onile ise kaakiri lori igbesẹ ijọba yii.
Iroyin ni ile nọọsi kan to jẹ aburo rẹ to ti n gba itọju fun ibọn to baa naa ni ọwọ ti tẹ ẹ nilu Eko.
0 434 Orilẹede Cambodia 0 0.
Ogbeni Femi Adesina so pe, titako isakoso isejoba aare Buhari ni ogbeni Oshuntokun yan laayo ni ti e.
 A si n tun fojusona fun ibasepo to monyan lori laarin orile ede mejeeji naa.
Olóhùn-ún-dùùrù sì dá a lóhùn pé òun lè fun fèèrè dáadáa.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Badagry ní ogún àjogúnbá tó pọ̀ yàtọ̀ sí òwò ẹrú Ọrọ yii sare tan kaakiri ori Facebook, eyi to mu ki awọn olori ẹsin o bu ẹnu ẹtẹ lu u, ti wọn si n kede pe ki wọn fi ofin mu wọn.
Ó fi àwọn ẹran ọ̀sìn wọn dí oúnjẹ fún wọn ní ọdún náà.
Gege bi iroyin to jade pe,lara ohun ti Trump yoo maa jiroro pelu aare  Buhari ni idagabsoke eto oro aje  ati gbigbokun ti ikọ awon  ọlọtẹ.
Bẹnaya ati Jahasieli, tí wọ́n jẹ́ alufaa, ni wọ́n ń fọn fèrè nígbà gbogbo níwájú Àpótí Majẹmu Ọlọrun.
Ben-Shoshan so pe,‘‘Odun to n bo ni ibasepo laarin
Davido: Mo fẹ́ràn Chioma púpọ̀, ọ̀la wa máa dára
Aare Muhammadu Buhari ni yoo jẹ adari kẹ́tàléláàdọ́ta fun ajo ECOWAS.
Josẹfu pàṣẹ fún alabojuto ilé rẹ̀, ó ní, “Ẹ di ọkà kún àpò àwọn ọkunrin wọnyi, bí wọ́n bá ti lè rù tó, kí ẹ sì fi owó olukuluku wọn sí ẹnu àpò rẹ̀, 
Iwe adehun naa ni Gomina Abiola Ajimobi fowosi loruko
ni deede aago mẹ́ta  osan oni.
Oríṣun àwòrán, Toba Babalola Àkọlé àwòrán, Oun to mu ki arakunrin Olaoye pokunso ko ye ẹnikankan Babalola salaye pe ni nnkan bi aago merin abọ ọjọ iṣẹgun ni Olaoye to jẹ ọmọ bibi ilu Igogo Ekiti, ni ijọba ibilẹ Moba,wa si ile oun ti o si n bọkan jẹ nipa ipenija aisiowo lọwọ ti o n ba finra.
O wa sísọ lójú rẹ fún àwọn olólùfẹ́ rẹ pé, òun ń pò ère kan pọ lọ́wọ́, tí àkọlé rẹ ń jé 'Alẹ́ lagba', èyí tí yóò kọ wọn ní ẹ̀kọ́ láti múra fún ọjọ́ alẹ wọn lati ìgbà òwúrọ̀, ó ní kí wọ́n má sì lo òwúrọ̀ wọn jatijati, èyí tó leè kò bá ọjọ́ alẹ wọn.
Awọn oṣiṣẹ ileejọsin naa mẹfa miran n jẹjọ pẹlu woli Babatunde lori ẹsun ijinigbe ati igbimọpọ huwa ijinigbe.
AbdulWahab Omotose Kayode ti jawe olubori nínu idibo abẹlẹ ipinlẹ Kwara gẹgẹ bi oludije.
Ajimobi naa fi idunnu re han bi eto idibo se n lọ  ni irọwọ ati irosẹ, o tun wa gbosuba fun Ajo eleto
Ọjọ kẹtalelogun oṣu Kẹrin ni wọn yoo bẹrẹ si ni ka esi ibo.
Gbà mí ninu gbogbo ẹ̀ṣẹ̀ ìrékọjá mi;má sọ mí di ẹni ẹ̀gàn lójú àwọn òmùgọ̀.
: Minista fun ọrọ obinrin fesi pe:.
Nígbà tí Jotamu kú, wọ́n sin ín ní ìlú Dafidi, Ahasi ọmọ rẹ̀ sì jọba lẹ́yìn rẹ̀.
Gbogbo ẹni tí ó bá sì fi ilé tabi arakunrin tabi arabinrin, baba tabi ìyá, ọmọ tabi ilẹ̀ sílẹ̀, nítorí orúkọ mi, yóo gba ìlọ́po-ìlọ́po ní ọ̀nà ọgọrun-un, yóo sì tún jogún ìyè ainipẹkun.
Awọn ti iṣẹlẹ naa ṣoju wọn sọ fun ileeṣẹ amohunmaworan Arab television pe niṣe ni awọn oṣiṣẹ alaabo ọhun bẹrẹ si ni yin ibọn, ti awọn afẹhonuhan naa si n sọ pe ọna lati da iwọde ti wọn n ṣe ni ita ileeṣẹ ijọba to wa fun eto aabo ru ni.
Mo di i lokun mo si gba ọrọ lẹnu rẹ.
Ọmọ bibi ilu Okpara nijọba ibilẹ ila oorun Ethiope, nipinlẹ Delta si ni akikanju oṣere tiata yii.
Bẹ́ẹ̀ gẹ́gẹ́, ìfarahàn díẹ̀díẹ̀ ti ètò iṣẹ́ àbójútó Ìjọ ni a fihàn pẹ̀lú pípè àwọn bíṣọ́pù, Àjọ Ààrẹ Ìkínní, Ìgbìmọ̀ ti àwọn Méjìlá, àti ti Àádọ́rin àti ìgbékalẹ̀ àwọn ipò iṣẹ́ ìdarí àti àwọn ìyejú mĩràn.
Aranṣọ, olórin àti àwọn mì í ti ko fẹ́ kí ìdìbò kásẹ̀ nílẹ̀ ní Nàìjíríà Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, #BBCNigeria2019: Nnamdi Kanu sọrọ lórí àwọn oludije PDP àti APC Nigba ti BBC tẹsiwaju lati beere alaye lori ọrọ yii, Ijeoma Igbokwe to jẹ ọkan lara awọn oṣiṣẹ Inec lẹka idanilẹkọ nipa idibo sọ pe ko si ika ti eeyan ko le lo lati fi tẹka.
OLUWA jókòó, ó gúnwà lórí ìkún omi;OLUWA jókòó, ó gúnwà bí ọba títí lae.
EFCC gbe osisẹ banki tẹlẹ lọ sile ẹjọ Ninu iroyin miran ẹwẹ, ajọ to n gbogun ti iwa ibajẹ ni Naijiria, EFCC ti gbe osisẹ ile-isẹ ifowopamọ tẹlẹri, Adejare Sonde re'le ẹjọ giga to wa ni Abeokuta, ni ipinlọẹ Ogun.
2) Kiakia ni ina ifẹ wọn maa n sare jo ni kete ti wọn ba ti dẹnu ifẹ kọ ara wọn.
Oríṣun àwòrán, Gold Kolawole Joseph ni, ni kete ti ọkunrin naa pe awọn lori aago, to si tun fi atẹjisẹ ransẹ lori owo to n beere yii, ni awọn bẹrẹ isẹ, to si foju han pe ilu Portharcourt lo ti n ba ileesẹ ọlọpa sọrọ, kii se ilu Akurẹ, gẹgẹ bo se sọ ninu ọrọ rẹ.
Ni ibẹrẹpẹpẹ, wọn ni ọpọ awọn ọmọbirin naa lo ti rari bọ, ati wi pe wọn ko ji enikankan gbe.
Ilẹ ti wọn san ọhun kun fun koko ati obi.
Bí wọ́n ti ń wakọ̀ lọ, Jesu bá sùn lọ.
Ọdọmọde agbabọọlu Phil Foden lo gba goolu sawọn fun Manchester City lẹyin iṣẹju marun un ti ere bọọlu naa bẹrẹ ti City si bori pẹlu ami ayo kan sodo.
Ẹwẹ, arabinrin Oluwatoyin Olutope Adaramodu to jẹ iya Daniel ko kọkọ gbagbọ nigba ti ọmọ dele royin pe gomina fẹ di ọrẹ oun.
Oríṣun àwòrán, Ile igbimo Àkọlé àwòrán, ọmọ ilé igbimọ Asofin Olubunmi tunji-ojo ní lati yọ ara rẹ̀ kuro ni ibujoko awon to n se iwadii.
Ti a o ba gbagbe pe aare Muhammadu
"O ni ""Ni owurọ yii ni mo gab esi ayẹwo fun arun Coronavisur, esi ọhun si fi han pe mo ti ni arun naa."
Awọn olufẹhonuhan naa duro wamu wamu sẹnu geeti to wọ ileeṣẹ ijọba ipinlẹ Oyo eleyi ti ko jẹ kawọn oṣiṣẹ ri aye wọle.
Lekki Tollgate shooting: Fídíò táa ní lọ́wọ́ kò ṣàfihàn gbogbo ohun tó ṣẹlẹ̀ nírọ̀lẹ́ ọjọ́ náà
'Àáfà aríran yóò jìyà ẹ̀ṣẹ̀ ìfipábánilòpọ̀' Kìnìún tí wọn ń sìn yarí, ó pa olówó ati ọmọ olówó rẹ̀ Lojiji lọganjọ oru lo gbọ ariwo nile idana rẹ to fi ri i pe ọọni aleegba ti wa ba oun lalejo.
Nígbà tí ó gbà á, àwọn ẹ̀dá alààyè mẹrin ati àwọn mẹrinlelogun náà dojúbolẹ̀ níwájú Ọ̀dọ́ Aguntan yìí.
Abo ko si fun wa rara bayi.
Oríṣun àwòrán, @others Àkọlé àwòrán, Nọ́mbà 6: Apoti fẹdẹko yii lo maa n jẹ ki idije bọọlu pẹlu awọn oyinbo maa dawati too baa yii si ẹgbe osi ju nigba ti eeyan dudu a jona too baa yii sẹgbẹ otun ju Oríṣun àwòrán, @others Àkọlé àwòrán, Nọ́mbà 7: Se ẹ ranti atupa oke Telifiṣọn yii?
Mẹta ninu awọn ẹgbẹ alatako lo ti ko ara wọn jọ labẹ aburada ẹgbẹ Umbrella for Democratic Change (UDC) Eto ipolongo ti wọn gbe kalẹ ni ileri ipese ẹgbẹrun lọna ọgọrun iṣẹ lorilẹede naa bi wọn ba wọle.
Bo ti lẹ jẹ wipe o ya eniyan lẹnu julọ, awọn dokita lorilẹ-ede Kenya ti yọ burọọsi ifọyin kuro ni ikun arakunrin kan to gbe e mi.
Ọlọrun gbọ́ ẹ̀bẹ̀ Lea, ó lóyún, ó bí ọmọkunrin karun-un.
Kí ló pa Bobrisky àti Olorì Aláàfin Oyo pọ̀?
Fi gbogbo àdáwọ́lé rẹ lé OLUWA lọ́wọ́,èrò ọkàn rẹ yóo sì yọrí sí rere.
Oríṣun àwòrán, @Sanwoolu Ìjọba ìpínlẹ̀ Eko kéde ọjọ́ tí àwọn iléèwé gígá yóò wọlé Gomina ipinlẹ Eko, Babajide Sanwo-Olu ti kede pe ọjọ kẹrinla, oṣu Kẹsan an, ọdun 2020 ni gbogbo ileewe giga to wa ni ipinlẹ naa yoo bẹrẹ pada.
Tó bá di ìgbà náà, ìlú marun-un yóo wà ní ilẹ̀ Ijipti, tí wọn yóo máa sọ èdè Kenaani; wọ́n óo búra láti jẹ́ ti OLUWA àwọn ọmọ ogun.
Aare tun tesiwaju pe iku George H.
Ile ise Munilla Construction Management lo ko afara naa.
Ní ọjọ́ náà, àárẹ̀ yóo mú àwọn tí wọ́n lè sáré; ipá àwọn alágbára yóo pin, akikanju kò sì ní lè gba ara rẹ̀ sílẹ̀.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù 'Ilé ìwòsàn ṣi abẹ́rẹ́ Formalin gún mí; n kò lè dá ìgbẹ́ àti ìtọ̀ dúró mọ́' Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ 'Ilé ìwòsàn ṣi abẹ́rẹ́ Formalin gún mí; n kò lè dá ìgbẹ́ àti ìtọ̀ dúró mọ́' 10 Owewe 2018 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 3 Èbibi 2020 Ọ̀rọ̀ ọmọ bíbí ni mo bá dé ilé ìwòsàn ìjọba kí wọn tó ṣi abẹ́rẹ́ gún mi.
 irú àwọn báyìí ni Ègùn tí wọn wá ni Àgọ ́ - Ègùn , Ìjàyè- ni Àgọ ́ - Ìjàyè , àti àwọn Ìbàràpá ni Ìbẹ ̀ rẹ ̀ kòdó àti ni arínlẹ ́ sẹ ̀ .
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Baldness: Àwọn tí irun wọ́n ti gbá rìfáàsì sọ ìrírí wọn àti àǹfàní tí wọ́n ń jẹ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Baldness: Àwọn tí irun wọ́n ti gbá rìfáàsì sọ ìrírí wọn àti àǹfàní tí wọ́n ń jẹ 31 Ọ̀wàrà 2020 Ṣé lóòtọ́ ni pé orí olówó ni ti apárí?
Ìdodo rẹ dàbí abọ́,tí kì í gbẹ fún àdàlú waini,ikùn rẹ dàbí òkítì ọkà,tí a fi òdòdó lílì yíká.
Wọn fi lede wi pe awọn ti se ẹrọ ti yoo mu ki eniyan ba ewe Tulip sọrọ,ti ewe naa yoo si ma a fun eniyan lesi.
Agbẹnusọ fun ẹgbẹ Nigerian Scrabble Federation, Akintunde Akinsemola, to fi idi iṣẹlẹ naa mulẹ fun BBC Yoruba ni, wọn ri oku rẹ ni agbegbe Idoani ni ijọba ibilẹ Ọṣẹ nipinlẹ Ondo.
Samuẹli ṣe àlàyé àwọn ẹ̀tọ́ ati iṣẹ́ ọba fún àwọn eniyan náà.
Taiwo Bamidele Ondo Dwarf Judge: Ọlọ́run kò ṣe àṣìṣe pé ó dá mi ní aràrá
#U20WC: Flying Eagles fìyà ṣínu ààwẹ̀ lórílẹ́èdè Poland Ọ̀gọ̀rọ̀ èèyàn lórí ayélujára bú Dalung lórí owó IAAF Orúkọ àwọn Super Falcons 23 tó ń lọ France ti jáde Ọ̀tá Nàíjíríà ni Saraki àti Dogara - Buhari Igba kẹfa niyi ti ikọ agbabọọlu Chelsea yoo ma koju Arsenal ni ifẹsẹwọnsẹ to jẹ asekagba Europa League.
Lẹyin ti iya wa ku, oun kan ṣoṣo to ran wa lọrọ ni ikẹdun ati ọfọ ti awọn oriṣiriṣi eniyan fi han.
Wo gbogbo àwọn agbéraga, kí o sì sọ wọ́n di yẹpẹrẹ,rún àwọn ẹni ibi mọ́lẹ̀ ní ipò wọn.
Ìbọn àti afẹ́fẹ́ aláta ní DSS fi tú wa ká lásìkò ìwọ́de fún ìdásílẹ̀ Sowore Adelabu wa kadi ọrọ rẹ nilẹ pe lẹyin okunkun imọlẹ yoo tan, ko si bo ti wu ko pẹ to, ti oorun ba ti n yọ, isẹgun daju fun oun ati awọn eeyan ipinlẹ Ọyọ.
Ìwọ ọmọ mi, gbọ́ ẹ̀kọ́ baba rẹ,má sì kọ ẹ̀kọ́ ìyá rẹ,
Apapa Accident: Ọ̀ga RRS ní kò sí ẹ̀mí tó nù lẹ̀yìn ti agolo akẹ́rù wó lu ọkọ̀
Bi a ko ba gbagbe wipe, lose
Dbanj wa ni orileede Amerika nibi ayeye idanilola BET.
Ẹwẹ, aarẹ ni oguna gbongbo ni olu ilu orilẹede yii, Abuja jẹ ni Naijiria eyi ti iṣejọba oun yoo mu ọrọ wọn lọkunkundun bi o tilẹ j pe wọn ko dibo fun oun ninu idibo to kọja lọ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Operation Amotekun: Amọ̀tẹ́kùn ṣetán láti gbérasọ, fọ́ọ̀mù ìgbaniṣíṣẹ́ ti dé!
Oríṣun àwòrán, Ogun State Governor's office Àkọlé àwòrán, Ìró ilu maa n jẹ ọna ibaraẹnisọrọ laarin eniyan meji tabi ju bẹẹ lọ, bi ẹrọ ibaraẹnisọrọ ṣe ri l'ode oni.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Akomolede Oyo round up: Àwọn Olúkọ ìpínlẹ̀ Oyo fakọyọ lórí ètò Akọ́mọlédè àti Àṣà púpọ̀ 27 Bélú 2020 Eto Akomolede ati Aṣa lori BBC tun ti jo lọ si ipinlẹ Oyo.
Wọ́n ni kò si àníàní, Laycon lo ni owó tó wà níle ẹgbọ́n àgbà, àti pé ki Terrywaya lọ wá owó tirẹ̀ síwájú, níwọ̀n ìgbà tó jẹ́ pé olówó ni bàbá òun.
da eto okoowo sile lorile ede Naijiria bayii.
Saaju, alaga igbimo ohun, Sir Henry Eteama so pe igbimo naa n se ojuse won bi o se to ati bio se ye ni ibamu pelu ofin ati ilana ile okere.
Niwọn igba ti ko ti si adehun ti wọn yoo fẹnu ko le lori, ilẹ Gẹẹsi yoo kuro ninu ajọ isọkan ilẹ Yuroopu ni kiamọsa lai se adehun kankan lori ọna ti igbesẹ lilọ wọn yoo da le lori.
Ìjọba ìpínlẹ̀ Ogun fún àwọn ọmọ ilé ìwé ní ìgbéga sí kílààsì tó kàn láì ṣe ìdánwó nítori Covid-19 Ẹ wo ààrẹ orílẹ̀-èdè tó ń ṣèdárò Ẹja akóredé tó d'olóògbé Ìjà ẹgbẹ́ òṣèré TAMPAN àti ANTP ni kò jẹ́ kí wọ́n pe Baba Legba sínú eré mọ́, kó tó kú - Owolabi Ajasa Owó lítà epo ní Nàíjíríà ló kéré jùlọ l‘Áfíríkà - Lai Muhammed Wọ́n ti fa Ààrẹ Amẹrika, Donald Trump kalẹ̀ fún àmì ẹ̀yẹ Nobel Peace Prize Wọ́n tun ka awọn nkan miran ti wọn ji bi ẹrọ amunawa, faanu, ina lanta igbalode, ati aga onike mẹrinlelogoji ti owo gbogbo rẹ si to ẹgbẹrun lona ọọdunrun naira din diẹ, sugbọn iwadii si n tẹ siwaju.
Bi o ba se n lọ nipa ọrọ yii, a tun mu wa fun yin.
"Emi gan ko pe mọ pe Ọlọrun ma gbe mi de ipo ti mo wa lonii, o si ma n dun mi pe n ko le kopa ninu ere tiata oloyinbo nitori aikawe mi, ti ero aitẹgbẹ si maa n mu mi.
niluu Abuja lọjọ Aje(Monday), ni aare Buhari ti se ikilo ohun.
A tun gbe igba oroke ninu ijakadi yii lọna ti eti ko gbọ ri ni ipinlẹ yii."
Àwọn afurasí tí ọlọ́pàá ká orí èèyàn mọ́ lọ́wọ́ ní ìlú Akure ti fojú balé ẹjọ́
Mama Nma tun jẹ aburo si Emir ikẹwaa to jẹ ni Ilorin ati iya to bi Emir to wa lori oye bayii, Alhaji Ibrahim Sulu-Gambari CFR.
Oríṣun àwòrán, Adewale Adeoye/Facebook Àkọlé àwòrán, Ẹnu pọ bii atakara.
Eeyan 8,253 lo ti ri iwosan gba, nigba ti awọn 554 ti dero ọrun nitori arun ọhun.
Ajẹ́pé Yoòbá gbọ́n Èèbó gbọ́n ni wọ́n fi dá ilẹ̀ London 🙂
Wo àwárí akọ́ṣẹ́mọṣẹ́ yìí Ọgbẹni Sulaiman rọ Tinubu pe ko gbọdọ ṣojo lati sọrọ bo tilẹ jẹ pe o n gbero lati dupo aarẹ orilẹede Naijiria.
Àwọn ọ̀gágun wá láti Makiri,àwọn olórí ogun sì wá láti Sebuluni.
Ṣugbọn inú bí àwọn kan níbẹ̀, wọ́n ń sọ̀ láàrin ara wọn pé, “Kí ló dé tí a fi ń fi òróró yìí ṣòfò báyìí?
GMT:  gbogbo eto lo ti to sile bayii fun ikede awon abajade esi
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Joyce Banda, Ààrẹ àná ni Malawi t'ajode Ààrẹ Brazil tẹ́lẹ̀ yóò f‘ẹ̀wọ̀n jura Ẹ múra fún ogun ijọba àpapọ̀ - Ọbásanjọ́ Àtẹ̀jáde ọ̀hún wáyé látàrí awuyewuye kan láti ọ̀dọ̀ àwọn alátakò pé ààrẹ Akufo tí fọwọ́ sì òfin náà lórílẹ̀èdè Ghana.
Oríṣun àwòrán, ProfOsinbajo Àkọlé àwòrán, ọrọ̀ ìfẹ bí àdánwò ní.
Jamilu Ibrahim-Boyi, ti o je alaga fun egbe awon agbe oniresi ni ijoba ibile Mani, ni o soro iwuri yii lasiko iforo wani-lenu wo pelu awon oniroyin lojo-Isegun.
S Oworonshoki - Ebute Ero Oworonsoki - Five Cowries Owó ọkọ̀ ojú omí kò ju ẹ̀dẹ́gbẹ́ta naira sí ẹgbẹ̀run kan naira ló, sùgbọ́n fún ẹ̀kúnrẹrẹ àláyé lórí bi owó náà ṣe jẹ́ wan ojú òpó twitter ìjóba ìpínlẹ̀ Eko yìí: Àkọlé àwòrán, Third mainland bridge mo foo Àwọn ibi ti ọkọ̀ ojú omi máa n ná Ọ̀pọ̀ ni ìbẹ̀ru ti mú pe'súnkẹrẹ fàkẹrẹ ọkọ lọ́la ọjọ́ ajé yóò lóyun sinu, yóò pọmọ kódà yóò tún fa báàgì.
Oríṣun àwòrán, POLICENG_PCRRU/TWITTER Àkọlé àwòrán, Iwa aṣemaṣe awọn oṣiṣẹ ikọ SARS ti di ohun ti gbogbo eeyan lorilẹede Naijiria n bu ẹnu atẹ lu bayii Ọgọọrọ awọn ọmọ orilẹede Naijiria lo si tun ti tọwọ bọ iwe ẹhonu kan ti wọn gbe ka iwaju ile aṣofin apapọ orilẹede naijiria lati pe fun wiwọgile ikọ naa, amọṣa lẹyin ọpọlọpọ oṣu, ikerora lori ikọ SARS ati aṣemaṣe wọn ko tii kuro lẹnu awọn ọmọ orilẹede Naijiria.
Wọ́n bá fà á jáde sẹ́yìn odi ìlú, wọ́n sì sọ ọ́ lókùúta pa.
Jẹ́ kí ìfẹ́ rẹ tí kì í yẹ̀ máa tù mí ninu,gẹ́gẹ́ bí ìlérí tí o ṣe fún èmi, iranṣẹ rẹ.
Shiite: Èmi kò ní kí Shiite má ṣe ẹ̀sìn wọn o -Muhammadu Buhari
Họ́wù o, èmi nìkan ló wà láyé ni?
Ohun ti wọn n bere fun ni ki ijọba san owo oṣu ti wọn jẹ wọn, ki wọn si san owo ajẹmọnu ti ijamba ba ṣẹlẹ si oṣiṣẹ ilera lẹnu iṣẹ.
O pari atẹjade ọhun pe, wọn ti fi ọrọ naa to awọn ẹbi oloogbe leti.
 A n koju opolopo idojuko lori isokan Naijiria lasiko yii lataari ede orisiirisii ti a ni pelu asa ati iran otooto ti o ye ki ajo fi fowosopo fi di osusu owo dipo eleyameya ti a n je ki o joba laarin wa.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ǹjẹ́ oòrùn tàbí oru leè pa àrùn Coronavirus bí?
Ó ní,“Wò ó, omi kan ń ru bọ̀ láti ìhà àríwá,yóo di àgbàrá tí ó lágbára;yóo ya bo ilẹ̀ yìí ati gbogbo ohun tí ó wà lórí rẹ̀,yóo ya bo ìlú yìí pẹlu, ati àwọn tí wọn ń gbé inú rẹ̀.
Inú bí bàbá mi, Olówó-ayé fọn bí erin, ó ní, Bí ìyà ńlá bá gbé ni ṣánlẹ̀, kéékèèkéé a gun orí ẹni, bí kò bá sí ìyà igbó ọdẹ, ìwọ a máa yáájú sí mi!
Ó sì tún wáá sọ bí ó tí jẹ́ pé ọ̀rọ̀ àwọn èkúté tí òun ń gbọ́ ni ó mú kí òun rẹ́rìn-ín tí ó sì di pé ìyàwó òun wí pé òun ń bú òun.
Ilé isẹ́ ìgbóhùsáfẹ́fẹ́ SSBC dá ètò Ilé isẹ́ BBC dúró
5M ti pọ̀ jù fún owó fọ́ọ̀mù ìdìbò abẹ́lẹ́ sípò gómìnà APC - SERAP Iwe iroyin The Sun sọ pe ọba naa gun ori oye lọdun 1981.
’’ Iwa otitọAare tun gbosuba fun Alaafin  lori iwa akin,otito ati imo to ye koro , ni eyi to je ipile ilu Oyo ,to jẹ agba fun gbogbo ilu to wa lorile ede Naijiria.
Ọlọ́pàá Germany ti mú àfurasí mẹ́rin nínú àwọn tó kọlu Ekweremadu ni Germany Ọwọ́ ti tẹ ọlọpàá mẹ́rìn to pa afurasí Nǹkan kò ṣẹnuure fáwọn obìnrin nínú ìgbìmọ̀ ìṣèjọba Buhari Àwọn ọmọ Yorùbá wo ni mínísítà ní ìjọba Buhari?
Wọ́n fi ògo fún Ọlọrun tí ó fi irú àṣẹ bẹ́ẹ̀ fún eniyan.
Aláàfin yẹ́ Lizzy Anjọrin sí níbi ayẹyẹ ìwúyè rẹ̀ Òṣìṣẹ́ ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́ gúnle ìyanṣẹ́lódì Ọpọlọpọ awọn ololufẹ awọn akọrin naa ni wọn n woye nigbati iroyin jade pe igbeyawo wọn yoo waye ṣugbọn iyalẹnu lo jẹ nigba ti wọn fi eto igbeyawo naa ṣe bonkẹlẹ.
A óo ré odò Jọdani kọjá láti jagun gẹ́gẹ́ bí o ti sọ.
Nítorí bí mànàmáná ti ń kọ ní ìlà oòrùn, tí ó sì ń mọ́lẹ̀ dé ìwọ̀ oòrùn, bẹ́ẹ̀ gan-an ni dídé Ọmọ-Eniyan yóo rí.
Ọna abayọ si ni lati ma a sinmi lati igba de igba Ẹjẹ Riru: Eyi naa le e fa iku ojiji.
Bi o tilẹ jẹ pe orilẹede Russia n pese okuta iyebiye yii ju Botswana lọ, sibẹ ibudo iwakusa mẹrin lorilẹede Botswana lo n pese okuta iyebiye Dayamọndi to dara julọ lagbaye.
Ẹgbẹ́ náà kọ ìdá mẹ́tàlélógun ti àwọn gómìnà ti ṣètò fún wọ́n, bó tilẹ̀ jẹ́ pé èyí gbé pééli díẹ̀ sí ìdá ogun o lé diẹ̀ ti wọ́n ń gba tẹ́lẹ̀ lọ.
 Pe  wọn  ti yi ipinnu  wọn  pada pe ki n wa si ago  wọn  sugbọn pe ki n kọwe lati fi ransẹ si  wọn  lori ẹsun ti  wọn  fi kan mi laarin wakati mejidinlaadọta – ni eyi ti mo lero lati se.
”Minista ko sai fi idunnu re han bi ise naa se n lo si , o tun wa so fun awon kongila naa lati tubo jara mo ise naa.
A ti fi owo to din ni  ọ́ọ̀dúnrún milionu
Bakan naa lo ni ki gbogbo ileewe o dawọ duro.
"Wo àwọn òṣèré tíátà Yorùbá tó ti kú àmọ́ tí iṣẹ́ wọn ń fọhùn síbẹ̀ Wo ohun tí a mọ̀ nípa iléeṣẹ́ ""ISON Xperiences"" tí òṣìṣẹ́ 78 ti kó àrùn coronavirus ní Ìbàdàn Kìí ṣe pé mo fẹ́ jẹ Ààrẹ Nàìjíríà ló mú kí n ṣe àtìlẹyìn fún ìfilọ́lẹ̀ ìkọ Amotekun - Fayemi Ènìyàn 339 ló ní àrùn Coronavirus ní Ọjọ́ọ́bọ̀ ní Nàíjíríà Ẹ wo bí ìpínlẹ̀ Eko, Ondo àti Oyo yóò ṣe dá ilé ìjọ̀sìn padà Nigba to n salaye bi oun ṣe pada mọ Seyi Makinde, baba Aderibigbe ni oun ko tete da akẹkọọ oun naa mọ rara ni ọjọ ti oun kọkọ fi oju kan an."
Nígbà tí wọn rí i, wọ́n júbà rẹ̀, ṣugbọn àwọn kan ninu wọn ń ṣiyèméjì.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Oyo NURTW: Okùn òfin Makinde ti dí ọ̀nà ìjẹ wa 25 Òkùdu 2019 Oríṣun àwòrán, @Oyoaffairs Ẹgbẹ awakọ ero NURTW nipinlẹ Ọyọ, ti figbe bọnu pe ki Gomina Seyi Makinde tu okun ofin to fi de awọn nitori aifararọ eto abo to n ba ipinlẹ Ọyọ finra losu karun ọdun 2019.
Lẹ́hìn èyí, ó súre fún mi pé n óò rí ẹran pa ó sì tún wí fún mi pé bí mo bá rí ẹyẹ àparò kí n pá ọ̀kan bọ̀, nítorí ẹyẹ àparò ń wu òun láti jẹ, ṣé bí àwọn obìnrin obìnrin bá ti lóyún àyípadà pàtàkì ti dé sí wọn, kì í ṣe gbogbo oúnjẹ ni ó máa ń wú wọ́n jẹ bẹ́ẹ̀ ni ẹni tí kò bá ṣe ìtọ́jú aboyún kúrò ni ipò ènìyàn, òun ni à bá máa pè ní paramọ́lẹ̀ tí ó gbe àwọ̀ ekòló borta: eejò olóró ni paramọ́lẹ̀ ṣùgbọ́n jẹ́ẹ́jẹ́ẹ́ ni ekòló ń siré tirẹ̀ kiri.
orilẹede South Korea ni idije iwẹ lilu lagbaye naa ti n lọ lọwọ Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Agbara ju agbara lọ, ọgbọn ju ọgbọn lọ.
O ni ayipada nla maa deba iṣelu ipinlẹ Imo ni guusu Naijiria ni 2020.
Ṣugbọn kò pa àwọn pẹpẹ oriṣa run; àwọn eniyan ṣì ń rú ẹbọ níbẹ̀, wọ́n sì ń sun turari.
O wa rọ awọn araalu ti o ba mọ ohun kan tabi omiiran nipa fidio ọhun lati kan si ileeṣẹ ọlọpaa.
”Ẹni náà bá dáhùn pé, “Èmi ni Jesu, ẹni tí ò ń ṣe inúnibíni sí.
Lati ṣe eyi wọn ni nọmba idanimọ gẹgẹ bi ọmọ orilẹede Naijiria ni awọn yoo lo eyi ti yoo jẹ nkan ara ọtọ lati da ẹni kọọkan mọ.
Saaju awọn ayẹwo diẹ diẹ kan fi han pe ida ogoji ninu ida ọgọrun awọn ọmọ ti ọjọ ori wọn ko ju osu marun un si mẹtadinlogun ni abẹrẹ naa n da aabo bo.
Oya, ẹ maa palẹmọ fun #Assurance2020 Gbaju-gbaja olorin takasufe e, Davido, ti ṣetan lati gbe ololufẹ rẹ, to tun jẹ iya ọkan ninu awọn ọmọ rẹ, Chioma, niyawo l'ọdun yii, lẹyin to fun un ni oruka adehun nilu London l'ọdun 2019.
 bharat gege bi oruko wa lati oruko oba olokiki bharata ninu awon itan-awaso hindu .
Eniyan Mẹrinlelogoji n gba itọju ni ijọba ibilẹ AriwaKogi Àkọlé àwòrán, Iba ọrẹrẹ pa alaisan, o tun pa dokita to n tọju wọn Bakanna nipinlẹ Kogi, Dokita kan to n sisẹ nile-iwosan ijọba apapọ to wa ni Lọkọja, Idowu Ahmed ti dologbe nipasẹ aisan iba ọrẹrẹ, ti eniyan mẹrinlelogoji si wa ni ile iwosan, ti wọn n gba itọju ni ijọba ibilẹ Ariwa-Kogi.
Kì báà ṣe àwọn oriṣa tí àwọn baba yín ń bọ ní òdìkejì odò, tabi oriṣa àwọn ará Amori tí ẹ̀ ń gbé ilẹ̀ wọn.
Bí ẹ̀san ti Kaini bá jẹ́ ẹ̀mí eniyan meje,ẹ̀san ti Lamẹki gbọdọ̀ jẹ́ aadọrin ẹ̀mí ó lé meje.
Venus Williams ti fagbahan aburo re Serena, ninu ifigagbaga sipele keta idije Indian Wells pelu ami-ayo mefa si meta(6-3), ami-ayo mefa si merin(6-4).
Nípa ìṣẹ̀dá ọmọ ènìyàn, Ó ṣ’èkan ní dúdú aró, ọ̀kan funfun gbòò bí aṣọ àlà.
Awọn eniyan kan ni ipinlẹ Kano n fura pe o ṣeeṣe ki ẹgbẹ to gbe ọrọ lọ sile ẹjọ lati da awọn aṣofin lọwọ kọ, jẹ awọn oloṣelu lo n fun wọn ni owo lati le da iṣẹ iwadi naa ru.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìwádìí bẹ̀rẹ̀ lórí iná tó sọ nileeṣẹ EFCC 20 Bélú 2018 Oríṣun àwòrán, @officialEFCC Àkọlé àwòrán, Lai pẹ yi ni wọn kọ olú iléeṣẹ́ tuntun fun EFCC kò le gba gbogbo àwọn òṣìṣẹ́ àjọ nàá tó wà ní ìlú Abuja.
Kòkòrò oyin sọ ọ̀pọ̀ èèyàn di aláìrílégbé, àwọn míràn tún farapa O ni awọn koko mẹfa ti ijọba aarẹ Buhari gbọdọ tete mu gbọ ree bi o ba fẹ ki opin de ba irufẹ ifẹmiṣofo naa.
Egbẹ agbabọọlu Super Eagles ti ilẹ Naijiria to lọ si orilẹ-ede Ukraine lati gba boolu ọlọrẹjọrẹ ninu eyi ti wọn ti gbagbe eroja wọn.
Saaju eyi ni, akọwe agba fun
Bakan naa lo sọ pe oun kẹdun pẹlu ẹbi awọn to ku, ati awọn to farapa nibi iṣẹlẹ to waye.
A kò gbà wọ́n láyè láti sọ̀rọ̀.
Coronavirus in Nigeria: Àwọn awakọ̀èrò, ọlọ́kadà arìnrìnàjò faragbá nínú ìpa Coronavirus
6 75395 Orilẹede Sudan 1295 3.
Naira Marley ti tèṣù mọ́lẹ̀ nílé ẹjọ́ májísíréètì lórí ẹ̀sùn ìjọ́kọ̀gbé Aláàfin Ọyọ: Ọba tó bá n mú ọtí ní ìta kò yẹ ní ẹni tàá bọ̀wọ̀ fún Bí ìtàn ayé Toyosi Arigbabuwo ṣe lọ rèé láti ẹnu Musiliu Dasofunjo àti Ogun Majek Àwọn omidan Naijiria ni wọ́n fi ń ṣerú ní Lebanon- Ọmọlọla Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Banki agbaye ti ṣe agbekalẹ awọn Okoowo kekeke, bi wọn ṣe le jẹ anfani awọn nkankan latọdọ ijọba.
Gbogbo owó tó ná fún ayẹyẹ nàá kò sì ju ẹgbẹ̀rún kan àti àádọ́ta Naira tàbí Dọ́là mẹ́ta lọ̀, eyi si jẹ owó ọkọ̀ tó gbe de ibùdó ayẹyẹ nàá, nítorí pé àwọn ọ̀rẹ́ rẹ̀ dá nkan ìpanu, owó àti ẹ̀bùn jọ fun un.
Ta ni yóo wá jogún gbogbo ohun tí o kó jọ wọnyi?
Ọba ńlá ni mí, gbogbo àwọn orílẹ̀-èdè ni wọ́n sì bẹ̀rù orúkọ mi.
Funke Akindele, oníròyìn, agbẹjọrò àti òṣèré; ohun tí ẹ kò lérò nípa rẹ̀
"Awọn akẹkọ to bawọn akọroyin sọrọ ni awọn ko tilẹ tii se '""silabọọsi"" ti saa yii tan, ati wipe ajọ Jamb n jẹ kawọn san owo toto ẹgbẹrun meji aabọ naira, tawọn ba se asemase kankan lasiko iforukọ silẹ fun idanwo UTME tọdun yii."
Má ba iranṣẹ jẹ́ lójú ọ̀gá rẹ̀,kí ó má baà gbé ọ ṣépè, kí o sì di ẹlẹ́bi.
Nígbà tí ó di ọjọ́ kan, angẹli OLUWA fi ara han iyawo Manoa yìí, ó wí fún un pé, “Lóòótọ́, àgàn ni ọ́, ṣugbọn o óo lóyún, o óo sì bí ọmọkunrin kan.
"Díẹ̀ ló kú kí owó tán l‘ápò mi torí ìrànwọ́ Coronavirus - Pasuma Olori Badra sọ̀rọ̀ nípa ayé rẹ̀, ó ní ẹ́ bá òun sọkún 'Èmi Oluwatoyin Abosede Aya Kolawole Ajeyemi ń sọ fún yín pé mo ti dé ""bus stop"" sinimá lọ́dún yìí' Remilekun Fatolu bú sẹ́kún fún ohun tó ti pàdánù láyé torí ọyàn ńla rẹ̀."
yàtọ̀ sí àwọn iranṣẹkunrin wọn ati àwọn iranṣẹbinrin wọn tí wọ́n jẹ́ ẹẹdẹgbaarin lé ọọdunrun ati mẹtadinlogoji (7,337), wọ́n sì ní àwọn akọrin tí wọ́n jẹ́ ojilerugba ó lé marun-un (245) lọkunrin ati lobinrin.
Iko egbe agba-boolu afigigba ti Nasarawa Flickers fagba han egbe agba-boolu Bauchi Flickers pelu ami ayo meji sodo(2-0), ninu idije boolu afifigba ti o n lo lowo ni ilu Abuja.
“Ní ọjọ́ keji, ẹ óo máa fi ẹgbọ̀rọ̀ akọ mààlúù mejila, àgbò meji, ati ọ̀dọ́ àgbò mẹrinla ọlọ́dún kọ̀ọ̀kan tí kò ní àbààwọ́n rúbọ.
Ati pe gbogbo ẹkọ igbaradi wọn wa lati rii pe wọn koju iṣoro janduku atawọn iwa ọdaran mii to n gbogo lorilẹede Naijiria.
Air Peace: 'Rárá o, kó bá 'má jẹ́ Onyema, èyí àtàwọn ọ̀rọ̀ míì tó ń yọjú
Ohun gbogbo wà gẹ́gẹ́ bí ìlànà rẹ, títí di òní,nítorí pé iranṣẹ rẹ ni gbogbo wọn.
Aare Buhari gbadura pe ki Olorun te gbogbo won si afefe rere.
Lulu sọ pé, bàbá òun kò tì sọ ohunkóhun nípa ìṣẹ̀lẹ̀ nàá, ọ̀rọ̀ nàá jẹ́ kàyéèfì fun un, ó sì tún dùn ún.
To ba jẹbi ẹsun ti wọn kan, o ṣeeṣe ko lọ sọgba ẹwọn fun nnkan bii ogun ọdun tabi ko san biliọnu kan owo orilẹ-ede ọhun gẹgẹ bii owo itanran.
Nítorí OLUWA ní kò ní sí ìgbà kan, tí kò ní jẹ́ pé ọkunrin kan ní ilé Dafidi ni yóo máa jẹ́ ọba ní ilẹ̀ Israẹli, 
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Working religious women: Ẹ̀lẹ́hàá kìí ṣe ọ̀lẹ- Aminat Adegoke Sugbọn, agbejọro Ibrahim Magu, Ọgbẹni Wahab Shittu, ti sọ pe oun ko ni i gbà ki ẹnikẹni tun fi ẹsun kan onibaara òun lẹyin awọn to ti wa nilẹ tẹlẹ.
18 Èbibi 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 24 Èbibi 2020 Oríṣun àwòrán, Alaafin oyo Yoruba ni 'Ajiṣe bi Ọyọ laa rí, Ọyọ kii ṣe bii baba ẹni kọọkan', eyi to tumọ si pe ilu Ọyọ lo n lewaju ninu agbega aṣa ati iṣe nilẹ Kaarọ o jiire.
Awọn eeyan bi miliọnu kan ni wọn n tẹle Julie lori Twitter , bẹẹ ni awọn bi ẹgbẹta lo n tẹle e lori Instagram, laarin iṣẹju akan ẹgbẹgbẹrun eeyan lo ti ri iroyin naa ti wọn si gbagbọ ọtitọ ni.
Èmi kò forí ṣọta ìjàmbá ọkọ̀ òfúrufú kankan - Obasanjo Ìròyìn ìbúrawọlé jákèjádò orílẹ̀èdè Nàìjíríà ní ẹ̀kúnrẹ́rẹ́.
Ta ló lè farada ibinu gbígbóná rẹ̀?
Ẹ̀wà pupa àti soya beans ọmọ iyá kan náà ni wọ́n.
'Ẹ̀yin tẹ́ẹ fẹ́ pa ara yín torí olóṣèlú, ẹ wò Fayemi àti Fayose' FUTA pàṣẹ lọ rọọ́kún nílé f'ákẹ́ẹ̀kọ́ méje tó lu akẹgbẹ́ wọ́n Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Ṣaaju ni iroyin kan gbode lori ayelujara pe agbaọjẹ olorin juju ọhun ti gbẹmi nile iwosan kan ni ilu London.
Ibo 2,772 lo ni ninu idibo abele eyi to waye ni ilu Ibadan.
Láti òkè Halaki títí lọ sí Seiri, títí dé Baaligadi ní àfonífojì Lẹbanoni ní ìsàlẹ̀ òkè Herimoni.
Ìdílé Ṣimei pàápàá yóo ṣọ̀fọ̀ tirẹ̀ lọ́tọ̀, àwọn iyawo wọn yóo ṣọ̀fọ̀ tiwọn náà lọ́tọ̀; 
Wale Rapper: Ìya mi gan ti lè yára sọ̀rọ̀ bí ẹni ń kọrin
Kọ́ńdọ̀mù tó bẹ́ gbé iléèṣẹ́ ìjọba àti aládáni kan dé ilé ẹjọ́ Wo ohun tí Adájọ́ ṣe sí àṣùwọ̀n ìfowópamọ́sí Wòlíì Sotitobire Ọkọ̀ tírélà agbépo ṣubú lulẹ̀, awakọ̀ sá lọ, obìnrin kàn pàdánù ẹ̀mí rẹ̀ nílùú Èkó Kí ló fa iná ńlá tó ṣẹ́yọ lọ́jà Ajman ní Dubai?
Ìjọba àpapọ̀ fi Austria, Sweden kún àwọn orílẹ̀èdè tí kò lè wọ Nàìjíríà Àwọn ìlànà tó tọ̀nà láti tọ̀ tí o bá funra pé o ní àrun Coronavirus Wo bí fóònu rẹ kó ṣe ní kó àrun Coronavirus bá ọ Lootọ, ilu Wuhan lorilẹede China ni wọn ti kọkọ kẹẹfin arun yii eleyi to ti wa gbẹrẹgẹjigẹ di igi nla laarin awọn ipenija agbaye lasiko yii bayii.
Yakubu Nkekeso ni obinrin naa sọ wi pe nnkan ko rọgbọ lawọn abule ti awọn ọmọ naa wa ti wọn si fẹ le ma ri ounjẹ jẹ nibẹ.
Wọ́n bá dámọ̀ràn láàrin ara wọn, wọ́n ní “Ẹ jẹ́ kí á ṣẹ́ gègé, kí á lè mọ ẹni tí ó fà á, tí nǹkan burúkú yìí fi dé bá wa.
Agbára Oluwa hàn ninu iṣẹ́ wọn.
Joabu, ọmọ Seruaya ni balogun rẹ̀, Jehoṣafati, ọmọ Ahiludi ni alákòóso gbogbo àwọn ìwé àkọsílẹ̀ rẹ̀.
12 Èrèlè 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 13 Èrèlè 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Orilẹede Naijiria ni eto ọrọ aje rẹ tobi julọ ni Afrika, oun naa si lo n pese eporọbi julọ.
" Gbogbo ìgbésẹ̀ Aláàfin láti jí mi gbé ló já sí pàbó, n kò le panumọ́ - Olori Anu Ilé ẹjọ́ tú ìgbéyàwó ọdún mẹ́sàn ká lẹ́yìn tí ọkọ fi ẹ̀sùn olè kan ìyàwó Ọkọ'yàwó jẹ àjẹranjú ìyà lẹ́yìn tí ìyàwò rẹ̀ yọjú síbi ìgbéyàwó òun àti obìnrin mìràn Iléẹjọ́ tú ìgbéyàwó ọdún méjé ká nítorí àìnáání ara ẹni Imam tó fẹ́ ọkùnrin míì níyàwó forí kó ìjìyà òfin Marlian, òfégè ìgbéyàwó Buhari, Fatoyinbo àtàwọn ìṣẹ̀lẹ̀ ńlá tó mi ìgboro tìtì ní 2019 Arabinrin Basirat ṣalaye pe oyun oṣu mẹta ti wa ninu oun ṣaaju asiko ibalopọ naa.
Amọ awọn Ẹgbẹ́ àwọn Imam, the Joint Action Committee for the Preservation of the Rights and Honours of Imams tako àyẹyẹ naa.
Ọba Gbadamọsi: Olúwòó, ọ̀pọ̀ ọmọ Naijiria fi ìkíni ránṣẹ́ si Ọlọ́fà fún ayẹyẹ ọdún mẹwàá lórí oyè Oríṣun àwòrán, Facebook Àkọlé àwòrán, Ọba tó ṣe fi yangàn láàrín ọba Nàìjíríà ni Ọlọ́fà ìlú Offa-Oluwo Oluwo ilu Iwo Oba Abdulrasheed Akanbi ti darapọ mọ awọn ọmọ Yoruba to n fi ikini ransẹ si Ọlọfa ilu Offa Oba Mufutau Gbadamosi Oloyede to pe ọdun mẹwa lori apere.
Ọmọ ọdun mẹrinlelogun naa darapọ mọ Anorthosis Famagusta lati ẹgbẹ Uniao da Madeira ilu Portugal losu kẹsan ọdun 2016.
Wahala lásán ni n óo lọ kó bá oluwa mi, ọba.
Nítorí pé kì í ṣe ọrun mi ni mo gbẹ́kẹ̀lé;idà mi kò sì le gbà mí.
Mose bá kúrò lọ́dọ̀ Farao, ó jáde kúrò ní ìlú; ó gbadura sí OLUWA, ààrá tí ń sán ati yìnyín tí ń bọ́ sì dáwọ́ dúró, òjò náà sì dá lórí ilẹ̀.
Robbie Dunne sọ wipeWọn gba Ronaldo nipa lori, o si beere fun ẹrọ ibanisọrọ lati wo bi apa naa ti se to."
Ọga Bello, lásìkò to ń kopa lórí eto kan pẹlu BBC Yoruba ni ọsan ọjọ́ Iṣẹgun, sísọ lójú rẹ pé, Ọlọ́run ló kọ ọ pé àwọn ọmọ òun yóò ṣe ère orí itage jẹun nitori pe, fúnra wọn ní wọn finnu-findọ pinnu láti máa ṣíṣẹ ère orí itage, òun sì kó lọ kàn-án nípa fún wọn.
Wọn tun ni ki awọn eniyan ṣọra fun dida idọti si oju agbara Àkọlé àwòrán, Ojo arọọrọda lo fa ẹkun omiyale naa Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
"Oríṣun àwòrán, Instagram/KolawoleAjeyemi O ni "" Ẹ́ jẹ ka maa tọju, ka si maa sikẹ awọn obinrin nitori awọn ni iya ati iyawo wa, ko si ohun meji to tọ si wọn ju ojurere wa lọ, mo si bọwọ fun awọn obinrin rere."
miiran wo le mo lati lee wa owo si apo orile ede yii yato si ti epo robi ?
Buhari: Àìsí ìtọ́jú tó péye ló mú ṣọ́jà gba iṣẹ́ ọlọ́pàá ṣe láwùjọ
ni awon omo orile ede Naijiria jẹ ẹni to  nifẹẹ , ti wọn si ko awon eniyan mọra.
Aarẹ ni imọ, oye ati ẹmi ifọkansin ti Katsina-Alu lo lati mu ipa ribiribi ba eto ijọba rere lorilẹ ede Naijiria ko se fọwọrọ sẹyin.
Amọ sa, fawọn akẹkọọ to to miliọnu mẹwaa din ni ọgọrun mẹsan an, eto ẹkọ ko ti i lojutu ba ti se n sọrọ yi.
Ojogbon James Adediran to je oludari ile ise iwadii nipa eto ogbin ninu ero tire ni iyanselodi yii yoo mu ifaseyin ba eto oro aje Naijiria lojo iwaju nitori ko si atileyin to ye fawon akekoo nipa iwadii lataari iyanselodi to n lo lowo yii.
Nítorí ẹni tí ó wà lábẹ́ àṣẹ ni èmi náà, mo ní àwọn ọmọ-ogun lábẹ́ mi.
Oríṣun àwòrán, Nigeria Police Àkọlé àwòrán, Adebisi àti Julian di àwáti l'ọjọ́ kéjìdínlọ́gbọ̀n oṣu karùń ùn, ọdun 2018.
Ní orígun alápàáǹdẹ̀dẹ̀ tí wọ́n tò lọ lẹ́sẹẹsẹ.
Won sagbekale igbimo ipolongo yii ki won le wa ojutu si isoro riri awon ohun eelo igbalode fun ifetosmobibi ati sise amojuto to ye si nina owo tijoba la kale fun ifetosomobibi ni ipinle Kaduna.
Idi ree ti ajọ Commonwealth fi fun ni ami ẹyẹ ọdọ to pegede julọ lọdun 2018, to Oluwaseun si n rọ awọn obinrin ti wọn ba fi tipa ba lopọ lati maa ke sita, ki wọn ma si fi se osun, fi kinra.
Ọpọlọpọ ileeṣẹ lo ti ṣiṣẹ, koda kan ileeṣẹ iroyin BBC world service.
 Amosa, ohun ti a ni fun aare ana ni pe o nilo dokita, fun
Àwọn nkan inú ẹ̀rọ tí wọ́n nmú u ṣiṣẹ́ náà a máa gbó pẹ̀lú.
Àwọn ará ìlú Beti ṣemeṣi ń kórè ọkà lọ́wọ́ ní àfonífojì náà, bí wọ́n ti gbójú sókè, wọ́n rí àpótí ẹ̀rí.
Ta ló mọ agbára ibinu rẹ?
OLUWA, ta ni ó lè máa gbé inú àgọ́ rẹ?
18 Agẹmo 2019 Oríṣun àwòrán, Laide Bakare Àkọlé àwòrán, Arugbo sogeri, ekisa logba ri ni aworan ọjọ ogbo Laide Bakare yii Ọpọlọpọ awuyewuye lo ti n lọ lori lilo ẹrọ to n pa ọjọ ori ẹni da FaceApp, ti o le mu ki aworan eniyan kere sii ni ọjọ ori, abi ki o dabi arugbo.
Gbogbo igba lo maa n doju kọ ifẹhonu han lasiko to wa lori alefa ṣugbọn nigba to ku diẹ ki oṣu kejila ọdun 2010 pari, atako nla yọju si aato rẹ ti awọn afhonu han si tu sigboro lati fi ibinu wọn han si ọrọ ọbayejẹ, ọwọngogo ounjẹ ati airilegbe.
MOSOP kọminu lórí iṣẹ́ inú àfọ̀mọ́ Ogoni Bi iṣé abẹ ìdí ńlá ṣé n seku pá àwọn obìnrin Ninu iwadii WHO, aworan isalẹ yii fi han awọn orilẹede ti atẹgun ti buruju.
Àwọn ìròyìn mìíràn tí ẹ lè nífẹ̀ẹ́ sí: Nnamdi Kanu yí ìpinnu padà, o ni ki àwọn Igbo kópa nínú ìdìbò 2019 Àwòrán aràmbarà nípa ìdìbò 2015 #BBCNigeria2019 INEC: Kò sí ìká tí o kò lè fí dìbò, ṣáà tí tẹ̀ ẹ́ sójú ẹ dáadáa Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Afẹnifẹre ni ọrọ atunto lawọ́n tori ẹ yan Atiku laayo Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Nigba to di alẹ ọjọ kọkanlelọgbọn oṣù Kejila ọdun 1983, ijọba ologun gba akoso Naijiria labẹ Ọgagun Muhammadu Buhari, ti Tunde Idiagbon si jẹ igbakeji rẹ.
Ẹni ọdún mẹtalelogun ni Jehoahasi nígbà tí ó jọba ó sì wà lórí oyè ní Jerusalẹmu fún oṣù mẹta.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù NGACMR: Ohùn tí àwọn alatilẹyin Super Eagles sọ lẹ́yìn tí Nàìjíríà borí Cameroon Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ NGACMR: Ohùn tí àwọn alatilẹyin Super Eagles sọ lẹ́yìn tí Nàìjíríà borí Cameroon 6 Agẹmo 2019 Awọn alatilẹyin ikọ Super Eagles Naijiria ti sọ nipa ireti wọn ninu idije Afcon lẹyin ti Naijiria bori ikọ Cameroon.
Mo mọ̀ pé òfin rẹ̀ ń tọ́ni sí ìyè ainipẹkun.
Ọlọrun sì ti mí ìmísí rẹ̀ sí i ninu láti kọ́ ẹlòmíràn, àtòun ati Oholiabu ọmọ Ahisamaki láti inú ẹ̀yà Dani.
Wọ́n ń kó ọrun ati ọ̀kọ̀ bọ̀,ìkà ni wọ́n, wọn kò sì lójú àánú.
Akowe ajo to n mojuto ẹtọ ọmọniyan
"Bàbá mi Aláàfin, ẹ ṣeun ẹ̀bùn owó tí ẹ fún èmí àti ọkọ mi- Lizzy Anjọrin Wo àwọn Gómìnà Naijiria tí àrùn Covid-19 ti bá fínra Sùgbọ́n, àwọn àjọ Civil Liberties Union tí ilẹ̀ Amẹrika sọ pé: "" Ìjọba kàn n lo ààrùn Coronavirus lati ṣe àtúnto àwọn òfin bí àwọn arìnrìnàjò ṣe ń wọ ilẹ̀ Amẹrika ni."
'Obìnrin ló ni ilé àti àdúgbò fún ìdí èyí wọ́n lè ṣe ìlú dáadáa'
“Ní ọjọ́ kinni àjọ̀dún ìkórè, nígbà tí ẹ óo bá mú ẹbọ ohun jíjẹ ti ọkà titun wá fún OLUWA, ẹ óo máa ní àpèjọ mímọ́, ẹ kò sì gbọdọ̀ ṣe iṣẹ́ líle kankan.
"Omotola Taiwo - BBC News Yorùbá BBC News, YorùbáFò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Omohtee Twitter: Ìrora púpọ̀ ni mo là kọjá lẹ́yìn iṣẹ́ abẹ tí mo ṣe láti jẹ́ kí ìdí mi tóbi sii - Omotola Taiwo 4 Agẹmo 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 10 Agẹmo 2020 Oríṣun àwòrán, @omoh_tee Omotola Taiwo, ti ọpọ eeyan mọ si ""Omohtee"" ti ṣalaye ohun toju rẹ ri lẹyin iṣẹ abẹ to ṣe ni ọdọ Dokita Anu, lọna ati jẹ ibadi rẹ tobi sii."
Ṣugbọn ó gòkè lọ sọ́dọ̀ Elija, ó sì kúnlẹ̀ níwájú rẹ̀, ó bẹ̀ ẹ́ pé, “Ìwọ eniyan Ọlọrun jọ̀wọ́ mo bẹ̀ ọ́, ṣàánú fún mi ati fún àwọn iranṣẹ rẹ wọnyi, kí o sì dá ẹ̀mí wa sí.
O ni bi oun ko tilẹ ri ipo gba, ko le di oun lowo lati simi oro sisọ si ààrẹ Buhari, Tinubu ati awọn èèkan inu ẹgbẹ oselu to miran Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Sogidi Lake: Kòṣẹja-kòṣèèyàn lá bá nínú adágún odò náà -Ojedele Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
 ni 2012 , ohun ati shinya yamanaka gba ebun nobel fun iwosan fun iwari won pe awon ahamo to ti dagba se sodi ahamo onihu .
Ẹ̀kọ́ ọ̀fẹ́, ètò ilera ọ̀fẹ́ àti iná ọba ló jẹ wá lógún- ọmọ Nàìjíríà Ògo tuntun yóò sọ ní ọdún 2020!
27 Ẹrẹ̀nà 2019 Àkọlé àwòrán, Ọ̀rẹ́kùnrin Khadijat Olubọyo gba ọjọ́ ikú Ile ẹjọ giga ni ipinlẹ Ondo ti da ẹjọ iku fun Seidu Adeyemi to pa ọmọ igbakeji gomina ipinlẹ Ondo, Khadijat Olubọyọ ní ọdun to kọja.
Wọ́n ti jẹ́ kí ògo mi yọ.
 báyí ọ ̀ pọ ̀ lọpọ ̀ orílẹ ̀ èdè a màa gba abẹ ́ rẹ ́ àjẹsára jẹ ̀ dọ ̀ jẹ ̀ dọ ̀ b fún àwon ọmọ ìkókó lati dènàn àìsàn jẹ ̀ dọ ̀ jẹ ̀ dọ ̀ b.
Ajo ti o n ri eto ilera lagbaye, World Health Organisation (WHO),ati ile –ise ti o n ri eto-ilera lorile-ede Naijiria Nigerian Ministry of Health, n gbero ati da awon akoroyin leka eto-ilera lola.
Ní ọjọ́ kẹta, Jeroboamu pẹlu àwọn ọmọ Israẹli bá pada wá sọ́dọ̀ Rehoboamu, gẹ́gẹ́ bí àdéhùn wọn.
,osu kefa , odun 2019 .
Wọn ni orin naa ti jade to si ti n tan ka ki Ganduje to di gomina.
Ṣebí àyọrísí iṣẹ́ mi ninu Oluwa ni yín?
 O wa ro awon omo ipinle naa ki won maa ba isẹ wọn lo pelu alaafia.
Orilẹede Ghana si ti kede ọdun ta wa yii, 2019, gẹgẹ bii ọdun ipadabọwale, pẹlu awọn oniruuru eto ti wọn gbe kalẹ, eyi to wa lati se iwuri fun awọn ọmọ ti orirun wọn jẹ Afirika, lati wa se abẹwo si Afirika, ki wọn si wa tẹdo sile.
Iwọde ti waye ri ni olu ilu orilẹede naa lodi si saa kẹta ti Nkurunziza n ja fun.
Osun Election 2018: Àwọn ọlọ́pàá fi tajútajú tú àwọn ọmọ ẹgbẹ́ PDP tó fẹ̀hónú hàn nítorí ìbò Ọṣun
“Agiripa Ọba Aláyélúwà, mo ka ara mi sí olóríire pé níwájú yín ni n óo ti dáhùn sí gbogbo ẹjọ́ tí àwọn Juu pè mí lónìí, 
orile ede naa lati fi ra oja nile okeere.
Ọdun 2018 ni Walcott fi Arsenal silẹ lọ Everton lẹyin ti wọn ta a ni ogun miliọnu pọun.
Ọjọ kẹsan an, ọsu Kọkanla, ọdun 2020 lo ṣe ayẹyẹ ọdun kan to ṣe igbeyawo.
Ẹbi, ara awọn ọmọ ati ojulumọ to fi mọ awọn osere tiata lo peju sibi isinku Ogun Majek.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Oyo Land Revocation: Ajimobi gbé Makinde lọ ilé ẹjọ́ lórí ilẹ̀ rẹ̀ tí ìjọba gbẹ́sẹ̀ lé 14 Èrèlè 2020 Gomina ana nipinlẹ Oyo, Sẹnatọ Abiola Ajimobi ti gbe Gomina Seyi Makinde ati awọn eeyan mii ninu ijọba rẹ lọ ile ẹjọ, lẹyin ti wọn gbẹsẹle ilẹ rẹ nilu Ibadan.
Oríṣun àwòrán, Reuters Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
N óo mú kí o sin àwọn ọ̀tá rẹ ní ilẹ̀ tí o kò dé rí.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Divorcee: Ó sàn kí wọ́n yàgò fúnra wọn ju ki wọ́n ṣe ara wọn léṣe- Fisayo Awọn aṣofin tun kepe ẹka ijọba to n ri si eto ilera lati pese iwosan ọfẹ fawọn to laarun arunmọleegun.
so pe orile ede Amerika ko ni  kaarẹ ninu
awon janduku nigba ti won wa si ile -ẹkọ Community Secondary School, Okposi
Arakunrin Okolieagu Abunike ṣẹṣẹ dahun ibeere tan lọwọ agbẹjọro ọlọpaa Emmanuel Eze ni.
Aláàánú ni OLUWA, olóore sì ni;kì í yára bínú, ìfẹ́ rẹ̀ tí kì í yẹ̀ sì pọ̀.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, ‘Ọmọ meji daku ninu eefi Olusosun’- Olugbe agbeegbe naa Ṣugbọn dokita kan, Femi Olusoji sọ fun BBC pe awọn olugbe gbọdọ yẹra fun ipalara ti fifa eefin yii simu maa n fa.
Jehoiakimu ọba gba owó orí lọ́wọ́ àwọn eniyan gẹ́gẹ́ bí ọrọ̀ wọn ti pọ̀ tó, láti rí owó san ìṣákọ́lẹ̀ fún ọba Ijipti gẹ́gẹ́ bí ó ti pa á láṣẹ fún un.
O ni bayii oun a le tẹsiwaju pẹlu eto igbeyawo oun to wa loju ọna.
O so pe ijọba orilẹ ede  Naijiria,yoo mojuto lilo  imo ero fun ala ile  ati lati loo fun  awọn  ala to pa orilẹ ede  Naijiria ati  awọn  orilẹ ede  miiran papo.
Nígbà tí ó di àkókò ìrúbọ ìrọ̀lẹ́, Elija súnmọ́ ibi pẹpẹ náà, ó sì gbadura pé, “OLUWA, Ọlọrun Abrahamu, Ọlọrun Isaaki ati Ọlọrun Israẹli, fi hàn lónìí pé ìwọ ni Ọlọrun Israẹli, ati pé iranṣẹ rẹ ni mí, ati pé gbogbo ohun tí mò ń ṣe yìí, pẹlu àṣẹ rẹ ni.
Koda, ọkan ninu mẹta awọn ọmọde ni Naijiria ni ko ri ounjẹ asara loore jẹ.
Kodesho Bridge, Oba Akran, Ikeja, Ijọba ibilẹ Ikeja Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Hepatitis: A kò leè kóo nípa dídìmọ́ ara ẹni 26.
Ṣugbọn nisinsinyii, kí ni mo rí yìí?
kó àwọn ọmọ ogun yòókù jọ, kí o kọlu ìlú náà, kí o sì gbà á fúnra rẹ.
Oríṣun àwòrán, Natalia Ojewska Àkọlé àwòrán, Ruwanda Genocide: Obi ni mi - mo pa obi awọn ọmọ wẹwẹ Ọpọ awọn obinrin yii ni eri ọkan ipaniyan yii n da laamu nitori wọn kuna ojuṣe wọn gẹgẹ bi abiyamọ.
Pẹlu iku Boumedienne ni 1978, orisun agara Bouteflika tan.
Ni Ọjọbọ ni iroyin gbòde pe Ileesẹ ọlọpaa kọwe igbẹjọ lati tako idasilẹ awọn igbimọ iwadii eyi to n gbẹjọ lawọn ipinlẹ Naijiria kọọkan lori aṣemase ìkọ ọlọpaa SARS.
Mo bá lọ fi pamọ́ sí ẹ̀bá odò Yufurate bí OLUWA ti pa á láṣẹ fún mi.
O ni awọn ajinigbe ọhun mọ pe awọn ti wa ni ahamọ awọn ologun tori wọn ni imọlara pe wọn ti wa lagbegbe lati inu afẹfẹ ati loriilẹ.
O ni lati ibẹrẹ pẹpẹ iwọde naa ni oun ti fi ara mọ, sugbọn o ni o kọni lomiinu bi awọn janduku ti ko nifẹ ijọba ati araalu, ṣe bẹrẹ si ni ba dukia ijọba jẹ.
Ìkà ṣíṣe ni oúnjẹ wọn,ìwà ipá sì ni ọtí waini wọn.
Nítorí pé ọjọ́ kan ń bọ̀, tí àwọn aṣọ́nà yóo pè yín láti orí òkè Efuraimu pé,‘Ẹ dìde, ẹ jẹ́ kí á lọ sí òkè Sioni,sí ọ̀dọ̀ OLUWA Ọlọrun wa.
Adari ile-ise  olopaa lorile ede Naijiria, Abubakar Adamu ti so di mimo fun ile- ise olopaa ni ipinle Oyo ati gbogbo ekun Gusu iwo oorun orile ede Naijiria  lapapo pe oun ti se agbekale akanse iko olopaa kan  ti yoo maa sisẹ pelu awon olopaa to ti wa tẹlẹ lati kun won lowo lenu isẹ ,ki ipinnu ijoba apapo lati fopin si ijinigbe-jinipa ati awon iwa janduku le di afiseyin ti eegun n fiso ni ekun Gusu orile ede  yii.
Bí ọba ti múra láti kọjá odò náà, Ṣimei wólẹ̀ níwájú rẹ̀.
O jẹ akojọpọ awọn awọn woli to ma n sọ asọtẹlẹ, awọn to ma n la ala, ariran ati awọn to ma n fi ede oriṣiriṣi sọrọ.
Ṣugbọn Jehu tẹ̀lé ẹ̀ṣẹ̀ Jeroboamu, ọmọ Nebati, tí ó mú kí Israẹli bọ ère ẹgbọ̀rọ̀ mààlúù, tí wọ́n fi wúrà ṣe, tí ó wà ní Bẹtẹli ati Dani.
OLUWA yóo pa àwọn igi ńlá inú igbó rẹ̀ run,yóo pa àwọn igi eléso ilẹ̀ rẹ́ tèsotèso,bí ìgbà tí àrùn bá gbẹ eniyan.
Kofi Wilson, ti o jẹ ọmọ ogun ọdun lati orilẹ̀ede Ghanan jade l lati lọọ ge irun ori rẹ nigbati o kagbako.
‘Lẹ́yìn èyí, n óo tún ilé Dafidi tí ó ti wó kọ́.
Nígbà tí ìjọba rẹ̀ fìdí múlẹ̀ tán, ó pa àwọn olórí ogun tí wọ́n pa baba rẹ̀.
4m òògùn ikọ́ codeine Ademọla Adeleke ni yóò sojú PDP nínú ìbò gómìnà Ọ̀sun Ìwọ́de, ìkọ̀wéfipò sílẹ̀, ìdìbò abẹ́lé Osun kò fé bí'mọ re Olùdíje ìbò abẹ́nú PDP, APC fárígá l‘Ọ́sun Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Lion Chaser: Richard, ọmọ ọdún mẹ́ẹ̀dógún se iná tó ń lé kìnìún Ìròyìn tó tẹwa lọwọ sọ̀ pé, ọtọtọ ní Uche Secondus se ìpàdé pẹlú àwọn ọmọ ẹgbẹ náà àti wí pé, o ṣeéṣe kí ìgbìmò alabe-sekele kan tun ṣepàdé láti tunbo wà woroko fi ṣada lórí ọrọ náà.
May 29, 2019: Láti 1999 títí di 2019, wo àwọn ààrẹ tó jẹ ní Nàìjíríà
Ṣugbọn Chelsea fi ye wọn pe agbo to tadi mẹyin, agbara lo lọ mu wa ni abala keji ere bọọlu naa.
Wọ́n da aṣọ ọ̀fọ̀ bora ní ìta gbangba.
Má jẹ́ kí àwọn agbéraga borí mi,má sì jẹ́ kí àwọn eniyan burúkú lé mi kúrò.
3 trillion ni CBN gbé jáde fún ọdun 2020 Ǹjẹ o yẹ kí èèyàn máa sùn lẹ́nu iṣẹ́?
sọ pe , ibo naa ni mọgo-mọgo ninu.
Ọ̀rọ̀ ẹnu rẹ̀ dùn ju oyin lọ,bẹ́ẹ̀ sì ni ìjà ni ó wà lọ́kàn rẹ̀;ọ̀rọ̀ rẹ̀ tutù ju omi àmù lọ,ṣugbọn idà aṣekúpani ni.
"Gẹgẹ bi atẹjade ti agbẹnusọ eka Morgan Ortagus fọwọ si lọjọ aje ṣe sọ ""ko ni fisa ilẹ Aměrika gbigba fun wọn."
Section 120 Awọn ọmọ Naijiria gbudọ gba aṣẹ ki wọn to gbẹ ilẹ fun ẹrọ omi borehole fun owo ṣiṣe tabi fun ile.
36 Ẹ máa wo ọ̀dọ̀ mi nínú gbogbo èrò inú, ẹ má ṣe iyè méjì, ẹ má bẹ̀rù.
OLUWA sọ níti Jerusalẹmu pé, “N óo dá ire wọn pada: ire Sodomu ati ti àwọn ọmọ rẹ̀ obinrin ati ire Samaria ati ti àwọn ọmọ rẹ̀ obinrin.
Dino ní ìyàwó ni Adeyemi jẹ́ f'óun lágbo òṣèlú, Adeyemi l'ọ́mọ ọ̀dọ̀ ni Dino jẹ́ Èso Apple tuntun tí ẹ lè fi pamọ́ fún ọdún kan ti wọ ọjà Kò sí súnkẹrẹ-fàkẹrẹ mọ lópópóna márosẹ̀ Eko si Ibadan Àwọn agbébọn pa ènìyàn mẹ́rinlá lásìkò ìjọsìn Ilakaka ijọba apapọ Naijiria ni lati mu idagbasoke ba awọn ti yoo dari eto reluwee jakejado Naijria.
Ọjọgbọn Biọdun Ogunyẹmi, to jẹ aarẹ ẹgbẹ àwọn olukọ ni Naijiria ni ipade naa yoo fun wọn laaye lati yanju ọrọ iyanṣẹlodi to n lọ lọ́wọ́.
Ati wi pe jagidijagan oṣelu lo bẹrẹ Boko Haram.
Àbí kò tíì hàn sí kabiyesi báyìí pé gbogbo Ijipti tí ń parun tán lọ ni?
Nibẹ lo si tun ti kekọọ imọ ofin ni ileewe imọ ofin, Mitchell Hamline.
Wọ́n sì ṣe aadọta ìkọ́ idẹ láti fi mú aṣọ àgọ́ náà papọ̀ kí ó lè di ẹyọ kan ṣoṣo.
NURTW Oyo: Ìjọba Ọyọ ní awakọ̀ kankan kò ní tẹ̀lé àṣẹ yíyan iṣẹ́ lódì táwọn NURTW fi ń halẹ̀ Oríṣun àwòrán, Others Ijọba ipinlẹ ọyọ ti fesi lori idunkoko ẹgbẹ awakọ ero NURTW lẹkun guusu Naijiria to n fẹ kijọba yi ipinnu rẹ pada lori yiyan awọn alakoso gareji ọkọ.
Ati obinrin, ati ọmọ ọkunrin to ba ti gbe ibi kọrun wa saye, Aina ni wọn maa n sọ wọn.
Wọn pa eeyan wọn tun pa obinrinbinrin, Kudirat Abiola ni ita gbangba, o tọ ki awọn fi ibẹru sa lọ.
Ẹni tí ó bá mú ìyọnu dé bá ìdílé rẹ̀ yóo jogún òfo,òmùgọ̀ ni yóo sì máa ṣe iranṣẹ ọlọ́gbọ́n.
Nítorí pé ó dúró ti aláìníláti gbà á lọ́wọ́ àwọn tí ó dájọ́ ikú fún un.
Àìsí ẹ̀rọ ìgbàlódé fún bàálù láti bà ní Nàíjíríà, mú káwọn bàálù láti òkè òkun lọ bà sí Ghana Sunday Igboho gba àwọn èèyàn Soka n‘Ibadan sílẹ̀ lọ́wọ́ àwọn ọmọ onílẹ̀ tó wá ṣọṣẹ́ Ẹ san ₦200,000 fún Sowore lórí bí ẹ ṣe ń fi ẹjọ́ falẹ̀ - Iléẹjọ́ pàṣẹ fún ìjọba Iṣẹ́ dókítà làwọn òbí fẹ́ kí ń ṣe àmọ́ lónìí, mo di ilúmọ̀ọ́ká ayàwòrán Ko ti di pe Yobo fẹyinti gẹgẹ agbalọọlu fun ikọ Super Eagles, o ti kopa ninu idioje ife ẹyẹ agbaye nigba mẹta, ati ninu idije ife ẹyẹ ilẹ Afrika nigba mẹfa.
Samuel Ajayi Crowther, òjíṣẹ́ Ọlọ́run tó gbé èdè Yoruba lárugẹ Oríṣun àwòrán, @DradrockE Gẹgẹ bi a ti se akojọ rẹ loju opo itakun agbaye, ibẹru Ẹfunroye Tinubu laye igba rẹ, ni ipilẹsẹ ọgbọn fun awọn oriade nilu Eko ati Ẹgba.
”Bí akọrin náà ti ń kọrin ni agbára OLUWA bà lé Eliṣa, 
O tenumo pe, sise ifilole ero DSO nipinle Osun bayii, yoo fun awon olugbe ipinle ohun lanfani lati wo oniruuru eto ti o le ni ogbon, pelu idaniloju aworan ti o labawon, leyin ti eni kookan ba ti ra ero apoti kulubu DSO ohun.
Nítorí nígbà kan, Tudasi kan dìde.
Oludari to n ri si eto iroyin Ncaa ọgbẹni Sam Adurogboye ni awọn alaṣẹ ncaa kii ṣe ajojisi awọn osiṣẹ wọn yio ati wi pe lai pe yi wọn yoo wa wọrọkọ fi sada lori oro yi.
Nípasẹ̀ Kristi kan náà ni Ọlọrun ti pín wa ní ogún.
A ti gbé Ọlọrun ga pẹlu ìhó ayọ̀,a ti gbé OLUWA ga pẹlu ìró fèrè.
Adamu sọ pe àwọn musulumi nikan ni àwọn n mu, ati pe àwọn ẹlẹsin miiran ni ẹtọ láti jẹun bo se wu wọn.
Àkọlé àwòrán, Ẹmi sofo ,ọkọ ati sọọbu tun jona nilu Eko lorilẹede Naijiria lasiko ti ina bu gbamu ni aarọ Ọjọbọ ladugbo Ijegun nibiti ọpa epo rọbi wa.
Bi awọn eeyan orilẹ-ede Amẹrika ba lọ dibo, kii ṣe oludije ipo aarẹ ni wọn n dibo fun bi ko ṣe akojọpọ awọn eeyan kan ti a n pe ni igbimọ agba ọjẹ oludibo alaṣẹ ti wọn n pe ni Electoral college.
 Àwọn tí ó ń sọ ọ ́ tó mílíònù méje .
Awọn iroyin kan tilẹ n sọ pe bi awọn ṣe gbọ ọ, ọrun lo n dun arabinrin Aisha ṣugbọn iroyin naa sọ pe awọn apẹrẹ ṣaa han pe tori ilera rẹ ni.
Bakan naa ni wọn sa tiya-tọmọ lọgbẹ ni ori, ti awọn mejeeji si wa nile iwosan fun itọju.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ọ̀pọ̀ dẹ́yẹ sí ni mo ti ri nítori mó ni ààrún ori pípa- Liliya Kukushkina By Diana Munasipova, & Kirill Glazkov BBC Russian Service 28 Ògún 2019 Àkọlé àwòrán, Liliya ní wan máa ń dẹ́yẹ sí òun nítori òun ń ni àrun tó máá fa irún èèyan lọsa ọ̀pọ̀ dẹ́yẹ sí mi nítori mó ni ààrún ori pípa- Liliya O lé ní ènìyàn ogóje mílíọ̀nù lágbàyé to ní ààrùn orí pípá lọ́kùnrin àti lóbìnrin.
Iku Sandra ṣe afihan iṣẹlẹ ki eeyan pa elomiran saaju ki o to pa ara naa Oríṣun àwòrán, PHOTOPQR/LE PROGRES/Photo Jean-Pierre BALFIN Àkọlé àwòrán, Aworan Marie-Amélie Vaillat Marie-Amélie Vaillat, ọmọ ọdun mẹrindinlogoji ọmọ ilẹ France Ọkọ Marie-Amélie,Sébastien Vaillat lo gun ni ọbẹ pa.
Atọkun eto naa, Ebuka Obi-Uchendu ti sọ pe, ẹni ti ibo rẹ ba pọju ninu awọn marun un to ku, ni yoo gbade BBNaija ti ọdun yii.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Aarẹ Trump tilẹ sọ lọjọ Ẹti pe enikan to le ba oun figagbaga ninu ẹgbẹ Democrat naa ni Ọgbẹni Bloomberg, amọ oun naa kere.
Nígbà tí Dafidi gbọ́ ohun tí Risipa, ọmọ Aya, obinrin Saulu ṣe, 
Ẹ óo jẹ oúnjẹ àjẹyó ati àjẹtẹ́rùn,ẹ óo sì yin orúkọ OLUWA Ọlọrun yín,tí ó ṣe ohun ìyanu ńlá fun yín,ojú kò sì ní ti àwọn eniyan mi mọ́ lae.
Kare o ‘Lúàmi, ku ọdún oni o, è í ra ṣàṣe mọ ri a (Àṣẹ)
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ruga Settlement: Osinbajo ta kété sí ọ̀rọ̀ Gàá Fúlàní 29 Òkùdu 2019 Oríṣun àwòrán, PROF YEMI OSINBAJO/TWITTER Àkọlé àwòrán, ỌJỌGBỌN YEMI OSINBAJO Igbakeji aarẹ orilẹede Naijiria, Ọjọgbọn yemi Osinbajo ni oun kọ loun wa nidi amojuto akanṣe eto Ruga Settlement bi awọn kan ṣe n gbe iroyin rẹ ka.
Amọ, awọn miran ni Chukwueze ati Ighalo tiraka ṣugbon Etebo ni fun awọn, ti awọn miiran si ni ẹni miran lo se moriya fun wọn.
Akókò yìí ni mo tóó wáá wo ọ̀gbẹ́nni náà dáradára, ìyàlẹ́nu ló si jẹ́ nígbà tí mo rí i pé ọ̀rẹ́ mi ayé àtijọ́ ni, ọkùnrin mẹ́ta, àkàrà-oògùn, a-bá-olóúnjẹ-kú, ẹni tí ó bá àgbákò jà nínú igbó Irúnmalẹ̀, ẹni tí ó rin ìrìn-àjò ti Òkè Láńgbòdó bọ̀, ẹni tí ó wá si ilé mi ní ijọ́sí, ti irohin náà si gba gbogbo orílẹ̀-èdè yí kankan.
ilẹ̀ Ireland ni ní ọdún 2000.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Miliọnu kan naira nileeṣẹ to ba fiya jẹ àkàndá ẹ̀dá a san lówó ìtanràn 24 Sẹ́rẹ́ 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ẹnikẹni ko gbọdọ dẹyẹ si akanda ẹda ni ibudo idikọ, ati wi pe awọn to ni ileeṣẹ irinna gbọdọ ṣeto to yẹ fun awọn ti ko le rin Aarẹ Muhammadu Buhari ti buwọlu ofin ti yoo maa sọ didẹyẹsi awọn akanda ẹda di iwa ọdaran ni Naijiria.
Joseph Smith Kékeré ni a bí ní 23 Oṣù Kejìlá, 1805, ní Sharon, Agbègbè Windsor, Vermont.
Dá wọn lẹ́bi, Ọlọrun, kí o sì fìyà jẹ wọ́n;jẹ́ kí ìgbìmọ̀pọ̀ wọn ó gbé wọn ṣubú.
Mọ́ṣáláṣí yóò kí ìrun Jumat padà ní Èkó lẹ́yìn oṣù mẹ́rin ìséde ààrùn Coronavirus Wo ohun tí Adájọ́ ṣe sí àṣùwọ̀n ìfowópamọ́sí Wòlíì Sotitobire Covid-19 ti rékọjáa 1 Miliọ̀nù l'Áfíríkà!
Kíni àmúyẹ àyẹ̀wò fún ipò lórílẹ̀èdè Nàìjíríà?
Oríṣun àwòrán, Lagos State Government Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí NÍ YÀJÓYÀJÓ US election update: Joe Biden fẹ́ káwọn ará Amẹrika ló ibòmu fún ọjọ́ àkọ́kọ́ rẹ̀ nípò Genevieve Nnaji: Ìbálòpọ̀ pẹlú ọ̀rẹ́kùnrin kọ́ ni ìfẹ́, bẹ́ẹ̀ ni ìfẹ́ kìí ṣe ìbálòpọ̀4 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Àtẹ Àwòrán, Oluwo, Olúgbò àtàwọn Ọba alayé míì ṣàbẹ̀wò sí Gómìnà ìpínlẹ̀ Eko, Oba ìlú Eko àti Bola Tinubu3 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Fídíò, Adebola Ademilua: Àìrísẹ́ ṣè lẹ́yìn ìwé kíkà ló sọ mi dí ìyá onírú, mo dúpẹ́ tèmi27 Bélú 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Òpùrọ́ ni, òun sì ni baba irọ́.
Sihoni ọba àwọn Amori,Ogu ọba Baṣani,ati gbogbo ọba ilẹ̀ Kenaani.
"Aláṣẹ ilé iṣẹ́ BBC ni, ""Inú wa kò dùn sí ìpinnu ìjọba orílẹ̀-èdè Burundi, láti f'òfin de Ilé iṣẹ́ BBC bẹ̀rẹ̀ láti ọjọ́ Ajé tó m bọ̀."
Ni Ọjọbọ, ọjọ kẹsan oṣu kinni ọdun 2020 ni awọn gomina ipinlẹ mẹfẹẹfa to wa nilẹ Yoruba yoo ṣefilọlẹ ikọ abo Amọtẹkun nilu Ibadan.
Grace Oshiagwu: Gómìnà Makinde ké sáwọn ọlọ́pàá, àwọn lọ́balọ́ba lágbègbè Akinyele
Nítorí ohun tí OLUWA Ọlọrun Israẹli wí ni pé, ìyẹ̀fun kò ní tán ninu ìkòkò rẹ, bẹ́ẹ̀ ni kólòbó òróró rẹ kò ní gbẹ títí tí OLUWA yóo fi rọ òjò sórí ilẹ̀.
Oríṣun àwòrán, DAPPER FOUNDATION Àkọlé àwòrán, Benin: UK ṣetán láti dá Adìyẹ 'Àkùkọ' Nàíjìrìa ti wọ́n gbé padà Ile iwe giga naa ni Ọba ilu Benin lo ni i, ati wi pe ibe ni wọn ti gbee wa, amọ wọn ko sọ igba tabi akoko ti wọn yoo da a pada.
Ó sọ fún wọn pé, “OLUWA ní ẹ ti kọ òun sílẹ̀, nítorí náà ni òun ṣe fi yín lé Ṣiṣaki lọ́wọ́.
 Ọjọ ́ yìí ní à ń pè ní ọjọ ́ ọ jímọ ́ ọ ̀ Ọlóyin .
Otútù ń bẹ níta n kò sì re'bìkan 🙂
diẹdiẹ ti wọn yoo maa ṣe si i.
7) Yakub Gobir - Ò yege.
" Oríṣun àwòrán, Others O sọ eyi nitori pe Hush ni N700,00 ni awakọ oun n gba l'oṣu.
“Fi aṣọ ọ̀gbọ̀ tí wọ́n ṣe iṣẹ́ ọnà sí dá ẹ̀wù fún Aaroni, kí o fi aṣọ ọ̀gbọ̀ rán fìlà rẹ̀ pẹlu, lẹ́yìn náà rán àmùrè tí a ṣe iṣẹ́ ọnà sí lára fún un.
 Ọfiisi reluwe ọhun ni ojuko ileeṣẹ ọkọ oju irin to so Itakpe ati ilu Warri papọ, oun naa lo tun so oju ọna Benin mọ Onitsha, atawọn ilu miran ni Naijiria."
“OLUWA ti fi ẹsẹ̀ tẹ àwọn akọni mi mọ́lẹ̀;ó pe ọpọlọpọ eniyan jọ sí mi,ó ní kí wọ́n pa àwọn ọdọmọkunrin mi;OLUWA ti tẹ àwọn ọmọ Juda ní àtẹ̀rẹ́,bí ẹni tẹ èso àjàrà fún ọtí waini.
O gba pe mimọ ootọ iṣẹlẹ yii yoo jẹ ki aato gidi wọ inu ere idaraya wọn gbogbo.
Efuraimu yóo di ahoro ní ọjọ́ ìjìyà; mo ti fi ohun tí yóo ṣẹlẹ̀ dájúdájú hàn, láàrin àwọn ẹ̀yà Israẹli.
Lọdun 1997, Abacha ṣe afikun owo ti Naijiria n fi pamọ silẹ okeere lati $494m to wa lọdun 1993 si $9.
Bakan naa lo ni oun maa n lọ sawọn papa isere idaraya nilu Eko lati wo ere bọọlu, ti oun si nifẹ ere sisa, awọn ere idaraya miran lorisirisi, paapaa ẹgbẹ agbabọọlu Arsenal.
Kii se ohun tuntun mọ wipe awọn ẹgbẹ ajafẹtọ osisẹ n fọ kaakiri bayii lorilẹede Naijiria, gẹgẹbi ati se rii ni aarin apapọ ẹgbẹ osisẹ gan an lorilẹede Naijiria, iyẹn NLC pẹlu.
gbogbonse to wa ni Oke-Ogun ati Ibarapa, tii se eka ile eko gbogbonse ti
Ọpọlọpọ àwọn obinrin mìíràn wà níbẹ̀ tí wọ́n bá a gòkè wá sí Jerusalẹmu.
Ṣugbọn nígbà tí Lọti bẹ̀rẹ̀ sí lọ́ra, àwọn angẹli meji náà mú òun ati aya rẹ̀, pẹlu àwọn ọmọbinrin rẹ̀ mejeeji, wọ́n kó wọn jáde lọ sí ẹ̀yìn odi ìlú, nítorí pé OLUWA ṣàánú Lọti.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù RuizJoshua2: Anthony Joshua di akànṣẹ́ kẹrin nínu ìtàn tí yóò gba ogo rẹ̀ padà lẹ́yìn tó sọ ọ́ nù 8 Ọ̀pẹ̀̀ 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Awọn odu akanṣẹ ti wọn ti padanu igbanu ẹyẹ wọn ṣugbọn ti wọn tun gba a pada niwọnyii: Muhammed Alli: ni ọjọ karundinlogun oṣu keji ọdun1978, Muhammed Ali sọ igbanu ẹyẹ rẹ nu fun Leon Spinks .
Ọba yín ń bọ̀ wá sọ́dọ̀ yín;ajagun-ṣẹ́gun ni,sibẹsibẹ ó jẹ́ onírẹ̀lẹ̀, ó sì gun kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́,kódà, ọmọ kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ ni ó gùn.
ati pé inú Isaaki, baba wọn kò dùn sí i pé kí wọn fẹ́ ọmọ ilẹ̀ Kenaani níyàwó.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ayẹyẹ igbeyawo melo ni Aarẹ Buhari lọ latigba to ti gori oye?
Awọn kan jawọ nitori idojuti to le jẹyọ ti awọn eniyan ba mọ pe wọn ni aarun naa.
NAWOJ) Abileko Jadesola Ajibola n soro lori ipa ti oniroyin le ko ninu eto yi,
Oṣinbajo ṣeleri fawọn eniyan Ọyọ pe laipẹ ni wọn yoo wa pin owo okowo 'Trader money' nibẹ lasiko to n gba wọn nimọran lati dibo fun Buhari nitori pe olootọ ni.
 O ti to ose kan ti omokunrin mi ti wa nibi yii.
Ìjà to ṣẹ́yọ láàrin àwọn àgbẹ̀ àti Darandaran: Àwòràn òfégè kan to tàn lori àtẹjiṣẹ́ twitter léyin ti ìjà bẹ́ silẹ̀ láàrin àgbẹ̀ àti danrandaran ti ìgbà ènìyàn sì báa lọ, ní wọ́n ni àwọn aworan náà jẹ ọkàn lara àwọn ti fúlani pa.
Orisun owo naa Luxembourg ni wọn ni Abacha ko owo naa pamo si.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Afẹnifẹre ni ọrọ atunto lawọ́n tori ẹ yan Atiku laayo Ileeṣẹ rẹdio naa ni wọn ni o jẹ ti gomina ana ni ipinlẹ Ekiti, Ayọdele Fayoṣe.
a ko lee wa lorile ede Naijiria , ki a si tun maa koju isoro lori eto aabo.
O fi kun ọrọ rẹ pe oun ko fi igba kankan ṣiwọ lu Ọba Agbowu tabi ọba kankan ati pe oun kun fun imoore awọn to n dari lọbalọba ilẹ Yoruba labẹ aṣẹ Oni Ile Ifẹ Oba Babatunde Enitan Ogunwusi.
O gboriyin fun Kelvin ti wọn jọ gbe ina woju ara wọn pé akin ni ninu ija.
Ó ní bíbá tí òun bá olórí ìgbìmọ̀ tó n mójútó ìdìbò abẹ́lé ní ìpínlẹ̀ Ogun, Alhaji Muhammed Idabawa, kò so èsò kankan, nítorí pé Idabawa nàá sọ pé omiinú n kọ òun nàá lórí bí èròjà ìdìbò kò ṣe tíì gúnlẹ̀ sí ìpínlẹ̀ Ogun.
Oníṣegùn rẹ ni àwọn yóò ṣì maa fún un ni ìtọ́jú láti ilé ìjọba, nítorí ararẹ̀ kò tíì dá tán.
Ààrẹ Muhammadu Buhari buwọ́lu owó ìṣúná ọdún 2019 Wọn kédé Narendra, oludije ẹgbẹ́ BJP ni India pẹ̀lú ariwo ńla Irawọ Bollywood Sridevi jade laye NBC fọwọ́ sí ìdásílẹ̀ ilé iṣẹ́ Fulani Radio Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Bode George: òòtọ́ ni ìkìlọ̀ Obasanjọ ati Soyinka Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Awọn sẹẹli ko ni le ṣiṣẹ daada lori ounjẹ ti a n jẹ mọ Bi ọjọ ṣe n gori ọjọ ni awọn sẹẹli n sọ agbara lati lọ awọn eroja ounjẹ bi i ọ̀rá ati ṣuga nu Eyi si le yọri si aisan itọ ṣuga.
AbdulHamid ti o je osise ajo INEC kede Dogara gege bi eni ti o gbegba oroke
Tori naa o kere tan o yẹ ki a máa sún wakati meje lojumọ fún ìlera ọpọlọ wa.
Lẹnu ọjọ mẹta yi ni ariwo ati iwọde bẹrẹ si ni gbalẹ tawọn eeyan Naijiria si ni ki ijọba tu FSARS ka.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Eduardo: Mo ń jí mọ́tò pẹ̀lú àwọn ọ̀rẹ́ mi nítorí pé mo fẹ́ di 'Big boy' Ayajọ ọjọ awọn ewe: ọjọ kẹtadinlọgbọn, oṣu karun un: Eyi ni ọjọ ti orilẹ-ede Naijiria ya sọtọ lati sami awọn ewe ti wọn jẹ ogo ilẹ wa.
O jẹ ko di mims fun gbogbo wọn pe aparo kan ko ga ju ọkan lọ laarin wọn nitori naa ko si eyi to ju eyi lọ ninu gbogbo wọn.
Nígbà tí Atalaya, ìyá Ahasaya rí i pé ọmọ òun ti kú, ó bẹ̀rẹ̀ sí pa gbogbo ìran ọba ní Juda.
Oríṣun àwòrán, @oluwole_dada Àkọlé àwòrán, O jẹ ara awọn eeyan to kọkọ laju, o kọ ẹkọ iwe, o lowo, o lọla, o gbajumọ, o si jẹ asaaju ilu.
Mo ti agbórinsétí bọ̀ ẹtí, mo yín ọrin aládùn síi lóri iPhone mi, kí afẹ́ bẹ̀rẹ̀ ní kẹlẹwu.
Ọ̀pọ̀lọpọ̀ òkú ẹyẹ igún ré bọ́ lọ́jà Eke-Ihe Bi o tilẹ jẹ wi pe awọn aladugbo sọ pe ko din ni eeyan meje to ba isẹlẹ naa lọ.
Lẹyin eyi si ni akọsilẹ wa pe owo ẹru ati iwa ẹlẹyamẹya bẹrẹ nigba ti iye awọn adulawọ to n wọ orilẹede Amẹrika n pọ si.
Ṣugbọn bí ọ̀kan ninu àwọn ọmọ Lefi kò bá lo ẹ̀tọ́ ìràpadà yìí, ẹni tí ó bá ra ilé náà lọ́wọ́ rẹ̀ ninu ìlú olódi, yóo jọ̀wọ́ ilé náà sílẹ̀ ní ọdún jubili, nítorí pé, àwọn ilé tí ó wà ní ìlú àwọn ọmọ Lefi jẹ́ ìní tiwọn láàrin àwọn eniyan Israẹli.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Awọn ìmúra tó dá orí ayélujára rú jùlọ lọ́dún 2018 28 Ọ̀pẹ̀̀ 2018 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 30 Ọ̀pẹ̀̀ 2018 Oríṣun àwòrán, FATHIABALOGUN, Tiannahsplacempire Àkọlé àwòrán, ìmúra lọdún 2018 Aṣọ Super Eagles Ìgbà layé, ìgbà lásọ, ìgbà ní gbogbo ǹkan.
Yewande Oyediran: Kò sí ohun tó burú nínú bí Ajimobi ṣe dá Yewande tó pa ọkọ rẹ̀ sílẹ̀
bí ó tilẹ ̀ jẹ ́ pé kò parí ẹ ̀ kọ ́ girama rẹ ̀ ní ìlú Èkìtì , síbẹ ̀ -síbẹ ̀ ó ti ní òye tí ó pọ ̀ jọjọ nínú ìwà ọmọlúwàbí àti ìṣẹ ̀ dálè ìlú Èkìtì , èyí t ́ i a mọ ̀ mọ àwọn ọmọ Èkìtì .
Ẹgbẹrun lè ṣubú ní ẹ̀gbẹ́ rẹ,tabi ẹgbaarun ni apá ọ̀tún rẹ;ṣugbọn kò ní súnmọ́ ọ̀dọ̀ rẹ.
lagbaye ninu ere idaraya boolu afigigba (World number one), Naomi Osaka yoo lo
"Wo àwọn ojúṣe àti èèwọ̀ fún ikọ̀ ọlọ́pàá SWAT tó gba iṣẹ́ lọ́wọ́ SARS Pásítọ̀ Enoch Adeboye darapọ̀ mọ̀ #ENDSARS, ó fún ìjọba Nàìjíríà ní ìmọ̀ràn ọ̀nà àbáyọ Mọ̀ nípa iPhone 12, fóònù ológo 5G tí kìí lo ""Charger” tó ṣẹ̀ṣẹ̀ jáde Ẹ̀yin olùwọ́de, ẹ lọ kọwọ́ ọmọ yín bọṣọ, bí bẹ́ẹ̀ kọ́."
Wò ó, mo ti múra ẹjọ́ mi sílẹ̀;mo sì mọ̀ pé n óo gba ìdáláre.
Kolade Johnson; Iléeṣẹ́ ọlọ́pàá ní ọwọ́ ti tẹ àwọn afurasí ọlọ́pàá tó ṣekúpaá Ààrẹ Algeria kò ní pẹ́ kọ̀wẹ́ fipò sílẹ̀ Àwọn àwòrán ìṣẹ̀lẹ̀ tó làmìlaaka láti ilẹ̀ Áfríkà l'ose tó kọjá Ǹjẹ o mọ bí 'April Fool's Day' se bẹ̀rẹ̀?
 Ẹ ̀ wẹ ̀ , Ìṣọ ̀ lá kò ṣàì kọ ọlọ ́ kan ò jọ ̀ kan ìtàn ní ̀ edè gẹ ̀ ẹ ́ sì tí ó sì tún ṣògbùfọ ̀ ọ ̀ pọ ̀ lọpọ ̀ iṣẹ ́ àpilẹ ̀ kọ ní èdè gèẹ ́ sì ( english ) si ede abinibi re tii se ede yoruba .
Duro Ladipọ, ìlúmọ̀ọ́ká òṣèré tíátà àti ọmọ àlúfà tí kò gbàgbé àṣà ìbílẹ̀ Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
"Nitori naa, ""sisun ni ihoho ma n mu ki ibalopọ o waye laarin tọkọ-taya Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!"
Ko sọrọ lori gbendeke asiko ti iṣẹ akanṣe yii yoo gba.
Ìpìlẹ̀ ilé náà mì títí nígbà tí ẹni náà kígbe, èéfín sì kún ilé náà.
Akiṣi bá sọ fún àwọn iranṣẹ rẹ̀ pé, “Ẹ kò rí i pé aṣiwèrè ni ọkunrin yìí ni, kí ló dé tí ẹ mú un wá sọ́dọ̀ mi?
Ìfẹ́ kì í rìn láì ní ìkọ̀sẹ̀ díẹ̀ ṣùgbọ́n ìfẹ́ pípé a máa sọ òkè di pẹ̀tẹ́lẹ̀, a máa rìn láàrin ẹ̀gún láìbìkítà, a sì máa sáré tete láàárin kòtò àti gegele.
Wọn ṣi n jiroro nipa rẹ,omi gbona fẹ suru lọrọ to wa nilẹ yi agaga to ba ti ni ohun ṣe pẹlu Huawei.
O ni ọpọ ohun ti awọn ọba n dimu lara ẹsin ilẹ okeere lo n tako ilana ilẹ Yoruba ati ohun ti ọba ni lati mọ.
Àkọlé àwòrán, Inú kànga yìí ni Zulaiha kú sí ní agbègbè Hotoro ní ìpínlẹ̀ Kano.
OLUWA wí fún Mose pé, “Kọ ọ̀rọ̀ wọnyi sílẹ̀, nítorí pé òun ni majẹmu mi dúró lé lórí pẹlu ìwọ ati Israẹli.
Wo ọ̀nà àbáyọ sí bo ṣe ń han‘run Lati jawe olubori, awọn olukopa gbọdọ ri eniyan to pọ to, lati dibo fun wọn lati ni ibo to ga julọ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìbádọ́gba nínú ìsèlú àti iṣẹ́ láwùjọ ṣe pàtàkì fún ìdàgbàsóké Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Ìbádọ́gba nínú ìsèlú àti iṣẹ́ láwùjọ ṣe pàtàkì fún ìdàgbàsóké 8 Ẹrẹ̀nà 2019 O ni ìdí ti Ọlọrun fi da àwọn obìnrin 'Obinrin jẹ amuludun'.
Ṣe awọn agba bọ wọn ni ajala ta n naa ọ, ẹyin naa kọhun.
Ọpọlọpọ imọran ti wọn gba iya yii, pabo lo ja si.
Adari egbe awon akekoo ohun, ti o tun ti figba kan je alaga egbe awon akekoo (NationalChairman of the National Association of Nigerian Student) teleri, ogbeni Idowu Odebunmi seleri pe, egbe naa yoo samulo awon ero ayelujara tigbalode lati kede atileyin ati ipolongo fun itesiwaju isejoba aare Buhari, bee si ni ipade lorisirisi ko ni gbeyin lojuna ati ri pe  awon akeko ati awon odo jake-jado orile-ede Naijiria ati loke okun se atileyin fun aare saaju idibo ohun to n bo lona.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Akẹ́kọ̀ọ́ ìmọ òfin ABU tí wọ́n jígbé lọnà Kaduna-Abuja ti gba ìdáǹdè -Ọlọ́pàá 29 Ògún 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Iṣẹ ọwọ agbofinro nikan kọ lo yọ wọn, awa mọlẹbi sanwo itanran fajinigbe ni Awọn mẹtẹẹta ti ri idande wọn gba -Ileeṣẹ ọlọpaa.
Alfa Ibrahim Igboho to jẹ ọkan ninu awọn alaṣẹ mosalasi naa sọ pe awọn salaye fawọn olujosin gẹgẹ bí ilana ijoba pe ki wọn lo ibomu wá sí mosalasi ṣugbọn kìí ṣe gbogbo eeyan lo tẹle ilana yi.
Bẹ́ẹ̀ ni o óo ṣe fún àwọn eniyan náà ati àwọn ẹran ọ̀sìn wọn ní omi.
Kíyèsí ìrìn ẹsẹ̀ rẹ, gbogbo ọ̀nà rẹ yóo sì là.
Princess Igho Williams Broadcast Journalist, BBC News Pidgin 7 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ghana Electoral Commission [EC] chairperson Jean Mensa on 2020 election results Jean Adukwei Mensa ni ẹni ti gbogbo eeyan yoo maa foju si lara gẹgẹ bi alaga ajọ eleto idibo Ghana lọdun 2020.
"Isọkusọ ni bi awọn eeyan ṣe n sọ pe mo ran awọn sọja jade lati pa awọn eeyan ẹ̀yà Igbo.
Ta ni arabinrin naa ti pe bawo ni ọrọ yoo jẹ ipo aarẹ ti ṣe waye?
Ó ní èwo ni oriṣa wọn gbà sílẹ̀ lọ́wọ́ òun, ninu gbogbo àwọn orílẹ̀-èdè wọnyi tí baba òun parun, tí Ọlọrun tiyín yóo fi wá gbà yín?
Bí irúgbìn tí a bá gbìn kò bá kọ́ kú, kò lè hù.
Oríṣun àwòrán, @AishaBuhari Aisha gboriyin fun igboya ti awakọ naa atawọn oṣiṣẹ toku ni si iṣẹ wọn.
Oríṣun àwòrán, @Olafaremoses Àkọlé àwòrán, Ere idaraya ko yọ agba silẹ nibudo awọn Aṣatipo Awọn ajọ aranilowo miran bii Development Support International(DSI) to jẹ awọn oniṣegun oyinbo naa wa si ibudo aṣatipo Wasa lati wa ṣeto ilera fawọn to wa ni ibudo naa.
Oríṣun àwòrán, @Hakeem Adarí àjọ NDDC, Pondei ṣetán láti sọ ohun tó mọ̀ nípa ìwàdíì tó bá ti gbádùn- NDDC Ọkùnrin kan pa ara rẹ̀ sínú ọgbà àjọ TRACE tó n mójútọ ìrìnnà ọkọ̀ nípìnlẹ̀ Ogun Kí ló dé tí ìjọba ìpínlẹ̀ Oyo kéde fífagilé Sáà ètò ẹ̀kọ́ kẹta fún àwọn akẹ́kọ̀ọ́?
Atiku - BBC News Yorùbá BBC News, YorùbáFò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Nigeria at 59: Nàiajíríà ni olú ìlú àwọn tó tòṣì jùlọ làgbáyé - Atiku 30 Owewe 2019 Oríṣun àwòrán, @atiku Àkọlé àwòrán, Atiku ni oun gbagbọ pe Naijiria yoo dara Oludije sipo aarẹ labẹ asia ẹgbe PDP, Alhajai Atiku Abubakar ti ni, bi orilẹ-ede Naijiria ti n ṣe ajọyọ ọdun mọkandinlọgọta to gba ominira, nnkan le koko fun awọn ọmọ orilẹ-ede yii.
Dájúdájú, gbogbo wa ni a óo kú.
Ẹ kò gbọdọ̀ bọ èyíkéyìí ninu àwọn oriṣa tí àwọn orílẹ̀-èdè tí wọ́n wà ní àyíká yín ń bọ, 
Naomi ku laarin osẹ to kọja pẹlu.
Fun apẹrẹ lọdun 1965 o wọ ile igbohunsafẹfẹ Western Nigeria Broadcasting Service nigba naa o si kede ipe fun ki wọn fagile idibo ẹkun Ila Oorun Naijiria.
Alamojuto fun ikọ agbabọọlu Super eagles fidi rẹ mulẹ wipe ile igbafẹ Radisson Blu lawọn agbabọọlu Super Eagles yoo wọ si lasiko igbaradi ati ifẹsẹwọnsẹ ọlọrẹsọrẹ naa ti yoo waye ni ọjọ ẹti.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Wòlíì Sotitobire yóò gba ìdájọ́ lórí ẹ̀ṣùn ìjọ́mọgbé lọ́la Ẹ̀yin olùkọ́, ìlànà àkànṣe owó oṣù tuntun dé fún yín Ibadan ń jó àjórẹ̀yìn láàrin ẹgbẹ́, ẹ fún wa ní ìpínlẹ̀ tiwa - Kola Balogun bẹ ilé aṣòfin 'Nítori ààbò ẹmí MC Murphy ló fi gbá #100,000 lọ́wọ́ K1 lọ́jọ́ ìṣẹ̀lẹ̀' Tani Akeredolu tó ń díje dupò gómìnà fún ìgbàkejì nípìnlẹ̀ Ondo?
Lẹyin orẹyin, ala d'ohun Awọn iroyin ti ẹ lee nifẹẹ si: Aworan aṣa ati iṣe awọn ọmọ Yoruba Kini 'pen' lede Yoruba?
Kiṣi bá sọ fún Saulu ọmọ rẹ̀ pé, “Mú ọ̀kan ninu àwọn iranṣẹ lẹ́yìn, kí ẹ lọ wá àwọn kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ náà wá.
Àkọlé àwòrán, Khadijat sọ pe fifikun owo osu oṣiṣẹ to kere ju lọ ki ṣe ọna abayọ fun eto ọrọ aje Khadijat ni fifikun owo oṣu kọ ni ọna abayọ lati mu idagbasoke ba eto ọrọ aje.
Wọn ni jibiti ni ki ijọba fikun owo tawọn araalu n san fun ina mọnamọna nigba ti ina ọhun n ṣe ṣegeṣege ni gbogbo igba.
Ilu Abuja ni wọn ti mu u Adoke l'Ọjọbọ to pada si Naijiria lẹyin to ti salọ si ilẹ okeere fun ọdun mẹẹrin ni EFCC mu.
Burna Boy to ti gba oriṣiriṣi mi ẹyẹ fi ọna ilu Afro beat wọle to si dapọ m olohun gooro Nomcebo Zikode ninu orin naa.
 Eleyii ni ọrọ alaga tuntun naa.
Mo fẹ́ kí ẹ mọ̀ pé agbowó-odè yìí lọ sí ilé rẹ̀ pẹlu ọkàn ìdáláre ju èyí Farisi lọ.
Ni iwoye wọn, wọn sọ pe awọn ṣe alaye yi niwaju adajọ to gbẹjọ Adeleke ni ilu Bwari L'abuja ṣugbọn wọn ko gba ọrọ naa wole.
” Ṣugbọn àwọn mìíràn ń sọ pé, “Rárá o, ó ń tan àwọn eniyan jẹ ni.
O tẹnu mọ ọ pe ko ṣeeṣe ki ogoji biliọnu naira sọ nu lapoo NDDC toripe asuwọn owo kan ṣoṣo ni wọn n lo.
Amọṣa, ikini ku oriire kan wa ti o ti n mu ki awọn ọmọ naijiria aatawọn ololufẹ Laycon kaakiri agbaye o maa pariwo 'ee ṣe' 'wọn tun de o' ati bẹẹbẹẹ lọ.
N óo sì ko yín wá sí ilẹ̀ tí mo búra láti fún Abrahamu, ati Isaaki ati Jakọbu; n óo fún yín gẹ́gẹ́ bí ìní, Èmi ni OLUWA.
- Sanwoolu Ìjọba kéde ọjọ́ ìwọlé àwọn àgùnbánirọ̀ sí ìpàgọ́ lẹ́yìn Covid 19- Sunday Dare Àjọ elétò ìdìbò kéde ọjọ́ tí ìdìbò aàrẹ Nàìjíríà 2023 yóò wáyé Àbádòfin ìṣúná 2021 ré kọjá ìpele ìkejì nílé aṣòfin àgbà Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Owó tí mo ń rí lórí Garri ni mo fi ń ran ọkọ lọ́wọ́' Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Iya Rainbow: Ó yẹ́ ká máa yẹ́ àwọn onítíátà sí ní ààyè, kìí ṣe òkú wọn16 Ọ̀wàrà 2020 Fídíò, Soyinka Cancer: Àṣe ara mi ni iso ti n run gbogbo bí mo ṣe n ṣèrànwọ́ lórí jẹjẹrẹ27 Bélú 2019 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Ọdun 2004 nigba to bẹrẹ pẹlu gbajugbaja oṣere Iyabo Ojo.
O ni wọn ti gba awọn ẹru naa pada lọwọ Kabir Rabiu lẹyin ti ọwọ ofin tẹẹ.
O ni oun yoo ro awọn ọdọ lagbara.
Ọpọlọpọ eniyan lo ti sọ pe Oyetọla ni igi lẹhin ọgba fun isejọba gomina Rauf Aregbesọla lati ọdun mẹjọ sẹhin.
24 Ẹrẹ̀nà 2016 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Bakan naa lo tun dupẹ lọwọ gbogbo awọn eeyan to ti mu kii ẹrin pa ẹẹkẹ rẹ latẹyinwa, , to si tun n ki awọn ọmọ rẹ ni ọkọọkan pe oun nifẹ wọn, to fi mọ iya to bii.
Oríṣun àwòrán, AFP Àkọlé àwòrán, Presido Nkuruziza ti wa n'ipo fun ọdun mẹrinla IGBEYAWO TI YOO MI IGBORO TITI NI NAIJIRIA !
Àwọn ìbéèrè tó yẹ kí o bi ara a rẹ̀ kí ó tó gba ìròyìn kankan nípa coronavirus gbọ́ Ọ̀rọ̀ Coronavirus kì ń ṣe ṣeréṣeré o-K1 de Ultimate, Toyin Abraham Wọ́n ti fi ọmọ orílẹ̀-èdè Italy tó kó coronavirus sílẹ̀ nílèéwòsàn Èyí làwọn ayẹyẹ nlá tí kò ní wáyé nítorí coronavirus Eeyan kan yooku jẹ ẹni to ti ni ajọṣepọ pẹlu ọkan lara awọn eeyan to ti ni arun naa.
Ìwà agídí dì sí ọkàn ọmọde,ṣugbọn pàṣán ìbáwí níí lé e jáde.
Ó wá fi ọ̀pọ̀ sùúrù fara da àwọn tí ó yẹ kí ó fi ibinu parun.
Lori eto ileeṣẹ iroyin TVC ta mọ si 'The View' lo ti sọ fun awọn olukopa pe oun kii ṣe ẹni to fi tara tara ko ọrọ ẹsin lekan, ṣugbọn ko tunmọ si pe oun ko gbagbọ ninu Ọlọrun.
Àwọn nǹkan wọnyi ni àwọn mìíràn kọ̀, tí ọkọ̀ ìgbé-ayé igbagbọ wọn fi rì.
Ọgbẹni Abdullahi sọ fun BBC pe awada ni ọrọ ti oun ati obinrin naa jọ sọ nipa igbeyawo lori Facebook.
Ko tii to ọpọlọpọ ọdun rara ti okiki Esther Ajayi ẹni ti gbogbo eniyan mọ si Iya Adura bẹrẹ si nii tan kaakiri agbaye gẹgẹ bi olowo to n ṣ'aanu t'ẹru t'ọmọ.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Naomi ni Serena Williams jẹ ẹni ti oun ma n wo gẹgẹ bi awokọse Serena Williams naa ko sanpa lo ile lasan.
Nítorí ní ọjọ́ tí mo kó àwọn baba yín jáde ní ilẹ̀ Ijipti, n kò bá wọn sọ̀rọ̀ ẹbọ sísun tabi ẹbọ rírú, bẹ́ẹ̀ ni n kò pàṣẹ rẹ̀ fún wọn.
Ẹ darapọ̀ mọ́n wa lórí Twitter lónìí fún ìgbélárugẹ èdè Yorùbá.
‘Ṣé kò ì kú,’ ni mo bèèrè, ó sì dámi lóhùn pé, ‘Ko ̀ ì kú.
Awọn ara sọọsi wa kan ni kọ́kọ́rọ́ maa n wa lọwọ wọn.
Hataki lọ bá Modekai ní ìta gbangba, níwájú ẹnu ọ̀nà ààfin ọba.
Ní àkókò náà, Hesekaya ṣàìsàn, àìsàn náà pọ̀; ó fẹ́rẹ̀ kú.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Prophet Israel Oladele: Kilo gbe e de ijọ Celestial?
O wa lara awon adari ifesewonse mejilelogun ti ajo CAF kede won lopin ose pe won jebi esun ohun.
Gíga àgbá kẹ̀kẹ́ kọ̀ọ̀kan sì jẹ́ igbọnwọ kan ààbọ̀.
Fọto bi ọkọ akẹru naa ṣe tẹ Immaculate pa jẹ ohun to ba ni ninu jẹ pupọ.
Mo ro pe o yẹ ka mu ọrọ ohun tí yoo sẹlẹ lẹyin arun Coronavirus ni ibaada, mo si gbagbọ pe awọn ijoba ilẹ Afirika yẹ ki wọn ronu bi wọn yoo ṣe ni oúnjẹ ni anisẹku, ki ọwọ ebi ma ba ka awọn eeyan wọn."
Ogun ẹlẹyamẹya kan to n lọ lọwọ ti le awọn eeyan mẹtadinlaadọrin (67) kuro ni ibugbe wọn l'agbegbe naa Oríṣun àwòrán, EPA Àkọlé àwòrán, Awọn arẹwa awọsọta n s'afihan asọ ti ọmọ ilẹ South Africa, Gavin Rajah, ran nigba ọsẹ ayẹyẹ aṣọ ọṣọ Afrika nigboro Cape Town, lorilẹede South Africa Oríṣun àwòrán, EPA Àkọlé àwòrán, Ọkunrin kan n tun opo ṣe lori ọkọjuomi to n gbe awọn arinajo kan lọ nirolẹ ni eti odo to wa ni erekusu Lamu, to jẹ ibugbafẹ to gbajumọ ni orilẹede Kenya.
Ó yẹ kí ẹ mọ irú àkókò tí a wà yìí, kí ẹ tají lójú oorun.
Olórí wọn ni Ahieseri, lẹ́yìn náà, Joaṣi, ọmọ Ṣemaa; ará Gibea ni àwọn mejeeji.
Ǹjẹ́, mo bèèrè: ṣé Ọlọrun ti wá kọ àwọn eniyan rẹ̀ sílẹ̀ ni?
Gbogbo ọ̀nà burúkú tí Jeroboamu ọmọ Nebati rìn ni òun náà ń tọ̀.
Abimeleki mú aguntan ati mààlúù ati ẹrukunrin ati ẹrubinrin, ó kó wọn fún Abrahamu, ó sì dá Sara, aya rẹ̀, pada fún un.
Dafidi ọba, yan òun ati àwọn arakunrin rẹ̀, tí gbogbo wọn jẹ́ ẹgbaa ó lé ẹẹdẹgbẹrin (2,700) alágbára, láti jẹ́ alámòójútó àwọn ẹ̀yà Reubẹni, ati ẹ̀yà Gadi ati ìdajì ẹ̀yà Manase nípa gbogbo nǹkan tí ó jẹ mọ́ ti Ọlọrun ati àwọn nǹkan tó jẹ́ ti ọba.
Oronsaye reports: Kí ló wà nínú àbájáde ìwádìí ìgbìmọ̀ Oronsaye gan an tó ń kó ọ̀pọ̀ òṣìṣẹ́ láyà sókè?
Akọkọ ni awọn tọrọ naa kan,iru ẹṣẹ ti wọn gbe lọ si ile ẹjọ ati iru agbara ti ile ẹjọ naa ni lati gbọ iru ẹjọ bẹ'' Ghali sọ pe ti ile ẹjọ to ba lagbara lati gbọ ẹjọ naa ba ti wa ni ilu ti wọn ti da ẹsẹ ti ọdaran naa si n gbe ilu naa,ibẹ ni wọn yoo ti gbẹjọ rẹ.
Nkan tó nṣẹlẹ̀ nipé lẹ́hìn bíi ọdún méjì láti ìgbà tí ènìà bá kọ́kọ́ ra ẹ̀rọ ní títun, ẹ̀rọ náà á bẹ̀rẹ̀ sí ígbọ́.
Ẹkọ keji ni pe o yẹ kawọn asiwaju maa setan lati gbọ tẹnu awọn araalu nigbakuugba ati nibikibi Ẹkọ kẹta ni pe ki araalu maa ni suuru ati ifarabalẹ, ki wọn si takete si iwa jagidi jagan nitori a ko mọ ẹmi ẹni to le e mu lọ Ẹkọ kẹrin ni pe ki ọwọ wa maṣe ya lati da ẹmi ẹnikẹni legbodo tabi fun ẹnikẹni ni ọgbẹ lasiko aigbọraẹniye nitori ọba oke nikan lo mọ iye ẹni ti wahala naa le kan Ẹkọ karun ni pe ka yẹra fun iwa ailaju nibikibi abi nigbakuugba nitori iwa ailaju lo le mu ka maa gba ẹmi ara wa tabi ti ọpọlọpọ eeyan lori ohun ti ko to nnkan Bakan naa, lo yẹ ki awọn agbofinro maa lọra lati yinbọn pa araalu lori nnkan kekere eyi to le fa bilisi lẹsẹ.
Ilé ẹjọ́ ju olè orí omi mẹ́ta sí ẹ̀wọ̀n, ó tún ní kí wọ́n san 60 miliọ̀nù Àgbo Covid-19 Madagascar kò ṣiṣẹ́, àwọn ènìyàn tí bẹ̀rẹ̀ sí ní kú níbẹ̀ Alaga igbimọ Tijjaniyya ni ipinlẹ Kano, Mallam Muhammed Nura Arzai lṣalaye fun BBC pe ohun ti ọdọkunrin olorin naa ṣe yii tako ikọni ati igbagbọ Sheikh Ibrahim Inyas to jẹ olori wọn, O ni: Awa ọmọ ẹyin Shehu Inyas gbagbọ pe idajọ Sharia tọna ninu ẹsin Islam.
Oríṣun àwòrán, others Nnkan oṣu obinrin wulo fun oogun owo: Igbagbọ kejì ti ko tun fi idi mulẹ nipa nnkan oṣu obinrin ni pe aṣọ, òwú , pata, páàdì abi ohunkohun ti obinrin ba fi ṣe nnkan oṣu lee wulo fun oogun owo lọdọ awọn adahunse tabi onisegun ibilẹ.
O ni awọn aisan naa ti kan nipa fun ajọ NAFDAC lati gbẹsẹle ipese ati kiko awọn oogun ọhun wọ Naijiria.
Oríṣun àwòrán, Google ''Gbogbo orilẹede to jẹ ọta amọ ti wọn n ṣe bi ọrẹ si Niajiria, yoo gba idajọ pẹlu'' ''Gbogbo ibi ti wọn ti sọ wi pe ko si Ọlọrun fun Naijiria,ni Ọlọrun yoo ti dide fun wọn.
Orílẹ̀-èdè Amẹrika kò ṣọ́ wọlé-wọ̀de mi àti ìdílé mi- Atiku fèsì Oríṣun àwòrán, Twitter/MSME survival fund FG Survival Fund: 'Àwọn oníṣòwò lẹ̀ka ètò ẹ̀kọ́ nìkan ló lè forúkọ sílẹ̀ báyìí fún ìrànwọ́ ìjọba àpapọ̀ Nàìjíríà' Awọn eeyan ipinlẹ Oyo ni ipenija lati forukọ silẹ lori itakun-agbaye fun iranwọ powo ''Survival Fund'' ti ijọba apapọ gbe kalẹ.
Oríṣun àwòrán, LASEMA Ki lara ilu le ṣe?
O ni paapaa lori awọn to ji nkan gbe nile itaja gbogbo ọhun nitori pe iwa ole ko ni orukọ meji.
"Iwe iroyin Hindustan Times jabọ pe obinrin naa ni ""ọkọ mi mu mi lọ si ileewosan aladani kan ni Kolkata, nibiti oun ati oṣiṣẹ eleto ilera kan ti sọ fun mi pe ara mi yoo balẹ̀ lẹyin ti wọn sẹ iṣẹ abẹ lati yọ okuta inu (appendix) mi."
Oríṣun àwòrán, others Ọwọ lile ni Tombalbaye fi ṣe ijọba rẹ ki wọn to paa lọdun 1975 lati ọwọ awọn ọmọ ogun kan.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Oman Returnees: Ọ̀kan lára àwọn obìnrin méjèèjì ní òun ṣiṣẹ́ ọdún kan láì mú ₦5 padà wálé Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Oman Returnees: Ọ̀kan lára àwọn obìnrin méjèèjì ní òun ṣiṣẹ́ ọdún kan láì mú ₦5 padà wálé 2 Ẹrẹ̀nà 2020 Awọn obinrin meji ree ti wọn lọ fi wọn sọfa ni orilẹede Oman, nibi ti oju wọn ti ri mabo.
 bákan náà , tẹ ̀ gbọ ́ n tàbúrò ni ìyá tí ó bí wọn .
Ní ọjọ́ tí Mose gbé Àgọ́ Àjọ dúró, tí ó sì ta òróró sí i tòun ti gbogbo nǹkan tí ó wà ninu rẹ̀, ati pẹpẹ pẹlu gbogbo ohun èlò rẹ̀, 
Amọ nigba to di osu kẹjọ ọdun 2016, ni ikọ Boko Haram fọ si wẹwẹ, lẹyin ti ikọ IS kede pe wọn ti rọ Shekau loye.
N óo fi ikú pa àwọn ọmọ rẹ̀.
O da lori iye owo ti kaluku n gba fun iṣẹ́ to ba ṣe - bi owo naa ba ṣe pọ si, ni aidgba naa yoo ṣe pọ to.
Aare Tayyip Erdogan to n tuko Turkey so eyi di mimo lojo Ru.
O so pe “A jiroro pelu adari ijoba orile ede Britain , paapaa julo lori bi awon onisowo orile ede Britain yoo se mu idagbasoke ba  eto okoowo niluu Eko.
Ṣugbọn àwọn kan rò pé ọlọ́gbọ́n ẹ̀wẹ́ ni mí, ati pé ẹ̀tàn ni mo fi mu yín.
Seyi Awolowo: Torí mo fẹ́ j'ólórúkọ ni mo ṣe lọ fún ètò Ẹlẹ́gbọ́n Àgbà
" Kí làwọn nǹkan tó lè rán ọkùnrin sí ọ̀run alákeji lásìkò ìbálòpọ̀ pẹ̀lú obìnrin?
Nítorí náà mo ṣe aájò dé góńgó kí ọ̀rẹ́ mi yìí ba mọ̀ pé mo mọ rírì ohun tí òun ṣe fún mi mo sì yọ̀ láti rí i pé òun náà mo iyì mi nítori nígbà tí pínyà pẹ̀lú ara wa, ẹ̀mí wa kò pìnyá pẹ̀ú ara wọn; a tún ń kọ̀wé sí ara; mo sì ń rí ìwé rẹ̀ gbà títí di òní olónìí, ẹ óò rí dìẹ̀ nínú àwọn ìwé tí a kọ sí ara wa kà níwájú.
'Mo ro pe minisista orilẹede Naijiria lo fẹ lo baalu wa fi rinrinajo ni, mi o mọ pe awọn eeyan radarada kan ni' Naira Marley: Ta ló ni ọkọ̀ òfurufú tó gbé Naira Marley lọ Abuja?
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Air Peace: 'Rárá o, kó bá 'má jẹ́ Onyema, èyí àtàwọn ọ̀rọ̀ míì tó ń yọjú 24 Bélú 2019 Oríṣun àwòrán, OTHER Bi inu ile tabi gbọngan ti ero ko ti gba ẹsẹ loju opo Twitter, Facebook, instagram atawọn ẹrọ alatagba mii kun fọ́fọ́ lori iroyin pe ilẹ Amẹrika fi ẹsun jibiti kan ọga agba ileeṣẹ ọkọ ofurufu Air Peace, Allen Onyema.
Eyes Allison lori Twitter sọ pe, o yẹ ki awa ọdọ orilẹ-ede yii ji giri, kii ṣe akoko yii lo yẹ ka simi, iranu ni gbogbo eyi ti Aarẹ n sọ."
#BBCNigeria2019 Muhammadu Buhari gba oye Grand Commander of the Fedral Republic (GCFR) ati ọpọlọpọ oye idalọla mii.
Lẹyin eyi ni ajọ Islam ti wọn pe ni Muslim Rights Concern ni ko ko awọn awo rẹ kuro lori igbá.
Ṣaaju ni alaga igbimọ ti ile aṣofin Naijiria gbekalẹ lati wadii awọn ẹsun iwa ibajẹ ninu ajọ to n mojuto idagbasoke agbegbe Niger Delta, NDDC, Olubunmi Tunji-Ojo ti kọwe fi ipo rẹ silẹ.
Elizabeth fúnrarẹ̀ wà nínú ọ̀ka nínú àwọn ọkọ̀-ojú-omi yìí.
O ni bi aarẹ tuntun to fẹ wọle ni orilẹede South Africa ba ti se lee mojuto ọrọ yii to yoo sọ bi isejọba rẹ yoo ti ri.
O ni awọn agbofinro ko wọ ile eyikeyi ninu awọn oṣiẹ rẹ rara.
Pilatu bi í pé, “Kí ni òtítọ́?
Àwọn tí ó ń kọjá lọ ń sọ ìsọkúsọ sí i.
Zmafara to wa ni ekun ila oorun, orile ede Naijiria.
Bí ẹnìkan bá fi iná jó eniyan, kí wọ́n fi iná jó òun náà, bí ẹnìkan bá ṣá eniyan lọ́gbẹ́, kí wọ́n ṣá òun náà lọ́gbẹ́, bí ẹnìkan bá na eniyan lẹ́gba, kí wọ́n na òun náà lẹ́gba.
Itan Ilu gangan Wòlíì Sotitobire gúnlẹ̀ sí ilé ẹjọ́ ní ìtẹ̀síwájú ìgbẹ́jọ́ rẹ̀ Ẹ̀kọ́ mẹ́jọ tó yẹ kí ilẹ̀ Afirika kọ́ lára àjàkálẹ̀ aàrùn coronavirus Awọn aworan awodamiẹnu latilẹ Afrika lọsẹ yi Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí 3 sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 2:23 Fídíò, Water Generator: Ó leè ṣiṣẹ fún wákàtí mẹfà, kó tó sinmi, Duration 2,2310 Òkùdu 2020 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
Oríṣun àwòrán, Instagram/Lady Peller Lásìkò tí Lady Peller ń sọ̀rọ̀ níbí ìfọ̀rọ̀wánilẹ́nuwo náà ló ní òun pàdé ọkọ oun ní ǹkan bi ààdọ́ta ọdún ṣẹ́yìn.
INEC: Àwọn ẹgbẹ́ òṣèlú yóò dìbò àbẹ́lé lóṣù Kẹjọ
Ẹgbẹ awọn agbagba Oke Ọya ni Naijiria, NEF, ti ke si Aarẹ Muhammadu Buhari pe ko kọwe fipo silẹ lẹyin to ti kuna lati daabo bo ẹmi ati dukia awọn ọmọ Naijiria.
Ìsinmi oṣù mẹ́fà lẹ́yìn ìbímọ yóò túbọ̀ mú àdínkù bá ikú mọ wẹ́wẹ́ - Àwọn Obìnrin Ekiti Àìsí ẹ̀rọ ìgbàlódé fún bàálù láti bà ní Nàíjíríà, mú káwọn bàálù láti òkè òkun lọ bà sí Ghana Ẹ san ₦200,000 fún Sowore lórí bí ẹ ṣe ń fi ẹjọ́ falẹ̀ - Iléẹjọ́ pàṣẹ fún ìjọba Buhari, èyí to fí ogún ọdún pilẹ̀ wèrè lórí ètò ààbò Nàìjíríà tó gẹ́ - Bishop Kukah Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Ṣọ́ọ̀ṣì tí wọ́n ti ń fi ọtí àmupara bá Ọlọ́run sọ̀rọ̀ ní kí ìjọba dẹwọ́ọ òfin títà ọtí lásìkò Covid-19 Ọtí tí wọ́n fi Sanitáísà àti Methanol pò pọ̀ ṣekú pá èèyàn 86 Ṣé ọtí leè dènà àrùn Coronavirus bi?
326 g / cm ³ , ni ekeji to gajulo larin awon planeti omiran efuufu .
yálà àwòrán ẹrankokẹ́ranko tí ó wà ní orílẹ̀ ayé, tabi àwòrán ẹyẹkẹ́yẹ tí ń fò lójú ọ̀run, 
Iku Kolade Johnson ni ipinlẹ Eko ati obinrin kan ni agbegbe Ajegunlẹ ni ipinlẹ kan naa ṣi wa lọkan awọn eeyan.
Wọ́n ṣe aṣọ tẹ́ẹ́rẹ́tẹ́ẹ́rẹ́ meji fún èjìká efodu náà, wọ́n rán wọn mọ́ ẹ̀gbẹ́ kinni keji rẹ̀ láti máa fi so wọ́n mọ́ ara wọn.
"Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ìgunnukó: Àwọn Tápà gbà pé ẹni tó bá ń sin Ìgunnukó kò ní ráùn ohun rere Bakan naa lo sọ pe ""agbo naa n fun awọn eeyan ni iwosan laarin ọjọ meje""."
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Olusegun Obasanjo: Ibrahim Ibuoye, ẹni ọgọ́ta ọdún dèrò ilé ẹjọ́ nítorí ó wọ inú oko Obasanjo láì gba àṣẹ 2 Owewe 2020 Oríṣun àwòrán, Others Ẹni ọgọta ọdun Ibrahim Ibuoye to foju bale ẹjọ majisireeti kan ni ipinlẹ Ogun nitori o wọ oko aarẹ orile-ede Naijiria nigba kan ri Olusegun Obasanjo ni Ota lai gba aṣẹ.
OLUWA sọ fún Jeremaya wolii pé kí ó sọ fún àwọn tí ọba Juda rán láti wá wádìí ọ̀rọ̀ lọ́wọ́ rẹ̀ pé, 
Ṣe lootọ ni awuyewuye to gbode kan pe Shoprite fẹ kogba wọn kuro ni Naijiria?
Babandede ni awọn ẹka ti yoo ma a gba iwe irinna naa ni awọn ti wọn fẹ wa gbafẹ, awọn ti wọn fẹ wa se karakata ati awọn ti wọn fẹ wa fẹyinti si orilẹ-ede Naijiria.
Èyí yóo sì jẹ́ ìkìlọ̀ fún àwọn ọmọ Israẹli.
"Gbogbo wa la mọ ohun to t'ẹyin rẹ bo"" ""Nitori naa mi o ni fi ọwọ yẹpẹrẹ mu ọrọ yi"" Fayose salaye pe oun ti fi ọrọ naa to awọn agbofinro leti ati pe wọn gbọdọ wadii awọn to wa lẹyin oro ti o fi n ke."
Wo ǹkan tó yẹ kí o mọ̀ nípa Joe Biden, tó ń kojú Trump nínú ìbò America 'Ṣọ́ọ́ṣì ni mọ ti ń bọ̀ kí n tó pàdé àwọn sójà tó fi abẹ gẹ irun fún mi' Bi ẹ ko ba gbagbe, wọn kede iroyin ijinigbe alaga kansu Iganna nipinlẹ Oyo, ọgbẹni Jacob Adeleke ni ọjọ kẹrindinlọgbọn oṣu kẹwaa.
Wọ́n fún obìnrin kan lọrùn pa, awuyewuye ti ń wáyé Ẹ wo Daniel tí wọ́n fẹ́ yẹgi fún lẹ́yìn tí US kò ṣe irú ẹ̀ fún odidi ọdún 17 Mí ò le nífẹ̀ẹ́ obìnrin Nàìjíríà kankan mọ lẹ́yìn ti mo ti tọ́ obìnrin òyìnbó wò- Issa Ẹ foríjìn wá ọmọ Nàìjíríà, mó mọ̀ pé ẹ̀ ń bínú tórí a kò tètè gbé ìgbésẹ̀ lórí ọ̀rọ̀ EndSARS- Osinbajo Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
tí mo fi awọsanma ṣe ẹ̀wù rẹ̀,tí òkùnkùn biribiri sì jẹ́ ọ̀já ìgbànú rẹ̀,
Ọpọ awọn akẹkọọ naa ni ko ti i di riri pada.
yoo tun maa jiroro lori ipa pataki ti imo ero igbalode yoo tun fi wulo fun
iwon eku niwon itẹ, ni ki a se ara wa.
Lẹ́yìn náà ó ní kí àwọn eniyan túká.
Kí ló ṣẹlẹ̀ tí àwọn ọmọogun Nàìjíríà tó lé ní 350 fẹ́ kọ̀we fi iṣẹ́ sílẹ̀?
Lara awọn ejo yi a maa dẹkun fun ẹran ti wọn ba fe paa jẹ, ti awọn ejo miran si ma a n wa ounjẹ jijẹ wọn lọ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù BB Naija: Ẹgbẹ́ MURIC figbe ta kí ìjọba dá a dúró lẹ́sẹ̀kẹsẹ̀ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ BB Naija: Ẹgbẹ́ MURIC figbe ta kí ìjọba dá a dúró lẹ́sẹ̀kẹsẹ̀ 12 Agẹmo 2019 Oludari ẹgbẹ to n ja fun ẹtọ gbogbo musulumi Naijiria MURIC, Ọjọgbọn Ishaq Akintola sọ fun BBC Yoruba pe ẹkọ buruku gbaa ni eto BB Naija ti awọn eniyan n pọnle n kọ awọn ọmọ.
Nigba ti Lizzy yoo pari ọrọ rẹ naa, o ni gbogbo awọn to n pariwo pe ki oun lọ fẹ ọkọ nigba naa, ni isisinyi ti oun n foju ko oro atarodo soju, oun o ri ẹnikẹni ninu wọn mọ o.
Ti awọn ẹlẹgan ni Lizzy fi kasẹ idupẹ rẹ nilẹ bi o ṣe sọ pe oun dupẹ lọwọ gbogbo eeyan to si gbadura pe gbogbo awọn ẹlẹgan awọn ni oju yoo ti pẹlu i royin iṣerere awọn ni sisẹ n tẹle ti wọn yoo maa gbọ.
osu kejila odun ti a wayii.
Man United vs Chelsea: Chelsea fún Man U lóújẹ àbùkù jè, Cuppy bínú yí jọ̀lọ́ọ̀fù dànù
Bí pàṣán ti rí lára ẹṣin, tí ìjánu sì rí lẹ́nu kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́,bẹ́ẹ̀ ni igi rí lẹ́yìn àwọn òmùgọ̀.
Buhari pàṣẹ lílo àgbo tí orílẹ̀-èdè Madagascar ṣe fún coronavirus fún ìtọ́jú ọmọ Nàìjíríà Madagascar herbal cure : Buhari pàṣẹ lílo àgbo Madagascar fún ìtọ́jú ọmọ Nàìjíríà tó ní covid-19 Oríṣun àwòrán, Twitter/Muhammadu Buhari Aarẹ Muhammadu Buhari ti paṣẹ lilo agbo lilo agbo coronavirus lati orilẹede Madagascar ṣe itọju awọn to lugbadi aarun ni Naijiria.
lorisirisi ni papa isere tuntun ti won sẹsẹ kọ,lati ki aare kaaabo si ipinle
Bó tilẹ̀ jẹ́ pé ìròyìn òfegè ni pé Buhari fẹ fẹ́ Sadiya, síbẹ̀ àwọn ọmọ Nàìjíríà ń ṣètò ìyàwò náà lórí ayélujára Ta ni Sadiya Umar Farouq tí ìròyìn ẹlẹ́jẹ̀ ń gbé pé òun ló fẹ́ dí ìyàwó tuntun Buhari?
Ṣugbọn Amnoni kọ̀, kò gbọ́ ohun tí Tamari sọ fún un.
Lojo Aiku yii ,ni Aare Muhammadu Buhari sedaro oloogbe Tony Anenih.
" Olusegun ni oun ko ni igbagbọ ninu banki naa mọ nitori o le gbẹsẹle owo oun lọjọ iwaju ti oun ba gbiyanju lati ja fẹtọ oun gẹgẹ bi ọmọ Naijiria.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Coronavirus: Gbogbo igbá ti ṣófo láwọn ilé ìtajà káàkiri London Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Coronavirus: Gbogbo igbá ti ṣófo láwọn ilé ìtajà káàkiri London 25 Ẹrẹ̀nà 2020 Iku tó n gbojugba ẹni.
Nítorí ó hàn lónìí sí gbogbo àwọn tí ó ń gbé Jerusalẹmu pé wọ́n ti ṣe iṣẹ́ abàmì.
0 2426 Agbegbe French Guiana 71 25.
Iroyin to n tẹ wa lọwọ lo sọ pe Tola Oyediran Awolowo ti papoda.
Olori Naomi Silekunola Ogunwusi ti bu ẹnu atẹ lu iroyin ofege to sọ wi pe igbeyawo oun ati Ooni ti Ile Ifẹ, Oba Adeyeye Ogunwusi ti fori sanpọn.
Bimbo ni oun tete kuro ninu igbeyawo naa tori oun ko fẹ padanu ọmọ ko si fẹ di apaniyan.
Ronaldo darapo mo Juventus lati iko agbaboolu Real Madrid pelu idunadura ti owo re je ọgọ́rùn ún millionu owo pounds(100 million pounds).
Steph Houton lo kọkọ jẹ goolu akọkọ ni iṣẹju kẹrinla ti Ellen White si fi ikeji si awọn Cameroon ni iṣẹju kaarundinlaadọta le diẹ.
Ọ̀rọ̀ Sotitobire tí a dá sí, àwọn aṣòfin àtàwọn àjọ kan ló fi lọ̀ wá- DSS Ojú pópó ni mo dàgbà sí àmọ́ n kò mu igbó, sìgá tàbí ọtí líle rí - MC Oluomo Ẹ̀yin tí ẹ lọ ra aṣọ àlòkù ní Ọjà Ọba Akure, ẹ lọ ṣàyẹ̀wò Coronavirus - Akeredolu figbe ta Òní ni ètò ìsìnkú George Floyd yóò wáyé Femi Adeoye to jẹ agbẹjọrọ fun awọn afunrasi ọhun pe funh sinsun ẹjọ naa siwaju lẹyin to ni ileeṣẹ ọlọpaa ko lẹtọ láti pè fún ẹjọ́ naa.
O ṣeleri pe ìyà tótọ́ nijoba yoo fi jẹ ile iṣẹ to ba lùgbàdì òfin ìlera.
Òkú àwọn tí OLUWA yóo pa ní ọjọ́ náà yóo kún inú ayé láti òpin kan dé ekeji.
1) Akire ti ilu Ikire: Ọba yii, Olatunde Falabi, la o fi si de, nitori pe wọn ṣẹṣẹ rọ ọ loye ni.
Ta ló sì ni àwọn ẹran tí wọ́n wà níwájú rẹ?
Lagos collapsed building: Àwọn èèyàn ìpínlẹ̀ Eko ní ìjọba, aráàlú lọ́wọ́ nínú bí ilé ṣe ń wó
Ìyá Leah Sharibu ké gbàjarè sí ìjọba Buhari Inec: Kò sí ìká tí o kò lè fí dìbò, ṣáà tí tẹ̀ ẹ́ sójú ẹ dáadáa Man City sán bàntẹ́ ìyà fún Chelsea pẹ̀lú 6-0 Ṣé ìgbéyàwó òṣèré tíátà leè pẹ́?
Bí Favour ṣe sùn, mo gbá ọmọ odó mọ́ ọ lórí a sì gé orí, ọkàn àti ọyàn rẹ̀ fún àsèjẹ - Kayeefi Ọmọ Yahoo yóò pọ̀ si tẹ bá ní kí ọ̀kadà má rìn lójú pópó Eko - Àwọn ọ̀dọ́ Okada Ban: ọjọ kini oṣù keji ni òfin tuńtun yóò bẹ̀rẹ̀ Uber ni mo fẹ́ máa gbé báyìí, mi ò tún fẹsẹ̀ rìn mọ́ - Agunbaniro to n gba N33,000 Wo iye ibùdó ìtójú ibà Lassa tó wà ní Nàìjíríà Ọlọ́pàá ní kí n bọra sílẹ láti mọ bóyá obìnrin ní mí torí mo ní irùngbọ̀n"" Sinimá tí Lateef Adedimeji dá nikan jẹ́ òṣèré yóò jáde, Yemi Solade fi ọ̀pọ̀ fọ́tò ""dẹngẹ pó"" lọ́jọ́ ìbí rẹ̀ Amọ olu ileeṣẹ ilẹ Amẹrika ṣalaye loju opo Twitter wọn pe irọ funfun balau ni iroyin naa."
OLUWA sọ̀kalẹ̀ ninu ìkùukùu láti bá Mose sọ̀rọ̀.
Ninu ọrọ tiẹ naa, Gomina tẹlẹ nipinlẹ Eko, Bola Ahmed Tinubu ni Jakande ni o maa n kọkọ se ohun akọkọ lasiko akoso rẹ, to si jẹ alakoso to dantọ lasiko to nira lati se adari lorilẹede Naijiria.
Ọmọ elési a gbàdá mo yóko
Bó bá jẹ́ òrìṣà kan ni wọ́n ń fi ẹ̀jẹ̀ bọ l' Akinyele, ẹ wáa jáde- Seyi Makinde Bí Naira Marley ṣe ri ọkọ̀ òfurufú tó gbée lọ si Abuja Báwo ní Adebayo Osinowo ṣe dágbére fáyé rèé Abiyamọ ni mi sùgbọ́n mo pa òbí àwọn ọmọ ọlọ́mọ lásìkò ìpìniyàn abéle Rwanda Kí ló ṣokùnfà afárá tó já tó pa ènìyàn kan ní Ilorin?
Èyí ni ọ̀nà tí àwọn obìnrin n gbà kó ara wọn sí wàhálà nítorí ara bíbó Gbọ́ àsọtẹ́lẹ̀ látẹnu Small Mummy Wo ìdí tí àwọn obìnrin kan fi n yọ ilé ọmọ wọn kúrò Gbenga gba pe awọn nkan wọnyii jẹ ohun iranti fawọn arinrin ajo afẹ ti wọn wa si Badagry.
Orisirisi ohun ija oloro ni awon olopaa gba lowo awon omo ogun olote elesin islam naa bi, ado oloro mọ́kànlélọ́gbọ̀, egbo igi oloro abbl, eyi ni o sokunfa ti ile-ise olopaa se fesun iwa ibajẹ kan won eleyi ti o lodi sofin orile-ede Naijiria.
Oríṣun àwòrán, Instagram/mcoluomo ASUU Strike lalẹ garaga oju opo ni tawọn eeyan fẹ ka nipa rẹ Ni abala ibeere nipa iroyin, iyanṣẹlodi awọn olukọ fasiti Naijiria ti o gbẹnu tolori tẹlẹmu wa lara awọn iroyin tawọn eeyan bere nipa rẹ julọ ni 2019 ni Naijiria.
Fayoṣe: Mi ò jẹ̀bi ẹ̀sùn kankan Oríṣun àwòrán, EPA Àkọlé àwòrán, Ilé ẹjọ́ sún ìgbẹ́jọ́ Fayoṣe síwájú di Ọjọ́rú Wọ́n ti gbé ẹjọ́ gómìnà ìpínlẹ̀ Ekiti tẹ́lẹ̀, Ayodele Fayose sí iwájú adájọ́ àgbà Ọlatoregun ní ilé ẹjọ́ gíga tó wà ní Ikoyi, ìpínlẹ̀ Eko.
'Tìbínú-tìbínú ni Liverpool fẹ́ fi kojú Man U' Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
WASSCE: Ìpínlẹ̀ Delta fòfin de olùkọ́ 41 tó ṣe màgòmágó nínú ìdánwò Wọ́n ti yìnbọn pa ọkùnrin ẹni ọgbọ̀n ọdún tó ń jà sí ogún ilẹ̀ bàbá rẹ̀ Ẹgbẹ́ NULGE Oyo dìbò yan olóyè ẹgbẹ́ tuntun èyí tó tako àṣẹ iléẹjọ́ Ilé iṣẹ́ ọmọogun òfurufú sọ orúkọ Tolulope Arotile di mánigbàgbé lórílẹ̀-èdè Nàìjíríà Daniel ń bọ̀ wá wò mí nítori mo ṣàìsàn ló dàwátì- Baba Daniel Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Akomolede àti Aṣa: Ọ̀rọ̀ Ẹ̀yán ni Bunmi Femi Amao ń kọ́ wa lórí ètò Akọ́mọlédè àti Àṣà lóri BBC Yoruba Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Fuel price hike: Wo iye ìgbà tí ẹgbẹ́ òṣìṣẹ́ àtàwọn ọmọ Nàìjíríà ti ṣèwọ́de lórí àfikún owó epo bẹntírò23 Owewe 2020 Fídíò, Wole Soyinka sọ ìdí tó fi ni òun a fi màálù Fulani ṣe súyà fáwọn èèyàn abúlé23 Owewe 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Ninu atẹjade kan to fi sita lọjọ Abamẹta, ọga agba ileeṣẹ mọnamọna lẹkun Ibadan, IBEDC, ọgbẹni Jọhn Ayọdele ni awọn ti n ba awọn mọlẹbi naa jiroro lọna ati tu wọn ninu bi o ti wulẹ o mọ.
Nitori naa ni gomina ṣe rọ awọn ẹbi ati ara Tiamiyu lati mu ọkan le, ati wi pe awọn yoo ṣe iranlọwọ fun wọn ni gbogbo ọna ti awọn lee gba.
Amọ ajakalẹ arun Coronavirus to gbode kan yii, n pa iṣẹ tiata lara gẹgẹ bo ṣe n waye ni awọn ẹka iṣẹ aayan laayo miran.
Ó mú Aaroni, ati àwọn ọmọ rẹ̀ jáde, ó fi omi wẹ̀ wọ́n.
Lẹyin eyi ni awọn alaṣẹ ileewe naa ba gbe ilẹkun rẹ ti pa ti wọn si paṣẹ fun gbogbo akẹkọọ ki wọn maa gba ile obi ati alagbatọ wọn lọ.
O ni oun ko gbagbọ pe iru eyi le waye lasiko ijọba awa ara wa nilu to ni Ọba to ni ijoye.
Ninu oro re lori eyo ayelujra Instagram, ti o ko pelu ede ile faranse, O dupe pupo lowo awon akegbe re, awon akonimoogba gbogbo ati awon ololufe iko agbaboolu PSG fun anfaani ti won fun lati je okan lara ebi naa.
Igbakeji Aare, Ojogbon Yemi Osinbajo, lo so eyi di mimo leyin ti igbimo teekoto tijoba yan lati wa ojutu si ija awon agbe ati darandaran n sabewo awon ohun ti ija yii baje ni agbegbe kookan.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Tinubu ti ń gba orí ayélujára kan, àwọn aráàlú ń fèsì Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Tinubu ti ń gba orí ayélujára kan, àwọn aráàlú ń fèsì 19 Èrèlè 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 24 Èrèlè 2020 Lori ibo to n bọ lọna lọdun 2023, ṣe lo da bii pe la ni ọdun ti a n sọrọ rẹ yii nitori bi awọn ọmọ Naijiria tagba tọmọde ṣe ko si sisọrọ nipa rẹ.
Nítorí ibinu OLUWA àwọn ọmọ ogun, ilẹ̀ náà jóná,àwọn eniyan ibẹ̀ dàbí èpò tí a dà sinu ináẹnikẹ́ni kò sì dá ẹnìkejì rẹ̀ sí.
Nítorí náà, Saulu pada lẹ́yìn Dafidi, ó sì lọ bá àwọn ará Filistia jà.
“Nítorí pé aláìlérò orílẹ̀-èdè ni Israẹli,òye kò sì yé wọn rárá.
kí Kristi fi ọkàn yín ṣe ilé nípa igbagbọ kí ẹ fi ẹsẹ̀ múlẹ̀ ninu ìfẹ́, kí ìpìlẹ̀ ìgbé-ayé yín jẹ́ ti ìfẹ́, 
Ko si dandan aṣa iwe igbelu.
N óo gbé ọ̀kẹ́ kan (20,000) ìwọ̀n kori ọkà tí a ti lọ̀, ati ọ̀kẹ́ kan (20,000) ìwọ̀n baali, ati ọ̀kẹ́ kan (20,000) ìwọ̀n bati ọtí, ati ọ̀kẹ́ kan (20,000) ìwọ̀n bati òróró fún àwọn iranṣẹ rẹ tí wọn yóo gé àwọn igi náà, wọn óo gbé wọn wá fún ọ.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Kí ló dé tí Ilé ẹjọ́ sún ìgbẹ́jọ́ Naira Marley sí ọ̀la?
Ṣugbọn nigba to ba BBC sọrọ, Akọwe ikede fun gomina Makinde, Taiwo Adisa sọ pe gbogbo igbesẹ to yẹ ni awọn gbe nibi ipade naa ni ibamu pẹlu imọran awọn eleto ilera.
Ṣaaju ni nkan bii oṣu diẹ sẹyin ni iroyin kan tan kalẹ pe o bimọ ti o si ni irọ ni awọn eniyan n pa.
A kò ní fi adé wa sílẹ̀ nítorí Olubadan - Àwọn Ọba 27 Arẹ́májà kò sí, Olubadan fi tìlù-tìfọn kí àwọn ìjòyè káàbọ̀ lẹ́yìn ọdún méjì Oyè Mọ́gàjí àti Báálẹ̀ ti di owó rèé, ọjà rèé ní Ibadan - Lekan Balogun Iléẹjọ́ kòtẹ́milọ́rùn ti ní Ajimobi létọ̀ọ́ láti yan ọba l’Ọyọ Kano Emirate: Ṣé àwọn gómìnà ò máa tọwọ́ bọ àṣà lójú báyìi?
aye ara won, ki  o lee ro won lorun lati
Donald Trump: ṣàbẹ́wò ọlọ́jọ́ mẹ́ta sílẹ̀ gẹ̀ẹ́sì
"Koda ajọ FIFA fi ofin de wiwọ rẹ ni idije ife agbaye ọdun 2002 to waye ni Japan, nitori pe ""ki i ṣe ṣaati, bikose awọtẹlẹ""."
Ọ̀nà wo ni mo lè gbà ṣe àtúnṣe ibi tí wọ́n ṣe si yín, kí ẹ baà lè súre fún àwọn eniyan OLUWA?
AFCON bọ́ mọ́ Cameroun lọ́wọ́ nítorí ìdí méjí-CAF CAF kéde orúkọ àwọn olùdíje àmì ẹ̀yẹ agbábọ́ọ̀lù Áfíríkà Klopp jẹjẹ lori Mane ati Salah Oríṣun àwòrán, PIUS UTOMI EKPEI Àkọlé àwòrán, Awọn agbabọọlu mẹta ti wọn jọ n du ami ẹyẹ Salah ti kọkọ gba ami ẹyẹ BBC African Footballer of the Year fun igba ẹkeji.
Àwọn ajínigbé jí adarí ìlú Daura gbé Kí ìjọ mi ní Sagamu le gbòòrò ni mo fi ń ṣiṣẹ́ ajínigbé pawó - Pásítọ̀ Àwọn ajínigbé bèèrè N20m fún ìyàwó ọba Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ìtàn ọ̀rẹ́ tó fi ògùn gba ọkọ ọ̀rẹ́ rẹ̀ ni Akomolede BBC Yorùbá fẹ́ kọ́ wa lònìí Ọga agba ajọ naa to n risi ọrọ idanilẹkọ ara ilu Bisi Kazeem fidi ọrọ yi mulẹ ninu atẹjade kan to fi sọwọ sawọn oniroyin.
FRSC No Parking: Wo ibi mẹ́rìnlá tí o kò gbọdọ̀ gbé ọkọ̀ rẹ sí lásìkò yìí.
láti Jafia, ó lọ sí apá ìlà oòrùn títí dé Gati Heferi ati Etikasini, nígbà tí ó dé Rimoni, ó yípo lọ sí apá Nea.
N óo ko yín kúrò ninu ìlú yìí, n óo sì ko yín lé àwọn àjèjì lọ́wọ́.
Àwọn tó ní ààrùn Coronavirus ní Nàìjíríà ti pé 29,789 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Ile-isẹ naa ninu atẹjade lori ẹrọ ayelujara sọ wi pe gbigbe ayẹyẹ iburawọle naa sori afẹfẹ jasi ipadiapopọ lati gba'jọba lọwọ aarẹ Uhuru Kenyatta, eleyi ti wọn sọ pe o le jasi iku ọpọlọpọ awọn ọmọ orilẹede Kenya.
Nígbà tí ẹ bá ti ka ìwé yìí tán, kí ẹ rí i pé ìjọ tí ó wà ní Laodikia kà á pẹlu.
hẹn ooo, gomina ana ni ipinlẹ Ekiti, Ayọdele Fayose naa ni.
67 fun oju ọna marose ibadan si Ilorin,abala keji oju ona Oyo Ogbomosho ni ipinle Oyo N5,000,000,000.
Ọjọ karun oṣu kẹta ọdun 1937 ni wọn bi Olusegun Matthew Okikiola Aremu Obasanjo.
OLUWA yóo jẹ́ kí ẹ gbọ́ ohùn rẹ̀ tí ó lógo,yóo sì jẹ́ kí ẹ rí ọwọ́ rẹ̀ tí yóo fà yọ pẹlu ibinu ńláati ninu iná ajónirun;pẹlu ẹ̀fúùfù ati ìjì líle ati òjò yìnyín.
yii,lati lo sile ejo lori bi ijoba apapo se yo adari ile-ejo orile ede
O óo wá ranti gbogbo ìwà rẹ, ojú yóo sì tì ọ́ nígbà tí mo bá mú ẹ̀gbọ́n rẹ obinrin ati àbúrò rẹ obinrin, tí mo sì fà wọ́n lé ọ lọ́wọ́ bí ọmọ; ṣugbọn tí kò ní jẹ́ pé torí majẹmu tí mo bá ọ dá ni.
Emiantor gba ijọba ni imọran lati maṣe fun awọn araalu ni anfaani lati gbe ibọn dani fun aabo ara wọn, amọ ki awọn ologun ṣe idanilẹkọ fun awọn araalu nipa bi wọn ṣe le daabo bo ara wọn.
Ẹ mọ̀ pé nígbà tí ẹ jẹ́ aláìmọ Ọlọrun, ẹ̀ ń bọ oriṣa tí kò lè fọhùn.
 tí ó gbón ; tí ó ní làá làáyè .
Bẹ́ẹ̀ ni Solomoni ṣe ṣe gbogbo iṣẹ́ tí ó ṣe láti ìgbà tí ó ti fi ìpìlẹ̀ ilé OLUWA lélẹ̀ títí di ìgbà tí ó parí iṣẹ́ náà patapata.
N óo jẹ́ kí àwọn eniyan mi, àní àwọn ọmọ Israẹli, máa rìn bọ̀ lórí yín.
 kò pẹ ́ kò jìnà tí wọ ́ n fi ń gbọ ́ àwo orin Àṣá káà kiri ilẹ ̀ aláwọ ̀ funfun àti ilé adúláwọ ̀ àti orí rédíò káà kiri .
“Ojo kejila, osu kefaa , ni ogunlogo awon omo orile ede Naijiria jade lati fi ehonu won han lori ibo ti won di ni alaafia, irorun , tiko ni mogo-mogo ninu,ti ko si tun si iru ibo bee lati igba ti a ti gba ominira, sugbon ti ijoba ologun fagile.
Iku oloogbe naa n waye ni nkan bii ọsẹ meji to lewaju iwọde jakejado orilẹede Naijiria, eyiti wọn fẹ fi dide tako bi awọn darandaran Fulani ṣe n pa awọn eeyan kaakiri.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù APC news in Ondo State: Yahaya Bello ni alága ìgbìmọ ìdìbò abẹ́lé gónìnà ìpińlẹ̀ Ondo 30 Òkùdu 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 16 Agẹmo 2020 Egbẹ́ òṣèlú APC nípìnlẹ̀ Ondo ti yan Gómìnà Kogi Yahaya Bello gẹ́gẹ́ bi alága ìgbìmọ̀ ìdìbò abẹ́lé fún àwọn olùdíje fun ipo gómìnà nípìnlẹ̀ Ondo.
Aba yii ni Ogbeni Kunle Ogundoro naa keji ki idibo to bẹrẹ laarin Tinubu ati Akintoye.
Awọn iroyin mii tilẹ sọ wi pe, aisan inu ọkan lo n da a laamu nigba ti awọn kan tun ni itọ ṣuga.
Rmilli, eni ti o dari iko awon onisowo lati orile-ede Tunisia so fun Aare naa pe, orile-ede oun n saniyan lori amugberu eto oro-aje pelu orile-ede Naijira.
nígbà tí ó wà láyé , ó fẹ ́ ràn ìlù Àgàdá púpọ ̀ .
pese isuna fun ile-ise olopa lojuna ati tun wa awon ona miiran ti won yoo maa
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Sextuplet: Àdúrà Ìbùkún ló kú lẹ́yìn ọmọ mẹ́fà yìí- Ifeoma Thelma àti Onyemaechi Chiaka Awọn ẹlẹwọn naa ku si olu ilu N'Djamena, awọn olupẹjọ ni awọn eeyan naa wa lara awọn mejidinlọgọta to jẹ afurasi Boko haram.
Ati pe titi di isinyii, ko tii si ijọba to wẹyin wọn wo.
Ó bá wí fún wọn pé, “Ẹnikẹ́ni tí ó bá kọ iyawo rẹ̀ sílẹ̀, tí ó gbé ẹlòmíràn ní iyawo, ó ṣe àgbèrè sí iyawo rẹ̀ àkọ́kọ́.
" Ṣé olorì ṣì ni Badirat Ọla láàfin ikú bàbá yèyé?
Oníṣẹ́ àdáni 250,000 ni ìjọba ṣe ìlànà yìí fún Àkùkọ dojú ìjà kọ ọlọ́pàá, ikú ló já sí fún agbófinró Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Kété tí wọ́n bá ti báa yín sùn tàn torí pé ẹ tóbi, ẹ gbà pé ìfẹ́ yẹn ti parí - Auntie Remi Ọlọ́yàn ńlá Bakan naa ni awọn ara ipinlẹ Yola ti bẹrẹ si ni da awọn ohun ini ti wọn ji pada lẹyin ti ijọba kede ayẹwọ ojule si ojule.
Amọ, ikọ SARS ko dawọ duro rara nitori wọn ko jawọ ninu irinkerindo wọn, tabi wiwu iwa ipa si awọn araalu.
Oun si lee fi ogun ọrọ yii gbari fawọn obi wọn,orilẹede Naijiria lapapọ ati awujọ agbaye pẹlu.
Oríṣun àwòrán, @HistoryVille Ni ọgbọnjọ oṣu kẹfa, ọdun 2012 ni wọn to dajọ iku nipa yiyẹgi fun Hamza Al- Mustapha ati Alhaji Lateef Shofolahan fun iku Kudirat Abiola.
” Iroyin so pe owo to le ni
Ó di ẹni ti ó ri ṣe ju àwọn ọmọ bàbá rẹ yoku.
Latẹyinwa Igba akọkọ ni yi ti France yoo de ipele aṣekagba idije ife ẹyẹ FIFA lati ọdun 2006.
Kí àwọn àgbààgbà ìlú tí ó bá súnmọ́ ibẹ̀ jùlọ wá ọ̀dọ́ akọ mààlúù kan tí ẹnikẹ́ni kò tíì so àjàgà mọ́ lọ́rùn láti fi ṣiṣẹ́ rí, 
Bi o tilẹ jẹ pe ko sẹni to le sọ iru isẹ ti Funkẹ ran si ọdọmọbinrin osere tiata naa to fi n fo fayọ, sibẹ, Bukunmi naa ko se alaye iru oore to jẹ ninu ọrọ rẹ.
nítorí náà ni n óo ṣe ṣe ilé yìí bí mo ti ṣe Ṣilo; n óo sì sọ ìlú yìí di ohun tí gbogbo orílẹ̀-èdè ayé yóo máa fi gégùn-ún.
Peteru Ròyìn fún Ìjọ ní Jerusalẹmu.
Bakan naa, Omo-Agege ni aayo ẹgbẹ to wa lori ijọba lọwọ lọwọ.
 Kò sí òfin kankan tó lòdì sí síse tàbí mímu oògùn ikọ́ olómi tó ní èròjà codeine sùgbọ́n òfin tako títa òògùn náà fáwọn èèyàn láìsí àsẹ látọ̀dọ̀ dókítà tàbí káwọn tí kò ní ìwé àsẹ máa tàá."
Èèyàn 562 tuntun nló tún ti lùgbàdì COVID-19 ní Nàìjíríà ní àná Wo ohun tó yẹ kí o mọ̀ nípa Laycon, akẹ́kọ̀ọ́jáde UNILAG tó ń kópa nínú BBNaija 2020 Gbogbo ohun tí Godswill Akpabio sọ níbi ẹ̀sùn ìnákùnàá tí wọ́n fi kàn án rèé Bí ẹgbẹ́ One Million Boys ṣe bẹ̀rẹ̀ rèé àti ọṣẹ́ tó ṣe n'Ibadan Ijọba ipinlẹ Eko gba awọn kan lara wọn siṣẹ Ninu oṣu Keje, ọdun 2019 ni Alaga igbimọ amuṣẹya nipinlẹ Eko, Ọgbẹni Olayinka Egbeyemi, kede pe ajọ naa ti gba mẹwa lara ọmọ ẹgbẹ Awawa siṣẹ.
Arọwa yi to wa lati ọdọ aarẹ ẹgbẹ naa ninu ifọrọwerọ pẹlu BBC ko ṣẹyin bi eto iyansipo ẹni ti yoo jẹ ọga fasiti naa lẹyin ti saa Ọjọgbọn Abel Olayinka to jẹ ọmọ ipinlẹ Osun ba pari.
O ni iyalẹnu lo kọkọ jẹ fun ọpọ awọn ẹlẹwọn nibẹ nitori ko sẹni to gbagbọ pe o ṣeeṣe ki wọn gbe fasiti wa sọgba ẹwọn.
Ọkọ mi kò fẹ́ràn oúnjẹ òyìnbó àfi ti ìbílẹ̀ - Lizzy Anjorin Mercy Aigbe ṣá ọmọ rẹ̀ sínúu fíìmù tuntun, wo itú tí ọmọ ọdún mẹ́wàá náà pa Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
 Èyí kan lílò fún àwọn tó ní àrùn kògbóògùn hiv / aids pàápàá .
" Oríṣun àwòrán, Getty Images Abiodun ṣalaye pe Anthony Joshua, to tun jẹ ọmọ bibi ipinlẹ Ogun ti gbe ogo Naijiria ga, o si tun fi han awọn eeyan pe orilẹ-ede Naijiria ṣi maa bori gbogbo idojukjọ to n la kọja.
Èyí ló tí ì pọ̀jù láti ìgbà tí wan ti n ṣọṣẹ́.
Ọdun oro yii waye ni 5:30 irọlẹ si 5:30 idají.
Ewe, akowe agba ajo to n mojuto oro ile okere,  Mustapha Suleiman ati akowe to n mojuto oro isuna lorile-ede Austria, Hebert Fuchs lo se alaga ipade ohun ”Awon olukopa ninu ipade ohun jiroro lori ipo eto aabo ati isomoniyan ni eka ila oorun orile-ede Naijiria.
Abrahamu tún yára lọ sinu agbo mààlúù rẹ̀, ó mú ọ̀dọ́ mààlúù kan tí ó lọ́ràá dáradára, ó fà á fún àwọn iranṣẹ rẹ̀, ó ní kí wọ́n yára pa á, kí wọ́n sì sè é.
Ojo arọọrọda to ya ogiri ọgba ẹwọn nilu Koton Karfe nipinlẹ Kogi, ti mu ki awọn ẹlẹwọn aadọjọ salọ mọ awọn ọga ẹlẹwọn lọwọ.
Ẹnikẹ́ni kò gbọdọ̀ dáná ní gbogbo ilé yín ní ọjọ́ ìsinmi.
''Nitori naa ko si ijọba kankan lati ipo aarẹ to fi mọ gomina to le tako ẹtọ awọn eniyan lati beere fun ẹni ti wọn ba fẹ.
Ohun tí OLUWA sọ nípa Damasku nìyí, Ó ní,“Ìdààmú dé bá Hamati ati Aripadi,nítorí pé wọ́n gbọ́ ìròyìn burúkú:Jìnnìjìnnì dà bò wọ́n, ọkàn wọn sì dàrú,bí omi òkun tí kò lè dákẹ́ jẹ́ẹ́.
Oloṣelu alatako, Mangosuthu Buthelezi sọ pe o jẹ oun to lapẹẹrẹ bi wọn ti dagba bi o ti jẹ pe awọn obi wọn ti ja nigba ti wọn wa ni ewe.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Mistura Oseni Akintunde: Ara múmú kìí ṣe oríṣun ìfipábánilòpọ̀, ìran àwòjù ló ń fà á Bakan naa lo sọ pe, lootọ ni oun jẹ iyawo nile olorogun, ṣugbọn oun ko le ki awọn ọmọ oun laya lati jẹ olorogun.
Àárẹ̀ mú Damasku,ó pẹ̀yìndà pé kí ó máa sálọ,ṣugbọn ìpayà mú un,ìrora ati ìbànújẹ́ sì dé bá a, bí obinrin tí ń rọbí.
“Ìwọ ọmọ eniyan, sọ àsọtẹ́lẹ̀ kí o fi bá àwọn olùṣọ́-aguntan Israẹli wí, fi àsọtẹ́lẹ̀ bá àwọn olórí Israẹli wí pé, OLUWA Ọlọrun ní, ‘Háà, ẹ̀yin olórí Israẹli tí ẹ̀ ń wá oúnjẹ fún ara yín, ṣé kò yẹ kí olùṣọ́-aguntan máa pèsè oúnjẹ fún àwọn aguntan rẹ̀?
Kete lẹyin eyi ni wọn gbe igbesẹ lati wa obinrin naa ri sugbọn pato ibi ti o gba kọja ni wọn ko mọ.
Nigba ti ẹ ba de ibẹ lẹ o mọ boya irọ tabi òótọ́ ni iroyin tẹ n gbọ nita Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, EndSars, EndSwat Protest: Òbí agbábọ̀ọ̀lù Gbenga Tiamiyu Kaka àtàwọn míì tí ọlapàá pa sọ̀r Sugbọn awọn eeyan kan to n gbe ni Oyigbo ti sa kuro nibẹ, nitori ibẹru pe ewu wa fun ẹ̀mí awọn, ati nitori isede ti ko jẹ ki wọn o raaye jade ṣe ohunkohun lati ọsẹ kan sẹyin."
Bii gbogbo ileeṣẹ ọlọpaa kaakiri agbaye, iṣẹ nla l'awọn ọlọpaa Naijiria pẹlu n ṣe lati daabo bo ẹmi ati dukia araalu.
My Mothers Story –Flora Suya- Malawi
won ba se n wọle lori ona ti won yoo gba lati ri i pe , a mu awon ileri , ti a
Forúkọ sílẹ̀ nínú ìròyìn yìí Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Akomolede ati asa Yoruba: Ẹ wá kọ́ nípa àpòtí ìṣura èdè wa lórí BBC Yorùbá Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí 5:58 Fídíò, Akomolede ati asa Yoruba: Ẹ wá kọ́ nípa àpòtí ìṣura èdè wa lórí BBC Yorùbá, Duration 5,5820 Ògún 2020 Akinyele Killings: Ilé iṣẹ́ ọlọ́pàá Ibadan fẹ́ fi owó kún móríya ẹni tó bá rí Sunday Shodipe23 Ògún 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Wọn pa ẹnikan ninu awọn oṣiṣẹ ọun ti o gbiyanju lati sa lọ nigba ti awọn ajinigbe naa de.
Jọ̀wọ́ wá bá mi ṣépè lé àwọn eniyan wọnyi.
Wọn ko ni ẹsun iwa ibajẹ kankan lẹnu i'sẹ 6.
Kó àwọn ohun ọdẹ rẹ: ọrun ati ọfà rẹ, lọ sí ìgbẹ́, kí o sì pa ẹran wá fún mi.
Maryam Sanda, ìyàwó tó pa ọkọ rẹ, ri ìdájọ ikú he Okada Ban: ọjọ kini oṣù keji ni òfin tuńtun yóò bẹ̀rẹ̀ Olùkọ́ fásitì gba ìdájọ́ iku 'torí pé ó sọ̀rọ̀ òdì sí Ànọ́bí lórí ayélujára Máṣe jẹ́ kí ibà Lassa pa ọ́, wo ọ̀nà láti dènà rẹ̀ Àgádágodo ní wọ́n fi ti ẹnú ọ̀nà káńṣù l‘Ọyọ, ọlọ́pàá gbàródan síbẹ̀ Amọ melo ni iru awọn eeyan to daran ipaniyan, ti ile ẹjọ dajọ iku fun, ti ẹyin ranti?
Àwọn ọmọ Hemani ni: Bukaya, Matanaya, Usieli, Ṣebueli, ati Jerimotu, Hananaya, Hanani, Eliata, Gidaliti, ati Romamiti Eseri, Joṣibekaṣa, Maloti, Hotiri, ati Mahasioti.
Architect Ben Channon ni bo ba ṣeeṣe fun ọ, gbe tabili si ẹgbẹ ferese koo si wọ aṣọ oju feree sẹgbẹ kan koo nu ferese rẹ ko mọ tinu tita.
 bí a bá ti ń pọn mọ ́ gbè .
Chelsea ṣetán láti gb'ẹ̀san 4-0 lára Manchester United Ọjọ n bọ ni Oluwa wi, ṣugbọn ọjọ ti ẹgbẹ agbabọọlu Chelsea ati Manchester United yoo tun jọ ta kan-ungbọn ti de lalẹ Ọjọru.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Nollywood: Àwọn obìnrin Yollywood tó ń tà wàrà-wàrà 3 Ògún 2018 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 13 Bélú 2018 Oríṣun àwòrán, ayoadesanya Àkọlé àwòrán, Ayo Adesanya Ayo Adesanya Ọjọ́ kọkànlá oṣù kẹjọ ọdún 1969 ni wọ́n bí gbajúgbajà òṣèrébìnrin Yollywood, Ayo Adesanya tó jẹ́ wí pé kìí ṣe eré Yorùbá nìkan ló ń ṣe.
F Odunjo ko ba fingba mọ, awọn eyi to ti fin silẹ ko lee parun laelae.
"Oyekanmi sọ pe ""irọ ni PDP pa pe ajọ INEC n ṣiṣẹ fun ẹgbẹ oṣelu APC."
Amọ bi eeyan ba se n rin lọ ninu oko yii, ni oorun awọn oku to wa nilẹ yoo gba imu eeyan kan, eyi to lee mu omije jade pe se awọn eeyan kan lo n rare bayii.
Nígbà tí àwọn arakunrin rẹ̀ dé, wọ́n kí i, wọ́n wólẹ̀ níwájú rẹ̀.
Bi a ko ba wa wọrọkọ fi ṣada ni kíá, o lè ṣe àkóbá fún ìpèsè oúnjẹ lọdun yìí''.
NDLEA: A kò tíì mọ àwọn tó ni Tramadol náà
Wo ohun tí Adájọ́ sọ nípa ìgbẹ́jọ́ Wòlíì Sotitobire l'Ondo Oludasilẹ ijọ Sọtitobirẹ ni ilu Akurẹ, Wolii Babatunde Alfa atawọn mẹfa miran ti fi ẹnu ẹjọ wọn jona sibikan bayii ti wọn si n reti bi idajọ ile ẹjọ giga nilu Akurẹ yoo ṣe ri fun wọn.
OLUWA ti dá èdè-àìyedè sílẹ̀ láàrin wọn,wọ́n sì ti ṣi Ijipti lọ́nà ninu gbogbo ìṣe rẹ̀,bí ìgbà tí ọ̀mùtí bá ń ta gbọ̀n-ọ́n-gbọ̀n-ọ́n ninu èébì rẹ̀.
Awọn ohun ti wọn si fẹnuko le lori nibi ipade naa niyi: Owona ti ijọba n bu fun awọn ọlọpaa ko to rara, o si yẹ ki wọn bu owo pupọ fun wọn lati ra awọn ohun eelo ti wọn nilo fun ipese eto aabo to peye Ki ilana isọwọ sisẹ awọn ọlọpaa ba ilana ọtẹlẹmuyẹ ode oni mu, ki irufẹ laasigbo to tẹle iwọde EndSARS ma baa waye mọ Agbeyẹwo abọ ipade apero ilẹ wa tọdun 2014 pẹlu ọna lati se amusẹ awọn aba to wa ninu rẹ bii eto aabo, ọrọ aje ati ibaradọgba awsn ọmọ orilẹede yii Awọn agbaagba ilẹ Yoruba naa tun n fẹ ki ijọba si awọn ẹnu bode ilẹ wa pada nitori eyi lo mu ki inira ọrọ aje tubọ pọ si, to si tun mu kawọn ọja gbogbo gbe owo lori Igbesẹ lati se atunse awọn dukia ti awọn janduku bajẹ lasiko rogbodiyan EndSARS nilẹ Kaarọ oojire, ti wọn si tun yin ijọba lawo pe o tete dahun ibeere tawọn ọdọ naa gbe siwaju rẹ Agbekalẹ eto ti yoo wa isẹ oojọ fun awọn ọdọ ati fifi ẹnu ọrọ jona pklu awọn oluks fasiti, ki awọn akẹkọọ lee wọle pada AWọn tun se atilẹyin fun aba ijọba apapọ lati se akoso awọn oju opo itakun agbaye nitori wọn ni awọn mọ ipa buruku ti iroyin eke n ni lawujọ ati bo se lewu si Amulo imọ ẹrọ igbalode lọna ti yoo mu agbega ba eto aabo wa, yatọ si bi wọn se n lo ẹrọ igbalode fun ibajẹ lori Facebook, Twitter, Instagram ati bẹẹ bẹẹ lọ Ko tan sibẹ, awọn asoju ilẹ Yoruba naa tun n fẹ agbekalẹ ajọ ti yoo maa ri si idagbasoke ẹkun iwọ oorun guusu Naijiria gẹgẹ bo se wa lawọn ẹkun yoku ni Naijiria.
Ààrẹ Trump tàpá sí àbájáde ìpàdé G7 Trump tọrọ aforiji lori asise rẹ Mo ni ọwọ nla fun Afrika-Trump Trump bu ẹnu atẹ lu FBI Trump ni oun kii ṣe ẹlẹyamẹya rara ti ko nifẹ ọmọlakeji rẹ lati iran tabi to ni aawọ miran.
Aare ati alaga igbimo ile-eko to n ri si ibara-ẹni-se papọ lorile ede Naijiria  Mukhtar Sirajo, lo gba awon odo nimoran  yii ,lasiko ti won n se eto itọnisọna fun awon odo ile-ẹkọ naa niluu Calabar ni ipinle Cross River.
Kaakiri agbegbe ibudokọ Alasiya ni wọn pin awọn oku naa si.
Sakaraya, ọmọ rẹ̀, olùdámọ̀ràn tí ó mòye, ni gègé mú fún ẹnu ọ̀nà ti ìhà àríwá.
Ìjà yìí pọ̀ rékọjá ohun tí ẹnu lè sọ ṣùgbọ̀n ní ìgbẹ̀hìn a dúpẹ́ lọ́wọ́ Ọlọ́run Ọba wí pé àwa ní ó borí.
Ẹ ṣí ilé ìwé padà ní Áfíríkà torí ọjọ́ iwájú àwọn akẹ́kọ̀ọ́ yín - WHO, UNICEF Bí ìyàwó rẹ bá lóyún tàbí bímọ ní ìpínlẹ̀ Oyo, wo bí o ti ṣe lé gba ìsinmi ìtọ́mọ (Paternity leave) Ẹ̀bùn #500,000 wà fún ẹni tọ bá ba wa rí afurasí ikú Akinyẹle tó sọnù- Iléeṣẹ́ Ọlọ́pàá 'Ẹ̀pa ò bóró mọ́!
Àbí, kí ni kí n tún ṣe fún àwọn eniyan yìí?
Nibẹ ni Ilẹ ti sọ fun pe, ọrọ ẹran ti awọn ọmọ rẹ di bi oku eeyan, nitori ki wọn o ma ba a fun ẹnikẹni jẹ lara rẹ, lo n fa akufa.
Eyi ni ohun ti eto laa han mi gbe yẹwo lọtẹ yii.
ninu eto iṣuna owo ọdun 2018 ati bo ṣe kọ lati wa siwaju Ile lati
Gomina ipinlẹ Eko, Babajide Sanwo-Olu naa ko gbẹyin ninu awọn to n ṣedaro ẹn'ire to lọ.
’ rèé Coronavirus and OCD: 'Mo fi ogún ọdún gbáradì fún àjàkálẹ̀ ààrùn yìí' Ìjọ Àgùdà yọ̀ǹda iléèwòsàn tó lé ní irínwó gẹ́gẹ́ bíi ibùdó ìtọ́jú àwọn aláàrùn COVID-19 ní Nàìjíríà Idahun si ibeere ami ohun yii ni: Awọlumatẹẹ: ẹni to wọ ilu ti ko tẹẹ: - re do mi do mi do mi Panumọ́, yé parọ́, ₦15m ni Sẹ́nétọ̀ kan ń gbà lówó oṣù - Itsey Sagay sí Lawan Ààrẹ fi nǹkan ọkùnrin rẹ̀ pa mí lójú, kó tó fipá bámi lòpọ̀ - Ọmọge Arẹwà Kí ló mú bàbá àti ọmọ rẹ̀ méjì rẹ́wọ̀n oṣù mẹ́fà he ?
’- ni a bá yára sáré padà.
Ìgbẹ́jọ́ bẹ̀rẹ̀ lórí Adeleke l'Abuja lónìí Ademọla Adeleke, Fayoṣe, Atiku sọ̀rọ̀ lórí ìdájọ́ ilé ẹjọ́ Ademọla Adeleke, Fayoṣe, Atiku sọ̀rọ̀ lórí ìdájọ́ ilé ẹjọ́ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Adeleke: Àwọn ará Ẹdẹ bẹ síta pẹ̀lú ìdùnnú lórí ìdájọ́ èsì ìdìbò gómínà Ọṣun Ẹwẹ, awọn oniroyin to fọrọ wa a lẹnu wo ni ko sọ pato awọn ẹsun ti wọn ka si i lẹsẹ.
" Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Saraki: Gbogbo wa ni ọ̀rọ̀ yíì kán báyìí Sẹnetọ naa ni Ile Igbimo Asofin yoo gbe ofin jade lati kápá aṣilo oogun ni orilẹ-ede yi, pẹlu ofin miran ti yoo ṣetò iwosan fun awọn ti aṣilo oogun ti ya ni were sẹyin.
 lára awọn onírúurú ọ ̀ nà-ìtọ ́ jú ni mími òògùn azithromycin tàbí kíkán òògùn tetracycline siÒ ojuò.
RRS ni wọn ti fa awọn afẹsun kan naa le ẹka to n ṣe iwadii awọn ẹsun ni Ipinlẹ eko (SCID) lọwọ fun iwadii.
nipa bo se kọwe fipo rẹ silẹ  lasiko
Àwọn iranṣẹ mi yóo máa yọ̀,ṣugbọn ìtìjú yóo máa ba yín.
Ariwo nla naa mu ki ọpọ o maa beere pe ki lo le pa iru ariwo bẹ ẹ.
Lóòótọ́, OLUWA ṣe nǹkan ńlá fún wa, nítorí náà à ń yọ̀ ṣẹ̀ṣẹ̀.
Wọn ṣalaye wipe, idajọ gbọdọ ṣẹlẹ lori ọrọ naa.
Olusegun Obasanjo: Màá fi ìyókù ayé mi sin Ọlọ́run áti ènìyàn
Orúkọ àwọn ọmọ Josaya mẹrẹẹrin, bí wọ́n ṣe tẹ̀lé ara wọn ni: Johanani, Jehoiakimu, Sedekaya ati Ṣalumu.
Oríṣun àwòrán, @davidoofficial Chioma, afẹsọna Davido lo ti kọkọ kede loju opo Twitter rẹ nirọlẹ ana pe oun wa nile igbẹbi, ti ọpọ eeyan si ti n se adura fun pe yoo bi wẹrẹ.
OUSMANE SEMBENE AMAA 2018 Ami eye fun ere ede ile Adulawo to dara ju
Abajade iwadii ti ajọ oluṣeṣiro, National Bureau of Statistics, NBS, ṣe fi han pe adinkun ti de ba iye ida okoowo to n jade ni Naijiria ni iwọn 3.
Ìparun ati isà òkú kò lè ní ìtẹ́lọ́rùn,bẹ́ẹ̀ náà ni ojú eniyan, kì í ní ìtẹ́lọ́rùn.
Oríṣun àwòrán, @Musk Ipin idokoowo Musk ni ileesẹ Tesla lo mu ki ọrọ rẹ o ga sii.
Ni bayi, adajọ ile ẹjọ giga to gbe idajọ kalẹ pe ki wọn fi Senetọ Ndume si gbaga ni Kuje ti ni ki wọn wọgi le beeli ti wọn fun ọmọ Maina, Faisal ki wọn si mu u tori pe o sa mọ ile ẹjọ lọwọ.
lọdun to n bo ,lati ni iwa otito ati emi ifokansin fun orile ede .
Fásítì Babcock lé akẹ́kọ̀ọ́bìnrin tó hàn nínú fídíò ìbálòpọ̀ lọ sílé Láti ọdún 2025 lọ, to bá ṣe ìgbọ̀nsẹ̀ sigboro, o rugi oyin - Buhari Àjọ Ìsọ̀kan Yúròòpù àti Amẹ́ríkà bẹnu ẹ̀tẹ́ lu ìdìbò Kogi àti Bayelsa Asofin Nwokolo to ṣaaju igbimọ lori banki ati owo Naijiria ni ki awọn oṣiṣẹ to jẹ oluranlọwọ naa jade lasiko naa.
 Èyí ló faa orúko rè yìí òkè olú .
OLUWA sì sọ fún wọn pé, “Ẹ gbọ́ ohun tí n óo sọ yìí: Nígbà tí àwọn wolii wà láàrin yín, èmi a máa fi ara hàn wọ́n ninu ìran, èmi a sì máa bá wọn sọ̀rọ̀ lójú àlá.
Sibẹsibẹ ó ní òun kò ní gba gbogbo ìjọba náà kúrò lọ́wọ́ Solomoni, òun óo fi sílẹ̀ láti máa ṣe ìjọba ní gbogbo ọjọ́ ayé rẹ̀, nítorí ti Dafidi, iranṣẹ òun, ẹni tí òun yàn, tí ó pa òfin òun mọ́, tí ó sì tẹ̀lé ìlànà òun.
Nínú àwọn méje to ku nínú ilé ni ẹlẹ́gbọ̀n àgbà Trikytee, Vee, Laycon, Neo, Dorathy Ozo ní pín si ẹgbẹ́ méjì láti yàn ènìyàn méjì nínú ẹgbẹ́ méjèèjì tí yóò lọ kúrò nínú ilé ẹlẹ́gbọ̀n àgbà.
Ohun ti wọn tun sọ fun wa ni pe lati igba ti wọn ti bi ọmọ naa ni iya rẹ ti n ṣaisan, ilu Ondo, Ọrẹ si ni o n gbe.
Awọn oludije labẹ asia ẹgbẹ AD, Oloye Owolabi Salis ati akẹgbẹ rẹ lati inu ẹgbẹ LP, Ọjọgbọn Ifagbemi Awamaridi ti saaju kọwe ẹjọ tako iyansipo Sanwoolu pe ko koju oṣunwọn lati dije ipo Gomina.
- Ẹgbẹ́ àgbẹ̀ kìlọ̀ Ọ̀nà àbáyọ fún olóyún lásìkò àjàkálẹ̀ ààrùn Covid-19 Ẹnìkan ṣoṣo nínú ìdílé kan ni yóò gbà N20, 000 owó ìdẹ̀rùn igbele Covid-19 - ìjọba àpapọ̀ O 'salaye pe awọn eeyan ti iṣẹ wọn jẹ koṣemaani nikan ni aaye yoo wa fun lati maa rin lasiko naa.
Taa ba si ka itan igbesi aye Annan yii, aa mọ pe ẹni ti Ọlọrun da nii se.
Mo fun yín ní àṣẹ láti tẹ ejò ati àkeekèé mọ́lẹ̀.
Ìlọ́po meji ni ìpín yín yóo jẹ́ ninu ilẹ̀ yín,ayọ̀ ayérayé yóo sì jẹ́ tiyín.
WAEC: Ìdá 82% àwọn tó jókòó ṣedánwò WASSCE 2019 ló yege
Ṣugbọn ileeṣẹ ologun ti fesi pe ko si ootọ ninu ọrọ ọhun, nitori awọn ko yibọn lu ẹnikẹni.
Awọn iroyin ti ẹ lee nifẹ si: WHO yoo kapa aisan Lassa Fever Awọn asofin Naijiria jiroro lori iba ọrẹrẹ Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
tori bibi ọmọ ni ilana IVF lawọn oyinbo tẹwọgba bayii ju nini oyun nilana abalaye lọ.
Èyí ṣẹlẹ̀ kí ọ̀rọ̀ tí wolii Jeremaya sọ lè ṣẹ pé,
Ta ni ẹ lè fi wé mi, kí á lè jọ jẹ́ bákan náà?
”Saulu dáhùn pé, “Àwọn kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ ni a wá lọ.
Lẹ́yìn náà, mo rí ìwé kan ní ọwọ́ ọ̀tún ẹni tí ó jókòó lórí ìtẹ́: wọ́n kọ nǹkan sí i ninu ati lóde, wọ́n sì fi èdìdì meje dì í.
Operation Puff Adder"" ni o pe iṣẹ akanṣẹ ọhun."
Òkú ọmọ ọdún mẹ́ta tó kó sí kàǹga ní Ipaja ni wọ́n yọ' 'Mo lè fọwọ̀ sọ̀yà fún yín pé Sunday Shodipe ti wà láhàmọ́ wa - Alukoro Ọlọ́pàá Oyo Orí àkìtàn ni wọ́n ti rí ọkùnrin tó ń fi ìgbẹ́ jẹ Búrẹ́dì -Iléeṣẹ́ ọlọ́pàá Oyo Owó dé!
bawo lo ṣé n ló ní ìgboro ẹyin ọ̀dọ́?
Awọn asofin ẹgbẹ oselu Democrat lo faake kọri lati faramọ aba ẹnawo naa, titi ti wọn yoo fi wa nkan se lori atunse ofin eto irinna silẹ Amẹrika, ti aabo yoo si wa fawọn ajoji atohunrinwa ọmọ ilẹ okeere toto ẹgbẹrun lọna ẹẹdẹgbẹjọ ti wọn ko ni iwe igbelu nilẹ Amẹrika amọ ti wọn wọ orilẹede naa gẹgẹbii ọmọde, bẹẹ si ni gbogbo aayan lati jẹ kawọn asofin naa faramọ aba eto isuna yi lọjọ isinmi ana lo fori sanpọn.
N óo máa fi ìfẹ́ mi tí kì í yẹ̀ hàn án títí lae;majẹmu èmi pẹlu rẹ̀ yóo sì dúró ṣinṣin.
Ó sì tún pọ̀ sí i títí tí ó fi ga ju àwọn òkè gíga lọ ní igbọnwọ mẹẹdogun (mita 7).
 awon ènìyàn wonyi a sì maa sinmi ni àbe àwon Ìgi yìí yàlà ní àlo tabì ní àbò .
Amọṣa, oniruru ariwisi lo ti waye lori afara olowo iyebiye naa, paapaa julọ lori idaboobo ayika.
7 117011 Orilẹede Japan 4204 3.
“OLUWA yóo ṣe ọ́ ní eniyan rẹ̀, tí ó yà sọ́tọ̀ fún ara rẹ̀, gẹ́gẹ́ bí ó ti búra fún ọ, bí o bá pa òfin rẹ̀ mọ́, tí o sì ń rìn ní ọ̀nà rẹ̀.
Oríṣun àwòrán, Reuters Àkọlé àwòrán, Orileede Amẹrika ti fun okun mọ orileede Iran pẹlu awọn ijiya orisirisi Lara awọn ẹsun ti wọn fi kan ni pe o parọ fawọn ile iṣẹ ifowopamọ ati orileede Amẹrika nipa ibaṣepọ pẹlu Iran.
Kí ló dé tí ibinu ńlá OLUWA fi dé sórí ilẹ̀ yìí?
Ní ọjọ́ kinni oṣù kinni ọdún keji ni wọ́n pa àgọ́ náà.
Èyíkéyìí ninu àwọn ọmọ alufaa tí ó bá jẹ́ ọkunrin lè jẹ ninu ohun ìrúbọ yìí; ó jẹ́ ohun mímọ́ jùlọ.
Arẹwa obinrin naa sọ pe Ọlọrun nikan lo ye bi ọrọ aye oun ṣe n lọ.
Ẹni to ba ri ni yoo tun bẹrẹ si ni wa awọn ekeji rẹ kiri.
Iya Guardiola, Dolors Sala Carrió ti di oloogbe lẹni ọdun mejilelọgọrin lẹyin to lugbadi aarun covid-19.
Ẹ jẹ ka ran ara wa leti diẹ lara awọn eto owo kiakia naa, ati ọna ti wọn gba pa ọpọlọpọ ọmọ Naijiria l'ẹkun.
elékùú : Àwon ènìyàn àdúgbò yí wí pé , ní ìgbà kan , tí àwon ènìyàn ma ń sepo , orí ni wón fi ma ń ru eyìn lo sí ìlú pàmò sùgbón nígbà tí ó yá , ìjá wà láàárín àwon ará ìlú méjèjì , ni àwon ará-òbà bá sòfin wípé enikéni nínú àwon obìnrin kò gbódù lo se epo ní ìlú-pàmò mó .
Lara awon ti won yan gege bi
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Imo Airport Fire Outbreak: Iná sọ ní pápákọ̀ òfurufú ìpínlẹ̀ Imo 8 Ìgbé 2019 Oríṣun àwòrán, DANIEL NWACHUKWU Àkọlé àwòrán, Papakọ ofurufu ipinlẹ Imo Lẹyin ti ijamba ina kọ lu papakọ ofurufu ipinlẹ Imo, igbokegbodo irinajo ti gberasọ pada.
Koda, mẹta ninu awọn olori naa la gbọ pe o wa nile ẹkọ olukọni onipo kinni to wa nilu Ọyọ, ( Emmanuel Alayande College of Education, Oyo) lasiko ti wọn fi ifẹ han si Alaafin pe, awọn fẹ jẹ olori rẹ.
Pẹlu ifẹsẹwọnsẹ yii, ẹgbẹ agbabọọlu Arsenal yoo si di ipo kẹfa rẹ mu ninu atẹ igbelewọn liigi premiership ni ilẹ Gẹẹsi nigbati Brighton yoo si maa wa ni ipo kejila rẹ.
“Àbí tàkúté a máa ta lásán láìṣe pé ó mú nǹkan?
Ile ijọba ni ilu Abuja ni ayẹyẹ ifilọlẹ iwe alabala mẹrinla naa ti waye.
Oríṣun àwòrán, @Naomi_Osaka_ Àkọlé àwòrán, Aworan Naomi Osaka,ẹgbọn rẹ Mama ati Baba rẹ Lẹyin to ari ẹkọ rẹ lo lọ si Japan nibi ti o ti pada iya Naomi,Tamaki Osaka to jẹ ọmọ Japan.
Mo fi ọ́ sí abẹ́ ààbò Ọlọ́run Ọba,
Ìparun Yóo Dé Bá Àwọn Ọmọ Juda.
‘Ṣé ẹ rí ohun tí èmi OLUWA fi ojú àwọn ará Ijipti rí, ati bí mo ti fi ẹ̀yìn pọ̀n yín títí tí mo fi kó yín wá sí ọ̀dọ̀ mi níhìn-ín?
Sugbọn, bi ẹkun pẹ lọ titi, ayọ n bọ lowurọ, pẹlu ifilọlẹ oju opo BBC Yoruba bayi, alafo naa ko ni pẹ dohun igbagbe.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Cannabis: Akeredolu késí ìjọba Nàíjíríà láti fi òfin ti àmúlò igbó lẹ́yìn 5 Èrèlè 2020 Oríṣun àwòrán, Getty Images Aarẹ ẹgbẹ awọn dokita onimọ iṣegun oyinbo ni Naijiria, Adedayo Faduyile, ti fesi lori igbesẹ gomina ipinlẹ Ondo, Rotimi Akeredolu lori sisọ gbigbin igbo ni Naijiria di nkan to ba ofin mu.
Ayé á tijú olóṣì fún- un l’ẹ́kọ mu
Báńkì ìdàgbàsókè Áfríkà yóò bẹ̀rẹ̀ àkọ̀tun ìwadìí lórí Olùdarí báńkì náà, Akinwumi Adesina Afipábánilòpọ̀ méjì tún ṣọṣẹ́ lára ọmọ ọdún 17 l'Ekiti 'Títẹ àwọn afipábánilopọ̀ lọ́dàá kọ́ ni ọ̀nà àbáyọ sí ìwà ìfipábánilopọ̀' Wo àwọn gbajúmọ̀ òṣèré Yorùbá tí kìí ṣe ọmọ káàárọ̀ oòjíire Oríṣun àwòrán, Twitter/aduke A ti bẹ̀rẹ̀ ìwádìí kíkún nípa àwọn tó lọ́wọ́ nínú ikú Barakat Bello - Iléeṣẹ́ ọlapàá Justice For Barakat: A ti bẹ̀rẹ̀ ìwádìí kíkún nípa àwọn tó lọ́wọ́ nínú ikú Barakat Bello - Iléeṣẹ́ ọlapàá Ileeṣẹ ọlọpaa ipinlẹ Oyo ti sọ pe oun ti gbe iwadii ọrọ Barakat Bello ti wọn pa lẹyin ti wọn fi ipa ba a lopọ tan lọ si ẹka ọtẹlẹmuyẹ to n ri si iwa ọdaran, CID, ni ilu Ibadan.
Ó sì ti rí ẹgbàágbèje ìwọ̀sí tí ènìyàn ń bá pàdé lẹ́yìn odi.
Nibi iwọde naa, ti agbarijọpọ ẹgbẹ ọmọbibi ilẹ Yoruba, Yoruba World Congress, ni asaaju iwọde naa nilu Ibadan, Kunle Adesọkan ti kede pe ẹnikẹni to ko ba fẹ tẹwọgba eto Amotekun, ni ko fẹran ilẹ Yoruba.
Ipele kò-mẹsẹ̀-o-yọ, esi idije to kangun si aṣekagba ni Russia ti awọn to ti fidi rẹmi ti pada sile.
Ara san pa eeyan 16 ninu ṣọọṣi ni Rwanda Ìbúgbàmù àdó olóró pá èèyàn 27 nílé ìjọsìn Wo ohun tó yẹ kóo mọ̀ nípa Notre-Dame tó jóná Awọn alaṣẹ lagbegbe KwaZulu Natal fi idi ọrọ yii mulẹ ti wọn si ni ojo arọda lagbegbe Empageni lo jọ bi ẹ ni ṣe okunfa bi ogiri ile ijọsin ijọ igbalode naa ti ṣe wo lulẹ.
Sugbọn ile ẹjọ to n ri si iṣẹlẹ apapọ ni Turkey ti ni Mọṣalaṣi ni iwe ilẹ ati fiorukó silé ibudo naa pẹlu ile iṣẹ ijọba to n mojuto ọrọ ilẹ pee lati ibẹrẹ.
Nisinsinyii, ẹlẹ́rìí mi ń bẹ lọ́run,alágbàwí mi sì ń bẹ lókè.
Awon eniyan metalelaadota o le ni oodunrun ni won gba o sele ti awon mejo ja si o seese nigba ti awon metalelogun leni eedegberin ko ni arun iba lassa.
OLUWA Ọlọrun yín yóo sì ranti yín, yóo sì gbà yín lọ́wọ́ àwọn ọ̀tá yín.
Ṣe bi ko ba nidi, obinrin kii jẹ Kumolu, ẹṣun to gbe ọkunrin naa de ahamọ ni pe, o ba ọmọdebinrin rẹ, ọmọ ọdun mẹjọ ni ajọsepọ.
Agbẹnusọ ile ẹkọ gbogboniṣe ti a mọ si Poly Ilu Ibadan, Ọgbẹni Soladoye Adewole lo lede ọrọ yii fun ile iṣẹ Iroyin BBC Yoruba.
Lẹyin ọjọ marun ni wọn tu Zlatan atawọn mẹta toku silẹ ti wọn si fi ẹsun mọkanla ọtọọtọ kan Naira Marley.
Oríṣun àwòrán, @wampa80 Saaju igba naa, wọn ṣe ẹmi awọn ara ilu kanna legbodo ni ilu Gamboru, lẹyin ti wọn yin ado oloro lori afara kan nibẹ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Fadele Adu: Kwara la gbà wọlé láti Germany Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Fadele Adu: Kwara la gbà wọlé láti Germany 3 Ògún 2018 Kìí ṣe ìgbà àkọ́kọ́ nìyìí tí Fadele ti ń gun Ọ̀kada fún ìrìnàjò láti orílẹ̀èdè kan sí òmííràn gẹ́gẹ́ bí ẹ̀gbọ́n rẹ̀ náà ṣe máa ń ṣe.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Pa Kasumu: Òṣèré tíátà Yorùbá ní àìsàn tó ń bá òun fínra kìí ṣojú lásán 14 Ọ̀pẹ̀̀ 2019 Oríṣun àwòrán, Twitter/Joba Bamiro Gbajugbaja osẹre tiatia, Kayode Odumosu ti ọpọ mọ si Pa Kasumu ti ke gbajare pe adura awọn eeyan loun nilo bayii nitori aisan to n ṣe oun, ejo lọwọ ninu ni.
Euthanasia in New Zealand: Kìí ṣe New Zealand nìkan ni òfin yìí yóò ti kọ́kọ́ wáye, Canada àti àwọn orílẹ̀-èdè míì rèé
Ó lọ pa irọ́ mọ́ mi lọ́dọ̀ ọba.
Igo tabi agolo Coca-Cola to ni odiwọn 330ml, gẹgẹ bi ohun ti ileeṣẹ naa kọ si ori ayelujara rẹ, ni giraamu ṣuga marundinlogoji, eyi to tumọ si ṣibi kekere meje.
Gbéra, kí o bá àwọn ọ̀tá mi jà ninu ìrúnú wọn;jí gìrì, Ọlọrun mi; ìwọ ni o ti fi ìlànà òdodo lélẹ̀.
Ninu ọrọ to ba awọn akọ̀royin sọ nibi ipade apapọ ẹgbẹ oṣelu APC to n lọ l'Abuja, lẹyin ti wọn ti kede rẹ gẹgẹ bii alaga tuntun fẹgbẹ oṣelu naa, Adams Oshiomole ni, nibi ti ọrọ de duro bayii laarin ẹgbẹ oṣelu APC, ati adari, ati ọmọlẹyin lo gbọdọ lẹnu lori bi idagbasoke yoo ṣe de ba ẹgbẹ oṣelu naa.
Wọ́n jẹ, wọ́n sì mu níwájú Ọlọrun ní ọjọ́ náà pẹlu ayọ̀ ńlá.
Ilé-iṣẹ́ ọlọpàá ní àwọn kìí ṣe arúfin súgbọn àwọn máa ń lépa ohun ti o máa ń mú ki ìjọba awa-ara-wa gbópọn síi.
Fatai Akinbade ADC Fatai Akinbade ti ADC ni oun yoo gbogun ti iwa ibajẹ yii ni nipa lilo 'Due Process' ninu ijọba ki aaye má si fun ole jija.
 o gba eso wura olympiki meji fun 10,000 metres ati ife-eye idije agbaye merin fun ijinna kanna .
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ilẹ Gẹ̀ẹ́sì le è ní olóòtú ìjọba tuntun láìpẹ́ Ọmọkùnrin tó pa ọmọ igbákejì Gómìnà Ondo gba ìdàjọ́ ikú Àwọn olùgbé ìpínlẹ̀ Ọṣun ṣèwọ́de tako ìdájọ́ tó ní Oyetọla kọ́ ló wọlé sípò gómìnà Ọpọ ọmọ Naijiria ni wọn ti n pariwo lori oju opo ayelujara, ero wọn lori ọrọ naa.
Adewole, salaye pe Adele aare ti pase fawon ile ise eto ilera lati ji giri sise ayewo yii kina esisi ma le jo wa leemeji.
Ile isẹ ọlọpaa sọ pe ijamba naa sẹlẹ nigba ti ọkọ ayokẹlẹ to n gbe wọn lọ si ode ariya sadeede kọlu ọkọ miran ti o si ya lọ ba awọn eeyan ni iwaju ile itaja kan.
O sọ pe ''to ba jẹ oludije fun ipo aarẹ ninu ẹgbẹ oṣelu wọn (PDP) lo fẹ ẹ lo papa iṣere naa, wọn ko ni i kọ.
Ọ̀jọ̀gbọ́n Karen ni adarí dídènà iṣan wíwú lọ́nà ti kò dára ní Fasiti Freiburg àti Ọ̀jọ̀gbọ́n Harvard TH Chan nílé ẹ̀kọ́ ilera.
Gómìnà márùn ún tó fojú winá ìbínú bàbá ìsàlẹ̀ wọ̀n Tọwọ́ tẹsẹ̀ laá fi gba ìrànwọ́ owó ẹ̀kọ́ Almajiri ní ìpinlẹ̀ Oyo- Alága Subeb Ẹlẹ́wọ̀n tẹ́lẹ̀ gboyè ìmọ̀ ìjìnlẹ̀ méjì lọ́gbà ẹ̀wọ̀n Wo àwòdamiẹnu àwòrán Mọ́ṣáláṣí Ànọ́bì ní Medina!
Má fi mí lé ìfẹ́ àwọn ọ̀tá mi lọ́wọ́;nítorí pé àwọn ẹlẹ́rìí èké dìde sí mi,ètè wọn sì kún fún ọ̀rọ̀ ìkà.
Awon awoju ojo ti so lati bi ose meji seyin, amo ijoba ko kobi ara si ikinlo naa, lati dekun ekunyale omi naa”.
Bá wo ni òrékelẹ́wà Adedoja tó gbàmì ẹ̀yẹ ''Miss Oyo 2020'' ṣe jẹ́ sí Alaafin?
“Ẹ ranti èyí, kí ẹ dà á rò,ẹ fi ọkàn rò ó, ẹ̀yin ẹlẹ́ṣẹ̀.
Kò sí ọ̀bẹ lọ́wọ́ mi rárá àfí àdá, mo sì bẹrẹ̀ sí pọ́n àdá mi.
Ní oṣù kinni ọdún kinni ìjọba rẹ̀, ó ṣí àwọn ìlẹ̀kùn ilé OLUWA, ó sì tún wọn ṣe.
"Bi ẹnikẹni ba ta ọmọ rẹ ni ọna yii, o daju yoo kabamọ.
Ìdílé márùn-ún tó gbajúmọ̀ fún òwò ẹrú nílẹ̀ Yorùbá Gómìnà Godwin Obaseki yóò d'ọmọ ẹgbẹ́ òṣèlú PDP lọ́sẹ̀ yìí Ẹgbẹ́ òṣèlú APC ti yan Abiola Ajimobi gẹgẹ bí Alága ẹgbẹ́ Ilé ẹjọ́ kòtẹ́mílọ́rùn yọ alága ẹgbẹ́ òṣèlú APC Adams Oshiomhole nípò Ninu ọrọ wọn, ajọ NCDC ni awọn ko i tii buwọlu oogun kankan wi pe ohun koju arun Coronavirus ni Naijiria ati wi pe iwadii si n lọ lori oogun Dexamethasaone.
O ni oun maa kede esi idibo naa laarin wakati mẹrinlelogun si asiko idibo ti o ba ṣeeṣẹ.
Ẹ̀kọ́ mẹ́jọ tó yẹ kí ilẹ̀ Afirika kọ́ lára àjàkálẹ̀ aàrùn coronavirus Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Oríṣí ìjìyà ní àwọn bíi Gómìnà El Rufai àti Fayemi ń bèèrè f'àwọn afipábánilòpọ̀ Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 3 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 5 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Ó sùn ní ìhòòhò ní ọ̀sán ati òru ọjọ́ náà.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Promise Akinlade: ọmọ ọdún mọ́kànlá tó ń fi ìlù dárà bíi àgbàlagbà sọ̀rọ̀ nípa tálẹ́ǹtì rẹ Arun ajogunba: Iwe iroyin Lancet Health Magazine lọdun 2013 ṣalaye pe, arun inu ẹjẹ obi le ṣakoba fun awọn ọmọ ti wọn ba bi.
17 Àti pé ẹ̀yin gbọ́dọ̀ dúró fun ìgbà díẹ̀ kan síi, nítorí a kò tíì yàn yín—
 ní tòótọ ́ ẹrú yìí ń rí ìtọ ́ jú kò sì sí ìdí fún-un láti kùn rárá , ìdí nìyí tí ẹrú yìí kò fi rí àtakò kankan fún ọ ̀ rọ ̀ olówó rẹ ̀ yìí .
Èyí si jẹ́ ọ̀kan paàtàkì lára ìdí ti a kò fi rí ojú àwọn òṣèré kan mọ́ lójú amóhùnmáwòràn wa.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Nigerian Traffic Laws: Ohùn tó yẹ ní mímọ nípa òfin ojú pópó Ẹ ma ṣe fẹrupọkọ yin Ọkọ kọọkan lo ni iye eeyan to le gbe ati iye ẹru ti o yẹ ki o di.
Abuja fun awon to farajin lati se ipolongo  lasiko eto idibo fun awon oludije ninu  egbe APC .
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ibadan Chieftancy Tussle: 'Ọba Balogun ní Olubadan kò le è lé àwọn kúrò nílùú láéláe 7 Èrèlè 2020 Oríṣun àwòrán, Facebook/High Chief Lekan Balogun Aawọ to wa laarin Olubadan ti ilẹ Ibadan, Ọba Saliu Adetunji atawọn Ọba ilu Ibadan tun ti gba ọna mii yọ.
Ṣugbọn kí ‘Bẹ́ẹ̀ ni’ yín jẹ́ ‘Bẹ́ẹ̀ ni,’ kí ‘Bẹ́ẹ̀ kọ́’ yín sì jẹ́ ‘Bẹ́ẹ̀ kọ́.
Ṣugbọn Ọlọrun tú ìdè ikú, ó jí i dìde ninu òkú!
Nígbà tí ẹ bá ti san ìdámẹ́wàá yín lára èyí tí ó dára jù, ìyókù jẹ́ tiyín, gẹ́gẹ́ bí àgbẹ̀ ṣe máa ń kórè oko rẹ̀ lẹ́yìn tí ó ti san ìdámẹ́wàá rẹ̀.
Nítorí pé àwa ni Ọlọrun ní lọ́kàn tí ó fi ṣe ètò tí ó dára jùlọ, pé kí àwa ati àwọn lè jọ rí ẹ̀kún ibukun gbà.
” Ẹ̀rù ba Mose, ó sì rò ó lọ́kàn rẹ̀ pé, “Láìsí àní àní, ọ̀rọ̀ yìí ti di mímọ̀.
Ọbadaya bá bèèrè pé, “Kí ni mo ṣe, tí o fi fẹ́ fa èmi iranṣẹ rẹ, lé Ahabu ọba lọ́wọ́ láti pa?
Ahabu ṣe ohun tí ó bí OLUWA Ọlọrun Israẹli ninu ju gbogbo àwọn ọba Israẹli tí wọ́n jẹ ṣáájú rẹ̀ lọ.
NIN lo se pataki ju niabi kaadi E-Card Erongba ijọba pẹlu nọmba idanimọ ni pe ki awọn eeyan ma lo fun gbogbo ohun to ba ni ṣe pẹlu iforukọsilẹ.
Bí mo ṣe ń dàgbà ni ǹkan ọmọkùnrin mi ń tóbi síi àmọ́ obìnrin ni mi' Nibẹ si ni wọn ti n pariwo pe awọn ọlọpaa atawọn ọlọpaa ọtẹlẹmuyẹ, n di awọn lọwọ lati se iwọde, bẹẹ ni awọn agbofinro naa n yẹ ara awọn eeyan to peju sibẹ wo, boya wọn gbe ohun ija oloro lọwọ.
Agbalagba ni gbogbo awọn to ku ninu ijamba ọkọ ohun.
eleyi ti awon minisita yoo kopa ninu re.
Ilé ìwòsàn l'Àbuja ti ya àwọn ìbejì tí wọ́n sọpọ̀ láyà lọ́fẹ̀ẹ́ Gómìnà mẹ́ta àtí ènìyàn 1,242 ló kó sí panpẹ EFCC ni ọdún 2019 Ẹ́ gba fóónù, ẹ pe ẹbí yín pé a fẹ́ dáná ṣun yín - Aráàlú sọ fún adigunjalè méji Àbọ̀ ìpàdé bòńkẹ́lẹ́ láàrin Tinubu àti Buhari rèé Ọpọ wa lo ka iwe onkọwe yii lasiko taa wa nile iwe, bẹẹ si ni bi onirese J.
Mike Bamiloye ni mi o ki n ṣe pasitọ, mo ni ijọ ti emi naa n lọ gẹgẹ bi ọmọ ijọ, ti mo si ni pasitọ pẹlu, nigba kuugba ti a ba wa nile lorilẹede Naijiria, a n darapọ mọ ijọsin""."
Igbiyanju ati iranwọ awọn ijọba ipinlẹ Ajọ INEC ni awọn ipinlẹ gbogbo lo n gbiyanju lati rii pe awọn eeyan wọn jade lati forukọ silẹ ati lati gba kaadi.
Alábòyun ṣe iṣẹ́ abẹ pẹ̀lú abẹfẹ́lẹ́, ó gbé ọmọ jádé nínú ara a rẹ̀ Eto aabo Lootọọ, kii ṣe ojuṣe ile aṣofin lati pese eto to mọnyan lori fawọn ara ilu, ṣugbọn ile aṣofin kẹjọ ṣe apero lori eto aabo ninu oṣu keji ọdun 2019.
Ó pa adiẹ dipò Igún, o din adiẹ ó jẹ ẹ, ṣùgbọ́n, ó da iyẹ́ Igún si ààtàn bi ẹni pé Igún lohun jẹ.
Ninu ẹ̀yà Bẹnjamini, àwọn tí wọ́n tó ẹni ogún ọdún, tí wọ́n tó lọ sójú ogun, gẹ́gẹ́ bí àkọsílẹ̀ wọn ní ìdílé-ìdílé 
Bẹ́ẹ̀ ni Ahabu ọba ṣe kú; wọ́n gbé òkú rẹ̀ lọ sí Samaria, wọ́n sì sin ín sibẹ.
Nigba to n fi idi isẹlẹ naa mulẹ, agbẹnusọ fun ileesẹ ọlọpaa nipinlẹ Rivers, Nnamdi Omoni salaye pe wọn ti mu osisẹ ọlọpaa ti aje iwa ika ọhun si mọ lori, ti iwadii si ti bẹrẹ nipa isẹlẹ naa.
Eyi to ṣokunfa bi àwọn adẹtẹẹ ṣe lọ maa n dagbo gbe papọ.
Gege bi Ali, ti o je olukoni nipa imo ijinle nilu Gaza“Eni je ojo nla fun wa, eleyi ti orile-ede Israel ati gbogbo aye ma mo pe, a ni gba ki ile Israeli gba gbogbo sakani wa.
Bẹ́ẹ̀ ni wọ́n ṣe ní ilé mi.
O ni orilẹ-ede Naijiria ni ofin to de ki ẹnikẹni maa gbe ibọn kiri laiyọ awọn Fulani darandaran silẹ̀.
Gbogbo ìjọ eniyan Israẹli gbéra láti aṣálẹ̀ Sini, wọ́n bẹ̀rẹ̀ sí lọ láti ibùsọ̀ kan dé ekeji, gẹ́gẹ́ bí àṣẹ tí OLUWA pa fún wọn.
"13bn síwájú Ilé Aṣòfin Ọmọ ẹgbẹ́ APC mẹ́ta bá ìpolongo ìbò lọ l‘Eko Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Bọlanle Aliyu: N kò nílò bàbá ìsàlẹ̀ láti di gómìnà ""O jẹ igba akọkọ ti a maa ri ni orilede Naijiria pe wọn ṣe eto isuna ti iye owo rẹ lọlẹ."
Gege bi adari eka eto idaraya fun Bayern, Hasan Salihamidzic se so“Inu wa dun pupo pe Franck si fe duro tiwa,”Ewe, Ribery darapo mo iko agbaboolu Bayern lodun 2007 lati iko agbaboolu Olympique de Marseille.
"com Igbesẹ keji: Tẹ ori akori kan to ni ""Creat new Account?"
Ladọja fun ara rẹ fi idi ẹ mulẹ fun ajọ ajafẹtọ ọmọniyan, Human RIghts Watch pe Adedibu ṣe bẹbẹ lasiko idibo lati jẹ ki o bori idibo naa.
Ṣugbọn nígbà tí wọ́n gba ìyìn rere tí Filipi waasu nípa ìjọba Ọlọrun ati orúkọ Jesu Kristi gbọ́, tọkunrin tobinrin wọn ṣe ìrìbọmi.
Wọn kólu wọn ni abule Badu-Abattari to wa ni bii ọgọfa kilomita si Maiduguri to jẹ olu ilu ipinlẹ Borno.
Ki ni iṣoro ijọba wa gan?
Wọn ṣalaye pe iwadii ti fidiẹmulẹ pe awọn ọmọ ati ẹbi rẹ wa ni alaafia lai ni aarun coronavirus.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Idajọ bẹrẹ nilu Kainji lori awọn afurasi to le ni ẹgbẹrun kan Wọn ti ju ọkunrin naa si ẹwọn ọdun mẹẹdogun.
Tori eyi, o gbagbọ pe afi dandan ki wọn fopin si ohun gbogbo to jọ mọ iwa aidaa awọn ọlọpaa ni Naijiria.
Awọn ti Tolani n wo niwaju ni awọn bii Kobe Bryant.
“Ọ̀pọ̀ eniyan yóo ti oríṣìíríṣìí ìlú wá sí Jerusalẹmu, 
Wolii àgbàlagbà náà bá bi wọ́n pé, “Ọ̀nà ibo ni ó gbà lọ?
Nigba ti oludije fun ipo gomina ni ipinle Ogun labe asia egbe APC ,
Development: Alexander Ivanov Ki ni 100 Women?
Wọ́n jù mí sí ilẹ̀ kan tí ń jẹ́ Patimosi nítorí mo waasu ọ̀rọ̀ Ọlọrun, mo sì jẹ́rìí pé Jesu ni mo gbàgbọ́.
Lásìkò tí wọn bá wà ni Oke Arafat, aṣọ yíi nikan ni wọn yóò wọ títí ti won yóò fi sọ oko tán lọjọ kejì.
Iwa naa si ti mu ki ọpọ awọn ololufẹ rẹ maa bu ẹnu atẹ lu ṣaaju ki wọn to fi ọwọ osiu juwe ile fun un.
Aarẹ ni ọpọ minisita t'oun yan ni saa kinni ijọba oun loun ko mọ denu tori ẹgbẹ oṣelu atawọn mii lo yan wọn fun oun.
Ajọ NCDC naa fi ikede naa si oju opo ikansiraẹni Twitter wọn, ti apapọ awọn eniyan to ni arun naa ti wa da 11166.
Iròyìn àyọ, àdínkù tún bá iye ènìyàn tó lùgbàdì Covid -19 ní Nàìjíríà lọ́jọ́ Àìkú Owó dé!
Pupọ ọrọ orilẹede Botswana lo da lori okuta iyebiye Dayamọndi.
Oríṣun àwòrán, Peju omobolanle Àkọlé àwòrán, Sunday Ọmọbọlanle (Aluwẹ) ati Peju Ọmọbọlanle (Peju Ogunmọla) Sunday Ọmọbọlanle (Aluwẹ) ati Peju Ọmọbọlanle (Peju Ogunmọla Sunday Ọmọbọlanle ati Peju Ogunmọla naa ti pẹ ninu irinajo ifẹ lagbo ere tiata Yoruba.
Àwọn olùdókòwò MMM ń fi apá jánú Nígbà tó ń sàlàyé ikú tó pa ọmọ rẹ̀, Asòfin Badru ní, ọmọ òun kò rin ìrìnkurìn nítorí ọ̀dọ̀ òun ló ti kúrò ní aago mẹ́sàn án alẹ́ ọjọ́ náà, tí àwọn méjéèjì sì jíròrò nípa ọ̀rẹ́bìnrin rẹ̀ tó fẹ́ dẹnu ìgbeyàwó kọ eyí tó kí àwọn fi se awo.
Àwọn ọmọ Aramu ni: Usi, Huli, Geteri, ati Maṣi.
Diẹ lara awọn ilana wọn ni pe: Ti alejo nile rẹ ba mu inu bi ọ, huwa si i laini aanu Ma ṣe ni ibalopọ ti ẹni naa ko ba fi ami han pe, oun fẹ ẹ ba ọ lopọ Ma ṣe pa awọn ọmọde lara Ma ṣe pa ẹranko, ayafi fun ounjẹ rẹ tabi ti o ba doju ija kọ ọ Ma ṣe wa ija ẹnikẹni, ṣugbọn o le pa ẹni to ba wa ija rẹ run, lẹyin ti o ba ti kilọ fun.
 Ẹni tí ó fi kọ ́ kọ ́ rọ ́ dán séèfù wò tí a ń sọ ̀ rọ ̀ rẹ ̀ lókè ni Àṣàkẹ ́ ìyá bándélé.
Ninu abajade ipade naa, wọn sọ wi pe aṣeyọri eto idibo nilẹ Sierra Leone rọ mọ ki awọn ara ilu gaan kopa lati mu ki eto naa lo ni irọwọ rọ sẹ.
Nígbà tó ṣe díẹ̀ tí a ti wà nínú ọkọ̀ náà, mo ṣe àkíyèsí pé afọ́jú náà nrọra rẹ́rìn-ín sí'ra rẹ̀.
Awon omo-ogun orile-ede America so pe, won ti seku pa awon omo-ogun olote meji ninu ikolu oju ofurufu  ti won se ni apa gusu iwo-orun lorile-ede Libya lojo-Abameta, gege bi akitiyan lati sigun mo awon olote naa.
Wọ́n wá ṣe àpẹẹrẹ sí baba rẹ̀ pé báwo ni ó fẹ́ kí á máa pe ọmọ náà.
Yatọ̀ sí pé ó ṣe sọ́jà, tó tún jẹ́ ọkọ Oriṣabunmi, wo àwọn nkan tí o kò mọ̀ nípa Jimoh Aliu Omijé bọ́ níbi ìsìnkú Ogun Majek Ìjà ẹgbẹ́ òṣèré TAMPAN àti ANTP ni kò jẹ́ kí wọ́n pe Baba Legba sínú eré mọ́, kó tó kú - Owolabi Ajasa Inú mi dùn lórí òfin títẹ àwọn àfipábánilòpọ̀ ní ọ̀dá - Foluke Daramola Ọdún mọ́kànlá rèé témi àti ọkọ mi bẹ̀rẹ̀ ìfẹ́ láti ilé ẹ̀kọ́ girama - Bukunmi Oluwasina Abasido gẹgẹ bi orukọ inagijẹ rẹ mii ṣalaye pe Eleduwa da oun gẹgẹ bi ọga, o ni bakan naa si ni Oba Aṣẹda fi ohun ti oun yoo maa fi ṣe ipo olori jinki oun.
Moshood Abiola stadium, (National Stadium) Abuja Oríṣun àwòrán, Getty Images Papa iṣire apapọ orilẹ-ede Naijiria, iyẹn National Stadium ni orukọ papa iṣere yii tẹlẹ ki wọn to yi orukọ rẹ pada si papa iṣere Moshood Abiọla ni ọdun 2019.
Ijoko igbimọ yi yoo maa waye ni gbogbo ọjọ Iṣẹgun,ọjọ Ẹti ati ọjọ Abamẹta ni ile ẹjọ apẹtusaawọ ipinlẹ Eko to wa ni 1A, Remi Olowude Street, Maruwa Roundabout, Lekki.
Láàárín ọjọ́ Ajé sì Ọjọ́bọ si ni àwọn èèyàn ní anfaani lati lọ si ẹnu isẹ Ajé wọn, tí ìjọba náà yóò sì leè ṣíṣẹ ìlú.
“ ‘Ẹ wà ninu aṣálẹ̀ fún ìgbà pípẹ́, 
awon eniyan wonyii ,fun gudugudu meje yaya mefa ti won ko lasiko eto idibo ,
tojo ori won ko ju metadinlogun lo lọfẹẹ.
Ọpọlọpọ ni èrò tí ó wà lọ́kàn ọmọ eniyan,ṣugbọn ìfẹ́ OLUWA ni àṣẹ.
O ni gbogbo eeyan lo mọ pe ipinlẹ oṣiṣẹ ijọba ni ipinlẹ Ọyọ leyi ti wọn ko si lee da gbogbo oṣiṣẹ sile fun ọjọ gbọrọ.
Angẹli OLUWA náà wí fún un pé, “Pada tọ oluwa rẹ lọ, kí o sì tẹríba fún un.
 Abiola Ajimobi seleri yii nigba ti gomina tuntun ohun se abewo si ile ise ijoba Ipinle Ọyọ to wa ni agbegbe Agodi niluu Ibadan.
Ọ̀gá àgbà iléèṣẹ́ ọlọ́pàá dín wákàtí iṣẹ́ ọlọ́pàá kù Kazaure lọ, Ibrahim di ọ̀gá àgbà àjọ NYSC Buhari to jẹ Alaga awọn olori orilẹede to wa ninu ajọ ECOWAS buwọlu pe ki minisita naa rinrinajo naa pẹlu Aarẹ ECOWAS, Jean-Claude Brou, lati ṣoju oun l'orilẹede Guinea.
Wọn óo dàbí ẹ̀gún, wọn óo máa gún yín lójú, títí tí ẹ óo fi parun patapata lórí ilẹ̀ dáradára tí OLUWA Ọlọrun yín fun yín.
olopaa lati mojuto eto aabo ẹmi ati dukia awon oloselu ati awon oludije  paapaa julo lasiko eto idibo 2019 to n bọ lona.
‘Mo lòdì sí ẹ̀yin olùṣọ́-aguntan, n óo sì bèèrè àwọn aguntan mi lọ́wọ́ yín.
Ogbon iseju  ni won fi se ipade alatilekun –mori  naa ni ofiisi aare to wa niluu Abuja.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Sanwo Olu dá Bello padà; ó yan kọ̀míṣọ́nnà 25 àtàwọn olùbádámọ́ràn 15 Agẹmo 2019 Oríṣun àwòrán, @Sanwoolu Àkọlé àwòrán, Sanwo Olu yan kọ̀míṣọ́nnà 25 àtàwọn olùbádámọ́ràn ti wọn yoo jọ ṣiṣẹ Yatọ si pe gomina Sanwo Olu forukọ awọn Kọmiṣọnna tọ fẹ ba ṣiṣẹ ranṣẹ sile, O tun yan awọn olubadamọran tuntun.
Bakan naa ni ẹgbẹ awọn agbẹ ọlọsin adiẹ ti mu igbe bọnu pe nibayii tijọba ti si awọn ẹnu bode ilẹ wa mẹrin pade, o gbọdọ ri daju pe wọn ko ko awọn ohun abiyẹ wọ orilẹede yii.
Buhari, Makinde, Sanwo-Olu kẹ́dùn pẹ̀lú ẹbí Tola Oyediran, àkọ́bí lóbìnrin tí Obafemi Awolowo bí tó papòdà Ẹ foríjìn wá ọmọ Nàìjíríà, mó mọ̀ pé ẹ̀ ń bínú tórí a kò tètè gbé ìgbésẹ̀ lórí ọ̀rọ̀ EndSARS- Osinbajo Ìjọba Nàìjíríà ti gbà láti san N30b owó àjẹmọ́nú fún ASUU Wo ìgbésẹ̀ mẹ́ta tí Gómìnà Obiano gbé lórí ọ̀rọ̀ SARS ní Anambra Iroyin naa jade loju opo twitter @AyooAkanji ṣugbọn arakunrin A.
Abenugan alatako oun ati agbejoro re ni won fi si ahamo, nigba ti o n gbiyanju, ati tun wo orile-ede naa lasiko ti o n bo lati orile-ede Canada ti won ti le kuro ninu osu to koja.
Saaju, aare Buhari ti ro awon
N óo gbà ọ́ sílẹ̀ ní ọjọ́ náà, wọn kò ní fà ọ́ lé àwọn tí ò ń bẹ̀rù lọ́wọ́.
fun Iko agbabọọlu orile ede Tunisia pe, asiko ti to lati maa lọ si orile ede
Ọmọkùnrin tí wọ́n yìnbọn fún ni Ogbomosho ti dágbere fáyé Nínú ọ̀rọ̀ rẹ̀, agbẹjọrò tó wà lórí ọ̀rọ̀ yìí, Hussein Afolabi nígbà tó bá BBC Yoruba sọ̀rọ̀ sàlàyé pé, ilé iṣẹ́ ọlọ́pàá ìpínlẹ̀ Oyo sọ pé àwọn kò yin ìbọn tàbi tajútaju fún àwọn olùwọ́de.
Gẹgẹ bi o ṣe wi, irufẹ idaamu ti orilẹ-ede Naijiria yoo koju yoo jẹ eyi ti ko tii waye ri ninu itan rẹ.
 aseyori niluu Maiduguri lori iko omo
"òru láwọn adigunjalè fi ń yọ gbogbo ẹ̀yà ara ọkọ̀ wa l‘Eko, dípò kí wọ́n ji gbé lọ"" ₦200m là ń pa wọlé lóṣooṣù, àmọ́ ẹ̀rọ àmúnáwá 75 tà ń lò, ń gbé owó lọ - Olùdarí UCH Coronavirus tún rán oníṣẹ́ ikú sí Saudi Arabia, orí omi ló gbà wọlé!"
Mọ èyí, kí ó sì yé ọ, pé láti ìgbà tí àṣẹ bá ti jáde lọ láti tún Jerusalẹmu kọ́, di ìgbà tí ẹni àmì òróró Ọlọrun, tíí ṣe ọmọ Aládé, yóo dé, yóo jẹ́ ọdún meje lọ́nà meje.
 iṣẹ ́ àkọ ́ kọ ́ tí ó kọ ́ kọ ́ ṣe ni ẹ ̀ gbà ọrùn tí a fi àǹkárá ṣe ṣẹ ̀ ṣọ ́ sí .
Mọ̀ sí i nípa díẹ̀ lára àwọn èèyàn tí ikú wọn 'láti ọwọ́ ọlọ́pàá' milẹ̀ tìtì ní Nàìjíríà Ọ̀rẹ́ wa ni Lawrence jẹ́, àmọ́ ó gbẹ̀yìn dẹ́nu ìfẹ́ kọ abúrò wa - Joshua àti Damilola Bamiloye Ó sàn fún mi kí n máá tíì lọ́kọ báyìí ju kí n lọ́kọ ṣùgbọ́n.
Ní ọdún kẹta tí Hoṣea, ọmọ Ela, jọba ní Israẹli ni Hesekaya, ọmọ Ahasi jọba ní Juda.
Ilẹ̀ tí ẹ óo ti máa jẹun, tí kò ní sí ọ̀wọ́n oúnjẹ, níbi tí ẹ kò ní ṣe aláìní ohunkohun.
Nígbà tí ó gbà fún un, Paulu dúró lórí àtẹ̀gùn, ó gbọ́wọ́ sókè kí àwọn eniyan lè dákẹ́.
Báyìí ni ìtàn rẹ lọ: kí ó tó kúrò ní òde ọ̀run wá sí aye o ti lọ wọ ẹ̀wù àìkú ni òde ọ̀run láìsí àṣẹ Olódùmarè níbẹ̀, ó jii wọ̀ ni, nígbà tí ẹ̀dá tí ó wà ní ìkáwọ́ ẹ̀wù àìkú kò sí níbẹ̀, orúkọ ẹni ti ń jẹ ògbódògo, bẹ́ẹ̀ ni ó wá sí ilé ayé, bí o si tilẹ̀ jẹ́ pé ènìyàn ni o bíi.
Kí ló mú àwọn aládùúgbò Mọ́ṣáláṣí Alhaja kọlu àwọn ọlọ́ọpàá?
Ọ̀kan ninu àwọn àgbààgbà mẹrinlelogun yìí wá sọ fún mi pé, “Má sunkún mọ́!
O ni eto okowo se Pataki si aare Buhari paapaa fawon olokowo keekeeke ati aladani alabele.
Kàyééfì BBC News Yorùbá gbé òtítọ́ òògun owó yẹ̀wò Ọmọ pupa làwọn olólùfẹ́ wa fẹ́ wò nínú fíìmù làwọn òṣèré tíátà fi ń bóra - Muka Ray Bí mo ṣe ṣẹ́gun Coronavirus rèé - Seyi Makinde Coronavirus: Ọmọ márùn ún ni mo ní, ṣùgbọ́n kò sí oúnjẹ fún wa lásìkò ìgbélé yìí -Olùgbé ìlú Eko Èèyàn mẹ́fà míràn tún ti ní àrùn Coronavirus ní Naijiria Kí ló mú àwọn aládùúgbò Mọ́ṣáláṣí Alhaja kọlu àwọn ọlọ́ọpàá?
Adaya ọmọ Jerohamu, ọmọ Pelalaya, ọmọ Amisi, ọmọ Sakaraya, ọmọ Paṣuri, ọmọ Malikija, 
Nítorí náà kí ẹ̀rù kí ó bà ọ́, ìwọ ọ̀run,kí o wárìrì, kí gbogbo nǹkan dàrú mọ́ ọ lójú.
O gba awọn eeyan nimọran pe ki wọn ma ṣe kori soju kan naa ti ọlọpaa ba fẹ yẹ ile wọn tabi ọkọ wọn wo.
Gbé ìbànújẹ́ kúrò lọ́kàn rẹ, má sì gba ìrora láàyè lára rẹ, nítorí asán ni ìgbà èwe ati ìgbà ọmọde.
Nígbà tí ó di ọjọ́ keji OLUWA ṣe bí ó ti wí; gbogbo àwọn ẹran ọ̀sìn àwọn ará Ijipti kú, ṣugbọn ẹyọ kan ṣoṣo kò kú ninu ẹran ọ̀sìn àwọn ọmọ Israẹli.
Bi o tilẹ jẹ pe a ko tii lee sọ ohun to sokunfa isẹlẹ naa tabi awọn to wa nidi rẹ, amọ awọn eeyan ni o see se ko jẹ ikọ agbesunmọmi Boko Haram lo n se ọsẹ naa.
Ọkọ ati aya ba pada pinu lati ṣegbeyawo wọn lọjọ kan naa ti wọn da iyẹn ọjọ kejidinlogun oṣu kẹrin ti pasitọ si dari isin igbeyawo naa lori aapu ayelujara kan to n jẹ 'Zoom'.
” Ṣugbọn àwàdà ni ọ̀rọ̀ náà jọ létí wọn.
Barakat Bello: Ọjọ Aiku, ọjọ kọkanlelọgbọn osu kẹfa ọdun 2020, ni wọn pa Barakat Bello lẹyin ti wọn fipa ba a lopọ tan Ẹni ọdun mọkandinlogun ni Barakat Bello nigba ti wọn pa Akẹkọọ ile ẹkọ imọ nipa iwadii eto ọgbin IAR&T nilu Ibadan ni Inu baluwẹ ni ẹyinkule ile rẹ ni Akinyele nilu Ibadan ni wọn ti fipa ba a lopọ, ti wọn si pa Ọwọ ọlọpaa ko tii tẹ afurasi kankan ninu iwadii wọn lati mọ ẹni to pa a Afojusun Barakat ni lati di onimọ giga nipa eto ọgbin, ko to ku ni aipe ọjọ.
‘Buhari ti gbàbọ̀dè fún Nàìjíríà’ Ikọ̀ aláàbò Nàìjìríà dojú kọ Shiite Ọlọ́pàá mú 115 ẹlẹ́sìn Shiite Àgùnbánirọ̀ akọ̀ròyìn Channels náà ti dágbére fáyé látààrí ìkọlù Shiite l'Abuja O ni ko ṣeeṣe ko jẹ pe awọn ọmọ ẹgbẹ Shiite to n ṣe iwọde lo yinbọn pa awọn mejeeji.
Ẹ padà wá láìpẹ́ fún àwọn àròkọ kan t’ọ́n ń bọ̀ lọ́nà.
Àní, bí èrò ọ̀nà, tí ó yà láti sùn mọ́jú?
O rọ gbogbo àwọn ti wọ́n n ta àwọn ǹkan wọ́n yìí láti maa rò pé àsìkò láti pawó rẹpẹtẹ rèé.
7 1739 Orilẹede Olominira Congo 99 1.
Coronavirus: Ǹjẹ́ fífi omi àti iyọ̀ yọnu leè dènà àrùn Coronavirus?
Alaga CAN, Alufa Samson Ayokunle parọwa si ijọ lati tẹlẹ amọran ti awọn eleto ilera gbe kalẹ lọna ati dena itankalẹ arun naa ni bi wọn ṣe n gbadura.
Goodluck Ebele Jonathan: Buhari pa orúkọ ọ́fíìsì reluwé tó wà ní ìlú Agbor dà s'órúkọ asáájú rẹ̀ Oríṣun àwòrán, facebook/kunle ariyo Lọna ati fi ẹmi imoore han si iṣẹ ribiribi to ṣe lasiko iṣejọba rẹ, aarẹ Muhammadu Buhari ti ni ki wọn fi orukọ ofiisi reluwe to wa ni Agbo, sọrii aarẹ ana, Goodluck Jonathan.
Bakan naa ,olori awon osise ni Ipinle Oyo, Comrade
Àwọn tí OLUWA rà pada yóo pada wá,pẹlu orin ni wọn óo pada wá sí Sioni.
OLUWA Ọlọrun ní: Wò ó, mo lòdì sí ọ, ìwọ Farao, ọba Ijipti, Ìwọ diragoni ńlá tí o wà láàrin odò rẹ; tí o wí pé, ‘Èmi ni mo ni odò Naili mi; ara mi ni mo dá a fún.
32 Lõtọ́, lõtọ́, ni mo wí fún yín, gẹ́gẹ́bí mo ti wí fún àwọn ọmọ ẹ̀hìn mi, níbi tí ẹni méjì tàbi mẹ́ta bá kó ara wọn jọ ní orúkọ mi, nípa ohun kan, kíyèsíi, níbẹ̀ ni èmi yíò wà lààrin wọn—àní bẹ́ẹ̀ni èmi ṣe wà lààrin yin.
Nigba ti wọn yoo fi gbe de ile iwosan Jaja, o ti ku'' O tẹsiwaju pe awọn alayẹwo ko ti gbe esi iwadi ohun to sọkunfa iku rẹ,fun idi eyi awọn ko le sọ iru iku to pa.
Gbogbo orin egúngún bìkiafù tí wọ́n kọ sí mi l'étí nípa Ajayi tí mi o gbọ̀ ló bu mí lọ́wọ́- Akeredolu Báwó ni òògùn dexamethasone ṣe ń ṣiṣẹ́ lára Àwọn àádọ́ta ọ̀dọ́ wọ gàù nítorí ilé ijó ní Ilorin Ǹjẹ o yẹ kí èèyàn máa sùn lẹ́nu iṣẹ́?
Kí ó rí fún ọ bí o ti fẹ́.
Ológo ni ọ́, ọlá rẹ sì pọ̀,ó ju ti àwọn òkè tí ó kún fún ẹran lọ.
Nítorí bí mo ti gbọ́ ohùn rẹ nígbà tí o kí mi, bẹ́ẹ̀ ni ọmọ inú mi sọ nítorí ó láyọ̀.
Ninu ọrọ rẹ, ọga agba ajọ BudgIT ni o yẹ ki awọn ijọba o tubọ ko akoyawọ lori bi wọn ṣe na owo naa ki araalu lee mọ pe ọwọ wọn mọ nipa rẹ.
ẹnikẹ́ni ninu ìran burúkú náà kò ní fi ojú kan ilẹ̀ dáradára tí òun ti búra pé òun óo fún àwọn baba yín; 
Ọmọ ènìyàn bá fún omi inú ìrèké, ó gbé e raná ti omi náa fi gbẹ, tí ó fi ku kiní kan funfun báláhú.
O ni awon yoo tun ro awon agbofinro lagbara.
"Inu mi dun loni pe ilu Owerri tii ṣe olu ilu ipinlẹ yii ti mo ba ni ipo abule ti de ipo olu ilu nitootọ.
Ìmẹ́lẹ́ máa ń fa òṣì,ṣugbọn ẹni tí ó bá tẹpá mọ́ṣẹ́ yóo di ọlọ́rọ̀.
Ojú nìkan ni óo kàn máa fi rí wọn,tí o óo sì máa fi wo èrè àwọn eniyan burúkú.
Wọ́n dí gbogbo orísun omi, wọ́n sì gé gbogbo àwọn igi dáradára.
Bi ẹ ko ba gbagbe, lọjọ diẹ sẹyin ni okiki ọmọdebinrin yii kan kaakiri agbaye lori ayelujara pẹlu aworan rẹ ti eeyan kan fi sori ayelujara.
Ogun: Amosun, ẹgbẹ́ òṣìṣẹ́ NLC fẹ́ forígbárí l'Ógùn ‘Gómìnà Amosun kò fẹ́ràn àwọn ará Ìjẹ̀bú’ Oríṣun àwòrán, Facebook/Ibikunle Amosun Àkọlé àwòrán, Idibo gomina ipinlẹ Ogun Loṣu kejila ọdun 2018 ni Gomina Amosun pinu pe oun ko ni gbaruku ti oludije fun ipo gomina labẹ asia ẹgbẹ oṣelu APC, Dapo Abiodun.
Lẹyin ọpọlọpọ ijiroro, awọn asofin agba duro lori ifẹnuko mẹta ọtọọtọ ninu eyi ti wọn ke si banki apapọ ilẹ Naijiria pẹlu ileese alaabo oludokoowo ilẹ Naijiria, NDIC pẹlu ileesẹ ọja idokoowo ilẹ Naijiria, NSE lati dide giri si ọrọ naa ki wọn si tete fọn rere ewu to mbẹ ninu idokoowo owo inu afẹfẹ bitcoin fun awọn araalu.
#WhereIsEspiritDCorp: Ohun tó kọjú sẹ́nìkan, ẹ̀yìn ló kọ sí ẹ́lòmíì lọ̀rọ̀ yìí lórí ayélejára
Bí a bá kí ẹbọra eléyìínì tán n óò mú ọ lọ sì ọ̀dọ̀ ìyàwó rẹ̀ nítorí ọ̀tọ̀ ni obìnrin náà ń gbé, ẹbọra tí orúkọ rẹ̀ ń jẹ́ Àrùn, oníròbìnújẹ́ obìnrin.
Ọ̀pọ̀ àwọn obinrin wà níbẹ̀ tí wọ́n dúró ní òkèèrè réré, tí wọn ń wo ohun tí ó ṣẹlẹ̀.
Ere idaraya yii lo kọ wa pe asegbe kankan ko si, asepamọ lo wa, ọjọ gbogbo si ni ti ole amọ ọjọ kan soso pere ni ti olohun.
Sise ayẹwo irufẹ́ kokoro Coronavirus to wọ Naijiria: Orilẹ-ede Naijiria ni orilẹ-ede akọkọ lagbaye ti wọn ti kọkọ ṣe ayẹwo irufẹ kokoro Coronavirus to wa lara ẹni to ko wọ Naijiria, ti wọn si ri pe iru rẹ naa lo kọkọ ṣẹyọ nilu Wuhan, ti arun ọhun ti bẹ silẹ.
Ajọ to n gbogun ti ajakalẹ arun lorilẹede Naijiria, NCDC lo kede bẹẹ loju opo Twitter rẹ l'Ọjọbọ.
Ni wọn igba ti ere olukọ ko si ni ọrun mọ, lọwọ lọwọ bayii, gomina Seyi Makinde ti fi orukọ baba Kamorudeen Aderibigbe sọwọ sile asofin ipinlẹ Oyo, lati fi ontẹ lu gẹgẹ bii alaga ajọ to n ṣe akoso iṣẹ ọba.
Kí ló dé tí yóo fi jẹ́ pé ẹ̀rí-ọkàn ẹlòmíràn ni yóo máa sọ bí n óo ti ṣe lo òmìníra mi?
Ile ejo kan lorile-ede Kenya ti dajo iku fun awon olopaa meji lorile-ede naa lataari siseku-pa akegbe won kan ati ara ilu meji lọdun 2014.
Wo àwọn àwòràn tó làmìlaaka nílẹ̀ Adúláwọ̀ lọ́sẹ̀ yìí Kí ni ó gbé ọlọ́pàá dé ibi àjọ̀dún ọjọ́ ìbí i Bobrisky?
Lẹ́yìn náà, Rehoboamu ọba rán Adoniramu, tí ó jẹ́ ọ̀gá àgbà àwọn tí wọn ń kó àwọn eniyan ṣiṣẹ́ tipátipá, láti lọ bá àwọn ọmọ Israẹli, wọ́n sì sọ ọ́ ní òkúta pa.
Pẹlu iye eeyan tuntun ti wọn kede l'Eko ati Benue, apapọ iye eeyan to ti ni arun naa ni Naijiria ti di mọ́kàndínláàdọ́rùn ún.
Àwọn Jàǹdùkú yabo ilé ìkó-ǹkan-pamọ́ sí, wọ́n kò 'Covid 19 Palliative lọ ní Eko Nibayii, ipinlẹ Edo ati Plateau ti jẹ ki ofin konile o-gbele rọlẹ si ni awọn ipinlẹ naa."
Fire Eater: Azonto ní àfojúṣùn òun ni láti lọ fi idán iná yìí pa owó lókè òkun
Báwo ni wọn yóo ṣe gba ẹni tí wọn kò gbúròó rẹ̀ gbọ́?
Ìwọ ati àwọn ọmọ rẹ nìkan ni yóo máa ṣiṣẹ́ ninu ibi mímọ́ ati níbi pẹpẹ, kí ibinu mi má baà wá sórí àwọn ọmọ Israẹli mọ́.
Wíwó rẹ̀ sì bani lẹ́rù lọpọlọpọ.
O ni ki ajo eleto idibo INEC tete bere igbese to ye ti yoo mu idibo rorun fawon akanda eda ni 2019.
Ọmọlẹyin Kristi to dantọ ni Dapọ Abiọdun n ṣe, to si gbagbọ pe Ọlọrun lo gbe oun de ipo gomina, laifi ti ọpọ atako to dide si oun ṣe.
(Kò sí àlejò tí ń sun ìta gbangba,nítorí ìlẹ̀kùn ilé mi ṣí sílẹ̀ fún àwọn arìnrìnàjò);
ọ̀dọ́ 47,000 fẹ́ di Amotekun, agbófinró yẹ̀ wọ́n wò yẹ́bẹ́yẹ́bẹ́ Lara awọn ti yoo maa tukọ igbimọ ọhun ni ọgbẹni Atedo Peterside ati minisita eto iṣuna, Zainab Ahmed.
Onidajọ Chuka Obiozor paṣẹ naa lọjọ Aje lẹyin ti ajọ to n gbogun ti iwa ibajẹ ni Naijiria, EFCC, kọ iwe ẹbẹ si ile ẹjọ pe ko ṣe bẹ ki oun le ri aaye ṣe iwadi iwa jibiti kan.
Oluwa mi, eniyan Ọlọrun ni ọ́, nítorí náà má ṣe parọ́ fún iranṣẹbinrin rẹ.
ẹ̀ báà bú mi di ọ̀la - Ọ̀gá Amotekun l'Osun Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Amotekun Osun: A ò gbé Amotekun kalẹ̀ láti máa yọjú sí ọ̀rọ̀ tí kò sí lábẹ́ òfin A ò gbé Amotekun kalẹ̀ láti máa yọjú sí ọ̀rọ̀ tí kò sí lábẹ́ òfin àgbékalẹ̀ rẹ̀ Ajọ to n ṣakoso ikọ alaabo nilẹ Yoruba, Amotekun, DAWN Commission, ti ni aṣigbọ ni awọn eeyan gbọ ọrọ ti ọga ikọ Amotekun ni ipinlẹ Osun sọ.
bí o ti yọ ilẹ̀ Israẹli nígbà tí ilé wọn di ahoro.
Nígbà náà ni n óo nawọ́ ìyà sí Ijipti, n óo sì kó àwọn ọmọ Israẹli, ìjọ eniyan mi, jáde kúrò ní ilẹ̀ Ijipti pẹlu iṣẹ́ ìyanu ati ìdájọ́ ńlá.
Ni kete to pada wa lati ilu Dubai ni awọn agbofinro nọwọ gan.
Ibùjókòó-òkè meji tí ó kọjú sí ara wọn wà ní àgbékà mẹtẹẹta; wọ́n wà lára ògiri láti nǹkan bíi ogún igbọnwọ sí ara gbọ̀ngàn inú, ati ibi tí ó kọjú sí pèpéle tí ó wà lára gbọ̀ngàn òde.
Àwọn ọmọ Israẹli ṣe oríṣìíríṣìí nǹkan níkọ̀kọ̀, tí OLUWA Ọlọrun wọn kò fẹ́.
Ìgbésí ayé Alákọ̀wé apá kejì ti bọ́ o.
Orin naa ṣafihan awọn nkan to n ṣẹlẹ ni Naijiria lasiko yii ni eyi to fi gbe awon idojukọ awọn kan ni Naijiria sita.
 tó bá dá wà , ó jẹ ́ ẹ ́ límẹ ̀ ntì mẹ ́ tàlì alkalínì ilẹ ̀ tó ní àwọ ̀ irin-idẹ , tó lágbára , fífúyẹ ́ àti rírún wẹ ́ wẹ ́ .
Nibayii, wọn ti bere ẹjọ pẹlu awọn mọlẹbi baba naa, nitori iwakuwa wọn lo jẹ ki arakunrin naa ku.
Bí ó ṣe jókòó tí ó takété sí ọmọ náà, ọmọ fi igbe ta, ó bẹ̀rẹ̀ sí sọkún.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Omoyele Sowore: Ẹgbẹ́ aṣòfin Amẹ́ríkà ní ìjọba ń tẹ ẹ̀tọ́ olùdíje ààrẹ́ tẹ́lẹ́ náà lóju 19 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Oríṣun àwòrán, @YeleSowore Ẹgbẹ awọn agbẹjọro ni orilẹede Amẹrika ti kesi ijọba ilẹ wa pe ko tu eekan lẹyin ọrun oludije tẹlẹ fun ipo aarẹ, Omoyele Sowore.
Lara awọn eekan ati opomulero to gbe fidio ṣiṣe lede Yoruba goke ni baba rẹ, Adebayọ Salami, ti ọpọ eeyan mọ si 'Bello'.
Fún fífẹ́ kọ, àgbèrè pọ́nbélé ni
Kí Ọlọrun wà pẹlu àwọn tí wọ́n jẹ́ eniyan rẹ̀.
Ní ìyálẹ̀ta ọjọ́ òní ni àwọn ẹlẹ́sìn ìbílẹ̀ ilẹ̀ yìí ti jí dé ibi àkójọpọ̀ okúta ayérayé nì tí wọ́n ń pè ní Stonehenge.
 O fi eyi mulẹ ninu ọrọ rẹ.
Eyi kò ṣẹyin bi ọpọ awọn ọmọ almajiri ṣe n di dida pada laarin ipinlẹ ariwa Naijira kan si ikeji lẹyin ti niinu wọn lugbadi ajakalẹ arun Coronavirus Ẹ̀ wo àwọn ìgbéṣẹ̀ tí ó ṣeeṣe kí ìjọba àpapọ̀ gbé lórí òfín kónílé ó gbélé ní Eko, Abuja, Ogun Àrùn Coronavirus ti mú ẹ̀mí ẹni àkọ́kọ́ lọ nílẹ̀ Madagascar Kí ló yẹ ká se sí ẹkùn tó pa ènìyàn márùn ún?
Awọn mẹta yooku ni ọmọ ile aṣofin nigba kan, Anna Kanopatskaya, Sergie Cherechen, ati Andrei Dmitriyev.
Bí ogún Ìjàyè àti ìṣubú Ààrẹ Kurunmi ṣe bẹ̀rẹ̀ rèé:Ilu Ọ̀yọ́ ijọ́hun ni ibujoko agbára àti ìṣàkóso àwọn ìlú yooku nílẹ Yoruba, ìlú Ọ̀yọ́ yìí sí ní àwọn ìlú yoku máa ń ṣàn isakọlẹ si lọdọ Aláàfin, tí wọn gba gẹgẹ bii olórí wọn.
Papa iṣere naa to wa lara awọn papa iṣere aadọta ti owo ti wọn fi kọ wọn wọn julọ lagbaye ni wọn fi sọri Abiọla ẹni ti ọpọ n pe ni akin eto iṣejọba tiwantiwa ni Naijiria.
NFF ti san owó àjẹ́mọ́nú Super Eagles 'A fún Super Eagles, ni rìmóòtù wa, torí ife' Àwọn olówó Naijiria 5 tí owó wọn ju owó ìsúnná Naijiria lọ!
"Ọmọ Nàíjíríà tako Nafdac lórí ọ̀rọ̀ Codine Àwọn ọ̀nà ti ẹ lè gbà kojú omí yale àgbára ya ṣọọbù ""Ọkọ̀ aképo náà forí sọ òpó iná ló fi laná ní Gowon Estate l'Èkó"" Ẹ̀yin mùsùlùmí, ẹ yé jẹ́ káwọn alákatakítí ẹ̀sìn b'ọmọ yín láyé jẹ́ - Buhari Toyin Abraham ní 'gbogbo wa loníbárà', Ijebu ta sí Odunlade Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ìbànújẹ́ ló pọ̀ nínú òṣèlú Nàìjíríà tórí a ti lo Pásítọ̀, Wòlìí, Ọ̀jọ̀gbọ́n Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?"
Kí ìwọ fẹ́ràn Oluwa Ọlọrun rẹ pẹlu gbogbo ọkàn rẹ, ati pẹlu gbogbo ẹ̀mí rẹ ati pẹlu gbogbo iyè inú rẹ, ati pẹlu gbogbo agbára rẹ.
Nígbà tí ó ná gbogbo ohun ìní rẹ̀ tán, ìyàn wá mú pupọ ní ìlú náà, ebi sì bẹ̀rẹ̀ sí pa á.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ọlọpa ko lee sọ boya 'were' lọkunrin to sa ọmọ meji pa l'Ogun 15 Ẹrẹ̀nà 2018 Oríṣun àwòrán, Ogun state police command Àkọlé àwòrán, Ileẹjọ ni yoo sọ boya ọlọdẹ ori ni arakunrin to sa ọmọ meji pa nile ẹkọ alakọbẹrẹ kan l'Ogun Ileesẹ ọlọpa ko ti lee fi idi rẹ mulẹ boya lootọ ni arakunrin to sa awọn ọmọ meji pa ni ipinlẹ ogun jẹ alanganna.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Èèèyàn mẹ́wàá péré ló leè lọ ayẹyẹ ìsinìkú ní Australia báyìí nítorí àrùn Coronavirus O ni ijọba ilẹ naa yoo wọgile ọpọ lara irin ajo okeere ati pe awọn ibi igbafẹ ita gbangba ni yoo di titi pa.
@BronzeBomber banks a Round 1 KO against @TroubleBoxing.
NÍTORÍ KÒ SÍ ẹni TÍ KÒ GBÉ ẹrù ÌSÒRO Tirẹ̀ LÉ ÈJÌKÉ, ẹrù Ìṣòro TI ẹnì KAN KÒ BÁ TI ẹni KEJÌ MU, ṣùgbọ́n Pẹ̀LÚ ÌFORÍTÌ, Ọlọ̀run ỌBA ṣetán ÀTI Sọ OLÚKÚLÙKÙNÍ ẹrù Ìṣòro Tirẹ̀ Kalẹ̀ PÁTÁPÁTÁ.
Manchester United (1990) Lootọ ni ẹgbẹ́ agbabọọlu Man U ti maa n wọ aṣọ ti ko ṣe fọwọ́rọsẹyin, sugbọn eyi tun peleke.
Dafidi sọ fún Saulu pé, “Ẹ má bẹ̀rù ọkunrin yìí; èmi, iranṣẹ rẹ óo lọ bá a jà.
 fífẹ ̀ rẹ ̀ tó bíi 6,354.
Ó ni lẹ́yín ti ọ̀jọ̀gbọ́n Abayomi ni ìbáṣepọ̀ pẹ̀lú ẹni kan ti ara rẹ̀ kò yá, to si ṣe àyẹ̀wò ààrùn Covid-19 lo ri pé, òun pẹ̀lú ti lùgbàdì ààrùn náà.
Idi si ree ti mo kuku fi mu siga naa han wọn lori Facebook, pe bi wọn yoo ba pa mi, ki wọn kuku pa mi.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Akomolede ati Asa: Mọ̀ si nípa àwọn ọ̀nà tí Yorùbá ń gbà ran ara wọn lọ́wọ́ 3) Arabinrin Funke aya Young to kọ wa ni Aṣa Yoruba, Koko ti a gbe yẹwo ni Aṣa Iranraẹnilọwọ bii Ajọ, aaro, ọwẹ ati bẹẹ bẹẹ lọ.
"Oríṣun àwòrán, Others Kọmiṣọna ọhun to sọrọ lorukọ gomina Gboyega Oyetola ni ""idi ti a ko ṣe fẹ ki ero pọ lapọju nibi ayẹyẹ ọdun yii, ni arun to wa lode, gẹgẹ bi gbogbo wa ṣe mọ, arun yii n pọ si ni ipinlẹ wa, nitori naa, a ni lati ṣọra."
Ifẹsẹwọnsẹ Arsenal pẹlu Napoli ni ifẹsẹwọnsẹ aadọta ti Emery yoo dari gẹgẹ bi adari ikọ naa.
Ọmọ daada ni Habib, ko lee pa wọn lara rara, bẹẹ ni ko ni fi ọwọ kan wọn tabi ko pa wọn Wakil fi kun pe oun nrọ awọn ọmọ Naijiria lati se suuru, ki wọn si kun fun adura nitori ohun gbogbo yoo pada yọri si rere.
Mo bá bèèrè pé, ‘Kí ni kí n ṣe Oluwa?
awon eniyan lati jade sita wa dibo.
O ni , o se pataki ki adari
Oríṣun àwòrán, Other Ninu iwadii CNN, wọn ni ọpọlọpọ wakati ni awọn fi yẹ awọn fidio kan ti awọn eeyan ya nibi iṣẹlẹ ọhun wo, bẹẹ ni wọn si tun gba ọrọ lẹnu awọn oṣoju mi koro, awọn ti ọrọ naa ṣe si atawọn ti wọn padanu ẹbi wọn nibi iwọde naa.
1842 ni wọn si se ifilọlẹ rẹ.
Wo dókítà ọmọ Nàìjíríà tí àgbáyé ń wárí fún nítorí abẹ́rẹ́ àjẹsára COVID-19 Abẹ́rẹ́ àjẹsára Covid-19 tí Pfizer kéde ló fa ọ̀wọ́ngógó epo ní Naijiria - Ìjọba àpapọ̀ Bí mo bá leè rí ọmọ alágbe t'áyé fẹnu sí pé mo fi ẹlẹ́rìndòdò lá lójú, máa kúnlẹ bẹ ẹ - Motara Ṣe lóòtọ́ ní ọmọ Nàíjíríà mílíọ́nù 25 yóò má ló ìná Solar látí Dec 1, 2020?
Iroyin fi mule pe, arakunrin agbesunmomi ohun, so ado oloro ohun mo ara re lara ti o si ko si aarin awon ti o se adura nile ijosin naa.
nguyễn thành nam , tí ó jẹ ́ onímọ ̀ ará vitman dá ẹ ̀ sìn àgbọn yìí sílẹ ̀ ní ọdún 1963 tí wọ ́ n tún mọ ̀ sí alàgbọn , Ìmọ ̀ Àgbọn rẹ , wòlí Ìṣọ ̀ kan , àti arákùnrin hai ( 1909 - 1990 ) .
" Oríṣun àwòrán, @BigBadDenis Ko din ni aadọta miliọnu eeyan to gbẹmi mi nitori arun Spanish to waye ọdun 1918.
Oríṣun àwòrán, @Auduofficial Àkọlé àwòrán, Rice Subsidy: Ìjọba àpapọ ṣétàn láti yá àwọn àgbẹ̀ ìrẹ̀sì lówó Ogbeh fí kún-un pé, ó sàn láti yá àwọn àgbẹ́ ìrẹ̀sì, àwọn tó n bó ìrẹ̀sì àtí àwọn alágbàtà lówó pẹ̀lú èlé tí kò guni lápá.
Ṣugbọn OLUWA àwọn ọmọ ogunni a óo gbéga ninu ẹ̀tọ́ nítorí ìdájọ́ òdodoỌlọrun Mímọ́ yóo fi ara rẹ̀ hàn, pé mímọ́ ni òun ninu òdodo.
Ọrẹ ti Elisuri ọmọ Ṣedeuri nìyí.
Mo mu yín wá sí ilẹ̀ tí ó lọ́ràá,pé kí ẹ máa gbádùn èso rẹ̀ ati àwọn nǹkan dáradára tí wọ́n wà ninu rẹ̀,ṣugbọn nígbà tí ẹ dé inú rẹ̀, ẹ sọ ilẹ̀ mi di aláìmọ́,ẹ sì sọ ogún mi di ohun ìríra.
 Èyí jẹ ́ oun pàtàkì lára ànfàní tó wa nínú ìṣọ ̀ kan nínú àwùjọ-ẹ ̀ dá .
Ile ẹjọ kotẹmilọrun ni o fagile iwe ipẹjọ ti Ajimọbi fi pe sẹnatọ naa ti o n ṣoju guusu Ipinlẹ naa lẹjọ.
 Wo ibi mẹ́rìnlá tí o kò gbọdọ̀ gbé ọkọ̀ rẹ sí lásìkò yìí."
Lodun 1997, ijoba aare Tony Blair  kuna lati satileyin fun aare Mugabe ninu erongba re lati mu ayipada otun de ba orile-ede ohun, bee si ni ogbeni Mugabe bu enu ate lu won pe, ile biritiko n se ayojuran si isejoba re, nipa sise iranwo owo ina fun egbe oselu alatako lorile-ede naa.
Abala keji idije aṣekagba laarin Netherlands ati America ni Megan Rapinoe ati Rose Lavelle ti jẹ goolu to mu ki America gbe igba oroke ninu idije naa.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Buhari gbé àbá ìṣúná ₦13.
Alápilẹkọ náà sọ pé, ọrẹ tímọtímọ ààrẹ Buhari tó wà nínú ìpejọpọ náà lo sàlàye fun ààrẹ, nipa ìpínnu ìgbákeji rẹ, èyí si lo fa gbọ́nmi-si-omi-oto tó wà láàrin ààrẹ àti igbákeji rẹ.
, ni  awon ipinlẹ bi i Abia, Bayelsa,
Idajọ̀ naa jẹ ohun to jẹ idunnu fun awọn ajafẹtọ ẹranko.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù World Happiness Day: Orílẹ̀èdè Austria ló gba ipò Australia nínú àwọn èèyàn tó láyọ̀ jùlọ 20 Ẹrẹ̀nà 2019 Oríṣun àwòrán, Mazi Ibe Ìdùnú jẹ́ ǹkan to ṣe pàtàkì nínú ìgbé àyé ọmọ ènìyàn, a lè fi ìdúnú wé ìmọ̀lára tí kò ṣe ṣe àkàweé sùgbọ́n tó ń dédé wá láti ìnú ènìyàn.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ọ̀gọ́rún sọ́ọ̀bù, àìmọye dúkìá ni iná tún jó lọ́jà Sabo nílùú Sagamu Malami, IGP àti alága APC Oyo ni yóò káwọ pọ̀'yìn rojọ nítori àwọn alaga Kansu tẹlẹri Ẹ ta kété sí àjọṣepọ̀ tí kò bá fún yín láyọ̀ torí ẹ̀mí kò ní ààrọ̀ - Àwọn òṣèré tíátà gbarata lórí ìdájọ́ ikú Ojora ń mú mi lọ́wọ́ lórí ìkọlù tó wáyé, ara mi kò tíì balẹ̀ - Toyosi Adesanya Gẹgẹ bi oludari fun ajọ ẹsọ oju popo, FRSC, ẹka tipinlẹ Ogun, Clement Oladele yi sọ fun awọn akọroyin, o seese ko jẹ pe o ti rẹ awọn arinrinajo naa dẹnu lo mu ki ijamba naa waye.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìdíje Champions league: Salah dá iná ayò sára Roma 25 Ìgbé 2018 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Àwọn èèyàn káàkiri àgbáyé ń pè fún gbígbé ádé agbábọ́ọ̀lù tó mọ̀ọ gbá jùlọ lágbáyé lé Salah lórí Mohammed Salah, agbábọ́ọ̀lù Liverpool tún jẹ́wọ́ ọmọ ọkọ ní àṣalẹ́ ọjọ́ ìṣẹ́gun, nígbà tí ẹgbẹ́ agbábọ́ọ̀lù Liverpool na Roma pẹ̀lù àmì ayò márùn ún sí méjì.
Tí a fiṣọwọ́ ní 8:56 14 Sẹ́rẹ́ 20218:56 14 Sẹ́rẹ́ 2021 Seyi Makinde ní ọwọ́jà Covid-19 kò rinlẹ̀ bí NCDC se kéde èèyàn 120 tó ní àrùn lọ́jọ́ kan l‘Oyo Atẹjade ajọ NCDC fihan pe eeyan to le ni irinwo lo ko coronavirus laarin ọsẹ meji nipinlẹ Oyo.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Alaafin, MC Oluomo, Ejiogbe àti ọmọ Tinubu wà lára àwọn tí yóò pèsè iṣẹ́ 774,000 Baba Suwe bọ́ lọ́wọ́ àìsàn, ó bẹ̀rẹ̀ tíátà padà Jàndùkú yabo ilé ìwòsàn ìjọba sáájú ìpàdé akọ̀ròyìn táwọn dókítà pè Ojú Shagbada Erigga rèé lẹ́yìn tó pa ọ̀rẹ́bìnrin rẹ̀ l'Akinyele ní Ibadan Ìdí tí lílọ Yúrópùù fi di èèwọ̀ fún Nàìjíríà àti àwọn orílẹ̀-èdè adúláwọ̀ míì Arúfin ni Seyi Makinde pẹ̀lú bó ṣe gbà kí wọ́n sin Ajimobi sí GRA - Amòfin Ẹgbẹ́ àwọn aladani tó n ta epo bẹtiró ní Nàìjíríà (IPMAN) ti sàlàyé pé, gbogbo ìlànà ti ìjọba là sílẹ̀ ni àwọ́n ń tẹ̀lé nípa títa epo bẹtiró.
Agbejoro fun Dasuki  ogbeni Ahmed Raji naa so pe ogbon ojo , osu kerin ni awon ri iwe ipejo, ti awon si ri I gba ni ojo kinni osu Karun un yii.
Òògùn ẹ̀fọn pa ọmọ mẹ́ta ní Ghana Àpanisáyé ni ẹ̀wà tí wọ́n n fí 'sniper' sí Ajalu kanna tun waye nipinlẹ Osogbo lọjọ kọkandinlọgbọn Osu kọkanla nibi ti eniyan mẹta ninu idile kan to n gbe ni agbole Olorisaoko ni Osogbo ni Ipinlẹ Osun gbẹmii mi.
Ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ parí, Germany di ẹrù ìyà aláwẹ́ mẹ́ta lé Najiria lórí Kàyééfì, oyún inú nínú ilé ìgbọ̀nsẹ ọkọ̀ òfurufú Ẹyẹ ju ẹyẹ lọ, Super Eagles fi àmì ayò kan gbé ẹyẹ Swallow ti Burundi mì Ọmọ Naijiria, ẹ ṣọ́ra lórí ọ̀rọ̀ Ebola Àwọn òṣèré Yollywood tó ń pàrònú rẹ́ O ni ọpọ igba ni awọn eniyan maa n ro pe opó fẹ gba ọkọ awọn ni eyi ti ko ri bẹẹ rara.
O bẹrẹ ere bọọlu pelu UNTL Kaduna ni ọdun 1981, to si tẹsiwaju lọ darapọ mọ ikọ agbabọọlu Naijiria ati Yuroopu.
”Tabi tí ó sọ fún pé,“Èmi yóo jẹ́ baba fún un,òun náà yóo sì jẹ́ ọmọ fún mi?
Adajọ Abang sun igbẹjọ naa si ọgbọn ọjọ, oṣu kẹwaa ati ọjọ kọkandinlogun oṣu kọkanla.
Bakan naa lo ni iṣẹlẹ naa ko ni fa ọwọngogo epo ni agbegbe ipinlẹ Eko atawọn ipinlẹ to yii ka ati pe atunṣe yoo de ba ọpa epo ti o jona naa lẹyẹ-o-ṣọka.
omi mimuO wa ro awon omo ipinle Nasarrawa lati tubo dibo fun aare
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ààrẹ tẹ́lẹ̀, Olusegun Obasanjo kọ̀wé ìbánikẹ́dùn sí aṣíwájú Afẹ́nifẹ́re, Rueben Fáṣọ̀ràntì lórí ikú ọmọ rẹ̀ 13 Agẹmo 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ọpọ awọn eekan lo ti n wi tẹnu wọn lori iṣẹlẹ buruku naa Ibi ọrọ de duro bayii ti fihan pe ipenija abo to mẹhẹ lorilẹede Naijiria nilo amojuto ni kiakia.
Ẹ̀yin náà, ẹ wà ní ìmúrasílẹ̀, nítorí ní àkókò tí ẹ kò nírètí ni Ọmọ-Eniyan yóo dé.
Jeroboamu mú kí wọ́n kọ OLUWA sílẹ̀, ó sì mú kí wọ́n dẹ́ṣẹ̀ ńlá.
Ki ni itumọ owe yii ati pe bawo ni owe naa ṣe jọ mọ ohun to n ṣẹlẹ laye ode oni?
O tun so pe , nigba ti ogagun ,Sadique Abubakar to je oga agba fun ile-ise omo oogun ofurufu orile ede yii,se abewo si ile-ise omo oogun ofurufu to wa ni Makurdi  ati Agatu ni ipinle Benue, lo fi eleyii mulẹ.
Oríṣun àwòrán, @Apata Ẹgbẹ́ Agbẹjọ́rò NBA ti kéde pé àwọn yóò ṣojú awọn Olùwọ́de #EndSARS lọ́fẹ̀ẹ́ nílé ẹjọ́ Ẹgbẹ awọn agbẹjọrọ ni Naijiria ti a mọ si Nigerian Bar Association (NBA) ti kede pe awọn ṣetan lati pese iranl\\woọ fun gbogbo oluwọde ti awọn agbofinro sọ si gbaga nitori iwọde #EndSARS.
Wọn ko gbogbo awọn ọmọbinrin naa, ọlọpaa si rọ wa lati wa ibugbe fun, a gba la fi ko wọn sile awọn ọmọ orukan Stella Obasanjo.
yoo pese ohun elo ati agbara lati ropo awon ohun ti o ba isele ibi naa lo.
O ni ofin tawọn aṣofin n gbero lori kẹlẹnu o ṣẹnu lori ayelujara, (social media bill) iyẹn social media bill jẹ eyi to tako ọpọlọ ati arojinlẹ.
Ti ẹ ba ranti, aarẹ ẹgbẹ́ àgbẹ̀ onìrẹsì ní orílẹ̀-ède Nigeria (RIFAN), Aminu Goroyo, sọ fún BBC pé, tọ́ọ́nù mẹ́sàn àti ààbọ mílíọ́nù ìrẹsì ni àwọn ọmọ Naijiria ń jẹ lọ́dọọdún.
A ko fẹ fi awọn ọmọ wa sinu ewu'' O fi kun pe ''ko si ile ẹkọ kankan to le da isẹ se laifi ti oun sẹlẹ lawujọ se'' Aworan atọnisọna Iye awọn to ti ni arun naa lagbaye Sunmọ aworan Àgbáyé Orilẹede Afrika Ariwa Amẹrika Apa Latin Amẹrika ati Caribbean Ilẹ Asia Ilẹ Yuroopu Agbegbe Middle East Erekusu Oceania Fihan 93418283 iye iṣẹlẹ arun naa 2000905 Iye awọn to ku Group 4 Jọwọ ṣe atunṣe ilana ikansi ayelujara rẹ lati ri ẹkunrẹrẹ rẹ Aworan n ṣafihan awọn ti ayẹwo ti fi han lorilẹede kọọkan Orisun: Johns Hopkins University atawọn ajọ eto ilera ilu Igba ti wọn kede iṣiro awọn to nii kẹyin 15 Oṣù Ṣẹ́rẹ́ 2021 20:44 WAT+3 Ẹkunrẹrẹ data Sun atẹ wa silẹ tabi oke lati ri ẹkunrẹrẹ akọsilẹ *Iye awọn to tọwọ aisan ku ni isọri eeyan ẹgbẹrun lọna ọgọrun Gbe e yẹwo: Àgbáyé Orilẹede Afrika Ariwa Amẹrika Apa Latin Amẹrika ati Caribbean Ilẹ Asia Ilẹ Yuroopu Agbegbe Middle East Erekusu Oceania Iye to ti ku Iye awọn to ku %* Apapọ awọn iṣẹlẹ arun Akọtun arun yii 0 10 100 1000 10000 ** Orilẹede Amẹrika 387741 118.
O fi kun un pe iṣẹlẹ igbesunmọmi ọtalelẹẹdẹgbẹta ati meji, 562 lo waye lọdun yii lorilẹ-ede Naijiria eleyi to gba ẹmi ojilelugba, 2040 ti Naijiria tun fi di ipo kẹta mu.
Obinrin lo mu mi fẹran orin kikọ
àwọn ohun tí ọwọ́ rẹ ati ètò rẹ ti ṣe ìlànà rẹ̀ tẹ́lẹ̀.
Ó mú burẹdi meje náà, ó dúpẹ́ lọ́wọ́ Ọlọrun, ó bù ú fún àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀, ó ní kí wọn pín in fún àwọn eniyan.
Ọta ara ni ọti lile Omi ara Ọ̀pọ̀lọ́ jẹ́ ẹlẹ́rìndòdò tó ń mára jípépé, ẹ máa mú Olè gbé òrùka ìgbéyàwó mì ní Eko Agolo akẹ́rù Apapa kò pa ènìyàn ṣùgbọ́n ó ba ọ̀pọ̀ ọkọ̀ jẹ́- Ọ̀ga RRS Ayaworan Shaw sọ fun BBC die lara awọn iṣe idan ti Mandrake ti ṣe ninu odo ti o ṣoju oun tẹlẹ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù El-Zakzaky: Aago méjìlá ọ̀sán ku ogún ìṣẹ́jú lọ́jọ́ Ẹtì ni bàálù rẹ̀ gúnlẹ̀ 16 Ògún 2019 Asaaju ikọ ẹlẹsin Shiite, Ibrahim El Zakzaky ati aya rẹ ti gunlẹ si orilẹede Naijiria bayii.
SERAP gbé ìjọba Nàìjíríà lọ iléẹjọ́ ọ̀daràn lórí ọmọ 13.
Ọkan lara awọn agbabọọlu Arsenal, Ainsley Maitland -Niles gba kaadi pupa ti wọn si lee jade nitori ikọlu rẹ si agbabọọẹu Aston Villa kan.
Ọba Israẹli ati Jehoṣafati ọba Juda wọ aṣọ ìgúnwà wọn, wọ́n sì jókòó lórí ìtẹ́ wọn, ní ibi ìpakà tí ó wà lẹ́nu bodè Samaria; gbogbo àwọn wolii sì bẹ̀rẹ̀ sí sọ àsọtẹ́lẹ̀ níwájú wọn.
Fuel Price Hike: Ìjọba Nàìjíríà rọ aráàlú láti yí ọkọ̀ àti gẹnẹrétọ̀ wọn sí èyí tó ń lo afẹ́fẹ́ gáàsì lọ́fẹ̀ẹ́
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Iba Gani Adams: Bẹ́ẹ gbé màláíkà kan lọ sí Aso Rock, kò lè ṣàṣeyọrí Oshoola ni awọn agbabọọlu ni Afirika n gbiyanju lati yi ero ọpọ eeyan nilẹ Adulawọ pada pe obinrin ko wa fun ile idana nikan.
Kìnìún pa okùnrin ọmọ aadọrin ọdún kan lorilẹ-èdè South Africa
Aare Buhari ni eto idibo odun 1993 ni o je eto idibo ti awon
Laarin oru ni wọn ṣe etutu igbaniwọle ṣẹgbẹ fun un ninu igbo kijikiji.
Idi kan pataki ti wọn kii fi ka awọn ibo kan ni bi iwe idibo naa ba pẹ de lati ọdọ awọn ileeṣẹ ifiweranṣẹ.
OLUWA ni Ọlọrun wa,ìdájọ́ rẹ̀ kárí gbogbo ayé.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Aṣíwájú ilẹ̀ Yorùbá tuntun sí ọmọ Yorùbá-Tọwọ́ tẹsẹ̀ ni mo fi gba ipò yìí 12 Owewe 2019 Àkọlé àwòrán, Gbogbo ohun ti Afẹnifẹrẹ mu ni pataki ni ẹmi naa yan laayo Oun ti o yẹ ka gbaju mọ lasiko yi ni isọkan awa Yoruba.
“Nítorí pé ẹ fi ara yín ṣe ọ̀pá tí àwọn ọmọ Israẹli gbára lé; ṣugbọn ọ̀pá tí kò gbani dúró ni yín.
O ní ọ̀gbẹ́ ni Adeoye yoo ran ìjọba lọ́wọ́ láti maa tan àwọn ipolongo lori ààrun corornavirus, yóò si jẹ ọ̀kan lára àwọn ìgbìmọ̀ amúṣẹ́ṣe lori ọ̀rọ̀ coronavirus nípìnlẹ̀ Ekiti Àwọn tó jí ìbejì mi gbé ti pè mí ṣùgbọ́n N50 mílíọ̀nù tí wọ́n ń béèrè pọ̀ ju agbára mi lọ-Akeugbagold TB Joshua, Apostle Suleman, Odumeje, D.
Bí o bá gbọ́n, o óo jèrè ọgbọ́n rẹ,Bí o bá sì jẹ́ pẹ̀gànpẹ̀gàn, ìwọ nìkan ni o óo jèrè rẹ̀.
Aare ni awon omo orile ede
N óo fìyà jẹ Farao ati àwọn tí wọ́n gbẹ́kẹ̀lé e.
Bayero Emir ìlúu Kano, ìyá rẹ̀ ọmọ Emir Kẹjọ ni ìlú Ilorin!
Ìwọ jù mi lọ, ìwọ tóbi nínú àwọn ọmọ ènìyàn, ìwọ pọ̀ lọ́kùnrin.
 Àwọn ènìyàn tó ń rin ìrìn-àjò lọ sí àwọn agbègbè ibití àrùn náà ti ń wáyé ní a tún gbọdọ ̀ fún ní àjẹsára náà .
Amọ awọn ekute yii gbọdọ jẹ eyi ti wọn sẹsẹ bi, ti ko i ti pẹ ju nilẹ.
Lẹyin naa lo sọ pe ko pọn dandan ki igbakeji gomina ọhun yọju ojuko ipade awọn igbimọ aṣejọba to ma n waye laarin ọsẹ.
'Ẹwọn ọdun mẹẹdọgbọn ko pọ ju fun afipabanilopọ' Àjọ ọlọpàá Eko kédé pé ìbalòpọ̀ nítà kò bójúmu 'Ǹkan ìṣeré ìbálòpọ̀ mi ńpaná iṣẹ́ mọ́ mi lára' Njẹ bawo wa ni awọn obi ṣe le fura tabi mọ pe, ọmọ wọn ọkunrin tabi obinrin ti n koju ifipabanilopọ?
Nítorí nígbà tí Olórí Alufaa bá wọ Ibi Mímọ́ lọ, wọ́n ń fi ẹ̀jẹ̀ ẹranko rúbọ fún ẹ̀ṣẹ̀.
Láti ọjọ́ tí wọ́n ti bí mi níbẹ̀ n kkò gbádùn rárá: ọmọ méje ni mo bí, méjì ti kú nínú wọn, ó dá mi lójú pé àwọn èjẹ́ ló pa méjì náà jẹ́.
Ara iredi iyansẹlodi awọn oṣiṣẹ ile asofin ni wi pe awọn ko ri ẹtọ awọn gba nipaṣẹ owo osu ati ajẹmọnu ti o tọ si awọn .
Wọ́n fi ìwà burúkú wọn mú OLUWA bínú,àjàkálẹ̀ àrùn sì bẹ́ sílẹ̀ láàrin wọn.
Kò sí ẹni tó léè dí àlàfo tí Funke fi sílẹ̀ - Ọkọ rẹ̀, Olakunrin lahùn fún ìgbà àkọ́kọ́ Olólùfẹ́ méjì jábọ́ láti àjà kẹsàn án lásìkò tí wọ́n n ṣe kerewà Ẹ má dá NEF lóhùn, kò síbi t'ọ́mọ Nàìjíríà kò lè gbé nílẹ̀ yìí - Buhari CAN kò rán ẹnikẹ́ni lọ ṣọ́ọ̀ṣì COZA, iṣẹ́ ara wọn ní wọ́n lọ jẹ́ -Samson Ayokunle Oyetọla ni aikun oju iwọn eto idibo orilẹede Naijiria lori yiyan awọn oludije lo fun iru awọn eeyan bi Adeleke lanfani lati dije tako oun.
Awọn obinrin ti ọjọ ori wọn bẹrẹ lati ọdun mejidinlogun soke lo wa ninu ẹgbẹ naa.
Ni ọsẹ to kọja ni BBC News Yoruba gbe iroyin jade to n beere ibi gan an ti ọkọ Florence wa.
Ni tirẹ, iṣe ti wọn fi n sun ọjọ isede ati irina siwaju ni gbogbo igba ti wa di ohun ti Ayokele ko lee gbagbọ mọ.
Fi ẹ̀sùn kún ẹ̀sùn wọn;má sì jẹ́ kí wọ́n rí ìdáláre lọ́dọ̀ rẹ.
Ọrọ awọn ọlọpa fihan pe ifẹ inu awọn mii tabi obi wọn ni lati mu lọ si ayédèrú ibudo atúnwàṣe yii ti wọn si san owo gọbọi fun alakoso ibẹ.
"Idojukọ ti mo dojukọ ni lo mu mi ke gbajarẹ si awọn ọmọ ile Yoruba lati jọwọ ṣeranwọ fun mi nipa pipese irinṣẹ ti mo nilo lati bẹrẹ si ni ṣe ere oritage pada ati ṣiṣẹ awọn sinima.
Peace Committee)lo rọ  omo orile ede
yọọ kuro ninu ewu oko ofufufu ti o sele ni ipinle  Kogi .
O ṣe igbeyawo pẹlu Olabisi Fayemi, wọn si bi ọmọ.
Pe àwọn eniyan náà jọ, ati ọkunrin ati obinrin, ati ọmọde ati àgbà, ati onílé ati àlejò, tí ó wà ninu ìlú yín, kí wọ́n lè gbọ́, kí wọ́n sì kọ́ láti bẹ̀rù OLUWA Ọlọrun yín, kí wọ́n sì máa fi pẹ̀lẹ́pẹ̀lẹ́ tẹ̀lé gbogbo àwọn ọ̀rọ̀ tí ó wà ninu òfin yìí.
O fikun pe baba oun lo kọ oun ni isẹ tiata, ọga oun si lo tun jẹ, to si ti kọ oun pe nigb-kuugba ti oun ba pade awọn agba osere lẹnu isẹ, oun ko gbọdọ bẹru rara .
Irọ́ ni pé wọ́n sèkọlù sí Gómìnà Seyi Makinde - Ọlọ́pàá Kogi Àyẹ̀wò ẹ̀jẹ̀ ti di dandan fáwọn tó bá fẹ́ ṣèyàwó ní Nàìjíríà- Ilé aṣojú-ṣòfin Ilé ẹjọ́ ni agbábọ́ọ̀lù ọmọ Nàìjíríà, Dickson Etuhu jẹ́bi ẹ̀sùn títa ìdíje Sweden Àwọn ọmọ Nàìjíríà bu ẹnu ẹ̀tẹ́ lu NTA lórí ìgbóhùnsáfẹ́fẹ́ ìdíje bọ́ọ̀lù Adigunjalẹ̀ fìbọn fọ́ ojú ọmọ tó fẹ́ lọ sìnrú ìlú nílùú Èkó Àgbẹdọ̀!
Okorie; Asoju egbe Miyeti Allah, Mohammadu Kabiru; awon igbakeji ati
Ẹ ka eero awọn ọmọ Naijiria ni oju opo isalẹ yii.
com/T8HglGev7v— Nigeria Police Force (@PoliceNG) October 31, 2018Ewe, ni irufe rogbodiyan naa to tun waye niluu Abuja, ogunlogo awon omo egbe El-Zazakky ni awon olopaa ti fowo sinkun mu si atimole , lataari gbigbogun ti awon ara ilu, ti won si tun dana sun oko olopaa kan.
Ninu ọkan, Mercy fi aworan sita to sọ pe o lee jẹ iṣẹju marun un fun iwọ (afipabanilopọ) ṣugbọn ayeraiye ni fun oun (ẹni ti wọn fipa ba lo pọ)."
Àwọn nkan rere àti àwọn nkan búburú pẹ̀lú.
Ìgbà tí o bá dáwọ́ ìpanirun dúró,nígbà náà ni a óo pa ìwọ gan-an run;nígbà tí o bá fi ìwà ọ̀dàlẹ̀ sílẹ̀,nígbà náà ni a óo dà ọ́.
Lara awọn obi awọn ọmọ ti wọn ti fipabalopọ ni ipinlẹ Kano ni iha Ariwa Naijiria ti fi atilẹyin wọn han si ipinu ile ẹjọ giga julọ ti ẹsin Islam ti wọn dajọ iku fun baba agbalagba kan fun ẹsun ifipabanilopọ.
Oríṣun àwòrán, @GovAyoFayose Àkọlé àwòrán, Ni ibẹrẹ ọdun 2018 Gomina Fayose ipinlẹ Ekiti se ipade pẹlu awọn ọdẹ lori ọrọ ipenija darandaran.
Nigba to n ba BBC Yoruba sọrọ, Agbẹnusọ fun aarẹ ẹgbẹ awọn ọmọlẹyin Kristi ni orilẹede Naijiria, CAN, Ẹniọwọ Bayọ Ọladeji ni ti a ba wo awọn ipinlẹ ti ikọlu yii ti sẹlẹ lo fihan wipe awọn agbegbe ti awọn ẹlẹsin kristẹni ti pọ julọ.
Ó ń fi ẹnu họlẹ̀ pẹlu ìgboyà ati ìwàǹwára,nígbà tí ipè dún, ara rẹ̀ kò balẹ̀.
Gómìnà ni àwọn ilé ẹ̀kọ́ fásiti gbogbo yóò sì wà ni títì pa, kí wọ́n tẹ̀síwájú nínú ètò ẹ̀kọ́ orí ayélujara.
Lisa ṣalaye fun onile rẹ pe oun ti gbọ ẹkọ ti o fẹ kọ oun nitori oun ko mọ pe ile oun dọti to bẹẹ ati pe iṣẹ lo gbomi mu fun oun ti oun ko si ri aaye tun ile ṣe.
Akọ̀ròyìn Morocco, Hajar gbà ìdájọ́ ẹ̀wọ̀n lórí ẹ̀sùn àgbèrè àti pé o ṣẹ́yún Amọ, Aarẹ Buhari ko sọ nipa gbigbogun ti iya ati isẹ ati eto rẹ lati koju wahala awọn Fulani darandaran lorilẹ-ede Naijiria.
O ti kopa ninu ere ede oyinbo ati ti Yoruba to pọ.
Kò mọ ẹ̀rù, ọkàn rẹ̀ kì í rẹ̀wẹ̀sì,bẹ́ẹ̀ ni kì í sá fún idà.
Àwọn orílẹ̀-èdè yóo máa bẹ̀rù orúkọ OLUWA,gbogbo ọba ayé ni yóo sì máa bẹ̀rù ògo rẹ̀.
Ọdun 2019 ni wọn yan Akintoye sipo gẹgẹ bi Aarẹ ẹgbẹ YWC lẹyin ti aga naa ti ṣofo fun ọpọ ọdun lẹyin ti oloye Abraham Adesanya jade laye.
Kí ni ìdí ti June 12 fi ṣe pàtàkì sí ẹkùn Iwọ-òòrun Guusu Nàíjíríà: Ní ọjọ́ Kejila oṣù Kẹfa ọdun 1993, ní ẹ̀yá Yoruba gbà pé, ìjọba awa ara wa wọle tọ wa ni Naijiria, lẹ́yìn ìdìbò ti wọ́n gbàgbọ́ pé kò ni ẹja ń bakan, nínú ìtàn orílẹ̀ ede Nàìjíríà.
Ogbeni  Ahmed Shittu,to je alamojuto ajo INEC  lo kede pe ogbeni  Danze,to je alaga ijoba ibile to wa lori
Nítorí pé, aláàánú ni OLUWA Ọlọrun yín, kò ní já yín kulẹ̀, kò ní pa yín run, bẹ́ẹ̀ ni kò ní gbàgbé majẹmu tí ó fi ìbúra bá àwọn baba ńlá yín dá.
Ohun tí mo ṣe tí ó di ẹ̀ṣẹ̀ yìí, òtítọ́ inú ati àìmọ̀ ni mo fi ṣe é.
 o se pataki gege bi aronu ogidi ninu asa marksisti .
Ẹ̀mí Ọlọrun bà lé e, ó sì bẹ̀rẹ̀ sí sọ àsọtẹ́lẹ̀ láàrin wọn.
"Amọ, iwa ọdaran to tako eredi ohun ti wọn n ja fun ni ki eeyan ṣe ikọlu si ọgba ewon"" O pari ọrọ rẹ pe ""aaye aabo to gbọngbọn ni ọgba ẹwọn jẹ."
BBCCopyright: BBC Aarẹ orilẹede Naijiria tẹlẹ ri Ọgagun Yakubu GowonImage caption: Aarẹ orilẹede Naijiria tẹlẹ ri Ọgagun Yakubu Gowon BBCCopyright: BBC Latọwọ osi, Abdulaziz Yari gomina ana ti Zamfara, Yahaya Bello ti Kogi, Rotimi Akeredolu ti OndoImage caption: Latọwọ osi, Abdulaziz Yari gomina ana ti Zamfara, Yahaya Bello ti Kogi, Rotimi Akeredolu ti Ondo BBCCopyright: BBC Latọwọ osi, Adams Oshiomole, Asiwaju Bola Ahmed Tinubu, Bisi AkandeImage caption: Latọwọ osi, Adams Oshiomole, Asiwaju Bola Ahmed Tinubu, Bisi Akande Article share tools Facebook Twitter ṢàpínlòView more share options Share this post Copy this linkKà síwájú síi nípa àwọn ìtọ́kasí wọ̀nyí.
Orúkọ Aisha Yesufu náà wọ inú BBC 100 Women tí a fi ń sọri àwọn obìnrin tó pegedé ní 2020 Nàìjíríà fohùn ránṣẹ́ padà sílé aṣofin UK pé ọ̀rọ̀ EndSars kò sí lẹ́nú wọn láìgbọ́ ìwádìí tán!
Kí o pàṣẹ fún wọn pé kí wọ́n gbé òkúta mejila láàrin odò Jọdani yìí, lọ́gangan ibi tí àwọn alufaa dúró sí, kí wọ́n gbé wọn lọ́wọ́ bí ẹ ti ń lọ, kí ẹ sì kó wọn jọ sí ibi tí ẹ óo sùn lálẹ́ òní.
Bẹ́ẹ̀ ni Solomoni ṣe parí ilé OLUWA ati ààfin rẹ̀.
Gomina Seyi Makinde tun paṣẹ pe ki gbogbo igbimọ oluṣakoso ni awọn ileeṣẹ ati lajọ-lajọ to jẹ tijọba Ọyọ di tituka.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Lórí ọ̀rọ̀ Pásítọ̀ COZA àti Dakolo, Ìwadìí ń tẹ̀ síwájú, ṣùgbọ́n a kò mọ ohunkohun nípa rẹ̀ mọ́- Iléeṣẹ́ ọlọ́pàá Èkó 22 Agẹmo 2019 Oríṣun àwòrán, @Timidakolo Ileeṣẹ ọlọpaa ni ipinlẹ Eko ni awọn ko mọ ohunkohun mọ nipa ẹjọ ẹsun ifipabanilopo ti iyawo gbajugbaja olorin Timi Dakolo, Busọla, pe tako Pasitọ Fatoyinbo.
Duro Ladipọ, ìlúmọ̀ọ́ká òṣèré tíátà àti ọmọ àlúfà tí kò gbàgbé àṣà ìbílẹ̀ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Oluwo: Mo lè jẹ Ọba ní Ile Ife Adajọ to gbẹ́jọ náà Karen Mason sọ pe bó tilẹ̀ jẹ pe oun ni igbagbọ pé Adeleye kìí ṣe ènìyàn burukú tí ó fẹ pa ọmọ sùgbọ́n ó yẹ ki ó mọ pé igbésẹ̀ náà le gba ẹmi ọmọ.
O ni aṣiri ikọkọ wa lori idajọ naa ti ko han si ọpọ eeyan.
Lara awon to tun wa nibi ipade pelu aare Buhari ni  Sheikh Hussain Al Nowais, alaga Ameato n pese  ina mona-mona(Power).
" Awọn nkan yii ni Mallam Musa Zabarmani sọ fun BBC nipa ọmọ rẹ, Musfau, to jẹ ẹnikan lara awọn eeyan ti afurasi Boko Haram pa lọjọ Satide lasiko ti wọn kọlu awọn agbẹ nilu Koshebe, nipinlẹ Borno.
Ṣafani bá pada lọ jíṣẹ́ fún ọba, ó sọ fún ọba pé, àwọn iranṣẹ rẹ̀ ti kó owó tí ó wà ninu ilé OLUWA fún àwọn tí wọ́n ń ṣe àkóso àtúnṣe ilé OLUWA, 
Gbogbo akitiyan lati kọ omiran lẹyin rẹ ni ko si tii ri oju ọjọ rere.
O ni aṣa ki a maa yinbọn popopo ninu fiimu lo kọ awọn ọmọ lole laye ode oni, dipo kiawọn ọmọde maa ri ẹkọ kọ nibẹ.
Ninu lẹta ti o jade lati ọfiisi gomina Seyi Makinde eleyii ti akọwe rẹ, Arabinrin Olubamiwo Adeosun fọwọ si lọjọ kẹwaa oṣu kẹjọ ọdun 2020, gomina ni loju ẹsẹ ni idaduro naa bẹrẹ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Corporal Punishment: Olùkọ́ fẹgba lu akẹ́kọ́ọ̀bìnrin ọmọ ọdún mẹ́rìnlá pa ní yàrá ìkàwé 30 Ọ̀wàrà 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Agba adura ni pe ki abiyamọ ma foju sọkun ọmọ laye.
Ọlọ́pàá gbé àwọn tó yìnbọn lu olólùfẹ́ ní Ajegunle Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, JAMB 2019: A ó fagi lé ìdànwò ẹni tó bá ṣe aṣemáṣe Bi awọn kan ṣe n sọ pe irọ ni ileeṣẹ naa n pa, ni awọn kan si n sọ pe ki wọn o maa da owo pada fun ẹnikẹni ti ko ba ṣe aṣeyọri ninu ibeere fun iwe irinna naa.
Lori mohunmaworan akọkọ nilẹ wa, to wa nilu Ibadan, (NTA Ibadan) ni orukọ Aluwẹ ti kọkọ gbalẹ kan, nigba to n sere Awada Kẹrikẹri pẹlu ọga rẹ, baba Mero ati Adebayọ Salami, ta mọ si ọga Bello.
Lai Mohammed ni iru igbesẹ bayi ti ya ju ati pe, o le mu iporuru ọkan wa fun awọn to ba fẹ dokowo pẹlu Naijiria.
Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Emir Of Zazzau: El-Rufai kéde ọjọ́ mẹ́ta fún ìdárò Emir Zazzau, Buhari, Babangida náà ń ṣèdárò21 Owewe 2020 Fídíò, Akomolede: Bolaji Faleke ni Olùkọ́ tó ń kọ́ wa ní àṣà oge ṣiṣe lórí BBC Yorùbá1 Owewe 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Ẹ óo mú ọrẹ tí ó jẹ́ ti OLUWA wá fún Aaroni alufaa.
Wo díẹ̀ nínú ipa tí ẹnu bodè ti Nàìjíríà tì pa kó nínú ọjà ọdún Kérésì Lásìkò ọdún yìí, Òbí gbọ́dọ̀ fi àsìkò sílẹ̀ fi tọ́jú àwọn ọmọ wọn Olè yabo báńkì,fọ́n owó ká fáwọn èrò lẹ́yìn tó pariwo 'Merry Christmas' Èyí ni bí wọ́n ṣe n dìbò yan Póópù tuntun nínú ìjọ Àgùdà Obinrin to ba ni awọn amuyẹ ti Fọlarin Falana (Falz) ka silẹ lasiko to n ṣabẹwo sile iṣẹ BBC nilu Eko yii le jade sita nitori a ko kuku mọ ori ọlọla ni ọrọ ile aye.
Agbenusọ fawọn agbofinro ni South Africa, Thembeka Mbele ni ọrọ naa jọni lọju gidi ṣugbọn iṣẹ iwadii ṣi n lọ.
Nigba ti Akọrọyin BBC Yoruba ṣe abẹwọ si ibudo ilera naa, awọn orule to wa nibẹ ti wo, ko si oogun fun awọn alaboyun, bẹẹ si ni ko si omi fun wọn.
N-Power Tech (Hardware): ₦20,000 -si ₦40,000 loṣu.
 O ni iṣẹ akin lati daabobo ijọba tiwantiwa orilẹ-ede yii ni obinrin naa ṣe.
Ajọ ẹsọ oju popo lagbegbe naa ni awọn oṣẹ ileeṣẹ aṣọna Julius Berger ni wọn bẹ ọpa gaasi naa lasiko ti wọn fi n wa ilẹ lagbegbe naa fun ibudo iṣẹ wọn.
Àwọn nǹkan tí ó bá sì yé wọn, bí nǹkan tíí yé ẹranko ni.
Nítorí nígbà tí a wà lọ́dọ̀ yín, a ti sọ fun yín tẹ́lẹ̀ pé a níláti jìyà.
Àwọn òńkọ̀wé ń dárò Okediji tí kò bá pé ẹni ọdún 90 lókè eèpẹ̀ lónìí Loni BBC Yoruba lọ wadii iru ọmọ ti Yoruba n pe ni Yetunde lẹyin ti a bii.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Bí o ṣe lè fí òǹkà, ọ̀mọ̀ ìka tàbí ìkúùkù wọn oúnjẹ́ Loju Dokita Adan, awọn eniyan Somalia ṣomọluwabi pupọ.
Ọmọkunrin ti wọn ti wọn yinbọn lu ti n gba itọju nile iwosan.
Sùgbọ́n lẹ́yìn ọ̀pọ̀lọpọ atótónú láti ọdọ àwọn ọmọ Nàìjíríà, ààrẹ Muhammadu Buhari, lọdun tó kọja kéde pé Nàìjíríà yóò ma ya June 12 sọ́tọ̀, láti fi ṣe àyájọ ọjọ ìjọba àwa ara wa, bákan náà ni ile ìgbìmọ aṣofin jan abádofin náà lóntẹ.
Bí ẹlẹ́gbẹ́ olóṣèlú kò bá mọ èyí, a jẹ́ wípé wọn kò ní ìkọbiarasí ìṣèlú wọ́n sì ti pàdánù ìlọsíwájúu wọn.
    N kò lè ṣàì gbà ọ́ níyànjú nípa ti ìdọ̀tí ilé rẹ, ọ̀bùn ọ̀nà rẹ àti èérí ara rẹ pẹ̀lú.
Fayemi ni awon opolopo eniyan to wa nibi ipade naa dojuko , bi o se wo gbongan ile ipade naa.
'Mo máa ń ta sí Tolu pé ọjọ́ wo ni wàá tó gà'- Musa, Ọ̀rẹ́ àti kékeré 'Mó sábà maa ń fi Tolu ṣe yẹ̀yẹ́ nítori bi ó ṣe kúrú' Ọ̀kàn nínú àwọn ọ̀rẹ́ Tolu ti wọ́n jọ lọ si ilé iwé ti wọ́n si tún jọ kọ ẹ̀kọ́ ojú omi ni ilé iṣẹ́ ọmọogun afẹ́fẹ́ Muhammed Musa ló sàlàyé fun BBC pé ǹkan ìbànújẹ́ gbáà ni ikú tó Tolu jẹ́."
Oríṣun àwòrán, NASir El-Rufai/Facebook Lati wa ri i daju pe ẹtọ awọn ọmọ Naijiria lati gbe tabi ṣiṣẹ ni ibi to ba wu wọn, Gomina El-Rufai sọ pe ijọba oun yoo tete ṣiṣẹ lati fi oju eniyan mẹẹdọgbọn ti ọwọ awọn agbofinro tẹ lori iṣẹlẹ to ṣẹṣẹ waye yii, ati awọn mẹtalelọgọta ti wọn mu lasiko eyi to waye ninu oṣu Keji, ọdun 2018 ni agbegbe Kasuwan Magani.
Níbo ni ọba Hamati, ati ti Aripadi, ati ti Sefafaimu, ati ti Hena, ati ti Ifa wà?
ijoba orile eede Naijiria ni paapaa julo lori awon eto amayederun  ni eyi ti o je ki ipinle naa gun oke agba
Wọn fi kún-un pé àwọn agbègbè tó kù kò tíì fararọ to nítori náà wọn fi ààyè díẹ̀ sílẹ̀ farailu láti ní àǹfàní fún ríra àwọn ǹkan ti wọn ba nílò nínú ilé.
Champions League Draw: Barcelona yóò kojú Man U ní ìpele 'quarter finals'
Wọn fẹsun kan Magu pe na owo ti ajọ ọhun rigba pada lọwọ awọn to lu owo ilu ni ponpo, o si tun lu awọn ohun ini jọba kan ni gbanjo fun awọn eeyan kan to sun mọ ọ.
Àwọn ẹ̀yà Josẹfu lọ bá Joṣua, wọ́n wí fún un pé, “Kí ló dé tí o fi fún wa ní ẹyọ ilẹ̀ kan ṣoṣo gẹ́gẹ́ bí ìpín tiwa, nígbà tí ó jẹ́ pé àwọn eniyan wa pọ̀ gan-an, nítorí pé OLUWA ti bukun wa?
Bukky dupẹ lọwọ Eleduwa to jẹ ko ri ọdun miiran laye.
Bí ọdún náà ti ń dópin lọ, àwọn ọmọ ogun Siria gbógun ti Joaṣi.
 yúnyún kò wọ ́ pọ ̀ .
Mo ti kó ọ̀fọ̀ bá wọn;mo ti pa àwọn eniyan mi run,nítorí wọn kò yipada kúrò ní ọ̀nà wọn.
Ni aala ilẹ Naijiria si Cameroon, ikọ naa nsamulo ilana to yatọ, ti wọn si nlo awọn aso ado iku mọra ju awọn agbebọn lọ.
(Nítorí pé àwọn Farisi ati gbogbo àwọn Juu yòókù kò jẹ́ jẹun láì wẹ ọwọ́ ní ọ̀nà tí òfin là sílẹ̀; wọ́n ń tẹ̀lé àṣà ìbílẹ̀ wọn.
Oloye Tunde ni laisi pe awọn ọmọ ẹgbẹ oṣelu naa mọ irufẹ ẹni naa iwọnba ni awọn ọmọ ile igbimọ le ṣe mọ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Mo ń ṣa ike jọ láti san owó ilé iwé ọmọ mẹ́ta' Ọpọ eekan ẹgbẹ lo fi ẹgbẹ silẹ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ese Oruru: Arákùnrin tó jí Ese Oruru gbé gba ìdájọ́ ẹ̀wọ̀n ọdún mẹ́rìndínlọ́gbọ̀n 21 Èbibi 2020 Oríṣun àwòrán, @HRFKingFGA Ile ẹjọ giga kan nilu Yenagoa tii ṣe olu ilu ipinlẹ Bayelsa ti dajọ ẹwọn ọdun mẹrindinlọgbọn farakunrin Yunusa Dahiru to ji ọmọbinrin Ese Oruru gbe ti o si tun fipa fẹ sile.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ọba Mohammed bin-Salman ti Saudi yọ ọmọ rẹ̀, Fahad, Abdulaaziz àti àbúrò rẹ̀, Ahmed kúrò nípò nítorí ìwà àjẹbánu 2 Owewe 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 3 Owewe 2020 Ọba Saudi Arabiajawe lọ rọọkun nile fun minisita to n ri si eto aabo orile-ede naa.
Idi èyi ni Yorùbá fi npa ni òwe pé “Ìjayà ló bá ọmọ Ẹkùn ti ó di Ológbò ti ó ńṣe ọde eku inú ilé.
Awọn ọmọ ẹgbẹ ti Gomina Akinwunmi Ambọde yan si ipo naa ni Oloye Ọlawale Mọgaji, gẹgẹ bi Alaga; Ọgbẹni Bayọ Balogun, Arabinrin Ajọkẹ Risikat, Ọgbẹni Bọde Tawak ati Ọgbẹni Afọlabi Ayantayọ ti awọn jẹ ọmọ ẹgbẹ igbimọ naa.
Koda o ni inu oun yoo dun gan an t'oun ba tun le rii ami ẹyẹ naa gba lọdun to mbọ.
Ọ̀rọ̀ Aguri, ọmọ Jake ará Masa nìyí:Ọkunrin yìí sọ fún Itieli ati Ukali pé,
Bi wọn ṣe n jo agọ ọlọpaa, ni wọn n ṣe wọn leṣe, ti wọn si tun n kọju ija si araalu, ọba alaye atawọn ileesẹ ijọba pẹlu ti aladani.
Ìlànà ati ẹ̀kọ́ eniyan ni wọ́n.
Nígbà tí mo wo ààrin àwọn ìkógun, mo rí ẹ̀wù àwọ̀lékè dáradára kan láti Ṣinari, ati igba ìwọ̀n Ṣekeli fadaka, ati ọ̀pá wúrà kan tí ìwọ̀n rẹ̀ jẹ́ aadọta Ṣekeli, wọ́n wọ̀ mí lójú, mo bá kó wọn, mo sì bò wọ́n mọ́lẹ̀ ninu àgọ́ mi.
Awuyewuye n lọ lọwọ lori esi idibo abẹnu PDP pẹlu bi Akin Ogunbiyi to ṣe ipo keji ninu idibo ọhun ṣe ti n f'apa janu bayii pe ohun lo bori ninu idibo naa.
Minisita  ti koko  dupe lowo  awon  osise fun ifokansin ,iwa akinkanju, ati ifarasin  won fun ijoba aare Buhari ati fun orile ede Naijria , o tun wa ki awon osise ku ayeye ajodun .
" Kò si fíìmù ti àwọn ènìyàn fẹ́ràn tó fíìmù ì fẹ́, ọ̀nà wo ni ẹ fẹ gba láti fi òfin de?
Àkọlé àwòrán, Ijọba Naijiria sọ pe awọn ko mọ ibi ti Nnamdi Kanu wa Muhammed ninu ọrọ rẹ sọ wipe ohun ko mọ irinajo Kanu, ati wipe iyawo rẹ nikan lo le sọ pato ibi ti ọkọ rẹ wa.
O ti to ọdun diẹ ti ogun ti n ja agbegbe Ọyọ laye igba naa, eyi to maa n mu ẹkun, ipayinkeke ati itajẹsilẹ nla wa, ti wọn yoo si ko ọps eeyan lẹru, isẹlẹ yii naa si yi kan ilu mi, Osogun nigba to ya.
naa ni Ọba Akiolu tun rọ awọn oloṣelu ati aṣiwaju yii lati yago fun awọn
Ikú Suga: UCH ní àwọn agbẹjọ́rò òun yóò fèsì fún mọ̀lẹ́bí Sugar
Ọ ̀ kan nínú àwọn ìtàn náà sọ pé ; Ọwà iléṣà kìíní ajíbógun àti Ọba Ìjẹ ̀ bú - jẹ ̀ ṣà kìíni , agígírí jẹ ́ tẹ ̀ gbọ ́ n tàbúrò .
Fidio naa mu ki ọpọlọpọ ọmọ Naijiria o koro oju si ẹgbẹ CAN.
Awakọ̀ tó gbé afurasí alárùn Covid-19 ní Kwara kò sí ní ibùdó ìyaraẹni sọ́tọ̀"" Yàtọ̀ si aríwo tó ń tàn ká pé gómínà ìpínlẹ̀ Kwara tí paṣẹ pé ki wọ́n fún awakọ̀ tó wà nínú fọ́rán kan to fójú hàn lórí ayélujára níbi ti wọ́n ti n gbé ènìyàn kan sí inú ọkọ pàjáwìrì aláàrùn Covid-19 níwèé ìdádúro, Kọmísọ́nà fún ètò ìlera ní ìpínlẹ̀ Kwara Raji Razaq ni ọ̀rọ̀ kò rí bẹ́ẹ̀ rárá."
OLUWA Ọlọrun ní, “Ẹ wò ó!
awon ko ni yi ipinnu won  pada lori ọgbọ̀n egberun (30,000)
Òfin kan náà ni ó wà fún gbogbo àwọn tí o bá ṣẹ̀ láìmọ̀, ìbáà ṣe ọmọ Israẹli tabi àjèjì tí ń gbé láàrin ilẹ̀ Israẹli.
Ǹjẹ́ o mọ̀ pé Baba Sala ló kọ́ Sunny Ade nísẹ́?
Bẹ́ẹ̀ ni wọn yóo ṣe máa bojútó Àgọ́ Àjọ ati ibi mímọ́, tí wọn yóo sì máa ran àwọn ọmọ Aaroni, àwọn arakunrin wọn lọ́wọ́, níbi iṣẹ́ ìsìn ilé OLUWA.
Iṣẹju diẹ sẹyin ni ikede naa jade pe lati oni ọjọ iṣẹgun ikejidinlogun oṣu ikẹfa pe ile iwe giga gbogboniṣe Rufus Giwa Polytechnic di titi pa.
“Lílọ ni à ń lọ sí Jerusalẹmu yìí o, wọn óo fi Ọmọ-Eniyan lé àwọn olórí alufaa ati àwọn amòfin lọ́wọ́, wọn óo sì dá a lẹ́bi ikú.
“Ohun tí o óo ṣe láti ya Aaroni ati àwọn ọmọ rẹ̀ sọ́tọ̀ kí wọ́n lè máa ṣe iṣẹ́ alufaa fún mi nìyí: mú ẹgbọ̀rọ̀ mààlúù kan, ati àgbò meji tí kò ní àbùkù, 
”Jesu dá a lóhùn pé, “O ti fi ẹnu ara rẹ wí pé Ọba ni mí.
Níbi tí àwọn oníṣẹ́ ibi kò ti lágbára mọ́,tí àwọn tí gbogbo nǹkan ti sú gbé ń sinmi.
Bakan naa lo ti ba Adari David Cameron ṣiṣẹ bii akọwe agba to ṣee finutan.
Bí bẹ́ẹ̀ kọ́, mò ń bọ̀ wá sọ́dọ̀ rẹ, bí o kò bá ronupiwada, n óo mú ọ̀pá fìtílà rẹ kúrò ní ipò rẹ̀.
Lẹ́yìn náà, jọ̀wọ́ jẹ́ kí n pada lọ sí ilé mi, kí n lè kú sí ìlú mi, nítòsí ibojì àwọn òbí mi.
Iru awọn iroyin ti ẹ le nifẹ si: Igbakeji gomina Eko sọrọ nipa obinrin Obi awọn akẹkọ Dapchi nbeere ọmọ wọn Fọlọrunṣọ Alakija: Imọ ṣe koko 'Ara sisan kii ṣe arun' Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Bí a ṣe pín àwọn ọmọ Aaroni nìyí: Aaroni ní ọmọkunrin mẹrin: Nadabu, Abihu, Eleasari ati Itamari.
Ẹ ranti bí ó tí sọ fun yín nígbà tí ó wà ní Galili pé, 
Bí mo bá ní kí n kà wọ́n,wọ́n pọ̀ ju iyanrìn lọ;nígbà tí mo bá sì jí,ọ̀dọ̀ rẹ náà ni n óo wà.
Tí ńkan to n lọ láyìká ẹni náà, kò bá ti ni ìtùmọ̀ si mọ́, tó kàn dà bi ẹni pe ó kàn gbe aye ṣá, o yẹ ka fura siru wọn.
O ni Fatoyinbo yoo yọju si igbimọ PFN tawọn ọlọpaa ba pari iṣẹ iwadii wọn lori ọrọ naa.
awon opopona ati oju ona ti won ti pa tẹlẹ nitori bi awon iko olote se n da won
Eyi ri bẹẹ nigba ti awọn eeyan meje ninu idile naa ta teru nipa lẹyin ti wọn jẹun alẹ tan ni alẹ ọjọ Ẹti.
Lara awọn to peju sibi ipade naa ni alaga ẹgbẹ ọmọlẹyin Kristi, CAN nipinlẹ Eko, Alexander bamgbola, Imamu agba ipinlẹ Eko Sheikh Suleiman Abou Nolla ati awọn olori ẹlẹ mii kaakiri ipinlẹ ọhun.
Badmos ṣàlàyé loju opo ikansiraẹni nstagram rẹ̀ pé, irú ẹ̀sùn náà ṣeéṣe nítorí àwọn olè ajípátá tí ọwọ́ tẹ̀, ní wọn n gbero lati se oògùn owó tí yóò ṣe ikú pa ẹni to ni pata naa.
“Ẹ yan àwọn adájọ́ ati àwọn olórí tí OLUWA Ọlọrun yín fi fun yín gẹ́gẹ́ bí ẹ̀yà yín, ní àwọn ìlú yín, wọn yóo sì máa ṣe ìdájọ́ òtítọ́ fún àwọn eniyan.
Nígbà tí Hẹrọdu rí Jesu, inú rẹ̀ dùn pupọ.
Ni ó bá jókòó ninu ọkọ̀, ó ń kọ́ àwọn eniyan.
" O wa fi da awọn eeyan ilu Eko loju pe, oun yoo sa ipa oun lati se awari awọn ohun to sẹlẹ ni Lekki lalẹ ọjọ Isẹgun.
Orin kikọ̀ naa wa lara awọn ayẹyẹ ibẹrẹ idije Afcon naa, ti ọpọlọpọ ayẹyẹ ti yoo gbe asa ga ni ilẹ Afirika yoo rinlẹ nibi ayẹyẹ iside idije naa.
Ṣùgbọ́n nígbà tí Èṣù gbé ẹebọ kọjá oríta, tí ó kọ etí dídi sí ọ̀rọ̀ Olódùmarè, àwọn ẹ̀dá òde ọ̀run lé jáde.
Onimọ Sayẹnsi Ivan Parr kọwe lati ṣalaye pe lóòtọ́ awọn nkan abẹ ilẹ kan wa biirẹ lati nkan bii ọọdunrun miliọnu ọdun sẹyin ti awọn mii si maa n lo to ọdun mẹẹdọgbọn laye.
Rogbodiyan yii maa n waye ni ọdọọdun, titi ti ọgagun Abacha fi tẹri gbasọ lojiji, ti MKO Abiọla naa si tẹle.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Góòlù tí mo fẹ́ràn ní World Cup' Irun alawọ rẹsurẹsu ni aawọ irun ori ẹlẹsẹ ayo Megan eyi ti ọpọ obinrin si ti ni wọn yoo sọ aawọ irun ori wọn da lẹyin idije naa.
Gẹgẹ bi awọn ti ọrọ naa soju wọn se sọ, o kere tan eniyan ogun lo jona guruguru ti wọn ko se damọ nibi iṣẹlẹ naa ṣugbọn awọn ọlọpaa sọ pe oku eniyan mẹta lo jona julọ ti ko ṣee damọ mọ rara.
Àwọn olólùfẹ̀ Toyin Abraham ati Liz Anjorin ti gbé ọ̀rọ̀ wọn rù sórí, ẹ wo òjò òkò ọ̀rọ̀ Ìjà Toyin àti Lizzy kìí ṣe àkọ́kọ́, àwọn òṣèré t'ọ́rọ̀ ìjà kàn rí rèé Ẹ ṣọ́ra fún ìròyìn ẹlẹ́jẹ̀ lórí ètò ààbò - Ọlọ́pàá Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Yollywood: Kò sí ẹni ti òbí mi kò lè sọ̀rọ̀ sí -Sisi Quadri Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
N óo fi lé ẹni tí ó lágbára jù láàrin àwọn orílẹ̀-èdè lọ́wọ́, yóo sì ṣe é fún un gẹ́gẹ́ bí ìwà ìkà rẹ̀.
Wọ́n ní kí ó yára, kí ó rékọjá sí òdìkejì odò náà kíá.
Lọ sí Ṣilo níbi tí wolii Ahija tí ó wí fún mi pé n óo jọba Israẹli, ń gbé.
Gomina Rochas Okorocha ti ipinlẹ Imo kii ṣe ajeji si ariyanjiyan ati ede aiyede.
O ni lootọ ni Tinubu fidi rẹ mulẹ pe, bi gbogbo ọmọ Naijiria yoku se gbọ nipa rogbodiyan n waye lẹnu bode Lekki, naa ni oun naa gbọ.
Atẹjade kan jade lọ́jọ́ Aiku niluu Abuja lati ọfiisi to n boju to akanṣe eto yii pe oju opo yoo ṣi silẹ laago mẹwa alẹ.
Tinubu: Emi ko mọ nipa ipẹtusaawọ APC ti Buhari ni kin se
Lizzy ni ẹni akọkọ toun dupẹ lọwọ rẹ ni Ọba to pe ni Baami, Alaafin ti Oyo fun ẹbun owo""."
Pepele iroyin lorilẹede Nigeria ti yipada pupọ bayi kuro ni ti aye atijọ, ọpọn iroyin ti sun siwaju, amọ sibẹsibẹ awọn eeyan Yoruba si fẹ maa mọ ohun to n lọ.
Ogun, ìyàn ati àjàkálẹ̀ àrùn yóo pa ẹni tí ó bá dúró sinu ìlú yìí; ṣugbọn ẹni tí ó bá jáde tí ó sì fa ara rẹ̀ fún àwọn ará Kalidea, tí ó gbé ogun tì yín, yóo yè, yóo dàbí ẹni tó ja àjàbọ́.
gbomi ewuro si enikeji rẹ to tẹle , iyẹn, Jeremiah Useni, ajagun fẹyinti ti o jẹ
N óo sọ wọ́n di alágbára ninu èmi OLUWA,wọn yóo sì máa ṣògo ninu orúkọ mi.
Ko si eya kankan to le pa eya omo Yoruba run, nitori pe
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Victor Agunbiade ni ojú àlá ni Ọlọrun ti yan iṣẹ́ ọmọ ogun ojú omi fún òun ní America Yatọ si eyi, o le le App ajọ naa, tabi lọ si ẹka ọfiisi wọn to ba sunmọ ọ lati fi ẹjọ sun lori iru ọja naa.
Fẹ́ sórí ọgbà mi,kí òórùn dídùn rẹ̀ lè tàn káàkiri.
Wọn ni kii ṣe fidio EndSARS ni koda fidio iṣẹlẹ laaṣigbo 'ẹ kuro lorilẹede wa'to waye ni South Africa ni fidio naa jẹ.
Ilé ẹjọ́ fagilé ìpè Dino láti wá kó Ọlọ́pàá kúrò nílé rẹ̀ Ipò àgbà ló yẹ́ kí a ti bá olórí - Fani-Kayode Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Wo àrà tí ọ̀rá omi tí òún jù nù ń dà Lọjọ abamẹta ni Dino kede eyi ni ẹkun idibo rẹ ni Ayetoro ipinlẹ Kogi nibi ti ba awọn ọmọ ẹgbẹ Peoples Democratic Party pade.
APC fun ijọba ipinlẹ lagbara fun isakoso ohun alumọọni
Ṣugbọn ninu gbogbo nǹkan, à ń fi ara wa sípò àyẹ́sí gẹ́gẹ́ bí iranṣẹ Ọlọrun.
Ipele kẹwaa ija rẹ pẹlu Conwell eyi to waye niluu Chicago lo ti fidi rẹmi lẹyin ti ẹṣẹ ṣakoba fun un lori.
Ẹsun oniga mọkandinlọgọta ni wọn fi kan an, ti iye owo ti wọn lo lu ni ponpo naa ni miliọnu mejilelẹẹdẹgbẹrin Naira, N702milion.
idagbasoke lorile ede Afirika (African Development Bank AFDB) ti gbosuba fun
O ni ijiya to wa fun ẹni to ba wọ aṣọ ọmọ ogun laarin igboro ni pe yoo san owo itanran ẹgbẹrun meji tabi ko ṣewọn oṣu kan.
"Oríṣun àwòrán, @GovAyoFayose ""Se bi ti ẹgbẹ ni o, abi o muti yo, abi o mugbo yo, o ti pẹ ti Fayose ti maa n fi ẹnu rẹ yẹn sọ isọkusọ bii ọmọ ti wọn ko bii re, ti kii si se ọmọluabi."
Ó ní àwọn ọmọ ológun, àwọn ọlọpàá àti àjọ elétò ààbò gbogbo yóò wà láwọn ibi kọ́lọ́fín, ti gbogbo àwọn ẹni ibi maa n fara pamọ́ sí.
nínú ìmọ̀ ọrọ̀ ajé (Economics) ní ilé ìwé gíga Fásitì ti ìlú Eko.
Igi firi láti Seniri ni wọ́n fi ṣe gbogbo ẹ̀gbẹ́ rẹ.
Kiniun baba Moradewun n jaye ọlọba, kii gba ẹbi bọ nile ẹjọ afi are, ọrọ ti owo ba ṣe ti ni ọrọ Gbadero, ilẹ ni yoo gbe, koda, a le e pe Gbadero ni ofin funra rẹ.
Gbogbo àwọn tí wọ́n wà ní ibùdó Reubẹni jẹ́ ẹgbaa marundinlọgọrin ó lé aadọta lé ní egbeje (151,450).
Nígbà tí a o fi dé ìbẹ̀ ní ọjọ́ kejì, gbogb igbó wọ̀n-ọnnì ti dìde wọ́n dúró ṣánṣán, igi ti gbòǹgbò rẹ̀ ti hu tún rí gboǹgbò mọ́lẹ̀, ewé tí ó já sílẹ̀ tún padà lọ sí orí igi, bẹ́ẹ̀ ni àwọn ẹka gbogbo padà lọ sí ibi tí wọn ti wà rí.
Ijọba naa pẹlu ọgọọrọ awọn ọmọ orilẹede Naijiria to jẹ akẹẹkọ, ti buwọlu ẹjọ ti wọn pe lori ẹsun ti wọn fi kan ile-iwe giga fasiti ti Alabama, lati ọdun 2016.
Eto ayẹwo ti wọn ṣe fun oun lo fihan pe kindinrin rẹ kan ti di awati.
Ìlànà OLUWA tọ́, ó ń mú ọkàn yọ̀,àṣẹ OLUWA péye, a máa lani lójú.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Presidency: Buhari kò leè ṣàtìlẹyìn fún olùdíje Amosun l'Ogun 7 Sẹ́rẹ́ 2019 Oríṣun àwòrán, oGUN STATE GOVERNMENT Àkọlé àwòrán, Èdèàìyedè ti ń wáyé nípínlẹ̀ Ogùn láàárín Gómìnà Amosun àtàwọn adarí ẹgbẹ́ òṣèlú APC lápapọ̀ Ileeṣẹ aarẹ orilẹ-ede Naijiria ti sọ pe ko si idi kan fun Buhari lati ṣatilẹyin fun oludije ipo gomina n lẹgbẹ oṣelu APM nipinlẹ Ogun, Adekunle Akinlade ti gomina Ibikunle Amosun mu wa baa ni ọjọ aiku.
    Èmi ni Adéforítì, ẹbọra tí ilé rẹ̀ ń bẹ lájùlé ọrun, orúkọ tí Olódùmarè fún mi ni èyí, nítorí emi ni ó ní ìforítì jùlọ láàrin ẹ̀dá.
Sibẹ sibẹ lori iru ọr bayii, ani lati fii lẹ bẹẹ ki alejo wa sọ oju abẹ niko nipa awọn ọrọ kọọkan ti ko ṣee tẹnu bọlẹ sọ nipa ibalopọ.
Ni ai pẹ yi, Olùkọ̀wé yi bẹ ilé wò fún bi ọ̀sẹ̀ mẹta.
” Ó ní, “Kọ ọ́ sílẹ̀, nítorí òdodo ọ̀rọ̀ ati òtítọ́ ni àwọn ọ̀rọ̀ yìí.
Nítorí pé ó ronú, ó sì yipada kúrò ninu ẹ̀ṣẹ̀ tí ó ti ń dá, dájúdájú yóo yè, kò ní kú.
tun gboriyin fun Ile Igbimọ Aṣofi naa fun idasilẹ eto ẹdawo fun eto aabo
Oríṣun àwòrán, @NIMC Fun awọn ẹlẹrọ Alagbeka ti ko ba ti forukọsilẹ tẹlẹ ilana ti wọn le tele ree: 1) Igbesẹ akọkọ:Ko iroyin nipa re sí inú fọọmu NIMC loju opo wọn tii ṣe: https://penrol.
Ọrọ naa se bi ẹni fẹ ba ibomiran yọ nigba ti iroyin tun kan wi pe ọlọdẹ ori ni arakunrin naa ati pe o ni aisan ọpọlọ.
Nítorí tìrẹ ni mo ṣe di ẹni ẹ̀gàn,tí ìtìjú sì bò mí.
Nígbà náà ẹ̀ ń hùwà gẹ́gẹ́ bí ẹni ti ayé yìí, ẹ̀ ń gbọ́ràn sí aláṣẹ àwọn ẹ̀mí tí ó wà ninu òfuurufú lẹ́nu, àwọn ẹ̀mí wọnyi ń ṣiṣẹ́ títí di ìsinsìnyìí ninu àwọn ọmọ tí kò gbọ́ràn sí Ọlọrun lẹ́nu.
Awọn wo ni N-power Agro wa fun?
Gbogbo awọn ibudokọero lo si gbọdọ yẹra fun akunfaya ero.
Ile ẹjọ ni oun fun Sẹnetọ Adeleke ni anfani oniduro nitori ipo rẹ lawujọ, amọṣa o gbọdọ fi iwe irinna rẹ soke okun ṣọwọ si akọwe agba ileẹjọ naa, ko si gbọdọ rinrin ajo lọ si oke okun lai gba aṣẹ lọwọ lọdọ ile ẹjọ.
Ike omi meji ti oloogbe pọn lati fi wẹ ṣi wa lẹgbẹ baluwẹ naa titi di asiko yii pẹlu ami agbara ẹjẹ oloogbe.
O ma n fi ẹjẹ yi eekana eeyan ni.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Àtẹ ìdíje Premier League fun sáà 2018 sí 2019 14 Òkùdu 2018 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Manchester City ló jáwé olu borí ní sáà tó lọ Manchester City, tó jáwé olú borí ní sáà tó kọjá, yóò lọ ṣàbẹ̀wò sí Arsenal ní ọjọ́ Kẹrinla àti Kejila ninu oṣù Kẹjọ, fún ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ akọkọ sáà tuntun Premier League.
Nítorí náà, a gba ààwẹ̀, a sì gbadura sí Ọlọ́run, ó sì gbọ́ tiwa.
Boxing Day Derby: Arsenal rọ̀jò ẹ̀sẹ́ lé Chelsea lórí, 3-1 ló parí sí ní Emirates
Ikò Real Madrid yóò gbéna wojú Bayern Munich lálẹ́ ọjọ́ ìsẹ́gun, nínú ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ tó kángun sí aṣekágbá ìdíje Champions League.
Ìròyìn Yàjóyàjó - Èèyàn mẹ́rin míràn ní àrùn Coronavirus ní ìpínlẹ̀ Èkó Wo ohun tó mú kí Ṣèyí Makinde ó tẹ̀síwájú pẹ̀lú ìpàdé ìtagbangba níbàdàn láàrín ìṣẹ̀lẹ̀ àrùn Coronavirus Ṣé Makinde kò wá rugi oyin báyìí lórí ìpàdé ìtagbangba PDP tó ṣe níbàdàn Láì náání àjàkálẹ̀ àrùn coronavirus?
Èèyàn 373 ni ààrùn coronavirus tún ṣẹ̀ṣẹ̀ ràn ní Nàìjíríà - NCDC Ìjọba ìpínlẹ̀ Osun tí búwọlù ìlànà àyẹyẹ Ọṣun-Oṣogboo ọdún 2020 Wo díẹ̀ nípa ohun tí Walter Carrington gbé ṣe nígbà ayé rẹ̀ Saaju ninu oṣu yii, aarẹ naa ṣi n pin agbo naa kaakiri pẹlu awọn ohun iranwọ miran bii irẹsi, ororo, suga fun awọn eniyan to wa ni igberiko.
Ìjọba Ọṣun ti dásí ìjà láàrin Oluwo àti Agbowu Aláàfin ìlú Oyo, Ikú Bàbá Yèyé tún bímọ tuntun làǹtì lanti Gbogbo aṣòfin ilẹ̀ Yoruba fẹnukò fún ìjíròrò ìta gbangba lórí àbádòfin ikọ̀ Amotekun Ṣeyi Makinde ṣé ìfilọ́lẹ̀ àwọn olùdarí ìbùdókọ́, ó yan Auxilliary lálaga ìgbìmọ̀ Ilé ìgbìmọ̀ aṣofin ti bẹ̀rẹ̀ òfin tí yóò máa mú àwọn olùkọ́ fásitì tó ń bèrè fún ìbálòpọ̀ Amọ gbogbo igbiyanju wa lati jẹ ki Olubadan fi ero rẹ lede lori ẹsun ti wọn fi kan an naa lo ja si pabo.
Nitori pe, iroyin ofege maa n da wahala silẹ ni.
Ki lo de to mu ọrẹ mi, ẹgbọn mi lọ?
Nisinsinyii, wò ó, mo tú ṣẹ́kẹ́ṣẹkẹ̀ ọwọ́ rẹ sílẹ̀, bí o bá fẹ́ bá mi lọ sí Babiloni, máa bá mi kálọ, n óo tọ́jú rẹ dáradára; bí o kò bá sì fẹ́ lọ, dúró.
"mo ro pé mó n lá àlákálàá ni, mo sì ń ròó pe èníkan yoo ji mi lójú orun.
Èèyàn 204 míràn tún ti ní àrùn Coronavirus ní Nàíjírìa Ká má ri!
Oríṣun àwòrán, Oyo insight Lara awọn agbaagba aafaa to wa nibi eto isinku Oloogbe ni Alaga gbogbo ẹgbẹ awọn musulumi nipinlẹ Oyo, Alhaji Kunle Saani, Sheikh Muiydeen Bello, Olori awọn Imamu ilu Ibadan, Sheikh Abubakar AbdulGaniyu Agbotomokekere ati awọn mii.
Ọlọrun, iyebíye ni èrò rẹ lójú mi!
yoo jade ni aago mẹ́fà irọlẹ oni, lọjọ Abameta.
Arabinrin Siddiqi sọ pe Mama ọkọ mi niyẹn, aburo ọkọ mi kan naa dẹ tun niyẹn"", ko to o ksju si iyawo tuntun pe: ""Ṣe o ko mọ pe ọkọ mi ni?"
Benue: Ọwọ ologun tẹ darandaran mẹwa to n ba oko jẹ
O ni nitori iṣẹ ologun n gba akoko ju awada lọ.
Nítorí náà, ọmọ mi, gbọ́ ohun tí n óo sọ fún ọ yìí, wá gbéra kí o sálọ bá Labani, arakunrin mi, ní Harani.
 Gege bi asoju orile ede Amerika si Naijiria, ogbeni Stuart Symington  ti o wa nibi orin itagbangba ohun, so pe,”Abiodun  ati awon akegbe  re tun ti fi orin mu ibasepo ti o donmoran jeyo larin orile ede Amerika ati Naijiria.
Lẹsẹkẹsẹ tí ó fọwọ́ kàn án ni ìsun ẹ̀jẹ̀ rẹ̀ bá dá.
eto pajawiri ti wa nibi isẹlẹ naa lati du ẹmi awon omode to ri sinu ile naa.
9%, eyi ti yoo kere niye, yato si asotele ti ko ni owo ori ninu.
Ó rán mi láti waasu ìtúsílẹ̀fún àwọn tí wọ́n wà ní ìgbèkùn,ati láti mú kí àwọn afọ́jú ríran;láti jẹ́ kí àwọn tí a ni lára lọ ní alaafia,
"Sibẹ sibẹ, o si wu mi lati kawe si, amọ yoo jẹ loke okun.
Awuyewuye ń wáyé lórí bí ìjọba Ìpínlẹ̀ Kaduna ṣe kó àwọn oníbárà sí àhámọ́ Ìyàwó Bukola Saraki fún tìyá-tọmọ olójú búlúù ní N250, 000!
Kini awọn ohun miran ti ajọ to n mojuto akoso ileeṣẹ ọlọpaa lorilẹede Naijiria tun yọ sita fun amojuto?
Gbogbo irúfẹ́ ata tí Olódùmarè dá sí ilé-ayé ni wọ́n péjọ sínú àwo.
Nígbà tí ó ṣe tí mo bẹ̀rẹ̀ síí ronu, n kò mọ ìgbà tí mo bẹ̀rẹ̀ síí sọ̀rọ̀ sí ìtà tí mo ni, “Ayé yìí kò mà dọ́gba o, ibi ti àgbẹ̀ ti ń jẹ onírúurú oúnjẹ nínú ahéré oko, ni aláàárù ti ń wa gaàrí mu káàkiri ojú ọ̀nà, ibi tí ọba ti ń jókòó lórí ìtẹ́ ni tálákà kò lè jókòó lórí àga, ọlọ́gọ́rùn-ún àpò ń káàkiri inú ayé bẹ́ẹ̀ ni ẹni ti kò rí tọ́rọ́ jẹun náà ń rìn kiri, àkókò tí àwọn ẹlòmíràn bá ń jó tí wọ́n ń yọ̀ ayọ̀ ńlá àwọn ẹlòmíràn a máa sọkún wọ́n á kún fún ìbánújẹ́ gidigidi.
Èyí ti wá mú kí ẹ̀rù ma ba àwọn aláṣẹ pé ó ṣeéṣe kí àìsàn nàá tàn yíká ìlú Mbandaka.
lara wọn ni adari awon obinrin  ni ẹlẹkunjẹkun,
Nupeng àti Pengassan gùnlé ìyanṣẹ́lódì Ààrẹ Mali tẹ́lẹ̀, Amadou Toumani Toure jáde láyé Làásìgbò ọ̀tun súyọ nínú ẹgbẹ́ òṣèlú APC Afurasí afipábánilópọ̀ kàgbákò, obìnrin tó jà lólè fi eyín gé nǹkan ọkùnrin rẹ̀ jábọ́ lásìkò ‘Blow Job’ Ipinlẹ Eko wa lara awọn ipinlẹ Naijiria to fi ofin gbe sisan owo yii lẹyin (Payment of Pension Law 2007) ṣugbọn awọn araalu n lọgun pe owo ti wọn n san fawọn to fi ipo silẹ naa ti pọju.
Àwọn Juu sì ní ìmọ́lẹ̀ ati inú dídùn, ayọ̀ ati ọlá.
Revolution Now: Ilé ẹjọ́ dá Omoyele Sowore padà sí àhámọ́ DSS
Adelegan wa rọ ijọba apapọ lati daabo bo àwọn nkan idibo yii ju ti tẹlẹ lọ.
Akintola tun wọle ibo gbogbogbo ọdun 1965 ṣugbọn o dije ninu eto idibo naa gẹgẹ bi adrari ẹgbẹ oṣelu tuntun Nigerian National Democratic Party (NNDP).
Ṣugbọn angẹli OLUWA pè é láti òkè ọ̀run, ó ní, “Abrahamu!
 lẹ ́ yìn ọ ̀ pọ ̀ lọpọ ̀ oṣù , ó na pápá bora .
Nígbà tí ó di ogún ọdún tí Jeroboamu ti jọba Israẹli ni Asa gorí oyè ní ilẹ̀ Juda.
Àyà mi já púpọ̀ nítorí igbe yìí nítorí igbe yìí nítorí mò ń bẹ̀rù kí ó má baà jẹ́ iwin burúkú tí òkìkí rẹ̀ ti kàn jákè jádò óde aayé tí à ń pè ní Ẹlẹ́gbára.
Pẹlu ìmọ̀ ni eniyan fi í kóoniruuru nǹkan ìní dáradáraolówó iyebíyekún àwọn yàrá rẹ̀
Nigba mii, obi le ma tete ri apẹrẹ aisan yii lara ọmọ ti wọn ba ṣẹṣẹ bi titi yoo fi pe oṣu mẹfa tabi ọdun kan ti ọmọ naa ba bẹrẹ si ni ṣe aisan ati to n padanu ẹjẹ.
 wọn fún Ọ ̀ rúnmìlà ní ẹ ̀ bùn ki wọn ó to fí ilé rẹ ̀ ṣílẹ ̀ .
Ìdílé kọ̀ọ̀kan ló ní orò- ilé tí obìnrin tó bí ọmọ gbọ́dọ̀ ṣe láti ọjọ́ tí ó bá ti bímọ títí di ọjọ́ ìsọmọlórúkọ.
6 Billion) gẹgẹ bi owona fun iṣẹ akanṣe nigba ti
Wọ́n bá mú Mose ati Aaroni pada tọ Farao lọ.
Ohun ti ikede nnkan ko fararọ yoo bi nidii iwa ifipa bani lopọ: Awọn ile asofin ipinlẹ yoo ṣe ofin to gbopọn tako iwa ifipa bani lopọ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ẹ yé fipá bá obìnrin lòpọ̀ mọ́, ìbálòpọ̀ kìí ṣe dandan - Afẹ̀hónúhàn O ṣee ṣe ki ijiya to le gidi bii ẹwọn gbere ati iku fidi mulẹ lori iwa ifipa bani lopọ Ijọba yoo bẹrẹ si gbe owona kalẹ fun amulo Ileesẹ to wa fun ọrọ awọn obinrin ati awọn ọlọpaa, ki wọn le gbogun ti iwa aidaa naa Asiko to ti ijọba yoo pese awọn irinsẹ ati imọ ẹ̀rọ igbalode lati gbogun ti iwa kotọ naa Abacha àtàwọn ọba àlàyé ló jọ pinnu láti kó owó pamọ́ sókè òkun - Al Mustafa Èèyàn 681 ló lùgbàdì àrùn Coronavirus ní Naijiria ní Ọjọ́bọ̀ Bí Gómìnà Makinde bá ṣẹ̀ mí, lẹ́tà lásán ló jẹ mí- Aláàfin Ọ̀yọ́ Fọ́ọ̀mù ìgbanisíṣẹ́ ikọ̀ Amotekun ti jáde - Ìjọba ìpínlẹ̀ Ondo Onimọ nipa ofin naa wa daba pe ijiya to yẹ ko kere julọ ta le fun ẹni to ba fipa bani lopọ ni ẹwọn gbere, pẹlu afikun wọn wọn tun lee ṣe idajọ iku fun onitọun.
Ona ile iwe naa nibi ti o ti pade ọmọbinrin miran, Miché Solomon to sẹsẹ wọ ile iwe wọn.
Máa ṣe ohun rere, o óo sì gba ìyìn láti ọ̀dọ̀ àwọn aṣòfin.
“Ẹnikẹ́ni ninu yín kò gbọdọ̀ tọ ìbátan rẹ̀ lọ láti bá a lòpọ̀.
10 Rántí pé láì sí ìgbàgbọ́ ìwọ kò lè ṣe ohunkóhun, nítorínáà bèerè pẹ̀lú ìgbàgbọ́.
Nítorí o óo tàn kálẹ̀, sí apá ọ̀tún ati apá òsì,àwọn ọmọ rẹ yóo gba ìtẹ́ àwọn orílẹ̀-èdè,wọn óo sì máa gbé àwọn ìlú tí ó ti di ahoro.
Gomina Abubakar sọ pe igbimọ naa yoo ronu lori owo iye owo epo bentiroolu pẹru irisi awọn orilẹ-ede ti o wa lagbegbe orilẹede Naijiria.
 Ó tó gẹ́, Atikulated àti àwọn àṣà ìpolongo tó gbòde lásìkò ìbò 2019 ""Àwa Mọ́gàjí ilẹ̀ Ibadan kò dásí ọ̀rọ̀ òṣèlú"" Ṣáájú ìdìbò Sátidé nípínlẹ̀ Ọyọ, ọwọ́ ọlọ́pàá tẹ àwọn afurasí pẹ̀lú ìbọn Kí ló mú àwọn obìririn meji yìí pa bàbá wọ́n?"
Lara awọn olugbe agbegbe naa to ba awọn akọroyin sọrọ ṣalaye ohun toju wọn ri nigba ti wọn ṣi daamu naa lọdun 2019.
Adájọ́ ti sún ìgbẹ́jọ́ náà sí ọjọ́ kẹjọ oṣù kẹfà, ní dédé aago mẹ́wàá ààbọ̀ òwúrò.
àwọn obinrin gbọdọ̀ panumọ́ ninu ìjọ.
Àwọn arọmọdọmọ rẹ̀ yóo jẹ́ alágbára láyé,a óo sì bukun ìran ẹni tí ó dúró ṣinṣin.
Idi ni pe akọni onkọwe naa kọ iwe kan to pe akọle rẹ ni Igbo Olodumare, ti ọpọ eeyan si maa n ro pe arosọ lasan ni iwe naa.
Wọn ni pe ẹṣẹ ti wọn ṣẹ ni iroyin kan lori ọga ọlọpaa Naijiria, Ibrahim Idris ti ko tẹ awọn ọlọpaa lọrun.
Ọọ̀ni Ilé Ifẹ̀ gbàlejò àwọn èwé sí ìdùnnú àwọn ọ̀dọ́ 'À ń bẹ Ààrẹ Buhari kó pèsè ààbò fún àwa ọ̀dọ́bìnrin' Mọ́ngòrò nìkan ni wọ́n fún mi jẹ ní àhámọ́ ajínigbé -Olùdarí eré Kannywood Ẹ̀gbẹ́ òṣìṣẹ́ ní ìpínlẹ̀ Oyo so ìyanṣẹ́lódì rọ̀!
Àkọlé àwòrán, Caracas, Venezuela Ninu oṣu karun un ọdun 2018, awọn ẹlẹwọn El Helicoide fi ẹhonu han lori ohun ti wọn n la kọja.
Wọ́n ń sọ̀rọ̀ èké, wọ́n ń woṣẹ́ irọ́, wọ́n ń wí pé, ‘OLUWA wí báyìí.
N óo fọn yín ká bí ìyàngbòtí afẹ́fẹ́ láti inú aṣálẹ̀ ń fẹ́ kiri.
Amọ, Amofin agba ni Naijiria ti ni ko ba ofin mu lati jẹ ki awọn ọmọ Naijiria ti kii ṣe ẹṣọ alaabo lati gbe ibọn.
Nígbà tí ọkàn mi rẹ̀wẹ̀sì,ó mọ ọ̀nà tí mo lè gbà.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Kubrat Pulev: Ajẹ̀sẹ́ pàdánù ìwé ìdíje nílùu California nítoríi fífẹnu ko ẹnu akọ̀ròyìn obìnrin 30 Ẹrẹ̀nà 2019 Oríṣun àwòrán, Jennifer Ravalo Àkọlé àwòrán, Aworan bi Pulev ti ṣe fẹnuko ẹnu Jennifer Awọn eleto ẹṣẹ kikan nilu California ti ni ki gbajugbaja ajẹsẹ ọmọ orileede Bulgaria, Kubrat Pulev, lọ rọọkun nile nitori pe o fi ipa fẹnu ko akọrọyin obinrin kan lasiko ifọrọwanilẹnuwo.
”Pagano, ti o dari iko awon oga agba mewaa , ti won soju fun orile ede mẹ́tàléláàdọ́rùn ún lagbaaye, so pe iko naa ti ri awon ise akanse ti banki agbaye lorile ede Naijiria ati pe won ti tun ba awon ti o je anfaaani ohun soro.
Ọdun 1312 yii lo fipo naa silẹ, to si gbera lọ si oke okun pẹlu ẹgbẹrun meji ọkọ oju omi ati ẹgbẹẹgbẹrun ọkunrin ati obinrin ti wọn ko si pada wale mọ.
Ojú olè rèé, Ọwọ́ tún tẹ lára olè Ọffa Ramadan 2018: Wákàtí àwẹ̀ káàkiri àgbáyé Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí kan sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
Ọgbẹni Adeleke Isiaka, ti o jẹ aṣoju ajọ panapana ipinlẹ Ọyọ fi ẹsun kan wi pe, awọn alaigbọran kan to sare lati gbọn epo bentiro to n jo danu pẹlu oniruuru ohun elo ipọnmi, lo ṣokunfa iṣẹlẹ naa.
Mo rò pé láti ìgbà tí ẹ tí n ka ìwé yìí, ẹ kò ní ṣàì máa fa ọgbọ́n jáde fún ara yín.
Ambọde: Kò sí ìjà láàrin èmi àti Tinubu Ìpàdé ìtagbangba ní Ọṣun, ṣẹ́ ti fi orúkọ sílẹ̀ ?
ìròyìn ní obìrin ní àwọn agbésùmọ̀mí mẹ́fà tó siṣẹ́ ọ̀hún bótilẹ̀ jẹ́ pe àwọn Boko Haram kò tí jáde wá pe àwọn ní àwọn ṣe ìkọ́lù ọ̀hún.
Ti eyi ba n waye lera lera o le ṣakoba fún ara wa.
o fi mo awon oro ibaje lasiko idibo, eleyi ti o si n waye lojuna ati so alafia
 Àwọn tí ó lọ ṣe àtìpó ní pàtàkì ní ilẹ ̀ faransé náà máa ń sọ èdè yìí .
Iroyin ni ọjọ ti pẹ ti awọn agbebọn ọhun to ṣeṣe ko jẹ darandaran n kọju ija si awọn agbẹ nitori ilẹ ati omi lagbegbe naa.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 2020: Oloye Awurela Ifaleke ti wúré ọdún ìgbéga fún kóówá Ààrẹ Buhari wa tọka si àwọn ètò amayédẹrun ti yóò gùnlé lọ́dun 2020 láti koju gbogbo kùdiẹ-kudiẹ̀ to n ba orilẹ̀-èdè Naijiria fínra.
Iroyin to n tẹ wa lọwọ sọ pe Eyitayo Jẹgẹdẹ to maa dije dupo gomina Ondo labẹ asia ẹgbẹ oṣelu PDP naa ko ni pẹ kede igbakeji tirẹ naa.
Irufẹ ọrọ yii kan naa ni ọga ajọ to n moju to ọrọ ọlọpaa ni Naijiria, Ikechukwu Ani kesi wọn lati pada si ẹnu iṣẹ wọn kiakia tabi ki wọn gba iwe idaduro.
Peteru bá bẹ̀rẹ̀ sí ṣépè, ó bá ń búra pé, “N kò mọ ọkunrin tí ẹ̀ ń sọ̀rọ̀ rẹ̀ yìí.
gbogbo omo bibi ati olugbe Ipinle Oyo lapapo.
’ rèé Kọmiṣana ọlọpaa ipinlẹ Bayelsa ni atoun ati ikọ amuṣẹya awọn ti ṣe ibẹwo si ibi ti iṣẹlẹ naa ti waye ati pe ile iṣẹ awọn pẹlu ajọṣep awọn mii tọrọ kan nipa aabo ti kan lu agbami wiwa awọn agbenipa yii ati lati doola iya ti wọn ji gbe.
N óo sọ orúkọ mímọ́ mi di mímọ̀ láàrin àwọn eniyan mi àwọn ọmọ Israẹli, n kò ní jẹ́ kí wọ́n ba orúkọ mímọ́ mi jẹ́ mọ́, àwọn orílẹ̀-èdè yòókù yóo sì mọ̀ pé èmi OLUWA, ni Ẹni Mímọ́ Israẹli.
“Ọkunrin kán wà tí ó lówó.
”Ogbeni Okechukwu ko fara mo odun mefa ti Ohaneze gbero fun ijoba orile ede Niajiria o ni”ti awon to wa lori aleefa ba mo pe  leyin odun merin ,awon oludibo ko ni dibo fun won mo,won yoo sa ipa won lati dun awon oludibo ninu, sugbon ti o ba je odun mefa nikan ni won yoo lo lori aleefa, iwa ibaje ti won yoo hu yoo po, a tun wa je ki iwa bi o –ba -ki -o -pa,bi -o–ba- ki- o- bu-lese waye.
Wọn dẹgun le iyanṣẹlodi naa lati fi ẹhonu han lori ikuna ijọba lati mu adehun ṣẹ.
 a sì máa ń ló àwọn èròjà bi ọ ̀ rọ ̀ , ìṣesí , orin , ijọ ́ àti ìwòran papọ ̀ mọ ́ eré ìtàgé sínú tíátà .
Ìjọba tó wà lóde yìí kò ní ìfẹ́ aráàlú la ṣe dá ẹgbẹ́ NCF sílẹ̀ - Femi Falana Adesoji Aderemi, Ọọ̀ni Ifẹ̀ àti gómìnà Adúláwọ̀ àkọ́kọ́ láyé eèbó amúnisìn Ìdí tí ìjóba ìpínlẹ̀ Eko fí ṣí àwọn ilé ìwé kan padà Èyí ni bí Hushpuppi ṣe gbìyànjú láti jí $124m lọ́wọ́ ẹgbẹ́ agbábọ́ọ́lù Premier League kan East Asia: Ẹ̀ka ẹgbẹ naa to wa ni East Asia tí ṣe ikọlu to pọ ni orilẹ-ede Philippines, ati Indonesia.
Àkọlé àwòrán, Lavona Solomon nile lẹyin to ni oun bimọ tuntun Ọdun 2016 ni wọn ran Lavona lọ si ẹwọn ọdun mẹwaa fun ẹsun ijinigbe ati aibọwọ fofin to tẹ itọju ọmọ kekere mọlẹ.
O dije dupo gomina fun ipinlẹ Ogun labẹ asia PDP lọdun 2019 ko to padanu ti Dapọ Abiodun ti APC si wọle gẹgẹ bii gomina ipinlẹ Ogun.
Ile ẹkọ alakọbẹrẹ Methodist to wa ni adugbo Ijokoo nilu Abẹokuta lo lọ, ko to bẹrẹ owo sise.
Abilekọ Racheal ni, aisan ọpọlọ ni ki eniyan o maa gbonara nigba ti o ba ni ija pẹlu alabagbe rẹ.
Ọpọ̀ èèyàn ní kó mọ pẹ pápákọ̀ ofurufú ń bẹ nílùú Ibadan- Òṣìṣẹ́ Òwò ẹrú pé irinwó ọdún tó bẹ̀rẹ̀, àwọn Amẹrika tó jẹ́ dúdú wá sí Afirika láti bẹ ilé wò Àkúntúnkú, ìgbà márùn ún rè é tí Shekau kú tí wọ́n ní kò kú mọ Ó sọ pé lẹ́yìn ìgbà tí òun wọ inú ẹgbẹ́ náà, òun rò pé òun ń ṣe gbogbo nǹkan fún ẹ̀sìn Islam ni, kí òtítọ́ tó wá padà yéè.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Kini Yorùbá ń pe Necklace?
A ko gbe iṣuna kalẹ fun un, a ko si ni ohunkohun un ṣe pẹlu rẹ.
Àmì tí ẹ óo fi mọ̀ ọ́n nìyí: ẹ óo rí ọmọ-ọwọ́ náà tí wọ́n fi ọ̀já wé, tí wọ́n tẹ́ sí ibùjẹ ẹran.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Covid-19 pa Ọlọ́lá Akin Olugbade, ẹ wo dúkìá jaburata tó fisílẹ̀ Ikọ̀ Àmọ̀tẹ́kùn ṣèsì yìnbọn pa akẹ́kọ̀ọ́ nílùú Ibadan NCDC àti NYSC bẹ̀rẹ̀ ìpàdé lórí ṣíṣí ìpàgọ́ àwọn àgùnbánirọ̀ Ìjọba ìpińlẹ̀ Kwara dá owó tí àwọn obìrin 25 fi kọ́ ilé Ẹ̀kọ́ fún àwọn ọmọ wọ́n pada Ìjọba àpapọ̀ pàṣẹ kí ilé-ẹ̀kọ́ wọlé ní ọjọ́ 18, oṣù kíní ọdún.
 Ọba Ìjẹ ̀ bú-jẹ ̀ ṣà ni ẹ ̀ gbọ ́ n tí Ọwá sì jẹ ́ àbúrò .
Bi Huawei ba fi le sagbatẹru imọ 5G yi,awọn akẹgbẹ orileede China ni anfaani re e fun China lati ma tọpinpin gbogbo atẹjiṣẹ awọn eeyan lori ẹrọ alatagba.
O ni ere kolekole bii adigunjale loun fi bẹrẹ ere Tiata ṣugbọn lọjọ ti o yẹ ki oun kopa ninu ere Saheed Balogun kan to yẹ ki oun ti kopa gẹgẹ bii adigunjale ni ọkan lara awọn aṣaraloge ba ni awọn ti wọn koun tunraṣe fun ti pe.
"Oju opo ""Whatssap Status"" lasan ni Omotara ni oun fi si to si ni to ba wu oun, oun gan le fi si orii Twitter amọ kii ṣe pe oun fẹ fi ṣe nkan ibi kankan."
Ṣebí ara kan náà ati ẹ̀jẹ̀ kan náà ni Ọlọrun ṣe ìwọ pẹlu rẹ̀?
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Sunday Igboho kàn ń gbé ‘Camera’ lẹ́yìn kiri, kí wọ̀n lè rò pé ó ń jà fún Yorùbá - Gani Adams Aṣọ́bodè ṣèèsì pa ‘Panel Beater, aya mẹ́rin àti ọmọ 18 ń bẹ̀bẹ̀ fún ìrànwọ́ ₦750m ni Akeredolu ń gbà lóṣù fún ‘Security Vote’ àti ₦150m owó oṣù - Agboola Ajayi fèsì INEC kéde agbègbè ẹsẹ̀ odò 270 ti èrú ìbò ti le wáyé ní ìpínlẹ̀ Ondo Ẹgbẹ́ tó ń fẹ́ Oduduwa Republic kọ̀wé ẹ̀hónú sí UN, EU, AU àti ìjọba Gẹ̀ẹ́sì Àjọ EFCC ti mú ọ̀dọ́kùnrin mẹ́wàá lórí ẹ̀sùn jìbìtì lílù lórí ayélujára ní Oyo Kíni ó lè mú kí ọmọbìnrin sá kúrò nílé láti ìpínlẹ̀ Plateau lọ sí Ekiti?
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Owó tí Àbáchà jí: Wo ohun tí ó lè ṣe fún ará ìlú 13 Ìgbé 2018 Oríṣun àwòrán, AFP Àkọlé àwòrán, Ijọba orileede Switzerland ti da ẹ̀ẹ́dẹ̀gbẹ̀rin milionu dollar pada ninu owo naa laarin odun mewa seyin.
 báyìí ni awon elégbe rè se ge orúko kéré di ' kútò tí ó sì wà dòní yìí.
Amọṣa gomina Yahaya Bello ti ṣalaye pe oun gẹgẹ bi alaga igbimọ ibo abẹle naa ko laṣẹ lati sun un siwaju.
 Maa lo iriri mi gege bii oga ile ise idagbasoke irin ajo afe fun idagbasoke ipinle yii.
Ọpọlọpọ idari latọdọ awọn alaṣẹ ni yoo maa wa lati ṣe ilanilọyẹ ati idanilẹkọọ to ni ṣe pẹlu ẹtọ ọmọniyan fun awọn ọlọpaa.
Femi Adesina: Bí àwọn ọmọ Nàìjíríà bá f'ara balẹ̀ wọ́n ó rí iṣẹ́ ribiribi tí Buhari ti ṣè
O ni odun mẹẹdọgbọn ni òun fi kọ iṣẹ́ tíátà lọdọ oga òun, Oyin Adejobi, àmọ́ ilé ẹ̀kọ́ alakọbẹrẹ ni òun ti ní ìfẹ́ sì ère tíátà nígbà tí olóògbé Adejobi máa ń wà ṣe ère nílé ẹ̀kọ́ òun.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ìrántí Moji Ọlaìyá lẹ́yìn ọdún kan Àkójọpọ̀ fọ́tò ìsìnku Aisha Abimbola Mo ti fọ́ bàbá mi, Ọ̀gá Bello létí rí - Fẹmi Adebayọ̀ BBC ṣèfilọ́lẹ̀ àmì ẹ̀yẹ 2019 Komla Dumor Award Èyí ni ipa t'àwọn bàbá ìsàlẹ̀ ń ní nínú ètò ìdìbò #BBCNigeria2019 Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Wọn ko ni nkan ṣe fún ipinlẹ Ọyọ ni' #BBCGovDebate Molebi arabinrin naa, Adebisi Ogunsola lo fi isẹlẹ naa lede loju opo ikansiraẹni Facebook rẹ.
Pẹlu gbogbo agbára tí ẹ ní, n óo tẹ̀ yín lórí ba; òjò yóo kọ̀, kò ní rọ̀, ilẹ̀ yóo sì le bí àpáta.
tí ó sì pàṣẹ fún un nítorí ọ̀rọ̀ yìí pé kò gbọdọ̀ bọ oriṣa.
Eyi ko sẹyin bi ile ẹjọ́ se wọ́gilé ìbò tó gbé Ikengboju Gboluga tó ń sojú ẹkùn ìdìbò Okitipupa/Irele nítorí ó jẹ́ ọmọ orílẹ̀èdè méjì, ti wọn si gbe e fun Albert Akintoye to ṣe ipo keji ninu eto idibo ọdun 2019.
” Jakọbu dáhùn, ó ní, “Mo ní kí n fi wọ́n wá ojurere Esau, oluwa mi ni.
11 Nítorínáà ohùn Olúwa nkọ sí awọn ìpẹ̀kun ilẹ̀ ayé, pé kí gbogbo àwọn tí ó bá fẹ́ gbọ́ lè gbọ́:
Adari ile isẹ BBC lapa iwọ-oorun Afirika, Toyọsi Ogunṣẹyẹ, rọ awọn ọdọ lati maa kopa ninu ṣiṣe ipinnu l'orilẹede Naijiria nipa lilọwọ si ohun to n ṣẹlẹ layika wọn.
“Gèlè ò dùn bi ká mọ̀ ọ́ wé, ká mọ̀ ọ́ wé, kò tó kó yẹni”: 
Wilder oun ko lanfaani lati ṣe igbaradi kankan bayii nitori oun ni lati ṣe iṣẹ abẹ nitori ipalara ti oun ni lori iṣan ọwọ oun nigba ti o koju Fury.
1969 Wọn ju s'ẹwọn, o si lo ẹẹdẹgbẹta ọjọ din mẹsan latimọle.
(Àwọn kan ń já àwọn ọmọ aláìníbaba gbà lẹ́nu ọmú,wọ́n sì ń gba ọmọ ọwọ́ lọ́wọ́ àwọn aláìní gẹ́gẹ́ bí ohun ìdógò.
Àwọn tí ń yọ̀, ẹ bá wọn yọ̀, àwọn tí ń sunkún, ẹ bá wọn sunkún.
Èmi OLUWA Ọlọrun ti fojú sí orílẹ̀-èdè tí ń dẹ́ṣẹ̀ lára, n óo sì pa á run lórí ilẹ̀ ayé; ṣugbọn, n kò ní run gbogbo ìran Jakọbu.
Lori oun to mu ki Alaafin wu lati fi ṣe ọkọ, Olori ni ọlọgbọn ni baba, ọba to yatọ ni, to si tun jẹ ẹni to fẹran iwe kika.
Ganduje koro oju si bi awọn Fulani ti n ṣi kiri lati apa ariwa Naijiria lọ si apa aarin gbungbun ati Guusu Naijiria.
Lara ohun ti ẹgbẹ awọn dokita nipinlẹ Ondo si mẹnuba ti wọn fi n yan isẹ lodi naa ni pe titi di akoko yii, wọn ko tii fi ẹnu ọrọ jona lori owo osu to kere julọ ati atunse rẹ, eyi tawọn ti kii se dokita nile iwosan ti n jẹ anfaani rẹ.
Ati àwọn wolii tí wọ́n ti kú?
Ìyàlẹ́nu ni ó jẹ́ fún mi ní alẹ́ àná nígbà tí wọ́n wí fún mi pé ìwọ ní ki n wa fi ojú gán-án ní rẹ, nítorí láìṣee àníàní, àti ajá àti ẹran ní ilẹ̀ yìí ni ó ti mọ̀ pé èmi kò ní nǹkan ṣe pọ̀ pẹ̀lú ilé Òmùgọ́parapọ̀ mọ́, ewúrẹ́ ilé ibẹ̀ kò gbọdọ̀ dé sàkání mi.
Bakan naa ni wọn ni gbogbo mọlẹbi to ba fẹ sinku ti gbọdọ nii lọkan pe awọn yoo ṣe inawo rira eroja apapkokoro sanitaisa (Sanitizer) eyi to gbọdọ wa ni ibi ti wọn ti fẹ sinku bẹẹni wọn gbọdọ rii pe awọn to ba wa nibẹ tẹle ofin ijinasiraẹni.
Àwọn ọmọ Naijiria fèsì sí Osinbajo tó ṣetán láti wàákò pẹ̀lú Timi Frank À ń dúró de ìwé ìrìnnà Sowore kí a tó fisílẹ̀ - DSS O tẹsiwaju pe, wọn ba oku ọkunrin naa ni ori ibusun ile itura naa ti ko si ẹni to mọ iru iku ti o pa lati ọwọ obinrin naa.
Ẹ jọwọ ẹ wọrọ miran sọ.
" Bakan naa ni eto igbani wọle miran tun gbọdọ bẹrẹ ni ọjọ kẹjọ, oṣu Kọkanla, nitori awọn ti yoo ṣe idanwo NABTEB.
Ṣugbọn Peteru sẹ́, ó ní, “Èmi kò mọ̀.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ekiti election appeal: Ilé ẹjọ́ kòtẹ́milọ́rùn dá Fayẹmi láàre lórí ẹjọ́ Ẹlẹka 29 Ẹrẹ̀nà 2019 Oríṣun àwòrán, @ekitistategov Àkọlé àwòrán, Ẹlẹka pe ẹjọ kotẹmilọrun lẹyin to fi idi rẹmi ni ile ẹjọ akọkọ ni oṣu kini ọdun 2019 Ile ẹjọ to n gbọ ẹjọ kotẹmilọrun ti gbe idajọ kalẹ pe Kayọde Fayẹmi gan an ni oludije ti ilu fi ibo yan sipo gomina ni ipinlẹ Ekiti.
Ibi ti iṣẹlẹ naa ti waye Awọn ibi ti ibugbamu naa palara bẹrẹ lati agbegbe Adegbola Olujobi, titi de opopona Otunba Gani Adams ni Abule-Ado.
0 12588 Orilẹede Equatorial Guinea 85 6.
Abass Akande: Obesere lóun ló kàn lẹ́yìn olóògbé Barrister àti Kollington nínú iṣẹ́ orin Fuji
Diẹ ni odiwọn nọmba to fi bori alatako rẹ ninu idibo to gbe Morsi wọle.
O ni oun o gbe lẹyin ẹnikan o tori iru ọrọ bayii loot a maa da ọgbẹ si ni lọkan ṣugbọn t'oun ti n ri iwosan.
4 Nítorí, kíyèsíi, oko ti funfun nísisìyí fún ìkórè; àti wòó, ẹnití ó bá sì fi dòjé rẹ̀ pẹ̀lú ipá rẹ̀, òun náà ni ó kórè sínú àká kí òun má baà ṣègbé, ṣùgbọ́n kí ó mú ìgbàlà wá fún ẹ̀mí rẹ̀;
Awọn eeyan oja naa ni awọn n rii gegebi ọkan lara awọn to n ba wọn ko agbo ninu ọja naa.
OLUWA ni ó sì pàṣẹ fún angẹli kan tí ó sọ fún mi pé kí n mú ọ lọ sí ilé, kí n sì fún ọ ní oúnjẹ ati omi.
Ọmọ ọdun meje si mẹrindinlogun ní àwọn ọmọ to wa ninu ọkọ náà gẹgẹ bii ọga agba ile-iwe náá, Ab el-Khayr Adam Yunis, ṣe sọ fun BBC àti pe ẹru lo ba awọn ọmọ náà nigba ti ẹngini sọsẹ silẹ ti gbogbo wọn si wọ jọ soju kan èyi to faa ti ọkọ oju omi náà fi doju de.
 Awọn agbabọọlu miran to n gbe l'orilẹ-ede Turkey bi i Radamel Falcao ati Didier Drogba f'esi si ọrọ naa pe bẹ ẹ gan lo ṣe yẹ ko ri."
Àwọn alufaa kò pọ̀ tó láti pa gbogbo ẹran náà, nítorí náà, kí ó tó di pé àwọn alufaa mìíràn yóo ya ara wọn sí mímọ́, àwọn arakunrin wọn, àwọn ọmọ Lefi, ràn wọ́n lọ́wọ́ títí iṣẹ́ náà fi parí.
Má ṣe dàbí ẹṣin tabi ìbaaka,tí kò ni ọgbọ́n ninu,tí a gbọdọ̀ kó ìjánu sí lẹ́nukí ó tó lè gbọ́ ti oluwa rẹ̀.
Ó pamọ́ lójú gbogbo ẹ̀dá alààyè,ati lójú àwọn ẹyẹ ojú ọ̀run.
wọ ́ n mú àkọ ́ lé lati ovid .
Oríṣun àwòrán, Nigeria Airforce Àkọlé àwòrán, Awọn eeyan ilu Dapchi fi ijo atayọ pade awọn akẹkọ naa Ayọ ati inu didun lawọn araalu Dapchi, paapaa julọ awọn obi awọn ọmọ naa, fi pade wọn.
Ilu Iwo ló yẹ kó kọ́kọ́ gba Sultan àkọ́kọ́ ní Nàìjíríà.
Bakan naa ni o so pe, ERGP ti erongba re da lori ibi ayewo, eyi ti Aare Buhari yoo fi lole lojo-Isegun lose to n bo, eyi ti o je ona kan gboogi ti ijoba fe fi se amulo naa.
Akole Awọn ere ti Baba Sala se nigba aye rẹ Orun Mooru (1982) Aare Agbaye (1983) Mosebolatan (1985) Obee Gbona (1989) Diamond (1990 Home video ) Agba Man (1992, Home Video) Return Match (1993, Home Video) Ana Gomina (1996, home video, ) Tokunbo (1985, TV) Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Orúkọ àwọn ọmọ Israẹli tí wọ́n bá Jakọbu wá sí Ijipti nìwọ̀nyí, olukuluku pẹlu ìdílé rẹ̀: 
gbogbo omo orile ede Naijiria ni gbogbo ipinle kaakiri orile ede ati olu ilu
Lara awọn to fara kasa ibinu erin naa ni baba ẹni ọdun mejidinlọgọta kan ati ọmọ rẹ ọkunrin.
Saaju ko to di pe Muhammadu Buhari, tii se ọkọ rẹ di aarẹ, ni Aisha Buhari ninu ifọrọwero kan pẹlu ile iṣẹ Iroyin TVC lọdun 2015 sọ pe, oun gbagbọ pe iyawo aarẹ ologun nigba kan ri, Mariam Babangida lo fi ipo First Lady lọlẹ.
"O ni eyi ko ṣẹyin bi ""awọn eeyan ilẹ Yoruba ni awọn ko fẹwọn"" Ọrọ yii ti da oniruuru ọrọ silẹ laarin awọn olugbe ipinlẹ Ọyọ ati ilẹ Yoruba lapapọ."
Ẹwẹ nigba ti ile iṣẹ BBC kan si minisita atawọn mii tọrọ kan lati gbọ tẹnu wọn, pabo lo ja si.
Mé loòó la ó kà lẹ́hín Adépèlé ni ọ̀rọ̀ wọn.
Díẹ̀ lára àwọn orin tó tí gbóríyìn fún àwọn ọmọ yahoo, àti okòwò wọn ni yìí: Orin ‘Yahoozee’ tí Olu Maintain kọ Oríṣun àwòrán, Olu Maintain/Instagram Àkọlé àwòrán, Orin Yahoozee gbaju-gbaja púpọ̀ láàárín àwọn ọ̀dọ́ Ọdún 2008 ni Olu Maintain gbé orin ọhun, tó pè ní 'Yahoozee' jáde.
Bi awọn alatilẹyin Obaseki ṣe n rapala wọ afin ọba naa ni awọn alatilẹyin Osagie Ize-Iyamu na n bu wọn.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 2020: Oloye Awurela Ifaleke ti wúré ọdún ìgbéga fún kóówá Oríṣun àwòrán, Kunle Afolayan Àkọlé àwòrán, Kunle Afolayan KunleAfọlayan.
 “Gege bi obi, mo je alaba-pin ninu ibanuje ati ekun okan awon obi awon omobinrin yii, mo lero pe akitiyan ijoba lori wiwa awon omo naa yoo yori sir ere”.
Ó rúbọ, ó sun turari ní àwọn ibi ìrúbọ, ati lórí òkè káàkiri ati lábẹ́ gbogbo igi tútù.
Agbaboolu iko Manchester City, omo orile-ede Ivory Coast, Yaya Toure ti pinnu lati pada sinu iko agbaboolu orile-ede re, leyin isinmi odun meta ti o ti kopa fun iko ohun ti o waye ninu ifesewonse olorejore pelu orile-ede France.
Praise ni oludasilẹ Girls Arise Initiative.
Kó má di ọ̀rọ̀ ọmọ ejò - Olu Falae Kazeem Tiamiyu: Mo fọṣọ, fọ ilẹ̀, ta omi tútù láti fi tọ Kazeem àtàwọn tó kù - Òbí Kazeem Alaga ajọ NAHCON naa ni o le ni aadọta ọmọ Naijiria to wa ni Saudi lọwọlọwọ,ati wi pe ijọba ko le wọn kuro nilẹ naa nitori wọn ṣe ayẹwo fun wọn , ti wọn si mọ wi pe ko si aarun naa ni Naijiria.
‘Ṣe é mi, ṣe é mi wàyí ṣá!
 funfun ni àwọ ̀ rẹ ̀ , sùgbọ ́ n ó sábà ní ìdọ ̀ tí triklorídì irin tó únsọ àwọ ̀ rẹ ̀ di pípọ ́ n .
Gbọ̀ngàn kan yí ìloro ẹnu ọ̀nà ká 
Ẹgbẹ agbabọọlu mẹrindinlogun ni yoo kopa fun igba akọkọ.
Wọ́n bá fà á sinu ọkọ̀ ńlá, wọ́n wá fi okùn so ó mọ́ ara ọkọ̀ ńlá.
Temilola OmoobaJesu ati Kehinde Taiwo ṣaa dede ri i ti awọ ara wọn bẹrẹ si ni yi pada lọjọ kan.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Diego Maradona lọ̀!
Nígbà tí Hadadi kú, Samila ti Masireka gorí oyè.
Àwọn ọmọ Juda tí ó bá ṣẹ́kù yóo fi gbòǹgbò múlẹ̀, wọn óo sì so èso.
Adeyẹmọ, ti gbogbo eeyan mọ si Willy, jẹ ẹni ọdun mẹrinlelọgbọn, oun si ni yoo maa se akoso ojuse ati isọwọ sisẹ ajọ naa lati igba de igba, ti yoo si maa ri si amusẹ awọn afojusun ajọ ọhun.
Irori Buhari ati Aisha ko papọ lọpọ igba Ọrọ ti Aisha Buhari sọ yii kọ ni yoo jẹ igba akọkọ, ti ọrọ rẹ ati ti ọkọ rẹ yoo ma a tase ara wọn.
Pupọ ninu awọn ọmọ orilẹede Naijiria lo lọgun sita ti wọn si koro oju si awọn ipinlẹ bii Akwa Ibom, Kwara, Rivers ati ipinlẹ Eko lori igbesọ yii.
O ni ni ile iwosan nla Adeoyo ko sí ẹrọ amunawa to dara.
 a sọ èrèdí iṣẹ ́ yìí , ọgbọ ́ n ìwádìí tí a lò àti àyẹ ̀ wò iṣẹ ́ tí ó wà nílẹ ̀ .
” Gege bi Totti se so lasiko iforowanilenuwo
O óo jẹ́ ẹni ìyàsọ́tọ̀ fún OLUWA Ọlọrun rẹ, gẹ́gẹ́ bí ó ti ṣèlérí.
Mo dìde, mo ṣílẹ̀kùn fún olùfẹ́ mi,gbogbo ọwọ́ mi kún fún òjíá,òróró òjíá sì ń kán ní ìka misára kọ́kọ́rọ́ ìlẹ̀kùn.
Omowe Abdulmumeen Yinka Ajia lo n dije dupo gomina nipinlẹ Kwara labẹ ẹgbẹ oṣelu Abundant Nigeria Renewal Party.
Abiola Ajimobi: Bàbá mi jẹ́ aránsọ, ìyá mi sì jẹ́ ọlọ́jà wóróbo
Láti ọjọ́ náà wá ni àyípadà rere ti dé bá ọkùnrin yìí tí ó di olówó tí òkìkí rẹ̀ sì gba gbogbo àgbègbè kankan.
”Kí àwọn tí ó kórìíra mi má baà yọ̀ bí mo bá ṣubú.
Ìṣesíi wọ́n múni rántí ọ̀rọ̀ kan nínú Bíbélì tó wípé “Ẹ̀mi ni olùṣọ́ àgùntàn rẹ, ìwọ kì yíò ṣe aláìní”.
Sunday Igboho, lasiko to n ba BBC Yoruba sọrọ salaye pe, lootọ ni oun lọ si adugbo Soka lana lati gba awọn eeyan adugbo naa silẹ lọwọ ijẹgaba awọn ọmọ onilẹ.
Oríṣun àwòrán, Durham Police Àkọlé àwòrán, Inu ọkọ Range Rover yii ni wọn ni o ti fẹ ba ọmọdebinrin naa ṣe ere ifẹ Àwọn ìròyìn mìíràn tí ẹ lè nífẹ̀ẹ́ sí: Super Eagles fi iyọ̀ sójú Seychelles pẹ̀lú àmì ayò 3-1 Man City pòkọ ìyà fún Swansea pẹ̀lú àmì ayò 3-2 nínu FA Cup Ilé ẹjọ́ kéde Ademọla Adeleke gẹ́gẹ́ bíi gómìnà ìpínlẹ̀ Ọṣun Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Demilade Adepegba: Mo má a ń gbàgbé fèrè ni, tí mo bá wà nílé ìwé Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Amofin Oke ni ṣaaju eto idibo naa loun ti pariwo sita pe o ni kudiẹkudiẹ ninu eleyi ti ẹnikẹni ko fi lee tọka si ọrọ oun gẹgẹ bii ẹni to n ṣawawi nigba ti oun fidirẹmi.
2359 debehogne jẹ ́ plánẹ ́ tì kékeré ní ibi ìgbàjá ástẹ ́ rọ ́ ìdì .
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù 'EFCC mo dé' àti àwọn àṣà míì táwọn olóṣèlú fi dagbo rú ní 2018 24 Ọ̀pẹ̀̀ 2018 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 25 Ọ̀pẹ̀̀ 2018 Oríṣun àwòrán, @OfficialPDPNig Àkọlé àwòrán, Niṣe ni Ayo Fayose daku gbaranganda nibi ipolongo idibo Gomina Ekiti Awọn oloṣelu Naijiria dagbo oṣelu ru daadaa lọdun 2018 Bi wọn ti ṣe sọ awọn nnkan to ṣe awọn eeyan ni kayefi, ni ọrọ wọn miran mu inu bi ara ilu ti awọn mii si n dẹrin pa wọn.
O ni ''lati ọjọ ki Gomina Makinde ti ti ọfiisi NURTW to wa ni Aduloju pa, oun atawọn ọmọlẹyin ou ko de ibẹ.
Nitori naa, ẹ fun wa ni iwe akosile ti ẹ ni nipa wọn .
Ewe, lasiko ipade ohun lojo aje(Monday), aare yoo yanyana ipinnu orile-ede Naijiria lori iyipada oju ojo lojuna ati mu awon ileri re se gege bi atileyin fun idagbasoke orile-ede.
A jẹ́ pé gbogbo àwọn agbolé ní ìlú Èkó, àti ní gbogbo Nàìjíríà lápapọ̀, kìkì epo-rọ̀bì ni.
Kòkòrò oyin sọ ọ̀pọ̀ èèyàn di aláìrílégbé, àwọn míràn tún farapa Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Yoruba Taboo: Èèwọ̀ ni fún ọba láti gbé Bibeli tabi Kurani dání dípò ifá- Elebuibon, Agẹṣin Àdìmúlà29 Bélú 2020 Obateru Akinruntan: Olugbo Obateru akinruntan ṣalaye ìdí ohun tó ń ṣẹlẹ̀ láàrín òhun àti Ooni Ile Ife30 Bélú 2020 Èyí tí a wò jùlọ 5:03 Fídíò, Omolola Arohunmolase Welder: Mo ti fí iṣẹ́ 'Welder' gbayì láwùjọ, tó mo fi tọ́ ọmọ yanjú, Duration 5,039 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 5:39 Fídíò, Akomolede ati Asa lori BBC: Olùkọ́ Kikelomo Ogunboye tan ìmọ́lẹ̀ sí ìwà olè ọ̀gá ọlọ́pàá Audu gẹ́gẹ́ bí àwòkọ́ṣe àsìkò yìí, Duration 5,398 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 4:11 Fídíò, Oba Adeyeye Ogunwusi: Ojú mi ti rí lọ́pọ̀ lọpọ̀, ọ̀pọ̀ èèyàn ni kò tilẹ̀ gbàgbọ́ pé mo lè jọba- Ooni, Duration 4,117 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 4:43 Fídíò, Promise Akinlade: ọmọ ọdún mọ́kànlá tó ń fi ìlù dárà bíi àgbàlagbà sọ̀rọ̀ nípa tálẹ́ǹtì rẹ̀, Duration 4,437 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 0:59 Gbọ́, Ìsẹ̀lẹ̀ jákèjádò orílẹ̀èdè àgbáyé láàárín ìṣẹ́jú kan, Duration 0,59wákàtí 5 sẹ́yìn 7:03 Fídíò, Olumuyiwa Bolade Adedeji Military Bruitality: Bí arákùnrin onípèníjà ara tí sọ́jà lù ṣe dé, Duration 7,035 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 4:45 Fídíò, Yoruba Films: Ẹ̀ẹ́ bẹ̀ mi kúrò láyé ni, mi ò lè kú - Fadeyi Oloro, Duration 4,4526 Èrèlè 2020 2:48 Fídíò, Esther Ajayi: Èmi náà ti borí ìṣòro rí ló ń mu mi ṣojú àánú, Duration 2,481 Ògún 2019 6:08 Fídíò, Adebola Ademilua: Àìrísẹ́ ṣè lẹ́yìn ìwé kíkà ló sọ mi dí ìyá onírú, mo dúpẹ́ tèmi, Duration 6,0827 Bélú 2020 2:36 Fídíò, Sotitobire: Ìdájọ́ òdòdò ló fẹsẹ̀ múlẹ̀ lórí ọ̀rọ̀ Pásítọ̀ Sotitobire - Agbẹjọ́rò fún ìjọba, Duration 2,367 Ọ̀wàrà 2020 BBC News, Yorùbá Ìdí tí ẹ fi le è nígbàagbọ́ nínú ìròyìn BBC Ìlànà Lílò Nípa BBC Òfin Àṣírí Cookies Kàn sí.
Kí ló dé tí o fi ń lépa èmi iranṣẹ rẹ?
tosin lawson jẹ ́ onímọ ̀ nipa oge àti olùdásílẹ ̀ ilé iṣẹ ́ tí wọ ́ n ń pè ní african design .
Nǹkankan tí ó ṣe pataki ni pé kí ẹ jẹ́ kí ìwà yín kí ó jẹ́ irú èyí tí ó bá ìyìn rere Kristi mu, tí ó jẹ́ pé bí mo bá wá tí mo ri yín, tabi bí n kò bá lè wá ṣugbọn tí mò ń gbúròó yín, kí n gbọ́ pé ẹ wà pọ̀ ninu ẹ̀mí kan ati ọkàn kan, ati pé gbogbo yín ń ṣiṣẹ́ pọ̀ pẹlu igbagbọ ninu iṣẹ́ ìyìn rere.
Ẹni tí kò jẹ gbì kò lè kú gbì, eré ọmọdé ni EFCC ń ṣe
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Wọ́n ta ère Ọ̀ṣun Osogbo sí Togo - Bàbá Ọṣun figbe ta El-Zakzaky fi India sílẹ̀, níbo ni yóò dé sí ní Nàìjíríà?
Nígbà náà ni àwọn eniyan náà dáhùn, wọ́n ní, “Kí á má rí i pé a kọ OLUWA sílẹ̀, a sì ń bọ oriṣa.
Wọ́n gbé wọn kalẹ̀ níwájú rẹ̀, ó bá wò wọ́n sàn.
Tó bá di ìgbà náà, a óo máa kọ “MÍMỌ́ SÍ OLUWA,” sí ara aago tí wọn ń so mọ́ ẹṣin lára.
”Beteṣasari dáhùn pé, “olúwa mi, kí àlá yìí ṣẹ mọ́ àwọn tí wọ́n kórìíra rẹ lára, kí ìtumọ̀ rẹ̀ sì dà lé àwọn ọ̀tá rẹ lórí.
Sotitobire church: Àwọn ọ̀dọ́ ilu dáná sun ilé ìjọsìn Sọtitobirẹ nílú Akure
Oríṣun àwòrán, Other Ọgbẹni Ọlọgbọndiyan sọ pe ni gbogbo igba ti Gomina Bello ipinlẹ Kogi ba ti ri wi pe ẹgbẹ mii fẹ fa eeyan ka lẹ lati koju òun ninu ibo lo maa n da iru eto bẹẹ ru.
Ayipada tuntun ohun ni o sun iko Super-Eagles sipo keta nile Afrika, labe iko agbaboolu orile-ede Tunisia ati Senegal.
Ìtàn Mánigbàgbé: Samuel Taiwo Oredein, àgbà òṣèlú tó fi ẹ̀wọ̀n jura lárúgbó ara
awon nnkan miiran lorile ede Naijiria.
“Nítorí o wí pé, ‘Èmi ni mo ni odò Naili, ara mi ni mo dá a fún,’ 
Bashorun Moshood Abiola , eni ti o jawe olubori ninu eto idibo aare to waye ni Ọjọ kéjìlá,osu kẹ́fà(June
Nígbà tí Ọlọrun bá dá ire àwọn eniyan rẹ̀ pada,Jakọbu yóo yọ̀, inú Israẹli yóo sì dùn.
Gbajugbaja wolii, Babatunde Alfa atawọn mẹfa kan ninu ijọ rẹ n jẹjọ lọwọ lori bi ọmọdekunrin ọmọ ọdun kan ti orukọ rẹ n jẹ Kọlawọle Gold ṣe poora ni ileejọsin naa ni oṣu kọkanla ọdun to kọja.
Ìròyin so pé láti igbà ti Yoel Romero ti n kopa nínú eré ìdaáraya abẹsẹ́ kù bi ojo, ko si ẹni to fi ojú rẹ̀ gbòlẹ̀ rìí, Sugbọ́n ní báyìí Isreal Adesanya fẹ́ tún ìtàn náà kọ.
Èyí tí ń mú kí ọpọlọ ọgbọ́n atinuda wọn láti mú ìgbádùn bá ara wọn àti ololufe wọn.
Oríṣun àwòrán, Twitter Ọpọ ọdọ ni wsn lo jalaisi lọjọ naa, tawọn miran si fara pa bi o tilẹ jẹ pe ileesẹ ologun ni oun ko yin ọta ibọn to le gbẹmi eeyan nibẹ.
Abiatari, alufaa náà wà láàrin wọn.
Lootọ ni pe jijẹ eso ati ewe, ati omi mimu lu mu ki ara o jipepe, ko ti i si ẹri pe ounjẹ kankan le gbogun ti arun yii.
” Mikali dá Saulu lóhùn pé, “Ó sọ wí pé òun yóo pa mí bí n kò bá jẹ́ kí òun sá lọ.
Iwáju iwájú ni ọ̀pá ẹ̀bìtì nré sí o!
Gomina Abia Bakan naa, gomina ipinlẹ Abia, Okezie Ikpeazu naa wa lara awọn olori ipinlẹ ti esi ayẹwo wọn fi han pe wọn ni arun Coronavirus lorilẹede Naijiria.
Ìtìjú ojọ́ náà pọ̀ jù fun ọ̀rẹ́ búburú yìí kí ó tó mọ̀ pé kùkùté igi lásán ló lọ́ mó òun láṣọ, Ìtìjú yìí ló sì mú u kúrò ní ìlú náà.
Nígbà tí ìrora bá dé, wọn yóo máa wá alaafia, ṣugbọn wọn kò ní rí i.
5 40741 Orilẹede Lebanon 1170 17.
Biden gbo ewuro soju Trump Ohun kẹta ti awọn onimọ nipa eto oṣelu Amẹrika tun sọ ni pe o ṣeṣe ki Biden bori Trump ni ọna ara ti awọn eeyan ko lero.
Akẹgbẹ rẹ, Kunle Afod, lo kede iku Satia loju opo Instagram rẹ ni ọjọ Iṣẹgun, ọjọ kọkanlelogun, oṣu Keje, ọdun 2020.
Kí á má rí i, pé àwa iranṣẹ rẹ ṣe ohun tí ó jọ bẹ́ẹ̀.
Òun ni ó dá ọkàn gbogbo wọn,tí ó sì ń mójútó gbogbo ìṣe wọn.
"Ọmọ Yahoo fẹ́ pa ìyá rẹ̀ ṣ'owó l'Eko Wo bí ọwọ́ orílẹ̀-èdè Dubai ṣe tẹ Ramoni Igbalode tí gbogbo ayé ń pè ní Hushpuppi Wo awọn Aàrẹ nílẹ̀ Áfríkà to ti gba oyè ""Field Marshal"" rí Labẹ iṣẹ iwadii akanṣe ọtẹlẹmuyẹ ti wọn pe ni ''Fox Hunt 2'', wọn mu awọn ọdaran kan to n pa awọn eeyan lẹkun jaye loju opo ayelujara, ti wọn si n lu awọn eeyan ni jibiti."
Eliaba, ará Ṣaaliboni, àwọn ọmọ Jaṣeni, ati Jonatani; 
Kunle Afolayan, òṣìṣẹ́ báńkì tẹ́lẹ̀ kó tó di gbajúgbajà òṣèré Ọwọ́ tẹ babaláwo àti adigunjalè márùń ni Imo - Olọpàá Wole Soyinka rèé láti kékeré Ẹ wo àwọn ìlúmọ̀ọ́ká olórin, òsèré tó ti sẹ̀wọ̀n rí!
Balogun ni o ti le logoji ọdun ti oun ti wa lori oye niluu Ibadan, bẹẹ ni oun ko ti ri Olubadan to dan iru rẹ wo ri.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ifa Worshippers: Àwọn ẹlẹ́sìn ìbílẹ̀ ń fẹ́ kíjọba pín èrè òṣèlú alágbádá yíká gbogbo ẹ̀sìn Ṣugbọn iṣẹlẹ buruku kan waye ni ọjọ kan.
naira fun  kikọ ile-ẹkọ ijọba apapọ ni jake jado orile ede Naijiria.
Bàbà ọmọ ọdún 75 kó HIV ran ọmọ ọdún 14 lẹ́yìn tó fi ipá báa lò Gẹgẹ bi a si ti ṣe gbọ, ọpọlọpọ awọn ọkunrin to n ba ọkunrin lo pọ atawọn obinrin to n ba obinrin lo pọ ni wọn peju pesẹ si ibi ayẹyẹ ọjọ ibi Bobrisky ti oun pẹlu jẹ akọ ti n ṣe iṣe abo.
Iwadii naa fihan pe ọpọlọpọ awọn ọkunrin naa ni ko mọ nitori wọn ko se ayẹwọ ni asiko eyi to si yọri si iku fun awọn ẹlomiran.
Gẹ́gẹ́ bi Oluyole, ile Olupoyi ni Adedibu naa ti wa ni Oja-Oba Ibadan sùgbọ́n ó tan mọ́ Oluyole lati ilé ìyá rẹ̀.
Ṣugbọn ẹ jẹ́ kí òtítọ́ máa ṣàn bí omi, kí òdodo sì máa ṣàn bí odò tí kò lè gbẹ.
Cole ati MigosEwe, lati gba ami-eye yii, Davido jawe olubori saaju awon akegbe re bi: Tiwa Savage, Booba (France), Cassper Nyovest (South Africa), Dadju (France), Distruction Boyz (South Africa), Fally Ipupa (DR Congo), J Hus(UK), Niska (France), Stefflon Don (UK) ato StormzyEyi je igba akoko ti omo orile-ede Naijiria yoo gba ami-eye “BET award” , lataari ogunlogo onkorin ti won du ami-eye naa lagbaye.
Nígbà tí Mikaaya ọmọ Gemaraya, ọmọ Ṣafani gbọ́ gbogbo ọ̀rọ̀ OLUWA tí ó wà ninu ìwé náà; 
" Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Èmi gan máa ń béèrè lọ́wọ́ ara mi pé ta ni Wole Soyinka gangan' Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 3 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 5 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Junior Ajayi (Al Ahly, Egypt); Valentine Ozornwafor (Enyimba FC).
Ko to dara pọ mọ oṣelu lọdun 1998, Jonathan ti jẹ oṣiṣẹ ọba ni ile iṣẹ to n ri si ọrọ ayika.
Bo tilẹ jẹ pe awọn ololufẹ rẹ ko pọ to bẹẹ, ori lo gbe de ipele to kẹyin nile Ẹlẹgbọn Agba.
Fi àgọ́ àwọn jagunjagun sí i, kí o wá gbẹ́ kòtò ńlá yí i ká.
Sedekaya ọba bá wí fún Jeremaya pé, “Ẹ̀rù àwọn ará Juda tí wọ́n sá lọ bá àwọn ará Kalidea ń bà mí.
 ""Ijọba Seyi Makinde yoo ri pe idajọ ododo waye lọna ati dena iru iṣẹlẹ bayii lọjọ iwaju."
Ọwọ́ rẹ ni o fi dá mi,ọwọ́ kan náà ni o sì tún fẹ́ fi pa mí run.
" Bákan náà ni ńkan ti wọ́n sọ níbẹ̀, kò sí ọgá kankan nílé, gbogbo wọn lo ti rìnrìn àjò, a ò sì le gba ẹnikẹni sí inú ọgbà wa"" Ẹ̀wẹ̀, ìwádìí BBC lọ́wọ́ agbẹnusọ ọlọ́pàá ìpínlẹ̀ Oyo Olugbenga Fadeyi lórí ọ̀rọ̀ náà ló ti sàlàyé pé, ó jọ bi ẹni pé, ikọ̀ Àmọ̀tẹ́kun fẹ́ràn láti máa fi àwọn oníròyin bá ọlọ́pàá jà."
Awọn ọmọ ogun ilẹ okeere si ran wọn lọwọ nipa ounjẹ, oogun ati nkan ijagun.
Eyi to ni iwe ẹri HND ninu wọn, kabiyesi ni oun ṣi tun ran an pada lọ sileewe giga fasiti.
Ẹ kò ní pẹ́ rárá lórí ilẹ̀ tí ẹ̀ ń gòkè Jọdani lọ gbà, tí yóo sì di tiyín.
ijoba apapo ,ki o to di ọgbọ̀njọ osu
"Àkọlé àwòrán, Ọpọlọpọ kudia ati ohun ini lo ti ṣegbe ninu ibugbamu ina to ṣẹlẹ ni ọja Binukonu ""Nigbati iṣẹlẹ ina yi waye lẹẹmeji sẹyin, a ṣe gbogbo ohun ti ijọba paṣẹ fun wa lati ṣe."
Kí wọn má baà yipada,kí n má baà wò wọ́n sàn.
Ojú alágbe ni wọ́n fi ń wo alága ìdúró- Ayo Oladokun Sugbọn iyalẹnu lo jẹ fun gbogbo awọn alejo to wa nibi ayẹyẹ ikẹkọjade ileẹkọ naa, ti wọn si la ẹnu silẹ, lai lee pa de, nigba ti akẹkọjade ti wọn jẹ ọmọ Naijiria, gba ami ẹyẹ mẹrindinlogun ninu ami ẹyẹ mẹtadinlọgbọn ti fasiti naa ko silẹ fawọn akẹkọ ti ọpọlọ wọn jipepe julọ.
”Lara ohun ti ko wo po ninu iko agbaboolu Germany ni agbaboolu owo eyin merin ti iko ohun lo, eleyi ti o mu Joshua Kimmich ti o n gba owo eyin di ipo arin mu.
Iyanṣẹlodi awọn olukọ nileẹkọ giga yii n waye lẹyin bi ọsẹ kan ti awọn olukọ nileẹkọṣẹ olukọni ni ilu Ileṣa naa ti gu le iyanṣẹlodi.
Tesiwaju si, lara awon eniyan jankan-jankan ti o ye asekagba idije ohun si, ti o si tun se agbekale ife-eye idije naa fun iko ti o jawe olubori, gomina ipinle Bayelsa, Seriake Dickson aare ajo to n mojuto boolu afesegba lorile-ede Naijiria,(NFF) Amaju Pinnick.
Gbogbo igba ni mo maa n fi ikanra sọ pe awọn obi baba mi ko le ran mi nilewe, o sọ fun BBC.
Nínú àtẹ̀jáde kan tí iléèṣẹ́ Ààrẹ fi síta lójú òpó Twitter ni wọ́n ti kéde ìyànsípò Magaji Bichi.
Èyí ló fa ìdí abájọ oo tí gbogbo àwọn ènìyàn ṣe ń bèrè lóri ẹ̀rọ àyélujara pé ọ̀nà wọ ní Davido gba kú ní àgọ́ agùnbánirọ̀ Lẹyin 'Assurance'; Davido ra ọkọ ofurufu kekere Oríṣun àwòrán, Instagram/Davido official Àkọlé àwòrán, Davido ti di asoju fun ile-isẹ ẹrọ ibaraẹnisọrọ, Infinix Olorin taka-sufe nnì,David Adeleke, ti gbogbo eniyan mọ si Davido, ti di ọdọmọde akọkọ lati orilẹede Naijiria ti yoo ra ọkọ baalu kekere fun ara rẹ.
O wa rọ awọn alatilẹyin rẹ lati fọwọsowọpọ ri i pe Sanwo-Olu lo jawe olubori, ninu idibo abẹle naa ti yoo waye lọjọ Aje, ọjọ kinni, oṣu kẹwaa.
Ẹ di ẹrù yín láti lọ sí ìgbèkùn, ẹ̀yin ará Ijipti!
Má jẹ́ kí oúnjẹ tí ò ń jẹ mú ìparun bá ẹni tí Jesu ti ìtorí rẹ̀ kú.
Ṣé n kò ní aṣiwèrè níhìn-ín ni, tí ẹ fi mú un wá siwaju mi kí ó wá ṣe wèrè rẹ̀?
Wọn wa sapejuwe ọjọ ti wọn gbe abẹrẹ naa, ti yoo koju arun Coronavirus jade, gẹgẹ bi ọjọ to lamilaaka ni igbe aye awọn onimọ sayẹnsi ati gbogbo ẹda alaaye.
Ṣugbọn èmi a máa fi ìfẹ́ mi tí kì í yẹ̀ hàn sí ẹgbẹẹgbẹrun àwọn tí wọ́n fẹ́ mi, tí wọ́n sì ń pa òfin mi mọ́.
Ni bayii, ile asofin ipinlẹ Ọyọ ti pe ipade pajawiri igbimọ ile to wa fọrọ eto aabo lati jiroro lori isẹlẹ yii.
(Wo Ẹ&M 20 àti Péálì Olówó Iyebíye, Joseph Smith—History 1.
Community Policing: ìjọba ìbílẹ kọọkan yóò gbà ààdọta òsìsẹ
Aláìsàn gbodo tí ni èròjà ara to ń gbogun ti ààrùn, ti wọn ba se àṣeyọrí láti bá aarun náà ja.
Ọba sọ fún Daniẹli pé, “Láìsí àní àní, Ọlọrun rẹ ni Ọlọrun àwọn ọlọrun, ati OLUWA àwọn ọba, òun níí fi ọ̀rọ̀ ìjìnlẹ̀ han eniyan, nítorí pé àṣírí ọ̀rọ̀ ìjìnlẹ̀ yìí gan-an ni o sọ.
Almajiri: Kíni ìjọba ń ṣe lórí ewu ẹkọ Almajiri àti covid 19 ní Nàìjíríà?
Bí ó bá ń bínú ta ló lè dúró?
eto ilana akanse ti íjoba to wa lori aleefa bayii fẹ gunle.
Oríṣun àwòrán, Eremosele Adene Lara ohun ti adajọ ti adajọ ṣe ni pe o gba ọrọ ti agbẹjọro ẹni afẹsunkan sọ pe ki wọn faaye gba ẹtọ onibara oun.
eniyan yoo maa jẹ anfaani rẹ lorile ede Naijiria.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ìdẹra dé fún Nàíjíríà!
"Buhari ti buwọ́lu #30,000 owó oṣù òsìsẹ́ ""Gbogbo òṣìṣẹ́ kọ́ ni #30,000 owó oṣù tuntun yóò kan"" O fi kun un wi pe bi o tilẹ jẹ pe ounjẹ, owo ile gbigbe ati owo irinna ọkọ ni yoo gba gbogbo owo naa lọ, amọ yoo kari awọn eniyan naa ti ko sisẹ ijọba nitori awon naa yoo ri ọja ta, eleyii ti yoo mu owo naa wọle fun wọn."
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù State Joint Local Government Accounts: Ìjìyà ti wà fún báńkì tó bá ṣí àṣùwọ̀n ìjọba ìbílẹ̀ sílẹ̀ fún gómìnà jẹgúdújẹrá 6 Èbibi 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, NFIU ni ko saye fun awọn gomina ipinlẹ lati maa lu owo ijọba ibilẹ ni ponpo mọ Ko saye iregbe mọ fawọn gomina to n fi owo aṣuwọn ajumọni ipinlẹ atijọba ibilẹ ta sere mọ bayii.
''A feran lati maa ṣadura lori gbogbo nkan ni Naijiria ṣugbọn ọlọrun ma jẹ ki ọrọ wa ṣu Ọlọrun.
inu isejoba re laarin ọdun merin yii.
Kọ̀ọ̀nkọ̀ kan kìí kọ ohun odò
Wọn ni pe ko ni iwe ẹri to daju lati fi du ipo aarẹ ninu eto idibo ọdun 2019.
Lọwọlọwọ, eniyan bi ẹgbẹrun mẹtadinlaadoje lo ti ku, ti miliọnu meji eniyan si ti ni aarun naa.
"O maa n din aarẹ ara ati ifoya ku ""Ti a ba n gba awọn ti ko ri oorun sun ni imọran nitori wahala ti wọn n ṣe, a maa n bi wọn pe aṣọ melo ni wọn maa n wọ sun, Kris sọ bẹ."
A ní àbúrò obinrin kékeré kan,tí kò lọ́mú.
Gege bi asofin eka guusu orile-ede naa, Mahad Dhoore,  se so fun awon akoroyin“ibugbamu ohun seku-pa eniyan marun un ti awon miran si farapa yanayana lori papa isere naa.
Mo gba pé ó ye kí àwọn to n kọ fiimu ó moju to ẹka míràn, sùgban ki wọn maa ṣe eré ìfẹ́ rárá, kò le siṣẹ́ rárá.
Bakan naa ni Shuijin salaye pe, odun ti a wa yii sami ayeye  odun metadinladota ti orile-ede mejeeji ohun ti bere  ajosepo ti o muna-doko.
Amọ, inu wa dun wi pe ko si ẹnikankan ninu awọn akẹkọọ ẹgbẹrun lọna mẹfa to ṣe idanwo naa to lugbadi arun Coronavirus.
Aare Buhari gbadura pe ki Olorun tubo fun Olusoagutan Adeboye ni emi gigun ati alaafia pelu ara lile lati sise yii de ibi ere laikose titi de opin.
Orúkọ idile Yorùbá ti ó nparẹ́ nitori èsìn.
Eyi ni ọro gbankọgbi ti Alaafin gbe kalẹ ni ilu Iwo lasiko to fi ṣe abẹwo si Oluwo ti ilu Iwo, Oba Abdulrasheed Akanbi nibẹ.
Tẹmpili Ọlọrun ti ṣí sílẹ̀ ní ọ̀run, tí a fi lè rí àpótí majẹmu ninu rẹ̀.
Iṣẹ akọroyin ti yatọ si ti tẹlẹ, o ti mu iṣẹ ọtẹlẹmuyẹ dani lasiko yii fun idande awọn eniyan agbaye.
‘Alẹ́ làwọn ọkùnrin fẹ́ bá mi jáde, torí mo kọ ilà’ Àwọn ìmúra tó làmìlaaka ní Nàìjíríà lọdún 2018 Gẹ́gẹ́ bi awọn aṣojuloge ṣe sọ ọ, kii ṣe bi ọpọlọpọ ṣe ro o naa ni akoko ṣiṣe oju loge ṣe gun tabi kuru si, o da lori irufẹ oge oju ti o ba yan lati ṣe ati pe fun iru ode wo.
Orílẹ̀-èdè Naijiria ti ri ẹni kẹẹta to tún ni àrùn Coronavirus lónìí ọjọ ìṣẹ́gun ti gbogbo rẹ̀ sì n tọka si orilẹ̀-èdè Italy àti UK ni bi tó jẹ́ àwọn agbègbè ti ààrun náà ti n ja fitafita.
Ṣugbọn ìwọ nìkan ju ẹgbaarun (10,000) wa lọ.
Awon osise ilera meji ni won ti kagbako arun iba yii nipinle Ebonyi, osise eleto ilera kan ni Nassarawa, eyo kan ni Kogi, ikan ni Benue, ikan ni Ondo, meta ni Edo.
Ọkunrin náà dáhùn, ó ní, “Obinrin tí o fi tì mí ni ó fún mi ninu èso igi náà, mo sì jẹ ẹ́.
“Ẹnu ya gbogbo àwọn tí ń gbé etí òkun nítorí ohun tí ó ṣẹlẹ̀ sí ọ.
Èyí tún kún àwọn ènìyàn tó lé ni ègbẹ̀rún lọ́nà ààdọ́jọ́ tí kò ní ni ààfàní láti gba ìwé ìgbelùú tẹ́lẹ̀ ti wọ́n sì ti forúkọ silẹ̀ - ìwé yìí (Green Card) ló máa n fún àwọn alèjo nílẹ̀ Amẹrika ni àànfàní láti maa gbé ilẹ̀ Amẹrika láì sí wàhàlá.
Ọpọlọpọ ọmọ Naijiria lo ti fesi si fidio ati awọn aworan Buhari ati Obasanjo ti wn fi sori itakun Twitter, Instagram ati Facebook nibi ipade ajọ AU ti wọ nfẹyin kẹẹ, ibeere wọn si ni wipe se awọn adari wa ti wa sọ wa di ayo ti wọn nta laarin ara wọn ni?
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Aguda Ogba Fire: Iná míì tún sọ ní Ọgba, nílùú Eko!
sise owo ilu basu-basu ni ipinle naa lati se iwadii lori owo to le ni milionu
"O lè tọ àwọn onímọ lọ, o lé ba dokita sọrọ tàbi ki o darapọ mọ àwọn ẹgbẹ́ fun ìrànwọ́ lọ́wọ́ àwọn ti wọ́n ti koju isoro kan náà láti ràn ọ lọ́wọ́"" Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!"
Lẹ́yìn náà, gba gbogbo àkàrà náà lọ́wọ́ wọn, kí o fi iná sun wọ́n lórí pẹpẹ pẹlu ẹbọ sísun olóòórùn dídùn níwájú OLUWA, ẹbọ tí a fi iná sun sí OLUWA ni.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Mọrèmi: Ọọ̀ni ní láìsi Mọrèmi, kò leè sí ilẹ̀ Yorùbá Amọ ju gbogbo rẹ lọ, DJ Sosogee ni ohun kan ti ko ṣee gbagbe ni pe, oloogbe DJXgee jẹ ẹni ti o fẹran awọn ọmọ rẹ gidigidi ti ko si fi ẹbi rẹ ṣere rara.
A kò ní fi ọ̀rọ̀ ilé Ọlọrun wa falẹ̀.
Wọ́n ń rúbọ lórí òkè gíga, wọ́n ń sun turari lórí òkè kéékèèké, ati lábẹ́ igi oaku, ati igi populari ati igi terebinti, nítorí òjìji abẹ́ wọn tutù.
Kọmiṣọnna eto iroyin ni ipinlẹ Eko, Gbenga Omotoso ninu atẹjade kan to fi sita ni ẹsun naa to n ja ranyin ranyin lori ayelujara jẹ ete awọn ọta lati ko nkan jọ lodi si ijọba.
Lagos doctors strike: Ẹgbẹ́ dókítà bẹ̀rẹ̀ ìyanṣẹ́lódì lórí owó oṣù àti ètò adójútòfò fún ìtọ́jú covid-19
Àhámọ ́ jẹ ́ ẹyọ aládìmú àti oníàmúṣe fún gbogbo àwọn ohun ẹlẹ ́ ẹ ̀ mì tí a mọ ̀ .
Ẹ wà níwájú mi ẹ kò máa gbọ̀n pẹ̀pẹ̀.
Ipinlẹ Eko wọ 70 afurasi ọmọ ẹgbẹ okunkun lọsile ẹjọ
Iku Fẹlẹ ti wọn kede lojiji yii lo mu ki ayẹyẹ ọdun ileya tete di wẹlo ninu ile rẹ, ti awọn ẹbi rẹ si bẹrẹ si se ọfọ rẹ.
Ẹni to bori: Senegal Guinea vs Guinea-Bissau.
Ni ọjọ kẹrindinlogun oṣu keji ni awọn oludibo lorilẹede Naijiria yoo jade lati dibo lori awọn ohun tawọn oludije wọnyii ti sọ.
Nítorí Ọlọrun kò pè wá sí ìwà èérí bíkòṣe ìwà mímọ́.
ayokele (Toyota Prado) ti owo ori re le die ni Milioni Mejila Naira, oko ayokele Peugeot 607 ti owo ori re
Ìgbà tí ó sì jẹ́ pé nǹkan abàmì ló kún inú Igbó Olódùmarè, mo ṣebí ọgbà náà wà níbẹ̀ láti máa fi tọ́jú àwọn tí ó bá ṣìnà sí inú igbó náà ni – mo bá bẹ̀rẹ̀ sí jẹun.
iko omo ogun naa maa fọwọsowọpọ pelu awon eniyan ati awon ẹsọ eleto aabo miiran,
Baalu awon olopaa orile ede yii ni won n lo lati  fi pese aabo nibi ipolongo naa.
Coronavirus update in Nigeria: Àwọn akẹ́kọ̀ọ́ 181 pẹ̀lú Olùkọ́ lùgbàdì Covid 19 níléèwé kan nípinlẹ̀ Eko
Eyi ko sẹyin bi o ti ṣeeṣe ki wọn kede orukọ rẹ lojobọ lara awọn meji to tẹsiwaju de abala ìkẹyìn eto iyansipo tó n lọ lọwọ.
Oluomo ilu Eko latọwọ Oba Adeyinka Oyekan ti Eko lọdun 1999 Ọjọ Aje, ọjọ kẹtala, oṣu Kinni, ọdun 2020, ni Alaafin ilu Oyo, Oba Lamidi Adeyemi kẹta fi Wasiu Ayinde jẹ oye Mayegun akọkọ nilẹ Yoruba.
Àwọn akọrin kọrin, Jesirahaya sì ni olórí wọn.
,lọjọ Eti to kọja  yii ni orile ede Democratic Republic of Congo, sagbako aarun Ebola màrúndínlógún
" Akeugbagold wa gba musulumi, ẹlẹsin ibilẹ ati Kristẹni niyanju lati maa lo ifẹ, ki wọn si tun yago fun iwa ẹlẹyamẹya nitori ijẹọmọniyan ju ọrọ ẹṣin lọ, aisi ifẹ si lo n ṣe okunfa ba ṣe n pa ara wa.
Lọjọ Iṣẹgun ni ile panupọ pe, o di dandan lati wadi kulẹ kulẹ nipa bo ṣe jẹ ọkọ okolelẹgbẹrin (820) ni ijọba Ambode ra dipo ẹgbẹrun marun un ọkọ̀ (5000) ti o daba.
Eko, iwadii ti pari lati bẹrẹ ile-ise yii.
Ètò tí alárinà bá lọ́wọ́ sí ti kúrò ní ti ẹyọ ẹnìkan.
Ẹ sọ ara yín di òmùgọ̀,kí ẹ sì máa ṣe bí òmùgọ̀.
Iwe ẹri ti ijọba fontẹ lu niwọn yi: •Iwe irina pasipọti •Kaadi idanimọ ti ajọ NIMC n fun awọn ara ilu •Iwe asẹ iwakọ ni Naijiria •Kaadi idibo ọlọjọ pipẹ,PVC •Ipele ayẹwo fini fini ka to pari: •Nibi ni waa ti yẹ gbogbo nkan to kọ daada ti o si fi sọwọ si oju opo naa •Bi o ba ti fi sọwọ si oju opo naa tan, wọn yoo fi nọmba idanimọ kan ransẹ si ọ,kọ silẹ ki o fi pamọ daada.
7 108017 Orilẹede Sudan 1576 3.
Aarẹ tẹlẹ ri lorile-ede Egypt, Mohammed Morsi, ti awọn ologun yọ loye lọdun 2013 ti fo sanlẹ ku ninu ile ẹjọ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù ENDSARS, End SWAT: Gomina Obiano yọ ọ̀gá ikọ̀ SARS nípò 16 Ọ̀wàrà 2020 Oríṣun àwòrán, facebook Chief Willie Obiano Gomina ipinle Anambra, Willie Obiano ti gba iṣẹ lọwọ James Nwafor to jẹ ọga awọn ọlọpaa SARS ni ipinlẹ naa to si ṣe ileri fun un pe yoo fimu ko ata ofin.
Oyo NLC mú ìlérí rẹ̀ ṣẹ, ó bẹ̀rẹ̀ ìyanṣẹ́lódì
Orọ igbẹyin ti Pius Adesanmi fi soju opo Facebook rẹ fi igbagbọ rẹ ninu Oluwa han pe: Oríṣun àwòrán, @Pius Àkọlé àwòrán, afi bii pe akọni n dagbere .
Oríṣun àwòrán, Others Wọn ni igbagbọ pe awọn yoo ri wọn gba pada, ti o si ni ileeṣẹ ọlọpaa ko mọ nipa owo itanran ti iroyin ni wọn n beere fun.
Naijiria, Femi Gbajabiamila  lo soro yii
Bẹ́ẹ̀, ìpolongo yìí mú èsì tí ó ń takoni wá láti ọ̀dọ̀ àwọn ọkùnrin kan tí wọ́n rí ìdí fún ìdáláre fún ìrúkèrúdò fífi ìyà jẹ obìnrin.
Ninu atẹjade kan ti ijọba ipinlẹ Eko fi sita lọjọ Iṣẹgun ni wọn ti kede pe ẹni ọgbọn ọdun naa, to jẹ obinrin pada de si orilẹ-ede Naijiria lati United Kingdom, UK, ni ọjọ kẹtala, oṣu Kẹta.
Saadede ni awọn ẹgbẹ Boko Haram kọlu ile iwe naa ti wọn si ji awọn akẹkọbinrin naa gbe lọ Ọdún kẹrin kò láì rí àwọn akẹ́kọ̀ọ́ Chibok pe Akẹkọ Dapchi pada de Awọn olori ileesẹ aabo tẹdo si Dapchi Lati igba naa, pabo ni ireti njasi lati rii pe gbogbo wọn pade sile pe.
O fi kun ọrọ rẹ pe ohun ijaya lo jẹ nigbati ipe pajiwiri kan dede wọle laarọ ọjọ keji wi pe iya oun ti re ibi agba n re, pẹlu afikun wi pe iya oun ki i fẹ ki ọmọ fi eto ẹkọ ṣere rara nigba aye rẹ.
“Èyí ni majẹmu tí n óo bá wọn dánígbà tí ó bá yá, Èmi Oluwa ni mo sọ bẹ́ẹ̀,Èmi óo fi òfin mi sí ọkàn wọn,n óo kọ wọ́n sí àyà wọn.
awọn adari ẹlẹsin lorile ede  Naijiria
Ọkùnrin tí kò ríran kan rèé tó ń lọ ẹ̀rọ ata Ọọ̀ni obìnrin, Lúwòó Gbàgídà rèé, akọni tó ń gun ọkùnrin ní ẹṣin rìn Jeewan ni ipo ti oun ba ilu naa ati awọn obi oun ko dun mọ oun ninu bi o tilẹ jẹ pe inu wọn dun lati foju kan oun pada.
Ọpọ si lo n yọ Trump pe ọwọ ara rẹ lo fi fa arun naa funra rẹ, nitori ọwọ yẹpẹrẹ to fi mu lati ilẹ wa.
Ninu atẹjade ti wọn fi sita ni NEMA ti ṣalaye ohun ti igbimọ naa gbe jade pé wọn kò ni nkan ṣe pẹlu awọn iwe aṣẹ ati aridaju ti awọn fi silẹ.
Ní báyìí, Iroyin kan ni ẹka ileesẹ ọlọ́pàá tó wà fún ààbò àwọn ọmọdé ni orílẹ̀ èdè Zambia tí ransẹ pé George Bester láti wá sọ ìdí tó fi tẹ́ ẹtọ ọmọ rẹ mọ́lẹ̀.
 eto aabo Lori eto aabo Guterres so pe opolopo ikolu ni awon iko olote Boko haram ti se ni apa aarin gbungbun iwo oorun orile ede Naijiria ati si ajo eleto aabo,osise ijọba, oloselu lorile ede Naijiria  ati ile Afirika.
Sibẹsibẹ, ọwọ́ yín náà ni a ṣì wà; ẹ ṣe wá bí ó bá ti tọ́ lójú yín.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù NEMA: Ìjọba ìbílẹ̀ 102, ní ìpínlẹ̀ 28 ni ẹ̀kún omi ń bọ̀, ẹ múra 29 Òkùdu 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 11 Agẹmo 2020 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Dukia ati ẹmi a ma saba wa ninu ewu lasiko omiyale ni Naijiria Igi gogoro ma gun mi loju, ati okeere la ti n lọ.
Ǹjẹ́ a ti mú ohun ìkọsẹ̀ agbelebu Kristi kúrò?
Ẹ̀kọ́ kejì ni pé a nílò abẹrẹ ajẹsara ni kíákíá lórílẹ̀-èdè yìí tí ẹkọ kẹta si n ke si wa pé àwọn ilé ìwòsàn wá nílò àtúnṣe lọgan.
” Bí wọ́n ti ń lọ, ara wọn bá dá.
EndSars, End SWAT, Nigeria protest: Buharii ní àkókò tó táwọn ọ̀dọ́ yóò fòpin sí ìwọ́de náà
Osinbajo ni ipa nla ti arun Coronavirus nni lori ọrọ aje ati igbayegbadun wa ni Naijiria lojoojumọ lagbara pupọ.
Nkan ko san mọna fun lọkọlaya naa nigba ti wọn de Amẹrika, inu ahere ti kii se ile rara, si ni wọn n gbe pẹlu ẹgbọn ọmọ naa.
Yoruba ni ajise bi Ọyọ laa ri, Ọyọ kii se bi baba ẹni kọọkan, a si lee ni asamọ yii faramọ ninu ilana igbe aye Oba Lamidi Olayiwola Adeyemi Kẹta ba ba wo isesi rẹ lori oye.
Bakan naa lo tun ba aarẹ Buhari ṣiṣẹ ninu ẹgbẹ CPC gẹgẹ bi akapo gbogboogbo lọdun 2013 si 2014.
Nítorí náà, majẹmu mi ti dópin lọ́jọ́ náà.
Clement Anade Agba (Edo)- Minisita abẹle fun aato ati inawo Ọtunba Adeniyi Adebayọ - Minisita fun ileeṣẹ, idokoowo ati karakata Geofery Onyeama (Enugu) - Minisita fun ọrọ okeere Ali Isa Ibrahim Pantami (Gombe)- Minisita fun ibaranisọrọ Emeka Nwajiuba (Imo)- Minisita abẹle fun eto Ẹkọ Suleiman Adamu (Jigawa) - Minisita fun ohun alumọni inu omi Zainab Shamsuna Ahmed (Kaduna) - Minisita feto iṣuna ati aato ilẹẹwa Mohammed Mahmud - Minisita fun ọrọ ayika Mohammed Sabo Nanono (Kano) - Minisita fun eto Ọgbin ati idagbasoke igberiko Bashir Magashiri (Kano) - Minisita fun eto abo Sẹnetọ Hadi Sirika - Minisita fun irinna ofurufu Abubakar Malami - Agbẹjọro agba ati minisita fun eto idajọ.
Lẹ́yìn tí Hẹrọdu ti kú, angẹli Oluwa kan fara han Josẹfu ní ojú àlá ní Ijipti.
 wọ ́ n ṣẹ ́ ọ ̀ pọ ̀ lọpọ ̀ ogun .
Bí ó bá gbàgbé nǹkan sílẹ̀, ki n mú u pamọ́ dè é.
 bí wọ ́ n bá ni kí wọ ́ n ka oríṣi fíìmù yorùbá tí ó ti jáde , yóò tó ìdá mẹ ́ fà fíìmù tí ó ti jáde ní ilé-iṣẹ ́ àwọn onífíìmù tí ó gbajúmọ ̀ nísìnyí .
ng Tẹ bọtinni ti wọn kọ 'apply here' si, ni oju ewe to ba kọkọ ṣi Fi orukọ rẹ silẹ, pẹlu nọmba BVN rẹ, si aaye to yẹ Lẹyin naa ni ki o kọ akọsilẹ nipa ọjọ ori rẹ, nọmba ẹrọ ibanisọrọ rẹ, adirẹsi rẹ, ipinlẹ ti o ti wa, ati imeeli rẹ, pẹlu awọn nkan miran.
igbimo to n ri samojutoile-isẹ to n  ipese ina- monomona, iyen, Nigerian
Akinlade ni yóò di gómìnà tuntun ní ìpínlẹ̀ Ogun- Amosun Gómìnà ìpínlẹ̀ Ogun Ibikunle Amosun sọ pé òun ti sàdúrà fún olùdíje Gomina nínú ẹgbẹ́ òṣèlú Alliied People's Movement APM ní ìpínlẹ̀ Ogun Adekunle Akinlade láti lépa ohun ti ọkan rẹ̀ ń fẹ́ nínú ẹgbẹ́ náà.
- Olukoya ti ìjọ MFM Àwọn òṣèré tíátà kan rèé, tí wọn fẹ́ ara wọn, tí ìgbeyàwó wọn sì pẹ́ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Òṣìṣẹ́ Bánkì ni mí l'Amẹ́ríkà kí n tó bẹ̀rẹ̀ Tíátà' Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
 wọ ́ n lọ bi ifá léèrè , ifá si ṣe atọ ́ nà ajẹbú wí pé kí ó lọ tẹ ̀ dó sí ibi kan , èyí tí à ń pè ní imẹ ̀ pẹ ̀ .
Sugbọn African Centre for Migration and Society (ACMS) to jẹ ajọ to n risi igbokegbodo awọn eniyan Adulawọ ni akọsilẹ nipa iṣẹlẹ ikọlu sawọn alejo ni South Africa.
A ti wá bọ́ sí ìgbà òjò wàyí o.
8 1069 Orilẹede Antigua ati Barmuda 4 4.
Ẹ má ka fífi èdè àjèjì sọ̀rọ̀ sí èèwọ̀.
Bi o ba n ṣe ọfinkin tabi ti o ba ni iba.
Lasiko ọkan lara ijọsin rẹ leti okun, o ba BBC Yoruba sọrọ lorii bi o ṣe jẹ ọmọ Musulumi to tun lo ogun ọdun ni ṣọọṣi gẹgẹ bii Kristẹni ati Wolii ijọ kan ko to wa gba ibi to ni ori da a lọ eyi tii ṣe bibọ okun.
Mo fẹ́ kí Ọlọ́run fún wa ní ọmọ olójú búlúù si lẹ́yìn yìgì - Ọkọ olójú búlúù Àwọn alákatakítí Islamic State West Africa Province kéde pé wọ́n tún ti pa àwọn ṣọ́jà ní Kukawa Ẹ̀bùn #500,000 wà fún ẹni tọ bá ba wa rí afurasí ikú Akinyẹle tó sọnù- Iléeṣẹ́ Ọlọ́pàá Wo àmúyẹ kí o tó lè di ọmọ ogun ilẹ̀ Nàìjíríà pẹ̀lú fọ́ọ́mù tó jáde yìí Komisonna ni afikun iye akoko isinmi itọju ọmọ naa ṣe pataki nitori ati fun awọn ọmọ ni itọju to peye ki awọn iya wọn naa le e tọju ara wọn.
Angẹli mìíràn tún jáde wá láti inú Tẹmpili ní ọ̀run, tí òun náà tún mú dòjé mímú lọ́wọ́.
Àwọn ọmọ Israẹli bá gbéra ní òwúrọ̀ ọjọ́ keji, wọ́n lọ pàgọ́ sí òdìkejì Gibea, 
Ọmọ náà yóo jẹ́ ẹni ńlá níwájú Oluwa.
“Bí ó bá jẹ́ pé èmi ni mò ń jẹ́rìí ara mi, ẹ̀rí mi lè má jẹ́ òtítọ́.
Gbogbo àwọn wọnyi ni ẹ̀rí rere nípa igbagbọ, ṣugbọn wọn kò rí ohun tí Ọlọrun ti ṣe ìlérí gbà.
Tabi àwọn mejidinlogun tí ilé-ìṣọ́ gíga ní Siloamu wólù, tí ó pa wọ́n, ṣé ẹ rò pé wọ́n burú ju gbogbo àwọn eniyan yòókù tí ó ń gbé Jerusalẹmu lọ ni?
Aṣofin naa tun fi kun ọrọ
Ti won ba mu mi gege bi oludije fun egbe won, inu mi a dun si I”.
oriṣa yìí kì báà jẹ́ èyí tí ó wà nítòsí, tí àwọn ará agbègbè yín ń bọ, tabi èyí tí ó jìnnà réré, tí àwọn tí wọ́n wà ní ilẹ̀ òkèèrè ń bọ.
Ojuti nla nla ni ipo ti awọn ọgba ẹwọn lorilẹede yii wa bayii."
bẹ́ẹ̀ ni Ọlọrun yan àwọn ẹni tí kò níláárí ati àwọn ẹni tí kò já mọ́ nǹkankan rárá, àwọn tí ẹnikẹ́ni kò kà sí, láti rẹ àwọn tí ayé ń gbé gẹ̀gẹ̀ sílẹ̀.
Èmi náà bá wòkè pé kí wa ló dé?
" Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Èmi ni Awùjalẹ̀ ti Iwo Oluwo Ìwo ṣ'àlàye lori oye Emir Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Buhari, Saraki, Dangote, abẹ́ mi ni wọ́n wà' Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Raufu: Ọ̀ọ̀nì wa máa ń gba adìyẹ ní Òjé ní Ìbàdàn Wàhálà bẹ́ sílẹ̀ níbi ìpolongo ìbò APC l'Eko MC Oluọmọ, fara gb'ọ̀bẹ níbi ìpolongo ìbò APC l'Eko Mohammed Salah gba àmì ẹ̀yẹ̀ CAF fún ìgbà kejì Bi o ba de ibi kan to rii ti wọn pa ọ̀ọ̀ni, a maa ba a lọkan jẹ pupọ.
Lara awọn adehun ti awọn olori orilẹede mejeeji naa fọwọ si ni pe, Jong-un yoo palẹ awọn nkan ogun ija oloro mọ́ nilẹ ní Korea.
Kíá ni Ọba ní kí àwọn ẹmẹ̀wà òun mú Ìjàpá kí wọ́n dìí tapá tẹsẹ̀ kí wọn ó ti ojú rẹ yọ idà, kí wọn sì ti ẹ̀yìn rẹ̀ tí bọ àkọ̀.
Ó tún sọ fún mi pé, “Ọmọ eniyan, lọ bá àwọn ọmọ Israẹli kí o sọ ọ̀rọ̀ mi fún wọn.
Bẹ́ẹ̀ ni àwọn ẹnìkan bá dé, wọ́n sọ fún wọn pé, “Àwọn ọkunrin tí ẹ tì mọ́lé wà ninu Tẹmpili, tí wọn ń kọ́ àwọn eniyan lẹ́kọ̀ọ́.
Nígbà tí bàbá mi dé igbó yìí, ohun gbogbo dákẹ́ pátápátá, àwọn ewé igi gbogbo doríkodò, ọ̀kan kò sì lu èkejì, bí ẹni pé kò tilẹ̀ si ẹ̀fúùfù rárá ni; àwọn ẹka igi gbogbo sì dúró ṣanṣan bi ìgbà tí jagunjagun bá dúróníwájú ọ̀gá rẹ̀, àwọn ìtàkùn dà bí olókùnrùn níbi ti wọ́n kájọ si, bẹ́ẹ̀ ni àwọn ẹranko ti kọ ibẹ̀ sílẹ̀ gẹ́gẹ́ bí ibùgbé wọn; àwọn ẹyẹ ti bá ibi gbogbo ti wọ́n rí lọ, àwọn ohun alààyè sì da bi ìgbà ti onígbèsè bá ń ronú gbèsè rẹ̀, gbogbo igbó dákẹ́ minimini bí ìgbà tí ọ̀fọ̀ pàtàkì bá ṣẹ ènìyàn ti ọ̀rẹ́ àti ojúlùmọ̀ dákẹ́ minimini.
 Èyí ni pé tán-án-ná gbọ ̀ n rìrì nígbà tí a pè wọ ́ n .
Mnisita to n mojuto ere idaraya ati idagbasoke awon odo lorile-ede Naijiria, ogbeni Solomon Dalung so pe, oun ni idanuloju pe iko agbaboolu Super Eagles yoo se daradara ninu awon ifesewonse won yooku.
OLUWA, nígbà tí o jáde lọ láti òkè Seiri,nígbà tí o jáde lọ láti agbègbè Edomu,ilẹ̀ mì tìtì,omi bẹ̀rẹ̀ sí bọ́,ọ̀wààrà òjò bẹ̀rẹ̀ sí rọ̀.
SIM Card yìí ni Ilé iṣẹ́ ẹ̀rọ ìbánisọ̀rọ̀ fi ndá alágbèéká kọ̀ọ̀kan mọn yàtọ̀ sí arawọn.
Wọ́n gbógun ti àwọn ará Hagiriti, Jeturi, Nafiṣi ati Nodabu.
Ó tún sọ pé, “Ẹ yin Oluwa, gbogbo ẹ̀yin orílẹ̀-èdèkí gbogbo eniyan yìn ín.
Àwọn olórí alufaa ati àwọn Farisi bá pe ìgbìmọ̀, wọ́n ní, “Kí ni a óo ṣe o, nítorí ọkunrin yìí ń ṣe iṣẹ́ ìyanu pupọ?
Wéré ni a rí àyípadà \.
Àjọ NCDC tún ti kéde èèyàn 220 míràn tó ní Coronavirus ní Nàìjíríà Ajọ to n gbogun ti ajakalẹ aarun ni Naijiria ti kede pe esi ayẹwo ti fihan pe okoolelọdunrun eeyan lo tun ti ni aarun Covid-19 l'orilẹ-ede Naijiria.
”Opolopo awon eniyan lo ti n fi iwe ikinni ranse si igbakeji aare Osinbajo
Ó pàgọ́ fún oòrùn lójú ọ̀run,
“Ògòǹgò lu ìyẹ́ rẹ̀ pẹ̀pẹ̀ ninu ọláńlá rẹ̀,ṣugbọn kò lè fò bí ẹyẹ àkọ̀?
Bi oloselu ba gbe igba ibo, abẹ ilana yiii ni yoo fi gbe eto ati erongba isejọba rẹ kalẹ fun awon ara ilu.
Ó ṣe ohun tí ó dára lójú OLUWA nítorí pé ó tẹ̀ sí ọ̀nà Usaya, baba rẹ̀.
Oladapo, to faramọ awọn ilana tijọba Ondo gbe kalẹ lori ijọsin tun ni, ohun to dara ni bi ijọba ṣe kọkọ tilẹkun ile ijọsin pa nitori igbagbọ ninu Kristi ko ni idiwọ, isẹ Ọlọrun si n tẹ siwaju.
Ogún àkànpọ̀ igi ni kí o ṣe sí ìhà gúsù àgọ́ náà.
Wọ́n níláti di ohun ìjìnlẹ̀ igbagbọ mú pẹlu ẹ̀rí-ọkàn tí ó mọ́.
Allen Onyema kii ṣe adigunjale tabi ọlọsa.
Wọn rawọ ẹbẹ si ijọba ipinlẹ Eko pe ki wọn dakun ma gbe iru igbesẹ afikun owo ori nla yii niru asiko ti gbogbo eto ọrọ aje dẹnukọle ni agbaye yii.
osu keji lati dibo fun aare Buhari.
Koda, iroyin sọ pe awọn agbaagba ninu ẹgbẹ oṣelu APC ati PDP, to fi mọ aarẹ Naijiria nigba kan, lo pé Makinde pe ko yọnda ilẹ naa fun wọn lati sin oku Ajimobi si.
Àwo omi kíkorò, tí ó ń mú ègún wá yóo sì wà lọ́wọ́ alufaa.
Ara mi ya bayii, ti ara mi si ti mokun pada, irinajo ibi lo lagbara pupọ amọ o yẹ lati see, gẹgẹ bi Oluwa ti kọ wa pe irin ajo irapada ko rọrun rara.
Fọdun mẹrin tọkọ rẹ fi ṣe ijọba, wọn ko pe Aisha Buhari ni First Lady, amọ aarẹ Buhari yan awọn amugbalẹgbẹ fun Aisha Buhari, ti iṣẹ wọn ko si fi bẹẹ yatọ si ki wọn ma ba First Lady ṣiṣẹ.
Dájúdájú, bí ó bá jẹ́ irú wọn ni mo rán ọ sí, wọn ìbá gbọ́ tìrẹ.
Ṣé lóòtọ́ ni Ngozi Okonjo-Iweala ti borí gẹ́gẹ́ bí obìnrin àkọ́kọ́ olórí ajọ okoòwò l'ágbàáyé, WTO?
Awọn kan lara wọn ti jẹ ẹbun irinajo igbafẹ, jijẹ aṣoju fun awọn ileeṣẹ to ṣe onigbọwọ eto naa.
Ni kete ti a ba gborọ lẹnu agbenuso ile isẹ ọlọpa nipinle Ekiti, ni a o jabọ fun yin.
Balaki bá bínú sí Balaamu gidigidi, ó bẹ̀rẹ̀ sí fi ọwọ́ lu ọwọ́.
Nígbà tí ẹ bá súnmọ́ ojú ogun, kí alufaa jáde kí ó sì bá àwọn eniyan náà sọ̀rọ̀, kí ó wí fún wọn pé, 
Bí iwájú àwọn tí mo rí lẹ́bàá odò Kebari ti rí gan-an ni iwájú wọn rí.
Ẹ di ara yín ní àmùrè;a óo fọ yín túútúú.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Mò ń tọ̀ s'ára ni mo fi gba ara à mi l'óko ẹrú ní Omar Ìgbẹ́jọ́ aṣaájú ìjọ Sotitobire kúrò nílé ẹjọ́ Mágísíréètì lọ sílé ẹjọ́ gíga l‘Akure Ẹ fi èmi àti àwọn alága káńṣù APC sílẹ̀, ká yanjú aáwọ̀ wa nítùbí-ǹnùbí - Makinde bẹ iléẹjọ́ Ìjà dópin, ogun tán lórí ìrọ̀lóyè Trump, ilé aṣòfin àgbà ní kó máa bá iṣẹ́ rẹ̀ lọ Ọlọ́pàá tó pa èèyàn pokùnso lọ́jọ́ kejì tó dé àhámọ́ àwọn ọ̀tẹlẹ̀múyẹ́ Ẹ dẹ́kun dídá abẹ́ fún ọmọbìnrin torí ọ̀pọ̀ ewu tó ń bẹ lọ́jọ́ iwájú nídìí rẹ̀ - Onímọ̀ Àwọn ọlọ́kadà alákatakítí ẹ̀sìn tí wọ ìpínlẹ̀ Eko - Charly Boy Lasiko igbẹjọ to waye lọjọbọ, adajọ to n gbọ ẹjọ naa faake kọri lati gba oniduro Babatunde, to si ni ki wọn da pada si ọgba ẹwọn.
Ki lẹ ranti ninu aṣekagba naa lọun?
Kòkòrò ajokorun tuntun wọ̀lú Eku ba oko ìrẹ́sì jẹ́ ni Kebbi O ni, ọdún 2016 láwọn kọkọ kojú ìpeníjà kòkòrò ajekorun náà.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ìtàn tó wà nídi òwe ‘Sebótimọ Ẹlẹ́wà Sàpọ́n’ Mo fẹ́ ọkọ mi torí bó se ń kọrin, kìí se torí owó - Ìyàwó Aràrá Mo fẹ́ kí àyẹyẹ ìgbeyàwó mi dùn ni mo se bú sẹ́kún - Ọkọ ìyàwó ẹlẹ́kún Samuel Ladoke Akintọla jẹ́ Agbẹjọ́rò àti Akọ̀ròyìn tí ọ̀rọ̀ dá lẹ́nu rẹ̀ Hubert Ogunde rèé, baba àwọn òsèré tíátà Ẹfunsetan Aniwura, obìnrin tó ju ọkùnrin lọ Igun OPC kò faramọ́ Osibotẹ gẹ́gẹ́ bíi olórí tuntun Tẹ̀gbọ́n-tàbúrò gé orí ọmọ aládùúgbò torí ₦200,000 owó ìkómọ Oyinbo s fun wa pe oke to kere ju lori Oke Idanre lo jẹm ẹgbẹ́run mẹta ẹsẹ bata nigbati eyi to ga julọ nibẹ jẹ ẹ́gbẹrun mẹfa.
 Oríṣun àwòrán, Getty Images Pẹlu gbogbo nkan to foju ri, o ṣaa tiraka wọ ile iwe fasiti Bahir Dar ni olu ilu Amhara nibi to ti kawe gboye imọ Chemical Engineering."
Ọgbẹni Odewale Omokehinde sọ fun BBC pe, o dara ki ijọba maa tẹ awọn okunrin to ba fi ipa ba obinrin lajọsẹpọ lọdaa.
Ileeṣẹ ọlọpaa nipinlẹ Eko sọ pe, ariwo ti ọmọ Patricia pa, lo jẹ ki awọn alajọgbele wọn o mọ nipa nkan to ṣẹlẹ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ogundiya: Àṣìṣe Dókítà ló sọ mi di aláàbọ̀ ara lórí kẹ̀kẹ́ Bakan naa ni ofin naa yoo fi aaye ọdun marun un silẹ fun awọn ile to wa fun lilo araalu lati ṣe atunṣe ti yoo mu ki awọn akanda ẹda, to fi mọ awọn to n lo kẹẹkẹ lara wọn lati le wọ awọn ile bẹ pẹlu irọrun.
ng, lẹyin naa, mu ipele tabi ẹka ti o ba fẹ darapọ mọ ninu SSC tabi DSSC.
to wa ni iluu Ado Ekiti ti pa bayii.
Àwọn ibùdó itaja si lo gbọ́dọ̀ pèsè ọ̀sẹ̀ ifọwọ àti omi fáwọn onibara wọn Ibùdó itaja ìgbàlódé taa mọ si Supermarket, kò gbọ́dọ̀ ni ju èèyàn mẹ́wàá lọ ní ẹẹkannaa Gbogbo ààlà ibodè Ìpínlẹ̀ Osun pẹlu awọn Ìpínlẹ̀ tó mule tíì ní yóò sì wà ní títì pá, tí kò sì ní si lílọ bibọ ọkọ àti èrò àyàfi àwọn ọkọ akẹru tó ń kó oogun, oúnjẹ, èròjà epo rọbi àti ohun ọ̀gbìn nìkan ni yóò rí Àwọn ọlọkọ èrò yóò leè ṣíṣẹ ni aarin ìgboro láti ọjọ́ Ajé si Ọjọ́bọ ni ọsọọṣẹ, bẹ̀rẹ̀ láti aago mẹ́fà àárọ̀ si márùn-ún irọlẹ, tí wọ́n ko si gbọdọ gbé ju èrò méjì si ìlà ijoko kọ̀ọ̀kan lọ nínú ọkọ wọn.
Àwọn ọmọ Seruaya mẹtẹẹta, Joabu, Abiṣai, ati Asaheli, wà lójú ogun náà.
Àròsọ àti ìgbàgbọ́ àwọn ènìyàn lórí gbígba ẹ̀jẹ̀ Dagunro ní ìtẹríba, tó sì ń gbé àṣà lárugẹ - Ọ̀gá Bello Kókó ọ̀rọ̀ tí Buhari sọ ní àyájọ́ June 12 Ghana ti mu àwọn afurasí ajínigbé ọmọ Naijiria mẹ́ta Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Bakan naa, ile igbinmo asoju naa tun jiroro lori
Ọlọ́pàá hú òkú akẹ́kọ̀ọ́ fásítì LASU tí ọ̀rẹ́kùnrin rẹ̀ àti pásítọ̀ ṣekúpa Ọ̀sẹ̀ àkọ́kọ́ ọdún 2020: Àwọn ìròyìn tó mí ìgboro tìtì Irọ́ ni pé àwọn ọ̀gá ọkùnrin ń béèrè fún ìbálòpọ̀ lọ́wọ́ àwọn òṣèrébìnrin- Jaiye Kuti 'Ipò àpọ́nlé ni mo fi Gómìnà Abdulrahman sí ṣugbọn kò hùwa àpọ́nlé' Arabi kede pe fun idi eyi ko si alekun owow ori ina mọnamọna rara.
eto aabo to peye wa ni jake –jado orile ede Naijiria  nipa fifowosowopo pelu ajo eleto aabo lorile
Oríṣun àwòrán, Genesis global Awọn akọrin-Ẹka awọn to n mojuto igbohunsafẹfẹ eto isin ninu ijọ naa.
Awọn agbófinró ti mú ọkùnrin agbébọn kan to yìnbọn lu àwọn olùkópa nínú ìdíje eré sísá ẹṣin ni Kano.
Ni kete ti awọn agbabọọlu Naijiria pari idije wọn pelu MAdagascar ni BBC Yoruba jade fọrọ wa awọn ololufẹ Super Eagles lẹnu woYan àwọn tí o fẹ̀ fún ẹgbẹ agbábọ́ọ́lù ààyò rẹ.
ede Naijiria, Mahmood Yakubu lo kede yii lasiko to n ba awon akoroyin soro
Ọga mi obinrin lo san owo irina mi.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Europa League: Arsenal fi Valencia ṣe àtẹ̀gùn wọ àṣekágbá 9 Èbibi 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Valencia ló kọ́kọ́ gbá bọ́ọ̀lù sáwọ̀n Gbogbo ẹni to ba wo ifẹsẹwọnsẹ to waye laarin ikọ agbabọọlu Arsenal ati Valencia l'Ọjọbọ ni yoo gba pe àwọn mejeeji lo mura giri.
Oríṣun àwòrán, @CBN Àkọlé àwòrán, Owó lowó n jẹ́, irọ ni pe a fẹ fofin de Naira to ti pẹ Ogbontarigi nidi iṣẹ ifowopamọsi yii ni koda banki Naijiria ti yọ owo ori kuro fun oṣu mẹta fun gbogbo baniki ki awọn le ri koriya fun igbesẹ owo didọti gbigba wọle yii.
Gomina El Rufai ni igbakeji oun yoo ma dari gbogbo eto nipa kikoju Coronavirus lasiko ti oun ba wa ni ayẹwo.
"Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù RCCG Virtual Convention: Kátàkárà mẹ́wàá tí yóò pàdánù àìsí ìpéjọpọ̀ ńlá RCCG lọ́dún yìí 7 Ògún 2020 Oríṣun àwòrán, RCCG Awọn agba maa n sọ pe ọdọọdun laa rorogbo, ọdọọdun laa rawusa Ṣugbọn atawusa atorogbo, ko seyi taa ri ninu awọn eto kọọkan to maa n waye lọdọọdun o - ""Coro"" lo fa a."
"Ikú Adewole Oniluola, tó ní ẹ̀bùn ìlù lílù jùlọ lágbàyéé, yóò nípa lórí Yorùbá - Tunde Kelani Ayinla Ọmọwura, orin èébú àti oríyìn lo fi di ọ̀rẹ́ àwọ̀n obìnrin Ẹ wo ojú àwọn afurasí tí yóò rojọ́ ẹ̀ṣùn àjẹbánu lọ́dún 2021 Bí Nàíjíríà bá fẹ́ kí ọdún 2021 dára, ohun tí yóò ṣe rèé - Obasanjo Ẹgbẹ́ ọ̀dọ́ méjì fìjà pẹẹ́ta, ẹ̀mí kan bọ́, ọ̀pọ̀ farapa ""Ìsìn oru ọdun tuntun ""Cross over service"" je ìsìn pàtàkì fawọn Kristẹni àti awọn musulumi kọọkan ṣugbọn nitori ajakalẹ Covid-19, ilana oriṣirisi ni wọn gbé kalẹ t'awọn mi sí wọgile ìsìn naa lodun yii."
Bẹẹ ba si gbagbe, Ayaba Fọlasade Adeyẹmi ti bi ibẹta fun Alaafin lọdun diẹ sẹyin.
tí mo fi kẹ̀yìn sí wọn, tí mo fi mú wọn wá sí ilẹ̀ àwọn ọ̀tá wọn; bí ọkàn wọn tí ó ti yigbì tẹ́lẹ̀ bá rọ̀, tí wọ́n bá sì ṣe àtúnṣe fún ẹ̀ṣẹ̀ wọn, 
Tani yoo jẹ aarẹ laarin awọn to n du ipo yi ni ibeere nla ti awọn eeyan n reti idahun si.
”OLUWA sì dáhùn pé, “Lépa wọn, o óo bá wọn, o óo sì gba àwọn eniyan rẹ.
Lẹyin ti idunadura naa pari ni Osimhen sọ loju opo Twitter rẹ pe inu oun dun lati darapọ mọ Napoli, koda o ni niṣe lo dabi pe ki oun ti wa lori papa.
Adesanmi n lọ fun ipade ajọ ilẹ Afirika ni Nairobi ko to ṣagbako iku ojiji ninu ijamba baalu ọhun.
Port Harcourt dumped babies: Iléeṣẹ́ ọlọ́pàá rí òkú ọmọ ọjọ́ kan he lórí ààtàn ní Port Harcourt
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'A fẹ́ kí àwọn sẹ́nétọ̀ gba ẹlòmíì láàyè' Samuel ni oun ko kabamọ lori iriri oun ni ahamọ ati pe o jẹ ohun ibanujẹ fun oun.
Pari pari ẹ lati fi awọn ọdaran ti wọn ba gbamu jofin.
3 1287092 Orilẹede Indonesia 18336 6.
Amọ, Ajọ to n ja fẹtọ ọmọniyan, Amnesty International sọ wi pe, orilẹede mejilelogoje lo ti fi ọwọ osi juwe ile si sise idajọ iku, ati wi pe, orilẹede mẹtalelọgbọn lo ti se idajọ iku laarin ọdun marun.
'Àwọn èèyànì ń fi orúkọ mi lu àwọn obinrin ní jìbìtì' 'Taló dà bí Ọlọ́run Fayose?
''Iṣẹṣe lagba, iṣẹṣe lo ni ile aye, babalawo nikan lo le ṣe etutu ti ọdalẹ ko fi ni raye wọ arin ikọ Amọtẹkun,'' Akoda Awo lo woye bẹẹ.
Egbe awon agbe  ti a mo si African Farmers and Cultural Organization (AFCO) nile-Afrika so pe, erongba won ni lati pese ise lopo yanturu fun  awon ti ko rise-se lorile-ede Naijiria nipase eto ogbin.
Oríṣun àwòrán, Others Ẹ fura o, Boko Haram ti pàgọ́ sí Abuja, yóò ṣe ìkọlù láìpẹ́ - Iléèṣẹ́ Aṣọ́bodè lọgun Ilé iṣẹ́ aṣọbode Naijiria (NCS) ti kéde fún àwọn òṣìṣẹ̀ rẹ̀ ní'lú Abuja láti bẹ̀rẹ̀ sí ni fi ojú ṣọ́rí nítorí asiri to tu pe ikọ̀ Boko Haram ti ni ìpagọ́ ni ilú Abuja ati gbogbo agbègbè rẹ̀.
O ni ijọba fun ra rẹ ati ẹgbẹ agbesunmọmi Boko Haram lo n tako alaafia orilẹede Naijiria.
Oríṣun àwòrán, @LFC Àkọlé àwòrán, Salah, Mane, Aurier, Wanyama yoo wọ ṣòkòtò kan náà láti gba ife ẹ̀yẹ UEFA Champions league ní ìlú Madrid Bakan naa ni Victor Wanyama, ọmọ orilẹede Kenya naa yoo wa nikalẹ fun ẹgbẹ agbabọọlu Tottenham hotspur.
80 Ijọba ti kede ẹkunwo epo bẹntiro lati ọgọrun un nairia le ni naira mọkanlelogun àbọ̀ (N121.
Michael's Primary School ti ilu Ado Ekiti lọjọ naa lọhun, bi Daniel ṣe ba gomina sọrọ ri bii ọmọ ọlọgbọn ni to bẹẹ ti gomina beere boya o lee wa ki oun sile.
Yorùbá fẹ́ràn ayẹyẹ ṣi ṣe púpọ̀, ṣùgbọ́n àṣà tó gbòde ni ayé òde òni, ni igbéyàwó àti ayẹyẹ bi ọjọ́ ìbí ṣi ṣe ni òkèrè.
Oríṣun àwòrán, Others Ọmọbinrin naa ko fi isẹlẹ yii se osun, ko fi kinra, amọ o dele, o sọ fun awọn obi rẹ, ti ọrọ naa si de etigbọ ẹgbẹ ajafẹtọ ẹni kan, to gba ẹjọ ọhun kanri.
Wọn kò gbọdọ̀ tà ninu rẹ̀, wọn kò gbọdọ̀ fi yáwó, wọn kò sì gbọdọ̀ fún ẹlòmíràn lára ilẹ̀ tí a yà sọ́tọ̀ yìí; nítorí pé mímọ́ ni, ti OLUWA sì ni.
Mi ò ní wọ Uber mọ́ tí wọ́n bá leè fi owó lée nítorí àfikún owó orí tí Sanwo Olu ṣe Èèyàn 373 ni ààrùn coronavirus tún ṣẹ̀ṣẹ̀ ràn ní Nàìjíríà - NCDC 'Inú mi dùn pé wọ́n dájọ́ sísọ̀kò pa bàbá arúgbó tó fipá b'ọ́mọ lòpọ̀' Ìjọba ìpínlẹ̀ Osun tí búwọlù ìlànà àyẹyẹ Ọṣun-Oṣogboo ọdún 2020 Ogundipe ni o farahan pẹlu awọn ẹgbẹ oluko NASU, SSANU àti ASUU nibi ti wọn ti n ṣe ifẹhọnu han lati inu ọgba fasiti naa titi de ẹnu abawọle ileewe giga naa.
"Alaye rẹ ni pe, ""O yẹ ki gbogbo aye mọ nisinyii pe ko si iṣẹ."
Òtítọ́ inú àwọn olódodo a máa tọ́ wọn,ṣugbọn ìwà aiṣootọ àwọn ọ̀dàlẹ̀ níí pa wọ́n.
ó bá wí fún gbogbo wọn pé, “Ẹ wo òkúta yìí, òun ni yóo jẹ́ ẹlẹ́rìí láàrin wa, nítorí pé ó gbọ́ gbogbo ọ̀rọ̀ tí OLUWA ti sọ fún wa, nítorí náà, òun ni yóo jẹ́ ẹlẹ́rìí fun yín, kí ẹ má baà hùwà aiṣododo sí Ọlọrun yín.
Àwọn ará Libia, àwọn ará Sukiimu, ati àwọn ará Etiopia wà ninu àwọn ọmọ ogun rẹ̀.
Ọdún ìbejì sọkutu-wọ̀wọ̀ ní Igboọrà, àṣírí bí wọn ṣe ń bí ìbejì tú Ìbejì Oníbẹ̀mbẹ́ Òru tí kò yara wọn lẹ́yìn ọgọ́ta ọdún Èèyàn 2,040 làwọn agbésùnmọ̀mí ti pa ní Nàìjíríà lọ́dún yìí- Ìwádìí Ẹ wo àwọn ọ̀dọ́mọdé Naijiria tó ń ṣe bẹbẹ nínú isẹ́ aládaní nílé Àkọlé àwòrán, A jijọ gbagbọ ninu Olorun ni lati igab ewe wa Awọn mejeeji ni lati inu oyun ni wọn ti sọ fun iya wọn pe iṣẹ Oluwa ni wọn maa ṣe.
Rivers Governorship Election: INEC ní Nyesom Wike ti PDP ló jáwé olúborí
Lẹyin to wọ ọdọkunrin yii sita tan lo dabọn bo o lẹsẹ.
 tíátà àṣà àti iṣe tí àwọn òsèrè máa ń lò latí ṣe ìgbélékè àṣà àti ìṣe tí ó ti dòkú , pàápàá ní ilẹ ̀ Áfíríkà .
 Ọba aládé sì ni gbogbo wọn .
Àti pé apá APC le máà ká ohun tó le tẹ̀yìn rẹ̀ yọ tí Buhari bá kọ̀ láti tú Zakzaky sílẹ̀.
Amọ ikede Ileesẹ Multichoice yii ti bọ sapo ibinu awọn ọmọ Naijiria lori ayelujara ati loju popo.
Aawọ ti ṣẹlẹ tẹlẹ laarin awọn akọnimọọgba Chelsea ati awọn to di owó ẹgbẹ agbabọọlu mu, ko si da bi ẹni wipe eyi yoo yi pada.
'Amọ, a gbọdọ wo ọrọ ti oun sọ fun itẹsiwaju orilẹede Naijiria ati awọn ikilọ rẹ lai bikita ibi ti ọrọ naa ti wa.
Bẹ́ẹ̀ náà ni àpótí ẹ̀rí pẹlu àwọn òpó rẹ̀ ati ìtẹ́ àánú náà; 
Dafidi tún fún un ní ìwé ètò pípín àwọn alufaa ati àwọn ọmọ Lefi sí ìsọ̀rí-ìsọ̀rí, ati ètò gbogbo iṣẹ́ ìsìn inú ilé OLUWA, ti àwọn ohun èlò fún ìsìn ninu ilé OLUWA; 
Ilana miran ti ijoba Ethiopia tún gunle ni lati ṣètò àwọn ilé ìtura kan fún àwọn arìnrìn-àjò tí wọn sì ti kan ń pá fún àwọn osise láti maa ṣiṣẹ láti ilé wọn àti pé gbogbo ẹnu ibodè tó wọ orileede náà ni kò wá ní titi pa.
Ọ̀sẹ̀ yìí ni orúkọ àwọn mínísítà yóò tẹ̀ wá lọ́wọ́ - Ilé aṣòfin àgbà Iṣu ló wà nínú mọ́tò mi, kìí ṣe èèyàn ni mo sọ di iṣu - Afurasí Ajínigbé figbe ta Mi ò m'àwọn ẹgbẹ́ tó ń gbé ''Tinubu 2023'' kiri- Bola Tinubu Ta ni Ọgágun àgbà Lamidi Adeosun tó ṣẹṣẹ gba ìgbéga?
Ṣùgbọ́n àwọn àgbàlagbà ronú pé ó ye kí kíni kan bí àmì wà, èyí tí wọn yóò fi máa mọ ara wọn.
Dokita yii sapejuwe eti gege bii eya ara elege ti ko faaye gba lilo oogun pupo fun itoju re nitori pe ohun to ba ti de bae ti, ti de ba imu ati ofun eniyan ni gegeg bi Eledaa se da eniyan.
Gbajugbaja abẹṣẹ-ku- bi-ojo ọmọ bibi orilẹede Naijiria, tó n sójú ilẹ Gẹẹsi, Anthony Joshua ni Ọbabinrin Elizabeth ilẹ Gẹẹsi ti fun ni àmì ẹ̀yẹ OBE.
Asofin Braimoh lo n soju ẹkun idibo Kosofe keji nile asofin ipinlẹ Eko.
Sísun mọ́ra pọ leè ṣe àkóbá, ó sì dáa kí wọ́n máa patẹ síwájú ilé wọn, dípò lílọ sì ọjà.
O Fagunwa ló kọ́kọ́ kọ ìwé kíkà Yorùbá àti ìwé l'édè Yorùbá.
Lọjọ Abamẹta yii naa ni Aarẹ Buhari pada siluu Abuja lẹyin isinmi ọdun Sallah to lọ ṣe niluu rẹ Daura lati ọjọ kẹjọ oṣu kẹjọ.
jankan-jakan ni won yoo foju bale ẹjọ ni ojo Aje fun iwa ibaje nipa sise owo ilu
Kí ni ẹ fi ṣe ohùn àwọn mẹ̀kúnnù?
Ṣùgbọ́n ẹni tí ó bá rí mi lákòókò yìí kò lè mọ̀ mí rárá nítorí aṣọ ara mi kún fún èérí, láàátọ́ mo ń gbìyànjú mo ń fọ̀ ọ́ nínú omi ṣùgbọ́n ko sí ọsẹ.
Awon bii Asojusofin Marco Rubio to je olori Cuba to wa nile okeere ti won fara pamo si nile America ti so fun Aare Donald Trump pe ko gbodo gba esi eto idibo naa wole nitori pe igbese eto idibo naa ko munadoko to.
"A nilo lati sowopọ, fimọṣọkan niru asiko bayii.
Mercy Aigbe: Èmi ni ìyá onílé tuntun Ẹni bá láyà: Ṣé ìwọ mọ àmì Yorùbá dáadàa?
Jerusalẹmu, ìwọ ilé ìṣọ́ agbo aguntan Sioni, ilé ọba rẹ àtijọ́ yóo pada sọ́dọ̀ rẹ, a óo dá ìjọba pada sí Jerusalẹmu.
Ìdomà jẹ ́ ẹ ̀ yà kan lára àwọn ẹ ̀ yà ilẹ ̀ nàìjíríà tí wọ ́ n ń sọ èdè Ìdomà ní bẹ ́ núé ìpínlẹ ̀ yi ni ó wà ní à ́ árín gbùngbùn orílẹ ̀ èdè nàìjíríà .
O ti fi igba kan ri jẹ olori ikọ alaabo ipinlẹ Eko, Rapid Respond Squad, RRS.
 awon the great red spot ' s egbegbe oju pupa ninla je 24-40,000 km × 12-14,000 km .
Wò ó bí Alaafin àti aya àkọ́fẹ́ rẹ̀, Olorì Abibat ṣe pàdé ní èwe Àwọn èrò yarí lórí sísan owó àyẹwò covid-19 bí bàálù ilẹ̀ òkèèrè ti ba s'Abuja lẹyìn oṣù márùn ún Ẹ wo ààrẹ orílẹ̀-èdè tó ń ṣèdárò Ẹja akóredé tó d'olóògbé Àbá àpérò 2014 CONFAB lojútùú sí àtúnṣe ìwé òfin Nàìjíríà- Afenifere sáwọn sẹ́nẹ́tọ̀ Ajọ NBS ni ọwọngogo ounjẹ buru jai lawọn nipinlẹ mẹrin wọnyii, amọ awọn eeyan ipinlẹ Rivers ati Abuja ko tii ri nkan nkan.
27 Ẹrẹ̀nà 2020 0:59 Fídíò, Chloroquine for coronavirus: Njẹ Chloroquine nipa kankan láti kojú Coronavirus?
Ọdun Ileya Ed el-Kabir yii jẹ eyi ti awọn musulumi maa n sami ọdun pipa ẹran agbo.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù George Floyd Funeral: Ìṣẹ̀lẹ̀ mẹ́fà tó mi àgbáyé nípasẹ̀ ikú George Floyd l'Ámẹ́ríkà 28 Èbibi 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 10 Òkùdu 2020 Oríṣun àwòrán, Getty Images Iku ọkunrin adulawọ kan ti a mọ si George Floyd kii ṣe iroyin tuntun mọ, koda wọn ti ṣe isinku rẹ pẹlu.
Bi Manchester United ni yoo bori ni bii Man City ni, ipade di ori papa.
“Awon omo egbe ECOWAS ti n seto ilana ti yoo tun je ki eto oro aje won ni idagbasoke sii.
Atẹjade kan ti ẹgbẹ Afenifere fisita ni awọn alaye ti wọn n ṣe nipa iku to pa awakọ baalu ologun naa tako ara wọn, to si nilo ẹkunrẹrẹ iwadii.
Aṣírí ìdí ti El-Zakzaky fi padà Nàìjíríà láti India Fayemi fojú Alufa to fipa bá ọmọde lòpọ̀ síta l'Ekiti 'Àlàyé rèé lórí ìdí ti mo fi na ọmọ òrukàn, tí mo sì tì í mọ́ ilé ajá' Samson Siasia fèsì lórí FIFA tó fòfin dèé Àwòrán àwòdamiẹnu rèé lásìkò ọdún Ọ̀ṣun Osogbo Àjẹ́ àti Aṣẹ́wó ní ìyá Rainbow - Òjòpagogo Wo orílẹ́èdè tí wọ́n tí ń dáwó ìsìnkú ara wọn pámọ́ Eekan lara awọn oṣiṣẹ eleto aabo sọ fun iwe iroyin Punch pe yoo nira fun ijọba lati fun El-Zakzaky ni iru aye bẹẹ nitori ohun tawọn ileeṣẹ ọtẹlẹmuyẹ jabọ fun ijọba lori eto aabo nilẹ India ko tẹ ijọba lọrun.
Patience Jonathan gbójú kúrò lára owó ẹ
Pelosi ni ile igbimọ maa to ṣe agbekalẹ ofin ti yoo din agbara ti aarẹ ni ku lati gbe iru igbesẹ to fi sibi kan yii nipa didina mọ awọn ọmọ orilede kan lati ma le wọ Amẹrika.
Wọ́n ti fi omi lú ọtí waini rẹ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Coronavirus: Ǹjẹ́ fífi omi àti iyọ̀ yọnu leè dènà àrùn Coronavirus?
Bakan naa lo sọ pe kokoro aarun covid-19 le wa laaye yala lara ohun elo ere idaraya ti ẹni to ni aarun naa ba ti lo, nitorinaa ''asiko yii ko dara fun ṣiṣe ere idaraya nitori ewu to wa nibẹ pọ.
Ìwọ wá wí fún wọn pé, èmi OLUWA ní n óo rọ àwọn tí wọn ń gbé ilẹ̀ yìí ní ọtí àrọyó, ati àwọn ọba tí wọn jókòó lórí ìtẹ́ Dafidi, ati àwọn alufaa, àwọn wolii ati gbogbo àwọn tí ń gbé Jerusalẹmu.
Samuel Eto o fi búùtù bọ́ọ̀lù rẹ̀ kọ́, Ó ní òun kò gbá bọ́ọ̀lù mọ́ Wo àwọn ẹranko tí wọ́n máa figagbaga ni Egypt nínú AFCON 2019 Ta ni Ọ̀jọ̀gbọ́n Tijjani Bande tó di Ààrẹ ẹ̀ka Isọ̀kan Àgbáyé UNGA?
Josẹfu lọ sin òkú baba rẹ̀, gbogbo àwọn iranṣẹ Farao sì bá a lọ, ati gbogbo àwọn ẹmẹ̀wà ààfin ọba, ati gbogbo àwọn àgbààgbà ìlú Ijipti, 
Imam tó fẹ́ ọkùnrin míì níyàwó forí kó ìjìyà òfin
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Illegal Rehab Centre: A le ni ogójì tí wan n kó 'sinú ìyará kékeré kan níle Ọlọrẹ Bakan naa lo sọ ninu oṣu kẹta ọdun yii pe oun ko ni dije ninu ibo aarẹ ọdun 2020.
Ṣugbọn, Adajọ ni ko si awawi kan fun Balogun nitori ẹri to daju wa wi pe o jẹbi ẹsun ti wọn fi ka an.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, South Africa: Àwọn ọmọ Nàìjíríà tó kù ní ìjọba SA ń kó ọ̀pọ̀ tó fẹ́ wále sí ọgbà ẹ̀wọ̀n Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Owo to le ni bilionu naira  ati awon opolopo dukia ni awon ajo to n ri si sise owo ilu kumo-kumo  ati esun miiran EFCC ati ICPC, ti ri nipase gbigbokun ti iwa ibaje.
Kí á lè là wọ́n lójú, kí á sì lè yí wọn pada láti inú òkùnkùn sinu ìmọ́lẹ̀, kí á lè gbà wọ́n lọ́wọ́ àṣẹ Satani, kí á sì fi wọ́n lé ọwọ́ Ọlọrun; kí wọ́n lè ní ìdáríjì ẹ̀ṣẹ̀ nípa gbígbà mí gbọ́; kí wọ́n sì lè ní ogún pẹlu àwọn tí a ti yà sọ́tọ̀ fún Ọlọrun.
Ajimobi ni ''a kii mọọ rin, k'ori ma mi,'' o ni oun gba pe oun ṣe awọn aṣiṣe kan ṣugbọn oun tọtọ aforiji lọwọ gbogbo ọmọ ẹgbẹ.
Iwadi awọn onimọ sayẹnsi sọ pe bi a ṣe n dagba ni awọn eroja ara yi n ku, to si n fa wahala fun agọ ara wa.
Àwọn akọrin nìwọ̀nyí: àwọn ọmọ Asafu jẹ́ mejidinlaadọjọ (148).
ẹ wárìrì níwájú rẹ̀, gbogbo ayé,ó fi ìdí ayé múlẹ̀ gbọningbọnin kò sì lè yẹ̀ lae.
Yomi Lanso wipe ka jọ gbadun laye
Pẹpẹ idẹ tí a ti yà sọ́tọ̀ fún OLUWA wà ní ààrin pẹpẹ tirẹ̀ ati ilé OLUWA.
Ṣùgbọ́n lẹ́yìn ejò náà ni a o ri ejò ọká tí ó ká jọ tí ó gb’’e ẹnu sókè hanha.
“ ‘O kò gbọdọ̀ bọ oriṣa, èmi OLUWA ni kí o máa sìn.
Oríṣun àwòrán, @Nigerian Army Àkọlé àwòrán, Aworan awọn ọmọ ogun naa farapa nibi iṣẹlẹ naa Eyi kii se igba akọkọ ti ikọlu yoo ma waye laarin awọn ọmọ ogun Naijiria ati ọmọ ẹgbẹ Shiite papajulọ lati igba ti awọn ologun ti sọ olori wọn Ibrahim El-Zakzakky si ahamọ.
Akori ipade ohun ni “awon akowe ile-ise ati awon oga akowe: ifowosowopo fun idagbasoke oja idokowo”.
gudu gudu meje , yaya mefa, ti won gbese lasiko eto idibo to waye lorile ede
Gege bi oro re, pipise eyawo ti ko lere-lori lati sise agbe, yoo sadinku ise ohun osi ati airise se awon eniyan.
America blacklisted Nigeria: Amẹ́ríkà fi orukọ Nàìjíríà sínú ìwé 'mágùn' nítorí òmìnira ẹ̀sìn.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Champions league: A jurawa lọ, Liverpool kó àjọ ìyà lọ́wọ́ọ Barcelona Kíní ìdájọ́ Caster Semenya túmọ̀ sí fún àwọn obìnrin eléré ìdáraya?
Ori ade yi gẹgẹ bi ohun ta ri gbọ lo ọdun mejidinlaadọta lori apere ki o to dagbere faye lọjọ Iṣẹgun ni aafin rẹ to wa ni agbegbe Okorun.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Aṣòfin méje yarí mọ́ Akeredolu lọ́wọ́ torí ọkọ̀ ayọ́kẹ́lẹ́ tí kò pín fún wọn Aya gómìnà Kwara gba ilé fún Risikat olójú búlúù àti ọkọ rẹ̀ Risikat, ìyá àwọn ọmọ olójú búlù tí bẹ̀rẹ̀ sí ní kọ́sẹ́ aṣojú lóge Àwọn ọ̀daràn tó jí ìbejì ọmọ Akeugbagold kó ti fojú ba ilé ẹjọ́ lòníì Àjọ ECOWAS yan Aàrẹ Ghana, Nana Akufo-Addo gẹgẹ bíi aàrẹ tuntun Àrà mánigbàgbé tí Baba Legba dá lágbo tíátà rèé Foluke to ni lootọ ni baba naa dagba, ti oun si ba sọrọ lọsẹ to kọja sugbọn ọwọ mi di pupọ nile ounjẹ ti oun da silẹ lati bẹ ẹ wo.
Iṣẹ awọn ọlọpaa SARS ni lati gbogun ti iwa ibajẹ lawujọ paapa julọ lati daabo bo awọn ara ilu lọwọ awọn adigunjale.
Eagle Square to wa niluu Abuja nibi ti ayẹyẹ naa yoo ti maa waye.
Lẹyin ọ rẹyin, Brighton ṣina iya fun Tottenham pẹlu ami ayo mẹta sodo lairo tẹlẹ.
Yakubu Dogara padà sí APC, Buhari kí i kúàbọ̀ ní Aso Rock Wo àwọn tí wòlíì ríran sí pé COVID-19 yóò pa ní ìpínlẹ̀ Edo l'óṣù kẹsàn án Nǹkan mẹ́sàn án tí Mùsùlùmí gbọdọ̀ ṣe nínú oṣù Dhual- Hijjah Ẹwẹ, eeyan 16,559 lo ti ri iwosan gba ti wọn si ti ja ajabọ lọwọ ajakalẹ arun naa.
Dino Melaye nàá tí kán l'ọ́rùn rí Láìpẹ́ yìí ni iléèṣẹ́ ọlọ́pàá Nàìjíríà gbé aṣòfin Dino Melaye lọ sílé ẹjọ́.
Wolii ni aṣọ́nà fún Efuraimu, àwọn eniyan Ọlọrun mi, sibẹsibẹ tàkúté àwọn pẹyẹpẹyẹ wà lójú gbogbo ọ̀nà rẹ̀, ìkórìíra sì wà ní ilé Ọlọrun rẹ̀.
Ninu iwe ikinni ti gomina naa fi ransẹ lati ọdọ oluranlọwọ  gomina lori eto iroyin ati isẹ akanse ,si
Wo àwọn ìlérí tàwọn Gómìnà tuntun ṣe nínú ìbúra wọn
Bakan naa ni awọn eekan ilu yii tun n rawọ ẹbẹ sawọn ọmọ Naijiria to n gbẹsan ikọlu ọhun lara awọn eeyan ati ileesẹ to jẹ ti ọmọ ilẹ South Africa to wa ni Naijiria pe, ki wọn bomi suuru mu nitori aforo yaro kii jẹ ki oro tan.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Bàbá tó pokùnso: Ọmọ ọdún mẹ́jọ ni ọmọdébìnrin tí baba rẹ̀ bá seré oge 17 Ẹrẹ̀nà 2019 Oríṣun àwòrán, Times Ọkunrin kan, Razak Hamed ti pokunso ni ahamọ awọn osisẹ aabo ara ẹni, laabo ilu, NSCDC, nilu Akurẹ.
Alaga ẹgbẹ NURTW nipinlẹ Ọyọ, Alhaji Abideen Olajide, ti gbogbo eeyan mọ si Ejiogbe lo n parọwa bẹẹ ninu atẹjade kan to fisita, pẹlu afikun pe bi gomina Makinde se fofin de isọwọ sisẹ awọn asaaju ẹgbẹ ọlọkọ ero, ti di ọna ijẹ wọn lojumọ.
Aubameyang tun gba yo mii sawọn, ki Cedric Soares to fi ẹlẹẹkẹrin le.
3)Sísọ oko mọ Asetani: Pàtàkì ìjọsìn yíi ni pé awọn alalaaji n fí kọ iṣé Anobi Ibrahim ati ọmọ rẹ, nígbà tí wọn sọ oko mọ Asetani to fẹ dena wọn nínú ìjọsìn.
Lopin ipade naa, awọn olori orilẹede mejeeji fi ọwọ si iwe adehun igbọraẹniye lori eto ọgbin, ọkọ ṣiṣe, to fi mọ ipese owo yiya fun awọn agbẹ.
Aare Muhammadu Buhari so pe orile-ede Naijiria yoo tesiwaju lati maa gbe papa ni irepo.
Leon van Biljon dí èrò ọrun nípasẹ̀ Kìnìún rẹ̀ FRSC dá N443,180 padà fún ẹbí ẹni to ní ìjàmbá mọ́tò Oríṣun àwòrán, EPA Àkọlé àwòrán, Mo ṣetan lati fi ẹmi mi wa ojutu si ọrọ Brexit - Boris Boris Johnson kede pe Obabinrin a ba awọn eniyan sọrọ ni ọjọ kẹrinla, oṣu kẹwaa dun ki awọn ọmọ ile igbimọ aṣofin to bẹrẹ ijokoo ile pada.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Cristiano Ronaldo: ''Ronaldo ṣì lè padà sí ẹgbẹ́ agbábọ́ọ̀lù Real Madrid'' 9 Ìgbé 2020 Oríṣun àwòrán, Instagram/Cristiano Ronaldo Ko le ja iyalẹnu ti agbabọjẹ agbabọọlu, Cristiano Ronaldo ba pada si ẹgbẹ agbabọọlu Real Madrid.
Wọn yóo máa fún ara wọn lẹ́bùn.
Fi mí sílẹ̀ kí n lè ní ìtura díẹ̀,
Ero mẹwa lo wa ninu ọkan lara awọn ọkọ oju omi naa, to nbọ lati agbegbe Ọjọ jetty, mẹjọ si wa ninu eyi to n bọ lati ileto Irewe, eyi to mu ki apapọ awọn ero to wa ninu awọn ọkọ oju omi naa, lasiko ti ijamba naa fi waye jẹ mejidinlogun.
” Jaeli bá ṣí ìdérí ìgò tí wọ́n fi awọ ṣe, tí wọ́n da wàrà sí, ó fún un ní wàrà mu, ó sì tún da aṣọ bò ó.
Dokita agba ni ileewosan naa, Dokita Gani Kalẹ ṣalaye fun aya aarẹ pe, ọmọ wẹwẹ mẹwa ni wọn ko wọ ileewosan naa lọjọ ti iṣẹlẹ naa ṣẹlẹ.
(Nítorí pé, Ogu, ọba Baṣani nìkan ni ó kù ninu ìran àwọn Refaimu.
Nigba to n salaye idi to fi se bẹẹ, Oshodi oke ni  ọrẹ mi ni ọ MC Oluọmọ, o maa n duro ti mi lọpọ igba, o maa n satilẹyin fun mi, to si maa n fun mi ni iwuri, to ba gbọ ọpọ ohun ti awọn ọrẹ ti se si mi."
Nítorí náà, Ọlọrun rán àjàkálẹ̀ àrùn sórí ilẹ̀ Israẹli, àwọn tí wọ́n kú sì jẹ́ ẹgbaa marundinlogoji (70,000) eniyan.
" Oríṣun àwòrán, Others Nigba to n sọrọ lori eto ọgbin ọlọpọ eniyan, Osinbajo ni ijọba ti se akọsilẹ miliọnu mẹrin agbẹ lati kopa ninu rẹ.
Angẹli náà bi mí pé, “Kí ni o rí?
Àwọn ẹran tí wọ́n yà sọ́tọ̀ fún ẹbọ jẹ́ ẹgbẹta (600) akọ mààlúù, ati ẹgbẹẹdogun (3,000) aguntan.
Ile ẹjo naa wa sun igbẹjọ naa si Ọjọ Aje, ki Onnoghen fi le raye wa wi ti ẹnu rẹ lori ẹsun ti ijọba apapọ fi kan an.
Aarẹ ẹgbẹ agbabọọlu lorilẹede Naijiria, Amaju Pinnick ati awọn mẹrin miiran ti fi oju ba ile ẹjọ lori ẹsun pe wọn lu owo to to ẹgbaarin o le ni irinwo owo dọla ilẹ okeere ti Ajọ erebọọlu ni Agbaye, FIFA san fun Ajọ erebọọlu Naijiria(NFF).
Ẹ̀rú ọkùnrin náà bà mí àfi bí mo bá máa purọ́, wéré ni mo dọ̀bálẹ̀ àìròtẹ́lẹ̀, bí mo fẹ́ bí mo kọ̀ ni mo bẹ̀rẹ̀ sí tẹríba, n kò lè wáá rí ọ̀ràn ọ jàre.
Banky W naa sọ pe iroyin ọ̀hún fọwọ ba oun lẹmi tohun ti iroyin isẹlẹ ipaniyan to waye ni ipinlẹ Plateau Olamide ati Davido ko gbẹyin Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, APC Primaries: 'Kò sí 'Faction' ni Kwara APC rárá, NWC ti sọ̀rọ̀' Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, #Oshimole: Àwọn aṣáájú APC kò mọ ohun ti wọ́n n ṣe lásìkò yí Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Mo maa n wo bawọn ọmọkunrin mẹta kan ṣe maa n ṣiṣẹ amurele wọn nile ọga mi onifa lagbegbe Oke Popo.
O fi han loju opo instagram rẹ pe kii ṣe nigba to rẹ ẹ nikan ni Ronke foju han gẹgẹ bi ọrẹ rẹ, ojo ti n pa igun wọn bọ ọjọ ti pẹ.
Wọn yóo gba ìlú mímọ́ fún oṣù mejilelogoji.
Nisinsinyii, ẹ̀yin ọmọ mi, ẹ gbọ́ ọ̀rọ̀ mi,ẹ má sì kọ ọ̀rọ̀ sí mi lẹ́nu.
Duro Ladipọ, ìlúmọ̀ọ́ká òṣèré tíátà àti ọmọ àlúfà tí kò gbàgbé àṣà ìbílẹ̀ Irọ́ ńlá ni pé a ǹ dá àwọn òṣìṣẹ́ wa dúró - Access Bank Obìnrin kan lu ọ̀gá ọlọ́pàá, ó tún gé ọmọ'ṣẹ́ ọlọ́pàá jẹ nítorí òfin ìséde ní Eruwa Ọwọ́ tẹ báàlẹ̀, Ṣinkó mẹ́tàdínlógún tó ń jí kùsà wà ní ìpínlẹ̀ Ọ̀ṣun Ṣáájú sì ni ìjọba Ìpínlẹ̀ Eko ti kede pé ìdá ọgọ́ta nínú ọgọ́rùn-ún èrò táwọn ọlọkọ ń gbé sínú ọkọ wọn tẹ́lẹ̀, ní kí wọ́n máa gbé báyìí, kí àwọn èrò leè ráyè takete síra wọn.
Ìwọ ọ̀rẹ́ mi, gẹ́gẹ́ bí mo ti sọ fún ọ ni ijọ́ sí ògbólógbòó àjẹ́ ni ìyá mi.
Anfaani ti Chelsea ri ko pọ ṣugbọn Tammy Abraham rapala jẹ goolu kan ti Jorghinho si padanu gbe silẹ gba sile ti wọn ri.
Awọn ẹlẹgbẹjẹgbẹ ti wọn n pe ni Rẹgbẹrẹgbẹ to wa ni isọri-isọri ọjọ ori kọọkan ni yoo se afihan bi wọn se lee tadireke si.
Àgùtàn Arsenal kò tíì paṣọ èṣí dà lábẹ́ Mikel Arteta Kí ló ṣẹlẹ̀ tí a fi ń pé ọjọ́ kejì Kérésì ní 'Boxing Day'?
Ni osu kọkanla ọdun 2017 eeyan mẹrinlelogun ni wọn se iku pa ti wọn si tun da ina sun awọn ile lasiko ti awọn ole aji maluu yii kọlu ileto mẹta ni ipinlẹ Zamfara yii kan naa.
Oríṣun àwòrán, others 9) Oluwatosin Ayoyinka Abass: Oluwatosin Ayoyinka Abasi jẹ akọrin lorilẹ-ede Amẹrika amọ to jẹ ojulowo ọmọ Oodua.
Aare Buhari tun tesiwaju pe eto idibo oni yii, ni nnkan se  pelu ojo iwaju orile ede Naijiria, boya lati tẹsiwaju tabi pada sẹyin sinu oko ẹru ati ijoba amunisin.
A máa ṣe pé n kò fẹ́ràn yín ni?
Kingston ti di ọmọ ilẹ Afirika keji bayii ti yoo gba ami ẹyẹ WrestleMania, bẹẹ oun ni ẹni kẹrin ti yoo di ajijakandi lagbaaye.
Eyi waye lẹyin abajade idajọ adajọ agba, Mojisola Olatoregun ni ile ẹjọ giga to wa ni ipinlẹ Eko to si paṣẹ pe ki iyawo aarẹ Patience Jonathan lati gbagbe $8.
ri daju pe iṣọwọṣiṣẹ awọn wa lọna to tọ gẹgẹ bi ilepa Ipinlẹ Eko ṣẹ
Minisita fọrọ ofurufu, Hadi Sirika lasiko to n fesi ṣalaye pe ẹsun naa ko ni idi nlẹ nitori pe ohun to pọn dandan ni ki wọn ṣe ayẹwo ọkọ ofufuru ati awọn eniyan to ba balẹ si papakọ ofurufu lorilẹ-ede Naijiria.
Ni kete ti awọn oyinbo naa ba si ti ra awọn ẹru yii, ni wọn yoo fi irin gbigbona kọ orukọ wọn siwaju ẹru wọn, Wọn yoo sọ ẹwọn irin si wọn lọwọ ati ọrun, fun ọjọ pipẹ, ki wọn to ko wọn lọ silu oyinbo.
Aarẹ Lukashenko bori pẹlu ida 80.
Kí ó yẹ àrùn náà wò, bí ó bá jẹ́ pé lára ògiri ilé ni àrùn yìí wà, tí ibi tí ó wà lára ògiri náà dàbí àwọ̀ ewéko tabi tí ó pọ́n, tí ọ̀gangan ibẹ̀ sì jìn ju ara ògiri lọ.
Awọn obinrin ileto naa ni awon da owo naa, lati lee dẹkuun ipenija ati iṣoro to rọ mọ gbigbe awọn alaboyun lọ si ileewosan, eyi to n koju wọn.
10,000 Police constables: Ilé ẹjọ́ wọ́gilé ètò ìgbanisíṣẹ́ tí ọgá ọlọ́pàá ṣé lọdun 2019
Ayantunde naa rọ wọn pe ki ọmọde kankan ma ṣe ri talẹnti wọn mọlẹ nitori pe Oluwa lo mọ ọjọ ọla ẹda.
Àkọlé àwòrán, Ballon D'or 2019: Ronaldo ló dáńtọ́ jùlọ (GOAT), bó tilẹ̀ jẹ́ pé Messi ló gb'àmì ẹ̀yẹ Ballon D'or Ija ilara ko le tan laelae, ajuwọn lọ ko ṣee wi lẹjọ, Virgil van Dijk to ṣe ipo keji ni Messi ni Eleduwa gbade ere bọọlu fun un.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Bakare Mubarak: ọ̀pọ̀ èèyàn ló máa ń fẹ́ dúró sí ẹgbẹ́ mí tójú si máa n tì mí Akintọla jẹ minisita eto ilera, ibaraẹnisọrọ ati minisita ọkọ ofurufu.
Bẹ́ẹ̀ ni àwọn ìlú tí a ti wó palẹ̀ yóo kún fún ọ̀pọ̀ eniyan.
Idagbasoke IsokanAare ro won pe “Bi ipinnu ati afojusun yin se jẹ lati tan ihinrere kaakiri gbogbo orile ede Naijiria , e  lo  emi irele ,otito, ife ati isokan lati tan ihinrere naa ka.
O ni awọn ọdọ pọ lori ayelujara ti wọn nifẹ Ramoni, ti wọn si bọwọ fun un.
Bakan naa ni wọn ṣeleri pe awọn yoo ma a fito awọn ara ilu leti bi o ba ṣe n lọ, lori eto iranwọ fun awọn eniyan agbeegbe naa.
Ṣé o lágbára bí èmi Ọlọrun,àbí o lè sán wàá bí ààrá, nígbà tí o bá ń sọ̀rọ̀?
Gambari sọrọ yii fawọn akọroyin lẹyin to bẹrẹ iṣẹ nileeṣẹ ijọba l'Ọjọru niluu Abuja.
Iru nkan bẹ ma n fi oró silẹ sinu agọ ara ni, to si le fa akoba lọjọ iwaju.
Èmi óo gbé ọ ga, Ọlọrun mi, Ọba mi,n óo máa yin orúkọ rẹ lae ati laelae.
Ìwọ ati ilé baba rẹ; nítorí ẹ ti kọ òfin OLUWA sílẹ̀, ẹ sì ń sin oriṣa Baali.
Ọwọ ti tẹ ọkunrin ẹni ọdun mejilelọgbọn kan ti orukọ rẹ n jẹ Muhammad Zulfara'u Alfa ni agbegbe Kwanar Dangora ni ipinlẹ Kano.
Buhari ti so di mimo fun onikaluuku lati igba ti o ti gori aleefa pe, oun ko ni
Coronavirus in Nigeria: Makinde kò yan Buhari ní pọ̀ṣìn, síbẹ̀ kò léè máa kọ lẹ́tà ìfẹ́ síi nítorí ṣekárími-PDP Oríṣun àwòrán, Seyi makinde Ko si ija laarin gomina Seyi Makinde ati aarẹ Buhari.
ni esi ibo ẹgbẹrun mọkandinlogun-le-ọọdunrunleaadọta ati mẹfa (29,356)
Covid-19 Vaccine: Joe Biden náà ti gba abẹ́rẹ́ àjẹsara
Ìsèjọba ìgbìmọ̀ asòfin dára ju ìsèjọba ààrẹ lọ -Femi Okunronmu Awọn ọmọ ìjọ sàtánì ń bínú sí Nàìjíríà Gbajabiamila kéde èróńgbà rẹ̀ láti jẹ adarí ilé aṣojú ṣòfin l'Abuja Keyamo àti Fani-Kayode faraya Femi ni iwa aida to ba irinajo ọjọ iwaju awọn ọdọ marun un jẹ ni ọlọpaa tẹlẹ yii hu.
abadofin yii lose meji to n bo.
Onidajọ Jide Falola ti ile ẹjọ giga naa to wa ni ilu Ikirun sọ pe awọn mẹtẹẹta, Nuhu Jimoh, Ndubisi David ati Aderibigbe Oluwaseun, jẹbi ẹsun jija banki mẹta l'ole nilu Ikirun l'ọdun 2016.
 Àwọn steroid , fún mímú ibití ó wú lọ sílẹ ̀ nígbà ìtọ ́ jú , àti àwọn egbògi tí ndènà gìrì ni a tún lè nílò pẹ ̀ lú .
Oun paapa sọ pe opin ko ti i deba irinajo ifẹ oun ati Vee, ṣugbọn oun kii ṣe ọkunrin to sare ma n mu ọrọ ifẹ ni kole-kole.
ati ijoba apapo se fowosowopo lati mu ipinnu won sẹ nipa ogbeni Godwin
Idahun iya ni wi pe bi o ba dan an wo, o fẹ sun ita niyẹn."
Oríṣun àwòrán, Others O fi kun un pe, ẹya gbogbo lo ni agbara ti Eleduwa fun un; lara agbara ti Eleduwa si fun ilẹ Yoruba ni Magun, ma debẹ si lẹrọ rẹ.
Mose bá rán àwọn ọkunrin tí wọ́n jẹ́ olórí ninu ẹ̀yà wọn lọ, láti aṣálẹ̀ Parani.
Ijamba ọkọ tirela to sẹlẹ lori afara Kara ni ilu Eko gbẹmi mẹrin
Pada kí àwọn ará ìlú rẹ gbogbo sì máa bá ọ lọ.
Ilé-iṣẹ́ ìpìlẹ̀ Sathi jẹ́ ilé-iṣẹ́ fún àlàáfíà àti ìmójútó ààbò ẹgbẹ́ abódiakọ-akọ́diabo ní Pakistan.
Ọjọ́ ìrántí ni ọjọ́ yìí yóo jẹ́ fún yín, ní ọdọọdún ni ẹ óo sì máa ṣe àjọ̀dún rẹ̀ fún OLUWA; àwọn arọmọdọmọ yín yóo sì máa ṣe àjọ̀dún yìí bí ìlànà, gẹ́gẹ́ bí ohun ìrántí títí lae.
 O ni kii ṣe akoko niyii lati maa sọ pe ọmọ tuntun ti Ooni bi ni yoo di Ọba lọla nitori wọn ko mọ iru ori to yan, Ọba le bi ọmọ mẹwaa, kii si ṣe dandan ni pe akọbi ni yoo gori itẹ lẹyin baba rẹ, o le jẹ abigbẹyin.
ẹ lè fi ẹnikẹ́ni tí OLUWA Ọlọrun yín bá yàn fun yín jọba, ọ̀kan ninu àwọn arakunrin yín ni ẹ gbọdọ̀ fi jọba, ẹ kò gbọdọ̀ fi àlejò, tí kì í ṣe ọ̀kan ninu àwọn arakunrin yín jọba.
Baba re to n gbin ẹfọ ati eso ninu oko rẹ ni Daura, ṣaaju ko to lọ France fun ipade apero 'One Planet' l'ọdun 2017 Oríṣun àwòrán, @buhari Àkọlé àwòrán, Ipade Aare Buhari pelu awon loba-loba nilu Jos Oríṣun àwòrán, @buhari Àkọlé àwòrán, Buhari nigba ti o n ṣabewo sawọn eniyan ipinlẹ Benue leyin ọpọlọpọ ikọlu BBC News, Yorùbá Ìdí tí ẹ fi le è nígbàagbọ́ nínú ìròyìn BBC Ìlànà Lílò Nípa BBC Òfin Àṣírí Cookies Kàn sí.
Bakan naa ni awọn sinima bii Iru ẹsin, Baba jayejaye ati ọpọ sinima miran tun gbe orukọ rẹ jade.
Wo àwọn ohun márùn ún tó yẹ kí o mọ̀ nípa Sanusi Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Gẹgẹ bi awọn itakun iroyin abẹle ṣe sọ, nigba ti ipade naa yoo fi pari, ẹrin ayọ lo gba ẹnu awọn ọbalade naa kan.
Ohun ti á fara ṣiṣẹ́ fún ní í pẹ́ lọ́wọ́ ẹni
Bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé imọ nípa isẹ agbẹjọro ni Samuel kọ ní fasiti, síbẹ̀ ere tíátà tó jogún lọdọ baba rẹ, lo yàn ni ààyò.
Ninu ọrọ wọn, ẹgbẹ NAAPE ni awọn ko ni da iyanṣẹlodi naa duro lai ṣe pe ileeṣẹ Bristow gbe igbese lati yi ipinnu wọn pada.
Ọ̀rọ̀ tí yóò bá ìbínú rẹ̀ pàdé, mo níláti kọ̀ ọ́ sílẹ̀, Oúnjẹ tí kò fẹ́ n kò gbọdọ̀ gbe fún un.
À ń retíi rẹ̀ kí ó dé kíákíá ní àlàáfíà ara àti ẹ̀mí, a ó máa gbé àwọn ìròyìn síta nípa ìròyìn yìí bí ó ba ṣe ń tẹ̀ wá lọ́wọ́.
Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Hanan Buhari wedding: 'Cartoon' tí Bulama yà nípa ìgbéyàwó ọmọ mi kò bójúmu tó - Aisha Buhari8 Owewe 2020 Fídíò, Akomolede: Bolaji Faleke ni Olùkọ́ tó ń kọ́ wa ní àṣà oge ṣiṣe lórí BBC Yorùbá1 Owewe 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 3 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 5 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Lẹ́yìn tí ó bí Metusela, ó wà ní ìrẹ́pọ̀ pẹlu Ọlọrun fún ọọdunrun (300) ọdún, ó sì bí àwọn ọmọ mìíràn lọkunrin ati lobinrin.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Victor Agunbiade ni ojú àlá ni Ọlọrun ti yan iṣẹ́ ọmọ ogun ojú omi fún òun ní America Ninu ọrọ rẹ, Ozekhome ni iditẹmọni ni ipade pajawiri ti wọn pe lati yọ Ogundipe kuro nipo.
Kini ọna abayọ si ijamba ina ninu ile?
Amọ ero awọn kan yatọ lori eyi, igbagbọ wọn ni pe irẹpọ ti ko si laarin igbimọ lọbalọba ati ijọba ipinlẹ Kano, lo fa igbesẹ naa.
Absalomu ati àwọn ọmọ ogun rẹ̀ pàgọ́ sí ilẹ̀ Gileadi.
Ninu fidio ọhun, Aisha Buhari n pariwo pe ki ẹbi Daura ko kuro ni ile ti wọn fun wọn gbe ninu Aso Rock.
Iná bo gbogbo eniyan ati àwọn ẹranko.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Fayose: Awọn to wa nijọba Buhari ko lee jẹ ki Boko Haram dẹkun 3 Ẹrẹ̀nà 2018 Oríṣun àwòrán, @GovAyoFayose Àkọlé àwòrán, Fayose ni ẹnu n kun awọn osisẹ ijọba Buhari lori ẹsun ijẹkujẹ Gomina ipinlẹ Ekiti lẹkun iwọ oorun Naijiria, Ọgbẹni Ayọdele Fayose, ti ke gbajare sita wipe n se ni awọn oṣiṣẹ ijọba to wa lode bayii n lo anfani awọn ibudo ti awọn atipo ati awọn ti ogun le kaakiri lorilẹede Naijiria lati fi palẹ obitibiti owo ijọba mọ.
Ọpọlọpọ ìmọ̀ràn tí wọn fún ọ ti sú ọ;jẹ́ kí wọn dìde nílẹ̀ kí wọ́n gbà ọ́ wàyí,àwọn tí ó ń wojú ọ̀run,ati àwọn awòràwọ̀;tí wọn ń sọ àsọtẹ́lẹ̀ ohun tí yóo ṣẹlẹ̀ sí ọ,nígbà tí oṣù bá ti lé.
Lásìkò tí BBC Yoruba ń ba àwọn alága ẹgbẹ́ òṣèlú méjèèjì sọ̀rọ̀ Ade Adesanmi ti NLC àti Odunayo Adesoye ti TUC sàlàyé pé gbogbo ẹni to bá ni ẹ̀rí lórí ọ̀rọ̀ náà kó jáde wa.
Olówó-ayé dúpẹ́ lọ́wọ́ obìnrin yìí, Àjẹ́dìran sì dúpẹ́ nítorí olùfẹ́ rẹ̀ tuntun yìí, lẹ́hìn náà gbogbo wọn múra wọ́n ń kó rẹirẹi lọ.
6 Ìgbé 2020 Ọpọ eeyan kaakiri agbaye papaa julọ lorilẹede Naijiria lo n gbe ahesọ ọrọ kan kiri pe itakun ayelujara 5G n ṣokunfa aarun coronavirus.
Gbogbo àwọn eniyan agbègbè Geraseni bá bẹ Jesu pé kí ó kúrò lọ́dọ̀ àwọn nítorí ẹ̀rù bà wọ́n pupọ.
Àwọn aya yín, àwọn ọmọ yín kéékèèké, ati àwọn ẹran ọ̀sìn yín ni yóo kù lẹ́yìn lórí ilẹ̀ tí Mose fun yín ní òdìkejì odò Jọdani; ṣugbọn gbogbo àwọn akọni láàrin yín yóo rékọjá sí òdìkejì odò náà pẹlu ihamọra ogun níwájú àwọn arakunrin yín, wọn yóo máa ràn wọ́n lọ́wọ́ 
Fún mi ní ọgbọ́n ati ìmọ̀ tí n óo fi máa ṣe àkóso àwọn eniyan wọnyi, nítorí pé ó ṣòro fún ẹnikẹ́ni láti ṣe àkóso àwọn eniyan rẹ tí wọ́n pọ̀ tó báyìí.
"W) se sọ pé ""Àdúrà tó lọlá jù ni àdúrà tí wọn ṣe lọjọ Arafat"" Ọlọrun maa n yọ awọn eeyan kuro ninu ọmọ ina: Ní ọjọ Arafat ni Ọlọrun máa n yọ àwọn eeyan kúrò nínú ọmọ iná jùlọ."
" o jẹ ́ ọ ̀ kan lára àwọn ẹbí kòkòrò-àìrùn "" hepacivirus "" "" flaviviridae "" ."
Ni kete ti o si ti wọle ni o ti kede pe oun n gba akoso ni ibamu pẹlu idajọ ile ẹjọ to ni o fun oun lagbara ati ṣe bẹẹ.
Wo ìdí tó fi tọrọ àforíjì fún ọ̀rọ̀ ẹ̀gbin tó sọ sí Pásítọ̀ David Oyedepo N kò gba owó rí lọ́wọ́ olùdíje kó tó dé ipò - Oyedepo Ejò lọ́wọ́ nínú lórí ìdájọ́ ẹ̀wọ̀n gbére tí wọ́n dá fún Wòlíì Sotitobire, àwọn ọmọ ìjọ rẹ̀ yarí Sotitobire: Ojú àwọn Wòlí tó tí lọ sẹ́wọ̀n lórí ẹ̀sùn ọdaràn tẹ́lẹ̀ rèé Nibo ni orisun iroyin naa ti wa?
Rebeka pe Jakọbu ọmọ rẹ̀, ó sọ fún un, ó ní, “Mo gbọ́ tí baba yín ń bá Esau ẹ̀gbọ́n rẹ sọ̀rọ̀, 
Bakana lo ni ijoba yoo gbogun ti ebi oun iṣẹ pẹlu mumu itẹsiwaju ba iṣẹ-ọgbin.
 Ajodun ayeye eto ijoba tiwa-n-tiwa todun yii da lori ominira, mo gbosuba fun awon omo orile ede yii fun igbekele, ifarasin ati  ipinnu ijoba yii lati mu awon ileri re si ati lati mu orile ede Naijiria lo si ibi ti idajo ati aseyori wa.
Níbẹ̀ ni àwọn kẹ̀kẹ́-ogun rẹ tí ó dára yóo wà, ìwọ tí ò ń kó ìtìjú bá ilé OLUWA rẹ.
Jehoiada, olóyè, wá láti inú ìran Aaroni pẹlu ẹgbaaji ó dín ọọdunrun (3,700) ọmọ ogun 
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù June 12: Sadik ní àwọn tó ṣiṣẹ́ pẹ̀lú Abacha ní kò kówó jẹ, ó fi pamọ́ fún ìdí kan ni Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ June 12: Sadik ní àwọn tó ṣiṣẹ́ pẹ̀lú Abacha ní kò kówó jẹ, ó fi pamọ́ fún ìdí kan ni 13 Òkùdu 2020 Ọmọ Ọgagun Sani Abacha ti sọ ohun to mọ nipa iru eniyan ti Baba oun jẹ ni igba aye rẹ.
"Oun ni oludari ati oludasilẹ eto orin ""Cool FM Praise Jam"" ti wọn ṣe ni ọdun 2004."
Láti Òkè Ṣeferi wọ́n lọ sí Harada.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ifa Worshippers: Àwọn ẹlẹ́sìn ìbílẹ̀ ń fẹ́ kíjọba pín èrè òṣèlú alágbádá yíká gbogbo ẹ̀sìn Amọ ko dabi ẹni pe igbaradi kankan ti n waye lati ṣe ipagọ naa lọdun yii.
Wọ́n Fi Ìhó Ayọ̀ Gba Saulu ní Ọba.
Eyi ni ibeere to gba ẹnu ọpọ ọmọ Naijiria kan bi iwadii ajọ ICPC to n risi iwa ajẹbanu ati iwa aitọ ni Naijiria ṣe jade.
Ẹ wo àwọn ọmọ tí bàbá wọn fi s'ílẹ̀ sálọ ní Ghana
Ó wí bí ó ti jẹ́ pé Olódùmarè ní ń ṣe alákòóso ìṣẹ́gun, tí ó si jẹ́ pé òun ni ó ni ohun gbogbo ti ń bẹ́ ń inú ayé àti èyí tí ń bẹ ní òde ọ̀run, dúkìá àwọn ọmọ ènìyàn àti ohun àlúmọ́nì ìsàlẹ̀ ilẹ̀, èyí tí ó ń bẹ  níi ojú omi àti èyí tí ó ń e ni òfuurufú, ó sì tún wípẹ̀lú bí ó ti jẹ́ pé kò si ìdíwọ́ fún Ọlọ́run Ọba : ohunkohun tí Ẹlẹ́dàá bá fẹ́ ní ń ṣe àti wí pé ẹnikẹ́ni kò le dí Ọlọ́run Ọba lọ́wọ́ àti gbé ẹnikẹ́ni ga; bẹ́l nni elékèé kò le dí Ọlọ́run Ọba lọ́wọ́ àti gbé ènìyàn ga.
Lebanon Explosion: Ibùdó tí igba èèyàn ti kú lóṣù kẹjọ ní iná míràn ti jó
Bakan naa lo gba awọn olori ẹka ile-iṣẹ ijọba gbogbo ni imọran lati bọwọ fun ẹka aṣofin, paapaa lati maa jẹ ipe wọn bi wọn ba pe wọn.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù AFCON 2019: Ṣé Super Eagles yóò rí agbábọ́ọ̀lù tí yóò mú ìyàtọ̀ wá bí Bright Omokaro ṣe ṣe ní Maroc '88?
NNPC n ronu afikun owo epo Omíyalé gbẹ̀mí èèyàn méje, o tún ba dúkìá púpọ̀ jẹ́ ‘A ti rí $470.
Láti ọjọ́ kinni oṣù keje ni wọ́n ti bẹ̀rẹ̀ sí rú ẹbọ sísun sí OLUWA bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé, wọn kò tíì fi ìpìlẹ̀ tẹmpili lélẹ̀.
Awọn ohun to yẹ ki o ṣe to ba n lo ẹrọ amunawa rẹ Ko jẹ tuntun mọ pe ọpọlọpọ ọmọ Naijiria lo gbọkan le ẹrọ amunawa fun ipese ina ẹlẹtiriiki ninu ile ati ibi iṣẹ wọn Bẹẹni kii si ṣe ẹẹkan tabi ẹẹmeji, ni iroyin ti gbe e pe, eefin ẹrọ amunawa ṣekupa mọlẹbi ni Naijiria Eefin ẹrọ amunawa ni eroja kan ti wọn n pe ni 'carbon monoxide' ninu, eyi to jẹ afẹfẹ to ni oro ninu, to si lee pa eeyan Oorun eroja naa ko ṣe e gbọ, nitori naa ti o ba ti n gboorun eefin ẹrọ amunawa rẹ, a jẹ wi pe eroja carbon monoxide lo n fin simu Ohun to daju, to si ṣe pataki ni pe ki gbogbo ẹni to n lo ẹrọ amunawa mọ ni pe, eefin to n jade lati ara ẹrọ amunawa le ṣekupani O ko gbọdọ gbe ẹrọ amunawa rẹ si ara ileti awọn eniyan n gbe Ẹrọ amunawa gbọdọ jinna si ibi ti ẹnu ilẹkun tabi ferese ba wa ni nkan ti ko din ni iwọn ẹsẹ bata ogun Ri i daju pe ọpa to n gbe eefin jade latara ẹrọ amunawa rẹ kọju si ibi ti afẹfẹ ti n fẹ Pa ẹrọ amunawa rẹ, ko si tutu daada ki o to rọ epo si i, nitori ti epo ba da si ori rẹ, o le gba ina Maa ranti nigba gbogbo pe eefin ẹrọ amunawa alagbagbepọ rẹ le le ṣe ipalara fun ọ, nitori na, ri i daju pe ibi ti o tọ ni alabagbepọ rẹ gbe ẹrọ amunawa rẹ si Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Láìpẹ yìí ni ìròyìn tàn ká pé àwọn ọmọ ikọ Super Eagles n bínu pé afi dandan ki awọn aláṣẹ san owo ajẹmọnu awọn, ti wọ́n si dún koko pe ó ṣeeṣe ki awọn ma lọ si ibi ipade apero kan ti yoo sáju ifẹsẹwọnsẹ wọ́n pẹ̀lú Guinea láàná.
INEC ni Fayẹmi bori lawọn ijọba ibilẹ Ilejemeje, Irepodun/Ifelodun, Ido/Osi, Oye, Moba, Ijero, Gbonyin, Ekiti West, Ikole, Ise/Orun, Ekiti East ati Ekiti Southwest.
Awọn ẹgbẹ agbabọọlu mejeeji ni wọn kọ lati ṣe iwuri fawọn ololufẹ lati igba ti saa bọọlu tuntun yii ti bẹrẹ.
Bakan naa ni mi o le rin daada fun ọjọ diẹ.
” Nítorí náà wọ́n jọ ń lọ.
Don Davis wa nileewosan lọwọlọwọ Lati bi ọjọ diẹ sẹyin ni Don Davis ti wa ni ileewosan, nibi to ti n gba itọju.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Alex Badeh: Àwọn agbenipa ojú pópó lásán ló paá 27 Ọ̀pẹ̀̀ 2018 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Alex Badeh: Ọwọ́ ba afunra sí mejì Ọwọ́ sìkún àjọ ọlọ́pàá orílẹ̀-èdè Náíjíríà tí ba àwọn ọdaràn tó pa ajagún fẹyinti ọmọogun ojú òfurufú Alex Badeh.
Àjọ wa ní ọjọ́ Satídé náà si dùn ju bí mo ti ní èrò lọ.
A fara da ewu to pọ lati tọju yin, koda a fi ẹmi awọn mọlẹbi wa sinu ewu lati tọju yin'' Stella fi kun pe ''A ni lati jẹ ki awọn eeyan mọ pe awọn eeyan tia le foju ri lo ti jẹ anfaani itọju yi'' Irọ́ ni o, kò sí ẹ̀rí pé Hydroxychloroquine leè kojú àrùn Coronavirus- Ẹgbẹ́ àwọn adarí ilé ìwòsàn ní Naijiria Ẹgbẹ awọn adari ile iwosan ni Najiria, GMD ti ni ọrọ ti dokita Stella Emmanuel, to jẹ oṣiṣẹ eto ilera nilẹ Amẹrika sọ pe oun lo Hydroxychloroquine (HCQ), Zinc ati Zithromax lati fi ṣetọju arun Covid-19 ko bojumu to.
naa ti wa ni ile-ise Ologun oju omi ni odun meji ki won to pari ise ara oko oju
 O ni ki awon eniyan ko bi a ti n lo nkan lona ti a maa tun un loo leekeji.
Inú rẹ̀ ìbá dùn láti máa jẹ ẹ̀rúnrún tí ó ń bọ́ sílẹ̀ láti orí tabili olówó yìí.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Saudi Arabia mosque: Wo àwòdamiẹnu àwòrán Mọ́ṣáláṣí Ànọ́bì ní Medina!
" Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Alaga igbimọ ọhun, to tun jẹ akọwe ìjọba apapọ, Boss Mustapha lo salaye ọrọ yii lasiko ijabọ bi nkan ṣe lọ fun ara ilu to ma n waye l'Abuja lojoojumọ.
Oríṣun àwòrán, @AAAjimobi Àkọlé àwòrán, ' awọn olori wa lati tubọ maa rii daju wipe a fi ẹyẹ ọwọ ati iyi to yẹ fun awọn iya wa, iyawo wa ati gbogbo obinrin lapapọ' Bi a se n se ajọyọ yii, o se pataki fun awọn baba wa ati awọn olori wa lati tubọ maa rii daju wipe a fi ẹyẹ, ọwọ ati iyi to yẹ fun awọn iya wa, iyawo wa ati gbogbo obinrin lapapọ ni ipokipo tabi aaye kaaye ti wọn ba wa.
Ǹjẹ́ bí Ẹ̀mí Ọlọrun, ẹni tí ó jí Jesu dìde kúrò ninu òkú, bá ń gbé inú yín, òun náà tí ó jí Kristi dìde kúrò ninu òkú yóo sọ ara yín, tí yóo kú, di alààyè nípa Ẹ̀mí rẹ̀, tí ó ń gbé inú yín.
29 Ẹrẹ̀nà 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 6 Èbibi 2020 Gbajugbaja ni ọrọ yii, Aguntaṣọọlo"" paapaa laarin awọn alagbe, olorin atawọn iyaagba ti wọn fẹ ki awọn ọmọ wọn."
Sugbọn ko pẹ si akoko ti wọn gba a mu lo ku si wọn lọwọ lahamọ ọlọpaa ti wọn fi si.
Mudashiru Ajayi Ọbasa rọ awọn ọmọ orilẹ-ede Naijiria lati fi ịfẹ han
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ọbasanjọ àti Atiku yóò jọ pàdánù nínú ìbò Ààrẹ Kíni ìwọ mọ̀ nípa Funmilayọ Ransome-Kuti?
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Lizzy anjorin ń kiri àgọ́ ọlọ́pàá láti gba àwọn ọ̀dọ́ afẹ̀hónúhàn, tó wà láhàámọ́ sílẹ̀ Àwọn ọ̀dọ́ se ìrẹsì jọ̀lọ̀ọ́fù ní márosẹ̀ Benin sí Ore láti fẹ̀hónú hàn Afárá Marina àti Eko yóò di ṣíṣí padà lọ́la Wo àwọn Ṣọ́ọ̀ṣì Nàìjíríà àti l'Áfíríkà tó ń wólẹ̀ àdúrà kí Trump lè wọlé ìbò ààrẹ America Iléeṣẹ́ ológun bẹ̀rẹ̀ 'Operation Crocodile Smile' yíká Naijiria fún oṣù méjì Òkú tó jí lọ́jọ́ kejì ní mọ́ṣúárì padà kú síléèwòsàn Ṣé lóòtọ́ ni àjọ ọlọ́pàá dá Abayomi Shogunle àti Dolapo Badmus dúró?
Ní ọjọ́ kẹjọ ni wọ́n kọ mí nílà.
 Írú ìdáhun báyìí má ń wáyé láàárìn 85 sí 90 % èèyàn .
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, England yoo koju Belgium fun ipo keta Àṣekágbá World Cup 2018 Orilẹ-ede England pada lọ sile lai duro gba ife ẹyẹ ti wọn fẹ gbe lọ sile nigba ti Belgium gbo ewuro si oju wọn pelu ami ayo meji sodo lọjọ Abamẹta.
Ó fi kún pe ìjọbá ní láti sàtúntò àwọn eléto ààbò nítori iṣẹ́ wọn kò tó.
Eyi gan lo faa ti ahesọ iroyin nipa aawọ laarin oun ati gomina ipinlẹ Ọyọ lori idasilẹ ọwọ ẹka ọlọpaa kogberegbe Police Mobile Squadron si ilu Agọ Arẹ fi jẹ eyi ti ọpọ ko lee fi oju fo da.
Gomina ipinlẹ Eko ni iwadii n lọ lọwọ lati mọ ohun to ṣe okunfa iṣẹlẹ ibugbamu ọhun gan an.
Ìgbà tí wọ́n dàgbà tán, tí ó di wí pé wọ́n ń wá ibùjókòó tí wọn yóò tẹ̀dó, àwọn méjèéji-Agígírì àti ajíbogun yìí náà ló jìjọ dìde láti Ilé-Ifẹ.
"Ohun to han si ileeṣẹ ọlọpaa ni pe baba ati ọmọ ni wọn, awọn mejeeji lo si fi ipa ba ọmọ ọdun mẹrinla naa lopọ.
Wo àwọn to ti rí ìwòsàn lọ́wọ́ àrùn coronavirus àti ibi tí wọ́n ti wá káàkiri Nàìjíríà Mẹ́rin nínú àwọn mọ́kànlá tó ń bọ̀ láti Sokoto tí wón mú l'Oyo ló ní Coronavirus Iye ìgbà tí Sani Abacha tí fi owó ransẹ si Nàìjíríà láti ọrun Ìlúmọọká akọròyìn NTA Nàìjíríà, Ayinde Soaga lùgbàdì Covid 19 Báyìí ni àwọn agbófinró ṣe dá ìrìnkèrindò ọkọ̀ dúró lẹ́nu ibodè Nasarawa sí Abuja Wọn pada bẹ awọn eeyan naa lati pada si ibudo naa, ṣugbọn wọn sọ pe ẹru n ba wọn nitori bi awọn alarun naa ṣe darapọ mọ awọn ara abule to jade wa a woran ohun to n ṣẹlẹ.
Awọn ọmọ ẹgbẹ Hakika gba pe, ti awọn ba ti de ipo kan to ga ninu iwa mimọ ati ninu ẹsin, awọn lee paarọ awọn iyawo awọn laarin ara awọn Ọmọ ijọ Hakika kii ki irun ni ẹẹmarun ni ojumọ gẹgẹ bi opo ẹsin Islam ti laa kalẹ Ọranyan si kọ ni gbigba aawẹ Ramadan fun awọn ọmọ ẹgbẹ Hakika Wọn ko ni Mọsalasi kankan ti wọn ti n jọsin, tabi ni asaaju kankan ti wọn mọ mọ wọn, to si jẹ peko ko bọ si ojutaye A lee se idamọ awọn ọmọ ijọ Hakika lati ipasẹ ọrọ̀ọ ẹnu wọn, ti wọn fi n tako irun kiki ati aawẹ gbigba Bakan naa ni wọn maa n se iwuri fun iwa pansaga ati agbere Ọpọ wọn lo jẹ ọdọ, ti ọjọ ori wọn si kere pupọ Ikọ ẹlẹsin Hakika kii gbe ibọn tabi lo ohun ija oloro kan-kan Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Ṣé Coronavirus leè tẹ̀lé ọjà Chinco wọ Nàìjíríà?
Koda, mi o tii gbagbọ pe mo ti mu ala naa ṣẹ.
Lẹ́hìn eléyìí ọba náà dáhùn ó wí pé:
Ni ti ẹlẹkunjẹkun, ẹkun aaringbungbun guusu Naijiria (South-south 35.
Mi ò le sọ iye ènìyàn tó gbẹ́mí mì sùgbọ́n a sì ń gbìyànjú láti mọ̀ ọ́.
ile ise ijoba ipinle Oyo latari iwa ifipa ba omobinrin lopo ati iwa ijinigbe to
(Nítorí OLUWA ti ṣetán láti dá ògo Jakọbu padabí ògo Israẹli,nítorí àwọn tí wọn ń kóni lẹ́rú ti kó wọn,wọ́n sì ti ba àwọn ẹ̀ka wọn jẹ́.
Aarẹ ẹgbẹ ọhun, Ibrahim Musa ninu atẹjade kan to fi sita lọjọ Iṣẹgun ṣalaye pe, ọta ibọn awọn ọlọpaa lo ba awọn mejeeji nitori awọn ẹgbẹ Shiite kii lo ibọn tabi ohun ija oloro kankan.
Gẹgẹ bi o ṣe sọ, owo ẹyin lawọn ọlọpaa naa n gba lọwọ awọn awakọ ti wọn si n jẹ ki wọn wọle.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, RAMADAN: Onímọ̀ ẹ̀sin sọ nípa isẹ́ láádá àti làádà Nkan bii ounjẹ to lomi dara lati kọkọ fi ṣinu lati le pese inu silẹ fun ounjẹ miiran.
A ni awọn irugbin koriko ni agbegbe Rogo, Gaya, Kura, Tudun-Wada, Ungogo ati awọn ibi ipamọ miiran nibiti awọn ohun eelo wa lati gba awọn darandaran ati awọn ẹran wọn si.
Akọwe ijọba apapọ, to tun jẹ Alaga fun igbimọ to n mojuto itankalẹ aarun Covid-19, Boss Mustapha, lo kede eyi lasiko ti o n ba ara ilu sọrọ l'Ọjọbọ.
Àkọlé àwòrán, Lẹ́yìn ìpèsè gbogbo ǹkan wọnyìí Godwin rọ ojò lẹyìn wákatí méjì, ti ojò náà rọ fun ìṣẹ́jú márùn kó to dá.
Lẹ́yìn náà, mo pàṣẹ létí odò Ahafa pé kí á gbààwẹ̀, kí á lè rẹ ara wa sílẹ̀ níwájú Ọlọrun wa, kí á sì bèèrè ìtọ́sọ́nà fún ara wa ati àwọn ọmọ wa, ati gbogbo ohun ìní wa.
O dára gan-an ni, olùfẹ́ mi!
Ǹjẹ́ eniyan lè gba ire lọ́wọ́ Ọlọrun kí ó má gba ibi?
 Muhammed ni : “Ipinnu wa fun orile ede Naijria ,ti
Ẹ̀rù Ọlọrun ba Dafidi ní ọjọ́ náà, ó ní, “Báwo ni mo ṣe lè gbé Àpótí Majẹmu Ọlọrun sọ́dọ̀?
Ayọ̀ ń bẹ fún ẹni tí ó fi Ọlọrun Jakọbu ṣe olùrànlọ́wọ́ rẹ̀,tí ó gbójú lé OLUWA, Ọlọrun rẹ̀.
Ìdí èyí ni pé ní aiyé àtijọ́ nígbàtí irú àwọn abúlé yìí fìdí múlẹ̀, ẹṣin àti kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ ni àwọn ṣe ọ̀nà fún.
Bóyá n óo dúró lọ́dọ̀ yín, mo tilẹ̀ lè wà lọ́dọ̀ yín ní àkókò òtútù, kí ẹ lè sìn mí lọ sí ibi tí mo bá tún ń lọ.
Ó láṣẹ láti gbà tó ọgọrun-un (100) ìwọ̀n talẹnti fadaka, ọgọrun-un (100) òṣùnwọ̀n kori ọkà, ọgọrun-un (100) òṣùnwọ̀n bati ọtí waini, ọgọrun-un (100) òṣùnwọ̀n bati òróró, ati ìwọ̀n iyọ̀ tí ó bá fẹ́.
Badagry ni pẹtẹsi akọkọ ni Naijiria wa
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Osinbajo gbarata lórí ìṣẹ̀lẹ̀ Lekki, ó ní ìdájọ́ òdodo yóò wà Ooni Ogunwusi àti Wole Soyinka kòrò ojú sí ìṣẹ̀lẹ̀ Lekki Tollgate Ọ̀rọ̀ Nàíjíríà kúrò ní sinimá àwòrẹ́rìn-ìn, Buhari gbé ìgbésẹ̀ bíi òbí àti olórí - Obasanjo gbarata Ilẹ̀ Amẹ́ríkà wà lẹ́yìn àwọn olùwọ́de, Buhari dẹ́kun ìpànìyàn - Joe Biden Mọ̀ nípa DJ Switch, akíkanjú obìrin sàfihàn fídíò ìpànìyàn Lekki bó ṣe ń wáyé Buhari, máṣe gbá ìpànìyàn Lekki sórí ààtàn, kò yẹ́ kí ológun yin ọ̀dọ́ níbọn - Bode George Ọ̀kan lára olùwọ́de tó fara gbọgbẹ́ ní Lekki jáde láyé - Sanwo-Olu Lara awọn agọ ọlọpaa ti ọrọ naa kan ni ti Igando, Layeni, Denton, Ilenbe Hausa, Ajah, Amukoko, Ilasa, Cele labẹ Ijesha.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ọmọkùnrin tó pa ọmọ igbákejì Gómìnà Ondo gba ìdàjọ́ ikú 'Iléèṣẹ́ ọlọ́pàá ló gbégbà orókè nínú ìwà jẹgudujẹra ní Nàìjíríà' Pím pim pim!
Nítorí pé Ọlọrun wà pẹlu wa.
Iyawo kanu sọ pe ẹ̀yà Igbo ko ni i dibo ti Kanu ko ba jẹ́ riri Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Idibo ko ni waye ti wọn ko ba mu ọkọ mi jade Ijọba Naijiria sọ pe awọn ko mọ ibi ti Nnamdi Kanu wa Ijọba orilẹede Naijiria ti sọ wipe awọn ko mo nkankan nipa ibi ti adari ikọ Ipob, Nnamdi Kanu farapamọ si lati igba ti Ikọ ọmọogun Naijiria ti se ikọlu Operation Python Dance"" lagbegbe Ila-Oorun Gunsu orilẹede Naijiria."
“Jáde kúrò ninu ọkọ̀, ìwọ ati aya rẹ, ati àwọn ọmọ rẹ, ati àwọn aya wọn.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ikare Monarch: Ọdún méjìdínláàdọ́ta ní Oba Adegbite-Adedoyin ló lókè èèpẹ̀, kó tó mí kanlẹ̀ 1 Owewe 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 2 Owewe 2020 Lẹyin ti Ọwá Ale Ikarẹ, Oba Adegbite-Adedoyin papòdà lẹ́ni ọdún márùndínláàdọ́rùn ún lánaa, ọjọ Iṣẹgun, ni ọjọ kinni, oṣu kẹsan an , ọdun 2020 ni BBC kan si ilu naa.
" Bákan náà ni wọ́n dúpẹ lọ́wọ́ àwọn tí wọ́n ṣe ìrànwọ́ láti mú kí iṣẹ́ náà ṣeese pàápà'jùlọ nípa pípèsè owó tí sì fún ọ̀pọ̀ ní ìwúrí láti ṣe iṣẹ́ abẹ náà Oríṣun àwòrán, UITH Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Kwara; Ìpínlẹ̀ Kwara yọ orukọ Saraki kúrò lára fasitì wọn4 Ẹrẹ̀nà 2020 Ile Arugbo: Ìdíle Saraki àti ìjọba ìpínlẹ̀ Kwara dájọ́ ìpàdé25 Sẹ́rẹ́ 2020 Ghost workers in Nigeria: Àkàrà tú s'épo fún ẹgbẹ̀rún kan ayédèrú òṣìṣẹ́ SUPEB ní Kwara -EFCC12 Òkùdu 2020 Onila/Agindigbi Communities: Ọdún mẹ́ta ní àwa 18 fi dá #400,000 tí a fi kọ́ ilé ìwé14 Sẹ́rẹ́ 2021 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Ẹ̀yin òkè, ati ẹ̀yin ìpìlẹ̀ ayérayé, ẹ gbọ́ ẹjọ́ OLUWA, nítorí ó ń bá àwọn eniyan rẹ̀ rojọ́, yóo sì bá Israẹli jà.
Ní ọjọ́ kẹsàn-án Oṣù Èrélé, àwọn akẹ́kọ̀ọ́ ti Ifáfitì Toronto, ọgbà Scarborough dìbò yan ọmọ ọdún méjìlél'ógún kan tí ìlú abínibíi rẹ̀ jẹ́ Tibet, gẹ́gẹ́ bí ààrẹ ìgbìmọ̀ àwọn akẹ́kọ̀ọ́.
Ó ti parí fun yín, ẹ̀yin ọmọ Kemoṣi,nítorí a ti kó àwọn ọmọkunrin yín lẹ́rú,a ti kó àwọn ọmọbinrin yín lọ sí ìgbèkùn.
Wọ́n ń fi ọkàn kan lọ sí Tẹmpili lojoojumọ.
Ooni of Ife: Inú ayọ̀ àti ìdùnú ni èmì àtí Ọoni wa, ǹkankan kò ṣe ìgbéyàwó wa- Olorì Naomi Oríṣun àwòrán, INSTAGRAM Àkọlé àwòrán, Ọdun 2018 ni Ooni ti Ile Ifẹ, Oba Adeyeye Ogunwusi gbe Olori Naomi Silekunola Ogunwusi ni iyawo.
S Embassy Domestic Violence: Ìjà láàrin lọkọlaya sọ aya dèrò ọ̀run N650,000 péré ni mò ń gbà gẹ́gẹ́ bíi owó oṣù -Gomina Ọyọ Bakan naa ni Ọga ọlọpaa ni ileeṣẹ wọn tuntun to wa ni ipinlẹ Ondo ni yoo ṣiṣẹ ni agbegbe ipinlẹ naa ati awọn ipinlẹ to wa ni Iwọ-oorun orilẹ-ede Naijiria.
Amọ, awọn oludari oju opo ikansira ẹni Twitter, ti sọ agadagodo si oju opo rẹ, ti wọn si ti pa fun iwa to wu yii.
Bàyìí ni àwọn méjèèjì pèrò pọ̀ láti fi Ilé - Ifẹ̀ sílẹ̀ kí wọn sì wá ibùjókòó tuntun fún ara wọn níbi tí wọ́n yóò ti máa ṣe ìjọba wọn.
 Awon oludije meji gboogi ti won n dupo aare ohun ni minisita kan ati adari omo-ogun teleri ti o di oloselu.
Nigba ti wọn de iloro akọkọ ni aafin Ọọni ni awọn ẹṣọ beere ohun ti wọn wa ṣe ti meji ninu wọn si bẹ silẹ ninu mọto ti wọn si fi ẹsẹ fẹẹ.
Bah N'Daw àti Assimi Goita di adarí tuntun láti tukọ̀ orílẹ̀-èdè Mali ní ọdún kan àti aàbọ̀ Wo àwọn ìlúmọ̀ọ́ká tó ṣe ìgbéyàwó ní ọdún 2020 yìí Èèyàn 195 ní àrùn Coronavirus tún ṣẹ̀ṣẹ̀ ràn ní Nàìjíríà ní Ọjọ́ Ajé Atiku fi owo ranṣẹ si ilẹ okeere lati ileeṣẹ rẹ, Guernsey Trust Company Nigeria Limited (GTCN) ati awọn ileeṣẹ miran.
Kí ẹ bá mi kí àwọn ọ̀rẹ́ tiyín náà.
No Bra Day: Àyájọ́ ‘Má wọ kọ́mú’ ló ń pe àkíyèsí àwọn obìnrin sí àìsàn jẹjẹrẹ ọyàn
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Buhari, kí ló dé tó fẹ́ dá $100m owó Abacha padà fún gómìnà Kebbi?
Wọ́n Dojú Ogun Mímọ́ kọ Midiani.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ìṣẹ̀lẹ̀ Kàyéèfì: Ìpáǹle tú Abass Owonikoko sí ìhòòhò ayé, kó tó gba kéú lọ́gbà ẹ̀wọ̀n Nibi ti ọrọ yii gbalẹ de, awọn kan ni ọmọ ọkunrin ni ọmọ naa.
Nítorí náà, ṣé ohun tí mò ń sọ ni pé ohun tí a fi rúbọ fún oriṣa jẹ́ nǹkan?
Nígbà tí ó bá tún di ọjọ́ keje, kí alufaa tún yẹ̀ ẹ́ wò.
ENDSARS: Ẹ̀yin ọmọ Nàìjíríà, ẹ ṣè ìrànwọ́ irinṣẹ́ fáwọn ọlọ́pàá- Naira Marley bẹ̀bẹ̀ Ẹ̀wọ̀n ni wàá gbẹ̀yìn sí, kò sí bóo ṣe dọ́gbọ́n tó - Seyi Makinde wa ègúná ọ̀rọ̀ lé Fayose Nibayii, awọn oṣiṣẹ pajawiri ti wa nibẹ lati ri wi pe ọkọ naa ko gbina, lẹyin ti wọn le awọn eniyan kuro ni agbegbe naa.
Awọn bii ọgọrun ninu wọn ṣi wa ninu ahamọ Boko Haram bayi.
Nígbà tí ó dé, tí ó rí bí Ọlọrun ti ṣiṣẹ́ láàrin wọn, inú rẹ̀ dùn.
Kí làwọn ọmọ Nàìjíríà rí sí iléeṣẹ́ tí ààrẹ yí padà sí Ministry of Communication and Digital Economy?
Koda Adele Aarẹ, Yemi Osinbajo ati Aarẹ ile asofin agba, Bukola Saraki naa kan saara si wọn.
 Ìtàn kan sọ fún wa pé àwọn yorùbá ti wà láti ìgbà ìwáṣẹ ̀ àti láti ìgbà ìṣẹ ̀ dá ayé .
Mose dáhùn pé, “Gbogbo wa ni à ń lọ, ati àgbà ati èwe; ati ọkunrin ati obinrin, ati gbogbo agbo mààlúù wa, ati gbogbo agbo ẹran wa, nítorí pé a níláti lọ ṣe àjọ̀dún kan fún OLUWA.
Àsọtẹ́lẹ̀ nípa Arabia nìyí:Ninu igbó Arabia ni ẹ óo sùn, ẹ̀yin èrò ará Didani.
Tí ó bá ṣe bẹ́ẹ̀, ọtí náà yóo bẹ́ àpò náà, ati ọtí ati àpò yóo bá ṣòfò.
Lẹyin oorun akọkọ lalẹ ọjọ igbeywao, ọkọ yoo na eso Apple pupa sita tabi asọ inuju funfun, ti ẹjẹ wa lara rẹ lati fihan awọn ẹbi pe oun ba iyawo oun nile.
Ọlọrun kò kọ àwọn eniyan rẹ̀ sílẹ̀, àwọn tí ó ti yàn láti ìpilẹ̀ṣẹ̀.
Àwọn dokita mejidinlọgọrin lorilẹ-ede Naijiria ti ṣisẹ papọ lati ya awọn ibeji to sopọ ni aya lati ọdun 2018 ti wọn ti bi wọn.
OLUWA bá fi Mose sílẹ̀, kò pa á mọ́.
Ìṣẹ́po ẹran ara rẹ̀ lẹ̀ pọ̀ mọ́ ara wọn,wọ́n lẹ̀ pọ̀, wọn kò sì ṣe é ṣí.
Bi ẹko ba ranti,eyi wa lara awọn idi ti wọn fi mu ọga ọrọ owo Huawei Meng Wanzhou ni Canada lọdun to kọja.
Ọ̀kan bọ́sí ìgbà ìrúwé tí ojúmọ́ ngùn síi.
Iwe irinna naa pin si ọna mẹta, ikan fun awọn ọmọ Naijiria, ikan fun awọn osisẹ pataki ati ikẹta fun awọn osisẹ pataki fun ijọba Naijiria.
ẹni tí ó dá àwọn ìmọ́lẹ̀ ńlá, nítorí pé ìfẹ́ rẹ̀ tí kì í yẹ̀ wà títí lae.
Àwọn eniyan náà bá kúrò ní agbègbè àgọ́ àwọn Kora ati Datani ati Abiramu.
Ṣaaju ni ijọba ipinlẹ Kogi ti sọ pe ko si arun Covid-19 ni ipinlẹ oun, ṣugbọn ajọ NDCD sọ pe irọ patapata ni ọrọ naa.
Kọmisọna sọ pe bi o tilẹ jẹ pe wọn gbero lati tunbọ gba oṣiṣẹ si i, awọn kan wa to ti yọnda ti wọn si ti ṣe idanilẹkọ fun wọn lati lọ maa ṣe itọju awọn alaisan nile laarin ọsẹ kan si meji.
Iṣẹ́ tí mò ń ṣe ní orúkọ Baba mi ń jẹ́rìí mi, 
Àwọn eniyan wọnyi sì ti gbọ́ pé ìwọ OLUWA wà pẹlu wa ati pé à máa rí ọ ninu ìkùukùu nígbà tí o bá dúró lókè ibi tí a wà; nígbà tí o bá ń lọ níwájú wa ninu ọ̀wọ̀n ìkùukùu lọ́sàn-án, ati ninu ọ̀wọ̀n iná lóru.
O bẹrẹ ere tiata ni bii odun marundinlogun sẹhin.
Oríṣun àwòrán, @uche_ezeonye O salaye pe, eyi ri bẹẹ ki awọn lee fun asoju agba fun ileesẹ asoju ilẹ South Africa ni anfaani lati se akojọpọ orukọ awọn ọmọ Naijiria to nifẹ lati pada sorilẹede wa.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Sọ àsọtẹ́lẹ̀ nípa ikọ̀ tí yóò gba ife ẹ̀yẹ àgbáyé 2018 pẹ̀lú eré ìdárayá tuntun ti BBC 8 Òkùdu 2018 Ǹ jẹ́ o leè sọ àsọtẹ́lẹ̀ tó dájú nípa ikọ̀ tí yóò borí ní Russia 2018?
Pupọ awon ilé ìtajà ni Ejigbo ni wọn sáré ti pa nitori wahala yii, ti won sì tun ti ileesẹ awọn oṣiṣẹ ijọba ibilẹ Ejigbo naa pa, ki awọn oṣiṣẹ pada sílé.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Africa Eye: Wo ìtàn ìyá kan ìyá kan àtàwọn olè ajọ́mọgbé tó n ta ọmọ ní Kenya Idi ni pe awọn araalu tinu n bi, ti wọn le ni igba, ti dana sun adigunjale to fara gbọgbẹ naa, tawọn ọlọpaa si ti gbe ajoku rẹ lọ sile igbokusi.
Aworan to fi soju opo Facebook rẹ n ṣafihan akọle Blue Lives Matter,"" eyii to n ṣapẹrẹ ibadọre pẹlu ileeṣẹ ọlọpaa, to tun jẹ atako si awọn alatilẹyin ""Black Lives Matter."
Oríṣun àwòrán, Getty Images Bakan naa lo ṣe fido ninu eyi to ti gbawọn eeyan lamọran lati joko sile, ki wọn si tẹle awọn ilana tawọn oṣiṣẹ eto ilera la kalẹ lasiko yii.
Àwọn ìhùwàsí tí kò bójúmu bii ìwà ibaje tí gbilẹ̀ nílé ẹ̀kọ́, ilé ẹ̀sìn, ádúgbò, laarin ìlú, lariwa, gusu, ìlà oòrùn àti ìwọ oòrùn, ọ̀nà láti wá ojútùú sì, ló bí ẹgbẹ́ Atunbi Yorùbá.
Diẹ lara ọrọ tawọn ọmọ Naijiria to n gbe loke okun sọ fun BBC ree lori oun to yẹ ki o jọba lọkan awọn eeyan layajọ awọn ọmọ Naijiria to n gbe oke okun.
Igbẹjọ Pasitọ ijọ Sotitobire n lọ nileẹjọ giga l'Akure Pasitọ ijọ Sotitobire, Alfa Babatunde ti wa nile ẹjọ giga ilu Akure bayii, ni itẹsiwaju igbẹjọ ọmọ ọdun kan to poora ninu ile ijọsin rẹ lọdun 2019.
Àkọlé àwòrán, Ọmọ ìyá kìí yà, ọmọ baba ló n ba.
Sugbọn awọn kan sọ pe o ṣeeṣe ko jẹ pe ara lo n ta Aisha Buhari, nitori pe aburo rẹ kan, Halilu Mahmud kuna ninu idibo abẹle sipo gomina nipinlẹ Adamawa.
Ẹ kò gbọdọ̀ bá wọn dá majẹmu, ẹ kò sì gbọdọ̀ ṣàánú fún wọn rárá.
Kò pẹ́ pupọ ni afẹ́fẹ́ líle kan láti erékùṣù náà bá bì lu ọkọ̀.
Ẹgbẹrun ninu yín yóo sá fún ẹyọ ọ̀tá yín kan,gbogbo yín yóo sì sá fún ẹyọ eniyan marun-untítí tí àwọn tí yóo kú ninu yín yóo fi dàbí igi àsíá lórí òkè.
Wọ́n pa ibùdó wọn sí Efesi Damimu, tí ó wà láàrin Soko ati Aseka.
Bakan naa ni wọn tun gba ẹrọ kọmputa mọkanlelogun, foonu mẹtadinlaadọta ati awọn ẹrọ iko nkan pamọ si 'memory stick' ati 'hard drive', ti o kun fun adirẹsi awọn eeyan ti wọn fẹ lu ni jibiti.
Mo maa n ba iya mi fọ awọtẹlẹ rẹ, se ounjẹ ati isẹ ile ti awsn obinrin maa n se, ibẹ si ni ise awọn obinrin ti wu mi.
ó sì bẹ̀rẹ̀ sí fi òwe sọ̀rọ̀, ó ní,“Ọ̀rọ̀ Balaamu ọmọ Beori nìyí,ọ̀rọ̀ ẹni tí ó ríran dájúdájú;
Iroyin sọ pe ija lo waye laarin Emmanuel ati ololufẹ rẹti wọn jọ n gbe, Patricia Ogunshola, ni ile wọn to wa ni Araromi, Morogbo nipinlẹ Eko.
Bakan naa ni Obasanjo n fika hanu lori ipo to mẹhẹ ti eto aabo Naijiria wa bayii, pẹlu afikun pe se ni eegun ẹyin ikọ afẹjẹwẹ Boko Haram n le si lati ọdun mejila sẹyin, kaka ki ewe agbọn wọn si dẹ, ko ko ko lo n le si.
láàárín ọpọ ̀ lọpọ ̀ ọmọ oyè tí Ọba tọ ́ sí ní ilé-ifẹ ̀ ni a ti yan Ọọ ̀ ni adéyẹyè Ògúnwúsì ní ọjọ ́ kẹrìndínlọ ́ gbọn oṣù kẹwàá Ọdún 2015 .
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù EPL: Watford lu Chelsea la'lubolẹ pẹlu amin ayo mẹrin 6 Èrèlè 2018 Oríṣun àwòrán, Getty Images Watford ti fa'gba han ẹgbẹ agbabọọlu Chelsea ninu idije Premier League pẹlu amin ayo mẹrin si ẹyọ kan soso.
Ní àsìkò tí à ń sọ̀rọ̀ọ rẹ̀ yìí, àwọn ẹgbẹ́ òṣèlú márùn-ún ọ̀tọ̀ọ̀tọ̀ ni ó fọwọ́ síi wípé kí Abacha ó jẹ́ olùdíje fún ipò Ààrẹ nínú ẹgbẹ́ òṣèlúu wọn.
O ni aare ni won yoo maa jabo fun pelu aown omo igbimo amusese eyi ti minista fune to isuna yoo je alaga re.
IMỌ ẸKỌ ATI ILEẸKỌ TI DAPỌ ABIỌDUN LỌ: Dapọ Abiọdun lọ sile ẹkọ alakọbẹrẹ ati girama, ko to morile ileẹkọ fasiti Ọbafẹmi Awolọwọ nilu Ile Ifẹ, nibi to ti kẹkọ gboye imọ nipa iṣẹ ẹrọ.
Bẹ́ẹ̀ ni Jakọbu ṣe di ọlọ́rọ̀ gidigidi, ó sì ní àwọn agbo ẹran ńláńlá, ọpọlọpọ iranṣẹbinrin ati iranṣẹkunrin, ràkúnmí ati kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́.
Ìyàwó mi kórira kí Odunlade Adekola máa bú mi nínú eré tíátà - Ijebu Wákàtí mẹ́rìn ni àwọn agbẹjọ́rọ̀ Sowore lò tí DSS kò si fí í sílẹ̀- Falana Rẹ́rẹ́ rún nínú ìjàmbá iná Okobaba l‘Eko, ọ̀pọ̀ àwòrán rèé láti mọ̀ bó ti burú tó Ìjàmbá iná míràn tún ṣẹlẹ̀ ní Okobaba l‘Eko àmọ́ kò mú ẹ̀mí lọ Ọgbẹni Bloomberg gan an ko tii kede fun ra rẹ wi pe oun yoo dije fun ipo aarẹ ninu ibo gbogbogbo ọdun to n bọ.
Ọpọ owo lawọn eeyan a si maa fi ta tẹtẹ lori irufẹ ija akukọ yi ni ilẹ Phillipines.
Mo dàbí igúnnugún inú aṣálẹ̀,àní, bí òwìwí inú ahoro.
Ẹ̀yin ọmọ Israẹli, ṣé ẹ óo tún máa wá wádìí ọ̀rọ̀ lọ́dọ̀ mi?
Dafidi sọ fún Joabu ati àwọn ọ̀gágun rẹ̀ pé, “Ẹ lọ ka àwọn ọmọ Israẹli láti Beeriṣeba títí dé Dani, kí ẹ wá fún mi lábọ̀, kí n lè mọ iye wọn.
Fun gbogo iṣoro ti awọn akọnimọọgba Chelsea maa n doju kọ, awọn ti yoo fẹ tẹ ori si iṣẹ naa yoo pọ.
Oriṣirṣi ọna ni awọn eeyan fi ṣe Keresi ọdun yii, bi awọn kan ṣe n jẹ ti wọn si n mu, lawọn mii n ṣe iranlọwọ fun awọn alaini.
Tí ènìà bá tún tẹ̀ síwájú diẹ̀ síi, á gun òkè kékeré kan á sì jáde nínú igbó náà.
minisita naa ati ile-ise ti won yoo tuko re ni kikun:  ení) Dokita Uchechukwu Ogah – Abia, Minisita abẹle fun idagbasoke Irin tutu ati iwakusa (Mines and Steel Development, State)méjì ) Muhammed Musa Bello – Adamawa, Minisita fun Olu ilu orile-ede Naijiria,  FCTmẹ́ta ) Sen.
Coronavirus ti ba ìfinimọ̀ jẹ́ fún àwọn àgùnbánirọ̀ Àwọn ọba Yorùbá kan rèé tí wọ́n rọ̀ lóyè, tí ọba míràn jẹ lójú ayé wọn Bí Fayemi bá tasẹ̀ àgẹ̀rẹ̀, àwọn oníbáwí rẹ̀ wà l'Ekiti-Peter Fatomilọla Wọ́n gbé òkú ọgá iléẹ̀kọ́ àti òṣìṣẹ́ méjì míì tó kú nínú ìbúgbàmù lọ sílé ìgbókùsí ológun ojú omi l‘Eko Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Làá hàn mí: Ètò yìí ló ń kìlọ̀ fún wa láti mú ìmọ́tótó ní pàtàkì láti dènà Coronavirus Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Lẹ́yìn èyí, wọn óo fi awọ dídán bò ó, wọn óo tẹ́ aṣọ aláwọ̀ aró lé e, wọn yóo sì ti ọ̀pá tí a fi ń gbé e bọ̀ ọ́.
" Victory ni ọrọ bi Cute Abiola yii se ni afẹsọna naa gbọdọ jẹ irọ nla, bẹẹ si ni to ba sẹ pe irọ ni oun n pa, oun setan lati gbe awọn aworan ihoho rẹ to wa lori foonu oun sita.
O ni  awon omo orile ede Britain ni anfaani lati lowo ninu opolopo okoowo to wa niluu Eko ,bi i eto agbara,imọ ẹrọ ,eto inawo, ohun amaye-dẹrun ati ile –ise.
Bi awọn akọkọ Kristiẹni si se ko ọpọ ipo kanka-kanka ninu idibo naa lo bi awọn akẹkọ musulumi ninu, ti wọn si jọ tako ara wọn.
Olori ile Lucy ati igbakeji rẹ Prince ni wọn ni 'imuniti' tori naa wọn ko ni si lara awọn ti wọn yoo dibọ lati ran lọ sile.
Gẹ́gẹ́ bi gómìnà ṣe sọ nítori ọ̀rọ̀ ètò àbò tó ti polukurumusu ni agbègbè náà àti pé ìgbìyànjú n lọ lọ́wọ́ láti dóòlà àwọn ọmọ ti wọ́n ji gbé.
“Tètè bá ẹni tí ó pè ọ́ lẹ́jọ́ rẹ́ nígbà tí ẹ bá jọ ń lọ sí ilé ẹjọ́.
Èyí tó ga jù nibẹ ni ti ọ̀gá agba àjọ tí ó ń rí sí eré bọ́ọ̀lù ni Ghana (GFA), Kwesi Nyantakyi, tí ó gba ẹgbẹ̀rún lọ́nà márunléọgọ́ta dọ́là gẹ́gẹ́ bíi rìbá.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Economic recession: Ìjọba ní àfàìmọ̀ kí ọrọ̀ ajé má tún dẹnu kọlẹ̀ fún ìgbà kejì láàrin ọdún mẹ́rin 21 Ògún 2020 Oríṣun àwòrán, Others Lai si eto itaniji to muna doko, afaimọ ki ọrọ aje orilẹede Naijiria maa tun dẹnu kọlẹ fun igba keji laarin ọdun mẹrin, ijọba apapọ lo ke gbajare bẹẹ.
Ìwọ ni o kó àwọn ọmọ Israẹli, àwọn eniyan rẹ, jáde láti ilẹ̀ Ijipti pẹlu iṣẹ́ abàmì ati iṣẹ́ ìyanu, pẹlu ọwọ́ agbára, ipá ati ìbẹ̀rù ńlá.
Oṣu Keje, Ọdun to kọja ni ija ti bẹrẹ laarin awọn ọmọ Ile, lẹyin ti awọn mẹsan an kan lalẹ Ọjọ Kẹtadinlogun, Oṣu Keje yan abẹnugan Ile laarin awọn mẹrinlelogun to jẹ ọmọ ile igbimọ aṣofin ipinlẹ naa, ti wọn ṣẹṣẹ dibo yan, labẹ aṣẹ gomina ipinlẹ Edo, Godwin Obaseki.
O tun tu aṣiri iha ti ọpọ ọmọ ilẹ America kọ si iṣejọba rẹ, to kun fun aini afojusun, aibikita fun imọ sayẹnsi, fifi ọwọ yẹpẹrẹ mu eto ilu, ati gbigbe ọrọ osẹlu ga ju bo ṣe yẹ.
Ewé-ẹ̀yẹ ni ó na iwin dé ibi ti iwin ti ń pohùn réré ẹkún, òun ni ó gba aṣọ lára òkú ti kò tètè lọ sí ọ̀run, ti o ń yọ sí àwọn ènìyàn kiri, a máa gbọ́ ohùn ẹyẹ, a máa gbọ́ ti ẹranko, a sì máa gbọ́ ọ̀rọ̀ tí igi bá sọ sí ara wọn.
Kini idi ti wọn fi ti oju opo Tunde Ednut pa?
Ṣugbọn, a gbayin ni imọran pe ọrọ rẹ ko gbọdọ da bi igba ti a da ọti kikan, sinu igo tuntun.
N óo jẹ́ kí ẹnu ya ọpọlọpọ eniyan nítorí yín, àwọn ọba àwọn orílẹ̀-èdè yóo sì wárìrì nítorí tiyín, nígbà tí mo bá ń fi idà mi lójú wọn, olukuluku wọn óo máa wárìrì nígbàkúùgbà nítorí ẹ̀mí ara rẹ̀, ní ọjọ́ ìṣubú rẹ.
ọ̀run ati ayé ń gbọ́ bí mo ti ń sọ yìí, pé ẹ óo parun patapata lórí ilẹ̀ tí ẹ̀ ń rékọjá lọ gbà ní òdìkejì Jọdani.
 shaikh hassan zaruq jẹ ́ olólùfẹ ́ ìmọ ̀ , tí ó sì ma ń wá ìmọ ̀ níbi tí ó bá ti ri , gẹ ̀ gẹ ́ bí àṣẹ òjíṣẹ ́ Ọlọ ́ run ànọ ́ bì muhammad tí ó nì :  ibikíbi tí ẹ bá ti rí ìmọ ̀ ni kí ẹ ti kọ ́ ọ , nítorí ìmọ ̀ ti sọnù lọ ́ jọ ́ tó ti pẹ ́ "" ."
Lẹ́yìn náà ni àwọn tí wọ́n wà lábẹ́ ọ̀págun ẹ̀yà Reubẹni ṣí, wọ́n tò ní ìsọ̀rí-ìsọ̀rí.
Ṣugbọn bí ẹni tí ó ṣẹ̀ náà bá ti kú, tí kò sì ní ìbátan tí ó lè gba owó ìtanràn náà, kí ó san owó náà fún àwọn alufaa OLUWA.
Àjàkálẹ̀ àrùn ń lọ níwájú rẹ̀,ìyọnu sì ń tẹ̀lé e lẹ́yìn pẹ́kípẹ́kí.
 Ó jókòó nibẹ ̀ , ó sí pe àwọn tí ó sì jẹ ́ olóòótọ ́ sí wọ ́ n múra láti ibé ogun ti ọmọ rẹ ̀ náà títí tí wọ ́ n fi ṣẹ ́ gun rẹ ̀ .
Maradona wa lati idile ti wọn ko ṣaaba rọwọ fi họri, o si goke agba di agbaọjẹ agbabọọlu kaakiri agbaaye.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ibe Kachikwu: Ọ̀nà àbáyọ sí èlé owó epo ni àtúnṣeàwọn ibùdó ìfọpo wa 17 Ìgbé 2019 Oríṣun àwòrán, Google Minisita fun ọrọ to niise pẹlu bẹntirolu, Ibe Kachikwu ni Naira marundinlogoji lo ti gun iye owo ti lita epo bẹntirol n ba wọ orilẹede Naijiria.
Ni dédé oṣù kéèjé ọdún ni àsìkò yìí bẹ̀rẹ̀.
Asiria kò lè gbà wá là, bẹ́ẹ̀ ni a kò ní gun ẹṣin; a kò sì ní pe oriṣa, tíí ṣe iṣẹ́ ọwọ́ wa, ní Ọlọrun wa mọ́.
“Bí alufaa bá yẹ̀ ẹ́ wò, tí àrùn náà kò bá ràn káàkiri lára aṣọ náà tabi ohun èlò awọ náà, 
OLUWA sọ fún mi pé, “Lọ ra aṣọ funfun kan, kí o lọ́ ọ mọ́ ìdí, má sì tì í bọ omi rárá.
Justice for Uwa: Ọwọ́ ọlọpàá tí tẹ ọ̀kan nínú àwọn ọ̀daràn tó ṣekú pa Uwaila Àkọlé àwòrán, Ọwọ́ ọlọpàá tí tẹ ọ̀kan nínú àwọn ọ̀daràn tó ṣekú pa Uwaila Ọwọ́ sìnkún ọlọ́pàá ti tẹ ọ̀kan nínú àwọn tó pa Uwaila Vera Omozuwa akẹ́kọ̀ọ́ ilé ẹ̀kọ́ Uniben tí wọ́n fipá bálòpọ̀ nínú ṣọ́ọ̀ṣì tí wọ́n sì tún paá síbẹ̀.
Wọ́n ti yipada kúrò ní ọ̀nà tí mo pa láṣẹ fún wọn, wọ́n ti yá ère mààlúù kan, wọ́n ti bẹ̀rẹ̀ sí bọ ọ́, wọ́n sì ti ń rúbọ sí i.
” Eyi ni ọrọ Agbẹnusọ Ile Igbimọ Aṣofin Ipinlẹ Eko
Osu kẹrin, ọdun yii niru omiyale bayii ṣẹle gbeyin ni Ghana.
Kọmísọ́nà túnn rọ gbogbo ará ilú láti móju to àwọn àfin ti ìjọba là silẹ̀, kí àwọn ènìyàn maa lo ìbomu wọ́n , ki wọ́n máa fọ́wọ́ déédé àti pé o ṣe pàtàkì ki wọ́n sa fun ìpéjọpọ̀ àwọn ènìuyàn tó pọ̀.
Ṣugbọn àwọn olórí alufaa ati àwọn ìjòyè wa fà á fún ìdájọ́ ikú, wọ́n bá kàn án mọ́ agbelebu.
Àkọlé àwòrán, Awọn ẹgbẹ oṣiṣẹ loriṣiiriṣii ni wọn wa nikalẹ nibi eto akanṣe lati fi ranti iṣẹ awọn akọni Naijiria ti wọn jija ominira 1960 Àkọlé àwòrán, Diẹ lara awọn ami ẹyẹ ti awọn akọni n ko lọ kuro ni Adamasingba loni nibi ayẹyẹ ayajọ ominira ni ipinlẹ Oyo Àkọlé àwòrán, Olori ile aṣofin ipinlẹ Oyo, Debo Ogundoyin ati Ṣina Olukolu, kọmiṣọnna ọlọpaa nipinlẹ Oyon sọrọ, Kini ẹ ro pe wọn n sọ?
Naijiria ti wọn fara gba ninu iwa ikọlu-ajoji to waye ni orilẹ-ede South
Ẹ máa ṣe iṣẹ́ yín pẹlu inú dídùn, bí ẹni pé fún Oluwa, kì í ṣe fún eniyan.
"Mo ń fura pupọ lórí ìṣẹ̀lẹ̀ yìí.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Oyo: Abass Bello rọ́pò ọmọ Akala bíi alága káńsù Ogbomọṣọ North 20 Èrèlè 2019 Oríṣun àwòrán, Insideoyo Àkọlé àwòrán, Awuyewuye ti ń wáyé fún ọjọ́ díẹ̀ báyìí lórí bí Ọlamiju Alao-Akala ṣe tẹ̀lé bàbá rẹ̀ lọ sí ẹgbẹ́ òṣèlú ADP Lẹyin ti wọn yọ Ọlamiju Alao Akala, to jẹ ọmọ gomina ana nipinlẹ Ọyọ kuro nipo gẹgẹ bii alaga ijọba ibilẹ ariwa Ogbomoṣọ, iyẹn Ogbomoso Noirth, ijọba ipinlẹ Ọyọ ti ṣebura fun igbakeji rẹ, Abass Bello Bayewuwọn gẹgẹ bii alaga ijọba ibilẹ naa.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Osun 2018: Àwọn olùdíje ADC, ADP, APC, SDP bá aráàlú sọ̀rọ̀ lórí èròǹgbà wọn Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Osun 2018: Àwọn olùdíje ADC, ADP, APC, SDP bá aráàlú sọ̀rọ̀ lórí èròǹgbà wọn 14 Owewe 2018 Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí kan sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
Gbogbo àwọn tí a kà ninu ẹ̀yà Reubẹni jẹ́ ẹgbaa mọkanlelogun ó lé ẹgbẹsan ó dín aadọrin (43,730).
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Wo nǹkan tí yóò ṣẹlẹ̀ sí ọba tí wọ́n bá gbé ọ̀pá àṣẹ rẹ̀ lọ nílẹ̀ Yorùbá Kò sọ́rọ̀ nínú ọ̀rọ̀ Buhari, àtúntò Nàíjíríà nìkan lọ̀nà àbáyọ - Àgbà Yorùbá Àìsọ̀rọ̀ Buhari lórí ìṣẹ̀lẹ̀ Lekki, ìkọjú ìjà sí Yoruba ni - YWC ₦147m la rí kójọ fún ìwọ́de, a kò fẹ́ owó mọ́, ìwọ́de ti parí - Feminist Coalition Wo ìròyìn, àwòrán àti fídíò èké nípa ìwọ́de EndSARS Super Eagles, ẹ máṣe gbá bọ́ọ̀lù fún Nàìjíríà mọ́ nítorí ìhà tí ìjọba kọ sí ìwọ́de EndSARS - John Ogu Ará Eko, ẹ pariwo ó tó gẹ́ẹ́ lórí làásìgbò tó gbòde torí ìwọ́de EndSARS - Sanwo-Olu Ọ̀tá Yorùbá ló lo ìwọ́de láti dojú ogun kọ wá - OPC Àwọn ọ̀tá Nàíjíríà tó fẹ́ dojú ìjọba bolẹ̀ ló wà lẹ́yìn ìwọ́de EndSARS"" Ó parí ni ohùn tó gbẹnu ọ̀pọ̀ ọmọ Nàíjíríà lẹ́yìn ọ̀rọ̀ Buhari O ni o ṣeni laanu pe aarẹ Buhari ""ko laanu awọn ọmọ Naijiria ti wọn pa."
”Ekinni náà tún dáhùn pé, “Irọ́ ni!
Nígbà náà ni mo rí i tí àwọn meji dúró létí bèbè odò kan, ọ̀kan lápá ìhín, ọ̀kan lápá ọ̀hún.
Awọn oloye miran to wa nibẹ ni awọn MODEWA eyi ti Lowa, Adimula Ife, Oloye Adeola Adeyeye dari, to fi mọ awọn EMESE eyi ti Sarun Oriowo Oyeyemi dari.
Wo ojú Akeem t'Ọlọ́pàá mú pé ó fipá bá ọ̀dọ́mọbìnrin kan sùn létí odò l'Oṣun Yàtọ̀ sí Eko, wo ohun t'áwọn ìpínlẹ̀ meje míràn ń sọ nípa ìwọlé àwọn akẹ́kọ̀ọ́ Wòlí àti Pásítọ́ ló máa ń rọ̀jọ̀ àdúrà sórí ibọ́n wa kí a tó lọ digunjalè- Kayode Williams Iléẹjọ gíga jùlọ da ẹjọ́ SDP àti PDP nù, wọ́n ní Yahaya Bello ló wọlé ìbò gómìnà Kogi Nigba ti tatoo yiya, atike igbalode kikun, ete kikun, eti lilu lọna to pọ, imu lilu, ṣokoto wiwọ fun obinrin ati bẹẹ bẹẹ lọ jẹ ti igbalode.
Won gbemi awon iko olote Boko
7 20556 Orilẹede Uzbekistan 619 1.
Nítorí pé gbogbo wọn fẹ́ dẹ́rù bà wá, wọ́n lérò pé a óo jáwọ́ kúrò ninu iṣẹ́ náà, a kò sì ní lè parí rẹ̀ mọ́.
Nígbà tí ó tó àkókò ìkórè, ó rán àwọn ẹrú rẹ̀ sí àwọn alágbàro náà láti gba ìpín tirẹ̀ wá ninu èso rẹ̀.
Oṣiṣẹ papakọ ofurufu naa ti o ba ikọ iroyin BBC Yoruba sọrọ tẹsiwaju wi pe ibi ti ijọba ipinlẹ Ọyọ ati ijọba apapọ yanju ọrọ naa si ni lati gbe igbesẹ akọkọ lori awọn arinrinajo to n lọ si irinajo mimọ nilu Mecca.
OLUWA wí pé, “Àwọn eniyan ń dá ọba ninu dùn, nípa ìwà ibi wọn, wọ́n ń mú àwọn ìjòyè lóríyá nípa ìwà ẹ̀tàn wọn.
”Nígbà tí gbogbo wọn sẹ́, Peteru ní, “Ọ̀gá, mélòó-mélòó ni àwọn eniyan tí wọn ń fún ọ, tí wọn ń tì ọ́?
Dr Ureya to kẹkọ imọ iwosan ati iṣẹ abẹ la gbọ pe o ku lẹyin ọjọ meji to gba iwe ẹri moyege ẹkọ.
 Àdùnní ni orúkọ ìyá rẹ ̀ òun nìkan ni ó sì bí fún bàbá rẹ ̀ .
Oríṣun àwòrán, Joke@official Àkọlé àwòrán, Joke Silva: Modupe lọ́wọ́ àwọn algbatọ mi fún itóju wọn Biba yii ti Jọkẹ Silva tun le ọdun kan, a wa n gbadura pe yoo se ọpọlọpọ ọdun laye, ti a si maa ri pẹ pẹ pẹ loke eepẹ.
Ọdun 1998 ni Ọgbẹni Adegbola de ori oye, lẹyin ti Ọba a Bolanle Olaniyan kú lọdun 1994.
Koda, eyi gan de awọn ọgba ile ẹkọ nitori iwa ọdaran nla ni fun ẹnikẹni lati ṣe magomago lasiko idanwo.
Lẹsẹkẹsẹ wọ́n bá ti gbogbo ìlẹ̀kùn.
Lẹ́yìn náà, ṣe òrùka wúrà mẹrin, kí o sì jó òrùka kọ̀ọ̀kan mọ́ ibi ẹsẹ̀ kọ̀ọ̀kan.
Awọn ọlọpaa naa lo gbe obinrin ọhun ti apa wa lara rẹ lọ si ile iwosan fun itọju niluu Nnewi.
Ní ọjọ́ kẹwaa oṣù karun-un, ọdún keje tí a ti wà ní ìgbèkùn, àwọn àgbààgbà Israẹli kan wá láti wádìí ọ̀rọ̀ lọ́dọ̀ OLUWA, wọ́n sì jókòó níwájú mi.
Kì í ṣe èmi ni mo wà ní gbogbo ọ̀run tí mo sì tún wà ní gbogbo ayé?
Weah ti figba kan ri jẹ agbabọọlu lagbaye.
awon eniyan, ki ebi maa baa pa won , nigba wo ni won ko ni palẹ gbogbo ọja naa.
Ẹ̀yin tó ń tajà lẹ́gbẹ́ẹ títì, ẹ̀ wá 'bi gbà kọ́jọ́ méje tó pé!
Wọ́n ń po yẹ̀ẹ̀pẹ̀, wọ́n ń mọ bíríkì, wọ́n ń ṣiṣẹ́ ninu oko.
Lọdun 2014, Seyi Makinde kara bọ didu ipo gomina labẹ asia ẹgbẹ oṣelu Peoples Democratic Party.
Ọga ọlọpaa Frank Mba ni awọn oloṣelu pẹlu iwa booba o pa, boo ba o bu u lẹsẹ ati iwa afemi-afemi wọn lo fa gbogbo rukerudo to waye lasiko idibo ni ipinlẹ mejeeji, paapaajulọ nipinlẹ Kogi.
Iṣẹlẹ bi Boko Haram ṣe dumbu ọpọ awọn agbẹ ti ko lonka bayii niha ariwa orilẹede Naijiria, ipinlẹ Borno ti n mu isrọngbesi jade lorii boya awọn ologun Naijiria tilẹ kapaa awn agbesunmmi rara.
Kò sí ìbẹ̀rù Ọlọrun ní ọkàn wọn.
Iyẹn nikan kọ, ati Gomina Amosun Akinlade ati Aarẹ Buhari wọn jijọ ya awọran kan nibi ti wọn ti nawọ soke lati ṣe afihan pe awọn faramọ iṣejọba ọdun mẹrin miran sii fun Aarẹ Buhari.
Sẹnẹtọ naa to n soju ẹkun idibo Ariwa ipinlẹ Adamawa sọ pe oun darapọ mọ APC nitori gomina ipinlẹ naa Umaru Fintiri to n dari ẹgbẹ radarada.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Sunday Igboho yarí, ó fohùn ránsẹ́ sáwọn èèyàn tó ń pẹ̀gàn rẹ̀ Ìkúnlẹ̀ ló bá dé fún Oshiomole, Ize-Iyamu láti bẹ̀bẹ̀ fún ìbò aráàlú ní Edo Sunday Igboho yari, o fohun ransẹ sawọn eeyan to n pẹgan rẹ Ikú Barakat Bello ní Akinyele gbé aláàánú pàdé ẹ́bí rẹ̀ A ṣe ọdún Ọ̀ṣun lásìkò yìí láti kó Coronavirus lọ ni - Ooni ṣàlàyé Wo àwọn nǹkan tí o kò mọ̀ nípa 'Church of Satan' Àwọn afurasí ajínigbé tó tan oníṣòwò jáde ní ṣọ́ọ́sì wọ gàù Ọlọpaa Mi o ni fi iru eleyii san an fun onikaluku o.
Àwọn ẹlòmíràn rí ilé ọkọ wọ́n gbàgbé ìdílé wọn, àwọn wọ̀nyí ni àfòmọ́ tí kò ni gbòǹgbò, tí kò lè dá dúró láì jẹ́ pé ó fi ẹ̀hín ti igi bẹ́ẹ̀ ni ọjọ́ tí igi ba wó ni ayé àfòmọ́ pin, ọjọ́ tí àwọn wọ̀n-ọnnì ba ri ìdíwọ́ ní ilé ọkọ àtisọ̀rọ̀ fún àwọn ara ilé wọn yóó di ǹkan: lẹ́hìn èyí wọ́n á pòṣé, wọ́n á bẹ̀rẹ̀ si ssọkún, omi òmùgọ̀ a máa jade láti ojú wọn, àmódi gọ̀ǹgọ̀ṣú a máa dààmú ihò imú wọn, àtijẹun á di ìṣìro.
Aaroni bá dáhùn, ó ní, “Má bínú, oluwa mi, ṣebí ìwọ náà mọ àwọn eniyan wọnyi pé eeyankeeyan ni wọ́n, 
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù 2020 Budget: 'Owó oṣù sísan ni ọ̀pọ̀ àbá ètò ìṣúná fún iléeṣẹ́ ọlọ́pàá àtàwọn ológun yóò bá lọ' 12 Ọ̀wàrà 2019 Oríṣun àwòrán, Nigerian Army Ohun ti wọn lee se ni ki wọn maa san owo ohun ti wọn ba ra diẹdiẹ -Onwoye Njẹ eto aabo to mẹhẹ lorilẹ-ede Naijiria le lojutu ni ko pẹ ko jina?
Òun ni ó fi agbára rẹ̀ dá ayé,tí ó fi ọgbọ́n fi ìpìlẹ̀ rẹ̀ sọlẹ̀,tí ó sì fi òye rẹ̀ ta ojú ọ̀run bí aṣọ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Toyin Abraham: Ìgbéyàwó la kọ́ gbọ́, ọmọ ló tẹ̀le lọ́jọ́bọ 15 Ògún 2019 Oríṣun àwòrán, fathiawilliams instagram Ayọ abara bintin, isubu ti subu lu ayọ nile gbajugbaja osere tiata nni, Toyin Abraham pẹlu bi ọba oke tun se fi ọmọkunrin kan ta lọrẹ.
gbodo gba owo ile to ju odun kan lo lowo ayalegbe rẹ yoo di ofin laipẹ .
Ṣugbọn èmi wá ń sọ fun yín pé ẹni tí ó bá kọ aya rẹ̀ sílẹ̀, láìjẹ́ pé aya yìí ṣe ìṣekúṣe, ó mú un ṣe àgbèrè.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Osun Governorship Elect: Dele àbúrò Adeleke ní PDP yóò borí nílé ẹjọ́ tó gajù lọ 12 Èbibi 2019 Oríṣun àwòrán, Facebook/Ademola Adeleke Àkọlé àwòrán, Ọrọ ibo gomina ipinlẹ Oṣun Ti ina ko ba tan laṣọ, ẹjẹ kii tan leekana lọrọ igbẹjọ idibo gomina ipinlẹ Oṣun da fawọn oludije ẹgbẹ osẹlu PDP Ademola Adeleke, lẹyin ti aburo rẹ Dele sọ pe Adeleleke yoo bori nile-ẹjọ to gaju lọ.
O tun ro awon omo egbe oselu APC lati fi okan won bale pe ki won ma se ri ti awon ti o fi egbe naa sile lo sinu egbe oselu alatako, pe “Olorun yoo tesiwaju lati maa fa awon eniyan buburu kuro laarin wa,”bi eto idibo odun 2019 se n sun mo etile.
Mo bá bínú sí wọn gan-an nítorí ẹ̀jẹ̀ tí wọ́n ta sílẹ̀ ní ilẹ̀ náà ati oriṣa tí wọ́n fi bà á jẹ́.
OLUWA ní, “Nígbà tí ó bá yá, n óo kó gbogbo àwọn arọ jọ, n óo kó àwọn tí mo ti túká jọ, ati àwọn tí mo ti pọ́n lójú.
Àkọlé àwòrán, Ibadan Àkọlé àwòrán, Kwara Awọn ladelade-loyeloye, tofimọ awọn aṣaaju ẹsin ti wa nikalẹ ni papa iṣere Liberty Stadium nibi ayẹyẹ ibura fun gomina tuntun nipinlẹ Ọyọ, ṣugbọn a ṣi n reti gomina tuntun, igbakeji rẹ ati awọn adari ẹgbẹ Oṣelu PDP Àkọlé àwòrán, Oyo, Ibadan Awọn gbalẹ gbalẹ gan n ṣe iṣẹ wọn bi iṣẹ ni gbagede iburawọle ti ipinlẹ Ogun.
'Ìnira ńlá ni coronavirus mú bá èmi àtàwọn ọmọ mi gẹ́gẹ́bí opó tó fọ́jú' Gomina Makinde gbàlejò àwọn Imam lásìkò àjàkálẹ̀ àrùn Coronavirus Kí ló ń mú àwọn adarí obìnrin lágbáyé rọwọ mú nípa kíkojú covid 19?
Nígbà tí mo bẹ ojú òkú yìí wò ara rẹ̀ kún fún ẹ̀jẹ̀ gidigidi, mo wọlé mo mú àdá, mo fi í sí abẹ́ aṣọ mo sì ké sí ìyàwó mi; orí àga tí o bá mi yìí náà ni mo jókòó lé, nígbà tí ìyàwó mi dé, ojú rẹ̀ ti yípadà sí tèmi, àṣé ó ti rí gbogbo nǹkan tí mo ń ṣe lẹ́hìn wọn-ọnnì, nítorí àjẹ́ ni.
Minisita f'ọrọ ilẹ okeere lorilẹede Amẹrika, Ọgbẹni Tillerson salaye wi pe ohun ti ohun n fẹ bayii ni ki awọn orilẹede yooku o gbọn ọwọ s'awo ikowojọ naa.
Ẹni to bori: Algeria Madagascar vs Benin.
Ẹ o ranti wipe, o ti dije ni ẹẹmẹta ṣaaju 2015 ti o si kuna.
Oríṣun àwòrán, @PoliceNG Àkọlé àwòrán, Aworan FSARS Koda, wọn n fẹ ki ileesẹ ọlọpaa gbe igbimọ kan, ti kii ṣe ti ọlọpaa kalẹ, ti yoo mojuto iwadii ati igbẹjọ gbogbo àwọn ọlọpaa ti wọn ba fi ẹsun kan pe o fiya jẹ tabi pa ẹnikẹni, laarin ọjọ mẹwaa.
Ṣugbọn nígbẹ̀yìn, n óo dá ire Elamu pada.
Ẹ̀rù rẹ bà mí, mo bá lọ fi àpò kan rẹ pamọ́ sinu ilẹ̀.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ara san p'eeyan mẹrindinlogun ninu ṣọọṣi kan ni Rwanda 12 Ẹrẹ̀nà 2018 Àkọlé àwòrán, Ni agbegbe Rwanda ni awọn eniyan ti ku'ku ara Ko din ni eniyan mẹrindinlogun to ku nigbati ara san pa wọn ni inu ile ijọsin kan ni orilẹede Rwanda lọjọ abamẹta.
Ní ọjọ́ kẹtadinlogun oṣù keje, ìdí ọkọ̀ náà kanlẹ̀ lórí òkè Ararati.
Lọwọ-lọwọ bayii, awọn dokita ọhun ko se itọju kankan fun awọn eeyan to ni arun Coronavirus mọ nile iwosan naa.
Lọ́dúnnìí, ọjọ́dọ́gba ìgbà irúwé bọ́sí 20 Ẹrẹ́nà (oṣù kẹta).
idibo se pẹ bẹrẹ ibo didi ,paapaa julo ni awon agbegbe kan ni Ilorin.
Ẹ̀mí mi wà fún ìlò rẹ, ẹ̀mí rẹ sì wà fún ìlò mi.
Bi ọjọ naa ṣe n sunmọ, awọn ileeṣẹ to n ko ero awọn oludibo jọ nipa ẹni ti wọn yan laayo ko ni dawọ iṣẹ duro.
Bakan naa ni wọn woye pe awọn gomina nilẹ Kaarọ oojire to wa ni Eko, Oyo, Osun,Ogun,Ekiti ati Ondo ti kuna ninu ojuse wọn lati pese aabo to jiire silẹ Yoruba.
Nítorí bí ó ti jẹ́ pé nípasẹ̀ eniyan ni ikú fi dé, nípasẹ̀ eniyan náà ni ajinde òkú fi dé.
Lẹyin Oṣu meji ti wọn ṣe ayẹwo oogun naa ni ara eniyan lo gba ontẹ ijọba gẹgẹ bi oogun to n sawotan arun Coronavirus.
" Wo ohun tí ilé ẹjọ́ ní kí wọ́n ṣe fún Sunday Shodipe, afunrasí ìṣekúpani l'Akinyele Gbajabiamila balẹ̀ sí Ghana láti pẹ̀tù sááwọ̀ láàrin Nàìjíríà àti Ghana Isiaka Busari, Mighty Joe tó jẹ́ adigunjalè tó rọ́pò Ọyenusi lẹ́yìn tí wọ́n pa á E wo ọmọ Yorùbá àkọ́kọ́ tó jà fún ẹ̀tọ́ àwọn aláwọ̀dúdú ní America!
OLUWA dá Mose lóhùn pé, “N óo ṣe ohun tí o wí, nítorí pé inú mi dùn sí ọ, mo sì mọ orúkọ rẹ.
Fi wọ́n sílẹ̀ pẹlu ìyá wọn fún ọjọ́ meje, ní ọjọ́ kẹjọ o níláti fi wọ́n rúbọ sí mi.
 láti ọdún àwọn 1980 , àwọn nọ ́ ńbà ìṣẹlẹ ̀ àrùn pọ ́ njú-pọ ́ ntọ ̀ ń pọ ̀ si .
Ta ni o sì ní níhìn-ín tí o fi gbẹ́ ibojì síhìn-ín fún ara rẹ?
Ní ìlú Èkó, àwọn jàǹdùkú wọ̀yá ìjà, ọ́rọ́ di bóòlọ o yàgò mi Àwọn ọmọ Nàìjíríà bu ẹnu àtẹ́ lu iléeṣẹ́ Netflix lórí fíìmù tó ní Jesu ní ìbálòdò akọ s'ákọ Èèwọ!
Bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé eniyan ẹlẹ́ran-ara ni mí,sibẹ n óo gbé ìgbé-ayé mi pẹlu ìrètí;
 O ni ẹnu wa n ya oun pe ki lo de ta fi maa ba awọn dukia ijọba jẹ."
Ẹgbẹ Oselu Labour Party ni ibo aadọjọ( 150), ti ẹgbe oselu Peoples Party of Nigeria (PPN) ni ibo mẹrindinlọgọrin(76) ti UPN si ni ibo mejilelogoji(42).
Ọmọbìnrin tó tayọ nínú ìdànwó WAEC ọdún 2019 pẹ̀lú A1 méje ti kú Kí lo mọ̀ nípa ìbẹta kan ṣoṣo tí Alaafin Oyo bí?
Nítorí ìwọ ni Ọlọrun tí mo sá di.
Oríṣun àwòrán, Emmanuel Anneh Amọ, ọfẹ ni awọn oṣiṣẹ ile iwosan ijọba ti National Hospital Abuja ṣe isẹ abẹ naa fun wọn nitori awn obi awọn ibeji naa- Michael Edeh ati Maria Onya Martins ko le e san owo ile iwosan naa.
Àwọn ọmọ ogun Jeroboamu wà níwájú àwọn ọmọ ogun Juda, àwọn tí ó rán tí wọ́n sápamọ́ sì wà lẹ́yìn wọn.
Agbẹjọro Farintọ fikun ọrọ rẹ pe iru ẹjọ ti ileẹjọ kotẹmilọrun ba da lo maa sọ boya awọn alaga ti Gomina ipinlẹ ba yan lo maa ṣakoso awọn ijọba ibilẹ tabi awọn alaga to wa nibẹ tẹlẹ ki ijọba tuntun to de.
Laipẹ yii ni ọrọ kan tun waye ni ile rẹ ti a gbọ pe ileeṣẹ ọlọpaa ko awọn eeyan wọn lọ si ile arabinrin yii ti wọn si n gbiyanju ati ja ilẹkun wọle lati lọ gbe e lori ẹsun ti wọn fi kan an.
A kò gbo̩dò̩ mú e̩niké̩ni ní e̩rú tàbí kí a mú un sìn; e̩rú níní àti ò wò e̩rú ni a gbo̩dò̩ fi òfin dè ní gbogbo ò̩nà.
Gomina Abiodun fi anfani eto yii kede pe iṣejọba oun ti yanju iṣoro ile iwe akọṣẹmọṣẹ Moshood Abiola ati ti wahala to n suyọ lori ile iwe olukọ̀ni Tai Solarin(TASCE) to wa ni Omu Ijebu ti wn si ti ṣagbekalẹ ibudo pataki kan fun eto ẹkọ ni ipinlẹ naa.
Ọjọ karundinlọgbọn, oṣu kẹsan an, ni awọn aṣofin agba pinnu lati pada si ẹnu iṣẹ.
Nígbà tí ọ̀rọ̀ náà dé etígbọ̀ọ́ ọba Ninefe ó dìde lórí ìtẹ́ rẹ̀, ó bọ́ ẹ̀wù oyè sílẹ̀, ó wọ aṣọ ọ̀fọ̀, ó sì jókòó ninu eérú.
Oríṣun àwòrán, facebook/Ekiti state government Àkọlé àwòrán, Wọn ti kọkọ yọ aṣofin Akinniyi ni ipo gẹgẹ bii akojanu ile loṣu karun un lati fi faa leti pé boya yoo yiwa pada Alaga igbimọ to n ri si iroyin nile aṣofin naa.
Nigba to n salaye ohun ti oju rẹ ri, Funkẹ ni ohun to dun oun julọ lasiko ti oun wa lori akete arun naa ni pe, oun ko fi oju ri ọmọ oun tii se ọmọ ọdun kan.
ti won yoo fi maa ri ara won  gege bi eni
Ajo agbaye to n ri si ọrọ eto ilera WHO ti so pe o le ni milionu mọ́kànlélọ́gọ́rin ọmọ orile ede Afirika ti wọn je abarapa , ti pupọ ninu wọn si n koju iwa ẹgan ati ikorira, ni eyi ti o le  pa anfaani wọn lati kopa ninu eto ẹkọ,isẹ ati igbaye gbadun wọn lara.
Ti wọn ko ba si ti ri eeyan sọ fun wọn, iku naa yoo tẹsiwaju ni.
Aàrẹ Donald Trump àti Melania aya rẹ̀ ti n jẹ oúnjẹ ọ̀sán pẹ̀lù Obabìnrin Elisa ni Buckingham Palace.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ìjà ẹgbẹ́ òṣèré TAMPAN àti ANTP ni kò jẹ́ kí wọ́n pe Baba Legba sínú eré mọ́, kó tó kú - Owolabi Ajasa Tí mo bá kú lónìí, Pásítọ̀ Ibiyeomie ló pa mi - Daddy Freeze kébòòsí Àwọn afurasí lórí ẹ̀ṣùn jíjí ìbejì Akeugbagold gbé yọnú sílé ẹjọ́ láì ní agbẹjọ́rò Aṣòfin méje yarí mọ́ Akeredolu lọ́wọ́ torí ọkọ̀ ayọ́kẹ́lẹ́ tí kò pín fún wọn Aya gómìnà Kwara gba ilé fún Risikat olójú búlúù àti ọkọ rẹ̀ Risikat, ìyá àwọn ọmọ olójú búlù tí bẹ̀rẹ̀ sí ní kọ́sẹ́ aṣojú lóge Àjọ ECOWAS yan Aàrẹ Ghana, Nana Akufo-Addo gẹgẹ bíi aàrẹ tuntun Osu Kẹwa ọdun 2020 ni Alaafin Adeyemi yoo pe ẹni ọdun mejilelọgọrin, nigba ti Ayaba Abibat yoo pe ẹni ọdun mejilelọgọrin losu Kejila ọdun.
Garba shehu sọ pe lootọ ni Naijiria n dojukọ itankalẹ ajakalẹ arun coronavirus bi gbogbo orilẹ-ede to ku lagbaye, ijọba Muhammadu Buhari si ti gbe awọn igbesẹ kan lati din ipa rẹ ku lara awọn ọmọ Naijiria.
Oríṣun àwòrán, EPA Àkọlé àwòrán, Lapa ibomiran lagbaye, lorilẹede South Korea, ọmọ bibi ilu Ghana to n kopa ninu ere idaraya fifi ayawọ, Akwasi Frimpong , n fi ọrẹ tuntun han ọmọ rẹ.
5bn eniyan to n lo ki wọn 'update Whatsapp' wọn.
Nínú ìgbésẹ́ láti mú jíjà ràìn-ràìn ìròyìn wálẹ̀ lórí dídá ẹgbẹ̀rún mẹ́ta olùkọ́ ilé ìwé alákọ́bẹ̀rẹ̀ dúró látàrí àìkún ojú òṣùwọ̀n wọ́n, ìjọba ìpínlẹ́ Kaduna sọ pé àwọn olùkọ́ ilé ìwé alákọ́bẹ̀rẹ̀ tí wọ́n ṣẹ̀sẹ̀ gbà yìí ti ṣe tán láti lọ sí ibi tí wọ́n bá pín wọn sí láti lọ dí àlàfo tó sí sílẹ̀ níbẹ̀.
Bákan náà ni ó jẹ́ òǹdíje sí ipò ààrẹ ní abẹ́ ẹgbẹ́ olóṣèlú Allied Congress Party ti Nàìjíríà.
 ( ojoibi 4 august , 1961 ) je oloselu ati aare orile-ede ile amerika tele .
O ni ohun itiju nla gbaa lo n ṣẹlẹ ninu ẹgbẹ oṣelu APC labẹ alaga Oshiomole.
Wo àwọn orílẹ̀èdè tí wákàtí ààwẹ̀ wọn gùn ju ti Nàìjíríà lọ
 “Eto aabo fun awon ara ilu je ojuse ijoba yii.
Ni ipari, Igwe Alfred Achebe to je alaga igbimo awon lobaloba ni ipinle Anambra ninu oro tire yombo ipinnu osere omo Igbo yii lati si oju awon eniyan si Pataki aiso orisun won nu lasiko yii.
Holy Thursday: Àlúfáà àgbà ìjọ́ Anglican sọ oun tó tọ́ láti máà ṣe
 Ipade ajo naa yoo tun waye ni  ọjọ kọ́kànlélógún osu kéjìlá  , odun 2018.
Adédèjì: Ìse ilé ló gbé ọlọ́pàá tó ń gba rìbá dé ìta
lára àwọn pàtàkì iṣẹ ́ àgbẹ ̀ ni pé , nípa iṣẹ ́ àgbẹ ̀ ni ati máa ń mú oúnjẹ jade fún gbogbo ènìyàn àti fún àwọn ẹranko pẹ ̀ lú .
Bakan naa ni Ajọ NDDC ti paṣẹ ki wọn bẹrẹ si ni wa gbogbo awọn to ti farakan adari eto isuna, Ibanga Etang to di oloogbe naa.
Kí ó sì da iná inú wọn káàkiri jìnnà jìnnà nítorí àwọn àwo turari náà jẹ́ mímọ́.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù US Election 2020: Wo ìyàtọ̀ láàrin ìjọba Joe Biden sí ti Donald Trump bó ṣe kan orílẹ̀èdè àgbáyé 7 Bélú 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 9 Bélú 2020 Oríṣun àwòrán, Getty Images Ohun akọkọ ti ijọba aarẹ orilẹede Amerika labẹ Aarẹ Donald Trump kọkọ ṣe nigba ti wọn de ipo ni lati fihan agbaye pe orilẹede Amerika ni yoo saju ninu ohun gbogbo,'America First'.
Eyi ni esi ifesewonse idije NPFL Nigeria Professional Football League, ti o waye lojo Aiku(Sunday):Katsina United 2-1 Rivers UnitedHeartland FC 0-0 Abia WarriorsLobi Stars 1-0 El-Kanemi WarriorsWikki Tourists 1-1 Kano PillarsFC IfeanyiUbah 3-1 Sunshine StarsNiger Tornadoes 1-0 Rangers InternationalYobe Desert Stars 1-0 Go Round FC.
Nítorí pé ní ọjọ́ iwájú, gbogbo wọn yóo di ẹni ìgbàgbé patapata.
 bí àwòrán-atóka igi won se rí nìyi .
Mide Martins Abiodun: Isẹ asọ tita lo tun mu lọkunkundun lẹyin ere sinima Ẹlomiran to tun mu okoowo mii mọ isẹ tiata ni Mide Martins aya Afeez Owo Abiọdun, ti awọ̀n mejeeji dijọ jẹ gbajumọ nidi isẹ tiata.
Gbaju gbaja osere tiata naa tun tẹ siwaju pe osu kẹfa si Ikeje ọdọọdun ni ebi maa n pa oun ati iya oun julọ, ti iya si maa n jẹ awọn ju.
"Ko sohun to n jẹ pe o sun ko ji mọ o, ko sohun to n jẹ o sun o rẹ ara.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Buhari wa ẹnu si àwọn ọdọ Nàìjíríà Johesu: Òsìsẹ́ ìlera ti bẹrẹ iyanselodi Ẹlẹ́wọ̀n gba máákì 248 ni ìdánwò Jamb Sani sọ wípé àjọ tí ó ńṣe àkóso ẹ̀kọ́ alákọ́bẹ̀rẹ̀ kọ́kọ́ gba àwọn olùkọ́ tí ó fẹ́ẹ̀ tó ẹgbàájọ sùgbọ́n nígbà tí wọ́n ṣe àwárí nípa ọ̀pọ̀lọ́pọ́ wọn, wọ́n ri wípé wọ́n rá pálá wọlé ni.
Ọmọ ilẹ̀ Iran 82 ló kú nínú bàálù tó já lórílẹ̀èdè naa Díẹ̀ lára àwọn ìṣẹ̀lẹ̀ tí yóò mi ìgboro tìtì l'ọ́dún 2020 rèé Pásítọ̀ pe Naira Marley ní ẹlẹ́mìí èṣù, Marley fèsì padà pé kí pásítọ̀ gan tẹ èṣù mọ́lẹ̀ Àbọ̀ ìpàdé bòńkẹ́lẹ́ láàrin Tinubu àti Buhari rèé Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Dambe fight: ìdíje ìjà láàrin àwọn akóni tó n ja ẹ̀ṣẹ̀ Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Ọjọ kejidinlọgbọn, oṣu Kejila, ọdun 2018 ni Shehu Shagari jade laye lẹni ọdun mẹtalelaadọrun.
Eyi si lo tumọ si pe ẹ maa gbe ni ailewu.
Ènìyàn 653 míràn tún kún iye àwọn tó ní COVID-19 ní Nàìjíríà Chelsea fún Man United lóúnjẹ ẹ̀tẹ́ jẹ, Cuppy bínú yí jọ̀lọ́ọ̀fù dànù Akanbi mi, má fọ̀ ọ́, mo wà pẹ̀lú ẹ; Ẹni tó ṣe ìgbéyàwó olórùka ló l'ọkọ- Lizzy Anjorin Wo díẹ̀ lára àwọn tí yóò kópa nínú ìdíje BBNaija ọdún yìí Ajọ NCDC tun ṣalaye pe o ti le ni ẹgbẹrun marundinlogun eeyan to ti ri iwosan lọwọ arun ọhun lorilẹ-ede Naijiria lọwọ bi a ṣe n sọrọ yii.
Ó gbé dígí kan báyìí lọ́wọ́, ó sì fi hàn mi o ní ki n wo inú rẹ̀.
Iwaadi naa so pe Iku lati ọwọ ololufẹ ẹni ṣi fi si ọdọ awọn obinrin ju okunrin lọ'' Àkọlé àwòrán, O ṣeeṣe ki awọn obinrin pade iku wọn lọwọ ololufẹ wọn tabi awọn to sunmọ wọn Obinrin mẹtadinlaadoọta,lorileede mọkanlelogun lọjọ kan Iwaadi ajọ isọkan orileede agbaye lọdun 2017 so iroyin to ri gba lati ọdọ awọn ijọba ni ṣoki nipa iṣekupani to n waye."
Ogbeni Garba wa fi oro re mule
Baṣọ̀run Gáà, tó yan ọba mẹ́rin, pa ọba mẹ́rin àmọ́ ọba karùn-ún ló pa á Wọ́n dóòlà ẹ̀mí èèyàn mẹ́rin níbi ilé mííràn tó wó l'Eko Wo àwọn òrílẹ̀èdè 10 tó láyọ̀ jùlọ lágbàyéé Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Àlàyé rèé lórí ilé kẹ̀ta tó wó l'Eko Bi o tilẹ jẹ pe ọpọ olugbe ipinlẹ Eko ni ko ni fẹ gba eyi gbọ nitori ohun ti oju wọn n ri lori awọn koko igbayegbadun bii ile gbigbe, ọkọ wiwọ, ohun jijẹ rira ati bẹẹbẹẹ lọ, ṣugbọn ajọ iwadii ọrọ aje agbaye naa ni sibẹsibẹ, gbigbe ni ilu Eko ṣi gba ọpọ ju ọpọ awọn ilu nlanla miran kaakiri agbaye.
Gege bi iroyin se so, ikolu naa ni awon toro kan so pe, o seese ko je pe awon omo ogun olote NATO ni o wa nidi re.
Inú rẹ ni mo fẹ́ kí ó ti wá.
 A ti fi owo to le ni bilionu merin
Nígbà wo ni èmi gan-an yóo tó bẹ̀rẹ̀ sí ṣe àkójọ àwọn ohun tí mo lè pè ní tèmi?
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Fasola ló jẹ̀bi ìdákúrekú iná ọba - ọmọ Nàìjíríà fárígá lórí òkùnkùn biribiri Sotitobire: Adájọ́ dá Pásítọ̀ Alfa Babatunde padà s'ẹ́wọ̀n fún ọjọ́ mọ́kàndílógún Ìtàn ìgbé ayé Bode Thomas rèé, ó kọ́ wa láti máa kó ẹnu wa ní ìjánu Ọta ìbọn ogun Biafra ṣì wà lọ́rùn mi lẹ́yìn àádọ́ta ọdún tí ogun parí - Umar Se ni wọn fi ẹrọ ti eeyan fi n mi, to ni afẹfẹ ninu si imu ọkunrin naa, ki eemi rẹ lee jake, ni kete ti wọn fa yọ tan.
Sunday Shodipe: Iléèṣẹ́ ọlọ́pàá ìpínlẹ̀ Oyo ṣe àfihàn afurásí tó n pààyàn ní Akinyele
"Izeowayi Victor jáwé olúborí nínú àròkọ̀ BBC Pidgin Ìtan Afíríkà wu ni lórí jọjọ́ pẹ̀lú àwòrán Victor Agunbiade gba awọn ọmọ Naijiria ni imọran lati fi ootọ inu ṣiṣe aje wọn nibiklibi ti ori ba da wọn si Wo díẹ̀ nípa ohun tí Walter Carrington gbé ṣe nígbà ayé rẹ̀ Ọ̀fẹ́ ní à ń kò àwọn ọmọ Nàìjíríà tó há sí Lebanon bọ̀ wá sílé- Abike Dabiri Ilé iṣẹ́ tó ri si ètò ẹ̀kọ́ l'Abuja kò tí ì rànsẹ́ pé UNILAG ti ni Giwa tuntun Immaculate Okochu ń múra ìyàwó lọ́wọ́ ló k'àgbákò ikú ""Mi ò ní wọ Uber mọ́ tí wọ́n bá leè fi owó lée nítorí àfikún owó orí tí Sanwo Olu ṣe"" Bakan naa lo mẹnuba ipa ti igbagbọ ninu Olorun n ko ninu igbiyanju ẹda laye pẹlu imọran pe ki awọn ọdọ maa beere lọwọ ori ki wọn to gbe igbesẹ nitori oju ala ni oun ti ri ara oun nidi iṣẹ to sọ oun di olokiki yii lẹyin adura."
Nígbà gbogbo ni ẹ ní àwọn talaka láàrin yín, ṣugbọn ẹ kò ní máa rí mi láàrin yín nígbà gbogbo.
Angẹli kẹta da ohun tí ó wà ninu àwo rẹ̀ sinu odò ati sinu ìsun omi, ó bá di ẹ̀jẹ̀.
Arọ ni alákùnrin yìí jẹ́, iye ọjọ́ orí i rẹ̀ sì nṣe mẹ́tàlélọ́gbọ̀n.
Atiku so pe  “A ni ipinnu lati je ki gbogbo awon omo orile ede Naijiria lowo ninu awon ipinnu wa , nitori pe  eleyii ni ohun akoko to wa ninu ipinnu egbe PDP.
Ọpọlọpọ awọn eniyan si lo ti n beere pe bawo ni ilana owo oṣu tuntun yii yoo ṣe lọ, ati wi pe, ki ni awọn alakalẹ tuntun naa da le lori.
Oju ọna to wọ inu ilu naa ni awọn ọkunrin ọhun ti fi ipa ba obinrin naa lopọ niwaju awọn ọmọ rẹ mejeeji.
Wọ́n jẹ́ amọ̀kòkò ní ààfin ọba, wọ́n sì ń gbé ìlú Netaimu ati Gedera.
Iroyin sọ pe ọkunrin naa, Fatai Salami, mu oogun apakokoro nitori pe awọn oṣiṣẹ ajọ TRACE, gba ọkọ rẹ.
” Gbogbo wọn bá dá a lẹ́bi, wọ́n ní ikú ni ó tọ́ sí i.
“A o gba isinmi ranpe ni kete ti idije boolu agbaye ba bere, ti a o si bere pada ti idije naa ba wa si ipari.
"Mo tiẹ kọkọ fẹ ẹ ma a sọ pe mi o bi ọmọ kankan, ṣugbọn o sọ fun mi pe awọn obi mi ti wa pẹlu ọmọ ni ileewosan.
eleto idibo ti ri awon aleebu ati awon agọ idibo ti eto idibo ko tete bẹrẹ nibẹ
Lara awọn to jagun ofurufu lasiko ogun agbaye keji ni ki o to wọ inu oṣelu lọ ni ọdun 1964 gẹgẹ bii ọmọ ẹgbẹ oṣelu Republican.
    Kò pẹ́ púpọ̀ tí Wèrédìran wá sí apá ibi tí mo wà tí ó sọ̀rọ̀ sí mi, a bá ara wa sọ̀rọ̀ dáadáa, èmi pàápàá tilẹ̀ ń fẹ́ láti bá a ṣe ọ̀rẹ́ ki n bà rí ààyè fún un ní ìmọ̀ràn díẹ̀, nítorí bí ó ti ṣe náwó yìí ko té mi lọ́rùn rárá.
Mika bá bi í pé, “Níbo ni o ti ń bọ̀?
Ògo tí ilé yìí yóo ní tó bá yá, yóo ju ti àtijọ́ lọ.
Ọlọ́run lágbára, síbẹ̀ a kò ṣàìrí àwọn olóye lórí ènìyàn, tìi wọ́n lówó tí wọ́n tún ní ìwà ìrẹ̀lẹ̀ ti wọ́n sì ń ba búrúbúrú níwájú Ọlọ̀run Ọba.
0 510 Orilẹede Bhutan 0 0.
Ọmọ rẹ̀, Paul sọ pé ''yóò dára tí wọ́n bá fun ní òmìnira, kó le bà á ní ànfàání láti kú ní ìrọ̀rùn ní ilé rẹ̀ ju pé kó kú sínú ọgbà ẹ̀wọ̀n.
je omo egbe oselu PDP, to ni iye ibo  9,337, ati ogbeni  Aiyenale Fred omo egbe ADC,ti o ni iye ibo
Ṣebí èyí ni à ń pè ní kí eniyan mọ OLUWA?
Aláàfin gbé àṣẹ kalẹ̀ láti dènà àtúnṣẹ̀ ìṣẹ̀lẹ̀ 'Soka'nílùú Ọ̀yọ̀ 'Ìnira ńlá ni coronavirus mú bá èmi àtàwọn ọmọ mi gẹ́gẹ́bí opó tó fọ́jú' Mo kábàámọ̀ pé n kò kàwé, kí n tó bẹ̀rẹ̀ iṣẹ́ tíátà - Sanyeri Ìdí táwọn apòògùn Nàìjíríà fi tako oògùn Coronavirus láti Madagascar Ọọni, Aláàfin, Ojisẹ Ọlọ́run àti oniṣẹ ìwádìí fi Ògún gbari pé òògùn ìbílẹ̀ le wo Covid-19 Aṣẹ ẹgbẹ TANPAN naa, to wa lati dena itankalẹ arun Coronavirus, ni awọn ọmọ ẹgbẹ naa tẹle, ti koowa wọn si joko sile lai gbe sinima kankan jade.
Aare orile ede Niajiria Muhammadu Buhari ti kedun iku  eni akoko to je alaga fun ajo to n ri si  sise owo ilu kumo- kumo teleri  lorile ede Naijiria; Independent Corrupt Practices and Other Related Offences Commission (ICPC),adajo agba Mustapha Akanbi,Aare sapejuwe oloogbe naa  gege bi olooto ati olufokansin eniyan.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ambode: Àwọn aṣòfin Eko kò le è wádìí mi, àwọn ló fòǹtẹ̀ lu owó tí mo ná 30 Ọ̀wàrà 2019 Oríṣun àwòrán, @AkinwunmiAmbode Sinima orita awoowo tan lọrọ iwadi ẹsun ajẹbanu to n waye laarin gomina ana ni ipinlẹ Eko, Akinwumi Ambọde atawọn aṣofin ipinlẹ naa.
Ile ẹjọ naa tun dena ijọba Oyo lati gbe igbesẹ kankan lori ọrọ ilẹ ọhun, titi ti igbẹjọ yoo fi bẹrẹ.
Láti àwọn orílède kan, ó ni erejú ilé àyẹwo tí o ni ìtẹ́wọ́ gbà lati mu esi ayẹwo wọn wa.
Ọpọ iroyin lo n tan ni ayelujara pe Aisha gbagbọ pe Daura lo fẹ fẹ iyawo keji fun Aarẹ Buhari ni eyi ti wọn ni ko ri bẹẹ rara.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Jacob Zuma fi ipo aarẹ orilẹede South Africa silẹ lẹyin ọpọlọpọ awuyewuye Oloselu to fa isẹ isowo dani ni Cyril Ramaphosa; o si wa lara awọn oloselu to lowo julọ lorilẹede naa.
Ó ní ká máa fi ọgbọ́n orí wa dárà ní ọlọ́kanòjọ̀kan.
 Eleyi ti awon eniyan n pe ni ijoba baba ati omo, “Bush 41” ati “Bush 43.
Ó bá pada lọ sí ilé rẹ̀, ó rí ọmọde náà tí ó dùbúlẹ̀ lórí ibùsùn, tí ẹ̀mí burúkú náà ti jáde kúrò lára rẹ̀.
Iléèwé Chrisland yóò wọlé padà lọ́jọ́ Ajé, wọ́n ní òfin ìgbélé coronavirus kò mú ìgbẹ̀kọ́ orí ayélujára Ewu ń bẹ!
Ọpọ onwoye lo si n wo pe o ṣeeṣe ko jẹ pe ni ibamu pẹlu ati pa eewọ yi mọ ni Yeyeluwa ilẹ Yoruba, iyẹn Olori Naomi ṣe fi aafin silẹ lọ ilu Ọwọ ṣaaju ibimọ rẹ.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Ọdun meji lo lo to n wa ọkọ ofurufu awn ologun.
Kia ni Ọ̀bọ bẹ̀rẹ̀ si ṣe “Àmin” lai dúró.
Ní ọ̀nà kan náà, nígbà tí Ọlọrun fẹ́ fihàn gbangba fún àwọn ajogún ìlérí wí pé èrò òun kò yipada, ó ṣe ìlérí, ó sì fi ìbúra tì í.
Nígbà tí ó di Ọjọ́ Oluwa, ni Ẹ̀mí bá gbé mi.
Ọjọ́ ìtàn ni ọjọ́ yìí: ojú yìí ni ogunlọ́gọ̀ ọmọ-ìlú Mozambique fi wo ìṣẹ̀lẹ̀ ọjọ́ 14, oṣù Ọ̀pẹ ọdún 2018 nígbà tí, fún ìgbà àkókọ́ nínú ìtàn ìgbésí ayé ètò ọkọ̀ òfuurufú ìlú náà, tí obìnrin jẹ́ atukọ̀.
Ní àkókò náà ni àwọn ọmọ ogun Nebukadinesari, ọba Babiloni, lọ gbógun ti Jerusalẹmu, wọ́n sì dó tì í.
Awọn ti a doola sọ fun wa pe awọn to kọlu wọn to mẹẹdogun niye, ti wọn si gbe ibọn alagbara dani.
Kọmisọna eto iroyin nipinlẹ naa, Muhammed Idris lo fidi ọrọ yii mulẹ fawọn oniroyin lọjọ Aiku.
Ṣaaju akoko yii, gbọnmi si i, omi o to o ti wa laarin ẹgbẹ oṣelu APC ni Ekiti ti ẹgbẹ naa ṣẹ pin si meji eyi ti awọn kan tẹle gomina ipinlẹ Ekiti, Kayode Fayemi, ti awọn miran si tẹle Sẹnetọ Ojudu.
orile ede Naijiria, Yemi Osinbajo tun gbe ipolongo idibo fun  idije ẹlẹẹkeji aare Muhammadu Buhari lo si ilu
Wọ́n bọ́ sápá kan, wọ́n ń sọ fún wọn pé, “Ọkunrin yìí kò ṣe ohunkohun tí ó fi jẹ̀bi ikú tabi ẹ̀wọ̀n.
Biobelemoye ní kí àwọn ọmọ ẹgbẹ́ JOHESU padà sí ẹnu íṣẹ́ ní ọjọ́ Ajé tó ń bọ̀.
Nigeria Kidnapping: Ọ̀gá ọlọ́pàá Adamu Pàṣẹ́ iṣẹ́ àkànṣe nílẹ̀ Yorùbá
Nítorí kì í ṣe eniyan ni à ń bá jagun, bíkòṣe àwọn ẹ̀mí burúkú ojú ọ̀run, àwọn aláṣẹ ati àwọn alágbára òkùnkùn ayé yìí.
Bí ó bá ń fẹ́ ìmọ̀ràn nípa nǹkan kan, n o fún un nì ìmọ̀ràn tí mo bá mọ̀, n kò ní sọ ilé wa di ilé ìbànújẹ́, ki n máa rojú kórókóró kiri, ki n máa dákẹ́ dúduudu.
Irọ́ ní, kìí ṣe àdó olóró ló bú gbàmù ní Akure - Ọ̀gá Ọ̀lọ́pàá Ondo!
Oga olopaa naa ti wa dari gbogbo komisona olopaa patapata lati tele ilana naa kiakia, ki won si kilo fun awon olopaa to wa labe eka SARS lati fopin si ise won.
Nigba to di ọdun 1964, o kọwe fipo rẹ silẹ ni fasiti gẹgẹ bi ifẹhonu han lori agbara aitọ ti awọn alaṣẹ ile iwe n lo lori wọn eyi to jẹmọ gbigbe lẹyin ijọba to wa lode.
“Kí ni a óo ṣe sí àwọn ọkunrin wọnyi o?
Ki wa ni itumọ Brexit ti ko ni adehun ninu"" ati ohun to duro fun?"
Ó kọ́ ilé ìṣọ́ gíga sí ààrin rẹ̀,ó sì ṣe ibi tí wọn yóo ti máa fún ọtí sibẹ.
Paapa awọn to n gbá awọn Kristẹni ti ko dakan mọ.
Ija ẹlẹyamẹya to ṣẹlẹ ni Rwanda wa lara awọn nkan ti o dun Kofi Annan titi to fi ku nitori pe, wọn ni ko gbe igbesẹ to to lati doola ẹmi awọn ara orilẹede naa.
Nígbà tí Hesironi di ẹni ọgọta ọdún, ó fẹ́ ọmọbinrin Makiri, baba Gileadi.
Àwọn oníròyìn náà ló ta professor Peller, lásìkò ìfọ̀rọ̀wánillnuwo ló ti sọ̀rọ̀ jù, tí ọ̀pọ̀ awọn aṣírí si hàn síta.
Oun funrarẹ lo tun pada wa pa ina ọtẹ yii.
Ọ̀rọ̀ ọ̀jọ̀gbọ́n, ọmọ Dafidi, Ọba Jerusalẹmu nìyí.
Iku Toke ni ikẹfa to ti waye nijọba ibilẹ Akinyele laarin oṣu meji.
Nígbà tí ó mọ̀ pé Juu ni, ó kà á sí ohun kékeré láti pa Modekai nìkan, nítorí náà, ó pinnu láti pa gbogbo àwọn Juu tí wọ́n jẹ́ eniyan Modekai run, ní gbogbo ilẹ̀ ìjọba Ahasu-erusi.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Àwòrán ìsẹ̀lẹ̀ ọkọ̀ àti ẹ̀mí tó jóná ní Èkó Iná Èkó: Ẹbí àwọn tó f'arapa kún fún ádùrá Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ijamba ina Eko; Awakọ ni omi gọta lo yọ oun ninu ijamba ina Awọn òṣìṣẹ́ náà sàlàyé pé, gbogbo àwọn òkú tí wọ́n gbé wá sibẹ̀ jóná kọjá ídámọ̀, èyí ló fáà tí wọn kò se gba ẹbi kankan láàyè láti gbe okú lọ̀, títí ti Gomina ìpínlẹ̀ Eko, Akinwumi Ambode yoo fi kéde bóya wọn yóò sín àwọn okú náà pọ̀ ní abi bẹ́ẹ̀kọ́.
“Ẹ máa yọ̀, ẹ̀yin ará Sioni,kí inú yín máa dùn ninu OLUWA Ọlọrun yín;nítorí ó ti da yín láre, ó ti fun yín ní àkọ́rọ̀ òjò,ó ti rọ ọpọlọpọ òjò fun yín:ati òjò àkọ́rọ̀, ati àrọ̀kẹ́yìn òjò, gẹ́gẹ́ bí ìṣe rẹ̀.
Awọn miiran tun gbadura pe Omotola ni yoo bori coronavirus, wọn covid-19 ko ni rẹyin rẹ.
Alex Iwobi ati Sophia Omidiji wa lara awon ti o safihan ewu boolu tuntun ohun.
Ẹ dákẹ́ ariwo orin yín; n kò fẹ́ gbọ́ ohùn orin hapu yín mọ́.
Araale: Ki lẹ́ ri kọ gan lori eto BBNaija?
EndSARS, EndSWAT Protests: Òbí agbábọ́ọ̀lù Kazim Tiamiyu Kaka àtàwọn míì tí ọlọ́pàá pa sọ̀rọ̀, omijé bọ́ lójú
Amitabh Bachchan bọ́ lọ́wọ́ COVID-19 Ni bayi, apapọ awọn to lugbadi arun naa lati igba to ti bẹrẹ ni Naijiria ti di 44,129.
John Whitmer di ọ̀kan nínú Àwọn Ẹlérìí Mẹ́jọ sí Ìwé ti Mọ́mọ́nì lẹ́hìn náà.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ilà kíkọ: Adetutu ní ilà tóun kọ̀ ni kò jẹ́ kí òun lọ ilé-ẹ̀kọ́ fásitì 3 Agẹmo 2018 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 13 Ọ̀wàrà 2018 Oríṣun àwòrán, @adetutuoj8811 Ni igba atijọ, asa ila kikọ jẹ ohun amuyangan ati ara oge sise fun tọkunrin-tobinrin ni ilẹ Yoruba.
" lẹ ́ yìn àwo yìí ni ó tún gbé àwo tí ó sọọ ́ di àyànfẹ ́ gbogbo àwọn ènìyàn ní 1984 tí ó pè ní "" talazo 84 "" ."
ṣugbọn kò lágbára tó láti ṣẹgun.
Kete ti wọn ṣide ipade ẹka ijiroro lori ọrọ awujọ oni lajọ iṣọkan agbaye ni Nairobi ni wọn ti dide iṣẹju kan fun gbogbo oloogbe inu iṣẹlẹ ijamba ọhun.
Ó dẹ́ṣẹ̀ sí OLUWA tóbẹ́ẹ̀ tí inú OLUWA fi bẹ̀rẹ̀ sí ru.
”’Ajo agbaye  ti setan lati pese eto irawo fun awon ti iye won le ni  milionu mefa lorile ede Naijiria , ti iko Boko Haram kọlu ni ekun Ila -oorun Ariwa  lorile ede Naijiria ki odun yii to pari.
Amaechi ati awon alatileyin egbe ni jake-jado orile ede Naijiria ti won mojuto
Ọkunrin ọlọ́gbọ́n kan wà níbẹ̀ tí ó jẹ́ talaka, ó gba ìlú náà sílẹ̀ pẹlu ọgbọ́n rẹ̀, ṣugbọn ẹnìkan kò ranti talaka náà mọ́.
Ó sì fún e̩yo̩ e̩nì kan tàbí àkójo̩pò̩ ènìyàn láàyè láti s̩e è̩sìn wo̩n àti ìgbàgbó̩ wo̩n bó s̩e je̩ mó̩ ti ìkó̩ni, ìs̩esí, ìjó̩sìn àti ìmús̩e ohun tí wó̩n gbàgbó̩ yálà ní ìkò̩kò̩ tàbí ní gban̄gba.
Ó sọ nípa igi, ó bẹ̀rẹ̀ láti orí igi kedari ti ilẹ̀ Lẹbanoni, títí kan Hisopu tí ó ń hù lára ògiri.
Araalu kan lo fi iṣẹlẹ naa to awọn ọlọpaa l'eti lẹyin.
Bí Jesu ti ń bá ìrìn àjò rẹ̀ lọ sí Jerusalẹmu, ó ń gba ààrin Samaria ati Galili kọjá.
"O ni ""Mi o lọwọ ninu Toll Gate, bẹẹ ni kọbọ mi ko si nibẹ."
Ẹ ka ekunrẹrẹ aroye wọn ni : Ṣugbọn o, oju ọtọ ni Dare Adediji fi wo afikun isede naa.
O fi kun un pe ikọ ilera lati ile iwosan ajakalẹ arun, IDH to wa lagbegbe Yaba ti bẹrẹ eto itọju fun gomina naa.
Nítorí òun fúnrarẹ̀ jẹ́rìí pé, “Wolii kan kò ní ọlá ninu ìlú baba rẹ̀.
Pe iroyin naa de ọdọ rẹ lati ọdọ ẹni ti o ni ẹmi igbagbọ ninu rẹ ko tumọ si pe awọn paapa ri iroyin naa gba lati ọdọ ẹni ti wọn mọ ri.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Kí ló lè mú aláboyún kábamọ̀ lásìkò ìrọbí?
"Ọgbẹni Adamu ni ""baa ba nsọ̀rọ̀ ẹtọ ọmọniyan, eniyan ẹlẹran ara ni ọlọpaa naa nitorinaa idaabobo fun ẹtọ awọn ọlọpaa naa yoo wa."
Àwọn eniyan bi í pé, “A gbọ́ ninu òfin pé Mesaya wà títí lae.
Nítorí pé wọn kò ka iṣẹ́ OLUWA sí,wọn kò sì bìkítà fún iṣẹ́ ọwọ́ rẹ̀,OLUWA yóo sọ wọ́n di ilẹ̀,kò sì ní gbé wọn dìde mọ́.
Iyawo ati ọmọ meje pẹlu ọmọọmọ meje lo gbẹyin rẹ.
Lasiko ti orilẹede Naijiria ri ọpọlọpọ owo latara epo bẹtiro, Shagari fi ipese ile gibgbe, kikọ ileesẹ ati idagbasoke eto irinna ati iṣẹ agbẹ ṣe afojusun ijọba rẹ.
”Ó sẹ́, ó ní, “Rárá o!
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Tollgate Fee: Àwọn ọmọ Naijiria ní àsìkò sísan owó 'tollgate' kò tíì tó báyìí 3 Ọ̀wàrà 2019 Oríṣun àwòrán, @johnnysleek Awọn ọmọ Naijiria ti bẹrẹ si ni fi erongba wọn lede lori ẹrọ ayelujara bayi, lẹyin ti ijọba apapọ kede ipadabọ owo oju popo.
Kí irú ẹni bẹ́ẹ̀ lọ ya ilé rẹ̀ sí mímọ́, kí ó má baà jẹ́ pé bí ó bá kú sí ogun, ẹlòmíràn ni yóo ya ilé rẹ̀ sí mímọ́.
Jesu sọ fún wọn pé, “Ẹ rò pé àwọn ará Galili wọnyi jẹ́ ẹlẹ́ṣẹ̀ ju gbogbo ará Galili yòókù lọ ni, tí wọ́n fi jẹ irú ìyà yìí?
Orí èmi náà wú, ọkàn mi kì sì sí nínú ayé yìí mọ́, nítorí láti ọjọ́ ti òun tilẹ̀ ti kú ni mo ti mọ̀ pé kò sí agbọ̀ràndùn tí ó dà bí ìyá, ìba ènìyàn díẹ̀ lóló ṣe bíi bàbá ẹni.
Dìbò fún un níbí Àkọ́dá oró.
Ighalo sọ pe ohun to ṣe pataki ni ki awọn ojugba oun gbagbọ ninu oun, gẹgẹ bi agbabọọlu to pegede.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, CAN: ó pọn dandan kí wọn fágile ìdánwò ọlọ́pàá Kíní ìhà tí Àjọ JAMB kọ sí ọ̀rọ̀ náà: Fabian Benjamin, tó jẹ agbẹnusọ fún àjọ JAMB, nínú àtẹjáde kan sàlàyé pé, ìyàlẹnu ló jẹ láti máa gbọ pé àjọ JAMB ló èdè Arabic láti fí dán àwọn olùkópa wò.
Ile ise ijoba apapo to n ri si iwadii oogun ni Naijiria ti a mo si: The National Institute of Pharmaceutical Research and Development (NIPRD) ni egberun meji ati etadinlaadoje eniyan to ti lugbadi arun HIV ni won n gba oogun fun itoju ara won ni Abuja ati agbegbe re.
Ọlọrun, gbé ìlànà òtítọ́ rẹ lé ọba lọ́wọ́;kọ́ ọmọ ọba ní ọ̀nà òdodo rẹ.
Iyẹn nikan kọ, Fayose ni ki ọrọ naa to le tan nilẹ afi ki wọn san ogún biliọnu Naira ki wọn si kowe mabinu soun.
Kiní ọ̀hún a máa dùn tí wọ́n bá dín in gbẹ dáadáa.
Osai Ojigho to jẹ adari Amnesty International ni Naijiria ni ni ko tii si ẹni ti ijọba mu ti wọn de foju ẹ wina ofin ninu awọn oṣiṣẹ eleto aabo wọn.
Páro-páro ni àwọn mọ́ṣálááṣí dá káàkiri Nàìjíríà lásìkò ìrun Jímọ̀ nítorí coronavirus Ìjọba àpapọ̀ fẹ́ f'òfin dé irina ọkọ̀ akero jakejado Nàìjíríà ‘Ọ̀pọ̀lọpọ̀ ni inú wọn kò dùn sí bí Hajj kò ṣe ní wáyé lọ́dún yii’ Ìbánújẹ́ gbọkàn àwọn èèyàn nílé abílékọ ọlọ́mọ mẹ́ta tí wọ́n ṣẹ̀ṣẹ̀ pa ní Ibadan Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Bí ẹnikẹ́ni bá wá mi dé ilé, wí fún olúwaarẹ̀ pé mo yára bọ́ sí ẹ̀hìn odi.
N3500,N5000 ni wọn n gba E-Card to ba sọnu,elo ni wọn fi n gba NIN miiran?
Bakan naa ni arabinrin Maduagwu fikun wi pe fiimu African Magic naa n fi agbara fun iwa ẹlẹyamẹya, nitori wọn n ṣe fiimu to n ṣe igbelarugẹ aṣa ati iṣe abalaye ni awọn agbegbe wọnyii.
Bí eniyan rere ti rí, bẹ́ẹ̀ ni ẹlẹ́ṣẹ̀ náà rí.
Owurọ Ọjọru ni iroyin gbe e jade pé lójúnà oko ni wọ́n ti jí Deji Adewole gbe ní ìlú Fiditi, ipinlẹ Oyo.
Sùgbọ́n, wọ́n ni ó kù, ó kù ni ìbọ́n ń ró lọ̀rọ̀ tó wà nílẹ̀ ní Nàìjíríà, ọ̀pọ̀ ló ti gba ojú òpó twitter kan báyìí pé, àwọn ọmọbìnrin Chibok tó kù ńkọ́?
Ogbeni Mohammed ni onkowe alara oto, Chimamanda Adichie to ko iwe Americanah, to wo ate iwe ti awon eniyan n ka julo lagbaye ti New York Times ikeedogun je obinrin to ni imo kikun pupo ti o o to awokose rere fawon odo iwoyi.
O tẹsiwaju wipe bi orilẹede Naijiria ba nilo atunṣe lootọ, lati ipinlẹ Ọṣun gan lo ti yẹ ki awọn oludibo fi apẹrẹ rẹ han lọjọ kejilelogun oṣu kẹẹsan ọdun yii.
Nígbà tí Farao gbà pé kí àwọn ọmọ Israẹli máa lọ, Ọlọrun kò mú wọn gba ọ̀nà ilẹ̀ àwọn ará Filistia, bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé ọ̀nà ibẹ̀ yá, nítorí pé Ọlọrun rò ó ninu ara rẹ̀ pé, “Kí àwọn eniyan yìí má lọ yí ọkàn pada, bí àwọn kan bá gbógun tì wọ́n lójú ọ̀nà, kí wọ́n sì sá pada sí ilẹ̀ Ijipti.
Diẹ ree ninu ọrọ rẹ, gẹgẹ bí o ti ṣe kaa silẹ loju opo Twitter: Tinubu tun sọ pe ohun to pọn awọn ọdọ le ni ki awọn oluwọde fún ìjọba nigba diẹ ki wọn le fi ṣe ayipada ti wọn n beere fun, amọ o ni eyi ko le waye ni kiakia Asiwaju ni bi ijọba ṣe yara da awọn oluwọde lohun lọtẹ yíi ṣafihan pe, ijọba ti yipada ni daada O ni awọn oluwọde ti ṣe aṣeyọri to gbọngbọn lẹnu igba ti iwode bẹrẹ amọ ki wọn sọra lati mase padanu aṣeyọri naa nipa aifi ẹlẹ ṣe ati aironujinlẹ Tinubu ko salai mẹnuba ọrọ bi awọn janduku se sa sabẹ iwọde lati maa dun koko mọ ara ilu, ti wọn n ba karibujẹ ti wọn kaakiri O ni erongba awọn agbatẹru iwọde naa ni ki ijọba mu iyipada ba iṣẹ ọlọpaa, eyi ti wọn sì ti n ṣe O ni wọn ko le wa yipada lati gba akoso mọ ijọba lọwọ amọ bi wọn ba wa ni ero ọkan yii lati gba ijọba, ijọba yoo gbe igbesẹ lati dẹkun wọn lọna ati fi idi ijọba awaarawa rinlẹ Bẹẹ naa ni Tinubu sọ pe iṣọwọ ṣe iwọde yii fi han pe ijọba tiwantiwa n gbooro si ni Naijiria Ṣugbọn o ni k'awọn oluwọde ṣe jẹjẹ ki wọn ma ba fi ọwọ ara wọn pa igi ominira ti wọn n lọ silẹ yii.
Bákan náà lo sàlàyé pé, kò tẹ̀wọ̀n tọ láti sọ pé òun máá n sábà tèlé ẹni to bá ni àgbára nínú ilé ni òun má n rìn mọ́.
Link Ni oṣu keji, ọdun 2016 ni ajọ EFCC fi ẹsun kan an pe o ṣe ẹgbẹlẹgbẹ owo ilu ti o to N3.
O kọ ẹkọ, o si ṣiṣẹ nipa eto imọ ẹrọ fun ọpọ ọdun ni ileeṣẹ NNPC ki aarẹ Muhammadu Buhari to yan an sipo ọga agba ileesẹ naa lọdun 2016.
Real Madrid ń gbáradì láti ra Paul Pogba pẹ̀lúu £70m Ẹ̀rù n ba àwọn agbábọ́ọ̀lù Premier League láti padà sórí pápá nítorí coronavirus Àwọn jẹsí tó gbajúmọ̀ nínú ìtàn ìdíje bọ́ọ́lù Bí ilumọọka agbabọọlu Drogba ṣe dáwọ ogun dúró ní Ivory Coast Ìjọba buwọ́lu ẹgbẹ̀rún mẹ́wàá náírà owó ìrànwọ́ oṣooṣù fún ìyá Rashidi Yekini Rashidi Yekini: Ìjọba buwọ́lu ẹgbẹ̀rún mẹ́wàá náírà owó ìrànwọ́ oṣooṣù fún ìyá Rashidi Yekini Ileeṣẹ ijọba to n ri si ere idaraya ati idagbasoke awọn ọdọ ti ṣeto lati maa fun mama oloogbe agbabọọlu Naijiria tẹlẹ, Rashidi Yekini ni ẹgbẹrun mẹwaa naira loṣooṣu gẹgẹ bi owo iranwọ.
Gẹ́gẹ́ bi kọmísọnà ọlọ́pàá ìpínlẹ̀ Kwara Kayode Egbetokun ṣe sọ àwọn ọlọ́pàá náà ṣẹ ẹ̀ṣẹ̀ tí o buru jáì tó fi mọ ìwá àìbíkítà fún àwọn adari ilé iṣẹ́ ọlọ́pàá.
Amọ Owoẹyẹ ni lẹyin-o-rẹyin, oun ko mọ ohun ti oun n se mọ, ti wọn si fi oogun gba owo to le ni miliọ̀nu lọna mejidinlogoji naira lọwọ oun.
Ó fi kùn un pé onírúuru awuyewuye ni òun ti n gbọ ti eti òun sì ti kún lóri ọ̀rọ náà.
Wò ó, gbogbo ilẹ̀ nìyí níwájú rẹ yìí, ibi tí o bá fẹ́ tí ó dára lójú rẹ ni kí o lọ.
Yollywood: Àwọn èèyàn fèsì pé Kemi ń díbọ́n ni, tórí ọ̀rọ̀ ọkùnrin ni
Ibi tí o ti ń sálọ, ìbàntẹ́ tu, ó wá fi ọwọ́ mú ìbàǹtẹ́ mọ́ ìdí, okùn eléyìí ní n fì dìròdìrò.
Àwọn ọmọ Eseri ni: Bilihani, Saafani, ati Akani.
Yoruba ni ẹsin iwaju ni tẹyin n wo sare, ẹyin ọdọ, ẹ sunmọ bi lati kọgbọn lọdọ ọkunrin onimọ nipa okoowo lori ayelujara yii nitori ẹni to ba mọ ọna, lo yẹ ka tẹle.
Mo ti sọ gbogbo àwọn ìlú òkè Esau di ahoro, mo sì sọ ilẹ̀ ìní rẹ̀ di ilé ajáko tí ó wà ní aṣálẹ̀.
” Wọ́n sì ṣe bí Mose ti wí.
”“Inu mi tun dun lati tun wa pada ba Vicky
Wọn gba Ariwa ilẹ Biafra ati ilu Nsukaa wọle.
Ṣugbọn ní ọjọ́ náà, èmi OLUWA yóo ya ilẹ̀ Goṣeni sọ́tọ̀, níbi tí àwọn eniyan mi ń gbé, kí ọ̀wọ́ eṣinṣin má baà lè débẹ̀, kí ẹ lè mọ̀ pé èmi ni OLUWA ní ayé yìí.
Àwọn onílù mí ló ń tú àṣírí ìkà èèyàn tó bá wọ ààfin mi - Aláàfin Eyí ni àwọn arẹwà 'ẹ̀lẹ̀ Daddy', àfẹ́fẹ́ tí Aláàfin fi ń mí Wò ó bí Alaafin àti aya àkọ́fẹ́ rẹ̀, Olorì Abibat ṣe pàdé ní èwe Àwọn alálẹ̀ kò ní forí jìn mí tí ń kò bá ṣe ọdún Ṣàngó - Alaafin Àwọn kókó ohun tó wà nínú lẹ́tà tí Aláàfin kọ sí Fayemi rèé Idasilẹ ipinlẹ Oyo tuntun: Lasiko ti ipe jade lati da ipinlẹ Ọyọ silẹ lọdun 1975, ipa kekere kọ ni Alaafin ko, pẹlu ajọṣepọ awọn eeyan mii, to mu ki idasilẹ ipinlẹ Ọyọ, Ogun ati Ondo dohun.
Alajo Somolu: Ọdún mẹ́ta ló fi gba àjọ láì kọ ọ́ sílẹ̀, kò sì si owó àjọ san
Iṣẹlẹ iṣekupani ọhun eleyi ti eeyan marun un ti gbẹmi mi waye laarin ilu Odessa ati Midland nipinlẹ Texas.
Ohun mẹ́wàá tó yẹ kóo mọ̀ nípa Kunle Afod Kíni ẹ mọ̀ nípa Mama Rainbow tó jẹ́ àgbà òṣẹ̀ré tíátà Yoruba?
O fikun ọrọ rẹ pe ko si ohun to jọ bẹẹ rara nigba ti oun fi n ṣere labẹ ogbontarigi oṣere, oloogbe Iṣhola Ogunsola ti ọpọ mọ si Isho Pepper.
"Pe owo yii ni yoo jẹ owo asọ isẹ, awọn ohun elo isẹ gbogbo.
Ó bá fi wọ́n sílẹ̀, ó tún wọ inú ọkọ̀ ojú omi, ó lọ sí òdìkejì òkun.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Coronavirus symtoms and cure: Seyi Makinde ní òun kìí ṣe dókítà tí yóò yan ògùn Coronavirus fún ẹnikẹ́ni Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Coronavirus symtoms and cure: Seyi Makinde ní òun kìí ṣe dókítà tí yóò yan ògùn Coronavirus fún ẹnikẹ́ni 7 Ìgbé 2020 Gomina ipinlẹ Ọyọ, Seyi Makinde kii ṣe dokita iṣegun oyinbo ti yoo maa pe ogun aisan fun eeyan nitorina oun ko fi igba kankan sọ fun ẹnikẹni ogun to n ṣẹgun arun Coronavirus.
Nígbà tí ẹ bá wọ ibẹ̀, ẹ óo rí kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ kan tí wọ́n so mọ́lẹ̀, tí ẹnikẹ́ni kò gùn rí.
Ààrẹ Buhari kí Akeredolu kú orííré bí ó ṣe jáwé olúborí nínú ìdìbò sípò gómínà EndSARS: Wo ohun táwọn gbajúgbajà tó n darí ìwọ́de ìfopinsí FSARS n sọ Mọ̀ sí i nípa díẹ̀ lára àwọn èèyàn tí ikú wọn 'láti ọwọ́ ọlọ́pàá' milẹ̀ tìtì ní Nàìjíríà Bí èsì ìdìbò gómìnà ìpínlẹ̀ Ondo se ń jáde rèé.
To ba jẹ pe bẹẹ ni, a jẹ wipe ẹ kii ṣe ikoko rara tori ọdun gbọọrọ sẹyin ni orukọ Mike Bamiloye ti maa n ro leti awọn eeyan, pẹlu awọn fiimu to n ṣe sita.
Trent Alexander-Arnold lo kọkọ gba goolu wọle fun Liverpool nigba ti ifẹsẹwọnsẹ naa wọ iṣẹju kẹrinla ki Roberto Firmino to dee lade funwọn.
Ọwọ́ tí a fi mú ìbáṣepọ̀ ti ìta.
Aare ni : “ọlọla julo , a dupe fun ipade to waye laarin orile ede China ati ajo ECOWAS , a tun dupe lowo aare Xi Jinping fun ileri  ti o se lati ko ile-ise ECOWAS tuntun fun  ajo  naa.
Tí ó bá jẹ́ pé oríkunkun ati ìwà ọ̀dàlẹ̀ ni a fẹ́ hù sí OLUWA ni a fi ṣe ohun tí a ṣe, ẹ má ṣàánú wa.
Ẹni to bori: Kenya Kenya Orilẹede Kenya lo se ipo kinni ninu idije ere idaraya Olympics, pẹlu wura mọkanlelọgbọn, fadaka mejidinlogoji ati baba mẹrinlelọgbọn.
Nígbà tí Jakọbu ń kú lọ, nípa igbagbọ ni ó fi súre fún ọ̀kọ̀ọ̀kan ninu àwọn ọmọ Josẹfu.
Wọ́n fi òróró yàn án ní ọba ní orúkọ OLUWA, Sadoku sì ni alufaa.
Aṣọ títa kan yóo wà ní ẹ̀gbẹ́ kinni ẹnu ọ̀nà àgbàlá náà, yóo gùn ní igbọnwọ mẹẹdogun, yóo ní òpó mẹta ati ìtẹ́lẹ̀ mẹta.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Nibayii Manchester United ti wa ni ipo kẹfa bayii ninu idije Premier League, Arsenal wa ni ipo kẹrin nigba ti Chelsea tẹ le wọn ni ipo karun un.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ṣẹ rántí pásítọ̀ South Afrika tó ní òun jí òkú díde?
un lasiko eto idibo aare (Buhari Support Group Centre)  fun iduroṣinṣin
Sanwo-Olu lo kede igbeṣe yii lẹyin iwọde End SARS ti awọn eeyan gunlẹ kaakiri orilẹ-ede Naijiria, paapaa ni ipinlẹ Eko.
Ẹni tó bá rí i yóo sáré sí i,yóo ká a, yóo sì jẹ ẹ́.
àwọn ọmọ Barikosi, àwọn ọmọ Sisera, ati àwọn ọmọ Tema, 
Ekuru pẹlu Ata ti won fi owolo, Ofada pẹlu Ata ṣiṣa Amala gbegiri Ewedu Ewa aganyin pẹlu ata dindin Iyan ti won fi odo gun.
Oun la gbọ pe o siwaju awọn eeyan kan lati wa ọrẹ rẹ to di awati, ki asiri ibùba naa to o tu.
Oríṣun àwòrán, Biodun Abdu-Raheem Àkọlé àwòrán, Agbébọn kọlu Kọmísọ́nnà fọ́rọ̀ ilẹ̀ àti ilégbèé ní Ọyọ, awakọ̀ dèrò ọ̀run Wọn pa awakọ kọmiṣọ́nna naa, ti wọn si tun yinbọn mọ ọlọpaa to n sọ pẹlu."
Ikolu omiyale ohun ni won fi mule pe o seese ko waye lataari omi lopo yanturu ti awon alakoso ijoba orile-ede Cameroon si sile lati omi odo Lagdo pelu apapo ojo to tun ro lojojumo yii, pe o le sokunfa omiyale laipe.
Okechukwu wa ro Ohaneze” ki won maa dena anfaani ti iwo oorun yoo je  lati je igbadun ipade gbogboo ti yoo waye laarin iwo oorun ati ila oorun.
”Dakingari so pe awon onifayawo ti pinnu lati maa  tesiwaju nipa lilo ona eburu lati maa hu iwa ibaje won.
Bakan naa la gbọ pe ọpọ eeyan lo farapa ninu ìjà yii, tó bẹrẹ ni irọlẹ ọjọ Aje ladugbo Ori Eru laarin awọn ọmọ ẹgbẹ Lion Base Club, ti agboole Olukola ati awọn ti Isalẹ Agooji Club.
Osun Supreme Court: PDP ní iléẹjọ́ ti sọ tirẹ̀, kò sí ohun tí ẹnikẹ́ni leè ṣe si
Agbẹnusọ fun Ajọ NDDC, Charles Obi Odili ni aisan to n ṣe adari naa peleke si ni aarọ Ọjọ Aje to n lọ si Ile Igbimọ Aṣofin, amọ o pinnu lati lọ ki awọn eniyan ma ro wi pe ko ni otitọ ni ko ṣe yọju.
10 Èrèlè 2020 Bi iroyin ṣe jade tan pe idibo ti pari lawọn ibido idibo kaakiri orilẹede Cameroon lati yan awọn aṣofin atawọn kansilọ ni iroyin mii jade pe ọwọ Ọlọpaa tẹ oludibo kan.
Wọn ni bi Tinubu ba di aarẹ, o lee tun gbe ọwọ to lo ni ipinlẹ Eko lọ si ijọba apapọ, fun idagbasoke orilẹede Naijiria lapapọ.
Ẹgbẹ oṣelu Movement Restoration and Defence of Democracy (MRRD) lo pe ẹjọ tako ajọ INEC lati fopin si atundi ibo nipinlẹ Adamawa.
Mo mo pe, ifarapa ma n waye nipase kikopa lori papa, ti a ba si ni oreofe lati ma ni ifarapa kankan ti idije naa yoo fi bere, eyi yoo se iranwo fun wa lopolopo.
Power: Ṣé ẹ̀mí ilé aṣòfin lè gbé ṣíṣe ìwádìí 16 bílíọ̀nù owó àgbàṣe iná ọba Nàìjíríà?
ọlọaa lee ni ki o kọ iwe 'wa wi tẹnu rẹ' (statement).
Àwọn wòòlí ń takora lórí Atiku àti Buhari Pásítọ̀ wọ gàù lórí ìran ikú, ọ̀dọ́ musulumi ya wọ ṣọ́ọ̀ṣì Èmi ni òpómúléró fún òtítọ̀ sísọ̀ - Oyedepo 'Ọdún 2019 pẹ̀lú àwọn àsọtẹ́lẹ̀ tó kó lọ́wọ́ dé' Idibo aarẹ ti waye a si ti mọ ẹni to gbegba oroke.
”“Bee si ni, bi mo tun se gbo, ile-ise to n ko ojuurin ohun China Civil Engineering Construction Company (CCECC) ti bere fun sisun asiko ti won yoo pari ise naa siwaju di aarin odun to n bo,” Tobi Sangotola.
Nítorí pé Rehoboamu ronupiwada, OLUWA yí ibinu rẹ̀ pada, kò pa á run patapata mọ́.
'Kò s'ówó oṣù, kò s'íbò'-JOHESU Aranṣọ, olórin àti àwọn mì í ti ko fẹ́ kí ìdìbò kásẹ̀ nílẹ̀ ní Nàìjíríà INEC tí bẹrẹ ipalẹmọ dé ìdìbò ọjọ ẹtì Àwọn nọmbà yìí ló le fi bá iléèṣẹ́ ológun sọ̀rọ̀ lásìkò ètò ìdìbò #NigeriaDecides Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, #BBCNigeria2019: Nnamdi Kanu sọrọ lórí àwọn oludije PDP àti APC Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Ìbéèrè àti ìdáhùn pẹ̀lú Seyi Awolowo ti BBNaija lórí BBC Yorùbá Buhari ti fòfin de àwọn mínísítà láti rìnrìn àjò lọ sí ilẹ̀ òkèrè Lateef Adedimeji: Lọsẹ yii bakan naa ni oṣerekunrin ni, Lateef Adedimeji gba ami ẹyẹ Emperor Award Stylish Actor.
Ààrẹ Donald Trump ti padà sí ilé ìjọba lẹ́yìn ọjọ díẹ̀ tó lùgbàdì ààrùn coronavirus Ṣé Biden lè fẹ̀yìn Trump kó di ààrẹ America tó kàn?
 ní àsìkò yìí kan náà ni bámijí Òjó ronú pé iṣẹ ́ ìròyìn ti orí rédíò sáá ní ó wu òun .
Ó ní, ‘Ẹ̀yin ará, arakunrin ara yín ni ẹ̀ ń ṣe.
Kí ló dé tí ìwọ ati àwọn eniyan rẹ fẹ́ kú ikú idà, ikú ìyàn ati ikú àjàkálẹ̀ àrùn bí OLUWA ti wí pé yóo rí fún orílẹ̀-èdè tí ó bá kọ̀ tí kò bá sin ọba Babiloni?
Abajade iwadii miran ti wọn ko ti i ṣe agbeyẹwo rẹ sọ pe botilẹjẹ pe ko si ibi ti aarun coronavirus tuntun yii ko de ni agbaye, itankalẹ rẹ kóra jọ si awọn agbegbe ti ọgbẹlẹ wá - ko to o di ọjọ kẹtalelogun, oṣu Kẹta.
Ọkan ni Colorado ni orilẹ-ede Amerika ati ikeji ni odo Adagun Ado Awaye nipinlẹ Oyo lorilẹ-ede Naijiria.
Won wa ro ile- ẹjọ lati yọ asofin
Oníṣẹ́ àdáni 250,000 ni ìjọba ṣe ìlànà yìí fún Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Kété tí wọ́n bá ti báa yín sùn tàn torí pé ẹ tóbi, ẹ gbà pé ìfẹ́ yẹn ti parí - Auntie Remi Ọlọ́yàn ńlá Ohun tí òṣèré àti aṣòfin, Desmond Elliot sọ táwọn ọmọ Nàìjíríà gbà sí ìbínú Oríṣun àwòrán, Desmond Elliot/Facebook Ọrọ Desmond Eliot ni awọn ọmọ Naijiria fi bọnu lori ẹrọ ayelujara nipa ọrọ to sọ lori bi awọn Ologun ṣe da ibọn bo awọn afẹhọnuhan tako ifiyajẹni awọn ọlọpaa ni Lekki Toll gate,ni ipinlẹ Eko.
Ile Igbimọ Asofin apapọ naa sọ eyi lasiko ijoko ile lẹyin ti wọn de lati isinmi ọlọsẹ marun un ni ọjọ Iṣẹgun.
It takes about one day for each time zone crossed for them to synchronise.
Ó ní wọ́n pa àwọn ènìyàn sùgbọ́n òun ko le fi ìdí rẹ̀ múlẹ̀, àpá ibi ti ó fì sí jù.
Awọn inagijẹ ti o wọpọ pẹlu Wasiu Ayinde ni: Igi Jegede Oba Orin Kwam1, K1 de Ultimate Ipa ti Wasiu Ayinde ko ni agbo amuludun ni Naijiria ti mu ko jẹ oye loriṣiriṣi nilẹ Yoruba, to si tun gba ami ẹyẹ kaakiri agbaye.
Oniruuru iroyin lo n lọ kaakiri lori ọna ti o lee gba dena arun yii ati ohun gbogbo ti o nilo lati mọ nipa COVID-19 ti a mọ si coronavirus.
láti inú ẹ̀yà Sebuluni: Iṣimaya, ọmọ Ọbadaya; láti inú ẹ̀yà Nafutali: Jeremotu, ọmọ Asirieli; 
Ọpọlọpọ awọn eeyan lo jẹ wi pe arun yii yoo kan ṣi ni fila lọ ni, ṣugbọn awọn miran a maa tipasẹ arun yii dero ọrun.
Rehoboamu bá dá wọn lóhùn pé, “Ẹ máa lọ ná, lẹ́yìn ọjọ́ mẹta, ẹ pada wá gbọ́ èsì.
Orileede Saudi Arabia kii fi ọrọ gbigbe ogun oloro ṣere rara.
Kí àwọn alufaa ọmọ Aaroni da ẹ̀jẹ̀ rẹ̀ sára pẹpẹ náà yípo.
Kò jẹ, bẹ́ẹ̀ ni kò mu nítorí pé ó ń banújẹ́ nítorí aiṣootọ àwọn tí wọ́n ti oko ẹrú pada dé.
"Bi o ba jẹ pe lootọ ni, Buhari fẹ da wahala silẹ lori ọrọ ofin niyẹn.
OLUWA jẹ́ kí àwọn eniyan Israẹli bá ojurere àwọn ará Ijipti pàdé, ati pé àwọn ará Ijipti ati àwọn ẹmẹ̀wà Farao ati àwọn eniyan rẹ̀ ka Mose kún eniyan pataki.
Gbogbo wa to lori ila lati ki aarẹ kaabọ, ti oun naa si n bọ wa lọwọ ni ẹyọ kọọkan, nigba to de iwaju mi lo ni 'Adesina, igba yii ni maa ri ẹ fun igba akọkọ to wọ asọ to dara julọ'.
Iṣẹ ọkada wiwa ni wọn sọ pe o n ṣe.
Kii se eyi nikan, a tun fẹ mọ awọn orilẹede ti wọn ti nko epo wọnyi wa pẹlu triliọnu lọna mẹwa naira ti orilẹede Naijiria ti na.
Ẹ̀rù sì ń bà wọ́n láti bi í nípa ọ̀rọ̀ yìí.
Ní kutukutu ọjọ́ kinni ọ̀sẹ̀, kí ilẹ̀ tó mọ́, Maria Magidaleni lọ sí ibojì náà, ó rí i pé wọ́n ti yí òkúta kúrò lẹ́nu rẹ̀.
Eyi tumọ si pe, ẹlẹwọn kookan yoo fi N202,404 jẹun fun ọdun kan tabi N16,867 fun oṣu kan, eyi to ja si N562 lojoojumọ.
Oríṣun àwòrán, others O fi kun pe ileeṣẹ ọlọpaa yoo tuṣu de isalẹ ikoko gbogbo bi ọrọ naa ṣe ṣẹ.
Iyawo meji ni Elikana yìí ní.
Nígbà tí àkókò ati jẹun tó, ó rán iranṣẹ rẹ̀ sọ́dọ̀ àwọn tí ó ti pè láti sọ fún wọn pé, ‘Ó yá o!
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ṣáájú ni obìrin náà ti kọ́kọ́ di àwátì ní nǹkan bíi ọ̀sẹ̀ méjì sẹ́yìn kí àṣírí tó tú 6 Owewe 2020 Oríṣun àwòrán, others Ileeṣẹ ọlọpaa ipinlẹ Delta ti wu oku obinrin ẹni ọdun mẹrindilogoji kan ti wọn sọ pe alabagbe ati ẹsọ ẹnu ọna rẹ ṣekupa ni ilu Asaba.
Èsì ìdánwò òhun tí a ṣé síwájú là n bá fínra báyìí ní Nàìjíríà- Yemi Shodimu Èèmọ̀!
ojo kerindinlogun, odun2018, ijamba ina  tun ba opolopo dukia iyebiye je ni oja Azare to wa ni Bauchi.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Nigeria Pensioners: Wàhálà àyẹ̀wò iwé ìfẹyinti yì ti pọ̀jù Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
láti pa ọ́ mọ́ kúrò lọ́wọ́ obinrin burúkú,ati lọ́wọ́ ẹnu alágbèrè obinrin tí ó dùn lọ́rọ̀.
Ìgbà tí ó sì ṣe, a rí òun pàápàá.
Àwọn ẹbọra péjọ, àwọn ẹranko péjọ, àwọn ẹyẹ péjọ, àwọn ejò sí lọ́ mọ́ igi.
Ni wọ́n bá kígbe, wọ́n fi ọwọ́ di etí, gbogbo wọ́n rọ́ lù ú; 
Ori bibẹ kọni oogun ori fifọ."
Ko tan si bẹẹ o, awọn eniyan naa ni anfaani lati ma a san ẹgbẹrun kan abo ni osoosẹ lati le tete san owo ina solar naa tan ni kiakia '' Ẹka Rural Electrification Agency ni ileeṣẹ ijọba to n risi ina ọba lo ṣe olugbọwọ ipese ina ọba Solar naa.
O sọ pe o nira fawọn ẹbi Majek Fashek lati ṣe ipinnu yii, ṣugbọn awọn bi lati ṣe bẹẹ nitori ohun ti o n ṣẹlẹ lọwọ lagbaaye bayii.
Nigba to n ba BBC sọrọ lori oju ati ohun ti awọn eeyan awujọ n sọ nipa rẹ, Chichi ni ọpọ eeyan lo ti fi ẹnu pa oun lai tii ku.
Oríṣun àwòrán, Twitter/rotimi akeredolu Awọn oludije mọkanla lo n dije fun aṣia ẹgbẹ oṣelu APC naa bayii lẹyin ti iroyin abẹle sọ pe Ifẹ Oyedele, ọkan lara awọn oludije naa to fi pe mejila tẹlẹ ti gba lati jawọ.
Asẹ ti wọn gbe jade ni kete ti aarẹ Trump pari ọrọ rẹ laa kalẹ pe, igbesẹ ọhun kan ẹnikẹni to ba ti wa ni ibode EU Schengen, laarin ọjọ mẹrinla ṣaaju ki wọn to de si Amẹrika.
Ẹ̀yà Gadi ni yóo pàgọ́ tẹ̀lé ẹ̀yà Simeoni; Eliasafu ọmọ Reueli ni yóo jẹ́ olórí wọn.
Olori oṣiṣẹ Aarẹ ni White House, Mike Meadows lo kede ọrọ naa nigba to sọ pe abẹrẹ ajẹsara nikan nii ọna abayọ.
Gold coast 2018: Nàìjíríà ní góòlù mẹ̀sán láti dúró ní ipò kẹsán
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù UN: Ìkọlù Boko Haram, darandaran pẹ̀lu ááwọ̀ ósèlú ń dẹ́rù bà wá 26 Ìgbé 2018 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 13 Ògún 2018 Oríṣun àwòrán, Getty Images Igbimọ eleto aabo labẹ ajọ isọkan orilẹ́-ede agbaye (United Nations), UN, ti figbe bọnu pe laasigbo to n waye lẹka eto oselu, ikọlu Boko Haram, iya to n jẹ awọn eeyan ti ko nile lori ati aawọ ojoojumọ laarin awọn agbẹ ati darandaran ni orilẹ-ede Naijiria to n peleke sii, n kọ oun lominu.
ìròyìn sọ pé àì gbáruku ti ìjọba Ganduje ni inú ìdìbò tó koja ló fàá.
Carrington helped in easing the move to democratic rule in the country.
Oríṣun àwòrán, others Tí ẹ o bá gbàgbé, irú ìròyìn báyìí náà ti ẹnu olórí ogún nílẹ̀ Yorùbá, Ààrẹ Ọ̀nà Kakanfo, Iba Gani Adams jáde ni ǹkan bi ọ̀sẹ̀ méjì sẹ́yìn.
Iṣẹ́ rẹ̀ tayọ ohun tí ẹ̀dá lè tú wò.
Bí ọ̀run ṣe ga ju ayé lọ,bẹ́ẹ̀ ni ọ̀nà mi ga ju ọ̀nà yín,tí èrò mi sì ga ju èrò yín.
 agbára àti ṣiṣẹ ́ àwọn àjẹsára náà a má a dàbí èyí tí ó dín kù pẹ ̀ lú ìwọ ̀ n 2 sí 10 % lọ ́ dún , pẹ ̀ lú díndínkù tó pọ ̀ jùlọ nínú àjẹsára aláìní sẹ ́ ẹ ̀ lì .
Saleh ni: “Ise ti a gbe le ajo NEMA to n mojuto isele pajawiri ni Naijiria lowo ni ki won maa pese iranlowo ojiji fawon tisele pajawiri ba sele si titi won yoo fi da won pada sipo won.
Ẹni ọdún mejilelọgbọn ni, nígbà tí ó jọba, ó sì jọba fún ọdún mẹjọ.
Saulu dáhùn pé, “Ó sọ fún wa pé, dájúdájú, wọ́n ti rí àwọn kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ náà.
Jesu bá para dà lójú wọn.
Ó tó oṣù mẹ́ta lẹ́hìn èyí ki wọ́n tóó gbé ara wọn ní ìyàwó ṣùgbọ́n nígbà tí wọ́n ti pinnu àti fẹ ara wọn tí bàbá mi sì tún ti gbé àpò ọdẹ rẹ̀ lé èjìká tí ó fi àdá rẹ̀ si àkọ̀ tí ó kọjú si ọ̀nà igbó Olódùmarè ni obìnrin náà ti tẹ̀lé e, òun àti ẹgbọn rẹ̀ ti wọ́n jọ ń rìn kiri.
Igbó olókìkí kan ni mo tọ̀ já.
Alhaji Ahmed wa ni lara eto ti won tun n se ni lati ipolongo lori ero
ọjọ Ẹti, ojo kejilelogun ,osu keji odun 2019.
O tẹsiwaju pe ki ẹnikẹni to ba ni ẹri pe awọn ologun ṣekupa ọpọ eeyan ni Lekki le lọ fi ẹri naa han niwaju igbimọ to n ṣewadii iṣẹlẹ ọhun, tabi ko gbẹnu dakẹ.
O ni eto ẹkọ alimajiri to wa lode bayi ko yatọ si ki wọn maa mu awọn ọmọ yi sin bi ẹru.
Nígbà tí ẹ jẹ́ ẹrú ẹ̀ṣẹ̀, kò sí ohun tí ẹ bá iṣẹ́ rere dàpọ̀.
Ó bá gbé ojú sókè sí àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀, ó sọ fún wọn pé,“Ayọ̀ ń bẹ fún ẹ̀yin talaka,nítorí tiyín ni ìjọba Ọlọrun.
Supplementary election: Ọlọpàá gbé ikọ kògbérégbè díde lọ si wọ́ọ̀dù ìdìbò Gama Olóṣèlú wọ gau torí pé o ní orí ààrẹ dàrú Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Rape: Oluwaseun Osowobi ní Commonwealth fún lámì ẹ̀yẹ ọ̀dọ́ tó pegedé jùlọ ní 2018 Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, #EkitiDecides: 'Ìjà ẹgbẹ́ òkùnkùn ló ń ṣẹlẹ̀ kìí ṣe ti òṣèlú' Alága àjọ náà n;í ìpínlẹ̀ Adamawa, Kassim Gaidam sàlàyé pé àjọ náà ti ṣe gbogbo ètò tó yẹ láti mú èto náà lọ ni ìrọwọrọsẹ̀ lọ́jọ́ méjì si àsìkò yìí.
Awọn dokita Australia lọgun lori ọti mimu Ronaldo ya ẹro ibanisọrọ dokita lati yẹ oju rẹ wo Dokita Stella Adadevoh kò bá pé ọdún 62 Wọn ni ṣebi Buhari n polongo pe ko si irinajo lọ silẹ okeere fun itọju mọ ti oun ba wọle nitori pe wọn a tun eto ilera Naijiria ṣe Kemi Adeosun: Minista fun eto iṣuna Oríṣun àwòrán, @Kemi Àkọlé àwòrán, O wu mi lati ṣiṣẹ fun Naijiria A ko le ṣai menuba ọrọ Kemi Adeosun to jẹ minista fun eto iṣuna Naijiria tẹlẹ.
Ṣugbọn ọba dá a lóhùn pé, “Rárá o, n óo san owó rẹ̀ fún ọ, nítorí pé ohunkohun tí kò bá ní ná mi lówó, n kò ní fi rúbọ sí OLUWA Ọlọrun mi.
Ibi tí ó bá wù ú ni ó lè gbé, ẹnikẹ́ni kò gbọdọ̀ ni ín lára.
“Kọ ìwé yìí sí angẹli ìjọ Laodikia pé:“Ẹni tí ń jẹ́ Amin, olóòótọ́ ati ẹlẹ́rìí òdodo, alákòóso ẹ̀dá Ọlọrun ní 
Àwọn orúkọ àwọn ọmọ jẹ ́ àṣà àtọwọ ́ dọ ́ wọ ́ nípa ifá dídá tí ọ ̀ pọ ̀ babaláwo bá dá , ṣùgbọ ́ n ní ayé òde-òní , orúkọ ọmọ tún lè wá láti ọ ̀ dọ àwọn tí ó bá ní ipò tóga nínú ẹbí pẹ ̀ lú bàbá , ìyá , òbí àwọn òbí méjéèjì tàbí ẹni tí ó súnmọ ́ wọn gbágbá.
O jẹ alaga ẹgbẹ awọn kọlekọle nipinlẹ Ọṣun lọdun 2006 si 2009 ati alakoso NIOB ni 2007 si 2009.
 fún ogórun - ọdún kan ó jẹ ́ ìwé pàtàkì nípa òrò ẹ ́ kọ ́ ni ilé britani .
Ẹlẹ́wọ̀n Kirikiri tó ń wọ́ke, olùdarí ọgbà ẹ̀wọ̀n ló ṣe onígbọ̀wọ́ fun - EFCC O fikun pe, ẹtọ araalu kọọkan ni wọn gbọdọ bọwọ fun laisi idunkooko lọdọ ijọba fun igbẹsan, ta si n foju sọna fun ilọsiwaju nidi awsn ohun to se koko ta mẹnuba naa.
 Bi a ko ba gbagbe, iko
Igbaniwọle ṣisẹ ọlọpaa bẹrẹ pẹlu ṣisi oju opo wọn lọjọ Kọkanlelọgbọn oṣu Keje ọdun 2020.
Ile-ise ologun ko iko medogun ninu ida ogorun ise-akanse naa, pelu ile-ise oro ile-kiko ni won yoo sa iyoku owo naa.
“Gbọ́ ohun tí OLUWA sọ, ìwọ ọba Juda, tí o jókòó lórí ìtẹ́ Dafidi, ìwọ ati àwọn ìjòyè rẹ ati àwọn eniyan rẹ, tí wọn ń gba àwọn ẹnubodè wọnyi wọlé: 
Aṣírí ìdí ti El-Zakzaky fi padà Nàìjíríà láti India Fayemi fojú Alufa to fipa bá ọmọde lòpọ̀ síta l'Ekiti Amọṣa, lojiji ni wọn gbọ ti iro ibọn n dun lakọlakọ.
Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Alaafin Oyo: Alaafin Oyo ní àwọn onílù láàfin ló ń tú ọ̀pọ̀ àṣírí fún òhun láàfin12 Owewe 2020 Ọba mẹ́wàá tí wọ́n ti lé kúrò nípò: Alaafin, Ọlọ́wọ̀, Elérúwà , Awujalẹ àti .
Nígbà tí Abramu di ẹni ọdún mọkandinlọgọrun-un, OLUWA farahàn án, ó sọ fún un pé, “Èmi ni Ọlọrun Olodumare, máa gbọ́ tèmi, kí o sì jẹ́ pípé.
Okele kan tuwo laarọ, lọsan ati alẹ ni wọn n fun wa lojumọ'' Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Àwọn kan ṣónú bí wọ́n bá di gómìnà, ẹ fún wa láyè láti wá parí iṣẹ́ táa bẹ̀rẹ̀ - Akeredolu Musa salaye pe nigba ti awọn ajinigbe yii sun, lawọn ribi tu okun, tawọn si yọ salọ.
Ó bi í pé, “Ǹjẹ́ ohun tí ò ń kà yé ọ?
Toyin Abraham bí ọmọkùnrin jòjòló Ọpẹmipọ ní ọkùnrin kò jẹ́ kí òun sinmi nínú tíátà Kí ló dé tí Ṣèyí Law ń de aago ọwọ́ méjì?
Àwọn tí wọ́n mọ iṣẹ́ jù lára àwọn òṣìṣẹ́ náà kọ́ ibi mímọ́ náà pẹlu aṣọ títa mẹ́wàá.
Nítorí Johanu sọ fún Hẹrọdu pé kò tọ́ fún un láti fi Hẹrọdiasi ṣaya.
Wọn fẹsun kan ile-iwe giga fasiti to wa fun awọn eniyan dudu, wipe wọn n gba ọgọọrọ owo ile gbigbe ati owo kilaasi ti wọn ko lo.
" ilana ibagbepo ile india ati lilo oro towopo ninu opo awon ede india bakanna tun seidamo "" bharat "" ( pipe ) gege bi oruko onibise iru kanna ."
Amofin pari ọrọ rẹ pe, gẹgẹ bi aṣa adayeba, ile igbimọ ko pe lai si ọpa aṣẹ, ṣugbọn niwọn igba ti ile naa ba le wa pese ọpa aṣẹ miran, ko ṣe nnkan.
Latari iṣẹ takun takun rẹ ninu ere tiata, Funke ti gba ọpọlọpọ ami ẹyẹ o si ti ṣe awọn iṣẹ akanṣe bii ipolowo fun oriṣiriṣi ọja ati ile iṣẹ.
Lara awọn eewọ ti Iyalufa ka fun Ọmọyẹ ni pe, iya ko gbọdọ pọn ọmọ rẹ sẹyin, ki ọmọ naa si jabọ lẹyin iya rẹ, bi eyi ba si ri bẹẹ, iya naa gbọdọ sare ni ihoho ọmọluabi wọ inu ọja ni kia-kia,were-were.
ati pé wọ́n ju oriṣa wọn sinu iná, nítorí pé wọn kì í ṣe Ọlọrun.
Lásìkò tí ó ń bẹ àwọn ọlọ́pàá Okunola ní kí wọn síjú àànú wo òun nítori pé owó tí òun yóò fí ṣe ayẹyẹ ìkọ́ṣẹ́ parí fún iṣẹ́ bábà tí oun kọ́ ni àti pé tí wọn bá tú oun sílẹ̀, oun kò ní fi ẹsẹ̀ tẹ ìlú Ekó mọ.
Ẹni tí ó fibi san oore,ibi kò ní kúrò ninu ilé rẹ̀ lae.
Aṣẹ́wó, olè, gbájúẹ̀ ni 723 ọmọ Naijiria ta lé padà sílé - Ghana Òtítọ́ ọ̀rọ̀ rè é lórí ilẹ̀ tó fa awuyewuye láàrin Ghana àti Nàìjíríà Wọn le awọn olutaja kuro niwaju ile Aarẹ Ghana Ìjọba Ghana ṣí iléeṣẹ́ àwọn ọmọ Nàìjíríà padà.
 a gbọ ́ ọ bákan náà pé àwọn ọmọ odùduwà ju méje lọ .
miran lati igun gomina ti ilu dibo yan, Seyi Makinde.
Wọ́n pe orúkọ ibẹ̀ ní Tabera, nítorí níbẹ̀ ni iná OLUWA ti jó láàrin wọn.
Ìyẹn tí ayé gan-an kò bá tíì parẹ́.
Nítorí bí ipá rẹ̀ ti tó,ati bí agbára rẹ̀ ti pọ̀ tó,ẹyọ ọ̀kan ninu wọn kò di àwátì.
Àwọn eniyan mi tí ó ṣẹ́kù ni yóo sì ni gbogbo nǹkan wọnyi.
"Ko si bi awọn ọmọ ẹgbẹ ṣe le parọ fún e to, gbogbo igba leru ma n ba wọn"" * A lo orukọ Roland la ti fi bo ẹni ta ba sọrọ lasiri ki ẹmi rẹ ma ba wa ninu ewu * Manuella Bonomi ileeṣẹ BBC lo ya gbogbo aworan ta fi ṣe akawe ọrọ Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!"
Ó kù díẹ̀ kí n padà lọ́nà kí n tó rí i pé okun lásán ni mo rí.
Gege bi Yakubu, egbe oselu márùndínlógójì ni yoo kopa ninu eto idibo naa, eyi ti yoo waye nijoba ibile mẹ́rìndínlógún nipinle Ekiti.
Otunba Nìyí Adebayo Oríṣun àwòrán, @SenAlasoadura Ọtunba Nìyí Adebayọ ni a bí ní ìlú ìyìn Ekiti ni ọjọ́ kẹrin, oṣù kejì, ọdún 1954.
Ninu atejade kan ti aare Muhammadu
Lasiko ipade kan ti awọn alaṣẹ ileeṣẹ to n mojuto eto ilera Naijiria ṣe pẹlu aṣoju ilẹ Aṣoju Russia si Naijiria ni ọrọ yii ti jẹyọ.
Wọ́n kéde jákèjádò Juda ati Jerusalẹmu pé kí gbogbo àwọn tí wọ́n ti oko ẹrú pada dé péjọ sí Jerusalẹmu.
Laarin ọdun 1903 si 1909 ni Oyinkan pari ẹkọ rẹ nile ẹkọ girama Anglican Girls, ko to morile ilu ọba lati tẹsiwaju.
"Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù APC NEC Meeting: Ẹkúnrẹ́rẹ́ ọ̀rọ̀ ìkini PDP sí APC bí àwọn adarí ẹgbẹ́ lápapọ̀ ṣe túká rèé 8 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Oríṣun àwòrán, Twitter/APC Nigeria Ẹgbẹ oṣelu oṣelu alatako lorilẹede Naijiria, Peoples Democratic Party, PDP ti fi ikini ku oriire ranṣẹ si gbogbo ọmọ ẹgbẹ All Progressives Congress, APC jakejado orilẹede Naijiria gẹgẹ bi ""ẹgbẹ to ti n dun mọhuru-mọhuru mọ wọn fun ọdun marun ṣe ti yọ́ danu kuro ni gbagede oṣelu""."
Gbogbo eniyan to ri awọn mejeeji lo sọ wi pe wọn jọ ibeji, ti Miche is sọ wi pe ni se lo dabi ẹni pe awọn ti mọ ara wọn fun ọpọlọpọ ọdun, ti ọdun mẹta to wa laarin ọjọ ori wọn ko si jẹ idiwọ tabi idena fun wọn.
Gomina gba ibẹ pada si ilu Monguno lẹyin iṣẹlẹ naa.
"Komla Dumor ni agbara lati sọ itan jakejado agbaye ki o si fi nkan to pa aye pọ ati oye olukuluku gbee kalẹ.
“Láti ìgbà tí wọn yóo mú ẹbọ ojoojumọ kúrò, tí wọn yóo gbé ohun ìríra sí ibi mímọ́, yóo jẹ́ eedegbeje ọjọ́ ó dín ọjọ́ mẹ́wàá (1,290).
” Ọkunrin yìí dáhùn pé òun óo ra ilẹ̀ náà pada.
Ni kete ti eni akoko ti jade fesun kan an ni won ti sagbekale egbe #MeToo (Emi naa) lori ero ayelujara ni eyi to fun opolopo awon obinrin loore ofe lati jade sita so awon koto ti o ti se si won seyin.
Bí mo ti wí ni n óo ṣe, n kò ní dáwọ́ dúró, n kò ní dá ẹnikẹ́ni sí, n kò sì ní yí ọkàn pada.
Ọ̀pọ̀ àwọn olólufẹ gbájúgbaja eléré tíátà náà ló ti ń baa dáwọ ìdúnu ní gbogbo rí ayélujára Ẹ̀wẹ́ lọ́jọ́ kan náà ni Laide Bakare náà tọwọ́ bọ ìwé àdéhùn pẹ̀lú ilé iṣẹ́ tó mójútó ilé àti ilẹ̀ rírì nílùú Ibadan láti jẹ asojú ilé iṣẹ́ náà.
Eyi ni ẹlẹẹkejilelọgbọn iru rẹ nilẹ Adulawọ.
Nigba to sọ nipa igbesi aye rẹ, Tọpẹ Alabi ṣalaye pe ọmọ ọdun meje si ni oun wa, ti wọn ti sọ asọtẹlẹ fun awọn obi oun pe, oun yoo sisẹ sin Ọlọrun.
'Iru nkan bayii ko ṣẹlẹ ri nipinlẹ Kaduna' Habu Muazu, to jẹ ọmọ jayejaye, to tun jẹ olugbe nipinlẹ Kaduna lati bi ọdun mẹẹdọgbọn, sọ fun BBC pe, igba akọkọ niyii ti oun ri iru nkan bẹ ẹ ri lati igba ti oun ti n lọ sile ijo.
Ṣugbọn ọjọ́ keje jẹ́ ọjọ́ ìsinmi tí olukuluku níláti yà sọ́tọ̀ fún èmi OLUWA Ọlọrun rẹ̀.
Wọn ni eeyan meji lo gbẹmi mi loju ẹsẹ ti ẹni ikẹta si wa ni ẹsẹ kan aye - ẹsẹ kan ọrun.
8 bílíọ̀nù) ni fásitì OAU jẹ ìjọba ìpínlẹ̀ Ọ̀ṣun Àjọ tó ń pawó wọlé lábẹ́lé, tó tún ń se kòkárí ówó orí nípínlẹ̀ Ọ̀ṣun, OIRS, ti gbé ìloro ọgbà fásitì Ọbáfẹ́mi Awólọ́wọ tó wa nílùú Ilé ifẹ̀ tì pa lórí ẹ̀sùn pé, ó jẹ owó orí to dín díẹ̀ ní bílíọ̀nù méjì náírà.
Àràmọ̀ǹdà àwòràn láti ilẹ̀ àdúláwọ̀ lọ́sẹ̀ yìí Ajimobi tako àṣẹ iléẹjọ́ pẹ̀lu ìbò ìjọba ìbílẹ̀ tó ṣe - Ìjọba Ọyọ N kò lẹ́bi pé ejò kó ₦36m owó àjọ JAMB mì -Philomina Kíni N11trn owó ìrànwọ́ epo tí ìjọba àpapọ̀ san fún àwọn agbépo lè rà?
Ọpọlọpọ idunadura awọn eniyan Estonia lo jẹ pe ẹrọ ayarabiaṣa kọmputa ni wọn n lo fi ṣee.
Oshiomọlẹ fi ẹsun naa kan Fayose ni ibi asekagba ipolongo idibo gomina fún Kayode Fayemi, tó n dije du ipo gomina labẹ ẹgbẹ oselu APC ni ipinlẹ Ekiti.
Ẹ gbọ́ Ohun tí Desmond Elliot àti Mojisola Alli-Macaulay sọ lórí ayélujára táwọn ọmọ Nàìjíríà fi ìbínú Ìrànwọ́ ikú fàwọn tó bá wà lórí àkéte àìsan tó leè já sí ikú ti di òfin tuntun tí wọ́n fẹ́ fọwọ́ sí!
Dokita to ṣetọju Zarka, Zalmai sọ pe oun ko gba kọbọ lọwọ rẹ bo tilẹ jẹ pe iye owo iṣẹ oun ko din ni ẹgbẹrun meji dọla.
Ṣugbọn Saulu ati àwọn eniyan rẹ̀ dá Agagi sí, wọn kò sì pa àwọn tí wọ́n dára jùlọ ninu àwọn aguntan, mààlúù, ati ọ̀dọ́ mààlúù ati ọ̀dọ́ aguntan wọn, ati àwọn nǹkan mìíràn tí ó dára.
Eleasari ọmọ Aaroni fẹ́ ọ̀kan ninu àwọn ọmọbinrin Putieli; ó sì bí Finehasi fún un; àwọn ni olórí àwọn ìdílé ẹ̀yà Lefi.
Bí ẹkún gbọn ni, bí kò gbọ ni, dandan ni kí olúwarẹ̀ ké hìíì!
 Adari rere gbodo ba awọn  eniyan kedun lori ijamba ina to sẹlẹ yii.
Ó bá kúrò lọ́dọ̀ wọn, ó lọ siwaju díẹ̀ sí i.
Ewé kékeré kò tó láti fi bò wọn, omi egbò ẹsẹ̀ awọn ara ìlú náà a sì maa kán sílẹ̀ bí wọ́n bá ti n rìn lọ.
Ni South Africa, ọpọ ile iwosan ni wọn ti fi dandan ti pa tori pe o ti di ibi ijẹsi fun aisan Covid19.
” Ọlọrun sì ṣe ohun tí ó fẹ́ fún un.
Àkọlé àwòrán, Oyedepo ni oun ko gba kọbọ ri lọwọ oludije kankan ko to de ipo, ti oun ko si setan lati gba owo lọwọ oloselu kankan.
Ajọ ẹsọ alabo oju popo lo sọ eyi di mimọ fun BBC Yoruba ninu ifọrọwero pẹlu olori ẹka wọn ni ipinlẹ Ogun,Clement Oladele.
Laasigbo to n lo jade-jado orile-ede South Sudan ti le ogunlogo awon eniyan kuro nibugbe won, amo, ni bayii, ijiroro alaafia ti yoo fopin si laasigbo ohun yoo waye laipe.
Oríṣun àwòrán, Adeleye Adekunle Adeleye Nínú ọrọ tirẹ, Adekunle Adeleye salaya pé gbogbo awọn iṣ ti oun ti ṣe kalẹ nilu Oyinbo, asiko ree lati ko ere rẹ.
Ẹ ṣe lè wí pé alágbára ni yín, ati pé ẹ jẹ́ akikanju lójú ogun?
Èmi pàápàá mọ̀ pé láti ọjọ́ tí mo ti wọ ẹ̀wù náà ni mo ti di onígbéraga, nǹkan mi ni o máa ń dára lójú mi, mo ń hùwà bí ẹni pé ta ni máa mú mi, ìrin ṣeẹ̀ mi, ọ̀rọ̀ ẹnu mi, ìṣe mi sí ẹnikẹ́ni, ti ìgbéraga ni.
Nítorí ọmọ ẹni tí ọkọ ṣátì pọ̀,ju ọmọ ẹni tí ń gbé ilé ọkọ lọ,OLUWA ló sọ bẹ́ẹ̀.
Ewe, jijawe olubori ohun ni yoo so Osaka di omobinrin orile-ede Japan akoko ti yoo gba ife-eye ati ami-eye idije naa.
Ọ̀ótọ́ nìkan ni Bísọ̀bù yìí máa ń sọ, gbogbo ènìyàn sì ti mọ̀ọ́ bẹ́ẹ̀ fún un.
Ẹ Máa Ṣe Ohun Tí Ó Tẹ́ Ẹlòmíràn lọ́rùn.
Ọjọ kẹrindinlọgbọn, oṣu Kejila, ọdun 2019, ni Pogba ti gba bọọlu kẹhin, lẹyin to ni ọgbẹ́ ni ẹsẹ̀ ni ibẹrẹ ṣaa.
Mike adeyẹmi, nigba ti oun naa da si ọrs ọhun ni inu agbekalẹ sinima mi kan, ti mo pe akọle rẹ ni 'Bad Market' ni a ti kọkọ pade, bi o tilẹ jẹ pe a foju kanra fun igba akọkọ lasiko ta lọ pade rẹ ni ibudokọ reluwe, ti ifẹ si ru bo wa loju lọgan."
Ẹ fetí sílẹ̀, gbogbo ẹ̀yin ará ilẹ̀ òkèèrè.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Barister lo bi gbogbo oníṣẹ́ fújì -Oṣupa Vera Songwe gba pé olori isọro okowo nilẹ Adulawọ ni eto irinna.
Ileewe naa jẹ eyi ti o ni ileegbe ti o si wa ni odi ilu naa .
orile ede Naijiria loju pe oun yoo tubọ maa sa ipa oun fun orile  ede yii , ni paapaa julo ni saa keji to gunle
”Iwe akosile orile ede Namibia so pe “Awon mesan an ni awon eranko buruku yii pa lodun 2016, ti mefa ku lodun 2017”.
Koda awọn isẹ ikinni ku oriire gan ko gbẹyin loju awn opo ikan sira ẹni Facebook ati Instagram, ti wn n ki Lizzy ku oriire oye tuntun.
lati se idiwo fun ile ise asobode  nipa
Ajàfẹ́tọ́ obìnrin náà sọrọ lori iriri rẹ ni ọ̀pọ̀ ìgbà gẹ́gẹ́ bi amofin tí ẹjọ́ bá de àgọ́ ọlọ́pàá ti ọ̀rọ̀ náà sì jẹmọ́ ọ̀rọ̀ ipá nínú ilé ati iwa awọn agbofinro lori iru ọrọ bẹẹ.
Àwọn ni yóo máa ṣáájú nígbà tí àwọn ọmọ Israẹli bá fẹ́ kó kúrò ní ibùdó kan lọ sí ibòmíràn.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Aarẹ Buhari n lọ sinmi ni London fun ọjọ mẹwa 1 Ògún 2018 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 2 Ògún 2018 Oríṣun àwòrán, Getty Images Ààrẹ Muhammadu Buhari ti sọ wí pé ní àìsí nílé òun, igbákejì rẹ̀ ni yó máa delé dè é.
Afi bi igba ti Aṣiwaju Tinubu gba ẹnu ọpọ ọmọ orilẹede Naijiria sọrọ lori ọrọ naa.
Lẹyin ti ariwo pọ ni Buhari mu iwe ẹri kan lọ fun ajọ naa, eyi to tun bẹrẹ awuyewuye mi i.
Ṣugbọn ni kete ti akọroyin BBC Yoruba kan si agbẹnusọ rẹ, Ọgbẹni Kehinde Akinyemi, lo ṣalaye wipe, aarẹ ana naa wa ni ẹgbẹ oun gan nilu Abẹokuta, ti ko si rin irinajo kankan kuro ni Naijiria.
Ohun táó jẹ, táó mu kò mà ni wọn wa o) (lẹmeji)
Amọ, o fikun un pe oun ni igberaga, bẹẹ si ni oun fẹran lati ma a rin irinajo.
Tope Alabi: Ìlúmọ̀ọ́ká akọrin ẹ̀mi náà ní ìdílé kòlà-kòṣagbe l'òun ti wá
Ará Kwara soríre bí mo se jáwé olúborí - Ọlawuyi Ìdá 35% obìnrin ní ìjọba àti àwọn nǹkan míràn tí #Next Level bá dé Aregbesola: mí ò gba owó oṣù gómìnà rí Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, World Toilet Day: Aráàlú ní woléwolé yẹ kó bẹ̀rẹ̀ àyẹ̀wò ojúlé dé ojúlé Amọ, iroyin fikun wi pe agbẹnusọ tẹlẹri fun Aarẹ, Reuben Abati naa ni yoo ma dije dupo gẹgẹbi igbakeji gomina labẹ ẹgbẹ oselu PDP naa ni ipinlẹ Ogun.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù JAMB: Ìgbésẹ̀ ti ń lọ lórí èsì ṣùgbọ́n kò tíì sí gbèdéke ọjọ́ tí yóò jáde 29 Ìgbé 2019 Oríṣun àwòrán, JAMB Àkọlé àwòrán, Àjọ JAMB ní àwọn akẹ́ẹ̀kọ́ tó lé ní mílíọ́nù kan tó kópa nínú ìdánwò JAMB tó wáyé ní Osù Kẹ́rin, ọdún 2019.
Oríṣun àwòrán, Funmi Sodiq Charlie Boy ni ojuse awọn ọmọ orilẹede yìí ni lati fi eto rere lelẹ fawọn iran ti o n bọ nipa eto idibo ti yoo ṣafihan ifẹ araalu ni tootọ.
Awon afurasi mejila ti won mu yii wa lara awon oruko ogun eniyan ti won fi sita lati ile olopaa ni Ankara pe won n wa tele.
A si n gbadura pe Ọlọrun yoo fi ọrun kẹ ẹ.
Nígbà tí ẹ bá sì dé ilẹ̀ tí OLUWA yóo fún yín gẹ́gẹ́ bí ó ti ṣe ìlérí, ẹ gbọdọ̀ máa ṣe ìsìn yìí.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 2020 in Retrospect: Ìjàmbá iná, ilé tó dàwó, ìwọ́de àti àrùn Covid-19 wà lára ìṣẹ̀lẹ̀ 2020 A tún padà gbọ pe awọn to dojú ìjà kọ ara wọn ọhun tun gbe ìjà wọn dé adugbo Sagan, Orieru, Port junction ati roundabout pẹlu nkan ija oloro titi di afẹmọju lojo Ìṣẹgun.
Sugbọn, ohun ti a ri dimu ni koko ni pe, wọn ti dana sun ile ijọsin naa bayii.
Mose bá gbé ọ̀pá rẹ̀, ó nà án sókè, sórí gbogbo ilẹ̀ Ijipti.
Ṣugbọn ẹni tí ó ń bọ̀ lẹ́yìn mi jù mí lọ; èmi kò tó ẹni tí ó lè kó bàtà rẹ̀.
Nibi ti aarẹ ti fi ye wọn pe iṣẹ wọn ṣẹṣẹ n bẹrẹ ni ati pe kekere kọ ni ike Ramọ iṣoro ti ijọba n wa ojutu si ni Naijria lasiko yii.
Sc Mathematics), iwe ẹri imọ ijinlẹ keji ni imọẹrọ, (M.
Gomina Oyetola ni ijọba oun ṣetan lati lo iṣẹ agbẹ pese iṣẹ fawọn eeyan ipinlẹ Oṣun.
Nítorí pé ìfẹ́ rẹ tí kì í yẹ̀ tóbi, ó ga ju ọ̀run lọ,òtítọ́ rẹ sì kan ojú ọ̀run.
Gẹ́gẹ́ bá ṣe rí ka lójú òpó itakun agbaye, a leè ṣe àpèjúwe Olunloyo bii ọmọ tí yóò jẹ Asamu, to ti kékeré jẹnu samusamu, torí láti ìgbà èwe rẹ lọ tí de ibi gíga, tó sì di àwọn ipò ńláńla mú.
Wọn ko pe wa si ipade ki wọn to ni awọn fẹ gbe ẹjọ kuro nile ẹjọ nitori naa ko lee seese.
Awọn ikọ naa lati ileeṣẹ ọlọpaa ẹkun Guusu-Ila Oorun ati ẹkun Guusu-Guusu yoo ṣe ẹkọ igbaradi tiwọn ni ile ẹkọ igbogun ti iwa idunkoko mọ ni to wa ni Nonwa-Tai, ipinlẹ Rivers.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ẹ́ gba fóónù, ẹ pe ẹbí yín pé a fẹ́ dáná ṣun yín - Aráàlú sọ fún adigunjalè méji N kìí gbádùn ara mi tí ń kò bá jà lọ́jọ́ kan- Ango Argungun Díẹ̀ lára àwọn ìṣẹ̀lẹ̀ tí yóò mi ìgboro tìtì l'ọ́dún 2020 rèé Ó ti di ogójì èèyàn tí wọ́n tẹ̀ pa níbi ìsìnkú Qasem Soleimani tí kò wáyé mọ́ Lẹyin naa ni Naira Marley funra rẹ fi ọrọ kan naa lede loju opo Twitter tiẹ naa.
Apapo iye awon ti won foruko sile fun idanwo odun 2018 ohun n lo bi milionu meji (1,652,825) One Million, Six Hundred and Fifty-Two Thousand, Eight Hundred and Twenty-Five”.
Ko tii si alaye ni pato lori isinku oloogbe, ṣugbọn iwadi fi idi rẹ mulẹ pe wọn ti tọju oku oloogbe si ileewosan ikọsẹ iṣegun oyinbo, UCH to n bẹ ni Ibadan.
OLUWA, ranti àánú rẹ, ati ìfẹ́ rẹ tí kì í yẹ̀,nítorí wọ́n ti wà ọjọ́ ti pẹ́.
3 3136 Orilẹede Taiwan 7 0.
Ẹgbẹ́ Ilẹ̀ Yorubà gba Aṣíwájú tuntun!
Ologun Nigeria gbakoso ibuba Boko Haram Boko Haram tu awọn olukọni UNIMAID silẹ Awọn agbesunmọmi Boko Haram tẹlẹ gba idande 'Ologun ko lee koju Boko Haram' Ogagun Abdulssalam Sani tó jẹ́ alukoro fun ileeṣẹ ọmọ ogun lori iṣẹ akanṣe ṣalaye pe awọn naa pada kọlu awọn oniṣẹ ibi naa.
Laipẹ yi ni ijọba apapọ kede pe awọn ti ṣeto owo iranwọ ẹgbẹrin din meje miliọnu naira feto ẹkọ Almajiri.
Mo si bi wọn pe ko si ijoko loni, emi nikan gẹgẹ bii olori ile nikan lo lee pe ipade ijoko ile.
" Ìtàn tí ó rọ̀ mọ́ ìbéèrè yìí ""Ẹja Ni Àbí Akán"" Akàn àti Ẹja jẹ́ pàtàki nínú àwọn ọ̀pọ̀lọpọ̀ ọmọ Yeyemoja Olókun."
Ẹ̀kún omi ń bọ̀ yanturu nílẹ̀ Yoruba, ẹ̀yin gómìnà, ẹ gbaradì - NEMA ń lọgun Mo gba àṣẹ lọ́wọ́ ọkọ, kí ń tó má ṣeré ìfẹ́ pẹ̀lú ìyàwó rẹ̀ - Àlè kan jẹ́wọ́ Kí ló mú Obasanjo ti ilẹ̀kùn mọ́ ẹbí, òṣìṣẹ́, ojúlùmọ̀ ní ibi òkú àna rẹ̀?
'Aṣẹ ti wa lati ọdọ kọmiṣọna ọlọpaa pe ki ẹka ọtẹlẹmuyẹ ileeṣẹ ọlọpaa, SCID bẹrẹ iwadi lori rẹ lati mọ bi iku rẹ ṣe jẹ'.
Mo mọ̀ pé ọba Ijipti kò ní jẹ́ kí ẹ lọ rárá, àfi bí mo bá fi ọwọ́ líle mú un.
Andrew Haruna: So-bàtà tó di ọ̀jọ̀gbọ́n fásitì tó di ọ̀gá àgbà
Ranti pé, ìwọ pàápàá ti jẹ́ ẹrú ní ilẹ̀ Ijipti rí, ati pé OLUWA Ọlọrun rẹ ni ó fi agbára rẹ̀ mú ọ jáde.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, libya Ajax (1971) Isẹ ara rẹ ko pọ rara, sugbọn o rẹwa pupọ.
Oríṣun àwòrán, @BadmosWaliu Ẹnikan ti isẹlẹ naa soju rẹ ni deede aago mẹjọ ku isẹju mẹẹdogun lawọn janduku naa pejọ si ayika agboole awọn Sanwo-Olu, ti wọn si n fi oko fọ awọn ferese digi to wa nibẹ.
Pẹlu bi nnkan ṣe ri yii, goolu meje ni o ti wọ inu awọn Chelsea ninu ifẹsẹwọnsẹ mẹta ti wọn ti gba bayii laarin ọsẹ kan si ara wọn Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Fayẹmi ṣe alaye wi pe, Amọtẹkun ipinlẹ kọọkan ni yoo maa mojuto ipinlẹ ti wọn pin wọn si lai rekọja lọ si ipinlẹ mii, ayafi ti iṣẹlẹ pajawiri ba waye.
O pe fun ajoṣepọ laarin awọn ajọ alaabo lorileede Naijiria.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ipinlẹ Eko wọ 70 afurasi ọmọ ẹgbẹ okunkun lọsile ẹjọ 2 Ẹrẹ̀nà 2018 Oríṣun àwòrán, Lagos State Government Àkọlé àwòrán, Nibi ti wọn ti'n se ipade lago meji oru ni ọlọpaa ti ko wọn Ijọba ipinlẹ Eko ti wọ awọn afurasi ọmọ ẹgbẹ okunkun aadọrin lọ si waju ile ẹjọ kekere.
Ileẹjọ f'ofin de ọdun oro nipinlẹ Ogun Ẹgbẹ naa koro oju si kikuna ti awọn ileesẹ alaabo n kuna lati pẹka awọn apanijaye gbogbo to n da omi alaafia orilẹede Naijiria ru ki o to di wipe wọn se ọṣẹ wọn.
Nigba to n dahun ibeere yii, ọga ọlọpaa nipinlẹ Ekiti sọ fun BBC Yoruba pe, ni ilakaka gbogbo ti ileeṣẹ ọlọpaa n ṣe nibẹ, lo mu ki wọn fọwọsowọpọ pẹlu awọn ọlọdẹ atawọn ẹgbẹ OPC lati se ọbẹ aabo jinna ni gbogbo agbegbe to wa nilẹ Yoruba.
Ni oṣu to lọ ni ilẹ Gẹẹsi, akọroyin kan Lyra Mckee ku nigba ti jagidijagan bẹ silẹ nibi ifẹhonu han kan ni Londonderry.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Soyinka: Buhari ti wọnu ẹmi lọ 13 Èrèlè 2018 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Aimọye igba ni Soyinka ti maa n tako asise awọn ijọba to ti kọja lọ lorilẹede Naijiria Agba onkọwe nni, Ọjọgbọn Wọle Soyinka, ti sapejuwe aarẹ orilẹede yi, Muhammadu Buhari gẹgẹbi ẹni to ti wọnu ẹmi lọ.
"Pasitọ naa ni ""owo Naira niye lori lọdun naa lọhun, yoo si tun niye lori lẹẹkan sii."
Amọṣa, ijọba apapọ ti fa awọn ipinlẹ to n gbe igbesẹ lati ṣi awọn ileewe pada leti pe ẹkọ gbigbona n fẹ suuru.
Wọ́n sì lọ sinu isà òkú ní àìkọlà abẹ́.
Agbẹnusọ fun ile iṣe ọtẹlẹmuyẹ sọ fun BBC awọn fọwọ ofin mu Ṣoworẹ nitori o n gbero lati ditẹ gbajọba orilẹede Naijiria pẹlu ifẹhonu han.
NURTW Oyo: Ìwà ìdàlùrù ní Ibadan ló mú kí Makinde gbẹ́sẹ̀ lé NURTW
Dokita àti Nọ́ọ̀sì fìyà jẹ mí lásìkò tí mò ń rọbí- Alaboyún Ǹkan mẹ́jọ tó máa kọ́kọ́ ṣẹlẹ̀ kí olólùfẹ́ méjì tó pa ara wọn EFCC ti ri mílíọ̀nù 65.
Oríṣun àwòrán, Akewugbagola Àkọlé àwòrán, Ìlànà IVF là fi bí ìbejì tẹ gbé lẹ́yìn idaduro ọdún méjìlá, ẹ jọ̀ọ́, ẹ tú wọn ṣílẹ̀ - Akeugbagold, aya rẹ bẹ̀bẹ̀.
 Awon ikọ ologun to n samojuto
Amọ, lai fi ti bi awọn to faramọ ṣe n fun ogun mọ ọ lọrun lati dabi awọn alatako rẹ, Biden ko yi ilana rẹ pada - ko polongo eto ilera ti ijọba n gbọ bukaata rẹ, ẹkọ ọfẹ, tabi owo ori lori ọrọ ti eeyan ba ni.
Wọ́n fa Jesu lọ sọ́dọ̀ Pilatu.
Ẹwẹ, awọn ologun sọ pe awọn ti gbiyanju agbara lati fopin si awọn agbesumọmi ati ijinigbe ṣugbọn egberin ọtẹ lọrọ ọhun.
"Láìpẹ́ yìí ló sẹ̀sẹ̀ gba òrùka 'sé oó fẹ mi' gẹ́gẹ́ bí ó ṣe sọ pé ""mó gbọ́, mo gbà"" sì ìbéèrè olólùfẹ́ rẹ tuntun láti di aya rẹ̀."
Nígbà tí ọkọ iyawo pẹ́ kí ó tó dé, gbogbo wọn bẹ̀rẹ̀ sí tòògbé, wọ́n bá sùn lọ.
Okunrin yi'n nawo si ọkọ ti wọn so ina si labule Barkin Kogi lọjọ kẹrinlẹlogun osu keji ọdun 2017.
Ile ẹjọ sọ pe ẹjọ́ naa da lori i idunkooko mọni to n jẹyọ lati ara igbagbọ pe awọn alawọ funfun ni laari ju awọn ẹya to ku lọ.
Bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé mo ti fọ́n wọn kásí ààrin àwọn orílẹ̀-èdè,sibẹsibẹ, wọn yóo ranti mi lọ́nà jíjìn tí wọ́n wà.
dìgbòlugi jẹ ́ kòkòrò àkóràn àrùn tí o ń fa ohun líle àrùn ọpọlọ nínu ènìyàn àti àwọn ẹlẹ ́ jẹ ̀ gbígbóná ẹranko míìràn .
World Hepatitis Day: A kò leè kó o nípa dídìmọ́ ara ẹni
O fikun ọrọ rẹ pe aarẹ kan n nawo Naijiria lori awọn irinajo yii papaa julọ bi o ti kọwọ rin pẹlu awọn gomina.
 Ọgbẹ ́ -inú buruli a má a sábà mú ni lọ ́ wọ ́ tàbí lẹ ́ sẹ ̀ ; ibà kò fi bẹ ́ ẹ ̀ wọ ́ pọ ̀ .
O kò sì gbọdọ̀ bá ẹranko lòpọ̀, bẹ́ẹ̀ ni obinrin kò sì gbọdọ̀ fi ara rẹ̀ sílẹ̀ fún ẹranko láti bá a lòpọ̀; ìwà burúkú ni.
Ó fọ́ gbogbo wọn túútúú, ó sì kó wọn dà sí àfonífojì Kidironi.
australopithecus africanus jẹ ́ èya australopithecines ìgbàanìelérò ayé àtijọ ́ tí ó jẹ ́ àkọ ́ kọ ́ ẹ ̀ yà ìnànkí tí a kà sí hominine ( ní 1924 ) .
NGRSenateCopyright: NGRSenate Apoti iboImage caption: Apoti ibo Article share tools Facebook Twitter ṢàpínlòView more share options Share this post Copy this linkKà síwájú síi nípa àwọn ìtọ́kasí wọ̀nyí.
Nibẹ naa ni wọn ti de ade fun Napoleon Bonaparte to gbiyanju lati daabo bo ile ijọsin naa lọdun 1804.
Ninu atẹjade ti oluranlọwọ pataki fun aarẹ Buhari, Laolu Akande fi lede ni Ọjọ Kini, Oṣu Kejila, ọdun 2020 ni wọn yo bẹrẹ si ni lo awọn ina Solar naa.
 Àwọn ẹkùn tí ìmọ ́ tótó kòsí àti tí àwọn ibi ti omi tó mọ ́ kò ti pọ ̀ ni àìsàn náà ti wọ ́ pọ ̀ ní àgbáyé .
Ní ọjọru, ọjọ kẹjọ,oṣù kíní ọdún 2020, ni Iran fi adó olóró ránsẹ́ si àwọn ọmọogun orilẹ̀-èdè Amerika ni bùdó wọ́n ni Iraq, lẹ́yin ti wọ́n ti ṣèléri pé àwọn náà yóò gbẹ̀san ikú ti wọ́n ṣe pa igbákeji olóri ogun Iran Soleiman .
Lẹ́yìn ìṣẹ̀lẹ̀ náà, iná ńlá kan bẹ̀rẹ̀ sí jó.
    Lẹ́yìn tí ọba fi wa hàn àwọn ara ìlú tán tí o sọ̀rọ̀ rere nípa wa ó ni bí mo bá fẹ́ sọ̀rọ̀ fún àwọn ènìyàn gbogbo lórúkọ àwọn ẹlẹgbẹ́ mi, mo lè sọ̀rọ̀.
Aarẹ Trump ti ibode pẹlu awọn orilẹede miran Lẹyin ọsẹ kan ti aarẹ Donald Trump gori oye ni o gbe ofin kalẹ to tako orilẹede meje to jẹ ti awọn ẹlẹsin Musulumi.
Nítorí OLUWA yóo máa lọ níwájú yín,Ọlọrun Israẹli yóo sì wà lẹ́yìn yín.
Saraki àgbà ló kọ́ ilé yìí fáwa arúgbó kìí ṣe Bùkọ́lá- Arúgbó Ilọrin Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
El-Zakzaky ti lọ sí India fún ìwòsàn - Femi Falana Àwọn agbébọn jí alága ẹgbẹ́ òsèlú PDP gbé ní Kogi Asọ́ ń pe aṣọ ránsẹ́ níbi ayẹyẹ ojúde Ọba ní'lùú Ijẹbu Khafi wọ gàu lẹ́nu iṣẹ́ lórí ẹ̀sùn ìbálòpọ̀ ní BB Naija Aṣiwaju Tinubu ko tii kede boya ootọ wa ni ọrọ yii abi bẹẹ kọ, bakan naa ni ko wi fun araye pe oun ko gbaa lero.
Nígbà tí Jesu dé ilé ìjòyè náà, ó rí àwọn tí wọn ń fun fèrè ati ọ̀pọ̀ eniyan tí wọn ń ké.
Ní àkókò ìyọnu Ahasi ọba, ó túbọ̀ ṣe alaiṣootọ sí OLUWA ju ti àtẹ̀yìnwá lọ.
Ìgbésẹ̀ yìí kò sàì so mọ́ bi àwọn ajàfẹ́tọ ọmọniyàn ṣe ń fún ogun mọ ìjọba lóri ẹ̀tọ́ obìnrin.
Ọjọ Aje, ọgbọnjọ, oṣu Keje, ni iyawo ẹgbọn ọkọ rẹ kan ṣẹṣẹ sọ fun un pe ọkọ rẹ ti ku lẹyin ti awọn pẹja-pẹja ri oku rẹ to lefo soju odo.
Iṣẹlẹ naa ni ko se lẹyin ikọlu ti awọn ọmọ orilẹede South Africa n ṣe si awọn ajeji to n bẹ nilẹ wọn, ninu eyi ti ọpọ ọmọ Naijiria ti fara gba.
Kí ló dé tí mo fi ń ṣọ̀fọ̀ kirinítorí ìnilára ọ̀tá?
 fún ìdí èyí , láìsí ènìyàn , kò le è sí àṣà rárá .
Koda, ọpọ eeyan si maa n fi oju ipa ti wọn n ko ninu ere se odiwọn igbe aye wọn loju aye nitori awọn miran to n ko ipa olowo ni wọn maa n fi oju olowo wo.
" Gbọ́ ọ̀rọ̀ lẹ́nu afurasí tí Ọlọ́pàá ní ó pa Barakat Bello, Grace Oshiagwu àtàwọn míì l'Akinyele Ibadan Èèmọ̀!
Èrò àwọn aráàlú kò jọ ara wọn lórí ọ̀rọ̀ Fayosẹ.
Orile ede Ghana ati Jamaica ti
 Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Kò sí olùwọ́de tó kú ní Lekki - Sanwo-Olu N kò lọ́wọ́ nínú ìpànìyàn, kò dáa bí wọn ṣe lo ọta ìbọn ní Lekki - Tinubu Ọjọ́ Ìsẹ́gun di ọjọ́ ìbànújẹ́ fún ọ̀pọ̀ ìdílé ní Nàíjíríà torí òkú tó ṣùn Ọ̀dọ́ 30 ń gba ìtọ́jú lọ́wọ́ nílé ìwòsàn torí ọ̀gbẹ́ ìbọn ní Lekki - Sanwo-Olu ṣàlàyé Àwọn ṣọ́jà ṣíná ìbọn bolẹ̀ ni Lekki Tollgate Àwọn ọlọ́dẹ darapọ̀ mọ́ ìwọ́de #EndSARS l'Osogbo, wọ́n ní kò sáyè fún jàǹdùkú mọ́ Kíní ìtumọ̀ ''Sọ̀rọ̀ Sókè'' tí àwọn afẹ̀họ́núhàn EndSars ń lò káàkiri Gomina ọhun fi kun pe, wọn ti tu awọn mẹta miran silẹ ki wọn maa lọ sile wọn lẹyin ti wọn gba itọju tan."
Àwọn mẹta tí wọ́n dàgbà jùlọ láàrin àwọn ọmọ Jese bá Saulu lọ sójú ogun.
 Ìlú Ọ ̀ gbàgì wà ní ojú ọ ̀ nà tó wá láti adó-Èkìtì sí ikàrẹ ́ , ó sì jẹ ́ kìlómítà mẹ ́ rìnláá sí ìlú Ìkàrẹ ́ .
Ọwọ́ Òṣúnlékè ni wọ́n ti r ailẹ̀ tí Orímóògùnjẹ́ fi ń kólé náà.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Yoruba Movie: Wumi Toriọla ṣàlàyé òun tó mú tírélà gbà àárín òun àti ọ̀rẹ́ rẹ̀ 31 Ọ̀wàrà 2020 Láti bi ọjọ́ mẹ́ta sẹyìn lọ̀rọ̀ ti n ṣe bi eré, bi ìjà láàrín àwọn òṣèré tíàtà Nollywood Yorùbá ti kò si yé ọ̀pọ̀ èèyàn ǹkan tó bẹ̀rẹ̀ ṣẹlẹ̀ ni pàtó.
– Nítorí ènìyàn ni bàbá mi, ọdẹ ni òun si í ṣe pẹ̀lú, lákòókò igbà tí mo ń sọ̀rọ̀ rẹ̀ yìí, ọjọ́ pẹ́, ṣùgbọ́n bàbá mi ló gbójú  jù nínú gbogbo àwọn ọdẹ inú ayé lákòókò tí wọ́n bí mi.
Eyi waye lojuna ati wa ojutu si ikolu awon omo ogun olote boko haram to n so se kaakiri, papaa julo ni eka ariwa ila oorun orile-ede Naijiria.
Ilu Kashmir ni kogun saarin orile-ede India ati Pakistan, ti o si je ilu to n fara kaasa awon isele oniruuru lodun melo kan seyin.
Mose ti kọ́kọ́ fún ìdajì ẹ̀yà Manase ní ilẹ̀ ní Baṣani; Joṣua sì fún ìdajì yòókù ní ilẹ̀ ní ẹ̀gbẹ́ ti àwọn arakunrin wọn, ní ìwọ̀ oòrùn odò Jọdani.
6 390,788 Saudi Arabia 6,313 18.
Nígbà tí Adadi gbọ́ ní Ijipti pé Dafidi ọba ti kú, ati pé Joabu, balogun rẹ̀ náà ti kú, ó wí fún Farao pé, “Jẹ́ kí n pada lọ sí ìlú mi.
Iyawo aare orile ede Naijiria,Aisha Buhari  ti ro awon obinrin inu egbe oselu APC lati fowosowopo pelu awon obinrin ati awon omo egbe tuntun, ki won si ri ara won gege bi  ẹbi kan naa,paapaa julo ni imura sile fun eto idibo to n bọ.
Ọ̀dọ̀ fásitì jànkàn Oxford ló ti jáde Kanye West ti bẹ̀rẹ̀ ìpolongo àti díje dupò aàrẹ ilẹ̀ Amẹrika Lapapọ eeyan ọtalelẹẹdẹgbẹta ati meji ni ajọ NCDC tun kede pe o kun iye awọn ti ayẹwo ti fihan pe o ni arun coronavirus lorilẹede Naijiria lọjọ Aje, ogunjọ oṣu keje, ọdun 2020.
" Nigba to n ṣalaye pataki nọmba idanimọ ọhun, o ni kaadi idanimọ ni ọjọ lori, ṣugbọn nọmba idanimọ wa titi lai.
Ilé iṣẹ ọlọpàá yóò gba ènìyàn 40,000 sí isẹ Òṣèré tíátà, Kemi Afolabi dùbúlẹ̀ àìsàn ní ìlú Mecca Ọkùnrin méjì, obìnrin mẹ́ta jáde láyé ní Mecca lásìkò Hajj 2019 - NAHCON Àṣírí mẹ́wàá tí mo mọ̀ nípa Boko Haram-Naomi Adamu O ni ko bojumu bi ijọba ṣe sọ wọn da ẹgbẹ agbesunmọmi labẹ ofin 'Anti-terrorism Act' to fi ofin de ki eniyan ma a hu iwa ipa ni awujọ.
BBC Yoruba wa n ba Ọba Lamidi Olayiwola Atanda Adeyemi Alowolodu yọ ayọ aadọta ọdun rẹ lori itẹ, ta si n gbadura pe ade yoo pẹ lori, bata yoo pẹ lẹsẹ, ẹsin ọba yoo si jẹ oko pẹ.
 wón tún ń so àwon èdè wònyí ní peru àti apá kan argentina .
Oloye Oyekanmi yii si lo di Iyalode ilẹ Ibadan Kẹrinla, to si ni igbega si ipo naa lẹyin ti Alhaja Aminat Abiọdun, tii se Iyalode ilẹ Ibadan Kẹtala papoda lọdun to kọja.
Oríṣun àwòrán, From The Palace of Ooni of Ife Sultan, ẹni to n fi ika gun awọn ọlaju lawujọ nimu pe se ni wọn n lo awọn mẹkunnu ti ko ni nkankan lati gba ohun ti wọn n fẹ, tun rawọ ẹbẹ sawọn ọba alaye pe ki wọn maa pariwo sita nipa isoro to n koju orilẹede yii, wọn sa ni igi gogogro ma gun mi loju, ati okeere laa tii lọọ.
 nígbà mìíràn , a kàn má a nwo irú àrùn báyìí ni .
Oriji tun so pe “Awon fe gbiyanju lati sẹda kaadi ibo ti awon eniyaa ko ti i gba , ki won si lẹẹ  si ara patako fun awon eniyan, bakan naa, si ni awon yoo tun fi oro ranse si awon ti won ko i ti gba kaadi ibo won lati ori ero alagbeeka.
Bẹ́ẹ̀ ni ahọ́n, ẹ̀yà ara kékeré ni, ṣugbọn ìhàlẹ̀ rẹ̀ pọ̀.
Èwo ninu yín ni kì í tú mààlúù tabi kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ rẹ̀ sílẹ̀ ní ibùjẹ ẹran kí ó lọ fún un ní omi ní Ọjọ́ Ìsinmi?
Akọroyin ileeṣẹ BBC to yọju si ile iwosan ọhun ri awọn eku to n jẹun kiri nibi ti wọn da idọti si.
fifi agba han awon akegbe won lati orile ede Afirika.
Ìpínlẹ̀ Oyo àti Eko kò nífẹ̀ẹ́ láti gba 'Ruga Settlement' láyè Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Rohr, Mikel, Musa ní àwọn ń padà bọ̀ bí Abija Bi o tilẹ jẹ wi pe agbẹjọro fun Pinnick atawọn ẹmẹwaa rẹ ṣalaye fun ile ẹjọ naa pe aiwa si ile ẹjọ wọn ko ṣẹyin bi wọn ṣe wa lara awọn ikọ ti ijọba apapọ ran lọ si orilẹ-ede Egypt fun idije ife ẹyẹ AFCON to n lọ lọwọ nibẹ.
Eniyan 11,462 ti ri iwosan, 634 si ti kú.
Somali, FIN FA niluu Enugu, FIN Angels, Ambassador Child Youth Club /Angels niluu
Ninu oṣu Keje, ile iṣẹ amohunmaworan kan to wa ni orilẹede Amẹrika(ESAT) gbe fidio kan jade to ṣafihan bi wọn ti n ti awọn Oromos ni Ethiopia sinu iboji ti ko jin.
Coronavirus tún ti ṣe ọṣẹ́ lórí iṣẹ́ líla ojú ọ̀nà relùwe láti Eko sí Ibadan - Ìjọba àpapọ̀ Àrùn Coronavirus fa'lẹ̀ya láwọn ìletò aláwọ̀dúdú ní Amẹ́ríkà Lagos lockdown: Iná jó dúkìá ẹgbẹ̀lẹ́gbẹ̀ owó l'Eko Ina nla kan tun sọ lọsan oni lagbegbe college Road Road, Abatan Ọgba ni ilu Eko.
SARS Operation in Nigeria: Òṣèré tíátà ń fẹ́ kíjọba pa ẹ̀ka ọlọ́pàá tó ń gbógun ti ìdigunjalè jẹ́
Ṣugbọn bí ẹni tí ó ń ṣiyèméjì bá jẹ kinní kan, ó jẹ̀bi, nítorí tí kò jẹ ẹ́ pẹlu igbagbọ.
Bakan naa lo rọ ijọba apapọ lati di ala ilẹ Naijiria ti awọn ọmọ ẹgbẹ agbesumọmi naa atawọn Fulani daran daran n gba wọle lati orilẹ-eded miran.
O fe funra ara re nikan we lawani fun Waziri akọkọ fun gbogbo ilẹ Yoruba.
Ọpọlọpọ àwọn ará Etiopia sì kú tóbẹ́ẹ̀ tí wọn kò lè gbá ara wọn jọ mọ́; wọn sì parun patapata níwájú OLUWA ati àwọn ọmọ ogun rẹ̀.
– ó mà tì o, kìí ṣe bẹ́l rárá, tàbí ẹ kò ní i bí mo ti pọn ìkólóbo dan?
Aarẹ Muhammadu Buhari pẹlu aṣẹ idaniduro ranpẹ̀ yọ Onnoghen kuro niṣẹ ni Ọjọ Kẹtalelogun, Ọdun 2019.
Bí àwọn kan bá kù, tí wọn sá àsálà, wọn yóo dàbí àdàbà àfonífojì lórí àwọn òkè.
 Awon ilu naa ni Port Harcourt, Aba, Enugu, Makurdi, Lafia, Gudi, Jos, Bauchi, ati Maiduguri.
OLUWA Ọlọrun tí ń kó àwọn tí ogun túká ní Israẹli jọ sọ pé,“N óo tún kó àwọn mìíràn jọ,kún àwọn tí mo ti kọ́ kó jọ.
Ọjọ Aje ni Aarẹ ile igbimọ aṣofin agba Bukola Saraki ṣe abẹwo tirẹ si Omisore nile rẹ ni Ile-Ife ni ọjọ Aje, eyi to fi han pe ootọ wa ninu ahesọ pe ẹgbẹ oṣelu PDP n wa iranlọwọ rẹ fun atundi ibo ti yoo waye ni ọjọ Ojọbọ.
 Lara igbese ti ijoba apapo  gbe ni lati tete san owo osu awon osise rẹ ,ikede
Coronavirus in Nigeria: Covid-19 wọ ìpínlẹ̀ Osun, èèyàn míì tún tí ni l'Eko, ó di èèyàn 46 tó níi ní Nàìjíríà Oríṣun àwòrán, Pius Utomi Ekpei Àkọlé àwòrán, Ajọ NCDC ṣalaye pe awọn mejeeji ṣẹṣẹ rinrin ajo de lati ilẹ okeere si Naijiria ni bi ọjọ meje sẹyin ni.
Ní Àwòrán: Ètò Ìsìnkú Winnie Madikizela-Mandela
Gboogi lara awọn wọnyii ni Fisayọ Soyọmbọ ti ọpọ mọ si oniroyin lori yaelujara.
“Ṣé eniyan lè fọn fèrè ogun láàrin ìlú kí àyà ará ìlú má já?
Ẹ ǹlẹ́ o ẹ̀yin ẹ̀dá Ọlọ́run wọ̀nyí.
O ni idi gaan niyi ti ọmọ oun, Eremosele nigba to ba ara rẹ laarin awọn oluwọde EndSARS pinu lati gbọ bukata wọn nipa ṣiṣe onigbọwọ awọn oluwọde naa to jẹ ọdọ bii tirẹ.
Ọkunrin kan tí ń jẹ́ Lasaru ń ṣàìsàn.
PDP tako Buhari lori awọn ọmọ Dapchi Ipinlẹ Ọsun gba awọn ọmọ rẹ pada lati Libya Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Yusuf Buhari never die - Nigeria Presidency Di government of Nigeria don deny di rumour wey dey fly around say di son of President Muhammadu Buhari wey bin get accident don die.
He was always looking out for his kinsfolk both at home and abroad.
N kò pa irú àṣẹ bẹ́ẹ̀ fún wọn; irú nǹkan bẹ́ẹ̀ kò tilẹ̀ fi ìgbà kan sí lọ́kàn mi.
O ṣalaye siwaju sii pe gbogbo awọn eeyan to ba ṣẹṣẹ n wọ orilẹede Naijiria lati oke okun gbọdọ fi ara wọn si igbele ọlọjọ mẹrinla, koda bi ohunkohun ko ba ṣe wọn lasiko ti wọn wọ orilẹede Naijiria.
Awọn ẹlẹsin Musulumi ni agbaye yoo bẹrẹ aawẹ Ramadan ni ọsẹ yii, eleyii ti yoo mu ki wọn yẹra fun jijẹ ati mimu lati owurọ titi di asalẹ.
Mo ki orí bọ́ inú ìpàǹtí yìí.
Lẹ́hìn náà ni ó sọ̀rọ̀ nípa Òjòlá-ìbínú tí í ṣe ọba ìlú àwọn ejò náà wí pé òun ni ẹ̀dá tí ó burú jùlọ nínú àwọn ẹ̀dá afàyàfà àti pé kí á ṣọ́ra kí á má ṣe bá àwọn ejò ìlú náà jà kí wọ́n máa baà mú wa lọ sí iwájú ọba burúkú tí ń bẹ ní ìlú wọn.
Eko,o tun lo si ile ẹkọ King William ni Isle -Man, lorile ede United Kingdom, o
Wí fún un pé OLUWA Ọlọrun ní,‘Wò ó!
Ọna lati mọ nipa bi agbekalẹ orin naa se waye, lo mu ki BBC Yoruba kan si asaaju ẹgbẹ akọrin obinrin ninu ijọ CAC to kọ orin naa, Mama Deborah Adebola Fasoyin.
Ó ní, “Èyí ni ara mi tí a fun yín.
Idi ni pe aba ofin kan ti wa niwaju ile asofin ipinlẹ ipinlẹ Ọyọ, eyi ti yoo sọ di eewọ fun awọn darandaran lati da ẹran jẹ loju popo, wọn si ti ka ofin naa, ti wọn pe ni Open Rearing and Grazing Regulation Bill ti ọdun 2019, fun igba keji bayii.
Oríṣun àwòrán, Getty Images To n tumọ si pe ninu eeyan ẹgbẹrun mẹwaa to ba ni, ọgọrun ninu wọn ni yoo ku, iye naa si pọ ju ohun ti iroyin naa sọ lọ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Wo àwọn ìlérí tàwọn Gómìnà tuntun ṣe nínú ìbúra wọn 30 Èbibi 2019 Oríṣun àwòrán, NIG/PRESIDENCY Àkọlé àwòrán, Ọrọ mi koi tii ya - Buhari Lọjọ kọkandinlọgbọn, oṣu karun un, ọdun 2019 ni wọn ṣe ibura fun aarẹ Buhari lẹekeji pẹlu awọn gomina tuntun.
 gẹ ́ gẹ ́ bí ó ti má a nwáyé , inú ríru , èébì , àti ìgbẹ ́ gbuuru a má a tẹ ̀ lẹ ́ èyí , pẹ ̀ lú àìṣedéédé iṣẹ ́ ẹ ̀ dọ ̀ àti àwọn kídìnrín .
Kìkì ibi ni èrò inú àwọn eniyankeniyan.
Ìyọnu ati ìpayà dé bá mi,ṣugbọn mo láyọ̀ ninu òfin rẹ.
Oríṣun àwòrán, @NLCHQ_ABUJA Idi ni pe awọn ẹgbẹ osisẹ ọhun ni awọn fẹ doju ija kọ gomina Akeredolu lori ọwọ yẹpẹrẹ to fi mu arun Coronavirus.
Oríṣun àwòrán, CBS Àkọlé àwòrán, Kelly sọ pe Azriel Clary àti Joyceln Savage jẹ ọ̀rẹ́binrin òun O ní  Mó ń sunkún, ẹ mọ òòtọ́,"" Ìrọ́ lásàn nítorí owó ní èyí"" Ẹ̀wẹ̀, àwọn òbi Alice àti Angelo Clary ti gbe àtẹjadé kan sita, tí wọn si tako iroyin to ni olokiki akọrin naa mu àwọn ọmọ àwọn pamọ, lòdì si ìfẹ́ inú wọn."
Cucumber: Eso miran to tun wulo fun isẹda ni eso Cucumber.
Ipo Ọba laye atijọ maa n fi ógbón agba tọni sọna ni, ṣugbón ko ri bẹẹ mọ laye ode oni to jẹ pe, ti wọn ko ba ṣe ti ijọba to wa lode, ijọba le fiya jẹ wọn.
Ipa ti awọn ọmọde n ko ni itankalẹ Coronavirus.
O ni awọn ara ilu ọhun ni lati ṣatunṣẹ orukọ wọn, bi bẹẹ kọ, o ṣeeṣe ko jẹ pe wọn mọ nipa idigunjale naa.
Ní oṣù kẹjọ, ọdún keji ìjọba Dariusi, OLUWA rán wolii Sakaraya, ọmọ Berekaya, ọmọ Ido, sí àwọn ọmọ Israẹli; ó ní, 
Lori ọrọ Codeine yi, aya aarẹ orile-ede yii ni ọrọ naa ba ni lẹru gan an ni gẹgẹ bi obi.
US-North Korea: Trump ati Kim John-un padé ni DM Zone
"Lásìkò Coronavirus yìí, mo ti rán aṣọ púpọ̀ mo dẹ̀ ti pawó gan"" Ẹwẹ oun naa gbagbọ pe gbogbo nkan ti eeyan ba n ṣe laye, o gbọdọ fi iwe kun un."
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Oba Adedokun Abolarin ti Oke Ila: Ó ya ọ̀pọ̀ tó súnmọ́ mi lẹ́nu bí mo ṣe ń kọ́ àwọn akẹ́kọ̀ọ́ pẹ̀lú ipò Ọba Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Oba Adedokun Abolarin ti Oke Ila: Ó ya ọ̀pọ̀ tó súnmọ́ mi lẹ́nu bí mo ṣe ń kọ́ àwọn akẹ́kọ̀ọ́ pẹ̀lú ipò Ọba 23 Bélú 2020 Oba Adedokun Omoniyi Abolarin Aroyinkeye 1, Orangun Oke Ila sọrọ ilẹ kun!
Nibayii awọn alaṣẹ ileeṣẹ ọlọpaa ti ni iwadii ti bẹrẹ lati mọ hulẹhulẹ iṣẹlẹ manigbagbe naa.
Ohun ta le sọ nipa arun yi re lasiko yi amọ awọn iwaadi kan n fi han pe arun naa le mu apẹrẹ mi to farapẹ ofinkin bi apẹrẹ ki imu ma yọ ikun.
 to wa ni iwo Gusu orile ede Naijiria lati pese  eto aabo fun eto idibo gomina ti yoo waye ni ojo kerinla osu keje ti a wa yii.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: L'Óṣogbo, Èéfín 'jẹnẹrétọ̀' gbẹ̀mí èèyàn mẹ́ta nínú ídílé kan Super Falcons pegedé fún àṣekágbá AWCON Super eagles fi ijó bẹ́ẹ lẹ́yìn tí wọ́n gbá ọ̀ọ̀mì pẹ̀lú Uganda Balogun ikọ Super eagles, Ahmed Musa ti o n gba bọọlu fun ẹgbẹ agbabọọlu Al-Nassr ni Saudi Arabia pẹlu Alex Iwobi ti ẹgbẹ agbabọọlu Arsenal ni agbabọọlu to wa ninu ipele ti ọkunrin.
 Ó jẹ ́ àjẹsára tó wà láàyè .
Akerele soro yii nibi iside ose oge todun 2018 to waye nipinle Eko ni Victoria
Ẹ ya ẹnu yín dáradára, n óo sì bọ yín ní àbọ́yó.
Fífẹ́ràn Ọlọrun ni pé kí á pa àwọn àṣẹ rẹ̀ mọ́: àwọn àṣẹ rẹ̀ kò sì wọni lọ́rùn, 
Beraya ati Ṣema ni olórí àwọn ìdílé tí wọn ń gbé ìlú Aijaloni, àwọn sì ni wọ́n lé àwọn tí wọn ń gbé ìlú Gati tẹ́lẹ̀ kúrò; 
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Olusegun Obasanjo: Ọmú ìyá mi ti mo fi ń mùkọ ni kekere ló jẹ ki ń lókun Isoro akọkọ ni pe ko lee fi ọmọ naa sile iwe nitori pe ko mọ boya ọkunrin ni ki oun pe abi obinrin, bẹẹ ni iwe ọjọ ibi to yẹ ko mu silẹ, ni dokita to gbẹ bi rẹ ti fi ami ibeere siwaju alafo ti wọn ti fẹ mọ boya ọkunrin ni ọmọ naa abi obinrin.
Nítorí ó tọ́ lójú Ọlọrun láti fi ìpọ́njú san ẹ̀san fún àwọn tí wọn ń pọn yín lójú, 
" O fikun pe lasiko ti ọwọn ọja n waye yii, nijọba tun jẹ awọn osisẹ kan lowo osu, owo ifẹyinti ati owo ajẹmọnu ifẹyinti lẹnu isẹ, eyi ti ko wu eti gbọọ rara.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Patrick Day: Akẹ̀ṣẹ́ kan, Day dèrò ọ̀run lẹ́yìn tó gba ẹ̀ṣẹ́ s'órí 17 Ọ̀wàrà 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Patrick Day: Akẹ̀ṣẹ́ kan, Day dèrò ọ̀run lẹ́yìn tó gba ẹ̀ṣẹ́ s'órí Iku ogun nii pa akinkanju, iku odo nii pa omuwẹ.
Ibi ọ̀rọ̀ dé dúró lórí ṣíṣí àwọn ilé ìwé padà ní Naijira rèé àti nílẹ̀ Afrika Wọn salaye pe, ti ojo ba rọ, n ṣe ni awọn maa n bẹ Ọlọrun ki ile ma da wo le awọn lori.
kí n tó pada síbi tí mo ti wá,sí ibi òkùnkùn biribiri,
'Mo máa tó dìde lórí àìsàn', Muyiwa Ademola sọ̀rọ̀ látorí àkéte àìsàn rẹ̀ Lọ́jọ́ ọdún Kérésìmesì, wàhálà bẹ́ sílẹ̀ l'Osogbo, iná ìbọn sọ Odunlade Adekọla, Lateef Adedimeji, , Mercy Aigbe àtàwọn òṣèré míì tó fi àsìkò Kérésì ya àwọn olólùfẹ́ wọn lẹ́nu Wó Ọkùnrin Mùsùlùmí kan tí ìrírí rẹ̀ nípa ọdún Kérésìmesì sọ iná"" sójú òpó Twitter O ni o ṣe pataki lati ""tẹsiwaju pẹlu igbagbọ ninu Ọlọrun"" lati mọ pe a o bori ajakalẹ aarun to n da aye laamu bayii."
Adari ajọ to n ri si ere idaraya nipinlẹ California, Andy Foster ti sọ tẹlẹ pe ija laarin Tyson ẹni ọdun mẹtalalaadọta ati Jones, ẹni ọdun mọkanlelaadọta da bii eremọde tabi igbaradi fun ija.
Abdelaziz Bouteflika dágbére ‘Kò tọ́sí Adeleke láti díje dupò gomina Ọṣun’ Àjọ INEC ti bẹ̀rẹ̀ ìkéde èsì ìdìbò gómìnà ìpínlẹ̀ Rivers 2019 Guber election: Mi ò fara mọ èsi ìdìbò Ọyọ́ Ikọ ọmọ oogun Algeria ti pé ààrẹ ẹni ọmọ ọdun mẹ́jilélọgọrin ọ̀hun láti kédé pe òun okóju osùwọn láti ṣe ìjọba mọ Láti ọdun mẹ́fa sẹ́yìn ni à[rẹ ti wa lóri akete àìsàn rapárọsẹ̀ ti ko si foju han si gbangba mọ.
ere na kogba iwuri ni awujo apapo .
O si n ṣe ikọlu si awọn ọmọ ogun Pakistan, àwọn ọlọpaa, ẹgbẹ Shia, àwọn Kristẹni.
Atamatase iko Super Falcons, Desire Oparanozie lo gba ami-ayo kinni wole, ti Francesca Ordega si gba ami-ayo keji wole ki saa kinni ifesewonse naa o to wa si ipari.
Wọnyi ni Àkójọpọ̀ àwọn àwòrán mánigbàgbé ọdún Àjínde l'Afrika.
SWAN fikun-un pe, iyansipo dokita Ayodeji Olarinoye ni o je akoko omo orile-ede Naijiria ti yoo se iru aseyori bayii, bee si ni won gbadura pe olorun yoo fun ni ogbon ati oye lati koju awon isoro lolokan-o-jokan bi o ba se n wa si iwaju re.
Nítorí pé ọwọ́ tí Joṣua fi na ọ̀kọ̀ sókè, kò gbé e sílẹ̀ títí tí wọ́n fi pa gbogbo àwọn ará Ai tán.
Dapọ jẹ ọkan lara awọn ọmọ gbajugbaja oniṣowo nni, Otunba Kunle Ojọra; oun si tun ni ẹgbọnToyin Saraki, to jẹ iyawo aarẹ ile aṣofin agba tẹlẹ, Sẹnetọ Bukọla Saraki.
Wọn yoo si lo afẹfẹ atọwọda (oxygen) fun ẹni naa.
"A kọkọ gbọdọ ri pe awọn eeyan fi ẹjọ sun ki a to gbe igbimọ ti yoo gbẹjọ yi le'lẹ O ni lọdọ t'awọn ni Oyo ""igbesẹ ni ṣiṣẹ n tẹle lawọn n gbe kii ṣe pe k'awọn maa fo ipele to kan lati bọ si omiran"" O ni awọn ko le sọ pe ọjọ bayi pato lawọn yoo ṣe agbekalẹ igbimọ ṣugbọn kọ ni pẹ t'awọn yoo fi ṣe."
Oluwa, máṣe dárí ẹ̀ṣẹ̀ wọn jì wọ́n.
Ilẹkun Baalu Dana fo yọ nilu Abuja Awọn asofin agba yoo sewadi ilẹkun baalu Dana to fo yọ Osisẹ kan l'orilẹede naa so wipe, kuru-kuru oju-ọjọ ko jẹ ki wọn le lo ọkọ baalu aba-sibi-o-ri, lati fi s'awari ibi tisẹlẹ naa ti waye.
Ninu idajọ to gbe kalẹ, adajọ to n gbọ ẹjọ awọn ẹ̀sun ti wọn fi kan Fayoṣe, Onidajọ Ọlatoregun, sọ pe ki wọn gba oniduro Fayose pẹlu aadọta miliọnu Naira, ati wi pe ko fi iwe idanimọ irinna silẹ okeere rẹ sile ẹjọ.
O kẹnu bọrọ, o ṣalaye fun BBC Yoruba ohun toju rẹ n ri nile ọkọ latọjọ to ti bẹrẹ si ni bimọ pẹlu awọ oju to yatọ si ti gbogbo eeyan.
Shariff-Aminu ni ile ẹjọ giga Sharia da ẹjọ iku fun lọjọ kẹwaa oṣu kẹjọ ọdun 2020 ṣugbọn ti wọn fun un ọgbọn ọjọ lati ẹjọ tirẹ bi idajọ wọn o ba tẹ ẹ lọrun.
Ohun tí a mọ̀ nìyí nípa gbọ́nmi síi omi ò tó lórí ọ̀rọ̀ oyè Babaloja-General ní ìpínlẹ̀ Oyo YWC yọ Ààrẹ Banji Akintoye nípò àbi Akintoye tú ìgbìmọ̀ aláṣẹ YWC ká?
Ó yani lẹ́nu pé àwọn ohun kan ṣì wà nínú ìyírí àwọn Channel One tí a kò mọ̀.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Olaitan Olamide: mò lè má nílò ìwé ẹ̀rí mi tí mo bá parí ní LASU Ọgbẹni Abolarinwa to jẹ akọṣẹmọṣẹ lori eto aabo ni: 1.
O woye pe, bi igbimo oro eleso lorile-ede Naijiria se n fi pipin eso naa fale ni ekun naa n mu ifaseyin ba awon agbe agbegbe naa.
Lati ọdun 1999, saa meji-meji ni gbogbo awọn gomina to ti jẹ nipinlẹ Eko maa n lo lori oye Kini ipilẹṣẹ ọrọ yii?
Ní àkókò ìkẹyìn yìí, ó wá bá wa sọ̀rọ̀ nípasẹ̀ Ọmọ rẹ̀, ẹni tí ó fi ṣe àrólé ohun gbogbo, nípasẹ̀ ẹni tí ó dá ayé.
Oríṣun àwòrán, Instagram/ronkeoshodioke Koda, ọna kan ko wọja ni a ba maa pe Oshodi Oke nitori kii se okoowo kan lo mu mọ ere itage, bo se n ta ipara ati ọsẹ ibora, naa lo tun n se atọkun eto.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Jakande: Osinbajo, Tinubu, Osoba kọwọrin lọ ki Jakande ọlọ́jọ́ ìbí 23 Agẹmo 2019 Oríṣun àwòrán, @followlasg Àkọlé àwòrán, Jakande: Osinbajo, Tinubu, Osoba kọwọrin lọ ki Jakande ọlọ́jọ́ ìbí Yoruba ni ti ọmọ ọni ba dara, o yẹ ka wi, ti pe a fẹ fi se aya kọ.
Ìwọ ọkọ, láti inú àmù rẹ ni kí o ti máa mu omi;omi tí ń sun láti inú kànga rẹ ni kí o máa mu.
Aarẹ Emmerson Munagagwa to gba ijọba lọwọ rẹ lo tu keke ọrọ yi nibi iwode oselu kan lagbegbe Murombedzi.
O le lo ile ifowopamọsi ti ko ni jẹ ki o gbe ọwọ le ẹrọ naa.
Wọn óo dì wọ́n ní ìdì kọ̀ọ̀kan kí wọ́n lè tù wọ́n gba ojú òkun lọ sí ibikíbi tí o bá fẹ́.
N óo gbé ọ jù sinu aṣálẹ̀, ìwọ ati gbogbo ẹja inú odò Naili rẹ.
Kò pẹ́ púpọ̀ tí mo ń yí igbó kiri tí òjò ńlá bẹrẹ̀ sí rọ̀ bẹ́ẹ̀ ni n kò ì tí ì dé ibùdó, mo sì sá pamọ́ si inú ihò kékeré kan .
Dokita Osagie ṣalaye awọn eeyan ti ijọba kọkọ ran lọ si ipinlẹ Kogi kuna nitori ede-ai-yede to ṣẹlẹ laarun awọn eeyan naa ati ijọba ipinlẹ Kogi.
O ni awọn yoo tako idajọ naa.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ọmọ ẹgbẹ́ òkùnkùn ṣoro ní Ijebu Ode, ọ̀pọ̀ ẹ̀mí sọnù Àlàyé rèé lórí ìdí tí mo fi lọ sílé Tinubu - Rashidi Ladoja ‘Sim Card’ títà àti ìforúkọsílẹ̀ rẹ̀ dèèwọ̀ ní Nàíjíríà - NCC Ààrẹ Akufo-Addo la Mahama mọ́lẹ̀ wọlé ìbò ààrẹ Ghana fún sáà kejì Ẹ̀yin tí ẹ máa ń bú àwon tó sanra ni ẹ ń jẹ́ kí wọ́n ronú pa ara wọn - Eniola Badmus Ilé aṣòfin kò láṣẹ kankan láti pe ààrẹ Buhari wá rojọ́ lórí ọ̀rọ̀ ètò àbò - Malami Ṣé lóòtọ́ ni tírélà ti gba ààrín Ronke Odusanya àti bàbá ọmọ rẹ̀, Jago?
Day 24: Ǹjẹ́ O lè dìbò fún olùdíje tí àlùfáà tàbí ìmámù rẹ́ bá yàn?
Awọn eniyan si n fi fidio bi wọn se da silẹ ni ihamọ ọlọpaa ni bi aago kan aabọ oru.
Lonii yii, ko si ibi kan ti iko Boko Haram ti n sako so mọ.
Oríṣun àwòrán, Instagram/teamwumitoriola Wunmi lo tun mu isẹ pipo ipara ati ọsẹ iwẹ to n bora mọ isẹ tiata lati ri taje se, to si fi orukọ ara rẹ pe idamọ eroja ipara to n ta.
"Ẹ ni suuru, ẹma fa rogbodiyan, to ba jẹ pe lootọ lẹ́ ni ifẹ́ mi, mo bẹ yin ni, ẹ mase jo ọkọ ijọba to wa nilẹ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ó di dandan kí ará India yìí sọ ìdí tó fi ń sìn kìnìhún- Egbeyemi Aṣofin Gudaji Kazure lọsẹ to kọja ti kọkọ bu ẹnu ẹ̀tẹ́ lu iye owo ti wọn kọ fun eto iṣuna naa, to ni iye owo naa ti pọju paapaa lasiko yii.
Ètò ìpìlẹ̀ kan wà tí ó ń pàṣẹ tí ó sì ń rẹ àwọn obìnrin sílẹ̀ sí ipò ẹ̀yìn tí èyí sì sọ wọ́n di olùfaragbá ìjìyà lóríṣiríṣi àti ní gbogbo ọ̀nà.
Iròyìn ni pé, àisan ọkàn náà lo pa òun náà.
Ó ti fi agbára iṣẹ́ rẹ̀ han àwọn eniyan rẹ̀,nípa fífún wọn ní ilẹ̀ àwọn orílẹ̀-èdè mìíràn.
OLUWA, ranti ohun tí ó ṣẹlẹ̀ sí wa,Ṣe akiyesi ẹ̀sín wa.
Tsoho ni awọn eniyan maa n pe omi naa ni Wawar rafi to tumọ si omi omugọ, lẹyin igba diẹ ni awọn eniyan bẹrẹ si ni pe ilu naa ni ilu awọn omugọ titi ti o fi di baraku.
Bakan naa nijọba tun koro oju si iwuwa si El-Zakzaky nigba to wa ni orilẹede India.
Bẹẹ ba gbagbe o ti to ọjọ melo kan ti igbẹjọ naa ti bẹrẹ nipa ẹsun ti wọn fi kan Pasitọ Alfa Babatunde, tii se asaaju ijọ Sotitobi rẹ nilu Akure, lori bi Gold Kolawole, ọmọ ọdun kan se di awati ninu ijọ rẹ.
Àwọn tí ń ṣe ìfẹ́ ẹran-ara wọn kò lè sin Ọlọrun.
Èmi ni Ọlọrun,láti ìsinsìnyìí lọ, Èmi ni.
Lati 1948 ni wọn ti n fun adari ọmọ ogun America ni tolotolo meji ṣaaju idupẹ naa ni eyi ti aarẹ yoo si gba ọkan ninu wọn la gẹgẹ bi aṣa.
Ó fi egungun náà mọ obinrin kan, ó sì mú un tọ ọkunrin náà lọ.
Ó ní, ‘Kọniliu, Ọlọrun ti gbọ́ adura rẹ, ó sì ti ranti iṣẹ́ àánú rẹ.
Ẹ máa là kàkà àti lọ síwájú nínú ohun rere gbogbo, ṣùgbọ́n ẹ má ṣe máa na ọwọ́ sí ohun tí ọwọ́ yín kò lè tó.
Ẹ̀wẹ̀ a lè rí àwọn ìdí tó le mú ọ̀rọ̀ òfin dáni, kí ó mú ewu dáni fún ọlọdani tàbi kí o ma ba ìlànà tí àn gba ṣe iṣẹ́ ìròyìn ni BBC ti a ko si le ṣe àtúnṣe si, à ki a yọ.
re, ni ile idibo to wa ni Ajia ni ipinle Adamawa, lojo Abamẹta yii.
Lẹ́yìn náà wọ́n ranṣẹ sí Jesebẹli pé àwọn ti sọ Naboti lókùúta pa.
Ọjọ Keji, Oṣu Kejila ni awọn agbofinro ni awọn ri Maina mu ni orilẹede Niger Republic lasiko to n tiraka lati sa kuro lorilẹede Naijiria, ki ajọ EFCC to gbe pada si Naijiria.
Nígbà tí ó dé ibẹ̀, ó ní, “Mo fẹ́ wọlé lọ bá iyawo mi ninu yàrá.
Ko si ǹkan to jọ Corona Virus ni Ivory Coast.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Òjò àrọ̀ọ̀rọ̀dá: Àwòrán káàkiri ìlú arómi-sá-lẹ̀gbẹlẹ̀gbẹ 20 Èbibi 2019 Iṣẹ́ òòjọ́ ṣebi ẹni dẹnu kọlẹ̀ l'Ékòó pẹlu ayagbayamu ojo to rọ lowurọ ọjọ aje.
m ni ojú mi déédé fọ́ níbi tí mo ti ń darí ọkọ̀ ni Ọrẹgun Ikẹja -LASTMA Yesufa Mo ti kó kúrò nílé Olu Jacobs rí lẹ́ẹ̀mejì- Joke Silva Ẹgbẹ Shiite tun tẹnumọ ipinnu rẹ lati wa ọna abayọ miran lati yanju isoro ọlọjọ pipẹ to n koju wọn ọhun, ti wọn si tun n beere fun itusilẹ asaaju wọn, iyawo rẹ ati ọpọ ọmọ ẹgbẹ Shiite miran to wa ni ahamọ, ti wọn si fi ẹtọ si ominira dun wọn lati ọdun 2015.
O ni o yẹ ki awọn eeyan maa ṣe iwadii ni kikun lori ọrọ ki wọn to bẹrẹ ahesọ to le da ẹbi, ilu tabi ipinlẹ ru bi eyi ti wọn n sọ lori Mọsalaṣi naa, eyi to jẹ irọ funfun balau.
Olori ajọ NIPRD, Dokita Obi Adigwe, sọ fun BBC pe iwadii ti a ṣe fihan pe agbo naa ni agbara lati mu ki eeyan hu ikọ jade, to si tun din iba ku lara awọn ẹranko ti wọn ti dan-an wo."
Àmọ́ ẹ̀rù ò b’odò, ibi líle làá ba ọkùnrin.
wọ́n kó gbogbo obinrin ati àwọn tí wọ́n wà níbẹ̀ lẹ́rú, àtọmọdé, àtàgbà, wọn kò sì pa ẹnikẹ́ni.
Ara mi sì ti yípadà, mo ti ń di pupa, eyín mi sì ti ń di funfun.
Bí a ti ń súnmọ́ o ni a rí ti gbogbo igbó púpa yòò, tyi ibi gbogbo lápá ọ̀tún àti lápá òsì pa lọ́lọ́, àti ewé àti ẹeka igi àti ìtànná àti eso wọn gbogbo ló pupa ko sí ẹ̀dá alààyè kan ṣoṣo, ẹyẹ kò ké, ọ̀kẹ́rẹ́ kò gun igi, labalábá kò tilẹ̀ fò kọjá, bẹ́ẹ̀ a kò gbúròó esinsin.
 Idowu je omo bibi Russia ati Naijiria, Musa n kopa fun iko agbaboolu CSKA Moscow.
N kò sọ fún arọmọdọmọ Jakọbu pé:‘Ẹ máa wá mi ninu rúdurùdu.
” Bẹ́ẹ̀ ni obinrin náà ṣe gba ọmọ, ó sì ń tọ́jú rẹ̀.
Ṣugbọn mo sọ fún ara mi pé,“Ìyà gan-an ni èyí jẹ́ fún mi,mo sì gbọdọ̀ fara dà á.
Lára wọn ni ìròyìn kan tó sọ pé Àlámòjútó ìjọ Ìràpadà Krístì (RCCG), Enoch Adeboye, bẹ adarí ẹgbẹ́ òṣèlú All Progressives Congress, APC, Bọla Tinubu, láti fàáyè gba gómínà ìpínlẹ̀ Eko, Akinwumi Ambọde láti dupò gómìnà lẹ́ẹ̀kan si i.
Leralera lawọn eeyan n fẹsun kan awọn ologun pe wọn ṣe iranwọ owo ati nkan ija fawọn ẹgbẹ okunkun lati le doju ija kọ awọn to n pe fun Ijọba alagbada.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Igbesẹ tita bata naa si lo bọ si akoko ti Ileesẹ Netflix gbe akanse ẹkunrẹrẹ fọnran aworan iroyin kan sita, to pe akori rẹ ni - The Last Dance.
"Ṣùgbọ́n bi ǹkan ṣe ń lọ báyìí à ń wo bí yóò ṣe kan àwọn kíláàsì to ku, èyí sì ni à ń ṣètò lọ́wọ́ ""Àwọn nkan míràn ti a tún n ṣe ni láti máa fún àwọn olùkọ́ wa ní ìmọ̀ nípa bí a ṣe n kọ́ akẹ́kọ̀ọ́ ní orí ayélujára àti láti mú kí àyíká ilé ẹ̀kọ́ ṣeé lò, ti gbogbo àwọn ǹkan wọ̀nyí bá ti délẹ̀ a ó jẹ́ kí ará ilú mọ̀."
Àwọn aládùúgbò wọn fi ohun èlò fadaka ati ti wúrà, ati dúkìá, ati ẹran ọ̀sìn, ati àwọn nǹkan olówó iyebíye ràn wọ́n lọ́wọ́, yàtọ̀ sí àwọn ọrẹ àtinúwá.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ahmed Musa padanu ìyá rẹ̀ lẹyin aisan ranpẹ 24 Sẹ́rẹ́ 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 25 Sẹ́rẹ́ 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ahmed Musa dabira Nàìjírìa nínú ìdíje ife ẹ̀yẹ àgbáyé lorílẹ́èdè Russia Agbabọọlu ọmọ Naijiria Ahmed Musa ti padanu iya rẹ bayi.
" nínú ẹsẹ ifá a lè rí ohun tí o jọ bayin "" ."
Àwọn ìròyìn mìíràn tí ẹ lè nífẹ̀ẹ́ sí: Ọba Adesoji Aderemi, Ọọ̀ni Ifẹ̀ tó gba ipò ọba mọ́ tòṣèlú Àìle è ka kéú ló sọ mí di Krìstíẹ̀nì - Adewale Ayuba Háà!
Bí mo bá ń wáyé nígbà igba, Olùkọ́ ni n ó yà fáàbàdà.
” Ni Tabita bá lajú, ó rí Peteru, ó bá dìde jókòó.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù 2023 Presidency: Adelé alága APC l'Eko ní àdéhùn wà láàrín Buhari àti Tinubu lórí ìdíje ipò ààrẹ lọ́dún 2023 13 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Oríṣun àwòrán, Facebook/Asiwaju Bola Tinubu Adele alaga ẹgbẹ oṣelu APC nipinlẹ Eko, ọgbẹni Tunde Balogun ti ṣalaye pe aarẹ Muhammadu Buhari, Asiwaju Bola Tinubu atawọn eekan mii ninu ẹgbẹ jọ ṣe adehun lọdun 2014 pe apa iwọ oorun Gusu ni oludije fun ipo aarẹ lọdun 2023 yoo ti wa.
Níbẹ̀ ni Aaroni óo kú sí.
Ìpínyà pẹ̀lú baba-Onírùngbọ̀n-yẹ́úkẹ́ ẹni tí ń gbé ibi gegele òkúta
Abenugan ile igbimo asofin wa so pe , o seni laaanu pe igbese pajawiri ti awon n gbe nipa eto idibo odun to n bo ko dara to.
Ọgbọ́n ọmọ ènìyàn ni ó fi ṣe ọkọ̀ orí-ìlẹ, ti orí-omi àti ti òfúrifú fún ìrìnkèrindò tí ó rọrùn.
Gẹgẹ bi ohun to sọ fun BBC, Zarka ni oun ko mọ pe ijiya pọmbele ni ipadabọ oun sile ọkunrin naa yoo jẹ.
Wọn yóo jó ilé Esau;àwọn ìran Esau yóo jó àjórun láìku ẹnìkan;nítorí pé OLUWA ló sọ bẹ́ẹ̀.
ṣugbọn òun óo rán àwọn oníṣẹ́ òun sí i ní ìwòyí ọ̀la láti yẹ ààfin rẹ̀ wò ati ilé àwọn oníṣẹ́ rẹ̀, kí wọ́n sì kó ohunkohun tí ó bá wù wọ́n.
Bí mo ṣe ń dàgbà ni ǹkan ọmọkùnrin mi ń tóbi síi àmọ́ obìnrin ni mi' Àwọn tó jí mi gbé ti fẹ́ẹ̀ pa mí, kí àwọn ọlọ́pàá tó dóòlà mi - Agbẹjọ́rò Bisola Ajayi Ọlọ́pàá f'ẹsẹ̀ fẹ́ẹ l'Eko lẹ́yìn tó ki ìbọn bọ ọ̀rẹ́bìnrin rẹ̀ lẹ́nu tó sì yìn ín Iroyin sọ pe lẹyin ti awọn ọlọpaa naa yinbọn si aarin awọn oluwọde ni awọn ọdọ naa gba ẹsan nipa pipa ọlọpaa naa.
16 Àti pé kíyèsíi, ẹnikẹ́ni tí ó bá gba àwọn ọ̀rọ̀ mi gbọ́, àwọn ni Emi yíò bẹ̀wò pẹ̀lú ìfarahàn Ẹ̀mí mi; wọn yíò sì di àtúnbí nípasẹ̀ mi, àní nípasẹ̀ omi àti Ẹ̀mí—
Amọ, o parọwa si awọn ọdọ lati mu isẹ wọn ni ọkunkundun, ti wọn si jẹ ki ọro ilu naa ka wọn lara lati le mu igbelarugẹ ba orilẹede Naijiria.
Gẹgẹ bi o se sọ, “ A
Láti ìgbà náà ni Pilatu ti ń wá ọ̀nà láti dá Jesu sílẹ̀.
Ṣaa ti ṣafihan ẹri pe kii ṣe pe lailai ni iru ẹni bẹe fẹ maa gbe ilẹ naa.
92 trillion) eyi to ti sọ aba owo iṣuna naa di lilo bayii.
"Oríṣun àwòrán, Facebook/Engr Remi Olaniyan Amọ, Amoju-ẹrọ Olaniyan sọ fun BBC pe, ""ohun to ba wu onikaluku lo le fi ẹnu rẹ sọ nitori ijọba awaarawa lo wa lode."
” OLUWA dáhùn pé, “Bí mo bá rí ọgbọ̀n olódodo, n kò ní pa ìlú náà run.
Ẹgbẹ Afẹnifẹre to n soju ọmọ Yoruba lapapọ ti ni awọn le oludije sipo gomina labẹ ẹgbẹ oselu SDP, Sẹnetọ Iyiola Omisore fun ọdun kan nitori ko fi inu han wọn lasiko idibo sipo gomina to waye ni ipinle Osun.
Buhari, pe ìpàdé àpérò ọmọ Nàíjíríà fún àgbékalẹ̀ òfin tuntun - Afe Babalola A ṣetán láti ran àjọ aláàbò alájùmọ̀ṣe lọwọ fún ààbò tó péye nílẹ Yorùbá - Ọlọ́pàá Ogun Nínú gbèsè Nàíjíríà, ₦121,000 ló kàn ẹnìkọ̀ọ̀kan, ṣó o ṣetán láti san tìẹ?
Tori na lati dẹrẹba Danfo to n na Ojo si Mile 2 l'Eko, wọn di ọkan lara awọn olorin ọmọ Naijiria lati Ajegunle ti awọn eniyan ti awọn eeyan si ti mọ lagbaye.
“Bí ẹni náà bá jẹ́ talaka tóbẹ́ẹ̀ tí kò lè san iye tí ó yẹ kí ó san, mú ẹni tí ó fi jẹ́jẹ̀ẹ́ wá sí ọ̀dọ̀ alufaa kí alufaa díye lé e gẹ́gẹ́ bí agbára ẹni tí ó jẹ́jẹ̀ẹ́ yìí.
Oríṣun àwòrán, Ayokunle Oladeji sàlàye pé, ó ṣeni láànu pé, sọ́ọ̀sì nìkan ni ìjọba n kọjú sí lórí títèlé àlàálẹ̀ òfin Covid-19, bí ó ti lẹ̀ jẹ́ pé gbogbo òfin yìí ni àwọn ìjọ ń tẹ̀lé.
" O tun tẹsiwaju pe ti waasi ita gbangba ba wa lasiko aawẹ Ramadan, ọkọọkan wọn yoo mu to ẹgbẹrun lọna ogun naira lọ sile, sugbọn o ni Covid-19 ko jẹ ki waasi aawẹ ṣee ṣe lọdun yii, eyi to lee mu ki owo wọn to na.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 2020: Ọdun 2020 yii ko nìí nira fún àwọn tó bá bẹ̀rù Olorun Àwọn òṣèré tíátà kan rèé, tí wọn fẹ́ ara wọn, tí ìgbeyàwó wọn sì pẹ́ Ọlọ́pàá ilẹ̀ Yorùbá 'Àmọ̀tẹ́kùn' ṣetán láti bẹ̀rẹ̀ iṣẹ́ káàkiri ilẹ̀ káàrọ́ọ̀ oò jíire Ògo tuntun yóò sọ ní ọdún 2020!
Inú sì ń bí mi gidigidi sí àwọn orílẹ̀-èdè tí wọ́n dákẹ́ jẹ́ẹ́ tí wọ́n sì wà ní alaafia; nítorí pé, nígbà tí mo bínú díẹ̀ sí àwọn eniyan mi, wọ́n tún dá kún ìṣòro wọn ni.
 Òkò ni olú ìlú wọn .
OLUWA Ọlọrun ní, “Ìwà ìtìjú rẹ ti hàn sí gbangba, o bọ́ra sí ìhòòhò níta, nígbà tí ò ń bá àwọn olólùfẹ́ rẹ ṣe àgbèrè, tí ò ń bọ àwọn oriṣa rẹ, o sì pa àwọn ọmọ rẹ, o fi wọ́n rúbọ sí àwọn oriṣa.
Lori ibaṣepọ rẹ pẹlu awọn olori to ku ni Aafin Oyo, Folashade sọ pe, kii ṣe pe awọn kii ja o, ṣugbọn eto ti wa nilẹ laarin awọn olori lati pari ija naa, lai jẹ pe Alaafin gbọ si.
Bukola Saraki kò kọjá òfin - EFCC Tottenham vs Ajax: Láti òní lọ,Lucas 'Miracle' lòó má jẹ!
Kí ẹ̀yà Isakari pàgọ́ tẹ̀lé ẹ̀yà Juda; Netaneli ọmọ Suari ni yóo jẹ́ olórí wọn.
Ó yẹ kí ẹ fara balẹ̀ nígbà náà; kí a má fi ìwàǹwára ṣe ohunkohun.
ijo jijo san ju ka lu owo ilu ni ponpo lọ"" Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Adeleke fọhùn, 'èmi ni gómìnà tí wọ́n dìbò yàn' O wa ranṣẹ ọrọ si Oyetọla pe, ""Jẹ ki n ran Oyetọla leti pe iwe rẹ gẹgẹ bii olori awọn oṣiṣẹ fun Rauf Arẹgbẹṣọla fihan gbangba peko kun oju iwọn gẹgẹ bii alakoso, ṣugbọn o jafafa ninu ka lu owo ilu ni ponpo."
OsunDecides: Omisore ní ẹni tó bá fẹ́ ra ìbò, àwọn yóò lọ lásọ mú ni
Anthony Joshua vs Andy Ruiz Jr: AJ lóun ṣetán láti kojú Ruiz nínú ìjà ọjọ́ Sátidé
Ile la n wo ni ilẹ Yoruba ki a to sọ ọmọ lorukọ!
awon omo ipinle naa bi won se dibo  gomina ati ile igbimo asofin ipinle ni irọwọ
Oríṣun àwòrán, Twitter Ogunyonwo ni ọga agba ọlọpaa ti gba iṣẹ lọwọ awọn ikọ Zonal Intervention Squad, Obada-Oko ni ipinlẹ Ogun to wa ni idi iṣẹlẹ iṣekupani naa.
Ọlọ́pàá ti mú ẹni márùn ún lórí ìjà láàrin Hausa àti Yorùbá l'Eko Ọ̀pọ̀ èèyàn bẹnu ẹ̀tẹ́ lu Mercy Aigbe lórí bó ṣe ki Adeniyi Johnson Ọlọ́pàá Ogun gb'ọmọ Ìmáàmù lọ́wọ́ ajínigbé, ṣùgbọ́n wọ́n gbé ọkọ̀ ojú omi ọlọ́pàá lọ Mo dáríjì àwọn IPOB tó nà mí ní Germany nítorí wọn o m'ohun tí wọ́n ń ṣe- Ekweremadu Aare Muhammadu Buhari to n tukọ orilẹ-ede Naijiria naa ti gboṣuba rabandẹ fawọn olu ọmọ wọnyii pe wọn gba ife ẹyẹ naa lẹẹkan sii.
Amaju Pinnick: Ìjọba Naijiria bèrè bó ṣe ná $8,400, N4bn
Ọ ̀ pọ ̀ lọpọ ̀ ni ẹsẹ ifá tí o jẹ mọ Ẹ ̀ sù .
Àgbà olórin, Victor Olaiya jáde láyé.
" Àwọn ohun tó wòye pé ó n ba ètò ẹ̀kọ́ Nàìjíríà jẹ́ nìyíì.
Ó ní ''ó ṣe pàtàkì kí ẹ mọ́ pé kò sí ẹjọ́ El-Zakzaky lọ́wa ìjọba apapọ̀ mọ́ sùgbọ́n ọwa ìjọba ìbílẹ̀'' ìjẹ́jọ tó ba tí niṣe pẹ̀lú ìpànìyàn, ìjọba kìí gba oníduro, èyí ló sokùnfa ti El-Zakzaky àti ìyàwó rẹ́ ṣe n gbà ààyẹ nítori ìlera wọ́n July 22, 2019 Igbákejì Kọmisọna ọlọpàá,Umar Umar, òṣìṣẹ́ Channels, Precious Owolabi, àti àwọn ọmọ IMN tí wọ́n pa lásìkò ìwóde tí o pada yìí sí wàhálà July 29, 2019 Adájọ Darius Khobo ti ilé ẹjọ́ gíga ti Kaduna tún sún ìgbẹ́jọ sí ọjọ́ ọsùn kẹ́jọ ọdún 2019, ti El-Zakzaky àti ìyàwó rẹ̀,wọ́n si tọrọ́ ààyè láti lọ fún ìwòsàn ní orílẹ̀-èdè India.
Awọn ọmọ ogun ọrẹ korikosun wọya ija, ti apa Timi si n lewaju, eyi to mu ki awọn ọmọ ogun Gbọnka sa sẹyin fun igba meji, lẹyin o rẹyin, wọn pinnu pe awọn olori ogun mejeeji ni ki wọn koju ija sira wọn, kawọn lee mọ ẹni ti yoo sẹgun Gbọnka, gẹgẹ bii jagunjagun to ni oogun, pasẹ pe ki Timi sun lọ fọnfọn lasiko ija naa, to si di i tọwọ tẹsẹ lọ silu Ọyọ.
Owó gọbọi wá nídìí oko-owo igbó gbingbin, Ìpínlẹ̀ Ondo kò ní pẹ gba àṣẹ láti gbin - Akeredolu Gómìnà Ṣèyí Mákindé ó ní ìdí tí òun kò fi leè ti ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́ pa nítorí COVID-19 Ọlọ́run ló kọọ pé àwọn ọmọ mi yóò ṣiṣẹ tíátà, èmi kọ lo kàn-án nípa fún wọn - Ọga Bello Eyi ti sun iye awọn to ti lugbadi arun naa siwaju di ẹmejilelaadọtadinlẹgbẹjọ.
O ni ariwo ile to n wo ni gbogbo igba, eyi to gbalẹ nipinlẹ Eko ati awọn ilu miran fi han wi pe, isẹkisẹ ni awọn akọle ma n se.
Wọ́n gbìyànjú àti yí Olódùmarè padà kúrò nínú ìpinnu tẹ̀ ṣùgbọ́n kò ṣe é ṣe.
Oríṣun àwòrán, Reuters Àkọlé àwòrán, DR Congo: Ọ̀pọ̀ ẹmí lo ti sọ́nu ni ìjàmba ọkọ ofurufú to waye lóòní Nkan to fa idi abájọ ko tii dájú títí di àsìkò yìí, sùgbọ́n àwọn kan sọ pé ẹnjini bàálù ló ni isoro ni kéte to gbéra, eyi ni akoroyin BBc Emery Makumeno sọ pe ẹnikan sọ ni Kinshasha.
Awọn kan tiẹ tun sọ pe ilu London lo salọ.
O so pe, bo ti wu ki isoro ti o koju orile-ede ohun po to, agbara ajinde Jesu Kirisiti yoo yanju gbogbo re laiku kan.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Bode George: òòtọ́ ni ìkìlọ̀ Obasanjọ ati Soyinka @LekeOluseyi tiẹ sọ pe otitọ to wa nibi ọrọ yii ni pe minisita ti na owo ọhun ni.
Buhari àti ọ̀ga àjọ NHIS, kí ló pa wọ́n pọ̀?
Oríṣun àwòrán, Instagram/nkechiblessingsunday O ni gbogbo eeyan lo mọ pe Ọlọrun pari iṣẹ si ẹyin oun, o ni awọn to ni ipenija oju kan to ba sun mọ oun le mọ bi ikebe oun ṣe tobi to.
to ṣe nigba ti Godwin Odiye fori gbe bọọlu wọnu awọn Naijiria lọdun 1977.
Ẹni tó bá ń bínú kàn ń bínú lásán ni
Coronavirus: Àwọn ohun tí a kò tíì mọ̀ nípa àrùn Covid-19 Ǹjẹ́ oòrùn leè pa àrùn Coronavirus bí?
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Ajayi: ṣé ìwọ mọ irúfẹ́ ọmọ tí Yorùbá ń pè bẹ́ẹ̀?
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ayọ̀ abara bíńtín!
‘Buhari kò bú àwọn ọdọ’ 'Shehu Shagari dáríji Buhari kó tó kú' Awọn miran tun ni: Chris Ngige fun ipinlẹ Anambra Godswill Akpabio fun ipinlẹ Akwa Ibom Rotimi Amaechi fun ipinlẹ Rivers Festus Keyamo fun ipinlẹ Delta Baba Shehuri fun ipinlẹ Borno Uche Ogah Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Okunrounmu: Ijọba Buhari jẹ ijiya Ọlọrun fun Naijiria Emeka Nwajuiba Sadiya Farouk Hadi Sirika Sharon Ikeazor Akpa Udo Dr.
Nítorí náà, ní kété tí ẹ bá gba ìwé yìí, 
Komisona yii salaye pe: “Ijoba Gomina Akinwunmi Ambode ti bere igbese lati mu idagbasoke ba eto oro-aje ipinle Eko nipase irinajo-afe ati afihan asa lorisiirisii bii ti ayeye Wazobia afihan asa ti o sele yii.
Nígbà tí ó sùn, ó lá àlá kan, ó rí àkàsọ̀ kan lójú àlá, wọ́n gbé e kalẹ̀, orí rẹ̀ kan ojú ọ̀run.
28 Ọ̀wàrà 2019 Oríṣun àwòrán, AFP / Getty Àkọlé àwòrán, Kurt sweater: Wo aṣọ òjò tó wọ́n jùlọ ní àgbáyé!
Bakan naa lo kọ pe irọ ni pe awọn ọlọpaa mu oun lasiko to fi wa lọdọ wọn.
láti ẹni ọgbọ̀n ọdún títí dé aadọta ọdún, gbogbo àwọn tí wọ́n lè ṣe iṣẹ́ ìsìn ati iṣẹ́ ẹrù rírù ninu Àgọ́ Àjọ 
Bakan naa ni o maa n fun awọn ọmọ Naijiria ni anfani ọgbọn ọjọ ki wọn to gba iwe aṣẹ igbelu.
Naara bí ọmọ mẹrin fún un: Ahusamu, Heferi, Temeni, ati Haahaṣitari.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Olusegun Obasanjo: Ọmú ìyá mi ti mo fi ń mùkọ ni kekere ló jẹ ki ń lókun Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Wọ́n ń kígbe pé, “Ẹ dúró!
Àkókò ẹkún wà, àkókò ẹ̀rín sì wà;àkókò ọ̀fọ̀ wà, àkókò ijó sì wà.
Ileeṣẹ naa wa sọ pe ọrọ naa kii ṣe eyi ti ileeṣẹ ologun le sedajọ rẹ, nitori naa ni wọn ṣe faa le ileeṣẹ ọlọpa lọwọ lati gbe ẹni to fi ọkọ gba Arotile lọ sile ẹjọ.
“Kọ ìwé yìí sí angẹli ìjọ Filadẹfia pé:“Ẹni mímọ́ ati olóòótọ́ nì, ẹni tí kọ́kọ́rọ́ Dafidi ń bẹ ní ọwọ́ rẹ̀, tíí ṣí ìlẹ̀kùn tí ẹnikẹ́ni kò lè tì í, tíí sìí tìlẹ̀kùn tí ẹnikẹ́ni kò lè ṣí i, ó ní: 
CBN: owó oníbara tó ha si ATM kò gbọdọ kója wákàtí 24
Ọlọrun ní, “Ẹ̀yin eniyan mi, kí ni mo fi ṣe yín?
Awọn ẹgbẹ oṣelu to wa nibi apero naa pẹlu ko sai rọ àwọn orileede agbaye lati mase kọpakọ si bi eto idibo àpapọ ọdun 2019 yóò ṣe lọ lorileede Naijiria.
Awọn eeyan to to ẹgbẹrun lọna ọtalelẹẹdẹgbẹta lo ti ku lati ipasẹ arun Coronavirus.
Ile ẹjọ giga ipinlẹ lo pada rọ ọ loye bayii, lọjọ Keji, oṣu Keje, ọdun 2020.
Wo ọ̀pọ̀ àsọtẹ́lẹ̀ igba tí Primate Ayodele gbé síta fọ́dún 2021 A ri pe ọkan lara awọn mọto to wa niwaju wa duro lojiji, tawọn gende agbebọn to jade lati inu igbo tiiki to wa laarin ilu mejeeji yii si yọ ibọn sawọn ero to wa ninu mọto naa."
Fídíò BBC yọ àwọn èèyàn FIFA níṣẹ́ ṣááju Russia 2018
Jesu tún fi òwe bá wọn sọ̀rọ̀.
"Bí ẹgbẹ́ One Million Boys ṣe bẹ̀rẹ̀ rèé àti ọṣẹ́ tó ṣe n'Ibadan 'Mo máa ń ta sí Tolu pé ""ọjọ́ wo ni wàá tó gà'- Musa, Ọ̀rẹ́ àti kékeré Kí ló mú Obasanjo ti ilẹ̀kùn mọ́ ẹbí, òṣìṣẹ́, ojúlùmọ̀ ní ibi òkú àna rẹ̀?"
Ọgbẹni Gaidam tun seranti irufẹ isẹlẹ yii kan naa to waye ni ileewe miran nipinlẹ naa lọdun 2014 nigbati awọn agbebọn naa du ọpọ akẹkọ ọkunrin lasiko ti wọn fi n sun ni yara wọn.
Ẹ mọ́kàn, ẹ má bẹ̀rù,nítorí ìròyìn tí ẹ̀ ń gbọ́ nípa ilẹ̀ náà,nígbà tí ẹ bá gbọ́ ìròyìn kan ní ọdún yìí,tí ẹ tún gbọ́ òmíràn ní ọdún tí ń bọ̀,tí ìwà ipá sì wà ní ilẹ̀ náà,tí àwọn ìjòyè sì ń dojú ìjà kọ ara wọn.
Nibayii, oju opo Twitter ti n yeruku lala lori iroyin pe oogun Chloroquine dara fun itọju aarun coronavirus.
' Ìpínlẹ̀ Ogun, Eko ti gbáradì fún ẹ̀kún omi yalé Dokita Ayinde Akinsanya to jẹ akọwe agba fun ileeṣẹ ijọba ipinlẹ Ogun to n ri si eto ilera ṣalaye fawọn akọroyin ni ọjọ Ẹti pe, Obinrin kan ni iṣẹlẹ akọkọ ti wọn kẹfin.
Ninu ọrọ ti wọn ba BBC News Yoruba sọ, awọn obi kan ni awọn ko ni ẹgbẹrun marundinlọgbọn naira lati san, ati pe awọn ko lee gba ki ọmọ awọn la wahala ti ayẹwo naa lee ko ba ironu awọn akẹkọọ.
Ọ̀gbẹ́ni Mugabe nínú ìfọ̀rọ̀wánilẹ́nuwò kan lórí ẹ̀rọ móhùnmáwòrán ti ìpínlẹ̀ kan fi ẹ̀sùn lílo àlùmọ̀kọ́rọ́yí fi jalè kan ilé isẹ́ tó ńrísí ọ̀rọ̀ ilẹ̀ òkèèrè.
Josẹfu jẹ́ ọmọ ọgbọ̀n ọdún nígbà tí ó bẹ̀rẹ̀ iṣẹ́ lábẹ́ Farao, ọba Ijipti.
Ọrọ miran tun ti n rugbo bọ nidile aarẹ orileede Naijiria Muhammadu Buhari pẹlu bi iyawo aarẹ Aisha Buhari ti se ke gbajare si ọga ọlọpaa lati tu awọn ẹsọ oun silẹ ki wọn ma ba lugbadi Covid-19 lọdọ wọn.
Ó gbọ́ ìró fèrè ṣugbọn kò bìkítà, nítorí náà orí ara rẹ̀ ni ẹ̀jẹ̀ rẹ̀ yóo wà.
Jesu dá wọn lóhùn pé, “Bí mo bá ń jẹ́rìí ara mi, sibẹ òtítọ́ ni ẹ̀rí mi, nítorí mo mọ ibi tí mo ti wá, mo sì mọ ibi tí mò ń lọ.
Bíọlá ni orúkọ ẹni tí ó ń ta ọtí Lóòótọ́, oníṣèègùn ni Ọ̀sanyìnnínbí síbẹ̀, kò wọ ẹgbẹ́ àwọn Oníṣèègùn tí orúkọ rẹ̀ ń jẹ́ Ẹgbẹ́ ìlera loògùn Ọrọ̀.
Miliọnu kan naira nileeṣẹ to ba fiya jẹ àkàndá ẹ̀dá a san lówó ìtanràn
Aarẹ Buhari ni iwe itan yoo sọ itan rere nipa awọn ọmọ ẹgbẹ APC lọjọ iwaju, ti onikaluku ba gbiyanju lati ri pe APC fẹsẹ mulẹ lẹkun wọn.
Eniyan marun si ti wa nile iwosan bayii.
seleri pe ijoba re ko ni dojuti won laarin odun merin ti  yoo lo.
Ọọni kede ọrọ yii lasiko to n gbalejo awọn ọmọ igbimọ alasẹ ẹgbẹ awọn eeyan to n seto irinajo afẹ ni Naijiria (NATOP), eyi ti aarẹ wọn, Bilikisu Abdul ko sodi, ni aafin rẹ.
 Ó tún mú kí àwon ará ìlú ni ìgbèkèlé nínú ìjòba alápapò .
Èmi ò ní báwọn kú pipìpi bí adìyẹ
Àsìkò tó láti dóòlà Nàíjíríà, a ti gbé ẹ̀ṣùn ìbò lọ sílé ẹjọ́ tó ga jùlọ - PDP ASUU ṣèpàdé pẹ̀lú ilé aṣòfin l'Abuja lórí fáàkája IPPIS pẹ̀lú ìjọba Ambode, wá sọ tẹnu rẹ lọ́jọ́rùú lórí owó àwọn àkànṣe iṣẹ́ to ná - Ilé aṣòfin Eko Adigunjalè fa ìjàmbá ọkọ̀ lọ́nà Ijẹbu Ode sí Ṣagamu, èèyàn mẹ́wàá dèrò ọ̀run Gomina ipinlẹ Borno, Babagana Zulum, Abubakar Bagudu ti ipinlẹ Kebbi ati Aminu Bello Masari ti ipinlẹ Katsina ni yoo kọwọ rin pẹlu aarẹ.
O ṣalaye pe abọ ounjẹ kan ati ẹẹdẹgbẹta naira ni oun n gba lori ọkọọkan awọn eeyan mẹfa to pa lagbegbe naa.
Ma se bọkan jẹ ninu gbogbo wahala idejumọle to wa nita yi, awọn to fi imọran sọwọ siwa ni ki a gba kamu ka si ma se ba ara wa lọkan jẹ.
Jeremaya jáde ní Jerusalẹmu ó fẹ́ lọ sí ilẹ̀ Bẹnjamini kí ó lọ gba ilẹ̀ rẹ̀ kan lọ́wọ́ àwọn eniyan tí wọ́n wà níbẹ̀.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Africa Eye: Ìjìjàgbara fún àwọn ọmọdébìnrin tó wà lọ́wọ́ ewu Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Africa Eye: Ìjìjàgbara fún àwọn ọmọdébìnrin tó wà lọ́wọ́ ewu 29 Sẹ́rẹ́ 2020 Ikọ ọtẹlẹmuyẹ Africa Eye tun de orilẹede Congo nibi to ti finmu finlẹ nipa igbe aye awọn ọdọbinrin ti wọn dagba soju popo.
Aarẹ Buhari nigbagbọ pe oloogbe Katsina-Alu ti fi imọ, oye ati ẹmi ifọkansin  silẹ fun awọn   adajọ to n bọ  lọna  lati tẹle.
Brighton vs Arsenal: Dákúdájí Arsenal tún paná pii lẹ́ẹ̀kan síi nílé Brighton Ajẹkun iya ni ẹgbẹ agbabọọlu Arsenal tun jẹ ninu idije Premier League lẹyin ti Brighton din dodo iya fun wọn ninu ifẹsẹwọnsẹ keji ti wọn gba lati igba ti Premier League ti bẹrẹ pada.
Obono-Obla: Buhari ti yan Dayọ Apata lati rọ́pò Obono-Obla
Ami-eye ohun naa fi ta ipinle naa lore lasiko ayeye ti o waye nilu Abuja ti ile-ise to n ri si ere-idaraya ati idagbasoke awon odo lorile-ede yii sagbateru re.
Ki a kọkọ bẹrẹ pe oun ni o gba ipo olori ile aṣoju-ṣofin lọwọ Yakubu Dogara gẹgẹ bi olori ile kẹẹdogun lorilẹede Naijiria.
Oríṣun àwòrán, Reuters Wọn ni o seese ki aisan naa tan kalẹ lati ara enikan si ẹlomiran lai si idiwọ kankan lati agbeegbe kan si omiran.
Aare Muhammadu Buhari ti kedun pelu awon eniyan ipinle Eko lataari isele ijamba ina eleyi ti oko epo robi sokunfa re lojoBo(Thursday), ti o si gba emi eniyan mesan, bee si ni oko irinna mẹ́rìnlélógójì jona deeru.
Messi di aláṣẹ lórí ohun eèlò tó gbé orúkọ rẹ̀ Man City padà sípò kínní nínú ìdíje Premier League Ìdíje bọ́ọ̀lù fa ìtàjẹ̀ sílẹ̀ ní Poly Ibadan Magu,'estimated billing' àti àwọn ohun míràn tí ilé aṣòfin Nàìjíríà kò rí yanjú Aṣọle Athletico Madrid, Jan Oblak gbiyanju pupọ lati koju awọn atamatase Barcelona ṣugbọn ẹpa ko boro nigba ti Luis Suarez jẹ goolu akọkọ ni iṣeju marun un si ipari ifẹsẹwọnṣẹ ọhun.
Ìfaradà yín jẹ́ ẹ̀rí ìdájọ́ òdodo Ọlọrun láti kà yín yẹ fún ìjọba rẹ̀ tí ẹ̀ ń tìtorí rẹ̀ jìyà.
Nadine Dorries ni ọmọ ile aṣofin akọkọ ti yoo ko aisan yi ninu awọn eeyan ejilelọgọrinlelọọdurun ti wọn funra si pe o ni aisan naa.
ti yoo fi mu idagbasoke ba orile ede Naijiria.
O ṣalaye pe ijọba ko gbe ọja tipa nitori ki ebi maa ba pa ọgọrọ araalu to jọ pe iṣẹ oojọ ni wọn n ṣe ki wọn to le jẹun.
Nígbà tí oòrùn mú, ó jó wọn pa, nítorí wọn kò ní gbòǹgbò tí ó jinlẹ̀; wọ́n bá kú.
N óo jẹ yín níyà,ṣugbọn n kò ní fi ìyà tí kò tọ́ jẹ yín.
Niyi ati Remilekun Folorunso ti wọn jẹ ọkọ ati iyawo, ni ọwọ sinku ọlọpaa tẹ pẹlu Muyideen Tolubi ati babalawo wọn, Sonubi Taiwo fun ẹsun gige ori oku nipinlẹ Ogun.
Ọkan gboogi lara awọn oludije naa, Nkeiruka Onyejiocha lo kọkọ kede atilẹyin rẹ fun Gbajabiamila.
Ko tii daju boya ejo lọwọ ninu pẹlu iṣẹlẹ ti EFCC yi ṣugbọn ireti wa wi pe ti iwadii ẹkunrẹrẹ ba waye, ohun to sokunkun nipa ijamba ina yi yoo di mimọ.
Omo iran Kanuri ati Elẹsin musulumi ni Abubakar.
Bí iṣu bá yí padà a dí iyán, bí àgbàdo bá yípadà a di ògi, bí ó sì tilẹ̀ jẹ́ pé èmi náà ń bọ̀ wáá jèrè iṣẹ́ ọwọ́ milọ́wọ́ àwọn ogun ọ̀run, síbẹ̀ n kò ní ṣáìlo agbára tí Ẹlẹ́dàá fi fún àwọn ẹ̀dá alááyé lórí ilẹ̀ ayé láti fi ṣe ọ́ ní ibi.
Ẹ̀ ń dúró de olólùfẹ́ lẹ́bàá ọ̀nà,bí àwọn obinrin Arabia ninu aṣálẹ̀.
Ohun to dun mi ni pe a ko ribi doola awọn eeyan mẹwa to ku.
'Ọdún 2019 pẹ̀lú àwọn àsọtẹ́lẹ̀ tó kó lọ́wọ́ dé' Ṣé ìwọ ní ìpinnu ọdún tuntun?
Tẹ o ba gbagbe, abi ko dayin loju wi pe o sọ ọrọ yi, ẹ wo fọnran fidio yi nibi ti Obasanjọ ti n sọrọ nipa Atiku ninu iwe rẹ to fi sita,''My Watch''.
Wúrà iyebíye kò lè rà á,fadaka kò sì ṣe é díwọ̀n iye rẹ̀.
Iṣẹlẹ Ali Must Go yii si lo tan jakejado agbaye, a si le e ri bii ibẹrẹ ifẹhonuhan abi ijijagbara awọn ọdọ lorile-ede Naijiria.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Sani Abacha: Olórí ológun tí ìjọba rẹ̀ ga ju ilé ẹjọ́ lọ 8 Òkùdu 2020 Oríṣun àwòrán, others Ọjọ nla ni ọjọ kẹjọ osu kẹfa ọdun 1998, nigba ti iroyin gba ilẹ kan pe, olori ijọba ologun ni Naijiria, ọgagun Sani Abacha ti silẹ bora Iku ojiji to pa olori wa nigba naa, eyi to pe ọdun mejilelogun bayii, si lo n ṣe ọpọ eeyan ni haa-hii.
Gbogbo oke yii ni wọn si mọ opo si.
Nítorí pé ẹ̀ ń tẹ̀lé ìlànà ọba Omiri, ati ti ìdílé ọba Ahabu, ẹ sì ti tẹ̀lé ìmọ̀ràn wọn; kí n lè sọ ìlú yín di ahoro, kí àwọn tí wọn ń gbé inú rẹ̀ sì di ohun ẹ̀gàn; kí àwọn eniyan sì máa fi yín ṣẹ̀sín.
Oyè adelé alága APC kúrò ní gúúṣù Nàíjíríà, ó bọ́ sẹ́kùn àríwá Oríṣun àwòrán, APCng Gomina ipinlẹ Yobe, Mai Mala Buni ti di Alaga ẹgbẹ oṣelu APC tuntun ni Naijiria.
"Ọmọwe Obiageli ""Oby"" Ezekweseli Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ohun ti ọpọ awọn ọdọ mọ Obiageli Ezekwesili fun ni ipa rẹ gẹgẹ bii aṣiwaju ẹgbẹ #BringBackourGirls Ohun ti ọpọ awọn ọdọ mọ Obiageli Ezekwesili fun ni ipa rẹ gẹgẹ bii aṣiwaju ẹgbẹ to n ja fun itusilẹ awọn akẹkọ ileewe giram kan ni Chibok ipinlẹ Borno, ti awọn ọmọogun Boko haram ji gbe ni ọdun 2014, #BringBackourGirls."
Wàhálà bẹ́ sílẹ̀ láàrín àwọn ọ̀dọ́ ní Oke Odo ní ìpínlẹ̀ Eko Ọlọ́pàá Ogun gb'ọmọ Ìmáàmù lọ́wọ́ ajínigbé, ṣùgbọ́n wọ́n gbé ọkọ̀ ojú omi ọlọ́pàá lọ Atẹjade kan ti olu ileeṣẹ ọlọpaa fi sita ṣalaye pe ọga agba ọlọpaa lorilẹ-ede Naijria, Mohammed Adamu ti kan sara sawọn ọlọpaa to mu u.
Adédèjì Balógun- Eletu jẹ Báálẹ̀ Abúlé Ọjà.
Awon ebi re nikan ni yoo wa nibi isinku re ni Slotskirke ni Copenhagen logunjo osu keji odun yii.
Bí orílẹ̀-èdè kan bá dẹ́ṣẹ̀,léraléra ni wọ́n ó máa jọba,ṣugbọn bí orílẹ̀-èdè kan bá ní àwọn eniyan tí wọn ní òye ati ìmọ̀,yóo wà fún ìgbà pípẹ́.
    Nígbà tí mo wo ààrin ibi tí òòrùn yìí wà mo rí àwọn iwin méjì, ọ̀kan jẹ́ ọkùnrin èkejì sì jẹ́ obìnrin.
Bakan naa, o tun ti figba kan je akowe agba ajo to n mojuto igberu afe ati idagbasoke awon odo.
Asìkò tó wà ní ilé ẹkọ́ Poly Ibadan ló fún ọmọbirin kan, Omolara Olatubosun lóyún tó sì bí ọmọbinrin kan, Adeola Anuoluwapo Ogunwusi ẹni tó ti pé ọmọ ọdún mẹ́rìndínlọ́gbọ̀n báyìí.
6bn ohun ìní Nàìjíríà Ọwọ́ EFCC tẹ ọ̀kan lára àwọn ti FBI fi èsún jìbìtì kàn!
Baruku bá dá wọn lóhùn pé, Jeremaya ni ó sọ gbogbo ọ̀rọ̀ náà fún òun ni òun fi kọ ọ́ sinu ìwé.
Ìgbéraga àwọn ọmọ Israẹli ń takò wọ́n, sibẹsibẹ wọn kò pada sọ́dọ̀ OLUWA Ọlọrun wọn, tabi kí wọ́n tilẹ̀ wá a nítorí gbogbo ohun tí wọ́n ti ṣe.
Kii si ṣe ojú opo ayelujara to han si gbangba ni wọn ti n ṣe e.
Ẹwẹ, agbẹjọro telọ Adeniyi, Jubril Mohammed ni oun ṣetan lati gbe ẹjọ naa lọ siwaju igbimọ igbẹjọ ti Gomina Seyi Makinde ipinlẹ Oyo ṣẹṣẹ ṣe ifilọlẹ rẹ.
Amọ, oludari ajọ DAWN to n ri si idagbasoke awọn ipinlẹ Yoruba, Ọmọwe Seye Oyeleye ni ko sọrọ kankan ninu gbogbo ohun ti Garba Shehu sọ kalẹ.
Etí ìbẹ̀ ni ilé Ikú wà, ilé Ikú kò jìnà sí ilé Àrùn ti ń ṣe ìyàwó rẹ̀, bẹ́ẹ̀ nì etí ibẹ̀ náà ni ilé ọkùnrin kan tí orúkọ rẹ̀ ń jẹ́ Bàbá-onírungbọ̀n- yẹ́úkẹ́ ẹni tí ń gbé ibi gegele òkúta.
Ọba Adetọna ṣalaye siwaju pe, inu oun dun de ibadi lati ri awọn igbesẹ idagbasoke ati ilọsiwaju to ti de ba ilẹ Ijẹbu.
Ṣé ilé kedari tí o kọ́ ni ó sọ ọ́ di ọba?
Nítorí orúkọ rẹ, OLUWA, dárí ẹ̀ṣẹ̀ mi jì mí,nítorí mo jẹ̀bi lọpọlọpọ.
N kò rìn jù bẹ́ẹ̀ lọ nígbà tí mo dé apá kan nínú Igbó Olódùmarè tí ó yà mí lẹ́nu gidigidi, nítorí níbẹ̀ ni àwọn igi kò ti ní gbòǹgbò ṣùgbọ́n síbẹ̀ ti wọ́n dúró ṣanṣan tí ewé wọ́n sì dúdú mirinmirin.
Ireti si wa pe awọn eeyan ilu Nairobi yoo seto idibo miran lati yan gomina tuntun laarin osu meji niwọn igba ti Sonko ko ni igbakeji.
Eeyan 1,115 ni aarun naa ti sẹkupa ni Naijiria, nigba ti 51,711 ti ri iwosan.
Miliọnu mẹfa ninu wọn ni ọkọ iwe wọn taku ni kete ti wọn pari iwe alakọbẹrẹ.
Jẹ́ kí a jọ sọ àǹfàní US fún Nàìjíríà -Osinbajo
Ni Ọjọ Arafa, awọn musulumi ti ko le e lọ si Mecca, ma n gba aawẹ ati adura, nigba ti awọn to lọ si oke Arafa yoo fi gbogbo ọjọ naa gba adura.
Mààlúù jẹ́ ẹgbaa mejidinlogun (36,000), ìpín ti OLUWA ninu rẹ̀ jẹ́ mejilelaadọrin.
Àwọn òkúta ọ̀hún tóbi tó bẹ́ẹ̀ gẹ́, nkan àdìtú ni bi wọ́n ṣe gbé wọn dé ibi tí wọ́n wà láàrin ọ̀dàn – tí kò sí àpata kankan ní ìtòsí.
Ọkọ̀ ọ̀fẹ́ ní ọmọ tuntun jòjòlò tí wọ́n bí sínú ọkọ̀ òfurufú yóò máa wọ̀ títí ayé rẹ̀- Egypt Air Irọ́ ni o!
Minisita eto irina Clément Beaune sọ pe oni ni oun yoo sọ igbesẹ ti orile-ede oun yoo gbe nipa nkan ti wọn yoo ṣe lori fifofinde igbokegbodo ero ati awọn ọkọ nla to n kẹru.
O ni Mo Abudu, to je oga agba ile ise amohunmaworan Ebony Life  ati gbajugbaja osere, Omotola Jalade-Ekeinde to wa laarin awon aadota obinrin ti won n se ohun ribiribi lagbaye lasiko yii je omoluwabi to n fi eko rere han.
Ni Naijiria, bo tilẹ jẹ ọpọ ibi tawọn obinrin lee foripamọ si ti di titi pa nitori ofin konile-o-gbele, awọn eeyan kan ṣi n ran awọn obinrin lọwọ lati gbawọn la kuro lọwọ ọkọ oniwa ipa.
Nígbà tí OLUWA gba Dafidi lọ́wọ́ gbogbo àwọn ọ̀tá rẹ̀ ati lọ́wọ́ Saulu, Dafidi kọ orin yìí sí OLUWA pé:
Wo àwọn oúnjẹ tí àṣẹ Buhari leè mú kó gbówó lórí Àjẹ́ àti Aṣẹ́wó ní ìyá Rainbow - Òjòpagogo Ko pẹ ti o de ibẹ ti iroyin ti n jade pe, aṣiwaju ẹsin naa ti n fi apa janu, to si ni wọn n fi awọn oṣiṣẹ alaabo dun mahurumahuru mọ oun atawọn dokita oun ni orilẹede India.
Ẹ̀ ń ṣe dáradára tí ẹ bá pa òfin ìjọba Ọlọrun mọ́, gẹ́gẹ́ bí Ìwé Mímọ́ ti sọ pé, “Ìwọ fẹ́ràn ọmọnikeji rẹ bí o ti fẹ́ràn ara rẹ.
Akinwumi Ambode: Awọn àgbà ọ̀jẹ̀ agbábọ̀ọ̀lù ní Afíríkà yẹ́ Gomina Ambode si
Ohun tí a mọ̀ nìyí nípa ìròyìn Ajimobi kú, kò kú, táyé ń gbé kiri Ìwadìí ti bẹ̀rẹ̀ lórí àrá tó sán pa òṣìṣẹ́ FRSC mẹ́ta nípínlẹ̀ Ogun- Ọ̀gá àjọ FRSC Ọ̀rọ̀ ńlá, àwọn adigunjalè ja àgọ́ ọ́lọ́pàá lólè Mo mọ̀ pé ibi tó dára ni Ibidun Ighodalo wà báyìí- Adeboye Lọwọlọwọ, ile iwosan kan lagbegbe Ikoyi ni ilu Eko ni iroyin ni Ajimobi wa lasiko yii.
” Lẹsẹkẹsẹ àrùn ẹ̀tẹ̀ náà fi í sílẹ̀.
mọṣalaṣi bayii, ti wọn fi n wa owo.
tí ẹ ti gbé ẹ̀dá titun wọ̀.
Ìdí rẹ̀ tí mo fi ní ẹ̀ ń tàbùkù orúkọ mi ni pé, ẹ̀ ń fi oúnjẹ àìmọ́ rúbọ lórí pẹpẹ mi.
Nọọsi ni wọ́n pé ìyàwó rẹ̀ náà Sherifat tó jẹ́ ẹni ọdún mẹ́rìndínlógún.
Awọn obi naa woye pe ipinu ileẹjọ yii yoo nipa pataki lati mu adinku ba bi iwa ọdaran ṣe n pọ sii, ṣugbọn wọn ni ijọba gbudọ jara mọ iṣẹ lori idajọ ileẹjọ fun awọn oniṣẹẹ laabi ọhun.
A ò fi físà dun Bísọ̀bù Oyedepo- US Embassy Ko si ǹkan to jọ Corona Virus ni Ivory Coast.
 kí àwọn Òyìnbó tó dé ní àwa yorùbá ti ni ètò ìsèlú tiwa tí ó fẹsẹ ̀ múlẹ ̀ .
’’Shehu,  tun so pe gbogbo igbese ni awon ti gbe bayii lati ri i pe won ri eto eyawo naa gba, bakan naa ni egbe naa ni yoo duro fun omo egbe won  lati ya owo naa.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Buhari kò tíì ṣe to lóri June 12- NADECO #Democracy Day: Pápá ìṣeré Abuja di MKO Abiola Stadium MKO Abiola, iṣẹ́ aṣẹ́gità ló fi bẹ̀rẹ̀ okoòwò O fikun wi pe, irọ patapata ni ijọba to wa lode yii n pa lori igbogun ti iwa ibajẹ ati ajẹbanu, nitori awọn ẹgbẹ alatako nikan ni ijọba n gbogun ti lori iwa ibajẹ.
Samuẹli kò tún fi ojú kan Saulu mọ títí tí Samuẹli fi kú, ṣugbọn inú Samuẹli bàjẹ́ nítorí rẹ̀.
“Bẹẹ ni ko le si idagbasoke to nitumọ laisi aabo ara ẹni, latari eyi, a ró awọn ile-iṣẹ panapana lagbara, paapaa fun amojuto ewu agbara ṣọṣẹ ni asiko yii”O ni awọn ẹlẹgbẹjẹgbẹ ati awọn onile-iṣẹ iroyin ni ipa pataki lati ko lati polongo pataki ijọba oṣelu tiwantiwa siwaju, ki wọn si mu ibaṣepọ awọn ara ilu ati ijọba gbooro sii gẹgẹ bi oluṣọ, pe, “Ile Igbimọ Aṣofin gan-an ni gbongbo fun aṣeyọri eto oṣelu tiwantiwa, mo rọ yin, ẹ jẹ ki a daabo bo o”.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Nigeria 2019 Elections: Akala ní APC kò tó bẹ́ẹ̀ láti yọ ọmọ òun nípò alága Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Nigeria 2019 Elections: Akala ní APC kò tó bẹ́ẹ̀ láti yọ ọmọ òun nípò alága 20 Èrèlè 2019 Ninu ifọrọwerọ rẹ pẹlu BBC Yoruba, oludije gomina fun ẹgbẹ oselu ADP nipinlẹ Ọyọ, Ọtunba Adebayọ Akala figbe ta pe ti ẹgb oselu APC ba fi yọ ọmọ oun nipo, wọn kan fẹ da ija igboro sil ni.
Àkọsílẹ̀ ìran Esau, tí àdàpè rẹ̀ ń jẹ́ Edomu nìyí: 
Mo fẹ́ kí ẹ yan ènìyàn pàtàkì kan tẹ̀lẹ́ mi kí a yí gbogbo agbegbe lọ kí á kéde ìrìnàjò sí òkè Ìrònú ti ń bẹ nínú Igbó Elégbèje.
A óo dáríjì gbogbo ìjọ eniyan Israẹli ati àwọn àjèjì tí ń gbé ààrin wọn nítorí pé gbogbo wọn ni ó lọ́wọ́ sí àṣìṣe náà.
Ṣùgbọ́n èmi gbẹ́kẹ̀lé ìfẹ́ rẹ tí kì í yẹ̀;n óo máa yọ̀ nítorí pé o óo gbà mí.
Obasanjọ ni iwọde yii lo n safihan inu to n bi awọn ọdọ Naijiria, eyi to yẹ ki ijọba tete kọbi ara si.
eniyan Ipinle Oyo lati mo ewu to wa ninu a n da idoti si ibi ti ko tona.
Níbo ni ogun ti ń wá?
bí ó bá rí ogun tí ń bọ̀ wá sí ilẹ̀ náà, tí ó bá fọn fèrè tí ó fi kìlọ̀ fún àwọn eniyan, 
Ìgbà tí wọ ́ n dàgbà tán , tí ó di wí pé wọ ́ n ń wá ibùjókòó tí wọn yóò tẹ ̀ dó , àwọn méjèéji-agígírì àti ajíbogun yìí náà ló jìjọ dìde láti ilé-ifẹ .
Spain yoo koju ẹgbẹ agbabọọlu orilẹ-ede Faranse nipele to kangun si aṣekagba ninu idije naa.
Mo fi kerubu tí a fi àmì òróró yàn tì ọ́.
Ó mú mi wá sí ilé àsè ńlá,ìfẹ́ ni ọ̀págun rẹ̀ lórí mi.
Lẹ́yìn rẹ̀, àwọn alufaa, àwọn ará pẹ̀tẹ́lẹ̀ Jọdani ṣe àtúnṣe ọ̀dọ̀ tiwọn.
Lafikun, a o ṣe ilanilọyẹ fun awọn araalu lori didaabo bo ara wọn ati ẹbi ati aladugbo wọn lasiko itọju alaisan nile yii.
Coronavirus in Nigeria: Ìjọba ní Covid-19 ba ọ̀rọ̀ ajé ìdílé jẹ́, ó fa àrùn ọpọlọ fọ́pọ̀ aráàlú
Lara awọn to ti ko arun naa ni a ti ri gomina, olori oṣiṣẹ aarẹ, awọn oṣiṣẹ eto ilera ati ọpọ awọn eeyan miran lawujọ.
ni eyi ti o mọ isoro ti won n dojukọ, ti o si setan lati ran won lọwọ pelu,
Assembly of All Yoruba Groups, Worldwide lo ṣeto idibo naa ni Ibadan lẹyin ti wọn yan Oloye Bola Tinubu àti Ọjọgbọn Adebanji Akintoye ki wọn to dibo.
 gbogbo nǹkan wọn sì ló létò .
Olùdìbò gé ìka ara rẹ̀ torí ó ṣèṣì dìbò fún ẹgbẹ́ mìíràn Wọn ti sọ fun gbogbo oṣiṣẹ ki wọn ma lọ si inu ile naa lọ ṣe iṣẹ titi di ọjọ kejilelogun oṣu kẹrin.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Saa bọọlu tuntun bẹrẹ Bakan naa, Sadio Mane ko ni kopa ninu ifẹsẹwọnsẹ Community Shield nitori oun naa ṣẹṣẹ de lati idije AFCON 2019 nibi ti orilẹede rẹ, Senegal fidi rẹmi ninu aṣekagba idije naa.
Loju opo Twitter rẹ, @BenMurrayBruce, ni Murray Bruce ti ṣiṣọ loju ọrọ yii faraye.
Atoun ati dẹrẹba rẹ ni wọn jigbe nirọlẹ ọjọ Aiku loju ọna Iseyin-Ado nigba ti wọn n lọ si Ibadan fun ipade kan pẹlu Gomina Seyi Makinde lowurọ ọjọ Aje.
Nígbà tí mo níláti jà fún ara mi ní ẹẹkinni, kò sí ẹni tí ó yọjú láti gbèjà mi: gbogbo wọn ni wọ́n fi mí sílẹ̀.
Àṣẹ jáde lọ pé kí wọ́n pa gbogbo àwọn ọlọ́gbọ́n; wọ́n bá bẹ̀rẹ̀ sí wá Daniẹli ati àwọn ẹlẹgbẹ́ rẹ̀ láti pa wọ́n.
Damọla Ọlatunji ati Bukọla Awoyẹmi (Arugba) Ọkan pataki ninu awọn oṣere tiata Yoruba ti wọn n ṣe lọkọlaya ni Bukọla Awoyẹmi ti ọpọ eeyan mọ si 'arugba' ati ọkọ rẹ Damola Olatunji.
Bi o ṣe jẹ ọga patapata nidi ọrọ oselu Naijiria, bẹẹ lo tun jẹ ọwọ ọtun Oloye Ọbafẹmi Awolọwọ nigba naa.
BBC African Footballer: Salah tún fẹ́ gba àmì ẹ̀yẹ̀ lọ́dún 2019
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Fire Eater: Azonto ní àfojúṣùn òun ni láti lọ fi idán iná yìí pa owó lókè òkun Ijọba ipinlẹ Ọyọ ni, eto idibo to gbe awọn alaga kansu naa wọle tako ofin, niwọn igba ti ile ẹjọ ti ni ki wọn nisuuru ki wọn gbọ ẹjọ wọn tan, ki wọn to ṣe idibo ọhun nigba naa.
Àwọn ọmọ Iṣimaeli sì ń gbé ilẹ̀ tí ó bẹ̀rẹ̀ láti Hafila títí dé Ṣuri, tí ó wà ní òdìkejì Ijipti, ní apá Asiria.
Laarin oṣu kẹjọ ọdun 1978 si oṣu Kẹwa ọdun 1979, Idiagbon ni alakoso ologun fun ipinlẹ Borno, lasiko ti Ọgagun Olusegun Obasanjo n dari ilẹ Naijiria bii ologun.
Bi awọn oluko mi to mọ mi ni fasiti ba ri mi, ara wọn a ka ti wọn a si ka oju kuro.
Ìgbà tí Ọlọ́run bá rii, Ọlọ́run á kọ́ wọn ni ọ̀nà à ti fì bá kòkòrò bẹ́ẹ̀ jà a sì fún wọn láṣẹ àti lọ kọ́ ọ sí ìgbá àyà àwọn ọmọ ènìyàn.
Ó bá pàṣẹ pé kí wọ́n gbé ìwé àkọsílẹ̀ àwọn ìṣẹ̀lẹ̀ ìjọba rẹ̀ wá, kí wọ́n sì kà á sí etígbọ̀ọ́ òun.
Lara awon omo Ethiopia ohun so pe, won ti rin irinajo lati bi ose mefa, ni eyi ti won so pe, won ti nawo oko pupo.
Èdè yìí jẹ ́ ọ ̀ kan lára àwọn èdè náíjíríà .
Wo bí èsì ìdìbò ìpínlẹ̀ Edo ṣe ń jáde Èèyàn 189 ní àrùn Coronavirus tún ṣẹ̀ṣẹ̀ ràn ní Nàìjíríà Lẹ́yìn olóògbé Barrister àti Kollington, èmi làgbà kàn nínú iṣẹ́ orin Fuji- Obesere yarí Kìí ṣe sinimá ni mò ń ṣe, ìṣẹ̀lẹ̀ ojú ayé gangan ní sùgbọ́n.
Agbẹnusọ gomina ipinlẹ ọhun, Segun Ajiboye to fi idi ọrọ naa mulẹ fun BBC sọ pe ọfẹ ni fọọmu ọhun.
Ti o ba sọrọ, pupọ ninu awọn ọmọ ijọ rẹ lo ma n tẹti lati gbọ.
Orilẹede Italy wọgile ifẹsẹwọnsẹ marun lopin ọsẹ to kọja nitori arun naa ninu eyi ti ifẹsẹwọnsẹ Juventus ati Intermilan wa.
Tí a fiṣọwọ́ ní 13:59 16 Sẹ́rẹ́ 202113:59 16 Sẹ́rẹ́ 2021 Ọwọ́ tẹ ènìyàn méjì tó ń ta ayédèrú aṣọ iṣẹ́ ikọ̀ Àmọ̀tẹ́kùn Laipẹ yii ni iwadii ikọ Amọtẹkun ni awọn ajoji ti kii ṣe ọmọ Naijiria n wọ ipinle Oyo ati Ogun.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Small Doctor: Mo kórira igbó, ọtí àti sìgá nítorí màmá mi lòdì si Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Small Doctor: Mo kórira igbó, ọtí àti sìgá nítorí màmá mi lòdì si 20 Agẹmo 2018 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 28 Ọ̀wàrà 2019 Ìlúmọ̀ọ́ká òǹkọrin tàka-súfé, Temi Adekunle, tí gbogbo èèyàn mọ̀ sí Small Doctor ti sọ fún BBC Yorùbá pé kò yé òun, ìdí tí ọ̀pọ̀ ọ̀dọ́ fi ń dá ẹ̀mí ara wọn ní ègbodò láti ipasẹ̀ mímu òògùn olóró.
Ó rọrùn fún ràkúnmí láti gba ojú abẹ́rẹ́ kọjá, jù fún ọlọ́rọ̀ láti wọ ìjọba Ọlọrun.
O ni irọ ni pe ijọba oun ko ni itara nipa aabo ẹmi ati dukia awọn ọmọ orilẹede Naijiria nitoripe oniruuru igbesẹ ati eto ni oun ti gbe kalẹ lati rii pe aye dẹrun fun araalu.
N óo yìn ọ́, OLUWA,nítorí pé o ti yọ mí jáde;o kò sì jẹ́ kí àwọn ọ̀tá mi ó yọ̀ mí.
Fulani kò leè dúró, táa bá lo ohun ta jogún lọ́dọ̀ àwọn bàbá wa - Sunday Igboho Fayemi fojú Alufa to fipa bá ọmọde lòpọ̀ síta l'Ekiti Yorùbá àti Igbo le kùnà láti jẹ ààrẹ lọ́dún 2023- Shehu Sani Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Àwọn ọmọ Israẹli rí ohun ńlá tí OLUWA ṣe sí àwọn ará Ijipti, wọ́n bẹ̀rù OLUWA, wọ́n sì gba OLUWA gbọ́, ati Mose, iranṣẹ rẹ̀.
Agbẹnusọ ẹka RRS sọ ninu atẹjade kan wipe ọwọ tẹ afẹsun kan naa nigba ti wọn ko awọn janduku ti o n ja awọn eniyan lole ni popo ni agbegbe Oshodi ati CMS nilu Eko ni ọjọ naa.
Àkọlé àwòrán, Àwọn èèyàn ń lọ ṣàbẹ̀wò sí àwọn mọlẹ́bí olóògbé náà Bakan naa, awọn agbofinro si ti mu ẹgbọn-kunrin afurasi ọhun.
Bukola Saraki, Adajọ Agba Tẹlẹri, Mohammed Uwais ti Aarẹ Buhari si fọwọbọwọ
Ewe, awon amoye eka naa gbagbo pe, aimoye oja goolu fayawo, ti ko ni akosile, ni o n jade lore-koore lorile-ede Ghana.
Uche tun rọ ile ẹjọ́ latí fagile iwe 'farahàn tipátipá' tí ajọ naa fi gbé Onnoghen, nitori pe adajọ agba naa ti funra rẹ wa sile ẹjọ.
"Otunba Olúwaṣeun Solomon ni ""Mo gbagbọ pe ko tii yẹ kí wọn dẹ igbele nigba ti wọn ṣe bẹẹ, nitori awọn èèyàn kò ní tẹle ofin laisepe wọn kan an nípa fún wọn."
'Kò sí ohun tó burú nínú bí Ajimobi ṣe dá Yewande tó pa ọkọ rẹ̀ sílẹ̀' Ìlú ò rẹ́rìn ín rárá, Alaafin Adeyemi III fárígá fún Buhari nínú lẹ́tà tuntun Trump bu ẹnu atẹ lu FBI Mo ni ọwọ nla fun Afrika-Trump Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí 5:47 Fídíò, Akomolede ati Asa: Mọ̀ si nípa àwọn ọ̀nà tí Yorùbá ń gbà ran ara wọn lọ́wọ́, Duration 5,4722 Ọ̀wàrà 2020 ENDSARS: Nítorí ìwọ́de #EndSARS, ìjọba gbé iléèwé tì pa ní Oyo, Ekiti, Ondo, Eko, Edo, Plateau àti Osun20 Ọ̀wàrà 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 3 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 5 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
"Ẹ kilọ fawọn ọmọ yin lati gba alaafia laaye, ẹ pariwo o to gẹẹ lori laasigbo to n lọ lọwọ yika ipinlẹ Eko lati ipasẹ iwọde EndSARS.
Mose bá pada tọ OLUWA lọ, ó ní, “Yéè!
OLUWA bá mi sọ̀rọ̀ ní ọjọ́ kẹwaa, oṣù kẹwaa, ọdún kẹsan-an tí a ti wà ní ìgbèkùn, ó ní, 
OLUWA sọ fún Mose ninu aṣálẹ̀ Sinai, ó ní, 
O ni 'ibatan mi lo fi ipa bamilopọ, mi o si sọ ọrọ naa fun ẹnikẹni.
O tesiwaju pe awon ko ti mo iye ti oja fayawo naa je, sugbon awon awon afurasi naa wa ni ikawo won,bee ni iwadii yoo si tun maa tesiwaju.
How to apply for Nigeria Youth Investment Fund: Wo ibi láti mọ̀ síi nípa àwọn ọ̀dọ́ tó máa ri owó náà gbà
Oríṣun àwòrán, @ekitistategov Àkọlé àwòrán, Ikinni ṣe pataki ninu aṣa ati iṣe Yoruba Ṣé o ránti mi báyìí, emi arakunrin to n gbe lori oke giga?"
Oríṣun àwòrán, oTHERS Fidio bi wọn ṣe tu ọmọkunrin naa silẹ gbode kan kaakiri ayelujara bii ina to n ran kiri.
Nínú àwọn ìfihàn náà, àwọn ẹ̀kọ́ ìhìnrere ni a gbé kalẹ̀ pẹ̀lú àwọn àlàyé nípa irú àwọn ọ̀rọ̀ ìpìlẹ̀ bí ìwà ọ̀run ti Ọlọ́run Olórí, orírun ènìyàn, jíjẹ́ òdodo Sátánì, èrèdí ara ikú, ṣíṣe dandan ìgbọ́ràn, ìdí fún ironúpìwàdà, àwọn iṣẹ́ ṣíṣe ti Ẹ̀mí Mímọ́, àwọn ìlànà àti ìṣesí tí wọ́n jẹ mọ́ ìgbàlà, àyànmọ́ ilẹ̀ ayé, àwọn ipò ènìyàn ní ọjọ́ iwájú lẹ́hìn Àjínde àti Ìdájọ́, jíjẹ́ ayérayé ìbáṣepọ̀ ìgbéyàwó, àti àdánída jíjẹ́ ayérayé ti ẹbí.
Fun ọdun diẹ sẹyin bayii ni ariyanjiyan ti n waye laarin awọn ọmọ Naijiria ati Ghana lori ikoko irẹsi jọlọọfu to ṣee jẹ ni ajẹpọnula julọ laarin orilẹede mejeeji.
Mo ti di darandaran agbo ẹran tí à ń dà lọ fún àwọn alápatà.
Koda wọn maa n ṣe atọwọda iwe ilẹ, iwe ile, iwe ileesẹ ati bẹẹbẹ lọ lati fi tan ile ẹjọ.
Nígbà tí ẹ̀ṣẹ̀ wa bá borí wa,ìwọ a máa dáríjì wá.
Lẹ́yìn àkókò díẹ̀ yìí, kí wọn tún máa bá ara wọn lòpọ̀, kí Satani má baà dán wọn wò, tí wọn kò bá lè mú ara dúró.
Gbogbo rẹ ni jijẹ fun wọn.
Ìbẹ̀wò ọ̀hún jẹ́ ìgbà àkọ́kọ̀ sí adarí Afẹnifẹre láti ogun ọdún sẹ́yìn.
Nígbẹ̀hìn, wọ́n fi olórí wọ́n yìí síbẹ̀, wọ́n pa àgó kan síbẹ̀ kí ó máa gbé e.
Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí 5:31 Fídíò, Victor Agunbiade ni ojú àlá ni Ọlọrun ti yan iṣẹ́ ọmọ ogun ojú omi fún òun ní America, Duration 5,3114 Ògún 2020 Olusegun Obasanjo sọ̀rọ̀ síta pé ọpẹ́lọpẹ́ Walter Carrington láyé òun nígbà tí Sani Abacha ń lé òun kíri18 Ògún 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù June 12: Àjọ eléto ìdìbò gbọdọ̀ kéde MKO Abiola bí ààrẹ Nigeria 12 Òkùdu 2019 Àkọlé àwòrán, NADECO tún pè fún ìdápada ètò ìjọba awa ara wá nítori pe ètò ìjọba to ń lọ lọ́wa yìí jẹ ti ìjọba ọlọgún, èyí ti ó gbé àgbára fún ìjọba àpapọ̀.
Yóo dùn ní ẹnu rẹ bí oyin, ṣugbọn yóo korò ní ikùn rẹ.
Abẹnugan ni òun yóò tọ́ àwọn ọmọ rẹ̀ méjèèjì ní ilé ìwé titi wọ́n yóò fi tójúú bọ́, bákan náà ni òun yóò fún ìyàwó rẹ̀ ni owó ti yóò maa fi ṣòwò.
Lara awọn to si wa nibi ipade naa tun ni awọn ọba alaye nilẹ Oodua, awọn minisita lati ẹkun iwọ oorun guusu Naijiria, awọn gomina ati ikọ asoju ijọba.
Awon obinrin agbe ohun pe ipe yii ninu iforo wani-lenu wo otooto pelu awon oniroyin nilu Keffi, ti n se olu ilu ipinle naa.
 bí bẹ ́ ẹ ̀ kọ ́ , wọ ́ n gbani nímọ ̀ ràn láti fún gbogbo àwọn tó wà lábẹ ́ ewu nlá láti kó àrùn náà ní àjẹsára náà .
Kí ẹ gba ilẹ̀ náà kí ẹ sì máa gbé inú rẹ̀, nítorí pé mo ti fun yín gẹ́gẹ́ bí ilẹ̀ ìní yín.
Orúkọ ìlú yìí yóo sì jẹ́ orúkọ ayọ̀ fún mi, yóo jẹ́ ohun ìyìn ati ògo níwájú gbogbo orílẹ̀-èdè ayé tí yóo gbọ́ nípa nǹkan rere tí n óo ṣe fún wọn; ẹ̀rù yóo bà wọ́n, wọn yóo sì wárìrì, nítorí gbogbo nǹkan rere tí n óo máa ṣe fún ìlú náà.
Awon ti isele naa soju re so pe won gbo ariwo nla kan , ko to di pe omiyale naa sele, ti o si ya wo oko kan nibi ti awon eniyan n gbe ati ibi ti won gbe n se ise won.
Bẹ́ẹ̀ ni a ṣe di ẹni tí ń gbé Jerusalẹmu.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Bí aya bá kọ ọkọ rẹ̀ silẹ̀, kó wà láì lọ́kọ̀' Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Adeyeye Ile Ife: Kílódé tí Ọọni Ife, Oba Ogunwusi kò fi gbọdọ̀ rí ọmọ rẹ̀ tuntun títí di ẹ̀yìn oṣù mẹ́fà?
“Ẹ máa kó ọpọlọpọ dúkìá pada lọ sí ilé yín, ati ọpọlọpọ ẹran ọ̀sìn, fadaka, wúrà, idẹ, irin, ati ọpọlọpọ aṣọ.
Nítorí ọjọ́ náà jẹ́ ìpalẹ̀mọ́ Àjọ̀dún Ìrékọjá, kí òkú má baà wà lórí agbelebu ní Ọjọ́ Ìsinmi, àwọn Juu bẹ Pilatu pé kí ó jẹ́ kí wọ́n dá àwọn tí wọ́n kàn mọ́ agbelebu ní ojúgun, kí wọ́n gbé wọn kúrò lórí agbelebu nítorí pé Ọjọ́ Ìsinmi pataki ni Ọjọ́ Ìsinmi náà.
Bí kò bá jẹ́ pé òfin rẹ jẹ́ ìdùnnú mi,ǹ bá ti ṣègbé ninu ìpọ́njú.
Ṣebí bí ọkunrin bá ṣe dàgbà sí ni yóo ṣe lágbára sí.
nítorí náà , èdè ni ó jẹ ́ òpómúléró fún àṣà yorùbá .
Bí gbogbo eniyan bá jogún ikú nítorí aṣemáṣe ẹnìkan, oore-ọ̀fẹ́ ati àánú tí Ọlọrun fún gbogbo eniyan láti ọwọ́ ẹnìkan, àní Jesu Kristi, ó pọ̀ pupọ; ó pọ̀ ju ogún ikú lọ.
Minisita to n ri si ọrọ omi ni Ethiopia, Seleshi Bekele lo sọ eyi ninu oṣu kẹsan ọdun to kọja.
Ìran tí a fi hàn mí yìí le:Àwọn oníjàgídíjàgan lọ digun kó ìkógun,abanǹkanjẹ́ sì ba nǹkan jẹ́.
Ǹjẹ́ ẹ̀ ń ṣe ìdájọ́ àwọn eniyan ní ọ̀nà ẹ̀tọ́?
Min Htin Ko Ko Gyi ni olùdásílẹ̀ iléeṣẹ́ Àjọ̀dún Eré Ajàfẹ́tọ̀ọ́ Iyì Ọmọnìyàn àti ìlúmọ̀nánká alátakò ìlọ́wọ́sí ikọ̀ ajagun nínú òṣèlú.
Lodun 2016, “Ajilete Warriors”(Crown FC), se gudugudu meje ohun yaya mefa, leyin ti won fagbahan Niger Tornadoes FC, Wikki Tourists FC ati Rangers International, ki won o to lo fagbahan 3SC ninu asekagba idije naa.
O fidi ọrọ yi mulẹ lasiko to n gbalejo Minisita feto ọrọ Obinrin ni Naijiria, Paulen Tallen nile ijọba Bauch lỌjọbọ.
Mo wá láti ọ̀dọ̀ Baba, mo jáde wá sinu ayé, n óo tún fi ayé sílẹ̀ láti lọ sọ́dọ̀ Baba.
igbimo asoju-sofin ati fun awon ẹkun to wa  lorile ede South Africa.
" Baba mi ko tiẹ gba rara ki n di onitiata.
Olúkúlùkù múra àti ja ìjà díẹ̀ kí á ṣe bí ọkùnrin.
Nibi idajọ naa, adajọ fi ẹsẹ rẹ mulẹ pe olupẹjọ fi han gedegbe pe tayọ ṣiṣe iye meji pe Arogundade ṣekupa ọlọpaa naa.
O ni ibi ti Elẹda da ipinlẹ Eko si yato, bẹẹ naa ni ijọba labẹ oun mọ riri eto ọrọ aje to rọ mọ irinajo afẹ lagbaye.
Nítòótọ́ o sọ ọ́ di ẹni ibukun títí lae;o sì mú kí inú rẹ̀ dùn nítorí pé o wà pẹlu rẹ̀.
Agbẹjọro fun Ọba Asusumasa Atewogboye ni Oloye Obafemi Awolowo nigba ti Bode Thomas jẹ agbẹjọro fun ikọ olujẹjọ yoku, tii se awọn babalawo.
Toyin Abraham, Femi Adebayo bá Funke Akindele kẹ́dùn MK Adam to jẹ agbẹnusọ awọn ajafẹtọmọniyan ni Kano sọ pe lopin igba tawọn ọkunrin ti wọn mu yi ti tasẹ agẹrẹ sofin, awọn ko le ṣe iranwọ kankan fun wọn.
Ṣé ìlú olókìkí yín náà nìyí,tí a ti tẹ̀dó láti ìgbà àtijọ́!
Ile ẹjọ kotẹmilọrun naa sọ pe ko si ofin to faaye gba ẹbí awọn ti wọn pa láti wa nibi ti wọn yoo ti pa awọn ọ̀daràn naa, ati pe awijare ẹbí naa ko fẹṣẹ mulẹ ninu ofin.
Oniroyin BBC, Chris Ewokor j'abọ wipe awọn ọmọbinrin de si ilu Abuja lati Maiduguri ni alẹ ọjọru.
Ṣáájú ni ààrẹ àwọn agbẹ̀bí Franka Cardee tí ké sí gbogbo àwọn obìnrin tí ó lè máa bẹ̀rù bí wọn yóò ṣe rùú là lásìkò yii, àti ọ̀nà tí yóò gbà láti dáàbò bo ara wọn.
cellulitis jẹ ́ àkóràn kòkòrò àìlèfojúrí bacteria tí ó ní ṣe pẹ ̀ lú inú ipele awọ ara .
‘Buhari ti wọnu ẹmi lọ’ Dáa padà Buhari, èmi kìí s'ọ̀lẹ Ohun ọkunrin naa gbalẹ debi wi pe Aarẹ Buhari gbọ ohun to so ti o si danuduro lati wo ẹni to sọ ọrọ naa.
Nitori ọrọ yii nijọba Babangida fi yẹba kuro lori aleefa, ti ijọba ologun miran, ti Sani Abacha lewaju rẹ, si gba akoso orilẹede yii lọwọ rẹ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Seyi Makinde: Èmi kò yẹsẹ̀ kúrò nínú àdéhùn àjùmọ̀ṣe láti pín ipò 2 Agẹmo 2019 Oríṣun àwòrán, Seyi Makinde Ijọba ipinlẹ Ọyọ ti sẹ lori ẹsun kan ti oludije fun ipo gomina to kọja, ninu ẹgbẹ oselu ADC, Sẹnetọ Olufẹmi Lanlẹyin, fi kan gomina ipinlẹ Ọyọ, Onimọ ẹrọ Seyi Makinde pe, o n se aisododo lori adehun ti wọn fi ẹnu ko le lori nipa agbekalẹ ijọba alajumọse.
Iwadii naa ti ile isẹ imọ PinkBlue ṣe fi han wi pe o seesẹ ki ọkunrin kan laarin awọn ọkunrin mẹrin o ni aisan jẹjẹrẹ asetọ.
Ẹṣẹ wo ni Ambode ṣẹ̀ tí ilé aṣòfin Eko fẹ́ fí ọlọ́pàá mú u?
Ìpínlẹ̀ Oyo àti Osun sàlàyé ìdí tí wọn kò fi tí ṣè ifilolẹ ìgbìmò igbẹjọ aṣemáṣe SARS Lara ẹdun ọkan awọn oluwọde ENDSARS ni Naijiria ni pe ki ijọba ṣe agbekalẹ igbimọ ti yoo gbọ ẹjọ aṣemáṣe tàwọn oṣiṣẹ SARS ba ṣe si arailu.
Èmi Oluwa Olodumare ni mo sọ bẹ́ẹ̀.
Shiite àtàwọn ológun ń wọ̀yá ìjà l'Abuja Èèmọ̀!
Mo dá a ní arẹwà, pẹlu ẹ̀ka tí ó pọ̀.
ASP Oyeyẹmi wi pe lootọ ni wipe awọn Fulani darandaran ogun lati ipinlẹ Kwara de si agbegbe Opeji lori ipe ti Baale agbegbe naa pe wọn lori ajọṣepọ rẹ pẹlu wọn lati pese ibi ijẹun fun awọn ẹran maaluu wọn ni agbegbe naa.
Bakan naa, Agbẹjọro agba, Wahab Shittu fi lede pe gomina Wike n lo agbara ijọba ologun ni pẹlu bi o ṣe tako ifẹhọnu han awọn eniyan tako ipaniyan awọn ọlọpaa loore-koore.
Ike Ekweremadu attack: Igbákejì adarí ilé aṣòfìn àgbà tẹ́lẹ̀ dáríjì àwọn IPOB tó nà mí ní Germany
Ikoro ni pe oju ọna to da paroparo fun awọn ajinigbe laaye lati ṣọṣẹ.
Ikọlu mẹfa ti o ti waye lawọn ileewe girama lorilẹede Naijiria
 tó bá jẹ ́ òtítọ ́ ní Ọbàlùfọ ̀ n aláyémọrẹ tún wa jọba lẹ ́ ẹ ̀ kejì ní ilé-ifẹ ̀ a jẹ ́ pé àsìkò aláàfin Àjàkáló jẹ ọba .
Ìpele ikọ̀ mẹrindinlogun Zimbabwe vs Tanzania.
Ó ti dé inú ayé nisinsinyii.
Bíótilẹ̀jẹ́pé púpọ̀ nínú àwọn kẹ̀kẹ́ Marwa náà ti gbo ti wọ́n ti fẹ́ẹ̀ẹ́ bàjẹ́, tí wọ́n sì rí jáku-jàku, wọ́n kópa pàtàkì nínú ètò-ìrìnsẹ̀ àwọn ará ìlú, pàápàá jùlọ fún àwọn mẹ̀kúnù.
Kí wá ló fa ẹ̀rín-àdárín afọ́jú?
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Manchester City vs Manchester United: Man United fọ́ Man City lẹ́nu yánkanyànkan mọ́lé 7 Ọ̀pẹ̀̀ 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Igba la a ni ẹnikan ko le lo ile aye gbo, bayii lọrọ ri fun ẹgbẹ agbabọọlu Manchester City ti ife ẹyẹ idije Premier League wa lọwọ wọn.
Ọna abayọ si ijamba omiyale ni Naijiria Ọna abayọ to jẹ gboogi si ọrọ omiyale lorilẹ-ede Naijria ni ki ajo to n risi ile kikọ máa bojuto ọna igbalode ti awọn eniyan n gba fi kọ ile, ki wọn dawọ lati maa ko ile si oju agbara tabi eti odo.
Àtúpalẹ̀ ìpínlẹ̀ kọ̀ọ̀kan rèé gẹ́gẹ́ bi o ṣe lọ lánàá Lagos-98 FCT-34 Àkọlé àwòrán, Bí Coronavirus ṣe n ṣe ni Afrika láti oṣù mẹ́fà sẹ́yìn Kaduna-30 Nasarawa-25 Benue-21 Plateau-17 Rivers-15 Adamawa-11 Ogun-11 Enugu-9 Edo-8 Delta-7 Ekiti-7 Gombe-5 Ebonyi-4 Bayelsa-3 Kano-3 Ondo-3 Cross River-2 Imo-2 Kebbi-2 Niger-2 Abia-1 Bauchi-1 Ìpínlẹ̀ Eko náà ló si ń léwájú nínú awọn ìpínlẹ̀ to ni ààrùn Coronavirus NCDC ní ènìyàn 322 míràn ló tún fara kásá ààrùn Covid-19 ní Nàìjíríà Yàtọ̀ sí ìròyìn tó gbòde ni àná ọjọ́ Àìkú lójú òpó Twitter àjọ tó ń gbógun ti àjàkálẹ̀ ààrùn lórílẹ̀-èdè Nàìjírà NCDC nípa bi iye ènìyàn to ni ààrun Covid-19 ṣe gbẹ́nu sókè, ọ̀tọ̀ ló rin nígbà ti iye ènìyàn ti ọjọ́ Àìkú jáde.
Won so eleyii leyin ipade ti igbimo naa se niluu Abuja.
Ogbeni Peter Hawkins to jẹ aṣoju ajọ UNICEF ni Naijiria sọ ninu atẹjade ti wọn fi sita pe awọn ikoko ti Naijiria a bi a jẹ ida meje ninu ọgọrun un gbogbo ọmọ ti wọn a bi lagbaye.
Imọran ti ọpọ fi sọwọ ni pe ki eeyan wa nkan ti awọn ọmọ yoo ma se lasiko ti eeyan ba n se isẹ rẹ bi ki wọn ma tun ile se,sise ere idaraya tabi ki lọkọlaya ma bawọn sere laarin ara wọn.
Ní tèmi o, mo máa ń ṣí ojú mi kalẹ̀ dáadáa ní gbogbo ìgbà ni.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Bi awọn ọmọde ṣe n sanra ju boṣeyẹ lọ ti lọ soke si kaakiri agbaye Ọkan lara nkan to n mu ki ẹru ba awọn alaṣẹ eto ilera ni ipa ti awọn nkan mimu to ni ṣuga ninu n ni lara awọn ọmọde ati ọ̀dọ́.
Gbogbo ibi tí ẹsẹ̀ yín bá tẹ̀, ẹ̀yin ni ẹ óo ni ín.
A yatọ sira wa patapata nitori ko kawe rara sugbọn mo fẹ mu inu mama mi dun, ọpọ ẹbi mi si lo ro pe wọn ti ja ibale mi nileewe.
Buhari kéde pé òun yóò se sáà kejì nípò Ará ìlú f'èrò hàn lórí sáà kejì Bùhárí Ni bayi tí ààrẹ ti wa ṣiṣo lójú eégún ọ̀rọ̀ náà, ibeere ti awọn oluwoye n beere ni pe: Ta ni yoo koju rẹ?
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ohun tẹ́ẹ gbúdọ mọ nípa kókó orí ọyàn yín lásìkò fífọ́mọlọ́yàn Ṣugbọn o ni baba oun ko dahun, gbogbo wọn kan n mu ọti ati siga lọ ni, wọn ti wọn si n ṣe faaji pẹrẹu.
Inú yín ń dùn sí owó iṣẹ́ àgbèrè ní gbogbo ibi ìpakà yín.
Kò sí àyè fún fíìmù eré ìfẹ ṣíṣe ni Kannywood mọ́ Ọlọ́pàá Adamawa ni #30,000 ni wọ́n fi bọ́ igún látìmọ́lé Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Bode George: òòtọ́ ni ìkìlọ̀ Obasanjọ ati Soyinka Ọ̀gá àgbà àjọ INEC ọjọgbọ́n Mahmood Yakubu to kede ìjáwe olubori ọhun sàlàye pe ìjẹjọ ilé ẹjọ to ga jùlọ to wáye ni àná ọjọ Jimọ ló mu ki àwọn yí ìkédé ẹni to jáwe olúbolri páda kuro ni APC ti àwọn ti kede tẹlẹ si PDP.
Ohun to jẹ ipenija ni pe ilẹ naa ko ni eronja ta fi n se ayẹwo arun naa tawọn osisẹ ilera Bangladesh si sọ pe awọn wa ninu ewu aini aso idaabo to peye.
eleto aabo miiran ti n se gudu-gudu meje, yaya mefa lati gbogun ti awon iko ọlọtẹ
iwe giga fafiti ilu Ibadan bale sipago naa lati wa kede abajade idibo ipinle Ekiti.
Abalọ aba bọ, gbogbo awọn tọrọ kan ṣaa jọ jokoo jiroro nilu Abuja pẹlu ileeṣẹ Aarẹ Naijiria.
Ojiṣẹ Ọlọrun naa ṣalaye pe oju n gba oun ti fun bi awọn ọmọbinrin orilẹede Naijiria ti wọn ko lọ ṣe owo kotọ loke okun ṣe di alagbe lawọn opopona ilu Rome atawọn ilu miiran lorilẹede Italy.
4 226,002 Czech Republic 14,029 131.
Wọn kopa ninu idije lọdun 1976 ati 1978 ṣugbọn wọn ko yege.
Lati igba ti arun Coronavirus ti bẹ silẹ nilu Wuhan lorilẹede China lọdun 2019, ọpọ orilẹede lagbaye ni arun naa ti rapala wọ, ilẹ Naijiria ko gbẹyin pẹlu.
A ri ara a wa gẹgẹ bi iran tuntun ti yoo gbe ilẹ Africa de ipo ti yoo 'se itẹwọgba loju gbogbo aye, ti yoo si le figa-gbaga pẹlu ẹnikẹni, ṣugbọn eyi ko ti ṣẹlẹ.
Oba Mohammed V1 ti orile ede
Àwọn arakunrin Josẹfu mẹ́wàá bá lọ sí Ijipti, wọ́n lọ ra ọkà.
Nítorí náà, ẹ má ṣe jẹ́ kí á máa sùn bí àwọn yòókù, ṣugbọn ẹ jẹ́ kí á máa ṣọ́nà, kí á sì máa ṣọ́ra.
Alade Aromire: Oríṣun àwòrán, others Ẹni ọdun marundinlaadọta ni Alade Aromire nigba to jade laye ninu ijamba ọkọ kan lopopona marosẹ Eko si Ibadan ni ọjọ kẹrin oṣu Keje ọdun 2008.
Apapa - Oshodi Expressway / 3rd Mainland Bridge Ijọba ibilẹ Ikeja Somolu / Kosofe 34.
Lẹyin ayẹwo naa, ileeṣẹ, ile ijọsin, tabi ile itaja bẹ ẹ yoo gba iwe ẹri pe o pa ilana ati ofin ti ijọba gbe kalẹ lati fi opin si Covid-19.
Ìpànìyàn Zamfara: Kò gbọdọ̀ sí ìwakùsà ní Zamfara Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Jawahir Roble:Hijab tí mò n lò kó jẹ́ kọ́kọ́ jẹ́ ìyàlẹ́nu fún àwọn agbábọ́ọ̀lù mi Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Orúkọ àwọn ọmọ Lefi tí wọ́n fẹ́ àwọn obinrin àjèjì nìwọ̀nyí:Josabadi, Ṣimei, Kelaya, (tí àdàpè rẹ̀ ń jẹ́ Kelita), Petahaya, Juda, ati Elieseri.
Nítorí pé, àwọn ọ̀tá wọn pàápàá mọ̀ pé,Ọlọrun, aláàbò Israẹli, kì í ṣe ẹgbẹ́ àwọn oriṣa wọn.
igba ti won pari ise lara oko ogun oju omi naa, ni won gbee lọ lati yẹẹ wo, ki
Aare Muhammadu Buhari ti kẹdun pelu ijoba ipinle Nassarawa ati awon eniyan lapapo lataari isele ibugbamu afefe gassi ti o waye nipinle naa.
Ọmọkùnrin tó ya 'Blue film' nínú igbó Osun Osogbo ti bayé ara rẹ̀ jẹ́ - Yemi Elebuibon Ọwọ́ tẹ èèyàn kan pẹ̀lú orí ọmọdé nílé aṣòfin àpapọ̀ Iṣẹ́ wo ni Ayo Akinwale ṣe sílẹ̀ kó tó rọ̀run àrèmabọ̀ lẹ́ni ọdun 69?
Minisita eto ẹkọ ilẹ naa, Pauline Lyonga ni igbesẹ ọhun jẹ ọna lati jẹ ki awọn ọmọ ile iwe má gbagbe awọn ohun ti wọn ti kọ ṣaaju igbele Coronavirus.
opo orile-ede ti o lami-laaka lagbaye bi ile Amerika, UK abbl satileyin fun
Ẹni tí ó bá ní Ọmọ ní ìyè; ẹni tí kò bá ní Ọmọ Ọlọrun kò ní ìyè.
Bí èmi alára kò tilẹ̀ sí lọ́dọ̀ yín mo wà lọ́dọ̀ yín ninu ẹ̀mí.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Nínú ìdíje Europa league, Arsenal gbẹ̀san Liverpool, Tottenham Champions league: A jurawa lọ, Liverpool kó àjọ ìyà lọ́wọ́ọ Barcelona Champions League: Ajax f'imú Tottenham fọn fèrè nigba ti oludari ere yoo fi fun fere fun ifẹ̀sẹ̀wọ̀nsẹ̀ naa lati pari, Bournemouth lo bori pẹlu ami ayo kan si odo.
Lati igba naa di asiko yi,ijọba Buhari ko ti ribi koju ipenija aabo ti o n ba awọn eeyan agbegbe ariwa Naijiria finra.
@ayemojubar, oun ni to ba jẹ pe Fatimah, ọmọ Daura ni ọkan lati gbena woju Aisha ati awọn agbofinro, ti Buhari ko si ri ohunkohun se si, ka ma sẹsẹ sọ Buhari gan funra rẹ, a jẹ pe ohun ara lo n sẹlẹ nile ijọba ni Abuja.
Ọgbẹni Rex Tillerson sekilọ yii ni ilu Adidas ababa tii se olu ilu orilẹede Ethiopia, orilẹede akọkọ ti o kskọ gunlẹ si lẹnu abẹwo rẹ akọkọ si orilẹede Afirika.
Ẹ̀yìnkùlé bàbá Tinubu kò dé Edo, kò ṣe mẹ̀dọ̀ lórí ọ̀rọ̀ Obaseki-PDP Aláwàdà ni Buhari - Fáyòṣe Dáa padà Buhari, èmi kìí s'ọ̀lẹ Ọmọ Ààrẹ lẹ́tọ̀ọ́ láti ṣe ìgbéyàwó yálà àwọn ará ìlú fẹ́ràn ìjọba bàbá rẹ̀ tàbí bẹ́ẹ̀ kọ́ - Aisha Buhari O ni gbogbo ọrọ ikilọ ti Obasanjo ti n fi lede labẹ iṣejọba aarẹ Buhari lo tọna ti o si yẹ ki wọn kiyesi, ṣugbọn ijọba keti ikun si nitori Obasanjo lọ sọ ọrọ yii.
Gege bi o se so:”inu wa baje lori isele burku ti o waye laarin igba die si ara won, ni eyi to je pe opolopo emi lo sonu nibe, koda to ba je orile ede kan tabi ekeji lo n koju ogun si ara won, iru isele buruku yii ko le  po to bayi.
Nítorí a kò mú ohunkohun wá sinu ayé, bẹ́ẹ̀ ni a kò lè mú ohunkohun kúrò ninu rẹ̀.
F Odunjo lọ sile ẹkọ alakọbẹrẹ St Augustine to wa nilu Abẹokuta, ko to gba ile ẹkọ girama ti ijọ Aguda lọ, eyiun Catholic Higher Elementary Training School Lẹyin eyi ni J.
A gbọdọ ri wipe ayipada de.
Akanbi Oluwasegun: Mo yá owó ni kí ẹ̀rọ tó ń tu ìyẹ́ adìyẹ yìí tó di odidi
ounje fun awon omo ile-iwe alakobere yii, NHGSFP, ni isakoso isejoba aare Muhammadu
O ni awọn ajinigbe naa papa bọ mọ awọn lọwọ.
Àwọn ará Filistia kó gbogbo àwọn ọmọ ogun wọn jọ sí Afeki, àwọn ọmọ ogun Israẹli sì pa ibùdó sí etí orísun omi tí ó wà ní àfonífojì Jesireeli.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Seun Kuti: Fela ló n pọ́n gbogbo òǹkọrin Afrobeat lagbaye 6.
Nítorí ẹ̀ṣẹ̀ wa, àwọn ọba ati àwọn alufaa wa ti bọ́ sọ́wọ́ àwọn ọba ilẹ̀ àjèjì; wọ́n pa wá, wọ́n dè wá ní ìgbèkùn, wọ́n sì kó wa lẹ́rù.
Coronavirus: Àwọn onímọ̀ sáyẹ́ǹsì Nàíjíríà ṣe ẹ̀rọ àyẹ̀wò àrùn jáde
Gbogbo nǹkan yòókù tí Jehoaṣi ṣe ati ìwà akọni rẹ̀ ninu ogun tí ó bá Amasaya, ọba Juda, jà ni a kọ sinu Ìwé Ìtàn Àwọn Ọba Israẹli.
ti oun ti gbọ ati isẹ to n lọ lọwọ-lọwọ bayii,
Nigba ti Kọmiṣọnna eto ilera ipinlẹ Ogun, Dokita Tomi Coker ba BBBC Yoruba sọrọ lo fidi ọrọ naa mulẹ.
Amnoni fẹ́ràn rẹ̀ tóbẹ́ẹ̀ gẹ́ẹ́ tí ó di àìsàn sí i lára.
Pẹ̀lú ìbànújẹ́ àti oríṣiríṣi èrò ni ọ̀rẹ́ fi padà sí ilé.
Nígbà tí wọ́n dé, ó wo Eliabu, ó sì wí ninu ara rẹ̀ pé, “Dájúdájú ẹni tí OLUWA yàn nìyí.
 bì ó file jè pé olàjú ti dé báyìí èyí kò yí oruko adugbo náà páde dì báyìí .
Iru ijinigbe yii gbilẹ nipinlẹ Ondo to muleti ipinlẹ Ekiti ni 2018, paapa loju ọna to lọ lati ilu Ọwọ si Ikarẹ-Akoko, ti awọn kan si n fi ẹsun kan pe awọn daran-daran Fulani lo wa nidi iṣẹlẹ naa.
Ina naa to sọ lẹka ajọ naa to wa ladugbo Wuse 2, lAbuja la gbọ pe o bẹrẹ lalẹ ọjọ Aje.
Oríṣun àwòrán, Reuters Oríṣun àwòrán, Reuters Oríṣun àwòrán, Reuters Àkọlé àwòrán, Ei Oríṣun àwòrán, AFP Oríṣun àwòrán, Reuters Oríṣun àwòrán, AFP Oríṣun àwòrán, Reuters Oríṣun àwòrán, AFP Oríṣun àwòrán, AFP Oríṣun àwòrán, AFP Oríṣun àwòrán, AFP Oríṣun àwòrán, AFP Oríṣun àwòrán, Reuters All pictures subject to copyright Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
co/yoruba ní gbogbo ìgbà fún àwn ìròyìn àtìgbà dé ìgbà.
Ọkùnrin kan pa ara rẹ̀ sínú ọgbà àjọ TRACE tó n mójútọ ìrìnnà ọkọ̀ nípìnlẹ̀ Ogun Wo bí ètò ìsìnkú Isa Funtua ṣe wáyé ní ìlú Abuja Kí ló dé tí ìjọba ìpínlẹ̀ Oyo kéde fífagilé Sáà ètò ẹ̀kọ́ kẹta fún àwọn akẹ́kọ̀ọ́?
Akọroyin BBC, Gilian Kikowe ni awọn ile itura kan ni awọn agbegbe ti katakara pọ si ati ibi igbafẹ Dar es Salaam ko fun awọn eeyan ni nkan idaabobo yii lọfẹ mọ.
Awọn olukọ naa, nipasẹ ọrọ kan ti ẹgbẹ ASUU fi sita lori ayelujara pe awọn n ro o lati tun lọ fun iyanṣẹlodi oṣu mẹta mi i, ti mu ki ọpọlọpọ eniyan fi ibinu han ‘ASUU da ìyanṣẹ́lódì dúró' ASUU strike: Ẹ wo ohun t'áwọn akẹ́kọ̀ọ́ ńṣe lásìkò ìyanṣẹ́lódì?
Remi Tinubu yoo jade laini alatako kankan ninu idibo abẹle ẹgbẹ APC naa.
Ẹ gbọ́, ẹ̀yin ọba;ẹ tẹ́tí sílẹ̀ ẹ̀yin ìjòyè;OLUWA ni n óo kọrin sí,n óo kọrin dídùn sí OLUWA, Ọlọrun Israẹli.
26 Òkùdu 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 28 Òkùdu 2020 Oríṣun àwòrán, Abiola Ajimobi Yoruba ni ariṣe ni arika, arika si ni baba iregun, ohun ti onikaluku ba se lonii, ọrọ itan ni yoo da bo ba d'ọla.
Ṣugbọn Banaba mú un lọ sọ́dọ̀ àwọn aposteli, ó ròyìn fún wọn bí ó ti rí Oluwa lọ́nà, bí Oluwa ti bá a sọ̀rọ̀, ati bí ó ti fi ìgboyà waasu lórúkọ Jesu ní Damasku.
Àwọn ni ó ta òróró sí lórí, láti yà wọ́n sọ́tọ̀ fún iṣẹ́ alufaa.
Àwọn olórí ogun rẹ̀ gbé òkú rẹ̀ sinu kẹ̀kẹ́ ogun kan lọ sí Jerusalẹmu.
awon to n lowo si iwa ibaje lawujo.
Wọ́n dàbí igi tí a gbìn sí ilé OLUWA,tí ó sì ń dàgbà ninu àgbàlá Ọlọrun wa.
ohun ni:Olopa egbe, eni owo Gibbion Gwari ati igbakeji re eni owo Adekoya
“N óo kọ yín ní ìmọ̀ agbára Ọlọ́run;n kò sì ní fi ohun tíí ṣe ti Olodumare pamọ́.
O buru jai to ba foju kan ina Àkọlé àwòrán, Bi eeyan jẹ ori ahun, yoo kawọ leri to ba de ibi ti ijamba ina ti waye ni Ijẹgun Àkọlé àwòrán, Ẹ ku isẹ o, Ọba oke yoo maa ran yin lọwọ.
Àbí amọ̀kòkò kò ní ẹ̀tọ́ láti ṣe amọ̀ rẹ̀ bí ó ti wù ú bí?
Ó fún wa ní gbogbo ọgbọ́n ati òye.
O ni opolopo awon omo ipinle Anambra lo ti wa gba kaadi idibo won, o tun wa ro awon eniyan yooku lati wa gba kaadi won pelu.
Aare ni awon orile ede Afrika ti gbosuba fun oun nipa igbese ti o n gbe lati gbokun ti iwa ibajẹ lorile ede Naijria, ni eyi ti o ti je ki ibasepo laarin awon  orile ede Afirika won tun gun rege  .
 Arole wá rọ àwọn olólùfẹ́ rẹ láti jókòó sínú ilé wọn lásìkò igbele Coronavirus yìí, kí wọn sì mú gbogbo ìmọ̀ràn àti arọwa tí ìjọba ń pa fún wọn lọ nítorí ẹ̀mí kò ní ààrọ̀."
eyi ti awon omo orile ede naa n fi esun kan an pe isejoba kanpa lo n lo.
 leon mantashev , ọmọ alexander mantashev , gbajúgbajà elépo ni ó fẹ ́ ràá tí ó sì tàá fun .
Àjàgà mààlúù mọkanla wà níwájú rẹ̀, bí wọ́n ti ń kọ ilẹ̀ lọ.
Gege bi alaga igbimo awon gomina naa, gomina ipinle Ebonyi, David Umahi se so, lasiko to n ba awon oniroyin soro leyin ipade ohun,”A ko bowolu didaran ni eka gusuu ila oorun orile-ede Naijiria,”Umahi tun tenumo pe,“ile ni eka gusuu ila oorun orile-ede Naijiria ko tobi to lati fi tore tabi faye gba didaran, ijọba ko I ti bi wa lere, bee si ni awa gan o setan lati daran nipinle wa.
Nígbà tí Anania gbọ́ gbolohun yìí, ó ṣubú lulẹ̀, ó kú.
“Ẹ kò gbọdọ̀ gbàgbé àwọn ọmọ Lefi tí wọ́n wà láàrin yín nítorí pé, wọn kò ní ìpín tabi ohun ìní láàrin yín.
Rohr soro ohun di mimo leyin ifesewonse olorejore eyi ti iko naa padanu sowo  England pelu ami-ayo kan si meji (1-2), eleyi ti o sokunfa ikunsinu laarin awon ololufe iko ohun pe, awon asole iko naa ko kaju osuwon to.
Won ni sinima “Black Panther” to jade lose keje seyin ti pa owo to le ni egbeta milionu owo dola ile okeere o le ni mejilelaadota nile iworan ariwa  ile Amerika, ti o de ti pa bilionu kan ati milionu meji le mejo owo dola nile iworan sinima lagbaye.
Ẹnikẹ́ni kò gbọdọ̀ jẹ ninu ìyẹ̀fun ẹbọ ohun jíjẹ ti alufaa, gbogbo rẹ̀ ni kí wọ́n fi rú ẹbọ sísun.
Máa gbé kẹ̀kẹ́ rẹ lọ, àwọn akọròyìn kọ̀ ìpàkọ́ sí Femi Fani Kayọde Èèyàn mẹ́tàlélógóje míì ṣẹ̀ṣẹ̀ kó COVID-19 ní Nàìjíríà Oríṣun àwòrán, others Ki ni Alhaji Aderẹmi Jimoh duro le?
Lẹ́yìn tí wọ́n gbà ọ̀rọ̀ lẹ́nu gbogbo ẹlẹ́rìí bi márùn nínú ìgbẹ́jọ náà ni àdájọ Olusegun Odusola ni nítori àwítúnwi ọ̀rọ̀, òun kò ni pé ẹlòmíràn mọ́.
Jẹfuta bá pada sí ilẹ̀ rẹ̀ nì Misipa, bí ó ti ń wọ̀lú bọ̀, ọmọ rẹ̀ obinrin wá pàdé rẹ̀ pẹlu ìlù ati ijó, ọmọbinrin yìí sì ni ọmọ kan ṣoṣo tí ó bí.
Nítorí náà, OLUWA Ọlọrun bu erùpẹ̀ ilẹ̀, ó fi mọ gbogbo ẹranko ati gbogbo ẹyẹ.
Aarẹ Buhari ti ni ijọba oun ko ni faaye gba ẹnikẹni lati maa ba awọn dukia ilu jẹ ati pe ẹnikẹni to ba ṣe bẹẹ n gbena woju abo orilẹede Naijiria ni ati pe ẹnikẹni to ba ṣe bẹẹ yoo foju wina ofin to ba yẹ.
Oríṣun àwòrán, PA Kanye West lo ni ileeṣẹ Yeezy to n ṣe bata Lati ọdun 2013 ni West ti gbe ileeṣẹ to n ṣe bata tirẹ jade, iyẹn Yeezy, pẹlu ajọṣepọ ileeṣẹ Adidas.
Eniyan mejila lara awọn ẹni tuntun yii lo wa ni ipinlẹ Eko, ti meji si wa ni ilu Abuja.
Ní gbogbo ojú ọ̀nà náà ni wọ́n ti ń rí àwọn aṣọ ati àwọn ohun ìjà tí àwọn ará Siria jù sọnù nígbà tí wọn ń sá lọ.
Àkọlé àwòrán, Dino Melaye lórí ìbùsùn Ninu ọdun 2018 kan naa lo pada tun sọ pe oun sa si ori igi fun wakati mọkanla nigba ti o ni awọn kan fẹ gbẹmi oun.
 ogbeni barack obama ni demokrati 15k ti yio bo sipo aare orile-ede amerika .
"Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fọ́nrán ohùn, Ruga settlement: YCE ní ìjọba àpapọ̀ ko tó bẹ̀ẹ́ láti kọ́ àgọ́ Fulani sílẹ̀ Yoruba Wọn tẹnu mọ ọ pe ""apapọ ẹgbẹ to dibo yan Ọjọgbọn Banji Akintoye gẹgẹ bi adari Yoruba lọdun kan sẹyin naa lo korajọ lati tun sọ pe awọn ni igbagbọ ninu rẹ'' Awọn mọkandinlogun to tọwọ bọwe ree:1."
Oríṣun àwòrán, Mujidat Adeyemi facebook Bi o tilẹ jẹ pe Kabiyesi ni ọpọ ayaba ninu aafin rẹ, tawọn olo, arẹwa ẹlẹyinju ẹgẹ ati ẹlẹ Daddy si kun inu agbala rẹ babi, sibẹ awọn obinrin miran wa to n gbe ẹmi ọba Adeyemi ro.
Awọn ara agbegbe naa ni wọn sin oku rẹ gẹgẹ bi ilana ẹsin Musulumi si ẹgbẹ Canal to wa ni agbegbe Onilegogoro, Rabiatu Thompson ni Surulere.
OLUWA yóo máa ṣọ́ ọ, yóo sì dá a sí.
ṣẹṣẹ gbe jade pe ogunlọgọ awọn alaboyun lorilẹ-ede Naijiria ati ni awọn orilẹ-ede kọọkan nilẹ Afirika ni wọn máa n fi iya jẹ lasiko iloyun ati ibimọ.
Gómìnà Godwin Obaseki yóò d'ọmọ ẹgbẹ́ òṣèlú PDP lọ́sẹ̀ yìí Ilé ẹjọ́ kòtẹ́mílọ́rùn yọ alága ẹgbẹ́ òṣèlú APC Adams Oshiomhole nípò Èèyàn 490 ló lùgbàdì àrùn Coronavirus ní Naijiria ní Ọjọ́ Ìṣẹ́gun Àbúrò mi Babatunde Fashola- Naira Marley Amọṣa ko pẹ pupọ ni ẹni to jẹ igbakeji akọwe agba ẹgbẹ oṣelu ọhun, Victor Giadom jade sigboro pẹlu iwe idajọ lati ile ẹjọ kan eleyi to ni oun ni o tọ si lati di ipo naa mu.
Ẹ kò gbọdọ̀ jẹ burẹdi tí ó ní ìwúkàrà ninu pẹlu ẹbọ náà; ọjọ́ meje ni ẹ óo fi jẹ ẹ́ pẹlu burẹdi tí kò ní ìwúkàrà.
gbeyin ni ifesewonse naa pada ja si.
Àwọn òfin tí a ti kà sílẹ̀ wọnyi ni OLUWA fún Mose lórí Òkè Sinai fún àwọn ọmọ Israẹli.
Àwọn ọmọ Rekabu pa òfin tí Jonadabu, baba ńlá wọn, fún wọn mọ́, pé kí wọn má mu ọtí waini, wọn kò sì mu ọtí rárá títí di òní olónìí, nítorí pé wọ́n pa àṣẹ baba ńlá wọn mọ́.
Bẹ́ẹ̀ ni mo kọ̀wé mo sì fi ìwé náà fún ẹbọra olójú kan kí ó bá mi fún ọ̀rẹ́ mi.
Ẹwẹ, nigba to n sọrọ nibi ayẹyẹ rẹ ni Abuja, Ọsinbajo sọwipe ọjọ ori oun ti gbe ojuuse n la le oun lori, atiwipe ọjọ ori ti n sun oun si ẹgbẹ awọn agbaagba to wa lawujọ orilẹede Naijiria.
"Dino, èyí o ṣe yìí kù díẹ̀ káàtó"" Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Éégún tó wà nídí Yoruba Bollywood, Samo Baba f'ojú hàn o!"
Nígbà tí Jeroboamu ọmọ Nebati gbọ́ ìròyìn yìí ní Ijipti, (níbẹ̀ ni ó ń gbé láti ìgbà tí ó ti sá lọ fún Solomoni ọba), ó pada wá sílé láti Ijipti.
Ìró rẹ ni mo gbọ́ tẹ́lẹ̀,ṣugbọn nisinsinyii mo ti rí ọ;
naa kedun lori ijamba to wa ye nibẹ, paapaa julo awọn ti o  n sakitiyan lati pese eto aabo fun ara ilu ati
musulumi nibi eto ti egbe Al-Habbibiya seto rẹ ni mosalasi National Mosque to
Nibayii, ipinlẹ Jos, Plateau naa ti darapọ mọ awọn aṣaaju ninu lilugbadi Covid-19 pẹlu bo ṣe bọ si ipo kẹta lọjọru.
Aarẹ Ọna Kakanfo fi ọrọ yii ran Femi Adesina si aarẹ Buhari lori ipo ti nkan wa lorilẹede Naijiria nitori latẹnu Adesina ni ọrọ aarẹ Buhari naa ti jade sita.
Nígbà tí Simiri rí i pé ọwọ́ ti tẹ ìlú náà, ó lọ sí ibi ààbò tí ó wà ninu ààfin, ó tiná bọ ààfin, ó sì kú sinu iná; 
"Iyatọ wa laarin awọn ọdọ iwoyii si awọn ọdọ igba tiwa.
Ni àwọn ọmọ Lefi láti inú ìdílé Kohati ati ti Kora bá dìde, wọ́n gbóhùn sókè, wọ́n sì yin OLUWA Ọlọrun Israẹli.
Ṣugbọn awọn to ja kule ko gbọdọ sa kuro ninu ẹgbẹ taki ki inu wọn ma dun si ẹgbẹ mọ.
com/UFo7LNCTdg😍😍😍Inside the dressing room at full-time with our Reds… pic.
 oju opopona na yoo din sunkere-gbakere oko ku loju popo, bakan naa ni yoo tun mu idagbasoke ba eto oro aje orile ede yii.
ede Naijria nitori ife ti awon ni si idagbasoke  orile ede yii ati igbagbo ti won ni si isejoba
Agbẹnusọ ile-iṣẹ ọlọpaa ni ipinlẹ Eko, Bala Elkanah ni awọn gbe igbeṣẹ naa leyin ti awọn ti ṣe iwadii iru eniyan ti wọn jẹ.
Alao-Akala sọ pe ilẹkun ile oun ṣi silẹ fun gbogbo ọmọ ẹgbẹ APC nipinlẹ bayii.
Jesu bá bi wọ́n léèrè pé, “Èwo ni ó dára: láti ṣe ìrànlọ́wọ́ ni tabi láti ṣe ìbàjẹ́ ní Ọjọ́ Ìsinmi?
Gaali bá kó àwọn ọkunrin Ṣekemu lẹ́yìn, wọ́n lọ gbógun ti Abimeleki.
Kò sí gbọdọ si ìpéjọpọ̀ ọpọ èrò ni àwọn ilé ìjọsìn gbogbo, tàbí nílé ìwé, agbo òṣèlú àti níbi kibi.
 Opolopo eniyan ko mo pataki iyanselodi naa ni pato sugbon o se pataki kijoba dide lati ba won soro ki won le jo fori ikooko soodun si rere”.
Lọwọ lọwọ, eniyan irinwo ati meje ni ajọ to n dena aarun ni Naijiria, NCDC, sọ pe o ni coronavirus.
O ni ọdun to kọja loun jawọ ninu fifi owo ranṣẹ fun itọju ọmọ awọn nitori owo kotọ lo maa n fi anfani owo itọju ọmọ ti oun maa n fi ranṣẹ beere fun.
Ní ọjọ́ náà ni OLUWA bá a dá majẹmu, ó sọ pé, “Àwọn ọmọ rẹ ni n óo fi ilẹ̀ yìí fún, láti odò Ijipti títí dé odò ńlá nì, àní odò Yufurate, 
Ó bá a sọ ọ̀rọ̀ rere, ó sì fi sí ipò tí ó ga jùlọ, àní ipò tí ó ga ju ti gbogbo àwọn ọba tí wọ́n wà pẹlu rẹ̀ ní Babiloni lọ.
Ìjọba yóò ti Afára Sagamu pa nítorí ìjàmbá iná- FRSC Àlùfáà ìjọ Redeem àti ọmọ rẹ̀ méjì kú sílé ìgbafẹ́ kan lásìkò Kérésì Èkìtì ṣé àgbéga àwọn Ọba Aládé mẹ́rìndínlógún Awakọ̀ Maruwa tó bá gbé okùnrin àti obìnrin papọ ní Kano yóò jẹ búlálà mẹ́wàá- Hisbah Lẹyin naa ni wọn sọ pe A pa awọn eeyan wọnyi lati gbẹsan iku awọn ọga wa, ti Abu Bakr al-Baghdadi wa lara wọn."
Buhari ni iwe moyege lati pada wa gẹgẹ bi aarẹ orile ede Naijiria  lọjọRu yii ninu eto idibo aare odun 2019  to pari yii.
Àwọn orílẹ̀-èdè yóo pòórá lórí ilẹ̀ rẹ.
Ọba bi àwọn iranṣẹ rẹ̀ pé, “Ṣé ẹ kò mọ̀ pé eniyan ńlá, ati alágbára kan ni ó ṣubú lónìí, ní ilẹ̀ Israẹli?
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ọpọlọpọ ẹmi sofo latari ikọlu awọn ọmọ ogun oju ofurufu 30 Sẹ́rẹ́ 2018 Oríṣun àwòrán, Nigerian Airforce Official Site Àkọlé àwòrán, Ọmọ ogun Naijiria ko naani ẹmi awọn araalu Ẹgbẹ ajafẹtọ awọn ti wọn ntẹ ẹtọ wọn loju mọlẹ, Amnesty International ti se atẹjade kan lori igbesẹ ti awọn alasẹ orilẹede Naijiria ngbe lati koju ikọlu to nwaye lawọn ilu igberiko.
Ohun tí ó mú èyí bani nínú jẹ́ jù ni fún ẹni láti rí ikú tí ó pa ẹ̀gbọ́n ẹni.
Ó ti pàṣẹ nípa ilẹ̀ Kenaanipé kí wọ́n pa gbogbo ibi ààbò rẹ̀ run.
Wọn ni niṣe ni ìdí tabi ọyàn awọn burẹwa si, tabi ko di ọgbẹ adaajina.
Oríṣun àwòrán, Others O ti to bii oṣu diẹ sẹyin bayii ti orilẹede naa ti n gbona jọinjọin nitori ọrọ oṣelu nibẹ ti ọpọlọpọ si n ṣe iwọde lori pe ki aarẹ naa fi ipo silẹ nitori ọkan o jọkan ikọlu awọn agbesunmọmi ẹsin ati iwa ijẹkujẹ to n waye.
Bẹ́ẹ̀ ni mo sì ti pèsè àwọn ewéko fún oúnjẹ àwọn ẹranko, ati àwọn ẹyẹ, ati àwọn ohun tí ń fàyà fà lórí ilẹ̀, ati gbogbo ẹ̀dá alààyè.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Nollywood: Wo àwọn òṣèré tíátà Yorùbá tó ti kú àmọ́ tí iṣẹ́ wọn ń fọhùn síbẹ̀ 22 Èbibi 2020 Oríṣun àwòrán, OTHERS Aimọye awọn oṣere tiata ni irawọ wọn n tan lọwọ lọwọ, bẹẹ si ni ọpọ lawọn ti irawọ wọn ti tan sẹyin, amọ to ti wọọkun pada nitori pe wọn ti jade laye.
Kyari jẹ eniyan pataki ninu eto iṣakoso Buhari, debi pe awọn iroyin kan sọ pe oun gan-an ni onílù tó n lu ìlù fún ìròmi Aarẹ Buhari.
Awọn obi rẹ ta a lati le kowo jọ fi tọju ọmọkunrin wn to wa ń ṣaisan iyẹn, aburo Nazanin.
Oju opo Flightradar to n tọ pipin irinajo awọn baalu sọ pe laarin iṣẹju kan to poora, niṣe ni o ti dẹnu kọlẹ niwọn ẹgbẹrun mẹta mita(10,000ft) Ileeṣẹ irinna orileede naa s pe awọn ti bẹrẹ si ni ṣe iwadii lati ṣawari baalu naa.
Àwọn aṣòfin Naijiria ṣọ̀rọ̀ ìwúrí nípa Ajimobi Haruna ni kò sí ààrùn Coronavirus ni ìpínlẹ̀ Kogi titi di àsìkò yìí gẹ́gẹ́ bi gómínà ìpínlẹ Yahaya Bello ṣe sọ.
Nibi ayẹyẹ igbalejo naa to maa n waye lọdọọdun, ni awọn arugba yoo ti maa jo yika igba Ọṣun, eyi to fihan pe isẹ igba ruru ti wọn se ko ja si asan.
Ṣugbọn ìwọ pẹlu àwọn ọmọ rẹ nìkan ni alufaa ti yóo máa ṣiṣẹ́ níbi pẹpẹ ìrúbọ ati níbi aṣọ ìbòjú.
Ó ku ẹ̀yà meje, ninu àwọn ẹ̀yà Israẹli, tí wọn kò tíì pín ilẹ̀ fún.
Ó bá mú Peteru ati àwọn ọmọ Sebede mejeeji lọ́wọ́, inú rẹ̀ bàjẹ́, ó sì dààmú.
Ninu ede Yoruba, gẹgẹ bo se wa pẹlu awọn ede miran lorilẹ aye, awọn ede kan wa ti akọsilẹ wọn jọra, amọ iro wọn ko papọ rara.
Monday Bakor, to n gbe ni Oyigbo, sọ fun BBC Pidgin pe ọwọ rẹ ni iyawo afẹsọna rẹ, Queen Nwazuo kú si, lẹyin ti ọta ìbọn fọ́ ilẹkun irin to wa lẹnu ọna sọọbu wọn, ti wọn ti pa mọ ara wọn nitori bi ìbọn ṣe n dun.
Ekun Amhara ati Oromia je agbegbe kan gboogi ti ifehonu-han tako ijoba maa ti n waye, eyi ti o sokunfa ikede ilu-o-fara ti o waye ninu osu kewaa odun 2016.
Bobrisky, lasiko to n kopa lori eto ori ayelujara kan pẹlu agba akọroyin kan, Dele Momodu, salaye pe ọkunrin ni oun amọ oun maa n mura bii obinrin.
Kò pẹ́ pupọ lẹ́yìn náà, Isaaki ti wá láti Beeri-lahai-roi, ó sì ń gbé ilẹ̀ Nẹgẹbu.
Bí ẹja yìí ṣe wá ni oró to ó sì jẹ́ ǹkan to wọ́pọ̀ ní àwọn orílẹ̀-èdè míràn.
O ni, “A ri wi pe ko si ijọba kan ti o le pese iwosan ni kikun fun gbogbo ara ilu.
Gomina ipinlẹ Ondo, Oluwarotimi Akeredolu ti ni iro ni iroyin to n kaakiri pe ado oloro lo bu gbamu ni ipinlẹ Ondo Akeredolu sọ eyi lasiko to n ba awọn oniroyin sọrọ niibi to ti lọ ṣe abẹwo si ibi ti isẹlẹ naa ti waye.
Nigba ti o n baa won oniroyin soro nilu Makurdi pe, ogoro awon agbe ni won koi ti le pada si oko won leyin ikolu ti o waye laarin won ati awon daran-daran.
Àwọn òpè a máa jogún àìgbọ́n,ṣugbọn àwọn ọlọ́gbọ́n a máa dé adé ìmọ̀.
“Tí ẹ bá tẹ̀lé òfin mi tí mo fun yín lónìí, tí ẹ fẹ́ràn OLUWA Ọlọrun yín, tí ẹ sì sìn ín pẹlu gbogbo ọkàn ati ẹ̀mí yín, 
Oluwo kọ̀ láti sọ̀rọ̀ lórí àwọn afọbajẹ tó fẹ́ yọ ọ́ nípò, aráàlú fọ́n síta láti fẹ̀hónú hàn APC Ekiti pàṣẹ lọ rọ́ọ́kún nílẹ̀ fún àna Tinubu àti Babafemi Ojudu Neo n fọ pátá Vee nílé ẹlẹ́gbọ́n àgbà BB Naija, wo ohun táwọn olólùfẹ́ ètò náà n sọ Aago mọ́kànlá alẹ́ ọjọ́ Ajé ni ìjọba ṣi ojú òpó ìforúkọ sílẹ̀ náà ti wọ́n pe ni MSME.
Gbajugbaja onímọ̀ kan nípa ẹṣin islam, Sheikh Taofeeq Akeugbagold àti aya rẹ, tí ń fi tomije Tomije rawọ ẹ̀bẹ̀ pé kí àwọn agbebọn tó jí ibeji àwọn gbé, tu àwọn ọmọ náà silẹ.
Òjíṣẹ́ ni Ifá jẹ́ fún àwa Yorùbá - Onímọ̀ Tiwa Savage tọwọ́ bọ'wé àdéhùn pẹ̀lú àwọn onígbọ̀wọ́ orin lágbàyé 'Ekute jẹ ogun oloro lagọ ọlọpa' #BBCGOVDEBATE: Ọgbọ́n ìmọ̀ àti òye ní ń ò fi ṣe ìjọba- GNI Ọdọmọde olorin yii ni oun maa n forin takasufe ti oun n kọ yii kilọ iwa ibajẹ ni awujọ wa.
 oludasilẹ tíọ ́ rì yìí ni karl marx .
Gẹ́gẹ́ bí ilé iṣẹ́ paná-paná ní ìpínlẹ̀ Kano ṣe sọ, ọmọdébìnrin ọ̀hún ni ẹnì kẹrìnlélọ́gbọ́n tí ìròyìn rẹ̀ tẹ àwọn lọ́wọ́ pé ó kú nípa kíkó sí kànga tàbí inú odò.
Ní àkókò kan Hesekaya ṣàìsàn tóbẹ́ẹ̀ tí ó fẹ́rẹ̀ kú.
A rán Wa Lone àti Kyaw Soe Oo sí ẹ̀wọ̀n ọdún  méje fún rírú òfin Ìkọ̀kọ̀ sáà-akónilẹ́rú.
Àdó ikú tí Boko Haram fi sójú ọ̀nà pa méje lára wọn Uber Lady: Bùkátà pọ̀ lọ́rùn mi ní mo ṣe ń wa taxi akérò Àwọn ọmọ ilé ìwé fi páálí bojú láti má se jí ìwé wò!
"Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Èmi àti Saheed kìí ṣe ọmọdé, a ti jọ ṣe Sinimá papọ̀, èyí túmọ̀ sí pé ìjà ti parí - Fathia Balogun ""Mo fẹ́ pa ara mi torí ojú àbùkù tí wọn ń fi wò mí pé mo fi iṣẹ́ abẹ bímọ"" Fulani kò leè dúró, táa bá lo ohun ta jogún lọ́dọ̀ àwọn bàbá wa - Sunday Igboho Ọjà Àgbáláta ní Badagry rèé, níbití ẹran ejò ti dùn ju ẹran adìẹ lọ Ẹlẹbubọn ṣalaye pe, ọrọ ti Sunday Igboho sọ yii pe fun apero awọn agbaagba Yoruba nitori ''ti eeyan yoo ba jagun, ọrọ lo n bẹ nidi rẹ, t'eeyan o ba si ni jagun, ọrọ naa ni n bẹ nidi rẹ."
 Ṣọ ́ ọ ̀ ṣì tí roof ti lọ pa àwọn ènìyàn ló jẹ ́ ìkan núnú àwọn ṣọ ́ ọ ̀ ṣì aláwọ ̀ dúdú tó dàgbàjùlọ ní orílẹ ̀ -èdè amẹ ́ ríkà , tó jẹ ́ ibùdó fún àgbájọ àwùjọ nípa àwọn ẹ ̀ tọ ́ aráàlú .
00) ati ipinle Cross Rivers (N1,877.
Ipaniyan Benue: Buhari sepade pẹlu awọn t'ọrọ kan
Okan ninu awọn panapana to ṣiṣẹ fi ara pa ninu ijamba ina naa.
Mose dá Farao lóhùn pé, “Sọ ìgbà tí o fẹ́ kí n gbadura fún ìwọ ati àwọn ẹmẹ̀wà rẹ, ati àwọn eniyan rẹ, kí Ọlọrun lè run gbogbo àwọn ọ̀pọ̀lọ́ tí wọ́n wà lọ́dọ̀ yín, ati ninu ilé yín; kí ó sì jẹ́ pé kìkì odò Naili nìkan ni ọ̀pọ̀lọ́ yóo kù sí.
Seyi Makinde: Iléẹjọ́ ní àwọn alága ìbílẹ̀ kó gbọdọ̀ gbé ìgbésẹ̀ kankan títí ìdájọ́ iléẹjọ́ Kòtẹ́milọ́rùn
OLUWA, iranṣẹ rẹ ni mo jẹ́,iranṣẹ rẹ ni mo jẹ́, àní, ọmọ iranṣẹbinrin rẹ.
Ṣugbọn bí kò bá fẹ́ ṣe ẹ̀tọ́ rẹ̀ gẹ́gẹ́ bí ìbátan, bí OLUWA ti wà láàyè, n óo ṣe ẹ̀tọ́, gẹ́gẹ́ bí ìbátan tí ó súnmọ́ ọn.
Kò sí nǹkan tí ó wà ní ìpamọ́ ní ààfin Hesekaya ní ilé rẹ̀ tí kò fihàn wọ́n.
co/0ZdCl5SMbf via thisdayliveDokita Jonathan so ninu iwe ateranse, eleyi ti o bowolu fun raa-re pe.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Coronavirus in Nigeria: Ẹ wo àǹfààní tó wà nínú àrùn Coronavirus Ìjọba Akeredolu kò ní omi àánú lójú, a kò tọ́jú alárùn Coronavirus mọ́ - Dókítá Ondo Kò ní sí ayẹyẹ ọdún Ojúde Oba lọ́dún yìí- Awujale ilẹ̀ Ijebu Wọ̀nyí ni àwọn ẹjọ́ tó làmìlaaka ti EFCC ṣe lásìkò Ibrahim Magu Ṣé lóòtọ́ ni Lateef Adedimeji àti Adebimpe Oyebade ṣe ìgbéyàwó?
Bakan naa si ni ipinlẹ naa ko ti i yan obinrin sipo Gomina ri lati igba ti wọn ti ṣe idasilẹ rẹ.
Àwọn òkè yóo wó lulẹ̀, àwọn òkè etí òkun yóo ṣubú sinu òkun.
O ni ofuutu fẹẹtẹ lasan ni erongba awọn obinrin kan to gbagbọ pe awọn le fi nini ibalopọ pẹlu ọkunrin mu un mọlẹ lati fẹ wọn gẹgẹ bi aya.
Eyi ti awọn onwoye ohun to n lọ nilẹ naa soọ pe o jẹ ọna lati jẹ ki ààrẹ ọhun wa lori oye pẹ titi sii.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: INEC tako àṣẹ Buhari lórí pípa ẹni tó bá jí ìbò gbé Kà nípa ìròyìn mánigbàgbé tí BBC News Yorùbá ṣe láàárín ọdún kan Jí àpótí ìbò, ko fi ikú ṣe ìfà jẹ - Iléeṣé ológun laago ìkìlọ̀ Ninu ọrọ rẹ nibi ipejọpọ naa, Kọmisana ajọ eleto idibo nipinlẹ Ọyọ, amofin Mutiu Agboke ṣe alaye wi pe gbogbo eto lo ti to lati rii daju pe eto idibo baa kẹsẹ jari.
Eekan kan nile ijọba Aso Rock nilu Abuja, ti ko fẹ fara han sita lo fi idi ọrọ naa mulẹ fun BBC lọsan ọjọ Isẹgun.
Hosni Mubarak si jẹjẹ lati maa sin il Egypt titi di igba ti ẹlẹmi gba ẹmi lọwọ rẹ.
Kí ni eniyan rí gbà ninu gbogbo làálàá rẹ̀, kí sì ni èrè eniyan lórí akitiyan, ati iṣẹ́ tí ó ń ṣe láyé.
Ènìyàn iyì ni àbúrò-ò mi Yínká; nítorí náà, bí mo fẹ́ bí mo kọ̀ mo ní láti sọ ìtàn tí mo ṣèlérí-i rẹ̀ fún-un yín.
Orílẹ̀-èdè tí mò ń lò bíi kùmọ̀, ati bíi ọ̀pánígbà tí inú bá bí mi.
Adamu gege bi adele oga agba ile-ise olopaa, lojo karundinlogun, inu osu kinni,
Ladọja sọ ọrọ naa nibi ipade awọn oniroyin ti o waye lọjọ Aiku ni ile rẹ to n bẹ ni agbegbe Bodija niluu Ibadan.
Oríṣun àwòrán, Reuters Àkọlé àwòrán, Amule France kawọmọri nigba to ṣe aṣiṣe to sọ idije pẹlu Croatia di 4-2 Ko pẹ ni Croatia jẹ ikeji lataari aṣiṣe France.
Bakan naa ni a dupẹ lọwọ rẹ fun ipa ribiribi to ko ninu itẹsiwaju ẹgbẹ agbabọọlu wa.
O wa rọ awọn eeyan ti ọrs gbigbogun ti ilokulo oogun oloro kan lati maa gbe igbesẹ to yẹ nidi didẹkun asa buburu yii.
Ikú Ọ̀jọ̀gbọ́n Adébọ́lá Pius Adésànmí kìí ṣe t'ọ̀fọ̀
"O ni, ""eeyan mẹjọ ni a ti fidi rẹ mulẹ pe wọn ti jalaisi ninu isẹlẹ naa nitori wọn jona guruguru ni."
Denmark (1986)Ara ni ẹgbẹ́ agbabọọlu orilẹ-ede Denmark fi aṣọ wọn da ni igba akọkọ ti wọn kopa ninu idije ife agbaye.
9 187,320 Palestinian Territories 1,687 34.
ng Awọn obi awọn akẹkọ ileewe aladani ni ipinlẹ Ogun ti fariga lori owo ayẹwo fun arun COVID-19 ti ijọba ipinlẹ naa bu fun awọn akẹkọ kọọkan ni sisan ki wọn to lee wọle pada sẹnu ẹkọ wọn ni ọjọ Iṣẹgun ọjọ kẹrin oṣu kẹjọ.
"O ni ""Ko ṣe e ṣe fun wa lati deede kọlu awọn eeyan."
 ibi isise isokan afrika to unje igbimo isokan afrika , budo si addis ababa , ethiopia .
Nítorí náà, n óo gba yín dànù kúrò ní ilẹ̀ yìí; n óo fọn yín dànù bí òkò, sí ilẹ̀ tí ẹ̀yin ati àwọn baba yín kò mọ̀ rí.
Òun náà bá bẹ̀rẹ̀ ó ni:
Gehasi sọ fún ọba pé, “Olúwa mi, obinrin náà nìyí, ọmọkunrin rẹ̀ tí Eliṣa jí dìde náà sì nìyí.
Ìròyìn ohun tí ó ṣe yìí tàn ká gbogbo Judia ati gbogbo agbègbè ibẹ̀.
Ọjọ́ orí wo ló yẹ kí ikùn ẹ̀dá bẹ̀rẹ̀ sí tóbi?
Oríṣun àwòrán, Reuters Àkọlé àwòrán, Ọna abayọ si ki batiri ẹrọ ibanisọrọ rẹ tete maa jo 13) Rii pe ṣájà ti o ba foonu ré wa ni o n lo fun foonu re nitori awọn ṣájà miran maa n ba foonu jẹ.
Nigba to n ṣalaye idi abajọ ti ko fi sọ iru iṣẹlẹ nla fun ẹnikẹni, Ohene ni oun o mọ ohun tawọn eeyan yoo sọ t'oun ba gbe igbesẹ lati sọ ohun to ṣẹlẹ si oun sita.
Kò tún sí ààyè epo tó tó fún ọkọ òfurufú ọ̀hun.
Ninu oro re ti o so lojobo(Thursday), aare ni, irufe awon eniyan bayii ni ko fe ki alaafia ati isokan joba lorile-ede yii.
@CallMeBiola sọ ń tiẹ̀ pé, bóyá Abba Kyari lo kú àbí ẹlòmíràn, inú òun kò dùn rárá pé àrùn Covid-19 ń pá ọmọ Nàìjíríà.
- Nkechi Blessing Awọn to n fẹhonuhan ọhun yari pe awọn fẹ ri aarẹ orilẹede Naijiria tẹlẹ ri, Oloye Olusegun Obasanjo to wa nibi ayẹyẹ Owu Day ti wọn n ṣe.
Kódà a rí ẹni tí kò ní jẹun kankan àfi tí ata bá wà níbẹ̀.
O fi ọpọlọpọ igba ṣiṣẹ olukọ ni fasiti Bayero ni ilu Kano titi di ọjọ iku rẹ.
One million boys nìkan kọ́ lẹgbẹ́ òkùnkùn tó n dá Eko rú, 'Awawa Boys' náà tún wà níbẹ̀
ede Naijiria, Muhammadu Buhari ti o tun jẹ alaga  Ecowas , fi sita niluu Abuja, lojoBọ  lati fi ba ijoba ati awon omo orile ede  Ethiopia kẹdun lori awon to padanu ẹmi won
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: ‘A ko mọ ibi ti Melaye wa lọwọlọwọ’ Ǹjẹ́ o mọ̀ pé Nàìjíríà kò pa ife ẹ̀yẹ àgbáyé jẹ rí?
Komisona so eleyii lasiko ti o
Àwọn Ogun Tí Dafidi Jà ní Àjàṣẹ́gun.
Ohun ti a gbọ ni pe ipade naa yoo waye lọjọ Aje ni deede agogo mẹwaa owurọ.
Awọn oúnjẹ to si saba ma n fa irora rẹ ni oúnjẹ to ni ata pupọ, oúnjẹ ti wọn din, ati ki eeyan fi ebi pa inu fun igba pipẹ.
Gbogbo yín ni yóo kú ninu aṣálẹ̀ yìí.
Òun ni ó tẹrí àwọn eniyan ba lábẹ́ rẹ̀.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ikú Suga: UCH ní àwọn agbẹjọ́rò òun yóò fèsì fún mọ̀lẹ́bí Sugar 19 Ẹrẹ̀nà 2019 Oríṣun àwòrán, Temitope Sugar Ile iwosan ẹkọṣẹ iṣegun yunifasiti Ibadan, UCH, ti sọ fun BBC Yoruba pe, oun yoo fesi to tọ si iwe ipẹjọ ti mọlẹbi ilumọka oloṣelu Temitope Olatoye 'Sugar' fi sọwọ si oun.
Èmi tí mo pàṣẹ fún agbami òkun pé, ‘Gbẹ!
Ó bá ń tá ràrà, ó ń wá ẹni tí yóo fà á lọ́wọ́ kiri.
Ṣugbọn pẹlu iwadii BBC, ọjọ́ mẹ́fà ni ọmọ ọdún mẹ́jọ olùwẹ̀ yìí fi maa ń gbaradì lọ́sẹ̀.
Gomina ipinlẹ Kogi,Yahaya Bello sọ pe awọn ti se appu kan eleyi ti oo jẹ ki awọn mọ apẹrẹ arun naa.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìdílé kan gbé ilé iṣẹ́ ọkọ̀ òfurufú lọ ilé ẹjọ́ lẹ́yìn tí wọ́n léwọ̀n dànù nínú ọkọ̀ pé ara wọ́n ń rùn 31 Sẹ́rẹ́ 2020 Oríṣun àwòrán, AFP Àkọlé àwòrán, Idíle kan gbé ilé iṣẹ́ ọkọ̀ òfurufu lọ ilé ẹjọ lẹ́yin ti wọ́n lẹwọ̀n dànu ninu ọkọ pé ara wọ́n ńrun Idile kan ni Michigan, ti àwọn ilé iṣẹ ọkọ ofurufu ilẹ Amẹrika kan lé kuro ninu ọkọ ofurufu wọ́n nítori pé wọ́n ni òòru ara (Body Odour) ti gbé ilé iṣk náà lọ ilé ẹjọ.
Mú àwọn ọjọ́ àtijọ́ wa pada.
Oríṣun àwòrán, LIB Àkọlé àwòrán, Ọmọ bíbí ìpínlẹ̀ Ondo ni olóògbé Bademosi Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Saraki pè fún ìwádìí ikú olórí ikọ̀ adigunjalè tó ṣọsẹ́ ní Offa 'Abẹ́ dídá f'óbìnrin ṣì wọ́pọ̀ ní Cameroon' Wọ́n ti sin okú Olóyè Ọpẹ Bademosi Ile ẹjọ fọmọ ọdọ satimọle Ile ẹjọ Majisireti to wa ni agbegbe Igbosere nipinlẹ Eko ti paṣẹ pe ki Sunday Anani, wa ni ẹ̀wọ̀n fun ọgbọnjọ.
Àbẹ̀tẹ́lẹ̀ gbi gbà àti àwọn iwà ibàjẹ́ ti ó ti gbilẹ̀ fún ọdún pi pẹ́ ti ba nkan jẹ ni orilẹ̀ èdè Nigeria.
"Oríṣun àwòrán, Instagram/queen__aanu ""Mo n pariwo sita lati daabo bo ẹmi mi ni nitori ko yẹ ki idunkooko mọ ẹmi mi wa tori pe mo ko kuro ninu Aafi N ko le di awọn ọmọ mi lọwọ lati mọ baba wọn laelae, amọ gẹgẹ bi iya, oun to tọ fun mi ni lati ko wọn sọdọ mi."
Ṣugbọn kí olukuluku ṣọ́ra pẹlu irú ohun tí ó ń mọ lé orí ìpìlẹ̀ yìí.
O sọrọ lori bi oun ṣe bẹ̀rẹ̀ iṣẹ́ yìí àtàwọn àfojúsùn rẹ gbogbọ.
Iroyin so pe, ni deedee agogo meje abo owuro, ni awon olopaa le ogoro awon afehonu-han , ti won fe lo kora jo sibi ti won yoo ti bere iwode naa ni gbangban ita Martyrs ti o wa ni Adjame, agbegbe kan ti o gbaju ni ilu Abidjan, ni eyi ti awon olopaa ohun ti ata taju-taju tu awon afehonu-han naa ka.
Tá bá fi rí ọ̀sẹ̀ díẹ̀ si, èmi àti aya mi yóò tún yìgì so - Ọkọ Risikat olójú búlúù Háà, èyí tún ga!
Nígbà náà ni Ẹsira kúrò níwájú ilé Ọlọrun, ó lọ sí yàrá Jehohanani, ọmọ Eliaṣibu, ibẹ̀ ni ó sùn ní alẹ́ ọjọ́ náà.
Ronú Wò Kí O tó Ṣèlérí.
Aare menuba awon igbese akin tijoba re gbe bii sise edinku odiwon iye ohun ogbin ti a n ko wole lati ile okeere ni eyi ti a fi n na owo ti a n fipamo si lateyinwa.
Peteru wà ní òkèèrè, ó ń tẹ̀lé e títí ó fi wọ agbo-ilé Olórí Alufaa, ó bá jókòó pẹlu àwọn iranṣẹ, wọ́n jọ ń yá iná.
Bẹrẹ lati ọjọ kokandinlogun awọn sọọsi ati mosalasi láánfàní lati maa ṣe ijosin lalai yọ ẹnikẹni silẹ.
com/Rvlr0M8tQK“Mo panupo pelu ebi, ara, ore, awon ololufe, awon afenifere ati ogunlogo
bale ni, nitori pe yoo mu ileri rẹ sẹ.
France 2019: orílẹ̀-èdè Adulawọ mẹ́ta ló n lọ ṣojú Afirika
Ó ṣe ọdún meje lórí oyè ní Heburoni, ó sì ṣe ọdún mẹtalelọgbọn ní Jerusalẹmu.
Ìyanṣẹ́lódì ni a máa fi ṣíde 2019 tí Buhari kò bá ṣe tiwa.
”Ọba dá a lóhùn pé, “Ìwọ náà ti dá ara rẹ lẹ́jọ́, bẹ́ẹ̀ gan-an ni yóo sì rí.
“N kò sọ àwọn nǹkan wọnyi fun yín láti ìbẹ̀rẹ̀ nítorí mo wà lọ́dọ̀ yín.
Ṣugbọn jẹ́ kí n kọ́kọ́ lọ dágbére fún àwọn ará ilé mi.
Lo difa fun bi awọn ọmọ Naijiria ṣe n fesi lọwọlọwọ si iṣoro abo ti ina rẹ n jo ajorẹyin bayii lorilẹede naa paapaa lasiko ti wọn n ṣọfọọ awọn agbẹ onirẹsi to le laadọfa ti wọn dunmbu nipinlẹ Borno.
Abala 24 Òfin Ẹ̀ṣẹ̀ orí-ayélujára fi ẹ̀sùn kan “ẹnikẹ́ni tí ó bá tan iṣẹ́-ìjẹ́ tí kò ní òótọ́ kan nínú, tí ó lè fa ìbínú, ìnira, ewu, ìdíwọ́, àfojúdi, ìdáyàfò ọ̀daràn, ọ̀tá, ìkórìíra, tàbí ìbínú láì ní ìdí sí ẹlòmíràn ká tàbí fa kí a fi irúfẹ́ iṣẹ́-ìjẹ́ bẹ́ẹ̀ ránṣẹ́.
Ṣugbọn iroyin kan pẹlu tun n sọ ọ pe eeyan kan lati ileeṣẹ aarẹ ni kii ṣe ootọ.
Ilé iṣẹ́ BBC ni Fayẹmi kọ́kọ́ bá sọ̀rọ̀ gẹ́gẹ́ bíi gómìnà tí Ekiti yàn Ẹlẹka: Ìdá àádọ́rin nínú ọgọ́rùn ni mo ní nínú ìbò Ekiti INEC: Èsì ìdìbò Ekiti lẹ́kùnrẹ́rẹ́ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ekiti Election: Kọmisana feto idibo ni ibo kika si n lọ lọwọ Loorọ kutukutu ni igun kan ninu ẹgbẹ awọn ọlọkada to n ṣatilẹyin fun ẹgbẹ oṣelu All Progressives Congress, APC, yabo ọpọlọpọ ẹka ile ẹgbẹ wọn lati le awọn alaga ẹgbẹ to wa ni iṣakoso.
tabi ohunkohun tí ó ti búra èké sí.
Mo nigbagbo pe a o ni baalu ti orilẹ ede  yii , ti yoo maa gbe oruko orilẹ ede  yii ga, baalu ti awa naa yoo lee ma fọwọ lu ookan àyà wa.
Ìjọba Nàìjíríà gbọdọ̀ ṣàlàyé ìdí tí 13.
Báwo ni ó ti ṣe wá ríran nisinsinyii?
Ògo ni ó jẹ́ fún Ọlọrun láti fi nǹkan pamọ́,ṣugbọn ògo ló sá tún jẹ́ fún ọbaláti wádìí nǹkan ní àwárí.
O ni ko sohun to tuntun ninu pe awọn jọ joko sinu ibi kan tori gbogbo awọn lawọn m ara awn ti ko si si ija kankan laarin wọn.
Ta ni àwọn wọnyi tí ń fò lọ bí ìkùukùu?
Bí wọn kò bá rí ọ ní ọjọ́ keji, wọn yóo mọ̀ dájú pé o kò sí láàrin wọn.
Ẹni ọdun merinlelogun ni Tolulope lasiko to dagbere fun aye.
Ẹnikẹ́ni tí ó bá gbọ́n, kí ó mọ àwọn nǹkan wọnyi; kí òye rẹ̀ sì yé ẹnikẹ́ni tí ó bá lóye; nítorí pé ọ̀nà OLUWA tọ́, àwọn tí wọ́n bá dúró ṣinṣin ni yóo máa tọ̀ ọ́, ṣugbọn àwọn ẹlẹ́ṣẹ̀ yóo kọsẹ̀ níbẹ̀.
Buhari ba osinbajo sayẹyẹ igbeyawo ọmọ rẹ Yemi Osinbajo: Ìgbákejì Ààrẹ tó gbọ́ nípa ẹ̀!
Èyí wáye lẹ́yìn ti ààrẹ Buhari kọ láti búwọlu àbádofin ilé igbe ti ijọba ń kọ àti àwọn abadofin méje míràn ti àwọn aṣòfin ṣẹ̀ṣẹ̀ buwọlu.
" Enahoro jẹ ẹni to fẹran ẹkọ gidi, o si ja ija rere fun orilẹ-ede yii ki o to papoda ni ipari ọdun 2010.
 Ile-ise naa n koju orisirisi idojuko, papaa julo nipa isuna, sugbon igbimo yii n sapa won lati la idojuko naa koja.
Gbé agbada omi náà sí ààrin, ní agbede meji àgọ́ àjọ ati pẹpẹ náà, kí o sì pọn omi sinu rẹ̀.
Ní ọ̀sán, Jesu a máa kọ́ àwọn eniyan lẹ́kọ̀ọ́ ninu Tẹmpili; lálẹ́, á lọ sùn ní orí Òkè Olifi.
O tun jẹ ẹrọ fun awn aisan to le sare pa agọ ara.
Ó tọ́ ọ̀kan ninu àwọn ọmọ rẹ̀ dàgbà;ó di ọ̀dọ́ kinniun.
Òun ni yóo jọba lórí àwọn eniyan mi.
Mo fi ìfẹ́ kí gbogbo yín ninu Kristi Jesu.
7 Ma ṣe lépa fún ọrọ̀ ṣugbọ́n fún ọgbọ́n; àti, kíyèsíi, àwọn ohun ìjìnlẹ̀ Ọlọ́run ni a ó ṣí fún ọ, àti nígbànáà ni a ó sọ ìwọ di ọlọ́rọ̀.
” Ni ọkunrin arọ náà bá fò sókè, ó bá ń rìn.
Wọn yóo sì mọ̀ pé èmi ni OLUWA Ọlọrun wọn, ẹni tí ó mú wọn jáde wá láti ilẹ̀ Ijipti, kí n lè máa gbé ààrin wọn.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù EndSARS protest Update: Afẹnifẹre ní ara ti kan àwọn èèyàn, ìjọba sì ló fà á 22 Ọ̀wàrà 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 23 Ọ̀wàrà 2020 Ẹgbẹ afẹnifẹre ti sọ pe atunto ni ọna abayọ kan ṣoṣo si iṣoro.
Oríṣun àwòrán, Other Àkọlé àwòrán, Victor Giadom Imọran Onwoye eto oṣelu lawujọ naa ni wi pe ki awọn ẹgbẹ oṣelu yii pari aawọ to wa laarin wọn, ki wọn si tun ile wọn tọ daadaa nitori awọn ara ilu.
Ko rọrun, ṣugbọn nitori pe ilepa ileeṣẹ BBC News Yoruba ni lati rii pe gbogbo eeyan lawujọ lo lanfani ati sọ ẹdun ọkan wọn, a ko tẹti Ekiti Election: Ẹ́gbẹ̀rún mẹ́rin nàirà ni ẹnikọ̀ọ̀kan ń gbà Nigba ti eto idibo ipinlẹ Ekiti ati Ọṣun waye, lati ibẹrẹ de opin ni ileeṣẹ BBC News Yoruba ti gbe iroyin mejeeji yi lai fi ohunkohun pamọ fun araalu.
Ninu oro gomina Ganduje, O ro awon omo orile-ede yii lati maa fi oye ati owo ba ara won gbe.
Nítorí a ti di àwọn tí ó ń bá Kristi kẹ́gbẹ́ bí a bá fi ọkàn tán an títí dé òpin gẹ́gẹ́ bí a ti fi ọkàn tán an ní ìbẹ̀rẹ̀ igbagbọ wa.
Kìí ṣe ààrùn Covid-19 ló pa adájọ́ àgba ìpínlẹ̀ Kogi-Kọmísọ́nà ìlera Eeyan 490 tuntun mii lo ṣẹṣẹ lugbadi arun Coronavirus ni Naijiria.
N óo ṣe ìdájọ́ fún ọ bí wọn tí ń ṣe ìdájọ́ fún àwọn obinrin tí wọ́n kọ ọkọ sílẹ̀, tabi àwọn tí wọ́n paniyan.
nitori iwa ibaje to ti gbilẹ nibẹ , ni eyi ti o mu won yọ aare ana lorile ede
Ta ló wà nidi wàhálà ílé aṣòfin Nàíjíríà?
Wọ́n dá a lóhùn pé, “Rárá, àwa óo dì ọ́, a óo sì gbé ọ lé wọn lọ́wọ́ ni, a kò ní pa ọ́ rárá.
'Kò sí ǹkan tí o kò lè ṣe tóo bá ní àfojúsùn' Àrà méèrírí , ẹ wo ọkùnrin tí eegun rẹ̀ rọ̀ bíi rọ́bà, tó ń ká bíi ẹja Oyindamọla ni oun ṣetan lati maa kọ awọn ewe iwoyi ni iṣẹ yii ko lè tubọ jẹ itẹwọgba sii lawujọ Yoruba.
Ṣaaju ki ọwọ to tẹ Hushpuppi, kii saba sọrọ nipa awọn mọlẹbi rẹ to bẹẹ loju opo ayelujara.
Ikú Williams Aanuoluwa lágbo òṣèré hú ọ̀pọ̀ ọ̀rọ̀ síta Makinde ti sọ̀rọ̀ lẹ́yìn tí asekúpani Akinyele sálo mọ́ àwọn ọlọ́pàá lọ́wọ́ ní àhámọ́ Iná sọ lóòtọ́ láàfin mi, ṣùgbọ́n kò sí gìrí- Ooni Ile Ife Wo ibùdó arẹwà tí ọ̀pọ̀ èrò ń ya lọ ní Abuja Risikat, ìyá àwọn ọmọ olójú búlù tí bẹ̀rẹ̀ sí ní kọ́sẹ́ aṣojú lóge Sorondinki sọ pe ọbẹ ni obinrin ọhun fi dubu ọmọ rẹ bi ẹni pa ẹran Ileya ni nnkan bi aago mẹjọ owurọ lọjọ naa lọhun.
òun kò le è yọ́ wá - Lekan Balogun Iléẹjọ́ gíga Akure kọ̀ láti gba onídùróó olórí ìjọ Sotitobire Ìjọba Eko sọ pé ká má tọrọ bárà mọ́, wọ́n tún fòfin de kẹ̀ẹ̀kẹ́ tá a fi n ṣiṣẹ́ - Àwọn àkàndá ẹ̀dá Mí ò bẹ̀bẹ̀ fún oyè igbákejì alága APC kí wọ́n tó ó fún mi - Abiola Ajimobi Saheed àti Fathia Balogun dìjọ ń ṣe ọjọ́ ìbí lónìí, ẹ wo àjọṣepọ̀ tó wà láàrin wọn Ọna ara ọtọ ni Barmasai ọmọ ilẹ Kenya gba jawe olubori ninu ere eje-gigun ọhun.
2 Ògún 2018 Oríṣun àwòrán, APC/twitter Àkọlé àwòrán, Alága ẹgbẹ́ APC, Adams Oshiomole ní kí Saraki ṣe ohun tó yẹ́ nípa fífí ipò sílẹ Ko yẹ ki o gbe ade ti wọn fi de ọ lori ninu ile kan lọ sí ilé ẹlomiran."
Ìyẹn Ishmael, tí í ṣe ọmọ rẹ̀ kan ṣoṣo.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Coronavirus in Nigeria: Ǹjẹ́ òògùn vitamin C lè pa coronavirus?
Láti ọjọ́ ti a ti ń bọ̀ ní ilẹ̀ yìí, ǹ jẹ́ báyìí ló yẹ kí ọgbọ́n wá mọ?
Eyi si n mu inu bi ọmọde ti wọn sọ di iyawo.
Donald Trump: Ilẹ̀ Amerika nìkan ni wọ́n ń bímọ sí láti gba ìwé ìgbéèlú
Rárá o, ojú kì í tì wọ́n,nítorí pé wọn kò lójútì.
Ẹ bèèrè, kí ẹ sì ṣe ìwádìí;ǹjẹ́ ọkunrin lè lóyún kí ó sì bímọ?
Ohun tó yẹ kí o mọ̀ nípa ìgbésẹ̀ tí Amẹ́ríkà fẹ́ gbé lórí Nàìjíríà nítorí ọ̀rọ̀ ẹ̀sìn Àwọn èèyàn tí bẹ̀rẹ̀ sì ní gba abẹ́rẹ́ àjẹsára fún ìdènà àrùn Coronavirus ni ilẹ̀ Gẹ̀ẹ́sì Mi ò kí n ṣe afẹfẹ-yẹ̀yẹ̀ lórí ayélujára nítorí pé mí ò ní dúkìá tí mó le fihàn- Ronke Oshodi-Oke Lóòtọ́ ni ọkọ mi lù mí bí àṣọ òfì, àmọ́ gómìnà ti bá wa parí ẹ̀, ẹ máa gbàdúrà fún ìdílé mi- Dokita Ifeyinwa Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí APC NEC Meeting: Ẹkúnrẹ́rẹ́ ọ̀rọ̀ ìkini PDP sí APC bí àwọn adarí ẹgbẹ́ lápapọ̀ ṣe túká rèé8 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Borno Zabamari Massare: Àjọ NCC fẹ́ tú ìwé owó àwọn olúpèsè ìtàkùn ìbánisọ̀rọ̀ wo10 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 UK Covid Vaccine: Arábìnrin ẹni àádọ̀rún ọdún ló kọ́kọ́ gba abẹ́rẹ́ àjẹsára tí Pfizer ṣe síta8 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Andrew Haruna: So-bàtà tó di ọ̀jọ̀gbọ́n fásitì tó di ọ̀gá àgbà9 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Ooni Ile Ife: Ooni Adeyeye Ogunwusi àti Olòrì Naomi gbé Àrẹ̀mọ tuntun wọ ààfin Ilé Oòduà9 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Secret Cults in Nigeria: Ìyá àti ọmọ tó wà nínú Márúwá bá ìjà ẹgbẹ́ òkùnkùn lọ10 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Lọjọ Aje ni awọn eniyan Zimbabwe rirnin ikẹyin fi ṣaponle aarẹ wọn nigba kan ri, Robert Mugabe.
" Àlàyé rèé lórí ìdí táwọn jàǹdùkú fi dáná ṣun àgọ́ ọlọ́pàá ní Iganmu Iwọde EndSARS to n lọ lọwọ yika Naijiria tun ti gba ọna miran yọ ni agbegbe Apapa Iganmu nipinlẹ Eko.
Ọbasanjọ ní òun ti fèsì sí gbogbo ẹ̀sùn tí wọ́n ti fi kan òun lọ́pọ̀lọpọ̀ ìgbà lórí iná ọba, tó fi mọ́ ìwé ''My Watch'' tí òun kọ.
Sugbọn ọjọ naa ko lọ lasan lai jẹ pe awọn olukọ beere ọkan o jọkan ohun ti wọn n poungbẹ lọwọ ijọba, pataki ibeere wọn si ni agbekalẹ akanse owo osu fun awọn osisẹ.
Oríṣun àwòrán, others Ẹwẹ, Lizzy sọ pe ọkọ oun ko mọ awọn obinrin ti aworan wọn gba ori ayelujara ri.
O ni idunnu pe oun ri ọmọ oun gbe jo, fi oun lọkan balẹ pe oun yoo dide rin ni ọjọ kan.
Kinniun buburu kan wà ní ìgboro!
Nítorí náà, ó ga sókè fíofío, ju gbogbo igi inú igbó lọ.
Ẹ̀wọ̀n oṣù mẹ́ta àti #3,000 ni awakọ̀ tí kò bá ní ‘speed limiter’ yóò fi jura- FRSC Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí 3 sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 2:23 Fídíò, Water Generator: Ó leè ṣiṣẹ fún wákàtí mẹfà, kó tó sinmi, Duration 2,2310 Òkùdu 2020 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Ọjọru ni Weistein fun igba akọkọ ba awọn oniroyin sọrọ, to si ni inu oun bajẹ fun gbogbo aṣiṣe ti oun ṣe, amọ ko i tii ye oun gbogbo bi iṣẹlẹ naa ṣe ṣẹlẹ.
'Gbé ìgbésẹ̀ tó ba wù ọ́ ni àsìkò tó wù ọ' Wo ojú àwọn ọmọ Nàìjíríà tó ń dá bírà rere ní àgbáyé Ìsèjọba ìgbìmọ̀ asòfin dára ju ìsèjọba ààrẹ lọ -Femi Okunronmu Oṣere agba, Ajimaṣan, ti gbogbo awọn eniyan mọ si agba ọjẹ apanilẹrin naa lọ loṣu kẹwaa.
Gbogbo nǹkan yòókù tí Jehu ṣe, ati bí ó ti lágbára tó, ni a kọ sinu Ìwé Ìtàn Àwọn Ọba Israẹli.
Duro Ladipọ, ìlúmọ̀ọ́ká òṣèré tíátà àti ọmọ àlúfà tí kò gbàgbé àṣà ìbílẹ̀ Hubert Ogunde rèé, baba àwọn òsèré tíátà 11.
Ẹ jọwọ, ẹ ba mi bẹ ìyàwó mi kí ìgbéyàwó mi ma baà túká - 9ice Báàgì Ghana Must Go pàwọ̀dà, ó di ohun táwọn ránsọ ránsọ fi ń dárà orísirísi Ọ̀kan lára àlàalẹ̀ gẹ́gẹ́ bi oníduro ti wọ́n fi àdéhùn sí ni pé, Ndumne yóò máà tẹ̀lé Maina wá si ilé ẹjọ́ ní gbogbo ìgbà ti wọn ba nílò rẹ̀.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Kàyééfì Promo: Ìyá, ọmọ tuntun àti olubi ló wà níbùdó ìgbókùsí, àmọ́ òkú ọmọ di àwátì Bawo gan an lo ṣe ṣẹlẹ?
Awọn onimọ ti rọ awọn Musulumi lati mu ọjọ mẹwaa akọkọ oṣu Dhul Hijjah lẹyin ti wọn ti kede ọjọru gẹgẹ bi ọjọ kinni, oṣu kejila kalẹnda musulumi.
Amẹrika ń gbẹ̀san lára Nàíjíríà, owó ‘Visa’ di ọ̀nà méjì láti wọ Amẹrika Ṣé obìnrin leè ní àǹfààní ọ̀gbọọgba pẹ̀lú ọkùnrin lágbo òṣèlú Nàíjíríà?
Iwọde naa, ti ẹgbẹ agbarijọpọ awọn ọmọ Yoruba, Yoruba World Congress (YWC) kede pe yoo gbera ni ibudo igbafẹ Gani Fawẹhinmi ladugbo Ọjọta nilu Eko ni awọn ọlọpaa ti pa.
O ni baba oun ko nifẹ si iṣẹ orin kikọ, ṣugbọn mama oun nifẹ ṣii, amọ ọrẹ baba oun lo ba baba oun sọrọ, ko to gba.
Lẹ́hìn èyí, ó yípadà ó ń bá ọ̀nà ilé rẹ̀ lọ, àwa náà ń tẹ̀lé e, bẹ́l ni òun àti Baba-ońrùngbọ̀n ń sọ̀rọ̀ bí wọ́n tí ń lọ, wọn kò sì sọ̀rọ̀ sí mi.
Ènìyàn 307 ló lùgbàdì àrùn Coronavirus ní Ọjọ́ Aiku Eniayn 387 tuntun ni akọsilẹ wa pe o ti ni aarun naa, o si ti wọ ipinlẹ marundinlogoji, ati ilu Abuja.
Ọjọ kọkandinlogun si ọjọ kọkanlelọgbọn, oṣu kẹjọ ni idije naa waye.
Shina Olukolu salaye pe owo sinkun osise ile ise olopa ipinle Oyo,ti  eka to n koju idigunjale (SARS) te awon
Ìpohùnréré Ẹkún nítorí Samaria ati Jerusalẹmu.
Ṣé nítorí pé o bẹ̀rù rẹ̀ ni ó ṣe bá ọ wí,tí ó sì ń dá ọ lẹ́jọ́?
N óo máa yin OLUWA níwọ̀n ìgbà tí mo wà láyé;n óo máa kọrin ìyìn sí Ọlọrun mi níwọ̀n ìgbà tí mo wà láàyè.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù 2019 Hajj: NAHCON ní Nàìjíríà pàdánù èèyàn 5 láti ipàsẹ̀ àìsàn 30 Agẹmo 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 31 Agẹmo 2019 Oku di marun un je Olorun nipe ninu irinajo Hajj todun 2019.
Nigba ti akọroyin BBC bere pe bawo gan an ni ilera ọgagun Babangida ṣe wa ni lọọlọ yii, agbẹnusọ rẹ fesi pe ko ko ko lara ọta baba n le""."
Saulu bá sọ fún Dafidi pé, “O kò lè bá Filistini yìí jà, nítorí pé ọmọde ni ọ́, òun sì ti jẹ́ jagunjagun láti ìgbà èwe rẹ̀ wá.
sise lori lila ona de tibu -tooro ibudo igbokosi ohun lati dekun sunkere-
"Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Coronavirus: Bóo ṣe lè sọ iṣẹ́ láti ilé lásìkò ""Coro” di ìgbádùn fún ara rẹ By David Brown BBC News 9 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Ọpọlọpọ eeyan lo nilo ọfiisi kan ninu ile wọn fun igba akọkọ lasiko yii."
Baba ni lootọ oro wa ti wọn maa n ṣe fun ẹni to ba fẹ jẹ ọba ni ilẹ Yoruba,oro yii ni wọn maa ni ki ọba jẹ ti wọn yoo si bii pe ki lo jẹ o ti oun naa yoo si dahun pe oun ti jẹ ọba, amọṣa gẹgẹ bi ayipada ti ṣe ba ọpọlọpọ nnkan lawọn ẹsin okeere wọnyii naa ni ayipada ti de ba ọpọlọpọ nnkan ni iṣẹṣe nilẹ Yoruba.
Ọjọgbọn naa to jẹ olukọ ni ile iwe fasiti Ipinlẹ Eko ni bo tilẹ jẹ pe oju bọrọ ko ṣee gbọmọ lọwọ ekurọ nitori owo yanturu ti wọn n na lori oṣelu ni orilẹede Naijiria, oun to ṣeeṣe ni.
Irin ni òkè ẹsẹ̀ rẹ̀, ìsàlẹ̀ ẹsẹ̀ rẹ̀ sì jẹ́ irin tí a lú pọ̀ mọ́ amọ̀.
Ìdàgbàsókè tí ó máa ń wà nínú àwùjọ kò sẹ̀yìn ìfọwọ́sowọ́pọ̀ bí àti ránmú un gángan ò ti sẹ̀yìn èékánná.
Baba Fatima ṣalaye pe, inu ọmọ oun dun si igbeyawo naa, ati pe ifẹ wa laarin oun ati ọkọ afẹsọna rẹ.
Ọlọpaa yii wọ inu yara Ledisi lọ fun ra rẹ lẹyin ti awọn ẹbi rẹ ko fẹ fi oju rẹ han.
Brighton, kò le ta pútú kí wọ́n tó lọ fún ìsimi ìdajì àsìkò.
Nítorí nípa Ẹ̀mí kan ni gbogbo wa fi ṣe ìrìbọmi tí a fi di ara kan, ìbáà ṣe pé a jẹ́ Juu tabi Giriki, à báà jẹ́ ẹrú tabi òmìnira, ninu Ẹ̀mí kan ṣoṣo ni a ti fún gbogbo wa mu.
@Nasirmagori sọ pe inu awọn ko dunsi bi aarẹ́ ko ṣe kọbi ara si ipenija aabo to n ba awọn eeyanipinlẹ Zamfara finra Ṣugbọn awọn kan fi ikini ranṣẹ si Buhari ti wọn si gbadura pe ki o gunlẹ layọ Awọn kan na ọwọ awada si aarẹ ti wn si bere pe ṣe o ranti fi owo kalẹ ti wọn yoo fi toju ile Lọjọ kejilelogun Osu Kẹta ọdun 2018,aarẹ Buhari ṣe abẹwo si ipinlẹ Zamfara nigba ti o n lọ kaakiri awọn ipinlẹ ti ikọlu ti waye kaakiri orilẹede Naijiria.
Fayemi: Gbèsè tí mo bá nílẹ̀ ni kò jẹ́ kí n ti yan kọmíṣọ́nà Wo àwòrán ńkan tó ń ṣẹlẹ̀ ní ìpádé ìran Yorùbá ní Ibadan báyìí Amotekun dé!
Ipinlẹ Ondo ni olukọ wa toni ti n ṣiṣẹ ni ile ẹkọ St Monica Girls Grammar School, Ondo.
Bawo ni iroyin pe awọn adigunjale n ja kaakiri ṣe bẹṛẹ?
Ogbeni  Adebayo so pe eredi ti awon se fẹ da ile-ifowopamo
Bẹẹ ni wọn n beere lọwọ rẹ pe, eelo lo ra ilẹ ọhun, lọwọ ta lo ti ra a, awọn eeyan wo ni ẹlẹri rẹ, ta si lo san owo ilẹ naa fun?
Lasiko to fẹ fi ipo silẹ ni ile igbimo asofin ipinlẹ Kwara se agbeyẹwo ofin lori iye owo ifẹyinti fun awọn gomina ati igba keji wọn.
Ẹ̀rù àti oríkunkun ló mú kíjọba máa fi ọlọ́pàá, ológun halẹ̀ mọ́ aráàlú - Ṣoyinka Toyin Abraham kìí bá èmi náà yọ̀, ni kò jẹ́ kí ń gbé e lárugẹ fún ayọ̀ ọmọ - Lizzy Anjorin Iṣẹ́ ọpọlọ ló yẹ ká ṣe nínú tíátà, kìí ṣe àfihàn ara bíbó àbí ìhòòhò wa - Binta Mọgaji Ìdẹ̀ra dé, Gẹnẹrátọ̀ tó ń lo omi dé, a bọ́ lọ́wọ́ òkùnkùn Idi ni pe ẹgbẹ APC ja Shittu kulẹ tori pe ko kopa ninu eto agunbanirọ ọlọdun kan, eleyi ti a mọ si NYSC.
Ṣe ni awọn waya to gbe ina lọ si Mali bẹrẹ si ni gbona ti wọn si da ina ọhun pada si ori ibudo amunawa Ghana.
Bibeli kii ṣe ohun elo ori itage.
Gẹgẹ bi Olukọ wa lọsẹ yii, Arabinrin Adetunji lati ileẹkọ girama Isabatudeen nilu Ibadan ti salaye, lara awọn igbeyawo ilẹ Yoruba la ti ri iyawo Ọsingin, nibi ti wọn yoo ti fẹ iyawo nisu lọka.
Aarẹ America naa tun yan Gina Haspel lati di alakoso obinrin akọkọ ọgaagba ileeṣẹ alami ilẹ Amẹrika (CIA).
Àwọn ìjòyè ati gbogbo àwọn eniyan bá sọ fún àwọn alufaa ati àwọn wolii pé, “Ẹjọ́ ikú kò tọ́ sí ọkunrin yìí, nítorí pé orúkọ OLUWA Ọlọrun wa ni ó fi ń bá wa sọ̀rọ̀.
'Black Friday' àyájọ́ ẹ̀dínwó ọjà tó gbá ayé kan.
Àwọn ọlọ́pàá fi agbára gba ẹ̀rọ ìbánisọ̀rọ̀ alágbèéká mẹ́ta, ẹ̀rọ ayárabíàṣá kọ̀mpútà kan, ẹ̀rọ ayárabíàṣá àgbélétan kan, iPad, ike pélébé ìrántí àti ẹ̀rọ ayàwòrán kékeré kan nígbà tí wọ́n wá sí ilée rẹ̀.
Yóo gbé ọwọ́ rẹ̀ mejeeji lé e lórí, yóo jẹ́wọ́ gbogbo àìṣedéédé ati ìrékọjá ati ẹ̀ṣẹ̀ àwọn ọmọ Israẹli lórí rẹ̀, yóo sì kó wọn lé e lórí, yóo fà á lé ẹnìkan tí ó ti múra sílẹ̀ lọ́wọ́, láti fà á lọ sinu aṣálẹ̀.
Labani bá dá a lọ́kàn le, ó ní, “Láìsí àní àní, ẹ̀jẹ̀ kan náà ni wá” Jakọbu sì wà lọ́dọ̀ rẹ̀ fún oṣù kan.
Oludije lẹgbẹ oselu PDP naa ni ọpọlọpọ igba ni wọn ti gbero lati pa oun, pẹlu iranwọ awọn to fẹsun kan.
 kí wọn tó lọ , wọ ́ n pín ẹrù tàbí ohùn ìní bàbá wọn láìfi nǹkan kan sílẹ ̀ fún àbúro wọn - ajíbógun .
- Ooni Ile Ife Ipenija akọkọ ni pe awọn eeyan gbọdọ gbagbọ ninu abẹrẹ naa pe o lagbara lati koju arun Covid-19, ati pe o le fun wọn ni alaafia.
Ọba aládé yìí sọ pé òun yóò lo ọjọ́ méje yìí gẹ́gẹ́ bí ànfàní láti bá elédùmarè, àwọn irúmọlẹ̀ àtàwọn igba irúmọlẹ̀ sọ̀rọ̀ fún ìlú, ìpínlẹ̀ àti orílẹ̀èdè Nàìjíríà lápapọ̀ fún ìgbà ọ̀tun.
Aare Xi Jinping seleri lati mu ayipada nla ba ile-ise alabo lorile-ede naa ki o to di odun 2050, besini aare ohun tun mu ohun ija igbalode lokunkundun, eyi ti o mu lati kowo lori kiko oko oju-omi nla miran.
Ni idahun, Motara ti fi ọrọ itọrọ aforiji sita fawọn ololufẹ rẹ pe oun ro pe ẹfẹ lohun ti oun ṣe yoo mu wa ni amọ oun tọrọ aforiji.
A fún un ní agbára láti fi èémí sinu ère ẹranko náà, kí ère ẹranko náà lè fọhùn, kí ó lè pa àwọn tí kò bá júbà ère ẹranko náà.
Coronavirus Lockdown: Iléèwé Chrisland ṣetán láti fún ìgbẹ̀kọ́ orí ayélujára lọ́jọ́ Ajé tó ń bọ̀
Wọ́n kọjá ní Amfipoli ati Apolonia kí wọn tó dé Tẹsalonika.
O tun gbosuba fun aare lori owo to ya soto lati fi gbogun ti aarun romo lapa, romo lese ati lati pese owo ina  si awon ile –eto ilera to wa nigberiko.
O tun ṣalaye pe jijẹ gbajumọ oṣere 'ti gba ominira' oun, nitori pe oun kii gbadun ara oun ti oun ba da jade, koda awọn ọmọ oun kii gbadun ara wọn ti awọn ba jọ jade.
Ohun tí a fi rà yín ni ẹ̀jẹ̀ Kristi, ẹ̀jẹ̀ iyebíye bíi ti ọ̀dọ́-aguntan tí kò ní àléébù, tí kò sì ní àbààwọ́n.
Lesbianism: Àwọn ará South-Africa yarí 'torí gbọ̀ngàn kọ̀ ìgbéyàwó abo-sábo
Ẹnikẹ́ni tí ó bá wọ ilé náà lẹ́yìn tí alufaa ti tì í pa, yóo di aláìmọ́ títí di ìrọ̀lẹ́.
Lasiko to n kopa lori eto kan ni ikanni BBC Yoruba, Tọpẹ Alabi sọ pe, Ọlọrun ti sọ fun oun tẹlẹ ki Ajanaku to ku pe, oun ko gbọdọ lọ si ile ijọsin rẹ mọ, bẹẹ si ni orilẹede Amẹrika ni oun wa nigba ti Ajanaku dagbere faye ati igba ti wọn sin in.
Mo kí Alàgbà Mábayọ̀jẹ́ fún iṣẹ́ ọpọlọ tí wọ́n ṣe lórí ọ̀rọ̀ yí.
Ologun Nigeria gbakoso ibuba Boko Haram Boko Haram tu awọn olukọni UNIMAID silẹ Ẹjọ ẹwọn ọdun mẹta si mẹẹdogun ni wọn da fun wọn.
Ilẹ Amẹrika tun fi oju Micheal Olorunyomi lede gẹgẹ bi oni jibiti to maa n lo ori ayelujara awọn to ba n wa ololufẹ lati fi ṣe gbajuẹ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù CJN: Ilé aṣòfin ti buwọ́lu Tanko Muhammad gẹ́gẹ́ bi adájọ́ àgbà Nàìjíríà 17 Agẹmo 2019 Oríṣun àwòrán, AsoRockVilla Àkọlé àwòrán, Aare Buhari yan Tanko Ibrahim lati dele de adajọ Onnoghen Ile igbimọ aṣofin agba Naijiria ti buwọlu iyansipo Tanko Muhammad gẹgẹ bi Adajọ Agba Naijiria.
 Bawo ni aarun Ebola se wọ ilu
Mercy Aigbe bu èpè jó àwọn tó ní gómìnà kan ló ra ilé fún-un Ẹ wo báwọn òṣèré tíátà kan yóò ṣe rí lọ́jọ́ ogbó O ṣeesẹ ko jẹ pe Ighalo lo maa gbami ẹyẹ agbabọọlu to gbayo sawọn julọ ninu idije AFCON 2019.
OLUWA wí fún Samuẹli pé, “Dìde, kí o ta òróró sí i lórí nítorí pé òun ni mo yàn.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, INEC ni eto iforukọ silẹ n tẹsiwaju ṣugbọn gbigba awọn kaadi to wa nilẹ lo n fa bii igbin O darukọ awọn ipinlẹ bii Anambra ati Ọṣun gẹgẹ bii ara awọn ipinlẹ to ti gbe igbesẹ láti fun awọn oṣiṣẹ ni isinmi lẹnu iṣẹ kí wọn lee gba kaadi ìdìbò naa.
Lara awọn ere sinima to ṣe nigba aye rẹ ni Ṣoṣo meji, Ọmọ inu oku, Olori, Oro Idile ati bẹẹ bẹẹ lọ.
29 Owewe 2020 Fídíò, Wole Soyinka sọ ìdí tó fi ni òun a fi màálù Fulani ṣe súyà fáwọn èèyàn abúlé23 Owewe 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Ijọba apapọ ti sọ pe aare
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù BBNaija: Terry Waya sọ oun tó fojú Kiddwaya rí nílé nígbà tó ń bẹ̀bẹ̀ láti lọ BBNaija 13 Agẹmo 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 28 Ògún 2020 Oríṣun àwòrán, @TERRYWAYA/@KIDDWAYA/INSTAGRAM Baba ọkan lara awọn akopa ninu eto agbelewo Big Brother Naija Kiddwaya ton jẹ Terry Waya ti sọrọ lori bi ọmọ rẹ ṣe n ṣe ninu ilee ẹlẹgbọn agba.
Ìyanṣẹ́lódì òṣìṣẹ́ ilé aṣòfin bẹ̀rẹ̀ ní pẹrẹwu nílé aṣòfin Nàìjíríà Ninu agbekalẹ aarẹ lori iṣuna ọdun 2019, ileeṣẹ ọrọ abẹle lo gba ipin owo ti o pọju pẹlu ẹẹdẹgbẹta biliọnu naira o le diẹ, (N569.
Iroyin  tun so pe opolopo awon awako  ati awon iya loja ati baba loja jade lati lo se ise oojo.
Ọgagunfẹyinti Toogun ni amọtẹkun ko si fun ṣiṣọ awọn dukia tabi ileeṣẹ aladani.
Bakan naa lo tun gba ami ẹyẹ akọrin ti ko lẹlẹgbẹ lẹkun iwọ oorun Afirika.
Kọmiṣọna feto ilera nipinlẹ Eko, Ọjọgbọn Akin Abayọmi lo ṣalaye eyi lẹyin to kede eeyan mẹrin miran pẹlu arun Coronavirus bayii.
Aṣa igbeyawo ni Bangladesh ni pe ki ọkọ iyawo ko ẹbi, ara ati iyekan rẹ sẹyin, ko gba agboole awọn iyawo rẹ to wuu lọ ki igbesẹ igbeyawo le bẹrẹ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù FFK: Buhari ló ń fún àwọn Fulani láàyè láti máa pa ènìyàn' Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ FFK: Buhari ló ń fún àwọn Fulani láàyè láti máa pa ènìyàn' 7 Agẹmo 2018 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 13 Agẹmo 2018 FFK: 'Ẹ má ránṣẹ́ ìbánikẹ́dùn sí wa mọ́' Fẹmi Fani Kayọde to ti jẹ minista fun eto irinna ọkọ̀ ofurufu ni Naijiria nigba kan ri sọrọ lori eto aabo Naijiria bayii ati ọna bayọ.
INEC: Ètò ìdìbò gómìnà Ọṣun ló dárajù nínú gbogbo èyí tá a ti ṣe Àwọn PDP méjìlá ló wù láti gba Nàìjíríà kúrò lọ́wọ́ APC Eto idibo abẹle ni ẹgbẹ APC ipinlẹ Jigawa: Gomina Badaru ti ipinlẹ Jigawa lo jawe olubori gẹgẹ bi oludije sipo gomina labẹ asia ẹgbẹ oṣelu APC ni ipinlẹ Jigawa.
Akosile ni ijọba ati ile isẹ to n risi imọtoto oju agbara ni ipinlẹ Eko ti gbe orisirisi àlakalẹ, lati ri dáju wi pe, omi ri aye koja bi o se yẹ.
Nígbà tí àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ gbọ́, wọ́n dojúbolẹ̀, ẹ̀rù sì bà wọ́n pupọ.
Wọ́n kó ara wọn jọ, wọ́n sápamọ́,wọ́n ń ṣọ́ ìrìn ẹsẹ̀ mi,bí wọn ṣé ń dọdẹ ẹ̀mí mi.
Ètò ọ̀rọ̀ ajé náà ti ti dẹnukọlẹ̀ láti ìdá ogún o lé díẹ̀ yàtọ̀ sí bí ó ṣe wà ni oṣù mẹ́ta àkọ́kọ́ nínú ọdún yìí.
Amotekun ni akọkọ ikọ alaabo tawọn gomina pawọpọ lati da silẹ ọkan lara awọn ẹkun Naijiria 2.
Nítorí pé àwọn aláfọ̀ṣẹ ará ìhà ìlà oòrùn pọ̀ láàrin wọn,àwọn alásọtẹ́lẹ̀ sì pọ̀ bíi ti àwọn ará Filistini,Wọ́n ti gba àṣà àwọn àjèjì.
Ọlọ́pàá ní kí n bọra sílẹ láti mọ bóyá obìnrin ní mí torí mo ní irùngbọ̀n Ìdùnnú ṣubú layọ̀ fáwọn obìnrin, ife ìtọ̀ tó ń dènà àrùn nílé ìgbọ̀nsẹ̀ ti dé Nkan akọkọ ti dokita kọkọ beere lọwọ mi ni pe igba wo ni mo ṣe nkan oṣu kẹhin.
Ó sọ fún alásè pé kí ó gbé ẹran tí òun ní kí ó fi sọ́tọ̀ wá.
Dapọ Abiọdun jáwé olúbori f'ẹgbẹ APC ní Ogun Àṣẹ̀yìn wá àṣẹ̀yìn bọ̀ Dapọ Abiọdun ní ẹgbẹ́ òsèlú APC kéde gẹ́gẹ́ bíi olùjáwé ilúbori níbi ìdìbò abélé fún ẹni ti yóò dupò gómìnà lábẹ́ àsíà APC ní ìpínlẹ̀ Ogun.
“ogoro awon omo ogun Taliban lo gba orisirisi ona eburu jade ti won si seku pa ogbon iko omo ogun Afghan nibudo won.
Ìjọba ìpínlẹ̀ Ogun gbá rìfáàsì lórí bó ṣe fẹ́ kí àwọn akẹ́kọ̀ọ́ sanwó fún àyẹ̀wò Covid-19 Ọkọ lé aya rẹ jáde nílé nítorí ìrísí ojú àwọn ọmọ rẹ méjì ní Ilorin Ìròyìn ayọ̀!
A kì í mọ̀, bóyá Ọlọrun lè yí ọkàn rẹ̀ pada, kí ó má jẹ wá níyà mọ́.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ooni: Ọọni àti Buhari tún ṣèpàdé fún ìgbà kejì láàrin ọ̀sẹ̀ kan 31 Agẹmo 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 1 Ògún 2019 Oríṣun àwòrán, @Bashir Ahmad Ọọni ile ifẹ, Ọba Adeyẹye Ogunwusi ti sọ pe ijọba Naijiria ti n ṣe eto, lati ṣe amulo ẹrọ dironu ati CCTV gẹgẹ bi ohun elo lati daabo dukia ati ẹmi awọn eeyan ilẹ kaarọ ojiire.
Ẹgbẹ́ alátakò to pọ̀ jùlọ lórílẹ̀-èdè Nàìjíríà People's Democratic Party (PDP) ti pegedé nínú ìdìbò alága kansu àti ti kánsẹlọ̀ tó wáyé lásìkò ìdìbò ìjọba ìbílẹ̀ to wáyé ní ìpínlẹ̀ Bayelsa ní ọjọ́ kẹwàá oṣù kẹ́jọ ọdun 2019.
Eku sé oko ìrẹ́si lọsẹ́ ni Kebbi
Ẹwẹ, aarẹ ni gbogbo awon alaalẹ yii ko kan ipinlẹ Kano Aarẹ Muhammadu Buhari rọ àwọn ọmọ Naijiria lati tubọ ni maa fọwọsowọpọ pẹlu ijọba àti àwọn eleto abo láti tubọ tẹsiwaju ninu gbigbogun ti aarun coronavirus O dupẹ lọwọ awọn osiṣẹ ilera, ajọ NCDC gbogbo ile iṣẹ ati aladani ti wọn nawọ iranwọ si ijọba àti awọn Naijiria Ààrẹ Buhari yóò bá àwọn ọmọ Nàìjíríà sọ̀rọ̀ lónìí Buhari to address the nation: Kí ni Ààrẹ Buhari yóò bá àwọn ọmọ Nàìjíríà sọ̀rọ̀ lónìí?
Gẹgẹ bi Oloye aya Elebuibon ti wi, ẹgbẹ Emere Onitẹsiwaju ti n sisẹ kara lati se amulo awọn abuda rere to wa ninu ọmọ ẹgbẹ kọọkan fun isẹ rere.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Òkè Ìdànrè: Òkè tó kéré jùlọ jẹ́ ẹsẹ̀ bàtà ẹgbẹ̀rún mẹ́ta Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Òkè Ìdànrè: Òkè tó kéré jùlọ jẹ́ ẹsẹ̀ bàtà ẹgbẹ̀rún mẹ́ta 4 Ọ̀pẹ̀̀ 2018 BBC Yoruba rin irinajo lọ silu Idanre nipinlẹ Ondo, niti ti Oke Idanre wa lati mọ nipa ohun to se ara ọtọ nipa ori oke yii.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Èmi gan máa ń béèrè lọ́wọ́ ara mi pé ta ni Wole Soyinka gangan' Ọjọ kẹtala, oṣu Kẹrin l'oun naa tun kede afikun ọsẹ meji si isede to wa nilẹ tẹlẹ.
Ijọba Ondo wa ọdẹ to p'erin ni Idanre
Kwam 1, lásìkò to ń takurọsọ lójú òpó Instagram pẹ̀lú agba ọjẹ akọroyin kan, Dele Momodu, ṣàlàyé pé, irọ lásán ni wọn pa mọ òun.
 Eyi to tumọ si pe ẹgbẹrun mẹrindinlogun tọọnu idọti onike ni wọn n danu ni Ipinlẹ Eko lojoojumọ.
Àwọn eniyan tí ó bá ń sọ̀rọ̀ báyìí fihàn pé wọ́n ń wá ìlú ti ara wọn.
Láti ìdí sí apá ìsàlẹ̀ dé àtẹ̀lẹsẹ̀ òkúta pátápátá gbáà ni.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, YPP, ADC, PPC ni tòótọ́ ni pé ọmọ oninakuna nijọba Eko lasiko yii Ọrọ yi mu iriwisi ọtọọtọ wa loju opo Twitter ti awọn kan si n bẹnu atẹ lu gomina pe ko na owo si ibi to yẹ Ero otọọtọ ni ọrọ owo naa n bí Koda awọn ẹgbẹ oṣelu PDP ni ipinlẹ Eko, gẹgẹ bi ohun ti Akosile sọ, kun awọn to gbe iroyin ẹlẹjẹ yi.
O fikun ọrọ rẹ wipe, ajọ SARS ko fa ọrọ gun rara, nibi adari wọn se lewaju iko to lọ koju awọn agbenipa ọhun, nibi ti wọn lugọ si.
Gaali ọmọ Ebedi bá jáde, ó dúró ní ẹnu ọ̀nà bodè ìlú náà, Abimeleki ati àwọn ọkunrin tí wọ́n wà pẹlu rẹ̀ sì jáde níbi tí wọ́n ba sí.
N óo da ìtìjú bo àwọn ọ̀tá rẹ̀ bí aṣọ,ṣugbọn adé orí rẹ̀ yóo máa tàn yinrinyinrin.
Kì í ṣe ẹ̀rí-ọkàn tiyín ni mò ń sọ bíkòṣe ẹ̀rí-ọkàn ti ẹni tí ó pe akiyesi yín sí oúnjẹ náà.
Nítorí àwa náà ti gbọ́ ìyìn rere bí àwọn tọ̀hún ti gbọ́.
Ẹ̀ ń pa àwọn tí kò yẹ kí ẹ pa, ẹ sì ń dá àwọn tí kò yẹ kí wọ́n wà láàyè sí, nípa irọ́ tí ẹ̀ ń pa fún àwọn eniyan mi, tí wọn ń fetí sí irọ́ yín.
Wọ́n bá bi í léèrè pé, “Kí ló dé tí àwọn amòfin fi sọ pé Elija ni ó níláti kọ́ dé?
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ìdílé tí ọkọ da ọmọ síta tóríi ojú Búlùú tí wọ́n ní bá BBC sọ̀rọ̀ Gomina Ọbaseki ṣalaye fun BBC News latẹnu agbẹnusọ rẹ, Crusoe Osagie pe awọn alagbara oloṣelu kan pẹlu gomina ipinlẹ kan lorilẹede Naijiria ni wọn gbimọ pọ lati fẹ fi tipa gba ileegbimọ aṣofin ipinlẹ Edo ki wọn lee da rugudu silẹ ṣaaju idibo gomina to fẹ waye nibẹ lọjọ kọkandinlogun oṣu kẹsan ọdun 2020.
Ọmọ Naijiria toto ẹgberun mefa ati egberin ole mefa (6,806) lo ti pada sile bayi lati orilẹede Libya.
Nigba ti BBC beere pe ki lo ṣe okunfa iṣẹlẹ naa Osanyintolu sọ pe ile yii ti wa lara awọn ile ti wọn ti pinu lati wo teletele.
Eto idibo kiakiaLojo-Aje, awon egbe oselu alatako lorile-ede South Africa pe fun eto idibo kiakia, bi aawo to wa laarin egbe oselu ANC se n gbile si.
Taiwo Akinkunmi, ọmọ Ibadan tó ya àsìá Nàíjíríà Ìròyìn èké lásán ni pé wọ́n yọ mí nínú ẹgbẹ́ YCE - Kunle Olajide Kí ló ń mú olóòtú ìjọba Merkel máa gbọ̀n pẹ̀pẹ̀ lóde?
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Osun Supreme: Àwọn èèyàn Ọṣun rọ Oyetọla láti jẹ́ kí àsìkò rẹ̀ tú aráàlú lára Gẹgẹ bi ajọ eto ilera l'agbaye, WHO, ṣe sọ, obinrin mẹrin ninu mẹwaa nilẹ Afrika lo n lo awọn eroja ibora.
Báyìí ni ìtàn náà ti lọ:
Wọ́n ní, “O mú wa wá láti ilẹ̀ ọlọ́ràá Ijipti tí ó kún fún wàrà ati fún oyin, o fẹ́ wá pa wá sinu aṣálẹ̀ yìí, sibẹ kò tó ọ, o tún fẹ́ sọ ara rẹ di ọba lórí gbogbo wa.
Bi o tilẹjẹpe wọn pada yan an s'ile igbimọ aṣofin, o jẹ gbajumọ laarin awọn talaka, awọn ọmọ South Africa to jẹ alawọ dudu, ati awọn ọdọ.
Chelsea naa fakọyọ nigba ti wọn pokọ iya fun Brighton pẹlu ami ayo mẹta sodo.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Onnoghen: Ọlọ́pàá ti ọ́fíísì adajọ́ àgbà, wọn tún lé àwọn òṣìṣẹ́ rẹ̀ jáde 28 Sẹ́rẹ́ 2019 Igbimọ to n gbọ̀ ẹsun ti wọn ba fi kan awọn to di ipo mu nilu, CCT ti dun igbẹjọ Adajọ agba nigba kan fun Naijiria, Walter Onnoghen siwaju.
Ẹni tí ó tó gbẹ́kẹ̀lé ni Ọlọrun tí ó pè yín sinu ìṣọ̀kan pẹlu ọmọ rẹ̀ Jesu Kristi, Oluwa wa.
Fun Oluwo ati awọn Oba Ile Yoruba, o ni o se pataki lati ni ifikunlukun lori iru igbese yi fun alafia ati isọkan.
Ṣùgbọ́n mo yà sí ọ̀dọ̀ ìyàwó mi nígbà ti a ń padà lọ sí ilé ní odo Ìràntí, o sì fi dúkìá rẹ̀ gbogbo hàn mi, o ni nǹkan tí ó dára ni pé ìgbà tí èmi àti àwọn ọdẹ bá padà dé ìlú wa, tí mo jíṣẹ́ fún ọba wa tán, ki ń padà wá sí ọ̀dọ̀ òun kí a jọ máa gbé aafin oun.
Ó ti pẹ́ tí ó ti fi aṣọ kanra gbẹ̀yìn, kò sì lè gbé inú ilé mọ́, àfi ní itẹ́ òkú.
Ìjọba Èkó figbé ìkìlọ̀ ta Hubert Ogunde rèé, baba àwọn òsèré tíátà Lara awọn èèwọ̀ rẹ gẹgẹ bi Ọba ree: Ko gbudọ kunlẹ ki ẹnikẹni koda ko jẹ iya rẹ.
Ṣugbọn iṣẹlẹ yii ko dabi ti tẹlẹ mọ, lati ọdun 2000, igba mejilelogun lawọn ologun ti gbiyanju lati gbajọba.
Ìbànújẹ́ ni ó jẹ́ fún mi pé nígbà tí mò ń ti Padani-aramu bọ̀, Rakẹli kú lọ́nà, ní ilẹ̀ Kenaani, ibi tí ó dákẹ́ sí kò jìnnà pupọ sí Efurati.
"Ní ti Alex Iwobi o ní "" ẹ jẹ́ ki a fí iyẹn sí ẹ̀gbẹ́ kan (ọ̀rọ̀ lóri owó ajẹmọnu tó n dá wàhálà sílẹ̀)láàrin ara wa, sùgban ǹkan to ṣẹlẹ̀ ni pe ǹkan ti a ba ṣe lóri pápá lo ṣe pàtàkì jù, kó si ǹkan ti yóò gbe oju wa kúro láti ṣe aṣe ọri, inú gbogbo wá lo dùn Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!"
Àkọlé àwòrán, Agbára ju agbára lọ: Wo bàbá Godwin to pe òjò Awọn ènìyàn míràn máa ń mú kí òjò rọ lásìkò tí wọn bá ń fẹ, ti àwọn ènìyàn sì máa ń kà wọn kún alágbara ẹ̀dá tó lè mú kí òjò rọ tàbí kí òjò dá.
Bí àwọn ọmọ ogun ọba Sodomu ati àwọn ọmọ ogun ọba Gomora ti ń sálọ, àwọn kan ninu wọn jìn sinu àwọn ihò náà, àwọn yòókù sá gun orí òkè lọ.
Aare Muhammadu Buhari lo so eleyii  nibi oro ikeyin to so nile aare  to wa niluu Abuja lasiko eto idagbere ti won se fun asoju  orile ede Britain, Paul Arkwright, lojo Aje, ti o n pada lo siluu re .
Nígbà tí ọmọkunrin náà rí i pé Saulu kú, òun náà fa idà rẹ̀ yọ, ó ṣubú lé e lórí ó sì kú.
Kí oore-ọ̀fẹ́ Oluwa wa Jesu kí ó wà pẹlu yín.
Tabi pé, oriṣa kan ti dìde rí, tí ó gbìdánwò àtifi ipá gba orílẹ̀-èdè kan fún ara rẹ̀ lọ́wọ́ orílẹ̀-èdè mìíràn, pẹlu àmì rẹ̀, ati iṣẹ́ ìyanu, ati ogun, ati agbára ati àwọn nǹkan tí ó bani lẹ́rù, gẹ́gẹ́ bí ẹ ti fi ojú yín rí i tí OLUWA Ọlọrun yín ṣe fun yín ní Ijipti?
Lẹ́yìn náà, OLUWA sọ fún mi pé, “Mú ìwé kan tí ó fẹ̀, kí o kọ Maheriṣalali-haṣi-basi sí i lórí gàdàgbà gàdàgbà.
Ajẹ́pé ẹ jẹ́ ká dúpẹ́ lọ́wọ́ Yorubaname.
Ẹ máa yọ̀ ninu OLUWA;ẹ fò fún ayọ̀, ẹ̀yin olódodo;kí ẹ sì hó fún ayọ̀, gbogbo ẹ̀yin ọlọ́kàn mímọ́.
N óo sọ ìlú Raba di pápá àwọn ràkúnmí, àwọn ìlú Amoni yóo sì di pápá ẹran.
kí ohun ìrúbọ náà baà lè jẹ́ ìtẹ́wọ́gbà, ó níláti jẹ́ akọ, tí kò ní àbùkù, ó lè jẹ́ akọ mààlúù, tabi àgbò, tabi òbúkọ.
Lẹ́yìn náà ó pada pẹlu àwọn iranṣẹ rẹ̀ sọ́dọ̀ Eliṣa, ó ní, “Nisinsinyii ni mo mọ̀ pé kò sí ọlọrun mìíràn ní gbogbo ayé àfi Ọlọrun Israẹli.
Ìyẹn ni pé AIDS fúnrarẹ̀ kọ́ ni nsẹkú pani, bí kìí ṣe ìyà nlá tó gbéni ṣánlẹ̀, tí kékèké wá ngorí ẹni.
N kò ní jẹ́ kí kòkòrò ajẹnirun jẹ ohun ọ̀gbìn yín lóko, ọgbà àjàrà yín yóo sì so jìnwìnnì.
Ọkùnrin kan tó yasó nínú ọkọ̀ Uber rí ẹ̀wọn he Àṣé àṣírí wà nínú Hijabu tí Aisha Yesufu ń wọ̀ lọ ìwọ́de Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí EndSWAT: Wo àwọn Májẹ̀kóbàjẹ́ tó wà nídìí ìwọ́de #EndSARS / End SWAT16 Ọ̀wàrà 2020 Fídíò, Soyinka Cancer: Àṣe ara mi ni iso ti n run gbogbo bí mo ṣe n ṣèrànwọ́ lórí jẹjẹrẹ27 Bélú 2019 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
O ni igba to lọ fi ẹjọ sun awọn aṣiwaju awọn Fulani naa ni wọn de e mọlẹ wọn si tẹẹ pa.
Àkókò òtútù ti lọ,òjò sì ti dáwọ́ dúró.
Ipinlẹ Zamfara ti wà lábẹ ìdámu àwọn adigunjale láti ǹkan bi ọdun díẹ̀ sẹyìn, sùgbọ́n ó dàbi éni pe o ń peleke síi ni ọdun 2019 yìí.
Mo fẹ́ kí ẹ mọ̀ dájúdájú pé ìran yìí ni yóo fi orí fá gbogbo ẹ̀bi yìí.
Awọn eeyan meji yoku to n kawọ pọnyin rojọ pẹlu Akala ni kọmisọna tẹlẹ fọrọ ijọba ibilẹ ati oye jijẹ nipinlẹ Ọyọ, Senator Hosea Ayọọla Agboọla ati gbajugbaja olokoowo kan nilu Ibadan, Fẹmi babalọla.
" Mama Tani salaye siwaju pe idi ree ti oun se fi email sọwọ si olukọni naa pe, se yoo gba Tani lati darapọ mọ ẹgbẹ alayo Chess wọn.
Ẹ̀yin ni ẹ óo máa jẹ ọrọ̀ àwọn orílẹ̀-èdè mìíràn,ọrọ̀ wọn ni ẹ óo sì máa fi ṣògo.
Gomina Jubrilla Bindow si ni ibo 334,995.
Ẹ̀yìn ò rẹyìn Dapọ̀ Abiodun ló wolé níbí àtúndi ìbò tí ìgbìmọ amúṣẹ́ṣe àpapọ̀ darí.
Látẹ̀yìnwá, nígbà tí Saulu pàápàá wà lórí oyè, ìwọ ni ò ń ṣáájú Israẹli lójú ogun.
Àwọn ọmọ Israẹli sin Egiloni, ọba ilẹ̀ Moabu, fún ọdún mejidinlogun.
Nígbà tí Jesu wọ ìlú Kapanaumu, ọ̀gágun kan tí ó ní ọgọrun-un ọmọ-ogun lábẹ́ rẹ̀ tọ̀ ọ́ wá, ó ń bẹ̀ ẹ́; ó ní, 
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Mama Arsenal: Màmá àgbà yìí máa ń lọ sí ìbùdó tí wọ́n ti ń wo bọ́ọ́lù láti wòran Nigba to n salaye boya otitọ wa ninu ọrọ kan to n ja rainrain nilẹ pe, oun naa fẹ fi ẹgbẹ oselu APC silẹ lati lọ dije fun ipo gomina ninu ẹgbẹ oselu miran.
Iye àwọn ọmọ Israẹli tí wọ́n pada láti oko ẹrú ní ìdílé ìdílé nìyí:
Ohun tí a óo dà kò ì tíì hàn sí wa.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ikọ̀ ẹlẹ́sìn Hàkíkà rèé, níbití wọn ti ń pààrọ̀ ìyàwó láàrín ara wọn Atagitá Fẹ́mi Aníkúlápó-Kútì bá obìnrin lọ l‘Amẹ́rika Àwọn ọmọ Iyabọ Ojo rí Bàbá lẹ́yìn ọdún mẹ́fà NFF bẹ̀rẹ̀ ìwáàdí olùkọ́ni Super Eagles lórí ẹ̀sun rìbá Buhari di alága àjọ Ecowas Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ìbaàrún pe ọdún kan Isoro kan gboogi to n fa idaduro nibi idije naa ni pe, papakọ ofurufu ti wọn fẹ balẹ si kere, eyi to mu ko ṣoro fun awọn baalu nla lati balẹ si bẹ.
O sọ pe Cameroon tuntun ti yoo faramọ bi nkan ṣe ri lasiko yii, ati afojusun fun ọjọ iwaju, ti n bẹrẹ.
Sùgbọ́n kò tán síbẹ̀ àtolówó àtolòsì ló ni orúkọ àrà ọ̀tọ̀ tí wọn sọ ojú ara ìbálòpọ̀ wọn, èyí ti wọn ń pè ni 'mele ma'i' Dókítà Milton Diamond, tó jẹ́ onímọ nínú ọnà ti àwọn ènìyàn Hawaii máa ńgba ní ìbálòpọ̀, sàpèjúwe bí Ayaba Lili'uokulani ki ojú ara rẹ̀ gẹ́gẹ́ bí èròjà ara tí ń ṣe fìkìfakà sókèsódò"" Awọn ará Japan kìí fi bẹ́ẹ̀ ní ìbálòpọ̀ ní tiwọn Oríṣun àwòrán, Getty Images Japan tún jẹ́ orílẹ̀-èdè kan tó tí fí àdíkù bá ọmọ bíbí."
Ọba bèèrè lọ́wọ́ rẹ̀ pé “Ṣé ìwọ ni Daniẹli, ọ̀kan ninu àwọn ẹrú, tí baba mi kó wá láti ilẹ̀ Juda?
Bí irin ti ń pọ́n irin,bẹ́ẹ̀ ni eniyan ń kẹ́kọ̀ọ́ lára ẹnìkejì rẹ̀.
O óo pe àwọn orílẹ̀-èdè tí o kò mọ̀ rí,àwọn orílẹ̀-èdè tí kò mọ̀ ọ́ rí yóo sáré wá sọ́dọ̀ rẹ,nítorí OLUWA Ọlọrun rẹ,ati nítorí Ẹni Mímọ́ Israẹli, tí ó ṣe ọ́ lógo.
 “Bi mo se maa n so, a ko ni orile-ede miiran ju orile-ede Naijiria lo; e mase je ka ba orile-ede yii je nitori oselu tabi ife okan wa.
Dino Melaye gan ló ké gbàjare síta pé, àyínikè, àti àdàmọndi fọtọ ló jẹyọ lórí ayélujára nítori pé, òun kò mọ ọmọbinrin náà ri.
Aare orile-ede Naijiria, Muhammadiu Buhari ti tenumo ipinnu isakoso isejoba re lati tesiwaju ninu mumu idagbasoke ati fifi ese isokan mule sinsin lorile-ede Naijiria.
Awọn obinrin mẹrin pẹlu Olufunmilayọ Ransome-Kuti ni wọn yan si ara igbimọ ijọba ibilẹ, ti wọn si fi ofin de ki obinrin maa san owọ orí.
Ewe, ti a ba ranti pe, adajo Musa Mohammed Dattijo lo dari igbimo eleni marun un kan tile ejo agba ohun yan lori oro naa, eleyi ti won fenuko lati sun igbejo naa si oni lori esun fifi ipa kede ohun ini re.
owo sinkun mu awon afurasi ajinigbe ti won si gba orisisi ohun ija ogun lowo
Bakan naa lo jẹ pe ohun ni ogbontagi agbabọọlu, Pele, wọ gbẹyin ko to o fẹyinti lẹ́nu bọọlu gbigba.
Òun àti ìyá mi fẹ́ràn ara wọn, wọ́n sì fi àpẹẹrẹ rere lé ilẹ̀ fún awa ọmọ - èyínì ni èmi, Adéyẹmí, Ojúọlápé, àti Ọmọ́túndé.
Awọn onimọ ti wa sọ pe, ọna kan ṣoṣo lati doola ẹmi awọn ọmọde lọwọ aisan lọjọ iwaju, ni kawọn obi wọn dẹkun siga fifa.
United States: Ni orilẹede Amẹrika, bii ọgọta ẹgbẹrun dola to jasi ẹgbẹrun mẹtalelogun naira l'awọn olopaa n gba bi o tile jẹ pe eyi a maa yatọ lati ipinlẹ si ipinlẹ ati bi iriri wọn lẹnu iṣẹ ba ti ṣe pẹ sii.
Ọ̀gbẹ́ni Okoduwa sọ̀rọ̀ òhún ní ìlú Benin lásìkò tí wọn ń ṣe ìpolongo ìta gbangba kan Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Àṣírí ìfàyàwọ́ ọmọnìyàn tú nílé ẹ̀ka kan nípìlẹ́ Edo Ó ní ìjọba ìpínlẹ̀ Edo kò ní fààyè gba irú ìwà búburú báyìí láti tèsíwájú nípìnlẹ̀ náà O ni ìjọba yóò fí irú nkan báyìí kún àwọn ìpolongo ìta gbangba tí wọn ń ṣe kí àwọn ará ìlú leè dẹ́kún fàyàwọ́ ọmọnìyàn, àti pé àjọ ìjọba tó ń rí sí gbígbígun ti fàyàwọ́ yóo máa tọ pinpin àwọn ọ̀bàyéjẹ́ ọ̀hún.
Mo rán àbúrò rẹ̀ padà, mo sì yára kọ̀wé kékeré kan wí pé inú mi ti dùn tó bẹ́ẹ̀ ti n kòí tíì lè fèsì nígbà náà, àti pé Ìfẹ́pàtàkì máa retí ìwé mi náà lóòótọ́.
Guru Maharaji ṣàlàyé fún aṣojúkọ̀ròyìn BBC Yorùbá, Adédayọ̀ Òkédáre, pé àwọn tó gbé ìròyìn ẹlẹ́jẹ̀ jáde pé òun ti kú kò mọ̀ pé iná tí a bá dá de igún, ẹyẹ míràn níí yáa ni.
N óo kó wọn pada sí ilẹ̀ wọn láti ilẹ̀ Ijipti wá,n óo kó wọn jọ láti ilẹ̀ Asiria;n óo sì kó wọn wá sí ilẹ̀ Gileadi ati ilẹ̀ Lẹbanoni,wọn óo kún ilẹ̀ náà tóbẹ́ẹ̀ tí kò fi ní sí ààyè mọ́.
Jakọbu bá dá Labani lóhùn, ó ní, “Ẹ̀rù ni ó bà mí, mo rò pé o óo fi ipá gba àwọn ọmọ rẹ lọ́wọ́ mi.
Sheik ni asiko yi lo yẹ ki awọn eeyan, papa awọn Musulumi ma ro ọjọ atisun, ki wọn si sun mọ Ọlọrun ati awọn ẹbi wọn.
Afeez to sọ ọrọ yii lasiko to n kopa lori eto BBC Yoruba loju opo Facebook ni, bi iṣesi yii ko ba dẹwọ, o le ṣe akoba fun idagbasoke ede Yoruba.
Obìnrin náà sì fa ìwé ńlá kan yọ ó fi han kìnnìún yìí, àṣé ìwé àṣẹ tí ó ní èdìdì Ọlọ́run ni èyìínì, ìgbà tí ó fi eléyìí han ẹranko náà, ilẹ̀ mì tìtì, ilẹ̀ la ẹnu, kìnnìún idẹ nì sì bá inú ihò ilẹ̀ lọ.
Ó dá mi lóhùn pé, Betueli ọmọ Nahori, tí Milika bí fún un ni baba òun.
 wón bí adler ní 1870 .
Wo àwọn tó ti dákú bíi Maina níwájú ìjẹ́jọ́ Irikefe lo tọ ile ẹjọ naa wa pe ko kede pe banki CBN ko lẹtọ lati maa yọ lara owo ti banki Zenith ba fi pamọ sọdọ rẹ tabi gba aadọta naira lori ẹgbẹrun kan naira bii owo sitanpu.
Joseph wi pe wọn ti fi panpẹ ọlọpa mu Usman ati awọn ọrẹ rẹ, sugbọn ọwọ sikun wọn ko tii mu fulani darandaran naa.
Yóo pa wọ́n run, kò ní dáwọ́ dúró láti má gba ẹ̀san lára gbogbo àwọn tí wọ́n kórìíra rẹ̀, yóo san ẹ̀san fún wọn ní ojúkoojú.
O ni oloogbe padanu ẹjẹ to pọ ki wọn to gbee de ile iwosan.
labaa lati fi kun owo-ori oja (VAT).
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Akomolede ati Aṣa: Mọ̀ síi nípa ìró afárànma àti agbárànmọ́ fáwẹ́ẹ̀lì Yorùbá Bakan naa ni wọn tun fi ẹsun iwa ibajẹ lọfiisi kan Adekolawole pe niṣe lo lọ gbe bẹẹdi nla sinu ọfiisi rẹ eyi ti yoo jẹ ko maa sun lẹnu iṣẹ.
Èyí yóo máa jẹ́ ẹbọ sísun, olóòórùn dídùn sí OLUWA.
Tí a fiṣọwọ́ ní 14:47 14 Sẹ́rẹ́ 202114:47 14 Sẹ́rẹ́ 2021 Covid-19 pa Ọlọ́lá Akin Olugbade, ẹ wo dúkìá jaburata tó fisílẹ̀ Agbẹjọro ni Akin-Olugbade, to si n ṣe idokowo ninu rira ile ati ile kikọ, epo rọbi, ile ifowopamọsi ati bẹẹ bẹẹ lọ, ki iku to mu lọ.
O ṣeeṣe ki bi awọn ipinlẹ kan ṣe n ṣe eto idibo jẹ ki kika idibo naa ya.
” Ó bá sọ ọmọ náà ní Gadi.
APC Crisis: Àwọn ọmọ ẹgbọ́ APC kan ti n yarí nítorí àì tí ṣe ìpàgọ́ ẹgbẹ́
 nílélóko ni wọn ti ń sọdún orò lọ ́ dọọdún .
Ní ìbẹ̀rẹ̀ ìjọba Jehoiakimu ọba Juda, ọmọ Josaya, 
Pẹlu ìgbéraga ni eniyan burúkú fi ń dọdẹ àwọn aláìní;jẹ́ kí ó bọ́ sinu tàkúté tí ó fi àrékérekè dẹ.
“Bákan náà, gbogbo àwọn ọrẹ ẹbọ, ati àwọn ẹbọ fífì tí àwọn ọmọ Israẹli bá mú wá fún mi, yóo jẹ́ tiyín.
Ìdí nìyí tí mo fi ní ìdènà nígbà pupọ láti wá sọ́dọ̀ yín.
 Ó pàdé adẹ ́ mu , Èṣù si jẹ ́ kí ó mu ẹmu yó .
Atari ajanaku Olọrun o mawada Awọn ẹbi ni àwọn yoo kéde ètò ìsìnkú láìpẹ́.
Awọn iroyin ti ẹ lee nifẹ si: Njẹ ọrọ awọn akẹkọbirin Dapchi jọ ti Chibok ?
 Musa Nuhu lo soro yii lasiko
Má gbé ara rẹ lọ́kàn gbóná nítorí àwọn eniyan burúkú;má sì jowú àwọn aṣebi;
Adamu ni awọn ọlọpaa to ti fẹhinti lẹnu iṣẹ gan an yoo ri owo ifẹyinti wọn gba.
Ọ̀rẹ́bìnrin míì dáná sí ọ̀rẹ́kùnrin rẹ̀ lára lẹ́yìn tó kọ̀ láti fẹ́ ẹ gẹ́gẹ́ bí aya Andrew Haruna: So-bàtà tó di ọ̀jọ̀gbọ́n fásitì tó tún jẹ́ ọ̀gá àgbà pátá (V.
Omowe  Muhtar  naa wa gbosuba fun aare Muhammadu Buhari fun
9 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Badirat Ajoke sọ pé òun fínnú-fíndọ̀ fi ààfìn Oyo sílẹ̀ ni, wọ́n kò lé òun9 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Muhammadu Buhari: Amòfin Adebayo wá kábàámọ̀ pé ọ̀pọ̀ nǹkan ni wọ́n ń tọwọ́ òṣèlú bọ10 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
"Oríṣun àwòrán, @nassnigeria Àkọlé àwòrán, ""Ẹrẹ naa kanawọn aṣofin apapọ ti wọn ṣe ayẹwo fun"" Ayẹwo ipilẹ ẹni bẹẹ: ""Lara awọn ohun ti a n wo ni ayẹwo ti awọn agbofinro ba ṣe lori ẹni bẹẹ."
Nígbà tí ó wo àwọn ará Keni, ó fi òwe sọ̀rọ̀ nípa wọn báyìí pé:“Ibi ìpamọ́ tí ẹ̀ ń gbédàbí ìtẹ́ tí ó wà lórí àpáta gíga.
"Iriri obinrin kan, Elmira ree lalẹ ọjọ igbeyawo rẹ: ""Ẹni ọdun mẹtadinlọgbọn ni mi nigba ti mo pari ẹkọ fasiti, awọn obi mi lo wa ọkọ fun mi, ẹni to jẹ aladugbo wa."
Bakan naa lo ni awọn ti setan lati fun ikọ ọmọogun Naijiria ni awọn ohun ija ti wọn nilo lati koju Boko Haram, ati wi pe Ilẹ Gẹẹsi n pe fun itusilẹ gbogbo awọn ti ikọ Boko Haram ti jigbe lagbeegbe Ariwa orilẹede Naijiria.
Ó súre fún wọn, ó ní, “Ẹ máa bímọ lémọ, kí ẹ máa pọ̀ sí i, kí ẹ kún gbogbo ayé.
“Ẹni tí ó bá gba òfin mi, tí ó sì pa wọ́n mọ́, òun ni ó fẹ́ràn mi.
OLUWA bá pèsè ẹja ńlá kan tí ó gbé Jona mì.
Awọn olugbe Akute ni, lati igba ti ọwọ ojo ọdun yii ti n le, ni oloko ko ti lee roko mọ, tawọn ko si lee sun tabi wo nitori isẹlẹ ẹkun omi.
O ti ṣe olóòótọ́ ninu nǹkan kékeré, a óo fi ọ́ ṣe alámòójútó nǹkan pupọ.
Ti ijọba ba ni ki wọn fi owo iranwọ epo rọbi kọ iru ibudo papakọ ofurufu yii, yoo fẹ kọ to ẹgbẹrin iru rẹ.
Won ni ki Gomina ipinlẹ Ekiti wa ṣalaye bó ṣe na owó iṣẹ́ àkànṣe Integrated Poultry Project / Biological Concepts Limited l'Ekiti.
ran won lowo lati tun jara mo ise won, ni eyi ti orile ede Naijiria yoo tun fi
Amọṣa, ayẹwo awakọ rẹ pẹlu arabinrin olutọju rẹ fihan pe awakọ naa ti ko arun Coronavirus, ṣugbọn ayẹwo ti arabinrin naa fihan pe oun ko ni.
 Ẹri itọju arun irufẹ ẹjẹ 6 ko wọpọ , ẹri itọju ti o wa si jẹ bi ọsẹ mejidinlaadọta ni irufẹ iye oògun kanna pẹlu àrùn irufẹ ẹjẹ 1 .
Idi ree ti ẹgbẹ Miyetti Allah to jẹ awọn olusin maalu lorilẹede Naijiria, ti wọn jẹ ẹya Fulani, naa fi n kede faraye pe awọn ko ni gbẹyin nibi ipade ita gbangba lori agbekalẹ ẹsẹ alaabo Amotekun ti yoo waye lọjọ Aje.
39 Nítorí kíyèsíi, àti wòó, Olúwa ni Ọlọ́run, Ẹ̀mí sì jẹ́ri àkọsílẹ̀, àkọsílẹ̀ náà sì jẹ́ òtítọ́, àti pé òtítọ́ náà dúró láé ati títí láéláé.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Dáa padà Buhari, èmi kìí s'ọ̀lẹ Àjọ̀dún ìlù bẹ̀rẹ̀ nílú Abẹ́òkúta Ọbabìnrin fẹ́ k’àrẹ̀mọ gbasẹ Commonwealth Nínú ọ̀rọ̀ kan, BBC ní àwọn kábamọ̀ pé ilé isẹ́ SSBC pinu làti dáwọ́ gbígbóhùnsáfẹ́fẹ́ àwọn ètò BBC fún olùgbọ́ ẹgbẹ̀rún lọ́nà irínwó lórílẹ̀èdè South Sudan dúró.
Nítorí pé wọn kì í tètè dá ẹjọ́ àwọn ẹni ibi, ni ọkàn ọmọ eniyan fi kún fún ìwà ibi.
"Makinde fọ̀rọ̀ yìí léde làsìkò to ń bá àwọn eeyan ilu Ogbomosọ sọrọ nígbà tó lọ sàbẹ̀wò ""ẹ ṣeun, mo dupẹ"" si wọ́n ní ìlú náà, fun atilẹyin ti wọn se fun lasiko eto idibo gomina to kọja."
Ó ń fọ́nnu lásán ni, kò lè ṣe nǹkankan tó yanjú.
Kí ni ó gbé ọlọ́pàá dé ibi àjọ̀dún ọjọ́ ìbí i Bobrisky?
Aare tun wa ro gbogbo omo orile ede
Wọn óo jẹ ẹran-ara rẹ̀, wọn óo bá dá iná sun ún títí yóo fi jóná ráúráú.
Ọjọgbọn Akindele fi oju ba ile ẹjọ ni ọjọ Aje, ọjọ Kọkandinlogun oṣu Kọkanla, lori ẹsun mẹrin to da lori lilo ipo rẹ gẹgẹ bii olukọni ni ẹka imọ nipa akoso ati iṣiro, lati beere fun ibalopọ lọwọ akẹkọ kan ki o lee gba ọna eru fun un ni maaki ninu ọkan lara awọn ẹkọ rẹ.
Eni akọkọ jẹ ọkunrin ẹni ọdun mọkanlelọgọta to ni otutu igba aya to ti jingiri nigba ti wọn gbe de ile iwosan.
Bẹẹ ba gbagbe, ofin konile o gbele naa lo ti kọkọ da awọn awọn eeyan lọwọ kọ lati lọ sibi to jinna, yatọ si ayika wọn.
“Bí oówo bá sọ eniyan lára, tí oówo náà sì san.
O mọ ẹ̀gàn mi,o mọ ìtìjú ati àbùkù mi;o sì mọ gbogbo àwọn ọ̀tá mi.
Femi Okunronmu sọ pe ni ilẹ Afirika, iṣejọba awọn amofin lo le kapa bi awọn adari ni ilẹ Adulawọ se fẹran lati maa di ipo mu fun ọpọlọpọ igba.
Nigeria vs Seychelles: Ikọ Super Eagles bori Seychelles pẹ̀lú 3-1 nínú ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ AFCON
Nítorí náà OLUWA ti gbé ọ̀tá dìde sí wọn:Ó ti rú àwọn ọ̀tá wọn sókè sí wọn:
Ṣugbọn bi ijọba ṣe sun gbedeke ọsẹ meji yii siwaju fun ọsẹ meji miiran, n kọ ọmọ Naijiria lominu wipe, o seeṣe ki aṣẹ naa ma fẹsẹ mulẹ.
’ Lẹsẹkẹsẹ wọn yóo jẹ́ kí ẹ mú wọn wá.
Ile ẹkọ College of Agriculture, Igboora ti yipada si Lam Adesina College of Agriculture, Igboora.
Ọkan lara awọn adari ẹgbẹ awọn oṣiṣẹ naa lo sọ fun BBC News Hausa pe awọn ko i tii ri iwe ipẹjọ ileẹjọ kankan to sọ wi pe ki awọn ma gunle iyanṣẹlodi.
Nínú fídíò náà, tí ó gbé-sórí-áfẹ́fẹ́ ní ọjọ́ 29, oṣù Ọ̀pẹ lẹ́yìn tí ìṣẹ̀lẹ̀ náà ṣẹ̀, arábìnrin Tasić Knežević ṣàlàyé pé bí òun ṣe ń jáde síta nínú ilé ìtajà ńlá náà pẹ̀lú ọ̀pọ̀ àwọn òǹrajà mìíràn ni ẹ̀rọ adènà àfọwọ́rá dún.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Èmi ò kí ń lu ìyàwó mi' O ni ile iṣẹ ijọba naa ni kawọn olugbe ilu Eko maa bẹru lori iroyin kan to gba oju Facebook pe afara naa ti ni iyọnu lawọn ibi kan.
"Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: ""Àhámọ́ ajínigbé ni ń bá wà lónìí, ọ̀pẹ́ awakọ̀ mi"" Kí ló dé tó jẹ́ sọ́ọ̀sì nìkàn ni ìjọba ń tìlẹ̀kùn mọ́ torí Covid-19?"
Rebeka sọ fún Isaaki, ó ní, “Ọ̀rọ̀ àwọn obinrin Hiti wọnyi mú kí ayé sú mi.
Ta ni awàdà rẹ̀ wú u yín lórí jù ní Yollywood?
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Àràmọ̀ǹdà àwòràn láti ilẹ̀ àdúláwọ̀ lọ́sẹ̀ yìí 31 Èbibi 2019 Akojọpọ awọn arimaleelọ awopadasẹyin aworan lati ilẹ adulawọ fun ọsẹ yii.
Wo ohun tó yẹ kóo mọ̀ nípa Notre-Dame tó jóná Naijiria gbọdọ̀ jáwọ́ nínú ìwà rádaràda kí ‘Change’ lè wáyé -Buhari Lẹyin igbeyawo yii ni iyawo ti sọ fun awọn obinrin Bangladesh lati jade gbe igbesẹ to yẹ ki wọn fi yanju ohun to ba wu wọn lọkan.
àwọn ife ati ọ̀pá tí wọ́n fi ń pa iná ẹnu fìtílà; àwokòtò ati àwo turari, àwo ìfọnná tí wọ́n fi ojúlówó wúrà ṣe, wọ́n fi wúrà ṣe àwọn ihò àgbékọ́ ìlẹ̀kùn Ibi-Mímọ́-Jùlọ ati ti ìlẹ̀kùn gbọ̀ngàn Tẹmpili náà.
Bẹẹ ba gbagbe, iroyin kan ti tan kalẹ pe awọn gomina to wa lẹkun Guusu iwọ oorun Naijiria ti gba asẹ ni Abuja lati se agbekalẹ ẹka alaabo alajumọse ọhun.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn òfégè: ìwádìí lórí ayédèrú ìròyìn l'Afirika fún ọdún kan 13 Bélú 2018 Àkọlé àwòrán, Àwòrán ayé Titan kalẹ iroyin ayederu nilẹ Afirika ni awọn kan ti sọ pe o n fa ija ẹlẹyamẹya ati rukerudo laarin awọn oludibo, bẹẹni o n ṣe akoba fun bi owo ṣe lọ soke ti o nlọ silẹ Ile iṣẹ iroyin BBC ṣe iwadi lori iroyin ayederu marun un to ni ipa nla nilẹ Afirika ni ọdun kan ṣeyin.
Bàbá mi kú, kò sówó ni mo ṣe kúrò ní fásitì Ilorin láti fọ gíláàsì ọkọ̀ lójú pópó Adúmáadán ni mí; ọmọ pé síbẹ̀!
Wó ọkùnrin táwọn obìnrin fipá bá lòpọ̀ ní ẹ̀ẹ̀mejì Bí ìyàwó rẹ bá lóyún tàbí bímọ ní ìpínlẹ̀ Oyo, wo bí o ti ṣe lé gba ìsinmi ìtọ́mọ (Paternity leave) Ẹ̀bùn #500,000 wà fún ẹni tọ bá ba wa rí afurasí ikú Akinyẹle tó sọnù- Iléeṣẹ́ Ọlọ́pàá Mo fẹ́ kí Ọlọ́run fún wa ní ọmọ olójú búlúù si lẹ́yìn yìgì - Ọkọ olójú búlúù Adamu Adamu, Minista ètò ẹ̀kọ́ ti fi òfin àátẹ̀lẹ́ síta kí àwọn ilé ìwé lè wọlé Igbimọ ajọ iṣokan agbaye to n ri si ọrọ awọn ọmọde, UNICEF ati WHO sọ pe, diduro sile awọn akẹkọọ ti jẹ ki ọpọ akẹkọọbinrin gboyun, bakan naa lo ti fi ebi pa awọn akẹkọọ.
osu kéje  ni won yoo lọ fun isinmi
Nàìjíríà ní ìgboyà láti kojú ilẹ̀ South Africa - Foluṣọ Philips Ninu ifọrọwerọ pelu awọn akọroyin lo ti ṣalaye pe ko si idi to yẹ ki oun fi tọrọ aforiji lọwọ ijọba tabi ọmọ orilẹ ede Naijiria.
John dara pọ mọ ajọ NNPC lọdun 1974 gẹgẹ bi amoju ẹrọ to si ti ṣamojuto ni ilu Warri ati Kaduna.
Pẹ̀lú ọ̀rọ̀ burúkú tí Channel One gbọ́ lórí ayélujára, Russia sì ní iṣẹ́ ńlá láti ṣe lórí ọ̀rọ̀ ìbádọ́gbà akọ àti abo.
Ṣugbọn àwọn eniyan fi wọ́n rẹ́rìn-ín, wọ́n sì fi wọ́n ṣe ẹlẹ́yà.
Coronavirus vaccine: Kí ló wà nínú àbá àkóso ajakalẹ àrùn tó fi ní àtakò?
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Kíni ìwọ mọ̀ nípa Funmilayọ Ransome-Kuti?
O ni iwa ọmọluwabi sọwọn laarin awọn oloṣelu ni wọn ṣe n kaakiri ẹgbẹ oselu ati wi pe awọn ẹgbẹ oṣelu naa ko ni afojusun ohun ti wọn fẹ ṣe fun ilu, eleyii ti wọn ma n pe ni ''party ideology''.
Ojúkòkòrò rẹ̀ dàbí isà òkú; nǹkan kì í sì í tó o, àfi bí ikú.
Bayii, Alaga APC ipinlẹ Ogun ti fidi ẹ mulẹ fun BBC pe ipinlẹ Ogun ti sun idibo abẹlẹ wọn siwaju nitori pe ilé ìyá ẹgbẹ ko gbe ohun elo ranṣẹ.
Ọga ọlọpàá Reedsburg Timothy Becker ni Kehinde funra rẹ lo wa si ileeṣẹ ọlọpàá lati wa funra rẹ jẹwọ pe ọmọ wọn ti gbẹmi mi ninu ile.
Ile iṣẹ amohunmaworan Nile News ni wọn ti gbe oku oloogbe naa lọ sile iwosan fun iwadii to yẹ.
Ọba Ogunwusi, ẹni to ke gbajare yii tọ aarẹ Buhari lọ lọjọbọ nilu Abuja tun kede pe, awọn ajeji ti gba akoso nilẹ Yoruba, ti ipenija eto aabo to n koju wa si jẹ ara eyi to n koju orilẹede Naijiria lapapọ.
Adedoyin tun fikun pe, ipinlẹ kọọkan ni yoo gba awọn ọmọ ikọ alaabo Amotekun sisẹ, kii se ajọ Dawn rara, amọ ajọ naa ti se agbekalẹ ilana tawọn gomina yoo tọ, nidi gbigba awọn eeyan ti yoo sisẹ bii ikọ Amotekun si ẹnu isẹ.
’’Bakan naa, asoju ohun tun lo anfaani naa lati kii aare ku oriire
Kò ní sí oníṣòwò ní ilé OLUWA àwọn ọmọ ogun mọ́ tó bá di ìgbà náà.
Awọn ọlọpaa sọ nigba naa wipe o dabi ẹni pe asiko baba ti to ni.
Jonathan wa gboṣuba rabandẹ fun IBB fun ifẹ nla to ni si Naijiria ati ipa rẹ lati rii pe orilẹede yii wa ni iṣọkan.
awon egbe oselu mẹ́wàá lo jọ
Bi ala awọn baba nla Yoruba ṣe ti wa n ṣẹ naa lo n mu ki awọn eniyan maa mu ọpọlọpọ ọgbọn ati gbe aṣa Yoruba ga jade.
 ewì rẹ ̀ máa ń kún fún òótọ ́ ó sì máa ń mú ènìyàn lára .
O sì fi ẹnu ko Ọmọ-Eniyan ní ẹ̀rẹ̀kẹ́ láti fi í lé àwọn ọ̀tá lọ́wọ́?
Iru nnkan bayi ko suwọn fara ilu.
Apo awọn eeyan kan si ni owo naa n lọ, eyi ti ko dara to.
Fún àpẹrẹ, àwọn Ìyálóde ni ó njẹ Olóri ọjà ni gbogo ilẹ̀ Yorùbá àti alá-bójútó fún ọ̀rọ̀ obinrin.
 Ìwádìí àìsàn ni nípa àyẹ ̀ wò ẹ ̀ jẹ ̀ , itọ ́ , tàbí itọ ́ fún àkóràn rna nígbà tí ènìyàn ba ṣàìsàn .
Ní agbègbè Champasak, gúúsù Laos, ìtàn àtọwọ́dọ́wọ́ọ ẹranko omi tí ó ti ń dínkù Irrawaddy dolphin àti ẹyẹ Sida ni a ń lò fi ṣe àpèjúwe bí iṣẹ́ ìdarí-omi-ṣíṣàn ṣe ń ṣe àkóbá fún ẹja inú odò Mekong.
Ǹjẹ́ o mọ̀ pé ètò ìdìbò kan wà tí erin àti òkúta Dáyámọ́ǹdì leè yí èsì rẹ̀ padà Tolulope Arotile: Ẹ wo ọgbọ́n tí wọ́n lò láti túfọ̀ ikú Tolu fún bàbá àti ìyá rẹ̀ 'Lẹ́yìn wákàtí mẹ́rin tí mo bá Tolulope sọ̀rọ̀ ni mo gbọ́ pé ó ti wà ní ilé ìgbókùú sí' Awọn obi ọmọ ogun oju ofurufu Naijiria to kú laipẹ yii, Tolulope Arotile, ti sọ pe iku rẹ ju ibanujẹ lọ fun awọn.
84 Gbogbo ọmọ ìjọ tí wọ́n bá ńkúrò nínú ìjọ ní ibití wọ́n ngbé, tí wọ́n bá nlọ sí ìjọ tí a kò ti mọ̀ wọ́n, wọ́n lè gba ìwé ṣíṣe ẹ̀rí pé wọ́n jẹ́ ọmọ ìjọ dáradára ati tí ó nṣe déédé, ìwé ẹ̀rí èyítí ó lè ní ìfọwọ́sí èyíkéyìí alàgbà tàbí àlùfáà kan bí ọmọ ìjọ tí ó fẹ́ gba ìwé ẹ̀rí náà jẹ́ ẹni mímọ̀ fún alàgbà tàbí àlùfáà náà, tàbí kí àwọn olùkọ́ni tàbí àwọn díakonì ìjọ fi ọwọ́ sí i.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Akomolede ati Asa lori BBC: Olùkọ́ Kikelomo Ogunboye tan ìmalẹ̀ sí ìwà olè ọ̀gá ọlọ́pàá Buhari le sọ ipò ààrẹ́ nù tí kò bá yọjú sáwọn aṣòfin - Amòfin Ẹgbẹ́ òṣèlú alátakò takú láti gba èsì ìbò ààrẹ ní Ghana Ọ̀pọ̀ nkan tó n ṣẹlẹ̀ kò jẹ́ kí n gbàgbọ́ pé Naijiria wà ní abẹ́ ìdarí ẹnikẹ́ni - Wole Soyinka Ọmọ ẹgbẹ́ òkùnkùn ṣoro ní Ijebu Ode, ọ̀pọ̀ ẹ̀mí sọnù Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Wọ́n pín ilẹ̀ Gileadi fún àwọn ọmọ Manase yòókù.
Wọ́n ti fi ẹ̀jẹ̀ Ọ̀dọ́ Aguntan ati ẹ̀rí ọ̀rọ̀ tí wọ́n jẹ́ ṣẹgun rẹ̀.
Kí ni ohun tí mo ṣe lẹ́gbẹ̀ẹ́ èyí tí ẹ̀yin ṣe?
Bello pari ọrọ rẹ pe ijọba ipinlẹ Eko ti n ṣiṣẹ takuntakun lati ri pe ọrọ omiyale dohun igbagbe ni ipinlẹ ọhun.
O fikun un oro re pe,“Mo n so fun yin, – e wa sile Afrika, e wa je ounje wa, wo aso wa, abbl”“E je ka jo sise papo,”Davido tun lo anfanni ohun lati kedun pelu D’Banj fun iku omo re, leni ti o padanu omo re lojo Aiku(Sunday), bee si ni, O tun ro awon onkorin nilu okere lati wa sise papo pelu awon onkorin Naijiria ati nile Afrika, ti o si daruko  J.
''Mi o fẹ ki ileeṣẹ ọlọpaa ri iwọde EndSARS gẹgẹ bi ọna lati tako awọn agbofinro bi ko ṣe ọna lati rii pe awujọ wa dun un gbe ju ti bi o ti wa lọ,'' Makinde lo sọ bẹẹ.
Ẹ̀mí láti ọ̀dọ̀ Ọlọrun ni ó fi fún wa, kí á lè mọ àwọn ẹ̀bùn tí Ọlọrun ti fún wa.
Gómìnà bá, Emir ilú Ilesha Baruba ọjọgbọ́n Halidu Abubakar àti ẹbi àwọn tí ẹ̀mí wọ́n sọnù nínú ìṣẹ̀lẹ̀ náà kẹ́dun nínú àtẹ̀jáde ti àkọ̀wé ìròyìn gómínà Rfafiu Ajakaye fọ́wọ́sí.
Ó bá pàṣẹ pé kí àwọn olórí alufaa ati gbogbo ìgbìmọ̀ péjọ.
Sibẹ, kì í ṣe pé ọ̀rọ̀ Ọlọrun ti kùnà patapata.
Wo àwọn ìbejì tó mú ẹ̀dọ̀ àti egungun àyà kan ṣoṣo wá látọ̀run Èèyàn mẹ́tàlélógóje míì ṣẹ̀ṣẹ̀ kó COVID-19 ní Nàìjíríà Atunyan rẹ kan jẹ ko ma da bii pe wọn ko tẹle ilana ni tori oun nikan ṣoṣo naa ni oludije to wa nibi eto idibo naa eyi to waye lori ayelujara nibi ipade banki naa to waye lọjọbọ.
Gbajúmọ̀ agbábọ́ọ̀lù ni ǹ bá jẹ́, ká ní ń ko ṣeré tíátà - Bàbá Wande O wa se ladura ki ọba naa pẹ lori oye ninu ọla nla ati alaafia ti yoo ma fi dari awọn eeyan rẹ.
pe egbe oselu APM ni yoo jawebori ninu eto idibo to n bo.
Nitori naa ti ara rẹ ba n fa tikọ nigbogbo igba kọda lẹyin ti o sun daada doju ami, o se pataki ki moju to dede omi ti o n mu.
“Ìwọ̀n ṣekeli tí wọn ń lò ninu ibi mímọ́ ni kí ẹ máa lò láti wọn ohun gbogbo: Ogún ìwọ̀n gera ni yóo jẹ́ ìwọ̀n ṣekeli kan.
  Ebi á sì ti bẹ̀ẹ̀rẹ̀ sí ní pá ènìà tí kò bá gbé oúnjẹ dání.
"O ni gbogbo iye owo yii ni wọn yoo ṣi pọ eyi ti wọn pe ni ""witholding tax"" lede oyinbo."
– Iyàn ni tàbí ọkà tàbí iṣu tàbí àgbàdo?
 Nigbati Gabon ati Cameroun yoo jo maa koo pa lasiko kan naa ni Port Gentil.
Lootọ mo ti gba kadara, a ti pe mo ti pade ọkunrin mi i to nifẹ mi, to si mọ nipa aarun mi.
Àwọn eniyan náà dáhùn pé, “Rárá o, o kò rẹ́ wa jẹ rí, o kò ni wá lára, bẹ́ẹ̀ ni o kò sì gba ohunkohun lọ́wọ́ ẹnikẹ́ni rí.
Ọ̀lẹ a máa sọ pé, “Kinniun wà níta!
Asaraya ni baba Amaraya, Amaraya ni ó bí Ahitubu; 
Ọ̀rọ̀ tí OLUWA sọ nípa Israẹli ati Juda nìyí:
A jọ ṣe ìyàwó pọ̀, a jọ bímọ ní ọjọ́ kan náà, a tún jọ máa ń ṣàìsàn pọ̀ ni Wòólì Ajayi kú ní ìlú Àgelú, òkú rẹ pòórá, ìjọ sin pósí lásán!
Aarẹ Buhari ni, o yẹ ki ijọba tubọ se agbeyẹwo atubọtan titọwọ bọ iwe adehun naa lori ọrọ aje ati eto aabo lorilẹede Naijiria.
Ìjọba paṣan ní Nàìjíríà dibo fún, yóò kàn gbogbo wà - Sowore 'Ohun tó ṣẹlẹ̀ sí Ezekwesili kò le ṣẹlẹ̀ sí mi' #BBCNigeria2019 Duro Ladipọ, ìlúmọ̀ọ́ká òṣèré tíátà àti ọmọ àlúfà tí kò gbàgbé àṣà ìbílẹ̀ Gẹgẹ bi igbimọ alaṣẹ ṣe sọ ọ, wọn ni ki Sowore lọ simi latari ẹsun ṣiṣe ohun to lodi si ofin ẹgbẹ, ṣiṣe owo baṣu baṣu ati pe o kuna lati pe ipade igbimọ.
Ironside ṣalaye pé ọmọ kan ninu ọmọ mẹta ti a bi ni Naijiria lo maa n ṣalaisi lataari awọn aisan to ṣee dena ni eyi ti o n mu ẹdinku ninu ẹmi gigun ba wọn.
Wọn ni suuru gidigidi ni awọn fi n ba awọn ọmọ Egypt gbe, ti ihuwasi ati asa wọn si yatọ gedegede si ti awa ọmọ Naijiria.
Nígbà tí mo lọ sí ẹnubodè ìlú,tí mo jókòó ní gbàgede,
” Saulu rò pé àwọn ará Filistia yóo tipa bẹ́ẹ̀ pa Dafidi.
N kò tilẹ̀ yẹ ní ẹni tí wọn ìbá máa pè ní aposteli, nítorí pé mo ṣe inúnibíni sí ìjọ Ọlọrun.
Mọlẹbi rẹ kan, alufaa meji ati olukọ kan ni awọn mẹrin to ka pe wọn ti fipa ba oun lo pọ rí.
Inu ọkan wa ni awa naa ti fẹ maa fi ẹhonu han.
" Àwọn kòkòrò àrùn àìlèfojúrí tí ó jẹ ́ ẹbí kan náà a má a fa ikọ ́ àwúgbẹ àti ẹ ̀ tẹ ̀ ( "" m."
Má jẹ́ kí àwọn eniyan láàrin àwọn orílẹ̀-èdè yòókù bèèrè pé,‘Níbo ni Ọlọrun wọn wà?
Iṣẹlẹ ijamba ina naa sọ ni idaji ọjọru lori ọkan lara awọn ọpa epo ajọ naa kan ti awọn ọbayejẹ ti bajẹ.
Kò dín ní èèyàn mọkànléláàdọ́ta tó j'Ọ́lọ́run nípè ní ìpìnlẹ̀ Kaduna, àwọn t'ọ́rọ̀ ṣojú wọn ló sọ bẹ́ẹ̀.
Sọ asọtẹlẹ ifẹsẹwọnsẹ to n bọ lọna 19/07/2019 Awọn ikọ Senegal vs Algeria Yege O sọ asọtẹlẹ pe Senegal yoo bori Algeria.
Lẹ́yìn náà, láìpẹ́ ẹ óo sì tún rí mi.
(Jesu sọ èyí nítorí wọ́n ń wí pé ó ní ẹ̀mí Èṣù.
àfonífojì Beti Nimra, Sukotu, ati Safoni, ìyókù ilẹ̀ ìjọba Sihoni, ọba Heṣiboni.
Alaafin tilu Ọyọ, Ọba Lamidi Ọlayiwọla Adeyẹmi ti kọkọ kọ lẹta si gomina ipinlẹ Ekiti lori ọrọ naa pe ko maṣe foju ohun to ṣẹlẹ si Emir Kano wo ọrọ aawọ lọbalọba nipinlẹ Ekiti.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Alaafin: Olori Aanu Adeyemi ṣàlàyé ìdí tó ṣe gẹ́ Oba Lamidi Adeyemi ti ìlú Oyo Nkiru ni oun kuro nilee Madaamu toripe ko san owo oṣu oun latọjọ yii ni.
Wo diẹ lara bo ṣe lọ laarin ọsẹ yii lagbo oṣere tiata Yoruba.
Wọn ni idasilẹ ẹgbẹ Hakika yii gan ti n da ẹru ba awọn eeyan Naijiria, eyi to n ran wọn leti bi ikọ mujẹ-mujẹ Boko Haram se bẹrẹ ni ọdun mẹwa sẹyin.
Ìtàkùn rẹ̀ tàn kálẹ̀,wọ́n kọjá sí òdìkejì òkun.
Èéfín iná oró àwọn tí wọ́n bá júbà ẹranko náà ati ère rẹ̀, tí wọ́n gba àmì orúkọ rẹ̀, yóo máa rú títí lae.
OLUWA ni ó lè pa eniyan tán, kí ó sì tún jí i dìde;òun ni ó lè múni lọ sinu isà òkú,tí ó sì tún lè fani yọ kúrò níbẹ̀.
 wọ ́ n jọra nínú ìṣesí wọn .
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Kìí ṣe ọmọbìnrin nìkan ni Ọlọ́run pàṣẹ fún láti pa ìbálé mọ́ Fun oṣu meji bayii inu gbọngan ipade nla to wa ni ileegbimọ aṣofin naa lawọn ọmọ ileegbimọ aṣofin ipinlẹ naa ti n ṣe ipade wọn.
Ètò ìdìbò tí yóò wáyé nínú osù tí ó ń bọ̀ yìí yóò lọ ní pẹ̀lẹ́-kùtù, gẹ́gẹ́ bí Ààrẹ Buhari ti ṣe ìlérí fún ọmọ orílẹ̀-èdè yìí àti àgbáyé.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ìgbátí ìgbámú àná látọwọ́ sọ́jà obìnrin ti bá arákùnrin náà dé iléèwòsàn Ohun miran to ya idije ti ọdun yii sọtọ ni pe awọn olugbe orilẹ-ede Ghana ti dan awọn mejeeji wo ri.
Ṣugbọn bí ó bá kú, á mú ọpọlọpọ èso wá.
Ohun ti wọ́n bá fi ogún ọdún tàbi ju bẹ́ ẹ̀ lọ kọ́, ṣe é bàjẹ́ ni iṣéjú akàn, ṣùgbọ́n lati ṣe àtúnṣe lè gba ọ̀pọ̀lọpọ̀ ọdún bakan na a.
"Kọmiṣọna ni '""ọrọ naa jẹ ọrọ to mumu layaa ọga agba awọn ọlọpaa, Muhammed Adamu to si ran ikọ akọṣẹmọṣẹ lọ si ilu Benin lati lọ ṣiṣẹ pẹlu awọn ọlọpaa wa"" ""Ohun taa n ri lonii jẹ abajade akitiyan awọn ọlọpaa lati de kulẹkulẹ ọrọ yii""."
 lára ìtàn tó fẹsẹ ̀ odùduwà múlẹ ̀ gẹ ́ gẹ ́ bí akọni ìgbà ìwáṣẹ ̀ nílẹ ̀ yorùbá sọ wípé ó jẹ ́ ọmọ ọbaáti ilẹ ̀ lárúbáwá tí wọ ́ n fogun lé kúrò nílùú baba rẹ ̀ nílẹ ̀ mẹ ́ kà tí ó wá di saudi arabia lónìí .
Ko si ẹni to mọ bi iṣẹ ọna naa ti ṣe kangun si filati naa ṣugbọn awọn to ni iṣẹ naa ni ki wọn f'orukọ bo awọn laṣiri.
Ṣugbọn n óo bá ọ dá majẹmu, o óo wọ inú ọkọ̀ náà, ìwọ pẹlu aya rẹ ati àwọn ọmọkunrin rẹ ati àwọn aya wọn.
Aarẹ Mohammadu Buhari fi oye Naijiria to ga julọ (GCFR) da Abiọla lọla lọjọ kejila, oṣu kéfa, ọdun 2018 yii.
Mo n gbaradi lati rinrinajo igbafẹ pẹlu awọn ọrẹ mi l'asiko naa, ọjọ to si fẹ ẹ lọ sile itura naa jẹ ọjọ keji ọjọ ti mo fẹ rinrinajo.
Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí NÍ YÀJÓYÀJÓ Covid 19: Ìjọba ìpínlẹ̀ Ogun pàṣẹ kí wọ́n ṣí gbogbo ilé ìjọsìn, ilé ìgbafẹ́ padà lẹ́kúnrẹ́rẹ́ Lebanon Explosion: Ibùdó tí igba èèyàn ti kú lóṣù kẹjọ ní iná míràn ti jó10 Owewe 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Wọn ti bẹrẹ ere ifẹ wọn lati ọdun 2002 ti wọn si n mura igbeyawo, ṣugbọn ere ifẹ ọhun fori sogi.
Ẹlẹ́wọ̀n Kirikiri tó ń wọ́ke, olùdarí ọgbà ẹ̀wọ̀n ló ṣe onígbọ̀wọ́ fun - EFCC Eku gba ìjọba ní Estonia, ìjọba pàdánù owó gọbọi Ilé ìwòsàn New Jersey ṣ'àṣìṣe ṣiṣẹ́ abẹ kìndìrín fún aláìṣàn l'Amẹrika Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Lẹ́ẹ̀kan sí i, angẹli náà lọ siwaju, ó dúró ní ọ̀nà tóóró kan níbi tí kò sí ààyè rárá láti yà sí.
Yóo kú nítorí àìgba ìtọ́ni,yóo sì sọnù nítorí ìwà òmùgọ̀ rẹ̀.
Iroyin miiran sọ pe ẹrọ ọkọ baalu naa ran ina loju ọna to ti n ba lẹyin to fi agbara kaka ba.
Adura Ẹni tí A Lé ní Ìlú.
Ìjọba pe ẹgbẹ́ yìí ni “afẹ̀míṣòfò” nítorí àtẹ̀jáde orí ẹ̀rọ-ayélujára wọn a sì ti wọ́n mọ́lé fún oṣù 18.
Bakan naa si ni igbimọ oluwadii naa tun da awọn ẹsun mejeeji to ku nu, to si tun kede pe ki ile asofn naa ṣe iwadii bi awọn iwe asiri ile ṣe de ọwọ awọn akọroyin, ki wọn si fi iya jẹ osisẹ to ba jẹbi.
Èmi ni Ọlọrun, kò sí ẹni tí ó dà bí mi.
Mo fẹ́ kí ẹ mọ̀ dájúdájú pé èmi kò mọ̀ yín.
 lẹ ́ yìn èyí ni gómìnà adekunle ajasin bẹ ̀ rẹ ̀ sí ní ṣagbátẹrù iké-ẹ ̀ kọ ́ náà ní kété tí ó gorí oyè àṣẹ ní ọdún 1980 .
Aisha Lawal Oríṣun àwòrán, Aisha Lawal Laarin awọn ọdọ oṣere Yoruba, Aisha Lawal ti di gbajugbaja pẹlu ara ọtọ to n gba fi itumọ si ipa ti wọn ba fun un lati ko ninu ere.
“Ní ọjọ́ náà, n óo gbé àgọ́ Dafidi tí ó ti wó ró.
" O ni awon lọ si ode inawo lọjọ kan ni awọn ṣe alapade oloogbe Lekan Lekinson ati Remi Shittabe, ti wọn si gba awọn nimọran lati dara pọ mọ ẹgbẹ tiata kan, ti awọn si dara pọ mọ ẹgbẹ tiata Fadeyi Caucus, ibẹ si ni awọn ti rí oloogbe Alaran, tii ṣe ẹgbọn Kamilu Compo lati ilu Oyo, amọ o ni o kọ lati gba awọn sinu ẹgbẹ naa.
Oríṣun àwòrán, Oyo Affairs Lasiko to n sọrọ lati ẹnu Igbakeji Olori oṣiṣẹ, Ọgbẹni Abdulmojeed Mogbonjubola l'Ọjọbọ, gomina sọ pe, ipinnu oun lati mu idagbasoke ba ẹka naa, lo fa igbesẹ ayipada ti oun gbe.
Ọba mú òrùka tí ó gbà lọ́wọ́ Hamani, ó fi bọ Modekai lọ́wọ́.
Ahabu kó sinu kẹ̀kẹ́ ogun rẹ̀, ó sì pada lọ sí Jesireeli.
A óo bá àwọn ọmọ Israẹli jagun ní pẹ̀tẹ́lẹ̀; láìsí àní àní, a óo sì ṣẹgun wọn.
O tẹsiwaju ninu ọrọ rẹ pe Ghana nifẹ si ibasepọ to wa laarin orilẹ-ede mejeeji.
Lateef Adedimeji rèé tó mú omi lójú àwon òbí rẹ̀ lọ́jọ́ ẹ̀yẹ Oríṣun àwòrán, @adedimejilateef Opin ọsẹ to kọja yii ni gbajumọ oṣere tiata Yoruba, Adedimeji Lateef ṣe ayẹyẹ ọjọ ibi ọdun kẹrinlelọgbọn rẹ loke eepẹ.
 Ogbeni Laolu Akande to ke oluranlowo agba fun Adele aare lori eto iroyin ati ifitonileti gbogbo naa so eyi ninu ero ayelujara re.
Ká ní ọmọ Buhari fẹ́ mi, màálù 150 ní màá fi dána - Olólùfẹ́ míì tó tún yọjú Tinubu, yé é sọ̀rọ̀ abẹ́lẹ̀, bọ́ sí gbangba láti bèèrè àtúntò Nàíjíríà lọ́dọ̀ Buhari - Afẹnifẹrẹ Ọjọ́ Ìṣẹ́gun yóò ro lásìkò ìwọ́de lórí èlé owó epo - Ẹgbẹ́ òṣìṣẹ́ Ènìyàn 162 ló tún ṣẹ̀ṣẹ̀ kó àrùn Coronavirus ní Nàìjíríà ní Àbámẹ́ta Nigba to n sọrọ lori pe awọn oloṣelu ti rapala wọ ẹgbẹ YWC, Adeniyi ni ko ṣeeṣe ki awọn oloṣelu darapọ mọ ẹgbẹ naa nitori awọn oloṣelu lo sọ orilẹ-ede naa di bo ṣe wa loni.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Emir of Kano: Gómìnà Kaduna, El-Rufai fi ipò kejì dá Sanusi lọlá láàrin ọjọ́ méjì 11 Ẹrẹ̀nà 2020 Oríṣun àwòrán, Faceboo/Nasir El-Rufai Emir ilu Kano tẹlẹ, lamido Sanusi tun ti gba oye miiran lẹyin ti ijọba Gomina Abdullahi Ganduje rọ loye lọjọ Aje.
Awọn iwadii kan si ti fihan pe bi ìdá ọgọrin awọn to ni aarun naa ni ko ni fi ami rẹ han, tabi ni ami diẹ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, World TB Day: Funkẹ Dosunmu ni ikọ́ ife kìí pani, ta bá lo òògùn rẹ̀ déédé Ni ipinlẹ Sokoto, ọrọ ko ri bakan naa o pẹlu oniruuru iwa ipa ti iroyin ṣalaye pe o waye nibẹ.
Ní àkókò náà mo rí àwọn ọmọ Juda tí wọn ń fún ọtí waini ní ọjọ́ ìsinmi, tí wọ́n sì ń kó ìtí ọkà jọ, tí wọn ń dì wọ́n ru kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́, tí wọn sì ń gbé waini, ati èso girepu, ati igi ọ̀pọ̀tọ́ ati oríṣìíríṣìí ẹrù wúwo wá sí Jerusalẹmu ní ọjọ́ ìsinmi, mo bá kìlọ̀ fún wọn nípa ọjọ́ tí ó yẹ kí wọ́n máa ta oúnjẹ.
Obìnrin kan bí ibejì lẹ́yìn ọjọ́ 26 tó bí ọmọkùnrin Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Àwọn ọkùnrin sọ èrò wọn lórí àríyànjiyàn ẹni tó ni ọyàn obìnrin láàrin bàbá àti ọmọ.
Ipinlẹ Eko, ti a mọ si Lagos State Neighbourhood Safety Corps (LNSC)  ni ẹtọ lati maa lo awọn nnkan ija lati le
Kùrù-kẹrẹ Coronavirus ṣeéṣe kó dópin láàrín ọdún méjì - WHO Géńdé agbébọn yabo àgọ́ ọlọ́pàá n‘Ibadan, ẹ̀mí ọlọ́pàá kan bọ́ Ọba Ilorin ló pàṣẹ pé kí ń padà sọ́dọ̀ ọkọ mi - Risikat olójú búlúù NCDC kéde èèyàn 340 míràn tó ṣẹ̀ṣẹ̀ lùgbàdì Covid-19 ní Nàìjíríà A fí ara mọ́ ìdájọ́ ikú Sharia tó tọ́ sí Olórin Yahaya- ẹgbẹ́ Amòfin Mùsùlùmí ẹ̀ka ìpínlẹ̀ Kano Ọkan lara awọn eeyan naa, tii tun se olufẹ ẹgbẹ oselu alatako lorilẹede naa, Mariam Cisse to ba BBC sọrọ ni Inu mi dun ladunju, a bori."
A wá ṣe ètò ìrètí tí ó dára ju òfin lọ nípa èyí tí a lè fi súnmọ́ Ọlọrun.
Rivers nibi ti isele buruku naa ti waye”.
Nítorí OLUWA ti dá ohun titun sórí ilẹ̀ ayé,bíi kí obinrin máa dáàbò bo ọkunrin.
Olójúkòkòrò eniyan a máa dá ìjà sílẹ̀,ṣugbọn ẹni tí ó gbẹ́kẹ̀lé OLUWA yóo ṣe rere.
Ǹjẹ́ nisinsinyii, kí Ọlọrun Baba wa fúnrarẹ̀ ati Oluwa wa Jesu kí ó tọ́ ẹsẹ̀ wa sí ọ̀nà dé ọ̀dọ̀ yín.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Òní ni àyàjọ́ ọjọ́ tí àwọn akẹ́kọ̀bìnrin Chibok sọnù 13 Ìgbé 2018 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ẹgbẹ BBOG se àyàjọ́ ọjọ́ tí àwọn akẹ́kọ̀bìnrin Chibok sọnù Ni ọjọ kẹrinla oṣu kẹrin, ọdun 2014, nileewe girama awọn obinrin ni ilu Chibok, nipinlẹ Borno, awọn akẹkọbinrin kan nṣe idanwo aṣekagba girama wọn lọwọ pẹlu ireti pe esi idanwo ayọ ni adura to ku fun wọn lẹyin eyi.
Ohun mẹ́wàá tó yẹ kóo mọ̀ nípa Kunle Afod Fasiti Kaduna ni ki olùkọ́ lọ rọọ́kún nílé látààrí ẹ̀sùn pé ó ń dúnkookò mọ́ akẹ́kọ̀ọ́ Ìlé ẹjọ́ ti pàṣẹ pé kí ilé iṣẹ́ ọ̀lọ́pàá dá ìgbaniwolé dúró Wo àdéhùn méje tí Buhari ṣe pẹ̀lú ilẹ̀ Russia Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Amọṣa ẹgbẹ naa yi pada di agbebọn ninu ilepa awọn afojusun rẹ.
Japan Visit: Ààrẹ Shinzo Abe kéde $413,000 owó ìrànwọ́ fún Nàìjíríà
Bi ere itage lo ri ni Ọjọ Aiku nigba ti Alaga ẹgbẹ oṣelu APC tẹlẹri, Adams Oshiomole ati oludije ẹgbẹ oṣelu APC, Osagie Ize-Iyamu kunlẹ lori ẹsẹ mejeeji fun awọn eniyan ni asiko ti ẹgbẹ oṣelu APC lo ṣe ipolongo rẹ ni ilu Benin.
Ṣugbọn nisinsinyii, wọn kò ní àwáwí fún ẹ̀ṣẹ̀ wọn.
 O ni, “o ti sọ gbogbo ipinlẹ yii ibi ti iṣẹ idagbasoke ilu ti n lọ kaakiri.
asofin lati fi ehonu han lori isele naa, nigba ti awon akegbe won to je okunrin
Ẹni tí ó bá pàdánù ẹ̀mí rẹ̀, yóo gbà á là.
Bakan naa ni wọn fun Nnamdi lọrun, ti Fada Obiekezie si n pariwo fun wọn lati dẹkun ikọlu naa sugbọn se ni wọn kọju ija si oun naa, ti wọn si gba ẹrọ ibaraẹnisọrọ rẹ pẹlu.
Efuraimu yóo sọ pé, ‘kí ni mo ní ṣe pẹlu àwọn oriṣa?
Inú bí ọba gidigidi, ó sì pàṣẹ pé kí wọ́n kó àwọn mẹtẹẹta wá siwaju òun, wọ́n bá kó Ṣadiraki, Meṣaki ati Abedinego lọ siwaju ọba.
Ìdáhùn nìyíì Lílo nkan ìbomú kò tóò láti dènà pé kóò má á nìí coronavirus Àjọṣepọ̀ wo ló wà láàrín Coronavirus àti Chloroquine?
Ninu ọkọ rẹ ni wọn pa a si pẹlu iru ibọn ti awọn sọja n lo.
Eroja kromosoonu yoo da iṣẹ silẹ Oríṣun àwòrán, Getty Àkọlé àwòrán, Awọn sẹẹli ara n bajẹ bi a ṣe n dagba Awọn eroja DNA ni ideri kan to n bo awọn kromosoonu wa.
Ẹwẹ, aarẹ Buhari tun mẹnu ba isunsiwaju ibo aarẹ fun ọsẹ kan
Ní ọjọ́ kẹrinlelogun oṣù kọkanla tíí ṣe oṣù Ṣebati, ní ọdún keji ìjọba Dariusi, OLUWA fi ìran kan han wolii Sakaraya ọmọ Berekaya, ọmọ Ido.
” Samsoni bá jí láti ojú oorun, ó ní, “N óo lọ bí mo ti máa ń ṣe tẹ́lẹ̀, n óo sì gba ara mi lọ́wọ́ wọn.
Bi iwọde ṣe n waye ni awọn agbegbe bii Lekki nilu Eko, lo n waye ni ilu Abuja ni Onitsha.
 Lojo kerindinlogbon, osu kerin odun nijoba apapo gbe oro owo yiya lati China naa wa siwaju ile $5,851 bilionu owo dola ni won fe ya  lati China Exim Bank ki won le rii fi se abala ti ipinle Eko-Kano, Kano-Kaduna, Eko-Ibadan, ati Eko-Calabar.
Ilé-ìwé Ajégúnlẹ̀ tó ń gba ike rọ́bà fún owó ilé-ìwé 'Ọmọ SS 1 mu èso olómi, ṣùgbọ́n ilé ìwé wa kọ́ ló kú sí' Sultan pàṣẹ fún àwọn mùsùlùmí láti ṣ'ọdẹ òṣùpá lónìí Àwọn òṣìṣẹ́ aláàbò kọlu àwọn tó n ṣe ìwọ́de ní Sudan Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí kan sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
O ni oun ko mọ ẹni to ṣe iṣẹ ibi ọhun, ṣugbọn bi iku ile o pani, tode ko le pani.
''Mo kuku fẹran Bunmi daa,tori wi pe ọrọ to gun,ọrọ igbesi aaye mi lẹ n beere yen'' O salaye wi pe ko si ootọ ninu ọrọ wi pe oun da Bunmi sita pẹlu ọmọ maarun nitori orekelẹwa Dolapo Awosika.
Àrá sán pa ènìyàn mẹ́ta A tún ti ṣàwárí omi àjèjì míràn ní Ilé-Ifẹ̀ - Ọọ̀ni Olórin Makossa, Koffi Olomidé rẹ́wọ̀n he lórí ẹ̀ṣùn ìfipábánilòpọ̀ Deji àti Charly Boy tako ara wọn lórí fọ́nrán tó jáde Iléeṣẹ́ asọ́bodè ṣe agbéga fún òṣìṣẹ́ rẹ̀ tó kọ̀ rìbá Yorùbá, ọmọ ọdún mẹ́jọ tà ọmọ òyìnbò yọ nínú ayò Chess l‘Amẹrika Obasanjo sí Makinde: yàgò fún òṣèlú sọ ọ́ sápò Kínni ó ń fa ilé wíwó?
Bẹẹ, ẹni Ṣango toju ẹ wọlẹ, ko ni ba wọn bu ọba ko so ni, nitori pe Tiffani ni lati igba naa ni oun ko ti le sun dadaa nitori ẹ̀rù.
Ọgbọ́n àti òye ìgbàlódé ni gbogbo èyí jẹ́ tó sì dàbí idán lójú aláìmòye.
Bí mo ti ń wo òde ni imọ̀nàmọ́ná bù lẹ́ẹ̀kọọkan, ibi tí n kò bá sì rí tẹ́lẹ̀ rí, ìgbà tí imọ̀nàmọ́ná bá bù báyìí èmi a rí wọn.
akitiyan láti dènà àrùn náà jẹ ́ nípa lílo ohun èlò ìdáàbòbò láti dènà fífarakanra nígbàtí ènìyàn bá ń ṣiṣẹ ́ pẹ ̀ lú ẹranko tó ti ní àrùn náà lára , fífọwọ ́ ẹni lẹ ́ yìn irú ìfarakanra báyìí , àti nípa dídín àwọn èkúté àti asín kù ní àwọn agbègbè ibi tí ènìyàn ń gbé tàbí tí wọ ́ n ti ń ṣiṣẹ ́ .
A ti ni alakalẹ ati aato lati bẹrẹ didi adagun odo yii tori asiko ojo to n bọ a o si bẹrẹ si ni loo lati pese ina ninu oṣu kejila ọdun 2020.
Àwọn tí wọn ń gba owó iṣẹ́ wọn, inú ajádìí-àpò ni wọ́n ń gbà á sí.
O wa rọ ile isẹ ilẹ China to n se oju ọna naa lati mura si isẹ, ki oju irin naa le see gba fun awọn osisẹ to n sisẹ ni agbeegbe iju ni ilu Eko ati Agbado ni ipinlẹ Ogun.
" Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Odumakin: Naijiria ko gbọdọ ja awọn ọmọdebinrin naa kulẹ nipa ririi daju pe wọn ri wọn gba pada O ni orilẹede Naijiria ko gbọdọ ja awọn ọmọdebinrin naa kulẹ nipa ririi daju pe wọn ri wọn gba pada.
Oríṣun àwòrán, @others Àkọlé àwòrán, A ju ara wa lọ, ijakadi kọ ni idije de duro bayii Ilu Monarco lorilẹ-ede Faranse ni ikede ẹlẹsẹ ayo naa yoo ti waye.
Ṣugbọn nígbà tí ó bá rí ẹ̀jẹ̀ lára àtẹ́rígbà ati lára òpó ẹnu ọ̀nà mejeeji, OLUWA yóo ré ẹnu ọ̀nà náà kọjá, kò sì ní jẹ́ kí apanirun wọ ilé yín láti pa yín.
OLUWA alára ní, “Mo wí, ṣugbọn ẹ kò gbọ́ tèmi; kí ẹ lè fi iṣẹ́ ọwọ́ yín mú mi bínú, fún ìpalára ara yín.
Aláìmọ̀kan ati òmùgọ̀ ni gbogbo wọn,ère kò lè kọ́ eniyan lọ́gbọ́n,nítorí igi lásán ni.
Gomina ti wa paṣẹ pe ki ọkan lara awọn ọga agba ileesẹ igbohunsafẹfẹ naa, Idowu Oguntuaṣe, di Ọga Agba fidiẹ titi ti igbesẹ yoo waye lori abọ iwadi igbimọ naa.
Domestic Chores: Ọ̀pọ̀ àbíkẹ́yìn ń bèèrè pé ṣé ègún ni láti kẹ́yìn nínú mọ̀lẹ́bí?
OLUWA àwọn ọmọ ogun ní, “Ẹ má fetí sí ọ̀rọ̀ àwọn wolii tí wọn ń sọ àsọtẹ́lẹ̀ fun yín, tí wọ́n ń mu yín gbẹ́kẹ̀lé irọ́.
Ní oṣù kẹwaa, ọdún kẹsan-an ìjọba Sedekaya, ọba Juda, Nebukadinesari, ọba Babiloni, ati àwọn ọmọ ogun rẹ̀ gbógun ti Jerusalẹmu, wọ́n sì dótì í.
Kini o kọkọ ṣẹlẹ ṣaaju asiko yii?
 'Èmi àti Toyin Abraham ṣẹ̀ sọ̀rọ̀ fún ìgbà àkọ́kọ́ láti ọdún méjì torí ìjà òun àti Lizzy' Funke Akindele, oníròyìn, agbẹjọrò àti òṣèré; ohun tí ẹ kò lérò nípa rẹ̀ Ààrẹ Buhari balẹ̀ bàgẹ̀ s'Abuja lẹ́yìn ìpádé àjọ UNO l'Amẹrika Kàyééfì rèé!"
Saaju idibo ọdun 2019 awọn olori ẹsin Naijiria kan kede asọtẹlẹ nipa ẹni ti yoo jẹ oye Aarẹ Naijiria, awọn Sẹnẹtọ ti yoo jawe olubori ati awọn ipo miran ninu ijọba lawọn ipinlẹ kan ni Naijiria.
Awọn lọbalọba naa sọrọ gba ẹnu alaga awọn lọbalọba nipinlẹ Ondo, Ọba Frederick Akinruntan to jẹ Olugbo ti Ugbo.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Wo itan omi gbigbona ati tutu ni Ikọgosi Ekiti Iku Henry Oloyede Fajemirokun: Ọjọ nla ni ọjọ Kẹẹdogun, osu Keji, ọdun 1978 ti wọn tufọ iku gbajumọ olokoowo naa pe o ti jade laye.
O pe ara rẹ ní ẹni tí ó lè bá àwọn tí kò gbọ́n wí, olùkọ́ àwọn ọ̀dọ́, ẹni tí ó mọ àwọn nǹkan tí ó jẹ́ kókó ati òtítọ́ tí ó wà ninu Òfin.
Ṣebí o mọ̀ pé, akikanju jagunjagun ni baba rẹ, ati àwọn eniyan tí wọ́n wà pẹlu rẹ̀?
Asa jáde lọ láti bá a jà.
Nítorí gbogbo wa ni à ń ṣe àṣìṣe ní ọ̀pọ̀ ìgbà.
Mose bá jáde kúrò níwájú Farao, ó lọ gbadura sí OLUWA.
Samuẹli bí ọmọkunrin meji: Joẹli ni àkọ́bí, Abija sì ni ikeji.
Ninu ifọrọwanilẹnuwo pẹlu ileeṣẹ BBC, Omotara sọ pe lati alẹ ọjọ ti fọnran fidio naa jade loun ti n sunkun toun ko si ri orun sun.
 osuwon ibimo po gidi ju osuwon iku lo , won je 40.
Okunnu to jẹ ọmọ ile Olokiti, Ijẹru ọja niluu Ogbomoṣo ni, ilu Ibadan ni wọn bi oun si, nibi ti oun ti dagba.
"Irinajo onikaluku yin naa ko ni dojuru o""."
Lẹyin eyi ni Salawa fun ra rẹ wa fi aworan ọhun lede.
Awọn oṣere gangan ti n bọ sori itage pada bayii pẹlu oniruuru sinima to ni akọle awoyanu atawọn eto pataki mii to yatọ si sinima tawọn oṣere gbe ṣe laarin ọsẹ to kogba wọle lọ yii.
Fidio ọhun ti wọn fi sita loju opo ayelujara lọjọru ṣe afihan awọn to ni arun naa pẹlu akọle lorisirisi lọwọ wọ iboju ninu fidio naa.
papa ofurufu orile ede Naijiria pelu balu orisi meji.
Oludari ile-akede Naijiria(Voice of Nigeria),ogbeni Osita Okechukwu so pe ikede idibo aare to waye ni  osu kejila, odun 1993 ,ti aare Muhammadu Buhari  kede re, ti salaye lori esi idibo naa.
Agbabọọlu Brazil tẹlẹ ri orilẹede Brazil to jẹ akẹgbẹ Messi ni ikọ Barcelona, Ronaldinho wa lara awọn to gbagbọ pe Messi kọ ni agbabọọlu to dantọ julọ ninu ere bọọlu.
Fun awọn gbọngan ayẹyẹ bakan naa, awọn ti yoo joko fun ayẹyẹ ko gbọdọ ju ìdá aadọta lọ, asiko ti wọn yoo lo nibẹ ko si gbọdọ kọja wakati mẹta.
Ileeṣẹ ọlọpaa ni awọn ọlọpaa ko ṣ'adeedee lọ si ibi iṣẹlẹ ọhún, wọn ni awọn kan lo ranṣẹ pe wọn pe ki wọn wa pẹtu si ija.
Wọ́n wá ń kígbe pé, “Ti Ọlọrun wa tí ó jókòó lórí ìtẹ́, ati ti Ọ̀dọ́ Aguntan ni ìgbàlà.
Ile Igbimọ Aṣofin Ipinlẹ lorilẹ-ede Naijiria, Aṣofin Mudashiru Ajayi
Àkọlé àwòrán, Ẹgbẹ Boko Haram ti fi adooloro kọlu Unifasiti Maiduguri ni ọpọigba lẹyin Atẹjade naa sọ wipe ileesẹ ọtẹlẹmuyẹ Naijiria (DSS) lo fi irọyin itusilẹ awọn olukọni unifasiti Maiduguri to wa ni ipinlẹ Borno naa to aarẹ Muhammadu Buhari lẹti ni ọjọ abamẹta.
Ẹgbẹ Shiite ni ijọba Naijiria ko bọwọ fun ofin orilẹede naa, eleyi to mu ijọba ma tẹle aṣẹ ileẹjọ wi pe ki wọn fun El-Zakzaky ati iyawo lominira.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Yollywood Yemi Shodimu sọ̀rọ̀ pé àṣìlò ẹ̀bùn kò jẹ́ kí Nàìjíríà dàgbà sókè mọ́ 4 Owewe 2020 Oríṣun àwòrán, Facebook/Yemi Shodimu Odu ni o jẹ lagbo oṣere tiata ni Naijiria kii ṣe aimọ f'oloko.
Mo kí-i yín pẹ̀lẹ́ ẹ̀yin ọ̀rẹ́-ẹ̀ mi àtàtá .
Kí ló dé tí o óo jẹ́ kí ó pa ọ́, tí gbogbo Juda tí wọn kóra jọ sí ọ̀dọ̀ rẹ yóo sì túká; tí àwọn tí wọn ṣẹ́kù ninu àwọn eniyan Juda yóo sì ṣègbé?
Yoruba ni lati taji, loju oorun won ki won fowosowopo lati se ara won
 ara won tún ni dídá ìpínlè méje mó méjìlá tó wà tèlé láti di mókàndínlógún .
Ninu ọrọ tirẹ @fingertrickz ni ọna àbáyọ kan ṣoṣo to yẹ, ni kí ijọba din owo awọn ọmọ ile ìgbímọ asofin ku, ti awọn miran si n fẹdun ọkan wọn han lori ọrọ airiṣẹse, lẹyin ọpọ ọdun ti wọn ti jade ile iwe.
Fayoṣe fẹ́ kí EFCC sàn owó Ìtanràn N20 biliọnu fún òun
Gẹgẹ bi atẹjade ti agbẹnusọ ileeṣẹ ọlọpaa ipinlẹ Eko, Bala Elkana sọ pe awọn gba lati agọ ọlọpaa Oke Odo, ede-ai-yede bẹ silẹ nigba ti Hausa kan to n ṣa ilẹ idọti ṣeeṣi ti ọkunrin Yoruba kan to rẹru lori to si ṣubu bẹẹ.
Ni ipari asofin Ekeremadu to je gbakeji aare nile ni yiyara sare te owo nlanla nile Adulawo je okan lara isoro ti o fa owon gogo owo wewe lasiko yii.
Àwọn ará Jebusi sọ fún Dafidi pé, “O ò ní wọ ìlú yìí.
Obinrin tí ó bá ní ilẹ̀-ìní gbọdọ̀ fẹ́ ọkọ láàrin ẹ̀yà rẹ̀, kí olukuluku àwọn ọmọ Israẹli lè máa jogún ilẹ̀ ìní baba rẹ̀.
Nínú ọ̀rọ̀ rẹ̀ Gbenga Omotosho ní, báyìí ìpínlẹ̀ Eko ti ranṣẹ́ si gbogbo àwọn to n tàá èròjà àyẹ̀wò náà tàbi to lé rìí, láti kan si ijọba, o ní gbogbo àwọn orilẹ̀-èdè ti o ṣeese ki wọ́n ni náà ni ìjọba ti kan si.
7 105478 Orilẹede Kosovo 1399 75.
Ọbabinrin Ilẹ̀ Gẹ̀ẹ́sì àti Ọmọọba Harry yóò sèpàdé ní Ọjọ́ Ajé Ikọ̀ Àmọ̀tẹ́kùn tí ó bá gbé ìbọn yóò wọ gàù- Ọlọ́pàá Naijiria Ǹjẹ́ ọmọ Buhari lásẹ láti wọ Ọkọ̀ òfúrufú Nigeria Air force lọ sí òde?
Ayẹyẹ Isinku ati igbeyawo ko ni kọja pe ki eeyan ogun ninu ipejọpọ wọn Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Èmi gan máa ń béèrè lọ́wọ́ ara mi pé ta ni Wole Soyinka gangan' Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Lati igba ti Atiku ti pegede si ni iriwisi ọtọọtọ ti n waye lori ẹrongba rẹ ati boya awọn ọmọ Naijiria yoo gba lati fi Atiku rọpo Buhari ni ile ijọba.
“Bí àrùn yìí bá tún jẹ jáde lára ilé náà, lẹ́yìn tí ó ti yọ àwọn òkúta àkọ́kọ́ jáde, tí ó ti ha ògiri ilé náà, tí ó sì ti tún un rẹ́, 
Nígbà tí Judasi, ẹni tí ó fi Jesu fún àwọn ọ̀tá rí i pé a dá Jesu lẹ́bi, ó ronupiwada.
Ẹ̀mí bá darí rẹ̀ lọ sí aṣálẹ̀.
Ẹnìkan ṣoṣo tí ó jẹ́ ọmọ bíbí Ọlọrun, kòríkòsùn Baba, ni ó fi ẹni tí Baba jẹ́ hàn.
"Sanusi pe Ọ̀gá ọlọ́pàá àti Ọ̀gá DSS lẹ́jọ́ A kò mọ ẹni tó pa ọlọ́pàá Ondo àti ìyàwó rẹ̀, òun kọ́ ló pa ara rẹ̀- ọlọ́pàá Nàìjíríà bèèrè ìrànwó lọ́wọ́ àjọ àgbáyé láti kápá Coronavirus ""Owó oṣù òṣìṣẹ́ yóò di gbèsè, oúnjẹ yóò wọ́n, ìlú yóò le, bí ọrọ̀ ajé Náíjíríà bá dagun"" Soyinka ni o ṣeni laanu pe Gomina Ganduje ko ni awọn ọrẹ gidi to le gba a silẹ ọwọ ara rẹ, ati pe, Sanusi ti wọn rọ loye jẹ ọkan pataki lara awọn to lee mu ayipada nla ba awọn ara Oke Ọya."
Ati pe wọn kii pa mọra lati jẹ ki araye mọ pe Ọba Adeyemi lo n se atilẹyin fun awọn Olori rẹ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Mí ò ya wèrè, mí ò burú, ọ̀nà àtijẹ là ń wá' Ó ti pẹ́ tí Sola Sobawale tí ń ṣe iṣẹ́ sinimá àgbéléwò.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù INEC: Yinka Ayefẹlẹ jẹ adari tootọ ni eto iroyin 16 Ọ̀pẹ̀̀ 2018 Oríṣun àwòrán, Google Àkọlé àwòrán, Ajọ eleto idibo lorilẹede Naijiria, INEC ti da gbajugbaja olorin, Yinka Ayefele lọla pẹlu oye asoju ajọ naa.
Oríṣun àwòrán, APCng O ni ẹẹmeji ni oun ti lọ soju ipinlẹ Ondo nile asoju-sofin nilu Abuja, ti oun ko si ko owo jẹ, ipo ti Akeredolu si fi oun si, oun ko ri owo kankan nibẹ debi pe oun yoo ko owo jẹ nibẹ, ki wa ni agbofinro fẹ gbẹ oun si?
Ọba Akanbi ni lootọọ ni oriṣa bibọ wa ninu itan Yoruba ṣugbọn o yẹ ki wọn ti ko gbogbo awọn oriṣa yii sinu ile iko nnkan iṣẹnbaye si bayii.
Ashiko: Oríṣun àwòrán, Others| Ilu miran to tun wọpọ laarin Yoruba ni Ashiko, asiko ajọdun tabi ayẹyẹ orisa ni wọn n lo ohun naa, ori rẹ a maa tobi nigba ti idi rẹ a se roboto.
Oríṣun àwòrán, Nigerian army Ọ̀fẹ́ ni iforukọsilẹ: Lẹyin naa ni ki o ti ọwọ bọ fọọmu to wa nibẹ.
Nígbà tí ẹ bá wà ninu ìpọ́njú, tí gbogbo nǹkan wọnyi bá ń ṣẹlẹ̀ sí yín lọ́jọ́ iwájú, ẹ óo pada sí ọ̀dọ̀ OLUWA Ọlọrun yín, ẹ óo sì gbọ́ tirẹ̀.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, egbòogi olóró igbo Ọ̀pọ̀lọpọ̀ orílẹ̀èdè míì ló ka igbó sí egbò igi olóró èyí tí kò tọ̀nà láti lò nítorí àwọn tọ́rọ̀ kàn ti tojú bọ̀ ọ́ pé bí o bá lò ó, ẹ̀hìn rẹ̀ kò dára rárá.
’ Bẹ́ẹ̀ ni kí o sọ fún àwọn ọmọ Israẹli.
Igbagbọ mi kò yẹ̀, nígbà tí mo tilẹ̀ wí pé,“Ìpọ́njú dé bá mi gidigidi.
Agbegbe Odẹ-Omi to paala laarin ẹya kan si ikeji laarin ipinlẹ Eko ati Ogun ni wọn ti ji wọn gbe.
Àdó okoró búrẹ́kẹ' Èyí túmọ̀ sí pé kò sí ẹni ti yóò ni ànfàni láti gbà àwọn ìjọba ìbílẹ̀ lọ sí ibi kankan, ọkọ̀ gan kò ni le gba ibẹ̀ kọjá pẹ̀lú.
Kò ní gbádùn oyin ati wàrà tí ń ṣàn bí odò.
Lẹ́yìn rẹ̀ ni Ṣalumu ọmọ Haloheṣi, aláṣẹ apá keji agbègbè Jerusalẹmu ṣe àtúnṣe apá ọ̀dọ̀ tirẹ̀, àtòun ati àwọn ọmọbinrin rẹ̀.
Fayemi to kuna ninu ibo ọhun to waye lọjọ kọkanlelogun oṣu kẹfa ọdun 2014 ṣalaye pe lagbegbe Mugbagba niluu Ado Ekiti lawọn ọlọpaa ti yin tajataju fun oun ti ko si tun jẹ kawọn gomina ẹgbẹ oṣelu APC wọ ipinlẹ Ekiti lati ṣe ipolongo ibo fun oun.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ìtàn ayé Henry Fajemirokun, olówó tó fi owó mọ Olúwa àti ènìyàn Àṣírí tú!
Ìjọba South Africa pèpàdé lórí ìkórìíra àlejò 'Fashọla, o ò dẹ̀ bẹ̀rù Ọlọ́run!
Ṣugbọn ó rọ̀ wọ́n gidigidi, wọ́n bá yà sí ilé rẹ̀, ó se àsè fún wọn, ó ṣe àkàrà tí a kò fi ìwúkàrà sí, wọ́n sì jẹun.
Lasiko to sisẹ gẹgẹ bi asoju orilẹede Naijiria ni ọdun 2018 si 2019, Ajọ UN sọ wi pe ọjọgbọn Bande naa sisẹ karakara, ti o si ni ibasepọ to dan mọran laarin oun ati awọn osisẹ aj naa lagbaye.
Kí a tóó lè lọ a níláti pa Òjòlà-ìbínú pàápàá, bẹ́ẹ̀ ni nǹkan ńlá ni eléyìínì.
Everton já Manchester United sí ìhòhò lọ́jọ́ Àjíǹde Man Utd Vs Man City: Ọ̀rẹ́ dì ọtá, ọtá dì ọ̀rẹ́ torí ife ẹ̀yẹ Neves Doherty ati Jota lo jẹ goolu mẹta naa.
Òní ni Shi'ite fẹ́ ṣe ìwọ́de ikú ọmọ ọmọ Anọ́bì ní èyí tí ó lòdí sí àṣẹ agbófinró Ọwọ́ EFCC tẹ ọ̀kan lára àwọn ti FBI fi èsún jìbìtì kàn!
Air India plane crash: Ìjàmbá bàálù India Express tó já ní Kerala pa èèyàn 16
A o ri wi pe a ṣe atunṣe lati dena iru isẹlẹ bayii lọjọ iwaju''.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Trump picture: ọjọ́ tí Trump kí mi kú iṣẹ́ lórí 'twitter' ní inú mi dùn jù- Oyedele Owo ti ọkọ to jẹ baba awọn ọmọ naa n pa nibi iṣẹ kunlekunle ni wọn fi n tọju awọn ọmọ naa tẹlẹ lati igba to ti bi wọn.
Mahrez dá Super Eagles dùbúlẹ̀ lórí pápá oko tútù Fulani nìkan kọ́ ló ń pa ènìyàn ní Naijiria -Tinubu Lẹ́tà Obasanjo: Àjálù ń bọ̀ bíi ti Rwanda, tí Buhari kò bá ṣàtúnṣe ètò ààbò Lẹyin eyi ni Fatoyinbo kede pe oun ti yẹba naa.
Ewe, oro ti o ko sara aso ohun ti sokunfa orisirisi ikunsinu laarin awon ololufe iko agbaboolu Germany, eleyi ti o mu won bu enu ate lu lopolopo ninu ifesewonse olorejore ti won gba pelu orile-ede Austria.
Gba gba gba lawọn ọlọpaa wa ni ile ẹjọ Majisireeti Yaba ti wọn ti n gbọ ẹjọ lori ẹsun ti wọn fi kan Eremosele.
Èéfín jáde láti ihò imú rẹ̀,iná ajónirun sì jáde láti ẹnu rẹ̀;ẹ̀yinná tí ó pọ́n rẹ̀rẹ̀ ń ti ọ̀dọ̀ rẹ̀ jáde.
Ekejila mú Haṣabaya, òun ati àwọn ọmọ rẹ̀ ọkunrin, ati àwọn arakunrin rẹ̀ jẹ́ mejila.
Wole Soyinka rèé láti kékeré Ìtàn tó rọ̀ mọ́ òwe ‘aṣọ kò bá Ọ́mọ́yẹ mọ́.
Akọnimọọgba Super Falcons Thomas Dennerby gborinyin fun ikọ obinrin Naijiria naa.
Ọti lile ko ni anfaani f‘ara
Ní ìṣojú àwọn baba ńlá wọn, ó ṣe ohun ìyanu,ní ilẹ̀ Ijipti, ní oko Soani.
"Wo àfipábánilòpọ̀ ẹni ọdún 51 tí ìjọba ìpínlẹ̀ Ekiti tú làṣirí ní gbangba ""Àwọn sójà ní mo káàbò sí ilé ìṣerun àgbáyé tí wọ́n tí ń ṣerun bó ṣe wu wọ́n"" Ìjọba ti buwọ́lu lílo hijab láwọn iléèwé ní ìpínlẹ̀ Osun Wọn ko tilẹ fi fọnran naa han igbimọ tabi araalu loni ti wọn mu u lọ siwaju igbimọ lẹyin ọrọ ti wọn sọ."
Awọn ileeṣẹ iroyin abẹle kan n gbe iroyin pe eeyan meji lo ku sinu ikọlu naa, ṣugbọn awọn agbẹnusọ fun ijsba ṣalaye pe, ijamba ọkada lo mu ẹmi wọn lọ ṣaaju ikslu naa.
O wa ro awon onibara won lati maa sanwo won deede , ki won si yago lori iwa ayederu ati jijale ina mona-mona.
Irinajo Abba Kyari lati igba to ti ni aarun Covid-19 Aarun coronavirus ti pa olori awọn oṣiṣẹ lọfiisi Aarẹ Muhammadu Buhari, Abba Kyari.
Oríṣun àwòrán, others Nígbà tó ń báwọn akọroyin sọ̀rọ̀ lórí ìṣẹ̀lẹ̀ náà, Kọmisana fún ètò ọgbin nipinlẹ Oyo, Jacob Ojemuyiwa ṣàlàyé pé, gbogbo ìyànjú òun láti kó àwọn irẹsi náà padà fún ileesẹ Aṣọbode lo ja si pàbó.
kò si ìjọba níbí , ti ìjọba bá wà ni gbogbo ǹkan yìí ní wọn o móju to'' ẹnikan ló sọ ọ̀rọ̀ yìí.
Mi ò kábàámọ̀ pé mo béèrè ìbéèrè tó fàbínú wá lọ́dọ̀ Femi Fani Kayode 'Ó tẹ́mi lọ́rùn kí n pàdánù ẹsẹ̀ mi, ju kí ǹkan ṣe oyún inú mi' Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Ìgbà tí mo máa fi lajú sáyé padà, ọ̀fọ̀ ikú mi ní wọ́n ń kígbe' Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
”Ṣugbọn Peteru ní, “Ọkunrin yìí, n kò sí níbẹ̀!
Awọn alariwisi gbagbọ pe eyi yoo mu ifasẹyin ba
"Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, akeugbagold video ""A ṣe oun lo ṣe kokari bi wọn ṣe ji awọn ibeji mi gbe, ọdalẹ ni."
Wọ́n kó wọn wá sọ́dọ̀ Mose ati Eleasari ati gbogbo àwọn ọmọ Israẹli tí wọ́n wà ní pẹ̀tẹ́lẹ̀ Moabu, ní òdìkejì odò Jọdani, lẹ́bàá Jẹriko.
Iya Oladele jẹ ẹnikan lara awọn obinrin inu ijọ naa ni owo, ti ko si ri i san.
    “Báyìí ni bàbá mi sọ, nígbà tí ó dákẹ́ èmi náà bẹ̀rẹ̀ sí ọ̀rọ̀ i sọ mo ní: À!
Ṣugbọn awọn to ba ti darugbo, ati awọn to ba ti n ṣaiṣan ko to o mu wọn ni yoo le koko.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Somalia rape death sentence: Ìdájọ́ ikú ló bá dé fáwọn méjì tó fipá bá ọmọ ọdún mẹ́rìnlá lò pọ̀ 5 Bélú 2020 Oríṣun àwòrán, Getty Images Ile ẹjọ kan ni agbegbe Puntland lorileede Somalia ti dajọ iku fawọn okunrin meji kan.
Ẹ jọwọ kinni ka ti pe eyi naa?
Ni ibamu pelu agbekale ijoba Ipinle Oyo lati ri daju pe
Sex For Marks: Ọwọ́ ọlọ́pàá tẹ olùkọ́ tó n fipa bá akẹ́kọ̀ọ́ tó n ṣe ìdánwò WAEC sùn' l'Ogun
Àwọn ìṣípayá àtọ̀runwá míràn tẹ̀lé e nínú èyítí a ti kọ́ ọ láti ọwọ́ ọ̀pọ̀lọpọ̀ àwọn ángẹ́lì; a fi hàn sí i pé Ọlọ́run ní iṣẹ́ pàtàkì fún un láti ṣe lórí ilẹ̀ ayé àti pé nípasẹ̀ rẹ̀ ni a ó mú Ìjọ Jésù Krístì padàbọ̀ sípò sí orí ilẹ̀ ayé.
'Awa ko tọwọ bọ iwe adehun ẹyawo kankan ko si si bi a ti ṣe le ya owo ti ile iṣe to n risi ọrọ gbese ati ile ise fun eto isuna ko nimọ nipa rẹ' Atejade lati ọdọ Lere Olayinka to jẹ agbenusọ fun Gomina Fayose ni niṣe ni Fayemi n ''wa awawi kale de bi ijọba rẹ yoo ba fori sanpọn.
Idahun ranpẹ: Wọn ko tii ka abadofin naa ni ipele kika akọkọ.
 Igbiyanju ijoba ko to lasiko yii rara nitoripe eto aabo ko kun to fawon asatipo nibudo won paapaa awon obinrin ati awon ewe.
Dino Melaye naa wa lara awọn ti o n lewaju lati ri asia ẹgbẹ PDP gba fun ipo gomina ti awọn kan si ni o ṣeeṣe ki o ri i gba.
Àwọn òkè mì tìtì níwájú rẹ, OLUWA, àní, ní òkè Sinai níwájú OLUWA, Ọlọrun Israẹli.
"Ayé mi kò bá dojú rú, ká ní mi o fẹ́ Gloria - Mike Bamiloye Oríṣun àwòrán, Instagram/gloriabamiloye ""Mo ki ara mi ku oriire laye, nitori pe mo fẹ ọ."
Oríṣun àwòrán, Instagram/Foluke Dramola Foluke ni iye kíyè táwọn ara ilu bá ní yóò seranwọ láti gba ẹ̀mí Ogun Majek la, àwọn ko si fẹ ki ẹ̀mí rẹ bọ lásìkò yìí tí wọn ṣẹ̀ṣẹ̀ pàdánù Pa Kasumi.
Nígbà tí mo wò ó, mo rrí ojú ọ̀nà kan tí ó tóbi, tí ó gbòòrò tí o sì ń dán, apá ọ̀tún àti apá òsì dàbí ẹni pe idẹ ni wọ́n fi ṣe ojú ọ̀nà náà ní ìpẹ̀kun ọ̀nà náà mo rí ilé kan tí ó lẹ́wà, tí ó bàbí aafin ọba.
Wọ́n sin egungun wọn sí abẹ́ igi tamarisiki, ní Jabeṣi Gileadi, wọ́n sì gbààwẹ̀ fún ọjọ́ meje.
Ọlọ́run nìkan ló mọ bí ìrìnàjò ìfẹ́ ẹ̀dá á ṣe rí láyé, ọ̀dọ́ Aláàfin ní orí gbémí yà sí, ó sì tẹ́milọ́rùn- Olorì Aanu Èèyàn 334 ló gbàwòsàn lọ́wọ́ Covid-19 l'Ọjọru, 453 míì tún lùgbàdì rẹ̀- NCDC Eyi gan an lo fa a to dabii pe wọn gbiyanju lati ja Harris walẹ tabi yan oludije mii lati oṣu melo kan sẹyin.
lorile-ede Naijiria, gomina ipinle naa ati awon gomina egbe APC miiran yoo wa n
Russia in Africa: Ṣé òun ni alágbára ńlá ní Áfíríkà báyìí?
Ṣe dáradára ni mo bá gbogbo yín o?
Yoo na ijọba ni nnkan bi $8,815,338,100.
"Eyi lawọn koko ẹkọ mẹjọ pataki to lee kọ awọn orilẹ-ede Afirika: Oyún oṣù méje ló wà nínú Azeezat, kí wọ́n tó f'òkúta fọ́ ọ lórí pa Ẹ yé fipá bá obìnrin lòpọ̀ mọ́, ìbálòpọ̀ kìí ṣe dandan - Afẹ̀hónúhàn ""Ẹ̀wọ̀n gbére leè jẹ́ ìjìyà fún afipábánilòpọ̀ bí àwọn gómìnà ṣe dìde si"" Ọwọ́ ọlọ́pàá tún tẹ afurasí tó fipá bá odi àti adití lòpọ̀ nílùú Ibadan Kollington, Bàbá Suwe, Ogun Majek wà lára àwọn gbajúmọ̀ tí ayé ti parọ́ ikú mọ́ sẹ́yìn 1."
Wọ́n gbẹ́ wọn bẹ́ẹ̀ sí ara Tẹmpili yíká.
Ó bi wọ́n pé, “Ta ni àwọn eniyan rò pé mo jẹ́?
Wo mi, ọ̀rẹ́ mi, ìyàlẹ́nu nínú ìtàn yí ni pé, ọ̀rọ̀ dídùn láti ẹnu obìnrin yìí mú kí bàbá mi tọ́ ìfẹ́ wò fún ìgbà kínní ní ìgbésí-ayé rẹ̀.
Ó ti lé ní ọ̀sẹ̀ méjì tí CBN ti gbẹ́sẹ̀ lé àsùnwọ̀n mi bánkì nítorí ìwọ́de ENDSARS - Adegoke Pamilerin Wo àwọn ọmọ Naijiria mẹ́ta tó jáwé olúborí nínú ìdìbò sílé aṣòfin ilẹ̀ Amẹrika US election 2020: Bi kò tilẹ̀ wọlé, ẹ wo ayípadà tí Ààrẹ Trump mú bá awọn orilẹede ní àgbáyé Bẹẹ naa ni Obasanjo ba Kamala Harris yọ gẹgẹ bi obinrin alawọdudu akọkọ ti yoo de ipo igbakeji aarẹ Amẹrika.
Cardiff tí tiẹ̀ ti jóná kóná ìyà mọ́ Manchester United Àwọn Afíríkà mẹ́tà to ṣe bẹbẹ nínú EPL sáà 2018/2019 Onimọ naa tẹsiwaju pe awọn akẹgbẹ akẹkọ naa ni ipa ti wọn n ko ati pe ko yẹ ki eeyan sọ ireti nu lori ijakulẹ ninu idanwo.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Olubadan of Ibadan: Olóye Ọ̀tún ní ìjà ti parí ṣùgbọ́n àwa ò gbé adé sílẹ̀ o!
”“A o tesiwaju lati se iranwo fun orile ede Naijiria nipa eto oro aje ati idagbasoke igbeaye-gbadun won , ni eyi ti yoo ran won lowo lati lo awon ohun alumooni won lona ti orile ede Naijiria yoo fi goke agba.
Ó jẹ́ igbọnwọ marun-un marun-un (mita 2½), ní ẹ̀gbẹ́ kinni ati ikeji; ìbú ẹnu ọ̀nà náà jẹ́ igbọnwọ mẹrinla (mita 7).
gbogun ti isẹ ati osi ni awon to n sẹlẹ ni awujọ ati lati mu idagbasoke ba eto
Ni bayii, Mbappe ti gbaa boolu merindinlogun sagbon ninu ifesewonse mokandinlogun ti o ti gba fun iko agbaboolu PSG ni saa yii, bi iko naa tun se tesiwaju lati kopa ribiribi si ninu idije ile won ati nile okere.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìtàn Mánigbàgbé: £100, tíí ṣe ₦42,150 àsìkò yìí, nìjọba fun Taiwo Akinkunmi lówó iṣẹ́ lọ́dún 1959 27 Òkùdu 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 28 Òkùdu 2019 Oríṣun àwòrán, @abdullarhi Oniruuru awọn eeyan to lami laaka lo ti jade lorilẹede Naijiria, paapa nilẹ kaarọ Oojire wa, ti ọkọọkan wọn si ti ko ipa to jọju si idagbasoke ati irẹpọ orilẹede yii.
Ko kọkọ gba esi ayẹwo naa gbọ, afi igba to bẹrẹ aisan, ti wọn si gbe e lọ sile iwosan ni aimọye igba.
Má gbàgbé ariwo àwọn ọ̀tá rẹ;àní, igbe àwọn tí ó gbógun tì ọ́, tí wọn ń ké láìdá ẹnu dúró.
Dípò bẹ́ẹ̀, Farao yipada, ó lọ sí ilé, kò ka ọ̀rọ̀ náà sí rara.
Afe Babalọla ni asiko to lati wa wọrọkọ fi ṣada lori awọn ipenija to n koju Naijiria nitori ofin ọdun 1999 ta n lo mẹhẹ pupọ, to si daba pe ọna abayọ to wa nilẹ ni pipe ipade apero apapọ ilẹ wa.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Níbo láyé kọjú sí: Kí ni ohun àmúyẹ tí ò ń wa lára ẹni tí o fẹ́ fẹ́?
Ẹ ṣèwádìí ikú Ọ̀jọ̀gbọ́n Gideon Okedayọ - ASUU Mo kọ̀ láti yí ọ̀rọ̀ mi padà lórí ètò ẹ̀kọ́ ọ̀fẹ́ - Gómìnà Dapo Abiọdun Àwọn ọmọ Nàìjíríà 320 yóò padà wálé láti South Africa lọ́jọ́rú - Adama Alásè Buhari kú, Buhari ń ṣọ̀fọ̀ Nigbati o n ṣedajọ lori idibo naa lọjọ Iṣẹgun, igbimọ ẹleni mẹta ti adajọ Daniel Adeck dari rẹ wọgile ibo to gbe Dayo Adeyẹye sipo Sẹnetọ lẹkun idibo guusu Ekiti, lẹyin naa lo kede pe Sẹnetọ Biodun Olujimi gan ni ojulowo ẹni to jaweolubori ninu idibo naa.
Ọdẹrinde Oníjaàálá: Ìjálá mi máa ń mú káwọn onísẹ́ ibi gbàgbé láti sebi
Mo sọ fún iranṣẹ mi pé kí ó di kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ mi ní gàárì, kí n lè gùn ún tẹ̀lé ọ, ṣugbọn ó hu ìwà ọ̀dàlẹ̀ sí mi.
Nọọsi mii tun sọ pe pẹlu ibẹrubojo ni oun fi n lọ si ibi iṣẹ lojojumọ.
"Àwọn ileesẹ abani fi nkan ránṣẹ nla ni ofin wà fun tẹlẹ, sugbọn ni bayii ti awọn ileesẹ kéékèèké ti darapọ mọ wọn, ofin naa ti gba afikun ati atunse.
Ọmọ igboro to di ayaworan pataki lawujọ
Bí ìjì líle tí ń fọ́n nǹkan káàkiri bẹ́ẹ̀ ni mo fọ́n wọn ká sáàrin àwọn orílẹ̀-èdè àjèjì.
Mo wọ inú ọgbà mi,arabinrin mi, iyawo mi.
Àwọn Ọmọ Mìíràn Tí Abrahamu Bí.
ó ṣẹ́ ẹ̀ka rẹ̀ lórí, ó gbé e lọ sí ilẹ̀ àwọn oníṣòwò; ó fi sí ìlú àwọn tí ń ta ọjà.
Naomi dá wọn lóhùn, ó ní, “Ẹ pada, ẹ̀yin ọmọ mi.
Abari fara jọ mọimọi, sugbọn agado ni wọn fi n ṣe abari dipo ẹwa.
Gbajugbaja elere bọọlu tennis ni naa ni ohun ti yoo dun mọ oun ninu ni lati kopa ninu idije tennis kan lori ilẹ Afirika.
O tẹsiwaju ninu ọrọ rẹ pe, ọkọ rẹ akọkọ ṣeleri fun lati tọju rẹ pẹlu ọmọ mẹtẹẹta.
Mo ṣe ọmọ owú ni àgbẹ̀dẹ mo sì ṣe ẹ̀mú mo rẹ wọ́n ni òògùn mo so wọ́n mọ ìdí mi, mo mú ìwo àgbáńréé, mo sọ ọ di àpótí mo kó òògùn kún inú rẹ̀ bámúbámú.
Ṣugbọn ni bayii, awọn eekan ẹgbẹ ti n jade gba iwe mo-fẹ-dije.
Amọ sa, ẹgbẹ APC ni awọn oludije fun igbakeji gomina ko ni san owo kankan fun wọn, ti wọn si tun faaye gba awọn eeyan to ni ipenija ara lati san idaji owo ọhun.
Ká tó șàlàyé tó yè kooro.
Bákan náà ni kí ẹ̀yin aya máa bọ̀wọ̀ fún àwọn ọkọ yín.
Amọ Anthony Joshua ti sọ pe 'Haa, akọni ọkunrin lo fidi mi janlẹ.
Ni kete ti iroyin naa jade sita, ni ọgọọrọ ọmọ Naijiria dide tako igbesẹ naa, ti aya gomina Kwara naa si da sọrọ wọn.
Alakoso-igboro London, Sadiq Khan, gboriyin fun irawọ osere naa lori akanni opo Twitter rẹ wipe: Inu mi dun lati pade Sri Devi to jẹ jankan ninu Bollywood nigba ti mo lọ si India lẹnu ijọ mẹta yii."
Awọn ọmọ Ile igbimọ aṣofin ipinlẹ Ekiti ni fi aṣẹ ranṣẹ si gomina ana ni ipinlẹ naa pe afira, ko yara tete yọju ni o lati wa wi ti ẹnu rẹ lori bi awọn owo kan to jẹ ti ijọba ibilẹ ṣe rin kọlọkọlọ bi ọka to de inu ọka lasiko to wa lori oye.
Titi di irọlẹ ọjọ Satide si ni wọn n yọ oku awọn eeyan to ba isẹlẹ naa rin, tawọn ọlọpaa atawọn osisẹ panapana naa si n tiraka lati sisẹ wọn.
mu igberu ba eto oro aje orile-ede Naijiria lati dekun ebi ati ise lawujo, a
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Oshisko twins: Ojú wa rí, ṣùgbọ́nÌgbọ́raẹniyé ló ń ràn wá lọ́wọ́ Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ògbólógbòó Ìjàpá tó máa ń sọ̀rọ̀ bí ènìyàn Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Ògbólógbòó Ìjàpá tó máa ń sọ̀rọ̀ bí ènìyàn 22 Èrèlè 2018 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 29 Agẹmo 2018 Ijapa aafin Sọun Ogbomọsọ ti le ni ọọdunrun ọdun.
Onidajọ Toyin Adegoke ninu idajọ rẹ lori ẹjọ ti alaga igun miran ninu ẹgbẹ ṣelu APC ni ipinlẹ Delta, Cyril Ogodo pe kede pe irọ nla ni gbogbo igbesẹ ti Jones Erue ba gbe gẹgẹ bii alaga ẹgbẹ oṣelu APC ati pe ko lẹsẹ nlẹ labẹ ofin.
 Àwọn ìpínlẹ ̀ tí a ti lè rí àwọn tó n sọ èdè yorùbá nílẹ ̀ nàìjíríà norílẹ ̀ èdè bìní .
Akọwe agba ẹgbẹ YFAN ni ko si nnkan koriya fun awọn agbẹ mọ lasiko yii, eyi to ti mu ki ọpọ pa iṣẹ naa ti.
Ọkọ iyawo naa, ti ọpọ eeyan mọ si Malivelihood lo jẹ ilumọọka onisowo okuta iyebiye bii goolu, diamond ati awọn ẹsọ ara lorisirisi.
Wo ohun tó ṣẹlẹ̀ sí àwọn ọba tó kọ ifá sílẹ̀ gbé Bíbélì àti Kùránì Omo Ghetto: Funke Akindele ṣàlàyé bí àwọn agbébọn ṣe kọlù wọn làsíkò tí wọ́n ń ya fíìmù Laolu Akande ni ipese ina Solar naa yoo pese iṣẹ fun ẹgbẹgbẹrun ọmọ Naijiria ti ko ni iṣẹ.
Oludari ileeṣẹ MultiChoice Group, John Ugbe lo sọrọ yii niwaju igbimọ ile aṣoju-ṣofin to ṣe iwadii afikun owo tariifu DSTV.
Ǹjẹ́ ẹ kò fi bẹ́ẹ̀ dá ìyapa sílẹ̀ láàrin ara yín, ǹjẹ́ ẹ kò sì máa ṣe ìdájọ́ pẹlu èrò burúkú.
Mercy Aigbe kò mọ ọ̀dá owó, ọkọ̀ ayọ́kẹ́lẹ́ tuntun ló fà yọ lásìkò Coronavirus Oríṣun àwòrán, Instagram/Mercy Aigbe Wọn ni ohun to kọju si ẹnikan, ẹyin lo kọ si ẹlomiran bii ilu gangan, bẹẹ lọrọ ri pẹlu gbajumọ oṣere tiata, Mercy Aigbe, ti dukia rẹ tun lekan si.
Biotilẹjẹpe Trump ti sẹ kanlẹ lori ọrọ naa, amọ ireti wa pe o seese kawọn asaaju ilẹ Afrika bii marundinlaadọta to wa ninu ajọ isọkan ilẹ Afrika (AU), bu ẹnu atẹ lu ọrọ yi.
Nígbà tí kò bí ọmọ, ó fi iyawo rẹ̀ sílẹ̀ fún àbúrò rẹ̀.
Iran lounjẹ oju ni o ba de bayii ni ipinlẹ Ondo lasiko yii Ọwọ́ tẹ́ àwọn ọkùnrin Fulani mẹ́ta tí wọ́n jí Màálù méjì kó ní Ogbomọṣọ- Àjọ NSCDC Ṣé lóòótọ́ ni Amcon gba ilé Toke Makinwa ti wọn ní bàbá olówó rà á fun?
Lẹ́yìn náà, mo bá àwọn alufaa ati gbogbo àwọn eniyan náà sọ̀rọ̀, mo ní, “OLUWA sọ pé ẹ kò gbọdọ̀ fetí sí ọ̀rọ̀ àwọn wolii yín tí wọn ń wí fun yín pé wọn kò ní pẹ́ kó àwọn ohun èlò ilé èmi OLUWA pada wá láti Babiloni.
''O le jẹ eeyan meji tabi mẹta ṣugbọn wọn ko gbọdọ maa fi ọgbọn kọkọ beere ọrọ lọwọ ẹni naa ki o ba ma baa lojiji'' Adegbenga ni ti o ba jẹ ẹni to nifura ni yoo ti ma woye pe ki lo mu wọn pe oun ati pe ko ni baa lojiji mọ nigba ti wọn yoo ba fi tufọ naa fun un.
Bí Jesu ti ń gòkè lọ sí Jerusalẹmu, ní ọ̀nà, ó pe àwọn ọmọ-ẹ̀yìn mejila sí apá kan, níkọ̀kọ̀, ó sọ fún wọn pé, 
Ọkùnrin kan di èrò ọ̀run nítorí pé o fi ẹ̀sùn kan alájọgbélé rẹ̀ pé o n yan ìyàwó ẹnìkan lálè Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí 5:58 Fídíò, Akomolede ati asa Yoruba: Ẹ wá kọ́ nípa àpòtí ìṣura èdè wa lórí BBC Yorùbá, Duration 5,5820 Ògún 2020 6:10 Fídíò, Yoruba Language: Akomolede ati Asa Yoruba tọ̀sẹ̀ yí rèé lẹ́nu olùkọ́ wa, Duration 6,1030 Ògún 2020 Èyí tí a wò jùlọ 5:03 Fídíò, Omolola Arohunmolase Welder: Mo ti fí iṣẹ́ 'Welder' gbayì láwùjọ, tó mo fi tọ́ ọmọ yanjú, Duration 5,039 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 5:39 Fídíò, Akomolede ati Asa lori BBC: Olùkọ́ Kikelomo Ogunboye tan ìmọ́lẹ̀ sí ìwà olè ọ̀gá ọlọ́pàá Audu gẹ́gẹ́ bí àwòkọ́ṣe àsìkò yìí, Duration 5,398 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 4:11 Fídíò, Oba Adeyeye Ogunwusi: Ojú mi ti rí lọ́pọ̀ lọpọ̀, ọ̀pọ̀ èèyàn ni kò tilẹ̀ gbàgbọ́ pé mo lè jọba- Ooni, Duration 4,117 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 4:43 Fídíò, Promise Akinlade: ọmọ ọdún mọ́kànlá tó ń fi ìlù dárà bíi àgbàlagbà sọ̀rọ̀ nípa tálẹ́ǹtì rẹ̀, Duration 4,437 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 0:59 Gbọ́, Ìsẹ̀lẹ̀ jákèjádò orílẹ̀èdè àgbáyé láàárín ìṣẹ́jú kan, Duration 0,59wákàtí 5 sẹ́yìn 7:03 Fídíò, Olumuyiwa Bolade Adedeji Military Bruitality: Bí arákùnrin onípèníjà ara tí sọ́jà lù ṣe dé, Duration 7,035 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 4:45 Fídíò, Yoruba Films: Ẹ̀ẹ́ bẹ̀ mi kúrò láyé ni, mi ò lè kú - Fadeyi Oloro, Duration 4,4526 Èrèlè 2020 2:48 Fídíò, Esther Ajayi: Èmi náà ti borí ìṣòro rí ló ń mu mi ṣojú àánú, Duration 2,481 Ògún 2019 6:08 Fídíò, Adebola Ademilua: Àìrísẹ́ ṣè lẹ́yìn ìwé kíkà ló sọ mi dí ìyá onírú, mo dúpẹ́ tèmi, Duration 6,0827 Bélú 2020 5:55 Fídíò, Soyinka Cancer: Àṣe ara mi ni iso ti n run gbogbo bí mo ṣe n ṣèrànwọ́ lórí jẹjẹrẹ, Duration 5,5527 Bélú 2019 BBC News, Yorùbá Ìdí tí ẹ fi le è nígbàagbọ́ nínú ìròyìn BBC Ìlànà Lílò Nípa BBC Òfin Àṣírí Cookies Kàn sí.
Nibẹ ni àwọn alẹnulọrọ loriṣirṣi lẹka eto ilera paapaa ni Ipinlẹ Eko ati awọn miiran ti fi ero ti wọn han si abadofin yii.
Ọmọ bibi ilu Ilesa nii ṣe, to si ṣe gudu gudu meje ati ya ya mẹfa ninu isẹ tiata, lara awọn ere to ti kopa ni Ija ọmọde, ẹru ẹlẹru, Pẹlumi ati Ẹtọ mi.
Bí mo bá rìn ní ọ̀nà aiṣododo,tí mo sì yára láti sọ̀rọ̀ ẹ̀tàn,
Akomolede ati Aṣa lori BBC Yoruba lo tun jade lonii.
Àwọn ọmọde ń tọrọ oúnjẹ,ṣugbọn kò sí ẹni tí ó fún wọn.
Parker, eni ti okun iro mo-di (WBO) wa lowo re, besini akegbe re Joshua ti gba okun iro mo-di (IBF) ati (WBA), won yoo jo wooya ija ni papa-isere Principality ni Cardiff ninu osu to n bo.
Fidio ọrọ rẹ ree loju opo Twitter.
Wọ́n pa àwọn ọmọ Amaleki yòókù tí wọ́n sá àsálà, wọ́n sì ń gbé orí ilẹ̀ wọn títí di òní olónìí.
Ọdun 2018 ni fidio kan ja ranyin kaakiri lori ẹrọ ayelujara nibi ti awọn soja ti ṣekupa obinrin ati awọn rẹ ti wọn pe ni ikọ agbesunmọmi Boko Haram, ti wọn si yinbọn pa wọn.
"Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Awakọ̀ 3rd Mainland Bridge: Ìjọba ko yanjú súnkẹrẹ fàkẹrẹ ọ̀nà Apapa Wọn ti kọkọ dájọ titi 3rd mainland tẹ́lẹ̀ Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Idi ti wọn fi sun ọjọ ti wọn yoo ti afara naa si iwaju niise pẹlu igbiyanju ijọba ipinlẹ Eko lati mu idiwọ ati ipara ti yoo jẹ fun awọn ara ilu kuro lasiko naa Ijọba apapọ ti sun ọjọ mẹta ti wọn fẹ fi se atunse afara ""Third mainland bridge"" lati ọjọ kẹtadinlọgbọn si ọgbọnjọ Osu yii, si ọjọ kẹrinlelogun si ọjọ kẹrindinlọgbọn, Osu kẹjọ ọdun 2018."
Ilu Amẹrika loun naa bimọ si, kete to kede lori ayelujara lọgọrọ awọn oṣere ẹgbẹ rẹ bẹrẹ si ni fi ikinni ranṣẹ sii.
won  tabi ti won farapa nibi isele naa
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: UEFA f'ẹ̀sùn kan Bayern Munich Ìpàniyàn Apó: Ìjọba san N135m gbà-má-bínú Kókó ìròyìn: Sẹ́nétọ̀ ń lo ayédérú ìwe-ẹ̀rí Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Àìsàn ibà; Àwọn ènìyàn sọ̀rọ̀ nípa lílo ewé áti egbò Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Gbogbo àwọn tí wọn ń fi oriṣa Aṣima ti Samaria búra, tí wọn ń wí pé: ‘Bí oriṣa rẹ ti wà láàyè, ìwọ Dani,’ ati, ‘Bí ọ̀nà Beeriṣeba ti wà láàyè;’ gbogbo wọn yóo ṣubú, wọn kò sì ní dìde mọ́.
Lẹ́yìn èyí ni yóo mú àgbò wá fún ẹbọ ètùtù ẹ̀ṣẹ̀ rẹ̀.
Ikorira, ipaniyan ati ika nsun Naijiria soju ogun-Arẹgbẹsọla Oríṣun àwòrán, RAUF AREGBESOLA/FACEBOOK Àkọlé àwòrán, Gomina ipinlẹ Ọsun, Ọgbẹni Rauf Arẹgbẹsọla nlọgun pe ki awọn ọmọ Naijiria sọra Gomina ipinlẹ Ọsun, Ọgbẹni Rauf Arẹgbẹsọla ti nlọgun too pe, ti awọn ọmọ Naijiria ko ba sọra, afaimọ ki wọn ma ti orilẹede yi lọ soju ogun nitori ọrọ ikorira, ipaniyan ati iwa ika ti wọn n hu laibikita.
àwọn ọba tí yóo máa gúnwà lórí ìtẹ́ Dafidi, yóo máa gba ẹnubodè ìlú yìí wọlé.
ni akegbe mi naa se daradara ninu ifigagbaga yii.
N óo mú kí o máa gbé ìsàlẹ̀ ilẹ̀ bí ìlú àwọn tí wọ́n ti ṣègbé nígbà àtijọ́, ati àwọn tí wọ́n ti lọ sinu ọ̀gbun; kí ẹnikẹ́ni má baà gbé inú rẹ mọ́, kí o má sì sí lórí ilẹ̀ alààyè mọ́.
Uba da lohun pe ko lodi si ofin lati kamẹra ọlọpaa to ba n ṣe ohun ti ko da, amọ o kilọ pe ki awọn ṣe mẹdọ pẹlu awọn oṣiṣẹ eleto aabo to ba gbebọn dani.
Bí ẹnikẹ́ni bá wá ní èrò tí ó yàtọ̀ sí èyí, Ọlọrun yóo fihàn yín.
[Díaz] jẹ́ oníròyìn fún ilé iṣẹ́ ìgbóhùnsáfẹ́fẹ́ Unión Radio Noticias , ó sì tún jẹ́ ajàfúnẹ̀tọ́ ọmọnìyàn.
 “A n fẹ ifọwọsowọpọ gbogbo ijọba
Nigba miran, yoo pariwo mọ mi pe ko si ọmọ to ni iru oju ara akọ ati abo bẹẹ ninu iran oun, yoo si dara ki n gbe ọmọ naa pada si ibi ti mo ti gbe wa.
Oríṣun àwòrán, OTHERS Àkọlé àwòrán, FRSC ní àwọn kò mọ̀ nípa nọ́mbà ọkọ̀‘CHIP WHIP’ Bakan naa ni wọn fi kun un wi pe awọn ko nii nkankan se pẹlu nọmba ọkọ ti wọn ni o wa lati ipinlẹ Kano, ti o si seese ko jẹ ti adari Ile Igbimọ Asofin ipinlẹ naa.
kongo tàbí kikongo - ó jẹ ́ èdè bantu , àwọn ènìyàn bakongo ni wọn ń sọ ọ ́ .
Ṣugbọn Josẹfu kọ̀, ó wí fún un pé, “Wò ó, níwọ̀n ìgbà tí mo wà lọ́dọ̀ ọ̀gá mi, kò bìkítà fún ohunkohun ninu ilé yìí, ó sì ti fi ohun gbogbo tí ó ní sí ìkáwọ́ mi.
Gabriel Afolayan Yatọ si pe o n sere tiata, Gabriel Afolayan tun ma n kọrin ifẹ lọpọ igba.
Ẹ gbà mí gbọ́ pé mo wà ninu Baba ati pé Baba wà ninu mi.
Àwọn ni ẹ̀ka igi tí mo gbìn, iṣẹ́ ọwọ́ mi,kí á baà lè yìn mí lógo.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Tolulope Arotile death: Afurasí tó wa ọkọ̀ pa Tolulope Arotile ti ń jẹ́jọ́ ẹ̀sùn ìgbìmọ̀pọ̀ ṣekúpani 12 Agẹmo 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 20 Ògún 2020 Oríṣun àwòrán, NAF Afurasi to wa ọkọ to pa Tolulọpẹ Arotilẹ, obinrin akọkọ ti yoo jẹ awabaluu ijagun lorilẹede Naijiria ti foju ba ile ẹjọ loni.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ekiti Election: Oludije PDP ní ìdigunjalè ọ̀sán gangan tí kò ṣẹlẹ̀ rí ni ìdìbò Ekiti 12 Agẹmo 2018 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 15 Agẹmo 2018 Oríṣun àwòrán, @Eleka Àkọlé àwòrán, Emi kọ èsì ìdìbò INEC-Eleka Elẹka yarí pé irọ́ ni èsì ìdìbò INEC.
Ẹ má jẹ́ kí á máa kọ ìpéjọpọ̀ ara wa sílẹ̀, bí àṣà àwọn mìíràn, ṣugbọn kí á máa gba ara wa níyànjú, pataki jùlọ gẹ́gẹ́ bí ẹ̀yin náà ti rí i pé ọjọ́ ńlá ọ̀hún súnmọ́ tòsí.
Ṣugbọn lẹ́yìn tí a bá ti jí mi dìde, n óo ṣiwaju yín lọ sí Galili.
Eyi yẹ ko jẹ ẹkọ fun awa naa pe o yẹ ka tiraka lati fi ipa manigbagbe lelẹ ninu isẹ ti a ba yan laayo nitori arise ni arika, arika ni baba iregun, ohun ta ba se loni, ọrọ itan ni yoo da lọla.
Idije Champions league Ninu eto ifẹsẹwọnsẹ ti wọn fi sita fun idije UEFA Champions league, ẹgbẹ agbabọọlu Bayern Munich ti orilẹede Germany ati Real Madrid ti orilẹede Spain ni yoo maa waako nigbati Liverpool ti ilẹ Gẹẹsi yoo maa kojú Roma lati orilẹede Italy.
Ilu Ibadan tii ṣe olu-ilu ijọba apa iwọ oorun Naijiria ni wọn pa Akintola si ninu iditẹ-gbajọba ti wọn ti pa ọpọ oloṣelu to jẹ ọmọ ẹgbẹ NPC (Northern People's Congress).
Ki ni ofin sọ nipa gbigba owo ori lori owo idije ti eeyan ba jẹ Naijiria ko yatọ si awọn orileede mii lagbaye ti awọn eeyan ti n san owo ori lori owo tẹtẹ tabi idije idaraya ti wọn ba jẹ.
Ọ̀sanyìn ẹlẹ́sẹ̀ mẹ́wàá náà lọ ṣùgbọ́n òun náà kú sí oko.
Látọwọ́ Yetunde Olugbenga àti Busayo Akogun tó ń jábọ̀, a dúpẹ́ púpọ́ lọ́wọ́ yín.
Mikali, ọmọ Saulu, bá lọ pàdé rẹ̀, ó ní, “Ọba Israẹli mà dárà lónìí!
Bẹ́ẹ̀ ni bàbá mi ri ẹ̀hìn oníbodè yìí, ìjà náà si di òwe káà kiri ayé ni àkókò ìgbà náà.
Oríṣun àwòrán, others Bakan naa ni ọkan lara awọn adari banki ti awọn adigunjale ọhun ṣakọlu si, ti ko fẹ ki wọn darukọ oun ṣalaye pe awọn ọlọdẹ ati ọmọ ẹgbẹ OPC ilu naa ṣe ọkan akin lati dojukọ awọn adigunjale ọhun nigba ti wọn n ṣọṣẹ.
Awọn si ri oku ọmọde kan ti wọn ti ge ori rẹ lagbegbe naa ni ọjọ kan naa.
Liverpool fi ojú Manchester United gbolẹ̀ ní Anfield Màá ra Arsenal ní 2021 tí mo bá kọ́ iléeṣẹ́ ìfọ́po rọ̀bì tán - Dangote Ife ẹ̀yẹ kẹrìnlélógùn d'ète fún Serena Williams Èyí ni ìdí tí Cameroon fi yí àkókò tó yẹ kí AFCON 2021 wáyé padà Akẹgbẹ rẹ tẹlẹ ninu ikọ Supper Eagles, Mikel Obi ni ọmọ Naijiria akọkọ ti yoo tọwọ bọwe adehun pẹlu ikọ Man United, ṣugbọn ko gba bọọlu fun ikọ ọhun.
Lẹyin naa lo sun igbẹjọ ọhun si ọjọ kẹjọ, ọsu Kẹwaa, ọdun 2020.
" Bakan naa lo sọ pe pẹlu ibẹta ti oun bi, ọkan oun ti fẹ ẹ balẹ.
Eyi si ti mu ki awọn eeyan maa beere pe, bawo ni ọlọpaa ṣe mọ pe Sanusi lo kọrin bu Gomina, nigba ti wọn ko ri oju rẹ.
Ìdájí níí tií jí láti wá oúnjẹ fún ìdílé rẹ̀,ati láti yan iṣẹ́ fún àwọn iranṣẹbinrin rẹ̀.
Nitori naa ko ya ni lẹnu nigba ti eto loniranran gbode kan fun ayẹyẹ ọjọ ibi ọgọta ọdun to ṣe.
Ìgbà tí wọ́n sì ròyìn ohun tí àwọn rí rà fún ara wọn tí ẹni tí ó ra ìwo agbáǹréré sọ nǹkan tí ó wà fún, wọ́n ní ó yẹ kí àwọn fi ìwo náà wo Ẹwadapọ̀ nítoríu ẹni tí àwọn tilẹ̀ ń ṣá kiri ṣùgbọ́n kí ni wọ́n máa rí?
Mo ní ìgboyà láti sọ wọ́n fun yín nítorí oore-ọ̀fẹ́ tí Ọlọrun fún mi 
Lara awọn ewi Faleti to gbajumọ ni Onibode Lalupọn, Alagbara Ile ati Alagbara Oko, Ijamba Odo Ọba, Adebimpe Ojedokun ati awọn miran.
, ti gbogbo awọn eeyan to wa nibẹ si ku silẹ fun ẹrin arintakiti."
Nigba to n fesi, Oduyọye ni irọ to jinna sootọ ni ọrọ ti Lanlẹyin sọ yii, koda, o ni afomọ ni ọrọ naa, ko lẹsẹ nlẹ, ti ko si ba ohun to n waye lọwọlọwọ bayii mu, nitori Makinde ti sa ipa rẹ lati ko gbogbo ẹgbẹ oselu ti wọn jọ se adehun ajumọse mọra.
Nígbà ti wọ́n yọ sí igbó Oódùmarè ti wọ́n ń wo oníbodè lọ́kàn-án-kán àwọn obìnrin méjì wọ̀n-ọnnì yí ara padà wọ́n di ẹyẹ nítorí èyìínì kò ṣòro fún wọn: àjẹ́ ni wọ́n.
Wọ́n dáná sun ìlú náà ati gbogbo nǹkan tí ó wà ninu rẹ̀, àfi fadaka ati wúrà, ati àwọn ohun èlò idẹ, ati ti irin, ni wọ́n kó lọ sinu ilé ìṣúra OLUWA.
lẹ ́ yìn àwọn ìwé ̀ itàn àr ̀ osọ òkè wọ ̀ nyí , ó tún tẹ ̀ síwájú láti kọ onírúurú àwọn ìwé eré onítàn , eré oníṣe , ìtàn ọlọ ́ rọ ̀ geere àti oríṣiríṣi àwọn ìtàn akọni ìgbà ìwáṣẹ ̀ .
Eleasari bá kó àwọn àwo turari náà tí àwọn tí ó jóná fi rú ẹbọ, ó fi wọ́n rọ àwo fẹ́lẹ́fẹ́lẹ́ fún ìbòrí pẹpẹ.
82% ọkùnrin ní kó mọ̀ pé òun ní àìsàn jẹjẹrẹ asẹtọ ní Naijiria Àìsàn jẹjẹrẹ mú ẹ̀mí Aisha Abimbọla lọ Ṣe lootọ ni pe bi eeyan ni arun jẹjẹrẹ, kii ṣe idajọ iku?
Duro Ladipọ, ìlúmọ̀ọ́ká òṣèré tíátà àti ọmọ àlúfà tí kò gbàgbé àṣà ìbílẹ̀ Ọ̀rọ̀ǹpọ̀tọ̀niyùn, Aláàfin obìnrin àkọ́kọ́ rèé, tó ní nǹkan ọkùnrin O ni o y ko koju mọ ṣiṣe awọn eto ti yoo ni ipa gidi ti yoo si kan aye awn eniyan to wa lẹsẹ kuku.
Awọn alaṣẹ ologun ilẹ naa wi pe o ṣeeṣe ko jẹ wi pe, arakunrin naa, Ramil Shamsutdinov, ni aarun ọpọlọ, ti wọn si ti fi si ihamọ.
O ní ti ààrẹ Muhammdu Buhari bá le lọ si ilé ẹjọ ní ẹ̀ẹ̀mẹ̀ta láti pé èsì ìdìbò lẹjọ nígbà ti kò tilẹ̀ sí ìdí kankan láti ṣe èyí, ọmọ Naijiria tó ba ro pé wọn yan òun jẹ ni ẹtọ láti lọ si ilé ẹjọ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Working religious women: Ẹ̀lẹ́hàá kìí ṣe ọ̀lẹ- Aminat Adegoke Afara 'Third Mainland' to jẹ ikẹta yii jẹ eyi to gun ju ninu awọn afara to so Mainland Eko pẹlu Erekusu Island Eko papọ, iyẹn afara Carter ati afara Eko.
Ọrọ ti wọn sọ si lo jẹ ki ọwọ tẹ babalawo ti wọn lo jẹ baba isalẹ wọn, to maa n ro wọn lagbara nigba kuugba ti wọn ba n lọ sisẹ idigunjale, tabi gba ọmọ ẹgbẹ tuntun sagbo wọn.
Orukọ abadofin naa ni Electric Power Sector Reform Act (Amendment) Bill, 2018; ti ireti si wa wi pe yoo sọ di ẹsẹ fun ẹnikẹni lati ma bu owo lu awọn ara ilu fun lilo ina ọba .
O se se ki ẹ ti gbo ki tọmọde tagba ma je ọrọ yi lẹnu.
“Bí ọkunrin kan tabi obinrin kan láàrin àwọn ìlú tí OLUWA Ọlọrun yín fun yín bá ṣe ohun tí ó burú lójú OLUWA Ọlọrun yín, nípa pé ó da majẹmu rẹ̀, 
Kò sí ẹnikẹ́ni nínú wọn tó tíì dé lásìkò tó yẹ kí ìkọ̀ọ̀kan wọn sọ̀rọ̀ Ní ibi ìpàdé náà ni wọ́n ti ń retí igbákejì ààrẹ, Yẹmí Ọsìnbájò, mínísítà fún ètò ẹ̀náwó, àti akẹẹgbẹ́ rẹ̀ ní ẹ̀ka epo rọ̀bì, ètò ọ̀gbìn, ètò ìròyìn, ìmọ̀ sáyẹ́ńsì,ohun àlùmọ́ọ́ní ilẹ̀ àti mínísítà fétò okoòwò, sùgbọ́n kò sí ẹnikẹ́ni nínú wọn tó tíì dé lásìkò tó yẹ kí ìkọ̀ọ̀kan wọn sọ̀rọ̀.
Abegunde ni oun ko dije fun ipo kankan rara nitori awọn to n dije ninu ẹgbẹ APC gan pọ.
Titi di bi a ṣe n sọrọ yii, ko si ẹni to le fọwọ sọya boya o ku tabi ko ku.
Idagbasoke ọrọ̀ ajé ti ko tete dagba Fun ọpọlọpọ dun lẹyin to de iṣakoso, ijọba ANC gbiyanju ninu mimu adinku ba ìṣẹ́, o si mu ayipada ba awọn nkan amayedrun to ṣe koko.
Agbegbe yii ni awọn adigunjale ti sọṣẹ ni Ọjọọru, ti ẹmi awọn eniyan kan si lọ si iṣẹlẹ naa.
Brexit Iṣẹlẹ nla miran ta tun maa foju sọna fun lọdun 2020 tun ni bi orilẹede Britain ṣe fẹ ẹ kuro ninu ajọ iṣọkan ilẹ Yuroopu.
Egbe osise tun ni ti ijoba ba ko lati san ekunwo ohun awon yoo bere iyanselodi alailojo  ni ojo kefa , osu kokanla .
Adájọ́ fi agbẹjọ́rò si àtìmọ́lé Ìbaàrún pe ọdún kan ‘Ẹ má gbé ara sílẹ̀ láti di òsèré tíátà’ 'Buhari, ṣé ìkíni ọdún níyìí tàbí ìpolongo ìdìbò?
OLUWA Ọlọrun ní, “Lẹ́yìn ogoji ọdún, n óo kó àwọn ará Ijipti jọ láti gbogbo orílẹ̀-èdè tí mo bá fọ́n wọn ká sí.
Ifẹhonuhan wa lab ofin ṣugbọn ki eeyan ṣe e ni alafia ni nkan to tọ.
A tun gbọ pe, wọn ma n fi ijo fa oju eero mọra, nibi ayẹyẹ, kanifa, ati nile ijo.
Fatai Atanda okan gbogi lara osise ajo to n mojuto ere idaraya Hockey lorile-ede Naijiiria Nigeria Hockey Federation (NHF), so lojoBo (Thursday) pe, idije 2018 Super League yoo bere lojo abameta(Saturday) ni papa isere ilu Abuja.
“Ka iye àwọn ọmọkunrin Lefi gẹ́gẹ́ bí ìdílé baba wọn.
Nínú ìfọ̀rọ̀wérọ̀ oríi ẹ̀rọ ìbánisọ̀rọ̀ pẹ̀lú BBC lórí ètò oríi redio kan nilu London, alukoro fásitì Ọbafẹ́mi Awólọ́wọ̀ ní Ìlú Ilé ifẹ̀, OAU, Ọ̀gbẹ́ni Abíọ́dún Ọláńrewájú ni àwọn aláṣẹ fásitì náà ti fìdí rẹ̀ múlẹ̀ pé ohùn rẹ̀ ni.
" Da ẹran jẹ̀ nígboro, ko fẹ̀wọ̀n oṣù méje jura tàbí san ₦200,000 - Ilé aṣòfin Ọyọ dábàá Kí ni Oluwo lọ ṣe ní Aso Rock lẹ́yìn lẹ́tà rẹ̀ sí ààrẹ Buhari?
Ọrọ eto aabo Aarẹ Naijiria tun dẹbi eto aabo to mẹhẹ lorilẹede yii ru awọn ọlọpaa ti wọn ko ṣiṣẹ wọn bi iṣẹ.
Fi tọkàntọkàn gbẹ́kẹ̀lé OLUWA,má sì tẹ̀lé ìmọ̀ ara rẹ.
Nígbà tí ó mú omi ó fi oògùn sí i ó lọ́ sí ọ̀dọ̀ ọkọ rẹ̀ ó dà á lù ú, ó ní Mo pa á laṣẹ fún ọ pé kí o ddìde kí o máa rìn kiri, orí kòo lè wúwo kí ó pa ọrùn lẹ́rù, ara kì í wúwo kí alárá má lè gbé e.
Oríṣun àwòrán, Makinde Ninu ọrs ibanikẹdun tirẹ, ẹgbẹ oṣelu PDP ninu atẹjade kan ti wọn fi sita eyi ti agbẹnusọ rẹ, Akeem Ọlatunji fọwọsi ṣe apejuwe Ayọọla gẹgẹ bi akinkanju ọmọogun to si tun jẹ ẹlẹyinju aanu nigba aye rẹ.
Akisa dá baba rẹ̀ lóhùn pé, “Fún mi ní ẹ̀bùn, níwọ̀n ìgbà tí o ti fún mi ní ilẹ̀ Nẹgẹbu, fún mi ní àwọn orísun omi pẹlu.
Pogba sọ pe airikan ṣe kan ti su oun tipẹ"", ati pe oun yoo pada sori pápá igbaradi nikete ti aarun coronavirus ba tan nilẹ."
Oríṣun àwòrán, Getty Images Evra to jẹ ọmọ orilẹede Faranse fikun ọrọ rẹ pe otittọ ni wi pe Arsenal dun un wo loju ti wọn ba n gbabọọlu, amọ o ni wọn ko jọ ikọ agbabọọlu to le maa fakọyọ ninu ere bọọlu.
Kaabo padaAwon orile-ede mejileladota ti won je omo egbe ajo naa ni won pawopo satileyin fun ipinnuipada boo rile-ede Gambia, ni eyi ti won yoo pe orile-ede naa pelu awon omo-egbe yoku fun ipade apero ti yoo waye ninu osu kerin odun ti a wa yii nilu London.
Ìmọ́lẹ̀ á máa tàn fún àwọn olódodo,ayọ̀ sì wà fún àwọn olótìítọ́ inú.
mọ ljo Isegun to ye ki won ti pe fun ijokoo pajawiri nitori pe, “Gege
Bo tilẹ jẹ pe Nkechi sọ ṣaaju pe oun ko fẹran bi oun ṣe n yọ jo, o ni oun fẹran bi ibadi oun ṣe ri lasiko yii nitori ẹru nla ni ibadi naa jẹ fun ẹsẹ oun lati maa gbe.
Aare Buhari tenumo ipinnu isakoso isejoba re ninu atejade kan ti amugbalegbe pataki lori eto iroyin ati igbodegba, Malam Garba Shehu te jade lojo abameta(Saturday), niluu Abuja lati mu aabo awon omo-ogun ati awon ara ilu lokunkun-dun.
Rishi ni idi ni pe iru imura sokoto igbalode yii ni oun fẹran julọ laye oun, nitori naa ni oun ṣe wo pe, o yẹ fun igbeyawo oun.
Ẹ wò ó bí ìlú tí ó kún fún eniyan tẹ́lẹ̀ ti di ahoro, tí ó wá dàbí opó!
Ẹwẹ, ẹgbẹ oṣelu PDP tun kilọ fun Gomina Yahaya Bello ati ẹgbẹ APC pe iwa jagidijagan ko le gba wọn ninu idibo gomina to n bọ ninu oṣu kọkanla.
Ìkádìí A bí Ademola Jackson Adeleke Ní ọjọ́ kẹtàlá oṣù karún-un ọdún 1960 ní ìpínlẹ̀ Enugu ní ìdílé sínatọ̀ Raji Ayoola àti Nnena Esther Adeleke ní ìlú Ede Ó lọ sí iléèwé alákọ̀ọ́bẹ̀rẹ̀ Methodist ní Surulere àti Nuwarudeen ní Ikire, bákan náà ló lọ iléèwé Seventh Day àti iléèwé Muslim Grammar ni ìlú Ede tí ó sì kọ́ ẹ̀kọ́ ìmọ̀ nípa ìwádìí ọ̀daràn ní Jacksonville State University Alabama USA.
“Wo ọmọ mi tí mo yàn,àyànfẹ́ mi, ẹni tí ọkàn mi yọ̀ mọ́Èmi óo fi Ẹ̀mí mi sí i lára,yóo kéde ìdájọ́ láàrin àwọn orílẹ̀-èdè tí kì í ṣe Juu.
Bí wọ́n ti ń lọ ní ọ̀nà, ó bi wọ́n pé, “Ta ni àwọn eniyan ń pè mí?
Wọn bii lọjọ kejilelogun oṣu kẹjo ọdun 1967, ni Washington, D.
Ibú omi bo gbogbo ayé, gbogbo rẹ̀ ṣókùnkùn biribiri, ẹ̀mí Ọlọrun sì ń rábàbà lójú omi.
NUJ ni niwọn igba ti awọn ọlọpaa ko ti lee gbe Tom lọ sile ẹjọ lati igba naa, bi wọn se fi si ahamọ tubọ tu asiri iwa tani yoo mu mi tawọn ọlọpaa n hu.
orile ede Naijiria Muhammadu Buhari ti seleri lati ri i pe eto aabo lo ni
O ni ile iwosan ko pọ ni Naijiria, awọn eyi to si wa naa, ko dantọ.
Igbimo eleni mokanlelogorin dibo fun ayipada yii lojo-Bo, igbese ohun ni won ri gege bi ona ati so Ahmed di olori ijoba orile-ede naaIroyin lati ile-ise iroyin Standard nilu Addis so pe, yiyan omowe Abiy gege bi alaga OPDO waye leyin ti igbimo eleni medogun egbe oselu naa, eyi ti Lemma Megeressa dari re  fori-kori fimo-sokan lojo-Aje lati yan elemiiran sipo alaga naa.
Ni oṣu keji ọdun 1964, wọn sọ ile iwe girama ọhun di ẹka ile iṣẹ ologun to laṣẹ lati sọ ni di ọmọ ogun alakọbẹrẹ wọn si sọ orukọ rẹ di ile ẹkọ awọn ọmọ ogun alaabo, Nigerian Defence Academy (NDA).
joseph jenkins roberts ( march 15 , 1809 - february 24 , 1876 ) jẹ ́ Ààrẹ kìnní àti keje ilẹ ̀ làìbéríà ( 1848-1856 ) àti ( 1872-1876 ) .
Àkọlé àwòrán, A o ni gba ọjẹgẹ rara ninu atilẹyin wa fun ikọ Super Eagles BBC News, Yorùbá Ìdí tí ẹ fi le è nígbàagbọ́ nínú ìròyìn BBC Ìlànà Lílò Nípa BBC Òfin Àṣírí Cookies Kàn sí.
Eyii si ti mu ki ọpọ awọn Musulumi maa bere pe bawo ni Ramadan ọdun yii yoo ṣe ri.
Nítorí náà, ohun gbogbo tí wọ́n bá sọ fun yín ni kí ẹ ṣe.
Covid-19 tún ti ran èèyàn 796 míràn ní Nàìjíríà Ìjọba ìpínlẹ̀ Ondo kéde òfin konile-o-gbele ní Ode ati Ishinigbo lẹ̀yìn rògbòdìyàn tó wáyé níbẹ̀ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Promise Akinlade: ọmọ ọdún mọ́kànlá tó ń fi ìlù dárà bíi àgbàlagbà sọ̀rọ̀ nípa tálẹ́ǹtì rẹ Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Victoria Kolawole: Òṣèré tíátà Yorùbá ní òun kò tíì ṣe ìgbéyáwó àmọ́ òun kò wá ọkọ''9 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Border Closure reoppening: Àarẹ Buhari ní àti dẹ́kun fàyàwọ́ ogun ati ìbọn ló fa títi ẹnubodè pa, ṣùgbọ́n yóò di ṣíṣí padà láìpẹ́9 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Badirat Ajoke sọ pé òun fínnú-fíndọ̀ fi ààfìn Oyo sílẹ̀ ni, wọ́n kò lé òun9 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Shiloh 2020: Oyedepo ní òun kò le tòṣì láéláé!
" Àsìkò yìí náà ni ó gbé àwo orin tuntun kan jáde tí ó pè ní "" Ìbà special track "" àti ' Àbọ ̀ dé mecca ' ní ọdún 1980 ."
Awọn iwadi kan fihan pe ṣiṣe atunṣe bi mitochondria ṣe n ṣiṣẹ le fikun ọdun ti awọn nkan abẹmi bi eniyan yoo lo.
Òṣèrébìnrin tí wọ́n bá fi ìbálòpọ̀ lọ̀ 'torí ìṣẹ́, kó bọ́ síta láti sọ̀rọ̀ - Kunle Afod Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 3 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 5 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Ìyókù tun di ẹ̀yìn ọdún ńlá.
Àwọn bíi: Efi, Rekemu, Ṣuri, Huru, ati Reba, ọmọ ọba Sihoni, tí ń gbé ilẹ̀ náà.
21 bn Ẹka ina ọba - (to fi mọ N150bn fun agbende ẹka ina ọba) N198 bn Ẹka iṣẹ ati ile gbigbe - N404 bn Ẹka irinna ọkọ oju irin (Lagos-Ibadan-Kano, Abuja-Kaduna, Port-Harcourt-Maiduguri ati Itakpe-Ajaokuta-Warri)- N256 bn Eto aabo: N121 bn Eto ọgbin ati idagbasoke awọn igberiko - N110 bn Eka ipese omi - N153 bn Ẹka idokowo ati karakata - N51 bn Eto ẹkọ - N127 bn Ajọ ẹkọ ọfẹ kariaye: N70 bn Eto ilera - N132 bn Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Aya mi, dáríjìn mí fún bí n kò ṣe fi ìfẹ́ hàn tó sí ọ bó ṣe yẹ - Mike Bamiloye Ìdí tí Gúúsù Akure, Owo àti ìwọ̀orun Ondo yóò fi sọ ẹni tí yóò jáwé olúborí nínú ìbò gómìnà Ondo Kẹ̀rẹ̀ kẹ̀rẹ̀ Okonjo-Iweala ń súnmọ́ ipò olórí WTO bọ̀ Bode George ní Fayose gọ̀, ó fẹnu họra, Fayose ní ''ẹ ò lè pa mí bí ẹ ṣe pa Bola Ige Ènìyàn 5, ilé 25 ilé ìtajà 16 àti àwọn ǹkan mírà lo bá ìṣẹ̀lẹ̀ iná náà rìn.
Ìlọsíwájú sì ti wà dájú-dájú, ṣùgbọ́n kò tíì sí àwárí kankan tó kápá àrùn kògbóògùn pátápátá, ọ̀pọ̀lọpọ̀ ènìà ló sì ti ti ipasẹ̀ àrùn yìí rè'wàlẹ̀àsà.
Nígbà tí Hamani rí i pé ọba ti pinnu ibi fún òun, ó dúró lẹ́yìn láti bẹ Ẹsita Ayaba fún ẹ̀mí rẹ̀.
Kọmiṣọna fun ileeṣẹ ọlọpaa ipinlẹ Eko, Edgal Imohimi, ni mimu ti awọn mu wọn ko ṣẹyin awọn oṣiṣẹ alaabo abẹle to sin ileesẹ ọlọpa ni gbẹrẹ ipakọ.
Gbogbo wa ń bú bí ẹranko beari,a sì ń ké igbe ẹ̀dùn bí àdàbà.
“Ẹ lọ dúró ninu Tẹmpili kí ẹ sọ gbogbo ọ̀rọ̀ ìyè yìí fún àwọn eniyan.
”Wọ́n dáhùn pé, “Ìbátan Ahasaya ni wá.
"Ọlọpaa ti ti awọn mejeeji mọ le bayii.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Kemi Dairo: Iṣẹ́ abẹ nínú ọpọlọ àti ẹ̀rọ ni mo fi ń gbọ́ ọ̀rọ̀ báyìí Èyí ni à n sọ lọ́wọ́ tí omíràn tún sẹ̀lẹ̀ nílùú Ibadan kan náà sí Azizat Somuyiwa eni ọdún makàndínlọ́gbọ̀n lágbàgbè Ijefun ni Moniya.
IPPIS ti ijọba gbe kalẹ ko faye gba sisan owo yii.
Nígbà tí à ń wá ọ̀nà ìdáláre ninu Kristi, bí a bá rí i pé ẹlẹ́ṣẹ̀ ni àwa náà, ṣé Kristi wá di iranṣẹ ẹ̀ṣẹ̀ ni?
''Bakan naa ni a ti ranṣẹ si awọn adari ileeṣẹ radio ati amọhunmaworan lati tẹlẹ aṣẹ wa lati maṣe lo orin Kwam 1 mọ.
Eyi lo difa fun gbajugbaja oṣere tiata Yoruba, Nkechi Blessing, to ke gbajare loju opo Instagram rẹ pe oun ko fẹran bi oun ṣe ri, lẹyin ti oun bẹrẹ si lo agbo kan lati dena ara sisan.
Akinwunmi Ishola rọrun Lẹ́yìn tórí yọọ́ nínú ìjambà ọkọ̀; Ọ̀jọ̀gbọ̀n Pius Adesanmi kú nínú ìjàmbá bàálù Ethiopia!
Gbogbo ilẹ̀ àwọn orílẹ̀-èdè yòókù tí a kò tíì ṣẹgun, ati gbogbo àwọn tí a ti ṣẹgun ni mo ti pín fun yín gẹ́gẹ́ bí ogún yín, ohun tí ó bẹ̀rẹ̀ láti odò Jọdani, títí dé Òkun Mẹditarenia ní apá ìwọ̀ oòrùn, 
Soyinka fi kun pe 'Orilẹede Naijiria ti n lọ si okun igbagbe nitori ko si ifẹ tabi ajọṣepọ to le e mu isọkan gbinlẹ mọ lorilẹede Naijiria.
Nítorí ẹ̀ṣẹ̀ Jakọbu, ati ti ilé Israẹli ni gbogbo nǹkan wọnyi yóo ṣe ṣẹlẹ̀.
Saaju ni, Dokita Ajayi ti se oludari ile- eko itoju oju,
Bí ó ti wá ní dúkìá àti orò tó yìí omo obìnrin kan soso ló bí.
ìwọ tí ò ń fi ìfẹ́ rẹ tí kì í yẹ̀ hàn fún ẹgbẹẹgbẹrun eniyan, ṣugbọn tí ò ń gba ẹ̀san àwọn baba lára àwọn ọmọ wọn lẹ́yìn ikú wọn, ìwọ Ọlọrun alágbára ńlá tí orúkọ rẹ̀ ń jẹ́ OLUWA àwọn ọmọ ogun, 
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ọ̀nà wo lowó osù tuntun yóò tọ̀, kó tó dé àpò òsìsẹ́?
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Fídíò BBC yọ àwọn èèyàn FIFA níṣẹ́ ṣááju Russia 2018 Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Fídíò BBC yọ àwọn èèyàn FIFA níṣẹ́ ṣááju Russia 2018 9 Òkùdu 2018 Ó lé ni ọgọ́rùn ún òṣìṣẹ́ eré bọọlu tó kó sí páńpẹ́ ìwádìí náà Anas tí ó jẹ́ akọ̀ròyin ọ̀tẹlẹ̀múyẹ́ tó máa ń da agọ̀ bojú kí wọn má baà lé rí ojú rẹ̀, sọ pé, màgòmágó àti rìba ti ba ere bọ́ọ̀lù jẹ́ ní Ghana.
osise orile ede Naijiria lẹtọọ lati gba ju ẹkunwo ọgbọ̀n ẹ̀gbẹ̀rún  lọ, ti owo ọhun ba wa lati san.
ede yii se ya wọ ile ikabo.
Igbakeji Gomina Oyo, to ba BBC Yoruba sọrọ l'Ọjọbọ ṣalaye pe, oun ko figba kan sọ sita pe ija wa laarin awọn mejeeji, bẹẹ ni Makinde fun ra rẹ naa ko sọ fun ẹnikan pe oun ati igbakeji oun n ja.
FCT lo tẹ̀lé pẹ̀lú mẹ́tàlélagbọ̀n, Kaduna náà pọ́wọ́ lèé pẹ̀lú mẹ́rìndinlógu, Rivers ní ènìyàn méjìdínlógún ti Ipinlẹ Eko sì wà ni ipò kaarún pẹ̀lú mẹ́tàdílógún.
ekun Gusu yii; awon oga olopa ni ipinle mefeefa to wa ni ekun Gusu yii ati gbogbo
O fi kún un pe ti àwọn ba ṣeesì mú ẹni ti ó jẹ onígbagbọ ti ó ba ti le ṣàlàye ara rẹ àwọn yóò fi ẹni náa silẹ ni kiakia.
‘Ọlọrun sọ pé, “Nígbà tí ó bá di àkókò ìkẹyìn,n óo tú Ẹ̀mí mi jáde sórí gbogbo eniyan.
Ẹgbẹ ọmọ bibi ilu Offa lawọn ṣi n dunadura pẹlu awọn ajinigbe lati doola ẹmi awọn ọmọ ilu Offa mẹfa ti wọn ji gbe.
Iko omo ogun Naijiria ti bu enu ate lu esun ti won fi kan pe iko
 Oríṣun àwòrán, @GovernorObaseki Idris, lasiko to n sọrọ lori akori ayajọ ọjọ olukọ naa, ti wọn pe ni 'Ọdọ Olukọ ni ọjọ ọla fun isẹ olukọ', tun kesi ijọba apapọ lati tete san owo ida mẹtadinlọgbọn ati aabọ owo ajẹmọnu isẹ fawọn olukọ to wa lawọn ileekọ girama tijọba apapọ, nitori eyi lo ni yoo jẹ ki ori awọn olukọ naa wu lati sisẹ bo se yẹ."
“Tí ẹnìkan bá kú ninu àgọ́ kan ẹnikẹ́ni tí ó bá wà ninu àgọ́ náà, ati ẹnikẹ́ni tí ó bá wọ ibẹ̀ yóo di aláìmọ́ fún ọjọ́ meje.
Aare Muhammadu Buhari yoo gbe ipolongo eto idibo saa keji re lo siluu
Nigba ti BBC ba a lalejo ni ẹnu iṣẹ rẹ, Ernest ṣalaye pe nigba mii, bi taya ọkọ ṣe ri lo maa n fun oun ni imisi ohun ti yoo pa a lara da si.
kopa ninu amojuto ayika ati lati fi aye gba awon ile ise miiran to n mojuto
N óo fi oríṣìíríṣìí ìyà tí ó níláti jẹ nítorí orúkọ mi hàn án.
Biden ni ọrọ ti ọgbẹni Meadows sọ n ṣapẹrẹ pe, ijọba Trump ti gba kadara pe wọn ti kuna lori ojuṣe wọn lati daabo bo awọn eeyan ilẹ Amerika.
Kàn sí ilé iforukọsilẹ NIMC to sunmọ ọ pẹlu ojulowo iwe idanimo to ba yẹ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Kollington ṣàlàyé bí orin Fuji ṣe bẹ̀rẹ̀ gan an ní Nàiìjíríà Bi o ba ti debẹ kan si kanta oṣiṣẹ wọn ti yoo ṣe ayẹwo gbogbo ìwé tó kọ lọwọ Ti gbogbo nkan rẹ bá pé daada oṣiṣẹ yi yoo gba oju ika rẹ mẹwẹwaa silẹ to fi mọ àwòrán oju rẹ.
COZA RAPE: Àjọ pẹntikọsita ní Nàìjíríà (PFN) sọ pé Biodun Fatoyinbo ní kò jẹ́ kí ìwádìí wọn parí
Oríṣun àwòrán, Joshua Paul for the BBC ''Amọ wahala to wa pẹlu Sharia ni Malaysia ni wi pe nnkan ti o n ṣe gẹlẹ ni yẹn, ofin Sharia ti wọn n lo máa n dẹyẹ si awọn ti a kà silẹ yii''.
" Eyi ni ero onimọ kan nipa ihuwasi ẹda ati imọ sayẹnsi nipa ọpọlọ, Matthew Walker, to wa lsgba fasiti California.
Ninu alaye rẹ, Sẹnetọ Marafa ni ko tii si ọna ati yanju aawọ nipinlẹ Zamfara ti oun ti wa, nitori to ba ri bẹẹ ni, o yẹ ki wọn ti kan si oun.
Wọn ni wọn ti fi afojusun lati na o din diẹ ni biliọnu marun un naira lori atunṣe ati ipese awọn wáyà ina.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ṣọ́ra fún ibi tí ò ń bọ́ bàtà rẹ sí Àwọn ọlọ́pàá ṣàlàyé fún Adajọ n'ile ẹjọ kekere ti Katsina pé ni abule Tsen Kura ni wọn ti gbiyanju lati já ọ̀kadà Bajaj gba lọwọ Tasiu Bello ko tó pariwo s'ita f'araye.
2 144 Orilẹede Monaco 3 7.
20 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Oríṣun àwòrán, Others Amọ, o fikun wi pe, ijiroro nlọ lọwọ pẹlu awọn orilẹ-ede to sumọ Naijiria lati bọwọ fun ofin katakara ti yoo mu ki ibasepọ to gbooro wa laarin awọn orilẹ-ede nilẹ Afirika.
Ọpọlọpọ iwọde ni wọn ti ṣe sẹyin lati igba ti ọrọ ẹsun ifipabanilopọ ti ṣẹlẹ pe pasitọ Biodun Fatoyinbo fipa ba arabinrin Busola Dakolo lo pọ Ọkọ mi kò le f'ipá bá ẹnikẹ́ni lò pọ̀ láíláí - Modele Fatoyinbo COZA: Mi ò fípá bá obìrin lò pọ̀ rí láyé mi - Pásítọ̀ Fatoyinbo CAN kò rán ẹnikẹ́ni lọ ṣọ́ọ̀ṣì COZA, iṣẹ́ ara wọn ní wọ́n lọ jẹ́ -Samson Ayokunle Àdúrà kò le pa ìfipábánilòpọ̀ rẹ́, àtàwọn àkọlé mìí tó jẹyọ lórí ọrọ Fatoyinbo Bukky Shonibare to jẹ ọkan pataki lara awọn to fẹ ṣe iwọde naa ni idi tawọn ṣe fẹ sẹ iwọde toni ni pe ko yẹ ki ẹgbẹ CAN dọwọ bo iṣẹlẹ naa.
Ile Igbimọ Aṣofin Ipinlẹ Eko ṣe ipade ita gbangba awọn alẹnulọrọ ni gbagede wọn ni Ikẹja.
Egbe to n ri si sise akoole oro ere idaraya ni Naijiria, Sports Writers Association of Nigeria (SWAN), ti panupo pelu ebi, ore, ara lati ki Dokita Ayodeji Olarinoye, ku oriire iyansipo tuntun gege bi alakoso eto ilera awon agbaboolu fun ajo to n ri si boolu afesegba lagbaye FIFA Doping Control Officer (DCO), eni ti o je dokita ti o n sakoso ilera iko agbaboolu odo Naijiria tojo ori won ko ju metadinlogun lo (Nigeria’s national Under-17 team).
asobode to n soju ekun ipinle Oyo/Osun lorilede Naijiria ti fi eka ile ise ohun
Joṣua ṣe bí OLUWA ti pàṣẹ pé kí ó ṣe sí wọn: ó dá àwọn ẹṣin wọn lẹ́sẹ̀, ó sì sun àwọn kẹ̀kẹ́ ogun wọn níná.
Awọn asofin apapọ lorilẹede Amerika lo nira fun lati panupọ buwọlu aba inawo naa, ti wọn si fi ibo didi yanju ọrọ naa, eyi to mu ki ọrọ pakasọ, ti awọn asofin to tako aba yi si pọ ju awọn to faramọ lọ, eyi to mu ki eto ijọba ilẹ Amerika gba isinmi fun igba diẹ lati sjs ẹti to kọja.
 johnson àti cynthia johnson nílùú houston , < nowiki > texas < / nowiki > .
Ṣé o óo máa bínú sí wa títí lae ni?
Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Insecurity: Àwọn aráàlú ní ìpànìyàn àti ìgbéṣùnmọ̀mí ni kò jẹ́ kí ẹnu sìn lára Buhari13 Èrèlè 2020 Insecurity: Monguno ní àsìkò ti tó láti f'òpin sí Almajiri ní Nàìjíríà4 Ọ̀pẹ̀̀ 2019 Insecurity: Agbẹkọya ní òògùn abẹnugọ̀ǹgọ̀ ní ọ̀nà àbáyọ fún ìjínigbé!
Xenophobia: Ọ̀sẹ̀ tó ń bọ̀ ni bàálù yóò lọ kó ọmọ Nàíjíríà wálé
Obìnrin ará Morocco pa olólùfẹ́ rẹ̀, ó fi se ìrẹsì
Ó bá yíjú pada sí wọn, ó ní, 
Toripe o ti wa du ipo aarẹ ri, ko jẹ aiṣeeṣe bi ọpọ ara Amẹrika ba ri i bi aarẹ lọjọ ọjọ kan.
Ana ni àkọ́bí aarẹ ṣi ile itaja náà silu Los Angeles, to si sọ pe nkan akọkọ ti oun ṣe àṣeyọrí sí rere lori rẹ ni yẹn.
Àwọn mọ̀lẹ́bí ajínigbé tó pàdánù ẹ̀mí l'Ondo kò tí ì yọjú Ọ̀tọ̀ọ̀tọ̀ lèrò àwọn èèyàn lórí ìyanṣẹ́lódì SSANU Ìyanṣẹ́lódì òṣìṣẹ́ ilé aṣòfin bẹ̀rẹ̀ ní perewu nílé aṣòfin Nàìjíríà Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ile isẹ ọlọpaa n gbe Ọrẹkunrin Khadijat rẹlẹ ẹjọ ni Ọjọ Aje Ọwọ wa tẹ awọn afurasi ajinigbe mẹjọ ni bi ọsẹ meji sẹyin, ko si si ẹya Fulani kankan lara wọn."
Lẹyin naa ni ọkunrin ọhun, Tijani Abdulkareem ke gbajare si awọn eeyan lori ayelujara fun iranlọwọ.
Ìdí táwọn olùwọ́de EndSARS fi kọ oúnjẹ àti ọtí ẹlẹ́rìndòdò tí MC Oluomo gbé wá rèé Ohun tí ojú ìyàwó mi rí lọ́wọ́ SARS kò ṣe é fẹnusọ- Poju Oyemade Ìjọba ìpínlẹ̀ Eko ti kéde orúkọ àwọn ọlọ́pàá tó fi ìyà jẹ àwọn olùwọ́de #EndSARS Ajínigbé tú ìyá àti ọmọ ọdún mẹ́ta sílẹ̀ lẹ́yìn tí wọ́n gba ₦1.
4m lórí báíró, ₦46m lórí ìwé, ₦56m fún tónà 12 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Oríṣun àwòrán, @MBuhari Ọrọ di agbọdamiẹnu lasiko tawọn ọmọ igbimọ tẹẹkoto lori aṣuwọn owo ilu nile aṣofin agba n gbọ ọrọ lẹnu oluyẹweowo wo agba lorilẹede Naijiria.
Pé n óo pa àwọn ará Asiria run lórí ilẹ̀ mi;n óo sì fẹsẹ̀ tẹ̀ wọ́n mọ́lẹ̀ lórí àwọn òkè mi.
Wọ́n bẹ̀ ẹ́ lọ́wẹ̀ kí ó lè dẹ́rù bà mí, kí n lè ṣe bí ó ti wí, kí n dẹ́ṣẹ̀, kí wọ́n lè bà mí ní orúkọ jẹ́, kí wọ́n wá kẹ́gàn mi.
Ó wọ inú tẹmpili OLUWA, ó lọ sun turari lórí pẹpẹ turari.
O ni oun ṣi wa ninu ikaya soke lori ti iya oun ti wọn ji gbe ti wọn ni ki oun ls maa wa ẹgbẹlẹgbẹ owo wa ki ajọ FIFA to tun gbe tiwọn de.
A kú ewu ọdún tuntun, ọdún ayọ̀,ìdùnnú, oríre ni yíò je fún gbogbo wa láṣẹ èdùmàrè.
Ẹ̀wẹ̀ Naira Marley náà ti kọ sí ojú òpó Twiiter rẹ @officialnairam1 pé àwọn kò ni ṣe ìfẹhonu hàn mọ́, ṣùgbọ́n ó ké si àwọn ọ̀dọ́ pé, ikéde náà wà fún ki àrá ìlú le ni ìfọ̀kanbalẹ̀.
"Koda, ori ẹni ni wọn ko awa obinrin mẹrin si ninu yara kan, ti awọn ọkun yoo si wa lati ba wa lopọ lasiko kannaa"" Sanwo-Olu pèsè ìpàgọ́ tó wà ní Igando fáwọn tí iná jólé wọn ní Abule Egba láti gbé Mọ̀ síi nípa ǹkan tí o lè ṣe láti dènà ibà Lassa Tinubu kò ṣékú, kò ṣé ẹyẹ, o n dibọn ní lórí ọ̀rọ̀ ikọ̀ Amotekun - Fani Kayode Ọ̀gá ọlọ́pàá tó wà ní 'Check Point' kàgbákò ikú òjijì lọ́wọ́ awakọ̀ l'Eko Lẹyin ọpọlọpọ iya ati iṣẹ, ọga Adeola le e kuro pe o ti san owo oun tan, ti Adeola si di ẹni ti n sun ita, ki obinrin kan to jẹ ọmọ Naijiria to seranwọ lati gbaa sile, nibẹ si lo ti foju han si pe o ti ko aisan to nii se pẹlu nini egbo loju ara."
"Bi mo ba ri i nibi nisinsinyii, maa kunlẹ maa bẹ ẹ""."
àwọn ọmọ Reaaya, àwọn ọmọ Resini, ati àwọn ọmọ Nekoda, 
 orílẹ ̀ -èdè àkọ ́ kọ ́ ló kọ ́ kọ ́ gba ìlú yìí lọ ́ wọ ́ ẹ ̀ kẹjì nínú ogun kan tó wáyé ní ọdún 1908 .
O ni oṣiṣẹ LASTMA kan lati ọfiisi wọn to wa ni agbegbe Masa-Masa da wọn duro, o si ko wọn lọ si ọfiisi wọn nibi to ti jade lọ ṣugbọn o sọ fun igbakeji rẹ ko gba ẹgbẹrun lọna aadọta lọwọ onikaluku wọn lai fun wọn ni iwe ẹri pe wọn sanwo.
Oríṣun àwòrán, Tunde ednut Diẹ lara nkan ti awọn eniyan n sọ loju opo twitter nitori oju opo Instagram ti wọn ti pa ree Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 3 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 5 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Bissau, ni eyi ti alaafia yoo se pada jọba lorile ede naa.
Abiṣai bá sọ fún Dafidi pé, “Ọlọrun ti fi ọ̀tá rẹ lé ọ lọ́wọ́ ní òní yìí, gbà mí láàyè kí n yọ ọ̀kọ̀, kí n sì gún un ní àgúnpa lẹ́ẹ̀kanṣoṣo.
" Oríṣun àwòrán, Instagram/iyaboojofespris Iyabọ ni to ba jẹ pe ijọba wa n gba imọran awọn gbajumọ ni, ko ba ti gba imọran Fẹla, ko to jade laye ati tawọn ilumọọka miran sugbọn ọpọ eeyan maa n yara tete di ẹbi fun ẹlomiran, to si gbagbe pe ika ko dọgba.
Bi ojumọ ti n mọ ni eeyan n dagba ti ara n darugbo sii.
Ki wa lo n sokunfa laasigbo awon elede geesi, ni awon ekun meji ti won so ede geesi yii, lakoko won so pe, awon elede Faranse to poju lorile-ede Cameroon pa won ti segbe kan, bakan naa ni won hu iwa ideyesi si won.
O tun gba wọn nimọran pe, ki wọn mase gbagbe lati mu awọn ileri ti wọn ṣe fawọn to dibo yan wọn lẹkun ti wọn n ṣoju sẹ, nibayii ti wọn ti wa nile aṣofin l'Abuja.
Ohun tó bá wù yín ni kẹ sọ, iṣẹ́ ló ká mi lára - Ighalo Watford tu ìyẹ́ apa Liverpool Ṣé Liverpool ṣì leè tẹ̀síwájú ní ìdíje Champions league?
Ẹni tí ó ju Jona lọ wà níhìn-ín.
O ni bii ẹẹdẹgbẹta pali ogun ikọ naa, ni awọn ja gba nigba ti wọ da ọkọ naa duro.
O ṣalaye pe eyi si ti mu ki ibaṣepọ to dara wa laarin ijọba ipinlẹ Oyo, ati awọn awakọ ero.
HIV/AIDS: Ìjọba Nàìjíríà gbé èsì ìwadìí tuntun jáde lóríi ọwọ́jà HIV/AIDS
Dokita Obinnaadigo sọ pe aaye to wa laarin aya ati ikun ni irora aisan ọgbẹ́ inu.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Kàyééfì BBC Yorùbá: Bí Ọba aládé ṣe jàjà bọ́ lọ́wọ́ àwọn afurasí ajínigbé 27 Owewe 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 28 Bélú 2020 Lori eto iroyin Kayeefi BBC Yoruba lọsẹ yii, a mu itan nipa bi awọn ajinigbe darandaran ti ṣe fẹ gbiyanju lati ji Ọba Alade gbe nilẹ Yoruba.
Wọ́n dàbí àgékù koríko,iná ni yóo jó wọn ráúráú,wọn kò sì ní lè gba ara wọn kalẹ̀, ninu ọ̀wọ́ iná.
Peteru bá gbéra, ó tẹ̀lé wọn.
Eyi ko sẹyin bi ìjọba ṣe tẹwọ gba idasilẹ ijọba ibilẹ Ọffa, ti wọn si fagile Ilorin Alkali to wa nilẹ tẹlẹ.
Oríṣun àwòrán, Twitter Amọ, iroyin fi lede wi pe ọpọlọpọ awọn eniyan ni Gomina Akeredolu ti farakan to fi mọ Aarẹ Buhari, awọn lọbalọba ati awọn aṣofin naa.
A dá ẹgbẹ́ yìí sílẹ̀ láti polongo èdè Yorùbá ní gbogbo ọ̀nà tí a lè gbà mú u wuyì fún tolórí- tẹlẹ́mù.
''O ti wa lori oye tẹlẹ, ko si yẹ ki idiwọ kankan waye lati maa tẹsiwaju pẹlu iṣejọba.
Ilé alájà méjì wó lu ọmọ mẹ́rin ni Bariga Ẹni mẹ́ta gbé Buhari lọ sílé ẹjọ́ nítorí pé ó parọ́ ìwé ẹ̀rí rẹ̀ fún àjọ INEC El-Zakzaky kò fojú hàn nílé ẹ́jọ́ ṣùgbọ́n wọ́n sún ẹjọ́ rẹ̀ síwájú Ibadan NURTW: Àwọn ti Auxilliary àtàwọn tí Ajanaku gangan ló ń dàgboro rú Igba karun un ti Shekau ku lọwọ ijọba: Awọn ọmọ ogun ofurufu Naijiria lo ṣe ikede ti ọtẹ yii.
Oun ti iya mi ko le mọ bayii ni bi iku rẹ ṣe mu iwuri ba ẹgbẹgbẹrun awọn eniyan ni Malta ati awọn ibo miiran.
Abimeleki tún lọ ń gbé Aruma.
Atẹjade ọhun ni awọn agbebọn ko ya bo agọ ọlọpa rara, amọ awọn to duro soju popo ni wọn se lọsẹ, ti ẹmi ọlọpaa kan si bọ.
Ẹ ̀ gbá aké ló dé gbẹ ̀ yìn .
Ṣugbọn òfin yìí kò bẹ̀rẹ̀ pẹlu Mose, àwọn baba-ńlá wa ni ó dá a sílẹ̀.
Dele, ọmọdé tó ń fi iná ẹ̀rọ ATM ṣe iṣẹ́ àmurelé sọ ìdí tó fi kára mọ́ ẹ̀kọ́ rẹ̀ fún BBC Yorùbá Ọ̀ọ̀ni kò láṣẹ láti yọ mí nípò, mi ò sì ní ááwọ̀ mọ́ pẹ́lú Aláàfin-Oluwo Ìgbà mẹ́rin tí ọ̀rọ̀ Oluwo dá awuyewuye sílẹ̀ Ọ̀rọ̀ èmi àti Olorì Chanel Chin kò yé ara wa mọ́ nínú ilé- Oluwo Ọba Abdulrasheed ni toun ti pe idajọ lọ rọọkun nile naa fẹ lagbara diẹ ṣugbọn oun yoo bọwọ fawọn to pa aṣẹ naa.
Cardiac Attack: Wo ọ̀nà méje bí o ṣe lè dẹ́kun ikú òjijì
Mo rán oníṣẹ́ mi ṣiwaju rẹ, òun ni yóo palẹ̀ mọ́ dè ọ́.
Dafidi bá mú ọ̀kọ̀ ati ìgò omi Saulu ní ìgbèrí rẹ̀, òun pẹlu Abiṣai sì jáde lọ.
Oríṣun àwòrán, @Oyoaffairs Seyi Makinde fofin de ẹgbẹ NURTW Ọyọ, o gbakoso gareji ọkọ Bẹẹ ba gbagbe, owurọ ọjọ Ẹti ni ijọba ipinlẹ Ọyọ kede pe oun ti fofin de ẹgbẹ awakọ ero nipinlẹ Ọyọ, NURTW, to si pasẹ pe eegun wọn ko tun gbọdọ sẹ mọ.
Olódodo a máa ronú kí ó tó fèsì ọ̀rọ̀,ṣugbọn ọ̀rọ̀ burúkú níí máa jáde lẹ́nu àwọn eniyan burúkú.
Ayaba wà ní ìjókòó lẹ́gbẹ̀ẹ́ ọba, ọba bá bèèrè lọ́wọ́ mi pé, “O óo lò tó ọjọ́ mélòó lọ́hùn-ún?
Òun náà lọ sí ilé, ó kó gbogbo ìní rẹ̀ jọ, ó fi wọ́n fún ìyàwó tí ó kọ́ ní tí í ṣe ìyáálé fún oníkúpani obìnrin ọmọ-ọba nì, ó múra láti kú.
Ṣé o lè fi okùn sí imú rẹ̀,tabi kí o fi ìwọ̀ kọ́ ọ ní àgbọ̀n?
Bo tilẹ jẹ pe ọkunrin naa ti wọn pe orukọ rẹ ni Jomaph sẹ́, aworan CCTV ọhun fi han pe o wọ iyẹwu tọ ọmọdebinrin naa lọ.
Akọwe ijọba ipinlẹ Kano ni awọn afọbajẹ mẹrin ti kọkọ dabaa Aminu Ado Bayero fun ipo Emir tẹlẹ.
Ọkunrin náà ni yóo gbà wọ́n kalẹ̀ lọ́wọ́ àwọn ará Filistia, nítorí mo ti rí àwọn eniyan mi tí ń jìyà, mo sì ti gbọ́ igbe wọn.
Magawa: Èkúté tó sàwárí bọ́mbù ilẹ̀ gbàmi ẹ̀ye wúrà PDSA
Ọkọ̀ ti kúrò ní èbúté, ó ti bọ́ sí agbami.
Nibayii, ọjọ kẹrinla oṣu karun ni igbẹjọ naa yoo maa waye bayii gẹgẹbii adajọ to n gbọ ẹjọ naa nilu Milan ṣe sọ.
Mo fẹ́ kí Ọlọ́run fún wa ní ọmọ olójú búlúù si lẹ́yìn yìgì - Ọkọ olójú búlúù Ọdún Hijri mùsùlùmí tuntun wọlé dé, ẹ wo kókó pàtàkì nípa rẹ̀ Afurasí lórí ikú Tolulope Arotile ti dé ilé ẹjọ́, èyí ni ẹ̀sùn tí wọ́n fi kàn án Ẹ̀yin gómìnà, Ifá nìkan ló le tọ yín sọ́nà láì kùnà lórí Amotekun - Babaláwo Ninu ọrọ tirẹ, Babalawo Jogodo ni ọdun naa ni wọn fi n ranti iṣẹṣe ilẹ Yoruba ni lati dupẹ lọwọ Olodumare.
Oyeyẹmi salaye siwaju si pe eto aabo jẹ iṣẹ ajumọṣe fun tolori tẹlẹmu lawujọ wa, ki ifọkanbalẹ le wa kaakiri ilu.
Bakan naa, ireti wa pe, awon akonimoogba iko Super Eagles ati amule iko ohun, Ikechukwu Ezenwa yoo teko leti lo sorile-ede Poland leni lati lo bere igbaradi ni kikun.
“Ṣugbọn bí ẹnikẹ́ni bá kórìíra aládùúgbò rẹ̀, tí ó bá ba dè é, tí ó mọ̀ọ́nmọ̀ pa á, tí ó sì sálọ sí ọ̀kan ninu àwọn ìlú wọnyi, 
Ṣugbọn nítorí pé kò ní ọmọkunrin kankan Joramu, arakunrin rẹ̀ jọba lẹ́yìn rẹ̀, ní ọdún keji tí Jehoramu ọmọ Jehoṣafati jọba ní Juda.
jawe olubori ninu eto idibo to waye ni ọjọ Abamẹta ikẹ́tàlélógún, osu
apejẹ ti aya igbakeji aare iyaafin Dolapo Osinbajo se, niluu Eko lati fi dupe
Bournemouth fi àáké da Tottenham lágbo nù ní eré ìje fún Champions league Champions League: Ajax f'imú Tottenham fọn fèrè Àwọn ọmọge wọ gàù l'Abuja nítorí asọ péńpé Ajimobi figbe ta, ó ní 'èmi kọ́ ló pa Ṣugar o!
Ethiopian Airline crash: Àbájáde ìwádìí ọkọ̀ bàálù Ethiopia wẹ awakọ̀ bàálù mọ̀ ọ́
Kí o tó ta ilẹ̀ náà, mo ṣebí tìrẹ ni?
Báwo ni a óo ṣe rí aya fún àwọn tí ó ṣẹ́kù; nítorí pé a ti fi OLUWA búra pé a kò ní fi àwọn ọmọbinrin wa fún wọn?
26 Owewe 2020 Alaafin: Ọmọ ọdún 17 ní Ayaba Abibat Adeyemi nígbà tó fẹ́ ọkọ rẹ̀8 Owewe 2020 Alaafin: Olorì Folashade ní òun ni olorì àkọ́kọ́ tó bí ìbẹta nílẹ̀ Yorùbá12 Owewe 2020 Fídíò, Ilu gangan: O jẹ́ atọ́nà fún Alaafin àti àwọn ara ilu- Rahman Wahab24 Agẹmo 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 3 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 5 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Oríṣìíríṣìí ẹranko ìgbẹ́ ni yóo máa gbé abẹ́ rẹ̀.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Àwọn òmùwẹ̀ ń wá èèyàn kan tó pòórá lẹ́yìn ìjàmbá ọkọ̀ ojú omi to dójúdé l'Eko 24 Òkùdu 2020 Oríṣun àwòrán, twitter/LASWA Lai tii pe ọsẹ kan lẹyin ti ijọba ipinlẹ Eko kede iroyin ayọ pe ko si ijamba ọkọ ojuomi lawọn ojuna agbami ni ipinlẹ naa laarin oṣu mẹfa, eeyan kan ti di wiwa bayii lẹyin ti ọkọ oju omi kan to n rinna lọ loju agbami agbegbe Lekki dojude.
Àwọn ọmọ Iyabọ Ojo rí Bàbá lẹ́yìn ọdún mẹ́fà To ba n wa ọkọ̀, yàgò fáwọn ìgbésẹ̀ yìí Ikọ̀ ẹlẹ́sìn Hàkíkà rèé, níbití wọn ti ń pààrọ̀ ìyàwó láàrín ara wọn Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ọ̀gá Bello: Àìgbọ́n ló ń da àwọn òsèré tíátà tó ń jà lórí ayélujára láàmú Ati pe o lu awọn nọọsi, to fi mọ Ọga Agba nileewosan naa, Dokita Akinwumi Akinloye, ni alaubami.
Wọ́n dojú kọ ọ́, wọ́n ní, “Usaya, kò tọ́ fún ọ láti sun turari sí OLUWA; iṣẹ́ àwọn alufaa tí wọ́n jẹ́ ọmọ Aaroni ni, àwọn tí a ti yà sọ́tọ̀ láti máa sun turari.
Bi o ti le je pe, Ashley Barnes da ami-ayo kan pada, lati so esi ifesewonse ohun di ami ayo kan si meji(1-2), sugbon omi po ju oka lo.
Oríṣun àwòrán, Ayourb Àkọlé àwòrán, Awọn aarẹ orile-ede naa ti de silu Abuja Bó tilẹ̀ jẹ́ pé ìròyìn yìí ko fẹ́sẹ̀ múlẹ, ti ko si si oun a ri gbámu kankan níbẹ̀, ọ̀pọ ọmọ Naijiria ti pari bi gbogbo ǹkan yóò ṣe lọ leto leto.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Kano: Gomina Kano yan Emir mẹ́rin bíi Ajimobi tó jẹ́ àna rẹ̀ 9 Èbibi 2019 Oríṣun àwòrán, WIKIPEDIA Àkọlé àwòrán, Ní ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́, Ọba kan ló wà kí gómìnà Abiola Ajimobi tó yan ọba 43 míràn dípò ọba Olúbàdàn kan tó wà tẹ́lẹ̀.
A wá ń yọ̀ ninu ògo Ọlọrun tí à ń retí.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Mo ti kó kúrò nílé Olu Jacobs rí lẹ́ẹ̀mejì- Joke Silva Àkúntúnkú, ìgbà márùn ún rè é tí Shekahu kú tí wọ́n ní kò kú mọ Kò sí ìfòyà lásìkò ọdún iléyá ní òpópónà Marosẹ Eko si Ibadan Ibadan NURTW: Àwọn ti Auxilliary àtàwọn tí Ajanaku gangan ló ń dàgboro rú Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Iya Adura Esther Ajayi sọ àṣírí owó rẹ̀ tó fi ń ṣàánú Iroyin ọhun salaye pe, Kẹmi lo ti n safihan pe ojojo n se ogun oun lati ilu Medinah, to si sun sinu ọkọ lasiko ti awọn olujọsin yoku lọ wo awọn ibudo manigbagbe to wa nilu Medinah.
Oríṣun àwòrán, Others Àkọlé àwòrán, Coronavirus: Alaye rèé lóri pò ti ni àwọn ọmọ Naijiria wà ní Italy Akintade fikun pe bo tilẹ̀ jẹ́ pe àwọn ko ṣiṣẹ́, síbẹ̀ ijọba n san owó fawọn laiyinjẹ ti oṣù bá ti pari, eyi ti ko jọ ohun to n waye nilẹ Afirika to jẹ pe ẹni to sisẹ gan ko ri owo osu rẹ gba.
Adajọ naa wa ni ọlọpaa ṣi le gbe Ogundipe ti mọle fun ọjọ marun miiran.
O dupẹ lọwọ awọn alatilẹyin ẹgbẹ Galaxy to si ni itan igbe aye oun ṣi n tẹsiwaju.
Ẹ má máa mu ọtí yó, òfò ni.
Isẹlẹ naa, to waye ladugbo Ijẹsatẹdo nipinlẹ Eko ni oludari agba fajọ Lasema, Olufemi Osanyintolu fi idi rẹ mulẹ fawọn akọroyin.
Ọ̀rọ̀ yìí di ẹ̀ṣẹ̀ sí wọn lọ́rùn nítorí pé àwọn eniyan náà bẹ̀rẹ̀ sí lọ sí ìlú Bẹtẹli ati ìlú Dani láti jọ́sìn.
Bakan naa lo fi awọn Oludibo ni ipinlẹ Ondo lọkan balẹ pe, ijamba ina naa ko ni ṣakoba kankan fun bi eto idibo naa yoo ṣe lọ ni ọjọ kẹwaa, oṣu kẹwaa, ọdun 2020.
Eid-el Kabir: Buhari rọ àwọn mùsùlùmí láti yàgò fún ìwà ipá nínú ìkíni ọdún
Ní àkókò ìkórè, n óo sọ fún àwọn olùkórè pé: ẹ kọ́ kó èpò jọ, kí ẹ dì wọ́n nítìí-nítìí, kí ẹ dáná sun ún.
Àwọn ọbá aláye ilẹ̀ Yorùbá márùn-ún pẹ̀lú ọ̀pá àṣẹ wọn Eko, Kwara, Osun àtàwọn ìpínlẹ̀ míì tí àwọn èèyàn ti jí oúnjẹ ìrànwọ́ Covid-19 kó Ìjọba ìpínlẹ̀ Eko tí kéde ìlànà ìséde tuntun fún ará ìlú Wo ohun tí Fashola rí níbi ìṣẹ̀lẹ̀ Lekki Tollgate tó ń fa ariwo lórí ayélujara Ẹwẹ, Asiwaju ṣapejuwe pe irọ patapata gbaa ni wipe awọn to n ditẹ mọ oun ninu oṣelu lo kan n lo wọn lati kẹyin oun ati ijọba ipinlẹ ati ijọba apapọ sira.
Ìjọba yóò lo BVN àtàwọn ọ̀nà méjì míràn láti pín owó ìrànwọ̀ fún aráàlú Ibeere meji ni Olúyẹmí Fásípè fi tirẹ ṣe loju opo Twitter rẹ nigba to beere lọwọ ijọba pe ṣe wọn fun awọn ẹbi awọn eeyan mii ti covid-19 ti pa lanfaani lati sin oku eeyan wọn bi ti Abba Kyari?
496Iye ibo to yege jẹ- 521, 016iye ibo ti won fagile jẹ- 32182Ademola Adepoju.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Black women live matters: Ọdún 2015 ní àwọn ọlọ́pàá pa India Kager láìní ìdí- Gina Best Iwadii fi han pe Adejoh ti wọn fẹsun kan pe o ṣekupa Tolulope kii ṣe jagunjagun.
Simoni ti ròyìn ọ̀nà tí Ọlọrun kọ́kọ́ fi ṣe ìkẹ́ àwọn tí kì í ṣe Juu kí ó lè mú ninu wọn fi ṣe eniyan tirẹ̀.
takeo miki jẹ alakoso agba orile-ede japan tele .
Ní ọjọ́ kẹta, ọdọmọkunrin kan wá, láti inú àgọ́ Saulu, ó ti fa aṣọ rẹ̀ ya, ó sì ku erùpẹ̀ sí orí, láti fi ìbànújẹ́ hàn.
Arakunrin ọmọ ile iwe giga fasiti kan ree lorilẹede Naijiria to sọ iriri ara rẹ bo ṣe bẹrẹ ati bi gbogbo awọn to n lu jibiti ori ayelujara ti gbogbo eeyan mọ si Yahoo Yahoo ṣe n ṣe iṣẹ wọn.
82% ọkùnrin ní kó mọ̀ pé òun ní àìsàn jẹjẹrẹ asẹtọ ní Naijiria Kíni ẹ mọ̀ nípa agbègbè Abẹ́sàn án?
OLUWA ni Ọlọrun, ó sì ti tan ìmọ́lẹ̀ sí wa.
káyọ ̀ dé jáwé olúborí nínú ifẹsẹ ̀ -wọnsẹ ̀ 4 x 100 m nínú ìdíje ti 1992 olympic games ní barcelona , spain , òun pẹ ̀ lú ikọ ̀ rẹ ̀ chidiimoh , olapade adeniken àti davidson ezinwa .
Àṣìṣe ló ṣẹlẹ̀ níbi ètò ìsìnkú Abba Kyari- FCTA Yewande bí'mọ tuntun jòjòló, Mercy Aigbe pàdánù èèyàn rẹ̀, Toyin Abraham fèsì lórí aṣoju NCDC Ìtàn Manigbagbe: Àwọn àjakalẹ-àrun to ti wáyé rí ṣáájú Coronavirus Èyí tí a wò jùlọ 5:03 Fídíò, Omolola Arohunmolase Welder: Mo ti fí iṣẹ́ 'Welder' gbayì láwùjọ, tó mo fi tọ́ ọmọ yanjú, Duration 5,039 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 5:39 Fídíò, Akomolede ati Asa lori BBC: Olùkọ́ Kikelomo Ogunboye tan ìmọ́lẹ̀ sí ìwà olè ọ̀gá ọlọ́pàá Audu gẹ́gẹ́ bí àwòkọ́ṣe àsìkò yìí, Duration 5,398 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 4:11 Fídíò, Oba Adeyeye Ogunwusi: Ojú mi ti rí lọ́pọ̀ lọpọ̀, ọ̀pọ̀ èèyàn ni kò tilẹ̀ gbàgbọ́ pé mo lè jọba- Ooni, Duration 4,117 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 4:43 Fídíò, Promise Akinlade: ọmọ ọdún mọ́kànlá tó ń fi ìlù dárà bíi àgbàlagbà sọ̀rọ̀ nípa tálẹ́ǹtì rẹ̀, Duration 4,437 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 0:59 Gbọ́, Ìsẹ̀lẹ̀ jákèjádò orílẹ̀èdè àgbáyé láàárín ìṣẹ́jú kan, Duration 0,59wákàtí 6 sẹ́yìn 7:03 Fídíò, Olumuyiwa Bolade Adedeji Military Bruitality: Bí arákùnrin onípèníjà ara tí sọ́jà lù ṣe dé, Duration 7,035 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 4:45 Fídíò, Yoruba Films: Ẹ̀ẹ́ bẹ̀ mi kúrò láyé ni, mi ò lè kú - Fadeyi Oloro, Duration 4,4526 Èrèlè 2020 2:48 Fídíò, Esther Ajayi: Èmi náà ti borí ìṣòro rí ló ń mu mi ṣojú àánú, Duration 2,481 Ògún 2019 6:08 Fídíò, Adebola Ademilua: Àìrísẹ́ ṣè lẹ́yìn ìwé kíkà ló sọ mi dí ìyá onírú, mo dúpẹ́ tèmi, Duration 6,0827 Bélú 2020 5:55 Fídíò, Soyinka Cancer: Àṣe ara mi ni iso ti n run gbogbo bí mo ṣe n ṣèrànwọ́ lórí jẹjẹrẹ, Duration 5,5527 Bélú 2019 BBC News, Yorùbá Ìdí tí ẹ fi le è nígbàagbọ́ nínú ìròyìn BBC Ìlànà Lílò Nípa BBC Òfin Àṣírí Cookies Kàn sí.
“Ẹ yipada, ẹ̀yin alaiṣootọ ọmọ, nítorí èmi ni Oluwa yín.
ILÉ YÌÍ WÀ NÍ ÌRÀNTÍ ẸNI Ọ̀WỌ̀ OLÓWÓ-AYÉ, ọ̀kan NÍNÚ Àwọn ọmọ ÈNÌYÀN TÍ Ó WÁ SÍ IGBÓ OLÓDÚMARÈ LÁTI ṣe ọdẹ.
Ìdí nìyí tí wọ́n fi ń pe ibẹ̀ ní Mahanedani títí di òní olónìí; ó wà ní apá ìwọ̀ oòrùn Kiriati Jearimu.
“Nítorí náà, sọ àsọtẹ́lẹ̀ yìí fún wọn pé:‘OLUWA yóo bú ramúramù láti òkè,yóo pariwo láti ibi mímọ́ rẹ̀.
OLUWA tún dáhùn pé, “Ibìkan wà, lẹ́gbẹ̀ẹ́ ọ̀dọ̀ mi, wá dúró lórí òkúta kan níbẹ̀.
O maa n gba a ni imọran, o maa n fun ni owo ati ẹbun.
Ọna ti awọn ohun to wa lori ẹrọ alagbeka yii fi n pin alaye ikọkọ yii fun ileeṣe Facebook jẹ nipa oun eelo kan ti wọn pe ni SDK.
Ìyẹ̀fun tí ó kúnná dáradára tí a fi òróró pò ni wọ́n gbọdọ̀ fi yan án, ó sì lè jẹ́ burẹdi fẹ́lẹ́fẹ́lẹ́ tí kò ní ìwúkàrà ninu tí a da òróró lé lórí.
 oríṣi aràn  ascaris "" mìíràn a má a ran àwọn ẹlẹ ́ dẹ ̀ ."
“Nígbà tí mo sùn, mo rí igi kan láàrin ayé, lójú ìran, igi náà ga lọpọlọpọ.
A fún ọ láṣẹ lórí ọba àri àwọn ọmọ aládé, lórí olówó àti tálákà, lórí oníṣègùn àti lórí adáhunṣe.
O ni ọpọ igba ni Kabiyesi Adeyemi ti ba oun sọrọ ọgbọn laafin Oyo nigba nigba ti oun fi jẹ akọroyin fun ileeṣẹ iroyin Tribune.
O ni obinrin naa ko ṣafihan apẹẹrẹ aisan naa nigba ti wọn ṣe ayẹwo ara rẹ ni kete to gunlẹ si papakọ ofurufu Kilimanjaro.
Ni ti awọn oṣiṣẹ ìjọba ìpínlè àti olùkọ ilé ẹkọ gírámà, Oṣù kíni ọdún yi ni wọn gbà owó oṣù kẹyìn.
Oríṣun àwòrán, Sunday Igboho Ẹnikan ti isẹlẹ naa soju rẹ salaye pe ọpẹlọpẹ asaaju ọmọ Yoruba kan, Oloye Sunday Adeyẹmọ, ti gbogbo eeyan mọ si Sunday Igboho to tete de sadugbo ọhun lasiko ti laasigbo naa gbona janin-jani.
Ìsọníṣókí Aráàlú yabo ọ̀pọ̀ ibùdó tíjọba kó èròjà oúnjẹ́ Covid-19 sí Buhari paṣẹ fáwọn àgbófinró láti fòpin sí ìwọ́de UN, Clinton, Biden, Ooni, Obasanjo ati Soyinka korò ojú síwà ìpànìyàn Àwọn sọja yibọn pa ọpọ ọdọ to n se iwọde ni Lekki Èrò ọ̀nà gbẹ̀bí aláboyún ìbejì, tìyá, tọmọ jáde láyé Adájọ́ rán bàbá ọlọ́mọ méjì tó fi ipá bá ọmọ ọdún mẹ́rin lò pọ̀ lẹ́wọ̀n gbére Àjọ DSS tú gbogbo pátá mi wò pé wọ́n ń wa ọmọ- Bisola aya Woli Alfa Wo fídíò bí àwọn jàndùkú ṣe yabò àwọn olùwọ́de #ENDSARS ní Alausa l'Eko Ìjàmbá ọkọ̀ akérò àti tírélà pa èèyàn mẹ́rin lọ́nà mọ́rosẹ̀ Ore sí Benin Jíjábọ̀ ohun tí ń lọ lọ́wọ́ Nípasẹ̀ Yetunde Olugbenga àti Yemisi Oyedepo Gbogbo àkókò tí a kọ jẹ́ ti UK Tí a fiṣọwọ́ ní 10:4710:47 Ẹ ṣọ́ra, ọwọ́jà Corovirus ń peléke si ní Nàíjíríà, a ń wọ abala kejì àjàkálẹ̀ àrùn lọ - Ìjọba àpàpọ̀ Ijọba kede pe iye eeyan to ti ba arun Coronavirus lọ ti to ọrinlelaadọfa o le mẹrin dipo ọtalelaadọfa ati meje to wa lọsẹ meji sẹyin.
Ó gba ẹ̀gbẹ́ mi kọjá, n kò rí i,ó ń kọjá lọ, n kò sì mọ̀.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Adebanji Akintoye fí ẹ̀yin Bola Tinubu janlẹ̀ láti jẹ́ Aṣíwáju gbogbo ilẹ̀ Yorùbá 23 Ògún 2019 Àkọlé àwòrán, Adebanji Akintoye fí ẹ̀yin Bola Ahmed gbálẹ̀ láti jẹ́ Aṣíwáju gbogbo ilẹ̀ Yoruba Awọn aṣoju ẹgbẹ ọmọ Yoruba loriṣiiriṣii lo peju pesẹ sibi eto idibo ọhun.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Xenophobia: Abala kíní àwọn ọmọ Nàìjíríà yóò padà wálé láti South Africa lọ́jọ́rú 10 Owewe 2019 Oríṣun àwòrán, Twitter/deji_of_lagos Aṣoju orilẹ-ede Naijiria si South Africa, Godwin Adama, ti wi pe, abala kini ninu awọn ọmọ Naijiria ti ijọba nko bọ wale yoo gbera kuro ni South Africa lọjọru.
Won ri oku omo orile-ede America Michael Sharp ati omo orile-ede Sweden Zaida Catalan  ni ekun Kasai, leyin ose meji ti won ji won gbe, nigba ti won lo se iwadii ifiya-jeni kan.
 Ijoba mii yoo tubo pese aabo fun won ki ogun dopin nitori awon ewe wa.
“Kò sí Ilẹ̀ Ọba Mọ́” ni a óo máa pè é.
OLUWA ní, “Bí ojú tíí ti olè nígbà tí ọwọ́ bá tẹ̀ ẹ́,bẹ́ẹ̀ ni ojú yóo tì yín, ẹ̀yin ọmọ Israẹli.
Pẹlu pe ko si ẹri fun eyi, nṣe ni ahesọ yii di kale n kako lori ayelujara.
Oṣere Ilẹ Gẹẹsi naa ni o di ilumọọka nitori ipa to ko ninu fiimu James Bond to si kaakiri agbaye nitori ipa akọni to ko ninu ere naa.
Oríṣun àwòrán, LASEMA/ TWITTER Bi eeyan ba jẹ ori ahun, to ba ri iru ijamba to waye nibẹ, yoo kanu awọn eeyan.
Àjálù meji ló dé bá ọ,ta ni yóo tù ọ́ ninu:Ìsọdahoro ati ìparun, ìyàn ati ogun,ta ni yóo tù ọ́ ninu?
Awọn ọmọ ati Naijiria lapapọ lo n ṣe idaro Wolii Olapade Agoro bayii.
Mo ké pè ọ́, dájúdájú ìwọ Ọlọrun yóo dá mi lóhùn,dẹ etí rẹ sí mi, kí o sì gbọ́ ọ̀rọ̀ mi.
eléyìí jẹ́ ohun ẹdùn fún mi.
Ó sọ fún un pé, “Alàgbà, bí o bá ti gbé e lọ, sọ ibi tí o tẹ́ ẹ sí fún mi, kí n lè lọ gbé e.
Wọ́n pàdé rẹ̀ ninu oko Naboti ara Jesireeli.
Ó fi àkísà ati eérú bo ara rẹ̀.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ṣiṣi awọn adagun omi Shinroro, Kainji ati Jebba nitori arọọrọda ojo ti n mu ki iṣẹlẹ ẹkun omi o maa kan ilẹkun ni Naijiria Awọn ajọ mejeeji yii ni idi ti awọn fi ke ibosi sita lori rẹ naa ni lati fun awọn eeyan orilẹede yii, paapaa awọn olugbe ipinlẹ ti ọrọ kan atawọn alẹnulọrọ laaye lati gbaradi.
Gbogbo ìgbésẹ́ to yẹ ni a gbé kí ató gba ọ̀daràn to ni ààrun Coronavirus sí ọgbà wa- Agbẹnusọ ọgbà ẹ̀wọ̀n
Òun ni ó gbọdọ̀ súre sí ẹbọ náà, kí àwọn tí wọ́n bá pè tó bẹ̀rẹ̀ sí jẹun.
Ilẹ̀ tí ó kù lápá ọ̀tún ati apá òsì ilẹ̀ mímọ́ náà, ati ti ìlú yóo jẹ́ ti ọba.
Igbimo amuseya to n sakoso egbe APC to wa lori aleefa lowo-lowo bayii, yoo fenuko lojo Aje, osu kerin, odun ti a wayii ,lori alekun odun, lori ipo  ti igbimo apapo ati  ipinle yoo lo si i.
Nígbà náà ni, Samuẹli mú kí ẹ̀yà kọ̀ọ̀kan tò kọjá níwájú OLUWA, gègé sì mú ẹ̀yà Bẹnjamini.
Ṣebí òun ni baba yín, tí ó da yín,Tí ó da yín tán, tí ó sì fi ìdí yín múlẹ̀.
Wọ́n pa ọ̀dọ́ aguntan Ìrékọjá, àwọn alufaa wọ́n ẹ̀jẹ̀ tí wọ́n gbà lára àwọn ẹran náà sórí pẹpẹ, àwọn ọmọ Lefi sì bó awọ àwọn ẹran náà.
Ẹ dàbí àwọn ibojì tí a kùn ní funfun, tí ó dùn-ún wò lóde, ṣugbọn inú wọn kún fún egungun òkú ati oríṣìíríṣìí ohun ẹ̀gbin.
Àkòjọpọ́ àwọn nkan tó ṣẹ́lẹ̀ lágbo tíátà Yoruba lọ́sẹ̀ yìí
Ṣé títí lae ni o óo máa fi ara pamọ́ fún mi?
Gómìnà Amosun f'ohùn sílẹ̀ láti kúrò ní APC Ilé ìgbìmọ̀ aṣòfin Ekiti yọ abẹnugan rẹ̀ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ṣọla Allyson: Obìnrin tí kò bá rẹwà ni yóò máa ṣí ara sílẹ̀ Fayose salaye pe, awọn oloṣelu kan le fẹ dunkoko mọ oun, ti oun ba lọ sibi eto naa lọjọ Iṣẹgun to n bọ.
Gẹ́gẹ́ bí ẹ ti mọ̀, lẹ́yìn tí a ti jìyà, tí a ti rí ẹ̀gbin ní Filipi, ni a fi ìgboyà nípa Ọlọrun wá tí a sọ̀rọ̀ ìyìn rere Ọlọrun fun yín láàrin ọpọlọpọ àtakò.
Awọn wọn yi a si ma wa awọn ọmọ obinrin fun won nigba to ba wu wọn lati ṣe Ibalopọ pẹlu wọn.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Marina-Eko Bridge: Ìjọba gbóṣùbà fún àtìlẹyìn aráàlú lásìkò tí wọn ti afárá méjèèjì pa 21 Ìgbé 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 18 Ọ̀wàrà 2020 Oríṣun àwòrán, Federal government Ijọba apapọ Naijiria ti kede pe afara Marina ati Eko yoo di sisi pada lati ọjọ Aje ọla.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Bawo ni abẹrẹ ajẹsara Coronavirus yii yoo ṣe ṣiṣẹ ni agọ ara?
N óo rú àwọn ará Media sókè sí wọn,àwọn tí wọn kò bìkítà fún fadakabẹ́ẹ̀ ni wọn kò ka wúrà sí.
Àwọn òṣèré tíátà Yorùbá kọjú ìjà síra wọn lórí ìdárò akẹẹgbẹ́ wọn tó kú Àlàyé rèé lórí bo ṣe le è dá Emèrè mọ̀ tàbí dara pọ̀ mọ́ ẹgbẹ́ wọn Wo oríṣìí ìlù Yorùbá, ìwúlò wọn àti ba ṣe ń lò wọ́n Ìwé èsì àyẹ̀wò arùn Covid-19 lè di kòṣeémàní fáwọn tí o bá fẹ́ rìnrìn àjò sí ilẹ̀ òkèèrè Létà náà ni yii:August 17, 2020Mrs.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ẹgbẹ́ PDP tọrọ̀ àforíjì lọ́wọ́ Ọbasanjọ Ìdìbò Ekiti: àáyá bẹ́ sílẹ̀, ó bẹ́ áré Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ekiti Election: Kọmísánà fétò ìdìbò ní jàǹdùkú já àpótí gbà ní wọ́ọ́dù mẹ́fà Atẹjade naa wa n fi to awọn ara ilu leti pe, ajọ eleto idibo si n ka awọn esi ibo naa lọwọ, bẹẹ si ni akojọpọ esi ibo si n lọ lọwọ lawọn ibudo akojọpọ esi ibo kan.
Ṣáájú ààwẹ̀ Ramadan, àwọn ọlọ́pàá Sharia ń mú aṣéwó àti ọ̀daràn nípínlẹ̀ Kano Yàtọ̀ sí coronavirus, wo ìgbà mẹ́wàá míì táwọn mùsùlùmí kò lè ṣiṣẹ́ Hajj Ikọ̀ ẹlẹ́sìn Hàkíkà rèé, níbití wọn ti ń pààrọ̀ ìyàwó láàrín ara wọn Rabi-Al Akhir: Oṣu yi tumọ si ipari asiko tiirugbin maa n ṣu yọ.
wọ́n ń wí pé, “Ìbá sàn kí OLUWA pa wá sí ilẹ̀ Ijipti, níbi tí olukuluku wa ti jókòó ti ìsaasùn ọbẹ̀ ẹran, tí a sì ń jẹ oúnjẹ àjẹyó, ju bí ẹ ti kó wa wá sí ààrin aṣálẹ̀ yìí lọ, láti fi ebi pa gbogbo wa kú.
Awon asoju orile ede ti wa ni ijokoo bayiiawon agbofinro gbe oko soju popo to lo si Eagles Square niluu Abuja,o si di agogo meta osan ki won to si oju ona naa.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ondo: Ọ̀rẹ́kùnrin Khadijat Olubọyo gba ọjọ́ ikú!
O óo jẹ ẹ́ bí àkàrà ọkà baali dídùn; ìgbẹ́ eniyan ni o óo máa fi dá iná tí o óo máa fi dín in lójú wọn.
Ilé ẹjọ́ dá pásítọ̀ ìjọ Sotitobire padà sọ́gbà ẹ̀wọ̀n, ó sún ẹjọ́ síwájú Kò tíì sí àrùn Coronavirus ní ìpínlẹ̀ Oyo, a ṣi ń retí èsì àyẹ̀wò - Ijọba Oyo Báwo ni o ṣe le mọ̀ pé o ní àrùn Coronavirus?
20 Ẹrẹ̀nà 2020 Oríṣun àwòrán, Obesere Àkọlé àwòrán, Ṣé ẹ̀yin mọ idí ti Abass Akande fi n jẹ Obesere?
Ìdájọ́ tí ó wà lórí wọn láti ìgbà àtijọ́ kò parẹ́, bẹ́ẹ̀ ni ìparun tí ń bọ̀ wá bá wọn kò sùn.
Idi ni pe onimọ kan nipa agbekalẹ oju opo ayelujara, Oke Obi-Enadhuze ni wọn ti kede pe asita ibọn ti dẹmi rẹ legbodo.
 Àwọn míràn maa ń ṣe àìsàn lójijì tí ó sì maa ń mú èébì , ara òfééfèé , rírẹra , ìtọ ̀ dúdú àti inú rúrú lọ ́ wọ ́ .
Tí wọ́n bá sọ fún wá ni ọjọ́ àìkú tó kọjá wipe àó wá sòkú Ayodeji ènìyàn yóò jiya Ọdún kẹtalá rẹ̀ẹ́ tí Ituah àti Ibidunni ti wà bíi tọkọtaya kí ó to dédé dolóògbé ní ilú Port harcourt láàrọ̀ kùtù ọjọ́ àìkí Oríṣun àwòrán, others Àkọlé àwòrán, Ibidun Ituah Ighodalo fayé silẹ̀ ìlúmọ̀ọ́ká arẹwà tí fáyésilẹ̀ Wo àwọn òṣèré tíátà Yorùbá tó bí ìbejì Ẹ̀kọ́ mẹ́jọ tó yẹ kí ilẹ̀ Afirika kọ́ lára àjàkálẹ̀ aàrùn coronavirus Alhaja Kudirat Abiola: Odindi géńdé ọkunrin mẹ́fà ni wọ́n gbé iṣẹ́ ikú rẹ̀ fún Mo kábámò pé mo fipá bá Ìyá ẹni ọgọrin ọdún sún ní Kano- Muhammad Zulfara'u Oríṣun àwòrán, @prettypearl Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Uhuotu ṣàlàyé wí pé, títí di àsìkò tí a ń sọ̀rọ̀ yìí, kò sí eni tí ó mọ, ibi tí alága náà wọlé sí.
Inú alufaa náà bá dùn, ó gbé ẹ̀wù efodu, ó kó àwọn ère kékeré náà ati ère dídà náà, ó ń bá àwọn eniyan náà lọ.
O ni inu ibẹrubojo lawọn eeyan wa amọ awọn ọmọ Yoruba ko ṣe ''ojo lati doju kọ awọn to fẹ gba ilẹ mọ wọn lọwọ'' Bakanna lo sọ pe iran Yoruba yoo jẹwọ orukọ wọn gẹgẹ bi wọn ti ṣe ṣe saaju ọdun 1840 nigba ti awọn kan fẹ kogun ja wọn.
Ipade na bẹrẹ ni kete ti Aarẹ Buhari dari lati abẹwo rẹ si ipinlẹ Benue.
Iwájú lèrò mbá èrò Kò si ohun téni kan ṣe, téni kò ṣe ri
m shoemaker et al ni palomoni ( * m 33867 ) .
Àyà mi kọ́kọ́ máa ń já nígbà ti mo ṣẹ̀ṣẹ̀ bẹ̀rẹ̀ -Alaga iduro ọkùnrin
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù D'Banj: A dúpẹ́ fún ìfẹ́ yín 4 Agẹmo 2018 Oríṣun àwòrán, Instagram/iambangalee Àkọlé àwòrán, Oṣù tó kárùún ọdún ní Daniel pé ọmọ ọdún kàn Ìlúmọ̀ọ́ká olórin tàkasúfèé ọmọ Nàìjíríà, Ọladapọ Oyebanjọ tí gbogbo ènìyàn mọ̀ sí D'Banj ti pàpà fọhùn síta nípa ikú ọmọkùnrin rẹ̀.
“Nítorí náà mo pàtẹ́wọ́ le yín lórí nítorí èrè aiṣootọ tí ẹ̀ ń jẹ ati eniyan tí ẹ̀ ń pa ninu ìlú.
Ninu ọrọ to kọ si oju opo Instagram rẹ, Ronke sọ pe oun yoo ṣe suuru lori ọrọ naa, nitori pe otitọ yoo pada farahan.
2023 Presidency: Àwọn ọmọ Nàìjíríà ń dá awuyewuye sílẹ̀ lórí Tinubu ní Twitter
Ó bá sọ fún wọn pé, “Mo fẹ́ kí ẹ mọ̀ dájúdájú pé kò sí ẹni tí ó fi ilé, iyawo, arakunrin, òbí tabi ọmọ sílẹ̀, nítorí ti ìjọba Ọlọrun, 
Súgbọ́n ó kọ̀ sí mi lẹ́nu.
O tun tesiwaju pe iye awon omo orile ede Naijiria jẹ milionu méjídínnígba, ni eyi ti o po ju nile Afirika.
Awon eniyan jankan-jankan ti n de si papa isere naa
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 2020: Ọdun 2020 yii ko nìí nira fún àwọn tó bá bẹ̀rù Olorun Ero to ku pọ nítori pe àwọn to ni iṣú ti ọkọ naa ko tun jòkọ sori ẹru wọ́n loke mọtò naa.
O fidi ọrọ naa mulẹ niwaju Ile Igbimọ Aṣofin Ipinlẹ kano to n se iwadi nipa fidio ọhun.
Afojusun rẹ si ni lati da yatọ si awọn ijọ Cele yooku, nipa iwaasu ati isẹsi wọn.
Ṣugbọn bí mo bá sọ fún un pé, ‘Wo àwọn ọfà náà níwájú rẹ,’ máa bá tìrẹ lọ nítorí OLUWA ni ó fẹ́ kí o lọ.
Ó kí Basilai, ó fi ẹnu kò ó ní ẹnu, ó sì súre fún un; Basilai bá pada sí ilé rẹ̀.
Èyí rí bẹ́ẹ̀ kí ọ̀rọ̀ tí àwọn wolii sọ lè ṣẹ pé, “A óo pè é ní ará Nasarẹti.
Adajọ Mobolanle Okikiolu-Ighile da ẹjọ naa lẹyin ti ọmọọdo naa jẹwọ wi pe lootọ ni oun fi ọbẹ kun ọga oun ni Ọjọ Kọkanlelọgbọn, Osu Kẹwa, ọdun 2018.
ile-ise eleto aabo, adari ile –ise  ọmọ ogun,adari  ile-ise omo ogun
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ijọba Nàìjíríà pinnu láti dá àwọn èèyàn lókowò N10,000 14 Ògún 2018 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, iṣẹ́ lòògùn ìṣẹ́ Ọṣinbajo ni káàdì ìdìbò kọ́ ni wan a fi san ẹgbẹrun mẹwaa náà fáwọn ènìyàn.
’ Ẹ̀yin ọmọ Israẹli, ṣé ọ̀nà mi ni kò tọ́, àbí tiyín?
Oríṣun àwòrán, Empics Àkọlé àwòrán, O soro fun awọn ara ita lati gbe pelu awọn ẹlẹsin wọn yii Ohun to yẹ ko o mọ nipa awọn ẹlẹsin Aghoris ni India Ihuwasi wọn da bi ẹni wi pe wọn sẹṣẹ bẹrẹ ẹsin naa ni saa nkan bii ẹgbẹrun un ọdun mejidinlogun (18th century) sẹyin ni.
Ìkọlu Ifọ: Ọlọ́pàá pòórá lẹ́yìn tí àwọn jàndùkú yọ àdá sí wọn,
Yóo dára fún àwọn tí wọ́n bá ṣẹ́kù ní Juda.
 fagunwa pè ní apá kẹ ́ ta Ògbójú Ọdẹ nínú igbó irúnmọlẹ ̀ .
Ṣugbọn jíjá ni ó máa ń já ẹ̀wọ̀n, tí ó sì máa ń rún ṣẹ́kẹ́ṣẹkẹ̀ tí wọ́n fi dè é.
"Awọn ọmọ orilẹede Naijiria fẹ mọ iye dukia gan ti ajọ to n gbogun ti sise owo ilu basubasu lorilẹede Naijiria, EFCC ti gba pẹlu awọn eeyan to ra awọn dukia yii.
Couldn’t be more proud of you @isaacdrogba11 @eaguingamp Fiers de toi @isaacdrogba11 @eaguingampA post shared by  didierdrogba (@didierdrogba) on Feb 19, 2018 at 10:30am PSTDrogba fi idunu re leyin ti o ki omo re ku orire lori ero ayelujara Instagram,”o je ohun iwuri fun mi lati ri pe Isaac darapo mo Guingamp”.
Alaga igbimọ awọn gomina naa to jẹ gomina ipinlẹ Zamfara, Abdulaziz Yari fi eyi lede lasiko to n ba awọn oniroyin sọrọ, lẹyin ipade ti wọn se ni ilu Abuja.
Libya Returnees: Àtìpó 161 míì dari dé padà láti Libya layajọ́ ominira Naijiria
Ṣé o kò rí àwọn ohun tí wọn ń ṣe ninu àwọn ìlú Juda ati ní ìgboro Jerusalẹmu ni?
NAFDAC sọ pe lilo awọn oogun wọnyii fun itọju ounjẹ lewu gidi nitori o lee yọri si iku.
Terry Waya wa lati ipinlẹ Benue ati ẹya Tiv to wa ni aarin gbungun orilẹ-ede Naijiria.
Buhari: ọmọ ni Lai Mohammed lóri lẹ́tà Ọbásanjó
Tunde Bello ṣalaye siwaju pe o han gedegbe wi pe kii ṣe pe gomina Amobode ṣi fẹ gbe igba ibo nitori pe o gbe eto isuna naa siwaju awọn eniyan, wn si gba a wọle.
Nígbà tí oníṣẹ́ padà dé, ó wí fún wa pé ọba nì kí a wá sí aafin ní òwúrọ̀ ojọ́ kejì ní agogo mẹ́jọ̀-àbọ̀.
Mo fi OLUWA búra pé, n óo sáré tẹ̀lé e láti gba nǹkan lọ́wọ́ rẹ̀.
Ẹ yé fipá bá obìnrin lòpọ̀ mọ́, ìbálòpọ̀ kìí ṣe dandan
Gbajabiamila ni fun igba akọkọ ninu itan ile igbimọ asofin, ile igbimọ asofin n lo ẹrọ igbalode ti awọn eniyan le ma fi wo ijoko ile loju ẹsẹ.
Ohun ti wọn n beere ni orukọ wọn, adugbo, ẹkun idibo wọn, iriri nipa sise aabo ilu, ẹgbẹ ọlọdẹ ti wọn wa ati Baalẹ wọn.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ọpọlọpọ awọn agbalagba ti ko le rin daadaa lo ha sinu omiyale naa.
“A le fowo soya lori awon aseyori ti a ti se nipa awon ohun elo to wa nikawo wa’’.
Oríṣun àwòrán, @falzthebahdguy Àkọlé àwòrán, Orilẹ̀èdè Ghana ni àmì ẹ̀yẹ náà ti wáyé Ko tan sori awọn olorin nikan, gomina ipinlẹ Eko, Akinwunmi Ambode pẹlugba ami ẹyẹ fun ipa ti o n ko lori idagbasoke aṣa ati irinajo afẹ, paapaa julọ gẹgẹ bii olugbalejo eto ami ẹyẹ ọhun laarin ọdun 2014 si 2017.
Èèyàn 5 farapa, ọ̀pọ̀ ọkọ̀ jóná nínú ìjàmbá iná márosẹ̀ Ibadan sí Eko Ìjìyà ń bẹ fún àwọn ti adé ọ̀rọ̀ náà bá ṣí mọ́ lóri -Ọga àgbà FRSC Missing Child: Òbí àti asọ́nà ṣọ́ọ̀ṣì 14, lọ́ búra nì'dí imọlẹ̀ l'Akure Awọn ofin wọn yi ṣebi ni pọ diẹ ṣugbọn nitori asiko diẹ ninu wọn la fẹ gbe yẹ wo lonii.
“Mo wà ní orí òkè fún odidi ogoji ọjọ́ gẹ́gẹ́ bíi ti àkọ́kọ́, OLUWA sì tún gbọ́ ohùn mi, ó gbà láti má pa yín run.
Àkókò tí mo bá sì fi wà lọ́dọ̀ rẹ pẹ̀lú, n kò ní í gbé ẹbọ kọjá oríta, n kò ni í kọjá ògiri rẹ, nítorí n kò fẹ́ẹ́ déédéé lọ sí ọ̀run lọ́sàn-án gangan.
Ènìyàn 33,616 ló ti lùgbàdì ààrùn Coronavirus ní àpapọ̀ ní Nàíjíríà  Ikú Tolu jẹ́ ìbànújẹ́ ọkàn fún mi, o ní ọjọ́ iwáju tó dára nínú iṣẹ́ tó yàn láàyò, ó jẹ́ ọmọ tó ṣe ṣamu-ṣámú láti ìgbà tí a ti wà nílé ìwé alákọ̀ọ́bẹ̀rẹ̀."
ilé ìtura yìí ní yàrá bíi 825 sí ilé alájà mẹ ́ rin tí ó tóbi , wọ ́ n kùú ní funfun , òkun wa ní iwájú rẹ ̀ àti etí ọsà kùrámọ ̀ .
Láìpẹ́ n óo lọ sinu ibojì.
Ó sì yan àwọn ọmọ Lefi kan láti máa ṣe ètò ìsìn níwájú Àpótí Majẹmu OLUWA: láti máa gbadura, láti máa dúpẹ́, ati láti máa yin OLUWA Ọlọrun Israẹli.
Ọjọ́ pàtàkì ni ọjọ́ yìí jẹ́ fún ọ, ọjọ́ ayọ̀ sì ni o.
Nígbà tí gbogbo ìdílé Farao gbọ́ pé àwọn arakunrin Josẹfu dé, inú Farao ati àwọn iranṣẹ rẹ̀ dùn pupọ.
6 Nítorí nípa síṣe àwọn ohun wọ̀nyí àwọn ẹnu ọ̀na ọ̀run àpáàdì kì yíò lè borí yín; bẹ́ẹ̀ni, àti pé Olúwa Ọlọ́run yíò tú gbogbo agbára òkùnkùn ká ní iwájú yín, àti yíò mú kí ọ̀run ó mì tìtì fún ire yín, àti nítorí ogo orúkọ rẹ̀.
Ni ọjọ kọkandinlogun oṣu keji ọdun 2018, gẹgẹ bi awọn akẹgbẹ wọn kaakiri orilẹede Naijiria, awọn akẹkọ nileewe girama Government Girls'Science and Technical College, Dapchi pẹlu ji lọ si ileewe wọn pẹlu ireti ati gba imọ kun imọ wọn.
Nígbà tí òùngbẹ ń gbẹ mí, ẹ fún mi ní omi mu.
Ati pe o tun ra ọkọ ayọkẹlẹ fun iya ati arakunrin Ronke, to si tun ya a lowo.
Ṣugbọn awọn kan faramọ fidio orin naa, ti wọn si n kan saara si Olamide.
Obinrin náà sọ fún un pé, “Alàgbà, o kò ní ohun tí o lè fi fa omi, kànga yìí sì jìn, níbo ni ìwọ óo ti mú omi ìyè wá?
 Òhun ni ẹyọ ẹ ̀ mí tó kéréjùlọ tó jẹ ́ tòsọ ́ tọ ̀ bí i ohun alàyè , wọ ́ n sì tún ùnpé bíi òkúta ìkọ ́ ẹ ̀ mí .
Oríṣun àwòrán, Trey Songz/twitter Trey Songz Ogbontagi akọrin takasufe nilẹ Amẹrica, sọ pe lẹyin ọpọlọpọ iwadii ti oun ṣe, o ye oun daju pe oun to tọ ni igbe awọn eeyan Naijiria lasiko yii.
Gẹgẹ bi ofin to da ajọ naa silẹ ṣe sọ, EFCC ni oju'se lati dena tabi wadii iwa ibajẹ.
O ni ki awọn awọn to n bu ẹnu atẹ lu ijọba lori afikun owo itanran naa mọ pe ọrọ kobakungbe ti da rogbodiyan silẹ lawọn orilẹ-ede kan.
Tamari dá a lóhùn pé, “Rárá, arakunrin mi, lílé tí ò ń lé mi jáde yìí burú ju ipá tí o fi bá mi lòpọ̀ lọ.
Ẹ̀yin ará, nígbà tí a kúrò lọ́dọ̀ yín fún ìgbà díẹ̀, bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé a pínyà nípa ti ara, sibẹ ọkàn wa kò kúrò lọ́dọ̀ yín, ọkàn yín tún ń fà wá gan-an ni.
Wọ́n dá a lóhùn pé, “A wá láti dì ọ́ tọwọ́ tẹsẹ̀ kí á sì gbé ọ lọ fún àwọn ará Filistia ni.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Adult Bedwetting: Kí ló ń fa kí àgbàlagbà má a tọ̀ sí ilé?
Ṣugbọn ní òru ọjọ́ náà, OLUWA wí fún Natani pé, 
Saraki àgbà ló kọ́ ilé yìí fáwa arúgbó kìí ṣe Bùkọ́lá- Arúgbó Ilọrin Bàbá akẹ́kọ̀ọ́ LASU tí ọ̀rẹ́kùnrin rẹ̀ àti pásítọ̀ fi ṣ'oògùn owó ń bèèrè fún ìdájọ́ òdodo Iroyin ni Dauda fi ọ̀rọ̀ naa to EFCC leti pé ẹgbẹ̀run lọ́na ogun dọla ni Sani bèèrè fún láti fi sọwọ si Magu ki ọ̀rọ̀ náà ba le di igbàgbé Sùgbọ́n oluranlọ́wọ́ pàtàkì si Sani, Ahmed Suleiman bu ẹnu àtẹ lu mimu ti wọ́n mu ọmọ ilé ìgbìmọ aṣofin tẹ́lẹ́ rí naa pe wọn ko tii wadii ootọ bi o ti yẹ.
Aadọrin ọmọ ni Gideoni bí, nítorí pé ó ní ọpọlọpọ aya.
Mo fi Ọlọrun bẹ̀ ọ́, má ṣe dá mi lóró.
 Bakan naa , ni won tun maa  n fun  awon omo opo  merin naa  ni anfaani eko ofe.
Boasi bá sì sọ fún àwọn àgbààgbà ati gbogbo àwọn eniyan, ó ní, “Ẹ̀yin ni ẹlẹ́rìí lónìí pé mo ti ra gbogbo ohun tí ó jẹ́ ti Elimeleki ati ti Kilioni ati ti Maloni lọ́wọ́ Naomi.
Gẹ́gẹ́ bí àwọn ará èkó ti máa ń wí fún mi -“o ò damọ̀”.
si bi awon obayeje kan se n ba ọpa epo rọbi jẹ, ni agbegbe won.
irin je àdàlú ni pataki julo idẹ pelu akoonu adú larin 0.
Ṣugbọn kí ó fi wọ́n ṣe alákòóso Àgọ́ Ẹ̀rí ati àwọn ohun èlò tí ó wà ninu rẹ̀.
Ni gbogbo àwọn tí Iṣimaeli kó lẹ́rú ní Misipa bá yipada kúrò lẹ́yìn rẹ̀, wọ́n lọ bá Johanani ọmọ Karea.
Obinrin naa ni awọn afẹsunkan naa ni awọn yoo pa wọn ti wọn ko ba fun awọn lowo.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Iṣoro keji ti idibo Amẹrika maa ń ní ni ipẹjọ Nigba ti ko ba si alafo to lamilaaka laarin esi awọn oludije, o ṣeṣe ki ipẹjọ wa lori awọn ibo ti wọn ko ka, eyii to le fa ki esi ibo naa falẹ.
 Gẹgẹ bi ẹni to n gbẹnusọ fun ikọ musulumi, a
Fuoye: NANS késí ẹ̀ka ẹ́gbẹ́ l‘Osun, Ondo, Kogi láti máa bọ̀ ní Ekiti
Akọroyin BBC Yoruba kan si Mba lati gbọ oun to nii sọ nipa esi ayẹwo yii ati igbesẹ ti ileeṣẹ ọlọpaa fẹ gbe lori ọrọ naa.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Wo àwọn nǹkan mẹ́rin tó yẹ kó wà nínú báàgì rẹ lásìkò Covid-19 yìí Sani Abacha tún pèsè ìrànwọ fún Nàìjíríà láti ipò òkú Oríṣun àwòrán, Nigeria High Commision Àkọlé àwòrán, Owo Abacha Akoójọ pọ iye ìgbà tí Nàìjíríà rí owó tí olórí ìjọba ológun tó ti di olóògbé, Sani Abacha kó pamọ si òkè òkun gbà, tó fi mọ $311m tí ilẹ̀ Amẹ́ríkà ṣẹ̀ṣẹ̀ fi ransẹ lọ́jọ́ Ajé.
Wọ́n bá rán ikọ̀ ṣiwaju rẹ̀ láti lọ sọ pé àwọn kò fẹ́ kí ọkunrin yìí jọba lórí àwọn!
 Lootọ ni awọn kan sọ wipe, igbesẹ yii pẹ ko to waye, ta ba ni ka wo iye ẹmi to ti sọnu, ṣugbọn ireti wa ni wipe afojusun igbesẹ naa yoo wa si imuṣẹ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Security Summit: Ìlànà òfin ní ó yẹ kí Naijiria tọ̀ kìí ṣe ipàdé àbòsí- Odumakin 29 Agẹmo 2019 Oríṣun àwòrán, AFfenifere Àkọlé àwòrán, Security Summit: Ìlànà òfin ní ó yẹ kí Nigeria tọ̀ kìí ṣe ipàdé àbòsí- Odumakin Láìpẹ̀ yìí ní ọ̀gá ológun Nàìjíríà nígbà kan ri, Abdulsalami Abubakar pé fun àpérò lóri ètò àbò tí yóò wáye ní ìlú Minna tíí se olú ìlú ìpínlẹ̀ Niger.
Ṣé èyí ni ẹ̀ ń pè ní ààwẹ̀, ati ọjọ́ tí ó ṣe ìtẹ́wọ́gbà lọ́dọ̀ OLUWA?
Pupọ lara awọn ọmọ Naijiria ti wọn fi ero wọn han loju opo Facebook BBC News Yoruba ni wọn fi aidunnu wọn han lori bi nnkan ṣe n lọ laarin awọn mejeeji yii.
Àwọn eniyan Bẹnjamini náà ń gbé Geba lọ sókè, títí dé Mikimaṣi, Aija, Bẹtẹli, ati àwọn ìletò àyíká rẹ̀, 
A gbọ wi pe ọkunrin naa ṣẹṣẹ rinrin ajo de lati ilẹ Gẹẹsi ni ki o to tẹri gbaṣọ ni Naijiria.
Ọsìn ni orúkọ oyè Ọba ìlú náà.
 o je omo-egbe ile asofin , nibi to ti soju fun agbegbe ile asofin 12k new york fun igba emeje lati 1969 de 1983 .
dari awon omo  egbe oselu to pọju nile
O ni Maxim jẹ ọkan lara awọn ọdọmọde abẹṣẹku bi ojo ti Russia n wo fun ọjọ iwaju rere.
"Miliọnu mẹtadinlogun o din ẹgbẹrun lọna ọgọrun naira ni Saraki gbe kalẹ fun sisan awọn owo oṣu ti wọn jẹ awọn oṣiṣẹ.
Ileeṣẹ Bristow Helicopters ni ko dun mọ awọn ninu pẹlu bi wọn ṣe gba iṣẹ lọwọ awọn oṣiṣẹ wọn, amọ ipa ti arun Coronavirus ni lara ileeṣe wọn lo mu ki wọn gbe igbesẹ naa.
Coronavirus in Nigeria: Èèyàn mẹ́ta ní ìpínlẹ̀ Ọ̀ṣun, ẹyọkan l'Ógùn tún ti kó àrùn Coronavirus Oríṣun àwòrán, Getty Images Ajọ to n gbogun ti ajakalẹ arun lorilẹede Naijiria tun ti kede eeyan mẹrin miran pẹlu arun Coronavirus lorilẹede Naijiria.
Seyi Makinde: Inú mi dùn láti rí àwọn ìjòyè lẹ́yìn Olúbàdàn
Mo fi ìlẹ̀kùn kan tí ó ṣí sílẹ̀ siwaju rẹ, tí ẹnikẹ́ni kò lè tì.
Oríṣi ẹja mẹ́ta tí ó wà nínú odò náà ni oríṣí ènìyàn mẹ́ta tí ó wà ní ilú mi, àwọn kan jẹ́ onígbàgbọ́, àwọn kan jẹ́ onímàle, àwọn kan sì jẹ́ kèfèrí.
Ninu atẹjade tirẹ, Ọọni Adeyẹye Ogunwusi ti ile Ifẹ kilọ fun ijọba apapọ lati tete wa wọrọkọ fi ṣada lori gulegule awọn darandaran Fulani ti wọn n da omi alaafia ilẹ Yoruba ru lọwọ yii.
OLUWA sì ja àjàṣẹ́gun ńlá ní ọjọ́ náà.
Gbogbo wọn lo dahun awọn ibeere ti wọn fun wọn, lori igbe aye wọn, asiko ti wọn n jẹun, bi wọn ṣe n sun, ati awọn nkan mi i.
Ọrọ to n ja rainrain ree, eyi to jade lẹnu iyawo aarẹ Naijiria, Aisha Buhari.
Lẹ́yìn ọpọlọpọ ọdún, ọba Ijipti kú, àwọn ọmọ Israẹli sì ń kérora ní oko ẹrú tí wọ́n wà, wọ́n kígbe fún ìrànlọ́wọ́.
BEST 2019  naa se lo Agbaboolu Okunrin ti o
Akọwe agba ajọ WAEC, Ọmọwe iyi Uwadiae lo fun aarẹ Buhari ni iwe ẹri tuntun yii ni gbsngan ipade kekeree to wa ni ile arẹ nilu Abuja.
Ó fẹ́ràn láti máa ṣépè;nítorí náà kí èpè rẹ̀ dà lé e lórí;inú rẹ̀ kò dùn sí ìre,nítorí náà kí ìre jìnnà sí i.
Ṣé àwọn tí a ṣẹ̀ṣẹ̀ gbọyàn lẹ́nu wọn,àbí àwọn tí wọ́n ṣẹ̀ṣẹ̀ já lẹ́nu ọmú?
Ṣugbọn Ọlọrun tọ Abimeleki wá lóru lójú àlá, ó sì wí fún un pé, “O jẹ́ mọ̀!
Ondo Governorship Election: Ọ̀pọ̀ dúkìá àti mọ́tò bíí 15 làwọn jàǹdùkú bàjẹ́
Ẹ lọ́ jáwé gbé jẹ́ẹ́ sọ́wọ́ bí bẹ́ẹ̀ kọ́.
@benmichael4ever fi fidi sita ninu eyi to ti gboriyin fun Pasitọ Adeboye to si wọ eebu le awọn obinrin to n bu u lori pe wọn ko lọpọlọ.
 ""Mo reti pe ko bẹ mi, nitori pe mi o sọ ọrọ kọrọ si, ibeere naa jẹ dandan."
"Ni ọdun 1977, 1978 ati 1980 ko si ẹni to ṣeleri ohunkohun fun awọn elere idaraya o, ẹbun gbogbo ti wọn fun ikọ naa ni wọn ti gba.
Oloye Abiọla ni tiẹ jẹ olowo, olokiki, gbajumọ, oloju aanu ati onisowo to ni ileesẹ nla-nla, ti awọn eeyan mọ bii isana ẹlẹẹta, nitori oju aanu to maa n se yika awọn ẹkun idibo to wa ni Naijiria, ko tiẹ to di pe o pinnu lati gbe igba ibo aarẹ rara.
Ọ̀dọ́mọdé ẹni ọdún 38 ń figagbága pẹ̀lù bàbá ẹni ọdún 76 nínú ìbò Ààrẹ Uganda tó ń lọ lọ́wọ́ Ọlọ́pàá Oyo n wa afurasí tó ṣekú pa oníṣòwò àti ọmọ ọdún mẹ́sán án méjì ní Ibarapa Ẹ̀yin oríadé, tẹ bá fẹ́ mọ ìtàn Yorùbá, ẹ lọ kọ́ lọ́dọ̀ Alaafin - Oluwo Covid-19 pa Ọlọ́lá Akin Olugbade, ẹ wo dúkìá jaburata tó fisílẹ̀ Ọkan ninu awọn ọmọ Yahoo yii pe ikọ Amọtẹkun lati wa pẹtu si aawọ.
ipinle naa,Kassim Gaidam naa tun so pe awon ti ko irinse idibo lo si gbogbo
Wọn kò ṣe ohun tí ó wu Ọlọrun, wọ́n sì ń lòdì sí àwọn ohun tí ó lè ṣe eniyan ní anfaani.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù 2019 Election: Reuben Abati ni igbakeji gomina fún Kashamu 6 Owewe 2018 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 19 Bélú 2018 Oríṣun àwòrán, Wikipedia Àkọlé àwòrán, Ìròyìn ní Adeleke Shittu tò borí ní ìdìbò abẹ́lẹ́ fipò sílẹ̀ fún Sẹ̀nétọ̀ Kashamu to n soju ẹkún ìdìbò Ìlá-Oorun ìpínlẹ̀ Ogun.
 ní àsìkò ayẹyẹ pàtàkì , màálù ni wọ ́ n máa ń fi rúbọ .
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Alápinni: Ìjọba kò gbárùkù tì wá nínú iṣẹ́ tíátà Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Alápinni: Ìjọba kò gbárùkù tì wá nínú iṣẹ́ tíátà 17 Ọ̀pẹ̀̀ 2018 'Ilẹ̀kùn tó wọ eré tìátà ti pọ̀ jù lásìkò yìí' Gbajugbaja oṣere, Ganiu Nafiu ti gbogbo eeyan mọ si Alapinni Ooṣa sọrọ nipa idojukọ ti ẹgbẹ oṣere n koju lori ayederu ẹda fiimu ti wọn n pe ni 'Piracy'.
Oríṣun àwòrán, @Laurestar Àkọlé àwòrán, Aisha buhari ati Fatoumatta Bah-Barrow ṣe pọpọsinsin ọjọ ibi naa pẹlu abẹwo si ileewosan Maitama nilu Abuja Ni oju opo twitter tirẹ, iyawo aarẹ orilẹede Naijiria, Aisha Buhari ni idi ti Fatoumatta Bah-Barrow fi sami ayajọ ibi rẹ lorilẹede Naijiria ko se lori bi ọjọ ibi rẹ ṣe ṣe kongẹ abẹwo iyawo aarẹ Gambia naa si Naijiria lati bẹ awọn akẹkọ orilẹede naa marun kan wo nileewe girama aladani kan lorilẹede Naijiria.
 eré ìje to saájú eré ìje àsekágbá .
Oríṣun àwòrán, NAira Marley/Facebook Gbajugbaja olorin ọmọ Naijiria, Naira Marley ti bọ soju opo ayelujara lati kede pe oun yoo lewaju iwọde ifẹhonuhan lodi si iwa ti awọn ọlọpaa SARS n wu ni lorilẹede.
Nígbà náà ni Simoni Peteru tí ó ní idà kan fà á yọ, ó bá ṣá ẹrú Olórí Alufaa, ó gé e létí ọ̀tún.
O dí ààrẹ awọn akẹ́kọ̀ọ́ Fasiti Eko láàrin 1992 si 1995 tí ó sì dári ìwóde ìfẹ̀honúhàn nla kan lodi si ìjọba ologun lẹ́yìn to ti wọ́n wagile June 12, lọdun 1993 ìdìbo, ààrẹ bákan náà lo koju ija sí ijọba lori ìwà ajẹbanú He also get Master's Degree (Public Administration) from Colombia University.
Ó fi ọwọ́ lé kẹ̀kẹ́ òwú,ó sì ń ran òwú.
Wọ́n fi àwọn ìwé náà rán àwọn òjíṣẹ́ sí gbogbo agbègbè ọba pé kí wọ́n pa gbogbo àwọn Juu run, ati kékeré ati àgbà, ati obinrin ati ọmọde ní ọjọ́ kan náà, tíí ṣe ọjọ́ kẹtala oṣù kejila oṣù Adari, kí wọ́n sì kó gbogbo ohun ìní wọn.
fun awon omo egbe naa pe “Mo mọ isoro wa.
Dagrin: Ikú Dagrin pé ọdún mẹ́wàá, wo àwọn nkan mánigbàgbé nípa rẹ̀
Awọn iwe miran ti Oladejọ Okediji tun kọ ni Rẹrẹ Run, Agbalagba Akan, Atoto Arere ati bẹẹ bẹẹ lọ.
Kí ló dé tí ọba Israẹli fi ń lépa èmi kékeré yìí, bí ẹni ń dọdẹ àparò lórí òkè?
Ọ̀pọ̀lọpọ̀ Onigbàgbọ́  ayé òde oni ki i fẹ fi èdè Yorùbá kọrin ṣùgbọ́n ẹ gbọ́ bi ọmọ Òyinbó ti kọ orin àwọn “Obinrin Rere” ni ojú iwé yi.
O le ni ida ọgọrin ninu ilẹ to wa orilẹede Algeria to jẹ asalẹ Sahara.
Koda oniruuru oriki lo wa fun awọn ibeji nilẹ Yoruba, wọn a pe wọn ni Ejirẹ eyilaki, ẹdunjọbi agbe ori igi reterete, ọkan ni n ba bi, eyi lo wọle tọ mi, wini-wini loju orogun, eji wọwọ loju iya rẹ.
Ní alaalẹ́, wọn á pada wá,wọn á máa hu bí ajá, wọn a sì máa kiri ìlú.
Ọmọ Aarẹ Buhari pada de lẹyin itọju nilẹ okeere
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Iwo Kingmakers: Ìlú fẹ́milóye ni Ọba Abdulrasheed Akanbi- Ẹgbẹ̀ Baálẹ̀ Iwo Ìwa jẹgúdú jẹra àti àjẹbánu ló ń da àwọn afọbajẹ ti wọ́n fẹ́ yọ Olúwo ọba Abdulraheed Akanbi nípò.
Orilẹ̀-èdè mẹ́wàá lo ni ìdá ọgọ́rin nínú àyẹwò aàrùn náà- South Africa, Morocco, Ghana, Egypt, Ethopia, Uganda, Mauritius, Kenya, Nigeria, Rwanda.
Ogundiya: Àṣìṣe Dókítà ló sọ mi di aláàbọ̀ ara lórí kẹ̀kẹ́
Nígbà tí iranṣẹ náà gbé ọmọ náà dé ọ̀dọ̀ ìyá rẹ̀, ìyá rẹ̀ gbé e lé ẹsẹ̀ títí ọmọ náà fi kú ní ọ̀sán ọjọ́ náà.
Wọn yinbọn pa ọkùnrin kan lẹyin to fi ìbọn ilewọ dunkooko mọ Ọlọpaa, ti wọn si tun kọlu ẹ̀ṣọ́ kan niwaju ile asoju ijọba Faranse to wa nilu Jeddah, nilẹ Saudi Arabia.
Christiana Morenike Owowmoyela ati baba rẹ Owomoyela lo bii ti wọn si jẹ ọmọ Owo ati Ifon ni ipinlẹ Ondo.
Nígbà tí Hesekaya ọba gbọ́, ó fa aṣọ rẹ̀ ya, ó fi aṣọ ọ̀fọ̀ bora, ó sì wọ inú ilé OLUWA lọ.
Àkọlé àwòrán, Àwọn gómìnà ilẹ̀ Yorùbá parapọ̀ láti gbógun ti ààbò tó mẹ́hẹ!
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Àjọ àgbáyé (UN) lo kéde pé ó ṣe pàtàkì láti wá ojúùtú sí ọ̀rọ̀ àìtó o Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ijamba ọkọ-ofurufu ologun pa 'yan mẹjọ ’Ọ̀gá Ọlọ́pàá láṣẹ láti kọ ìpè àwọn aṣòfin’ Ẹ̀ni ọgọ́ta ọdún gbẹ̀mí ara rẹ̀ ní UCH Ibadan Àjọ àgbáyé to ń rí sì ọ̀rọ̀ ohun ogbin, àti Oúnjẹ sọ pé ojo ti ko ro daradara làwọn agbègbè Senegal, Mali, Niger, Burkina Faso àti orile-ede Chad lọ́dún tó kọjá lọ ṣokùnfà ohun tó ń dá igbayegbadun àwọn ènìyàn tó sì ṣokùnfà ìyàn lásìkò yìí.
Àwọn ọmọ Nàìjíríà yarí lórí àfikún ọjọ ìséde tí Ààrẹ Buhari kéde Bàbá ẹni ọdún 71 fi ẹ̀ṣẹ́ rán ìyàwó rẹ̀ lọ s'ọ́run àpàpàǹdodo ní Ìdànrè Sunday Igboho rán agbénipa sí mi láti gb'ẹ́mi mi-Auxilliary Ìrìnàjò Toyin Abraham, láti orí gbèsè jíjẹ, ó di onílé, onimọto àti aya lọ́ọ̀dẹ̀ ọkọ gomina Akeredolu ninu ọrọ to ba awọn eeyan ipinlẹ naa sọ lọsan ọjọ Iṣẹgun kminu lori iha kokanmi tawọn eeyan, paapaa awọn ọlọja, awọn onile ọti, awọn onile ijọsin atawọn eeyan kan n kọ si ilakaka gbogbo ti ijọba n sa lati dena itankalẹ arun naa.
Ǹ bá ro ẹjọ́ mi níwájú rẹ̀,gbogbo ẹnu ni ǹ bá fi ṣàròyé.
com/4rlN6zQNZ8Okan lara awon asofin naa  , Sabina Wanjiru Chege soro nipa isele naa, o
Bakan naa lo sọ pe oun ṣi n duro de iroyin lori boya awọn ọmọ Naijiria ṣi ku to ku sinu iṣẹlẹ naa.
Aina, idije fun ipo aare wa laarin awon erin meji to fẹ migbo , awon naa ni
“Nígbà tí Efuraimu rí àìsàn rẹ̀, tí Juda sì rí ọgbẹ́ rẹ̀, Efuraimu sá tọ Asiria lọ, ó sì ranṣẹ sí ọba ńlá ibẹ̀.
Ilé ẹjọ́ ní kí Gómìnà Ganduje ṣe mẹ̀dọ̀ lórí ọ̀rọ̀ Emir Kano 'Àwọn kọ́ńsítébù t'ílé iṣẹ́ ọlọ́pàá fẹ́ gbà kò ní gbébọn' o wi pe akẹẹkọ to le ni ẹgbẹrun lọna ọgbọn (34,120) ni awọn ti awọn ko ni fi esi idanwo wọn sita.
Bí ó bá jẹ́ pé láti ọdún jubili ni ó ti ya ilẹ̀ náà sọ́tọ̀ fún OLUWA, iyekíye tí ilẹ̀ náà bá tó lójú yín kò gbọdọ̀ dín.
Lori ọrọ Jo Bonfere ti ẹ n sọ yii, mi o fi bẹẹ mọ."
Sultan ni awọn gbe ẹsẹ le ipejọpọ awọn Musulumi lasiko ọdun yii kaakiri orilẹede Naijiria, lati le daabo bo awọn eniyan lọwọ arun Coronavirus.
Wúndía àti Ọba nìkan ló lè dé Orí Òkè Ọwá ní Ìjàrẹ Ondo- Àgbà Oloye Iro ni ile Amerika pa mo mi lori esun jibiti- Allen Onyema Uganda kó rọ́bà ìdáàbòbò mílíọ̀nù kan kúrò ní ìlú Ẹ wo ìdí tí ẹ gbọdọ̀ fi gba abẹ́rẹ́ àjẹsára fún ọmọ yín!
Bẹ́ẹ̀ ni Ọlọrun ṣe gbẹ̀san lára Abimeleki fún ẹ̀ṣẹ̀ tí ó ṣẹ baba rẹ̀, nítorí pé, ó pa aadọrin àwọn arakunrin rẹ̀.
Ìran tí Amosi, ọ̀kan ninu àwọn darandaran Tekoa, rí nípa Israẹli nìyí, nígbà ayé Usaya, ọba Juda, ati Jeroboamu, ọmọ Jehoaṣi, ọba Israẹli, ní ọdún meji ṣáájú ìṣẹ̀lẹ̀ tí ó ṣẹlẹ̀ tí ilẹ̀ fi mì jìgìjìgì.
Ile ẹjọ ni ko pada si ahamọ titi di ọjọ Ẹti, ọjọ kẹrin, oṣu kẹwaa fun akọtun ibeere Ile ẹjọ kan ti kọkọ da a silẹ, sugbọn ajọ ọtẹlẹmuyẹ orilẹ-ede yii kọ lati tu silẹ.
Yorùbá dùn lédè, ẹ máa sọọ́ Ẹfunroye Tinubu - Ògbóǹtagí oníṣòwò, olówò ẹrú àti afọbajẹ Samuel Ajayi Crowther, òjíṣẹ́ Ọlọ́run tó gbé èdè Yoruba lárugẹ Àrà méèrírí, ọkùnrin kan ń fi ìyarun fọn fèrè tó ń dún bíi gìtá Àwọn òṣèré Yollywood tó ń pàrònú rẹ́ Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí kan sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù #FIFAWWC : Chile fi àmì àyo méjì gbógo fún Naijiria 20 Òkùdu 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 21 Òkùdu 2019 Oríṣun àwòrán, @Daniela Àkọlé àwòrán, Super Falcons gòkè odò bọ́ sípele ìkẹrìndínlógún ní France Cameroun ati Naijiria ti yege fun ipele to kan ni FIFAWWC.
Ikọ ọlọpaa ni wọn gbe ọmọbinrin naa digba-digba lọ si ile iwosan Fasiti Ibadan, amọ arabinrin naa papoda ni owurọ ọjọ keji ni ileewosan.
 béè náà nit í a bá bèèrè ìbéèrè nípa òrò-orúko tí ó ń yán òrò-orúko mìíràn .
Merkel ti se abẹwo si awọn adari orilẹede Senegal ati ilẹ Ghana ni ọsẹ yii lati jiroro lori ibugboro ọrọ aje laaarin ilẹ Germany ati Iwọ-Oorun Afirika.
Láti inú àwọn orílẹ̀-èdè mìíràn ni a ti ṣa àwọn eniyan rẹ̀ jọ; nisinsinyii, gbogbo wọn wà láìléwu.
naa Festus Okoye gbe jade pe , ” Ajo naa ti tepele mo igbese won pe
Ẹ máa gbé ilẹ̀ yìí, kí ẹ máa sin ọba Babiloni, yóo sì dára fun yín.
Ninu atẹjade kan ti agbẹjọro agba, Abubakar Balarabe Mahmoud, fi sita l'orukọ igbimọ agbẹjọro fun Emir Sanusi, ni wọn ti sọ pe awọn n ṣiṣẹ niluu Kano ati Abuja lọwọlọwọ lati pe ẹjọ, ayaafi ti wọn ba tu Emir naa silẹ ni ihamọ ni kiakia ni ko ni i jẹ ki awọn o gbe igbesẹ nilan ofin.
Farao bá tún tají, ó sì tún rí i pé àlá ni òun ń lá.
"Wo àwọn oúnjẹ tí àṣẹ Buhari leè mú kó gbówó lórí Àjẹ́ àti Aṣẹ́wó ní ìyá Rainbow - Òjòpagogo ""Ẹ̀yin obìnrin, ẹ lọ kọ́ iṣẹ́ káfíńtà torí ó lówó lórí ju iṣẹ́ aránṣọ lọ"" Àwọn ọmọbíbí ìpínlẹ̀ Ọyọ nìkan ni yóò rí iṣẹ́ àgbàṣe gbà lábẹ́ ìjọba mi - Seyi Makinde Lara awọn wọ ki ilu mọ ni ilẹ Yoruba to wa nibi ayẹyẹ ọdun Ọsun Osogbo ti ọdun yii ni, Aare Ọna Kakanfo ti ilẹ Yoruba, Aare Gani Adams, Oloye Nikẹ Davies Okundaye, ti gbogbo eeyan mọ̀ si Nikky Afrikana ati awọn lọba lọba nilẹ Yoruba."
Ṣugbọn ṣa, orilẹ-ede kọọkan lo ni aṣẹ lati sọ ẹni to jẹ ọmọ orilẹ-ede rẹ.
wo àwọn nọ́mba ọlọ́pàá tí o lé pé láti mọ ọ̀nà àbáyọ Níbo lọ̀rọ̀ dé dúró nípa iṣẹ́ àwọn tó n wa iṣẹ́ N-Power?
Eleyii mu ki ọpọlọpọ awọn to wa lati idile eru yii tete darapọ mọ ẹsin Kristẹni, nitori o waasu ominira fun wọn lasiko ti awọn ara wọn yoku ko Gbagbọ ninu rẹ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Facebook: Atunto tuntun se idinku awọn alamulo 1 Èrèlè 2018 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Adari Facebook, Mark Zuckerberg sọ pe dun 2017 gbona pupọ fun ile ise naa Facebook ti sọ wi pe awọn to n samulo itakun ayelujara naa ti lọ silẹ ju tatẹyin wa lọ, lẹyin ti wọn se atunto miran ti yoo maa faaye silẹ fun awọn eniyan lati ri ohun ti awọn ibatan ati ọrẹ wọn ba fi sori itakun naa ju ipolongo lọ.
    Ìyàwó mi ti fi hàn mi pée iwin ni òun.
Ọ̀nà àbáyọ dé fún àìsàn ibà Kò dín ní $500 mílíọ́nù tí ìjọba ti ná lórí nǹkan ogun -Iléeṣẹ́ ààrẹ Nàìjíríà Ọmọ Naijiria di asofin agba ni Italy Oladejo Okediji àti ìgbé ayé ìtàn kíkọ rẹ̀ Si idahun pé boya Oloyede a gba iṣẹ minista ti a ba fun un ninu iṣejọba aarẹ Buhari yii, O ni ọmọ ọdun marundinlaadọrin ti kuro lọmọde, isinmi lo ku ti ara n fẹ ati pe, ifọwọsowọpọ lo yẹ ki a ṣe fun minista to n tukọ eto ẹkọ Naijiria lọwọ nitori o n ṣiṣẹ daadaa.
“Bẹ́ẹ̀ ni yóo rí fún arọmọdọmọ mi níwájú Ọlọrun,nítorí pé, ó ti bá mi dá majẹmu ayérayé nípa ohun gbogbo,majẹmu tí kò lè yipada, ati ìlérí tí kò ní yẹ̀.
Nítori àjàkálẹ̀ ààrùn Coronavirus, ti ètò kónílé o gbélé sì wà, ọ̀pọ̀ àwọn olókoòwò ló n ló àwọn ilé iṣẹ́ ìfẹ̀rujíṣẹ́ láti tẹ̀síwájú nínú ọ̀rọ̀ ajé wọn.
Agbẹjọro Bulama ni ewu nla wa ninu ki wọn gba awọn puruntu ọdọ ti ko lẹkọ tori yoo kan jẹ asiko fun wn lati tun da orilẹede sinu hila-hilo ni.
Trump-Mo ni ọwọ nla fun ilẹ Afrika
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Awọn ogbontarigii olorin ile Afrika ṣe ẹyẹ ikẹyin fun Arafat Kíni ẹ mọ̀ nípa àwọn gbajúgbaja Yollywood?
Mo bẹ yin, ẹ da si ọrọ to wa nilẹ yii.
bayii, ti won si ti bẹrẹ  isẹ ni pẹrẹu.
Nítorí pé ọpọlọpọ àwọn ará Juda ni wọ́n ti bá a dá majẹmu, nítorí àna Ṣekanaya ọmọ Ara ni: ọmọ rẹ̀ ọkunrin, Jehohanani, ló fẹ́ ọmọbinrin Meṣulamu, ọmọ Berekaya.
”Amosa, o ni ajo INEC yoo
Lori itakun agbaye naa ni wa ti ri awọn idahun miran to kan ọrọ ọkùnrin ati obinrin.
Ẹ̀wẹ̀, adarí ẹgbẹ́ APC níjọba ìbílẹ̀ náà lásiko to n ba awọn akoròyìn sọ̀rọ̀ ni ìlú Akure sọ pé Ayiloge ko tilẹ̀ ni káàdì ti a fi le pèé ni ọmọ égbẹ́ bo tilẹ̀ jẹ́ pe o ni ọmọ ẹgbẹ́ ni òun.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Aadota odun ree ti e ti n paro atunse ise yin fawon omo Naijiria lero awon kan O ni ileeṣẹ awọn yoo kọkọ yọ iye owo gbese ti irufẹ ẹni bẹẹ jẹ tẹlẹ, ki wọn to fi iye owo to ku fun ni ina.
"O si ṣe e ṣe ki awọn aṣofin ma ṣe nkankan fun Buhari ti ko ba yọju si wọn, nitori pe ọmọ ẹgbẹ oṣelu rẹ, APC, lo pọju nibẹ.
Nítorí pé mò ń wo gbogbo ohun tí wọn ń ṣe, kò sí èyí tí n kò rí, bẹ́ẹ̀ ni ẹ̀ṣẹ̀ wọn kò sápamọ́ fún mi.
Solomoni yan àwọn mejila gẹ́gẹ́ bí alákòóso ní ilẹ̀ Israẹli.
Mo si fẹ maa rin, maa yan kiri lati bẹru pe ẹnikẹni n sọ mi kiri.
Aṣẹ́wó rán awakọ̀ ajàfẹ́tọ̀ọ́ l'ẹ̀wọ̀n Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, '500 level'' ni mo wà nígbà tí mo di adélé Ọba' O ni ''Ko dara ka fi aaye gba awọn ọmọbinrin wa lati maa ṣe nkan ti ko tọ tabi ta ara awọn nile ijo.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù South Africa: Èrò àwọn èèyàn ṣọ̀tọ̀ọ̀tọ̀ lórí fidio ti Aisha Buhari fi síta 25 Èbibi 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 26 Èbibi 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Aisha Buhari si aarẹ South Africa Ọrọ̀ n bọ́rọ̀ bọ.
A ti fara da ọpọlọpọ nǹkan ní àkókò inúnibíni, ninu ìdààmú, ati ninu ìṣòro; 
Àwọn ọmọ Israẹli ranṣẹ pè é, òun ati gbogbo wọ́n sì tọ Rehoboamu lọ, wọ́n wí fún un pé, 
Dúró – Òun ni àkọ́bí nínú àwọn ọmọ Orímóògùnjẹ́.
Tierney sọ lẹyin ifẹsẹwọnsẹ naa pe igbiyanju awọn agbabọọlu Arsenal lori papa kudiẹ kaato.
Ni ọjọ kọkanla ọdun 1997 ni Holyfield ati Moorer wa ja papda.
Akọroyin ileesẹ BBC, Ishaq Khalid jabọ latilu Abuja pe awọn ọmọ ikọ Boko Haram naa ti lanfaani lati maa rin, maa yan laarin ilu.
 koda, iwa ibajẹ yii ni awon opo eniyna n lo lati so ara won di olowo ati oloro .
Ojelarinaka jẹ agba eegun to maa n sere to tun n pidan lagbo lati ileto kan si ikeji.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Muslim Marriage: Lẹ́yin ìsopọ̀ ogún ọdún, ìyàwò fẹ́ ṣèyàwó lábẹ́ òfin 15 Èrèlè 2020 Oríṣun àwòrán, Getty Images Ileejọ kan ti fagile igbeyawo nilana ẹsin Musulumi lẹyin to da idajọ ileẹjọ kan nu, eyi to fontẹ lu pe, igbeyawo nilana ẹsin Islam ba ofin mu ni ilu Ọba, United Kingdom.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Coronavirus: Bàyíì ní àwọn ọmọbìnrin Afghanistan ṣe fi èròjà ara ọkọ ṣe fẹntilátọ 23 Èbibi 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 26 Èbibi 2020 Oríṣun àwòrán, Reuters Awọn ọmọbinrin ikọ to n se robọti ni Afghanistan ti doju isẹ wọn kọ́ awọn to ni Coronavirus Ọhun to ku ti wọn n se bayi ni pe wọn n fi eroja ọkọ se fẹnitilatọ, to jẹ ẹrọ to n mu eemi ja geere sii olowopọọku.
0 35 Orilẹede Timor-Laste 0 0.
O fikun ọrọ rẹ pe awọn ọmọ Naijiria lo maa fori ko ju, ti awọn ileeṣẹ orilẹede South Africa ba di titi pa.
Alaafin: Yóò dára kí Fayemi máṣe fọwọ́ yẹpẹrẹ àwọn oríadé nílẹ̀ Yorùbá
Ó bá pàṣẹ pé, “Ẹ fi aṣọ mímọ́ wé e lórí.
Ṣáájú, ilé ẹjọ gíga tíó kalẹ̀ sí Lokoja ti kọ́kọ́ sún ìdájọ́ lórí gbígba onídùró fún Dino èyí tí agbẹjọ́rò rẹ Amofin àgbà Mike Ozekhome gbé wà.
” Gbogbo wọn sì ṣe bí ó ti wí; òun pàápàá sì sán idà tirẹ̀ náà mọ́ ìdí.
àwọn tí wọ́n ti pada lẹ́yìn OLUWA, tí wọn kò wá a, tí wọn kì í sì í wádìí ọ̀rọ̀ lọ́dọ̀ rẹ̀.
Ọ̀pọ̀ ìgbà ni n kò lè sùn.
Ó bá bi wọ́n pé, “Ẹ̀yin ṣe lójo bẹ́ẹ̀?
Building Collapse: Àwọn èèyàn mẹ́rìndínlọ́gbọ̀n ló n ṣiṣẹ́ níbẹ kí ilé náà tó wó
Yatọ si pe oke Olumọ jẹ ibudo asa ajogunba ati irinajo afẹ nipinlẹ Ogun, ohun pataki to tun maa n waye lori oke yii ni ọpọ orisati wọn n bọ nibẹ.
Lẹ́yìn òkò ọ̀rọ̀, Buhari àti Ọbasanjọ fẹ̀rín pàdé ara wọn l‘Abuja Agbẹjọro fun Elzakzaky, Femi Falana sọ fun ile ẹjọ pe lati ọjọ kẹrinla, oṣu kejila, ọdun 2015 ti wọn ti wa latimọle ni wọn ko ti ni itọju to peye.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Year end: Gbogbo ènìyàn ló wọ agbádá ikú, ẹni tó kàn lẹnìkan kò mọ̀ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Year end: Gbogbo ènìyàn ló wọ agbádá ikú, ẹni tó kàn lẹnìkan kò mọ̀ 16 Ọ̀pẹ̀̀ 2018 Ọpọlọpọ àwọn to lorukọ ati awọn mii ti ayé kò mọ̀ nipa wọn rara ni wọn ti doloogbe ni 2018.
Gbogbo àwọn eniyan tí kò bá ní èdìdì Ọlọrun ní iwájú wọn nìkan ni kí wọ́n ṣe léṣe.
Gẹgẹ bii iroyin kan lori ikanni twitter oluranlọwọ aarẹ lori ọrọ iroyin ayelujara, Lauretta Onoche, Aisha buhari ati Fatoumatta Bah-Barrow ṣe pọpọsinsin ọjọ ibi naa pẹlu abẹwo si ileewosan Maitama nilu Abuja.
Lọjọru ni ile ẹjọ giga kan nilu ilorin fi idajọ sita eleyi to tunmọ si wi pe oludije ti idibo abẹnu Ishola Balogun sakoso rẹ ni o tọ lati du ipo Gomina labẹ asia ẹgbẹ APC.
Gẹgẹ bi ẹbi se sọ, Odiogor kulẹyin ọpọlọpọ ọjọ to ti n ṣaisan eyi to si ti mu rinrin ajo lọ si orilede India.
Àwa pàápàá gba Kristi Jesu gbọ́, kí Ọlọrun lè dá wa láre nípa igbagbọ ninu rẹ̀, kì í ṣe nípa iṣẹ́ òfin.
Wọ́n rí Adewura nínú adágún omí ńlá kan lẹ́yìn ti òkìkí tàn kálẹ̀ pé wọ́n ń wá.
Lati owurọ Ọjọbọ ti ti fidio igbeyawo rẹ ti jade si ori ayelujara, ni awọn ololufẹ rẹ ati awọn akẹẹgbẹ rẹ kan ti n sọ boṣe ya wọn lẹnu pe o ṣe igbeyawo bi ikọkọ.
Aare ni ipa pataki ti Ojogbon akinwunmi Isola ko ninu idagbasoke ede Yoruba ninu iwe kiko, ere onise ati awon iwe akada lorisiirisii fun lilo lojo iwaju kuro ni keremi.
Àwọn ọmọ Israẹli bẹ̀rẹ̀ sí pa wọ́n láì dáwọ́ dúró bí wọn ti ń lé wọn lọ.
Eyi si ti mu ki awọn onimọ nipa ohun to n lọ ni Naijiria, sọ pe eyi le ṣe akoba fun eto idibo gbogboogbo naa.
O ni ewu to wa ninu awọn igbẹbi bẹẹ kun ara wahala iṣoro igbẹbi ti awọn iwadii wọnyii gbe kalẹ.
Ọrọ rẹ yi n waye lasiko ti ipenija aabo ti ṣe n koju awọn ipinlẹ kọọkan lariwa Naijiria bi Zamfara ati Kaduna.
Ikọ ẹgbẹ ti eeyan yoo ma wu lasikoyi ko ni mu kẹlẹbẹ wa.
Àwọn ìtàn mánigbàgbé tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ọba Adesoji Aderemi, Ọọ̀ni Ifẹ̀ tó gba ipò ọba mọ́ tòṣèlú MKO Abiola, iṣẹ́ aṣẹ́gità ló fi bẹ̀rẹ̀ okoòwò Iṣọla Oyenusi rèé, ẹnití ìfẹ́ obìnrin ṣun dé ìwà ìdigunjalè Taiwo Akinkunmi, ọmọ Ibadan tó ya àsìá Naijiria Ayinla Ọmọwura, orin èébú àti oríyìn lo fi di ọ̀rẹ́ àwọ̀n obìnrin Ìtàn tó rọ̀ mọ́ òwe ‘aṣọ kò bá Ọ́mọ́yẹ mọ́.
Lónìí ni wọ́n rú ẹbọ ìmúkúrò ẹ̀ṣẹ̀ ati ẹbọ sísun wọn sí OLUWA, sibẹsibẹ irú nǹkan yìí ṣẹlẹ̀ sí mi.
Ọjọ́ kẹta nìyí tí oluwa mi ti fi mí sílẹ̀ níhìn-ín, nítorí pé ara mi kò dá.
Bi tọkọ taya ti gba ogiri ilé wọn laaye lati lanu silẹ naa ni alangba ti n wọ inu ilé naa.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Kid boxer: Ọmọọba 'The Buzz' Larbie rèé, ọmọ ọdún méje tó ń fi ẹ̀ṣẹ́ dá bírà Ileesẹ ọlọpa Eko ni ni kete ti wọn fi isẹlẹ naa to oun leti, ni oun ran awọn ọlọpa oluwadii lọ sibẹ, ti wọn si ba obinrin naa ninu ẹjẹ ara rẹ pẹlu ọgbẹ to jin lori rẹ, nigba ti ọkunrin naa n pọ nnkan funfun lẹnu, eyi to seese ko jẹ oogun apakokoro Sniper.
Bakanaa losu kọkanla ọdun 2016, awọn onisegun oyinbo fi isẹ abẹ ya awọn ibeji kan ti wọn lẹpọ amọ ti wọn jẹ ọmọ ilẹ Naijiria nile iwosan Tennessee lorilẹede Amẹrika nigba to ku ọjọ diẹ ki wọn se ọjọ ibi ọdun kan.
Oríṣun àwòrán, @Akeredolu Àkọlé àwòrán, Akeredolu ati igbakeji rẹ Akeredolu lo gba ju bẹrẹ lati ijọba ibilẹ Akoko North West, Akoko North East, Akoko South East ati Akoko South West.
Wàhálà máa ń fa ọ̀tẹ̀, ọ̀tẹ̀ ń di ogun, ogun sì ń fa ikú àti fífi dúkàá sòfò.
Yóo lò ó bí abẹ ìfárí, yóo fi fá irun orí ati irun ẹsẹ̀ dànù, ati gbogbo irùngbọ̀n pàápàá.
Ni idakeji ẹwẹ, awọn alatilẹyin tirẹ ni o jare tori ile aṣofin lo kọkọ yan an sipo lọdun 2005 kii ṣe awọn oludibo gẹgẹ bi ile ẹjọ Burundi ṣe sọ ọ.
Awọn mẹta ti wọn yọ ninu ewu naa sọ pe ọpọlọpọ awọn ti o ri s'omi jẹ ọmọbibi orilẹ-ede Pakistan.
Lati oṣu Keje, ọdun 2018, ni ìjà ti n waye laarin IS ati ẹka al-Qaeda ni Yemen.
“I am obviously worried about the things we have to improve.
Coronavirus cure: Olùdásílẹ̀ Yemkem ní ''Olóde'' ni Yorùbá ń pe coronavirus, iléeṣẹ́ Yemkem ti rí òògùn rẹ̀ báyìí
”Gbogbo àwọn ọmọ-ẹ̀yìn bá fi í sílẹ̀, wọ́n sálọ.
Wọn fi kun pe, awọn ko ni dẹkun lati maa se iwọde naa fun itusilẹ Soworẹ, ti ẹru ọta ibọn awọn ọlọpaa ati sọja naa ko si ba awọn, o si di igba ti wọn ba tu Soworẹ silẹ, ki awọn to sinmi iwọde.
Biu tun tesiwaju  pe, bi epo-robi ba wa ni arowo to  kaakiri ilu, o di dandan, owon-gogo epo-robi yoo di afiseyin seegun n fiso.
Lagos-219 FCT-168 Kaduna-52 Kwara-19 Kano-15 Rivers-15 Sokoto-10 Enugu-9 Gombe-8 Plateau-7 Osun-7 Anambra-5 Oyo-5 Jigawa-4 Ogun-4 Bauchi-2 Edo-1 Akojọpọ awọn to ti ni aarun naa ni 70,195.
OLUWA yóo ṣe sí ọ jù bí ó ti sọ fún ọ lọ, bí o bá fi nǹkankan pamọ́ fún mi ninu ohun tí ó sọ fún ọ.
Ilẹẹṣẹ DSS gbe e lẹyin ti iroyin naa kaakiri ayelujara ti wọn si fi ọrọ wa a lẹnu wo.
nígbà tí a rìn sí iwájú díẹ̀, a bẹ̀rẹ̀ sii wo ìlú náà ní ọ̀kánkán ṣùgbọ́n ọ̀nà tí à ń tọ̀ lọ túbọ̀ ń di kékeré sii àfi bí ẹni pé ènìyàn kò ń gbá ìlú náà ni, nígbà tí ó sa pẹ́ sá, a yọ sí ìlú yìí.
Ọ̀pọ̀lọpọ̀ àwọn ọmọbìnrin a máa kọ etí dídi sí àwọn ìbátan wọn ńigbà tí ìfẹ́ bá ru bò wọ́n lójú bí omi gbígbóná ti ń ru bo èlùbọ́.
 Ero wa ni lati ri Super Eagles ki o kopa daradara koja erongba wa.
Mose sọ gbogbo iṣẹ́ tí OLUWA rán an fún un, ati gbogbo iṣẹ́ ìyanu tí OLUWA pa láṣẹ pé kí ó ṣe.
Àwọn ẹnìkan gbé ọkunrin arọ kan wá tí ó dùbúlẹ̀ sórí ibùsùn rẹ̀.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ìtàn Olaniyi Balogun, ọ̀jọ̀gbọ́n tó fi Nàìjíríà sílẹ̀ lọ gba iṣẹ̀ àgbẹ̀ l'Ámẹ́ríkà Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Òun ni ó sọ fún wa nípa ìfẹ́ yín ninu nǹkan ti ẹ̀mí.
Kò ní sí ẹnikẹ́ni ninu Àgọ́ Àjọ nígbà tí ó bá wọlé lọ láti ṣe ètùtù ninu ibi mímọ́ náà, títí tí yóo fi jáde, lẹ́yìn tí ó bá ti ṣe ètùtù fún ara rẹ̀, ati ilé rẹ̀, ati fún gbogbo ìjọ eniyan Israẹli.
O ni ''nigba ti mo de ile,mo wo owo naa niwo pe lootọ ni pe emi ni mo ni.
 Oríṣun àwòrán, Instagran/kingwasiuayindemarshal Murphy ni oun lọ siwaju Kwam 1 lati nawo fun ni, ki o le ki ẹnikan ti oun n ba se onigbọwọ, ki oun si fi ọrọ ẹni naa to leti pe onitọun fẹ wa na lowo fun loju agbo."
Dafidi pín àwọn ọmọ Lefi ní ìdílé ìdílé: ti Geriṣomu, ti Kohati, ati ti Merari.
Ìwé náà gùn ní ìwọ̀n ogún igbọnwọ, (mita 9); ìbú rẹ̀ sì jẹ́ igbọnwọ mẹ́wàá (mita 4½).
Sùgbọn, àwọn ọmọ Nàìjíríà tí ń bẹ̀rẹ̀ pé ta ni yóò jẹ àǹfàní ẹgbẹ̀rùn mẹwaa nàìríà tó jẹ́ owó ìtanràn fún ilé ìfowópamọ tó bá kùna lati sanwo tó han láàrin wákàtí mẹ́rìnlélógún.
Ní báyìí, Aare Muhammadu Buhari só ọ di minisita fún ọrọ abele lorile-èdè Nàìjíríà.
Ile igbimo asoju-sofin so pe, alekun ti o ba owo isuna odun 2018, eleyi ti o le ni ẹ̀ẹ́dẹ́gbẹ̀ta bilionu owo Naira (508 billion Naira), waye lataari awon olokan-o-jokan ise akanse eyi ti ijoba apapo yoo maa gbese lati fi mu igberu de ba eto oro aje orile-ede yii fun anfaani awon ara-ilu.
Ipinlẹ Eko lo ni eniyan to poju pẹlu eniyan 163 ni Ojo Iṣẹgun nikan soso.
bí mo bá ti rí ẹni tí ó ń kú lọ,nítorí àìrí aṣọ bora,tabi talaka tí kò rí ẹ̀wù wọ̀,
Angelique kidjo pe fun anfani f'awọn obinrin Kíni ìdí ti wọn fi ń lọ ọmú obinrin nílẹ Adúláwọ?
Eto iranwo owo yii ti wọn pe ni MSME Survival Fund initiative jẹ akanṣe eto ti ijọba Naijiria gbe kalẹ fun awọn olokoowo kekeke to padanu ohun kan tabi omiran torii ajakalẹ arun Coronavirus.
Ààwẹ Ramandan àti irú ouńjẹ tí o lè jẹ Ramadan bẹ̀rẹ̀ jákè-jádò àgbáyé Láwọn orílèèdè kàn, ìyè wákàtí àwẹ̀ ko kọjá àfaradà ṣugbọn láwọn ibòmìíràn,a máa dàbí pé àwẹ̀ ò ní tán.
Awọn ẹlomiran ni awọn gomina Dafidi Umahi ti ipinlẹ Ebonyi, Simon Lalong ti o jẹ gomina ipinlẹ Plateau ati alaga ẹgbẹ awọn gomina orilẹede Naijiria, Abdulaziz Yari ti o jẹ gomina ipinle Zamfara.
Lara wọn ni ere: Apaadi Asọ funfun Ajẹ Mẹta Apadi Si gbogbo Obinrin Ọba Adegbọrọ Ẹni akọkọ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ọ̀gá Bello: Àìgbọ́n ló ń da àwọn òsèré tíátà tó ń jà lórí ayélujára láàmú Iyawo onise Asiri Ọla Ọmọ iya alakara Egun T'Oluwa lasẹ Ayọ ọjọkan Asẹ Ntedumare Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Èmi ò kí ń lu ìyàwó mi' Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Àwọn alufaa, ọmọ Aaroni yóo wà pẹlu àwọn ọmọ Lefi nígbà tí àwọn ọmọ Lefi bá ń gba ìdámẹ́wàá, àwọn ọmọ Lefi yóo yọ ìdámẹ́wàá gbogbo ìdámẹ́wàá tí wọ́n bá gbà lọ sí ilé Ọlọrun wa.
Nínú àtẹ̀jáde ojoojúmọ́ ilé iṣẹ́ náà lójú òpó twitter rẹ̀ ló lo ti salaye pé, ìpínlẹ̀ méjìlá ni ọwọ́jà ààrùn náà dé dúró ní Nàìjíríà fún tí ọjọ́ kẹrin osù kejìlá ọdún 2020.
Ọ̀kan ló tiẹ̀ ṣemí bí ẹ̀rín bí ẹ̀rù o.
Bi yoo ṣe mu wọn ni ẹyọ kọọkan niyẹn ti wọn yoo si lọ sa pamọ titi yoo fi ku ẹnikan ti yoo wa lọ wa awọn to ku.
Ṣugbọn kí ó má baà tún máa tàn kálẹ̀ sí i láàrin àwọn eniyan, ẹ jẹ́ kí á kìlọ̀ fún wọn pé wọn kò gbọdọ̀ dárúkọ Jesu fún ẹnikẹ́ni mọ́.
Àwọn eniyan Juda pa àwọn tí wọ́n dìtẹ̀ mọ́ Amoni ọba, wọ́n sì fi Josaya ọmọ rẹ̀ jọba lẹ́yìn rẹ̀.
CON, aare egbe musulumi lorile ede Naijiria, Fatwa( Committee Supreme Council
"Orúkọ àwọn tó yege láti darapọ̀ mọ́ ikọ̀ Amotekun ní ìpínlẹ̀ Oyo ti jáde Wo ojú àwọn òṣèré yìí láì lo ""Make-up"" orí ìtàgé bó ṣe rí gẹ́lẹ́ Gbajúgbajà òṣèré tó ṣe fíìmù James Bond tí jáde láyé lẹ́ní ọdún 90 Wumi Toriọla ti sọ̀rọ̀ sóke láti fi idí rẹ̀ múlẹ̀ pé òun àti ọ̀rẹ́ òun níjà Ṣe Lootọ ni Minisita Babatunde Fashola ri fidio ipaniyan ni Lekki Tollgate?"
Nítorí ọgbọ́n yóo wọnú ọkàn rẹ,ìmọ̀ yóo sì tu ẹ̀mí rẹ lára,
Kinni aba to n fa awuyewuye yi da le lori?
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù JAMB: Ẹ̀ṣùn oníkókó mẹ́jọ ni EFCC fi kan Philomina àtàwọn 5 míràn 31 Èbibi 2019 Ajọ EFCC lo gbe arabinrin Philomina atawọn to ku lọ sile ẹjọ lori sise owo ajọ to n sedanwo JAMB kumọ-kumọ.
Ofin tuntun yii yoo lee dena atunṣẹ irufẹ iṣẹlẹ to mu ẹmi George Floyd lọ lọwọ awọn ọlọpaa ipinlẹ Minneapolis nigba ti ọlọpaa kan ti orukọ rẹ n jẹ Derek Chauvin gbe orokun lee lọrun mọlẹ.
Èmi àti Bọla Tinubu fẹ́ lo ‘German Mercenaries’ láti gbé MKO Abiọla kúrò lẹ́wọ̀n - Dele Momodu O dùn mí pé Buhari kò yàn mí sípò Mínísítà lẹ́ẹ̀kejì àmọ́ mò gbà kádàrá - Adebayo Shittu Buhari, ṣí ìwé àkọsílẹ̀ orúkọ àwọn gómìnà tó jẹ̀bi ìkówójẹ, káráyé mọ̀ wọ́n - SERAP Òfin nìkan ló lè gbadé lórí àwa Ọba ìlú lbadan- Oba Lekan Balogun Èdè Akurẹ àti Ibadan ni wọ́n fi fà mí léti pé ẹni re kìí 'se òṣèlú - Seyi Makinde Àlàyé rèé lórí bí wọ́n ṣe mú mi lẹ́rú ní 1837 - Ajayi Crowther Àjẹ́ àti Aṣẹ́wó ní ìyá Rainbow - Òjòpagogo Femi Adesina ni awọn ma ri ma sọ eeyan kan lo gbe iru iroyin yii kiri pẹlu ayederu fọnran lati tan ọpọlọpọ jẹ.
 gbogbo ènìyàn ló ń gbé wọn gẹ ̀ gẹ ́ ní gbogbo ibi ti wọ ́ n lọ .
Lẹyin iṣẹju meji pere ti ere bọọlu naa bẹrẹ ni ọkan lara awọn agbabọọlu Algeria, Baghdad Bounedjah gba goolu aramọnda kan wọ le, eyi to mu Algeria siwaju.
"Oríṣun àwòrán, Akeugbagold "" Gbogbo ba ṣe n wa awọn ibeji mi, ko si eleyi ti kii gbọ, idi si ree to fi nira lati tete ri wọn mu, adura mi si lo gba, ta fi tete ri wọn mu."
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, A nilo agọ ọlọpa ni Orin Ekiti fún aabo wa -Falua Nkan daadaa ti ijọba ni Ruga yoo mu wa: Garba Sheu to jẹ agbẹnusọ fun ijọba salaye fun awọn akọroyin pe, Ruga jẹ ọna kan lati mu idagbasoke ba agbegbe ti wọn ba daa silẹ si.
’’Ijoba yoo san owo itọjuGomina Ambode tun tesiwaju pe igbakeji oun arabinrin, Oluranti Adebule,
Ṣugbọn, nítorí pé OLUWA fẹ́ràn yín, ati nítorí ìbúra tí ó ti ṣe fún àwọn baba yín, ni ó ṣe fi agbára ko yín jáde, tí ó sì rà yín pada kúrò ní oko ẹrú, lọ́wọ́ Farao, ọba Ijipti.
A óo ṣe bí o ti wí.
Amujo ní ìgbìyànjú láti ṣe idanilẹkọ fún àwọn àgbẹ̀ n lọ káàkiri lórí kòkòrò ajokorun yii ṣùgbọ́n tí kòkòrò náà bá tí wọ inú okò tán, afi kí èèyàn máà gbà ádùrá.
Ọ̀fọ̀ ṣẹ̀ Donald Trump, àbúrò rẹ̀ Robert, dèrò ọrun Ninu alaye rẹ fun BBC Yoruba, alakoso ẹgbẹ awọn Emere Onitẹsiwaju lọrun, ti wọn pe ni Progressive 'Peers of Heaven' Society, Oloye Oyelola aya Elebuibon ni iroyin to ni awọn ajẹ lo se ipade ko ri bẹẹ.
Gbogbo ọ̀gbọ̀ ati ọkà Baali tí ó wà lóko ni ó ti bàjẹ́ patapata, nítorí pé ọkà baali ati ọ̀gbọ̀ náà ṣẹ̀ṣẹ̀ bẹ̀rẹ̀ sí so ni.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Mompha: Dúkìá rẹ̀ ní Mompha lọ gbà lọ́dọ̀ EFCC, ló bá kó sí àhámọ́ 25 Bélú 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 18 Ògún 2020 Oríṣun àwòrán, Instagram/mompha Ajọ to n gbogun ti iwa ibajẹ ati iṣowo ilu kumọkumọ, EFCC tun ti gbe Ismaila Mustapha ti inagijẹ rẹ njẹ Mompha pada.
Iya rẹ si ti fẹ ọkọ mii.
Nigeria Slave Trade Descendant: Wo àwọn ìran ẹrú tí kìí lọ́kọ tàbí aya ní Nàìjíríà
Nítorí pé bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé Ọlọrun bukun yín, ẹ kọ̀, ẹ kò sìn ín pẹlu ayọ̀ ati inú dídùn.
 Ewe, ojogbon Yemi Osinbajo so lasiko to n
Peju Ogunmola Gbajugbaja osẹre, Peju Ogunmola dupẹ lọwọ Eleduwa fun anfaani lati wa laaye bi o ti n ṣe ayẹyẹ ọjọ ibi rẹ.
Àwọn ọmọ Juda ti kọ́ ọpọlọpọ ìlú olódi sí i; ṣugbọn n óo sọ iná sí àwọn ìlú wọn, yóo sì jó àwọn ibi ààbò wọn ní àjórun.
’Tabi kí ó bi ìyá rẹ̀ léèrè pé:‘Irú ọmọ wo ni o bí yìí?
Omotola Jalade Ekeinde: Òjòjò Covid-19 ló mú mi, mò ń gba ìtọ́jú lọ́wọ́
Ṣugbọn o ku diẹ ki ifẹsẹwọnsẹ naa o pari ni Aboubacar Konte gba goolu keji wọ le Argentina, lọrọ bi wo mi ki n gba siọ ti wọn pe ni pẹnariti.
Amọ lero ti awọn eeyan kan, orilẹede yii ko tii kọgbọn rara lati ipasẹ ogun abẹle naa, eyi ta n sami ọdun Kọkanlelaadọta to wa sopin lonii, ta ba wo awọn iwa adaluru ta n hu.
Ninu atẹjade ti Ajọ pajawiri ni ipinlẹ Eko, LASEMA gbe lede ni wọn ti sọ wi pe lẹyin wakati mẹrinlelogun ni wọn ṣẹṣẹ ri oku arabinrin naa.
Nkan ń bẹ ẹ̀yin ọmọ ènìyàn!
O ni ohun ti wọn gbọ ni pe Zaharadeen ya ọrẹ rẹ Farawa to ti di oloogbe bayii ni ogoji naira ti Farawa ko si ri san ni asiko to da fun Zaharadeen.
 ilé Òkè olá : Ìwádìí fi hàn mí pé gbogbo àwon tó ńgbé àdùgbò yìí lóní owó lówó ní ìgbà ìwásè .
Láti ibẹ̀, a lọ sí Filipi tíí ṣe olú-ìlú ilẹ̀ Masedonia.
Ìpàdé náà tún fẹ́nukò pé àwọn agbófinro yóò yí àwọn àdúgbò àti ọja ká láti mójú tó kùdìẹ́-kúdíẹ̀ tó ba wà nílẹ̀.
Pẹlu ipinnu ọkan, ọkan akin ati akikanju, Idiagbon ṣe ifilọlẹ eto igbogun tiwa ibajẹ ni Naijiria, ti wọn pe ni War Against Indiscipline (WAI), eyi to wa ni iṣọri marun: Wo ojú àwọn afurasí tó fipá bá Uwaila, akẹ́kọ̀ọ́ Uniben sùn tí wọ́n tún pa á sínúu ṣọ́ọ̀ṣì Ọlọ́pàá Funso ló fi ààyè sílẹ̀ fún mi láti sá kúrò ní àgọ́ ọlọ́pàá tó wà ní Mokola - Sunday Shodipe Aráyé ẹ gbà mí, nǹkan ń ṣe mí, èyí tó ju àìsàn lọ - Kanran Oríṣun àwòrán, OTHERS Ofin WAI onisọri marun ti Idiagbon gbe kalẹ Iṣọri akọkọ ni ofin tito sori ila: Ofin yii lo pọn ni dandan fun awọn ọmọ Naijiria lati maa to si ori ila nibikibi ti ero ba pọ si, bii ile ifowopamọ, ile ifiweransẹ, ibudo itaja, ibudokọ ati bẹẹ bẹẹ lọ.
Al-Bashir ti n kawọ sẹyin rojọ lori sise owo
Ṣugbọn bí ojú rẹ kò bá ríran, gbogbo ara rẹ ni yóo ṣókùnkùn.
Ààgo mẹjọ alẹ si si aago mẹfa aarọ, eyi tumọ si pe ko ni si igbokegbodo eniyan ati ọkọ laaarin asiko yii.
Ati ìwọ, Kapanaumu, o rò pé a óo gbé ọ ga dé ọ̀run ni?
”O ni lati igba ti won ti da ajo naa sile lọdun 2008, ajo naa se ipade akoko lọdun 2013, bakan naa ni won tun se ipade iru rẹ lọdun 2017.
Najeem Salaam naa se niluu Ejigbo.
Ọrọ apilẹkọ naa, ti wọn pe akori rẹ ni, “Fifun Ipinle ni Agbara Kikun Lati Fopin Si Iṣẹ ati Oṣi” ni Igbakeji Aarẹ fi mulẹ pe bi wọn ba fun awọn ipinlẹ ni agbara kikun pẹlu ẹka Idajọ, ẹka Amuṣẹṣe ati ẹka Aṣofin, pe eleyii yoo le fun wọn lanfani lati ṣamulo awọn owo ti wọn ba n pa wọle funra wọn lori ipese ọrọ fun awọn ara ilu, ti wọn yoo si fi opin si iṣẹ ati oṣi.
Ẹ̀rọ CCTV tú àsírí ọkùnrin ẹni ọgbọ̀n ọdún tó fi ipá bá ọmọ ọdún mọ́kànlá lòpọ̀
Bí kò bá rí bẹ́ẹ̀, kí ẹnìkan já mi nírọ́,kí ó sì fi hàn pé ìsọkúsọ ni mò ń sọ.
naa o to pari saami ayo merin-merin(4-4).
Ni owurọ Ọjọru ni okiki kan pe kabiyesi Ọọni Adeyeye Ogunwusi ti ni Arẹmọ lẹyin ti wọn gbẹbi olori rẹ, Yeyeluwa Naomi Silekunola Ogunwusi; lati igba naa si ni wẹjẹwẹmu ti n lọ kaakiri.
Lara awọn ere manigbagbe ti Oyin Adejobi ṣe ko to dagbere faye ni Orogun Adedigba, Kuyẹ, Kootu Asipa, Ọgba iwosan, Ekurọ ọlọja, Iyekan Sọja ati bẹẹ bẹẹ lọ.
Ohun ti oju awọn oniroyin n ri lorilẹede Naijiria Fifi arakunrin yii si ahamọ ti ko ibẹru bojo ba ọpọ awọn oniroyin lorilẹede Naijiria.
A ti mu awon afurasi naa“lonii,gege bi ojo miiran,oko agbepo to ye ki o gbe epo  ati oko to ye ki o ko oti elerin-dodo ni won fi se fayawo iresi.
Covid-19 tún ran èèyàn 56 ní Naijiria, ó ṣekú pa ẹni kan ní 22/11/2020 Eeyan marundinlaadọjọ ni esi ayẹwo fihan pe o tun ti ni aarun Covid-19 ni Naijiria.
Ekiti Election: Oludije PDP ní ìdigunjalè ọ̀sán gangan tí kò ṣẹlẹ̀ rí ni ìdìbò Ekiti
Tẹnumọ́ ọn ní àkókò tí ó wọ̀ ati àkókò tí kò wọ̀.
Ipo kẹwaa ni Arsenal wa lori tabili idije liigi ilẹ Gẹẹsi(Premier League), lẹyin ti Mikel Arteta di akọnimọọgba tuntun lẹyin ti Unai Emery kuro tan.
” O tesiwaju pe: ”aare ti ni ki n ri I daju pe gbogbo atunse yii di sise.
ìran ẹni tí ó ń gbọ́ ọ̀rọ̀ Ọlọ́run,mo sì lajú sílẹ̀ kedere rí ìran láti ọ̀dọ̀ Olodumare.
Ṣugbọn ó bọ́ ògo rẹ̀ sílẹ̀, ó gbé àwòrán ẹrú wọ̀, ó wá farahàn ní àwọ̀ eniyan.
Bí o bá bẹ̀rẹ̀ sí sọ ọ̀rọ̀ gidi, tí o dákẹ́ ìsọkúsọ, o óo tún pada di òjíṣẹ́ mi.
 láàrin 1955 àti 1968 , ìwọ ́ de aláìníjàgídíjàgan àti àìgbọràn aráàlú fa rògbòdìyàn láàrin àwọn alákitiyan àti àwọn aláṣe ìjọba .
Ajọ to n gbogun ti ajakalẹ aarun lorilẹede Naijiria, NCDC lo fidi ọrọ naa mulẹ loju opo Twitter rẹ.
"O ni ""Nigba ti Abiola fi atẹjisẹ ransẹ si mi, ẹnu ya mi, tori oju opo Instagram mi la ti kọkọ bẹrẹ nibi to ti ni oun fẹ maa ba mi jade."
Ṣugbọn nígbà tí oòrùn mú, ó jó o pa, nítorí kò ní gbòǹgbò tí ó jinlẹ̀; ó bá rọ.
Nitorinaa, igun mejeeji lo gbe ọrọ wọn kalẹ pẹlu ọgbọn ori.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, German Shepherd Rotweilers: Ẹya aja yii naa jẹ eyi to wọpọ laarin awọn eniyan, amọ to loro lara pupọ ju.
Awọn ọmọ ogun to wa ni ipo kekere naa sọ wi pe awọn gba nitori awọn fẹ da ijọba tiwantiwa pada si orilẹede naa.
Àwọn agbègbè tí àtùndi ìbò yóò kàn lọ́jọ́ Àbámẹ́ta nípìnlẹ̀ Eko rèé Adolf Hitler gbé àpótí ìbò, aráàlú yàn án sípò gẹ́gẹ́ bíi Káńsílọ̀ Àwọn ohun tó bá lè fa ìwà ọ̀daràn bíi aṣọ ìwọ̀kuwọ̀ ló yẹ ká ti ọwọ́ rẹẹ̀ baṣọ - Amotekun Osun Díẹ̀ ló kù kí ọjọ́ ìkúnlẹ̀ di ọjọ́ ikú fún ìyá mi lọ́jọ́ tó bí mi - Seyi Makinde Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ìgbátí ìgbámú àná látọwọ́ sọ́jà obìnrin ti bá arákùnrin náà dé iléèwòsàn Agbẹnusọ àjọ ìsọkan agbáyé fún ètò ìlera (WHO) Tarik Jasarevic sọ pé láti ọdún 2017, orílẹ̀-èdè Nàìjíríà kò tí jàjàbọ́ lọ́wọ́ ààrùn iba pójú (Yellow Fever).
    Gbogbo ìwọ̀nyí sẹlẹ̀ lóru, ìgbà tí àwọn iwin méjì yìí dúpẹ́ lọ́wọ́ wa tí wọ́n lọ tán, àwa náà sun oorun díẹ̀ si i, kò sì pẹ́ lẹ́yìn èyí ilẹ̀ mọ́.
Igba kan ṣoṣo ni ijọba ti gbiyanju lati la ọnade agbegbe yii ni ipinlẹ Niger ni lọdun 1985.
aare so fun ile igbimo asofin pe ki won yi ọjọ kọ́kàndínlọ́gbọ̀n, osu kárùn ún  (May 29),ti won n sami ayeye eto ijoba
" A ti n gbé igbesẹ lati mọ bi ẹyà kokoro tuntun yi ti ṣe waye.
Lati ori obinrin yii si ni awọn apọnbeporẹ wa, yatọ si awọn agbaagba olori to siwaju rẹ Bi o tilẹ jẹ pe Olori Abiodun kii fi bẹẹ na oju opo ayelujara bii ti awọn olori to de lẹyin rẹ, sibẹ ara awọn olo, ẹlẹjẹ tutu ti Alaafin fi n gbe ẹmi ro ni.
Ọgbẹni Adesina sọ pe oun ko jẹbi ẹsun kankan.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Obasanjo: Buhari ní àìlera lẹ́mìí, lára, àti lọ́kàn.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Iran war: Wọ́n ti mu aṣojú ọmọ Britikó ní orílẹ̀-èdè Iran 12 Sẹ́rẹ́ 2020 Oríṣun àwòrán, EPA Àkọlé àwòrán, Ni Tehran to jẹ olú-ìlú Iran ni wọ́n ti mú Rob Macaire to jẹ́ aṣojú ilẹ̀ Gẹ́ẹ̀sí.
Èyí mú kí wọ́n pariwo kí wọ́n sì pàtẹ́wọ́ kárakára, tí inú u gbogbo wọ́n ndùn gigi nítorípé wọ́n nífẹ̀ ẹ Ọba-bìnrin yìí púpọ̀.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Polio: Bàbá kọ abẹ́rẹ́ àjẹsára kí ọmọ rẹ̀ tó ní àìsàn polio!
Awọn ilé oúnjẹ kò gbọdọ gbà kí àwọn ènìyàn jòkó jẹ́un, kí wọ́n ràá ki wọ́n sì máa lọ ni.
Ọ̀pọ̀ òṣèré tíátà tó ń sàìsàn ni kò ṣe dáadáa fẹ́gbẹ́ - Jide Kosọkọ Wòlíì Kasali ní Dolapo Awosika kò lé ìyàwó òun jáde Mr Latin: Ó ṣeéṣe kí TAMPAN àti ANTP di ọkàn lọ́jọ́ iwájú, tí.
Siwaju si, aare tun fi aabo to
Coronavirus: Àwọn ohun tí a kò tíì mọ̀ nípa àrùn Covid-19 Kí lo mọ̀ nípa fẹntilétọ̀, ohun èlò aṣèrànwọ́ èémí A fẹ́ lo ẹ̀jẹ̀ àwọn èèyàn tó ye àrùn Coronavirus láti fi ṣe ìwòsàn fún àwọn tó wà lórí àárẹ- UK Coronavirus: Kíni àwọn àmì tuntun tó n fihàn?
Ẹbọra lágbó ẹgẹ, Ọ̀bá di méji; a gbẹwọ̀n gbẹ̀gẹ̀dẹ̀
Ní ọdún kẹrindinlogoji ìjọba Asa, ní ilẹ̀ Juda, Baaṣa ọba Israẹli gbógun ti Juda, ó sì bẹ̀rẹ̀ sí mọ odi Rama láti dí ojú ọ̀nà tí ó lọ sí ilẹ̀ Juda, kí ẹnikẹ́ni má baà lè lọ sí ọ̀dọ̀ Asa, ọba Juda, kí àwọn tí wọ́n wà lọ́dọ̀ rẹ̀ má sì lè jáde.
Mo kéde ìlú-kò-fararọ lori eto ẹkọ ipinlẹ Yobe!
 nígbà tí adágbà rí i , ó pariwo lé won lórì pé : ah !
Awọn iroyin ti ẹ lee nifẹẹ si: Ẹwa Agọnyin ni aayo ounjẹ Badagry Awọn eni ilumọọka lu wa lontẹ Aworan aṣa ati iṣe awọn ọmọ Yoruba Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí kan sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
Ibẹ si ni wọn ti sọ pe mo ni ailera MRKH.
Lori ajọṣepọ rẹ pẹlu osere tiata miran Tayọ Amokade, taa mọ si Ijẹbu, Sanyeri ni Amugbalẹgbẹẹ mi ni Ijẹbu, koda o gbe inu ile ọdọ mi ri."
Amọ̀, nigba to ya, Bukọla di igba ati agbọn rẹ pada si ilẹ Naijiria, nitori ile ni abọ isinmi oko, to si di oludari ile ifowopamọ Société Générale (to ti kogba wọle bayii) laarin ọdun 1990 si 2000.
Yatọ si pe ere tiata maa n dani laraya, o tun maa n kọni lẹkọ, fun ni loye, to si tun n mu ayipada ba awọn iwa ibajẹ lawujọ wa latipasẹ awọn ohun awokọgbọn to wa ninu rẹ.
Wọ́n ṣẹgun àwọn ará Amoni, wọ́n sì dó ti ìlú Raba, ṣugbọn Dafidi dúró ní Jerusalẹmu.
Kii ṣe orilẹede Naijiria nikan ni Boko Haram wa mọ bayii, itakun rẹ ti kan de awọn orilẹede to fẹgbẹkẹgbẹ pẹlu Naijiria bii Chad, Niger ati Cameroun.
Iroyin naa ṣalaye pe lara ẹsun ti awọn aṣofin naa fi kan igbakeji gomina ọhun ni iwa aṣemaṣe lẹnu iṣẹ, ṣiṣowo ilu baṣubaṣu, aṣilo ipo, eyii to lee da oju ijọba bolẹ, atawọn ẹsun miran.
"Ṣugbọn o gba o si sọ pe ""emi ni alagbatẹru ati oludari agba ileeṣẹ iroyin the Nation ati ileeṣ amohunmaworan TVC"" eyi ti awọn janduku tun kọlu ti wọn si jo nina rau-rau."
mẹ́tàdínlọ́gbọ̀n ekunwo owo osu ti awon igbimo naa fenuko le lori , egbe awon osise ni
”Esun ti won fi kan Qudaril lodi sofin ati ilana eka(section 22(4)(b),  ti o si leto si ijiya labe ofin (Section 22(4) eka lilu eniyan ni jibiti lori ero ayarabiasa (Cyber Crimes (Prohibition, Prevention e.
Olubadan lati maa yan awon Oloye, Mogaji ati Baale leyin awon igbimo Olubadan
Ibadan Sallah Killing: Ẹbí ọmọ tí wọ́n rí òkú rẹ̀ nínú odò ní Ibadan ní ikú rẹ̀ kìí ṣe ojú lásán
Nítorí wọ́n ń wí pé, “Kí ó má jẹ́ àkókò àjọ̀dún, kí rògbòdìyàn má baà bẹ́ sílẹ̀ láàrin àwọn eniyan.
Bakan naa lo fun orilẹede naa ni ẹgbẹrun lọna ẹẹdẹgbẹta Dọla lati fi ran an lọwọ fun eto idibo to fẹ ẹ ṣe.
Eèyàn ẹgbẹ̀rún lọ́nà ọrinlelẹgbẹta ó dín marun un, 675,000 sì tẹrí gbasọ lorilẹ-ede Amerika nìkan.
Nítorí àwọn ẹgbẹ́ kọ̀ọ̀kan ní wọ́n njó tẹ̀lé ọkọ̀ tiwọn, wọn a máa mú u bí ìdíje ni.
Awọn afurasi mejeeji si ti n ka boroboro fun awọn ọlọ[pa nipa ipa ti ikọọkan wọn ko si ijinigbe Aisha.
Ojo Aje to lo ni Obasanjo ti benu ate lu ijoba Muhammadu Buhari pe ko ni imo kikun nipa isejoba ati eto iselu.
O kesi awọn eniyan ara ipinlẹ naa lati kuro ni agbeegbe ti níbí ìbúgbàmù naa nítorí àrùn Coronavirus.
Gbogbo ọṣẹ ti mo ngbiyanju lati fi wẹ mọ, pabo lo n ja si.
Kò gbọdọ̀ da òróró sí orí rẹ̀, bẹ́ẹ̀ ni kò sì gbọdọ̀ fi turari sinu rẹ̀, nítorí pé ẹbọ owú ni, tí a rú láti múni ranti àìdára tí eniyan ṣe.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Fatai Owoseni: O dìgbà tí mo bá bẹ̀rẹ̀ iṣẹ́ kí ń tó sọ ìpinnu mi 19 Ògún 2019 Oríṣun àwòrán, @others Àkọlé àwòrán, Fatai Owoseni: O dìgbà tí mo bá bẹ̀rẹ̀ iṣẹ́ kí ń tó sọ ìpinnu mi Láìpé a máa to sọ àlákalè wa fún aṣeyọri eto aabo ipinlẹ oyo - Fatai Owoṣeni Olubadamọran tuntun ti Gomina Seyi Makinde yan lori eto aabo ipinlẹ Oyo, Fatai Owoṣeni ti ni igbesẹ pọ ti yoo mu idagbasoke ba ipinlẹ Oyo.
Iṣẹ́ meji ti ó wọ́pò ni ayé àtijọ́ ni iṣẹ́ àgbẹ̀ àti òwò nipa ti ta irè oko ni ọjọ́ Ọjà Oko lati Abúlé kan si ekeji.
Oríṣun àwòrán, others Akskọ ni ibo gomina ni ipinlẹ Edo.
O ni fun idi eyi, ẹnikẹni ko gbọdọ fi ọkọ rẹ silẹ lori popo mọ lati igba naa lọ.
Nítorí náà ni ibinu Ọlọrun ṣe ru sí wọn nígbà náà.
 Ó dara pọ ̀ mọ ́ connacht ní ọdún 2014 láti ilé-ẹ ̀ kọ ́ ' trinity college ' .
Oríṣun àwòrán, Twitter screenshot Ileeṣẹ naa kọjalẹ pe ohun ti Motara ṣe lodi si igbagbọ ati afojusun awọn pe o n foju tẹmbẹlu eeyan.
Bakan naa lo gba oye imọ ijinlẹ akọkọ ninu imọ ofin ni Fasiti ilu Cambridge.
Àmọ́ ṣá, ènìyàn ò lè ṣàì ronú oun tí nbọ̀ lọ́nà níoripé afẹ́fẹ́ tútù ní í fẹ́.
Owo naa ni wọn pe ni Nigeria Youth Investment Fund (NYIF).
"Oyedepo ni ""Ida mẹwaa jẹ majẹmu pẹlu Ọlọrun ti ko ṣe e yẹ, laisi ida mẹwaa, ko see ṣe lati ṣe rere tabi ni ọrọ, aisan ida mẹwaa si lo n fi ẹ sinu egun ọda owo."
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: PDP sèwọ́de tako ìwà ipá l‘Èkìtì Àwòrán ìbò Èkìtì lọ́dún 2014 fún àwòkọ́gbọ́n Ìdìbò Ekiti; àáyá bẹ́ sílẹ̀, ó bẹ́ áré Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ekiti Election: Awọn oludibo ko mọ idi ti wọn fi n yin tajutaju ni Okesha Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ọbẹ Ẹgusi sise ati jijẹ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Femi Adebayo: Ẹyin ọ̀dọ́, ẹ káàbọ̀ ságbo ilé Tíátà Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Atejade ọ̀hun ti Eugene Aliegba tó jẹ akọwe ikọ ìpolngo Jime Ode fọwọ si sàlàyé pé, ilé ẹjọ ni àwọn yóò ti yanju gbogbo ọ̀rọ̀ náà.
FCT-89 Gombe-89 Kaduna-62 Lagos-35 Kwara-15 Borno-13 Nasarawa-10 Rivers-10 Bauchi-8 Ogun-8 Osun-7 Bayelsa-7 Kano-7 Edo-6 Taraba-6 Ekiti-5 Katsina-5 Akwa Ibom-4 Delta-3 Sokoto-1 Èèyàn 318 tún ti ní COVID-19 ní Nàìjíríà, sùgbọ́n ara ará ilú 60 ló dá Àjọ tó n gbógun ti ìtàkálẹ̀ ààrùn ní Nàìjíríà (NCDC) ti kéde pé ènìyàn 318 ló tí ni ààrùn coronavirus ní Nàìjíríà.
Ọba jókòó lórí ìtẹ́ ninu gbọ̀ngàn rẹ̀, ó kọjú sí ẹnu ọ̀nà.
Èmi OLUWA, Olùràpadà rẹ ni mo sọ bẹ́ẹ̀.
Wo inú ihò tí Adewura kó sí nínú òjò l'Eko Ọ̀gọ̀rọ̀ èèyàn lórí ayélujára bú Dalung lórí owó IAAF Ẹ̀gbẹ́ òṣìṣẹ́ ní ìpínlẹ̀ Oyo so ìyanṣẹ́lódì rọ̀!
- MC Oluomo Díẹ̀ ló kù kí bàlúù arìnrìnàjò sílẹ̀ mímọ́ Hajj gbaná Arumọjẹ ti wọn si n ṣe fun awọn araalu atawọn awakọ ẹgbẹ wọn ni pe, aṣẹ ti ijọba fi gbe ẹsẹ le ẹgbẹ naa ti yọ bi ori inu oorun ni ọjọ kọkanlelọgbọn, oṣu karun un, ọdun 2019.
Dafidi lọ ń gbé ibi ààbò náà, nítorí náà ni wọ́n ṣe ń pe ibẹ̀ ní ìlú Dafidi.
Wọn ó máa ní agbára kún agbára,títí wọn ó fi farahàn níwájú Ọlọrun ní Sioni.
Awọn onwoye eto idibo ni o ṣeeṣe ki ija naa niiṣe pẹlu eto idibo sipo gomina ti yoo waye ni ipinlẹ naa ni ọdun 2022.
Nnnamani so pe“A samojuto awon esun naa dara-dara.
“Máa bọ̀, wá jẹ lára oúnjẹ mi,kí o sì mu ninu ọtí waini tí mo ti pò.
Gomina ipinlẹ Ekiti, Ọmọwe Kayode Fayemi ti fasẹ si pe ki adari fasiti ipinlẹ Ekiti, EKSU, Ọjọgbọn Samuel Oye Bandele.
''Awa ọmọ Ibadan kii ṣe oni wahala nii nitori rẹ lo fi dabi ẹni pe a ko tii sọrọ lati nkan bi ọdun mejilelaadọrin ti wọn ti da fasiti Ibadan silẹ pe ki wọn yan ọmọ Ibadan ni ọga fasiti naa.
Elebuibon ni iṣẹ Ifa ti gbe oun de orilẹede Amerika ati kaakiri agbaaye.
Ọgọrun-un talẹnti ni wọ́n lò láti ṣe ọgọrun-un ìtẹ́lẹ̀, talẹnti kọ̀ọ̀kan fún ìtẹ́lẹ̀ kọ̀ọ̀kan.
Wọ́n ń káàkiri bí afọ́jú láàrin ìgboro,ẹ̀jẹ̀ àwọn tí wọ́n pa sọ wọ́n di aláìmọ́tóbẹ́ẹ̀ tí ẹnikẹ́ni kò lè fọwọ́ kan aṣọ wọn.
Bí mo ti ń kọ̀wé yìí, ẹ̀yín ni ó ára jù lọ lode ayé lójú mì: orí yín wù mi, ọrùn yin wù mi, irun ori yin wu mi, èékán ọwọ àti ẹsẹ yin ń wù mi, iwájú yín dára, ìpàkọ́ yín dára, ẹyìnlójú yín dara, ipéǹpéjú yín dára, eyín yín dára, ètè òkè àti ti ìsàlẹ̀ yín dára pẹ̀lú, mo fẹ́ràn apá yin, mo fẹ́ràn ẹsẹ̀ yín, mo fẹ́ràn orukun yin, mo fẹ́ràn ọrùn ẹsẹ yín, àtẹ́lẹwọ́ àti àtẹ́lẹsẹ̀ yín dára ju ti ẹnikẹ́ni lọ.
Ọpọ awọn eniyan naa lo ni lai naani ìnira ti arun Coronavirus ko ba ọrọ aje awọn, ati iṣẹ pẹlu òsì to gogo si lawujọ wa, sibẹ Ileesẹ DSTV si tun n fara ni awọn.
”Wolii náà bá dákẹ́, ṣugbọn, kí ó tó dákẹ́ ó ní, “Mo mọ̀ pé Ọlọrun ti pinnu láti pa ọ́ run fún ohun tí o ṣe yìí, ati pé, o kò tún fetí sí ìmọ̀ràn mi.
Ọmọ Ọ̀gá Ògo ni a óo máa pè é.
Josẹfu sì mú kí àwọn ọmọ Israẹli búra fún un pé, nígbà tí Ọlọrun bá mú wọn pada sí ilẹ̀ Kenaani, wọn yóo kó egungun òun lọ́wọ́ lọ.
Ìròyìn kan ni pé ó ṣeéṣe kí Iniesta darapọ̀ mọ́ ẹgbẹ́ agbábọ́ọ̀lù Chongqing Dangdai Lifan ní ìdíje líìgì orílẹ́-èdè China Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Ninu ọrọ ibanikẹdun tiẹ, Gomina ipinlẹ Oyo, Seyi Makinde ṣe apejuwe iku Oloye Akande gẹgẹ bi adanu nla fun ipinlẹ Oyo ati fun orilẹede Najiria lapapọ.
Wo àwọn nkan tí o le ṣe gẹ́gẹ́ bi aláboyún lásìkò àjàkálẹ̀ ààrùn Covid-19 Ìgbẹ́jọ́ ti bẹ̀rẹ̀ lórí àwọn afurasí tó pa ọmọ Fasoranti, Funke Olakunrin Afọnja, ẹni tó finú wénú ní Ilọrin, àmọ́ tó jẹ iwọ Ṣé o mọ̀ pé àwọn kan ń fi onídùúró ṣe òwò?
Láti inú ẹ̀yà Juda, àwọn ọmọ ogun tí wọ́n wá jẹ́ ẹẹdẹgbaarin ó dín igba (6,800) wọ́n di ihamọra pẹlu apata ati ọ̀kọ̀.
Aarẹ́ Buhari - BBC News Yorùbá BBC News, YorùbáFò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù NGARSA: Ọmọ Nàìjíríà ń retí ifẹ ẹ̀yẹ lọ́dọ̀ yín - Aarẹ́ Buhari 11 Agẹmo 2019 Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Àríyá ò lópin láti ìgbà tí Nàìjíríà ti júwe ilé fún South Africa Ni Naijiria ati lorilẹede Egypt ni gbogbo awọn ọmọ Naijiria ti n fi idunu han si bi Super Eagles ṣe da sẹria iya fun Bafana Bafana.
Ó bá bi wọ́n pé, “Èéṣe tí ojú yín fi rẹ̀wẹ̀sì lónìí?
Nígbà tí o tà á tán, mo ṣebí o ní àṣẹ lórí owó tí o tà á?
Awakọ̀ òfúrúfú agba ati onimọ nipa irinna ofurufu tó ti fẹ̀yinti, John Ojikutu ni otubantẹ ni papakọ ofurufu ni ipinle naa, nitori orisirisi ipenija lo wa nipinlẹ naa to yẹ ki ijọba dojukọ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Mike Ifabunmi: Òrìṣà ló gbè wà jù ni Brazil Yoruba ni ati oore, ati ika, ọkan kii gbe, nitori naa lo se yẹ ka se aye re.
Nígbà tí ọba dìde tí ó lọ sí inú àa[fin lọ́hùn-ún tí ó simi tán ó ránńṣẹ́ sí ọkùnrin apẹja yìí ó sì tún wí fún un kí ó bá òun wá ẹja mẹ́ta sí i.
Nítorí àwọn kerubu yìí na ìyẹ́ wọn bo ibi tí wọ́n gbé Àpótí Ẹ̀rí náà sí, wọ́n sì dàbí ìbòrí fún Àpótí Ẹ̀rí ati àwọn ọ̀pá rẹ̀.
Nígbà tí ó dáhùn báyìí inú obìnrin yìí dùn tó bẹ́ẹ̀ tí ó fi jẹ́ wí pé ibi tí ó ti ń sáré lọ mú oògun tí yòó fi yí ọkọ rẹ̀ padà, gèlè rẹ̀ bọ́ sọnù, aṣọ rẹ̀ tú, yẹ̀rì ló kù sí ìdí rẹ̀ tí ó fi ń sáré lọ.
Ẹni tí ó fún un ní ẹran sìn yóo faramọ́ ìbúra yìí, kò sì ní gbẹ̀san mọ́.
òkú méjìlá jóná mọ inú mọ́ṣúárì Fásítì OAU Àwọn jàndùkú dáná sun Aṣáájú obìnrìn ẹgbẹ́ òṣèlú PDP mọlé ní Kogi Goodluck Jonathan jẹ́ olùfọkànsìn àti ìwúrí fún ìrandíran ní Nàìjíríà- Buhari Seyi Makinde kò leè gba adé lórí àwa ọba 21, iléẹjọ́ ni yóò là wá níjà - Lekan Balogun Obinrin to wa ninu fidio yii jẹ akẹkọọ ọlọdun kẹta ni ẹka ẹkọ imọ nipa iṣiro owo, Accountancy, ki wọn to sọ fun un pe ko lọ gbele ẹ.
Ọkọ rẹ̀ yóo fi tọkàntọkàn gbẹ́kẹ̀lé e,kò sì ní ṣaláì ní ohunkohun.
Ohun ti Ibitoye Olatunde Michael gba lero pe ọkọ ti oun ba se funra ara oun, ni oun yoo kọkọ lo, ti wa si imusẹ.
 Ọ ̀ pọ ̀ nínú àwọn alẹ ́ nu-lọ ́ rọ ̀ láeùjọ ló yi pè fún ìwagbọò dẹ ́ kun sí iṣẹ ́ àjọ náà látàrí ètò àbò tó mẹ ́ hẹ ní orílẹ ̀ -èdè nàìjíríà .
Àwọn eniyan náà sì ṣí kúrò níbẹ̀ lọ sí Haserotu, wọ́n sì pàgọ́ wọn sibẹ.
Toyin Abraham wa n gba awọn lọkọlaya nimọran pe ti ede wọn ko ba yede mọ, ti igbeyawo wọn si n la ina kọja, yoo kuku dara ki tọkọtaya yago funra wọn, dipo ki wọn sekupa ara wọn.
Wọn ṣe gẹgẹ bi awọn obinrin ilu Aba ṣe ṣe lọdun 1929, nigba ti wọn n ja pe owọ orí ti áwọn n san ti pọ̀ ju.
Sheffield faṣọ iyì ya mọ́ Chelsea lára lọ́nà ìrìnàjò sí Champions Leaguee Ọlọ́run ló yàn mí ti Arsenal, mi ò lè fi wọ́n sílẹ̀ láéláé- Mama Arsenal yarí West Ham fi omi àbùkù wẹ Chelsea láwọlé sùn, Arsenal yìnbọn pa Norwich Mo jọ ọkùnrin pẹ̀lú iṣan, ìdí àti egungun líle, síbẹ̀ obìnrin ni mi - Àgbábọ́ọ́lù obìnrin tẹ́lẹ̀ Funke Akindele fún mi lówó tí mo fi gba ilé, kò ra ilé fún mi o - Ajirebi Ọ̀rọ̀ǹpọ̀tọ̀niyùn, Aláàfin obìnrin àkọ́kọ́ rèé, tó ní nǹkan ọkùnrin Ṣugbọn ni bayii, ẹgbẹ ololufẹ awọn ikọ agbabọọlu Naijiria, Authentic Nigeria Supporters' Club ti fun mama ni ẹbun owo rọgun rọgun.
Nítorí náà ẹ jẹ́ kí á ṣe Àjọ̀dún Ìrékọjá wa, kì í ṣe burẹdi tí ó ní ìwúkàrà àtijọ́ ti ẹ̀ṣẹ̀ ati ìwà burúkú ni kí á fi ṣe é, ṣugbọn pẹlu burẹdi tí kò ní ìwúkàrà ninu, burẹdi ìwà mímọ́ ati òtítọ́.
Àjọ àpapọ̀ tó ń rí sí ìṣẹ̀lẹ̀ pàjáwìrì NEMA sọ pé àgbàrá náà kò ṣẹ̀yìn òjò àrọ̀ọ̀rọ̀dá tó mú kí odò Niger àti Benue kún àkúnfàya.
Ìdí rèé táwọn àkàndá ẹ̀dá fi dí iwájú iléeṣẹ́ ìjọba ìpínlẹ̀ Oyo pa l'Agodi n'Ibadan Ọlọ́pàá, sójà yabo Lekki Toll Plaza láti dènà ìfẹ̀hónúhàn míràn Lóòtọ́ ni ọkọ mi lù mí bí àṣọ òfì, àmọ́ gómìnà ti bá wa parí ẹ̀, ẹ máa gbàdúrà fún ìdílé mi- Dokita Ifeyinwa Mi ò kí n ṣe afẹfẹ-yẹ̀yẹ̀ lórí ayélujára nítorí pé mí ò ní dúkìá tí mó le fihàn- Ronke Oshodi-Oke Àwọn èèyàn tí bẹ̀rẹ̀ sì ní gba abẹ́rẹ́ àjẹsára fún ìdènà àrùn Coronavirus ni ilẹ̀ Gẹ̀ẹ́sì Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Death During Sex: Àwọn nǹkan mẹ́ta tó le ṣekú pa ọkùnrin lásìkò ìbálòpọ̀ rèé9 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Overweight and pot belly: Wo oríṣìí oúnjẹ márùn ún tó lè dẹ́kun ikùn yíyọ àti ara àsanjù8 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Fake Kidnap: Ọlọ́pàá Eko ń wá arákùnrin tó parọ́ gba owó ìjínigbé 700k lọ́wọ́ mọ̀lẹ́bí ọ̀rẹ́bìnrin rẹ̀8 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Male Fertility: Wo àwọn oúnjẹ márùn ún tó ń mú kí àtọ̀ ọkùnrin dára sí i7 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Laarin ọjọ kẹtadinlogun, oṣu kẹjọ, ọdun 2020 lawọn akẹkọọ ṣe idanwo naa eleyi to yẹ ki esi rẹ jade lọjọ ketadinlọgbọn, oṣu kẹwaa tii ṣe ọjọ marundinlaadọta ti wọn ṣe idanwo ọhun.
Ninu atẹjade ti Kọmisọnna fun ọrọ iroyin Muhammad Garba buwọlu ni wọn ti gbe ọrọ yii jade.
Ṣugbọn, ṣe fifi omi ati iyọ yọnu lee dena arun naa?
Yoruba World Assembly: Ìlú Ibadan ni wọ́n tí ṣe àgbẹ́kalẹ̀ ẹgbẹ́ ọmọ Yorúbá tuntun
South Africa fofin de arinrin ajo lati Amẹrika, UK ati Italy: Aarẹ South Africa, Cyril Ramaphosa sọ pe wọn yoo fi ofin de awọn ajoji lati orilẹ-ede US, UK, Italy ati awọn orilẹ-ede miran ti aarun naa pọ si, lọjọru.
    Ní ọjọ́ tí mo lọ bẹ̀ ẹ́ wo tí mo rí ilé rẹ̀ àti irú ipò ọlá tí ó wà ó yà mi lẹ́nu pé irú ọlọ́lá bẹ́ẹ̀ lè wí pé òun máa fẹ́ èmi ọdẹ.
Nítori àwọn àtúgbẹ́yẹ̀wò, o níra láti ṣe àkójọpọ fún àwọn ọkọ́ naa Orisun: Johns Hopkins University atawọn ajọ eto ilera ilu Iye akọsilẹ to waye gbẹyin 7 Oṣù Ọ̀pẹ̀ 2020 14:22 WAT+3 Murder: Alága ẹgbẹ́ NURTW tó gún ọlọ́pàá pá, gba ìdájọ́ ikú Oríṣun àwòrán, Other Ilé ẹjọ́ gíga ti Ikeja n'ilu Èkó tí dá ẹjọ́ ikú fún alaga ẹgbẹ́ awakọ èrò NURTW, ẹ̀ka ti Boundary/Ayetoro nipinlẹ Eko, Saheed Arogundade lórí ẹ̀sùn pé ó pa ọlọ́pàá kan.
ti  mu awọn afurasi  fayawọ mẹjọ ni ẹkun  Gusu Ọyọ/Ọsun orile ede yii, ti won si ri awon
Awọn ami ẹyẹ Olympics ati awọn ibudo ajogunba agbaye ti Unesco nikan ni ofin yii ko kan.
Àwọn aláṣẹ ìjọba China ti fi ayàwòrán eré aṣakọ̀sílẹ̀-ìṣẹ̀lẹ̀ Deng Chuanbin sí àtìmọ́lé lẹ́yìn tí ó ṣe túwíìtì àwòrán ìgò ọtí-líle kan tí a sààmìi “64” sí lára – tí ó ń tọ́ka sí ọjọ́ burúkú Èṣù gbomi mu Ìpaninípakúpa tí ó wáyé ní Tiananmen Square ní ọjọ́ 4, oṣù Òkúdù ọdún-un 1989.
 Ṣùgbọ ́ n kí ó tó dé àwọn ènìyàn pàápàá àwọn ẹ ̀ gbọ ́ n rẹ ̀ rò wí pé ó ti kú , wọ ́ n sì ti fi bàbá wọn sílẹ ̀ fún àwọn ìyàwó rẹ fún ìtọ ́ jú .
Láti inú ilẹ̀ ẹ̀yà Efuraimu ni wọ́n ti gba ìlú fún àwọn ọmọ Kohati yòókù, tí wọ́n jẹ́ ẹ̀yà Lefi.
Ileeṣẹ Privacy International ni awọn ohun elo ori ẹrọ alagbeka bii Period Tracker, Period Track Flo ati Clue Period Tracker kii pin abajade iwadii wọn pẹlu Facebook.
”Ahabu wí fún wọn pé, “Ẹ lọ mú un wá.
Wọ́n fi idà pa wọ́n, wọn kò ṣẹ́ ẹnikẹ́ni kù ninu wọn.
Chelsea kọ́wọ̀ọ́ rìn pẹ̀lú Arsenal lọ àṣekágbá Europa Ọmọdé ológun bíi 900 ti gba ìtúsílẹ̀ - UNICEF Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ǹjẹ́ o mọ Yoruba daju?
Ààlà náà tún yípo lọ sí ìwọ̀ oòrùn Baala, sí apá òkè Seiri, lọ sí apá ìhà àríwá òkè Jearimu (tí a tún ń pè ní Kesaloni), ó bá tún dà gẹ̀rẹ́gẹ̀rẹ́ lọ sí Beti Ṣemeṣi títí dé ìkọjá Timna.
Oríṣun àwòrán, @Ebuka Àkọlé àwòrán, Ta ni Ebuka Obi-Uchendu tó ń gbàlejò BBNaija 2020?
Ni ṣoki ohun ti ''atunṣe'' tumọ si ni pe awọn yoo wọgile eto igbanisiṣẹ ti ijọba Fayose ṣe ati pe awọn to gba siṣẹ ni igba perete si ipari saa ijọba rẹ yoo padanu iṣẹ wọn.
Lati igba naa disin,awọn mẹtalelọgbọn lo n gba itọju ni ileewosan lori arun yi ti iroyin si sọ pe mẹfa lara wọn ti ya lẹyin tayẹwo ni ko si arun naa lara wọn mọ.
 Àwọn Ẹ ̀ gbá kò kó iyán wọn kéré wọn kò sì yé bu ọlá fún wọn bí ó tilẹ ̀ jẹ ́ pé wọ ́ n ti kú .
Má dákẹ́, ìwọ Ọlọrun tí mò ń yìn.
Ọgagun Komolafe ni ọdunrun un eeyan le mẹẹdogbọn(325) lo wẹ yan kain-kain ninu awọn igba eeyan le ni ẹgbẹrun mẹta(3,261).
Saulu mú un kúrò lọ́dọ̀ ara rẹ̀, ó fi ṣe olórí ẹgbẹrun ọmọ ogun, Dafidi sì ń darí àwọn ọmọ ogun rẹ̀.
Grace Oshiagwu: Gómìnà Makinde ké sáwọn ọlọ́pàá, àwọn lọ́balọ́ba lágbègbè Akinyele Bí Naira Marley ṣe ri ọkọ̀ òfurufú tó gbée lọ si Abuja Báwo ní Adebayo Osinowo ṣe dágbére fáyé rèé Abiyamọ ni mi sùgbọ́n mo pa òbí àwọn ọmọ ọlọ́mọ lásìkò ìpìniyàn abéle Rwanda Eeyan 5,349 lo ti ri iwosan gba, nigba ti awọn 424 ti dero ọrun nitori arun ọhun.
Ninu gbogbo ìdílé ọmọkunrin yìí, òun ni ó jẹ́ eniyan pataki jùlọ.
Ẹni tí ó bá ń gbé inú ẹ̀kọ́ Kristi mọ Baba ati Ọmọ.
Èyí ni pé àwọn tí ó gbàgbọ́ rí ibukun gbà, bí Abrahamu ti rí ibukun gbà nítorí pé ó gbàgbọ́.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù CBN gbé ọ̀nà àbáyọ dé sí owó tó dọ̀tí 1 Èbibi 2019 Àkọlé àwòrán, Ọgọrun naira owo Naijiria Ile ifowopamọ to ga ju lọ lorilẹede Naijiria ti bẹrẹ igbesẹ tuntun ti wọn yoo lo fi ko gbogbo owo idọti kuro lode.
Ṣugbọn ní tiyín, ẹ kò hùwà gẹ́gẹ́ bí àwọn tí ẹran-ara ń darí mọ́; Ẹ̀mí ló ń ṣamọ̀nà yín, bí Ẹ̀mí Ọlọrun bá ń gbé inú yín nítòótọ́.
pelu awon eniyan ni ijọba ibilẹ Abadam , ni ipinlẹ Borno .
Ṣe ni gbogbo àdúgbò dákẹ́ rọ́ọ́rọ́ báyìí, bóyá títí di ìgbà tí D'banj náà bá dé.
gbọ́ adura ati ẹ̀bẹ̀ wọn láti ibùgbé rẹ lọ́run, jà fún àwọn eniyan rẹ, kí o sì dárí ẹ̀ṣẹ̀ tí wọ́n bá ṣẹ̀ ọ́ jì wọ́n.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Unai Emery: Àwọn olólùfẹ́ Arsenal ní Emery gbọdọ̀ fipò rẹ̀ sílẹ̀ dandan 25 Bélú 2019 Oríṣun àwòrán, Twitter/Arsenal FC Ina ti jo dori koko bayii fun akọnimọọgba ẹgbẹ agbabọọlu Arsenal, Unai Emery.
Nítorí náà ni o ṣe jẹ́ kí àwọn tí ń gbé ilẹ̀ náà ṣẹgun wọn.
 nitori pe, o se e ba sise po,”  Omo odun mẹ́tàlélógún ohun ti gba boolu méjílélógójì  sagbon ninu ifesewonse mọ́kànlélọ́gọ́jọ ti o ti gba fun iko Manchester United bayii, o gba ife-eye FA ,  Europa League  ati League Cup.
Ẹ ti gbàgbé pé wọ́n lè bẹ̀rẹ̀ sí ta ọfà láti orí ògiri wọn ni?
PDP Convention 2018: ta ni yóò kojú Buhari lati ínú ẹgbẹ́ PDP?
Yatọ fun awọn ọmọ ti Funke n tọ gẹgẹ bii ọmọ tirẹ gangan, Ọlọrun fi ibeji ọmọ ọkunrin ta oun ati ọkọ rẹ lọrẹ ninu oṣu kejila ọdun 2018.
Healthline sọ pe o le da wọn mọ nipa kiki ika ọwọ to mọ si inu oju ara rẹ, ki o si pa awọn iṣan oju ara naa pọ daadaa mọ ika naa.
Oríṣun àwòrán, @Odolz Ẹ̀ẹ̀mejì ni mo pe ààrẹ Buhari lánàá lórí ìṣẹ̀lẹ̀ Lekki, àmọ́ ń kò ri bá sọ̀rọ̀ - Sanwo-Olu Sanwo-Olu tun salaye pe oun ko tii ri aaye ba aarẹ Muhammadu Buhari sọrọ lori isẹlẹ naa, titi di akoko yii.
Ikú Kofi Annan dorí àwùjọ àgbáyé kodó Wo oríṣiríṣi ìgbádun ibálòpọ̀ láwọn orílẹ̀èdè mìíràn Ọlọ́pàá SARS bíi ọgọ́fà fẹ́ sá kúrò ní Èkó Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Erelu Ọba Oṣunfunmike Ajike rèé tí wan tọrọ nídìí Ọṣun Kọmisọna naa tun gba awọn ara ilu Eko ni imọran, lati palẹ idọti wọn ninu ọdun, ki ayika wọn le mọ tonitoni, papaa julọ ki wọn o le dena ajakalẹ-arun.
Egbe oselu Oromo People Democratic Organization (OPDO) ti yan omowe Abiy Ahmed gege bi adari tuntun .
Makinde, Dele Momodu ń ṣèdárò Àgbà Oyè Ilẹ̀ Ibadan, Harry Akande tó jáde láyé Kò bá àṣà wa mu kí obìnrin máa kó ọmú síta!
Bí ìtàn ìbí Jesu Kristi ti rí nìyí.
Bẹ́ẹ̀ ni ó yẹ kí àwọn ọkọ fẹ́ràn àwọn aya wọn, bí wọ́n ti fẹ́ràn ara tiwọn.
Oba Abiodun Kola-Daisi ati Oba Hamidu Ajibade naa wa fi
 bákan náà ni wọ ́ n fún àwọn olùkọ ́ ilé-ẹ ̀ kọ ́ ọlọ ́ dún mẹ ́ fà onípele kejì ( secondary school teachers ) ní ìdáni lẹ ́ kọ ̀ ọ ́ pàá pàá jùlọ nínú ìmọ ̀ syẹ ́ nsì .
Oṣu mẹrin pere ni Joy Nunieh lo gẹgẹ bi alakoso fidihẹ fun ajọ NDDC ki wọn to yọ ọ bi jiga loṣu Keji ọdun 2020.
” Nítorí ọpọlọpọ eniyan ni wọ́n ń lọ, tí wọn ń bọ̀, tóbẹ́ẹ̀ tí kò fi sí àyè láti jẹun.
“Wọ́n sọ pé, ‘Ẹni tí ó bá kọ aya rẹ̀ sílẹ̀ níláti fún un ní ìwé ìkọ̀sílẹ̀.
Ìlẹ̀kùn kan kọjú sí ìhà àríwá, ekeji kọjú sí ìhà gúsù.
Lọdun 2015, aisan jẹjẹrẹ ọpọlọ, pa ọmọ rẹ Beau, lẹni ọdun mẹrindinlaadọta.
Oṣu mẹfa sẹyin ni ijọba ti awọn ileewe, ile ijọsin ati awọn ojuko iṣere to fi mọ sinima lọna ati dẹkun arun Coronavirus.
Loṣu to kọja lo pada sile lẹyin to lọ fun ilera ni orilẹede Belgium.
Èyí sì lo mu kí ajọ eleto ìlera lórílẹ̀-èdè naa maa rọ àwọn èèyàn kan tó ti jajabọ lọ́wọ́ àrùn Coronavirus láti wá fi ẹ̀jẹ̀ wọn silẹ, kí wọn le e dan ẹ̀jẹ̀ náà wò.
Aarẹ gbadura wi pe ki ọlọrun tẹ mama si afẹfẹ rere ki O si tun awọn ẹbi rẹ ninu.
egbe oselu naa ni ẹmi gigun , ilera to pe ati imọ lati fi sin orilẹ ede ati
Ninu atẹjade kan ti agbẹnusọ rẹ Yusuph Olaniyonu fọwọ si, Saraki ke pe ileeṣẹ aarẹ lati gbe igbimọ dide lati ṣe iwadii na.
Bí orin reggae àti dancehall ṣe ń lọ ni àwọn ìpolongo tí ó ń sọ nípa ohun gbogbo láti ọṣẹ ìfọṣọ àbùfọ̀ sí oúnjẹ àsèsílẹ̀, orin ni ènìyán lè gbà dé ọkàn ọmọ Jamaica  èyí ló mú Panos Caribbean, ẹni tí ó ní ilé iṣẹ́ ìròyìn tí kì í ṣe ti ìjọba, láti fi orin kéde nípa ọ̀rọ̀ àyíká.
Ki la tun wa ri gbọ bayii?
Wọ́n tóbi púpọ̀, ọ̀kọ̀ọ̀kan wọ́n tóbi tó màlúù dáadáa, a pa nínú wọn, gbogbo wa jẹ, Ìbẹ̀ǹbẹ́-olókùnrùn sì pa púpọ̀ jẹ nínú wọn.
Gbajugba onkọrin ni, Ukeleke Onwubuya, ti apeja rẹ n jẹ Ras Kimono ni ọpọlọpọ awọn eniyan Naijiria n ṣọfọ rẹ.
Kò ní sí ẹni tí yóo fún ẹni tí ń ṣọ̀fọ̀ ní oúnjẹ láti tù ú ninu, bẹ́ẹ̀ ni ẹnìkan kò sì ní bu omi fún ẹnìkan mu, nítorí ikú baba tabi ìyá rẹ̀.
Christmas: Ìdí rè é tí Gómìnà Sanwo-Olu ṣe buwọ́lùú kí wọn tú ẹléwòn sílẹ
Labani ní ọmọbinrin meji, èyí ẹ̀gbọ́n ń jẹ́ Lea, èyí àbúrò sì ń jẹ́ Rakẹli.
Eto ikabo ti gomina ati ile igbimo asofin  ipinle to wa lorile ede Naijiria ti bere ni pereu  nile-ikabo ajo eleto idibo lorile ede Naijiria (INEC).
"Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ademola Adeleke kí Gómìnà Oyetola kú oríire Ọmọ Nàíjíríà gba àmì ẹ̀yẹ akẹ́kọ̀ọ́ tó pegedé jùlọ ní fásitì òkè òkun Ìdí tí mo fi fẹ́ di Gómìnà Kogi - Dino Melaye ""Grandpa àti Uncle mi, ń fipá bá mi lòpọ̀ láti ọmọ ọdún mẹ́rin"" Awọn eeyan ipinlẹ Ọsun tun panupọ parọwa si gomina Oyetọla, lati jẹ ki igba rẹ tu awọn lara, ko ma si jẹ awọn osisẹ ọba lowo osu wọn."
Ọkan lara wọn tilẹ sọ pe arun Covid-19 to de lo fun wọn ni anfani lati lee sọ ohun ti oju wọn n ri lẹnu iṣẹ ọhun.
Soyinka: Buhari ti wọnu ẹmi lọ
Olórin obìnrin tí kìí ṣi ìhòhò rẹ silẹ̀- Olólúfẹ Teni Ọlọ́pàá kò rí ǹkankan lábẹ́ pẹpẹ ilé ìjọsìn mi - Olùṣọ́àgùntàn Akure Hubert Ogunde rèé, baba àwọn òsèré tíátà Ilé ẹjọ́ ní kí wọ́n lọ yẹgi f'ọmọ Ọba ìlú Eko tẹ́lẹ̀ Akọroyin BBC to wa nilu Akure nigba ti iṣẹlẹ ọhun waye jabọ pe, oun ko tii le fidi rẹ mulẹ pe wọn ri oku ọmọ naa nile ijọsin ọhun tabi bẹẹ kọ ṣugbọn wọn ko gbe oku ọmọ kankan sita ṣaaju didan sun ile ijọsin naa.
nítorí pé OLUWA ti sọ fún Mose pé, 
 Naijiria, Supreme Court ti sun idajọ eto
Nígbà tí àwọn oníṣẹ́ náà pada wá jábọ̀ fún Jakọbu, wọ́n sọ fún un pé, “A jíṣẹ́ rẹ fún Esau arakunrin rẹ, ó sì ń bọ̀ wá pàdé rẹ pẹlu irinwo (400) ọkunrin.
Eyi jẹyọ ninu atẹjade kan lati ọwọ Akọwe Apapọ fun ẹgbẹ naa, Ọmọwe Peter Ozo-Ezon.
“Si awon ololufe wa , e ri daju lati se itoju awon ohun ini wa gbogbo.
Saa ọdun 1990 yii si jẹ manigbagbe ninu itan Naijiria, to fi mọ bi wọn se wọgile ibo aarẹ ọdun 1993 ati isejọba Ọgagun Sani Abacha lọdun 1998.
Nigeria Swearing in 2019: Kà nípa gómìnà tuntun ni Kwara
Òṣìṣẹ́ àjọ FRSC méjì bọ́ sọ́wọ́ àwọn ajínigbé l'Ọsun Buhari gbóṣùbà fún D'Tigress lẹ́yìn tí wọ́n lu Senegal gba ife AfroBasketWomen Òyìnbó sísọ di èèwọ̀ ní ìpínlẹ̀ Ekiti 60,000 àwakọ ló ń lo iwé ìrinà ọ̀kọ̀ tí kò k'oju oṣùwọn ní ìpínlẹ̀ Eko - FRSC O sọrọ yii lasiko to ń bá ilé ise lroyin BBC Yorùbá sọ̀rọ̀ látàrí àwọn ọmọ àjọ náà tí owo tẹ ní ìpínlè náà.
O mọ̀ pé èmi a máa kórè níbi tí n kò fúnrúgbìn sí, ati pé èmi a máa fojú wá nǹkan níbi tí n kò fi pamọ́ sí.
o, oni je ojo ti gbogbo ọmọ Naijiria ti n reti, bẹẹ si ni awọn orilẹ-ede lagbaye
"Iléeṣẹ́ Instagram wọ́gilé App ""Augmented Reality filters"" lórí ẹ̀rọ rẹ̀ 'Àwọn ti Micra ló jẹ̀bi rògbòdìyàn awakọ̀ tó wáyé lánàá n'Ìbàdàn' Bobrisky dárò pé EFCC gbé Mompha, ọ̀dọ́mọdé olówó tó ń lo aago ₦20m Ọkọ mẹ́sàn-án tó forí-gbárí lórí afárá Otedola mú ẹ̀mí méjì lọ Hubert Ogunde rèé, baba àwọn òsèré tíátà Bakan naa wọn tun fi ẹsun pe wọn ba ọpọlọpọ ẹrọ ibanisọrọ iphone to ji lọwọ rẹ."
Iṣẹ to n ṣe nile olounjé je ki okan re fa si ẹkọ nipa ounje to fi lọ si Culinary Institute of America, nibi to ti kawe gboye jade lodun 1978.
“Ẹnikẹ́ni kò gbọdọ̀ pọ́n àlejò lójú tabi kí ó ni ín lára, nítorí pé ẹ̀yin náà ti jẹ́ àlejò rí ní ilẹ̀ Ijipti.
so pe aseyori isejoba oun ninu ise Akanse, eto Ilera, eto eko, ise agbe ati
Amọ, jẹjẹrẹ naa pada pẹlu agbara ju ti tẹlẹ lọ.
Amọ bayii ti Naijiria ti gbewuro soju South Afrika, nnkan ti yi pada ti awọn ọmọ Naijiria si ni asiko to bayi ki awọn naa ṣe idẹyẹ si sawọn ọmọ Naijiria.
Nigba ti wọn ri i pe o bẹrẹ si ni ran ka, ijọba ipinlẹ naa gbe igbesẹ kanmọ kanmọ lati tete kasẹ aisan naa nilẹ O jẹ ko di mimọ wipe ipinlẹ Ondo ni odun gbogbo teeyan nilo lati tọju awọn to ba ni aisan naa ati pe fun awọn eleto ilera, ko sewu niwọn igba ti wọn ba wọ iru ẹwu to yẹ ki wọn wọ ki wọn to fọwọ kan alaisan iba Lassa.
US presidential election 2020: Esther Agbaje, Oye Owolewa àti Nnamdi Chukwuocha jáwé olúborí nínú ìdìbò Amẹrika
Edo, Kwara àti Borno ni èèyàn mẹ́ta, nígbà ti ẹyọ kọ̀ọ̀kan jẹyọ ni Bauchi, Nasarawa àti Ondo.
Orile ede South Africa je okan lara orile
Obasanjo: Buhari ní àìlera lẹ́mìí, lára, àti lọ́kàn.
Nigba ti idibo ọdun 2019 ti wa to ti lọ, Aarẹ Buhari jawe olubori lẹẹkan sii gẹ́gẹ́ bi aarẹ Naijiria.
Mo si n rọ yin lati fọwọowọpọ pẹlu awọn agbofinro, ẹ mase gba ikọ Boko Haram laaye lati de ọdọ awọn araalu, mo si n rọ awọn ti wọn le kuro nile wọn lati pada sile.
"Ọ̀rọ̀ Aisha Buhari sí Ramaphosa wú ọ̀rọ̀ síta lẹ́nu àwọn ọmọ Nàìjíríà Kò sí àyè fún fíìmù eré ìfẹ ṣíṣe ni Kannywood mọ́ ""Àlùfàá méjì wà lára àwọn mẹ́rin tó fi ipá bámilòpọ̀"" Muiz Sanni to dagba jù ninu wọn jẹ ọmọ ọdun mẹrinla nigba ti Fawas Sanni jẹ ọmọ ọdun méwaa ti Malik Sanni to kere julọ ninu wọn jẹ ọmọ ọdun mẹjọ Ṣé ìwọ ní ìpinnu ọdún tuntun?"
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Afro Brazilians: ìlú Rio ni a máa kọ ilé ìṣẹmbáyé náà sí Oba Adeyeye nigba ti o n ba awọn ọmọ ẹgbẹ Ohaneze Ndigbo kan to ba lalejo laafin rẹ sọ pe Ile Ifẹ ni orisun Igbo ati pe ibaṣepo laarin awọn ko ṣẹṣẹ bẹrẹ.
Ó dàgbà níwájú rẹ̀ bí nǹkan ọ̀gbìn tí ó ṣẹ̀ṣẹ̀ rúwéati bíi gbòǹgbò láti inú ilẹ̀ gbígbẹ.
Àb'bẹ́ẹ̀ ríi pé ìrọ̀rùn gbáà ni?
Jeteri bí: Jefune, Pisipa, ati Ara.
Kékere àkin ní Oluwapamilerin, ọmọ ọdún mọ́kànlá to yan ìṣẹ́ bàbá rẹ̀ láàyò láti kekere, bó se ń lu omele, gángan, ìyá ìlù, bákàn náà lo n lu àpapọ̀ ìlù ìgbàlódé tí wọ́n ń pe ni (Drum Set).
------------------------------------------------------------------------------------------------------------------ Liz Anjorin Vs Toyin Abraham Oríṣun àwòrán, @trafficwaka Laipẹ yii ni ija bẹ silẹ laarin oṣerebinrin meji naa, Toyin ati Liz.
Nígbà tí ó wí báyìí tán ó tún ń bá ìyókù ọ̀rọ̀ rẹ̀ lọ, o ní, Olówó-ayé, nígbà tí mo bá ronú títí nígbà míràn, tí mo bbá ronú nípa aìnítẹ̀ẹ́lọ́rùn àwọn ọmọ aráyé, a dà bí ẹni pé ẹni kan pàtàkì ti fi àwọn aráyé ṣẹ́ èpè ni.
Nítorí ọgbẹ́ àwọn eniyan mi ni ọkàn mi ṣe gbọgbẹ́.
Bákan náà, ẹ káàánú fún àwọn ilé aláyọ̀ ninu ìlú tí ó kún fún ayọ̀,
O ni oun maa n ṣaaba lọ si Amẹrika lati kọ awọn eeyan lẹkọọ lori aṣa Yoruba ati ilẹ Afirika, bakan naa lo ni oun maa n ṣe etutu fawọn onibara oun nibẹ.
seleri pe ti ẹ ba dibo fun mi gẹgẹ bi aare orile ede yii ,maa pari oju ona to lọ
Nítorí mo mọ̀ pé ẹ ti ń ṣe onídàájọ́ ní orílẹ̀-èdè wa yìí fún ọpọlọpọ ọdún.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìtàn Mánigbàgbé: Ó pé ọdún mẹ́rìnlélàádọ̀ta tí Akintola kú, ìdí abájọ ìja rẹ̀ pẹ̀lú Awolowo rè é 15 Sẹ́rẹ́ 2020 Oríṣun àwòrán, Other Àkọlé àwòrán, Ladoke Akintola: Ó pé ọdún mẹ́rìnlélàádọ̀ta tí Akintola kú, ìdí abájọ ìja rẹ̀ pẹ̀lú Awolowo rè é Iku ogun nii pa Akikanju, iku odo nii pa omuwẹ.
Nígbà tí ó wo ojú mi, ó dùn ún, ṣìgbọ́n síbẹ̀síbẹ̀ ìfẹ́ tí ó ní sí mi kò kúrò níbẹ̀, Ó yípadà, ó dọ̀bálẹ̀ ó sì kí mi dáadáa.
Àwọn olùdíje Ọṣun jẹ́wọ́ ara wọ́n Hẹlo!
Èyí yóo ṣe àwọn tí ó bá gbọ́ ní anfaani.
Akeredolu lo fi ọrọ naa lede ninu ifọrọwerọ kan pẹlu BBC Yoruba.
Aare ni ijoba oun ko ni kaare lati tubo maa gbogun ti iwa ibaje lorile ede Naijiria.
Bí Herbert Ogunde tilẹ̀ tí dagbere faye, sibẹ, Adelaja, to jọ baba rẹ bíi imumu, sì ń di odi mu lọ lagbo ere tíátà.
Lójoojúmọ́ ni obìnrin náà máa ń wá sí ilé yìí ní àfẹ́mọ́júmọ́, ní nǹkan bí agogo márùn-ún òwúrọ̀ a máa gbé ẹrù pàṣán kọ̀ọ̀kan lọ́wọ́m ìgbà tí ó bá sì dé a bẹ̀rẹ̀ sí fi pàṣán nà mí,ìgbà tí ó bá sì tóó nà mí ní ọgọ́rùn-ún pàṣán ni yóò tóó dákẹ́.
Fulani darandaran lo iwa ipa ni guusu Akurẹ Òṣìṣẹ́ OSCOTECH gb'òmìnira lọ́wọ́ ajínigbé darandaran Fulani Ẹ̀yin tẹ́ẹ tako àgbékalẹ̀ àgọ́ Fulani, ìkórira ló ń yọ yín lẹ́nu - Ìjọba àpapọ̀ Ọmọogun pa darandaran mẹwa ni Adamawa O ni òde inawo kan ni oun lọ ni Ekiti ki oun to ko sọwọ awọn agbebọn Fulani Darandaran ti wọn n fẹmi ọpọ ṣofo.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ebola Virus: ìdí tí Ebola fi ń tàn kálẹ̀ Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Àwọn tíí ṣe ti Kristi Jesu ti kan àwọn nǹkan ti ara mọ́ agbelebu pẹlu ìfẹ́kúfẹ̀ẹ́ ati ìgbádùn ara.
orilede South Africa ti  o wa ni orilede Naijiria jẹ, boya lati fi gba ẹsan iwa ikọlu ajoji orilẹ-ede South Africa yii”Aṣofin
 wọ ́ n máa ń lò ó fún púpọ ̀ nínú àyẹ ̀ wò ojoojúmọ ́ .
Coronavirus tún ti bẹ́ gìjà sí Ghana àti Gabon Akiri ma dale si arun Corona virus tun ti se ẹ n lẹ n bẹun si wọn lorilẹede Ghana, to si tun fi ẹsẹ kan ya ki wọn nilẹ Garbon, ti gbogbo wọn wa nilẹ Afirika wa niha-hin.
"Nigba ti iṣẹlẹ naa ṣẹlẹ ti awọn ọlọpaa si bẹrẹ iwadii lai mọ pe awọn mejeeji naa wa lara awọn to ṣe ọṣẹ naa.
OLUWA tún fi ara hàn ní Ṣilo, nítorí pé níbẹ̀ ni ó ti kọ́ fi ara han Samuẹli, tí ó sì bá a sọ̀rọ̀.
Melaye ti sọ pe oun yoo gbe ẹjọ idibo naa lọ siwaju igbimọ igbẹjọ to n ri si awuyewuye to jẹyọ ninu eto idibo.
”Ẹ̀mí jẹ́rìí sí i pé, “Bẹ́ẹ̀ ni dájúdájú, nítorí wọn yóo sinmi ninu làálàá wọn, nítorí iṣẹ́ wọn yóo máa tọ̀ wọ́n lẹ́yìn.
  Nítorí èyí, ènìà ní láti fetí sílẹ̀ gidigidi kí ó máa fura bí ó ṣe nrìn lọ kí ó lè yàgò lọ́nà tí ọkọ̀ bá nbọ̀.
Wọ́n ṣẹgun Ijoni, Dani, Abeli Maimu ati gbogbo ìlú tí wọ́n kó ìṣúra pamọ́ sí ní ilẹ̀ Nafutali.
“Beeni owo dara, ere naa dara pelu sugbon imo eko lori ofin ,je ojuse lati se ni eyi ti idagbasoke yoo se de baa.
Biodun ni lyin ipade yi ni awọn yoo sọ boya iyanṣẹlodi yoo tẹsiwaju si tabi yoo dopin.
Oṣu Kẹfa ọdun 2020 ni idije La Liga gberasọ pada lẹyin ti wọn ti kọkọ da a duro nitori ajakalẹ arun Covid-19.
Kò sì ní sí ẹni tí yóo dẹ́rù bà yín.
Gbogbo àwọn ará àdúgbò ni kìí fẹ́ kí ọmọ àwọn dé sàkání rẹ̀.
Kani wipe o ti bẹrẹ isẹ lati Odun 1758, o ba ti maa gba iye owo won bayii Iye owo sẹnatọ kan losu le ra apo iresi toto 866, nigbati iye owo osu rẹ yoo ra apo irẹsi mẹta To o ba n gba ₦100,000: Yoo gba sẹnatọ ni wakati marun ati isẹju 39 lati pa iye owo to n pa losu.
Ìdájọ́ kan náà ni wọ́n dá fún un bíi tiwa.
ṣé n kò ní lè ṣe sí Jerusalẹmu ati àwọn oriṣa rẹ̀bí mo ti ṣe Samaria ati àwọn oriṣa rẹ̀?
Ẹ óo sá àsálà gba ọ̀nà pẹ̀tẹ́lẹ̀ tí ó pín òkè náà sí meji.
Oun ni yoo maa dari ẹka awọn oṣiṣẹ ọba ni Naijiria gẹgẹ bi adele.
Iyawo rẹ Ọjọgbọn Dijeh Kurawa toun pẹlu jẹ olukọ ni ẹka imọ nipa iṣiro owo ni fasiti Bayero atawọn ọmọ mẹfa lo fi silẹ saye lọ.
Gbolohun tí ó sọ fún wọn yìí kò sì yé wọn.
Ojú Ajíbógun korò, inú sì bi pé àwọn ẹ̀gbọ́n òun ti fi bàbá wọn sílẹ̀ tí wọ́n sì kó ohun ìnú rẹ̀ lọ.
December 31, 2017 si January 2, 2018: Awọn Fulani darandaran pa eniyan mẹtalelaadọrin ni Benue January 10, 2018; Eniyan 55 lo padanu ẹmi wọn ni Taraba Jan 14 2018; Eniyan 10 ni awọn Fulani darandaran pa ni ipinlẹ Kaduna February 12, 2018; Afunrasi Fulani darandaran pa agbẹ kan nilu Ipao Ekiti February 13, 2018; Awọn darandaran le awọn osisẹ ijọba kuro ni ile isẹ wọn ni Akure March 6, 2018; Fulani darandaran pa eniyan 24 ni Benue April 5, 2018; Awọn darandaran pa eniyan mẹrin ni Taraba April 12, 2018; Eniyan marun gbẹ ẹmi mi ninu ikọlu awọn darandaran si Nasarawa April 13, 2018; Oku mẹẹdọgbọn tun sun nibi isinku apapọ ni Ikọlu Plateau April 15, 2018; Darandaran tun gbẹmi mẹẹdọgbọn ni Kogi Èèyàn mẹ́wàá kú nínú ìkọ̀lù tuntun ni Benue 21 04 2018 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Àti gbogbo àwọn ẹ̀yà tí o so gbogbo orílẹ̀ èdè Nàìjíríà papọ ni èyí tí yóò je ki agbe ìgbẹ́ ayò àti àlàáfíà laarin ara wa.
Walcott pada si Southampton lẹyin ọdun mẹẹdogun to fi ẹgbẹ agbabọọlu silẹ darapọ mọ Arsenal.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Akure okada attack: Ọlọ́kadà tí àwọn afunrasí darandaran ṣá ní òun mọ ọ̀kan lára àwọn tó ṣa òun ní àdá Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Akure okada attack: Ọlọ́kadà tí àwọn afunrasí darandaran ṣá ní òun mọ ọ̀kan lára àwọn tó ṣa òun ní àdá 18 Èbibi 2020 Bi a ba n wa ọna atijẹ kiri, afi kaa yara maa gbadura ki a maa pade ohun ti yoo jẹ wa o.
O tun fẹsun kan ẹgbẹ oselu APC wi pe, wọn lo ọkọ baalu lati fi dẹruba awọn eniyan lasiko ti wọn n dibo, eleyii ti wọn ni pe, ko fun wọn laaye lati dibo pẹlu irọrun.
Olóríire ni ẹni tí ọkàn rẹ̀ kò bá dá lẹ́bi lórí nǹkan tí ó bá gbà láti ṣe.
Oo ni anfani ati pe nọmba ẹrọ ibanisọrọ kan lati fi ẹjọ banki ti ko ba gba lati parọ owo idọti rẹ fun ọ.
Ó dá wọn lóhùn pé, “Nítorí igbagbọ yín tí ó kéré ni.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, JAMB 2019: A ó fagi lé ìdànwò ẹni tó bá ṣe aṣemáṣe Ọjọgbọn naa foju ọrọ naa lede ni ọjọ Eti nibi to tun ti ṣalaye wipe ajọ naa ti ti awọn ileeṣẹ mẹrindinlọgọta to n ṣe idanwo UTME ni ajọ JAMB ti ti pa lori oriṣiriṣi ẹsun.
Wọ́n mọ odi gíga gíga yípo gbogbo àwọn ìlú ọ̀hún, olukuluku wọ́n sì ní odi tí ó ga ati ẹnubodè pẹlu ọ̀pá ìdábùú, láìka ọpọlọpọ àwọn ìlú kéékèèké tí kò ní odi.
Ayé àwọn eniyan burúkú nìwọ̀nyí;ara dẹ̀ wọ́n nígbà gbogbo, ọrọ̀ wọn sì ń pọ̀ sí i.
ina-monomono lorile ede Naijiiria, pe ki won pase fun ile ise amunawa niluu Eko
to jẹ olori ẹka idajọ lapa ariwa ẹkun Georgia sọ ninu atẹjade naa pe Onyema lo ipo rẹ gẹgẹ bi gbajugbaja oniṣowo ati oludasilẹ ile iṣẹ Air Peace lati lu jibiti pẹlu ayederu iwe.
Orúkọ wọn ni: Efi, Rekemu, Suri, Huri ati Reba.
Bí mo bá sọ pé n óo fa orílẹ̀-èdè kan, tabi ìjọba kan tu, n óo wó o lulẹ̀, n óo sì pa á run, 
Joseph Parker, omo orile-ede  New Zealand ti soro pelu igboya saaju ifigagbaga heavyweight title pelu Anthony Joshua, eyi ti yoo waye lojo ketalelogbon osu keta odun ti a wa yii.
Leyin ogun abele to sele ni, ila-oorun Somalia yapa lati orile ede naa , ti o si kede  lati di ominira gege bi  orile ede tire .
Làásìgbò nínú òṣèlú Burundi le sí i ní ọdún 2015 lẹ́yìn tí ààrẹ́ kéde èròńgbàa rẹ̀ láti lọ fún sáà kẹ́ta.
Ara kan wọ́n báyìí, wọn yóo sì rorò ju abo ẹkùn beari tí ọdẹ jí lọ́mọ kó lọ.
O ni ẹgbẹrun meji naira si ẹgbẹrun marun naira ni awọn ti wọn ba fi jẹ oye ni ilu Ibadan ma n san, amọ awọn n gbọ pe Olubadan n ta oye fun awọn eniyan ni ọgbọn miliọnu naira.
Mo sì lee rántí pé Baba mi jẹ́ èèyàn rere, kò si ẹni ti kii se oore fún, kò si mọ bá ṣe ń kọ láti ṣe nkan fún èèyàn, tí onitọun bá nílò iranlọwọ."
Awọn iroyin ti ẹ le nifẹ si Lẹ́yìn ọdún mẹ́ta l'ẹ̀wọ̀n akọrin ẹ̀mi gbẹ̀mí ará rẹ̀ látìmọ́lé Ìjọba Ọṣun ti dásí ìjà láàrin Oluwo àti Agbowu 'Mi ò fẹ́ gbé àrùn Coronavirus lọ sí Áfíríkà' Ilé ìgbìmọ̀ aṣofin ti bẹ̀rẹ̀ òfin tí yóò máa mú àwọn olùkọ́ fásitì tó ń bèrè fún ìbálòpọ̀ Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 3 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 5 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
56 Ṣùgbọ́n àwọn ẹnití kò bẹ̀rù mi, tàbí pa àwọn òfin mi mọ́ ṣùgbọ́n tí wọn kọ́ àwọn ìjọ fún ara wọn fún èrè jíjẹ, bẹ́ẹ̀ni, àti gbogbo àwọn wọ̃nnì tí wọn nṣe búburú tí wọn ngbé ìjọba èṣù ró—bẹ́ẹ̀ni, lõtọ́, lõtọ́, ni mo wí fún ọ, pé àwọn ni èmi yíò dí lọ́wọ́, èmi yíó mú kí wọn ó wárìrì àti wọn yíò sì gbọ̀n dé ààrin gbùngbùn.
Wọn ti wa sun ijoko ile di Ọjọ Kẹrin,Osu Keji, ọdun to n bọ.
Gẹgẹbi iroyin ṣe sọ, opopona Eruwa si Igboọra lagbegbe Ibarapa nipinlẹ Ọyọ.
Ọwọ Ọlọpàá ti tẹ ilé ìfìyà jẹni tí wọ́n fi ń pe ilé kéú ní Katsina Funke Adesiyan, òṣèré Yollywood tó di olùrànlọ́wọ́ aya ààrẹ, Aisha Buhari Àgungùnlá!
11 Ìgbé 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 12 Ìgbé 2019 Oríṣun àwòrán, Google Àkọlé àwòrán, Ogúnjọ́, Osu Kini, ọdún tó kọjá ni ilé ẹjọ́ gíga nípínlẹ̀ Ọyọ ní gomina Ajimobi kó lásẹ láti yan ọba.
Mo kọ ìwé kan sí ìjọ ṣugbọn Diotirefe tí ó fẹ́ ipò aṣiwaju láàrin ìjọ kò gba ohun tí mo sọ.
2019 Elections: Ìpàdé ìtagbangba BBC Yorùba ń ṣẹlẹ̀ ní gbọ̀ngàn fásitì ìlú Ilorin
kí ó lè fi ìdí yín múlẹ̀ bí eniyan rẹ̀, kí ó sì máa jẹ́ Ọlọrun yín; gẹ́gẹ́ bí ó ti ṣèlérí fun yín, ati bí ó ti búra fún Abrahamu, Isaaki, ati Jakọbu àwọn baba ńlá yín.
Ogunyemi kede pe UTAS ti wa nilẹ lasiko apero kan to waye nilu Abuja, bakan naa lo pe aarẹ Muhammadu Buhari lati da si rogbodiyan to n lọ ni fasiti Eko (UNILAG), ko si se agbekalẹ igbimọ olubẹwo si ile iwe naa.
baba Sabadi, baba Ṣutela, Eseri, ati Eleadi; Eseri ati Eleadi yìí ni àwọn ará ìlú Gati pa nígbà tí wọ́n lọ kó ẹran ọ̀sìn àwọn ará Gati.
Ọpọ eekan ilu nilẹ Ibadan, nipinlẹ Ọyọ ati nilẹ Yoruba lo peju sibi ẹyẹ ikẹyin ti wọn se fun Oloye Aminat Abiọdun.
Fún ẹbọ ohun jíjẹ, yóo tọ́jú ìwọ̀n eefa ọkà kan fún akọ mààlúù kọ̀ọ̀kan, ati eefa ọkà kan fún àgbò kọ̀ọ̀kan ati ìwọ̀n ọkà tí ó bá ti lágbára fún àwọn àgbò, yóo fi hini òróró kọ̀ọ̀kan ti eefa ọkà kọ̀ọ̀kan.
Arabinrin kan ti wọn mu sọ wipe, ọmọ oun tẹle oun wa nitori naa, ki wọn jẹ ki oun gbe ọmọ lọwọ lọ agọ wọn lẹyin ti ọwọ ba a tan.
Daddy mi lo sọ wi pe ko buru'' Laarin awọn akẹgbẹ rẹ, Sekinat jẹ ọmọ to fi ọkan si ẹṣẹ jija ti ọrọ rẹ a si ma ya olukọni rẹ lẹnu.
 apa kinni dalelori iforukosile awon amioro leta meji .
Ahieseri ọmọ Amiṣadai ni yóo jẹ́ olórí láti inú ẹ̀yà Dani.
Ṣugbọn, o ni o ṣe e ṣe ki ileeṣẹ DisCos o ma a pese ina fun awon to le sanwo rẹ nìkan.
Eleyii  jẹ  idanloju pe, atunse to monyan lori yoo wa fun ajo eleto aabo yii  laipẹ yii…A ki awọn   igbimọ  tuntun naa pe isẹ yii ko ni  jẹ  inira fun   wọn.
awon eniyan agbegbe Kishi lati jawo ninu ise ti ko ba ofin mu ati ipinnu won
Solomoni ṣe àjọyọ̀ yìí fún ọjọ́ meje gbáko, ogunlọ́gọ̀ àwọn ọmọ Israẹli wà pẹlu rẹ̀, eniyan pọ̀ lọ bí eṣú, láti ẹnu bodè Hamati títí dé odò Ijipti.
ẹnikẹ́ni tí ó bá sì fẹ́ jẹ́ aṣaaju ninu yín níláti máa ṣe ẹrú gbogbo yín.
Ìdájọ́ m bọ̀ fún ọ̀rẹ́kùnrin Khadijat Oluboyo Obìnrin míì tún ti kú lórí ìṣẹ́ abẹ ìdí ńlá Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ẹ wo àrà tí ẹ le fi gèlè dá láàrín ìṣẹ́jú mẹ́ta Akeredolu to kẹdun pẹlu ẹbi ati ara ọmọbinrin to doloogbe naa ni oun yoo ri daju wi pe awọn to sekupa ọmọbinrin naa ko lọ lai fi oju wina ofin.
4m fagbábọ́ọ̀lù Super Eagles 8 Agẹmo 2019 Oríṣun àwòrán, @jidesanwoolu Àkọlé àwòrán, Ẹ yé irọ́ pa, mí o fún Super Eagles ní ẹbùn owó kánkan -Sanwo Olu ''Orukọ Sanwo Olu maa n ta iroyin daadaa; amọ, lori eleyi ti wọn gbe wi pe mo san owo ẹbun fawọn Super Eagles, irọ pọnbele ni'' Idahun re e ti Gomina ipinlẹ Eko fọ lori ọrọ to n ja ranyin-ranyin pe o ta agbabọọlu kọọkan lara ikọ Super Eagles Naijiria lọrẹ ẹgbẹrun marun un dọla.
Ní alẹ́ ọjọ́ kan, ó sùn lé ọmọ tirẹ̀ mọ́lẹ̀, ọmọ tirẹ̀ bá kú.
Wọn kò tíì ní òye ọ̀nà tí Ọlọrun fi ń dáni láre, nítorí náà wọ́n wá ọ̀nà ti ara wọn, wọn kò sì fi ara wọn sábẹ́ ètò tí Ọlọrun ṣe fún ìdániláre.
Janga  ti ni ile-ise agbofinro ti gbaradi
Ikolu ibugbamu ado oloro ti o waye lolu ilu Afghan ti n se Kabul, ti seku pa eniyan marundinlogbon.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Akọroyin ọmọ Saudi Jamal Khashoggi ni wọn pa ni oṣu kẹjọ ọdun 2018 A ti n yọ okuta idena to wa niwaju wa diẹdiẹ bayii.
Godson mẹnuba iwaasu Baba Adeboye ti ijọ RCCG to fi sọrọ lori ibalopọ awọn olukọ ni fasiti lasiko to yi n ṣiṣẹ olukọ.
O gba awọn awakọ nimoran lati máa ṣọra ṣe loju popo.
Adele aare Esmon Saimon  lo dari ayeye naa , to waye nile aare Vanuatu.
Meghan ti sọ fun awọn ololufẹ nigba to ṣabẹwo si agbegbe Merseyside pe awọn ko tii mọ boya akọ tabi abo lọmọ to wa ninu oun.
Àwọn jàndùkú ṣọṣẹ́ nílé aṣòfin ìpínlẹ̀ Ogun, ọ̀pá aṣẹ dàwátì!
Ṣé mo sọ níjọ́sí pé ìfẹ́ àfẹ́jù tí ń bẹ láàrin ọmọ ènìyàn àti ṣúgà bímọ.
Nítorí ohun tí OLUWA sọ nípa àwọn ọmọkunrin ati àwọn ọmọbinrin tí a bí ní ibí yìí, ati nípa ìyá tí ó bí wọn, ati baba tí a bí wọn fún ni pé, 
“Òfin tí ó jẹmọ́ ti ọjọ́ ìwẹ̀nùmọ́ adẹ́tẹ̀ nìyí: kí wọ́n mú adẹ́tẹ̀ náà wá sí ọ̀dọ̀ alufaa.
Àpérò àwọn àjẹ́ kò gbọdọ̀ wáyé - Àjọ PFN Pasuma kìí ṣe ọkọ mi o!
Iwadii n lo lowo lori oro to nii se pelu awon adunkoko-moni, awon agbani-pa ati awon ti won n gbiyanju ati pani.
Bakan naa, gomina ipinle Osun, Rauf Aragbesola, gomina ipinle Ondo, Rotimi Akeredolu, ati gomina ipinle Oyo, Abiola Ajimobi.
"Olorì àgbà mẹ́rin tó jẹ́ igi lẹ́yìn ọgbà fún Aláàfin Adeyemi Ohun tí o kò mọ̀ nípa Ebila ""One Million Boys"" àti Ekugbemi, olórí ẹgbẹ́ òkùnkùn méjì tó da ìlú Ibadan rú Sotitobire: Kò sí èléyìí tó kàn mí nípa ìjínígbé Gold Kolawole!"
5m) ko to di ojo karundinlogbon osu kerin odun yii, ki ajo to n mojuto irinajo lo si Hajj lorile ede Naijiria  to kede iye awon arinrinajo to n lo lodun yii.
Ọmọ Yahoo fẹ́ pa ìyá rẹ̀ ṣ'owó l'Eko Òbí tó n fa sìgá n fi ọmọ rẹ̀ sínú ìdè àìsàn l'ọ́jọ́ iwájú Ninu ọrọ rẹ pẹlu BBC News Yoruba, agbẹnusọ fun ẹgbẹ Afẹnifẹre, Alagba Yinka Odumakin ṣalaye pe Yoruba ko sọ pe gbogbo Fulani lo n gbẹmi awọn eeyan nilẹ Yoruba.
ng Àkọlé àwòrán, Awọn oṣiṣẹ ẹlẹwọn gbe ibeji lọ́wọ́ Ẹlẹ́wọ̀n obinrin kan ni ọgba ẹwọn Calabar, ipinlẹ Cross River ti bi ibeji lanti lanti, ọkunrin kan, obinrin kan.
 Ó jọ pé àjẹsára náà máa n ṣiṣẹ ́ lára títí láí ni .
Olè wọ ilégbèé obìnrin ní fásitì Ibadan, àkẹ́kọ̀ọ́ méjì farapa Ọkùnrin mẹrin wọ gàù torí ìgbéyàwó orí Facebook Ìgbín ní èmi àti ìyá mi máa ń he kiri, ká tó lee jẹun - Lizzy Anjọrin Ni ọdun 2018 ni wahala lori wiwọ ibori Hijab bẹrẹ ni ileewe girama ISI ni fasiti ilu Ibadan, eleyi ti o tilẹ ti de ile ẹjọ pada.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'A ò tíì rí omi mu, ẹ ní ká máa fọwọ́ tóríi Coronavirus' Wò àpapọ̀ àwọn tó ti ní ibalopo lórí ètò BBNaija to ń lọ lọ́wọ́ Oríṣun àwòrán, @BBNaija/twitter Ariwo Erica ati Kiddwaya ni awọn eeyan tun n pa lori ayelujara bayii.
” Debora bá gbéra, ó bá Baraki lọ sí Kedeṣi.
N óo fi èyí dán wọn wò, kí n fi mọ̀ bóyá wọn yóo máa tẹ̀lé òfin mi tabi wọn kò ní tẹ̀lé e.
Wọ́n bá rán ọkunrin meji lọ sibẹ, kí wọ́n lọ bẹ̀ ẹ́ pé kí ó má jáfara kí ó yára wá sọ́dọ̀ wọn.
Lati igba to ti jade ni awọn eeyan ti n gabdun rẹ ti wọn ti n foju sọna fun apa keji.
O ni lootọ araalu lẹtọ lati wọde ki wọn si fi ẹhonu wọn han gẹgẹ bi iwe ofin Naijiria ṣe laa kalẹ, Amọṣa ofin naa jẹ ko di mimọ pe ko si araalu ti iwe ofin fun laaye lati fi erongba ti fi ẹhonu rẹ han fi di araalu miran lọwọ.
Laasigbo ohun, ti o seku pa eniyan meta, bere nigba ti awon ologun fipa gbajoba lowo Aare Mohamed Mursi ti o je omo egbe Brotherhood lorile-ede Egypt.
Àwọn ọdaràn mẹ́tẹ̀ẹ̀ta dí èrò ẹwọ́n lẹ̀yìn ti wọ́n fẹsun kan wọ́n pe, wọ́n ji igi gẹdu gbé, èyí ti owó rẹ̀ tó ẹgbẹ̀rún lọ́nà ọgọ́run náírà.
Àwọn tí wọ́n wá ṣe ìrúbọ yóo máa se ẹran ẹbọ wọn ninu ìkòkò wọnyi.
OLUWA nìkan ṣoṣo ni ó ṣáájú àwọn eniyan rẹ̀,láìsí ìrànlọ́wọ́ oriṣa kankan.
Dafidi ti wí pé, “Ṣé lásán ni mo dáàbò bo agbo ẹran Nabali ninu aṣálẹ̀, tí kò sí ohun ìní rẹ̀ kan tí ó sọnù.
“Ẹ máa ranti láti máa ṣe àjọ̀dún àjọ ìrékọjá fún OLUWA Ọlọrun yín ninu oṣù Abibu nítorí ninu oṣù Abibu ni ó kó yín jáde ní ilẹ̀ Ijipti, lálẹ́.
Gbọ́ ìtàn bí ikọ̀ SARS ṣe dà bó ṣe dà láti ẹnu Ọ̀gá ọlọ́pàá tó dá SARS sílẹ̀ Lọjọbo to kọja ni aarẹ Buhari tẹ abadofin naa siwaju ile aṣofin.
Bí ìgbà tí ẹni tí ebi ń pa bá lá àlá pé òun ń jẹun,tí ó jí, tí ó rí i pé ebi sì tún pa òun,tabi tí ẹni tí òùngbẹ ń gbẹ́ lá àlápé òun ń mu omiṣugbọn tí ó jí, tí ó rí i pé òùngbẹ ṣì ń gbẹ òun,bẹ́ẹ̀ ni yóo rí fún ogunlọ́gọ̀ orílẹ̀-èdè tí ń bá Jerusalẹmu jà.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ọmọ Aarẹ Buhari pada de lẹyin itọju nilẹ okeere 1 Ẹrẹ̀nà 2018 Oríṣun àwòrán, @aishambuhari Àkọlé àwòrán, Yusuf ko gba itọju ni Naijiria ki wọn to gbe lo ile okere Ọmọ Aarẹ orilẹẹde Naijiria, Yusuf Buhari, ti pada de lati ilẹ okeere nibi ti o ti'n gba itọju.
Lẹ́hìn èyí ọkùnrin náà bẹ̀rẹ̀ mú ìtàn ara rẹ̀ ó ń sọ ọ́, ó ní: ju ẹ̀sín fún mi.
Irú ẹ̀ṣẹ̀ wo ni mo ṣẹ̀ ọ́ tí o fi ti ẹ̀ṣẹ̀ ńlá yìí sí èmi ati ìjọba mi lọ́rùn?
Three sports judges in Switzerland have taken more than two months to reach this verdict - indicating the sensitivity and complexity of the case.
 Ó wà lára àwọn èdè ti ìjọba ń lò níbẹ ̀ .
Emefiele maa tesiwaju gege bi adari ile ifowopamo  ọhun.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Coronavirus in Nigeria: Àwọn ìpéjọpọ̀ ṣọ́ọ́ṣì àti ayẹyẹ nlá tí kò ní wáyé nítorí coronavirus 20 Ẹrẹ̀nà 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 23 Ẹrẹ̀nà 2020 Oríṣun àwòrán, Twitter/rccg Lẹyin ti ajọ eleto ilera agabye WHO ti kede arun Coronavirus gẹgẹ bi ajakalẹ arun, ọpọ awọn apero, ipade ati awọn ayẹyẹ miran to yẹ ko waye ni wọn ti gbe ṣegbẹ kan.
Yoo si lo ọgbọn inu rẹ lati da isọkan pada si orilẹ-ede Malawi.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Buhari: Ẹ̀yin òṣìṣẹ́ aláàbò, ẹ ṣe ohun tó yẹ láti pèsè ààbò tó péye 28 Èbibi 2019 Oríṣun àwòrán, Google Àkọlé àwòrán, Adari awọn ologun oju omi ni aarẹ Buhari ti gbe igbimọ kalẹ ti yoo ma risi oro eto aabo to mehe lorilẹede Naijiria.
Ninu atẹjade kan to fi sita ni ajọ naa ti sọ wi pe, itanjẹ ni awọn oniroyin kan n gbe kaakiri ninu iroyin wọn pe ajọ naa n gba awọn eeyan si iṣẹ.
N óo pa gbogbo ẹran ọ̀sìn Ijipti tí ó wà ní etí odò run.
Ta sì ni àpáta ààbò bí kò ṣe Ọlọrun wa?
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Coronavirus guidelines: Kí ló ń mú àwọn adarí obìnrin lágbáyé rọwọmú nípa kíkojú covid 19?
“Ẹ ṣọ́ra yín, kí ẹ má jẹ́ kí ayẹyẹ, tabi ìfiṣòfò, tabi ọtí mímu, ati àníyàn ayé gba ọkàn yín, tí ó fi jẹ́ pé lójijì ni ọjọ́ náà yóo dé ba yín bí ìgbà tí tàkúté bá mú ẹran.
Wọn kò ní jẹ́ kí wọ́n sin wọ́n.
Ẹlòmíràn ninu àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ sọ fún un pé, “Alàgbà, jẹ́ kí n kọ́ lọ sìnkú baba mi.
Pásítọ̀ ìjọ Redeem, Ọ́mọ́ọ́ba kan l'Eko ati èèyàn mẹ́ta míì rèé to ti gba ìdájọ́ ikú rí Sise idajọ iku fawọn ti ile ẹjọ ba fi idi ẹri mulẹ pe wọn ṣeku pa eeyan akẹẹgbẹ wọn, kii ṣe nkan tuntun.
Ninu ayẹwo ileesẹ ologun lo ti farahan pe, Ọgagun kan, AP Ubah ati awọn ọlọpaa mẹta; DSP Oyoku Ifelle, Inspẹkitọ Hycent Oboi ati Sajẹnti Nketan Chuks ati Akanu Garba, gba owo ẹyin lọwọ awọn oluranlọwọ Gomina Wike.
Commission, INEC) lorile ede Naijiria ti so pe iran oju alla lasan ni egbe PDP
Miyetti Allah ní kí wọn wọ́gilé Amotekun, Sunday Igboho yarí Ìfẹ́ Yorùbá ló mú mi fi ẹ̀mí wéwu láti kojú ajínigbé ní Kishi - Sunday Igboho Sunday Igboho yarí, ó fohùn ránsẹ́ sáwọn èèyàn tó ń pẹ̀gàn rẹ̀ Sunday Igboho kàn ń gbé ‘Camera’ lẹ́yìn kiri, kí wọ̀n lè rò pé ó ń jà fún Yorùbá - Gani Adams Ìlànà ‘Referendum’ nìkan la fi le gba orílẹ̀èdè Oduduwa, kìí ṣe ìwọ́de Igboho, to tun jẹ alaga ayẹyẹ naa, sọrọ nipa idasilẹ awọn eto idagbasoke to jẹ tilẹ Kaarọ Oojire.
 géńdé ti ko ba dara rẹ loju ko le gbe nìlẹ .
Ó wá mú Peteru, Jakọbu ati Johanu pẹlu rẹ̀.
A ní àwọn èèyàn bi tirẹ, sùgbọ́n wọ́n o gbé Nàìjíríà.
Nigba ti o n fi oju ọrọ naa lede, Minisita fun eto isuna, Kemi Adeosun sọ pe, ọjọ kẹrin osu kẹfa ni ofin yii yoo gbera sọ, idi eyi ni lati fun awọn ileesẹ tọ'rọ ọun kan ni anfaani osu mẹta lati gbaradi fun aleekun ọun.
Bakan naa ni awọn bii Aliyu ti wọn wa kirun naa gba awọn ọmọ Naijiria nimọran lati ma gba gbogbo nkan ti wọn ba ka lori ayelujara gbọ nitori irọ pọ nibẹ.
Ẹ óo na àwọn mìíràn ninu wọn ní ilé ìpàdé yín, ẹ óo sì máa lépa wọn láti ìlú dé ìlú.
Asaraya tún ìlú Elati kọ́, ó sì dá a pada fún Juda lẹ́yìn ikú baba rẹ̀.
O tun tesiwaju lati gboriyin fun ajo isokan agbaye(UN-OCHA) fun ibasepo won pelu ile-ise omo ogun, papaajulo fun pipese awon ohun elo idanileko lasiko idanileko naa.
N30,000 ni mo gbà fún orí, ọwọ́ àti ẹran ara wòlíì Bosede - Kayeefi Ẹ kọ́ nípa ohun tí Yorùbá ń pè ní Àrígiṣẹ́gi Wọ́n ta ère Ọ̀ṣun Osogbo sí Togo - Bàbá Ọṣun figbe ta Baṣọ̀run Gáà, tó yan ọba mẹ́rin, pa ọba mẹ́rin àmọ́ ọba karùn-ún ló pa á Asiko yii ni awọn oluwọde naa to mọ isẹlẹ yii lọran, ti wọn si yan lai duro gba ọbẹ.
 túmọ ̀ sí pé orísìí àyísódì méjì ni a máa gbé yèwò .
imo sayensi, imo ero igbalode lati le je ki orile ede Naijiria ni idagbasoke.
Bakan naa ni wọn ibugbamu naa la ọna naa si meji, to fi mọ ile ijọsin ni agbeegbe naa.
Lẹyin rẹ, awọn oludari ati iranṣẹ Ọlọrun mejidinlogoji lo tun wa lẹyin rẹ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ka nípa ọ̀nà tí agogo inú ara rẹ ń gbà ṣiṣẹ́ 19 Ọ̀wàrà 2018 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Gbéra kí o tàn - ọjọ́ tuntun wà ní iwájú re Ǹjẹ́ o mọ̀ pẹ́ gbogbo ńǹkan abẹ̀mí lo ní agogo ara, láti orí kòkòrò àf'ojúrí (fungi) sí ènìyàn?
Anfaani ile-ise naa “Afojusun wa ki i se, eni ti o ba jare nile ejo, bi ki I baa se bi eka ile-ise ohun yoo se maa mojuto pipese eto igbafe, eto irinna ati awon ohun mere-mere miiran ti awon eniyan yoo maa je anfaani re.
"Amẹ́rika dá akẹ́kọ̀ọ́ padá nítori Facebook Àkọlé àwòrán, Bobrisky fún ọ̀gá Arts & Culture lésì, ó ni àwọn ọgá rẹ̀ ló ń ba ṣe Nínú èsì rẹ̀ tó fi léde lójú òpo Instagram, Bobrisky ní "" mo gbọ́ pé ẹnikan nínú ìjọba sọ̀rọ̀ nípa mí láìpẹ́ yìí."
Ìdí nìyí tí wọ́n fi sọ ibẹ̀ ní Helikati-hasurimu.
Gẹgẹ bi iroyin to n lọ labẹle, awọn oṣiṣẹ alaabo to to ẹgbẹrun mẹẹdogun ni yoo ṣiṣẹ ni awọn ilu mẹrẹẹrin ti idije naa yoo ti waye; Cairo, Alexandria, Suez ati Ismailia.
ó kó àwọn ìbátan rẹ̀, ó sì tọpa rẹ̀ fún ọjọ́ meje, ó bá a ní agbègbè olókè Gileadi.
Ìgbà yí padà fún ẹ̀yà Yorùbá nígbà ayé ọba Arólẹ̀ àti ààrẹ ọ̀nà kakanfò Àfọ̀njá.
Bí ẹ ti ń súnmọ́ wájú,bẹ́ẹ̀ ni ó ń lé àwọn ọ̀tá yín jáde,tí ó sì ní kí ẹ máa pa wọ́n run.
"Florence Ajimobi tahùn sí igbákeji gómìnà Oyo lórí ikú ọkọ rẹ̀, ""Gbogbo wa làó kú"" Àjọ NCDC kéde ènìyàn 490 tó tún ṣẹ̀ṣẹ̀ ní Coronavirus ní Nàìjíríà Ilé ìfowópámọ́ Access ti gbà láti dá owó àwọn oníbàráà wọ́n padà Ẹ wo àwòrán bí ìsìnkú Abiola Ajimobi ṣe lọ!"
Lẹyin iṣẹju mẹta pere ti wọn bẹrẹ ere bọọlu ọhun ni ẹlẹsẹ ayo, Odion Ighalo gba bọọlu sawọn eyi fun Naijiria lanfani lati siwaju ninu ifẹsẹwọnsẹ to kangun su aṣekagba.
“Nígbà tí ibìkan bá lé lára eniyan, tabi tí ara eniyan bá wú tí ọ̀gangan ibẹ̀ sì ń dán, tí ó bá jọ ẹ̀tẹ̀ ní ara rẹ̀, kí wọ́n mú olúwarẹ̀ tọ Aaroni, alufaa wá; tabi kí wọ́n mú un wá sí ọ̀dọ̀ ọ̀kan ninu àwọn ọmọ Aaroni, tí ó jẹ́ alufaa.
Olùkọ́ fẹgba lu akẹ́kọ́ọ̀bìnrin ọmọ ọdún mẹ́rìnlá pa ní yàrá ìkàwé Àwọn ọkùnrin tó wà nínú ayé wa gbúdọ̀ bọ̀wọ̀ fún wa - Olùdásílẹ̀ FIN Mo bí ìyá mi padà lẹ́yìn tó yọ sí mi lójú oorun- Iya Yetunde Ọmọ Nàìjíríà ló lè sọ bó yá ìdájọ́ òdodo nilé ẹjọ́ dá- Atiku Abubakar Wo orílẹ́èdè tí wọ́n tí ń dáwó ìsìnkú ara wọn pámọ́ Ilẹ iroyin ESPN tiẹ sọ pe Mourinho ṣetan lati ṣe akọnimọọgba ikọ Arsenal ti wọn ti fọwọ osi juwe ile fun Unai Emery.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù June 12: Ère tuntun tí Ìpínlẹ̀ Eko mọ fún MKO Abiola 12 Òkùdu 2018 Oríṣun àwòrán, Lagos State Government Àkọlé àwòrán, Ere Abiola náà rọ́pò èyí tó wà níbẹ̀ tẹ́lẹ̀ Gómínà Ìpínlẹ̀ Eko, Akinwunmi Ambode ti ṣí ère olóògbé Moshood Abiola tuntun, èyí tíí se ára àwọn ètò tí wọ́n fi ṣe ayẹyẹ àyájọ́ ọjọ́ June 12.
Báyìí ni ìtàn kejì ṣe lọ:
Àkókò ìwòsàn ni à ń retí,ṣugbọn ìpayà ni a rí.
Oríṣun àwòrán, EFCC Wayio, ajọ EFCC ti sọ agadagodo si ẹnu ọna ileẹkọ Yahoo naa, to si ti fi ọda pupa kọ akọle si ara ile naa pe ẹnikẹni ko gbọdọ sun mọ ibẹ.
Wọ́n wí fún obinrin náà pé, “Kì í ṣe nítorí ohun tí o sọ ni a fi gbàgbọ́, nítorí àwa fúnra wa ti gbọ́ ọ̀rọ̀ rẹ̀, a wá mọ̀ nítòótọ́ pé òun ni Olùgbàlà aráyé.
Anunobi ni won seto yii nipato lati fi ta awon eniyan ji lori itoju to ye ki won maa se fun kindinrin won ni eyi to san ju itoju aisan re peluowo goboi nile yii ati nile okeere.
Báyìí ni àwọn ọmọ-ọ̀dọ̀ wọ̀nyí bẹ̀rẹ̀ si sọ láìmọ̀ pè gbogbo ọ̀rọ̀ tí wọ́n ń sọ bẹ ni àtẹ́lẹwọ́ mi.
Manase fẹ́ obinrin kan, ará Aramea; ọmọ meji ni obinrin náà bí fún un; Asirieli, ati Makiri, baba Gileadi.
Adele akọwe ipolongo ẹgbẹ oṣelu APC, Ọgbẹni Yekini Nabena, ninu ikede kan to fi sita ni irọ patapata ni pe alaga apapọ fun ẹgbẹ APC, Adams Oshiomole lo wa ni idi rogbodiyan to waye naa.
OLUWA ń ṣọ́ àwọn olódodo,Ó sì ń dẹ etí sí igbe wọn.
iroyin tun so pe, won ni ki aare ana naa maa se wa si orile ede Amerika nitori iwa ibaje to hu lasiko ijoba re.
the Ẹ ̀ ni tí ó bá dá ojú ewé lè má lè yọ àdàkọ píparẹ ́ láìrosẹ ̀ kúrò ní ojú ewé tí wọ ́ n bá kọ .
Wọ́n ń fi ìyìn fún Ọlọrun.
Nítorí pé Ọlọrun tí ó tóbi ni OLUWA,ọba tí ó tóbi ni, ó ju gbogbo oriṣa lọ.
1 6633 Orilẹede Gambia 123 5.
Inu igo ọti ẹlẹrindodo ni awọn mii a rọ ọ si ti ẹ o ni mọ Koda awọn ileeṣẹ to ni ontẹ ijọba lo n ta a.
Iranṣẹ tí ó ṣe é gbẹ́kẹ̀lé ni ati ẹrú bí àwa náà ninu iṣẹ́ Oluwa.
Ó ṣeéṣe kí ènìyàn fàá gùn, raá ródóródó tàbi ṣeé ní bíbọ̀ kí a tún ṣe àdàlú rẹ̀ pẹ̀lú àwọn èròjà odò bíí edé, ẹja, akàn, ó tún lé jẹ́ wàá sá kí wọn si maa tàá nínú abọ.
Àkọlé àwòrán, Onidajọ to n gbọ ẹjọ naa ni ọgba ẹwọn ikoyi ni Fayoṣe yoo wa titi ti yoo fi mu awọn ilana beeli rẹ ọhun ṣẹ Onidajọ Ọlatoregun to n gbọ ẹjọ naa ninu idajọ to gbe kalẹ lori boya ki wọn gba beeli rẹ tabi rara, ni ile ẹjọ naa yoo faye silẹ fun un gbigba oniduro rẹ bi o ba ti lee mu awọn ilana ti ile ẹjọ la kalẹ fun beeli rẹ ṣẹ.
Àkọlé àwòrán, EFCC ń pe Fayoṣe lẹ́jọ́ lórí ẹ̀sùn ìkówójẹ oní biliọ̀nù méje dọ́la ó lé Obanikoro ni ajọṣepọ to dan mọran to wa laarin oun ati Fayoṣe, ko ni lee jẹ ki oun ko tu ọpọlọpọ aṣiri ohun to waye laarin awọn.
”Bi a ko ba gbagbe wipe, aare Buhari yan Mohammed
Bakan naa lo fikun pe, Fayose ko le wọ aarin ero ni Eko bi, sebi se lo gbe oku baba rẹ pamọ fun ọdun kan, eyi to fihan pe kii se ọmọ gidi.
“Mo kórìíra ìkọ̀sílẹ̀ láàrin tọkọtaya, mo kórìíra irú ìwà ìkà bẹ́ẹ̀ sí olólùfẹ́ ẹni.
K Odukoya 'ń gun orí òkè àdúrà nítorí COVID-19'-Wò báwọn èèyàn fi wò wọ́n
Sùgbọ́n látì ìgbà tí ààrùn Coronavirus ti bẹ̀rẹ̀ ni ìjọba ìpínlẹ̀ Oyo ti paa lásẹ pé kò ni sí ipejọpọ̀ elérò, yálà fún ayẹyẹ, iṣílé, ìkọ́mọ jáde àti ìgbéyàwọ.
O jẹ ẹni ti o maa n sowo ilẹ ati ile, o si maa n ko awọn ọja rẹ si inu ile Shoprite kaakiri ilẹ Afrika.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Gbogbo olùdíje Ogun fi dá àwọn ènìyàn lójú pé.
Dokita Krychman to jẹ onimọ nipa ilera ibalopọ ni oun gba pe awọn eeyan n jẹ eroja ifẹ nitori pe o ti ṣiṣe fun ẹlomii ri ni.
Boríborí gbogbo nǹkan wọnyi, ni pé kí ẹ gbé ìfẹ́ wọ̀.
Ti ẹ ba ni aanfani lati ko awọn ọmọ ẹgbẹ agbabọọlu ti yin jọ, ta ni yoo wa nibe?
Ṣugbọn OLUWA kò sí ninu ẹ̀fúùfù líle náà.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Bukola Saraki ni adari wa' - Razaq Atunwa, Kwara Awọn ajọ ọmọlẹyin Jesu ni Kaduna ti a mọ si Christian Association of Nigeria (CAN) naa ko ṣai fi ero tiwọn han lori koko yii.
Musiliu Dasofunjo ni awọn ẹgbẹ oṣere Yoruba ni yoo ṣeto isinku rẹ.
Ọjọ naa gan an ni mo ti yofẹ fun un, mo si gbagbọ pe oun naa ko mi jẹ.
Nítorí ọmọ mi yìí ti kú, ṣugbọn ó tún wà láàyè; ó ti sọnù, ṣugbọn a ti rí i.
Leah Sharibu ti lo ọjọ mejilelaadọta ni ahamọ, ki ni a n beere fun?
Àkọlé àwòrán, Ní Ìpínlẹ̀ Ọyọ lórilẹ̀ èdè Naijíríà àwọn mùsùlúmi ó gbẹ́yìn láti lọ sàdúra ní yidi fún ìtúnu àwẹ Oríṣun àwòrán, Reuters Àkọlé àwòrán, Ní ọjọru kan náà ní àwọn mùsúlùmí ṣe ọdún Ramanda, bẹẹni ọmọdebínrin yìí kọ́ọ̀wọ́rin lọ fún àdúra yídì ní olú ilú Kenya tí a mọ si Nairobi.
Ìdajì rẹ̀ tí ó jẹ́ ti àwọn ọmọ ogun jẹ́ ẹgbaa mejidinlaadọsan-an ó lé ẹẹdẹgbẹjọ (337,500) aguntan.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Ọdun 2011 ni Aarẹ Goodluck Jonathan, to yan Farida Waziri sipo alaga ajọ EFCC, gba iṣẹ lọwọ rẹ.
Isuna owo 2018 ti ileeṣẹ ijọba fun ọrọ abẹle eyi ti o n ṣe akoso awọn ọgba ẹwọn Naijiria ṣe fihan pe N15.
Àkọlé àwòrán, Gbongan kilaasi kan ni yi ni Fasiti ikọni nimọ ijinlẹ sayẹnsi ni Fasiti Pọta nipinlẹ Rivers.
Ohun ti won so ni pe” A wa fun ipade  bonkẹlẹ.
Wọ́n ń fọ́nnu lásán; wọ́n ń fi ìbúra asán dá majẹmu; nítorí náà ni ìdájọ́ ṣe dìde sí wọn bíi koríko olóró, ní poro oko.
Lori eyi, Ọgbẹni Agunbiade ni ile ko sọ pe ki gomina Ambode ma pari saa iṣejọba rẹ ṣugbọn tori awọn ọrọ to so mọ isuna ọdun 2019 ni ile fi pe e.
Ninu lẹta naa lo ti ri ka pe iya oun ni ajọsepọ pẹlu ọkunrin alawọ dudu kan nigba to ku diẹ, ko se igbeyawo pẹlu ọkọ afẹsọna rẹ to jẹ alawọ funfun.
Idi niyi ti owo ori epo fi n wa soke-wasilẹ lẹnu ọjọ mẹta yii nitori segesege to n waye lori owo epo lọja agbaye.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ẹ sá àwọn akẹ́kọ̀ọ́ sínú òòrùn fún ọgbọ̀n ìṣẹ́jú lójojúmọ́ - Ìjọba Oyo pàṣẹ Mà á gbẹ̀san bàálù àjọ UN tó já ní Borno - Buhari yarí Òṣìṣẹ́ LASTMA gún olólùfẹ́ rẹ̀ l'ọ́bẹ, ó tún gba ẹ̀mí ara rẹ̀ l'Eko Ikọ̀ ìjọba Ọ̀yọ́ dé lásìkò tí kò yẹ ni wọn kò ṣe wọlé - Ẹ̀bí Ajimobi fèsì O fikun pe aarẹ naa gba lati tẹle amọran awọn dokita naa nitori o kere tan eniyan kan ninu awọn ti wọn jọ n ṣiṣẹ pọ ti ko arun Coronavirus.
Torinaa o ni ọdaran lawọn afipabanilopọ bi ọdaran si ni ki wọn ṣe fiya jẹ wọn.
Owó yìí ni yóò ràn àwọn ti àjàkálẹ̀ ààrùn Coronavirus ti mú okòwò wọ́n dénu kọlẹ̀ tí wọ́n kò si lágbára láti ṣe ojúṣe wọn bótitọ́ àti bóti yẹ mọ́.
Igbese naa waye leyin aba ti asofin  Tunde Braimoh ati awon akẹgbẹ re nile igbimo
Eyi n lọ si bii ida kan ninu mẹrin gbogbo ọmọ orilẹede Naijiria.
Ọmọkunrin mẹfa ni wọ́n bí fún Dafidi nígbà tí ó wà ní Heburoni.
Òkú alákàn kan kì í wàràn
Ẹ má jáfara, ẹ wọ ilẹ̀ náà, kí ẹ sì gbà á.
Má ṣe gbéraga níwájú ọba, tabi kí o jókòó ní ipò àwọn eniyan pataki,
A sì fún Ẹni Ayérayé ní àṣẹ, ògo ati ìjọba, pé kí gbogbo eniyan ní gbogbo orílẹ̀-èdè ati ẹ̀yà máa sìn ín.
Adeyinka Godson fún ẹ̀yà Igbo ní gbèdéke láti fi ilẹ̀ Yorubá sílẹ̀
Ẹ̀kọ́ àti àwọn Májẹ̀mú ni àkójọpọ̀ àwọn ìfihàn àtọ̀runwá àti àwọn ìkéde tí ó ní ìmísí ti a fúnni fún ìdásílẹ̀ àti ìlànà ti ìjọba Ọlọ́run lórí ilẹ̀ ayé ní àwọn ọjọ́ tí ó kẹ́hìn.
Polio eradication in nigeria: Orísúnmibáre ni àìsàn 'Polio' tó kọlù mí ní kékeré
Bakan naa ni ọpọlọpọ eniyan yabo ile ijọsin rẹ lasiko naa, ti wọn ko si jẹ ki wọn raaye ṣe isin.
A kò tíì rí ọmọ ọdún méjì tó kó sí kànga- Olootu India Aguti to loyun osù mẹ́fa ti fún àwọn ọkọ rẹ ni ilé mẹ́ta nínú mẹje to wa ni àgbàlá rẹ̀.
Akọkọ ninu iroyin yii ni pe aarẹ ti tẹwọ gba abajade iwadi igbimọ ti aarẹ gbe kalẹ fun atunto ikọ agboguntiwa idigunjale nileeṣẹ Ọlọpaa, SARS, ekeji iroyin si ni pe aarẹ Buhari ti buwọlu eto ọlọpa agbegbe fun orilẹede Naijiria.
Wò ó, yóo pa mí; n kò ní ìrètí;sibẹ n óo wí àwíjàre tèmi níwájú rẹ̀.
"Mo gba owo mo si fi ọmọ wa obinrin to dagba ju le ọkọ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àwọ̀tẹ́lẹ̀: Èwo lo ní ìfẹ́ sí nínú orísirísi kọ́mú yìí?
 láti jẹ ́ rì ipò afurasí , àyẹwò ìdánwò ẹ ̀ jẹ ̀ pẹ ̀ lú polymerase chain reaction ní a nílò .
Sugbọn kii ṣe gbogbo eniyan ni ilana iṣẹ tuntun ti mọ l'ara.
Lọdun 1954, wọn dibo yan an fun igba akọkọ si ipo ọmọ ile aṣofin apapọ lati ṣoju ẹkùn idibo Iwọ Oorun Sokoto.
Eyi lo si mu ki igbesẹ pẹlẹ putu jẹ ọna to ṣe itẹwọgba."
O jade laye lọjọ Aiku, ọjọ kẹtalelogun, oṣu keje, ọdun 2017.
" Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Pẹ̀lú gbogbo bùkátà, Bàbá 80 gboyè Masters Bakan naa ni aarẹ tẹlẹ naa tun gbe imọran kalẹ pe o yẹ ki alekun eto ilanilọyẹ wa, ki awọn ọmọ Naijiria lee ni iyipada rere ti wọn n fi oju sọna fun.
Púpọ̀ wọn ni kò ṣe dáàda tó níléèwé girama tí wọ́n ti jáde.
Lọdọ ileeṣẹ ọkọ ofurufu Qatar afihan iwe ẹri mo moribọ lọwọ arun Covid 19 jẹ nkan ti eeyan gbọdọ mu wa paapa to ba n bọ lati orile-ede miran bi Turkey to si fẹ wọ Qatar.
Bisobu Rugagi, eni ti o  dari “ijo Abacunguwe”( Redeemed Gospel Church) ni won fesun kan pe, o n tako igbese ti ijoba n gbe lati maa je ki awon ile ijosin se ojuse won.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ọ̀tọ̀ ni nkan tí wọ́n sọ fún ẹbí rẹ̀, iṣẹ́ aṣẹ́wó ni wọ́n fi n ṣe O dabi pe idibo 2019 maa bi ige ati adubi nitori onikaluku lo ni idi to fi n ṣatilẹyin fawọn oludije ọtọọtọ paapaa ninu idle kan ṣoṣo.
Ẹ ti pa ọpọlọpọ eniyan ní ààrin ìlú yìí; ẹ sì ti da òkú wọn kún gbogbo ìgboro ati òpópónà ìlú.
 O wa fi kun oro re pe igbese ti ijoba gbe pelu bi o se
N óo jẹ yín níyà gẹ́gẹ́ bí iṣẹ́ ọwọ́ yín;èmi OLUWA ni mo sọ bẹ́ẹ̀.
Cisse bẹ́ sí Kàǹga nítori fóònù N3,000 Ìyá òòṣà fẹ̀sùn àjẹ́ kan ìyá ẹni ọdún 90, aráàlú bá sọ ọ́ lókò pa Bakan naa lo kọ sibẹ pe oun lọ si ile ẹkọ Cameroon Protestant College.
Italy fáìnì ọmọ Nàìjíríà tó ń gbálẹ̀ àdúgbò lọ́fẹ̀ẹ́ Ijọba orilẹede Italy ti fagile faani ti wọn fun ọmọ orilẹede Naijiria kan to n gba ilẹ awọn adugbo kọọkan lai gba aṣẹ.
Amọ ṣa, yatọ si eyi, awọn aisan miran wa to n baa finra eyi to ran an lọ si ileewosan lọpọ igba.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ṣìṣe-ṣìṣe bá Man City, Norwich fi wọ́n ṣe fàájì òpin ọ̀sẹ̀ 14 Owewe 2019 Oríṣun àwòrán, PA Media Ile mi jiji ni papa iṣere Carrol road nibi ti Norwhich ti da Man City lagbo sina pẹlu goolu mẹta si meji.
Awọn janduku yii lọpọ igba maa n da eto ipolongo ibo tabi iwọde oṣelu ẹgbẹ tabi ẹni to jẹ alatako fun ẹni to bẹ wọn niṣẹ ru.
Nigba to n bawọn akọroyin sọrọ lẹyin ipade pajawiri naa, Ọrangun Ile Ila ni asẹ ti igbimọ naa pa pe ki Oluwo lọ rọọkun nile na ko ni ohunkohun se pẹlu ija to waye laarin rẹ ati Oluwo.
Aare Naijiria tepele mo ipinnu ijoba re lati daabo bo awon ogo weere Naijiria, pe ayajo ojo won loni ojo ketadinlogbon, osu karun un yii n pe fun ajo ironu fun obi, alagbato ati ijoba fun ise atunse to wa niwaju onikaluku.
Mo jẹ́wọ́ àṣìṣe mi,mo sì káàánú fún ẹ̀ṣẹ̀ mi.
OLUWA, ọba Israẹli wà lọ́dọ̀ yín;ẹ kò sì ní bẹ̀rù ibi mọ́.
Aare wa ro awon oba naa lati
Oloyede ni amofin agba kan ni yoo ṣe ẹjọ awọn ọgọrun naa.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Idije Premier League Lẹyin iṣẹju mẹta pere ti wọn bẹrẹ ere bọọlu ọhun ni Tammy Abraham gba bọọlu sawọn fun Chelsea.
Ajàfẹ́tọ: Awàkọ̀ mi sùn ẹ̀wọ̀n ọjọ́ márùń t'orí aṣẹ́wó
 Awon metadinlogoji si wa nibudo ayewo ti wonIpinle mejidinlogun ni won ti kefin isele bayii.
yoo tẹle ofin ninu ojuṣe wọn eleyii ti o fi aaye gba ile naa lati gbe
Ṣugbọn Farao dá wọn lóhùn pé, “Ọ̀lẹ ni yín, ẹ kò fẹ́ ṣiṣẹ́ ni ẹ fi ń sọ pé kí n jẹ́ kí ẹ lọ rúbọ sí OLUWA.
Ikọ ẹlẹni mẹta to n risi ipẹjọ ti adajọ A.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Opeyemi Ayeola: Inú sinimá ni ọkọ mi ti rí mi, ọdún mẹ́ta ló fi wá nọ́mbà mi, kó tó fẹ́ mi 22 Òkùdu 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 6 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Oríṣun àwòrán, Joshua Adetunji Ori lo mọ iṣẹ aṣela, ohun gbogbo si wa lọwọ ori nitori ko si ẹda to mọ ọna ọlà, Ọlọrun lo n fi ọna han ẹda.
Mo pàdánù ọkọ méjì láàrin ọdún kan lórí Facebook"" Ta ni agbábọ́ọ̀lù obìnrin tí o fẹ́ràn jù?"
 ní àfíkún , àádọ ́ rùn-ún ònírúrú kóńsónáǹtì kílíìkì ni wọ ́ n n lo ni gwi tí òhun náà jẹ ́ ọ ̀ kan lára èdè khosian wọ ̀ nyí .
Gbogbo nǹkan yòókù tí Jehoṣafati ṣe láti ìbẹ̀rẹ̀ dé òpin, ni a kọ sinu ìwé ìtàn Jehu ọmọ Hanani, tí ó jẹ́ apá kan ìtàn àwọn ọba Israẹli.
Goodluck Jonathan jẹ́ olùfọkànsìn àti ìwúrí fún ìrandíran ní Nàìjíríà - Buhari Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ẹ wo fídíò Kìnìhún ní ibùgbé rẹ̀ tuntun ní Bogije, Lekki Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
O ṣalaye bi iṣẹlẹ̀ naa ṣe ṣakoba fun ọpọlọpọ idile.
Leon van Biljon dí èrò ọrun nípasẹ̀ Kìnìún rẹ̀ Ikú dóró!
- MC Oluomo 'MC Oluọmọ kò kú o, kò sí ikú lójù rẹ̀' Ṣe saaju ni awọn kan ti kora jọ ni bii Ọsẹ diẹ sẹyin lati fi ẹhonu han lori fifi MC Oluọmọ jẹ alaga fidihẹ ẹgbe naa.
Wọ́n fẹ́ ṣe màgòmágó ìbò tó ń bọ̀ - Danjuma figbe bọnu Àrà méèrírí , ẹ wo ọkùnrin tí eegun rẹ̀ rọ̀ bíi rọ́bà, tó ń ká bíi ẹja Kíni ìdí tí NLC fi kọ N27,000 owó osù òsìsẹ́?
Ní ọdọọdún tí wọ́n bá ti lọ sí ilé OLUWA ni Penina máa ń mú Hana bínú tóbẹ́ẹ̀ tí Hana fi máa ń sọkún, tí kò sì ní jẹun.
Mo wọn ẹgbẹta lé aadọta (650) ìwọ̀n talẹnti fadaka, ohun èlò fadaka tí a wọ̀n tó ọgọrun-un (100) ìwọ̀n talẹnti fadaka, ọgọrun-un (100) ìwọ̀n talẹnti wúrà, 
Àwòrán nǹkan aláràmbarà oríṣiríṣi táwọn jàǹdùkú jí gbé lẹ̀yìn ìwọ́de EndSARS Irọ́ ní pé bàbá wa, Soun Ogbomoso paradà di ọmọ tuntun, báyìí ni àwọn ọ̀rẹ́ ṣe dalẹ̀ rẹ̀ tí wọ́n pa á Àwọn ọbá aláye ilẹ̀ Yorùbá márùn-ún pẹ̀lú ọ̀pá àṣẹ wọn Mo ti tọrọ aṣọ àti yẹtí etí rí, kí n tó leè ṣe àwo orin - Tope Alabi Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí kan sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
 murtala tún fó egbàárùn owo-ogun sí wéwé .
Ni deede aago mẹsan aarọ si ni awọn osisẹ ọgba ẹwọn ti gbe Alfa Babatunde de sileẹjọ ati awọn afurasi ọmọ ijọ rẹ miran ti wọn fi ẹsun ajọmọgbe kan pẹlu rẹ.
Gomina ipinle Ekiti, ogbeni Fayemi so pe
O seese kawọn asaaju ilẹ Afrika bu ẹnu atẹ lu ọrọ abuku Trump.
Ọkan lara awọn ọmọ oloogbe ti orukọ rẹ n jẹ Goke ṣalaye pe idaji owurọ Ọjọru ni ẹlẹmi gbaa ti baba rewalẹ asa.
Mama agba yii, to nifẹ ẹgbẹ agbabọọlu Arsenal bii oju, ti ọjọ ori rẹ yoo si to aadọrin ọdun, lo nifẹ ere bọọlu ju ọmọde tabi awọn ọkunrin miran lọ.
marun-un fún àwọn àkànpọ̀ igi tí wọ́n wà ní ẹ̀gbẹ́ keji, marun-un yòókù fún àwọn àkànpọ̀ igi tí wọ́n wà ní ẹ̀yìn ní apá ìwọ̀ oòrùn.
O sọ eyi nibi ayẹyẹ ikojade iwe rẹ tuntun, 'Chronicles of the happiest people on earth', nilu Eko.
Kò yàtọ̀ sí ẹni tí ń pe eérú ní oúnjẹ.
lara awon fafiti to gba ami eye
omo-ogun 1 Operation LAFIA DOLE ti orile ede Naijiria , pelu ifọwọsowọpọ ikọ omo-ogun eleto aabo  orile ede  Cameroon ,ni won jọ sekọlu si  ikọ
" Ẹ sọ èdè Yorùbá kíkà di kàńpá níléẹ̀kọ́ alákọ̀bẹ̀rẹ̀ àti girama - Ẹgbẹ́ Akọ́mọlédè A ò ní fààyè gba pípa ọmọ Naijirià nípakúpa ní South Africa mọ- Abike Dabiri Busola Daakolo: Mi ò fọwọ́ sí ìwé kankan tó takò ẹ̀sùn tí mo fi kan Fatoyinbo Sowore takú, kò jẹun ní àgọ́ ọlọ́pàá torí májèlé - Deji Adeyanju Owó dé!
Àbí pípè tí o pè wá wá sí ibí yìí, o fẹ́ sọ wá di aláìní ni?
O ni ijọba yoo gbe igbesẹ lati ri i wi pe iru nkan bayii ko tun waye mọ.
ede Naijiria ni ajo agbaye, United Nations  ati awon eniyan pataki miiran.
Ninu ọrọ lo ti gba aarẹ Buhari niyanju lati mu ẹkọ rẹ lọkunkundun.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Ninu rogbodiyan igbesunmọmi to n lọ lọwọ ni ariwa-oorun Naijiria, o le ni 3,500 ọmọde ni wọn ti fi ipa mu lati darapọ mọ ikọ ologun abẹle laaarin ọdun 2013-2017.
Asamoah Gyan: O ṣeéṣe kí èyí jẹ́ ìdíje AFCON ìkẹyìn mi O tẹsiwaju pe ti ko ba rọrun lati gbọ ẹjọ naa ni ile ẹjọ yi to ri pe ọdaran naa ko gbe ilu ohun,ibi ti o n gbe nibi ti ọrọ kan lati gbọ ẹjọ naa''lopin igba ti ile ẹjọ to ba ka oju osunwọn ba ti wa nibẹ.
O ni: osisẹ agba ere ori papa kan lorilẹede Naijiria sọ fun mi pe bi mo ba wa si hotẹẹli oun ti mo si mu 'nu oun dun, yoo fun mi ni iroyin pataki ti mo le gbe jade lori afẹfẹ""."
Jesu dá a lóhùn pé, “Kò ì tíì yé ẹ̀yin náà títí di ìwòyí?
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ó kù díẹ̀ kí UNN rán akẹ́kọ̀ọ́ kan sọ́run àrèmabọ̀ Wo ibi tí ìgbáradì fún ìbò gómìnà l'Ékìtì dé dúró Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ekiti Election: Àwọn ará Èkìtì ń fẹ́ gómìnà tí kò ní f‘ebi pa wọ́n Bi ẹnikan se ni Fayẹmi ni, ni ẹlomin ni PDP ni, eyi ti ko jẹ ka ri arigbamu gidi.
Wọ́n dáhùn pé, “Mose yọ̀ǹda pé kí ọkọ kọ ìwé ìkọ̀sílẹ̀ fún iyawo rẹ̀, kí ó sì kọ̀ ọ́.
O ni oun gbọ pe ọkọ mi akọkọ sọ pe oun yoo gba mi pada.
Gbọ́ ìtàn bí ikọ̀ SARS ṣe dà bó ṣe dà láti ẹnu Ọ̀gá ọlọ́pàá tó dá SARS sílẹ̀ Ìjọba kéde ọjọ́ ìwọlé àwọn àgùnbánirọ̀ sí ìpàgọ́ lẹ́yìn Covid 19- Sunday Dare #EndSARS: Àwọn olùwọ́de kọ etí ikún sí àṣẹ ijọba, wọ́n tẹ̀sìwájú ìwọ́de l'Abuja Kí ló ń ṣẹlẹ̀ láàfin Oyo táwọn èèyàn fi ń ki Alaafin ní mẹ́sàn án mẹ́wàá?
Coronavirus: Borussia Dortmund fẹ̀yìn Schalke 04 gbolẹ̀ bí Líìgì ilẹ̀ Germany ṣe padà bẹ̀rẹ̀
Wọn óo máa ròyìn ògo ìjọba rẹ,wọn óo sì máa sọ nípa agbára rẹ,
Nítorí bí ó bá jẹ́ pé àwọn tí ń tẹ̀lé ètò Òfin ni yóo jogún ìlérí Ọlọrun, a jẹ́ pé ọ̀ràn àwọn tí ó dúró lórí igbagbọ di òfo, ìlérí Ọlọrun sì di òtúbáńtẹ́.
Ẹjọ kòtẹ́mílọrun ti ọgbẹ́ni Adegbola àti àwọn mẹ́fà míran fi ṣọ́wọ́ lòdì sí ọgbẹ́ni James Idowu àti àwọn mẹ́rin míràn wáye nítori idajọ Adájọ Abimbola pé ọnà to gbà de ori àpèrè kò tọ̀nà.
Komla Dumor: Victoria Rubadir ọmọ Kenya ló gba àmì ẹ̀yẹ Komla Dumor BBC World News
OLUWA bá mi sọ̀rọ̀, ó ní, “Ìwọ ọmọ eniyan, sọkún tẹ̀dùntẹ̀dùn lórí ogunlọ́gọ̀ àwọn eniyan Ijipti, rán àwọn ati àwọn orílẹ̀-èdè ọlọ́lá yòókù lọ sinu isà òkú, sọ́dọ̀ àwọn tí wọ́n ti fi ilẹ̀ bora.
Bakanna ni ajọ WHO ti se sọ fun wa pe ọwọ fifọ ati imọtoto se koko ti a ba fẹ dena ajakalẹ arun.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Shehu Shagari; Àwọn ohun tó yẹ kí o mọ̀ nípa olóògbé 28 Ọ̀pẹ̀̀ 2018 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Oun ni aarẹ alagbada akọkọ ati aarẹ kan ṣoṣo to jẹ lasiko eto oṣelu awaarawa keji (1979-1983).
N óo mú lára ẹ̀mí tí ó wà lára rẹ, n óo fi sí wọn lára; kí wọn lè máa ràn ọ́ lọ́wọ́, láti gbé ẹrù àwọn eniyan náà, kí ìwọ nìkan má baà máa ṣe iṣẹ́ náà.
Nínú ìpè kan lẹ́yìn ìgbà náà, wọ́n sọ fún aṣojú iléeṣẹ́ BlaBlaCar pé ètò náà ti yí padà, pé àwọn á máa ṣe ìfọ̀rọ̀wọ́rọ̀ pẹ̀lú àwọn oníbàáràa wọn dípò wọn.
O tẹnu mọ ọ pe ki wọn ṣọra nipa bi wọn ṣe n gbé ohun ija lẹnu iṣẹ wọn o si fi aridaju han pe ẹni ti ayẹwo naa ba mu, wn o ni kọkọ yọ ọ niṣẹ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Pinnick: Danny Jordaan láti South Africa ló rọ́pò rẹ̀ 18 Agẹmo 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Ajọ to n mojuto bọọlu afẹsẹgba nilẹ Afrika, CAF, ti gba iṣẹ lọwọ Amaju Pinnick, ọmọ orilẹede Naijiria, gẹgẹ bi igbakeji aarẹ wọn, ti wọn si fi Danny Jordaan lati orilẹede South Africa rọpo rẹ.
láti inú ẹ̀yà Efuraimu: Hoṣea, ọmọ Asasaya; láti inú ìdajì ẹ̀yà Manase: Joẹli, ọmọ Pedaya; 
Sọ àsọtẹ́lẹ̀, kí o sì wí fún àwọn tí wọn ń sọ àsọtẹ́lẹ̀ ti ara wọn pé, ‘Ẹ gbọ́ ọ̀rọ̀ OLUWA!
Nígbà tí o bá gbé e fún alufaa, yóo gbé e wá síbi pẹpẹ.
Gomina tun so fun awon to n gbe ipinle naa, awon awako ati awon olokada lati maa se ise won.
Iroyin naa ni Abdullahi lo ji Aisha naa gbe, to si fi pamọ si ọdọ mama rẹ, nigba to n kesi awọn obi Aisha lati wa san owo idande rẹ.
Ìgbáradì yóò gbérasọ l'Ekiti lọ́jọ́ Àìkú tó ń bọ̀ 8 Ògún 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 24 Owewe 2020 Oríṣun àwòrán, Western Nigeria security network Amọtẹkun dee!
Ololufẹ rẹ kan si n na a lowo loju agbo.
Ìgbà tí mo da orí tèmi tí ó jẹ́ ti wúrà kọ ilẹ̀, owó góòlù bẹ̀rẹ̀ sí jáde, ṣùgbọ́n Ènìyàn-ṣe-pẹ̀lẹ́ mú ti fàdákà, ìgbà tí òun náà sì mú tirẹ̀ tí ó jẹ fàdákà tí ó da orí rẹ̀ kọ ìsàlẹ̀ owó ṣílè bẹ̀rẹ̀ sí jáde.
"Ko si igba kan ti a binu jade kuro nibi ipade wa pẹlu ijọba ṣugbọn ijọba apapọ ko jẹ olootọ si ijiroro pẹlu ASUU lori adehun yii.
Mo ti dé ibi tí ó ga jùlọ ní ilẹ̀ rẹ̀,ati igbó rẹ̀ tí ó dí jùlọ.
ede mejeeji, bakan naa, ni igbakeji aare 
afurasi meji kan lataari lilowo si iku omode kunrin omo odun mejila afin kan.
Òun náà sì dáhùn, ó ní, Hòo, Olówó-ayé, èmi nìyí lọ́wọ́ rẹ.
Wọn ní Bàbá olówó jẹ báńkì kan ní ₦240bn ni Amcon ṣe gba ilé náà Ariwo orúkọ gbajugbaja oṣiṣẹ radio kan nilu Eko, Toke Makinwa, lo gba ori ayelujara lati ọjọ Aje.
Won fi esun kan an pe “o n tapa si ofin eeto aabo  ilu naa” lati osu keje ni o ti wa latimole.
Ó dá wọn lóhùn pé, “Ẹni tí ó ń fi òkèlè run ọbẹ̀ ninu àwo kan náà pẹlu mi ni ẹni náà tí yóo fi mí fún àwọn ọ̀tá.
Lẹ́yìn èyí, ó pe àbúrò rẹ ọkùnrin, nígbà tí ó dé, o wí fún un pé kí o lọ gbé ọkọ̀ wá kí ó tù mí kọjá sí apá kejì odo, wéré wọ́n ti mu ọkọ̀ dé, àti èmi àti oun sì rékojá sí òdì kejìo lápá ibi tí mo wà.
O óo sì ta ọtí líle náà sílẹ̀ lẹ́bàá pẹpẹ ìrúbọ bí ẹbọ sí OLUWA.
stars ati African Legends), eleyi ti o mu ki awon agbaboolu bi Stephen Appiah lati
Wọn maa n fi eyi parọwa fun wa, kọ wa lọgbọn, fun wa loye, to si tun maa n tọ wa sọna ninu igbe aye wa lojoojumọ.
Nítorí náà, mú àwọn ọba mejeejilelọgbọn kúrò ní ààyè wọn gẹ́gẹ́ bí olórí ogun, kí o sì fi àwọn ọ̀gágun gidi dípò wọn.
Mitchy Batshuayi lo gba goolu ẹkẹrin wọle fun Chelsea ti ifẹsẹwọnsẹ naa si pari si ami ayo mẹrin sẹyọkan.
 bakanna o tun je omo egbe agbajo fun abo ati ifowosowopo ni europe ( osce ) .
Iroyin sọ di mimọ pe, awọn ọlọpaa meji wa lara awọn to farapa nibi ti wọn ti n dari awọn to n ṣe iwode naa.
Agbẹnusọ ilé iṣẹ́ náà, Franklin Alao, nínú àtẹjáde tó fi síta fún àwọn NPO lọ́jọ́ Ẹti ló ti sàlàyé pé, àwọn tó jẹ́ ojúlówó oníṣẹ́ ìfẹrù ránṣẹ́, to mọ ìtumọ̀ iṣẹ́ yìí, kò ni bá wọ́n sí nídi irú ìfẹ̀hónú hàn bẹ́ẹ̀.
Osun Osogbo: Ọdọọdún ni Àtáója ń gbàlejò gbogbo Arugbá lásìkò ọdún Ọ̀ṣun Òṣogbo
Dokita Emmanuel ni irinwo ẹyin lo wa lara obinrin, ati wi pe osoosu ti obinrin ba n se nkan osu ni awọn ẹyin wọn yii n dinku lara, ti awọn homoonu ara a si bẹrẹ si ni dinku, ti ẹwa ara a si bẹrẹ si ni dinku.
Bí ọ̀gangan ibi tí àrùn yìí ràn mọ́ kò bá mọ́, bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé kò tàn káàkiri sí i; sibẹ kò mọ́; jíjó ni ó níláti jó o níná, kì báà jẹ́ iwájú, tabi ẹ̀yìn aṣọ tabi awọ náà ni àrùn ràn mọ́.
Agbẹjọro Hush, Gal Pissetzky, lo sọ bẹẹ fun iwe iroyin Forbes, lasiko ifọrọwanilẹnuwo kan.
Ẹ máa pa òfin rẹ̀ mọ́, kí ẹ sì máa gbọ́ tirẹ̀; ẹ máa sìn ín, kí ẹ sì súnmọ́ ọn pẹ́kípẹ́kí.
Ikọ olubanikẹdun ọhun lọ si ilu Ido-Ekiti nibiti wọn ti ṣabẹwo si arabinrin Esther Okunofua, to jẹ iya Joseph akẹkọọ ipele kẹta ẹka imọ Biology ni fasiti FUOYE, ki o to jade laye.
OLUWA sọ̀kalẹ̀ láti wo ìlú tí àwọn ọmọ eniyan ń tẹ̀dó ati ilé ìṣọ́ gíga tí wọn ń kọ́.
Iyalẹnu lo jẹ fun wa pe ọdọmọbinrin to ni anfaani banta-banta lati jẹ adari NIPOSt, bọ si gbangba lati ta ẹrẹ si aṣọ ala ileeṣẹ FIRS ati ile aṣofin to ṣe ofin to gbe ileeṣẹ mejeeji kalẹ."
Àwọn oníṣòwò Ṣeba ati ti Raama náà a máa bá ọ ra ọjà, oríṣìíríṣìí turari olóòórùn dídùn ati òkúta olówó iyebíye ati wúrà ni wọ́n fi ń ṣe pàṣípààrọ̀ ọjà lọ́wọ́ rẹ.
Mose bá dá àwọn eniyan náà lóhùn pé, “Ẹ má jẹ́ kí ẹ̀rù bà yín, Ọlọrun wá dán yín wò ni, kí ẹ lè máa bẹ̀rù rẹ̀, kí ẹ má baà dẹ́ṣẹ̀.
Èyí fi hàn wá pé làákáyè ńlá ni àwọn tí wọ́n kọ́ ọ ní.
"Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí World Oral Health Day: Meet di 70 years old man wey never buy toothbrush for im life20 Ẹrẹ̀nà 2019 Nigeria Education enrolement: ""We dey wait for goment to come arrest us ontop dis school children mata""19 Ẹrẹ̀nà 2019 Commissioner nominee for Kano no vex as dem do am drug test9 Sẹ́rẹ́ 2019 Kano Governorship Election 2019: Elections dey INCONCLUSIVE!"
Orile ede mejeeji naa jọ tọwọbọ iwe adehun leyin ipade ti minista to n ri si Orile
3 496646 Orilẹede Bolivia 9530 83.
6 Wo ìgbà tí Ààrẹ Buhari yóò ṣí 'bọ́dà' padà 7 Háà!
Ní báyìí enìyàn ọgọ́jọléméje ló ti kú látàrí ààrùn Covid-19 Àjọ NCDC kéde èèyàn 184 míràn tó ni ààrùn Covid-19 lórílẹ̀-èdè Naijíríà Àkọlé àwòrán, Àjọ NCDC kéde èèyàn 184 míràn tó ni ààrùn Covid-19 lórílẹ̀-èdè Naijíríà Àjọ tó ń gbógun ti àjàkálẹ̀ ààrùn lórílẹ̀-èdè Nàìjíríà NCDC ti kéde pé ènìyàn mẹ́rinleọgọ́sàn (184) ni àyẹ̀wò tuntun fi hàn pé ó ní ààrùn Covid-19 lórílè-èdè Nàìjíríà ti àpapọ̀ àwọn tó ní ààrùn náà sì tì di ẹgbẹ̀rúnmẹ́rin àti ọ̀rìlélélẹ́ẹ̀gbẹ̀rún o dín mẹ́sàn-án (4971) Gẹ́gẹ́ bi àjọ náà ṣe sọ lójú òpó twitter rẹ̀ lálẹ́ ọjọ́ ìṣẹ́gun ènìyàn mẹ́rìlélọ́gọ́jọ ló ti kú nígbà ti ẹgbẹ̀rúnkan lé ni ààdọ́rin ti ri ìwòsàn gbà.
(Sky Sports) Ẹgbẹ agbabọọlu Wolves naa ti n ba Real Madrid sọrọ lati ra Jesus Vallejo fun saa kan, nigba ti Real Madrid naa ti n sunmọ bebe ati fẹnuko lati gba miliọnu mẹtadinlogun Pọnhun lọwọ AC Milan lati ra atamatase, ọmọ orilẹede Italy Patrick Cutrone.
"Buhari ni ifesi si ọrọ yii, lasiko to wa ni orilẹede Germany nigba ti iyawo rẹ sọrọ naa, sọ pe ""mi o mọ ẹgbẹ oṣelu ti iyawo mi n ṣe, ṣugbọn ibujoko rẹ n bẹ nile idana mi, to fi mọ iyara igbalejo mi, ati inu yara miran."
ijoba si n reti awon osise naa lati pada senu ise.
Reuters ni Abba Kyari rinrin ajo lọ si orilẹ-ede Germany nibẹrẹ oṣu yii pẹlu ikọ awọn oṣiṣẹ ijọba kan lati ṣe ipade pẹlu Siemes.
"Àwọn obìnrin mánigbàgbé sáà ìjọba tiwantiwa yìí Ọwọ́jà coronavirus yóò ṣì wà pẹ̀lú àgbáyé fún ìgbà pípẹ́- Ngozi Okonjo-Iweala Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Wo imọran Fọlọrunṣọ Alakija fun awọn ọdọ adulawọ Ọkan lara awọn akọroyin lati Naijiria to ni anfaani lati mojuto eto idibo naa, Oluwamayowa Tijani, sọ fun BBC Pidgin pe ""iṣoro to wa nibẹ ni pe orilẹ-ede America ko faramọ Okonjo-Iweala""."
Aṣofin Ọbasa sọ pe, “oṣu Ramadan jẹ asiko ti a n tẹri ọkan wa ba niwaju Olọrun Allah.
Nítorí OLUWA yóo na ọwọ́ ààbò rẹ̀ sórí òkè yìí.
Bayii ni Folarin Falana, ọkan pataki lara awọn to n fọn rere ifopinsi #End Sars naa ti fesi pe oun ko ni kopa ninu eto naa.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Kaduna: Ẹ̀mí tó sọ nú nínú àkọlù àwọn agbébọn pọ̀ 6 Èbibi 2018 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Púpọ̀ nínú àwọn tó pàdánù ẹ̀mí wọn ni ìròyìn sọ pé, wọ́n jẹ́ ọmọ ẹgbẹ́ ọdẹ ìbílẹ̀ kan.
Lẹ́yìn náà, Naomi pe Rutu, ó ní, “Ọmọ mi, ó tó àkókò láti wá ọkọ fún ọ, kí ó lè dára fún ọ.
mo si (Sustainable Development Goals) maa se aseyori to lapẹẹrẹ.
Lẹ́yìn náà, Ọlọrun sọ fún Jakọbu pé, “Dìde, lọ sí Bẹtẹli kí o máa gbé ibẹ̀, kí o tẹ́ pẹpẹ kan fún Ọlọrun tí ó farahàn ọ́ nígbà tí ò ń sálọ fún Esau, arakunrin rẹ.
a bí ọ ̀ mọ ̀ wé nwaichi si Ìpínlẹ ̀ Ábíá sí idílé Ọ ̀ gbẹ ́ donatus nwaichi ti ìlú Ábíá .
COZA: Ọpọ èrò ló jáde ṣe lòdì sí ẹ̀sùn ìfipábánilòpọ̀ Fatoyinbo
Gbogbo àwọn eniyan Dafidi, ati gbogbo àwọn ọmọ Israẹli ni ó hàn sí gbangba pé, ọba kò lọ́wọ́ ninu pípa tí wọ́n pa Abineri.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Arsenal vs Burnley: Kí ló kàn fún Arsenal báyìí lẹ́yìn tí Burnley yẹ̀yẹ́ wọn mọ́lé ní Emirates?
I, Iceberg Slim, Omobaba, Terry G, Omawumi, ati Konga kọrin pọ.
Eekan ninu ẹgbẹ APC ọhun pari ọrọ rẹ pe ijọba gomina ọhun yoo wa sopin laipẹ ọjọ.
Bí ẹgbẹ́ òsèlú APC ṣe ń seto ìdìbò Abẹ́lé kò tó rárá Lárá ǹkan ti o tún dá awuyewuye sílẹ̀ ní bi aya ààrẹ ṣe kọlu alága ẹgbẹ́ òṣèlú APC Adams Oshiomhole.
“Ẹni tí Ọlọrun bá dárí ẹ̀ṣẹ̀ rẹ̀ jì, tí Ọlọrun bo ẹ̀ṣẹ̀ rẹ̀ mọ́lẹ̀, ó ṣoríire.
Ṣeṣibasari kó wọn lọ́wọ́ bí àwọn tí wọn kúrò ní oko ẹrú Babiloni ti ń bọ̀ wá sí Jerusalẹmu.
Ó lé gba ìwé ìrìnnà (Visa) láti wá fẹ̀yìntì sí Naijiria Wo aṣọ òtútù tó wọ́n jùlọ ní àgbáyé!
 Mo le ka aṣeyọri nla to waye lalẹ ana ni London gẹgẹ bi ẹbun ọdun Keresimesi lati ọdọ Ọlọrun ati Anthony Joshua fun gbogbo wa ni ipinlẹ Ogun.
Ẹ ta àwọn ohun tí ẹ ní, kí ẹ fi ṣe ìtọrẹ-àánú.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Badagry ní ogún àjogúnbá tó pọ̀ yàtọ̀ sí òwò ẹrú Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Badagry ní ogún àjogúnbá tó pọ̀ yàtọ̀ sí òwò ẹrú 10 Agẹmo 2019 Mo n fi àgbọn kọ́ odindi abúlé - Gbenga Olusegun Ilu Badagry jẹ ilu ti itan fihan pé owo ẹru gbilẹ nibẹ lasiko ijọba awọn amunisin laye atijọ.
Bakan naa, Marcelo ko kopa ninu ifesewose pelu Mexico lataari isoro eyin ti o mu, leyi ti o mu ki Filipe Luis ropo re.
''Buhari àti Tinubu ṣ'àdéhùn pé Yorùbá ni yóò jẹ́ olùdíje ipò ààrẹ APC lọ́dún 2023 '' Iléeṣẹ́ epo rọ̀bì ná ₦116m lórí báírò, ìwé ìkọ̀wé, àwọn aṣòfin fìka hánu Ara mi rẹwà ló jẹ́ kí n máa ṣí ara sílẹ̀- Victoria Kolawole Èyí ni bí gómìnà Babajide SanwoOlu ti ìpínlẹ̀ Eko ṣe kó COVID-19 'Ẹ̀ṣọ́ ọgbà ẹ̀wọ̀n bọ́ mi sí ìhòhò, ó ki ìka rẹ̀ bọ ìdí mi látẹ̀yìn' Ìwà ìbàjẹ̀ bíi olé jíjà, ìjínigbé àti rìbá gbígbà ní Okediji fi ṣàpèjúwe ǹkan tó ń ṣẹlẹ̀ ní Nàìjíríà Kìí ṣe gbogbo ohun tí dókìtà ni kí n má jẹ torí àìsàn jẹjẹrẹ ni mo tẹ̀lé- Soyinka Ninu atẹjade ti Shehu fi lede ọhun ni o ti sọ pe ko si ikankan to fara gbọgbẹ ninu awọn akẹkọọ ti wọn gbe lọ bo tilẹ jẹ pe awọn sọja atawọn agbebọn naa kọju ija si ara wọn.
Àkọlé àwòrán, Àwọn ìgò oògùn ikọ́ olómi tó ní èròjà codeine ń polówó èròjà codeine tó wà nínú wọn Mímu òògùn ikọ́ olómi kò kan ipò, ìran tàbí ẹ̀ya Hamza Umar ti NDLEA Kano ní, mímu òògùn ikọ́ olómi kò ní nkàn ṣe pẹ̀lú boya olówó.
 Àwọn ajalèlókun jáagbà lẹgbẹ ́ somalia ní ọdún 2009 , wọ ́ sí mú àwọn atukọ ̀ ẹ lati gba owó ìdásilẹ ̀ .
Kaduna-74 FCT-42 Lagos-17 Kano-8 Ogun-6 Oyo-6 Rivers-6 Ekiti-3 Bauchi-3 Katsina-2 Delta-1 Ondo-1 Apapọ awọn to ti ni - 66,974 Awọn to ti ri iwosan - 62,585 Awọn to ti ku - 1,169 Èèyàn 198 ni Covid-19 ṣẹ̀ṣẹ̀ ràn ní Naijiria ní 25/11/2020 Eeyan igba din meji lo tun ti ni aarun Covid-19 ni Naijiria.
Kíyèsíi, ẹnikẹ́ni tí ó bá ní ìyè àìnípẹ̀kun ni ọlọ́rọ̀.
Gbogbo akitiyan atamatase Chelsea, Tammy Abraham lati yọ ikọ rẹ jade ninu ọfin Liverpool lo ja si pabo.
kí ìjọba rẹ dé,ìfẹ́ tìrẹ ni kí á ṣe ní ayébí wọ́n ti ń ṣe ní ọ̀run.
Óun ń gun òkè bọ̀ lórí àpáta, ibi tí o sì ti ń fi iwọra sáré bọ̀ kò mọ ìgbà tí mo fi rọra sọ̀ kalẹ̀ sí òsì kejì.
'Selfie' yiyá ki ṣé oun ti eeyán n gbaju mọ ni Hajj.
OLUWA pàṣẹ fún Mose pé kí ó bá àwọn ọmọ Israẹli dá majẹmu mìíràn ní ilẹ̀ Moabu, yàtọ̀ sí èyí tí ó ti bá wọn dá ní òkè Horebu.
O ni awọn ipinlẹ to ti ṣe bẹ ṣaaju kan gbe igbimọ kalẹ ni lai so ni koko ohun ti yoo jẹ ilana ti wọn yoo tẹlẹ.
Lati igba to ti bẹrẹ awọn ọmọ Naijiria ti tẹwọ gba a, ti wọn ni awọn yoo fi aato si ti yoo fi bi eso iyipada rere ti wọn n fẹ koda awọn to wa nilẹ okeere naa gbaruku ti wọn.
Ṣé n kò ní gbẹ̀san pípa tí ẹ pa á lára yín, kí n sì pa yín rẹ́ kúrò lórí ilẹ̀ ayé?
Igbokegbodo ọkọ si ti n lọ bi o ti yẹ loju opopona Eko si Ibadan bayii Ajínigbé tú ìyá àti ọmọ ọdún mẹ́ta sílẹ̀ lẹ́yìn tí wọ́n gba ₦1.
Ogbeni Okechukwu wa n gbosuba fun awon onigbonwo ipade yii ,ti won pe akole re ni Atunse Awujo,”to ba je pe won n sise fun ife gbogbo eniyan.
Lati New Zealand to fi de Germany,Taiwan titi de Norway lati ri awọn orile-ede tobinrin n dari wọn ti wọn si n ṣe aseyọri nipa kikoju arun Covid 19.
Ìgbà tí a rìn díẹ̀ ni Èṣù wí pe: Adéforítì, ibi tí mo fẹ́ kọ́ mu ọ lọ ni ibi tí à ń pè ni “Pàkúté Èṣù” ibẹ̀ wà láti máa ran mi létí àti ṣe ibi ki n má ba gbàgbé.
Ohun tí eṣú wẹẹrẹ jẹ kù,ọ̀wọ́ àwọn eṣú ńláńlá jẹ ẹ́.
Cameroon first daughter: Ọmọ ààrẹ lọ ṣí sọ́ọ́bù irun ṣí Amerika
Bí ẹnikẹ́ni bá jẹ́ aláìkọlà nígbà tí a pè é, kí ó má ṣe kọlà.
Boya wọn yoo ri Trump yọ tabi ko ni ri bẹ, ni ohun to ku ti awọn eeyan n tẹti leko le lori ọrọ to wa nilẹ yi.
Eléyìí ní ìgbà kẹẹ̀sán tí ààrùn Ebola yóò ṣẹlẹ ní DR Congo.
 Lẹyin eyi lo gbe “Rum Bar Stylee” jade ni 1989.
Ninu ere naa ọkọ akero tansi lo wọ de ibi iburasipo rẹ ti o si kọ lati ṣe ileri to gbongbon.
Bayii lọrọ ri nigba ti Wolves kọkọ na Manchester City mọle.
Oríṣun àwòrán, others O ni yóò dáa kí ìjọba gba àwọn èèyàn tó mọ nípa ẹ̀rọ alatagba naa láàyè láti jíròrò lórí ire àti ibi tó wà nínú ẹrọ itakun agbaye náà.
Oríṣun àwòrán, @others Àkọlé àwòrán, Nọ́mbà 1: Eyi ni agba ninu awọn amohumaworan ni aye igbaa ni to n gbe ninu kọbọọdu, ti a n fọwọ yii ti yoo maa dun kẹkẹkẹkẹ Oríṣun àwòrán, @others Àkọlé àwòrán, Nọ́mbà 2: Àwa mẹ́lòó la ránti tẹlifiṣọn ẹlẹsẹ mẹrin yii?
Alaga ajo naa so pe  “E je ki n fi asiko yii dupe lowo adari ile igbimo asofin fun ipade yii.
O ni bi won ba gbe owo wa ki won gba a nitori won n fi owo abu se abu lalejo ni.
Ipa wo ni wón máa ń kó jù nínú eré tí wọ́n máa ń ṣe?
Ìṣọ ̀ kan Áfríkà ( kikekuru bi au ni ede geesi tabi ua ni awon ede onibise yioku ) je egbe isokan to ni awon orile-ede afrika 54 bi omo egbe .
Nitori naa, igbesẹ ti ko bojumu ni bi wọn ṣe sọ pe ki idije o bẹrẹ pada.
Ọgbẹni Akojede ni ''aṣọ kan naa ni wọn jọ maa n wọ, ohun kan naa ni wọn jọ gbagbọ, bakan naa ni wọn maa n gbamọran lọwọ ara wọn.
Idi si niyii ti ifa fi ṣaba ma n sọ pe ki iru wsn o fẹ babalawo gẹgẹ bi ọkọ, fun amojuto.
” Àwọn tí wọ́n sápamọ́ sì wà ninu yàrá inú.
Aàrẹ Buhari buwọlu yíyí orùkó àwọn ibùdókọ ọkọ ojú ìrìn bíi ti Apapa padà fi sọrí àwọn èèkàn ìlú 'kò sí ẹ̀rí àrídájú níńu ọ̀rọ̀ Akpabio' Ìyá òòṣà fẹ̀sùn àjẹ́ kan ìyá ẹni ọdún 90, aráàlú bá sọ ọ́ lókò pa Nàìjíríà ṣí àwọn ilé ìwé padà; Ìdánwò WAEC á bẹrẹ lẹyìn ọdún Iléyá!
Awọn oṣiṣẹ ileeṣẹ naa ni ijọba ti fun awọn laṣẹ lati kuro ni agbegbe naa, ti wọn ko si si ni ori afẹfẹ lọwọlọwọ bayii.
Ẹ̀rù ló sọ ọmọ Ẹkùn di Ológbò/Ológìní tó fi di Ẹran-àmúsìn – Ọdẹ peku-peku
Àwọn ọmọ Sakai jẹ́ ojidinlẹgbẹrin (760).
- Ẹgbẹ osi loju popo ni eyi to le di ọna fun awọn ti wọn n bọ lati odi keji opopona naa.
Nitori naa, ẹ jẹ ka ṣe agbeyẹwo diẹ lara awọn ọba ilẹ Yoruba ti wọn rọ loye.
Àríyànjiyàn nípa ẹ̀sìn oriṣa wọn, ati nípa ẹnìkan tí ń jẹ́ Jesu ni ohun tí wọn ń jà sí.
Abrahamu baba wa, tí ó ti kú ńkọ́?
Ẹwẹ, ijọba ipinlẹ Edo ti sun iwọle awọn akẹkọọ nipinlẹ naa si oṣu to n bọ nitori bi coronavirus ṣe n gbilẹ sii lojoojumọ ni ipinlẹ naa.
Bí owó rẹ ṣe dojude, o ko lọ si ile fulaati kékeré kan, ibi gan ni àwọn iya kekeke tí bẹ̀rẹ̀ si ni gorii ńlá to gbe e sanlẹ.
O fihan pe ẹsin ko sọ pe ki eeyan ma ni apa lati ṣiṣẹ.
Àwọn ni ẹlẹ́rìí fún gbogbo eniyan pé bẹ́ẹ̀ ni ọ̀rọ̀ rí.
ibo to yege jẹ 1,159,954, awon ibo ti ko yege jẹ 16,188, gbogbo ibo ti wọn di jẹ
Ìjàmbá ṣe wá ní Barcelona, aṣọ ò bá Ọmọ́ye wa mọ́- Gerard Pique Paa lẹẹkinni, paa lẹẹkeji, paa lẹẹkẹta, bi oju ọhun ko ba fọ tan, yoo pada di bai bai.
Ìwo kékeré yìí ní ojú bí eniyan, ó sì ní ẹnu tí ó fi ń sọ ọ̀rọ̀ ńláńlá.
Irufe idije nla yii ti o waye keyin nile Afrika, waye lorile-ede South Africa lodun 2010, eyi ti Blatter kosi kabamo pe ile-Afrika sagbateru re.
Ta ni ó ń tọ́jú àwọn aguntan rẹ ninu pápá?
Eyawo yi ni ireti wa wipe yo ran ipinle Kano lowo lati ri wi pe awon olugbe ipinle Kano ri omi ti o dara mu ,ti aleekun yo si ba owo eyi ti  o wo apo ile ise to n mu owo wole ni ipinle naa.
Ọlórí ẹ̀sọ́ ààrẹ ni Al-Mustapha jẹ́ nígbà ti Shofolahan jẹ olùránlọ́wọ́ pàtàkì fún olóògbé náà.
  Aare soro naa di mimo lasiko ipade apero
Kashamu lo ṣoju ila orun ipinlẹ Ogun laarin ọdun 2015 si ọdun 2019.
Àwọn ará Amoni sì tún kọjá sí òdìkejì odò Jọdani, wọ́n bá àwọn ẹ̀yà Juda, ẹ̀yà Bẹnjamini ati ẹ̀yà Manase jà, gbogbo Israẹli patapata ni wọ́n ń pọ́n lójú.
Yewande Famakin: Oríṣun àwòrán, Yewande Àkọlé àwòrán, MVCA7 Award: Ronke Odusanya, Oyebade Adebimpe, Funke Akindele àti Yewande Famakin tani ami ẹyẹ yoo já mọ lọ́wọ́?
Irú ìtara tí ẹ fẹ́ fi ṣe é ni kí ẹ fi parí rẹ̀.
Ní ọjọ́ kan àwọn arakunrin rẹ̀ ń da agbo aguntan baba wọn lẹ́bàá Ṣekemu, 
Ó wà lórí oyè fún oṣù mẹta ati ọjọ́ mẹ́wàá ní Jerusalẹmu.
Goriola Hassan: ‘Tattoo’ tó wà lára mi, kò dí ọba jíjẹ lọ́wọ́, ara oge ṣíṣe ni
Ọpọ igba ni opopona Naijiria ti ko dara ti ṣokunfa ijamba ọkọ ni eyi to ti mu ẹmi awọn eeyan to pọ lọ si ọrun aremabọ.
Igba ẹlẹẹkẹta ree ti ijọba Naijiria yoo fi owo kun owo bẹntiroo lẹnu oṣu meloo sẹyin.
Paulu dáhùn ó ní, “Juu ni mí, ará Tasu ní ilẹ̀ Silisia.
Eyi ko ṣẹyin bi coronavirus ṣe ti ṣakoba fun ọrọ aje.
 Ó jẹ ́ ògun tàbí àwọn ìtọ ́ jú sí àìsàn .
O salaye pe, oun ni igbagbo pe, igberu yoo tunbo ba ajosepo won, ni eyi ti o ki awon omo orile-ede China to wa lorile-ede Nigeria ku amoju ba odun tuntun.
R, da a lọla l'ọdun 1982.
eto idibo yii, yoo lo ni irowo ati irose.
Baruku bá ka ọ̀rọ̀ Jeremaya tí ó kọ sinu ìwé, sí etígbọ̀ọ́ gbogbo eniyan ní yàrá Gemaraya, ọmọ Ṣafani, akọ̀wé, tí ó wà ní gbọ̀ngàn òkè ní Ẹnu Ọ̀nà Titun ilé OLUWA.
Gomina ipinlẹ ipinlẹ Ọyọ, amojuẹrọ Seyi Makinde si ti da si ọrọ naa lọna lati yanju rẹ.
Bi ọrọ naa ṣe n lọ, lootọ ni Okonjo-Iweala, ni ibo to pọju, amọ iyansipo rẹ ko ti i fi ẹsẹ mulẹ.
Eyi ribẹ ẹ lẹyin ti eyan mọkanlelaadọfa, 111, ni ni ọjọ Satide, gẹgẹ bi esi ayẹwo ti ajọ to n gbogun ti ajakalẹ aarun, NCDC, ṣe fi ikede sita.
Bersant Celina lo gbayo keji wọle fun Swansea.
Wọn tun sọ pe idagbere ikẹyin yoo waye lori ẹrọ amohunmaworan AIT, lori ikanni DSTV channel 253.
Wo ohun tó yẹ kí o mọ̀ nípa akínkanjú obìnrin alága àjọ elétò ìdìbò Ghana 2020 Aisha Buhari ké sí àwọn aya gómìnà pé kí wọ́n lọ paná ìdàrúdàpọ̀ lágbègbè yín Góòlù pọ̀ ní ìlú Madaka ṣùgbọ́n wọn kò ní ọ̀nà fún ọgọ́rùn ún ọdún Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ojú mi ti rí lọ́pọ̀ lọpọ̀, àmọ́ mo dúpẹ́ pé mo ti pé ọdún márùn ún lórí oyé- Ooni Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Ondo 2020 Tribunal: Ìgbìmọ̀ olùgbẹ̀jọ́ ìbò gómìnà yóò gbérasọ lọ́jọ́ Iṣẹgun7 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 ASUU strike: Mi ò tíì lè sọ ní pàtó ìgbà tí a ó fòpin sí ìyanṣẹ́lódì wa - Aarẹ ASUU7 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 EndSars in Portharcourt: Ọjọ́ méjì sẹ́yìn ni aya awakọ̀ Márúwá tí ọlọ́pàá pa bímọ tuntun10 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Akure shooting: Àlááfíà ti padà sí ìlú Akure, ẹnikẹ́ni kò kú - Deji ilu Akure7 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Ghana elections result 2020: Èsì ìdìbò tó gbé aàrẹ tuntun wọlẹ́ ní Ghana rèé.
Àwọn ẹran mejeeji yìí kò gbọdọ̀ ní àbààwọ́n.
Awọn onimọ nipa oju ọjọ sọ pe ohun ti yoo fa ijamba ni ki eniyan duro si ita ninu otutu to lagbara naa fun iṣẹju mẹwaa.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Aarẹ Paul Biya ṣe ipade ijiroro lori wahala to n waye ni ẹkùn Anglophone Rogbodiyan Anglophone ni Cameroon Kini yoo ṣẹlẹ nipa rogbodiyan to n waye ni Cameroon, ati ni agbegbe Anglophone , eyi to ti bẹrẹ lati ọdun 2017, to si yọri si iku ọpọ eniyan?
A ní oríṣìíríṣìí ìṣòro, ṣugbọn wọn kò wó wa mọ́lẹ̀; ọkàn wa ń dààmú, ṣugbọn a kò ṣe aláìní ìrètí.
’ rèé Ọlọ́pàá Ondo sọ ohun tí wọ́n mọ̀ nípa ẹni tó pa Ọmọ Fasoranti Ẹ̀bùn Ọlọ́run ni ọmọ bíbí ni mo ṣe bí ọmọ 17 Oloye Oluṣẹgun Ọbasanjọ koro oju si bi awọn agbebọn kan ṣe pa arabinrin naa to si pe awọn agbofinro nija lori riri awọn to ṣiṣẹ laabi ọhun.
Ní èṣí, Ọbásanjọ́ gba Buhari ni ìmọ̀ràn láti má díje fún ipò Ààrẹ fún ìgbà kejì, ṣùgbọ́n kí ó “da ìfẹ̀yìntì rò nítorí ọjọ́ oríi rẹ̀.
Oríṣun àwòrán, Presidency Lẹyin to ṣe bẹ ẹ ni awọn eniyan nlanla lagbo oṣelu naa fi ẹgbẹ naa silẹ - Lara wọn ni akọwe ikede fun APC, Bolaji Abdullahi, ati gomina ipinlẹ Sokoto, Aminu Tambuwal, ati awọn mi i.
Ṣugbọn tí ó bá jẹ́ pé lojumọmọ ni, ẹ̀bi wà fún ẹni tí ó lù ú pa.
O ti lẹ ni ọgbọn ọdun ti wọn ti n ṣiṣẹ lori ti awọn onimọ sayẹnsi lati ile iṣẹ ipoogun GSK bẹrẹ iṣẹ lori rẹ.
Nibẹ ni wọn si ti fun mi ni oògùn lati ṣẹ oyun náà.
Wọn sin oku rẹ si iboji iku Ikorodu nilu Eko.
Kí wọn pọ̀ bí ọ̀wọ́ ẹran, àní bí ọ̀wọ́ ẹran ìrúbọ tíí pọ̀ ní Jerusalẹmu ní àkókò àjọ̀dún.
Mikaya bá sọ pé, “Mo rí i tí gbogbo ọmọ ogun Israẹli fọ́n káàkiri lórí òkè, bí aguntan tí kò ní olùṣọ́.
Minisita fọrọ ilẹ okeere lorilẹede Naijiria, Gofferey Onyeama lo tẹ pẹpẹ ibeere naa siwaju asoju ijọba ilẹ South Africa to ransẹ pe laarọ oni.
Gẹgẹ aabọ iroyin akọroyin BBC, Chris Ewokor, nilu Abuja, ọpọlọpọ eniyan lo f'ara ṣeṣe ninu isẹlẹ naa.
Oríṣun àwòrán, Wellcome Collection Àkọlé àwòrán, Eefin taba jẹ oun kan ti wọn fi koju ajakalẹ aarun 1665 ni London Awọn to n sin oku bẹrẹ si ni fa taba lati le ajakalẹ arun lọ ni agbegbe wọn ni eyi to tun fi jẹ ki iwulo taba pọ sii.
Nígbà tí àwọn ọmọ Israẹli tí wọ́n ti farapamọ́ káàkiri agbègbè olókè Efuraimu gbọ́ pé àwọn ará Filistia ti bẹ̀rẹ̀ sí sá lọ; wọ́n yára dara pọ̀ mọ́ Saulu, wọ́n dojú ìjà kọ àwọn ọmọ ogun Filistini.
Lẹ́yìn náà ó wá sọ pé, “Èmi nìyí, mo dé láti ṣe ìfẹ́ rẹ.
folúkẹ́ ni ó sọ fún ìyá rẹ̀ pé Àṣàké ń fi kọ́kọ́rọ́ dán séèfù wò.
Okunfa ariyanjiyan laarin awọn obi awọn omọ to sọnu, ati awọn alase ni iye ọmọ ile ẹkọ to sọnu ni pato.
Bí ẹni mejì tàbí mẹta bá ti ń sọ ǹkan kan àwọn ìyókù kò ní ronú ní tiwọn mọ́, àwọn náà a si máa sọ ohun tí ojú wọn kò tó.
Ambode gbé ilé aṣòfin Eko relé ẹjọ́ APC, ẹ bá wa bẹ Buhari kó ṣí bodè ká kó ìrẹsì wọlé - Ìjọba Vietnam ń bẹ̀bẹ̀ Àwọn ológun tó fẹ́ maa yẹ káádì ìdánimọ́ aráàlú wò, ìwà àìríṣẹ́ ṣe ni - Ilé aṣòfin Ọjọ́ mẹ́rin sí ìgbéyàwó wa ní ìyàwó mi b'ómi lọ- Ibrahim Abubakar Ẹsun ti wọn fi kan awọn afurasi ọhun ni pe wọn lẹdi apo pọ lati gba owo lọna ti ko tọ, eyi taa mọ si 419.
B Joshua nítori ìṣòro ẹsẹ tí mo ní-Angel Gomes Ọmọ agbábọ̀ọ̀lù Manchester United Angel Gomes ti fèsì fún àwọn olólùfẹ́ rẹ̀ lórí ayélujára ìdí tó fi sàbẹ̀wò sí ìjọ T.
Ibeji ni Kofi Anna jẹ; ekeji rẹ Efua Atta, ku ni ọdun 1991.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Marcus the Pig: Kini ẹlẹ́dẹ̀ aríran fi ṣẹ Naijiria?
Agbajẹ wa tu igbeyawo naa ka ki alaafia le jọba laarin wọn.
Ahasu-erusi ọba gbé Hamani, ọmọ Hamedata, ará Agagi, ga ju gbogbo àwọn ìjòyè yòókù lọ.
Bí òun ti ń bọ̀ ni ẹesẹ̀ rẹ̀ ń dún jinwinjinwin nítorí ọ̀pọ̀lọpọ̀ ìkaraun ìgbín ni wọ́n gé wẹ́lẹ́wẹ́lẹ́, tí etí ọ̀kọ̀ọ̀kan sì ri kiribiti bi etí owó ṣílè, ti wọ́n sì fi okùn so gbogbo wọn pọ̀ ìlẹ̀kẹ̀; tí ẹbọra náà tò wọ̀nyí láti ọrùn ẹsẹ̀ rẹ̀ títí dé orúnkún koko; bẹ́ẹ̀ ni òrùka irin tí ó dúdú bí ọmọ ìka ọwọ́ ìyá aláró ni òun tò si ọwọ́ rẹ̀ gbogbo.
”Wọ́n dá wọn lóhùn pé, “Samsoni ni a wá mú; ohun tí ó ṣe sí wa ni àwa náà fẹ́ ṣe sí i.
Òkúta wúwo, yanrìn sì tẹ̀wọ̀n,ṣugbọn ìmúnibínú aṣiwèrè wúwo lọ́kàn ẹni ju mejeeji lọ.
Ni bayii, ko tii si ọna abayọ si arun naa, amọ iwadii n lọ lọwọ lati ara awọn ti wọn ko arun naa lati wa ọna abayọ si arun Coronavirus naa.
Iyi ti won n fun Aisha Buhari ati igbekele ti won ni ninu aya Aare orile-ede Naijiria naa, yoo safaani fun wa lati le tete dekun atagba aarun HIV laarin awon omo-wewe, bakan naa lati le setoju awon omode ti won n gbe pelu aarun yii”.
Club/ RD Congo), Paul-José Mpoku (Standard de Liège/ Belgique), Gaël Kakuta (Amiens SC/ France), Chadrack Akolo Ababa (VFB Stuttgart/ Allemagne), Cédric Bakambu (Beijing Guoan/ Chine), Benik Afobe (Wolverhampton)/ Grande Bretagne), Britt Assombalanga (Middlesbourgh/ Grande Bretagne), Harrisson Manzala Amiens SC/ France), Firmin Mubele Ndombe (FC Toulouse/ France), Padoue Bompunga Botuli (AS V.
"Ilé ẹjọ sún ìgbéjọ Maina síwájú lati fi okodoro àìlera rẹ hàn Ìhàlẹ̀ Agbaṣẹ́ṣe láti gbé ìjọba lọ sílé ẹjọ́ fẹ tàbùkù ará Ọyọ ni- Ilé Aṣòfin ""Fasola, Nàíjíríà tó ǹ gbé yàtọ̀ sí tiwa lo ṣe ní àsọdùn ni pé ọ̀nà wa kò dára"" Adigunjalè ń bèérè ẹyin, ouńjẹ ati aṣọ lọ́wọ́ àwọn tí wọ́n ń jà lólè Sibẹ awọn miran ninu wọn gba pe iyatọ ti de ba igbesi aye awọn nitori pe ti iya ba to iya fọmọde, o maa yipada ni tipa ni."
Hatami so pe,“Syria wa ni ikorita ti o se pataki bayii, nitori awon ohun ti orile-ede yii ti lakoja seyin lagbara pupo, bee si ni ojuna lati bere atunse ni O wa lowolowo,”Gege bi eka to n mojuto eto oro aje ilu ati oro ayika ninu ajo isokan agbaye, won fi mule pe orile-ede Syria ti padanu ọ́ọ̀dúnrún bilionu o le méjídínláàdọ́rùn ún owo dollar($388bn) lataari oniruuru ijamba ati ogun ti o ti n waye lati odun 2011 seyin.
Lẹ́yìn gbogbo nǹkan wọnyi, OLUWA fi àrùn inú kan tí kò ṣe é wò bá Jehoramu jà.
Àwọn ará Ijipti yóo sì mọ̀ pé èmi ni OLUWA, nígbà tí mo bá gba ògo lórí Farao ati kẹ̀kẹ́ ogun rẹ̀, ati àwọn ẹlẹ́ṣin rẹ̀.
 koda, ile-iwe wa ninu awon ibi ti omiyale naa baje.
Nitori ati lee ṣe iṣẹ ti ọkan rẹ fẹ, Nehar Sharma ni lati daa bi ọgbọn nitori ati lee ṣe iṣẹ ti o yan laayo.
Wòlíì èké 'John of God' tó bá obìnrin 300 lò pọ́ gba ìdájọ́ ẹ̀wọ̀n ọ́dún 19 Páńpẹ́ EFCC ti mú Mínísítà ètò ìdájọ Nàìjíríà tẹlẹ lórí ẹsùn ajẹbanu $1.
" Àwọn ẹ ̀ yà "" p."
''Ofin gbawọn laaye lori igbesẹ yii ati pe, awọn ileeṣẹ to n pese ina ọba ti ṣadehun pẹlu ijọba lati ma san owo ina ọba ti ijọba n pese, ko si le pe wọn ti wọn ko ba ri ọja wọn ta loju owo ti wọn fi ra'' Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Pupọ eeyan lo n lo ẹrọ amunawa lati pese ina fun ara wọn ni Naijiria Olubiyo ni kii ṣe gbogbo eeyan lo le ma fara da aiṣedeede ina ọba paapa julọ, awọn to ba ni ile iṣẹ to n mu owo wa lojumọ.
Olanrewaju ni o jẹ iyalẹnu fun oun pe ẹrọ ibaraẹnisọrọ kan naa lawọn mejeeji jọ lo pọ.
Simeoni bí ọmọkunrin mẹfa: Jemueli, Jamini, Ohadi, Jakini, Sohari ati Ṣaulu, tí obinrin ará Kenaani kan bí fún un; àwọn ni olórí àwọn ìdílé ẹ̀yà Simeoni.
Ile-iroyin AFP so oro inu atejade ilee-ise oko oju ofurufu Emirates naa pe, “Okan lara awon osise oko oju ofurufu jabo ninu oko oju ofurufu naa, nigba ti o n pale oko naa mo lati gbera”.
Lasiko to n ba BBC Yoruba sọrọ ni ayajọ ọjọ ibi rẹ, Alhaja Balogun ni ko si agbẹkẹle mii fun ohun ju Ọlọrunlọ, to si tun n gbadura ẹmi gigun ati alaafia fun ara rẹ ni ọjọ iwaju.
 nígbàtí ó wà pàpà je oba , ibi tí ó fi se ibùgbé tèlè ni wón ńpè ní ilé ató-oba-télè lónìí .
Ọ̀pọ̀ eniyan ni ó ń tẹ̀lé Jesu, pẹlu àwọn obinrin tí wọn ń dárò, tí wọn ń sunkún nítorí rẹ̀.
Ti o ba wa ni ilẹ Gẹẹsi ti o si nilo ayẹwo, mu diẹ lara itọ, igbẹ tabi ẹjẹ rẹ lọ sile iwosan fun ayẹwo naa.
Èyí ni n óo fi mọ̀ pé o ti fi ìfẹ́ rẹ tí kì í yẹ̀ hàn sí oluwa mi.
Ó ní, “Alàgbà, ṣàánú ọmọ mi, nítorí wárápá a máa gbé e, a sì máa joró pupọ.
Wọn kì í tún ṣe ẹni meji mọ́ bíkòṣe ọ̀kan.
Nítorí náà n óo gba waini ati ọkà mi pada ní àkókò wọn, n óo sì gba aṣọ òtútù ati ẹ̀wù fẹ́lẹ́fẹ́lẹ́ funfun mi, tí kì bá fi bo ìhòòhò rẹ̀.
 Ọ ̀ pọ ̀ lọpọ ̀ máàpù ni òǹkọ ̀ wé yà sínú ìwé yìí .
Nigba ti BBC Yoruba tiraka titi titi lati ri ọkọ Risikat ba sọrọ, ọpọlọpọ ọjọ la fi da fidio yii duro tori idọgba gbudọ wa ninu iṣẹ wa gẹgẹ bi ohun ti ẹ fi n wari fun iṣẹ BBC Yoruba, a pada ri baba awọn ọmọ yii ba sọ̀rọ̀.
ba awon akoroyin ile-aare soro leyin ti oun naa ti ba aare Muhammadu Buhari
Ki ni aarẹ ti wọn ṣẹṣẹ dibo yan, Joe Biden ati Donald Trump sọ lẹyin rẹ?
Wòlíì bá obìnrin 300 lò pọ́, ó gba ìdájọ́ ẹ̀wọ̀n ọ́dún 19
Kaakiri orilẹede Naijiria ni awọn janduku ti lọ jo ileeṣẹ ọlọpaa, ti wọn tun lọ si ibugbe ikohunpamọsi, ti wọn si ko awọn nkan elo ounjẹ iranwọ fun aarun Coronavirus, ti ijọba fẹ pin fun awọn eniyan.
Ni Ọjọ Aje ni awọn adari ile isẹ Diamond Bank naa kede idarapọ mọ ile isẹ Access Bank.
NASS 2019: Gbùngbùn Àríwá ní Agbẹnusọ kàn- Umar Bago Nigeria Senate Decides: Ta ni àṣẹ ilé aṣòfin àgbà Nàìjíríà yóò já mọ́ lọ́wọ́?
Akeredolu ni awọn akẹkọọ fasiti ipinle naa to wa ni Akungba, ti fara mọ owo ile ẹkọ tuntun naa.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ogun Majek: Lórí ọ̀rọ̀ Ogun Majek, mi ò lọ́rọ́ láti sọ, ẹ lọ pe ẹni tára rẹ̀ kò Mr.
Wọ́n bá mú Daniẹli wá siwaju ọba.
Ọlọ́pàá gbé àwọn tó yìnbọn lu olólùfẹ́ ní Ajegunle Ọlọ́pàá yìnbọn pa Linda, àgùnbánirọ̀ l'Ábujá 'Ọjọ́ lọjọ́ tí mo mọ̀ pé wọ́n bí mi láì ní ojú ara obìnrin àti ilé ọmọ' Igbesẹ wọn naa si maa n mu ko dabi ẹnipe oju awọn ọlọpaa to ibi gbogbo ni awọn agbegbe naa ni Kenya.
Ninu igbohunsafẹfẹ naa ni Aarẹ ti kọkọ ka awọn aṣeyọri rẹ lati igba to ti gori alefa, lẹyin naa lo kede pe, ijọba ti n gbe igbesẹ lati ṣeto ẹkunwo owo oṣu fun awọn oṣiṣẹ ọlọpaa.
Oladele Michael, eni ti o gba ami-eye ere-idaraya ohun fun igba meji lorile-ede yii, ti o tun je akonimoogba agba ninu egbe Springdale Area Recreation, lopin awon ohun elo naa fun awon olukopa nipinle Eko.
Akanda ẹ̀dá 35 ni mo gbà sẹnu iṣẹ́, màá sì ṣe jù bẹ́ẹ̀ lọ Gomina Ipinlẹ Ondo, Rotimi Akeredolu ti salaye pe oun ti yan àwọn olóṣèlú sípò igbimo olùdarí Ileesẹ ìjọba dáadáa.
Koda, wọn si koro oju si ofin sisan owo ori ti wọn gbe kalẹ Wọn fi ẹhonu yii le ọba ni aafin, lọ se atipo ni ilu Osogbo, amọ wọn pe pada wa sori itẹ lẹyin ọdun meji.
ede Naijiria, asofn Ibrahim Layode, ni  iwe abadofin to da lori adehun igbọra-ẹniye
32 Àti pé nísisìyí, nítorípé mo rí i tẹ́lẹ̀, ète ti ó dúró láti pa ọ run, bẹ́ẹ̀ni, mo rí i tẹ́lẹ̀ pé bí ìránṣẹ́ mi Martin Harris kò bá rẹ ara rẹ̀ sílẹ̀ kí ó sì gba ẹ̀rí láti ọwọ́ mi, pé òun yíò ṣubú sínú ìrékọjá;
Bo tilẹ jẹ wi pe Senegal fiya jẹ Naijiria pẹlu ami ayo meji sodo ninu idije WAFU lọdun 2018, Utin ni didun lọsan yoo so fun ikọ Flying Eagles nigba ti wọn ba koju Senegal lonii.
Nibi ti ajọ to n ri si ọrọ pajawiri lorilẹ-ede Ghana (NADMDO) ti n doola ẹmi awọn eeyan ni wọn ti ri oku eeyan mẹrin lagbegbe Ashaiman, bẹẹ ni wọn tun ri omiran lagbegbe Odorna.
Bi awọn ipinlẹ to ni Coronavirus ṣe lọ ni yii: FCT-75 Eko-71 Benue-53 Delta-39 Borno-30 Enugu-25 Plateau-24 Osun-20 Abia-19 Oyo-17 Kaduna-16 Kano-13 Ebonyi-13 Ogun-9 Kwara-7 Ondo-6 Gombe-3 Ekiti-2 Akwa Ibom-1 Rivers-1 Èèyàn mẹ́tàdínláàdọ́fà jàjàbọ́ lọ́wọ́ Covid-19, 443 míì tún lùgbàdì rẹ̀ lọ́jọ́ Ẹtì Wọn ti kede eeyan mẹtadinlaadọfa to ṣẹṣẹ jajabọ lọwọ arun Covid-19, bẹẹ naa ni wọn tun kede eeyan 443 miran to ṣẹṣẹ ni arun ọhun ni Naijiria bayii.
 Awon oluworan ko sai fi idunnu won han lasiko ti won n fi eti won gbo orin to n  jade bi igba ti awon angeli ba n korin.
Seun Fakorede jẹ ọmọ ọdun mẹtadinlọgbọn ti a bi ni Idere ni ipinlẹ Oyo ni guusu iwọ oorun Naijiria.
wa gba awon igbimo ohun nimoran lati ri daju pe won mu awon eto naa wa si
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 2019 Elections: Èrò àwọn ọmọ Nàíjíríà se ọ̀tọ̀ọ̀tọ̀ lóri ètó àlùfáà tàbí ìmámù lásìkò ìbò Oríṣun àwòrán, FACEBOOK Àkọlé àwòrán, Alaga ẹgbẹ oselu APC, Adams Oshiomole ati Godwin Obaseki lọdun 2016 ni aworan jade ti wọn n jẹ agbado sise laarin igboro.
OLUWA dá a lóhùn pé, “Má ṣe kọlù wọ́n níhìn-ín, ṣugbọn múra, kí o yípo lọ sẹ́yìn wọn, kí o sì kọlù wọ́n ní apá òdìkejì àwọn igi basamu.
Stephen Keshi ni olukọni ikọ Super Eagles ni ọdun naa.
 kí a kúkú sọ pé , láìsí iṣẹ ́ àgbẹ ̀ , kò lé sí ènìyàn nítorí pá oúnjẹ ni ọ ̀ rẹ ́ àwọ ̀ .
Ó sì wí fún mi pé ìhín ni ibi mímọ́ jùlọ.
Ọba Adeyemi ni ''Ijọba Ajimobi jẹ tolori tẹlẹmu sugbọn eeyan ko le ri nkan gba lọwọ ijọba rẹ bi ko ba dara pọ mọ afojusun eto atunto, imupadabọsipo ati gbigbe Oyo si ipo to ga, to ni lọkan'' Alaafin Oyo wa kan saara si awọn isẹ ati ipasẹ rere ti Ajimobi fi lelẹ, eyi to ni ko ni parẹ laelae.
Muideen Ibrahim, to jẹ akọwe apapọ ẹgbẹ naa ni ohun to ṣe pataki sawọn ni lati doola ẹmi awọn ti wọn jigbe.
Aare orile ede Naijiria Muhammadu Buhari ti tun gba ami eye ti aarun romo lapa , romo lese  fun gudugudu meje, yaya mefa ti ijoba re ti se lati gbogun ti aarun yii lorile ede Naijiria.
Nítorí iṣẹ́ ṣíṣe kò jẹ́ kí àwọn alufaa rí ààyè, láti àárọ̀ títí di alẹ́.
Kí Ẹ̀mí Mímọ́ sọ yín di ẹni titun ninu ọkàn yín.
"Lootọ ni wọn pa eeyan kan ni ilu Ipao Ekiti sugbọn ileesẹ ọlọpa si n se iwadi lati mọ boya darandaran fulani lo sisẹ naa tabi awọn kọ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Sextuplet: Àdúrà Ìbùkún ló kú lẹ́yìn ọmọ mẹ́fà yìí- Ifeoma Thelma àti Onyemaechi Chiaka Etò Ẹkọ / Awọn to ti kàwé tán Àwọn ọmọ ilẹ̀ adúláwọ ti wọ́n fẹ̀ lọ sí ilẹ̀ òkèrè láti kàwé, kò ni sí owó ìrànwọ́ tàbi ètò ẹkọ ọfẹ́ nílùú òkèrè bi ti tẹ́lẹ̀ mọ́ Ní àsìkò idẹnukọlẹ̀ ètò ọ̀rọ̀ ajé ọdún 2009, ilé Ekọ UK mú àdínkù bá àwọn owó ti wọ́n fi n rà àwọn akẹ́kọ̀ọ́ túntun lọ́wọ́.
Inu mi kii dun nigba ti mo n ba ri awon omode ti won toro owo ati ounje loju titi.
Oríṣun àwòrán, KoffiOlomide_MM Bakan náà ni ilé ẹjọ Nanterre to wa ní àgbegbè Pari, tún ni ko san iye owo kan náà, nítori ó ràn àwọn obinrin méji kan lọ́wọ́ láti wọ ilẹ̀ France lanà àìtọ́ Agbéjọro Olomidé lásìkò tó ń ba àwọn akọroyin sọ̀rọ̀ sọ pé, òun ri ìgbéjọ náà gẹ́gẹ́ bi àṣeyori nítori èyí yoo yọ Koffi kúro nínú ìwé ìpẹ̀jọ àgbáyé, to fẹ fi sẹ́wọ̀n.
Máa lọ sí Giligali ṣiwaju mi.
“Ṣé eniyan meji lè jọ máa lọ sí ibìkan láìjẹ́ pé wọ́n ní àdéhùn?
Wọ́n ń wí láàrin ara wọn pé, “Ọba Dafidi ni ó gbà wá lọ́wọ́ àwọn ọ̀tá wa, òun ni ó gbà wá lọ́wọ́ àwọn ará Filistia, ṣugbọn nisinsinyii, ó ti sá kúrò nílùú fún Absalomu.
Ṣaaju ni awọn gomina ipinlẹ mẹrindinlogoji lorilẹ-ede Naijiria kede pe awọn ko le san ju ẹgbẹrun mejilelogun ataabọ naira lọ gẹgẹ bi owo osu oṣiṣẹ to kere julọ lẹyin ipade pajawiri ti wọn ṣe lọjọ Iṣẹgun.
Ranṣẹ pe Daniẹli yìí, yóo sì sọ ìtumọ̀ fún ọ.
eto idibo aare ti yoo waye lọjọ kẹ́rìndínlógún, osu keji, ni minista fun abẹle
Davido sọ̀kò ọ̀rọ̀ sí Oyetola lẹ́yìn tí 'èèyàn méjì pádánù ẹ̀mí wọn' níbi ìwọ́de End SARS Osogbo Tọkọtaya arúgbó: Eré ìfẹ́ wa kò wà láti bímọ, a kàn ń tẹ̀ẹ́ sójú rẹ̀ ni Òkú tó jí lọ́jọ́ kejì ní mọ́ṣúárì padà kú síléèwòsàn Ogbomosho shooting, End Sars, End SWAT: Isiaka Jimoh fi ọmọbìnrin kan àti ìyàwó tó lóyún sínú sílẹ̀ ló- Òbí Isiaka Ileesẹ ologun ni akanse eto ni Crocodile smile ọdun yii nitori ogun nla lo fẹ gbe ti iwa ọdaran lori ayelujara.
Lẹ́yìn ọpọlọpọ ọjọ́ a óo ko yín jọ.
Gbogbo nǹkan yòókù tí Josaya ṣe ni a kọ sinu Ìwé Ìtàn Àwọn Ọba Juda.
O ni irọ ni awọn amugbalẹgbẹ igbakeji gomina naa n pa pe, ijọba ipinlẹ Ondo n dẹyẹ si wọn, ati pe amofin agba ni gomina Rotimi Akeredolu, ko si ni ṣe ohun kankan ti yoo lodi si ofin.
ditẹ gba  ijoba nipa lilo iko omo –ogun.
Ọjọ Aje ni Abeokuta ni Adajọ Wakkil Alkali Gana ti dajọ wi pe ibo ti o gbe Kọlapọ wọle ko dan mọnran.
2 Nítorí tí ó ní ìmísí ti Ẹ̀mí Mímọ́ láti fi ìpìlẹ̀ náà lélẹ̀, àti lati kọ́ọ sókè sí ìgbàgbọ́ mímọ́ jùlọ.
Ojelade wa di agba ọjẹ laarin awọn eleegun to si lokiki pupọ de ibi pe Alaafin Oyo nigba naa pada fi jẹ oye Baalẹ Arẹkujaye lẹyin to dije pẹlu Duduyẹmi, agba eleegun miran.
Bakan naa ni ayẹwo ẹjẹ gbogbo wa fihan pe orisun kan naa (Philippe) ni kokoro aarun naa gba wọ ara wa.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù L'Ondo, àwọn agbébọn jí alága káńsù tẹ́lẹ̀ gbé 29 Agẹmo 2018 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Iṣẹlẹ ijinigbe ti n di gbọnmọgbọnmọ bayi nipinlẹ Ondo Awọn agbebọn ti ji alaga tẹlẹ fun ijọba ibilẹ ariwa Akurẹ nipinlẹ Ondo, ọgbẹni Dele Fagoriọla gbe.
Bí igi ọ̀pọ̀tọ́ kò tilẹ̀ rúwé,tí àjàrà kò sì so,tí kò sí èso lórí igi olifi;tí àwọn irúgbìn kò sì so lóko,tí àwọn agbo aguntan run,tí kò sì sí mààlúù ninu agbo mọ́,
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Forceful Penetration: Bí ó bá ṣe obìnrin ló fi agídí mú ọ̀kùnrin bá a lò pọ̀ ńkọ́?
Nígbà tí wọ́n sọ fún Jakọbu pé Josẹfu ọmọ rẹ̀ dé, ó ṣe ara gírí, ó jókòó lórí ibùsùn rẹ̀.
Ó ní gbogbo ọ̀nà tó ń gbà láti mú ìdàgbàsoké ba ilé yorùba jẹ ohun ìwúrí.
Ni ọjọ kan, nigba ti Shina wa ni ọmọ ọdun meje, baba rẹ gbe apo nla kan to kun fun owo pupọ wa sile.
 Bakan naa ni wọn yan awọn ọndije  marundinlaadọta miiran si ipo, eleyii to waye lọjọ Abamẹta to kọja ni Alausa ni ilu Ikeja.
O ni awọn ri owo yii lọna meji nibi ijamba ọkọ to ṣẹlẹ ni Birnin Kebbi ati ni ijoba ibilẹ Argungun nipinlẹ Kebbi.
Ṣé Ọlọrun ti gbàgbé láti máa ṣoore ni;àbí ó ti fi ibinu pa ojú àánú rẹ̀ dé?
Ẹ ranti bí ilẹ̀ ti lanu, tí ó sì gbé wọn mì ati àwọn ati gbogbo ìdílé wọn, ati àgọ́ wọn, ati gbogbo iranṣẹ ati ẹran ọ̀sìn wọn, láàrin gbogbo Israẹli.
Nígbà tí a dé òkè tán ó tún yà sí apá ọ̀tún, bẹ́ẹ̀ ni mo yà tì í,nígbà tí a sì rin bí ẹsẹ̀ mẹ́fà ó yà si apá òsì, mo sì tún yà ti í, nígbà tí a tún rin bí ẹsẹ̀ mẹ́fà lẹ́hìn èyí ó tún yà sí apá ọ̀tún, bẹ́ẹ̀ ni èmi náà si tún yà tì í, lẹ́hìn eléyìí wàyí o, mo wáá rí àkàsọ̀ kékeré kan, nígbà tí òun sì gun eléyìí, mo gùn ún tẹ̀lé, nígbà tí a sì dé òkè tán mo bá ara mi ní orí òrùlé tí ó tẹ́jú pẹrẹsẹ tí ó si jẹ́ òkùta pátápátá.
Salkidatun sọ pe awọn agbesunmọmi naa ninu fọnran fidio ti oun ri ṣeleri lati pa awọn oṣiṣẹ to ku.
O ni oun ti ba gbogbo awọn ọmọ APC to n binu atawọn to ti kuro sọrọ, wọn si ti gba lati pada sinu ẹgbẹ.
Saulu bèèrè pé, “Báwo ló rí?
Nítorí náà, kí ló dé tí a óo fi kú?
Ìdí nìyí tí a fi ń ki ìlú náà pé;
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Water Resources Bill: Wo ohun tó wà nínú òfin nípà àbádòfin lórí omi tí ìjọba rẹ́ buwọ́lù 23 Owewe 2020 Oríṣun àwòrán, Others Ọdun 2018 ni ijọba Naijiria kọkọ mu aba naa wa siwaju ile igbimọ aṣofin kẹjọ.
Oludari agba ile iṣẹ to n ṣamojuto awọn ọgba ẹwọn ni Naijiria ti wa fọrọ sita si awọn araalu lati dakun pese ọrọ to ba wulo ti wn ba ri to lee muṣẹ ya lati ri awn to sa lọ yii pada.
Ijamba baalu mu ẹmi mejilelọgbọn lọ Ijamba baalu pa eeyan 66 ni Iran A kò lè gba àwọn jandùkú Fulani láàyé nílẹ̀ Yoruba -Awọn gómínà Háà!
Aare Buahri ni: “Inu mi n dun fun aseyori awon ewe Naijiria nile ati loke okun.
Amọ o se ni laanu pe, wọn ka ibo naa de idaji, ni ijọba ologun nigba naa lọhun lai ni idi kan pato kede pe, wọn ko gbọdọ ka esi ibo naa mọ.
Ní ọjọ́ keji mo jókòó ní kóòtù, mo pàṣẹ kí wọ́n mú ọkunrin náà wá.
Mo sunkún lọpọlọpọ nítorí kò sí ẹnikẹ́ni tí ó yẹ láti ṣí ìwé náà ati láti wò ó.
A si ti di tọkọtaya fun bi ogun ọdun, bẹẹ la ti bimọ.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Biṣọ̀bu ijọ Katoliiki niluu Abuja, Ẹniọwọ John Onaiyekan kilọ pe awọn adari lorilẹede NAijiria gbọdọ ṣe ohun to tọ fun atunṣe ati idagbasoke orilẹede Naijiria Ni oṣu keji ọdun yii ni aarẹ Buhari bori ninu idibo sipo aarẹ lorilẹede Naijiria to jẹ orilẹede to n pọn epo rọbi julọ nilẹ Afirika ṣugbọn ti ida kan ninu mẹrin awọn eeyan rẹ ko ri iṣẹ ṣe.
Gẹgẹ bi ohun ti ajọ naa sọ, wọn ni awọn ileto bi mẹrindinlọgọta lawọn de lawọn ilu bi Adamawa,Banue,Kaduna Taraba ati Zamfara lati fi idi ọrọ naa mulẹ.
Wọ́n tú aṣọ lára rẹ̀, wọ́n kó àwọn ọmọ rẹ̀ lọkunrin ati lobinrin; wọ́n sì fi idà pa òun alára.
Jesu wí fún un pé, “Èmi ni ọ̀nà, ati òtítọ́ ati ìyè.
) Baba yín sá mọ̀ pé ẹ nílò wọn.
pari boolu won ni  William Troost
O ni, Kodaa wọn ti sọ awọn yara ikẹkọọ di ibi ti wọn n sun si gẹgẹ bi wọn ṣe fọn gbogbo ohun ini wọn si ayika ile ẹkọ naa""."
Ètò ìsìnkú Ibidunni Ighodalo wáyé lórí ẹ̀rọ amóhùnmáwòrán Ijọ Trinity House ti sọ pe eto isinkun aya oludasilẹ rẹ to doloogbe, Ibidunni Ighodalo yoo waye lori ẹrọ amohunmaworan bo ba ṣe n lọ lọwọ.
Ó rí i tí ará Ijipti kan ń lu ọ̀kan ninu àwọn Heberu, ẹlẹgbẹ́ rẹ̀.
Gbogbo àwọn onigbagbọ bá túká lọ sí gbogbo agbègbè Judia ati Samaria.
Oríṣun àwòrán, EKITI STATE GOVERNMENT Ọjọ iwaju awa ọdọ ni wọn fi n ṣere yẹn.
 a bi ní ìlú abẹ ́ òkúta ní Ìpínlẹ ̀ Ògùn .
Aṣofin Obasa tun rọ awọn ọmọ orilẹ-ede Naijiria
Ajakale àrùn yìí sí lọ wáyé láàárín ọdún 1855 sì 1959.
Gege bi ile-ise eka panapana se so, won ni isele ohun lagbara pupo ti awon eniyan metadinlogbon miran si farapa yanayana.
Àmọ́ fún àwọn tó ngbé ní ìhà aríwá tàbí gùsù àgbálá-aiyé, ìyàtọ̀ hàn gedegbe.
"Ofin to de ọrọ yi ti wa lati dun 1881 ti wọn si n pe ni ""lese majeste."
Òṣì lásìkò ǹkan oṣù máa n wáye ti àwọn ènìyàn kò bá níṣẹ́ tó n mówó jáde láti ra àwọn páàdì ǹkan oṣù tó jẹ́ ojúlówó.
"Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Say no to rape: Àwọn òṣèré tíátà Yorùbá pariwo síta lórí wàhálà ìfipábánilòpọ̀ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Àwọn fíìmì òde òní ń kọ́mọ lólè àti ọ̀pọ̀ ìwà burúkú Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Niyi Akinmolayan tó ṣe fíìmu àwòrán-dèèyàn Cartoon nípa COVID-19 tó la ayé já ní N Ṣe abinibi ni ede Ijesha ninu fiimu ni tabi ""ability""?"
Pẹlu agba oṣere mii bii Yinka Quadri, Antar Laniyan, wọn ni aarẹ ẹgbẹ awọn ti fi agba ba wọn sọrọ.
Ẹ ní ìtara láti pa ìṣọ̀kan ti Ẹ̀mí mọ́ ninu alaafia tí ó so yín pọ̀.
Àwọn òṣèré tíátà kan rèé, tí wọn fẹ́ ara wọn, tí ìgbeyàwó wọn sì pẹ́ Òṣèrébìnrin tí wọ́n bá fi ìbálòpọ̀ lọ̀ 'torí ìṣẹ́, kó bọ́ síta láti sọ̀rọ̀ - Kunle Afod Saraki àgbà ló kọ́ ilé yìí fáwa arúgbó kìí ṣe Bùkọ́lá- Arúgbó Ilọrin Wo àwọn èèyàn jáńkán tí yóò ṣe ọdún tuntun ní ọgbà ẹ̀wọ̀n Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Ohun tí ó bá sì ti di ògbólógbòó, kò níí pẹ́ parẹ́.
Lafikun,awọn amoye kan ni sisi ipo pada lati inu ẹgbẹ APC lo si PDP le fe se idiwọ fun awọn oludije yi nitori o ni awọn kan to wa ninu gbẹ PDP tele ti awn naa f du ip Gomina nipinlẹ Kwara.
lorile ede Naijiria, (christian Association of Nigeria ,CAN) ni agbegbe naa,
"Ni ọdun diẹ sẹyin nigba ti o n ṣe odiwọn boya yoo kara bọ idije aark lọdun 2016, Biden sọ pe ""mo lee ku gẹgẹ bi eeyan ti inu rẹ dun bi mi o ba jẹ aarẹ""."
Baba Lẹgba lo maa n sere awada pẹlu baba Sala laye ọjọsi, ki agba to de.
Aare Buhari wa fokan  awon omo orile ede Naijiria balẹ pe egbe APC yoo tesiwaju lati maa pese eto isejoba rere , ni eyi ti yoo fi mu igbeaye –iderun ba tonile-talejo.
Wọn fi ẹsun kan Adanlawo pe o fi ipa ba ọmọbinrin, ọmọ ọdun mẹwaa, to jẹ ti oludasilẹ ṣọọṣi to n lọ lopọ lọjọ kẹrinlelogun, oṣu Kẹjọ, ọdun 2018 ni ile awọn obi rẹ ni Iju, nipinlẹ Ọndo.
Buhari ti rinrin ajo silẹ okeere nigba mẹrin laarin oṣu mẹta to kọja.
Ṣé ìjìnà síra-ẹni ṣe paàtàkì lẹ́yìn lílo ìbòmú?
Nkan bii ida marundinlaadọrun olu ilu orilẹede naa, Minsk lo bajẹ ninu iṣẹlẹ ibugbamu ado oloro ti wọn si tun un kọ ni 1950s ati 60s.
Diẹ lara awọn oju opo ololufẹ to gbajumọ lori ayelujara nilẹ Naijiria ni matchbybade, halal_matchmaking ati abujamatchmaking.
Eto idibo to m bọ lọna ni awọn orilẹ-ede bii Burkina Faso, Cote d'Ivoire, Ghana ati Niger ki gbogbo rẹ lọ ni rọwọ-rọsẹ lai mu ẹmi ara ilu dani.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ìwà ipá nínú ìdílé máa ń bí ìgè àti àdùbí ni tó lè já sí ikú Ṣé ó tọ̀nà kí obìnrin máa bímọ sílé?
Ọmọ ọdún marundinlogoji ni Jehoṣafati nígbà tí ó jọba, ó sì wà lórí oyè ní Jerusalẹmu fún ọdún mẹẹdọgbọn.
Dúró lẹ́bàá ọ̀nà kí o máa ṣọ́nà, ìwọ tí ò ń gbé Aroeri!
Ẹ̀ṣẹ̀ tí àwọn ọmọ Eli ń dá yìí burú pupọ lójú OLUWA, nítorí pé wọn kò náání ẹbọ OLUWA.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: N3.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù APC: Wọn kò fún wa láàyè láti dibo nígbà ti ẹ̀ri wà pe ẹgbẹ́ PDP ń díbo ní àìmọye ìgbà 25 Ẹrẹ̀nà 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Aminu Tambuwal to jawé olúbori ńi ìpínll Sokoto Ẹgbẹ́ òsèlú APC, ẹka ti ìpínlẹ̀ Sokoto ti fi ààké kọ́ri pe àwọn kò faramọ èsì àtúndi ìbò tó wáye lọjọ Sátide, nibi ti Gomina Aminu Tambuwal, oludije ẹgbẹ òṣèlú PDP ti jáwé olúbori.
Ìjọba pàṣán ni ìjọba Buhari yóò jẹ́ fún Nàìjíríà ní sáà kejì- Ṣoworẹ Ọjọ́ Àbámẹ́ta la ó mọ ẹni tí yóò lékè láàrín bàbá ìsàlẹ̀ àti àwọn mẹ̀kúnnù nipinlẹ̀ Ọyọ.
Ikú Floyd fa iwọde jakejado America.
Ìpìlẹ̀ ilé Ọlọrun tí Solomoni fi lélẹ̀ gùn ní ọgọta igbọnwọ (mita 27), ìbú rẹ̀ sì jẹ́ ogún igbọnwọ (mita 9).
jo je omo orile-ede kan naa David Ferrer,
21 Àti pé mo pàṣẹ fún ọ pé kí o má ṣe wàásù ohun míràn ṣùgbọ́n ìrònúpìwàdà, àti kí o máṣe fi àwọn ohun wọ̀nyí hàn fún ayé títí yíò fi jẹ́ ọgbọ́n nínú mi.
Àkọlé àwòrán, Ariwo gee lori awon omo ijo lati enu awon oluwode Àwọn olùwọ́de ń hó lé àwọn ọmọ ijọ COZA ni Eko bi wọ́n ṣe n jáde.
Senato Dino Melaye ati Senatọ Ben Murray Bruce, naa ṣọfọ Ras Kimono pe: “iku oro rẹ da?
Nítorí pé oriṣa Moleki yóo lọ sí ìgbèkùn,pẹlu àwọn babalóòṣà rẹ̀ ati àwọn ìjòyè ní ibi ìsìn rẹ̀.
Ṣugbọn nkan ti idajọ naa tumọ si nipe ijọba le tẹsiwaju lati fa abẹrẹ olóró si ara àwọn ọ̀daràn naa lati sekupa wọn.
Ó kó àwọn nǹkan wọnyi kalẹ̀ fún ẹbọ alaafia: akọ mààlúù meji, àgbò marun-un, òbúkọ marun-un ati ọ̀dọ́ àgbò marun-un ọlọ́dún kọ̀ọ̀kan.
gbomi ewuro si  ikọ agbabọọlu indomitable lions  ti orile ede Cameroon loju.
Ní òwúrọ̀ kutukutu ọjọ́ keji, wọ́n ṣe ìbúra láàrin ara wọn, Isaaki bá sìn wọ́n sọ́nà, wọ́n sì kúrò lọ́dọ̀ rẹ̀ ní alaafia.
Bí inú OLUWA bá dùn sí mi, bí mo bá bá ojurere OLUWA pàdé, yóo mú mi pada, n óo tún fi ojú kan Àpótí Ẹ̀rí náà ati ilé OLUWA.
Ọ̀kanòjọ̀kan ìfẹ̀hànnúhàn kò ṣe nǹkan kan, àwọn iṣẹ́ ìdarí-omi ṣíṣàn ṣì ń lọ, pàápàá jù lọ ní Laos àti Thailand.
Ọpọ awọn ọmọ Naijiria ti bẹrẹ si ni n fi ero wọn lede, lẹyin iroyin iku agbabọọlu naa, ti wọn si n bu atẹ lu ikọ SARs naa.
org le ràn án ọ́ lọ́wọ́, bákan nàá ni ti BBC Reality Check .
Aarẹ aṣa: Ibeere nla ni pe ṣe Oluwo ṣe ohun gbogbo to yẹ ko too gori oye?
Aare Buhari so pe , “
” Ṣugbọn àwọn alufaa kò tètè lọ.
kankan ti o duro lati gbẹjo fun awon eniyan naa.
Kete lẹyin eyi ni iroyin gba igboro kan pé wọn ti taku sinu iyara ile itura wọn pe awọn ko ni tẹ̀ta afi ti ijọba Naijiria ba san owó ajẹmọnu awọn.
 Adura mi ni pe , ki idibo naa lo ni irowo ati irose.
thomas stearns eliot om ( Ọjọ ́ kẹrìndínlọ ́ gbọ ̀ n oṣù kẹsán Ọdún 1888 - Ọjọ ́ kẹrìn oṣù kínín Ọdún 1965 ) jẹ ́ akọ-ewì ará amẹ ́ ríkà , olùkọ ̀ wé ere orí-ìtàgé àti olùyẹ ̀ wò lítíréṣò .
O jẹ ọmọ ogun labẹ idari Ọgagun Adeniran, o si jagun nilu Akwa, Abagana ati Onitsha.
Nígbà tí wọ́n ti la Misia kọjá, wọ́n dé Tiroasi.
24 Nítorínáà, gbogbo ènìyàn gbọ́dọ̀ gba orúkọ náà sí orí ara wọn èyítí Bàbá fi fúnni, nítorí nínú orúkọ yìí ni a ó pè wọ́n ní ọjọ́ ìkẹhìn;
Ẹ sin OLUWA ninu ẹwà ìwà mímọ́;gbogbo ayé, ẹ wárìrì níwájú rẹ̀.
Ṣugbọn mò ń sọ fun yín pé kí ẹ jẹ́ kí Ẹ̀mí máa darí ìgbé-ayé yín, tí ẹ bá ń ṣe bẹ́ẹ̀ ẹ kò ní mú ìfẹ́kúfẹ̀ẹ́ ara ṣẹ.
Ẹ o ba tilẹ ro wipe ori itage ni ṣugbọn pẹlu akọle to kọ sita, ko si ani ani pe o wa lori akete aisan.
Oba Olugbo ti Ugbo wa rọ Gomina Oluwarotimi Akeredolu lati lo gbogbo ohun to wa ni ikawọ rẹ lati gbogun ti awọn aṣekupani ni ipinlẹ Ondo.
Nígbà tí Saulu gbọ́ ohun tí ó ṣẹlẹ̀ sí àwọn oníṣẹ́ rẹ̀, ó rán àwọn mìíràn, àwọn náà sì bẹ̀rẹ̀ sí sọ àsọtẹ́lẹ̀.
Lagos 2019: Àwọn ọmọ ẹgbẹ́ awakọ̀ èrò ṣíná ìbọn níbi ìpolongo ìbò Sanwo-Olu l'Eko
Ajọ eleto ilera agbaye, WHO ti sọ pe ko si otitọ ninu ahesọ bẹ.
Bẹ́ẹ̀ ni kí ẹ má ṣe kùn bí àwọn mìíràn ninu wọn ṣe kùn, tí Apani sì pa wọ́n.
26 Bélú 2020 Amos Dauda, Iphone: Ilé ẹjọ́ dájọ́ ẹgba mẹ́ẹ̀dóògún fún ọ̀daràn tó jí Iphone ní Kaduna25 Bélú 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Awọn iroyin ti ẹ lee nifẹẹ si: Ishaq Oloyede: Jamb ko ni fi esi idanwo silẹ lẹsẹkẹsẹ EFCC: Akala se magomago biliọnu mọkanla at'aabọ naira Sugbọn iroyin fi ye ni wipe nigba ti arabinrin naa koju aajọ EFCC nibi iwadi ti wọn nse, o sọ wipe ọrọ naa ko ri bẹẹ mọ, ati wipe, ejo kọ lo gbe owo naa mi, sugbọn ọga oun lọọfisi, Samuel Sale Umoru, to jẹ adari ajọ Jamb ni Markurdi lo gba owo naa lọwọ oun.
Working religious women: Ẹ̀lẹ́hàá kìí ṣe ọ̀lẹ- Aminat Adegoke
“Nítorí náà, ẹ̀yin, olùṣọ́-aguntan, ẹ gbọ́ ohun tí OLUWA wí.
 ogójì ọjọ ́ tàbí jù bẹ ́ ẹ ̀ lọ ni wọ ́ n máa ń fi ṣe opó .
Iṣẹlẹ naa waye ni agbegbe Mazamaza ni ijọba ibilẹ Amuwo Odofin ni ipinlẹ Eko.
Olukuluku kọjú sí ìhà mẹrin, ó sì lè lọ tààrà sí ìhà ibi tí ẹ̀mí rẹ̀ bá darí sí láì ṣẹ̀ṣẹ̀ yí ojú pada kí ó tó máa lọ.
Aare ni: “Inu mi dun pe, ẹ wa lati ba mi yọ  fun aseyọri eto idibo aare ti mo se.
Arakunrin kan, Michael Adeniran sọ pe wọn ko gba oun laye lati wọle sinu ọgba ileeṣẹ naa, to si fi kun pe, wọn ni igbeṣẹ naa ko ṣẹyin ikede nipa arun Covid-19 lati ọdọ ileeṣẹ eto ilera Naijiria.
Wọ́n gé ẹran àgbò náà sí wẹ́wẹ́, ó sun gbogbo rẹ̀ pẹlu orí rẹ̀ ati ọ̀rá rẹ̀ lórí pẹpẹ.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: ‘Jẹgúdújẹrá làwọn olórí tó ń lọ sókè òkun láti sèpàdé’ Ọ̀gá àgbà iléèṣẹ́ ọlọ́pàá dín wákàtí iṣẹ́ ọlọ́pàá kù Ìyàwó mi gbà kí n kó ipa ìfẹnukonu tó wọra - Yemi Blaq Mí ò lè kúnlẹ̀ kí ìyá mi mọ, ìyámi ló ń kúnlẹ̀ ki mi Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí kan sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
Wọn gbe igbesẹ yii lẹyin ti ariwo pọ lori bi awọn Gomina tele ri kan nipinlẹ ọhun, ti n gba owo laaye wọn gẹgẹ bi Sẹnẹtọ ati lakoto ijọba ipinlẹ bakanna.
Ó ti gba onírúurú àmì ẹ̀yẹ níle àti lẹ́yìn odi.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Jesus in Kenya:Ta ni ọkùnrin tí wọ́n ń pè ní ayédèrú Jesu yìí gan an?
Ti OLUWA ni gbogbo ọ̀rá ẹran.
Má sọkún nítorí wọn, má sì bẹ̀bẹ̀ fún wọn, nítorí n kò ní gbọ́, nígbà tí wọn bá ké pè mí nígbà ìṣòro wọn.
Sugbọn ni ogunjọ osu Kẹwa ọdun 2020, tijọba ipinlẹ Eko kede ofin konile o gbele tiẹ, ni iroyin tan kalẹ ni irọlẹ ọjọ naa pe awọn ologun ti lọ kọlu awọn ọdọ to n se iwọde lẹnu iloro Lekki nilu Eko.
- Nkechi Blessing Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Nigeria movie industry: Àgbà òṣèré, Lere Paimo ní àìgbọràn ló ń da ọ̀pọ̀lọpọ̀ àwọn Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Ondo State Election result 2020: Bí èsì ìdìbò gómìnà ìpínlẹ̀ Ondo ṣe ń jáde rèé.
Fi ọ̀nà rẹ hàn mí, OLUWA,kọ́ mi ní ọ̀nà rẹ.
Ẹnìkan wà tí ó ń jẹ́ Baraba, tí ó wà ninu ẹ̀wọ̀n pẹlu àwọn ọlọ̀tẹ̀ kan tí wọ́n pa eniyan ní àkókò ọ̀tẹ̀.
Ìbọn pa èèyàn mẹ́ta lásìkò ayẹyẹ Ọdun Oúnjẹ Inú mi dùn pé ẹni tó gbà ìjọba lọ́wọ́ mi ń san gbèsè tí mo fi kalẹ - Aregbesola EFCC: Àwọn ọba aládé àti olóṣèlú ṣé àpapín owó ìrànwọ́ N2bn ní Kwara Ẹni mẹ́ta gbé Buhari lọ sílé ẹjọ́ nítorí pé ó parọ́ ìwé ẹ̀rí rẹ̀ fún àjọ INEC Alákoso iṣẹ́ àti ìrìnnà ní ìpínlẹ̀ Eko, ọgbẹ́ni Adedamola Kuti sàlàyé pé pẹ̀lú ìwòye àwọn lóri bí ìgbòkègbodò ọkọ̀ yóò ṣe pọ̀ tó, ó di dandan kí ẹdínkù bá ìṣẹ́ tí wọ́n yóò ṣe ni àsìkò náà.
Akintayo Blessing Christiana safihan ero rẹ naa lasiko to n ba BBC Yoruba sọrọ lori fidio Wonma ti Olamide Baddo ṣẹṣẹ ṣe sita.
Gẹgẹ bi awọn mọlẹbi rẹ ṣe sọ ọ, lati ọjọ iṣẹgun ọjọ kẹtalelogun oṣu kẹrin lo ti di awati laafin nigba tawọn kan ba a lalejo.
O fi kun imọ ẹkọ rẹ ni Army Mechanincal Transport School, Borden ni ilẹ United Kingdom.
Ahmed Musa (Al Nassar FC, Saudi Arabia); Victor Osimhen (Royal Charleroi SC,
"Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Làá hàn mí: Ètò yìí ló ń kìlọ̀ fún wa láti mú ìmọ́tótó ní pàtàkì láti dènà Coronavirus ""Ijọba wa ti se gudugudu meje ati ya ya mẹfa, lati dena itankalẹ arun Coronavirus, o si yẹ ka gbe osuba nla fun awọn adari wa lori bi wọn se tete kofiri arun naa, ko to bẹrẹ si ni se ọsẹ fun wa, ti wọn si tun tọpasẹ awọn eeyan to se alabapade ẹni to ni arun naa."
Lowuro Ojo Aje ni awon agbofinro dena awon omo ile igbimo asofin méjìlélógún lati wọ ile igbimo naa.
Awọn agunbanirọ naa n rinrin ajo lati ilu Ibadan lọ si Ipinlẹ Rivers ati Akwa Ibom l'Ọjọru ki wọn to ji wọn gbe loju ọna mọrosẹ ilu Owerri si Port Harcourt.
Egbe awon olowu ni Naijiria ti a mo si Cotton Ginners Association of Nigeria ti parowa fun ijoba apapo pe ki won fi ofin de kiko owu wole lasiko yiiAare egbe naa, Salman Abdullahi, lo so eyi di mimo fawon akoroyin lasiko to n soro lori akoba ti kiko owu wole n se ninu oko Naijiria pe:“A ti rii pe awon olokowo kan latile okeere n gbiyanju lati dokowo po pelu Naijiria pelu ipinnu nini agbara sii lati maa ko owu wole lati orile ede won ni eyi ti a ko faramo nitoripe yoo ba ise awon agbe olowu gbigbin je nile ni ni eyi ti yoo so owu rira di goolu mo wa lowo ti aso yoo si tubo gbowo lori sii ni.
Malam Bello Danbatta, ti o  je oludari ajo to n mojuto isele pajawiri  ni ipinle Borno, to wa nibi isele naa ,so pe awon okunrin olote meji naa gbemi mi ,nigba ti ado oloro ti won de mo ara won,  ja si won lara ni agbegbe Kaleri.
jọ̀wọ́, gbọ́ láti ọ̀run, kí o sì dáríjì àwọn eniyan Israẹli, àwọn iranṣẹ rẹ.
Jahati ni baba Ahumai ati Lahadi.
a Akala sàlàyé fún àwọn oníròyìn pé, ẹni tó gbé okú ọkùnrin náà ni wọ́n ń pe ni Eze, àti pé ni kété tó gbée kálẹ si ibi eti kana ni agbègbè afára Aboru ló kó àwọn jàǹdùkú míràn láti Aboru ló bá àwọn ara Mosan.
Laipẹ yii ni ijọba ipinlẹ eko kede pe awọn ile ijọsin le di ṣiṣi pada lẹyin bi oṣu maarun ti wọn ti wa ni titi pa nitori aarun coronavirus.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù FRSC: èyí kọ́ ni ìgbà àkọ́kọ́ tí èyí máa ṣẹlẹ̀ 20 Ògún 2019 Oríṣun àwòrán, @FRSC Àkọlé àwòrán, Iwa ibajẹ riba gbigba gbọdọ dopin ni Naijiria Ọwọ òfin ti tẹ àwọn oṣiṣẹ aabo oju popo mẹtadinlogoji nitori rìbá gbígbà.
Oríṣun àwòrán, Reuters Àkọlé àwòrán, Omí pọ̀ ju ọkà lọ fún Unai Emery, ìfìdírẹ̀mi mí ló bade fún lọ́wọ́ Frankfurt Niṣe ni igbe ọọbi gba nu awọn alatilẹyin ẹgbẹ naa lẹyin ifẹsẹwọnsẹ pẹlu Frankfurt ti oju opo Twitter si kun fun ikunsinu lori bi o ti ṣe n tukọ ẹgbẹ naa.
Èrè ti Nàìjíríà yóò jẹ nínú Báwo ni ọ̀rọ̀ Iran àti US yìí ṣe kan ilẹ̀ adúláwọ̀ gan Njẹ́ ẹ mọ̀ pé orílẹ̀-èdè Nàìjíríà ló n wo 'Blue film' jù?
Ajọ NCDC lo fi lẹde bẹẹ soju opo ikansiraẹni Twitter won lẹyin ti awọn onimọ sayẹnsi ni Ilẹ Gẹẹsi ti fi lede pe oogun Dexamethasone n ṣiṣẹ koju ajakalẹ arun Coronavirus.
Mi ò to iṣẹ́ Regina Daniels rárá kí n tó fẹ́ ẹ láàrin ọ̀sẹ̀ mẹ́ta, mo sì tún le fẹ́ ìyàwó míì - Ned Nwoko Ohun tó yẹ kẹ́ẹ mọ nípà olùdíje mèjì tó lágbára nínú ìdìbò Ghana rèé Àyà mi já nígbà tí Ganduje rọ Sanusi lóyè Emir Kano tó fi Bayero síi, ṣùgbọ́n.
Obasanjo/Facebook Àkọlé àwòrán, Nile ẹjọ nibi ti Gbenga ati iyawo rẹ ti fẹ ẹ tu ara wọn ka lo ti fi ẹsun naa kan baba rẹ gẹgẹ bi ẹri l'ọdun 2008.
Pàápàá nígbà ooru tí oòrùn máa ń tètè là ní ìlú yìí.
O ba BBC Yoruba sọrọ lori ọna ti àwọn àsáwọ̀ oṣere ṣe n wọ agbo wọn nigba ti BBC Yorùbá n fọrọ waa lẹnu wo ni Port Novo lorilé-ede Bẹnin Republic.
Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Pierre Nkurunziza: Three girls wey draw ontop dia president face don go prison21 Ẹrẹ̀nà 2019 Burundi: ''Stop to dey threaten our people.
    ‘Kùtù hàì òwúrọ̀ ọjọ́ kejì ni a tún lọ bẹ ibẹ̀ wò.
Ọdun 1957 ni ofin oye jijẹ nilu Ibadan ti wa fun lilo.
Boko Haram: ile ejọ dá ẹ̀wọn ọdún 20 fún Banzana Yusuf
Wọ́n gbá Adénlé tí ó fẹ́ là là wọ́n ní ẹ̀sẹ̀ nínú.
Iru awọn iroyin ti ẹ le nifẹ si: Ishaq Oloyede: Jamb ko nii fi esi idanwo silẹ ni kiakia Saraki pe fun ajọṣepọ Ghana ati Naijiria Abẹwo Buhari si Taraba Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Kii ṣe aṣiri to bo rara laarin agbami oṣelu nipinlẹ Ondo ati laarin awọn onwoye oṣelu nibẹ pe ọdọ gomina Rotimi Akeredolu ni olori ile aṣofin ipinlẹ Ondo, Bamidele Oloyelogun ti wọn yọ kuro nipo fi ara ti si Eyi ni ọrọ ọpọ awọn onwoye to ba BBC News Yoruba sọrọ sọ.
Àwọn amòfin dẹ́yẹsí ilé ẹjọ́ lórí ọ̀rọ̀ Onnoghen Tani Kingsley Moghalu tó ń dupò ààrẹ Naijiria?
''Ọrẹbinrin mi jẹ́ mí ní ₦20,000 ní mò fí dáná sún àwọn ẹbí rẹ'' Ọjọ Ẹti mọju ọjọ Abamẹta ni wahala bẹrẹ ninu aye awọn ọmọbinrin naa nigba ti awọn oṣiṣẹ alaabo yabo awọn agbegbe kan nilu Abuja.
Onuachu (FC Midtjyland, Denmark); Kelechi Iheanacho (Leicester City, England);
Ajíbógun ló lọ bomi òkun wá fún bàbá wọn - ọlọ́fin tí ó fọ́jú láti fi ṣe egbogi fún un kí ó lè ríran padà ó lọ, Ó si bọ̀.
Nítorí ọmọ wo ni ó wà tí baba rẹ̀ kò ní tọ́ sọ́nà?
Ìgbà tí Ayédèru-ẹ̀dá ń bọ̀, bí ó ti dé ìdajì afá gan-an ni irin dá sí méjì tí ó já sínú odò, wéré bí o ti dé inu odò ni a sì rí ẹranko kan sáré si i, ojú wa báyìí sì ni ẹranko náà ṣe gé apa rẹ̀ kúrò tí o gbé apá ha ẹnu tí o ń jẹ apa náà tí Ayédèrú-ẹ̀dá bẹ̀rẹ̀ sí í gbé kùkùté apá kiri odò Ẹ̀jẹ̀ tí o ń kígbe.
Amọṣa, minisita f'ọrọilẹ okeere l'Amẹrika ko ṣalaye siwaju lori idi ti wọn fi fi orukọ Naijiria nibi ti ẹsin Kristiani ati Musulumi ti gbilẹ sara awọn orilẹede ti ọrọ naa kan.
Láìpẹ́ yìí ni ẹnìkan wọ inú àgọ́ yín láti pa oluwa rẹ.
Gẹ́gẹ́ bi ó ṣe sọ lẹ́yìn ìpàde tí ní GOC pe Gomina nítorí àwọn ìpè àjòjì tí ó ri lórí aago rẹ̀.
Láti ibẹ̀ a lọ sí Patara.
kí erùpẹ̀ tó pada sí ilẹ̀ tí ó wà tẹ́lẹ̀, kí ẹ̀mí tó pada tọ Ọlọrun tí ó fúnni lọ.
Ltd tawọn arakunrin naa n ba sisẹ mọ nipa rẹ.
Àwòrán rèé nípa bí 'Hand of God' ṣé dí inagijẹ Diego Maradona Diego Maradona ìlúmọọká agbábọ́ọ̀lù dágbére f'áyé Taa ni Ọọni àná tí Ọba Ogunwusi forúkọ ọmọ rẹ̀ sọ?
Ilẹ̀ ti gbẹ, ó ń ṣọ̀fọ̀,nítorí a ti run ọkà, àjàrà ti tán, epo olifi sì ń tán lọ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù OsunDecides: Saraki ní kò sí ìpínlẹ̀ tó jẹ òsìsẹ́ lówó tó Ọ̀sun 1 Owewe 2018 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 20 Owewe 2018 Àkọlé àwòrán, Saraki ni inira ati awọn ipenija to n ba awọn eeyan ipinlẹ Ọṣun finra ko lẹgbẹ lorilẹede Naijiria Aarẹ ile igbimọ aṣofin Bukọla Saraki ni ko yẹ ki itẹsiwaju de ba ẹgbẹ tabi ijọba ti ko ṣe anfani fun awọn eeyan ilu.
"Loni ọjọ ẹti ọjọ kẹrinlelogun ni igbesẹ yii yoo gberasọ yoo si jẹ ohun ti yoo mu opin wa si ohun ti ọpọ eeyan mọ si ""birth tourism"" iyẹn gbigba iwe aṣẹ irina ati lọ bimọ Labẹ ofin yii, awọn aboyun to fẹ gba iwe aṣẹ irina olubẹwo si US yoo ni lati sọ idi pataki ti wọn fi fẹ lọ yatọ si pe wn fẹ lọ bimọ sori ilẹ Amẹrika."
Owó ìtanràn N40,000 ni mo san nítorí pé mí ò wọ ìbòmú- Vincent Bakan naa lo sọ pe ijọ naa tun ti jọwọ ile kan niluu Abẹokuta fun ijọba ipinlẹ Ogun lati lo fun itọju awọn to laarun covid-19.
Ẹwẹ, Conwell ti wọn jọ ja naa kẹdun pẹlu ẹbi Day, o ni oun ko gbero iku sii nigba yawọn n ja.
Bi a ṣe n dagba, awọn ideri naa n gbo, aabo si n sọnu fun awọn kromosoonu naa.
Tí ó bá di ọ̀la, n ó-ò parí ìtàn náà fún-un yín
Eyi jasi dọla merin, ẹgbẹrun meji o din irinwo Naira lojumọ.
Bakan naa ni wọn ri oku ẹlomiran nile igbokusi to wa ni Yaba, ti ọgbẹ ọta ibọn si wa lara rẹ, amọ ko sẹni to le sọ boya asiko iwọde EndSARS ni oloogbe naa ti jade laye.
51 Àti láti ṣe àbẹ̀wò sí ilé ọ̀kọ̀ọ̀kan ọmọ ìjọ, ní gbígbà wọ́n níyànjú láti máa gbàdúrà lóhùn òkè àti ní ìkọ̀kọ̀, àti láti ṣe gbogbo àwọn ojúṣe ẹbí.
Nínú ìfọ̀rọ̀wánilẹ́nuwò pẹ̀lú ìwé ìròyìn Bangla Tribune, Dókítà Gulzar sọ wípé kò sí bí a ṣe lè wo ibà ẹ̀fọn yìí nígbà àkọ́kọ́ tó, kí ó máà tún ṣeni lẹ́ẹ̀ẹkejì.
Àdari NIDCOM to ka àwọn orúkọ bíi mẹ́ẹ̀dógún nińú èèyàn bi ẹgbẹ̀rún kan ti wọ́n ti pa ní Ariwa Cyprus, àti pé o sọ pe o níra láti ṣe ìwádìí gẹ́gẹ́ bi orílẹ̀-èdè nítorí Turkey níkan lo ri gẹ́gẹ́ bi orilẹ̀-èdè.
"Iyabọ Ojo gan funra rẹ, to jẹ mama awọn ọmọ mejeeji yii, loju opo Instagram rẹ, iyaboojofespris, ni ""Ẹ́ wo awọn ẹbi Ojo, awọn ọmọ baba wọn""."
Ìgbésẹ̀ náà wáyé gẹ́gẹ́ bí ọ̀nà àti kojú ìkọlù tó wá sórí orílẹ̀èdè Syria tó sì mú ẹ̀mí ọ̀pọ̀lọpọ̀ lọ.
Kosoko ati Oshodi Tapa gbogun ti Ọba Oluwole, ti wọn si gba akoso isalẹ Eko, ogun naa gbona giri-giri; amọ, ọba Oluwole lo bori, tawọn mejeeji si sa kuro nilu Eko.
Wọ́n dáàbò bò wá tọ̀sán tòru, ní gbogbo ìgbà tí a wà lọ́dọ̀ wọn, tí à ń tọ́jú agbo ẹran wa.
Idi wo ni Ẹṣa Eegun fi bẹrẹ?
Ilana alagbara kan ti wọn n pe ni 'mining', ni wọn n gba ṣẹ̀dá Bitcoin, ọpọlọpọ kọ̀mpútà to já ara wọn ni wọn si fi ń ṣe amojuto ati ìdarí rẹ jakejado agbaye.
Oludari eto irinna ofurufu nilẹ India ni ọkọ ofurufu naa lo ja sinu afonifoji kan, to si pin si meji ni kete to kuro loju opo rẹ.
Badirat Ajoke sọ pe fun'ra oun ni oun finufindọ kuro ni aafin.
" Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ademola Adeleke lẹ́tọ̀ọ́ láti du ipo gómìnà l‘Ọ̀ṣun - Ileẹjọ́ Kòtẹ́milọ́rùn Dapọ Abiọdun ree, ẹni tó dépò gómìnà ní àyájọ́ ọjọ́ ìbí rẹ̀ Irọ́ ni o!
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Alaafin: Olori Aanu Adeyemi ṣàlàyé ìdí tó ṣe gẹ́ Oba Lamidi Adeyemi ti ìlú Oyo Bó tilẹ̀ jẹ́ pé ìrú ìdájọ lórí ẹ̀ṣùn ìfipábanilòpọ̀ kìí sábà wáyé, sùgbọ́n ọkùnrin náà tó ni ìyàwó nílé ni wọ́n ti ni o jẹ̀bi ikú àti pé wọ́n ni láti sọ ọ́ lókuta pa ni gẹ́gẹ́ bi ìlànà òfin Sharia lórí irú ìwà bẹ́ẹ̀.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Osun after protest: Mo pinu látí dá Iphone ti mo mú padà, ṣùgbọ́n ọlọpàá mú mi- Afurasí 28 Ọ̀wàrà 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 31 Ọ̀wàrà 2020 Oríṣun àwòrán, Punch Suliya Tajudeen, ẹni ogun ọdún kan to wà lára àwọn ènìyàn mẹ́rìndíláàdọ́rún ti wọ́n mú pé wọ́n ja sọọbu ti wọ́n sì kẹ́rù ní ìpińlẹ̀ Osun Nínú ọ̀rọ̀ rẹ sí àwọn oníròyìn ló ti sàlàye pé ọjọ́ ti òun ń pinu láti dá fóònù ti ó ń mú lásìkò ìwọ́de #EndSars ni àwọn ọlọ́pàá mú òun.
Mi o kii n ṣe Dokita rara o, ibi ti mo ti ṣiṣẹ ri ni wọn ti fun mi lorukọ yẹn o 'Doc' lati igba naa lawọn eeyan ti n pe mi bẹẹ.
Wọ́n á máa wí pé, “Mo pàṣẹ fun yín lórúkọ Jesu tí Paulu ń ròyìn nípa rẹ̀.
’ rèé Bí òbìnrin ò bá jọba, Adé tèmi rèé - Nike Davies- Ni abule yii, ẹ ro pe iya àti baba ọmọ n ṣun ẹkun ni, lasiko ti wọn ba n fi ohun aro pe ọmọ wọn.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Taiwo Akinkunmi, ọmọ Ibadan tó ya àsìá Nàíjíríà OPC: Bí a ṣe gbéná wojú awọn ọ̀daràn tó ń d'àlú Ikire rú rèé Ayédèrú Afenifere ló bá Buhari ṣépàdé - Odumakin gbanájẹ Ààrẹ fi nǹkan ọkùnrin rẹ̀ pa mí lójú, kó tó fipá bámi lòpọ̀ - Ọmọge Arẹwà Adesina ni ''Ajọ to n ri si ọrọ ajẹ ṣe agbekalẹ igbimọ kan, ti wọn si ṣe abẹwo sawọn ipinlẹ kan nibi tawọn Gomina ti fọwọ si pe, ki wọn da awọn agọ yii silẹ lati dẹkun aawọ to ma n waye laarin awọn agbẹ ati darandaran.
Orukọ agba oloselu naa ni Samuel Taiwo Ọrẹdẹin, o si wa lara awọn eekan oloselu to da ẹgbẹ oselu Ọlọpẹ, Action Group silẹ pẹlu Awolọwọ, ẹgbẹ yii si lo fa olootu ijọba akọkọ silẹ lẹkun iwọ oorun guusu Naijiria lọdun 1955.
Awọn alasẹ nipinlẹ Bauchi salaye pe eyi to jẹ ọkunrin ninu awọn ibeji naa gbẹmi mi amọ eyi to jẹ obinrin si n gba itọju lọwọ bo se yẹ.
ti ẹgbẹ oṣelu APC ni esi ibo ẹgbẹrun mẹrinla-le-ẹẹdẹgbẹtalenigba ati
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Agbẹjọ́rò sọ̀rọ̀ lórí ìtumọ̀ nǹkan kò fararọ táwọn gomina kéde lórí ìfipá báni lòpọ̀ 12 Òkùdu 2020 Oríṣun àwòrán, others Yoruba ni onbọ onbọ awọn laa dẹ de e, amọ lode oni, oju ni wọn n mu to.
O dara bẹẹ, ṣugbọn wọn ko da Baba Keresi alaṣọ pupa ati funfun kalẹ lati polowo Coca Cola, ṣugbọn nitori pe o n du ọja pẹlu White Rock l'ọdun 1923 ni.
O kere tan eeyan marundinlogoje lo ti ku ninu iṣẹlẹ naa ti awọn to le ni ẹgbẹrun mẹrin si ti farapa.
 Ó wọ ́ pọ ̀ l ' áwọn apa ẹkùn kan lágbayé tí wọn kìí tíṣe ìmọtótó dáradára àti tí kòsí omi tó .
Àwọn àṣà àti ìse tó yọ obìnrin sílẹ̀ nílẹ̀ Yorùbá Koda, iroyin sọ pe Sunday Adefonou yi ẹrọ rẹdio inu ile naa soke ki awọn aladugbo ma ba gbo bi o ṣe n gba ẹmi ọga rẹ ọhun.
Ìwádìí fi hàn pé ilé iṣẹ ọmọogun kò ti ṣàbẹ̀wò si Tàrábà nígbà ti àwọn ọlọpàá ti débẹ, sùgban adelé olùdari ìgóhùn sáfẹ́fẹ́ fún ilé iṣẹ́ ọmọogun Col.
Ṣugbọn bí wọ́n ti gbé e dé Ekironi ni àwọn ará ìlú fi igbe ta pé, “Wọ́n ti gbé àpótí Ọlọrun Israẹli dé síhìn-ín, láti pa gbogbo wa run.
Aisaya wolii, ọmọ Amosi tọ̀ ọ́ wá ní ọjọ́ kan, ó wí fún un pé: “OLUWA ní kí n sọ fún ọ pé kí o ṣe ètò ilé rẹ, nítorí pé o óo kú ni, o kò ní yè.
Bakannaa, orile-ede Faranse nipa ile ise to n se amojuto idagbasoke ayika lorile-ede ile okeere  eyi ti a mo si Francaise de Development (AFD)yoo ya ipinle Kano ni iye owo ti o to million lona maarundinlogorin owo dola lati mu idagbasoke deba ipese omi ero ni ipinle Kano, ni apa iwo – oorun ariwa orile-ede Najiria.
Minisita fun eto irina lorilẹede Ethiopia Dagmawit Moges sọ pe wọn ti ayẹwo DNA fawọn ẹbi awọn oloogbe lati le ṣeranwọ nipa mimọ oku ẹnikọọkan.
Bakan naa ni awakọ ero ẹgbẹrun mẹrin ati aabọ yoo jẹ anfaani rẹ, eyi ti yoo mu ki apapọ akopa nipinlẹ kan jẹ ẹgbẹrun mẹsan.
Ṣugbọn ẹnikẹ́ni tí ó bá mu ninu omi tí èmi yóo fi fún un, òùngbẹ kò ní gbẹ ẹ́ mọ́ lae, ṣugbọn omi tí n óo fún un yóo di orísun omi ninu rẹ̀ tí yóo máa sun títí dé ìyè ainipẹkun.
Yóo dára fún ẹni tí ó bá ń gbọ́ràn,ẹni tí ó bá sì gbẹ́kẹ̀lé OLUWA yóo ní ayọ̀.
Àkọlé àwòrán, Awọn osisẹ alaabo ti gba asẹ lati maa tan ina wa ọrọ ikorira lori ikanni ayelujara, social media.
Enugu: O ni àwọn alatilẹyin Ogara George Tabugbo to jẹ ọkan lara awọn oludije sipo gomina ni Enugu ya bo ibudo idibo naa ni eyi to di wahala ti awọn to fẹ ṣeto idibo ọhun tẹlẹ si kuro.
Ti eniyan ba n binu lọwọ, gbogbo isan ara onitọun ni yoo ran jade, ti gbogbo ẹya ara eniyan a si setan lati sa asala fun ewu to n bọ, tabi ki o duro lati koju ewu naa.
Oludije yii fidunnu rẹ han pẹlu ileri pe oun yoo saipa oun ki ẹgbẹ APC wọle lọdun to m bọ̀.
Iwe yi si lo fi sọwọ lẹyin ọrọ kan ti Trump fi ransẹ ibinu sawọn assaju ilẹ Afrika losu taa wa yi nibi to ti pe awọn orilẹede adulawọ ni salanga ati akitan.
ni ọrọ ijamba ina ninu ọja Anambra n di nitori baibai lo ku ti oju awọn oniṣowo n wo bayii Ọpọ lo n di ẹbi ina yii ru gomina ipinlẹ Anambra pe ko gbe igbesẹ aabo lọwọ ina to yẹ fun ọja nla bii ti Onitsha yii Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ti o bá dá ara ẹ lójú, ki ẹni tó n ṣe irun kí n gbọ́?
Ṣugbọn agbẹjọro fun Oxford, arabinrin Funke Adekoya (SAN) naa ti kọwe lodi si ipẹjọ naa pe ko ni ẹri to peye ati pe ki ile ẹjọ da ipẹjọ naa nu.
 wọ ́ n wàá lọ sí denmark .
Oríṣun àwòrán, @osunosogbo2019 Titan Fitila Oloju mẹrindinlogun: Eto keji to tun kan fun ọdun Ọṣun Oṣogbo ni titan fitila oloju mẹrindinlogun.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Kayode Fayemi: Kìí ṣe torí àti di ààrẹ ni mo ṣe sapá mi fún Àmọ̀tẹ́kùn ṣùgbọ́n tó bá yá, máa sọ̀rọ̀ lórí bóyá a ó jẹ ààrẹ tàbí rárá 22 Èbibi 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 27 Èbibi 2020 Oríṣun àwòrán, Presidency nigeria Gomina ipinlẹ Ekiti, Dokita Kayode ti sisọ loju rẹ pe ifilọlẹ ikọ alaabo Amotekun lo wa fun ipese eto aabo to jiire fun ilẹ Yoruba, tilẹ jẹ p o fẹ fa ikunsinu laarin awọn gomina ẹkun kaarọ o jiire.
Cristiano Ronaldo lo ṣi keji lẹyin ti oun naa ti gba ami ẹyẹ Ballon d'or fun igba marun un.
O ni ẹrọ ti oun n sọ nipa rẹ yoo dabi ami tatuu lara eeyan ti ko ni han si gbangba.
Child Abuse: Oyinye Mbadike ní ìbátan òun mu ọti yó ni òun ṣe dín dùǹdú ìyà fun
Oludije fun ipo gomina labe asia  egbe oselu PDP  Peoples Democratic Party, onimọ-ẹrọ Seyi Makinde naa sẹsẹ  dibo rẹ ni agọ idibo to wa ni Unit 1, Ward 11, Abayomi Iwo Road ni ijoba ibilẹ Ibadan Northeast   ni ekun Gusu ni ipinle Oyo.
Ninu ipo ate ohun, eleyi ti ajo FIFA gbe jade lori ero ayelujara lojoBo(Thursday), iko Super-Eagles ni apapo ami mọ́kànlélọ́gbọ̀n le legbèje(1431 points) ju ami ti iko ohun ni losu ti o koja.
Àkọlé àwòrán, Awọn panti yii ti sọ awọn adugbo kan ni ilu ibadan ti o jẹ olu ilu ipinlẹ Ọyọ ti aatan.
Pẹlu àìlera ati ọpọlọpọ ìbẹ̀rù ati ìkọminú ni mo fi wá sọ́dọ̀ yín.
Ẹsun meji to nii ṣe pẹlu aṣilo ipo ati titako iwadii ile aṣofin ni wọn fi kan an.
Àwọn aláìníláárí ati àwọn oníjàgídíjàgan kan bá kó ara wọn jọ sọ́dọ̀ rẹ̀, wọ́n bá ń bá a digun jalè káàkiri.
Ọ̀pọ̀ àwòrán tó ń ṣeni láàánú rèè nípa ogun abẹ́lé Nàíjíríà Irọ̀ ni ìjọba ń pa, Ikọ Amọtẹkun ba ofin Naijiria mu- Ìgbìmọ̀ Yoruba Wo ohun tó yẹ kó mọ̀ nípa Gomina Imo ti ilé ẹjọ́ giga ye àga mọ́ nídí Èyí ni bí ogun abẹ́lé Biafra ṣe bẹ̀rẹ̀ ní Nàìjíríà Kini ero awọn olori ẹkun Guusu àti Aarin Gbungbun Naijiria?
Awọn aja miran wa ti wọn ma n hu iwa ipa , ti wọn si le e bu eniyan jẹ nigbakuugba to ba wu wọn eyi to jẹ ewu nla.
Orisabunmi: Àbúrò èèkàn òṣèré Orisabunmi tó jáde láyé ní ọjọ́ méjì péré ló lò níléèwòsàn kí ikú tó dé
Awọn to tun ba wọn kọwọ rin lọ APC ni igbakeji gomina ipinlẹ naa nigba kan ri Abdulmalik Mahmud ati ọkan lara awọn oloye ẹgbẹ oṣelu PDP kan, Babayo Gamawa.
Yorùbá parapọ̀ láti gbógun ti ààbò tó mẹ́hẹ!
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Yorùbá dùn lédè, sáré pé gbólóhùn yìí wò tóo bá dá ara rẹ lójú Abẹwo ọmọ ẹgbẹ si Aarẹ Buhari, èso wo ló máa n bí?
Ọjọ Keji, Oṣu Kẹrin, ọdun 1956 ni wọn bi Akin-Olugbade si idile baba ọlọla ati oniṣowo to tun jẹ Balogun Owu nilu Abeokuta, Babatunde Akin-Olugbade.
Awọn akanṣe iṣẹ miran ti ọrọ kan tun ni opopona marosẹ Abuja si Kano pẹlu akanṣe iṣẹ lori ipese ina ọba lati Mambilla.
Ilé yóò dà wó lọ́wọ́ àwọn onímọ̀-ẹ̀rọ bẹ́ẹ̀.
Kò sí ibùdó ayẹwo àrùn Coronavirus ní UCH, ẹ má wá fún ayẹwo lọ́dọ̀ wa - Ọga àgbà UCH TB Joshua, Apostle Suleman, Odumeje, D.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Baba Suwe: Àwọn ǹkan tí ọ̀pọ̀ kò mọ̀ nípa Baba Suwe Yemisi Oyedepo Broadcast Journalist 11 Èrèlè 2020 Oríṣun àwòrán, others Àkọlé àwòrán, Baba Suwe: Àwọn ǹkan ti ọ̀pọ̀ ko mọ nípa Baba Suwe Ilẹ̀ to mọ lówùrọ̀ òní, ọ̀rọ̀ àwọn adẹrinpòsónu eléré tíàtà Yorùbá lo gba orí ayélujára kan.
Ṣugbọn kò lè fọ́nnu níwájú Ọlọrun.
Wọn yóo máa wí pé,“Àwa ni a ṣẹgun wọn,kìí ṣe OLUWA ló ṣe é rárá.
Àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ bá a lọ.
- Iya Rainbow Toyin Abraham jọ̀wọ́ dáríjì mí - Yomi Fabiyi Òṣèré tíátà Toyin Abraham daya Kolawole Ajeyemi Àwọn olólùfẹ̀ Toyin Abraham ati Liz Anjorin ti gbé ọ̀rọ̀ wọn rù sórí, ẹ wo òjò òkò ọ̀rọ̀ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Wùnmí Toríọlá: Toyin Abraham kìí se ọ̀gá mi nínú tíátà O ní kò si ìgbà kankan ti Toyin parọ pé òkè okun ni òun bímọ sí bíkoṣe ìlú Eko.
Idalu ni iṣelu, bi a ti n ṣe ni ile wa, eewọ ibomiran si ni si ni Yoruba maa n wi.
Lóòtọ́ ni mo yìnbọn níbi yánpọnyánrin tó wáyé ládúgbò mi-Seun Kuti Ṣé lóòtọ́ọ́ làwọn ọlọ́ṣà tún gbẹ̀mí èèyàn kan ní Moniya, Ibadan?
Ìjọba Amẹrika yọ orúkọ Sudan kúrò nínú ìwé orílẹ̀-èdè tó ń ṣagbátẹrù ẹgbẹ́ agbésùnmọ̀mí Wo dókítà ọmọ Nàìjíríà tí àgbáyé ń wárí fún nítorí abẹ́rẹ́ àjẹsára COVID-19 Aàrẹ Trump kọ̀ láti jẹ Tòlótòló ìsìn ìdúpẹ́ 2019 nílé, ó gba Afghanista lọ!
Joe Biden: Ṣé ó lè fẹ̀yìn Trump kó di ààrẹ America tó kàn?
 Ẹgbẹ oṣiṣẹ TUC to jẹ agbarijọpọ ẹgbẹ oṣiṣẹ n lọ kaakiri lati ti ilẹkun awọn ileeṣẹ to n pin ina mọnamọna lorilẹede Naijiria, TCN kaakiri orilẹede Naijiria lori ẹsun pe o n fi iya jẹ awọn oṣiṣẹ rẹ."
siso loju eegun eto naa wi pe, isakoso isejoba aare Buhari se agbekale eto ohun
'A ó ran ara wa lọ́wọ́ o bẹ́ẹ bá lẹ́ ò ní ṣiṣẹ́ẹ yín, àwọn àgbẹ̀ Ikoyi Ile síjọba ìpínlẹ̀ Oyo!
Tí ọ̀pọ̀ àwọn eniyan láwujọ ba rí i dáju pé wọ́n n gba abẹ́rẹ́ ajẹsara yóò mú àdinku ba àwọn ajakálẹ̀ ààrun yóò si le àìsàn jina si àwọn ọmọ wẹ́wẹ́ ti wọ́n ko ti ni àwọn èròja ara ti yóò maa ja fún wọ́n lái ti gba abẹ́rẹ́ ajẹsára.
Ohun mẹ́fà tí àgbáyé kò mọ̀ nípa Majek Fashek tó d'olóògbé nìyí ‘Àrùn Coronavirus ló pá adarí ètò ìṣúná Àjọ NDDC ’ Auxiliary korò ojú sí àwọn ọmọ ẹ̀yìn rẹ̀ tó ń dàlú rú George Floyd ní àrùn coronavirus kó tó jáde láyé Aṣoju ile isẹ Women Consortium of Nigeria, Morenike Omaiboje sọ fun BBC pe, ipa ti iṣẹlẹ ifipabanilopọ n ko ninu aye awọn ti iṣẹlẹ naa ṣẹlẹ si pọ ju ki ijọba da awọn afurasi ẹsun naa lọdaa lọ.
Oshiomole pe ipe yii nilu Abuja nibi apejẹ kan ti wọn fi n bu ọla fun oludari agba fun ajọ to n risi ọrọ osisẹ lagbaye, ILO, ọgbẹni Guy Ryder.
Arakunrin Joabu, tí ń jẹ́ Abiṣai, ọmọ Seruaya ni aṣiwaju fún “Àwọn Ọgbọ̀n Akọni Olókìkí.
Yóo yọ́ gbogbo ọ̀rá akọ mààlúù tí ó fi rú ẹbọ ìmúkúrò ẹ̀ṣẹ̀ kúrò, ati gbogbo ọ̀rá tí ó bo nǹkan inú rẹ̀; 
Ki a ba le gbọ ọrọ yii ye daadaa ni ki a mu awọn gbajugbaja kọmẹntatọ ni Naijiria to dantọ ki a baa le mọ ohun ti wọn ṣe taraye fi gba wọn lọga nidi iṣẹ kọmẹntari.
ti ile-ise omo ogun ofurufu ti orile ede yii Nigerian Air Force Boeing aircraft
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ọ̀dọ́kùnrin tó kọ́kọ́ ṣe ẹ̀rọ tó ń tu ìyẹ́ lára adìyẹ Alaanu pọ̀ ninu eniyan ilẹ Somalia Wiwa owo fun iranlọwọ maa n gbomi mu ṣugbọn awọn eniyan Somalia maa n ṣoore pupọ.
Ọmọwe Akinreti to tun pe fun alekun owo oṣu awọn oniroyin, paapaa awọn to n ṣiṣẹ pẹlu ijọba ipinlẹ yii woye pe ṣiṣe agbekalẹ abadofin ti wọn lero tẹlẹ to jẹ mọ ‘Igbe-aye Irorun awọn Oniroyin’ (Media Enactment Bill) ṣe pataki lati ṣe aṣeyọri eyi.
Eniyan 436 lo ni aarun Covid-19 ni Naijiria ni 21/06/2020 Awọn ti ajakalẹ aarun coronavirus ti kọlu ni Naijiria ti pe 20,244 bayii.
Arsenal vs Burnley: Kí ló kàn fún Arsenal báyìí lẹ́yìn tí Burnley yẹ̀yẹ́ wọn mọ́lé ní Emirates?
Kíni ẹ̀yin rántí nínú ǹkan ti o ti ṣẹlẹ lọ́dun díẹ̀ sẹ́yìn àti nísìnyìí Kini ootọ inu Fidio ti Ayisha ti n binu to n tan lori ayelujara bayii?
"Awọn iroyin ti ẹ le nifẹ si Ẹ má rán ọmọ lọ ilé ìwé ní Cyprus mọ́ - Abike Dabiri John Blake wà ní ICU, ọlọ́pàá tó yìnbọn fún un bẹ̀rẹ̀ ìsinmi tipá tipá Adigunjalè pa oníbàárà báńki tó ṣẹ̀ṣẹ̀ gba owó n'Ibadan Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Bí ẹ ṣe mọ̀wé tó, ẹ wá dánrawò níbí pẹ̀lú ""Àpólà Ọ̀rọ̀ Orúkọ - Noun Phrase Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!"
Ibadan Death: Àwọn ará àdúgbò Akinyele ké sita lórí iṣékúpani tó ń wáyé ní ìlú Ibadan Yàtọ̀ sí coronavirus, wo ìgbà mẹ́wàá míì táwọn mùsùlùmí kò lè ṣiṣẹ́ Hajj Wo bí o ṣe lè fí orúkọ rẹ sílẹ̀ fún iṣẹ́ N Power tuntun ti ọdún 2020 Ẹbí Abiola Ajimobi kéde bí ètò ìsìnkú rẹ̀ yóò ṣe rí pé.
Nígbà ti Olófìn-íntótó àti Ilésanmí dé Ilé-Ifè tí wọn ń lọ, ọ̀dọ̀ Àlàó ni wọ́n dé sí.
Ẹyin ọdọ, ẹ yago fun jiji apoti idibo - Tinubu Aṣiwaju ẹgbẹ oṣelu APC, Bọla Tinubu ti paroko ikilọ ranṣẹ sawọn ọdọ nipinlẹ Eko pe ki wọn yago fun jiji apoti idibo gbe lasiko idibo aarẹ ati ile aṣofin apapọ to n bọ lọjọ abamẹta.
Ilẹkun Baalu Dana fo yọ nilu Abuja
O kẹkọọ nipa aato ile kikọ ni agbegbe ni Fasiti Ahmadu Bello ni Zaria.
Bí èyí ṣe ń lọ, ọ̀kan lára àwọn olùgbaninímọ̀ràn fún Ààrẹ Muhammadu Buhari, Lauretta Onochie fi àwòràn ìwè morajà tí Fayoṣe fi sanwó láti tẹkọ̀ òfurufú létí lọ sí ilẹ̀ Faranse síta lórí Twitter.
" Oríṣun àwòrán, Getty Images O ni ibanujẹ nla lo jẹ pe aarẹ lee ba awọn ọmọ Naijiria sọrọ lai darukọ awọn eeyan ti wọn pa kaakiri orilẹede Naijiria lasiko iwọde naa.
Bi o ti le je pe, iko agbaboolu orile-ede Saudi Arabia fagbahan Egypt pelu ami-ayo meji sookan, esi ifesewonse ohun ko to fun iko naa lati tesiwaju sipele ti o kan ninu idije agbaye ohun.
Folashade bẹrẹ iṣẹ gẹgẹ bi oṣiṣẹ́ ijọba ni ile iṣẹ to n ri si eto ilera nibi ti o ti goke titi to fi di oludari.
Ni abala akọkọ ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ naa, ọrọ fẹ ṣebi a'n gba ona mi yo nígbà tí CSKA Moscow ṣáájú je ayo méjì.
 Ras Kimono jẹ ọkan lara awọn ọmọ igbimọ olorin wa”Aarẹ ẹgbẹ awọn oṣere olorin fun Naijiria (PMAN), Ọgbẹni Pretty Okafor ni o ya oun lẹnu nigba ti oun gbọ iku Ras Kimono pe: “ọfọ nla lo ṣe”.
okeere ni jibiti , ni owo sinkun ajo EFCC mu ni agbegbe  igboro ilu Ibadan nigba ti iroyin isẹ ibi  ti wọn n se tẹ ajo ohun leti.
Àwọn orílẹ̀-èdè yóo kó ọrọ̀ wọn wá fún ọ.
 O fikùn pe ilo afẹfẹ gaasi ba oju ọjọ wa mu ni Naijiria, ti eyi ba si dohun tán, Naijiria yoo ri iranwọ gba lati ilẹ okeere."
"Latin fikun pe ""ifọwọsowọpọ ọpọ eeyan ni sinima ṣiṣe gba, eyi to si le tako awọn ofin to rọ mọ idena arun Covid-19 nitori ogun eeyan tabi ju bẹẹ lọ lo n kopa ninu sinima kan."
Tí a fiṣọwọ́ ní 11:41 10 Ọ̀pẹ̀ 202011:41 10 Ọ̀pẹ̀ 2020 Amotekun yóò gba owó oṣù kẹtàlá ní ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́ - Seyi Makinde Ìjọba ìpínlẹ̀ Oyo ṣèlérí láti san owó oṣù Kẹtàlá fún fún àwọn òṣìṣẹ́ aláàbò Amotekun.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Ní ìjọ wa, ọtí mímú la fi ń pe ẹ̀mí Ọlọ́run sọ̀kalẹ̀' Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí EndSARS Protest Update: Aisha Yesufu ní Buhari jẹ́wọ́ pé òun kò láànú aráàlú nínú ọ̀rọ̀ rẹ̀23 Ọ̀wàrà 2020 Fídíò, EndSars, EndSwat: Ọlọ́pàá ti fi ìbọn lù mí láyà rí torí mó ní 'extra tyre' méjì- afẹ́hònúhàn15 Ọ̀wàrà 2020 Fídíò, Soyinka Cancer: Àṣe ara mi ni iso ti n run gbogbo bí mo ṣe n ṣèrànwọ́ lórí jẹjẹrẹ27 Bélú 2019 EndSARS Protest: Àwọn olùwọ́de ní ''májèlè ni oúnjẹ tí MC Oluomo gbé wá fún wa, a ò jẹ''17 Ọ̀wàrà 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Ṣugbọn kii ṣe eefin ẹrọ amunawa nikan lo n ṣe ijamba fun ẹmi ninu ile.
 ní ọjọ ́ kẹta ni ilẹ ̀ germany kéde ogun lé ilẹ ̀ france lórí padà .
Yóo mú mi wá sinu ìmọ́lẹ̀; ojú mi yóo sì rí ìdáǹdè rẹ̀.
Àwọn ni ìlànà ati òfin tí OLUWA fi lélẹ̀ láàrin òun ati àwọn ọmọ Israẹli, láti ọwọ́ Mose.
Crimes Commission (EFCC) lati gbẹse le owo naa.
O wi pe iku ọkan pataki lara awọn ọmọ ẹgbẹ awakọ ti ẹka Lagos Island, ti o tun jẹ oluranlọwọ fun Alaga Kunle Poly lo se okunfa isẹ pajawiri fun awọn ọlọpa.
Oniṣowo nla ni ọkọ mi, o si maa n rinrinajo loorekoore nitori iṣẹ rẹ.
Agbẹnusọ àjọ náà, Sunday James sọ fún BBC pé gbogbo ọmọ orílẹ̀èdè yìí ní láti sapá wọn kí àìsàn búburú náà ti àwọn eléto ilera DR Congo ni ó ti pa eniyan mẹ́tàdínlógún báyìí, kó má ri 'bi jòkó ni ilẹ̀ẹ wa.
Ọkọ̀ òfúrufú ọlọ́pàá yóò bẹ̀rẹ̀ sí ní káàkiri Naijiria - Ọgá Ọlọ́pàá Kìí ṣe gbájúẹ̀ nìkan lọmọ Nàìjá ń ṣe lókè òkun!
Iroyin ni baba naa fi ọmọ rẹ silẹ lọ ra ọja ni, ṣugbọn ko tete pada sile nitori pe o n ta tẹtẹ.
Ewe, orisirisi iko agbaboolu ni Ancelotti ti tuko re, ti o fimo ife eye lolokan-o-jokan, O tuko agbaboolu Chelsea, Real Madrid, AC Milan, Juventus, Roma ati Paris Saint-Germain, bee si ni O gba ife eye idije Champions League meta.
Paulu bá wọ iyàrá tọ̀ ọ́ lọ.
Ọmọ Yorùbá mẹ́wàá tó jẹ́ àmúlùúdùn ní Amẹ́ríkà àti Yúróòpù Èèyàn 38,344 ló ti ní COVID-19 ní Nàìjíríà lẹ́yìn tí 543 kún un lọ́jọ̀rú Bàbá mi Aláàfin, ẹ ṣeun ẹ̀bùn owó tí ẹ fún èmí àti ọkọ mi- Lizzy Anjọrin Wo àwọn Gómìnà Naijiria tí àrùn Covid-19 ti bá fínra Ṣé Akpabio ṣetán láti dárúkọ àwọn Aṣòfin tó gba iṣẹ́ àkànṣe lọ́wọ́ NDDC?
Obìnrin bíi Ruth Bader ni yóò gba ipò rẹ́ ní iléẹjọ́ tó gajùlọ nílẹ̀ Amerika- Donald Trump Ọkùnrin tí wọ́n fẹ̀sùn kàn pé ó jí ǹkan nílé ìjọsìn rí ẹ̀wọ̀n he!
O salaye pe asẹ ti aarẹ Muhammadu Buhari pa ninu ọrọ to ba awọn ọmọ Naijiria sọ, pe ki wọn fi opin si iwọde wọn, lo mu ki oun se ipinnu ọhun.
( Kano State Broadcasting Corporation), Malam Umar Sa’id Tudun Wada ti o jẹ Ọlọrun
Ẹ kó gbogbo ìpayà yín tọ̀ ọ́ lọ, nítorí ìtọ́jú yín jẹ ẹ́ lógún.
Ase yii ni yoo fun ijoba apapo lagbara lati gbẹsẹ le awọn  dukia ti to je ti  awọn  ti won ba fura si pe o se owo ilu kumo-kumo.
O ni wọn yoo ran awọn wolewole ilu naa lọ sawọn ṣọọbu itaja lati rii pe awọn eeyan n tẹle ilana ijinasiraẹni nigba gbogbo.
Ẹ o ranti pe ẹgbẹ oṣiṣẹ gunle iyanṣẹlodi ninu oṣu kẹsan lati fi ẹhonu han lori owo oṣu oṣiṣẹ to kere julọ lorilẹede Naijiria.
Ó bá dá Batiṣeba lóhùn pé, “Ṣé o mọ̀ pé èmi ni ó yẹ kí n jọba, ati pé gbogbo àwọn ọmọ Israẹli ni wọ́n lérò pé èmi ni n óo jọba.
idagbasoke lori iṣẹ-ogbin ati  eto ẹkọ.
Bakan naa ni wọn fikun wi pe awọn to wa ninu ọkọ naa pẹlu awakọ oju omi naa ko wọ asọ ti kii muni ri sinu omi( life jacket) lasiko ti wọn fi wa lori omi.
Oyinkan Abayomi ko nilo lati paarọ orúkọ mọ nitori orúkọ ọkọ aarọ rẹ, naa ni orúkọ ọkọ rẹ keji.
Ó ń gba ìtọ́jú lọ́wọ́lọ́wọ́ báyìí.
Ó jẹ ẹbun aadọta ẹgbẹrun dola.
 a dá ìlú Ògbómọ ̀ sọ ́ sílẹ ̀ ní 17th century .
Ó dá wọn lóhùn pé, “Kì í ṣe tiyín láti mọ àkókò tabi ìgbà tí Baba ti fi sí ìkáwọ́ ara rẹ̀ nìkan ṣoṣo.
Ìsekúpani darandaran; ọlọ́pàá mẹ́rin forí káásà ní Benue
Òun pẹlu àwọn ọkunrin mẹ́wàá bá lọ sọ́dọ̀ Gedalaya ọmọ Ahikamu ní Misipa.
Aare Muhammadu Buhari ti fi idunnu re han si gbajugbaja onimo ijinle lori oro isiro nile Afrika, ogbeni Akintola Williams, bi O se pe omo odun mọ́kàndínlọ́gọ́rùn ún leni.
O fikun pe, ohun ti ko kan Ajimọbi lo n da si lasiko to fi wa lori oye, idi si ree ti awọn eeyan ipinlẹ Oyo se fi ibo sọrọ̀ fun pe, ijọba rẹ ko se daada.
Bí ọjọ́ tí ń gorí ọjọ́ àwọn Juu gbèrò pọ̀ bí wọn yóo ti ṣe pa á.
“Nítorí náà, ẹ gbọdọ̀ pa gbogbo òfin tí mo fun yín lónìí mọ́ kí ẹ lè ní agbára tó láti gba ilẹ̀ tí ẹ̀ ń rékọjá lọ láti gbà.
Oríṣun àwòrán, MUHAMMADU BUHARI Àkọlé àwòrán, Aarẹ Orilẹ ede Naijiria, Muhammadu Buhari seleri lati se imusẹ ileri eto aabo to muna-doko fun gbogbo ọmọ orilẹ-ede A o ranti wipe awọn eniyan bii mẹtalelaadorin niwọn padanu ẹmin wọn sọwọ ija ti o waye laarin awọn darandaran ati awọn agbẹ nilu Makurdi ti o jẹ olu ilu ipinle Benue.
Tí ó bá jẹ́ odò, tabi kànga tí ó ní omi ni, wọn kì í ṣe aláìmọ́, ṣugbọn gbogbo nǹkan yòókù tí ó fara kan òkú wọn di aláìmọ́.
Egbe to n mojuto oro awon osise lorile-ede Naijiria, The Nigeria labour congress NLC, ti pase fun awon omo egbe re gbogbo jake-jado orile-ede Naijiria lati bere iyanselodi, bere lati ojoBo(Thursday) ojo ketadinlogbon osu kesan, odun ti a wayii.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ondo Governorship Elections 2020: Ìjọba ìbílẹ̀ mẹ́ta yìí ní yóò sọ ẹni tí yóò jáwé olúbori ninú ìdìbò Ondo 1 Ọ̀wàrà 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 8 Ọ̀wàrà 2020 Kẹ̀rẹ̀kẹ̀rẹ̀, ọjọ́ ìdìbò sípò gómìnà ìpínlẹ̀ Ondo yóò wáyé lọ́jọ́ Satide ọjọ́ kẹwàá, oṣù kẹwàá ọdún 2020, ibi yìí ni àwọn ènìyàn ìpínlẹ̀ náà yóò fi ọwọ́ ara wọn yan ẹni tí yóò tún dári wọ́n fún ọdún mẹ́rin míran.
Ẹ̀ wo àwọn ìgbéṣẹ̀ tí ó ṣeeṣe kí ìjọba àpapọ̀ gbé lórí òfín kónílé ó gbélé ní Eko, Abuja, Ogun Coronavirus ti di ara wa, kò le è kúrò mọ láéláé - WHO Kí ló ń mú àwọn adarí obìnrin lágbáyé rọwọ mú nípa kíkojú covid 19?
O salaye pe, ijiroro laarin awon ti oro kan ati awon olukopa, yoo wa iyanju si awon ipenija ti o n koju awon oludokowo ni ipinle ohun.
 tí àwọn obìnrin ilé wọ ̀ nyí kò ń ṣe gbogbo ìgbà .
Bí wọ́n ti ṣe sọ, iná amọ́roro ìtàgé wálẹ̀ díẹ̀.
Dafidi bá bèèrè lọ́wọ́ Ahimeleki, ará Hiti ati Abiṣai ọmọ Seruaya, arakunrin Joabu pé, “Ta ni yóo bá mi lọ sí ibùdó Saulu?
iko omo ogun oju omi naa lagbara lati maa se irinse lorile ede yii, laijẹ pe wọn
,ni won ko ja aare kule ninu ipo ti won dimu.
Ibi tí mo ti ń ronú eléyìí, ni mo rí omi tí ó kán sílẹ̀ lára ẹ̀wù Ìgbéraga-ìbànújẹ́, mo lọ sí ibi tí ẹ̀wù náà wà, nígbà tí mo sì fi ọwọ́ kan omi náà ó dàbí afárá oyin.
44tn ki won to gba a wole.
Lasiko ti wọn n ba awọn akọroyin sọrọ ni ilu Eko ni wọn jabọ pe awọn ti mu awọn onijibiti orile-ede Naijiria mẹtadinlaadọsan an EFCC gba ọkọ ayọ́kẹ́lẹ́ 30, òògùn ìbilẹ̀ àti ọ̀pọ̀ fóònù lọ́wọ́ àwọn gbájúẹ̀.
Gẹgẹ bi ohun ti ikede naa sọ,bi wọn ba ti pari iwaadi na wọn yoo fi abajade rẹ sita fun gbogbo ara ilu.
Nígbà tí Gideoni dé ibẹ̀, ó gbọ́ tí ẹnìkan ń rọ́ àlá tí ó lá fún ẹlẹgbẹ́ rẹ̀ kan pé, “Mo lá àlá kan, mo rí i tí àkàrà ọkà baali kan ré bọ́ sinu ibùdó àwọn ará Midiani.
A parí oko yìí kí ilẹ̀ tó ṣú, a sì fa gbòǹgbò àwọn igi àti ìtàkùn tu, a dá iná ti igi ìrókò tí ó wà níbẹ̀ ní ọrùn, a wú gbòǹgbò awùsá, a sì to igi gbígbẹ yí ọ̀gànwò ká, a dá iná ńlá yí àwọn igi burúkú wọ̀n-ọnnì po.
 agba apase wa lowo ijobat .
"Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Badagry Historical Wells: Omi inú kànga Wawú ló ń kó ọpọlọ àwọn ẹrú lọ Ọgbẹni Ndayishimiye jẹ baba ọlọmọ marun o si jẹ ọmọ ijọ katoliki tọkan tọkan to tun tẹle ọgbọn amulo ẹni to gbesẹ le e lọwọ nipa ""titẹnumọ ohun tii ṣe ti Ọlọrun"" ninu oṣelu."
Alafo yii si ni ipolongo ibo Biden ṣe amulo rẹ.
Alaga ẹgbẹ oṣelu PDP ni ipinlẹ Edo, Tony Aziegbemi lo fi to BBC News leti bẹẹ.
Ó sọ aṣálẹ̀ di adágún omi,ó sì sọ ilẹ̀ gbígbẹ di orísun omi.
Idi ni pe wọọrọwọ ni wọn fẹ se ibura gomina ti ilu dibo yan, Abdulrahman Abdulrazak ti ipinlẹ Kwara, ti ayẹyẹ naa ko si ni kọja ile ijọba ipinlẹ naa.
ile-iwe AME Zion Ward 5  ni ijoba
Ọlọrun mi, má mú mi kúrò láyé láìpé ọjọ́,ìwọ tí ọjọ́ ayé rẹ kò lópin.
Iwe iroyin magasiini Healthline Health sọ pe ere idaraya Kegel ma n jẹ ki ile itọ ṣiṣẹ daadaa.
Nigba wo ni wọn yoo bi ọmọ yii?
Mòlúmọ̀ká òsìsẹ́ ilé isẹ́ ìgbóhùsáfẹ́fẹ́ South Sudan iyẹn SSBC, Magok Chilim sọ wípé ilé isẹ́ BBC kọ̀ láti san àwọn owó tí wọ́n njẹ ẹ́ lẹ́yìn tí ó tún rán ilé isẹ́ náà létí nínú osù kínní ọdún.
Oríṣun àwòrán, BBNaija/Twitter Àkọlé àwòrán, Ebuka Obi-Uchendu ni atọkun eto naa Ni gbogbo ọjọ Aiku lawọn oludije yoo kopa ninu idibo iyọnikuro ninu ile ẹlẹgbọn.
Àkọlé àwòrán, Won jo n sin Olorun ninu iṣẹ iranṣẹ pẹlu awọn ọkọ wọn ni Èyí tí a wò jùlọ 5:03 Fídíò, Omolola Arohunmolase Welder: Mo ti fí iṣẹ́ 'Welder' gbayì láwùjọ, tó mo fi tọ́ ọmọ yanjú, Duration 5,039 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 5:39 Fídíò, Akomolede ati Asa lori BBC: Olùkọ́ Kikelomo Ogunboye tan ìmọ́lẹ̀ sí ìwà olè ọ̀gá ọlọ́pàá Audu gẹ́gẹ́ bí àwòkọ́ṣe àsìkò yìí, Duration 5,398 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 4:11 Fídíò, Oba Adeyeye Ogunwusi: Ojú mi ti rí lọ́pọ̀ lọpọ̀, ọ̀pọ̀ èèyàn ni kò tilẹ̀ gbàgbọ́ pé mo lè jọba- Ooni, Duration 4,117 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 4:43 Fídíò, Promise Akinlade: ọmọ ọdún mọ́kànlá tó ń fi ìlù dárà bíi àgbàlagbà sọ̀rọ̀ nípa tálẹ́ǹtì rẹ̀, Duration 4,437 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 0:59 Gbọ́, Ìsẹ̀lẹ̀ jákèjádò orílẹ̀èdè àgbáyé láàárín ìṣẹ́jú kan, Duration 0,59wákàtí 5 sẹ́yìn 7:03 Fídíò, Olumuyiwa Bolade Adedeji Military Bruitality: Bí arákùnrin onípèníjà ara tí sọ́jà lù ṣe dé, Duration 7,035 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 4:45 Fídíò, Yoruba Films: Ẹ̀ẹ́ bẹ̀ mi kúrò láyé ni, mi ò lè kú - Fadeyi Oloro, Duration 4,4526 Èrèlè 2020 2:48 Fídíò, Esther Ajayi: Èmi náà ti borí ìṣòro rí ló ń mu mi ṣojú àánú, Duration 2,481 Ògún 2019 6:08 Fídíò, Adebola Ademilua: Àìrísẹ́ ṣè lẹ́yìn ìwé kíkà ló sọ mi dí ìyá onírú, mo dúpẹ́ tèmi, Duration 6,0827 Bélú 2020 5:55 Fídíò, Soyinka Cancer: Àṣe ara mi ni iso ti n run gbogbo bí mo ṣe n ṣèrànwọ́ lórí jẹjẹrẹ, Duration 5,5527 Bélú 2019 BBC News, Yorùbá Ìdí tí ẹ fi le è nígbàagbọ́ nínú ìròyìn BBC Ìlànà Lílò Nípa BBC Òfin Àṣírí Cookies Kàn sí.
Lori awọn oju opo ikansira ẹni lori itakun agbaye si lawọn eeyan ti mọ fun ọna to n gba gbe asa ati ise ilẹ Yoruba larugẹ.
Ọkùnrin kan bá ọmọ oṣù mẹ́ta lòpọ̀, ìfun ọmọ tú jáde!
Ohun kan ti ẹbi rẹ mọ ni pe wọn lọ gun kẹkẹ lọ sita.
Igbesẹ yii yoo mu ki ile ifowopamọ to ga ju lọ nitirẹ maa pese owo tuntun fun aọn banki ti yoo maa fi rọpo fun awọn eniyan.
Ẹ̀wẹ̀ àwọn aláṣẹ ti fi ìlàna bi àwọn ọkọ òfúrufú náà yóò ṣe ma rìn láti òní ọjmọ́ Sátidé, ọja karún, oṣù kẹjọ ọdún 2020.
Bi ọrọ ṣe ri gẹlẹ ree o ni agbegbe Tongov ni ipinlẹ Benue nigba ti awọn eeyan kan n fẹ lọ sin oku ọkan lara awọn ijoye pataki lagbegbe naa ti orukọ rẹ n jẹ, Tor Gbev Amaafu ni owurọ ọjọ Satide.
Agbára OLUWA sọ̀kalẹ̀ sórí Elija, ó di àmùrè rẹ̀ mọ́ ẹ̀gbẹ́, ó bẹ̀rẹ̀ sí sáré lọ; ó sì ṣáájú Ahabu dé ẹnubodè Jesireeli.
won lati lo gbagede ohun, leyin ti o ko jale tele lati maa je ki won lo gbagede
When would schools reopen in Nigeria?
Iroyin fi ye ni pe aago mejila ọsan ọjo aje ni aarẹ Muhammadu Buhari fi asiko igbalejo wọn si.
Pillay nínú akọtọ kan tó kọ ní ọ̀pọ̀ àwọn obìnrin yan iṣẹ́ kan láàyò kòṣèyìn pé ìtòjú ọmọ àti ilé ní ojúṣe wọn.
Sáájú ni Ndume ti ṣe oníduró fún Maina ti wan fi ẹ̀sun méjìlá kan, tó fi mọ́ kíkó owó Nàìjíríà pamọ́ ní ìlú òkèrè.
Resini, ọba Siria, ati Peka, ọba Israẹli, gbógun ti Jerusalẹmu, wọ́n sì dó ti Ahasi, ṣugbọn wọn kò lè ṣẹgun rẹ̀.
"Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Risikat Moromoke Azeez: Inú èmí àti Òbí mi dùn nígbà ti Risi bí ọmọ olójú búlù- Wasiu ""Inu mi yoo dun pupọ ta ba tun bi ọmọ ti oju rẹ yoo bulu, koda, ki ni mo fẹ fi ọmọ olju funfun se mọ, mo tiẹ n gbadura pe gbogbo ọmọ ti Ọlọrun yoo ba fun mi siwaju, ki wọn jẹ oloju bulu."
 Lara ohun ija ogun ti won ri
A wọ̀nà títí ojú wa di bàìbàì,asán ni ìrànlọ́wọ́ tí à ń retí jásí.
Lasiko yii ni àwọn agbabọọlu Arsenal naa ti pakiti mọlẹ, ti Pierre-Emerick Aubameyang si da ayo kan pada fun Valencia laarin iṣẹju mẹtadinlogun ti idije ọhun bẹrẹ.
Bí ó bá jẹ́ agbára Beelisebulu ni èmi fi ń lé ẹ̀mí èṣù jáde, agbára wo ni àwọn ọmọ yín fi ń lé wọn jáde?
Tamari, iyawo ọmọ Juda, bí ọmọ meji fún un: Peresi ati Sera.
 nítorí pé , kò sí ẹni tí kò ní kú .
Wò ó, OLUWA ń jáde bọ̀ láti inú ilé rẹ̀,yóo sọ̀kalẹ̀, yóo sì rìn lórí àwọn òkè gíga ayé.
Kí ó tó di ọjọ́ ìsọmọlórúkọ, oríṣiríṣi orúkọ ni a máa ń pe ọmọ titun tí a ṣẹ̀ṣẹ̀ bí.
Gbogbo àwọn tí wọ́n wà ní àpéjọpọ̀ náà jẹ́ ọ̀kẹ́ meji ati ẹgbaa ó lé ojidinnirinwo (42,360), 
Àìsàn jẹjẹrẹ mú ẹ̀mí Aisha Abimbọla lọ Tí Mágà ẹ bá ti lè yó ìfẹ́, kò kọ̀ kí ọ́mọ tirẹ̀ kú - Yahoo Boy Lọjọ keji ti wọn ṣiṣẹ abẹ naa tan ni ile iwosan naa ṣẹṣẹ mọ pe aṣiṣe ti waye lori ẹni ti wọn parọ kindirin rẹ.
" Oloye Alabi tẹsiwaju pe ibatan oun ni Ajimọbi, bẹẹ si ni lati kekere lo ti n fihan pe oun yoo de ibi giga nile aye.
Cerebral Palsy: àrùn tó n gba omijé lójú ẹni láìnídìí
O dara ki ọkunrin ma a jẹ tomato daradara, ki atọ rẹ le dara.
Ìwọ ni mo fi lu tọkunrin tobinrin pa,ìwọ ni mo fi lu tọmọde, tàgbà pa,ìwọ ni mo sì fi run àwọn ọdọmọkunrin ati ọdọmọbinrin.
Oríṣun àwòrán, Other Àkọlé àwòrán, Awọn ẹgbẹ okunkun fasiti Naijiria: Buccaneers,Black Axe ati awọn ẹgbẹ ijaiya mìíràn Lawọn ilu bi Eko ati Portharcourt awọn ẹgbẹ okunkun yi a ma saba fa awọn ọmọ keekeke wọnu ẹgbẹ janduku ladugbo ti iru awọn wọnyi a si wa pada wa di booran nigba ti wọn ba de fasiti.
Ẹkunrẹrẹ alaye ree lori igbesẹ to tọna Mo ṣetán láti ta ilé tí mo ń gbé, kí n le rí àwọn ìbejì mi padà - Akeugbagold Àjọ ọlọpàá ìpínlẹ̀ Ondo kò gbọ́ ǹkankan nípa ọ̀daràn tó ní ààrun Corornavirus Ààrẹ Buhari yóò bá àwọn ọmọ Nàìjíríà sọ̀rọ̀ lónìí Èèyàn 91 míràn tún ti ní àrùn Coronavirus ní Nàíjírìa Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí kan sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
Funke Akindele (Jenifa) Oṣere apanilẹrin nni Jenifa kọ ọ si oju opo instagram rẹ pe gbogbo bo ṣe n lọ yii kan ṣaa su oun.
Ta ba si n sọrọ nipa ọla, iyi ati ẹyẹ, a le sapejuwe Alaafin Adeyemi bi ọba alade to n fi ọla wu ni, ẹni to jẹ atọbatẹlẹ, ko to jọba.
Ọwọ́ ṣìnkú ọlọ́pàá tẹ àwọn adigunjalè apanìyàn Ọfa míràn.
fun eto idibo gomina ati ile igbimo asofin ti ipinle Bauchi.
Ọmọ ọdun mọkanla ni Fopefoluwa Ayo-Oyalowo to tete mọ iru ẹbun ti Ọlọrun fun un to si n mu u lo lati majesin.
O fikun-un pe, “o je ohun iyalenu fun mi.
eleto idibo INEC  lo n samojuto eto idibo
O ṣe kọmiṣọna fun karakata, kọmiṣọna fun iṣuna ati kọmiṣọna fun eto idagbasoke oṣiṣẹ.
Agbẹnusọ fun gomina feto iroyin, Ọgbẹni Taiwo Adisa lo ni gomina naa fi ọgọta miliọnu Naira silẹ lati fi tọju awọn ọmọ alaini lati ipinlẹ Ọyọ to n kẹkọ gboye imọ ofin ni saa ọdun 2019/2020.
Gbogbo àwọn eniyan Ọlọrun ki yín, pàápàá jùlọ àwọn ti ìdílé Kesari.
Láìṣe àní àní, èmi náà mọ̀ pé ẹ kò fẹ́ bẹ́ẹ̀, dípò eléyìí nì, àfi ọ̀tá mi ni ẹ lè ni èrò burúkú sí.
Sugbọn Fredrick, lotitọ ati lododo, ni mọlẹbi.
Ninu iwe ti aare ko si adari ile igbimo asofin, ni eyi ti won ka nile-igbimo asofin agba lojoRu.
    `Bí a ti dé ibi kan báyìí tí ó ttẹ́jú díẹ̀ tí a dúró tí a jẹun tán ni a déédéé gbọ́ ariwo ogunlọ́gọ̀ àwọn ọmọdé ní apá ọ̀nà ibì tí à ń lọ tí wọ́n ń ké bọ̀ lápá ọ̀dọ̀ wa.
O wa ṣalaye idi pataki ti iru ipade yii fi waye, pe.
Àwọn ẹṣin dúdú ń fa kẹ̀kẹ́ tiwọn lọ sí ìhà àríwá, àwọn ẹṣin funfun ń lọ sí ìhà ìwọ̀ oòrùn, àwọn tí wọ́n jẹ́ kàláńkìnní ń lọ sí ìhà gúsù.
Elèyìí ni a fi ń pè wọ́n ní “Òṣómàáló” nítorí kò sí ibi tí a kó ti lè rí Ìjẹ̀ṣà ti ọ̀rọ̀ ìṣòwò bá délẹ̀, bẹ́ẹ̀ ni kò sí irúfẹ́ owo tí wọn kò lè ṣe, ohun tí ó kó wọn ni irìnra ni olé àti ọ̀lẹ.
Amọ,apere arun naa diẹdiẹ ni wọn ma n ṣe afihan ti ko si wọpọ pe ki awọn ọmọde gba ti ọwọ arun yi lọ niafiwe ti awọn eeyan ọjọ ori toku.
    L Murby jẹ ọ̀rẹ́ ọ̀pọ̀lọpọ̀ àwọn ọmọ Yorùbá, o fi ìwà rẹ̀ fà wọ́n mọ́ra, ó jẹ́ àpẹẹrẹ pé ènìyàn dúdú àti ènìyàn funfun lè jẹ ọ̀rẹ́ ara wọn.
Turkey: Minisita fun eto igbafẹ lorilẹede naa sọ wi pe, awọn yoo ṣi gbogbo ile iṣẹ eto igbafẹ lorilẹede naa lati Oṣu Keje, amọ awọn arinrinajo lati Germany nikan lo le wọle.
Lẹyin ọdun meji ati aabọ, ẹnu awọn aṣofin ko tii ko lori esi idibo itagbangba to waye lorilẹ-ede naa.
Gẹgẹbi iroyin iku rẹ se tẹ BBC Yoruba lọwọ, ọjọgbọn Akinwunmi Ishola ṣalaisi ni owurọ ọjọ abamẹta ni ilu Ibadan.
Fun Obio-Akpor, AAC ni ibo 7495, nigba ti PDP ni ibo 281164.
Kí lo mọ̀ nípa fẹntilétọ̀, ohun èlò aṣèrànwọ́ èémí 'Màálù tó bá tàsẹ̀ àgẹ̀rẹ̀ níwájú ilé mi, ó dẹran àsun!
Mukadam:Ipo yii lo wa ni ọpọ ọna kaakiri.
Àwọn ọlọ́pàá dí ìwọ̀de Shia lọ́wọ́ lójúnà wọn lọ sí Zaria fún ìsìn mímọ́ ọlọ́dọọdún.
 Ṣaaju, Aarẹ Buhari ni ina ijọba ti gbooro si, awọn ti sẹgun Boko Haram de ibi to lamilaaka ati pe eto isuna fun awọn onisowo n ran ọpọlọpọ eniyan lọwọ."
"O sọ pe ""nigba ti wọn si n sadura, mo sa n sọ pe bẹẹni, bẹẹni , bẹẹni nitori pe nkankan na ni ohun to jẹ wa logun, mo si fẹ kẹkọọ lọdọ rẹ."
Simiatu Gbesa, tii se igbakeji iya olorisa labẹ Olumọ salaye pe ko si ohun tawọn beere lọwọ awọn orisa naa, ti wọn kii fun awọn, koda bi alaisan ba mu omi kan to wa labẹ oke naa, kiamọsa ni ara rẹ yoo ya.
Ire ṣ'ọjọ́-ìbí, Mide àti ọkọ rẹ̀ lẹ̀pọ̀, Iyabo Ojo f'aṣọ ilẹ̀ Afirika dárà Funke Akindele fún mi lówó tí mo fi gba ilé, kò ra ilé fún mi o - Ajirebi Poly Ibadan ṣe bẹbẹ pẹ̀lú àgbéjáde ẹ̀rọ tuntun méjì tó ń dènà àrùn Coronavirus Èèkàn ẹgbẹ́ òṣèlú APC mií Lanre Razak jáde láyé lẹ́yìn àìsàn ráńpẹ́ Ọ̀rọ̀ ìtàjẹ̀sílẹ̀ ní Nàìjíríà yìí tí ń kọ àwa Oṣo àti Àjẹ́ lóminú, a fẹ́ wa ǹkan ṣe síi Ìpànìyàn tún wáyé ní Akinyele, àwọn ará àdúgbò ṣe ìwọ́de O ṣeleri lati maa sọ fawọn ololufẹ rẹ, bi ara rẹ ba ti n ṣe sii looree kooree.
Ijamba ọkọ naa ṣẹlẹ lẹyin ti ọkọ nla kan to ko okuta ikọle kọlu ọkọ Lexus agbera pa lori afara ọhun.
Onírúurú ọ̀rọ̀ lón tí n lọ lórí ǹkan ti bàbá Kiddwaya sọ.
Oríṣun àwòrán, wiki/Babatunde_Fashola Àkọlé àwòrán, Ọgba igbafẹ ti ijọba Gomina Fasola fi sọ orukọ Ọjọgbọn Ayodele ni Yaba Ayodele Awojobi ko jẹ onimọ lasan bi kii ṣe wi pe o fẹran ki o ma ṣe agbelẹrọ nnkan orisirisi.
;*Ile igbinmo asofin ipinle Eko tun  rọ  Ile
Mo sì tún bẹ̀ yín pé bí ó ti wù kí ó rí, kí ẹ má ṣàì fèsì ìwé yìí, kí ẹ sì jọ̀wọ̀ kí ẹ máṣe jẹ́ kí èsì náà pẹ́ rárá.
Ṣugbọn ó gbọdọ̀ fi òróró hini kọ̀ọ̀kan ti eefa ìyẹ̀fun kọ̀ọ̀kan.
" Oyedepo, ẹni ti iwaasu rẹ kun fun ire fawọn olujọsin rẹ, ati egun lori awọn ẹni apaniyan ni Naijiria, tun gegun pe ẹnikẹni to ba ni oun yoo pa eniyan ko to de ipo oselu, ko ni de ori ipo naa laelae.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Femi Falana: kò yé kí ìdájọ́ òfin yàtó síra wọn ni Naijiria 'Ti ami naa ba ti kọja alafo naa, ibo oludibo bẹẹ ti gbofo ni yẹn.
”“Nipa bayii, ojogbon Yemi Osinbajo wa fi n da gbogbo omo orile ede Naijiria loju pe , gbogbo awon ti won lowo nibi iwa ibajẹ ati aibofin mu naa, ni awon yoo foju won han  , ti won yoo si  je iya labe ofin.
Nítorí náà OLUWA fìdí ìjọba rẹ̀ múlẹ̀, gbogbo àwọn ọmọ Juda sì ń san owó orí fún un.
Nígbà tí wọn bá gba agbára lọ́wọ́ àwọn eniyan Ọlọrun patapata, ni gbogbo nǹkan wọnyi yóo ṣẹlẹ̀.
Ó kọ̀ láti gba ìbọ̀rìṣà láàyè, nítorí náà ni n kò ṣe ní fi ibinu pa àwọn ọmọ Israẹli run.
Akọmọna ayajọ naa fun ọdun yii ni ajafẹtọ ibaradọgba ni mi: mimu ẹtọ awọn obinrin ṣẹ."
Oriṣii ara ni Iyabo da ninu aṣọ to wọ ọhun, bi o ṣe n yanu si atẹgun lo tun duro siwaju ile awo dami ẹnu kan to fi ya fọto.
mẹrindinlaadọta ninu ida ọgọrun lo duro fun inawo onigbadegba.
Wọn ti pa ọkan ninu wa, iru rẹ ko si ni sẹlẹ mọ.
Ọlayinka ni ofin to dena lilẹ patako ipolongo nilẹkulẹ ko jẹ tuntun ati wi pe igbese na ki se lati dunkukulaja mọ ọmọ ẹgbẹ oselu kankan bi ko se lati rii pe ohun gbogbo lọ leto leto.
Toyin pòórá lẹ́yìn tó figbe ta nípa ìfipábálòpọ̀ lójú òpó Twitter - Àwọn ǹkan ti BBC mọ nípa rẹ̀ rèé Wọ́n ti pa ẹni to yìnbọn pa ará Texas márùn ún -ọlọ́pàá Laipẹ́, ọmọ tí kò bá pé ọdún méjìdínlógún kò ní leè jáde girama l’Ọṣun Ǹkan mẹ́jọ tó máa kọ́kọ́ ṣẹlẹ̀ kí olólùfẹ́ méjì tó pa ara wọn Ajọdun ọdun bọọli maa n waye lẹẹkan lọdun ni ilu Pọta nibi ti gbogbo eniyan a ti ni oore ọfẹ lati jẹ oriṣiriṣi bọọli, ẹja didin, ẹran didin ati ata dindin.
 oníkálùkù jókòó sáyè rẹ ̀ .
Ṣé mo lè jí i dìde ni?
Chelsea fi 4-0 kan Everton mọ́lẹ̀ bí àgbò lábẹ́ òrùlé Stamford Bridge Oríṣun àwòrán, Getty Images/premier league Àkọlé àwòrán, Ode iya ni Everton lọ pẹlu bi Chelsea ṣe fi iya ajẹbolori ṣe wọn lalejo ni Stamford Bridge.
Bẹẹ ba gbagbe, ana Ọjọru ni ileeṣẹ aarẹ kesi awọn gomina mẹfẹẹfa to n bẹ nilẹ Yoruba lati wa wi tẹnu wọn lori agbẹkalẹ eto aabo Amọtẹkun naa, amọ titi di akoko yii, a ko tii mọ ohun ti wọn ba bọ lati ileesẹ aarẹ.
Oríṣun àwòrán, Olatunji family Àkọlé àwòrán, Babatunde Olatunji fẹ iyawo rẹ Ammiebelle Bush ni ọdun 1957 Awọn ẹbi Olatunji sapejuwe rẹ gẹgẹ bi akinkanju eniyan Iyawo Olatunji, Iyafin Ammiebelle Olatunji to jẹ ẹni ọdun mọkandinlaadọrun ṣe apejuwe ọkọ rẹ gẹgẹ bi ẹni to gbe igbeaye rẹ lati ṣe igbelarugẹ fun ifimọsọkan awọn ọmọ ilẹ Afrika.
Bakan naa, iwọ ni wa a san owo ti ile ẹjọ ba beere fun lasiko to fẹ ẹ gba oniduro ẹni to n jẹjọ, ti ẹni naa ba fi salọ.
Nítorí náà nígbà tó bá yá, a kò ní pè é ní Tofeti tabi àfonífojì ọmọ Hinomu mọ́, àfonífojì ìpànìyàn ni a óo sì máa pè é.
Àkọlé àwòrán, Àwọn kan ti lẹ̀ pé è ní aláwàdà Ṣùgbọ́n Fayose kọ́ ni olóṣèlú Nàìjíríà àkọ́kọ́ tí àwọn ọmọ orílẹ̀-èdè Nàìjíríà fẹ́sùn kàn pé ó parọ́ pé ìlera àwọn kò pé, yálà nítorí pé wọ́n ní ẹjọ́ láti jẹ́ tàbí nínú wàhálà òṣèlú.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Violence against women: Ilé aṣòfin Kano buwọ́ lu òfin gígé ǹkan ọkùnrin afipabánilòpọ̀ 27 Agẹmo 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 28 Agẹmo 2020 Oríṣun àwòrán, Others Igbimọ awọn Ulamas nipinlẹ Kano ti kọ abadofin ti ile igbimọ Aṣofin ipinlẹ naa buwọlu, lati ge nnkan ọkunrin ẹnikẹni ti o ba fi ipa ba obinrin lopọ.
Iwe iroyin ori ayelujara kan, NCA sọ ni Ọjọru pe agbẹjọro rẹ ti kọkọ sọ pe diẹ lara awọn ẹsun ti wọn fi kan Omotosho ko lagbara to nkan ti onibaara oun yoo wi awijare le lori, ṣugbọn adajọ to gbọ ẹjọ naa fagile ẹbẹ rẹ.
Amọṣa Adajọ naa ti laago ikilọ fun awọn agbẹjọro to n lọwọ ninu igbẹjọ naa to ba fẹ gbẹyinbẹbọjẹ lori ẹjọ naa.
Buhari: Àwọn ọ̀dọ́ ní kò rọrùn láti ṣiṣẹ́ ọ̀gbìn láìsí ohun èèlò ìgbàlódé
Ẹnikẹ́ni tí ó bá fi ọwọ́ kàn án, òkúta ni kí wọ́n sọ pa á tabi kí wọ́n ta á ní ọfà; kì báà ṣe ẹranko tabi eniyan, dandan ni kí ó kú.
Ọmọ ilu Igboore ni ilu Abeokuta ipinlẹ Ogun ni woli Israel Oladele ṣugbọn ọmọ atapata dìde ni to si jẹ iya ki o to de ipo to wa.
Ijamba oju-ojo naa waye ni ekun mountainous ti o wa leba orile-ede Burundi losan ojo-Abameta, nigba ti awon eniyan ilu Gihemvu n josin lowo.
Nigeria Election 2019:El-Rufai, lọ tọwọ́ ọmọ rẹ bọ aṣọ!
Alámì ẹ̀yẹ Scrabble Paul Sodje àti ọ̀rẹ́ rẹ́ kú lásìkò tó fẹ́ lọ́ sanwó ìdóòlà ẹ̀mí àbúrò rẹ̀, tí afurasí darandaran jí gbé Àìsí iṣẹ́ nígboro lọ̀pọ̀ ọ̀dọ́ fi fẹ́ gba iṣẹ́ Amotekun - Toogun Gbèsè Nàìjíríà ti lé ní 18 tírílíọ́ọ́nù lábẹ́ ìṣèjọba Ààrẹ Buhari- DMO Bàbálọ́jà márùn ún la ó ò ní l'Oyo tí Makinde bá lè buwọ́lu ìyànsípò YK Abass Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Oyo traders crisis: Ẹgbẹ́ oníṣòwò ṣèwọ́de lórí ìyànsípò YK Abass gẹ́gẹ́ bí bàbálọ́jà tuntun9 Owewe 2020 Fídíò, Akomolede ati Aṣa lori BBC: Mọ̀ si nípa oríṣìí ẹ̀ka ìsọ̀rí ọ̀rọ̀ àti ìwúlò wọn8 Owewe 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Fruits and Vegetables: Ǹ jẹ́ o mọ̀ pé ó yẹ ko se Carrot rẹ, ko tó jẹ ẹ́ 30 Ọ̀wàrà 2019 Oniruuru ounjẹ ni asẹda fi jinki wa nilẹ Yoruba, orilẹede Naijiria ati nilẹ adulawọ lapapọ.
Bẹẹ lo tun sọ pe ọna Ikorodu si Maryland naa ti di lilo lẹyin ti ijọba ṣe atunṣẹ rẹ.
Awọn ẹṣọ alaabo to wa pẹlu rẹ naa daa ina ibọn bolẹ.
Nibayii, ọjọ kọkandinlogun oṣu Kẹjọ,ọdun 2019 ni ipade miran yoo tun waye ni aafin laarin Olubadan ati awọn ijoye rẹ.
Fayẹmi ti ṣiṣẹ gẹgẹ bi olukọ kaakiri ilẹ Afirika, Yuropu, Amẹrika ati ilẹ Asia.
awọn oṣiṣẹ ile iṣẹ pajawiri atawọn adoola ẹmi ti wa nibi iṣẹlẹ naa.
Àwọn mẹ́rin t'íjọba Buhari k'etí ikún s'àṣẹ òmìnira iléẹjọ́ lórí wọn rèé Èmi kò jẹ̀bi pẹ̀lú àlàyé -Omoyele soworẹ ISWAP ti ṣekú pa òṣìṣẹ́ ẹgbẹ́ aláànù Action Against Hunger Ọmọ Uganda gba àmi ẹ̀yẹ Komla Dumor BBC tọdun yii Ipinlẹ Oyo ti kede pe wọn ti pari igbesẹ lati tun bẹre eto ile iwe ki awọn akẹkọọ yoo maa gbe ni ile iwe.
Loju opo Twitter ọrọ naa jọ bi ẹrin ṣugbọn awọn kan ni ''Sai Baba'' lo mu ki ọrọ aje Dangote dẹnu kọlẹ.
Aare Buhari n lo se ikinni ibanikedun sawon eniyan ipinle Benue lori iku awon agbe ti awon afurasi darandaran pa lojo kinni osu kinni odun yii nijoba ibile Guma, iyen abule Logo ati Okpokwu nipinle Benue.
Nwachukwu, ti o je igbakeji adari eka iroyin fun ile ise omo ogun Operation
Nigba ta n sọrọ rẹ yii, owo ribiribi ni aadọta kọbọ, koda, owo osu oṣiṣẹ ọba mii ko to aadọta kọbọ nigba naa.
Fani Kayọ̀de ṣàlàyé ìdí àjọṣepọ̀ rẹ̀ pẹ̀lú IPOB Fani kayọde ti ṣalaye pe kii ṣe nitori ati pin orilẹede Naijiria ni oun ṣe n fẹran Nnamdi kanu to jẹ aṣiwaju ẹgbẹ to n ja fun idasilẹ orilẹede olominira Biafra, IPOB.
Ohun ti iroyin sọ ni wi pe aisan to jẹ mọ ọkan lo da ẹmi ẹni to ti fi igba kan jẹ adari ile igbimọ aṣofin ipinlẹ Ọyọ naa tẹlẹri legbodo.
Mose dá a lóhùn pé, “Kò ní tọ̀nà bí a bá ṣe bẹ́ẹ̀; nítorí pé àwọn nǹkan mìíràn lè wà ninu ohun tí a óo fi rúbọ sí OLUWA Ọlọrun wa tí ó lè jẹ́ ìríra fún àwọn ará Ijipti.
nítorí pé ó dá a lójú pé ẹni tí ó ṣe ìlérí lè mú un ṣẹ.
San gbogbo owó tí wọn óo bá ná ati tìrẹ náà.
’Ẹ̀yin ará Madimeni pàápàá, kẹ́kẹ́ yóo pa mọ yín lẹ́nu;ogun yóo máa le yín kiri.
Bẹ̀rẹ̀ si yọ omi ori Ògì si sẹ bi ó bá ti tòrò
Yakubu ti ni esi idibo ti aarẹ ati ile igbimo asoju sofin lorile ede Naijiria
igbimo ijoba apapo , ti igbakeji aare orile ede Naijiria ojogbon Yemi Osinbajo
O ni kiko awọn fijilante, ọdẹ ibilẹ atawọn ọmọ ẹgbẹ OPC mọra fun ikọ naa yoo mu ko so eso rere daadaa.
Àtẹ ìfẹ́kà ń bẹ lọ́wọ́ rẹ̀ tí yóo fi fẹ́ ọkà inú oko rẹ̀; yóo kó ọkà rẹ̀ sinu abà, yóo sì sun fùlùfúlù ninu iná àjóòkú.
 Sibẹ maa rọ yin pe ki ẹ jinna réré si iwa lilọwọ ninu ẹgbẹ okunkun, ki ẹ si sa fun awọn iwa ọdaran.
Ilé Orímóògùnjẹ́ kò ju ilé kẹ́rin lọ sí ilé Àlàó.
Omishore, eni ti o je olugbani nimoran kan pataki fun Aare ile-igbimo asofin lori oro ile-okere ati ibasepo lagbaaye, so eyi di mimo niluu  Abuja lojo-Aiku.
7 2373115 Orilẹede Ukraine 21479 48.
Ẹ máa lọ; ṣugbọn ẹ súre fún èmi náà!
O si tun le jẹ ti ileewosan, ijọba ibilẹ, tabi ibura ( age declaration) Ẹni to ba fẹ ẹ fi orukọ silẹ gbọdọ ni iwe ẹri ti ko kere ju ti imọ ijinlẹ akọkọ (first degree), pẹlu maaki ti ko kere ju 'Second Class Lower Division' lọ O le lo iwe ẹri HND naa, pẹlu maaki ti ko kere ju 'Lower Credit' lọ Awọn iwe ẹri yii gbọdọ jẹ lori ẹ̀kọ́ nipa 'arts,' science' , tabi' humanities' , lati ileewe ti ijọba fi ontẹ lu Ko tan sibẹ o, àwọn olukopa gbọdọ fi lẹta ijẹri lati ileewe giga ti wọn lọ, silẹ Olukopa kankan ko gbọdọ ni tatuu tabi kọ ohunkohun si ara Olukopa gbọdọ ti pari eto agunbanirọ (NYSC), ni iwe ẹri NYSC, tabi iwe ti ajọ naa ma n fun awọn ti ko ba lọ fun eto naa Awọn olukopa ko gbọdọ jẹ ọmọ ẹgbẹ okunkun kankan.
Gbogbo agbaye si ni awọn onile itaja ti maa n lo ede yii.
Pasitọ Enoch Adeboye Ni ọpọlọpọ igba naa ni adari ijọ Redeem, Pasitọ Enoch Adeboye ti ma n kesi awọn eniyan to wa nipo lati ṣe ohun to tọ lawujọ, ti yoo tun sọrọ nipa idile ati igbe aye onigbagbọ.
Ó gba ohun tí wọ́n wí, ó sì dán wọn wò fún ọjọ́ mẹ́wàá.
Oríṣun àwòrán, Ronke Oshodi Oke/Facebook Àkọlé àwòrán, Òsèré Tíátà Ronke Oshodi Oke Ronke Ojo Ọmọ bíbí ìpínlẹ̀ Ondo sùgbọ́n tí wọ́n bí ní agbègbè Oworonshoki ni ìpínlẹ̀ Eko ni.
Lẹyin ti awọn eniyan paapaa awọn aṣofin lorileede Amerika koju oro si, nitori ọpọ ẹmi to ti ṣofo ninu ogun abẹle Yemen naa.
koda mi o tiẹ gbọdọ roo lọkan depo ki n ṣe nnkan to jọ' Makinde ni gómìnà, èmi ni igbákejì rẹ̀; kò sí ìjà láàrin wa-Rauf Adeniyan, igbákejì gómìnà ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́ Ṣé lóòtọ́ ni Kayode Fayemi, gómìnà ìpínlẹ̀ Ekiti fẹ́ du ipò ààrẹ orílẹ̀èdè Nàìjíríà?
Bi ko ṣe si ọna lati da awọn oludokowo owó orí ayelujara mọ, lo fa ọpọlọpọ eeyan to fẹ ẹ ra àwọn nkan ti ko ba ofin mu lori ayelujara, mọ́ra.
 Ile ise FIGG Engineering ni won jo se ise afara yii ni pe eyi ni akoko iru re ti yoo sele logoji odun ti won ti bere ise seyin.
O fi kun ọrọ rẹ wi pe eto aabo agbegbe naa ko yọ awọn ọlọdẹ ati awọn agbaagba to n bẹ layika silẹ ki wọn le fi agbajọwọ ṣẹgun awọn amọọkunṣeka naa.
Sagamu: Ìkọlù ń wáyé bí ará ìlú ṣe gbéná wòjú ọlọ́pàá torí ikú agbábọ́ọ̀lù Ó lòdì s'òfin kí ọlọ́páà fìyà jẹ ẹnikẹ́ni tó bá wọ aṣọ ológun - Amofin Fásitì UI f''orin tàkasúfèé wá ojúùtú si ìṣòro ẹ̀kọ́ ìṣirò Ẹ wọ aṣọ fẹ́lẹ́fẹ́lẹ́ láti kojú ooru gbígbóná lásìkò yìí - Dokita Ọga ọlọpaa patapata ti ba awọn ẹbi ologbe naa kẹdun, to si fi da wọn loju pe wọn yoo ri idajọ ododo gba lori iṣẹlẹ naa.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, America yóò tutù ju bó ti yẹ lọ Koda wọn ti kede konile o gbele lawọn apa ibi kọkan ni il naa.
Ní ọjọ́ tí wọn pa Àgọ́ Àjọ, èyí tí í ṣe Àgọ́ Ẹ̀rí, ìkùukùu bò ó.
Má ṣé tọrọ aforijin lọ́wọ́ Buhari lásìkò àbẹwò rẹ- South Africa Díẹ̀ lára àwọn òṣèré Nollywood ti wọ́n ti ṣe ìgbéyàwó lẹ́ẹ̀kejì Ọpọlọpọ ọmọ Naijiria lo gboriyin fun ileeṣẹ BBC fun iṣẹ ọpọlọ to n fọ awujọ mọ tó n jade lagbalaBBC nigba gbogbo: Díẹ̀ lára àwọn òṣèré Nollywood ti wọ́n ti ṣe ìgbéyàwó lẹ́ẹ̀kejì Awakọ̀ 700 kò sí páńpẹ́ òfin, 191 ṣẹ̀wọ̀n lórí ẹsùn wíwakọ̀ lẹ́yìn tí wọ́n mu ọtí Orìlẹ-èdè mẹrindínlọgbọn tí ọmọ Nàìjíríá lè wọ̀ láì ní àṣe ìwé ìgbélùú Àwọn òbí ní lóòtọ́ ni àìsàn bẹ́ sílẹ̀ ní Queens College lèyín tí Ọmọ 85 dùbúlẹ̀ àìsàn Awọn ọmọ Naijiria miran ni ki ijọba gbe igbesẹ to yẹ lati wagbo dẹkun fawọn olukọ to n huwa ibajẹ yii ki ọkan awọn akẹkọọ le balẹ.
Àwọn ọmọ Àlàó kò bá wọn kọ ẹsẹ kejì tí ó sọ wí pé ‘Ọjọ́ ayéè mi ń sáré lọ sópin’.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Child Engineer: Olamide Odukọya nílò ìrànlọ́wọ́ láti lọ síléẹ̀kọ́ ìmọ̀ ẹ̀rọ Ọkùnrin kan sálọ lẹ́yìn tó gbẹ̀mi ènìyàn mẹ́ta Díẹ̀ ló kù kí bàlúù arìnrìnàjò sílẹ̀ mímọ́ Hajj gbaná Ṣé lóòtọ́ ni àdó olóró bú níléeṣẹ́ ìjọba South Africa tó wà nílùú Abuja?
O ṣalaye pe bi awọn eeyan ṣe n wọ aṣọ laye ode ni jẹ iwa atọhunrinwa, eyii to lodi si aṣa Yoruba.
Ogun náà tàn káàkiri gbogbo agbègbè; àwọn tí wọ́n sì sọnù sinu igbó pọ̀ ju àwọn tí wọ́n fi idà pa lójú ogun lọ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó Fun awọn kan, bi eto oselu orilẹde Naijiria ṣe dagun lo mu ki ijọ maa kede awẹ ọlọjọ gbọọrọ bii eyi ti ijọ RCCG kede naa.
Liverpool fí ògùn ẹ̀yìn ja Barcelona Ààrẹ ẹgbẹ́ agbábọ́ọ̀lù Nàìjíríà, Pinnick yóò fojú ba ilé ẹjọ́ Kini awọn ohun to yẹ ko o mọ nipa Àarẹ UNGA tuntun?
Ọpọlọpọ yóo kùnà ninu igbagbọ; wọn yóo tú àwọn mìíràn fó; wọn yóo sì kórìíra àwọn mìíràn.
"Ìjọba kò tú Dasuki àti Sowore sílẹ̀ látàri akitiyan ilẹ̀ Amẹrika- Dasuki Èyí ni ìdí tí Bàbá Kérésì fi máa n wọ aṣọ pupa àti funfun nígbà gbogbo Olè yabo báńkì,fọ́n owó ká fáwọn èrò lẹ́yìn tó pariwo 'Merry Christmas' Ẹ ronúpìwàdà lásíkò ọdún, àti àwọn ìkíni mìrán tó jẹ yọ fún Kérésì Ninu atẹjade naa, Shehu sọ pe ""Lati igba ti aarẹ Buhari ti gori aleefa lọdun 2015, ko tii fi akọroyin kankan satimọle."
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Èmi gan máa ń béèrè lọ́wọ́ ara mi pé ta ni Wole Soyinka gangan' Lẹyin naa ni wọn fa wọn le ajọ FBI nilẹ Amẹrika lọwọ, lati lọ koju igbẹjọ lori ẹsun wọn fi kan wọn.
gbogbo omo orile ede Naijiria bi a se n sajọyọ ọdun tuntun 2019, ni eyi ti yoo
Oríṣun àwòrán, IamDayo Àkọlé àwòrán, Tenientertainer: Olórin obìnrin tí kìí ṣi ìhòhò rẹ silẹ̀- Olólúfẹ Teni Ọpọlọpọ lo n sọrọ lori ayelujara pe awokọṣe to yẹ ki awọn ọdọbinrin iwoyi maa wo ni Teni jẹ nitori pe eyi fihan pé ko si nkan ti o ko le da laye ti Olorun ba ti gab funẹ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Arun iba ọrẹrẹ: ipinlẹ Anambra pasẹ ma mu Gaari mọ 24 Sẹ́rẹ́ 2018 Oríṣun àwòrán, Reuters Àkọlé àwòrán, Igbẹ ati ito eku ninu garri a ma fa iba ọrẹrẹ Lati dẹkun arun iba ọrẹrẹ to gbode kan, Ijọba ipinlẹ Anambra ti pasẹ ki awọn ara ilu ma mu gaari mọ.
Lafikun wọn gbudọ fin gbogbo ileewe pẹlu kẹmika apakokoro ki wọn to wọle.
0 113207 Orilẹede Israel 2962 35.
Nígbà tí àwọn ọmọ Israẹli pàgọ́ sí Giligali, wọ́n ṣe àjọ̀dún àjọ ìrékọjá ní ìrọ̀lẹ́ ọjọ́ kẹrinla oṣù náà, ní pẹ̀tẹ́lẹ̀ Jẹriko.
Dokita Zalmai ni iriri ọdun mẹwaa nipa ṣiṣetọju awọn obinrin ti ọkọ wọn ba ge ẹya ara wọn sọnu latari iwa jagidijagan ninu ile.
Ilera rẹ gbọdọ duro daadaa Ko gbọdọ si akọsilẹ pe ile ẹjọ ti da ọ l'ẹbi ri fun iwa ọdaran Ọjọ ori ẹni to fẹ ẹ fi orukọ silẹ gbọdọ ti pe ọdun mẹtalelogun si mẹtadinlọgbọn ti yoo ba fi di oṣu Kinni, ọdun 2021 O gbọdọ ni iwe ẹri ọjọ ori ti ajọ to n mojuto bi eeyan ṣe pọ si ni Naijiria, National Population Commission fi ọwọ si.
Ọ̀rọ̀ àgbà rèé, kì báà pẹ́, a máa padà ṣẹ nígbẹ̀yìn ni.
Elebuibon lasiko to n ba BBC News Yoruba sọrọ ni, awọn asofin naa fẹ pa asa ati iṣe ilẹ Yoruba run ni.
“Mose yìí kan náà, tí wọ́n kọ̀, tí wọ́n sọ fún pé, ‘Ta ni ó fi ọ́ ṣe olórí ati onídàájọ́?
PDP South West: Ọ̀rọ̀ ọkọ̀ ayọ́kẹ́lẹ́ ìjọba tó pòórá kìí ṣe ìṣẹ̀lẹ̀ àfojúfò
Àwọn ìkookò yóo máa ké ninu ilé ìṣọ́ rẹ̀, ààfin rẹ̀ yóo di ibùgbé àwọn ajáko,àkókò rẹ̀ súnmọ́ etílé,ọjọ́ rẹ̀ kò sì ní pẹ́ mọ́.
Wọ́n ń ṣe ìdínà fún wa kí á má baà lè waasu fún àwọn tí kì í ṣe Juu, kí wọn má baà rí ìgbàlà, kí òṣùnwọ̀n ẹ̀ṣẹ̀ wọn baà lè kún.
Orilẹ-ede Amerika ati Ajọ Iṣọkan ilẹ Yuroopu, EU ti kọ ẹsi idibo naa.
‘Mo tara lori ijinigbe ju ijọba ana lọ’ Njẹ ọrọ awọn akẹkọbirin Dapchi jọ ti Chibok ?
Bakan naa, bi ọkọ tabi aya kan ba ku ti ẹni keji si fẹ gba nkan ini rẹ, o ti di ọrọ rẹpẹtẹ tori oo ni le ri yanju.
Àwọn òṣìṣẹ́ aláàbò kọlu àwọn tó n ṣe ìwọ́de ní Sudan Ilé wó pa Jide, ọmọ ọdún mọ́kànlá, l'Oṣogbo Amẹ́ríkà ń béèrè ìròyìn facebook, email arìnrìnàjò tó f'ẹ́ gbà'wé àṣẹ Sẹ́nétọ̀ Dino Melaye kéde láti dupò gómìnà Kogi Bakan naa ni Trump a kan si Obabinrin Elizabeth ni Burckingham Palace ninu abẹwo yii.
Ọrẹ kori-kosun, iyekan, àti alabarìn tòótọ́ si ọba Olateru-Olagbegi ni Oloye Michael Adekunle Ajasin, tí òun náà jẹ èèkàn nínú ẹgbẹ́ Ọlọpẹ n'ilu Ọwọ, àwọn méjèèjì si ni wọn dijọ ń ṣíṣẹ fún idagbasoke ìlú naa.
Ajọ to n mojuto itankalẹ aarun ni Naijiria, NCDC fidiẹ mulẹ pe ọdọọdun lo n ṣẹlẹ.
Ṣugbọn mo pè yín ní ọ̀rẹ́, nítorí ohun gbogbo tí mo ti gbọ́ lọ́dọ̀ Baba mi ni mo ti fihàn yín.
Akiyesi BBCnipa aworan igbeyawo Lateef ati Adebimpe: Lateef kii lo yẹti tẹlẹ, nitori pe musulumi ododo ni.
Eyi ni àwọn kan fi ro pe o jẹ ki o yọ orukọ oyinbo kuro lara orukọ rẹ, to fi n jẹ Olufunmilayọ nikan.
1 88632 Orilẹede Senegal 343 2.
Ẹ̀yin afọ́jú tí ń fọ̀nà han eniyan.
Ọmọbìnrin ọdún 25 gún ọ̀rẹ́kùnrin rẹ̀ pa nítorí ó ní ko lọ ṣẹ́ oyún Ọlọ́pàá hú òkú akẹ́kọ̀ọ́ fásítì LASU tí ọ̀rẹ́kùnrin rẹ̀ àti pásítọ̀ ṣekúpa Ninu alaye rẹ, o ni Precious ati Ujunwa jẹ ọrẹbinrin si Ifesinachi to n ṣiṣẹ awakọ takisi Uber.
L’ọmọ titun fí ń gbé ilé ọmọ rẹ̀ wáyé
Ọ̀rọ̀ǹpọ̀tọ̀niyùn, Aláàfin obìnrin àkọ́kọ́ rèé, tó ní nǹkan ọkùnrin Àjẹ́ àti Aṣẹ́wó ní ìyá Rainbow - Òjòpagogo Ṣẹ gbọ́ nípa Alájọ Ṣómólú, tó ta mọ́tò ra kẹ̀kẹ́?
Lọ́dún 1951 sì lo lewaju idasilẹ ilé ẹ̀kọ́ gírámà Imade College.
Nítorí nígbà tí ilẹ̀ bá ń mu omi òjò tí ń rọ̀ sórí rẹ̀ lọ́pọ̀ ìgbà, tí ó sì ń mú kí ohun ọ̀gbìn hù fún àwọn àgbẹ̀ tí ń roko níbẹ̀, ilẹ̀ náà ń gba ibukun Ọlọrun ni.
Naijiria  ti fi ami ayo kan si odo (1-0)fi
Ó sọ odò di aṣálẹ̀,ó sọ orísun omi di ilẹ̀ gbígbẹ,
A gbé ọ ka inú àwọn nǹkan ọ̀ṣọ́ wúrà tí a ṣe fún ọ ní ọjọ́ tí a dá ọ.
Èso rẹ̀ ni gbogbo ẹ̀dá alààyè ń jẹ.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: 'Nàìjíríà ló ń ta Nàìjíríà nilu òyìnbó' Omiṣore fi ẹgbẹ́ PDP sílẹ̀ Nàìjíríà ń ṣọ́ pápákọ̀ òfurufú tórí Ebola Ọlọ́pàá mú èèyan mẹ́ta pé wọ́n so akẹ́kọ̀ọ́ mọ́gi Sé o leè yẹ ara Ọlọ́pàá wò, kó tó yẹ̀ ọ́ wò ?
Atejade ohun so pe, “a ko fara mo ipinnu ijoba orile-ede Ethiopia nipa ikede ilu-o-fara ro naa, lara eyi ti a ti ri fifon de eto omo eniyan, nipa kikora eni jo ati fifi ehonu-eni han”.
Amọ ṣa o ni kaka ki wọn ni ileeṣẹ ti ko ni ṣanfani fọmọ Naijiria, o san ki wọn kuku ti wọn pa.
Ọpọlọpọ ri i pe iwọn ṣe pataki ninu ounjẹ sise yala ko ma di wi pe ounjẹ ko to tabi o pọ ju.
Bí wón bá ní ènìyàn n féwó ohun tí ó túmò sí ni wí pé; bí irú onítòun bá gba ègbé odidi nnkan kojá, nnkan náà yóò di ààbò/ìlàjì.
Yóo gba ẹnu ọ̀nà ìloro wọlé, ibẹ̀ náà ni yóo sì gbà jáde.
Àwọn ègún náà yóo wà lórí yín gẹ́gẹ́ bí àmì ati ohun ìyanu, ati lórí àwọn arọmọdọmọ yín títí lae.
Igbakeji  aare  ana fun orile ede  Naijiria Atiku Abubakar  ati iyawo  rẹ ,Titi  Abubakar dibo  ni deede aago mẹwaa owurọ oni,  niluu Ajiya ni ipinle Adamawa .
gbe iroyin nipa awọn ikọlu buruku yii kaakiri ori awọn ẹrọ kalekako.
Àwọn olórí alufaa ati àwọn amòfin dúró níbẹ̀, wọ́n ń tẹnu mọ́ ẹ̀sùn tí wọn fi kàn án.
"Oun eri ewi oun eri ero Adewale seun epe ko se Oba dara o d'ẹjọ lati ilu Iwo, ilu to rẹwa julọ ni gbogbo agbaye"" Ìjọba ìpínlẹ̀ Kano tí wọ́gilé ayẹyẹ lẹ́yìn ìrun ọdún Iléyá!"
Lara awọn ileejọsin yii ni ijọ CAC Okelisa, ijọ TAJEM ni Irese, ijs Assemblies of God lagbegbe olufoam nibi ti awọn ọmọ ijọ ti tilẹkun mọ ara wọn sinu ijọ naa ki awọn ọmọ ikọ amuṣẹya naa to fi tipatipa ṣi ilẹkun naa.
A tún rí ẹnìkan tí ó wà nínú ìkòkò irin, ìkòkò náà gbóná tó bẹ́ẹ̀ ti ó jẹ́ pé gbogbo ara rẹ̀ ló pupa dẹ̀dẹ̀, gbogbo ara ọkùnrin náà bó bòròkòtò ó ń ké, ‘Ara ń ta mi o, ara n  ta mi o, ara ń ta mi o’.
Peters tun gboroyin fun Gomina ipinle Eko, ogbeni Akinwumi Ambode ati ijoba re fun atileyin won lati mu igberu ba boolu afesegba ni Naijria ati ni ile-Afrika.
Ṣugbọn bí ó ti jẹ́ pé òtítọ́ ni gbogbo nǹkan tí a ti sọ fun yín, bẹ́ẹ̀ náà ni ọwọ́ yín tí a fi sọ̀yà fún Titu jẹ́ òtítọ́.
"Ogunlesi ni ""Aarẹ Muhammadu Buhari ti fọwọsi pe ki wọn fi ọfiisi reluwe to wa ni Agbo, ni ipinlẹ Delta sọri aarẹ Goodluck Jonathan."
Lojoojumọ ni Modekai máa ń rìn sókè sódò níwájú àgbàlá ibi tí àwọn ayaba ń gbé, láti bèèrè alaafia Ẹsita, ati bí ó ti ń ṣe sí.
O salaye pe, “ ni temi o, a ko le fi gbigbo salaigbo lori bi awon eniyan se n bere fun atunto orile-ede yii, ti o ba je eyi ti yoo fun gbogbo awon ti oro kan ni eto dogba-dogba ninu ise-akanse orile-ede Naijiria”.
Ọwọ́ ọlọ́pàá ìpínlẹ̀ Oyo tẹ àwọn afurasí lórí ìpànìyàn tó wáyé ní Akinyele Ohun tí ọlọ́pàá ń ṣe rèé láti sàwárí àwọn ‘mùjẹ̀-mùjẹ̀’ ní Akinyele Àwọn aṣekúpani tún ti pa ọmọ ọdún 16 ní Akinyele nípìnlẹ̀ Oyo Ìyá Barakat fi ẹ̀mí ìmoore hàn sí gbogbo àwọn tó nawọ́ síi lẹ́yìn ikú ọmọ rẹ̀ Ipaniyan to n lọ si bi i meje lo ti waye ni agbegbe Akinyele laarin oṣu mẹta, ti ọpọ si n sọ pe awọn to n fi eeyan ṣe oogun owo lo n pa awọn eniyan naa.
lati siwaju ninu ifẹsẹwọnsẹ to kangun aṣekagba ti AFCON yii.
Àbí ẹni tó fẹ jẹ àmàlà, kí ìgùnwọ́ olúwarẹ̀ yáa gbáradì nítorí ọmọrogùn àti ìkòkò ọkà wọn kìí ṣ’ọ̀rẹ́ arawọn.
Amos Dauda, Iphone: Ilé ẹjọ́ dájọ́ ẹgba mẹ́ẹ̀dóògún fún ọ̀daràn tó jí Iphone ní Kaduna
Ọmọbibi ipinlẹ Anambra lorilẹede Naijiria ni, amọ to rekọja si orilẹede Bahrain lọmọ ọdun mẹrinla, ko lee ri anfaani lati tẹsiwaju ninu ere sisa to yan laayo, to si n soju arin gbungbun agbaye bayii.
Ìròyìn fi ìdí rẹ múlẹ pé àwọn ọmọ ogun orílẹèdè Nàìjíríà pẹlú àwọn ọmọ ẹgbẹ adúnkùkùlajà Boko haram fìjà pẹẹta láwọn ìletò kan tí kò jìnà sí ìlú Maiduguri ni alẹ ọjọ àìkú.
4 133378 Orilẹede Georgia 2893 72.
 Ó wà nínú ẹgbẹ ́ 18 ( àwọn ẹ ̀ fúùfù abíire ) lórí tábìlì ìdásìkò àwọn ẹ ́ límẹ ̀ ntì .
Koda, o gba abẹrẹ lọjọ ti yoo joko ṣe idanwo Further Maths.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Pastor Adeboye: Ariwo lórí ayélujára nítorí ọ̀rọ̀ ìkíni kú ọjọ́ọ́bí tí Pásítọ̀ Adeboye kọ sí ìyàwó rẹ̀, Folu 14 Agẹmo 2020 Oríṣun àwòrán, Pastor Adeboye Pasitọ ijọ Redeem tun ti m'oke patapata lara awọn ti wọn n ka atẹjade wọn ju lori ayelujara.
lati daabo bo awon ohun adayeba to wa jake jado orile ede Naijiria.
Ìgbà tí Àkàndé mú owó kẹ́yìn nínú séèfù yìí kí ó tó kú, owó tí ó wà nínú rẹ̀ ju ẹgbàáta náírà (N30,000.
Gbajugbaja akoroyin nipa oriṣi ohun jijẹ kaakiri agbaye,Anthony Bourdain, to jẹ ilumọọka to n ṣe koriya fun ọpọlọpọ eniyan kaakiri agbaye lo ti doloogbe bayii.
gbọ́ adura rẹ̀ láti ibùgbé rẹ lọ́run, kí o sì ṣe gbogbo ohun tí ó bá bèèrè fún un, kí gbogbo aráyé lè mọ orúkọ rẹ, kí wọ́n sì lè bẹ̀rù rẹ bí àwọn ọmọ Israẹli, àwọn eniyan rẹ tí ń ṣe, wọn yóo sì mọ̀ pé ilé ìsìn rẹ ni ilé tí mo kọ́ yìí.
aarun Ebola lati odun to koja, won ti seto ibi bi ti awon eniyan naa yoo gbe
Èmi mọ̀ pé OLUWA tóbi,ati pé ó ju gbogbo oriṣa lọ.
Ko tan sibẹ, awọn obinrin ni Saudi ti lẹtọ labẹ ofin lati lọ wo sinima nile sinima, wọn tun ti le da okowo tiwọn silẹ lai lọwọ ọkọ wọn ninu.
Wúrà ni wọ́n fi ṣe àwọn ìlẹ̀kùn ìta tẹmpili, ati ìlẹ̀kùn síbi mímọ́ jùlọ, ati ìlẹ̀kùn gbọ̀ngàn tẹmpili náà.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fọ́nrán ohùn, NUJ: Ẹ̀yin Akọ̀ròyìn, ẹ sọ́ra nípa kíkọ ìròyìn tó léwu fétò ààbò O ni igbesẹ NBC yii ko faaye gba ominira awọn akoroyin to yẹ ko wa ni Naijiria bayii.
Nígbà tí àwọn baba wọn, tabi àwọn arakunrin wọn bá wá fi ẹjọ́ sùn wá, a óo dá wọn lóhùn pé, ‘Ẹ fi wọ́n sílẹ̀ fún wọn nítorí pé àwọn obinrin tí a rí fún wọn ninu ogún kò kárí; kì í kúkú ṣe pé ẹ fi àwọn ọmọbinrin wọnyi fún wọn ni, tí ègún yóo fi ṣẹ le yín lórí.
Idi ree ti BBC Yoruba fi kan si ibi isẹlẹ naa, ta si gbọ pe ọpọ igba ni wọn ti n kilọ fun awọn ọlọkọ akoyọyọ lati dẹkun wiwa erupẹ ni ibudo naa.
Nitori pe o wa lati idile olorogun,titiraka lati pese ijẹ imu jẹ ohun ti o ti n ba finra tipe ti eyi si mu ki o pinu lati ri wi pe ohun lo gbogbo ọna lati mu iyipada ba awujọ.
Wọn ni o na owo to yẹ ki wọn fi ra ohun eelo ijagun ni inakuna.
”Aare Buhari tun ri leta iwe ase gba lati odo asoju orile ede Serbia ,ni orile ede Naijiria , ogbeni Dura Likar.
Oríṣun àwòrán, others Àkọlé àwòrán, Michael ati ọmọ Miche nigba ti wọn n lọwo Lavona ni ọgba ẹwọn Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 3 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 5 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
 Àwọn ológun pa á nígbà tí àwọn ológun fẹ ́ gba ìjọba ní 1966 .
N ó fi tó o yín létí láìpẹ́.
Ọwọ ọlọpaa ti tẹ eeyan mẹwa lori wahala to waye ni ilu Kaduna, lẹkun iwọ oorun orilẹede Naijiria, ni ọjọ aje.
Ijọba ipinlẹ Ogun wa parọwa si awọn ara ilu lati ri wi pe wọn ko di oju omi lọwọ, ki omi le ma a ri aye lati ma a kọja, nitori irọrun igi ni irọrun ẹyẹ.
Ìrántí Moji Ọlaìyá lẹ́yìn ọdún kan Satia di mimọ fun awọn ololufẹ rẹ fun ipa to ko ninu ere agbelewo Yoruba kan, Ijinlẹ Pam Pam to gbe jade logun ọdun sẹyin.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Kid boxer: Ọmọọba 'The Buzz' Larbie rèé, ọmọ ọdún méje tó ń fi ẹ̀ṣẹ́ dá bírà Kí ni awọn onwoye n ri sọ nipa rẹ?
Lẹ́yìn tí wọ́n tú ìgbín sílẹ̀ tán, ó sọ fún Ọba pé láti mọ ẹni tí ó pa abuké Ọba wọ́n ní láti fún òun ní ẹṣin ńlá kan àti àwọn Onílù.
30 Ẹrẹ̀nà 2019 Oríṣun àwòrán, Facebook/Greg Nwoko Lagbo oṣelu Naijiria, ko jẹ tuntun pe ki awọn oloṣelu ma pe fun ifagile ibo paapa eleyi ti esi rẹ ko ba gbe wọn.
 iye àsìkò tí ààbò egbògi náà fi ń wà lára kò tíì fi bẹ ́ ẹ ̀ ye ni dáradára , ṣùgbọ ́ n agbára iṣẹ ́ rẹ ̀ dàbí èyí tó má a ń dínkù bí àsìkò tí ń lọ síi .
Amọ oju tiẹ gan ko fi bẹẹ se deede mọ ninu ere tiata.
O ni ile ise oko ofurufu ti Aero
Àwọn ará Samaria wárìrì fún ère ẹgbọ̀rọ̀ mààlúù, oriṣa ìlú Betafeni.
Sugbọn kaka ki wọn duro de idajọ ileẹjọ, se ni wọn doju akọtun ija kọ ara wọn bẹrẹ lati ọsẹ to kọja.
BBC Yoruba wa bọ sigboro lati mọ ohun tawọn osisẹ yii ri lọbẹ, ti wọn se wa iru sọwọ.
Akani ọmọ Karimi, ọmọ Sabidi, ọmọ Sera, láti inú ẹ̀yà Juda, mú ninu àwọn ohun ìyàsọ́tọ̀, inú sì bí OLUWA gidigidi sí àwọn ọmọ Israẹli.
 eye tí ó ń fò lóríi ìtànsán òòrùn ná ̀ à túmọ ̀ sí okun àti agbára àwọn adágún odò náà .
1 Sẹ́rẹ́ 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 12 Sẹ́rẹ́ 2020 Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Prophecy 2020: Adeboye àti Ayọdele sọ nípa ọjọ́ ìwájú 2020 Primate Ayodel kilọ lori ohun to le ṣẹlẹ ninu idibo ipinlẹ Edo ati Ondo.
"Èmi àti Sanyeri nìkan là dá ṣe fíìmù ni Malaysia, àwa ní osere ati a yàwòrán, kò sì nkankan tó wà nínú ṣíṣe sinima jade, tí ń kó mọ.
Kọmisna ọlọpa Adeoye wa sekilọ fun awọn ti o nlo ẹrọ ayelujara lati tan iroyin irọ kaakiri ki wọn jawọ.
yii nibi apero ipade keji ti odun 2019 ti ile-ise ologun ,to waye ni ipinle
''Buhari àti Tinubu ṣ'àdéhùn pé Yorùbá ni yóò jẹ́ olùdíje ipò ààrẹ APC lọ́dún 2023 '' Iléeṣẹ́ epo rọ̀bì ná ₦116m lórí báírò, ìwé ìkọ̀wé, àwọn aṣòfin fìka hánu Iléeṣẹ́ ológun ti yabo ibùdó àwọn jàndùkú tó jí àwọn akẹ́kọ̀ọ́ gbé níléèwé katsina- Garba Shehu O ṣalaye pe niwọn igba ti orun ba n yọ loke ti ilẹ si n su u, majẹmu to sọ oun di ọlọrọ ko le yipada laelae.
Iru eyi ko ti i ṣẹlẹ ri ninu iyansipo Baba'salẹ ni Fasiti kankan ni Naijiria.
Má ta mí nù ní ìgbà ogbó mi;má sì gbàgbé mi nígbà tí n kò bá lágbára mọ́.
Asita ibọn ọlọpaa lo pa Oke ninu ile rẹ ni Mafoluku: Iroyin miran lo ni asita ibọn tawọn ọlọpaa yin lo ba ọkunrin kan lọjọru, lasiko taọn janduku fẹ jo agọ ọlọpaa Makinde to wa ni Mafoluku.
9th Assembly: Olùdíje mẹ́rin ṣàtìlẹyìn fún Gbajabiamila ṣáájú ìbò ilé aṣojú ṣòfin
Gbàrà tí ẹ bá ti gba ìlú náà tán, ẹ ti iná bọ̀ ọ́, kí ẹ sì ṣe bí àṣẹ OLUWA.
Ninu ifọrọwanilẹnuwo ti BBC ni pẹlu agbẹnusọ rẹ Lere Olayinka, Fayose sọ pe ija lo de lorin dowe lo mu ki awọn to n ba oun lorukọ jẹ fẹsun bẹẹ kan oun.
Adewole ni awọn ko ṣẹsẹ fi ikilọ sita fawọn akẹkọ lati ma ṣe gbe ẹrọ ibanisọrọ wọ yara idanwo mọ.
Àkọlé àwòrán, Iṣẹ́ yá, aṣọ ilẹ̀ Yoruba kò ní ká ma ṣiṣẹ́ Àkọlé àwòrán, Ọkan lara àwọn oṣiṣẹ Ipinlẹ Oyo yii ni aṣọ wiwọ ati aṣa bii iya ati ọmọ ni.
Awọn yoku ni igbakeji gomina Ajimobi, Moses Adeyemo, Sẹnetọ Teslim Folarin, Asofin Segun Odebunmi, Adebayo Adelabu atawon agba Alfa loniruuru.
Atẹjade kan ti alakoso feto iroyin fun ijọba ipinlẹ Ọsun, Adelani Baderinwa fisita lo sisọ loju ọrọ yii pẹlu afikun pe Makinde ko ni awọn akọsilẹ to peye lori ọrọ naa.
Nigba ti o di oṣu kẹsan an ọdun naa lẹyin ti ọpọ ti fi idunnu han pe wọn rẹyin odì ni fidio kan ba tun jade ti Shekau ti ni laaye ni oun ṣi wa.
Tí a kò bá gbàgbé, ọ̀pọ̀lọpọ̀ awuyewuye ló tẹ̀lẹ́ ìdúnàádúrà fún Ife Àgbáyé ti ọdún 2018 àti ọdún 2022.
Bí wọn ti ń pa ikán n’ikán ń pa wọ́n.
O gbiyanju lati tun idan naa ṣe nipa bibẹ sinu odo lẹyin ti wọn ti soo pẹlu ẹ̀wọ̀n tan.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ìjẹ̀bú: Àgbàlàgbà ni mo máa ń ṣe nínú eré tẹ́lẹ̀ Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Awọn tó sàbẹ̀wò sibẹ̀ ni ìgbákeji gómìnà ìpińlẹ̀ Eko, Obafemi Hamzat Kọmísọnà ètò ìrìnà ìpińlẹ̀ Eko, Frederic Oladeinde àti kọmísọ́nà ètò ìlera, Akin Abayomi àti àwọn èèkan míràn nípìnlẹ̀ Eko.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Oxford English Dictionary: 'Àwọn ọ̀rọ̀ Nàìjíríà ti wọ́n fi kún un lọ́dun 2020 22 Sẹ́rẹ́ 2020 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Oxford English Dictionary: Ọ̀rọ̀ 28 túntun ti wọ́n fi kún-un lọ́dun 2020 Ní ọdun 2020 ni Oxford English Dictionary ṣe afikún àwón ọ̀rọ̀ tuntun omíràn sínú ìwé náà.
Bakan naa, ni owo sinku iko SARS niluu Ibadan te afurasi
Kò pẹ́ púpọ̀, ó padà dé, ó ní kò sí ẹnìyàn kankan ní ilé títí kan ọmọ- ọ̀dọ̀ wọn.
Ijoba orile ede Naijiria ti setan lati gbalejo ajo to n mojuto irinajo afe ninu ajo isokan agbaye ti UNWTO/CAF nilu Abuja to je olu ilu Naijiria lojo kerin si ojo kefa osu kefa odun 2018.
Kọmisọnna ọlọpaa ni ipinlẹ Eko, Imohimi Edgal to fi eyi lede ninu atẹjade bu ẹnu atẹ lu ọrọ ti Ọga ọlọpaa Abayọmi Shogunlẹ sọ ni Ọjọ Isẹgun pe awọn ọmọ Naijiria lẹtọ labẹ ofin lati ofin lati ni ibalopọ ninu ọkọ ni ojutaye.
  Iko agbofinro Greater Manchester ni awon to ye ko sayewo oku re ko tii rii pe fun idi eyi, awon ko tii ni soro pupo lori arakunrin naa.
Osinbajo kò gbàdúrà ikú fún Buhari lórí àìsàn, ẹ sinmi ìbàjẹ́- Agbẹnusọ Osinbajo Wo bí wọ́n ṣe ṣe ọjọ́ ìbí Anabi ní Abuja ati ní Ghana Àwọn tó jí ọmọ mi gbé nílé ìjọsìn ní ń kò gbọdọ̀ wa tàbí kí ẹ̀mí mi lọ si"" Ẹ dẹ́kun àbùkù tẹ fi ń kan Nàíjíríà, ẹ fi Sowore sílẹ̀ láhàmọ́- Soyinka Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 3 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 5 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!"
N óo dá ire wọn pada, n óo kó wọn pada sí ilẹ̀ Patirosi, níbi tí a bí wọn sí.
“ Laifi Ojo pe Aina,mo mọ pe.
Abẹ́ ìrọ̀rí rẹ̀ ni kọ́kọ́rọ́ ojú ńlá séèfù rẹ̀ máa ń wà.
Ti o ba jẹbi ẹsun ifipabanilopọ ti wọn fi kan an, yoo fi ẹwọn to to aadọrun ọdun jura.
Loju awọn kan, awọn ologun ti n fẹsẹ falẹ lati mu ileri wọn sẹ lasiko yii.
Báwo ni ẹ ṣe mọ ìyàtọ̀ nínú àwọn tó ní ààrùn Coronavirus àti àwọn tí kò ní?
Ni ọkọ ba ti mọ oju aya tan, Ki gbogbo alarina yẹba lo ku.
Nibi ayẹyẹ ami ẹyẹ yii to waye lọjọ aje ni wọn ti fun agbabọọlu ọmọ orilẹede Naijiria ni, Victor Moses ni ami ẹyẹ gẹgẹbii odu agbabọọlu ọkunrin lorilẹede Naijiria ti Asisat Oshoala si gba ami ẹyẹ odu agbabọọlu lobinrin lorilẹede Naijiria.
Aarẹ Buhari ṣalaye fun Cyril Ramaphosa ti ilẹ South Africa pé oun ko ni pé tọwọbọ iwe adehun naa.
"Bó tilẹ̀ jẹ́ pé, Professor Peller ku', idán ò kú o, Prof Peller ni ọmọ kan tó ń jẹ́ Zeeto Peller, agbẹjọrò ni, sùgbọ́n òun náà gbówọ́ nínú idán pípa.
Ẹ̀mí 18 ṣòfò ní Òpópónà Akure sí Ọwọ Háà!
OLUWA ni ó fi ẹnu ara rẹ̀ sọ bẹ́ẹ̀.
1850 ni New York Ademola Adepoju.
O jẹ apapọ ọdun mejila ti alaafin lo gẹgẹ bi Baba'salẹ fasiti naa.
N kò tilẹ̀ rántí bí wọ́n se óúnjẹ nígbà ti ẹ̀gbọ́n mi, ṣùgbọ́n ti emi yìí jẹ́ ǹkan tí n kò le gbàgbé.
Ẹni tí ó bá gbọ́ ọ̀rọ̀ ìjọba ọ̀run, tí nǹkan tí ó gbọ́ kò yé e, tí èṣù wá, tí ó mú ohun tí a gbìn sọ́kàn rẹ̀ lọ: òun ni irúgbìn ti ẹ̀bá ọ̀nà.
Ọmọ onínúure a má a pọ́njú
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, BBC Africa Eye: ìwádìí ìkọ̀ks BBC fihàn pé àwọn kan ń jí ohun èèlò ìdáàbòbò ìjọba tà nígbo Wọn ti lẹ pe e ni iya awọn gbajuẹ ati yahoo-yahoo ni Naijiria.
Tinubu ni iṣẹ awọn ọta leleyii tori wọn n sọ pe oun n pa owo latara Lekki Tollgate ọhun tẹlẹ toun si ti n padanu rẹ lọpọlọpọ nitori iwọde.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Olúwòó ní àwọn Ọba ń se ẹgbẹ́ òkùnkùn Ti ofin yi ba kẹsẹjari,eyikeyi Ọba to ba ku yoo ni anfaani isinku ni ilana ẹsin to ba yan laayo yatọ si aṣa tẹlẹ pe wọn yoo sin nilana iṣẹmbaye.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Àgùnbánirọ̀ gbẹ́mìí mì látàrí 'Snipper' tó fi fọ irun rẹ̀ 9 Agẹmo 2019 Oríṣun àwòrán, Ayomikun Juliana Ayomikun Ademorayo Juliana tó jẹ agunbanirọ to n sin ilẹ̀ baba rẹ nipinlẹ Ọṣun ti doloogbe.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ajax vs Chelsea: VAR ṣ'ègbè lẹ́yìn Chelsea f'ogun ẹ̀yín ja Ajax mọ́lé 23 Ọ̀wàrà 2019 Oríṣun àwòrán, @Chelsea4Pidgin Àkọlé àwòrán, VAR ṣègbè lẹ́yìn Chelsea fogun ẹ̀yín ja Ajax mọ́lé Ifẹsẹwọnsẹ UEFA Champions League laarin ikọ Ajax ati Chelsea to waye lalẹ oni le koko bi oju ẹja, ṣugbọn ikọ Chelsea fẹ Ajax danu nile wọn.
Ninu hílàhílo ni ẹ óo máa wà nígbà gbogbo, ninu ẹ̀rù ati ìpayà ni ẹ óo máa wà tọ̀sán-tòru.
Ẹ̀ ń fẹ́ nǹkankan, ọwọ́ yín kò sì tẹ̀ ẹ́; ẹ bá ń tìtorí rẹ̀ paniyan; ẹ̀ ń jowú nítorí nǹkankan, ọwọ́ yín kò bá ohun tí ẹ̀ ń jowú lé lórí, ẹ bá sọ ọ́ di ọ̀ràn ìjà ati ogun.
1Bílíọnù), Federal Medical Centre Bayelsa bílíọnu kan o dín díẹ (915 miliọnu) Fasiti Nnamdi Azikwe, bílíọnu kan o dín díẹ̀ (907 miliọnu).
Àṣírí ilé tí wọ́n ti ń fipá bá àwọn ọmọdékùnrin lò tú síta Ta ni 'Mad Melon' ọ̀kan lára àwọn akọrin Danfo Driver tó d'olóògbé?
Tọ́ mi lọ sí ibi àpáta tí ó ga jù mí lọ,
'Wọn fipa bami lopọ, wọn si tun huwa ipa si mi, ọrọ igbe aye mi ree.
Ta ló jẹ́ dá oko láì má jẹ ninu èso rẹ̀?
Yoòbá ni ọba ìlù, àwa ni ọba gbogbo orin.
Ní ọjọ́ náà ẹ̀gà tún wá oúnjẹ òòjọ́ lọ, ìgbà tí ó sì dè o béèrè lọ́wọ́ àwọn ọmọ rẹ̀ bí àgbẹ̀ ti wí, wọ́n wí fún un pé àgbẹ̀ ti ránṣẹ́ sí àwọn ìbátan rẹ̀ kí wọ́n wá ya àgbàdo, ẹ̀gà dáhùn, ẹ̀gà ní, ‘Ẹ jókòó, ẹ máa jẹ, ẹ máa mu, kò sí nǹkan kan, nítorí púpọ̀ nínú àwọn ibátan ọmọ ènìyàn kò ṣé é gbẹ́kẹ̀lé, wọ́n kò ni ya àgbàdo.
O gbọ́ ẹ̀bẹ̀ tí mò ń bẹ̀ pé,‘Má ṣe di etí rẹ sí igbe tí mò ń ké fún ìrànlọ́wọ́.
Naijiria(Federal Airport Authority of Nigeria ati ile-ise alaabo lojuna ati fi
    Báyìí ni mo sọ lójú gbogbo àwọn tí o wá sí ibi ìgbéyàwó mi.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Mí ò ya wèrè, mí ò burú, ọ̀nà àtijẹ là ń wá' Mo ti ni ọmọ obinrin kan tẹlẹ."
Ijoba ipinle Edo titun se akotun erongba re, lati polongo ajosepo to muna-doko laarin ijoba ati eka aladani, lojuna ati mu iwuri ba awon oludokowo.
pẹlu awọn ohun to yii ka nilu to mọ lolo yii Oríṣun àwòrán, @Masjid Àkọlé àwòrán, Orule mọṣalaṣi nla ti Medina ni orilẹ-ede Saudi Arabia Oríṣun àwòrán, @Masjid Àkọlé àwòrán, Enu iboji oku Anobi Muhammed (SAW) bi wọn ṣe n ṣọọ titi di asiko yii Oríṣun àwòrán, @masjid Àkọlé àwòrán, Awọn ina alarabara ti wọn fi ṣe ọṣọ si ara awọn òpó to di mọṣalaṣi nla naa mu Oríṣun àwòrán, @mosjid Àkọlé àwòrán, Aworan orule apa kan ninu mọṣalaṣi naa ti awọn ile nlanla to kun fun itan ninu Kuran yii ka.
Mubarak ṣe iṣẹ abẹ ni ipari oṣu kinni ọdun yii ti ọmọ rẹ, Alaa si sọ ni ọjọ abamẹta pe o wa ni ibudo awn to nilo itọju pataki.
Oríṣun àwòrán, Facebook/Haramain Sharifain Àkọlé àwòrán, Aarẹ mọṣalaṣi mejeeji Haram ati Masjid Nabawiy, Sheikh Abdul Rehman Al Sudais lasiko abẹwo si Haram Saaju asiko yii, ọdun marun marun lawọn to n gbe Saudi ma n kopa ninu Hajj ṣugbọn nitori ajakalẹ Covid-19 yii, wọn yoo gba wọn laye lati kopa ninu Hajj tọdun 2020.
Yatọ si Dagrin, awọn orukọ bi i Barack O'Grin, Lyricle Wayray, Akogun, Omo ogun, ni wọn tun mọ ọ si.
Nígbà tí Josẹfu sin òkú baba rẹ̀ tán, ó pada lọ sí ilẹ̀ Ijipti pẹlu àwọn arakunrin rẹ̀, ati gbogbo àwọn tí wọ́n bá a lọ.
"shavkat miromonovich mirziyoyev ( lede rosia Шавкат Мираманович Мирзиёев "" shavkat miramanovich mirziyoyev "" loun lo ) ( ojoibi 1957 ) ni alakoso agba orile-ede uzbekistan ."
------------------------------------------------------------ Igbeyawo ofege laarin Aarẹ Muhammadu Buhari ati Hajiya Sadiya Umar Farouq Oriṣiiriṣi aworan ati akọle to pani lẹrin lo kun ori ayelujara ni eyi ti awọn eniyan fi n ṣeto ipalẹmọ igbeyawo ofege ti wọn ni o yẹ ko waye laarin Aarẹ Muhammadu Buhari ati Hajiya Sadiya Umar Farouq.
 ká má ṣẹ ̀ ṣẹ ̀ wá sọ ti ọsàn wẹ ́ wẹ ́ .
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ikọ̀ ọmọogun Naijiria ti kéde ‘Operation positive identification’!
Egbe  APC ,All Progressives Congress ,lo pe ipe yii
Ọlọrun mi, ṣe wọ́n bí ààjà tíí ṣe ewé,àní, bí afẹ́fẹ́ tíí ṣe fùlùfúlù.
8 Àti pé lõtọ́ ni mo wí fún yin, pé àwọn tí wọ́n jade lọ, ní jíjẹ́ àwọn ìhìn wọ̀nyí fún àwọn olùgbé ilẹ̀ ayé, àwọn ni a fi agbára fún lati fi èdídí dì lórí ilẹ̀ ayé àti ní ọ̀run, awọn aláìgbàgbọ́ àti awọn ọlọ̀tẹ̀;
Ibi isadi ni ileewe jẹ fawọn akẹkọọ nilẹ Afirika, alakoso ẹlẹkunjẹkun ajọ WHO, Matshidiso Moeti lo sọ bẹẹ.
Taani ewu Covid-19 le wu julọ?
 Ajọ INEC ma n le iwe yii ki awọn eniyan le lọ yẹ orukọ wọn wo
lati se abbl, ti ase yi ko si yoo awon oludari ile-ise ijoba kankan sile, eleyi
Dafidi bá lọ jókòó níwájú OLUWA, ó gbadura báyìí pé, “Kí ni èmi ati ilé mi jẹ́, tí o fi gbé mi dé ipò tí mo dé yìí?
Ẹ kò gbọdọ̀ fi akọ tí ó jẹ́ àkọ́bí ninu agbo mààlúù yín ṣiṣẹ́, bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò sì gbọdọ̀ rẹ́ irun àgbò tí ó jẹ́ àkọ́bí aguntan yín.
Tinubu kò ṣékú, kò ṣé ẹyẹ, o n dibọn ní lórí ọ̀rọ̀ ikọ̀ Amotekun - Fani Kayode Mọ̀ síi nípa ǹkan tí o lè ṣe láti dènà ibà Lassa Wo àwọn àdúgbò tí ìpínlẹ̀ Eko ti fòfin de ọ̀kadà àti Marwa Oxford English Dictionary: Ọ̀rọ̀ 28 túntun ti wọ́n fi kún-un lọ́dun 2020 Èyí tí a wò jùlọ 5:03 Fídíò, Omolola Arohunmolase Welder: Mo ti fí iṣẹ́ 'Welder' gbayì láwùjọ, tó mo fi tọ́ ọmọ yanjú, Duration 5,039 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 5:39 Fídíò, Akomolede ati Asa lori BBC: Olùkọ́ Kikelomo Ogunboye tan ìmọ́lẹ̀ sí ìwà olè ọ̀gá ọlọ́pàá Audu gẹ́gẹ́ bí àwòkọ́ṣe àsìkò yìí, Duration 5,398 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 4:11 Fídíò, Oba Adeyeye Ogunwusi: Ojú mi ti rí lọ́pọ̀ lọpọ̀, ọ̀pọ̀ èèyàn ni kò tilẹ̀ gbàgbọ́ pé mo lè jọba- Ooni, Duration 4,117 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 4:43 Fídíò, Promise Akinlade: ọmọ ọdún mọ́kànlá tó ń fi ìlù dárà bíi àgbàlagbà sọ̀rọ̀ nípa tálẹ́ǹtì rẹ̀, Duration 4,437 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 0:59 Gbọ́, Ìsẹ̀lẹ̀ jákèjádò orílẹ̀èdè àgbáyé láàárín ìṣẹ́jú kan, Duration 0,59wákàtí 5 sẹ́yìn 7:03 Fídíò, Olumuyiwa Bolade Adedeji Military Bruitality: Bí arákùnrin onípèníjà ara tí sọ́jà lù ṣe dé, Duration 7,035 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 4:45 Fídíò, Yoruba Films: Ẹ̀ẹ́ bẹ̀ mi kúrò láyé ni, mi ò lè kú - Fadeyi Oloro, Duration 4,4526 Èrèlè 2020 2:48 Fídíò, Esther Ajayi: Èmi náà ti borí ìṣòro rí ló ń mu mi ṣojú àánú, Duration 2,481 Ògún 2019 6:08 Fídíò, Adebola Ademilua: Àìrísẹ́ ṣè lẹ́yìn ìwé kíkà ló sọ mi dí ìyá onírú, mo dúpẹ́ tèmi, Duration 6,0827 Bélú 2020 2:36 Fídíò, Sotitobire: Ìdájọ́ òdòdò ló fẹsẹ̀ múlẹ̀ lórí ọ̀rọ̀ Pásítọ̀ Sotitobire - Agbẹjọ́rò fún ìjọba, Duration 2,367 Ọ̀wàrà 2020 BBC News, Yorùbá Ìdí tí ẹ fi le è nígbàagbọ́ nínú ìròyìn BBC Ìlànà Lílò Nípa BBC Òfin Àṣírí Cookies Kàn sí.
Ní ọjọ́ kinni Àjọ̀dún Àìwúkàrà, ní ọjọ́ tí wọn máa ń pa aguntan láti ṣe Àjọ̀dún Ìrékọjá, àwọn ọmọ-ẹ̀yìn Jesu bi í pé, “Níbo ni o fẹ́ kí á tọ́jú fún ọ láti jẹ àsè Ìrékọjá?
Oríṣun àwòrán, other Àkọlé àwòrán, Igbakẹta re e ti ọrọ aje Naijiria dẹnukọlẹ labẹ iṣakoso Aarẹ Muhammadu Buhari Ijọba yoo ma a ya owo si - Nitori iṣoro aisi iṣẹ, ijọba yoo nilo lati na owo ju ti tẹlẹ lọ.
Ìbejì Oníbẹ̀mbẹ́ Òru tí kò yara wọn lẹ́yìn ọgọ́ta ọdún Aláàfin yẹ́ Lizzy Anjọrin sí níbi ayẹyẹ ìwúyè rẹ̀ Obìnrin tó lágbára láti yan ìyàwó míì fún ọkọ Ọkùnrin tó pa ìyàwó rẹ̀ tí gba ìdájọ́ ikú BBC Yoruba ṣe iṣẹ iwadii iroyin yii de gongo ti a fi ba ọpọlọpọ ero to nii ṣe pẹlu iṣẹlẹ yii sọrọ.
Oríṣun àwòrán, Fredie Blom Blom maa n mu siga daadaa nigba aye rẹ, ṣugbọn o fi ọti silẹ lọpọ ọdun ko to jade laye.
Ǹjẹ́ àwa tí a ṣẹ́kù yìí tún gbọdọ̀ máa rú òfin rẹ, kí á máa fẹ́ aya láàrin àwọn orílẹ̀-èdè tí wọn ń ṣe ohun ìríra?
Oríṣun àwòrán, Facebook/Ademola Adeleke Laipe yii ni sẹnetọ Adeleke kuna ni ile ẹjọ to gaju, lẹyin ti ile ẹjọ ni Oyetola lo jawe olubori ninu idibo si ipo gomina to waye ni ọdun 2018 ni ipinlẹ Osun.
 ní odún 1948 ó gba ebun nobel nínú lítíréṣọ ̀ .
Igbakeji aare ni,ayika orile ede Naijiria fi ye wa pe ojo iwaju orile ede yii dara, ti a ba lee samulo igba ati akoko naa daradara.
2/95 ti wọn buwọlu lọjọ Keje osu Kẹjọ ọdun 2000.
Oríṣun àwòrán, @Chibuzo76881211 Eyi ko si sẹyin orin lilọ laa lọ, bilẹ yii ko ba wọ mọ, a lọ ilọ miran tuntun, ti ọpọ ẹya to wa ni Naijiria n kọ lẹnu.
Bí o bá fẹ́ gbọ́n, bẹ̀rẹ̀ sí kọ́gbọ́n,ohun yòówù tí o lè tún ní,ọgbọ́n ló jù, nítorí náà jẹ́ ọlọ́gbọ́n.
Nǹkan ti ẹ̀mí ni, kì í ṣe ti inú ìwé.
Ijọba Osun wa gbadura pe ki Ọba oke tẹ oloogbe naa si afẹfẹ rere.
Imọran yii ni aya aarẹ fi n se atilẹyin fun awọn ọdọ kan ninu ẹgbẹ oselu APC, ti wọn n fi apa janu pe awọn alatako ti ko gbagbọ ninu awọn afojusun ijọba Muhammadu Buhari, ni awọn ọmọ ẹgbẹ oselu APC n yan sipo .
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 300 mílíọ̀nù náírà ní mò fí gbé àwọn ọmọ Nàìjíríà wálé-Allen Onyeama Nibo ni awọn ajoji ilẹ South Africa ti wa?
tí ó bá wí fún mi pé, “Omi nìyí, mu, n óo sì pọn fún àwọn ràkúnmí rẹ pẹlu”, nígbà náà ni n óo mọ̀ pé òun ni obinrin náà tí ìwọ OLUWA ti yàn láti jẹ́ aya ọmọ oluwa mi.
Ọmọ Atiku Mohammed ti wọ́n fi si ipamọ ni ilé ikwosan ikọni to wà ni Gwagwalad nilú Abuja nítori pé àyẹwo fi han pé o ni ààrun Coronavirus lọ́jọ́ Aiku.
 Sugbon omo odun mẹ́tàlélọ́gọ́ta ohun ti ni aheso oro lasan lasan ni gbogbo oro naa, pe kosi ooto kan ninu re rara.
I Language Centre: Yorùbá ló làṣà àti èdè Gẹ́gẹ́ bí àjọ NCDC ṣe sọ ènìyàn méjílédinlọ́gọ́ta ló ṣẹ̀ṣẹ̀ jẹyọ nípínlẹ̀ Eko, mẹ́rìndíláàdọ́ta ni Kano, márùnlélọ́gbọ̀n ni Jigawa àti méjìlá ni Yobe.
Bi o ba ni iba, ikọ ati iṣoro lati mi, tete tọ awọn oniṣegun oyinbo lọ fun ayẹwo ati itọju.
sibẹ, ọ̀kan ṣoṣo ni àdàbà mi, olùfẹ́ mi tí ó péye.
Irú kí ni yóo sì máa ṣe?
Mọremi ni ifẹ ilu rẹ lọkan, to si maa n wa igbega ati alaafia rẹ, bakan naa lo y ki awa pẹlu nifẹ iran Yoruba ati orilẹede wa Naijiria lapapọ.
Gbogbo ènìyàn tí ọ̀rọ̀ yìí bà ké gbànjarè.
Bí ìka ẹsẹ̀ rẹ̀ sì ti jẹ́ àdàlú amọ̀ ati irin, bẹ́ẹ̀ ni apá kan ìjọba náà yóo lágbára, apá kan kò sì ní lágbára.
Tí kò bá ní ohun tí yóo fi tán ọ̀ràn náà, wọn yóo ta òun fúnra rẹ̀ láti san ohun tí ó jí.
Ọ̀tá gbogbo nǹkan tí ó dára!
”owό  sisẹ ati agbe lo je isẹ ti awọn onisowo okunrin ati obinrin n se.
Saulu bèèrè pé, “Ta ni ọ́, Oluwa?
Gomina  Ortom kede ekunwo yii lasiko ipade apero ti
Kò lè kún ọwọ́ ẹni tí ń pa koríko;kò sì lè kún ọwọ́ ẹni tí ń di koríko ní ìtí.
Lẹyin ti awọn ọlọpaa doju ija kọ awọn afurasi ọmọ ẹlẹgbẹ okunkun naa tan, ni ọwọ ba tẹ wọn.
kí alufaa yẹ̀ ẹ́ wò, bí ó bá jìn wọnú ju awọ ara lọ, tí irun ọ̀gangan ibẹ̀ bá pọ́n, tí ó sì fẹ́lẹ́, kí alufaa pè é ní aláìmọ́; àrùn ẹ̀yi ni, tíí ṣe àrùn ẹ̀tẹ̀ irun orí tabi ti irùngbọ̀n.
Ẹwẹ, Kọmisọna fun ọrọ ayika nipinlẹ Ọyọ, Oloye Isaac Ishọla ni ko ni nkankan ṣe pẹlu Yinka Ayefẹlẹ, bi ko ṣe ofin ijọba to sọpe ẹni to ba fẹ ẹ k'ọle gbọdọ fi alafo amita marunlelogoji silẹ si oju popo.
Lasiko ti a kan si Toyosi lori aago ilewọ rẹ fun ifọrọwerọ, obinrin ti ori ko yọ ninu ikọlu naa, ti ko lee sọrọ daada, fi to wa leti pe ojora si n mu oun lọwọ nipa isẹlẹ laabi naa, to si han ninu ohun rẹ pẹlu.
“Ẹ fi ààrin ìlú sílẹ̀, kí ẹ lọ máa gbé inú àpáta, ẹ̀yin ará Moabu!
Kí wọ́n fọ́ kòkò tí ẹni tí nǹkan dà lára rẹ̀ yìí bá fi ọwọ́ kàn.
”Wọ́n dá a lóhùn pé, “Bẹ́ẹ̀ ni, kabiyesi.
Iye awọn to ku ju ti ọdun 2017, ṣugbọn ko to ti awọn ọdun ti tẹlẹ nigba ti ogun Iraq ati Syria n gbona janjan.
Dúkìá àti ọkọ̀ jóná, ọlọ́pàá mẹ́sàn-án fara gbọta lásìkò ìwọ́de Shiite Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
"Ojuṣe igbimọ ti alaga ajọ yii fi arabinrin Amina Zakari ṣe olori fun ni lati rii pe gbọngan ti wọn yoo lo fun ibo kika wa ni sẹpẹ, gbogbo eto ati ohun elo ti wọn yoo lo nibẹ pẹlu bii eto abo, ohun elo ayelujara ati bẹẹ bẹẹ wa ni sẹpẹ lai si idiwọ.
O ni oun fun ra oun lo sọ fun Kenyamo pe ko gbeṣẹ f'oun, iṣẹ ọhun naa l'oun si ṣe fun un.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Njẹ́ ẹ mọ̀ oé àlákálàá lè jẹ́ àfihàn aàrun ọpọlọ?
Jọọ tun ikọ agbabọọlu rẹ tò Yan ikọ agbabọọlu ara rẹ Ṣe alabapin ikọ AFCON XI rẹ pẹlu awọn ọrẹ rẹ Whatsapp Facebook Twitter Ọlawale Malọmọ lo ṣagbekalẹ rẹ, Ọlaniyi Adebimpe lo yàá Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: NFF ti san owó àjẹ́mọ́nú Super Eagles Akọni ṣubú l'ójú ìjà, Madagascar fi 2-0 la Super Eagles mọ́lẹ̀ Sọ àsọtẹ́lẹ̀ orílẹ̀èdè tí yóò borí ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ t'òní Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Afcon 2019: Àwọn olólùfẹ́ Super Eagles fẹ́ kí Rohr tún wọn tò Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Iraq, Palestine wà nínú orílẹ̀-èdè mẹ́wàá tí ìwádìí BBC ti wáyé Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Oríṣun àwòrán, BIGBROTHER NAIJA/AFRICA MAGIC Ṣugbọn Ikede yi to jẹ eyi to maa n waye lọsọọsẹ lẹyin tawọn olukopa ninu ere ile ẹlẹgbọn ba dibo tan kọ lawọn eeyan n ran lẹnu loju opo Twitter.
Àbéòkúta ni Pópóọlá wà tẹ̀lẹ̀ kí wọ́n tí wá gbé e wá sí Morèmi ní Ifẹ̀ níbi tí ó ti jẹ́ ọ̀gá àwọn ọlọ́pàá ibẹ̀.
Ó ní, “Lọ kó gbogbo àwọn àgbààgbà Israẹli jọ, kí o sì sọ fún wọn pé, èmi OLUWA, Ọlọrun àwọn baba yín, Ọlọrun Abrahamu, Ọlọrun Isaaki ati Ọlọrun Jakọbu, ni ó farahàn ọ́, ati pé, mo ti ń ṣàkíyèsí wọn, mo ti rí ohun tí àwọn ará Ijipti ti ṣe sí wọn.
 Àwọn eṣinṣin yíì ń gbé lẹ ̀ bá àwọn odò èyí tí ó ṣòkunfà orúkọ àrùn náà .
A gbọ pe lati ibẹrẹ ọdun yii, awọn ọmọ Naijiria ti o gba iwe irinna lọ si Amerika laipẹ yii lo pọ ju ninu awọn ti o n sa wọ Canada.
Mikel fi fọto ara rẹ soju opo Instagram, o sọ pe orilẹede Egypt loun ti bẹrẹ si soju Naijiria, nibẹ naa si ni oun pari rẹ si.
Angẹli mìíràn jáde láti inú Tẹmpili wá, ó kígbe sí ẹni tí ó jókòó lórí ìkùukùu, pé, “Iṣẹ́ bẹ̀rẹ̀ fún dòjé rẹ; àkókò ìkórè tó: ilé ayé ti tó kórè.
Kí ni ẹ jáde lọ wò?
Ṣugbọn ohun ti agbẹnusọ ile iwe naa sọ ni pe oun gbọ pe igbimọ alaṣẹ ni ki ọga agba ileewe naa yẹba fun ọfiisi amọ oun ko ri iwe apilẹkọ to fidi rẹ mulẹ.
Ọlọrun rán angẹli kan pé kí ó lọ pa Jerusalẹmu run; ṣugbọn bí ó ti fẹ́ pa á run, OLUWA rí i, ó sì yí ọkàn pada, ó wí fún apanirun náà pé, “Ó tó gẹ́ẹ́, dáwọ́ dúró.
Kíni ìtumọ̀ oyè Balógun káàfàtà tí wọ́n fí Asamoah Gyan jẹ?
Nǹkan tí mo lè ṣe ni eléyìí, n kò ní í pe Ikú kí ó wáá bá mi jẹ àsè nítorí rẹ mọ́, nígbà tí a bá sì dé ilé ẹbọra náà lọ́la, a ko ní í wọlé, dípò èyínì a óò dúró sí òde a óò wí pé a ń lọ sí ibi kan ni á wí pé kí á yà gẹ́gẹ́ bí ìlérí tí a ṣe fún un.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, ‘Ara fu mí nígbàtí bàbá gbé Bíbélì ìdílé fúnmi’ Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Iya ibẹrin ọhun, Suliyat Adulkareem, bi ọkunrin meji ati obinrin meji lọjọ ikunlẹ kan ṣoṣo nile iwosan Latifa ni Dubai lọjọ kinni, oṣu Keje, ọdun 2020.
O ti ṣiṣẹ ni ileeṣẹ redio bii Hughes Radio One, Virgin Island and Mix 106.
Ida-omi yii ti wọn n pe orukọ ni Haew Narok ni wọn sọ pe iru iṣẹlẹ bayii ti wọpọ ni bẹ.
Afojusun ni lati ri i daju pe wọn tete ri ibà ti agbara egboogi ko ba ka, ki wọn si kọju ija si ni kiakia ati l'ọna to yẹ.
Sì dá ẹ̀wù mímọ́ kan fún Aaroni, arakunrin rẹ, kí ó lè fún un ní iyì ati ọlá.
Awọn igbesẹ ti a ti gbe n ṣiṣẹ daradara, ti awọn miran si n wo awokọṣe wa.
Mo n fi okan awon omo orile ede Naijiria bale pe , a o ni sinmi titi ti a o  fi mu awon odaran naa, ti won yoo si jiya labe ofin.
Nigba ti yoo fi di ibẹrẹ oṣu Kẹwaa, ikọ ipolongo Biden ti ni to miliọnu mẹrinlelogoje dọla, $144m, ju ti Trump lọ.
Ni ibẹrẹ osẹ yii ni ajọ oluranlọwọ naa fi atẹjade kan sita pe awọn eeyan kan kọlu awọn oṣiṣẹ wọn to n rinrin ajo lọ si ilu Damasak, nipinlẹ Borno.
Nítorí kì í ṣe pé a kọjá àyè wa nígbà tí a dé ọ̀dọ̀ yín, àwa ni a sì kọ́kọ́ mú ìyìn rere Kristi dé ọ̀dọ̀ yín.
Ní ọdọọdún ni ìyá rẹ̀ máa ń dá ẹ̀wù kékeré, a sì mú un lọ́wọ́ lọ fún un, nígbà tí ó bá bá ọkọ rẹ̀ lọ, láti lọ rúbọ.
Iroyin tilẹ sọ laipẹ yii pe, wọn kọ lati kuro ni ile itura lẹyin ti wọn ja kuro ni idije ife agbaye awọn obinrin to n lọ lọwọ ni France, nitori ọrọ yii kan naa.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Mohammed Yusuf: Àwọn ohùn tó yẹ kí o mọ nípa olùdásílẹ̀ Boko Haram 30 Agẹmo 2019 Àkọlé àwòrán, Mohammed Yusuf: Àwọn ohùn tó yẹ kí o mọ nípa olùdásílẹ̀ Boko Haram Bi onirese ba ni oun ko fingba mọ eyi to ti fin silẹ ko ni parun laelae lọrọ Mohammed Yusuf to jẹ oludisilẹ ẹgbẹ agbesunmọmi Boko Haram.
Ó pé ọdún mọ́kànlélọ́gbọ̀n tí Samuel Okwaraji ṣubú lójú ìjà Pique ni kii ṣe igba akọkọ, tabi ekeji tabi ẹkẹta ti irufẹ abuku yii yoo kan Barcelona.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Lassa Fever: Ọ̀nà márùn ún láti dènà ìbà ọ̀rẹ̀rẹ̀ 4 Èrèlè 2019 Àkọlé àwòrán, Dokita mẹjọ lo ti ba arun lassa lọ ni Naijiria Ẹgbẹ awọn ọmọ lẹyin Kristi, CAN ti kede pe ọgọrun un eniyan lo ti lugbadi aisan iba ọrẹrẹ ti gbogbo eniyan mọ si Lassa Fever ni ipinlẹ Ondo.
Bí a bá sì wí pé, ‘Láti ọ̀dọ̀ eniyan ni,’ a bẹ̀rù àwọn eniyan, nítorí gbogbo eniyan gbà pé wolii tòótọ́ ni Johanu.
Ijọba sọ pe awọn meji akọkọ ti n gbadun nileewosan.
Wọn a máa lọ sọ́dọ̀ àwọn oriṣa, wọ́n a máa bọ wọ́n, wọn a sì máa foríbalẹ̀ fún wọn.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ooni Crown Prince: Èyí ni bí wọ́n ṣe bí Àrẹ̀mọ tuntun Ọọ̀ni Adeyeye ti Ile Ife àti orúkọ tí ó kọ́kọ́ jẹ́ 16 Ògún 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 19 Bélú 2020 Oríṣun àwòrán, Olori Moronke Shilekunola Ogunwusi Iroyin tuntun nipa Arẹmọ kabiyesi Ọọni ile ifẹ to n jade fihan pe ni ileewosan nla ti ijọba apapọ, FMC to wa ni ilu Ọwọ ni wọn bi i si.
Kìí ṣe gbogbo ohun tí dókìtà ni kí n má jẹ torí àìsàn jẹjẹrẹ ni mo tẹ̀lé- Soyinka Ẹ̀ka olókoòwò kékèké ló ń fara gbá ìṣòro kónílé-ó-gbélé, ìjọba gbọ́dọ̀ ṣètò fún wọn Titi di bi mo ṣe n sọrọ yii emi funra mi o mọ ọ gidi, ẹni ti Wole Soyinka jẹ"" lèsì Ọjọgbọn fun BBC Yoruba nigba ti a ni ki o juwe ara rẹ."
Jeremaya bá sọ fún àwọn ìjòyè ati gbogbo àwọn eniyan pé, “OLUWA ni ó rán mi láti sọ àsọtẹ́lẹ̀ tí ẹ gbọ́ sí ilé yìí ati ìlú yìí.
N óo ṣe bẹ́ẹ̀, kí ẹ̀yin ọmọ Israẹli má baà ṣáko kúrò lọ́dọ̀ mi mọ́, tabi kí ẹ máa fi ẹ̀ṣẹ̀ sọ ara yín di aláìmọ́.
Èyí ni láti fi ọ̀nà tí Ọlọrun yóo fi dá eniyan láre hàn, nítorí pé ó fi ojú fo àwọn ẹ̀ṣẹ̀ àtijọ́ dá, nípa ìyọ́nú rẹ̀, kí ó lè fi òdodo rẹ̀ hàn ní àkókò yìí, kí ó lè hàn pé olódodo ni òun, ati pé òun ń dá ẹni tí ó bá gba Jesu gbọ́ láre.
19 Ìgbé 2019 Oríṣun àwòrán, Yogesh Kumar Singh Àkọlé àwòrán, Ogbẹni Kumar ni ọtọ ni ẹgbẹ ti oun dibo yan Ika to ba ṣe lọba n ge.
Tabi bí ó ṣe ń sán ààrá láti inú àgọ́ rẹ̀?
 O ni  “A maa gbe oro yii lo soke gege bi o se ye pelu awon igbimo amusese, eyi lo mu iyato die de ba leta Aare.
ibi ti ko ni si ewu.
 Àti ẹ ̀ ni tí a bá tan , àti ẹni tí a kò tan mọ ́ , gbogbo wa náà la parapọ ̀ di àwùjọ-ẹ ̀ dá .
Nígbà tí àkókò tó fún OLUWA láti fi ààjà gbé Elija lọ sí ọ̀run, Elija ati Eliṣa kúrò ní Giligali.
Sibẹ bí a bá rí àwọn tí wọ́n yè ninu wọn lọkunrin ati lobinrin, tí wọ́n bá wá sọ́dọ̀ rẹ, tí o rí ìwà ati ìṣe wọn, o óo gbà pé mo jàre ní ti ibi tí mo jẹ́ kí ó ṣẹlẹ̀ sí Jerusalẹmu.
"Mo mọọmọ fẹ dupẹ pupọ lọwọ aarẹ orilẹ-ede Togo, Faure Gnassingbe, fun isẹ takun-takun to gbe se lasiko to n ko ajọ Ecowas sodi.
Bakan naa, won yoo lo koju iko agbaboolu Spain lojo karun un si ifesewonse akoko nilu Kazan, ki won O to teko leti lo gba ifesewonse ti o keyin nipele keji(Group B) pelu iko agbaboolu Portugal lojo karundinlogbon osu kefa odun ti a wayii.
N óo sọ wọ́n di orílẹ̀-èdè kan ní orí òkè Israẹli, ọba kanṣoṣo ni yóo sì jẹ lé gbogbo wọn lórí.
Lara ẹsun ti wọn fi kan ọgbẹni Adekolawole ni pe o fi iṣẹ rẹ silẹ lai ṣe fun odidi oṣu kan.
Ẹ wá wo ibi tí wọ́n tẹ́ ẹ sí.
 ""Mo wo iwe akọsilẹ nipa ara rẹ to mu wa, mo si ri pe ile ẹkọ St Michael ni Yemetu lo lọ lasiko ti mo jẹ olukọ nibẹ, ti mo si tete da mọ kiakia pe ara akẹkọọ ti mo ti kọ nile iwe ri ni."
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Buhari: Ìkọlù Fulani àti ẹlẹ́gbẹ́ òkùnkùn ní Kaduna àti Rivers burú jáì 9 Ìgbé 2019 Oríṣun àwòrán, Presidency Aarẹ Muhammadu Buhari ti bu ẹnu ẹtẹ lu ikọlu laarin awọn Fulani ati awọn eeyan lawujọ Adara ni ipinlẹ Kaduna.
Ilé-iṣẹ́ ti sọ ayẹyẹ àjọyọ̀ àjọ̀dún Òyìnbó di èèwọ̀.
Nítorí náà ìyàn ni kí ó pa àwọn ọmọ wọn,kí ogun pa wọ́n,kí àwọn aya wọn di aláìlọ́mọ ati opó,kí àjàkálẹ̀ àrùn pa àwọn ọmọkunrin wọn,kí idà ọ̀tá sì pa àwọn ọ̀dọ̀ wọn lójú ogun.
ẹni tí ó di alufaa nípa agbára ìyà tí kò lópin, tí kì í ṣe nípa ìlànà àṣẹ tí a ti ọwọ́ eniyan ṣe ètò.
Ó ní àwọn gómìnà àti àwọn ọba aláde ilẹ̀ Yorùbá ti sùn àsùn píye ti gbogbo àwọn oríṣirisi ṣì n wọle tọ wọ́n wá.
" O ni oun naa ti se aṣiṣe, ṣugbọn oun ati ololufẹ oun ma n bẹ ara awọn.
Fidio naa si ti mu ki ọpọlọpọ fara ya lori ayelujara.
Bákan náà, wọ́n kó àwọn àwo ìfọnná, ati àwọn àwo kòtò, gbogbo ohun tí ó jẹ́ ti wúrà ati fadaka, ni olórí àwọn tí wọn ń ṣọ́ ọba Babiloni kó lọ.
Ó ranṣẹ pe Banaba ati Saulu nítorí ó fẹ́ gbọ́ ọ̀rọ̀ Ọlọrun.
Oyeyemi ni Babatunde wa ni ahamọ ẹka ileeṣẹ ọlọpaa to n ṣe iwadi ẹsun ipaniyan to wa ni Eleweran, Abeokuta.
Kí ní kan péré ló wá kù tí mo fẹ kí o ṣe fún mi.
Mo kìlọ̀ fun yín, ẹ̀yin obinrin Jerusalẹmu,pé ẹ kò gbọdọ̀ jí olùfẹ́ mi,títí tí yóo fi wù ú láti jí.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ọlọ́pàá kan rèé tí kìí gba àbẹ̀tẹ́lẹ̀ Agbẹjọ́rò àgbà lọ sẹ́wọ̀n nílùú Èkó A ò gba ìbálòpọ̀ akọ ṣákọ tàbí abo sábo Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí 2 sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
Iranṣẹ Ọlọrun naa ni gbogbo eyi lo n mu ki ẹrin o maa pa eniyan lori igbesẹ awọn ijsba gbogbo.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìtàn Mánigbàgbé: Ẹfunsetan Aniwura lọ́lá, ó lówó, ó sì tún gbajúmọ̀ 11 Ọ̀pẹ̀̀ 2018 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 13 Ọ̀wàrà 2020 Oríṣun àwòrán, @ibadaninsider Eledua fi awọn obinrin takuntakun jinki ilẹ adulawọ, ti ọpọ wọn ko si se fi ọwọ rọ sẹyin rara.
Oyinlola ni baba Obasanjo ni oun n wo niwaju, ti oun si mu bii baba ninu oṣelu ni Naijiria.
ACCORD, ANRP Kwara: Ẹ kòlè tìtorí APC, PDP fagilé ìwóde
Minimum Wage: Buhari gbọdọ̀ fi àbá owó osù tuntun sọwọ́ sáwọn asòfin
OLUWA ní òun óo jẹ́ kí ibi bá ọ, òun óo pa ọ́ rẹ́, òun ó sì run gbogbo ọkunrin tí ń bẹ ninu ìdílé rẹ, ati ẹrú ati ọmọ.
Oríṣun àwòrán, Twitter Iru ipa wo ni iroyin yii ni?
Wọn ni 'awọn mẹta ni yanrin naa bo mọlẹ, awọn mẹta miran n ko yanrin ọhun si inu ọkọ akẹru lasiko ti ijamba yii ṣẹlẹ."
Nígbà tí wọn kò rí ọ̀nà gbé e dé ọ̀dọ̀ rẹ̀ nítorí ọ̀pọ̀ eniyan, wọ́n gbé e gun orí òrùlé.
Ki a maa hu iwa ti ko dara, nitori pe o je obinrin.
Fellaini to darapọ mọ ẹgbẹ agbabọọlu Shandong Luneng ninu oṣu kinni lati Manchester United pada si China lọjọ Ẹti to kọja lọ ko to di pe ayẹwo fihan pe o ti lugbadi arun covid-19.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Wọ́n fi ikú Tunde Braimoh dá wa lóró ni o - Ẹbí pariwo Ìdùnnú ṣubú layọ̀!
Ababọ ipade Aarẹ Buhari ati Aarẹ Trump Rira ọkọ okurufu mejila: Awọn adari mejeeji fi ipinnu wọn han lati gbogun ti iwa ipa lagbaye.
Àwọn dókítà ya ìbejì tó lẹ̀pọ̀ l'Abuja 'À kò lè san ju #22,500 fún owó osù òsìsẹ́' Ẹgbẹ Afẹnifẹre naa wa fikun wi pe awọn ko i ti i sọ ẹni ti awọn yoo basẹ ninu idibo gbogboogbo ti yoo waye ni ọdun 2019, ati wi pe ahesọ ni iroyin pe ẹgbẹ oselu APC ni awọn fẹ dibo fun ni idibo gbogboogbo ti ọdun to n bọ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Obateru Akinruntan: Olugbo Obateru akinruntan ṣalaye ìdí ohun tó ń ṣẹlẹ̀ láàrín òhun àti Ooni Ile Ife 30 Bélú 2020 Oríṣun àwòrán, Twitter/Obatakinruntan Olugbo ti ilu Ugbo, Ọba Frederick Ọbatẹru Akinruntan ti ṣalaye ohun to n ṣẹlẹ laarin oun ati Ọọni ile ifẹ.
Idi ti a fi fi ọrọ naa kọ ẹgbẹ lọrun ni lati rii pe gbogbo eeyan lo lọwọ si yiyan awọn ti yoo jẹ kọmiṣọna.
A óo sì dárí ẹ̀ṣẹ̀ yín jì yín, ẹ óo wá gba ẹ̀bùn Ẹ̀mí Mímọ́.
Awon ti yan si ile-ejo giga ti ijoba apapo ni won yoo bura fun ni osu kefa , ojo kárùndínlọ́gbọ̀n,ojo Aje, won yoo bura fun awon adajo ni ojo kẹ́rìndínlọ́gbọ̀n,ojo Isegun, odun 2018.
Jesu wá sọ́dọ̀ wọn, ó fọwọ́ kàn wọ́n, ó ní, “Ẹ dìde.
Tí ẹ bá ń kí àwọn arakunrin yín nìkan, kí ni ẹ ṣe ju àwọn ẹlòmíràn lọ?
Nígbà tí wọ́n wádìí ọ̀rọ̀ náà, tí wọ́n sì rí i pé òtítọ́ ni, wọ́n so àwọn ọlọ̀tẹ̀ mejeeji náà kọ́ sórí igi.
Mi ò tí ì mọ obìnrin rí; kódà, mí ò ní 'Girlfriend'- Mr Macaroni Funke Akindele fún mi lówó tí mo fi gba ilé, kò ra ilé fún mi o - Ajirebi Ọ̀rọ̀ ìtàjẹ̀sílẹ̀ ní Nàìjíríà yìí tí ń kọ àwa Oṣo àti Àjẹ́ lóminú, a fẹ́ wa ǹkan ṣe síi Ìpànìyàn tún wáyé ní Akinyele, àwọn ará àdúgbò ṣe ìwọ́de Mọ̀ síi nípa Shina Rambo tó pàdé Jesu lọ́gbà ẹ̀wọn lẹ́yìn tó ti jalè Ìjàmbá ṣe wá ní Barcelona, aṣọ ò bá Ọmọ́ye wa mọ́- Gerard Pique Ọjọ kẹtala oṣu kẹjọ ọdun 2020 yii naa ni Ire pe ọmọ ọdun kan loke eepẹ, eyi ti awọn obi rẹ fi n dupẹ lọwọ Eleduwa ti O da ọmọ naa si i.
Ó hùwà tí ó burú gidigidi níwájú OLUWA, ó sì rú ibinu OLUWA sókè.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Wo itan omi gbigbona ati tutu ni Ikọgosi Ekiti Ọgagun Buratai to n dari gbogbo ọmọ ogun Naijiria ni lilo awọn irinṣe igbalode bi eyi yoo tete jẹ ki iṣẹ naa rọrun lati ṣe.
Ṣugbọn Hana kò bá wọn lọ.
Ọkùnrin ni ẹbi ọkọ na a ti bẹ̀rẹ̀ si kọ àṣà ṣì ṣúpó silẹ̀ pàtàki àwọn ti ó bá kàwé, nitori ó ti lè ni iyàwó tàbi ki ó ni àfẹ́sọ́nà.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ìjà bẹ́sílẹ̀ nílé ẹgbẹ́ PDP APC pàdánù aṣòfin míràn ní'pínlẹ̀ Osun Ìdí tí wọ́n fi dá mi padà láti Ilẹ̀ Gẹ̀ẹ́sì - Bobrisky Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Adebisi Idikan: Òun ló gba Ìbàdàn sílẹ̀ lọ́wọ́ ìyà owó orí sísan O ni iyalẹnu lo jẹ bi gbese ipinlẹ naa ṣe gbera lati biliọnu mejidinlogun lasiko ti oun fi ipo silẹ di biliọnu mẹtadinlọgọfa labẹ iṣejọba Fayose, gẹgẹ bii ileeṣẹ to n mojuto ọrọ gbese lorilẹede Naijiria, DMO ṣe sọ.
“Nisinsinyii, ó tó àkókò fún mi láti kú, gbogbo yín ni ẹ sì mọ̀ dájúdájú ninu ọkàn yín pé, ninu gbogbo àwọn ohun rere tí OLUWA Ọlọrun yín ṣèlérí fun yín, kò sí èyí tí kò mú ṣẹ.
Dìde, lọ sí ìsàlẹ̀, kí o bá wọn lọ láì kọminú nítorí èmi ni mo rán wọn.
Egbe oselu APC ni apapo ibo (152,224 votes), ti egbe oselu PDP si ni,
Àwọn ni yóo máa ṣe ìtọ́jú Àpótí majẹmu ati tabili, ọ̀pá fìtílà ati àwọn pẹpẹ, ati àwọn ohun èlò ní ibi mímọ́, tí àwọn alufaa máa ń lò fún iṣẹ́ ìsìn; ati aṣọ ìbòjú, ati gbogbo iṣẹ́ tí ó jẹ mọ́ ti àwọn ohun èlò wọnyi.
nígbà náà ni èmi gan-an yóo wá kẹ̀yìn sí olúwarẹ̀ ati gbogbo ìdílé rẹ̀, n óo sì yọ wọ́n kúrò lára àwọn eniyan wọn, ati òun, ati gbogbo àwọn tí wọ́n wà lẹ́yìn rẹ̀, tí wọ́n jọ ń bọ oriṣa Moleki.
Bákan náà lo ni Trypsin, eyi a si maa ṣàkóba fun ǹkan to n mú ounjẹ da lára.
Iwọnba eyi ti wọn ri ni Demark yii lo mu ki Sweden naa tilẹkun ibode rẹ mọ wọn, eyi ni igba akọkọ ti Sweden yoko tilẹkun mọ aladugbo rẹ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Akomolede Yoruba: Ìtàn ọ̀rẹ́ tó fi ògùn gba ọkọ ọ̀rẹ́ rẹ̀ nílùú òyìnbó rèé Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Akomolede Yoruba: Ìtàn ọ̀rẹ́ tó fi ògùn gba ọkọ ọ̀rẹ́ rẹ̀ nílùú òyìnbó rèé 15 Owewe 2020 Arabinrin Olaitan Zainab ni olukọ wa lonii, o ṣalaye iru oju ti ọrẹ meji fi wo ọkunrin kan ti wọn pade ti ọkan fi oju tẹmbẹlu rẹ amọ oun gan lo pada n wa lati fa oju rẹ mọra tori owo Ṣe ẹ ranti bi inu kilaasi yin ṣe maa n ri lasiko ti ẹ ba fẹ ka awọn iwe ayọka Yoruba nigba ti ẹ ṣi wa nileewe girama?
Iru wahala bayi ko ye mi rara, o sọ.
Donald Trump: Àkọbí ọmọ ààrẹ, Donald Trump Jr ti lùgbàdì Covid-19
Ó ti fi èdìdì rẹ̀ sí wa lára, ó tún fi Ẹ̀mí Mímọ́ ṣe onídùúró sí ọkàn wa gẹ́gẹ́ bí ẹ̀rí ohun tí yóo tún fún wa.
 Emi ni ojulowo Oluwo nitori Ọlọrun Eledumare gangan ni Ọlọrun Iwo, emi Ọba Abdulrasheed Adewale Akanbi Tẹlu 1 si ni aṣoju Ọlọrun ninu ẹran ara gẹgẹ bii Oluwo.
N óo fi yín fún ogun pa,gbogbo yín ni ẹ óo sì bọ́ sọ́wọ́ àwọn apànìyàn;nítorí pé nígbà tí mo pè yín, ẹ kò dáhùn,nígbà tí mo sọ̀rọ̀, ẹ kò gbọ́,ẹ ṣe nǹkan tí ó burú lójú mi;ẹ yan ohun tí inú mi kò dùn sí.
Mose bá sọ fún Aaroni pé, “Mú ìkòkò kan kí o fi ìwọ̀n omeri mana kan sinu rẹ̀, kí o gbé e kalẹ̀ níwájú OLUWA, kí ẹ pa á mọ́ láti ìrandíran yín.
Àwọn ọmọ Imeri jẹ́ ẹgbẹrun ó lé mejilelaadọta (1,052)
 Ó kú ní ọdún mẹ ́ ta sáájú ọkọ rẹ ̀ .
A lè lo òwe “A ki i fi ọjọ́ kan bọ́ ọmọ tó rù” ṣe àlàyé pé iwà ìbàjẹ́ àti ohun tò bàjẹ́ fún ọdún pi pẹ́ kò ṣe tún ṣe ni ọjọ́ kan, nitori eyi, ki ará ilú ṣe sùúrù fún Ìjọba tuntun lati ṣe àtúnṣe lati ìbẹ̀rẹ̀.
Bí ọmọdé àti àgbà bá lọ sí oko ìbáà ṣe ọkùnrin ìbáà ṣe obìnrin, àgbà ni ó nílati ru erù bọ̀.
pé kí ó sọ fún àwọn eniyan Israẹli pé, “Àwọn àjọ̀dún tí èmi OLUWA yàn tí ó gbọdọ̀ kéde gẹ́gẹ́ bí ìpéjọ mímọ́ nìwọ̀nyí: 
Ẹ̀wẹ̀, èyí kìí ṣe ìgbà àkọkọ láàrin àwọn agbábọọlu Nàìjíríà ti agbá bọọlu yóò dédé kú lóri pápá.
Ẹnikan ti isẹlẹ naa soju rẹ ti salaye pe obinrin kan to n ta ọti lo sokunfa ija awọn ọlapa mejeeji yi, ẹni to tun jẹ ọrẹbinrin ọkan lara awọn ọlọpa naa.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ọbasanjo kọ́ ni yóò fi ààrẹ jẹ nínú ìdìbò 2019 - Oshiomole SERAP ní kí Buhari gbé Dasuki, Jonathan lọ síwaju kóòtù àgbáyé Iléẹ̀kọ́ girama fásitì Ibadan wọlé padà lẹ́yìn aáwọ̀ Hijab Ẹ máse sá gaàrí síta mọ́ torí ibà Lassa - ìjọba Ondo figbe bọnu Àràbarà pósí rèé, ibùgbé ìkẹyìn tó jẹ ojú ní gbèsè Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Adedoyin: Tí mo bá rí Buhari, màá sọ fun kó rántí pé Ọlọ́run wà Ṣugbọn awọn ile iṣẹ mejeeji lawọn ko jẹbi ẹsun ti wọn fi kan wọn.
Lórí ìṣẹ̀lẹ̀ yìí, agbẹnusọ ọlọ́paàá sàlàyé pé, kò sí ǹka ti àjọ ọlọ́pàá yóò fi pamọ́ fún ará ìlú.
Níbẹ̀ ni àwọn ọmọ ogun Edomu ti yí wọn ká.
Kí o sì kó oniruuru oúnjẹ sinu ọkọ̀ náà fún ara rẹ ati fún wọn.
Mo mọ  ojuse mi si Ọlọrun ati orile ede mi.
Mo ri ọrọ yii bii eyi ti ko ba Bibeli mu, to si jẹ iwa ika si ọmọniyan?
Duro Ladipọ, ìlúmọ̀ọ́ká òṣèré tíátà àti ọmọ àlúfà tí kò gbàgbé àṣà ìbílẹ̀ Ọ̀rọ̀ǹpọ̀tọ̀niyùn, Aláàfin obìnrin àkọ́kọ́ rèé, tó ní nǹkan ọkùnrin Oríṣun àwòrán, Getty Images Amọ ni igba ti o di iṣẹju ọgọrin, Papastathopoulos da goolu kan pada fun Arsenal.
Ebola: Ènìyàn méji ló ti kú lórí àìsàn Ebola lórílẹ̀èdè DRC
 SUNA so pe “ Akanse  igbese pajawiri” lo
Babatunde Gbadamosi, ọkan lara awon oludije dupo gomina ipinlẹ Eko ninu eto idibo to kọja sọrọ lori awon mẹta ti wọn yọ nipo eti ero rẹ pe ọmọ ẹni ko le ṣe idi bẹbẹrẹ ki a ko ilẹkẹ sidii ọmọ ẹlomii.
Ọjọ keje, oṣu kẹfa ni idije ife ẹyẹ agbaye fawọn agbabọọlu obìnrin naa a bẹrẹ.
Nígbà tí Jesu súnmọ́ etí ìlú Jẹriko, afọ́jú kan wà lẹ́bàá ọ̀nà, ó jókòó, ó ń ṣagbe.
General Tukur Yusufu Buratai ti paṣẹ tẹlẹ fun awọn ologun lati wa ọgagun naa ri ni kiakia atoku ataye rẹ.
Wọn fi ikede yi soju opo Twitter wọn.
Olori awọn oṣiṣẹ ni Naijiria, Ọmọwe Folashade Yemi-Esan lo sọrọ naa ninu atẹjade kan to fi sita lọjọ kẹwaa oṣu kẹjọ, ọdun 2020 yii.
Ọkọ Amina, bi o tilẹ jẹ pe o ti ku, ọmọ ilu Kazaure naa ni.
Ojú ọjọ́ yóo ṣókùnkùn ní Tehafinehesi nígbà tí mo bá ṣẹ́ ọ̀pá ìjọba Ijipti, agbára tí ó ń gbéraga sí yóo sì dópin.
’ Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
O sọ fun BBC Sinhala pe, ''mo fẹ ki ara mi o pupa, ṣugbọn ṣe ni gbogbo aàwọ mi jona.
"Àràmọ̀ǹdà ọmọ, wọ́n bi ní ọjọ́ 9/11, láago 9/11 tó si wọn 9/11 ""Lẹ́yìn ọdún méjìlá, mo gun òkè fún ọjọ́ márùn-ún kí ń tó rí ìyá mi"" NANS kò ṣe ọ̀fọ̀ mọ́, a fẹ́ bèèrè ìdájọ́ lórí ikú akẹẹgbẹ́ wa ní Fuoye - ẹgbẹ́ akẹ́kọ̀ọ́ yarí Àwa obìnrin, ẹ jẹ́ ká di fijilanté kí ọmọbìnrin wa má baà ya pòkíì - Aya Osinbajo O tun fẹ di ilumọọka agbabọọlu fun awọn gbajugbaja ẹgbẹ agbabọọlu agbaye bii Super Eagles ilk wa, Barcelona, Real madrid ati Chelsea."
Ẹ gbé Ọlọrun mi ga,ẹni tíí ṣe àpáta ìgbàlà mi.
Àhámọ́ Leah àtàwọ́n ọmọbìnrin míì ṣì ń kọni lóminú
Dafidi ati àwọn jagunjagun rẹ̀ lọ pa igba (200) Filistini, ó sì kó awọ adọ̀dọ́ wọn wá fún ọba, kí ó lè fẹ́ ọmọ ọba.
Ẹ̀rù ba Elija, ó sì sá fún ikú.
Bakan naa, lo tun wa ran won leti lati se ojuse won bi isẹ, ki
 “Ojuse igbimo awon Gomina ni lati sin awon ara
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ẹ̀yin ọmọ ìta tó ní Funke Akindele ra ilé fún mi, irọ́ ni o - Ajirebi Iṣẹ́ abẹ tí mo ṣe láti fi kún ìkébé mi ṣàkóbá fún mi- Omotola Taiwo Wo ohun tó yẹ ko mọ̀ nípa olùdarí àjọ EFCC tuntun Ìtàn ayé Henry Fajemirokun, olówó tó fi owó mọ Olúwa àti ènìyàn Báwo ni Coronavirus ṣe n tànkálẹ̀ l'Afrika?
Kíni ẹ mọ̀ nípa Ọmọ́táyọ̀ Olútóyè, Ọ̀jọ̀gbọ́n obìnrin àkọ́kọ́ nínú ẹkọ́ èdè Yorùbá lágbàyé À ti fi àwọ̀n ọlọ́kadà 123 láti Jigawa sílẹ̀ -Ọlọpaa Àwọn jàǹdùkú pa fadá ní Taraba-Iléeṣẹ́ ọlọ́pàá Ọkọ̀ òfúrufú ọlọ́pàá yóò bẹ̀rẹ̀ sí ní káàkiri Naijiria - Ọgá Ọlọ́pàá Ọgbẹni Omotosho ni ti ilu Eko ba jẹ ilu to lewu julọ lati gbe lootọ, awọn eeyan bi aarẹ ilẹ Faranse, Emmanuel Macron ati abẹṣẹ-ku-ojo Anthony kò ba tíi ṣe abẹwo wa silu Eko laipẹ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Wo bí Sunday Orimola ṣe gba ikú ẹranko kú ní Ifon ni Ondo lórí ọ̀nà àtijẹ Lẹyin ti igbimọ oludajọ ṣe agbeyẹwo koko marun un ti ẹgbẹ oṣelu PDP fi gbe Gomina Bello APC lọ si ileẹjọ, ileẹjọ giga ni awọn ẹsun naa ko lẹsẹ nlẹ.
Adari ile igbimọ aṣoju-ṣofin, Nancy Pelosi ni igbes aarẹ Trump yii foju keree ipo adari ti US wa lagbaye, ofin ati bi nkan ṣe ti wa nilẹ tẹlẹ.
O ni awọn maraarun naa ni wọn ti rinrinajo lọ sorilẹede Amẹrika ati ilẹ Gẹẹsi laipẹ yii.
Mò ń kérora pé wọ́n dá mi lóró,ṣugbọn kò sí ẹni tí ó dá mi lóhùn;mo pariwo, pariwo,ṣugbọn kò sí ẹni tí ó dìde láti ṣe ẹ̀tọ́.
Mercy ló gbadé BBNaija ọdún 2019 Àṣírí tú!
"Wọn gbiyanju lati ya wọ inu ọgba ẹwọn Ikoyi ni Eko, to fi mọ ẹka ileeṣẹ ọlọpaa 81 Division atawọn ọlọpaa lo ṣeranwọ lati dena wọn.
Ismail Ajjawi tí wọ́n ṣẹ̀ṣẹ̀ gbà wọlé fún ẹ̀kọ́ ọ̀fẹ́ sí Harvard, sùgbọ́n àwọn aláṣẹ US kọ̀ láti jẹ́ kó wọ ìlú láti pápákọ̀ ofurufu ni wọ́n ti dáa pada.
Inu mi dun pe a ni awon eri ti a le mu lo sile fun awon eniyan wa.
Bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé ó ti lè ní ìgbà méfa ti àrùn onigbameji tún ti bẹ silẹ leyin ti ọdún 1817 náà, síbẹ̀, manigbagbe ni ajakale àrùn Kọlẹra àkọ́kọ́ ọhun.
Ni kete ti o ba ti de ọfiisi naa, wọn o fun ọ ni nọmba lati to si ori ila, ko ma ba a si idaru-dapọ, ati lati daabo bo awọn eeyan lọwọ Covid-19.
ipade ti won se da lori ni “Bi
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ọwọ́ ọlọ́pàá tẹ ọlọ́kọ̀ epo tó fa ìjàmbá nílú Eko Ilé ẹjọ́ ń retí ìwé ẹ̀rí Fásitì Sẹ́nétọ̀ Adeleke Kini o wa ninu agba ikọja si naa?
Ninu atẹjade kan ti ASUU fi lede, o ni ọpọ ile iwe to jẹ ti ijọba ni awọn akẹkọọ rẹ pọ ju kilaasi lọ.
Ẹgbọn baba ọmọ naa to ba wa sọrọ, Arakunrin Sarafa Arowolo sọ fun wa pe aṣọ ọdun mẹta ọtọọtọ ni wọn ran fun ọmọ naa lọjọ ọdun ku ọla.
Aregbesol̀a lo pe ipe yii nibi ifilọlẹ iwe itan ilu , asa ati ise ipinle Osun , lati  fi se ajodun ikẹ́tàdínlọ́gbọ̀n ti won da ipinle naa sile.
 Iwode ti o waye lojo-Aiku ni lati sami ayajo ogorun odun ti o je ojo ibi ologbe Nelson Mandela, bakan naa, o tun je erongba Ramaphosa lati yanju aawo egbe naa saaju eto idibo gbogbo ti yo waye ni odun to n bo.
Ìwọ ni n óo máa yìn nígbà gbogbo.
 gẹgẹ bi aarẹ ẹgbẹ awọn oṣere Yoruba, Bolaji Amusan ti ẹ mọ si Mr Latin ṣe kilọ fun wọn."
Ó ní, “Saulu arakunrin mi, Oluwa ni ó rán mi sí ọ.
Ọ̀rọ̀ǹpọ̀tọ̀niyùn, Aláàfin obìnrin àkọ́kọ́ rèé, tó ní nǹkan ọkùnrin Ìdí rèé tí a fí dá àwọn dókítà Nàìjíríà 58 tó fẹ́ lọ sí London padà- NIS Funke Akindele fún mi lówó tí mo fi gba ilé, kò ra ilé fún mi o - Ajirebi Lẹyin naa ni Dabiri-Erewa kede pe panpẹ ọba ti mu arakunrin naa ti awọn si ti bẹrẹ eto lati mu arabinrin Busari pada sile.
"Bakan naa ni wọn ko fun ni anfaani lati rojọ tabi ṣalaye lori awọn ẹsun ti wọn fi kan an.
Ẹnikẹ́ni tí ó bá sì fi ara kàn án jẹ́ aláìmọ́ títí di ìrọ̀lẹ́.
''Mo sọ fun Adedibu pe ko jẹ ki o ṣeeṣe, ababọ rẹ ni gbogbo wa pada ri wi pe PDP wọle Gomina''.
Ọkàn ìyá tí ó ni ààyè ọmọ kò gbà á, nítorí ìfẹ́ tí ó ní sí ọmọ rẹ̀, ó wí fún ọba pé, “Kabiyesi, gbé ààyè ọmọ yìí fún ekeji mi, má pa á rárá.
Olukuluku ni yóo kú nítorí ẹ̀ṣẹ̀ ara rẹ̀.
O ni mo gbe igbesẹ yii ki awa obinrin le bọ diẹ kuro ninu aṣa a n fogun ọdun duro de ọkunrin to nifẹ ẹ wa ṣugbọn ti ara kii ré lasiko' 'Awọn obinrin nilo ajọ iranwọ fun oṣelu' Angelique kidjo pe fun anfani f'awọn obinrin Ilẹ China ń sàmì àádọrin ọdun tí wọn gbòmìnira pẹ̀lú ìfẹ̀hònúhàn Kíni ìdí ti wọn fi ń lọ ọmú obinrin Ọlọpa kan yinbọn mọ ọga rẹ nitori obinrin Oríṣun àwòrán, AFP Àkọlé àwòrán, Enikẹni lo yẹ ko le dẹnu ifẹ kọ ara wọn ninu irinajo ifẹ Lọjọ Satide to kọja ni awọn lọkọlaya naa di ọkan ni ona ara ọtọ ni India.
E je ki a gbadura fun awon adari wa, oselu to pin yele-yele, alaafia ati isokan orile-ede wa NaijiriaE je ki a kepe Olorun ko fowo to okan awon adari wa ni ona ti won yoo gba lati tunko orile-ede yii, lati si emi iyapa, aini imumora, ifungun-moni ti o gbinle bi olu oran.
Nisinyi ti gbendeke naa ti kọja ti ọdun tuntun ti wọle bayii, ibeere to gbẹnu ọpọ onwoye ni irufẹ ẹbun wo ati pe ọna wo ni ẹbun yii yoo gba wa.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Coronavirus: Èèyàn kan péré ló ní àrùn aṣekúpani náà ní Nàíjíríà báyìí 13 Ẹrẹ̀nà 2020 Oríṣun àwòrán, Others Ijọba orilẹede Naijiria ti fi lede pe, ẹnikeji to ni Coronavirus lorilẹede Naijiria ti ri iwosan gba.
“Bí ẹrú kan bá jẹ́ olóòótọ́ ati ọlọ́gbọ́n, ọ̀gá rẹ̀ á fi ilé rẹ̀ lé e lọ́wọ́, pé kí ó máa fún àwọn eniyan ní oúnjẹ lásìkò.
Lede kan, agbọ-mujojo ni orin Ayinla Ọmọwura nigba aye rẹ Yatọ si pe orin Ayinla Ọmọwura n mu iyipada rere ba awujọ, orin rẹ tun kun fun ọfọ, ayajọ ati epe nigba miran eyi to mu ki ọpọ eeyan maa ri i bi oloogun.
Ọjọ́ mẹ́rin sí ìgbéyàwó wa ní ìyàwó mi b'ómi lọ- Ibrahim Abubakar À ń ṣọ́ọ yín lórí ayélujára yín bàyìí o!
Àkọsílẹ̀ àwọn eniyan ati àwọn baálé baálé tí wọ́n bá mi pada wá láti Babiloni ní àkókò Atasasesi, ọba, nìyí:
Taní Ibidunni Ighodalo tí gbogbo ọmọ Nàìjíríà ń selédè lẹ́yìn rẹ̀ Ààrẹ Buhari kò sí nínú ewu àjàkálẹ̀ àrùn kankan tórí ẹ̀ṣọ́ rẹ̀ tó ṣẹ̀ṣẹ̀ dé sí Aso Rock-Garba Shehu Àjọ ọlọ́pàá, Ìjọba ìpínlẹ̀ Ọyọ jẹ́jẹ̀ẹ́ láti ṣàwárí òòsà tó ń mu ẹ̀jẹ̀ nílùú Ìbàdàn Wo àwọn òṣèré tíátà Yorùbá tó bí ìbejì Eeyan 5220 lo ti ri iwosan gba, nigba ti awọn 420 ti dero ọrun nitori arun ọhun.
Òun ni ó pa wá mọ́ tí ó sì fún wa ní ìṣẹ́gun lórí àwọn ọmọ ogun tí wọ́n dojú ìjà kọ wá.
Ona kan naa ohun ni akonimoogba agba iko agbaboolu Germany, Joachim Low n samulo fun awon agbaboolu re.
Asiko idarudapọ yii ni awọn akonilẹru raye wọ aarin wọn, ti wọn si so okun mọ ikọọkan wa lọrun bii ẹran, koda wọn pin lọkọ-laya niya, ti wọn si ta awọn ọmọ wọn sọtọ, lati igba yii si ni ipinya ayeraye ti de, ti wọn ko si fi oju ri ara wa mọ.
Aare Muhammadu Buhari soro yii nibi ifilole ipade ijo awon onigbagbo  ti won se lati fi se ayeye odun ikéjìléláàdọ́sàn án ti  won da ijo naa sile  lorile ede Naijiria , .
Àwọn ọmọdé kú ikú ìbọn :
Ẹ bá mi dúpẹ́ lọ́wọ́ Sunday Igboho, Ajimobi, Seyi Makinde àti àwọn ọlọ́pàá fún iranwọ wọn láti rí ìbejì gbà padà Ilumọọka onímọ̀ nípa ẹṣin Islam, Sheikh Taofeeq Akeugbagold tí kesi àwọn olórí wá ní Naijiria lati mojuto ìpèsè ètò ààbò tó péye.
Lalẹ ọjọbọ ni wọn gba ami ẹyẹ naa lẹyin ti awọn adajọ eto kaakiri agbanlaaye se ayẹwo isẹ wọn.
Awolowo gbe apoti idibo lati wọ ile igbimọ aṣofin labẹ asai ẹgbẹ Action Group, sugbọn o kuna lọdun 1979 ati 1983.
Ìròyìn ohun tí àwọn eniyan Israẹli ń wí kan Dafidi ọba lára.
2bn fún Obanikoro Senetọ Olabiyi Durojaye tó jẹ aarẹ Afẹnifẹre ki Buhari ati Osinbajo igbakeji rẹ ku oriire wiwọle wọn leekeji.
Wọ́n dáná fún wa nítorí pé òjò ti bẹ̀rẹ̀ sí rọ̀, òtútù sì mú.
Gege bi o se sọ , o ni woo yoo lo ami idanimo orisirisi fun apoti ati
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Ere ki laja n ba ẹkun se?
Oríṣun àwòrán, EFCC Ọna marun to fi lee mọ eke Babalawo: Awọn babalawo ayederu kii le ki ifa ati awọn odu ijinlẹ to wa ninu rẹ Awọn ayederu babalawo ko farabalẹ kọ ẹkọ bi o ti yẹ nitori ẹkọ isẹ babalawo muna doko ju tawọn onisegun lọ Asọ awọn ayederu babalawo ma n pọn ni , nitori pe wọn yoo jẹ iya ni aye, wọn a tun jẹ ni ọrun Iya ati isẹ lo ma n gbẹyin awọn ayederu babalawo Gbajuẹ babalawo kii sọrọ ko sẹ tabi se iwosan to muna doko.
Youlegrave ni abúlé tí ìrìnàjò yìí ti bẹ̀rẹ̀ .
Ni ọsan ọjọ Iṣẹgun ni iroyin ti kọkọ lu si igboro pe Ọjọgbọn Ibrahim Gambari ni aarẹ pada fontẹ lu fun ipo naa bi o tilẹ jẹ wi pe ileeṣẹ aarẹ kọkọ sẹ jalẹ pe awọn ko mọ nipa ikede orukọ naa nigba naa.
Yóo fún àwọn orílẹ̀-èdè ní alaafia,ilẹ̀ ìjọba rẹ̀ yóo jẹ́ láti òkun dé òkunati láti odò Yufurate títí dé òpin ayé.
Ọbasanjọ fi ika hanu bẹẹ nibi ipejọpọ awọn eeyan nilẹ yi ati loke okun to waa ba se ajọyọ ọjọ ibi ọdun kọkanlelọgọrin rẹ loke eepẹ eyi to waye nile rẹ nilu Abẹokuta.
Iṣẹ owo ṣiṣe lo yan laayo ko to kan wọ agbami ere Tiata.
ede China, o ni gbogbo nnkan ti won lo  lati fi se ise won , jẹ eyi ti awon onisowo ba
21 Bélú 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 19 Agẹmo 2020 Ijọba ilẹ̀ Amẹrika ti sọ pé ewú wà ti ẹnikẹni bá n sún òòrun lẹnu iṣẹ́, sùgbọ́n àwọn onimọ nipa oorun sàlàye pé ìjọba ni láti tún èrò rẹ̀ pa.
Bi awọn iya ti ṣe n to lawọn ọmọdebinrin wọnyi n ṣa ododo nibi awọn ile ti o wo ni ilu Beira lọjọ Aiku.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Contortionist: Mo lè gbé ìfun mi pamọ́ ki n tún se èémí!
Ipaya yii ti dori ẹmi ọpọ oṣiṣẹ to bẹẹ gẹ ti alaga ẹgbẹ oṣelu APC to n ṣejọba lorilẹede Naijiria, Adams Oshiomhole, toun pẹlu ti figbakan ri jẹ aarẹ ẹgbẹ oṣiṣẹ lorilẹede Naijiria fi rawọ ẹbẹ sawọn agbanisisẹ lati maṣe da awọn oṣiṣẹ silẹ tabi dinowo wọn ku.
Yollywood: Ẹ wo àwọn gbajumọ òṣèré tíátà tó jogún ere ṣíṣe lọ́dọ̀ òbí wọn Ǹkan mẹ́wàá tí o yẹ kí o mọ̀ nípa Odumejeje Èèyàn 196 míràn tún ti ní àrùn Coronavirus ní Nàíjírìa Wo àwọn èèkàn ìlú Kano tó kú láàrín ọjọ́ mẹ́rin sí ara wọn Ìròyín sọ pé ìgbìms náà lọ sí ibi ayẹyẹ náà ni lẹ́yìn ìgbà tí àwọn ará ìlú ta wọ́n lólobó.
Gomina Arẹgbẹsọla fikun pe ilẹ Naijiria sorire lati tete jajabọ ninu ogun abẹle akọkọ pẹlu afikun pe eyi lee ma ri bẹẹ mọ fun ilẹ Naijiria to ba tun fi lọ si ogun abẹle ẹlẹẹkeji, nitori oju apa ko lee jọ oju ara mọ.
Idi ree ti wọn fi gba awọn awakọ ni iyanju lati ri wi pe wọn ko gbe ọkọ sita nigba ti agbara ojo ba wa lori popo.
Ejá àwọn ọlọ́pàá náà a rí i ó ń bọ̀ ní ìsàlẹ̀ a sì mọ̀ pé àwọn ọlọ́pàá wọ̀nyí kò lè jí lójú oorun títí òun yóó fi ré wọn kọjá.
Àwọn eniyan rẹ rí ibùgbé lórí rẹ̀;Ọlọrun, ninu oore ọwọ́ rẹ, o pèsè fún àwọn aláìní.
N óo fún ọ ní ohun tí o bèèrè.
Ààrẹ Buhari bínú sí àwọn afẹ̀họ́nú hàn Aarẹ orilẹ-ede Naijiria, Muhammadu Buhari ti sọ òkò ọrọ si awọn afẹhọnu han ti wọn ni ko kọ ibi ara si ipaniyan to n waye ni ilu Zamfara.
Nítorí náà, ẹ ṣe ọkàn yìn gírí.
Ní ọjọ́ kẹwaa oṣù kinni ni àwọn eniyan náà gun òkè odò Jọdani.
Bobrisky sàlàyé ipò tó wà gẹ́gẹ́ bi ọkunrin tàbí obinrin
Ilé ẹjọ́ dajọ ikú fun ọkunrin tó pa olólùfẹ́ rẹ̀ Obìnrin pa olólùfẹ́ rẹ̀, ó fi se ìrẹsì Ohun tó wù kí ileẹjọ́ kòtẹ́milọ́rùn sọ, Adeleke kò lè di gómínà Ọ́ṣun - APC Wo àwọn ìlérí tàwọn Gómìnà tuntun ṣe nínú ìbúra wọn Awọn ara abule naa ni awọn gbe igbesẹ naa nitori pe eewọ ni iku ti Ojemba fi pa ẹgbọn rẹ, Obok.
Ọkan nínú osiṣẹ ọgbà náà tó ní ki BBC má dá orúkọ oun sàlàyé pe, ọlọ́pàá ti mú gbogbo àwọn to wà lẹ́nu iṣẹ́ lásikò ti owó náà pòòrá Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Sogidi Lake: Kòṣẹja-kòṣèèyàn lá bá nínú adágún odò náà -Ojedele Bákan náà ni ilé iṣẹ́ ọlọ́pàá fi ìdí ọ̀rọ̀ náà múlẹ̀.
Ṣugbọn amòfin náà fẹ́ wẹ ara rẹ̀ mọ́.
Èmi kò sí nílé, ọkọ́ mi ló leè sọ bóyá lóòtọ́ọ́ ló fẹ́ gbéyàwó àbí bẹ́ẹ̀ kọ́ - Aisha fèsì Yatọ si ẹsun yi, Aisha Buhari tun fi awọn ẹsun miran kan Garba Sheu ṣugbọn koko nkan to jẹ yọ ni pe Garba Sheu nikan kọ ni Aisha n sọko ọrọ ba.
Wọ́n sọ fún un pé, “O kò gbọ́ ohun tí àwọn wọnyi ń wí ni?
Ẹ́ gbọ Oluwatẹru siwaju si: Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Amb.
 ”Ohun ti o bani-ninu je lojo Aiku(Sunday) ni pe, asekagba idije ohun ni igba akoko ti Del Potro yoo pegede sinu re, ti o si padanu ife-eye naa, yatosi lọdun 2009 ti o gba ife-eye kan soso ti o ti gba loju agbami Flushing Meadows.
4 3413 Orilẹede Guinea Bissau 45 2.
Oga agba ajo NDLEA ohun, wa benu ate lu amulo egbogi oloro ti o gbode kan
Ojú tì mí láti gbà pé àwa kò lágbára tó láti hu irú ìwà bẹ́ẹ̀!
O wa rọ gbogbo awọn olugbe nipinlẹ naa lati faaye gba ara wọn, nitori pe ofin orilẹede Naijiria fi aaye silẹ fun gbogbo eniyan lati gbe ni ibi to ba wu wọn.
“OLUWA sọ fún mi pé, ‘Wò ó, mo ti bẹ̀rẹ̀ sí fi Sihoni ati ilẹ̀ rẹ̀ le yín lọ́wọ́, ẹ bẹ̀rẹ̀ sí gbà á, kí ẹ lè máa gbé ibẹ̀.
Àwọn ọmọ Saulu lọkunrin ni Jonatani, Iṣifi, ati Malikiṣua.
Wọ́n ṣe àgbékalẹ̀ rẹ̀ fún àjọyọ̀ gbogbo ọmọ káàárọ̀-oòjíire ni, àti àwọn ti ibi tí àṣà wa tàn dé káàkiri àgbáyé bíi Brasil àti Kuba.
Ọrọ kan ṣoṣo le tumọ si itumọ mẹfa tabi ju bẹẹ lọ pẹlu iyatọ to ba wa lori ami ohùn rẹ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Chichi Igbo: Ọ̀pọ̀ máa ń rò pé mo ní nǹkan ọkùnrin lábẹ́ torí ìrísí mi jọ ti ọkùnrin Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Chichi Igbo: Ọ̀pọ̀ máa ń rò pé mo ní nǹkan ọkùnrin lábẹ́ torí ìrísí mi jọ ti ọkùnrin 11 Agẹmo 2020 Ọkan lara awọn ọmọ ẹgbẹ agbabọọlu lobinrin fun orilẹede Naijiria, Super Falcons, to ti fẹyin ti ni Chichi Igbo jẹ.
Bí obinrin onigbagbọ bá ní ọkọ tí kì í ṣe onigbagbọ, tí ó bá wu ọkọ rẹ̀ láti máa bá a gbé, kí ó má ṣe kọ ọkọ rẹ̀.
òun nìkan tí kì í kú, tí ó ń gbé inú ìmọ́lẹ̀ tí eniyan kò lè súnmọ́, tí ẹnikẹ́ni kò rí rí, tí eniyan kò tilẹ̀ lè rí.
ijọba apapọ lati tete gbe igbesẹ to yẹ lori ọrọ ikọlu nitori ikọlu naa
37 Ẹ kíyèsí àwọn ọgbẹ́ tí wọn gún ìhà mi, àti bákannáà àwọn àpá ìṣó tí ó wà ní awọn ọwọ́ àti ẹsẹ̀ mi; ẹ jẹ́ olõtọ́, ẹ pa àwọn òfin mi mọ́, ẹ̀yin yíò sì jogún ìjọba ọ̀run.
Ọmọ atàpátadìde ni mí, télọ̀ ni bàbá mi- Abiola Ajimobi Àwọn tó ń wojú ọjọ́ rí ihò dúdú tó tóbi jù láyé àtọ̀run Àwọn ológun ti yọ Omar al-Bashir, olórí ìjọba Sudan nípò Olori awọn ọba ti gomina Ajimobi yan,Sẹnetọ Lekan Balogun lasiko to n ba BBC sọrọ fi idi ẹjọ naa mulẹ, pẹlu ero wi pe lati ayebaye ni gomina ilu ti n yan awọn ọba ilu.
Awọn kan n sọ wi pe ni bayi, ẹkun idibo ariwa Kwara lo kan lati yan Gomina sugbọn ko si ẹni to le so pato boya adehun yi le di mimusẹ.
Nibayii, minisita tẹlẹ feto irinna, Femi Fani-Kayode naa ti da si isẹlẹ yii loju opo Twitter rẹ l'Ọjọru.
nigba ti ngo fi jade sita,se ni mo ri ọpọ eeyan to farapa nilẹ ti awọn miran si ti ku'' Lai ọdun 1991 ni orileede Somalia ti n koju ipenija rukerudo ati iwa janduku lati igba ti awọn kan gba ij ba lọwọ awọn ologun.
“Nígbà tí ẹ bá ń kórè oko yín, ẹ kò gbọdọ̀ kórè títí dé ààlà patapata.
Ọ̀sẹ̀ yìí ni orúkọ àwọn mínísítà yóò tẹ̀ wá lọ́wọ́ - Ilé aṣòfin àgbà Mi ò m'àwọn ẹgbẹ́ tó ń gbé ''Tinubu 2023'' kiri- Bola Tinubu Èrò àwọn ọmọ Naijiria ṣọ̀tọ̀ọ̀tọ̀ lórí Tinubu àti Abbo Ẹlẹbuibọn, ninu ọrọ rẹ salaye lẹsẹẹsẹ nipa ba se le e mọ gbajuẹ babalawo, ta ba n sọrọ nipa eto isegun ati ẹsin ibilẹ.
 Ileeṣẹ ajọ Social Development ni olu ilu orilẹede Naijiria ti sọ pe lootọ ni awọn yabo awọn ile-ijo kan nilu Abuja, lati pa iṣekuṣe run nitori bi awọn aṣẹwo ṣe pọ nilu Abuja."
Ti awọn orilẹede bi Amerika, Ilẹ Gẹẹsi ati Faranse laarin awọn ọpọlọpọ miran si n ri arun naa to n peleke si lagbegbe wọn, bẹẹ si ni ko i tii tan ni orilẹede Naijiria.
Wọ́n bá ń yin Ọlọrun lógo nítorí mi.
72%  ninu osu kinni odun 2017 si iko medogun o-le ninu ida ogorun to 15.
lati dẹkun ikọ ọlọtẹ ati awon agbesunmọmi , orile ede Naijiria ni lati mojuto
Ẹ̀mí Mímọ́ ati iná ni òun yóo fi wẹ̀ yín mọ́.
Ó ní wọ́n gbọdọ̀ pa àwọn ìlànà, àṣẹ ati òfin tí ó kọ sílẹ̀ fún wọn mọ́.
Ọkùnrin tí kò ríran kan rèé tó ń lọ ẹ̀rọ ata 'Alífábẹ́ẹ́tì Ohùn Oduduwa di ìtẹ́wọ́gbà ni Ajaṣẹ' Ṣẹ gbọ́ nípa Alájọ Ṣómólú, tó ta mọ́tò ra kẹ̀kẹ́?
45 Nítorí-èyí, àwọn ìbùkún tí èmi fi fún yín ju ohun gbogbo lọ.
Awọn olufẹhonuhan naa ni iwọde naa yoo tẹsiwaju fun ọsẹ kan gbako ayafi ti ileẹjọ ọhun ba yi idajọ rẹ pada.
International flights resumption: Bàálù ilẹ̀ òkèèrè bà l'Abuja léyìn ìṣéde oṣù márùn ún coronavirus
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Insecurity: Ọọ̀ni ni báwọn ọba alayé ṣe lọ́wọ́ nínú àgbékalẹ̀ Amotekun, ni yóò ṣe tọ́jọ́ 13 Èrèlè 2020 Oríṣun àwòrán, From The Palace of Ooni of Ife Yoruba ni agba kii wa lọja kori ọmọ tuntun wọ, bẹẹ si ni agba ti ko ba kẹhun sọrọ, afaimọ ko ma kẹtan sare.
Fasiti Eko ni gbogbo olukọ ti ade iwadii BBC ba si mọ lori lo maa foju wina ijiya to tọ.
"Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Kayeefi: 'Ọkọ mi ṣẹ̀ṣẹ̀ ní kí n lọ se mọ́í-mọ́í, tó ṣẹ̀ bá mi ṣeré tán ni mo gbọ́ pé ""Mopol"" yìnbọn pa á' Makinde sọ pe igbeaye ti iya oun gbe kii ṣe fun ara rẹ nikan, ṣugbọn o gbe igbe aye rẹ fun oun to jẹ ọmọ rẹ atawọn eeyan miran pẹlu."
Lasiko eto yii ni Ataoja to wa lori oye yoo wa nikalẹ, to fi mọ Arugba Ọṣun, Yeye Ọṣun, awọn arugba to ti gbe igba Ọṣun tẹlẹ, to fi mọ awọn olujọsin Ọṣun miran.
Ninu idajọ rẹ lọjọ Aje niluu Abuja, ileẹjọ naa tu ẹjọ ti ẹgbẹ oṣelu PDP pe ẹgbẹ oṣelu APC tii ṣe ẹgbẹ Bello ka.
Eyi waye nile ijọba lọjọ iṣẹgun ọsẹ yii nigba ti igakeji aarẹ Osinbajo dari Sẹnetọ Phillip pẹlu ikọ aṣoju kan lati olu ilu Abuja lọ ki aarẹ sile fun ti ọdun Sallah.
Oloye Adedayọ ti oun pẹlu jẹ ọkan lara awọn Afọbajẹ ilu Ila, to jẹ ọkan lara awọn ilu iṣẹmbaye nilẹ Yoruba fi idi rẹ mulẹ pe lara awọn eewọ ti Ọbalaye ni ilẹ Yoruba patapata ko gbọdọ ṣe ni riri ọmọ tuntun wa.
Ọgba fasiti Eko, University of Lagos, Unilag si ni iṣẹlẹ naa ti waye, bẹẹ ni awọn ile iwosan ijọba kọ lati tọju oju ọgbẹ naa, eyi to mu ki ẹjẹ da lara akẹkọọ ọhun, titi to fi gbe ẹmi mi.
Bí èyíkéyìí ninu arọmọdọmọ wọn bá súnmọ́ àwọn nǹkan mímọ́ wọ̀n-ọn-nì, tí àwọn eniyan Israẹli ti yà sí mímọ́ fún OLUWA; nígbà tí ó wà ní ipò àìmọ́, a óo mú ẹni náà kúrò lọ́dọ̀ mi.
Eniyan meloo lo ni owo lati wọ ọkọ ofurufu ni Ekiti?
Àkọlé àwòrán, Awon obinrin nilẹ Afrika wa ninu ewu lọwọ awọn ololufẹ wọn tabi mọlẹbi Ilẹ Afrika ni ibi ti iwaadi UN naa sọ wi pe awọn obinrin wa ninu ewu iku lọwọ awọn ololufẹ wọn tabi mọlẹbi wọn.
Bí ẹlòmíràn tí ó jókòó ní àwùjọ bá ní ìfihàn, ẹni kinni tí ó ti ń sọ̀rọ̀ níláti dákẹ́.
Ohun ti awọn ọlọdẹ naa sọ ni pe, ijọba ko daabo bo awọn lọwọ awọn agbesunmọmi jihadi naa.
O ti le ni ọdun mẹwaa bayii ti eto aabo ni Naijiria ti dẹnukọlẹ kaakiri gbogbo ẹkun to wa ni Naijiria.
Ẹ gbọdọ̀ ra gbogbo àkọ́bí yín tí wọ́n jẹ́ ọkunrin pada.
lorile ede Naijiria, Lai Mohammed ti ni igbimo ijoba apapo lorile ede Naijiria
(laptop) kan; ero amunawa SUMEC  irinwo-le-mewa(410);
Bakan naa lo mu 'le fun Naijiria ninu idije AFCON marun un ko to fi ikọ agbabọọlu Super Eagles silẹ.
Bẹ́ẹ̀ gan-an ni ó rí pẹlu wa.
Nítorí pé gbogbo òfin rẹ̀ ni mo tẹ̀lé,n kò sì yà kúrò ninu ìlànà rẹ̀.
Àwọn èèyàn jàǹkànjàǹkàn l'Akure bí Funke Olakunrin ti wọ káà ilẹ̀ lọ Àwọn kan fẹ́ da Naijiria rú torí ààbò tó mẹ́hẹ - Osinbajo gbarata Iroyin wo lo n jade nibi ikọlu Shiite ati awọn agbofinro: Ẹgbẹ shiite sọ pe ọmọ ẹgbẹ awọn mọkanla lo gbẹmi mi ti ọpọ eeyan si fara pa nibi ikọlu to waye laarin ẹgbẹ naa atawọn ọlọpaa lọjọ Aje loluulu orilẹ-ede Naijiria, Abuja.
Akonimoogba agba iko agbaboolu OGC Nice, ni ajo NFF yan gege bi akonimoogba agba Super Eagles lodun 2016, ti o si ran iko ohun lowo lati pegede fun idije boolu agbaye to n lo lowo lorile-ede Russia.
Ohun asán kan tún wà tí ń ṣẹlẹ̀ nílé ayé yìí, a rí àwọn olódodo tí wọn ń jẹ ìyà àwọn eniyan burúkú, tí eniyan burúkú sì ń gba èrè olódodo, asán ni èyí pẹlu.
” Joabu bá mú ọ̀kọ̀ mẹta, ó sọ wọ́n lu Absalomu ní igbá àyà lórí igi oaku tí ó há sí.
orile-ede olominira ile kẹ ́ nyà je orile-ede ni Ìlaòrùn Áfríkà .
Koda wọn fẹsun kan pe o se magomago ninu idanwo: Igba kigba ti Onyeama ko ba se daada ninu ẹkọ rẹ tabi lagbo idaraya, wọn a ma sọ pe nitori to jẹ alawọdudu lo fa ti ko fi se daada.
Agbaọjẹ agbabọọlu meji lagbaye Cristiano Ronaldo ati Lionel Messi lọle lati Russia lọjọ kan naa.
ninu okunkun ati lawon aginju abbl .
”O ni idajo ti ile –ejo naa da,
Oríṣun àwòrán, Salizu Muazu Àkọlé àwòrán, Salisu sọ pe mọngoro nikan ni awọn ajinigbe naa fun awọn jẹ f'ọjọ mẹta.
 Àwọn tí wọn ní àìsàn ẹ ̀ dọ ̀ cirrhosis tàbí jẹjẹrẹ ẹ ̀ dọ ̀ lè nílò ìpààrọ ̀ ẹ ̀ dọ ̀ , sùgbọ ́ n kòkòrò-àisàn yìí a tún lè jẹ jáde lẹyìn ìpààrọ ̀ ẹ ̀ dọ ̀ náà .
America yóò tutù ju bó ti yẹ lọ Aṣòfin ọmọ Naijiria ní Ilẹ̀ Gẹ̀ẹ́sì rẹ́wọ̀n oṣù mẹ́ta he Lẹyin naa ni Aarẹ yoo gbe imọran naa lọ si Ile Igbimo Asofin Agba, nibi ti awọn asofin yoo ti dibo lati yọ Adajọ Agba naa kuro.
A kò hùwà ẹ̀tàn, bẹ́ẹ̀ ni a kò yí ọ̀rọ̀ Ọlọrun po.
Ewe, ojo ifigagbaga naa tun je, ojo ti oju gbogbo eniyan wa lori ayeye igbeyawo aremo oba, Prince Harry ati omidan Meghan Markle to n lo lowo ni agbegbe kan ti ko jina si papa isere Wembley, Windsor.
1bn ilu jẹ ti wọn fi kan Orji Uzor Kalu to jẹ Gomina ipinlẹ Abia tẹlẹ ri.
Ẹ lọ kíá, ẹ̀yin iranṣẹ ayára-bí-àṣá,ẹ lọ sọ́dọ̀ orílẹ̀-èdè tí ó lágbára, tí ara wọn ń dán,àwọn tí àwọn eniyan tí wọ́n súnmọ́ wọnati àwọn tí ó jìnnà sí wọn ń bẹ̀rù.
O ti se diẹ si isinyi ni awọn Fulani darandaran ti n se ọsẹ ni agbeegbe naa, ti o si fa ibẹru bojo fun awọn eniyan ni agbeegbe naa.
 wọ ́ n gbàá bí ìkan nínú àwọn akọewì pàtàkì ní ogún orundún sẹ ́ yìn àti ẹni bí aṣíwájú fún ẹgbẹ ́ ìrinkankan ìṣe òdeòní nínú ewì .
37 Ṣùgbọ́n níwọ̀n ìgbàtí ìwọ kò lè fi ìgbà gbogbo ṣe ìdájọ́ olódodo, tàbí níwọ̀n ìgbàtí ìwọ kò lè fi ìgbà gbogbo mọ ẹni búburú yàtọ̀ sí olódodo, nítorínáà mo wí fún ọ, pa ẹnu rẹ mọ́ títí tí èmi yíò fi ríi pé ó tọ́ láti sọ ohun gbogbo di mímọ̀ sí ayé nípa ohun náà.
Àwọn ọlọ́kàn gíga yóo di ẹni ilẹ̀,a óo sì rẹ àwọn onigbeeraga sílẹ̀.
- Olukoya ti ìjọ MFM Shiek Yahaya Samadaani- Ọdún 2020 yìí á sàn ẹni tó bá fọkàn sín Olorun Ṣugbọn o ṣalaye ninu atẹjade naa pe ko si akọsilẹ wi pe wọn sanwo fun ilẹ ti wọn gba ọhun.
'El-Zakzaky lè má láńfààní láti lọ gba ìtọ́jú mọ́ lókè òkun' Ayédèrú Ọ̀ṣun ni wọ́n ń bọ lónìí, kìí ṣe ojúlówó - Bàbá Ọlọ́ṣun tún figbe ta Fayemi fojú Alufa to fipa bá ọmọde lòpọ̀ síta l'Ekiti Buhari júwe ọ̀nà ilé fún Obono-Obla lórí ẹ̀ṣùn ayédèrú ìwé ẹ̀rí Facebook fi kọ́kọ́rọ́ ti àwọn ojú òpó ayédèrú ìròyìn léde Yorùbá àti Igbo Gẹgẹ bi iroyin ti agbọ ṣe sọ, nṣe ni wọn fi iwe pe Sẹnetọ Ekweremadu si ibi eto nla kan ti awọn ọmọ ẹya igbo to n gbe ni ilu naa gbe kalẹ.
Igbakeji Aarẹ Yemi Osinbajo ko jẹ ki ọrọ na bale ki o to fẹsi pada lori bi Atiku ti se n polongo ọrọ atunto eto iṣejọba lorilẹede Naijiria.
Wọn óo kọ̀ mí sílẹ̀, wọn óo sì da majẹmu mi.
Iroyin naa ni awọn agbofinro ko jẹ ki ẹnikẹni tabi akọroyin kankan fi oju kan Zakzaky ati aya rẹ, titi ti wọn fi gbe wọn gba ọna miran lọ fi si ahamọ.
Simona Omo odun merindinlogbon ohun, ko kopa bi eni to ni ifarapa rara, leyin ti o ko lati tesiwaju ninu idije Qatar Total Open nilu Doha losu ti o koja.
Pẹ̀lú gbígbé ọwọ́ léni lórí, nígbànáà Joseph yan Oliver bíi alàgbà ìjọ, Oliver náà sì yan Joseph ní ọ̀nà kannáà.
'Iwe Chinua Achebe 'Things Fall Apart' fi agbara fun idẹyẹsi idile ẹru'- Bisọọbu Agba Ijọ AgudaBakan naa ni awọn iwe kika bii Iwe Chinua Achebe, 'Things Fall Apart' naa sọ itan bi Osu ṣe ri, ati iru igbeaye ti wọn ko le e gbe.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Yomi Shogunlẹ: Ọ̀rẹ́kùnrin Yahoo Yahoo ló fi Khadijat Olubọyọ ṣe ògùn owó 9 Agẹmo 2018 Oríṣun àwòrán, Princess Khadijat Nikky Oluboyo/Facebook Àkọlé àwòrán, 'Ọ̀rẹ́kùnrin ọmọ Yahoo ló fi Khadijat ṣe ògùn owó' Igbákejì kọmíṣánà Ọlọ́pàá, Yọmi Shogunlẹ ti fi ìṣẹ̀lẹ̀ ikú ọmọ igbákejì gómìnà ìpínlẹ̀ Ondo tẹ́lẹ̀rí naa gba àwọn ọ̀dọ́mọbìnrin ní ìmọ̀ràn lójú òpó Twitter rẹ̀ pé kí wọ́n mase dọ́rẹ̀ẹ́ pẹ̀lú àwọn ọmọ Yahoo Yahoo.
Ondo atijọ ni ọjọgbọn yii ṣoju fun nile igbimọ aṣojuṣofi lasiko yii.
Oludamọran si gomina ipinlẹ Ondo fọrọ igboke gbodo ọkọ, Hon Tobi Ogunlẹyẹ lo kede eyi fawọn akọroyin nilu Akurẹ, tii se olu ilu ipinlẹ Ondo.
Gbogbo àwọn tí wọ́n yí i ká ni n óo túká: gbogbo àwọn olùrànlọ́wọ́ ati àwọn ọmọ ogun rẹ̀ ni n óo sì jẹ́ kí ogun máa lé lọ.
Oríṣun àwòrán, @UNICEF_Nigeria Abamọ kii tete lọ: Nigba ti wọn kọkọ fun ọmọ mi ni ounjẹ inu agolo, o sun fun ọpọ wakati, ti mo si n roo ninu ọkan mi pe igbakuugba ti mo ba fẹ sun, maa fun ọms naa ni ounjẹ inu agolo.
O gbadura pe ki Ọlọrun fun wọn ni okun lati le gba iku rẹ mọra.
Ẹ ka itan arabinrin Abimbọla Ọlayinka, arugbo to n ṣe iṣẹ omidan nibi: https://www.
Ọjọ karun un oṣu karun un ọdun 2010 ni Aarẹ Umaru Musa Yar'Adua jade laye.
Onidajọ Oluṣẹgun Oduṣala to n gbọ ẹjọ ọhun wa sun igbẹjọ si ọjọ Aje to n bọ tii ṣe ọjọ karundinlogun osu yii.
First symptom of Coronavirus: Àwọn èèyàn kò bìkítà sí àlàkalẹ̀ ìjọba lórí àrùn Covid-19
Ninu ọrọ rẹ, Samuel ni awọn ipenija ti Naijiria yoo koju ni ati maa san owo osu ọhun, nitori ijọba Naijiria n ya owo oṣu lati san tẹlẹ fun awọn osisẹ, eleyii ti yoo tun mọ si wi pe wọn yoo tun maa ya owo sii ni.
Nigerian Recession: Ọ̀rọ̀ ajé Naijiria tó dẹnu kọlẹ̀ yóò kan gbogbo èèyàn
Iṣọla Oyenusi rèé, ẹnití ìfẹ́ obìnrin ṣun dé ìwà ìdigunjalè Taiwo Akinkunmi, ọmọ Ibadan tó ya àsìá Nàíjíríà Ayinla Ọmọwura, orin èébú àti oríyìn lo fi di ọ̀rẹ́ àwọ̀n obìnrin Ẹfunroye Tinubu - Ògbóǹtagí oníṣòwò, olówò ẹrú àti afọbajẹ Samuel Ajayi Crowther, òjíṣẹ́ Ọlọ́run tó gbé èdè Yoruba lárugẹ Oke Oriṣa ni ilu baba rẹ eyi ti ko fi bẹẹ jinna ju bi Atorin naa ṣe ri si Ileṣa lọ ti wọn si jọ wa ni ijọba ibilẹ kan naa, Atakomosa East Local Government Area.
ogun marun un to padanu emi won ati oloogbe Mohammed Bello Baba-Ari,ti o je
Yoo din sunkere-gbakere oko kuLojoru ose yii ti minisita n sayewo awon ise akanse ti ijoba apapo ni jake-jado orile ede Naijiria , lo fi da awon eniyan loju pe gbara ti atunse oju opopona naa ba ti pari ni awon eniyan yoo bere si maa lo o.
Oríṣun àwòrán, @seyiamakinse Bakan naa ni gomina Makinde kede pe, o di ọsẹ kini, Oṣu Kejila, ọdun 2020 ki oun to ṣe oku iya oun to papoda.
Ọgbẹni Brian Wheeler ti lo ọdun mọkanla nilẹ Afrika, botilẹ jẹ pe ọmọ bibi Amẹrika ni, o ni ilẹ Afrika ni oun ri gẹgẹ bi ile.
Ààrẹ Buhari kẹ́dùn pẹ̀lú ẹbí àwọn èèyàn 207 tí wọ́n pa lọ́jọ́ Àjíǹde Omotola Jalade ní Nàìjíríà dàbí ọ̀run àpáàdì lábẹ́ ìjọba Buhari Ẹlẹ́wọ̀n bí ìbejì làǹtì lànti!
Jones ni ijọba ipinlẹ naa kede igbesẹ yii lẹyin ti wọn ṣe ifọrọwerọ pẹlu awọn eniyan ti ọrọ naa kan ni ẹka eto ẹkọ.
"Mi o l'ero pe ma a fẹ oniyawo pupọ, ṣugbọn mo ba ara mi nibẹ.
Oríṣun àwòrán, Lagos Police Bakan naa ni wọn ri awọn ohun ini gba lọwọ wọn bi ẹrọ ilewọ ati awọn ohun ini miran.
Bí ìwọ ti rí mi lónìí, iṣẹ́ ni àwọn ẹranko rán mi, nítorí òní ni ọjọ́ ìpàdé wọn.
Gẹgẹ bi ohun to sọ, o ni oun ati awọn to n ta iwe iroyin wọnyi ti mọra tipẹ nitori ọdọ wọn loun ti n ra iwe iroyin lati igba ti oun ti de si Abuja.
Israẹli fẹ́ràn Josẹfu ju gbogbo àwọn ọmọ rẹ̀ yòókù lọ, nítorí pé ó ti di arúgbó kí ó tó bí i, nítorí náà ó dá ẹ̀wù aláràbarà kan fún un.
Nítorí ìdí èyí, gbogbo ẹ̀ri fí han pé ọ̀jọ̀gbọ́n Akindele jẹbi gbogbo ẹ̀sùn tí wọn fi kàn-àn, nítorí náà ni wọn se fún ní ìwé ìdádúro láti jẹ́ àríkógbọ́n fún àwọn ènìyàn bíi tirẹ̀.
Má jẹ́ kí n kú sílẹ̀ àjèjì níbi tí OLUWA kò sí.
Òṣèrébìnrin tí wọ́n bá fi ìbálòpọ̀ lọ̀ 'torí ìṣẹ́, kó bọ́ síta láti sọ̀rọ̀ - Kunle Afod Stephen Sotonwa: Gbajúgbajà oníròyìn wọlẹ̀ sùn Ìjọba yóò ti Afára Sagamu pa nítorí ìjàmbá iná- FRSC Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Akure Kidnap: E túbọ̀ ní sùúrù, a máa wá ọmọ náà rí- Alukoro ọlọ́pàá Ìwádìí fi han pé ọ̀rọ̀ wọ́n bẹ̀rẹ̀ bi ifẹ́ òtítọ ni ọdun 2016, ṣùgbọ́n ọ̀rọ̀ dojuru ni kéte ti Igboke lóyún.
”“Nigba ti alaga igbimo naa n dupe lowo olorun lati da emi Saraki si ati fun awon aseyori ti o ti se.
Idi si niyii ti mo fi ma n ya owo sọtọ lati fi ra ounjẹ ati awọn nkan mii, lati pin fun awọn ọrẹ ati ẹbi mi.
Olùdije ipò gómínà ní Ìpínlẹ̀ Ekiti, Kole Ajayi, jáde láyé
 Ó lọ sí ilé-ẹ ̀ kọ ́ olùkọ ́ ni leo mímọ ́ ti Ìjọ Àgùdà ní ìlú abẹ ́ òkúta .
Nígbà tí Jehoṣafati ati àwọn ọmọ ogun rẹ̀ lọ láti kó ìkógun, wọ́n rí ọpọlọpọ mààlúù, ati ẹrù aṣọ ati nǹkan ọ̀ṣọ́ olówó iyebíye.
Iwe abadofin naa ,ni won yoo fi ranse si ile-igbimo asofin agba lati gbe igbese lori re  , ki o si  lee di ofin leyin ti aare orile ede South Afirika ba bowo lu u.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Tunde Kelani; Èmi ò jẹ́ Baba Wande ní owó lórí fíímù Tolúwanilẹ̀ Nipa isọkan Yoruba ati ọrọ iṣelu: Sodiumu ni Yoruba ni lati pawọpọ ti wọn ba fẹ jana.
O fi kun un pe, ohun to dun mọ oun ninu julọ lasiko iwọde naa ni pe, awọn ọdọ ti ri okun ati agbara lati sọrọ soke, wọn si ti n sọrọ soke bayii.
Ẹ wo fidio naa, lati kọ ọgbọn nipa ohun ti itọ rẹ n sọ nipa ilera rẹ.
Bí gbogbo ara bá jẹ́ ojú, báwo ni yóo ti ṣe gbọ́ràn?
Ó ní “Ẹẹdẹgbaarin (7,000) eniyan ṣì kù fún mi tí wọn kò tíì wólẹ̀ bọ Baali rí.
Ninu okun, awọn nkan abẹmi naa a wu ilẹ ni dedee bi ẹya ara wọn ṣe ri bii lẹta U"" ti yoo si gun daa daa."
Auxiliary gan an lo sọrọ yii fawọn akọroyin l'Ọjọru niluu Ibadan.
Awọn mẹ́tàdínlọ́gbọ̀n lodibo lati yọ abẹnugan naa ninu awọn  ogójì (40) to wa nile Igbimọ asofin.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Logo Benz: Ìtanijí ni orin wa wà fún, Ẹ má ká wa lọ́wọ́ kò -Olamide 21 Ọ̀pẹ̀̀ 2018 Oríṣun àwòrán, Olamide/Facebook Àkọlé àwòrán, Gbajugbaja ilumọka olorin takasufe ni Olamide Igbe Olamide ati Lil Kesh lo gbẹnu awọn ọmọ Naijiria loju opo Twitter bayii.
Lasiko abẹwo ti ileeṣẹ ọlọpaa ati awọn aṣoju ijọba ipinlẹ Ọyọ ṣe si inu ile naa lọjọ Aiku, oludamọran pataki fun gomina Ṣeyi Makinde lori eto aabo, Arakunrin Fatai Owoṣeni ṣe alaye wi pe alaga ijọba ibilẹ Akinyẹle ti iṣẹlẹ naa ti ṣẹlẹ, ati awọn agbofinro to n ṣiṣẹ iwadii to fi mọ awọn agbaagba to n bẹ ni agbe naa ni gomina ipinlẹ Ọyọ ti paa laṣẹ fun lati ṣe awari ohun ti o n ṣẹlẹ ni agbegbe Akinyẹle ti ifipabanilopọ ati iṣekupani fi di tọrọfọnkale.
Awọn ọlọpaa sọ pe ọwọ tẹ Eke Kanu, lẹyin ti wọn ẹgbẹ awọn agbejọro l'obinrin (FIDA), fi ọrọ to àwọn l'eti.
“The quick brown fox jumps over the lazy dog” ni ó túmọ̀ sí ní Gẹ̀ẹ́sì.
Akanbi mi, má fọ̀ ọ́, mo wà pẹ̀lú ẹ; Ẹni tó ṣe ìgbéyàwó olórùka ló l'ọkọ- Lizzy Anjorin Báwó ni òògùn dexamethasone ṣe ń ṣiṣẹ́ lára Gbogbo orin egúngún bìkiafù tí wọ́n kọ sí mi l'étí nípa Ajayi tí mi o gbọ̀ ló bu mí lọ́wọ́- Akeredolu Wo àwọn olorì àgbà mẹ́rin tí Aláàfin ń wárí fún Wo bí ètò ìdìbò abẹ́lé APC yóò ṣe lọ ní ìpínlẹ̀ Ondo lónìí Oríṣun àwòrán, twitter/ Arakunrin rotimi akeredolu Loni ni ireti wa pe awọn aṣoju oludibo lẹgbẹ oṣelu APC nipinlẹ Ondo yoo gbe ipinnu wọn kalẹ lori ẹni gan an ti wọn fẹ ko gbe aṣia ẹgbẹ oṣelu naa ninu eto idibo sipo gomina to n bọ lọna.
Ní ogúnjọ́ oṣù kẹsan-an ni gbogbo wọn péjọ, wọn jókòó sí ìta gbangba níwájú ilé Ọlọrun.
 Ée ṣe ni wúnrẹ ̀ n tí Ẹi máa ń lò fún ìyísódì olùwà nínu gbólóhùn àkíyèsí alátẹnumọ ́ .
Nigeria) sọ ninu iroyin rẹ pe awon igbimo to n ri si eto alaafia , ti alufa Josiah
 awọn èèyan jakanjakan ni ó wá se àyẹ ́ sí rẹ ́ .
Wọ́n sì ń tún sọ wípé àwọn yóò sì padà da iṣẹ́ sílẹ̀ tí ìjọba kọ̀ bá gbé owó oṣù tuntun jáde.
Abdulrahman Abdulrasaq ti ẹgbẹ APC la Atunwa mọ lẹ ni gbogbo ijọba ibilẹ mẹrindinlogun to wa nipinlẹ naa.
Lẹyin naa lo gba ileewe girama Ikolaba Grammar School, St Luke's College, Molete ati Alugbo Comprehensive High School, Egbeda lọ, ti gbogbo rẹ ni ilu Ibadan.
“Tí ìwọ bá lè jẹun láì mu omi lóòótọ́, èmi Jin ọmọ ilẹ̀ Yiwu ní Ṣáínà ni yíò sanwó.
 Àgbẹ ̀ oníkòkó ni Àkàngbé orímóògùnjẹ ́ , bàbá dúró nígbà ayé rẹ ̀ .
fesun kan , igbimo naa ri i pe awon  ọlọpaa mẹ́tàdínlógójì ni
Bakan naa ni wọn tun kọlu ọọfisi SARS to wa ni Ajegunle, Ebute-Ero Mushin nibi ti wọn ti ṣina ibọn fun ọlọpaa meji, pẹlu Ojo ati Ajegunle nibi ti wọn ti jo ọkọ ọlọpaa meji-meji.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Salawa Abeni:Ọwọ́ ọlọ́pàá ti tẹ ẹni tó fẹ́ ba Queen Waka lórúkọjẹ́ lọ́jọ́sí 1 Ìgbé 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 31 Èbibi 2020 Oríṣun àwòrán, Nigeria Police Àkọlé àwòrán, Mó rí káàdì ìránti kan hé ní, mó kàn fẹ́ gbà owó díẹ̀ ni- Afurasí Ọlọpàá RRS sọ pé ọwọ́ tẹ ọmọkurin ẹni ọdun mọ́kàndinlógún náà tó tún jẹ akẹ́kọ̀ọ́ gboyè National Diploma ní Yaba College of Technology tí ìpinlẹ̀ Eko ní Magboro ni Ipinlẹ Ogun Afurasí náà Olufowoke Oladunjoye Emmanuel ni wọ́n lọ gbé nílé àwọn òbí rẹ lọ́jọ́bọ lẹ́yìn ọjọ́ mẹ́ta ti wọ́n ti n ṣọ́ọ kiri.
Ìtìjú ni fún obinrin láti sọ̀rọ̀ ninu ìjọ.
" Afod tẹsiwaju lati sọ pe ere mẹta lo gbe oun jade; Owo Blow, Solo Makinde, ati Pata pupa.
tí kò ní rí ilé, arakunrin ati arabinrin, ìyá ati ọmọ, ati ilẹ̀ gbà ní ọgọrun-un ìlọ́po ní ìgbà ìsinsìnyìí bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé pẹlu inúnibíni ni, yóo sì tún rí ìyè ainipẹkun ní ayé tí ń bọ̀.
Omar Robert Hamilton, olùkùu Alaa, to àwọn ète ìpolongo náà lẹ́sẹẹsẹ lóríi Twitter:
to wa si ipinle Cross River , ni Gusu orile ede Naijiria fun ti ayẹyẹ  Itighidi lati fi mo eni to ni ogbon atinuda
Bí a bá mú fóníìmù yìí lọ́kọ̀ọ̀kan.
Kọmisana feto idajọ ati agbẹjọro agba nipinlẹ Ọyọ, Ọjọgbọn Oyelọwọ Oyewọ lo fi ọwọ idaniloju yii sọya lasiko to n bawọn akọroyin jẹwọ ni ọọfisi rẹ.
Ìgbà tí mo sì la ojú tí mo wo olúwaarẹ̀ mo rí i ó di ọmọkùnrin arẹwà kan tí ó wọ aṣọ funfun tí ó sì dé fìlà funfun tí ó sì wọ ṣòkòtò funfun oẹ̀lú.
Àkàrà-oògùn ni a ó máa pe orúkọ rẹ̀, nítorí oṣó kò ní í lè jẹ ẹ́, àjẹ́ kò ní í lè rí i gbé ṣe, bẹ́ẹ̀ ni ẹlẹ́bọlóògùn kò ní í lè pa á lára.
Ati pe wọn tun ni ẹka eto ilera to duro deedee lati koju isẹlẹ pajawiri.
Wọn fi panpẹ mu Junaid Hafeez, ẹni ọgbọn ọdun le mẹta, l'oṣu Kẹta, ọdun 2013, ti wọn si fi ẹsun kan an pe o kọ awọn ọrọ arifin nipa Anọbi Muhammaed lori ẹrọ ayelujara.
Kí n tó ṣẹ́jú pẹ́, iṣan ti dé ara wọn, ẹran ti bo iṣan, awọ ara sì ti bò wọ́n, ṣugbọn kò tíì sí èémí ninu wọn.
Kí n má dàgbà ìranù, àgbà ìyà
Igbakeji agbenusọ fun Gomina Sanwo Olu, Gboyega Akosile lo fi atẹjade naa sita pé Sanwo Olu fi ara balẹ woye yan awọn orukọ naa sipo ni.
Michal Prasek ni olóńgbò nla, eyiun kiniun to ti n sin fun ọdún mẹ́sàn, bó tilẹ̀ jẹ́ pé àwọn aládugbò n ké gbàjarè lórí ọ̀rọ̀ náà tẹ́lẹ̀.
Aarẹ ana Jonathan gba pe oun fidi rẹmi ninu ibo aarẹ ọdun 2015, ki ajọ eleto idibo INEC to kede Buhari gẹgẹ bi ẹni to jawe olubori ninu ibo ọhun.
Bakanna ni ajọ naa ninu atẹjade rẹ tun kọminu lori bi awọn ọlọpaa ṣe n ko awọn to wa lẹka akanṣe iṣẹ si ẹnu iṣẹ ọlọpaa igboro laiko fi ti eto ati ilana gbogbo to yẹ ṣe?
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù South Africa: Oyún inú nínú ilé ìgbọ̀nsẹ ọkọ̀ bàálú tó fẹ rinrin àjò 22 Òkùdu 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, South Africa: Oyún inú nínú ilé ìgbọ̀nsẹ ọkọ̀ bàálú tó fẹ rinrin àjò Ó jọ bi ẹ ni pe ẹni kan to ni oyún ti kò fẹ ọmọ ti yọ oyun ọmọ náà si inú ilé ìgbẹ́ inú ọkọ òfurufú.
ede Naijiria  ,ni ipinle Cross River  awon oludije fun ipo gomina nikan jẹ.
Ṣebí ìwọ ni ọba Israẹli, àbí ìwọ kọ́?
Mo mọ̀ pé kò ní kọ̀ sí ọ lẹ́nu.
Ni olu ilu Naijiria, ni Dokpesi ti fẹhonuhan pe ko yẹ kijọba tile iṣẹ oun pa.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Say no to rape: Àwọn òṣèré tíátà Yorùbá pariwo síta lórí wàhálà ìfipábánilòpọ̀ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Say no to rape: Àwọn òṣèré tíátà Yorùbá pariwo síta lórí wàhálà ìfipábánilòpọ̀ 8 Òkùdu 2020 Lootọ iwa ifipabanilopọ ko ṣẹṣẹ maa waye, koda awọn kan tilẹ n sọ wi pe atigba iwaṣẹ lo ti n ṣẹlẹ.
Àwọn tó jí ọmọ mi gbé nílé ìjọsìn ní ń kò gbọdọ̀ wa tàbí kí ẹ̀mí mi lọ si"" Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!"
Ṣugbọn abule Zokutu ko ni ọna to dara, ko si họsibitu koda ko si itakun agbaye lati wo ori ẹrọ ayelujara fun iroyin.
Iṣẹ́ Oluwa ni èyí,Ìyanu ni ó jẹ́ ní ojú wa.
Eyii to buru ju ni bi awọn mọlẹbi atawọn ọkọ awọn obinrin naa ṣe ma n na wọn, ti wọn si maa n da kẹmika acid si wọn lara, tabi gun wọn lọbẹ.
Akọsilẹ to wa nipa awọn iru iku bayi soro lati ri nitori pe wọn kii mu iru ẹsun bayi wa si ọdọ awọn agbofinro.
Bọ̀wọ̀ fún baba ati ìyá rẹ.
Awọn ere ọmọde to wọpọ laye igba kan: Oríṣun àwòrán, Others Ere Tẹ́ntẹ́: Ti wọn ba fẹ ṣe ere yii, awọn ọmọdebinrin a kọju si ara wọn, wọn a si ma a patẹwọ, ti wọn a si maa gbe ẹsẹ wọn bakan naa si orin Tẹ́ntẹ́ ti wọn ba n kọ.
Kí ó má baà ké pe OLUWA nítorí yín, kí ó sì di ẹ̀ṣẹ̀ si yín lọ́rùn.
Ẹni to bori: Namibia Namibia Ni orilẹede Namibia, ida mẹrindinlaadọta ninu ọgọrun ni awọn obinrin ko nile aṣofin kekere rẹ.
Àwọn tí ń jẹ́rìí wọn kò ríran, bẹ́ẹ̀ ni wọn kò mọ nǹkan, ojú ìbá le tì wọ́n.
Ti mo ba kọ, yoo bẹrẹ si ni lu mi tabi fi nkan gba mi, debi wi pe ẹru maa n ba mi ti akoko ti yoo de lati ibiṣẹ ba ti n sunmọ.
O ni ijomitoro lori ọ̀rọ̀ eto aabo ilẹ Yoruba ni ipade naa da le lori ṣugbọn ko fi bẹẹ kii ṣe ohun teeyan kan le maa sọ lori ẹrọ ibara ẹni sọrọ.
naa n gbe igbesẹ yii fun ifẹ awọn ara ilu ati awọn ti o n san owo-ori
Ni ọdun 2017 ni Cyril Ramaphosadi alaga ẹgbẹ oselu ANC lasiko yii gan ni o dabi ẹni wipe edeaiyede bẹrẹ laarin oun ati ọgbẹni Zuma pẹlu bi Zuma se fẹ fi iyawo rẹ, Nkosazana Dlamini-Zuma, jẹ alaga ẹgbẹ oselu naa.
 ni 2006 ikaniyan , awọn oniwe-olugbe wà 14.
Aisha Abimbola, Omọge Campus to jẹ gbajugbaja oṣere taye n fẹ ni Naijiria naa doloogbe ni Canada lẹyin to ba arun jẹjẹrẹ faa, ko to lọ sinmi.
Ijọba ipinlẹ ọhun sọ pe ijọba ibilẹ kan lo ni ounjẹ naa nitori wọn ti pinpin gbogbo eyii to ku fun awọn ara ilu.
Nebukadinesari ní, “Lẹ́yìn ọdún meje náà, èmi, Nebukadinesari, gbé ojú sí òkè ọ̀run, iyè mi pada bọ̀ sípò.
Mudashiru Ọbasa sọ pe ijọba gbọdọ ṣe ijọba lọna ti gbogbo ara ilu yoo
Ìjọba rẹ̀ yóo máa tóbi sí i, alaafia kò sì ní lópin ní ìjọba rẹ̀ lórí ìtẹ́ Dafidi.
Bakan naa ni wọn tun fi idi rẹ mulẹ pe, lasiko ti aṣẹ yii yoo fi fidi mulẹ, ko ni si aye a n fun ẹnikẹni ni iwe aṣẹ iwọlu-gbelu ti a mọ si visa.
ṣùgbọ́n bí ìwọ kò bá mú sùúrù tó, tí ìwọ ń bá olórí-burúkú ènìyàn bínú pọ̀, òun óò kó ìwà òmùgọ̀ ràn ọ́, òun á sì mọ̀ pé òun ṣe dùn ọ́, òun á gbé ẹ̀wù ìgbéraga wọ̀ sí èjìká, bẹ́ẹ̀ ni òun kò ní ìrètí àti lọ sí iwájú mọ́ ní tirẹ̀, nígbà tí òun bá si kkó ìbànújẹ̀ bá ọ lónìí, a ṣe bẹ́ẹ̀ dí ọ lọ́wọ́ ìlọsíwájú ẹ̀hìn ọ̀la.
Ní àkókò tí ogun wà láàrin àwọn eniyan Dafidi ati àwọn eniyan Saulu, agbára Abineri bẹ̀rẹ̀ sí pọ̀ sí i láàrin àwọn tí wọ́n wà lẹ́yìn Saulu.
Oríṣun àwòrán, @mosjid Àkọlé àwòrán, Ina ti wọn kan ṣe si inu Raudah ti ẹwa rẹ kọja fifi riran lasan.
agbègbè Ìlá-Ọ ̀ ràngún ni Ọ ̀ ra-Ìgbómìnà wà .
Ẹ̀yin eniyan mi, nígbà tí mo bá ṣí ibojì yín, tí mo sì gbe yín dìde, ẹ óo mọ̀ pé èmi ni OLUWA.
Ṣé, “Kí á kúkú máa ṣe ibi kí rere lè ti ibẹ̀ jáde?
oro naa, alaga igbimo awon loba-loba ohun Ooni ile-Ife, Oba Adeyeye Enitan
O tesiwaju pe “Ti a o ba mu eto idagbasoke ba ara wa, tabi lati mu idagbasoke ba ise ti a yan laayo, akoba nla ni yoo je fun eto ijoba tiwa-n-tiwa, koda adanu nla ni yoo je fun eto idajo ati isejoba.
peginterferon àti ribavirin ni àwọn òògùn tí ó yẹ fún kòkòrò-àrùn hcv .
Eyi wa lara ohun ti o mu ki awọn eeyan Naijiria ma faraya, bi awọn ọmọ South Afrika ko ti ṣe ni ẹmi amumọra fun awọn eeyan miran.
nipinle Eko ninu eto idibo gbogbogbo-o to n lo lowo bayii.
Ìgbà tí inú tọkọtaya bá dùn ni wọ́n tóó lè gbádùn ọmọp wọn.
Ìgbà wo ni àjọ ọ́lọ́pàá yóò káwọ́ SARS?
''To ba jẹ ijọba lo yan Iyalọja, ko si nnkan ti ẹnikankan le ṣe nitori pe ijọba lalaṣẹ lori oun gbogbo'' Ijọba ipinlẹ Oyo ti pe fun alaafia ni asiko yii laarin awọn ọja Ibadan.
obe, ada abbl ti n won si n gbero lati sekolu si awon olopaa agbegbe ohun.
Ta ni ẹ lè fi Ọlọrun wé,tabi kí ni ẹ lè fi ṣe àkàwé rẹ̀?
77 Áà Ọlọ́run, Bàbá Ayérayé, àwa béèrè lọ́dọ̀ rẹ ní orúkọ Ọmọ rẹ, Jésù Krístì, láti súre àti lati yà àkàrà yìí sí mímọ́ sí ẹ̀mí gbogbo àwọn ẹnití ó ní ìpín nínú rẹ̀, kí wọ́n lè jẹ ní ìrántí ti ara Ọmọ rẹ, àti kí wọ́n jẹ́rìí sí ọ, Áà Ọlọ́run, Bàbá Ayérayé, pé wọ́n fẹ́ láti gba orúkọ Ọmọ rẹ sí órí wọn, àti láti rántí rẹ̀ nígbàgbogbo àti láti pa àwọn òfin rẹ̀ mọ́ èyítí ó ti fi fún wọn; pé kí wọn lè ní Ẹ̀mí rẹ̀ láti wà pẹ̀lú wọn nígbàgbogbo.
Ile-ise oro abele lorile-ede naa so pe, nigba kan ti Abol Fotouh n se ipade idakonko pelu awon adari egbe Muslim Brotherhood lasiko ti o wa nilu London, ni iyanju ati gbimo po da howu-howu sile  lorile-ede ohun, ni eyi ti o se esun naa.
Kò ní lè tẹ́ ọkàn wọn lọ́rùn, bẹ́ẹ̀ ni wọn kò ní lè jẹ ẹ́ yó.
Adajọ ni iku ki wọn ye igi fun ni Babatunde yoo ku, nitori wipe o pẹlu awọn adigunjale mẹrin kan ti wọn tun gba foonu alagbeka oniyebiye lọwọ awọn eniyan.
Aare bọ silẹ ninu oko ofurufu
Ó ní èmi Isikiẹli óo jẹ́ àmì fun yín, gbogbo bí mo bá ti ṣe ni ẹ̀yin náà gbọdọ̀ ṣe nígbà tí ọ̀rọ̀ yìí bá ṣẹlẹ̀.
Eyi waye lẹyin ti awọn ọdọ Naijiria tu sigboro lati ja fun ki ijọba fi opin si iṣẹ awọn ikọ SARS ati iwa aidaa ti awọn ọlọpaa n hu si awọn araalu.
Níti dáadáa pẹlu ìṣe ọpọlọ tó múyán lórí tó gbé ṣe
Oríṣun àwòrán, @VoiceofOndo Lọwọ lọwọ bayii, iwọde naa si n tẹ siwaju nilu Eko, tawọn oluwọde si ti di awọn opopona nlanla to wa nilu naa.
Ki ni apapọ iṣiro ọṣẹ arun coronavirus ni Chicago?
Nkan bí ẹgbẹ̀rún méjì ọdún ṣẹ́hìn ni wọ́n tẹ ìlú náà dó sí etí odò Avon.
Awọn nnkan marun miran ti ẹ ko mọ nipa Sowore -O ti sa ere ọlọgbọnrangandan (Marathon) mẹjọ lẹnu igba ti o daye -Sowore gbagbo wi pe ẹtọ gbogbo obinrin ni ki wọn di ipo oselu mu.
Lati igba naa titi di asiko yii, iye awọn to ku ni ilẹ Gẹẹsi ti le lẹbẹrun mejila.
yóo da omi mímọ́ sinu àwo kan, yóo bù lára erùpẹ̀ ilẹ̀ Àgọ́ Àjọ sinu omi náà.
Lórí ìpè àwọn ènìyàn pé kí ààrẹ Buhari yọ àwọn ọgagun elétò ààbò nípò, Obasanjo ni òun kọ́ ni òun yàn wọ́n sípò, nítorí náà, òun kò le pè fún ìyọ̀ nípò wọ́n.
Ó bá mú un bọ́ sí apá kan, kúrò láàrin àwọn ọ̀pọ̀ eniyan, ó ti ìka rẹ̀ bọ ọkunrin náà létí, ó tutọ́, ó fi kan ahọ́n rẹ̀.
O ni kii ṣe iriri to rọrun fun oun lati ma a tọju iyawo to wa nileewosan, ati awọn ọmọ meji to wa nile, ti oun naa si gbọdọ lọ si ibi'ṣẹ oun.
OLUWA sọ fún Aaroni pé, “Mo ti fún ọ ní gbogbo ohun tí ó kù ninu àwọn ohun tí wọ́n bá fi rúbọ sí mi, ati gbogbo ohun tí àwọn ọmọ Israẹli bá yà sọ́tọ̀.
Lẹ́yìn ìgbà díẹ̀, mo gba ààyè lọ́wọ́ ọba, 
Oloyede ni kaakiri agbaye ni awọn ọmọbinrin ẹlẹsin musulumi ti n lo ibori Hijab sinu imura wọn, ati pe, ọgbọn ati fi ẹtọ ẹkọ dun awọn ọmọbinrin to jẹ ẹlẹsin musulumi ni ileewe naa.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Zlatan: Ọ̀rẹ́ ni mo sìn lọ ‘studio’ tí mo fi bẹ̀rẹ̀ orin lẹ́yìn tí mo kùnà ìdánwò WAEC Abdulwasiu Dada wa se adura fun alaanu wọn, to fun awọn ọmọ rẹ mejeeji ni ẹbun ẹkọ ọfẹ naa pe Ọlọrun yoo tubọ maa mu ọwọ rẹ lọ siwaju.
Amọ apa rẹ ati ọgbẹ rẹ ko lee laye laye kuro lọkan awọn eeyan kọọkan.
Nígbà tí wolii kan bá jíṣẹ́ ní orúkọ OLUWA, bí ohun tí ó sọ pé yóo ṣẹlẹ̀ kò bá ṣẹlẹ̀, a jẹ́ pé kì í ṣe OLUWA ni ó rán an; wolii náà ń dá iṣẹ́ ara rẹ̀ jẹ́ ni, ẹ má bẹ̀rù rẹ̀.
Àgùntàn kò yó Òjòlá-ìbínú lẹ́ẹ̀kan ṣoṣo, a máa jẹ tó odidi mààlúù méjì bíó bá ń fẹ́ẹ́ jẹun.
Bẹẹ ni ọ̀rọ̀ rí pẹ̀lú àwọn àgbà ọjẹ òṣèré tíátà kan nílẹ̀ Yorùbá, tí wọ́n fi iṣẹ oojọ tí wọn yan láàyò lé ọmọ bibi wọn lọ́wọ́ láti jogún rẹ.
Amọṣa, fun awọn ti ko ba tii fi orukọ silẹ rara, gbedeke ọjọ kẹsan oṣu keji ọdun 2021 ni wọn fun wọn.
Mo rí i tí àwọn ẹrú ń gun ẹṣin, nígbà tí àwọn ọmọ-aládé ń fẹsẹ̀ rìn bí ẹrú.
Koda, awọn ọkọ miran to n lọ gbiyanju lati ran wa lọwọ.
Nigba ti igbakeji aare n sọrọ lori akori to pe ni ‘ Odun mefa  orile ede lati ipele kan si ipele miiran:Orile
ti fohun sọkan lati fowosowopo pelu ile- ise olopaa orile ede Najiria lati
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Báyìí ni ayẹyẹ wíwé láwàní fún ọmọ China, olóyè Zhang ṣe lọ Haruna ni awọn ti sọ Idris si gbaga ati pe ẹsun rẹ pọ bẹrẹ lati ibi ti Idris ti ri ibọn to yin atawọn ẹsun miran.
Ìfẹ́ kì í ṣe ohun tí kò tọ́, bẹ́ẹ̀ ni kì í hùwà ìmọ-tara-ẹni-nìkan.
e wo ohun ti aare Buhari ti se .
com Àkọlé àwòrán, Aworan ere Ọjọgbọn Awojobi Lati kekere ni Ayodele Awojobi ti fakọyọ ninu Eko rẹ ti ko si ye gbegbaoroke ninu gbogbo idanwo ti o ba ṣe.
 nínú gbogbo ìgbòkè-gbodò iṣẹ ́ rè yí náà ni dúró ládípọ ̀ ti kọ ìtàn yorùbá mẹ ́ wàá tí ó kún fún orin , ìlù , ijó , òwe , ìsínjẹ àti àwọn orin ìwúrí lọ ́ kan ò jọ ̀ kan .
Mo ba beere pe ṣe ati isin ori ayelujara?
N óo tún wá ọtí mìíràn mu.
Bí mo ti ń jókòó ní ó bẹ̀ mí pé ki n fún òun ní omi mu, mo bá dìde mo bu omi fún un.
Aaroni ati àwọn ọmọ rẹ̀ sì ṣe gbogbo ohun tí OLUWA pa láṣẹ láti ẹnu Mose.
Ọkan lara wọn, Fola sọ pe oun dagba ba ipa aisan naa ninu ayeoun ni.
Ìwọ fi ọwọ́ kan ara ati eegun rẹ̀ wò, bí kò bá ní sọ̀rọ̀ àfojúdi sí ọ lójú ara rẹ.
ọmọwe Briyai ni ajo naa ti bẹrẹ si maa pin awon ohun elo ati irinse ti awon
Gẹgẹ bi Adeniran ṣe sọ, awọn eeyan mẹjọ to n ta ọjọ lọna aitọ ninu ọgba ile ẹkọ ijọba ni yoo fi oju ba ile ẹjọ ti wọn yoo si jẹjọ nilana ofin.
Ẹ jẹ́ kí á máa fẹ́ ọmọ lọ́wọ́ wọn, kí àwọn náà sì máa fẹ́ ọmọ lọ́wọ́ wa.
Ni tiwa, a ti de opin akanse ikọlu yi, eyiti ise lile awọn adunkoko mọni kuro ninu igbo Sambisa.
ninu ikọlu si awọn ajoji naa, pẹlu awọn ti wọn padanu nnkan ini wọn ninu
ni won gbe asofin Adeleke lo sile ẹjọ lodun 2018,
“Bí o bá yá ẹnikẹ́ni lówó ninu àwọn eniyan mi, tí wọ́n wà lọ́dọ̀ rẹ, tí ó ṣe aláìní, má ṣe bí àwọn tí wọn ń fi owó wọn gba èlé, má gba èlé lórí owó tí o yá a.
Amọ ẹnikan ti isẹlẹ naa soju rẹ ni owo to to miliọnu marun naira lo wa ninu apo naa, ti ọkunrin ọhun to jẹ olokoowo gbe lọwọ.
julo, abileko Ajibola fi asiko ohun beere fun iranlowo ile ise yii lasiko ti
Alágbára ńlá tó dá àwa ọmọ ènìyàn sórí ilẹ̀ pẹ̀pẹ̀ àgbáyé.
Àwọn ọmọ eniyan a máa sá sí abẹ́ òjìji ìyẹ́ apá rẹ.
A sì tún fi àǹfààní sílẹ̀ láti mọ ara wa ju báyìí lọ.
Bi o ba rii bẹẹ, elo gan an ni iye rẹ lorilẹede Naijiria?
O ṣe ìlérí fún un nítòótọ́, o sì mú un ṣẹ lónìí.
Adamu jẹ onkọwe to ti kọ ọpọlọpọ nkan nipa bi o ṣe n lọ l'orilẹ-ede Naijiria.
Igbe aye ati ohun manigbagbe ti Sani Abacha ṣe: Ogunjọ oṣu kẹsan-an ọdun 1943 ni Sani Abacha dele aye nipinlẹ Borno, to si jẹ ẹya Kanuri amọ ilu Kano lo ti dagba, to si lọ sile ẹkọ nibẹ.
Sibẹsibẹ OLUWA kò pa ìdílé Dafidi run nítorí majẹmu tí ó ti bá Dafidi dá, ati ìlérí tí ó ti ṣe pé ọmọ rẹ̀ ni yóo máa wà lórí oyè títí lae.
Ìjọba South Africa pèpàdé lórí ìkórìíra àlejò Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Ẹni tí ó wà nínú ayé tí kò ní òye ó dábì ẹranko tí ó ṣègbé.
Pilatu bá fa Jesu fún wọn láti kàn mọ́ agbelebu.
 Eyi ti je ki oja adin-agbon maa ta daadaa fun enikeni to ba mo nipa sise e re.
Lai si ani ani o darukọ ọgọta ọjọ gẹgẹ bi gbedeke ti oun da lati mu opin ba sunkẹrẹ fakẹrẹ Apapa Ẹ wo fidio naa nibi Ẹlẹkeji fidio ti a ri gẹgẹ bi ẹri pe o sọrọ yi naa ko fẹ yatọ si akọkọ nipa oun to ṣeleri lati ṣe .
Ni ipari o gboriyin fun fun awon agbaboolu Naijiria fun gbigba ami ife eye idije awon agbaboolu oje wewe tojo ori won ko ju odun metadinlogun lo leemarun un bere lati akoko re ni orile ede China lodun 1985.
Rọ òjò ibinu rẹ lé wọn lórí,kí o sì jẹ́ kí wọ́n rí gbígbóná ibinu rẹ.
Wọn ni awọn ti n fura sii ti pe pe o n ṣe awọn 'ọmọ Yahoo'ti wọn n gba awọn eeyan lori ayelujara.
Ọlọrun tí ó dá ayé ati gbogbo nǹkan tí ó wà ninu rẹ̀, Oluwa ọ̀run ati ayé, kì í gbé ilé oriṣa àfọwọ́kọ́; 
Oriṣiriṣi awọn gbajumọ ni Naijiria ati lawọn orilẹ-ede miran lagbaye lo ti n ṣegbe lẹyin iwọde ọhun.
“Nítorí náà ẹ gbọ́ tèmi, ẹ̀yin olóye,Ọlọrun kì í ṣe ibi,Olodumare kì í ṣe ohun tí kò tọ́.
Ariwo náà yóo kàn dé òpin ayé,nítorí pé OLUWA ní ẹjọ́ láti bá àwọn orílẹ̀-èdè rò.
 Bakan naa ni eyi obinrin ni, Priscilla Ajọkẹ Ojo sọ loju opo Instagram rẹ, its priscy pe Ẹyin eeyan, ẹ wo baba mi, a ko fi oju ri ara wa fun ọdun mẹfa, amọ inu mi dun lati jade pẹlu rẹ loni, lati dara pọ di ẹbi kan soso.
Agbenuso Ahmad Al-Mismari so nibi ipade awon oniroyin ti o waye ni apa ila-orun ilu Benghazi pe, “orile-ede Turkey n satileyin fun awon olote lorile-ede wa, koda ki awon ologun to bere igbogun awon olote naa lati bi odun meta seyin”.
Adari igbimọ to n ṣakoso ile iwosan naa, Ọjọgbọn Wasiu Adeyemo sọ fun BBC pe, ofin wa nilẹ ni LUTH, eyii ti ko fi aaye gba ẹbi awọn alaisan lati sun pẹlu ẹbi wọn ninu ile iwosan ọhun.
Pásítọ̀ gún ìyàwó rẹ̀ lọ́bẹ nínú ṣọ́ọ̀ṣì, ló bá tì í bọ ara rẹ̀ náà níkùn Soleimani ń gbìmọ̀ràn láti kọ lù wá l'Amerika la ṣe kọ́kọ́ yára mú u balẹ̀ - Trump 'Ipò àpọ́nlé ni mo fi Gómìnà Abdulrahman sí ṣugbọn kò hùwa àpọ́nlé' Ó ṣeésẹ kí ọkùnrin tó n mu àmujù ọtí ó maa lo ìwà ipá pẹ̀lú ìyàwó rẹ̀ Irọ́ ni pé àwọn ọ̀gá ọkùnrin ń béèrè fún ìbálòpọ̀ lọ́wọ́ àwọn òṣèrébìnrin- Jaiye Kuti 4.
Awọn eekan meji ni ariwo pọ lori iyansipo wọn.
Wọn ni o le fa arun iba ọrẹrẹ, Lassa Fever.
OLUWA ní: “Mo ti gbọ́ ọ̀rọ̀ àbùkù tí àwọn ará Moabu ń sọ ati bí àwọn ará Amoni tí ń fọ́nnu, bí wọn tí ń fi àwọn eniyan mi ṣe yẹ̀yẹ́, tí wọ́n sì ń lérí pé àwọn yóo gba ilẹ̀ wọn.
Loun naa ba fi adura ranṣ si Oloye Reuben Fasoranti ati ẹbi ati gbogobo ẹgbẹ Afenifere.
Ẹ̀yin ọkọ, ẹ fẹ́ràn àwọn aya yín, gẹ́gẹ́ bí Kristi ti fẹ́ràn ìjọ, tí ó sì fi ara rẹ̀ fún un.
Oṣù meje ni yóo gba àwọn ọmọ Israẹli láti sin òkú wọn, kí wọ́n baà lè fọ ilẹ̀ náà mọ́.
Wọn fi asiko yii sọ fun awọn olukọ ati akẹẹko lati lo asiko naa lati fi sisẹ ati kọ awọn ẹkọ ti o yẹ ki wọn ti kọ lati ọjọ melo sẹyin.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Shiite: Èmi kò ní kí Shiite má ṣe ẹ̀sìn wọn o -Muhammadu Buhari 28 Agẹmo 2019 Oríṣun àwòrán, others Àkọlé àwòrán, Emi ko ni ki ẹ dẹkun ẹsin Shiite o - Buhari Aarẹ Muhammadu Buhari ti kedé pé oun ko ni ki ẹlẹsin Shiite ma sin ẹsin to wu wọn.
Èèyàn 930 míràn tún lùgbàdì àrùn Covid-19 ní Naijiria Eniyan ẹẹdẹgbẹrun o le ọgbọn lo tun ṣẹṣẹ lugbadi aarun Covid-19 ni Naijiria.
Jesu sọ fún un pé, “Ọkunrin kan se àsè ńlá kan; ó pe ọ̀pọ̀ eniyan sibẹ.
 ní ilẹ ̀ amẹ ́ ríkà , a gbani nímọ ̀ ràn láti fún àwọn tó wà lábẹ ́ ewu nlá níkan , bíi àwọn arìnrìnàjò lọ sí àwọn agbègbè ibi tí àrùn náà ti wọ ́ pọ ̀ , ní àjẹsára náà .
"Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Odumakin sọrọ lori Fulani darandaran Ijọba Mali ti gbogun ti awọn ẹgbẹ ""Dan Na Ambassagou' lẹyin ikọlu Ogossagou."
Ẹ máa banújẹ́ dípò yíyọ̀ tí ẹ̀ ń yọ̀.
Bayii ni a n ṣe nile wa, eewọ ibo mii ni ọrọ aṣa jẹ kaakiri agbaye.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Urine Colour: Fídíò Lahanmi yìí ló ń ṣàlàyé nípa ọ̀pọ̀ àìsàǹ tó rọ̀ mọ́ bí ìtọ̀ wa ṣe rí Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Urine Colour: Fídíò Lahanmi yìí ló ń ṣàlàyé nípa ọ̀pọ̀ àìsàǹ tó rọ̀ mọ́ bí ìtọ̀ wa ṣe rí 10 Agẹmo 2020 Ọpọ aisan ni kii tete fi oju han ninu agọ ara titi ti yoo fi se ipalara.
Lizzy ni igbe aye alariwo lo n mu owo wọle fun oun, nitori naa, oun ko fẹ lati gbe igbe aye to tutu rọrọ rara.
Ìwọ́de #RevolutionNow forí ṣánpọ́n ní Ibadan, àgbófinró gbàkóso ojú pópó 'Ohun tó ṣẹlẹ̀ sí Ezekwesili kò le ṣẹlẹ̀ sí mi' #BBCNigeria2019 Ìjọba pàṣán ni ìjọba Buhari yóò jẹ́ fún Nàìjíríà ní sáà kejì- Ṣoworẹ Sowore: olùdíje Ààrẹ tó fẹ gbà Nàìjíríà padà fún àwọn ọdọ Ó tó gẹ́ẹ́!
BBC Yoruba tiraka lati gbọ tẹnu osisẹ alarina fun ileesẹ ọlọpa nipinlẹ Ondo, Femi Joseph, ko lee fidi isẹlẹ naa mulẹ, amọ ko tii gbe ipe wa lori aago.
Ṣaaju ni oludije sipo aarẹ ninu ẹgbẹ oṣelu Democrat, Joe Biden ti sọ pe ẹgbẹ Republican ti n ṣafihan ijakulẹ ninu idibo naa to n bọ laipẹ.
O ni oun yoo gbajumọ eto aabo awọn eniyan oun ni saa keji ti o ṣẹṣẹ ṣe ibura rẹ yii.
O fi kun un pe bi wọn ba tilẹ kọ awọn ọdọ ologun niṣẹ, awọn to kawe ni ki wọn gba.
 O woye pe awon ilu kan jasi ekun merin ni Naijiria bii guusu-guusu si guusu ila oorun si aarin gbungbun ariwa si ila oorun ariwa.
 nígbà tí bàbá wọn kú .
Ko fẹẹ si ọba kankan laye Tinubu, ti yoo kọ iyan akọni obinrin naa, ti ko ni fi ewe boo, nitori pe alagbara ni, to si n fi ọba jẹ, bẹẹ lo n rọ ọba loye.
Awọn araalu bẹrẹ si ni jo taya ọkọ ti wọn ni awọn agbegbe to wa ni ẹnu ibode ipinlẹ Eko ati Ogun, ti wọn si da awọn ẹgbẹ vigilante keekeeke silẹ lati le da aabo bo ara wọn ti awọn adigunjale ba de.
“A mo nipa itankale Ebola to ti bere ni Congo DRC bayii.
àwọn tí wọ́n ti fi ẹ̀mí wọn lélẹ̀ nítorí orúkọ Oluwa wa Jesu Kristi.
Ki ni abadofin lori omi fun ọdun 2020?
Gomina ipinlẹ Ọyọ, Seyi Makinde ti fi ipinnu rẹ han lati da ajọ silẹ ti yoo ma a gbogun ti iwa ibajẹ ni ipinlẹ naa.
Ẹni to bori: Angola Algeria vs Zimbabwe.
Oríṣun àwòrán, Facebook/NLC Àkọlé àwòrán, NUPENG ti ìyanṣẹ́lódì NLC lẹ́yìn Ẹ̀wẹ̀, ẹgbẹ́ oṣiṣẹ lapapọ lorilẹede Naijiria ti fi aake kọri wọn ni dandan laa, awọn yoo gun le iyanṣẹlodi miran lọjọ Iṣẹgun ti i ṣe ọjọ kẹfa oṣu kọkanla ti ijọba ba kọ lati maa san ọgbọn ẹgbẹrun naira gẹgẹ owo oṣu oṣiṣẹ to kere julọ.
Lẹ́yìn náà, Solomoni ọba ati gbogbo àwọn eniyan rú ẹbọ sí OLUWA.
"Ìjọba Eko pàdánù ₦234m láàrín ọ̀sẹ̀ kan torí ìwọ́de End SARS ""Buhari, ìwọ́de yóò yíwọ́, tó ba jẹ́ ki ológun bẹ̀rẹ̀ ‘Operation Crocodile Smile’ "" Bí o bá fẹ́ darapọ̀ mọ́ ikọ̀ ọlọ́pàá SWAT tí yóò rọ́pò SARS, wo àmúyẹ tí o gbọ́dọ̀ ní Blind Couples: Pẹ̀lú ìpèníjà ojú, tọkọtaya bímọ mẹ́ta, tí wọn sì tún ń ṣiṣẹ́ olùkọ́ O fikun wi pe ki awọn afẹhọnuhan murasilẹ lati koju ijọba lori igbesẹ ti wọn gunle."
Oríṣun àwòrán, Getty Images Awọn ami ẹyẹ miran ti wọn kede ni iwọnyii: Aṣọle to pegede julọ lagbaye- 1.
Otunba Akala sọrọ yii lori eto kan to waye ni ileeṣẹ redio kan niluu Ibadan lọjọ Abamẹta, ọjọ kọkandinlọgbọn oṣu kẹjọ ọdun 2020 yii.
Koda, ilu Akure, Osogbo ati Ado Ekiti ni rogbodiyan ti fọnna soju, tawọn gomina lawọn ipinlẹ yii si kede pe kawọn ile ẹkọ wa ni titipa.
Ikọ agbabọọlu Naijiria, Super Eagles, ti fi agba han ikọ Benin Republic ninu ifẹsẹwọnsẹ ipegede fun idije ifẹsẹwọnsẹ ilẹ Afirika.
Babangida tun lo anfani naa lati kepe awọn aṣofin gbọdọ ṣiṣẹ takuntakun lati rii wi pe orilẹede Naijiria wa ni iṣọkan.
Èmi fúnra mi ni n óo ba yín jà.
Ní ti àwọn ère oriṣa rẹ, bí o bá bá a lọ́wọ́ ẹnikẹ́ni, pípa ni a óo pa olúwarẹ̀.
Ninu wọn la ti ri Naeem Rasheed, to jẹ ọmọ orileede Pakistan to padanu ẹmi rẹ .
Amọ, o sọ pe oun le pada bayii nitori ilẹ Gẹẹsi ni ẹgbẹ agbabọọlu Manchester United ti oun n ṣoju wa.
Atejade ohun tun so pe, ile-ifowopamo agba kowe si awon ile-ifowopamo gbogbo ninu osu kinni odun 2017, lori eto idokowo oja owo takada lorile-ede Nigeria.
 Osagie Ehanire – Edo, Minisita fun eto ilera.
Hesekaya ní igbagbọ ninu OLUWA Ọlọrun Israẹli.
O ni iye owo ti sẹnetọ kọọkan n na ti pọju loju toun ati pe o yẹ kijọba din wọn ku si ẹyọ kan lati ipinlẹ kọọkan dipo mẹta yii.
Awọn ọlọpaa fidi ọrọ naa mul wi pe awọn obi rẹ ko fi owo si ibaṣepo rẹ pẹlu ọrẹkunrin rẹ ohun.
fopin si oogun oloro Sniper ti awon eniyan n 
APC ati  Useni ti egbe  PDP jẹ 48,769 .
olu- Ilu ile wa FCT, ipinle Nasarawa ati Plateau je ipin keji, Ipinle Kano,
" Wọn yii ni diẹ lara ọrọ ti ogbontarigi osere fiimu ẹṣin Kristẹni, to tun jẹ Oludasilẹ ileesẹ Mount Zion Ministries, Mike Bamiloye, sọ lati fi mọ riri iyawo rẹ, Gloria Olusola Bamiloye, ni ayajọ ọdun kejilelọgbọn ti wọn ṣe igbeyawo.
   Aare pase ohun lasiko to n se
Ìwọ óo dìde, o óo sì ṣàánú Sioni,nítorí ó tó àkókò láti fi ojú àánú wò ó.
Wo àwọn ìgbẹ́sẹ̀ mẹ́wàá tí o nílò láti wò èsì ìdìbò Edo, Ondo bí wọ́n ṣe ń kàá Ajọ eleto idibo lorilẹede Naijiria, INEC ti gbe ara tuntun yọ bayii lori eto idibo ati wiwo esi idibo lorilẹede Naijiria pẹlu ikede agbekalẹ oju opo ayelujara kan eyi to pe ni IreV, ti yoo wa fun ikede esi ibo.
Aare Buhari yoo tun lo anfaani ohun lati kedun pelu ijọba ipinle naa ati awon olugbe ipinle ohun lataari ijamba omiyale, agbara ya soobu ti o gbemi awon eniyan, ti o si tun ba ohun ini awon ara ilu je lopolopo.
Ẹni tí ó bá ń hùwà rere, kí ó máa hùwà rere rẹ̀ bọ̀.
Adé ògo ni ewú orí,nípa ìgbé ayé òdodo ni a fi lè ní i.
APC primary: Nkan kò tìí ṣẹnu ire fún àná Gómìnà Rochas ní Imo Ọkọ ọmọ Rochas Okorocha to jẹ gomina ipinlẹ Imo, Uche Nwosu, ti padanu ni wọọdu kan ninu idibo abẹlẹ APC fun oludije si ipo gomina.
Ẹni-ìyìn ni OLUWA Ọlọrun Israẹli,ẹni tí ó ń ṣe iṣẹ́ ìyanu tí ẹlòmíràn kò lè ṣe.
 Ẹ jẹ ́ kí á wo ìlé kíkọ ́ àwọn ohun èlò ìgbàlódé ti wà tí a le fi kọ ́ ilé alájàmẹ ́ ẹ ̀ dọ ́ gbọ ̀ n tàbí ju bẹ ́ ẹ ̀ lọ .
Kenneth Omeruo (CD Leganes, Spain); Jamilu Collins (SC Padeborn 07, Germany);
Ni bayii, ọjọ marun un pere ni awọn ẹgbẹ fẹ fi kilọ fun ijọba lati mu adehun ṣẹ.
Kí ń ṣe ilé mi kí ó mọ́ tóní tóní, kí ohun gbogbo wà ní ètò, ki n sì ṣe iṣẹ́ tí ó bá kàn mi gẹ́gẹ́ bí ìyàwó, ki n tó lè ṣe ti ara mi.
” Bí ó sì ti kúrò lóòótọ́, kinniun kan yọ sí i, ó sì pa á.
Ní ọjọ́ kan, Akisa lọ bá baba rẹ̀, bí ó ti ń sọ̀kalẹ̀ lórí kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ ni baba rẹ̀ bi í pé, “Kí lo fẹ́?
Ní ọjọ́ náà, n óo pa àwọn ẹṣin yín run, n óo sì run gbogbo kẹ̀kẹ́ ogun yín.
Ilana isede tìrẹ naa ko yatọ si ti ipinlẹ Eko.
 Òsilẹ ̀ ni ọba wọn .
Aṣaájú olùwọ́de EndSARS 50 dèrò iléẹ́jọ́ lórí ìfẹ̀hónúhàn àti ìdàlúrú Ìṣúná 2021 yóò ṣíjú ọ̀dọ́ kúrò nínú ìwá Yahoo-Yahoo - Sanwo-Olu Agbẹjọ́rò wọ́ ìjọba lọ sílé ẹjọ́ pé kó yọ kéú kúrò lára owó Náírà Àwọn orílẹ̀-èdè kan tún ti kéde kó nílé-ó-gbélé nítorí coronavirus Fidio asọtẹlẹ naa ti wa lori ayelujara ṣaaju ibo aarẹ Amẹrika, amọ awọn eeyan bẹrẹ si ni sọ nipa rẹ lẹyin ti Trump fidi rẹmi tan.
Koda Joshua sọ pe oun ko ni dunnu ti oun ba jawe olubori ninu ija ọjọ Abamẹta.
Nígbà tí ó bá di ọjọ́ kẹjọ, kí ó mú àdàbà meji, tabi ọmọ ẹyẹlé meji tọ alufaa lọ ní ẹnu ọ̀nà Àgọ́ Àjọ.
Oríṣun àwòrán, others Àwọn Dókítà fárígá ní ìpínlẹ̀ Ondo, wọ́n ní kí Gómìnà san owó oṣù mẹ́ta tó jẹ wọ́n!
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Aregbesola: Ó se bẹbẹ ní ọdún mẹ́jọ tó fi sèjọba l‘Ọ́sun 27 Bélú 2018 Oríṣun àwòrán, @raufaregbesola Ariṣe la ri ka, arika si ni baba iregun, Yoruba ni ohun taa ba se loni, ọrọ itan ni yoo da bo dọla.
Mo wí lọ́kàn ara mi pé, “Mo ti kọ́ ọpọlọpọ ọgbọ́n, ju gbogbo àwọn tí wọ́n ti jọba ní Jerusalẹmu ṣáájú mi lọ.
Ẹ̀gbọ́n ìyàwó mi náà yí padà pẹ̀lú, nítorí ojú òun náà tutù bí ọ̀jẹ̀lẹ́ ewé òroǹbó, ara rẹ̀ si mọ́ bí ara ọmọ tí a bí ní ìjẹta, nítorí gbogbo wa ni a jẹ óunjẹ tí ó gbádùn, a jẹ ọbẹ̀ tí ó níláárí, a jẹ apá ẹran, a jẹ itan ẹran, a jẹ ẹ̀dọ̀, a jẹ iwe, a sì jẹ gògòńgò ọ̀nà ọ̀fun.
Wọn fi ẹsun ijọba ẹni ti ko fẹ gbe agbara silẹ kan an nigba to fẹ gbe igba saa kẹta.
Nkan ti o se pàtàkì jù lọ ní pe ki aboyún sá gbogbo ipá rẹ̀ láti dènà níní ààrùn Coronavirus, àmọ́ óò, tí ó bá lóyún tàbí ó ṣẹ̀ṣẹ̀ bímọ, ó ṣe pàtàkì láti àwọn elétò ìlera kí ó sì tẹ̀lé ìlànà tí wọ́n bá ní kí ó tọ̀ Mo ń ròó láti bímọ sí ilé ìwòsàn, ṣe ìpinnu tó tọ̀nà ni?
Arsenal: Cazorla jẹ́ agbábọ́ọ̀lù tí irú rẹ̀ ṣ'ọ̀wọ́n
O sọ ọ siwaju sii pe kii ṣe igba akọkọ niyi ti orilẹede Naijiria yoo maa gba awọn ajagunta fi koju wahala Boko Haram.
Gomina ipinlẹ Kaduna naa wa rọ awọn ara ilu lati se jẹjẹ lasiko yii, ki wọn si ta ijọba lolobo, ti wọn ba mọ awọn to sisẹ ibi naa.
Àwọn òdòdó ti hù jáde,àkókò orin kíkọ ti tó,a sì ti ń gbọ́ ohùn àwọn àdàbà ní ilẹ̀ wa.
Wọn ko gun un ni abẹ́rẹ́ ri tabi ki awọn onimọ iṣegun oyinbo ṣe ayẹwo fun un ri.
Pẹ̀lú ayọ̀ ni àwa náà fi padà bọ̀, nítorí ṣe ni gbogbo ibẹ̀ ń rùn ṣùù, kò sí nǹkan kan tí ènìyàn rí tí ó bá ni lójú mu, kò sí orin kikọ, kò sí ẹ̀rín rírín, kò sí kí ènìyàn bá ẹnìkejì ṣiré, ìbànújẹ́ kún ibẹ̀ dé ẹnu.
Dokita Adan ni awọn ni awọn olutọju alaisan atawọn oṣiṣẹ eleto ilera ti wọn jọ n ṣiṣẹ papọ fun ilera awọn eniyan Somalia.
Minisita to n mojuto oro imo ero ati sayensi lorile-ede Naijiria, dokita Ogbonnya Onu ti ro awon olokoowo jankan-jankan lagbaye, papaa julo nile Canada lati se amulo opo yanturu torile-ede Naijiria je da ile-ise sile.
Kin lo faa ti Daddy Freeze fi n tako idamẹwa?
Se eyi wa lee jẹ ootọ bi lati ọdọ ileesẹ agba ọjẹ agbohunsafẹfẹ bii ti BBC?
Wọ́n ti fi ẹ̀sùn ghost worker"" kan ọmọ olórí òṣìṣẹ́ ìjọba ìpínlè Oyo Oríṣun àwòrán, Makinde Àkọlé àwòrán, Oyo LGA Chairmen: Malami, IGP àti alága APC ni yóò káwọ pọ̀'yìn rojọ l'Oyo Wọn ti fẹsun kan ọmọ olori oṣiṣẹ ìjọba ìpínlè Oyo pé o gbiyanju lati lo ipo iya rẹ lati gba ""ghost worker"" siṣẹ."
tabi kí o bi àwọn koríko, wọn yóo sì kọ́ ọ,àwọn ẹja inú òkun yóo sì ṣe àlàyé fún ọ.
"O ni ""ihalẹmọ lasan ni ero pe ijọba yoo doju bolẹ ti wọn ba ti ji ọpa aṣẹ gbe lọ."
Wọ́n bá dá òrùlé lu kí wọ́n fi lè gbé arọ náà pẹlu ibùsùn rẹ̀ sí ààrin àwọn eniyan níwájú Jesu.
Olódodo ní ojú àánú, a sì máa yáni ní nǹkan,ayọ̀ ń bẹ fún àwọn ọmọ rẹ̀.
Ó ní, “Ìwọ ọmọ eniyan, kọjú rẹ sí Farao ọba Ijipti, kí o sì sọ àsọtẹ́lẹ̀ nípa òun ati gbogbo àwọn ará Ijipti pé, 
Ẹwẹ, ẹni a fẹsun kan naa ni oun ko jẹbi ẹsun ohun ti wọ́n fi kan oun tan.
Gẹgẹ bi akọsilẹ Ajọ Nigerian Education Data Survey (NEDS) ni ọdun 2015, 44% awọn akẹẹkọ to wa ni ile-iwe alakọbẹrẹ ti ijọba lo mọ iwee ka, nigbati 74% awọn akẹẹkọ to wa ni ile iwe aladani lo mọ iwe ka.
" Oríṣun àwòrán, Twitter/EFCC Amọ, Ọgbẹni Abba ṣọ pe, ajọ EFCC gbiyanju lati ṣe aṣeyọri to pọ, bo tilẹ jẹ pe idojukọ naa pọ lọdun 2020.
Ọ̀rọ̀ yìí mú kí inú bí Asa sí wolii Hanani, ó sì kan ààbà mọ́ ọn lẹ́sẹ̀ ninu túbú, nítorí inú bí i sí i fún ohun tí ó sọ.
Ẹ lé àwọn aya àwọn eniyan mi jáde kúrò ninu ilé tí wọ́n fẹ́ràn; ẹ sì gba ògo mi kúrò lọ́wọ́ àwọn ọmọ wọn títí lae.
Ilé ẹjọ́ kòtẹ́milọ́rùn ti ìlú Abuja ti da ẹjọ́ kòtẹ́milọ́rùn tí adájọ́ àgbà Naijiria tẹ́lẹ̀rí, Walter Onnoghen pè láti tako aṣẹ idaniduro ranpẹ̀ ti ile ẹjọ to n gbọ ẹsun iwa ibajẹ ati aṣemaṣe awọn to di ipo ilu mu, CCT pa to yọọ niṣẹ́ ni Ọjọ Kẹtalelogun, Ọdun 2019 saaju igbẹjọ rẹ.
Eto adura naa, Fidau, wa ni ibamu pẹlu aṣa ati iṣe ẹsin Islam.
Ìbẹ̀rù OLUWA ni yóo jẹ́ ìdùnnú rẹ̀kì í ṣe ohun tí ó fojú rí,tabi èyí tí ó fi etí gbọ́ ni yóo fi ṣe ìdájọ́.
“Saraki wa rọ gbogbo awon adari
Nígbà tí ọbabinrin Ṣeba gbọ́ òkìkí ọgbọ́n Solomoni, ó wá sí Jerusalẹmu láti fi àwọn ìbéèrè tí ó takókó dán an wò.
Ayọ̀ ń bẹ fún àwọn aláàánú,nítorí Ọlọrun yóo ṣàánú wọn.
O óo ta òróró sí i lórí láti yàn án ní ọba Israẹli, àwọn eniyan mi.
Aare tun so nipa bi igbakeji re to wa lati ipinle Kwara  se pada wa si orile ede Naijiria lasiko ti eto iselu orile ede yii n gbona gid-gidi.
- Oshonaike 'Èmi àti Toyin Abraham ṣẹ̀ sọ̀rọ̀ fún ìgbà àkọ́kọ́ láti ọdún méjì torí ìjà òun àti Lizzy' Ifẹsẹwọnsẹ meji pere ni Manchester UNited ti jawe olubori ninu ere bọọlu mẹfa ti wọn kopa ninu rẹ.
Lóòótọ́ ìwọ ni o níláti kọ wí pé kí ó fẹ́ ọ kí ó tóó fèsì fún ọ ṣùgbọ́n rí i pé òun pàápàá fẹ́ràn rẹ.
Bakan naa ni wọn se alaye wipe, odun naa le mu owo to pọ wọle fun ijọba ipinlẹ Ọṣun lẹka irin ajo igbafe, ti wọn ba ṣe amojuto rẹ bi o ti tọ ati bi o ti ye.
Femi tún ṣàlàyé pé, lára ìpènija tí òun koju bíi osere tíátà ni pé, òun kò leè gbé ayé ara òun mọ nítorí pé òun ti di gbajumọ, tí òun kò sì leè ṣe bo se wù òun.
Oṣù mẹfa ni wọ́n fi ń kun òróró ati òjíá, wọn á sì fi oṣù mẹfa kun òróró olóòórùn dídùn ati ìpara àwọn obinrin.
Joṣua bá súre fún Kalebu ọmọ Jefune, ó sì fún un ní òkè Heburoni, bí ìpín tirẹ̀.
Coronavirus: Orílẹ̀-èdè Tanzania àti Somalia náà ti gbàlejò àrùn Coronavirus
Twinamasiko so lori ero amohun-maworan pe, “ gege bi okunrin, o niloo lati ba iyawo re wi, fowo kan die, fegba tabi ese lu, lati ko lekoo daadaa”.
Ní ìlànà ìwé ofin olrilẹ̀-èdè Nàìjíríà tọdun 2006, o fún gómìnà ni agbára áti dá àwọn alaga ìjọba ìbilẹ̀ dúró fún oṣù mẹ́fà.
Boko Haram, ti Abubakar Shekau n dari rẹ, lo ti jẹjẹ atilẹyin rẹ fun ikọ tamọ ntiye ISIS losu kẹta ọdun 2015.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ìdílé tí ọkọ da ọmọ síta tóríi ojú Búlùú tí wọ́n ní bá BBC sọ̀rọ̀ 'Bi ibugbamu naa ṣe ṣẹlẹ, ti gbogbo gilaasi ferese ati ti orule si fọ, ni mo bẹrẹ si ni wa iyawo mi to n rọbi lọwọ.
Omo bibi ipinle Kaduna oun so pe, osuwon akosile ajo UNICEF laipe yii safihan iku alaboyun ati awon omo-wewe lorile-ede Naijiria si ipo keji lagbaye, eyi ti o tunmo si pe, a n padanu egberun lona mokanla o-le 2, 300 awon omowewe ti ojo ori won koi ti pe odun marun-un ati aadojo 145awon alaboyun lasiko ibimo lojoojumo.
Ẹ kò gbọdọ̀ ya ara yín lábẹ nítorí òkú, bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò gbọdọ̀ fín ara yín rárá.
Ìpinnu kan tí à bá ṣe ni pé, kí á má ṣe fi ohun ìkọsẹ̀ kan, tabi ohunkohun tí yóo ṣi arakunrin wa lọ́nà, sí ojú ọ̀nà rẹ̀.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ooni Adeyeye: Ọmọ Nàìjíríà Mílíọ̀nù márùn ún yóò jànfàní ẹ̀kọ́ ọ̀fẹ́ látọ̀dọ̀ Arole Oodua ti Ile Ife 10 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Oríṣun àwòrán, ooniadimulaife Arole Oodua to tun jẹ Ọọni ti Ile Ife, Ọba Adeyeye Enitan Ogunwusi Ọjaja II ti ṣi aṣọ loju akanṣe eto iranwọ owo ileewe to pe akọle rẹ ni Ooni of Ife Tertiary Tuition Fund"" eyi ti wọn yoo fi doju kọ sisan lara owo ileewe akẹkọọ miliọnu marun jakejado awọn fasiti Naijiria."
Àkọlé àwòrán, D'Banj fọhùn lẹ́yìn ọjọ́ mẹ́wàá tí ó pàdánù ọmọ Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Nígbà tí ó pẹ́ díẹ̀ mo pe àwọn ẹlẹgbẹ́ mi gbogbo jọ mo bi wọ́n kí olúkúlùkù jẹ́ kí n mọ ohun ìjà tí ó wà lọ́wọ́ wọn mo sì wí fún wọn pàtó wí pé ó yẹ kí á ṣe nǹkan kan dandan kí ó tóó di pé ẹ̀dá náà pa wá jẹ.
ipade ti won se ni gbongan Mapo, Oba Lekan Balogun ti o tun jẹ Otun Olubadan je
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Xenophobia: Naijiria á kọ́kọ́ pèsè ọ̀nà láti bá ẹbí sọ̀rọ̀ fún wọn Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Xenophobia: Naijiria á kọ́kọ́ pèsè ọ̀nà láti bá ẹbí sọ̀rọ̀ fún wọn 11 Owewe 2019 Awọn eniyan mejidinlọgọsan ni wọn ti fidiẹ mulẹ pe wọn n gbera.
ọkàn tí ń pète ìkà,ẹsẹ̀ tí ń sáré sí ibi,
Ọpọlọpọ ẹ̀mí ati dukia lo ti sọnu sinu ogun ti Somalia ti n ja lati ọdun to pẹ.
Awọn gomina naa wa n kọminu pe, ki lo de ti iwọde naa si tẹwaju lẹyin ti ijọba apapọ ti wọgile awọn ọlọpaa SARS naa.
Èrè ìrẹ̀lẹ̀ ati ìbẹ̀rù OLUWA ni ọrọ̀, ọlá, ati ìyè.
Ó fún wọn ni imọ̀ràn pe ki wọn kó ara pọ̀ si ibi òkiti-ọ̀gán ti ohun ti lè tètè ri wọn, ṣùgbọ́n wọn kò gbọ́dọ̀ bẹ̀rù fún ohunkóhun tàbi ẹranko ti ó bá wá si sàkáni wọn.
Nítorí pé nígbà tí Farao ṣe orí kunkun, tí ó sì kọ̀, tí kò jẹ́ kí á lọ, OLUWA pa gbogbo àwọn àkọ́bí ilẹ̀ Ijipti, ti eniyan ati ti ẹranko.
Oga agba fun ile-ise olopaa, Ibrahim Idris ati akowe agba fun ile-ise aare, Jalal Arabi naa o gbeyin lara awon ti o lo ki aare kaabo sile baba re.
Ó ní àwọn ẹ̀rọ tí àwọn alágbẹ̀dẹ ṣe sórí àwọn ilé ìṣọ́ ati àwọn igun odi ní Jerusalẹmu láti máa tafà ati láti máa sọ àwọn òkúta ńláńlá.
O dabi ẹni pe awọn agbegbe kan to ṣẹṣẹ ni akọsilẹ aarun naa laipẹ yii ti n sawokọse awọn akẹgbẹ wọn ní Asia ati Europe.
Nítorí náà, OLUWA tí ó ra Abrahamu pada sọ nípa ilé Jakọbu pé,“Ojú kò ní ti Jakọbu mọ́bẹ́ẹ̀ ni ojú rẹ̀ kò ní rẹ̀wẹ̀sì mọ́.
Ẹni to bori: Angola Tunisia vs South Africa.
Ikọlu mii tun mu ẹmi eeyan mẹẹdọgbọn lọ Idi ni pe ẹmi eeyan mẹẹdọgbọn mii lo tun bọ nibi akọtun ikọlu to tun waye laarọ ọjọ aje eyi to tun da eto isinku apapọ fawọn eeyan tawọn Fulani darandaran pa ru.
orile ede Naijiria nipa eto ironilagbara N POWER ju awon  egberun lona ẹ́dẹ́gbẹ̀ta awon akọsẹmọsẹ
Ọlọrun mi yóo pa wọ́n run, nítorí pé wọn kò fetí sí ọ̀rọ̀ rẹ̀; wọn yóo di alárìnkiri láàrin àwọn orílẹ̀-èdè.
Wo ìgbẹ́sẹ̀ méjọ tí ilé aṣòfin ìpínlẹ̀ gbọdọ̀ tẹ̀lé láti yọ igbákejì gómìnà Wo ìgbẹ́sẹ̀ méjọ tí ilé aṣòfin ìpínlẹ̀ gbọdọ̀ tẹ̀lé láti yọ igbákejì gómìnà Oríṣun àwòrán, @Ondo House of assembly Àkọlé àwòrán, Aṣòfin Iroju Ogundeji, Favour Tomowewo àti Williams Adewale ń lọ rọọkún nílé Awọn ọmọ ile igbimọ aṣofin to ku ti wọn fọwọ si aṣẹ lọ rọọkun nile awọn akẹgbẹ wọn ni orukọ ati ibuwọlu wọn hande loke yii.
Òtítọ́ làwọn sọ́jà gbé ìbọn tó lọ́ta gidi nínú lọ sí Lekki Toll Gate lásìkò ìwọ́de EndSARS- Ọ̀gágun Taiwo Abunike to ni oun ni ọmọ marun un ṣalaye ninu ijẹri rẹ pe awọn ọlọpaa SARS fi oun si atimọle fọjọ mẹtadinlaadọta ni ọọfisi wọn to wa ni Ikeja lai gbe oun lọ si ile ẹjọ.
Ìgbà àkọ́kọ́ kọ́ nìyíì tí ìrú ẹ̀sùn bẹ̀ yóò jẹjáde lórí bí àwọn ìṣ'[akóso tó kọjá ṣe ná owó lórí ìná ọba, tí àwọn owó nàá kò sí mú àyípadà tó dára bá ẹ̀ka tó n pèsè ìná ní Nàìjíríà.
-Olorì Aláàfin, Memunat Adeyemi Kókó ohun tó wà nínú àbọ̀ ìwádìí Orosanye, tó le gba iṣẹ́ lọ́wọ́ òṣìṣẹ́ Buhari pàṣẹ lílo àgbo tí orílẹ̀-èdè Madagascar ṣe fún coronavirus fún ìtọ́jú ọmọ Nàìjíríà El-Rufai sọ̀kò ọ̀rọ̀ sí igbákejì ààrẹ, Yemi Osinbajo, Ó ní òun ni alága àwọn èèyàn kúkurú EFCC sọ pe awọn n se iwaadi aṣemaṣe ti awọn fura si pe ileesẹ Zhonghao Nig.
Ondo: Yánpọnyánrin ní ilé aṣòfin ìpínlẹ̀ Ondo nítorí olórí tuntun Oríṣun àwòrán, APC Ondo Àkọlé àwòrán, Ẹsun ti wọn fi kan awọn mejeeji ti wọn yọ nipo naa ni iwa ibajẹ lẹnu iṣẹ Ọrọ di iṣu ata yan-an-yan-an ni ile aṣofin ipinlẹ ondo lọjọ ẹti pẹlu bi awọn aṣofin meji ṣe n pe ara wọn ni olori ile naa.
Ayẹwo DNA lọjọ iwaju si le fihan pe ọmọ ale ni iyawo gbe wale.
Simon Chelugui to jẹ akọwe igbimọ iṣẹ ati idaabobo awujọ ṣeleri pe ọwọ ofin yoo kọ gbogbo wọn Sarah sọ idi to fi gbiyanju lati ta ọmọ rẹ.
Oríṣun àwòrán, @Sanwo Olu Àkọlé àwòrán, Opo ero lo n rọ awọn kọmiṣona tuntun lati ṣiṣẹ daadaa Iroyin ni awọn ọmọ ile igbimọ aṣofin ipinlẹ Eko lo yọ orukọ wọn lẹyin ti Sanwo Olu fi ranṣẹ sile.
O ni bi wọn ba lo awọn agbara to wa ninu rẹ daadaa, o lee mu ayipada rere ba imọ ẹrọ orilẹ-ede kan, ko si tun gba ogo wọn pada fun idagbasoke.
" Ọjoọ́ mélòó ni Coronavirus ń lò lára kí ènìyàn tó gba ìwòsàn?
Eto oro-aje orile-ede Nigeria tunbo gberu si ju ti saa kerin odun 2017, lati iko o din die ni meji ninu ida ogorun1.
Dogara soro yii lasiko ayeye odun ibi Maulud Nabiyy.
Ó bí ọmọkunrin mejilelọgbọn, ó sì ní ọgbọ̀n ọmọbinrin.
Iyanselodi jokoo sile ni ilu Gondar ti o wa ni apa ariwa Amhara lorile-ede Ethiopia wo ojo keta bayii, ifehonu-han ohun waye, latari bi ijoba se kede ilu-o-fara ro lose to koja lorile-ede naa.
 Àkọ ́ kọ ́ nínú wọn ni àwọn ológbòóni .
BBCCopyright: BBC Idile Obafemi HamzatImage caption: Idile Obafemi Hamzat BBCCopyright: BBC Igbakeji gomina EkoImage caption: Igbakeji gomina Eko Article share tools Facebook Twitter ṢàpínlòView more share options Share this post Copy this linkKà síwájú síi nípa àwọn ìtọ́kasí wọ̀nyí.
Bakan naa ni ẹni to fa kẹẹgi epo pẹtroolu lọwọ fara gbọgbẹ diẹ, ti oun naa si n gba itọju lọwọ nile iwosan.
 Ọ ́ pọ ̀ àwọn ọ ́ fọ ́ agùnbánirọ ̀ ló sì yi ké gbàjarè nípa bí àjọ náà ṣe rán wọn lọ síbi tí ẹ ̀ mí wọn kò ṣe dè látàrí ìjà ẹ ̀ sìn , ẹ ̀ yà àti tòṣèlú ṣe ń ṣekú pa wọn láìrò tẹ ́ lẹ ̀ .
Ṣugbọn baba rẹ̀ kọ̀, ó ní, “Mo mọ̀, ọmọ mi, mo mọ̀, òun náà yóo di eniyan, yóo sì di alágbára, ṣugbọn sibẹsibẹ àbúrò rẹ̀ yóo jù ú lọ, àwọn ọmọ ọmọ rẹ̀ yóo sì di ọpọlọpọ orílẹ̀ èdè.
Awọn akẹẹgbe Neil Armstrong, Buzz Aldrin ati Michael Collins ti wọn jọ de inu Osupa, ni wọn bi ni ọdun 1930.
Ninu atẹjade rẹ kan to fi sita ni ọjọ Aje, ajọ BudgIT ni awọn ipinlẹ mẹjọ pere lo tii jẹwọ ilakalẹ lori bi wọn ṣe na owo naa.
Adágún yìí ní ìloro marun-un tí wọn fi òrùlé bò.
 Ìjọba ń fi àsìkò yìí sọ fún àwùjọ pé ayẹyẹ Osun-Osogbo ti ọdún yìí yóò yàtọ̀ si bí wọ́n yóò ṣe jẹ pé àwọn olùjọ́sìn Osun nikan ni yóò ráàyè láti wọ ojúbọ láti ṣe gbogbo ìrúbọ tó bá yẹ."
Nigba miran, Baba Legba tun maa n ba awọn akẹẹgbẹ rẹ ninu isẹ tiata sere itage, awọn bii Bolaji Amusan taa mọ si Mr Latin ati Segun Ogungbe.
Ìjọba ko ti i ṣe ìpèsè omi ẹ̀rọ, ọ̀nà àdúgbò àti ohun amáyédẹrùn igbàlódé pàtàki ni àwọn agbègbè tuntun.
Ọbasanjọ yòǹbó Atiku, ó ní kò ní já Nàíjíríà kulẹ̀ ''Ki ṣe ọrọ boya maa fidirẹmi lo delẹ yi, ohun to ṣe pataki julọ ni boya idibo yi ko ni ni mago mago ninu.
Gomina Obaseki ti o jẹ Gomina labẹ ẹgbẹ oṣelu APC la ti ri pe o pada si ẹgbẹ oselu PDP, eyi to ti bẹnu atẹ lu tẹlẹ ri.
Naijiria, ki o le dẹkun bi awon ikọ ọlọtẹ se n pa awon eniyan bi ẹran lorile
Ajo ti o n se amojuto awon ile-ise ona ibara-eni soro lorile-ede Nigeria so pe, eto isuna owo ti o lokimi ni awon ile-ise ero ibara-eni soro lorile-ede Nigeria yoo dekun asise gbese ti o fa ijakule ile-ise ero ibara-eni soro Etisalat lodun to koja, bakan naa lati satileyin iduro-sinsin fun eka naa.
 láti lè ṣe ìwádìí àrùn náà , àwọn àrùn mìíràn tó ní àmì tó jọ mọ ́ èyí bíi akọ ibà , àrùn onígbáméjì kọ ́ lẹ ́ rà àti àwọn ibà ẹ ̀ jẹ ̀ sísun lára tó wáyé nípasẹ ̀ kòkòrò àìlèfojúrí afàìsàn mìíràn ni a ó ò kọ ́ kọ ́ mú kúrò .
Ọlọ́pàá ti mú afurasí ajínigbé Hamisu Wadume Njẹ ìjọba yóò dá àwọn ilé iṣẹ́ tuntun yii silẹ̀ ni?
Èyí tó bá wù kó wọlé, pàtàkì rẹ̀ ni pé kí olúkálukú tó bá lẹ́tọ̀ọ́ ìdìbò kó jáde lọ dìbò.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ole aji maluu pa eeyan marundinlogoji ni Zamfara 16 Èrèlè 2018 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ọpọlọpọ ẹmi ati maluu ni awọn ọdaran agbebọn naa ti pa kaakiri ipinlẹ Zamfara ati awọn ipinlẹ miran.
Awon omo orile-ede Uganda ti gbaradi,  nipa pipe fun ikowe sipo sile omo egbe ile-igbimo asofin kan ti o satileyin fun ikolu awon obinrin lori ero amohun-maworan.
Kẹkẹ alajọwa ni wọn n pe, eyi to jẹ itẹwọgba bayii laarin awọn ọdọ, ti wọn fi n da awọn eeyan kanka laujọ lọla, koda, ileẹkọ nipa rẹ gan ti wa.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Domestic Violence: Ìjà láàrin lọkọlaya sọ aya dèrò ọ̀run Ijọba tí júwọlẹ̀ fún Amẹrika lóri iwé ìrìna!
Bí ara ti ẹ̀dá ti wà, bẹ́ẹ̀ ni ti ẹ̀mí wà.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Kini Yoruba n pe ni 'pen'?
Ǹjẹ́ nisinsinyii, ẹ mọ ohun tí ó ń ká a lọ́wọ́ kò, tí kò jẹ́ kí ó farahàn títí àkókò rẹ̀ yóo fi tó.
Obìnrin náà ṣì ń kópa nínú àwọn eré sinimá àgbéléwò Yorùbá ni ọlọ́kan-ọ̀-jọ̀-kan.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, ọrọ ifẹ bii adanwo ni Iwadii fihan pe eroja síǹkì maa n jẹ ki nkan ọmọ ọkunrin le sii ki àtọ̀ ọkunrin si pọ sii.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Mayowa Omoniyi: Kò sí orin Obey, Sunny Ade abí tàkasúfèé tí ń kò le ta gìtá sí Awọn olufẹhonuhan naa to lọ si ọfiisi ẹgbẹ awọn akọroyin ni Ibadan sọ pe yiyan babalọja kii ṣee ojuṣe Olubadan.
Nígbà tí ọkunrin tí ó dúró ti òkú náà rí i pé gbogbo eniyan ní ń dúró, ó wọ́ òkú náà kúrò lójú ọ̀nà, sinu igbó, ó sì fi aṣọ bò ó.
Babajide Sanwo-Olu 'pa'lù ẹnu dá',o lóun kò ṣèlérí nípa súnkẹrẹ-fàkẹrẹ Apapa láàrín ọgọta ọjọ
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Mastiff Aja Akita: Eyi jẹ aja ti ko buru pupọ, amọ o jẹ aja to gboju, ti eniyan gbọdọ kọ ni ẹkọ.
Àwọn wo ló ti lọ sílé lẹ́yin ipele ṣikejì?
Ni ti ile iṣẹ P&ID, wọn ni ipa ti ijọba to yẹ ko tẹle rawọn lati pari iṣẹ naa lo fa ijakulẹ rẹpẹtẹ.
Igbakeji Aare ile-igbimo asofin, asofin Ike Ekweremadu ti pe awon omo orile-ede Naijiria lati gbadura kikan-kikan fun idasi atoke wa fun orile-ede Naijiria.
A ni awon eri idaniloju lori ileri ti aare se fun awon eniyan lasiko ipolongo eto idibo lọdun 2015 , ni eyi ti o ti mu sẹ,bo tile je pe o koju awon isoro.
Ijọba Naijiria ni bi wọn ṣe n da awọn ohun eelo epo rọbi si titi yii n ṣakoba to pọ nibẹ ni.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Nimet: Ẹ ma tii dako nitori ojo akọrọ 20 Èrèlè 2018 Oríṣun àwòrán, @SuccessfulFarm Àkọlé àwòrán, Nimet ni ko si ohun tuntun ninu ojo akọr yi, igba ẹẹrun lo n kogba wọle Ajọ to nwo sakun bi oju ọjọ ti ri, Nimet, ti sin awọn agbẹ ni gbẹrẹ ipakọ lati mase dako lasiko ojo akọrọ yi.
Àwọn ọmọ ogun Siria yòókù sì sá lọ sí ìlú Afeki; odi ìlú náà sì wó pa ọ̀kẹ́ kan ati ẹẹdẹgbaarin (27,000) tí ó kù ninu wọn.
Òdodo rẹ wà títí lae,òtítọ́ sì ni òfin rẹ.
" Bí nǹkan ọkùnrin bá há sójú ara obìnrin, kìí ṣe Mágùn, ẹ má páyà Ẹ fún ọ̀já kó le, lítà epo kan le tó ₦250 àbí ju ₦300 lọ"" Ìdí tí mo ṣe se oúnjẹ nínú ilé ẹni tí mo lọ jà lólè rèé- Afurasí adigunjalè Owó tí Kiddwaya bá rí ní BB Naija, ìdá kan fún Erica, ìkejì fọ́mọ aláìníyàá - Baba Kiddwaya Wọ́n ti dáwọ́ ìdánwò àbẹ́rẹ̀ àjẹsára Oxford dúró lẹ́yìn ti olùkopa kan ṣàìsàn Bakan naa ni wọn rọ awọn kristẹni ati musulumi lati bawọn bẹ ijọba pe ki o maa fawọn naa lọlude bi awọn ẹlẹsin meji to ku."
Koda ọba alade kan gba miliọnu méjídínlọ́gọ́rin naira ninu owo naa ti ko si da pada, EFCC ni ''oba alade yi gba owo iranwọ naa lorukọ ileeṣẹ rẹ Yafy International Ventures Limited ti ko si tẹlẹ ilana to yẹ'' Ipele kan náà kó ní Yorùbá àti ẹgbẹ́ darandaran Miyetti Allah wà- Afẹnifẹre Kí ló mú ọlọ́pàá ilẹ̀ Gẹ̀ẹ́sì san owó gbà má bínú £2500 fún pásítọ̀ yí?
Bó tilẹ̀ jẹ́ pé ìròyìn òfegè ni pé Buhari fẹ fẹ́ Sadiya, síbẹ̀ àwọn ọmọ Nàìjíríà ń ṣètò ìyàwò náà lórí ayélujára Ọpẹ́ o!
Henry Fajemirokun: Olókoòwò yíká àgbáyé tó bẹ̀rẹ̀ ètò okoòwò lábẹ́ Ecowas
Misago sọ pe ọmọ oun ku ninu yara ikawe lẹyin ti olukọ yii na a tan, koda ọfiisi ọga ile iwe ọhun ni wọn gbe oku rẹ si.
Sanwo-Olu , ninu ikede rẹ to waye ni owurọ ọjọ Isẹgun salaye pe oun sepade peẹlu awọn asaaju ẹsin ati ẹgbẹ ajafẹtọẹni, tawọn si fẹnuko pe kawọn oluwọde naa maa pejọ si Alausa ati ẹnu iloro bode Lekki.
Awọn onisẹ abẹ meje, dokita oyinbo, atawọn olutọju alaisan mii, lo se isẹ abẹ naa, eyi to waye fun wakati meji gbako.
0 2435 Agbegbe French Guiana 71 25.
Nígbà náà ni oníṣẹ́ kan wá sọ fún Saulu pé, “Pada wá kíákíá, nítorí pé àwọn ará Filistia ti gbógun ti ilẹ̀ wa.
 ohun tí ó selè nip é léyìn ìgbà tí a ti fi òfin ìhun gbólóhùn sèdá ( 58 ) tán ni a wá so atóka ìbéèrè mó on .
Ọ̀rọ̀ epo kìí ṣe bi iṣu àti ata lọ́ja, wọ́n maa n pé olúkúlúkù láti wá gbé epo ni, iyé ti ẹni náà ba si báa ni yóò ràá, nítori náà iye ti olúkúlúkò yóò si taa yoo yàtọ̀ si ara wọ́n Ẹkúnrẹ́rẹ́ àlàyé Mike Osatuyi rèé Ìjọba dín owó epo bẹntiró sí N108 Fuel price: Ìjọba dín owó epo bẹntiró láwọn ibùdó ìjápo (depot) sí N108 láti N113 Oríṣun àwòrán, AFP/Getty Images Ijọba apapọ orilẹede Naijiria ti kede adinku owo epo bẹntiro kuro ni naira mẹtalelaadọfa naira to wa tẹlẹ si naira mejidinlaadọfa naira gẹgẹ bi iye ti wọn yoo maa ta jala epo lawọn ibudo igbepo gbogbo lorilẹede Naijiria.
Wọ́n wá bi wọ́n pé, “Irú agbára wo ni ẹ fi ṣe ohun tí ẹ ṣe yìí?
Ìlú tí ó ti jẹ́ olódodo rí tí ń ṣe bí aṣẹ́wó,ìlú tí ó ti kún fún ẹ̀tọ́ ati òdodo rí, ti kún fún ìpànìyàn.
Ori ẹni si lo n gbe ni, ti a fi de ade owo, ori ẹni naa lo n gbe ni, ti a fi tẹ ọpa ilẹkẹ, ori yii naa si lo gb'Ọmọọba Dapọ Abiọdun, to fi di gomina tuntun ni ipinlẹ Ogun.
Ṣugbọn Ọlọrun bi àwọn eniyan burúkú pé,“Ẹ̀tọ́ wo ni ẹ níláti máa ka àwọn òfin mi,tabi láti máa mú ẹnu ba ìlànà mi?
Iko Agbaboolu Bafana Bafana ni kikun:Awon Asole(Goalkeepers): (Itumeleng Khume (Chiefs0, Ronwen Williams (Supersport), Darren Keet (Wits)Awon agbaboolu owo eyin(Defenders): Ramahle Mphahlele (Chiefs), Motjeka Madisha (Sundowns), Siyanda Xulu (Maritzburg), Thulani Hlatshwayo (Wits), Innocent Maela (Pirates), S’Fiso Hlanti (Wits), Buhle MKhwanazi (Bidvest Wits), Thamsanqa Mkhize (Cape Town City)Awon agbaboolu aarin(Mifielders): Vincent Pule (Pirates), Lebogang Maboe (Sundowns), Hlompho Kekana (Sundowns), Fortune Makaringe (Maritzburg), Teboho Mokoena (Supersport), Samuel Mabunda (Sundowns), Thembinkosi Lorch (Pirates), Thulani Serero (SBV Vitesse),Awon agbabooluiwaju(Strikers): Themba Zwane (Sundowns), Lebo Mothiba (Racing Club De Strasbourg FC), Dino Ndlovu (Zhejiang Greentown FC, China), Percy Tau (Royal Union Saint FC, Belgium) Tobi Sangotola.
Ó kéré tán, ènìyàn mẹ́rìnlá tí kú nínú àjálù ọkọ̀ òfurufú tó já Àlùfáà ìjọ Redeem àti ọmọ rẹ̀ méjì kú sílé ìgbafẹ́ kan lásìkò Kérésì Ìjọba yóò ti Afára Sagamu pa nítorí ìjàmbá iná- FRSC Chelsea kò rọ́wọ̀ mú lẹ́yìn tí Southampton dáná sun Stamford Bridge Lori awọn oṣerebinrin to maa n sọ pe awọn ọkunrin awọn maa n fi ilọkulọ lọ awọn, Afod sọ pe pupọ ninu nkan ti wọn n sọ nipa awọn osere ọkunrin jẹirọ ni.
Ọpọ n beere pe ṣe ẹṣe ni lati lọ ile iwosan lọ ri dokita ẹni abi kini aye n di lorukọ ẹsin to ba wu ni lati sin lọna to wu eeyan bayii?
Agbeyẹwo naa yoo da lori awọn akọsilẹ to han si gbangba.
Aarẹ ni ti Saraki ati Dogara ba ni ifẹ Naijiria lọkan, wọn ko ni gba ki aba iṣuna wa ni iwaju ile fun oṣu meje lai buwọ lu u.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Nigeria movie industry: Àgbà òṣèré, Lere Paimo ní àìgbọràn ló ń da ọ̀pọ̀lọpọ̀ àwọn Wọn ni pe wọn lọwọ si bi wọn ṣe ṣe owo to le ni biliọnu mejila dola ( $12.
Oṣerebinrin, Dorcas Shola Fapson sọ pe oun ti ba Seyitan sọrọ.
OLUWA wà pẹlu Jehoṣafati nítorí pé ó tẹ̀lé àpẹẹrẹ ìgbà ọ̀dọ̀ Dafidi, baba rẹ̀; kò sì bọ oriṣa Baali.
Ọlọ́pàá kò rí ǹkankan lábẹ́ pẹpẹ ilé ìjọsìn mi - Olùṣọ́àgùntàn Akure Ọmọdé 27 jóna ráuráu mọ́'le níléèwè Liberia Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, South Africa: Àwọn ọmọ Nàìjíríà tó kù ní ìjọba SA ń kó ọ̀pọ̀ tó fẹ́ wále sí ọgbà ẹ̀wọ̀n Gómìnà ìpínlẹ Kwara yan Kọmíṣónnà tí ó kéré julọ!
Ìpínlẹ̀ Eko, Ọṣun àti Ondo yóò bẹ̀rẹ̀ sí ní lo ‘Drone’ fún ààbò Owó dé!
Wọn ìbáà rú ẹbọ sísun ati ẹbọ ohun jíjẹ, n kò ní tẹ́wọ́ gbà wọ́n.
Charleroi SC, Belgium); Moses Simon (Levante FC, Spain); Henry Onyekuru
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Barister lo bi gbogbo oníṣẹ́ fújì -Oṣupa Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Yorùbá ni “Bàbá, bàbá gbogbo ayé”, bi iyàwó kò bá ni iṣẹ́ lati tọ́jú ọmọ wọn, ìṣẹ́ dé, nitori eyi, ọ̀pọ̀lọpọ̀ obinrin Yorùbá ma ntẹpá mọ́ṣẹ́ lati lè tọ́jú ọmọ wọn lai dúró de ọkọ.
"Nàìjíríà tí a wà lọ́wọ́ yìí kò lè san ẹ̀yà Yorùbá, Ìgbò, Haúsá tàbí ẹ̀yàkẹ́yà-Ọ̀jọ̀gbọ́n Banji Akintoye ""Ọ̀pọ̀ ènìyàn tó ń gbé ní Eko, Ibadan, Osogbo ló ti kú."
Oríṣun àwòrán, Getty Images Amọṣa, ọrọ agbabọọlu ọwọ ẹyin fun Arsenal, iyẹn David Luiz ni ọpọlọpọ mu bs ẹnu lẹyin ifẹsẹwọnsẹ naa.
Ṣugbọn ọpọ eeyan lo ti bu ẹnu ẹtẹ lu igbesẹ awọn ẹṣọ alaabo Amọtẹkun ipinlẹ Ọsun lori ayelujara.
"Bo tilẹ jẹ pe ko darukọ pasitọ to n sọrọ si, o pe ẹni naa ni ""apari adiyẹ"", to si sọrọ bi ẹni naa ṣe ma n sọrọ."
Bi ẹ ko ba gbagbe, ọdun to kọja ni ipo Oniru ṣofo nigba ti Oniru ikẹrinla, Ọba Idowu Oniru filẹ bora bi aṣọ.
Ẹ̀yin ará mi, níwọ̀n ìgbà tí ẹ ní igbagbọ ninu Oluwa wa, Jesu Kristi, Oluwa tí ó lógo, ẹ má máa ṣe ojuṣaaju.
Tí a fiṣọwọ́ ní 11:46 11 Òkùdu 201911:46 11 Òkùdu 2019 Ojú olùdíje alátakò rèé!
Wọn gba pe ohun to ba too pe ori akọni lo yẹ ki a fi pee bi awọn to ku ni agbaye ṣe n ṣe.
Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
 Awon Panthers ti ja bayii nitori pe orile-ede Guinea naa fagbahan won pelu ami ayo marun un si ookan ninu idije ti won fi side eto ohun.
Sugbọn ọdún 1966 ni awọn ara ilu Ọwọ kọ ẹyin si Ọba wọn yii, ti wọn si le e kuro niluu.
Ó bá fò sókè, ó dúró, ó sì ń rìn.
Àkọlé àwòrán, Ìgbà kẹsàn án nìyí tí àìsàn Ebola yóò bú jáde ní orílẹ̀èdè DR Congo.
"Sanusi pe Ọ̀gá ọlọ́pàá àti Ọ̀gá DSS lẹ́jọ́ UEFA wọ́gilé ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ Real Madrid àti Manchester City nítorí coronavirus ""Owó oṣù òṣìṣẹ́ yóò di gbèsè, oúnjẹ yóò wọ́n, ìlú yóò le, bí ọrọ̀ ajé Náíjíríà bá dagun"" Nàìjíríà bèèrè ìrànwó lọ́wọ́ àjọ àgbáyé láti kápá Coronavirus Ǹ jẹ́ o mọ̀ pé ìdọ̀tí rẹ le è sọ ẹ́ di olówó?"
 Bi o ti le je pe, orisirisi aheso oro lo gbode kan kaakiri oja kara-kata pe, o seese ki agbaboolu naa ko kuro ninu iko  Manchester United  .
Ile ẹjọ ti n ri si igbẹjọ eto idibo ni ipinlẹ Ogun ti pe fun atundi ido to gbe Aṣojuṣofin Kọlapọ Osunsanya wọle.
6 Nísisìyí, nítorítí ìwọ ti béèrè, kíyèsíi, mo wí fún ọ, pa àwọn òfin mi mọ́, kí o sì lépa lati mú iṣẹ́ Síónì jáde wá ati lati fi ìdí rẹ̀ múlẹ̀.
Agbegbe Idumọta ni ilu Eko ni wọn bi Dẹjọ tunfulu si ni ọdun 1969, ṣugbọn ọmọ ilu Abẹokuta ni.
Ó ti kọ́kọ́ gba ipò àgbà lọ́wọ́ mi, ó tún wá jí ìre mi gbà lọ.
Nigba to n salaye ohun to n fa aawọ laarin awọn igun ijọba ati ti ẹgbẹ osisẹ, ọkan lara awọn asaaju gb osis to wa nibi ipade idunadura naa, Lawrence Amaechi salaye pe atunto owo osu lo n fa aawọn ọhun.
”Jesu wí fún wọn pé, “Bí ó bá jẹ́ pé ọmọ Abrahamu ni yín, irú ohun tí Abrahamu ṣe ni ẹ̀ bá máa ṣe.
Ẹ̀wẹ̀, WhatsApp jẹ́ ọ̀kan pàtàkì lára àwọn àpùù tó wọ́pọ̀ jùlọ tí àwọn ènìyàn máa ń lò, ti ó sì tó ènìyàn bílíọ̀nù méjì lagbaye tó n lòó.
Awọn eeyan bii@dami_lanre, @ifebanjo, @Babel411, @Abbey0057 Oríṣun àwòrán, Olubayode Alebiosu Bakan naa lawọn miran bii @Henry_EI, @alrhemist naa n pariwo lori ayelujara pe ṣe gbogbo iroyin pe awọn oṣiṣẹ ajọ gbalẹ-gbadọti ni ipinlẹ Eko, LAWMA ti gba agbegbe Lekki Tollgate naa ṣaaju abẹwo awọn gomina ọhun ko kan ibi ti ẹrọ ayaworan naa wa ni.
“Ẹnikẹ́ni tí ó bá mú ọ̀kan ninu àwọn kéékèèké wọnyi tí ó gbà mí gbọ́ kọsẹ̀, ó sàn fún un kí á so ọlọ ńlá mọ́ ọn lọ́rùn, kí á gbé e sọ sinu òkun.
Wọn óo wá mọ̀ bí mo ti lè gbẹ̀san tó.
Ó ti fún àwọn eniyan rẹ̀ ní agbára,ó sì fún àwọn eniyan rẹ̀ mímọ́ ní ìyìn;ó fún àwọn eniyan Israẹli, tí ó wà lẹ́bàá ọ̀dọ̀ rẹ̀.
Ni ipari, O so pe  didasile awon olopaa ipinle ni gbogbo awon ipinle to wa jake jado orile ede Naijiria  yii se pataki.
“Ní àkókò náà ni n óo tanná wo Jerusalẹmu fínnífínní, n óo jẹ àwọn ọkunrin tí wọ́n rò pé àwọn gbọ́n lójú ara wọn níyà, àwọn tí ń sọ ninu ọkàn wọn pé, ‘kò sí ohun tí Ọlọrun yóo ṣe.
DR Congo kéde ìtànkálẹ̀ ní ìhà àríwá orílèèdè - BBC News Yorùbá BBC News, YorùbáFò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ebola - DR Congo kéde ìtànkálẹ̀ ní ìhà àríwá orílèèdè 9 Èbibi 2018 Oríṣun àwòrán, AFP Àkọlé àwòrán, Ìtànkálẹ̀ ààrùn Ebola tó wáyé kẹyìn lọdun 2017 pá èèyàn mẹ́rin.
Orúkọ ọmọ rẹ̀ keji ni Selofehadi; tí gbogbo ọmọ tirẹ̀ jẹ́ kìkì obinrin.
'Osimhen àti Aribo ni Lesotho bẹ̀rù jù nínú ẹgbẹ́ agbábọ́ọ̀lù Nàìjíríà' Bi ẹgbẹ agbabọọlu Naijiria, Super Eagles ti ṣetan lati koju Lesotho, akọnimọọgba Lesotho, Thabo Senong ti sọ pe ẹlẹsẹ ayo, Victor Osimhen ati Joe Aribo lawọn bẹru ju.
Àwòrán apanilẹ́rìn-ín fún ọ̀sẹ̀ yìí, ìtọ́wò rèé Osinbajo ta kété sí ọ̀rọ̀ 'Ruga Settlement' 'Dókítà ló ṣe iṣẹ́ abẹ tó pa ìyàwó mi láì gba àṣẹ lọ́wọ́ mi' Buhari fi àmì ẹ̀yẹ dá olóògbé Adadevoh tó dènà Ebola l'ọ́lá Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí kan sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
” Arkwright, to ti lo odun meta lorile ede Naijiria naa so pe ohun ti  lo si  ipinle ọgbọ̀n ninu ipinle mẹ́rìndínlógójì to wa lorile ede yii.
''A fẹ ki Gomina Makinde kilọ fun Alaafin wi pe ko maa da aarin awọn lọbalọba ru nipinlẹ Ekiti nitori Ekiti kii ṣe ilẹ Oyo,'' Alawe lo woye bẹẹ.
Ó ṣe ohun tí ó burú lójú OLUWA, ó tẹ̀lé ìwà ẹ̀ṣẹ̀ àwọn baba ńlá rẹ̀.
Bukky Wright ṣ'ọjọ́ ìbí, Lizzy Anjorin f'orin bọnu, Femi Adebayo sọ ẹran àgbò rẹ̀ lórúkọ tuntun Mohammed, ọmọ Abubakar Atiku sọ̀rọ̀ lórí àrùn Coronavirus tó ń báa finra Kí ló pa bàbá Adeboye, bàbá Davido àti Ọ̀ọ̀ni Ifẹ̀ pọ̀ lásìkò ìgbélé l'Ọ́ṣun?
O so pe, o je ohun edun okan lati ri pe, igbimo eleso lorile-ede Naijiria maa n ko eso fun awon agbe ninu osu keje, leyin ti o ba ti bo sori tan ni apa gusu ila-orun, ni eyi ti o n ro gomina Willie Obiano ti ipinle Anambra lati se amulo ilana eto ogbin ni ipinle naa, pelu erongba ati fopin si awon ipenija ti o n koju awon agbe ipinle ohun.
Àwọn ọrọ̀ inú rẹ̀ sì di ti àwọn ọba tí wọn ń mú wa sìn nítorí ẹ̀ṣẹ̀ wa, wọ́n ń lo agbára lórí wa ati lórí àwọn mààlúù wa bí ó ṣe wù wọ́n, a sì wà ninu ìpọ́njú ńlá.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Adekunle se agbekalẹ Rọbọti akọkọ rẹ eyi tii se Rọbọti akọkọ fun ere idaraya Lọdun 2017, nigba to wa nileesẹ MekaMon, ni Adekunle se agbekalẹ Rọbọti akọkọ rẹ eyi tii se Rọbọti akọkọ fun ere idaraya, ti ẹrọ naa si lee sisẹ bii eniyan.
Ifa Priest: ọdún mọ́kànlá ni mo fi ṣe iṣẹ́ agbejọ́rọ̀ kí n tó gbọ́ràn si Ifá lẹ́nu
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Gbajúgbajà òsèré tó tún mọ́ ọbẹ̀ sè Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
“Bí ààlà ilẹ̀ náà yóo ti lọ nìyí: ní apá àríwá, ilẹ̀ náà yóo bẹ̀rẹ̀ láti Òkun Ńlá, yóo gba Etiloni títí dé ẹnubodè Hamati, títí dé ẹnu ibodè Sedadi, 
ekunwo ti o din ni ọgbọ̀n egberun.
PDPPeter Obi ni ida ogoji ninu ogorun un ni ipa ti awon ile-ise
Bi eléré ìbílẹ̀ kan ti nlọ ni òmíràn yio de, eleyi lo njẹ́ ki ilú kékeré dùn.
Bakan naa, iroyin sọ pe awọn akẹkọọ ti ha sabẹ ile naa.
Bí ó bá jẹ́ pé èmi ni ẹ̀ ń wá, ẹ jẹ́ kí àwọn wọnyi máa lọ.
Agbaboolu U-17 yoo maa wako pelu awon akegbe won meji ninu ipele ti won wa, nitori agbaboolu orile ede Benin ti won yọ kuro ninu idije naa.
Emefiele kede eyi lasiko to n sepade pẹlu awọn akọroyin nilu Eko.
Wọn tọ Mose, Aaroni, ati àwọn ọmọ Israẹli lọ ní Kadeṣi ní aṣálẹ̀ Parani.
Àwọn obinrin bá bẹ̀rẹ̀ sí bèèrè pé, “Ṣé Naomi nìyí?
Ìmọ́lẹ̀ sì wà ní gbogbo àyíká rẹ̀.
Ó bá gbéra, ó ń lọ, títí tí wọ́n fi dé ibìkan tí ó dojú kọ Jebusi (tí wọ́n yí orúkọ rẹ̀ pada sí Jerusalẹmu); àwọn kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ rẹ̀ wà lọ́dọ̀ rẹ̀, obinrin rẹ̀ sì wà pẹlu rẹ̀.
Fashola EndSARS Protest: Fashola rí kámẹ́rà he ní ibùdó ìṣẹ̀lẹ̀ Lekki Tollgate, àwọn ọmọ Nàìjíríà bá figbe ta
Mi ò ní ìyàwó nílé, àmọ́ mo ní ọmọ tó pọ̀-Saheed Oṣupa Ọ̀rúnmìlà ni ó kọ́kọ́ lo 'Google' láàgbáyé-Ọ̀ọ̀ni Ìlẹ̀ ifẹ̀ 'Ìdùnnù wa kọ́ ni kí á má fún ọmọ Nàìjíríà ní 'Visa' Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Lábẹ́ odò!
A kò tí ẹnu Bodè pa rárá- iléeṣẹ́ Aṣọ́bodè Ajínigbé ń bèèrè fún epo, iṣu àti ọ̀tí Schinap gẹ́gẹ́ bí owó ìtanràn Wo ohun tó yẹ kí o mọ̀ nípa àwọn obìnrin méje ti Buhari fẹ́ yàn sípò minista Àwọn ọmọ Yorùbá wo ni mínísítà ní ìjọba Buhari?
Wọ́n ní kí gbogbo ènìyàn yẹra o, wọ́n ń gbé òkú bọ̀.
"Ati pe emi ati Alaafin ko fẹ ara wa ni ilana ofin.
Eyi tumọ si peawọn to n ta epo gan lo n sanwo fawo orilẹede to n ra epo lati wa ko epo rọbi naa kuro lori igba wọn.
Ní ọdún kejila tí Ahasi jọba ní Juda, ni Hoṣea ọmọ Ela jọba lórí Israẹli, ní Samaria, ó sì jọba fún ọdún mẹsan-an.
Àlùfàá méjì wà lára àwọn mẹ́rin tó fi ipá bámilòpọ̀"" Ọ̀rọ̀ Aisha Buhari sí Ramaphosa wú ọ̀rọ̀ síta lẹ́nu àwọn ọmọ Nàìjíríà Aisha Buhari ké gbàjare pé ètò ìjọba Buhari kò ṣànfàní f'óbìrin Bukola Saraki Sẹnẹtọ Bukola Saraki to jẹ Adari ile igbimo aṣofin agba l'Abuja kọkọ fidi rẹmi ninu ibo lati pada sile aṣofin agba mi olu olu orilẹede Naijiria."
A máa kígbe pe àwọn tí ń kọjá lọ,àwọn tí ń bá tiwọn lọ jẹ́ẹ́jẹ́ wọn, pé,
Nítorí náà OLUWA ní,“Ẹ bèèrè láàrin gbogbo orílẹ̀-èdè,bí ẹnikẹ́ni bá gbọ́ irú rẹ̀ rí.
Ìbọ̀wọ̀ fófin ni bí wọ́n se fi Sowore sílẹ̀ Ta ni Oba Idowu Abiọdun Oniru tó wàjà nípinlẹ̀ Eko?
Idà ni wọn yóo fi máa ṣe àkóso ilẹ̀ Asiria ati ilẹ̀ Nimrodu; wọn yóo sì gbà wá lọ́wọ́ àwọn ará Asiria, nígbà tí wọ́n bá wọ inú ilẹ̀ wa tí wọ́n sì gbógun tì wá.
Elias Mudzuri ti o je okan lara igbakeji Aare ati awon agbaagba egbe oselu naa ni won ko wa sibi ipade igbimo amusese egbe naa.
Amọ ṣa ko saburu ti obinrin naa ba ni oun nifẹ ọkunrin yala labẹ ẹsin tabi aṣa Yoruba.
Idi ree ti BBC fi se akojọpọ awọn ọrọ to safihan bi Donald Trump ṣefi ọwọ yẹpẹrẹ mu Coronavirus: Awọn igba ti Donald Trump ti sọrọ Coronavirus bii nnkan yẹpẹrẹ: Lati igba ti aarun Coronavirus tí bẹrẹ naa ni aarẹ Donald Trump ti n fi ọwọ yẹpẹrẹ mu New York wa ninu isoro, sugbọn mo ń igbagbọ pe wọn yoo jajabọ.
ẹni tí ó ńi oògùn ti kò ní àyà kò lágbára tó ẹni tí ó ní àyà tíkò ní oògùn rárá.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Awọn olukọ gbọdọ tẹle ilana itakete-sira-ẹni lasiko ti wọn ba n kọ awọn ọmọ.
Ṣugbọn OLUWA tí ó wà láàrin ìlú Jerusalẹmu jẹ́ olódodo, kì í ṣe ibi, kìí kùnà láti fi ìdájọ́ òdodo rẹ̀ hàn sí àwọn eniyan rẹ̀ lojoojumọ.
Àwọn oniròyìn ló tú àṣírí ààbò Prof Peller, tí wọn fi ri pa - Lady Peller Donald Trump ní Joe Biden wọlé ìbò ààrẹ Amẹrika ṣùgbọ́n.
Ẹfunroye Tinubu - Ògbóǹtagí oníṣòwò, olówò ẹrú àti afọbajẹ Ẹfunsetan Aniwura, obìnrin tó ju ọkùnrin lọ O ni ko si aniani pe, awọn obinrin lo ni idile ati orilẹede, nitori naa bantẹ adura wọn gbọdọ le, bẹẹni wọn ko gbọdọ kaarẹ ninu ṣiṣe ojuṣe wọn gẹgẹ bii iya.
" Adari ipolongo fun ile iṣe redio naa, David Ajiboye lo sọ ọrọ ọhun di mimọ lasiko to n ba awọn oniroyin sọrọ ninu ọgba ile iṣẹ naa to wa ni opopona Challenge, Ibadan.
Ẹ̀ ń yọ kòkòrò tín-tìn-tín kúrò ninu ohun tí ẹ̀ ń mu, ṣugbọn ẹ̀ ń gbé ràkúnmí mì mọ́ omi yín!
Elihu ti fẹ́ bá Jobu sọ̀rọ̀ tẹ́lẹ̀, ṣugbọn ó dákẹ́, nítorí àwọn àgbà tí wọ́n jù ú lọ ni wọ́n ń sọ̀rọ̀.
Cardi B leaked video: Cardi B ṣàlàyé ohun tó gbé fọ́tò ìhòhò rẹ̀ d'órí ayélujára Instagram
Ẹ ̀ rọ Ìmúsáré hádrónì gbàngbà tabi large hadron collider ( lhc ) ni ero imusare eruku pelu okun totobijulo ati togajulo lagbaye .
“Ṣugbọn, kí ni mo jẹ́, kí sì ni àwọn eniyan mi jẹ́, tí a fi lè mú ọrẹ tí ó pọ̀ tó báyìí wá fún Ọlọrun tọkàntọkàn?
Àwọn eniyan Bẹtẹli ati Ai jẹ́ igba ó lé mẹtalelogun (223)
Bí àwọn afọ́jú náà ti jáde, bẹ́ẹ̀ ni àwọn kan mú ọkunrin kan, tí ẹ̀mí èṣù mú kí ó yadi, wá sọ́dọ̀ Jesu.
Wọn yóo kọjá lọ lórí ilẹ̀ náà ninu ìnira ati ebi; nígbà tí ebi bá pa wọ́n, wọn yóo máa kanra, wọn óo gbé ojú wọn sókè, wọn óo sì gbé ọba ati Ọlọrun wọn ṣépè.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Àjọ FIFA f'àmì ẹ̀yẹ dá Luka Modric lọ́lá Ọpọlọpọ ololufẹ ere bọọlu ti wọn fi ero wọn han loju opo Twitter ni wọn bu ẹnu atẹ lu igbẹsẹ ajọ FIFA lati gbe ami ẹyẹ naa fun Modric, fun apẹrẹ Vic Rattlehead ati Carter V sọ pe Cristiano Ronaldo ni ami ẹyẹ naa tọsi ju.
Eyi ko si sẹyin iroyin ibọn yinyin awọn ṣọja si awọn oluwọde nibẹ, ti ọpọlọpọ si n fi ero wọn han lori iṣẹlẹ naa atawọn ohun gbogbo to tẹle.
Oríṣun àwòrán, Eniola Gold Asoju fun alukoro Olopaa nipinle Ondo, Funmi J.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Kò bújúmu kí owó epo ní Nàíjíríà dínwó ju ti Saudi lọ - Buhari Bọ́ síta láti ṣe ìwọ́de mọ́ ìjọba Nàìjíríà lónìí, ko rugi oyin - Iléeṣẹ́ ọlọ́pàá Ẹ̀yin ọlọ́pàá 10,000 tí ọ̀gá ọlọ́pàá gbà ṣíṣẹ́ ní 2019, ẹ padà sílé - Iléẹjọ́ pàṣẹ Ọjọ́ ìbí bàbá mi ni aàrùn ọkàn ṣekúpa màmá mi lójijì- Davido Ìjọba Kwara kéde ọjọ iwọlé àwọn akẹkọọ lẹyìn ìséde Covid 19!
Olukuluku mú ohun tí ó fi ń sun turari lọ́wọ́, èéfín turari sì ń fẹ́ lọ sókè.
abajade esi ibo naa ni ọjọ keji ati ọjọ kárùn ún ,osu kẹ́rin , odun yii.
Orúkọ Amutọrunwa jẹ ọkan lara orukọ ti iran Yoruba maa n sọ ọmọ wọn yatọ si orukọ abísọ, orukọ ẹ̀sìn, orukọ inagijẹ, oriki, orukọ idile ati bẹẹ bẹẹ lọ.
Nigba ti asofin Saraki n ba awon
Ọdun 2012, 2016 àti 2020 ni John Mahama àti Nana Akufo-Addo ti jọ ń figagbága dupò aàrẹ Ghana Irọ́ ni pé mò kò Palliatives"" pamọ́ sí ilé mí-Abike Dabiri-Erewa Gbọ́yì-sọ̀yí àti ìròyìn èké láti ọ̀dọ̀ àwọn olólùfẹ́ wa ló ṣáábà ma ń da ìgbéyàwó àwọn òṣèré rú- Ọpẹ Ayeola Ọlọ́jọ́ padà dé!"
Ẹni keji ti a gbọ pe o koju agbebọn naa lanfaani lati sọ iriri rẹ fun awọn akọroyin, ti awọn eeyan si kan sara si oun naa.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù ACCORD, ANRP Kwara: Ẹ kòlè tìtorí APC, PDP fagilé ìwóde 16 Sẹ́rẹ́ 2019 Oríṣun àwòrán, Google Àkọlé àwòrán, Ẹgbẹ òsèlú ANRP àti ACCORD ti fèsì sì ìgbésẹ̀ ìpínlẹ̀ Kwara láti fagilé ìwóde ìtagbangba nítorí ìwà jàgídíjàgan.
"Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Jude Chukwuka: Wọ́n yóò fi ojú ọlọgbọ́n wo akúrí tó bá sọ ojúlówó èdè Yorùbá Ghebreyesus ṣalaye pe ""Ni temi o, iwa ipaniyan ni ki eeyan maa ṣe jibiti lori irinṣẹ idabo bo ara ẹni, nitori ti awọn oṣiṣẹ eto ile ilera ko ba ni awọn irinṣẹ naa, a n fi ẹmi wọn ati awọn ti wọn n tọju sinu ewu ni."
Nítorí bẹ́ẹ̀ ni Oluwa pa láṣẹ fún wa nígbà tí ó sọ pé: ‘Mo ti fi ọ́ ṣe ìmọ́lẹ̀ fún àwọn orílẹ̀-èdè yòókù,kí ìgbàlà mi lè dé òpin ilẹ̀ ayé.
Bi awọn kan ṣe n sọ pe odaa bẹ, lawọn miran n sọ pe ko yẹ ko ri bẹẹ nitrori akoko awọn akẹkọọ n lọ lai duro.
Ero mi lori awọn nnkan wọnyii wa fidi mulẹ lasiko idibo lati yan oludije fun ipo gomina eleyi ti o waye laipẹ yii.
 Àwọn òṣìṣé ìlera bùràsílí gbaninímọ ̀ ràn ní ọdún 2015 pé kí àwọn òbí ronú mímú oyún kúrò nítorí ìtànkálẹ ̀ asì gbaninímọ ̀ ràn pé àwọn aláboyún kò gbọdọ ̀ rin ìrìn-ajò lọ ibi tí àjàkálẹ ̀ àrùn wà .
Ní ti èémí ko sí eni tó mọ iye kòkòrò Coronavirus yìí to n jáde lẹ́ẹ̀kan náà, Ṣùgbọ́n Bromage sọ pé ìwé ìgbà dé gbà kan sọ pé ẹnikẹ́ni to bá ní ọ̀fìnkìn, ó máa ń ti kòkòrò mẹ́ta sí ogún jáde láàrín ìṣẹ́jú kan.
Oríṣun àwòrán, Twitter/HQNigerianArmy Inu igbo ni pupo awọn to ba gomina ipinlẹ Borno naa rin ,fi aya wọ pamọ si Awọn ikọ agbebọn Boko Haram n ṣe ọpọlọpọ ọṣẹ lagbegbe ila oorun ariwa orilẹede Naijiria, iroyin to si n jade ni pe ọpọ emi ati dukia ni wọn fi ṣofo nibẹ.
Kò pẹ́ tí wọ́n tún fi gbàgbé iṣẹ́ rẹ̀,wọn kò sì dúró gba ìmọ̀ràn rẹ̀.
Johanu wí fún un pé, “Olùkọ́ni, a rí ẹnìkan tí ó ń fi orúkọ rẹ lé àwọn ẹ̀mí èṣù jáde, ṣugbọn a gbìyànjú láti dá a lẹ́kun, nítorí kì í ṣe ara wa.
Gbogbo àwọn tí wọ́n bá ti dé ibi tí Asaheli kú sí, ni wọ́n ń dúró.
Akin àti Ilésanmí wá filísíà yìí lọ sí pètéèsì aláwò pupa rúsúsúsú.
Bakan naa, Makinde fi kun un pe awọn yoo mojuto iṣoro ọrọ aje to ti pa awọn araalu lara.
O ni ni asiko ti igbakeji aarẹ ti kọkọ wa ba oun lalejo ni ipinlẹ Imo lo ti fun oun ni imọran lati maa fọnrere awọn iṣẹ ti oun ba n ṣe.
Ẹ má bẹ̀rù àwọn tí wọ́n lè pa ara yín, tí wọn kò lè pa ẹ̀mí yín.
N óo gbé darandaran kan dìde tí kò ní bìkítà fún àwọn ẹran tí wọ́n ń ṣègbé, kò ní tọpa àwọn tí wọn ń ṣáko lọ, tabi kí ó wo àwọn tí ń ṣàìsàn sàn, tabi kí ó fún àwọn tí ara wọn le ní oúnjẹ.
Musa Shuabu so pe”A ti mu ipinnu wa sẹ, nitori ifẹ ti a ni si orile ede Naijiria lati da ajọ kan silẹ, ti yoo maa gbogun ti itankale aarun kogboogun .
 Awon adari mejeeji naa koko   pade ni ipade ajo isokan agbaye nibi aseje ti Trump se pelu awon adari orile ede Afirika kan.
Awon akonimoogba miiran ti ajo ohun tun ni lokan lati pe ni: Roberto Mancini, Antonio Conte ati akonimoogba iko agbaboolu Leicester ri, Claudio Ranieri, leni ti o n tuko agbaboolu Nantes bayii.
    Ìgbà tí a de “pàkúté Èṣù” yìí nǹkan tí ó kọ́ fi hàn án ni owó góòlù tí ó pọ̀ tí ó pupa dẹ̀dẹ̀ tí o ń dán yinrinyinrin.
Ọrọ yii da wahala sil laarin aarẹ Buhari ati awọn aṣofin, eyi to mu ki owo iṣuna naa o pẹ ki wsn to fọwọ si i.
Inú wọn dùn nítorí Bádérù ti ṣọṣẹ́ fún ọ̀pọ̀lọpọ̀ ènìyàn láàrin ìlú.
Nígbà tí Sedekaya ọba Juda ati àwọn ọmọ ogun rẹ̀ rí wọn, wọ́n sá.
Ilé ìgbìmọ aṣofin ti dájọ tí wọn ó fọwọsi àbádofin ìsúna 2019 Ààrẹ Abdulaziz Bouteflika ti kowe fipo silẹ Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Èéfín turari ati adura àwọn eniyan Ọlọrun gòkè lọ siwaju Ọlọrun láti ọwọ́ angẹli náà.
Ẹ le fẹ̀ jù báyìí lọ tàbí kí ẹ rẹ̀ lọ́nà tí yíò mu kúnrẹ́rẹ́.
Ọkan lara awọn ajunilọ, tii fi ọwọ ọla gba ni loju ni ọkunrin kan nilu Eko, ti ọpọ eeyan mọ si Eji Gbadero, o lowo, o lọla, to si gbajumọ ni saa ọdun 1970 wa soke, bi igbe aye ati iku rẹ si ṣe lọ ree, gẹgẹ bi a ṣe ka a ni oju opo itakun agbaye.
Iru awọn iroyin ti ẹ le nifẹ si: Fela ni awokọṣe mi -Ọga akọrin RCCG Ọbẹ ẹgusi Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí 3 sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 2:23 Fídíò, Water Generator: Ó leè ṣiṣẹ fún wákàtí mẹfà, kó tó sinmi, Duration 2,2310 Òkùdu 2020 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
Adari iwọde Amotekun nilu Akure, Tola Ogunlalaka ṣàlàyé pé, akoko ti tó kí ètò alajumọse naa bẹ̀rẹ̀ àti wí pé, ẹranko tí ó jẹ Amotekun leè ṣọdẹ dáadáa.
 Díẹ̀ ló kù kí ọjọ́ ìkúnlẹ̀ di ọjọ́ ikú fún ìyá mi lọ́jọ́ tó bí mi - Seyi Makinde Àwọn àgbàgbà òkè ọya ń fẹ́ kí Ààrẹ Buhari kọ̀wé fipò sílẹ̀ Àwọn afurasí ṣá ìgbákejì kọmísọ́nà ọ̀gá ọlọ́pàá láàké dójú ikú Wo ọ̀rọ̀ tí Asiwaju Bola Tinubu fi síta lórí ìṣòro ètò àbò Nàìjíríà Sójà obìnrin lù mí lálù bami nílùú Ibadan Nkechi Blessing vs Toyin Abraham: Nkechi tí tọrọ ìdáríjí ẹ̀ṣẹ̀ lọ́wọ́ akẹgbẹ́ rẹ̀, Toyin Abraham Nigba ti mo wa ni kekere orukọ naa ko jẹ ajoji si mi.
eto idibo to tun n bọ.
Ajimajaṣan Àkọlé àwòrán, Ere ọlọsọọsẹ ni o mu ki Ajimajaṣan o di gbajugbaja Ni ọjọ kejidinlogun oṣu kẹwa ọdun 2018 ni alagba Ọla Ọmọnitan ti ọpọ mọ si Ajimajaṣan jade laye.
Oshiomole sọrọ yii nibi ipolongo oṣelu ẹgbẹ APC nilu Kano, nibi to ti n ki awọn ti wọn ṣẹṣẹ darapọ mọ ẹgbẹ APC latinu ẹgbẹ oṣelu alatako PDP, kaabọ sagbo ẹgbẹ naa.
Ati pe awọn n fi ifẹ han si ẹni to ba tọ si, ati ibinu si ẹni to ba mu inu bi wọn, tabi tapa si igbagbọ wọn.
Njẹ́ o dá ayédèrú ìròyìn mọ̀ tí o bá ri i?
Day 22: Ṣé ẹni tí yóó borí ní ìdìbò 2019 ṣe pàtàkì bí?
ADEBOYE/FACEBOOK Àkọlé àwòrán, Alufa Agba Adeboye Oju opo Twitter ti n gbana lati nnkan bi wakati melo kan.
Síbẹ̀, àwọn akẹ́kọ̀ọ́ ilé-ẹ̀kọ́ gíga ṣe àròjinlẹ̀.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Amotekun: APC ń fẹ́ káwọn ẹkùn yókù wàwòkọ́ṣe Ikọ̀ àbò àmọ̀tẹ́kùn fún àbò ẹkùn wọn 9 Sẹ́rẹ́ 2020 Oríṣun àwòrán, @PoliceNG Ẹgbẹ oṣelu APC ti rọ awọn ẹkun miran lorilẹede Naijiria lati ya omi ọgbọn bu mu lori eto abo tuntun 'Operation Amọtẹkun' tawọn ijọba lẹkun iwọ orun gusu orilẹede Naijiria ṣẹṣẹ fẹ gbe sita eyi ti wọn yoo fi lọọlẹ lonii.
atunse si), won ko letoo lati foruko oludije sile.
Èmi kọ́ ni mo fi mo fi fídíò ọmọ mi sí ayélujára - Ìyá 'Mummy calm down' Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí 2 sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
Helicopter crash in Lagos: Àbájáde ìwádìí ẹlikọ́pítà to já ni Opebi laipẹ yii ti jáde
Ṣugbọn nisinsinyii, a ti wẹ̀ yín mọ́, a ti yà yín sọ́tọ̀, a ti da yín láre nípa orúkọ Oluwa Jesu Kristi ati nípa Ẹ̀mí Ọlọrun wa.
Wọn yọ Aarẹ Tunisia nigba kan ri, Zine el-Abedine Ben Ali ni ọdun 2011 lẹyin to lo ọdun mẹtalelogun ni ipo.
Eyi lo mu ki BBC kan si akọwe iroyin agba fun gomina ipinlẹ Ekiti fun alaye lati yọ kọọkundun ọrọ naa sita.
Àwọn ọmọ rẹ̀ yóo máa wá ojurere àwọn aláìní,wọn yóo sì san ohun tí baba wọn gbà lọ́wọ́ aláìní pada.
Ó kìlọ̀ fún wọn kí wọn má ṣe polongo òun, 
Arabinrin Philomina Chieshe ni wọn fẹsun kan pe, o na owo ajọ to n mojuto ṣiṣe idanwo igbaniwọle sile iwe giga ni Naijiria, JAMB.
Igbimo naa tun fi oro ohun mule, ijọba apapo ko lati fi oro naa lo awon, nitori won mo pe, ko si ile ti o po repete ti o le fayegba didaran ohun.
9 183630 Orilẹede Moldova 2500 61.
Ẹni tí ó rán òmùgọ̀ níṣẹ́ gé ara rẹ̀ lẹ́sẹ̀,ó sì ń mu omi ìjàngbọ̀n.
Sunday Igboho dá sí ọ̀rọ̀ ìbejì Akeugbagold tí wọ́n jí gbé Ọwọ́ àwọn alásẹ ọgbà ẹ̀wọn ní ọ̀daràn to ni Corornavirus wà báyìí-Kọmísọ́nà ìlera Ondo 'Ó ṣeéṣe kí Ààrẹ Buhari pàṣẹ ìgbélé jákèjádò Nàìjíríà lónìí' Àwọn àràmọ̀ndà ìbomú-bẹnu tó gbòde lásìkò Coronavirus yìí O ni oun fi ọrọ to awọn alaṣẹ ijọba apapọ titi kan igbakeji aarẹ leti pe ina wahala ajakalẹ arun Coronavirus n jo dorii koko ni ipinlẹ Kano ṣugbọn ko si ohunkohun ti ohun ri gbọ pada lori rẹ.
"O ni eto kan ti ikọ̀ oun s'agbekalẹ̀ rẹ̀, ti wọn n pe ni DEEP PUNCH lo ti tu ipagọ awọn Bokoharam ka, ti awọn si ti gba ibudo wọn kan ti wọn n pe ""Camp Zaro"" ninu igbo Sambisa."
Wọn ni bi ayẹwo DNA wa waye lori iru ọmọ bẹẹ, ni ọkọ yoo to mọ pe ọmọ ọlọmọ ni oun n pe ni ọmọ oun.
Gomina naa tun seleri pea won yoo fi iya jẹ enikeni to ba lọwọ ninu isẹlẹ
Ile ẹjọ giga niluu Abuja ri aridaju pe Ọgbẹni Olisa Metuh jẹbi gbogbo ẹsun ti wọn fi kan an lori owo irinwo miliọnu naira pe o gba lọwọ Sambo Dasuki laye ijoba Jonathan.
Moghalu ti ṣiṣẹ́ rí ní United Nations láti ọdún 1992 sí 2008.
 àkóràn kòkòrò àìlèfojúrí bacteria ran àwọn ènìyàn bíi mílíọnù 155 tí cellulitis sì ran ènìyàn bí mẹ ́ tàdínlógójì ní ọdún 2013 .
Nigba to n fesi si ọrọ naa, Adagunodo salaye pe PDP yoo lo ẹbi ati ara Adeleke fun idije si ipo oselu ni ipinlẹ naa nitori wọn ni ero to pọ lẹyin wọn, paapaa awọn ọmọ ẹgbẹ to pọju.
Àwọn ènìyàn nìkan ni irúfẹ ́ ẹranko tí àràn sòbìà ń mú .
"Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Plea Bargain: Agbẹjọ́rò ní apanìyàn nìkan ní kò le è bẹ̀bẹ̀ láti dá ẹ̀mí tó pa padà 26 Bélú 2019 Oríṣun àwòrán, Pulse Àkọlé àwòrán, 'Olóṣèlú o, ọ̀dọ́ o, afurasí o, kò sẹ́ni tí kò lè dúnàá dúrà ""ẹ má fi mí jófin' Laipẹ yii, ọpọlọpọ iwa jibiti, jẹgudujẹra, lilu owo ilu ni ponpon tabi ṣiṣe e baṣubaṣu wọ pọ lorilẹede Naijiria, ti ijọba si n fi awọn eeyan kanjofin."
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ghana Vs Nigeria trade war: Eyín àti ahọ́n a máa bá ara wọn jà, ọ̀kan ṣoṣo ni Nàìjíríà àti Ghana 31 Ògún 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 2 Owewe 2020 Oríṣun àwòrán, Speaker media department Agbẹnusọ ile igbimọ aṣojuṣofin Naijiria, Femi Gbajabiamila ti ṣe ipade pẹlu akẹgbẹ rẹ nilẹ Ghana lọna ati petu saawọ to n waye laarin orile-ede mejeeji.
Bí mo sì ti rii pé wọ́n n sunmọ wa, mo dìde dúró, mo ké ní ohùn rara, mo ni, ‘Àlááfìaà ni ẹ̀yin ń bá bọ̀ àbí kùmọ̀?
Irufẹ eso ajaabalẹ yii wulo fun awọn eeyan ti ẹjẹ ara wọn ko to rara, ti eroja Iron to wa ninu rẹ yoo si tete mu ki ẹjẹ pọ lara wọn.
Wọ́n fi Èdìdì Di Majẹmu Wọn Pẹlu Ọlọrun.
Èémí wọ inú wọn, wọ́n sì di alààyè; ogunlọ́gọ̀ eniyan ni wọ́n, wọ́n bá dìde dúró!
Àkọlé àwòrán, Ọrọ lori iroyin ofege Ṣoyinka ṣalaye pe ọpọ igba ni oun paapa ti lugbadi ayederu iroyin.
Ìrìnkánkán náà jẹ ́ dídámọ ̀ pẹ ̀ lú ìwọ ́ de nínlá ìkọ ̀ yà aráàlú .
Wọ́n dá a lóhùn pé, “Máa lọ, nítorí OLUWA yóo jẹ́ kí ọwọ́ rẹ tẹ̀ ẹ́, yóo fún ọ ní ìṣẹ́gun lórí rẹ̀.
Igbimọ amuṣẹya ti ijsba apapọ gbe kalẹ lori arun coronavirus lo sọ bẹẹ lasiko ifọrọwerọ rẹ pẹlawọn oniroyin.
Ṣugbọn àwọn tí wọn kò ka ọ̀rọ̀ OLUWA sí fi àwọn ẹrú ati àwọn ohun ọ̀sìn wọn sílẹ̀ ninu pápá.
Oríṣun àwòrán, @Makinde Ni ibẹrẹ ọdun yii ni wọn ṣe ayẹyẹ ọgọrin ọdun ti mama naa pe lorilẹ aye.
Ṣugbọn bí ó bá jẹ́ pé fèrè kan ni wọ́n fọn, àwọn olórí ẹ̀yà Israẹli nìkan ni yóo wá sọ́dọ̀ rẹ.
Èṣù tọ́ka sí i ó wí pé ‘Ìgbà tí mo ba wa sí ayé tí mo ti ọmọ ènìyàn mu owó wó, owó tí kì í ṣe tíwọn, wọn kò ń mọ̀ pé ejò ọka ni àwọn ti ọwọ́ bọ̀ lẹ́nu.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Nigeria 2019 election: Jàndùkú yìnbọn f'ọ́mọ ọdún mọ́kànlá lẹ́sẹ̀ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Nigeria 2019 election: Jàndùkú yìnbọn f'ọ́mọ ọdún mọ́kànlá lẹ́sẹ̀ 18 Èrèlè 2019 Kayefi nla ṣẹlẹ nipinlẹ Oṣun lẹyin ti afurasi janduku oloṣelu kan yinbọn fun ọmọdebinrin kan Rukayat Balogun ọmọ ọdun mọkanla nilu Iwara.
Lootọ ni wi pe irufẹ iwa yi a ma mu iriwisi ọtọọtọ wa ṣugbọn ko daju wi pe awọn ara ilu ko ni ye wu iru iwa bayi si awọn olori wọn.
Popona Ikorodu (Laarin ọjọta si iyana Anthony) 6.
Ẹ̀yin tí ẹ̀ ń fi ipá kó èrè burúkú jọ tí ẹ óo fi kọ́ ibùgbé sí ibi gíga, kí nǹkan burúkú kankan má baà ṣẹlẹ̀ si yín!
 oun ni alase ati oludasile ile ise akojopo eleganza , ti o n ta oja jake jado ile adulawo ( western africa ) .
23 Ìgbé 2019 Oríṣun àwòrán, Google Àkọlé àwòrán, Àjọ ìdánwò JAMB ti bẹ̀rẹ̀ ìwádìí lórí àwọn tó se màgòmágó lásìkò ìdánwò láti ọdún 2009 sí 2019.
Oríṣun àwòrán, @Virtua Health Àkọlé àwòrán, Oto leni ti won fe fun ni kindinrin, oto ni eni ti won sise fun Amọ, Blaber ni o yẹ ki ayẹwo finifini le dena aṣiṣe yii, bo tilẹ jẹ pe iru rẹ ko wọ pọ.
Ìkọlù Afghanistan: Akọ̀ròyìn BBC àti èèyàn mẹ́jọ jáláìsí
yii nitori pe mo bowo pupo fun orile-ede Naijiria ati awon agbaboolu re ti a ti
Aaroni ati àwọn àgbààgbà Israẹli sì wá sọ́dọ̀ Jẹtiro, láti bá a jẹun níwájú Ọlọrun.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Osun Strike: Gbèdéke ọjọ́ méje ni àwọn olùkọ́ ilé ẹkọ́ gíga fún ìjọba 3 Agẹmo 2019 O da bi ẹni pe gbẹgẹdẹ fẹ gbina laarin awọn olukọni kaakiri awọn ileewe giga mẹrẹẹrin to wa ni ipinlẹ Ọṣun.
"A maa fun wọn ni ọwọ ti wọn, a maa se nkan to tọ si wọn, ti gbonmisi-omi o to ba si wa baba le pe mi a o si yanju rẹ ni pẹlẹpẹlẹ"" Iléeṣẹ́ ìròyìn Daily Trust gbọdọ̀ san N6 bilion nítorí ìbanilórúkọjẹ́- Femi Fani Kayode Sinimá àwòdamiẹnu, Ẹ̀fáńjẹ́líìsì jìyà àjẹmumi nílé aṣẹ́wó l'Ejigbo ní ìlú Eko Ìjàmbá ọkọ̀ tó ṣẹlẹ̀ sí Adams Oshiomole kìí ṣe ojú lásan, àwọn kan ló fẹ́ pa á- APC Ọba Saudi Arabia yọ ọmọ rẹ̀ àti àbúrò rẹ̀ kúrò nípò nítorí ìwà àjẹbánu lórí owó tó yẹ fún ààbò ìlú Ìjọba ìpínlẹ̀ Kogi kéde ọjọ́ ìwọlé àwọn akẹ́kọ̀ọ́ padà sí iléèwé Oríṣun àwòrán, Nigerian Tribune Ohun tí a mọ̀ nìyí nípa gbọ́nmi síi omi ò tó lórí ọ̀rọ̀ oyè Babaloja-General ní ìpínlẹ̀ Oyo Kí ló ń fa gbọ́nmi síi omi ò tó lórí ọ̀rọ̀ oyè Babaloja-General ní ìpínlẹ̀ Oyo?"
N30m lawọn to ji Komisana gbe l'Ekiti fẹ gba kí wọn tó tú u sílẹ̀-Mọlẹbi Oríṣun àwòrán, Getty Images Awọn to ji Komisana eto ọgbin gbe ni ipinlẹ Ekiti ọgbẹni Folorunsho Olabode gbe ti beere ọgbọn miliọnu naira gẹgẹ bi owo tawọn yoo gba ki wọn to tu silẹ.
Ile-isẹ márùn ún to n setọju aarun Ebola  ni ikọlu ti de ba losu to kọju, nigba miiran
Mo ti mú kí opó pọ̀ láàrin wọn ju iyanrìn inú òkun lọ.
Ọgbọ́n ní ń mú kí ojú ọlọ́gbọ́n máa dán, á mú kí ó tújúká kí ó gbàgbé ìṣòro.
K Odukoya 'ń gun orí òkè àdúrà nítorí COVID-19'-Wò báwọn èèyàn fi wò wọ́n Iléeṣẹ́ aṣọ́bodè yarí, kò gba ìrẹsì tó bàjẹ́ padà lọ́wọ́ Ṣeyi Makinde Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Megabite: Ilé-ìwé ni mo ti bẹ̀rẹ̀ orin kíkọ Àkọlé àwòrán, Corornavirus: Kini Gómìnà ìpínlẹ̀ Ekiti ṣe fun baba tọ ni ọmọ òun ko gbọdọ tèlé oun déle nitori o ṣẹ̀ṣẹ̀ de lati Eko O kò leè wọ inú ilé mi lẹ́yìn ìrìnàjò láti Eko, lai ṣe àyẹ̀wò Coronavirus - Bàbá yari fún ọmọ Coronavirus symptoms vs cold-O kò leè wọ inú ilé mi lẹ́yìn ìrìnàjò láti Eko, lai ṣe àyẹ̀wò Coronavirus - Bàbá yari fún ọmọ Oríṣun àwòrán, others Yorùbá ni ọmọ ẹni kii burú títí, ká lè fún ẹkùn pa jẹ àmọ́ èyí kò rí bẹ́ẹ̀ pẹlu bàbá kan ni Ondo, tó le ọmọ rẹ síta nítorí ibẹru àrùn Coronavirus.
Idi ree ti awọn ẹbi rẹ se gbe digbadigba lọ sile iwosan fun itọju nigba ti agọ ara rẹ ko mokun mọ Iwadii fi ye wa wi pe, akẹkọọ naa ko ṣẹṣẹ maa gba iru aawẹ bẹẹ nitori ogun idile to ni oun n koju.
N óo fun yín ní ọkàn titun, n óo sì fi ẹ̀mí titun si yín ninu.
Nṣe lo dabi ẹni pe wọn pe ara wọn jọ lati ṣigun bo awọn araadugbo ni.
mo pe orile-ede Naijiria kun fun awon eniyan ti o lamilaaka lauwjo.
ile igbimo asoju lorile ede Naijiria,Femi Gbajabiamila ti fi ibinu rẹ  han bi awon adari ile-ise eleto aabo lorile
Yoruba: Mi ò fẹ́ kí àwọn ọmọ má gbọ́ èdè Yorùbá níbi tí a wà yìí
Ẹni to bori: Guinea Senegal vs Madagascar.
Lẹ́bàá orísun wọnyini àwọn ẹyẹ ń gbé,wọ́n sì ń kọrin lórí igi.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Oman Slave: Ó pe mi kí n máa mu Gari ní Nàìjíríà ju ìlú yẹn lọ o Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Oman Slave: Ó pe mi kí n máa mu Gari ní Nàìjíríà ju ìlú yẹn lọ o 4 Èbibi 2020 Ohun taa jẹ, taa mu, taa fi r'ile aye gbe lo mu arabinrin yii ti a ko le fi oju rẹ han kuro ni Naijiria lọ gba iṣẹ ni orilẹede Oman.
Kò tún ní sí ìró ìdàrúdàpọ̀ ní ilẹ̀ rẹ mọ́,kò sì ní sí ìdágìrì ati ìparun ní ibodè rẹ,o óo máa pe odi rẹ ní ìgbàlà,o óo sì máa pe ẹnubodè rẹ ní ìyìn.
Bi ẹ ko ba ni gbagbe, ni ọjọ Aje ni ileeṣẹ ọlọpaa ni ipinlẹ Ọyọ ṣe afihan awọn afunrasi ti ọwọ awọn ọtẹlẹmuyẹ ọlọpaa mu fun jiji ọmọ Akeugbagold gbe ti wọn si gba miliọnu mẹrin naira ki wọn to fi awọn ibeji naa silẹ.
Ẹ̀tọ́ nìkan ṣoṣo ni kí ẹ máa ṣe, kí ẹ lè wà láàyè, kí ẹ sì lè jogún ilẹ̀ tí OLUWA Ọlọrun yín fun yín.
Bẹẹ ba gbagbe, a mu iroyin wa fun yin laipẹ yii pe lọjọbọ to kọja nileesẹ ọlọpa ipinlẹ Kwara safihan awọn ọmọge, ọkunrin ati ọmọde, ti wọn tu silẹ nile ọmọ alaigbọran kan to wa ladugbo Gaa Odota nilu Ilọrin.
Ní ọdọọdún, Solomoni a máa fún Hiramu ní ọ̀kẹ́ kan (20,000) òṣùnwọ̀n kori ọkà, ati ọ̀kẹ́ kan (20,000) òṣùnwọ̀n kori òróró dáradára fún ìtọ́jú oúnjẹ fún Hiramu ati àwọn eniyan rẹ̀.
Àwọn ọmọ Israẹli tí ó wà níbẹ̀ sì sálọ nígbà tí wọn gbọ́ igbe wọn.
Bàbá mi wí pẹ̀lú féèrè rẹ̀ pé elékèé dìde ní owúrọ̀ ó dúdú bí ọ̀gẹ̀dẹ̀ etí odò, nígbà tí ó di ọ̀sán, elékèé gbẹ bí igi, nígbà tí ó si di àṣáálẹ́ ó ti jóná pátápátá.
Bí ó bá fa ọfà jáde kúrò lára rẹ̀,tí ṣóńṣó orí ọfà jáde láti inú òróòro rẹ̀,ìbẹ̀rùbojo yóo dé bá a.
'A sinmi ìwádìí lóri Kemi Adeosun' Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ọ̀rọ̀ Trump àti Russia kò yàtọ̀ pé àhesọ lásán ni èyí jẹ́ Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Ogunlogo awon omo orile-ede Naijiria, awon oloselu, awon oni-ise owo, awon adari ijoba ologun teleri ti panupo lati ki aare Muhammadu Buhari ku ori-ire ayeye ojo ibi odun mẹ́rìndínlọ́gọ́rin(76th birthday), lori ero ayelujara won kookan.
Bàntẹ́  Ọmọ gbàgbé mi sóko Ègbè Bàntẹ́ 
Ó ti wà lọ́kàn rẹ̀ pé lọ́jọ́ keji ni òun óo tún gbéra.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù #67yearoldmother: Mo kojú ọ̀pọ̀lọpọ̀ àìsàn fún ọdún 35 lẹ̀yín ìgbéyàwò Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ #67yearoldmother: Mo kojú ọ̀pọ̀lọpọ̀ àìsàn fún ọdún 35 lẹ̀yín ìgbéyàwò 28 Ọ̀wàrà 2018 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 29 Ọ̀wàrà 2018 Ìyá ọmọ tuntun: aṣiwèrè ló máa sọ pé Ọlọrun kò sí, Ìyanu ni ọmọ ti mo bí yìí.
Àwọn afurasí lórí ẹ̀ṣùn jíjí ìbejì Akeugbagold gbé yọnú sílé ẹjọ́ láì ní agbẹjọ́rò Tí òṣèré tíátà yóò fi kú, eré ni wọn yóò ló ń ṣe - Ibrahim Chatta Aṣòfin méje yarí mọ́ Akeredolu lọ́wọ́ torí ọkọ̀ ayọ́kẹ́lẹ́ tí kò pín fún wọn Aya gómìnà Kwara gba ilé fún Risikat olójú búlúù àti ọkọ rẹ̀ Ni ti awọn ọmọ ile iwe lati ọmọ ọdun mẹta si marun un, o ni wọn ko lanfaani lati pada sile iwe lasiko yii.
Mẹrin ninu ayẹwo ọhun lo ja si tootọ.
ASUU Strike: Ìpàdé láàárín ẹgbẹ́ olùkọ́ fásitì àti ìjọba jásí pàbó!
N kò ni dá ẹnikẹ́ni sí, ninu àwọn tí wọ́n gbógun tì mí,ati àwọn tí wọ́n ti fara gbọgbẹ́,ati àwọn tí wọ́n dì nígbèkùn,gbogbo wọn ni n óo pa.
Ekunrẹrẹ fidio ifọrọwanilẹnuwo pẹlu Mr Latin wa nibi yi.
O ni gbogbo gomina lo bura lati bọwọ fun ofin nipa ṣiṣe agbekale eto aabo ti yoo rẹsẹwalẹ fun gbogbo awọn araalu.
Wọ́n bá ṣe ère ọmọ mààlúù kan ní àkókò náà, wọ́n rúbọ sí i.
Minisita ilu Abuja, Muhammad Bello sọ pe awọn oluwọde naa ko tẹle ilana coronavirus lo jẹ ki ajọ FCTA gbe igbesẹ yii.
Ó dìde, ó bá tirẹ̀ lọ, ó ṣí ìbòjú rẹ̀ kúrò, ó sì tún wọ aṣọ ọ̀fọ̀ rẹ̀.
Bẹ́ẹ̀ ni ẹnìkan kò rí mi pé mo kó àwọn eniyan jọ láti dá rúkèrúdò sílẹ̀, ìbáà ṣe ninu ilé ìpàdé ni tabi níbikíbi láàrin ìlú.
Àfàìmọ̀ ká máa dá ìforúkọsílẹ NIN dúró tórí ewu coronavirus- Mamora Pásítọ̀ Adeboye kéde ààwẹ̀ ọjọ́ 63 fọ́mọ ìjọ rẹ̀, ariwo sọ lórí ayélujára Iroyin kan ti ko fidi mulẹ lo ni awọn agbegbọn naa n korajọpọ lati gbẹsan ikọlu to waye si wọn lati ọwọ ikọ Amotẹkun lagbegbe naa lọjọ Abamẹta to kọja.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Nítorí ìwọ́de, Amosun àti ẹgbẹ́ òṣìṣẹ́ NLC tutọ́ síra wọn lójú nípínlẹ̀ Ògùn 3 Ẹrẹ̀nà 2019 Oríṣun àwòrán, Amosun ibikunle Àkọlé àwòrán, NLC fẹ́ ṣe ìwọ́de nítorí àìsan owó òṣìṣẹ́, ṣùgbọ́n gómìnà Amosun ní kò sóhun tó jọọ́ Ẹgbẹ oṣiṣẹ NLC ati Gomina ipinlẹ Ogun, Ibikunle Amosun ṣi wa lẹnu ileri 'bi ikun lo loko, bi pakute ni'.
O ni awọn ba Akeredolu se magomago ibo, lati jẹ ko moke ninu idibo naa ni.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Akomolede àti Asa lórí BBC Yorùbá: Mọ̀ síi nípa ẹ̀kún ìyàwó níbí 5) Ekun Iyawo ni aṣa Yoruba ti Alagba Tayọ Saanuade kọ wa ni kilaasi yii.
Nígbà tí ó wí báyìí tán àwọn yanrin wọn-ọnnì yìpadà lóòótọ́ wọ́n di èèrà wọn sì bẹ̀rẹ̀ sí gé àwọn ejò wọn-ọnnì jẹ.
Femi Joseph to jẹ alukoro ni ipinlẹ Ondo lo sọ fun BBC News Yoruba pe awọn eniyan pa ọpọlọpọ irọ nipa ijinigbe naa.
Lọgan ni ẹgbẹ agbaboolu Arsenal ti fi ikan si fun ojugbaa rẹ nigba ti o ku iṣẹju meji ki ere pari.
 idiye ni 2006 so pe iye eniyan ti ojo-ori won wa larin odun 0-14 je 42.
"Ko si si ẹni to fẹ ta oúnjẹ fun wa, ayafi fun awọn to ba mu owo dani lara wa""."
“Lẹ́yìn náà, mú akọ mààlúù náà wá siwaju àgọ́ àjọ, kí Aaroni ati àwọn ọmọ rẹ̀ gbé ọwọ́ lé akọ mààlúù náà lórí.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Olufunke Oshonaike: Ewu ń bẹ fún àwọn obìnrin tó ń fẹ́ ọkọ ọlọ́kọ 26 Owewe 2019 Oríṣun àwòrán, Google Àkọlé àwòrán, Ẹ̀ yin baálé ilé, ẹ yé sátẹ̀lé mi kiri mọ́!
Kí ẹ tilẹ̀ fa ọkà yọ fún un ninu ìtí, kí ẹ sì tún fi í sílẹ̀ láti ṣa ọkà, ẹnikẹ́ni kò gbọdọ̀ yọ ọ́ lẹ́nu.
I must say I received the news of the demise of this great brother and friend with mixed feelings of sadness and gratitude to God.
Obinrin naa, ẹni ọgbọn ọdun, Joyce Kalinda ni wọn sọ pe, o sọ ara rẹ di onimọ iṣegun oyinbo ọsan gangan, to si gbẹbi ara rẹ.
ara àwọn nǹkan tí ó sokùn fa ogun àgbáyé àkọ ́ kọ ́ nìyí ogun àgbáyé àkọ ́ kọ ́ yìí bẹ ̀ rẹ ̀ láàárin orílẹ ̀ -èdè méjì kan tí orúkọ wọn ń jẹ ́ austria-humgary ati serbia .
Ilẹ̀ sì mu àmutẹ́rùn nípa iṣẹ́ ọwọ́ rẹ.
Bi awọn kan ṣe n wi pe ẹyẹ naa nii ṣe pẹlu ikọ agbebọn Boko haram ni wsn ṣe muu lawọn miran n pe arakunrin kan ni o yipada di igun naa lati maa da awọn alabagbe rẹ laamu.
Mo mà tún rí nkan o.
Ohun akọkọ ti o ni lati ṣe lati igba de igba ni ki o ma a ṣe ere idaraya ki ara rẹ ko le mokun, nitori ti ẹ ba koju ole tabi ijamba, ẹni ti ara rẹ ba mokun lo le e sare daadaa tabi farapamọ daadaa.
Amọ, lẹyin to lo ọdun mẹsan lẹwọn, Olootu Ijọba, Abiy Ahmed tu silẹ ni ọdun to kọja.
Komla Dumor: Solomon Serwanjja ọmọ Uganda jáwé olúborí nínú Àmì ẹ̀yẹ BBC Kunle Afolayan, òṣìṣẹ́ báńkì tẹ́lẹ̀ kó tó di gbajúgbajà òṣèré Kíni àwọn ìpèníjà ẹtọ ààbò ṣáájú òmìnira Nàìjíríà?
Egba, Oba Adedotun Gbadebo je ko di mimo pe ohun to le yanju ipenija to n
Afinjú ẹyẹ tí ń jẹ ní gbangban ilé ọba
Àwọn ọmọ ti Lefi ni: Geriṣoni, Kohati, ati Merari.
 alimu ti gbe ni eko , nibi ti o lọ si ile-iwe akọkọ ati ile-iwe giga .
Wọn óo máa pè yín ní,“Àwọn-tí-a-wá-ní-àwárí”;wọn óo sì máa pe Jerusalẹmu ní,“Ìlú tí a kò patì”.
Tani ọlọpọlọ pipe oludokowo Adebayo Ogunlesi to gba aarẹ ile ifowopamọ agbaye ṣiṣẹ?
Kíló ṣẹlẹ̀ gan tí Erica fi tú bí ejò táa gé nírù?
BBNaija: Khafi la Mercy àti Cindi mọ́lẹ̀ nínú abala tó kẹ́yìn ìdíje ọ̀rọ̀ nípa Nàíjíríà
Ṣugbọn pẹlu ìbúra ni, nígbà tí Ọlọrun sọ fún un pé,“Oluwa ti búra,kò ní yí ọ̀rọ̀ rẹ̀ pada:‘Ìwọ máa jẹ́ alufaa títí lae.
Orí Jesu tún wú, ó bá lọ síbi ibojì.
O ni afojusun oun ni lati kọ ẹgbẹ agbọọlu to dantọ, kii kan ṣe lati ko eniyan jọ saa.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù UK Covid Vaccine: Abẹ́rẹ́ àjẹsára Covid-19 yóò dé sí Nàìjíríà nínú oṣù kíní ọdún 2021 10 Bélú 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 16 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Oríṣun àwòrán, WHO Ìjọba orílẹ̀-èdè Nàìjíríà tí kéde pé abẹ́rẹ́ àjẹsára Covid-19 yóò dé sí Nàìjíríà ni inú oṣù kíní ọdún 2021.
Kíló burú nínú kí Sanwo-Olu fún Super Eagles lówó?
Mínísítà ní kò bójúmu fáwọn dókítà láti woṣẹ́ níran lásìkò àrùn Covid-19 Oríṣun àwòrán, others Ijọba apapọ ti paṣẹ fun awọn dokita agba nile iwosan rẹ gbogbo, pe ki wọn fi awọn agunbanirọ to jẹ dokita rọpo awọn dokita to n yanṣẹ lodi.
Orilẹede Naijiria ti bẹrẹ si ni wa ọna lati dẹkun iwa ifipabanilopọ to ti gogo bayii lawujọ, Funke wa lara awọn ilumọọka ọmọ Naijiria to n sọ iriri wọn lori ifipabanilopọ fun igba akọkọ.
Lagos Police: Àwọ̀n ọlọ́kadà 123 láti Jigawa kìí se àwọn agbésùnmọ̀mì
Ńṣe ni eniyan máa ń tọ́jú ara rẹ̀, tí ó sì máa ń kẹ́ ẹ.
Ni bayi ti wọn ti gbe abadofin kalẹ,ti Gomina Matawaale ba file buwọlu,ko ni si Gomina kankan ti yoo ma gba owo ifẹyinti miran lọdọ ijọba ipinlẹ yatọ si eleyi ti igbimọ to n risi pipin owo oṣu fawọn to fi ipo oṣelu silẹ ba la kalẹ fun wọn.
Ayọ̀ ń bẹ fún ẹni tí o yàn,tí o mú wá sí ọ̀dọ̀ rẹ,láti máa gbé inú àgbàlá rẹ.
"À ń bá àwọn onímọ ṣiṣẹ.
Gbigbe ti yoo gbe oju soke, o ṣakiyesi pe ọmọkunrin to n mu onibara naa rin jọ aburo rẹ, ti wọn ti n wa fun ọdun pipẹ, t'oun ti aṣọ idọti lọrun.
O ni eyi ko sọ pe ọdun ohun ko yi pada ati pe o yẹ ki awọn eeyan mọ pe awada lati mu inu ara oun dun lo n jẹ ki oun ṣe ayẹyẹ ọjọ ibi ọdun naa nigba gbogbo.
Iroyin so pe won ti fiya jẹ
Ẹni ti o ṣoju Magu nibi ifọrọwerọ kan pẹlu awọn oniroyin, Friday Ebelo, lọ sọ ọrọ yi nilu Ibadan.
Abba ni eeyan to le ni ẹgbẹrun mẹwaa (10,152) ti wọn fẹsun kan ninu awọn afurasi naa.
Awọn 51,735 ti ri iwosan, 1,115 si ti ku.
Amọ ipele ikeji sikẹta ni awọn arinrinajo ti o ba ṣe abẹwo sibẹ tin pada.
siyaku furest gaskiya Dokin large 160.
Ọgbẹni Shittu to fi ọrọ yii lede ninu ifọrọwanilẹnuwo pẹlu ile iṣẹ akoroyinjọ ilẹ wa, NANS, nilu Abuja wa fikun pe, oun ti gba ọrọ naa gẹgẹ bi akọọlẹ Ọlọrun nilana ẹsin musulumi.
Ilé ìṣẹ́ BBC Yorùbá ṣe àkójọpọ̀ ǹkan Márun ti ó mú Atiku Abubakar fìdírẹmi nínú ìdìbò ọdún 2019 PDP pè fún ìwọ́gilé èsì ìdìbò ààrẹ ní ìpínlẹ̀ mẹ́rin PDP fáríga lórí èsì Idibò Àwọn agbókùú fẹ́ pásítọ̀ tó fi irọ́ jí òkú dìdé ní South Afrika lọ ilé ẹjọ́ Ọkan lára àwọn ọmọ Naàìjíríà tó bá BBC Yoruba sọ̀rọ̀ ọjọgbọ́n Dikirullai sàlàyé pé Bí Atiku ṣe wọ inú ìdíje ní ọ̀pọ̀ àbàwọn nínú nítori àwọn ǹkan tí ààrẹ Obasanjọ ti sọ nípa rẹ̀ tẹ́lẹ̀.
Ṣaaju ni aworan oloogbe kan ti wọn pe orukọ rẹ ni Francis jade si ori ayelujara.
O dabi ẹni pe irufẹ ara yii naa ni wọn fẹ fi bẹrẹ pẹlu eroja aka ohun silẹ naa.
John McCain jẹ akinkanju ajagunfẹhinti ogun Vietnam to pada wa di ọkan gboogi lara awọn oloselu ni ilẹ Amerika.
Ẹni tí ó fẹ́ràn wa, tí ó fi ẹ̀jẹ̀ rẹ̀ dá wa nídè kúrò lọ́wọ́ ẹ̀ṣẹ̀ wa.
Lọjọbọ ni idajọ t'awọn eeyan ti n reti yi waye niwaju ile ẹjọ ti adajọ Jane Inyang dari rẹ.
8bn) ti ariwa owo-ifilọlẹ idasi, ti ile-igbinmọ sọ pe olodi s'ofin.
” Wọ́n bá ju Jesebẹli sí ìsàlẹ̀, ẹ̀jẹ̀ rẹ̀ sì ta sí ara ògiri ati sí ara àwọn ẹṣin, àwọn ẹṣin Jehu sì tẹ̀ ẹ́ mọ́lẹ̀ kọjá.
Oríṣun àwòrán, Kayode Ajulo Àkọlé àwòrán, Ajulọ ni lẹyin agbeyẹwo ipade yi lawọn yoo to sọ ohun to kan Bẹẹ́ ba gbagbe, Ogbeni Afegbua pe alukoro ileesẹ ọlọpa, Jimoh Moshood ati awọn ileesẹ iroyin meji mii lẹjọ ibanilorukọ jẹ.
Ati pe ti aye yoo si parẹ ni ọdun 2000 yii.
Awọn ohun miran ti awọn oludije naa sọrọ le lori ni itẹsiwaju ijọba, iyẹn Kọntínúítì, gbèsè ti ijoba ipinle osun jẹ ile ifowopamọsi banki agbaye, eto ẹkọ fásitì LAUTECH to dẹnu kole, eto ilera alabọde àti àwọn ìbéèrè mìíràn lo jẹyọ ní ìpàdé ìtagbangba Ọṣun.
Jesebẹli, aya rẹ̀, wọlé tọ̀ ọ́ lọ, ó sì bi í pé, “Kí ló dé tí ọkàn rẹ fi rẹ̀wẹ̀sì tóbẹ́ẹ̀ tí o kò fi jẹun?
Gbajabiamila ni oun fẹ dije lati je ki isọkan
Asiwaju sọrọ, o fa kumookun rẹ yọ, o ni ''to ba wu Atiku o le lọ ṣepade ninu aginju igbo tabi ni Abu Dhabi, ohun to wa nibẹ nipe awọn eeyan lanfani lati pade nibi kibi to ba wu wọn.
Nitori naa, awọn asoju ẹgbẹ oselu maraarun, ni ireti wa pe yoo kopa ninu eto ipade ita gbangba naa, iyẹn Ọmọọba Ayọrinde Adedoyin ti ẹgbẹ oṣelu Accord, Alhaji Abdulrazak Abdulrahman, ti ẹgbẹ oṣelu APC ati Komuredi issa Arẹmu, ti ẹgbẹ oṣelu Labour.
Àwọn tó jí wa gbé fi tìpá-tìkúùkù bọ́ Hijab mi, wọ́n lù mí ní ìlù bàrà - ọmọ ọdún mẹ́rìndínlógún Adari ayẹyẹ naa sọ fun BBC pe ootọ ni pe ilana tuntun ọhun yoo pa iṣẹ wa lara, ṣugbọn idi niyẹn ti a fi din iye ero ti yoo wa nibi eto naa ku""."
Etí ọkunrin náà bá ṣí, okùn ahọ́n rẹ̀ tú, ó bá ń sọ̀rọ̀ gaara.
Ọ̀kan ninu wọn yóo bu ẹ̀kúnwọ́ ìyẹ̀fun kan ninu ẹbọ ohun jíjẹ náà, pẹlu òróró ati turari tí ó wà lórí rẹ̀, yóo sì sun ún gẹ́gẹ́ bí ẹbọ ìrántí lórí pẹpẹ, ẹbọ olóòórùn dídùn sí OLUWA ni.
O ni ẹni to kan lo mọ ni ọrọ ọhun lo fi dabi pe ko ka ijọba lara tó.
Nígbà náà ni Jesu wá pàṣẹ fún àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ pé kí wọn má sọ fún ẹnikẹ́ni pé òun ni Mesaya.
Laifi Ojo pe Aina , eto idibo ti bẹrẹ  ni awon ibudo idibo to wa ni ipinle oyo, ti eto
Dangote, Fayemi pari ìjà láàrin Ganduje àti Emir Sanusi Saraki pín owó ìyọ̀nda rẹ̀ fún ẹbí Leah Sharibu àtàwọn míì Onnoghen k'ọ̀wé ìfẹ́yìntì, Buhari tẹ́wọ́ gbà á Gomina Oyo fẹ́ dá àjọ tó ń gbógun ti ìwà ìbàjẹ́ sílẹ̀ l'Oyo Ijọba ipinlẹ Kaduna to ṣagbekalẹ ofin yii ni awọn eeyan n ṣi ofin naa tumọ ni.
Wò ó bí Alaafin àti aya àkọ́fẹ́ rẹ̀, Olorì Abibat ṣe pàdé ní èwe Wo ọ̀nà tí àwọn ‘ẹ̀lẹ̀ Daddy’ gbà dé ààfin Ọyọ Wo àwọn olorì àgbà mẹ́rin tí Aláàfin ń wárí fún A o ranti pe ni ọdun to kọja ni Ayaba Badra se ayẹyẹ ọgbọn ọdun ni aafin Oyo tilu tifọn, to si n pokiki rẹ lori awọn oju opo ayelujara.
Gbogbo àwọn ọ̀rẹ́ wa níhìn-ín kí ọ.
Ìtàn Mánigbàgbé: Oyenusi ní òun kò bá tí digunjalè, táwọn òbí òun bá lágbára láti rán òun níléèwé
Ẹ wá ojurere OLUWA ati agbára rẹ̀,ẹ máa wá ojurere rẹ̀ nígbà gbogbo.
O dupẹ fun Ọlọrun fun ọpọlọpọ ibukun to fi fun oun lati igba ti oun ti wa loke eepẹ.
OLUWA Ọlọrun ní, “Ní ọjọ́ náà èròkerò yóo wá sí ọkàn rẹ, 
Bá ọmọde wí;bí o bá fi pàṣán nà án, kò ní kú.
Ni ẹka eto ẹko, ipese ina ọba, sisan owo osisẹ ati dida abo bo ilu, owo naa le ni ipa ti yoo ko.
    Èyí àkọ́bí lọ, o rí ẹni kan rà.
À ń dúpẹ́ lọ́wọ́ Ọlọrun nígbà gbogbo nítorí gbogbo yín, a sì ń ranti yín ninu adura wa nígbà gbogbo.
Election Tribunal: Ẹ̀rù tó ń ba APC ni wọ́n ṣe kọ̀wé sáwọn ọ̀tẹlẹ̀múyẹ́
8 wọlé lójúmọ́ lẹ́yìn tíjọba ti ẹnu bodè -Ali Aarẹ Buhari ti de si ọdọ Aarẹ Ramaphosa ni Pretoria ni South Africa Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Nigeria Independence Day: Wo ìlérí tí àwọn ènìyàn ṣe Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
A níláti kó àwọn ẹran ọ̀sìn wa lọ, a kò ní fi ohunkohun sílẹ̀ lẹ́yìn, nítorí pé ninu wọn ni a óo ti mú láti fi rúbọ sí OLUWA Ọlọrun wa; a kò sì tíì mọ ohun tí a óo fi rúbọ, àfi ìgbà tí a bá débẹ̀.
O ni nitori naa bi aarẹ ana ọhun ṣe le e sọrọ ni awọn eeyan ọhun naa ni ẹtọ lati sọ tinu wọn.
Eto ẹkọ ti bẹrẹ ni pẹrẹwu nile ẹkọ 'The International School' to n bẹ ninu ọgba fasiti ilẹ Ibadan, lẹhin ọṣẹ kan ti wọn ti gbe ilẹkun ile ẹkọ naa ti lori awuyewuye to waye nipasẹ awọn akẹkọ kan to wọ Hijab lọ sinu kilaasi wọn.
Ó ń tẹ̀lé e lọ pẹlu àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀.
" Ẹgbọn oloogbe naa, Chinenye, ke gbajare lori Twitter pe oun fẹ idajọ to tọ lori iku aburo oun.
Wọ́n rò pé ìkáwọ́ wọn ni ọlà wọn wà,nítèmi n kò lè tẹ̀lé ìmọ̀ràn àwọn eniyan burúkú.
Èkejì sì dáhùn, ó ní ‘Ó yà mí lẹ́nu ṣùgbọ́n oògùn náà mà kúkú lágbára o, bí ó bá ti fi í fún ọ̀gá wa, wéré ọ̀gá a sùn kò sì ní i jí àfi bí obìnrin náà bá tìkaraarẹ̀ jí i.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Mama Arsenal: Màmá àgbà yìí máa ń lọ sí ìbùdó tí wọ́n ti ń wo bọ́ọ́lù láti wòran O pọn dandan ki awọn akẹkọọ to ba n bọ ni ileewe lo ohun elo ibomu, nigba ti awọn alaṣẹ ileewe yoo ri pe awọn akẹkọọ tẹle ofin ijinasiraẹni, ipese omi lati fọ ọwọ wọn lore-koore, ipese ẹrọ ti wọn fi n mọ bi ara ṣe gbona si, ati bẹẹ bẹẹ lọ."
Wọ́n fún àwọn aláṣẹ ati àwọn gomina tí ọba yàn fún àwọn ìgbèríko tí wọ́n wà ní òdìkejì odò ní ìwé àṣẹ tí ọba pa; àwọn aláṣẹ náà sì ṣe ìrànlọ́wọ́ fún wọn ati fún iṣẹ́ ilé Ọlọrun.
AFCON2019: Idije òní á yàtọ̀ láàrin Super Eagles ati BafanaBafana
N kò ní agbára kankan mọ́, kò sì sí èémí kankan ninu mi, báwo ni èmi iranṣẹ rẹ ti ṣe lè bá ìwọ oluwa mi sọ̀rọ̀?
Yinka Ayefele di asojú Àjọ INEC Ayefẹlẹ bá BBC sọ̀rọ̀ lórí ilé orin rẹ̀ tí Ajimọbí ń tún kọ́ Ayédèrú Afenifere ló bá Buhari ṣépàdé - Odumakin gbanájẹ A kò lè gba àwọn jandùkú Fulani láàyé nílẹ̀ Yoruba -Awọn gómínà Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
buruku yii , o  wa fi okan awon omo ipinle
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Cerebral Palsy: àrùn tó n gba omijé lójú ẹni láìnídìí Ni ipari àwọn mejeeji tun ṣe ileri lati gbiyanju agbara wọn ki wọn fọwọsowọpọ pẹlu awọn to n wa alaafia ati idagbasoke iran Yoruba ati Naijiria lapapọ.
Kwara Bursary: Àwọn akẹ́kọ̀ọ́ Kwara Poly ṣèwọ́de fún owó ìrànwọ́ ẹ̀kọ́
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Church of Satan: Báwo ni ìjọ́sìn ṣe n rí nínú ìjọ Sátánì?
Ìjọ̀ba Saudi ti tú Zainab tí wọ́n fẹ̀sùn òògùn olóró kàn sílẹ̀ Ijọba Naijiria ti kede pe wọn Zainab Habib Aliyu to wa ni ẹ̀wọ̀n l'orilẹede Saudi Arabia lori ẹsun gbigbe oogun oloro ti gba ominira.
Ṣugbọn ìwọ, OLUWA, má jìnnà sí mi!
fun awon agbofinro ati iko  omo ogun
O ni nitori Oluwo jinna si oun, koda ko si ninu abile kẹta si oun, ti ko si roo wo pe agbalagba ni oun, ko to maa gba iru oun leti, kii se epe, oun ko lee de aafin Oluwo mọ, yoo si dara ki oun fi ọwọ mu aafin rẹ.
Ìwé Ẹ̀kọ́ àti àwọn Májẹ̀mú jẹ́ ọ̀kan nínú àwọn idíwọ̀n iṣẹ́ Ìjọ ní àpapọ̀ pẹ̀lú Bíbélì Mímọ́, Ìwé ti Mọ́mọ́nì, àti Péálì Olówó Iyebíye.
Lati aago mewaa owuro yii nipade idakonko naa ti bere.
Ní ọjọ́ kan, Jonatani, ọmọ Saulu, wí fún ọdọmọkunrin tí ó ń ru ihamọra rẹ̀ pé, “Jẹ́ kí á lọ sí òdìkejì ibùdó àwọn ọmọ ogun Filistini.
Awọn naa ni arogun matidi, abawọnja ma se ojo, awọn ti ilu ṣee gbọkanle, iru wọn si ni Timi Agbale Ọlafa ina ati Gbọnka Ebiri.
Lẹyin iṣẹ abẹ yii ni ko pada ji mọ.
Kí ẹ sọ fún baálé ilé tí ó bá wọ̀ pé, ‘Olùkọ́ni wí pé yàrá wo ni ààyè wà fún mi, níbi tí èmi ati àwọn ọmọ-ẹ̀yìn mi ti lè jẹ àsè Ìrékọjá?
ó rán amí láti rí i dájú pé Saulu wà níbẹ̀.
Awọn nkan mii ti Sẹnetọ Godswill Akpabio tun mẹnu ba lonii ree pẹlu bi ọrọ ṣe di fa ki n fa a pẹlu igbimọ to n gbẹjọ gẹgẹ bi wọn ṣe da ọpọlọpọ ibeere bo o.
Nígbà tí Reubẹni pada dé ibi kànga gbígbẹ tí wọ́n ju Josẹfu sí, tí ó rí i pé kò sí níbẹ̀ mọ́, ó fa aṣọ rẹ̀ ya láti fi ìbànújẹ́ rẹ̀ hàn.
Ọkàn Beṣasari dàrú, ojú rẹ̀ yipada.
"Kíni ẹ̀yin rántí nínú ǹkan ti o ti ṣẹlẹ lọ́dun díẹ̀ sẹ́yìn àti nísìnyìí Ilé aṣọ̀fin Nàìjíríà ń gbèrò ẹ̀wọ̀n f'áwọn olùkọ̀ tó bá dẹnu ìfẹ́ kọ akẹ́kọ̀bìnrin Ìṣòro Nàíjíríà kọjá kí Bobrisky àtàwọn ẹlẹgbẹ́ rẹ̀ dá ní ilé ìgbọ̀nsẹ̀ lọ́tọ̀"" Lasiko ti wọn n sisẹ abẹ fun obinrin naa, awọn onisẹ abẹ, Dokita ati Nọọsi n fi oun wo fiimu lori ẹrọ amohunmaworan ko to di wi pe wọn wa ṣe isẹ abẹ fun oun."
Ohun ni ọmọbinrin kan ṣoṣo ni idile Mike-Bamiloye oun naa si jẹ oṣere Kristẹni bii ti baba rẹ, iya ati awọn ẹgbọn rẹ ọkunrin meji.
Àjẹ́ àti Aṣẹ́wó ní ìyá Rainbow - Òjòpagogo Èmi àti Saheed kìí ṣe ọmọdé, a ti jọ ṣe Sinimá papọ̀, èyí túmọ̀ sí pé ìjà ti parí - Fathia Balogun Leon van Biljon dí èrò ọrun nípasẹ̀ Kìnìún rẹ̀ Ọpọlọpọ awọn eniyan lo ti gboriyin fun Seyi Makinde pe awọn ọdọ Naijiria ko kere ju lati di ipo oṣelu mu lasiko yii.
Ipolongo fun Biafra lo fa ogun abẹle to waye ni Naijiria l'ọdun 1967.
Gbé ọgbọ́n lárugẹ, yóo sì gbé ọ ga,yóo bu ọlá fún ọ, bí o bá gbà á mọ́ra.
 aláàfín àti àwọn emẹ ̀ wà rẹ ̀ yìí àrokọ ̀ náà títí , wọ ́ n sì mọ ̀ ọ ́ tì .
Èyínì ni ibib tí Ọba Igbó Olódùmarè wà tí mo fi ìyàwó mi sí  nígbà tí mo múra àti lọ ṣe ọdẹ tí ó fi di pé mo bá ara mi tí mo lé ténté lórí igi fún ìgbà pípẹ́.
Ìtàn ìgbé ayé Bamidele Olumilua, àgbà òṣèlú tó jáde láyé George Floyd ní àrùn coronavirus kó tó jáde láyé Auxiliary korò ojú sí àwọn ọmọ ẹ̀yìn rẹ̀ tó ń dàlú rú Eyín ọ̀ọ́kán mi ni Barakat tí wọ́n pa lẹ́yìn tí wọ́n fipá bá a lòpọ̀- Ìyá Barakat Ofin yii n waye lẹyin ọkan-o-jọkan iṣẹlẹ awọn omidan ti awọn eeyan kan n ṣekupa lẹyin ti wọn ba ti fipa ba wọn lo pọ tan.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Yollywood: Sinimá Ajé Ọjà tún so Fathia àti Saheed Balogun pọ̀ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Yollywood: Sinimá Ajé Ọjà tún so Fathia àti Saheed Balogun pọ̀ 8 Ògún 2019 Yoruba ni ọja ti ọmọ ba ti wọ, o di okuta, bẹẹ si ni ija ifẹ ko lọ titi, ki ẹlẹnu sọnu.
Awọn adari ni ilu Idoani ti Otunba Oladele Olapeju ṣe adari fun ni, wọn ri oku Paul Sodje ati ọrẹ rẹ ni ilu Ajagbale, ti ko jina si ilu Ifọn.
Bukola Saraki ti ke si awọn ile igbimọ asofin to ku tọrọ naa kan lati fi Kwara se awokọse.
Tofunmi ni o ṣeni laanu pe ijọba n gbaradi fun eto idibo, ṣugbọn ijọba o fẹ kawọn akẹkọọ ṣe idanwo.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Alaafin: Olori Aanu Adeyemi ṣàlàyé ìdí tó ṣe gẹ́ Oba Lamidi Adeyemi ti ìlú Oyo Gẹgẹ bi ajọ Viasna ṣe sọ, eeyan to le ni ẹgbẹrun meji, ni wọn ti fi si ahamọ, lati igba ti ipolongo ibo ti bẹrẹ.
Bí ó ti ṣe sí ọba Jẹriko náà ló ṣe sí ọba Makeda.
A gbà yín níyànjú kí ẹwọlé, bótilẹ̀jẹ́pẹ́ kò pọndandan.
"Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Rape: Oluwaseun Osowobi ní Commonwealth fún lámì ẹ̀yẹ ọ̀dọ́ tó pegedé jùlọ ní 2018 Nigba ta bi leere pe se ko si ẹnikẹni to lee fi isẹlẹ yii to leti ni, ọmọge ọhun ni oun sọ fun aburo iya oun pe ọkọ rẹ n ni ajọsepọ kotọ pẹlu oun, amọ aburo iya rẹ ni ""ẹnikẹni to ba ba ọkọ mi lo pọ, yoo ku ni""."
Nibi ipade kan ti aarẹ Muhammadu Buhari se lori ọrọ abo pẹlu awọn lọgalọga ileesẹ alaabo ati ologun lorilẹede Naijiria, eyi to waye nilu Abuja ni asẹ yii ti jade.
Mr Latin wọlé di ààrẹ ẹgbẹ́ tíátà, TAMPAN
6 Nítorí lẹ́hìn àkókò yìí a ó yàn ọ́, ìwọ yíò sì jade lọ láti fi àwọn ọ̀rọ̀ mi fún àwọn ọmọ ènìyàn.
Gbogbo ẹ̀sùn tí wọ́n fi kàn wá jẹ́ ti òṣèlú torí ìdí èyí ó yẹ kí wọ́n ṣe àtúnṣe gẹ́gẹ́ bíi ọ̀rọ̀ òṣèlú.
Lati igba ti Ronaldo ti wa ni Manchester United lo ti bẹrẹ si ni gba oniruuru ami ẹyẹ, ṣugbọn nigba to darapọ mọ Real Madrid lo gba oriṣiiriṣii ami ẹyẹ.
Nítorí náà ó jẹ́ kí wọ́n rí ibinu òun,ó sì fi agbára ogun rẹ̀ hàn wọ́n.
Buhari ní òun kò gbàgbé àwọn ọmọ Chibok Ọ̀rọ̀ǹpọ̀tọ̀niyùn, Aláàfin obìnrin àkọ́kọ́ rèé, tó ní nǹkan ọkùnrin Ọmọ atàpátadìde ni mí, télọ̀ ni bàbá mi- Abiola Ajimobi Oladejo Okediji àti ìgbé ayé ìtàn kíkọ rẹ̀ Ọmọ Naijiria pẹlu ibinu ni awọn fi n fi ẹhọnu han lori ẹrọ ayelujara Twitter wọn lori ẹsun pe awọn ọlọpaa ko bikita nipa ẹmi awọn eniyan.
Oríṣun àwòrán, Channels Television Alukoro Ọlọpaa ipinlẹ Ogun, Abimbola Oyeyemi ni awọn ti bẹrẹ iwadii lori bi awọn janduku yii ṣe ri ọna wọle ji ọpa aṣẹ naa gbe.
ti rọ awon omo orile ede Naijiria ni awon ipinle ti atundi ibo naa yoo ti waye
    Báyìí ni iwin náà sọ, lẹ́yìn èyí mo wo ojú sánmọ̀ mo ra ọwọ́ sí òkè mo ke pe Ọlọrun ọba pé kí ó máṣe bínú sí mi pé mo fẹ́ ṣe oore fún iwin náà, kàkà bẹ́ẹ̀ kí ó kàá kún iṣẹ́ rere kan pàtàkì tí mo ṣe ni òde ayé, mo bá pe Ìgbéraga-ìbànújẹ́ kí ó súnmọ́ mi, lẹ́yìn tí ó ṣe bẹ́ẹ̀ mo wo ẹ̀wù náà bí ó ti ri, mo ríi, ó lẹ̀ mọ́ ọ lára típẹ́típẹ́, mo tilẹ̀ kọ́ ṣe bí ẹ̀wù náà lẹ̀ mọ́ ọ lára ni, ṣùgbọ́n kò rí bẹ́ẹ̀ irun ara iwin náà gùn púpọ̀ òun lo sì wé mọ ara ẹ̀wùi náà.
O kò gbọdọ̀ bá ọ̀pọ̀ eniyan kẹ́gbẹ́ láti ṣe ibi, tabi kí o tẹ̀lé ọ̀pọ̀ eniyan láti jẹ́rìí èké tí ó lè yí ìdájọ́ po.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ta ni wọn yóò búra fún bíi gómínà Bayelsa lónìí, olùdíje PDP ni àbí olórí ilé aṣòfin?
Gbogbo bí a ti ṣe lónìí ni OLUWA pa láṣẹ pé kí á ṣe, láti ṣe ètùtù fún ẹ̀ṣẹ̀ yín.
Ìwọ ni ibi ààbò nígbà òjò,ati ìbòòji ninu oòrùn.
Amọṣa adajọ ti o n gbọ ẹjọ naa, Halima Salman, ti sun igbẹjọ di ọgbọn ọjọ, oṣu kọkanla, ọdun 2018 lati fun olupẹjọ lanfani ati ṣe awọn atunṣe to yẹ lori iwe ipẹjọ wọn.
Gbogbo Ìjọba Ìpínlẹ̀ Ilẹ̀ Kú-òórọ̀-oòjííre ni wọ́n ni kín n kí ọ
Guri to jẹ ọmọ ọdun mẹrindinlọgbọn jẹ ọmọde ọmọ ogun ilẹ̀ fun awọn Tamil Tigers.
Àwọn àgbàlagbà Yorùbá ti parí ọ̀rọ̀ tipẹ́-tipẹ́.
Àwọn àwòrán mánigbàgbé nípa Ààrẹ Muhammadu Buhari Kini o yẹ koo mọ nipa Badeh?
Ọ̀gá EFCC ní ọkọ̀ ayọkẹ́lẹ̀ bí ọgbọ̀n, Kọmputa agbélétan, fọóònù, àti òògun ìbílẹ ní wọn ti gba lọ́wọ́ àwọn ọdaran náà.
Ìyíbiri ẹyo kan ló nfúnwa ni ẹyọ ọjọ́ kan.
Ọkùnrin náà ti pa púpọ̀ núnú àwọn ọmọdé àti àgbà, ó sì ti ṣe ọ̀pọ̀lọpọ̀ léṣe.
Jacinta Igbke - BBC News Yorùbá BBC News, YorùbáFò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìdí tí mo fi gún olólùfẹ́ mi tẹ́lẹ̀ pa - Jacinta Igbke 28 Ọ̀pẹ̀̀ 2019 Oríṣun àwòrán, Others Àkọlé àwòrán, Idí ti mo fi gún olólùfẹ́ mi tẹ́lẹ̀ pa- Jacinta Igboke Olùkọ́binrin nilé ẹkọ alákọbẹrẹ kan nílú Eko tó gún ololufẹ rẹ nigbakan ri lọ́bẹ pa nigba ti igbéyàwó rẹ̀ ku ọjọ díẹ̀ lo ti wà ni gbaga àwọn ọlọpàá bayii.
Ní ìgbà tí yόò sì ṣírò èlé orí oko, èlé owó tό ní kí wọ́n san ju àpò mẹ́fa lọ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Àrọ́bá June 12: Ó yẹ MKO Abiọla, ẹ̀gàn ni hẹ̀ẹ̀ 12 Òkùdu 2018 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 15 Òkùdu 2018 Àwọn àwòrán yìí ló ń sàlàyé bí ayẹyẹ June 12 lọ́dún 2018 se dùn, tó lárinrin sí ní ìlú Abuja, Eko àti Ibadan.
Agbẹnusọ ilé kede yiyansipo Ogbẹni Sonuga gẹgẹ bi olori ọmọ ile to pọju lọ lasiko yii.
Dide to de pada, o ranṣẹ si Dupe pe ko wa a gba owo ounjẹ fun ọmọ rẹ ọkunrin to bi fun.
”Asofin Ken soro re di mimo pe, oun wa sile igbimo yii fun ise ni, bee si ni lati ri bi isakoso ijoba yii yoo se gba awon oludokoowo ti mo mu wa.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Kamaru Usman: Ǹ jẹ́ o mọ ìlú akẹ̀ṣẹ́ UFC yìí ?
Amọ asaaju afọbajẹ tilu Iwo, tii tun se Osa ilu naa, Oloye Yekeen Bello, lasiko to n bawọn akọroyin sọrọ salaye pe, bi Oluwo fẹ, bo kọ, lilọ ni yoo lọ lori oye naa.
Wọn yinbọn pa marun un nigba ti awọn agbebọn ṣe ikọlu si iwe iroyin Capital Gazette ni Mariland.
Ajasa ni, baba ni Baba Lẹgba jẹ fun wọn nigba to wa laye, to si tun jẹ awokọṣe iwa ọmọluwabi laarin wọn, to si ma n gba wọn nimọran.
Ṣe ni ẹnu aipẹ yii ni awón ọmọ Orilẹ ede South Africa ṣe ikọlu si awón ọmọ Naijiria to n gbe ni ilẹ naa ti wọn si ba ọpọlọpọ dukia olowo iyebiye jẹ ti ọpọ si di alairile gbe.
Oríṣun àwòrán, ALLSPORT/Getty Images Àkọlé àwòrán, O daju wipe abajade ifẹsẹwọnsẹ yii yoo tubọ mu ki ẹnu o maa kun olukọni ikọ agbabọọlu naa, Arsene Wenger Amọsa, Pierre-Emerick Aubameyang da ẹyọkan pada ni igbati o ku isẹju meji ki wọn pari abala akọkọ ifẹsẹwọnsẹ naa.
Wọ́n fẹ́ ba dáadáa ààrẹ Buhari jẹ́ ni wọ́n ṣe ń lọ́ kíkojú ìṣòro àbò mọ́ ikú àwọn àgbẹ̀ Koshebe Ẹ wo ọmọ Yoruba, Adewale Adeyemo tí yóò jẹ igbákejì akọ̀wé akápò ní ilẹ̀ Amẹrika Ṣe lóòtọ́ ní ọmọ Nàíjíríà mílíọ́nù 25 yóò má ló ìná Solar látí Dec 1, 2020?
Koda, ọkọ ati iyawo rẹ Ademola ati Yinka ko ri gbogbo ọrọ odi ti ẹnikẹni le maa ro o, wọn sọ bi idunu wọn ko ṣe ṣee fẹnu sọ rara.
Nkwocha Ernest: Ìdọ́tí ni wọ́n ń pè é ṣùgbọ́n èmi pè é ni ohun èlò
O kò fẹ́ mi tán kí o tún máa bá ẹlòmíràn sọ̀rọ̀ kẹ́lẹ́kẹ́lẹ́ ní kọ̀kọ̀, n kò sì bá ọ ní ìdí àgàgebè kan láti ọjọ tí a ti ń fẹ́ ara wa.
Ninu atẹjade kan ti o fi sọwọ sawọn akọroyin o sọ pe lasuba ọjọbọ lawọn bẹrẹ si ni wo ile naa tawọn agbofinro si duro wamu lalai doju ija kọ awọn to n tawọn laya.
Ogbó ti dé sí mi, n kò tún lè ní ọkọ mọ́.
Àfojúsùn àtúntò FSARS ni láti mú àgbéga bá iṣẹ́ ọlọ́pàá- IG Ọgbẹni Joseph ṣalaye Aado abugbamu ti wọn n pe ni 'Dynamite' ni wọn fi fọ ilẹkun wọle sinu ileefowopamọ ọhun.
Èmi ni Johanu, arakunrin yín ati alábàápín pẹlu yín ninu ìpọ́njú tí ẹni tí ó bá tẹ̀lé Jesu níláti rí, ati ìfaradà tí ó níláti ní.
Gẹ́gẹ́ bí a ti mọ̀ pé wón ti ka èdè Yorùbá sí èdè tí kò ní sí lórílẹ̀ ayé mọ́ bí àwọn elédè gan-an ò ṣe káràmáásìkìí èdè wọn.
Dókítà Allin-khan so pé òun ti ṣe itoju àwọn ọ̀dọ́ tí kò ní ààrùn kankan lára tẹ́lẹ̀ ṣúgbọ́n wọ́n wà níbi tí wọn tí n du ẹ̀mí wọn.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Iṣọla Oyenusi rèé, ẹnití ìfẹ́ obìnrin ṣun dé ìwà ìdigunjalè Taiwo Akinkunmi, ọmọ Ibadan tó ya àsìá Naijiria Ayinla Ọmọwura, orin èébú àti oríyìn lo fi di ọ̀rẹ́ àwọ̀n obìnrin Ìtàn tó rọ̀ mọ́ òwe ‘aṣọ kò bá Ọ́mọ́yẹ mọ́.
Fìlà orí rẹ̀ dàbí adé, bàtá ẹsẹ̀ rẹ̀ dàbí bàtà ẹsẹ̀ àwọn alágbára, bẹ́ẹ̀ ni ẹ̀wù ọrùn rẹ̀ kò yàtọ̀ aí ti ọba tí ó ti gba adé láti ọwọ́ òdùduwà, ọ̀pọ̀lọpọ̀ àwọn iwin mìíràn ni ó tèlé e.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fọ́nrán ohùn, Lẹ́yìn ọ̀pọ̀lọ́pọ̀ oṣù tí òjò kò rọ̀ ní orílẹ̀èdè Cuba, Ọba ilẹ̀ Yorùbá ló Ọgbẹni Onyekachi ṣalaye pe kii ṣe ọrọ agbekọrọ iyẹwu sọ mọ pe apa ti kun ileeṣẹ smọogun orilẹede yii, nitori naa, ẹni to ba lee ṣe lo yẹ ka bẹ lọwẹ.
Aare Buhari gba pe ogbon, imo ati awon eniyan pataki pataki ti Oba Tejuoso ni yoo wulo fawon eniyan orile-ede yii lapapo.
"Àkọlé àwòrán, Awọn ọmọ China miran kọwọrin pẹlu rẹ nibi ayẹyẹ naa O ni ""Wakilin Yan China, mo ki ọ ku orire, o ti jẹwọ pe o ni ipa rere, mo si lero wi pe oye yii yoo mu ki o tẹramọ iṣe daada ti a mọ ọ si'' Ojojumọ ni iye ọmọ China to n ṣowo nipinlẹ Kano n pọ sii."
Ilumọọka olorin nni, Tiwa Savage ni iroyin sọ pe oun ni obinrin akọkọ to ti gba ami ẹyẹ MTV EMA fun olorin ilẹ Afirika to dara ju.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Aisan iba ṣe e dena, o si ṣe e tọju Bi ọjọ kẹẹdọgbọn, oṣu kẹrin ṣe wa a jẹ Ayajọ aisan iba l'agbaye, awọn nkan to yẹ ki o mọ nipa aisan naa ni yii.
Pataki akọni to ti dara ilẹ yii lo mu ki BBC Yoruba se fẹ ka mọ itan igbe aye rẹ gẹgẹ bi a se rii ka loju opo ayelujara nitori bi onirese rẹ ko ba fin igba mọ, eyi to ti fin silẹ, ko lee parun.
Òun ni ó kọ nǹkan wọnyi: a mọ̀ pé òtítọ́ ni ẹ̀rí rẹ̀.
ẹni tíí ṣe ohun ńlátí eniyan kò lè rídìí,ati àwọn ohun ìyanu tí kò lóǹkà.
2 39911 Orilẹede Yemen 612 2.
Ko tan sibẹ o, akọrin takasufe naa ṣalaye pe oun ati ọkọ oun, Offset, lo jọ n ya fọto nigba ti oun ṣe e ṣi tẹ bọtini miran, to si gbe e lọ sori ayelujara Instagram.
Bi Bukky Ajayi, to dele aye lọdun 1934, ṣe n sere lede oyinbo naa lo n ṣe ti Yoruba, lara awọn ere to ṣe, ko to jade laye ni Critical Assignments, Diamond Ring, Wiches, Iya mi tootọ, Bolode o ku, Amoye, Orere Aye ati bẹẹ bẹẹ lọ.
Nígbà ti ó pé ọmọ ọdun mẹ́rin ló ti ń fi kọmpta ṣe ìdánilẹkọọ fún awọn èrò to lé ni ìgbá sí ẹgbẹ̀rún mẹ́ta nípa kíkọ wọ́n ni ẹ̀yà àra ènìyàn lásiko ètò ìkowojọ fún kan ni ilú wọ́n.
Kò tán síbẹ̀, lára òfin náà ló tún ní, igbákejì ààrẹ tó bá parí sáà pẹ̀lú ọ̀gá rẹ̀, tó tún fẹ́ lọ se ààrẹ, yóò lo sáà kan soso péré.
Èèyàn 296 ló forí kó Covid -19 ní Nàìjíríà lọ́jọ́bọ Wo ojú àwọn afurasí tó fipá bá Uwaila, akẹ́kọ̀ọ́ Uniben sùn tí wọ́n tún pa á sínúu ṣọ́ọ̀ṣì Kìí ṣe torí ìbèérè ni mo ṣe bẹ́ Fani-Kayode, àwọn akẹẹgbẹ́ mi ló kó mi láyà jẹ - Eyo Charles Ìjọba Nàìjíríà ti sún ọjọ́ tí ìrìnàjò bàálù sílẹ̀ òkèèrè yóò bẹ̀rẹ̀ padà síwájú Damola sọ pe oun atawọn ti wọn jọ n ṣiṣẹ yọ eeyan meji jade ninu ọkọ ofuru naa ṣugbọ ko ri aye yọ ẹnikan to ku tititi awọn adoola ẹmi fi de.
O ni aba yii kan naa lo yẹ fun gbigba oṣiṣẹ eleto ilera eyi to mu ki awọn dokita gba ijọba nimọran pe ki wọn gba awọn akẹkọọ dokita tabi awọn to ti fẹyin ti ju ki wọn lọ maa ko awọn dokita ilẹ okeere wa ati orilẹede bii Cuba.
Aláàfin: Àìrí iṣẹ́ ṣe ọ̀dọ́ lágbègbè mi ń peléke, ó sì nílò àmójútó
Alufa ijọ Canterbury naa koro oju si isẹlẹ ipaniyan Lekki Lara awọn ilumọọka l'agbaye to tun ti koro oju si ipaniyan ati idaru-dapọ to n waye ni Naijiria ni Olori Alufa ijọ Church of England ni Canterbury, Justin Welby.
Wọ́n ní bí wọn kò bá tètè lọ, gbogbo àwọn ni àwọn yóo di òkú.
Àwọn ẹ̀yà Juda ṣẹ̀ sí OLUWA, wọ́n sì ṣe ohun tí ó mú un bínú lọpọlọpọ ju gbogbo àwọn baba ńlá wọn lọ.
Máa ja ìjà rere ti igbagbọ.
Wolii Gadi sọ fún Dafidi pé, “Má dúró níbi ìpamọ́ yìí mọ́, múra, kí o lọ sí ilẹ̀ Juda.
Ajínigbé: Afurasi Ajínigbé jí ọmọkùnrin kan gbé ní Ibadan, ọwọ́ tẹ̀ẹ́ ní Eko
Àwọn aposteli ati àwọn onigbagbọ yòókù tí ó wà ní Judia gbọ́ pé àwọn tí kì í ṣe Juu náà ti gba ọ̀rọ̀ Ọlọrun.
Lojo-Abameta nile-ejo ti o ga ju lorile-ede Egypt  fagile awon ofin kan to wa nile, eyi o je ipenija fun adehun ifenuko lori jijowo odo Red Sea meji fun ile Saudi Arabia, leyin ojo keji ti aremo Saudi Arabia se abewo si orile-ede Egypt.
Nígbà tí wọ́n yọ, ẹ̀gún fún wọn pa.
Inu agbara ẹjẹ lo ti ba aya rẹ pẹlu apa ibi ti wọn ti fi nnkan ṣaa lori ti wọn si salọ.
Bayii gbogbo ọmọ Naijiria lo n reti ohun to maa ṣẹlẹ lonii ti gbendeke ti Gbajabiamila fun Akpabio pe yii Amofin Bulama Bukarti to jẹ agbẹjọrọ ni ilu Oba ṣalaye fun BBC pe ti Akpabio ba kọ lati kede orukọ naa, awọn ile igbimọ Aṣofin le sọ fun Aarẹ Buhari lati gab ipo minista naa lọwọ rẹ.
Bakan naa lo ni awọn kọmiṣọna ipinlẹ naa ti fi ọrọ to aarẹ leti gẹgẹ bi awọn onimọ pe ohun ti orilẹede Naijiria nilo bayii lati koju itankalẹ Coronavirus.
Olori Badra, tii se iya ibeji ni aafin Ọyọ, lo n polowo ọsẹ ati ororo ipara amaradan, agbo to n fa ọrọ kuro ni agọ ara tabi eyi to n se ikun pẹlẹbẹ.
Ṣáàjú ni ìròyìn kan látí iléèṣẹ́ ìròyìn AFP gbé e pé àwọn ọmọ ikọ̀ Boko Haram ṣekú pa ọgbọ̀n ọmọ ogun Nàìjíríà ní ìpínlẹ̀ Borno.
Ògo OLUWA sọ̀kalẹ̀ sórí òkè Sinai, ìkùukùu sì bò ó fún ọjọ́ mẹfa, ní ọjọ́ keje, OLUWA pe Mose láti inú ìkùukùu náà.
Wọ́n ní, “Irú eniyan wo ni èyí, tí afẹ́fẹ́ ati òkun ń gbọ́ràn sí i lẹ́nu?
Edem, ti o fun Okina ni owo ileewe Frederick ati Kelvin gba ami ẹyẹ pataki, ti inu rẹ si dun debi wipe o bu s'ẹkun.
Ẹ̀wà pẹ̀lú ẹja wẹẹrẹ àti edé tí wọ́n pa láti inú òkun tí wọ́n sì ti yan tí ó gbẹ tọọli ni wọ́n sè pọ̀ tí wọ́n gbé ìwọ̀nyí sílẹ̀ kítikìti.
Lẹ́yìn ọdún mẹta ni mo tó gòkè lọ sí Jerusalẹmu láti lọ rí Peteru, mo sì wà lọ́dọ̀ rẹ̀ fún ọjọ́ mẹẹdogun.
Rakẹli bá dáhùn, ó ní, “Biliha, iranṣẹbinrin mi nìyí, bá a lòpọ̀, kí ó bímọ sí mi lọ́wọ́, kí èmi náà sì lè ti ipa rẹ̀ di ọlọ́mọ.
Ni igba ti yoo fi di ọjọ isinmi tii ṣe ọjọ Aiku, eeyan marun miran ti dero ọrun ọrun o.
 Ẹyin, ẹ wo igba ti ijọba n sọrọ ‘Mega City’, gbagbagba ni wọn duro ti ijọba ni asiko naa, ti wọn si tun ṣe bẹẹ ni asiko ‘Smart City yii naa”.
Ṣé o wá pa wá run ni?
tesiwaju gege bi adari ile ifowopamo ijoba apapo fun odun marun un fun saa keji
 thi darapọ ̀ mọ ́ ọmọ ogun ilẹ ̀ faransé nígbà tí ó pé ọmọ ọdún mẹ ́ tàdínlógún , ti àwọn japan sì kóo mógun lọ nígbà tí wọ ́ n dojú ogun kọ french indochina nígbà ogun àgbáyé kejì .
Ó nawọ́ láti òkè wá, ó sì dì mí mú,ó fà mí jáde láti inú ibú omi.
Aago mẹ́jọ alẹ oni ọjọ kẹrinla, oṣu keje ni lala o lu ti pẹpẹyẹ maa pọnmọ laarin Naijiria àti Algeria.
Bí eniyan bá wọ àlàfo náà, ògiri kan dábùú rẹ̀ níwájú.
Ọ̀sán máa ń mú ara dá ní gbogbo ìgbà Oríṣun àwòrán, EPA Àkọlé àwòrán, O ní láti rí ọ̀pọ̀lọpọ̀ òye ọ̀sán l'ojojúmọ́ fún ìlẹra Tí o bá [wa nínú òkùnkùn, agogo ara rẹ yóò tàsé agogo wákàtí mẹ́rìnlélogún (24).
Ojiṣẹ Ọlọrun Femi Aladelola ti ijọ World Mission for Souls International ṣalaye lori idán, agbara okunkun ati agbara Ọlọrun alaaye to fidi iru iṣẹlẹ bayii mulẹ.
Nítorí náà, nígbà tí ìyá mi fẹ́ẹ́ lọ mo tún pa guuru sí i bí ẹni pé kí n dì í mú ṣùgbọ́n òfo ni mo dì mú; mo ṣe bẹ́ẹ̀ lẹ́ẹ̀kejì kò bọ́ sí i; nígbà tí mo sì ṣe bẹ́ẹ̀ lẹ́ẹ̀kẹta, síbẹ̀ tí n kò lè dì í mú mo ké igbe ńlá mo wí tàánútàánú pé, ‘Jọ̀wọ́ ìyá mi, máa mú mi lọ; jọ̀wọ́ ìyá mi, máa mú mi lọ, àti bẹ́ẹ̀ lọ.
Oṣu Kinni ọdun 2019 ni aarẹ yan Muhammad lẹyin to paṣẹ fun Adajọ Agba tẹlẹ, Walter Onnoghen lati lọ rọọkun nile nitori ẹsun ṣiṣe mago-mago lasiko to kede dukia rẹ gẹgẹ bi adajọ agba.
Awon gbajugbaja osere miran to kopa ni Chadwick Boseman, Michael B.
ará Tire ni baba rẹ̀, ṣugbọn opó ọmọ ẹ̀yà Nafutali kan ni ìyá rẹ̀.
Nígbà tí àwọn ọmọ Israẹli rí i pé Rehoboamu kò gbọ́ tiwọn, wọ́n dáhùn pé,“Kí ló kàn wá pẹlu ilé Dafidi?
Bawo ni o ṣe lee mọ boya ailera lasan lo ni tabi boya awọn ifarahan arun coronavirus lo n jẹyọ lara rẹ?
Wo ọ̀pọ̀ àsọtẹ́lẹ̀ igba tí Primate Ayodele gbé síta fọ́dún 2021 Nibayii ti ọdun 2020 ku ọjọ meji ko kogba wọle, ta si ki ọdun tuntun 2021 kaabọ, ẹ wo diẹ lara awọn eekan ilu ati ilumọọka ọmọ Naijiria to ba ogbologbo ọdun naa lọ.
Wọ́n gba gbogbo ilẹ̀ àwọn ará Amori láti Anoni títí dé odò Jaboku ati láti aṣálẹ̀ títí dé odò Jọdani.
Gomina wa fi asiko naa ro gbogbo osise lati fi iwa  omoluabi lenu ise san an pada fun ijoba nipa
Afáárá òpópónà Mokwa sí Jebba wó lulẹ̀ Small Doctor, Afolayan bá Buhari ṣínu ààwẹ̀ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ọrọ ìfẹ́: Tunrayọ Adeoye kú lọ́sẹ̀ karun ti a sin ọkọ rẹ̀ Ìròyin sọ fún wa pé Ras Kimono ń lọ orílẹ̀-èdè Amẹ́rika kí ó tó dipé ó dá kú, tí wọ́n sì gbée lọ sí ilé ìwòsàn.
Òfin yìí wà fún obinrin tí ó bá bímọ, kì báà jẹ́ ọmọkunrin ni ó bí tabi ọmọbinrin.
Sugbọn gẹgẹ bii ise awọn eeyan to n wa ifa, lainaani ikilọ tawọn ọlọpa to wa nibi isẹlẹ naa n se fun wọn, wọn ti ọwọ ifa bọnu, pẹlu bi wọn se n gbọn epo pẹtiroolu to da silẹ latinu tanka naa, amọ ofo nla lo wọle tọ wọn nigba ti ọkọ epo naa sadede gba ina, eyi to mu ẹmi ọpọ wọn lọ.
Ọpọlọpọ iyanṣẹlodi Ìpàdé ìjọba ati ASUU forí sánpọ́n, ifẹhonuhan Àwòrán ìwọ́de NLC, TUC, ULC lónìí ati NLC, TUC: Àwa ò gba owó lọ́wọ́ Fayose ooo ileri titi ilẹkun ọrọ aje Kíni ìdí tí NLC fi kọ N27,000 owó osù òsìsẹ́?
lati ori omi wa si ilu Ibadan, yoo mu ki oro aje ibudo igbokosi ohun ru gogo
Frank Mba ni afurasi Paitọ yii lẹdi apo pọ pẹlu awọn ọdaran mẹta mii, lati ji Jonathan Ekpo gbe.
Ẹ má ṣe rò lọ́kàn yín pé, ‘A ní Abrahamu ní baba.
Oríṣun àwòrán, AFP Àkọlé àwòrán, Awọn aarẹ Afrika duro ya aworan nigba ipade ajọ isọkan Afrika lati se agbekalẹ ibudo kara-kata ọfẹ ni Kigali, ilẹ Rwanda l'Ọjọru eleyi ti yoo jẹ ọkan lara awọn ibudo kara-kata ọfẹ to tobi ju l'agbaye.
Bayii ni ọrọ ri fun awọn to n gbe agbeegbe Sardinia ni orilẹede Italy, ti wọn fi idin se ounjẹ ajẹpọnnula, ti wọn yoo si dupẹ lọwọ ẹnikẹni to ba fun wọn ni burẹdi onidin jẹ.
O ́tó agogo mẹ́jọ tí wọ́n dá ońjẹ padà yìí ni, a rí alùfáà ìjọ wa, àti alùfáà àdúgbọ̀ wa tí kì í ṣe ti ìjọ wa.
( 2 ) Òrò àti Àpólà : Òrò ti a bat ò pò ni ó ń di àpólà .
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù NIN Registration: Mínísítà ní bó yá n'ìjọba kò ní dá ìforúkọsílẹ NIN dúró tórí ewu Covid-19 7 Sẹ́rẹ́ 2021 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 11 Sẹ́rẹ́ 2021 Oríṣun àwòrán, NIMC Minisita keji fun eto ilera ni Naijiria, Dokita Olorunnimbe Mamora ti sọ pe o ṣeeṣe ki ijọba so iforukọsilẹ kaadi idanimọ NIN rọ nitori ewu coronavirus.
”Peteru dáhùn pé, “Bẹ́ẹ̀ ni, Oluwa, o mọ̀ pé mo fẹ́ràn rẹ.
orile-ede Zimbabwe, ni papa isere Stephen Keshi lojo kejo osu kan naa.
"Irora yii pọ fun ọmọ mi ọkunrin.
Ìró ìbọn dún lákọ ní Iwo road n‘Ibadan, Seyi Makinde yọjú síbẹ̀ Àwọn jàndùkú kọlu ọgbà ẹ̀wọ̀n Ikoyi, agbófinró gba àkóso ibẹ̀ 7000 Jàǹdùkú ló fọ́ ọgbà ẹ̀wọ̀n Okitipupa, jó mọ́tò, tí wọn si se òṣìṣẹ́ léṣe"" Lodun 2008 ni komisonna fun oro obinrin ati idagbasoke agbegbe nigba naa, Arabinrin Deborah Oyelade fi Oloogbe Wuraola je iyaloja lasiko gomina Adebayo alao Akala."
Ó bá sọ fún ọkunrin náà pé, “Na ọwọ́ rẹ.
Ọjọ́ meje ni ẹ óo fi máa rú ẹbọ sísun sí OLUWA.
Oríṣun àwòrán, Foluke Daramola Instagram Aisan kidinrin ati aisan itọ suga ni Majek ti n ba finra fun ọpọlọpọ ọdun ko to jade laye.
Kí sì ni anfaani tí talaka rí ninu pé ó mọ̀ ọ́n ṣe ní àwùjọ eniyan.
Igun mẹrẹẹrin ìlú náà dọ́gba, bákan náà ni gígùn rẹ̀ ati ìbú rẹ̀.
Wọ́n jálù mí, bí ìgbà tí ọpọlọpọ ọmọ ogun bá gba ihò ara odi ìlú wọlé,wọ́n ya lù mí, wọ́n wó mi mọ́lẹ̀.
Ọgbẹni Shina Akinpẹlu, to jẹ alukoro fun igun new Era ninu ẹgbẹ OPC ṣalaye fun BBC news Yoruba pe, lootọ ni OPC n gbe igbesẹ labẹnu lati ṣe ajọṣepọ pẹlu awọn agbofinro.
Lọwọlọwọ, iroyin ti a gbọ ni wi pe, gomina ana ni ipinlẹ Oyo, to tun ti jẹ sẹnetọ tẹlẹ nile igbimọ aṣofin agba Naijiria, Sẹnetọ Isiaka Abiola Ajimobi ti dagbere f'aye.
”O tesiwaju pe , oko- ogun  ofurufu meji   ti awon fikun oko-ogun  to maa n sayewo  ayika ati agbegbe re, ni eyi ti won ti  fi koko ranse tele ni ipinle naa  ni ojo kéjìlélógún, osu kẹ́wàá odun 2018.
Sibẹsibẹ, a sawari pe awọn owo kan ti wọn ni awọn fi pese ounjẹ fun awọn akẹkọọ lasiko isede ajakalẹ arun coronavirus ni awọn ile iwe kan ko ri bẹẹ rara.
Amọṣa, awọn eeyan miran n ṣalaye lori ẹrọ ayelujara pe ni iwoye tiwọn, Tinubu wa lara awọn iṣoro orilẹede Naijiria.
"Awọn ọsere Bollywood ati oloselu bọkanjẹ lori iku rẹ Olootu orilẹede India Narendra Modi sọ lori akanni faran Twitter rẹ wipe iku osere na ""ba oun lọkan jẹ "", nigbati Aarẹ India President Ram Nath Kovind sọ wipe iku rẹ ti ko awọn ololufẹ rẹ ti wọn le ni miliọnu sinu ọfọ."
Yatọ si orukọ Abisọ, Inagijẹ, Adape, Ẹsin, Iṣẹ idile ati bẹẹ bẹẹ lọ, orukọ amutọrunwa ni a n sọ ọmọ nipasẹ bi a ṣe bii ati irufẹ ipo to fi wa saye.
gba lọwọ awon eniyan ibi naa, ti won si danu sun gbogbo rẹ.
Ìròyìn tó ni létí wípé àwọn ikọ̀ ọ̀tẹlẹ̀múyẹ́ ọlọ́pàá alágbára ló kó àwọn afurasí apànìyàn náà.
 Duro Ladipọ, ìlúmọ̀ọ́ká òṣèré tíátà àti ọmọ àlúfà tí kò gbàgbé àṣà ìbílẹ̀ Obìnrin kan lu ọ̀gá ọlọ́pàá, ó tún gé ọmọ'ṣẹ́ ọlọ́pàá jẹ nítorí òfin ìséde ní Eruwa Ọwọ́ tẹ báàlẹ̀, Ṣinkó mẹ́tàdínlógún tó ń jí kùsà wà ní ìpínlẹ̀ Ọ̀ṣun Bí Eko ati Abuja ṣe rí rèé lónìí lẹ́yìn igbele Coronavirus Oríṣun àwòrán, Access Bank Ko si ile ifowopamọ kankan to le ti ilẹkun ẹka rẹ lai kọkọ gba aṣẹ lọwọ banki apapọ, CBN, ohun ti a ṣẹ ni pe a da iṣẹ duro lawọn ẹka wa kan ni, a ko da ẹnikẹni duro lẹnu iṣẹ.
O ku diẹ ki Mama Florence Adenekan pe ẹni aadọrun ọdun lo jade laye.
Ta ló sì lè fi gbogbo ìyìn rẹ̀ hàn?
Wọ́n sàpèjúwe nọ́ọ̀sì náà gẹ́gẹ́ bí ẹni tó máa ńsisẹ́ lójoojúmọ́ láti mú ìgbega bá ìlera àwọn ara Somalia.
Bẹẹ naa ni awọn Gomina ipinlẹ kan kilọ fun ijọba pe, ko ma ṣe daba lati da awọn agọ wọnyii silẹ lagbegbe awọn.
Mo kan saara si awọn obinrin ti wọn ti ko ipa ribiribi, ti wọn si tun si n ko ipa ribiribi ninu idagbasoke orilẹede wa ni ẹka gbogbo, ni ọna gbogbo ati ni gbogbo igba ninu itan wa.
"Ki awọn ole naa to de ile rẹ, wọn ti kọlu ile meji mii.
Ẹ má jẹ́ kí á máa gbèrò láti ṣe àwọn ohun tí ara fẹ́.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Eyi lo di ọrọ ileejọ ni eyi ti ileeṣẹ naa ni lati san owo gọbọi gẹgẹ bii owo gba mabinu fawọn eeyan Omode mọkanla lo ṣalaisi nigba ti awọn miran di abirun lẹyin ti wọn lo oogun antibiotics awogba arun naa tan.
Wayii o, aarẹ Buhari ti yan adajọ tuntun Ibrahim Tanko Muhammed
Ajọ to n risi idena ati amojuto ajakalẹ arun, NCDC lo fi ikede naa sita loju opo Twitter rẹ.
’ Wọn óo wá máa gbé orí ilẹ̀ wọn nígbà náà.
To bá fẹ́ jàǹfààní iná ọba tí kò ṣẹ́jú látọ̀dọ̀ ìjọba, ọ̀nà ẹ̀bùrú tó gbà rèé Ẹ̀tọ́ wa ni!
Inu ibanujẹ la wa ni mọlẹbi mi,igba yi buru púpọ fún wa"" ni oun ti Nzakame Julius sọ lasiko to n sin oku ọmọ rẹ Nzakame Rema to jẹ ọmọ ọdún mọkanla."
Ṣugbọn aya Lọti tí ó wà lẹ́yìn ọkọ rẹ̀ wo ẹ̀yìn, ó sì di ọ̀wọ̀n iyọ̀.
Àwọn ni wọ́n ń sanwó fún àwọn tí wọn ń tún ilé OLUWA ṣe.
Ẹwẹ, ajọ eleto idibo ni Naijiria, INEC ti kede pe ọjọ kọkanlelọgbọn ọdun 2020 yii ni idibo mii yoo waye lati dibo yan awọn ti yoo rọpo awọn sẹnẹtọ to ku yii atawọn meji to jẹ gomina ati igbakeji gomina Bayelsa bayii.
Awọn olukopa ogun lo wọ inu ile naa nigba kan naa, ṣugbọn ẹnikan sọṣo ni yoo jaweolubori.
Naijria ti won fẹ tẹsiwaju nipa ẹkọ wọn lorile ede Naijiria.
Osinbajo fi kun oro re pe, “a ni igbagbo pe a le sise papo, ni iyanju ati se aseyori  awon erongba ti o wa niwaju wa”.
Bakan naa, awọn eniyan to n fi ero wọn han lori ẹrọ ikansiraẹni Twitter ni ko ye ki ẹgbẹ oṣelu APC fi ẹni to wa lori idubulẹ aisan ṣe alaga ẹgbẹ lasiko ti idibo n bọ lọna ni ipinlẹ Ondo ati Edo.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Agogo méje ń lọ lù láàrọ̀ la gbọ́ ariwo ńlá kan' Bi wọn ṣe n ka eto idibo naa tẹlẹ Adari ilẹ India láti ọdun 2014, Narendra Modi naa ni o ti n lewaju bayii ninu èsì idibo to ti jade ni orilẹ-ede India.
Osinbajo tun fi mule pe, erongba ijoba apapo ni lati pese awon ayika to rewa fun idokowo, ni iyanju ati je ki erongba ijoba lori ona ati mu igberu ba eto oro-aje orile-ede Nigeria wa si imuse.
Ìjọba Ondo, inú fìfo la fi ń ṣiṣẹ́, ẹ ṣan ọ̀pọ̀ owó oṣù tẹ jẹ wa - Àwọn dókítà fárígá Ẹ́ kéde iye ọlọ́pá tó gba rìbá, kẹ tó máa yin ara yín - Aráàlú sọ fún ọlọ́pàá Kí ló ṣẹlẹ̀ lágbo tíátà lọ́sẹ̀ yìí?
Awọn to ku ni Ifedayo Adedipe, Garba Tetengi, Suraj Sa'eda, Funke Aboyade, Nesser Dangiri, Ernest Ojukwu, ati H.
Ni ó bá lọ, ó fi ọwọ́ kan pósí.
0 905 Orilẹede Eritrea 0 0.
O ni gomina ko fun awọn agbabọọlu Super Eagles ni owo kankan.
Òye kí ni o ní, tí ó jẹ́ ohun ìpamọ́ fún àwa?
Oríṣun àwòrán, Razak Atunwa Saaju ka to mu awọn oludije latinu ẹgbẹ oṣelu maraarun naa, ni BBC Yoruba ti kọkọ beere ero awọn araalu ni ipinlẹ kọọkan, nipa awọn ẹgbẹ oṣelu marun ti wọn gbaju-gbaja julọ ninu gbogbo ẹgbẹ oṣelu to wa lorilẹede yii, ti wọn n fẹ ki awọn oludije wọn kopa ninu ariyanjiyan naa.
(Ẹ̀yà Bẹnjamini ni wọ́n ka Beeroti kún.
Ẹ̀ka ológun Agbègbè Yangon kọ ìwé ẹ̀sùn-un ìbanilórúkọjẹ́ sí olóòtú èdèe-Burmese U Ye Ni wípé ibùdó-ìtakùn-àgbáyé akọ̀ròyìn náà gbè lẹ́yìn ẹnìkan nínú ìròyìn ìkọlù láàárín-in ọmọ-ogun ìjọba àti àwọn adárúgúdù sílẹ̀ Ọmọ ogun  Arakan ní Ìpínlẹ̀ Rakhine tí ó tẹ̀ jáde.
Nipasẹ ile ẹkọ oṣere ti Muyiwa Ademola ni Ijebu lo gba a wọ agbo oṣere.
Àwa obìnrin lọ́kọ̀ọ̀kan àti àpapọ̀ọ wa, a máa tẹ̀síwajú láti máa pariwo kí ‘ẹ yéé pa wá’ kí ẹ sì ‘yéé ṣe wá léṣe’.
Oríṣun àwòrán, @HQNigerianArmy sẹlẹ yii lo mu ki awọn arinrin ajo Hajj to wa ni papakọ ofurufu naa, to fẹ wọ baalu lọ si Saudi Arabia, tete sa asala fun ẹmi wọn.
Tinubu parí aáwọ̀ Ambode àtàwọn aṣòfin ìpínlẹ̀ Eko #BBCNigeria2019 Ile Asofin Eko ránṣẹ́ pe Ambọde láti wá sọ tẹnu rẹ̀ lórí ẹ̀ṣùn aṣemáṣe Ninu iwe ti EFCC gbe lọ siwaju ile ẹjọ, o fojuhan bi Adesanya ati awọn kan to ni anfaani si apo asuwọn naa ṣe n gba owo jade ninu apo asuwọn ijọba ti wọn si n da a si apo asuwọn miran.
“Lọ sọ fún Hananaya pé OLUWA ní àjàgà igi ni ó ṣẹ́, ṣugbọn àjàgà irin ni òun óo fi rọ́pò rẹ̀.
A gé díẹ̀ ninu àwọn ẹ̀ka igi olifi inú oko kúrò, a wá lọ́ ẹ̀ka igi olifi inú tí ó lalẹ̀ hù ninu ìgbẹ́ dípò rẹ̀.
Amọ nibayii, ti ijsba fẹ lo ilana kikuro ninu ajọ isọkan ilẹ Yuroopu lai lọwọ adehun ninu, awọn asofin apapọ yoo fontẹ lu aba to n beere fun ilana yiyapa lati sọ di ofin, bakan naa ni wọn yoo beere afikun ọjọ ti wọn yoo kuro lọwọ ajọ isọkan ilẹ Yuroopu tabi ki wọn wọgile igbesẹ yiyapa kuro ninu ajọ ọhun patapata.
”Ogbeni  Mohammed tun so pe ijọba n sa gbogbo ipa re lati le la awọn eniyan  lọyẹ nipa sise ikede lori ewu to wa nibi iroyin eke.
Nítorí náà, wọ́n ké pe OLUWA fún ìrànlọ́wọ́.
Ile-ejo ajo to n mojuto isoowo po awon orile-ede ile Afrika ti o kogun si iwo-oorun, Economic Community of West African States, ECOWAS ti pe fun ibasepo nile okere lojuna ati jo gbogunti iwa-ibaje, janduku ati awon iwa ipanle miiran to n dojuko ile Afrika.
Donald Trump Jr jẹ akọṣẹmọṣẹ ninu sisọrọ nita niwaju araalu to jẹ pe o ko ipa pataki ninu ipolongo idibo baba rẹ.
Seyi Makinde: Ọdún 2023 ni màá jíyìn iṣẹ́ ìríjú mi ní ẹ̀kúnrẹ́rẹ́
Àwọn ìròyìn tí ẹ lè nífẹ̀ẹ́ sí: 'IBB dalẹ̀ Abiola lẹ́yìn tó búra pẹ̀lú Koran' Sé o ti rí ère MKO Abiola tuntun?
Ó tó ba ni lẹ́rù, ó tó nǹkan ti o lè lé ènìyàn padà.
 Nigba ti o n ba awon oniroyin soro lori ero alagbeka pe, “ni orile-ede ti won sakoso ijoba tiwa-n-tiwa a leto lati seto iwode, lati fi ehonu wa han si awon ohun ti ko te wa lorun, nipase iwode wooro-wo”.
Se ni àwọn ọmọ àwùjọ mùsùlùmí yìí ńju òkúta bá àwọn ọlọ́pàá tí àwọn òsìsẹ́ aláàbò sì fín gáàsì padà tí wọ́n fi mú púpọ̀ lára àwọn afẹ̀hónú náà.
Ọjọgbọn Faduyile ṣalaye pe lootọ ni akọsilẹ fihan pe awọn to n lugbadi aarun covid-19 lojoojumọ ko pọ mọ.
Oríṣun àwòrán, Thinkstock Fun idi eyi, onimọ Chijioke ni asiko re ti aarẹ Naijiria ati awọn Gomina ni lati ṣan ṣokoto wọn daada ki wọn si mu adinku ba owo inakuna.
Yoòbá ní a rí ẹni tó lórí tí kò ní fìlà, a r’ẹ́ni tó ní fìlà tí kò lórí.
Awọn eniyan erekuṣu Gbẹ̀rẹ̀fù nitosi Badagry ni ipinlẹ Eko ni wọn n gbe ni aarin gbungbun odo nla.
Fún àpẹrẹ, obinrin ti kò múra dáradára tàbi ẹni ti ó bá wọ bàtà, Eégún á le lati naa.
Wọ́n jẹ́ ìlú olódi, wọ́n ní ìlẹ̀kùn ati ọ̀pá ìdábùú ìlẹ̀kùn, 
Oríṣun àwòrán, Ooni Adeyeye Ogunwusu, Ojaja 11 Mọremi ko ri ara rẹ bii obinrin lasan, ti ko lagbara lati se ohunkohun, amọ pẹlu ọgbọn atinuda, lilo ẹwa rẹ lọ to tọ pẹlu igboya, o gba ilu rẹ silẹ lọwọ igbekun.
Oriki Ibeji: Wíníwíní lójú orogún Ejìwọ̀rọ̀ lojú ìyá ẹ̀, Ẹ̀jìrẹ́ ará ìṣokún, Ẹdúnjobí, ọmọ a gbórí igi rétẹréte, Ọkàn ń bá bí méjì ló wọlé tọ míwá, Ọ́bẹ́kíṣì bẹ́kéṣé, Ó bé sílé alákìísa, Ó salákìísà donígba aṣọ.
" Wo ìdí márùn-ún tí Biden fi bórí nínú ìdìbò ààrẹ America Wo àwọn ọmọ Naijiria mẹ́ta tó jáwé olúborí nínú ìdìbò sílé aṣòfin ilẹ̀ Amẹrika Báwo ni Joe Biden yóò ṣe mú ìyípadà bá òfin tí Trump fi de orílẹ̀èdè àgbáyé?
Nibayi, Naijiria n dojuko ibẹsilẹ arun iba-pọnju eyiti o bẹrẹ ni iwọ-oorun orilẹ ede ni oṣu kẹsan ọdun to kọja.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù AWCON: Nàìjírìa gba ife ẹ̀yẹ AWCON fún ìgbà kẹsàn-án 1 Ọ̀pẹ̀̀ 2018 Oríṣun àwòrán, @NGsuper_falcons Àkọlé àwòrán, Ìdùnnú ṣubú layọ̀ fún àwọn ọmọ orílẹ̀èdè Nàìjíríà Aarẹ Muhammadu Buhari ti ki awọn agbabọọlu ikọ Super Falcons ku oriire bi wọn ṣe jawe olu bori ninu aṣekagba idije ife ẹyẹ ilẹ Afirika ti àwọn obinrin lọjọ Abamẹta Buhari fi idunnu rẹ han lori bi ikọ agbabọọlu naa ṣe gba ife ẹyẹ idije naa nigba kẹsan-an .
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ilé ẹ́jọ́ tó ń gb'ẹ́sùn ìdìbò wọ́gilé ẹjọ́ tí Ajimọbi pè tako Kọla Balogun 10 Owewe 2019 Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Iléẹ́jọ́ tó ń gb'ẹ́sùn ìdìbò wọ́gilé ẹjọ́ tí Ajimọbi pè tako Kọla Balogun Sẹnẹtọ to n ṣoju ẹkun idibo guusu ipinlẹ Oyọ, Kola Balogun ti sọrọ lori ifidirẹmi Sẹnetọ Abiola Ajimobi to pẹjọ tako lori ipo Senetọ.
Ọsẹ ipawọ apakokoro (Hand sanitiser) ti a ṣe nile Awọn iroyin kan ti wa kaakiri pe ọṣẹ apakokoro ti wọn nigboro, botilẹjẹ pe fifọ ọwọ rẹ jẹ ọkan lara ọna lati dena itankalẹ arun naa.
ẹni tí ń bọ̀ lẹ́yìn mi, ṣugbọn n kò tó tú okùn bàtà rẹ̀.
Oun kan naa ló gbé ọpa aṣẹ Ọba ati Ade le Ṣọun tí Ogbomoso, Oba Jimoh Oyewumi Ajagungbade Kẹta lásìkò tó wà ní ipò Kọmíṣọnna náà.
Mo sá wọ abẹ́ ìpàǹtí síbẹ̀ àlàáfíà kò sí fún mi, mo sápamọ́ si igọ̀ igi, síbẹ̀ òjò ń fẹ́ lù mí, gbogbo aṣọ mi tutù wọ́n sì lẹ̀ mọ́ mi lára.
 Stuart Symington  lo soro yii lasiko ayẹyẹ lati fi sami ajọdun
Ní Ìpínlẹ̀ Ogun, Ọmọ ọgbọ̀n ọdún fi àdá bẹ́ ikùn bàbá rẹ̀ ̀
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ekiti Oba Crisis: Ọọ̀ni ṣalàyé ìdí tí ààwọ̀ àwọn ọba Ekiti fi yàtọ̀ sí ti ẹ̀ẹ̀yà míràn 17 Ẹrẹ̀nà 2020 Oríṣun àwòrán, Ekiti state government Ni ipo rẹ gẹgẹ bi Arole Oodua nibi ti igi gbogbo ọmọ kootu oo jiire bi ti ṣan jade wa, Ọọni ile ifẹ ti pana aawọ laarin awsn lọbalọba ni ipinlẹ Ekiti.
Akomolede ati Aṣa: Mọ̀ síi nípa ìró afárànma àti agbárànmọ́ fáwẹ́ẹ̀lì Yorùbá
Nígbà tí Hamani rí i pé Modekai kọ̀, kò foríbalẹ̀ fún òun, inú bí i pupọ.
Gbogbo ohun tí ìwo náà ń ṣe, ni ó ṣe ní àṣeyọrí.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Elédùmarè ló rán mi sí gbogbo Ọba Yorùbá - Oluwo Toyin Abraham ọkọ rẹ̀ àti Ire ní London, Odunlade 'kòlábò' pẹ̀lú Mercy Aigbe Èlé owó iná ọba kọ́ ló kàn, ẹ kọ́ ṣàtúnṣe sí ìlànà àdánú tẹ́ ń ṣe fún wa - Iléeṣẹ́ apínná sọ fún ìjọba Àdínkù bá owó ojúmọ́ ọlọ́kadà l‘Ọyọ láti ₦200 si ₦100, owó gbígbà bẹ̀rẹ̀ lónìí A fẹ́ ìtọ́jú fún Boko Haram tó bá ronúpìwàdà, ẹ dá iléeṣẹ́ sílẹ̀ fún ìtọ́jú wọn - Ilé aṣòfin Olùkọ́ tó fi tipá gba ìbálé akẹ́kọ̀ọ́ tó fẹ́ wọ fásitì rí ẹ̀wọ̀n ọdún 21 he Fayose, o kò ní àmúyẹ gidi láti di ọmọ ẹgbẹ́ wa, àyè kò sí fún ọ - APC Ekiti O dabi ẹni pe inu wọn ko dun bi mo se maa n sakọ, ti wọn si n binu mi."
Ibi Musa Wọn bi Mansa Musa lọdun 1280 si idile awọn to ṣe olori.
Yóo fọ́ àwọn ìjọba wọnyi túútúú, yóo pa wọ́n run, yóo sì dúró laelae.
Iji lile Cyclone Fani ti da ijamba silẹ ni ila-oorun orilẹede India, ti ọpọlọpọ ile si ti wo lagbeegbe naa.
A gbà pé a ó ba a ṣíṣẹ́ rẹ̀.
Ìdajì owó iṣẹ́ àgbàṣe ló ń padà sápò gómìnà àná àti aya rẹ̀ l‘Ọyọ - Seyi Makinde Kíni ìwọ mọ̀ nípa Funmilayọ Ransome-Kuti?
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ìgbátí ìgbámú àná látọwọ́ sọ́jà obìnrin ti bá arákùnrin náà dé iléèwòsàn Sùgbọ́n lẹ́yìn àtótónù àwọn orílẹ̀-èdè méjèèjì, Nàìjíríà mú àdínkù bá owó físà fún Amẹrika ti Amẹrika náà sì tì mú àdínkù bá tiwọn báyìí.
Ileeṣẹ ọlọpaa Orlando ṣalaye pe wọn gbe Tommey digba digba lọ si ile iwosan, ṣugbọn ẹlẹmi ti gba a.
robi  si bi o se wa tele, ki won ma si da
Itọ rẹ yoo dinku: Ti ara ba gbẹ fun omi to nilo, ọkan yoo gba gbogbo omi to ri ni ayika lati le mu iṣẹ pipọ ẹjẹ tẹsiwaju, nitori naa ko ni si omi pupọ to ṣẹku ni ara fun itọ bi o ti yẹ.
Àdàwólulẹ̀ ilé ayé-àtijọ́ ọlọ́dún-un 150 fi àìkáràmáìsìkí ìjọba sí àwọn ibi àjogúnbáa Bangladesh hàn
Ipokipo ti a ba wa, o yẹ ka maa ri daju pe a sa ipa wa, lati fi ọgbọn ori wa han, ka si se iwọn ti a lee se.
"Oríṣun àwòrán, @nigeria_true ""Mo ti n gbe nibudo naa lati ọdun marun sẹyin, mo si maa n ni ibalopọ loore koore pẹlu awọn ọmọ ati mọlẹbi Mallam Owotutu, ko si din ni marun ninu awọn alakoso to n setọju ibudo naa, to ti ba mi ni ajọsepọ."
Ṣé o óo dákẹ́, o óo máa fìyà jẹ wá ni?
Ibi àyẹ̀wò mẹ́ta ló wà fún Coronavirus ní Naijiria O ṣalaye bo ṣe ṣẹlẹ gan to ṣe kongẹ mọde yii ni ipo to wa to bẹrẹ sidi ẹrọ ATM to si n kọ iwe.
Loni,Ọjọ April Fool ti ọdun yii ni ile isẹ iroyin kan fi lede wi pe agbabọọlu Super Eagles, Alex Iwobi ti kuro ni Arsenal lọ si Barcelona.
37 billion; thus, showing an increase of 24.
Sisera wí fún un pé, “Jọ̀wọ́ dúró ní ẹnu ọ̀nà àgọ́.
Wọ́n ń pa àwọn ọmọ Israẹli bí wọ́n ti ń dà gẹ̀rẹ́gẹ̀rẹ́ òkè náà.
Sotitobire: Adájọ́ sọ̀rọ̀ nípa ọjọ́ ìdájọ́ fún Wòlíì Sotitobire Alfa Babatunde
Pẹlu bi nnkan ṣe ri yii, goolu meje ni o ti wọ inu awọn Chelsea ninu ifẹsẹwọnsẹ mẹta ti wọn ti gba bayii laarin ọsẹ kan si ara wọn Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
36 Kíyèsíi, èmi kò sọ pé ìwọ kò ní fi hàn àwọn olódodo.
Nígbà tí àwọn ẹ̀dá wọn-ọnnì sì gbé àjàgà tí í ó wúwo, tí wọ́n sì ru ẹ̀rù tí kò fúyẹ́, wọ́n di rìkísí ńlá mọ́ oníbodè, títí onítọ̀hún fi fi iṣẹ́ sí ilẹ̀ tí ó wá si Igbó Irúnmọlẹ̀ tí ó ń gbé ibẹ̀ di bí mo ti ń sọ̀rọ̀ yìí.
Ó ní ''nínú ìwé nàá lòun ti ṣàlàyé ní ẹ̀kúnrẹ́rẹ́ tí òun sì tun ṣàfihàn àbọ̀ ìwádìí tí àjọ EFCC, àti ìgbìmọ̀ ilé aṣòfin tó wádìí àwn ẹ̀sùn tí bí wọ́n ṣe ná owó bàntà-banta nàá sórí ìpèsè àti pípín ìná ọba láàrin oṣù Kẹfà, 1999 sí oṣù Karùn ún, 2007, láì so èso rere.
orile ede Naijiria to n gbe ni ilu okeere lati beere fun ofin ti yoo gba won
Mo yọjú wo ìta,láti ojú fèrèsé ilé mi.
Ẹgbẹ́ òṣèlú AAC fi ọwọ́ òsì júwe ilé fún Ṣowore!
Ó ní, “Ẹ kéde ní Ijipti,ẹ polongo ní Migidoli, ní Memfisi ati ní Tapanhesi.
Opo ero lo wa nita ile re ni Mumbai ti won wa kedun iku  Sridevi ki won to sun oku re.
Ẹgbẹ́ Agbẹjọ́rò NBA ti kéde pé àwọn yóò ṣojú awọn Olùwọ́de #EndSARS lọ́fẹ̀ẹ́ nílé ẹjọ́ 'Mo jíṣẹ́ ẹ rán mi'!
Awọn eniyan n wo o boya wọn yoo ri awọn ọmọ ti wọn jigbe yii gba pada.
A ń gbà a ladura pé àrùn burúkú kò ní fi agọ̀ ara wa se ibùgbé, bí àwọn ará iwájú tí ṣe borí àwọn ajakale àrùn tó rekọja lọ, naa ni àwa yóò borí Covid-19.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Kété tí wọ́n bá ti báa yín sùn tàn torí pé ẹ tóbi, ẹ gbà pé ìfẹ́ yẹn ti parí - Auntie Remi Ọlọ́yàn ńlá Gómìnà Oyetola: Kò sí àfikún ọjọ́ ìdáríjì fáwọn jàndùkú tó jí ohun iyebíye gbé lọ nípinlẹ̀ Osun Oríṣun àwòrán, @GboyegaOyetola Gomina ipinlẹ Osun, Adegboyega Oyetola ti ni oun ko ni ṣe afikun ọjọ idariji fun awọn janduku to gbe ohun ini ijọba lọ lati da pada.
Wọn fikun pe ọjọ kẹrinlelogun, osu keji, ni ẹni naa wọ orilẹede wọn ti awọn si tete ṣe akiyesi nitori awọn eto ayẹwo ti awọn ti fi lele Nibayii, ọkunrin naa ti wa ni ipamọ ni ile iwosan to wa ni Yaounde lorilẹede naa.
Ìṣọwọ́ gbá bọ́ọ́lù Atletico kò tọ̀nà àmọ́ a gba ìjákulẹ̀ wa - Liverpool Bakan naa lo fikun pe orilẹede Naijiria ko ṣetan lati ti awọn papako rẹ, tabi fi ofin de irinna ọkọ ofurufu lati orilẹede kan si omiran to n ba arun Coronavirus finran.
Nítorí náà, mo ti búra fún ilé Eli pé, kò sí ẹbọ kan tabi ọrẹ tí ó lè wẹ ẹ̀ṣẹ̀ burúkú náà kúrò laelae.
Ẹni tí kò bá ní idà, kí ó ta ẹ̀wù rẹ̀ kí ó fi ra idà kan.
Nigba to n rọ ijọba Oyo lati yago fun oselu buruku, aya Ajimobi ni ololufẹ alaafia ni ọkọ oun, to si sin ipinlẹ Oyo fun ọdun mẹjọ gbako.
Kò ní sí ọba ní ilẹ̀ Ijipti mọ́, n óo jẹ́ kí ìbẹ̀rù dé bá ilẹ̀ Ijipti.
Igbo yii lo jẹ̀ ilegbe fun ọ̀pọ̀ awọn ẹranko ti wọn wa ninu ewu jù lẹkun ìwọ̀ oorun Afrika.
 Ẹ ̀ yà ìṣáájú àjẹsára náà níí ṣe pẹ ̀ lú lílọ ́ pọ ̀ ìfun , ṣùgbọ ́ n ẹ ̀ yà titun rẹ ̀ ní báyìí kò tíì ní ohunkóhun ṣe pẹ ̀ lú èyí dájúdájú .
Nítorí nígbà tí mo wà ní Tẹsalonika kì í ṣe ẹ̀ẹ̀kan mọ, ó tó ẹẹmeji tí ẹ fi nǹkan ranṣẹ sí mi.
Paapaa lori oogun fun nkan ọmọkunrin ati oju ara obinrin laiyọ atike ikoko silẹ.
1958 lo ra ẹgbẹ agbabọọlu ti orukọ rẹ n jẹ Oluwole Philips Football Club ti o si yi orukọ rẹ pada si Stationery Stores Football Club.
Nigba ti oludari CBM fun ekun  Oyo ati Ogun, Clement
Eeyan merin lo ko aarun naa l'Ogun, mẹta ni Kaduna ati Oyo nigba ti ẹnikan lugbadi aarun naa nipinlẹ Osun.
Inú oṣù kẹ́jọ ọdún 2016 ní ọ̀rọ̀ ajé orílẹ̀-èdè Naìjìríà ti dẹnukọlẹ̀ kẹ́yìn.
Àbí eniyan ha lè dákẹ́ bí?
Àwọn àjọ̀dún wọ̀nyí lè mú ìkóúnjẹjẹ gbòòrò, kí ni ó burú nínú ìyẹn?
Ile itaja epọ NNPC ti o jẹ ti ijọba apapọ orilẹede yii ni akọkọ ṣe abẹwo si ni agbegbe Ajanla ati opopona marọsẹ Ọjọọ nilu Ibadan.
Ní ìhà àríwá aiyé, ìgbà ìwọ́wé ni a wà báyìí.
Ìtàn Bí A ṣe Dá Ayé.
Ọgbẹni Yinka Odumakin to jẹ alukoro agba ẹgbẹ naa ni ohun ti ijọba ko fi fopin si Myetti Allah ati awọn darandaran to n gbe ibọn kiri naa lo difa pe wọn ko le fopin si ikọ Amotekun.
Wo ìlànà ìgbani síṣẹ́ márùn-ún fún àwọn ọlọ́pàá SWAT tó rọ́pò SARS Ọlọ́pàá mẹ́sàn án tó farapa nínú ìjàmbá ọkọ̀ Akure t'éèyàn méjì ti kú sì wà nílé ìwòsàn Mo ṣèlérí láti ṣe ju ohun tí mo ti ṣe lọ fún ẹbí àwọn tó kú torí EndSARS - Seyi Makinde Ìwọ́de 'End SARS' lè tan àjàkálẹ̀ arùn coronavirus lẹ́ẹ̀kejì ní Nàìjíríà- Ọjọ̀gbọ́n Faduyile Bawo ni ikọ SWAT yoo ṣe ma a ṣiṣẹ?
Ni oṣu kẹjọ ọdun 1991, wọn ya ipinlẹ Yobe latara Borno nigba ti wọn pin ipinlẹ Gongola si meji, Taraba ati Adamawa.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Wole Soyinka: Kò sí ààyè fún ẹnikẹ́ni láti gba ilẹ̀ ìràn Yorùbá 8 Agẹmo 2019 Oríṣun àwòrán, @Olafare Àkọlé àwòrán, O to gẹẹ nilẹ Yoruba, o yẹ ki a mọ ohun to kan Kò sí ààyè fún ẹnikẹ́ni láti gba ilẹ̀ ìràn Yorùbá -Ọọni Ifẹ̀ Ọrọ awọn Fulani darandaran ati awọn agbebọn ajinigbe laarin wọn gba ipade agbaagba Yoruba.
Mo so fun aare nipa bi eto iforuko sile se n lo.
Ogagun Ibikunle Daramola to jẹ alukoro ileeṣẹ yii ni Nehemiah Adejoh, Igbekele Folorunsho ati Festus Gbayegun lo wa ninu ọkọ ti o pa Tolulọpẹ Arotile.
Bunkunmi Oluwasina ṣe ìgbèyàwó, ẹ̀yin bẹ́lẹ́jayán ẹ lọ sẹ́mpẹ́ Njẹ́ o mọ̀ pé bíi ọdún 700 sẹ́yìn ni wọ́n ti ń bọ Osun-Osogbo?
Oríṣun àwòrán, Wale Àkọlé àwòrán, Orúkọ Abiku ni Okunnu tí mo ń jẹ nínú eré, inú orin Barrister ni mo sì ti ri - Wale Akorede O ni Ọlọ́run nìkan ló máa ń fún oun ní iwuri àti ìtọ́ni láti kọ ìtàn fún èrè ṣíṣe, bẹ́ẹ̀ sì ni òun nìkan lo máa ń fún ní ní ọgbọ́n àti làákàyè, ìdí sì rèé tí òun ṣe máa ń ṣe àdúrà pé kí Ọlọ́run dárí oun, àti pé, oun ni lọ́kàn pé oun fẹ́ kọ ìtàn, ó kàn máa ń wà ní.
Wọ́n bọ àwọn oriṣa wọn,èyí sì fa ìpalára fún wọn.
“Ní àkókò tí àwọn ẹran náà ń gùn, mo rí i lójú àlá pé àwọn òbúkọ tí wọn ń gun àwọn ẹran jẹ́ àwọn tí àwọ̀ wọn dàbí ti adíkálà ati àwọn onífunfun tóótòòtóó ati àwọn abilà.
Amọ awọn ẹrọ naa ko ni ka oju osunwọn ti a mọ wọn si tẹlẹ nitori bi ile iṣẹ Google ti ṣe gbegidina mimu ayipada ba awọn aapu kọọkan lori ẹrọ alagbeka Huawei.
765bn lati ran ileeṣẹ ọlọpaa lọwọ.
Mo gbé òkúta léná kí àwon ọmọ mi le rò pé oúnjẹ ni mo ń sè- Obìnrin Opó Coronavirus updates: Mo gbé òkúta léná kí àwon ọmọ mi le rò pé oúnjẹ ni mo ń sè- Obìnrin Opó Oríṣun àwòrán, Getty Images Obinrin kan ti wọn pe orukọ rẹ ni Kisauni lórilede Kenya ni o gbe okuta léna nitori ko si ounjẹ kankan ti yoo fun wọn jẹ Kasauni ọlọmọ mẹwàá to tun jẹ opo ni, láti igba ti igbele aarun coronavirus ti bẹrẹ ni o ti nira fun oun láti bọ àwọn ọmọ mẹjọ yìí.
" Bi mo ba sọrọ daadaa nipa eeyan kan tabi kọ iroyin mi lai lẹja mbakan ninu, ẹ o ni wọn ti san owo fun mi""."
Má jẹ́ kí á bá ọ ní ìdí ìtàn àgbọ́sọ tí kò wúlò ati àwọn ìtànkítàn tí àwọn ìyá arúgbó fẹ́ràn.
Gẹgẹ bi awọn to ti di agba ọjẹ ṣe wa laarin wọn ti wọn ṣi dun un wo loju bẹẹ naa lawọn to ti n yọri bọ atawọn to ṣẹṣẹ n yọri naa ni ololufẹ wọn.
Lọpọ igba iru awọn iwosan bayii ko l''ewu, sugbọn wọn tun le fa wahala si agọ ara.
Igi lotusi ni ó ń ṣíji bò ó,igi tí ó wà létí odò yí i ká.
Joseph ni oku rẹ si wa nileewosan, ti ileeṣẹ ọlọpaa si n duro de ayẹwo lati mọ ohun to ṣekupa, ki wọn to yọnda rẹ fun awọn eniyan rẹ.
Àwọn mìíràn ń sọ pé, “Èyí kì í ṣe ọ̀rọ̀ ẹni tí ó ní ẹ̀mí èṣù.
Nigba ti isẹ naa ko ba lara mu, lo ba ko awọn owo to ri fi pamọ pada si Uganda, to si n se ọgbin eso ati agbo.
Bẹẹ naa ni awọn olupẹjọ tun mu awọtẹlẹ ọmọ naa ti ẹjẹ wa lara rẹ, atawọn nnkan miran wa siwaju adajọ fun ẹri.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Orlando Owoh: Èmí àti Oladipupo Owomoyela jọ lọ ẹ̀wọ̀n Alágbọn- Caroline Owoh, aya Orlando Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Australia: Igbe ayekòótọ́ sàànfàní, ó kó olówó rẹ̀ yọ lọ́wọ́ ikú gbígbóná4 Bélú 2020 Oyinkan Abayomi: Ajàfẹ́tọ̀ọ́ ẹni tó dá ẹgbẹ́ òṣèlú obìnrin àkọ́kọ́ sílẹ̀, tó tún jà fún ètò ẹ̀kọ́, ìṣèlú àti òmìnira obìnrin5 Bélú 2020 Diego Maradona: Àgbàọ̀jẹ̀ agbábọ́ọ̀lù Argentina ṣiṣẹ́ abẹ lórí ẹ̀jẹ̀ tó dì sí i lọ́pọlọ lẹ́yìn ọjọ́ ìbí ọgọ́ta ọdún4 Bélú 2020 Fídíò, Soyinka Cancer: Àṣe ara mi ni iso ti n run gbogbo bí mo ṣe n ṣèrànwọ́ lórí jẹjẹrẹ27 Bélú 2019 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 3 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 5 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
A fẹ́ bẹ̀rẹ̀ òfin má lo fóònù mọ́ fàwọn ọmọ wa -Òbí Òní nilé ẹjọ́ tó ga jùlọ yóò gbẹ́jọ́ ẹ̀sùn ayédèrú sabuké tí wọ́n fi kan Buhari Àwọn akọni Nàìjíríà padà sílé pẹ̀lú àmì ẹ̀yẹ 121 láti Morocco Wike kìí ṣe dọ́là tí Ganduje leè kó sápò- Agbẹ́nuso ìjọba ìpínlẹ Rivers Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
O ni: 'Eniyan ko mọ igba ti ọlọjọ yoo de, nitori naa ṣe oun to yẹ, nitori ọjọ n lọ' Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Working religious women: Ẹ̀lẹ́hàá kìí ṣe ọ̀lẹ- Aminat Adegoke 'Ohun ti mo ṣe to wu mi lori ni bi mọ ṣe ṣe ere idaraya to mu adinku ba bi mo ṣe sanra tẹlẹ.
Asofin Sirika ko sai fi idunnu re han pe “Inu mi dun lati so fun un yin pe, a ti wa loju ona bayii lati ni baalu tiwa ti yoo maa gbe asia orilẹ ede  yii ga: Baalu Naijiria.
Ewe, o kere tan ogorun-un eniyan ni o ti ba isele ohun lo lati ojo kejidinlogun osu keji odun ti a wa yii, ti ikolu naa ti bere.
Sibẹ kò sí ọ̀kan ninu wọn tí Ọlọrun fi ojú fò dá.
Fasiti Ahmadu Bello ni Zaria lo ti kọ ẹkọ nipa iṣiro owo ko to gba oye keji ni Fasiti Olabisi Onabanjọ ni ipinlẹ Ogun.
Bi ó bá ti gbóná, a lè fi ṣibi tàbi ọwọ́ da ewùrà ri-rin ti a ti pò pẹ̀lú èlò́ yi si inú epo to gbóná lati din
OLUWA, n kò ṣe ìgbéraga,bẹ́ẹ̀ ni ojú mi kò gbé sókè.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Divorcee: Ó sàn kí wọ́n yàgò fúnra wọn ju ki wọ́n ṣe ara wọn léṣe- Fisayo Iṣẹ agbẹ ni iṣẹ ti ọjọgbọn Andrew Haruna mu lọkunkundun lati igba ewe.
Oloṣelu ni ẹgbẹ oṣelu PDP, Femi Fani-Kayode ti fi lẹta itagbangba ranṣẹ si Asiwaju Bola Ahmed Tinubu lori igbesẹ Aarẹ Buhari to yan gomina ipinlẹ Yobẹ gẹgẹ bi Alaga fidiẹ fun ẹgbẹ oṣelu APC.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Gọngọ sọ, ẹlẹ́há pàdé àwọn tó lùú ní jìbìtì nílùú Eko lọ́jà Ibadan Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Tafawa Balewa jẹ akinkanju oloṣelu ati adari igbimọ ijọba kan ṣoṣo ti Naijiria ni lẹyin ominira.
23 Kíyèsíi, Jésu Krísti ni orúkọ tí Bàbá fi fúnni, àti pé kò sí orúkọ míràn tí a fi fúnni nípa èyí tí ènìyàn lè rí ìgbàlà.
Oríṣun àwòrán, others 'Mo lee ku tori Goodluck Jonathan.
Àwọn orílẹ̀-èdè tí OLUWA fi sílẹ̀ nìwọ̀nyí: àwọn olú-ìlú Filistini maraarun ati gbogbo ilẹ̀ Kenaani, àwọn ará Sidoni ati àwọn ará Hifi tí wọn ń gbé òkè Lẹbanoni, láti òkè Baali Herimoni títí dé ẹnubodè Hamati.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Akomolede ati asa Yoruba: Ẹ wá kọ́ nípa àpòtí ìṣura èdè wa lórí BBC Yorùbá Ṣugbọn ko tii si ẹni to tii fi idi igbesẹ naa mulẹ ninu imọ sayẹnsi pe o lagbara lati wo ikọkan ninu awọn aisan ọhun.
Ọpọlọpọ wakati ni awọn ololufẹ Super Eagles fi to ni ile itaja Nike nilu London lati ra jẹsi naa.
Ilé wó pa Jide, ọmọ ọdún mọ́kànlá, l'Oṣogbo ìjọba Nàìjíríà ti kéde ìsinmi lọ́jọ́ Ìṣẹ́gun àti Ọjọ́rú Sultan pàṣẹ fún àwọn mùsùlùmí láti ṣ'ọdẹ òṣùpá lónìí Donald Trump ti pàdé Ọbabìnrin Elisabeth tilẹ̀ Gẹ̀ẹ̀sì Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Mo ń ṣa ike jọ láti san owó ilé iwé ọmọ mẹ́ta' Ileẹjọ tun dajọ ẹwọn ọdun mejilelogoji fun Ọgbẹni Alu Dismas to jẹ oluranlọwọ fun ọga NIMASA tẹlẹ, Patrick Akpobolokemi.
Awọn ibeere to ni awọn oluwọde naa gbọdọ fesi si niyi.
Wó ọkùnrin táwọn obìnrin fipá bá lòpọ̀ ní ẹ̀ẹ̀mejì Bí ìyàwó rẹ bá lóyún tàbí bímọ ní ìpínlẹ̀ Oyo, wo bí o ti ṣe lé gba ìsinmi ìtọ́mọ (Paternity leave) Ẹ̀bùn #500,000 wà fún ẹni tọ bá ba wa rí afurasí ikú Akinyẹle tó sọnù- Iléeṣẹ́ Ọlọ́pàá Wo àmúyẹ kí o tó lè di ọmọ ogun ilẹ̀ Nàìjíríà pẹ̀lú fọ́ọ́mù tó jáde yìí Ṣé òótọ́ ni pé ìgbẹ́ erin le è wo arùn Coronavirus sàn?
m ni ojú mi déédé fọ́ níbi tí mo ti ń darí ọkọ̀ ni Ọrẹgun Ikẹja -LASTMA Yesufa Mamora, Lai Mohammed, Gbemi Saraki wà lára minista Buhari tuntun Òkìtì iyanrìn wó pa èèyàn méjí nílùú Ibadan Àgùnbánirọ̀ akọ̀ròyìn Channels náà ti dágbére fáyé látààrí ìkọlù Shiite l'Abuja Lọsan kan, oru kan, UK yoo kuro ni ọja kansoso alajumọse ati asa nini ajọsepọ - eto ti wọn gbe kalẹ lati dokoowo papọ laarin awọn orilẹede to wa labẹ isọkan ilẹ Yuroopu, ti ko si ni lọwọ ayẹwo ọja abi sisan owo ori ninu.
Reueli bá bi àwọn ọmọ rẹ̀ léèrè pé, “Níbo ni ará Ijipti ọ̀hún wà?
Hamani jáde pẹlu ayọ̀ ńlá, ati ìdùnnú.
Pa pọ̀ mọ́ ipari ọdún ni àwọn ti ó fi ayẹyẹ iyàwó, òkú, ọdún Kérésìmesì àti ṣíṣe miràn si àsikò yi.
Bode George ni iwa ti ko tọ fun ologun ni lati kọju ibọn si awọn eeyan ti ko di ihamọra ogun, paapaa julọ nigba tawọn ti wọn n dojukọ jẹ ọdọ orilẹẹde ti wọn jẹjẹ lati maa daabobo.
Igbimọ naa yoo maa gbọ ẹsun t'awọn eeyan ba gbe wa siwaju rẹ ni gbogbo ọjọ Aje, Ọjọru ati Ọjọbọ ni ile ẹjọ majisireti to wa ni Isabo Abeokuta.
Ìdílé Barrister àti K1 Wasiu Ayinde sọ àsọyépọ̀ nílé Obey Commander 2 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Oríṣun àwòrán, Olasunkanmi Marshal/Facebook Ko sí a gbé ma já, aja ma tan ni ko daa.
Ọdun 1984 si ni Ayanfẹmi, ti gbogbo eeyan mọ si ‘Baba Rainbow’ jade laye.
3 86949 Orilẹede Uzbekistan 611 1.
  Ara rẹ̀ la ti ń rí epo pupa tí í ṣe agbátẹrù iṣu lọ́nàfun.
3 sí ló fi n ṣiṣẹ́.
Iya to bi ọkan lara awọn oluponlongo to ṣe agbatẹru iwọde EndSARS to waye laipẹ yii ni ipinlẹ Eko, Eromosele Adene to wa latimọle ọlọpaa ti faake kọri nile ẹjọ.
Fury vs Wilder: Ìbínú ni Wilder fi kúrò níbí ìjà, tó sì ní síbẹ̀-síbẹ̀, akọni ni òun
Ti a ba si ni ka kọ itan orilẹ-ede Naijiria, abala diẹ kọ ni oloogbe ọgagun Sani Abacha yoo ko nitori ipa manigbagbe to ko ninu isejọba Naijiria.
Ìjọba Burundi ti bẹ̀rẹ̀ sí í fi ìkanra mú ìwà àtakò láti ọdún 2015, lẹ́yìn ìjákulẹ̀ ìṣọ̀tẹ̀ kan, ìdojúkọ pẹ̀lú àwọn ẹgbẹ́ adìtẹ̀ kan, àtakò lórí ìlòkulò ẹ̀tọ́, òfin kànńpá, ìnira pẹ̀lú ètò ọrọ̀-ajé àti rògbòdìyàn àwọn asásàálà.
Bi a ko ba gbagbe, Inec ti saaju rọ awọn oludije ati awọn alatilẹyin wọn pe ki wọn ma ṣe pede abuku sira wọn lasiko ipolongo naa.
Nítorí iṣẹ́ rere ni ó ṣe sí mi lára.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ilé ẹjọ́ kéde Ademọla Adeleke gẹ́gẹ́ bíi gómìnà ìpínlẹ̀ Ọṣun 22 Ẹrẹ̀nà 2019 Ìròyìn tó ń tẹ̀ wa lọ́wọ́lọ́wọ́ ní wí pé ilé ilé ẹjọ́ tó ń gbọ́ ẹjọ́ ìdìbò gómìnà ìpínlẹ̀ Ọṣun ti kede oludije fun ẹgbẹ oṣelu PDP, Ademọla Adeleke gẹgẹ bii gomina ti ilu dibo yan ni Ọ̀ṣun.
Ami ayo pẹnariti marun un si mẹrin ni wọn fi ṣagba Chelsea lẹyin ti wọn ti kọkọ ta ọmi alayo mejemeji.
Kọmiṣọna ajọ eleto idibo INEC, Festus Okoye lo ṣalaye ọrọ naa nigba to ba BBC sọrọ lọjọ Ẹti.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Bakan naa ni wọn tun fi kun un pe, awọn mẹtẹẹta lo ti rinrinajo lọ sawọn orilẹede ti arun yii ti wọpọ lagbaye laarin ọjọ meje sẹyin.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: INEC-Àwọn jándùkú àti ọmọ ilé ìṣẹ́ ológun lo dá ètò ìdìbò Gómìnà Rivers rú Wike fẹ́ lò wá láti da ìdìbò rú pẹ̀lú rìbá - Iléeṣẹ́ ológun APC gba ìjòkò tó pọ̀ jùlọ ní ilé aṣòfin àgbà A tún ti ṣàwárí omi àjèjì míràn ní Ilé-Ifẹ̀ - Ọọ̀ni Òkùnkùn biribiri ni ìjìyà ẹ̀ṣẹ̀ ìjọba ìbílẹ̀ mẹ́fà nílẹ̀ Ìjẹ̀ṣà tó na òṣìṣẹ́ àjọ amúnáwá Bàbá pokùnso ní àhámọ́ lórí ẹ̀ṣùn pé ó bá ọmọ rẹ̀ lòpọ̀ Aago mẹsan alẹ ni ikọ ọtẹlẹmuyẹ, ti ọga ọlọpa kan lati agọ ọlọpa Marọkọ, Isah Abdulmajid ko sodi, lọ paraaro afara kan to so adugbo Lekki pọ mọ Ikoyi, asiko yii si ni wọn ri awọn omidan meji kan, ti wọn n gbọn jinni-jinni.
sọ fún àwọn ọmọ Israẹli pé, “Bí obinrin kan bá lóyún tí ó sì bí ọmọkunrin, ó di aláìmọ́ fún ọjọ́ meje, gẹ́gẹ́ bí ó ti jẹ́ aláìmọ́ nígbà tí ó bá ń ṣe nǹkan oṣù rẹ̀.
Nítorí pé ìwọ Ọlọrun mi, ti fi han èmi iranṣẹ rẹ pé o óo fìdí ìdílé mi múlẹ̀, nítorí náà ni mo ṣe ní ìgboyà láti gbadura sí ọ.
N óo máa tọ yín sọ́nà nígbà gbogbo,n óo fi nǹkan rere tẹ yín lọ́rùn;n óo mú kí egungun yín ó le,ẹ óo sì dàbí ọgbà tí à ń bomi rin,ati bí orísun omi, tí omi rẹ̀ kì í gbẹ.
Ija eerin meji: Oluwo ati Ọọni Ani sẹ, Ọọni ran alaabo rẹ simi - Oluwo Sugbọn igbese naa ti mu ariwisi ọtọọto wa, paapa julo, lati ọdọ awọn onimo ẹsin Islam ni ilẹ Yoruba.
 Àwọn wọ ̀ nyí únjẹ ́ wíwà láti inú ilẹ ̀ ní ilé-iṣẹ ́ gẹ ́ gẹ ́ bí ìṣágbẹ , bíi bóráksì àti kẹ ́ rnítì .
 eyi lo si maa n fa wahala laarin awon
 Gbọ́ ọ̀rọ̀ lẹ́nu afurasí tí Ọlọ́pàá ní ó pa Barakat Bello, Grace Oshiagwu àtàwọn míì l'Akinyele Ibadan Eruku sọ lálá níbi ayẹyẹ ìgbéyàwó Lizzy Anjorin, àwòrán àti fídíò nìyíì Orin ìsìn ọjọ́ ìbí àṣẹ̀yìndè Ibidunni Ighodalo yóò wáyé, Tope Alabi, Kenolly àtàwọn míì tí yóò kọrin níbẹ̀ rèé Wo àwọn olorì àgbà mẹ́rin tí Aláàfin ń wárí fún Ninu fidio ọhun ti Arole Oduduwa ti kopa lo ti sọ pe Awa ti a wa lati iran Yoruba, ati kaakiri agbaye ni lati maa bọwọ fun awọn agbalagba.
Ètò ìkówó jọ ti wọ́n ń ṣe fún Erica ṣì n lọ lọ́wọ́ títi di àsìkò yìí.
Lára àwọn àpẹẹrẹ àrùn alefọ náà ni ibà, orí fifọ àti èébì.
Igbeyawo naa la ọpọlọpọ iji kọja to jẹ pe bi wọn ṣe n ja ni wọn n pari rẹ ki o to di pe wọn kuku ja ajatuka lẹyin lẹyin ọdun diẹ, iyẹn lọdun 2017.
Oríṣun àwòrán, AFP/Getty Images Àkọlé àwòrán, George Weah gba ipo lowo Ellen Johnson Sirleaf gege bi aare orilẹede Liberia Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Ko pẹ si igba ti iroyin jade lo ni lootọ ni to si bẹrẹ si ni gba itọju ni ibudo iyasọtọ ni ipinlẹ Katsina.
Google Map: Ànfààní wo ló wà nínú lílo ẹ̀rọ̀ ajuwe ọnà pẹ̀l'óhùn Nàìjíríà?
Fayoṣe ní ìbéèrè mẹ́rin fún Buhari lórí ìwé ẹ̀rí rẹ̀ Ohun márùn ún to se kókó fún ọ lásìkò ìyanṣẹ́lódì òṣìṣẹ́ Èéfín gẹnẹratọ gbé ayálégbé délé ẹjọ́ #30,000 Minimum Wage: 'Ẹ ṣì ṣe sùúrù fún wa' Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Grandma Maruwa: Ó yẹ kí obìnrin sisẹ́ láì wojú ọkọ kó tó jẹun Loju awọn eeyan miran, Chris, ẹni ọdun mẹtalelọgbọn kan n gbe igbe aye lasan ni, amọ ko yatọ si ère isẹ ọna ti wọn gbẹ silẹ, eyi ti wọn fi aworan tattoo bo lara lati ori de ẹsẹ ni awọn aworan to fa ni mọra.
Gbogbo àwọn ọ̀tá yín patapata, ni yóo lọ sí ìgbèkùn.
Èèyàn 1,300 ni ìjọba Nàìjíríà ń wá báyìí nítorí àrùn Coronavirus Kò tíì sí àrùn Coronavirus ní ìpínlẹ̀ Oyo, a ṣi ń retí èsì àyẹ̀wò - Ijọba Oyo Ìyá ọmọ tó sọnú níléèjọ́sìn l'Akure bú sẹ́kún nílé ẹjọ Ki lo ti ṣẹlẹ sẹyin?
Ọpọlọpọ obinrin ode oni lo n fi gbogbo iṣẹ lẹ fun mọ ọdọ.
"Ṣe ka wa lọ fa ara wa le ọlọpaa lọwọ ni abi ka duro sile ki ọlọpaa wa mu wa?
Bí ẹ bá sọ pé ẹ kò mọ nǹkan nípa rẹ̀,ṣé ẹni tí ó mọ èrò ọkàn kò rí i?
Ẹwẹ, ikọ olupolongo rẹ ṣi tun bu ẹnu atẹ lu eyi.
Iyẹ́ agbe, iyẹ àlùkò, ìyẹ́ àkàlà, atí ìkóódẹ ni wọ́n ffi dí àdó náà lẹnu, bẹ́ẹ̀ ni ẹ̀jẹ̀ gbogbo ń bẹ ní ẹ̀gbẹ́ rẹ̀, bàbá ńlá wa tí mo sì ń sọ̀rọ̀ rẹ̀ yìí ni ẹni kìíní tí ó kọ́ ṣe ọdẹ ninú Igbó Irúnmalẹ̀ jákèjádòìlú wa, ìgbà náà ni ó sì ti pa erè tí mo ń sọ̀rọ̀ rẹ̀ yìí tí olúwaarẹ̀ sì dárúkọ ibi tí òun ń lọ wéré ni atẹ́gùn yóò fẹ́ àwọn ìyẹ́ wọ́n-ọnnì wwọ́n ó si dojukọ ọ̀nà ibẹ̀ gan-an; wò mí ọ̀rẹ́ mi, bí kò ṣe pé mo gbàgbé àwọn ọfọ̀ náà ni, èmi ìbá kọ́ ọ, nítorí kò ju gbólóhùn mẹ́ẹ̀ẹ́dọ́gbọ̀n péré lọ.
“Ẹ kò gbọdọ̀ kórìíra àwọn ọmọ Edomu, nítorí pé arakunrin yín ni wọ́n.
Ààrẹ lọ́wọ́lọ́wọ́ tí ó jẹ́ òǹdíje lábẹ́ àsíá APC, Buhari ló jáwé olúborí nínú ìbò ààrẹ ti ọdún 2011 tí ààrẹ ìgbà kan Goodluck Jónátánì sí pàdánù.
Kọmiṣọna feto iroyin nibẹ, Muhammad Garba to fi atẹjade naa sita ṣalaye pe gomina Abdullahi Ganduje ti paṣẹ fun ileeṣẹ ijọba to n mojuto eto ilera nipinlẹ naa lati ṣewadii ohun gan to n ṣẹlẹ.
Àwọn orílẹ̀-èdè yóo sì mọ̀ pé ẹ̀ṣẹ̀ ni àwọn ọmọ Israẹli dá tí wọ́n fi di ẹni tí ó lọ sí ìgbèkùn, ati pé wọ́n ṣọ̀tẹ̀ sí mi ni mo ṣe dijú sí wọn, tí mo fi wọ́n lé àwọn ọ̀tá wọn lọ́wọ́, tí wọ́n sì fi idà pa wọ́n.
Ni ipinlẹ Eko, Gomina Babajide Sanwo Olu ti kede wi pe ti awọn eniyan ba kọ lati tẹlẹ asẹ konile-o-gbele, yiyagofunraẹni ati fifọwọ ni gbogbo igba, oun yoo paṣẹ ki konile-o-gbele ọlọjọyipo pada.
Àjọ tí ó ń rí sí ìwọlé wọ̀de ní àwọn yóò bẹ̀rẹ̀ sí ní ṣa ipa ju ti ẹ̀hìn wá lọ láti ríi pe Ebola tí ó ṣẹ̀ṣẹ̀ ṣẹ́ yọ ni DR Congo kò wọ 'nú orílẹ̀ èdè Naijiria.
Oro inu rẹ l'agbara pupọ, to si ma n bugbamu to ba fi ara kan ina - to ba si ti bugbamu tan, ammonium nitrate ma n fọn afẹfẹ gaasi oloro nitrogen oxides ati ammonia gas sita.
OLUWA, ìwọ ni Israẹli gbójú lé,ojú yóo ti gbogbo àwọn tí wọ́n kọ̀ ọ́ sílẹ̀.
Ẹ̀yin olólùfẹ́ mi àti ẹbí ni mo bẹ̀ Ìjà Toyin àti Lizzy kìí ṣe àkọ́kọ́, àwọn òṣèré t'ọ́rọ̀ ìjà kàn rí rèé Awọn ololufẹ Toyin Abraham Ololufẹ Toyin kan ni, bi Lizzy Anjorin ṣe n nọ'ka abuku si Toyin ti jẹ ki oun ni ifẹ Toyin ju ti atẹyinwa lọ.
Bakan naa ni Alhaji Aliyu sọ pe nkan to ṣẹlẹ si ọmọ oun fihan pe ọpọ alaiṣẹ lo n jiya ẹsun ti wọn ko mọ nkankan nipa a rẹ.
la ti fi se isẹ won ,lara awon to wa nibi igbimo naa ni  gomina ipinle Kebbi ana to tun je asofin to n
Ṣé ìwọ lò ń mú kí ó máa ta pọ́nún bí eṣú,tí kíké rẹ̀ sì ń bani lẹ́rù?
Agbẹjọro Ajulọ ní '' Ìdí tí a fí n ṣé àyẹwò yí ní kí iyansipo yí maba mú àbuku bá Ààrẹ tó yan ẹni náà sìpo.
Ile ẹjọ naa ni Ogodo gan an ni alaga ẹgbẹ oṣelu APC ti ofin mọ ni ipinlẹ Delta.
Gègé ni kí ẹ fi pín ilẹ̀ náà fún àwọn ẹ̀yà Israẹli.
Filipi dá a lóhùn pé, “Burẹdi igba owó fadaka kò tó kí ẹnìkọ̀ọ̀kan wọn lè fi rí díẹ̀díẹ̀ panu!
Ní tèmi, Misipa ni n óo máa gbé kí n lè máa rí ààyè bá àwọn ará Kalidea tí wọn wá dótì wá sọ̀rọ̀.
Ó bẹ̀rẹ̀ sí ṣe bí ó ti wù ú, ó sì ń gbéraga.
Ìwé Karun-un Mose, tí à ń pè ní Diutaronomi.
Wòlíì Kasali ní Dolapo Awosika kò lé ìyàwó òun jáde Ọladapọ ni Ibrahim Hamed lo wa fi ẹjọ baba rẹ sun pe o ba aburo oun, Zenab, ọmọ ọdun mẹjọ lo pọ, eyi to mu ki ẹru maa ba oun.
Memkani bá dáhùn níwájú ọba ati àwọn ìjòyè pé, “Kì í ṣe ọba nìkan ni Faṣiti kò kà sí, bíkòṣe gbogbo àwọn ìjòyè ati gbogbo àwọn tí wọ́n wà ní agbègbè ìjọba Ahasu-erusi ọba.
Nítorí náà, n óo sọ iná sí Juda, yóo sì jó àwọn ibi ààbò Jerusalẹmu ní àjórun.
“Nítorí èyí, n óo sọkún, n óo sì pohùnréré ẹkún; n óo rìn káàkiri ní ìhòòhò láìwọ bàtà.
''Ipò ni Ọgá ile iṣẹ asobode.
Itan omi gbigbona ati tutu ni Ikọgosi Ekiti Ṣé ìwọ mọ odò adágún Adó Àwáyè tí kò ní òpin ní ìsàlẹ̀?
Ọpọ lo ti n sọ pe aramọnda agbabọọlu Barcelona ati Argentina, Lionel Messi ni agbabọọlu to dara julọ ninu itan.
Afojusun rẹ gẹgẹ bi oloṣelu ni lati ri i daju pe awọn ti wọn ba dibo yan n tẹti si awọn to dibo yan wọn.
Wọ́n ṣe akiyesi pé ẹni tí ó ti máa ń jókòó ṣagbe lẹ́nu Ọ̀nà Dáradára Tẹmpili ni.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Alao Akala:Èmi àti Ajimọbi kò ṣe ìlérí kankan fún ara wa Alukoro ileeṣẹ ọlọpaa nipinlẹ Eko, Chike Otti ni oju awọn agbofinro to gbogbo ohunkorun to ba fẹ da omi alaafia ipinlẹ naa ru.
Gomina ipinlẹ Pará,Helder Barbalho, sọ fun awọn oniroyin pe ohun to je awọn logun ni ''ṣiṣe awari awn to farakasa iṣẹlẹ naa ati ṣiṣe iranwọ fun mọlẹbi wọn'' Ọgbẹni Barbalho fi fọnran fidio iṣẹlẹ naa si oju opo Twitter rẹ.
Ẹnikẹ́ni tí kò bá máa gbé inú ẹ̀kọ́ Kristi, ṣugbọn tí ó bá tayọ rẹ̀, kò mọ Ọlọrun.
 Àwọn míràn tí wọ́n yìnbọn mọ́ tí wọ́n sì sá lọ pada lọ kú sínú igbo"" Bákan náà ni ẹlòmíràn tí sọ pé, ààrin àwọn ikọ̀ àmọ̀tẹ́kùn àti àwọn Bororo ni ìjà náà ti wáye."
" Oríṣun àwòrán, Instagram/adedimeji lateef Ẹwẹ, nigba ti wọn beere lọwọ rẹ pe, bawo lo ṣe n mojuto iṣẹ, ti ko fi pa irinajo ifẹ rẹ lara, Lateef Adedimeji sọ pe, ko si ẹni kankan ti kii ṣe ẹlẹṣẹ.
Jannat Ali, tí orúkọ ìnagijẹ rẹ̀ ń jẹ́ Lahore's Trans Diva, ni olùdásílẹ̀ Abódiakọ-akọ́diabo Track Transgender àti Olùdarí Ètò fún Ilé-iṣẹ́ Sathi tí ó ṣe àgbékalẹ̀ Ìwọ́de Afẹ́ náà.
65 billion dollars), fun odun 2020 yoo je
Ọgọrun un miliọnu pọn-un(£100million) ni Juve san fun Madrid ki Ronaldo to darapọ mọ wọn.
Wọ́n fi idà tí ó wà lẹ́nu ẹni tí ó gun ẹṣin funfun pa àwọn yòókù.
Ẹ má bẹ̀rẹ̀ láti máa rò ninu ara yín pé, ‘A ní Abrahamu ní baba.
1 Kíyèsíi, mo wí fún yín, pé ẹ gbọ́dọ̀ gbẹ́kẹ̀lé ọ̀rọ̀ mi, èyí tí ó jẹ́ pé bí o bá ṣe é pẹ̀lú ẹ̀kúnrẹ́rẹ́ èrèdí ti ọkàn, ẹ̀yin yíò rí àwọn àwo náà, àti àwo ìgbàyà bákannáà, idà ti Lábánì, Urímù àti Túmmímù, èyítí a kó fún arákùnrin Járedì ní orí òkè, nígbàtí ó bá Olúwa sọ̀rọ̀ ní ojú korojú, àti àwọn ìdarí ìyanu èyí tí a fún Léhì nígbàtí ó wà nínú aginjù, ní ààlà Òkun Pupa.
Israẹli, o wá ń pè mí nisinsinyii, ò ń sọ pé,‘Ìwọ ni baba mi, ìwọ ni ọ̀rẹ́ mi láti ìgbà èwe mi.
ipade ohun ni Igbakei aare orile ede Naijiria, ojogbon Yemi Osinbajo,Bola  Tinubu abblAdemola Adepoju.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Lagos building collapse: LASEMA ní ìwadìí yòó yàtọ̀ lórí ilé tó wó nítorí ààrẹ àtàwọn èèkàn ti gbọ́ sí ìsẹ̀lẹ̀ náà 14 Ẹrẹ̀nà 2019 Àkọlé àwòrán, LASEMA ni iwadii yoo waye Ijọba ipinlẹ Eko ti ni iwadii yoo bẹrẹ laipẹ lati mọ ẹni to lẹbi gan lori iṣẹlẹ ijamba ile to wo ni agbegbe Ita faaji nilu Eko.
Dr Rev King Oríṣun àwòrán, Google Àkọlé àwòrán, Ìdájọ ikú ni wọ́n dá fún Rev King Chukwu Emeka Ezeugo ti gbogbo ènìyàn mọ̀ sí Reverend King ni olùdásílẹ̀ àti alákoso ijọ Christian Praying Assembly (CPA) lọ sẹ́wọ̀n ní ọjọ́ kẹ́rìndínlọ́gbọ̀n, oṣù kẹsàn ọdún 2006 lẹ́yìn tí ilé ẹjọ́ ni ó jẹ̀bi ẹ̀sùn pípa ọmọ ìjọ rẹ̀, Ann Uzoh.
LASU student killing: Ilé ẹjọ́ pàṣẹ kí wọ́n fi àwọn tó pa àkẹ́kọ̀ọ́ LASU sí ẹ̀wọ̀n
Ìjìyà ń bẹ fún àwọn ti adé ọ̀rọ̀ náà bá ṣí mọ́ lóri -Ọga àgbà FRSC Ajínigbé ń bèèrè fún epo, iṣu àti ọ̀tí Schinap gẹ́gẹ́ bí owó ìtanràn Kò sí àṣà tó faramọ́ fífi èmí ènìyàn ṣe ìrúbọ - Olúwó FRSC dá N443,180 padà fún ẹbí ẹni to ní ìjàmbá mọ́tò Ojọgbọn Oni tẹsiwaju ninu ifọrọwerọ rẹ pẹlu BBC pe: Ijọba ni lati pese iṣẹ fun awọn ọdọ to n fẹsẹ gbalẹ kiri.
Eji Gbadero ni olugbeja ẹni ti wọn ba gba ilẹ rẹ, tabi ẹni to fẹ fi tipa gba ilẹ lọwọ ẹlomiran, to fi mọ ipese aabo to peye fun awọn ilẹ ti ẹnikẹni ko le e gba, to si di ọrẹ ọlọpaa.
Ó kó wọn sí ìlú Hala ati sí etí odò Habori tí ó wà ní agbègbè Gosani, ati sí àwọn ìlú Media.
Nítorí pé o lọ́ wọ́ọ́rọ́wọ́ lásán, o kò gbóná, bẹ́ẹ̀ ni o kò tutù, n óo pọ̀ ọ́ jáde lẹ́nu mi.
Sultan wá rọ àwọn musulumi lati maa kan sáwọn ojú òpó ikansira ẹni bíi Facebook, Skype, YouTube, Zoom, Instagram ati bẹẹ bẹẹ lọ, fun waasi aawẹ àti ìtọ́ni àwọn asaaju ẹṣin lásìkò oṣù Alapọnle náà .
N óo dáná sun kẹ̀kẹ́ ogun rẹ, n óo sì fi idà pa àwọn ọmọ ogun rẹ.
Ọ̀pọ̀lọpọ̀ Aṣọ-Òfì/Òkè wúwo, ṣùgbọ́n ti ìgbàlódé ti bẹ̀rẹ̀ si fúyẹ́ nitori òwú igbalode.
Ṣọ́ra, 'Loom Money Nigeria' kọ́ ni ètò sogún-dogójì tí yóò kọ́kọ́ wọ Nàìjíríà 'Iṣẹ́ ni mó ń wá kí wọ́n tó lo orúkọ mi fi gbé Sẹ́nétọ̀ Adeleke lọ sí ilé ẹjọ́' Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, N1 mílíọ́nù leè mú kí, orílẹ̀èdè Nàìjíríà, Pẹ̀lúmi Akínṣọlá ó pàdánú àmì ẹ̀yẹ Olympiad Ọmọwe Ẹgbẹdokun woye pe ọwọja iṣẹlẹ ijinigbe atawọn iwa ipa miran to n waye lorilẹede Naijiria bayii fihan pe ijọba ti kuna lori eto ipese abo fawọn eeyan orilẹede Naijiria.
“Pada lọ sọ́dọ̀ Hesekaya, olórí àwọn eniyan mi, kí o sì sọ fún un pé, ‘Èmi OLUWA Ọlọrun Dafidi baba ńlá rẹ̀ ti gbọ́ adura rẹ̀, mo sì ti rí omijé rẹ̀.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Alaafin: Olori Aanu Adeyemi ṣàlàyé ìdí tó ṣe gẹ́ Oba Lamidi Adeyemi ti ìlú Oyo Ki lo ti ṣẹlẹ sẹyin?
Asofin Kehinde Ayoola lo jẹ kọmiṣọna fun ọrọ ayika Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
O sọ pe igbagbọ oun ni pe èdè wọn yoo yera, nitori pe iṣẹ wọn papọ.
Ninu atejade kan ti abẹnugọ awọn gomina, Abdulrazaq Barkindo fi sita lọjọ Isinmi ọsẹ yii, O ni pe ko si ohun to jọ bẹẹ rara.
Àwọn akọrin láti Kingston, Clarendon àti Spanish Town ń ṣiṣẹ́ pọ̀ lóríi ọ̀rọ̀ orin níbi ìdánilẹ́kọ̀ọ́ Ìfiṣẹ́ránṣẹ́ Àyípadà Ojú-ọjọ́.
Àkọlé àwòrán, Àṣìlò òògùn Tramadol ati àwọn mi i bi codeine le ṣe àkóbá fún ara Awọn akẹgbẹ rẹ meji ti wọn jọ lọ fun iṣẹ buruka naa ja ọkada ẹnikan to wa ra oogun nile itaja oogun naa, ti wọn si gbe e salọ.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Èkúté tọ n wá ọmi-ilẹ gbàmì ẹyẹ wúrà PDSA Gẹ́gẹ́ bí àjọ kan ti kìí ṣe ti ìjọbaHALO Trust, tó ń ri si ọ̀rọ̀ imọ-ilẹ Cambodia ti ni àkọsilẹ̀ àwọn ènìyàn tó le ni ẹgbẹ̀rún mẹ́rìnlélẹgbẹ̀ta tí imọ̀l-ilẹ ti pa àti ẹgbẹ̀rún lọ́nà mẹ́ẹ̀dọ́gbọ̀n àwọn mírà tó ti gé ni ọwọ ati ẹsẹ nítori imọ-ilẹ láti ọdun 1979.
A yìnbọn lu Precious láti dáa dúró ni, akò mọ̀ pé o máa kú- Ọlọ́pàá Èèyàn 576 míràn tún kún àwọn tó ní àrùn COVID-19 ní Nàìjíríà Alaafin Oyo kò dàgbà jù fún mi, ohun tó wù mí ní mo ṣe pẹ̀lú ayé mi- Olori Aanu Adarí àjọ NDDC, Pondei ṣetán láti sọ ohun tó mọ̀ nípa ìwàdíì tó bá ti gbádùn- NDDC Awọn miran to tun n dije fun aṣia ẹgbẹ oṣelu naa ni igbakeji alaga apapọ ẹgbẹ oṣelu PDP fun ẹkun Iwọ Oorun Gusu orilẹede Naijiria, Eddy Olafẹsọ, Sola Ebiseni, Bọde Ayọrinde, Boluwaji Kunlere, Bamidele Akingboye, Banji Okunọmọ ati Godey Erewa.
Ni bí ogoji ọdun sẹyin, awọn alakoso ọgba ile ẹkọ fasiti kọọkan lo maa n pese oúnjẹ fáwọn akẹkọọ wọn pẹlu owo perete, tijọba yoo si fi owo kun.
‘Ohun gbogbo tí ẹ bá rí lórí ẹ̀rọ ayélujára kọ́ ni òtítọ́’ N se ni ẹnu ya Arlene, to si pinnu pe oun ati ọrẹ oun naa yoo ya aworan miran ni aaye ọtọ, lori aga ti wọn ma n pese fun awọn ọkọ ati iyawo lọjọ igbeyawo wọn, lati fi kọ awọn eniyan ni ọgbọn wi pe, ohun gbogbo to dan kọ ni wura.
soro yii lẹyin ti onidajo agba fun ipinle Oyo, Mukhtar Abimbola  bura fun un gẹgẹ bi gomina tuntutn fun ipinle
Ṣugbọn wọ́n ń dàníyàn fún ìlú tí ó dára ju èyí tí wọ́n ti jáde kúrò lọ, tíí ṣe ìlú ti ọ̀run.
Ìrònúpìwàdà tòótọ́ ni mò ń fẹ́,kì í ṣe pé kí ẹ fa aṣọ yín ya nìkan.
Oríṣun àwòrán, Obasanjo/instagram Nínú ọ̀rọ̀ Makinde ló ti sàlàyé fún ààrẹ àná pé, ipasẹ̀ rẹ̀ ni òun ń tọ ní ìpínlẹ̀ Oyo pàápàá jùló nínú isẹ́ ọgbìn.
mò ń bẹ̀ ọ́ nítorí ti ọmọ mi, Onisimu, ọmọ tí mo bí ninu ẹ̀wọ̀n.
Oludije ninu ẹgbẹ oṣelu PDP ti o jẹ olupejọ, Ọgbẹni Taiwo Shotẹ, ni ibo ọjọ kẹtalelogun, oṣu keji, ọdun yii ni awuruju ninu.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Klopp seleri lati mu Salah ati Mane gba ami ẹyẹ Ballon d’Or 9 Ẹrẹ̀nà 2018 Oríṣun àwòrán, Reuters Àkọlé àwòrán, Klopp ni ko si iyatọ laarin awọn agbabọọlu ilẹ Afirika ati awọn agbabọọlu yooku lagbaye bi awọn anfani to wa fun awọn yooku ba si silẹ fun awọn naa Olukọni ẹgbẹ agbabọọlu Liverpool, Jurgen Klopp ti seleri lati ran awọn agbabọọlu rẹ meji Sadio Mane ati Mohamed Salah lati di agbabọọlu to lee gba ami ẹyẹ agbabọọlu to gbayi julo lagbaye, Ballon d'Or."
Ọmọ kai, eó gbé si yàn ún
Ninu atẹjade kan ti Kọmisanna fun irinajo afẹ, iṣẹ ọna, ati aṣa, Arabinrin Uzamat Akinbile-Yussuf, fi sita ni opin ọsẹ, o sọ pe ilana tuntun naa kan awọn ile itura, ile gbigbe alasiko diẹ, ootẹli, gbọngan ayẹyẹ, ile ounjẹ, ile ọti, ati ile sinima.
"Igba ti ijọba wa ba fi idi mulẹ, ta a joko, ti a jọ sọrọ pọ lati mọ boya ki a wa lọtọọtọ tabi ṣepọ ni yoo dara fun wa, nkan ti a ba fẹnuko le lori ni yoo sọ ibi ti ọrọ nlọ.
Sinimá tí Lateef Adedimeji dá nikan jẹ́ òṣèré yóò jáde, Yemi Solade fi ọ̀pọ̀ fọ́tò dẹngẹ pó"" lọ́jọ́ ìbí rẹ̀ Ọ̀pọ̀ nǹkan tí kò yé èmi àti Bàbá Wande, ló fa ìjà lórí sinimá Tolúwa Nilẹ̀ - Tunde Kelani Ṣé lóòtọ́ ni Bimpe Oyebade lóyún fún Lateef Adedimeji?"
" Ebi ló ń pami ti mo fi já sọọbu láti jí bisikitì- Afurasi Asuquo Ó lé gba ìwé ìrìnnà (Visa) láti wá fẹ̀yìntì sí Naijiria Wo aṣọ òtútù tó wọ́n jùlọ ní àgbáyé!
 Ẹlomiran ti iṣẹlẹ naa ṣoju rẹ, to tun jẹ ọmọ ẹyin ọkọ miran to n lọ lasiko naa sọ fun ileeṣẹ OSBC pe irin nla kan lati ara ọkọ to bu gbamu ọhun lo ba oun ti oun fi deero ileewosan."
Mo mọ ìgbà òtútù ati ìgbà tí aṣọ kò tó láti fi bora.
"O fikun pe ""Ẹgbẹ oselu to n se ijọba lọwọ mọọmọ fi tipa-tipa gbe ifẹ ọkan wọn le awọn araalu lori ni, pẹlu bo se ko awọn janduku lati awọn ipinlẹ miran wa dunkoko mọ awọn araalu atawọn akọroyin."
to ba waye lorile ede kankan nilẹ Afirika.
Àwọn kan dá iná sáàrin agbo-ilé, wọ́n jókòó yí i ká, Peteru náà wà láàrin wọn.
Peteru ati ọmọ-ẹ̀yìn náà bá jáde, wọ́n lọ sí ibojì náà.
Wọ́n dá òṣìṣẹ́ FSARS yìí dúró lẹ́yìn tí afẹ́fẹ́ fẹ́, tí àṣírí owó tó máa ń gbà tú síta pẹ̀lú bí arábìnrin kan Princess Ifẹ ṣe kéde lórí Twitter rẹ̀ ní ọjọ́ kẹrìndínlógún oṣù kaàrùn-ún wí pé Ọmọtọshọ dẹ́rù yínyìnbọn pa àwọn bí wọn kò bá fún un ní ẹgbẹ̀rún márùn-ún Náírà.
Lẹ́yìn Ibisani, Eloni, láti inú ẹ̀yà Sebuluni, jẹ́ aṣiwaju ní ilẹ̀ Israẹli fún ọdún mẹ́wàá.
Ọga Bello sọ fun Mr Latin to jẹ aarẹ pe Ọlọrun ọba to baa bẹrẹ naa ni ko maa gbe oju le ko ma ṣe gba gbọyi sọyii to maa n jẹ jade latọdọ awọn akẹgbẹ wọn.
Bola Tinubu Colloquium: Tinubu kìlọ̀ fún Buhari lórí ohun tó leè ṣàkóbá fún sáà kejì rẹ̀
“Ṣugbọn àwọn eniyan mi kò gbọ́ràn sí mi lẹ́nu,Israẹli kò sì gba tèmi.
Mustapha sọ fun awọn oniroyin wipe abẹwo naa ni lati fidi rẹ mulẹ pe aṣiwaju ni Omisore jẹ ni Osun ati orilẹede Nigeria.
“Ṣebí OLUWA ni ó fi ọ̀rọ̀ rẹ̀ lé lọ́wọ́;kí OLUWA ọ̀hún yọ ọ́, kí ó sì gbà á là,ṣebí inú rẹ̀ dùn sí i!
Saulu Ṣe Inúnibíni Sí Ìjọ Kristi.
Lẹẹkan si a tọ agbẹnusọ fun oloye Ajimọbi lọ, ohun pẹlu si ni lootọ ara rẹ ko ya amọ irọ to jinna sootọ ni pe o daku lọ gbọrangandan nileewosan gẹgẹ bi awọn kan ṣe n sọ ọ kaakiri nigba naa.
Wọn yóo lù yín ninu àwọn ilé ìpàdé.
Conjoined Twins: Kìí ṣe ìdájọ́ ikú ṣùgbọ́n gbígbé ayé á nira
Ìgbà tí Aisha Buhari ti f'ọ̀rọ̀ da ìgboro rú lórí ìjọba ọkọ rẹ̀ Mo sọ̀rọ̀ tako ọkọ mi torí òtítọ́ - aya Bùhárí Àkójọpọ̀ àwòrán láti àpéjẹ ìdúpẹ́ Aisha Buhari DSS gbé olùrànlọ́wọ́ Aisha Buhari tì mọ́lé lórí N2.
Nípa bẹ́ẹ̀ Ọwá Ajíbógun àti Agígírì jọ dàgbà pọ̀.
kaare lati daabo bo awon onibara ati ile-ise eto ibanisọrọ lorile ede Naijria.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Bournemouth vs Tottenham: Báwo ni Tottenham se gba káàdì pupa méjì láàárín ìṣẹ́jú márùn ún?
7 240089 Orilẹede Greece 3003 28.
Ẹgbẹgbẹ̀rún mílíọ́nù Kristẹni ṣe Àyájọ́ Ọjọ Ijiya Jẹsu nínú kónílé-ó-gbélé Coronavirus Kìí ṣe gbogbo ohun tí dókìtà ni kí n má jẹ torí àìsàn jẹjẹrẹ ni mo tẹ̀lé- Soyinka Ọmọ to n ko ọmọ alainile kuro lori titi Tíńko-Tíńko jẹ́ eré tó ń mú ìṣọ̀kan bá àwọn èwe Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí 2 sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 2:23 Fídíò, Water Generator: Ó leè ṣiṣẹ fún wákàtí mẹfà, kó tó sinmi, Duration 2,2310 Òkùdu 2020 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
''Ko si ẹni ti yoo gba ki wọn gbe ẹlomiran wa jẹ ọga le lori lati ita ti kii ṣe wi pe ko kaju oṣunwọn.
Ekinni, àwọn Juu ni Ọlọrun fún ní ọ̀rọ̀ ìjìnlẹ̀ rẹ̀.
Ọ̀sẹ̀ méjì péré la fẹ́ kí iṣẹ́ reluwe Eko sí Ibadan parí - Amaechi Ọmọ́ Yorùbá korò ojú sí Buhari bí kò ṣe fi orúkọ Obasanjo sọ ibùdókọ̀ ojú'rin Rélùwéè tẹ alágbe kan pa ní Eko Èrò ọmọ Nàìjíríà ṣé ọ̀tọ̀ọ̀tọ̀ lóríi ìkéde Rélùwéè ọ́fẹ́ Èkó sí Ìbàdàn Ileesẹ reluwe ilẹ wa ni awọn ọkọ reluwe naa, ti yoo maa na Eko si Ibadan, ni yoo maa rin ni igba mẹrindinlogun lojoojumọ.
Oríṣun àwòrán, facebook Igbẹjọ lori ẹsun ijọmọgbe ti ijọba n ba Wolii Alfa Babatunde ti ijọ Sotitobire si n tẹsiwaju ni ọjọ Aje to n bọ.
Bí kò bá jẹ́ pá àwọn ọmọ aráyé ń fi ara da ibànújẹ́ ni, ojoojúmọ́ nì wọn ìbá máa pa ara weọn.
Aare tun wa gbadura fun awon
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Democracy Day: Àkójọpọ̀ àwòrán láti ìpínlẹ̀ Ọyọ, Ogun àti Kwara fún ìbúra gómìnà tuntun 28 Èbibi 2019 Ẹ wo awọn aworan igbaradi fun iburawole ni awọn ipinlẹ: Ipinlẹ Ọyọ: N jẹ ẹ mọ pe gomina ti yoo se ibura lọjọru ni ipinlẹ Ọyọ, Onimọ ẹrọ Seyi Makinde ti kan si papa iṣere Obafemi Awolowo nibi ti ayẹyẹ ibura naa yoo ti waye.
Àròsọ ni ó ti wọkọ̀ lọ sí Ifẹ̀ láti lọ ṣe ìwádìí owó náà.
Apocalypse: Ìgbà mọ́kànlá tí ayé ò bá ti parẹ́
Wọn ni ọpọlọpọ awọn to n tẹle wọn lori Facebook ati Twitter ṣugbọn wn ko reeyan kankan tẹle wn lọ sile baba wọn.
to wa ni agbegbe Ikolaba niluu Ibadan.
Ohun ti BBC Yoruba gbọ ni wi pe awọn ọdọ to wa lajọ yii ni wọn san owo fun ati wọle si bẹ.
Ṣugbọn ṣa, irun Jimọ waye ni awọn mọṣalaaṣi kan.
Jọ̀wọ́ fún wọn ní ìwọ̀n talẹnti fadaka kan ati aṣọ meji.
Ṣugbọn OLUWA Ọlọrun yín kò fetí sí ti Balaamu, ó yí èpè náà sí ìre fun yín nítorí pé ó fẹ́ràn yín.
Ọgbẹni yii ni tirẹ ti sare ro o to si mu ni ranti ore banta banta ti Ọga ileeṣẹ ọkọ baalu Air Peace ṣe fun Naijiria to fi ko awọn ọmọ Naijiria pada wa sile lọwọ pipa ti wọn n pa wọn lorilẹede South Africa.
Obinrinn yii ni wọn ni awọn agbebọn ti awọn eeyan fura si pe o ṣeeṣe ko jẹ darandarn fulani yinbọn pa ni ọjọ Ẹti.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Adeleke: 'Èmi ò kú o, koko lara mi le' 19 Owewe 2018 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 8 Bélú 2018 Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Èmi ò kú o Ademọla Adeleke ti kede pe oun ko ku o lẹyin tim ọrọ kan ti tan kaakiri pe o ti jade laye.
Idi ni pe Florence, aya oloogbe Abiola Ajimobi, ti n tahun si ijọba ipinlẹ Oyo lori ọna to gba huwa si ọkọ rẹ lasiko to n ṣe aisan.
Àtúndì ìbò Kwara: Raheem Ọlawuyi ní èsì ìbò náà jẹ́ àseyọrí ire tó ń bọ̀
 Sugbon pe , won feti sile lati gbo edun okan re.
 Èyí ni aáyan láti má jẹ ́ kí àwọn ènìyàn sùn gbàgbera , kí wọn sì jí wéré láti ṣàdúrà òórọ ̀ .
Ninu ọrọ ti rẹ, Imaamu agba mọsalaṣi Kano,Abdullahi Idris ni awọn to n duro de ki wọn ri oṣu fun ara wọn ko ṣe ohun to tọ.
A ka gbogbo wọn, a sì ṣe àkọsílẹ̀ ohun tí ìwọ̀n ọ̀kọ̀ọ̀kan jẹ́.
Aarẹ Buhari Buwọlu aba igbimọ eleto idajọ to ga julọ lorilẹede Naijiria lori awọn adajọ mejeeji yii nibamu pẹlu ẹsẹ akọkọ abala ofin ọọdunrun o din mẹjọ, iwe ofin ilẹ wa tọdun 1999.
Satani ti gba àṣẹ láti dán gbogbo yín wò, bí ìgbà tí eniyan bá ń fẹ́ fùlùfúlù kúrò lára ọkà.
Lara awọn ti aarẹ Buhari n gbalejo wọn ni osisẹbinrin ni ileesẹ ọlọpa ati ara ilu mẹsan tawọn ikọ eṣinokọku Boko Haram ji gbe nibi ikọlu t'oṣẹlẹ loju ọna Damboa, nilu Maiduguri, nipinlẹ Borno.
O mẹnuba ifẹ Naijiria ti oun fi n sin ilẹ baba oun nipa didari ọkọ loju titi.
Ó wá fi ẹ̀yìn tì ní ọdún 1984 
 lẹ ́ hìn èyí , ó gba ọ ̀ nà Ìṣẹri dé Ìbẹsẹ ̀ , títí ó fi dúró ní Ìjẹ ̀ bú-Òde .
Kí a tó sanwó ajínigbé ní àwọn agbófinró dóòlà ọmọ Ọffa mẹ́fà -ODU Gbàgbé ẹ̀sọ́ ara $40m rẹ pátápátá - Ilé ẹjọ́ sí Dienzani Ile ẹjọ ti wọgile ẹsun pé Buhari parọ lori ẹkọ ọfẹ rẹ Alásè Buhari kú, Buhari ń ṣọ̀fọ̀ Dabiri parọwa fawon ọmọ Naijiria loke okun ki wọn maa huwa rere ti yoo gbe ogo Naijiria ga nibikibi ti wọn ba wa.
O jẹ́ ààrun tó maa ń mú kí ẹni ti ara rẹ̀ dá tàbí tí kò láàrun kankan lára ní ààrún tí irún ori rẹ̀ yóò maa re, nígbà míràn irun ojú àtí ti ìpénpéju àwọn ti irú àwọn tó ba ni àrun bẹ́ẹ̀ Liliya Kukushkina-Nugmanova ní àwọn ọmọ ilé iwé maa n dẹ́yẹ sí òun nílé ìwé nítori ìrísí òun.
Ọọni fi ọrọ yii lede lẹyin ipade ti oun ati awọn ọba alade lati agbegbe naa se pẹlu aarẹ Buhari nile ijọba.
latari owo ori epo ti ijoba n yo sile, ẹ n yọ tirilionu naira lori epo, e si n
Awọn ẹnikọókan to forukọ silẹ naa yoo jẹ ninu anfani ọhun.
Àwọn dókítà Eko bẹ̀rẹ̀ ìyanṣẹ́lódì lórí owó oṣù àti ètò adójútòfò fún ìtọ́jú Coronavirus Kò sí ìfòyà, ọkọ̀ bààlù wà tí ìjọba ba ti afárá 3rd Mainland lósù yìí Wole Soyinka rèé láti kékeré Ọgbẹ́ni Otubela sọ pe oni ọna ti awọn yoo gba lati mọ àwọn ileewe to jẹ oṣiṣẹ wọn lowo oṣu, nitori pe akọsilẹ wa fun awọn ọmọ ẹgbẹ NAPS.
Èmi kò forí ṣọta ìjàmbá ọkọ̀ òfúrufú kankan - Obasanjo Aṣọ ń pe aṣọ ránṣẹ́ ni lásìkò ìbúra gómìnà àti ààrẹ Sanwo Olu- Ijọba mi ko ni yọ ẹnikẹni silẹ nipinlẹ Eko Babajide Sanwo Olu to jawe olubori gẹgẹ bi gomina ipinlẹ Eko labẹ Asia ẹgbẹ oṣelu APC naa ṣe ọpọlọpọ ileri fawọn olugbe ipinlẹ Eko.
"Ìdójútì gbàá ni kí Òṣèré máa tọrọ owó tórí àìsàn - Femi Adebayo Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Africa Eye: Olùkọ́ méjì ní fásitì Eko àti Ghana lùgbàdì ọ̀fíntótó BBC lórí ìwà ìbàjẹ́ Nnkan ti mo maa n ṣe niyi lẹyin ti mo ba kuro ni ileewe"" ni ọrọ to ti ẹnu Tẹjuoṣo jade."
Bawo ni Mohammed Morsi ṣe doloogbe?
Ẹwẹ, ìṣẹlẹ iṣekupani naa ti mu ki ogunlọgọ eniyan maa fi ibugbe wọn silẹ ki wọn o maa ba tun sẹ kongẹ iru iṣẹlẹ bẹ mọ.
Kódà gbọingbọin la wà lẹ́yìn Akintoye gẹ́gẹ́ bíi adarí YWC nílé, lẹ́yìn odi Ohun tí a mọ̀ nìyí nípa gbọ́nmi síi omi ò tó lórí ọ̀rọ̀ oyè Babaloja-General ní ìpínlẹ̀ Oyo Koda, ọrọ yii lagbara de ibi pe, o ni lati igba ti oun ti loyun ni oun ti mọ pe oun maa sọ ọmọ naa nu ni nitori ko si bi oun ṣe fẹ ri owo fi tọ ọ rara.
- Agbẹnusọ Kassim Kamaru Usman, Ọmọ Naijiria f'ẹ̀ṣẹ́ gba ìgbànú ẹ̀yẹ mọ́ Covington lọ́wọ́ ní ìdíje UFC 'À ń gbé àkàsọ̀ bọ̀ wá já iná yín ní Togo, Benin bí ẹ kò bá sanwó' Àìsàn tó ń ṣe mí kìí ṣojú lásán!
isejoba ati ipinnu meta ti o fe gunle nibi isejoba re.
Nigba naa, gomina to wa nibẹ, Babatunde Fashola fẹ ki kọmisọnna fun eto idajọ nipinlẹ naa, Supo Shasore dije dupo sipo gomina lasiko naa, Amọ Tinubu kọ jalẹ pe Ambode ni yoo ṣe gomina naa pẹlu gbogbo agbara rẹ.
ọbẹ̀ tin be nílé kò mọ ilé baba tó bí wọn lọmọ
 O wu mi ki a ko ife ooto lara Omowe yii ni eni to feran gbogbo eniyan laifi iran tabi esin se ni eyi ti mo ri ni awon igba ti o sabewo sile ijoba l’Abuja nibi ati ni London nigba ti o re mi.
Ni Peteru bá pè é sí ẹ̀gbẹ́ kan, ó bẹ̀rẹ̀ sí bá a wí pé, “Ọlọrun má jẹ́!
Lasiko ti a bii lọdun 1972, ijọba ibilẹ Isanlu ṣi wa labẹ ipinlẹ Kwara nibi ti wọn ti yọ apa kan ipinlẹ Ondo.
OLUWA bá mi sọ̀rọ̀, ó ní: “Ìwọ ọmọ eniyan ṣé o óo dá ẹjọ́ Ohola ati Oholiba?
Akowe agba fun Amerika, Rex Tillerson ni opolopo eniyan n koju isoro ati ri ohunjije je ni ekun yii lataari ogbele ati ikolu orisirisi to sele.
Oríṣun àwòrán, @ooniadimulaife O ni eyi ko ni jẹ kawọn da wahala miran silẹ lasiko ti awọn n wa ọna lati yanju isoro kan.
Ile iṣẹ ologun ni Ipinlẹ Plateau tun fi lede pe kosi otitọ kankan ninu iroyin ti awọn kan n gbe kiri lori ayelujara pe ọkọ mọkanla ati oku eeyan meji ni awọn yọ jade ninu adgun odo ọhun.
Bakan naa ni awọn orilẹede kọọkan ni yoo sọ ẹni ti yoo kọkọ ni anfaani si awọn abẹrẹ ajẹsara yii.
Bí o bá yipada sí Olodumare, tí o sì rẹ ara rẹ sílẹ̀,tí o bá mú ìwà aiṣododo kúrò ní ibùgbé rẹ,
Ìṣẹ́jú méjì péré tó máa fi bàlẹ̀ ni pápákọ̀ òfurufú ni ẹlikọ́pítà Quarom aviation já lulẹ̀ ní Opebi, Ikeja Arinrinajo kẹta to wa ninu ẹlikọpita to ja lulẹ ni Opebi, Ikeja niluu Eko ko pada ye e, o ti rekọja s'alakeji.
O ni bi wọn ba n sisẹ ni,ijamba bi ti teko to sẹlẹ ko ba ma waye.
Wọ́n bá bẹ̀rẹ̀ sí bú u, wọ́n ní, “Ìwọ ni ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀, ní tiwa, ọmọ-ẹ̀yìn Mose ni wá.
Iyiọla Omiṣore SDP Iyiọla Omiṣore n dije labẹ ẹgbẹ oṣelu SDP, o ni ijọba òun ko ni jẹ ti Omiṣore bikoṣe ijọba to gba gbogbo eeyan laaye pẹlu ilana àátẹ̀lé fún idagbasoke.
Àwọn tí ń bá ọ jà yóo di asán,wọn óo sì ṣègbé.
Laipẹ yii ni awuyewuye kan waye pe ọba Fuji, Wasiu Ayinde Mashal n lo ifẹ ikọkọ pẹlu olori naa, amọ ti ayaba Badirat ti sẹ pe ko si ohun to jọ eyi rara.
Idi ni pe iwadi kan fihan pe, awọn to maa n jẹun alẹ ki aago mẹsan alẹ to o lu, tabi o kere tan, wakati meji ki wọn to o sun lalẹ, ni anfaani ida ogun, lati maa ni aisan jẹjẹrẹ ọyan ati jẹjẹrẹ ile itọ ọkunrin, ju awọn to maa n jẹun alẹ ti wọn lẹyin aago mẹwa tabi awọn to maa n sun loju ẹsẹ ti wọn jẹun tan.
Ààrẹ fi nǹkan ọkùnrin rẹ̀ pa mí lójú, kó tó fipá bámi lòpọ̀ - Ọmọge Arẹwà Agba amofin naa sọ pe awọn ọmọ Naijiria fẹ mọ iye ti asofin kọọkan n mu lọ sile losu, ko si yẹ ki ẹnikẹni maa fi ẹkọ tanna fun wọn.
“Ní ọjọ́ náà, gbogbo ibi tí ẹgbẹrun ìtàkùn àjàrà wà, tí owó rẹ̀ tó ẹgbẹrun ṣekeli fadaka, yóo di igbó ẹ̀gún ẹ̀wọ̀n agogo ati ẹ̀gún ọ̀gàn.
"Wo àwọn Gómìnà Naijiria tí àrùn Covid-19 ti bá fínra Adisa tun ni ""Ile iwe to ba ṣe awọn nnkan to yẹ nikan lo maa koju osuwọn lati wa ni ṣiṣi."
Wọn ni ki Oluwa maa ba ijọba rẹ lọ wi pe o tẹ awọn lọrun.
INEC leti ojuse won saaju eto idibo naa.
Wọ́n fún gomina ní ìwé, wọ́n sì fa Paulu lé e lọ́wọ́.
Gẹgẹ bi awọn alasẹ nileesẹ ofurufu India sọ, ọkọ baalu ofurufu naa, lo yẹ kuro loju opo rẹ, to si pin si meji ni papakọ ofurufu Calicut ni kete to balẹ.
Ṣugbọn ọba fi mẹ́wàá ninu àwọn obinrin rẹ̀ sílẹ̀ láti máa bojútó ààfin.
com Àkọlé àwòrán, Ayipada ti de ba inawo ṣiṣe bayii Ayẹyẹ ṣiṣe nilẹ Yoruba jẹ nkan ti o maa n kun fun oriṣiriṣi ipalẹmọ lati rii pe ọjọ naa dun, o si larinrin.
Ò ń mú kí ìwà àgbèrè rẹ pọ̀ sí i láti mú mi bínú.
Aisha Buhari ké gbàjare pé ètò ìjọba Buhari kò ṣànfàní f'óbìrin Ọ̀gọ̀rọ̀ èèyàn lórí ayélujára bú Dalung lórí owó IAAF NBC fọwọ́ sí ìdásílẹ̀ ilé iṣẹ́ Fulani Radio Àwọn bàbá ìsàlẹ̀ òṣèlú tó bá ìtìjú bọ̀ nínú ìbò Gómìnà rèé Joshua Robert Poshjosh (NAIJIRIA) Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Josh Posh: Inú mi máa ń dùn láti kọrin fún àbúrò mi ní kékeré Joshua Robert (Poshjosh) jẹ ọmọ bíbí Nàìjíríà tí a bí sí òkè òkun.
Elkana fikun un pe lootọ ni awọn ti fi panpẹ ọba mu awọn eniyan ọgọrun un ti wọn jẹ ọmọ ẹgbẹ okunkun ti wọn n ja laarin ara wọn.
Èyí yóo máa jẹ́ ìlànà fún àwọn ọmọ Israẹli gẹ́gẹ́ bí OLUWA ti pàṣẹ fún Mose.
Iṣẹ́ ìṣàkóso Buhari ọdún mẹ́ta ni yóò “gbè é” lẹ́yìn àti pé yóò bá ìfi Nàìjíríà sí ipò olú orílẹ̀-èdè tí ìṣẹ́ ti pọ̀ jù.
Aya, awọn ọmọ ati ọpọ ẹbi oloogbe naa lo ti de sibẹ, ti gbogbo agbegbe naa si kan gogo.
Ìdúnàdúrà ṣì n lọ láti dóòlà ọmọ Ọffa mẹ́fà lọ́wọ́ ajínigbé- ODU Ṣe saaju ni ijọba apapọ ti paṣẹ ki Minisita fun ọrọ ilẹ okeere, Geoffery Onyeama, lati kan si gbogbo ẹni ti ọrọ kan lati dẹkun idunkooko mọ awọn ọmọ Naijiria.
Gbogbo àwọn ará Juda tí wọ́n wà ní ìgbèkùn ní Babiloni yóo máa fi ọ̀rọ̀ wọn ṣépè fún eniyan pé: ‘OLUWA yóo ṣe ọ́ bíi Sedekaya ati Ahabu tí ọba Babiloni sun níná,’ 
Àwa ti fi ohun gbogbo tí a ní sílẹ̀, a sì ti ń tẹ̀lé ọ.
- Sowore O ṣe iyawo pẹlu Susan Brown-Meyer lọdun 1975, ṣugbọn wọn kọ ara wọn sile lọdun 1993.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Mí ò ya wèrè, mí ò burú, ọ̀nà àtijẹ là ń wá' Adari ere tiata ni iṣẹ ti Kunle gbaju mọ julọ.
Ijoba orile ede Naijiria ti so pe awon ko ni kaare lati ri I pe atunse to monyan lori ba awon ohun amayederun lorile ede yii, paapaa julo lori ile-gbigbe ati oju-ona to wa jake-jade orile ede Naijiria.
akanṣe to n lọ lọwọ ni ipinlẹ yii”.
Gẹgẹ bii atẹjade kan ti giwa fasiti naa, Ọjọgbọn Idowu Ọlayinka fi sita ṣalaye wi pe awọn alejo ọkunrin to ba fẹ bẹ awọn akẹkọbinrin ni ibugbe Awolowo hall, Queen Idia hall ati Elizabeth hall ko gbọdọ wọ inu ibugbe awọn obinrin naa ms o.
Ìfẹ́ tí kì í yẹ̀ ni mo fẹ́, kì í ṣe ẹbọ rírú; ìmọ̀ Ọlọrun ni mo bèèrè, kì í ṣe ẹbọ sísun.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Mo ń ṣa ike jọ láti san owó ilé iwé ọmọ mẹ́ta' Rochas Okorocha fa ọkọ ọmọ rẹ, Uche Nwosu siilẹ gẹgẹ bii gomina, Amosun ni tirẹ naa fa eeyan tirẹ silẹ ni ipinlẹ Ogun.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Lagosians: Eni tó ní owó ló ń kọ Will Seyi Makinde wa fi ọwọ idaniloju sọya pe oun ko yan igun ẹgbẹ awakọero kankan nipọsin, nitori ko si ẹmi to kọja ofin,pẹlu afikun pe oun ti kesi ileesẹ ọlọpaa lati fi imu ẹnikẹni to ba sokunfa rogbodiyan danrin.
Lilọbibọ ọkọ ti dawọ duro lati owurọ oni ọjọ kẹtala oṣu kẹwa ọdun 2020 yii.
Nígbà tí ó dé ibẹ̀, ó bẹ̀rẹ̀ sí fọn fèrè ní agbègbè olókè Efuraimu.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Naijiria lo tun se ipo karun un laarin awọn orilẹede Afirika to n gba oju oku mẹditarenia lọ si ilẹ Yuroopu Lẹyin o rẹyin, ọdun meji ni mo lo ni orilẹede Russia.
Aláìsàn náà dáhùn pé, “Alàgbà, n kò ní ẹni tí yóo gbé mi sinu adágún nígbà tí omi bá rú pọ̀, nígbà tí n óo bá fi dé ibẹ̀, ẹlòmíràn á ti wọ inú omi ṣiwaju mi.
Lọjọbọ ọsẹ yii ni Funke gbe ọrọ kan lede loju opo Intsgram rẹ, nibi to ti n beere lọwọ awọn ololufẹ rẹ erongba wọn lori isinmi lorilẹ-ede United Arab Emirates.
Ikọ Ọmọogun orilẹede Naijiria lo fi lede pe ijamba ọkọ to waye ninu ile igbe awọn ikọ ọmọogun Naijiria lo ṣekupa a.
Lẹyin ọpọlọpọ ipade ati akitiyan lati ọdọ ijọba apapọ ati ẹgbẹ oṣiṣẹ ASUU, wọn gba pe ki wọn gbe ajọ UTAS silẹ ti yoo gbogun ti iwa ibajẹ ni eto isuna ile ẹkọ giga, ẹleyii ti ko nilo eto IPPIS.
Àwọn ọmọ yín lọkunrin ati lobinrin yóo sọ àsọtẹ́lẹ̀àwọn ọdọmọkunrin yín yóo rí ìran,àwọn àgbà yín yóo sì lá àlá.
Ileeṣẹ ọlọpaa ipinlẹ Eko lo kede bẹẹ ninu Atẹjade kan ti alukoro ileeṣẹ ọlọpaa naa, Muyiwa Adejobi fi sita lọjọ Iṣẹgun.
Ìjọ Redeem: Á se àyẹ̀wò ojú ara fáwọn àfẹ́sọ́nà sáájú ìgbeyàwó
ni igbakeji aare alaga egbe APC  (ila
Audu Ogbeh: Mínísítà fẹ́tò ọ̀gbìn ní pápánu Pizza ìlú London làwọn kan ń jẹ ní Nàìjíríà
"Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Lizzy Anjọnrin fẹ̀si fáwọn agbọ́yì-sọ̀yí lórí ìgbéyàwó rẹ̀, Madam Sajẹ dasójú ilé iṣẹ́, àti àwọn ǹkan míràn tó ṣẹlẹ̀ lágbo tíátà lọ́sẹ̀ yìí Bí o ṣe lè forúkọ silẹ̀ fún ètò ""N75BN Nigerian Youth Investment Fund"" rèé."
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Turkey n fi omi ara ọpọlọ ti wọn ti rẹ se ara rindin Ohun to wọpọ ni orilẹede Turkey ni lati fi igba aya ati ọmu akukọ se ounjẹ jijẹ.
Awọn to ṣe agbatẹru eto naa ni yoo jẹ aaye lati kede ipinu awọn to ba fẹ lati to sẹyin agba ẹgbẹ oṣelu All Progressives Congress, Bola Ahmed Tinubu ki wọn lee fi orukọ rẹ ṣọwọ fun ipo aarẹ lọdun 2023.
Ibùsùn kò ní na eniyan tán.
O fikun oro re pe, oludije dupo gomina egbe naa, Gboyega Oyetola ni iriri ti o po, ti o si da Oun loju pe yoo le tuko ijoba ipinle Osun.
"Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ẹ wo adúrú ǹkan tí Softface ma ń tò pọ̀ láti sín àwọn òṣèré, gbajúgbajà jẹ A fura pé ejò lọ́wọ́ nínú ikú Tolu Arotile, ẹ ṣe ìwádìí ikú rẹ̀ - Afenifere, Gani Adams, Huriwa Ohun tí o kò mọ̀ nípa Ebila ""One Million Boys"" àti Ekugbemi, olórí ẹgbẹ́ òkùnkùn méjì tó da ìlú Ibadan rú Mo ti pinnu láti túṣu dé ìsàlẹ̀ ìkòkò lóríì ìdí tí kò sí ìdàgbàsókè ní Niger Delta - Buhari Ènìyàn 156 ló tún ṣẹ̀ṣẹ̀ lùgbàdì ààrùn Coronavirus ní ìpínlẹ̀ Eko Ki o to di pe awọn apọnbeporẹ olori de sinu aye Ọba Adeyemi, awọn obinrin to fẹ nigba ewe rẹ naa wa, ti wọn si jẹ igi lẹyin ọgba fun Alaafin."
Generator)  ati galonu epo moto (Conoil
Ó ní, “Ó dàbí wóró musitadi kan tí a gbìn.
Footballers: ìkà láwọn aṣojú agbábọ̀ọ̀lù míì lágbàyé
O ni gbogbo awon oludije fun ipo
Femi, nígbà tó ń dáhùn ìbéèrè lórí bí àwọn osere tíátà ṣe máa ń safihan ibalopọ àti wiwọ aṣọ iwọkuwọ ninu sinima, ṣàlàyé pé ẹgbẹ́ Tanpan tí ń ṣíṣẹ pelu àjọ ti ìjọba gbé kalẹ fún akoso sinima, láti dẹkùn irú ìwà aidaa báyìí.
Ìgbà tí òògùn ẹ̀jẹ̀ ríru lè ṣiṣẹ́ jù rèé- Onímọ̀ Ọwọ ṣìkún òfin ti tẹ Maina, alága àná fún ọrọ owó ìfèyìntì - DSS Khadijah, obìnrin àkọ́kọ́ tó dẹnu ìfẹ́ kọ àyànfẹ́ rẹ̀ Àrá tún ti sán pa màálù mẹ́jọ ní ìpínlẹ̀ Ondo Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Òwe: Kí ni ìtumọ̀ òwe ikú tó ń pa ojúgbà ẹni?
Àwọn àlejò tí wọ́n wọ̀ sí ilé mi ti gbàgbé mi.
Ó tún dàrìnnàkòÓ tún dojú àláÓ tún di bẹ́ni jọ́niÓ tún di béèyàn jọ̀ọ̀yàn.
Lẹ́yìn náà, ó yípo lọ sí apá àríwá, kí ó tó wa lọ sí Enṣemeṣi títí lọ dé Gelilotu tí ó dojú kọ gẹ̀rẹ́gẹ̀rẹ́ Adumimu, lẹ́yìn náà ó wá sí ìsàlẹ̀ ní ibi tí òkúta Bohani ọmọ Reubẹni wà.
’”Ninu oro asoju orile ede Mali, o so pe oun yoo sa ipa oun lati je ki ifowosowopo tun fese mule si laarin orile ede mejeeji yii, paapaa julo nipa imo ise iwadii laarin awon ajo eleto aabo orile ede mejeeji ati awon ohun to le mu idagbasoke ba eto oro aje won.
Ile iwosan kan niluu New Jersey lorilẹ-ede Amẹrika lo ṣaṣiṣe fun ẹnikan kindirin ti kii ṣe tiẹ.
O sọ pe wọn ko le ṣii awọn ferese wọn tabi awọn ilẹkun fun afẹfẹ tutu nitoripe ayika wọn nigbagbogbo ni oorun ati eefin.
Ọgbẹni Thomas to jẹ baba Meghan Markle ko lee farahan nibi igbeyawo naa nitori ailera ara rẹ.
Bakan naa ni wọn ni baalu ọkọ adani ni wọn haya fi rin irin ajo ọhun.
Sani Abacha tún gbé owó míì dé láti Ireland Ibùdó ìyàsọ́tọ̀ ni mo wà, ló fi pẹ́ kí ń tó sọ̀rọ̀ lórí tírélà tó já l‘Eko - Omotola Jalade Ekeinde Ire ṣ'ọjọ́-ìbí, Mide àti ọkọ rẹ̀ lẹ̀pọ̀, Iyabo Ojo f'aṣọ ilẹ̀ Afirika dárà Funke Akindele fún mi lówó tí mo fi gba ilé, kò ra ilé fún mi o - Ajirebi Èèkàn ẹgbẹ́ òṣèlú APC mií Lanre Razak jáde láyé lẹ́yìn àìsàn ráńpẹ́ Ìpànìyàn tún wáyé ní Akinyele, àwọn ará àdúgbò ṣe ìwọ́de Lara awọn to dagbere faye naa la ti ri iyawo ọkọ kan naa meji ati ọmọ wọn marun-un, nigba ti ko si ẹnikẹni to m ibi ti baale ile naa wa, lasiko ti isẹlẹ ọhun waye.
Eyi ni igba keji ti Man United yoo fidi rẹmi ni papa isere Old Trafford ni saa bọọlu tuntun yii.
Olùṣọ́-aguntan agbo rẹ̀,tí ó fi Ẹ̀mí Mímọ́ rẹ̀ sáàrin wọn?
Lẹ́yìn ìgbaniníyànjú lóríṣiirisii, Aarẹ Mohammadu Buhari tọwọ́ bọ ìwé àdéhùn ibúdó olókowò kan fún ilẹ̀ Afrika.
O ní ti gbogbo ènìyàn ba le gbáradì láti gbadura ati ààwẹ fun orilẹ̀-èdè yìí, Ọlọrun yóò boju wolẹ̀ láti Ọrun yóò si gbọ ẹbẹ̀ àdura ti yoò mu ki ilú rojú ki o ráye, ti gbogbo nkan yóò si maa lọ dede.
Iroyin to tẹ wa lọwọ ni pe awọn adigunjale ya wọ ile ifowopamọ kan ni ipinlẹ Ondo ni ọsan ọjọ Aje.
Bẹ́ẹ̀ irú ìwà yìí ní ń sọ ni lórúkọ, ó ń sọ àǹfààní ènìyàn nù, a máa sọ ẹni títóbidi ènìyàn kékeré, ọmọlúwàbí tí ó bá rí i pé ìwà irú eléyìí ń di ti òun ní láti yára yàgò fún ìwà náà nítorí àbàwọ́n ni lára ẹni.
Awọn to n woju ọjọ ti ya aworan iho dudu to tobi julọ ni gbogbo aye ati ọrun ti o wa ni ọrun galaxy fun igba akọkọ.
Wọ́n ní, “Ẹ̀yin ará Galili, kí ló dé tí ẹ fi dúró tí ẹ̀ ń wòkè bẹ́ẹ̀?
Adagun odo nla yii ti fa ọbitibiti wahala laarin orilẹ-ede Egypt ati Ethiopia, Yoruba si bọ wọn ni bi erin meji ba n ja, koriko abẹ wọn a jiya - orilẹ-ede Sudan wa laarin awọn mejeji yii Bẹẹ si ni awọn kan n bẹru pe o lee yọri si ogun bakan naa lorilẹ-ede Amẹrika ti n kẹnu bọ ọrọ naa.
Jákèjádò Juda ni Hesekaya ti ṣe ètò yìí, ó ṣe ohun tí ó dára, tí ó tọ́, tí ó sì jẹ́ òtítọ́ lójú OLUWA Ọlọrun rẹ̀.
Nígbà tí, àwọn ọmọ Israẹli ṣebí ẹni ń sá lọ fún àwọn ara Bẹnjamini, wọ́n ń tàn wọ́n jáde ni, wọ́n sì ti gbẹ́kẹ̀lé àwọn ará wọn tí wọ́n ba ní ibùba yípo Gibea láti gbógun ti àwọn ará Bẹnjamini.
Ni orile ede Naijiria, iṣe asẹwo lodi s'ofin.
Bayii, wọn ti ni ọkọ gbigbe alaisan to to ogun pẹlu awakọ fun ọkọọkan.
World Food Day: Wo àwọn oúnjẹ ìṣẹ̀mbáyé Yorùbá tó ti ń di àpatì Ẹ gbà mi o!
Àwọn kan fẹ́ da Naijiria rú torí ààbò tó mẹ́hẹ - Osinbajo gbarata Mo mọ̀ọ́mọ̀ dá €37,000 ti mo rí he padà ni -Ọmọ ogun Bashir Buhari yóò gbìyànjú láti lọ fún sáà kẹta Ìlú ò rẹ́rìn ín rárá, Alaafin Adeyemi III fárígá fún Buhari nínú lẹ́tà tuntun 'Kò sí ohun tó burú nínú bí Ajimobi ṣe dá Yewande tó pa ọkọ rẹ̀ sílẹ̀' Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí kan sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
Ile-ejo to wa lorile ede Madagascar ti pase fun aare orile ede naa Hery Rajaonarimampianina lati yan olori ijoba tuntun.
Ó sì rìnnà ko ibi tí Ọlọ́run dá lọ́lá, ṣùgbọ́n tí àwọn èdá ibẹ̀ kò bìkítà rárá.
Ọrọ naa to sọ niwaju igbimọ ile aṣofin jọ bi igba pe o ni ko si aburu ki Naijiria jọwọ ominira rẹ fun China.
Alaga Ajọ Isọkan Agbaye (UN), Antonio Guterres ti ni idẹyẹ si awọn obinrin lawujọ gbogbo jẹ ohun itiju fun tọmọde ti agba ni awujọ, ti awọn eniyan si gbọdọ pawọpọ lati fi opin si.
Nítorí pé, ọba ní àwọn ọkọ̀ ojú omi tí àwọn iranṣẹ Huramu máa ń gbé lọ sí Taṣiṣi.
Ìgbẹ̀hìn onírìkíṣí kì í dára, ìṣubú rẹ̀ a sì da bí ìgbà tí ilé pẹ̀tẹ́ẹ̀sì méjìlá bá wó lulé lẹ́ẹ̀kan ṣoṣo, nítorí òun dàbí ìkuuku tí ó funfun bí i fàdákà níwájú, ṣùgbọ́n tí a dé ibẹ̀ tí ó di òfo.
Èmi náà sì múra mo fi iré si í.
Awọn ọlọpaa naa ni Isipẹkitọ Bagou Michael, Isipẹkitọ Ekpoudom Etop, Sajẹnti Nnamdi Majura, ati Sajẹnti Akinyemi Benson.
Aare orile ede Guinea  Bissau, Jose Mario Vazlo fi idunnu re han lasiko to n ba awon akoroyin soro nile aare to wa niluu Abuja, leyin ipade alati- lekun -mori ti o se pelu aare Muhammadu Buhari.
"Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Man United vs Chelsea: Ajá to bá wọlé tí ẹkùn yóò fẹjẹ̀ wẹ̀ 11 Ògún 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 13 Ògún 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Man United vs Chelsea: Man U fí han Chelsea pe ajá to wọlé ti ẹkun yóò fẹ̀jẹ̀ wẹ̀ Manchester Unite ti fàgbà han Chelsea pe ẹni o ṣe lásìkò tí wọ́n kọlu ara wan nínu ìfẹsẹ̀wọ́nṣe ti wọ́n fi ṣide premiere League sáà yìí, pẹ̀lú àmi ayò mẹ́rì si òdo Àmì ayò méjì ni Marcus Rashford fi sẹ ogun Frank Lampard nínú ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ àkọ́kọ́ lẹ́yìn to gba iṣẹ́ akanimọ̀ọ́gbá Chelsea àti àwọn ọmọ ẹyìn rẹ̀ ní ìpele ìkíní àti ìkejì Arsenal jáwé e ""ó tó gẹ́ẹ́"" fún Manchester United EPL: Chelsea, Man Utd f'idi rẹ'mi Jose Mourinho gbàwé ìdádúró ní Manchester United 'Man Utd ko ri anfani to tọ lara Sanchez' Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Wolii Arole Anthony Martial àti Daniel james náà ràn Red Devil lọ́wọ́ láti jáwe olúbori Chelsea ninu ìdíje tó dabi pé ó fẹ́ kó Chelsea lóyìí ojú."
Ọpọlọpọ àwọn mìíràn tún gbàgbọ́ nítorí ọ̀rọ̀ rẹ̀.
Awọn elétò ààbò to wà nibẹ̀ ni awakọ ofurufu aladani kan to ń bọ lẹ́yìn lo sáré ké gbajari ki wọ́n tó mú ọkùnrin náà.
Oríṣun àwòrán, Office of the Ghana president Àkọlé àwòrán, Kini o maa ṣẹlẹ̀ sí Aarẹ Akufo-Addo?
7 152263 Orilẹede Slovenia 3121 150.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ogun Cholera: Ọdọọdún ni àrùn onígbá-méjì máa n ṣọṣẹ́ ní Nàìjíríà-NCDC Akọsilẹ fihan pe erin mẹjọ lo ku lọdun 1992 nibẹ, eyi to jẹ ki ijọba Thailand jiroro lori ọrọ naa.
lorile ede Naijiria , ogbeni Tony Ojukwu, ti o tun je alaga igbimo aare fun eto
Nígbà tí Esau gbé ojú sókè, tí ó rí àwọn obinrin ati àwọn ọmọ, ó ní, “Ta ni àwọn wọnyi tí wọ́n wà pẹlu rẹ?
Ìyá Alájé: Ṣé ìyẹn kìí ṣe ‘sixty nairà’ bí
Ìròyìn sọọ dì mimọ pé ilé-iṣẹ́ náà kọ̀ lati san owo osu oṣiṣẹ fún oṣù méjì, ẹrú sí n bá àwọn oṣiṣẹ náà láti sọrọ jáde nítorí wọn o fe pàdánù owo wọn ti wọn bá dawọ iṣẹ dúró.
Ẹ̀yin ọ̀jẹ̀lu Nàìjíríà, ẹ fi ìhùwàsí Adébọ́lá ṣe àkọ̀mọ̀nà
O so pe “Mo wa lati wa je olubori, laarin odun kan, gbogbo ipinnu mi, ni mo mu se , nitori naa, mo n lọ gẹgẹ bi alaseyori.
 lẹ ́ yìn ìsìnkú , àwọn àgbà ilé ni wọ ́ n máa pín ogún olóògbé fún àwọn ọmọ rẹ ̀ , bí ó bá jẹ ́ òkú olọ ́ mọ .
Ọpọlọpọ awọn to fi ero wọn han ni sọ pe awọn olowo nikan lo le kọ will nitori awọn lo ni dukia ti wọn fẹ pin.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ìwọ́de #RevolutionNow forí ṣánpọ́n ní Ibadan, àgbófinró gbàkóso ojú pópó Ọlọ́pàá àti àwọn olùfẹ̀hónúhàn gbéná wojú ara wọn níbi ìwọ́de Revolution Now Soworẹ ń déte láti dìtẹ̀ gba ìjọba Nàíjíríà lá ṣe gbé e - DSS Dangote, jọ̀ọ́ nawọ́ ìrànwọ́ láti dá iléeṣé sílẹ̀ fún wa ní Ọyọ - Aláàfin rawọ́ ẹ̀bẹ̀ Gẹgẹ bi itan ti fi ye ni, awọn eeyan kan ti Olutimẹyin, ogboju ọdẹ ko sodi, lo de idi agbami odo nla kan, ti wọn n pe ni odo Ọṣun.
Asiko ti wọn si ri aaye sunmọ Ọba Adeyemi ni wọn n fi ọrọ ransẹ lori aago pe awọn nifẹ rẹ, to si wu awọn lati di olori laafin rẹ.
Ninu atẹjade kan ti ileeṣẹ ọlọpaa fi sita lọjọ Ẹti, Ọga ọlọpaa, Adamu sọ pe abajade ajọ Amnesty International to hande lọjọ kọkanlelogun oṣu kẹwa dun 2020 to kọ pe awọn ọlọpaa yinbọn ba awọn to n ṣe iwọde wọọrọwọ n ṣi awọn eeyan lọkan ko si ki n ṣe ootọ wipe o lodi si gbogbo aridaju to wa nilẹ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Nigeria 2019 Election: Ọjọ́ Sátidé tí wọ́n sún ìbò ààrẹ sí ni ìgbéyàwo àwọn ìbejì yìí Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Nigeria 2019 Election: Ọjọ́ Sátidé tí wọ́n sún ìbò ààrẹ sí ni ìgbéyàwo àwọn ìbejì yìí 21 Èrèlè 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 22 Èrèlè 2019 Ọjọ ayọ ni ọjọ igbeyawo jẹ fun ẹnikẹni papaa julọ laarin awọn Yoruba.
Nígbà tí a sì ń sún mọ́ ibi tí àwọn ọlọ́pàá wọn-ọnnì wà ó ní òun fẹ́ẹ́ ṣe ìgbọ̀nsẹ̀ a sì dúró pé kí ó tètè ṣe tán ìgbà tí kò si tètè ṣetán a múra a ń rìn lọ sí iwájú dè é.
”Samuẹli bá wí fún Jese, pé, “Ranṣẹ lọ pè é wá, nítorí pé a kò ní jókòó títí yóo fi dé.
Ẹ má yọ̀ ní ti pé àwọn ẹ̀mí èṣù gbọ́ràn si yín lẹ́nu; ṣugbọn ẹ máa yọ̀ nítorí a ti kọ orúkọ yín sí ọ̀run.
Lẹyin ọdun mẹrindinlogun, ọpọlọpọ awọn eniyan lo ṣi n bu ẹnu atẹ lu idajo to ni wi pe ki wọn yẹgi fun wọn.
Ṣebí ọjọ́ díẹ̀ ni mo níláti lò láyé?
Oríṣun àwòrán, @Sanwo olu Ninu awọn iwọde yii ni awọn agbofinro ipinlẹ Eko ti mu awọn afẹhonuhan kọọkan si atimọle.
ile-ise alabo lorile-ede naa tenumo pe, “ile-ise alabo Afghan je igbimo ti won sagbekale re lati daabo bo ara ilu ati ohun ini won gbogbo,”.
O ni ti eeyan ba ronu jinlẹ lori ọrọ to wa ninu iwe ipe awọn ọlọpaa naa, o fihan pe esuro ti n padi da, maa le aja lori ẹsun ifipabanilopọ naa, tawọn ọlọpaa si ti fẹ fi ẹsun irọ pipa ati ibanilorukọjẹ we oun ati iyawo oun lọrun.
N kò ní ẹlòmíràn tí ó dàbí rẹ̀ tí ọkàn wa rí bákan náà, tí ó sì tún ń fi tìfẹ́tìfẹ́ ṣe àwọn nǹkan tí ó bá jẹ mọ́ tiyín.
 Eleyii ti o ti ṣamulo owo-ori ati owo koko lati fi mu idagbasoke ba ẹkun naa.
 kò sí igi eléso bí ọsàn tàbí àgbálúmọ ̀ rárá .
“Kí ní ṣe tí ẹ̀ ń ṣe àníyàn nípa ohun tí ẹ óo wọ̀?
Ni oṣu karun ọdun 2017 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Awọn ologun ti bẹrẹ sii ni gbogun ti awọn ik boko haram Awọn agbebọn kọlu ileewe girama Government Model College, Igbonla, Epe ni ipinlẹ Eko.
Ǹjẹ́ o lè ní ìgboyà ati agbára ní ọjọ́ tí n óo bá jẹ ọ́ níyà.
Sunkanmi to fi fọto ati ikede ibi ọmọ rẹ si oju opo Instagram rẹ ni Aderinsọla ni wọn sọ orukọ ọmọ naa.
Ó bá lọ gbà á sílẹ̀.
Ninu atetaje kan latodo adele oga agba eka eto iroyin nile-ifowopamo naa lojo-aje, Isaac Okoroafor so pe ogorun 100 milionu dollars lo sodo awon ti won ni ase si sise pasi-paro owo ni abala oja  idokowo naa.
Igi náà wà nínú igbó ìgbàlẹ̀ kan tí ó wà ni téńté orí òkè tí à ń pè ní òkè Ìgbéega.
 ‘‘Lati bi ogun odun seyin ni orile ede Naijiria ti n je igi leyin ogba fun ile-ejo agbaye , paapaa julo lorile ede Afirika.
Aṣọ funfun onílà tẹ́ẹ́rẹ́tẹ́ẹ́rẹ́ ni wọ́n fi ṣe gbogbo aṣọ títa tí ó wà ninu àgbàlá náà.
Wọ́n ṣẹ́ gègé lórí àwọn ọlọ́lá ibẹ̀, wọ́n sì fi ṣẹ́kẹ́ṣẹkẹ̀ de àwọn eniyan pataki wọn.
Ọgbọnjọ osu Kẹfa ọdun 1943 si lo de ile aye.
Saaju ni aworan kan gba ori ẹrọ ayelujara, pe Gomina Fayose ati igbakeji rẹ, to tun jẹ oludije sipo gomina ninu eto idibo to waye ninu oṣu Keje, 2018 ni ipinlẹ Ekiti, Ọjọgbọn Oluṣọla Ẹlẹka, ṣe abẹwo si ile Bola Tinubu to wa ni ilu Eko.
Shanta Roy, to n ya aworan ni orile ede India yombo awon onise ona ile Naijiria pe won gbounje fegbe gbawo bo lagbaye.
Ẹ jẹ́ kí á fi ìyìn fún Ọlọrun Baba Oluwa wa Jesu Kristi, tí ó ti fi ọpọlọpọ ibukun ti ẹ̀mí fún wa lọ́run nípasẹ̀ Kristi.
Minimum wage: Buhari ti buwọ́lu sísan ẹ̀kúnwó oṣù tuntun fáwọn òṣìṣẹ́ àpapọ̀
Diẹ lara awọn orin to tà dáadáa ti awọn eeyan ilẹ iwọ oorun adulawọ tẹwọgba ni 2018 niwọnyii; nọmba yi ko nii ṣe lori bi wọn ṣe ta tó: 1) Wizkid - Fever Wizkid onkọrin ọmọ Naijiria kan lo kọ orin 'Fever' ni eyi to gbajugbaja nigba ti wọn gbe awo naa sita.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù DAAR Communications: AIT, RayPower padà lẹ́yìn àṣẹ ilé ẹjọ́ 7 Òkùdu 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 8 Òkùdu 2019 Oríṣun àwòrán, @AIT Àkọlé àwòrán, NBC: AIT kọ̀ láti tẹ̀le ìlànà òfin ìgbóhùnsáfẹ́fẹ́ Naijiria Ileeṣẹ amohunmaworan AIT ati ti asọrọmagbesi RayPower FM pada si ori afẹfẹ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù South Korea: Èèwọ̀, ẹ kò gbọdọ̀ jẹ ajá mọ́ 21 Òkùdu 2018 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 16 Èbibi 2020 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Mase jaja mọ Ile ẹjọ kan ti pase ki wọn ma pa aja fun ẹran jijẹ mọ̀ ni ilu South Korea.
Ìyẹn ni pé kí a tó jẹ ìgbádùn, iṣẹ́ ní í ṣíwájú ẹ̀.
"Ohun ti wọn si sọ fun wa ni wipe lati oke ni asẹ owo yii ti n wa.
Federer, eni ti o ti gba ami-eye Grand Slam igba ogun bayi, yoo tun gba ipo kinni re pada ti ipo ate tuntun ATP miran ba jade lose ti a wayii.
ti fi ipilẹ silẹ, a o si rii pe a se ede opin.
Nítorí ẹni tí ó ṣe wọ́n gbẹ́kẹ̀lé iṣẹ́ ọwọ́ rẹ̀, ère tí ó gbẹ́ tán tí kò lè sọ̀rọ̀!
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ronke Odusanya sọ̀rọ̀ lórí ìròyìn tó ní ó ti jẹ bàbá ọmọ rẹ̀, Jago run 9 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Oríṣun àwòrán, Ronke Odusanya/Instagram Gbajugbaja oṣerebinrin, Ronke Odusanya 'Flakky Ididowo', ti sọ pe didakẹ ti oun dakẹ kii ṣe ti ojo.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Cristiano Ronaldo wá lára àwọn àgbàọ̀jẹ̀ agbábọ́ọ̀lù tí kò gba ife ẹ̀yẹ àgbáyé rí Ẹlẹsẹ ayo Romelu Lukaku to n gba bọọlu fun Belgium naa ti gba ayo mẹrin sawọn, o si ni anfani lati fikun ami ayo rẹ nigbati Belgium ba koju France.
Koda ẹgbẹ naa labẹ oludari rẹ, Ọgbẹni Adeniyi Sulaiman fun Tinubu ni wakati mẹrinlelogun lati sọ ero rẹ lori eto Amọtẹkun.
Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Sex is painful for nearly one in 10 women, study finds Nearly one in 10 British women finds sex painful, according to a large study.
Awọn alamojuto idije naa ṣi n reti awọn olukopa lati orilẹede bi Congo ati Burkina Faso.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Dambe fight: ìdíje ìjà láàrin àwọn akóni tó n ja ẹ̀ṣẹ̀ 10.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Nkechi Blessing: Ọ̀rọ̀ ìfẹ́ wa dàbí ti Romeo àti Juliet 9 Sẹ́rẹ́ 2020 Oríṣun àwòrán, Nkechi Blessing Ọrọ ifẹ, awamaridi ni, ko si si ẹni to lee mọ ibẹrẹ abi opin rẹ, koda, awọn eeyan miran tun maa n se apejuwe ifẹ bii adanwo.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Pásítọ̀ ló sọ fún mi pé Ọlọ́run pè mí láti di Olokun tó ń bọ omi' Láàrin ọ̀sẹ̀ kan ṣóṣó Òṣèré fíìmù Yorùbá méjì gorí akéte àìsàn Loju opo Instagram rẹ, ko fi oju ara rẹ han ṣugbn Muyiwa Ademola fi aworan sita to wa lori ibusun ile iwosan ti wọn si n fa diriipu si i lọwọ.
Ogun Doctor's Strike: Ẹgbẹ́ dókíta ló ra ìbòmú fúnra wa- Alága NMA Ogun Lánàá òde yìí ni àwọn dókíta ilé ìwòsàn ìkọ́ni Olabisi Onabanjọ (OOUTH) Sagamu ní àwọn yóò dásẹ́ kalẹ̀ fún ọjọ mẹ́ta láti kilọ fun ìjọba lórí àwọn ìbéèrè tó wà níwáju wọ́n láti ọjọ́ pípẹ́.
Nigba to n ba akọroyin sọrọ, ọga agba ile iwosan Lafia to wa ladugbo Apata nilu Ibadan, Dokita Ọladipupọ Sule salaye pe, ọmọ oun Kayọde ati osisẹ meji nile iwosan naa ni wọn fori sọta isẹlẹ ijinigbe naa, to si pe orukọ awọn eeyan meji yoku ni Ọpẹyẹmi Abifarin ati Dele Adigun.
O so pe, botileje pe, ikolu ohun waye lasiko ti o ye ki won maa kore iresi ati soya beans, eyi ti o sakoba fun ikore naa”.
Ọ̀pọ̀ aráàlú Owo wà nílé ìwòsàn, síbẹ̀ APC àti PDP kò gba ẹ̀bi Makinde gba àwọn òṣìṣẹ́ LAUTECH 41 tí ìjọba Ajimobi dá dúró lẹ́nu iṣẹ́ padà Obabinrin Elizabeth kejì kí Nàìjíríà kú oríire òmìnira ọgọ́ta ọdún YIAGA ni eyi ri bẹẹ nitori awọn nnkan tawọn ti foju ri lasiko ipolongo ibo, bii iwa ipa, ikọlu si alatako, biba ọkọ jẹ ati lilọ kaakiri pẹlu ohun ija oloro, se gbilẹ lawọn agbegbe naa.
Loni, itumọ International Passport ni a fẹ kọ ara wa ni ede Yoruba.
Mo ṣe tan lati ku tọmọ tọmọ bi wọn ko ba tu ọga wa silẹ tori ẹmi gbogbo awa ọmọ ẹgbẹ ko ni itumọ bi olori wa ba ṣi wa lahamọ."
Amọ niwọn igba to jẹ pe a kii ri ẹni sagbara, ọwọọwọ si ni ọmọ ejo n rin, Sunday Igboho ko da nikan lọ silu igbo naa.
Wọ́n wà níbẹ̀ pẹlu Dafidi fún ọjọ́ mẹta, wọ́n ń jẹ, wọ́n ń mu, nítorí àwọn arakunrin wọn ti pèsè oúnjẹ sílẹ̀ dè wọ́n.
NURTW: Agbẹnusọ Sanwo-Olu ní gómínà ti gbé ọ̀rọ̀ ìjà NURTW lé ọlọ́pàá lọ́wọ́
Ṣá ti gbà pé o jẹ̀bi,ati pé o ti ṣọ̀tẹ̀ sí èmi OLUWA Ọlọrun rẹ.
Abajade iwadi naa, ti wọn pe orukọ rẹ ni ''A Tale of Two Continents'' ṣafihan bi iṣẹ ṣe n lọ soke ni Naijiria ati ilẹ ni Afrika, ti aiṣedeede ọrọ aje si tun n da kun iṣoro kikoju aini nilẹ naa.
Inú bí Agígírì a sì gbé e bú.
Ọkùnrin kan tó yasó nínú ọkọ̀ Uber rí ẹ̀wọn he Ninu ọrọ rẹ o ni, ọga agba ọlọpaa patapata lorilẹ-ede Naijiria nigba naa, Etim Inyang lo pe ipade kan pẹlu awọn eekan ileeṣẹ ọlọpaa lati dẹkun ọwọja idigunjale lasiko naa.
Dolapo Osinbajo: Dolapo, ìyàwó igbákejì ààrẹ ránṣẹ́ mẹ́ta sáwọn obìnrin
- iléeṣẹ́ ológun kìlọ̀ Ẹ lọ ki ọwọ ọmọ bọ aṣọ, bii bẹẹ kọọ, ẹ o kan idin ninu iyọ.
Àwọn ọmọ marun-un tí Midiani bí ni Efa, Eferi ati Hanoku, Abida ati Elidaa.
Kò sí agbára kankan fún mi mọ́; ojú mi sì yipada, ó wá rẹ̀ mí dẹẹ.
Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Ayinla Ọmọwura kò kàwé, àmọ́ ó kópa sí àgbéga orin àti èdè Yorùbá19 Òkùdu 2019 Àlàyé rèé lórí bí 'Popular Jingo' ṣé dí inagijẹ akọrin Juju tó bí Wale Thompson 'Lalalẹ Friday'24 Owewe 2020 Fídíò, Wo àwọn nǹkan mẹ́rin tó yẹ kó wà nínú báàgì rẹ lásìkò Covid-19 yìí6 Èbibi 2020 Fídíò, Ilaramokin: Ọba yarí pé àṣá àìlajú ni kí ará ìlú máa na ara wọn lẹ́gba14 Owewe 2019 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 3 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 5 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
O rán àwọn iranṣẹ rẹ láti fi OLUWA ṣe ẹlẹ́yà,o ní,‘Mo ti fi ọpọlọpọ kẹ̀kẹ́ ogun mi gun orí àwọn òkè gíga lọ,mo dé góńgó orí òkè Lẹbanoni.
Katagum ni, àwọn to wà ni ẹ̀ka olókoòwò tó n rí si ìlé itura àti ìgbàlejò ni yóò kan ni ìfórukọsílẹ̀ tí yóò bẹ̀rẹ̀ ní òní, ọjọ́karùnlélógún oṣù kẹsán, ọdún 2020, nígbà ti yóò kan ẹ̀ka àwọn oníṣẹ́ ọwọ́ àti àwọn oníṣẹ́ ètò ìrìnà.
Ó dúró fún ọjọ́ meje kí ó tó tún rán àdàbà náà jáde.
Adari awọn agbẹjọrọ rẹ, Lateef Fagbemi lọ pẹjọ mọ Ọga agba ọlọpaa, ọga agba ajọ ọtẹmuyẹ, DSS ati olotu eto idajọ ni ipinlẹ Kano naa ni wọn gbe lọ si ile ẹjọ giga ti ilu Abuja.
Àbọ̀ ìpàdé bòńkẹ́lẹ́ láàrin Tinubu àti Buhari rèé Pásítọ̀ pe Naira Marley ní ẹlẹ́mìí èṣù, Marley fèsì padà pé kí pásítọ̀ gan tẹ èṣù mọ́lẹ̀ Díẹ̀ lára àwọn ìṣẹ̀lẹ̀ tí yóò mi ìgboro tìtì l'ọ́dún 2020 rèé Ọmọdé tó ń ṣeré pẹ̀lú àdò olóró ló fa ìbúgbàmu Borno- Cameroon Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Olaitan Olamide: mò lè má nílò ìwé ẹ̀rí mi tí mo bá parí ní LASU Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Wò ó, a ti di ẹrú lórí ilẹ̀ náà.
Saulu dá a lóhùn pé, “Mo ti pa òfin OLUWA mọ́, mo jáde lọ bí o ti wí fún mi pé kí n jáde lọ, mo mú Agagi ọba pada bọ̀, mo sì pa gbogbo àwọn ará Amaleki run.
Miguna to je alatako ijoba ni won le kuro lorile ede naa
O fẹ aya, o bimọ nibẹ koda o riṣẹ gidi kaakiri.
O ni Fayose nikan lo da ta ilẹ naa fun wọlẹwọde rẹ ti igbimọ amuṣẹya ẹgbẹ ko si mọ nipa rẹ.
OLUWA a máa pa àwọn onírẹ̀lẹ̀ mọ́;nígbà tí a rẹ̀ mí sílẹ̀, ó gbà mí.
Irú ìwọ̀n tí ẹ bá lò fún eniyan ni Ọlọrun yóo lò fún ẹ̀yin náà.
sọ fún àwọn ọmọ Israẹli pé, “Èmi ni OLUWA Ọlọrun yín.
Loju opo twitter re, @elrufai, gomina ipinlẹ́ Kaduna foju laifi wo isẹlẹ naa, to si n fewe ọmọ mọ awọn eeyan agbegbe naa leti lati mase gbẹsan.
Dafidi kọlu àwọn Filistini, ó pa pupọ ninu wọn tóbẹ́ẹ̀ tí àwọn Filistini fi sá lójú ogun.
Awọn ara adugbo ko loju orun, ti wọn si n dana sun taya ọkọ laarin oru ti wọn ba n ṣọ adugbo koowa wọn.
Aya gomina ipinlẹ Kwara, Olufolake Abdulrazaq, ti kede pe oun ti setan lati ran iya ati ọmọbinrin meji ti wọn ni oju buluu lọwọ .
Ẹranko tí kò lè fọhùn sọ̀rọ̀ bí eniyan, ó dí wolii náà lọ́wọ́ ninu ìwà aṣiwèrè rẹ̀.
Oríṣun àwòrán, @Mohammed Jagunma ati Gold Abdulrafiu Níbo lọ̀rọ̀ dé dúró nípa iṣẹ́ àwọn tó n wa iṣẹ́ N-Power?
Nítorí ó wà ní àkọsílẹ̀ pé,‘Yóo pàṣẹ fún àwọn angẹli rẹ̀ nítorí rẹ,kí wọ́n tẹ́wọ́ gbà ọ́,kí o má baà fi ẹsẹ̀ gbún òkúta.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Nigeria: Afunrasí ẹ̀sùn jìbìtì ló ni iléeṣẹ́ tó ń ṣe ìwé àṣẹ wọléwọ̀de ní Nàìjíríà 8 Ìgbé 2020 Iwadii ajumọṣe laarin BBC ati iwe iroyin Premium Times ti fihan pe ẹni to ni ileeṣẹ ti ijọba apapọ lorilẹede Naijiria gbe kalẹ si idi iṣakoso titẹ iwe aṣẹ irinna wọle sorilẹede Naijira lati orilẹede gbogbo lagbaye n jẹ ẹjọ lori ẹsun ikowojẹ ati gbigbọna ẹburu ko owo lọ soke okun.
"Oyedepo ni ""akoko ọtun lo de yii, ti Ọlọrun yoo si gbe agbara asẹ fun awọn ijọ lati dẹkun awọn ilana ofin to mẹhẹ atawọn oloselu ti ko pegede to ni Naijiria."
Olori ikọ Operation 'Lafiya Dole', Rogers Nicholas sọ eyi nibi ìfilọ́lẹ̀ ikọ̀ ọmọ ogun apapọ orilẹede Naijiria ati orilẹede Cameroon ni ilu Maiduguru lọjọ aiku.
Iṣẹ́ agbẹjọrọ ni o n ṣe pelu iyawo rẹ.
Aṣẹ̀yinwá àṣẹyin bọ, bi Liverpool ṣe lọ maa loṣe bọ Champions League: Ajax f'imú Tottenham fọn fèrè Ṣé àìdọ́gba n pọ̀ si ní South Africa?
Ààrẹ Abdulaziz Bouteflika ti kowe fipo silẹ ‘Kò tọ́sí Adeleke láti díje dupò gomina Ọṣun’ 2019 Guber election: Mi ò fara mọ èsi ìdìbò Ọyọ́ Magu,'estimated billing' àti àwọn ohun míràn tí ilé aṣòfin Nàìjíríà kò rí yanjú Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Àyà mi kọ́kọ́ máa ń já nígbà ti mo ṣẹ̀ṣẹ̀ bẹ̀rẹ̀ -Alaga iduro ọkùnrin Ààrẹ ilé ìgbìmọ àṣofin àgbà Bukola Saraki ló kede ọ̀rọ̀ náà lásikò ìjòkò ilé.
Báyìí ni a tún ìlú wọn ṣe.
Oral Sex: Bóo bá ń gba ẹnu ní ìbálòpọ̀, wo àìsàn tóo lè kó lójú ara rẹ Ìdí tí mo fi gbàdúrà ìyàwó bíi Chanel Chin fáwọn tó d'ẹ̀bi ìkọ̀sílẹ̀ rẹ̀ rù mí rèé - Oluwo 'Gómìnà Akeredolu ló wà nídí ìgbésẹ̀ yíyọ igbákejì rẹ̀, ìdí wàhálà wa nìyí' Wo sẹ́nẹ́tọ̀ mẹ́rin tó jáde láyé ní Nàìjíríà láàrin oṣù mẹ́fà sẹ́yìn Ilu Port Harcourt, nipinlẹ Rivers, lo ti gbera, to si n bọ nipinlẹ Eko.
Ṣowore ṣalaye pe, lara awọn to n fẹhonu han yoo lọ si ile igbimọ aṣofin agba l'Abuja lati sọ ẹdun ọkun wọn fawọn aṣofin.
Nigba miiran owo gọbọi bii miliọnu marun un ni obinrin mii a gbe ka ẹ laya pe ki wọn wa pẹlu ẹ ninu yara fun ọjọ mẹrin nigba to ṣe pe o le ma gba ju ẹgbẹrun lọna ẹgbẹrin fun sinima kan ti o fara han ninu rẹ lọ.
Kí eniyan lè mọ ẹ̀ṣẹ̀ lẹ́ṣẹ̀ ni Ọlọrun ṣe fi òfin kún ìlérí, títí irú-ọmọ tí ó ṣe ìlérí rẹ̀ fún yóo fi dé.
Orukọ rẹ 'Kofi' tumọ si Ọjọ Ẹti ni ede Akan.
Gbogbo ìrìn tí ènìà ti rìn nígbà tí ó bá kọjá oko àgùntà yìí tán á ti máa fẹ́ tó bíi wájàtí mẹ́ta sí mẹ́ta-àbọ̀.
"Ambọde f'agbara fun ede Yoruba Awọn ọmọ Yoruba ni Hollywood ""Bi mo tilẹ̀ jẹ́ apárí síbẹ̀ kò tìmí lójú"", ọ̀pọ̀ dẹ́yẹ sí mi nítori mó ni ààrún ori pípa- Liliya Kukushkina Oludari yii ni lọdọọdun ni ijọba ilẹ Amẹrika n fọmọ wọn ranṣẹ si Fasiti Ibadan lati wa kọ nipa ede ati aṣa Yoruba."
Wọ́n jẹ́ aláfojúdi, onigbeeraga, afọ́nnu, ati elérò burúkú; wọn kì í gbọ́ràn sí òbí lẹ́nu; 
Doctors on Strike: Coro wà Coro ò sí o, èmi á lọ́ sókè òkún bí mo bá ríṣẹ́
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ọ̀pá epo bẹntiróò gbina nílu Èko Bùhárí padà dé sí Nàíjíríà Àwọn mọ̀lẹ́bí tó ti kópa nínú ife ẹ̀yẹ àgbáyé Èyí tí a wò jùlọ 5:03 Fídíò, Omolola Arohunmolase Welder: Mo ti fí iṣẹ́ 'Welder' gbayì láwùjọ, tó mo fi tọ́ ọmọ yanjú, Duration 5,039 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 5:39 Fídíò, Akomolede ati Asa lori BBC: Olùkọ́ Kikelomo Ogunboye tan ìmọ́lẹ̀ sí ìwà olè ọ̀gá ọlọ́pàá Audu gẹ́gẹ́ bí àwòkọ́ṣe àsìkò yìí, Duration 5,398 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 4:11 Fídíò, Oba Adeyeye Ogunwusi: Ojú mi ti rí lọ́pọ̀ lọpọ̀, ọ̀pọ̀ èèyàn ni kò tilẹ̀ gbàgbọ́ pé mo lè jọba- Ooni, Duration 4,117 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 4:43 Fídíò, Promise Akinlade: ọmọ ọdún mọ́kànlá tó ń fi ìlù dárà bíi àgbàlagbà sọ̀rọ̀ nípa tálẹ́ǹtì rẹ̀, Duration 4,437 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 0:59 Gbọ́, Ìsẹ̀lẹ̀ jákèjádò orílẹ̀èdè àgbáyé láàárín ìṣẹ́jú kan, Duration 0,59wákàtí 5 sẹ́yìn 7:03 Fídíò, Olumuyiwa Bolade Adedeji Military Bruitality: Bí arákùnrin onípèníjà ara tí sọ́jà lù ṣe dé, Duration 7,035 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 4:45 Fídíò, Yoruba Films: Ẹ̀ẹ́ bẹ̀ mi kúrò láyé ni, mi ò lè kú - Fadeyi Oloro, Duration 4,4526 Èrèlè 2020 2:48 Fídíò, Esther Ajayi: Èmi náà ti borí ìṣòro rí ló ń mu mi ṣojú àánú, Duration 2,481 Ògún 2019 6:08 Fídíò, Adebola Ademilua: Àìrísẹ́ ṣè lẹ́yìn ìwé kíkà ló sọ mi dí ìyá onírú, mo dúpẹ́ tèmi, Duration 6,0827 Bélú 2020 5:55 Fídíò, Soyinka Cancer: Àṣe ara mi ni iso ti n run gbogbo bí mo ṣe n ṣèrànwọ́ lórí jẹjẹrẹ, Duration 5,5527 Bélú 2019 BBC News, Yorùbá Ìdí tí ẹ fi le è nígbàagbọ́ nínú ìròyìn BBC Ìlànà Lílò Nípa BBC Òfin Àṣírí Cookies Kàn sí.
Kí ló dé tí o fi ta mí nù?
Oríṣun àwòrán, others Ileeṣẹ ọlọpaa ni wahala naa waye laaring awọn ọmọ Hausa kan ti wọn maa n ṣa ilẹ kaakiri atawọn ọmọ ẹgbẹ okunkun kan ti orukọ wọn n jẹ Awawa boys.
" Ẹgbẹ naa n fẹ ki awọn eniyan orilẹede Sudan dide fun iranlọwọ wọn.
ati rogbodiyan ti o ti gbode saaju isejoba re pada si Ipinle Oyo.
  Awọn to wa ni ibi ipade ohun ni:Adari Orilẹ-ede Naijiria tẹlẹri, awọn Adajọ Agba Naijiria, awon
Ẹwẹ, ijọba ipinlẹ Eko fun ara rẹ ati ti ipinlẹ Ogun ti ni, ko ni si afẹfẹ yẹyẹ kankan lasiko ajọdun ominira Naijiria.
Kò sí bí inú yín kò ti dùn tó nígbà náà.
Orilẹ-ede Guinea-Bissau ti agbo naa de si, si ni Naijiria ti lọ ọ ko ti ẹ.
Aare banuje pupo lori ijiya awon ti o fara kaasa ikolu awon omo ogun olote naa: “Ikolu awon omo ogun olote Boko Haram lorisiri je edun kan awon omo orile-ede yii.
Opolopo ipenija ni a ti ba pade ninu irinajo yii , ti awon omo orile ede Najiria si duro ti wa lati mu awon ipinnu yii wa si imuse, awon ipinnu yii ni:eto aabo,iwa –ibaje ati eto oro aje.
Nígbà tí ó gbọ́ ìròyìn ọ̀gágun náà, ó yọ̀ǹda òkú Jesu fún Josẹfu.
Àkọlé àwòrán, Ohun oju ri to!
Èlé orí owóyàá China rọjú la ṣe fẹ́ gbà á - Ìjọba àpapọ̀ Ẹjọ́ ìfìyàjẹni dojú dé!
Lara ilana tuntun naa ni pe wọn gbọdọ ni akọsilẹ pẹlu ajọ National Identification Number (NIN).
Àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ bá wá sọ fún un pé, “Lé obinrin yìí lọ, nítorí ó ń pariwo tẹ̀lé wa lẹ́yìn.
Ọdún mọkanlelogoji ni ó fi jọba ní Jerusalẹmu.
 Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Èmi nìkàn kọ́ ni mó n ṣe àkójọ orin- Fasoyin Pasitọ Ajifowowe ni ""lilọ si ""Cross-over night"" ko ni ki ọdun o yabo fun eeyan, bi ko ṣe ki eeyan ni ipinnu lori ọdun tuntun."
Igi tí kò ní èso ní àkókò ìkórè ni wọ́n, wọ́n ti kú sára.
Tó bá di ìgbà náà, wọn yóo tẹ́ pẹpẹ kan fún OLUWA láàrin ilẹ̀ Ijipti, ọ̀wọ̀n OLUWA kan yóo sì wà lẹ́gbẹ̀ẹ̀gbẹ́ ààlà ilẹ̀ rẹ̀.
Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Barrister - K1 rift: Ìjà parí!
Chineme Martins: NFF ní àyẹ̀wò gbogbo irinṣẹ́ ètò ìlera ti di dandan báyìí ṣáájú eré bọ́ọ̀lù kankan
Ṣé ó tọ́ kì Ààrẹ Trump máa fi Bíbélì jẹ́rìí?
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Àwọn ọ̀dọ́ orílẹ̀èdè Nàìjíríà sọ èrò wọn lórí Nàìjíríà 15.
Theresa May bọ́ lọ́wọ́ ìgbésẹ̀ láti yọ́ nípò Theresa May bú sẹ́kún, ó ní òun kò ṣe olóòtú ìjọba UK mọ́ ‘UK yóò pèsè isẹ́ 100,000 ní Nàìjíríà’ Minisita fọ́rọ̀ ilẹ̀ òkèèrè kọ̀wẹ́ fipò sílẹ̀ Saaju abẹwo yii ni Trump ti fihan pe oun wa lẹyin Boris Johnson pe ko gba ipo Theresa May.
Ṣugbọn Ọlọrun ti ṣe é, nígbà tí ó dá ẹ̀bi ikú fún ẹ̀ṣẹ̀ tí ń bẹ ninu ẹ̀yà ara eniyan.
Abajade ipinlẹ kọọkan ninu esi tuntun naa re e: Eko-224 Oyo-85 FCT-68 Rivers-49 Kaduna-39 Edo-31 Enugu-30 Delta-11 Niger-10 Katsina-9 Ebonyi-5 Gombe-3 Jigawa-3 Plateau-2 Nassarawa-2 Borno-2 Kano-1 Abia-1 Ajọ to n ṣamojuto ajakalẹ aarun ni Naijiria, NCDC, kede pe 499 lo tun ṣẹṣẹ ni Covid-19 ni Naijiria.
Idahun yii wa lara awọn ohun ti agba ọjẹ apẹṣa yii sọrọ nipa rẹ.
Eléyìí wáá fún mi ní ìbànújẹ́ tó bẹ́ẹ̀ tí mo fẹ́rẹ̀ sọ ìrètí nù pátápátá, mo kígbe rara mo sì wí pé:’Tèmi fi ọwọ́ Rẹ o, Ọlọ́run Ọba.
Ibinu rẹ pa wá run;ìrúnú rẹ sì bò wá mọ́lẹ̀.
ati pe eewọ yii naa ta ba awọn afọbajẹ pẹlu.
Toyin Abraham pé 40, wo ohun márùn ún tó mú dá yàtọ̀ láàrín ogójì ọdún Facebook mú àyípadà bá àtẹ̀jíṣẹ́ síra ẹni lórí òpó Instagram, wo àwọn ǹkan tó kàn ọ níbẹ̀ Bí mo bá wọlé padà, mí ò lè yàn Ize Iyamu tàbí Osagiobare sípò olùbádámọ́ràn- Obaseki Oríṣun àwòrán, Aishabuhari Amọ, ni Ọjọ Eti opin ọṣẹ yii ni Hanan Buhari ṣe igbeyawo pẹlu Turad Shaban.
Nítorí pé a máa gba talaka tí ó bá ké pè é sílẹ̀;a sì máa gba àwọn tí ìyà ń jẹ sílẹ̀,ati àwọn tí kò ní olùrànlọ́wọ́.
"‘Bí ẹ se gba Zainab sílẹ̀, ẹ gba Leah Sharibu lọ́wọ́ Boko Haram’ Champions League: Ajax f'imú Tottenham fọn fèrè Àwọn ọmọge wọ gàù l'Abuja nítorí ìwọ̀kuwọ̀ "" Bi o ba ni awọn owo to ti ya tabi dọti, ko wọn lọ si banki, wọn yoo parọ rẹ fun ọ."
Oríṣun àwòrán, iyaboojofespris Àkọlé àwòrán, Oṣere naa pẹlu awọn ololufẹ rẹ bii Alhajoi Ajibola Pasuma lo peju sibẹ.
Awọn olugbe Akute wa n rawọ ẹbẹ sijọba ipinlẹ Ogun lati tete bawọn wa nkan se si isẹlẹ ẹkun omi naa, eyi to ti n di isẹlẹ ọdọọdun bayii.
Ibẹ ni aṣiri ti tu si mi lọwọ pe emi nikan kọ lo n fẹ.
Wọ́n wọ ilé OLUWA láti tọ́jú rẹ̀ bí ọba ti pa á láṣẹ, gẹ́gẹ́ bí òfin OLUWA.
NFF fi #30,000 kún #10,000 owó ìrànwọ́ oṣooṣù fún ìyá Rashidi Yekini àti Samuel Okwaraji Thai king: Ọ̀nà wo ní ẹ̀ṣọ́ ọba gbà di olorì láàfin?
Ṣiṣe ọna lati igboro lọ si igberiko tori kiko ere oko lọ si ọja.
Soyinka tẹsiwaju pe gbigba awọn darandaran yii laaye fun igba pipẹ ni ohun ti o fa bi iwa ipaniyan yii se waa peleke si lorilẹ-ede Naijiria bayii.
Àwọn ile itaja oúnjẹ àti òògùn nìkan ni ofin naa yọ silẹ.
Eleyii fa rogbodiyan ni agbegbe naa, ti awọn ọlọja si palẹ ọja wọn mọ fun ọjọ naa.
" Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Sotitotbire: Ilé ẹjọ́ dá Alfa Babatunde padà sí áhàmọ́ọ́ bẹ́ẹ̀ni ó tún sún ìgbẹ́jọ́ si Ọjọ́-Bo̩16 Ẹrẹ̀nà 2020 Fídíò, Sotitobire: Mọ̀lẹ́bí ọmọ ọdún kan tó pòórá ní ṣọ́ọ̀ṣì figbe ta30 Òkùdu 2020 Fídíò, Sotitobire: Ìdájọ́ òdòdò ló fẹsẹ̀ múlẹ̀ lórí ọ̀rọ̀ Pásítọ̀ Sotitobire - Agbẹjọ́rò fún ìjọba7 Ọ̀wàrà 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Lọgan lo ba bẹrẹ si nii ronu ọna mii ti wọn lee gba ṣe inawo wọn.
Alakoso egbe akorin naa ti won ko so oruko re ni ori oun wu si bi awon omo naa se se daadaa nitori pe iran Xhosa lo ni orin kiko ati inkciyo iledi ti awon akekoobinrin naa wo.
OLUWA wá láti orí òkè Sinai,ó yọ gẹ́gẹ́ bí oòrùn láti Edomu,ó ràn sórí àwọn eniyan rẹ̀ láti òkè Parani.
Dírẹ́bà wọn ń sáré gan-an ni.
ECOWAS: Aàrẹ Ghana, Nana Akufo-Addo ti di aàrẹ ẹgbẹ́ ìṣọ̀kan ilẹ̀ adúláwọ̀ tuntun
Ọmọbíbí ìlú Benin di ìlúmọ̀ọ́ká akẹ̀ṣẹ́ lágbàáyé Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fọ́nrán ohùn, Kanu ní ikọ̀ Ajax lè gba ìdíje Champions League ní sáà yìí Xhaka lo gba goolu akọkọ wọle ni iṣẹju kejila ifẹsẹwọnsẹ naa, nigba ti Aubameyang gba gbeelẹ ko gba si goli, (Penalty) wọle nigba ti ifẹsẹwọnsẹ naa wọ iṣẹju mọkandinlaadọrin.
Ọrọ naa ti di yanpanyanrin Ọrọ naa ti n fa ikanra fun awọn ọmọ Naijria lati igba ti iroyin ti kan nipa iku Linda, latari pe bi oṣu meloo kan sẹyin ni wọn ti n ke gbajare nipa iwakiwa awọn ọlọpaa ni Nigeria.
Dìde nisinsinyii, kí o jáde kúrò ní ilẹ̀ yìí, kí o sì pada sí ilẹ̀ tí wọ́n gbé bí ọ.
Oríṣun àwòrán, Bashir Ahmad Ní ọjọ́ Isẹgun nílé asofin àpapọ̀ ilẹ̀ wa fi ontẹ lu ọgbọn biliọnu dọla ($30bn) owo tí ijọba àpapọ̀ ilẹ̀ wá fẹ gba lọdọ àjọ ayanilowo lagbaye IMF.
O tun wa seleri fun awon
Èmi ń bu ọlá fún Baba mi, ṣugbọn ẹ̀yin ń bu ẹ̀tẹ́ lù mí.
“Bí ó bá jẹ́ pé láti inú agbo mààlúù ni ó ti mú un láti fi rú ẹbọ sísun, akọ mààlúù tí kò ní àbààwọ́n ni kí ó mú wá, kí ó mú un wá sí ẹnu ọ̀nà Àgọ́ Àjọ láti fi rúbọ, kí ó lè jẹ́ ìtẹ́wọ́gbà níwájú OLUWA.
Agbẹnusọ fun ileeṣẹ ọlọpaa Ogun, Abimbola Oyeyemi ṣalaye pe awọn agbofinro mu awọn oluwọde naa lẹyin ti ifẹhonuhan wọọrọwọ di afipa ṣe.
Ó bá bi wọ́n pé, “Igbagbọ yín dà?
Nítorí ìgbà tí ìjà ńlá yìí ti bẹ̀rẹ̀ ni agogo ti lù káà kiri Igbó Olódùmarè tí onírúurú àwọn abàmì ẹ̀dá ti bẹ̀rẹ̀ sí kó ara wọn jọ, wọ́n wá láti wòran.
Ẹdọfooro ni aarun Covid-19 maa n baaja.
Kí ó mú ẹbọ ìmúkúrò ẹ̀bi tọ alufaa wá, ohun ìrúbọ náà ni àgbò kan tí kò ní àbààwọ́n, kí ó rí i pé àgbò náà tó iye tí eniyan lè ra ẹran fún ẹbọ ìmúkúrò ẹ̀bi.
Nigba ti yoo fi faye silẹ lẹni ọmọ ọdun mọkandinlaadọta, orukọ Adebajo ti tan kaakiri ti o si ti lapa lagbo ere bọọlu nitori bi o ti ṣe dari ikọ ẹgbẹ agbabọọlu Stationery Stores.
Ẹnikan ni orile-ede ti a n ṣe ayẹyẹ rẹ yii, kii se eyi to yẹ wa.
Gẹgẹ bí ohùn tí alága ẹgbẹ́ náà Kola Shittu sọ nínú atẹjade kàn, o ní ìgbésẹ yí lòdì sí òfin àti pé kò tọ́ kí ilé aṣòfin daba yíyọ àwọn alága náà lópin ìgbà tí wọn kò tí ṣé iwadi tó péye.
Elédùmarè, Alágbára, ìbà Rẹ o Baba, Atóbijù!
1–6, Àwọn àkọsílẹ̀ àtijọ́ mìíràn ni a kò tíì túmọ̀; 7–14, Ìwé Ti Mọ́mọ́nì ni a túmọ̀ pẹ̀lú àṣàrò àti pẹ̀lú ìfìdímúlẹ̀ ti ẹ̀mí.
Ni kete lẹyin eyi, si la wo ile naa kanlẹ.
Afọ́jú ni àwọn aṣọ́de Israẹligbogbo wọn kò mọ nǹkankan.
Ó ní, “N kò bá ọmọ rẹ nílé.
Ọjọ kẹtalelogun oṣu keji ọdun 209 ni idibo aarẹ ati tawọn aṣofin agba waye lorilẹede Naijiria ti ti awọn gomina ati aṣojuṣofin naa si waye ni ọsẹ meji tẹle e lẹyin ti wọn sun un siwaju kuro ni ọsẹ to tẹle ti aarẹ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Christmas: Jesu ni ọjọ́ ọ̀la àti ibi ìyanu mi- Jaga Ṣugbọn ọjọ kẹtadinlogun oṣu Kẹrin ọdunn 2019 ni ile ẹjọ giga kan nilu Abuja ni ki wọn fi pampẹ ofin gbe ati awọn mii lori ọrọ owo naa.
Bẹ́ẹ̀ ni ìgbásí-ayé ọkùnrin yìí burúu tó bẹ́ẹ̀ tí ayé sú u pátápátá, ọ̀run sì bẹ̀rẹ̀ sí wù ú lọ.
Ẹ kò gbọdọ̀ ba orúkọ mímọ́ mi jẹ́, ẹ gbọdọ̀ máa bọ̀wọ̀ fún mi láàrin gbogbo eniyan Israẹli.
Sunday Igboho: Òǹyẹ̀ kankan kò lè yẹ àgbékalẹ̀ Amotekun nílẹ̀ Yorùbá
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Gani Adams: OPC ti ṣe tán láti kojú ìpèníjà ààbò ilẹ̀ Yorùbá 19 Òkùdu 2019 Oríṣun àwòrán, Gani Adams/facebook Aarẹ Ọna Kakanfo ilẹ Yoruba, to tun jẹ olori ẹgbẹ ajijagbara Oodua Peoples Congress, OPC sọ pe ẹgbẹ naa ti ṣe tan lati ṣiṣẹ pẹlu ileeṣẹ ọlọpaa lati gbogun ti ijinigbe ati awọn ipenija mii to n koju eto aabo nilẹ Yoruba.
com/0vIgQ2Tbs1Awon miiran ti o tun kopa ni:
Eyi kọ wa pé ko si ohun daradara to wu ilẹ Adulawọ lati ṣe ti a ko le ṣe.
 Ó gbajúmọ ̀ fún ipa tí ókó nínú eré  the green mile "" ( 1999 ) tí wọ ́ n sì fa orúkọ rẹ ̀ sílẹ fún àmì ẹ ̀ yẹ akádẹ ́ mì ."
Agbẹnusọ Ile Igbimọ Aṣofin Ipinlẹ Eko, Aṣofin Mudashiru Ọbasa ba ijọba Ipinlẹ Ọyọ ati awọn eniyan ipinlẹ naa kẹdun lori iku Agbẹnusọ Ile Igbimọ Aṣofin Ipinlẹ Ọyọ, Aṣofin Micheal Adeyẹmọ.
Ile-ise olopaa so pe, awon n se iwadii isele naa, ni eyi ti won so pe, o je ohun abamo.
Ikeokwu tẹsiwaju pe wọn ti gbe Duncan Mighty ṣaaju akoko yii, to si jẹwọ pe lootọ ni oun gba owo naa.
Ìkọlù Borno: Obìnrin mẹ́fà ló gbé àdò olóró ní Borno
Àwọn ọmọ Israẹli bá tún lọ gbógun ti àwọn ọmọ ogun Bẹnjamini ní ọjọ́ keji.
Ifigagbaga sise amulo eto ilana ipese ohun elo abele yoo seranwo lopolopo fun idagbasoke etooro aje lorile-ede Naijiria laarin awon orile-ede akegbe re to ku.
Iṣi bí Ṣeṣani, Ṣeṣani sì bí Ahilai.
”Opolopo orile ede lo ni ọrọ pupo bi tiwa, baka naa ni awon orile ede kan wa ti won ko ni ọrọ rara.
Iwa buruku yii ko jẹ tuntun loju awọn eniyan mọ nitori ọpọ agbalagba olukọ lade iwa ibajẹ yii ti ṣimọ lori ‘Lóòótọ́ ni ọ̀jọ̀gbọ́n fẹ́ bá mi lòpọ̀’.
Samuel Omohon to jẹ omuwẹ naa kọ lati maa wẹ ni sapẹlẹ ninu omi nla Niger Delta nigba to n dagba.
“Ọ̀gá ọmọ-ọ̀dọ̀ ọlọ́gbọ́n ẹ̀wẹ́ náà yìn ín nítorí pé ó gbọ́n.
Ọba yan àwọn òṣìṣẹ́ láti mọ gbogbo àwọn odi tí ó wó lulẹ̀, ati láti kọ́ ilé ìṣọ́ sí orí wọn.
Nigeria Police recruitment 2020: Bàyìí ni o ṣe leè di ọlọ́pàá Nàìjíríà Àwọn dókítà Eko bẹ̀rẹ̀ ìyanṣẹ́lódì lórí owó oṣù àti ètò adójútòfò fún ìtọ́jú coronavirus Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ọmọ ọdún méjìlá yìí sọ bó ṣe di téélọ̀ táwọn àgbà ń bẹ́rí fún Sugbọn awọn kan tako o pe, igbesẹ oṣelu ni, ti wọn si tun sọ pe igbesẹ naa yoo mu ki wọn o ma a fi ikanju ṣe igbẹjọ.
Gomina Kaduna, Nasiru El-Rufai ṣalaye lẹyin ipade naa pe idi ti wọn fi fọwọ osi juwe ile fun Eta ni pe o kuna lati jami lọrọ ẹjọ kan to lodi si igbimọ fidihẹ ẹgbẹ.
Ewe, ifigagbaga idije naa yoo tun waye ni gbagede Carnoustie fun igba akoko lati odun 2007, nigba ti Woods gba ife eye naa fun igba kejila.
" Bakan naa, olotu ijọba ilẹ Gẹẹsi, Theresa May ti ranṣẹ ikini ku oriire si ọmọọba Harry ati Meghan fun ti ọmọọkunrin wọn.
Ó dùn mí fun yín pé OLUWA ti bá mi jà.
 Ó maa ń dojú kọ ipele tí ó wà láàrín inú àti ìta ara pẹ ̀ lú ìpele ibí olọ ́ rá nínú awọ ara .
Ọga, lootọ ni ajọsepọ wa pẹlu yin dan mọrin lati ẹyin wa, a ko si fẹ ki ẹ maa fi oju aja inu iwe, ti ko lee se ọdẹ wo wa, ko to di pe a gbe igbesẹ to yẹ, nitori igi gogoro ma gun ni loju, ati okeere la ti n lọ ọ."
Ṣugbọn mo wí fun yín pé ẹ kò ní rí mi títí di ìgbà tí ẹ óo wí pé, ‘Alábùkún ni ẹni tí ó ń bọ̀ wá ní orúkọ Oluwa.
Aarẹ orilẹede Naijiria, Muhammadu Buhari ti fi ọwọ osi juwe ile fun adari ajọ eleto idanwo aṣekagba ti girama, NECO ati awọn mẹrin miran lori ẹsun pe wọn ṣe magomago.
Ọjọ́ ńlá OLUWA súnmọ́lé, ó súnmọ́ etílé, ó ń bọ̀ kíákíá.
Ṣọ́ọ̀ṣì tí wọ́n ti ń fi ọtí àmupara bá Ọlọ́run sọ̀rọ̀ ní kí ìjọba dẹwọ́ọ òfin títà ọtí lásìkò Covid-19 'Ọ̀rọ̀ Amotekun ti dàrú bíi ẹsẹ̀ télọ̀ ní ìpínlẹ̀ Oyo' Wo atẹ àlàkalẹ̀ ìdánwò WAEC fún ọdún 2020 tí yóò bẹ̀rẹ̀ ní August 17 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Obasanjo ṣatilẹyin fun Atiku Awọn ajagunfẹ́yinti kan ni ilẹ Yoruba ti se atilẹyin fun aarẹ orilẹ-ede yii tẹlẹ, Oloye Olusẹgun Ọbasanjọ lori bo se n se atilẹyin fun igbakeji rẹ, Atiku Abubakar lati lọ dije fun ipo aarẹ orilẹ-ede yii.
Lẹyin iwadii lẹkunrẹrẹ, mo fi n da yin loju pe a sọ abajade nkan to ṣẹlẹ ni gbangba, a o si tun wọn pe ninu ọsẹ yii.
Kayode Ajulọ tun mọ pansaga gẹgẹ bi ibaṣepọ tabi ibalopo laarin eniyan meji ti wọn kii se lọkọlaya, abi ti wọn ko ṣe igbeyawo labẹ ofin to rọ mọ igbeyawo lorilẹede Naijiria.
Ní ọdún kẹẹdọ́gbọ̀n tí wọ́n ti ṣe ìsẹ̀dálẹ̀ mi, ẹ̀ẹ́dẹ́gbẹ̀ta iwin ni wọ́n wí pé àwọn ń fẹ́ fẹ́ mi, ṣùgbọ́n mo kọ̀ fún wọn; ní ọdún kẹrìndínlọ́gbọ̀n, ẹ̀ẹ́dẹ́gbẹ̀rin ni wọn tún n fẹ́ fẹ́ mi, ṣùgbọ́n mo tún kọ̀ fún wọn.
Ero ara ilu lori owo awọn sẹnatọ Naijiria Ará ìlú fárígá, wọ́n wọ́ alàkóso ìlú nilẹ́ pẹ̀lú ọkọ̀ Àwọn olùgbé ilu Ẹdẹ lu akẹ́kọ̀ọ́ pa Kò sí súnkẹrẹ-fàkẹrẹ mọ lópópóna márosẹ̀ Eko si Ibadan Pataki ileeṣẹ agbegbe ni lati maa gbọ aroye ati ẹdun ọkan awọn eeyan agbegbe ti irufẹ aṣofin bẹẹ n ṣoju fun.
Maarati, Betanotu, ati Elitekoni, gbogbo ìlú ati ìletò wọn jẹ́ mẹfa.
Abigaili bá yára mú igba (200) burẹdi ati ìgò ọtí waini meji ati aguntan marun-un tí wọ́n ti sè ati òṣùnwọ̀n ọkà yíyan marun-un ati ọgọrun-un ìdì àjàrà gbígbẹ ati igba (200) àkàrà tí wọ́n fi èso ọ̀pọ̀tọ́ dín, ó sì dì wọ́n ru kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́.
''Irọ ni pe ọba tuntun maa n jẹ ọkan ọba to ku bii ara etutu ni ipebi,'' Oloye Elebuibon lo wi bẹẹ.
Mo dúpẹ̀ lọ́wọ́ rẹ fún orín arò tí o kọ, orin ọlọ́gbọ́ntí ó rán mi létí ẹni tí ó dá mi, bi kò bá sí orin ti iwọ kọ yìí ńkọ́, èmi ìbá jà fún odidi ọjọ́ mẹ́ta -  nítorí mo ti ja ìjà bẹ́ẹ̀ rí, mo jà ìjà oṣù mẹ́fà, mo ja ìjà oṣù mẹ́ta, mo sì ja ìjà ọdùn kan gbáko – èmi náà, ẹbọra kékeré inú ọ̀gán, orúkọ ẹni tí ń jẹ́ Èṣù-kékeré-òde.
“ ‘Nítorí náà, ẹni tí kò bá kọlà ọkàn ati ti ara ninu àwọn àlejò tí wọn ń gbé ààrin àwọn ọmọ Israẹli kò gbọdọ̀ wọ ibi mímọ́ mi.
Ṣaaju ni olubadamọran agba fun aarẹ lori ọrọ to n lọ, Femi Adesina kede loju opo Twitter rẹ pe Aarẹ Buhari ko ni ba awọn ọmọ Naijiria sọrọ lọjọ Aje.
Trump Impeachment: Ilé aṣojú-ṣòfin Amẹ́ríkà dìbò yọ Donald Trump nípò ààrẹ Wọn ti yọ Aarẹ orilẹ-ede Amẹrika, Donald Trump nipo.
Ṣé Van Dijk lè borí Ronaldo àti Messi nínú ìdíje UEFA?
Ni ọjọ diẹ sẹyin ni Davido funrarẹ gbe iroyin jade pe iyawo oun, Chioma ti ko arun Coronavirus, bakan naa si ni gomina Seyi Makinde pẹlu kede pe oun pẹlu ti ni arun naa lẹyin ọjọ diẹ to gbalejo Davido ni ile ijọba nilu Ibadan.
Ó to òkúta gbígbẹ́ dí ọ̀nà mi,ó mú kí ọ̀nà mí wọ́.
Kí ló dé tí o fi ń fi ojú pamọ́?
Eniyan 238 tun ti ni Coronavirus ni Naijiria Ajọ to n gbogun ti itankalẹ ajakalẹ aarun ni orilẹ-ede Naijiria, NCDC tun ti kede esi ayẹwo ojilerugba din meji eniyan to tun ti ni aarun Covid-19.
Ayé kórìíra wọn nítorí wọn kì í ṣe ti ayé, gẹ́gẹ́ bí èmi náà kì í ti ṣe tíí ayé.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìtàn Mánigbàgbé: Aláàfin Ọ̀rọ̀ǹpọ̀tọ̀niyùn, jagun-jagun orí ẹṣin tí kò ṣe fi ṣeré 9 Ìgbé 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 11 Agẹmo 2020 Oríṣun àwòrán, @kalonge93 Yoruba maa n sọ pe a ko ri iru eyi ri, a fi n dẹru ba ọlọrọ ni, nitori ko si ohun ti ko sẹlẹ ri.
Ajo EFCC wa je ko di mimo pe awon afurasi odaran yii yoo
" Lizzy wa yan pe lootọ ni awọn mejeeji ti bimọ fun ẹlomiran tẹlẹ saaju igbeyawo awọn, amọ ọkọ oun ko se igbeyawo pẹlu ẹnikẹni ninu awọn obinrin to bimọ fun.
Laipẹ́, ọmọ tí kò bá pé ọdún méjìdínlógún kò ní leè jáde girama l’Ọṣun Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Oko oloyun: Àwọn agbébọn pa gbajúgbajà apòògùn ìbílẹ̀, Àláájì Fàtáì ọkọ olóyún
N óo run ilẹ̀ yín, tóbẹ́ẹ̀ tí ẹnu yóo fi ya àwọn ọ̀tá yín, tí wọn yóo pada wá tẹ̀dó ninu rẹ̀.
Mo ti dàgbà t́o láti mọ ǹkan tí ìyá mi ń sọ, ṣùgbọ́n gbogbo rẹ̀ sì dàrú mọ́ mi lórí.
Awọn Iroyin ti ẹ le nifẹ si Ìtàn tó wà nídi òwe ‘Sebótimọ Ẹlẹ́wà Sàpọ́n’ Ìtàn tó rọ̀ mọ́ òwe ‘aṣọ kò bá Ọ́mọ́yẹ mọ́.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ibadan Traditional worshippers: Àwọn ẹlẹ́sìn ìbílẹ̀ ń bèèrè ọludé lọ́dọọdún fún àyájọ́ ìṣẹ̀ẹ̀ṣe 9 Owewe 2020 Oríṣun àwòrán, others Awọn ẹlẹsin ibilẹ ẹka ti ipinlẹ Oyo ṣe iwọde niluu Ibadan to jẹ olu ilu ipinlẹ Oyo ni guusu iwọ oorun Naijiria lati kepe ijọba pe ko dẹkun idẹyẹsi awọn ẹlẹsin ibilẹ.
A o ranti pe o ti to obinrin mẹrin ati ọkunrin kan, Mujeeb Tirimisiyu, Barakat Bello, Grace Oshiagwu, Azeezat Shomuyiwa ati Olusayo Fagbemi, ti wọn ti pa ni Akinyele naa.
Lai sọ̀rọ̀ pupọ, mo fẹ kẹ wa wọ bata ti mo bọ silẹ wo, ẹ ki ẹsẹ bọ wo, kẹ le mọ bo ṣe ri ati bo ṣe n ta mi lẹsẹ si, kẹ to maa da mi lẹjọ.
Lodun  2016,ni ajo orile ede Afrika  bere lati maa lo iwe irinna kan naa  lorile ede Afirika, ki  won  jẹ
Lati ọdun 1972 titi di igba to jẹ alaisi, lo ti jẹ oye toto mẹtadinnigba lati ilu mejildinlaadọrin yika Naijiria.
Ìdí tí a fi pa àwọn àgbẹ̀ onírẹ̀sì ní Borno, Boko Haram ṣàlàyé nínú fídíò tuntun Èèyàn 281 ló kó covid-19 lọ́jọ́ Ìṣẹ́gun, 123 wá láti ìpínlẹ̀ Eko nìkan Wọ́n ti rẹ ipò ọ̀gágun Olusegun Adeniyi sílẹ̀ lẹ́yìn tó jẹ̀bi títú àṣírí kùdiẹ-kudiẹ iléeṣẹ́ ológun lórí ayélujára Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Ọkọ mi wa ọkọ̀ tẹ Poly Bag"" lásán, àfi gbùùàà!"
Bisi ni eeyan to le ni ẹgbẹrun mẹfa ati ẹẹdẹgbẹta ni wọn farapa ninu awọn ijamba ọkọ to waye naa.
Nígbà tí bàbá mi ti rí ẹ̀hìn ẹbọra náà tán, gbogbo àwọn ará Igbo Olódùmarè pa èrò pé kí wọ́n mú un lọ sí ọ̀dọ̀ oba wọn: wéré, wọ́n ti bọ́ ẹ̀wù ọdẹ kúrò ní ọrùn bàbá mi wọ́n sì gbé ẹ̀wù agbádá àrán ńlá kan bọ̀ ọ́ lọ́rùn, wọ́n fún un ní ṣòkòtò àrán, wọ́n sì dé e ní fìlà àràn tí ó rí gòǹgò bí adé tí wọ́n fi góòlù ṣe ọ̀ṣọ́ sí lára tí ó ń dán yinrinyinrin, bàtá idẹ  ni wọ́n fi bọ̀ ọ́ ní ẹsẹ̀, òrùka góòlù win wọ́n fi sí i ní ọwọ́, ẹ̀wọ̀n góòlù ni wọ́n fi bọ̀ ọ́ ní ọrùn.
Àbòsí ló fa ìjà láàrin èmi àti Ajimobi kìí ṣe ọ̀rọ̀ NYSC -Shittu Owó bọ̀ọ̀lì ni mo fi rán ọmọ mi mẹ́rin jáde ilé ìwé gíga -Grace Ọmọ ọdún méjìlá ni mo ti ń ṣe bàálù, ọkọ̀, ilé àti ọkọ̀ ojú omi - Ọdọ́mọdé ‘Engineer’ Omijé bọ lójú mí nígbà tí wọn n kọ orin ilẹ̀ wà Bakan naa ni Àrà ti orukọ rẹ n jẹ Aralọla Olamuyiwa lapeja sọrọ lori ọmọbinrin mii to n lu ilu bii tirẹ.
Ọdọmọkunrin kan tí ó jẹ́ pé aṣọ funfun nìkan ni ó dà bo ara ń tẹ̀lé e.
9th Assembly: Saraki kí àwọn adarí aṣòfin tuntun kú oríire
Ilé Ifẹ̀ jẹ́ ilú pàtàki ni ilẹ̀ Yorùbá nitori itàn sọ wi pé ibẹ̀ ni orisun Yorùbá pẹ̀lú Bàbá nla Yorùbá “Oduduwa” ti ó tẹ ibẹ̀ dó.
Coronavirus: Èyí ni ipa tí àdínkù owó epo bẹtiró yóò mú bá ọ̀rọ̀ ajé Nàìjíríà Oríṣun àwòrán, Getty Images Aarẹ orilẹ-ede Naijiria, Muhammadu Buhari ti buwọlu u pe ki adinku ba owo epo bẹtiro nitori bi owo eporọọbi ṣe ja walẹ l'agbaye.
Oloogbe Adedoyin fayesile lomoodun mẹ́rìnlélógójì, O ti figba kan je minisita to n mojuto oro ilera ni eka ipinle, bee si ni O tun je igbakeji alaga igbimo to n mojuto oro awon omo ogun ki o to doloogbe.
Agbẹjọ́rò tí kò ní apa méjì Mo leè di ààrẹ láì lọ sí Amẹ́ríkà - Àtíkù Ẹ múra fún ogun ijọba àpapọ̀ - Ọbásanjọ́ Ṣùgbọ́n ilé ẹjọ́ fi àwọn ìfìwéránṣẹ́ rẹ̀ pẹlú àwọn òṣìṣẹ́ ilé ẹjọ́ méjì sọ̀rọ̀ déédé lórí ète yìí.
Bí a bá rí ọmọ tó ń hùwà ìpáǹle nínú ẹbí, àwọn mọ̀lẹ́bí á máa kìlọ̀ fún un kí ó má ba orúkọ ẹbí wọn jẹ́.
PDP ni bi awọn ṣe jawe olubori naa ni ipinlẹ Edo fun awọn ni agbara lati ṣiṣẹ takuntakun, ki awọn le jawe olubori ninu idibo ti yoo waye ni ipinlẹ Ondo ni oṣu to n bọ.
Oríṣun àwòrán, Twitter/@NGRPRESIDENT Ibeere ti ọpọ n beere ni pe ṣe lootọ ni Adajọ Agba Naijiria, Tanko Muhammad ti ni aarun Covid-19?
osisẹ Ajọ INEC ti wọn n ṣabẹwo si awọn agbegbe idibo lati mọ bo se n lọ.
nítorí pé gbogbo ìdámẹ́wàá tí àwọn ọmọ Israẹli mú wá fún mi ni mo ti fún wọn gẹ́gẹ́ bí ìní.
Bákan náà ni ọ̀rọ̀ ẹnu ibode Naijiria jẹ ẹlòmiran lógun bi wọ́n ṣe n bẹ ààrẹ kí o maa ṣi ẹnu ibode mọ rárá.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù APC sí Atiku: Kò tọ́ sí Atiku láti du ìpò nítorí ọmọ Cameroon ni 13 Ìgbé 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Aarẹ Buhari ati Atiku Abubakar Oludije lẹgbẹ oselu PDP ninu idibo si ipo aarẹ to kọja, Atiku Abubakar ti ni ọmọ Naijiria lọọtọ ni oun, ati wi pe ọrọ ẹgbẹ oselu APC ko ja mọ nkankan.
Agbẹnusọ ileeṣẹ ọlọpaa nipinlẹ Ondo naa fikun pe awọn ti wọn fi panpẹ ọba mu naa kii ṣe awọn afẹhọnuhan EndSars, amọ awọn janduku ni.
Síbẹ̀síbẹ̀ n ó sọ díẹ̀ nínú ìbéèrè wọn.
Aare orile ede Naijiria,ti gbosuba fun aare ana omowe Goodluck Jonathan , lati gba alaafia laaye lasiko ti o padanu ipo aare lasiko eto idibo to waye lọdun 2015, aare ni Jonathan je oloselu rere.
Ẹ ṣeun, mò ń bọ̀ ná.
Obasa lo yọju niwaju igbimọ oluwadii naa lọjọ Abamẹta, lati dahun awọn ẹsun ajẹbanu ti wọn fi kan an ninu iroyin ori ayelujara kan.
Opopona mọrosẹ agbegbe Iwo Road ni ilu Ibadan ti kun fọfọ fun ọgọrọ awọn ọdọ to n wọde tako ọlọpaa SARS.
Apá kan òkè náà yóo lọ ìhà àríwá, apá keji yóo sì lọ sí ìhà gúsù.
Ninu ọrọ rẹ si awọn ọmọ ile iwe ọhun, Buhari ni ki wọn mu ẹkọ imọ ẹrọ lọkunkundun nitori ẹni to ba ni imọ ẹrọ ni yoo ni anfaani lati ri iṣẹ lọjọ iwaju.
Kano, Rasheed Segun Adegoke ni ile-eko naa  ti se orisirisi idanilekoo  fun awon osise won lati lee ni imọ tuntun nipa
'Buhari ló lè sọ ìgbà tó máa yan minisita míì' 'Ó ku Shittu, ó ku Ọlọ́run lórí ohun tó fẹ́ fi san ẹgbẹ́ APC l'ẹ́san' Àwọn Asòfin Naijiria yarí lórí ètò ìsúná 2019 'Ìwà ìdòjútì láwọn olólùfẹ́ Chelsea hù' Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Mo ti gba kádàrá lórí bí Ọlọrun ṣe dá mi' Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
"Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Bí ẹ ṣe mọ̀wé tó, ẹ wá dánrawò níbí pẹ̀lú ""Àpólà Ọ̀rọ̀ Orúkọ - Noun Phrase Ènìyàn 321 ló tún forí kó ààrùn Covid -19 ní Nàìjíríà lọ́jọ́ Ajé Adigunjalè pa oníbàárà báńki tó ṣẹ̀ṣẹ̀ gba owó n'Ibadan Èkúté gbà ìjọba ilé ìwòsan, Mínísítà ìlera fárígá, ó ní k'àwọn alákóso wà jẹ́jọ́ Irú ẹ̀dá wo ni Ọjọgbọn Folasade Ogunsola jẹ́?"
Oríṣun àwòrán, iyaboojofespris Àkọlé àwòrán, Wẹjẹwẹmu ko gbẹyin nibi ayẹyẹ iṣile naa.
O ni gbogbo awọn ọja nla ati ọja igbalode ni yoo di titi pa, yatọ si awọn ibi ti wọn ti n ta ogun ati ounjẹ.
Mo fún wọn ní gbogbo ẹbọ sísun tí àwọn ọmọ Israẹli bá rú sí mi.
1 Èbibi 2019 Ọjọ kẹjọ, oṣu Karun un ni eto idibo yoo waye l'orilẹede South Africa, ti alafo to wa laarin awọn olowo ati otoṣi si jẹ ọ̀rọ̀ gboogi.
Àti pé kò tọ́ fún ẹnikẹ́ni láti maa sọ pé àwọn ọmọ ogun tó pọ̀ tó bẹ̀ẹ̀ ni àwọn pàdánù.
Amofin naa rọ awọn aṣofin ati awọn alaṣẹ ijọba lati ṣe ayẹwo iwe ofin Naijiria papaa julọ ẹka to nii ṣe pẹlu eto aabo.
Ìyaa folúké, ọ̀kan nínú àwọn ìyàwó wọ̀nyí, ni ìríjú àkándé, Orímóògùnjẹ, ìyẹn ni pé òun ni ó fẹ́ran jù.
Ọdun 1960 tii ṣe aadọta ọdun sẹyin, ni Ọba Sikiru Adetọna gun ori itẹ; ọmọ ọdun marundinlọgbọn si ni nigba naa, to gun ori itẹ.
Ọpọlọpọ nǹkan ni yóo ṣòfò: ẹrù inú ọkọ̀, ati ọkọ̀ fúnrarẹ̀.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Madrid-Bayern, Arsenal-Athletico yóò wàákò Kíkojú sísálo àwọn eléré ìdárayá Àwòrán ìrántí ní ìdíje Madrid, Juventus Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 3 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 5 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Bẹni wọn kò lo ìgò oúnjẹ lati fún ọmọ tuntun ni oúnjẹ.
Ẹgbé agbábóólù orílẹ-èdè Naìjíríà gba ẹbuǹ wúrà ilẹ Afrika Van Dijk gbadé UEFA mọ́ Messi àti Ronaldo lọ́wọ́ Liverpool kun Arsenal wẹ́lẹ́wẹ́lẹ́ bí ẹran àsun 'lójúbọ' Anfield Ikú dóró!
Democratic Party, PDP, Alhaji Atiku Abubakar ti ni ohun yoo satunse to monya
Nítorí náà, ẹ má fi àwọn ọmọbinrin yín fún àwọn ọmọkunrin wọn, bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò gbọdọ̀ fẹ́ àwọn ọmọbinrin wọn fún àwọn ọmọkunrin yín.
Oríṣun àwòrán, Instagram/kwam1_official Lara awọn oye naa ni Badabarawu ilu Ogijo - 1985 Ekerin Amuludun ilẹ Ibadan - 1986 Golden Mercury of Africa Title - 1986 Oluomo ti ilu Eko - 1999 Oluaye Fuji Music ni NTA Ibadan - 1993.
Awọn alabaṣiṣẹ pọ aarẹ ti sọ fun un pe ko fi oju miran wo ọrọ Coronavirus nitori awon to ni aarun naa n peleke sii ni nilẹ Amẹrika.
Bí Paulu ti fẹ́ lanu láti fèsì, Galio sọ fún àwọn Juu pé, “Ẹ̀yin Juu, bí ó bá jẹ́ ẹ̀ṣẹ̀ kan tabi ọ̀ràn burúkú kan ni ẹ mú wá, ǹ bá gbọ́ ohun tí ẹ ní sọ; 
Ṣeṣani fi ọmọ rẹ̀ obinrin fún Jariha, ẹrú rẹ̀, ó sì bí Atai fún ẹrú náà.
Nítorí náà, mo bẹ̀ ọ́ tọ́kàntọ́kàn, bá mi wí fún Ọlọ́run Ọba pé kí ó fi ìlú mìíràn fún mi kí wọ́n sì kéde fún àwọn ọmọ ènìyàn pé ìlú burúkú yìí kì í ṣe tèmi mọ́, àti pé ìbòmíràn ní a gbé bí mi.
Alakoso eto irorin fun ileeṣẹ ologun, Ọgagun John Enenche ati oludari ẹka ọgbọ tẹlẹ nileeṣẹ ologun, Ọgagunfẹyinti Ahmed Jibrin lo ṣe ẹkunrẹrẹ alaye bi wọn ṣe ṣe e lọjọ Abamẹta lori eto oroorọ ileeṣẹ amohunmaworan Nigerian Television Authority, NTA.
Ó ká gbogbo eniyan lọ́wọ́ iṣẹ́ kò,kí wọ́n lè mọ iṣẹ́ rẹ̀.
ati iwa aparo kan, ko ga ju okan lọ(Federal Character and Gender Commission).
O ni ko si ẹsin yala ẹsin ibilẹ, musulumi tabi kristẹni to fọwọ si ki wọn maa fi eeyan ṣe irubọ.
Iroyin ni iṣẹlẹ yii yọri rogbodiyan to pọ to bẹ, ti awọn kan bẹrẹ si n yinbọn.
" Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Kìí ṣe torí gbígba àmì ẹ̀yẹ ni ọmọ wa ṣe kú, a dúpẹ́ lọ́wọ́ ìjọba tẹ rántí rẹ̀ - Ẹbí Adadevoh Ibà Lassa wọ ìpínlẹ̀ Èkó!
Mamure ati àwọn arakunrin rẹ̀ Eṣikolu ati Aneri bá Abramu dá majẹmu.
Báyìí ni Egúngún àti Orò ṣe jọ bí Ẹ̀ṣà Egúngún nílẹ̀ Yorùba Àjákálẹ̀ àrùn tuntun tí ayé ń sọtẹ́lẹ̀ nípa rẹ̀ rèé.
Gẹgẹ bii orilẹede to sẹsẹ seto ididbo tan lawọn ipinlẹ ati nijọba apapọ, ko si idi kankan fun awọn eeyan kan tabi ẹgbẹ kankan lati wa ọna ti wọn yoo fi se ayipada ijọba to wa lode.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: N kò lọ́wọ́ nínú ìpànìyàn, kò dáa bí wọn ṣe lo ọta ìbọn ní Lekki - Tinubu Ọjọ́ Ìsẹ́gun di ọjọ́ ìbànújẹ́ fún ọ̀pọ̀ ìdílé ní Nàíjíríà torí òkú tó ṣùn Ọ̀dọ́ 30 ń gba ìtọ́jú lọ́wọ́ nílé ìwòsàn torí ọ̀gbẹ́ ìbọn ní Lekki - Sanwo-Olu ṣàlàyé Àwọn ṣọ́jà ṣíná ìbọn bolẹ̀ ni Lekki Tollgate Àwọn ọlọ́dẹ darapọ̀ mọ́ ìwọ́de #EndSARS l'Osogbo, wọ́n ní kò sáyè fún jàǹdùkú mọ́ Kíní ìtumọ̀ ''Sọ̀rọ̀ Sókè'' tí àwọn afẹ̀họ́núhàn EndSars ń lò káàkiri Ìpínlẹ̀ Ogun náà ti ilé ìwé títí dí ọjọ́ Ajé tó m bọ̀, kò ní sí lílọ bíbọ̀ ọ̀kádà fún wákàtí 24 O wa fọwọ gbaya pe kó si eeyan kankan to ku ninu ikọlu ologun Naijiria s'awọn oluwọde ENDSARS ni Lekki lọjọ Isẹgun.
Oríṣun àwòrán, Instagram/kwam1-official O ṣiṣẹ pẹlu ẹgbẹ akọrin Barrister, Supreme Fuji Commander, laarin ọdun 1975 si 1978.
Ìjàmbá iná pa èèyàn 23, tó fi mọ ọmọ iléèwé àlákọ́bẹ̀rẹ̀ ní Lokoja-Abuja Wo nkan tó yẹ kí o mọ̀ nípa ààrùn SC tí Laycon BBNaija sọ pé òun ní.
 nínú ètò mọ ̀ lẹ ́ bí lati rí baálé , ìyáálé ilé , Ọkùnrin ilé , obìnrin ilé , Ọbàkan , iyèkan , Ẹrúbílé àti Àràbátan .
Babaláwo rèé pẹ̀lú afurasí adigunjalè mẹ́rin láhàmọ́ọ́ ọlọ́pàá Agolo gáásì kéeké tó ń jò bú gbàmù l‘Eko, ẹ̀mí kan bọ́, mẹ́ta fara pa Ìyá òòṣà fẹ̀sùn àjẹ́ kan ìyá ẹni ọdún 90, aráàlú bá sọ ọ́ lókò pa Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Olusegun Obasanjo: Ọmú ìyá mi ti mo fi ń mùkọ ni kekere ló jẹ ki ń lókun Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Oríṣun àwòrán, Twitter O fikun wi pe, NJC lo ma a fi lẹta ransẹ si ile ẹjọ to n gbọ ẹjọ iwa ibajẹ,Code of Conduct Tribunal lati le se iwadii ẹsun ti wọn fi kan an.
 bákan nán , ní ìbẹ ̀ rẹ ̀ pẹ ̀ pẹ ̀ ọdún 1922 pinnock ríi dájú wípé ibùgbé olórí ilé ẹ ̀ kọ ́ náà di kíkọ , tí ó sì tún jẹ ́ ilé àwọn ajíyìnrere tí abeokuta ; yàrá ìkàwé márún , ilé ìjọsìn àti yàrá fún àwọn ọkùnrin .
'Àwa Emèrè Onítẹ̀síwájú la ṣèpàdé nílé Elebuibon, kìí ṣe Oṣó àti Àjẹ́' Oríṣun àwòrán, others Alaye ni ẹkunrẹrẹ ti n waye lori ipade kan to waye laipẹ yii nile Oloye Ifayemi Elebuibọn ninu eyi ti wọn ni awọn Oso ati Ajẹ peju si.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Kloe: Èmi kìí mu òògùn olóró, àmọ́ mo fẹ́ràn láti máa wà lẹ́bà omi Bawo lo ṣe le dibo ninu ti eto BB Naija 2020?
Ó ṣe àwọn kinní kan bí òdòdó alimọndi mẹta mẹta sórí ọ̀kọ̀ọ̀kan ninu àwọn ẹ̀ka mẹfẹẹfa tí ó yọ lára ọ̀pá fìtílà náà.
Ni ile ẹgbọn rẹ obinrin ni awọn ọlọpaa ti lọ gbe e, ẹgbọn rẹ si ni awọn ọlọpaa o tilẹ fi to agbẹjọro rẹ tabi mọlẹbi r leti ki wọn to tun ti i lọ si ipinlẹ Eko.
Ẹwẹ, gẹgẹ bi ikọ apapọ awọn oṣiṣẹ alaabo ipinlẹ Ọyọ iyẹn Operation Burst ṣe sọ ọ, wn ti gba eeyan marun mu ti wọn lọwọ ninu iṣẹlẹ naa ti wọn si ni ijọba atawọn oṣiṣẹ alaabo to ku ti da si i.
Nínú àtẹjáde kan ti agbẹnusọ rẹ̀ Simeon Nwakaudu fí síta sàlàyé pé Gómìnà Ganduje ń sọ̀rọ̀ sàkàṣàkà nípa ìpínlẹ̀ Rivers.
Ṣugbọn a óo ka àwọn ilé tí wọ́n wà ní àwọn ìlú tí kò ní odi pọ̀ mọ́ ilẹ̀ tí wọ́n kọ́ wọn lé lórí.
Brazil vs Nigeria: Ọ̀mì aláyò kọ̀ọ̀kan lakitiyan Super Eagles pẹ̀lú Brazil jásí
Èdè Akurẹ àti Ibadan ni wọ́n fi fà mí léti pé ẹni re kìí 'se òṣèlú - Seyi Makinde ‘Pussypedia’ rèé, ojú òpó tó ń mú àdínkù bá ìṣòro ìmọ̀ nípa ẹ̀yà ara obìnrin Ìkúnlẹ̀ àbiyamọ o!
 bákan náà ni ó tún bí àwọ ̀ n àbúrò mẹ ́ ri lẹ ́ yìn rẹ ̀ , àmọ ́ tí ọ ̀ kan nínú wọn jọ babátúndé tìwà tìṣe , ẹni tí orúkọ rẹ ̀ ń jẹ ́ isaac babátúndé akínyẹlé tí gbogbo wọn sì jẹ ́ ọ ̀ mọ ̀ wé , ẹlẹ ́ sìn àti òṣèlú pàtàkì ní ìlú Ìbàdàn ṣe ibùgbé láti ọ ̀ rùndún kọkàndínlógún .
Femi Fani Kayode ni bi o tilẹ jẹ pe Asiwaju ti gbekele ara rẹ wi pe oun ko le e ṣi ṣe, ọrọ yii ti ba ẹyin yọ pẹlu bu Aarẹ Buhari ṣe pada lẹyin rẹ, ti wọn si ri pe ko ni ipo kankan mọ ninu ẹgbẹ oṣelu APC.
Abramu jẹ́ ẹni ọdún mẹrindinlaadọrun nígbà tí Hagari bí Iṣimaeli fún un.
Lẹyin awuyewuye yii ni ajọ DSS da diẹ lara awọn oṣiṣẹ eleto aabo Saraki ati Dogara pada fun wọn, lẹyin ipade kan to da lori eto aabo ti Igbakeji Aarẹ, Yemi Ọsinbajo ṣe pẹlu awọn mejeeji.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ofin wa fun awọn akọsiakọ to ba fẹ fi ẹjẹ silẹ Awọn igbesẹ to léwu"" Igbe aye ẹda kun fun ewu ninu eyi to le ma jẹ ki o rọrun fun eeyan lati fi ẹjẹ silẹ ni asiko kan."
Ẹsa ninu aworan Afrika: 9-15, ose kẹta ọdun 2018
Ṣugbọn nígbà tí ẹ rí i pé Nahaṣi, ọba Amoni fẹ́ gbé ogun tì yín, ẹ kọ OLUWA lọ́ba, ẹ wí fún mi pé, ẹ fẹ́ ọba tí yóo jẹ́ alákòóso yín.
Mercy sọ pe oun n duro de asiko ti wiwọ aṣọ ọlọpaa ninu ere tiata yoo jẹ nkan iwuri fun oun.
 idibo abẹle egbe APC ni ipinle Zamfara ,je
Ó béèrè bí ẹnìkan wá bá a lẹ́hùn-ún, ó dáhùn, o ní ọ̀rẹ́ òun ọkùnrin wá báa òun, kò dárúkọ ọ̀rẹ́ rẹ̀ náà.
n óo fà yín tu kúrò lórí ilẹ̀ tí mo fun yín bí ẹni fa igi tu.
Irọ́ ni pé wọ́n hú òkú Kolawole Gold lórí pẹpẹ ìjọ ọkọ mi- Bisola aya Sotitobire Ẹ wo èrò bìbà níbi ìwọ́de #EndSARS ní ìlú Ibadan Wo bí àwọn jàndùkú ṣe yabò àwọn olùwọ́de #ENDSARS ní Alausa l'Eko àti Abuja Èèyàn 179 ló tún ṣẹ̀ṣẹ̀ ní àrùn Coronavirus ní Nàìjíríà Wo ìdí tí Tẹni, ọ̀dọ́mọdé olórin obìnrin kìí fi ń ṣí ìhòhò rẹ silẹ̀ Rògbòdìyàn bẹ́ sílẹ̀ l'Ogbomọṣọ, àwọn ọ̀dọ́ kọlu ààfin Ṣọun Lọdun 2019 ni iṣẹlẹ ọhun ṣẹlẹ nigba ti James Mallett to n gbe ni Kingswood yaso nibi to joko si lẹyin ọkọ pẹlu awọn eeyan mẹta mii niga ti wọn n lọ si ile ijo lalẹ.
Ó jẹ́ àṣà àwọn ọmọdé wọ̀nyí- Dáúdà, Sàká àti Kúnlé, láti máa lọ ran bàbá wọn lọ́wọ́ nínú oko lẹ́hìn tí wọ́n bá ti ilé ẹ̀kọ́ dé.
Awọn ẹkọ ti itan Adegbọrọ kọ wa: Itan Adegbọrọ kọ wa lati maa ni iforiti O kọ wa lati maa tẹpamọsẹ A kọ ọgbọn lati maa ni ajẹsẹku, ka si mase maa fi ọwọ mẹwẹẹwa jẹun O tun n ran wa leti pe ka mase gbagbe ile ta ba wa ni ajo Itan naa tun kọ wa pe ipokipo ta ba wa, ka maa wọna bii a se ni igbega kuro nibẹ.
Awọn kan n gboriyin fun aya aarẹ pé akin obinrin to n soju abẹ niko ni.
Ó ni ẹgbẹ́ alátakò náà ló dúró fún oko ẹrú tí ará ìlú kò gbódọ̀ padà sí Oludije náà ní òun yòó yanjú ọ̀rọ̀ ojú gọ́tà àtí ojú àgbàrá tó ti bàjẹ́ Sanwo-Olu ní òun ti ṣe ìwádìí àwọn oríkò àádọ́tà tó ń fa súnkẹrẹ-gbákẹrẹ ọkọ̀ nilú Eko.
Senator Ishaku Abbo: ìdí rèé tí mò fi fi kọ̀wé fi PDP sílẹ̀ darapọ̀ mọ́ ẹgbẹ́ òṣèlú APC
O tẹsiwaju pe titi di asiko ti iroyin yii jade, wọn ko i tii mọ orisun iku rẹ.
Ní Ẹnubodè Orísun, wọ́n gòkè lọ tààrà sí ibi àtẹ̀gùn ìlú Dafidi, ní igun odi ìlú, ní òkè ààfin Dafidi, títí lọ dé Ẹnubodè Omi ní apá ìlà oòrùn ìlú.
Ọkùnrin kan dèrò àtìmọ́lé lórí ẹ̀sùn fífi ipá bá ọmọ bíbí inú rẹ̀ méjì lòpọ̀ Ọwọ́ ọlọ́pàá tẹ ọkùnrin mẹ́rin pẹ̀lú orí èèyàn ní ìlú Akure Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 3 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 5 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Ọ̀jọ̀gbọ́n Olusegun Osoba, to wà lara àwọn tó se àpérò lórí ìwé ìlànà àti òfin Naijiria ní ọdún 1976 tun ni ‘Irọ patapata ni atunto Naijria, awọn ti wọn beere fun ko ni otitọ, wọn fẹ dari ohun alumọni orilẹede Naijiria ni.
Akọnimọọgba agba iko agbaboolu Chelsea, Maurizio Sarri ti je ki Eden Hazard mo pe oun ko da duro, ti o ba pinnu lati fe maa lo.
Aarẹ Muhammadu Buhari sọwipe ọmọogun ori ilẹ ati ti ofurufu ni awọn yoo lọ lati sawari awọn ọmọ Daphchi ti wọn ji gbe naa.
Èmi kii pá aago ìbánisọ̀rọ̀ mi, igbakuugba táwọn aráàlú bá sì pé mi, ní wọn máa ń rí mi bá sọ̀rọ̀, mo sì leè fọwọ́ gbaya pé, kò sí aráàlú Iwo tí kò ní nọ́mbà ẹ̀rọ ibaraẹnisọrọ mi lọ́wọ́Bákan ni Ọba Akanbi ni ìjọba nìkan kò leè dá gbé ẹrù ìpèsè oúnjẹ fún aráàlú, kódà, ìjọba Ìpínlẹ̀ Osun kò leè dá gbé ẹrù oúnjẹ fún àwọn èèyàn ìlú Iwo nìkan, nitori naa, o yẹ ki aráàlú dìde lásìkò yìí, láti ran ìjọba lọ́wọ́.
Ẹgbẹ ASUP ni iwọde awọn wa lati fi ẹhonu han lori ainaani itọju oṣiṣẹ ti awọn alaṣẹ gbe wọ bi ẹwu.
Tukumbo Adesonya oludije lati ile-ise akoroyin News Agency of Nigeria NAN gba ife-eye ifigagbaga ti iko okunrin ninu idije naa, leyin ti o fagbahan Henry Onosanya ondije lati ile-ise akoroyin information,Sangotola Tobi okan lara oludije meta ti o lo soju fun ile-ise akoroyin Voice of Nigeria, sugbon o padanu nipele keta si asekagba idije ohun.
”Ó dáhùn pé, “OLUWA lè fún ọ ní ohun tí ó jù bẹ́ẹ̀ lọ.
Sugbọn ko ti i figba kankan da wọn lohun.
Wọ́n tẹ àádọ́ta olùdárò pa níbi ìsìnkú Qasem Soleimani tí kò wáyé mọ́ Àbọ̀ ìpàdé bòńkẹ́lẹ́ láàrin Tinubu àti Buhari rèé Ẹ́ gba fóónù, ẹ pe ẹbí yín pé a fẹ́ dáná ṣun yín - Aráàlú sọ fún adigunjalè méji Pásítọ̀ pe Naira Marley ní ẹlẹ́mìí èṣù, Marley fèsì padà pé kí pásítọ̀ gan tẹ èṣù mọ́lẹ̀ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Alapinni Oosa ṣàdúrà fún gogbo ọmọ kúoótù, oò jíire bí?
Arabinrin Rofiat Ọladepo ati Abdullahi Oladepo ti wọn jẹ iyawo ati ọmọ akọwe agba ileewe girama Ẹdẹ Muslim Grammar School ni ilu Ẹdẹ, ipinlẹ Ọṣun ti gbe ileeṣẹ ọlọpaa orilẹede Naijiria lọ si ile ẹjọ lori ẹsun fifi ipa gbe ni si atimọle lọna aitọ.
O ni o ṣeeṣe ko jẹ ẹhonu lori awọn ẹtọ to yẹ ati bi awọn kan ko ṣe ni anfani ati dije fun ijoko ile naa ni ibo ọdun 2019 wa lara ohun ti o n fa ikunsinu wọn.
Onírúurú ọ̀nà ni a sì gbà ti a fi ń jagun náà lọ.
Ṣaaju ni ẹgbẹ kan t'oun naa n jijagbara nilẹ Yoruba, Ẹgbẹ Agbẹkọya sọ fun BBC pe 'oogun abẹnugọngọ ni na abayọ si ọrọ awọn ajinigbe.
Ohun ti i tan leegun ọdun, ọmọ alagbaa a kọri sokò.
O tun ṣe alakoso ọdọ-ọdọ fun Dubai FA ti o dẹ tun sisẹ ni awọn orisirisi ipo fun ọmọ ẹgbẹ Hammarby laarin 1993 ati 2001.
Lara awọn isẹlẹ arimaleelọ to waye nibi ọdun naa ni, asọ alaranbara ati asọ funfun ti awọn olujọsin Ọsun wọ, awọn alageere lọkunrin lobirin tiwọn n fi ijo da awọn eniyan laraya ati ọpọlọpọ awọn ọdọmọkunrin ti wọn mu pankẹrẹ lọwọ ti wọn si n na ara wọn.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Sogidi Lake: Kòṣẹja-kòṣèèyàn lá bá nínú adágún odò náà -Ojedele Bisi Kareem ṣalaye pe ko si otitọ kan ninu iroyin to n tan kalẹ pe ajọ FRSC yan Saraki ṣọju ni.
Ẹlẹ́dàá ò ní jẹ́ kí àgbà àti ọ̀jọ̀gbọ́n ó tán nílùú o.
Bẹẹ ni awọn ti ko ri ọkọ oju omi sọ awọn ẹru inu ile wọn di ọkọ oju omi.
òṣèré àti ọ̀jọ̀gbọ́n Tiatia, Ayo Akinwale jáde láyé Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ìtàn ọ̀rẹ́ tó fi ògùn gba ọkọ ọ̀rẹ́ rẹ̀ ni Akomolede BBC Yorùbá fẹ́ kọ́ wa lònìí Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Buns ni ọmọ mi jẹ tán ní ṣọ́ọ̀ṣì, ló bá di àwátì' Ó mà ṣe o!
Ikọ Belgium ti wọn jẹ ẹgbẹ agbabọọlu to gbayo s'awọn julọ ninu idije naa ti ni ami ayo mẹrinla ninu ifẹsẹwọnsẹ marun-un ti wọn ti gba.
Iroyin naa ni lara awọn ikọ agbofinro to wa nikalẹ la ti ri awọn ọlọpaa, osisẹ ọtẹlẹmuyẹ DSS, awọn ologun, ati osisẹ aabo ara ẹni laabo ilu ( Civil Defence).
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Irú ẹ̀dá wo ni Lamidi Adeyemi?
Elija dáhùn pé, “Mò ń jowú nítorí ìwọ OLUWA, Ọlọrun àwọn ọmọ ogun nítorí pé àwọn ọmọ Israẹli ti kọ majẹmu rẹ tì, wọ́n ti wó pẹpẹ rẹ lulẹ̀, wọ́n sì ti fi idà pa àwọn wolii rẹ.
Labani pe Jakọbu, ó ní, “Èéṣe tí o fi ṣe báyìí?
O ni fún idi eyi, Saraki ni ọga agba patapata lẹyin alaga gbogboogbo ẹgbẹ naa.
" Oladoye ni ibi ti isẹlẹ naa ti waye ko to kilomita meji si ibi tawọn sọja duro si, ti wọn ko si yọju rara sibi isẹlẹ naa.
ipinle  ti egbe oselu APC ko maa dari, ni
Gege bi oro Ashade naa pe, awon eka ile-ise ijoba ati ti awon aladani gbodo fowosowopo lati mi idagbasoke ba orile-ede Nigeria ni abala awon ohun amayederun.
Ó fún Ẹsita ati àwọn iranṣẹbinrin rẹ̀ ní ibi tí ó dára jùlọ ní ibi tí àwọn ayaba ń gbé.
“Ṣugbọn bí kò bá ní agbára láti mú àdàbà meji tabi ọmọ ẹyẹlé meji wá, ohun tí yóo mú wá fún ẹbọ ẹ̀ṣẹ̀ tí ó dá ni, ìdámẹ́wàá ìwọ̀n efa ìyẹ̀fun tí ó kúnná dáradára, kí ó má fi òróró tabi turari olóòórùn dídùn sórí rẹ̀, nítorí ẹbọ ìmúkúrò ẹ̀ṣẹ̀ ni.
“A ti mo pe, ipinle Gombe lo n sepese owu ti o dara ti o si tun pojulo lorile-ede yii.
Koda, o le se iku pa ẹni tó bá n mu Siga amupara.
9 Nítorí, kíyèsíi, èmi yíò bùkún fún àwọn wọ̃nnì tí wọ́n ṣiṣẹ́ nínú ọgbà ajarà mi pẹ̀lú ìbùkún nlá, wọn yíò sì gbàgbọ́ nínú àwọn ọ̀rọ̀ rẹ̀, èyítí a fi fún òun nípasẹ̀ èmi lati ọwọ́ Olùtùnú, èyítí ó sọ ọ di mímọ̀ pé àwọn ẹlẹ́ṣẹ̀ ni wọ́n kan Jésù mọ́ àgbélèbú fún àwọn ẹ̀ṣẹ̀ arayé, bẹ́ẹ̀ni, fún ìmúkúrò àwọn ẹ̀ṣẹ̀ sí ìròbìnújẹ́ ọkàn.
Ṣugbọn wọ́n dá a lóhùn pé, “O kò ní bá wa lọ, nítorí pé bí a bá sá lójú ogun ní tiwa, tabi tí ìdajì ninu wa bá kú, kò jẹ́ ohunkohun fún àwọn ọ̀tá wa.
Ẹtọ ọmọ eniyan ni Benue; Aarẹ Donald Trump ti sọ wipe opin gbọdọ de ba asa pipa awọn ọmọlẹyin Kristi kaakiri orilẹede Naijiria.
Kohati bí ọmọ mẹrin: Amramu, Iṣari, Heburoni ati Usieli.
Bi o tilẹ jẹpe awọn eniyan mọ nipa Ọ̀ọ̀nì to wa ninu omi nla lagbeegbe naa, ori lo yo aja to n sere ni bebe iku yọ.
Nígbà tí mo ssọ báyìí Baba-ońirùngbọ̀n wí fún wa pé tòótọ́ ọ̀nà tí a lè bá dé ilé wà ṣùgbọ́n ó sọ fún wa pẹ̀lú pé ọ̀nà léwu gidigidi.
Bayìí ni Àjẹ́dìran sọ tí ó gbé ẹ̀gbọ́n rẹ̀ lé ibi gíga.
Nígbà náà ni wọn yóo bẹ̀rẹ̀ sí máa sọ fún àwọn òkè ńlá pé, ‘Ẹ wó lù wá,’ wọ́n óo sì máa sọ fún àwọn òkè kékeré pé, ‘Ẹ bò wá mọ́lẹ̀.
Mọ̀ dájú pé bẹ́ẹ̀ ni ọgbọ́n yóo rí fún ọ,bí o bá ní i, yóo dára fún ọ lẹ́yìn ọ̀la,ìrètí rẹ kò sì ní di asán.
Amọ, ohun ti alaga APC ipinlẹ Eko n sọ ni pe ki awọn agbaagba to da ẹgbẹ oṣelu APC silẹ ma gbagbe adehun ọdun 2014.
Dayo Adewole to jẹ ọmọ minisita tẹlẹ ri fun eto ilera ni àwọ̀n àwọn ajinigbe tun gbe lọtẹ yii.
Ìkejì ni pé àwa ọ̀mọ̀wé ilẹ̀ Káàárọ̀oòjíire ti kọ̀ ọ́ sílẹ̀ pátápátá.
Ajọ naa si fi lede gbogbo bi wọn ṣe na owo labẹ isakoso Ọjọgbọn Pondei.
Ijoba orile-ede Naijiria ti gbe oruko awon akekoobinrin ile iwe girama ti Dapchi nipinle Yobe ti awon onise ibi boko haram lo jigbe nile iwe Government Girls Science and Technical College lojo kokandinlogun osu keji odun yii sita lekunrere.
Bakan naa, ko si irinse ohun elo idibo Kankan ti dana sunAgbaje ni “Mi o ti awon nnkan ti won dana
Ilẹ̀ Tí Ó Dára fún Ìní.
owo ori won le die ni Milionu Marunlelogorun (N105,097,529.
OLUWA bá rán Mose, ó ní, 
bee si ni o salaye ipinnu ijoba lati mu igba pada bosipo nipinle ohun.
Kinni alaṣẹ Azman àti FAAN ati NCAA n sọ?
Má jẹ́ kí ojú tì mí, OLUWA,nítorí ìwọ ni mò ń ké pè.
Àwọn kan ni, kàkà kí o kọjú mọ awọn tó ṣe iṣẹ ajambaku lórí afárá to já, n sẹ ní ọ n dùn kọkọ mọ àwọn akoroyin.
Lati nnkan bii ẹgbẹrun marun eeyan lọdun 2015, iye awọn eeyan to ku nipasẹ ikọlu Boko Haram ti wa silẹ si bii ẹgbẹrun kan laarin ọdun mẹta sẹyin.
Ṣugbọn ohun iyalẹnu ni wi pe pupọ ninu awọn olugbẹ ilu naa ni ko mọ wi pe papakọ ofurufu to n bẹ nibẹ n ṣiṣẹ titi di asiko yii.
Coronavirus in Nigeria: Èèyàn mẹjọ míràn tún ti ní àrùn Coronavirus ní Naijira
F Odunjo ti ku, amọ isẹ ọwọ rẹ si n fọhun sibẹ, ti iran Yoruba ko si le gbagbe rẹ titi aye.
Odun 1960 ni o da ẹgbẹ olorin rẹ sile eyi to pe ni Orlando Owoh and his Omimah Band.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Toyin Atoyebi mechanic: Ẹ wo Toyin, ọmọbinrin ọdún 16 tó ń tún skadà àti gẹnẹrátọ̀ ṣe ní Oṣu Kẹjọ 2020, eeyan kan ku ni Alakia Ibugbamu gaasi naa ni eleyi to waye ni ibudo iwọkọ Alakia ni orile Iganm,u nilu Eko.
Nígbà tí Kọ́là sọ̀ kalẹ̀ tí ó ń lọ, ó gbàgbé àpò rẹ̀ ṣùgbọ́n wọ́n dá a padà fún un.
Lasiko ti a ṣe akojọpọ iroyin yii, awọn osiṣẹ aabo duro wamuwamu si ofisi ẹṣọ aabo oju to n bẹ ni agbegbe 'High School' niluu Ogbomọṣọ lati dena akolu awọn ara ilu to n fapajanu nitori ijamba naa.
Boya wọn si gbọ, wọn fi mọra ni awa o mọ o.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Buhari fi ọ̀kadà, ọkọ̀ àti $500,000 ta orílẹ̀èdè Guinea Bissau l'ọ́rẹ fún ètò ìdìbò wọ̀n 27 Ìgbé 2019 Oríṣun àwòrán, MBuhari/Twitter Aarẹ orilẹede Naijiria, Mohammadu Buhari ti fi ọwọ si pe ki wọn o ko ọtalelọọdunrun din mẹwa irinṣẹ idibo, ọkada mẹwaa, to fi mọ ọkọ Hilux maarun ati ọkọ akẹru meji fun orilẹede Guinea-Bissau.
Ènìyàn 8, ilé 25 ilé ìtajà 16 àti àwọn ǹkan míran ló bá ìṣẹ̀lẹ̀ iná ná rìn Kanu Ejike fipá bá ọmọ ọdún méje lò pọ̀ nínú sọ́ọ̀bù ìyàwó rẹ̀ Ìdí táwọn èèyàn fi gbádún ìtàkurọ̀sọ àwọn ìgbákejì Trump àti Biden ju tiwọn lọ rèé Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ondo Elections 2020: Ọgọ́rùn-ún ọdún tí a máa lò lórí oyè l'Ondo, ẹ ó rí àrà - Ojon YPP Kí ló wà nídìí ìsọ̀rọ̀ǹgbèsì láàrin Makinde ati Fayose?
Ìmọ́lẹ̀ Israẹli yóo di iná,Ẹni Mímọ́ rẹ̀ yóo di ahọ́n iná;yóo sì jó àwọn ẹ̀gún wẹ́wẹ́ ati ẹ̀gún ọ̀gàn rẹ̀ run ní ọjọ́ kan.
Lára igi wilo níbẹ̀ ni a fi hapu wa kọ́ sí,
Ọbasanjọ, to ti fi atilẹyin rẹ han fun oludije fẹgbẹ́ oṣelu Peoples Democratic Party, PDP, Atiku Abubakar sọ pe, ohun ti yoo ṣe awọn ọmọ Naijiria ni anfaani ni oun faramọ.
N óo lọ kó wọn lẹ́rù, n óo sì kó ìkógun.
Ajọ to n risi idena ati amojuto ajakalẹ aarun ni, NCDC lo fi ikede naa sita lalẹ ọjọ Abamẹta loju opo Twitter rẹ.
eto igbafẹ yoo tun je ki eto idagbasoke igbafẹ lorile ede yii tun fa sẹyin.
Ọgbẹni Joseph Akojede to jẹ akọbi wọn lọkunrin ṣalaye pe iyalẹnu ni iṣẹlẹ naa jẹ fun gbogbo ẹbi.
Olalekan sọ siwaju pe  Akoba to wa ninu gbigba awẹ slọjọ gbọọrọ naa ni pe ewu nla n bẹ fun ẹni to ba gba aawẹ naa ti adinku ba fi ba iye odiwọn suga ati ounjẹ afara lokun to wa nipamọ ninu ara rẹ abi ko tiẹ tan patapata nigba ti onitọun ko ba jẹ ounjẹ miran dipo eyi to n lo nitori pe o n gba aawẹ."
 Èyí tí ó tún túmọ ̀ sí pé , iṣẹ ́ àgbẹ ̀ jẹ ́ ọ ̀ nà sí ìpèsè iṣẹ ́ fún àwọn ènìyàn .
Oríṣun àwòrán, @MBuhari Sugbọn ọkunrin naa, ni kete to gbọ pe oloruka ti gba oruka, ti Hanan si ti lọ sile ọkọ rẹ, lo ba gba fun Ọlọrun.
Al-Mustapha yii ti jẹ adari awọn oṣiṣẹ alaabo fun ijoba to wa lori aleefa nigba ti Shofolahan ti jẹ oluranlọwọ pataki fun oloogbe.
ó sì di baba fún àwọn tí ó kọlà ṣugbọn tí wọn kò gbẹ́kẹ̀lé ilà tí wọ́n kọ, ṣugbọn tí wọn ń rìn ní irú ọ̀nà igbagbọ tí baba wa Abrahamu ní kí ó tó kọlà.
Bí ẹ kò bá ní irú ìtọ́sọ́nà tí gbogbo ọmọ máa ń ní, á jẹ́ pé ọmọ àlè ni yín, ẹ kì í ṣe ọmọ tòótọ́.
Eyii to n tumọ si pe, kii ṣe pe Biden bori Trump nikan, ṣugbọn o gbo ewuro soju Trump lọna ti awọn eeyan ko lero.
Ìjọba ìpínlẹ̀ Ondo - BBC News Yorùbá BBC News, YorùbáFò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Coronavirus Lockdown: À ń gbáradì láti pàṣẹ òfin kóníléógbélé tó bá dójúẹ̀ tán - Ìjọba ìpínlẹ̀ Ondo 13 Ìgbé 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 15 Ìgbé 2020 Oríṣun àwòrán, Rotimi akeredolu Ijọba ipinlẹ Ondo ti sọ pe idi ti oun ko ṣe tii paṣẹ igbele patapata ni awọn iṣoro to rọ mọ igbele ọhun.
Nígbà tí ó yá tí Dafidi gbé ìbànújẹ́ ikú Amnoni ọmọ rẹ̀ kúrò lára, ọkàn Absalomu ọmọ rẹ̀ bẹ̀rẹ̀ sí fà á.
Wọn kò dá ẹnìkan sí, wọ́n sì gba ilẹ̀ wọn.
"Iṣẹ́ ọpọlọ ló yẹ ká ṣe nínú tíátà, kìí ṣe àfihàn ara bíbó àbí ìhòòhò wa - Binta Mọgaji Irọ́ ló pa, a kò mọ̀ ọ́ rí tàbí fún ọ ní ₦13m - APC tako afurasí ajínigbé Ìdẹ̀ra dé, Gẹnẹrátọ̀ tó ń lo omi dé, a bọ́ lọ́wọ́ òkùnkùn ""Ojú wa rí tó ní Egypt, bí wọ́n ṣe ń tẹ̀ wá lọ́mú, ni wọ́n ń gbá wa ní ìdí"" Yorùbá àti Igbo le kùnà láti jẹ ààrẹ lọ́dún 2023- Shehu Sani Á máa ṣíjú àánú wo ẹlẹ́wọ̀n láti mú àdínkù bá ọgbà ẹ̀wọ̀n - Ìjọba Ọyọ Lati igba naa ni awọn ọlọpaa ti bẹrẹ si ni tọ ipasẹ tọkọ-taya naa, ṣugbọn ti wọn lọ fi ara pamọ si ilu Ikarẹ Akoko."
"Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, SS3 ní mo wà báyìí, mo sì ti gba àmì ẹ̀yẹ̀ púpò nílé-lóko gẹ́gẹ́ bí onílù - Ayansike ""A ṣẹṣẹ ti ilu Abuja nibi ti a ti ṣe ipade pẹlu aarẹ apapọ ẹgbẹ wa lorilẹede Naijiria tan ni lori ọrọ ẹkunwo naa."
Eyi tunmọ si wi pe awọn olukọni fasiti to ba wa labẹ ẹgbẹ ASUU nikan ni aṣẹ wọn mulẹ le lori.
Ọ̀rọ̀ Aisha Buhari sí Ramaphosa wú ọ̀rọ̀ síta lẹ́nu àwọn ọmọ Nàìjíríà Àìle è ka kéú ló sọ mí di Krìstíẹ̀nì - Adewale Ayuba Ẹ̀mí 18 ṣòfò ní Òpópónà Akure sí Ọwọ NURTW yóò fikùnlukùn pẹ̀lú Gómìnà Makinde láìpẹ́ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Mo ń ṣa ike jọ láti san owó ilé iwé ọmọ mẹ́ta' Yusuf fi kun pe wọn yan Sanusi gẹ́gk bi Emir ni ọdún 2014, owó ti ó wà ni àpò ẹmireeti ko ju bílíọnu kan lé díẹ̀ l, èyí jìnì gédégédé si bílíọnu mẹta lé ọwọ mẹ́rìn tí àwọn ajọ to gbógun ti ṣ\\iṣe owó ìlú makumọ̀ku ń sọ pe Emir na láàrin ọdún 2014 si 2017 lọ.
Ṣugbọn o lè ṣe é, nítorí pé ẹ̀mí Ọlọrun mímọ́ wà ninu rẹ.
Ó lawọ́, á máa ṣoore fún àwọn talaka,òdodo rẹ̀ wà títí lae,yóo di alágbára, a óo sì dá a lọ́lá.
Wọn si ti fẹnu ko lori ọrọ itẹsiwaju ikọ naa.
” Ṣugbọn àwọn oriṣa ọ̀hún ni wọ́n fa ìparun bá òun ati orílẹ̀-èdè rẹ̀.
Ekiti Ni ipinlẹ Ekiti, ijọba ipinlẹ naa ti ti gbogbo ileewe pa; yala ileewe aladani ni tabi ti ijọba fun iyoku ọsẹ yii.
Wò ó, Ọlọrun tóbi lọ́ba, ju ìmọ̀ wa lọ,kò sí ẹni tí ó lè mọ ọjọ́ orí rẹ̀.
Ṣugbọn awọn kan ti ọrọ náà sójú wọn sọ fún BBC Yoruba pe, looto ni isẹlẹ naa waye.
 Ko si ibi ipamo rara fun idibo awa akanda eda bee naa ni ko si anfani lati mu eni to wu mi lati ran mi lowo ninu idibo naa ni eyi ti ko pese aabo to ye fun awa akanda eda to n dibo”Ogbontarigi yii ti gbe orin Tu face, Asa atawon onkorin miran sita.
Koda, olori ile naa Mudashiru Ọbasa tilẹ fọwọ lalẹ pe, bi Ambọde ko ba farahan niwaju ile naa, aṣẹ ẹ fi kele ofin gbe lawọn yoo pa ki wọn fi gbe e.
Ọgá àgbà èré bọọlu òun ni àwọn yóò ṣe àyẹwò okú náà láti mọ irú ikú to pa Martins ni pàtó.
 Baba agbabọọlu naa, Neymar dos Santos sọ lori ẹrọ amohunmaworan Band TV ni Brazil pe panpẹ gbaa ni.
Díẹ̀ lára àwọn ìṣẹ̀lẹ̀ tí yóò mi ìgboro tìtì l'ọ́dún 2020 rèé Obìnrin Kwara tí wọ́n tà sóko ẹrú ní Lebanon figbe ta, ọwọ́ tẹ èèbó kọ̀ráà tó ṣiṣẹ́ náà Ǹjẹ́ ọmọ Buhari lásẹ láti wọ Ọkọ̀ òfúrufú Nigeria Air force lọ sí òde?
ẹ má jẹ́ kí ọkàn yín tètè mì, tabi kí èrò yín dàrú lórí ọ̀rọ̀ pé Ọjọ́ Oluwa ti dé.
Ni ọjọ Kẹwaa, osu karun un, ọdun 1944, ni Oyinkan tun da ẹgbẹ oselu akọkọ to wa fun obinrin nikan silẹ ti orukọ rẹ n jẹ Nigerian Women Party, NWP pẹlu obinrin mejila mii.
Lẹ́yìn náà, ó lọ sí ààfin ọba, ó kó gbogbo ìṣúra tí ó wà níbẹ̀ ati àwọn eniyan, ó sì pada sí Samaria.
awon adari egbe oselu PDP lẹnuwo lori ọrọ  ti wọn fẹnu ara won sọ pe awon ri abajade esi
 Nigba ti n se minisita ni odun 2013, won ba gbogbo abule mi je, eniyan metaleladota ni won padanu emi won lasiko naa, amo, mo lero pe, igbimo ti o n ri si oro eto-aje eyi ti igbakeji Aare dari re yoo se ohun to ye.
ogbeni  Jean-Claude Kassi Brou, ti lo si
Gbọ́ ẹ̀bẹ̀ èmi iranṣẹ rẹ, ati ti Israẹli, eniyan rẹ, nígbà tí wọ́n bá kọjú sí ibí yìí láti gbadura.
Ọbasa sọrọ iṣiti yii ninu ọrọ ikini ọdun Ileya ti ọdun 2019 yii si
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Obasanjo: Ìpasẹ̀ ìparun ni Nàíjíríà ń tọ̀ lábẹ́ Buhari 12 Òkùdu 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ààrẹ tẹ́lẹ̀rí lórílẹ̀èdè Nàíjíríà náà se àtìlẹyìn fún olùdíje lábeẹ́ ẹgbẹ́ òsèlú PDP, Atiku Abubakar nínú ìdìbò sípò ààrẹ tó kọjá.
Awọn alaṣẹ ilẹ naa yoo gba ẹri pe kii ṣe wi pe lati gbe ni ile naa patapata ṣugbọn fun igba diẹ.
O salaye pe, “ a n ro awon eniyan lati dokowo, a tun n fe awon oludokowo nipinle Benue, bi beeko, a n rin ni bebe ise ohun osi”.
Lara wọn ni Oluwo ti Iwo t'oun naa da si ọrọ abo Naijiria laipẹ yii pẹlu lẹta to kọ si aarẹ ninu eyi ti o ti kìlọ̀ fún ìjọba láti dojú kọ ètò ààbò tó mẹ́hẹ kí ogun má bá a wáyé.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Oyo TUC: A ṣì fa ìjọ̀ba léti ni pẹ̀lú ìyanṣẹ́lódì 17 Sẹ́rẹ́ 2019 Oríṣun àwòrán, Emmanuel Diran/Facebook Àkọlé àwòrán, Emmanuel Diran Ẹgbẹ awọn lọgalga lẹnu iṣẹ Ọba ni ipinlẹ ọyọ, TUC ti pa ẹnu p sọ pe awọn ko ni jami lori ọrọ ifẹhonu han bi ijọba ba kọ lati ṣe ohun ti wọn n beere fun.
Nígbà tí mo dé inú ilé lọ́hùn-ún tán, ẹ̀rù bà mí àti fi ẹsẹ̀ tẹ ilẹ̀ ibẹ̀ nítorí ó dárá púpọ̀, ó ń dán yinrinyinrin, ṣùgbọ́n mo ń tẹ̀lé ọkùnrin náà bí ó ti ń lọ.
Buhari se'pade pajawiri Moshood Jimoh ni orukọ wọn ni Halilu Garba, ọmọ ọdun marundinlaadọta ti inagijẹ rẹ njẹ Mabushi, Zubairu Marafa, ọmọ ọdun marundinlaadọta ti wọn mọ si Wakili ati Nafiu Badamasi, ọmọ ogoji ọdun ti wọn tun maa n pe ni Zakiru.
Yóo dàbí ìgbà tí Ọlọrun pa Sodomu ati Gomora run, pẹlu àwọn ìlú tí ó yí wọn ká; nítorí náà ẹnikẹ́ni kò ní gbé ibẹ̀ mọ́, bẹ́ẹ̀ ni eniyan kò ní máa dé sibẹ.
Àjọ̀dún ìbẹ̀rẹ̀ oṣù titun, ọjọ́ ìsinmi, ati pípe àpéjọ.
Lóòótọ́ èmi ni mo fọn yín ká bí afẹ́fẹ́ sí igun mẹrẹẹrin ayé, 
Ẹ gbẹ agbabọọlu Manchester City ti fidi rẹmi ninu ifẹsẹwọnsẹ mẹta ni saa yii, nigba ti Chelsea kuna ninu meji.
Ọpọ awọn agbabọọlu ni wọn ti n sọrọ nipa ifẹsẹwọnsẹ alẹ oni wi pe yoo yeruku lala niluu Madrid.
“Bákan náà, ẹnikẹ́ni ninu àwọn ọmọ Israẹli tabi àlejò tí ń ṣe àtìpó láàrin wọn, tí ó bá rú ẹbọ sísun tabi ẹbọ mìíràn, 
Ajo to n mojuto boolu afesegba lorile-ede Brazil CBF, ti fun akonimoogba agba iko agbaboolu orile-ede ohun, Tite ni iwe adehun ibasise po odun merin, bi o ti le je pe, won ti ja iko ohun kuro ninu idije agbaye to n lo lowo.
Nigba to n sọrọ siwaju, o ni irọ ni pe awọn ti ko ni anfani ati pada ni wọn n da wahala silẹ.
Ẹni to bori: Congo DR Nigeria vs Ghana.
Ojo soro yii nibi iforowanilenuwo pelu awon oniroyin nilu Eko nibi eto Nutri-Pitch ti won sese pari.
Iṣẹ́ ọwọ́ eniyan ni wọ́n, tí wọ́n fi igi ati òkúta ṣe, nítorí náà ni wọ́n ṣe lè pa wọ́n run.
"Newcastle run Manchester United mọ́lẹ̀ jégéjégé Ìjọba, ẹ yé fi ẹ̀tọ́ ọmọnìyàn dun ọmọ Nàìjíríà mọ́- SERAP ""Nína afurasí ní àhámọ́ nínú eré tíátà, bí àwọn ọlọ́pàá ti ń ṣe lójú ayé burú jáì"" Gẹgẹ bi itan igbe aye rẹ ti sọ fun wa lori ayelujara, baba to bi baba Olasope ni iyawo mẹwa, ti iya tirẹ si jẹ iyawo keji, ti oun naa si jẹ ọmọ kẹfa ninu ọmọ mẹrindinlọgbọn."
Ẹ fi hapu kọ orin ìyìn sí OLUWA,àní, hapu ati ohùn orin dídùn.
Amọ awọn ọmọ Naijiria to tako ọrọ ti Adeboye sọ ni wi pe, ki lo de to jẹ obinrin ni Baba ni ki wọn le, nigba to jẹ wi pe ọkunrin lo n ni ifẹkufẹ si ọmọbinrin to n ba a ṣiṣẹ.
Kí ìrora obí tó mú un,ó ti bí ọmọkunrin kan.
Oríṣun àwòrán, mydemartins Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Pẹsẹ́ ní Ọlọ́pàá Naijiria wà látàrí ìṣekúpani Ọ̀gágun Iran- Ọ̀gá Ọlọ́pàá Buhari, Osinbajo, ẹ̀yin gómìnà, ẹ kéde dúkìá yín kọ́jọ́ méje tó pé-SERAP 'Ipò àpọ́nlé ni mo fi Gómìnà Abdulrahman sí ṣugbọn kò hùwa àpọ́nlé' A kò yìnbon pa èèyàn kankan níbi iná tó jó ọjà Akesan ní Oyo- Ọlọ́pàá Ṣe lootọ ni afikun owo maa gori ina mọnamọna?
O ni eeyan meje lawọn doola labẹ ile na ṣugbọn ko si ẹnikẹni to padanu ẹmi nibẹ.
Ohun ti o le jẹ Eso olomi Ogi agbado Ewebẹ Anọmọ Iṣu to rọ ati bẹẹ bẹẹ lọ ṣaaju ounjẹ to le.
O sọ fun ile iṣẹ BBC pe, awọn onile maa n kọkọ beere lọwọ lọwọ oun boya oun ti ṣe igbeyawo.
Láti 462 sí 386, àwọn tó ní àrùn Covid-19 já wálẹ̀ ní Nàìjíríà lọ́jọ́ àbámẹ́ta Dúkìá àti ọjà jóná ráúráú lásìkò tí iná sọ ní ọjà Mushin ní Eko Lampard laná!
Oríṣun àwòrán, Ronke Ojo Anthony Loju opo Instagram rẹ ati lori Facebook ni Ronkẹ gbe awo orin to danikan kọ naa si, to si n fi ohun to rẹ dodo, kọrin fun ọlọjọ ibi naa.
Àwọn alágbára ni mo bá díje ṣùgbọ́n mo ti gbà f'Olọrun- Agboola Ajayi Kí ló pa Bobrisky àti Olorì Aláàfin Oyo pọ̀?
"Ikọ̀ ẹlẹ́sìn Hàkíkà rèé, níbití wọn ti ń pààrọ̀ ìyàwó láàrín ara wọn Wo oríṣiríṣi ìgbádun ibálòpọ̀ láwọn orílẹ̀èdè mìíràn ""Ohun tí ojú opó ń rí láwùjọ kò kéré"" Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Megabite: Ilé-ìwé ni mo ti bẹ̀rẹ̀ orin kíkọ Owo to le ni billiọnu lọna ojilenirinwo ati meji (N242bn) ni aarẹ Muhammadu Buhari gbe kalẹ siwaju ile asoju apapọ ilẹ wa, gẹgẹ bii owo isuna fun ajọ eleto idibo Naijiria, Inec, feto idibo ọdun to n bọ."
O soro lori, “ Awon odo ile-Africa ati ipenija irinajo lona aibofin mu”.
eni ti o gba ami-eye 2018 NNMA ohun wi pe o leto si lopolopo lataari ise
Pearson so lasiko to n ba awon akoroyin soro lojoBo(Thursday).
O mú ìrúnú rẹ kúrò;o dáwọ́ ibinu gbígbóná rẹ dúró.
Ayálégbé wa tó fi tipá já àbálé mi ṣe àkóbá fún ìgbé ayé mi - Foluke Daramola Ọmọ pupa làwọn olólùfẹ́ wa fẹ́ wò nínú fíìmù làwọn òṣèré tíátà fi ń bóra- Muka Ray Níbo ni Sẹ́nétọ̀ Abiola Ajimobi, gómìnà àná ní ìpínlẹ̀ Oyo wà?
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Aṣọ ń pe aṣọ ráńṣẹ́ láàrin àwọn òṣèré tíátà ní àyájọ́ olúlùfẹ́ Gbogbo ẹ̀yin ọ̀ba abẹ́ mi, tí ẹ̀ ń ta ilẹ̀ ìlú, ẹ kò ní fara re lọ - Oluwo Ìjọba Ọ́ṣun, Oluwo kò yẹ lẹ́ni tó leè darí ìlú, ẹ bá wa le kúrò lórí ìtẹ́ - Olú ti Ilé-Ogbó A kò yan Auxiliary ni adarí gáréjì, ọjọ́ Ajé lá kéde orúkọ̀ àwọn alákòsóo tuntun - Ìjọba Ọyọ Ọjọ́ orí wo ló yẹ kí ikùn ẹ̀dá bẹ̀rẹ̀ sí tóbi?
Nínú àtẹjáde gómìnà Yahaya Bello, ó ní ki gbogbo àwọn to wà ni àyíka àti ni ipinlẹ Kogi maa tẹ̀lé àwọn ìlànà àjọ NCDC bótilẹ̀ jẹ́ pé ko sí ààrùn náà ni ìpínlẹ̀ Kogi Kogi jẹ́ ọ̀kan lára àwọn ìpínlẹ̀ méjì tí kò tíí ní ààrùn náà ní Naijiria.
a n rọ awon oludibo lati jade dibo laijẹ pe ẹnikakan n dun ikooko mọ wọn.
Solomoni ṣe ọ̀pá fìtílà wúrà mẹ́wàá bí àpẹẹrẹ tí wọ́n fún un.
OLUWA, Oluwa wa,orúkọ rẹ níyìn pupọ ní gbogbo ayé!
O sọ wi pe orilẹede aadọsan lo ti fofin de idajọ iku tabi ti wọn ti wọgile ọna isekupani yiii, nigbati awọn orilẹede miran ti se ofin to n gbero lati fagile ise naa, ti wọn ko si se idajọ iku ni ọdun mẹwa.
wi pe, Olorun yoo fun ni okun ati agbara, emi gigun lati maa ti egbe oselu APC
 O ni opolopo eran osin ati ire oko ni yoo sofo dani lataari aisise awon olusewadii wonyii.
Olaniyan, to jẹ oludari agba ni ẹka eto ẹkọ ipinlẹ Osun fi sita lẹyin ti ọrọ naa ti wa nile ẹjọ fun ọjọ pipẹ.
Ó ní, “Ẹni ìyìn ni Ọlọrun títí ayérayé,ẹni tí ó ní ọgbọ́n ati agbára.
O ni awọn fẹ ki araye mọ pe ki wọn mase ya ẹgbẹ mọ.
Gbogbo àwọn tí a kà ninu ìdílé Manase jẹ́ ẹgbaa mẹrindinlọgbọn ó lé ẹẹdẹgbẹrin (52,700).
Nigba ti a o ba fi ri opin ọsẹ yii, Agboọla Ajayi yoo kede ibi to fẹ lọ, ṣugbọn o daju pe yoo fi ẹgbẹ oṣelu PDP silẹ Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Solomoni bẹ̀rẹ̀ sí kọ́ tẹmpili OLUWA ní Jerusalẹmu, níbi ìpakà Onani, ará Jebusi, lórí òkè Moraya, níbi tí OLUWA ti fi ara han Dafidi, baba rẹ̀; Dafidi ti tọ́jú ibẹ̀ sílẹ̀ tẹ́lẹ̀.
 a má a ń fúnni yálà bí abẹ ́ rẹ ́ tí a gún sínú ẹran ara ẹni tàbí sábẹ ́ awọ ara ẹni .
Fọwọ́ kan obìnrin lọ́nà àìtọ́, kí o rẹ́wọ̀n ọdún mẹ́rìnlá he- Àwọn aṣòfin yarí Ọwọ́ ọlọ́pàá ìpínlẹ̀ Oyo tẹ àwọn afurasí lórí ìpànìyàn tó wáyé ní Akinyele Ó ṣeéṣe kí àrùn Coronavirus tànkálẹ̀ gba inú afẹ́fẹ́- WHO Bí àrùn Coronavirus ṣe dá gbogbo àgbáyé gúnlẹ̀ sójú kan náà nìyí Ile ijọsin ni Russia to jẹ ibugbe awọn kristiẹni to pọju lọ naa ni o ṣeesẹ ki igbesẹ ijọba yii fa ẹlẹyamẹya ni eyi ti ko darar to lasiko yii.
Nítorí pé mo ti rí angẹli OLUWA lojukooju.
"Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìtàn Mánigbàgbé: Ìtàn Adegbọrọ kọ́ wa láti ṣiṣẹ́ kára pẹ̀lú ìforítì 23 Agẹmo 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ìtàn tó rọ̀ mọ́ òwe ""Ẹni tí kò ṣe bíi aláàárù l'Oyingbo."
Ojogbon Adewale fi kun oro pe, gbogbo iroyin ti won ba gbe sita ni won yoo iyanju si.
Ó bá kìlọ̀ fún wọn pé kí wọn má ṣe sọ fún ẹnikẹ́ni.
  Irú àwọn eranko àti ẹiyẹ tí ènìà lè rìnàkò nínú igbó náà ni ehoro, ọ̀kẹ́rẹ́, ọ̀yà, pẹ́pẹ́íyẹ, ọ̀kín, àparò, ẹiyẹlé, àti bẹ́ẹ̀bẹ́ẹ̀lọ.
Ninu atẹjade kan ti alukoro fun ileeṣẹ ọlọpaa ipinlẹ Eko, Bala Elkanah fi ṣọwọ si BBC, Mbadike, to jẹ ẹni ọdun mẹrinlelogun sọ pe oun ṣina iya f'ọmọ ọdun mẹwaa naa, Chibike EziAmaka, nitori o ti mu ọti yoo.
Òótọ́-inú ni yóò fún ọ ní orúkọ títóbi, àwọn tí ó ti ń bú ọ lẹ́hìn yóó máa yẹ́ ọ sí lójú rẹ, àwọn tí ó tí ń ṣẹ́ èpè ní ìkọ̀kọ̀ yóó ba búrúbúrú nígbà tí ìwọ bá ṣe alábàápádé wọn, ìwọ yóó tẹ apànìyàn mọ́lẹ̀ lábẹ́ àtẹ́lẹsẹ̀, ìrẹ̀wẹ̀sì yóò dé bá aṣnibánidárò; arírebánijẹ yóò dúró tì ọ́ ní ìgbà ìpọ́njú, ènìyàn líle yóó rọ̀ bí ọ̀gẹ̀dẹ̀ pupa, olórí-burúkú kì yóó sì dé sàkání rẹ.
Coronavirus in Nigeria: Ǹjẹ́ òògùn vitamin C lè pa coronavirus?
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ọlọ́paà Ọ̀ṣun: Ààbò wà fún ẹ̀mí àti dúkìá aráàlú 14 Òkùdu 2019 Oríṣun àwòrán, @PoliceNG Ileeṣẹ ọlọpaa Ipinlẹ Osun ti mu awọn janduku mẹtala ti wọn n ṣọṣẹ ni awọn opopona to wa ni ipinlẹ naa.
Ewe, idije ohun ni o wa lojuna erongba ijọba apapo lati mu idagbasoke ba ere idaraya hockey laarin awon omo orile-ede yii, papaajulo laarin awon odo.
Ọshun wa ṣe ileri pe Ile Igbimọ Aṣofin yii yoo sa gbgbo ipa fun awọn aṣagbeyẹwo
lati maa se ojuse won , ni eyi ti ifẹ orile ede ati awon eniyan yoo se jọba lọkan
Àwọn ọ̀tá ń fi mí ṣe yẹ̀yẹ́ tọ̀sán-tòru,àwọn tí wọn ń pẹ̀gàn mi ń fi orúkọ mi ṣépè.
Ó tò wọ́n sí ara èjìká efodu náà gẹ́gẹ́ bí òkúta ìrántí fún àwọn ọmọ Israẹli, bí OLUWA ti pàṣẹ fún Mose.
O ti le ni aadọta ọdun bayii ti ẹbi Gnassingbe ti n ṣe ijọba orilẹede Togo.
Iwadii BBC fihan pe awọn agbabọọlu yii wa lati oriṣii orilẹ-ede ni, kii ṣe Naijiria nikan.
Gbogbo eto iforukọ silẹ ko gbọdọ kọja ọjọ kọkandinlọgbọn, oṣu Kẹsàn-án, ọdun 2020.
Orji Uzor Kalu Gomina ipinlẹ Abia tẹlẹ, Orji Uzor Kalu jẹ ọkan lara awọn oloṣelu ti orukọ rẹ tan lọdun 2019 lori ẹsun ṣisọwo ilu baṣubaṣu.
Gbogbo bí nǹkan bá ti rí níhìn-ín ni wọn óo ròyìn fun yín.
"Oríṣun àwòrán, Nicholas Bamulanzeki Wo ohun tí yóò ṣẹlẹ̀ ní ìpàdé àwọn èèkàn Yorùbá láti mú kẹ́ẹ dìbò fún Tinubu ní 2023 Wọ́n ní kí ọ̀gá àgbà ""Ede Poly"" lọ rọ́kún nílé lórí ẹ̀sùn pé 'ó kan bẹ́ẹ̀dì sí ọ́fíìsì' Adajọ́ Àgbà Naijiria, Tanko Muhammad ti ní Covid-19 Ileeṣẹ ọlọpaa ilẹ Uganda fi ẹsun kan Stanley Omah Didia ti inagijẹ rẹ jẹ Omah Lay, Temilade Openiyi to n jẹ Tems ati ọmọ Naijiria kan, Muyiwa Awoniyi pe wọn n mọọmọ ṣe ohun to lee pin arun to lee ran ka kiri."
A kọ òfin gígé nǹkan ọkùnrin tó bá fipá bá obìnrin lòpọ̀ - Àwọn Alfa yarí Agolo gáásì kéeké tó ń jò bú gbàmù l‘Eko, ẹ̀mí kan bọ́, mẹ́ta fara pa Ewé ṣunko!
Orilẹ-ede Naijiria lo ni odo meji to tobi julọ ni agbaye.
, Duration 4,2617 Bélú 2020 4:48 Fídíò, Akọ́mọlédè àti Àṣà lórí BBC Yorùbá: Kọ́ síi nípa iṣẹ́ tí oúnjẹ ń ṣe lára níbí, Duration 4,4824 Bélú 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Oríṣun àwòrán, Ajimobi Lives on Àkọlé àwòrán, Ni nkan bii ago mẹwaa kọja iṣẹju marun owurọ yii ni wọn sin in.
Ẹnikẹ́ni tí wọ́n bá mú pẹlu àwọn ohun ìyàsọ́tọ̀ náà, iná ni a óo dá sun àtòun, ati gbogbo nǹkan tí ó ní, nítorí pé ó ti ṣẹ̀ sí majẹmu OLUWA.
Bí a bá dà’gbà, à á yé ogun jà
”Aare ajo NFF, Amaju Pinnick gboriyin bantabanta fun ile-ise Cadbury Nigeria Plc fun ibasepo ati atileyin won to gboro ni ona lati mu igberu ba iko Super Eagles“Adupe fun TomTom lopolopo fun olokan-o-jokan atileyin won.
Ṣugbọn bí ẹrú bá jẹ́ olubi, tí ó bá rò ní ọkàn rẹ̀ pé, ‘Ọ̀gá mi kò ní tètè dé!
" Àbádòfin ìdájọ́ yíyẹ igi fún 'ni tórí ọ̀rọ̀ ìkóríra!
Borossia Dortmund naa ti n duna-dura lati ra ọmọ orilẹede Brazil, Malcom ni miliọnu mejilelogoji Euro.
Ìgbà tí ó parí àgbọ̀nrín kejì ni o tó wa wò mí dáadáa tí ó dáhùn tí ó wí pé: ‘Kí lò ń wa?
Ní àkokò tí a dé ìletò yìoí ní iná kan bẹ́ sílẹ̀ nínú ilé Ìbẹ̀rùàrapọ̀ tí ó jó ilé náà kanlẹ̀ ko.
Gbogbo ilẹ̀ tí ẹ óo yà sọ́tọ̀ yóo jẹ́ ọ̀kẹ́ kan ati ẹẹdẹgbaata (25,000) igbọnwọ (kilomita 12½) ní òòró ati ìbú.
Òkúu rẹ̀ ń fì ní ìta ògiri ilé náà ní títì ní àárín alẹ́, àmọ́ kò sí ẹni tí ó se àkíyèsí àfi ní ìgbà tí ó di fẹ̀ẹ̀rẹ̀ nígbà tí àwọn alùgbé ilé òdì kejì ṣí fèrèsée wọn.
Oríṣun àwòrán, TWITTER/AJIMOBI Wọn fikun wi pe, Ajimobi ko fun wọn ni Kọbọ kan to kereju nitori awọn kọ lati jẹ ki o ti eto oṣelu bọ oku baba awọn, bi o ṣe wu u.
Commission) ni gbogbo igba yoowu ti oun ba hu iwa ibaje.
Mo gbágbè adẹ́dà, mo sì ń dá wu ìwà tèmi.
Àwọn eniyan náà dá Joṣua lóhùn pé, “OLUWA Ọlọrun wa ni a óo máa sìn, tirẹ̀ ni a óo sì máa gbọ́.
Wọ́n ní àjò kìí dùn ká gbàgbé ilé.
Igbesẹ yii lo waye lẹyin wakati mẹrinlelogun ti ọga agba ọlọpa nilẹ yii, Mohammed Adamu kede ijọba ti fofin de ẹgbẹ Shiite.
Ile Igbimọ Aṣofin Ipinlẹ Eko, ti o tun jẹ alaga igbimọ awọn agbenusọ ile
Oríṣun àwòrán, Others Ọkan nínú àwọn to bá BBC sọ̀rọ̀, Wale Akintade sàlàye pé, aláfíà ni àwọn wà bo tilẹ̀ jẹ́ pé ààrun náà n bá àwọn ènìyàn Italy fira gidigidi, o ni ko kan àwọn alawọ dúdú to wa nibẹ, àwọn ọmọ ilẹ Italy àti àwọn ọmọ China ni ọ̀rọ̀ náà kan jùlọ.
Oríṣun àwòrán, @Presidency Àkọlé àwòrán, Minimum Wage: Ẹgbẹ́ àwọn òṣìṣẹ́ TUC fárígá sí ìjọba Naijiria lórí owó oṣù tuntun Titi di asiko yii ni ẹgbẹ awọn oṣiṣẹ ti fariga pe awọn yoo bẹrẹ iyanṣẹlodi ni ti ijọba ba kọ̀ lati mu ileri wọn ṣẹ lori eyi ti wọn fẹnuko le lori tẹlẹ.
Gege bi alaga igbimo ti o sagbateru idije ohun, ogbeni Malachy Ndubuzor, O se lalaye pe, won yoo ri daju lati fojusile mu awon  agbaboolu ti o ba fakoyo ninu idije naa sinu iko agbaboolu TREM Football Academy.
Oríṣun àwòrán, GIUSEPPE CACACE Àkọlé àwòrán, Ẹni a ba laba ni baba Labala awọn olorin ti awọn eeyan n wadi iroyin nipa wọn julọ ni Naijiria lọdun 2019, Zlatan, Burna Boy,Naira Marley,Teni ati Kizz Daniel wa lara wọn.
BBC ki Ogogo ku ayẹyẹ ọjọ ibi o.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Wọle Ṣoyinka: Owe maa n ran mi leti MKO Abiọla Lọna ati fi opin si aṣa ṣiṣe mọkaruru esi ibo, eyi to wọpọ ni Naijiria latẹyinwa, lo mu ki Ọgagun Babangida se agbekalẹ ilana eto idibo gbangba laṣa n ta, eyi ti awọn oloyinbo n pe ni Option A4.
Nígbà tí ó bá di ọdún Jubili, ilẹ̀ yìí yóo pada di ti ẹni tí wọ́n rà á lọ́wọ́ rẹ̀, tí ilẹ̀ yìí jẹ́ ilẹ̀ àjogúnbá rẹ̀ láàárọ̀ ọjọ́.
wọ́n fún un ní ọtí kíkorò mu.
Nítorí náà ni Abrahamu ṣe sọ ibẹ̀ ní “OLUWA yóo pèsè,” bí wọ́n ti ń wí títí di òní, pé, “Ní orí òkè OLUWA ni yóo ti pèsè.
Àkọlé àwòrán, Awọn gomina ẹkun iwọorun-guusu orilẹede yii korajọpọ lati ṣe ipade pajawiri lorii wahala awọn ajinigbe, iwa ọdaran ati eto aabo nilẹ Yoruba.
olubori ninu abajade esi idibo aarẹ.
Lẹyin tijọba ṣe ìkede yii ni BBC jade lọ ṣe iwadii oriṣii irufẹ ọja tabi okòwò ti èèyàn le fi ẹgbẹrun mẹwaa naira ṣe lasiko yii pẹlu bi ìta ṣe rí.
Wọn tun n fẹ ki ileesẹ fiyajẹ awọn ọlọpaa to ti sẹku pa eeyan ni Naijiria lai ṣe egbe.
 ní àwọn agbègbè ibití iye ènìyàn tó ju méjìlélógún nínú ọgọrun ( 20 % ) lọ ti ní àkóràn àrùn náà , a dámọ ̀ ràn pé kí a ṣe ìtọ ́ jú gbogbo ènìyàn láti ìgbà dé ìgbà ní tẹ ̀ lé-n-tẹ ̀ lé .
Nitori ifẹ nla to ni si Oyinkan, a ka a pe Kofoworola naa ṣe bẹẹ, idi ti eyi fi ri bẹẹ, ko si ẹni to ye.
Tanker explosion on Otedola bridge: Ọkọ̀ agbépo gbiná ní orí afárá Otedola!
Ọlọ́pàá Adamawa ni #30,000 ni wọ́n fi bọ́ igún látìmọ́lé Ọwọ́ ọlọ́páá tẹ ẹyẹ ayékòótọ́ tó maa n ṣ'òfófó!
O san ki o maa ran ara rẹ leti pe fun igba diẹ naa ni waa fi gbe oyun naa.
Nígbà tí Samuẹli gbọ́ gbogbo ohun tí wọ́n wí, ó lọ sọ fún OLUWA.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Secret Cults in Nigeria: Iléèṣẹ́ ọlọ́pàá ní kò sí ààyè fún àjọ̀dún 7/7 ní ìpínlẹ̀ Oyo, Ogun 7 Agẹmo 2020 Àkọlé àwòrán, Àdá, àáké, ati fila pupa jẹ́ diẹ lara ami idanimọ awọn ẹgbẹ okunkun ni Naijiria Ileeṣẹ ọlọpaa ipinlẹ Oyo ati Ogun ti kede pe, aṣiri tu si oun lọwọ pe awọn ẹgbẹ okunkun kan n mura lati ṣe ajọdun nipinlẹ naa.
Bakan naa lo tun rọ awọn ọdọ to n wọde naa pe, ki awọn pẹlu gba alaafia laaye bi wọn ṣe n gbe ẹhonu wọn sita.
Mo rí oòrùn, ati òṣùpá, ati àwọn ìràwọ̀ mọkanla ní ojú àlá, gbogbo wọn foríbalẹ̀ fún mi.
Alukoro ileeṣẹ ọlọpaa sọ pe ọga agba ọlọpaa ipinlẹ Oyo ti gbọ si ọrọ naa, yoo si wa nkan ṣe sii.
Eyi ko si sẹyin ohun to jẹyọ latara awọn sinima rẹ ati iru awọn ọrọ to maa n fi sita lori ayelujara loore koore lẹnu ọjọ mẹta yii, to jọ mọ ka maa bu ẹnu atẹ lu awọn iwa kọọkan tawọn ọdọ n hu.
Nígbà tí wọ́n ké sí Hesekaya ọba, Eliakimu, ọmọ Hilikaya tí ó ń ṣe àkóso ààfin, ati Ṣebina akọ̀wé ọba, ati Joa ọmọ Asafu, tí ń ṣe àkóso ìwé ìrántí ni wọ́n jáde sí wọn.
Alábàárù ni mò ń ṣe lọ́jà Ketu àti Mile 12, kí ń tó bẹ̀rẹ̀ Fuji - Atawẹ́wẹ́ Ǹjẹ́ o mọ ìdí tí mílíọ̀nù 16 ọmọdé kò fi rí iléèwé lọ ní Nàìjíríà?
Kosi aba owo iṣuna ti Aarẹ Muhammadu Buhari gbe lọ siwaju awọn aṣofin ti ko mu rogbodiyan dani.
Iṣé nlá n bẹ̀ níwájú ààrẹ Buhari àti àwọn Gómìnà lórí owó èpo robi tó dénú kọ́lẹ̀ Oju ọjọ lẹka ọrọ aje ni Naijiria ṣe bi ẹni ṣokunkun latari bi iye owo epo rọbi lagbaye ti ṣe dẹnu kọlẹ.
Idibo nipasẹ ileeṣẹ ifiweranṣẹ Lọdun 2016, miliọnu mẹtalelọgbọn awọn ọmọ ilẹ Amẹrika lo di ibo wọn nipasẹ awọn ileeṣẹ ifiweranṣẹ.
Àwọn Olúkọ ìpínlẹ̀ Oyo fakọyọ lórí ètò Akọ́mọlédè àti Àṣà púpọ̀ Látilẹ̀ ni mo ti fẹ́ràn orin ìjọ Kérúbù àmọ́ ẹlẹ́sìn mùsùlùmí àti krìstẹ́nì ni mí- Qdot Ọkùnrin kan lu ìyàwó rẹ̀ pa"" nítorí ó lọ síbi ayẹyẹ ìsọmọlórúkọ Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Abike Dabiri-Erewa: Ìròyìn òfégè ní pé mò kò ""Palliatives""pamọ́ sí ilé mí6 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Lagos Senatorial Elections: Abiru ṣ'àbẹ̀wò sí Tinubu lẹ́yìn tó wọlé àtúndi ìbò Sẹnẹtọ ìlà oòrùn ìpínlẹ̀ Eko7 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Opeyemi Ayeola: Inú sinimá ni ọkọ mi ti rí mi, ọdún mẹ́ta ló fi wá nọ́mbà mi, kó tó fẹ́ mi6 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Enuduisu Odili sexual Port Harcourt death: Ọkùnrin kan gba ibi ìbálòpọ̀ jásí ọ̀run alákeji6 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?"
Wọ́n ṣe akiyesi wọn pé wọ́n ti wà pẹlu Jesu.
Igi sikamore ni a fi kọ́ èyí tí wọ́n dà wó,ṣugbọn igi kedari dáradára ni a óo lò dípò wọn.
Awon marun un to gbegba oroke ninu awon olukopa naa yoo soju Naijiria ni Nairobi ni orile ede Kenya losu kewaa odun nibi apero elekunjekun to m bo lona.
Ní àkókò náà ni àwọn kan ninu àwọn amòfin ati ninu àwọn Farisi bi í pé, “Olùkọ́ni, a fẹ́ rí àmì láti ọwọ́ rẹ.
Aṣoju ṣofin Gbajabiamila gan ni ẹgbẹ oṣelu All Progressive Congress(APC) fọwọ sii pe ko jẹ adari ile aṣoju ṣofin l'Abuja.
Nígbà tí mo máa jáde, orí mi kún fún onírúurú ewé gbígbẹ, pẹ̀lú ẹ̀rún igi.
Ogunbayo, ẹni to salaye pe lasiko ti obinrin ba n ṣe nnkan oṣu, o ṣee ṣe ko maa kanra, ki ẹjẹ maa ya ni ara rẹ, ki inu si maa run, wa rọ awọn ọkunrin to wa lẹgbẹ wọn lati ni ifarada pẹlu wọn.
Mo lé fi òjò dá àrà tò wù mi f'áwọn oníbárà mi lásìkò tó wù mí
Ọmọ Ọba Dubai yóò san owó ìtọ́jú ọmọ Nàìjíríà tó bí ìbẹrin sí Dubai tí kò sí rówó san Inú ibojì kan náà pẹ̀lú aya rẹ̀ ní wọ́n a sin Bàbá Fasanmi sí lọ́jọ́ kẹrin, osù kẹjọ!
Ṣugbọn òkè Sioni ni ẹ wá, ìlú Ọlọrun alààyè, Jerusalẹmu ti ọ̀run, pẹlu ẹgbẹẹgbẹrun ọ̀nà ẹgbẹrun angẹli.
"O si pinnu lati fi opin si ""iye rira, ati abosi, ti awọn ṣọọṣi ẹsin Kristiẹni n polongo""."
"Abala ilana yii kan wa ninu iwe adehun naa ni lati fidi rẹ mulẹ pe orilẹede Naijiria yoo da owoya naa pada, kii si se pe a fẹ gbe ominira wa le ilẹ China lọwọ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Àwọn àwòrán tó ṣé àfihàn Osinbajo lẹni tí kò mú ayé le 9 Òkùdu 2018 Wọ̀nyìí ni àwòrán oríṣiríṣi to se àfihàn Ọjọgbọn Oníwàásù to di olóṣèlú, ìgbákejì Ààrẹ Yemi Osinbajo gẹgẹ bí ẹni tó já síi Oríṣun àwòrán, @hmkstudious_ng Àkọlé àwòrán, Àwòrán Osinbajo yí ní ilé oúnjẹ kàn labuja wà lára àwọn àwòrán Osinbajo tó kọ́kọ́ mú kí àwọn ọmọ Nàìjíríà fẹràn rè Oríṣun àwòrán, @ProfOsinbajo Àkọlé àwòrán, Ẹ jẹ kí ọmọdé wà.
Ọmọ meje ni Kudirat bi fun ọkọ MKO Abiola - Yisau Olalekan, Hafsat Olaronke, Abdul Mumuni Khafila, Hadi, Moriam, Jamiu Abiodun ati Olalekan Yisau Abiola.
Jakande pé 90 láì gba àmì ẹ̀yẹ kankan ní Nàíjíríà -Osoba Àlàyé rèé nípa bí èrùpẹ̀ ṣe wó pa òṣìṣẹ́ akóyọyọ méjì n‘Ibadan Nitori ki awọn ọmọde ati ọdọ Yoruba le ranti pataki ikinni nilẹ Oodua ni BBC Yoruba ṣe jade lọ beere bi a ti n ki ọlọmọ lọwọ awọn eniyan.
Ẹgbẹ́ ọhún tún rọ ilé iṣẹ́ ọlọpàá lati le ọgá náà lẹ́nu iṣẹ́ gẹ́gẹ́ bii àra àwọn Eagle Crack to jẹ́ awọn to fi iya jẹ Chima titi di ojú ikú àti àwọn ọ̀rẹ rẹ Ifeanyi Onyekwere, Victor Ogbonna, Osaze Friday àti Ifeanyi Osuji.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Awọn ileeṣẹ ọtẹlẹmuye Amẹrika bi NASA ko fi ọwọ yẹpẹrẹ mu ọrọ Huawei yi 5G: O yara bi aṣa ṣugbọn ṣe kii ṣe wi pe o lewu?
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, A nilo agọ ọlọpa ni Orin Ekiti fún aabo wa -Falua Ki ni Don Jazzy, MrP, Kate Henshaw àtàwọn èèkàn ìlú míràn sọ lórí Sẹ́nétọ̀ tó lu obìnrin l'Abuja Oríṣun àwòrán, Don Jazzy Àkọlé àwòrán, Don Jazzy, MrP, Kate Henshaw àtàwọn èèkàn ìlú míràn sọ̀rọ̀ lórí Sẹ́nétọ̀ tó lu obìnrin l'Abuja Iwa ipá ninu idile ati lawujọ nilo amojuto lasiko yii.
Ẹ jẹ́ kí á gun òkè OLUWA lọ,kí á lọ sí ilé Ọlọrun Jakọbu,kí ó lè kọ́ wa ní ìlànà rẹ̀,kí á sì lè rìn ní ọ̀nà rẹ̀.
Ko din ni 225,000 eeyan ilẹ Amẹrika to ti dagbere faye nitori arun Covid-19, eyi to jẹ iye eeyan to pọ ju lagbaye.
 nínú ètò ẹ ̀ kọ ́ rẹ ̀ yí ló ti gba àwọn ètò ìmọ ̀ ẹ ̀ kọ ́ ọ ̀ fẹ ́ àti àwọ ̀ n àmì ẹ ̀ yẹ ̀ lọóríṣiríṣi .
ba di, o ni bi opo eniyan se jade lasiko ipolongo to waye ni ipinle Kano fihan
Kò tún sí ibòmíràn ní gbogbo àgbáyé tí èro pọ̀ báyìí fún ayẹyẹ àjọ̀dún ti gbangba ojú títì, àfi ní ìlú Rio de Janeiro ni orílẹ̀  Brasil.
Wo bí àwọn obìnrin kan ṣe n sọ ara wọn di 'fágìn' lẹ́ẹ̀kejì Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Marie Bonaparte ati ọkọ rẹ, Ọmọọba George ti Greece ati Denmark Lati gbe agbekalẹ rẹ lẹyin, obinrin to le ni 240 lo fi ṣe ayẹwo ni nkan bi ọdun 1920.
China: Ni orilẹede China, wọn ma n jẹ oko akọ maluu.
Kí ni kí á ṣe fún arabinrin wa náàní ọjọ́ tí wọ́n bá wá tọrọ rẹ̀?
Sanusi: Ìyọnípò mi kò ṣẹ̀yìn Ọlọ́run Èyí ni àwọn ìdí tí ìjọba ìpínlẹ̀ Kano ṣe rọ Emir Sanusi Lamido l'óyè Buhari, ìjọba rẹ ń jọ bí ègún f'órílẹ̀èdè Nàìjíríà-Oyedepo Kini awọn nkan miran to yẹ ni mimọ nipa Emir Ado Bayero?
Ẹgbẹ PDP ni awọn ko ni igbagbọ pe pẹlu iru ọrọ to n jade lẹnu El Rufaiu yi,awọn yoo ni lati se agbeyẹwo iwe adehun idibo alafia ti awọn buwọlu.
O ṣe pataki ki a fun awọn ọmọ ni Abẹrẹ-ajẹsara 1.
kaarẹ lati tubọ maa gbogun ti iwa buruku yii pẹlu gbogbo agbara to ba wa  nikawọ oun.
’ Nítorí náà gbé òkú rẹ̀ jù sinu oko Naboti gẹ́gẹ́ bí ọ̀rọ̀ OLUWA.
Akowe agba tun so pe lopo igba ni awon iko ogun olote  maa n pa awon eniyan, jiji eniyan gbe , didana sun ile-iwe, tabi dun ikooko mo awon osise lorile ede Naijiria.
A ń fikunlukun pẹ̀lú FBI láti mú àwọn Yahoo Boys"" tó kù- EFCC Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?"
Nigba miran, wọn a gba owo to to N1,500 tabi N2,500 lọwọ wa.
Bata: Oríṣun àwòrán, Others Ilu pataki miran nilẹ Yoruba tun ni, ilu oloju meji sugbọn ti oju kan a maa tobi ju ekeji lọ, ni ọpọ igba ibi ayẹyẹ orisa ni wọn ti n lo, bi iwuye, ifọbajẹ tabi ajọdun orisa kan.
fun eto aabo , ogagun feyinti Babagana Monguno (Rtd) ati awon osise agba
Awọn mejeeji wa ni iyasọtọ .
Nítorí Ọmọ-Eniyan wá láti gba àwọn tí ó ti sọnù là.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù US Embassy ní bí o bá fẹ gbà Visa, àfi kò yọjú funrararẹ 14 Èbibi 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 15 Èbibi 2019 Oríṣun àwòrán, Twitter/@USEmbassyAbuja Àkọlé àwòrán, US Embassy Abuja Ileeṣẹ aṣoju Amerika lorileede Naijiria ti mu iyipada ba eto irina lati Naijiria lọ si ilẹ wọn.
O tún ní àwọn kan tí àwọn náà gba ẹ̀kọ́ àwọn Nikolaiti.
Ẹ má ṣe jẹ́ kí ẹnikẹ́ni da yín lẹ́bi, kí ó sọ fun yín pé kí ẹ máa fi ìyà jẹ ara yín, kí ẹ máa sin àwọn angẹli.
Groeneveld bere sini n sise pelu Sharapova lati odun 2014, ti o si ran lowo lati gba ife-eye idije French Open fun saa naa.
Lasiko abewo naa, Aare orile-ede Sudan tun pe fun ajosepo ohun amusagbara laarin orile-ede mejeeji ohun.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Bi eeyan ba ti tẹka tan wọn a ma fi ọda ṣaami si ika na pe ẹni ọhun ti dibo.
"Lóòtọ a n lọ ile ijọsin ṣùgbọ́n nítori pe ǹkan ti òbí n fẹ́ ni"" ""Wọ́n a sọ fun wá pe ẹ sá fun ọkùnrin a ṣe èyi títí a o ni ọ̀rẹ́kùnrin, ṣùgbọ́n wàá dàgbà tán ko sọkọ wọ́n à sì bẹ̀rẹ̀ si ni pé oníruuru pasitọ lati wá gbàdura."
 Ọ ̀ kan nit i apá Ìlà oòrùn tí wọ ́ n gbé lé orí ẹ ̀ ka-èdè tí wọ ́ n ń sọ ní , ìpínlẹ ̀ yeravan .
Ileeṣẹ naa n ṣe awọn nkan ti ẹnu n jẹ bi i Laziz salad cream, Laziz mayonnaise, Laziz vegetable oil, ati awọn nakn miran.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ẹ wo àrà àwọn ọmọ kékeré ń fi ẹ̀kọ́ kọ̀mpútà dá Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Awọn meje ninu awọn mẹwaa ti wọn ṣẹṣẹ ṣawari naa ni wọn wa lati ilu Eko, mẹta lati ilu Abuja.
Ó tún bi wọ́n ní ẹẹkẹta pé, “Kí ni nǹkan burúkú tí ó ṣe?
Ṣugbọn kò sọ ohun tí ó ṣẹlẹ̀ fún baba tabi ìyá rẹ̀.
Lea ní “Ọlọrun san ẹ̀san fún mi, nítorí pé mo fún ọkọ mi ní iranṣẹbinrin mi.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Awọn oluwọde ENDSARS ba BBC sọrọ Ile aṣofin United Kingdom si fesi pe rogbodiyan to waye lasiko iwọde ENDSARS kọ oun lomiinu.
Gege bi igbakeji aare se sọ, “Awon onisowo ti won nifẹẹ lati da
Itan igbe aye MKO Abiọla: Ọjọ Kẹrinlelogun osu Kẹjọ ọdun 1937 ni Salawu ati Wuraọla Abisla bi Moshood sile aye lẹyin ti wọn ti bi ọpọ ọmọ to to mẹtalelogun sẹyin, ti ireti wọn si ti dinku pe o seese ki ọmọ tuntun naa ye Idi ree ti wọn fi kọkọ pe ni orukọ rẹ ni Kasimawo, nitori pe wọn lero pe oun naa lee gbọna ọrun lọ bii awọn ọmọ to siwaju rẹ.
Nígbà tí wọ́n tilẹ̀ yá ère ọmọ mààlúù, tí wọn ń sọ pé, ‘Ọlọrun wọn tí ó kó wọn kúrò ní ilẹ̀ Ijipti ni,’ tí wọ́n sì ń hu ìwà ìmúnibínú, 
Ní ti kí eniyan pọ̀, n óo sọ ọ́ di pupọ.
Ọpẹ́ ni kí ẹ fi rúbọ sí Ọlọrun,kí ẹ sì máa san ẹ̀jẹ́ yín fún Ọ̀gá Ògo.
Wọ́n tilẹ̀ mú Banaba pàápàá wọ ẹgbẹ́ àgàbàgebè wọn!
Nítorí náà, fi ẹnìkan ranṣẹ sí mi, tí ó mọ̀ nípa iṣẹ́ wúrà, fadaka, bàbà, ati irin, ẹni tí ó lè ṣiṣẹ́ ọnà sí ara aṣọ elése àlùkò, ati àlàárì, ati aṣọ aláwọ̀ aró, tí ó sì mọ̀ nípa iṣẹ́ gbẹ́nàgbẹ́nà.
Àgùnbánirọ̀ akọ̀ròyìn Channels náà ti dágbére fáyé látààrí ìkọlù Shiite l'Abuja Àwọn èèyàn jàǹkànjàǹkàn l'Akure bí Funke Olakunrin ti wọ káà ilẹ̀ lọ Amọ, o ni ti ẹnikan ba sọ pe Barrister kọ lo da Fuji silẹ, o ni ko si ija nibẹ nitori ohun to kọju si ẹnikan, ẹyin lo kọ si ẹlomiran.
Nígbà tí ó jẹ́ pé àwọn angẹli tí wọ́n ní agbára ati ipá ju eniyan lọ, kò jẹ́ sọ ìsọkúsọ sí wọn nígbà tí wọn bá ń mú wọn lọ fún ìdájọ́ Ọlọrun.
Yoruba Films: Òṣèrè tíátà Muideen Oladapo gbàràdá lórí ètò 'Ṣé o láyà?
George Floyd lọ kawe ni Texas George gbabọọlu alapẹrẹ fun ileewe South Florida State to wa Avon Park, ni Florida nibi to ti kẹkọọ laarin ọdun 1993 si 1995.
Ohun ti o n kọ ọpọ lominu lori iroyin yii ko sẹyin bi aarẹ orilẹede Amẹrika, Donald Trump kii se yee tẹnu mọọ wi pe ohun yoo din gbogbo owo ti orilẹede naa n na silẹ okeere ku lati igba to ti de ori oye lọdun 2017.
Nígbà náà ni ìyá ọmọ náà wí pé “Bí OLUWA tí ń bẹ láàyè tí ẹ̀mí ìwọ pàápàá sì ń bẹ, n kò ní fi ọ́ sílẹ̀.
Elba lo fi ọrọ naa lede ninu fidio kan loju opo Twitter rẹ.
"Amọ ta ba gbe oju kuro lori ohun to n lọ lori ọdan, a lee da ara wa laraya lati beere pe ""Ta ni orilẹede ti yoo gbegba oroke ninu awọn nkan miran yatọ si ere bọọlu laarin awọn to n kopa ninu AFCON naa?"
OLUWA tún sọ fún mi pé “Tún fi ara rẹ sí ipò darandaran tí kò wúlò fún nǹkankan.
Gege bi atejade kan lati odo oga agba fun eto iroyin ati igbode-gba nile ise omo-ogun naa, Olatokunbo Adesanya, O ni: lara awon ogagun ti atunto ipo ohun simo lori tun ni, awon oga agba merin ti o wa lolu ile-ise omo-ogun naa ati oga agba adari oko ofurufu kan.
” Nígbà tí ó ti sọ báyìí tán, ó mí kanlẹ̀, ó bá kú.
Ó bá pe Samsoni, ó ní, “Samsoni àwọn ará Filistia dé.
 Èyí náà ló sì fìyà jẹ wọ ́ n .
Akure Church Kidnap: Òbí ọmọ tí wọ́n jígbé àti asọ́nà ṣọ́ọ̀ṣì 14, lọ́ búra nì'dí imọlẹ̀ l'Akure
AFCON 2019: Egypt dá akọ́nimọ̀ọ́gbá Aguirre dúró lẹ̀yìn ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀
Àwọn wolii yòókù ń sọ bákan náà, wọ́n ń wí pé, “Lọ gbógun ti Ramoti Gileadi, o óo ṣẹgun.
Fun ọlọpaa lati tun gbe ẹsun yii kan naa dide fi han pe o ni ohun miran ti wọn n wa.
Àwọn kòkòrò yìí a ma wa láti ibi kọ́lọ́fín ẹ̀dọ̀ fóóró níbi tó jé pé ààrùn náà ti gbilẹ̀ sí nítorí agbára lo fi n jáde nítorí ariwo tí ẹni náà ń pa.
Awọn irin'ṣẹ oloro keekeke bi bileedi, ìṣó, irin ẹlẹnu ṣomu-ṣomu, tabi aake ati ada lasiko ti 'ogun ba le'.
Bi ara ẹni ba ti n powe fun eeyan ni onikaluku a ti mọ pe oun nilo itọju lasiko.
Ko si ẹni to mọ ohun to ṣe okunfa iku to pa Ọgbẹni Robert, amọ o ti n ṣaarẹ fun igba diẹ ki ẹlẹmi to gba a.
6 Àti pé kíyèsíi, ìgbà púpọ̀ ni o ti ré àwọn àṣẹ ati òfin Ọlọ́run kọjá, tí o sì ti tẹ̀síwájú nínú ìyílọ́kànpadà ti àwọn ènìyàn.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Your Poo and You: Ṣé o mọ̀ pé ìgbẹ́ rẹ leè sọ nípa ìlera rẹ?
 o tun jẹ olukọni iwadi ni ile- ẹkọ ile-ẹkọ giga fun awọn Ẹya eniyan , ile- iṣẹ fun ilera ati welfare , ile- iṣẹ awọn ile-ijinlẹ ile-iṣẹ william s.
Olori ọgba ẹwọn naa ni awọn n sa ipa lati ri i pe awọn ẹlẹwọn naa ṣe daadaa ninu idanwo wọn.
20 Ọ̀wàrà 2020 Oríṣun àwòrán, @femigbaja Olori ile asoju-sofin nilẹ wa, Femi Gbajabiamila ti sọrọ nipa awọn isẹlẹ to se koko to n waye nilẹ wa, paapaa iwọde EndSARS.
    Mo gun orí igi kan lọ lẹ́yìn ìgba ti n kò gbúrò rẹ̀ mọ́, ṣùgbọ́n kò pẹ́ púpọ̀ náà tí mo ń wo Ẹlẹ́gbára tí o ń wò ọ̀hún tí o ń wo ìhín tí o ń pòṣé tí ó n wá wa kiri, mo bẹ̀rẹ̀ sí í gbọ́ ó ń sọ báyìí!
 O ni o ti wu oun lati de ade arewa obinrin South Africa ti pe nitori Rolene Strauss ni awokose oun pelu awon obi oun.
'Ko ni nkankan ṣe pẹlu eto aabo tabi aṣẹ lati ọdọ ẹnikẹni.
Funke jẹ ọkan gboogi lara aṣere sinima Yoruba.
Bakan náà ni Ọọni ni ki wọ́n fi ọkàn wọ́n balẹ̀ pé wọ́n o mú wọ́n si ilé Orisà Oodua láti lọ wádìí ibi ti ọmọ náà wa.
” Wọ́n pe gbogbo àwọn ọkunrin Efuraimu jáde, wọ́n sì gba gbogbo odò títí dé Bẹtibara ati odò Jọdani pẹlu.
Ẹ kó wọn jáde, kí á pa wọ́n.
Eyi mú ìlọsíwájú bá ilẹ̀ Yorùbá ju ọ̀pọ̀lọpọ̀ ilẹ̀ Aláwọ̀dúdú.
Ẹ̀dá ọmọ ènìyàn kọ̀ ó ní oyin ò dùn tó o.
Iba Gani Adams: Bẹ́ẹ gbé Yorùbá síbẹ́, ó lè burú ju àwọn míì lọ
Eto Akomolede ati Asa lori BBC Yoruba yii n waye pẹlu ajọṣepọ BBC ati ẹgbẹ onimọ YSAN ati ẹgbẹ Akomolede Naijiria lapapọ Kàyééfì!
Mo ti sọ ohun tí Ọlọrun wí fun yín lónìí, ṣugbọn ẹ kò tẹ̀lé ọ̀kan kan ninu ohun tí OLUWA Ọlọrun yín ní kí n sọ fun yín.
 ní bíi ìkẹyìn ọdún 1935 , àwọn ènìyàn gbọ ́ ìró wípé ọmọbìrin tí ó jẹ ́ àwòran yìí jẹ ẹnìkan tí ìyà ń jẹ ́ tí ó n gba lẹ ́ tà láti ọ ̀ dọ ̀ àwọn ènìyàn ní u.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù NASS: Àbádòfin 2019 yóò fori sánpọ́n ti mínísìtà ò bá bẹ̀bẹ̀ 13 Ọ̀pẹ̀̀ 2018 Oríṣun àwòrán, @NGRSenate Àkọlé àwòrán, Àwọn asofin tí kọ̀ láti jòkó ní ilé lẹ́yìn tí Ààrẹ Buhari pinnu láti wá sàlàyé ètò ìsúná ọdun 2019 fún wọn ní ọ̀sẹ̀ tó ń bọ̀.
Àbí ẹ kò mọ̀ pé gbogbo àwa tí a ti rì bọmi lórúkọ Jesu a ti kú bí Jesu ti kú?
Àmì ohùn ṣe pataki ninu èdè Yoruba nitori pe àmì ohùn lo maa n ya itumọ ọ̀rọ̀ Yoruba sọtọ.
Stella sọ pe, looto loun gun alabagbele oun lọbẹ laya amọ lẹẹkan ṣoṣo ni.
Ní báyìí ẹgbẹ̀rún mẹ́tàléláàdọ́ta àtí ọọdúnrún le díẹ̀ lo ti lugbadi ààrùn náà.
 Ọpọ awọn ara ilu ni o jẹ pe omi odo ni wọn si n pọn bayii fun mimu, fifọ aṣọ, wiwẹ ati awọn iṣẹ ile miiran.
Ajọ eleto ilera l'agbaye, WHO, sọ pe aarin ọjọ mẹrinla ni aarun naa ma n lo ninu ara ko to fi ami han.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù UNICEF: ọmọ tuntun 395, 072 máa wá sáyé lagbaye lónìí 1 Sẹ́rẹ́ 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 6 Sẹ́rẹ́ 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Abiyamọ ku ọrọ ọmọ Ajọ agbaye to n risi ọrọ awọn ọmọde, UNICEF, ni ọmọ 395, 072 ni awọn eeyan yoo bi loni ọjọ kinni, oṣu kinni, ọdun 2019 kaakiri agbaye.
Gbọ́ igbe mi;nítorí wọ́n ti rẹ̀ mí sílẹ̀ patapata.
”Adari ijoba orile ede Britain fi idunnu re han nigba ti o n  ba awon akoroyin soro ni papa baalu to wa niluu Eko , pe inu ohun dun lati wa si orile ede Naijiria paapaa julo,si ilu Eko lati ri bi awon ile ise se n se aseyọri.
gege bi alaga igbimo awon gomina lorile-ede Naijriia(Nigeria Governors’ Forum),
Àwọn ọ̀pọ̀lọ́ yóo máa gbá yìnìn ninu odò Naili, wọn yóo sì wọ inú ààfin rẹ ati yàrá tí ò ń sùn, wọn yóo gun orí ibùsùn rẹ, wọn yóo sì wọ ilé àwọn ẹmẹ̀wà rẹ, ati ti àwọn eniyan rẹ.
Oriṣiiriṣii aṣẹ nile ẹjọ ti pa pe ti ẹnikan fi ipo oludije fẹgbẹ oṣelu APC silẹ fun ẹnikan, ṣugbọn ko si eyi to kẹsẹ jari.
Sọ fún un pé, ‘OLUWA, Ọlọrun àwọn Heberu rán mi sí ọ, pé kí o jẹ́ kí àwọn eniyan òun lọ, kí wọ́n lè sin òun ní aṣálẹ̀, sibẹ o kò gbọ́.
Ile-ise aare ti sekilo fun awon ti won yan sipo ati awon osise
I join other Nigerians to celebrate his Excellency President Muhammadu Buhari @MBuhari at 76.
Akọni ṣubú l'ójú ìjà, Madagascar fi 2-0 la Super Eagles mọ́lẹ̀ Ọkọ mi kò le f'ipá bá ẹnikẹ́ni lò pọ̀ láíláí - Modele Fatoyinbo Àwọn orílẹ̀èdè àjọ ECOWAS yóò máa ná owó kan nàá l'ọ́dún 2020 Damasus, Omotola, Ezekwesili, Funmi Iyanda dá sí ẹ̀sùn ìfipábánilòpọ̀ Fatoyinbo Bakan naa ni awọn kan di ẹbi ru awọn agbabọọlu naa.
Láìpẹ́, àwọn ará Filistia tún wá gbógun ti àwọn tí wọ́n wà ní àfonífojì, wọ́n sì kó wọn lẹ́rú.
ise amusẹya- Mallam Nuhu RibaduOludari eto
Femi Okunronmu to sọ eyi lasiko to n ba BBC sọrọ ni awọn eniyan bii ti oun to n ja fun atunto Naijiria naa ti n ja fun isejọba to fi agbara fun awọn asofin lorilẹ-ede Naijiria tipẹ́ Buhari, tọwọ́ ọmọ rẹ basọ- Timi Frank 'Buhari ló lè sọ ìgbà tó máa yan minisita míì' Èrò àwọn ọmọ Nàìjíríà ṣọ̀tọ̀ọ̀tọ̀ lórí ọ̀rọ̀ Faṣọla àti iná Ọba Ninu ọrọ rẹ, isejọba to fi agbara fun awọn aṣofin yoo fun awọn ara ilu ni anfaani lati le kopa ninu iṣejọba ilẹ wọn, eleyii to yatọ si eyi to fi agbara fun aarẹ nikan ṣoṣo lọ.
Seyi Makinde fojú hàn n'íta lẹ́yìn tó ṣẹ́gun Coronavirus Ilé ẹjọ́ kàn-án nípá fún Wòlíì Sọtítóbirẹ̀ kó tó wọ ilé ẹjọ́ Bí ilumọọka agbabọọlu Drogba ṣe dáwọ ogun dúró ní Ivory Coast Agbábọ́ọ̀lù Manchester United tẹ́lẹ̀, Marouane Fellaini lùgbàdì àrun coronavirus Mo mọ ẹ̀wà lóúnjẹ àjẹsùn látìgbà tí mo ti ń dá ọmọ mi tọ́-Davido Ẹgbẹ agbabọọlu Manchester City lo fọrọ naa lede loju opo Twitter wọn nibi ti wọn ti kẹdun pẹlu Guardiola lori iku mama rẹ.
" Ọkọ rẹ Afeez Olayiwola Abiodun ti ọpọ eeyan mọ si Afeez owo lo n dari fiimu naa.
Alukoro ile iṣẹ ọlọpaa ipinlẹ Eko ni kii ṣe ẹbi wa pe o ṣi wa lẹwọn, tori ko ri ẹnikẹni gba beeli rẹ ni""."
“Ikolu ti o koko waye  ni Arege farahan pe opolopo awon oko to je ti iko Boko Haram ni won dana sun patapata, ti gbogbo awon awako naa si je olorun nipe.
Ẹ tẹ́ tabili siwaju; ẹ wá gbé turari ati òróró mi lé e lórí.
Wọn si tun fi ẹsun pipete ija ẹlẹyamẹya, ati igbesunmọmi kan-an.
Níwọ̀n ìgbà tí ẹ ti wẹ ọkàn yín mọ́ nípa ìgbọràn sí òtítọ́, tí ẹ sì ní ìfẹ́ àìlẹ́tàn sí àwọn onigbagbọ ara yín, ẹ fi tinútinú fẹ́ràn ọmọnikeji yín.
"- Madam Saje Lẹyin ọpọ awuyewuye, ipẹtu si alaafia laarin awọn mejeeji, ti o si jẹ pe kaka ki ewe agbọn ọrọ naa dẹ, lile lo tun n le sii, awọn alaṣẹ ẹgbẹ oṣere tiata Yoruba ti wa paroko ""Ẹ sinmẹdọ ranṣẹ si awọn mejeeji atawọn oṣere miran ti wọn ba ni iru rẹ lọwọ tabi lọkan."
O ni gbogbo awọn ọmọ ẹgbẹ SSANU ati NASU lo ti wa ni imurasilẹ fun iyanṣẹlodi naa eleyi ti wọn ni awọn yoo fi naa tan bi owo pẹlu ijọba.
Arákunrin náà ti ara rẹ̀ mọ inu ilé, ó sì ń kìlọ̀ pé ẹnikẹ́ni tó bá sún mọ́ òun, yóò fara gbọgbẹ́ bí i ti ẹ̀gbọ́n òun.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Coronavirus: Odaran tíì kí bá ṣé ọmọ orílẹ̀èdè Ethiopia yóò padà sí ìlú abinibi rẹ 25 Ẹrẹ̀nà 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 26 Ẹrẹ̀nà 2020 Oríṣun àwòrán, Getty Images Ẹgbẹrun mẹrin awọn to wa lọgba ẹwọn lorileede Ethiopia ni ijọba ilẹ naa ti ni oun yoo tusilẹ nitori ajakalẹ aarun Coronavirus.
Isakoso isajoba gomina Ifeanyi Okowa nife
Ìjàmbá Eko: Èèyàn méjì dàwátì lásìkò ìjàmbá ọkọ̀ ojú omi
Ìbànújẹ́ ńlá ni ikú agbábọ́ọ̀lù Rangers, Ifeanyi George jẹ́ fún wa- Mínísítà àti NFF Iku agbabọọlu ikọ Rangers International ti ilu Enugu Ifeanyi George ṣe ni laanu gan na, bayii ni minisita fun ere idaraya ati ọrọ ọdọ, Sunday Dare ṣe n kẹdun Ifeanyi di oloogbe lẹni ọdun mẹrindinlọgbọn pẹlu awọn akẹgbẹ rẹ meji, Emmanuel Ogbu ati Eteka Gabrielinu ijamba ọkọ to ṣẹlẹ lanaa ọjọ Aiku.
Iranṣẹ Abrahamu bá sáré tẹ̀lé e, ó bẹ̀ ẹ́ pé, “Jọ̀wọ́ fún mi ní omi díẹ̀ mu ninu ìkòkò rẹ.
Ileeṣẹ ọlọpaa naa sọ pe ẹ̀sìn meji to gbajumọ ju ni Naijiria Oríṣun àwòrán, PIUS UTOMI EKPEI Àkọlé àwòrán, Ileeṣẹ ọlọpaa naa f'esi si ọrọ naa pe ẹ̀sìn meji to gbajumọ ju ni Naijiria tako iṣẹ aṣẹwo ṣiṣe Ọkan lara awọn ọmọbinrin naa ti a fi orukọ bo ni aṣiri, sọ pe oun sin ọrẹ oun kan lọ gbe akara oyinbo fun onibara rẹ kan ni wọn mu awọn nigba ti awọn n fẹ ẹ jade lati maa lọ sile.
 Àwọn tí ó ń sọ ọ ́ ní orílẹ ̀ -èdè armenia jẹ ́ mílíọ ̀ nù mẹ ́ ta àti ẹgbẹ ̀ rún mẹ ́ fà ( 3.
Àkọlé àwòrán, Awọn ẹya ara kan n jẹra Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Olùdíje fún ipò gómìnà 24 ló pegedé ní APC Jimi Agbaje ni yóò dupò gómìnà f'ẹ́gbẹ́ PDP nipinlẹ Eko Akọwe ikede fun alaga ajọ INEC, Rotimi Oyekanmi sọ pe ajọ naa ko fọwọsowọpọ pẹlu ẹgbẹ osṣelu kankan lati jale ibo ni Ọṣun.
Ọkeke to jẹ ọmọ ọdun mejilelọgbọn ni awọn ajọ ọtẹlẹmuye mu pe, o wuwa ibajẹ lori ẹrọ ayelujara ni ọdun 2015 si ọdun 2019.
Èèwọ̀ ni láti pa ẹja nínú odò Sogidi ni Aáwẹ́ nipinlẹ Oyo Ọjọ buruku esu gbomi mu 'Èèwọ̀!
Iṣẹ́ Paulu ati Banaba ní Ikoniomu.
Wọ́n ń gba ìdámẹ́wàá lọ́wọ́ àwọn eniyan wọn tí wọ́n jẹ́ ìran Abrahamu.
O fikun pe awọn ijọba Naijiria ti gbagbe pe orisun eto irinajo afẹ orilẹede kan ko lee gbẹ gẹgẹ bi epo rọbi to ni igba ati akoko to lee gbẹ.
Ẹ fetí sí ìbáwí mi,n óo ṣí ọkàn mi payá fun yín,n óo sì jẹ́ kí ọ̀rọ̀ mi ye yín.
 gbogbo ìgbésí ayé wọn ló wà létòlétò , èyí ló mú kí àwùjọ yorùbá láyé ọjọ ́ un jẹ ́ àwùjọ ìfọ ̀ kànbalẹ ̀ , àlàáfíà àti ìtẹ ̀ síwájú .
 Bakan naa ni Ayefẹlẹ tun dupẹ́ pupọ lọwọ ijọba ipinlẹ Ọyọ fun ibi ti wọn sin oun de, o si tun dupẹ lọwọ kọmisana f'eto iroyin, Toye Arulogun, pe oun lo pilẹ ọrọ bi wọn yoo se wo ile oun, oun si ki pe o ku aseyọri lori isẹ naa.
Latin lórí àìsàn Ogun Majek 19 Ìgbé 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 21 Ìgbé 2020 Oríṣun àwòrán, Other Ni ọjọ Aiku ni gbajumọ oṣere tiata kan lorilẹede Naijiria, Folukẹ daramọla gbee sita pe ojojo n ṣogun ara ogun o le fun eekan oṣere, Ogun Majek ti o si nilo amojuto to peye.
O ni ijọba ko gbaruku ti awọn to n fi ewe ati egbo ṣe ọmọ araye loore.
Ọpọlọpọ ara Algeria lo kan sara si i pe o da alafia pada si orilẹede naa wọn si ro o wi pe o nilo saa kan sii ni ijọba.
Ẹ yé irọ́ pa, mí o fún Super Eagles ní ẹbùn owó kánkan -Sanwo Olu Ṣé o ti gbọ́ ohun ti Ọọni Ifẹ́ àti Soyinka parí ọ̀rọ̀ Yorùbá sí?
Túndé Atọ̀pinpin ní kí àwọn yẹ yàrá Fọláṣadé wò.
Eeyan mẹwa miran ni awọn ọlọpaa ilu Dubai, ko pọ mọ Hushpuppi ati Woodberry, ninu akanṣe iṣẹ kan ti wọn pe ni 'Fox Hunt 2'.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Aṣọ òkè: Alákọ̀wé ní ọ̀nà láti wá oúnjẹ fáwọn tó ń ṣe aṣọ òkè ló ṣún òun débẹ̀ Amọ, oorun yii gbọdọ wa funra rẹ ni, kii se afioogun pe, eyi to lee sokunfa aisan jẹjẹrẹ, kokoro ti a ko lee fi oju ri ati iku aitọjọ.
Moon ni ipade yii yoo so dundun fawọn eniyan Korean Pennisula.
Inú kò bí mi,ǹ bá rí ẹ̀gún ati pàǹtí ninu rẹ̀,ǹ bá gbógun tì wọ́n,ǹ bá jó gbogbo wọn níná papọ̀.
Ọmọ ọdún mẹ́rìnlá kàwé gboyè jáde ni Oxford Fayemi fojú Alufa to fipa bá ọmọde lòpọ̀ síta l'Ekiti Ìtàn ayé Henry Fajemirokun, olówó tó fi owó mọ Olúwa àti ènìyàn Kí ló mú Obasanjo ti ilẹ̀kùn mọ́ ẹbí, òṣìṣẹ́, ojúlùmọ̀ ní ibi òkú àna rẹ̀?
Ṣaaju ni oshiomole ti rọ ile ẹjọ kotẹmilọrun naa lati gbe idajọ iyọnipo rẹ naa ti ṣdegbẹ kan.
Nítorí náà ni mo ṣe mú kí gbogbo ọ̀rọ̀ majẹmu yìí ṣẹ mọ́ wọn lára, bí mo ti pa á láṣẹ fún wọn pé kí wọn ṣe, ṣugbọn tí wọn kò ṣe.
Wahala ni lọ́tùn-ún lósì, ìjà lóde, ẹ̀rù ninu.
Ẹ̀yin olólùfẹ́ mi àti ẹbí ni mo bẹ̀ Aláàfin yẹ́ Lizzy Anjọrin sí níbi ayẹyẹ ìwúyè rẹ̀ Lizzy Anjorin yóò jàre Toyin Abraham tó bá jẹ́ pé wọ́n lọ sílé ẹjọ́ - Yomi Fabiyi Àwa kìí jà lásìkò tiwa, ta ló bí ẹ tí wàa máa jà?
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Seyi Makinde: Màá fẹ́ káwọn aráàlú mọ ìpa ìjọba mi lára sí rere Sáájú ní ìjọba ti kọ láti fun láàyè láti kọ́lé fún pé, ó ń sí eranko lọ́nà àìtọ́, sùgbọ́n èdè àìyedè bẹ́ sílẹ̀ nígbà to kọ̀ láti jẹ́ ki àwọn aláṣẹ̀ wọ inú ọgbà rẹ.
 Eyi ti o se afihan jagunjagun gbogun ti iwa ibaje ,eyi ti won fi da Aare Orile-ede Naijiria lola nibi ipade ologbon odun ti Ajo isokan ile Afirika  AU ti won sese paari.
"Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Gabola Church: Ẹnu gbẹ ní Ṣọ́ọ̀ṣì wa torí òfin ìséde Covid-19 Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Gabola Church: Ẹnu gbẹ ní Ṣọ́ọ̀ṣì wa torí òfin ìséde Covid-19 25 Ògún 2020 ""Ẹ wa ṣe iribọmi yin pẹlu ọti ti ẹ fẹran ju ninu isin wa ni gbogbo ọjọ Aiku laago mọkanla""."
Victoria Derbyshire tún ṣe ìwàdìí pé obìnrin ilẹ̀ gẹ̀ẹ́sì mii tó ku díẹ̀ kó tó ọmọ ọgbọ̀n ọdún naa tun ku ni eyi ti ìwádìí sì ń lọ lọ́wọ́ lórí ohun tó ṣokùnfà ikú rẹ̀.
Saraki: Ìwà àrékérekè ni ilé mi tí EFCC tì pa Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Bí ìrẹsì tèmi Ayinde bá ń pàkùta, kò tọ́ sẹ́nu aláàrù Barrymaade' Facebook ni ‘Israeli security firm NSO Group’, lo se isẹ ibi yii.
PDP ni aarẹ sẹ awọn eeyan ẹkun iwọ oorun Naijiria pupọ, boya Ọlọrun si da si lati se ọjọ ibi ọdun kejidinlọgọrin ni, ko ba le ni anfaani lati ronu nipa awọn asise rẹ, ko si ronu piwada.
Bakan naa, ohun ti o tun yanilenu, ti o si tun je idagbasoke lorile-ede naa ni, igbakeji aare ti o je obinrin ti o wa lati abe asia egbe oselu to wa lori alefa lowo naa, the People’s Movement for the Liberation of Angola, MPLA.
Ọlọrun ní, “Bí wọn kò bá fẹ́ gbà ọ́ gbọ́, tabi bí wọn kò bá náání àmì ti àkọ́kọ́, ó ṣeéṣe kí wọ́n gba àmì keji yìí gbọ́.
Owo osu ti mo n san fun awọn osisẹ mi gan losoosu lasan sun mọ miliọnu kan naira, elo wa ni ọkunrin kan fẹ fi fa mi loju mọra?
Tí a bá wí pé “Ayára kọ̀lọ̀kọ̀lọ̀ aláwọ̀ èèpẹ̀ fò gborí ọ̀lẹ ajá kọjá”.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ilé ìtura Amazonia ní wọn kó àwọn ọmọ òhun pamọ́ si Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí NUJ ìpínlẹ Oyo bà àwọn ọmọ ẹgbẹ́ tó lọ ìpàdé tí Femi Fani Kayode pè ní Ibadan wí7 Owewe 2020 Fídíò, Natalia Mufutau ìyá Yakub, Kamil àti Adam sọ̀rọ̀ lórí bí wọ́n ń sọ èdè mẹ́rin pàpọ31 Ògún 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Nítorí náà, kí oluwa mi má gba ìròyìn tí wọ́n mú wá gbọ́, pé gbogbo àwọn ọmọ rẹ̀ ni wọ́n ti kú.
Ǹjẹ́ ìwọ mọ̀ pé ẹni tí o wà nínú ìdààmú owó tí a yá lówó tún lè padà kí ó wí pé a yá òun nítorí a jẹ́ amùsùwà ni !
Agbẹnusọ fun ileesẹ ọlọpaa nipinlẹ Ogun, Abimbola Oyeyemi ni ẹkun ileesẹ ọlọpaa to wa nilu Ado Odo ni wọn mu ẹsun naa lọ.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ìkọlù àwọn Fulani Darandaran ti mún ọ̀ps ẹ̀mí lọ Bakan naa, Olori ijọ Living Faith, ti wọn n pe ni Winners Chapel, Bisọọ́bu David Oyedepo ti kepe Aarẹ orilẹede Naijiria, Muhammadu Buhari, lati kọwe fipo silẹ lori ọrọ awọn Fulani darandaran ti wọn n fẹmi awọn eeyan ṣofo.
Femi Fani-Kayode nàá kò gbẹ́yìn Ẹlòmìí tó tún ti ṣe bẹ̀ ẹ́ ni mínísítà fún ìgbòkè-gbodò ìrìnnà ojú òfurufú, Femi Fani-Kayọde, lásìkò tí agbẹjọ́rò rẹ̀, Norrison Quakers, sọ nílé ẹjọ́ lọ̀jọ́ kọkàndínlọ́gbọ̀n, oṣù Kínní, 2018, pé oníbàárà òun kò lè wá fún ìgbẹ́jọ́ nítorí àìsàn tó ní i ṣe pẹ̀lú ọkàn.
kí ẹ máa ṣọ́ àwọn ọmọbinrin Ṣilo bí wọ́n bá wá jó; ẹ jáde láti inú ọgbà àjàrà, kí ẹnìkọ̀ọ̀kan yín ki iyawo kọ̀ọ̀kan mọ́lẹ̀ ninu àwọn ọmọbinrin Ṣilo, kí ẹ sì gbé wọn sá lọ sí ilẹ̀ Bẹnjamini.
Ọwọ́ rẹ̀ ni ìyè gbogbo ẹ̀dá wà,ati ẹ̀mí gbogbo eniyan.
Angẹli náà bá pàṣẹ fún wọn pé kí wọ́n lọ; wọ́n sì lọ.
AWON IKO AGBABOOLU OHUN NI KIKUN:Awon Asole(Goalkeepers): Francis Uzoho (Deportivo La Coruna, Spain); Ikechukwu Ezenwa (Enyimba FC) ati Daniel Akpeyi (Chippa United, South Africa).
Àmúwá Ọlọ́run lásán ní ìṣẹ̀lẹ̀ tó wáyé ní Iba-Eburu Iba Oba Okunoye Ènìyàn 27 lo ti bá iṣẹ̀lẹ̀ ọkọ̀ ofúrufú tó já rìnrìn ajò Ǹjẹ o yẹ kí èèyàn máa sùn lẹ́nu iṣẹ́?
Yéwándé/ Yéjídé/ Yétúndé/ Ìyábọ̀dé/ Yésìdé: Ọmọbìnrin tí a bí ní kété tí ìyá bàbá rẹ̀ kú
Ibọriade: Eyi ni etutu ti wọn n ṣe lati yẹ awọn Ọba ti wọn ti jẹ ṣaaju si.
Ó ní, “Ẹ ṣọ́ ara yín nípa ìwúkàrà àwọn Farisi, àwọn alágàbàgebè.
Rashidi Yekini: Ijọba Kwara ti ṣetán látí má ṣèrántí gbajúgbajà agbábọ́ọ̀lù tó ti dolóògbé
Kò sí ẹni tí ó lè ká èso àjàrà lórí igi ẹ̀wọ̀n agogo tabi kí ó rí èso ọ̀pọ̀tọ́ lórí igi ẹ̀gún ọ̀gàn.
Ìran èké ni wọ́n ń rí; iṣẹ́ asán ni wọ́n ń wò.
Covenant Christian Centre to wa ni Eko sọ pe awọn eeyan yoo kopa ninu isin awọn laarin ago meje alẹ si ago mẹsan alẹ.
Bí bẹ́ẹ̀ kọ́, ẹ gbà mí gbọ́ nítorí iṣẹ́ wọnyi.
Nítorí náà, OLUWA Ọlọrun àwọn ọmọ ogun, àní OLUWA ní: “Ẹkún yóo wà ní gbogbo ìta gbangba, wọn yóo sì máa kọ ‘Háà!
O ti pe ọdun mẹwaa bayi ti gbogbo rẹ bẹrẹ.
irinwó (360)  Bakan naa ni idibo funi
bí ẹ bá lè pa gbogbo òfin rẹ̀ tí mo fun yín lónìí mọ́, tí ẹ fẹ́ràn OLUWA Ọlọrun yín, tí ẹ sì ń rìn ní ọ̀nà rẹ̀, nígbà náà, ẹ tún fi ìlú mẹta mìíràn kún àwọn ìlú mẹta ti àkọ́kọ́.
Ǹ báà gòkè re ọ̀run, o wà níbẹ̀!
Nígbà tí ó kú, kò sí ẹni tí ó sọkún, tabi tí ó ṣọ̀fọ̀ níbi òkú rẹ̀.
Àwọn ìṣẹ̀lẹ̀ abanilẹ́rù ti wáyé ní Azlatt, Sony Malé, Wothie, Walata, Jreida àti nínú àfonífojì.
9 Mo ti ní ìyàwó àfẹ́sọ́nà, ayẹyẹ ìgbeyàwó mi ń bọ̀ láìpẹ́ - Lateef Adedimeji 10 Ọwọ́ tẹ ènìyàn méjì tó ń ta ayédèrú aṣọ iṣẹ́ ikọ̀ Àmọ̀tẹ́kùn BBC News, Yorùbá Ìdí tí ẹ fi le è nígbàagbọ́ nínú ìròyìn BBC Ìlànà Lílò Nípa BBC Òfin Àṣírí Cookies Kàn sí.
N óo wá bá ọ níbẹ̀ láti rú ẹbọ sísun ati ẹbọ alaafia.
Aṣebi a máa tẹ́tí sí ẹni ibi,òpùrọ́ a sì máa fetí sílẹ̀ sí ọ̀rọ̀ ìkà.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Japan Visit: Ààrẹ Shinzo Abe kéde $413,000 owó ìrànwọ́ fún Nàìjíríà 29 Ògún 2019 Oríṣun àwòrán, Twitter/Bashir Ahmad Ijọba orilẹede Japan ti kede iranwọn iye owo to le ni ọkandinlaadọjọ miliọnu Naira, N149,919,000m( $413,000) fun orilẹede Naijiria ni Ọjọbọ ni ilu Yokohama.
Osuolale, gẹ́gẹ́ bíi agbẹjọro àgbà fún ẹgbẹ́ òṣèlú NPN, ẹgbẹ́ Onílé nígbà náà, gba inagijẹ Mr two third ọhun, nítorí bo se kéde lórí redio lọ́dún 1979 lẹ́yìn ibo aarẹ tó gbé Alhaji Shehu Shagari wọlé pé, idà méjì nínú mẹta ìpínlẹ̀ mọkandinlogun tó wà ní Nàìjíríà jẹ́ 12 2/3.
 Gege bi asoju ajo IHRC lorile-ede Naijiria ati awon ile alawodudu yooku, ogbeni Friday Sani, o ni, lataari iwe ateranse kan ti o jade lojo kerindinlogun, osu keta, odun ti a wayii, eleyi ti akowe agba ajo IHRC lagbaye bowolu, ajo naa yan dokita Saraki sara awon asoju re lagbaye.
Lojoojumọ ni wọ́n ń wá inú Ìwé Mímọ́ wò láti rí bí àwọn ohun tí wọ́n kọ́ wọn rí bẹ́ẹ̀.
Bakan naa, Wole Soyinka tun ni awọn aṣayan ọrọ bi owe to fi mọ akanlo ede to ṣe pe ọlọgbọn lo lee tu u.
Tẹ si waju lati lọ fi oogun apakokoro fọ ọwọ rẹ ati finfin ẹru rẹ ni awọn ibi ti wọn ba ti la kalẹ.
Ọgbọ́n ìlà kíkọ yìí kì í ṣe ti gbogbo orílè èdè yìí ni láti ìbẹ̀rẹ̀ bikose ohun tí àwọn ènìyàn orílẹ̀ èdè yí jogún láti Iwọ̀ Oòrùn níbi tí àṣà náà tí kọ́kọ́ bẹ̀rẹ̀.
daruko ohun so pe “A o tesiwaju ninu ifehonuhan naa lati mu ifẹ  ati ipinnu awon ti o ti ku sẹ.
Ẹ ṣora fun ibalopo ai lo roba idaboobo.
Onnoghen ni oun ko jẹbi awọn ẹsun naa.
Ṣugbọn n óo fi ọ̀nà kan tí ó dára jùlọ hàn yín.
Ogiri ile naa wo lu ọmọdekunrin kan to n kọja lọ, o si ku.
Wọn kò fi ipá mú ẹnikẹ́ni, nítorí pé ọba ti pàṣẹ fún àwọn òṣìṣẹ́ ààfin pé ohun tí olukuluku bá fẹ́ ni kí wọn fi tẹ́ ẹ lọ́rùn.
Nene kowe fise sile leyin esun ti won fi kan pe O ni ibasepo pelu ebi Gupta ore aare orile-ede naa teleri, Jacob Zuma leni ti won fesun iwa ibajẹ kan lorisirisi.
"Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: ""Àlàyé rèé lórí bí mo ṣe fi ọsàn híhó fẹ́ ìyàwó mi"" Ọwọ́ tẹ ọkùnrin kan ní pápákọ̀ òfurufú l‘Eko tó ń kó ike ATM 2,886 lọ si Dubai Lẹ́yìn ọ̀pọ̀ ọdún, ìjọba Kwara fẹ́ sọ orúkọ Rashidi Yẹkini di mánigbàgbé Ọ̀kẹ àìmọye ẹ̀rọ àyẹ̀wò káàdì olùdìbò jóná mọ́lé l' Ondo Wo iye àwọn tó ti gbẹ̀mí ara wọn ní Nàìjíríà láàrin ọdún mẹ́rin ìjọba Buhari Lọ́pọ̀ ìgbà, gbígba ẹ̀mi ara ẹni ni òpin fún ọ̀pọ̀ àwọn tó ni àrun to niṣe pẹ̀lú ọ̀pọ̀, bí 'Bipolar', 'Depression', 'Schiophrenia' tó fi mọ́ 'Anxiety disorder'."
Ẹgbẹ agbabọọlu Chelsea ni yoo koju ikọ Arsenal ninu aṣekagba idije FA Cup saa yii ti yoo waye lọjọ Kinni oṣu Kẹjọ ọdun 2020.
Eyi jẹ ni iranti Ọgagun Mobọlaji Johnson to fi igbakan ri jẹ gomina ologun ni ipinlẹ Eko laarin ọdun 1966 si 1967.
Awon torokan gbangban ninu ajo NFF ti lo sabewo si amule iko agbaboolu Super Eagles, Carl Ikeme ti o n gba itoju nile iwosan Christie Clinic, Manchester nilu London.
tí ń ni talaka ati aláìní lára, tí ń fi ipá jalè, tí kì í dá ohun tí onígbèsè rẹ̀ bá fi ṣe ìdúró pada fún un, tí ń bọ oriṣa, tí ń ṣe ohun ìríra, 
SCN: 000014, ati SCN: 000015, ti oun fọwọ si ko ju pe oun ko tii ṣi awọn aṣuwọn ifowopamọsi naa nigba ti oun buwọlu fọọmu akọkọ ni o jẹ ki oun fi sinu fọọmu keji ti oun fọwọ si .
Ẹ ranti àwọn tí wọ́n wà lẹ́wọ̀n, kí ẹ ṣe bí ẹni pé ẹ̀yin náà wà lẹ́wọ̀n pẹlu wọn.
Awọn atipo ẹya Oromo ti wọn wa ni Djibouti sọ fun BBC pe wọn na awọn, bẹẹni wọn ja awọn lole nitori fidio ọhun.
Àwọn obìnrin wọn náà a máa ṣe oríṣìíríṣìí iṣẹ́-ọwọ́, lára wọn ni aró dídá, apẹ ati ìkòkò mímọ àti aṣọ híhun pẹ̀lú.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù 9th Assembly: Olùdíje mẹ́rin ṣàtìlẹyìn fún Gbajabiamila ṣáájú ìbò ilé aṣojú ṣòfin 10 Òkùdu 2019 Oríṣun àwòrán, @femigbaja Àkọlé àwòrán, Femi Gbajabiamila Bi idibo adari ile igbimọ aṣoju ṣofin l'Abuja ti wọle de, awọn oludije mẹrin ọtọọtọ lo ti sọ pe awọn ko ni dupo naa mọ, ti wọn ṣeleri lati ṣatilẹyin fun Femi Gbajabiamila.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Atiku: Ọ̀dọ́ yóò gba isẹ́ 40%, obìnrin yóò mú 30% 11 Ọ̀wàrà 2018 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 22 Bélú 2018 Oríṣun àwòrán, @Atiku Àkọlé àwòrán, Mo ti ṣetan lati sin Naijiria Oludije si ipo aarẹ lẹgbẹ oselu PDP ni Naijiria fun idibo 2019, Atiku Abubakar ti ni ida aadọrin ninu awọn ti awọn yoo jọ se ijọba yoo jẹ ọdọ ati obinrin.
Òwe yìí ni Jesu fi bá wọn sọ̀rọ̀, ṣugbọn ohun tí ó ń bá wọn sọ kò yé wọn.
Marun-un ninu yín yóo lé ọgọrun-un ọ̀tá sẹ́yìn, ọgọrun-un ninu yín yóo sì lé ẹgbaarun (10,000) àwọn ọ̀tá yín sẹ́yìn, idà ni ẹ óo fi máa pa wọ́n.
”Eliṣa dáhùn pé, “Bẹ́ẹ̀ ni, mo mọ̀, ṣugbọn ẹ má ṣe sọ ohunkohun nípa rẹ̀.
Ẹ̀rù èrò ọkàn mi bà mí gidigidi, tóbẹ́ẹ̀ tí ojú mi yipada, ṣugbọn inú ara mi ni mo mọ ọ̀rọ̀ náà sí.
naa sugbon egbe awon osise NLC ko ni kọ lati da si ijiroro naa, ti egbe osise
Russia infanticide: 11,000 ọmọdé làwọn òbí ti pa láàrin ọdún 1976 sí 1997
A ṣetán láti ran àjọ aláàbò alájùmọ̀ṣe lọwọ fún ààbò tó péye nílẹ Yorùbá - Ọlọ́pàá Ogun Buhari, pe ìpàdé àpérò ọmọ Nàíjíríà fún àgbékalẹ̀ òfin tuntun - Afe Babalola Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Eyi ọpọ gbagbọ pe wọn maa n ṣe e ki ọmọ ti wọn bi sọhun lee di ọmọ ilẹ Amẹrika nipa ibi nikan eyi ti ofin fi aye gba tẹlẹ bẹẹ si ni aarẹ Donald Trump bu ẹnu atẹ lu eyi.
Tí a fiṣọwọ́ ní 10:55 29 Èbibi 201910:55 29 Èbibi 2019 Abdulrazak Abdulrahman ti Kwara jẹ́jẹ̀ẹ́ níwájú adájọ́ Video content Video caption: Nigeria Swearing in: Abdulrahman Abdulrazak búra wọle bíi gómìnà tuntun ní KwaraNigeria Swearing in: Abdulrahman Abdulrazak búra wọle bíi gómìnà tuntun ní Kwara Article share tools Facebook Twitter ṢàpínlòView more share options Share this post Copy this linkKà síwájú síi nípa àwọn ìtọ́kasí wọ̀nyí.
kí ó tó já Ijamba ọkọ-ofurufu ologun pa 'yan mẹjọ Iroyin fi han pe ilu Chicago ni orile-ede Amerika ni wọn ti pe ẹjọ naa.
Ìyókù tún di ọdún tí ń bọ̀, kí Ẹlẹ́mìí ó má gbà á.
A kò rin púpọ̀ nígbà tí a bá ọ̀kan pàdé tí o tilẹ̀ di ọ̀rẹ́ wa gidi, Ìrànlọ́wọ́ ni orúkọ rẹ̀ ń jẹ́.
Peteru náà dúró lọ́dọ̀ wọn, òun náà ń yáná.
Bí o bá yọ mí n kò ní í gbàgbé rẹ láéláé èmi yóò mú ọ lọ sí oko àgbẹ̀ kan tí ilá pọ̀ sí, ìwọ yóó sì jẹun ikùn rẹ yóó yọ bọ̀ǹbọ̀.
Oríṣun àwòrán, Mo Styles Àkọlé àwòrán, Ti ara rẹ ba wu wo la lẹ, rọra jẹ oju abo agbo.
Gẹgẹbii abajade iroyin kan lati ọdọ ajọ to n mojuto igbogunti arun lorilẹede Naijiria, eeyan mejilelogoje lo ti ba arun iba lassa lọ lorilẹede Naijiria lati ibere ọdun 2018.
Nínú àwọn tí o wá ni ejò wà, pẹ̀lú ayọ̀ ni wọn fi ń bá wa gbé tó bẹ́l ti n kì í fẹ́ kúrò lọ́dọ̀ wọn nítorí ènìyàn ń fi ọwọ́ ba ọká ní ìrù láìjẹ́ pé ó ń buni ṣan.
Rose Oko, sẹnẹtọ ẹkun ariwa Cross River Lọjọ kẹrinlelogun oṣu kẹta ọdun 2020 yii ni iroyin jade pe sẹnẹtọ to n ṣoju ẹkun ariwa ipinlẹ Cross River, Rose Oko ti papoda.
Iran Laipẹ yii ni awọn obinrin ni orilẹ-ede Iran yoo lanfani lati wo idije bọọlu alafẹsẹgba lori papa fun igba akọkọ lati ọpọlọpọ ọdun sẹyin.
Ileeṣẹ ọlọpaa ni ipinlẹ Ekiti ni ọjọbọ to kọja ni iṣẹlẹ naa ṣẹ nilu Ado Ekiti.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Covid-19 60seconds: Ṣé ìjìnà síra-ẹni ṣe paàtàkì lẹ́yìn lílo ìbòmú?
''O kàn n sọ ọrọ òṣèlú ní.
A ti ṣe àgbékalẹ̀ ìdánilẹ́kọ̀ọ́ ní ilé-ìwé àti ní ìlú ìbílẹ̀ láti tọ́ àwọn èwe sọ́nà, àti àwọn àgbà nígbà mìíràn, láti ṣe àkọsílẹ̀ ìtàn ẹnu àwọn àgbàlagbà, fi ìtàn náà kọ́gbọ́n, àti láti sọ wọ́n di kíkà.
Dafidi bá kọ́ àgọ́ àwọn ọmọ ogun kan sí Aramu, ní Damasku, gbogbo àwọn ará Siria sì ń sin Dafidi, wọ́n sì ń san owó ìṣákọ́lẹ̀ fún un.
“Israẹli, o óo mọ̀ pé èmi ni OLUWA, Ọlọrun rẹ,èmi ni mò ń gbé Sioni, òkè mímọ́ mi.
Ẹgbẹ oṣelu PDP ni adajọ naa n ṣegbe lẹyin APC.
O nioun atawọn mọlẹbi oun ti fi ara wọn si igbele titi di igba ti aisan naa yoo fi wọn silẹ.
 Ọjọ ́ orí ni wọ ́ n máa fi ń ṣe ìjọba ní ilẹ ̀ yìí , obìnrin wọn kìí sìí pẹ ́ ní ọkọ ṣùgbọ ́ n ọkùnrin gbọ ́ dọ ̀ ní owó lọ ́ wọ ́ kí ó tó fẹ ́ aya .
PDPKo si anfaani kankan ti awon omo orile ede Naijiria n je
Oríṣun àwòrán, others Awọn afurasi ti wọn foju wọn han naa ni Nelson Ogbebor, Akato Valentine, Arabinrin Tina Samuel, Arabinrin Mary Ade, Nosa Osabohien ati Collins Ulegbe.
Ẹ̀ṣẹ̀ ni ó fún ikú lóró.
Ní ọjọ́ kan, Iṣiboṣẹti ọmọ Saulu fi ẹ̀sùn kan Abineri pé ó bá obinrin Saulu kan, tí wọn ń pè ní Risipa, ọmọ Aya, lòpọ̀.
Oríṣun àwòrán, Isaac Haastrup Àkọlé àwòrán, Won gbe iwe ibanikedun kale ti awọn eeyan si n fọwọ si Baba Sala jẹ Baba Adura ijọ Kẹrubu ati Serafu ẹka ti Idasa model Parish.
Wonyi ni ekunrere bi ayeye FIFA
Arabinrin mi, iyawo mi,ìfẹ́ rẹ dùn ju waini lọ.
Minisita ni igbesẹ ti ijọba yoo gbe naa ni lati ṣabẹwo si awọn ipinlẹ pada.
Fulani kò leè dúró, táa bá lo ohun ta jogún lọ́dọ̀ àwọn bàbá wa - Sunday Igboho Dangote, jọ̀ọ́ nawọ́ ìrànwọ́ láti dá iléeṣé sílẹ̀ fún wa ní Ọyọ - Aláàfin rawọ́ ẹ̀bẹ̀ Láti orí 'Our Mumu don do' sí 'Revolution Now' Bí ọdún Ọ̀ṣun Oṣogbo ṣe bẹ̀rẹ̀ rèé àti pàtàkì rẹ̀ fún Nàíjíríà Saudi ṣàtúnṣe lílẹ òkò mọ́ Asitani láti dẹ́kun títẹra-ẹni-pa Adeniran wa kilọ fun awọn ara ilu wi pe, awon n sa ipa lati mu awọn to gbe iroyin ẹlẹjẹ yii ni ori ẹrọ ayelujara, ki awọn lee fi wọn jofin ijọba.
Irinajo lati lọ pọnmi fun ina dida ounjẹ aarọ lasan wa di ǹkan ti Fortunate Mukankuranga daran ipaniyan si.
Ati alatako ati awọn ọmọ Naijiria mii, niṣe lawọn eeyan ṣigun bo oju opo Twitter ti wọn si ni ohun to sọ yi ku diẹ kaato.
Kí ẹni tí ó gbọ́n kíyèsí nǹkan wọnyi;kí ó sì fi òye gbé ìfẹ́ OLUWA tí kì í yẹ̀.
 ohun tí ó fà á ti a ó fi mú gíràmà yìí lò nip é ó gbìyànjú láti sàlàyé ìmò àbinibí elédè nípa èdè rè .
Àgbẹ́kọ̀yá yarí; Afẹnífẹ́re ní ilé ẹjọ́ ló kàn lórí ọ̀rọ̀ Àmọ̀tẹ́kùn Ilé ẹjọ́ rán ọmọ ìjọ lẹ́wọ̀n ọdún 18 lórí ẹ̀sùn pé ó jí ₦ 15m owo ìjọ Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Nítorí náà, bí ẹ bá ní ìwúrí kankan ninu Kristi, bí ìfẹ́ rẹ̀ bá fun yín ní ìtùnú, bí ẹ bá ní ìrẹ́pọ̀ ninu Ẹ̀mí, bí ẹ bá ní ojú àánú, 
Coronavirus ti di àjàkálẹ̀ àrùn káàkiri àgbáyé- WHO Coronavirus: Kí ni àwọn àpẹrẹ àrùn náà?
Ṣùgbọ́n kí ó tó dé àwọn ènìyàn pàápàá àwọn ẹ̀gbọ́n rẹ̀ rò wí pé ó ti kú, wọ́n sì ti fi bàbá wọn sílẹ̀ fún àwọn ìyàwó rẹ fún ìtọ́jú.
Ìbẹ̀rù-bojo dé bá mi,wọ́n ń lépa ọlá mi bí afẹ́fẹ́,ọlà mi sì parẹ́ bí ìkùukùu.
Ko tii ju ọjọ mẹta lọ ti awọn afọbajẹ atawọn agbaagba ilu Iru yan an laarin awọn arẹmọ ọba to n du itẹ naa.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Coronavirus and sport: Paul Onuachu ni agbábọ́ọ̀lù Super Eagles Nàìjíríà àkọ́kọ́ tó lùgbàdì Covid 19 9 Agẹmo 2020 Oríṣun àwòrán, @Paul Àkọlé àwòrán, Paul Onuachu ni agbábọ́ọ̀lù Super Eagles Nàìjíríà àkọ́kọ́ tó lùgbàdì Covid 19 Ẹlẹsẹ ayo, ọmọ Naijiria to n gbabọọbu jẹun fun ìkọ Genk lorilẹ-ede Belgium, Paul Onuachu ti ko aarun coronavirus.
mọṣalaṣi ọrun wa lọrun ni ipele meje, ati pe eleyii to sun mọ awa ẹda eniyan ju ni ti Kabbah, to wa ni ilu Mecca.
Bakan naa, iroyin kan sọ pe awọn alaṣẹ ileeṣẹ naa fiwe ransẹ si awọn ileeṣẹ mii ti wọn n ba ṣiṣẹ pe, idaduro ti de ba ipade ojukoju ti wọn maa n se loore-koore, ti wọn si sun awọn ipade wọn si ori itakun agbaye.
Okunrin naa, Leon van Biljon, ni o wọ ile awọn kiniun naa lọ, ni igba ti o fẹ tun odi ti o yi ile naa ka se, ki kiniun naa to kọluu lati ẹyin.
Sakaraya bi angẹli náà pé, “Báwo ni n óo ti ṣe mọ̀?
Bàbá Adamu tó jẹ́ ọmọ ogun Nàìjíríà tó dàgbà jùlọ jáláìsí Fadele rọ àwọn ọ̀dọ́ Naijiria lati pinnu nkan rere fun ẹ̀kọ́ ọjọ ola wọn.
Ọ̀rọ̀ yìí gún àwọn tí ó gbọ́ ọ lọ́kàn tóbẹ́ẹ̀ tí wọ́n fi fẹ́ pa wọ́n.
Bíodun Fatoyinbo ti fojú hàn ní àgọ ọlọpàá Biodun Fatoyinbo fi ipò sílẹ̀ lorí ẹ̀sùn ìfipábánilòpọ̀ COZA: Mi ò fípá bá obìrin lò pọ̀ rí láyé mi - Pásítọ̀ Fatoyinbo Ìdí rèé tí mi ò fi yọjú sí ìgbìmọ̀ àjọ PFN- Fatoyinbo O ni awọn ni igbagbọ pe ile ẹjọ naa yoo se oun to tọ ju nkan ti ile ẹjọ kekere se.
Gbogbo iṣé àṣepatì ni yóò di mìmù ṣe lọgán- Alaṣọadura Ẹ dẹ́kun lílo ilé ìwòsàn àwọn nọ́ọ̀sì abẹ ilé - Àjọ HEFAMAA kìlọ̀ Láìsì nọ́mbà ìdánimọ̀ NIN ní 2020; kò sí ìdánwò- JAMB Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Bí ẹ bá dán ọ̀rọ̀ kòbákùngbé wò - Lai Mohammed Mo kan wàhálà lálẹ ọjọ ìgbeyàwó torí ìbálé mi kò ṣe ẹjẹ - Ìyàwó ọ̀sìngín Ṣe ẹ ri pe kannakanna n'ọmọ ẹga, ija lori ọrọ naa ṣẹṣẹ n bọ ni, ko tii de.
Oríṣun àwòrán, Twitter Brighto Ezekiel Bright 'Brighto' Osemudiame naa jẹ ẹni ọdun mọkandinlọgbọn.
Nitori naa ohun ti awon alakoso egbe ti fenuko le lori lasiko ipade to koja, si duro sibe’’.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Emir of Kano: Gómìnà ìpínlẹ̀ Kaduna fún Sanusi ní ipò tuntun 10 Ẹrẹ̀nà 2020 Oríṣun àwòrán, SANI MAIKATANGA Gomina ipinlẹ Kaduna ti yan Mahammadu Sanusi keji gẹgẹ bi ọkan lara awọn ajọ to n risi ọrọ karakata ni ipinlẹ Kaduna,(KADIPA).
Ẹ gbọdọ̀ fi wúrà yá ère kókó ọlọ́yún yín ati ti èkúté tí ń ba ilẹ̀ yín jẹ́, kí ẹ sì fi ògo fún Ọlọrun Israẹli bóyá ó lè dáwọ́ ìjìyà rẹ̀ dúró lórí ẹ̀yin ati oriṣa yín, ati ilẹ̀ yín.
Oríṣun àwòrán, Amiloaded media hub Gẹgẹ bi ọrọ ti alakoso ọrọ iroyin fun Ọọni, Kọmureedi Ọlafare ṣe ṣalaye fun BBC News Yoruba, Aja kan ti wọn ni arakunrin naa gbe sinu ọkọ ti o si tu silẹ ni awọn agbofinro n le kiri.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Bi eeyan ba lọ si oju opo Twitter tabi Instagram, to si tẹ ọrọ matchmaking sibẹ, yoo ri pe awọn oju opo alarina tọkọ-taya pọ nibẹ jaburata.
Wo àwọn orilẹ́èdè àgbáyé tó ti sí pápákọ̀ òfurufú wọn fún ìrìnàjò Ààrùn coronavirus tún ti ran ènìyàn 499 l'órílẹ̀-èdè Nàìjíríà Nigba to n sọ tẹnu rẹ fun BBC, dokita Anu ni oun kọṣe mọṣẹ, ati pe oun gba iwe ẹri to dantọ.
Ibugbamu ohun waye ni agbegbe Barawe, lakoko ti ifesewonse lo lowo, bee si ni ile-ise olopaa fi mule pe, o seese ki o je awon omo ogun olote al Shabaab lo wa ni idi isele n la ibi ohun.
Nigbati àwọn òbí ti ó fẹ́ràn ọmọ bi Olóògbé Olóyè Ọbáfẹ́mi Awólọ́wọ̀ àti àwọn àgbà ti ó bèrè fún Ominira lọwọ Ilú-Ọba, ṣe Òsèlú, ilú kò rù, pàtàki ọmọ Yorùbá.
Gbogbo wọn ni wọ́n ti dira ogun, tí wọ́n wá sí Heburoni pẹlu ìpinnu láti fi Dafidi jọba lórí Israẹli.
Lassa Fever:Ondo, Oyo, Kwara wà lára ìpínlẹ̀ tó kásáa ibà Lassa
Akẹ́kọ̀ọ́ ìmọ̀ òfin kọ̀ọ̀kan yóò gba ₦500,000 owó ìrànwọ́ l‘Oyo Babangida fun wọn ni idaniloju pe, oun wa pẹlu wọn ninu igbesẹ wiwa ilọsiwaju fun orilẹede Naijiria.
Kínni ife ẹ̀yẹ ti Tiger Woods gbà ní Augusta fi yàtọ́?
Nípa ìyàwó rẹ, má ṣe bẹ̀rù, òun ti bímọ, ọmọ kì í sì í ṣe ọmọ lásán, ọmọ tí yóò gbé orúkọ rẹ ga lẹ́hìn ọ̀la ni.
Diṣoni, Eseri, ati Diṣani, àwọn ni ìjòyè ní ilẹ̀ Hori, wọ́n sì jẹ́ ọmọ Seiri ní ilẹ̀ Edomu.
Ajọ ajafẹtọ ọmọniyan lagbaye, Amnesty International sọ pe ko din ni eeyan mejila to ku nibi iṣẹlẹ naa.
"West to jẹ ẹni ọdun mẹtalelogoji ti bẹrẹ ipolongo rẹ, eyii ti o pe ni ""Birthday Party."
A wá óńjẹ jẹ, ṣùgbọ́n t’ìjayà t’ìjayà ni.
    Wéré ọkùnrin yìí gbá, ó jókòó ti ọmọ aládé ìsàlẹ̀ ilẹ̀ kò sì sí nǹkan tí onítọ̀hún kò ṣe tan láti mú kí inú rẹ dùn.
Wọn óo dojú kọ ọ́ láti ìhà àríwá, pẹlu kẹ̀kẹ́ ogun, kẹ̀kẹ́ ẹrù, ati ogunlọ́gọ̀ àwọn ọmọ ogun.
“Ajo naa tun un tẹpẹlẹ mọ ọrọ rẹ pe ,
Awọn kan n se faaji lọ ni ti wọn ni.
Olori imaamu awọn musulumi Yoruba ni Ilorin, Sheik Abdulkareem Aduranigba to ṣoju fun awọn Yoruba Kwara ati Kogi lo da aba orukọ Akintoye.
Ẹni to bori: Kenya Aṣekagba South Africa Kenya South Africa vs Kenya.
'Orí ló kó ọmọ mi yọ' Ileewosan gba ọmọ silẹ nitori airowo san Ẹbí D'banj sọ̀rọ̀ lórí ikú ọmọ ọdún kan rẹ̀ Tọkọtaya lu ọmọ ni gbanjo fun 400k Awọn alagbatọ jẹ ko di mimọ pe bi kii ba ṣe bi awọn ọga to gba awọn ṣe n mu awọn ni, ko sohun to buru ninu ibaṣepọ to dan mọran.
Pẹlu gbogbo àwọn oriṣa rẹ̀,ó ti wó lulẹ̀ patapata.
"Oríṣun àwòrán, others ""Lẹyin naa alarena yoo tọ ẹbi obinrin ọhun lọ, kii ṣe pe ki ọkunrin mu oruka lọwọ, ko si kunlẹ lati beere pe ki obinrin fẹ ọhun."
Ikilọ sì ti ń lọ káàkiri pé tí wọn kò bá pèsè ọtí ìbílẹ̀ náà pẹ̀lú imọtoto, a jẹ pe ewu ń bẹ ní oko longẹ.
Iroyin taa gbọ ni Ọgbẹni Ibrahim Abdullahi to jẹ Kọmisọna eto ẹkọ ṣe ikede yii nigba to n ba awọn oniroyin sọrọ nilu Gusau, olu ilu ipinlẹ naa.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ìgbà méèló ni ẹgbẹ́ òsìsẹ́ ti yansẹ́lódì lábé Ayuba Wabba?
Naijiria fi ìgbájú mẹ́ta lé Cameroon kúrò ní AFCON Kí ló mú kí àwọn èèyàn máa jẹ ọ̀rọ̀ Adeboye lẹ́nu lórí Twitter Wo àwọn ẹ̀ṣọ́ ara tó tó $40m Diezani Madueke tí ilé ẹjọ́ gbẹ́sẹ̀ lé Ogedengbe Agbógun Gbórò, Akọni tó ń dẹ́rù ba ikú.
Alamojuto ere bọọlu meji rẹwọn he ni Burundi Nàìjíríà wà ní ìsọ̀rí kejì pẹ̀lú Burundi, Madagascar àti Guinea Ẹnu ń kun ààrẹ Burundi tó jú akẹ́kọ̀ọ́ mẹ́ta sẹ́wọ̀n nítorí wọ́n fi nǹkan kun àwòrán rẹ̀ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Oúnjẹ alẹ́ ni wọ́n ń fi Ọ̀ọ̀nì ṣe níbí Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Xenophobia: Naijiria á kọ́kọ́ pèsè ọ̀nà láti bá ẹbí sọ̀rọ̀ fún wọn Ekun Western Cape ati KwaZulu-Natal nibi ti Durban wa naa lo tun tẹlẹ (ACSM).
Kloe ni oun ko fẹran ọkunrin to ba ti pupa ju, bikose dudu, pẹlu afikun pe, oun maa n gun ọkada tabi wọ ọkọ ero tẹlẹ, amọ nibayii, ko seese mọ.
Wọ́n bi í pé, “Ṣé alaafia ni?
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Coronavirus tips: Ìlànà ojúlówó márùn ún tó kápá ìtànkálẹ̀ COVID-19 12 Ìgbé 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 16 Ìgbé 2020 Oríṣun àwòrán, Getty Images Arun Coronavirus ti tan kalẹ jakejado agbaye ti o si ti da ipaiya silẹ toun ti bi iye eeyan to n ko arun naa se n pọ tawọn to tọwọ rẹ ku naa ko si din ku.
Wo bóo ṣe lè mọ̀ ayédèrú Oríṣun àwòrán, Twitter?
Ó fẹ́ tútù nini tí gbogbo aráyé ń gbọ̀n tí wọ́n ń wa'yín keke.
awon teliskopu ofurufu je dida laba lati odun 1923 .
Mo nawọ́ ìpanu aláta tí mo ń jẹ sí i – “ó dáa náà gbà èyí kí o tọ́ ọ wò.
 Ó fi àwọn mìíràn sílé .
Ní ìgbà àtijọ́, ó sọ ilẹ̀ Sebuluni ati ilẹ̀ Nafutali di yẹpẹrẹ, ṣugbọn nígbà ìkẹyìn yóo ṣe ilẹ̀ àwọn tí ó ń gbé apá ọ̀nà òkun lógo, títí lọ dé òdìkejì odò Jọdani, ati Galili níbi tí àwọn ọmọ orílẹ̀-èdè mìíràn ń gbé.
Mo ṣe ìlérí fún ọ, mo bá ọ dá majẹmu, o sì di tèmi.
Akọ̀wé APC ní Ìpínlẹ̀ Ekiti, Taiwo Olatunbosun, ni ibanujẹ́ ńláálà ni iku reẹ̀ jẹ́ fun gbogbo ọmọ ẹgbẹ́ náà ní Ekiti.
Kí gbogbo yín lè bá OLUWA Ọlọrun yín dá majẹmu lónìí, 
Òògùn olóró tí àwọn ọmọ Naijiria ń tà ló fa ìkọlù - South Africa Ṣé Zimbabwe dùn gbé bí lásìkò yìí ju àkókò ìṣèjọ̀ba Mugabe lọ?
ati awọn ọdaran yii, ti won yoo si foju wina ofin.
Awọn miran ti lẹ n se awada wipe se Access Bank yoo tun gba oju opo ikansiraẹni Twitter ti Diamond Bank.
Ile iwe tawon elede geesi to wa ni Arusha ni orile-ede Tanzania ti wole pada lojo Aje leyin ti oko-ofurufu ti gbe awon meta pere tori ko yo ninu ijmba oko to sele naa lo si orile-ede America fun itoju.
Abdullahi Haruna ni ipinlẹ Kano yii naa lo gun Mujitapha Musa ọrẹ rẹ pa lẹyin ti wọn ni ariyanjiyan lori idije El Classico laarin Real Madrid ati Barcelona loṣu kẹta ọdun yii.
nítorí àwọn baba wa ti ṣe aiṣododo, wọ́n sì ṣe nǹkan burúkú lójú OLUWA, Ọlọrun wa.
Ó fi ìmọ́lẹ̀ bora bí aṣọ,ó ta ojú ọ̀run bí ẹni taṣọ.
Ajọ eleto aabo ẹṣọ oju popo ti a mọ si Federal Road Safety Commission.
Nkan mii to ṣeeṣe ki o waye ni pe awọn ọmọ ile aṣofin agba le daba lasiko ti wọn ba n dibo ki Trump fipo silẹ pe ki o ma le di ipo miran mu lọjọ iwaju.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù ENDSARS Protest: Akẹ́kọ̀ọ́ àti ọ̀gá iléèwé ń kérora torí ìdánwò NECO tó ṣún síwájú 3 Owewe 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 19 Ọ̀wàrà 2020 Oríṣun àwòrán, @Gidi_Traffic Awọn akẹẹkọ ati ọga ileewe to n kopa ninu idanwo NECO, ti ke gbajare sí ijọba lati wa ojutu si ọrọ iwọde ENDSARS to gbòde.
Bí ó bá jẹ́ pé OLUWA ni ó gbé ọ dìde sí mi, kí ó gba ẹbọ ẹ̀bẹ̀, ṣugbọn bí ó bá jẹ́ pé eniyan ni, kí ègún OLUWA wá sórí olúwarẹ̀, nítorí wọ́n lé mi jáde, kí n má baà ní ìpín ninu ilẹ̀ ìní tí OLUWA fún àwọn eniyan rẹ̀.
Ni ipinlẹ Eko, awn ọlọpaa naijiria ni awọn ti mu oṣiṣẹ aṣọbode meje lori sun pipa arabinrin Patience Oni ti wọn si mu ki eniyan kan fara pa ni ile epo Forte Oil lba orita Badagry nipinlẹ Eko.
Sowore to ṣagbatẹru iwode ''Revolation Now'' sọrọ yii nibi ijiroro itagbangba lori abadofin naa lọjọ Aje, ọjọ kẹsan an oṣu kẹta ọdun 2020.
Arabinrin oluwọde ti ọlọpaa ko pa awọn arakunrin rẹ Aworan kan jade lori ayelujara to ṣafihan arabinrin kan, Ugwu Blessing Ugochukwu to joko sori ere kan pẹlu omije loju ati aṣia orilẹede Naijiria lọwọ rẹ eyi to rinlẹ lori ayelujara.
Àwọn ọmọ Lefi yóo wí ketekete fún gbogbo àwọn ọmọ Israẹli pé:
Sara wí pé, “Ọlọ́run ti pa mí lẹ́rìn-ín, gbogbo ẹni tí ó bá gbọ́ ni yóo sì rẹ́rìn-ín.
Má gbé ara rẹ lọ́kàn gbóná; ibi ni àyọrísí rẹ̀.
, Duration 1,0927 Ẹrẹ̀nà 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Chief Daddy Gbogbo aye ti mọ Ebony Life pe wọn maa n gbe fiimu jade lopin ọdun ni.
N óo gba òun ati Jerusalẹmu lọ́wọ́ ọba Asiria.
Ó dáhùn, ó sí wí pé: ‘Olówó-ayé, nǹkan kan wà tí mo fẹ́ẹ́ sọ fún ọ lónìí, mo fẹ́ ki’o ṣe àkíyèesí nǹkan náà kí o sì fi ṣe àríkọ́gbọ́n.
Wọn wa fikun wi pe awọn ti dẹkun lilo paali naa nitori bi awọn eniyan se bu ẹnu atẹ lu u.
eyi ti alakatakiti omo orile-ede Burkina Faso Malam Ibrahim Dicko dari re nigba naa.
Agbẹnusọ fun ile iwe naa to ba BBC sọrọ ṣalaye pe, oṣu kẹrin ọdun yii awọn mejeeji ni ibalopọ ṣugbọn kii ṣe ninu ọgba ile iwe naa.
Alix Fox: Ìdáhùn yẹ nise pelu ìdí tí ó kii fi lọ roba ifaabobo tẹ́lẹ̀.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ibadan Oba Crisis: Lekan Balogun ní ìjọba kò pe àwọn sípàdé kó tó gbé ẹjọ́ kúrò nílé ẹjọ́ 20 Bélú 2019 Oríṣun àwòrán, Others Awọn ọba mọkanlelogun to n de ade lẹyin Olubadan tilẹ Ibadan ti fesi lori iroyin kan to n ja rainrain nilẹ pe ileeẹjọ ti fẹ gba ade lori wọn.
Lẹ́yìn náà ni ìran àwọn ará Kenaani tàn káàkiri.
N óo fi ọ́ lé àwọn olólùfẹ́ rẹ lọ́wọ́, wọn óo wó ilé oriṣa ati ibi ìrúbọ rẹ palẹ̀.
ó sì gbà wá lọ́wọ́ àwọn ọ̀tá wa,nítorí pé ìfẹ́ rẹ̀ tí kì í yẹ̀ wà títí lae.
Alaga igbimọ amuṣẹya ti ijọba gbe kalẹ, Boss Mustapha lo kede aṣẹ yii lasiko to n ba awọn akọroyin sọrọ nilu Abuja lọjọ Aje.
Arakunrin Joseph wa rọ awọn ọmọ ile iwe fasiti Akungba ti o faragba nibi isẹlẹ naa, ati awọn ti o soju wọn lati wa si agọ ọlọọpa fun ẹri nitori ko tii si ẹri wi pe awọn ọlọ́pàá SARS naa fi iya jẹ akẹkọọ.
kí ogunlọ́gọ̀ eniyan wọnyi óo sọ wọ́n lókùúta, wọn óo sì gún wọn ní idà.
Olusola wa ro awọn ọmọ ipinle Ekiti lati maa lowo ninu iwa ijamba sugbon egbe oselu PDP yoo gbe igbese lati ja fun ẹtọ wọn labe ofin.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Bill, Melinda Gates: Ebi, ikú ìyálọ́mọ àti ọmọ wẹ́wẹ́ nìsòro Nàíjíríà 23 Ẹrẹ̀nà 2018 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 19 Owewe 2018 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Bill Gates ati iyawo rẹ, Melinda lo da ajọ naa silẹ Abajade kan ajọ Bill ati Melinda Gates Foundation maa n gbe jade ni ọdọọdun lori itẹsiwaju ọmọ eniyan ni agbaye ti fi han wipe nigba to ba maa di ọdun 2050, awọn ọmọ Naijiria ati Congo ni yoo jẹ ida mẹrin ninu mẹwaa awọn to toṣi ju ni agbaye.
Igbesẹ Google yi ko ṣẹyin ikede aarẹ Amerika Donald Trump pe ohun fẹ da aabo bo ẹrọ alatagba kọmputa orileede naa lọwọ awọn aṣebi lati ilẹ okere.
Tí ó bá ń kọjá lọ, tí ó sì ti eniyan mọ́lé,tí ó pe olúwarẹ̀ lẹ́jọ́,ta ló lè yẹ̀ ẹ́ lọ́wọ́ wò?
Akọkọ nibẹ ni aba ti o n risi ẹka igbokegbodo ọkọ ati eleyi ti o n se amojuto ẹka eto ekọ.
Ó sì mú lára ẹ̀mí tí ó wà lára Mose, ó fi sára àwọn aadọrin olórí náà.
Peter's Basilica, ọjọ kini, oṣu kini ,ọdun 1000 de, o kọja lọ ṣugbọn aye o ma parẹ lọjọ naa.
Phone Battery: Wo bí o ṣe lè jẹ́ kí bátììrì fóònù rẹ pẹ́ síi
Makinde júwe ilé fún Kọmíṣọ́ná iṣẹ́ òde, ó ṣe pàsípàrọ̀ àwọn kọmíṣọ́nà méjì míì Ẹgbẹ́ àwọn awakọ̀ epo rọ̀bì NUPENG so ìyanṣẹ́lódì tí wọ́n gùnlé l'Eko rọ̀ Ẹgbẹ́ òṣèlú ZLP gbàmí tọwọ́tẹsẹ̀ láti díbò gómínà ní Ondo- Agboola Ajayi Buruji Kashamu jẹ́ ènìyàn tó nífẹ̀ aráàlú- Gómínà Dapo Abiodun Ki lo ti ṣẹlẹ sẹyin?
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Theresa May bú sẹ́kún, ó ní òun kò ṣe olóòtú ìjọba UK mọ́ 24 Èbibi 2019 Àkọlé àwòrán, Pẹlu omije ni May fi ṣe ikede rẹ ni adugbo Downing Olootu ijọba ilẹ Gẹẹsi, Theresa May ti kede ọjọ ti yoo kuro lori aga iṣakoso.
Awọn ipinlẹ to ti pin ounjẹ tiwọn tan: Ipinlẹ Zamfara ati Bauchi wa lara awọn ipinlẹ to sọ pe wọn ti pin ounjẹ Covid-19 awọn tan nitori wọn ni ko si ounjẹ Kankan mọ nile ti wọn ko pamọ si.
Adájọ́ yọ ọwọ́ ní ẹjọ́ Sowore CBN dín owó sísan lóri lílo ATM kù Woli Arole, Gbenga Adeyinka àtàwọn míràn kẹ́dùn 'Sweet Steve' Wò ìdí tí téélọ̀ rẹ fi já ọ kulẹ̀ lásìkò ọdún Kérésìmesì Sugbon báyìí, ilé ẹjọ́ ni kí gbogbo àwọn mẹ́tàlá náà lọ roọkun sì ọgbà ẹ̀wọ̀n Olokuta ni ipinlẹ Ondodi ìgbà tí igbejo wọn yóò bere ni ọjọ́ kẹta oṣù, Kínní ọdún tó ń bọ̀.
Ó ti pa èèyàn 172 ni Nàìjíríà - WHO Díẹ̀ ló kù kí ọjọ́ ìkúnlẹ̀ di ọjọ́ ikú fún ìyá mi lọ́jọ́ tó bí mi - Seyi Makinde Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ìgbátí ìgbámú àná látọwọ́ sọ́jà obìnrin ti bá arákùnrin náà dé iléèwòsàn Ajọ DAWN ṣalaye wipe ihuwasi aṣa ati ede awọn to n gbe lẹkun Guusu-Iwọ Oorun yatọ si idi ti wọn if gbe ikọ Amotekun kalẹ.
Ọlọrun, ki a si fara jin fun Un.
Ikọ agbabọọlu Naijiria nilo lati jawe olubori nigba ti wọn ba koju Ukraine lati le tẹsiwaju si ipele komẹsẹọyọ.
Nígbà tí Jesu sọ ọ̀rọ̀ rẹ̀ tán, Farisi kan pè é pé kí ó wá jẹun ninu ilé rẹ̀.
Àwọn àkànpọ̀ igi náà wà lọ́tọ̀ọ̀tọ̀ ní ìsàlẹ̀, ṣugbọn wọ́n so wọ́n pọ̀ ní òkè ní ibi òrùka kinni, bẹ́ẹ̀ ni wọ́n ṣe àwọn àkànpọ̀ igi kinni ati ekeji fún igun mejeeji àgọ́ náà.
Agbegbe Jeppestown to sunmọ Johannesburg to jẹ ibudo itaja nla gan an ni iṣẹlẹ yii ti kọnilominu julọ.
Ibile Akinyele ati ijoba Ibile Ona-Ara, eleyii to mu ki won fagile eesi idibo
Gẹgẹ bi iroyin naa ṣe sọ, ikọ SARS yinbọn pa ọkunrin naa tan wọn si na papa bora.
"O ni ""Ọrọ aje orilẹ-ede wa ko ṣe dede nitori awọn to n ṣelu ko gbọ eyii ti awọn ara ilu n ṣe bikoṣe eyii ti ajo IMF ati banki agbaye ba sọ."
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Boxing Day Derby: Arsenal rọ̀jò ẹ̀sẹ́ lé Chelsea lórí, 3-1 ló parí sí ní Emirates 26 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Oríṣun àwòrán, Reuters Xhaka ati Bukayọ Saka wa lara awọn agbabọọlu to gbimọran pọ ṣe Chelsea ṣakaṣaka lọjọ Boxing Day.
Nibi ijoko wọn to waye loni, awsn asoju-sofin ti pasẹ fun ileesẹ asọbode ilẹ wa pe ko gbẹsẹ kuro lori ofin to fi de gbigbe eroja epo rọbi lọ si awsn ilu to wa leti bode orilẹede yii.
Nítorí wọ́n rò pé yóo ti rẹ̀ wọ́n, ebi yóo ti máa pa wọ́n, òùngbẹ yóo sì ti máa gbẹ wọ́n, ninu aṣálẹ̀ tí wọ́n wà.
Àkọlé àwòrán, Michelle n sabewo sawon oju opo kan lori erọ kọmputa Awọn oniroyin Senegal ni iroyin ofege ti gbilẹ lẹnu perete ki idibo waye.
Oba Lamidi Adeyemi 111; Olubadan ti ile Ibadan, Oba Saliu Adetunji,
" Ẹ yàgò fún gbájúẹ̀, a kò tíì gba ẹnikẹni fún iṣẹ́ tíṣà - Ìjọba Ọyọ lọgun Ọdún iṣu tuntun wáyé ní Ilé Ifẹ̀, Ọọ̀ni rawọ́ ẹ̀bẹ̀ sáwọn àgbẹ̀ àti darandaran Gbígba onídùròó Zakzaky ṣàfihàn àṣeyọrí ìfaradà wa lásìkò ìfìyajẹni - Shiite Ó tó gẹ́ẹ́!
Ogun nla ni Ogun Kiriji jẹ ninu itan Yoruba.
Ẹsun oniga mọkandinlogoji ni wọn fi kan an ni ileẹjọ giga ti ipinlẹ Eko, amọ ileẹjọ to ga julọ lorilẹede da ẹjọ naa nu, ti wọn si ni ki Ajọ EFCC ṣẹṣẹ bẹrẹ igbẹjọ rẹ lati ibẹrẹ.
Wọn ni ilana agbekalẹ eto Amotekun gbọdọ wa nibamu pẹlu ilana sise isẹ ọlọpa agbegbe tijọba apapọ gbekalẹ nitori ojuse tolori tẹlẹmu ni lati ri si eto aabo orilẹede yii.
Bashir Umar to ri ẹgbẹrun lọna mẹtadinlogoji owo pọun ilẹ okeere he ni papakọ ofurufun ti Kano ni wọn ti da lọlaMo mọ̀ọ́mọ̀ dá €37,000 ti mo rí he padà ni -Ọmọ ogun Bashir.
Bi awọn kan ṣe n dunnu pe iru rẹ waye, ni awọn kan n yọ ṣuti ete si i.
Ọlọrun, gbọ́ ìráhùn mi;pa mí mọ́ lọ́wọ́ ìdẹ́rùbà ọ̀tá;
Ó kọlu gbogbo àkọ́bí ilẹ̀ wọn,àní, gbogbo àrẹ̀mọ ilẹ̀ wọn.
Ọọnirisa pa àwọn aṣàtìpó lẹ́rin ayọ̀ ni Ibùdó Wasa Osun rerun election: A kò ní gba èsì àtúndì ìbò tó wáyé-PDP Oyetọla ní àsìkò ọ̀rọ̀ kòì yá lórí ìbò Ọṣun báyìí Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Bakan naa ni ibudo ayẹwo pọ yika papa iṣere ti eto naa ti waye lalẹ ọjọ Ẹti.
Nítorí náà ni mo fi jẹ́ kí àwọn wolii mi ké wọn lulẹ̀, mo ti fi ọ̀rọ̀ ẹnu mi pa wọ́n, ìdájọ́ mi sì yọ bí ìmọ́lẹ̀.
Sùgbọ́n kò tíì yé bóyá ààrẹ Buhari yóò gbà láti fara hàn níwájú ilé ìgbìmọ̀.
Èyí tí ó tilẹ̀ tún burú jù ni pé ìlú náà pàápàá ti kéré jù wọn kò sì tilẹ̀ mọ́ ọn níbòmíràn jù bẹ́ẹ̀ lọ, ojú a sì máa tí mí ní ìdálẹ̀ nígbà tí wọ́n bá béèrè ìlú mi.
'Irọ́ ni Lai Mohammed pa pé #3.
Ida ọgbọn ninu ọgọrun owo osu rẹ gẹgẹbii ajẹmọnu owo fun atunse ọkọ.
5 164976 Orilẹede Kenya 1526 3.
Bó ṣe n lọ ni àwọn ipinlẹ tó kù Awọn ipinlẹ yoku bii ipinlẹ Ekiti, Ondo ati Ọsun ti seto idibo gomina tiwọn, ti wọn ko si ni kopa ninu eto idibo gomina ti yoo waye lawọn ipionlẹ yoku lọ̀dun 2019.
Iwe naa ni Adebayo Faleti fi yaworan ohun ti awọn eeyan la kọja ṣaaju ominira lọwọ amunisin oyinbo ati ti eeyan dudu to wa ni ipo adari.
 ninu imo isiro itumo nomba ti s ' akomo awon nomba afoyemo bi ida ( fraction ) , nomba apaosi ( negative ) , tikonionka ( transcendental ) ati nomba tosoro ( complex ) .
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Sleeping at work: Ǹjẹ o yẹ kí èèyàn máa sùn lẹ́nu iṣẹ́?
 Akintayo wa gba awọn eeyan nimọran lati dẹkun bíbu ẹnu atẹ lu gbogbo Nọọsi, tori awọn n ṣiṣẹ kara lati doola ẹmi awọn alaisan ni."
Àti pé kíló kù nlẹ̀ tí ng kò tíì ṣe?
Fọláṣadé wà lára àwọn tí wọ́n bí séèfù lójú rẹ̀ ní ilé Orímóògùnjẹ́ tí wọn kò bá nnkan kan níbẹ̀.
Ewe, West bere aye re gege bi agbaboolu ninu iko Obanta United ki o to darapo mo iko agbaboolu miran lorisirisi O kopa fun Sharks, Enugu Rangers, Julius Berger, Auxerre, Internazionale, AC Milan, Derby County, Kaiserslautern, Partizan, Al-Arabi ati Plymouth Argyle.
Ṣe ọkàn rẹ gírí, jẹ́ kí á jà gidigidi fún àwọn eniyan wa, ati fún àwọn ìlú Ọlọrun wa; kí OLUWA ṣe ohun tí ó bá dára lójú rẹ̀.
" Barrister ló sọ mí di èèyàn ńlá - Ayinla Kollington Supreme Court : Oyetola fẹ̀yìn Adeleke janlẹ̀ nílé ẹjọ́ tó ga jù lọ!
O tun ṣiṣẹ oniroyin nile igbohun safẹfẹ ti ijọba apapọ Naijiria, eyi ni Radio Nigeria, ni ọdun 1970 si ọdun 1971.
Mercy Aigbe Gbajugbaja oṣerebinrin fi ọpọlọpọ ọrọ ati aworan sita ni ipa tirẹ lati waasu didẹkun iwa ifipabanilopọ.
Wo ìṣẹ̀lẹ̀ márùn-ún tí kò bá pín Nàíjíríà sí yẹ́lẹ-yẹ̀lẹ Iwe yii fọrọ yaworan itan iran Yoruba ninu iṣẹlu, awọn ohun to ṣẹlẹ ṣaju ominira ati awọn ọna ijijangbara oriṣii ti awọn eeyan n lo lati fi bọ ninu ajaga ijẹgaba ninu itan Adulawọ.
Ẹni tí ó wá láti òkè ju gbogbo eniyan lọ.
Ọsan ọjọru lo yẹ ki wọn o gunlẹ si Naijiria, ṣugbọn obinrin alaboyun kan to jẹ ara wọn bimọ sinu baalu, eyi to mu ki wọn o ni idaduro diẹ.
Ajọ EFCC ti ẹka ti o wa ni Ibadan fi ẹsun ole jija ati yiyi iwe lori iye owo ti o to milliọnu mẹrinlelọgọfa naira.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ìjà ẹ̀sìn Kaduna dènà ètò àgùnbánirọ̀ Fayoṣe: Mi ò jẹ̀bi ẹ̀sùn kankan Paul Biya wọlé s'ipò àarẹ Cameroon fún ìgbà kejèe Akori arokọ naa ni: Ṣé Ọ̀dọ́ Afrika ti ṣetán fun ipò adarí nínú òṣèlú?
Ọmọ Yoruba di ẹni akọkọ to kawe f'ọgọfa wakati
Osinbajo, alaga egbe APC, Adams Oshiomhole,adari egbe  APC, Bola Tinubu ati awon gomina lati ipinle
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìdíje Madrid, Juventus: Àwọn àwòràn mánigbàgbè 12 Ìgbé 2018 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ronaldo gbá bọ́ọ̀lú (penalty) wọlé Mario Mandzukic ló kọ́kọ́ gbá góòlù wọlé ní iṣẹ́jú kejì Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Mario Mandzukic ló kọ́kọ́ gbá góòlù wọlé ní iṣẹ́jú kejì Mario Mandzukic tún jẹ góòlù míràn ní ìṣẹ́jú kẹtàdínlógójì Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Mario Mandzukic tún jẹ góòlù míràn ní ìṣẹ́jú kẹtàdínlógójì Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Mario Mandzukic tún jẹ góòlù míràn ní ìṣẹ́jú kẹtàdínlógójì Isco góòlù ṣùgbọ́n alamójútó ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ naa wọ́gilé e Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Isco góòlù ṣùgbọ́n alamójútó ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ naa wọ́gilé e Àṣìṣe aṣọ́lé e Real Madrid, Navas fún Juventus láǹfàní láti gbá bọ́ọ̀lù kẹta wọ àwọn rẹ̀ Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Àṣìṣe aṣọ́lé e Real Madrid, Navas fún Juventus láǹfàní láti gbá bọ́ọ̀lù kẹta wọ àwọn rẹ̀ Matuidi gbá góòlù kẹta sínú àwọ̀n Real Madrid lati sọ àpapọ̀ góòlù ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ wọn di mẹ́ta-mẹ́ta, 3-3.
Bí àlejò èyí bá dé, á ní ‘Ẹ kú aájò o, Olúwa á mú ẹsẹ̀ rẹ̀ padà sí ilé o’.
Àwọn ọkunrin ìlú náà wá sọ́dọ̀ Eliṣa, wọ́n sọ fún un pé, “Ìlú yìí dára gẹ́gẹ́ bí ẹ̀yin náà ti mọ̀, ṣugbọn omi tí à ń mu kò dára, bẹ́ẹ̀ ni ilẹ̀ náà sì jẹ́ aṣálẹ̀.
”0gbeni Dare wa fokan awon onibara bale pe ajo NCC ko ni
Ọ̀dọ̀ fásitì jànkàn Oxford ló ti jáde À kò gba owó kankan lọ́wọ́ àwọn ẹgbẹ́ agbésùmọ̀mí ISWAP- MURIC ‘Àwọn òlóṣèlú kò ní ìwà ọmọlúwàbí ló jẹ́ kí wọ́n má a lọ láti ẹgbẹ́ òṣèlú kan lọ sí òmìràn’ Àmọ̀tẹ́kùn gbéra!
Ìgbésẹ̀ tí ó gbé láì pẹ́ yìí láti ṣe ìgbẹ́jọ́ Adájọ́ Àgbà orílẹ̀ èdè  tí ó ti sún mọ́ ìbò ààrẹ  ni Àjọ Adájọ́ orílẹ̀ èdè Nàìjíríà  Nigerian Bar Association pè ní “àwòṣe ìkọlù ní lemọ́lemọ́ ní orí àwọn àgbà ẹ̀ka ìjọba méjèèjì tí-kò-gbáralé ìjọba” ní abẹ́ ìṣàkóso Buhari.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Asisat Oshoala: ìbẹ̀rẹ̀ mi kò rọrùn rárá nínú eré bọ́ọ̀lù Loju akọnimọọgba Emery, Iwobi gbiyanju ninu idije naa fun odindin iṣẹju aadọrun un idije ọhun.
Yatọ si eyi, Ọgbẹni Nkrumah sọ pe irọ ni pe awọn fi ọmọ Naijiria bi i 700 sì ẹ̀wọ̀n lai nidi.
West Ham vs Chelsea: West Ham fi omi àbùkù wẹ Chelsea láwọlé sùn, Arsenal yìnbọn pa Norwich
Ajafẹtọ ọmọniyan lori iwa ipa akọ si abo kan ni Naijiria, Dorothy Njemanze sọ fun BBC pe bi iṣẹlẹ ọhun ṣe n peleke si ni Naijiria n kọ oun lominu.
’ rèé Afọnja, ẹni tó finú wénú ní Ilọrin, àmọ́ tó jẹ iwọ Ẹfunsetan Aniwura, obìnrin tó ju ọkùnrin lọ Ọ̀rọ̀ǹpọ̀tọ̀niyùn, Aláàfin obìnrin àkọ́kọ́ rèé, tó ní nǹkan ọkùnrin Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ìran kan si ìkejì ló n gbèrò láti ṣe ìrú ìgbéyàwo àjùmọ̀ṣe 'Shao' fọ́mọ wọn Akọwe agba ni o ni ibi ti ẹ le lọ loju opo ayelujara ile iṣẹ to n ri si ọrọ abẹnu lati wo o boya ijọ yin ni iwe aṣẹ""."
Kò pẹ́ rárá, lẹ́yìn náà, ọmọ ogun tí ń ṣọ́ ọ̀nà tí ó wọ ìlú rí ogunlọ́gọ̀ eniyan, wọ́n ń bọ̀ láti ọ̀nà Horonaimu, lẹ́bàá òkè.
OLUWA ní,“Wò ó, àwọn eniyan kan ń bọ̀ láti ilẹ̀ àríwá,orílẹ̀-èdè ńlá ń gbéra bọ̀ láti òpin ayé.
5m 20 Ẹrẹ̀nà 2019 Oríṣun àwòrán, Facebook/Atiku Abubakar Àkọlé àwòrán, Ẹto idibo aarẹ Oludije fun ipo aarẹ labẹ asia ẹgbẹ oselu PDP, Alhaji Atiku Abubakar sọ pe, ẹrọ kọmputa ajọ eleto idibo INEC fihan pe ibo to le ni miliọnu kan aabọ, l'oun fi bori aarẹ Muhammadu Buhari, to n soju ẹgbẹ oselu APC ninu idibo aarẹ to lọ.
'Ìwadìí yòó yàtọ̀ lórí ilé tó wó nítorí ààrẹ ti gbọ́ síi' Èèyàn mẹ́sàn-án ti kú ní ilé alájà tó wó l'Eko Akọrọyin wa to kalẹ sibi ti wọn ti n wo awọn ile naa ti n fi awọn aworan ile ti wọn yoo wo ranṣẹ si wa Àkọlé àwòrán, Aworan ọkọ katapila nibi ti ile ti wo nilu Eko Àkọlé àwòrán, Ile ti ijọba fẹ wo ni Lagos Island Lara ohun ti awọn eeyan ke ni gbajare lasiko ti wọn doola ẹmi awọn ti ile wo pa ni Ita faji lọjọru ni pe ki ijọba wa wọrọkọ fi ṣada lori awọn ile to fẹ wo tan ti awọn eeyan wa ninu wọn.
Oríṣun àwòrán, others Ìròyìn ayọ ló jẹ́ nígbà ti Lizzy Anjonrin kéde síta pé òun ti ṣe ìgbéyàwó lọ̀jọ́ kẹrìndínlógún, oṣu Kẹjọ.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Ki ni awọn Fulani n sọ bayii?
''Arakunrin Palmer n mura lati lo gbe awọn eniyan ọgbọn ti wọn fẹ wọ ọkọ naa lọ si ibi ayẹyẹ, ko to di wi pe o bẹrẹ si ni gbo oorun bẹntirol ninu ọkọ'' ''O wa ọkọ naa gunlẹ, to si lo ṣi ibi éngine'ọkọ, ni eefi ba yọ, ti ọkọ naa si gbina.
Oníṣòwò kan wó ọ́fíìsì Nàìjíríà ní Ghana lulẹ̀, ìjọba Nàìjíríà faraya O sọ pe ọkọ aladani ọga oun lo pada gbe jade kuro ni ile ijọba, to si fi ọkọ ijọba to da wahala silẹ sibi ti ọrọ ti waye.
Ṣé o óo máa dẹ́rùba ewé lásán tí afẹ́fẹ́ ń fẹ́ kiri,tabi o óo máa lépa ìyàngbò gbígbẹ?
Bakan naa, ileeṣẹ Ọlọpa ti fi ikede sita pe awọn ti ran ikọ amuṣẹya lọ si oriko iṣẹlẹ naa lọgan.
Lalẹ oni si laa mọ ẹni ti yoo jade kuro ninu ile ẹlẹkọ agba.
 nígbà tí ó bá ti fi pàṣán kẹta na ilẹ ̀ lẹ ́ ẹ ́ kẹ ́ ta tí ó sì tún pe orúkọ ẹni tí ó ti kú náà , ẹni tí ó ti wà nínú igbó ìgbàlẹ ̀ yóò dáùn , yóò sì máa bọ ̀ pẹ ̀ lú aṣọ fúnfún báláú lọ ́ rí rẹ ̀ .
Josẹfu rí àwọn arakunrin rẹ̀, ó sì mọ̀ wọ́n, ṣugbọn ó bá wọn sọ̀rọ̀ pẹlu ohùn líle bí ẹni pé kò mọ̀ wọ́n rí, ó ní, “Níbo ni ẹ ti wá?
Awọn eeyan naa ti wọn ba BBC Yoruba sọrọ ṣalaye pe ijọba Gomina AbdulRahman AbdulRazaq ko laṣẹ lati wo ile ọhun nitori ọrọ ile naa wa nile ẹjọ.
Ó dáa ẹ jẹ́ ká mú’kan níbẹ̀ ká gbé e yẹ̀wò.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Àwọn akẹ́ẹ̀kọ́ ni Ọ̀jọ̀gbọ́n tó ń bèèrè ìbálòpọ̀ lọ̀wọ̀ akẹ́ẹ̀kọ́ kò ṣẹ̀ṣẹ̀ máa ṣe bẹ́ẹ̀ 11 Ìgbé 2018 Oríṣun àwòrán, @OfficialOAU Àkọlé àwòrán, Fásitì OAU ní ààbò àṣírí wà fún akẹ́kọ̀ọ́ yóówù tó bá ta àwọn aláṣẹ fásitì náà lólobó ìwà ìbàjẹ́ Ọ̀jọ̀gbọ́n kan nílééwé fásitì OAU Ile-Ife, ni ariwo rẹ̀ ti gbòde kan báyìí pé ó bèèrè àti bà akẹ́ẹ̀kọ́ obìnrin lájọṣepọ̀ fún ìgbà máàrún ọ̀tọ̀ọ̀tọ̀ láti fún ní máàkì.
Nítorí náà, ó pe orúkọ OLUWA tí ó bá a sọ̀rọ̀ ní “Ìwọ ni Ọlọrun tí ń rí nǹkan.
Nígbà tí wọ́n dé oko, wọ́n rí òkú ọmọ wọn nílè àti bàntẹ́ tí ọmọ padà wá mú lóko.
13 Ẹnití ó ti ka àwọn ìmọràn Ọlọ́run sí asán, àti tí ó ti ṣẹ́ àwọn ìlérí mímọ́ jùlọ tí a ṣe níwájú Ọlọ́run, àti tí ó ti gbé ara lé ìdájọ́ ti ara rẹ̀ tí ó sì ṣògo nínú ọgbọ́n ti ara rẹ̀.
Bẹẹ si ni nkan to le mu opin ba wahala yii kii se amulo awọn ọmọ ologun, bi ko se wiwa ojutu si awọn nkan to n fa wahala yii gan, bi aisi ilẹ fun awọn daran-daran lati fi ẹran jẹko ati ayipada oju ọjọ nipato.
"Femi Adebayo, Bimbo Akinsanya sọ ìdí tí wọ́n ṣe fi ìgbéyàwó wọn àkọ́kọ́ sílẹ̀ kó tó bọ́ sórí Sinimá tí Lateef Adedimeji dá nikan jẹ́ òṣèré yóò jáde, Yemi Solade fi ọ̀pọ̀ fọ́tò ""dẹngẹ pó"" lọ́jọ́ ìbí rẹ̀ Bí Favour ṣe sùn, mo gbá ọmọ odó mọ́ ọ lórí a sì gé orí, ọkàn àti ọyàn rẹ̀ fún àsèjẹ - Kayeefi Uber ni mo fẹ́ máa gbé báyìí, mi ò tún fẹsẹ̀ rìn mọ́ - Agunbaniro to n gba N33,000 Adeboye, ìmọ̀ràn rẹ láti dènà panṣágà tako àwọn obìnrin - Ọmọ Nàíjíríà Ọpọ awọn ọmọ orilẹ-ede UK lo korajọ si ile igbafẹ lati ṣajọyọ ipinya orilẹ-ede ọhun pẹlu ajọ EU."
Kcee wuwa ọmọluabi ti o si ṣika adehun rẹ si Chidozie.
Ó jẹ́ olùfọkànsìn nípa ti Òfin Mose; gbogbo àwọn ẹni tí ń gbé Judia ni wọ́n sì jẹ́rìí rere nípa rẹ̀.
Ni ile ijọba ni Marina ni wọn ti ṣe ibura fun awọn ọmọ igbimọ naa.
Ìtàn míràn sọ fún wa pé ọmọ ìyá ni agígírí àti ajíbógun ni Ìlé-ifẹ ̀ .
Ilé alájá mẹ́ta wó pa èèyan mẹ́rin ní Obalende, Eko Àwọn ọ̀dọ́ yabo ààfin, Ṣọun Ògbómọ̀ṣọ́ àti mínísítà sá àsálà fẹ́mi wọn Ààrẹ Buhari kí Akeredolu kú orííré bí ó ṣe jáwé olúborí nínú ìdìbò sípò gómínà Gomina Kano tí ní kí olùrànlọ́wọ́ rẹ̀ lọ rọ́kún nílé nítori o bu Ààrẹ Buhari lórí #EndSars EndSARS: Wo ohun táwọn gbajúgbajà tó n darí ìwọ́de ìfopinsí FSARS n sọ Gbogbo igboro Naijiria lo ti kun fun ajọyọ paapaa laarin awọn ọdọ nitoripe ohun ti wọn n bere fun lọwọ ijọba papa tẹ wọn lọwọ.
Kí wọ́n dìde, kí wọ́n ràn yín lọ́wọ́ nisinsinyii,kí wọ́n sì dáàbò bò yín.
Amọṣa bi a ba woo finifini, iṣẹ oun oṣi, aṣa ati iṣẹṣe tofi mọ aisi eto ilera alabọde kun ara ohun ti o n sun awọn aboyun lọ si ile igbẹbi ibilẹ.
"Buhari o, tètè ṣètò àtúntò Nàíjíríà ká le è dènà ogun abẹ́lé lẹ́ẹ̀kejì - Obasanjo figbe bọnu Ó ṣeéṣe kó má sí ẹ̀ṣọ́ aláàbò Amotekun l‘Eko - Ìjọba Eko Ẹ̀yin ẹkùn yókù, ẹ fi ikọ̀ àbò ""Amotekun ṣe àwòkọ́ṣe rere - APC Ìpínlẹ̀ Oyo, Ogun, Ondo buwọ́lu àbádòfin Àmọ̀tẹ́kùn Ẹgbẹ́ kan fún Tinubu ní wákàtí mẹ́rìnlélógún láti sọ èrò rẹ lórí Amọtẹkun Gomina Akeredolu, ẹni ti olugbani nimọran rẹ feto aabo, Alhaji Jimoh Dojumo gba ẹnu rẹ sọrọ, tun fikun pe gbogbo eto lo ti doju ọgbagade bayii lati ri pe ikọ Amotekun bẹrẹ, eyi ti yoo gbogun ti aifararọ feto aabo nilẹ Yoruba."
Ó ṣe tabili mẹ́wàá, ó gbé wọn kalẹ̀ ninu tẹmpili: marun-un ní ìhà gúsù, marun-un yòókù ní ìhà àríwá.
Oríṣun àwòrán, @OndoAPC Awọn eeyan naa ni Segun Abraham, Ife Oyedele ati Jimi Odimayo.
Ni ko pẹ ti ifẹsẹwọnsẹ ọhun tó n waye ni London bẹrẹ ni ọkan gboogi lara agbabọọlu Tottnham Jan Vertonghen, fara pa tí imu rẹ si n da ẹjẹ sorosoro.
Oríṣun àwòrán, Usman Okai Austin Àkọlé àwòrán, Atiku bẹ Ọbasanjọ wo pẹlu ireti pe yoo ṣe atilẹyin fun erongba rẹ lati di aarẹ orilẹede Naijiria.
bí àwọn tí wọn ń gbé inú àgọ́ mi kò bá wí pé,‘Ta ló kù tí kò tíì yó?
Èmi OLUWA ni mo sọ bẹ́ẹ̀ 
Samson Ajayi, okan lara awon akonimoogba nipinle Eko royin akitiyan oloogbe naa fun idagbasoke ere idaraya yii kolojo to de.
Amọṣa, awọn ọga ọlọpaa ni ipinlẹ mẹtẹẹta naa ni wọn fi ohun kan sọrọ pe, isẹ ọlọpaa lẹsẹkuku jẹ eyi to jẹ ileeṣẹ ọlọpaa logun pupọ bayii.
 bí ilẹ ̀ austria-hungary ṣe ṣe èyí tan ni orílẹ ̀ -èdè russia náà kéde ogun lé ilẹ ̀ austria-hungary lórí .
Ṣugbọn ''inu mi dun wi pe mo ti lanfaani lati pada si orilẹede Naijiria, ṣugbọn ibẹrubojo ni mo fi kuro nilẹ Gẹẹsi silẹ.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Lara awọn aṣeyọri rẹ ni bo ṣe mu Gomina ipinlẹ Delta nigba kan, James Ibori, to ji obitibiti owo ipinlẹ rẹ ko.
Ayajọ ọjọ awọn adẹtẹ jẹ ọjọ ti a fi n pe fun ironu ati iranlọwọ lori awọn ti o ti lugbadi aisan yii.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ta ni Kamala Harris obìnrin àkọ́kọ́ tí yóò jẹ igbá-kejì ààrẹ orílẹ̀èdè Amẹrika?
Pásítọ̀ bẹ́'rí ọmọ ìjọ ní ìpínlẹ̀ Ògùn COZA: Mi ò fípá bá obìrin lò pọ̀ rí láyé mi - Pásítọ̀ Fatoyinbo Ìgbà mẹ́rin tí ẹ̀sùn àgbèrè ta bá adarí ìjọ olókìkí ní Naijiria Mo ṣe tán láti kú tọmọ taya bí wọn kò bá fi El-Zakzaky sílẹ̀ - ọmọ ẹgbẹ́ Shiite O tẹsiwaju pe ''Iṣẹlẹ naa jami laya nigba ti wọn mu mi, ṣugbọn ko ko irẹwẹsi ọkan bami lati pada lọ Southgate lọ ma ṣe iwaasu nitagbangba.
Huawei: Àwọn ohun márun un ti o n ja ilẹ Amẹrika laya nipa ile iṣẹ China yi
Ìrànlọ́wọ́ mi ń ti ọ̀dọ̀ OLUWA wá,ẹni tí ó dá ọ̀run ati ayé.
Aseyin ti ilu Iseyin, Oba Dr.
Àkọlé àwòrán, Baba Obasanjọ gbe ijọba alagbada fun Shehu Shagari ko to di wi pe ọgagun Sani Abacha wa gba ijọba ni ọdun 1993.
"O ni ""ki wa ni wọn fẹ fi kiko o ni papamọra yii ṣe, ṣe lati fi tẹ ẹ ri ni, fi iya jẹ ẹ, da a laamu ninu ọpọlọ tabi lara""?"
 O ni “o digba tise naa ba pari ki oye ise akanse nla naa to ye gbogbo eniyan”Abaribe ni nigba to je pe gbogbo ekun ni yoo kopa ninu sisan owo ya naa, o dara ki ise naa kari ekun kookan.
“Mo le jẹrii si i pe awọn alẹnulọrọ bayii ti ṣe gudugudu meje ni ti lila awọn ara ilu lọyẹ lori eto idibo, paapaa ni asiko eto iforukọsilẹ ti a ṣẹsẹ pari laipẹ yii.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Kí ló yẹ kí ílẹ̀ India se sí ẹkùn tó pa ènìyàn márùń?
 ní ọdún 1949 , wọ ́ n yan alexander akínyẹlé gẹ ́ gẹ ́ bí alákòóso olùdarí order ti ilẹ ̀ bíritènì .
Báwo lo se gbọ́ èdè Yorùbá sí ?
Ọrọ di boo lọ ki o ya fun mi lọwurọ ọjọ Iṣegun ni agbegbe gate nilu Ibadan nibi ti rogbodiyan ti bẹ silẹ laarin awọn ọlọkada ati awọn oṣiṣẹ ọgba ẹwọn to n bẹ ni Agodi.
Àwọn eniyan bá sọ fún un pé, “Ìyá rẹ ati àwọn arakunrin rẹ dúró lóde, wọ́n fẹ́ fi ojú kàn ọ́.
Ọrùn rẹ dàbí ilé ìṣọ́ Dafidi,tí a kọ́ fún ihamọra,ìlẹ̀kẹ̀ ọrùn rẹ dàbí ẹgbẹrun (1000) asà tí a kó kọ́,bí apata àwọn akọni jagunjagun tí a kó jọ.
’’Mamosa ni  ile ise MSF  ko so nipato bayii , nigba ti won yoo bere ise
Ìgbàgbọ ́ yorùbá ni wípé ní ìgbà kan rí , ifá gbé ọ ̀ de-ayé fún ìgbà pípẹ ́ kí o tóó padà lọ sí ọ ̀ rùn .
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Búrẹ́dì Brazil: Èròjà protein tó wà lára Aáyán dára fún ènìyàn 16 Ọ̀wàrà 2018 Oríṣun àwòrán, FURG Àkọlé àwòrán, Àwọn onímọ̀ ẹ̀rọ nípa oúnjẹ lórílẹ̀èdè Brazil ti se ìyẹ̀fun búrẹ́dì pẹ̀lú àwọn kòkòrò bíi aáyán tó wọ́pọ̀ ní ilẹ̀ Àfíríkà.
Ẹ wo ìdí tí Oby Ezekwesili ṣe ń pè fún àyẹ̀wò ọpọlọ fún Ààrẹ Buhari Bí mo bá leè rí ọmọ alágbe t'áyé fẹnu sí pé mo fi ẹlẹ́rìndòdò lá lójú, máa kúnlẹ bẹ ẹ - Motara Níbo ni Ọ̀gbẹ́ni 'Emma', tíṣà tí wọ́n ní ó lu ọmọ pa ní Ikorodu wà bayìí?
Ẹ̀gbọ́n mi kan ti ó ti lọ sí ìdálẹ̀ ṣẹ̀ṣẹ̀ dé ní ìjẹta, ǹjẹ́ kí n lọ wò ó lánàá, n kì rí àyè rárá, gbogbo àwọn àlejò tí ó wá’kí yín lánàá kò jẹ́ kí n rí àyè lọ, àfi ìgbà tí ó di òwúrọ̀ lónìí tí mo déédéé rí oniṣẹ pé ẹ̀gbọ́n mi náà tí ṣe aláìsí.
Amọṣa, ileeṣẹ Ọlọpaa nipinlẹ Eko ni awọn ṣi n ṣe iwadii lori ọrọ naa ati pe laipẹ ni atẹjade yoo jade lori rẹ.
” Àwọn alufaa bá dáhùn pé, “Rárá.
Nigba to n ba akọroyin BBC sọrọ, osisẹ alarina fun ileesẹ ọrọ ilẹ okeere lorilẹede Naijiria kede pe, wọn ti sun igbesẹ kiko awọn ọmọ Naijiria naa wale lati South Africa di ọsẹ to n bọ.
Ìkìlọ̀ nípa Àwọn tí Ó Kúrò ninu Ẹ̀sìn Igbagbọ.
6 87920 Orilẹede Costa Rica 1773 35.
Ko kere ninu awọn ọmọ orilẹede Naijiria ti o n pariwo pe ọrọ to jinna si otitọ ni minisita Fashọla sọ yii, bẹẹni ko ṣai si awọn miran ti wọn sọ pe o fẹ jọ bẹẹ lootọ.
N óo le yín lọ sí ìgbèkùn, ẹ óo kọjá Babiloni.
Ni ilẹ Afirika nikan, orilẹede Ivory Coast ati Namibia naa n foju wina tiwọn titi kan awọn orilẹede bii Hong Kong, Thailand, Chile ati Belarus lawọn eeyan ti n fi ẹhonu wọn han lori ọkọ o jọkan idi to kan koowa wọn.
O óo jọba lórí Israẹli, n óo sì jẹ́ igbákejì rẹ.
amofin naa ni ṣugbọn ti ade iwa ibajẹ yii ba jẹ ootọ, ofin ni agbara lati yọ awọn Aṣofin ti Akpabio ba darukọ wọn kuro nipo.
"Ìrun àpapọ̀ dèèwọ̀ lọ́jọ́ Jímọ̀, kò sí oúnjẹ alẹ́ Olúwa mọ́ fún Kristiẹni Háà, Coronavirus ba ọjọ́ ìbí mi jẹ́ tán, díẹ̀ ló kù, mo yára ṣàtúnṣe sí i - Obasanjo Ẹ wo ọpọ eré ìdárayá nílẹ̀ Yorùbá tó ti ń di ohun ìgbàgbé Coronavirus tún ti ṣe ọṣẹ́ lórí iṣẹ́ líla ojú ọ̀nà relùwe láti Eko sí Ibadan - Ìjọba àpapọ̀ A n ṣé àyẹwò ẹni tá fúnra sí pé o ní Coronavirus l'Eko-Kọmísánà ìlera ""Awọn asofin yii fẹ ba asa Ẹgba jẹ, ti yoo si se akoba fun gbogbo ọmọ ilẹ Yoruba nitori ọba ti ko ba ṣe etutu, kii ṣe ọba."
Ẹnu yà wọ́n pé ó pẹ́ ninu iyàrá Tẹmpili.
Báyìí ni ọkùnrin náà sọ tí ó lọ ní ọjọ́ náà, bí ilẹ̀ si ti ń mọ́ ní òwùrọ̀ ọjọ́ kejì ni mo tún rí i.
tubọ maa gbogun ti iwa janduku, igbesunmọmi ati ọdaran lorile ede yii.
Nítorí kí ọjọ́ Oluwa tó dé, ọ̀tẹ̀ nípa ti ẹ̀sìn níláti kọ́kọ́ ṣẹlẹ̀, kí Ẹni Ibi nnì, ẹni ègbé nnì sì farahàn.
Bí ó bá jẹ́ ọkùnrin, ẹ̀ẹ̀mẹsàn án ni.
Ninu ijọ RCCG miracle Mega Parish ni ilu Benin city lawọn eeyan kan ti lọ fi ipa ba omidan naa lo pọ ni Ọjọru to kọja ki wọn to la agolo panapana, fire extinguisher mọọ lori to si ku; lati igbayi wa si lawọn ọmọ orilẹede Naijiria ti n ke ibosi lori rẹ.
Ṣugbọn awọn kan beere fun iwe irinna naa lẹnu ọna ibode atiwọle si orilẹ-ede wọn.
Kí ẹ̀yin ati àwọn ọmọ yín lè pẹ́ lórí ilẹ̀ tí OLUWA Ọlọrun búra fún àwọn baba yín, pé òun yóo fún wọn títí lae, níwọ̀n ìgbà tí ojú ọ̀run bá wà lókè.
Alaga ajo eleto idibo ( Independent National Electoral Commission ,INEC)Mahomood
Bakanaa ni wọn lo ilana yi lawọn orilẹede mejeeji lọdun 2016.
O ni irọ́ pata ni pe INEC n gba awọn eniyan sísé fun ìdìbò 2019.
Mo já sí ibi tí ó jìn jùlọ ninu òkun,àní ibi tí ẹnikẹ́ni kò lọ ní àlọ-bọ̀ rí.
Ó bá òkun wí, ó mú kí ó gbẹ,ó sì mú kí gbogbo odò gbẹ pẹlu;koríko ilẹ̀ Baṣani ati ti òkè Kamẹli gbẹ,òdòdó ilẹ̀ Lẹbanoni sì rẹ̀.
Ayẹwo awọn idibo to ti kọja fi han pe awọn ileeṣẹ tẹlifiṣọn Amẹrika ti kede esi ibo ri, bo tilẹ jẹ pe ajọ to n ri si eto idibo naa ṣi n ka ibo ọhun lọwọ.
Jada, arakunrin Ṣamai, bí ọmọ meji: Jeteri ati Jonatani, ṣugbọn Jeteri kò bímọ títí tí ó fi kú.
Ṣugbọn OLUWA sọ fún Mose pé, “Má bẹ̀rù rẹ̀, mo ti fi òun ati ilẹ̀ rẹ̀ lé ọ lọ́wọ́.
17 Mo sọ àwọn nkan wọ̀nyí fún ọ gẹ́gẹ́bí ẹ̀rí sí ọ—pé àwọn ọ̀rọ̀ tàbí iṣẹ́ èyítí o ti ńkọ jẹ́ òtítọ́.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Mò kabamọ́ ìṣẹlẹ tó wáyé láàárín èmi àti Agbowu,màá tẹlé àṣẹ lọ rọọ́kún nílé-Oluwo 24 Èrèlè 2020 Oríṣun àwòrán, Instagram/Telu1 Eti to ba gbọ alọ ni ọrọ yii,ko ni da ki o ma gbọ abọ.
Absalomu sì se àsè rẹpẹtẹ, bí ẹni pé ọba ni ó fẹ́ ṣe lálejò.
Ìpín kọ̀ọ̀kan a máa ṣiṣẹ́ fún oṣù kan ní Lẹbanoni, wọn á sì pada sílé fún oṣù meji.
Ọjọ Kejidinlọgbọn, oṣu Kọkanla, ọdun 1979, to jẹ ọdun mọkanlelogoji sẹyin ni wọn bi Chamillionaire silu Texas, lorilẹ-ede Amẹrika.
Ẹwẹ, ṣe ni awọn olugbe adugbo naa dede taji sinu ipaya pẹlu bi awọn ọkọ to taku ṣe pọ loju titi pẹlu ẹjẹ lara awọn ọkọ naa.
Bí o bá jókòó, ẹ̀rù kò ní bà ọ́,bí o bá sùn, oorun yóo máa dùn mọ́ ọ.
" Bi ẹ ko ba gbagbe, gomina Ayọ Fayoṣe naa n jẹjọ niwaju ile ẹjọ lori awọn ẹsun ti ajọ EFCC fi kan an.
Mo şe ìwà burúkú, ó kún gédégbé, ẹ̀yìn lẹ́yìn ni mo wá tẹ.
Ní ọjọ́ àyájọ́ ọdúnìí tó pé ọgọ́ta ọdún tí Elizabth gorí oyè, àkànṣe nlá gidi ló jẹ́.
Ẹni to bori: Senegal South Africa vs Benin.
Ó ní ìwọ̀n owó tí òun ń rí nínú isẹ́ ere síse mọ́ òun lọ́wọ́, tí òun kò sí mú isẹ́ míì mọ.
alaafia ati isokan joba lorile-ede Naijiria Lara awon ti o tun se idanileko nibi apero naa lati ri Gomina ipinle Kebbi, ogbeni Atiku Bagudu ti o je alejo pataki nibi apero ohun, o so pe niru asiko yii ibasepo to donmonron se pataki laarin awon agbegbe wa pata-pata.
 kóòdù iso 4217 ẹ ̀ jẹ ́ ars .
Ọbabinrin Elizabeth sọ ero ọkan rẹ ọ̀hún ni ilu London, nigba to n ṣi ipade àwọn adari orilẹede to wa l'ajọ Commonwealth.
Oladele da obinrin kan lọla ninu iwaasu Ọdun 2018 ni Oladele da obinrin lọla ti ko ro tẹlẹ ninu ijọ rẹ.
Àwọn sójà ní mo káàbò sí ilé ìṣerun àgbáyé tí wọ́n tí ń ṣerun bó ṣe wu wọ́n"" Ìjọba ti buwọ́lu lílo hijab láwọn iléèwé ní ìpínlẹ̀ Osun Akomolede àti Asa lórí BBC Yorùbá: Mọ̀ síi nípa ẹ̀kún ìyàwó níbí Banki Nàìjíríà, CBN ṣàlàyé nípa àwọn tó máa rí gbà nínú owó ìrànwọ́ N75b tíjọba gbé kalẹ̀ Èmi kọ́ ló pàṣẹ fún àwọn sọ́jà láti má a pa èèyàn ní Oyigbo - Nyesom Wike Mọ̀ sí i nípa àwọn ọmọ Nàìjíríà mẹ́sàn-án tó ń díje nínú ìdìbò ilẹ America lọ́jọ́ Ìṣẹ́gun Bakan naa, atẹjade ọhun fihan pe labẹ akoso afikun igbesẹ ti agbẹjọro agba naa tun gbe jade, wọn yoo tun lẹ orukọ ati aworan awọn afipabanilopọ ti ofin ba gbamu si adirẹsi ile ti wọn ba mọ wọn mọ ati ni ibi to ba gbajumọ daadaa ladugbo ibi ti ẹni to ṣe aṣemaṣe yii n gbe."
kwara ( ) jẹ ìpínlẹ ̀ ní apá ìwọ ̀ -oòrùn ní orílẹ ̀ èdè nàìjíríà .
Ogun TRACE: Ọkùnrin kan pa ara rẹ̀ sínú ọgbà àjọ tó n mójútọ ìrìnnà ọkọ̀ nípìnlẹ̀ Ogun
Baba mi ni ó bu ọlá fún mi, òun ni ẹ̀yin ń pè ní Ọlọrun yín.
Gẹgẹ bo ṣe sọ ọ, ni bayii, ipinlẹ Edo, Ondo, Bauchi, Nasarawa, Ebonyi, Plateau, Taraba, Adamawa, Gombe, Kaduna, Kwara, Benue, Rivers, Kogi, Enugu, Imo, Delta, Oyo ati Kebbi to fi mọ ilu Abuja ni kọọkan lo ti ni akọsilẹ iṣẹlẹ iba Lassa.
Ọmọ Yahoo fẹ́ pa ìyá rẹ̀ ṣ'owó l'Eko Mo ti fọ́ bàbá mi, Ọ̀gá Bello létí rí - Fẹmi Adebayọ̀ Irú ẹ̀dá wo ni Kofi Annan jẹ́?
Ṣugbọn wọn le gba ki ẹru maa wọle.
Israẹli ti ṣẹ̀, wọ́n ti rú òfin mi.
 Ó kó àwọn ọkùnrin wọ ̀ nyí jọ sí ilé oúnjẹ kan lẹ ́ ba ìlú , ní ìgbìyànjú lati dá ọ ̀ kọ ̀ tíó gbé ààrẹ lọ ́ nà tí ó bá ń padá bọ ̀ lati ilé ìwòsàn .
Ninu iwe esi ayẹwo iku rẹ ti ileṣẹ ilera Hennepin County Medical center office gbe jade ni wsn ti ṣalaye pe ayẹwo iku rẹ fihan pe o laarun coronavirus ni ọjọ kẹta oṣu kẹrin.
Gomina to n tukọ ipinlẹ Eko, ti paṣẹ pe to ba ṣe di ọjọ Aje ki awọn oṣiṣẹ eleto aabo ipinlẹ Eko ṣe afikun si eto aabo awọn okowo South Africa.
Kò sí ní ìkáwọ́ ẹni tí ń rìn láti tọ́ ìṣísẹ̀ ara rẹ̀.
Ahmed Rufai lawọn yoo gba 200,000 olukọni jakejado orileede Naijiria ati wi pe awọn yoo faye gba iṣẹ ohun amuludun lorisirisi.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Àwọn onímọ̀ ṣàwárí 'ihò ìyọ̀ tó gùn jù láyé' nítòsí ìbì tí ìyàwó Lọti inú Bíbélì ti di iyọ̀ 28 Ẹrẹ̀nà 2019 Oríṣun àwòrán, Reuters Awọn amoye kan lorilẹede Isreal sọ pe awọn ti ṣawari iho inu apata to kun fun iyọ̀ ju lagbaye.
Akosilẹ ikọlu si ẹmi ati dukia awọn alejo ni South Africa: Àkọlé àwòrán, Akọsilẹ lati ọdun 2007 si ọdun 2019.
Nítorí pé látijọ́, ní ìgbà ayé Dafidi ati Asafu, wọ́n ní olórí fún àwọn akọrin, wọ́n sì ní àwọn orin ìyìn ati orin ọpẹ́ sí Ọlọ́run.
Ninu atẹjade ti kọmisọnna fun eto iroyin, Harriet Afolabi- Oshatimehin fi lede awọn ijọba mẹrindinlogun lo ni ohun iranwọ ti awọn eniyan jigbe lọ naa.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Pasuma: Mọ dúpẹ́ lọ́wọ́ Ọlórun fún oríire ọjọ́ ìbí òní 3 Bélú 2018 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 27 Bélú 2018 Oríṣun àwòrán, Instagram Àkọlé àwòrán, Pasuma ní nínú gbogbo ìlú àgbáyé, òun kò lè lọ kọrin ní Saudi Arabia ko si iye owo tí wọ́n lè gbé sílẹ̀.
Lọ́wọ́ Efuroni ará Hiti ni Abrahamu ti rà á pọ̀ mọ́ ilẹ̀ náà, kí ó lè rí ibi fi ṣe itẹ́ òkú.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Widows Day 2019: Mo máa ń sá kiri wá owó ilé ni -Opó Awọn alaṣẹ Air Canada ni awọn n ṣiṣẹ iwadii lori ọrọ naa lọwọ lai ṣe alaye ni kikun.
Ẹ rẹ ara yín sílẹ̀ níwájú Oluwa, yóo wá gbe yín ga.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù World War III: Wo ohun tó yẹ kí o mọ̀ nípa awuyewuye tó ń wáyé láàárín India àti China 18 Òkùdu 2020 Oríṣun àwòrán, Getty Images Ariwo World war 3 lawọn eeyan n pa bayii lori ayelujara lẹyin awuyewuye to waye laarin ilẹ India ati China lori ala ilẹ Himalayas, eyi to ti mu ẹmi awọn eeyan kan lọ.
Irú òmìnira yìí ni a ní.
Adari ijọ Eastern Orthodox Church pẹlu awọn miran ti bu ẹnu ẹ̀tẹ́ lu igbesẹ Aarẹ Turkey yii.
asoju osise ijoba apapo  n se gbodo waye
Gbogbo ọba alayé, tó fi mọ́ Ọọ̀ni àná, Sijuwade ló mọ̀ pé mo fẹ́ jẹ Mayegun - Wasiu Ayinde Ìyàwó gómìnà tọ́jọ́ orí rẹ̀ kéré jù ní Nàìjíríà rèé, ohun tóo lè fẹ́ mọ̀ nípa rẹ̀ Àṣìta ìbọn sọ́já pa ẹgbọn Kamsi tó pé sọ́ja kó wá fìyà jẹ aládùúgbò rẹ̀ Ọsanyintolu ni isẹ idoola ẹmi ti n lọ lọwọ lati fa ọkunrin naa yọ, ti isẹlẹ naa si ti se akoba fun awsn ile to yii ile awoku naa ka.
Ìṣẹ̀lẹ̀ kan ṣẹlẹ̀ nígbàtí akérò kan ṣàìgbọràn, tí ó ngbé èrò lọ lórí títì nlá tó lọ́ sí Ibadan láti Èkó.
Àwọn kan yóo máa rọ ohun ìjà fún un, ati àwọn ohun èlò kẹ̀kẹ́ ogun rẹ̀.
Ẹni ọdun méjilelogoji ọmọ Cuba oun kuna ri ni ẹ̀ẹ̀mẹta láti ọjọ to ti n dije, ẹ̀ẹ̀mta náà si rèé, igbimọ jòkó ni láti mọ ẹni ti wọ́n yoo gbe ade fún.
Bakanna ni oludamọran fun Gomina ipinlẹ Ondo lori ọrọ aabo, Alhaji Jimoh Dojumo sọ pe bi Amotekun yoo ṣe maa ṣiṣẹ wa ninu ofin to gbe e kalẹ.
Gbogbo ẹyin ti ẹ ro pe ẹ le tun ṣe ju bi awọn to n ṣe wa nibẹ yii, ẹ jade wa gba fọọmu lati darapọ mọ awon ọmọ ogun ilẹ ni Naijiria.
4343 tetsuya jẹ ́ plánẹ ́ tì kékeré ní ibi ìgbàjá ástẹ ́ rọ ́ ìdì .
Gege bi iko agbaboolu Barcelona se so, “Castro  doloogbe leyin ti o saare arun-okan, adura wa ni pe, ki olorun tE si afefe rere.
Òkúta ẹnu ibojì ṣí, a sì jí ọ̀pọ̀ òkú àwọn olódodo dìde.
A kò ní ranti gbogbo ẹ̀ṣẹ̀ rẹ̀, yóo yè nítorí òdodo rẹ̀.
Bákan nàá ló ti bí ìbẹta rí.
Ijoba ni awọn ko laṣ lati tu Zakzaky silẹ pe iwaju ile ẹjọ ipinlẹ Kaduna ni ọrọ rẹ wa.
Kí sì ni ọmọ eniyan tí o fi ń ranti rẹ̀?
O ṣalaye ninu ọrọ to fi si oju opo Twitter rẹ pe orin naa niiṣe pẹlu ilanilọyẹ lori ẹgbẹ awọn ọkunrin naa.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù JAMB 2019: Wo àwọn ibùdó CBT tó wà nítòsí rẹ 12 Sẹ́rẹ́ 2019 Oríṣun àwòrán, JAMB/FACEBOOK Àkọlé àwòrán, Àjọ JAMB Ajọ to n ri si idanwo asewọle iwe giga JAMB ti bẹrẹ tita fọọ mu fun awọn ọmọ Naiiria to fẹ ṣe idanwo naa.
O wa fikun pe oun gbogbo lo n sisẹ pọ fun rere ni, nitori pe ko ye oun lasiko ti oun n la awọn isẹlẹ naa kọja pe oun fẹ lọ sipo to tun ga ju ipo ti oun wa lọ ni.
Ninu ọrọ rẹ, Igbakeji Agbẹnuso Ile naa, Aṣofin Wasiu Sanni Eṣinlokun dupẹ lọwọ awọn ara rẹ pe wọn mọ riri Ọba Akiolu, Bakan naa lo gboriyin fun akititiyan Ọba naa lati fi ẹmi iṣokan ati ifẹ mulẹ ni Ipinlẹ yii.
A jẹ́ pé ó ka nkan tó pàá lẹ́rìn-ín nínú àkọsílẹ̀ tó nkà ni.
Buhari gbe ami ẹyẹ naa fun ọmọ oloogbe Adadevoh, Ọgbẹni Bankole Cardoso to sọju iya rẹ nibi eto naa.
O ni pe àwọn igun kan nínú àwọn ọlọ́pàá to ń moju to ijinigbe ṣi wa nibi kọ́lọ́fin àti inu igbó níbi ti àwọn ọdàràn náà sápàmọ si láti ṣẹgun wọn.
O ni ọga agba ileeṣẹ ọlọpaa, Mohammed Adamu kò paṣẹ ki wọn mu Sẹnetọ Abbo ti iroyin n ja ranyinranyin pe o lu obinrin kan nilee itaja nilu Abuja.
OLUWA Ọlọrun mi, n óo máa fi ọpẹ́ fún ọ títí lae.
Ko tan sibẹ o, àwọn ijoye naa tun fi ẹsun kan Oba Akanbi pe o doju ija kọ awọn eeyan pataki nilu Iwo, ati ibomiran.
Olùkọ́ aláàánú: Ìda mẹ́jọ sí mẹ́wàá owó oṣù Peter Tabichi, ló ń fún aláìni
Ní ọ̀nà yìí ati ní oríṣìíríṣìí ọ̀nà mìíràn, Johanu ń gba àwọn eniyan níyànjú, ó sì ń sọ̀rọ̀ ìyìn rere fún wọn.
Ẹ̀yin ẹ máa kó ọtí, èso, ati òróró jọ sinu ìkòkò yín, kí ẹ sì máa gbé àwọn ìlú tí ẹ ti gbà.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ogún ọdún ni mo fi gbáradì fún àjàkálẹ̀ ààrùn coronavirus 11 Èbibi 2020 Oríṣun àwòrán, Emma Russell Igbe aye lasiko itankalẹ aarun coronavirus yii le nira pupọ, paapa fun awọn ti ipaya ipa ti aarun naa le ni l'ara wọn.
egbe oselu  APC, fi ranse ni asofin
Omo ogun odun ohun,  kopa ribiribi lati ron orile-ede France lowo gba ife-eye idije boolu afesegba lagbaye, lorile-ede Russia.
Bá wa kí gbogbo àwọn ọ̀rẹ́ wa ninu igbagbọ.
Ọpọlọpọ ẹmi sofo latari ikọlu awọn ọmọ ogun oju ofurufu
"- Ooni Ile Ife O ni ""ifẹ aiṣẹtan kii fi tipa mu obinrin lati ni Ibalopọ pẹlu rẹ."
Illesẹ ọmọ ogun orilẹede Naijiria ni aisi iroyin to kuna nipa ogun ti wọn n dojukọ gan an lo fa a ti ina gbigbogun ti iwa idukukulaja fi n jo ajorẹyin.
Òǹlo Sajid Islam Khan túwíìtì pé òún nílò ẹ̀jẹ̀ fún àbúrò òun tí ibà-ẹ̀fọn ń bá fínra.
Ọgba ọlọpa ijọba ibilẹ Broward, Scott Israel, sọ̀ fun awọn akọroyin wipe ọgbẹni Cruz pa eeyan mẹta ko to ile-ile iwe naa o si pa eeyan mejila ninu rẹ Eniyan meji pada ku lẹyin igba ti wọn gbe wọn lo si ilẹ iwosan.
Oniruuru edeaiyede lo wọ tọ Mugabe lẹyin fun nnkan bi ogoji ọdun to fi lo ipo lagbo oṣelu lorilẹede Zimbabwe ti ọpọ si n fi oju wo o gẹgẹ bii akinkanju to gba orilẹede naa la lọwọ awọn amunisin Gẹẹsi ọpọlọpọ awọn alatako lo n na ika aleebu sii gẹgẹ bi ẹni to tẹ oju ẹtọ ọpọlọpọ mọlẹ to si tun hiu ọpọlọpọ iwa ibajẹ gbogbo Laurent Gbagbo orilẹede Ivory Coast Oríṣun àwòrán, others Ọpọ lo fi oju aṣiwaju to ṣetan ati tu orilẹede rẹ ka nitori aifẹ gba fun esi ijakulẹ rẹ nibi idibo.
Nítorí náà, ẹ mú gbogbo ìwà èérí ati gbogbo ìwàkiwà à-ń-wá-ipò-aṣaaju kúrò, kí á lè wà ní ipò kinni.
Ni agbegbe Alausa, ẹnikan tilẹ gbe kẹkẹ ati aja rẹ wa, ti oun ati aja rẹ si n fi kẹkẹ ọhun dárà.
Ó pẹ́ díẹ̀ kí oníṣẹ́ náà tó padà, o wí fún ni pé ọba ti dé àti pe o n fẹ́ ri wa ní ọjọ́ kéjì ní déedée agogo mẹ́sàn-án àbọ̀.
Ẹ̀yin orílẹ̀-èdè, ẹ kó ara yín jọ!
Ìjọba àpapọ̀ kéde ọjọ́ tí ìdánwò NECO, NABTEB àti BECE yóò bẹ̀rẹ̀ Sinimá àwòdamiẹnu, Ẹ̀fáńjẹ́líìsì jìyà àjẹmumi nílé aṣẹ́wó l'Ejigbo ní ìlú Eko Ọba Saudi Arabia yọ ọmọ rẹ̀ àti àbúrò rẹ̀ kúrò nípò nítorí ìwà àjẹbánu lórí owó tó yẹ fún ààbò ìlú O ṣalaye pe anfaani ti wa fun awọn ile sinima, ibudo ti wọn ti n sẹ ere idaraya, ati awọn ibudo faaji to ku, lati bẹrẹ isẹ pada.
Judith, to jẹ ọlọmọ mẹta , ti ohun ati ọkọ rẹ Laban Kamuren, ṣeṣẹ kọ ara wọn, pada wa si abule awọn obi rẹ to wa ni ariwa orileede Kenya.
15 million ti o to N71.
Àwọn ọmọ onílẹ̀ tí wọ́n wà níbẹ̀ kí àwọn Gẹ̀ẹ́sì tó dé ni wọ́n ń bọ òrìṣà náà nígbà náà.
Botile jẹpe ko si ẹni to mọ ẹni to se iṣẹ nla ibi naa bayii ni awọn ajajagbara Hutu bẹrẹ si ni naka alebu si àwọn alatako ijọba Hutsi ti wahala si bẹrẹ, laarin wakati diẹ ẹgbẹlẹgbẹ awọn ọmọ Hutus ti wọn ti n lodi si ẹya hutsi fun ọpọ ọdun darapọ ti wọn si bẹrẹ ipaniyan.
O ni atako ko wulo rara lasiko yii, yoo si dara ki wọn lo ohun wọn fun nnkan miran to ba wulo fun iran ọmọniyan, eto oselu ibaradọgba ati idajọ ododo.
Orin yii bi ige ati adubi laarin awọn eniyan Naijiria ni eyi ti awọn kan gbà si òdì debi pe ajọ to n mojuto ere idanilaraya ti a n gbe sita ni Naijiria, iyẹn, National Broadcasting Commission fi ofin dee.
Ewe, Ado-oloro ti osuwon re je oorun-un giramu, ni won ri ni King George V Dock ni papa-ko ofurufu ohun lasiko ti ise ikole n lo lowo.
Ṣugbọn ohun taa tun ri gbọ lati ileeṣẹ ọlọpaa ipinlẹ Ogun, wọn ti ribi doola mẹta ninu awọn ọlọpaa tawọn janduku ji gbe yi.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Jesu Oyingbo rèé, pásítọ̀ tó láṣẹ ìbálòpọ̀ lóri ọmọ ìjọ obìnrin Igbó mímu lè ṣe kóríyá, kò lé fi kún orín ẹnu òṣèré - 9ice Ìtàn tó wà nídi òwe ‘Sebótimọ Ẹlẹ́wà Sàpọ́n’ Ọba Adesoji Aderemi, Ọọ̀ni Ifẹ̀ tó gba ipò ọba mọ́ tòṣèlú Ó dàbi ẹni pé ìgbésẹ̀ ààrẹ Buhari kò ti tó, Kini NADECO tún fẹ?
  Igbimọ naa ṣayẹwo fun awọn mẹjọ ni Ọjọbọ.
Ni ilu Benin ni wọn ti bi Kamaru Usman lọjọ kọkanla Oṣu Karun un ọdun 1987.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ọlọ́pàá Èkó gbé ẹni tó pa ìyàwó àti ọmọ rẹ̀ re'lé ẹjọ́ 11 Ìgbé 2018 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, ọlọ́pàá gbé ẹni tó pa ìyàwó àti ọmọ rẹ̀ re'lé ẹjọ́ Ile isẹ ọlọpa ni ipinlẹ Eko sọ wipe ọmọkunrin kan lati orilẹede Denmark, Peter Nielsen ti wọn fẹsun kan wipe o pa iyawo ati ọmọ rẹ ni awọn yoo gbe rele ẹjọ ni Ọjọru.
"' "" Awọn alami kan lo ta wa lolobo pe awọn kan ji eeyan kan gbe pamọ sinu akọku ile kan lagbegbe Kudẹti."
Bakan naa ni wọn tun n fẹhonu han lori owo oṣu ti wọn jẹ wọn pẹlu awọn wahala miiran ti wọn ni o wa nile iwosan naa.
Mo tẹ̀lée ọ̀nà yìí kí n baà wá àyè bòyá mo lè rí ibi fi orí pamọ́ sí, ṣùgbọ́n ìyàlẹ́nu ló jẹ́ fún mi wí pé wéré tí mo ti rìn tó bí ẹsẹ̀ bàtà mẹ́fà ni mo bá ara mi nínú ilé ńlá kan tí ó tóbi gidigidi tí ó sì lẹ́wà púpọ̀.
Èyí o ṣe yìí náà tó o jàre.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Air India plane crash: Ìjàmbá bàálù India Express tó já ní Kerala pa èèyàn 16 7 Ògún 2020 Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Aftermath of the Kerala plane crash shows the plane broken in two Ọkọ baalu ofurufu ilẹ India to ko ero mọkanlelaadọwa ti ja ni papakọ ofurufu ilu Kerala.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Widows Day 2019: Mo máa ń sá kiri wá owó ilé ni -Opó Bakan naa lo ṣalaye pe ni kete ti ijamba naa ti waye ni wọn ti doola ẹmi awọn mẹta ninu awọn ero ti ọkọ naa da somi.
Ninu ọrọ rẹ, Olufunke sọ wi pe awọn ọkunrin ti foju oun wina nitori ọpọlọpọ aisotitọ ati ododo ti wọn ti fi ba oun lo.
Samuẹli dìde, ó tún tọ Eli lọ, ó ní, “Ìwọ ni o pè mí; mo dé.
Ìdí ti àwọn kọmísọna ṣe to láti kí ìyáwó gómìnà tuntun káàbọ̀
Ó tún sọ fún mi pé, “Òdodo ati òtítọ́ ni àwọn ọ̀rọ̀ yìí.
Ẹni tí ó bá gbé ara rẹ̀ ga ni a óo rẹ̀ sílẹ̀; ẹni tí ó bá rẹ ara rẹ̀ sílẹ̀ ni a óo gbé ga.
asoju  lori iroyin ati ikede, Turaki
Níbẹ̀ ni Juda ti rí ọmọbinrin ará Kenaani kan, tí baba rẹ̀ ń jẹ́ Ṣua, ó gbé e níyàwó, ó sì bá a lòpọ̀.
Kí o da òróró inú ìgò yìí sí i lórí, kí o sì wí pé, OLUWA sọ pé, ‘Mo fi òróró yàn ọ́ ní ọba lórí Israẹli.
Ogunlọ́gọ̀ àwọn tí ó ńwo eré bọ́ọ̀lù ní Nàìjíríà ni wọ́n ti ńfi èrò ọkàn wọn hàn l'órí ọ̀rọ̀ yí ní orí Twitter.
Awọn iroyin ti ẹ lee nifẹ si: Bi Baalu Dana ṣe ya wọ'gbo Philomina nikan kọ lo ṣe magomago owo JAMB Ohun marun t'ejo n jẹ Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Bí ẹnìkan kò bá pèsè fún àwọn ẹbí rẹ̀, pataki jùlọ fún àwọn ìdílé rẹ̀, olúwarẹ̀ ti lòdì sí ẹ̀sìn igbagbọ wa, ó sì burú ju alaigbagbọ lọ.
ti o fihan gbangba-gbangba pe aare ti n mura slle lati mu atunse ba isakoso
Owasanoye ṣàlàyé pé ICPC ti gba bílíọnu meji Naira nípa bi wọn ṣe f'imú fin'lẹ láti rí àwọn iṣẹ́ akanṣe awọn ọmọ ilé ìgbìmọ asòfin (Constituency projects).
N kò ní rà wọ́n pada kúrò lọ́wọ́ agbára isà òkú, n kò ní rà wọ́n pada kúrò lọ́wọ́ ikú.
OLUWA yóo bukun yín ju gbogbo àwọn eniyan yòókù lọ; kò ní sí ọkunrin kan tabi obinrin kan tí yóo yàgàn láàrin yín, tabi láàrin àwọn ẹran ọ̀sìn yín.
Ibi tí mo bá ìtàn náà dé ní ẹ̀ẹ̀kan ni ibi tí wọ́n tí kọ orúkọ bàbá mi sí ẹ̀gbẹ́ ògiri, ti wọ́n sọ̀rọ̀ rẹ dáradára.
”O tun tesiwaju pe , “awon ko fikun owo oko oju irin naa.
O ni oun ba di ẹrujẹjẹ ninu papakọ ofurufu ọhun to di apewo.
Iyanṣẹ́lódì lẹ́ka ìlera Naijiria kìi ṣe ohun tuntun mọ́, ọ̀pọ̀lọ́pọ̀ àwọn ilé ìwòsan ni ó ti ní àwọn yóò lé àwọn ọmọ ẹgbẹ́ Johesu lẹ́nu iṣẹ́, tí wọn ko bá padà fòpin sí ìyanṣẹ́lódì náà.
Aṣọ ìkélé ti àgbàlá tí ó yí ibi mímọ́ ati pẹpẹ ká, aṣọ ìkélé fún ẹnu ọ̀nà àgbàlá, ati okùn wọn, ati gbogbo àwọn ohun tí wọn ń lò pẹlu wọn.
Asofin Peter Nwaoboshi to n soju ekun Naija-Delta nile igbimo asofin agba lAbuja lo koko soro lori koko naa siwaju awon omo ile lojo Isegun.
O ki awon omo orile-ede Naijiria ku ayeye odun ajinde, ni eyi ti o fi mule pe, Olorun o ni fi orile-ede Naijiria sile, ati pe ileri Oluwa nikan ni yoo se lorile-ede Naijiria.
Mo ni igbagbo pe, ma a tun ri yin lodun to n bo.
Ẹ̀yin ará, ẹ mú sùúrù títí Oluwa yóo fi dé.
Ìjọba Eko bẹ̀rẹ̀ sísan N35,000 owó oṣù tuntun ní November Mẹ̀kúnnù 80,000 l'Ọṣun ti j'ànfàaní ètò ìlera láìsan kọ́bọ̀ - Oyetola Ilé aṣòfin Amẹrika gbọnmú lórí ìtìmọ́lé Sowore, ó ní ìjọba Nàíjíríà tako òmìnira aráàlú Iná mọ̀nàmọ́ná lọ fún wákàtí 24 ní Ghana, lariwo bá sọ!
Gẹgẹ bi ohun tawọn ọlọpaa wi, Iya awọn ọmọ naa lo tu asiri rẹ nigba to saa deede ri pe eeyan kan sa n pa ina ọba ninu iyara awọn ọmọ naa lera lera ti ọkan si n pariwo.
Wọ́n ni oríṣiriṣi sbẹ láàri lọ́jọ́ ikú eerin, oríṣirisi àsọ lo n pe aṣọ ránṣẹ.
Ẹ wo bí Amotekun ṣe gba ilẹ̀ Yoruba silẹ̀ lọ́wọ́ agbéṣùnmọ̀ní ní igba ọdún sẹ́yìn Tí ìjọbá bá kọ̀ láti san owó oṣù wa, a o da iṣẹ́ sílẹ̀ - ASUU Maryam Sanda, ìyàwó tó pa ọkọ rẹ, ri ìdájọ ikú he Wo ìgbésẹ̀ tó yẹ ko gbé tí kokoro bá ba irè oko rẹ jẹ́ Gẹgẹ baa se gbọ, oju ọna marosẹ ilu Omu Aran si Ilọrin la gbọ pe awọn mejeeji ti n rekọja lọ, nigba ti awọn eeyan mẹrin kan ya bo wọn, ti wọn si se wọn lọsẹ.
Wọn yóo gé igi inú igbó rẹ̀ lulẹ̀.
Asọtẹlẹ naa si lo sẹ lẹyin ọdun meje to ti kede nipa rẹ.
Ukriane lo wa loke tente pẹlu ami ayo mẹfa lẹyin ti wọn jawe olubori ninu ifẹsẹwọnsẹ meji ti wọn gba pẹlu Amẹrika ati Qatar.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Akomolede ati Aṣa: Mọ̀ síi nípa ìró afárànma àti agbárànmọ́ fáwẹ́ẹ̀lì Yorùbá Amọṣa EFCC ni iwadii awọn fihan pe, ile nla ni Afaa Jamiu kọ silu Ilọrin lara owo to gba lọwọ oyinbo Koraa, Keun Sig Kim.
Awọn orisun iroyin kan sọ fun BBC pe ẹẹdẹgbẹrin awọn afurasi ni ile ẹjọ ilu mẹẹrin ọtọọtọ yoo f'oju wọn wina ẹjọ nibudo awọn ologun kan to wa niluu Kainji lọsẹ yii.
figagbaga nipele keji si asekagba idije clay-court leyin ti o fagba han Hsieh
Ọ̀pọ̀ àwọn ilẹ́ Afíríká ní Coronavirus tí ń tànkálẹ̀ láàrin ìlú gẹ́gẹ́ bi WHO.
"Siga tita d‘eewọ lẹba ile ẹkọ O see se ki ọti ati siga gbowoleri Òbí tó n fa sìgá n fi ọmọ rẹ̀ sínú ìdè àìsàn l'ọ́jọ́ iwájú Wo ohun márùn-ún tó ń fa ìjàmbá iná nínú ilé Fun ọpọlọpọ ọdun, siga jẹ oun to dara fun ilera, kóda àwọn kan tilẹ n pe taba naa ni ""ewe mimọ"" nigba kan."
''Ṣe Dubai lo ti ṣagbelẹrọ ibo1.
Nigba ti awọn eeyan ti jade sibudo idibo mii ti wọn si n duro de awọn ohun eelo idibo kaakiri.
Gẹgẹ bi ẹsun naa ti ri, Raji Adio, ti o jẹ ololufẹ ikọkọ arabinrin naa lo gbekuru jẹ lọwọ ẹbọra nigba ti awọn mejeeji n sẹre ifẹ ni ile itura River Bank.
Eyi ni esi ifesewonse idije boolu afesegba torile-ede Niajiria NPFL ti o waye lopin ose:Wikki Tourists 1-0 FC IfeanyiUbahAkwa United 3-0 Kwara UnitedLobi Stars 3-1 Niger TornadoesHeartland FC 1-1 Yobe Desert StarsKatsina United 3-0 Go Round FCRivers United 1-1 Enyimba InternationalAbia Warriors 0-0 Sunshine StarsEl-Kanemi Warriors 0-0 Kano PillarsPlayed on Saturday, Jan.
Wọ́n bá ranṣẹ sí àwọn ará ìlú Kiriati Jearimu pé, “Àwọn ará Filistia ti dá àpótí OLUWA pada.
Funke gba awọn oloufẹ rẹ lamọran lati ma na gbogbo owo tan lasiko ọdun, nitori oṣu kinnin ọdun 2020 n kan lẹkun.
Oríṣun àwòrán, Reuters Àkọlé àwòrán, Awọn ọmọogun se ohun iyalẹnu fun minisita feto abo ni ilẹ Amẹrika Lẹyin ti wọn pari oniruuru awọn eto igbaradi yii tan ni wọn gunle igbaradi lorii kikoju awọn ajinigbe pẹlu aja ọlọpaa ati baluu.
Awọn cardinal ni awọn olóyè ijọ to tobi ju.
Sọ àsọtẹ́lẹ̀ orílẹ̀èdè tí yóò borí ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ t'òní AFCON bọ́ mọ́ Cameroun lọ́wọ́ nítorí ìdí méjí-CAF Ọmọ Nàíjíríà gba àmì ẹ̀yẹ akẹ́kọ̀ọ́ tó pegedé jùlọ ní fásitì òkè òkun Bi idije ife ẹyẹ AFCON ṣe ti n lọ lọwọ ni Alexandria orilẹede Egypt, awọn ọmọ Naijiria ni awọn ọmọ Naijiria ṣe n tu jade lọ si ibudo iworan bọọlu.
Oríṣun àwòrán, CDC Minisita naa fikun un wi pe gbogbo orilẹede gbọdọ pawọpọ lati gbogun ti arun naa, ki gbogbo arun naa le di ohun igbagbe.
Lọ́jọ́ 'wájú, mo fẹ́ di ǹkan mẹ́ta, dókítà, sọ̀rọ̀sọ̀rọ̀, ránṣọ-ránṣọ.
Bakan naa ni awọn kan sọ pe ko mẹnuba ọrọ eto aabo lasiko yii.
Awọn owu ti wọn fi ran yoo tu u ti obinrin ba ti ni ibalopọ.
O ṣalaye pe akufa ti wa tipẹ, to ba si jẹ pe ni aye atijọ ni, aṣiri iṣẹlẹ naa yoo ti tu sita, ko to o ṣẹlẹ.
Iroyin ni Ogbẹni Macaire n gbadura fawọn toku ninu iṣẹlẹ ijamba ọkọ ofurufu ni lasiko ti wọn n yinbọn naa to pada di iwọde ni Tehran.
Dbanj, pàdánù ọmọ rẹ tí orúkọ rẹ n jẹ Daniel ẹni tó pé ọmọ ọdún kan láìpẹ́ yìí.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Oríṣun àwòrán, Getty Images Ile ijọsin Fountain of Praise ni eto isinkun naa ti waye.
Ṣaaju aṣẹ tuntun yii, awọn arinrinajo ti wọn ba fura si nikan ni wọn maa n beere iroyin nipa oju opo ayelujara lọwọ wọn, papaa awọn to ba ti rinrinajo lọ sawọn orilẹede to ni ajọṣepọ pẹlu awọn ẹgbẹ agbesumọmi.
Idi niyi ti ile igbimo asofin se
Nígbà tí Jesu gbé ojú sókè, ó bi obinrin náà pé, “Obinrin, àwọn dà?
Ìbẹ̀rù OLUWA pé, ó wà títí lae,ìdájọ́ OLUWA tọ́, òdodo ni gbogbo wọn.
” Ibí yìí ni àwọn ọ̀rọ̀ tí Jeremaya sọ parí sí.
Obinrin náà sọ fún ọkọ rẹ̀ pé, “Mo wòye pé ọkunrin tí ó ń wá síbí yìí jẹ́ ẹni mímọ́ Ọlọ́run.
Ajafẹtọ ọmọniyan naa wa parọwa si awọn adari ni ile aarẹ ni Abuja ati Ile Asofin ni apaapọ lati ye e kun, amọ ki wọn wa wọrọkọ fi sada lori eto abo ara ilu.
Amo, aworan to n jayin lori ayelujara fihan gbangba bi awọn eniyan ṣe n gbe awọn ohun elo ounjẹ kuro ni ibẹ, ti aẉọn ẹsọ alaabo ko si se wọn ni ijamba.
Èké ni wọ́n, nítorí náà wọn óo jìyà ẹ̀ṣẹ̀ wọn, OLUWA yóo wó pẹpẹ wọn lulẹ̀, yóo sì fọ́ àwọn ọ̀wọ̀n oriṣa wọn.
Ẹni tó pa ìyàwó rẹ̀ ká'wọ́ pọ̀nyìn rojọ́ Ààwẹ̀ gbẹ̀mí ọmọ Naijiria ní orílẹ̀èdè Amẹ́ríkà Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí kan sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
Idunnu ko ṣee fi pamọ fun iya Daniel to ni ibẹwo yii jẹ ijọloju fun oun ati pe inu oun dun lati ri ọmọ rẹ lori aga gomina.
Ni nnkan bi aago mọkanla owurọ Ọjọru ni kọmisana ajọ ọlọpaa nipinlẹ Ọyọ, Joe Nwachukwu Enwonwu fi oju Sunday ati awọn ọdaran mii ti wọn ri mu han fun gbogbo aye ri ninu ipade awọn oniroyin to waye ni olu ileeṣẹ ọlọpaa to n bẹ ni agbegbe Ẹlẹyẹle nilu Ibadan.
Komisana isẹ agbẹ ni ipinlẹ naa, Alhaji Garba Dan dika, sọ wipe lati igba ti iroyin naa ti tẹ wọn l'ọwọ lati ọsẹ meji sẹyin ni wọn ti s'alaye isoro naa fun ijọba ipinlẹ naa.
’’iwa aparo kan ga ju okan lo.
Ẹlẹ́wọ̀n Kirikiri tó ń wọ́ke, olùdarí ọgbà ẹ̀wọ̀n ló ṣe onígbọ̀wọ́ fun - EFCC Awọn bii Alagba Moses Amọo, Sunday Akintobi àti iyawo Wooli laiyọ awọn ara ilu silẹ ti BBC Yoruba ba ṣalaye kikun nipa ohun to ṣoju wọn lori iṣẹlẹ.
Mò ń bẹ̀bẹ̀ pé kí o bukun arọmọdọmọ mi, kí wọ́n lè máa bá ojurere rẹ pàdé nígbà gbogbo.
Yatọ si awọn ohun ti a ka kalẹ yii, wọn tun n gba ọkọ ayọkẹlẹ mẹfa pẹlu awọn ajẹmọnu miran pẹlu oṣiṣẹ ti yoo ma ba wọn ṣiṣẹ.
Andrew Haruna: So-bàtà tó di ọ̀jọ̀gbọ́n fásitì tó tún jẹ́ ọ̀gá àgbà pátá (V.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ìdílé tí ọkọ da ọmọ síta tóríi ojú Búlùú tí wọ́n ní bá BBC sọ̀rọ̀ Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Ajọ Nimet ni ko si ohun to jẹ tuntun ninu ojo akọrọ to nwaye lasiko yi nitoripe bo se maa nwaye ree lasiko ti ẹẹrun ba n kogba wọle.
Àwọn ará Israẹli ṣẹgun àwọn ará Juda, olukuluku sì fọ́nká lọ sí ilé rẹ̀.
Àwọn igi tí ẹ bá mọ̀ pé èso wọn kìí ṣe jíjẹ nìkan ni kí ẹ máa gé, kí ẹ máa fi ṣe àtẹ̀gùn, tí ẹ fi lè wọ ìlú náà, títí tí ọwọ́ yín yóo fi tẹ̀ ẹ́.
Gege bi ayewo abajade  iwadii ajo eleto-ilera lorile-ede Uganda ni odun 2016, o ju eniyan enikan ninu awon obinrin marun-un, ti ojo ori won wa laarin odun medogunsi odunmokandinladota 15–49, eyi ti o je iko mejilelogun (22%) ninu ida ogorun ni iroyin so pe, won ti ni iriri ikolu tabi ifipa banilopo lojo aye won.
Ijoba orile-ede Togo ti fofin de igbese lorisirisi
Ọgagun Sagir ti fi lede pe gbogbo awọn olukopa atioun funrarẹ ni wọn ti pọn ni dandan ki wọn wa ni iyasọtọ gẹgẹ bi ofin ati ilana ijọba apapọ fun asiko arun Covid-19.
Bakan naa ni won tun n beere fun ipese owo iranwo fun ise iwadii ati sisan owo ajeseyin fun osu mejila tijoba je won pelu afikun owo osu won pelu ida metalelaadota ati fifopinsi ifitonileti pe ki won maa salaifo ipele ise kookan mo.
Ẹni tí ó bá sọ fún arakunrin rẹ̀ pé, ‘Ìwọ òmùgọ̀ yìí’ yóo wà ninu ewu iná ọ̀run àpáàdì.
Nítorí pé bí ẹ bá fi tọkàntọkàn fetí sí ọ̀rọ̀ mi, àwọn ọba yóo máa wọlé, wọn yóo sì máa jókòó lórí ìtẹ́ Dafidi.
Joe Biden tun wa fi ọrọ ranṣẹ si awọn araa Amẹrika pe ki wọn ma foya tori ko si idi kankan lati bẹruu gbigba abẹrẹ ajẹsara naa.
Ẹwẹ, Aarẹ Trump ko gba pe oun lọwọ si ikọlu ọhún lọna kọna.
Ṣugbọn ó ní, “Kí ni ń bà yín lẹ́rù.
Ṣebí àwọn arabinrin rẹ̀ nìwọ̀nyí lọ́dọ̀ wa yìí?
Ewe, igbimo naa kun fun orile-ede mewaa nile Afrika to n soju fun awon orile-ede nile Afrika ti yoo jo jiroro papo lati yanana awon isoro ti iyipada oju ojo n dasile lawujo.
Eyi jẹ lẹyin t'awon aladugbo rẹ pariwo sita lọ si agọ ọlọpaa Adatan nilu Abẹokuta pe ọbẹ gbigbona ati ada lo fi n da batani sara ọmọ naa.
(Iwe ilana ohun ṣiṣe fun aarẹ lẹgbẹ oṣelu AAC) Ayẹwo<br>lati mọ otitọ.
Lizzy Anjorin: Àsìkò 'Honeymoon' ni mo dédé rí Aláàfin àti olorì méjì tó wá súre fún wa
"Ayédèrú Ọ̀ṣun ni wọ́n ń bọ lónìí, kìí ṣe ojúlówó - Bàbá Ọlọ́ṣun tún figbe ta ""Ojú wa rí tó ní Egypt, bí wọ́n ṣe ń tẹ̀ wá lọ́mú, ni wọ́n ń gbá wa ní ìdí"" Ìdẹ̀ra dé, Gẹnẹrátọ̀ tó ń lo omi dé, a bọ́ lọ́wọ́ òkùnkùn Èmi àti Bọla Tinubu fẹ́ lo ‘German Mercenaries’ láti gbé MKO Abiọla kúrò lẹ́wọ̀n - Dele Momodu Àwọn ọmọ Nàíjíríà ló ṣiṣẹ́ takò mí ní Ireland kí ń má baà wọlé ìbò Káńsélọ̀ - Yemi Adenuga Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!"
Nisinsinyii, a ti fi odi yi yín ká, ogun sì ti dótì wá; wọ́n fi ọ̀pá na olórí Israẹli ní ẹ̀rẹ̀kẹ́.
Ó bá dá wọn lóhùn pé, “Nígbà tí ẹ bá wọ inú ìlú, ọkunrin kan tí ó ru ìkòkò omi yóo pàdé yín.
Wundia ni Tamari, kò tíì mọ ọkunrin rí; nítorí náà ó dàbí ẹni pé kò ṣeéṣe fún Amnoni láti bá a ṣe nǹkankan.
Gomina Sanwo-Olu tun kede pe awọn ile ounjẹ yoo bẹrẹ si ni fi aaye gba awọn onibaara wọn lati joko jẹun.
Bakan naa ni wọn ni awọn yoo tẹsiwaju lati ma a ri orilẹede Naijiria gẹgẹ bi asaaju ni ile adunlawọ ati orilẹede to bọwọ fun ifẹ araalu lọna ati mu itẹsiwaju ati alaafia ba orilẹede Naijiria.
gbogbo ohun tí ó ṣe láti ìbẹ̀rẹ̀ dé òpin, wà ninu Ìwé Ìtàn Àwọn Ọba Israẹli ati ti Juda.
Idi ni pe ọpọlọpọ awọn ipinlẹ lo ti sọrọ sita lasiko ti awọn oṣiṣẹ n ja fun owo oṣu tuntun, pe awọn ko ni le san ẹgbẹrun lọna ọgbọn Naira ti ẹgbẹ oṣiṣẹ n beere fun, bi ko ṣe ẹgbẹrun mejilelogun ataabọ Naira ti agbara awọn ka.
Oro ohun waye leyin bi won se tun sawari arun ohun nilu Mbandaka, ilu ti o kun fun opolopo eniyan ti o le ni milionu, eleyi ti o mu iberu gbojo jade ki arun naa ma lo tan kakaakiri olu ilu orile-ede ohun ti n se Kinshasa tabi awon orile-ede miiran.
Ẹ̀mí OLUWA bá bà lé Jẹfuta, ó bá kọjá láàrin Gileadi ati Manase, ó lọ sí Misipa ní ilẹ̀ Gileadi, láti ibẹ̀ ni ó ti lọ sí ilẹ̀ àwọn ará Amoni.
Nígbà tó ń ṣàlàyé ọ̀pọ̀ ipenija tó ti dojú kọ, Tope Alabi ni onírúurú irọ tí kò ní ẹsẹ nílẹ, ni àwọn èèyàn máa ń ṣàdédé pá mọ òun bíi kí wọn ní òun wà ní ọgbà ẹ̀wọ̀n torí gbígbé oogun oloro tàbí pé, òun àti ọkọ̀ òun ti pínyà, tó fi dé orí pé àwọn ènìyàn kii fẹ́ san owó láti gbọ orin ìyìn nínú gbọ̀ngàn.
"Akẹ́kọ̀ọ́ ìmọ̀ ẹ̀kọ́ ìsègùn òyinbo ni mi, mo wa nipele tó parí mo n ta ẹ̀sọ́ ọwọ́ ati t'ọrun mo si tun n se owo sise eto igbeyawo atawọn inawo mii.
Àtúnṣe òpópónà Lagos-Ibadan àwọn ọ̀ná míràn ti e lè gba Díẹ̀ ló kù kí bàlúù arìnrìnàjò sílẹ̀ mímọ́ Hajj gbaná Ṣé lóòtọ́ ni àdó olóró bú níléeṣẹ́ ìjọba South Africa tó wà nílùú Abuja?
Èsì ọrọ ree láti ọdọ ìjọba Buhari sí Obasanjo to so pe Buhari n pète láti ka ẹsùn sí òun lọrùn lasiko yii.
‘Ṣé kò sí nkan’ ni èmi àti ẹ̀gbọ́n mi ḿ bèèrè, ‘Kò sí nkan, ‘ ni wọ́n dáhùn.
Muhammadu Buhari: Iléẹjọ́ tó ga jùlọ bẹ̀rẹ̀ ìgbẹ́jọ́ ẹ̀sùn ayédèrú sabuké Buhari
Èèyàn mọ́kànléláádọta ló wá láti ìpínlẹ̀ Eko nínú èèyàn 72 tó kó ààrùn covid-19 lọ́jọ́ Ajé 'Ṣọ́ọ́ṣì ni mọ ti ń bọ̀ kí n tó pàdé àwọn sójà tó fi abẹ gẹ irun fún mi' EndSARS, EndSWAT Protests: Òbí agbábọ́ọ̀lù Kazim Tiamiyu Kaka àtàwọn míì tí ọlọ́pàá pa sọ̀rọ̀, omijé bọ́ lójú ''Àjọ NERC ti fún Disco láṣẹ láti padà sí owó tàríìfù tuntun iná mọ̀nàmọ́ná'' Ẹ dẹ̀kun lílo Sniper àti Dichlorvos fún ìtọ́jú oúnjẹ- NAFDAC kìlọ̀ Ẹni ọdun mẹtalelọgọrun un ni Pa Akojede ti o gbe ni agbegbe Gbonagun Obantoko ṣe nigba ti aya rẹ jẹ ẹni ọdun mejidinlọgọrun un ki ọlọjọ to de.
Wo àwọn òṣèré tó bímọ s'Amẹrika lọ́dún 2019 kí Trump tó f'òfin dèé Mercy Aigbe bu èpè jó àwọn tó ní gómìnà kan ló ra ilé fún-un Wo fọ́tò àrà MC Oluomo, Pasuma àtàwọn òṣèré tíátà míì níbi ìṣílé Iyabo Ojo Ọdún mọ́kànlá rèé témi àti ọkọ mi bẹ̀rẹ̀ ìfẹ́ láti ilé ẹ̀kọ́ girama - Bukunmi Oluwasina Ẹ wo nkan tí àwọn akẹẹgbẹ́ Lateef Adedimeji sọ nípa f'ọ́tò ìgbéyàwó òun àti Adebimpe tó jáde Ninu iroyin to jade bayii, akọroyin naa sọ pe Ronke 'Flakky', gbe Jago lọ sile ẹjọ, lati pẹlu iranlọwọ gbajugbaja agbẹjọro, to tun jẹ Minisita Naijiria keji fun ọrọ awọn oṣiṣẹ, ati igbanisiṣẹ, ki ọmọ le wa lọdọ rẹ.
Ninu atẹjade kan to fi lede loju opo Twitter rẹ, ileeṣẹ ọlọpaa ni ayẹwo ọhun yoo waye fun ọsẹ meji gbako.
Má ṣe fa ọwọ́ ire sẹ́yìn lọ́dọ̀ àwọn tí ó tọ́ sí, nígbà tí ó bá wà ní ìkáwọ́ rẹ láti ṣe é.
Ki alagba yii to papoda lo ti n sọrọ lori opo ikansiraẹni lori itakun agbaye pe, oun ko bẹru iku.
Ṣugbọn nígbà tí àwọn kan ṣe agídí, tí wọn kò gba ọ̀rọ̀ rẹ̀ gbọ́, tí wọn ń sọ̀rọ̀ burúkú sí ọ̀nà Oluwa níwájú gbogbo àwùjọ, Paulu yẹra kúrò lọ́dọ̀ wọn, ó kó àwọn ọmọ-ẹ̀yìn Jesu lọ sí gbọ̀ngàn Tirani, ó sì ń bá wọn sọ̀rọ̀ níbẹ̀ lojoojumọ.
Egypt ati akẹgbẹ wọn ni Zimbabwe ni wọn jọ figagbaga ti wọn ṣide idije naa ni ana.
Koda, o tun sọ wi pe ẹnikẹni to ba le sọ iru ọkọ ti oun n lo lọdun 2011; oun ṣetan lati fun iru ẹni bẹẹ lẹbun ẹgbẹrun un marun un owo naira.
Naomi bá sọ fún Rutu, ó ní, “Ṣé o rí i pé arabinrin rẹ ti pada sọ́dọ̀ àwọn eniyan rẹ̀ ati àwọn oriṣa rẹ̀, ìwọ náà pada, kí ẹ jọ máa lọ.
Ohun ìríra náà yóo sì wà níbẹ̀ títí tí ìgbẹ̀yìn tí Ọlọrun ti fàṣẹ sí yóo fi dé bá olùsọdahoro náà.
O so siwaju wi pe ile-ise naa ni ojuse lati je ki awon odo ni ife kikopa ninu ise agbe nipa agbekale ise olutona re ondokowo lori ise agbe ti awon elede geesi n pe ni agri-prenuer programme.
Gómìnà ìpínlẹ̀ Ekiti, Kayode Fayemi nàá ti ni aàrùn Coronavirus Àwọn aṣekúpani tún ti pa ọmọ ọdún 16 ní Akinyele nípìnlẹ̀ Oyo Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
‘Buhari ti wọnu ẹmi lọ’ Osinbajo: Mo ṣetán láti wàákò pẹ́lù àwọn tó ń bàmí lórúkọ jẹ́ Ki a to ka awọn orileede naa seti igbọ yin,ka sare sọ fun yin pe iyawo Sowore n lewaju iwọde nibi apero awọn olori orileede to n waye nilu New York.
Oríṣun àwòrán, Other Ọmọ ọdún mọ́kànlá tó bá wọn fọ́ àgọ́ ọlọ́pàá, wọ gàù ọlọ́pàá ní Edo Ọmọ ọdun mọkanla kan ti awọn ọlọpaa ni o wa lara awon janduku to kọlu ileeṣẹ olopaa kan ni ipinlẹ Edo nibi to ti wọ aṣọ iṣẹ sajẹnti kan ti wa ni ahamọ awọn ọlọpaa bayii.
Kii se pe awọn eeyan kan lo ba ẹrọ naa jẹ, nitori awọn sọja wa nibudo naa, ti wọn n sọ awọn ọpa afẹfẹ gaasi naa, irinsẹ rẹ kan lo bajẹ, amọ o ti ya ju fun mi lati kede iye ẹmi to ba isẹlẹ naa lọ."
 ijose tenis awon obinrin ( wta ) ti fisipo kini lagbaye ni igba otooto marun .
Gomina Kano tí ní kí olùrànlọ́wọ́ rẹ̀ lọ rọ́kún nílé nítori o bu Ààrẹ Buhari lórí #EndSars Ogbeni Olalere Ola to jẹ aṣoju ADP sọ nipa bo ṣe pe ebi ati iṣẹ lo jẹ ki awọn eeyan ta ibo wọn laiwo ẹyin wo ni Ondo.
OLUWA ranṣẹ ìdájọ́ sí Jakọbu,àní, sórí àwọn ọmọ Israẹli.
Ni papa iṣere MKO Abiola to wa ni Kutọ, nilu Abẹokuta ni Dapo ti ṣeleri lati ṣe atunṣe si igbe aye awọn oṣiṣẹ ijọba ipinlẹ Ogun.
Jakande pé 90 láì gba àmì ẹ̀yẹ kankan ní Nàíjíríà -Osoba Jeremy Hunt ni òun gbà pé Boris Johnson á ṣiṣẹ́ dáadáa Dalung, Audu Ogbe, Shittu Adebayo àti Isaac Adewole kò wọlé Ìbọn ọlọ́pàá ló pa èèyàn, ẹgbẹ́ wa kìí lo ìbọn - Shiite fárígá Wọn ni awọn ti ṣetan lati rii pe wọn gbe igbesẹ yii ki onikaluku le kọ ẹkọ to yẹ ninu iwa ọmọluwabi lasiko idibo.
john adams je oloselu omo ile amerika .
Lẹ́hìn èyí ọkùnrin náà tún gb’é àkèǹgbè títóbi kan fún Ewédayépọ̀, ara alèǹgbè náà dúdú mọnamọna, wọ́n so egungun ejò yí ọrùn rẹ̀ ká, ìyẹ́ onírúurú ẹyẹ ni wọ́n sì fi dí ílẹ́nu.
Ṣugbọn Jakọbu dá Rebeka ìyá rẹ̀ lóhùn, ó ní, “Onírun lára ni Esau, ẹ̀gbọ́n mi, n kò sì ní irun lára.
Ojọ́-orí àwọn igi wònyí ò tíì ju nkan bíi ọgọ́rùn-ún kan ọdún lọ.
Bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé Aigbe kò sọ agbègbè tí ilé náà wà, síbẹ̀ ọ̀pọ̀ àwọ̀n akẹgbẹ́ rẹ̀ ló ti ń ki kú oríire ní ojú òpó Twitter wọn.
Orílẹ̀èdè Amẹ́ríkà ni ìpínlẹ̀ náà wà.
"Wọn ti kesi adajọ ile ẹjọ ibilẹ naa lati f'oju wo o boya ẹri to peye wa lati fi ẹsun ""ole jija"" kan wọn."
Ó sì ti ṣe amúgbálẹ́gbẹ̀ẹ́ ààrẹ Ilé ìfowópamọ́ Àgbáyé ẹ̀ka ti Ilẹ̀ Adúláwọ̀ ìgbà kan láti oṣù Igbe ọdún 2007 sí oṣù Igbe ọdún 2012.
Ṣugbọn bí àmì yìí kò bá paradà níbi tí ó wà, tí kò sì tàn káàkiri, àpá oówo lásán ni, kí alufaa pe ẹni náà ní mímọ́.
Iroyin to hande ni wi pe wọn pa a laṣẹ ki ọkọ baalu Aeroflot ti orilẹede Russia pada si papakọ ofurufu nitori iṣoro to nii ṣe pẹlu ọkọ naa.
Mo wa ro awon oludibo ki won ri eto idibo gege bi idije, ki idibo naa si waye ni  irowo –irose ,ona alaafia , ati lai si wahala.
Ọlọrun Ṣèlérí láti Yan Olórí ní Bẹtilẹhẹmu.
Ọ̀pọ̀ kò ní ibití wọ́n máa sùn bí ìjọba ìpínlẹ̀ Èkó se bẹ̀rẹ̀ ilé wíwó Kínni ó ń fa ilé wíwó?
Oun ni enikeji ti yoo gba ami ẹyẹ naa ni orileede Kenya.
Eyi yoo jẹ ida ọọdunrun owo osu re laarin ọdun meji-meji Awọn osisẹ atọju ile marun ti awọn pẹlu lẹtọ sii owo ifẹyinti Ọlọpa mẹjọ, osisẹ ọtẹlẹmuyẹ SSS mẹta, ti ọkan ninu wọn si gbọdọ jẹ obinrin Eto iwosan ọfẹ fun awọn gomina, igbakeji gomina ati awọn ẹbi i wọn Isinmi ọlọgbẹ ọjọ ni oke okun pẹlu owoona fun gbogbo ọgbọ ọjọ naa Ida ọgbọn ninu ọgọrun owo osu rẹ gẹgẹbii ajẹmọnu owo fun atunse ọkọ Ida ogun ninu ọgọrun owo osu rẹ gẹgẹbii ajẹmọnu owoona atigbadegba Ida mẹwa ninu ọgọrun owo osu rẹ gẹgẹbii ajẹmonu owo igbafẹ Ida mẹwa ninu ọgọrun owo osu rẹ gẹgẹbii ajẹmonu owo itọju ile.
Aworan ti ẹ fi sọwọ si wa re e.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Sextuplet: Àdúrà Ìbùkún ló kú lẹ́yìn ọmọ mẹ́fà yìí- Ifeoma Thelma àti Onyemaechi Chiaka Adájọ́ ilé ẹjọ́ Sharia ti wọ́n ń pe ni Alkali maa n ni ẹkọ ìmọ̀ Islam àti ti ìgbàlódé.
Ní ọjọ́ kejì, wọ́n sọ wípé bí ó ṣe jí, tí ó wẹ̀ tán ni kó gbogbo kọ́kọ́rọ́ ilé lé ọmọ rè obinrín lọ́wọ́.
Àwọn ohun èèlò tí Olóògbé Olóyè Obafemi Awọ́lọ́wọ̀ lò gbẹ́yìn Gomina Makinde gbàlejò àwọn Imam lásìkò àjàkálẹ̀ àrùn Coronavirus Dòkítà tó ṣe iṣẹ́ abẹ fún oyún inú l‘Amẹrika ló ń sọ Yorùbá yìí, bíi ẹní la oyin Ìgunnukó nìyí, òrìsà Tápà, òrìsà olówó àti tọlọ́mọ O ṣalaye pe ileeṣẹ Yemkem n ṣiṣẹ lori ṣiṣe oogun coronavirus ni koro ati olomi, laipẹ yii ni ileeṣẹ naa yoo fi ṣọwọ si ajọ NAFDAC fun ayẹwo.
Awọn Boko Haram ti wọn jẹ alakatakiti ẹsin Islam ni awọn orilẹ-ede Naijiria, Cameroon, Nijer ati Chad n ba finra gẹgẹ bii agbesunmọmi lasiko yii.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Aborisade: Mẹ̀kúnù gbọ́dọ̀ funra sí Obasanjo Iranṣẹ Ọlọrun naa kun ara awọn ohun to n fọn tan-tan-tan lori wahala ọrọ aabo lorilẹede Naijiria, paapaa julọ, ni idi didaabo bo awọn ọmọlẹyin Kristi.
Awọn èèyàn tó sì jẹ oúnjẹ tí eku ohun tí fẹnu kàn, lọ ní àrùn ọhun, èyí tó ń tàn kalẹ kiri.
Ikede yii waye leyin ipade ti
Mallam Abdullahi sapejuwe oloogbe Akanbi gege bi eni to nifee si alaafia, otito ati ola, gege bi agbejoro ati adajo , o ko ipa pataki lori idagbasoke eto idajo lorile ede Najiria.
Gẹgẹ ba ti ka itan rẹ lori itakun agbaye ati Wikipedia, Alaafin akọkọ to jẹ obinrin ni Aláàfin Ọ̀rọ̀ǹpọ̀tọ̀niyùn.
Idẹ yìí ni ó lò láti ṣe ìtẹ́lẹ̀ àwọn ìlẹ̀kùn àgọ́ àjọ, ati pẹpẹ onídẹ, ati àwọn idẹ inú rẹ̀ ati gbogbo àwọn ohun èlò ibi pẹpẹ náà.
Ẹbọ sísun ni, ẹbọ olóòórùn dídùn tí a fi iná sun sí OLUWA.
Jesu bá sọ fún àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ pé, “Bí ẹnikẹ́ni bá fẹ́ tọ̀ mí lẹ́yìn, ó níláti sẹ́ ara rẹ̀, kí ó gbé agbelebu rẹ̀, kí ó sì máa tọ̀ mí lẹ́yìn.
O doju kọ iṣoro gan pe o lo aṣẹ konile o gbele lati doju kọ awọn alatako oloṣelu; si eyi igbẹyin aye rẹ, gbigbogun ti iwa ibajẹ lo fi ṣe.
Ofin ko si faaye gba abẹ dida fun smọbinrin nibi to ti wa.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ọ̀dọ́kùnrin tó kọ́kọ́ ṣe ẹ̀rọ tó ń tu ìyẹ́ lára adìyẹ Wọn ni igba awọn oyinbo amunisin, orilẹede Germany lo n dari orilẹede Cameroon nigba naa ko to di ẹyin ogun ti orilẹede naa yapa.
"Àwọn kókó ohun tó wà nínú lẹ́tà tí Aláàfin kọ sí Fayemi rèé Ìjọba Kano kò tẹ̀lé ìlànà tó tọ́ láti rọ̀ mí lóyè - Sanusi AMVCA7Award: Yewande Famakin lo gba àmì ẹ̀yẹ sinima èdè ibílẹ̀ Ronke Oshodi Oke ṣe àwo orin jáde fún MC Oluomo fún ọjọ́ ìbí rẹ̀ ""Inú ìbẹ̀rù bojo làwa ọmọ Nàíjíríà wà ní Italy, a kò leè jáde tàbí ra ọjà"" Nigba to n salaye siwaju lori lẹta naa, Alaafin ni oun ko ni kọnu n kọhọ kankan si gomina naa, koda inu oun ms si amọ oun gbe igbesẹ naa gẹgẹ bii oludaabo bo asa ati ise Yoruba ni."
 Ó tún fi ẹja síbú .
ọrọ yii woye pe Gomina fi iwe ifitonileti naa ranṣẹ ni ọjọ
Nítorí a gbọ́ tí ẹkún sọ ní Sioni,wọ́n ń ké pé, ‘A gbé!
Bi wọn ṣe kọlura wọn yii lo jẹ ki ina sọ ti o si di ijamba naa.
Gẹgẹ bi iroyin ṣe sọ ilu Canada ni kabiyesi Oluwo wa nigba ti ipe ati wa gun ori apere awsn babanla rẹ jade sii lọdun mẹrin sẹyin.
Bẹ́ẹ̀ ni àkùkọ kan bá kọ.
Gbogbo ère rẹ̀ ni n óo kójọ bí òkítì, a óo sì kọ̀ wọ́n tì; nítorí pé owó àgbèrè ni ó fi kó wọn jọ, ọrọ̀ rẹ̀ yóo pada sí ọ̀dọ̀ àwọn tí ń bá a ṣe àgbèrè.
l atọ ́ lágbé àti i.
Lẹ́yìn àlàyé Akọgun Adeniyi yìí ni BBC tún bá, ọjọ̀gbọ́n Akintoye to jẹ olórí ẹgbẹ́ YWC sọ̀rọ̀.
Àwọn ẹlẹ́gàn a máa dá rúkèrúdò sílẹ̀ láàrin ìlú,ṣugbọn àwọn ọlọ́gbọ́n a máa paná ibinu.
Atẹjade kan ti ijọba ipinlẹ Ekiti fi sita ṣalaye pe ọmọ ipinlẹ naa kan ti ko arun Coronavirus lẹyin to ni ajọṣepọ pẹlu ọmọ orilẹede Amẹrika kan to wọ orilẹede Naijiria ni ọjọ kẹta, oṣu kẹta ọdun 2020.
Ìdí tí n kò fi wá sí Kọrinti mọ́ ni pé n kò fẹ́ yọ yín lẹ́nu.
"Odunayo kan sẹkun niwaju Kamẹra BBC, ""mo fẹ ẹsan lorii iku London Tailor tori ọmọ mẹta to fi silẹ fun emi nikan""."
Abdulrahaman, Ọmọ ọdún 17 kó sí páńpẹ́ EFCC lórí ẹ̀sùn yahoo-yahoo ní Ibadan Báwo ni gbogbo alága kánsú Kwara ṣe de àhàmọ́ EFCC?
Omele Akọ: Oríṣun àwòrán, Others Omele ni a maa n saba pe eleyi, a mọ si ilu ti a n lu si orin sakara, asiko ayẹyẹ igbeyawo, iwuye, ati ajọdun ni a saba maa n lo.
 wón wí pé , enì kan tí ó so wí pé , òun kò le kó ilé sí ibi tí wón ń sin òkú sí ni ó sí kúrò ní àdúgbò imojì lo sí ibòmíràn tí ó sì pe ibè ní ibè ní ibi-ìdèra fún òun .
Bẹ́ẹ̀ ní kí ẹ má kí ẹnikẹ́ni ní ọ̀nà.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Election Update 2019: Àwọn ọlọ́pàá dá ìpàdé àwọn alátakò Tinubu dúró l'Eko 28 Èrèlè 2019 Oríṣun àwòrán, Facebook/Tinubu Àkọlé àwòrán, Ọrọ lori ibo gomina nipinlẹ Eko Awọn ọlọpaa yabo ile itura Airport Hotel ni Ikeja nipinlẹ Eko nibi ti awọn ajijagbara olosẹlu kan ti n ṣe ipolongo ibo lati ta ko Asiwaju Bola Tinubu ṣaaju ibo gomina ọjọ Abamẹta ọsẹ to n bọ.
Hagai bá dáhùn, ó ní: “Bẹ́ẹ̀ gan-an ni ó rí fún àwọn eniyan wọnyi ati fún orílẹ̀-èdè yìí pẹlu iṣẹ́ ọwọ́ wọn níwájú OLUWA; gbogbo ohun tí wọ́n fi ń rúbọ jẹ́ aláìmọ́.
Ọ̀kan lára àwọn olorì rẹ̀, Anuoluwapọ Adeyẹmi ló tún bí ìbejì ọkùnrin kan àti obìnrin láìpẹ́ yìí, èyí tó sọ ọ́ di ìkẹta láàrin oṣù mẹ́jọ.
Ninu alaye wọn, eyi ti asaaju ikọ agbẹjọro to n soju igun mejeeji, agba amofin Livy Uzoukwu gbe siwaju igbimọ olugbẹjọ naa, o ni asise waye nidi isiro awọn esi ibo aarẹ ni ipinlẹ mọkanla.
Progressives Congress, APC, o n soju fun ekun Surulere 1 , ni ipinle Eko.
sibẹsibẹ, n óo yọ̀ ninu OLUWA,n óo yọ̀ ninu Ọlọrun Olùgbàlà mi.
Nígbà tó tún yá, ọkọ̀ ojú omi tún gbé jàmbá nlá dé.
Wolii Jeremaya kọ orin arò fún Josaya ọba.
Ìwọ tí o níláárí ní òde ayé, ìwọ tún lọ níláárí ni òde ọ̀run.
Ọfiisi aarẹ tun ni, ijọba ko ni fọwọ si owo miiran lẹyin ti irin naa ba ti pari.
Ẹ wo ìṣẹ̀lẹ̀ nípa ẹ̀sùn ìfipábánilòpọ̀ tí wọ́n fi kan D'banj ní sísẹ̀-n-tẹ̀lé Eji Gbadero, ọmọ Ibadan àti jayé-jayé ọmọ ónílẹ̀ ti wọn yẹgi fun l'Eko Ìdílé márùn-ún tó gbajúmọ̀ fún òwò ẹrú nílẹ̀ Yorùbá Ìhòhò ọmọlúàbí ni mo má a ń bá àwọn ọmọkùnrin mi wí - Elesho Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ìtàn Olaniyi Balogun, ọ̀jọ̀gbọ́n tó fi Nàìjíríà sílẹ̀ lọ gba iṣẹ̀ àgbẹ̀ l'Ámẹ́ríkà Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 3 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 5 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Muhammadu Buhari ti kopa ribiribi lasiko ogun fun Naijiria.
Alaga ẹgbẹ osisẹ naa ni awọn gbe ọrọ aje Naijiria wo, owo ti awọn eniyan fi n wọ ọkọ, ile ti awọn eniyan n gbe, ati ọpọlọpọ nkan miran ni awọn gbe yẹwo.
Oríṣun àwòrán, @deji_of_lagos Kini a le so nipa June 12 ni soki?
ti rọ awon omo orile ede yii to n gbe ni ilẹ okeere lati fọkan balẹ pe ijoba
Nigba to n sọrọ lori bi pasipaarọ owo dọla ṣe n ṣakoba fun ọrọ aje Naijiria, minisita ni banki apapọ Naijiria, CBN gbe owo dọla kan to wa ni ọta le lọdunrun un (N360) naira tẹlẹ lọ si ọrin le lọdunrun un o din kan(N379).
Ó bá rí ọkunrin ará Etiopia kan.
“Ní ọjọ́ náà, ni n óo pa àwọn ọlọ́gbọ́n run ní Edomu,òye wọn yóo sì di òfo ní òkè Esau.
Báwó ni òògùn dexamethasone ṣe ń ṣiṣẹ́ lára Àwọn tó ní Covid-19 ní Nàìjíríà tún ti pọ̀ si, ènìyàn 661 ló tún ṣẹ̀ṣẹ̀ ni i Ìséde ká mi mọ́ orí afára Kara ni mo ní kí n sùn, ki ọkọ̀ mi tó jóná Oníṣòwò kan wó ọ́fíìsì Nàìjíríà ní Ghana lulẹ̀, ìjọba Nàìjíríà faraya Ó di gbéré!
Ọjọ kọkanlelogun, oṣu kẹsan ni adajọ a kede idajo lati ran wọn lọ ẹwọn.
O fi idaniloju han pe gbogbo iwadii to yẹ ni wọn yoo ṣe bayii.
Oríṣun àwòrán, Jaye Kuti/Facebook Àkọlé àwòrán, Òsèré Tíátà Jaye Kuti Jaye Kuti A bí i ní ìlú Ilaro, ìpínlẹ̀ Ogun ní ọjọ́ kẹ́wàá osù keje.
Bakan naa ni ijọba pasẹ pe ki wọn pin aṣọ iboju ni ọfẹ fun gbogbo akẹkọọ to wa nipinlẹ naa, boya nile ẹkọ ijọba ni tabi ti aladani.
Oríṣun àwòrán, Joke/instagram Àkọlé àwòrán, Joke Silva: Modupe lọ́wọ́ àwọn algbatọ mi fún itóju wọn Amọ Jọkẹ salaye pe, akara tu sepo ni ọjọ kan ti oun n wa iwe asẹ irinna oun, taa mọ si Passport.
Òfìfo ṣọ́ọ̀ṣì pa aṣọ dà fún àwọn Páṣítọ̀ Nàìjíríà Dánáfojúrà nìyí, abàmì eégún tí ń gbé inú iná ṣọlá Ìrìnàjò Toyin Abraham, láti orí gbèsè jíjẹ, ó di onílé, onimọto àti aya lọ́ọ̀dẹ̀ ọkọ Àwọn Alákòso gárèjì ló kó ìbọn àti àdá tọ ọlọ́kadà wá ní Soka-Alága ẹgbẹ́ ọlọ́kadà Ọyọ Èèyàn 5 mííràn tún ti lùgbàdì ààrùn Coronavirus ní Naijiria Ijọba ipinlẹ Ondo ati ẹgbẹ ọmọlẹyin kristi nibẹ ti kọkọ fi ẹnu ko pe awsn yoo ṣeto ipade ajọyọ ọdun Ajinde ni ọjọ Aiku ki ijsba to yi ohun pada nitori eeyan kan to tun ni arun naa nipinlẹ ọhun.
Ṣugbọn ọba Juda ṣọ̀tẹ̀ sí ti Babiloni, ó rán ikọ̀ lọ sí Ijipti pé kí wọ́n fún òun ní ẹṣin ati ọpọlọpọ ọmọ ogun.
Lagos -Ogun Tanker Explosion: Ọkọ̀ agbépo kan tí gbiná lórí afárá Magboro
O ni botilẹjẹ wi pe oun ko ti i ba ọmọ oun sọrọ, ọkan oun balẹ bayii.
Ewuro ti egbe agbaboolu Arsenal gbo si oju Frankurt yii mu irẹwẹsi ba gbogbo awọn alatilẹyin wọn lọpolọpọ.
Oríṣun àwòrán, oGUN STATE GOVERNMENT Àkọlé àwòrán, Ohun to ru ọpọ loju ni oludije ti kan aarẹ Buhari wa pẹlu ni ipinlẹ Ogun O ni aarẹ ko lee kọ ipakọ si ẹnikẹni tabi oludije lati awọn ẹgbẹ oṣelu miran ti o ba wa kii; bẹẹni ko lee sọ pe ohun ko fẹ atilẹyin wọn.
Trump ni o yẹ ki wọn sun ọjọ idibo naa siwaju sii nitori ajakalẹ arun coronavirus to n ab gbogbo agbaye finra lati ibẹrẹ ọdun yii.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ó tó gẹ́ ní àṣà ìpolongo tó fakọyọ lásìkò ìbò 2019 3 Ẹrẹ̀nà 2019 Oríṣun àwòrán, @RealAARahman Àkọlé àwòrán, Oofisi lo n rẹyin akọwe ni igbagbọ ọpọ eniyan Lagbo oṣelu,ti awọn oloṣelu ba fẹ ṣe koriya fun awọn alatilẹyin wọn, wọn a máa fun wọn ni awọn ọrọ akọmọna eleyi ti yoo ma da wọn laraya.
Ninu ohun ta ri gbọ, n ṣe ni awọn agbofinro to wa nibi isinku naa da ọkọ wọn pada, ti ọrọ naa si fẹ di fa ki n fa ki wọn to fi ibẹ silẹ.
 Àwọn tí wọ ́ n kọ ́ láàrín ọdún 1984 sí 1988 gbọ ́ dọ ̀ ní ohun èlò yìí ní Ọjọ ́ kínín oṣù kérin Ọdun 1990 ; àwọn tí wọ ́ n kọ ́ láàrín ọdún 1974 sí 1983 gbọ ́ dọ ̀ ní ohun èlò yìí ní Ọjọ ́ kínín oṣù kérin Ọdun 1991 .
Oríṣun àwòrán, Yinka TNT/Facebook Koda lasiko ti a n fi ọrọ wa Yinka TNT lẹnu wo, o ni i lara gan lati maa ṣẹnu ku pe awọn ẹya ara yii eyi to ti mọ ọ lara gẹgẹ bi onimọ nipa ibalopọ lakọ labo.
Àwọn obinrin tí ó lóyún ati àwọn tí ó ń tọ́ ọmọ lọ́wọ́ gbé!
Ìjọba ìpínlẹ̀ Osun ṣetán láti tilẹ́kùn ibodè rẹ̀ nítorí Coronavirus Oríṣun àwòrán, @GboyegaOyetola Ijọba ipinlẹ Osun ti kede igbeṣẹ lati tilẹkun ibode rẹ lọna ati dena itankalẹ arun Coronavirus nipinlẹ ọhun.
Ni ipari o ki aare ajo agbaye fun ilera WHO Onisegun oyinbo Margaret Chan  fun sise atileyin fun ile Adulawo.
A máa jí ní òwúrọ̀ kutukutu, a sì dúró ní ẹ̀bá ọ̀nà, ní ẹnu ibodè ìlú.
Mo bá rí Ọ̀dọ́ Aguntan tí ó dúró láàrin ìtẹ́ náà, àwọn ẹ̀dá alààyè mẹrin ati àwọn àgbààgbà mẹrinlelogun náà yí i ká.
Ìkíní ni pé l’óòótọ́ a kò ní ètò ìkọ̀wésílẹ̀ ní ilẹ̀ Yorùbá kí àwọn Lárúbáwá àti àwọn ará Úróòpù tó dé.
isuna odun 2019 wa si imuse.
Ó ní “Wá, n óo fi iyawo Ọ̀dọ́ Aguntan hàn ọ́.
O ni ijọba ko lodi si ibaṣepo ti yoo mu ki eto idibo to n bọ lọna kẹsẹjari.
lorile ede yii , ni eyi ti o bẹrẹ lati ojo kéjídínlọ́gbọ̀n
Robbery Squad SARS ,  nile aare to wa
O wa ke si ijọba lati ṣe ayẹwo bi o ṣe n na owo, paapaa julọ owo ti awọn to wa ni ijọba n gba.
India: Arakunrin ti wọn doola ẹmi rẹ kuro ni Ile igbokusi pada jade laye
igbagbo  ti won ni nipa ipinnu aare  Buhari ati igbakeji rẹ  Osinbajo, ni eyi ti o mu won lati tun dibo yan
Agbègbè Somolu f'ojú winá ìjà ní ìpínlẹ̀ Èkó
Àwọn ará ìlú wọnyi bá fi ohùn ṣọ̀kan, wọ́n wá sọ́dọ̀ rẹ̀.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù International Day Against Drug Abuse and Trafficking: ìdí ti mo fi ń mu oògùn olóró Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ International Day Against Drug Abuse and Trafficking: ìdí ti mo fi ń mu oògùn olóró 26 Òkùdu 2019 Ko si ẹni ti kò le fi oogun oloro silẹ nitori o n ba ni laye jẹ ni - Seyi Adeyemi Oni ni ni ayajọ gbigbogunti oogun oloro lilo ati gbigbe oogun oloro kiri ni agbaye fun ọdun 2019 ni eyi to jẹ ki BBC Yoruba wa awọn to ti lugbadi ẹ lọ.
gẹ ́ gẹ ́ bi ó ti jẹ ́ pé oríṣìíríṣìí iṣẹ ́ ni ó wà ní ilẹ ̀ yorùbá láyé àtijọ ́ àti lóde òní , bẹ ́ ẹ ̀ náà ni a lè rí i ní ìlú Ọ ̀ gbàgì níbi tó jẹ ́ pé púpọ ̀ nínú àwọn iṣẹ ́ àtijọ ́ ni ilẹ ̀ yorùbá ni wọn ń ṣe .
“Nígbà tí a pada dé ọ̀dọ̀ baba wa, iranṣẹ rẹ, a rò fún un bí o ti wí.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Buhari, tètè gba isẹ́ lọ́wọ́ àwọn ọ̀gá ológun - Afẹnifẹre CAF kéde orúkọ àwọn olùdíje àmì ẹ̀yẹ agbábọ́ọ̀lù Áfíríkà Ọrọ abo ni o ga ju ninu awọn igbelewọn eleyii to ja orilẹede Cameroun kulẹ.
Muhammadu Buhari: APC ẹ ṣọ́ra, ẹgbẹ́ kò gbọdọ̀ túká lẹ́yìn ìsàkóso mi
sagbon, ti o si tun fi iketa le niseju márùndínláàdọ́rin
Àwọn Olúkọ ìpínlẹ̀ Oyo fakọyọ lórí ètò Akọ́mọlédè àti Àṣà púpọ̀ Kílódé tí Ọọni Ife, Oba Ogunwusi kò fi gbọdọ̀ rí ọmọ rẹ̀ tuntun ti Olorì Naomi bí títí di bíi ẹ̀yìn oṣù mẹ́fà?
Bo ba ṣe pe mo lagbara ẹ ni, maa wa ọna ti wọn a fi fopin si lilo awọn ohun eelo onike ni ipinlẹ Eko, paapaa awọn ti wọn ko ni le ṣamulo wọn mọ, to jẹ pe ẹẹkan ti wọn ba ti lo wọn ni wọn gbọdọ sọ wọn nu.
Cardi B ṣàlàyé ohun tó gbé fọ́tò ìhòhò rẹ̀ d'órí ayélujára Instagram Ìdí táwọn olùwọ́de EndSARS fi kọ oúnjẹ àti ọtí ẹlẹ́rìndòdò tí MC Oluomo gbé wá rèé Wo nọ́mbà tí o le è pè láti gba owó gbà-má-bínú tí ọlọ́pàá bá fìyà jẹ ọ́ lọ́nà àìtọ́ l'Eko Tola Oyediran ọmọ Obafemi Awolowo ti jáde láyé Àwọn olùwọ́de ṣetán láti bá mínísítà FCT Abuja wọ̀ ṣòkòtò kan lórí àṣẹ má ṣe ìwọ̀de Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí 7:57 Fídíò, End SARS, End SWAT: Ó pé mi bí SARS kò ṣe sọ mí dolówọ́- Fulani Kwajafa, Duration 7,5717 Ọ̀wàrà 2020 5:55 Fídíò, Soyinka Cancer: Àṣe ara mi ni iso ti n run gbogbo bí mo ṣe n ṣèrànwọ́ lórí jẹjẹrẹ, Duration 5,5527 Bélú 2019 Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí kan sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
Nígbà tí Jesu jáde, bí ó ti ń lọ lọ́nà, ọkunrin kan sáré tọ̀ ọ́ lọ, ó kúnlẹ̀ níwájú rẹ̀, ó bi í pé, “Olùkọ́ni rere, kí ni kí n ṣe kí n lè jogún ìyè ainipẹkun?
Ni ó bá lé wọn kúrò ní kóòtù.
Nigba to n salaye awọn eto ti yoo waye nilu Dubai lasiko ayẹyẹ ọjọ ibi ọdun kẹtadinlọgọrin Iya Rainbow, ati idi ti wọn fi gbe eto naa, eyi ti yoo waye laarin ọjọ Kẹtadinlọgbọn osu Kẹwa si ọjọ Kẹta osu Kọkanla ọdun 2019 lọ silu Dubai.
Jakọbu ṣa àwọn ọmọ aguntan wọnyi sọ́tọ̀, ó sì tún mú kí gbogbo agbo ẹran Labani dojú kọ àwọn ẹran tí àwọ̀ wọn ní funfun tóótòòtóó tabi tí ó dàbí adíkálà, tabi àwọn tí wọ́n jẹ́ dúdú, ó bá bẹ̀rẹ̀ sí ṣa àwọn ẹran tirẹ̀ sinu agbo kan lọ́tọ̀, kò pa wọ́n pọ̀ pẹlu ti Labani.
ti yoo tun darapo mo won ni, olugbani-nimoran pataki lori oro abo, oga agba
Akẹ́kọ̀bìnrin Chibok kan tó ráàyè sálọ kàwé gboyè l'Amẹrika
Ninu àwọn ìlú tí ẹ óo fún àwọn ọmọ Lefi, mẹfa ninu wọn yóo jẹ́ ìlú ààbò tí ẹni tí ó bá ṣèèṣì paniyan lè sá lọ.
" Idi ni pe, ti kii ba ṣe ti aisan yii, mi o ni ronu pe mo fẹ ẹ da ajọ alaanu silẹ.
Ìgbàjọba Seyi Makinde: Hosea Agboọla, Bisi Ilaka wà lára ọmọ ìgbìmọ̀
Ọpọ eeyan lo ro pe Pitana fi igba kan bọkan ninu lẹyin ti o fun France ni ''penalty'' naa ti France si bẹrẹ si ṣiwaaju pẹlu ami ayo 2-1.
Arabinrin Ifeyinwa sọ pe oun ti gba ẹbẹ ti ọkọ oun bẹ oun.
Ṣugbọn Jonatani kò gbọ́ nígbà tí baba rẹ̀ ń fi ìbúra pàṣẹ fún àwọn eniyan náà.
Minisita naa wa ki awon osise
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ World Aids Day: Wo bí kòkòrò ààrùn HIV se bẹ̀rẹ̀ lágbàyé!
Ṣé ẹ kò ní ọba ni?
Gẹ́gẹ́ bí ìtàn náà ti sọ fún ni, Àǹjànnú-ìbẹ̀rù fẹ́rẹ̀ dá bàbá mi nì ẹ̀hìn níbi tí ó ti ń fi ẹ̀hìn rẹ̀ na igi.
Koda, bi o ko ba ri oorun sun, iwọ sa ti jẹ ewe Lettuce, bi ọmọ tuntun jojolo lo sun fọnfọn.
Àti pé títẹ̀lé ìlànà ètò ààbò ni ọ̀nà àbáyọ̀.
Ẹni tí ń tọ́jú igi ọ̀pọ̀tọ́ yóo rí èso rẹ̀ jẹ,ẹni tí ń tọ́jú ọ̀gá rẹ̀ yóo gba ìyìn rẹ̀.
Wo ohun tí òfin àgbáyé sọ nípa ọmọ tí a bí sí inú bàlúù Àjọ NCDC kéde ènìyàn 381 míràn tó ní ààrùn Covid-19 l'órílẹ̀-èdè Nàìjíríà Kí ló wà nínú àbá àkóso ajakalẹ àrùn tó fi ní àtakò?
Lasiko ti ilumọọka ojisẹ Ọlọrun naa si n ba BBC Yoruba sọrọ lori aifararọ eto aabo lorilẹede Naijiria, Abiara salaye pe, kii se orilẹede Naijiria nikan ni eto aabo ti mẹhẹ, kaakiri awọn orilẹede lagbaye ni.
Ṣaaju wọn ti jawe lọ sinmi nile fun Onnoghen latari ọrọ to ni ṣe pẹlu aikede dukia rẹ laipẹ rẹ si ni iroyin kan n ja rayin rain pe Ṣé lòótọ́ ní pé adájọ àgbà Nàìjíríà Walter Onnoghen tí kọwe fiṣe sílẹ?
Ikede ohun waye lori ero Ethiopia Broadcasting Coporation EBC lale  lojo-Eti, leyin lojo keji ti olori ijoba Hailemariam Desalegn kowe fipo re sile.
Minista tun so pe ijoba ti pase
Nigba to n beere pe iru orilẹede wo lo yẹ ki eeyan fi ẹmi rẹ lelẹ fun, Bakare ni ko sẹni ti yoo fi ẹmi rẹ lelẹ fun orilẹede ti ko lee san owo osu to yẹ fawọn ologun atawọn osisẹ rẹ, tawọn oloselu rẹ si n gba owo gọbọi.
Èso mi dára ju wúrà dáradára lọ,àyọrísí mi sì dára ju ojúlówó fadaka lọ.
Nígbà tí pátákò ẹsẹ̀ ẹṣin bá ń dún,tí àwọn kẹ̀kẹ́ ogun rẹ̀ bá ń sáré,tí ẹsẹ̀ àwọn kẹ̀kẹ́ ogun sì ń pariwo,Àwọn baba kò ní lè wo àwọn ọmọ wọn lẹ́yìn pé kí àwọn fà wọ́n,nítorí pé ọwọ́ wọn yóo rọ;
Kọ ọ́ sílẹ̀, nítorí ohun tí yóo ṣẹlẹ̀ ní ọjọ́ iwájú ni; ọjọ́ náà kò ní pẹ́ dé, ohun tí o rí kì í ṣe irọ́, dájúdájú yóo ṣẹ.
ẹnu wọn kún fún èpè ati ọ̀rọ̀ burúkú.
marundinlogbon lo sile, tabi eni to n sise ninu oko oju omi, bee si ni o tun yo
Ó kígbe pe ọkọ rẹ̀ pé, “Jọ̀wọ́ rán iranṣẹ kan sí mi pẹlu kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ kan.
Chukwuebuka Anaekwe, lo gba ami miran wole fun iko egbe ABS FC ti ilu Ilorin ki saa keji to bo si ipari.
Ninu igbo iṣọdẹ-gbafẹ Kruger National Park ni erin ti ṣèṣì tẹ ọkunrin ọdẹ kan pa lọjọ Iṣẹgun ni eyi ti awọn oṣiṣẹ ibẹ fura si pe o dabi pe ko gbaaye to yeẹ kó gbà ki o to lọ ṣọdẹ nibẹ.
Bi awọn ẹgbẹ okunkun ti ṣe yapa bẹrẹ si ni ju iwa janduku Ipinya laarin awọn ọmọ ẹgbẹ Pyrates ni igba naa lo mu ki awọn kan yapa lati lọ da ẹgbẹ Buccaneer ati awọn ẹgbẹ mi silẹ.
Nigba to n kopa lori eto ori redio kan nilu Ibadan ni aarọ Ọjọru, Akeugbagold sọ pe irọ nla ni bi obinrin to wa laarin awọn afurasi naa ṣe sẹ pe, oun ko mọ ohunkohun nipa bi ọkọ rẹ ati awọn afurasi yoku ṣe ji awọn ibeji oun gbe.
Ọga ọlọpaa Galadanchi fi kun ọrọ rẹ pe miliọnu marun naira lawọn ajinigbe ọhun kọkọ beere lọwọ ẹbi awọn agunbanirọ naa ki awọn to fi wọn silẹ.
Nigba miran ẹwẹ, awọn obi ọmọdebinrin ti wọn ba lopọ kii tete mọ nipa isẹlẹ ifipabanilopọ naa, ti yoo si maa waye ni igba gbogbo.
6) Kelvin Olusola: Ọjọ Karun-un, oṣu Kẹwaa, ọdun 1988, ọdun mejilelọgbọn ṣẹyin ni Kelvin Oluwole Olusola dele aye, ọmọ Oodua pọnbele si ni baba rẹ, iya rẹ si jẹ Akata.
Toun ti ikede yii, awọn to jade lawọn agbegbe kan ke irora latari sunkẹrẹ fakẹrẹ ọkọ to waye.
Ọmọ orilẹede South Africa kan to jẹ onimọ nipa ọ̀rọ̀ aje, Carlene van Westhuizen, sọ ninu abọ iwadi kan to ṣe fun ile ẹ̀kọ́ Brookings Institution to wa ni orilẹede America sọ pe awọn talaka ko fi bẹ ẹ janfaani idagbasoke to ba ọrọ̀ aje."
 Nitori naa, igbese to waye ni ipinle Benue, ko bojumu ,mo lero pe won a se nnkan nipa re.
Ẹsẹ̀ lásán ló fi kọ, ṣùgbọ́n nítorí kò ka ẹsẹ̀ náà sí, ẹsẹ̀ di egbò, kò tètè san mọ́ kòkòrò búburú sí bá ibẹ̀ wọlé.
Ẹwẹ, ida o le ni ida mẹtalelọgọta to n lọ ile igbọnsẹ laarọ, ida mejielogun lọsan ati o fẹrẹẹ to ida mẹta lalaalẹ.
àwọn èèrà kò lágbára,ṣugbọn wọn a máa kó oúnjẹ wọn jọ ní ìgbà ẹ̀ẹ̀rùn.
Koda, si ọrọ yi debi ti yoo yanju rẹ titi ti o fi wa sakoba fẹgbẹ naa lapapọ.
Awuyewuye naa ṣi n lọ lọwọ lori boya awọn janduku ti da ọpa aṣẹ ọba ilu Eko pada abi bẹẹ kọ.
Ero ọpọlọpọ awọn ololufẹ Naira Marley lo jọra wọn lori ọrọ naa, n ṣe ni awọn naa fi orin ''Se bi omo jesu niwo, gbese ko Tesumole '' bọ ẹnu ni idahun wọn si esi Naira Marley.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Owó oúnjẹ ni mo lọ ọ gbà, oyún ọmọ tí mo jù sí àkìtàn ni mó gbé wálé- Dupe, ìyá Muiz 5 Owewe 2020 Àkọlé àwòrán, Ekọ ni ọrọ Iya Muiz jẹ fun awọn ọdọ isiyi Ti gbogbo obinrin ba loyun, adura wa a bi wẹrẹ, wa ri ọmọ gbejo ni diẹ lara adura ti awọn eeyan ma n gba fun wọn.
Àkọlé àwòrán, Níbo láyé kọjú Bi o tilẹ jẹ wi pe arabinrin Adebiyi ni ọpọlọpọ igba ti obinrin ba da si sisan owo ile iwe ọmọ, o n furugbin si ọjọ la rẹ ati tawọn ọmọ ni.
Kí ògo kí ó jẹ́ ti Ọlọrun Baba wa lae ati laelae.
Owo naa to o biliọnu kan aabọ Naira (1.
Dokita Sunday Ibrahim to jẹ akọwe ẹgbẹ naa nipinlẹ Kaduna ṣalaye fun BBC pé awọn ti gbe igbesẹ to yẹ lori ofin naa.
Èmi náà yóo ṣe yín dáradára, nítorí ohun tí ẹ ṣe yìí.
kí wọ́n lè ní ìṣúra fún ara wọn tí yóo jẹ́ ìpìlẹ̀ rere fún ẹ̀yìn ọ̀la, kí ọwọ́ wọn lè tẹ ìyè tòótọ́.
E̩kó̩ ní ilé‐è̩kó̩ alákò̩ó̩bè̩rè̩ yìí sì gbo̩dò̩ jé̩ dandan.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìkànìyàn: A ti tó igba mílíọ́nù èèyàn ní Nàìjíríá 11 Ìgbé 2018 Oríṣun àwòrán, Reuters Àkọlé àwòrán, Àádọ́ta ọdún sẹ́yìn ni iye ènìyàn ti pọ̀ gan láì sí ìgbéga tó báa àwọn ohun amáyérọrùn.
Bakan naa lo tun n ba awọn ileeṣẹ agboworin ori ayelujara kan bii Wester Union sọrọ nitori awọn ọna olowo pọọku ati ayarabi aṣa ti o n wa fun awọn eeyan ti ko ni apo ifowopamọsi lati fi owo ranṣẹ tabi gba owo.
9 5181 Orilẹede San Marino 48 142.
Divorce: Ilé ẹjọ́ tú ìgbéyàwó ọdún mọ́kànlá ká nítórí pé ìyàwó fí ìbálòpọ̀ dun ọkọ rẹ̀
"Oríṣun àwòrán, Oluwo/instagram Àkọlé àwòrán, Oluwo ati Olulufẹ rẹ Kabiyesi fi iyawo rẹ yangan - ""Ṣé bóo rí ìyàwó mi bó ṣe dùn, ṣe ìyàwó Ààfàá ló wá ń kàn?"
Bẹ́ẹ̀ ni o óo ṣe ya àwọn ọmọ Lefi sọ́tọ̀ láàrin àwọn ọmọ Israẹli, wọn óo sì jẹ́ tèmi.
Nibiti orilẹede meji ba ti wa nipo kannaa ninu igbelewọn kan, igbelewọn awọn dun to ti kọja ni wọn yoo lo lati yanju rẹ.
'Iwadii naa fikun wi pe, pupọ ninu awọn ajoji wọnyii kii ṣe ọmọ Naijiria.
Ìyàn náà mú tóbẹ́ẹ̀ tí ìdààmú bá gbogbo ilẹ̀ Ijipti ati ilẹ̀ Kenaani nítorí pé kò sí oúnjẹ rárá ní ilẹ̀ Kenaani.
Bakan naa lo salaye pe nibamu pklu isẹ titan ina yika ipinlẹ Ọyọ ti oun ti dawọ le, oun yoo tun ri daju pe gbogbo ipinlẹ Ọyọ ni wọn tan ina oju popo si, to fi de awọn aafin awọn ọba alaye bii Olubadan tilẹ Ibadan, Alaafin tilu Ọyọ ati Sọun ti Ogbomọsọ.
Ààrẹ Beji Caid Essebsi, torílẹ̀èdè Tunisia jáde fáyé
Laarin oṣu mẹfa ninu ọdun 2020 yii, sẹnẹtọ mẹta ọtọtọ nile aṣofin agba l'Abuja tii ṣe olu ilu Naijiria lo ti jade laye.
ẹ kò gbọdọ̀ dà á sí ara àwọn eniyan lásán, ẹ kò sì gbọdọ̀ ṣe òróró mìíràn tí ó dàbí rẹ̀.
Atiku yii lo jẹ́ alátakò Buhari fun ipò àarẹ lásìkò ìdìbò ọdún 2019 Buhari fẹ́ fẹ́ ìyáwó túntun: Eyí to súnmọ etílẹ̀ jùlọ ni ìròyìn to gbòde láipẹ pé àarẹ Buhari ń mura láti fẹ́ ọkàn nínú àwọn mínísítà rẹ̀ Sadiya Umar Faruq.
Lati ọmọ ọdun mẹjọ ni Chinonso ti bẹrẹ ege gige, to si fẹ dabi Messi, Ronaldo ati Okocha.
Ìdí rèé tó fi yà mí lẹ́nu pé igi pàtàkì yìí kò da nǹkankan lóju wọn, tí èso rẹ̀ sì ń ṣòfò dànù bẹ́ẹ̀.
O gbe Hannah Idowu Dideolu ni iyawo, wọn si bi ọmọ.
Bakan naa ni Olori ni arun Coronavirus ti ohun kọ oun lominu lo jẹ ki oun kurọ lori ẹrọ ayelujara fun igba diẹ lati le e gbadura nipa ohun to n sẹlẹ lagbaye.
Oludamọran si gomina ipinlẹ Oyo lori eto aabo, to tun jẹ Kọmisana ọlọpaa tẹlẹ, Fatai Owoseni ti wa salaye idi to fi rọrun fun awọn ajeji naa lati raye wọle si aarin wa.
Yàtọ̀ sí èyí, ènìyàn bii ọgbọ̀n ló wá ní ẹsẹ̀ kan ayé ẹsẹ̀ kan ọ̀rún ni onírúurú ilé ìwòsàn ní ìjọba ìbílẹ̀ Ikeduru àti Mbatoli ìpínlẹ̀ náà báyìí nítori wọ́n fa èèfi ẹ̀rọ amúna wá símú.
Ọmọ ọdun mẹrinlelogn ni Dorathy Bachor ti o si jẹ agbanisiṣẹ ni ipinlẹ Delta.
Koda, obinrin to ba n ṣe nnkan oṣu ni wọn kii gba ko jokoo ti ẹni to ni oogun ibilẹ lara nitori igbagbọ pe, oogun naa yoo bajẹ.
Infantino to jẹ akọwe ajọ Uefa tẹlẹ lo wa lẹyin imugboro ife ẹyẹ agbaye lati ikọ agbabọọlu mejilelọgbọn si mejidinlaadọta ti yoo dije lọdun 2026 ti yoo waye ni orilẹede America, Canada, Mexico.
 Ó padà di ọlọ ̀ tẹ ̀ alákòóso àgbàm , tí ó ń jẹ ́ kí gbogbo ìgbìyànjú smith lati ri pé ìrẹ ́ pọ wà láàrin àwọn èèyàn dúdú nígbà ogun abẹ ́ lé ti ilẹ ̀ rhodesi dàbí ohun tí kò dára lójú àwọn ènìyan .
Ajọ to n risi ọrọ oju ọjọ ni iji lile Cyclone Fani ni agbeegbe Orissa, ti wọn tun n pe ni Odisha lo wa ni ọgangan ibi ti iji lile naa n gba.
Bẹẹ naa si ni awọn ontaja ti maa n foju sọna de asiko yii lati wọ́ owo lọle pẹlu oniruuru nkan ti wọn ba n ta.
Ọdun 1983 ni wọn gba a wọle si iṣẹ aṣofin ni Naijiria, lẹyin to lọ si ileewe imọ ofin Naijiria, Nigeria Law School.
Láti ìgbà náà ni wọ́n ti ń pe ibẹ̀ ní Peresi Usa, títí di òní olónìí.
O ni yatọ si pe wọn fi ọrọ wa Pasitọ naa lẹnu wo, ko si nnkan kan gboogi ti wọn lee mu jade gẹgẹ bi ẹri lẹyin ti wọn yẹ ile ẹjọ naa wo.
Nigba ti aare tun n soro lori bi ijoba ana se ba eto oro aje orile ede yii jẹ, o ni ijoba naa, ko ni idagbasoke ati ero okan rere fun orile ede Naijiria.
O ni pe kò si ǹkan ti òun fẹ́ lọ mu níle ìjọba lọ́dun 2023 bakan náà ni òun ko ni gbé ìgba ìdìbo kankan lọ́jọ́ iwaju sùgbọ́n òun yóò ri i dáju pé ètò ìṣèjọba àwa ara wa fi ẹsẹ̀ mulẹ̀ dáradára lórilẹ̀-èdè Naijiria.
Lọti bá jáde sí wọn, ó ti ìlẹ̀kùn mọ́ àwọn àlejò sinu ilé, 
INEC: Àìmọ̀kan-mọ̀kàn ló ń ṣe àwọn tó ń sọ̀rọ̀ tako ìyànsípò Amina Zakari Dino Melaye ṣubú lulẹ̀, ó d'èrò ilé ìwòsàn BBC Yorùbá yóò se ìpàdé ìtagbangba ní Kwara Àkọlé àwòrán, Amina Zakari O fi kun un wi pe ojuṣe oun ko tilẹ̀ tan mọ ohun ti àwn to n pariwo n ro rara.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ẹ̀mí 27 bọ́ nínú ìkọlù Kaduna Simí, Davido gba àmì ẹ̀yẹ 'Headies' 'Iṣẹ́ orí rán mi ní mo lọ kọ́, ti mò ń ṣe fi jẹun' Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
mimo pe laisi ifetosomo-bibi, o se e se ki eto ‘IDAGBASOKE ALALỌPẸ’ ti a
Ọ̀pá rẹ̀ yóo wà lórí òkun.
" Oríṣun àwòrán, FRSC/ TWITTER Àkọlé àwòrán, Ọ̀gá àgbà àjọ ẹ̀ṣọ́ aláàbò ojúpópó (FRSC) ní ìpínlẹ̀ Òndó ti jáde láyé Adarí ẹ̀ka ìsẹ́ nínú àjọ nàá ní ìpínlẹ̀ Òndó, Ọ̀gbẹ́ni Oluṣẹ́gun Ògúngbémidé sọ fún BBC pé Ọ̀gbẹ́ni Jack jáde láyé lóòrọ̀ kùtù ọjọ́ kejì, oṣù Karùn, lẹ́yìn àìsàn ránpẹ́.
Oríṣun àwòrán, others Àkọlé àwòrán, Nọ́mbà 10: Ọmọ taye bi, laye n pọn ni nigba ti telifiṣọn yii jade, lọrọ di oni kọ́lọ̀kọ́lọ̀ lori amohumaworan ti awọn ọdọkunrin n ru pọnunpọnun ati birisope ki wọn le ra sinu iyara kan ti wọn n gbe lọdun naa!
Iroyin ti a gbọ ṣalaye pe, baba agbalagba naa n gba itọju fun kokoro arun HIV ni ileewosan kan ni ipinlẹ Rivers.
Ìdíje bọọlu ti gba iṣiro lọ́tẹ̀ yìí.
Nigbati o n s'ọrọ lori awọn igbesẹ ijọba rẹ lati dẹkun iwa ibajẹ,Aarẹ Buhari sọ pe awọn eto ti wa ni pẹsẹ lati tun gba awọn ilẹ ti awọn oṣiṣẹ ijọba fi ọna ẹburu gba tẹlẹ.
Ọkunrin kan láti inú ẹ̀yà Bẹnjamini, ti ojú ogun sáré pada lọ sí Ṣilo, ó sì dé ibẹ̀ lọ́jọ́ náà.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù #sackFestusAdedayo: Àwọn ọmọ Naijiria kẹ̀yìn si ìyànsípò Festus Adedayo 19 Òkùdu 2019 Oríṣun àwòrán, Festus Adedayo Awọn ọmọ Naijiria ti bu ẹnu atẹ lu igbesẹ ijọba lati yan Festus Adedayo gẹgẹ bi amugbalẹgbẹ feto iroyin fun Aarẹ Ile Igbimọ Asofin Agba, Ahmed Lawan.
Ṣaaju ni nkan bii oṣu kan o le diẹ sẹyin ni awọn rẹdio ẹlẹjẹ n gbe iroyin kiri nigba ọjọ ibi ko tii to pe Ọọni ti bimọ ṣugbọn ti BBC Yoruba kan si aafin Ọọni Adimula gangan, a bu ẹnu atẹ lu iroyin ofege pe ko ri bẹẹ.
Mọ̀ síi nípa Shina Rambo tó pàdé Jesu lọ́gbà ẹ̀wọn lẹ́yìn tó ti jalè Ǹjẹ́ o mọ àwọn òṣèré bí Oyin Adejọbi, Funmi Martins àtàwọn míì tó ti dágbére fáyé?
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Nigeria Air Force: Mo mọ̀ọ́mọ̀ dá €37,000 ti mo rí he padà ni -Ọmọ ogun Bashir 22 Agẹmo 2019 Oríṣun àwòrán, Nigeria Air Force Àkọlé àwòrán, O wu mi lati jẹ awokọṣe rere ni Omo ogun ofurufu Naijiria, Bashir Umar ni o ri owo nla tilẹ okeere he ni papakọ ofurufu ti Kano.
Nigeria's Under-19: Ẹ wo bí Ikọ̀ Cricket Naijiria ṣé mí àgbáyé titi
Lanre Kuti ni mo fẹ́ - Jaiye Kuti Ikú àwọn màálú tó jẹ́ ti Fulani to n gbé inú ilú Iba kò mú idí kankan dáni ju pé amúwá ọlọrun ni lọ, eyi wáye látàrí àrá tó sán nínú ìlú náà to si pa àwọn màálú náà.
ẹni tí ó tẹ́ ilẹ̀ lé orí omi,nítorí pé ìfẹ́ rẹ̀ tí kì í yẹ̀ wà títí lae; 
Laipẹ yii lo ṣe ayẹyẹ ọjọ ibi ọgọta ọdun.
Ina ti ọpọ eeyan maa n sa fun tori ọsẹ to lee ni se ni ọkunrin kan to n jẹ Timi, n jẹ bii ounjẹ, o fi n pa ara, to si tun n fi sere.
A tilẹ̀ gba àwọn owó kan lọ́wọ́ àwọn kan nípínlẹ̀ Anambra, ṣùgbọ́n irúfẹ́ èyí kò ní wáyé ní ìbò Èkìtì.
Òótọ́ náà nígbà tí ilẹ̀ ọjọ́ kejì mọ́ egungun bàbá mi le ju ti ìnàkí lọ ojú rẹ̀ si ti yípadà, bàbá mi di olójú-pupa, lílù tí ó si lu ìyàwó tuntun yìí níbi tí ó ti ń bá onítọ́hùn ṣe àwàdà fẹ́rẹ̀ ṣe é ní èṣe.
Ìró wíwó rẹ̀ yóo mi àwọn orílẹ̀-èdè tìtì.
Mikaaya dáhùn pé, “Ó dára, fetí sílẹ̀, kí o gbọ́ ohun tí OLUWA wí, mo rí i tí OLUWA jókòó lórí ìtẹ́ rẹ̀ ní ọ̀run, gbogbo ogun ọ̀run sì dúró lẹ́gbẹ̀ẹ́ rẹ̀ ọ̀tún ati tòsì, 
 ""Igbesẹ ileesẹ ologun ko le yanju awọn ọrọ wọn yi, o yẹ ka gbe igbesẹ to yẹ lati hu wahala yi tigbongbo-tigbongbo ni."
Bàbá mi tí mo fi sílẹ̀ tì yípadà ó di ibojì!
Tí ó ń fi agbo ẹran sílẹ̀.
salaye lẹẹkunrẹrẹ nipa awon ohun ini re gege bi ofin orile ede yii se laa sile.
Nígbà tí mo bá sì ń retí ìmọ́lẹ̀,òkùnkùn ni mò ń rí.
Awọn ọja ti wọn ti n ta ounjẹ yoo ma jẹ ṣiṣi lọjọ Iṣẹgun, Ọjọbọ ati Abamẹta laarin aago mẹsan owurọ si mẹta ọsan.
"Itan naa si lo di owe, ti wọn fi n sọ pe ""Asọ ko ba Ọmọyẹ mọ, Ọmọyẹ ti rin ihoho wọja."
Àwọn nkan tó ṣe kókó nípa olùdíje gómìnà ADP l'Ogun, Dimeji Bankọle Keyamo àti Fani-Kayode faraya Ipò àgbà ló yẹ́ kí a ti bá olórí - Fani-Kayode Eyi kii ṣe igba akọkọ ti El Rufai yoo ma sọ ọrọ to n da wahala silẹ.
Wọ́n bá nahùn pe Jonatani ati ọdọmọkunrin tí ó ń ru ihamọra rẹ̀; wọ́n ní, “Ẹ máa gòkè tọ̀ wá bọ̀ níhìn-ín, a óo fi nǹkankan hàn yín.
 perry dojú ìjà kọ ọ ̀ gá àwon ajalèlókun lẹ ́ yìn tí ó lée mú nínú òkùnkùn ní yàrá ẹ ̀ rọ .
Ilu Auckland lorilẹede New Zealand lo fi ṣe ibugbe, amọ ilu Eko ni wọn bi Israel si lọjọ kejilelogun oṣu keje ọdun 1989.
Mi ò kọ̀wé fipò sílẹ́ - Osinbajo Ẹ̀yin jàǹdùkú olóṣèlú, ẹ so ewé gbéjẹ́ mọ́wọ́ - Ọ̀gá ọlọ́pàá Ọjọ́ Sátidé lá fẹnu PDP gbolẹ̀ -Tinubu Èmi àti ìjọba Ọyọ yóò pàdé nílé ẹjọ́ lóri ìyọnípò mi - Ọmọ Akala Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí kan sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
Ajo to n koju arun Coronavirus ni Naijiria, NCDC to fi lede ni Ọjọọbọ, ni iye awọn to ti ni arun naa ti di ẹgbẹrun meje ati mẹrindinlogun (7016).
Bàbá mi náà sì tún fèsí pẹ̀lú, ó ní, Kí Ọlọ́run bùn yín lẹ́mìí, ọ̀nà tí mo gbà kò ju kékeré lọ: mo pinnu àti bá ẹbọra náà jà, mo bẹ̀rẹ̀ ìjà, mo fi ara da ìṣòro ìjà, mo sì gbẹ́kẹ̀lé Ọlọ́run Ọba tí Ó dá mi.
" Eyi jẹ ọrọ Dokita Bharat Pankhania lati fasiti Exeter sọ.
Abrahamu rò fún Abimeleki bí àwọn iranṣẹ Abimeleki ti fi ipá gba kànga omi kan lọ́wọ́ rẹ̀, 
Ṣùgbọ́n ilé iṣẹ́ ológun ní kò rí bẹ́ẹ̀.
Ó wá pa òwe yìí fún àwọn eniyan.
Bi o tilẹ jẹ wi pe amojuẹrọ Seyi Makinde ni oun fesi si ohun ti wọn sọ pe ki wọn jẹ ki oun gbajumọ awọn iṣẹ to dawọle ni lọọlọ yii.
Bí ó ti súnmọ́ tòsí àgọ́, bẹ́ẹ̀ ni ó rí ère ọmọ mààlúù, ó sì rí àwọn eniyan tí wọn ń jó.
Adari iroyin fun ile-ise to n risi aisan jẹjẹrẹ nile Geesi , Micheal Chapman sọ wi pe idi ti aisan jẹjẹrẹ fi n paniyan ju tatẹyinwa lọ ni pe ojojumọ ni iye awọn eniyan n pọsi lagbaye ati pe awọn Ọkunrin n pe laye ju ti tẹlẹ lọ.
OLUWA yóo fọ́ gbogbo ayé wómúwómúyóo sì sọ ọ́ di ahoro.
''Eyi lo mu ki n sakuro ni awọn ile ti mo n gbe naa, ti mo si sa asala fun ẹmi mi nipa sisalọ si ile ijọsin ni ibi ti mọ n gbe lọwọlọwo.
9 82857 Orilẹede Albania 1265 43.
Wọn óo wá mọ̀ nígbà náà pé èmi ni OLUWA Ọlọrun wọn, nítorí pé mo kó wọn lọ sí ìgbèkùn láàrin àwọn orílẹ̀-èdè mìíràn, mo sì tún kó wọn pada sí ilẹ̀ wọn.
 Ṣé lóòótọ́ ni pé Ambode ni APC fún ní tíkẹ́étì sẹ́nétọ́ fi dípò Osinọwo?"
OLUWA tún sọ fún Ahasi pé: 
ni iru asiko yii ni isele
Wọ́n wá wo Daniẹli níbi tí ó ti ń gbadura, tí ó sì ń bẹ̀bẹ̀ níwájú Ọlọrun rẹ̀.
BBC: A fẹ mọ idi tijọba Eko fi kọlu akọroyin wa
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Coronavirus ti di ara wa, kò le è kúrò mọ láéláé - WHO ìfipábánilòpọ̀: Má dákẹ́ - Oluwaseun Wọ́n ta ère Ọ̀ṣun Osogbo sí Togo - Bàbá Ọṣun figbe ta Baṣọ̀run Gáà, tó yan ọba mẹ́rin, pa ọba mẹ́rin àmọ́ ọba karùn-ún ló pa á Ọbasanjọ sọ àsírí sàgbàdèwe rẹ̀ Itan igbe aye Jesu Oyingbo yii dun pupọ, to si yẹ ka ri ọgbọn kan abi meji kọ ninu rẹ nitori arise ni arika, arika si ni baba iregun, ohun ti eeyan kan ba si se ni oni, ni yoo di itan to ba di ọla.
Ọmi ayo kan naa ni Manchester United ati Liverpool gba ni idije Premier League to n lọ lọwọ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Bọde George: Àwọn èèyàn mọ ẹni to yìnbọn pa Adeniyi Aboriṣade Edgal ni awọn ọdọmọkunrin to le ni ọgọrin ni awọn ọlọpaa ba nibẹ ni nkan bi aago meji oru ti wọn n mu oriṣiriṣi ọti lile, to fi mọ Tramadol ati Shisha ti wọn po igbo mọ.
Irú ẹ̀dá wo ni aṣòfin Bukola Saraki jẹ́?
Ipago igbaradi iko agbaboolu Super Eagles, niluu Uyo yoo wa ni sisi lati oni lo, leyin ti akonimoogba agba iko ohun, Gernot Rohr n reti agbaboolu merindinlogun loni lati bere igbaradi ni kikun saaju ifesewonse ipegede fun idije boolu ile Afrika to n lona lọdun 2019, eyi ti iko ohun yoo maa waako pelu iko agbaboolu orile-ede Libya lojo abameta(Saturday).
Ẹ ko nọ́mbà tí ẹ rí
Everton sọ pé ọrọ náà ṣe àwọn ní kàyéfì bí ọkan ninu ogbontarigi agbaboolu àwọn yóò ṣe tapa sí òfin ìjọba àti ìlànà ẹgbẹ náà lásìkò àjàkálẹ̀ Covid 19 yí.
Ọjọ Kejilelogun, Osu kẹsan an, ọdun 2018 ni idibo si ipo gomina yoo waye kaakiri ipinlẹ Osun.
Nigba ti awọn miran n fun wọn ni imọran ki wọn le bori idije wọn pẹlu orilẹ-ede Tunisia ti wọn jo n dije du ipo kẹta.
Ó san owó ọkọ̀, ó bá bọ́ sinu ọkọ̀, ó fẹ́ máa bá a lọ sí Taṣiṣi kí ó sì sá kúrò níwájú OLUWA.
"Ọkan lara awọn olugbe ile naa to ba awọn akọroyin sọrọ ṣalaye pe ""inu ile mi ni mo wa ti mo si ṣa dede gbọ iro nla kan, mo jade lati wo ohun to ṣẹlẹ ni mo ba rii pe apa kan ile ti mo n gbe ti wo lulẹ."
Wo ìdí ti ìjọba ṣe ka ẹ̀sùn méje tán yányán mọ́ Sowore lẹ́sẹ̀ Ẹ wo àwọn àwòrán BBC tó lààmì laaka lọ́sẹ̀ yìí.
Lẹyin ọjọ diẹ ti ayẹyẹ ifinijoye naa waye, ni awọn agbẹ ati ọdẹ nilu Ogbomoso taku pe awọn ko le san iye owo ori ti wọn bu fun awọn, ti wọn si n bẹ ọba Olayode lati bawọn se adinku rẹ.
Qasem Soleimani: Iran ni Trump gbọdọ̀ jẹ́jọ́ lórí ikú ọ̀gágun tí Amerika pa
 O wa fi da wọn loju pe ijọba ni gbogbo ipele wọn, ti n sa ipa lati tubọ mu igberu ba igbe-aye irọrun awọn oṣiṣẹ.
Oríṣun àwòrán, Ekiti state government Bakan naa ni wọn tun de ilu Uṣi Ekiti, nibi ti wọn ti ki alagba Adedayọ Dada to jẹ baba fun Kẹhinde.
Kò sí ìwé ẹ̀rí fun olùdíje tí tó ba wóle lábẹ hílàhílo Bí Ganduje bá pàdánù ìdìbò gómínà, kí ni yóò ṣe?
Ọrọ aabo ilu lasan ni wọn yoo maa ri si lati ran awọn Ọlọpaa lọwọ ninu iṣẹ wọn.
Jesu sọ fún un pé, “Nítorí kí ni o ṣe ń bi mí nípa ohun rere?
Ile ẹjọ kotẹmilọrun ti Ọba naa gbe ẹjọ lọ lẹyin idajọ ile ẹjọ giga to sọ pe idajọ to gbe Ọba Adegbola wọle lọdun 2011 kìí ṣe eyi to tọna rara.
Ija si ti n waye ni olu ile ẹgbẹ, to si ṣe eṣe ko ni ipa lori ẹni tio yoo ṣoju ẹgbẹ.
Gẹgẹ bi akọroyin BBC to wa nibi isẹlẹ naa ti salaye, ọpọ ero ti pejọ fun isinku naa nitẹ oku Atan to wa ladugbo Yaba nilu Eko, ki iroyin to de pe eto isinku naa ko ni lee waye mọ.
Ọ̀nà tó fi le è mọ gbájúẹ̀ babaláwo - Ẹlẹ́buìbọn Ẹ gbiyanju tiyin, ti awọn ololufẹ BBC News Yoruba kan ree.
O fi kun ọrọ rẹ pe nkan ti gbogbo ọmọ Naijiria, ati gbogbo ẹ̀yà yoo kan sara si ni wọn yoo fun Obasanjo, eyi to wúwo lọwọ ju fífi orukọ rẹ sọ ibudokọ oju'rin.
Àṣé ìṣe ènìyà náà ni ìṣe igi níbìkan.
Ọba ati ìjọ eniyan bá bẹ̀rẹ̀ sí sin OLUWA, àwọn akọrin ń kọrin, àwọn afunfèrè ń fun fèrè títí tí ẹbọ sísun náà fi parí.
A máa ṣe ìtọ́jú ìdílé rẹ̀ dáradára,kì í sì í hùwà ọ̀lẹ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Àyájọ́ èdè abínibí: Onímọ̀ ní èdè Yorùbá kò ṣe é fọwọ́ rọ́ sẹ́yìn, ó rẹwà Tinubu tun rawọ ẹbẹ sawọn ọmọ ẹgbẹ APC lati ko awọn ọmọ ẹgbẹ PDPto n ya wa sinu ẹgbẹ oselu ọhun mọra nitori gbogbo wọn ni wọn ti di ojulowo ọmọ ẹgbẹ.
Nígbà tí ó tó àkókò, ó rán ẹrú rẹ̀ kan lọ sí ọ̀dọ̀ àwọn alágbàro náà pé, kí ó lọ gbà ninu èso àjàrà wá lọ́wọ́ wọn.
Huṣai tún fi kún un pé, kí wọ́n ranṣẹ kíákíá lọ sọ fún Dafidi pé, kò gbọdọ̀ sùn níbi tí wọ́n ti ń ré odò Jọdani kọjá ninu aṣálẹ̀ ní òru ọjọ́ náà.
atunse si ekunwo owo osu awon osise naa.
Bi awọn mọlẹbi re ṣe fi ẹbun ranṣẹ si i naa ni awọn ololufẹ rẹ n ki i ni mẹsan an-mẹwaa lori ẹrọ ayelujara.
epo tita lorile ede Naijiria, ti gba lati din iye owo ti won n ta epo robi lati
Bakan naa lo jẹ pe ijọba Aarẹ Buhari naa lo yan Magu si ipo.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Wo imọran Fọlọrunṣọ Alakija fun awọn ọdọ adulawọ .
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Arsenal gba ami ayo kẹrin wọle ni idije Premier League fun igba akọkọ ni saa yi pẹlu aṣeyọri wọn ni Craven Cottage Iṣẹju kẹtadinlaadọrin ni Ramsey wọle ti o si gba ami ayo kan wọle ki o to pe iṣẹju kan.
Wọ́n sọ fún un pé, “Oluwa, wò ó!
"Àwọn èèyàn fi ìtara ba ilé ìjọsìn jẹ́ ""Àwọn tó jí ọmọ mi gbé nílé ìjọsìn ní ń kò gbọdọ̀ wa tàbí kí ẹ̀mí mi lọ si"" Òbítíbitì ẹ̀gbin ti sọ ìlú Ibadan di ààtàn - Aráàlú figbe bọnu Àwọn ẹni òkùnkùn ló já ìṣẹ́gun mi gbà, mò ń lọ sílé ẹjọ́ tó ga jùlọ - Bayo Adelabu ""Aug 2018 ni ìgbìmọ̀ aláṣẹ APC ti ṣe ìpàdé kẹ́yìn, Oshiomole ti kùnà"" Adedayọ lo sọ pé wọ́n bú oun gbọ́ pé Osinbajo, to jẹ Olusọ-aguntan àgbà ninu ijọ RCCG lo ń gbadura pẹ̀lú àwọn ọmọ ijọ rẹ̀ pe, ki ààrẹ Buhari kú lásìkò to gbàyè lọ fun ìtọjú ara rẹ̀ loke okun."
Àkọlé àwòrán, Aw#on agbofinro lo duro senu ona soosi COZA ni Eko Àwọn agbofinro ti dé sí ṣọ̀ọ̀sì COZA ni Eko Ojo ti bẹrẹ ni Ikeja nibi ti awọn eniyan ko ara wọn jọ si lati ṣe iwọde lori ọrọ ifipabanilopọ adari ijọ COZA.
Awọn eeyan ti aarun Covid-19 ti ran l'orilẹ-ede Naijiria ti pe ẹgbẹrun lọna ọgọta ati aarundinlọgtalelgbẹta (60,655) bayii.
Ọmọ Yorùbá mẹ́wàá tó jẹ́ àmúlùúdùn ní Amẹ́ríkà àti Yúróòpù Donald Trump ti gbà pé Coronavirus yóò burú jáì kí ǹkan tó dára fún Amẹ́ríkà Ṣé lóòtọ́ ni pé Hushpuppi ti kúrò ní ọgbà ẹ̀wọ̀n l'America?
Òun náà sọ àsọtẹ́lẹ̀ nípa ilẹ̀ yìí ati ilẹ̀ wa bí Jeremaya ti sọ yìí.
Nítorí ìdí èyí, mo pinnu àti ṣe ìtọ́jú ara mi.
 Oríṣun àwòrán, @jesusemmanuel_ty47 Ọrọ yii lo bọ si apo ibinu Daddy Freeze, to si fesi pada fun ọkunrin naa pe: Ẹ wo ẹni to n ja fun Pasitọ rẹ, o yẹ ko mọ pe ki eeyan lo ọgbọn ọdun ninu igbeyawo ko tumọ si pe igbeyawo naa se aseyọri.
Ó kàn gba ìyàrá méjì l’ágbàsanwó oṣoòṣù ni.
Mo ti rí òmùgọ̀ tí ó fìdí múlẹ̀,ṣugbọn lójijì, ibùgbé rẹ̀ di ìfibú.
Ní apá ìhà àríwá, ààlà ilẹ̀ wọn bẹ̀rẹ̀ ní etí odò Jọdani, lọ sí ara òkè ní ìhà àríwá Jẹriko.
Odò kékeré kan ń ṣàn jáde láti ìhà gúsù.
'Awọn obinrin nilo ajọ iranwọ fun oṣelu' Angelique kidjo pe fun anfani f'awọn obinrin Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Yaa Asantewaa: Ti ẹyin ọkunrin Ashanti kò bá tẹsiwaju, awa obinrin yóò lọ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Obinrin jẹ amuludun' Iru ẹjọ wo ni ó n dá?
Ọpọ lo koro oju si igbesẹ ti Gomina Ajimọbi gbe, pe o fẹ ẹ pa ilana ti awọn baba nla ilẹ Ibadan da silẹ da.
Awọn Baba Iṣalẹ yii ni wọn maa n lo owo ati ipọ wọn lati fi gbaruku ti ẹni ti wọn ba tilẹyin ninu ididbo naa.
Ó ní ipò tí ó ga ju ti àwọn angẹli lọ, gẹ́gẹ́ bí ó ti ní orúkọ tí ó ju tiwọn lọ.
ede to le ni idagbasoke laije pe , o mu eto imo sayensi ati imo ero
Ẹ̀yin ati ẹbí yín lè jẹ ìyókù níbikíbi tí ẹ bá fẹ́, nítorí pé ó jẹ́ èrè yín fún iṣẹ́ tí ẹ̀ ń ṣe ninu Àgọ́ Àjọ.
Tinubu kìlọ̀ fún Buhari, Osinbajọ lórí àfikún owó orí ọjà VAT Tinubu kìlọ̀ fún Buhari lórí ohun tó leè ṣàkóbá fún sáà kejì rẹ̀ Ṣé ìwọ mọ odò adágún Adó Àwáyè tí kò ní òpin ní ìsàlẹ̀?
 Ó ti kópa nínú oríṣiríṣi eré ti nollywood ní èdè yorùbá àti ní èdè gẹ ̀ ẹ ́ sì .
Nígbà tí ẹ bá dé ilẹ̀ náà, ẹ óo ranti ìṣe yín, ati gbogbo ìwà èérí tí ẹ hù tí ẹ fi ba ara yín jẹ́.
Bi awọn esi naa ṣe lọ niyii: FCT-27 Oyo-27 Bayelsa-9 Rivers-9 Delta-7 Edo-5 Kaduna-5 Ogun-5 Anambra-3 Katsina-3 Ondo-3 Osun-3 Plateau-3 Niger-2 Kano-1 Àjàkálẹ̀ àrùn Covid-19 búrẹ́kẹ́ si ní Nàìjíríà, èèyàn 212 ló tún ràn Itankalẹ Covid-19 ni Naijiria tun ṣe bi ẹni l'agbara si, pẹlu esi ayẹwo to fihan pe eeyan 212 tun ti ni, l'Ọjọbọ.
 Ó ní ẹ ̀ rọ ìwárí mẹ ́ fà tí ìkọ ̀ ọ ̀ kan wà fún ìwàdìí ohun pàtó kan .
Gege bi akole ero ayelujara naa,“iroyin eka ile ise amuna wa: ina mona-mona ti won pese ati ti won ta jade, onraja ati bi o se jade ni saa kerin odun, 2017.
"A ni lati sa kuro nilu nitori ko si abo fun ẹmi wa mọ.
Alága afúnṣọ́ dé fún APC, níbo ni ìbò abẹ́lé l‘Ondo yóò já sí?
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Port harcourt Bole: Mi kò mọ́ pé bọ̀ọ̀lì títà lè gbé mi dé ipò yìí láyé mi!
Ajọ aladani kan tilẹ sọ pe o ti na to aadọrun biliọnu FCFA laarin ọdun 1982 si 2017.
Àwọn míràn máa nwá pọ́n òkúta yìí ni, nítorí ó dùn-ún pọ́n gidigidi fún wọ́n.
Igba bilionu  naira , ni a tun ri latari awon ti oruko won ko si ninu iwe igbanisise ti ijoba apapo.
N kò ní dé iwájú rẹ mọ́.
EFCC kó akẹ́kọ̀ọ́ fásitì UNIOSUN làwọn akẹ́kọ̀ọ́ náà bá fọ́n sígboro
Ọpọ ọrọ ni awọn eniyan ti n sọ lori ayelujara lori ṣẹlẹ yii lai yọ awọn musulumi omiran silẹ.
“Tabi bí mo bá rán àjàkálẹ̀ àrùn sí orílẹ̀-èdè náà, tí mo sì fi ibinu bá a jà, débi pé eniyan kú níbẹ̀, tí mo pa ati eniyan ati ẹranko run ninu rẹ̀, 
Dájúdájú Ọlọrun ti fi lé yín lọ́wọ́, kò sí ohun tí eniyan ń fẹ́ ní ayé yìí tí kò sí níbẹ̀.
Kí oore-ọ̀fẹ́ Ọlọrun wà pẹlu gbogbo yín.
“Ẹ gbọdọ̀ máa ṣe àjọ àìwúkàrà, burẹdi tí kò ní ìwúkàrà ni ẹ gbọdọ̀ máa jẹ fún ọjọ́ meje ní àkókò àjọ náà, ninu oṣù Abibu, gẹ́gẹ́ bí mo ti pàṣẹ fún yín, nítorí pé ninu oṣù Abibu ni ẹ jáde ní ilẹ̀ Ijipti.
Oríṣun àwòrán, OTHER Makinde fẹ́ fọwọ́ ọlá gbá wa lójú ni, a ò sì ní gbà-ALGON Wo ìdí tí wọ́n fi dá Alága àjọ EFCC Ibrahim Magu sílẹ̀ Gbajugbaja janduku ni Ekugbemi nigba aye rẹ, ti awọn iroyin kan si sọ pe olori ẹgbẹ okunkun kan, to n da wahala silẹ nilu Ibadan ni.
''A n parọwa si awọn awujọ agbaye lati gbaruku ti wa ki eto idibo yi lọ ni irọwọrọsẹ'' Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Lórí ìdìbò 2019, kí ni Ọọ̀ni bá Atiku sọ?
Ko seeyan kan ni pato, gbogbo wa ni padi.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Owoẹyẹ ni oun ko mọ ohun ti oun n se mọ, ti wọn si fi oogun gba owo to le ni miliọ̀nu lọna mejidinlogoji naira lọwọ oun.
A ti hùwà burúkú sí ọ, a kò sì pa àwọn òfin, ati ìlànà ati àṣẹ rẹ tí o pa fún Mose iranṣẹ rẹ mọ́.
Nígbà tí Sila ati Timoti dé láti Masedonia, Paulu wá fi gbogbo àkókò rẹ̀ sílẹ̀ fún iwaasu, ó ń tẹnu mọ́ ọn fún àwọn Juu pé Jesu ni Mesaya.
AFCON 2019: Ki akọnimọọgba Naijira bá wọn sọ̀rọ̀ kóríyá
Ó já ni aago méjìlá kọ́já ìṣẹ́jú mẹ́rìnlá.
Ààrùn náà titàn kiri ní agbègbè orùn àti agbègbè orùn díẹ ̀ àwọn ẹkùn tí ó wà ní àyiká ti arín ilà aayé .
Ọpọ awọn ọmọ Naijiria lo ti fi aidunnu wọn han lori bi ijọba ko ṣe tete jigiri si ọrọ ọkọ agbepo to gbana ni Anambra.
Ọkunrin náà tún wọn ẹgbẹrun igbọnwọ (mita 450) mìíràn sí ìsàlẹ̀, ó tún mú mi la odò náà kọjá: ó sì mù mí dé ìbàdí.
Oríṣun àwòrán, Nigerian Polcie Force Ileeṣẹ ọlọpaa ipinlẹ Oyo ti fi hande pe lootọ ni awọn ajinigbe ji ọmọ orilẹede India meji ni ipinlẹ Oyo.
Mo lọ sinu ọgbà igi eléso,mo lọ wo ẹ̀ka igi tútù ní àfonífojì,pé bóyá àwọn àjàrà ti rúwé,ati pé bóyá àwọn igi èso pomegiranate tí ń tanná.
Ta ló léè bá Odunlade Adekola dù ú pẹ̀lú àwọn àmúyẹ yìí?
Nitori naa ni ko sẹ si ija.
Eleyii yoo mu ki ọfiisi akọwe ijọba le buwọ lu irufẹ irinajo bẹẹ ni ibẹrẹ ọdun, ko to di pe ijọba yoo fi aye gba irin ajo ọhun.
LAFIYA DOLE ti gbegi dina opopona oko ti o lo lati ilu Maiduguri siluu Monguno,
Lara awọn ọrọ to ti sọ lati fi soro sọke ni pe'' gbogbo eniyan lo lẹtọ si idajọ ododo, ati ẹtọ ọmọniyan'', '' orilẹede Naijiria ti la iṣọrọ kọja nitori awọn onijẹgudujẹra, o si ti su wọn.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Alaafin: Olori Aanu Adeyemi ṣàlàyé ìdí tó ṣe gẹ́ Oba Lamidi Adeyemi ti ìlú Oyo Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 3 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 5 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Abramu la ilẹ̀ náà kọjá lọ sí ibi igi Oaku ti More, ní Ṣekemu.
“Bojúwò mí, OLUWA,nítorí mo wà ninu ìpọ́njú,ọkàn mi ti dàrú, inú mi bàjẹ́,nítorí pé mo ti hùwà ọ̀tẹ̀ lọpọlọpọ.
Ó wá sọ fún àwọn ọmọ-ẹ̀yìn pé, “Ọjọ́ ń bọ̀ tí ẹ óo fẹ́ rí ọ̀kan ninu ọjọ́ dídé Ọmọ-Eniyan, ṣugbọn ẹ kò ní rí i.
Àkọlé àwòrán, Ilu Abuja Ọkan lara awọn afẹhonu han sọ fun BBC pe o ti di eeyan bii mẹfa to ku ti oun ri nibi ija naa ṣugbọn ko tii si aridaju eyi.
Àwọn ìránńṣẹ́ ọba rọra ń yọ́ kẹ́lẹ́kẹ́lẹ́ sọ̀rọ̀ náà ni ṣùgbọ́n èmi dúró sún mọ́ ògiri ilé oúnjẹ náà mo sì ń gbọ́ ohun tí wọn ń sọ.
Awọn alufa Katoliki rin lọwọọwọ lati se atilẹyin fun iwọde EndSARS: Ẹbu iroyin miran to tun gba ori ayelujara ni aworan ati iroyin kan to safihan awọn alufa ijọ aguda, ti wọn n rin lọwọ.
Ọwọ́ ni INEC fi kọ èsì ìbò ààrẹ, kò sí lórí ''server''-Okoye Akẹ́kọ̀ọ́ LAUTECH 15 wọ gàù l‘Ọyọ torí ẹ̀ṣùn olè àti ṣíṣe ẹgbẹ́ òkùnkùn Ààrẹ àwọn awakọ̀ òhun tó kọ́wọ̀ọ́ rìn pẹ̀lú àwọn olóyè ẹgbẹ́, sàlàyé pé, gómìnà Makinde ti fí ọkàn àwọn balẹ̀ pé òun ti ṣetan láti kásẹ̀ òfin náà nilẹ̀, ti àwọn ọmọ ẹgbẹ́ awakọ̀ ìpínlẹ̀ Ọyọ bá ti ṣetan láti tọpasẹ̀ aláfíà.
Ki ṣe ohun tuntun mọ pe aarẹ orileede Naijiria Muhammadu Buhari yoo du ipo aarẹ lọdun 2019.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Bí ẹ ṣe mọ̀wé tó, ẹ wá dánrawò níbí pẹ̀lú Àpólà Ọ̀rọ̀ Orúkọ - Noun Phrase Oluwo ni ''emi ti mu iyẹn kuro ninu aye mi, mo ti kọ ọ silẹ."
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: ‘Omo-Agege ló da ìjókòó ilé rú’ Kín lo fa orogún àwọn dókítà àti Johesu?
A kò lè jẹ́ kí àpótí Ọlọrun Israẹli yìí wà lọ́dọ̀ wa níhìn-ín mọ́ rárá.
Ònkọ̀wé yìí ní ìdàmú vaginismus nígbà tó ń súnmọ́ ogún ọdún tí àwọn onímọ̀ nípa ojú ara obìnrin èyí tó mú u tóbi díẹ̀ síi kára lè balẹ̀.
Ọpọ ninu awọn aṣoju orilẹ-ede ninu ajọ naa, to parapọ mọ awọn ọmọ igbimọ lati yan Ọga Agba tuntun, lo fọwọ si iyansipo Okonjo-Iweala.
O so pe “laisi ani-ani , ibabuje ni iku oloogbe yii je fun egbe akoroyin , ebi ati orile ede Naijiria lapapo,Jonathan je olopolo ati  akinkanju akoroyin.
Lagos State Assembly: Ó takò òfin kí àwọn obí jẹ̀yà ti ọmọ ba darapọ̀ mọ́ ẹgbẹ́ òkùnkùn
O ni Ronaldo ma fi n fi aye a ti dagbere silẹ nibi kibi to ba wa lati pada si ẹgbẹ agbabọọlu to wa tẹlẹ.
Ile-igbimo naa bowolu isuna eto idibo odun 2019 ohun leyin ti igbimo to n mojuto eto idibo nile igbimo naa ti se orisirisi agbeyewo ati atunse to muna doko lori iwe isuna naa.
Jehu sì pàṣẹ fún ẹni tí ń tọ́jú ibi tí wọn ń kó aṣọ ìsìn pamọ́ sí pé kí ó kó wọn jáde fún àwọn tí ń bọ Baali.
ajo INEC, ojogbon Yakubu Mahmoud ni yoo maa tuko eto ohun nipase sise afihan
" Chris lo sọ fun BBC bẹẹ.
Àkọlé àwòrán, Awọn èèkàn tó wá yẹ èto ọlọdọọdún tí Tony Elumelu máa ń ṣe yìí sí ni Ààrẹ orílẹ̀èdè Ghana Àkọlé àwòrán, Mahassin yìí ó ti kọ̀kọ́ gba ẹgbẹ̀rún mẹ́fà dọ́là fún áápù Cashmadam tó ṣe,sùgbọn ní báyìí yóò tún gbà ẹgbẹ̀rún lọ́nà ààdọ́ta dọ́là láti fi mú ìdàgbàsókè bá áápù nàá Àkọlé àwòrán, Ọdọọdun ní Tony Elumelu Foundation máa ń fún àwọn ọdọ tí wọn ni ìmọ̀ lóri ètò ọrọ̀ ajé ní ànfàání láti wa sọ tẹnu wọn lọ́rí ọ̀nà úntun ti etò ọ̀rọ̀ ajé le gba ní Afirika BBC News, Yorùbá Ìdí tí ẹ fi le è nígbàagbọ́ nínú ìròyìn BBC Ìlànà Lílò Nípa BBC Òfin Àṣírí Cookies Kàn sí.
Oluwo wa pari ọrọ rẹ pẹlu ibeere pe Ta lo fẹ wọ gọmbọ fun ọmọ rẹ lode oni?"
Ẹ̀ ń san ìdámẹ́wàá àwọn èròjà ọbẹ̀ tí wọ́n jẹ́ eléwé, nígbà tí ẹ gbàgbé àwọn ohun tí ó ṣe pataki ninu òfin: bíi ìdájọ́ òdodo, àánú, ati igbagbọ.
Bobrisky: Ìjọba ní kí àwọn ọmọ Naijiria yàgò fún Bobrisky
Nítorí náà, má ṣe fọ́nnu bí ẹni pé o sàn ju àwọn ẹ̀ka ti àkọ́kọ́ lọ.
Nigba ti ọjọ pe, awọn agbẹ ati ọdẹ peju biba si aafin ọba lai mọ pe ọba naa ti ransẹ pe awọn agbofinro, pe ki wọn maa bọ lati koju awọn eeyan naa.
FRA: ✅✅✅❌❌CHE: ✅❌✅✅✅#CHEFRASee you in Baku, @Arsenal!
Eniyan tabi ẹranko kò ní gba ibẹ̀ kọjá, ẹnikẹ́ni kò ní gbé ibẹ̀ fún ogoji ọdún.
Wọn yóo ka ọmọkunrin kinni tí opó yìí bá bí sí ọmọ ọkọ rẹ̀ tí ó kú, kí orúkọ ọkọ rẹ̀ náà má baà parẹ́ ní Israẹli.
    Ìgbà tí ọkùnrin náà máa jáde nínú ààfin ìsàlẹ̀ ilẹ̀, ó jáde bí ọba.
  Mbappe ron orile-ede France lowo lati gbo ewuro soju orile-ede Croatia pelu ami ayo merin si meji (4-2) ninu asekagba idije boolu agbaye naa.
Ògo ni fún OLUWA Ọlọrun rẹ, tí inú rẹ̀ dùn sí ọ, tí ó gbé ọ gorí oyè láti jọba ní orúkọ rẹ̀.
Lẹ́yìn náà, ó mú ọ̀rá àgbò náà, ati ọ̀rá ìrù rẹ̀, ati gbogbo ọ̀rá tí ó bo àwọn nǹkan inú rẹ̀, ati ẹ̀dọ̀ rẹ̀, ati kíndìnrín rẹ̀ mejeeji pẹlu ọ̀rá tí ó wà lára wọn, ati itan ọ̀tún rẹ̀.
Àkọlé àwòrán, Ẹ ma fi orukọ Ọlọrun daabo bo afipabanilopọ Àkọlé àwòrán, Sọrọ sita lasiko yii, ma pa ẹnu rẹ mọ ti wọn ba fi ipa ba ọ l'opọ.
Ile iwe giga, Cambridge University lo kede wi pe awọn yoo da ọkan lara awọn idẹ ti wọn ji ni ẹgbẹrun ọdun ṣẹyin lasiko ti wọn ṣigun bo Naijiria pada.
Gege bi adari agba ile-ise Cadbury Nigeria Plc se so, ogbeni Amir Shamsi lasiko ipade naa, “Inu wa dun pupo lati kede ibasepo olodun meta si pelu ajo NFF.
Àwọn aṣekúpani tún ti pa ọmọ ọdún 16 ní Akinyele nípìnlẹ̀ Oyo Ki lo ti nṣelẹ sẹyin?
Pẹlu orin, ijo, ilu ati ayọ ọkan si ni awọn ẹlẹgbẹjẹgbẹ lọkanojọkan fi maa n lọ ki ọba naa to wa nikalẹ, lati igba ti ọdun Ojude Ọba si ti bẹrẹ lati bii ọgọrun ọdun sẹyin ni asa yii ko ti parun.
''Ọjọ ti baba mi ri mi nibi ti mo ti n wa Maruwa, ni mo fii silẹ ti mo si pada sile.
Oríṣun àwòrán, Goldmyne Àkọlé àwòrán, Lagos -Ibadan Express: Súnkẹ́rẹ fakẹrẹ ọkọ òpópónà marosẹ̀ tòní tún kọ sísọ Ọ̀pọ̀ àwọn ènìyàn lọ́ri àtẹjuiiṣẹ́ twitter lo ti n sọ bi ìṣẹ̀lẹ̀ náà ṣe n lọ lọ́wọ́lọ́wọ́ Ọ̀rọ̀ di kọ̀!
Bo tilẹ̀ jẹ́ pé ìròyìn òfegè ni pé Buhari fẹ fẹ́ Sadiya, síbẹ̀ àwọn ọmọ Nàìjíríà ṣètò ìyàwò náà lórí ayélujára Ta ni Sadiya Umar Farouq tí ìròyìn ẹlẹ́jẹ̀ ń gbé pé òun ló fẹ́ dí ìyàwó tuntun Buhari?
Ọkàn àwọn ọmọ Israẹli bá dààmú, àyà wọn sì já.
"Wo ọmọbìnrin ọdún méjìlá tó ṣè'gbéyàwó pẹ̀lú ọkùnrin méjì láàrin oṣù kan 'Mo máa ń ta sí Tolu pé ""ọjọ́ wo ni wàá tó gà'- Musa, Ọ̀rẹ́ àti kékeré Kí ló mú Obasanjo ti ilẹ̀kùn mọ́ ẹbí, òṣìṣẹ́, ojúlùmọ̀ ní ibi òkú àna rẹ̀?"
" Ohun mẹ́wàá tó yẹ kóo mọ̀ nípa Kunle Afod Jumọkẹ Odetola ṣe ọjọ́ ìbí, Wumi Toriola bímọ, Ṣé ẹ fẹ́ tẹ̀lẹ́ Funkẹ Akindele lọ si Dubai?
    Ó yà mi lẹ́nu púpọ̀ pé ogunlọ́gọ̀ lóde ayé koi tii mọ̀ nípa pé kí a máa bu apa fún ni kí Ifẹ̀ẹ́gbóná má ba ṣe ni, ni àwọn Èdìdàarẹ́ ti mọ̀.
Àpò àsùnwọ̀n Bitcoin ma n ṣe akọsilẹ awọn adirẹsi naa, o si n lo o lati mojuto eto fifi owó pamọ.
 Awon mẹ́tàdínláàdọ́rin omo egbe oselu APC pere ni won dibo yan pada ninu awon okòólénígba le mẹ́tà ti o wa nile igbimo asofin, ti awon omo egbe to ku si je oju tuntun.
Gbogbo ọ̀nà tí OLUWA Ọlọrun yín là sílẹ̀ ni kí ẹ máa tọ̀, kí ẹ lè wà láàyè, kí ó lè dára fun yín, kí ẹ sì lè pẹ́ lórí ilẹ̀ tí ẹ óo gbà.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Olu Jacobs: Àwọn gbajúmọ̀ òṣèré márùn-ún tí wọn ti pa irọ́ ikú mọ́ sẹ́yìn rèé 13 Òkùdu 2020 Oríṣun àwòrán, Others Ọwọ kekere kọ ni Yoruba fi n mu aṣa ki wọn pa irọ iku mọ ẹnikan nigba to wa laaye, nitori ẹnikan kii gbọ ọjọ iku rẹ ko dunnu.
Baba Sala Àkọlé àwòrán, Ayẹyẹ ikẹyin fun Baba Sala Ni irọlẹ, ọjọ aiku ọjọ keje oṣu kẹwa ọdun 2018 ni alagba Moses Adejumọ ti ọpọ eeyan mọ si baba sala jade laye.
Nípa ìṣẹ̀dá igi inú igbó, Ọba Lókè tún dá a bí àrà ọ̀tọ̀.
Ni nnkan aago mewa aro lojooru ni Afegbua, ti ileesẹ ọlọpaa kede pe wọn nwa sepade pelu awon oga olopa naa.
Oun ni ara Yuroopu akọkọ to kọ nipa ṣokoleeti.
Bí ìgbà tí àwọn àdàbà bá ń fò lọ sí ibi ìtẹ́ wọn?
Ẹ̀ ń pa mààlúù, ẹ̀ ń pa aguntan,ẹ̀ ń jẹ ẹran, ẹ̀ ń mu ọtí waini.
Mó nílò ìrànlọ́wọ́,"" Kelly sọ fun King."
Ọba tún bi í pé, “Ǹjẹ́ ẹnikẹ́ni kù ninu ìdílé Saulu, tí mo lè fi àánú Ọlọrun hàn, gẹ́gẹ́ bí mo ti ṣèlérí fún Ọlọrun pé n óo ṣe?
Mo fi ibinu tẹ̀ wọ́n bí èso àjàrà,mo fi ìrúnú tẹ̀ wọ́n mọ́lẹ̀.
OLUWA nígbà tí wọ́n wà ninu ìpọ́njú, wọ́n wá ọ,wọ́n fọkàn gbadura nígbà tí o jẹ wọ́n ní ìyà.
Àkọlé àwòrán, Ipade Itagbangba BBC Yoruba Gbọngan Mapo tobi gan, bẹẹ lo laye daadaa lati gba ọpọlọpọ eeyan.
Awọn ọlọpaa ni ipinlẹ Oyo ti mu awon meji ti wọn ni wọn fẹsun kan pe wọn n sunẹran ọlọpaa jẹ lasiko iwọde #EndSARS to kọja.
Amọ, o rọ awọn eeyan lati ni igbagbọ ninu Ọlọrun to da ọrun ati aye nitori Oun lo ti wa ṣaaju awọn oke gbogbo.
Buhari fọwọsi aba igbimọ onidajọ lati yọ adajọ meji nipo
Mercy Aigbe ni iwuri ni eyi jẹ fun oun gẹgẹ bi iya Juwon to ṣẹṣẹ bẹrẹ iṣẹ gẹgẹ bi oṣere.
Iroyin to gbode ni pe yoo pada soju ija laarin oṣu kẹfa si ikẹjọ ọdun yii.
Ambode tun woye lati ri i daju pe bii adugbo to din diẹ nirinwo plu marunlelọgbọn lo ni ina ọba tori o gbagbọ pe bi ina ba wa lEko, iwa ọdaran yoo dinku.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Yollywood: Odunlade fẹ́ j'ọba, Bolanle Ninalowo fun ìyàwó rẹ̀ ni ẹ̀bun kanka, Pá Kasumu rebi àgbà ree 6 Ẹrẹ̀nà 2020 Oríṣun àwòrán, toyin_abraham Ninu awọn iroyin to migboro titi lagbo oṣere tiata Yoruba bawọn kan ṣe n pawọpọ fi gbe ere sita ni idile awọn oṣere miran n bawọn daawọ idunnu ayọ ọjọ ibi.
N-Power Build: ₦27,000 - si ₦30,000 losu.
“Nítorí náà wí fún wọn pé èmi, OLUWA Ọlọrun ní, bí mo tilẹ̀ kó wọn lọ jìnnà sí ààrin àwọn orílẹ̀-èdè, tí mo sì fọ́n wọn káàkiri ilẹ̀ ayé, sibẹsibẹ mo jẹ́ ibi mímọ́ fún wọn fún ìgbà díẹ̀ ní ilẹ̀ tí wọ́n lọ.
Nígbà tí ó wo gbogbo àwọn tí ó jókòó yí i ká lọ́tùn-ún lósì, ó ní, “Ẹ̀yin ni ìyá mi ati arakunrin mi.
Ṣugbọn bí o bá gbọ́ tirẹ̀, tí o sì ṣe bí mo ti wí, nígbà náà ni n óo gbógun ti àwọn tí ó bá gbógun tì ọ́, n óo sì dojú ìjà kọ àwọn ọ̀tá rẹ.
Ẹ fọwọ́ kàn mí kí ẹ rí i, nítorí iwin kò ní ẹran-ara ati egungun bí ẹ ti rí i pé mo ní.
Ohun mìíràn tí ẹ tún ń ṣe nìyí.
Ile-ise olopaa ti o sese fesun kan asofin Melaye pe, O lowo si kiko ohun ija oloro fun awon omo ogun olote.
Kí ni wọn óo ṣe ní ọjọ́ àjọ̀dún tí a yà sọ́tọ̀, kí ni wọn óo ṣe ní ọjọ́ àsè OLUWA?
Ẹwẹ, ninu iwe ikọsilẹ kootu to tẹ oniroyin lọwọ fi han pe Gloria kọ ọkọ rẹ labẹ ẹsun pe o n muti, siga, ko si itoju ati pe ko si ifẹ laarin awọn mọ.
Ipo yii lo di mu titi di oṣu kẹfa, ọdun 2009.
Ọpo dukia lo si baa lọ.
Ọpọ orilẹ-ede lo ti gbe ilana alagbara lati koju rẹ.
Lati atẹyinwa ni awọn to di ipo mu ni Naijiria to fi mọ iyawo aarẹ Buhari, Aisha Buhari ni wọn ti ṣe ikilọ lori sisọrọ kubakugbe lorilẹede Naijiria.
Jìnnìjìnnì láti ọ̀dọ̀ Ọlọrun sì dà bo gbogbo àwọn ìlú tí ó wà ní àyíká wọn, wọn kò sì lépa àwọn ọmọ Jakọbu.
Logo Benz: Ìtanijí ni orin wa wà fún, Ẹ má ká wa lọ́wọ́ kò -Olamide
Oríṣun àwòrán, Facebook Iroyin to ń tẹ wá lọ́wọ́ ni yajo yajo tí kéde pé, àwọn gende agbebọn tí jí ìbejì gbajugbaja onímọ̀ kan nípa ẹṣin islam, Sheikh Taofeeq Akeugbagold gbe lọ.
Ọ̀kan nínú ìkìlọ̀ náà (ọ̀tún) ń tọ́ka sí òfin “Ìmọ̀ràn” ó sì rọ olùkọ́ àti akẹ́kọ̀ọ́ láti kọ àyájọ́ tí ó fi ara jọ ti Òyìnbó sílẹ̀.
Obasanjo ni:  “Beeni, idagbasoke se pataki ni Bayelsa.
"O ṣalaye pe ọmọ ọhun kii ṣe onijọgbọn, kii ba eeyan ja ati pe kii ṣe oni jibiti ori ẹrọ ayelujara ti ọpọ mọ si ""Yahoo boy gẹgẹ bi awọn Ọlọpaa ọhun ṣe fi ẹsun kan an."
Akọsil ileeṣẹ ọlọpaa Orlando ṣafihan pe wọn ti mu Ofori ri lọdun 2016 nitori pe o ba iyawo rẹ ja.
Femi Gbajabiamila: DSS ti fi ẹ̀sọ́ àbò Gbajabiamila tó pa fẹ́ndọ̀ l'Abuja sátìmọ́lé
Ninu Kristi ni Ọlọrun fi gbogbo ìṣúra ọgbọ́n ati ìmọ̀ pamọ́ sí.
Ẹni tí ó dá àwọn ìràwọ̀ Pileiadesi ati Orioni,tí ó sọ òkùnkùn biribiri di ìmọ́lẹ̀ òwúrọ̀,òun níí sọ ọ̀sán di òru;òun ni ó dá omi òkun sórí ilẹ̀,OLUWA ni orúkọ rẹ̀.
Àwọn orúkọ ìdílé wọnyi kò di ẹlẹ́sìn lọ́wọ́ lati ṣe iṣẹ́ rere tàbi dé ọ̀run,
Bakan naa ni Awolowo ba awọn Agbekoya dunadura lori fanfa to wa laarin wọn ati ijọba, ti wọn si sọ ohun ti wọn n fẹ fun.
” “Inu wa dun pupo lati wa lorile-ede yii.
Ìbejì ọmọ ọdún méjì Mínísítà fún ọ̀rọ̀ omi bá odò lọ Àgbedọ̀!
aṣe fun lilo ohun ija lati ọdọ Giwa Ọlọpaa, bi ẹ ba da iru ikọ bayii silẹ,
Awọn si ni ẹya kristẹni to pọ julọ lagbegbe Larubawa.
Awọn ọba alaye ati awọn asaaju ẹsin ti wa rọ awọn araalu lati mase dara pọ mọ ijọ Hakika nitori ẹkọ ati ilana wọn yatọ si ti Islam.
Oríṣun àwòrán, others Bẹẹ bá gbàgbé, a ti mú ìròyìn wá ṣáájú nípa bí Sunday Igboho ṣe kesi gomina Ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́, onímọ̀ ẹ̀rọ Seyi Makinde láti yọ Auxiliary nípò Alakoso gareji, torí ìwà jagidijagan tó ń hù.
Bakan naa lo fi kun wi pe ohun ko ni ẹjọ kan kan ba ijọba ipinlẹ Kaduna ro.
Kí wọn máa fara balẹ̀, kí wọn sì fara mọ́ ọkọ wọn nìkan.
" Ó jẹ ́ erékùṣù tí ó tàn káàkiri jùlọ nínú gbogbo èyà galápagos ti "" microlophus "" , a máa ń rí àwọn tókù lẹ ́ ẹ ̀ kànkan ní àwọn erékùṣù ."
Gbogbo làálàá tí eniyan ń ṣe, nítorí àtijẹun ni, sibẹsibẹ oúnjẹ kì í yó ni.
Wọn si ni awọn ṣetan lati gbena woju Minisita Mohammed Bello lori aṣẹ to pa ki wọn máa ṣe iwọde.
Minisita meji ninu eto iṣakoso Muhammadu Buhari ni wọn fi ẹsun ayederu iwe ẹri agunbanirọ kan; Kẹmi Adeọṣun ati Adebayọ Shittu.
Kí Aaroni máa sun turari olóòórùn dídùn lórí rẹ̀, ní àràárọ̀, nígbà tí ó bá ń tọ́jú àwọn fìtílà.
Iná àtùpà kan kò ní tàn ninu rẹ mọ́, bẹ́ẹ̀ ni a kò ní gbọ́ ohùn ọkọ iyawo ati ti iyawo ninu rẹ mọ́.
Ṣugbọn wolii náà dáhùn pé, “Bí o bá tilẹ̀ fẹ́ fún mi ní ìdajì ohun tí o ní, n kò ní bá ọ lọ, n kò ní fi ẹnu kan nǹkankan ní ilẹ̀ yìí.
Coronavirus in nigeria: Ọlọ́pàá ni yóò ma mú ẹnikẹni tó bá tàpa sófin ìjọba Eko Ijọba Eko ti ko ọlọpaa sita lati ri wi pe awọn eniyan ko rin irin gberegbere lasiko arun Coronavirus yii.
Idiwọn bi wọn ti jẹ irẹsi si ni ọdun 2018.
Ó bá bẹ̀rẹ̀ sí jẹ ẹ́ níyà, agbára rẹ̀ sì fi í sílẹ̀.
Nítorí Ọlọrun yóo gba Sioni là;yóo sì tún àwọn ìlú Juda kọ́;àwọn iranṣẹ rẹ̀ yóo máa gbé inú rẹ̀,yóo sì di tiwọn.
"Ni ti Sudan ati Tanzania, awọn ko lanfani lati kọwe gba iwe irina fun oniruuru nkan ti wọn ba fẹ ṣe eyi ti wọn maa n ri gba tẹlẹ nipasẹ ""lottery""."
tí wọ́n fi tọkàntọkàn wá OLUWA Ọlọrun àwọn baba wọn, bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé ó lè má jẹ́ ọ̀nà ẹ̀tọ́ ni wọ́n fi jẹ àsè àjọ náà gẹ́gẹ́ bí òfin ìwẹ̀nùmọ́ ti ibi mímọ́.
  Eyi nikan kọ, ki eka  FSARS naa si maa jabọ fun ẹka ile eṣẹ olopaa ni Abuja to n ri si iwa ọdaranMoshood, ni ile-ise olopaa ti gbe igbese lati maa  mojuto bi eka FSARSse n ise won lati tele ilana ti ile-ise aare la sile.
Ogunjọbi jade laye lẹni ọdun marun le lọgọta nigba ti o pe ọdun marunlelọgbọn ti o ṣoju orilẹede Naijiria fun igba akọkọ ninu ifẹsẹwọnsẹ pẹlu Morocco lọdun 1984.
 Awọn ohun to n sẹlẹ lẹkun iwọ oorun ati aarin gbungbun ariwa Naijiria n ba ni ninu jẹ pupọ.
Buhari gbasẹ lọwọ adajọ meji Buhari ba Aarẹ China yọ O fi kun wipe mẹsan ninu awọn ti wọn sekupa naa jẹ ọmọ Naijiria to wa ni ilu London ati awọn agbeegbe miran ni ilu Geesi Arabinrin Dabiri-Erewa naa fikun wipe oun ti kọ lẹta ifẹhọnu han si asoju ilẹ Geesi ni Naijiria, ti oun si bẹrẹ fun iwadii ati idajo otito lori isẹlẹ naa.
Oríṣun àwòrán, Nigeria Museum O lẹmi iwa ikora ẹni nijanu, to si korira irọ pipa.
OLUWA bá rán iná kan jáde, iná náà jó wọn pa, wọ́n sì kú níwájú OLUWA.
Igi ère oriṣa Aṣera tí o bá gé lulẹ̀ ni kí o fi ṣe igi ẹbọ sísun náà.
Nítorí ọwọ́ agbára ni OLUWA fi lé mi lára, nígbà tí ó ń sọ èyí fún mi.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ìtàn ayé Seyi Makinde, gómìnà tuntun ní Ọ̀yọ́ Mà á ṣiṣẹ́ bí i gómìnà tó ní èrò aráàlú lọ́kàn - Seyi Makinde Ṣeyi Makinde fòfin de ẹgbẹ́ NURTW Ọyọ, ó gbàkóso gáréjì ọkọ̀ Olori oṣiṣẹ ọba lọfiisi gomina sọ pe, ijọba n reti ki awọn alaga naa lọ si ileẹjọ, ti igbesẹ yii ko ba tẹ wọn lọrun.
Akinwumi Adesina: Ọdún márùn ún ní Adesina yóò lò ní sáà kejì ipò adarí Báńkì AFDB
Bẹ́ẹ̀ ni a mú ọpọlọpọ àwọn arọ ati àwọn tí wọ́n ní àbùkù ara lára dá.
Gẹ́gẹ́ bí Ìwé Mímọ́ ti sọ, pé, “Nítorí náà ni ọkunrin yóo ṣe fi baba ati ìyá rẹ̀ sílẹ̀, tí yóo darapọ̀ pẹlu aya rẹ̀, àwọn mejeeji yóo wá di ara kan.
Ní ọdún kẹta tí Beṣasari jọba ni èmi Daniẹli rí ìran kan lẹ́yìn ti àkọ́kọ́.
Isọri melo lo wa ninu eto naa?
" Who is Squeezing Tunde Bakare's Ball?
Lọjọọru ni awọn asofin agba buwọlu orukọ Ẹniọwọ Rufai Imam lẹyin ti igbimọ to n se kokaari ọrọ eto idajọ, ẹtọ ọmọniyan ati ọrọ ofin gbe orukọ rẹ kalẹ niwaju awọn asofin agba naa.
BBC ko ribi fidi mulẹ iye ti owo ayẹwo yi jẹ gaan ṣugbọn awọn obi kan to ba awọn ile iṣẹ iroyin Naijiria sọrọ lori iṣẹlẹ yi ni awọn ko ni le san ẹgbẹrun mẹẹdọgbọn naira ti ijọba fẹ gba fun ayẹwo yi.
37  eyi ti alekun iko merinlelogun-o-le ninu ida ogorun24.
Balogun fi kun un wi pe yiyọ Olubadan ni ipo lee ba ilu Ibadan jẹ, eleyii ti awọn ko fẹ ko ṣẹlẹ.
Awọn eeyan sọ pe eyi lo mu ki awọn janduku wọnyi d'aṣọ okunkun boju lati le fi ja awọn eeyan lole ninu ile wọn.
Awọn oni sayẹnsi n pe e ni Chrysophyllum Albidum.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ẹ wo adúrú ǹkan tí Softface ma ń tò pọ̀ láti sín àwọn òṣèré, gbajúgbajà jẹ Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí 2:36 Fídíò, Cancer Marriage: Oṣù kan péré ni Tash fi ṣe ìgbéyàwó pẹ̀lú Simon kó tó kú, Duration 2,3626 Agẹmo 2020 Church of Satan: Báwo ni ìjọ́sìn ṣe n rí nínú ìjọ Sátánì?
Oríṣun àwòrán, Ayinla Omowura Àkọlé àwòrán, Kokoro ko si jẹ ka gbadun obi Ayinla to gbo, ti iku ko jẹ ka gbadun ohun aladun ti Ẹlẹda fi jinki Ayinla Ọmọwura.
Makinde bẹ Alaafin - BBC News Yorùbá BBC News, YorùbáFò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Alaafin: Kabiyesi ẹ má bínú, àìmọ̀ lo fa ìgbésẹ̀ mi, n kò takò yín - Makinde bẹ Alaafin 11 Òkùdu 2020 Oríṣun àwòrán, others Bi wọn ba n sọ nipa awọn ọba alade ti ko ṣee maa fi ọwọ rọ sẹyin nilẹ Yoruba, orilẹede Naijiria ati agbaye, ọkan gboogi ni alaafin ilu Ọyọ jẹ ko si si ijọba kan to n ko iyan rẹ kere.
Àwọn alufaa ni: Jedaaya ọmọ Joiaribu ati Jakini; 
Yóo máa sùn tì ọ́ kí ara rẹ lè máa móoru.
Awuyewuye naa lo n waye lẹyin ti awọn kan sọ pe awọn lo jawe olubori ninu idibo naa sugbọn ti INEC gbe ipo wọn fun elomiran.
Lasiko ti aare orile ede South
Àwọn ẹ̀ṣẹ̀ bíi kí ènìyàn ṣe àgbere (Zina), èyí túmọ sí pé tí wọ́n bá ka ọkùnrin tàbi obinrin mọ́ níbi ìbálòpọ̀ ti kìí sì ṣe pẹ̀lú ọkọ tàbi aya wọ́n.
A ti fi ìdí ayé múlẹ̀, kò sì ní yẹ̀ lae;OLUWA yóo fi òtítọ́ ṣe ìdájọ́ àwọn eniyan.
Odumakin sọ pe, ohun to n ṣẹlẹ lọwọ pẹlu iwọde EndSARS kii ṣe ọrọ ẹlẹyamẹya, ṣugbọn o ti pẹ ti ara ti n kan awọn eeyan.
Nítorí pé n óo ko yín jáde láti inú àwọn orílẹ̀-èdè yòókù, n óo gba yín jọ láti gbogbo ilẹ̀ ayé, n óo sì mu yín pada sórí ilẹ̀ yín.
Idahun: Eyi ni alakalẹ diẹ lara ilana owo oṣu ọlọpaa ni Naijiria: 1.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Igba akọkọ ti Pedro yoo gba bọọlu sinu awọn niyẹn ni saa Premier League yii.
Àwọn ọmọ wolii tí wọn ń gbé Jẹriko tọ Eliṣa wá, wọ́n sì bi í pé, “Ǹjẹ́ o mọ̀ pé OLUWA yóo mú ọ̀gá rẹ lọ lónìí?
Ní ǹkan bi ago mẹ́rìn ìdáji òní ni àbẹnuga ilé ìgbìmọ̀ aṣòfin Mudashiru Obasa pada yọju sí wọ́n láti buwọ́lu ìwé ẹsùn ti wọ́n mú wá fún ìjọba.
Afcon 2019: Super Eagles ti wa gba owó àjẹ́mọ́nú wọn báyìí
Àwọn ọmọ Juda wọnyi ni wọ́n pada dé láti oko ẹrú ní Babiloni, níbi tí Nebukadinesari, ọba Babiloni, kó wọn lẹ́rú lọ.
South Africa killings: Ìjọba àpapọ̀ ní kò sóun tó jọ ìbúgbàmù àdó olóró níléeṣẹ́ ìjọba South Africa tó wà nílùú Abuja
Coronavirus dòjú ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ PSG àti Strasbourg bolẹ̀ Bawo ni mo ṣe lee dabo bo ara mi?
Agbẹnusọ fun ileeṣẹ ọlọpaa nipinlẹ naa, Bala Elkana lo fi idi ọrọ naa mulẹ fun akọroyin BBC to n tọ pinpin iṣẹlẹ yi.
Ladodo ní  ẹ̀rọ amúná wá náà sì wà ní títàn sílẹ̀ nínú yàrá ìdána títí ilẹ̀ fi mọ tí ilẹkun àti fèrèsé ti àwọn alejo sùn si wà ni títì pa."
Femi, ẹni to daju pe o n sin agba aafa kan jẹ ni, lo wọ agbada buluu gbagẹrẹ, to si we lawani sori, nigba ti obinrin kan, ti oun naa jẹ osere tiata rẹ, ṣe bii dadani fun.
Nínú ìmọ̀ ìjìnlẹ̀ iṣẹ́ ìkọ̀ròyìn ni  ó ti fi lélẹ̀ wípé a gbọdọ̀ tànmọ́lẹ̀ sí ìjìyà àwọn ènìyàn ní ibi tí rògbòdìyàn bá wà.
 gégé bí olórí fún apis , ó pon dandan kí òrò-ìse wà nínú gbólóhùn yálà pèlú àwon emèwà rè tàbí ní òun nìkan .
Olόwό-Ìbínú àti Ìdààmú-Ayé ṣe ìgbéyàwό, ọjọ́ ìgbéyàwό-o wọn lárinrin púpọ̀, ayé gbọ́, ọ̀run sì mọ̀ pẹ̀lú wí pé àwọn gbajúmọ̀ méjì-í fẹ́ ara wọn.
Jiji ti mo si ji ni mo ri D'banj ninu yaara mi.
Tinubu kọ lẹta si Odigie pe o'n gbegi di'na iṣẹ oun
OPC sọ pe lọjọru ọsẹ lẹyin ti wọ́n fẹsun kan pe awọn ọdaran naa ṣọṣẹ lẹyin Ile ẹjọ giga ti ilu Ikire to wa lẹba opopona ni ọwọ tẹ wọn.
 Bo tile je pe eyi ni igba ikeji , ninu iwe iranti orile ede Naijiria ti ijoba Ologun yoo  fi aaye gba eto  ijoba tiwa-n-tiwa.
"Iná ẹ̀lẹ́ńtíríkì pa ọlọ́kadà, obìnrin kan ní Ibadan, àjọ IBEDC ní àwọn ti bẹ̀rẹ̀ ìwadìí Allwell Ademola sọ̀rọ̀ lórí ìdí tó fi ń ṣe ọjọ́ ìbí 35 lọ́dọọdún Àwọn àmi méje tó ń tọ́ka sí pé oò kí ń mu omi bí ó ti tó Òhun tó yẹ̀ kí o mọ̀ nípa ""Bone Straight Hair"" ""Ẹkun ariwa Naijiria ko ni fi oju rere wo ẹya miran to ba fẹ gba akoso lọwọ ijọba Buhari, nitori naa, ẹlomiran lati apa oke ọya ni Buhari yoo fa akoso orilẹede yii le lọwọ."
Ṣugbọn nisinsinyii, n óo gbé wọn dìde níbi tí ẹ tà wọ́n sí, n óo sì gbẹ̀san ìwà yín lára ẹ̀yin alára.
Wo ohun tí Adájọ́ ṣe sí àṣùwọ̀n ìfowópamọ́sí Wòlíì Sotitobire Ìwà Bashorun Gaa ni Obaseki hù ní ipínlẹ̀ Edo -Tinubu Ẹ wo ìkìlọ̀ tí ìjọba America fi léde lórí ìdìbò gómínà Ondo, Edo Ìdí tí a fi ṣàfikún owó ìtanràn ọ̀rọ̀ kòbákùngbé ní Nàìjíríà sí 5 Mílíọ̀nù rèé - Lai Mahammed Ẹwẹ, ajọ WAEC ti sọ pe oun ti bẹrẹ iwadii lati mọ idi ti awọn ọmọ ile iwe naa ṣe ṣakọlu si awọn eeyan ọhun.
Ile-ise omo ogun Naijiria, Nigerian Army ni ifowossowopo pelu ile-ise omo ogun ile Amerika ti eka ile Afrika (United State Army African Command) yoo maa sagbateru ipade apero awon omo ogun ile Afrika bere lati ojo kerindinlogun si ojo kokandinlogun osu ti a wa yii nilu Abuja.
Ọgbẹni Ayeni sọ pe awọn nilo ki ajọ NAFDAC fun oogun naa ni nọmba ki awọn to le bẹrẹ si ni taa, bi bẹẹ kọ, oogun naa ko le di tita lori igba.
Paapaa julọ awọn ti aisan semi-semi, ẹjẹ ruru, itọ ṣuga ati warapa n ba finra.
Yóo ranti gbogbo ẹbọ ọrẹ rẹ,yóo sì gba ẹbọ sísun rẹ.
Ohun ti ẹṣọ Amọtẹkun wa fun mi lati maa ṣe iranwọ fawọn agbofinro lori ati dẹkun iwa ibajẹ lawọn ipinlẹ to wa nilẹ Yoruba.
Ìwádìí BBC náà ṣe agbéyẹ̀wò àwọn àtẹ̀ránṣẹ́ orí WhatsApp àti Facebook láàrin àwọn ọmọ orílẹ̀è-dè Naijiria, Kenya àti India, tí àwọn onímọ̀ ìjìnlẹ̀ sì fìdí tí àwọn ènìyan fi máa ń pín ìròyìn òfégè káàkiri múlẹ̀.
'Wọ́n ní a kò lówó tó láti díje dupò ní Nàìjíríà' Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Somalia: 'Wọ́n pàṣẹ fún mi láti dá Ramla dúró ká tò lè ṣe igbeyàwó' Lẹyin naa ni ọmọ̀ ọdọ naa sọ ọga rẹ mọ igi ibusun, ko to di wi pe ọga naa gbiyanju lati gba ara rẹ silẹ, eleyi ti o jasi iku, lẹyin ti o gun ọga rẹ lọna mẹta.
Fayemi: Àwọn àwòrán tó jẹ ojú ní gbèsè níbi ìbúra
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Nigeria 2019 Elections: Àwọn aráàlú kan ní ìṣúnsíwájú ìbò ṣàkóbá fún ọrọ̀ ajé Ẹgbẹ oṣelu kọọkan lo ni aṣoju nibi apero naa, gbogbo wọn sini wọn ni anfani lati beere ohun gbogbo to ru wọn loju nipa eto idibo ati ojuṣe awọn agbofinro.
Àwa, nítorínáà, ní ìfẹ́ láti jẹ́rìí sí gbogbo aráyé, sí olúkúlùkù èdá lórí ilẹ̀ ayé, pé Olúwa ti jẹ́rìí sí ọkàn wa, nípasẹ̀ Ẹ̀mí Mímọ́ tí a tú sí orí wa, pé àwọn òfin wọ̀nyí jẹ́ fífi fúnni nípa ìmísí Ọlọ́run, àti tí ó ní èrè fún gbogbo ènìyàn wọ́n sì jẹ́ òtítọ́ gan an.
"Kò ní sí ìpéjọpọ̀ musulumi fún waasi lásìkò aawẹ, irun isinu àti irun janmọ làwọn mọsalasi gbogbo títí tí ohun gbogbo yóò fi padà bọ sípò.
Kí o pa mi, ki ń kú, Ìrìnkèrindò!
“Nítorí náà, OLUWA ní kí n pe ẹ̀yin, ọmọ Israẹli, kí n sọ fun yín pé, òun OLUWA Ọlọrun ní, Kì í ṣe nítorí tiyín ni mo fi ń ṣe ohun tí mò ń ṣe, bíkòṣe nítorí orúkọ mímọ́ mi, tí ẹ̀ ń bàjẹ́ láàrin àwọn orílẹ̀-èdè tí ẹ sálọ.
Àwọn ọmọ Asigadi jẹ́ ẹgbẹfa ó lé mejilelogun (1,222)
Oluwo ni mo mọ̀, n kò mọ orukọ oye míràn -Ọọ̀ni
Oríṣun àwòrán, @atiku Àkọlé àwòrán, 'Mo n ke si awọn ọkunrin, awọn baba, awọn olori ẹsin ati ọrọ oselu gbogbo lati parapọ hu iwa gẹgẹ bii eniyan lati mu ayipada rere ba igbe aye awọn obinrin' Loni ti a n se ayajọ awọn obinrin lagbaye, mo n ke si awọn ọkunrin, awọn baba, awọn olori ẹsin ati ọrọ oselu gbogbo lati para pọ hu iwa gẹgẹ bii eniyan lati mu ayipada rere ba igbe aye awọn obinrin."
Wọ́n pé ọdún méjìlá báyìí Ìbálòpọ̀ ọ̀lọ́jọ́ méje mú kí ilé ẹjọ́ tú ìgbéyàwó ọdún mẹ́wàá ká ní Ibadan Rògbòdìyàn bẹ́ sílẹ̀ láàrin àwọn ọlọ́kadà àti àwọn òṣìṣẹ́ ọgbà ẹ̀wọ̀n ní Ibadan Bakan naa lo sọ pe o yẹ ki eeyan ni gbedeke ounjẹ ti yoo maa jẹ nigba kuu gba.
OLUWA dá wọn lóhùn pé ẹ̀yà Juda ni yóo kọ́kọ́ gbógun tì wọ́n.
Rochas Okorocha, káàbọ̀ sí àwùjọ àwọn gómìnà tí EFCC ń wá - Fayose Ará ìlú dájọ́ oró fún ọkùnrin to bẹ́ orí ẹ̀gbọ́n rẹ̀ ní Cross River Èrè ńlá ńbẹ fáwọn obìnrin nínú okoòwò ọ̀fẹ́ ní Áfíríkà Wo àwọn ìlérí tàwọn Gómìnà tuntun ṣe nínú ìbúra wọn Ni ọdun 2016 ni wọn ni ida ogun ninu ọgọrun un eniyan lagbaye lo n mu taba bẹẹ wọn ida metadinlọgbọn ni lọdun 2010.
Wọ́n ń rí oúnjẹ jẹ ní àjẹyó ní ilé rẹ;nǹkan mímu tí ń ṣàn bí odò,ni o sì ń fún wọn mu.
Ṣùgbọ́n ó béèrè àlàáfíà mi o.
Femi Adesina - BBC News Yorùbá BBC News, YorùbáFò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù EndSARS Protest: Àwọn olùwọ́de Endsars ló já sọ́ọ̀bù kìí ṣe torí ebi - Femi Adesina 20 Ọ̀wàrà 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 30 Ọ̀wàrà 2020 Oríṣun àwòrán, femi Adesina/twitter Agbẹnusọ ààrẹ Muhammadu Buhari lórí ìròyìn àti ìpolongo, Femi Adesina ni kìí ṣe ebi tàbi òsì ló mú ki àwọn ènìyàn maa já ilé, já sọ́ọ̀bù tàbi bá ǹkan jẹ́ bí kò ṣe ìfẹ̀hónúhàn #EndSars.
"O sọ pe ""Awọn to ba fẹ rinin ajo ilẹ okere nikan ni ofin to rọ mọ abẹrẹ ajẹsara kan, gẹgẹ bi awọn eeyan ṣe ma n gba kaadi abẹrẹ ajẹsara fun iba ponju pontọ ti wọn ba fẹ lọ orilẹede miran."
OLUWA bá bi Kaini, ó ní, “Kí ló dé tí ò ń bínú, tí o sì fa ojú ro?
Kìnìún mẹ́rìnlá bọ́ sígboro Naijiria bori South Afrika pẹlu ami ayo meji sookan ti o si tumọ si pe wọn yoo tẹ siwaju lọ abala to kangun si aṣekagba.
O fẹ́ láti kọ ilé ìwòsàn ńla márùn-un ńlánlá sí ilẹ̀ Afirika láti mú ìdẹ̀rùn bá àwọn ti o bá ń kojú irú àìlera yìí, bákan náà ní ajọ rẹ̀ ti gbèrú síi láti maa ṣerànwọ́ fún àwọn tí kò níle.
O ní orílẹ̀-èdè Nàíjíríà ti làkàkà láti wá nǹkan ṣe sí ìpèníjà yìí bii fífọwọ́sowọ́pọ̀ pẹ̀lú àwọn àjọ aṣèrànwọ àti alátìlẹ́yìn gbogbo láti ríi pé ààbò wà fún àwọn akẹ́kọ̀ọ́, olùkọ́ àti iléèwé lẹ́kùn náà.
Àkọlé àwòrán, Awọn musulumi ododo nipinlẹ Ọyọ naa darapọ mọ awọn akẹgbẹ wọn lagbaye lati ṣe ajọyọ ọdun itunu awẹ.
"Akeredolu ni ""owó wá nibẹ, èwe ọlá sì lawa ń pè igbó."
”“ Nitori naa, ohun ti a n se ni lati mura sile , ki a si maa gbe igbese lati dena ohun ti  yoo je ki iru isele naa tun waye.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Awa America la tun gba ife tọdun 2019 Megan ni awọn amohunmaworan ṣafihan rẹ pe ko kọ orin ogo ilẹ Amerika jade ṣaaju idije wọn.
Iyawo olukọ naa, Bernice Adegbehingbe lo fidi ọrọ mulẹ fawọn oniroyin.
Euthanasia jẹ́ ọ̀nà tí àwọn ènìyàn ń gba láti ran ẹbí tàbi aláìsàn tí o ni àìsàn tí yóò já sí ikú láàrín oṣù mẹ́fà, ṣùgbọ́n ẹni náà ni ànfani láti yàn pé kí ò n jẹ ìrora títí di ọjọ́ ikú tàbi kí wọ́n fún ni abẹ́rẹ̀ ikú sáájú kí o ma ba rí ìrora.
Àwòrán àjọyọ̀ ìjọba ológun ní Sudan Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Bí o ṣe lè fí òǹkà, ọ̀mọ̀ ìka tàbí ìkúùkù wọn oúnjẹ́ Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Apapọ ajọ to n se agbekalẹ idanwo yii ba ṣe ohun tuntun lọdun yii, wọn fagile fiforukọ ni ibudo cyber cafe ti awọn aṣedanwo maa n lọ tẹlẹ.
Ó tún sùn, ó sì lá àlá mìíràn, rírí tí yóo tún rí, ó rí ṣiiri ọkà meje lórí ẹyọ igi ọkà kan, wọ́n tóbi, wọ́n sì yọmọ.
Ṣùgbọ́n l'áwọn ọdún tó gbẹ̀yìn ayé rẹ̀, abilekọ Mandela dúró bí i àmì àwọn ohun tó ṣẹlẹ̀ sẹ́yìn - óun ránni létí àwọn akọni ọkùnrin àti obìnrin tó mú òpin dé bá ìṣèjọba àwọn aláwọ̀ funfun.
Fulani darandaran lo iwa ipa ni guusu Akurẹ Ọmọogun pa darandaran mẹwa ni Adamawa NBC fọwọ́ sí ìdásílẹ̀ ilé iṣẹ́ Fulani Radio Gani Adams kilọ f'awọn darandaran Àwa ọba alayé ń wọ́nà láti ṣẹ́ eegun ẹ̀yin ọ̀daràn Fulani - Ọọ̀ni Lọjọ Eti ni wọn ṣe ifilọlẹ awọn ẹrọ yii ni Osi ni Akurẹ to jẹ olu ilu ipinlẹ Ondo.
- Olukoya ti ìjọ MFM Shiek Yahaya Samadaani- Ọdún 2020 yìí á sàn ẹni tó bá fọkàn sín Olorun Òṣèrébìnrin tí wọ́n bá fi ìbálòpọ̀ lọ̀ 'torí ìṣẹ́, kó bọ́ síta láti sọ̀rọ̀ - Kunle Afod O ni lootọọ ni pe iwa ọdaran ko le tan nilẹ patapata, amọ awọn gomina mẹfẹẹfa ti fẹnu ko lati rii wi pe iwa ọdaran dinku kaakiri ilẹ kaarọ o jiire.
Omowe Frankland Briyai so pe “
níbáyí , Ìṣọ ̀ kan ti ń yapa .
Eto idibo si ipo gomina ipinlẹ Ọṣun yoo waye lọjọ kejilelogun oṣu kẹẹsan ọdun yii, Ademọla Adeleke yoo si maa takangbọn pẹlu awọn oludije mẹtadinlaadọta mii.
James Park ninu idije Premier League.
 Ìtọ ́ jú ipele kejì a má a wáyé nípasẹ ̀ egbògi tí a ńpe ní eflornithine tàbí àdàpọ ̀ nifurtimox àti eflornithine fún t.
Ó sàn kí á jẹ́ talaka, kí á sì ní ìbẹ̀rù OLUWA,ju kí á jẹ́ ọlọ́rọ̀, kí á sì kún fún ìyọnu lọ.
Sùgbọ́n ó jọ bí ẹni pé, ìràn àwọn òṣèré tó n dìde ni lọ́ọ́lọ́ yìí ti fí àwọn àgbà òṣèré náà si ìjòkó ẹ̀yìn nínú ká dáni lara yá.
INEC ní kíkùnà ààrẹ láti buwọ́lu òfin ìdìbò kò dí ìbò Ọ̀ṣun, 2019 lọ́wọ́ Oríṣun àwòrán, Olu Alebiosu Àkọlé àwòrán, Abajade ipade naa si ni pe ijọba yoo san ajẹẹlẹ owo oṣu mẹrin to ku ninu ọdun 2015 fawọn oṣiṣẹ Awọn adari ẹgbẹ oṣiṣẹ nipinlẹ Ọṣun ti fi iwe ikede gbedeke ọlọjọ meje sita lopin ọsẹ fun ijọba lati san ajẹẹlẹ owo oṣu fawọn oṣiṣẹ abi ki wọn maa reti iyanṣẹlodi awọn oṣiṣẹ laipẹ.
Bakanaa ni jẹbẹtẹ gbọmọ lee lọwọ lai lee salaye idi to fi fi tipa tikuuku gba awọn irinsẹ osisẹ BBC naa, to si tun fi tipa wọle sori awọn irinsẹ naa ati idi to fi pa awọn fidio ati ohun to wa lori ẹrọ agbohun ati aworan silẹ naa.
Agbo ilée Bajimọn ní Òkè -Ọjà ni Agígírì sọ́kọ́ fi ṣe ibùjókòó.
Lẹ́yìn náà, ṣe ìgbátí kan yíká etí tabili náà, kí ó fẹ̀ ní ìbú àtẹ́lẹwọ́ kan, kí o sì yọ́ wúrà bo ìgbátí náà yípo.
OLUWA àwọn ọmọ-ogun ní, “Ní ọjọ́ náà, èèkàn tí a kàn mọ́lẹ̀ gbọningbọnin yóo yọ, wọn yóo gé e, yóo sì wó lulẹ̀, ẹrù tí wọn fi kọ́ lórí rẹ̀ yóo sì já dànù.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Èyí ni àwọn arẹwà ‘ẹ̀lẹ̀ Daddy’, àfẹ́fẹ́ tí Aláàfin fi ń mí APC kò ní olórí tí yòó tọwọ́ bọ̀wé, INEC yarí fún ìbò abẹ́nú l‘Ondo Ìhòhò ọmọlúàbí ni mo má a ń bá àwọn ọmọkùnrin mi wí - Elesho Ọ̀dàlẹ̀ ni Igbákejì Gómìnà, kìí ṣe pé a dẹ́yẹ si - ìjọba Ondo Onyeama, jọ̀ọ́ má bínú ìdẹ́yẹsí tá a ṣe torí pé o jẹ́ adúláwọ̀ - Ilé ẹ̀kọ́ Eton Iroyin taa gbọ ni pe, Yaro lọ si ile baba ọmọ naa ni oṣu mẹta sẹyin, ọmọ naa si n sun jẹjẹ lẹgbẹ baba rẹ ni, nigba to gbe e, o si ba a sun, koda, o buru titi, ifun ọmọ ọhun tu sita.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Kunle Olasope: Lekan Alabi ní onírẹ̀lẹ bíi àgbà àgbóhùnsáfẹ́fẹ́ náà sọ̀wọ́n 7 Ọ̀wàrà 2019 Oríṣun àwòrán, Others Kìí ṣe ohun tuntun mọ pé ọkunrin akọkọ to farahan lori amohunmaworan, Kunle Olasope ti fí duniyan silẹ sùgbọ́n àwọn alábasisẹ́ pọ̀ rẹ nigba ayé rẹ tí n jẹri si ǹkan ti wọn mọ̀ọ nipa rẹ.
Mi ò ní wọ Uber mọ́ tí wọ́n bá leè fi owó lée nítorí àfikún owó orí tí Sanwo Olu ṣe Immaculate Okochu ń múra ìyàwó lọ́wọ́ ló k'àgbákò ikú 'Inú mi dùn pé wọ́n dájọ́ sísọ̀kò pa bàbá arúgbó tó fipá b'ọ́mọ lòpọ̀' Ilé iṣẹ́ tó ri si ètò ẹ̀kọ́ l'Abuja kò tí ì rànsẹ́ pé UNILAG ti ni Giwa tuntun Eniyan ẹgbẹrun lọna mẹtala lo ti lugbadi arun naa, ti eniyan mejilelọgọjọ si ti ku.
Eyi tumọ si pe o ni lati pa awọn ọta rẹ lẹnu mọ koo si gba ohun too fẹ gba lai yin ọta ibọn kan ṣoṣo.
Ni iyanju ile-ifowopamo agba lorile-ede Nigeria CBN, lati je ki awon onibara oja owo pasi-paro ri owo lore-koore, ile-ifowopamo ohun tun da igba-o-le mewaa milionu owo dollars $210 sinu oja pasi-paro naa.
Nígbà tí ó súnmọ́ gẹ̀rẹ́gẹ̀rẹ́ òkè Olifi, ogunlọ́gọ̀ àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ bẹ̀rẹ̀ sí fi ayọ̀ kígbe sókè, wọ́n ń yin Ọlọrun nítorí gbogbo ohun ńlá tí wọ́n ti rí.
Nígbà tí Jesu di ọmọ ọdún mejila, wọ́n lọ sí àjọ yìí gẹ́gẹ́ bí ìṣe wọn.
Ẹni tí ó gbé agbára rẹ̀ tí ó lógo wọ Mose, tí ó pín òkun níyà níwájú wọn,kí orúkọ rẹ̀ lè lókìkí títí lae.
Bakan naa, ni Aare Donald Trump so lose ti o koja pe,”Awon omo ogun re yoo filu Syria sile laipe”.
Kí ó gbé ọwọ́ lé orí ẹran náà, kí ó sì pa á lẹ́nu ọ̀nà Àgọ́ Àjọ.
Ẹ kò gbọdọ̀ dá ẹnikẹ́ni sí, ẹ kò sì gbọdọ̀ ṣàánú ẹnikẹ́ni.
Ọlọpàá gba owó ilé ìwé #150,000 lọ́wọ́ akẹ́kọ̀ọ́ DELSU kan Ẹ̀rù kò bà mí láti padà sí Bolivia- Evo Morales Ikú ni fífi oògùn 'Paracetamol' bọ ẹran tàbí se ẹ̀wà- Iléeṣẹ́ ìlera Messi gọ̀ láti sọ fun akọ́nimọ̀ọ́gbá Brazil pé kó gbẹ́nu dákẹ́- Thiago Silva Tani Aisha Raheem to fẹ gba ami ẹyẹ 2020 Africa Price?
Ìjọba Nàìjíríà ti ṣẹ́gun Boko Haram- Ààrẹ Muhammadu Buhari
Gbogbo ohun ti kaluku wa ba n se ni ka yipada, abi, ta a ni sọ.
"Wọn ni awon kan ti wọn pe ara wọn ni awọn idile ""oloogbe"", wa si ọdọ awọn ile agbokujo naa wipe awọn fẹ fun wọn niṣẹ."
Bẹẹ ba gbagbe, ọjọ kejidinlọgbọn osu kẹsan ọdun 2016 n'ile pasẹ fun asofin ọhun pe ko lọ rọọkun nile na fun ọgọsan ọjọ.
Lai pẹ yi ni ajọ to n ja fun ifẹsẹmulẹ ẹtọ ọmọniyan (SERAP), gba idajọ nile ẹjọ wipe wọn lẹtọ lati pe awọn asofin ati minista ti wọn figba kan jẹ gomina tẹlẹri ni ipinlẹ , ti wọn si n gba owo ifeyinti pelu owo asofin lọwọlọwọ lẹjọ.
ní àwùjọ adúláwọ ̀ káàkiri ayé , orúkọ ṣe pàtàkì púpọ ̀ .
“O kò gbọdọ̀ ní ọlọrun mìíràn lẹ́yìn mi.
Wọn fun Gyan ni oye tuntun yi lẹyin ti wọn gba ipo Balogun lọwọ rẹ ti wọn si gbe fun Ayew.
Iroyin to jade ni pe awọn aṣofin naa yọ awọn akanṣe iṣẹ kan kuro lara awọn eyi ti ẹka alaṣẹ fẹ ẹ ṣe, ti wọn si fi awọn miran ti ileesẹ aarẹ ko ni lọkan lati ṣe.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: ''Buhari, fi kùráànì búra lórí èsì WAEC rẹ'' N3.
Gbogbo apa ti Arsenal ṣa,pabo lo jasi ti ifẹsẹwọnsẹ naa si pari ni ayo mẹta si ọkan.
Nígbà tí à ń pada lọ tí a dé ibi tí a fẹ́ sùn, a tú àpò wa, olukuluku wa bá owó tirẹ̀ lẹ́nu àpò rẹ̀, kò sí ti ẹni tí ó dín rárá, a mú owó náà lọ́wọ́ báyìí.
Àwọn ọ̀rẹ́ mi ki yín púpọ̀.
Oríṣun àwòrán, @Emiearth Àkọlé àwòrán, Taiwo Ogunjobi Lẹyin igba naa ni Ogunjobi di oloogbe laarọ ọjọ Aje, ile iwosan ko sọ iru aisan kan gbogi to pa oloogbe naa.
Ẹgbẹ to ba si gbegba oroke ni wọn yoo fun ni ẹbun to jọju lasiko ọdun Ojude Ọba, ninu eyi ti wọn yoo maa yin ibọn soke loore koore.
Ìséde ń bọ̀ káàkiri Nàìjíríà, àwọn gómìnà ìpínlẹ̀ fẹ́nukò Awọn gomina ipinlẹ gbogbo lorilẹede Naijiria ti fẹnu kolori titit gbogbo ẹnubode ipinlẹ si ipinlẹ pa jakejado orilẹede Naijiria fun ọsẹ meji bayii lati pinwọ itankalẹ ajakalẹ arun Coronavirus lorilẹede Naijiria.
Wọn ni bi wọn ba ti jẹ ẹ, ara a rẹ wọn, wọn a si gba ibẹ ku ki awọn to ji wọn pa le lọ ko wọn.
Wo ohun tó yẹ kí o mọ̀ nípa Laycon, akẹ́kọ̀ọ́jáde UNILAG tó ń kópa nínú BBNaija 2020 Àwọn àádọ́ta ọ̀dọ́ wọ gàù nítorí ilé ijó ní Ilorin Ènìyàn 653 míràn tún kún iye àwọn tó ní COVID-19 ní Nàìjíríà Báwó ni òògùn dexamethasone ṣe ń ṣiṣẹ́ lára Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Human trafficking: Ààrẹ Buhari, ẹ̀yin gómìnà ìpínlẹ̀ Yorùbá, ẹ rántí wa ní Oman, àwọn ọmọ Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
ile-ise yii yoo se ni idagbasoke lati mu ipinuu wọn sẹ.
 ju gbogbo rẹ ̀ lọ , ibi tí a bá gbé ń ṣe nǹkan tí ó lè mú ìdùnnú lọwọ , yálà ilé ṣíṣí ní tàbí ìwuyè ni a ti i máa ń rí àwọn asunrárà .
Abigaili fẹ́ Jeteri láti inú ìran Iṣimaeli, ó sì bí Amasa fún un.
Wọ́n fagi lé ìfìwépè Adarí iléeṣẹ́ tó ń ṣètò Ìṣàjò-papọ̀-wa-ọkọ̀-kí-n-wa-ọkọ̀ sí iléeṣẹ́ tẹlifíṣàn Russia lẹ́yìn tí olóòtú ètò rí i pé obìnrin ni
Bo ṣe n mura lati ṣe iburawọle ipo sẹnetọ to wọle fun ni iyawo rẹ, Neilla ati ọmọbinrin rẹ, Naomi ku ninu ijamba ọkọ kan eyi to tun pa awọn ọmọkunrin rẹ meji, Beau ati Hunter lara.
Alukoro ileeṣẹ ọlọpaa, Frank Mba lo ṣalaye ọrọ yii lasiko to fi n sọrọ lori ileeṣẹ mohunmaworan abẹle kan lorilẹede Naijiria lalẹ ọjọ Satide lẹyin ti ibo didi pari lawọn ipinlẹ mejeeji.
Won ti seku pa awon osise alaanu meji lorile-ede Democratic Republic of Congo (DR Congo), nigba ti enikan si poora bayii.
Awọn ọlọpaa n ṣe iwadii lọwọ lori awọn irufẹ ẹsẹ yi.
Àwọn ọmọ ogun Israẹli ati ti Filistini dúró ní ipò wọn, wọ́n ń wo ara wọn.
Nítorí náà, ìran yìí ni yóo dáhùn fún ẹ̀jẹ̀ gbogbo àwọn wolii tí a ti ta sílẹ̀ láti ìpìlẹ̀ ayé, 
Ohun tawọn Gomina lawọn fẹ fi owo yi ṣe ni eto ipese ohun amayedẹrun fara ilu ti Gomina Kayode Fayemi to jẹ alaga ẹgbẹ awọn Gomina si ni awọn ti buwọlu aba owo yiya yi pẹlu eyi ti banki apapọ naa sọ pe awọn fẹ ya ninu owo ifẹyinti oṣiṣẹ.
Lẹyín ìgbà tí àwọn èèyàn bẹ̀rẹ̀ sí fi ìbànújẹ́ hàn lórí fídíò náà ni alága àjọ INEC, Ọ̀mọ̀wé Mahmoud Yakubu yan ìgbìmọ̀ ti Abubakar Nahuce lewajú ko ṣe ìwádi lórí iwe ìf'orúkọ́ silẹ̀ tí wọ́n lò ni Kano.
Eyi ko sẹyin eto aabo to mẹhẹ lorilẹede Naijiria pẹlu ijinigbe ati ipaniyan ni awọn opopona kaakiri orilẹede Naijiria.
Akintọla Williams: Àwọn nkan tó ṣe pàtàkì tó yẹ kí o mọ̀ nípa Olùṣirò owó Àgbà àkọ́kọ́ ní Afrika
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fọ́nrán ohùn, IMF gba Naijiria níyànjú lórí pàsípààrọ̀ owo Dola O ni fun idi eyi, ẹni to ni owo ti ko dara mọ nile le koo lọ sile ifowopamọsi to ba wuu lati lọ ṣe paṣipaarọ rẹ si owo tuntun.
Eto yii waye ni Scheveningen nitosi Hague.
Sadoku alufaa ati Natani wolii sì ti fi àmì òróró yàn án ní ọba ní odò Gihoni.
Aláìníláárí ẹ̀dá ni àwọn ọmọ Eli mejeeji.
Ileeṣẹ ọlọpaa ti pe ipade lori iṣẹlẹ naa pẹlu ileri pe irufẹ iṣẹlẹ bẹẹ ko ni ṣẹyọ mọ ṣsaju ati lasiko idibo gomina ni ipinlẹ Ondo to n bọ lọna.
“Olúwa mi, gbọ́, ilẹ̀ yìí kò ju irinwo (400) ìwọ̀n ṣekeli fadaka lọ, èyí kò tó nǹkankan láàrin èmi pẹlu rẹ.
" Ikoro fi kun pe gbogbo awọn ọna to ṣe pataki ni ilu naa ni awọn oluwọde naa di ti, wọn ko si jẹ ki awọn to nibi re ri ọna kọja.
Poopu mimọ sọ pe awọn ko ni ṣe amulo ofin yi mọ, paapa julọ fawọn ẹsun to niiṣe pẹlu nini ibalopọ pẹlu ọmọde ki idajọ to dara ba le waye lori rẹ.
Ó rí igi ọ̀pọ̀tọ́ kan tí ó ní ewé lókèèrè, ó bá lọ wò ó bí yóo rí èso lórí rẹ̀.
Bẹ́ẹ̀ púpọ̀ nínú àwọn olùkọ́ náà ni wọn fara gbọta.
Ẹ maa jẹ ko ya yin lẹnu o, nitori pe gomina ipinlẹ Ekiti, Kayọde Fayẹmilo paṣẹ bẹẹ ni ọjọ aje.
Nítorí náà, ẹ fi OLUWA búra fún mi nisinsinyii pé, bí mo ti ṣe yín lóore yìí, bẹ́ẹ̀ ni ẹ̀yin náà yóo ṣe ilé baba mi lóore, kí ẹ sì fún mi ní àmì tí ó dájú.
Fayoṣe ṣalaye ninu atẹjade kan loju opo twitter rẹ pe ko si idi kan fun kọmiṣọna ọlọpaa ni ipinlẹ Ondo lati de igbakeji gomina lọna nitori pe o n ko ẹru rẹ lọ sẹgbẹ oṣelu PDP.
Iheanacho, Edmund Biriomoni, Wole Jimi-Bada aatawọn mẹta miran.
Ọ̀rọ̀ ọgbọ́n níí máa jáde lẹ́nu ẹni rere,a sì máa sọ ọ̀rọ̀ ẹ̀tọ́.
Nítorí náà, ìwọ ọmọ ènìyàn, lẹ́yìn ìgbà tí ìwọ bá jẹun tán, gọngọ máa sọ, múra kí o fún ṣòkòtò rẹ̀ le, nítorí ójú rẹ ń bọ̀ wáá rí nǹkan.
Kìnìhún joko jẹ ẹran ara afurásí ọdẹ tí kò gbààyè kó tó ṣọdẹ Kingston lọmọ Áfíríkà tó gba ohun tí Hulk Hogan kò rí gbà Dangote: Mo ti gbà $10m ri ní bánkì kí n lè mọ bí o tí ṣé rí lójú Nàìjíríà ló wà nípò kẹfà nínú ewu ikú àìtọ́jọ́ l'ágbàáyé nítorí nkan mímú tó ní ṣúgà Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ayekofẹnifọrọ: Ó yá, ẹ fi àmì sórí ọ̀rọ̀ náà.
Loju opo Twitter rẹ lọjọ Aiku, Ezekwwesili fi ikede sita wi pe isin idupe nile ijọsin lohun fẹ fi bẹrẹ ipolongo.
yẹ ki awọn olujọsin maa lo fun.
Ní ọjọ́ kan, Adonija ọmọ Hagiti, lọ sí ọ̀dọ̀ Batiṣeba, ìyá Solomoni.
Ijo mimo ni Jerusalem ti won gba pe ori ibudo ti won ti kan Jesu Kristi sori agbelebu, ti won sin in si bi iboji ko to ji dide kuro nipo oku ni o ti di sisi pada lojo Ru leyin ti Isreal gbese kuro lori ofin ti won fi de e.
” Tabi, “Kí ni OLUWA wí?
Ìtumọ̀ rẹ̀ ni “Pápá Idà”; ó wà ní Gibeoni.
 Ìdí tí mo fi fẹ́ di Gómìnà Kogi - Dino Melaye Kí ló mú ọmọ Nàìjíríà mẹ́sàn án forí la ikú nínú ìkọlù Libya?"
”Asoju orile ede Russia tun so pe, oun ni ireti pe ife ẹyẹ agbaye ti yoo waye lorile ede Russia yoo tun je ki ibasepo to wa laarin orile ede Russia ati awon orile ede miran tun fese mule sii.
1 Èbibi 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 2 Èbibi 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Champions league: Ajurawa ló, Liverpool kó àjọ ìyà lọ́wọ́ọ Barcelona Bí wọn bá ní pé èèyàn jù ní lọ, a kìí béèrè pé kí ló fi s'agba ẹni ní agbabọọlu Barcelona fí ṣé fún Liverpool nínú abala kíni asekagba idije Champions League.
Nítorí ẹnikẹ́ni tí ó bá ń ṣe ohun tí ó wu Ọlọrun, òun ni arakunrin mi, ati arabinrin mi, ati ìyá mi.
"Iru iyalọmọ bẹẹ yoo si maa beere pe "" Ki lo n sẹlẹ si mi, Se agọ ara mi fẹ kọ isẹ iyalọmọ ni?"
Lati odun 2015 ni orile ede Burundi ti wa ni hila-hilo .
Mi o fẹ gba ohun to n ṣẹlẹ gbọ nigba ti iyawo mi sọ fun mi, irọ ni mo pe e tabi mo n la ala ni Ọgbẹni romero sọ.
Sheikh Othman ni akoko ti to fun awọn adari ẹsin Musulumi lati gbe ero atijọ ti sẹgbẹ kan, ki wọn si bẹrẹ si n lo ẹrọ ayelujara fun isin wọn.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ikorodu Bois: Ko si ẹni ti a kò lè sín jẹ!
Ninu esi ayẹwo tuntun naa, ipinlẹ Eko ni apapọ eeyan 113, Kaduna si ni 21.
awon bode bangladesh lowolowo loni je didasile pelu ipinya bengal ati india ni 1947 , nigbati agbegbe na di egbe apailaorun orile-ede tuntun pakistan .
Eyi kò si ṣẹyin bi àwọn ilé iṣẹ́ tó n pèsè òunjẹ kò ṣe lágbára mọ.
Osun Osogbo: Àṣọ ń pe àṣọ ránṣẹ́ lásìkò ọdún
Oríṣun àwòrán, WATER AID/MACILAU Àkọlé àwòrán, Omi adagun Muassi tii se orisun omi kan soso ti awọn ara abule Muassi npọn Oríṣun àwòrán, WATER AID/MACILAU Àkọlé àwòrán, Ori ni awọn omo obirin to npon omi ọhun fi nru omi lọ ọna jinjin Oríṣun àwòrán, WATER AID/MACILAU Àkọlé àwòrán, Omi adagun ti awọn ara abule Muassi npọn Ni asiko ojo, odo Lurio kii see mu mọ nitori idọti ati ẹgbin ti wọn ma nda si inu rẹ Labule M'mele, nise ni ojo ba ile alamo kan je latari ojo to rọ arọọ'rọda lọdun mẹta sẹyin.
 nitorina , eda eniyan ko ni idẹ ninu ẹṣẹ , ṣugbọn o ni ominira lati darapọ mọ Ọlọhun nipasẹ igbagbọ ninu jésù .
Makinde sọ ninu ọrọ ibanikẹdun to fi ranṣẹ si idile oloogbe naa pe ilẹ Ibadan ati ipinlẹ Oyo ti padanu eeyan nla mii.
Ondo police: Ìwádìí ń tẹ̀síwájú lórí ìjínigbé náà
Ẹ jẹ́ kí ó hàn sí gbogbo eniyan pé ẹ ní ẹ̀mí ìfaradà.
Wọn ni igbesẹ to yẹ ki Malami gbe ni pe ko fi iṣọkan han laarin awọn eniyan Naijiria ni lai dẹyẹ si iran kankan Oríṣun àwòrán, @ekitistategov Àkọlé àwòrán, Ọjọ kẹsan an Oṣu Kinni ọdun yii ni awọn gomina ipinlẹ mẹfa lati ilẹ Yoruba ṣe ifilọlẹ ikọ Amọtẹkun nilu Ibadan Ọ̀rọ̀ rírùn ni ìjọba àpapọ̀ ń sọ lórí ìdásílẹ̀ ikọ̀ Amotekun - Itse Sagay Àwọn ọmọ Nàìjíríà kan ti ń fi èròńgbà wọn léde lẹ́yìn tí agbẹjọ́rò Abubakar Malami sọ pé ikọ̀ Amọtẹkun kò bá òfin mu.
Iyaafin Winifred Oyo-Ita so pe igbese ti igbakeji aare ati awon igbimo to n sakoso ajo naa, gbe wa ni ibamu pelu ilana ofin to ro mo awon osise  ijoba lati da awon adari eka  ajo  naa ati awon osise won duro .
Àkọlé àwòrán, Ọpọ eeyan lo ti n reti ibi ti Omisore yoo fi adagba atilẹyin rẹ rọ si ninu atundi ibo Gomina ipinlẹ Osun Alaye to se fun igbesẹ naa ni wi pe ẹgbẹ oselu APC ni erongba rẹ papọ mọ ti ẹgbẹ SDP ti wọn si ti fi da oun loju wi pe awọn yoo tele adehun lati mu awn adisokan won yi sẹ.
Gege bi ile-ise akoroyin Gazzetta,”Mancini bowolu iwe lati se ise oloodun meji, eyi ti yoo mu  wa ninu iko ohun titi di odun 2020, ti yoo si maa gba milionu merin  owo ile okere euro lodoodun.
Nígbà tí ó wí báyìí tán àwọn \moọ aráyé bá inú ayé lọ òun náà sì bá òde ọ̀run lọ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Keyamo: N kò nígbàgbọ́ nínú àwọn tó ń sisẹ́ pẹ̀lú Buhari 14 Òkùdu 2018 Oríṣun àwòrán, @fkeyamo Àkọlé àwòrán, Keyamo ni kìí ṣe ààrẹ ní yóò kó orúkọ àwọn tí yóò ṣiṣẹ́ jọ, àwọn òsìsẹ́ ni Olùdarí féka ètò ìbánísọ̀rọ̀ lábẹ àjọ ìpolongo ìbò fún Muhammadu Buhari, Festus Keyamo ( SAN) sọ pé, ààrẹ Muhammadu Buhari nìkan ní òún le fọwọ́sọ̀yà fún, gẹ́gẹ́ bí olóòtọ́ọ́ nínú gbogbo àwọn tó ń báa ṣiṣẹ́.
Ṣugbọn tí ẹnìkan bá ka nǹkan sí èèwọ̀, èèwọ̀ ni fún irú ẹni bẹ́ẹ̀.
AFCON 2019: A bọ̀wọ̀ fún orílẹ̀èdè wa ju àwọn ikọ̀ míì tí à gba fún
Ṣalumu ọmọ Kolihose, aláṣẹ agbègbè Misipa tún Ẹnubodè Orísun ṣe, ó tún un kọ́, ó bò ó, ó sì ṣe àwọn ìlẹ̀kùn rẹ̀ ati ọ̀pá ìdábùú rẹ̀, ó sì tún mọ odi Adágún Ṣela ti ọgbà ọba títí kan àtẹ̀gùn tí ó wá láti ìlú Dafidi.
ọjọ Abameta ọsẹ yii, bakan naa ni igbimo ohun tun jiroro lori igbese ti won yoo
Ọpọlọpọ eniyan mọ obinrin naa bii ẹni to ma n se bi odi ninu ere tiata.
Àwọn eniyan yóo sì máa dáhùn pé, ‘Nítorí pé wọ́n kọ majẹmu OLUWA Ọlọrun wọn sílẹ̀ ni, wọ́n ń bọ oriṣa, wọ́n sì ń sìn wọ́n.
Oríṣun àwòrán, federal ministry of info&culture Ileeṣẹ ijọba fun awọn ọdọ ati idagbasoke ere idaraya,lo ṣe agbatẹru eto yii, pẹlu ajọṣepọ banki apapọ, to gbe owo silẹ.
"Awọn oṣiṣẹ Banki naa n jade, wọn si maa n pẹ wọle, bẹẹ naa ni iṣ wa ṣe maa n gbe eeyan rinrinajo pupọ.
Nollywood: Femi Adebayo, Damola Olatunji àti Muyiwa Ademola wà lára àwọn òṣèré tíátà Yorùbá tó bí ìbejì
Gabriel Batistuta ni o gba goolu kan ṣoṣo ti Argentina fi gba ogo mọ Super Eagles lọwọ ni ọdun naa nigba ti ifẹsẹwọnsẹ naa wọ iṣẹju kẹtalelọgọta.
Gomina Akeredolu ni wọn kede gẹgẹ bii olubori ibo abẹnu lati mọ ẹni ti yii gbe aṣia ẹgbẹ oṣelu APC ni idibo gomina ipinlẹ Ondo to n bọ lọna ti amofin Oluṣọla Oke si gbe ipo keji.
Nígbà tí ó wí báyìí tán, ó tún dúró ní ilẹ̀ Galili.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ajimọbi: Pé Ayefẹlẹ jẹ́ àkàndá kò fún láṣẹ láti rú òfin Kò sẹ́ni tó tayọ òfin Ṣáájú àkókò yìí, gomina ipinlẹ Ọyọ Abiọla Ajimọbi ti sọ ninu fọnran awọran tó wà loke yii pe oun yoo wa nnkan ṣe si ọrọ ileeṣẹ Fresh Fm, to jẹ ti gbaju-gbaja onkọrin Yinka Ayefẹlẹ, eleyi to ti di orisun awuyewuye bayii lẹyin ti ijọba wo ile naa ni owurọ ọjọ aiku.
Kì í ṣe òkè ọ̀run ni ó wà, tí ẹ óo fi wí pé, ‘Ta ni yóo gun òkè ọ̀run lọ, tí yóo lọ bá wa mú un sọ̀kalẹ̀ wá, kí á lè gbọ́ kí á sì pa á mọ́?
Lai pẹ yi, àwọn Òṣèlú bẹ̀rẹ̀ si polongo pé “ki ará́ ilu ra ọja ilú, ki Naira (owo Nigeria) lè gòkè”.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Issa Aremu: ṣàlàyé kíkún nípa èròńgbà ẹgbẹ́ Labour to bá jáde Ti a ko ba gbagbe, Bukola Saraki fidirẹmi ninu igbiyanju rẹ lati pada si ile igbimọ asofin agba lorilẹ-ede Naijiria ninu idibo gbogboogbo to waye ni Ọjọ Kẹtalelogun, Osu Keji, ọdun 2019.
Oríṣun àwòrán, @Mohammed Jagunma ati Gold Abdulrafiu Abi ẹ o riṣẹ Olorun bi?
Awakọ̀ agbókùú, ọlọ́pàá, ológun, oníròyìn ló máa ń kọ́kọ́ dìbò ní Ghana, bó ṣe ń lọ rèé Ohun tó yẹ kẹ́ẹ mọ nípà olùdíje mèjì tó lágbára nínú ìdìbò Ghana rèé Ẹ dín iye ìgbà tẹ n gorí obìnrin kù torí ìdìbò tó n bọ̀, kẹ́ẹ lè lágbára láti ṣe .
Igbimo awon gomina naa wa kilo fun awon amunubini tabi awon ti o le fa laasigbo sile lati mo pe, ko si ile ni eka gusuu ila oorun orile-ede Naijiria ti won pese fun didaran  bi o ti le wu ko mo.
Oríṣun àwòrán, @creamsnigeria Dejo lo sọ bẹ lasiko to ba BBC Yoruba lalejo ninu ifọwerọ kan to waye laarin ọsẹ yii.
Ẹ̀mí àwa ẹni àmì òróró OLUWA bọ́ sinu kòtò wọn,OLUWA tí à ń sọ nípa rẹ̀ pé,lábẹ́ òjìji rẹ̀ ni a óo máa gbé láàrin àwọn orílẹ̀-èdè.
Yatọ fun itan to wa ni akọsilẹ nipa Ọjọgbọn yii, manigbagbe ni awọn iriri ti awọn aladani ti ni pẹlu rẹ ti wọn ṣi tun n ni tori aaye ọtọ ni Wole Soyinka wa.
Kí ni ò ń ṣe níhìn-ín?
Lorilẹede Mexico, ounjẹ ati papanu ni ẹyin kokoro.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ìkéde Buhari: Ta ni yóò kojú u rẹ̀?
Wo ọ̀nà àbáyọ níbí Ọsẹ́ tí ọkọ̀ aképo tó gbiná lẹ́bàá Otedola Estate l'Eko ṣe rèé Ojúlówó ọmọ Oluyole gan ni Adedibu, ìpasẹ̀ akọni náà ló tọ̀ nígbà ayé rẹ̀ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Pásítọ̀ ló sọ fún mi pé Ọlọ́run pè mí láti di Olokun tó ń bọ omi' Ọ̀nà àbáyọ rèé lórí bi ó ṣe lé yẹ NIN rẹ̀ wò nípa lílo kóòdì USSD lórí ọẹ̀rọ ìléwọ́ rẹ.
Mọ̀ síi nípa ìtàn ojúbọ̀ nàá Kí ni apẹ̀rẹ̀ ikòlẹ̀sí ti Eko fi yàtọ̀ sí ti Ekiti tí ọ́ọ́físà mú wa mọ́lẹ̀?
Diezani Alison-Madueke ni oṣe ni laanu pe awọn oniwa jibiti ni awọn eniyan n gbe larugẹ, ti wọn si n wo gẹgẹ bi awọkọṣe ni Naijiria.
Aṣiri yii tu sita nigba ti awọn ọlọpaa orilẹ-ede Uganda mu Tumushabe nigba ti wọn fura pe o ji ẹrọ amohunmaworan ati aṣọ awọn aladugbo wọn nile ti oun ati ọkọ rẹ n gbe.
Alukoro ọlọpaa ipinlẹ Ogun, Abimbola Oyeyemi lo fi ọrọ yi to awọn akọroyin lati ọjọ Abamẹta.
Ileeṣẹ ọlọpaa kede bẹẹ ninu atẹjade kan to fi ṣọwọ si awọn akọroyin, eyi ti alukoro ileeṣẹ naa ni ipinlẹ Eko, Olumuyiwa Adejobi, buwọlu.
Bí ó ti ń lọ, àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ wá, wọ́n pe akiyesi rẹ̀ sí bí a ti ṣe kọ́ ilé náà.
Tẹmpili náà ní ògiri yíká, òòró rẹ̀ jẹ́ ẹẹdẹgbẹta (500) igbọnwọ (mita 250), ìbú rẹ̀ sì jẹ́ ẹẹdẹgbẹta (500) igbọnwọ (mita 250), èyí ni ó jẹ́ ààlà láàrin ibi mímọ́ ati ibi tí ó jẹ́ ti gbogbo eniyan.
O gba wọn nimọran lati maa fi awọn Naijiria ati ọrọ to ba kan wọn ṣe ọkunkundun ki wọn si da abo bo ẹka iṣofin Naijiria.
Ìwé mìíràn tún wà ní ṣíṣí, tí orúkọ àwọn alààyè wà ninu rẹ̀.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Oba Adedokun Abolarin ti Oke Ila: Ó ya ọ̀pọ̀ tó súnmọ́ mi lẹ́nu bí mo ṣe ń kọ́ Kabiyesi onirẹsi ilu Irẹsini ipinlẹ Ondo, Oba David Olajide ni Oba Alade ti a ba sọrọ ti wọn si tu kẹkẹ ọrọ kalẹ nipa bi awọn Fulani darandaran kan ti ṣe n ṣọṣẹ lagbegbe rẹ.
Iroyin ti o tẹ wa lọwọ sọ wi pe awọn agbesunmọmi Boko Haram kọlu abule Kofa ti o wa ni adojukọ ibudo ifiniwọsi fun awọn ti isẹlẹ ṣi nipo ti Dalori n'ilu Maiduguri loru anọ.
Òfin titun ni mo fi fun yín, pé kí ẹ fẹ́ràn ara yín; gẹ́gẹ́ bí mo ti fẹ́ràn yín ni kí ẹ fẹ́ràn ara yín.
Ninu eto idibo gomina to waye lọjọ kẹsan oṣu Kẹta, oludije ẹgbẹ PDP, Hammadu Fintiri lewaju pẹlu ibo 32,476, lẹyin to ni akojọpọ ibo 367,471.
mẹ́wàá ninu ogún awon agbaboolu omo orile ede Benin ni won ko yege lasiko ero igbalode to n gba aworan silẹ.
Samoa: aṣẹ iwe igbelu fun osu meji Senegal: Ọfẹ ni Seychelles: Iwe aṣẹ fun ọgbọn ọjọ Somalia: Gbigba aṣẹ iwe igbelu Sri Lanka Tanzania: de pelu iwe aṣẹ igbelu Timor - Leste: Iwe aṣe igbelu fun ọgbọn ọjọ Togo: laisi iwe aṣe igbelu Tuvalu: de pelu iwe aṣẹ lẹyin oṣu kan.
Arẹgbẹṣọla: 'Lóòtọ́ ni mo jẹ gbèsè l'Ọṣun ṣùgbọ́n gbèsè ayọ̀ ni'
Muhammadu Buhari: PDP ṣàlàyé àwọn ẹ̀ṣẹ̀ ààrẹ bó ṣe ń ṣàjọyọ̀ ọ̀jọ́ ìbí
Gbogbo nǹkan ni ó mọ́ fún àwọn ẹni mímọ́, ṣugbọn kò sí nǹkankan tí ó mọ́ fún àwọn alaigbagbọ tí èrò wọn ti wọ́, nítorí èrò wọn ati ẹ̀rí ọkàn wọn ti wọ́.
Oríṣun àwòrán, Others Àkọlé àwòrán, Iran Yoruba maa n ba ara wọn ṣajọyọ papọ, wọn gbagbọ pe igi kan ko le da igbo ṣe.
Àjọyọ̀ àjọ̀dún ti wa di ọ̀rọ̀ ìṣèlú.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Mpape Crushed Rock: Àrímáleèlọ, àwòpadàsẹ́yìn ni ẹwà ibùdó yìí 19 Ògún 2020 Oríṣun àwòrán, Fatima Muhammad Wọn ni bi Oluwa ba n se rere, a lo n se ibi ni nitori awamaridi ni isẹ Olodumare.
- Ijebu Mide Martins Oríṣun àwòrán, ?
Ẹ máṣe gbàgbé eyí ẹ̀yín ènìyàn wa.
Ilu Ogbese ni wọn ni Onweniwe ti pa ọmọdebinrin naa ni oṣu keji ọdun 2017.
mu ki won se aseyege ninu isẹ okoowo wọn.
Oríṣun àwòrán, @Austin Moses Àkọlé àwòrán, Asọtẹlẹ nipa ẹni ti yoo jawe olubori ninu ibo jẹ nnkan ti awọn arìran kan tẹnumọ saaju idibo; ṣugbọn ṣe wọn jana?
Àjàfúnẹ̀tọ́ ìkẹ́gbẹ́ Mauro Brito sọ ní tirẹ̀ wípé obìrin gbọ́dọ̀ ní ìgbéraga “nígbàtí [wọ́n] bá jẹ́ aṣojú nínú iṣẹ́ gbogbo”:
Ọdun 1993 ni o gba ami ẹyẹ Agbabọọlu Ilẹ Afrika to lamilaaka julọ.
ile igbimo asoju ni ekun Gusu Maru  labe
 apor olùwà ti a sì pa je ni iwo .
Lasiko ti a n ko iroyin yii jọ, a ko tii mọ ohun to ṣe okunfa iku rẹ.
Helen Paul: Ọmọ atàpáta dìde ni mí, ẹ má fójú ajẹbọ́ wò mí Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí kan sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
Oríṣun àwòrán, EPA Oríṣun àwòrán, EPA Ifẹ̀họ̀núhàn ń lọ lọ́wọ́ ní Belarus lẹ́yìn tí ìdìbò tùn gbé Ààrẹ̀ Lukashenko tó ti wà nípò fún ọdún 26 wọlé Ifẹhọnuhan ti wọ ọjọ keji bayii lorilẹede Belarus lẹyin ti iroyin fihan pe Aarẹ Lukashenko to ti wa ni ipo fun ọdun mẹrindinlọgbọn tun ti wọle idibo aarẹ.
Wọn bi awọn eeyan to ti pe aadọta ọdun pe bawo ni wọn se n ṣe mẹrin ninu nkan marun un yii?
Shehu sọ pe :“Aare Muhammadu Buhari wa gbosuba fun iwa akin  ti igbakeji aare Yemi Osinbajo, ni eyi ti o
Ọyọ ko ju Ifẹ lọ tori ti Ọyọ ba ju Ifẹ lọ ni Ọ̀ramiyan ko ni kúro ni Ọjọ ko tun lọ gba Ade ni Ifẹ, nígbà ti o de bẹ, o mu ẹjẹ Odudua pada.
Atẹjade kan ti ileesẹ Reluwe nilẹ wa fisita loju opo Twitter rẹ lọjọ Ẹti kede pe ọkọ reluwe mẹrindinlogun lo ti de bayii.
Ó rorò sí àwọn tí ó kùnà.
NBC ti iléesẹ́ ìgbóhùnsáfẹ́fẹ́ Èkìtì pa Ilé iṣẹ́ BBC ni Fayẹmi kọ́kọ́ bá sọ̀rọ̀ gẹ́gẹ́ bíi gómìnà tí Ekiti yàn INEC: Èsì ìdìbò Ekiti lẹ́kùnrẹ́rẹ́ Gẹgẹ bi ikede kan ti ijọba ipinlẹ naa fi sita loju opo ayelujara rẹ, ṣiṣi ti ajọ NBC pada ṣi ileeṣẹ igbohunsafẹfẹ ọhun waye lẹyin ti igbimọ ti ijọba gbe kalẹ lati wadii awọn ohun to ṣokunfa bi wọn ṣe ti i pa, ti gomina Fayẹmi naa si da si ọrọ naa.
Oríṣun àwòrán, AFP Àkọlé àwòrán, Dele Alli Ẹ ma gbagbe pe ọdun 1996 ni ikọ Ajax ti de ipele ipari ninu idije Champions Legaue kẹyin , ti ikọ agbábọ́ọ̀lù Tottenham ko ti ẹ tii de'bẹ ri n inu itan wọn .
Bakan naa ni DJ Buckz sa awọn ohun elo ibilẹ si i ninu to fi fakọyọ.
Ẹwẹ, ijọba UK atawọn onimọ ijinlẹ ti ni ko si ootọ ninu ọrọ ti awọn kan sọ kiri pe nẹtiwọọki 5G naa lee ṣokunfa arun Coronavirus.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Dangote, jọ̀ọ́ nawọ́ ìrànwọ́ láti dá iléeṣé sílẹ̀ fún wa ní Ọyọ - Aláàfin rawọ́ ẹ̀bẹ̀ Ọlọkọ tó ṣàfihàn ìhòòhò obìnrin ní Lekki n fí ẹwọn ọdún mẹ́ta runmú- Ìjọba Èkó Ó tó gẹ́ẹ́!
Sanyeri tun sọ pe ọjọ ti inu oun julọ lagbaaye lọjọ ti oun gba fisa ilẹ Amẹrika.
Sọrọ ori rẹdio yii ba kii fi para rara bẹẹ si ni kii ṣẹ ẹnu rẹ ku nipa ọrọ ibalopọ.
ninu ile naa lo ti wọlẹ bayii.
Fulani darandaran: Ẹ ma wa ija Yoruba
Itan fi ye wa pe Alaafin tilu Ọyọ lọwọlọwọ, Ọba Lamidi Ọlayiwọla Adeyẹmi kẹta, naa ba ọba Ademọla lọ silu Osogbo, nitori ọdọ ọba naa lo n gbe lasiko ti isẹlẹ iyọloye naa waye.
Oríṣun àwòrán, Instagram/iamnino Ni akotan ọrọ rẹ o jẹwọ pe ẹẹkan ṣoṣo loun ti de ṣọọṣi ri laye oun.
Ewe, ni eka irin wuwo gbigbe(heavyweight category), Ndidi Nwosu gba ami-eye goolu lati so apapo ami-eye iko Naijiria di mejo, goolu merin ati Silver merin lapapo.
Ẹbi, ara, ọrẹ, alabaṣiṣẹpọ ati awọn aṣoju ijọba ipinlẹ Ọyọ ko gbẹyin ninu awọn ọgọrọ eeyan to korajọpọ sile oloogbe naa.
A si tun nigbagbo lori ipinnu aare lati  mu eto aabo orile ede yii lokunkundun.
Aarẹ Buhari ti ṣe iru ipade bẹ ẹ ri pẹlu awọn gomina l'ọjọ kọkandinlogun, oṣu Kọkanla, lẹyin ti igbimọ ẹlẹni mẹta gbe aabọ iwadi rẹ kalẹ fun Aarẹ Buhari.
Awọn agbaagba ilẹ Yoruba ni Atiku lawọn n ba lọ Bakan naa, awọn agbagbagba ilẹ Yoruba ti kede pe, igbakeji Aarẹ tẹlẹ ri Atiku Abubakar ni awọn yoo satilẹyin fun ninu ibo Aarẹ lọdun 2019, lẹyin ti Aarẹ ana Oluṣẹgun Obasanjọ kede atilẹyin rẹ fun Atiku.
A wá bẹ̀rẹ̀ sí ṣe ìdájọ́ àwọn òkú gẹ́gẹ́ bí iṣẹ́ wọn tí ó wà ninu àwọn ìwé àkọsílẹ̀.
Lọpọ igba gan lo ti wọ agọ ọlọpaa lọ, ti yoo si pa gbogbo awọn ọlọpaa to ba wa nibẹ lọsan gangan, to si buru ju alujannu oloju kan lọ.
Ṣugbọn bawo lo ṣe di gbajugbaja obinrin, to n ṣe iṣẹ iwadii lori ọrọ ibalopọ fun awọn obinrin?
Ọpọ lo n sọ pe inira yoo de ba araalu bi ijọba ba gbe igbesẹ yii lootọ.
Sùgbọ́n kí wá ni àwọn àmìn tí wọ́n lé fi han gàn, tí ẹbi, ará àti ọ̀rẹ́ fi lè ràn wọ́n lọ́wọ́.
Aisha Buhari-Aya ààrẹ, Aisha Buhari ni ààrẹ gan kó mọ nípa ọ̀rọ̀ ìyàwò tuntun
Ẹni tí ó bá ń sọ òtítọ́ a máa jẹ́rìí òdodo,ṣugbọn irọ́ ni ẹlẹ́rìí èké máa ń pa.
Oríṣun àwòrán, PA Àkọlé àwòrán, 5G yoo mu ayipada ba bi a ti ṣe n lo awọn ẹrọ alagbeka wa Amẹrika ti tutọ soke foju gba pe eyikeyi ninu awọn orileede Five-Eye to ba tẹwọgba 5G Huawei,awọn ko ni ba ni ajọṣepo mọ.
Olayiwola salaye pe “A fe ki ijoba san ogbon egberun naira ti ijoba apapo bu owo lu, a
A fẹ́ kí ẹ̀yin ati gbogbo wa ranṣẹ sí ọ̀gá àwọn ọmọ-ogun pé kí ó fi Paulu ranṣẹ sí yín nítorí ẹ fẹ́ wádìí ọ̀rọ̀ rẹ̀ fínnífínní.
paapaa nipasẹ awọn eniyan to ti moju awọn adugbo naa daadaa”Ṣaaju
Yoo dara ki Naijiria se amulo ijọba apapọ tootọ tabi ko pin si yẹlẹyẹlẹ niotir ọrọ lee bẹyin yọ lẹyin ibo ọdun 2023."
Ẹ wá rí i pé, Ișẹ́ tó lápẹpẹ yéye ní í ṣe.
Lọ́gán ó yọ sókè, nítorí kò ní erùpẹ̀ tí ó jinlẹ̀.
naa yoo ni Alaga ti yoo jẹ oṣiṣẹ ijọba ti o ti ni iriri daradara lẹnu iṣẹ
Falz tun fi ara rẹ we Fela nigba aye rẹ, didojukọ ijọba.
"Ajọ FRSC ti fi awọn n mojuto aabo awọn awakọ loju opopona Naijiria ni ki awọn eeyan ṣọra fun awọn nkan wọnyii nipa titẹle ofin yii: - O ko gbọdọ gbe ọkọ rẹ silẹ nibikibi ti wọn ba fi ami: ""No Parking"" si."
Ẹ̀rò àwọn ènìyàn se ọ̀tọ̀ọ̀tọ̀ lórí lẹ́tà Ọbasanjo sí Buhari Ọbasanjọ: Ó yẹ kí Amina Zakari kọ̀wé fipò sílẹ̀ Lẹ́yìn òkò ọ̀rọ̀, Buhari àti Ọbasanjọ fẹ̀rín pàdé ara wọn l‘Abuja Obasanjo gan an ló ń ṣe ìpínyà Nàìjíríà, Buhari ló ń tún ṣe -Iléeṣẹ́ ààrẹ Ileeṣẹ aarẹ orileede Naijiria ti sọko ọrọ pada si aarẹ ana, Olusegun Obasanjo pe ohun gan an lo n gbe igbesẹ lati mu ipinya ba Naijiria.
Ẹsun mẹrinla ọtọọtọ ni wọn fi kan Mompha eyi to da lori jibiti lori ayelujara.
Oríṣun àwòrán, @others Àkọlé àwòrán, Ẹru Iran ko ba odo America rara, akọ okuta ni USA lọjọkọjọ- Trump Aarẹ Trump fi lede loju opo twitter rẹ pe America ṣi n ṣe iwadii bi ọ̀ṣẹ́ náà ṣe pọ̀ tó ni ki wọn to mọ ọna ti awọn maa gba ba Iran sọrọ pada lori ikọlu naa.
Ọmọ igbimọ daba ni tirẹ pe ki wọn ja ewe gbele ẹ fun Ọjọgbọn naa fun igba diẹ.
Láti ojú ọ̀run ni òjò ti ń rọ̀ sí i.
Ọgba ẹwọn to wa ni agbegbe Reservation Road Junction ni Sapele Road, Benin City ni iṣẹlẹ naa ti waye.
'Èèwọ̀' gààrí fún àwọn èèyàn ipínlẹ̀ Ondo Pizza: Èló ni yóò ná ọ láti ra ìpápánu Pizza wá láti London?
láti máa rú ẹbọ sísun sí OLUWA lórí pẹpẹ ẹbọ sísun, ní àràárọ̀ ati ní alaalẹ́, bí wọ́n ti kọ ọ́ sinu ìwé òfin OLUWA, gẹ́gẹ́ bí ó ti pa á láṣẹ fún Israẹli.
àwọn ará Babiloni ati gbogbo àwọn ará Kalidea láti Pekodi, ati Ṣoa ati Koa, pẹlu gbogbo àwọn ará Asiria: àwọn ọdọmọkunrin tí ojú wọn fanimọ́ra, àwọn gomina, ati àwọn ọ̀gágun, tí gbogbo wọn jẹ́ olórí ogun, tí wọ́n sì ń gun ẹṣin.
Àwọn ìjòyè ní Israẹli ati Rehoboamu ọba bá wí pẹlu ìtẹríba pé, “Olódodo ni Ọlọrun.
Nítorí náà, nisinsinyii, mo mú àkọ́so èso ilẹ̀ tí ìwọ OLUWA ti fi fún mi wá.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Èèyàn 5 farapa, ọ̀pọ̀ ọkọ̀ jóná nínú ìjàmbá iná márosẹ̀ Ibadan sí Eko Dúkìá mi ò lé kan o, mo ti dá fọ́ọ̀mù padà bó ṣe wà tẹ́lẹ̀ - Buhari, Osinbajo Boko Haram àti àwọn Fulani daran daran jẹ́ ọgbọ́n áti sọ Nàíjíríà di ìlú mùsùlùmí - Wale Oke 'A sọ fún ọlọ́kadà pé omi kún, omi kún, ṣùgbọ́n ó kọ etí ikún' #Adewura Koda, wọn ni awọn ni iya ati baba to yẹ ki awọn maa fun lowo, amọ ti ebi n pa wọn, nitori airi isẹ se awọn.
Ni ipari, aare Buhari yoo teko leti losi ilu re, Daura nipinle Katsina fun ayeye odun Eid-el-Kabir.
to je olu ilu  Federal Democratic Republic
"Ni ti agba oṣerebinrin, Fausat Balogun ti gbogbo eniyan mọ si Madam Saje sọ fun awọn oniroyin pe ni ni toun o ""mi o fẹ da si ija to wa laarin Toyin!"
Ijọba fikun un pe awọn to ye ninu ina naa ti wa ni ile iwosan miran lati tẹsiwaju iwosan wọn ni ile iyasọtọ miran.
Alaga ile igbinmo naa lori Idajo, eto’moniyan, eto
Lọjọ aje ni ayeye agbekale ẹto ipolongo Atiku Buhari yoo waye.
Ẹ wọnú àpáta lọ, kí ẹ sì farapamọ́ sinu ilẹ̀.
Iya Emir Sulu Gambari ni ọmọ ọmọ Emir ikeeje to jẹ ni ilu Ilorin, ọmọ Emir ikẹjọ, to fi wa jẹ iyawo Emir ikẹsan, oloogbe Alhaji Sulu Karnaini Gambari.
Oríṣun àwòrán, NTA ado-ekiti/city people magazine Ṣaaju iku rẹ, Aliu n ṣiṣẹ lori fiimu maarun, ti ireti wa pe awọn agbaagba oṣere Nollywood yoo kopa ninu rẹ.
Ṣùgbọ́n ó yẹ ki ń fi ẹnu ba ọjọ tí èmi àti ìyàwó mi lọ sí ilé kan ní ìlú náà tí orúkọ rẹ̀ ń jẹ́ Òpìtánparapọ̀.
Bákannáà wọ́n dáamọ̀ pé ó ṣeéṣe kí àwọn àṣìṣe àìtinúwá ti ṣẹlẹ̀ nípasẹ̀ ìgbésẹ̀ ti ṣíṣe ẹ̀dà àwọn ìfihàn náà ati ṣíṣe ìpalẹ̀mọ́ wọn fún títẹ̀jáde.
Ṣugbọn a ju ara wa lọ bi ti ijankadi kọ o, Alex Iwobi lo dayo naa pada lẹyin iṣẹju mẹẹdogun tawọn Lesotho gbayo wọle Naijiria.
"Ojú ń tì mí láti rí àwọn ọmọbìnrin Nàìjíríà tó ń ṣe aṣẹ́wó ní Italy Duro Ladipọ, ìlúmọ̀ọ́ká òṣèré tíátà àti ọmọ àlúfà tí kò gbàgbé àṣà ìbílẹ̀ Gẹgẹ bi wọn ṣe sọ ọ, ana ni PDP ní Ọlọ́pàá ti mú Sẹ́nétọ̀ Ademọla Adeleke sí àhámọ́ latari ọrọ ti ẹgbẹ ṣapejuwe gẹgẹ bii ""aibọwọ fun alakalẹ ofin ile ẹjọ giga""."
Dokita onimọ obinrin wa parọwa si awọn obi lati ko ọmọ nipa ewu to wa ninu ibalopọ pẹlu ọpọlọpo eniyan, eyi to le fa aisan ibalopọ, to le le di oju ile ọmọ ati awọn arun ti ko gbogun miran to le fa iku aitọjọ tabi airọmọbi ni ọjọ iwaju.
Ewe, iko agbaboolu Super Eagles nilo ami kan soso ninu ifigagbaga naa lati pegede fun idije ohun.
Awọn kan ni ẹwọn gbere lo yẹ fun iru ọkunrin bẹẹ, awọn mii sọ pe idajọ iku ni, bẹẹ lọpọ awọn mii ni titẹ lọdaa lo yẹ awọn oniṣẹ ibi ọhun.
"Mo n ki awọn ikọ oludije orilẹede Naijiria ti wọn dide pẹlu asia orilẹede Naijiria nibi idije ere idaraya ori yinyin lagbaye, Winter olympics to n waye lorilẹede South Korea.
Ipinle Ogun ti so odun yii di ilu mooka, eto abo to peye ni a ti pese sile fawon to m bo kaakiri.
FIFA Women World Cup 2019: Orúkọ agbábọ́ọ̀lù Super Falcons 23 tí yóò lọ sí France ti ṣarajọ
“A n sọ eyi lati jẹ ki awọn ẹgbẹ ti wọn fẹhonu han lori ọrọ yii mọ
Oríṣun àwòrán, Facebook/Pastor Enoch Adeboye Alufaa Adeboye ni o da oun loju pe ọpọ eeyan ni yoo kọ orin iyin si Ọlọrun lẹyin ti coronavirus ba di afisẹyin ti eegun fi aṣọ tan.
Nítorí ṣáájú àkókò náà, kò sí owó iṣẹ́ fún eniyan tabi ẹranko, eniyan kò sì lè rin ìrìn àjò láìléwu; nítorí àwọn ọ̀tá tí wọ́n wà káàkiri, nítorí mo mú kí olukuluku lòdì sí ẹnìkejì rẹ̀.
Bẹ́ẹ̀ ni OLUWA ṣe ṣẹgun fún àwọn ọmọ Israẹli ní ọjọ́ náà, wọ́n sì ja ogun náà kọjá Betafeni.
Oṣere taiata si ni oun naa pẹlu.
Ẹwẹ, awọn ẹlẹsin tuntun bii Kiristẹni ati Islam ko fara mọ eyi.
Opolopo awuyewuye ni ikede yii ti n bi lori ayelujara ti awọn eniyan si n fi ero ọtọọtọ han nipa iṣẹlẹ yii.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Obasanjọ sabẹwo ibanikẹdun si Benue Buhari, Obasanjo ṣe'pade nilu Abuja Ni ipade AU Buhari ati Obasanjo d'ọrẹ apapandodo Lara ohun ti Secondus tun gbekalẹ nibi ipade naa ni ti iwe adehun ti awọn ẹgbẹ kan fọwọ si, lati da ẹgbẹ oṣelu Coalition of United Political Party, CUPP, silẹ.
Mo fẹ́ kí ẹ jẹ́ amòye ninu nǹkan rere, ṣugbọn kí ẹ jẹ́ òpè ní ti àwọn nǹkan burúkú.
Wọn óo fi ọ̀rọ̀ dídùn tàn yín nítorí ojúkòkòrò, kí wọ́n lè fi yín ṣe èrè jẹ.
Aarẹ Donald Trump ti fesi si iroyin pe alatako rẹ Joe Biden lo jaweolubori ninu idibo aarẹ ilẹ Amẹrika.
Gbogbo ibi tí igi bá pọ̀ sí a wá dùn ún wò gidi-gaan nítorí àwọn ewé àti èso aláràbarà t'ọ́n nbẹ lórí wọn.
Ajọ ajafẹtọ kan lo mu ọmọbinrin ọdun mẹtadinlogun wa si ileeṣẹ ọlọpaa to wa ni agbegbe Toro, ni ijọba ipinlẹ Bauchi, lẹyin ti wọn fi lede pe o bi ọmọkunrin kan ni ọjọ Kẹrinla, Osu Kẹsan an, ọdun 2020.
Ewe, lara awon ohun elo ohun lati ri: igi igba boolu, bata, akete, boolu, awon ohun idera abbl.
Ṣugbọn ile ẹjọ dajọ are fun un ko jẹbi ẹsun ti wọn kan an lẹyin iwadi ti wọn ṣe.
Wọn ni ki ẹnikẹni to ba yẹ ko wa fun ifọrọwanilẹnuwo lati gba iwe irinna yọjú lasiko to yẹ.
Kí ni a fẹ́ lọ ṣe níbẹ̀?
Àmọ́ àwọn óṣeré yìí kan ń kí àwọn olólùfẹ́ wọn kú oṣù Alapọnle tó wọlé de ni.
Alix Fox: ó sì pọn dandan kí a mo pe bí ìwọ bá ní aarun náà tí ó sì àwọn àmì tí kò nira, má ro pe bẹẹ naa ni yoo ri fún enikeji rẹ, bí ó bá ti rí àpẹẹrẹ, yẹra fún olólùfẹ́ rẹ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Yahaya Bello: Iléẹjọ́ tó ga jùlọ fòǹtẹ̀ lu Yahaya Bello, wọ́n da ẹjọ́ PDP àti SDP nù 31 Ògún 2020 Oríṣun àwòrán, Facebook Iléẹjọ́ tó ga jùlọ fòǹtẹ̀ lu Yahaya Bello gẹ́gẹ́ bí Gómìnà ìpínlẹ̀ Kogi Ileẹjọ to ga julọ ni Naijiria ti fi ontẹ lu eto idibo to gbe Yahaya Bello wọle gẹgẹ bi Gomina ipinlẹ Kogi.
ati tabili, ati gbogbo àwọn ohun èlò tí wọn yóo máa lò pẹlu rẹ̀, ọ̀pá fìtílà tí wọ́n fi ojúlówó wúrà ṣe, ati gbogbo àwọn ohun èlò tí wọn yóo máa lò pẹlu rẹ̀, pẹpẹ turari, 
Wayii o, iroyin fi mule pe aare Buhari yoo koko lo sabewo si awon omo orile-ede Naijriia ti o fi ilu Krakow, orile-ede Poland se ibugbe nirole ojo Aiku(Sunday).
Burundi Oríṣun àwòrán, Twitter Àkọlé àwòrán, Awọn eeyan fi aworan aarẹ Burundi ṣe yẹyẹ lẹyin tawọn akẹkọbinrin kan kun oju rẹ laro Ni Burundi o le lo to ọdun marun un lẹwọn ti o ba ṣẹ nkankan to jọ mọ pe o bẹnu atẹ lu aarẹ.
Ó fi òòlù lu wúrà, ó sì gé e tẹ́ẹ́rẹ́tẹ́ẹ́rẹ́ bí okùn, wọ́n fi ṣe iṣẹ́ ọnà sára aṣọ aláwọ̀ aró ati ti elése àlùkò ati aṣọ pupa ati aṣọ funfun onílà tẹ́ẹ́rẹ́tẹ́ẹ́rẹ́.
Bí ẹ bá ń ṣe rere sí àwọn tí wọn ń ṣe rere si yín, kí ni fáàrí yín?
Oríṣun àwòrán, Lizzy Anjorin Lizzy Anjọrin ree pẹlu awọn afẹnifẹre miran lasiko ayẹyẹ iwuye ọhun.
Koko iroyin: Lai Mohammed fèsì sí ọrọ Obasanjo, Ìjọ́ba ìpínlẹ̀ Ògùn kéde ìsinmi ní June 12
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Damilọla pàdánù ọ̀rẹ́kùnrin rẹ̀ nítorí ilà kíkọ Awọn kan ko ri ohun to buru ninu ila kikọ Ni ero ti @iamtito lori Instagram BBC Yoruba, 'a ko gbọdọ titori pe awọn to kọla n dojukọ idẹyẹsi, ka pa aṣa wa run.
A-ji-jagbara kan  fun ajo isokan agbaye to n gbe  Paris lo ti soro sinu ero ayelujara re pe won ti so a-ji-jagbara omo orile ede Burundi, Germain Rukuki si ewon odun mejilelogbon.
Koda awọn ololufẹ Naira Marley kan tilẹ kọlu Ruggedman ni ilu Gẹẹsi lori ọrọ yii gẹgẹ bi iroyin ṣe sọ.
Bí ó tilẹ̀ rí bẹ́ẹ̀, ìgbìdánwò àkọ́kọ́ yìí láti tẹ̀ àwọn ìfihàn náà parí, nígbàtí àwọn jàndùkú èrò kan ba ilé iṣẹ́ ìtẹ̀wé ti Àwọn Ènìyàn Mímọ́ jẹ́ ní Jackson County ní 20 Oṣù Keje, 1833.
“Ṣugbọn bí eniyan burúkú bá yipada kúrò ninu gbogbo ẹ̀ṣẹ̀ tí ó ń dá, tí ó ń pa òfin mi mọ́, tí ó ń ṣe ohun tí ó tọ́, tí ó sì bá òfin mu, dájúdájú yóo yè ni, kò ní kú.
Kí ni ó kàn wọ́n pẹlu ilé wọn mọ́, lẹ́yìn tí wọn bá ti kú,nígbà tí a bá ti ké ọjọ́ wọn kúrò lórí ilẹ̀.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, libya Níbo ni ọrọ coronavirus de duro bayii ni Naijiria?
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Kollington ṣàlàyé bí orin Fuji ṣe bẹ̀rẹ̀ gan an ní Nàiìjíríà Eyi ko ṣẹyin nitori pe ọpọlọ ko ri ibi sinmi bo ti ṣe yẹ.
Mo dẹ tàkúté sílẹ̀ fun yín, ẹ̀yin ará Babiloni:Tàkúté náà mu yín, ẹ kò sì mọ̀.
8bn owó àìtọ́ lọ́wọ́ mi ní tipá - Ẹlẹ́rìí Ọ̀pọ̀ ohun tó gbé mi kúrò nínú ẹgbẹ́ PDP rèé - Dogara ṣàlàyé Lizzy Anjọnrin fẹ̀si fáwọn agbọ́yì-sọ̀yí lórí ìgbéyàwó rẹ̀, Madam Sajẹ dasójú ilé iṣẹ́, àti àwọn ǹkan míràn tó ṣẹlẹ̀ lágbo tíátà lọ́sẹ̀ yìí Gẹ́gẹ́ bi ẹni kan ti ọ̀rọ̀ náà kàn ṣe sọ yíyí ibi ti wọ́n yóò ti ṣe ìgbéyàwó pada ní kí wọ́n sọ ìbi tó bá wù wọ̀n lọ́kan, àwọn òṣìsẹ́ kóòtù yóò lọ síbẹ̀ láti ṣe ètò náà.
Abubakar sọ eyi lasiko to n se ipolongo ni ipinlẹ Yola.
Ṣugbọn kii ṣe Shoprite ni akọkọ ile iṣẹ lati ilẹ okeere ti yoo kogbawọle ni Naijiria, ọpọ ileeṣẹ lo ti wa to si ti lọ ṣaaju rẹ, lara wọn ree: Woolworths Holdings Ltd Ileeṣẹ naa to n ta ounjẹ ati aṣọ loju pali ṣi ṣọọbu rẹ ni Naijiria lọdun 2011 ṣugbọn lẹyin ọdun kan atabọ lọ lo kogbawọle, to si tilẹkun ṣọọbu rẹ mẹtẹta to wa lorile¬ede yii.
Àkọlé àwòrán, Bi wọn se kọ orukọ ẹya ara ni ede Yoruba fun eniyan naa ni wọn kọ fun awọn ẹranko, a jẹ pe ise eniyan nise ẹranko Àkọlé àwòrán, Bi inu eniiyan se ni itumọ orukọ lede Yoruba naa ni ita ni Àkọlé àwòrán, Igbagbọ wọn ni wi pe ko tọ ki a maa fi ede gẹẹsi kọ ogidi ọmọ Yoruba ni eto ẹkọ, paapaa julọ awọn to n kẹkọ lẹka imọ iṣegun oyinbo Àkọlé àwòrán, Ise eniyan nise ẹranko, ẹya ara ẹranko naa tun ni orukọ Àkọlé àwòrán, Awọn ọjọgbọn marun un ọtọọtọ ni fasiti ilẹ Ibadan lo ṣe akojọpọ iwe atumọ ede naa ki ede Yoruba le tẹsiwaju Àkọlé àwòrán, O to ọjọ mẹta ti wọn ti n gbero akanṣe iṣẹ naa ki o to di ohun ti wọn n ko jade bi ọmọ tuntun.
bacterial vaginosis ( bv ) jẹ ́ àrùn òbò tí ó maa ń wáyé tí ìdàgbàsókè kòkòrò àìlèfojúrí afàìsàn tí à ń pè ní bacteria bá ti pọ ̀ jù ní ojú ara obìnrin .
Ọjọ́ dé ọjọ́ ń sọ ọ́ ní àsọgbàòru dé òru sì ń fi ìmọ̀ rẹ̀ hàn.
Kò sí níhìn-ín, nítorí ó ti jí dìde, gẹ́gẹ́ bí ó ti sọ.
Ńkan akọkọ to ṣe kókó ni pé kò tílẹ̀ si ilé kankan tàbi pé wọ́n ti kóle si orí rẹ̀ rí wọ́n kan n pe ni mọsálási gbogboogbo ti ó wà ni Trans-Amadi ti wọ́n si ti n fa ọ̀rọ̀ náà láti bi ọjọ́ mẹ́ta.
Ẹlẹ́wọ̀n Kirikiri tó ń wọ́ke, olùdarí ọgbà ẹ̀wọ̀n ló ṣe onígbọ̀wọ́ fun - EFCC O ni ijọba ipinlẹ pinnu lati san ju owo oṣu ti apapọ gan an n san fawọn oṣiṣẹ rẹ nitori igbayegbadun awọn oṣiṣẹ lo jẹ ijọba ipinlẹ Eko logun.
Oníbàjẹ́ ènìyàn ni Àgùntàn-ìnàkí, ó jẹ́ ọ̀kan nínú àwọn wọn-ọnnì tí wọn kì í mọ ìgbà tí ènìyàn bá ń fi wọ́n ṣiré; bí wọ́n wọ ẹ̀wù bùbá báyìí tí o bá ń pọ́n wọn tí o wí pé dànádóógó sányán ni wọ́n wọ̀ inú wọn a máa dùn sí ọ, bí wọ́n wọ aṣọ tí kòbá wọn mu tí o wí pé aṣọ tiwọn dára ju ti ọba lọ inú wọn a máa dùn sí ọ, bí wọ́n bá sọ̀rọ̀ láàrin ìpàdé wọn a máa ṣe ìbéèrè lemọ́lemọ́ pé, ‘Ǹjẹ́ o kò rí i pé ọ̀rọ̀ tèmi ló dára ju ti àwọn ìyókù lọ?
- Mike Bamiloye Ọkùnrin kan da ṣọ́ọ̀ṣì rú lásìkò ìgbéyàwó, Ó ní òun lọkọ àárọ̀ ìyàwó tuntun Akọroyin wa to fidi ọrọ yi mulẹ sọ pe niṣe ni gbogbo ilu Ikare n kẹdun Ọba wọn ti ilu si pa lọọlọ.
Ni ọdun 1949 ni wọn bi Ọmọwe Kurawa si kawe titi to fi gboye imọ ijinlẹ ninu imọ iṣe ati ironu ẹda, iyẹn Sociology ati Psychology Oríṣun àwòrán, kurawa family Igba meji ọtọọtọ lo ti di ipo igbakeji giwa fasiti Bayero mu lẹyin to bẹrẹ iṣẹ ni fasiti naa lọdun 1978.
Fayẹmi sèbúra l‘Ekiti, àwọn èèkàn ìlú péjú INEC: Èsì ìdìbò Ekiti lẹ́kùnrẹ́rẹ́ Agbébọn pa ènìyàn 14, ọmọọ̀gun Naijiria sígun ni Kaduna Kíni yóò sẹlẹ̀ sí àwọn òsìsẹ́ Diamond Bank?
Ṣàngó je okan lara awon orisa ti awon yorùbá n bọ ̀ wọ ́ a ni àjànàkú kọjá a morí nǹkan fìrí , bí a bá rí erin , káwípe a rí erin ní òrọ ̀ Ṣàngó jẹ ́ láàárin àwon òrìsà ileẹ yorùbá .
Ṣugbọn wọ́n ṣá a lọ́gbẹ́ nítorí àìdára wa, wọ́n pa á lára nítorí ẹ̀ṣẹ̀ wa;ìyà tí wọ́n fi jẹ ẹ́ ni ó fún wa ní alaafia,nínà tí a nà án ni ó mú wa lára dá.
Níwọ̀n ìgbà tí mo jẹ́ Aposteli láàrin yín, mò ń ṣe àpọ́nlé iṣẹ́ mi, 
“Fernandes fi kun oro re pe, ajo IOM yoo seranwo ati je ki won bere okowo kekeke, latari ati maa je ki won sora won di arinrinajo lona aibofin-mu mo”.
Mr Latin tun woye ninu ọrọ rẹ pe, ni wọn igba ti ijọba ti paṣẹ pe ẹnikẹni ko gbọdọ rin irin ajo lati ipinlẹ kan si omiran yika Naijiria, bawo wa ni yoo ṣe rọrun fun awọn oṣere ori tiata lati rinrin ajo lati ipinlẹ kan si omiran lọ kopa ninu yiya sinima?
Gbogbo ayé wà ní ìsinmi ati alaafiawọ́n bẹ̀rẹ̀ sí kọ orin ayọ̀.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Catholic Church: A kò ní bó àṣírí àlùfáà tó bá bá ọmọdé lòpọ̀ mọ́ 17 Ọ̀pẹ̀̀ 2019 Oríṣun àwòrán, Reuters Poopu Francis ti wọgile dida aṣọ aṣiri bo alufaa ti wọn ba fi ẹsun ibalopọ kotọọ kan ninu ijọ Aguda.
    Ẹni kẹẹ̀sán ni ọkùnrin kan báyìí tí orúkọ rẹ̀ ń jẹ́ Ìrèké tí ó sọ ijó jíjó di iṣẹ́ ńlá tí ó sọ orin kíkọ di òwò pàtàkì tí o sì fi fèrè rẹ̀ sí ipò ọmọ.
Ki wa lawọn ẹkọ ta le ri dimu ninu ere agbelewo ti gbogbo ọmọ Naijiria n reti ibi ti yoo kangun si yi?
Osu Kefa, ọdun 2019 ni Naijiria bẹrẹ si ni lo iwe irinna to n lo ẹrọ ayelujara, eleyii ti yoo faye gba awọn eniyan lati lo iwe irinna wọn fun ọdun mẹwa, o si tun le woye ibi ti eniyan wa ni igba de igba.
Esi naa ree: Eddy Olafeso - 175Ajayi Agboola - 657Banji Okunomo - 90Ayorinde Olabode - 95Boluwaji Kunlere - 33Ebiseni Olusola - 29Erewa Godday - 14Eyitayo Jegede - 888 Lẹyin ti wọn kede esi idibo yii ni wọn fa Eyitayọ Jegẹde kalẹ lorukọ ẹgbẹ oṣelu PDP pe ko dide giri bi ọmọkunrin lati koju Arakunrin APC ati awọn aṣoju ẹgbẹ to ku ti wọn jọ maa dije idibo to m bọ naa.
World environment day: MOSOP ní Ààrẹ Buhari kò sòótọ́ lórí àfọ̀mọ́ Ogoni
Njẹ́ ìwọ kọ́le gíga sókè réré?
Ati pe ajọ naa ti gba lati ṣe ipade pẹlu awọn aṣoju orilẹ-ede mẹrin miran ni Afrika ti wọn ti n ṣe idanwo WAEC lati mu ọjọ mii fun idanwo ọhun.
Ó ti fi ojú àánú wò mí, ó sì ti mú ohun tí ó jẹ́ ẹ̀gàn fún mi lójú eniyan kúrò.
idibo pari ni awon agbegbe naa.
 “Eto itaniji gbogbogbo kan wa bayii pe, ojo iwaju ajo isokan ile Euro ni ojo iwaju ile Africa”.
Ó dá wọn lóhùn pé, “Mo ti sọ fun yín lẹ́ẹ̀kan ná, ṣugbọn ẹ kò fẹ́ gbọ́.
Kò sáyè iwọ́de mọ́ l'Eko ẹ lọ tọwọ́ yín bọṣọ - Ọlọ́pàá Ìwọ́de #EndSARS rán èèyàn méjì sọ́run n‘Ibadan, Seyi Makinde da ikọ̀ Operation Burst sígboro Tẹ́ bá fẹ́ lo ìwọ́de láti gba àkóso ìjọba, wọn yóò dá yín lẹ́kun - Tinubu Wo àwọn Ṣọ́ọ̀ṣì Nàìjíríà àti l'Áfíríkà tó ń wólẹ̀ àdúrà kí Trump lè wọlé ìbò ààrẹ America Wahala bẹ silẹ nigba tawọn oluwọde naa bẹrẹ si ni gbọ iro ibọn ni kikankikan ti ọrọ naa si di boo lọ o yago.
Ní oṣù kinni, àwọn ọmọ Israẹli dé aṣálẹ̀ Sini, wọ́n sì ṣe ibùdó wọn sí Kadeṣi.
Ggẹ bi iroyin iwadii ti wọn ṣe ṣe sọ ọ ati ọrọ lẹnu awọn eeyan oṣojumikoro, ohun to fa sababii iṣẹlẹ aburu yii ni afẹfẹ gaasi to rọra n yọọ fiiin jo jade lataraagolo nla gaasi to si fa iku olukọṣ to n lo o lati fi jo irin mọ irin.
Àgbo Covid-19 Madagascar kò ṣiṣẹ́, àwọn ènìyàn tí bẹ̀rẹ̀ sí ní kú níbẹ̀ A ti ń sin òkú méjì sínú ibójì kan náà nítorí ọ̀wọ́ngógó ibojì ìsìnkú"" Wo díẹ̀ nípa ohun tí Walter Carrington gbé ṣe nígbà ayé rẹ̀ Ẹgbẹgbẹ̀rún ọmọ Nàìjíríà ní yóò má a kú lójoojúmọ́ tí wọn bá gbà wọ́n láàyè láti gbébọn dání- Amofin Oludari awọn agbẹjọro to ṣoju ijọba, Labaran Magaji, sọ pe àṣeyọrí nla ni idajọ naa jẹ, nitori pe oun ni idajọ akọkọ to waye nipa ofin ọdun 2019 to de ole jija ati ijinigbe lori omi."
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Lautech: Ìjọba Ọ̀ṣun ní òun kò jẹ òṣìṣẹ́ fásitì náà lówó oṣù 7 Owewe 2019 Oríṣun àwòrán, @Awesome206 Ijọba ipinlẹ Ọsun ti fariga, to si tako ẹsun ti gomina ipinlẹ Ọyọ, Onimọ ẹrọ Seyi Makinde fi kan ijọba ipinlẹ naa pe o tun ti kuna lati san owo osu awọn osisẹ fasiti imọ ẹrọ Ladoke Akintọla, LAUTECH.
antonio gramsci ( ) ( january 22 , 1891 - april 27 , 1937 ) je was an amoye ara itali , olukowe , oloselu ati oniro oloselu .
Àwọ̀tẹ́lẹ̀ yìí kò ní ojúùrán, híhun ni wọ́n hun ún láti òkè dé ilẹ̀.
Ajọ NYSC ni, awọn eeyan naa lo gbe ayederu iwe ẹri kalẹ ni ibi iforukọsilẹ lati wọle si ibi ipagọ awọn agunbanirọ ọhun.
Bákan náà ni ni olùrànlọ́wọ́ pàtàkì fún Deji Akure olóyè Taiwo Fagite náà wà lára àwọn to wá jẹ́rìí nilé ẹjọ́ lónìí.
UEFA wọgile le ere bọọlu lẹyin iyatọ gbogbo awọn agbabọọlu Real Madrid fun ayẹwo ki wọn le mọ bo ya wọn ti lugbadi aarun coronavirus.
OLUWA Bá Israẹli Wí nítorí Ìwà Ìbọ̀rìṣà.
Ṣugbọn Jehoramu ni ó fi ìjọba lé lọ́wọ́, nítorí pé òun ni àkọ́bí rẹ̀.
Messi to jẹ balogun ikọ orilẹede Argentina ati Barcelona n gba ami ẹyẹ naa fun igba kẹfa.
Kí oore-ọ̀fẹ́ kí ó wà pẹlu yín.
Owo to wa lọwọ Biden mu ki ipolongo rẹ de ọdọ awọn oludibo daadaa, paapaa nitori pe coronavirus mu ki bi awọn eeyan ṣe n wo amohunmaworan ninu ile wọn o pọ si i.
Ìhìn náà kò dùn ní ẹnu mi, wò mí, ọ̀rẹ́ mi ìbá ṣe pé ìwọ gbọ́ ọ láti ẹnu bàbá mi ni, ẹnu ìbá yà ọ́ gidigidi – nítorí wọ́n fi ẹsẹ̀ hú gbòǹgbò, wọ́n tẹ igi dá, wọ́n fa ew’wko tu, gìrìgìrì ẹsẹ̀ wọn sì dàbí ìlú ìbẹ̀ǹbẹ́, ara wọ́n tutù bí ara ẹni tí òjò ń pa; ṣùgbọ́n nígbà tí ó pẹ́ wọ́n tú ọwọ́, wọ́n jókòó, wọ́n ń simi.
Ninu ọrọ ikini ku ọdun ajinde to fi ṣọwọ sawọn ọmọ orilẹ-ede Naijiria, paapaajulọ awọn ọmọlẹyin Kirisiti lọrọ naa ti jade.
Aare wa pe fun ara oloogbe naa pe ki won gbe oku re wo orile-ede Naijiria la i fi oro naa faale rara.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Láì lọ́wọ́ ẹ̀yin aráàlú nínú, yóò nira fún Boko Haram láti ṣọṣẹ́ - Buhari sọ fáwọn èèyàn Borno Sunday Igboho gba àwọn èèyàn Soka n‘Ibadan sílẹ̀ lọ́wọ́ àwọn ọmọ onílẹ̀ tó wá ṣọṣẹ́ Àgbà olórin, Victor Olaiya jáde láyé.
Nigba to n fidi otitọ ọrọ yii mulẹ fun BBC Yoruba, Agbẹnusọ fun Ọọni, Moses Olafare sọ pe irọ nla ni ahesọ ọrọ naa.
Ọ̀tọ̀ọ̀tọ̀ lèrò àwọn èèyàn lórí ìyanṣẹ́lódì SSANU Àwọn àwòrán mánigbàgbé nípa Ààrẹ Muhammadu Buhari Èrò àwọn ọmọ Nàìjíríà ṣọ̀tọ̀ọ̀tọ̀ lórí ọ̀rọ̀ Obi àti Ọṣinbajo Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Tayọ̀tayọ̀ ni mó fẹ́ ṣiṣẹ́ pẹ̀lú INEC ki ìdìbò 2019 lé dára' Ko ti daju boya awọn alaṣẹ yoo wa wọrọkọ fi ṣada lori ọrọ to wa nile yi ṣugbọn bi nnkan ti ṣe n lọ yi,o le ṣe akoba fun iṣakoso eto gbogbo nile asofin paapa julọ aba isuna ti Aarẹ Buhari fẹ gbe wa si iwaju ile asofin lọjọru.
"Nkan ti a fi ma n ki ara wa ni pe "" Elére ọmọ!"
Oríṣun àwòrán, Getty Images Ọjọgbọn Adeniji tun sọ pe o lewu ti iya ba bẹrẹ si ni jẹ ounjẹ aṣaraloore lẹyin to ti loyun, nitori pe laarin oṣu mẹta akọkọ ni oyun ina ti ma n ni gbogbo nkan to yẹ.
Akintola nní àwọn olùkọ náà nílò ìwúrí to tọ, o fíkun pé ààyè ti ìjọba fí àwọn olùkọ síí kò mú ìwúri dáǹí láti ori owo osù òṣìṣẹ́ títí tó fi mọ ọ̀nà ti wọn ń gbà láti ṣiṣẹ́.
Ààrẹ Buhari pàsẹ kí wọ́n ṣí àwọn ibodè Nàìjíríà padà kíákíá!
Olufunke Oshonaike: Ewu ń bẹ fún àwọn obìnrin tó ń fẹ́ ọkọ ọlọ́kọ
"Diẹ lara awọn ọmọbinrin ti ikọ̀ amuṣẹya naa mu lo fi ẹsun kan wọn pe ""wọn fi ipa ba diẹ lara wọn lopọ."
jẹ́ kí iyawo mi máa se oúnjẹ fún ẹlòmíràn,kí ẹlòmíràn sì máa bá a lòpọ̀.
 eros wà níwájú ẹ ̀ pẹ ̀ lú ajá ọdẹ kan .
 Bakan naa, ni ẹkun Koṣọfẹ keji, Aṣofin Tunde Braimoh
Wọn ko ti darukọ agbebọn naa.
( d ) bẹmbẹ : ojú méjì ni bẹ ̀ mbẹ ́ ní .
Àwọn wọ̀nyí kìí ṣábàá ga lọ títí.
Oríṣun àwòrán, WHO Àkọlé àwòrán, Ajọ ilera agbaye ni Naijiria wa lara orilẹede ti atẹgun oró ti n pa awọn eniyan ju.
Ẹ̀mí ológun kan bọ́, ọ̀pọ̀ arìnrìn àjò bọ́ sọ́wọ́ ajínigbé Baba Samuel jẹ oniyawo mẹrin, o si bi ọmọ mẹtadinlogun.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Tí kìí bá ṣe ti Barrister, iṣẹ́ ‘Gateman’ ni ń bá máa ṣe - Ayinla Kollington Buhari gbà wá, àwọn àjèjì ti gbàkóso ilẹ̀ Yorùbá - Ọọ̀ni figbeta Afọnja, ẹni tó finú wénú ní Ilọrin, àmọ́ tó jẹ iwọ Òpin ọ̀ṣẹ̀ dé, ẹ jẹ́ ká jọ fi àwòrán aláyọ̀ ṣararindin Sugbọn iwadi BBC ti fihan pe, ọrọ naa ti di ẹkọ ẹlẹkọ ni ẹgba ẹlẹgba bayii nitori awọn ipinlẹ kan ti n fi ifẹ han lati se agbekalẹ abule Ruga ni ipinlẹ wọn.
‘Buhari ti wọnu ẹmi lọ’ Buhari ṣ'eleri iṣẹ f'awọn ọdọ ‘Buhari kò bú àwọn ọdọ’ Buhari yóò mú gbogbo ìlérí rẹ̀ ṣẹ Oríṣun àwòrán, @others Àkọlé àwòrán, Obinrin ti setan lati ba Aare Buhari sise ni saa yii.
Àwọn olólùfẹ́ Arsenal ní kí Emery kọ̀wé fipò sílẹ̀ Manchester City pàdí ọrẹ dà f'ogun ẹ̀yìn ja Chelsea Ilé aṣòfin Amẹrika gbọnmú lórí ìtìmọ́lé Sowore, ó ní ìjọba Nàíjíríà tako òmìnira aráàlú Ìgbà ọ̀tun dé!
Ẹ wí pé, ‘Ẹ gbáradì kí ẹ sì múra sílẹ̀,nítorí ogun yóo run yín yíká.
Ìjọba Nàìjíríà ti ránsẹ pé àsoju ijọba ni South Africa láti dari wálé Ọlọ́pàá fi afẹ́fẹ́ tajú-tajú àti omi tú àwọn tó fẹ́ ṣun ilé ìtajà ShopRite l‘Abuja ká Èèmọ̀ rèé o!
Ọpọ eeyan lo ti n pin aworan ati fọnran ọkunrin yii lori ayelujara, koda aṣofin kan lorilẹede South Africa, Julius Malema sọ pe, alufa ijọ kan lorilẹede ọhun gbalejo Jesu yii, lati wa ṣe iwaasu ninu ijọ rẹ.
 Lara awon oludije fun ipo aare ni  Social Democratic Party, SDP  Donald Duke, Oby Ezekwesili, Allied Congress
Ọ̀gá ọlọ́pàá Adamu Pàṣẹ́ iṣẹ́ àkànṣe nílẹ̀ Yorùbá EFCC ń wádìí iléeṣẹ́ 'Bola Tinubu,' Alpha Beta Consulting Ltd' Amọ, adari ẹgbẹ oselu APC lorilẹ-ede Naijiria, Asiwaju Bola Ahmed Tinubu ti ni awọn Fulani darandaran nikan kọ lo n jinigbe tabi paniyan, amọ awọn ẹya miran naa n se ibi pẹlu.
Bakan naa lo tun rọ awọn ọmọlẹyin Kristi lati joko sile wọn lọjọ Aiku ki wọn si jina si ile ijọsin wọn gbogbo.
Àwọn wolii tí wọ́n ṣe ìkéde oore-ọ̀fẹ́ tún fẹ̀sọ̀ wádìí nípa ìgbàlà yìí.
Andre Ayew: Baba mi loni ki n pada si Swansea City
Ile ẹjọ naa ni ki wọn yẹgi fun Adewale titi ti ẹmi yoo fi bọ lara rẹ lẹyin ti wọn ni o jẹbi ṣiṣekupa ọga rẹ, Alhaja Sikirat Ekun.
Nígbà tí Saulu gbọ́ pé Dafidi ti kúrò ní Keila, kò lọ gbógun ti Keila mọ́.
Iṣẹ́ Oníbúrẹ́dì ní mo kọ́, ìfẹ́ àṣà Yorùbá ló sún mi dé ìdí ẹ̀ṣà pípé tí mo fi là- Ajobiewe Ẹfunsetan Aniwura, ọmọ Ẹ̀gbá tó di akíkanjú obìnrin nílẹ̀ Ibadan Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí End SARS, End SWAT: MC Oluomo ní òun kọ́ ló rán àwọn jàǹdùkú sáwọn olùwọ́de l'Eko15 Ọ̀wàrà 2020 10:43 Fídíò, Wole Soyinka sọ ìdí tó fi ni òun a fi màálù Fulani ṣe súyà fáwọn èèyàn abúlé, Duration 10,4323 Owewe 2020 Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí 2 sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
 Ọmọ ilẹ ̀ Àmẹ ́ ríkà ni ṣùgbọ ́ n jámànì ni àwọn òbí rẹ ̀ ti wá .
Oríṣun àwòrán, Getty Images Ajọ ilera ni agbaye, WHO ni orilẹ-ede Naijiria ko i tii lugbadi aisan polio lati ọdun mẹta sẹyin.
Lẹ́yìn náà, Mose fa àgbò ẹbọ sísun kalẹ̀, Aaroni ati àwọn ọmọ rẹ̀ ọkunrin sì gbé ọwọ́ wọn lé e lórí.
Ipade ajọ banki agabye Ipade ajọ banki agabye ọlọdọdun to yẹ ko waye ni Washington ni wọn ti ṣatunto rẹ bayii.
Ọ̀nà kan wà níwájú àwọn yàrá tí ó lọ sinu, ó fẹ̀ ní igbọnwọ mẹ́wàá (mita 5), ó sì gùn ní ọgọrun-un (100) igbọnwọ (mita 50), àwọn ìlẹ̀kùn rẹ̀ wà ní ìhà àríwá.
Ní ọjọ́ keji ni Netaneli ọmọ Suari olórí ẹ̀yà Isakari mú ọrẹ tirẹ̀ wá.
ún to waye ni New York lojo
Bí i ti àwọn tẹ̀gbọ́n-tàbúrò, Diallo Oumar Demba àti àbúròo rẹ̀ Diallo Ibrahima tí a yẹgi fún pẹ̀lú àkọsílẹ̀ nọ́ḿbà tí ó tẹ̀lé ara wọn tí a fi gègé kọ sí wọn lára.
Saudi fẹ́ gbẹ̀mí 23 ọmọ Nàìjíríà tó gbé òògùn olóró Makinde, jọ̀ọ́ kéde Aug 20 ọdọọdún bíi ọjọ́ ìsinmi fún ìṣẹ̀ṣe - Àwọn oníṣẹ̀ṣe Ọyọ Àwọn alálẹ̀ kò ní forí jìn mí tí ń kò bá ṣe ọdún Ṣàngó - Alaafin Èmi àti Bọla Tinubu fẹ́ lo ‘German Mercenaries’ láti gbé MKO Abiọla kúrò lẹ́wọ̀n - Dele Momodu Ìdẹ̀ra dé, Gẹnẹrátọ̀ tó ń lo omi dé Èdè Akurẹ àti Ibadan ni wọ́n fi fà mí léti pé ẹni re kìí 'se òṣèlú - Seyi Makinde , a bọ́ lọ́wọ́ òkùnkùn O fikun ọrọ re wi pe ''ọjọ mẹẹdogun-mẹẹdogun ni a maa n ṣe ipade pelu Olubadan.
Aisha ló s]ọ èyí di mímọ.
O ni ẹgbẹ CAN sọ pe oun ko lọwọ si abẹwo ọhun ati fidio rẹ to gba ori ayelujara.
Lush Beauties: Ẹ má jẹ́ k‘ójú tì yín torí pé ẹ sanra, ẹ jáde síta
OLUWA kò bìkítà fún pẹpẹ rẹ̀ mọ́,ó sì ti kọ ibi mímọ́ rẹ̀ sílẹ̀.
Ibugbamu ibudo epo ni Ijegun Ìbúgbàmù nínú ọkọ̀ f'ẹ̀mí èèyàn 76 ṣ'òfò ní Mogadishu Afẹ́fẹ́ Gáàsì tó ń yọ́ọ́ jò pa Ajibola lẹ́nu iṣẹ́ jórin-jórin Aaarẹ Michel Aoun sọ pe nkan bi ẹgbẹrun mẹta tọọnu ammonium nitrate ti o ti wa ni ile iko nkan pamọ si yi fun bi odun mẹfa lawọn funra si pe o ṣokunfa ibugbamu naa.
Ariwo wíwó odi Edomu wọn yóo mi ilẹ̀ tìtì, a óo sì gbọ́ ìró rẹ̀ títí dé etí òkun pupa.
” Ó wá jáde lọ sí apá ẹnu ọ̀nà agbo-ilé.
Àwọn tí ó bọ́ sórí òkúta ni àwọn tí ó gbọ́, tí wọ́n fi tayọ̀tayọ̀ gba ọ̀rọ̀ náà, ṣugbọn wọn kò ní gbòǹgbò.
O salaye pe, “ajo UNICEF tun fowosowopo pelu awon ajafeto omoniyan, lati ri daju pe, awon omo kookan gba itoju to peye”.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Buhari: Naijiria ko kabamọ lilewaju fun ijijagbara South Africa 2 Èrèlè 2018 Oríṣun àwòrán, @GarShehu Àkọlé àwòrán, Ọpọlọpọ inawo ati inara ni Naijiria na si ijijagbara orilẹede SouthAfrica Aarẹ orilẹede Naijiria, Muhammadu Buhari ti sọ wipe, nkan diẹ kọ ni orilẹede Naijiria padanu lasiko to fi n lewaju ijijagbara kuro labẹ ijọba amunisin ni orilẹede South Africa.
Progressives Congress ,APC) lati sajọyọ  pelu alaga
 O ni won yoo pin saare ile yii fawon odo ti won nife si ise agbe ni.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ìsẹ́yìn: Ilé aṣọ òkè alárà ǹ barà Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Ile ijọsin Deeper Life Bible Church, to jẹ ti Alufa W.
Ko din ni ọmọ orilẹ-ede Naijiria mẹsan an to n dije ninu idibo gbogboogbo ti yoo waye nilẹ America lọjọ Iṣẹgun.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Adeleke fọhùn, 'èmi ni gómìnà tí wọ́n dìbò yàn' Àbábọ̀ ìwádìí Ọlọ́pàá Ní kété ti ilé iṣẹ́ ọlọ́pàá tẹ́wọ́ gba ìwé látọ̀dọ̀ arábìnrin Buharí ni wọ́n mú olùrànlọ́wọ́ náà tí ìwádìí sì bẹ̀rẹ̀.
Funfun rẹ̀ wà, àmọ́ dúdú bíi kóró isin ni ẹ̀rọ tèmi.
Apá ìlà oòrùn tí ó jẹ́ ẹgbaa meji ó lé ẹẹdẹgbẹta (4,500) igbọnwọ (mita 2,250), yóo ní ẹnu ọ̀nà mẹta.
Agbẹnusọ fun Minisita Kemi Adeosun, Oluyinka Akintunde sọ pe, aarẹ Buhari ti fọwọ si abadofin ọun.
Aṣofin Sẹgun Olulade, Adele Alaga Igbimọ to n ri si eto Ilera ninu Ile naa fi idunnu han si eto ironilagbara ti Aṣofin Ṣolaja-Saka ṣe yii.
Gónìmà ni èyí rí bẹ́ẹ̀ láti lè jẹ́ ki wọ́n gbáradì fún ìdánwò tó ń bọ̀ lọ́nà àti kí àwọn onípele kààrún nílé ẹ̀kọ́ girama ba à lè múrasílẹ̀ fún ipele kẹfa.
Funmilayo ni iya to bi gbajugbagbja olorin ati ajijangbara, Fela Anikulapo Kuti, pẹlu Bẹẹko Ransome-Kuti ati ọjọgbọn Olikoye Ransome-Kuti to jẹ minisita fun eto ilera nigbakan ri ni Naijiria.
78  owo dollars, nipa tita oja goolu sile-okeere ninu odun to koja, eyi ti o le ni iko metadinlogun ninu ida ogorun ni odun 2016.
Àkọlé àwòrán, Èyí ni àdúgbo ti àwọn musulumi àti ìjọba ìpínlẹ̀ Rivers ń gbe gọ́nmisi omim o tó lé lọ́ri.
Pẹ̀lú onírúurú ìfúngunmọ́ tí orílẹ̀ede Ghana ń kojú, ààrẹ Akufo-Addo ti korò ojú sí ìbálòpọ̀ akọ ṣákọ tàbí abo sábo.
Eniyan to le ni ọọdunrun lo si ti ni i nilẹ Afica.
Òun náà tún dá mi lóhùn pẹ̀lú, ó wí pé: Baba tí ó ju baba ẹlòmíràn ni baba tí ó bí mi.
ti ẹ ba  tun wo oju ona Eko -Ibadan , ki
Ìwọ ̀ nba ìdá mẹ ́ ẹ ̀ dógún ninu ọgọrun un àìsàn jẹ ̀ dọ ̀ jẹ ̀ dọ ̀ c ni ó máa n mú ìmọ ̀ lára-àìsàn lọ ́ wọ ́ .
A jẹ́ pé mo kí gbogbo yín kú ọdún titun o.
Wọn ni ẹgbẹ agbabọọlu alatako ko gbọdọ di aarẹ lọwọ, nireti pe aarẹ gbodo gba bọọlu un sinu awọn, sugbọn nise ni a gbọ pe nise ni awọn ati po meji kan lati orilẹede Kongo ti awọn ko mọ bi nnkan se n lọ fi ẹyin aarẹ bẹlẹ.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Funmilayọ gba agbára lọ́wọ́ Ọba Ladapọ Ademọla keji Olufunmilayọ ni olori ẹgbe ìṣọ̀kan àwọn obinrin Ẹ̀gbá nigba naa.
’ Tí ó bá yá, á tún kì í lọ bí ilẹ̀ bí ẹní, á tún bú sí ẹkún.
Ó tó ọdún mẹ́wàá dáadáa kí báálẹ míì tún tó jẹ, ọdun 1984 sì ni.
Iru igbese yii ti ran wa lowo lati segun tabi se adinku iwa odaran ati awon iwa laabi miiran jake-jado orile-ede Naijiria”Bakan naa ni iru ise-akanse bee ti o n lowo bayii ni ‘Ayem Akpatuma’ ti  n so eso rere.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìjọba ìpínlẹ̀ Èkó kéde ìyè èèyàn tókú ní ilé alájà tó wó l'Eko 16 Ẹrẹ̀nà 2019 Àkọlé àwòrán, Aworan awọn ti wọn gba itọju Lẹyin ọjọ meji ti ile wo pa awọn eeyan nilu Eko,ijọba ipinlẹ Eko ti kede iye eeyan ti o ku ninu iṣẹlẹ ohun.
ilu Medina, nigba ti ibi kẹta jẹ Jerusalem”.
panu lowo Wilder ninu ifigagbaga igbanu alemodi WBC ti o waye niluu New York,
Àwọn àwòrán ẹ̀yìn ìtàgé níbi ìpàdé ìfọ̀rọ̀wérọ̀ BBC Yorùbá l'Eko Sanwo-Olu, Jimi Agbaje yọ kúrò nínú ìfọ̀rọ̀wérọ̀ ìtagbangba BBC ní Eko Adájọ́ àgbà tuntun búra wọlé fún àwọn olùgbẹ́jọ́ ètò ìdìbò Onnoghen: Ẹ má yọ́nú sí ọ̀rọ̀ orílẹ́èdè wa - Buhari Ọmọlara Adesanya (YPP) Àkọlé àwòrán, àwọn olùdíje ìpínlẹ̀ Eko Arabinrin Ọmọlara Adesanya gbagbọ pe kii ṣe keeyan kan ni ibudo ilera tabi ile iwosan ti ijọba nikan ṣugbọn pipese oogun ṣe pataki.
    Bí àwọn Èdìdàrẹ́ ti ṣe lẹ́yìn ikú rẹ̀ yà mi lẹ́nu.
"Fulani kò leè dúró, táa bá lo ohun ta jogún lọ́dọ̀ àwọn bàbá wa - Sunday Igboho Fayemi fojú Alufa to fipa bá ọmọde lòpọ̀ síta l'Ekiti Aṣírí ìdí ti El-Zakzaky fi padà Nàìjíríà láti India 'Àlàyé rèé lórí ìdí ti mo fi na ọmọ òrukàn, tí mo sì tì í mọ́ ilé ajá' Wo orílẹ́èdè tí wọ́n tí ń dáwó ìsìnkú ara wọn pámọ́ Àjẹ́ àti Aṣẹ́wó ní ìyá Rainbow - Òjòpagogo Buhari rọ awọn ologun naa ti wọn pe ọrukọ wọn ni ""Operation Hadarin Daji,"" lati ṣiṣẹ eto aabo ti ijọba gbe fun wọn takuntakun."
Ruga Settlement: Ganduje ní káwọn Fulani darandaran kúrò lápá gúúsù Nàìjíríà
Ajẹkun iya ti Barcelona jẹ lọwọ Osasuna yii n tumọ si pe ẹgbẹ agbabọọlu Real Madrid ni yoo gba ife ẹyẹ naa lai wo ohun ti ifẹsẹwọnsẹ rẹ pẹlu Villarreal yoo ba jade.
Wọ́n ń waasu ìyìn rere ní ọpọlọpọ àwọn abúlé ilẹ̀ Samaria bí wọ́n ti ń pada lọ.
Má ṣe hú ohun tí wọ́n rì mọ́lẹ̀ fi pa ààlà láti ìgbà àtijọ́,má sì gba ilẹ̀ ọmọ aláìníbaba;
Èdè náà sì wáá yé gbogbo aráyé wí pé, bí èenìyàn búburú bá ń gbilẹ̀, kí àwọn ẹni rere má ṣe yí ìwà wọn padà nítorí èyínì, ọjọ́ kan ń bọ̀ fún ẹni tí ń hu ìwà ìkà, tí gbogbo ènìyàn yóò fẹ́rẹ̀ máa bá a sọkún.
 Alamojuto  fun ajo eleto idibo ni ipinle Osun , ogbeni Olusegun Agbaje naa ti so pe awon ti fi awon ohun eto idibo ranse si gbogbo ibilẹ ijoba to wa ni ipinle Osun .
Àwọn kan rò pé bóyá òun ni ó jí owó Orímóògùnjẹ́ tí ó sọnù.
Ó tún ṣeéṣe láti lọ sókè síi ṣùgọ́n ẹni ba fẹ́ débẹ̀, ẹsẹ̀ lásán ni yó fi gun àwọn àkàsọ̀ fún bí ọgbọ̀n ìṣẹ́jú.
Kano: Idibo ti bẹrẹ nibudo kọọkan nipinlẹ Kano bayii.
Gbogbo eniyan ni wọ́n sì ń fi ìyìn fún Ọlọrun fún ohun tí ó ti ṣẹlẹ̀.
Serubabeli bí ọmọ meji: Meṣulamu ati Hananaya, ati ọmọbinrin kan tí ń jẹ́ Ṣelomiti.
 nígbà tí ó dé orílẹ ̀ èdè nàìjíríà , ó gbé ní erékùṣù Èkó kí ó tó kọjá sí Ìlú badagry .
Nígbà tí ó yá, Kaini pe Abeli lọ sinu oko.
Ní òde, ara wọn dàbí olùfọkànsìn, ṣugbọn wọn kò mọ agbára ẹ̀sìn tòótọ́.
Kilomita marundinlọgọta ni gigun rẹ, Ogun biliọnu dọla $20b ni wọn si fi kọọ.
Lẹyin ti ọba Adeyemi gori itẹ awọn baba rẹ ni wọn tun bi obinrin meji si, ti apapọ ọmọ ti wọn bi jẹ marun, obinrin mẹta ati ọkunrin meji.
Ṣaaju ni Ogbeni Laolu akande to jẹ oluranlọwọ fun igbakeji aarẹ Oṣinbajo ti kọkọ fi sita pe irọ to jina si ootọ ni pe Aarẹ Buhari da awọn oluranlọwọ Oṣinbajo marundinlogoji duro lẹnu iṣẹ wọn Ṣugbọn akọwe agba ajọ ẹgbẹ agbaagba Yoruba, Ọmọwe Kunle Olajide sọ pe awọn ti wọn n gbogun ti Osinbajo n ṣe bẹẹ nitori ibo aarẹ ọdun 2023 ni.
Mú ọjọ́ ibi dé bá wọn; pa wọ́n run ní àpatúnpa.
Anfaani wo ló wà ninu pé kí n kú?
27 Sẹ́rẹ́ 2018 Oríṣun àwòrán, @dinomelaye Àkọlé àwòrán, Asofin Melaye ti figba kan korin 'Ajekun Iya' si awọn alatako rẹ ni ọdun 2017.
ẹ̀yin ni ẹ óo ni agbègbè olókè wọnyi pẹlu.
Ẹ̀wọ̀n gbére ni fún ẹnikẹ́ni tó bá fipá bánilòpọ̀ ní ìpínlẹ̀ Ọ̀ṣun Wo àwọn gómìnà Naijiria tí àrùn Covid-19 ti bá fínra Mùsùlùmí tó ń gbèrò láti lọ hajj ni Alhaji, Alhaja - Onímọ̀ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Badagry Historical Wells: Omi inú kànga Wawú ló ń kó ọpọlọ àwọn ẹrú lọ Ẹwẹ, akọroyin abẹlẹ bii ọtẹlẹmuyẹ lai gbowo oṣu ni mi, aimọye iroyin ti mi o kọ ni wọn ti forukọ mi si - mo mọ pe emi kọ ni mo kọ eleyi ti wọn n sọ yii ṣugbọn awọn koko iroyin to jade ninu rẹ gan mi mi titi bo ṣe wa di pe wọn lọ ọ mọ mi lẹsẹ ko ye mi.
79bn ni wọn yoo fi san owo ọ̀yà fawọn agbẹjọroN1.
òun kò le è yọ́ wá - Lekan Balogun Ajimobi, ninu ọrọ naa to fi sita latẹnu agbẹnusọ rẹ, Bolaji Tunji, sọ pe awọn eniyan ipinlẹ Oyo ko le gbagbe ipa ribiribi ti oun ko lasiko iṣejọba bii Gomina ipinlẹ Oyo.
Marylove ti gba àmì ẹ̀yẹ lóríṣiríṣi bíi ti USTA Celsius Level 6 fawọn obinrin nilẹ̀ America nibi ti ó ti fàgbàhan àwón èèkàn agbábọ́ọ̀lù orí pákó bii Nina Sidhu, Anastasia Pestereva, Nicole Ciemark àti bẹ́ẹ̀ bẹ́ẹ̀ lọ.
Ilé ìwòsàn MSF ní gbogbo akitiyan àwọn òṣìṣẹ́ ilé ìwòsàn nà láti káwọn lọ́wọ́ kò, ló já sí pàbó.
Fun apẹrẹ lorilẹ-ede South Africa ni awọn eeyan miliọnu meji ati igba eeyan padanu iṣẹ wọn.
"Motara ni ni ti awọn to n sọ pe oun n rẹrin, kii ṣe ọmọ naa loun n fi rẹrin bi ko ṣe iya kan to n taja to n wo oun ""pe ki lo n ṣe anti yii""."
Oríṣun àwòrán, Rotimi Akeredolu Aketi Ohun ti a gbọ ni pe aarin Akeredolu ati igbakeji ko dan mọran lati igba ti igbakeji ko ti da si awọn eto ijọba ipinlẹ Ondo kan to fi mọ ẹgbẹ oṣelu APC.
O se igbakeji Aarẹ ri O wa lara awọn ti wọn du ipo Aarẹ pẹlu Buhari lọdun 2015 Odu ni ki s'aimo foloko O ti kede pe ohun fe je Aarẹ lọdun 2019 Awọn ọdọ La i pe yi ni awọn odo oludije miran kan naa yoju sugbọn ko ti daju ẹgbẹ ti won yoo dije labe rẹ.
Hurai, ará etí odò Gaaṣi, ati Abieli, ará Aribati; 
asale, gege bi isiro ajo isokan ohun, okere tan won yoo niloo ogóje bilonu owo dola(140.
Akowe agba ohun yoo kopa nibi ayeye ajayo ogun odun igbimo alajo sowopo awon orile-ede apa ila-orun ile-Afrika, nibi ti, yoo ti tenumo pataki  anfaani ti o wa nigba ti awon orile-ede ti won je omo egbe ajo naa ba n ba ara won sowo po.
OLUWA, má fi ibinu bá mi wí!
Ó dá a lóhùn, ó ní, “A kò ní wọ̀ ní ìlú àjèjì, lọ́dọ̀ àwọn tí kì í ṣe ọmọ Israẹli, kàkà bẹ́ẹ̀, a óo kọjá lọ sí Gibea.
Iṣoro ṣe ọtọọtọ bayii fun gbajugbaja ojiṣẹ Ọlọrun ijọ Sọtitobirẹ ni ilu Akurẹ, Wolii Alfa babatunde bayii nitori bi gbogbo aye ṣe n du ori wọn ki wọn maa ko arun coronavirus ni Wolii Sotitobirẹ n du ori rẹ niwaju adajọ ile ẹjọ giga nilu Akurẹ.
lati kan si Emir ti Daura lati tepele mo oro re pe eto eko to yanranti jẹ atẹgun
Nítorí ó wo ọpọlọpọ sàn tóbẹ́ẹ̀ tí àwọn aláìsàn ń ti ara wọn, kí wọ́n lè fi ọwọ́ kàn án.
Nítorí pé baba mi fi ẹ̀mí ara rẹ̀ wéwu nígbà tí ó ń jà fun yín, ó sì gbà yín kalẹ̀ lọ́wọ́ àwọn ará Midiani.
Eyi lo ti wa mu ki awọn elere idaraya naa maa lo awọn baalu kekeeke to nko wọn wọ Naijiria diẹ-diẹ.
Hesekaya dá Aisaya lóhùn, ó ní, “Ohun rere ni OLUWA sọ.
Òṣùnwọ̀n rere, tí a kì tí ó kún, tí a mì dáradára, tí ó kún tí ó ń ṣàn sílẹ̀ ni a óo fi wọ̀n ọ́n le yín lọ́wọ́.
Ọsun Election 2018: Ilé isẹ́ ọlọ́pàá ti bẹ̀rẹ̀ ìmúrasílẹ̀
Akori oro Festus Keyamo ni ‘Mu igberu ba orile-ede Naijiria: ajosepo laarin awon asiwaju ati awon odo’.
Ẹ̀mí ní ń sọ eniyan di alààyè, ẹran-ara kò ṣe anfaani kankan.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Naira Marley gba àṣẹ onídúró nílé ẹjọ́ pẹ̀lú mílíọ́nù méjì náírà 30 Èbibi 2019 Oríṣun àwòrán, Efcc Àkọlé àwòrán, Àjọ EFCC fi panpẹ́ òfin gbé Naira Marley láìpẹ́ yìí fún ẹ̀sùn lílu jìbìtì lórí ayélujára Ile ẹjọ giga apapọ kan to fikalẹ si Ikoyi nilu Eko ti da akọrin taka-sufe ni Naira Marley ti wọn fi ẹsun jibiti ori ayelujara kan laipẹ yii silẹ.
II, ti ọga agba ilé iṣẹ́ náà fi ọwọ si ni olu ile iṣẹ̀ aṣọ́bodè, ti agbegbe H.
 “Eyi je ohun itan ninu ere idaraya boolu afesegba nile Afrika.
Ni awọn iha miran, awọn ọkunrin ile naa yoo fi ipa ba opo naa lopo ti yoo si fa irun ori rẹ.
O pọ debi pe wọn sare gbe e lọ si ile iwosan ṣugbọn o gbẹmi mi ki wọn to de ibẹ.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Mo fẹ́ kí Ọlọ́run fún wa ní ọmọ olójú búlúù si lẹ́yìn yìgì - Ọkọ olójú búlúù Bí ìyàwó rẹ bá lóyún tàbí bímọ ní ìpínlẹ̀ Oyo, wo bí o ti ṣe lé gba ìsinmi ìtọ́mọ (Paternity leave) Ẹ̀bùn #500,000 wà fún ẹni tọ bá ba wa rí afurasí ikú Akinyẹle tó sọnù- Iléeṣẹ́ Ọlọ́pàá Wo àmúyẹ kí o tó lè di ọmọ ogun ilẹ̀ Nàìjíríà pẹ̀lú fọ́ọ́mù tó jáde yìí Ṣé òótọ́ ni pé ìgbẹ́ erin le è wo arùn Coronavirus sàn?
Aare tun wa ran awon omo orile ede Naijiria leti awon ipinnu ijoba re, lati mojuto eto aabo,gbigbokun ti iwa ibaje ati atunse lori eto oro aje orile ede yii, ni eyi ti awon omo orile ede Naijiria dibo fun.
 Ó kópa nínu ìgbìmọ ̀ láti gba ìjọba oríléèdè nàìjíríà lówo ̀ Ọgágun Àgú ̀ iyí ̀ iróǹsí ní ọdún 1966 .
 Oba Alayeluwa Adedapo Adewale Tejuoso pe omo ogorin odun lojo kokandinlogun osu keji odun 2018.
Nigba to n sọrọ lori bi wọn se ti ọna ọhun pa, Ademọla Kuti, tii se oludari feto isẹ ode nileesẹ to wa fọrọ isẹ ode labẹ ijọba apapọ, fi ọwọ gbaya pe isẹ yoo ya kiakia lori atunse opopona naa nitori akoko ẹẹrun ti a wa.
46 Àti pé lẹ́hìn tí ẹ̀yin bá ti gba èyí, bí ẹ̀yin kò bá pa àwọn òfin mi mọ́, a kì yíò gbà yín là nínú ìjọba Bàbá mi.
, ẹgbẹ́ òṣèré tíátà pàṣẹ fún Lizzy àti Toyin Ìjà Toyin àti Lizzy kìí ṣe àkọ́kọ́, àwọn òṣèré t'ọ́rọ̀ ìjà kàn rí rèé Àgbo ṣiṣẹ́ fún mi l'asìkò tí mò ń wojú Olúwa fún ọmọ- Toyin Abraham Niṣe ni awọn ololufẹ awọn oṣere mejeeji ọhun gbe ọrọ ija naa ru sori.
Russia wà ní ipò 75 nínú àwọn orílẹ̀-èdè 149 tí Àjọ tó-ń-ṣètò-ọrọ̀-Ajé Lágbàáyé ṣàyẹ̀wò fún lọ́dún 2018 nínú Ìjábọ̀ Àlàfo tó wà láàárín Akọ àti Abo Lágbàáyé, ó ń ṣe dáadáa ní ti ìbádọ́gbà nínú rírí ètò ìlera àti ètò ẹ̀kọ́ lò fún àwọn obìnrin, ṣùgbọ́n wọ́n ń fà sẹ́yìn nínú ètò ìṣòfin láti jà fún ẹ̀tọ́ọ wọn.
Ọ̀kan ninu àwọn ọmọ-ẹ̀yìn mejila ni Judasi Iskariotu yìí.
Ìwọ èkúté Igbó Olódùmarè, ìwọ kéré lójú ènìyàn, bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé ìwọ tóbi ju òkété ibòmíràn lọ, ṣùgbọ́n kinní kan ni mo fẹ́ kí o mọ̀: ìwọ kò kéré níwájú Ọlọ́run Ọba.
 A maa je ki awon obinrin agbe mo bi won se le ri eto won gba paapaa lori ile ti won fi n gbin nkan atawon nkan miran bii ajile ti won nilo ki awon naa le sa ipa won si sise afikun si eto oro aje Naijiria.
Ta ni ń yọ bọ̀ bí ìmọ́lẹ̀ òwúrọ̀ yìí,tí ó mọ́ bí ọjọ́,tí ó lẹ́wà bí òṣùpá.
" Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ọkọ̀ rélùwéè 16 yóò ná Eko sí Ibadan láti oṣù tó ń bọ̀ lọ - Iléeṣẹ́ Rélùwéè kéde Àwọn ọmọ orílẹ̀èdè Mali ń fò fáyọ̀ pé ológun gba ìjọba mọ́ alágbádá lọ́wọ́ Ìròyìn ayọ̀!
Ẹlẹ́nu yíyá lọ́rọ̀ Oríṣun àwòrán, Getty Biden kii ṣe ajoji lawọn ibi ipolongo idibo - o kara bọ eyi niluu Washington lọdun mẹ́tadinlaadọta sẹyin - 1973, ipolongo rẹ akọkọ fun ipo aarẹ lọdun 1987.
Kíní ìtumọ̀ ''Sọ̀rọ̀ Sókè'' tí àwọn afẹ̀họ́núhàn EndSars ń lò káàkiri Ẹ̀mí ọ̀pọ̀ ènìyàn yóò lọ tí ààrẹ Trump kò bá gbé ìpò sílẹ̀ - Joe Biden Báwo làwọn agbébọn ṣe rí ASP Ọlọ́pàá méjìlá jígbé lójú ìbọn?
O sọ wipe owo to to ẹgbeta miliọnu dọla ni wọn ti da pada sugbọn ilọpo rẹ lọna meji si wa ni ile ifowopamọ ilẹ okere.
 sayensi , teknoloji , ise-ero , ise-ona , ogbon , ede , litireso , mathematiiki , itorawo , esin ati imo-oye di olokunkun labe itoju awon oba wonyi .
Ti ẹ ko ba gbagbe, lọdun 2018 ni Aarẹ Buhari kede ''June 12'' gẹgẹ ayajọ ọjọ ijọba awarawa dipo ọjọ kọkandinlọgbọn oṣu karun ti ijọba ologun gbejọba fun alagbada ti ijọba kede tẹlẹ.
Ọlọ́run ló bámi ṣé kìí ṣèèyàn.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Olè Lekki: Obìnrin méjì ni wọ́n dá lọ́nà, tọ́wọ́ ọlọ́pàá fi tẹ̀ wọ́n 18 Ẹrẹ̀nà 2019 Oríṣun àwòrán, @policeNG Yoruba ni ọjọ gbogbo ni ti ole, amọ ọjọ kansoso pere ni ti olohun.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìtakurọ̀sọ máa ń jẹ́ kí ìsọ̀ ìwé ìròyìn dùn Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Ìtakurọ̀sọ máa ń jẹ́ kí ìsọ̀ ìwé ìròyìn dùn 22 Èbibi 2018 Àwọn ọ̀rọ̀ tó se kókó nínú ìwé ìròyìn a máa rí ìhà orísirísi ní ìsọ̀ oníwe ìròyìn.
Ileesẹ iroyin Sahara reporters naa ti iroyin sita nipa isẹlẹ yi loju opo ikansira ẹni Facebook rẹ.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Àlàyé rèé lórí ikú tó pa Ogun Majek Oyè adelé alága APC kúrò ní gúúṣù Nàíjíríà, ó bọ́ sẹ́kùn àríwá Abisola, aya wòlíì Babatunde ti ń jẹrìí nípa bí ọmọ ọdún kan ṣe sọnù Eji Gbadero, ọmọ Ibadan àti jayé-jayé ọmọ ónílẹ̀ ti wọn yẹgi fun l'Eko Èyí ni àwọn arẹwà ‘ẹ̀lẹ̀ Daddy’, àfẹ́fẹ́ tí Aláàfin fi ń mí Amọ ile iwosan naa ti figbe bọnu pe irọ to jinna sootọ ni ikede ijọba yii nitori oun ko gba owo naa lọwọ ijọba.
Àwọn kan jókòó ninu òkùnkùn pẹlu ìrẹ̀wẹ̀sì ọkàn,wọ́n wà ninu ìgbèkùn ati ìpọ́njú, a sì fi ṣẹ́kẹ́ṣẹkẹ̀ dè wọ́n,
Ṣugbọn gẹ́gẹ́ bí òróró rẹ̀ ninu yín ti ń kọ yín nípa ohun gbogbo, òtítọ́ ni, kì í ṣe irọ́, ẹ máa gbé inú rẹ̀, bí ó ti kọ yín.
Ọjọgbọn 'Bisoye Ẹlẹsin ni o yẹ ka kọ ọmọ l'ede Yoruba
Àwọn ọmọ-ogun bá fi ìtàkùn ẹlẹ́gùn-ún hun adé, wọ́n fi dé e lórí; wọn wọ̀ ọ́ ní ẹ̀wù kan bíi ẹ̀wù àlàárì, 
Àwọn ọmọ Nàìjíríà tó ṣẹ̀ṣẹ̀ dé láti UK ti dèrò ibùdó ìyàsọ́tọ̀ nítori Coronavirus Ijọba ti ko awọn ọmọ Naijiria 253 to pada sile lọjọ Ẹti lati ilẹ Geẹṣi lọ si ibudo iyatọ aibaamọ awọn mii ninu wọn le laarun coronaviris.
”Alaga egbe  People’s Democratic Party, omooba  Uche Secondus, naa wa fi idunnu re han pe  egbe PDP ni yoo jawe olubori ninu eto idibo ti
PEA ni eroja to maa n mu ki ifẹ ko si ololufẹ meji ti wọn ṣẹṣẹ bẹrẹ ọrọ ifẹ wọn lori.
Ọga ọlọpaa ni Dallas, Renee Hall ni awọn alaṣẹ ipinlẹ Dallas ti tẹwọ gba ofin to kan an ni dandan fawọn ọlọpaa lati maa da awọn akẹgbẹ wọn to ba n huwa aitọ lọwọ kọ.
 Àwọn olùgbọ ́ máa ń gbe orin pẹ ̀ lú àwọn òṣèré .
- Afẹnifẹre Arákùnrin tó bá wọ́n ṣàgbékalẹ̀ òfin ẹgba jíjẹ lórí ìwà àgbèrè kó sínú àgbèrè Ogogo ṣe ọjọ́ ìbí, Toyin Adegbola fọmọ fọkọ, àtàwọn ohun mìràn lágbo òṣèré lọ́sẹ̀ yìí Báwo ni gbogbo alága kánsú Kwara ṣe de àhàmọ́ EFCC?
Bakaana ni awọn alaṣẹ eto ilera nipinlẹ naa n ko awọn dokita ati nọọsi lọ si awọn ibudo ti wọn ti n tọju iba lassa.
Gẹgẹ bi ohun ti ileeṣẹ naa sọ, Richard dero lẹyin ijamba to waye nile iṣẹ naa nigab to n ṣiṣẹ alẹ loṣu Keje ọdun 2020.
Ṣugbọn wọn kò lé àwọn ará Kenaani tí ń gbé Geseri jáde, nítorí náà, àwọn ará Kenaani ń gbé ààrin ẹ̀yà Efuraimu títí di òní olónìí.
Ó wọ inú ilé Sakaraya, ó bá kí Elisabẹti.
Ti oo ba wa ni aṣọ tuntun; o ṣe pataki lati wọ eyi to dara ju ninu awọn aṣọ ti o ni.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Oyo Grazing Bill: Ilé aṣòfin ní yóò di èèwọ̀ láìpẹ́ láti ta ilẹ̀ fún darandaran 1 Ògún 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Laipẹ ni yoo di eewọ nipinlẹ Ọyọ fun awọn darandaran lati maa da ẹran jẹ laarin igboro tabi loju popo, ti ọkọọkan awọn daradaran yii yoo si tun lọ gba iwe idanimọ lọdọ ijọba.
Wọ́n wá ń sọ pé àwọn rí àwọn angẹli tí wọ́n sọ pé ó ti wà láàyè.
” Bẹ́ẹ̀ ni, ṣugbọn kì í ṣe gbogbo nǹkan tí o lè ṣe ni yóo ṣe ọ́ ní anfaani.
 awon agbe ti bere ise ogbin pada pelu iranlowo owo yiya lati banki Naijiria ti won pe eto igbese akanse naa ni Anchor borrower.
''Titi da igba ti ijọba ba da owo epo ati ina ọba pada si bo ṣẹ wa tẹlẹ ni awọn yoo to jawọ ninu iyanṣẹlodi naa.
Oríṣun àwòrán, YouTube/Boko Haram Eyi ko ni igba akọkọ tawon agbebon yii yoo maa kọlu ipinlẹ Borno.
Awọn ọdọ naa ti awọn adari ẹgbẹ akẹkọọ NANS lewaju fun ni wọn bẹrẹ iwọde naa ni iyalẹta Ọjọbọ.
Ìjọba kó àwọn ìpele arìnrìnàjò míràn dé láti UK nítori ààrùn Coronavirus Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fọ́nrán ohùn, Nigerians Evacuated from UK: Ko tẹ́wa lọ́rùn bi ijọba ṣe ń ṣe wá Lánàá odé yii ni ìjọba ko àwọn ipele arìnrìnajò míràn dé láti ilẹ̀ gẹ̀ẹ̀sí.
O ti to ọdun marun un bayi ti aawọ ti n waye laarin ẹgbẹ Shiite ati ijọba Naijiria lori idande olori wọn, Ibrahim El Zakzaky.
Ọkọ̀ akérò BRT gbiná lórí afárá 3rd Mainland Mi ò gbè lẹ́yìn Naira Mailey fún ìwà ìbàjẹ́- Daddyshowkey Iṣẹ́ kásẹ̀ rọ̀ làwọn pápákọ̀ òfurufú Nàìjíríà tórí ìyanṣẹ́lódì Tinubu gbéra lọ odidi Mecca láti lọ ṣàbòsí - PDP Ni saa to kọja, ọpọ sọ iei ti wọn fi fẹran iṣẹ ti awọn aṣofin kan atawọn minisita ṣe ti wọn si fẹ ki wọn tẹsiwaju.
Àwọn aworan yii wa lati oju ikansiraẹni Instagram Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
ati awon irinse fun  eto aabo ni jake
Wọ́n kó ara wọn jọ sójú kan ṣoṣo níwájú OLUWA ní Misipa.
Wọ́n fi ẹ̀sùn “títa àbùkù bá Ààrẹ orílẹ̀-èdè” kàn àwọn akẹ́kọ̀ọ́ náà.
 Ọpọ biliọnu naira ni ijọba n na lati ṣẹgun Boko Haram, airisẹse awọn ọdọ si lo faa, amọ o yẹ ki wọn ro awọn ọdọ lagbara, iru owo Abacha yẹn, wọn le pin N2m fun ọdọ kọọkan lati ro lagbara, ki ipese ina ọba to duro re si wa pẹlu."
Ṣugbọn ekeji bá a wí, ó ní, “Ìwọ yìí, o kò bẹ̀rù Ọlọrun.
Oniruru aisan ninu eyi ti aisan gbẹmi-gbẹmi igbẹ gbuuru wa ti o si lee waye nitori awọn ounjẹ ati omi ti ko mọ ati ayika ti ko ni imọtoto, eto kolẹ-kodọti ti ko duro deede atawọn iwa ilera to mẹhẹ bii aikii fi ọṣẹ ati omi fọwọ.
Ogun yóo kó ilé ayé,yóo di òfo patapata.
 Dokita naa tẹsiwaju pe nigba ti a ba n ṣiṣẹ wa ko si ẹni to maa n fipa mu wa, ṣugbọn ko bojumu ki a maa ba ijọba ja ki a to ri owo oṣu wa gba.
Abdulrasheed Maina: Oríṣun àwòrán, Twitter Abdulrasheed Maina ti fi ọpọ igba sa kuro mọ ijọba lọwọ, lẹyin ti wọn fi ẹsun iwa ajẹbanu kan lasiko to jẹ Ọga Agba ajọ to n se akoso owo awọn osisẹ-fẹyinti (Pension Board) lorilẹede Naijiria.
O rí ara rẹ̀ gẹ́gẹ́ bí onímọ̀ nípa bi a ṣe lè lanilọ́yẹ̀ nípa ǹkan ti sáyẹ́nsì sọ ju kí a pèé ní onímọ̀ nípa ààrùn kan ni pàtó lọ, o tí kọ àwọn ǹkan to pọ̀ nípa Coronavirus lórí ayélujára ti àwọn ènìyàn to le ni mílíọ̀nù mẹ́rindínlógún sì ti kà á ní àkà tún kà.
Sugbọn ileeṣẹ Executive jet to ni baluu na ti bọ si ita lati tọrọ aforiji lọwọ ijọba apapọ atawọn ọmọ orilẹede Naijiria lori iṣẹlẹ naa ninu eyi ti wọn ti ni kii ṣe afojudi o, orukọ lo dapọ mọ ara wọn Oríṣun àwòrán, Instagram/@nairamarley Àkọlé àwòrán, Naira Marley Ọga agba ileeṣẹ naa, Ọmọwe Sam Iwuajoku, ninu atẹjade kan to fi sita ṣalaye pe lootọ adajọ kan ni awọn gba aṣẹ lati gbe rin pẹlu baluu awọn sugbọn adajọ naa pe ṣalaye fun awọn pe oun ti ba baluu miran ls si ilu Abuja.
Ọkàn rẹ̀ dàbí tàkúté ati àwọ̀n, tí ọwọ́ rẹ̀ dàbí ṣẹ́kẹ́ṣẹkẹ̀.
Fasọla bẹbẹ fun atilẹyin awọn asoju-sofin lori atunse marosẹ Ibadan si Eko Oríṣun àwòrán, Fasola/twitter Àkọlé àwòrán, Ijọba nilo atilẹyin awọn asofin lori atunse marosẹ Ibadan silu Eko O wa rawọ ẹbẹ sawọn asofin naa pe, taa ba fẹ gbọ bukata isẹ akanse mejeeji yi, igbọraẹniye ati atilẹyin gbọdọ wa lati ẹka asofin, to si n fi ewe ọmọ mọ awọn asofin naa leti pe ijafara lewu o, nitori taa ba jẹ ki asepari isẹ atunse opopona marosẹ Ibadan silu Eko maa fa nilẹ bii igbin, eyi lee lewu pupọ lori ọrọ aje ilẹ Naijiria, ti ọrọ aje wa yoo si bẹrẹ si ni mọ asepati isẹ naa lara laipẹ.
Ni ipinlẹ Ogun, wamu wamu lawọn ologun ti duro.
Bakan naa ni wọn fikun pe, gbogbo awọn eniyan ti wọn fi si ipamọ lẹyin ti wọn ni ibaṣepọ pẹlu arakunrin ara ilẹ Italy ohun, ni ara wọn da sakasaka, ti awọn yoo si fi silẹ lati ma a lọ ile wọn lẹyin ọsẹ meji.
” Wọ́n bá pọnmi kún wọn.
Ó fi ẹgbaa (2,000) ninu wọn sọ́dọ̀ ara rẹ̀ ní Mikimaṣi, ní agbègbè olókè ti Bẹtẹli.
Ta ló lè gba ẹ̀mí ara rẹ̀ lọ́wọ́ agbára isà òkú?
Bákan náà ni òun náà níláti ní àwọn ohun tí yóo máa mú wá siwaju Ọlọrun.
29 Sẹ́rẹ́ 2019 Eyi ni abala ikeji agbejade ileeṣẹ lori  bibeere ibeere lọwọ awọn oludije fun ipo aarẹ lorilẹede Naijiria.
Ṣugbọn nígbà tí àwọn kan takò ó, tí wọn ń sọ ìsọkúsọ, ó gbọn ẹ̀wù rẹ̀ sí wọn lójú, ó ní, “Ẹ̀jẹ̀ yín wà lọ́rùn yín.
Nítorí àwọn kan ń sọ pé, “Àwọn ìwé tí Paulu kọ jinlẹ̀, wọ́n sì le, ṣugbọn bí ẹ bá rí òun alára, bí ọlọ́kùnrùn ni ó rí, ọ̀rọ̀ rẹ̀ kò sì ta eniyan lára.
Ileesẹ ọlọpaa kọkọ sọ pe awọn n wa alamojuto ileesẹ ọlọpaa ni agbegbe naa, nitori pe o kuna pe 'ko mọ' nipa iwa ọdaran to n waye ni agbegbe rẹ.
Erongba lati gbo oro lenu omo Aare ana naa forisanpon , bee si ni awon agbejoro re ko si nitosi lati foroworo lenu won.
owo naa wọle, nigba ti Aṣofin Funmilayọ Tejuoṣo ṣe atileyin fun aba naaWọn fọwọ si abadofin iṣuna owo naa, lẹyin ti Akọwe-Agba
Eleyii to fihan gbangba pe Gomina Akeredolu ti ẹgbẹ Oṣelu APC yoo di ariwa ipinlẹ Ondo mu nibi ti o ti wa, Jegede ti ẹgbẹ oṣelu PDP yoo di gbungun mu ni ibi ti o ti ṣẹ wa, nigba ti Agboola Ajayi ti ẹgbẹ oṣelu ZLP yoo di guusu mu ni ibi ti o ti wa.
” Ẹ̀mí èṣù náà bá gbé ọkunrin náà ṣánlẹ̀ lójú gbogbo wọn, ó bá jáde kúrò lára rẹ̀, láì pa á lára.
Atẹjade kan ti Oluranlọwọ fun olori Ile, Ibrahim Sheriff fi lede sọ wi pe, ko ba ofin mu bi ijọba ana ni ipinlẹ naa, se fun Saraki ni ilẹ ọhun, nitori ofin to jẹ mọ eto ifẹyinti ni ipinlẹ Kwara ti pin ẹtọ Saraki fun un.
Naomi bá dáhùn, ó ní, “Fara balẹ̀ ọmọ mi, títí tí o óo fi gbọ́ bí ọ̀rọ̀ náà yóo ti yọrí sí; nítorí pé ara ọkunrin yìí kò ní balẹ̀ títí tí yóo fi yanjú ọ̀rọ̀ náà lónìí.
Kazeem di oloogbe lopin ọsẹ to kọja yii, lẹyin ti wọn ni awọn ọtẹlẹmuyẹ Special Anti-Robbery Squad, SARS lo fa ṣababi iku rẹ lopopona Sagamu si Abeokuta.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Abiola Ajimobi: Àwọn ìgbà tí aráàlú fajúro lórí ìṣèjọba rẹ̀!
Tí o fi ń gbọ́ bí àwọn olùṣọ́-aguntan ti ń fọn fèrè fún àwọn aguntan wọn.
Àwọn ìpińlẹ̀ yìí ló máa n sọ ẹni ti yóò wọlé ìdìbò Gbogbo ìpínlẹ̀ tí wọ́n bá sì ti wọlé ni yóò sọ ọ̀nà ti wọ́n yóò gbà láti rí rí ìdìbò 270 tí àwọn kọ́lẹ̀jì ìdìbò nílò Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Joe Biden: Ṣé ó lè fẹ̀yìn Trump kó di ààrẹ America tó kàn?
Ó ní, “Ó di ọjọ́ mẹrinla lónìí, tí ọkàn yín kò tíì balẹ̀ tí ẹ̀ ń gbààwẹ̀; tí ẹ kò jẹ ohunkohun.
Aare Buhari tun ki ebi, ara, ore ati awon ojulumo re ku ayeye ojo ibi naa.
OLUWA bá mi sọ̀rọ̀ ní ilẹ̀ àwọn ará Kalidea lẹ́bàá odò Kebari; agbára OLUWA sì sọ̀kalẹ̀ sí mi lára.
Àwọn ẹni tí ẹ bá dárí ẹ̀ṣẹ̀ jì, Ọlọrun dáríjì wọ́n.
Gẹgẹ bi ọmọ idile oye, wọn bi i lọdun 1927 si idile Oloye Olagunju ni Ede, ipinlẹ Oṣun.
Ẹni tí ó bá jẹ oúnjẹ yìí yóo wà láàyè laelae.
 Àwọn ọ ̀ nà wo nì à ń gbà ṣiṣẹ ́ àgbẹ ̀ ?
Ọgọta ọdun ninu gbigbọkan le epo rọọbi nikan ati aini isokan laarin awọn ẹya rẹ.
Wàhálà lílo oògùn ikọ́ olómi Codeine gẹ́gẹ́ bíi oògùn olóró ti di káríayé nilẹ̀ Afrika báyìí pẹ̀lú ìròyìn láti Kenya, Chad, Ghana ati Niger.
Ilé ẹjọ́ tó ga jùlọ ni UK ti pàṣẹ pé títì tí Johnson ti ilé aṣòfin kùnà Fún ojú lóúnjẹ lórí ohun tó n ṣẹlẹ̀ nílé Oba Idowu Oniru tó wàjà Ẹ wo ohun tó yẹ kí ẹ mọ̀ nípa gbajúgbajà òṣèré tíátà Yoruba Tóyìn Afọlayan Kíni Prince Harry, Meghan aya rẹ́ àti ọmọ wá ṣé ní Áfríkà?
Fashola fi orúkọ àwọn ilé isẹ́ tó jẹ́ àjẹbánu síta.
Ò ń fi ìmọ̀ràn rẹ tọ́ mi sọ́nà;lẹ́yìn náà, o óo sì gbà mí sinu ògo.
Ìwé Mímọ́ kò ṣe é parẹ́.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Àwọn onimọ sọ pe ọna kan ṣoṣo lati daabo bo àwọn ọmọde ni lati dẹkun siga mimu.
Iye owó tó tọọrọ kò tó ìdajì owo frapuccinno tí mo gbé síwájú mi.
Ẹ wo Daniel tí wọ́n fẹ́ yẹgi fún lẹ́yìn tí US kò ṣe irú ẹ̀ fún odidi ọdún 17 Ẹ wo ìkìlọ̀ tí ìjọba America fi léde lórí ìdìbò gómínà Ondo, Edo Agbára Oṣó àti Àjẹ́ yóò mú àgbéga bá ìmọ̀ ẹ̀rọ Nàíjíríà - Elebuibon Ilé ẹjọ́ ní kí ''Yahoo boy'' lọ darí ọkọ̀ f'óṣù mẹ́ta pẹ̀lú N50,000 owó ìtanràn Mọ̀ síi nípa Shina Rambo tó pàdé Jesu lọ́gbà ẹ̀wọn lẹ́yìn tó ti jalè ''Pẹlu ibanujẹ ọkan ni mo fi sẹ ikede yii pe aburo mi atata, Robert ti fi aye silẹ.
Jíjáwé oluborí Joe Biden jẹ ìborí ìmọ́lẹ̀ lórí òkùnkùn-Obasanjo Mo ṣèlérí láti rí sí ìrẹ́pọ̀ àti ìwòsàn Amẹ́ríkà - Joe Biden Ta ni Kamala Harris obìnrin àkọ́kọ́ tí yóò jẹ igbá-kejì ààrẹ orílẹ̀èdè Amẹrika?
Ninu fidio naa lo ti tẹle ofin ijinasiraẹni gẹgẹ bi ko ṣe pe ero ayafi awọn perete ta n gbọ ohun wọn labẹlẹ ati olorin kan to pe ti a ri ninu fidio naa to n kọrin yin Ọlọrun logo nitorii Funke Akindele.
Nítorí mò ń ṣe ìlara àwọn onigbeeraganígbà tí mo rí ọrọ̀ àwọn eniyan burúkú.
Inu iya wọn Zainab Bibi dun, o ni ala oun ti wa si imuṣẹ bayii tori oun le maa gbe wọn ni kọọkan.
Bakan naa lo ni gbogbo awọn ọba yoku nilẹ Ibadan ni inu wọn kodun si ilana ‘owo ree, ọja ree’, tawọn eeyan n gba jẹ oye Mọgaji ati Baalẹ, eyi to n mu ki Mọgaji meji maa wa lati inu agbo ile kansoso.
Lacazette, atamatase ikọ Arsenal lo gba goolu naa wọle.
Bẹ́ẹ̀ ni ó gbọ́n,ó sì mọ ọ̀nà tí ó fi lè mú kí àjálù dé bá eniyan,kì í sọ̀rọ̀ tán, kó yí ọ̀rọ̀ rẹ̀ pada.
mu ninu ijoba fun saa keji rẹ yii,Awon obinrin lo soro yii lasiko
West Brom, to wa ni isalẹ tabili Premier League, ti wa nibudo igbaradi lorilẹede Spain.
Awọn oṣiṣe ajọ EFCC ko ti ni ẹri to daju nidi itọpinpin ati iwadi wọn nipa eniyan mọkandinlọgbọn ninu awọn eeyan ati ileesẹ mọkanlelọgbọn ti wọn fi ẹsun kan wipe wọn gbe owo to nfa awuyewuye naa sinu apo asunwọn Patience Jonathan, eyi to n fidi ahesọ ọrọ to nja nipa isẹlẹ naa mulẹ pe irọ ni pe awọn kan lo gbe owo naa sibẹ.
 kò tí ì sí ẹni tí a rí tó wọ ̀ láti ojú ọ ̀ run rí .
Oluṣoagutan yii ni onikaluku lo mọ iru ìpè ti oun gbà ati iṣẹ ti Oluwa ran oun lati ṣe.
Ẹ̀ṣẹ̀ ni ó ṣiwaju Òfin dáyé, bẹ́ẹ̀ bí kò bá sí òfin a kì í ka ẹ̀ṣẹ̀ sí eniyan lọ́rùn.
Laycon, ẹni to sisọ loju ọrọ yii lasiko to n kopa lori akanse eto kan ni ikanni BBC Yoruba, salaye pe eeyan meji ni oun fi igbesẹ oun naa to leti, eyiun Maneja ati ẹgbọn oun.
Afonja salaye pe, egbe ohun gbagbo pe, awon adaari bi Tinubu, eni ti o n pese isakoso rere fun awon eniyan re, ti o si n ro awon adari miiran lagbara, iru eni bee ye ni eni ti a n bu ola fun, nigba to o wa laaye.
Kí ẹ rí i pé ẹ tọ́jú gbogbo nǹkan tí Ọlọrun ọ̀run bá pa láṣẹ fún lílò ninu Tẹmpili rẹ̀, kí ibinu rẹ̀ má baà wá sórí ibùjókòó ọba ati àwọn ọmọ rẹ̀.
Minisita naa wa ki awon omo orile-ede Naijiria ku ayeye odun ileya “Happy Eid-El-Adha celebration”.
àní, òfin tí o ṣe, tí o fi rán àwọn wolii sí wa pé, ilẹ̀ tí ẹ̀ ń lọ gbà yìí jẹ́ ilẹ̀ tí ó kún fún ẹ̀gbin ati ohun ìríra, pẹlu ìwà ẹ̀gbin àwọn eniyan jákèjádò ilẹ̀ náà ti sọ ọ́ di aláìmọ́.
Ọpọ awọn akẹẹgbẹ rẹ nidi iṣẹ tiata bii Iyabo Ojo, Femi Adebayo, Bimbo Thomas, Bimbo Oshin ati bẹẹ bẹẹ lọ, lo peju sibi ayẹyẹ ọjọ ibi ọhun, koda, Ọọni Ile Ife wa nibẹ pẹlu.
Àkọlé àwòrán, Ẹku oni leesi, fun eegun igbalode la ba pe ẹku yii Àkọlé àwòrán, Egungun alare ree o pẹlu ilu ati ijo to sọkutu-wọwọ Àkọlé àwòrán, Egungun ọlọmọ yọyọ ree, n se lo ko ọmọ yọyọ sẹyin Àkọlé àwòrán, Ẹni to ba gba pasan meji sara ninu awọn pasan yii, yoo wa ibi wọ si ni Àkọlé àwòrán, Ẹni to ba sẹ ọmọde yii, ko tete ba ẹsẹ rẹ sọrọ, atori yii lee mu ki gende bu sẹkun Àkọlé àwòrán, Ẹgan ni ẹ, awon eeyan woran ọdun eegun 2018 nilu Iwo Àkọlé àwòrán, Tilu-tifọn ni awọn eeyan ilu Iwo fi ki awọn ara ọrun kaabọ Àkọlé àwòrán, Awọn obinrin gan ja ọrẹ lasiko ọdun eegun ọdun yii Àkọlé àwòrán, Ara meriri ma tun leyi, ewo ni ti odo lẹyin egungun BBC News, Yorùbá Ìdí tí ẹ fi le è nígbàagbọ́ nínú ìròyìn BBC Ìlànà Lílò Nípa BBC Òfin Àṣírí Cookies Kàn sí.
    Báyìí ni àlejò mi sọ ìtàn ara rẹ̀, ìgbà tí ó sì fi máa sọ ọ́ dé ibi tí a dé yìí, ilẹ̀ ń ṣu, mo bá dámọ̀ràn pé kí a fi ìyókù sílẹ̀ di ọjọ́ kejì kí á tó tún máa bá ọ̀rọ̀ wa lọ.
Gbajabiamila ni olori ọmọ ẹgbẹ oṣelu to pọ julọ tẹlẹ ni ile asoju sofin kẹjọ to sẹsẹ kogba wọle.
35 Nítorí ohùn ti èmi ni èyítí ó sọ wọ́n jade fún yín; nítorí a fi wọ́n fúnni nípa Ẹ̀mí mi síi yín, àti nípa agbára mi ẹ̀yin le kà wọ́n, ẹ̀nìkan sí ẹlòmíràn; àti pé bíkòṣe nípa agbára mi ẹ̀yin kò lè ní wọn.
Awon meteeta ni won yonda  lati maa se kopa nibi ipade amusese ijoba, lati le je ki won irinajorin lo si Dapchi naa, ireti wa pe, won yoo pada silu Abuja nirole oni.
"Gẹgẹ bo ṣe sọ, o ni ""Ẹni akọkọ gbẹmi mi ninu ijamba alupupu ni nnkan bi aago mejila ọsan, ki n to de ibi ti iwọde naa ti waye."
Ọdún kan- àbọ̀ péré ni Òmùgọ́dimẹ́ta fi ju Dánásungbo lọ, ṣùgbọ́n ìkíni tí ó kí ni kò jọ ìkíni àbúrò ọba, dípò kí àwa dọ̀bálẹ̀ fun un, òun ló tún dọ̀bálẹ̀ fún wa, kò sì dọ̀bálẹ̀ lẹ́ẹ̀kan ṣoṣo, ggbogbo wa lo kí lọ́tọ́ọ̀tọ̀ tí o dọ̀bálẹ̀ fún olúkúlùkù káàkiri.
Ni mo bá bá eré tèmi lọ, mo sì ti fi ọkàn sí I pé tí ó bá ṣe díẹ̀, ara rẹ̀ yóò yǎ, a ó sì tuńn rí I ní Sátidé tí ó ń bọ̀ gẹ́gẹ́ bí ìṣe rẹ̀.
Ṣugbọn nígbà tí ó wá pàdé mi létí odò Jọdani, mo jẹ́jẹ̀ẹ́ fún un ní orúkọ OLUWA pé, n kò ní pa á.
Gbogbo nnkan to niiṣe pẹlu rẹ ni mo n ṣafẹri.
Wo àwọn olùdíje < Padà lọ sí ọ̀dọ̀ Olùdíje Ìkádìí ‘Dancing Senatọ’ni baba olorin Takasufe meji Ti a ba ni ki a sọrọ nipa iriri rẹ nipa oselu, ko fẹ si ọrọ pupo ju wi pe, o bẹrẹ irinajo oselu pẹlu ẹgbọn rẹ, Isiaka Adeleke ni ọdun 2001.
"Oluwo kò gbọdọ̀ kọrin òwe tàbí bá àkọ̀ròyìn sọ̀rọ̀, kó má baà ba ẹjọ́ ara rẹ̀ jẹ́ - Ọ̀ràngún ṣàlàyé ""Mo le jẹ iná, fi iná ra ara, fi omi tan iná láti pa owó gidi láì ṣe oníṣàngó"" Toyin Abraham ọkọ rẹ̀ àti Ire ní London, Odunlade 'kòlábò' pẹ̀lú Mercy Aigbe Olùkọ́ tó fi tipá gba ìbálé akẹ́kọ̀ọ́ tó fẹ́ wọ fásitì rí ẹ̀wọ̀n ọdún 21 he Bàbà ìyàwó ló yẹ kí ọkùnrin dọ̀bálẹ̀ fún, kìí ṣe ìyàwò tó fẹ́ fẹ́ - Yemi Elebuibon Ọ̀ọ̀ni kò láṣẹ láti yọ mí nípò, mi ò sì ní ááwọ̀ mọ́ pẹ́lú Aláàfin-Oluwo Nisẹ ni akọnimọọgba Tottenha, Jose Mourinho dori kodo lẹyin ti ọwọ iya ba ikọ agbabọọlu rẹ Tottenham Hotspurs."
Lasiko iwọde yi awọn eeyan sọ nkan nu paapaa lasiko ti o ba di pe wọn n sa fun awọn agbofinro.
asofin  Ali Ndume ti won jo n dupo ni iye ibo méjídínlọ́gbọ̀n (28).
"Ẹni ti Ọlọrun da ti ko ṣee fara we ni Ọjọgbọn Ayo Akinwale.
Yomi Shogunlẹ: Ọ̀rẹ́kùnrin Yahoo Yahoo ló fi Khadijat Olubọyọ ṣe ògùn owó
Àwọn eniyan bà jáde láti lọ wo ohun tí ó ṣẹlẹ̀.
Èrò ọkàn olódodo dára,ṣugbọn ẹ̀tàn ni ìmọ̀ràn àwọn eniyan burúkú.
Kò sí nǹkan tí ó dùn mọ inú Olódùmarè rékọjá pé kí ènìyàn mú kí ayé ẹlòmíràn ddi dáadáa, kò sí nǹkan tí ó dùn mọ́ inú Olódùmarè bí i kí ènìyàn jẹ, kí o fún ẹlòmíràn ní ààyè àti jẹ kí ènìyàn mu kí ó sì fún ọmọ ẹlòmíràn ni ààyé àti mu.
Ibeere ti Attah bi akọroyin wa niyi, bo tilẹ jẹ pe o gba pe lootọ ni oṣiṣẹ aṣọbode to yinbọn pa ọkunrin naa, ko tẹ ohun to le dena ki ibọn naa o maa yin ara rẹ.
Aarun Covid-19 ti ṣekúpa olórí àwọn òṣìṣẹ́ ní ilé ìjọba ní Abuja tó tún jẹ amúgbálẹgbẹ fún Ààrẹ Muhammadu Buhari.
Aarẹ orilẹede Cuba, Miguel Diaz-Canel, to wa nibi isẹlẹ naa sọ wi pe, o seese ki ọgọọrọ eniyan segbe sinu ijamba ọkọ ofurufu naa.
Adari iko omo ogun owo keji, Ogagun Bamidele
Amọ, Ajo Eleto Ilera Lagbaye, WHO ni awọn ṣe agbatẹru fun awọn oogun iwosan ibilẹ, amọ awọn gbọdọ ri ẹri ayẹwo imọ sayẹnsi wi pe awọn agbo yii le e ṣe awotan aarun Coronavirus.
Nigba ti wọn wọn ri ẹgbẹrun mẹtalelogoji o le ni ogun naira ni ijamba ọkọ to waye ni opopona Cemetry atijọ ni Birnin Kebbi.
Èrò àwọn ọmọ Naijiria ṣọ̀tọ̀ọ̀tọ̀ lórí àwọn ti Sanwo Olu yàn sípò Ọwọ́ ti tẹ ọlọpàá mẹ́rìn to pa afurasí O ṣalaye pe ọgọrin lawọn afurasi ọun ti ọpọ wọn si jẹ ọmọ orilẹede Naijiria.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Jude Chukwuka: Wọ́n yóò fi ojú ọlọgbọ́n wo akúrí tó bá sọ ojúlówó èdè Yorùbá Nigba to n sọrọ lori iṣẹlẹ naa, agbẹnusọ ileesẹ ọlọpaa ipinlẹ Eko, Bala Elkana ni iwadii n lọ lọwọ lati mọ bi awọn ọmọ naa ṣe rin ṣugbọn yoo gba akoko diẹ.
Ṣé kí ẹ máa jẹ oko ninu pápá dáradára kò to yín ni ẹ ṣe ń fi ẹsẹ̀ tẹ àjẹkù yín mọ́lẹ̀?
1 15226 Orilẹede Cote d‘ivoire 132 0.
fásitì odùduwà jẹ ́ ilé-ẹ ̀ kọ ́ àdáni tí wọ ̀ n dá sílẹ ̀ ní ọdún 2009 .
Àwa ti rí i, a sì ń jẹ́rìí pé Baba ti rán Ọmọ rẹ̀ láti jẹ́ olùgbàlà aráyé.
Agbẹnusọ ileeṣẹ ọlọpaa nipinlẹ Ondo, Tee-Leo Ikoro lo fi idi ọrọ naa mulẹ.
Kí alufaa ju igi kedari ati hisopu ati aṣọ pupa sinu iná náà.
'Rọ́bọ́ọ̀tì ni yóò máa yẹ̀ yìn wò kẹ́ẹ tó rìnrìnàjò òfurufú ní Nàìjíríà' Koda, fọnran aworan kan to nii ṣe nipa iṣẹlẹ naa ti gba awọn oju opo ori ayelujara kan.
Wọ́n bá kúrò lọ́dọ̀ rẹ̀, wọ́n bá tiwọn lọ.
Ìtura ìgbà díẹ̀ ni bọ́dà tí ìjọba ṣí padà, kò lóòre nínú - Onímọ̀ ọrọ̀ ajé Wo ìdí tí ààrẹ Buhari kìí fi ṣe ẹ̀dà Jubril láti Sudan Ẹ dín agbára ìjọba àpapọ̀ kù, kẹ ṣì ṣe àgbékalẹ̀ ọlọ́pàá ìpínlẹ̀ - Tinubu bẹ̀bẹ̀ Wo eyi to súnmọ́ ọ nínú àwọn ibùdó 203 fún ìforúkọsílẹ̀ fún NIN rẹ Adigunjalè méjì ko ìjàmbá ọ̀kadà lẹ́yìn ìṣẹ́ ibi n‘Ibadan, ọ̀kan kú lójijì, aráàlú dáná sun èkejì Àwọn ohun kàyéèfì tó le mú kí ọmọbìnrin ní oyún ìju Ìrẹ̀sì kò gbọdọ̀ wọlé níbáyìí ta ṣí ẹnu bodè padà - Ìjọba àpapọ̀ Jide Kosoko forin sẹ́nu pé òun ni igi lẹ́yìn ọgbà Mr Latin lórí ipò ààrẹ TAMPAN tó wà Atẹjade ẹgbẹ oselu PDP naa, ti akọwe ipolongo ẹgbẹ fun ẹkun iwọ oorun guusu, Lere Olayinka fọwọsi, wa mu wa siranti nipa ohun ti Buhari se awọn eeyan ẹkun iwọ oorun Naijiria.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Àlàyé rèé lórí ìdí tí ẹgbẹ́ òṣìṣẹ́ kò fi ní bẹ̀rẹ̀ ìyanṣẹ́lódì mọ́ lónìí Ẹgbẹ́ òkùnkùn yìnbọn lu ọmọ kan ní ikùn lásìkò ìdárò akẹẹgbẹ́ wọn Laycon ni ọmọ ológo tó jáwé olúborí ní ètò BBNaija season 5 'Lockdown' Kí ló wà láàrin Olorì Badra àti Bobrisky, tí ọ̀rọ̀ wọn fi wọ̀?
Owo ti o to $17,600 ni wọn ri pe eku ti jẹ, nigbati wọn ṣii ẹrọ naa.
Àwọn ni wọn óo ni yín, ẹ óo sì di ogún wọn, ẹ kò ní pa wọ́n lọ́mọ mọ́.
Òun ní àwa ti ń retí pé yóo fún Israẹli ní òmìnira.
Olootu ere Yoruba yii ti fi igba kan ri jẹ ọkọ afẹsọna gbajugbaja oṣere, Toyin Abraham.
Ọjọgbọn Mike Ogrima, to jẹ Ààrẹ ẹgbẹ onimo ìṣegun ni '' A lòdì sí kí àwọn Dókítà àti oṣiṣẹ ilera jijo ma gba iye owo kannáà.
Lẹyin naa lo tun gberasọ lọ si Texas lati tẹsiwaju ẹkọ rẹ ni fasiti A&M to wa ni Kingsville, amọ ko gboye jade ni fasiti ọhun.
Wo ìṣẹ̀lẹ̀ márùn-ún tí kò bá pín Nàíjíríà sí yẹ́lẹ-yẹ̀lẹ Ọ̀fẹ́ ni ohun eèlò àyẹ̀wò Covid-19 tí a ṣẹ̀sẹ̀ gbé jáde bá dé - NIMR Ilé ẹjọ́ gíga ní kí òsìsẹ́ First Bank tẹ́lẹ̀ lọ sí ẹ̀wọ̀n ọdún 98 lórí ẹ̀sùn pé o jí mílíọnù 49 àti $368, 000 níbẹ̀ Ìbò 900m làwọn èèyàn di lórí ètò BBNaija tó ṣẹ̀ṣẹ̀ parí - MultiChoice Falana pari ọrọ rẹ pe o yẹ ki ijọba wo iru iya to n jẹ awọn ara ilu, ko si wa ọna abayọ sii ko to maa ṣafiwe iye owo epo.
Super Eagles naa wa nibẹ o, Eyimba Eyimba naa si wa nibẹ ṣugbọn Manu U ni mi o.
je ko di mimo pe awon agbalagba lo je anfaani ltoju oju ninu abala akoko eto ti
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ẹ wo àwòrán àti ọ̀rọ̀ ìrántí àwọn akẹ́kọbìrin Chibok 14 Ìgbé 2018 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Òní ni àyàjọ́ ọjọ́ tí àwọn akẹ́kọ̀bìnrin Chibok sọnù Ọjọ kẹrinla oṣu kẹrin, ọdun 2014, nileewe girama awọn obinrin ni ilu Chibok, nipinlẹ Borno, awọn akẹkọbinrin kan nṣe idanwo aṣekagba girama wọn lọwọ pẹlu ireti idanwo ayọ.
Awọn ọlọpaa naa, ti wọn ti kọkọ yin afẹfẹ tajutaju, ti ko ran awọn oluwọde naa, lo tun bẹrẹ si ni yin afẹfẹ alata si wọn.
títí tí OLUWA yóo fi fún àwọn arakunrin yín ní ìsinmi gẹ́gẹ́ bí ó ti fun yín, tí wọn yóo sì fi gba ilẹ̀ tí OLUWA Ọlọrun yín yóo fún wọn.
Oríṣun àwòrán, @Yakasai Àkọlé àwòrán, Mo ṣetan lati tunra mu ninu iṣẹ ilu ti mo n ṣe ni Kano- Ganduje Buhari mórí lé Saudi lẹ́yìn ìbúrawọlé fún sáà kejì Nigeria swearing-in: Ọjọ́ kò!
Joabu ni balogun àwọn ọmọ ogun ní Israẹli.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ìpòrúuru bá ìyàwó mi bó ṣe gbọ ohun ọmọ wa Akẹkọ Dapchi mọkanlelọgọrun lo pada de Ijọba apapọ Naijiria ti fi atẹjade kan sita wi pe awọn akẹkọbirin mọkanlelọgọrun ninu awọn akẹkọ Dapchi ni wọn ikọ Boko Haram tu silẹ l'Ọjọru (Wednesday).
Gbin àwọn kan síhìn-ín, gbin àwọn kan sọ́hùn-ún, gbìn ín káàkiri oko nítorí o kò mọ ohun tí ó lè ṣẹlẹ̀ lẹ́yìn ọ̀la.
Oríṣun àwòrán, @thesignalng Akintoye ni Ede aiyede maa n waye ninu idile, ṣugbọn o di dandan ki wọn pari iru aawọ bẹẹ."
Awọn ọlọpaa ti fi panpẹ ọba mu iya ọmọ naa, ti wọn si n wa baba ọmọ naa.
akanse ti ijoba ipinle Eko ti gbe se.
Ipo ate tuntun miiran yoo jade lojo kọ́kàndínlógún osu keje odun ti a wayii.
Awọn irinṣẹ to n ṣayẹwo bi ara eeyan ṣe n gbona si, omi ati ọṣẹ fun ọwọ fifọ atawọn ohun miran ti wa ni sẹpẹ lawọn ile iwe ọhun.
Ó ti lọ ṣe ìsìn ní Jerusalẹmu, 
Ọlọ́pàá Eko ní kí olùkọ́ UNILAG Boniface wá sọ tẹnu rẹ̀ lórí ẹ̀sùn ìfipábánilòpọ̀ A ti mọ òbí 40 nínú 108 t'ọ́mọ wọn bọ́ ní ayédèrú ibùdó atúnwàṣe Ilorin - Ọlọ́pàá Kwara Ta ni Funmilayọ Ransome-Kuti?
0 9 Erekusu Marshall islands 0 0.
EFCC: Nítorí ẹ̀sùn 419 laaṣe mú Naira Mailey àti ikọ̀ rẹ̀
Nígbà tí wọ́n dé ọ̀dọ̀ mi wọ́n mú ọkùnrin kan báyìí tí ó dúró tì mí tí ó sanra díẹ̀ jù mí lọ, nígbà tí wọ́n sì yẹ̀ ẹ́ wò dáadáa, wọ́n pa á lójú wa.
“Ẹ má ṣe fi nǹkan mímọ́ fún ajá, ẹ má sì ṣe fi ìlẹ̀kẹ̀ iyebíye yín siwaju ẹlẹ́dẹ̀.
F Kumuyi Laipẹ yii ni Alufa Agba fun ìjọ Deeper Christian Life Ministry, W.
Chelsea dìgbájú ru Watford bí olè tó jí ike owó Amọ eleyi ti o fa iriwisi lọdọ awọn alatilẹyin ere boolu ni ti Lucas Moura ẹgbẹ Tottenham to jẹ goolu mẹta ni abala keji ifẹsẹwọnṣẹ Tottenham ati Ajax.
 wọ ́ n mú èyí tí ó wà ẹnìkan lórí .
Darasimi ni abigbẹyin, ọmọ kẹta fun idile oṣere Kristẹni Mike ati Gloria Bamiloye ti wọn jẹ gbajugbaja ninu awọn fiimu ẹsin Kristẹni ti awọn eeyan mọ si Mount Zion Films.
Ta òróró yìí sí ara àgọ́ àjọ, ati sí ara àpótí ẹ̀rí, 
@ververngida ni ohun ti Dalung n gbiyanju lati sọ fun ajọ IAAF ni pe ọlọlẹ to ba bi ti wọ inu ẹkọ ko le jade mọ.
Sugbọn o kú nitori pe o padanu ẹ̀jẹ̀ to pọ.
Imọ nipa itọju ọmọde lo kọ nipa bawo lo ṣe wa n tọju alarun Covid-19 Oríṣun àwòrán, Twitter Ibeere yi wa lara ohun tawọn to n tako ọrọ rẹ n beere nipa bi o ti ṣe ni ohun n tọju alarun Covid 19.
Sudan: Omar al-Bashir, oníyàwó méjì tí kò bí'mọ kankan
Ajo eleto idibo naa ti gbe iwe
Iroyin so pe, ogoro eniyan ni won ti di alainile-lori nilu Nairobi ti n se olu ilu orile-ede Kenya, leyin aroro da ojo ti o waye ni ilu naa.
Ẹwẹ, ileeṣẹ ọlọpaa pada bẹrẹ igbesẹ lori ọrọ yii latari awọn ọmọ Naijiria to n gbe atẹjade Olumide lori Twitter ru ti wọn si n pin in kaakiri lori ayejlujara titi ti o ṣe to awọn ọga ọlọpaa leti.
Ṣugbọn awọ akọ mààlúù náà, ati gbogbo ẹran rẹ̀ ati orí rẹ̀ ati ẹsẹ̀ rẹ̀ ati nǹkan inú rẹ̀, ati ìgbẹ́ rẹ̀; 
Lowurọ Ọjọru nileẹjọ giga ti wọn ti n gbẹjọ lAbuja la ti gbọ pe agbẹjọro Maina ti fariga pe oun ko ṣoju Maina mọ.
Ọ̀rọ̀ ọ́ pọ̀ níbẹ̀ o ẹ̀yin ará mi.
0 11203 Orilẹede Chad 102 0.
”Juda bá dáhùn, ó ní, “Ẹ lọ mú un wá kí wọ́n dáná sun ún.
" Ṣugbọn Okina ko fi bẹ ẹ ni owo lọwọ.
Àwọn kan tilẹ̀ ń kú sínú túbú ọlọ́pàá.
Idẹ yìí ni Solomoni fi ṣe agbada omi ńlá ati òpó ati àwọn ohun èlò idẹ fún ilé OLUWA.
Ta ni Ọjọgbọn Ibrahim Gambari gan an?
Labẹ eto iselu alagbada, aba ẹnawo naa nilo awọn asofin bii ọgọta lati fontẹ luu, ninu ọgọrun asofin to wa nile asofin agba ilẹ Amẹrika.
” “Won nilo lati se awon atunse
Ẹ máa wà ní alaafia láàrin ara yín.
Kódà ni Hong Kong, àyè láti sọ ọ̀rọ̀ ẹnu ẹni jáde àti láti bá èèyàn ṣe pọ̀ ti jákulẹ̀.
Wọn ni nitori pe eyi jẹ igba kjarun un ti ijọba maa kede lori ọrọ SARS ṣugbọn to jẹ irọ.
Oludari ikede ati  iroyin fun ile-ise omo oogun ofurufu lorile ede Naijiria,Ibikunle Daramola, so pe ” Iroyin te ile-ise omo oogun ofurufu lowo pe  iko omo-oogun olote ti lo si ilu Gashigar lati dojuko won nibe, ko to di pe won dari iko omo oogun ofurufu to ye ko lọ si ibi ti won kọkọ dari wọn si, lọ si Gashigar lati lọ gba ilu naa silẹ lọwọ iko omo-oogun olote.
Bi ẹ ko ba gbagbe, oṣu to lọ ni Olubadan yan YK Abass gẹgẹ bi Babalọja gbogbogbo tuntun nipinlẹ Oyo.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Omotola Jalade ní Nàìjíríà dàbí ọ̀run àpáàdì lábẹ́ ìjọba Buhari Duro Ladipọ, ìlúmọ̀ọ́ká òṣèré tíátà àti ọmọ àlúfà tí kò gbàgbé àṣà ìbílẹ̀ ‘Ọgbọ́n tí mo dá rèé kí àwọn bàbá lè pọn ọmọ sẹ́yìn’ Jega salaye pe awọn oloselu kan nipinlẹ Kano gan tiẹ lo awọn olukọ fasiti ọhun lati se ọpọ aise deede lasiko eto idibo 2019 to kọja yii.
Iṣẹ́ ọwọ́ yín yóo sì mú un bínú.
Nígbà náà kí àwọn tí ó bá wà ní Judia sálọ sórí òkè.
Dájúdájú ibinu a máa pa òmùgọ̀,owú jíjẹ a sì máa pa aláìmọ̀kan.
Ìrètí wọn di òfonítorí wọ́n ní ìdánilójú.
Ẹsita Pe Ọba ati Hamani sí Àsè.
Eyi lo jẹ ki ajọ LASTMA fi to awọn olugbe ipinlẹ naa leti awọn ọna ti irin aarẹ yoo de.
Biden lo ti ni ibo to pọju julọ ninu itan eto idibo aarẹ orilẹ-ede Amẹrika.
Ìwà ipá hù, ó dàgbà, ó di ọ̀pá ìwà ibi; bí ẹ ti pọ̀ tó, ẹ kò ní ṣẹ́ku ẹyọ ẹnìkan, àtẹ̀yin ati àwọn ohun ìní yín, ati ọrọ̀ yín ati ògo yín.
Nguma, to to ẹni ọgbọn ọdun, sọ pe awọn soja orilẹede Cameroun bọ asọ lọrun oun ati awon obirin miran.
Ìwọ ọ̀rẹ́ mi, nígbà tí Olówó-ayé wo inú ìwé oníbodè, àti búra di ìṣòro.
O ni Mo ti gbọ ẹdun ọkan yin nipa iwọde ti a ṣe lana, mo si fẹ sọ wipe a pinu lati ṣe miwọde naa lasiko yii nitori awọn iroyin to tẹ wa lọwọ lasiko naa."
Èyí ni àsọtẹ́lẹ̀ nípa àfonífojì ìran:Kí ni gbogbo yín ń rò tí ẹ fi gun orí òrùlé lọ,
Mose bá bẹ̀rẹ̀ sí kó àwọn ọmọ Israẹli tẹ̀síwájú láti ibi Òkun Pupa, wọ́n ń lọ sí aṣálẹ̀ Ṣuri, ọjọ́ mẹta ni wọ́n fi rìn ninu aṣálẹ̀ láìrí omi.
Bí ó ti rìn siwaju díẹ̀ sí i, ó rí Jakọbu ọmọ Sebede ati Johanu arakunrin rẹ̀ ninu ọkọ̀, wọ́n ń tún àwọ̀n wọn ṣe.
Gege bi ogbeni Ayuba se so, O ni igbimo ohun sepade olojo meji lati jiroro wa bi atunse yoo se de ba owo osu awon osise, eleyi ti egbe NLC yoo tewogba jabo fun awon osise re.
Ìgbà tí ètè rẹ tilẹ̀ ń sọ̀rọ̀, kò jẹ́wọ́ pé Ewe-ẹ̀yẹ pa ènìyàn rí tàbí kí ó ṣe ẹnikẹ́ni ní ibi.
Ó gbà wá ní ọjọ́ mejilelaadọta.
O wa lara akọnimọọgba to dara ju ninu itan Arsenall Wenger ni ọrọ Mourinho naa ya oun lẹnu pupọ nigba to gba ami ẹyẹ naa.
O maa maa ronu awọn igbesẹ ati ọna ti oun a gba ṣiṣẹ ibi naa ti ko fi ni lẹyin lọjọ iwaju.
Mose bá wí fún OLUWA pé, “Kí ló dé tí o ṣe mí báyìí?
Oludije fun ẹgbẹ oselu APC, tii sun ṣe gomina ipinlẹ Ondo, Rotimi Akeredolu lo sísọ loju ọrọ yii lọjọ Isẹgun lasiko to n kopa lori akanse eto lori BBC Yoruba pẹlu awọn Oludije gomina miran nipinlẹ naa, ti akori rẹ n jẹ itakurọsọ pẹlu awọn Oludije nipinlẹ Ondo.
Gbogbo eeyan lo mọ mi ni Awolowo, Seyi, ọmọ Awolowo ṣugbọn mo fẹ ni orukọ temi to bẹẹ to jẹ pe ti mo ba ṣe nkan ni'ta, wọn a sọ pe Seyi lo ṣe e, kii ṣe Awolowo.
Arkwright  so pe “ile-ise asoju fun orile ede Britain yoo ran iko  asoju jade lasiko eto idibo , ni eyi ti won yoo fi ri I pe eto idibo lo ni irowo-irose ati lati ri I pe ajo eleto idibo se ojuse won,ki iko omo ologun naa si lee se ojuse won , ni eyi ti won yoo fi lee ri I pe awon omo ipinle Ekiti jade lati lo dibo won ni irowo-irose.
Ìdáhùn kíkún a máa fúnni láyọ̀,kí ọ̀rọ̀ bọ́ sí àsìkò dára lọpọlọpọ!
igbakeji aare fi oro naa mule pe, minisita to n mojuto oro ilr-okere, ogbeni
Nínú fọ́nrán tó jẹ́yọ lórí ayélujára ni ọgbẹni Debo Adebayọ, Mr Macaroni ti ń sọ̀rọ̀ pé bi Gómìnà ìpińlẹ̀ Eko, Babajide Sanwo-Olu ko ba le jáde, tí igbákeji rẹ̀ náà pẹ̀lú kò sí rí ààyè, ó di dandan ki abẹnugan ilé ìgbìmọ̀ aṣofin ìpílẹ̀ Eko yọju.
Iroyin fi mule pe, arabinrin omo odun mokandinlogun alaboyun ohun ni awon agbebon kan yinbon mo, ninu isele ikolu oko meji ti o waye lopopona oko ti o jina si ile-ise awon agbofinro Memphis.
Nítorí kí ni a ṣe ń fi ẹ̀mí wa wéwu nígbà gbogbo?
Àkọlé àwòrán, Ere ori itage Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, YSAN 2018: llú Ondo gbàlejò Àpérò Ẹgbẹ́ Onímọ̀ èdè Yorùbá Nàìjírìa Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
 láti ọmọ omún ni ìyá ajíbógun Ọwá iléṣà ti kú ìyá agígírì tí ó jẹ ́ ẹ ̀ gbọ ́ n ìyá rẹ ̀ ló wò ó dàgbà , ọmún rẹ ̀ ló sì mún dàgbà .
Kò sí nǹkankan tí ẹnìkan lè ṣe fún Ijipti,kì báà jẹ́ ọlọ́lá tabi mẹ̀kúnnù,kì báà jẹ́ eniyan pataki tabi ẹni tí kò jẹ́ nǹkan.
CAN: Ìbànújẹ́ ńlá ni iku ọ̀mọ̀wé Musa Asake jẹ
" Aarẹ tuntun naa, ẹni to gun ori pepele lati sọrọ pẹlu ibomu lẹnu rẹ tun kede pe, oun yoo se agbekalẹ igbimọ to yoo maa tete gbogun ti arun Coronavirus.
Wọ́n lè run ọ̀tá wọn láì ku ẹnìkan, kí wọ́n sì gba gbogbo ìní wọn.
Asiko ti mo wa ni America ni mo di atunbi."
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Inú jìn!
Oríṣun àwòrán, Getty Images Lọdun 2005 ni Walcott bẹrẹ si ni ṣoju Southampton nigba to pe ọmọ ọdun mẹrindinlogun.
Meji ninu wọn lo ti pada bọ sipo alaafia ti mẹta si ti ku.
Ó wó àgọ́ rẹ̀ lulẹ̀,bí ìgbà tí eniyan wó ahéré oko.
Iwe irinna tuntun ti wọn fẹ ẹ fi sita yii laarin oṣu mẹrin ni yoo fi aaye gba awọn arinrinajo igbafẹ lati wọ orilẹ-ede naa laimọye igba fun ọdun marun o le.
nígbà tí mo ti yan àwọn adájọ́ láti darí Israẹli, àwọn eniyan mi.
Òfo ni yín, òfo sì ni iṣẹ́ ọwọ́ yín,ẹni ìríra ni ẹni tí ó bá yàn yín.
O ni koda oun fi imoore han pe wọn ronu kan oun lati fi siru ipo ẹlẹgẹ bẹẹ.
Bí a bá sọ wá di ọ̀kan náà pẹlu Jesu ninu ikú, a óo sọ wá di ọ̀kan náà pẹlu rẹ̀ ninu ajinde.
Ibeere ti ọpọ eeyan si n beere ni pe se ojulowo iwe idanwo isiro WAEC ree abi ayederu, nibayii ti awọn akẹkọọ yoo joko se idanwo Isiro naa lonii ọjọ Aje.
Ó sì sọ Èkó di ibi àmúyangan – ibi iyì, ibi ẹ̀yẹ.
Ijoba orile-ede ohun so pe,”isele naa ni o lagbara julo ninu isele omiyale ti o ti n waye lorile-ede ohun seyin.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Oronpoto Animation: Akin Alabi ní kò dára bí eré aláwòrán fáwọn ọmọdé ṣe jẹ́ aláwọ̀ funfun Sugbọn ilẹ pooyi fun wọn lọjọ naa, nigba ti awọn ọdẹ ibilẹ to wa nilu naa gba ya wọn, ti mẹta ninu wọn si juba ehoro.
Pásítọ̀ gún ìyàwó rẹ̀ lọ́bẹ nínú ṣọ́ọ̀ṣì, ló bá tì í bọ ara rẹ̀ náà níkùn Wo àwọn ọ̀tá tó ń da orílẹ̀èdè Nàìjíríà láàmú Kano: À ti fa àwọn oníbalòpọ̀ akọsákọ tí a mú le òbi wọ́n lọ́wọ́- Ọlọpàá Hisbah Bauchi State: Okú 596 ló ṣì ń gba owó oṣù Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Inu mi bàjẹ́ nígbà tí mo bí i, odidi oṣù mẹ́ta, mi ò lè gbàdúrà s'Ọ́lọ́run' Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Adamu ti wa di eni to n gba awon eniyan ni iyanju lati ma a gba abẹrẹ ajesara ni igbakugba fun awon ọmọ won lati dena aarun to le gba ẹmi wọn.
Lara wọn lo tun ma n tun pẹpẹ ile ijọsin ṣe, ti wọn si tun ma n gba ọrẹ.
Owo ni wọn fẹ ẹ gba lọwọ awọn eniyan wa.
Ileejọ Magistrate ti Ikẹja nipinlẹ Eko ti dajọ ọdun meji latimọle fun ọdọmọkunrin Kabir Rabiu.
Farao bá sọ fún Josẹfu pé, “Wò ó, lójú àlá, bí mo ti dúró létí bèbè odò Naili, 
” Mo kó wọn jọ, mo sì dá wọn pada sí ààyè wọn.
Aposteli Suleiman Johnson ni nitori iru awọn akoko bayii ni awọn iranṣẹ Ọlọrun gbogbo wa fun.
Oko oju ofurufu ti o fi Ilu Dubai se ibujoo seleri kikun fun iwadii naa.
Lẹyin osu diẹ ti ọrọ naa ja rain-rain wọn pada so yigi fun tọkọ taya naa, ti aya gomina si gba ile fun wọn pẹlu silu Ilorin lati maa gbe.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Sex workers strike: Àwọn aṣẹ́wó kílọ̀ fún Buhari kó dá'wó epo padà, bíbẹ́ẹ̀kọ̀, ìyanṣẹ́lódì ló kù 25 Owewe 2020 Laarin ọpọlọpọ eeyan lagbaye, iṣẹ aṣẹwo ni wọn mọ gẹgẹ bi iṣẹ to dagba julọ lagbaye.
''Ko si ohun ti ẹgbẹ PDP fẹ ṣe lori ọrọ Ile Arugbo ti ijọba wo, PDP ko ni tori rẹ lọ si ile ẹjọ,'' Ọgbẹni Shittu lo woye bẹẹ.
Gẹgẹ bi ṣe gbọ, ikọ tuntun yii yoo ni oniruuru ẹwu ti wọn yoo maa wọ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Free Pad: Scotland ti di orílẹ̀-èdè àkọ́kọ́ tó bẹ́rẹ̀ pínpín páàdì ǹkan osu fún gbogbo obìnrin lọ́fẹ̀ẹ́ 25 Bélú 2020 Oríṣun àwòrán, Getty Images Orílẹ̀-èdè Scotland ti di orílẹ̀-èdè àkọ́kọ́ to n pin ìlédìí ìkàn oṣù lọ́fẹ̀ẹ́ fún gbogbo obìnrin.
” Nígbà tí ó ti fi òkèlè run ọbẹ̀, ó mú un fún Judasi ọmọ Iskariotu.
Oba Balogun wa fi kun un  pe ,awon pe ipade yii lati pe akiyesi ara ilu Ibadan
Ọpọlọpọ orílẹ̀-èdè ni yóo parapọ̀ láti di eniyan mi nígbà náà.
Ogbeni Usman Arabi, to jẹ ọga agba ẹka ọrọ ara ilu nile iṣẹ mọnamọna NERC kede ninu atẹjade kan pe irọ to jina si ootọ ni iropyin naa.
Ní ọjọ́ náà, odi yóo gbọ́ ohun tí a kọ sinu ìwé,ojú afọ́jú yóo ríran, ninu òkùnkùn biribiri rẹ̀.
Pẹlu gbogbo ohun ti ẹ ti ka yii, a lero pe ẹ le gbe igbesẹ to dara lori abẹrẹ ajẹsara naa to ba ti wa ni arọwọto yin.
Ẹwẹ, nipinlẹ Kwara, to jẹ ara ilẹ Oodua, ẹgbẹ oselu APC ṣẹṣẹ kede orukọ awọn eeyan to yege lati dije fun ipo gomina nibẹ.
Ní àkókò náà ni OLUWA bẹ̀rẹ̀ sí dín ilẹ̀ Israẹli kù.
"Aláàfin tó rí ìbẹ̀rẹ̀ àti opin sáà gómìnà mọ́kànlélógún l‘Oyo Àwọn olorì Aláàfin fi oríkì awúnilórí yẹ́ ọkọ wọn sí fún àádọ́ta ọdún tó gorí ìtẹ́ Àwọn onílù mí ló ń tú àṣírí ìkà èèyàn tó bá wọ ààfin mi - Aláàfin Bí Gómìnà Makinde bá ṣẹ̀ mí, lẹ́tà lásán ló jẹ mí- Aláàfin Ọ̀yọ́ Ọba Lamidi Adeyẹmi, òṣìṣẹ́ adójútòfò àti Abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò kó tó jọba ""Mo nifẹ baba laiṣẹtan, gẹgẹ bi ọmọ."
Gomina ipinlẹ Edo, Godwin Obaseki ti fi ẹgbẹ oṣelu APC silẹ lẹyin ọpọlọpọ awuyewuye lori yiyọ ti wọn yọ ọwọ rẹ kuro lawo idije fun ipo gomina labẹ aṣia ẹgbẹ oṣelu APC ni ipinlẹ Edo.
Oríṣun àwòrán, Instagram/Okunnu_1 ''Ẹni to lọ ṣoogun owo kẹyin to wo ere tiata tan ti fẹ ṣe oogun tẹlẹ ni, kii ṣe pe ninu ere tiata lo ti rii,'' Okunnu lo woye bẹẹ.
Ní ọjọ́ kan ní àkókò tí Dafidi ọba ń gbe ààfin rẹ̀, ó sọ fún Natani, wolii, pé, “Wò ó, èmi ń gbé ilé tí a fi igi kedari kọ́, ṣugbọn Àpótí Majẹmu OLUWA wà ninu àgọ́.
O salaye pe, igbese ohun ni lati seto idanileko fun awon odo ni orisirisi ona eto ogbin.
Fún àpẹẹrẹ; “Bá mi na ỌMỌ mi, kò dẹ́nú ọlọ́mo.
Gold Kolawole, ọmọ tó sọnù ní ṣọ́ọ́ṣì Sotitobire kò bá pé ọdún méjì lónìí Daddy Freeze túbá!
”Aare tun wa ro gbogbo omo orile ede Naijiria lati tubo maa gbaruku ti awon asoju yii pelu adura ati atileyin olokan-o-jokan.
OLUWA ní, Nígbà tí ó bá yá, tí àkókò bá tó, a óo wá ẹ̀ṣẹ̀ tì ní Israẹli ati Juda; nítorí pé n óo dáríjì àwọn tí mo bá ṣẹ́kù.
 awon kan ti wi pe zardari ni ikan larin awon olowojulo marun ni pakistan pelu idiye iyi ohun ini to to us $ 1.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Àbẹ̀wò Buhari sí Eko: Àwọn ọ̀nà láti yàgò fún àyàfi tí ẹ ba gbé ibùsùn dání 23 Ìgbé 2019 Oríṣun àwòrán, @MBuhari Aarẹ Muhammadu Buhari yoo ṣe abẹwo si Ipinlẹ Eko ni Ọjọru lati ṣi awọn iṣẹ akanṣe ti ijọba Ipinlẹ Eko ṣe labẹ iṣakoso Gomina Akinwunmi Ambode.
 A wa ri i pe bi awọn ara ilu naa ba ni iye kan ti wọn n san gege bi owo ti ko to owo ti wọn le lo fun iwosan, ti o maa jẹ pe ọpọlọpọ ile-iṣẹ, ati awọn tỌlọrun bukun yoo le ṣeranwọ fun awọn to ku diẹ kaa to fun lat le ni anfani si eto ilera to peye.
 Ó ti fi ìgbàkan jẹ ́ alága nigerian bar association ti ẹ ̀ ka calabar .
100 ọjọ́ fún Alaa: Ẹbí ajàfúnẹ̀tọ́ ọmọ Íjípìtì ń ka ọjọ́ fún ìdásílẹ̀ẹ rẹ̀ nínú ẹ̀wọ̀n
Ilu Manchester City - Aymeric Laporte: O yẹ ki a rii iyipo pada Aymeric Laporte lati Athletic Bilbao si Ilu Manchester City loni.
” Ó yí kẹ̀kẹ́ ogun rẹ̀ pada, ó ń sá lọ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Alaafin of Oyo: Wo olorì Aláàfin tí àwọn èèyàn ń pariwo pé ó jọ Bobrisky 21 Agẹmo 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 22 Agẹmo 2020 Oríṣun àwòrán, Instagram/Olori anu ati Bobrisky Gbogbo ọmọ Naijiria lo fẹẹ mọ Bobrisky, iyẹn Idrisu Okunẹyẹ, Ọdọkunrin to n ṣe iṣe obinrin, to n mura bii obinrin.
Mo ri i pe wọn ko tan ina ile rẹ, ọkọ ayọkẹlẹ rẹ ko si si ni ita.
Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Wo tuntun tó ṣẹlẹ̀ lágbo àwọn òṣèré Yollywood bíi Femi Adebayo, Odunlade Adekola, Toyin Abraham, Funke Akindele lọ́sè̩ yìí5 Owewe 2020 Fídíò, Akomolede: Bolaji Faleke ni Olùkọ́ tó ń kọ́ wa ní àṣà oge ṣiṣe lórí BBC Yorùbá1 Owewe 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
O ni isẹlẹ naa waye nitori pe iya wọn ma n pẹ ko to o kuro ni ibi to ti n ta ọja.
Kí ẹ ṣe é gẹ́gẹ́ bí ẹ ti ní tó.
Ati pe awọn ti fi iṣẹlẹ yii to olu ile iṣẹ Agunbanirọ to wa ni Abuja leti bi o ti yẹ labẹ ofin.
Gẹgẹ bii atẹjade kan ti akọwe iroyin fun igbimọ lọbalọba ilu Akurẹ, Adeyẹye Micheal fi sita, lọdọọdun ti ọdun yii ba ti fẹ waye lati igba iwasẹ wa ni wọn ti maa n ti ọja pa fun ọjọ kan ti ajọdun naa yoo fi waye.
Èmi àti Sanyeri ti tọrọ oúnjẹ jẹ rí nílé oninawo torí ebi, ká tó di gbajumọ oṣere Bukky Wright ṣ'ọjọ́ ìbí, Lizzy Anjorin f'orin bọnu, Femi Adebayo sọ ẹran àgbò rẹ̀ lórúkọ tuntun Saheed Balogun sìnkú ìyá rẹ̀, Ogogo ní ẹgbẹ́ agbábọ́ọ̀lù!
Nitori idi eyi ni a fi n keesi gbogbo ẹlẹyinju aanu lati fi ifẹ han si awọn to kudiẹ kaato fun.
Seyi Makinde-Olaniyan: Igbákejì Gómìnà Oyo ní kò síjà láàrin òun àti Gómìnà
Labẹ akoso Gomina ipinlẹ Ondo, Rotimi Akeredolu gẹgẹ bii adari, o ti wa delẹ bayii ṣugbọn o tun da bi ẹni pe awọn kan o fẹ lọwọ si i to si jẹ pe pataki ni wọn ninu ọrọ to wa nilẹ yii.
Ọjọ́ yi gan si ni Aarẹ Buhari gbera kuro nile lọ si orileede China.
Ẹjọ́ tí wọ́n bá dá fun yín ni kí ẹ gbà, kí ẹ sì tẹ̀lé gbogbo ìlànà tí wọ́n bá là sílẹ̀.
Sara, aya oluwa mi bí ọmọkunrin kan fún un lẹ́yìn tí ó ti di arúgbó, ọmọ yìí sì ni oluwa mi fi ohun gbogbo tí ó ní fún.
Awon oloja fi idunnu won han nigba ti igbakeji aare n lo  lati iso si iso lati lo ba won soro ni kọọkan.
Ni kete ti isẹlẹ́ yii waye, ti ori si ko Yẹmi Ọsinbajo yọ, lo ba wọ inu ọ̀kọ lati kuro nibẹ.
O ni bi o tilẹ jẹ pe awọn parọwa sawọn oluwọde lati tuka ki aago mẹrin irọlẹ to lu, amọ arọwa awọn ko se aseyọri ni Lekki.
Orilade fikun ọrọ rẹ pe, Mailey nikan kọ ni awọn fi panpẹ ọba mu, awọn miiran to wa pẹlu rẹ naa wa lara awọn ti awọn mu.
Igbakeji aare soro yii lasiko ipade
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Omar Al-Bashir ti wọ́n gbajọba lọ́wọ́ ẹ ló di wàhálà Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Omar Al-Bashir ti wọ́n gbajọba lọ́wọ́ ẹ ló di wàhálà 3 Òkùdu 2019 Iroyin ni ẹ̀mí mẹjọ lo ti lọ sinu iwọde naa.
Sọ fún mi, èló ni o fẹ́ máa gbà?
Nkan ti ko dara ni pẹlu!
Bí wọ́n ti ń jà, àárẹ̀ mú Dafidi.
Aarẹ Muhammadu Buhari ti ke si awọn Fulani darandaran ni Guusu iwọ Naijiria lati da asẹ ẹgbẹ Northern Elders Forum (NEF) nu to ni ki wọn pada wa si oke ọya ni kiakia.
Èèyàn tó fi tiẹ̀ sílẹ̀, Tó ń gbọ́ tẹni ẹlẹ́ni; Ọba-òkè nìkan ní í bá wọn gbọ́ tiwọn.
Olóòtú ìjọba Gẹ̀ẹ́sì yan ọmọ Yorùbá ní Mínísítà Òṣèré tíátà, Kemi Afolabi dùbúlẹ̀ àìsàn ní ìlú Mecca Ìbọn pa èèyàn mẹ́ta lásìkò ayẹyẹ Ọdun Oúnjẹ Inú mi dùn pé ẹni tó gbà ìjọba lọ́wọ́ mi ń san gbèsè tí mo fi kalẹ - Aregbesola 3.
Agbẹnusọ awọn ọlọpaa ni ipinlẹ Oyo, Olugbenga Fadeyi lo fi idi ọrọ naa mulẹ fun BBC.
Àwọn ǹkan míràn ti yóò tún wáyé lásìkò ipele kejì yìí rèé.
Àṣírí ilé tí wọ́n ti ń fipá bá àwọn ọmọdékùnrin lò tú síta Ọdún méjì, wàhálà méjì lójúbọ Osun Osogbo, Wo bí o ṣe lè ṣe eré ìdárayá tí yóò fún ọ ní adùn àti okun fún ìbálòpọ̀ Àráàlú yarí fún fásitì Babcock fún bo ṣe lé akẹ́kọ̀ọ́ tí wọn bá lòpọ̀ nínú fídíò Ìbálòpọ̀ ọ̀lọ́jọ́ méje mú kí ilé ẹjọ́ tú ìgbéyàwó ọdún mẹ́wàá ká ní Ibadan Bawo lo ṣe yẹ ki eto naa lọ?
Megan ti gba ami ẹyẹ bii ti NWSL Sheild pẹlu Reign FC lẹẹmeji yatọ si ti goolu olimpiiki ati ti ife ẹyẹ agbaye ẹẹmeji bayii.
Ọladapọ ni, ojisẹ Ọlọrun ni oun, bẹẹ ni oun ko mu ẹmu ri debi eroja Codeine, kii si se orogun iya oun lo duro bii iya oun lọjọ igbeyawo naa.
Ko si si ọba alaye ti yoo ni bawo ni ti Alaafin se jẹ nitori odu nla ni, kii se aimọ fun oloko, ko si si ẹni ti yoo kọ iyan rẹ, ti ko ni fi ewe boo.
Awon gomina lati ekun Ariwa ti
Wọ́n dá a lóhùn pé, ‘Nítorí ẹnikẹ́ni kò gbà wá síṣẹ́ ni.
Dolapo ko le ọlọmọ maruun sita,ko ba nile'' Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: ‘Isẹ́ tíátà pé mi láì mú nkàn míì mọ’ Mr Latin: Ó ṣeéṣe kí TAMPAN àti ANTP di ọkàn lọ́jọ́ iwájú, tí.
"Ikú Adewole Oniluola, tó ní ẹ̀bùn ìlù lílù jùlọ lágbàyéé, yóò nípa lórí Yorùbá - Tunde Kelani Ayinla Ọmọwura, orin èébú àti oríyìn lo fi di ọ̀rẹ́ àwọ̀n obìnrin Ẹ wo ojú àwọn afurasí tí yóò rojọ́ ẹ̀ṣùn àjẹbánu lọ́dún 2021 Bí Nàíjíríà bá fẹ́ kí ọdún 2021 dára, ohun tí yóò ṣe rèé - Obasanjo Ẹgbẹ́ ọ̀dọ́ méjì fìjà pẹẹ́ta, ẹ̀mí kan bọ́, ọ̀pọ̀ farapa ""Ipò àpọ́nlé tí mo fi pásítọ̀ Bakare sí kò le yingin, Mó dúpẹ́ lọ́wọ́ Mogaji àti ọgbẹ́ni Dele Momodu, fún ọ̀nà ti wọn gbà láti yanjú aáwọ̀ náà."
O ti sọ mí di ẹni àmúpòwe láàrin àwọn eniyan,mo di ẹni tí à ń tutọ́ sí lára.
Ẹ jọwọ, ẹ tun oju opo iroyin yi yẹwo, ki ẹ lee ri ẹkunrẹrẹ iroyin ọtun laipẹ.
 adu ati awon apilese miran n sise bi imule sinsin lati dena ifo ninu atomu ayonu .
Koda, nko lee mu ara ro mọ.
A gbọ́ pé olóògbé ẹni ọdún mọkànleláàdọ́ta náà ń lọ ṣe ìpàdé kan ni ilú Eko ní ọjọ Etì ni àárẹ̀ ba mu tí wọn sì gbe lọ ilé ìwòsan níbi tí ó ti gbẹ́mìí mì.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Zlatan: Ọ̀rẹ́ ni mo sìn lọ ‘studio’ tí mo fi bẹ̀rẹ̀ orin lẹ́yìn tí mo kùnà ìdánwò WAEC Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Gẹ́gẹ́ bí ó ṣe sọ ọ́, ipò àwọn tọ́rọ̀kàn nínú tí di mímọ̀ láìpẹ́ yìí lásìkò tí olùdíje fún ipò ààrẹ tẹ́lẹ̀rí Alhaji Mumakai Unagha.
Ni wọ́n fi n ki gbogbo àwọn Ìkamọ̀dù pé:
Ọkọ̀ tí ó nbọ̀ láti iwájú ṣeérí láti òkèrè nítorípé ọ̀nà tààrà ni ọ̀nà nlá yìí nṣe.
Èlé lori idokoowo yoo ja walẹ - Lasiko ti ọrọ aje orilẹ-ede ko ba lọ deede, èlé to n gun ori owo idokowo yoo ja walẹ.
Nítorí ẹni tí ó ga ju ọ̀gá àgbà lọ ń ṣọ́ ọ̀gá àgbà.
Nígbà tí ó bá ṣe, wọn á wó lulẹ̀ tigbòǹgbò-tigbòǹgbò.
bí o kò bá mọ bó ṣe ńrí, òó kàn máa tiraka lásán ni.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ogun flood: ọ̀ps àwọn olùgbé agbegbe yii ti fi iṣẹ́ sílẹ̀ nítorí wọn kò lè jáde Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Òun ni ẹ óo fi jẹ́ eniyan mi, tí èmi náà óo sì fi jẹ́ Ọlọrun yín.
Ọpọlọpọ awọn eniyan lo ti bu ẹnu atẹ lu bii ijọba se fi Ọmọyẹle Sowore si atimọle ni Olu ile isẹ Ajọ DSS ni ilu Abuja.
O ni awọn mẹrin naa ti wa ni ile iwosan ti wọn ya sọtọ fun awọn to ni arun Covid-19, eyi to wa ni Olodo.
Ọba Siria dáhùn pé, “Tètè lọ, n óo sì fi ìwé ranṣẹ sí ọba Israẹli.
Bí Ṣalimani ti pa Betabeli run, ní ọjọ́ ogun, ní ọjọ́ tí wọ́n pa ìyá tòun tọmọ; 
Bukola Saraki kò kọjá òfin - EFCC EFCC tun gbe Akala yọju sile ẹjọ Olùdásílẹ̀, akẹ́kọ̀ọ́ iléẹ̀kọ́ Yahoo-Yahoo wọ gàù EFCC Gẹgẹ bi atẹjade naa ti ṣe sọ, oludari ileeṣẹ naa ko tẹle ilana to yẹ nipa pipin owo to yẹ ki wọn fun awọn oniṣowo kaakiri ijọba ibilẹ mẹẹdogun ipinlẹ Kwara.
Pásítọ̀ Bakare kéde orúkọ àwọn ọ̀tá tó ń da Nàìjíríà láàmú
Iṣọri kẹta ni nini ifẹ Naijiria tọkantọkan: Ofin yii ni wọn gbe kalẹ lati ṣe koriya fun lilo awọn eroja ta n pese labẹle, eyi ti yoo mu agbega ba awọn Ileesẹ nlanla to wa ni Naijiria.
Bi awọn eniyan Iran ṣe n ṣe iwọde lodi si aṣiṣe ti awọn adari wọn ṣelori ọkọ ofurufu to jabọ naa ni wọn ti mu aṣoju ile Gẹẹsi kan Àwọn ọmọ Iran yarí mọ́ ìjọba lọ́wọ́ lẹ́yìn tó jẹ́wọ́ọ jíjá bàálù Ukrain lulẹ̀ Rob Macaire ni wọn mu fun wakati mẹta ni ilẹ Iran to jẹ ọmọ United Kingdom lori ofin agbaye.
Wọ́n di ẹni ẹ̀gàn ati ẹni àrípòṣé, gẹ́gẹ́ bí ẹ ti rí i lónìí.
” Ní kété tí ọba sọ̀rọ̀ yìí tán, wọ́n faṣọ bo Hamani lójú.
O tesiwaju ninu oro re wi pe sise eyi, yoo mu alekun ati idagbasoke deba eto oro-aje orile-ede Naijiria.
" Ẹ̀jẹ̀ mi ni Jésù, n kò sì tíì dé ibi tó ń mú mi lọ.
Ṣugbọn Ọlọrun ti yan àwọn nǹkan tí ayé kà sí agọ̀ láti fi dójú ti àwọn ọlọ́gbọ́n, ó yan àwọn nǹkan tí kò lágbára ti ayé, láti fi dójú ti àwọn alágbára; 
Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Aláàfin ní tí kìí bá ṣe òṣèlú ni, Ìwó ló yẹ kó jẹ́ olú ìlú ìpínlẹ̀ Osun2 Bélú 2020 Ọba mẹ́wàá tí wọ́n ti lé kúrò nípò: Alaafin, Ọlọ́wọ̀, Elérúwà , Awujalẹ àti .
Alukoro ọlọpaa ipinlẹ Oyo, Olugbenga Fadeyi sọ fun BBC Yoruba pe awọn n ṣe akitiyan lati doola wọn ki wọn si fi panpẹ ofin mu awọn kọlọransi ẹda to ji wọn gbe ọhun.
Abdurasheed Maina: Adájọ́ ní kí ọ̀gá àjọ tó rí sí owó ìfẹ̀yìntì tẹ́lẹ̀ sí wà látìmọ́lé
Ọ̀pọ̀ òrùlé ilé ni atẹ́gùn òjò náà gbé lọ; tí àwọn òpó iná àti ìbánisọ̀rọ̀ pẹ̀lú pátákó ajúwe ọ̀nà pẹ̀lú wó lulẹ̀.
Ẹyẹkòsọkà, ọba ti ránńṣẹ́ sí ọkùnrin yìí, nígbà tì ó dé tí ó sọ fún ọba pé òun kò lè sọ ohun ti ó ń pá òun lẹ́rìn-ín inú bí ọba ó sì wí fún un pé pípa ni òun ó pa á ọkùnrin náà sì gbà bẹ́ẹ̀ fún ọba.
Awọn ajagunfẹyinti naa, ti wọn jẹ ẹya Yoruba, ninu eyi ti a ti ri David Medayese Jẹmibẹwọn ati Ajibọla Togun ni, ko si ohun to buru ninu ohun ti Ọbasanjọ se yii, gẹgẹ bo se n sugba Atiku lati di aarẹ Naijiria lọdun 2019.
Kí lo mọ̀ nípa ìgbeyàwó Àbẹ̀ẹ́lẹ̀, Àṣàǹte, Ọkọ Káalẹ́ àti Gbàmí o ràmí?
Ó kọjú sí bàbá mi ó fi èso igi tí ń bẹ lọ́wọ́ rẹ̀ fún un ó si wí pé: gbá eléyìí, mo ti dán an wò lójú rẹ ó sì ti jẹ́, ìgbàkígbà tí ìjàǹbá bá dé, sọ ọ́ si ẹnu, dárúkọ ǹkan tí iwọ ba fẹ láti dà ìwọ yóó si yí padà si ǹkan náà wéréwéré.
O da ẹbi yii sori ọrọ gbọyi sọyii laarin awọn ologun abẹle ati awọn orilẹede agbaye."
O ni awọn ọmọ ogun orileede Naijiria ti gba gbogbo agbegbe ti Boko Haram gba lọdun 2014 pada lọwọ wọn.
Èmi Ọba tí wọ́n ń kó jẹ nígboro- Oluwo ti ilú Iwo Nǹkan mẹ́sàn án tí Mùsùlùmí gbọdọ̀ ṣe nínú oṣù Dhual- Hijjah Bawo lo ṣe le wo eto BBNaija?
ìlú kan rèé l'Abuja tí kò mọ̀ rárá nípa Covid-19 Àwọn òbí àti àbúrò mi kò le sọ̀rọ̀- Ifeoluwa Anthony Joshua ni ìwúrí ọmọ ọdún méje tó ń kàn'ṣẹ́ yìí ‘Ẹsẹ kikan kọ mi lati di alagbara’ 'Obinrin lo mu mi fẹran orin kikọ' Ẹ wo òtítọ́ ọ̀rọ̀ nípa bí àwọn agbébọn ṣe wó ile ní iléèṣẹ́ aṣojú Nàìjíríà ní Ghana Wọ́n ti pàṣẹ lọ rọọ́kún nílé fún òṣìṣẹ́ káńsù tó lú obìnrin kan ní ìpínlẹ̀ Ogun Èyí tí a wò jùlọ 5:03 Fídíò, Omolola Arohunmolase Welder: Mo ti fí iṣẹ́ 'Welder' gbayì láwùjọ, tó mo fi tọ́ ọmọ yanjú, Duration 5,039 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 5:39 Fídíò, Akomolede ati Asa lori BBC: Olùkọ́ Kikelomo Ogunboye tan ìmọ́lẹ̀ sí ìwà olè ọ̀gá ọlọ́pàá Audu gẹ́gẹ́ bí àwòkọ́ṣe àsìkò yìí, Duration 5,398 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 4:11 Fídíò, Oba Adeyeye Ogunwusi: Ojú mi ti rí lọ́pọ̀ lọpọ̀, ọ̀pọ̀ èèyàn ni kò tilẹ̀ gbàgbọ́ pé mo lè jọba- Ooni, Duration 4,117 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 4:43 Fídíò, Promise Akinlade: ọmọ ọdún mọ́kànlá tó ń fi ìlù dárà bíi àgbàlagbà sọ̀rọ̀ nípa tálẹ́ǹtì rẹ̀, Duration 4,437 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 0:59 Gbọ́, Ìsẹ̀lẹ̀ jákèjádò orílẹ̀èdè àgbáyé láàárín ìṣẹ́jú kan, Duration 0,59wákàtí 5 sẹ́yìn 7:03 Fídíò, Olumuyiwa Bolade Adedeji Military Bruitality: Bí arákùnrin onípèníjà ara tí sọ́jà lù ṣe dé, Duration 7,035 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 4:45 Fídíò, Yoruba Films: Ẹ̀ẹ́ bẹ̀ mi kúrò láyé ni, mi ò lè kú - Fadeyi Oloro, Duration 4,4526 Èrèlè 2020 2:48 Fídíò, Esther Ajayi: Èmi náà ti borí ìṣòro rí ló ń mu mi ṣojú àánú, Duration 2,481 Ògún 2019 6:08 Fídíò, Adebola Ademilua: Àìrísẹ́ ṣè lẹ́yìn ìwé kíkà ló sọ mi dí ìyá onírú, mo dúpẹ́ tèmi, Duration 6,0827 Bélú 2020 2:36 Fídíò, Sotitobire: Ìdájọ́ òdòdò ló fẹsẹ̀ múlẹ̀ lórí ọ̀rọ̀ Pásítọ̀ Sotitobire - Agbẹjọ́rò fún ìjọba, Duration 2,367 Ọ̀wàrà 2020 BBC News, Yorùbá Ìdí tí ẹ fi le è nígbàagbọ́ nínú ìròyìn BBC Ìlànà Lílò Nípa BBC Òfin Àṣírí Cookies Kàn sí.
Àwọn ọ̀dọ́ oníwọ̀kuwọ̀ àtàwọn tó ń tàbùkù èdè Yorùbá ti wọ gàù Amọtẹkun de!
Ẹ fi burẹdi tí ó ní ìwúkàrà rú ẹbọ ọpẹ́, ẹ kéde ẹbọ àtinúwá, kí ẹ sì fọ́nnu nípa rẹ̀; nítorí bẹ́ẹ̀ ni ẹ fẹ́ máa ṣe, ẹ̀yin ọmọ Israẹli.
Wọ́n yọ 'aṣofin olóorun' nílé aṣòfin Èkìtì Amẹrika àti North Korea fi ìtàn àlàáfíà lélẹ̀ 'Ò yẹ kí Nàìjíríà lo àwọn agbábọ́ọ̀lù tuntun' Ọgbẹni James to jẹ baale ile ọhun ni oun féran lati maa gbọ iroyin ati lati maa wo bọọlu ni eyi ti awọn to ku kò fẹran ṣugbọn inu oun dun pe ẹbi oun ti gbagbọ ninu Naijiria pe, Super Eagles a de ipele keji to kangun si aṣekagba ni Russia.
Sẹ́nétọ̀ Dino Melaye kéde láti dupò gómìnà Kogi Amẹ́ríkà ń béèrè ìròyìn facebook, email arìnrìnàjò tó f'ẹ́ gbà'wé àṣẹ EFCC ju Babachir silẹ 'Ọmọ SS 1 mu èso olómi, ṣùgbọ́n ilé ìwé wa kọ́ ló kú sí' 'Èmí ló nilé tí EFCC tì pa kìí ṣe Fayose' Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
" Wo àwọn orilẹ́èdè àgbáyé tó ti sí pápákọ̀ òfurufú wọn fún ìrìnàjò N kò gba ₦4bn lọ́wọ́ Magu, ẹ má ró àjẹbánu mọ́ mi láṣọ - Osinbajo pariwo Ìtàn ayé Henry Fajemirokun, olówó tó fi owó mọ Olúwa àti ènìyàn Coronavirus tún gbẹ̀mí dókítà míì l'Ondo Ṣaaju ni iroyin kan ti kọkọ jade pe akọwe ile naa, Adeyelu Bode sọ pe ile ọhun ti fun Agboola Ajayi ni iwe ifitonileti naa.
Makinde júwe ilé fún Kọmíṣọ́ná iṣẹ́ òde, ó ṣe pàsípàrọ̀ àwọn kọmíṣọ́nà méjì míì Ẹ̀kún omi ń bọ̀ yanturu nílẹ̀ Yoruba, ẹ̀yin gómìnà, ẹ gbaradì - NEMA ń lọgun Ṣé àbáwọle sójú òpó NPF policerecruitment.
- Olorì Naomi Wọn tí fòfin de iléeṣẹ́ ìròyìn Chris Oyakhilome nítorí ó sọ pé 5G ló ṣokùnfà àrùn Coronavirus Ọmọilẹ Cameroon pa ọga rẹ ni Park View Estate Oríṣun àwòrán, others Ọkan lara awọn iṣẹlẹ to tun jẹ ibanujẹ ni eyi to waye logunjọ, oṣu Kejila, ọdun 2019 ni Parkview Estate, nilu Eko.
Idi si niyi ti BBC Yoruba fi jade sita lati ba awọn ilumọọka agbohunsafẹfẹ sọrọ nipa iriri wọn lknu isẹ ati awọn ipenija to n koju wọn.
Nigba ti yoo parí ọrọ rẹ, Sẹnetọ Adeleke ni.
 ""Fun apẹrẹ, ipinlẹ Eko lee gbe owo kalẹ fun ikọ Amotekun nipinlẹ rẹ ju ipinlẹ Ọsun lọ, sugbọn gbedeke yoo wa lori iye to kere julọ ti ipinlẹ kọọkan gbọdọ gbe kalẹ."
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Gani Adams gb'oriyin fun'pinlẹ Eko lori igbelarugẹ ede Yoruba 14 Èrèlè 2018 Oríṣun àwòrán, @AkinwunmiAmbode Àkọlé àwòrán, Gani Adams gb'oriyin fun'pinlẹ Eko Aarẹ Ọna Kakanfo ilẹ Yoruba, Gani Adams ti s'apejuwe Gomina Akinwunmi Ambọde ti ipinlẹ Eko gẹgẹbi aṣaaju nipa gbigbe ede Yoruba larugẹ.
Ọjọ́dọ́gba ìgbà ìwọ́wé bọ́sí 21 Ọ̀wẹ́wẹ́ (ọsù kẹsàn-án), tí nṣe àná!
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ayinla Kollington: ọ̀rẹ́ ni èmí àti Barrister kó tó jáde láyé Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Ayinla Kollington: ọ̀rẹ́ ni èmí àti Barrister kó tó jáde láyé 31 Agẹmo 2019 Omo ni Wasiu Ayinde Marshall jẹ́ si mi -Kollington.
Àbí o ti jẹ ninu èso igi tí mo pàṣẹ fún ọ pé o kò gbọdọ̀ jẹ?
21 Ìgbé 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 28 Ìgbé 2020 Oríṣun àwòrán, Getty Images Arun Coronavirus bẹrẹ ni ipari ọdun 2019, amọ o le e ṣe diẹ ki awọn eniyan to ba ni arun naa to ri iwosan gba.
fọ́n owó ká fáwọn èrò lẹ́yìn tó pariwo 'Merry Christmas' Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Wọn kò kọ iṣẹ́ ọwọ́ wọn tí wọn ń bọ sílẹ̀.
Bẹ́ẹ̀ ni ẹ óo ṣe mú ohun burúkú yìí kúrò láàrin yín.
ti ijoba apapo gunle ni lati fopin  isẹ
Ìranú ati Àìnírònú ńfi ọwọ́ kọ́ ara lọ́rùn nìbi tí Òfò ti ńṣe sisí, tí Àìbìkítà sí ńṣe ojúlόwό Ọkùnrin.
Sugbọn ọpọ eeyan ni ko mọ pe Igbo kiji-kiji kan wa nipinlẹ Ondo lagbegbe ilu Okegbo, tii se ilu abinibi Fagunwa, ti wọn n pe ni Igbo Olodumare.
” “Mo n fojusona fun idije World Championships ti yoo waye lorile-ede Hungary, bee si ni ifigagbaga yii yoo se anfaani fun wa lati fi gbaradi saaju idije agbaye ohun.
O fi kun pe, baba oun lo tun ja fun ilu Ibadan, ti ọba wọn fi kuro ni Baalẹ lasan, to si di ọba alade, ti wọn n pe ni Olubadan ni oni.
OLUWA bá Jeremaya sọ̀rọ̀ ní ìgbà ayé Jehoiakimu ọmọ Josaya, ọba Juda; ó ní, 
Ó wá rọ ìjọba láti sètọ́jú àwọn ọlọ́pàá dáadáa bí wọn kò bá fẹ́ kí wọn máa gba àbẹ̀tẹ́lẹ̀.
Bí mo bá tilẹ̀ ṣe ìdájọ́, òtítọ́ ni ìdájọ́ mi, nítorí kì í ṣe èmi nìkan ni mò ń ṣe ìdájọ́, èmi ati Baba tí ó rán mi níṣẹ́ ni.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, End SARS, End SWAT: Ó pé mi bí SARS kò ṣe sọ mí dolówọ́- Fulani Kwajafa Mi ò mọ̀ nípa àwọn tọ́ọ̀gì tó da ìwọ́de EndSARS Alausa rú, mo ṣì wà lẹ́yìn yín digbí!
A mú àwọn olótìítọ́ kúrò, kò sì sí ẹni tí ó yé,pé à ń yọ olódodo kúrò ninu ìdààmú ni.
ọkọ̀ ojú omi tuntun bẹ̀rẹ̀ iṣẹ́ Ìbéèrè àti ìdáhùn pẹ̀lú Seyi Awolowo ti BBNaija lórí BBC Yorùbá Ìran Yorùbá: Àṣà ju àṣà lọ!
2019: Marlian, òfégè ìgbéyàwó Buhari, Fatoyinbo àtàwọn ìṣẹ̀lẹ̀ ńlá tó mi ìgboro tìtì ní 2019
Ògiri àgbékà tí ó wà ní òkè patapata kò nípọn tó ti èyí tí ó wà ní ààrin, ti ààrin kò sì nípọn tó ti èyí tí ó wà ní ìsàlẹ̀ patapata; tí ó fi jẹ́ pé àwọn yàrá náà lè jókòó lórí ògiri láìfi òpó gbé wọn ró.
Awọn ijọba ibilẹ ti Ajọ INEC ti kede esi idibo naa ni Port Harcourt, Ikwerre, Andoni, Oyigbo, Eleme, Opobo Nkoro, Bonny, Okrika, Akuku Toru, Omuma, Tai, Ahoada East, Emohua, Etche ati Ogba/Egbema/Ndoni, Ogu Bolo, Obio-Akpor ati Asari Toru.
Ilé Aṣòfin yóò pe Godswill Akpabio l'ẹ́jọ́ fún ìbanilórúkọ jẹ́ Ènìyàn 653 míràn tún kún iye àwọn tó ní COVID-19 ní Nàìjíríà Kí ló pa Bobrisky àti Olorì Aláàfin Oyo pọ̀?
Olayanju ni ko si idi fun awọn ọdẹ ibilẹ to fẹ kopa ninu ikọ Amotekun lati tako igbesẹ fifi orukọ silẹ lori ayelujara.
Má dákẹ́, kí o ṣe ìdájọ́ òdodo,bá talaka ati aláìní gba ẹ̀tọ́ wọn.
Kọmiṣọna ọlọpaa ipinlẹ naa, Adeyinka Adeleke sọ fun awọn oniroyin wipe awọn ṣi n fi oju sunukun wo ọrọ naa nitori wipe ko si iwe ayẹwo ile iwosan to fi han wipe ni tootọ ni pe ara san pa awọn oloogbe naa.
" Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ìyá àkàndá ẹ̀dá: Àwọn ẹbí mi fẹ́ kí n pa ọmọ mi torí ó jẹ́ àkàndá ẹ̀dá Awọn ajagunfẹyinti naa ni Ọbasanjọ ko ti s si ofin lori igbesẹ rẹ yii, o si ni ẹtọ labẹ ofin lati sọ tabi se ohun to ba ba ero ọkan rẹ lọ.
Yóo gba ìdámẹ́wàá agbo aguntan yín, ẹ̀yin gan-an yóo sì di ẹrú rẹ̀.
Naijiria ti sepinnu pe ko ni sewu bo tile wu ko mọ fun  awon arinrinajo ati lati jegbadun irinajo won
“Nítorí náà, Agiripa Ọba Aláyélúwà, n kò ṣe àìgbọràn sí ìran tí ó ti ọ̀run wá.
Yóo sàn kí àwọn tí ó bá kù ninu ìran burúkú yìí kú ju kí wọ́n wà láàyè lọ, ní ibikíbi tí mo bá lé wọn lọ.
Nítorí náà, ayé kò mọ̀ wá, nítorí wọn kò mọ Ọlọrun.
Jesse Duplantis ní, Ọlọrun sọ fún òun pé kí òun ra bàálù ayọkẹlẹ Falcon 7X, ti ìyè owó rẹ̀ jẹ́ millionu mẹrinlelaadọta dọla.
Wọn ni ìwádìí yóò bẹ̀rẹ̀ ní perewu láti mọ bi omi ṣe tẹ̀yìn wọgbín lẹ́nu lóri ọ̀rọ̀ náà.
78 Ọ̀nà tí a fi nṣe ìpínfúnni wáìnì—òun yíò mú ago náà pẹ̀lú, yíò sì wipe:
Amọ, o ti ṣekupa eeyan 1,169.
Jesus gbá góòlù sáwọ̀n gba ife Community Shield fún Man City Lyon fìgbájú gba Emirate Cup lọ́wọ́ Arsenal, wọ́n fi pánda rọ́pò Abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò dágbére fáyé lẹ́yìn ìjà rẹ Ilé ìgbìmọ̀ Ìpínlẹ̀ Oyo buwọ́lu ìyànsípò kọmíṣọ́nà mẹ́rìnlá àtàwọn míì Òṣùká kékeré kò rẹrùn àgbà, orílẹ́èdè Nàìjíríà ṣòro púpọ̀ láti darí - Ibrahim Babangida Ìjọba Buhari ń wùwà bíi ìjọba Abacha lórí ọ̀rọ̀ Ṣoworẹ- Ṣoyinka Akọnimọọgba Arsenal Unai Emery ni Iwobi ṣiṣẹ takuntakun nigba to fi wa pẹlu ikọ Arsenal.
Gbigbe igbesẹ lasiko Olootu ijọba Iceland, Katrin Jakobsdottir ti se ayẹwo to pọ jantirẹrẹ fawọn eeyan ilẹ rẹ.
Ti awọn ile iṣẹ aladani ba gbaruku ti ìjọba eré ìdárayá yóò gbórò lorilede wà."
Osun 2018: Àwọn olùdíje ADC, ADP, APC, SDP bá aráàlú sọ̀rọ̀ lórí èròǹgbà wọn
idunnu lo je pe , a ti se ise takun-takun lori re, ni eyi to je pe opolopo ise ni awon omo orile ede yii ti n je anfaani re.
Awọn ọmọ Yoruba n pariwo pe eto aabo ilẹ Oodua n fẹ amojuto Naira Marley ti tèṣù mọ́lẹ̀ nílé ẹjọ́ májísíréètì lórí ẹ̀sùn ìjọ́kọ̀gbé Aláàfin Ọyọ: Ọba tó bá n mú ọtí ní ìta kò yẹ ní ẹni tàá bọ̀wọ̀ fún Àwọn omidan Naijiria ni wọ́n fi ń ṣerú ní Lebanon- Ọmọlọla Ọ̀pọ̀ àwòrán tó ń ṣeni láàánú rèè nípa ogun abẹ́lé Nàíjíríà Àkọlé àwòrán, Awa ko ni gba ọrọ MAlami lori Amọtẹkun Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Wo bí Joshua ṣe fẹ̀ṣẹ́ dá Pulev lẹ́kun àńṣekándúkándú Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
O tẹsiwaju pe ọpọ oṣiṣẹ ni awọn ẹka ile iwosan rẹ lo wa ninu ibeorubojo nitori wọn ko mọ iru aisan to le kolu wọn lọjọ iwaju.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fọ́nrán ohùn, Ọ̀nà àbáyọ de láti gbẹ̀san lára Ẹ̀fọ̀n mùjẹ̀mùjẹ̀ Àbẹ̀wò ikọ̀ BBC sì láàbù àwọn àṣèwádìí ọ̀hún ní ìwọ̀-oòrùn Kenya fi hàn pé ẹnití o ba ti lo òògùn Ivermectin, ẹ̀jẹ̀ wọn yóò jẹ májelè fáwọn ẹfon, èyí pẹ̀lú yóò jẹ́ ìrànwọ́ láti jẹ́ kí ẹ̀fọn má máa tàn kalẹ mọ́.
COM @SENATOR DINO Àkọlé àwòrán, Dino Melaye ni isẹ ọwọ awọn ọta oun ni eyi Sinatọ to n soju aarin gbungbun Kogi, Dino Melaye ti sọ pe irọ patapata ni iwe ipolongo ibo kan to n lọ kaakiri lati polongo didu ipo aarẹ fun oun lọdun 2019.
Fawọlé: Ó wà lára àwọn ẹni tí ó wá wo Orímóògùnjẹ́ nígbà tí ara rè kò yá.
Àwọn tí òkúta ńláńlá wọnyi pa pọ̀ ju àwọn tí àwọn ọmọ Israẹli fi idà pa lọ.
Ẹ kò ní jagun rárá, ẹ sá dúró ní ààyè yín, kí ẹ sì farabalẹ̀, ẹ óo sì rí bí OLUWA yóo ti gba ẹ̀yin ará Juda ati Jerusalẹmu là.
Ẹ máa fi orúkọ mímọ́ rẹ̀ yangàn,kí ọkàn àwọn tí ń wá OLUWA ó máa yọ̀.
Mínísítà 43 ni Ààrẹ Muhammadu Buhari ṣe ìbúra fún to yàn sípò
O ni ipinya laarin awọn ojuṣe ati agbara ẹka ijọba ko fayegba ki ẹka iṣejọba kan máa dasi iṣẹ ẹka miran bi ki ṣe nilana ohun ti iwe ofin ilẹ Naijiria sọ.
 ninu ayika olomi ahamo , awon ide π adarapo awon ipile nukleotidi naro mo ipo horo dna , láti dín iye ìbáṣepọ ̀ wọn pọ ̀ mọ ́ igbá ìṣèdàlú kù ati bíi bẹ ́ ẹ ̀ , okun òmìnira gibbs .
Aare egbe Rotary International lagbaye Barry Rassin ,lo soro yii , nigba ti o n fuiani eye da  aare Buhar lola nile aare to wa lorile ede Naijria,Barry Basin wa fun irinajo olojo merin si orile ede Naijiria.
Wọn mu mi, ti wọn si pin mi mọ ibiti iya mi wa ati aburo mi obinrin meji, ti ọkan ninu wọn ko si ju ọmọ osu mẹwa lọ, pẹlu ibatan mi kan, ti n ko si foju kan baba mi mọ lati ọjọ naa, tori mo gbọ pe o ba ogun miran lọ.
Olubadan tilẹ Ibadan, Ọba Saliu Akanmu Adetunji, Aje Ogungunniso kinni tún paṣẹ fun awọn egungun nilẹ Ibadan lati ṣe etutu ọdun egungun ninu ile wọn, ki wọn si maa ṣe adura fun opin arun Covid-19.
Oun ni ikẹsan ninu gbogbo fiimu agbaye ti awọn eeyan wo julọ ni eyi ti wọn gbe kiri sinima kaakiri agbaye ti wọn si pa owo pupọ lori.
Ati pe, eyi yoo jẹ ẹkọ fun gbogbo oṣiṣẹ ere bọọlu lagbaye Ajọ FIFA ti tẹpẹlẹ mọọ pe o lodi si ìṣe wọn lati gba ẹ̀bùn lọwọ ẹnikẹni.
Igba keji ree ti agbabọọlu yoo gbẹmi mi ni papa isẹre Nasarawa United niluu Lafia.
" Olori Badra fikun pe, oun tun ka ọpọ iroyin lawọn oju opo ayelujara nipa ara oun, ti oun gan alara ko mọ nipa rẹ rara, eyi to se ajeji si oun alara.
Aarẹ Buhari ko ṣe é gbọkanle pe o ni baba ni igbẹjọ tabi pe o máa ṣe iṣe baba isalẹ fun ọ: Ẹkọ pataki yii la ri kọ lati ara aawọ to waye laarin Adams Oshiomole ati Godwin Obaseki.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, JAMB 2019: A ó fagi lé ìdànwò ẹni tó bá ṣe aṣemáṣe Ọrọ yii jẹ esi Keyamo si ọrọ to jẹyọ ninu eto kan lori ẹrọ amohunmaworan niluu Eko lọjọ Aiku nibi ti ẹgbẹ oṣelu ti sọ pe Aarẹ Buhari ko koju oṣuwọn lati jẹ aarẹ nitori awuyewuye to wa lori iwe ẹri WAEC rẹ.
Oun naa ti gbogbo ileewe pa, o fofin de ipejọpọ ọpọ eniyan, o ti awọn ọjà pa, o ti gbogbo ẹnu ibode ipinlẹ naa, o fofin de lílọ bibọ ọkọ.
Ohun tí a mọ̀ nípa ikú ọ̀wọọ̀wọ́ ní Kano nìyí Èèyàn 91 míràn tún ti ní àrùn Coronavirus ní Nàíjírìa Lara awọn ohun ti wọn pin faraalu ni irẹsi, gaari atawọn ohun jijẹ miran.
 Sunday Igboho wa se sadankata si ileesẹ ologun ilẹ wa atawọn ileesẹ agbofinro yoku to tii lẹyin lati gbogun ti iwa ọdaran lagbegbe Oke Ogun."
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù AFCON 2019: Àmì ayò tí Nàíjíríà àti South Afrika gbá rèé 10 Agẹmo 2019 Oríṣun àwòrán, GIUSEPPE CACACE Àkọlé àwòrán, Ẹni a ba laba ni baba Ikọ agbabọọlu orileede Naijiria Super Eagles ti gbewuro soju ikọ Bafana Bafana ti South Africa lati tẹsiwaju ninu idije Afcon 2019 to n waye ni Egypt.
Awọn agbebọn Boko Haram pa Hauwa lẹyin ti gbedeke oṣu mẹsan ti wọn fun ijọba lati duna dura pẹlu wọn lori itusilẹ rẹ kọja laisi igbesẹ kankan latọdọ ijọba apapọ.
Nígbà tí ẹ bá péjọ pọ̀, tí ẹ̀mí mi sì wà pẹlu yín, pẹlu agbára Oluwa wa Jesu, 
Ìròyìn ta gbọ ni pe, Iya wọn fin ogún oloro náà silẹ̀, lati dẹkùn bi ááyán ṣe n daamu wọn.
Fun ọpọ eeyan ati awọn ọdọ aye ode oni, asamọ lasan tabi arosọ ni ọrọ yii, ti wọn ko si gbagbọ wipe ori eeyan kan lee pe to eyi, ti yoo gba ajọ lai kọ silẹ, ti ko si tun ni si owo san.
Jega: Àwọn olùkọ́ fásitì sisẹ́ fáwọn olóṣèlú láti sèrú ìbò
Otunba Christopher Adebayọ Alao Akala ba BBC Yorùbá sọrọ lori nkan to ṣẹlẹ laarin oun ati gomina Ajimọbi to n tukọ ipinlẹ Oyo lọwọ.
"Igba ti mo laju saye lẹyin iṣẹ abẹ naa, ọmọ mi ni mo kọkọ n beere.
Osinbajo sefilọlẹ rẹ ni Fafiti ipinle Eko ni  ile -isẹ tuntun fun imọ ẹrọ igbalode, ile-isẹ itẹwe,
èdè àìyedè tàbí ìjà láàrí ín ẹni méjì
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù NBC fọwọ́ sí ìdásílẹ̀ ilé iṣẹ́ Fulani Radio 26 Èbibi 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ọrọ lori Fulani radio Ajọ to n ri si igbohunsafẹfẹ lorilede Naijiria, NBC ti fun 'pe si gbogbo ile iṣẹ igbohunsafẹfẹ lati yago fun ọrọ to le ṣakoba fun irẹpọ ati iduroṣinṣin Naijiria.
Ninu ọrọ to ba awọn ọmọ Naijiria sọ lalẹ ọjọ Aje ni Arẹ Buhari ti sọ eyi di mimọ.
Arẹgbẹṣọla lọ àmọ́ ọ̀pọ̀ isẹ́ rẹ̀ ń fọhùn síbẹ̀ l‘Ọ́sun Gómìnà ìpínlẹ̀ Osun wọ́gilé ìrìnàjò àwọn alága sí Dubai Èrò àwọn ọmọ Naijiria yàtọ̀ lórí ohun ìní Seyi Makinde Oríṣun àwòrán, @PeckyOfficial/Twitter Àkọlé àwòrán, Mínísítà tó bá kọ̀ láti kéde dùkìá yóò kojú òfin Siwaju si, ajọ naa yoo tun ṣiṣẹ pẹlu ile iṣẹ otẹlẹmuyẹ lati wadi awọn dukia ti wọn ba ni ni oke okun.
Iyaniwura ni o lewu nitori wi pe ijọba ko fi ohun gbogbo ti awọn ọmọ naa nilo lati pada si ileewe sibẹ, ki ijọba to paṣẹ ki awọn ọmọ kekeke pada si ileewe.
Oríṣun àwòrán, Greatkay Àkọlé àwòrán, Ọwọ́ tẹ àwọn olóṣèlú tó ń fowó ràbò ní Kwara Niba yii na, awọn ẹgbẹ oselu meji to gbaju gbja julọ nipinlẹ Kwara, eyiun ẹgbẹ oselu PDP ati APC ti n sọ oko ọrọ si ara wọn nibayi ti eto atundi ibo naa wọle de.
Ọmọkùnrin mi ti kó coronavirus, ẹ bá mi fi sínú àdúrà yín- Atiku Ìjọba ń ṣiṣẹ́ pẹ̀lú àwọn elétò ìlera láti gbógun ti Coronavirus - Buhari O rọ ọpọ oṣere ti wọn ko tii lọ kẹkọọ ere tiata ṣiṣe nibi kankan pe ki wọn yara tete lọ kẹkọọ nitori ko si oṣere kan ti ko kẹkọọ labẹ ẹnikan nigba tawọn naa.
Ileeṣẹ ọlọpaa sọ pe awọn oluwọde naa mu iwa janduku mọ, ti wọn si ti ipa bẹ ẹ pa Kọburu ọlọpaa kan, Etaga Stanley, ni ipa ika.
Bàbá mi sì mú ejò ọká náà ó dá iná sun ún, ó sì kó eérú rẹ̀ dànù sí orí ààtàn, ṣùgbọ́n nígbà tí òjò rọ̀ àgbàrá òjò gbá apá kan rẹ̀ sí inú odò kékeré kan, níbẹ̀ ni eérú náà sì ti yípadà tí ó di ẹja olóró kan títí di òní yìí, ní ọjọ́ tí mo bá rí ẹja náà, ìwọ ọ̀rẹ́ mi, n ó fi hàn ọ́.
Ohun taa le sọni pe o kere tan ara ile mẹta lo dibo yan Praise pe oun ni ko maa lọ ile.
Báyìí ni ọkùnrin náà sọ tí ó lọ ni ọjọ́ náà: bẹ́ẹ̀ ni ọmọlúwàbí ni, kì í tàsé ọ̀rọ̀ rẹ̀.
Musa tun ko ọpọlọpọ ewurẹ ati agutan dani, ti wọn n pa fun ounjẹ loju ọna.
Wọn sangun lati farada eto idanilẹkọ ati igbaradi ikọ SWAT Ọga ọlọpaa Adamu ṣeleri pe awọn ọlọpaa iks naa yoo ṣe iṣẹ wọn bi iṣẹ bi o ti tọ ati bi o ti tọna.
Fẹla: Àwọn olólùfẹ́ Abàmì Ẹdá s'ayẹyẹ ọjọ́ ìbí ọgọ́rin ọdún rẹ̀
Aarẹ ilẹ Faranse, Emmanuel Macron sọ wi pe laarin ọdun mẹrin ni oun yoo da gbogbo rẹ pada fun Afrika.
Asiko ko dẹrun fun minisita fun eto iṣuna lorilẹede Naijiria, Kẹmi Adeoṣun lọwọlọwọ pẹlu iroyin kan to n ja kaakiri bayii pe ó lo ayederu iwe ẹri iyọnda kikopa gẹgẹ bi agunbanirọ.
Adina ni baálé ní ìdílé Harimu,Helikai ni baálé ní ìdílé Meraiotu,
Ṣaaju ni ileeṣẹ BBC Yoruba ti jabọ pe wọn pa alaboyun kan ti wọn fi okuta fọ lori lagbegbe ọhun, yatọ si awọn eeyan miran ti wọn ti pa lagbegbe naa.
Lọdun 2019, irinwolemẹrindinlogun miliọnu Naira ni wọn yoo na, nigba ti wọn yoo na ọọdunrunlenimọkandinlọgbọn naira le diẹ ni 2020, milionu mẹrindinlogoji naira ni wọn yoo na ni 2021 ti owo ina lori eto yi lọdun 2022 si jẹ miliọnu mọkanla naira le diẹ.
Water Theraphy: Àwọn àmi méje tó ń tọ́ka sí pé oò kí ń mu omi bí ó ti tó
Ọga agba ọlọpaa tun ṣabẹwo si awọn agọ ọlọpaa ti awọn janduku kan dana sun niluu Benin.
    Ṣùgbọ́n bí mo ti ní ki ń jáde nínú igbó náà ni mo pàdé ẹnìkan tí ó wọ aṣọ funfun tí o wí fun mi pé n kò i tíì parí iṣẹ mi tí ó yẹ ki n ṣe, nígbà tí mo sì bi í léèrè iṣẹ́ tí ó kù, ó ní èso igi ìrònú kò já mọ́ nnkan kàn àfi bí mo bá ká èso igi mìíràn tí à ń pè ni Ìfẹ̀yìntì-Olódùmarè pẹ̀lú rẹ̀.
Ta ló ti lọ sí ọ̀run rí, tí ó sì tún pada wá?
Jehoiakini, ọmọ rẹ̀ sì jọba lẹ́yìn rẹ̀.
O fi kun oro re pe, a n gbe igbese to nipon lati ri daju pe, abajade esi ibo ohun ko ni kolofin ninu rara.
O ní eyi nikan kọ, nkan to se pataki julọ ti oun ko fi le se ere agbelewo ni pe , oun n tete gbagbe nkan.
Buhari lo sọ ọrọ naa loju opo Twitter rẹ nibi to ti sọ pe afojusun ijọba oun ni lati mu ki idagbasoke de ba agbegbe naa.
nítorí pé o fẹ́ràn àwọn tí wọ́n kórìíra rẹ, o sì kórìíra àwọn tí wọ́n fẹ́ràn rẹ.
Ẹgbẹ́ akọ̀ròyìn NUJ ìpínlẹ Oyo bà àwọn ọmọ ẹgbẹ́ tó lọ ìpàdé tí Femi Fani Kayode pè ní Ibadan wí Àrà mánigbàgbé tí Baba Legba dá lágbo tíátà rèé Àwọn ọ̀daràn tó jí ìbejì ọmọ Akeugbagold kó ti fojú ba ilé ẹjọ́ lòníì Àjọ ECOWAS yan Aàrẹ Ghana, Nana Akufo-Addo gẹgẹ bíi aàrẹ tuntun Fìdíhẹẹ́ ní Banji Akintoye nínú YWC, lílọ ni yóò lọ - Tola Adeniyi Ninu ọrọ to sọ lorukọ awọn ẹgbẹ naa, alaga apapọ, JOHESU, Bio Josiahrọ minisita keji fun ọrọ oṣiṣẹ, Festus Keyamọ SAN lati kewaju ijiroro naa dipi Chris Ngige to n ṣe kokaari rẹ tẹlẹ Lara awon ẹdun ọkan awọn oṣiṣẹ naa ni sisan aṣẹku owo ajẹmọnu oo asiko ajakalẹ arun COVID-19 fun awọn oṣiṣẹ naa ni ileewosan ijoba apapọ eleyii ti wọn ni o jẹ ida mẹwaa dipo ida ọgọta ninu ọgọrun ti o jẹ adehun ẹgbẹ oṣiṣẹ naa ati ijoba.
“Ẹ rí gbogbo nǹkan wọnyi, ọjọ́ ń bọ̀ nígbà tí kò ní sí òkúta kan lórí ekeji tí a kò ní wó lulẹ̀.
Nítorí ọkàn gbogbo yín ń fà á, ọkàn rẹ̀ kò sì balẹ̀ nítorí gbígbọ́ tí ẹ ti gbọ́ pé ó ṣàìsàn.
Kòṣẹlẹ̀rí ni Hajj ọdún 2020, wo ìyàtọ̀ tó wà nínú rẹ̀ sí ti tẹ́lẹ̀ Ẹ̀yin ẹlẹ́gbẹ́ òkùnkùn tẹ fẹ́ ṣe àjọ̀dún lónìí, lákọ la ń dúró dè yín - Iléeṣẹ́ ọlọ́pàá Ìjọba Akeredolu kò ní omi àánú lójú, a kò tọ́jú alárùn Coronavirus mọ́ - Dókítá Ondo Bí àwọn adarí ìjọba ṣe ń kó Coronavirus, ń kọ wá lóminú - Ìjọba àpapọ̀ Ẹsun iṣowo ilu kumọkumọ ti EFCC fi kan Gomina ipinlẹ Ekiti tẹlẹ, Ayodele Fayose Ọkan lara awọn ẹsun iwa ibajẹ ni ijọba ni ti ajọ EFCC ṣagbatẹru nigba ti Ibrahim Magu fi jẹ adele alaga ajọ ni ẹjọ Gomina ipinlẹ Ekiti tẹlẹ.
Gbogbo ohun tí mo ní kò ju ẹ̀kúnwọ́ ìyẹ̀fun kan lọ, tí ó wà ninu àwokòtò kan; ati ìwọ̀nba òróró olifi díẹ̀, ninu kólòbó kan.
Ọ̀pá epo rọ̀bí tún bẹ́ pẹ̀lú ìbúgbàmù ńlá l'Eko, àwọn òrùlé ilé ṣí lọ rẹrẹ Oju opo Twitter ti kun fun ariwo awọn eeyan to gburo ibugbamu naa eyi to se ọsẹ pus fun ọpọ ile.
2019 Nigeria Budget: Wo pàsán ojú Buhari tó dá awuyewuye sílẹ
Kọ̀lọ̀kọ̀lọ̀ Algeria là kìnìún Senegal mọ́ lẹ̀ lẹ́ẹ̀kejì gba ife AFCON Ta ni agbábọ́ọ̀lù tó fakọyọ jù lọ ní Afcon 2019?
 Ìdíwọ ́ yìí parí lẹ ̀ yin akitiyan ológun ojú omi fún Àwọn Ìpínlẹ ̀ aṣọ ̀ kan amẹ ́ ríkà lati gbàwọn sílẹ ̀ .
bí ó bá ṣeéṣe kí n lè dé ipò ajinde ninu òkú.
Àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ ati ọ̀pọ̀ eniyan ń bá a lọ.
Obinrin naa Chibike mu ọti amupara debi pe, o fi oko fọ gilaasi ọkọ oun nigba ti ọti to mu n pa a.
nítorí náà, mo lòdì sí ìwọ ati àwọn odò rẹ, n óo sì sọ ilẹ̀ Ijipti di ahoro ati aṣálẹ̀ patapata láti Migidoli dé Siene, títí dé ààlà Etiopia.
Ọwọ́ ọlọ́pàá tẹ àwọn méji tó jẹ ẹran ara ọlọ́pàá tí wọ́n pa n'Ibadan
Lẹyin to fi ọfisi rẹ silẹ tori awọn ejo meji,Aarẹ orileede Liberia George Weah George Weah ti pada sibẹ lati ma ba iṣẹ lọ.
International Day for Elimination of Violence against Women: Àlùfáà Joel Olugbenga: Bíbélì kò ní kéèyàn dúró títí ọkọ rẹ̀ yóò fi lù ú pa
Ṣugbọn eniyan ẹlẹ́ran-ara kò lè gba àwọn nǹkan ti Ẹ̀mí Ọlọrun, nítorí bí ọ̀rọ̀ òmùgọ̀ ni yóo rí lójú rẹ̀.
 tí ó sì sin ilẹ ̀ baba rẹ ̀ fún ọdún mẹ ́ fà gbáko .
Ẹgbẹ́ alatako sọ pe eyi ti buru si i l'abẹ iṣejọba ANC to ti wa ni iṣakoso fun bi aadọta ọdun.
won jẹ méjídínlọ́gbọ̀n ti won ko ti ni oludije fun ipo gomina ni ipinle naa ,
Bo tilẹ jẹ wi pe ọpọ n daro Kyari, ọgọrọ ọmọ Naijiria lo bu ẹnu atẹ lu ọpọ eeyan to pejọ sibi eto isinku rẹ niluu Abuja lọjọ Abamẹta.
Sugbọn ileesẹ ọkọ-ofurufu naa to kalẹ si Dubai ti fidi ọrọ naa mulẹ fun ileese iroyin Khaleej Times: A le fidirẹ mulẹ wi pe, ọkan lara awọn oṣiṣẹ baalu wa jabọ lati ilẹkun nigba ti o n palẹmọ bi baalu to ni nọmba EK729 yoo ṣe gbera lati Entebbe lọjọ kẹrinla oṣu kẹta."
Nígbà tí ó yá, ọdún meje tí ọ̀pọ̀ oúnjẹ wà ní Ijipti dópin.
Lórí ìpèsè àwọn ohun èlò amayedẹrun si agbegbe Ikalẹ, gomina Akeredolu wa rọ awon ọmọ bibi agbegbe naa pé kí wọn fi ọkàn balẹ, nítorí wọ́n kò ní pẹ máa wa ohun àlùmọ́ọ́nì bítúmẹ́nì tó sodo sì agbegbe Ikalẹ, tí ibùdó ojú omi yóò sì tẹdo sí àgbègbè náà pẹlu.
Ẹlòmíràn tún ti lùgbàdì àrùn Corona Virus nílùú Abuja àti Eko Ijọba ìpínlẹ̀ Eko àti Kwara ti kéde konile o gbélé Ìgbésẹ̀ ìjọba láti kojú àrùn coronavirus ń pani lẹ́rìn ín- Pásítọ̀ Adeboye Báwo ni àrùn coronavirus ṣe ń wọ Nàìjíríà Ìjọba ti pápákọ̀ òfúrufú Eko àti Abuja pa nítorí coronavirus Ijọba ìpínlẹ̀ Ogun dá sẹria f'àwọn aláigbọrọ jófin Wọn ni o ti n gba itọju lori awọn aisan naa ki arun COVID-19 to mu lọ.
Ìjìnlẹ̀ àṣírí nìyí, ó ti wà ní ìpamọ́ láti ìgbà àtijọ́ ati láti ìrandíran, ṣugbọn Ọlọrun fihan àwọn eniyan rẹ̀ ní àkókò yìí.
- Nkechi Blessing Bí èsì ìdìbò gómìnà ìpínlẹ̀ Ondo se ń jáde rèé.
Ko tan sibẹ, ọmọ ọdọ ọhun tun fi ẹrọ ibanisọrọ ọga rẹ tẹ atẹjajiṣẹ kan si ọrẹbinrin ọga rẹ ọhun lori ede ayede kan ti wọn ni lọna ati fi ko ba a.
Igbo Olodumare to safihan itan Olowo aye to jẹ́ baba Akara Oogun ni wie ti Fagunwa geb jade tẹ́le Ogboju ọdẹ nibi o se tà lori igba tó Oríṣun àwòrán, @Amazon books Iya ré lo pa ọma mẹjọ mii ti baba rẹ bi pẹlu iyawo mẹta ti wọn jẹ orogun iya rẹ.
Ọ̀rọ̀ lórí Ijipti: Nípa àwọn ọmọ ogun Farao Neko, ọba Ijipti, tí wọ́n wà létí odò Yufurate ní Kakemiṣi, àwọn tí Nebukadinesari, ọba Babiloni, ṣẹgun ní ọdún kẹrin tí Jehoiakimu ọmọ Josaya jọba Juda.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ní orílẹ̀-èdè Nàìjíríà ofín tirẹ̀ le púpọ̀ fún ìṣẹ́yún tí wọn fi ààyè gba ìṣẹyún tí obìnrin náà bá wà nínú ewu nìkan.
COTE D'IVOIRE: Orilẹ ede yii la n pe ni Ivory Coast tẹlẹ ti o ni ọpọ ohun alumọni ti yoo mu dide larinnrin.
A ni o le nigba awọn ọmọ ogun ni Aso Rock yatọ si igba ọlọpaa to n ṣọ wa.
6 mílíọ̀nù ni-APC Gẹgẹ bi ohun ti Keyamo sọ, wi pe awọn ẹgbẹ PDP le ni anfaani lati gba iroyin loju opo Inec ṣafihan pe awọn ọdaran kan lati inu gbẹ naa ni na alumọkọrọyi lati le fọna ẹburu gbe esi ibo wọle.
leyin ti o jẹ igbati olooyi lati ọwọ ọgbẹni Rashid Kassim , ni won gbe sori ero
ọkọ irin lati ilu Abuja lo si Kaduna, ju awon ogunlogo eniyan  ti won n wọ ọkọ oju irin lojoojumo lo si ilu
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Oxfam: Olówó mẹ́ta ní Afirika lówó ju 650m aláìní lọ 4 Owewe 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Aarẹ ile aṣofin agba Naijiria nibi to ti joko ti awọn ọkunrin meji lara awọn to lowo julọ ni Naijiria,Aliko Dangote ati Jim Ovia.
Awọn adajọ mejeeji ọhun ni Adajọ Adeniyi Ademọla, tileẹjọ giga apapọ to wa nilu Abuja, ti wọn fun ni asẹ ifẹyinti tipatipa pẹlu Adajọ O.
Ọkàn mi lọ sọ́dọ̀ àwọn balogun Israẹli,tí wọ́n fi tọkàntọkàn fa ara wọn kalẹ̀ láàrin àwọn eniyan.
PFN: Fatoyinbo kọ̀ láti yọjú ni ìwádìí wa kò ṣe parí Ilé iṣẹ́ márùn ún tí wọ́n dárukọ kìí ṣe túntun- Garba Sheu FRSC dá N443,180 padà fún ẹbí ẹni to ní ìjàmbá mọ́tò Ọlọ́pàá Germany ń wádìí àfurasí mẹ́rin nínú àwọn tó kọlu Ekweremadu ni Germany Alhaji Zubair Mai Mala, ọkan lara awọn oniṣowo ni ẹkun yii ni nitootọ ni awọn aniyan ti n duna dura ni ẹnubode yii.
Naira Marley: Wo àwọn ìṣẹ̀lẹ̀ tó mú Naira Marley di òrìṣà àkúnlẹ̀bọ lọ́dún 2019
Aláìsí náà, tíí se ọmọ kan soso tí ìyá rẹ̀ bí, ni àwọn kan sádédé yìnbọn fún níwájú ilé ìyá rẹ̀ lásìkò tó ń bọ́ sílẹ̀ nínú ọkọ̀ rẹ̀, èyí tó mú kí ìyá rẹ̀ sáré jáde síta, tó sì di òkú ọmọ rẹ̀ mọ́ àyà.
Wayii o, ogbeni Abubakar Chika to n mojuto ekun kan nipinle Niger so o ebi oro ohun mo minisita to n mojuto eto isuna ati ilana eto, asofin Udoma Udo Udoma lataari oro kan tabi keji ti o so, eleyi ti o sokunfa ojo ti aare yan lati sagbekale iwe isuna naa.
Ọkan lara awọn alaga naa, Abass Alẹṣinlọyẹ sọ pe awọn alaga naa ti kọwe si gbogbo awọn to le ranwọn lọwọ lori ọrọ naa.
Kò sí ìbi tí òfin náà tí sọ wípé èèyàn gbọdọ ní ìwé ikẹkọjáde yunifásítì tàbí ìwé erí pé o sìnrú ìlú labẹ ètò àgùnbánirọ̀ kí o tó lè jẹ aṣojú ilé aṣòfin àgbà.
Ìbọ̀rìṣà ti wọ Efuraimu lẹ́wù, ẹ fi wọ́n sílẹ̀.
Olalekan sọ pe, DJXgee ni 'baba isalẹ' iyẹn 'School father' fun oun lasiko ti wọn wa ni ile iwe girama.
Alanilọyẹ fun ajọ naa, ẹsọ CPEO Bisi Kazeem lo sọ eyi di mimọ ni ilu Abuja.
Àwọn ìyá àgbà bíi Saray ní ẹ̀mí ìforítì òun ìlọra tí ó mú àwọn ọmọ Orílẹ̀ Azerbaijan yàtọ̀.
Pogba ni oju oun ti kuro ni Machester United, ati pe yoo wu oun lati kẹru oun lọ si orilẹede Spain ki saa tuntun mii to bẹrẹ.
OLUWA yóo jẹ́ kí ẹ máa bí sí i,àtẹ̀yin àtàwọn ọmọ yín.
Aadọjọ (150) ọjọ́ gbáko ni omi fi bo gbogbo ilẹ̀.
Yoo kan sure fun ikoko naa ni lati okeere ni.
Itahunsira yii waye ni ile igbalejo ti wọn npe ni Presidential Hotel, Port Harcourt.
Àwọn ọdẹ jókòó sí apá kan tábìlí lọ, àwọn iwin ló sì jòkòó kọjú sí wọn.
 johnson ( 1921 : 144 ) gbà pé Àjàká ló wá lórí oyè gẹ ́ gẹ ́ bí aláàfin Ọ ̀ yọ ́ nígbà tí Ọ ̀ rànmíyàn kú .
Okoroafor fid a awon ara-ilu loju pe, ile-ifowopamo CBN yoo tesiwaju lati maa fowo satileyin  owo ori oja fun awon ile-ifowopamo, ni ibamu pelu  erongba ati mu igberu ba owo ori oja ile-okeere naa.
Bí ẹ bá rò pé ẹ sàn jù mí lọ,tí ẹ sì rò pé ìjìyà ẹ̀ṣẹ̀ mi ni ìdààmú mi,
Oríṣun àwòrán, @Haramain Awọn alaṣẹ mọṣalaṣi nlanla mejeeji ni igbesẹ yii di dandan lasiko yii lati pese aabo fawọn imaamu wọn nitori ọpọ eeyan lo ti da wọn mọ lagbaye.
Bakan naa lo mẹnuba iriri lori awọn to ti dẹ́jàá sẹyin nipa pipa ẹja inu odo yii ṣeyin.
Bi ko ba ti ni, gbargudu ni wọn gbe le ọ lọwọ.
Dafidi bèèrè lọ́wọ́ àwọn ọkunrin náà pé, “Kí ni ọba ṣe ìlérí pé òun ó fún ẹni tí ó bá pa Filistini yìí, tí ó sì mú ẹ̀gàn kúrò lára Israẹli?
Wọ́n ti fọ aṣọ wọn, wọ́n ti sọ wọ́n di funfun ninu ẹ̀jẹ̀ Ọ̀dọ́ Aguntan.
O fi kun-un pe, CBN yoo wa ona ati mu atunto ba ilana ti awon miiran yoo fi seto eyawo to ko ni ere lori fun anfaani awon ara-ilu.
Jesu bá sọ fún un pé, “Máa bọ̀!
1 Bélú 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 3 Bélú 2020 Oríṣun àwòrán, Road safety Ileeṣẹ ọlọpaa nipinlẹ Ondo ti ni awọn ti fi ami si ọja Akungba pe ki ẹnikẹni ma lọ sibẹ lasiko yii.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Awọn Obinrin Dahomey: Awọn obinrin ilẹ Afirika ti wọn yii itan pada re e Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Bí ó ti dé ẹnu ọ̀nà ibodè ìlú náà, ó rí obinrin opó kan tí ń wá igi ìdáná.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Awọn ilana bi itakete-sira-ẹni, lilo ibomu, ọkọ ti wọn seto lọtọ ati oju ọna ti wọn la kalẹ si kilaasi kọọkan wa lara nkan ti China n se bayi tawọn akẹkọọ ti pada sile iwe.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìyibọ́npaniyan ile-iwe Florida: Eeyan mẹ́tadinlogun ti ku 15 Èrèlè 2018 Oríṣun àwòrán, EVN Àkọlé àwòrán, Aworan amohunmọworan s'afihan bi wọn tin ko awọn ọmọ ile iwe jade kuro ninu ewu Ọmọ ile-iwe metadinlogun ni wọn ku lẹyin igba ti ọmọ ọdun mokandinlogun kan yinbọn fun awọn eeyan ni ọgba ile-iwe giga kan ni Parkland, to wa ni ipinlẹ Florida l'orilẹ̀ede America.
Toun ti gbajugbaja oyinbo mii, Hamza Koudeih ti ọwọ tẹ lagbegbe Banana Island lEko.
apá kan nínú Ìlànà ìgbaniwọlé gẹ ́ gẹ ́ bí ọmọ awo ni wípé , ọmọ awo gbọ ́ dọ ̀ jẹ ̀ ọkùnrin nìgbà tí apá kejì wípé wọn le gba obìnrin náà gẹ ́ gẹ ́ bí ọmọ awo .
Lati inu awọn manigbagbe sinima bii 'Ogbori Ẹlẹmọṣọ' de Aṣiri nla' atawọn sinima miran, ni agba oṣere yii ti fi ara rẹ si aaye manigbagbe lọkan awọn ololufẹ sinima ati igbelarugẹ itan, aṣa ati iṣe Yoruba.
- Iya Rainbow Kemi Olunloyo dá sí ìjà Toyin Abraham àti Lizzy Anjorin Ẹsun ti wọn fi kan Sowore: Bakan naa, wọn tun fi ẹsun kan pe wọn fẹ ko ero jọ ninu oṣu kẹjọ kaakiri ipinlẹ Eko, Abuja atawọn ibomiran lorilẹ-ede Naijiria lati ṣe iwọde ifẹhonu han #RevolutionNow lati le yọ aarẹ nipo.
Sọja naa tun fikun ọrọ rẹ pe iyawo oun kọ lati buwọ luwe nigba ti dokita to n tọju oun ni ko ṣe bẹẹ nigba ti ara oun ko ya.
ati idamẹrin òṣùnwọ̀n hini ọtí fún ẹbọ ohun mímu, pẹlu ẹbọ sísun tabi ẹbọ ọ̀dọ́ aguntan kan.
Ní ọjọ́ náà, OLUWA yóo já gbogbo nǹkan ọ̀ṣọ́ wọn dànù; ati ṣaworo ẹsẹ̀ wọn ni, ati ẹ̀gbà orí wọn; ẹ̀gbà ọrùn wọn; 
'Ambode ṣì gbọdọ̀ yọjú sí wa - Ilé aṣòfin Eko' Ambode gbé ìsúná N852.
Sẹnatọ Sani ni ko yẹ ko jẹ ori ileesẹ ọgba ẹwọn ni wọn yoo maa di ẹru igbesẹ gba-maa-binu ti wọn yoo maa san fun awọn ẹlẹwọn le.
Awọn agbẹjọro wọn, Femi Falana to pe ẹjọ naa lorukọ Ṣowore ati Bakare, tun ni ọga ajọ DSS ati ti ẹka eto idajọ tun tapa sofin orilẹede Naijiria gẹgẹ bi o ti wa ni akọsilẹ ninu iwe ofin.
Eyi lo si mu ki iye ọrọ rẹ ni owo dọla ilẹ Amẹrika o wọ biliọnu mẹtadilaadoje o le ($127.
Kí wọn máa fi ijó yin orúkọ rẹ̀,kí wọn máa fi ìlù ati hapu kọ orin aládùn sí i.
" Oríṣun àwòrán, @adetutuoj8811 Adetutu fi kun pe, o de asiko kan, ti oun lọ ba awọn obi oun lati mọ idi ti wọn se kọ oun ni ila, amọ alaye wọn ni pe ara asa ilẹ Yoruba ni ila kikọ, eyi ti yoo bu kun ẹwa oun.
Ó bá sọ fún un pé, “Gbogbo nǹkan wọnyi ni n óo fún ọ bí o bá wolẹ̀ tí o júbà mi.
Ọrọ ree lati ọdọ ọkan lara awọn ololufẹ oju opo BBC Yoruba, arakunrin Olayemi Patrick Edema nigba ti o ri aworan Dokita Stella Adadevoh ti Google se iranti ọjọ ibi méjílélọ́gọ́ta ti ko ba ṣe kani pe o wa laye.
A gbọ́ pe níṣe ni wọ́n fọ́n sí àárin ìlú, tí wọ́n sì bẹ̀rẹ̀ sí ni fi oríṣiríṣi nkan ìjà olóró bá ara wọn jà.
Lábẹ́ igi èso ápù ni mo ti jí ọ,níbi tí ìyá rẹ ti rọbí rẹ,níbi tí ẹni tí ó bí ọ ti rọbí.
Ṣugbọn bí ó bá ti gbéra ni àwọn náà yóo tẹ̀síwájú.
Ọmọ mi, ìwọ ni o kó mi sinu ìbànújẹ́ yìí?
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Ijọba fẹ le wa kuro ni Ọjọta' Koda, ko tiẹ naani igbe ati ẹkun awọn to ni sọọbu nibudo naa, ti wọn n bẹbẹ pe ki ijọba tubọ fun awọn ni akoko diẹ sii lati ko awọn ọkọ awọn onibara awọn kuro nibudo naa, bẹẹ ni ọpọ wọn ntiraka lati wa tabi wọ awọn ọkọ naa jade.
Bakan naa ni Lawal sọ pe Tinubu lo ko owo jọ fun ipolongo, nigba ti Buhari ko ni owo lọwọ lati gbọ bukata eto idibo.
Ọmọyẹle Ṣoworẹ ni afi bi oun yoo ba pa irọ tan ara oun atawọn to n tẹle oun lẹyin ni oun yoo fi sọ pe lootọ ni Buhari bori lọna to tọ.
A gbọ pe ọwọ awakọ Salami, ni wọn ti gba ọkọ akẹru naa nitori pe o ru ofin to rọ mọ jijade lasiko arun Covid-19.
Òun ati àwọn eniyan rẹ̀ bá pada sí Jerusalẹmu.
 Ààre kúrunmí fé láti gba òmìnira fún ìlú re ( Ìjàyè ) kúrò lábé àse àti ìmúni sìn ìlú Òyó sùgbón , òrò náà kèkí púpò .
“Mo sọ fun yín, gbogbo ẹni tí ó bá jẹ́wọ́ mi níwájú eniyan, Ọmọ-Eniyan yóo jẹ́wọ́ rẹ̀ níwájú àwọn angẹli Ọlọrun.
Sẹnetọ Sani ni kii ṣe aye yii ni ipinlẹ kan yoo ti maa lo ina ọba fun wakati mẹrinlelogun.
Ẹni to ba fẹ ẹ kopa yoo kọkọ san, fun apẹẹrẹ, ẹgbẹrun kan Naira fun olukopa mi i, ti awọn ọmọ ẹgbẹ mẹẹrin mi i yoo si da ẹgbẹrun kọọkan Naira si apo asunwọn ti ẹ naa laarin ọjọ meje.
Ìmọ̀ràn fún àwọn ti ó gbé ìyá wọn wá si ìlú-oyinbo, ni ki wọn gbiyànjú lati ṣe ètò fún àwọn ìyá-àgbà lati lọ si ilé ni asiko òtútù lati fara mọ́ àwọn enia wọn.
Omotosho pari ọrọ rẹ pe, ijọba Eko yoo maa wo bi ọrọ naa ṣe n lọ lati mọ igbesẹ to kan.
Lóri àtẹ̀jíṣẹ́ twitter, àwọn ọmọ Nàìjíríà sọ èrò ọkàn wọn fún ilé iṣẹ́ ààrẹ .
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Certificate forgery: Olùpẹ̀jọ́ ni òun kò ṣẹjọ́ mọ pẹ̀lú gómìnà Kwara 26 Òkùdu 2019 Oríṣun àwòrán, Abdulrahaman official Àkọlé àwòrán, Sááju àsìkò yiìí ni Abdulrazaq ti ni ìppejọ́ náà ni ọwọ́ òṣèlú nínú ti ó sì fẹ́ dènà ati dibò wolé gẹ́gẹ́ bi gomina ìpínlẹ̀ Kwara to wáye ninu oṣù kẹta Ilé ẹjọ́ giga to fi ilu Ilọrin se ibujoko, ti wọgile ẹjọ kan to ni gomina ipinlẹ Kwara, Abdulrahman Abdulrazaq, lo ayederu sabuke láti fi dije dupo Gomina ni ipinlẹ Kwara.
Awọn SSANU, NASU ati NAT naa ti gunle iyanṣẹlodi ọlọjọ marun un lati kilọ fun ijọba apapọ lori awọn ẹtọ wọn ti wọn n beere fun.
 Onimọ nipa eto aabo naa wa salaye pe maalu mẹjọ ninu mẹwa ti darandaran kan ba n da, awọn eeyan wa lo ni wọn, paapaa awọn ọlọla wa."
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ekiti Election: NBC ní EKBC ń gbé ayédèrú èsì ìbò síta 14 Agẹmo 2018 Oríṣun àwòrán, @nbcgovng Àkọlé àwòrán, NBC ni ileesẹ igbohun-safẹfẹ Ekiti n hu awọn iwa to tako ofin isẹ igbohunsafẹfẹ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 2016 ni Angel kọ́kọ́ gbé àwo orin rẹ̀ síta láti fi bèrè ìdí tí òun fi yàtọ̀ Ati wi pe oṣiṣẹ tabi ileeṣẹ ijọba to ba buwọlu kikọ ile ti ko pa ofin naa mọ yoo san miliọnu kan Naira owo itanran, fi ẹwọn ọdun meji jura tabi mejeeji.
Amọṣa nigba to di ọdun 2016 ni iroyin jade pe Toyin fẹ yi orukọ rẹ pada.
Inu Iyalufa n dun si ọpọ aseyọri Ọmọlufa amọ ibanujẹ nla lo n dori agba rẹ kodo lori ọrọ Ọmọyẹ.
O dagba ni abule lẹyin odi Birmingham, nilẹ England o ti da nikan wa fun ọdun meji nigba to wọ ọkọ oju irin lọ sinu igboro lọsan ọjọ abamẹta kan.
Nigba ti yoo fi wa si igbẹjọ nileẹjọ, gbalaja bayii ni Metuh sun sori bẹẹdi alaarẹ, Stretcher wa si ile ẹjọ Oríṣun àwòrán, other Abdulrasheed Maina Ni ọdun 2019, Alaga nigbakan ri fun ajọ to n ṣamojuto owo ifẹyinti lorilẹede Naijiria, Abdulrasheed Maina naa foju ba ile ẹjọ lori owo to to biliọnu meji naira.
Ọba pàṣẹ fún àwọn tí wọn ń gbé Jerusalẹmu pé kí wọ́n mú ọrẹ tí ó tọ́ sí àwọn alufaa ati àwọn ọmọ Lefi wa, kí wọ́n lè fi gbogbo àkókò wọn sílẹ̀ láti máa kọ́ àwọn eniyan ní òfin OLUWA.
Saulu gbọ́rọ̀ sí Jonatani lẹ́nu, ó sì búra ní orúkọ OLUWA pé, “Bí OLUWA ti ń bẹ, n kò ní pa á.
Obaseki to jẹ́ olùdíje dupò gómìnà lábẹ́ ẹgbẹ́ òṣèlú PDP ló fi ìdí akẹgbẹ́ rẹ̀ labẹ̀ ẹgbẹ òṣèlú APC jánlẹ.
Ọrọ̀ yóo lọ mọ́ ọn lọ́wọ́ lọ́sàn-án gangan,nígbẹ̀yìn yóo di òmùgọ̀.
Boko Haram pa èèyàn 25 ní Màìdúgùri Ọmọdé kan pàdánù ẹ̀mí nílé ìjọsìn tó wó lulẹ̀ Awọn ile to wa ni tosi isẹlẹ naa to fi mọ mọsalasi kan la gbọ pe ibugbamu naa ko ba.
Agbẹnusọ Ile Igbimọ Aṣofin Ipinlẹ Eko, Aṣofin Mudashiru Ọbasa, ti o ṣaaju ijiroro naa kede pe IIe ti fọwọ si awọn ọmọ igbịmọ naa ti Gomina yan.
N óo fun yín ní ọkà, waini ati òróró,ẹ óo ní ànítẹ́rùn.
Ìwádìí jẹ ́ kí á mọ ̀ pé àwọn ayaba kì í gbé ewì yìí jáde kọjá àsìkò ayẹyẹ tàbí ìṣẹ ̀ ṣe inú ààfin ọba láyé àtijọ ́ .
Lẹyin isenu fun oṣu Ramadan, olori ijọ ẹsin Islam gbogbo lorilẹede Naijiria, to tun jẹ Sultan ti ilu Sokoto, Alhaji Saád Abubakar III ti kede oni, ọjọ iṣẹgun ọjọ kẹrin oṣu kẹfa gẹgẹ bii ọjọ ọdun itunu aawẹ, Eid-el-Fitr fun gbogbo musulumi lorilẹede Naijiria.
Òun ni baba rẹ, Nebukadinesari ọba, fi ṣe olórí gbogbo àwọn pidánpidán, àwọn aláfọ̀ṣẹ, àwọn Kalidea ati àwọn awòràwọ̀; 
Hajara sọ siwaju si pe, wahala lati kọja odo ati ọna ti ko dara lo fa ṣababi bi oun ṣe padanu ọmọ oun.
Ọlọrun mi, ìwọ ni mo gbẹ́kẹ̀lé,má jẹ́ kí ojú ó tì mí;má jẹ́ kí ọ̀tá ó yọ̀ mí.
"Bi mo ṣe ji ni yẹn ti mo ṣi n gbọ oorun eefin to pọ"" O ni ""kia ni mo gbe Eric,ti mo fẹ gba ọna eyinkule sa jade ṣugbọn mo ri ti ina n jọ nibe ti mo ṣi gba isalẹ ile mi sa jade"" Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, EndSars Protest:Ọ̀gá Àgba Ọlọ́pàá ṣàbẹ̀wò sí ìpínlẹ̀ Eko lẹ́yìn ìfẹ̀họ́núhàn EndSars Nigba t'awọn panapana yoo fi de ni nkan bi ago kan oru, ina ti gba gbogbo ile kan."
Kódà àgbára àti làákáyè àwá ọmọ ènìyàn ti gá dé’bi pé àwọn mìíran a máa sọ pé kòsí Ọlọrun, pé àwa gan-an là ń bẹ ní ìdí orò.
Ounjẹ bi irẹsi loriṣiriṣi, amala, iyan, sẹmo, ati awọn ọbẹ loriṣiriṣi lo maa n peju-pesẹ sibi ayẹyẹ nilẹ Yoruba.
Ọ ̀ pọ ̀ lọpọ ̀ ènìyàn jàǹkànjàǹkàn tó ti fi ẹ ̀ mí wọn wu ewu fún Ẹ ̀ gbá ni wọ ́ n máa ń ráńtí nínú gbogbo orin wọn .
Ìtàn pàápàá sì sọ wí pé ní ìgbà tí Olόyè Ògbójú má-a fẹ́ ìyàwó-o rẹ̀, Ilé Alájẹjù lọ́dọ̀ Balόgun Ojúkòkòrò ọkọ Gbèsè lόti lọ m’obìnrin.
Ayọ̀ ń bẹ fún àwọn tí ń pa òfin rẹ̀ mọ́,tí wọn ń fi tọkàntọkàn ṣe ìfẹ́ rẹ̀.
Ọlọrun yín ní, “Ẹ tù wọ́n ninu,ẹ tu àwọn eniyan mi ninu.
Sanwo fun iforukọsilẹ nọmba rẹ Nibayii, o ni lati gba fọọmu miiran eleyi ti wa tun fọwọ si.
Ajọ NCDC to fi ikede naa sita sọ pe eeyan 159 lo ni, nipinlẹ Eko, 106 si ni nipinlẹ Delta.
Oríṣun àwòrán, others Aarẹ ẹgbẹ Emere ni ko dara bi awọn ile ijọsin ṣe ma n fi igbalẹ na awọn elere ọmọ lati le wọn kuro ninu ẹgbẹ.
Ó ń jẹ̀rora bí ó ti fẹ́ bímọ.
UN: Orílẹ̀èdè 170 ló ti fi àjàkálẹ̀ àrun Ẹ̀yi tó wa létí ní 2019
Aare igbimo NCWS, dokita Laraba Shoda gbosuba kare lai fun aare Buhari fun kikun awon obinrin lowo lataari pipese eto kikose aladaani lorisirisi.
Àsikò ti olè npọ̀ si niyi pàtàki ni ilú Èkó, nitori ọ̀pọ̀lọpọ̀ fẹ na owó ti wọn kò ni lati ṣe ọdún.
Bi awọn esi naa ṣe lọ niyii: Lagos-74 Oyo-41 FCT-19 Kaduna-19 Bauchi-12 Ogun-7 Rivers-4 Cross River-2 Edo-2 Èèyàn 152 míràn ló ṣẹ̀ṣẹ̀ coronavirus ní Nàìjíríà Esi ayẹwo ti ajọ to n mojuto ajakalẹ arun ni Naijiria, NCDC, fi sita lọjọ Iṣẹgun fihan pe eeyan mejilelaadọjọ lo tun ti ni coronavirus.
    Báyìí ni wọn n lu ìlù náà, èyí tí o sì tilẹ̀ yà ni lẹ́nu ni bi Wèrédìran ti ń jó ijó ìyà náà tayọ̀tayọ̀, nítorí ìgbà tí àwọn ońlì bá fi ìlù wi pé ‘Wèrédìran, òun á dáhùn á ní ‘ó jẹ gọngọ gbèsè, gbèsè, ó jẹ gọngọ.
 Murtala Mohammed ni awon omo egbe igbimo asofin ipinle ohun ati awon eyan jankan-jankan lorisirisi nipinle naa ati lorile-ede Naijria.
Wọ́n tún fẹ́ pa mi o!
Ṣugbọn agbára Abija bẹ̀rẹ̀ sí pọ̀ síi.
Arabia ni ỌjọBọ, ojo kerindinlogun , osu karun un.
Olugbe kan lagbegbe naa ni lẹyin to ti ran eeyan mẹta sọrun nibẹrẹ ọdun yii, afurasi naa tun pa eeyan meji miran nipari osu keje ọdun yii.
Mi ò gbèrò láti lọ fún sáà kẹ́ta gẹ́gẹ́ bí ààrẹ - Buhari Ọ̀yẹ̀ yóò là fún abẹ́rẹ́ ìfètòsọ́mọbíbí fáwọn ọkùnrin láìpẹ́ Ìtọ́jú ara di ìrọ̀rùn!
Ó kìlọ̀ fún un pé kí ó má sọ fún ẹnikẹ́ni pé ó ti fi ọ̀rọ̀ yìí tó òun létí.
Ó bá fi ọwọ́ kàn wọ́n lójú, ó ní, “Kí ó rí fun yín gẹ́gẹ́ bí igbagbọ yín.
Lalẹ Ọjọru ni Fayemi di alaga tuntun awọn gomina lẹyin idibo- afọwọ sii to waye nibi ipade awọn gomina lolu-ilu Naijiria, Abuja.
Àwọn ọ̀rẹ́ àti ojúlùmọ̀ tó n ṣelédè lẹ́yìn rẹ̀ Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Gbajugbaja agbabọọlu tẹniisi ori tabili to jẹ ọmọ Naijiria, Funke Oshonaike lo si aṣọ loju eegun ọrọ ri.
O ni aṣẹ ti aarẹ pa pe ki wọn gbẹmi lẹnu ẹnikẹni to ba ji apoti ibo gbe ati bi awọn ologun ṣe pọ biba lasiko idibo naa kun ara ohun to fa bi awọn eeyan ṣe dẹyẹ si eto idibo naa.
Arsenal domi sí Burnley lára lórí tiransifọ́mà ní Emirates Samson Siasia fèsì lórí FIFA tó fòfin dèé Ayọ̀ abara bíńtín!
Ijọba apapọ àti ile ìgbimọ asofin agba si ti nṣisẹ lati dẹkun iba lassa lorilẹede Naijiria.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Black women live matters: Ọdún 2015 ní àwọn ọlọ́pàá pa India Kager láìní ìdí- Gina Best Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Ni Calabar, wọn mu afura ọgọrin, gomina Ben Ayade si ti kede ẹbun owo ọgọrun miliọnu naira fun ẹnikẹni to ba le ṣamọna bi ijọba ṣe le ri awọn afurasi to ku.
A gbọ pe awọn obi Toke lo ran an lọ ọ ra epo bẹtiro ni nkan bi aago mẹsan an alẹ lọjọ Aje, ṣugbọn ko pada sile.
Eko, Oyo, Kwara, Anambra gba Ọ̀gá Ọ̀lọ́pàá tuntun Kíni itunmọ ọrọ 'body bag' tí Gómìnà El-Rufai sọ?
Nítorí náà, inú bí wọn gan-an sí Juda, wọ́n sì pada sílé pẹlu ìrúnú.
Ni aago mẹjọ owurọ ọjọbọ ni awọn dokita ni ileewosan nla naa, labẹ aṣia ARD bẹrẹ iyanṣẹlodi ọhun.
anfaani lati pejọ lọjọ toni lati jiroro lori eto aabo, ọrọ aje ati ọrọ oselu fun ilọsiwaju
Àkọlé àwòrán, Wọn ti sin oku iyawo Sani ti omiyale gbe lo Sani Yahaya to padanu ẹmi iyawo rẹ so fun BBC pe orileede Niger lawọn ti ri oku rẹ nibi ti omi gbe lọ.
Adeleke jẹ ẹni ọdun mejilelọgbọn nigba naa.
Nítorí a máa san ẹ̀san fún eniyan gẹ́gẹ́ bí iṣẹ́ rẹ̀ati gẹ́gẹ́ bí ìwà rẹ̀.
Ẹni to bori: South Africa Madagascar vs Ghana.
Alukoro ileeṣẹ Ọlọpaa ipinlẹ Eko, DSP Elkana Bala ti ṣapejuwe iṣẹlẹ naa gẹgẹ bi iku ojiji ti ko si wa lasan.
Leyin atotonu olupẹjọ ati olujẹjọ ni adajọ ọhun da ibo naa nu, to wa paṣe pe ki wọn tun ibo naa di ni awọn agbegbe kan laarin oṣu mẹta.
Koda, awọn kan sọ pe Joshua fẹ ki wọn sun ija oun ati Ruiz siwaju, ki ija naa to bẹrẹ nitori bi ara rẹ ṣe ri.
ti wo lulẹ , awon oju ọna agbara naa tun di, ti awon opo ina mona-mona naa tun
Ìgbà mẹ́ta ọ̀tọ̀ọ̀tọ̀ tí ìjọba Nàìjíríà ti gbẹsan lára orilẹ-ède mí tó dẹ́yẹsí i Ṣé o fẹ́ ṣiṣẹ́ ológun?
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Codine: Ọ̀pọ̀ èèyàn tako iléesẹ́ mẹ́ta tíjọba tì pa 8 Èbibi 2018 Oríṣun àwòrán, Huw Evans picture agency Àkọlé àwòrán, Ìjọba fi òté lẹ títa oògùn ikọ́ olómi Codeine Awọn eeyan ti bẹrẹ si sọrọ lori bi ajọ NAFDAC se ti ile iṣẹ apoogun mẹta, ti n se oogun ikọ olomi Coedine pa.
Mo ro pe ọlọgbọn eeyan ni, ti mo si ti fi orukọ rẹ silẹ mọ ara awọn eeyan ti yoo lọ si Mecca lọdun yii, bẹẹ ni mo tun seleri lati gbe gbogbo bukata ayẹyẹ inawo igbeyawo rẹ ni oṣu Kejila ọdun yii.
Wo àwọn míniístà mẹ́fà tí ẹnu ń kùn jùlọ Ọlọ́pàá Adamawa ni #30,000 ni wọ́n fi bọ́ igún látìmọ́lé Ò ṣe f'ọ́mọ tí ń jeérú!
akoko si eyi to ga ju” .
Bí mo bá sì wọ ààrin ìlú,àwọn tí ìyàn di àìsàn sí lára ni wọ́n kún bẹ̀.
”Jehoṣafati dá a lóhùn pé, “Kabiyesi, má wí bẹ́ẹ̀.
Akinwumi Adeṣina ti jẹ minisita eto ọgbin fun orilẹede Naijiria ri.
Ki wa ni ọna abayọ lati koju ibẹru lasiko idanwo tabi lati yago fun magomago lasiko idanwo?
Boya eyi lo mu ki Sultan ilu Sokoto, Alhaji Sa'ad Abubakar Kẹta fi n lọgun too fun awọn ọba alaye pe wọn ti n dakẹ pupọ ju lai sọrọ lori eto aabo to mẹhẹ ni Naijiria, tori bi ara ile ẹni ba n jẹ kokoro buruku, ti a ko ba wi fun, hẹrẹhuru rẹ ko ni jẹ ka sun loru.
Gbogbo wọn ni a óo fi idà pa pẹlu àwọn eniyan mi.
Orogun wọn ti wọn jọ wa niluu kan naa, Manchester United lo fiya ajẹtun iya jẹwọn lairo tẹlẹ nile wọn.
Nítorí bí eniyan bá ṣe ìwé bí òun ti fẹ́ kí wọ́n pín ogún òun, ìdánilójú kọ́kọ́ gbọdọ̀ wà pé ó ti kú kí ẹnikẹ́ni tó lè mú ìwé náà lò.
Ìwé ẹ̀rí nìyí fún ohun gbogbo tí ẹ fún mi, ó tilẹ̀ ti pọ̀jù.
16 billion sọtọ lati gbe oju awọn ọdọ kuro nibi iwa yahoo yahoo ati iwa ọdaran mi.
Ó ti di àṣà ní Israẹli fún àwọn akọrin, lọkunrin ati lobinrin láti máa mẹ́nu ba Josaya nígbàkúùgbà tí wọ́n bá ń kọrin arò.
''Olóde'' ni Yorùbá ń pe coronavirus, iléeṣẹ́ Yemkem ti rí òògùn rẹ̀ báyìí- Olùdásílẹ̀ Yemkem Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí 2 sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 2:23 Fídíò, Water Generator: Ó leè ṣiṣẹ fún wákàtí mẹfà, kó tó sinmi, Duration 2,2310 Òkùdu 2020 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
Àkọsilẹ̀ láti iléèṣẹ́ ọgbà ẹ̀wọ̀n Nàìjíríà fihàn pé àwọn ẹlẹ́wọ̀n tó lé ní ẹgbẹ̀rún méjì ló n retí ikú ní àwọn ọgbà ẹ̀wọ̀n ní Nàìjíríà.
YIAGA: Gbájú-ẹ̀ ni Saraki lò fún wa Tambuwal fẹ́ dúpò Ààrẹ ní PDP Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Èmi ni Awùjalẹ̀ ti Iwo O fikun wipe, wiwa ti awọn adari naa wa yoo bu iyi kun oriẹede Naijiria, yoo si tun mu ibugbooro ba ọrọ aje Naijiria, eleyii ti yoo bukun igbe aye awọn ara ilu Naijiria.
Ọpọlọpọ ẹsun lo n lọ lori ayelujara paapaa julọ lọju opo Instagram pe wọn yọ kuro nitori pe awọn nkan to n gbe soju opo naa ko ba ofin Instagram mu.
Ẹ wo àwọn ẹ̀kọ́ tí ikú Abba Kyari kọ olóṣèlú Nàìjíríà - Aráàlú ṣàlàyé Yoruba ni bàa kú laa dere, èèyàn kò sunwọn ni aaye àmọ́ èyí kò rí bẹ́ẹ̀ pẹ̀lú ikú olórí òṣìṣẹ́ nílé isẹ Ààrẹ, Abba Kyari tó dara ilẹ̀.
Ṣùgbọ́n Cadée nígbà gbọ́ pé ó ṣe pàtàkì kí aláboyún ni ẹni tí yóò wà ní àyíká rẹ̀ lásìkò ìrọbí níwọ̀n ìgbà tí ẹni náà bá ti dáàbò bo ara rẹ̀, bí àpẹẹrẹ kí ó wọ ìbòjú-bomu ni yàrá ìgbẹ̀bi kí ó sì máa fọ ọwọ rẹ lóòrè kóòrè pẹ̀lú ọmọ àti ọșẹ Ikú Dagrin pé ọdún mẹ́wàá, wo àwọn nǹkan mánigbàgbé nípa rẹ̀ Ẹnìkan ṣoṣo nínú ìdílé kan ni yóò gbà N20, 000 owó ìdẹ̀rùn igbele Covid-19 - ìjọba àpapọ̀ Lórí ọ̀rọ̀ Ogun Majek, mi ò lọ́rọ́ láti sọ, ẹ lọ pe ẹni tára rẹ̀ kò yá- Mr.
Kòsí àṣà tó faramọ́ fífi èmí ènìyàn ṣe ìrúbọ - Olúwó Ajínigbé ń bèèrè fún epo, iṣu àti ọ̀tí Schinap gẹ́gẹ́ bí owó ìtanràn Ọlọ́pàá ti mú afurasí ajínigbé Hamisu Wadume Lara awọn minisita ti o ti wa ni ipo tẹlẹ ti o si tun n pada bọ nibẹ ni Babatunde Fashola, lati ilu Eko, eni ti o jẹ minisita fun ohun amuṣagbara, ọrọ iṣẹ ati ile gbigbe.
Asoju orile ede  India  ni orile ede Naijiria, Abhay Thakur lo soro
Ida mẹwa ninu ọgọrun owo osu rẹ gẹgẹbii ajẹmonu owo igbafẹ Ida ogun ninu ọgọrun owo osu rẹ gẹgẹbii ajẹmọnu owoona atigbadegba Awakọ ti oun pẹlu yoo maa gba owo ifẹyinti.
yoo bere nipinle Akwa Ibom nitori pe ipinle naa ti gba aare ni towo tese.
Ọlọrun ni ó fún àwa ati ẹ̀yin ní ìdánilójú pé a wà ninu Kristi, òun ni ó ti fi òróró yàn wá.
Ṣugbọn bí wọn kò bá gbọ́ràn,a óo fi idà pa wọ́n,wọn yóo sì kú láìní ìmọ̀.
Ina jo ọja binukonu lọjọta nipinlẹ Eko
O fi kun un wi pe oloogbe ṣẹṣẹ rinrinajo de lati ipinlẹ Kano ninu oṣu keji ni nibi ti ọkọ rẹ, Dhikirullahi ti ṣẹṣẹ ri iṣẹ lẹyin ọdun kan eto agunbanirọ rẹ.
Àwọn àjèjì tí wọ́n wà láàrin àwọn ọmọ Israẹli bẹ̀rẹ̀ sí kùn, pé àwọn kò rí ẹran jẹ bí ìgbà tí àwọn wà ní Ijipti.
Ninu eyi ti ẹgbẹrun mẹrinla ati ojilelẹbẹta o din meje eeyan ti ri iwosan, ọrinlelẹẹdẹgbẹrin o din mẹjọ lo ti gba ekuru jẹ lọwọ ẹbọra nipasẹ arun naa.
Ní ọjọ́ méjéèjì wọ̀nyí ni ilé-aiyé kọ ẹ̀gbẹ́ sí òòrùn.
Bakare ni lasiko ipalẹmọ fun eto idibo yii, Buhari ti n salaye ohun to se lati daabo bo Naijiria ati ọna ti wọn fẹ gba gbe Naijiria lọ si ipele to kan, ti Atiku Abubakar naa si ti n bu ẹnu atẹ lu awọn aseyọri yii, to si pinnu lati se atunto ẹka eto isejọba.
Ninu ọrọ tirẹ, Sanwo-Olu ni oun ko ran wọn lati lọ pa awọn eniyan, amọ ki wọn jẹ ki alaafia jọba lorilẹede Naijiria.
Lara awọn ibi ti Odusanya ti kawe ni Ilẹ Gẹẹsi, ilu Abeokuta ati ipinlẹ Eko.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ivory Coast: Lẹ́yìn ìpàdé aláṣẹ ìjọba ni wọn gbé lọ sílé ìwòsàn níbi tó kú sí 9 Agẹmo 2020 Oríṣun àwòrán, AFP Inu ọfọ nla ni ijọba ati awọn eeyan orilẹede Ivory Coast wa bayii nitori iku ojiji to sadede mu olootu ijọba, Amadou Gon Coulibaly lọ.
Sanwo-Olu fẹ́ fojú-rinjú pẹ̀lú ọmọ tó ní kí ìyá òun ‘Calm down’ Mamman Daura rí ìjà ọmọ Nàíjíríà torí ó pè fún wíwọ́gilé pínpín ipò ààrẹ lẹ́lẹ́kùn jẹkùn Ìjọba Èkó yóò fi òfin dè títà afẹ́fẹ́ gáàsì létílé láti dènà ìbúgbàmú láwùjọ Kini awon eniyan n sọ nipa ẹkun rẹ: Bi awon kan se n kii, ni awọn mii n buu pe ki lo muu.
Ìran Noa nìyí: àwọn ọmọ rẹ̀ ni Ṣemu, Hamu ati Jafẹti.
Lẹyin ti wọn ba kirun Maghreb ati Isha papọ, ni wọn yoo wa bẹrẹ adura.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Illegal Orphanage: Ìjọba ti ayédèrú ilé ọmọ aláìlóbìí pa, ọmọdé mẹ́tàdínlọ́gbọ̀n gbòmìnira 9 Sẹ́rẹ́ 2020 Awọn alaṣẹ tọrọ kan lorilẹede Naijiria ti ko agadagodo silẹkun ile ọmọ alailobi kan ti ko niwe ofin ni ipinlẹ Kaduna, ti wọn si tu ọmọde mẹtadinlọgbọn silẹ.
Mose ati àwọn alufaa, ọmọ Lefi, bá wí fún gbogbo ọmọ Israẹli pé, “Ẹ dákẹ́ jẹ́ẹ́, kí ẹ sì gbọ́, ẹ̀yin ọmọ Israẹli, òní ni ẹ di eniyan OLUWA Ọlọrun yín.
Ìgbà wo ni ẹ óo ṣe iyèméjì dà, ẹ̀yin alainigbagbọ wọnyi?
Wilder to jẹ ọmọ ọdun mẹtalelọgbọn lo ba ọmọ ilẹ Amerika ẹgbẹ rẹ,Dominic Breazeale ja.
Wọ́n gbẹ́ kòtò sílẹ̀ dè mí,ṣugbọn àwọn fúnra wọn ni wọ́n jìn sí i.
Ó dùn bí oyin ní ẹnu mi.
O le jẹ nigba ti eto iyansipo wọn bẹrẹ, ti wọn ba bẹrẹ isẹ, tabi ti wọn ba ti n ṣiṣẹ lọ.
Iroyin kan ti ajọ NFF fi si oju opo Tweeter rẹ lo kede bẹẹ pẹlu afikun pe ibo mẹrinlelọgbọn ni Pinnick ni, lati bori awọn oludije mẹta yoku, to si gba ipo rẹ pada.
Ó da kẹ̀kẹ́ ogun Farao ati àwọn ọmọ ogun rẹ̀ sinu òkun,ó sì ri àwọn akọni ọmọ ogun rẹ̀ sinu Òkun Pupa.
Ìbò gómìná Bayelsa ku ọjọ́ méjì, Iléejọ́ yẹ àga mọ́ olùdíje APC ńídìí, Góòlù pọ̀ ní ìlú Madaka ṣùgbọ́n wọn kò ní ọ̀nà fún ọgọ́rùn ún ọdún Àwọn ọmọ Nàìjíríà bu ẹnu ẹ̀tẹ́ lu NTA lórí ìgbóhùnsáfẹ́fẹ́ ìdíje bọ́ọ̀lù Ilé ẹjọ́ ni agbábọ́ọ̀lù ọmọ Nàìjíríà, Dickson Etuhu jẹ́bi ẹ̀sùn títa ìdíje Sweden Lori boya aisan itọ ṣuga le ran ẹlomiran, o ni ko ṣeeṣẹ ki aisan naa ran ẹlomiran.
Ó dá a lóhùn, ó ní, “Betueli, ọmọ tí Milika bí fún Nahori ni baba mi.
Oríṣun àwòrán, Others Ọmọ ti yoo jẹ́ Ásàmú ni ọrọ Osuolale, kékeré lọ tí ń jẹ ẹnu samu-samu nítorí esi idanwo ipele àkọ́kọ́, taa mọ sì Grade one ni Osuolale mú jáde nínú ìdánwò asejade, gbogbo iṣẹ tó sì jókòó sedanwo rẹ, lo yege pátápátá.
Ajọ naa ni idi ti awọn fi ṣe alakalẹ naa ni lati ri wi pe awọn akẹkọọ to ṣi n reti esi idanwo asekagba nileewe girama naa oo ni anfaani lati kọ idanwo Post UTME naa.
Orúko Pópíọlá ni ó fi ń ṣeré níbí yìí.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ọ̀sun Election: Akin Ogunbiyi àti Moshood Adeoti kọ èsì ìbò 23 Agẹmo 2018 Oríṣun àwòrán, @akmediaonline Àkọlé àwòrán, Akin Ogunbiyi àti Moshood Adeoti kọ èsì ìbò abẹnu ẹgbẹ koowa wọn Ọmwe Akin Ogunbiyi, ti oun ati Senatọ Ademọla Adeleke dijọ dije ninu ibo abẹnu fun ipo gomina labẹ ẹgbẹ oselu PDP nipinlẹ Ọsun, ti fariga lati faramọ esi ibo abẹnu ti wọn kede naa lọjọ Abamẹta, to si leri leka pe oun yoo gbe igbesẹ lati wa iyipada lori ọrọ yii ninu ẹgbẹ naa.
Laarin oṣu marun un pere to gori oye, wọn tẹwọ gboriyin fun un lori aato rẹ fun iyanju aawọ eyi to fun ọpọlọpọ ẹgbẹ Islam.
Ó ti lo ọdún méjìdínlógún ní ọgbà ẹwọn lẹ́yìn tí wọ́n ní ó kó àwọn kan jọ láti ṣekúpa ẹnìkan.
Àwọn ìròyìn mìíràn tí ẹ lè nífẹ̀ẹ́ sí: Àwọn òrin tó ń k'ókìkí àwọn ọmọ Yahoo R Kelly sunkún lóri Tẹlifísàn nípa ẹ̀ṣùn ìbálòpọ̀ Hubert Ogunde ló m'órí mi yá láti di òṣèré Mo n wa'yawo - Falz 'Gbogbo mọ̀lẹ́bí mi ló wọ bàtà ti Fẹla bọ́ sìlẹ̀' Èyí tí a wò jùlọ 5:03 Fídíò, Omolola Arohunmolase Welder: Mo ti fí iṣẹ́ 'Welder' gbayì láwùjọ, tó mo fi tọ́ ọmọ yanjú, Duration 5,039 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 5:39 Fídíò, Akomolede ati Asa lori BBC: Olùkọ́ Kikelomo Ogunboye tan ìmọ́lẹ̀ sí ìwà olè ọ̀gá ọlọ́pàá Audu gẹ́gẹ́ bí àwòkọ́ṣe àsìkò yìí, Duration 5,398 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 4:11 Fídíò, Oba Adeyeye Ogunwusi: Ojú mi ti rí lọ́pọ̀ lọpọ̀, ọ̀pọ̀ èèyàn ni kò tilẹ̀ gbàgbọ́ pé mo lè jọba- Ooni, Duration 4,117 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 4:43 Fídíò, Promise Akinlade: ọmọ ọdún mọ́kànlá tó ń fi ìlù dárà bíi àgbàlagbà sọ̀rọ̀ nípa tálẹ́ǹtì rẹ̀, Duration 4,437 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 0:59 Gbọ́, Ìsẹ̀lẹ̀ jákèjádò orílẹ̀èdè àgbáyé láàárín ìṣẹ́jú kan, Duration 0,59wákàtí 5 sẹ́yìn 7:03 Fídíò, Olumuyiwa Bolade Adedeji Military Bruitality: Bí arákùnrin onípèníjà ara tí sọ́jà lù ṣe dé, Duration 7,035 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 4:45 Fídíò, Yoruba Films: Ẹ̀ẹ́ bẹ̀ mi kúrò láyé ni, mi ò lè kú - Fadeyi Oloro, Duration 4,4526 Èrèlè 2020 2:48 Fídíò, Esther Ajayi: Èmi náà ti borí ìṣòro rí ló ń mu mi ṣojú àánú, Duration 2,481 Ògún 2019 6:08 Fídíò, Adebola Ademilua: Àìrísẹ́ ṣè lẹ́yìn ìwé kíkà ló sọ mi dí ìyá onírú, mo dúpẹ́ tèmi, Duration 6,0827 Bélú 2020 5:55 Fídíò, Soyinka Cancer: Àṣe ara mi ni iso ti n run gbogbo bí mo ṣe n ṣèrànwọ́ lórí jẹjẹrẹ, Duration 5,5527 Bélú 2019 BBC News, Yorùbá Ìdí tí ẹ fi le è nígbàagbọ́ nínú ìròyìn BBC Ìlànà Lílò Nípa BBC Òfin Àṣírí Cookies Kàn sí.
Aarẹ Buhari ni gbogbo ipa to ba yẹ ni ijọba oun yoo sa lati rii pe wọn dẹkun wahala igbesumọmi ati ijinigbe gbogbo to n waye lorilẹede Naijiria ati pe gbogbo awọn to ba wa ni idi ibajẹ ni wọn yoo lọ si i.
Igbesẹ yii lo waye nile igbimọ aṣofin agba lẹyin ti ilẹeṣẹ BBC gbe fiimu kan jade, leyi to tu asṣiri awọn olukọ Fasiti kan lorilẹede Ghana ati Naijiria, ti wọn gbiyanju lati ba awọn akẹkọ ni ibalopo.
Àwọn ọmọ ogun kò mọ̀ pé Jonatani ti kúrò lọ́dọ̀ àwọn.
Yàrá àbáwọlé ẹnu ọ̀nà yìí ni ọba yóo gbà wọlé, yóo sì dúró lẹ́gbẹ̀ẹ́ òpó ẹnu ọ̀nà.
Àwọn awakọ ero náà, tó fi ẹ̀sùn kan àwọn ọmọlẹ́yìn alága àwọn alákòóso gareji ọkọ nipinlẹ Ọ̀yọ́, Alhaji Mukaila Lamidi, tí ọ̀pọ̀ èèyàn mọ si Auxiliary pé, wọn kàn-án nípa fún àwọn láti máa san owó ni ibudokọ kọ̀ọ̀kan lojoojumọ, yàtọ̀ sí owo ti jọba ní kí àwọn máa san.
Minista fun  eto isẹ lorile ede Naijiria,  Chris Ngige  ti ki awọn osisẹ lorile ede Naijiria  ku ori ire  bi won se n sayẹyẹ ayajọ ọdun awon  osisẹ lagbaaye, lọjọ kinni, osu kárùn ún  .
Bakan naa la tun gbọ pe, ọkọ akoyọyọ ti awọn osisẹ naa gbe lọ wa erupẹ lo wo lu ọkan ninu wọn mọlẹ.
Ọmọ ọba nìyí, ó tó àkókò láti fi jọba nisinsinyii, gẹ́gẹ́ bí ìlérí tí OLUWA ṣe pé ìran Dafidi ni yóo máa jọba.
Osinbajo wa dupe lowo ajo agbaye to n mojuto iye awon eniyan lagbaaye (United Nations Population Fund UNFPA) fun ipa rere ti won n ko.
Bí ó ti ń sọ̀rọ̀ lọ́wọ́ iranṣẹ mìíràn dé, ó ní, “Bí àwọn ọmọ rẹ tí ń jẹ àsè ninu ilé ẹ̀gbọ́n wọn àgbà, 
ile-isẹ omo ogun ofurufu ( Nigerian Air Force NAF) ati awon ẹsọ to n pese  aabo fun ifọwọsowọpọ wọn lori aseyori lati gbogun
Dipo ki Olubadan fesi si awọn ẹsun ta fi kan, se lo tun n tabuku wa.
Ninu ifọrọwerọ rẹ pẹlu BBC Yoruba, ọjọgbọn ninu imọ nipa ajọsepọ orilẹede si orilẹede,Bọlaji Akinyẹmi ni omi n bẹ laamu fun orilẹede South Africa lẹyin ikọwefiposilẹ Zuma.
Ẹ̀yin ọmọ Abrahamu, iranṣẹ rẹ̀,ẹ̀yin ọmọ Jakọbu, àyànfẹ́ rẹ̀.
Èèyàn kan kú, ọmọ méjì sọnù nínú òjò tó rọ̀ nílùú Ilorin Èèyàn 97 ní àrùn Coronavirus tún ṣẹ̀ṣẹ̀ ràn ní Nàìjíríà ní Ọjọ́ Àìkú 'Mo mọ̀ọ́mọ̀ sin ọmọ-ọmọ mi, ìkókó jòjòló láàyè ni, nítorí wọ́n fipá bá ọmọbìnrin mi lòpọ̀ ló fi lóyún rẹ̀'!
Yahoo Yahoo: Ọ̀pọ̀ olórin ti kọ́rin ìwúrí fún àgbéga rẹ̀
Bí nǹkan ṣe ń ṣe ẹnu ire fún àwọn ọmọ ẹgbẹ́ Abódiakọ-akọ́diabo a sì ń gbà wọ́n gẹ́gẹ́ bí ènìyàn, ìrìnàjò náà kò yàrá.
Kòo jjẹ́ ronú lọ́jọ́ kan, bí ènìyàn bá sí ń hu ìwà òmùgọ̀ ní ìlú wa wọn a máa fi olúwaarẹ̀ wé Àgùntàn-ìnàkí, ẹni tí oríkì rẹ̀ ń jẹ́ dọ̀ǹgíṣọlá ọkùnrin.
Ile igbimo asoju-sofin yoo sewadii iwa itapa sofin awon egbe oselu ati ajo to n mojuto eto idibo lorile-ede Naijiria, INEC, eyi ti o waye lasiko eto idibo abele saaju idibo gbo-gbo-gbo to n bo lọdun 2019.
Báyìí ni wọ́n kọ ìwé sí ẹ̀gbẹ́ ilé náà tí orúkọ bàbá mi sì wà ní ibẹ̀ títí di oní.
OLUWA Ọlọrun ní ọkàn rẹ ti kún fún ìfẹ́kúfẹ̀ẹ́ jù!
Wọ́n sì kó aguntan wá pẹlu, láti inú agbo wọn fún Dafidi ati àwọn eniyan rẹ̀, kí wọ́n lè rí nǹkan jẹ.
Ọjọ ori ọpọlọpọ wọn kii si i ju ọdun mẹẹdogun si mọkandinlogun.
IBB tẹ ń pariwo pé ó kú, kò kú o, Ko ko lara ọta ń le- Agbẹnusọ Kassim Bi ẹ ba ri bi Ọgagun Ibrahim Babangida ṣe n ṣe kébékébé pẹlu okun ara to dara lonii.
Awọn aṣofin ti wọn n ja orilẹ-ede naijiria lole labẹ iboju iṣẹ idagbasoke ilu ti wọn si n ṣe ofin to n dena ominira araalu ti wọn si n ti ipasẹ bẹẹ da omi alaafia ru.
Tunde wa lara aìmọye mílíọ̀nù eniyan lagbaye to padanu owo wọn sọwọ Sergei Mavrodi laarin ọdun 1990 si 2017, sugbọn ko banuje lori iroyin iku Mavrodi.
Amọ, wọn sowipe lootọ ni wọn kọ awọn ọmọogun kuro nibe nitoriwipe awọn ri wipe alaafia ti jọba lagbeegbe naa.
Sugbọn, oore ẹ̀dẹ ni awọn anfaani yii, nitori pe lẹyin to bẹrẹ idije fun ipo aarẹ lọdun 2020, lo ti bẹrẹ si ni wi awijare.
Nítorí náà, ó yẹ kí á túbọ̀ ṣe akiyesi àwọn ohun tí à ń gbọ́, kí á má baà gbá wa lọ bí ìgbà tí odò gbá nǹkan lọ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Arsene Wenger: Idi tawọn ololufẹ Arsenal se nfi we Mugabe 8 Ẹrẹ̀nà 2018 Àkọlé àwòrán, Ọdun mọkanlelogun ni Arsene Wenger lo lati dari Arsenal nigbati Robert Mugabe lo ọdun mẹtadinlogoji lati dari orilẹede Zimbabwe Ọpọ awọn alatilẹyin ẹgbẹ Arsenal lori opo ikansiraẹni Twitter loju opo itakun agbaye, ni wọn ti ngba oniruuru ọna alumọkọrọyi lati beere pe ki opin de ba akoso ọdun mọkanlelogun Arsene Wenger.
A kò fòfin de owó naira tó ti pẹ́ ní Naijiria -CBN Ẹ yé gba owó orí níbi ìdána ìyàwó mọ́, sísọmọbìnrin s'óko ẹrú ni- Daddy Freeze Ọwọ́ ọlọ́pàá ti tẹ ọkùnrin kan tó pa ọ̀rẹ́ rẹ̀ nítorí N40 ní Kano Iku lo yọ ọwọ Audu lawo ti Yahaya Bello fi jẹ gomina gẹgẹ bi ẹni toṣe ipo keji ninu idibo abẹle ẹgbẹ.
Nígbà tí àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rékọjá sí òdìkejì òkun, wọ́n gbàgbé láti mú oúnjẹ lọ́wọ́.
”Saulu dáhùn pé, “Mò ń gbọ́.
"Ó ti pa èèyàn 172 ni Nàìjíríà - WHO Gẹgẹ bi aya oloogbe, Odunayo Abolarinwa ṣe ṣalaye fun ikọ iroyin Kayeefi tio BBC Yoruba, odidi ọlọpaa Mopol meji lo yinbọn ba a ni ilu Oye Ekiti nigba to n lọ sile lati ṣọọbu rẹ to ti n ṣiṣẹ ""Tailor""."
O kò gbọdọ̀ gbọ́ tirẹ̀, bẹ́ẹ̀ ni o kò gbọdọ̀ dá a lóhùn.
Bẹ́ẹ̀ ni Joabu ati Abiṣai, arakunrin rẹ̀, ṣe pa Abineri tí wọ́n sì gbẹ̀san ikú Asaheli, arakunrin wọn, tí Abineri pa lójú ogun Gibeoni.
Sugbọn ere ori itage ni John Adedayo B.
Wo àwọn ọ̀nà to fi leè ní owó lọ́wọ́ láti ipasẹ̀ iṣẹ́ amọ̀ Amọ ọkan lara awọn to jogun ba asa Kengbe lilu naa, Ramat Olowo sọ fun BBC Yoruba pe, oun ti pinnu lati tun se agbende asa naa pada ko ma parun.
A dé ibi tí a bá ọkùnrin kan tí ó rọra jókòó ní òun nìkan tí o ń sọkùn tí ẹnikẹ́ni kò sí ni agbegbe ibi tí ọkùnrin náà wà rárá, ìgbà tí Èṣù si fi í han adéforítì ó ní, ‘Olówó pátápátá ni eléyìí nígbà tí ó wà ní ayé ṣùgbọ́n kò fi owó rẹ̀ ṣe ẹnikẹ́ni lóòre, ó lé gbogbo ènìyàn kúrò lọ́dọ̀ rẹ, kìí fẹ́ kí ẹnikẹ́ni súnmọ́ òun.
Ìwọ ọ̀rẹ́ mi, ikú tí ń pa ojúgbà ẹni ń pòwe, nígbà tí Olówó-ayé rí ìwọ̀nyí òun náà mọ̀ pé Igbó Olódùmarè sún mọ́ etílé, bàbá mi múra ó tún ṣòkòtò ṣe.
Àwọn adigunjalè pa èèyàn mẹ́fà ní báńkì kan nìpínlẹ̀ Ondo Àwọn Dókítà fárígá ní ìpínlẹ̀ Ondo, wọ́n ní kí Gómìnà san owó oṣù mẹ́ta tó jẹ wọ́n!
Nítorí ọ̀rọ̀ OLUWA dúró ṣinṣin;òtítọ́ sì ni ó fi ń ṣe gbogbo iṣẹ́ rẹ̀.
Ìkíni gbogbo ọmọ Nàìjíríà jákè-jádò nílé lóko lódò lẹ́hìn odi àti níbikíbi tó wù kí ẹ wà.
Mà á ṣiṣẹ́ bí i gómìnà tó ní èrò aráàlú lọ́kàn - Seyi Makinde Sugbọn niwọn igba to jẹ pe ọjọ ti eeyan ba gun kọ lo n kan ọrun, ojo ti n pa igun Dapọ bọ nidi ko lee jẹ eeyan laye, ọjọ ti pẹ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ethiopian Airline crash: Àbájáde ìwádìí ọkọ̀ bàálù Ethiopia wẹ awakọ̀ bàálù mọ̀ ọ́ 4 Ìgbé 2019 Oríṣun àwòrán, Ethiopian Airline Àkọlé àwòrán, Baalu naa ko eero mọkandinlaadọjọ, to fi mọ awọn oṣiṣẹ baalu mẹjọ.
9 245650 Orilẹede Kenya 1568 3.
Mubarak lo ọgbọn ọdun nipo gẹgẹ bi aarẹ Egypt ki wahala nla kan to suyọ nilẹ Egypt.
Ọdun 1972 ni ile ẹjọ to gaju lọ l'America fofin de idajọ iku, to si wọgile awọn idajọ iku to wa nilẹ lasiko naa.
Ọ̀sẹ̀ melo kan sẹhin ni Alake ti Ilẹ Ẹgba, Oba Adedotun Gbadebo, naa sọ pe oun fara mọ ki Buhari gbe igba ibo fun saa keji.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Taa gan ló ń jí orin àti ohùn ara wọn lò nínú Adewale Ayuba àti Ajebori Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 3 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 5 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
“Bí ọkunrin kan bá bá ẹrubinrin tí ó jẹ́ àfẹ́sọ́nà ẹlòmíràn lòpọ̀, tí wọn kò bá tíì ra ẹrubinrin náà pada, tabi kí wọ́n fún un ní òmìnira rẹ̀, kí wọ́n wádìí ọ̀rọ̀ náà, ṣugbọn wọn kò gbọdọ̀ tìtorí pé ẹrú ni kí wọn pa wọ́n.
Onkọroyin lori ayelujara to tun jẹ gbajugbaja lori ẹrọ mohunmaworan, Sophie Elise ṣe iṣẹ abẹ afikun idi rẹ nigba to wa lọmọ ogun ọdun.
Akeugbagold, ẹni tó ṣàlàyé pé ọdún méjìlá ni ìyá àwọn ọmọ náà fi ń woju Ọlọ́run, kò tó rí àwọn ìbejì náà bí, tún rawọ ẹ̀bẹ̀ sì àwọn gende agbebọn náà láti tètè dá àwọn ọmọ òun padà fún òun torí Ọlọ́run.
Mo rí nǹkankan tí ó bani lẹ́rù lọ́wọ́ àwọn wolii Jerusalẹmu: Wọ́n ń ṣe àgbèrè ẹ̀sìn,wọ́n ń hùwà èké;wọ́n ń ran àwọn ẹni ibi lọ́wọ́,kò jẹ́ kí ẹnikẹ́ni yipada kúrò ninu iṣẹ́ ibi rẹ̀.
iforowanilenuwo ti o se pelu awon akoroyin.
Wo àwọn nkan tí ó yẹ kí o mọ̀ nípa Bitcoin, kí o tó ó dáwọ́ le e Nigeria Police recruitment 2020: Bí ó bá fẹ́ dara pọ̀ mọ́ ìṣẹ́ ọlọ́pàá, forúkọ́ sílẹ̀ níbí Bii sinima orita lo ri lẹyin ti awọn aṣoju ajọ NDDC naa jade kuro niwaju igbimọ iwadii ọhun, ti wọn si fi awọn oluwadii silẹ lori ijoko.
Bẹẹ si ni ọgọọrọ awọn araa apa Ila-Oorun Ariwa Afirika ti ko si larọwọto riri omi amọloolo lo n koju wahala bi arun naa ṣe n jẹ wọra sii bayii.
Ẹni líle ni Olόyè Ògbójú, Ọkùnrin náà sì gbóná ju àpáàrà lọ.
"Mi o le yi ohun to ti ṣẹlẹ pada.
B Joshua-Angel Gomes Premier League gbìnàyá padà, ọ̀gá àti ọmọṣẹ́ fìjà pẹ̀ta Mò ń ronú láti padà sí ẹgbẹ́ agbábọ́ọ̀lù Nàìjíríà, Super Eagles láìpẹ́- Odion Ighalo Mo fẹ́ kí Ighalo gba ife pẹ̀lú Manchester United kó tó kúrò lọ́dún 2021- Solskjaer Ọpọ awọn ololufẹ wọn lo ti n sọ pe o yẹ ki Arsenal le na Brighton nigba ti wọn ba pade.
Lori bo ya wọn ṣe etutu ki wọn to ko awọn oriṣa naa kuro laafin, Oluwo ni ko si etutu kankan nitori ṣiṣe etutu tumọ si ibọriṣa eyi t'oun ko le ṣe.
 ilé ìtura yìí wà lẹ ́ gbẹ ́ omi bí omi òkun kùrámọ ̀ .
Ìbá ṣe pé ìkáwọ́ mi ni àwọn eniyan yìí wà, ǹ bá yọ Abimeleki kúrò lórí oyè.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Global Vaccine crisis: Ìgbẹ́kẹ̀lé nínú abẹ́rẹ́ àjẹsára ń di òkú l'ágbáyé!
Bẹ́ẹ̀ gan-an ni a sì jẹ́.
 Àkọsílẹ ̀ àkọ ́ kọ ́ tí a kọ ́ kọ ́ rí ni tí johannes jacob wecker ní ọdún 1609 .
Ní ìdílé Ọlọ́fà, ọjọ́ méje ni à ń sọ ọmọkùnrin lọ́rúkọ.
Wo orúkọ àwọn ẹ̀yà ara rẹ̀ ní èdé Yorùbá Àwọn iròyin ẹlẹ́jẹ̀ márùn ún tó fẹ́ẹ̀ tú Nàìjíríà ká Adigunjalè fọ́ báńkì ní Oye Ekiti, wọ́n tún ṣun ọkọ̀ ọlọ́pàá níná Ó gbẹnután!
Awon ko ti mo ohun to fa ijamba ina naa.
2 10 Orilẹede Mongolia 0 0.
Dúkìá mi ò lé kan o, mo ti dá fọ́ọ̀mù padà bó ṣe wà tẹ́lẹ̀ - Buhari, Osinbajo Ìtàn ayé Seyi Makinde, gómìnà tuntun ní Ọ̀yọ́ Èèyàn 5 farapa, ọ̀pọ̀ ọkọ̀ jóná nínú ìjàmbá iná márosẹ̀ Ibadan sí Eko Ta ni Babajide Sanwo Olu, gomina tuntun l‘Eko?
Lizzy tẹ̀síwájú nínú ọ̀rọ̀ rẹ̀ pé, ààrùn Covid-19 tó wà l'óde ni kò jẹ́ kí ayẹyẹ nàá kó jẹ́ rẹpẹtẹ.
Agbègbè Western Cape ní ilú ti Cape Town wa ló ni ìdaji gbogbo Covid-19 àti ikú rẹ ni South Africa.
Eliṣa bèèrè pé, “Kí ni o fẹ́ kí n ṣe fún ọ?
SERAP: Owo ifẹyinti ko tọ si ẹni ti o sisẹ gẹgẹ bii gomina
Nítorí àwa kì í ṣe àwọn tí ń ba ọ̀rọ̀ Ọlọrun jẹ́ nítorí èrè tí wọn óo rí jẹ níbẹ̀, bí ọpọlọpọ tí ń ṣe.
6 1849101 Orilẹede Germany 45622 54.
Wọ́n ṣa àwọn aguntan ati àwọn mààlúù tí wọ́n dára jùlọ pamọ́ láti fi rúbọ sí OLUWA Ọlọrun rẹ.
Eeyan mejidinlogoji lo laarun naa lati Kaduna, marundinlogun lati Imo, mọkanla lati ipinlẹ Rivers nigba ti eeyan mẹjọ ni ni Plateau.
O ni ipinlẹ Ondo ni wọn mọ si ipinlẹ to gbooro ju pẹlu gbingbin igbo.
Oríṣun àwòrán, Others Bi ifẹhonu han to gba ẹmi ọba ṣe bẹrẹ: Ọjọ nla, ọjọ manigbagbe ni ọjọ kinni oṣu Keje ọdun 1969 nilu Ogbomoso lasiko ti ogun abẹle n lọ lọwọ ni Naijiria.
tile je pe orile ede yii  koju awon
Oluṣọaguntan Adeboye to ṣalaye ninu iwaasu rẹ to ṣe fun awọn ọmọ ijọ naa lagbaye lori ẹrọ ayelujara ati mohunmaworan ṣalaye pe oun ti paṣẹ fun gbogbo ẹka ijs naa lati tẹle aṣẹ ijsba lori pe ko gbọdọ si ipejọpọ ero to ba ju aadọta lọ kaakiri.
“Níwọ̀n ìgbà tí mo ti fi ìwà mímọ́ mi búra:n kò ní purọ́ fún Dafidi.
Bẹ́ẹ̀ náà ni, ẹ̀yin ará mi, ẹ̀yin náà ti kú ní ti Òfin, nígbà tí ẹ di ara kan náà pẹlu Kristi.
OLUWA rán wolii kan sí Eli, kí ó sọ fún un pé, “Mo fara han ìdílé baba rẹ nígbà tí wọ́n jẹ́ ẹrú Farao ọba ní ilẹ̀ Ijipti.
Ṣugbọn ẹpa ko boro mọ, nitori pe nigba ti yoo fi yi oju foonu rẹ pada si ibi to yẹ, fọto naa ti lọ sori Instagram, awọn ololufẹ rẹ to ju miliọnu mẹrindinlọgọrin lọ, si ti ri ihoho rẹ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Fayẹmi: Ọ̀pọ̀ èèkàn ìlú ló bá se ayẹyẹ ìbúra Kinni o mọ nipa Kayode Fayemí?
wọ́n sì ṣe ogoji ìtẹ́lẹ̀ fadaka tí wọ́n fi sí abẹ́ ogún àkànpọ̀ igi náà, ìtẹ́lẹ̀ meji meji lábẹ́ àkànpọ̀ igi kọ̀ọ̀kan fún àwọn ìkọ́ rẹ̀ mejeeji.
’ Ṣugbọn nítorí àkókò yìí gan-an ni mo ṣe wá sí ayé.
Àkọlé àwòrán, Níbo láyé kọjú sí Àkọlé àwòrán, Níbo láyé kọjú sí 'Ọkùnrin tí kò bá sanwó iléèwé ọmọ, kó lọ wẹrí' Àkọlé àwòrán, Níbo láyé kọjú Ọkan lara awọn alejo ninu abala mii lori eto 'Níbo láyé kọjú' tẹnu mọ ọ pe ọkunrin ti ko ba le san owo ile iwe ọmọ n ta ibukun rẹ ni.
Sùn títí di òwúrọ̀, nígbà tí ó bá di òwúrọ̀ bí ó bá tẹ́ ẹ lọ́rùn láti ṣú ọ lópó gẹ́gẹ́ bí ẹ̀tọ́ rẹ̀, ó dára, jẹ́ kí ó ṣe bẹ́ẹ̀.
Igbesẹ karun un: lẹta kan yoo dun ninu apo iwe atẹranṣẹ ori ayelujara rẹ ti a mọ si Email eleyi to o fi silẹ lawọn apoti to ti yọ sita loke ṣaaju.
Tí a fiṣọwọ́ ní 5:025:02 Ǹjẹ́ ó ṣeéṣe kí ìyáwò rẹ gbé ọmọ àlè wá sílé láì mọ̀?
Wo bi wọ́n ṣe n ṣe àmójútó ilé ìjọsìn Prophet Israel Oladele, CCC Genesis Global Seyi Makinde fún olórin Fuji Taye Currency lẹ́bùn ọkọ̀ bọ̀kìnnì Toyota Prado 2020 Òtítọ́ làwọn sọ́jà gbé ìbọn tó lọ́ta gidi nínú lọ sí Lekki Toll Gate lásìkò ìwọ́de EndSARS- Ọ̀gágun Taiwo Ìjọba àpapọ̀ pàṣẹ pé kí gbogbo ọkọ̀ agbépo kúrò ní márosẹ̀ Lagos-Ibadan Wọ́n ti rí òkú Alága ẹgbẹ́ APC ní Nasarawa tí àwọn agbébọn jí gbé lọ́jọ́ Satide Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Fídíò, The New Pandemic: Kíni àwọn onímọ̀ sáyẹ́ńsì ń sọ nípa rẹ̀?
A n ranti awọn asẹda wa ni, ko si yẹ ka maa pe awọn eeyan to n se eyi ni abọrisa.
Ṣugbọn ọkunrin náà tí Jesu wòsàn kò mọ ẹni tí ó wo òun sàn, nítorí pé eniyan pọ̀ níbẹ̀, ati pé Jesu ti yẹra kúrò níbẹ̀.
Wo bí ètò ìsìnkú Isa Funtua ṣe wáyé ní ìlú Abuja Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Peters Ijagbemi dá àrá lórí ètò 'Ṣé o láyà' ti BBC Yorùbá lọ̀sẹ̀ yìí Ìbúwọ́lù ọ̀hún wáyé lẹ́yìn ti mínísítà fún ọ̀rọ̀ ọdọ́ àti eré ìdarayá ṣe àgbékalẹ̀ iwé kan lásìkò ìpàdé àwọn ìgbìmọ̀ àláṣẹ ìjọba àpapọ̀ níbi tó ti sàlàyé bi ọ̀rọ̀ ajé orílẹ̀-èdè Nàìjíríà yóò ṣe ri ti ìjọba bá ṣe ètò tó yẹ lórí àwọn ọdọ́.
Nítorí pé àṣẹ ni, fún àwọn ọmọ Israẹli,ìlànà sì ni, láti ọ̀dọ̀ Ọlọrun Jakọbu.
Nigerian Muslims will join their counterparts across the world to commence the Ramadan fast on Thursday.
 Ọjọ ́ yìí máa ń pé ní ọjọ kọkàndílọ ́ gbọ ̀ n sí ara wọn .
Àwọn ti ó nja ilú lólè ni ó nkó ẹ̀rọ wọnyi wọlé, wọn kò gbèrò ki iná mọ̀nàmọ́ná wa nitori wọn kò ni ri ẹni ra ọjà wọn.
Ẹnikẹ́ni ninu yín kò gbọdọ̀ bá ìyá rẹ̀ lòpọ̀, nítorí pé, bí ẹni ń tú baba ẹni síhòòhò ni, ìyá rẹ ni, o kò gbọdọ̀ tú ìyá rẹ síhòòhò.
    Àtètè sùn làtètè jí, èmi ni mo jí kẹ́yìn nínú ilé wa ní ọjọ́ kejì.
Kí OLUWA yọ irú eniyan bẹ́ẹ̀ kúrò ní àwùjọ Jakọbu, kí ó má lè jẹ́rìí tabi kí ó dáhùn sí ohun tíí ṣe ti OLUWA, kí ó má sì lọ́wọ́ ninu ẹbọ rírú sí OLUWA àwọn ọmọ ogun mọ́ lae!
Nígbà tí ó rí wọn, ó sọ fún wọn pé, “Ẹ lọ fi ara yín hàn alufaa.
Nígbà tí ó di òwúrọ̀ ọjọ́ kejì, ní kùtùkùtù, Òjòlá-ìbínú múra lóòótọ́ ó ń lọ wẹ̀ láìmọ̀ pé ọjọ́ ti pé tí Olódùmarè ó sọ fún pé òun ń bẹ.
US election 2020: Àlàyé rèé lórí bí èèyàn 538 ṣe ń yan ààrẹ lé èèyàn mílíọ̀nù 331 ní Amẹ́ríkà
N óo wọ́ ọ jù sórí ilẹ̀; inú pápá ni n óo sọ ọ́ sí, n óo jẹ́ kí gbogbo ẹyẹ ojú ọ̀run pa ìtẹ́ wọn lé e lórí.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Sekinat Quadri ọmọ ọdun meje ajẹsẹ to fẹ dabi Anthony Joshua Lati idaji ni gbogbo eniyan lori ayelujara ti n reti ohun ti ija yii yoo bi.
Nínú ọ̀rọ̀ rẹ̀, Fagite ni àwọn òbí ọmọ tó sọnu náà ko ṣe tó bó ti tọ́ àti bó ti yẹ.
Pupọ ninu awọn ero ọkọ lo n bọọlẹ ti wọn si n fi ẹsẹ wọn rin lọ si ibi ti ọkọ n gbewọn lọ.
“Lẹ́yìn náà, nígbà tí ó bá yá,n óo tú ẹ̀mí mi jáde sára gbogbo eniyan,àwọn ọmọkunrin ati àwọn ọmọbinrinyín yóo máa sọ àsọtẹ́lẹ̀,àwọn àgbààgbà yín yóo máa lá àlá,àwọn ọdọmọkunrin yín yóo sì máa ríran.
Awọn ẹṣọ oju popo ati awọn panapana ti wa nibẹ lati doola ẹmi awọn eniyan gẹgẹ bi a ṣe gbọ.
A ati B, arun kogbogun HIV, ayewo aato (Sugar level), Oral, Eye, BMI, Stress
Asad Zaidi túwíìtì nípa ojú tí àwọn ènìyàn Pakistan fi wo ẹgbẹ́ Abódiakọ-akọ́diabo:
Wéré a yára di ẹru wa, bí a sì ti ń dìí tán náà ni a wo iwájú tí àwọn ọmọ Ẹlẹ́gbára yọ sí wa.
Oríṣun àwòrán, Shaharudeen Galaje Àkọlé àwòrán, Bala Muhammed ni minisita fún ilu Abuja tẹ́lẹ̀ Natasha Mariana ní ìyàwo tuntun ti Gomina Bauchi ṣẹṣeẹ fẹ́, o si dé si ìlú Bauchi fún ìgbà àkọkọ lẹ́yìn ti wọ́n ṣe ìgbéyàwo ní opin ọ̀sẹ̀ to kọkja Kìí ṣe gomina Bauchi ni ẹni akọkọ ti yóò gbe ìyawo tuntun ninu àwọn gomina to ṣẹṣẹ gori alef, Gomina ìpínlẹ̀ Yobe Maimala Buni yan aya tuntun lẹ́yin ọjọ kini to wọle gẹ́gẹ́ bi gomina, ọmọ gomina àná ni ìpiínlẹ̀ rẹ̀ náà sì lo fẹ́.
Ẹ má rán ọmọ lọ ilé ìwé ní Cyprus mọ́ - Abike Dabiri A ò ní fààyè gba pípa ọmọ Naijirià nípakúpa ní South Africa mọ- Abike Dabiri Èrò ọmọ Nàìjíríà sọ̀tọ̀tọ̀ lórí fàákájáa láàrin Abike Dabiri-Erewa àti mínísítà ètò ìbárẹ̀nisọrọ̀, Àwọn Olúkọ ìpínlẹ̀ Oyo fakọyọ lórí ètò Akọ́mọlédè àti Àṣà púpọ̀ Gẹgẹ bi iwe iroyin Vanguard ti ṣe sọ, wọn ni awọn kan ti ko foju han lo gbe iroyin naa sita loju opo ayelujara pe Dabiri ko awọn nkan iranwọ yi pamọ si ile rẹ to wa ni GRA Ikorodu.
Lodun yii egberun mewaa ni a gba, nipa bayii awon olopaa orile ede yii n
O tesiwaju ninu oro re wi pe ,”ipade yoo waye lojo kokandinlogbon osu yii, fun itesiwaju iko agba-boolu naa, ati lati kede akonimoogba miran ti yoo maa tuko egbe agba-boolu ohun.
“Ṣugbọn gbogbo àwọn ìlú tí ó wà ninu àwọn orílẹ̀-èdè tí OLUWA Ọlọrun yín yóo fi fun yín, gẹ́gẹ́ bí ìní yín, ẹ kò gbọdọ̀ dá ohun alààyè kan sí ninu wọn.
“Ṣebí OLUWA ranti turari tí ẹ̀yin ati àwọn baba yín, ati àwọn ọba yín, ati àwọn ìjòyè yín, ati gbogbo àwọn eniyan ilẹ̀ náà sun ninu àwọn ìlú Juda ati ní ìgboro Jerusalẹmu, ṣebí OLUWA ranti.
Iṣari bí ọmọkunrin kan, Ṣelomiti, tí ó jẹ́ olórí ìdílé rẹ̀.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ooni Ile Ife: Emir Kano bẹ ààfin Ọọ̀ni wò, Ọọni Ogunwusi ṣàlàyé ìpayà tó gbòde lórí yíyọ tí Ganduje yọ Sanusi lóyé Emir Kano 3 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Oríṣun àwòrán, Ile oodua Ọọni ile ifẹ, Ọba Adeyẹye Ogunwusi ni ibẹru bojo gbode nigba ti ayipada ipo waye ni ilu Kano nitori gbogbo eeyan lo mọ pe bi wahala ba ṣẹlẹ ni ilu Kano, nnkan o lee rọrun lorilẹede Naijiria.
Nígbà kan rí mò ń gbé ìgbésí-ayé mi láìsí òfin.
Aworan naa si ti fa awuyewuye ni orilẹ-ede Brazil, paapa nitori pe iru iṣẹlẹ naa ti waye ri nilẹ America lasiko ti ọlọpaa fi orunkun fun ọkùnrin aláwọ̀ dúdú kan, George Floyd, lọrun pa l'oṣu Karun un.
Aisha Buhari, iyawo aarẹ orilẹede Naijiria sọrọ lori ayajọ awọn obinrin Bi ajọ agbaye ti se ya ọjọ kẹjọ osu kẹta sọtọ gẹgẹbii ayajọ awọn obinrin lagbaye, oniruuru ọrọ igbaniniyanju lo ti n jade fun awọn obinrin lorilẹede naijiria bi awọn naa se n darapọ mọ ajọyọ naa.
Kò tíì sí ìrànlọwọ owó f'àwọn ọmọ Nàìjíríà tí ń bọ láti South Africa -Abike Dabiri.
Ẹwẹ, Toyosi Kolawole ati Tofunmi Bello ti wọn jẹ akẹkọọ naa sọrọ lori ilana ijọba to da lori kikọ idanwo WAEC loṣu kẹjọ ọdun 2020.
Ìyà óo jẹ ọ́ lọpọlọpọ,ìbànújẹ́ óo sì dé bá ọ.
Bẹẹ gẹlẹ ni ọrọ ri pẹlu mama agba ololufẹ ẹgbẹ agbabọọlu Arsenal, Nosimatu Hassan.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Goitre Patients: Àwọn èèyàn tó ní àrùn gẹ̀gẹ̀ ní ọ̀pọ̀ ìkórira àti ìdẹ́yẹsí ní àwọn ń kojú Adajọ Olabisi Ige, to jẹ adajọ to lewaju ninu idajọ naa ni iwe akoso isẹ ọlọpaa lo fun ajọ PSC ni agbara, lati le gba eeyan ṣiṣẹ ọlọpaa.
Ṣugbọn nígbà tí mo yẹ̀ ẹ́ wò fínnífínní, mo rí i pé kì í ṣe ọmọ tèmi ni.
Ṣòkèṣodò a máa dá ìjà sílẹ̀, ọ̀rọ̀ àhesọ a máa tú ọ̀rẹ́ kòríkòsùn.
Èyí ti fi ìgbà pípẹ́ jẹ́ ìdáhùn mi sí ìbéèrè náà “báwo ni a ṣe lè ṣe ìrànwọ́?
pajawiri, won ni isele iji lile naa koko sose ni eka ila oorun ilu Bengal ki o
Kí ló dé tí ilẹ̀ náà fi parun, tí ó sì dàbí aṣálẹ̀ tóbẹ́ẹ̀, tí ẹnikẹ́ni kò fi gba ibẹ̀ kọjá?
Loju opo Twitter, niṣe lawọn eeyan orileede naa n bẹnu atẹ lu awọn ijọba ati alakoso ile iwosan naa.
Bí ó bá sọ àsọtẹ́lẹ̀, baba ati ìyá rẹ̀ yóo gún un pa.
Cultism in Nigeria: Afurasí sọ fúnlé ẹjọ pé ẹgbẹ́ búburú tóun kó ló ṣàkóbá fún òun
Ní ọdún yìí ati ọdún tí ń bọ̀, ẹ óo jẹ àjàrà tí ó lalẹ̀ hù, ṣugbọn ní ọdún tí ó tẹ̀lé e, ẹ óo le gbin ohun ọ̀gbìn yín, ẹ óo sì kórè rẹ̀, ẹ óo gbin ọgbà àjàrà, ẹ óo sì jẹ èso àjàrà rẹ̀.
Bakan naa ikọ Boko Haram ti ji aimọye obinrin ati ọmọde gbe lọsaaju akoko naa.
Tí ẹ bá fún mi láyé lẹ́ẹ̀kan síi, máa dá bírà."
Igi tí ó bá dára kò lè so èso burúkú; bẹ́ẹ̀ ni igi burúkú kò lè so èso rere.
Bakan naa, ajọ JAMB ti ṣe ọna ti afọju tabi odi lee fi joko ṣe idanwo ọhun.
Ifenuko yii waye nigba ti ile igbimo asofin  fenuko lori abaa lati wa woroko fi sada lori bi won se n pa awon eniyan bi eran ni ipinle Benue.
Oríṣun àwòrán, Nairaland Àkọlé àwòrán, Ọjọ kọkandinlogun, oṣu karun ọdun 1964 ni wọn bi agbabọọlu naa Ajọ ni ohun ko le gbagbe ipa ribiribi ti Okwaraji ko ninu ere bọọlu ni Naijiria.
Ọkan ninu awọn ẹbi oloogbe to ba wa sọrọ salaye pe, Ọjọbọ ni dokita naa sọ fun iyawo rẹ pe o dabi ẹni pe oun ti ko arun Coronavirus.
Lẹ́yìn tí àwọn tí wọ́n ru àpótí ẹ̀rí náà ti gbé ìṣísẹ̀ mẹfa, Dafidi dá wọn dúró, ó sì fi akọ mààlúù kan ati ọmọ mààlúù àbọ́pa kan rúbọ sí OLUWA.
Olukuluku yín gbọdọ̀ bọ̀wọ̀ fún ìyá ati baba rẹ̀, kí ó sì pa ọjọ́ ìsinmi mi mọ́.
O tun ran awon akẹgbẹ rẹ to wa
Bẹ́ẹ̀ ni Ọlọrun kò dáríjì àwọn ará àtijọ́, nígbà tí ó fi ìkún omi pa ayé run pẹlu àwọn tí wọn kò bẹ̀rù rẹ̀, àfi Noa, ọ̀kan ninu àwọn mẹjọ, tí ń waasu òdodo, ni ó gbà là.
Eyi to wa loju ọpn to n ran kiri ni lọọlọ yii ni ti awọn ọ̀kan lara awọn arinrinajo kan ninu ọkọ Iyare laarin opopona Benin si Ọrẹ ti wọn ni oṣiṣẹ ajọ aṣọbode yinbọn pa latari pe wn ntahun sira lori ẹgbẹrun marun naira.
O si di dandan ki gbogbo awọn orilẹede ti wọn wa nilẹ Afirika lati tọwọ bọwe adehun yii, ko to lee d'ohun.
Lara wọn ni bi awọn olukopa kan ṣe ṣe ere ifẹ.
Nígbà tí Hesekaya, ọba Juda wà lórí oyè, àwọn tí a ti dárúkọ wọnyi lọ sí Meuni, wọ́n ba àgọ́ àwọn tí wọn ń gbé ibẹ̀ jẹ́, wọ́n pa wọ́n run títí di òní, wọ́n sì sọ ibẹ̀ di ilẹ̀ tiwọn, nítorí pé koríko tútù pọ̀ níbẹ̀ fún àwọn ẹran ọ̀sìn wọn.
Ìtàn Mánigbàgbé: Duro Ladipọ fi òjò àti àrá ńlá sàmì ìpapòdà rẹ̀
Ẹ̀bùn Adégborúwà: Àwọn ọmọ-onílẹ̀ lo n fi tipa gba ilẹ̀
O bẹ̀rẹ̀ pẹ̀lú títa ìpára tí wọ́n fi n bóra, ní sin yìí ó ti gúnmú, o tún yọdi naa.
Tinubu fi kun un pe o jẹ ohun idunu pe wọn tete doola ẹmi awọn ọmọ ile iwe naa lai fi akoko ṣofo.
Ẹnikan ti isẹlẹ ina naa soju rẹ sọ fun ileesẹ BBC Yoruba wipe ibudo ikerusi lo n jona ninu ọja naa.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Wọ́n fi ẹyin adìyẹ lé Ike Ekweremadu, kúrò níbi àṣeyẹ kan ní Germany 17 Ògún 2019 Oríṣun àwòrán, Ike Ekweremadu Ẹyin eeyan wa, aṣe nnkan n ṣẹlẹ niju ara etile o gbọ ni.
Ẹwẹ, ajọ ajafeto-ọmọniyan kan ni Naijiria, SERAP ati awọn eeyan mejilelọọdunrun mii, ti pe aarẹ Buhari ati ile aṣofin lẹjọ tẹlẹ lori afikun owo epo bentiroo ati owó ina ọba.
Ṣégun adéwálé lọ sí ilé-ìwé alákọ ̀ bẹ ̀ rẹ ̀ ti seventh day adventist , tí ó wà ní abúlé Ọjà , ní ìlú Èkó láàrín ọdún 1972 àti 1978 .
Àpótí ìkẹ́rùsí jálu ọkọ̀ méjì lórí l'Eko Bakan naa la ti mu iroyin wa fun yin ni osu diẹ sẹyin pe apoti ikẹru si(container) lo ja lu ọkọ meji lagbegbe Maryland nilu Eko lọjọ Abamẹta.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù CAF Awards: Mo Salah gbà àmì ẹ̀yẹ agbábọ́ọ̀lù Áfíríkà fún ìgbà kejì 8 Sẹ́rẹ́ 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 9 Sẹ́rẹ́ 2019 Oríṣun àwòrán, PIUS UTOMI EKPEI Agbabọọlu Liverpool, Mohamed Salah ni agbabọọlu ajọ Confederation of African Football Player of the Year fun ọdun 2018.
Bí mo ti ṣe ìdílé Jeroboamu, bẹ́ẹ̀ ni n óo ṣe ìdílé tìrẹ náà.
Ó kọ́ ìlú náà yíká, bẹ̀rẹ̀ láti Milo, níbi tí wọ́n ti kún ilẹ̀ ní ìhà ìwọ̀ oòrùn òkè náà.
Ẹya Fulani ni Mallam Adamu Hardo, o si tun jẹ oloye nilu Daura nigba aye rẹ.
Caster Semenya: kíní ìdájó yìí dà fún obìnrin àti eré ìdáraya
Ilu Hyderabad lo da gbere fun mi pe oun ma wa fun ọjọ mẹta.
Iṣẹ́ olóri ẹbi ni lati kó ẹbi jọ fún ilọsiwájú ẹbi, nipa pi pari ijà, ijoko àgbà ni ibi igbéyàwó, ìsìnkú, pi pin ogún, ìsọmọ-lórúkọ, ọdún ìbílẹ̀ àti ayẹyẹ yoku.
Ọkọ mẹ́sàn-án tó forí-gbárí lórí afárá Otedola mú ẹ̀mí méjì lọ A kò mọ̀ bóyá a le è san owó osù tuntun fún òsìsẹ́ - Ìjọba Ondo, Oyo, Kwara jẹ́wọ́ Géńdé agbébọn jí adájọ́ gbé lọ ní ìpínlẹ̀ Ondo Eyi si lo mu ki ẹka ileesẹ BBC to maa n wadi ọfintoto nipa iroyin kan, ti wọn n pe ni BBC Reality Check, fi n beere pe bawo ni ojuse orilẹede Russia ni ilẹ Afirika ti se pataki si lọwọlọwọ bayii?
George Floyd bi ọmọbinin lọdun 2014 George Floyd bi ọmọbinrin Gianna Floyd pẹlu ọrẹbinrin rẹ, Roxie Washington lọdun 2014.
Orúkọ Messi ti di oní àmì ìdánimọ̀ láti ìsìnyí lọ.
Púpọ̀ lára àwọ̀n akẹ́kọ̀ọ́ jáde níléèwé gíga ni kò lè fi ọwọ́ sọ̀yà lórí ìwé ẹ̀rí tí wọ́n gbà.
Kò dẹ̀ sí ọ̀kan nínú àwọn ilé wọ̀nyí tí wọ́n kùn lọ́ dà rárá.
Farao dáhùn, ó ní, “Lọ sin òkú baba rẹ gẹ́gẹ́ bí o ti búra fún un.
Asiwaju Tinubu fikun ọrọ rẹ pe, Oshiomole ti ṣisẹ takun takun fun ẹgbẹ oṣelu APC papaa julọ, lasiko ibo gbogbo-gbo to kọja.
@MakemeslayC kọ nkan to da bi ewi lori ọrọ yii, o ni ologun pa ọlọpaa, ọlọpaa n pe awọn ologun lapaniyan loju opo Twitter.
Àdéhùn wọn kò yẹ̀ fún odidi ọdún kan gbáko èkíní kò mọ̀ pé ẹranko ni èkejì, ó sebí ènìyàn ni kí a ma sa fa ọ̀rọ̀ gùn lọ títí, ẹekùn lóyún fún erin, wọ́n bí Kùmọ́dìran.
awon adugbo ile ghana je titungbajo ni 1988 / 1989 lati mu ise ijoba sunmo awon aralu ati lati koju iwabaje to gbale larin awon onibise.
Nítorí náà, ẹ tún ọ̀nà yín ṣe, ẹ pa ìṣe yín dà, kí ẹ sì gbọ́ràn sí OLUWA Ọlọrun yín lẹ́nu, yóo sì yí ọkàn rẹ̀ pada kúrò ninu ibi tí ó sọ pé òun yóo ṣe sí i yín.
 “Iru ibasepo laarin ipinle otooto meji yii ni orile-ede yii nilo.
" Èèyàn 38,344 ló ti ní COVID-19 ní Nàìjíríà lẹ́yìn tí 543 kún un lọ́jọ̀rú Eyitayọ Jegede (PDP) ló máa gbéná wojú Rotimi Akeredolu (APC) nínú ètò ìdìbò Ondo tó ń bọ̀!
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ọrọ lori Ballon D'or Bẹẹ ni oun naa lo gba ami ẹyẹ agbabọọlu to n dantọ julọ ninu idije ife ẹyẹ agbaye to waye lorilẹede Russia ninu oṣu kẹfa.
Ó ti ayé kúrò ní ipò rẹ̀,àwọn òpó rẹ̀ sì wárìrì.
N óo yà sọ́dọ̀ yín nígbà tí mo bá ń kọjá lọ sí Spania.
Tí mo bá ṣe àìgbọràn sí òfin ọba, tí mo sì pa Absalomu, ó pẹ́ ni, ó yá ni, ọba yóo gbọ́, bí ọba bá sì gbọ́, ìwọ gan-an kò ní gbà mí sílẹ̀.
Ṣugbọn àwọn eniyan mi ni wọ́n kó ìkógun aguntan ati àwọn mààlúù tí ó dára jùlọ lára àwọn ohun tí a ti yà sọ́tọ̀ fún ìparun láti fi wọ́n rúbọ sí OLUWA Ọlọrun rẹ ní Giligali.
Amọ, boya wọn ri awọn ejo naa tabi wọn ko ri i, aarẹ Weah yoo pada si ọfiisi rẹ.
6%, ti o je apapo ni odun 2016, ti o je US$5,124 million.
O fi kun un pe igbimọ naa yoo
Aarẹ ana, Jonathan lo ṣẹṣẹ gba iṣẹ akanṣe ti ajọ ECOWAS, ohun ati aarẹ orilẹede Niger Republic, Mahamadou Issoufou ti pohun pọ lati pade ni Mali fun ijiroro lati yanju aawọ to wa laarin aarẹ orilẹede Mali, Boubacar Keita ati alatako rẹ.
Wo bí ìlànà tuntun lórí gbígba físà UK lẹyìn Brexit ṣe kàn ọ́ Abẹ́rẹ́ àjẹsára Covid-19 ti Pfizer ṣe yóò di lílò láti ọ̀sẹ̀ tó ń bọ̀ Àwọn afurasí ṣá ìgbákejì kọmísọ́nà ọ̀gá ọlọ́pàá láàké dójú ikú Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Ọkọ mi wa ọkọ̀ tẹ Poly Bag"" lásán, àfi gbùùàà!"
ibi kan, nitori pe, ibo naa ni kọhun-kọhun .
Awọn akẹkọ naa, Moshood Walik, lasiko ti wọn n ba BBC Yoruba sọrọ fi ẹṣun kàn ijọba ipinlẹ Kwara pe, o n fun awọn ni ẹgbẹrun marun naira pere fun owo iranwọ eto ẹkọ, to si tun ti pẹ tijọba ti san owo naa.
Osinbajo: Idasilẹ ọlọpa agbegbe yoo dẹkun ikọlu lorilẹede Naijiria
Ẹ̀rọ ayàwòrán ara ọlọ́pàá fihàn pé ìgbà ogún ni George Floyd pariwo, kó tó kú Iléesẹ́ rẹ́kọ́ọ̀dù tí mo ti bẹ̀bẹ̀ láti kọrin, padà di tèmi lónìí - Ebenezer Obey Èyí kò wa pọ̀ jù, kí ló ń pa ọ̀pọ̀ dókítà ní Ondo báyìí?
O ni: “Isele iyanselodi yii kii se eyi ti a maa tete kefin re bikose eyi ti o di ojo iwaju ko to hande.
Nísisì yìí wàyí, Ìrìnkèrindò; ọ̀ràn mìíràn ti dé ilẹ̀ o, bẹ́ẹ̀ ni bí bàbá rẹ bá wà láyé, òun ni n bá rán ni iṣẹ́ náà kí ó lọ ṣeé fún mi.
Oríṣun àwòrán, Google Iwe pelebe ti wọn ma n fun eeyan lẹyin to ba pari iforukọsilẹ ti aworan wa lara rẹ ni wọn kọ NIN nọmba si.
"Coronavirus: Bóo ṣe lè sọ iṣẹ́ láti ilé lásìkò \""Coro” di ìgbádùn fún ara rẹ"
lori adinku owo to ye ko maa lo soke okun, ni won yoo maa lo lati fi se idagbasoke
Oríṣun àwòrán, @HQNigerianArmy Àkọlé àwòrán, Aimọye ẹmi lo ti ku lori ikọlu darandaran fulani ati agbẹ oloko lorilẹede Naijiria Awọn eeyan ileto naa lo ke gbajare sita sawọn ọmọogun ọwọ kọkanlelọgọrun ileesẹ ọmọogun orilẹede Naijiria ti wọn n seto abo Ayem Akpatuma ti ijọba apapọ sẹsẹ ko lọ si agbegbe naa lati kapa gulegule ikọlu awọn darandaran fulani lagbegbe naa.
Ighalo sọrọ yii nigba to n kopa ninu ifọrọwanilẹnuwo kan lori ileeṣẹ redio Brila FM.
Pataki iwaadi yi ni pe, o ni ṣe pẹlu aarẹ Amẹrika ati alatako rẹ to n lewaju lara awọn to fẹ gba ijọba lọwọ Trump ninu idibo aarẹ ọdun 2020.
Mò ń fi lẹ̀kẹ̀ ya àwọnran láti jèrè ǹkan méjì
N kò ní gba nǹkan burúkú láyè níwájú mi.
OLUWA mú ìdàrúdàpọ̀ bá Sisera ati gbogbo kẹ̀kẹ́ ogun rẹ̀ ati àwọn ọmọ ogun rẹ̀ níwájú Baraki.
Mínísítà mẹ́tàlélógójì ni Ààrẹ Muhammadu Buhari ṣe ìbúra fún Aare Muhammadu Buhari ti pari ikede to fi yan awọn minista tuntun sipo loni.
Ní àkókò yìí, ojú Eli ti di bàìbàì, kò ríran dáradára mọ́.
Àwọn Kerubu náà na ìyẹ́ wọn bo ìtẹ́ àánú náà; wọ́n kọjú sí ara wọn, wọ́n ń wo ìtẹ́ àánú.
  Gbogbo ọna si ni a n gba lati tubọ mu
Eyo fi aidunnu re han lori bi
Ninu oṣu kinni ọdun 2016, Metuh ni oun ko jẹbi awọn ẹsun ti wọn fi kan an.
Sugbọn ọlọpaa kan ni ko gbẹnu dakẹ.
Ọ̀kan ninu àwọn ẹ̀dá alààyè náà fún ọ̀kọ̀ọ̀kan ninu àwọn angẹli meje náà ní àwo wúrà kéékèèké kọ̀ọ̀kan, àwọn àwo wúrà yìí kún fún ibinu Ọlọrun, ẹni tí ó wà láàyè lae ati laelae.
Lẹ́yìn náà kí ó wẹ̀, kí ó fọ aṣọ rẹ̀, kí ó sì pada sí ibùdó.
O óo dàbí ẹni tí ó dùbúlẹ̀ lórí agbami òkun,bí ẹni tí ó sùn lórí òpó ọkọ̀.
Ọwọ́ àwọn tí wọn ń lépa rẹ̀ ti tẹ̀ ẹ́,ninu ìdààmú rẹ̀.
N óo bínú sí ọ lọpọlọpọ, ìrúnú mi yóo jó ọ bí iná, n óo fà ọ́ lé àwọn oníjàgídíjàgan lọ́wọ́, àwọn tí wọ́n mọ̀ bí wọ́n ṣe ń panirun.
Bi awọn ipinlẹ to ni Coronavirus ṣe lọ ni yii: Eko-212 Oyo-69 Niger-49 Kano-37 Osun-37 FCT-35 Plateau-34 Gombe-33 Edo-28 Enugu-28 Ebonyi-17 Delta-10 Katsina-9 Ogun-8 Rivers-7 Ondo-5 Kaduna-4 Nasarawa-2 Èèyàn 2 kú, 648 míràn tún kó COVID-19 ní Nàìjíríà l'Ọ́jọ́ Àjé Eeyan 648 ni wọn kede pe ayẹwo tun fihan pe o laarun COVID-19 lorilẹede Naijiria bayii.
"Fani-Kayode ni ""Isẹlẹ naa safihan iwa abuku ati ọyaju si ni nikan fawọn ọmọ bibi ilu Ile Ife, amọ iwa naa tabuku gbogbo ọmọ ilẹ Yoruba lọkunrin ati lobinrin."
Dokita Ayinde ni iwadii n lọ lọwọ ati igbesẹ lati dẹkun itankalẹ arun naa ni ipinlẹ Ogun.
" Ayaba Adeyemi naa wa rọ awọn ololufẹ rẹ lati se adura fun oun ni ayajọ ọjọ ibi rẹ naa.
Ọ̀rọ̀ LAUTECH gba àpérò f'áwọn Olúdíje Ọṣun Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Osun 2018: Àwọn olùdíje ADC, ADP, APC, SDP bá aráàlú sọ̀rọ̀ lórí èròǹgbà wọn INEC ni oun kò kede ẹnikẹni gẹgẹ bi ẹni to jawe olubori nitori ibo ti wọn fagile ni ibudo meje ti wọn ti ni ki atundi ìbò waye loni pọ ju iye ti PDP fi ju APC lọ.
Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí NEPA: Kò ní sí iná mọ̀nàmọ́ná ní Eko láwọn èèyàn n sọ̀rọ̀ lé lọrí9 Bélú 2019 Electricity Tarrif: A kò tíì gbé àwọn oníbàrà wa sórí tàríìfù tuntun - IKEDC31 Ọ̀wàrà 2020 Coronavirus in Nigeria: Èèyàn 474 ló tún ti ní Covid-19 ní Naijiria10 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Idi eyi ko ju ibẹrubojo pe oṣeeṣe ko maa si aye lati ko epo rọbi pams si mọ nigba to oṣu karun ọdun yii ba fi wọle.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Afeez Agoro: O ṣòro fún mi láti wọ Danfo jáde Ẹni to n ba aarẹ dupo, Lazarus Chakwera to se ipo keji bu ẹnu ẹ̀tẹ́ lu idajọ naa lori ẹsun magomago lasiko idibo.
Lẹyin ti Ọjọgbọn Pondei daku lasiko ti wọn n fi ọrọ waa lẹnu wo lori nina owo ilu mọkukọku ninu ajọ to yẹ ko mojuto awọn eeyan ẹkun ti Naijiria ti n wa epo rọbi ni ọrọ tun gbẹyin yọ.
Àwọn eniyan ní ẹbọ kan tí wọn óo rú ní orí òkè lónìí.
Ayé ati gbogbo nǹkan inú rẹ̀ yóo wá wà ní ìhòòhò.
Orúkọ tí à ń pè é ni Ọ̀rọ̀ Ọlọrun.
Ọ̀pọ̀lọpọ̀ àwọn ìfihan ni a ti rígba láti ọwọ́ Olúwa sáájú àkókò yìí, àti pé àkójọpọ̀ ti àwọn wọ̀nyi fún títẹ̀ jade ní ẹ̀dà ìwé jẹ́ ọ̀kan pàtàkì nínú ohun tí a gbà wọlé ní ìpàdé àpapọ̀ náà.
Say no to rape: Àwọn òṣèré tíátà Yorùbá pariwo síta lórí wàhálà ìfipábánilòpọ̀
Nígbà tí ó bí Isaaki, ó kọ ọ́ nílà ní ọjọ́ kẹjọ.
Ati wi pe ti obinrin ba ti dawọ nkan osu, awọn eroja ara homoonu ara a bẹrẹ si ni ku, eleyi ti o ma n fa ọpọlọpọ ipenija fun awọn obinrin.
Si iyalẹnu wọn ati ọpọ eeyan nibẹ lati rii pe oku arabinrin naa nikan ni wọn ba, wọn ko ri oku ọmọtuntun jojolo naa gbe.
 Bayii, Naijiria ti gba lati pe awon to ba n soro ikorira ni onise ibi to n dunkooko mo awon elomiran.
Fayemi ṣèlérí owó ìtọ́jú àwọn tó fara gbá nínú ìjámba l'Ékiti Kí gan an ni ẹgbẹ́ NURTW ní ṣe pẹ̀lú òṣèlú Nàìjíríà?
2b) to jẹ  owo iyawo aare ana,Dame Patience Jonathan pe ki gbogbo owo naa jẹ ti ijoba apapo.
Ọ́pọ́ isẹlẹ miran to n sẹlẹ si ẹda to maa n mu omije, idaamu ati iya nla wa, ni a maa n kọ, lai ms pe ọna ti a tọ de ibi ayọ wa ni.
Ilé ẹjọ́ rán àwọn mérìndínlógún lẹ́wọ̀n gbére fún dídáná-sun Nusrat Wọ́n ti ṣí ilé oúńjẹ oní ọgbọ̀n náírà (N30) ní Kano Ìdí tí mo ṣe fẹ́ yọ ayédèrú ìdí ńlá tí mo ní- Sophie Ìlú kò mọ ohunkóhun nípa iṣẹlẹ màálù tó kú nilu Ikarẹ- Oba Olukarẹ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Yoruba Culture: ọjọ́ méje ni wọ́n fí n rẹ ẹ̀kú Danafojura kó tó jáde Bi ẹ ko ba ni gbagbe, ni kete ti iroyin ijinigbe rẹ kan sita ni Ọga agba ọlọpaa lorilẹ-ede Naijiria, ti dari ikọ ọtẹlẹmuyẹ eleyi ti ọga ọlọpaa, Abba Kyari ko sodi lati tete ṣawari Onidajọ Abdu Dogo ni kiakia.
Ta ló ń lọ sílé lónìí nílé ẹlẹ́gbọ̀n ọ́n àgbà?
Wọ́n tún kígbe pé, “Òun kọ́!
Tí àtúntò kò bá wáyé ní Naijiria, ó ṣeéṣe kó túká- Pásítọ̀ Adeboye Orí yọ dírẹ́bà ọkọ̀ tó jóná ráúráú ní Delta Kò yẹ mi ìdí tí Wasiu Ayinde fi hu ìwà àbùkù tó hù sí mí- MC Murphy Àdigunjalè báńkì ní Iyin-Ekiti fẹsẹ̀ fẹ, bí wọ́n ṣe rí wa - Iléeṣẹ́ ọlọ́pàá Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Ta ló lè rí iyawo tí ó ní ìwà rere fẹ́?
( october 19 , 1910 - august 21 , 1995 ) je onimo fisiksi-irawo omo india amerika .
Ni igba ti ibugbamu ti Abule Ado waye, alaga ijọba ibilẹ Ifakọ Ijaiye to fi mọ awọn ọmọ ile aṣofin to n ṣoju agbegbe naa mẹnu ba fifi ofin lelẹ eyi ti yoo kọdi tita afẹfẹ gaasi letile.
Eto irin ajo lọ silẹ okeere awọn ọmọ Naijiria lo nilo igbaradi to muna doko latari ipo ti paali irinajo naa wa.
Ile-ise iroyin lorile-ede Egypt so pe, won pe agbejoro fun iko eleto abo orile-ede Egypt lojo-Bo, latari bi o se foro wa oludije dupo aare teleri lenu wo, eni ti won fi si atimole, latari  esun pe, o ni ajosepo pelu egbe  Muslim Brotherhood ti ijoba fofin de.
Òun nìkan ṣoṣo ní ń ṣe iṣẹ́ ìyanu ńlá,nítorí pé ìfẹ́ rẹ̀ tí kì í yẹ̀ wà títí lae.
Jehudi bá kà á fún ọba ati gbogbo àwọn ìjòyè tí wọn dúró lẹ́gbẹ̀ẹ́ rẹ̀.
Mo wò yíká, n kò rí ẹnìkan,gbogbo ẹyẹ ojú ọ̀run ti fò sálọ.
Àwọn mìíràn gbẹ́kẹ̀lé kẹ̀kẹ́ ogun,àwọn mìíràn gbẹ́kẹ̀lé ẹṣin,ṣugbọn ní tiwa, àwa gbẹ́kẹ̀lé orúkọ OLUWA Ọlọrun wa.
Asisat Oshoala ni yoo ṣaaju awọn ẹlẹsẹ ayo ninu idije naa.
Bakan naa ni wọn kede afurasí ọmọ ọdúin méjìdínlógun kan, Taiwo Rasak pe oun ní wọ́n jọ pa awọ́n ololufẹ naa.
Nítorí mo ti mọ̀ pé ìba díẹ̀ nínú obìnrin ni wọn lò fi ẹnu ara wọn sọ fún ọkùnrin kí ó fẹ́ àwọn, bí ìfẹ́ tilẹ̀ ń pa wọn bí ọtí, tí o tì wọ́n ká bí ẹni tí òrìṣà gùn, àti la ẹnu sọ̀rọ̀ náà jáde a máa jẹ́ ìṣòro.
Nítorí náà, mo wá ya ọmọ náà sọ́tọ̀ fún OLUWA, ní gbogbo ọjọ́ ayé rẹ̀ yóo jẹ́ ti OLUWA.
Awọn Iroyin tẹẹ le nifẹ si Inú odò ni wọ́n ti rí òkú ọmọ ọdún méjì tó sọnù l'ọ́jọ́ ọdún Eid nílùú Ibadan Ọkọ kọ àwọn ọmọ méjì lé ìyàwó lọ́wọ́ nítorí ìrísí ojú wọn ní Ilorin Èèyàn 78 kú ó lé ní 4000 tó farapa níbi ìbúgbàmù tó wáyé ní Beirut, Lebanon Abuja lékè bì Coronavirus ṣe já padà sókè, èèyàn 304 ló kó o lọ́jọ́ ìṣẹgun Iwọde naa, to pe ni #Revolution Now lo sọ pe yoo bẹrẹ ni aago mẹjọ aarọ ladugbo Ikeja nilu Eko ati Unity Fountain nilu Abuja.
Bí obìnrin náà tí dakẹ́ ọ̀rọ̀ yí tí bàbá mi si ń fẹ́ẹ́ fún un ní èsì ni ìyàwó rẹ̀ àfẹ́sọ́nà tuntun dáhùn, ó rẹ́rìn-ín músẹ́, ó wo ẹ̀gbọ́n rẹ lójú ó si si pé: Ìwọ ẹ̀gbọ́n mi ọ̀wọ́n, ẹni tí ó ti ń tọjú mi láti ìgbà èwe mi wa, máṣe fi mi silẹ̀ ní èmi nìkan, nítorí àlàáfíà ẹ̀gbọ́n ti àbúrò ni, ibànújẹ́ ẹ̀gbọ́n, tí àbúrò ni; bí iyèkan si ń dide si iyèkan tí ìbátan ń fi igi gún ara wọn lójú, síbẹ̀síbẹ̀ ara ilé ẹni kò ní ṣàì ṣe ará ilé ẹni.
Wọn ní àwọn afunrasi náà ni insipẹkitọ Olalekan Ogunyemi àti Godwin Orji ti wọn ń siṣẹ́ pẹ̀lú ẹka to ń gbógun ti ìwà ẹgbẹ́ okunkun àti ìdigunjale.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù EFCC /FBI: Ọwọ́ EFCC / FBI tẹ àwọn gbájúẹ̀ 167, wọ́n gbà owó púpọ̀ padà 10 Owewe 2019 Àkọlé àwòrán, Asoju FBI ni Naijiri ati akẹgbẹ rẹ lati EFCC Ajọṣepọ EFCC ti Naijiria ati FBI ti America ti n bi eso irapada owo gọbọi A ń fikunlukun pẹ̀lú FBI láti mú àwọn Yahoo Boys"" tó kù- EFCC."
 Paapaa julo awon to ba fe
Coronavirus: Seyi Makinde ní ẹgbẹ̀rún mẹ́wàá ọṣẹ apakòkòrò 'hand sanitiser' lòun fi dènà coronavirus nípàdé ẹgbẹ PDP ní'bàdàn
Gẹgẹ bi a se gbọ, eeyan nii mu ni mọ eeyan lọrọ ọba Adeyemi ati aya rẹ akọkọ nitori lati ipasẹ aburo rẹ obinrin ni wọn ti pade.
Nígbà tí ó ń lọ, ó mú akọ mààlúù ọlọ́dún mẹta kan lọ́wọ́, ati ìyẹ̀fun ìwọ̀n efa kan, ati ọtí waini ẹ̀kún ìgò aláwọ kan.
Láti orúnkún sì lọ dé ẹsẹ̀ rẹ̀ ni ó to ẹ̀gbà idẹ sí, àwọn ẹ̀gbà idẹ yìí tó bii méédogun ni ẹsẹ̀ kọ̀ọ̀kan.
Ni ọgbọn ọjọ, oṣu kẹwaa ni saa kẹta to ku yoo pari fun awọn akẹkọọ lati le e lọ fun isinmi ranpẹ eyi ti yoo pari ni ọjọ kẹsan an, oṣu kọkanla, ọdun 2020.
Ẹ máa yí nílẹ̀, kí ẹ sì máa kérora bí obinrin tí ń rọbí, ẹ̀yin ará Jerusalẹmu; nítorí pé ẹ gbọdọ̀ jáde ní ìlú yín wàyí, ẹ óo lọ máa gbé inú pápá; ẹ óo lọ sí Babiloni.
Àwọn ọmọ Israẹli gba gbogbo ilẹ̀ wọn pada lọ́wọ́ àwọn ará Filistia.
Ajimobi to jẹ igbakeji alaga ẹgbẹ APC lapa gusu orilẹede Naijiria lo ṣe agbekalẹ igbimọ ẹlẹni mẹrindinlogun naa ti gomina ipinlẹ Oyo tẹlẹ, Adebayo Alao Akala jẹ alaga rẹ.
Telọ Lukman Adeniyi wọ gau niluu Ibadan lẹyin ti DPO ileeṣẹ ọlọpaa to wa lagbegbe Iyaganku gbe lọ sile ẹjọ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù 2021 Nigerian Budget: Àbádòfin ìṣúná 2021 ré kọjá ìpele ìkejì nílé aṣòfin àgbà 8 Ọ̀wàrà 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 15 Ọ̀wàrà 2020 Oríṣun àwòrán, SENATE NIGERIA Aba isuna oni triliọnu mẹtala ti aarẹ Muhammadu Buhari fi ṣọwọ s'awọn aṣofin ti rẹ kọja ipele kika Ikeji ni ile aṣofin agba.
Ta ni Seun Fakorede, ọmọ ọdún 27 tó fẹ́ di kọmiṣọna?
Ó gbẹ̀san ìyà tí wọ́n ti fi jẹ ẹ́, ó lu ará Ijipti náà pa.
Iroyin sọ pe ṣe ni wọn kọkọ ṣe ikọlu si agọ ọlọpaa kan ni tosii aafin Soun ki wọn to raaye wọle si wọn lara.
Minisita fun imo sayensi ati imo
Ọwọ ileesẹ ọlọpaa ti tẹ awọn afurasi ajinigbe mẹtalelaadọrun ni awọn agbegbe kan ni ẹkun Ariwa Naijiria.
Ọpọ n woo pe boya Aarẹ Buhari yoo lo anfani ọrọ rẹ lati fi ọkan araalu balẹ lori ohun to n ṣẹlẹ gan an ni ipinlẹ Kano, ṣugbọn ninu ohun ti aarẹ ka, yatọ si pe o ni aṣẹ konile-o-gbele ọlọjọyipo yoo wa nikalẹ nibẹ, ko daju pe aarẹ gan an funrarẹ tii mọ ohunkohun nipa okunfa iku ọwọọwọ ni ilu Kano.
Ẹni to bori: Algeria Guinea vs Ghana.
gbigbogun ti iwa  igbesunmomi, ipaniyan ati
Ẹni kan ṣe ikọlu si i lọjọ Aje; iṣẹlẹ naa lo si mu ki oun ati awọn ọrẹ rẹ o jade nibi ti wọn fi ara pamọ si, ti wọn si fi ẹjọ sun awọn ọlọpaa ẹsin (Hisbah).
Ìjọba àpapọ̀ bẹ̀rẹ̀ ìwáàdí ẹ̀sùn tí wọ́n fi kan Usman Yusuf Naijiria yoo ṣe ajesara fun eniyan bii miliọnu mẹẹdọgbọn Buhari d'akọwe eto ilera pada s'ẹnu iṣẹ 'Awọn ipinlẹ ni iṣẹ lati ṣe lori iba lassa' Abajade naa jade lẹyin oṣu keji ti ijọba apapọ gbe igbimọ ẹleni meje naa dide.
1 648 Saint Barthelemy 1 10.
Ahmadu Ali Must Go Protest: Àfikún owó oúnjẹ akẹ́kọ̀ọ́ ní Fáṣítì fa ẹ̀hónú tó mú ọ̀pọ̀ ẹ̀mí lọ
Akọroyin BBC to sare de ibi isẹlẹ naa ni ileesẹ panapana ijọba ti wa de sibi isẹ́lẹ́ naa, ti wọn si ti n pa ina naa.
Wo ibi fún èsì ìdìbò yíyan aàrẹ tuntun ní orílẹ̀-èdè Ghana Ọlọ́pàá, sójà yabo Lekki Toll Plaza láti dènà ìfẹ̀hónúhàn míràn Ìdí rèé táwọn àkàndá ẹ̀dá fi dí iwájú iléeṣẹ́ ìjọba ìpínlẹ̀ Oyo pa l'Agodi n'Ibadan A kò ní padà sílé ìwé àyàfi t́i ìjọba bá san owó oṣù tó jẹ wá - ASUU Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ojú mi ti rí lọ́pọ̀ lọpọ̀, àmọ́ mo dúpẹ́ pé mo ti pé ọdún márùn ún lórí oyé- Ooni Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Ọ̀rọ̀ àwọn eniyan burúkú dàbí ẹni tí ó lúgọ láti pa eniyan,ṣugbọn ọ̀rọ̀ ẹnu olódodo a máa gbani là.
Ogagun Adesanya so pe “Ile-ise omo-ogun ofurufu ATF ti orile ede Naijiria  yoo lo baalu ogun  ofurufu Alpha Jet ati F-7Ni, ti orile ede Niger  naa yoo lo  baalu ogun ISR lati se ikolu si ibi ti awon iko olote Boko Haram  fi se ibugbe”.
Ọkunrin kan to n jẹ Iberemi Osadebe ati ẹbi rẹ ya wọ sọọsi ti wọn ti n seto igbeyawo lọwọ pe eto naa ko le tẹsiwaju.
Wọn yin Tabichi fun iṣẹ takuntakun rẹ ni ile iwe to wa ni abule kan, ni ibi ti ami ẹyẹ naa ti waye ni Dubai.
Amọ, ọdun to kọja ni aisan asetọ taa mọ si prostate mu, eyi to ṣekupa nitori ọjọ ogbo rẹ.
Nítorí Ọlọrun kì í ṣe alaiṣootọ, tí yóo fi gbàgbé iṣẹ́ yín ati ìfẹ́ yín tí ẹ fihàn sí orúkọ rẹ̀, nígbà tí ẹ ṣe iṣẹ́ iranṣẹ fún àwọn onigbagbọ, bí ẹ ti tún ń ṣe nisinsinyii.
fun irin-ajo eto adua nile mimo lorile-ede Israel.
 Ṣùgbọ ́ n ojọ yìí ní ibi wọn wolẹ nítorí bibẹ ní oníkòròmebi bẹ àwọn mejeeji .
Akonimoogba iko Barcelona ohun, Luis Enrique, ti so ninu osu keta odun yii, wipe, oun yoo fi iko agba-boolu naa sile ni kete ti saa ohun ba pari, leyi to sokunfa gbigba akonimogba miran fun iko agba-boolu naa.
"Aliyu ni "" ọkunrin ti wan gbé lọ ni dédé àgo kan oru yẹn ni à[run Coronavirus, sùgbọ́n ìyáwó àwti àwọn ọmọ rẹ ko ni, sùgbọ́n o àwọn náà yóò wà ni igbélé fún ọjọ mẹrinla, mo si dúpẹ lọ́wọ́ ìyàwó rẹ pe o fọwọsowọpọ pẹlu wá""."
Wọ́n kó owó náà sínú ibi kan báyìí tí ó dábí ilé tí ènìyàn kàn fún ẹyẹ.
Ṣugbọn ẹni ibi ni ọ̀kan ninu yín.
Má máa dúró, kí o máa retí ọjọ́ alẹ́,nígbà tí à ń pa àwọn eniyan run.
Google searches Nigeria 2020: Hushpuppi, Naira Marley, Rema, ASUU wà lára ohun táwọn èèyàn ń wá
Ó bẹ̀rẹ̀ sí kọ́ wọn pé, “Ọmọ-Eniyan níláti jìyà pupọ.
Àwọn eniyan burúkú kò rí bẹ́ẹ̀,ṣugbọn wọ́n dàbí fùlùfúlù tí afẹ́fẹ́ ń fẹ́ lọ.
Ki lawọn eeyan ri si ohun ti Dokita Stella sọ nipa hydroxychloroquine Ero ṣe ọtọọtọ lori ohun ti Dokita Stella sọ loju opo Twitter nipa lilo hydroxychloroquine lati koju arun Covid 19.
Ikọ̀ ẹlẹ́sìn Hàkíkà rèé, níbití wọn ti ń pààrọ̀ ìyàwó láàrín ara wọn Àwọn ọmọ Iyabọ Ojo rí Bàbá lẹ́yìn ọdún mẹ́fà To ba n wa ọkọ̀, yàgò fáwọn ìgbésẹ̀ yìí Buhari, ó yá, tètè kọ̀wé fipò sílẹ̀ - Oyedepo Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Irú ẹ̀dá wo ni Fẹla Jẹ́?
Nadabu ati Abihu kú ṣáájú baba wọn láì bí ọmọ kankan.
Bí Ọlọrun ti jí Oluwa dìde kúrò ninu òkú, bẹ́ẹ̀ ní yóo jí àwa náà pẹlu agbára rẹ̀.
Ipo adele alaga lo wa titi iyọnipo rẹ lọjọ Keje, oṣu Keje, ọdun 2020.
Ṣé ó lè sọ nípa òdodo rẹ?
Láti bi oṣù díẹ̀ sẹyìn ni mo ti n ro àwọn ìlànà ìjọba ti a lè gbé silẹ̀ tí yóò ràn ìjọba lọ́wọ́ níhìn àti lọ́hùn.
Hearn sọ pe, koko lara Joshua le ko to ba Ruiz ja.
Ilé ẹjọ́ gíga jùlọ dúró gbọingbọin lórí ìdájọ́ ìdìbò gómìnà Bayelsa Ọ̀jọ́ eérú t'ọdún yìí bẹ̀rẹ̀ pẹ̀lú aṣọ ọ̀fọ̀ Súnkẹ́rẹ fakẹrẹ ọkọ òpópónà marosẹ̀ Lagos-Ibadan tòní tún kọ sísọ Ọmọ mi ti ṣèlérí pé oun máa mú mi lọ sí òkè òkun k'àwọn SARS tó pá á - Iya Kazeem Tiamiyu Èyí tí a wò jùlọ 5:03 Fídíò, Omolola Arohunmolase Welder: Mo ti fí iṣẹ́ 'Welder' gbayì láwùjọ, tó mo fi tọ́ ọmọ yanjú, Duration 5,039 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 5:39 Fídíò, Akomolede ati Asa lori BBC: Olùkọ́ Kikelomo Ogunboye tan ìmọ́lẹ̀ sí ìwà olè ọ̀gá ọlọ́pàá Audu gẹ́gẹ́ bí àwòkọ́ṣe àsìkò yìí, Duration 5,398 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 4:11 Fídíò, Oba Adeyeye Ogunwusi: Ojú mi ti rí lọ́pọ̀ lọpọ̀, ọ̀pọ̀ èèyàn ni kò tilẹ̀ gbàgbọ́ pé mo lè jọba- Ooni, Duration 4,117 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 4:43 Fídíò, Promise Akinlade: ọmọ ọdún mọ́kànlá tó ń fi ìlù dárà bíi àgbàlagbà sọ̀rọ̀ nípa tálẹ́ǹtì rẹ̀, Duration 4,437 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 0:59 Gbọ́, Ìsẹ̀lẹ̀ jákèjádò orílẹ̀èdè àgbáyé láàárín ìṣẹ́jú kan, Duration 0,59wákàtí 5 sẹ́yìn 7:03 Fídíò, Olumuyiwa Bolade Adedeji Military Bruitality: Bí arákùnrin onípèníjà ara tí sọ́jà lù ṣe dé, Duration 7,035 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 4:45 Fídíò, Yoruba Films: Ẹ̀ẹ́ bẹ̀ mi kúrò láyé ni, mi ò lè kú - Fadeyi Oloro, Duration 4,4526 Èrèlè 2020 2:48 Fídíò, Esther Ajayi: Èmi náà ti borí ìṣòro rí ló ń mu mi ṣojú àánú, Duration 2,481 Ògún 2019 6:08 Fídíò, Adebola Ademilua: Àìrísẹ́ ṣè lẹ́yìn ìwé kíkà ló sọ mi dí ìyá onírú, mo dúpẹ́ tèmi, Duration 6,0827 Bélú 2020 2:36 Fídíò, Sotitobire: Ìdájọ́ òdòdò ló fẹsẹ̀ múlẹ̀ lórí ọ̀rọ̀ Pásítọ̀ Sotitobire - Agbẹjọ́rò fún ìjọba, Duration 2,367 Ọ̀wàrà 2020 BBC News, Yorùbá Ìdí tí ẹ fi le è nígbàagbọ́ nínú ìròyìn BBC Ìlànà Lílò Nípa BBC Òfin Àṣírí Cookies Kàn sí.
" Àwọn aṣojú-ṣòfin gbarata lórí ọ̀rọ̀ náà ṣùgbọ́n Dogara rọ̀ wọ́n láti fí ọkàn balẹ̀ nítorí àwọn aṣòfin àgbà tí ń yẹ ọ̀rọ̀ náà wò.
Kí oore-ọ̀fẹ́ ati alaafia láti ọ̀dọ̀ Ọlọrun Baba ati Oluwa Jesu Kristi máa wà pẹlu yín.
PDP Enugu East ati Uche Ekwunife, PDP Anambra Central.
Oríṣun àwòrán, @BolanleCole Àkọlé àwòrán, Oseni laanu wipe ijọba apapọ ko kọbi ara si iwa ipanijaye ti o gbode kan lorilẹ-ede wa Kosi aṣa ti o faramọ fifi emi eniyan se irubọ.
Ilé-aiyé kún fún àìmọye àrùn tí nbá ọmọ ènìà jà.
Oju kan ṣoṣo kọ lo ti n ṣẹlẹ.
Ninu fidio kan to lu ori ayelujara pa ni Ibiyeomie ti faraya, to si n ju oko ọrọ pada si Daddy Freeze pe ko ni ẹtọ lati tabuku Oyedepo, tii se baba oun ninu Oluwa.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù World Radio Day: Àwọn òṣìṣẹ́ rédíò ní àwọn ń pa ìsòro àwọn mọ́ra ni láti mú inú aráàlú dùn 13 Èrèlè 2020 Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, World Radio Day: Àwọn òṣìṣẹ́ rédíò ní àwọn ń pa ìsòro àwọn mọ́ra ni láti mú inú aráàlú dùn Loni tii se Ọjọbọ, ọjọ Kẹtala osu keji tun ni ayajọ miran fun eto igbohunsafẹfẹ lori redio tun ko.
Àwọn ẹmẹ̀wà Farao sọ fún un pé, “Kabiyesi, ìgbà wo ni ọkunrin yìí yóo yọ wá lẹ́nu dà?
18 Àti pé bákannáà mo fi àwọn òfin fún àwọn míràn, pé wọn nílati kéde àwọn nkan wọ̀nyi sí ayé; àti gbogbo eléyi kí ó lè wá sí ìmúṣẹ, èyítí a ti kọ láti ọwọ́ àwọn wolíì—
Ẹwẹ, Ọga agba awọn ọlọpaa ni Ipinlẹ Eko, Ọgbẹni Omohimi Edgal sọrọ idaniloju ninu ipade alẹnulorọ naa pe asiko jagidijagan ninu eto idibo ti di ohun afisẹyin ti eegun fiṣọ ni ipinlẹ yii.
Eruku ẹjọ́ tún sọ lórí ìgbéyàwó Toyin Abraham àti Adeniyi Johnson tó forí ṣánpọ́n Wo ọ̀rọ̀ 'àbùkù' tí òṣèré sinimá, Adesuwa Etomi Wellington sọ nípa ọbẹ̀ gbẹ̀gìrì Ẹ wo bí ìpínlẹ̀ Eko, Ondo àti Oyo yóò ṣe dá ilé ìjọ̀sìn padà Ìtàn ìgbésí ayé Oshodi, ọmọ Tápà léǹpe tó di akọni ní ìlú Eko Ènìyàn kan kú, méje farapa nínú ìjàmbá afárá Otedola ní Eko Oríṣun àwòrán, Twitter Eniyan kan ti gbe ẹmi mi, ti eniyan meje si faragba ninu ijamba ọkọ to waye lori afara Otedola ni ipinlẹ Eko laarin ọkọ agbepo ati ọkọ igbooro ti eniyan mẹwa.
Ẹka ileesẹ BBC, ti wọn n pe ni BBC Reality Check lo n tanna wadi otitọ to ba wa nidi iroyin kan lati mọ boya ootọ ni abi irọ.
Bí omi tíí fi bí ojú ẹni ti rí han ni,bẹ́ẹ̀ ni ọkàn eniyan ń fi irú ẹni tí eniyan jẹ́ hàn.
Aare gbadura pe Olorun a duroti ebi, ara, iyekan ati awon eniyan ti won n kedun iku oloogbe naa lasiko yii.
Ọ̀pọ̀ àwọn èèyàn tó bá wa sọ̀rọ̀ ló ní, kò sí àdánù kankan tí ìpínlẹ̀ Kwara yóò rí, nítorí pé Saraki kò di ipò kẹta mú mọ́ ní Nàíjíríà.
Ìwà burúkú ti di ẹ̀ ninú àwọn Ọlọpa funfun yi hu ki ṣe ìwà ti ó wọ́pọ̀ laarin ọ̀pọ̀lọpọ̀ Ọlọpa aláwọ̀ funfun tàbi gbogbo Ọlọpa ti wọn nṣe iṣẹ́ ribiribi lati dá àbò bo àwọn ará ilú.
kí àwọn igi tí yóo dúró ní òòró gùn ní igbọnwọ mẹ́wàá, kí àwọn tí o óo fi dábùú rẹ̀ jẹ́ igbọnwọ kọ̀ọ̀kan ààbọ̀.
1 154392 Orilẹede Naijiria 1190 0.
Àjọ̀dún Òyìnbó ń bọ̀ lọ́nà dẹ̀dẹ̀.
Ọmú rẹ mejeeji dàbí ọmọ àgbọ̀nrín meji, tí wọn jẹ́ ìbejì,tí wọn ń jẹko láàrin òdòdó lílì.
Ṣùgbọ́n àsẹ̀hìnwá-àsẹ̀hìnbọ̀ erin náà kú, àti ọjọ́ náà ní gbogbo ènìyàn sì ti ń pè é ní Ìjàǹbáforítì baba erin.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Àjọ CAN bẹ̀rẹ̀ ìwọ́de L'òndó Fídíò àkàndá ẹ̀dá tó di amòfin Ẹwo ọlọpaa Naijiria ti kin gba abẹtẹlẹ Ọrọ Poopu naa waye ni asiko ti Ajọ ọmọ lẹyin Kiristi lorilẹede Naijira, CAN, kesi awọn Kiristẹni lati tu jade lọwọọwọ, lati fẹhọnu han lori isekupani awọn onigbagbọ kaakiri orilẹede Naijiria.
Awa o kọlu darandaran kankan lagbegbe yii sugbọn wọn ti pa eeyan kan laarin ileto wa, a si maa rii daju pe wọn o da irufẹ asọ bẹẹ soro mọ."
O n jẹjọ lori ẹsun pe o lẹdi apo pọ lati ko obitibiti miliọnu owo Dọla pamọ lọna aitọ.
Ìlù yìí sí ní ikọ ogún Ibadan lù láti tán àwọn ọmọ ogún Ìjàyè jáde pé kí wọ́n rekọjá odò Ọsẹ, tí kò jìnnà sí ibi tí wọ́n wa, èyí to yí ogun Ìjàyè lọ́wọ́ pátápátá.
Yatọ si eyi, wọn tun di alafo nla to wa laarin ọna ti ileesẹ ọlọpa agbegbe ati ti gbogboogbo n gba ṣiṣẹ.
Gomina ipinlẹ Rivers, Nysome Wike wọgile ofin isede lawọn agbegbe kan niluu Port Harcourt lọjọ kejidinlọgbọn oṣu kẹwaa ṣugbọn eyi ko kan ijọba ibilẹ Oyigbo.
 Amosa awon ti won ba ni kaadi idibo nikan ni won lee
Lẹ́hìn èyí, Baba-onírùngbọ̀n fi èsì fún mi, èsì rẹ̀ náà sì kún fún mi, èsì rẹ̀ náà sì kún fún ọgbọ́n gidigidi.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Anti social media bill: Ilé aṣòfin ní ìjíròrò ìtagbangba ló kù lórí àbá láti mójútó ayélujára 23 Bélú 2019 Oríṣun àwòrán, Facebook/Elisha Ishaku Abbo Àkọlé àwòrán, Anti social media bill: Ilé aṣòfin ní ìjíròrò ìtagbangba ló kù lórí àbá láti mójútó ayélujára, Iduro ko si, ibẹrẹ ko si fun ẹni to gbodo mi lọrọ aba to wa niwaju ile aṣofin lati ma mojuto ohun to n lọ lori ayelujara lọrọ da bayii o.
Akọ̀ròyìn Vladimir Villegas sọ wípé kò rí bẹ́ẹ̀ mọ́ wípé ìjọba ni ó fi ọwọ́ agbára mú u:
Esi ifesewonse ohun pari si ami-ayo meji-meji (2-2), ti apapo ami ayo naa si je ami ayo merin si meta (4-3).
Wọ́n bá dáhùn pé, “Àwọn tí wọ́n kù ninu àwọn ara Bẹnjamini gbọdọ̀ ní ogún tiwọn, kí odidi ẹ̀yà kan má baà parun patapata ní Israẹli.
Ọlatoyan ni oun maa n pa to ẹgbẹrun kan si meji naira lojumọ ti aje ba bu igba jẹ, to si tun fikun pe oun ti ta omi inu ọra ri ni Idumọta nipinlẹ Eko lati ran ara oun nileewe.
Ẹ̀yin ọlọ́pàá, ẹ di ìhàmọ́ra kẹ́ẹ já àlàfíà ìlú gbà padà - Ọ̀gá àgbà ọlọ́pàá Àwọn ọ̀nà láti dẹ́kun ìwọ́de ọ̀dọ́ lọ́jọ́ iwájú nìyí Èèyàn 229 ló ti wà ní gbaga òfin fún wàhálà tó wáyé l'Eko Ara awọn ohun to ṣokunfa laaṣigbo to ti ara iwọde naa ṣẹyọ ni oniruuru iroyin ofege gbogbo to lu ori ayelujara pa.
Ọjọgbọn Gambari jẹ oludamọran pataki lori ọrọ ilẹ Afirika labẹ akọwe agba ajọ iṣọkan agbaye, Ban Ki-Moon lọdun 2000 si ọdun 2005.
Bo tilẹjẹ wi pe aisan yii jẹ ohun to ṣe e dena, to si ni itọju, o ṣi n ṣeku pa ọpọlọpọ.
Oríṣun àwòrán, others Àkọlé àwòrán, WHO tí kéde pé Ó ṣeéṣe kí àrùn Coronavirus tànkálẹ̀ gba inú afẹ́fẹ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ǹjẹ àgbo lè ṣe òògùn coronavirus?
Ninu igbinyanju BBC Yoruba lati fi idi isẹlẹ yii mulẹ lo mu ka pe alukoro fun ileesẹ ọlọpa nípinlẹ Ekiti, DSP Caleb Ikechukwu, ẹni to sọ pé àwọn kò tí gbọ nipa iṣẹlẹ òhun.
OLUWA ní,“Ẹ̀yin ará Jerusalẹmu, ta ni yóo ṣàánú yín?
Àmọ́, ó ṣeé ṣe ki sunkẹrẹ-fakẹrẹ ọkọ ko lagbara laarin ọsẹ ju opin ọsẹ ti a sọ yii, nitori pe ọkọ má n pọ ni oju ọna.
AFCON 2019: Ẹgbẹ́ agbábọ́ọ́lù 24 ni yóò kópa nínú rẹ̀
7 Ìgbé 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 30 Ìgbé 2020 Oríṣun àwòrán, Fayemi Àkọlé àwòrán, kini Gómìnà ìpínlẹ̀ Ekiti, Kayode Fayemi ṣe fun baba tó ni ọmọ òun ko gbọdọ tèlé oun déle Gómìnà ìpínlẹ Ekiti, Kayode Fayemi ni òun ti yan baba ti fọran rẹ tan ka ori ayelujara lásìkò to n ba ọmọ rẹ jà pe ko le tẹ̀lé òun lọ ile lai ṣe ayẹwò Covid-19 lẹ́yìn to ti irin ajo de lati ìpínẹ̀ Eko gẹ́gẹ́ bi asoj;u ìjọba lori ọ̀rọ̀ Covid-19 nipinlẹ Ekiti.
O fikun ọrọ rẹ pe akitiyan Saheed lati ran awọn to ba ni iṣoro kan tabi omiiran lọwọ wa lara awọn ohun to jẹ ki oun nifẹ rẹ.
"Adunni Oluwole, akọni obìnrin tó tako òmìnira Nàìjíríà, ó ní òyìnbó kò gbọ́dọ̀ lọ Àwòrán òkú ọmọ mi ni mo kọ́kọ́ rí lójú òpó ayelujara - Bàbá ọmọ tí SARS lé dójú ikú Òṣèré méjì yìí ń fi ẹ̀wọ̀n runmú tóríi fíìmù ""Ife"" táwọn obìnrin ń bá ara wọn lòpọ̀ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ìtàn ọ̀rẹ́ tó fi ògùn gba ọkọ ọ̀rẹ́ rẹ̀ ni Akomolede BBC Yorùbá fẹ́ kọ́ wa lònìí Awọ́n akẹ́gbẹ́ Bunkunmi Oluwasina gan ji ri i lowurọ kutukutu ni bi inu wọn si ṣe dun to ni awọn naa ṣe bẹrẹ si ni fi aworan rẹ sita pẹlu ikini."
Àwọn àgbààgbà ti sá kúrò ní ẹnubodè;àwọn ọdọmọkunrin sì ti dákẹ́ orin kíkọ.
Iroyin sọ pe, iṣẹlẹ yii ti sọ gbogbo awọn olugbe ilu Iba sinu hilahilo bayii nitori irufẹ iṣẹlẹ naa ko waye ri ati pe alaafia ni awọn olugbe ilu naa atawọn darandaran Fulani n gbe nibẹ.
Balaki ṣe gẹ́gẹ́ bí Balaamu ti wí, àwọn mejeeji sì fi akọ mààlúù kọ̀ọ̀kan ati àgbò kọ̀ọ̀kan rúbọ lórí pẹpẹ kọ̀ọ̀kan.
Dori, tí ó wà ní etí òkun; Goiimu, tí ó wà ní Galili, 
Ṣugbọn wọn kò gbà á, nítorí ó hàn dájú pé ó ń lọ sí Jerusalẹmu.
Nígbà tí àjàkálẹ̀ àrùn náà dáwọ́ dúró, Aaroni pada sọ́dọ̀ Mose lẹ́nu ọ̀nà Àgọ́ Àjọ.
Ogun ebi ni Nàìjíríà ń bá fínra lọ́wọ́, ogun coronavirus kò gbọdọ̀ kún un-Oluwo Èyí làwọn ayẹyẹ nlá tí kò ní wáyé nítorí coronavirus Mo gbà pé mo jẹ̀bi láti ṣe ìpàdé ìta gbangba ẹgbẹ́ PDP tó wáyé ní Ibadan - Makinde Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Peter Fatomilola ní àìsí ẹ̀kọ́ ń mú káwọn òṣèré tíátà ó máá ṣe oun tí kò tọ́.
Taiwo Akinlami ni ẹnikẹni to ba ti ju ẹni ọdun mejidinlogun lọ lẹtọ labẹ ofin lati jẹjọ ẹsun ni ile ẹjọ.
Ẹwẹ, akọwe iroyin rẹ sọ fun BBC Yoruba pe lọjọ Aje ni Ọgbẹni Ajayi yoo bawọn akọroyin sọrọ lori idi to fi kuro ninu ẹgbẹ APC lọ si PDP ati igbesẹ to kan fun un.
Ìkéde dúkìá tí Yar'adua ṣe yìí, si ni àwọn èèyàn fi ń ṣe odiwọn fún Ààrẹ tuntun to ń jẹ lẹ́yìn rẹ, láti mọ bóyá onítọ̀ún yóò kó akoyawọ bíi Umar Yar'adua.
PDP: Ẹní jẹ fùfú lará ń fu, ọmọ ẹgbẹ́ wà kò hùwà àìtọ́ lásìkò ìdìbò Ṣé irúfẹ́ oúnjẹ tí ò ń jẹ́ lè jẹ́ kí o gbádùn ìbálòpọ̀ rẹ síi?
Àwọn òṣìṣẹ́ Pápákọ̀ òfurufú ti MMA2 pa 'A gbọ́dọ̀ gbé ìgbésẹ̀ tí ìpínlẹ̀ Eko gbé nípa èdè Yoruba’ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Bí aya bá kọ ọkọ rẹ̀ silẹ̀, kó wà láì lọ́kọ̀' Awọn ti ọrọ naa se oju rẹ ni Ọkunrin ti wọn sekupaa naa, Femi Makanjuọla lọ ra ounjẹ lasiko ti awọn eleegun naa bere owo lọwọ rẹ, ti o si kọ lati fun wọn.
 Ki i se aare akọkọ fun orile
Fayose fi ikede naa sita l'oju opo ikansiraẹni Twitter rẹ pe.
Aṣọ ìkélé Tẹmpili ya sí meji.
Comrade Abioye fikun un wi pe ti ijọba ba pe ipade gbogboogbo, eleyii ti yoo se ijiroro pẹlu awọn adari ijọba ibilẹ ati awọn gomina pẹlu awọn ẹgbẹ bii Agbẹkọya ti yoo fun wọn ni ilana lati fopin si ijinigbe.
omi Onne to wa ni ipinle Rivers lojo Ẹti.
 “Erongba ohun ni lati je ki awon ti oro kan ni eka ile-ise aladani ati ti ijoba se aseyori ninu amugberu eto oro-aje naa bi o ba fi maa di odun 2020”.
''Akọkọ ni pe ijọba ti ọrọ kan gaan ni lati gbajumọ kikoju awọn agbesunmọmi yi kawọn to ba fẹ gbaruku tiwọn le ri wi pe wọn mura sii.
9m kalẹ̀ fún owó oṣù òṣìṣẹ́ ní Kwara Àwọn olùdíje sípò gómìnà ní ìpínlẹ̀ Ogun fakọyọ Minista fun eto ẹ̀kọ́: Adamu Adamu Awọn eeyan ko fi bẹẹ sọrọ nipa minista yii pupọ ni eyi ti awọn kan gba pe ko fi daa tó.
" ibì ti Ìyá yìí wá kólé sí ní àdúgbò rè ni won so di "" ita ìyálódè ."
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Walter Onnoghen kọ̀wé ìfẹ́yìntì ara rẹ̀ gẹ́gẹ́ bí adájọ́ àgbà Nàìjíríà 10 Òkùdu 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Adajọ agba, Walter Onnoghen Aarẹ Muhammadu Buhari ti tẹ́wọ́ gba iwe ifẹyinti eyi ti adajọ agba, Walter Onnoghen kọ funra rẹ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Buhari: Èsì mi lórí orúkọ àwọn mínísítà 12 Agẹmo 2019 Oríṣun àwòrán, Bayo Omoboriowo Aarẹ Muhammadu Buhari ti ni bi o tilẹ jẹ pe awọn ọmọ Naijiria wa lọrun oun lati gbe orukọ awọn minisita jade, awọn t'oun mọ ni oun yoo yan.
Wọn ni lai jẹ pe ijọba gbe igbesẹ lori awọn ẹdun ọkan wọn ti wọn gbe ka iwaju ijọba awọn yoo tẹsiwaju lori igbesẹ naa.
Kí n tọ̀ yín wá pẹlu pàṣán ni, tabi pẹlu ẹ̀mí ìfẹ́ ati ní ìrẹ̀lẹ̀?
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Vaccine rumours debunked: Àwọn ìròyìn òfegè nípa abẹ́rẹ́ àjẹsára Covid-19 4 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Oríṣun àwòrán, Getty Images A ṣe agbeyẹwo awọn iroyin ofege ti awọn eeyan n gbe kiri nipa abẹrẹ ajẹsara Covid-19.
"A ko ni ẹrọ amuletutu, faanu nikan la ni, agbegbe yii si gbona pupọ.
Ní orilẹ̀-èdè China, Núdùlù ń sàfihan ẹmí gígùn Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Tani yóò kẹ̀yìn sí Núdùlù tí máa mú ẹmi ẹni gùn tó tún máa ń fun ni àláfìà Núdùlù jẹ àmì ẹmí gígùn ní China, bí núdùlù náà ba ṣe gùn tó ní ẹmi ẹni náà yóò ṣe gùn ìgbàgba àwọn China rèé.
Yinka Ayefẹlẹ: Àdúrà lẹ ṣe pé mo bí ìbẹta, yóò sì rí bẹ́ẹ̀
Ikede yi n waye pẹlu bi iye awọn to lugbadi arun yi ti se kọja ẹgbẹrun mẹrinlelogun.
Erin wọ̀lú, ó pa ènìyàn méjì Kiniun pa olusọ ọgba ẹranko Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ronke Oṣodi: òótọ́ ọ̀rọ̀ máa ń korò gan ni f'áwa èèyàn Ọkan nínú àwọn ọmọbinrin náà ti di àwáti nígbàti àwọn méjì míràn àtí ọkunrin Kan ṣì wà ní ilé ìwòsàn ni Cape coast.
 lori akitiyan ati iranlọwọ won  fun eto  alaafia ati idagbasoke ti won ko lorile ede
Atẹjade naa ni baba Fasanmi fi ọwọ rọri ku ni nile rẹ to wa nilu Osogbo, ti wọn yoo si maa kede eto isinku rẹ laipẹ.
Oríṣun àwòrán, Twitter/Nigeria Railway Corporation O ni nkan to ba yẹ ki ijọba Buhari fi si iwaju lo n fi sẹyin.
láti inú ẹ̀yà Juda: Elihu, ọ̀kan ninu àwọn arakunrin Dafidi; láti inú ẹ̀yà Isakari: Omiri, ọmọ Mikaeli; 
Wọ́n ń sọ fún mi pé kí n lọ máa bọ oriṣa.
Idi ni pe orilẹede Naijiria tun ti n reti owo miran to jẹ eyi ti Abacha ko pamọ lasiko to n dari orilẹede yii.
Agbowu pe Oluwo l'ẹ́jọ̀, ó ń bèèrè ₦100m owó gbà má bínú Oríṣun àwòrán, Ọba Dikrulahi Ọlaleke Akinrọpo, Ọlabiran Kẹta.
Kalu ṣalaye pe Abadofin yoo de ipele ti wọn yoo ti ka ni gbagede, ti awọn onimọ nipa ajakalẹ arun yoo si dasi."
Ìwọ ni o sì ń gbèrò láti jọba lé wọn lórí, 
Àwọn ọmọ FIBAN kò gbọdọ̀ lo orin Wasiu Ayinde mọ́ lẹ́yìn ìfìyàjẹní Murphy- FIBAN Yoruba wo ló fẹ́ gbé Oduduwa Republic tẹ́ n pariwo - Lizzy Anjorin ''Láti òní lọ, FSARS ò gbọdọ̀ káàkiri ìlú mọ́ tàbí tú ẹrù aráàlú wò mọ́''- Ọ̀gá ọlọ́pàá pàṣẹ Àwọn olùpolongo ìdìbò Aketi àti Jegede ń forígbárí l'Ondo, bí wọ́n ṣe n yìnbọn ni wọn n sun táyà O fikun wi pe gbogbo awọn to n tiraka lati da orilẹede Naijiria pada si oko ẹru naa yoo jẹ ninu iya awọn ẹni ibi.
Òní lóyẹ k'ọ̀gá ọlapàá Ibrahim Idris fẹ̀yìntì Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Àkọlé àwòrán, Wọ́n ní ògiri ló la ẹnu tí ọ̀rọ̀ náà ṣe lu síta Kódà bí ẹ bá ṣe ń súnmọ́ agbo ilé gbajúgbajà náà, ìdàkejì gbáà ni afẹ́fẹ́ ibẹ̀ jẹ́ sí bó ṣe ń gbóná níta káàkiri àwọn ẹ̀rọ ayélujára láti ìgbà tí ìṣẹ̀lẹ̀ náà ti ṣẹlẹ̀.
Zola Saphetha, to je akowe agba fun National Education, Health and Allied Workers’ Union (NEHAWU), ni esi igbakeji aare, iyen, David Mabuza, seese ko mu edinku ba nkan to po.
Ẹlẹ́rìí òtítọ́ kì í parọ́,ṣugbọn irọ́ ṣá ni ti ẹlẹ́rìí èké.
“Kígbe sókè, má dákẹ́,ké sókè bíi fèrè ogun,sọ ìrékọjá àwọn eniyan mi fún wọn ní àsọyé,sọ ẹ̀ṣẹ̀ ilé Jakọbu fún wọn.
Yóo jẹ́ aláìmọ́, níwọ̀n ìgbà tí àrùn yìí bá wà lára rẹ̀.
OLUWA yóo gbé orílẹ̀-èdè kan, tí ẹ kò gbọ́ èdè wọn, dìde si yín láti òpin ayé; wọn óo yára bí àṣá.
Akanṣe awọn aworan aṣa ati iṣe awọn ọmọ Yoruba
" Lootọ awọn obi awọn ọmọ Dapchi wọn ko ni sọ ireti nu sugbọn awọn kan lara awọn obi awọn akẹkọbirin Chibok sin reti awọn ọmọ wọn lẹyin ọdun mẹrin ti wọn ti ji wọn gbe.
Orji so pe“Ajo yii n gbero lati se atunse si ibi ti awon eniyan ti maa n dibo won ,lati dena bi won yoo se ri eni ti  oludibo  yoo dibo fun un.
Nígbà míì gan-an, tí òjò bá ṣú dẹdẹ láti òwúrọ̀ dé ìrọ̀lẹ́, á máa dàbí ẹni pé ilẹ̀ ò mọ́n rárá lọ́jọ́ náà ni.
Sugbọn pabo ni eyi ja si nitori kete to kuro nipade pẹlu aarẹ lo sọ fun awọn akọroyin pe oun yoo lọ si ẹgbẹ miran lati dije dupo lẹyin toun ba kọwe fi ẹgbẹ oselu APC silẹ.
 Ọjọgbọn Afọlabi Olumide, Giwa tẹlẹ fun Ile Ekọ Fafiti Ipinlẹ Eko (LASU) ti oun naa jẹ akọrin ati oniduuru tẹlẹ ninu Ijọ Methodst wa nibẹ pẹlu awon eniyan pataki miiran.
Abilekọ Olawale, nínú ọ̀rọ̀ rẹ ni pé níní ọmọbinrin nikan jẹ́ ìdùnú òhun lójoojúmọ nítori ìwuri ni wọ́n jẹ́ àti pé kò si nkan ti ọkunrin ń ṣe ti obinrin wọ́n o lé ṣe.
Onnoghen k'ọ̀wé ìfẹ́yìntì, Buhari tẹ́wọ́ gbà á Saraki pín owó ìyọ̀nda rẹ̀ fún ẹbí Leah Sharibu àtàwọn míì Iṣẹ́ Kudirat Abiọla ṣì ń fọhùn síbẹ̀, lẹ́yìn ọdún 23 tó papòdà Ìpínlẹ̀ Oyo gba ipò ìkíní mọ́ Edo lọ́wọ́ nínú fífí ọmọdé ṣ'ẹrú Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Iba Gani Adams: Bẹ́ẹ gbé màláíkà kan lọ sí Aso Rock, kò lè ṣàṣeyọrí Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ondo: Dejí sun ọmọ méje àtagbalagba meji mọ́lé nítorí pé ó ń bínú Wọn ni idi abajọ irinajo naa ni lati jẹ ki awọn alaga ipinlẹ naa ni iriri iṣejọba ibilẹ, gẹgẹ bi o ti rii kaakiri agbaye.
O ni wọn sọ fun awọn ologun naa iru iha to yẹ ki wọn kọ si awọn oluwọde ki wọn to de iloro Lekki ti awọn oluwọde wa, ati pe wọn ko yin ibọ pa eeyan kankan.
Laipẹ yii ni iroyin jade pe ẹgbẹ oṣelu APC n pariwo sita pe iṣejọba gomina naa ko ba awọn aṣaaju ẹgbẹ oṣelu rẹ, iyẹn PDP lara mu, wọn si ti n kọ ẹyin wọn sii lọkọọkan ejeeji.
Ìdí márùn ún tí agbára Covid 19 ní ilẹ̀ Adúláwọ̀ kò fi tó tí àwọn ilẹ̀ àgbáyé míràn Ààrẹ Buhari kí Akeredolu kú orííré bí ó ṣe jáwé olúborí nínú ìdìbò sípò gómínà Gomina Kano tí ní kí olùrànlọ́wọ́ rẹ̀ lọ rọ́kún nílé nítori o bu Ààrẹ Buhari lórí #EndSars Àwọn ọ̀dọ́ yabo ààfin, Ṣọun Ògbómọ̀ṣọ́ àti mínísítà sá àsálà fẹ́mi wọn Lọwọlọwọ bo ṣe n kan wa lara ni pe awọn kan ti yabo aafin Soun Ogbomoso, Oba Oladunni Oyewumi Ajagungbade kẹta ti wọn si ti ba ọpọ dukia jẹ.
Wọ́n dàbí àlá tíí pòórá nígbà tí eniyan bá ta jí.
Ni gbogbo wọn patapata láìku ẹnìkan bá bẹ̀rẹ̀ sí ṣe àwáwí.
Ọpọ eeyan to si ti kagbako ijamba lọdọ awọn ọmọ ẹgbẹ yii, lo le sọ bo sẹ ri, nitori pe iroyin ko to afojuba.
Eleasari bá sọ fún wọn pé, “Ẹ gbọ́ ìlànà tí OLUWA ti fi lélẹ̀ láti ẹnu Mose.
Níní àtẹjáde kan ti ijọba ìpiínlẹ̀ Borno fi síta sàlàyé pé ECHO ni yóò ṣe agbátẹru ètò náà.
29 Bélú 2020 Oríṣun àwòrán, Getty Images Eden Hazard agbabọọlu ọmọ Belgium to n ṣoju ẹgbẹ Real Madrid ti tun farapa lori papa iṣere.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Èmi gan máa ń béèrè lọ́wọ́ ara mi pé ta ni Wole Soyinka gangan' Bakan naa ni wọn sọ pe jijẹ ounjẹ aṣaraloore naa ni ipa to n ko ninu idena awọn aleebu to le fẹ ẹ ba ọmọ tuntun.
Olórin náà tó ti wà látìmọ́lé báyìí ti pé ẹjọ́ kòtẹ́milọ́rùn lòdì sí ìgbẹ́jọ́ náà.
Ohun tí yóo sì jẹ́ àmì tí o óo fi mọ̀ pé OLUWA ló yàn ọ́ láti jọba lórí àwọn eniyan rẹ̀ nìyí: 
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Illegal Rehab Centre: A le ni ogójì tí wọ́n n kó sinú ìyará kékeré kan níle Ọlọrẹ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Illegal Rehab Centre: A le ni ogójì tí wọ́n n kó sinú ìyará kékeré kan níle Ọlọrẹ 9 Bélú 2019 Wọn mu mi wa sibi nitori pe mo n mu siga- ọmọbinrin kan.
Ó ti parí, n óo lọ fi ojú kàn án kí n tó kú.
Opolopo awon adari  orile ede Afirika ni won ti n fiwe ati ipe
Angẹli náà bá rọra lu Peteru lẹ́gbẹ̀ẹ́, ó jí i, ó ní, “Dìde kíá.
Iko agbaboolu Arsenal kopa daradara ninu ifesewonse ipele keta si asekagba idije Europa League, leyin ti fagbahan iko agbaboolu  CSKA Moscow pelu ami-ayo merin sookan(4-1) ninu ifigagbaga akoko ifesewonse naa,Bakan naa si ni, iko agbaboolu Atletico Madrid ko gbeyin, leyin ti iko ohun naa fagbahan Sporting Lisbon pelu ami-ayo meji sodo(2-0) lojoBo(Thursday).
A kò gbo̩dò̩ lo àwo̩n è̩tó̩ àti òmìnira wò̩nyí rárá, ní ò̩nà yòówù kó jé̩, tó bá lòdì sí àwo̩n ète àti ìgbékalè̩ Ajo̩‐àpapò̩ orílè̩‐èdè agbáyé.
Nígbà tí wọn ń ríran èké, tí wọ́n sì ń woṣẹ́ irọ́ fún ọ, a óo gbé idà náà lé ọrùn àwọn aláìmọ́ ati ẹni ibi, tí ọjọ́ wọn ti pé, àní ọjọ́ ìjìyà ìkẹyìn wọn.
Bawo lawọn eeyan se sami ọjọ ‘Ma wọ kọmu’?
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Afe Babalola: Adarí Nàíjíríà kankan kò leè ṣàṣeyọrí pẹ̀lú òfin ọdún 1999 28 Ògún 2019 Oríṣun àwòrán, @hartarmah1 Agba amofin nni, Afẹ Babalọla ti kede pe ofin ti orilẹede Naijiria n lo lọwọlọwọ bayii ko kun to, to si mẹhẹ lati yanju oniruuru isoro to n ba orilẹede yii finra.
Ọ̀nà àbáyọ kan ṣoṣo tó wà ní pe kí àwọn asáájú ọba jìjàgbara.
Ondo Election 2020: Olùdíje ẹgbẹ́ òṣèlú PDP, Eyitayo Jegede ti yan Gboluga Ikengboju gẹ́gẹ́ bí ìgbákejì
Agbẹnúsọ ilé ìgbìmọ̀ asòfin àgbà Ajibola Bashiru to kéde ìdádúró ètò náà lásìkò to n bá àwọn oníròyìn sọ̀rọ̀ nílùú Abuja, ó sọ pé ilé ìgbìmọ̀ asòfin àgbà pé Festus Keyamo láti yọjú sí ilé aṣòfin láti sàlàyé lóri ọ̀nà ti wọ́n fẹ́ gbà láti gba àwọn ènìyàn sísẹ́ lábẹ́ ètò náà.
Èwo ni ó rọrùn jù, láti sọ pé, ‘A dárí ẹ̀ṣẹ̀ rẹ jì ọ́ ni,’ tabi láti sọ pé, ‘Dìde kí o máa rìn’?
Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí 6:18 Fídíò, Natalia Mufutau ìyá Yakub, Kamil àti Adam sọ̀rọ̀ lórí bí wọ́n ń sọ èdè mẹ́rin pàpọ, Duration 6,1831 Ògún 2020 Fídíò, Yoruba Language: Akomolede ati Asa Yoruba tọ̀sẹ̀ yí rèé lẹ́nu olùkọ́ wa30 Ògún 2020 Coronavirus in Nigeria: Èèyàn 675 ló tún ti ní Covid-19 ní Naijiria11 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Alága àwọn onílé ní agbèègbè náà, Adigun Olaleye sọ fún ilé-isẹ́ ìròyìn tí ìjọba orílẹ̀èdé Nàíjíríà, NAN wípé àwọn kò mọ ohun tí àwọn yóò se nípa àwọn ọ̀bọ náà mọ́.
Irọ́ ọjọ́ ìbí kò ṣé e pa nítorí gbogbo àwọn ọ̀rẹ́ mi ni wọ́n mọ ọjọ́ ìbí mi.
Eyi ko ṣẹyin bi awọn iya arugbo kan nilu Ilorin ti ṣe ṣe iwọde ladugbo Iloffa Road ti ile Baba Saraki ''Oloye'' kalẹ si.
Ìwọ tí ò ń tu àkọ̀ kúrò lára ọrun,tí o fi ọfà lé ọsán ọrun;tí o wá fi omi pín ilẹ̀ ayé.
Gbogbo àwọn tí wọ́n wà níbẹ̀ ni ó parun, kò dá ẹnikẹ́ni sí.
Ṣugbọn igbiyanju ko to o lẹyin ti Spain yọ wọn ninu idije naa ti wọn si ti dero ile bayii.
Ṣugbọn ó ṣe bí àwọn ọba Israẹli, ó tilẹ̀ yá ère fún oriṣa Baali.
Ọjọ yii jẹ ọjọ ti ẹsin Musulumi gba ibukun ati ire lẹnu Allah gẹgẹ bi ẹsẹ Iwe Mimọ Quran ti kọ silẹ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Cancer: Àṣe ara mi ni iso ti n run gbogbo bí mo ṣe n ṣèrànwọ́ lórí jẹjẹrẹ Bakan naa lo gba Ph.
Honourable SOB Agunbiade: Ọ̀tọ̀ ni \Palliatives\"" ìjọba, ọ̀tọ̀ ni ǹkan ìní tèmi náà tí wọ́n jí kó"
 o tun je ikan ninu awon oludasile ( lapapo mo ronald fisher ati sewall wright ) of ìṣiṣẹ ́ àbímọ ́ alábùgbé .
" Arabinrin Dupe ṣalaye pe oun ni akọbi iya ati baba oun, to si jẹ pe ọmọ mejidinlogun ni baba rẹ bi.
Báwo ni ìdìbò abẹ́nú APC l‘Ọ́sun yóò se lọ lónìí ?
Eeyan 42,208 ni apapọ ni arun naa ti fara kan labẹ ayẹwo lorilẹede Naijiria.
Ọmọwe Niyi Sunmọnu to jẹ alaga Congress of University Academy (CONUA) ṣalaye pe ko si olukọni ti o lagbara lati paṣẹ ki akẹkọ maṣe wa sile iwe ati pe ẹni to ba jẹ ninu owo adebisi nii pe ni baba layẹyẹ.
Bí ẹnìkan ninu yín bá rò pé òun gbọ́n ọgbọ́n ti ayé yìí, kí ó ka ara rẹ̀ sí òmùgọ̀ kí ó lè gbọ́n.
Wọn ji wọn gbe loju ọna Ọwọ si Ikarẹ-Akoko lasiko ti wọn n pada si ilu Akurẹ lati ilu Ikarẹ-Akoko lẹyin ipolongo oṣelu.
Nítorí wọ́n pa àgọ́ àkọ́kàn, ninu rẹ̀ ni ọ̀pá fìtílà ati tabili wà.
Saulu bèèrè lọ́wọ́ Jonatani pé kí ó sọ ohun tí ó ṣe fún òun.
Ohun to n ba ijọba ipinlẹ Oyo lẹru ni pe awọn eeyan to n lugbadi arun Covid-19 n pọ si dipo ki wọn dinku, eyi lo mu ko tilẹkun ile ijọsin, ẹni to si kan lo mọ, amọ gbogbo ọkan lo n pohungbẹ lati wa sile Ọlọrun, ipa ti adura si n ko, kii ṣe ipa kekere."
 Ọmọ ọdún mẹ ́ fà àti oṣù méje ni ó jẹ ́ nígbà tí ó wọ santa rosa junior college , california ní ilẹ ̀ amẹ ́ ríkà ní 1990 .
Akẹ́kọ̀ọ́ fasiti kan ni Malaysia ni Olusegun ki wọ́n tó mú u, ṣùgbọ́n kò fi ìgbà kankan simi iṣẹ́ gbájuẹ, lẹ́wọ́n gan ko dáduró láti tẹsíwájú iṣẹ́ gbájúẹ̀ rẹ to n ṣe.
Obìnrin bíi Ruth Bader ni yóò gba ipò rẹ́ ní iléẹjọ́ tó gajùlọ nílẹ̀ Amerika- Donald Trump Ilé ìjọsìn lè bẹ̀rẹ̀ ìsìn àárín ọ̀sẹ̀ padà, Mọ́sáláṣí àti Ṣọ́ọ̀ṣì lé gba iye èèyàn tó wù wọ́n ṣùgbọ́n.
Gẹgẹ bi alukoro ileeṣẹ naa ṣe sọ ọ, Ọgagun Babandede fi ọrọ yii lede nibi akanṣe eto ayipada ilana ẹkọ ni ile ẹkọ akọkọ ti ileeṣẹ to n ri si iwọle wọde ajoji ni ipinlẹ Kano.
Èyí nì ni pé olúwarẹ̀ kò ni dé oríta ọ̀nà òkè Láńgbòdó kí ó tó yà.
''Ninu oṣelu Naijiria, agba ọjẹ ni Fayose jẹ.
Saraki àgbà ló kọ́ ilé yìí fáwa arúgbó kìí ṣe Bùkọ́lá- Arúgbó Ilọrin Àwọn fóònù wọ̀nyìí kò ní lè ṣe WhatsApp láti ọdún 2020 Àfàìmọ̀ kí Naira Marley má fi ẹ̀wọ̀n bẹ̀rẹ̀ ọdún 2020 Odunlade àti Femi Adebayọ: Wo ohun tó yà wá sọ́tọ̀ nínú àwọn arẹwà ọkùnrin Aduku ni ọmọkunrin naa ni iwadii fihan pe ọmọ ogun ni ati pe Salikawa lorukọ rẹ.
Ọlọrun dá Solomoni lóhùn pé, “Nítorí pé irú èrò yìí ló wà lọ́kàn rẹ, ati pé o kò sì tọrọ nǹkan ìní, tabi ọrọ̀, ọlá, tabi ẹ̀mí àwọn ọ̀tá rẹ, o kò tilẹ̀ tọrọ ẹ̀mí gígùn, ṣugbọn ọgbọ́n ati ìmọ̀ ni o tọrọ, láti máa ṣe àkóso àwọn eniyan mi tí mo fi ọ́ jọba lé lórí, 
Awọn mejeeji ni ohun ti awọn mọ ni pe, bi ẹnikẹni ba ni iroyin to lee ṣe ọlọpaa lanfani lati lee dẹkun iwa ọdaran lawujọ, onitọhun lee mu tọ ọlọpaa wa.
Lara awọn ohun ti awọn ajafẹtọ naa salaye gẹgẹ bii aleebu ara idibo naa ni, ṣiṣe segesege awọn ẹrọ ti n yẹ kaadi oludibo wo, didun mọhuru mọ awọn akọroyin, pẹlu ohun ti wọn pe ni àìsí ootọ awọn oṣiṣẹ eleto idibo lasiko ti ibo naa waye.
 O so pe” Ise ti a n se ni atunse si awon  oju opopona lati tun je ki o fe si,pipese awon oju ona agbara –ojo ati atunse si awon Afárá irnna ese.
, Ki eledua ṣe ọkọ ati aya rere fun gbogbo mutumuwa.
Adiẹyin mu Luke Shaw lo ṣeeṣi gba goolu sile ara rẹ, eleyi to mu ki Barca jawe olubori ninu ifẹsẹwọnsẹ naa.
NigeriaRoadAccident- Ọkọ àjàgbé kọlu obìnrin kan lórí ọkadá ó sì kú
Ẹbi ọmọ yii ke gbajare si ijọba apapọ lati ṣe idajọ to tọ.
Favour ni inu oun dun si anfani toun ni lasiko Covid19 yii.
"Ilẹ mimọ ni"" Lori ajọṣepọ to wa laarin oun ati Gbajugbaja Olorin fuji miran, Saheed Oṣupa, Pasuma ni iṣẹ ti pọ lọwọ awọn bayii ju ki awọn mejeeji máa ta'hun orin sira."
Àwọn eniyan burúkú fa idà yọ, wọ́n sì kẹ́ ọfà wọnláti gba ẹ̀mí talaka ati aláìní,láti pa àwọn tí ń rìn lọ́nà ẹ̀tọ́.
Epo pupa ati iyọ ṣe pataki lojubọ ki danafojura to jade.
”Ọ̀gágun wá bi í léèrè pé, “O gbọ́ èdè Giriki?
Ọpọ oṣere tiata lo kọ iṣẹ lọdọ oloogbe Oyin Adejobi, lara wọn ni Baba Wande ati oloogbe Alabi Yellow, ti akọni oṣere naa si faye silẹ ni ọdun 2000 lẹni ọdun mẹrinlelaadọrin.
Komisona naa ni: “Ise akanse ti Ikenne yoo wa fun oko to to egberun meji abo eeka ile nigba ti tijebu Ode yoo wa fun egberun kan eeka ile.
” Wọ́n ṣẹ́ gègé, gègé bá mú Jona.
Akọwe ajọ eleto ilera ilẹ UK, Matt Hancock ṣalaye pe abẹrẹ bii 800,000 ni yoo wa fun nilo lati ọṣẹ to n bọ lọ.
Àwọn ọmọbinrin Diboni ti gun àwọn ibi pẹpẹ tí wọ́n ti ń bọ̀rìṣà lọ, wọ́n lọ sọkún.
Jesu bẹ̀rẹ̀ sí fi òwe bá wọn sọ̀rọ̀ pé, “Ọkunrin kan gbin àjàrà sinu oko kan, ó sì ṣe ọgbà yí i ká.
Nítorínáà ènìà máa nṣábàá bá yìnyín tí ó rọ̀ sóríi koríko orí òkè wọ̀nyìi.
E je ki won dibo fun eni to wu won, yala eya tabi  esin, ki won si ni ase lori ohun ti won fe.
Lẹyin èyí ni ìpàdé míràn wáyé ní ìlu Ibadan níbi ti wọ́n ti yan òun gẹ́gẹ́ bii ààrẹ ẹgbẹ́.
"16 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Florence sọrọ nipa gbigbe lagboole ti ero pọ si ati iṣoro rẹ fun ẹni to n woju Oluwa Florence Onwuasoanya ni abiyamọ to sọ ohun ti oju rẹ ri to lọwọ ẹjẹ ti oloyinbo n pe ni "" Rhesus Negative"" ni eyi to fi n sunkun asunrin."
Agbẹnusọ ajọ ọlọpaa, Jimoh Moshood, to fi ọrọ naa lede ni Olu-Ilu Naijria, Abuja fikun un pe awọn tun ti ri owo miran to le ni biliọnu mẹjọ Naira to jẹ ti NNPC/LNG ti wọn ko fi si apo asuwọn ijọba to yẹ ko wa.
“OLUWA ní, ẹni tí ó bá dúró ní ìlú Jerusalẹmu yóo kú ikú idà, ìyàn ati àjàkálẹ̀ àrùn; ṣugbọn àwọn tí wọn bá jáde tọ àwọn ará Kalidea lọ yóo yè.
Adari ile-ise to n mojuto awon osise lorile ede Naijiria ,arabinrin Winifred Oyo-Ita ti ni ,bi  igbimo ti igbakeji aare orile-ede Naijiria Yemi Osinbanjo n sakoso le lori  se da awon oga agba mefa to n sakoso ajo to n mojuto isele pajawiri iyen NEMA duro wa ni ibamu pelu ilana.
Àwọn àádọ́ta ọ̀dọ́ wọ gàù nítorí ilé ijó ní Ilorin BBNaija tọdún 2020 gbéra sọ, wo ohun tó fi yàtọ̀ sí tọdún tó kù!
com ati islamicfinder Ramadan ti bẹrẹ ni pẹrẹu, bi ààwẹ̀ gbigba ṣe pọn dandan bẹẹ naa ni awọn ounjẹ ti ẹnikẹni to ba n gbawẹ nilo akiyesi.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ado Ekiti Blind Couple: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú Amọ, kii se nkan ti ijọba ipinlẹ Ọyọ nikan le mojuto.
Bi ko ba ti si gbọn mi si i, omi o to o laarin oṣere meji, iṣọwọ yẹra ẹni si laarin wọn maa wu ni jọjọ.
Sotitobire: Mọ̀lẹ́bí ọmọ ọdún kan tó pòórá ní ṣọ́ọ̀ṣì figbe ta
Mo wá sọ pé, “Ohun tí ẹ̀ ń ṣe kò dára.
Nítorí ẹnikẹ́ni tí ó bá bèèrè ni ó ń rí gbà; ẹnikẹ́ni tí ó bá ń wá nǹkan kiri ni ó ń rí i; ẹnikẹ́ni tí ó bá ń kanlẹ̀kùn ni à ń ṣí i sílẹ̀ fún.
Ayuba Wabba ni awon wa ki aare  fun, bi o
"Bawo lo se fẹ fun wa ni ohun ti iwọ gan ko ni, awa ọba Ekiti kii se Ajẹlẹ Alaafin nitori naa ayọnisọ rẹ si ọrọ abẹle lọbalọba Ekiti ko tọ"" Ìjọba Kano kò tẹ̀lé ìlànà tó tọ́ láti rọ̀ mí lóyè - Sanusi AMVCA7Award: Yewande Famakin lo gba àmì ẹ̀yẹ sinima èdè ibílẹ̀ Ronke Oshodi Oke ṣe àwo orin jáde fún MC Oluomo fún ọjọ́ ìbí rẹ̀ ""Inú ìbẹ̀rù bojo làwa ọmọ Nàíjíríà wà ní Italy, a kò leè jáde tàbí ra ọjà"" Alawẹ ni awọn ọba Ekiti wa n rọ Makinde lati fewe ọmọ mọ Alaafin leti, ko yee da si ọrọ ti ko kan, paapa lori ọrọ to wa nile ẹjọ."
Wọn yóo gba wúrà, aṣọ aláwọ̀ aró, aláwọ̀ elése àlùkò, aláwọ̀ pupa ati aṣọ ọ̀gbọ̀ tí ó ní ìlà tẹ́ẹ́rẹ́tẹ́ẹ́rẹ́.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Drug Trafficking: Ọmọ Yorùbá 16 ló wà nínú 23 tíjọba Saudi fẹ pa 25 Ògún 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images O kere tan ọmọ Naijiria mẹtalelogun lo wa lara awọn ti wọn fẹ pa lorilẹede Saudi Arabia bayii lori ẹsun pe wọn gbe oogun oloro wọ ilẹ naa.
Aarẹ ile Aṣofin Agba, Bukola Saraki lo ka igbese ile mejeeji naa jade, lẹyin ipade wọn.
Nínú igbó kìjikìji níbi tí àwọn igi ń wó sí
Ọwọ ijọba ipinlẹ Ọyọ tẹ awọn eeyan mẹjọ kan to sọ ile ẹkọ ijọba di ileeṣẹ bulọku ati ile igbe
Ó rán wọn létí pé, ìyekan wọn ni òun jẹ́.
Ọlọrun, o mọ ìwà òmùgọ̀ mi,àwọn àṣìṣe mi kò sì fara pamọ́ fún ọ.
O ni awọn alaisan ti wọn n nio wọn ko ri dokita ko tẹlẹ igbesẹ to yẹ nile iwosan ti w'ọn lọ ki wọn to le ri dokita ni.
Gbogbo àwọn oriṣa ni a óo dójú tì,ìdààmú yóo sì bá wọn.
Ilé ẹjọ́ fún Elzakzaky àti ìyàwó ní ẹ̀tọ́ sí ètò ìwòsàn El-Zakzaky: Arúfin ni ijọba Muhammadu Buhari gan-an - Ladoja Ẹ̀yin mùsùlùmí, ẹ yàgò fún ìwà ipá- Buhari Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Kílò fa èdè àìyedè láàrin ìjọba àti àwọn ọmọ lẹ́yìn El-Zakzaky?
Ifesewonse ohun lo je ogun ninu idije boolu alafesegba 2016/2017 torile-ede Naijiria (NPFL).
Seyi Makinde: Èmi kò yẹsẹ̀ kúrò nínú àdéhùn àjùmọ̀ṣe láti pín ipò
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Okùnrin SARS náà sọ pé òun máa pa èèyàn síbi ni- Aladugbo Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, SARS ti bẹ̀rẹ̀ ìgbésẹ̀ láti yọ àwọn ọ̀bàyéjẹ́ kúro Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Òkìkí ẹwà rẹ wá kàn ká gbogbo orílẹ̀-èdè; o dára nítorí pé èmi ni mo fún ọ ní ẹwà.
Ninu atẹjade gba ọwọ Akọwe ijọba ipinlẹ Osun,Wole Oyebamiji lo fi lede pe gomina Oyetola ri bi awọn eniyan ṣe tẹlẹ ofin isẹde naa lo jẹ ki o fa ọwọ rẹ sẹyin.
Nigba to n ki awọn alejo to peju sibi ayẹyẹ ọhun kaabọ, alaga ẹgbẹ Akọmọlede ati Asa nipinlẹ Eko, Zainab Ọlaide aya Ọlaitan mọ riri ipa takuntakun tijọba ipinlẹ Eko n ko si idagbasoke eto ẹkọ.
O ni ẹgbẹ oun, SDP, ko ni fi Ipinlẹ Osun silẹ fun awọn jẹgudujẹra.
Bakan naa ni wọn fikun un wi pe Ajọ awọn aladani CACOVID lo fun ijọba ni awọn eelo ounjẹ naa, Ki wọn le e pin fun araalu lati Ọjọ Kejilelogun, Oṣu Kẹsan, odun 2020, ko to di wi pe awọn eniyan ṣekọlu si agbegbe naa.
Angẹli OLUWA náà kò tún fara han Manoa ati iyawo rẹ̀ mọ́.
Gomina Bello Masari ṣalaye lasiko to ba aarẹ Buhari lalejo nileerẹ nilu Daura pe awọn ileeṣẹ alaabo ati ologun ti ri ibuba awọn janduku naa wọn si ti n gbe igbesẹ lori rẹ.
 ni odun 1936 ni oko eru sese di fifofin lu .
Gomina ipinle naa, Muhammed Abubakar ati awon osise ijoba, abenugan ile igbimo asofin ti ipinle ,Kawuwa Damina, akowe ijoba ipinle Mohammed Nadada ni won tewogba aare nigba ti o de si ipinle naa.
Tinubu gbe ọwọ Abiru soke laarun ọpọ eeyan ti wọn n dunnu lori bi Abiru ti jawe olubori.
Ninu ikede ti agbẹnusọ ẹgbẹ, Seye Oladejo, fi sita, wọn ba ẹbi ati ẹka ẹgbẹ naa nipinlẹ Oyo kẹdun.
Eyi ni wọn fi n mọ riri awọn eeyan ti ko ko ile aye le aya.
Èmi iranṣẹ rẹ yìí ti pa àwọn kinniun ati àwọn ẹranko beari rí, aláìkọlà Filistini yìí yóo sì dàbí ọ̀kan ninu wọn, nítorí pé, ó ti pe àwọn ọmọ ogun Ọlọrun alààyè níjà.
aisan fun iya, ọmọ, nitori naa ni ijoba fi gbe igbimo yii kalẹ” O wa fikun un  pe,
Ó dá wọn lóhùn pé, “Dídé ìjọba Ọlọrun kò ní àmì tí a óo máa fẹjú kí á tó ri pé ó dé tabi kò dé.
“Ẹni tí ó bá ní etí, kí ó gbọ́ ohun tí Ẹ̀mí ń bá àwọn ìjọ sọ.
Nítorí náà ẹ jẹ́wọ́ ẹ̀ṣẹ̀ yín fún OLUWA Ọlọrun àwọn baba yín, kí ẹ sì máa ṣe ìfẹ́ rẹ̀.
Seyi Makinde palẹ̀ ẹ̀gbin Ibadan mọ́ lóru mọ́jú, ó ṣèlérí ọ̀sẹ̀ mẹ́rin fún ìmọ́tòtó àyíká Oríṣun àwòrán, Seyi Makinde Owurọ kutu Ọjọ Iṣegun ni gomina ipinlẹ Oyo, Seyi Makinde ati ikọ rẹ gba igboro Ibadan lọ lati palẹ awọn idọti to dabi oke nilu Ibadan mọ.
 Omowe George Mavrotas to je olori IFPRI ni Naijiria ninu oro iside re gba pe Naijiria ti bere igbese ilosiwaju to ye fun idagbasoke oselu awa ara wa  lona to to.
Mo bá ranṣẹ pada sí wọn pé, mò ń ṣe iṣẹ́ pataki kan lọ́wọ́, kò ní jẹ́ kí n lè wá.
Ó sì ṣe ọgọrun-un (100) èso pomegiranate, ó so wọ́n mọ́ àwọn ẹ̀wọ̀n náà.
igbakeji aare ninu egbe APC ati iyawo rẹ Dolapo Osinbajo  ti dibo  wọn ni Victoria Garden City,nile idibo to wa ni Lekki, ni ipinle Eko.
Láti orí tabili Josẹfu ni wọ́n ti bu oúnjẹ fún olukuluku, ṣugbọn oúnjẹ ti Bẹnjamini tó ìlọ́po marun-un ti ẹnìkọ̀ọ̀kan wọn.
A o ranti pe Sẹnatọ Abiola Ajimobi dagbere faye ni ọsan Ọjọbọ nile iwosan kan nilu Eko lasiko to n se aisan ti wọn lo nii se pẹlu Coronavirus.
ldílé ọla Agbedegbede ní ilé oye Giesi ni wn ti bii, ó sì jẹ́ ọmọ Ọmọọba Aderopo àti Margaret Wuraola Ogunwusi.
”Dafidi dáhùn pé, “N óo kó wọn lé yín lọ́wọ́.
lule  ti awon eniyan si n subu le
Ọ̀nà ọ̀fun, kọ́ ni ọ̀nà ọ̀run t’èmi
Ẹlẹ́wọ̀n tẹ́lẹ̀ gboyè ìmọ̀ ìjìnlẹ̀ méjì lọ́gbà ẹ̀wọ̀n Ramil, omọ ogun ilẹ̀ ní Russia yìnbọn pa akẹgbẹ́ rẹ̀ mẹ́jọ!
Awọn ọba mẹrindinlogun lo si maa n wa ninu igbimọ Pelupelu ninu gbogbo ọba to wa l'Ekiti.
tabi fi awọn arinrinajo si ipamọ.
Eyi waye lẹyin ti awọn ọmọ Naijiria kan sọ oko eebu si Toyin lori ayelujara Twitter nitori bo sẹ polowo sinima rẹ, Fate of Alakada, lori Twitter lasiko ti iwọde #ENDSARS n gbona girigiri.
    Lọ́jọ́ tí mo ti dé inú ayé n ò gbádùn tó bí mmo ṣe gbádùn nínú ilé iwin yìí rí.
Bákan náà ni ó tún lọ sí ìsàlẹ̀ ní apá ìwọ̀ oòrùn títí dé agbègbè àwọn ará Jafileti, títí dé apá ìsàlẹ̀ Beti Horoni.
OLUWA tún sọ fún mi pé: “Lọ fẹ́ aya tí ń ṣe àgbèrè pada, kí o fẹ́ràn rẹ̀, bí mo ti fẹ́ràn Israẹli, bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé wọ́n yipada sí ọlọrun mìíràn, wọ́n sì fẹ́ràn láti máa jẹ àkàrà tí ó ní èso resini ninu.
O wa ro awon oludibo lati jade lo dibo won.
”Jesu ní, “O ti fi ẹnu ara rẹ sọ ọ́.
Àwọn ọmọ ogun tí a kà ninu wọn jẹ́ ẹgbaa mejidinlọgbọn ó lé egbeje (57,400).
Kwara: Dókítà 66 ló síṣẹ́ abẹ fún àwọn ìbejì tó lẹ̀pọ̀ ní ilé ìwòsàn fasiti Ilorin
Ọba Adesoji Aderemi, Ọọ̀ni Ifẹ̀ tó gba ipò ọba mọ́ tòṣèlú MKO Abiola, iṣẹ́ aṣẹ́gità ló fi bẹ̀rẹ̀ okoòwò Iṣọla Oyenusi rèé, ẹnití ìfẹ́ obìnrin ṣun dé ìwà ìdigunjalè Taiwo Akinkunmi, ọmọ Ibadan tó ya àsìá Naijiria Ninu atẹjiṣẹ ti alukoro ileesẹ ọlọpaa nipinlẹ Ọyọ, Olugbenga Fadeyi fi ṣọwọ si ikọ iroyin BBC Yoruba, o fi idi iṣẹlẹ naa mulẹ, bakan naa lo ṣe alaye wi pe eeyan mẹsan lo fi ara pa ninu iṣẹlẹ naa.
·Gẹgẹ bi ajọ NERC ṣe sọ, ileeṣẹ DisCos yoo le fi kun owo ina ti awọn ti ko ni mita n san ti: ·O ba jiroro pẹlu onibaara, to si sọ iye wakati ti wọn o fi ma a ni ina fun wọn ·O gbọdọ fun wọn ni mita ·Awọn ti ko ni mita ko gbọdọ ma a san ele owo to ju iye ti awọn to ni mita n san lọ ni agbegbe kan naa.
"Kelly gbà pé ""mo ti ṣe àwọn ǹkan tí kò da tó pọ̀ pàápàá lóri ọ̀rọ̀ obìnrin"" sùgbọ́n ""Mo tọrọ aforijin lásìkò àwọn ajọṣepọ̀ nígbà náà."
O ṣalaye pe lasiko yii, ọna ti oun n gba sọrọ lori awọn ilana ati eto ẹsin Kristiẹni ti kuro ni ti atako tabi sisọ ọrọ binu.
Ó ti wà pẹlu yín láti ogoji ọdún sẹ́yìn wá, ohunkohun kò sì jẹ yín níyà.
Alẹ Ọjọbọ ni ajọ to n gbogun ti itankalẹ ajakalẹ aarun ni Naijiria, NCDC, kede eyi lori ayelujara Twitter rẹ.
lọ sí ọ̀dọ̀ Hilikaya olórí alufaa, kí ó ṣírò iye owó tí àwọn alufaa tí wọ́n wà lẹ́nu ọ̀nà ti gbà lọ́wọ́ àwọn eniyan, 
Lẹ́yìn náà, ó pe ìbátan ọkọ Rutu yìí, ó ní, “Naomi tí ó ṣẹ̀ṣẹ̀ ti ilẹ̀ àwọn ará Moabu pada dé, fẹ́ ta ilẹ̀ kan tí ó jẹ́ ti Elimeleki ìbátan wa.
Aaye wa fun awọn ọmọ ilẹ Amerika lati wọle, ṣugbọn wọn yoo ṣayẹwo oju wọn.
Bí Hushpuppi ṣe tiraka rèé l‘Eko, kí ọlà ‘òjijì’ tó dé Àjọ NCDC kéde èsì àyẹ̀wò ènìyàn 575 tó tún ti ní ààrùn Coronavirus ní Nàìjíríà Magu lọ farahàn níwájú ìgbìmọ̀ tó ń ṣ'àyẹ̀wò EFCC, DSS kò mú un- EFCC Ọjọ́ Kẹrin oṣu Kẹ́jọ ni ìdánwò WAEC yóò bẹ̀rẹ̀ - Ìjọba àpapọ̀ Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 3 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 5 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
” Orí Peteru wú, ó bá bú sẹ́kún.
Bí wọn bá gbéra nílẹ̀, àwọn àgbá náà a gbéra nílẹ̀, nítorí pé ninu àwọn àgbá wọnyi ni ẹ̀mí àwọn ẹ̀dá alààyè náà wà.
BBCCopyright: BBC Atọkun n fọrọ wa Omoyele Sowore lẹnu woImage caption: Atọkun n fọrọ wa Omoyele Sowore lẹnu wo BBCCopyright: BBC Omoyele SoworeImage caption: Omoyele Sowore Article share tools Facebook Twitter ṢàpínlòView more share options Share this post Copy this linkKà síwájú síi nípa àwọn ìtọ́kasí wọ̀nyí.
Jẹ́ kí ó dára fún Sioni ninu ìdùnnú rẹ;tún odi Jerusalẹmu mọ.
"òun kò le è yọ́ wá - Lekan Balogun ""Òfo lásán ni ìgbésẹ̀ INEC tó fagilé gbẹ́ òṣèlú 74, torí àwa àti INEC ṣì ń jẹ́jọ́ lọ́wọ́"" Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Ọwọ́ tó bá dilẹ̀ ni èṣù ń bl ní iṣẹ́kíṣẹ́' Awọn akanda ẹda naa, ti wọn ni oniruuru ipenija ara, gbe ọpọ akọle lorisirisi lọwọ lati pe akiyesi ijọba si wahala ti wọn n koju latipasẹ fifi ofin de ọkada."
Ni bi ṣe n sọrọ yii gomina Sanwo-Olu ni ko si titẹle aṣẹ yii latọdọ ọlọkọ ero leyi to mu ki oun tilẹ paṣẹ fawọn agbofinro lati maa fi wọn jofin.
Liverpool fí ogun ẹ̀yìn ja Barcelona Yéèpà!
ni kaarẹ lati  tubọ maa gbogun ti aarun
Ọpọlọpọ eniyan ń wọ́ tẹ̀lé e lẹ́yìn láti ìlú dé ìlú.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Sogidi Lake: Kòṣẹja-kòṣèèyàn lá bá nínú adágún odò náà -Ojedele Idile Mobee ni Badagry: Ilu Badagry, taa tun mọ si Agbadarigi to wa nipinlẹ Eko, jẹ ilu to gbajumọ fun oko-owo ẹru laye ijọhun nitori bo ṣe sunmọ eti okun ti wọn n gba ko awọn ẹru sọda soke okun.
Wọn ni ninu bọndulu owo lọna mọkanlelọgọrin ni odiwọn ẹgbẹrun kan naira ati bọndulu mẹtadinlọgọrun ni ẹẹdẹgbẹta naira ati iye mẹrindinlọgọrun un to lẹe ni wọn ri nibẹ.
Boss ma n jẹ alagbara eniyan, amọ Actor lo ma n bori lẹyin idije naa nitori oninu ire ni.
O ni ki ẹni to ba ri alejo lati ilẹ okeere ti ko yẹ ko wa ni Naijiria tete fi to ileeṣẹ Immigration leti nitori aabo ati alaafia gbogbo olugbe Naijiria.
Olùsọdahoro yóo gbé ohun ìríra ka téńté orí pẹpẹ ní Jerusalẹmu.
Ìjọba Nàìjíríà ti ránsẹ pé àsoju ijọba ni South Africa láti dari wálé ShopRite Ibadan gbé ìlẹ̀kùn tìpa torí ìkọlù àwọn tó ń fẹ̀hónú hàn Ọlọ́pàá fi afẹ́fẹ́ tajú-tajú àti omi tú àwọn tó fẹ́ ṣun ilé ìtajà ShopRite l‘Abuja ká Àwọn èèyàn Gómìnà Yahaya Bello ló da ìbò abẹ́nú PDP rú- Ọlọgbọndiyan Wike kìí ṣe dọ́là tí Ganduje leè kó sápò- Agbẹ́nuso ìjọba ìpínlẹ Rivers Ọ̀pọ̀ èèyàn bẹnu ẹ̀tẹ́ lu Mercy Aigbe lórí bó ṣe ki Adeniyi Johnson Ko si ẹni to mọ pato ohun to ṣe okunfa iku wọn ṣugbọn awọn kan ni o ṣeeṣe ki wọn jẹ majele mọ ọunjẹ.
BBC gbadura pe ki Olorun tu ẹbi ti ọrọ kan naa ninu lasiko yii Wo ìgbésẹ̀ mẹ́ta tí Gómìnà Obiano gbé lórí ọ̀rọ̀ SARS ní Anambra Wo nọ́mbà tí o le è pè láti gba owó gbà-má-bínú tí ọlọ́pàá bá fìyà jẹ ọ́ lọ́nà àìtọ́ l'Eko Mo kọ̀ láti kópa nínú ìpàdé orí ayélujára Nàìjíríà yìí- Falz Ìjọba Nàìjíríà ti gbà láti san N30b owó àjẹmọ́nú fún ASUU Ẹ ṣọ́ra ní òpópónà AIT, ọkọ̀ agbépo kan ti yí dánù lọ́nà agbègbè Alagbado Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Gbajúgbajà òsèré tó tún mọ́ ọbẹ̀ sè Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Fídíò, End SARS, End SWAT: Ó pé mi bí SARS kò ṣe sọ mí dolówọ́- Fulani Kwajafa17 Ọ̀wàrà 2020 Fídíò, Soyinka Cancer: Àṣe ara mi ni iso ti n run gbogbo bí mo ṣe n ṣèrànwọ́ lórí jẹjẹrẹ27 Bélú 2019 US Elections 2020: Primate Ayodele ní òun ti sọ àsọtẹ́lẹ̀ pé Trump yóò fìdírẹmi, tí kò bá ṣọ́ra ṣe8 Bélú 2020 EndSWAT: Wo àwọn Májẹ̀kóbàjẹ́ tó wà nídìí ìwọ́de #EndSARS / End SWAT16 Ọ̀wàrà 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Bẹẹ ba gbagbe, eyi kii se igba akọkọ ti orilẹede Naijiria yoo gba owo ti Abacha ji ko pada lati ilẹ okeere.
kòkòrò-àrùn hepatitis c náà jẹ ́ àìlèfojúrí , tí ó ní èèpo , onífọ ́ nrán kan , fáírọ ́ ọ ̀ sì rna .
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Tinubu sọ̀kò òrò sí Obaseki lẹ́yìn tó yọ òrùlé ilé ìgbìmọ̀ aṣòfin ìpínlẹ̀ Edo 20 Òkùdu 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 8 Ògún 2020 Oríṣun àwòrán, @AsiwajuTinubu Adari gbogboogbo fun ẹgbẹ oṣelu APC, Bola Ahmed Tinubu ti sọko ọrọ si gomina ipinlẹ Edo, Godwin Obaseki lẹyin to paṣẹ ki wọn yọ orule Ile Igbimọ Aṣofin ipinlẹ naa.
Ó ń ki àbúrò bàá mi yìí ní oríkì ìran wọn ní mẹ́sǎn mẹ́wǎ.
ẹ gbọdọ lee pese ise fun awon eniyan , paapaa julo awon ọdọ.
O si ni alẹ ni ki a maa pade.
Amosun ni, lọdun 2011, isoro nla kan gboogi to n ba ipinlẹ Ogun finra ni aifararọ eto aabo, ipaniyan nitori oselu, ipani nipakupa lainidi to pọ nigba naa, eyi to mu kawọn ileesẹ nlanla dẹnu kọlẹ, ti ọrọ aje ipinlẹ Ogun si dorikodo.
Don Jr ni ọmọ Trump ẹlẹẹkeji ti esi Covid-19 rẹ yoo jẹ bẹẹni.
Si awọn to ro pe ọta ni emi atiẹ yoo jẹ titi lai, ki lero yin bayi?
"Oríṣun àwòrán, Others ""Mo n yonbo aburo mi, ọmọ mi, Amadou Gon Coulibaly, ẹni to ti jẹ alabasisẹ pọ mi fun ọgbọn ọdun gbako, ti mo si tun yin iranti akinkanju ọmọ ilẹ yii naa, fun atilẹyin tootọ rẹ, ifọkansin ati ifẹ si ilẹ baba rẹ."
Oríṣun àwòrán, Ajimobi Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Oríṣun àwòrán, PAstor Adeboye/twitter Àkọlé àwòrán, Alufaa Enoch Adeboye sọ pe awọn ọdọ ko ni le sọ asọtẹlẹ tabi riran, ti 'a ko ba jẹ ki wọn o wa laaye' Pásítọ̀ Enoch Adeboye darapọ̀ mọ̀ #ENDSARS, ó fún ìjọba Nàìjíríà ní ìmọ̀ràn ọ̀nà àbáyọ Ìjọ RCCG nàá darapọ̀ mọ́ #ENDSARS Ijọ The Redeemed Christian Church of God sọ pé bí àwọn ọlọ́pàá Nàìjíríà ṣe n tẹ ẹ́tọ́ ọmọnìyàn lójú kò dára.
Mo yan díẹ̀ lára àwọn iranṣẹ mi sí àwọn ẹnubodè náà, kí wọ́n má baà kó ẹrù kankan wọlé ní ọjọ́ ìsinmi.
Iṣoro ko ni si fun ọdọ mọ lọjọ iwaju Sowore dupe lọwọ awọn ọmọ Naijiria to gbaruku ti ẹgbẹ rẹ ti wọn fi ṣe ipo kẹta ninu ibo naa.
Eeyan mẹtalelogoji ni wọn fi ranṣẹ.
Eyi waye lẹyin ipade kan ti Ọbabinrin naa ṣe pẹlu tọkọ-taya naa, ati ẹgbọn Harry, Williams, lọjọ Aje.
Abi ṣe ti Oluwo ti Iwo, Ọba Abdurasheed Akanbi to sọ pe ki gbogbo aarun coronavirus to yẹ ko ṣe gbogbo ọmọ Naijiria, maa bọ lọdọ oun, ki baba tun to pahun da?
Agbejoro re so pe, esun ohun ija oloro ti awon olopaa ni won ba ni sakani re, ko si eridaju to fidire mule pe otito oro ni, leyin ti kosi aworan Kankan tio safihan awon ohun ija oloro yii ni sakani re.
Coronaviris in Nigeria: Ọmọ Nàìjíríà kan ẹni ọdún 67 tó kó àrùn COVID-19 ti di olóògbé Oríṣun àwòrán, Twitter/Federal Ministry of Health Ọmọ Naijiria kan ẹni ọdun mẹtadinlaadọrin ti jẹ Ọlọrun ni pe lẹyin to lugbadi arun corona virus.
Ọmọkùnrin tó pa ọmọ igbákejì Gómìnà Ondo gba ìdàjọ́ ikú Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Oluwakaponeski ní iṣẹ́ ọmọogun ilẹ̀ Amẹ́ríkà ni òun tẹ́lẹ̀ kí òun tó di aláwàdà Onimo naa ni elẹyi to gbomi lọkan awọn ọmọ Naijiria ni ki awọn oloselu tun ilu se, ki wọn si se ilu daadaa, ki iyipada le deba awọn ọmọ Naijiria.
Bí ó bá doríkọ ọ̀nà ìlú Beti Ṣemeṣi, a jẹ́ pé Ọlọrun àwọn ọmọ Israẹli ni ó kó gbogbo àjálù yìí bá wa.
Ajọ NDDC yii ni awọn Minsita ati olori wọn ṣi n jẹjọ lori inakuna owo ajọ naa lọwọ ni Abuja pẹlu sinima orita awoowotan loriṣiiriṣii.
- Madam Saje Ǹjẹ́ ewu wà nínú lílò ẹ̀rọ FaceApp?
Iṣu ló wà nínú mọ́tò mi, kìí ṣe èèyàn ni mo sọ di iṣu - Afurasí Ajínigbé figbe ta Wo ìdí tí àwọn obìnrin kan fi n yọ ilé ọmọ wọn kúrò Èyí ni ọ̀nà tí àwọn obìnrin n gbà kó ara wọn sí wàhálà nítorí ara bíbó Ṣé o ti gbọ́ ohun ti Ọọni Ifẹ́ àti Soyinka parí ọ̀rọ̀ Yorùbá sí?
31 Nítorí èmi Olúwa kò lè bojúwo ẹ̀ṣẹ̀ pẹ̀lú ìwọ̀n ìyọ́nú tí ó kéré jùlọ;
"Wọn pe akọle eyi ni ""See Gobe"", ti wọn si ṣe afihan rẹ ni inu oṣu kinni, ọdun 2017, eniyan mejilelogun lo kopa, ti wọn si fẹ gba miliọnu marundinlọgbọn Naira."
Ikú gbé òrònròó òun yèrèpè wọ agbárí mi lọ
Ṣaaju ni ọpọlọpọ ti fi ọkan sii pe ṣokoto yoo ṣo idi Mikel Arteta atawọn agbabọọlu rẹ lẹyin ifẹsẹwọnsẹ ọhun.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Fake money: Àgbà òṣèré sinimá ní ìfẹ́ owó, àti ṣekárími ló ń dá wàhálà sílẹ̀ láwùjọ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Fake money: Àgbà òṣèré sinimá ní ìfẹ́ owó, àti ṣekárími ló ń dá wàhálà sílẹ̀ láwùjọ 14 Ìgbé 2020 Inú ìbèrù bojo ni àn gbé báyìí- Awọn ènìyàn àdúgbo, Ogba, Agbado Ijaye àti Agege Ìrìnàjò Toyin Abraham, láti orí gbèsè jíjẹ, ó di onílé, onimọto àti aya lọ́ọ̀dẹ̀ ọkọ Òfìfo ṣọ́ọ̀ṣì pa aṣọ dà fún àwọn Páṣítọ̀ Nàìjíríà Baba Latin ṣe bẹbẹ lori èto Se o láya, sùgbọ́n.
" Ọlọ́run ló kọọ pé àwọn ọmọ mi yóò ṣiṣẹ tíátà, èmi kọ lo kàn-án nípa fún wọn - Ọga Bello Àwọn tó jí kọmíṣọ́nnà gbé l'Ekiti ń bèèrè fún N30 mílìọnù kí wọ́n tó le è tú u sílẹ̀ Mo ṣetán láti ta ilé tí mo ń gbé, kí n le rí àwọn ìbejì mi padà - Akeugbagold Olórí ẹ̀ṣọ́ Adarí ẹgbẹ́ òṣèlú APC, Bola Ahmed Tinubu ti kú lẹ́yìn tó lùgbàdì àrùn Coronavirus Nígbà tó ń ṣàlàyé lórí bí ẹ̀ka aladani àti àwọn ileeṣẹ ṣe leè kopa nìdí gbingbin èwe ọlá náà torí owó pupọ tó wá nídìí rẹ, Akeredolu ni àwọn gbọdọ gba àṣẹ na, láti rí dájú pé wọn kò loo nílò kulo.
Gbogbo ohun alààyè tí ń rìn ni yóo jẹ́ oúnjẹ fún yín, bí mo ti fún yín ní gbogbo ewéko, bẹ́ẹ̀ náà ni mo fún yín ní ohun gbogbo.
Ọjọ kejilelogun oṣu kẹfa ọdun 2020 ni awọn eekan ninu ẹgbẹ oṣelu PDP, ṣe ayẹyẹ kaabọ ọmọ ọdọ rere fun igbakeji gomina ọhun.
Oríṣun àwòrán, @Lagos Àkọlé àwòrán, Ẹyọ jẹ ọdun kan pataki ni ipinlẹ Eko nibi ti awọn ọmọ isalẹ Eko ti maa n fidunnu wọn si alaṣọ aala funfun gbooo kanlẹ.
Supreme Court: Atiku ní ìdájọ́ ilé ẹjọ́ tó dá Buhari láre kò b'òun nínú jẹ́
N óo sọ òkè Seiri di aṣálẹ̀ ati ahoro.
“OLUWA àwọn ọmọ ogun, Ọlọrun Israẹli ní, ‘N óo mú kí ibi tí mo ti kéde rẹ̀ dé bá ìlú yìí ati àwọn ìlú tí wọn yí i ká, nítorí wọ́n ti ṣe oríkunkun, wọn kò sì gbọ́ ọ̀rọ̀ mi.
El-Zakzaky: Ọ̀pọ̀ ẹ̀sùn aṣemáṣe ni ìjọba àpapọ̀ fi kan Zakzaky ní India
Ọkà baali ni wọ́n gbìn, ṣugbọn ẹ̀gún ni wọ́n kórè.
Orílẹ̀-èdè yín ti di ahoro,wọ́n ti dáná sun àwọn ìlú yín.
Ṣugbọn ẹlẹsẹ ayo Odion Ighalo dayo naa pada ni abala keji ere bọọlu ọhun.
Ijọba sọ pe ohun yoo na owo to ba jade lati ibẹ sori ẹka eto ẹkọ ati ilera.
ati sí Afia, arabinrin wa ati sí Akipu: ọmọ-ogun ẹlẹgbẹ́ wa fún Kristi, ati sí ìjọ tí ó wà ninu ilé rẹ̀.
Oruko awon to je alaisi meta pere ni won ti kede pe: Saffie Rose Roussos, to je omo odun mejo; Georgina Callande ati John Atkinson.
Pẹlu ìmísí Ọlọrun ni ọba fi ń sọ̀rọ̀,ìdájọ́ aiṣododo kò gbọdọ̀ ti ẹnu rẹ̀ jáde.
Enyimba, Akwa United gunlẹ fun idije ife ẹyẹ CAF
- Ijebu Iléèwé míràn tún dàwó ní ìpínlẹ̀ Eko Saaju ni oṣu yii ni pasitọ kan ti kọkọ pa iyawo rẹ ni America Àlàyé rèé láti ẹ́nu mọ̀lẹ́bí ìyàwó Pásítọ̀ Sylvester Ofori ọmọ Ghana tó yìnbọn pá aya rẹ̀ l'Amẹrika Mọlẹbi Barbara Tommey, iyawo Pasitọ ilẹ Ghana ti wọn fura si pe ọkọ rẹ Sylvester Ofori lo yinbọn lu laimọye igba ti mẹnu ba idi ti o fi ṣeku pa.
Ilúmọ̀ọ̀ká gbajumọ tó n ta àsara lóge Idris Olarewaju Okuneye ti gbogbo eniyan mọ sí Bobrisky tí fi ara rẹ̀ han bí ọkunrin.
N óo sì fún ọ ní ipò láàrin àwọn tí wọ́n dúró wọnyi.
Oríṣun àwòrán, others Àkọlé àwòrán, Ta ni Morsi?
Oríṣun àwòrán, Twitter/Serena Williams Àkọlé àwòrán, Serena ti jáwé olúborí lẹ́ẹ̀rìn ọ̀tọ̀ọ̀tọ́ nínú ìdíje Italian Open Ní oṣù kẹta ni Serena pada sori papa, ni idije tẹniisi to wáyé ni Indian Wells ati Miami, léyìn tó bímọ.
yoo tẹ awon to padanu ẹmi won  si afẹfẹ
Oríṣun àwòrán, AFP Àkọlé àwòrán, Tom Kajwang ti wa ni ihamo ijoba leyin iburafuni yii Wẹrẹ ti Minista yi fọrọ yi lede ni wọn fi panpẹ ọba mu asofin fun ẹgbẹ alatako, MP Tom Kajwang ti o ko'pa to pọju ninu ayẹyẹ to fi Raila Odinga jẹ Aarẹ awọn eniyan""."
Lorii bi Boko Haram ṣe n pariwo pe awọn lawọn ji wọn gbe, Jibrin ni irọ ni, wọn kan n wa ọna ati gbajumọ sii ni.
Oun ni Oludasilẹ ileewe Hassan Ibrahim Gwarzo ni ilu Kano.
Àwọn tí wọ́n dìtẹ̀ yìí ju bí ogoji lọ.
Ọpọlọpọ iroyin lo ṣi n ja ranyin nilẹ lori ọpa aṣẹ ọba ilu Eko, Ọba Rilwan lẹyin ti awọn janduku ṣekọlu si aafin rẹ, ti wọn si gbe ọpa aṣẹ rẹ lọ.
Ọmọ Yorùbá mẹ́wàá tó jẹ́ àmúlùúdùn ní Amẹ́ríkà àti Yúróòpù O ti lé ní ènìyàn mẹ́wàá tí ina jó gúrúgúrú nínú ìjàmbá tó wáyé ní Delta Aminat jẹ iyawo ile ẹni ọdun mọkanlelọgbọn ti o gba ẹha lọdọ ọkọ rẹ ninu ẹsin Islam lai kabamọ O ṣalaye bi oun ṣe lọ kọṣe ọwọ bata ṣiṣe ati irufẹ atilẹyin ti ọkọ rẹ fun un lasiko naa.
Nítorí n kò dánu dúró láti sọ gbogbo ohun tí Ọlọrun fẹ́ fun yín.
Hadadi, Tema, Jeturi, Nafiṣi ati Kedema.
Bakan naa ni Ogbeni Adegboyega Adefarati to je komisona fun eto ogbin nipinle Ondo soro lori awon eso ti won se lona igbalode to maa n tete so eso koko ati kasuu tijoba n sise le lori bayii fun idagbasoke eto ogbin.
Bí o bá fẹ́ darapọ̀ mọ́ ikọ̀ ọlọ́pàá SWAT tí yóò rọ́pò SARS, wo àmúyẹ tí o gbọ́dọ̀ ní Wo ohun tí ìwọ́de ENDSARS ṣé fáwọn akẹ́kọ̀ọ́ tó fẹ́ ṣèdánwò NECO Láàrin wákàtí mẹ́ta, wọ́n dá ₦4m fún àkàndá ẹ̀dá tó kópa nínú ìwọ́de Aisha Buhari polongo àwo orin tó ní Nàíjíríà ń ṣun ẹ̀jẹ̀ lásìkò ìwọ́de Obaseki ni ẹtọ ijọba ni lati bojuto ẹmi ati dukia awọn eniyan nipinlẹ Edo, nitori naa ẹnikẹni ti wọn ba gbamu to tapa si ofin isede naa yoo foju wina ijọba.
Gẹgẹ bi ohun ti Segun sọ ninu fọnran fidio kan o ni ''bayi ti ohun ti ni ẹni ti yoo ṣe onigbọwọ ẹkọ ọfẹ fun oun ni ile iwe giga ni oun ko wa rọwọ mu ninu idanwo naa.
Bí ẹnikẹ́ni bá fẹ́ máa jiyàn lórí ọ̀rọ̀ yìí, kí ẹ mọ̀ pé ní tiwa, a kò ní oríṣìí àṣà mìíràn, bẹ́ẹ̀ ni kò sí ninu àwọn ìjọ Ọlọrun.
Àkọlé àwòrán, Oriṣiriṣi ọna ni eto igbani wọle maa n gba ninu awọn ẹgbẹ okunkun Iwadii kan ti BBC ṣe fihan pe, orin kikọ, ijo, ọti mimu, fifi nkan bo oju awọn to ṣẹṣẹ fẹ ẹ darapọ, tabi lilu wọn ni alubami, lo maa n waye lasiko ajọdun naa.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Kété tí wọ́n bá ti báa yín sùn tàn torí pé ẹ tóbi, ẹ gbà pé ìfẹ́ yẹn ti parí - Auntie Remi Ọlọ́yàn ńlá Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
marc fleurbaey jẹ niwon ọdun 2011 oludaniloju oro-oro aje ati ile-iwe agbegbe robert e.
Wọ́n bá tún rán oníṣẹ́ mìíràn lọ láti bèèrè ìbéèrè kan náà lọ́wọ́ Jehu.
Mose ni ó jẹ́ oníwà ìrẹ̀lẹ̀ jù ninu gbogbo ẹni tí ó wà láyé.
Ẹ̀yin olólùfẹ́ mi àti ẹbí ni mo bẹ̀ Ọlọ́pàá kò rí ǹkankan lábẹ́ pẹpẹ ilé ìjọsìn mi - Olùṣọ́àgùntàn Akure Liverpool ṣubú dàánù ní Napoli Tani yóò gba ife ẹ̀yẹ UEFA Champions League ti saa yi?
Nígbà tó yá, kò sì owó fún mi láti jẹun, mo wa lọ gbé ní orílẹ̀ èdè Saudi Arabia fún ọdún mẹ́tàlá.
”Awon odo ti ojo ori  won ko ju mẹ́tàlélọ́gbọ̀n  si ogójì lọ, ti won tun n ba aare se ise papo ninu ijoba re ,lo wa nibi ayeye naa.
Ó kú ikú àìtọ́jọ́ lóri pápá níbi to ti n gba bọ́ọ̀lù níwáju àwọn èrò ìwòràn tó lé ni ọgọ́rùn lọ́nà ogun ní pápá ìṣeré National Stadium, ní ìlú Eko.
Data Usage: Ọ̀nà márún-ún láti mú àdínkù bá dátà fóònù lílò
"Wike kìí ṣe dọ́là tí Ganduje leè kó sápò- Agbẹ́nuso ìjọba ìpínlẹ Rivers Àwọn òṣèré tíátà kan rèé, tí wọn fẹ́ ara wọn, tí ìgbeyàwó wọn sì pẹ́ ""Bàbá mi kú, kò sówó ni mo ṣe kúrò ní fásitì Ilorin láti fọ gíláàsì ọkọ̀ lójú pópó"" Ẹfunsetan Aniwura, obìnrin tó ju ọkùnrin lọ Àwọn ọmọ Naijiria kóju ija sí àwọn South Africa wọ́n ní ""Ó tó gẹ́"" Ìjọba South Africa pèpàdé lórí ìkórìíra àlejò Àwọn òṣèré tíátà kan rèé, tí wọn fẹ́ ara wọn, tí ìgbeyàwó wọn sì pẹ́ N kò lóyún, bẹ́ẹ̀ ni ń kò ní ọkọ, ẹ fi mí lọ́rùn sílẹ̀ - Dayo Amusa ""Bàbá mi kú, kò sówó ni mo ṣe kúrò ní fásitì Ilorin láti fọ gíláàsì ọkọ̀ lójú pópó"" Lai Mohammed ni awọn ọmọ Naijiria ni oludokowo lawọn ileeṣẹ orilẹede South Africa, nitorinaa fifi ọwọ ara ẹni ṣera ẹni ni kawọn ọmọ Nigeria maa ba iru awọn ileeṣẹ bẹẹ jẹ."
Akọwe ẹka ikẹkọọ ninu ẹgbẹ naa, Abdullahi Mohammed Musa, sọ fun akọroyin BBC, Onyinye Chime, pe ara ohun ti yoo waye nibi ifẹhonuhan naa ni gbigbe aworan awọn ọmọ ẹgbẹ ti awọn ọmọ ogun Naijiria pa, kaakiri gẹgẹ bi ẹri, nitori ileeṣẹ ogun sọ pe mẹta pere l'awọn pa.
Ọpọlọpọ àwọn àgbàlagbà àti àwọn ọdọ ni wọn tú jáde ní witiwiti láti fi ìfẹ́ hàn sí idasile eto Amotekun tí ìjọba káàkiri ilé Yoruba gbé kalẹ.
Ilé ìjọsìn lè bẹ̀rẹ̀ ìsìn àárín ọ̀sẹ̀ padà, Mọ́sáláṣí àti Ṣọ́ọ̀ṣì lé gba iye èèyàn tó wù wọ́n ṣùgbọ́n.
Ajo isokan agbaye so pe ipa
Nígbà tí ilẹ̀ mọ́, àwọn adájọ́ rán àwọn iranṣẹ sí ẹni tí ń ṣọ́ ilé ẹ̀wọ̀n pé, kí ó dá àwọn eniyan náà sílẹ̀.
9 Kíyèsíi, lõtọ́ ni mo wí fún ọ, mo ti fi àwọn ohun wọ̃nnì pamọ́ èyítí mo ti fà fún ọ, ìránṣẹ́ mi Joseph, fún ìdí tí ó jẹ́ ọgbọ́n nínú mi, a ó sì fi í hàn fún àwọn ìran ọjọ́ iwájú.
Ṣé ẹ rántí orin - 'Má ṣe jẹ́jẹ́ ma wà mi lọ'?
Oríṣun àwòrán, @go4esther Agbaje to kawe gbowe ninu ẹkọ imọ ofin lati fasiti Harvad jẹ ọkan pataki lara awọn ọmọ Naijiria mẹsan an to n kopa ninu eto idibo ọhun.
Olu ilu orilẹede Naijiria, Abuja lo ṣe ipo keji pẹlu eeyan mẹfa, nigba ti ipinlẹ Ogun tẹ le e nibi ti eeyan mẹrin ti fara kaasa aarun naa.
"Onimọ isegun nipa ajakalẹ arun labẹ ajọ WHO, Maria Van Kerkhove, naa sọ nibi ipade awọn akọroyin naa pe, ""a nilo lati fi sọkan pe, yoo gba akoko diẹ ka to bọ lọwọ ajakalẹ arun Covid-19 ọhun."
”Oludije mewa ninu egbe oselu lorisirisi
Olusọaguntan ni pẹlu, ó jẹ olukọ ati onisesẹ Aposteli.
Ọlọrun wa wà ní ọ̀run,ó ń ṣe ohun tí ó wù ú.
Ọmọ bibi ilu Abeokuta ni Efunsetan pẹlu, oko-owo si lo gbe de ilu Ibadan nibi to ti gbọrẹgẹ-jigẹ ninu owo ẹrú ṣíṣe, to si di ara awọn alagbara to n dari ilu Ibadan.
Olúbádámọran lórí ètò ààbò Babangida Munguno ló sísọ lójú ọ̀rọ̀ náà lẹ́yìn ìpàdé àwọn aláṣẹ ìjọba, èyí ti adele ààrẹ ọjọ̀gbọ́n Yemi Osinbanjo ní ile ààrẹ l'Abuja lónìí.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù FRSC: Awakọ̀ tó bá tàpá sófin ojú pópó yóò ṣọdún lẹ́wọ̀n 15 Ọ̀pẹ̀̀ 2018 Oríṣun àwòrán, Twitter/FRSC Nigeria Àkọlé àwòrán, Ọrọ ofon oju popo Bi pọpọṣinṣin ọdun Keresi ati ọdun tuntun ti n kanlẹkun, ajọ to n risi aabo loju popo(FRSC) ti kede pe ile-ẹjọ alagbeka fawọn to ba tako ofin oju popo yoo bẹrẹ lọjọ Aje.
 Always ready to serve in any capacity💪 pic.
Canada sọ igbó mímu àti títà rẹ̀ di ìrọ̀rùn Akeredolu fidirẹmi lori ibo rẹ nileẹjọ Eto naa bẹrẹ lọjọ aje ọsẹ yii eyi to da lori ọna ti a le gbe gbin, gba iwe aṣẹ ati kikore igbo.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Akeredolu, Okowa, àtàwọn gómìnà Nàìjíríà míì tó ti kó àrùn Coronavirus 1 Agẹmo 2020 Oríṣun àwòrán, Twitter Gomina ipinlẹ Delta, Ọmọwe Ifeanyi Arthur Okowa ti di gomina to wa loju ọpọn lọwọlọwọ lara awọn to ṣẹṣẹ lugbadi arun Coronavirus.
Gẹ́gẹ́ bi ìṣe rẹ̀ aya ààrẹ gbá ojú òpó twitter rẹ̀ lọ láti pa òhun pọ pẹ̀lú àwan ọmọ égbẹ òṣèlú APC tó kù láti tako Festus Adedayo pé kò ṣesṣe ki ènìyàn maa tèlé ìjọba ti kò ni ìgbàgbọ ninu rẹ̀.
Nígbà tí àwọn ọ̀tá mi pẹ̀yìndà,wọ́n ṣubú, wọ́n sì parun níwájú rẹ.
Link Àjọ NCDC kéde èèyàn 184 míràn tó ni ààrùn Covid-19 lórílẹ̀-èdè Naijíríà Coronavirus: Ǹjẹ́ àwọn dókítà tó ń tọ́jú eyín ń ṣisẹ́ lásìkò pàjáwìrì?
Ìpínlẹ̀ méjìlá nínú ewu àgbárá òjò ní Nàìjíríà Àwọn olùdíje Ọṣun jẹ́wọ́ ara wọ́n Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Osun Decides: Adegoke ni òun kò ni lo kọngilá n Kẹmi Adeọṣun kọwe fipo rẹ silẹ Mínísítà tẹ́lẹ̀rí kòwé fipò sílẹ̀ lọ́jọ Etì lẹ̀yìn tó gbà pé ayédèrú ní ìwé ẹ̀rí àgùnbánirọ̀ ti òun ní.
Ni Jesu bá pè wọ́n, ó wí fún wọn pé, “Ẹ mọ̀ pé àwọn aláṣẹ láàrin àwọn alaigbagbọ a máa jẹ ọlá lórí wọn, àwọn eniyan ńláńlá ninu wọn a sì máa lo agbára lórí wọn, 
Wada yoo ta kaungbọn pẹlu Gomina Yahaya Bello to jẹ ọmọ ẹgbẹ APC atawọn oludigbe ẹgbẹ oṣelu miiran ninu ibo ọhun.
Ronke Odusanya sọ̀rọ̀ lórí ìròyìn tó ní ó ti jẹ bàbá ọmọ rẹ̀, Jago run
Ọwọ́ ọlọ́pàá tẹ afurasí ọkùnrin tó gé akẹ́kọ̀ọ́ ọ̀rẹ́bìnrin rẹ̀ wẹ́lẹ́ wẹ́lẹ́ fún òògùn owó ní Ikorodu Èèmọ̀!
Àwọn ará Filistia tí wọn ìbá pa ìbá ti pọ̀ ju èyí lọ.
Tọkọ taya kú lọ́jọ́ kan náà l'Abeokuta lẹ́yìn ìgbéyàwó ọdún méjìléláàdọ́rin 72 US Election 2020: Ṣé èsì ìdìbò Ààrẹ Amẹrika yóò jáde lálẹ́ ọjọ́ ìdìbò?
Lọjọ Aje ni Saudi kede pe eeyan kan to jẹ ọmọ Saudi ni ẹni akọkọ ti yoo ko aisan naa.
Nisinsinyii n óo sọ ohun tí n óo ṣe sí ọgbà àjàrà mi fun yín.
Wọ́n yọ 'aṣofin olóorun' nílé aṣòfin Èkìtì Alaga naa lo ijọba ibilẹ rẹ Ise/Ọrun gẹgẹ bi apẹẹrẹ.
Bí o bá ń gbadura ọpẹ́ ní ọkàn rẹ, bí ẹnìkan bá wà níbẹ̀ tí ó ṣẹ̀ṣẹ̀ ń kọ́ nǹkan nípa igbagbọ, báwo ni yóo ṣe lè ṣe “Amin” sí adura ọpẹ́ tí ò ń gbà nígbà tí kò mọ ohun tí ò ń sọ?
Belgium Wọn gbe ere King Leopold II kuro Awọn alaṣẹ Antwerp gbe ere Ọba orilẹede Belgium tẹlẹ lasiko ijọba amunisin, Leopold II kuro lẹyin ti awọn oluwọde dana sun un lati fi ẹhonu han lori iṣejọba amunisin.
Wọn yóo di ibùgbé fún àwọn ọ̀fàfà ati ẹyẹ ògòǹgò,
Gbogbo wọn ń gbọ̀n nítorí ọ̀rọ̀ tí wọ́n pè wọ́n fún ati nítorí òjò tí ń rọ̀.
Áí ma le e sun deedee ati ai ki n sun fun odiwọn wakati to pọ to lo maa n fa iru igbagbe bayi.
Àwọn ìjọba ìbílẹ̀ méjìdínlógún yìí kò tíì lè bọ́ lọ́wọ́ ìséde - Ìjọba àpapọ̀ Oríṣun àwòrán, @BAshirAhmad Saaju la ti mu iroyin wa fun yin pe ijọba apapọ ti ni o ṣee ṣe ki oun ṣi gbe ofin isede le awọn ijọba ibilẹ mejidinlogun kan ni Naijiria.
Ìdájọ́ Ọlọrun lórí Àwọn Orílẹ̀-Èdè tí Ó yí Israẹli ká Siria.
Àwọn akọrin ati àwọn afunfèrè ati àwọn tí ń jó yóo máa sọ pé,“Ìwọ, Sioni, ni orísun gbogbo ire wa.
Jeremaya dáhùn pé, “Wọn kò ní fà ọ́ lé wọn lọ́wọ́.
Bakan naa lo ni iwadii ti ijọba ṣe ti fihan pe, ibọn tabi gaasi tajutaju ko ba ikankan lara awọn janduku naa.
Ìlà mẹta mẹta ni wọ́n to fèrèsé sí, àwọn fèrèsé ilé náà kọjú sí ara wọn ní àgbékà mẹta.
Ẹ ní ọkàn kan náà láàrin ara yín.
Ado Bayero: Èyí ni àwọn ohun tó yẹ kí o mọ̀ nípa Emir ìlú Kano tuntun
Níbẹ̀, ninu pápá oko tí ó dára ni wọn óo dùbúlẹ̀ sí; ninu pápá oko tútù, wọn yóo sì máa jẹ lórí àwọn òkè Israẹli.
"oríkì tún lè jẹ ́ ẹlẹ ́ yọ ọ ̀ rọ ̀ bì i "" Àdúnní "" tàbí kí ó jẹ ́ ẹṣẹ ̀ ìwé tàbí jáǹtìrẹrẹ."
Bakan naa si ni ọmọ sori lawọn adugbo miran ti ijadugu ti maa n waye nilu Ibadan.
  O wa gbadura pe ki Olorun tẹ oku awon ti won ku inu isẹlẹ naa si
Bakan naa ni ọgbẹni Ogundokun ni wọn maa n kọ awọn akẹkọọ ni ẹkọ ile, ati wi pe igbakigba ti awọn akẹkọọ ba wale, iyatọ maa n wa laarin wọn ati awon omo ti ko gbe ile iwe.
Ile ẹjọ tun pa a lașẹ pe oniduro naa gbọdọ ni ilẹ ni ayika ibi ti ile ẹjọ Majisisreeti ohun wa pẹlu ki wọn to le gba oniduro fun.
“gbogbo rukerudo, ipaniyan lotun-losi ni paapaa julo ni ipinle Benue, eyi toka si iwa ibaje awon ota ti ko fe ki alaafia ati isokan joba, ti won si n gbero lati so orile-ede yii sinu iporuru okan: ki egbon maa gbemi egbon, kii alabaagbepo ki o ma gbemi ara won, kii agbegbe kan ki o ma gbemi ara ilu miiran, eyi je ohun ti o buru jai,”Aare ro gbogbo omo orile-ede yii lati se gafara fun oniruuru igbimo ti o ba n wa isubu orile-ede yii.
ohun tó máa ń tètè hàn sí ènìyàn tó bá fẹ ́ tú ìfun àti ẹ ̀ dọ ̀ iṣẹ ́ kan wò ni ohun tó jẹ etí lógún .
O buru to bẹẹ ni opin ọsẹ ni awọn ipinlẹ bii Nasarawa ati Niger nitori iyanṣẹlodi naa bẹrẹ ni Ọjọ Ẹti,ọsẹ to kọja.
Kí ni ìbá pa onigbagbọ ati alaigbagbọ pọ̀?
aya igbaeji aare , iyaafin Osinbajo “fun
A máa pète ìkà lórí ibùsùn rẹ̀;a máa rin ọ̀nà tí kò tọ́;kò sì kórìíra ibi.
Ará Dani ni ìyá rẹ̀, ṣugbọn ará Tire ni baba rẹ̀.
Iye àwọn ọmọ-ẹ̀yìn Jesu túbọ̀ ń pọ̀ sí i ní Jerusalẹmu.
Ta ló fi ìdí gbogbo òpin ayé múlẹ̀?
Ẹ̀yin ará, ẹ̀yin kò sí ninu òkùnkùn ní tiyín, tí ọjọ́ náà yóo fi dé ba yín bí ìgbà tí olè bá dé.
Èṣù tún mú un lọ sí Jerusalẹmu.
"Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ará Eko, ẹ pariwo ó tó gẹ́ẹ́ lórí làásìgbò tó gbòde torí ìwọ́de EndSARS - Sanwo-Olu Ọ̀tá Yorùbá ló lo ìwọ́de láti dojú ogun kọ wá - OPC ""Àwọn ọ̀tá Nàíjíríà tó fẹ́ dojú ìjọba bolẹ̀ ló wà lẹ́yìn ìwọ́de EndSARS"" Ó parí ni ohùn tó gbẹnu ọ̀pọ̀ ọmọ Nàíjíríà lẹ́yìn ọ̀rọ̀ Buhari Ìwọ́de EndSARS kìí ṣe ọ̀rọ̀ ẹlẹ́yàmẹ̀yà, ara ti kan àwọn èèyàn ni - Afenifere Buhari kọ́ ni ìṣòro wa, bó ṣe wà láti láéláé rèé - Fr Mbaka Àwọn ọ̀dọ́ fi ọ̀nà àrífín pe Tinubu lórí aago àmọ́ ó ní òun kò mọwọ́-mẹsẹ̀ nípa ìpànìyàn Lekki Á ràgà bo CCTV Lekki bí i ẹ̀rí tó dájú fún ìwádìí ìpànìyàn - Sanwo-Olu SERAP gbé ìjọba àpapọ̀ lọ ilé ẹjọ́ àgbáyé ICC lọrí ẹ̀sùn ìpànìyàn O ni kawọn oloselu kesi awọ̀n ọmọ wọn lati maa lọ soju Naijiria ninu ifẹsẹwọnsẹ Super Eagles to n bọ Kii ṣe Ogu nikan ni ọmọ Naijiria to jẹ agbabọọlu to bu ẹnu atẹ lu ọwọ ti ijọba fi mu iwọde naa, paapaa lẹyin ifẹmiṣofo to waye ni Lekki."
 bí ó tilẹ ̀ jẹ ́ pé a ti sọ kòkòrò náà di aláìlágbára , ó ṣì wà láàyè .
“Ẹ fetí sí mi, ẹ̀yin aláìgbọràn, ẹ̀yin tí ẹ jìnnà sí ìgbàlà.
Ó rí i pé kò sí ẹnìkan tí yóo ṣe onílàjà, ẹnu sì yà á, pé kò sí ẹnìkankan.
Asoju orile ede Korea fun orile ede Naijiria ajagun
Oludari eka to n mojuto ikede
(Bàbá-ń- sìnkúni ẹni tí ń darí gbogbo òpò àti wàhálà ìsìnkú ní ilẹ̀ Yorùbá.
Mo gbọ́ pé ò ń gé irun àwọn aguntan rẹ, mo sì fẹ́ kí o mọ̀ pé àwọn olùṣọ́ aguntan rẹ wà lọ́dọ̀ wa fún ìgbà pípẹ́, n kò sì ṣe wọ́n ní ibi kankan.
Ajọ SERAP fi iwe ipẹjọ ṣọwọ si oludari igbimọ igbẹjọ nile ẹjọ ọhun, arabinrin Fatou Bensouda, lati lo ofiisi rẹ fi ṣe iwadii idi abajọ ti ọgọrọ ọmọde ko ṣe lanfani lati lọ sile ẹkọ.
Ni opin ọsẹ ni iroyin gbe e gbe awọn okunrin mẹrin kan fi ipa ba ọmọbinrin lọpọ ni ibi to ti n kawe ni ile ijọsin, ti wọn si ṣekupa a.
Ṣugbọn ẹni tí ó gbọ́ ọ̀rọ̀ mi, tí kò ṣe é, ó dàbí ọkunrin kan tí ó ń kọ́ ilé kalẹ̀ láì ní ìpìlẹ̀.
Amọ awọn ero mejeeji naa lo ni ewu ninu.
Àwọn Heberu ń jáde bọ̀ wá láti inú ihò òkúta tí wọ́n farapamọ́ sí.
“Ẹ ké pè mí, n óo sì da yín lóhùn; n óo sọ nǹkan ìjìnlẹ̀ ati ìyanu ńlá, tí ẹ kò mọ̀ tẹ́lẹ̀ fun yín.
naa, kii won si fi oju won jofin.
Fola - BBC News Yorùbá BBC News, YorùbáFò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Polio eradication in nigeria: Orísúnmibáre ni àìsàn 'Polio' tó kọlù mí ní kékeré - Fola 25 Ògún 2020 Oríṣun àwòrán, folajogun akinlami Oni, ọjọ kẹẹdọgbọn, oṣu Kẹjọ, ọdun 2020, ni ajọ eto ilera ni agbaye, World Health Organization, kede pe Naijiria ti bọ patapata lọwọ aisan rọmọ lapa-lẹsẹ, polio.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Risikat Azeez: Aya gómìnà tún fẹ́ gba sọ́ọ́bù, ra ọjà fún obìnrin olójú búlúù 20 Ògún 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 8 Owewe 2020 Oríṣun àwòrán, @Mohammed Jagunma ati Gold Abdulrafiu Ojo oriire si n rọ siwaju fun idile Risikat Oloju Buluu ati ọkọ rẹ, Abdulwasiu pẹlu awọn ọmọ wọn.
Ohun ti igbimọ naa sọ fun Fayẹmi ni pe, gbese ti a n sọrọ rẹ yii ko mọ owo oṣu ti ijọba jẹ awọn oṣisẹ ati oṣiṣẹ fẹyinti atawọn owo to yẹ ni sisan fawọn Agbasẹṣe to n ṣiṣẹ fun ijọba nibẹ.
Iheanacho ati Ajayi wa lara awọn agbabọọlu mẹẹdọgbọn ti akọnimọọgba Super Eagles, Gernot Rohr kọkọ f'orukọ wọn sita, ṣugbọn o yọ wọn kuro ninu ikọ agbabọọlu ti yoo ṣoju Naijiria lorilẹ-ede Egypt.
Nítorí náà ó dáàbò bò ó.
Wo ohun tí Adájọ́ sọ nípa ìgbẹ́jọ́ Wòlíì Sotitobire l'Ondo Wo àwọn tí wòlíì ríran sí pé COVID-19 yóò pa ní ìpínlẹ̀ Edo l'óṣù kẹsàn án Èèyàn 591 míràn tún kó COVID-19 ní Nàìjíríà l'Ọ́jọ́ Ẹtì Ọwọ́ tẹ àwọn ọlọ́pàá tó fìyà jẹ obìnrin kan lọ́nà àìtọ́ n'Ibadan Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Itan Ilu gangan Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Nigeria Air Force recruitment 2020: Ilé iṣẹ́ ọmọogun Nàìjíríà ti ṣí ojú opó rẹ̀ fún ìforúkọ silẹ̀ àti ọ̀nà ti ó le gbà ṣe ìfọ̀rọ̀wánilẹ̀nuwò orí ayélujára fún iṣẹ́ náà25 Agẹmo 2020 Tolulope Arotile death: Afurasí tó wa ọkọ̀ pa Tolulope Arotile ti ń jẹ́jọ́ ẹ̀sùn ìgbìmọ̀pọ̀ ṣekúpani20 Ògún 2020 Adebayo Faleti: Ọdún mẹ́ta lẹ́yìn Adebayo Faleti, ìran Yorùbá ń ṣe ilédè rẹ!
Coronavirus in Nigeria: Nítorí COVID-19, ìjọba ìpínlẹ̀ Kwara kó ọ̀dọ́ 50 tó lọ sí ilé ijó sí gbaga
Ladọja ni nigba ti Ajimọbi ri pe ọpọ eeyan lo fidi rẹmi lasiko ibo naa, wa gba lati maa se bii Jagaban ti ipinlẹ Oyo.
Ọwọ ṣìkún òfin ti tẹ Maina, alága àná fún ọrọ owó ìfèyìntì - DSS Awọn akọroyin naa yoo siṣẹ lori ẹrọ asọrọmagbesi ati ẹrọ ayelujara ni ẹka ileesẹ BBC to wa ni Nairobi, pẹlu awọn akẹgbẹ wọn miran lati orilẹ-ede Afirika.
Samuẹli wí fún Saulu pé, “Wò ó, ohun tí a ti pèsè sílẹ̀ dè ọ́ ni wọ́n gbé ka iwájú rẹ yìí.
Omo odun mẹ́tàlélógójì  ohun ni ireti wa pe yoo bere ise laipe gege bi akonimoogba iko agbaboolu orile-ede Italy.
Alaga ajọ WHO, Dokita Tedros Adhanom Ghebreyesus ni iye awọn eniyan to ti lugbadi awọn arun naa ni awọn orilẹede miran yatọ si China ti peleke si ni ida mẹtala laarin ọsẹ meji.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Wole Soyinka: A ti f'aaye gba ipaniyan darandaran fun igba pipẹ 14 Èrèlè 2018 Oríṣun àwòrán, @MBuhari Àkọlé àwòrán, Ojogbon Soyinka maa n s'ọrọ lori eto ilu loore-koore Ọjọgbọn Wọle Soyinka ti sọrọ lori iwa ipaniyan awọn darandaran fulani ati awọn iṣẹ wọn jakejado orilẹ-ede Naijiria, nigbati o sọ pe orilẹ-ede naa ti f'aaye gba iwa ipaniyan ati ipanirun ti awọn darandaran nṣe fun igba pipẹ.
Aare n pese isẹ fun awon ọdọ lojoojumọ.
Alukoro ileesẹ ọlọpaa ipinlẹ Ogun, Abimbola Oyeyemi lo fidi ọrọ yi mulẹ fun BBC Yoruba.
Wọn yóo lọ máa wádìí ọ̀rọ̀ lọ́dọ̀ àwọn oriṣa ati àwọn aláfọ̀ṣẹati lọ́dọ̀ àwọn abókùúsọ̀rọ̀, ati àwọn oṣó.
Nigeria Police: Ilé iṣẹ́ ọlọ́pàá fẹ́ gba ọ̀pọ̀ kọ́ńsítébù láti ranwọ́ lórí ètò ààbò
Ẹyẹ meji kii jẹ aṣa, ti ẹ ba ti n gbọ 'Up Stores!
"A kò sí lára àwọn tó ń ṣèwọ́de tako èlé owó epo àti iná ọba - NLC Jàńdùkú olóṣèlú gbàkóso ilé aṣòfin l‘Ondo Gbogbo ẹni tó bá tàbùkù David Oyedepo ni màá ya pẹ́rẹpẹ̀rẹ - Pásítọ̀ Ibiyeomie Ọmọ Nàíjíríà kó N6m jọ lórí ayélujára fún Erica tí wọn lé ní BB Naija Aliyu ṣalaye pe ""Katun ti Mustapha Bulama ya ko bojumu rara nitori igbeyawo ọhun kii ṣe ọna aibikita fun awọn ara ilu, idi eyii lo mu ki aya Aarẹ ṣe ipade pẹlu awọn alabaṣiṣẹ rẹ pe oun ko fẹ igbeyawo alariwo ṣaaju ọjọ igbeyawo naa."
EndSars Protest: Wo awọn iroyin manigbagbe to waye ni ọsẹ yii
Ní ọjọ́ náà, n óo ṣe gbogbo ohun tí mo ti sọ pé n óo ṣe sí ìdílé Eli, láti ìbẹ̀rẹ̀ títí dé òpin.
“Sọ fún Eleasari ọmọ Aaroni, alufaa pé kí ó kó àwọn àwo turari wọ̀n-ọn-nì kúrò láàrin àjókù àwọn eniyan náà.
"O ni, ""Ni ọdun 2015, Ipinlẹ Eko nikan, labẹ iṣakoso Gomina Akinwunmi Ambode, na N4."
Ní ọ̀pọ̀ ìgbà a máa n tọ́kasi àtẹjáde ìjọba, èyí to ba jẹ mọ ìṣìrò tàbi orísun ọ̀rọ̀ kan to n lọ nita, lati fun yin ni anfani lati dẹjọ fun ara yin lori alaye ipilẹ ìròyìn tábi àlàyé lóri ìròyìn ti à n ṣe.
Olukuluku wọn pa ẹni tí ó dojú ìjà kọ.
Aisaya bá sọ fún Hesekaya pé kí wọn bá a wá èso ọ̀pọ̀tọ́ kí wọn lọ̀ ọ́, kí wọn fi lé ojú oówo tí ó mú un, kí ó lè gbádùn.
A ti lọ si ipinlẹ Eko Àwọn Olùkọ́ ìpínlẹ̀ Eko dárà lórí Akọ́mọlédè àti Àṣà lórí BBC nibi ti a ti kọ ẹkọ loriṣiriṣi ki a to wa si ọdọ awọn olukọ ipinlẹ Oyo yii.
Bí ọ̀run ti tóbi tó, kò gbà ọ́, mélòó mélòó ni ilé tí mo kọ́ yìí?
Ọpọ eeyan si lo maa n pa owe pe bi ọba kan ko ba ku, ọba miran ko lee jẹ, eyi to ti n di irọ nla bayii nitori awọn oriade ana kan wa nilẹ Yoruba, to jẹ pe loju aye wọn bayii, ni wọn se fi ọba miran jẹ lati rọpo wọn.
Afi gbaa ti mo ri i lori Twitter.
Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí 11:51 Fídíò, EndSARS, EndSWAT Protests: Òbí agbábọ́ọ̀lù Kazim Tiamiyu Kaka àtàwọn míì tí ọlọ́pàá pa sọ̀rọ̀, omijé bọ́ lójú, Duration 11,513 Bélú 2020 US presidential election 2020: Ta a ni Joe Biden tó ń díje fún ipò aárẹ America4 Bélú 2020 Fídíò, Soyinka Cancer: Àṣe ara mi ni iso ti n run gbogbo bí mo ṣe n ṣèrànwọ́ lórí jẹjẹrẹ27 Bélú 2019 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 3 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 5 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Oyo Grazing Bill: Ilé aṣòfin ní yóò di èèwọ̀ láìpẹ́ láti ta ilẹ̀ fún darandaran
Igba ti aarẹ wa l'ọmọ ọdun mẹẹrin ni baba naa ku, nilu Daura nipinlẹ Katsina.
Labẹ ofin ipinlẹ Eko, ẹni kẹni to ba kopa ninu afihan ti ko bojumu yala pẹlu ẹlomiran, tiṣẹ si ofin, ti ẹni naa si le ṣẹwọn ọdun mẹta ti ile ẹjọ ba ni o jẹbi ẹsun naa.
Djokovic tun fitan bale leyin ti o jawe olubori ninu ifigagbaga ogun otooto lori ara won, lati wa ni ibamu pelu itan re ti o fi bale seyin, ni eyi ti o jawe olubori ninu ifigagbaga mọ́kàndínlọ́gbọ̀n ti o gba lori ara won.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù A nilo agọ ọlọpaa ni Orin Ekiti fún aabo wa -Falua Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ A nilo agọ ọlọpaa ni Orin Ekiti fún aabo wa -Falua 2 Agẹmo 2019 A nilo agọ ọlọpaa ni Orin Ekiti -Joseph Falua Opolopo igba ni ikọlu ti maa n wa ni Orin Ekiti ti awọn ole maa n fẹ wa ji nkan ninu igbo ọba to wa nibẹ.
Remmy Hazzan ni aṣẹ ijọba apapọ lawọn tẹle ni ipinlẹ Ogun.
Lara rẹ ni Ọmọ Olokun Eṣin, Ogboju Ọdẹ ninu Igbo Irunmọle nigba ti awọn miran bii O le ku ti di sinima agbelewo bayii.
“Tẹmpili yìí gbayì gidigidi nisinsinyii, ṣugbọn nígbà náà, àwọn ẹni tó bá ń rékọjá lọ yóo máa sọ tìyanu-tìyanu pé, ‘Kí ló dé tí Ọlọrun fi ṣe báyìí sí ilẹ̀ yìí ati sí tẹmpili yìí?
Ilẹ̀ Tí Ó kù láti Gbà.
Ile iwosan naa wa lara eyi to dara ju ni agbaye nitori awọn irinṣẹ igbalode to wa nibẹ.
Oludari to n mojuto ibudo iko omo ogun ohun, Abdul Qafoor Malikzai so pe, ikolu naa ni yoo je e akoko re leyin isinmi odun Eid al-Fitr, ti won si fopin si ikolu ohun lojo Aiku(Sunday).
Ẹlòmíì a pọ́n kuku bí aṣọ àparò, Elédùà ló ní kó máa rí bẹ́ẹ̀.
Jotamu kú, wọ́n sin ín sinu ibojì àwọn ọba ní ìlú Dafidi; Ahasi ọmọ rẹ̀, sì jọba lẹ́yìn rẹ̀.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù 2019 elections: Kíni ó ń fa èdèàìyedè lẹ́gbẹ́ APC ìpínlẹ̀ Eko 11 Owewe 2018 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 13 Owewe 2018 Oríṣun àwòrán, @AkinwunmiAmbode Àkọlé àwòrán, Ni ọjọ aje ni gomina Ambọde gba fọọmu iferongba han lati dije fun ipo gomina lolu ileeṣẹ ẹgbẹ oṣelu APC nilu Abuja Gomina ìpínlẹ̀ Eko, Akinwumi Ambọde ni ko si ija kankan laarin oun ati aṣiwaju ẹgbẹ oṣelu All Progressives Congress (APC), Aṣiwaju Bọla Tinubu, bí àwọn kan sẹ n sọ.
Awọn iroyin ti ẹ lee nifẹẹ si: Mama Boko Haram: Alaafia ni akẹẹkọ Dapchi wa Ijọba ti ileesẹ amohunmaworan mẹta ni Kenya Bakannaa ni aarẹ ẹgbẹ akọroyin lorilẹede yi kaanu pe kii se isẹlẹ to dara rara ki awọn eeyan maa padanu isẹ wọn lasiko yi ti ọrọ aje Naijiria ko rẹrin rara.
Ẹ wo ibinu OLUWA bí ó ṣe ń jà bí ìjì!
’ Ni wọ́n bá bẹ̀rẹ̀ sí ṣe àríyá.
Oun ati awọn ọmọ rẹ mẹtẹẹta ni wọn ti yọnda ohun èèlo ti a fi n dari eto ti a n wo lori amohunmaworan, rìmóòtù, ile wọn fún ọkọ rẹ̀ lati fi wo idije World Cup 2018 to n lọ lọwọ ni Russia.
Wolii náà tún tọ Ahabu ọba lọ, ó wí fún un pé, “Pada lọ kó àwọn ọmọ ogun rẹ jọ, kí o sì ṣètò dáradára; nítorí pé, ọba Siria yóo tún bá ọ jagun ní ìbẹ̀rẹ̀ àkókò òjò.
Gómìnà Ganduje wọlé fún sáà kejì ní ìpínlẹ̀ Kano Gómínà Bauchi tẹ́lẹ̀, alága PDP tẹ́lẹ̀ fí PDP sílẹ̀ lọ APC Ọkan ninu ibeji to lẹpọ ye isẹ abẹ ni Bauchi Mohammed ni apapọ ibo to le ni ẹẹdẹgbẹta ẹgbẹrun (515,113) ti Gomina Abubakar si ni apapọ ibo to le ni ẹẹdẹgbẹta ẹẹgbẹrun bakanna (500,625).
0% awọn to lugbadi Covid-19 lo gbawosan.
Àkọlé àwòrán, Awọn ọmọ ogun ti ṣetan lati yan bi ologun ni ipinlẹ Oyo Àkọlé àwòrán, Onimọ ẹrọ Rauf Olaniran to jẹ igbakeji gomina ipinlẹ Oyo ti ṣetan lati lọ yẹ awọn ọmọ ogun to n yan fanda wo ni Adamasingba Àkọlé àwòrán, Ogbẹni Rauf Olaniyan ti n yan lọ ṣabẹwo saarin awọn ọmọ ogun ni ipinle Oyo Àkọlé àwòrán, Awọn ọmọ ogun 'Brigade' naa wa nikalẹ ni papa iṣere Adamasingba ni Mọkọla ni Ibadan fun ayẹyẹ ayajọ ominira Naijiria tọdun 2019 Àkọlé àwòrán, Awọn ori ade lati Ibadan ati agbegbe rẹ naa ko gbẹyin nibi ayẹyẹ ayajọ ọdun ominira Naijiria loni Àkọlé àwòrán, Awọn akẹkọ ile iwe girama kaakiri ipinlẹ Oyo naa wa nibi ayẹyẹ ayajọ ominira to ṣẹlẹ ni ilu Ibadan to jẹ olu ilu ipinlẹ Oyo Àkọlé àwòrán, Awọn iya agbalẹ ti wọn n tun papa iṣere Adamasingba ṣe naa fun oju lounjẹ nibi ayajọ ominira ọdun mọkandinlọgọta Naijiria ni Ibadan Àkọlé àwòrán, Wamu ni àwọn agbofinro duro ni papa iṣere Adamasingba nibi ayajọ ominira Naijiria ti ipinlẹ Oyo n ṣe Àkọlé àwòrán, Ẹsẹ ko gbero ni papa iṣere Lekan Salami nibi ti igbakeji gomina ipinlẹ Oyo ti ṣoju gomina Seyi Makinde nibi ayẹyẹ ayajọ ominira Naijiria tọdun 2019.
Nítorí náà, n óo gbé ohun ìdínà sọ́nà fún àwọn eniyan wọnyi,wọn óo sì fẹsẹ̀ kọ;ati baba, àtọmọ wọn,àtaládùúgbò, àtọ̀rẹ́,gbogbo wọn ni yóo parun.
"Iru awọn iroyin ti ẹ lẹ nifẹ si: Itan Omi Erin Njẹ o mọ oju yi ni ""Yollywood"" Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí kan sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn."
(gẹ́gẹ́ bí ó ti máa ń yọ wọ́n lára mààlúù tí wọn ń fi rú ẹbọ alaafia), yóo sì sun wọ́n níná lórí pẹpẹ ẹbọ sísun.
Àwa yìí ni ẹlẹ́rìí gbogbo ohun tí ó ṣe ní ilẹ̀ àwọn Juu ati ní Jerusalẹmu.
Gẹgẹ bi ohun ti gomina Eko tẹlẹ ri naa sọ, o ṣeeṣe ki o jẹ pe awọn kọlọransi kan ṣaaju iṣẹlẹ to ṣẹ nibẹ lọjọ Iṣẹgun.
"Idaniloju wa fun mi nipa atundi ibo yii nitori pe ati ṣe atunṣe si awọn aṣiṣe ti a ṣe lọsẹ meji sẹyin, ṣugbọn mo ti ṣetan lati gba kadara ti n ba kuna, maa si ki ẹni to ba jawe olubori ku oriire nitori mo gbagbọ pe ẹni ti Ọlọrun ba fẹ l'oun gbe agbara fun.
5 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 UK Covid Vaccine: Arábìnrin ẹni àádọ̀rún ọdún ló kọ́kọ́ gba abẹ́rẹ́ àjẹsára tí Pfizer ṣe síta8 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Nígbà tí mo rí i mo bẹ̀rẹ̀ sí pè é ní oríkì rẹ̀, mo ní ‘Ewédayépọ̀, oníṣègùn ayé, Ewédayépọ̀, oníṣègùn ọ̀run, pàtàkì nínú àwọn babaláwo, irúnmọlẹ̀ ọkùnrin, Ewédayépọ̀, ó ṣe bi iré bí iré ó di ọkọ gbogbo wọn, ẹni tí ó ṣe bí àwàdà tí ó di baba àǹjànnú, ẹni tí ó fi ṣìgìdì ṣe ọmọ-ọ̀dọ̀, tí ó fi ońdè ṣe ìbàǹtẹ́, Ewédayépọ̀ ọkùnrin, ìwọ ni baba wọn ìwọ la fi ṣe é, ìwọ ni baba àgbàlagbà, ìwọ la fi ṣe é, ẹni tí ń rìn kọ́ńdúkọ̀ńdú, ẹ̀tẹ́ ni yòó fi rí.
 láàrin ìṣẹ ́ jú méjì ààbọ , éńjìnnì tìpéle àkọ ́ kọ ́ ti gbé ọkọ ̀ yìí rin kìlómità ọgọrun mẹ ́ fà 600km.
Ẹkọ nla ti Bianca fẹ ki awọn ọdọ kọ ni pe ki wọn maa di eti wọn si ariwo ọja ati pe ki wọn ma bẹru ogbontarigi ti wọn ba fẹ koju lẹnu iṣẹ wọn.
Àwọn ọ̀jọ̀gbọ́n kan ninu àwọn ọmọlẹ́yìn Epikurusi ati àwọn Sitoiki bẹ̀rẹ̀ sí bá a jiyàn.
Àwọn ọmọ Ṣimei jẹ́ mẹrin: Jahati, Sina, Jeuṣi, ati Beraya.
Coronavirus tún ti ṣe ọṣẹ́ lórí iṣẹ́ líla ojú ọ̀nà relùwe láti Eko sí Ibadan - Ìjọba àpapọ̀ Àrùn Coronavirus fa'lẹ̀ya láwọn ìletò aláwọ̀dúdú ní Amẹ́ríkà Lockdown: Ká ní kò sí kónílé ó gbélé, èmi àti Chioma ì bá ti dàgboro rú- Davido Oríṣun àwòrán, davido/instagram Ilumọọka olorin takasufe Davido ti kọ iwe ifẹ kan ṣọwọ si afẹsọna rẹ ati ọmọ wọn ni ọjọ ibi Chioma to n waye lọjọbọ Eyi wa loju opo Instagram rẹ.
Ẹ wò bí OLUWA ti fi ibinufi ìkùukùu bo Sioni mọ́lẹ̀.
Ohun ti wọn sọ ni pe kudiẹ kudiẹ si wa ninu awọn iwe ẹri rẹ ti fi mọ iwe ẹri agunbanirọ rẹ.
Mo sọ fun yín, ní ọjọ́ náà, eniyan meji yóo sùn lórí ibùsùn kan, a óo mú ọ̀kan, a óo fi ekeji sílẹ̀.
adéwọlé ( 1990 : 73-80 ) gbà pé múùdù jé ọ ̀ kan lára àwọn ìsọ ̀ ri gírámà yorùbá .
Nígbà tí àwọn ará Siria wá láti Damasku, láti ran Hadadeseri, ọba Soba lọ́wọ́, Dafidi gbógun tì wọ́n, ó sì pa ẹgbaa mọkanla (22,000) ninu àwọn ọmọ ogun wọn.
Oríṣun àwòrán, WATER AID/MARIO MACILAU Àkọlé àwòrán, Ọkan lara aworan ti Mario Macilau ya Bi o se nya aworan awọn ọmọ igboro ti won ngbe inu awọn ile ti ko ri eeyan gbe inu wọn, bẹẹ ni a maa ya aworan awọn osisẹ ile ise to npo simenti.
Ṣaaju ni ibẹrẹ ọdun yii, iwe itẹka to tutu fa wahala lasiko idibo ẹkun kan ni New Hampshire.
Opo eniyan ko lero pe iko agbaboolu orile-ede Russia yoo lanfaani lati jade kuro nipele kinni idije boolu agbaye to n lo lowo, eleyi ti orile-ede Russia ohun sagbateru re.
Rhoda ni: o tun lee ni ibẹru okunrin lọkan ni igbakugba to ba n ranti iṣẹlẹ ọhun.
Ẹ̀yin rí ẹnì kan kí ó dé ipò ńlá láìjẹ́ pé ó tti ṣe nǹkan ńlá sẹ́hìn?
Wọn si le e kuro nileewe naa.
Ní gbogbo alẹ́ ọjọ́ náà wọn kò rí ẹja kankan pa.
Aare Muhammadu Buhari so pe isakoso ijoba re yoo tesiwaju lati maa sagbekale eto ati ilana ti yoo sanfaani fun idagbasoke eto oro aje orile-ede Naijiria.
APC kò ní olórí tí yòó tọwọ́ bọ̀wé, INEC yarí fún ìbò abẹ́nú l‘Ondo Ìgbésẹ̀ míràn ṣúyọ lórí ọ̀rọ̀ Abiola Ajimobi Ọ̀dàlẹ̀ ni Igbákejì Gómìnà, kìí ṣe pé a dẹ́yẹ si - ìjọba Ondo Lẹyin eyi lo kọwe si ajọ eleto idibo, INEC, pe oun ti fagile eto idibo abẹle lati yan oludije fun ipo gomina ipinlẹ Edo.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ṣé Salah dáa ju Messi lọ lọ́wọ́lọ́wọ́ yìí?
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Tinubu: Buhari kò leè du ipò fún sáà kẹta láéláé 7 Sẹ́rẹ́ 2020 Oríṣun àwòrán, Presidency Aarẹ Muhammadu Buhari ati Asiwaju Bola Ahmed Tinubu sepade pọ nilu Abuja lọjọ Isẹgun.
Ó ti di ogún èèyàn tó kú ní ilé alájà tó wó l'Eko O ni idunnu nla lo jẹ lati rii pe awọn ti ori ko yọ ninu iṣẹlẹ naa n gba itọju to pe ye, ara wọn si ti n pada bọ sipo.
Amọ, o ṣalaye pe Alhaji Ibrahim Tudu, oludije ẹgbẹ oṣelu PDP lo si n lewaju ninu ibo naa.
Ògiri ṣọ́ọ̀ṣì wó pa àwọn olùjọ́sìn mẹ́tàlá Napoli Vs Arsenal: Àwọn olólùfẹ́ Arsenal ń gara pẹ̀lú àṣeyọrí Europa Fidio kan to wa loju opo ile iṣẹ iroyin Front Page Africa safihan bi awọn oṣiṣẹ ṣe n gbiyanju lati pa awọn ejo naa to yri sita ni ibi igbalejo ile iṣẹ naa.
Kọmisọnna fun eto ẹkọ, imọ sayẹnsi ati imọ ẹrọ nipinlẹ naa,Arakunrin Wemi Jones lo kede rẹ ni ilu Lokoja.
Aarẹ ileegbimọ asofin agba orilẹede Naijiria, Sẹnatọ Bukọla Saraki tun pasẹ fun igbimọ tẹẹkoto lori ọrọ eto ọgbin, eto iṣuna ati ileesẹ asọbode lati lọ jumọ joko pọ pẹlu ileesẹ eto iṣuna ijọba apapọ lori ọna ati se agbeyẹwo owo ori ọja to nwọle lati ilẹ okeere.
Wayii o, ireti wa pe iko agbaboolu mejeeji gbodo safihan bi won se gbaradi si fun ifesewonse AFCON.
Wo àwọn ẹranko tí wọ́n máa figagbaga ni Egypt Super Falcons gòkè odò bọ́ sípele ìkẹrìndínlógún ní France Oko òkú rèé, níbití òkú ti ń jẹrà mọ́lẹ̀ fún àyẹ̀wò Buhari gb'alejo asoju orilẹede South Africa Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ebola Virus: ìdí tí Ebola fi ń tàn kálẹ̀ Alaṣẹ Ọkọ̀ ofúrúfu Fly Safari sọ nínú àtẹjade rẹ lori ẹrọ alátagbà wọn pé inu ilé igbẹ ni wọ́n ti ri ẹjẹ ọrun tuntun ọ̀hun, èyí to si nílò ìwádìí nílànà òfin.
Gbogbo àwọn tí ó gbọ́ ń da ọ̀rọ̀ náà rò ninu ọkàn wọn, wọ́n ń sọ pé, “Irú ọmọ wo ni èyí yóo jẹ́?
Oriṣiriṣi awuye-wuye lo ti waye lori igbesẹ naa lati igba ti wọn ti ṣe ifilọlẹ rẹ, paapa lati ẹnu agbẹjọro agba Naijiria, to tun jẹ Minisita fun eto idajọ, Abubakar Malami to sọ pe idasilẹ rẹ ko ba ofin mu.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, End SARS, End SWAT: Ó pé mi bí SARS kò ṣe sọ mí dolówọ́- Fulani Kwajafa O gbiyanju lati yara pa foonu naa lati da fọto naa duro, ṣugbọn o ti pẹ ju.
Ẹkunrẹrẹ alaye re e ninu fidio yii.
Ko si ohun to ṣe ọkọ mi, koda, ó ń palẹ mọ lọwọ bayii lati ṣe ayẹyẹ ọjọ ibi ọdun kejidinlọgọrin to de ile aye losu keje to n bọ, bẹẹ ni ẹnu ya awọn nigba ti ọpọ eeyan n beere pe ki lo ṣe ọkọ òun."
Àwọn ọmọ ẹgbẹ́ nàá n ṣe ìwọ́de láti bèérè fún ìtúsílẹ̀ olórí wọn, Ibrahim El-Zakzaky, tó ti wà ní àhámọ́ àwọn ológun láti bi i ọdún méjì.
Ogun Majek: Lórí ọ̀rọ̀ Ogun Majek, mi ò lọ́rọ́ láti sọ, ẹ lọ pe ẹni tára rẹ̀ kò yá- Mr.
Ẹ wo àwọn ilànà tuntun tí ìjọba Nàìjíríà kéde lẹ́yìn tó fi kún ìséde Covid-19 Oríṣun àwòrán, @Buhari Awọn nkan to tun wa ninu aṣẹ tuntun ti ijọba kede Awọn ile itura ti le ṣi ilẹkun wọn Ile sinima, ibi ti wọn ti n ṣe ere idaraya le ṣi pada, ṣugbọn ero wọn ko gbọdọ ju ida aadọta lọ Awọn gbọngan ayẹyẹ le ṣi pada, ṣugbọn ko gbọdọ ju ida aadọta lọ Awọn ile ounjẹ ko gbọdọ gba ki ẹnikẹni joko jẹun lọdọ wọn Bàbá ẹni ọgọ́ta ọdún dèrò ilé ẹjọ́ nítorí ó wọ inú oko Obasanjo láì gba àṣẹ Mi ò fẹ́ ìrànwọ́ ẹgbẹ́ òṣèré, àwọn kọ́ ló kóbá mi- Chief Kanran Mi ò fẹ́ ìrànwọ́ ẹgbẹ́ òṣèré, àwọn kọ́ ló kóbá mi- Chief Kanran Kí ló wá nínú àbádòfin pínpín omi àti àwọn ǹkan inú omi tó ń mú awuyewuye wa?
 O je okan gbpgi laarin awon akegbe re loja.
Lẹ́yìn náà, wọ́n gbógun ti àwọn ará ilẹ̀ Kenaani tí wọ́n ń gbé orí òkè, ati ìhà gúsù tí à ń pè ní Nẹgẹbu, ati àwọn tí wọn ń gbé ẹsẹ̀ òkè náà pẹlu.
Oni, Ọjọ Iṣẹgun ni wọn yoo sin oku rẹ ni ilana ẹsin Musulumi.
Oríṣun àwòrán, @NLCHeadquarters O ni ọrọ to wa nilẹ kii ṣe ọrọ iwa ọdaran ti ọlọpaa le da si, ọrọ iṣẹ ni.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fọ́nrán ohùn, Oluwo Ìwo ṣ'àlàye lori oyé oba oni lawàni Kíló de ti ìdílé fi ń daru nílẹ̀ Yoruba la'yé òde oní Láye àtijọ, okùnrin kò lè dá obinrin fẹ́, bi kò ṣe larin òun àti àwọn ẹbi rẹ̀, tí o ba wá di pe ìjà fẹ́ wáye gbogbo àwọn àgbààgbà ni yóò dide láti dá síi.
Àsẹ̀hìnwwá-àsẹ̀hinbọ̀, bàbá mi rí i nínú igbó ó sì fẹ́ ọ, gẹ́gẹ́ bí ìtàn náà ti lọ, bàbá mi ti gbúròó ẹbọra náà rí ó sì bẹ̀rẹ̀ sí wá a kiri.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Operation Amotekun: Atiku ní ẹ̀ṣọ́ alábòò Amọtẹkun yóò ṣ'èrànwọ́ lórí ètò ààbò tó mẹ́hẹ 20 Sẹ́rẹ́ 2020 Oríṣun àwòrán, Twitter/Atiku Abubakar Àkọlé àwòrán, Atiku ní ẹ̀ṣọ́ aláábòò Amọtẹkun yóò ṣ'èrànwọ́ lórí ètò ààbò tó mẹ́hẹ Oludije fun ipo aarẹ labẹ asia ẹgbẹ oṣelu PDP ninu ibo gbogboogbo ọdun 2019, Atiku Abubakar naa ti kede atilẹyin rẹ fun ẹṣọ alaabo Amọtẹkun.
Idi pataki fun abadofin naa ni lati lodi si awọn ọrọ ti ko ri bo ṣe tọ ati lati ṣe ofin ti yoo lodi si agbejade iru iroyin bẹẹ lori ayelujara.
Ṣé kí a túbọ̀ máa dẹ́ṣẹ̀ kí oore-ọ̀fẹ́ Ọlọrun lè máa pọ̀ sí i?
Àwọn agbébọn kọlu Kọmísánà fọ́rọ̀ ilẹ̀ àti ilégbèé ní Ọyọ, awakọ̀ dèrò ọ̀run Èwo nínú àwọn amóhùnmáwòrán yìí lẹ rántí?
SSANU, NASU gbé fásitì Ibadan tì pa nítorí ìyanṣẹ́lódì ọlọ́jọ́ márùn ún
’ Ṣugbọn ọba Edomu kò gbà wọ́n láàyè rárá, bákan náà, wọ́n ranṣẹ sí ọba Moabu, òun náà kò fún wọn láàyè, àwọn ọmọ Israẹli bá jókòó sí Kadeṣi.
Oríṣun àwòrán, @nassnigeria Nigba to n ki aarẹ ile asofin agba tuntun ati igbakeji rẹ ku oriire ipo tuntun to ja mọ wọn lọwọ naa, ẹgbẹ PDP wa gba wọn nimọran lati mase lọ nipa ilana ẹlẹgbẹ oselu de, amọ ki wọn fi ifẹ ati idagbasoke Naijiria si ookan aya wọn, lasiko ti wọn ba n sisẹ ti ofin gbe le wọn lọwọ.
Lawọn eeyan ba n fọnmu pe loun to mọ aawọ iṣẹ to si tọ ọ wo daadaa, ko yẹ ki Motara ṣe ọmọbinrin kekere yẹn bẹẹ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Yoruba Culture: Ìran Yorùbá: Àṣà ju àṣà lọ!
Ni eyi ti o si seese ki wọn sọ wi pe Naijiria ko le e gburọ aisan polio mọ ti ko ba si iru aisan naa mọ titi di ọdun 2020.
Bákan náà ni isẹ àánú tó ń ṣe lásìkò igbele Covid-19 yìí tún gbe dé ọdọ Ìyá Awero.
Saraki: Ìwà àrékérekè ni ilé mi tí EFCC tì pa Wo àwọn míniístà mẹ́fà tí ẹnu ń kùn jùlọ Oríṣun àwòrán, Facebook/Bukola Saraki Àkọlé àwòrán, Ibo gomina ipinlẹ Kwara Bi iya nla ba gbe ni san lẹ, kekere a gori ẹni, Abdulrazaq Atunwa, oludije fẹgbẹ PDP ti Saraki tun ṣatilẹyin fun ninu ibo gomina ipinlẹ Kwara tun fidi rẹmi.
Èsì wo ni a óo fún àwọn ikọ̀ orílẹ̀-èdè Filistini?
ṣugbọn ó yan ẹ̀yà Juda,ó sì yan òkè Sioni tí ó fẹ́ràn.
“Nítorí náà kí gbogbo ilé Israẹli mọ̀ dájú pé Jesu yìí tí ẹ̀yin kàn mọ́ agbelebu ni Ọlọrun ti fi ṣe Oluwa ati Mesaya!
Ní òní olónìí yìí, ó ti fi ọpọlọpọ akọ mààlúù, ati aguntan, ati àbọ́pa mààlúù rúbọ.
Wo àwọn dúkìá ìlú tí a fi sọ orí àwọn akọni N kò mọ̀ pé ojú mi ṣì lè là mọ́ lọ́wọ́ ìgbájú- Boluwatifẹ FUTA Ìya lọ ṣọ́ọ̀ṣì, ló bá pàdánù ọmọ!
Kò sí ibùdó ayẹwo àrùn Coronavirus ní UCH, ẹ má wá fún ayẹwo lọ́dọ̀ wa - Ọga àgbà UCH Èèyàn 114 míràn tún ti ní àrùn Coronavirus ní Nàíjírìa Àwọn àràmọ̀ndà ìbomú-bẹnu tó gbòde lásìkò Coronavirus yìí Ìkórira pé mo jẹ Mayegun ni wọn ṣe parọ́ pé mo ń fẹ́ olorì Aláàfin, kò rí bẹ́ẹ̀ rárá- Kwam 1 Oríṣun àwòrán, Oluwo/instagram Àkọlé àwòrán, Mo ti bá ọba Olúwò lóri ọmọbinrin ọdún mẹ́tàlá rìí- Olorì chanel Bi o tilẹ jẹ wi pe ileeṣẹ BBC News Yoruba ti ṣaaju bi Kabiyesi Oluwo, Ọba Abdulrasheed Akanbi leere ọrọ nipa aawọ aarin oun ati Olori rẹ ana, ti Kabiyesi si fesi pe oun ko ṣetan lati sọ ohunkohun lori rẹ.
Oríṣi orúkọ ní wọn ń lò láti sàpèjúwe Núdùlù láti sàkàwé ǹkan gbọ̀ọrọ tó dàbí okùn.
Wọn fi ẹsun kan an pe, o ṣe oniduro fun gomina ipinlẹ Benue tẹlẹ, Gerorge Akume, ti EFCC fi ẹsun iwa ibajẹ kan labẹ iṣakoso Nuhu Ribadu.
Kókó ọlọ́yún wúrà marun-un ati èkúté marun-un dúró fún àwọn ọba Filistini maraarun.
Ẹnu rẹ̀ kún fún èpè, ẹ̀tàn ati ìhàlẹ̀;ìjàngbọ̀n ati ọ̀rọ̀ ibi sì wà lábẹ́ ahọ́n rẹ̀.
Kí a sì jọ gbádùn ara wa bí ọ̀rẹ́ ìmùlẹ̀ tó rí ṅkan ayọ̀ yọ̀ sí.
Yorùbá Homograph: Àmì èdè ló mú káwọn ọ̀rọ̀ yìí ní ìtumọ̀ ọ̀tọ̀ọ̀tọ̀
Igbesẹ ọhun bi China ninu to bẹ ti oun naa fi lọ kọ ile kan sẹba ọna ti India ṣe, eyi to mu ki orilẹ-ede meji ọhun ko ọmọ ogun lọ sojuko naa.
Awọn Aarẹ to ti jẹ ni Chad sẹyin: Francois Tombalbaye lati 11 - 08- 1960 si 13- 04- 1975 Noel Milarew Odinger lati 13- 08- 1975 si 15 -04- 1975 Felix Malloum lati 15- 04- 1975 si 23 -03 1979 Goukonni Queddei 23 - 03- 1979 si 29- 04- 1979 Loi Mohamat Choua lati 29- 04- 1979 si 03- 09 1979 Goukouni Queddei lati 03- 09 - 1979 si 07- 06- 1982 Hissene Habre lati 07- 06- 1982 si 02 12- 1990 Idriss Deby lati 02- 12- 1990 si asiko yii Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Alaafin: Olori Aanu Adeyemi ṣàlàyé ìdí tó ṣe gẹ́ Oba Lamidi Adeyemi ti ìlú Oyo Wo ohun to yẹ ki o mọ nipa awọn adari ilẹ Adulawọ to ti gba 'Field Marshal'ri: Field Marshal ni oye to tobi julọ ninu iṣẹ ologun to tun kọja ti ọgagun agba.
Awọn nkan ti ijọba yoo yẹwo kii wọn o to o fun wọn ni iwe ẹri ni, ilana ijina sira ẹni ti wọn ti gbe kalẹ, ati fun imọtoto.
Mo ti fi ẹsẹ̀ mi tẹ gbogbo omi odò kéékèèké ilẹ̀ Ijipti ní àtẹ̀gbẹ.
Mo pe gbogbo wọn jọ síbi odò tí ń ṣàn lọ sí Ahafa, a sì pàgọ́ sibẹ fún ọjọ́ mẹta.
" Oríṣun àwòrán, AFP Abọ iwadi kan ti Banki Agbaye ati ijọba South Africa jọ ṣe fihan pe awọn iyatọ to wa ninu owo ti onikaluku n gba lẹnu iṣẹ́ wọn jẹ ọ̀kan pataki lara ohun to fa aidọgba ni South Africa laarin ọdun 2006 si 2015.
Ẹni tí ó bá kọ̀ mí, tí kò gba ọ̀rọ̀ mi gbọ́, ó ní ohun tí yóo dá a lẹ́jọ́, ọ̀rọ̀ tí mo ti sọ ni yóo dá a lẹ́jọ́ ní ọjọ́ ìkẹyìn.
Yiyan  sipo re ko mu ariyanjiyan lowo rara.
Ṣugbọn ẹrẹ lẹ n ko rọ ara yin pẹlu dida si ọrọ ti ko kan yin."
Àjòjì tobawo gboro yio di ebora ile baba tobi wan lomo
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, International Day Against Drug Abuse and Trafficking: ìdí ti mo fi ń mu oògùn olóró Buhari ṣepade pẹlu ọmọ ẹgbẹ Afẹnifere Ninu ipade naa Buhari ṣalaye kikun lori idi ti oun fi yọ olori oko eto idajọ Naijiria ni ṣe, iyẹn Walter Onnoghen lori ẹsun ajẹbanu.
 Ilé ẹjọ Kano wọ́gilé ìdájọ́ tó ní kí Oshiomhole lọ rọọ́kún nílé Ìpínlẹ̀ Ogun fẹ́ fi òfin wọ́gilé ìsìnkú ọba lọ́nà ìṣẹ̀mbáyé Mi o tíì rí olórí tó fẹ́ràn Naijiria tó Baba Obasanjo- Yoruba Council of Elders Lẹ́yìn ò rẹyìn, Amotekun dòhun, gbogbo ilé aṣòfin nílẹ̀ Yorùbá fòǹtẹ̀ lu Baba tẹ siwaju pe Mo lero pe to ba di ọjọ iwaju, aye maa wa fun wa lati ṣeto ọhun nitori ọpọ nnkan la lee kọ lati ara wọn nipa awọn aṣeyọri ti wọn ti gbe ṣe, ati bi wọn ṣe ṣe.
"Oríṣun àwòrán, Reuters Àkọlé àwòrán, T Cell le wa ninu ara fun opo ọdun Ìròyìn àyọ̀ àti ìbànújẹ́ tó wà níbẹ̀ ""Tí a bá wo àwọn tó ni ààrùn Coronavirus sùgbọ́n ti wọ́n kò nílò láti de ilé ìwòsàn, ó túmọ̀ sí pé wọn ni ""T Cell"" ni"" gẹ́gẹ́ bi Heyday ṣe sọ."
    Báyìí ni ọkùnrin náà sọ, nígbà ti o sì parí ọ̀rọ̀ rẹ̀ èmi náà bẹ̀rẹ̀ sí ọ̀rọ̀ tèmi mo ni, “ọ̀rẹ́ mi, Ìrìnkèrindò, ìwọ ni mo ṣe báyìí rí!
Àmọ́ ní òde òní, àwọn ẹ̀rọ ìbánisọ̀rọ̀ alágbèéká tí wọ́n ń ṣe jáde ti gba'ṣẹ́ lọ́wọ́ àwọn ẹ̀rọ ìgbàlódé ìyókù ẹgbẹ́ ẹ wọn o.
"Kí ló ṣe jẹ́ pé èmi ni yóò ní àrùn jẹjẹrẹ lẹ́ni ọdún mẹ́rìnlá?
‘Olùkọ́ fipá bá akẹ́ẹ̀kọ́ girama lòpò nítorí máàkì’ Ìjọba South Africa pèpàdé lórí ìkórìíra àlejò Gómìnà mẹ́rin yóò jẹ́jọ́ lẹ́yìn sáà wọn - EFCC Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Colorado ni Amẹrika àti odò Awaye ní Naijiria nikeji àdágún órí àpáta ní gbogbo àgbáyé!
Ṣereṣi ni ó bí Ulamu ati Rakemu; 
 Kí obìnrin to àtòrìn,Kí Ọkùnrin to àtòrìn,ká wo ẹni tí ó ma lómi léyìn ẹsẹ̀ ju ara wọn lo.
Ramadan Fast: wo àwọn orílẹ̀èdè tí wákàtí ààwẹ̀ wọn gùn ju ti Nàìjíríà lọ àti àwọn èèwọ̀ oúnjẹ lásìkò ààwẹ̀
Doctor Alex: Bí ó bá fi ẹnu kò ènìyàn lenu, tàbí salabapade ẹni tí ó ní aarun náà, ri dájú pé o di ara rẹ sí igbele.
Ile itaja nla naa gba o kere tan ẹgbẹrun meji ọmọ Naijiria siṣẹ.
Bi ẹ ko ba ni gbagbe, iku Wasilat Adeola, Barakat Bello, Grace Oshiagwu, Mojeed Tirimisiyu to jẹ ọmọ ọdun marun wa lara awọn ti awọn ọlọpaa ni arakunrin naa jẹwọ pe oun pa.
Nigerian schools resumption: ASUU ní kí ìjọba má tíì ṣí àwọn ilé ìwé nítorí Coronavirus
Ninu ọrọ to sọ nile ẹjọ, Basirat ni ara bẹrẹ si ni fun oun , nigba ti ọkọ oun (Niyi) ko ṣe idaro lẹyin ti oun padanu oyun, nitori pe ibalopọ ti awọn n ni ti pọju.
Ọdun 2006, 2010, 2014, 2018 ni wọn ko ti yege lati kopa rara ninu idije ife ẹyẹ agbaye.
 Nipa itan ti ọpọlọpọ ma n sọ lori bi ẹgbẹ okunkun ṣe bẹrẹ lawọn ile iwe giga oni eyi ti wọ́n ma n lọ mọ ẹgbẹ ""Pirate Fraternity"" ti Wole Soyinka atawọn ọrẹ rẹ mẹfa kan da silẹ lọdun 1952."
Oríṣun àwòrán, Others Fani-Kayode wa n beere pe se asaaju oloselu lẹkun ariwa Naijiria lee kọ lati dide ki ọba alaye nibẹ?
Àwọn olólùfẹ́ Bayern Munich ya wọ orí pápá lẹ́yìn ìdíje
Nígbà tí ogun yìí bẹ̀rẹ̀, àwọn àgbààgbà Gileadi lọ mú Jẹfuta wá láti ilẹ̀ Tobu.
Bí OLUWA ti wà pẹlu kabiyesi, bẹ́ẹ̀ náà ni kí ó wà pẹlu Solomoni, kí ó sì mú kí ìgbà tirẹ̀ tún dára ju ìgbà ti kabiyesi, oluwa mi, Dafidi ọba lọ.
Lara awọn agba oye mẹsan ilẹ Ibadan, mẹfa lo wa nibi abẹwo naa.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Taye Currency: Seyi Makinde fún Taye Currency lẹ́bùn ọkọ̀ bọ̀kìnnì Toyota Prado 2020 22 Bélú 2020 Oríṣun àwòrán, Instagram/Taye Currency Ori lo mọ iṣẹ aṣela laye.
Ẹkun Gauteng lo tobi ju, nibẹ naa ni Johanesburg to jẹ ilu to tobi ju ni south Africa naa wa.
Jehoramu kú, wọ́n sì sin ín sí ibojì àwọn ọba ní ìlú Dafidi.
Ìlù sákárà jẹ ́ ìlù kan lára àwọn ìlù mẹ ́ rin tó jẹ ́ ẹbí kan náà nínú ìlù tó ṣe gbòógì mẹ ́ rin nílẹ ̀ yorùbá .
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Tẹniọla: Pè mí láago tí o bá mọ iyán gún pẹ̀lú ọbẹ̀ ilá tó dùn Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'A máa ń bẹ́ orí ẹni tó bá gbé imọlẹ̀ ọdún ìjẹṣu tó bá ṣubú ni' Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Rara, ṣugbọn kii ṣe eyi ti ko mu gbogbo awọn to wo o maa da omi ẹni nitori awogbadun rẹ.
Alaafia mi ni mo fun yín.
Ọba Akanbi fikun pe ohun ta mọ laa mọ, ohun to daju ni pe ẹni to n singba ko lowo lọwọ, ko si si ọna abayọ lọrun ọpẹ, ayafi tijọba ba wa atunse ati atunso si ẹka isẹ ọba ko lee dangajia si.
Oshiomhole, ni gbogbo awon eniyan ni yoo mo igba ti awon ba fe se idibo egbe lati yan awon oludije, leyin ti awon oloye egbe ba ti bu ọwọ lu ona ti won yoo gba di ibo naa.
"Jago gba lati ṣe bẹ lootọ, ṣugbọn iya rẹ ti iwe ile naa wa lọwọ rẹ kọ lati ko silẹ.
Eleasari yóo gbà ninu ẹ̀jẹ̀ rẹ̀, yóo fi ìka rẹ̀ wọ́n ọn sí apá ìhà Àgọ́ Àjọ ní ìgbà meje.
OLUWA, ìtìjú yìí pọ̀ fún àwọn ọba wa, àwọn olórí wa, ati àwọn baba wa, nítorí a ti ṣẹ̀ ọ́.
#justiceforDonDavis: Orí ayélujára n gbóná janjan fún ariwo ìdájọ́ fún akẹ́kọ̀ọ́ kan níléèwé Kumuyi
 Mo ki O kaabo saafin olori mi, eni ti okan mi yan.
Ìrìnàjò afẹ́ yìí rán wa létí wípé a nílòo sùúrù bí a bá ń dá àwọn aláàárẹ̀ lóhùn.
Wahala ni ipolongo Lasiko ti gomina ana fun ipinle Osun Rauf Aregbesola bere lati ba awon
Laarin  iṣẹju mẹta ti wọn bẹrẹ ere bọọlu ọhun ni ẹlẹsẹ
Arsenal padanu anfaani lati bọ si ipo kẹta ninu idije Premier League lẹyin ti wọn rẹmi papa iṣere Bramall Lane.
Ṣe Super Falcons le yi ero Afirika pada lori ere bọọlu awọn obinrin?
Salimoni bí Boasi, ìyá Boasi ni Rahabu, Boasi bí Obedi.
Olori osise naa tun tenumo pe isejoba Seyi Makinde ti
Gbogbo awọn ami buruku yii to waye ni ipinlẹ Zamfara, Rivers, Bauchi ati Adamawa lo tun fẹ suyọ abyi ni Bayelsa.
Ọlọ́pàá mú afẹ̀sùnkàn Boko Haram tó ti pa ju ènìyàn 200 Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Larisa: Má jẹ́ kí ọjọ́ orí rẹ dí ẹ lọ́wọ́ láti bẹ̀rẹ̀ ohunkóhun to wù ọ Awọn mii gba pé ileri yii naa ni wọn ti ṣe fun iran Igbo tẹlẹ ni eyi to fi fẹ jọ irọ́ loju ti wọn pé Nigba ti awọn kan gbà pé iwa yii ku diẹ káà to nitori pe iran Yoruba ti gbọ́n sii.
 kò wọ ́ pọ ̀ kí àrùn yí ó mú ikú dání .
Ní òwúrọ̀ ọjọ́ keji, Dafidi kọlù wọ́n, ó sì pa wọ́n títí di ìrọ̀lẹ́ ọjọ́ náà.
bi o ti le je pe ko saseyori taara ninu iko agbaboolu orile-ede re, Argentina
World Food Day: Wo àwọn oúnjẹ ìṣẹ̀mbáyé Yorùbá tó ti ń di àpatì Díẹ ree ninu wọn: 1)Kikọ lati maa jẹ ounjẹ aarọ: Pupo ninu wa lo maa n huwa aibikita yii paapa julọ lawọn ilu nla nla nibi ti kirakita atijẹ atimu kii jẹ ki awọn eeyan rántí lati je ounjẹ aarọ lasiko.
Ogbeni  Gbajabiamila ni atunse gbodo ba oruko ile ise
Awọn ipinlẹ wọnyi si lawọn oludije maa n doju kọ lati lee ri ibo to giriki gba nibẹ.
Oriṣiriṣi àwọn oniṣẹ́ “Abániwálé” wá pọ̀ si.
Nítorí pé gbogbo àwọn ohun ìríra wọnyi ni àwọn tí wọ́n ti gbé ilẹ̀ náà ṣáájú yín ti ṣe, tí wọ́n sì fi ba ilẹ̀ náà jẹ́.
Wọ́n ti rí ìbejì Taofeeq Akeugbagold tí wọ́n jígbé nílùú Ibadan Oríṣun àwòrán, Facebook Iroyin to n tẹwa lọwọ ni pe wọn ti ri awọn ibeji olori ẹsin Isalm, Taofeeq Akeugbagold ti wọn jigbe nilu Ibadan.
Male Fertility: Wo àwọn oúnjẹ márùn ún tó ń mú kí àtọ̀ ọkùnrin dára sí i
Eniyan meji sàn ju ẹnìkan ṣoṣo lọ,nítorí wọn yóo lè jọ ṣiṣẹ́,èrè wọn yóo sì pọ̀.
O ni A ti ṣe iwọn ti a le ṣe pẹlu ajọ WAEC, a dẹ n fi akoko yi sọ fun yin pe idanwo naa yoo bẹrẹ lati ọjọ kẹrin oṣu Kẹjọ titi di ọjọ karun un oṣu kẹsan an ọdun 2020."
Akeugbagold wa sísọ lójú rẹ pé, inú igbó kan ládùúgbò Mufu Lanihun lójú ọna marosẹ Ibadan sì Eko ni òun ti rí àwọn ìbejì náà nibiti àwọn ajinigbe dá wọn padà sí, tó sì ni òun kò leè sọ iye owó idande tí òun san fún wọn fún aráyé.
Ní gbogbo ìgbà ayé Rehoboamu ati ti Jeroboamu ni àwọn mejeeji í máa gbógun ti ara wọn.
Asán ati ìmúlẹ̀mófo ni èyí pẹlu.
A sì ṣí lọ sí òdìkejì odò Seredi.
FF - BBC News Yorùbá BBC News, YorùbáFò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Joseph Yobo ni igbákejì akọ́nimọ̀ọ́gbá Super Eagles tuntun - NFF 12 Èrèlè 2020 Oríṣun àwòrán, @NGfooty Ajọ to n ri si ọrọ ere bọọlu ni Naijiria, NFF ti kede Joseph Yobo gẹgẹ bi igbakeji akọnimọgba ikọ naa tuntun.
 kòíti sí ikú lákókò àkorán àkọkọ ́ ní ọdún 2015 .
Bí mo bá ṣáájú ìwọ́de ENDSARS, kẹ́ẹ mọ̀ pé ẹ̀wọ̀n Kirikiri ni wọ́n á gbé mi lọ jàntò - Naira Marley Àìgbọ́n àti àìmọ̀kanmọ̀kàn ló ń da Fayose láàmù, kò gba ẹnu rẹ̀ láti sọ̀rọ̀ sí mi - Bode George A ti ń bimọ ju ǹkan tí apá orílẹ̀èdè lè ká lọ, ẹ má bí ju méjì, mẹ́ta lọ mọ́ o!
16 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Nigeria Borders open: Onímọ̀ ọrọ̀ ajé ní ìlànà tẹ́tẹ́ títa ní ìjọba ń lò fétò ọ̀rọ̀ ajé17 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Íye owo bẹntirol le goke to N250 si N300 lati igba yii lọ'' ‘Apẹẹrẹ ni Sim Card ti a n ra bayii ni ọgọrun naira, amọ nigba ti o kọkọ jade, ẹgbẹrun lọna ọgbọn naira ni wọn n ta.
Orí ọ̀pá fìtílà ni wọ́n ń gbé e kà, kí gbogbo ẹni tí ó bá ń wọlé lè ríran.
Àwọn Farisi ni ó rán àwọn eniyan sí i.
O si to ọdun mẹẹdogun ti wọn ti bi sile aye, ki wọn to sọ ni suna Moshood.
Mo bá kó àwọn ìjòyè Juda lọ sórí odi náà, mo sì yan ọ̀wọ́ meji pataki tí wọ́n ṣe ìdúpẹ́ tí wọ́n sì tò kọjá ní ọ̀wọ̀ọ̀wọ́.
Ohun ti awọn iroyin miran to n lọ kaakiri tilẹ tun n sọ ni pe ileewosan kan lagbegbe Ikoyi ni ilu Eko ni wọn gbe agba oṣelu naa lọ bayii fun itọju.
Àwọn òbí kan tilẹ̀ tún maa n ra ìwé ẹ̀rí fún ọmọ wọn.
"O ní "" ó ṣeni láànú pé asọtẹlẹ̀ mi lóri Super Falcons kùnà, èyí túmọ si pé ìsípaya náà kìí ṣe láti ọ̀dọ̀ Ọlọ́run."
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù FIFA: Infantino máa bá'ṣẹ́ rẹ lọ 5 Òkùdu 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Wọn ti tun yan Gianni Infantino lẹ́ẹ̀kan síi gẹgẹ bi aarẹ ajọ to n moju to ọ̀rọ̀ bọọlu alafẹsẹgba lagbaye, FIFA.
Ǹjẹ́ bí ẹ̀yin tí ẹ burú báyìí bá mọ̀ bí a tií fi ohun tí ó dára fún ọmọ yín, mélòó-mélòó ni Baba yín tí ń bẹ ní ọ̀run yóo fi ohun rere fún àwọn tí ó bá bèèrè lọ́dọ̀ rẹ̀.
Wọn óo máa wí pé, “Ó ṣe!
Eyi waye nitori pe ẹnikẹni ninu wọn to ba wọle yoo pari saa keji rẹ ni eyi to jẹ aṣegbẹyin nitrori pe ko si saa kẹta.
Èèyàn 145 tún ti ní COVID-19 ní Nàìjíríà Esi ayẹwo coronavirus lati ipinlẹ mẹjọ ti ajọ NCDC fi sita ni Ọjọ Aje, ọjọ kọkandinlọgbọn, oṣu Kọkanla, fihan pe, eeyan marundlaadọjọ tun ti ni aarun naa ni Naijiria.
Àwọn tí wọ́n ṣẹ́kù ní Israẹli kò ní hùwà burúkú mọ́, wọn kò ní purọ́ mọ́, bẹ́ẹ̀ ni a kò sì ní bá ẹ̀tàn lẹ́nu wọn mọ́.
Ṣugbọn o ni ọpọ eeyan lo n ṣe asise lati maa pe awọn Hausa ni Mọla abi Malam.
25 Agẹmo 2018 Àmì jẹ́ ara èdè Yorùbá, tó fi ń jẹ́ kí èdè náà rẹwà púpọ̀.
Ní ọdún kẹta, ẹ gbin nǹkan ọ̀gbìn, kí ẹ sì kórè rẹ̀, ẹ ṣe ọgbà àjàrà kí ẹ sì máa jẹ èso inú rẹ̀.
Ní ọjọ́ kan, bí Akisa ti sọ̀kalẹ̀ ní orí kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ rẹ̀, baba rẹ̀ bi í pé, “Kí ni ò ń fẹ́?
Ahmed Saka salaye pe aba Agbo, lẹba agbegbe Odumakin ni baba oun n gbe.
Ǹjẹ́ mo gba mààlúù ẹnikẹ́ni ninu yín rí?
Wòlíì náà àti àwọn akẹgbẹ́ rẹ̀ wá ìtọ́ni àtọ̀runwá, àwọn ìfihàn wọ̀nyí sì jẹ́ ẹ̀rí pé wọ́n rí i gbà.
Sugbọn o se ni laanu pe asa ila kikọ yii ti wa di ohun itiju nitori ọlaju to de ba wa.
Làá hàn mí dé, ètò tó ń ṣàlàyé ohun tó yẹ ká ṣe láti dènà àrùn Coronavirus Lẹ́yìn ò rẹyìn, Amotekun dòhun, gbogbo ilé aṣòfin nílẹ̀ Yorùbá fòǹtẹ̀ lu Ilé ẹjọ l'Abuja ní kí Oshiomole lọ rọọ́kún nílé gẹ́gẹ́ bí Alága APC Minisita feto ẹkọ nilẹ naa Lucia Azzolina nigba to n fesi si iroyin yi ti ọpọ ileeṣẹ iroyin ti gbe sọ pe awọn ko ti fẹnuko lori igbesẹ yi ṣugbọn awọn yoo bun wọn gbọ laipẹ.
Ẹ kíyèsára lọ́dọ̀ àwọn eniyan, nítorí wọn yóo fà yín lọ siwaju ìgbìmọ̀ láti fẹ̀sùn kàn yín; wọn yóo nà yín ninu àwọn ilé ìpàdé wọn.
Oríṣun àwòrán, Bashir Ahmad/twitter Ìfẹ́ orílẹ̀-èdè Nàìjíríà ló sọkùnfà ikú Kyari - Lai Mohammed Abba Kyari: Lai Mohammed sọ pé aájò kí Nàìjíríà le dára ló sọkùnfà ikú Kyari Minisita fun eto iroyin ati aṣa ni Naijiria, Lai Mohammed ti sọ pe aajo Naijiria lo pa Abba Kyari.
Saulu bá pàṣẹ fún àwọn iranṣẹ rẹ̀ pé kí wọ́n wá ọkunrin kan tí ó mọ hapu ta dáradára, kí wọ́n sì mú un wá siwaju òun.
aṣọ tí wọ́n ń ta sí àgbàlá, aṣọ tí wọ́n ń ta sí ẹnu ọ̀nà àbáwọ àgbàlá tí ó yí ibi mímọ́ ati pẹpẹ ká, ati okùn, ati gbogbo nǹkan tí wọ́n ń lò pẹlu rẹ̀.
Ṣugbọn sibẹ, dájúdájú, n óo sọ ọ́ di aṣálẹ̀;o óo sì di ìlú tí ẹnikẹ́ni kò ní gbé.
maa se foya, ijoba ti n gbe igbesẹ lati fopin si wahala to  maa n waye laarin awon agbẹ ati daran-daran,igbesunmọmi
Òun ni mo fi yà á l’áwòrán kí n tó mu ú o jàre.
Nígbà tí àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rí wọn, wọ́n bẹ̀rẹ̀ sí bá àwọn tí wọ́n gbé wọn wá wí.
Abenugan ile  igbimo asofin agba lorile ede Niajiria ,
 lọ ́ dọọdún a má a ń fún iye àwọn ọmọ-ọwọ ́ tó tó 100 mílíọ ̀ nù ní àjẹsára náà .
O wa fọwọ gbaya pe ọjọ Aje to n bọ ni wọn yoo fi oju Chibuzor Elike ba ile ẹjọ lori ẹsun lilu jibiti.
Omisore naa dahun wipe oun ṣe ipinnu lati wa ilọsiwaju ni awujọ ṣugbọn pe kii ṣe pe oun fi SDP silẹ lọ APC.
Ó ké sí ọkunrin tí ó wọ aṣọ funfun náà, tí ó sì ní àpótí ìkọ̀wé kan lẹ́gbẹ̀ẹ́.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Kidnapping: Aago méje alẹ́ ọjọ́ Ìṣẹ́gun làwọn agbégbọn dí ọ̀nà márosẹ̀ Ibadan 24 Agẹmo 2019 Oríṣun àwòrán, @renoomokri Kaka ki ewe agbọn dẹ nidi eto aaboorilẹede naijiria to mẹhẹ, n se lo tun n le koko sii.
Bí oluwa mi bá gbé ara lé apá mi, tí èmi náà sì tẹríba ninu tẹmpili Rimoni, kí OLUWA dáríjì iranṣẹ rẹ.
O ti le ni ọdun meji bayii ti Davido ati Chioma ti bẹrẹ irinajo ifẹ wọn ti Eleduwa si ti fi ọmọkunrin kan tawọn lọrẹ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Abayọmi Aranmọlatẹ, Dr Laser: Vagino Plasty àti iṣẹ́ abẹ ẹwà Obìnrin ló jẹ mí lógún Aarẹ ẹgbẹ awọn dokita ni Naijira, NMA tẹlẹ tun sọ pe afaimọ ki aarun covid-19 maa tun bẹ silẹ lẹẹkeji pẹlu bi ọpọ eeyan ti n ṣe iwọde #EndSARS lai bikita nipa coronavirus.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fọ́nrán ohùn, State of Osun: Pípe ìpínlẹ̀ Osun ni State of State Osun kò bá òfin mu-Adájọ́ Agboola Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Fídíò, Yoruba Language: Akomolede ati Asa Yoruba tọ̀sẹ̀ yí rèé lẹ́nu olùkọ́ wa30 Ògún 2020 Fídíò, Akomolede: Bolaji Faleke ni Olùkọ́ tó ń kọ́ wa ní àṣà oge ṣiṣe lórí BBC Yorùbá1 Owewe 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Àwọn ẹlẹ́rìí fi ẹ̀wù wọn lélẹ̀ níwájú ọdọmọkunrin kan tí à ń pè ní Saulu.
’  Nígbà tí ó wí báyìí tán ìyàwó mi kúnlẹ̀ ó bẹ̀rẹ̀ sí bẹ̀ ẹ́ ó ní kí ó má ṣe bínú, pé n kò tètè sùn ni, ó dì mọ́ ọkùnrin yìí wọ́n sì bẹ̀rẹ̀ sí fi ẹnu ko ara wọn lẹ́nu.
Àwọn ọmọ Kuṣi ni: Seba, Hafila, Sabita, Raama ati Sabiteka.
Ṣugbọn ẹni tí kò ṣe nǹkankan, ṣugbọn tí ó ṣá ní igbagbọ sí ẹni tí ó ń dá ẹni tí kò yẹ láre, Ọlọrun kà á sí ẹni rere nípa igbagbọ rẹ̀.
Ninu ìwé Dafidi, tí ó kọ lẹ́yìn ọdún pupọ, ó sọ pé, “Lónìí”, níbi tí atọ́ka sí, tí ó kà báyìí pé,“Lónìí, bí ẹ bá gbọ́ ohùn rẹ̀,Ẹ má ṣe agídí.
E̩nì kò̩ò̩kan ló ní è̩tó̩ láti wà láàyè, è̩tó̩ sí òmìnira àti è̩tó̩ sí ààbò ara rè̩.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ẹ wo ìdí tí ẹ gbọdọ̀ fi gba abẹ́rẹ́ àjẹsára fún ọmọ yín!
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù RUGA: Afenifere, Kunle Akinjide sọ̀rọ̀ lórí ìkéde ìjọba àpapọ̀ láti dáwọ́ dúró lórí RUGA 4 Agẹmo 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ijọba apapọ kede lalẹ Ọjọru pe awọ̀n n dawọ duro lori idasilẹ awọn gaa darandaran RUGA to ti n fa awuyewuye fun ọjọ diẹ sẹyin bayii Lẹyin ti aarẹ Buhari ti kede pe ijọba apapọ yoo jami lori igbesẹ ati da awọn Gaa darandaran RUGA silẹ bayii, ẹgbẹ Afẹnifẹre ti pariwo sita pe ete lasan ni ọrọ naa nitori kii ṣe pe aarẹ ni awọn wọgile e patapata.
Àkọlé àwòrán, Ọọ̀ni ti Ifẹ déjú mọ́lé fún ọjọ́ méje Ìsélé yìí bẹ̀rẹ̀ ní alẹ́ ọjọ́ àìkú lẹ́yìn tí ìrètí wà pé Ọọ̀ni tó jẹ́ àrólé Oduduwa yóò fara hàn ní gbangba pẹ̀lú adé ìṣẹ̀mbáyé tó jẹ́ wí pé ẹ̀ẹ̀kan lọ́dún ló máa ń dé e.
Wọn gbiyanju lati tun ofin 'se k'Ọbasanjo ba le ṣe saa kẹta sugbọn ile asofin ko gba a wọle lọdun 2007.
Amọ ṣa, igbesẹ Ezekwesili yi mu ariwisi ọtọọtọ wa laarin awọn ọmọ Naijiria.
Bẹẹ si ni iye eeyan to ko aisan naa ti fo lati ẹgbẹfa(1200) si ẹgbẹrun marun un ati ọọrinlelẹgbẹrin ati mẹta(5883) lọjọ Abamẹta.
Yagọ fun oti mimu lasiko to ba n wakọ Njẹ iwọ fẹran ọti mimu?
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Osogbo Building collapse: Ògiri ilé wó pa Jide ọmọ ọdún mọ́kànlá l'Oṣogbo 3 Òkùdu 2019 Oríṣun àwòrán, citymirrornews.
Kódà n óo di ohun ìríra sí aṣọ ara mi.
Wo orúkọ àwọn ẹ̀yà ara rẹ̀ ní èdé Yorùbá Èyí ni ọ̀nà tí àwọn obìnrin n gbà kó ara wọn sí wàhálà nítorí ara bíbó Ṣugbọn ni bayii, wọn ti tọju debi pe wọn kọ ọ bi eeyan ṣe n gbe aye oun naa si jẹ ọmọ to maa n dunnu A maa rẹrin musẹ bii ẹrin igba ayeraye.
" Ọrọ Ajimobi yii si lo da họhu-họhu silẹ nigba naa.
Iru awọn iroyin ti ẹ le nifẹ si: Àwọn ọmọ Iyabọ Ojo: Bàbá wa rèé, ẹ̀yin tẹ̀ mọ bàbá wa Báwo ni ìlù gángan se bẹ̀rẹ̀ ?
Ẹ pa àwọn àgbàlagbà patapata, ati àwọn ọdọmọkunrin ati ọdọmọbinrin pẹlu, ati àwọn ọmọde ati àwọn obinrin.
Sugbọn nigba miran, ọpọ ọmọ Yoruba to ba wa isẹ aje lọ silu miran kii gbagbe ile nitori igbagbọ wọn ni pe ọmọ to ba sọ ile nu, o so apo iya kọ.
A fi idà pa àwọn mìíràn.
com Tẹ nọmba idanwo rẹ ati ''pin'' ti ajọ WAEC fun ọ ki o to ṣe idanwo sibẹ Fi ọdun idanwo sibẹ ati irufẹ idanwo ti o ṣe sibẹ bo ya GCE tabi SSCE.
Oríṣun àwòrán, Nguher Gabrielle Zaki '' O jẹ ohun to fọwọ kan wa lẹmi wi pe, idibo Gomina yii le mu ki awọn iwa ti ko tọ waye, paapa bi awọn ti ọrọ kan ṣe n huwa ipa bayii'' Ajọ ọhun wa mẹnuba awọn alatilẹyin ẹgbẹ oṣelu APC, PDP, ZLP ati LP gẹgẹ bi awọn to n hu iwa ipa yii, ti wọn si tun jẹ ẹni to n fara ko iwa jagidijagan pẹlu.
Divock Origi lo kọkọ jẹ goolu ni iṣẹju keje ifẹsẹwọnsẹ naa ti o si fi goolu mi da Barcelona loro ni iṣẹju kọkandinlogọrin ti o fi jẹ goolu mẹrin si odo.
Oríṣun àwòrán, Igboho O fi ikilọ yii lede nigba to n sọrọ lori ifẹhọnuhan EndSars ti awọn janduku n lo lati fa rogbodiyan kaakiri orilẹede Naijiria.
Ohun ti pupọ ninu awọn onile epo sọ ni wipe awọn onimọẹrọ yoo nilo lati yi iye ti wọn n ta epo pada lori awọn ẹrọ ti wọn fi n ta epo ki o to di wi pe awọn onibara wọn yoo lanfani lati maa raa ni iye ti ijọba apapọ kede rẹ.
    “Ẹyin jànmọ́ọ̀ọ̀, mo kii yín ẹ kú ìjókòó o.
Ikolu naa waye lojo kejidinlogun osu keji odun ti a wayii.
Oríṣun àwòrán, @Akinyemi Abajade ayẹwo naa ni Ọjọ Isinmi, Ọjọ Kẹsan an, Oṣu Kẹjọ lo fi lede pe saka ni ara Baba da lọwọ arun Coronavirus.
Jonatani ni baálé ní ìdílé Maluki,Josẹfu ni baálé ní ìdílé Ṣebanaya,
Oríṣun àwòrán, Others Osu Kejila ọdun 2018 ni Funke, ti ọpọ eeyan mọ si Jenifa, bi awọn ibeji naa, eyi to pa orukọ rẹ da si mama ibeji.
Ọmọ Ijeṣa ni ere - Ogedengbe gboya ninu ilu rẹ o si ni ifẹ aiṣẹtan fun awọn ara ilu Ijeṣa bi o tilẹ jẹ pe o jẹ ẹnikan ti ko gba igbakugba ti ko si bẹru ẹnikẹni.
bí mo bá fi ibi san án fún olóore,tabi tí mo bá kó ọ̀tá mi lẹ́rú láìnídìí,
Bo ti lẹ jẹ pe awọn akọnimọọgba Chelsea n yi pada, o ya ni lẹnu wipe ẹgbẹ agbabọọlu na ṣi n ṣe ribiribi.
Eleyi lo mu ki awọn aṣofin ṣe ipade idakọnkọ, lẹyin ipade yii ni wọn jọ gba lati so apero rọ lori ọrọ naa.
Lẹyin naa ni wọn yoo yinbọn pa wọn lẹyin ọsẹ kan tabi oṣu kan.
Lẹyin rẹ, ile ẹjọ Burundi kan dajọ iku fun aarẹ Nkurunziza lọdun 1998 ṣugbọn o tun gba idalare eyi to mu ki ija dopin.
Ìjọba ìpínlẹ̀ Osun tí búwọlù ìlànà àyẹyẹ Ọṣun-Oṣogboo ọdún 2020 'Inú mi dùn pé wọ́n dájọ́ sísọ̀kò pa bàbá arúgbó tó fipá b'ọ́mọ lòpọ̀' Ilé ẹjọ́ ju ọmọ ìjọ tó fi ìpá bá ọmọ pásítọ̀ rẹ̀ sùn ní ìpínlẹ̀ Ondo sí ẹ̀wọ̀n gbére Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, jkkkkk Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí 5:31 Fídíò, Victor Agunbiade ni ojú àlá ni Ọlọrun ti yan iṣẹ́ ọmọ ogun ojú omi fún òun ní America, Duration 5,3114 Ògún 2020 6:44 Fídíò, Risikat Moromoke Azeez: Inú èmí àti Òbí mi dùn nígbà ti Risi bí ọmọ olójú búlù- Wasiu, Duration 6,4420 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 3 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 5 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Eyi lo difa fun pe ki o ṣọra fun lilo ṣájà inu mọto ti ko dara to.
Ikú wé mọ́ mi bí okùn,ìparun sì bò mí mọ́lẹ̀ bíi rírú omi.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Operation Falcon: Omi tẹ̀yìn wọ̀gbín lẹ́nu fáwọn ọmọ Nàìjíríà mẹ́ta tó lu èèyàn 50,000 ní gbájúẹ̀ jákèjádò àgbáyé 26 Bélú 2020 Oríṣun àwòrán, Interpol Awọn afurasi ọmọ Naijiria mẹta kan to lu ijọba ati awọn ọlọdani lorileede to le ni aadọjọ ni gbajuẹ lọwọ ti tẹ nilu Eko.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Fuel hike protest: Àwọn akẹ́kọ̀ọ́ ìpínlẹ̀ Oyo, Osun àti Ondo ṣe ìfẹ̀hónúhàn lórí èlé owó iná àti owó epo 2 Owewe 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 8 Owewe 2020 Oríṣun àwòrán, @eniola_opeyemi Awọn akẹkọọ ile iwe giga ni ipinlẹ Oyo, Osun ati Ondo ti gunle ifẹhonuhan nitori ele to gori owo ina ijọba ati epo bẹntiro ni Naijiria.
 bí ẹrú bá sì jọra , ó dájú pé ilé kan náà ni wọ ́ n ti jáde .
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Oyenusi ló mú mi wọ ẹgbẹ́ adigunjalè kó tó di pé mo b'Ólúwa pàdé' Àwọn òṣèré Nollywood tí wọn ò sí lóri amóhùmáwòrán mọ́ Ìtàn ayé Tunde Idiagbon, ọ̀gágun Kògbagbẹ̀rẹ́ tí kò ṣeé fowó rà Aráyé ẹ gbà mí, nǹkan ń ṣe mí, èyí tó ju àìsàn lọ - Kanran Ọlọ́pàá Funso ló fi ààyè sílẹ̀ fún mi láti sá kúrò ní àgọ́ ọlọ́pàá tó wà ní Mokola - Sunday Shodipe Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 3 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 5 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Nítorí òun ni ó dá wa bí a ti rí, ó dá wa fún iṣẹ́ rere nípasẹ̀ Kristi Jesu, àwọn iṣẹ́ tí Ọlọrun ti ṣe tẹ́lẹ̀, pé kí á máa ṣe.
 A n be ijoba lati ran awa agbe olohun osin naa lowo nipa ipese owo iranwo ati eto eyawo ti ko ga ni lara lasiko yii paapaa awo agbe elewure ati aguntan ti a kere ni ye lasiko yii ki awon ere oko tiwa naa le po sii.
agbegbe ati ipese omi ni Ipinle Oyo (Ministry of Environment and Water
Orile-ede Naijiria ati Faranse ti towobo iwe adehun ibasepo ipese ohun amayederun ati igi gbingbin eyi ti iye owo re to million irinwo o le ni maarundinlogorin owo dola.
Èyí ti àwọn agbófinró fi tọpinpin rẹ̀.
Yoruba bo, won ni oju ni imole ara.
Kini idi ti wọn fi maa n pa tolotolo?
A ṣe agbeyẹwo diẹ lara awọn ileri naa.
Ilu Abẹokuta, tii se ilẹ Ẹgba, eyi to jẹ olu ilu ipinlẹ Ogun lode oni, ni Ẹfunsetan fori sọlẹ si Baba rẹ, Oloye Ogunrin jẹ akọni takuntakun lati agbegbe Ikija, nigba ti iya rẹ jẹ ọmọ bibi ilu Ile Ifẹ, to wa ni ipinlẹ Ọsun bayi Onisowo pẹpẹpẹ ni iya Ẹfunsetan, eyi ti Aniwura jogun lọdọ iya rẹ, amugbooro eto okoowo yii naa lo si n ti Ẹfunsetan ni ọpọnpọn, lasiko to ba kọwọ rin pẹlu iya rẹ lọ sawọn ọja gbogbo Itan ni Ẹfunsetan rin irinajo wa silu Ibadan lati wa se okoowo to gbooro nitori ilu to tobi nilu Ibadan lasiko naa, to si faaye gba okoowo nla Ẹfunsetan ri jajẹ, o lowo lọwọ, o ni ẹru toto ẹgbẹrun meji ati ọpọ oko, to si n ko ire oko lọ sawọn ilu bii Porto Novo, Badagry ati Ikorodu O tun dokowo ninu siga tita ati owo ẹru sise, bẹẹ lo tun maa n se eroja itọju ara labẹle Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Èmi gan máa ń béèrè lọ́wọ́ ara mi pé ta ni Wole Soyinka gangan' Ẹfunsetan se igbeyawo fun ọpọ igba amọ ọkan soso ni Ọba Oke fi ta lọrẹ, nigba ti itan miran ni ko tilẹ bimọ rara laye A tun gbọ pe ọmọ ti Ẹfunsetan bi jade laye lọjọ to bi, sugbọn itan miran ni ori ikunlẹ ni ọmọ kansoso ti Ẹfunsetan bi ku si lasiko ti ọmọ naa n rọbilati bi ọmọ Ìsẹ̀lẹ̀ yìí ni awọn eeyan kan sọ pe o sokunfa bi Ẹfunsetan se kilọ fun awọn ẹru rẹ pe ọkankan ninu wọn ko gbọdọ bimọ tabi loyun rara, iku ni ere ẹsẹ fawọn to ba bimọ Ẹfunsetan la gbọ pe o jẹ iya isalẹ ijọ Anglican nilẹ Ibadan nitori ipa to n ko lati se amugbooro ẹsin igbagbọ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Florida: Ọ̀ọ̀nì àléègbà dé ba Mary lálejò lọ́gànjọ́ òru Ọdun 1860 ni wọn fi Aniwura jẹ Iyalode ilẹ Ibadan amọitan ni Aarẹ Latoosa gba oye naa lọwọ rẹ lọdun 1874 Ọ́pọ igba la gbọ pe aawọ maa n waye laarin Latoosa ati Ẹfunsetan, ti wọn kii si ri imi ara wọn latan, tori pe Ẹfunsetan maa n gbo lẹnu Itan kan ni, oju orun ni Ẹfunsetan gba de oju iku nigba ti iroyin miran ni wọn fun ni majele jẹ ni.
Nínú àtẹ̀jáde náà tí Major Osoba Olaniyi tó jẹ́ adélé ìgbákeji àdári alukoro 81 Division fọwọ́sí ló ti sàlàyé pé, ilé iṣk ọmọogun ṣe àkíyèsí ìròyìn tó ń jà ràìn-ràìn lórí ayélujára pé, àwọn ọmọ ogún 81 Division ló yìnbọ pa àwọn olùwade ìfẹ̀hónúhan ni ìloro Lekki lógúnjọ, oṣù kẹ̀wàá, ọdún 2020.
Elkanah fikun un wi pe lara awọn ọgọfa yii ti wa ni ipinlẹ Eko tẹlẹ.
Nígbà tí wọ́n súnmọ́ Jerusalẹmu, nítòsí Bẹtifage ati Bẹtani, ní orí Òkè Olifi, ó rán meji ninu àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀; 
O ni awọn ọdaran to n da omi alafia ilu ru ko bọwọ fun ipo ti ẹnikẹni wa lawujọ, tabi odiwọn ọrọ ti wọn ni.
Idi ree ti wọn fi sọ ni inagijẹ Isiaka wolewole lasiko naa.
2%) awọn ọmọde ati ọṣọrọ ọdọ to ko arun yii to jade laye; nigba ti ida marundinlogun (15%) awọn agbalagba ti ọjọ ori wọn ti ju ọgọrin ọdun lọ laisan Coronavirus ti ran lọ sọrun.
Ẹ máa gbadura fún àwọn tí ó ṣe inúnibíni yín.
00 Oju omi gbogbo - 11,782,323,245.
Inú kànga ni wọ́n jù ú sí, ebi ni yóo sì pa á sibẹ nítorí pé kò sí burẹdi ní ìlú mọ́.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Imam tó ṣí Mọ́ṣálásì fáwọn Krístẹ́nì sọ ìdí tí kò fi lè ta wọ́n nù Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Ẹ kọ ara yín ní ilà abẹ́ fún OLUWA, kí ẹ sì kọ ara yín ní ilà ọkàn, ẹ̀yin ará Juda ati ẹ̀yin tí ẹ̀ ń gbé Jerusalẹmu; kí ibinu mi má baà dé, bí iná tí ó ń jó tí kò sí ẹni tí ó lè pa á, nítorí iṣẹ́ ibi yín.
Ṣugbọn ọkọ̀ rọ́lu ilẹ̀ níbi tí òkun kò jìn, ni ó bá dúró gbọnin.
Wọ́n fi ikú Tunde Braimoh dá wa lóró ni o - Ẹbí pariwo Ẹ̀yin ọmọ ìta tó ní Funke Akindele ra ilé fún mi, irọ́ ni o - Ajirebi Ìtàn ayé Henry Fajemirokun, olówó tó fi owó mọ Olúwa àti ènìyàn Báwo ni Coronavirus ṣe n tànkálẹ̀ l'Afrika?
Gbogbo igbesi aye rẹ waye laarin ọdun 1951 si ọjọ kẹrin, oṣu kẹfa ọdun 1996.
DiBella ni Day pinu lati maa ja ẹṣẹ nitori ẹṣẹ kikan ni iṣẹ to yan laayo, ohun si ni o jẹ nnkan iwuri fun un.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Wo bí ìyàwó ṣe le gbé ọmọ Ọbà fún Ọ̀ṣun láì yan àlè Ẹ wo ọba kan nílẹ̀ Yorùbá, tí kò ṣe ètùtù tàbí náwó ànájù, kó tó jọba Irú ẹ̀dá wo ni Lamidi Adeyemi?
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ilé aṣòfin àgbà: Ìsìnmi olóṣù méjì wa kò le è ṣàkóbá fún àyẹ̀wò mínísítà 10 Agẹmo 2019 Oríṣun àwòrán, @Bashirahmaad Aarẹ ile asofin agba, Ahmad Lawan ti kede pe, aarẹ Muhammadu Buhari yoo gbe orukọ awọn eeyan to fẹ yan sipo minisita wa siwaju ile asofin agba lati sagbeyẹwo wọn ki ọsẹ yii to pari.
Òkùnkùn biribiri ń dúró dè é,iná tí eniyan kò dá ni yóo jó o ní àjórun,ohun ìní tí ó kù ní ibùgbé rẹ̀ yóo sì parun.
Ondo: Gómìnà Akeredolu fa ìjọba lé igbákejì rẹ̀ lọ́wọ́
OLUWA àwọn ọmọ ogun ní, “Wọn yóo jẹ́ eniyan mi, ní ọjọ́ tí mo bá fi agbára mi hàn, wọn yóo jẹ́ ohun ìní mi pataki.
George Floyd ní àrùn coronavirus Arakunrin adulawọ, George Floyd ti iku rẹ ti n da rogbodiyan silẹ kaakiri orilẹede Amẹrika atawọn ilu nlanla miran jakejado agbaye ni wọn ni ayẹwo fihan pe o laarun coronavirus ko to jade laye.
Lẹ́yìn èyí ni àwọn ará Amaleki wá, wọ́n sì bá àwọn ọmọ Israẹli jagun ní Refidimu.
Buhari: Sáà kan ṣoṣo loó máa lò látìsinyìí lọ Sọ àsọtẹ́lẹ̀ nípa ikọ̀ tí yóò gba ife ẹ̀yẹ àgbáyé 2018 pẹ̀lú eré ìdárayá tuntun ti BBC Anthony Joshua gba àmì ẹ̀yẹ kejì lọdọ Ọbabìnrin Elizabeth Gbọ iroyin iṣẹju kan BBC Fidio wa fun toni 'Bóo rántí ikú Gáà kóo ṣòótọ́ ni ọ̀rọ̀ Abacha' Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Ọpọ̀ ẹ̀mí èèyàn ló bọ́ lọ́wọ́ Abacha láàrín 1993 sí 1998' Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Ẹni ọdún mẹrindinlogun ni, nígbà tí ó jọba.
8 165560 Orilẹede Afganistan 2324 6.
Awọn kan ni eyi tumọ si pe ooya (cutting comb) ti awọn iya wa fi n yarun laye atijọ a ya irun naa daadaa ni.
Egypt ṣíná fún Zimbabwe, ẹ̀kọ́ mẹ́rin tó yẹ ní kíkọ́ Ẹyẹ ju ẹyẹ lọ, Super Eagles fi àmì ayò kan gbé ẹyẹ Swallow ti Burundi mì Ọmọ Naijiria, ẹ ṣọ́ra lórí ọ̀rọ̀ Ebola Oko òkú rèé, níbití òkú ti ń jẹrà mọ́lẹ̀ fún àyẹ̀wò Ìgbà Marún-un ti Aisha Buhari ti tako ìjọba Buhari Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí kan sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
O le yi ọkan rẹ pada ko kuku moju kuro lara ololufẹ ọhun patapata ki o tẹ siwaju ninu irin ajo aye rẹ.
Ko si si idi meji ti wọn so mọ ọrọ yii ju edeaiyede lori ikọlu awọn ajeji lorilẹede South Africa lọwọlọwọ.
Akonimoogba agba iko agbaboolu Super Eagles, Gernot Rohr ni igbagbo pe iko re lee gba ami dogba-dogba tabi ki won fagbahan iko agbaboolu orile-ede South Africa lati pegede fun idije boolu afesegba ile Afrika to n bo lona lọdun 2019 (AFCON).
Ẹwẹ, baba kan ẹni ọdun marundinlọgọrin to jẹ alakoso ibudo yii, Abdulraheem Owotutu ni oun ko fipa mu ẹnikẹni ninu awọn to wa ni ibudo yii.
Nítorí èyí ni wọn kò fi lè gbàgbọ́, nítorí Aisaya tún sọ pé,
Orileede Amẹrika ni iyawo rẹ n gbe ni gbogbo igba ti wọn tuka.
Wo àwọn oúnjẹ tí àṣẹ Buhari leè mú kó gbówó lórí Àjẹ́ àti Aṣẹ́wó ní ìyá Rainbow - Òjòpagogo Akọwe ijọba apapọ ni aarẹ Buhari gbe igbesẹ naa lọna ati fun Obono-Obla ni anfaani lati dahun awọn ẹsun iwa ọdaran to nii se pẹlu iwa ajẹbanu ti ajọ to n tanna wadi iwa ibajẹ ICPC fi kan-an.
Àwọn eniyan yóo jọ́sìn ní ẹnu ọ̀nà àbáwọlé níwájú OLUWA ní ọjọ́ ìsinmi ati ní ọjọ́ ìbẹ̀rẹ̀ oṣù.
’ Bí angẹli kan ti ń sọ ọ̀kan bẹ́ẹ̀ ni òmíràn sì ń sọ nǹkan mìíràn.
Ogunrinu ati bẹẹ bẹẹ lọ Kini ‘technology’ ni ede Yoruba?
Wọ́n yí i ká bí àwọn tí ó ń ṣọ́ oko,nítorí pé ó ti ṣọ̀tẹ̀ sí OLUWA.
Fun ọpọlọpọ ọjọ lẹyin ti aarẹ Madagascar sọ pe oun ti ri iwosan fun Covid-19, ni ọpọ eniyan ti n gba ọrọ naa bi ẹni gba igba ọti.
Mo fòpin sí àjẹbánu lórí owó ìrànwọ́ epo àti iná ọba, ní èlé ṣe wáyé - Buhari Ijọba Aarẹ Buhari ti ni o pọn dandan fun oun lati gbe igbesẹ to gbe nipa fifi owo le owo epo bentirol ati ina mọnamọna.
Atẹjade kan ti alukoro ileesẹ ọlọpaa ni ipinlẹ Ọsun, Fọlasade Aduro fọwọsi lo sisọ loju ọrọ yii, to si tun kede orukọ awọn afurasi to wa nidi ẹsun naa.
Àwọn akikanju yòókù bẹ̀rẹ̀ sí yan bọ̀,àwọn eniyan OLUWA náà sì ń wọ́ bọ̀,láti gbógun ti alágbára.
Orisun isẹ iroyin tuntun Ẹni-ọwọ Henry Townsend se agbekalẹ ileesẹ itẹwe akọkọ lorilẹede Nigeria lọdun 1854, eyi to papa lo, lẹyin ọdun marun to se ifilọlẹ rẹ, lati fi tẹ iwe iroyin akọkọ lorilẹede Nigeria sita ni ede abinibi Yoruba,eyi to pe ni Iwe Irohin Fun Awọn Ara Ẹgba Ati Yoruba""."
Se ẹ wa rii pe eyi lo ṣalaye idi ti ẹni ti wọn ni kii lọ ṣọọsi deede sibẹ to tun wa n ja fun ki wọn ṣi awọn ile ijọsin silẹ titi ọjọ kejilelogun, oṣu karun un bibẹẹ kọ oun yoo gbe igbesẹ lai fi tawọn gomina ṣe.
O fikun wi pe awọn ko mọ nipa owo itọnran ti awọn ajinigbe n beere ni ọwọ awọn ẹbi ẹni ti wọn jigbe, ati wi pe awọn ko fi ọwọ si i.
"Mo wa n daba pe ki wọn tete fi ami ẹyẹ da Jakande lọla, wọn ko si gbọdọ fun ni ami ẹyẹ to kere si Commander of the Federal Republic.
Àwọn kan bá lọ sọ fún ọba Jẹriko pé, “Àwọn ọkunrin kan, lára àwọn ọmọ Israẹli, wá sí ibí ní alẹ́ yìí láti ṣe amí ilẹ̀ yìí.
” Ó da oúnjẹ náà sinu ìkòkò, ó sì wí pé, “Bu oúnjẹ fún àwọn ọkunrin náà, kí wọ́n lè jẹun.
Àwọn ẹ̀ṣọ́ náà kò fi ipá mú wọn, nítorí wọ́n bẹ̀rù àwọn eniyan kí àwọn eniyan má baà sọ wọ́n ní òkúta.
Adewole nikan lo ku ninu awọn ti wọn dijọ wa ninu ẹgbẹ olorin Ayinla Omowura, gbogbo awọn eeyan yoku ti lọ.
Odu ifa to ba jade ni yoo sọ nkan ti yoo wa ninu ẹbọ ajẹ.
wọn á ní kí ó pe, “Ṣiboleti.
< Atiku Abubakar 57 miliọnu awọn ọmọ Naijiria ni ko lanfani si omi to mọ gaara bẹẹni aadoje miliọnu ninu ọmọ orilẹede Naijiria lo n gbe ni ayika to dọti laisi eto imọtoto gidi.
Abubakar sọrọ ọhún níbi ìfọrọwanilẹnuwo kan táwọn akọ̀ròyìn se fun.
Yatọ̀ sí pé ó ṣe sọ́jà, tó tún jẹ́ ọkọ Oriṣabunmi, wo àwọn nkan tí o kò mọ̀ nípa Jimoh Aliu Ọdún mọ́kànlá rèé témi àti ọkọ mi bẹ̀rẹ̀ ìfẹ́ láti ilé ẹ̀kọ́ girama - Bukunmi Oluwasina Wo ọ̀rọ̀ Fani-Kayode sí akọ̀ròyìn blog"" tó ní lílù ìyàwó rẹ̀ bíi bàrà ló mú wọn túká Ki a ma wulẹ dena pẹnu pupọ, ẹkunrẹrẹ ohun to ṣẹlẹ ree Falana gbọ tiẹ,Ọlọrun ti doju ti yin naa-Seyi Edun Esi yi ni gbajugbaja oṣere Seyi Edun fọ fun eeyan kan @dorathy_137 to bọ sori opo rẹ ni Instagram lati sọ fun pe ko wa bi yoo ti ṣe loyun fun ọkọ rẹ."
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, O sa kuro ni Cote d'Ivoire ko to tun lọ si orilẹ-ede France Wọn pada fii silẹ kuro ni ẹwọn gbere lọdun 1993 lẹyin ti o ṣẹwọn.
Ó gbọ́ pé Saulu ti lọ sí Kamẹli, níbi tí ó ti gbé ọ̀wọ̀n kan kalẹ̀, ní ìrántí ara rẹ̀, ati pé ó ti gba ibẹ̀ lọ sí Giligali.
anfaani yii lati je ki ibasepọ tun fẹsẹ mulẹ sii laarin awon to n gbe ni
Awon asofin ohun se ipade alatilekun mori, eleyi ti o waye fun wakati kan gbako.
 awon iwe re olokan-o-jokan lo gun opolopo awon onkowe ile yoruba lonii ni kese ni eyi ti o mu ilosiwaju ba ede yoruba lapapo .
Eyi si ni akọsilẹ awọn Olori Oṣiṣẹ aarẹ to ti jẹ lati igba naa: Abdullahi Mohammed - Oṣu Karun 1999 si oṣu Kẹfa 2008 Gbolade Oṣinowo - Oṣu Kẹfa, 2008 si oṣu Kẹsan, 2008 Mike Oghiadomhe - Oṣu Karun 2010 si oṣu Keji 2014 Jones Arogbofa - Oṣu Keji 2014 si oṣu Karun 2015 Abba Kyari - Oṣu Kẹjọ 2015 si oṣu Kẹrin 2020 Awọn ojuṣe olori awọn oṣiṣẹ fun aarẹ Naijiria Ojuṣe Olori awọn oṣiṣẹ aarẹ yatọ sira wọn lati iṣejọba kan si omiran.
Àwọn ọmọ Israẹli ṣí kúrò níbẹ̀, wọ́n pa àgọ́ wọn sí Obotu.
Cape Verde: Orilẹ ede yii jẹ ibi omi ti o wa ni ila Oorun Adulawọ.
ohun fi idunnu won han, ti won si n ki ara won terin toyaya.
N óo ti wà pẹlu yín pẹ́ tó?
Oríṣun àwòrán, @Love96047280 O ni ọpọ ọja ti owo rẹ to aimọye miliọnu naira ni wọn ko lọ nibẹ lai jẹ pe ara South Africa lo ni ibudo itaja naa.
Àkọlé àwòrán, Ninu awọn olori Kabiesi Olori ni onikaluku lo mọ idi to fi fẹ ọkọ rẹ ati pe oun ko kabamọ pe oun fẹ Kabiesi.
Oríṣun àwòrán, Mercy Blankson/Facebook Àkọlé àwòrán, Mercy, aya oloogbe Blankson ni o da bi ẹni pe awọn ri awọn apẹẹrẹ ki iṣẹlẹ buruku naa to waye.
Eyi ko si ṣẹyin kẹkẹ igbalode kan to ni awọn eroja irọrun to ṣe e yi si ọtun ati osi, oke ati ilẹ, ibi to ba si wu eeyan, lo le e yi kẹkẹ naa si.
Awọn to ku ni: Rivers-56 Delta-31 Ebonyi-30 Gombe-28 Ondo-20 Kaduna-20 Kwara-20 Ogun-17 FCT-16 Edo-13 Abia-10 Nasarawa-9 Imo-9 Bayelsa-8 Borno-8 Katsina-8 Sokoto-3 Bauchi-3 Plateau-2 Lọwọlọwọ, o ti pe eniyan 20,919 to ti ni aarun naa.
Iléẹjọ́ ní Elijah Abbo kò lẹ́jọ́ jẹ́ Ẹ̀sín wa kò ní bọ́ sọ́wọ́ ọ̀tá, Arsenal gbọdọ̀ na Chelsea lónìí - Lacazette Oríṣun àwòrán, Lasema Àkọlé àwòrán, Ṣọọbu ti wọn ti n ta ibusun kan nibẹ ni ina naa ti kọkọ sọ ki o to ran de awọn ṣọọbu itaja miran to sun mọ ọ.
Ṣugbọn ní ti àwọn tí ó jẹ́ pé ti ara wọn nìkan ni wọ́n mọ̀, ati àwọn tí kò gba òtítọ́, àwọn tí wọ́n gba ohun burúkú, Ọlọrun yóo fi ibinu ati ìrúnú rẹ̀ hàn wọ́n; 
Ọkọ Risikat ní ojú búlúù tí ìyàwó òun ní gan an lòun ṣe fẹ́ ẹ Ọkọ Risikat Moromoke Azeez, iya awọn ọmọ oloju buluu, Wasiu Dada ti sọ pe ija lode ni orin di owe, o ni oun ko le iyawo oun nitori o bi awọn ọmọ oloju buluu.
Ogbontarigi onisowo orile-ede Sudan ati ile Geesi Ibrahin so pe, inu oun dun lati ri pe, Johnson-Sirleaf gba ami eye obinrin akoko naa.
Èdè Yorùbá kógo àbùdá wọ̀nyí já.
Yíyọ Orúkọ Eniyan kúrò ninu Orúkọ Àwọn Eniyan OLUWA.
Gomina Abdullahi Ganduje so pe, sise itore owo ohun ni o waye, ni ona lati mu idagbasoke ti o yekooro ba iko kookan nipinle naa.
Ẹnikẹni to ba tapa sawọn ofin tuntun yi yoo san owo itanran.
Ni bayii, iforukọsilẹ awọn oludibo ni wọn n ṣe lọwọ ki idibo gangan to bẹrẹ.
Nigba to n ba awọn akọroyin sọrọ lori ikede ile ẹjọ naa, igbakeji aarẹ fun ẹgbẹ TUC, Chika Onuegbu sisọ loju rẹ pe, awọn ko tii ri iwe kankan gba lati ile ẹjọ to tako iwọde ti awọn n gbero yii.
Àpáta ayérayé, mo sá di Ọ ́o
Security: Ìpínlẹ̀ 9 yóò lo ẹ̀rọ ayàwòrán díróònù láti paná ìpèníjà ààbò
Egbe yii ti oruko won n je Muslim Lawyers' Association (MULAN) ẹ̀ka ti ipinlẹ̀ Kano salaye ipo ti asẹ ofin Sharia wa ninu eto ilana ofin Naijiria.
O fikun oro re pe, eto irnna oko oju-omi yoo tun bo gberu si, ti ile-igbimo asofin ba bowolu iwe abadofin ile-ise NIWA tuntun ti o wa niwaju won.
Oríṣun àwòrán, Screenshot Bakan naa ni wọn n sekilọ pe, tawọn janduku naa ba kọ eti ọgbọin si ikilọ naa, lai da asẹ ọba pada, ohun ti oju wọn ba ri, ki wọn fara mọ.
nínú bíbélì , Áárọ ́ nì ni ègbón mósè .
''Owo bentirol yoo lọ soke si lasiko ti ijọba ni ki awọn elepo maa diye le owo epo.
Agbabọọlu naa, to ti gba bọọlu fun Naijiria ni igba mẹrindinlọgbọn sọ pe, ṣiṣe bẹẹ yoo jẹ ki ijọba apapọ mọ bi ọrọ ṣe gbona si lara wọn.
Ó sọ pé, àwọn ẹ̀gbọ́n òun ti pa á láṣẹ fún òun láti wá sí ibi àjọ̀dún ẹbọ ọdọọdún ti ìdílé wọn.
Nigba ti awọn miran ni wi pe ko ṣe nkankan ati pe ko buru nitori awọn miran n gba owo lori iṣẹ ti wọn n se.
Ìdí tí ó fi ṣe èyí ni pé, ó fẹ́ràn àwọn baba ńlá yín, ó sì yan ẹ̀yin tí ẹ jẹ́ ọmọ ọmọ wọn; ó fi agbára ko yín jáde láti ilẹ̀ Ijipti, ó sì wà pẹlu yín.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Fake Lawyer: ₦300,000 ló gbà lọ́wọ́ obìnrin kan, tó sì fẹsẹ̀ fẹ 24 Owewe 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 1 Agẹmo 2020 Oríṣun àwòrán, Others Ọwọ awọn agbofinro ni ipinlẹ Ogun ti tẹ arakunrin kan to n pe ara rẹ ni agbẹjọro lati fi tu awọn eeyan jẹ.
Oyedepo lo sọ ọrọ naa lọjọ Abamẹta to jẹ aṣekagba ipade adura Shiloh, eyii to maa n waye lọdọdun.
Nítorí gbogbo ẹ̀dá ojú ọ̀run ni a óo mì tìtì.
com Àkọlé àwòrán, ìtọ̀ di ohun mimu ni China Awọn ọlọpaa ìpín Zunyi mu awọn oluṣakoso mẹta, wọn sì tí gbà idajọ ẹwọn.
Mo kawe o ṣugbọn mi o kawe to oye dokita (PhD), oye onipele ikini (BSc) ni mo kawe gba oye rẹ ninu imọ ẹkọ Psychology.
5M ti pọ̀ jù fún owó fọ́ọ̀mù ìdìbò abẹ́lẹ́ sípò gómìnà APC - SERAP 21 Èbibi 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 25 Èbibi 2020 Oríṣun àwòrán, @Pristinenetwor1 Adari agba ajọ SERAP, Adetokunbo Mumuni ti sọ fun BBC pe oṣẹlu ko ni rọrun ti awọn ẹgbẹ oṣẹlu ba n gba owo gọbọi lọwọ awọn to fẹ gbe apoti ibo.
 wọn kì í dédé sọ ̀ rọ ̀ bí kò bá ṣe wí pé ó lóhun tí ònkọ ̀ tàn rí .
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Plastic Bags: Kíni ìdí tí wọn fi fẹ́ fòfin de lílo nylon ní Naijiria?
Ranti ìjọ eniyan rẹ tí o ti rà ní ìgbà àtijọ́,àwọn ẹ̀yà tí o rà pada láti fi ṣe ogún tìrẹ;ranti òkè Sioni níbi tí o ti ń gbé rí.
Ni eyi ti wọn ti fun Burundi ni ami ayo ookan si odo lọjọ kẹtadinlọgbọn, oṣu kẹfa.
Jobu bá dá OLUWA lóhùn ó ní:
Amọ, o sọ pe ewu nla lo wa ninu akọsilẹ to n fihan pe eeyan perete lo n ko aarun covid-19 lojoojumọ nitori ọpọ lo ti n sinmi bayii pe corovavirus ti lọ.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Awọn gomina lawọn o le san ọgbọn ẹgbẹrun Naira f'oṣiṣẹ Aarẹ ẹgbẹ oṣisẹ, NLC Ayuba Wabba ni ẹgbẹ naa ko mọ ohun kankan nipa aṣẹ ti ile-ẹjọ pa, bẹẹ ni awọn ko gba iwe kankan lati ile-ẹjọ.
Kò sí àléébù ninu ìgbé-ayé wọn.
 Àwọn kan tán sí Èkìtì , àwọn mìíràn si tan sí ìpínlẹ ̀ kwárà .
Ìyàlẹ́nu ńlá ni ó jẹ́ fún gbogbo wọn.
“Ya àwọn ọmọ Lefi sọ́tọ̀ fún mi gẹ́gẹ́ bí ọrẹ fífì láti ọ̀dọ̀ àwọn ọmọ Israẹli; wọn óo sì máa ṣe iranṣẹ fún Aaroni alufaa ati àwọn ọmọ rẹ̀.
Gbogbo ipele ijoba meteeta lo ti n sise takun-takun  pelu awon adari ati awon elesin lati rii pe alaafia joba lawon agbegbe naa.
Ẹwẹ, o sọ pe kii se wipe awọn oniroyin ko fẹ gbe iru isẹlẹ bayii sori afẹfẹ sugbọn ko ya awọn obinrin to ni iriri yii gaan lori lati sọrọ.
Amọ awọn akọsilẹ kan sọ pe igbesẹ wọn yii ko dun mọ awọn olori apa Ariwa lọrun, ti wọn si n bẹru pe ominira yoo fi agbara fun awọn to wa ni Gusu lati maa dari ọrọ aje ati oṣelu.
Ewe wonyii ni awon ilana to
A bi Ọmọwe John Olukayọde ọmọ Fayẹmi lọjọ kẹsan an, oṣu kejì, ọdun 1965 ni Iṣan- Ekiti, nijọba ibilẹ Ọyẹ Ekiti nipinlẹ Ekiti.
N óo yọ́nú si yín bí ìgbà tí mo bá gbọ́ òórùn ẹbọ dídùn, nígbà tí mo bá ń ko yín jáde kúrò láàrin àwọn orílẹ̀-èdè mìíràn, tí mò ń ko yín jọ kúrò láàrin gbogbo orílẹ̀-èdè tí ẹ fọ́nká sí.
Láti ìgbà tí ọba ti kúrò ní Jerusalẹmu, títí tí ó fi pada dé ní alaafia, Mẹfiboṣẹti kò fọ ẹsẹ̀ rẹ̀; bẹ́ẹ̀ ni kò gé irùngbọ̀n rẹ̀, tabi kí ó fọ aṣọ rẹ̀.
OLUWA ni ìmọ́lẹ̀ ati ìgbàlà mi;ta ni n óo bẹ̀rù?
Kò wúlò fún ohunkohun mọ́ àfi kí á dà á nù, kí eniyan máa tẹ̀ ẹ́ mọ́lẹ̀.
 gẹ ́ gẹ ́ bí akọ ́ nimọ ̀ ọ ́ gbá , ìwé ìrántí rẹ ̀ fiwàn wípé bethany borí ní ìgbà méje , ósì pàdánù ní ìgbà mẹ ́ tàlá .
eto iroyin ati ikede, Garba Shehu ni aare Buhari ti fọkan gbogbo omo orile ede
Ó ṣe nǹkan tó burú lójú OLUWA, ó rìn ní ọ̀nà Jeroboamu, ó sì dá ẹ̀ṣẹ̀ tí Jeroboamu mú kí Israẹli dá.
Ogagun  Otiki soro yii lasiko to n ba awon akoroyin
Nígbà tí ilẹ̀ ṣú, àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ sọ̀kalẹ̀ lọ sí èbúté, 
Pagieli ọmọ Okirani ni olórí ẹ̀yà Aṣeri.
Orile-ede Ghana, Burkina Faso ati Algeria naa tele ra-won pelu ipo kejo, kesan-an ati ikewa lori ipo ate tuntun ohun.
Àwọn arakunrin rẹ̀, ati gbogbo àwọn ará ilé rẹ̀ bá wá gbé òkú rẹ̀, wọ́n lọ sin ín sáàrin Sora ati Eṣitaolu ninu ibojì Manoa, baba rẹ̀.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Idaamu Boko Haram: Igbẹjọ awọn afunrasi bẹrẹ ni gbangba loni 12 Èrèlè 2018 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Orilẹede Chad se igbẹjọ ati idajọ fun awọn Boko Haram Igbẹjọ ọlọgọọrọ eniyan ni gbangba yoo bẹrẹ fun awọn afunrasi ọmọ ikọ Boko Haram loni, (ọjọ aje) ni ile-iṣe awọn ologun ni agbegbe aarin gbungun orilẹede Naijiria, ni ilu Kainji.
 lẹ ́ yìn tí ó kàwé-gboyè tán , ó forúkọ sílẹ ̀ láti dara pọ ̀ mọ ́ ọmọ ogun ilẹ ̀ amẹ ́ ríkà u.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Lagos Police: Àwọ̀n ọlọ́kadà 123 láti Jigawa kìí se àwọn agbésùnmọ̀mì 31 Ògún 2019 Oríṣun àwòrán, Twitter/The Lagos State Govt Àkọlé àwòrán, Kini aduru gbogbo ero yii n bọ wa ṣe lEko lati ariwa ni ibeere awọn eniyan Ile iṣẹ ọlọpaa ni ipinlẹ Eko ni awọn ti fi awọn ọlọkada to le ni ọgọfa to wa lati ipinlẹ Jigawa wa si ipinlẹ Eko silẹ nitori wọn kii ṣe ọdaran.
Biṣọọbu naa tun rọ awọn ọmọ orilẹ-ede Naijiria lati tubọ fara sin Oluwa ninu ipo gbogbo.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Oluwọde tako ele owo epo ni Ghana Kòkòrò ajokorun tuntun wọ̀lú Super Falcons f'idi rẹmi ninu WAFU Àláìsàn Ebola sá kúrò níléwòsàn lọ sí ṣọ́ọ̀ṣì Àwọn ọlọ́pàá sọ fún ikọ̀ ìròyìn BBC pé wọn ó pèé lẹ́jọ́ ní ìlànà òfín ní kété tí ìwádìí bá ti parí.
O fi apẹrẹ orukọ awọn to sọrọ nipa wọn sita.
Dida lọna ti Isah loun n sọ ni eleyi to ni ṣe pẹlu ikọlu to waye laarin awọn ọlọpaa ati awọn to ji olori ilu Daura naa gbe.
Wọ́n mú ní papámọ́ra wá sí ilé Ọba.
"Pẹlu gbogbo ogo si Ọlọrun to ga julọ to mu mi de ibi ti mo de yii lori it awọn baba mi.
Lasiko abẹwo naa to waye nile ijọba ipinlẹ ọhun to wa ni Marina nilu Eko, ni Tinubu ti ba awọn oniroyin sọrọ, to si sọ pe irọ ni iroyin to sọ pe oun sa kuro ni Naijiria lasiko rogbodiyan to waye.
Madam Ṣajẹ yóò ma sojú wọn ilé iṣẹ kan ti wọ́n ntale talẹ.
95bn sórí reluwé làti Kano sí Niger Republic- PDP Nínú akànṣẹ́ mẹ́ta ọmọ Nàìjíríà tó dáńtọ́ lágbàáyé, Yorùbá méjì wà nínu wọn Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 3 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 5 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
 Bakanaa ni agbẹnusọ fun ileesẹ ọlọpa nipinlẹ Plateau, Mattias Tyopev, fidi isẹlẹ yii mulẹ amọ to ni, ko tii si ẹkunrẹrẹ iroyin nipa isẹlẹ yii."
Ẹ̀yin ará Elamu, ẹ gòkè lọ!
Yorùbá dùn lédè, ẹ máa sọọ́ 'Mo máa ń parọ́ díẹ̀díẹ̀ ṣùgbọ́n kò pọ̀' Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí OPC láwọn mú afurasí agbébọn ajínigbé mẹ́rin l'Oyo, ọlọ́pàá ní àpapọ̀ òṣìṣẹ́ elétò aàbò ló ṣiṣẹ́ náa22 Owewe 2020 Fídíò, Akomolede àti Aṣa: Ọ̀rọ̀ Ẹ̀yán ni Bunmi Femi Amao ń kọ́ wa lórí ètò Akọ́mọlédè àti Àṣà lórí BBC Yorùbá24 Owewe 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Ajọ Isokan Agbaye ni ẹnikan ninu ogun eniyan to ba ni arun Coronavirus lo ma n nilo itọju pajawiri, eleyii le jẹ ki wọn kun ẹni naa loorun ni ileewosan tabi ki wọn bẹrẹ si ni lo ẹrọ ventilator lati mi fun ara wọn.
Amọ ki gaan lawọn ohun to jẹ ojulowo to n fa aisan iba?
Oríṣun àwòrán, Twitter Àkọlé àwòrán, Ijọba ìpínlẹ̀ Eko ti ní ó ṣeeṣe kí òfín kónílé-ó-gbélé ó tẹ̀síwájú nítórí iye àwọn tó ní àrùn náà ń peléke si.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Kò tán síbẹ̀, ọkọ aladani ni orileede Uganda kò gbogbo kò ju èrò mẹta lọ tó fi mọ awako.
16 Òkùdu 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 27 Òkùdu 2020 Oríṣun àwòrán, Makinde Gómìnà ìpínlẹ̀ Oyo, Seyi Makinde tí fi léde lórí ojú òpó ìkànsíraẹni Facebook rẹ̀ pé, mẹ́ta nínú àwọn ìgbìmọ̀ aláṣe ìjọba ìpínlẹ̀ Oyo ló ti ni ààrùn Coronavirus bayìí.
Èèyàn mẹ́jọ jónà ráúráú nínú ìjàmbá ọkọ̀ akérò tó ṣẹlẹ̀ ní mọ́rosẹ̀ Eko sí Ibadan Ẹ̀rí tuntun BBC Africa Eye yìí tú àṣírí ohun tó ṣẹlẹ̀ gangan nínú ìbúgbàmù Abule Ado Wo àwọn báńkì tó wà lẹ́yìn àwọn olówó èlé bí MMM Ọ̀wọ́ngógó búrẹ́dì gbòde kàn lẹ́yìn tí àwọn oníbúrẹ́dì da iṣẹ́ sílẹ̀ Ọlọ́jọ́ Festival 2020:Ọ̀ọ̀ni ti Ilé Ifẹ̀ tí wọ ìléèdí ọlọjọ méje tí kò ní rí ẹnikẹ́ni sójú Eyan Ajorukọ Ẹyan Aṣapejuwe Eyan Asorukọ Eyan Atọka Aṣafihan Eyan Aṣonka Àwọn ọba Yorùbá kan rèé tí wọ́n rọ̀ lóyè, tí ọba míràn jẹ lójú ayé wọn Duro Ladipọ, ìlúmọ̀ọ́ká òṣèré tíátà àti ọmọ àlúfà tí kò gbàgbé àṣà ìbílẹ̀ Ọba Lamidi Adeyẹmi, òṣìṣẹ́ adójútòfò àti Abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò kó tó jọba Wole Soyinka rèé láti kékeré Àlàyé rèé lórí bí wọ́n ṣe mú mi lẹ́rú ní 1837 - Ajayi Crowther Eyan Arọpo Orukọ Eyan Afarajorukọ Eyan Awẹ gbolohun Afarahe Aṣapejuwe.
Ṣugbọn ṣá, èmi kì bá tí mọ ẹ̀ṣẹ̀ bí Òfin kò bá fi í hàn mí.
“Bí kò bá ní agbára láti mú ọ̀dọ́ aguntan wá, ohun tí ó tún lè mú tọ OLUWA wá gẹ́gẹ́ bí ẹbọ ìmúkúrò ẹ̀ṣẹ̀ ni àdàbà meji tabi ọmọ ẹyẹlé meji, ọ̀kan fún ẹbọ ìmúkúrò ẹ̀ṣẹ̀, ekeji fún ẹbọ sísun.
DSP Oyeyemi fidi rẹ mu lẹ pe ibọn ọkan lara awọn to doju ika kọ awọn ọlọpaa naa gbẹmi mi tawọn yoku si farapa.
lati samulo re fun idagbasoke eto oro aje orile-ede Naijiria.
Awọn yii kan naa ni wọn a ni nilẹ Yoruba, bi wọn ba ti le kọja ọgbọn ọdun laye, wọn ti ye e niyẹn.
Ọmọ Nàìjíríà, àfikún owó iná tuntun bẹ̀rẹ̀ lónìí: ọjọ́ kínní, oṣù kẹsàn án, ọdún 2020- NERC, Disco Ìjọba ìpínlẹ̀ Eko ti bẹ̀rẹ̀ àtúnkọ́ ilé tí ẹlikọ́pútà tó jábọ́ bàjẹ́ ní ìlú Eko Àṣírí tú!
Mompha: Dúkìá rẹ̀ ní Mompha lọ gbà lọ́dọ̀ EFCC, ló bá kó sí àhámọ́
O fidi ẹ mulẹ pe bi ẹfọn to n fa àìsaǹ ibà ṣe maa n gboorun naa ni o ti hande pe àwọn ajá naa n gboorun.
Ní ìkẹyìn gbogbo wọn, obinrin náà wá kú.
Ẹwẹ, ijọba ti fi ọrọ sita pe ofin aisi irina yii ko kan awọn to n kọ idanwo aṣekagba girama WAEC nipinlẹ Eko ati ni Bayelsa.
Nígbà tí ìjà yìí kọ́ bẹ̀rẹ̀, Èṣù-kékeré gbìyànjú láti ri àyè sọ mọ́ bàbá mi ni ìbàdí, kí ó fi ẹ̀hìn rẹ̀ ti igi ẹlẹ́gùn-ún, kí gbé ẹsẹ̀ onítọ̀hún dé èjìká.
 mo ranjú kankan mọ ́ mọ ́ lúbi Ọ ̀ nà riri lẹ ̀ gbọ ́ n ; agbára làbúrò ènìyàn le lagbára kó máà rí ọ ̀ nà .
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Mobile Wash: iṣẹ́ fífọ́ mọ́tò tà ni mó yàn láààyò- Slay Mama Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
O tun ti kọni ni fasiti Oxford, Havard ati Yale ati bẹẹ bẹẹ lọ loke okun.
Jeremaya bá pe Johanani, ọmọ Karea ati gbogbo àwọn olórí ogun tí wọ́n wà pẹlu rẹ̀, ati gbogbo àwọn eniyan, ati àwọn mẹ̀kúnnù ati àwọn eniyan pataki pataki.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Bí Hushpuppi ṣe tiraka rèé l‘Eko, kí ọlà ‘òjijì’ tó dé Akẹ́kọ̀ọ́ wọlé padà, ìjọba Oyo kò pèsè ìbòmú lòdì sí ìlérí rẹ̀ Ẹ wo bí ọ̀rọ̀ òṣèlú, ẹ̀sìn àti ẹ̀yà ṣe fa ogun abẹ́lé Biafra Kàkà k‘éwé àgbọn dẹ̀ lágbo òṣèlú l‘Ondo, akọ̀wé ìjọba tún kọ̀wé fipò sílẹ̀ Ẹ wo bí ọ̀rọ̀ òṣèlú, ẹ̀sìn àti ẹ̀yà ṣe fa ogun abẹ́lé Biafra Lọtẹ yii, o dabi ẹni pe ọrọ ẹnu Bimpe yatọ si awọn aworan tuntun yii.
Aluwẹ, ọmọ iya Alaro: Oríṣun àwòrán, Aluwe/instagram Àkọlé àwòrán, Ko si aniani pe yoruba lo pilẹ ere sinima agbelewo lorilẹede Naijiria Ṣaṣa ni awọn ti o mọ ipilẹ ere sinima ede Yoruba, ti ko mọ nipa Sunday Ọmọbọlanle ti ọpọ eeyan mọ si Aluwẹ tabi Papi Luwẹ.
Coronavirus: Àwọn ọmọ Nàìjíríà ń kán Seyi Makinde níkòó fún ìgbàlejò ìpàdé ìtagbangba PDP níbàdàn lásìkò àjàkálẹ̀ àrùn coronavirus Oríṣun àwòrán, Facebook/PDP Àwọn ọmọ Nàìjíríà ń kán Seyi Makinde níkòó fún ìgbàlejò ìpàdé ìtagbangba PDP níbàdàn lásìkò àjàkálẹ̀ àrùn coronavirus Ọpọ lo ti n bu ẹnu atẹ lu bi Gomina Seyi Makinde ipinlẹ Oyo ti ṣe ipade itagbangbe oṣelu ẹgbẹ oṣelu PDP niluu Ibadan l'Ọjọru, bo tilẹ jẹ wi pe ibẹrubojo awọn arun coronavirus wa nita.
nile eko giga ohun lati yi orile ede Naijiria pada si rere.
Ayọ̀ mi kì í lópin, nígbà tí mo bá gbọ́ pé àwọn ọmọ mi ń gbé ìgbé-ayé òtítọ́.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ sí: Ilé ìgbìmọ̀ aṣòfin Ekiti yọ abẹnugan rẹ̀ Kachikwu: Mi ò sọ wí pé mo gba ìwé ẹ̀rí tó tayọ jùlọ Ẹlẹ́wọ̀n tó ti pé ẹni ọgọ́rùn ọdún ní Nàìjíríà' n bẹ̀bẹ̀ fún òmìnira Èyí wáyé lẹ́yìn wákàtí díẹ̀ tí Gómìnà Akinwumi Ambode ti ìpínlẹ̀ Eko, Rochas Okorocha ti Imo, Umar Ganduje ti Kano, Mohammed Abubakar ti Bauchi and Kashim Shettima ti Borno ṣèpàdé pẹ̀lú ààrẹ Muhammadu Buhari láti mú u kí ó dá sí ọ̀rọ̀ ìdìbò abẹ́lé ìpínlẹ̀ wọn.
Bo tilẹ jẹ pe Aarẹ Buhari ko ti i le sọ owo oṣu tuntun naa di ofin, lai jẹ pe ile aṣofin buwọlu, ọpọlọpọ awọn gomina Nairia ti sọ pe awọn ko le san ju ẹgbẹrun mejilelogun atẹẹdẹgbẹta Naira.
Ileẹkọ yii ni Taiwo Akinkunmi wa, to fi ri ikede kan ka loju ewe iwe iroyin pe wọn n wa awọn to lee ya aworan asia fun orilẹede Naijiria, to n gbaradi lati gba ominira lọwọ awọn oyinbo aminisin nigba naa, aworan asia Naijiria to ya si ni awọn eebo kan saara si pe o pegede, o fi gbọọrọ jẹka, laarin awọn asia yoku ti awọn miran se lọdun 1958 Awọ eweko ati funfun si ni Taiwo Akinkunmi fi se asia Naijiria.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Báyìí ni ẹgbẹ́ ajàfẹ́tọmọnìyàn ṣe pè fún ìdájọ́ ikú fún àwọn afipábánilòpọ̀ Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Ní gbogbo agbègbè, ati ní àwọn ìlú tí ìkéde yìí dé, ìdùnnú ati ayọ̀ kún inú àwọn Juu, wọ́n se àsè pẹlu ayẹyẹ, wọ́n sì gba ìsinmi.
Edo State House of Assembly: Obaseki ní Oshiomole fẹ́ fipá gbàjọba lọ́wọ́ òun
Ṣugbọn nígbà tí àwọn Juu kò gbà pé kí wọ́n dá mi sílẹ̀, kò sí ohun tí mo tún lè ṣe jù pé kí n gbé ẹjọ́ mi wá siwaju Kesari lọ.
 lẹ ́ yìn tí ó kúrò níbẹ ̀ , ó dara pọ ̀ mọ ́ ẹgbẹ de la salle tí ó jẹ ́ ikọ ̀ àgbà fụn ilé-ẹ ̀ kọ ́ náà .
Ó ṣe díẹ̀ si, àwọn tí ó dúró níbẹ̀ tọ Peteru lọ, wọ́n sọ fún un pé, “Òtítọ́ ni pé ọ̀kan ninu wọn ni ìwọ náà í ṣe nítorí ọ̀rọ̀ rẹ fihàn bẹ́ẹ̀!
Kiki Osinbajo gbóṣùbà fún Seyi Awolowo, MC Oluomo tọrọ ìbò fún Mike ní BBNaija Seyi Awolowo, ọmọ-ọmọ Awolowo, kí ló ń wà lórí ètò BB Naija?
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìjàmbá Eko: Èèyàn méjì dàwátì lásìkò ìjàmbá ọkọ̀ ojú omi 14 Ògún 2019 Oríṣun àwòrán, @TalktoLaswa Àkọlé àwòrán, Eyi ni igba keji ti iṣẹlẹ ijamba oju omi yoo maa waye laarin oṣu keje si ikẹjọ ọdun 2019 Ajọ irinna oju omi nipinlẹ Eko, LASWA ti kede pe, ijamba ọkọ oju omi kan ti ran eeyan mẹta lọ sọrun ti wọn si tun n wa awọn meji miran lagbegbe ileto Irewe ni Ọjọ.
Okùn òpó-ọkọ̀ rẹ̀ ti tú,kò lè mú òpó-ọkọ̀ náà dáradára ní ipò rẹ̀ mọ́;kò sì lè gbé ìgbòkun dúró.
Ni tirẹ, olukọni Manchester United, Olu Gunner Solkjaer ni awọn mọ pe aja to wọle ts ẹkun lọrọ awọn nitori ibi to le gidigodo lawọn wa yii, ikọ to si ja fafa lawọn wa koju.
Waec f'ofin de ile'we mẹtadinlaadọta Ajọ t'o n risi idanwo lapa iwọ-oorun Afrika (Waec) ti fi ofin de ile ẹkọ Girama mẹtadinlaadọta ni ipinlẹ Kogi, ti wọn f'ẹsun sise agbatẹru magomago lasiko idanwo ajọ naa kan.
Àwọn ni wọn dúró bí i àgbàlagbà amòyé tí wọ́n máa nsàlàyé àwọn ọ̀rọ̀ kẹ̀nkẹ̀ ọ̀rọ̀ àgbà.
, ni lara isoro ti orile ede Naijiria n koju ni iwa ibajẹ, airisẹ ati aini ohun
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Liverpool vs Chelsea: Lampard wọ gàu!
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Kogi PDP Primaries: Wada fẹ̀yìn Dino gbálẹ̀ nínú ìbò abẹ́lé PDP fún ìpò gómìnà ní Kogi 4 Owewe 2019 Oríṣun àwòrán, Twitter/Dino Melaye Amoju ẹro Musa Wada la Sẹnẹtọ Dino Melaye mọ lẹ ninu ibo abẹnu ẹgbẹ oṣelu PDP fun ibo gomina ipinlẹ Kogi oṣi kọkanla.
Iwobi bọwọ́ lu àdéhùn tuntun pẹ̀lú Arsenal Ahmed Musa gbéré bọ́ọ̀lù lọ Saudi Arabia Iwobi fakọyọ bí Arsenal ti na Chelsea Oríṣun àwòrán, Getty Images Adari eto Idije Ife Ẹyẹ Rogers Cup, Eugene Lapierre, ni ko dun mọ awọn ninu bii Serena Williams se yẹra kuro ninu idije naa, amọ O wi pe ọpọlọpọ awọn ilumọọka agbabọọlu ẹlẹyin ni yoo kopa ninu idije naa ti yoo bẹrẹ ni ọsẹ to n bo ni Canada.
Omotoke ati Makinde David ni kii ṣe bi Buhari ni pe adinku ba owo Dangote Kini Forbes sọ?
Ofin naa n se odiwọn ipese igbokegbodo ti owo rẹ ko ga ju ara lọ.
Amofin Vincent Uche to jẹ akọbi ọmọ ọba ilu naa sọ fun BBC pe wahala bẹ silẹ nigba ti ọlọpaa kan kọkọ gun ọdọ ilu kan lọbẹ pa.
Ó ní, “Kí ló dé tí ẹ fi ń dẹ mí ẹ̀yin alárèékérekè yìí?
Paulu Sọ Ti Ẹnu Rẹ̀ níwájú Agiripa.
 Àràn yíì a fẹ ̀ ní ìwọ ̀ n mìlímítà méjì àwọn tí ó ti dàgbà nínu wọn a maa gùn tó 60 sí 100 sẹ ̀ ntìmítà ( àwọn akọ ló kúrú jù ) .
"Wiwọn rẹ to ogoji biliọnu kilomita to tobi ju aye lọ lọna miliọnu mẹta, ti awọn onimọ sayẹnsi si pe ni abamiẹda ""a monster""."
Ṣugbọn tí ẹ bá ń rìn lọ́nà ti Ẹ̀mí, tí ẹ kò sì hu ìwà ẹ̀ṣẹ̀ mọ́, ẹ óo yè.
tako ofin ati iwa ọmọluabi ninu ọdun Ileya yii, iyẹn ‘El-el-Kabir’ ati
bolude , tí ó jẹ ́ ẹlẹ ́ sìn ìbílẹ ̀ tí ó sì jẹ ́ oníṣègùn ìbílẹ ̀ tí ó tún jẹ ́ ìlú Ìbàdànjagunjagun tí ó lààmì laaka lásìkò ìjọba Ọ ̀ yọ .
11 Òkùdu 2019 Oríṣun àwòrán, @femigbaja, @HonBago Àkọlé àwòrán, Bago àti Gbajabiamila O kéré tan ènìyàn mẹ́ẹ̀dógún ló bẹ̀rẹ̀ eré ìje láti di agbẹnusọ ilé ìgbìmọ̀ àṣojú-ṣòfin orílẹ̀-èdè Nàìjíríà láti gba ipò Yakubu Dogara to jẹ ẹ́ ní ilé ìgbìmọ̀ aṣojú-ṣòfín ti ẹlẹ́kẹjọ.
Idi si ree ti BBC Yoruba fi n beere pe: Ṣé lootọ ni pe epe ti Alaafin Aole ṣẹ yii n ja iran Yoruba abi irọ ni?
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Saraki: Ilé ẹjọ́ ní yóò yanjú ọ̀rọ̀ lórí ilé mí tí Ìjọba gbẹ̀sẹ̀ lé 3 Ọ̀pẹ̀̀ 2019 Oríṣun àwòrán, EFCC Àkọlé àwòrán, Ilé ẹjọ́ ní yóò yanjú ọ̀rọ̀ lórí ilé mí tí Ìjọba gbẹ̀sẹ̀ lé Aarẹ ana ni ile aṣofin agba orile-ede Naijiria Sẹnẹtọ Bukola Saraki ti fesi pe ile ẹjọ ni yoo yanju ọrọ laarin oun ati ijọba Naijiria to gbẹsẹ le ile rẹ kan to wa nilu Ilorin.
Gẹgẹ bi BBC Yoruba se gbọ, idaji ọjọbọ ni Dagunro mi kanlẹ nile rẹ nilu Eko lasiko aisan ranpẹ to ti n ba finra lati bii ọdun melo kan sẹyin, eyi ti a ko tii lee sọ iru aisan ti o jẹ.
Àwọn iranṣẹ náà sọ èsì tí Dafidi fún wọn fún Saulu.
Àwọn bàbá ìsàlẹ̀ òṣèlú tó bá ìtìjú bọ̀ nínú ìbò Gómìnà rèé Beckham, àgbábọ́ọ́lù tẹ́lẹ̀ rèé tó ń sọ èdè Yorùbá Ọjọbọ ni Naijiria yoo koju Ukraine ninu ifẹsẹwọnsẹ to kẹyin ni abala akọkọ ninu idije FIFA U-20 to n lọ lọwọ lorilẹede Poland.
Amọṣa ọrọ kọ sisọ nitori nṣe lawọn oṣiṣẹ ajọ naa dabu rẹ ti wọn pẹlu iwọde ti wọn ko si fun un lanfani lati wọ ileeṣẹ naa.
Idajọ iku yii da lori ẹsun ti wọn fi kan an pe o pa ọlọpaa ẹni ọdun mejilelọgbọn, Gbenga Oladipupọ.
Ireti ọpọ si ni pe ikọ Falconets yoo lee gba ife naa lọdun yii lẹyin ti awọn agbabọọlu ọkunrin, Super eagles ti ja ireti ọpọ ọmọ Naijiria kulẹ lorilẹede Russia nibi idije ife ẹyẹ agbaye Russia 2018.
Koda o mu ki ijọba apapọ pàṣẹ ki ọga agba ọlọpaa nigba naa, Solomon Arase da Eseoghene pada si ipinlẹ Bayelsa lọdọ awọn obi rẹ.
Ọpọ wọn lo pada gba ominira sugbọn lẹyin ti won gba lati sa marundinlaasorin bilionu poun sapo ijoba Saudi ni.
Ẹ̀ ń kún fún ìjà ati asọ̀ ní àkókò ààwẹ̀ yín,ẹ̀ ń lu ara yín ní ìlù ìkà.
Ọ̀pọ̀ ìgbá si ni gbígbe ọba fún ẹni to kàn lẹ́yìn kìí níra lẹ̀yín ti Emir to wà lóri oye ba ti gbésẹ̀.
Ajọ eleto ilera lagbaye, WHO fi eewu to wa ninu iru eemi bẹẹ we ewu to wa ninu ki eniyan fa siga mejila lojoojumọ.
Ìfihàn tí a fi fún Wòlíì Joseph Smith àti Oliver Cowdery, ní Harmony, Pennsylvania, ní oṣù kẹrin ọdún 1829.
Ó sọ pé ''kò sí ohun tó jọ ìwé ẹ̀rí tó tayọ jù lọ l'ọ́dún náà, ṣùgbọ́n ìwé ẹ̀rí tí mo gbà ṣe déédéé kí èèyàn gba ìwé ẹ̀rí tó tayọ l'óde òní.
Ohun tí wọ́n kọ sinu ìwé tí ọba Atasasesi fún Ẹsira nìyí,
Ó wá kígbe pé, “Ó tú!
Chinonso Eche: Mo fẹ́ dà bíi Messi, Ronaldo àti Okocha
"Bi ẹẹmẹwaa ni mo gbiyanju lati pa ara mi, nitori pe ko si ẹni kankan nilee wa to mọ tabi ni òye nkan ti mo n la kọja.
Awon agbaboolu ti o kopa ninu igbaradi ohun lojo isegun ni: Ahmed Musa, Daniel Akpeyi, Theophilus Afelokhai, Ikechukwu Ezenwa, Olaoluwa Aina, Adeleye Aniyikaye, Semi Ajayi, Bryan Idowu, William Troost-Ekong, Leon Balogun, Kenneth Omeruo ati  Jamilu Collins.
Gbogbo èniyan lo mọ Romero fún bi o ṣe maa n ja ija tirẹ pẹlu ìwà ipa àti wáranwanran sise Kìí ṣe ẹni ti ẹnikẹni máà n fẹ́ bá ja"" Adesanya lo sọ eyi."
Maa ko ounjẹ rẹ si inu ike to ni smọri, ko si de daada.
Gbàrà tí ó rí ìran náà, a wá ọ̀nà láti lọ sí Masedonia; a pinnu pé Ọlọrun ni ó pè wá láti lọ waasu fún wọn níbẹ̀.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ogun TRACE: Ọkùnrin kan pa ara rẹ̀ sínú ọgbà àjọ tó n mójútọ ìrìnnà ọkọ̀ nípìnlẹ̀ Ogun 21 Agẹmo 2020 Oríṣun àwòrán, oguntoday.
Ó sọ àsọtẹ́lẹ̀ nípa Brexit ati àwọn èsi ìfẹ̀sẹ̀wọnsẹ̀ mìíran tẹ́lẹ̀.
Ní ọjọ́ kan àwọn ọmọ àwọn wolii tí wọ́n wà lábẹ́ àkóso Eliṣa sọ fún un pé, “Ibi tí à ń gbé kéré jù fún wa.
Ipinlẹ kọọkan ni aye ti wọn fi kalẹ labẹ Electoral College yi tapapọ rẹ si jẹ ibo ejidinlogojilenieedegbeta.
Ranti bí mo ti dúró níwájú rẹ tí mo sọ ọ̀rọ̀ wọn ní rere,kí o baà lè yí ibinu rẹ pada lórí wọn.
Amọ, awọn eniyan 200 lo ri iwosan gba lọwọ arun naa ni Ọjọ́bọ̀ ohun.
Sọ àsọtẹ́lẹ̀ orílẹ̀èdè tí yóò borí ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ t'òní Ẹyẹ ju ẹyẹ lọ, Super Eagles fi àmì ayò kan gbé ẹyẹ Swallow ti Burundi mì Panumọ́, yé parọ́, ₦15m ni Sẹ́nétọ̀ kan ń gbà lówó oṣù - Itsey Sagay sí Lawan Kí ló mú bàbá àti ọmọ rẹ̀ méjì rẹ́wọ̀n oṣù mẹ́fà he ?
Igbesẹ yii lo waye lẹyin ti iroyin gbalẹ kan pe awọn ilu to wa leti bode ilẹ wa lo ti n jẹrora ọwọn gogo epo pẹtirolu atatawọn eroja epo rọbi miran.
Ko si ohun elo to le je ki won pegede bee sini ko si iwuri to peye'' Ọnà abayọ Ni papa isere apapọ ile wa nilu Eko, Adu Uruemu n ko àwọn ojẹwẹwẹ nipa are sisa.
Obaseki la Ize-Iyamu mọ́lẹ̀ wọlé ìbò gómìnà lẹ́ẹ̀kejì ní ìpínlẹ̀ Edo Wo àwọn báńkì tó wà lẹ́yìn àwọn olówó èlé bí MMM Ìjọba Kaduna kéde ọjọ́ mẹ́ta fún ìdárò Emir Zazzau, Buhari, Tinubu, Babangida náà ń ṣèdárò Ọlọ́jọ́ Festival 2020:Ọ̀ọ̀ni ti Ilé Ifẹ̀ tí wọ ìléèdí ọlọjọ méje tí kò ní rí ẹnikẹ́ni sójú Èèyàn mẹ́jọ jónà ráúráú nínú ìjàmbá ọkọ̀ akérò tó ṣẹlẹ̀ ní mọ́rosẹ̀ Eko sí Ibadan Koda awon kan ni awọn tilẹ ṣi rii ni ọjọ to pa arabinrin naa ṣugbọn ko si ẹni to rokan pe irufẹ ọdaran bẹẹ lee tun bọ mọ ọlọpaa lasiko naa.
Mo dàbí igi sipirẹsi tí kì í wọ́wé tòjò tẹ̀ẹ̀rùn.
MKO Abiola, iṣẹ́ aṣẹ́gità ló fi bẹ̀rẹ̀ okoòwò ‘Buhari kìí fá orí apákan, dá apakan sí’ Ìjọba Nàìjíríà gbọdọ̀ ṣàlàyé ìdí tí 13.
Bi a ko ba gbagbe pe, ninu irufe idije naa todun ti o koja, iko agbaboolu Rivers Angels FC fagba han Ibom Angels FC tilu Uyo ninu asekagba idije ohun ti o waye ni papa isere Samson Siasia niluu Yenagoa, ti n se olu ilu ipinle Bayelsa.
Ní àkókò yìí, mo láyọ̀ ninu ìyà tí mò ń jẹ nítorí yín.
“Ṣugbọn bí ẹ bá kọ̀, tí ẹ kò pa àwọn òfin wọnyi, tí OLUWA fún Mose mọ́, 
Nígbà tí ó rí àwòrán àwọn ọkunrin, ará Kalidea tí a fi ọ̀dà pupa kùn lára ògiri, 
Yóo wọ́n ọn sí ara ẹni tí wọ́n fẹ́ wẹ̀ mọ́ kúrò ninu àrùn ẹ̀tẹ̀ náà nígbà meje.
Bí ó bá wọlé lọ́dún 2023, ní tèmi, èṣù ló wọlé - Bode George Buhari, máṣe gbá ìpànìyàn Lekki sórí ààtàn, kò yẹ́ kí ológun yin ọ̀dọ́ níbọn - Bode George Ó ti pẹ́ tí Fayose ti máa ń sọ̀sọkúsọ, ṣé ó mutí yó ni àbí ó mugbó?
ti won ri gba laarin osu kerin si osu kefa odun yii.
"Oríṣun àwòrán, others Èèyàn 389 ló tún lùgbàdì àrùn Coronavirus ní ọjọ́ Àbámẹ́ta ní Naijiria Nàìjíríà kò ní olórí, ẹ pín sí ẹlẹ́kùnjẹkùn - Soyinka Ìyá àádọ́rin ọdún sọ bí ọkùnrin ọdún márùndínlọ́gbọ̀n ṣe fipá bá òun lòpọ̀ 'Bí Covid19 bá peléke síi l'Eko, ilé la ó ti máa tọ́jú àwọn kan' - Ìjọba ìpínlẹ̀ Eko "" A fun ọkọọkan iyawo asofin to kopa ninu idanilekọọ naa ni miliọnu mẹrin naira, eyi to wa fun owo baalu, gbigba ile ìtura, ounjẹ ati irinajo laarin ilu Dubai"" Bakan naa tun ni Obasa sẹ lori ẹsun kan to ni o na miliọnu mẹtalelaadọta lori irinajo kan to ṣe lọ silẹ Amẹrika pẹlu ale rẹ kan."
Igbakeji aarẹ ajọ to n risi ọrọ erebọọlu ni Naijiria, Seyi Akinwunmi lo fi idi ọrọ naa mulẹ pe ajọ naa pa lara owo ajẹmọnu wọn ni owurọ Ọjọ Isegun, ti ohun gbogbo si ti pada si ipo.
"Lẹta naa fikun pe ""Awọn ọba mẹtadinlogun ni Ekiti lo n tọkasi pe awọn wa lara ilana Pẹlupẹlu ninu igbimọ lọbalọba ni Ekiti, amọ pẹlu akọọlẹ ilana ofin ijọba tọdun 2018, ọba meji pere ni ijọba fọwọsi."
Ọlọrun tún fi kún un pé, “Èmi ni Ọlọrun baba rẹ, Ọlọrun Abrahamu, Ọlọrun Isaaki, ati Ọlọrun Jakọbu.
Nigba ti oludari ile-eko naa ojogbon Danladi Matawal  n soro lori akole kan ti o pe ni” ile-kiko ati oju-ona gege bi irinse fun idagbasoke ayika lorile ede Naijiria”,o so pe ile-eko naa yoo wulo lati koju awon ipenija to maa n waye lori bi oju-ojo se n yi , ilẹ lilo , omi ati awon eroja ile.
Apapa -OShodi Expressway / Alapere Bridge Ijọba ibilẹ Ikeja Somolu / Kosofe32.
 Anselm Adodo, wa ro ijoba ipinle Edo lati fowosowopo pelu ile-ise iwadii naa, latari ati le pese ise lopo yanturu.
Olukuluku tẹ́ ibùdó ogun rẹ̀ sí àfonífojì Sefata ní Mareṣa.
Àwọn ọ̀pá tí wọ́n fi ń gbé Àpótí Ẹ̀rí náà gùn tóbẹ́ẹ̀ tí ẹni tí ó bá dúró ninu Ibi-Mímọ́ fi lè rí orí wọn níwájú Ibi-Mímọ́ ti inú.
Kete to jẹri yi tan lo gba iyọnda lọdọ alaga igbimọ pe ọrọ ku ti oun fẹ sọ.
”Wọ́n sọ fún un pé, “Oluwa, wá wò ó.
“Ó rán iná láti òkè ọ̀run wá;ó dá a sí egungun mi;ó dẹ àwọ̀n sílẹ̀ fún mi;ó sì dá mi pada.
Ki a sare wo ipinle Osun, ka mo bi eto idibo se n lo nibe.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Umai Emery: Villarael yan akọ́nimọ̀ọ́gbá Arsenal tẹ́lẹ̀, Emery gẹ́gẹ́ bí akọ́nimọ̀ọ́gbá rẹ̀ tuntun 24 Agẹmo 2020 Oríṣun àwòrán, Getty Images Unai Emery, akọnimọọgba ẹgbẹ agbabọọlu Arsenal tẹlẹ ni wọn ti yan gẹgẹ bi akọnimọọgba Villareal fun ọdun mẹta.
Ẹni to bori: Mali Algeria vs Congo DR.
“Óyá Alákọ̀wé oúnjẹ yá, àbí bóo ni?
Ileeṣẹ ọlọpa ipinlẹ naa la gbọ pe, o gbe ọkunrin alarun ọpọlọ naa lọ sileewosan nitori pe ọrọ rẹ ko baramu lasiko to jẹwọ fun awọn ọlọpa pe, oun wa lara awọn to pa Khadijat, ọmọ igbakeji gomina ipinlẹ Ondo nigba kan, Lasisi Olubọyọ.
Wo ọna abayọ lọwọ sunkẹrẹ fakẹrẹ ọkọ bi ijọba se ti afara Third mainland: Oríṣun àwòrán, LASG Ọjọ́ Ajé ọjọ́ kẹtàdínlọ́gbọ̀n ọṣù keje, ọdún 2020 ti àwọn olúgbé ìpińlẹ̀ Eko yóò mọ ìpa ti àpá kan afára 3rd mainland tí ìjọba ti pa yóò ṣe ko ìnira ba àwọn arfá ìlú tó.
Lọdun 2006 ni Ebuka kọkọ kopa ninu eto BB Naija fun igba akọkọ.
Ẹwẹ, oludari ikọ naa ni wọn ti bẹrẹ afikun iwadii, ati pe awọn yoo ko wọn le ọlọpaa lọwọ lati tẹsiwaju ninu iwadii ati fifi wọn jofin.
Jin ni orúkọ rẹ̀, èmi àti arákùrin náà sì ti mọ̀nrawa fún nkan bí ọdún kàn nípasẹ̀ iṣẹ́ òòjọ́ wa.
Igbakeji aarẹ Yemi Oṣinbajo ni o ṣe ifilọlẹ irinajo ọfẹ lori reluwe loṣu keji ọdun 2019.
 bakanna o tun ni imo ninu kurani .
Ní ọjọ́ kan, Jesu wá láti Nasarẹti ìlú kan ní Galili, Johanu bá ṣe ìrìbọmi fún un ninu odò Jọdani.
Aare pe ilana ofin tuntun naa ni eyi ti a sagbekale re fun sise erongba awon ise akanse, fun idagbasoke awon ohun abele Naijiria paapaa ise agbase si imo sayensi atimo ero fun igberu eto oro-aje Naijiria.
Òun pẹlu àwọn balogun, àwọn eniyan jàǹkànjàǹkàn, àwọn gomina, ati gbogbo eniyan ilẹ̀ náà mú ọba láti ilé OLUWA, wọ́n gba ẹnu ọ̀nà òkè wá sí ààfin, wọ́n sì fi í jókòó lórí ìtẹ́.
Ki o to ku, oloogbe Temitọpẹ Ọlatoye lo n ṣoju fun ẹkun idibo apapọ Lagelu/Akinyele ni ipinlẹ Ọyọ Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Ṣùgbọ́n bí mo tún ti fẹ́ wọlé ogiri padà, n kò rí ojú ọ̀nà mọ́, mo tún lọ.
Koda, ko si ero ni titi nitori gbogbo adugbo naa da waiwai ni.
Lopetegui, omo odun mọ́kànléláàdọ́ta ohun, yoo ropo Zinedine Zidane, leni ti o kowe fipo re sile leyin ti o ran iko ohun lowo lati gba ife-eye idije UEFA Champions League nigba meta otooto le ra won.
Ọkan lara awọn agbẹbi to maa n ṣe e sọ pe lootọ ni oun korira rẹ, ṣugbọn oun maa n ṣe ti oun ba nilo owo fun itọju awọn ọmọ ọmọ oun ti iya wọn ti ku.
ibura fun awon ti gomina sese yan sipo yoo waye leni ti n se ogbon ojo, osu
Gbogbo wọn lo sọ pe awọn ti padanu awọn mọlẹbi, ti ọjọ ori wọn wa laarin ọdun mẹẹdogun si mẹrinlelogun.
Àkọlé àwòrán, Ebun nla n duro de ẹni to ba bori Bawo ni idije naa ṣe lọ?
 Ó wà lórí Àkójọ Àwọn egbògi kòṣeémáàní ti Àjọ Ìlera Àgbáyé , àwọn òògùn tó ṣe pàtàkì jùlọ tí a nílò fún ètò ìlera ìbẹ ̀ rẹ ̀ pẹ ̀ pẹ ̀ yòówù .
Kí o fi àkọsílẹ̀ majẹmu ẹ̀rí tí n óo gbé lé ọ lọ́wọ́ sinu àpótí náà.
12 Ẹ múra, ẹ múra nítorí èyí tí ó mbọ̀, nítorí Olúwa súnmọ́ itosí;
Ó ni, ‘A kàn ń sọp pé Oyíndayépọ̀ lágbára ni, eléyìí máa ṣe ju Oyíndayépọ̀ lọ.
Lasiko to n ba BBC Yoruba sọrọ, ọkunrin naa ti inagijẹ rẹ tun n jẹ Azonto fikun pe oun lee fi omi lasan tan ina, bi o tilẹ jẹ pe awọn eeyan gba pe ina ati omi kii se ọrẹ.
Liverpool Bridge, Apapa, Ijọba ibilẹ Apapa 13.
Bakan naa o jẹ ko di mimọ pe ijọba gan ko ṣe e dara tori bo ba ṣe nkan to nii ṣe pẹlu aṣa ni wọn lee kede isinmi ṣugbọn nkan ti Ọlọrun ni ijọba ko ki n fẹ kede isinmi fun.
”Ọba Benhadadi gba ìmọ̀ràn wọn, ó sì ṣe ohun tí wọ́n wí.
Fún mi ní ayọ̀ ati inú dídùn,kí gbogbo egungun mi tí ó ti rún lè máa yọ̀.
Iye àwọn ọmọ ogun tí ó kó jọ nìyí gẹ́gẹ́ bí ìdílé wọn: Adinai ni olórí ogun ẹ̀yà Juda, ó sì ní ọ̀kẹ́ mẹẹdogun (300,000) akọni ọmọ ogun lábẹ́ rẹ̀.
Dogara tun so pe “mo fẹ fi daa yin loju pe ile igbimo asofin ko ni kaare lati tẹpẹlẹ mọ ọna ti eto idibo odun to n bọ yoo se dara ju ti ọdun 2015 lọ.
Àwọn ọlọ́pàá kò kọbiara si ọ̀rọ̀ ìwà ipá lásìkò ìgbéle Covid -19 ni ìwà ipá ṣe pọ̀ - Ajàfẹ́tọ obìnrin Àwọn nǹkan tí obìnrin lè ṣe pẹ̀lú olólùfẹ́ oníwà ipá lásìkò ìgbélé Coronavirus yìí Ìmọ̀ràn márùn ùn láti ẹnu olùkọ́ni tó fakọyọ lágbàyé lórí kíkọ ọmọ lásìkò yìí Olu Jacobs: Ipò wo ni gbajúmọ̀ òṣèré tíátà yìí wà?
- Ààrẹ Akufo-Addo Ọ̀jọ̀gbọ́n fásitì OAU pàdánù ẹ̀mí lópoópónà Benin sí Auchi.
Ṣọn Àgbàdo kúrò ninú omi lati yọ ẹ̀gbin bi ò̀kúta kúrò
 Èyí ṣi mu kì Òrùnmìlà fẹran Ààbò .
Ẹni tíó béèrè ọmọ mìíràn tí ó wí pé ọmọ òun kò mọ ìwé ti ní ọmọ mìíràn tí ó mọ ìwé ṣùgbọ́n ọmọ tuntun yìí ti wọ inú ẹ̀wọ̀n kí Aṣojú-Olódùmarè tóó dé nítorí ẹni tí ó mọ ìwé tí kò ní ìwà burú ju ẹni tí ó ní ìwà tí kò mọ ìwé lọ.
" Àwọn ọ̀nà tí obìnrin fi le gbádùn ìbálòpọ̀ A ò gba ìbálòpọ̀ akọ ṣákọ tàbí abo sábo Ènìyàn 26,000 ni àìsàn jẹjẹrẹ ń pa lóòjọ́ Ẹ wo àwọn ẹlẹ́sìn Hindu tó ń jẹ ènìyàn Yatọ si eyi, o tun fi nkan miran so ọwọ rẹ keji, o si n gbiyanju lati fi ipa mu John ni ibalopọ.
Ta ba si ni ka maa ka awọn erin nla to ti wo naa ni eni, eji, ẹta, ilẹ ti wẹ, nitori ọpọ ojo lo ti rọ, ti ilẹ si ti fi mu, ni oniruuru ẹka igbe aye ọmọniyan paapa ni ẹka awọn amuludun.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Iléẹjọ́ fún Seyi Makinde láṣẹ láti yan adelé alága ìbílẹ̀ ní ìpínlẹ̀ Oyo Olóòtú ìjọba Gẹ̀ẹ́sì yan ọmọ Yorùbá ní Mínísítà Òṣèré tíátà, Kemi Afolabi dùbúlẹ̀ àìsàn ní ìlú Mecca Àṣírí mẹ́wàá tí mo mọ̀ nípa Boko Haram-Naomi Adamu Lara awọn eekan miran lati ipinlẹ Ogun to se abẹwo si aarẹ Buhari ni arẹmọ oloogbe MKO Abiọla, Kọla Abiọla, ọmọ Abiọla obinrin, Hafzat Abiọla, gomina tẹlẹ nipinlẹ Ogun, Oloye Olusẹgun Ọsọba, awọn ọba alaye ati awọn eeyan jankanjankan miran.
Àwọn ọmọ ogun Kalidea fọ́ àwọn òpó bàbà tí ó wà ninu ilé OLUWA ati agbada bàbà ńlá tí ó wà ninu ilé OLUWA pẹlu ìtẹ́lẹ̀ rẹ̀, wọ́n fọ́ wọn sí wẹ́wẹ́, wọ́n sì kó gbogbo bàbà wọn lọ sí Babiloni.
Igbesẹ yii ti wa sọ ọ di ọrọ kannakanna na ọmọ ẹga bayii nigba ti ijiroro lati buwọlu iyọnipo naa ba waye ni ile aṣofin agba nibẹ.
O fikun un pe lati igba ti wọn ti ji oun gbe kò sì ọjọ kan toun kii sunkun titi ti awọn ikọ ẹlẹyinju aanu Al Amin wa saanu fun oun.
Ṣugbọn diẹ lara awọn ohun elo ti wọn yoo fi ṣatunsẹ afara ọhun ko si lorilẹ-ede Naijria ni ijọba ṣe pinnu lati ko wọle lati oke okun.
Awọn ọdaràn to ṣiṣẹ́ ńlá ibi yìí ní àjọ ọlọ́pàá ní wọn yóò fóju wọn han fún gbogbo oníròyìn lónìí lólú ilé iṣẹ́ ọlọ́pàá nílu Abuja.
Àwọn ohun tí Ọmọ rí pé Baba ń ṣe ni òun náà ń ṣe.
Mò ń kọ nǹkan wọnyi si yín nípa àwọn kan tí wọn ń tàn yín jẹ; 
Ọkàn mi sọkún fún Moabu;àwọn ìsáǹsá rẹ̀ sá lọ sí Soari ati Egilati Ṣeliṣiya.
Nigba to n ba BBC sọrọ, ọkan lara awọn akanda ẹda naa, salaye pe awọn bọ sigboro lati ke gbajare tọ araalu wa, ki wọn lee mọ isoro tawọn akanda ẹda n koju nitori bijọba se fofin de ilo ọkada ati kẹkẹ Maruwa.
Àlejò àpàndodo ni Fayoṣe, a kò fìwé pèé - Afuye Yahaya Bello lẹ́ẹ̀kan síi ni APC ṣe ní ìdìbò abẹ́lé ní Kogi Minisita keji fun eto ilera, Sẹnẹtọ Olọrunnibẹ Mamora lo kepe awọn ileewe giga fasiti ni Naijiria lati ṣagbekalẹ ẹkọ iṣegun ibilẹ fun eto ilera to peye ni Naijiria.
Àwọn mọ̀lẹ́bí ajínigbé tó pàdánù ẹ̀mí l'Ondo kò tí ì yọjú Ohun mẹ́fà tí kò yẹ́ kí o gbàgbé nípa Gómìnà Ambode Awọn àgbà ọ̀jẹ̀ agbábọ̀ọ̀lù ní Afíríkà yẹ́ Gomina Ambode si Ta ni Naira Marley jẹ́ gan?
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Akure Kidnap: E túbọ̀ ní sùúrù, a máa wá ọmọ náà rí- Alukoro ọlọ́pàá Mo fẹran orin, ṣugbọn boya ohun mi ko dara to.
Bi Egúngún/Eégún bá ńlé ni ki a má rọ́jú, bi ó ṣe ńrẹ ará ayé, ló ńrẹ ará Ọrun
OLUWA àwọn ọmọ ogun ni ó pinnu láti ba gbogbo iyì ògo jẹ,ati láti tẹ́ gbogbo àwọn ọlọ́lá ayé.
Nítorí Paulu ti pinnu láti wọkọ̀ kọjá Efesu, kí ó má baà pẹ́ pupọ ní Esia, nítorí ó ń dàníyàn pé bí ó bá ṣeéṣe, òun fẹ́ ṣe Àjọ̀dún Pẹntikọsti ní Jerusalẹmu.
Ni owurọ ọjọ Satide ni awuyewuye bẹrẹ lori ayelujara nitori iku to pa ọmọbìnrin, ẹni ọdun mejilelogun kan nipinlẹ Edo.
 Eyi ni Aṣofin Ọbasa fi kasẹ ọrọ rẹ nilẹ.
Awọn kan tilẹ sọ pe eniyan bi miliọnu mẹta lo ku nitori ogun naa.
N óo gbá ọ mú, n óo tì ọ́ lulẹ̀ láti orí àpáta,n óo sì sọ ọ́ di òkè tí ó jóná.
 nítorí náà , ó dàbí ẹni pé iye ìlú tí a lẹ ̀ rí ní agbègbè àríwá Àkókó tàbí ní Àkókó ní àpapọ ̀ ní iye ẹ ̀ yà èdè tí a lè rí .
3) Gbiyanju lati ṣe ohun to yẹ ti wọn ba fun ọ ni ipo airotẹlẹ.
àfi ìbúra èké ati irọ́ pípa; ìpànìyàn, olè jíjà ati àgbèrè ni ó pọ̀ láàrin wọn.
Oró agbọ́n leè wo àìsàn jẹjẹrẹ ọmú sàn, wo ohun tí wàá lò pọ̀ mọ́ra wọn Ọpọ awọn olufẹhonuhan lo gbe beeba lọwọ eyi ti wọn kọ oriṣiiriṣii ọrọ sii bi ''awa o faramọ afikun owo epo''(NO TO FUEL PRICE INCREMENT), ''O TO GẸẸ''(ENOUGH IS ENOUGH) ati bẹẹ lọ.
Ìfihàn tí a fi fún Wòlíì Joseph Smith, ní Harmony, Pennsylvania, tí ó ṣeéṣe kí ó jẹ́ àyíká Oṣù Kẹrin 1829, bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé àwọn abala kan le ti jẹ́ gbígbà láti ìbẹ̀rẹ̀ bíi ìgbà ẹ̀ẹ̀rùn 1828.
Nígbà tí àwọn aṣebi bá ń gbógun bọ̀ wá bá mi,tí wọ́n fẹ́ pa mí,àwọn alátakò ati àwọn ọ̀tá mi,wọn óo kọsẹ̀, wọn óo sì ṣubú.
Iji n ja wa, iji pataki ni."
2002 Ipele ẹlẹgbẹjẹgbẹ) Bamako Nigeria 1-0 Algeria 30.
Etiopia ati Ijipti ni agbára rẹ̀ tí kò lópin; Puti ati Libia sì ni olùrànlọ́wọ́ rẹ̀.
Ó sì níláti san ìlọ́po mẹrin ọmọ aguntan tí ó gbà pada, nítorí nǹkan burúkú tí ó ṣe, ati nítorí pé kò ní ojú àánú.
Olùṣọ́ kanṣoṣo ni n óo yàn fún wọn, òun náà sì ni Dafidi, iranṣẹ mi.
Esi lati ipinlẹ mẹjọ pere ni wọn fi sita, ko si si Eko lara wọn.
A mọ̀ pé à ń gbé inú Ọlọrun ati pé òun náà ń gbé inú wa nítorí pé ó fún wa ní ẹ̀mí rẹ̀.
Kábíyèsí, mo fẹ́ kí ẹ mọ̀ dájú láti òní lọ pé, ẹni tí ó bá ń fẹ́ẹ́ ṣe nǹkan rere, tí ó fi ara da ìṣòro tí ń bẹ nínú nǹkan rere, tí ó sì gbẹ́kẹ̀lé Ọlọ́run Ọba eléyìínì kò ní sí láàárin àwọn èrò ẹ̀hìn láéláé.
Àyẹwò yìí jáde lẹyin ọjọ kan ti bàbá ọkọ rẹ̀ Amitabh Bachchan náà lùgbàdì ààrùn Covid-19.
Ó ni mo gbọdọ̀ wá síhìn-ín, ní ilé baba òun ati sọ́dọ̀ àwọn ẹbí òun láti fẹ́ aya fún ọmọ òun.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Wùnmí Toríọlá: Toyin Abraham kìí se ọ̀gá mi nínú tíátà O ti kopa ninu ọpọlọpọ ere to le ni aadọta oun naa si ti ṣe agbejade ere tirẹ gangan to to bii mẹta.
"'Kò tọ̀ọ́ kí olórí Nàìjíríà tó bá ní coronavirus gba ìtọ́jú ní ìlú tí kìí ṣe tirẹ̀' Ìjọba ipínlẹ̀ Ondo ko fi ojú ire wó bí sójà to lú akọròyìn- Ìjọba ìpínlẹ̀ Ondo Ìtàn Manigbagbe: Àwọn àjakalẹ-àrun to ti wáyé rí ṣáájú Coronavirus Ìjọba yóò lo BVN àtàwọn ọ̀nà méjì míràn láti pín owó ìrànwọ̀ fún aráàlú ""Germany to lọ to ti kagbako coronavirus, ko lọ fun igbadun ara rẹ."
Adelé Adejuyigbe ni ẹgbẹrun lọna marundinlogoji naira ni oun n gba lowo osu eyi ti ko ran nkankan, bẹẹ ni ijọba ko fun oun ni ọkọ ayọkẹlẹ nidii.
nítorí náà bákan méjì lọ́rọ̀ ọ̀hún.
Yoruba wo ló fẹ́ gbé Oduduwa Republic tẹ́ n pariwo - Lizzy Anjorin ''Láti òní lọ, FSARS ò gbọdọ̀ káàkiri ìlú mọ́ tàbí tú ẹrù aráàlú wò mọ́''- Ọ̀gá ọlọ́pàá pàṣẹ Adìyẹ́ jẹ̀fun ara wọn!
Deontay Wilder: Wilder ní òun sì ń gba ìtọ́jú lọ́wọ́ lẹ́yìn tí Fury fẹ̀ṣẹ́ já iṣan ọwọ́ rẹ̀ loṣù kejì
Awọn obi rẹ naa si ti pinnu lati tọju ọmọ tuntun ọhun.
Fayoṣe: Mi ò jẹ̀bi ẹ̀sùn kankan Agbẹjọ́rò: Pe Fayose tun gba owo kan laarin ọjọ kẹrindinlọgbọn oṣu kẹfa si ọjọ kẹtadinlọgbọn oṣu kẹjọ ti owo naa ko si bofinmu.
Iroyin naa sọ pe aarẹ sọrọ niwaju awọn ọkunrin bi ẹgbẹrun mẹrinla, nibi to ti sọ fun pe obinrin bi aadọrin miliọnu lo wa lorilẹede naa ti awọn ọkunrin kosi ju ọgbọn miliọnu lọ.
(Olóòtú ètò “Ojúmọ́ Ire”): Báyìí ni a ṣe gbèrò láti ṣe é; akọ̀ròyìn-in wa á máa wa ọkọ̀ bí yóò ṣe máa fi ọ̀rọ̀ wá ọ̀rọ̀ lẹ́nu alámọ̀dájúu yín.
’ Ǹjẹ́ ó ṣeéṣe fún eniyan láti ja Ọlọrun lólè?
Lílọ bibọ eniyan lojupopo ti dinku pupọ ko to o di pe ijoba kede konile o gbele ni awọn ìlú nla kaakiri agbaye.
O ni osu meje loun a fi yanju awon ohun to ye ni sise ati lati fi wa onko ere naa atawon osise miran to ku pelu ipinnu nina owo to to ogun si milionu meedogbon owo dola ile okeereBoyega ni ohun yoo fowosopo pelu awon osere Nollywood lati jo gbe fiimu lorisiirisii sitaNollywood Naijiria: Ona idagbasoke?
"Àdó okoró búrẹ́kẹ' Oríṣun àwòrán, Olasunkanmi Marshal/Facebook Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Lagos -Ogun Tanker Explosion: Ọkọ̀ agbépo kan tí gbiná lórí afárá Magboro2 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Gbọ́, Elebuibon: Lẹ́yìn ọ̀pọ̀lọ́pọ̀ oṣù tí òjò kò rọ̀ ní orílẹ̀èdè Cuba, Ọba ilẹ̀ Yorùbá ló pàṣẹ kí ó rọ̀ tó sì rọ̀1 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Fídíò, Akomolede ati Asa Yoruba: Kí ni ""Future tense"" lédè Yorùbá?"
Koda, o sọ pe nkan iwuri ni ayipada to n deba awọn ounjẹ ti wọn n pin fun alejo nibi ayẹyẹ.
Visa to Nigeria: Ó lé gba ìwé ìrìnnà (Visa) láti wá fẹ̀yìntì sí Naijiria
Bí Sanwo-Olu bá fún Super Eagles lówó ń kọ̀; Ṣebí kìí ṣ'owó ìjọba
Kò si ẹni ti o ńdúpẹ́ ti inú rẹ ńbàjẹ́, tijó tayọ̀ ni enia fi nṣe idúpẹ́.
Mò ń retí ìgbàlà rẹ, OLUWA,mo sì ń pa àwọn òfin rẹ mọ́.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù #U17WC: Mínísítà ní orí ìdúró l'òun ti wo ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ Nàìjíríà àti Hungary tán 27 Ọ̀wàrà 2019 Oríṣun àwòrán, Twitter/NFF Ẹgbẹ agbabọọlu Naijiria ti ọjọ ori wọn ko ju ọdun mẹtadinlogun, the Golden Eaglets ya agbado ha si ọpọ lẹnu lẹyin ti wọn gbẹyẹ lọwọ ilẹ Hungary ninu idije ife ẹyẹ agbaye FIFA U-17 World Cup lorilẹede Brazil lalẹ ọjọ Satide.
25 Sẹ́rẹ́ 2017 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Bí wọ́n tilẹ̀ kọ́ ọpọlọpọ ilé, wọn kò ní gbébẹ̀; bí wọ́n sì gbin ọgbà àjàrà, wọn kò ní mu ninu waini rẹ̀.
“Ǹjẹ́ nisinsinyii, OLUWA Ọlọrun, jẹ́ kí ìlérí tí o ṣe nípa èmi ati arọmọdọmọ mi ṣẹ nígbà gbogbo, sì ṣe ohun tí o ti ṣèlérí pé o óo ṣe.
Wo ìdí tí Osun fi kede ìsinmi fún ọdún ìṣẹ̀ṣe, tàwọn ìpínlẹ̀ yókù kò dáhùn, Ilu Lanlate nijọba ibilẹ Ibarapa nipinlẹ Oyo si ni isẹlẹ naa ti waye.
Aare soro lori akori “Ibajẹ sise owo ilu basu-basu: Ipenija lori isejoba’’Awon àádọ́rin adari orile ede agbaye ati ijoba lo wa nibi ipade naa .
"Ibeere nla to wa nibẹ bayii ni wipe, se yoo lee mu isọkan ba awọn igun gbogbo to n suyọ nibẹ"" Ọbun keji ti Ọjọgbọn Bọlaji Akinyẹmi tun salaye ni ẹhonu awọn lookọ lookọ ati alagbara ti wọn fi ẹsun kan pe wọn lẹdi apo pọ mọ Jacob Zuma lori ẹsun iwa ijẹkujẹ ati ibajẹ ti wọn fi kan an."
Àjọ náà ní, ipa ti mínísítà tẹ́lẹ̀rí kó nínú rẹ̀ jẹ èyí to ń pe fún ìbéèrè lẹ́yìn ti ICPC rí lásìkò ìwádìí pé ìwé àlàsilẹ̀ láti gbé ìṣẹ́ náà jáde (DSO) bí Modibo Kawu ṣe lòó kó tọ ìlànà tó yẹ.
Àwọn alufaa dúró ní ipò wọn, àwọn ọmọ Lefi náà dúró láti kọrin sí OLUWA pẹlu ohun èlò orin tí Dafidi ṣe ati ìlànà tí ó fi lélẹ̀ láti máa fi kọrin ọpẹ́ sí OLUWA pé, “Ìfẹ́ rẹ̀ tí kìí yẹ̀ wà títí lae;” ní gbogbo ìgbà tí Dafidi bá lò wọ́n láti kọrin ìyìn.
"NFF fi #30,000 kún #10,000 owó ìrànwọ́ oṣooṣù fún ìyá Rashidi Yekini àti Samuel Okwaraji Àwọn jẹsí tó gbajúmọ̀ nínú ìtàn ìdíje bọ́ọ́lù Arsenal rántí ""Invincibles,"" ó pé ọdún mẹ́rìndínlógún tí Arsenal gba ife Premier League Real Madrid ń gbáradì láti ra Paul Pogba pẹ̀lúu £70m Thorgan Hazard naa ko gbẹyin rara nigba to ṣe bi ọkunrin laarin iṣẹju diẹ ninu abala keji ifẹsẹwọnsẹ naa."
Ẹ gbọ́ ohun tí wọn ń sọ jáde lẹ́nu,ẹ wo ahọ́n wọn bí idà;wọ́n sì ń wí ninu ara wọn pé, “Ta ni yóo gbọ́ ohun tí à ń sọ?
Ọgbẹni Ajayii ni eeyan kan ti orukọ rẹ n jẹ Bukọla Adewale lo fi ọna eburu lo orukọ oun lati pe ẹjọ naa lẹyin to ti wa ba oun nile pe oun ti ba oun ri iṣẹ.
to n ba won wọya ija bi asọ lorile ede yii.
Adajọ Majisreeti Akande sọ ninu idajọ rẹ pe bi ẹjọ to pe telọ yìí ba ṣe pataki si i, yoo waye lati wa nile ẹjọ fun igbẹjọ.
"Bẹẹ ba de isọ awọn ti wọn n pe ni ""Lekulẹja tabi Elewe Ọmọ"", ẹ o ki aje ku ikalẹ."
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí Gẹ̀ẹ́sí gbé £1m kalẹ̀ láti tako Boko haram Òṣìsẹ́ iléeṣẹ́ amúnáwá gan mọ́'ná ni Oǹdó Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ilẹ̀ gbígbẹ́ ní Bọ́ùn: Ìpìnlẹ̀ mẹ́fà leè má nìí iná ọba Ogbẹ́ni Usman Mohammed to je olùdarí ẹ̀ka tó ń pín iná mọ̀nàmọ̀nà ní Nàìjíríà wá pè fún àtúnse sí àwọn ohun eèlò tí wọn ń lò fi n mú iná wá pẹ̀lú àjọsepọ̀ àwọn olókoòwò ńlánlá láti ilẹ̀ òkèèrè.
Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Prophet Shepherd Bushiri: Iléẹjọ́ gbẹ́sẹ̀ lé ilé wòlíì tí iye rẹ̀ tó $350,00021 Bélú 2020 4:25 Fídíò, Erelu Elemure: Ìyá mi rò pé mi ò lè tibi kíkọrin bíi bàbá mi là, Duration 4,2521 Bélú 2020 Prophet Israel Oladele: Àwọn ìlúmọ̀ọ́ka tó ti jọ́sìn ní ijọ CCC, Genesis Global rèé21 Bélú 2020 Professor Peller: Ọlọ́wọ́ idán àkọ́kọ́ nílẹ̀ Áfíríkà tó ń pidán fáwọn aṣaájú orílẹ̀èdè19 Bélú 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Alagbara ati ajafẹtọ araalu ni gẹgẹ bii awọn aṣiwaju rẹ bi Iyalode Ẹfunṣetan Aniwura ati Humani Alaga.
Jesu dá wọn lóhùn pé, “Mo fẹ́ kí ẹ mọ̀ dájúdájú pé ẹnikẹ́ni tí ó bá ń dẹ́ṣẹ̀, ẹrú ẹ̀ṣẹ̀ ni.
Ṣíbí wúrà kan tí ìwọ̀n rẹ̀ jẹ́ ṣekeli mẹ́wàá tí ó sì kún fún turari.
OLUWA óo dá ọ lóhùn ní ọjọ́ ìpọ́njú,orúkọ Ọlọrun Jakọbu óo dáàbò bò ọ́.
Arabinrin Felicia to jẹ oniṣowo Garri ni agbègbè ilu Akure ṣalaye ilana ti wọn maa n tẹle lati yan ounjẹ ilẹ Naijiria yii, Garri.
Àwọn krómósómù yàtọ ́ gidigidi sí ra wọn láàrin orísi àwọn ohun ẹlẹ ́ ẹ ̀ mí .
Òkùnkùn ti ṣú ṣugbọn Jesu kò ì tíì dé ọ̀dọ̀ wọn.
Ewe, ope pataki lowo ami ayo keyin ti atamatase iko Croatia, Tin Jedvaj  gba wole sagbon niseju perete ki ifesewonse naa wa si ipari.
Somalia rape death sentence: Ìdájọ́ ikú ló bá dé fáwọn méjì tó fipá bá ọmọ ọdún mẹ́rìnlá lò pọ̀
Oríṣun àwòrán, @RotimiAkeredolu Àkọlé àwòrán, Awọn nọọsi ti daṣẹ silẹ lẹyin ti wọn ni ijọba n jẹ wọn lowo oṣu Òtítọ́ ọ̀rọ̀ rè é lórí ilẹ̀ tó fa awuyewuye láàrin Ghana àti Nàìjíríà Wo bí ọwọ́ orílẹ̀-èdè Dubai ṣe tẹ Ramoni Igbalode tí gbogbo ayé ń pè ní Hushpuppi Ìtàn ìgbésí àyé olóògbé Isiaka Abiola Ajimobi Omijé bọ́ níbi ìsìnkú Ogun Majek Ẹwẹ, ẹgbẹ awọn dokita ipinlẹ Ondo ti gunle iyanṣelodi ọlọjọ gbọọrọ lati ọjọ kẹrinlelogun, oṣu kẹfa, ọdun 2020.
ó ní, “Ẹ fi gbogbo ọ̀rọ̀ tí mo ba yín sọ lónìí sọ́kàn, kí ẹ sì pa á láṣẹ fún àwọn ọmọ yín, kí wọ́n lè pa gbogbo òfin wọnyi mọ́ lẹ́sẹẹsẹ.
Yóo kọjá lọ bí òjìji, kò sì ní sí mọ́.
“Lẹ́yìn náà, mú òróró ìyàsímímọ́, kí o ta á sí ara àgọ́ náà, ati sí ara ohun gbogbo tí ó wà ninu rẹ̀, kí o yà á sí mímọ́ pẹlu gbogbo àwọn ohun èlò inú rẹ̀, wọn yóo sì di mímọ́.
Coronavirus domestic violence: Àwọn nǹkan tí obìnrin leè ṣe pẹ̀lú olólùfẹ́ oníwa ipá lásìkò ìgbélé Coronavirus yí
WHO rọ awọn olori orilẹede nilẹ Adulawọ lati ri pe eto to mọyan lori wa nilẹ, lori ilana ati idena itankalẹ arun Coronavirus, tawọn akẹkọọ yoo tẹle ti wọn ba wọle pada.
Bakan naa, ni a tun wa bere boya O le je alejo wa pataki ninu ifesewonse olorejore ti Super Eagles yoo gba pelu England ni papa isere Wembley lojo keji osu kefa odun yii.
O ni ajoji ti ko ni iwe irinna, tabi iwe idanimọ kankan ni wọn.
Gomina ipinlẹ Kaduna, Nasir El Rufai Oríṣun àwòrán, Twitter/Nasir Ahmad El-Rufai Lọjọ kọkandinlọgbọn oṣu kẹta, gomina Nasir El-Rufai ti Kano naa kede pe oun ti ni arun Coronavirus.
ri i pe eto ijoba tiwa-n-tiwa , paapaa julọ  eto idibo yii lọ ni irọwọ irọsẹ” .
O ni aimoye lo da awọn ti wọn sọrọ sii laamu.
Nigba ti batiiri ọkọ baalu bẹrẹ iṣẹ kiṣẹ lo ba ya si inu ile naa.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Àwọn olówó Naijiria 5 tí owó wọn ju owó ìsúnná Naijiria lọ!
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Yoruba Culture: ọjọ́ méje ni wọ́n fí n rẹ ẹ̀kú Danafojura kó tó jáde Alukoro ileeṣẹ ọlọpaa ni ko si aniani pe eto idibo gomina nipinlẹ Kogi gbomi lara awọn agbofinro ju ti ipinlẹ bayelsa lọ.
Belgium fakọyọ lẹyin ti wọn sin ikọ Brazil to ti gba ife ẹyẹ agbaye lẹẹmarun-un ọtọtọtọ lọ'le lati Russia pẹlu ami ayo 2-1 ni ipele ''quarter finals.
Eroja wo ni awọn ayaba n lo lati tigba?
 Nibi ti wọn ti kọ oriṣiṣi orin imisi ẹmi lati inu iwe orin wọn, ni ti alakọpọ ati lẹnikọọkan.
Bi a ko ba gbagbe bi wọn ti se n sọ fun wa, ọwọ fifọ pẹlu omi ati osẹ se pataki.
Ninu ọrọ to ba BBC News Yoruba sọ aarẹ apapọ ẹgbẹ olukọ fasiti, ASUU lorilẹede Naijiria, Ọjọgbọn Biọdun Ogunyẹmi ṣalaye pe aijolootọ ijọba apapọ lori ijiroro to n waye lori imuṣẹ adehun eyi to fa iyanṣẹlodi naa.
Ṣugbọn olúwarẹ̀ níláti bèèrè pẹlu igbagbọ, láì ṣiyèméjì.
2trn) pọ ju ti ọdun to kọja lọ, eyi to din diẹ ni triliọnu mskanla naira (₦10.
Nisinsinyii, ìdẹ̀ra ti dé bá Lasaru nígbà tí ìwọ ń jẹ̀rora.
igbimo ajo FIFA ati ajo NFF nile-ise ijoba apapo, lojobo(Thursday), niluu Abuja.
ife-eye La Liga ninu idije orile-ede Spain, ti o si tun gba ami eye agbaboolu
"'Ìdìbò 2019 yóò nílò oun ìjà bíi drone f'awọn Ológun' L'Óṣogbo, Èéfín 'jẹnẹrétọ̀' gbẹ̀mí èèyàn mẹ́ta nínú ídílé kan CAF kéde orúkọ àwọn olùdíje àmì ẹ̀yẹ agbábọ́ọ̀lù Áfíríkà Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Goodluck Jonathan ní òun nìkan kọ́ ló l'ẹ̀bi ìjínigbé akẹ́kọ̀ọ́ Chibok àti Boko Haram O ni ile isẹ ọmọogun Naijiria ni awọn ohun ija igbalode bii ""super tonados"" ti o tilẹ le sisẹ lalẹ ti yoo si koju awọn ikọ Boko Haram naa."
Fasiti Johns Hopkins lo ti kọkọ kawe ko to gboye MBA ni fasiti Harvard.
Àwọn alufaa rẹ̀ ti kọ òfin mi sílẹ̀, wọ́n ti sọ ibi mímọ́ mi di aláìmọ́.
Mo ti ròó pé kò sí láàyè mọ ni, sùgbọ́n mo mọ̀ pé ohùn ọmọ mi ni mo gbọ́.
Lara awọn ilana to rọ mọ ikowojọ fuun oloṣelu ni pe ọmọ ilẹ Amẹrika nikan lo ni anfani lati lọwọ si irufẹ ikowojọ bẹẹ.
Elkana sàlàyé pé ìwádìí fihan pé ìrọ panbele ni gbogbo ẹ̀rí náà, ti wọ́n si mu àwọn afurasi náà lásìkò ìṣọ́ oru.
Ẹ máà wòran o, ọ̀bẹ ìyà tún ti ba Manchester United ní ìrù ìdí o Wọ àwòrán àwọn ẹbí òṣèré Nollywood yii!
BBC Hausa, Swahili ati bẹẹ lọ la maa n gbọ po wa fun ọpọlọpọ ọdun.
 bí orúko ìlé yìí se jeyo nì yìí.
Nítorí náà, níwọ̀n ìgbà tí a ní Olórí Alufaa ńlá tí ó ti kọjá lọ sí ọ̀run tíí ṣe Jesu Ọmọ Ọlọrun, ẹ jẹ́ kí á di ohun ti a fi igbagbọ jẹ́wọ́ mú ṣinṣin.
Wọn ni ọpọ òun ti Johesu n béèrè fún ko bójú mu.
 Bayii eniyan mesan an lo ti doloogbe lataari isele yii, eni meji nipinle Ondo, meji nipinle Edo ati meta nipinle Ebonyi.
Ọlọ́jọ́ Festival 2018: Ayẹyẹ ọdún Ọlọ́jọ́ ti Ilẹ Ifẹ̀ á parí pẹ̀lú àyájọ́ òmìnira Nàìjíríà
" Oyeyemi àwọn janduku naa lọ wa kun ara wọn ti wọn si lọ ile oloṣelu ti wọn pe orukọ rẹ ni Oluọmọ lati lọ sọ ina si.
Ó ní “ní ìlú afọ́jú, olójúkan ni ọba wọn”.
Ìgbà tí ó yìpadà tí ó di erin, èmi kò di erin, ṣùgbọ́n mo ni ki egbé gbé mi lọ sí ẹ̀yìn erin, mo si ń gun Ìnàkí-ìbẹ̀rù kiri: ìgbà tí ó ṣe ó di ẹfọ̀n, o n fẹ́ fi iwo gun mi, ṣùgbọ́n emi yípadà mo di òkúta, ìgbà tí o sì gbá ìwo rẹ̀ mọ́ òkúta díẹ̀ ló kù kí ó dá.
Ẹ tú ẹ̀dùn ọkàn yín jáde bí omi níwájú OLUWA!
Ó sì búra pé kí OLUWA ṣe jù bẹ́ẹ̀ sí òun bí òun kò bá gé orí Eliṣa, ọmọ Ṣafati, kí ilẹ̀ ọjọ́ náà tó ṣú.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Justice Osei le dún bíi ẹranko 50 Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Justice Osei le dún bíi ẹranko 50 31 Ẹrẹ̀nà 2018 Justice Osei, ọmọ orilẹede Ghana tó le dún bíi ẹranko 50 ni ẹni àkókó í ó le ṣe bẹ́ẹ̀.
Nítorí náà, ẹnikẹ́ni tí ó bá fẹ́ jẹ́ ọ̀rẹ́ ayé ti yàn láti jẹ́ ọ̀tá Ọlọrun.
Ṣugbọn kí ó jẹ́ ẹni tí ó ní ẹ̀rí rere lọ́dọ̀ àwọn tí kì í ṣe onigbagbọ, kí ó má baà bọ̀ sinu ẹ̀gàn, kí tàkúté Satani má baà mú un.
Òun ló ṣe ètò bẹ́ẹ̀ nítorí ó fẹ́ fẹsẹ̀ rìn dé ibẹ̀.
Àsẹ̀hìnwá-àsẹ̀hìnbọ̀ ọ̀rọ̀ náà, inú bí wa, a wá àjẹ́ lọ a sì rí i, a sì fi ìbínú sọ ara wa di àjẹ́ láti ọjọ́ náà títí ó fi di òní olónìí.
Òmùgọ̀ eniyan a máa bínú,ṣugbọn ọlọ́gbọ́n a máa mú sùúrù.
Orilẹede China: Eleyii ya ni lẹnu pupọ ju.
Wọ́n wá bi í pé, “Ǹjẹ́ a lè mọ ohun tí ẹ̀kọ́ titun tí ò ń sọ̀rọ̀ rẹ̀ yìí jẹ́?
Bawo ni ọrọ ṣe jẹ tẹlẹ?
Àwọn ọmọ Josẹfu náà gbógun ti ìlú Bẹtẹli, OLUWA sì wà pẹlu wọn.
Melaye tako èsì ìbò tó gbé Smart Adeyemi wọlé sẹ́nẹ́tọ̀ Ìwọ̀-òòrùn Kogi
Àwọn yàrá ti gbọ̀ngàn ìta gùn ní aadọta igbọnwọ (mita 25), ṣugbọn àwọn tí wọ́n wà níwájú tẹmpili jẹ́ ọgọrun-un (100) igbọnwọ (mita 50).
Nigba ti ile iṣẹ iroyin BBC ṣebẹwo si agbegbe naa, ikọ ọlọpaa to nimọ nipa ado oloro yẹ ayika ṣọọṣi naa wo bẹẹ si ni awọn ẹṣọ alaabo wa nibẹ wamuwamu.
Gómìnà Kẹtàlá – Ọ̀gbẹ́ni Babátúndé Rájí Fáṣọlá – Gómìnà Ìjọba Alágbádá fún ọdún mẹ́jọ – ọdún mẹwa titi di ọdún meji sẹhin
òkùnkùn birimùbirimù ń bọ̀ ní Nàìjíríà!
Akẹ́kọ̀ọ́ ìmọ òfin ABU tí wọ́n jígbé lọnà Kaduna-Abuja ti gba ìdáǹdè -Ọlọ́pàá
Bẹ́ẹ̀ ni wọ́n jọ sin wá pọ̀ nígbà tí wọ́n rì wá bọmi, tí wọ́n sọ wá di òkú, kí àwa náà lè máa gbé ìgbé-ayé titun gẹ́gẹ́ bí Ọlọrun baba ògo ti jí Kristi dìde kúrò ninu òkú.
Ọmọ marun un ni Nkurunziza funrarẹ bi.
Ṣugbọn Hẹrọdu ní “Ní ti Johanu, mo ti bẹ́ ẹ lórí.
Ìbú rẹ̀ náà sì jẹ́ ogún igbọnwọ (mita 9).
Níwọ̀n ìgbà tó jẹ́ pé, àwọn ibi taa fi ojú si lagbaye lórí wíwà ìwòsàn fún àrùn yìí, ọna kò gba ibẹ lọ, lo mú ki awọn ọmọ ilẹ̀ Áfíríkà kan dìde láti wá ìwòsàn pẹ̀lú oògùn ìbílẹ̀.
Michael Adikwu ni ẹni keji ti ọwọ́ tẹ̀.
Iceland Lati ọdun 1961 ni orilẹ-ede Iceland ti n san owo oṣu to kere fun awọn obinrin, ti ko si ribẹ fun awọn okunrin.
 Eleyii yoo le jẹ ka bori awọn ipenija ati iṣoro wa gbogbo.
yii forri-kori pelu gbogbo eso alaabo ati awon agbofinro lati se ipade ti yoo
ati pe ko si eni ti o sọ pe awon kan n fawọn sẹyin.
Ni bi a ṣe n sọrọ yii, ọkan lara awọn ọlọpaa ti o wa nibẹ ti di awati, a ko mọ oun to ṣẹlẹ si."
Lẹ́yìn wọn ni Meremoti, ọmọ Uraya, ọmọ Hakosi ṣe àtúnṣe abala ọ̀dọ̀ wọn.
Imana sọ fun ileẹjọ naa pe Nkem ko kuro nile oun, o si ko lọ si ile ọkunrin mii ninu baraaki kan naa tawọn n gbe.
Ìrí àwọn alángbá yìí káàkiri àti ìrísí , àwọ ̀ , àti ìwà tí ó yàtọ ̀ ṣe àfihàn nkan tí àwọn olóyìnbo ń pè ní adaptive radiation tí ó ní ṣe pẹ ̀ lú àwọn tí ó ń gbé ní archipelago yìí .
 Èyí túmọ ̀ sí pé àpapọ ̀ àwọn tí ó ń sọ èdè adamawa-ubangi ní ìbẹ ̀ rẹ ̀ pẹ ̀ pẹ ̀ jẹ ́ mílíọ ̀ nù mẹ ́ rindín ní ẹgbàá lọ ́ nà ọgọ ́ rùn-ún láì ka àwọ ̣ n tí ó ń sọ èdè sango mọ ́ ọ .
Ohun ti igbesẹ yii tumọ si ni pe lati akoko yii lọ, ko ni si isinmi lọjọ kọkandinlọgbọn oṣu karun un mọ to jẹ ayajọ ọjọ ijọba awarawa tẹlẹ.
Nígbà tí ó súnmọ́ ọn pé kí òun wò ó fínnífínní, ó gbọ́ ohùn Oluwa tí ó sọ pé, 
‘ASUU da ìyanṣẹ́lódì dúró' Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Grandma Maruwa: Ó yẹ kí obìnrin sisẹ́ láì wojú ọkọ kó tó jẹun Sibẹ laisko re ni ijọba apapọ gba lati maa san N30,000 gẹgẹ bii owo ọya oṣiṣẹ to kere julọ ni NaijiriaBuhari ti buwọ́lu #30,000 owó oṣù òsìsẹ́ .
"Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ẹ má bínú, mo kábàmọ́ pé mo na obìnrin -Elisha Abbo Ẹ̀tàn lásán ni ìkéde ìjọba àpapọ̀ lórí RUGA - Afenifere Gbẹgẹdẹ fẹ́ gbiná l‘Ọṣun, àwọn olùkọ́ iléẹ̀kọ́ gíga fẹ́ gba àjẹẹ́lẹ̀ owó oṣù ìdajì ""Grandpa àti Uncle mi, ń fipá bá mi lòpọ̀ láti ọmọ ọdún mẹ́rin"" ''Kii ṣe igba ti wọn bi mi ni mo ko aarun naa."
Darandaran tí mo mọ̀ wà lára àwọn tó ṣá mi ní àdá-Ọlọ́kadà Ṣé ìwọ leè wa kẹ̀kẹ́ lórí ìgò?
Oríṣun àwòrán, Femi Adesina Bi alakalẹ eto isuna fun ọdun 2021 yoo ṣe lọ niyii: Ileeṣẹ ijọba to n risi ọrọ abẹle - N227.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ọpọ ẹlẹwọn ni ko ni ireti lẹyin ti wọn ba kuro lọgba ẹwọn Nigba ti o nsọrọ lori akoko to lo ninu ọkan lara awọn ọgba ẹwọn lorilẹede Naijria, ọkan ninu awọn asofin naa, Sẹnatọ Shehu Sani ni ohun ti oju oun ri lẹwọn ko see maa fi ẹnu sọ.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Njẹ o ṣeeṣe ki isoro kan suyọ lasiko abẹrẹ ajẹsara naa?
Àdúrà mi ni kò jẹ́ kí ìyà Manchester United ó pọ̀ jù lọ́wọ́ Barcelona- Wòlíì Àrólé Fasiti Ọbafẹmi Awolowo University pariwo síta pé àwọn èèyàn ilé ifẹ̀ kan da májèlé sómi iléèwé Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, JAMB 2019: A ó fagi lé ìdànwò ẹni tó bá ṣe aṣemáṣe O ni ọmọ atapata dide ni oun bi ọpọ ọmọ Naijiria, ti baba oun si jẹ aransọ, nigba ti iya oun jẹ ọlọja.
"Asiko si ti to bayi tileesẹ agbohunsafẹfẹ BBC yoo da oju opo Yoruba silẹ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù #Pittsburg shooting: agbófinró gbé afurasí lọ sílé ẹjọ́ 28 Ọ̀wàrà 2018 Oríṣun àwòrán, Reuters Àkọlé àwòrán, Àwọn ọlọpaa ati akanṣe SWAT di ẹnu ọna Sinagọọgu naa pa Pittsburg ni ipinlẹ Pennsylvania niṣẹlẹ yii ti wáyé ni orilẹ-ede Amẹrika.
Iroyin ni foonu Vosco lo jabọ si kanga nigba to n fa omi lọwọ, lasiko igbiyanju rẹ lati yọ foonu naa lo ba rebọ.
“Bi àwọn ọlọ̀tẹ̀ wọnyi pé, ṣé wọn kò mọ ìtumọ̀ òwe wọnyi ni?
ó tún ranṣẹ sí Ẹsita pada, ó ní, “Má rò pé ìwọ nìkan óo là láàrin àwọn Juu, nítorí pé o wà ní ààfin ọba.
Oòrùn yóo ṣókùnkùn nígbà tí ó bá yọ,òṣùpá kò sì ní tan ìmọ́lẹ̀.
Alabojuto ọgbà ẹ̀wọ̀n náà fi wọ́n sábẹ́ àkóso Josẹfu, wọ́n sì wà ní ọgbà ẹ̀wọ̀n náà fún ìgbà díẹ̀.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Lizzy Anjorin: Ibadan ní ọkọ mi, ata wíwẹ́ lo fẹ́ràn 12 Owewe 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 13 Owewe 2020 Oríṣun àwòrán, Instagram/lizzy Anjorin Lawal Lẹyin oṣu meji to ṣe igbeyawo, o dabi ẹni pe gbogbo afẹfẹ-yẹyẹ igbeyawo ti dopin bayii fun gbajugbaja oṣere tiata ati eekan ori ayelujara, Lizzy Anjọrin.
Mose bá pe gbogbo àwọn àgbààgbà Israẹli jọ, ó sọ fún wọn pé, “Ẹ ṣa ọ̀dọ́ aguntan kọ̀ọ̀kan ní ìdílé yín kọ̀ọ̀kan, kí ẹ sì pa á fún ìrékọjá.
Gbèsè Nàìjíríà yóò di $50b tí wọ́n bá tún yáwó- Shehu Sani EFCC fẹ́ gbẹ́sẹ̀ lé ilé tí mo fi owó ìfẹ̀yìntì kọ́ nílùú Ilorin- Saraki Missing Child: Òbí àti asọ́nà ṣọ́ọ̀ṣì 14, lọ́ búra nì'dí imọlẹ̀ l'Akure Ibodè tí a tì ló fa ọ̀wọ́ngógó owó ọjà- Ìjọba Naijiria Ilé ẹjọ gíga ni ìpínlẹ̀ Oyo nínu oṣù kínní ọdun 2011 ti yọ ọba náà nípò lo tún fi morilé ilé ẹjọ kotẹmilọrun láti wọ́gile ìdájọ ilé ẹjọ ipinlẹ Oyo.
Ni gbogbo àwùjọ bá dìde, wọ́n fa Jesu lọ sọ́dọ̀ Pilatu.
Adari ikọ ọmọogun oju omi naa, Shuaibu Muhammed-Ahmed, ni awọn ọmọogun naa mu ileri wọn ṣẹ lati fi oju awọn aṣebajẹ han ni agbegbe oju omi to wa lorilẹede Naijiria.
Nígbà tí Jesu sọ̀kalẹ̀ láti orí òkè pẹlu wọn, ó dúró ní ibi tí ilẹ̀ gbé tẹ́jú.
Àgbo tí mò ń lò láti jò kó bá mi, ìdí mi ti yọ́ tán - Nkechi Blessing figbe ta Ọlọ́pàá tún yìnbọn pa awakọ̀ Márúwá, ìwọ́de gba Portharcourt kan Ọọni to ṣalaye pe riro awọn ọdọ lagbara ti jẹ afojusun oun tipẹ ni ori tentele ipojude ni Naijiria joko le o bi wọn ko ba doju kọ iṣoro awọn akẹkọọ.
Nítorí náà, Balaki ọmọ Sipori, ọba Moabu ranṣẹ lọ pe Balaamu ọmọ Beori ní Petori lẹ́bàá Odò Yufurate ní ilẹ̀ Amawi pé, “Àwọn eniyan kan jáde ti ilẹ̀ Ijipti wá, wọ́n pàgọ́ sórí ilẹ̀ mi, wọ́n sì bo gbogbo ilẹ̀ náà.
Ọkan ninu awọn olugbe adugbo naa to pe ara rẹ ni Chinedu ni afurasi naa ṣeeṣi yin ẹni ọdun marundinlogoji ọhun nibọn ni.
omo ti ko sile iwe , ni eyi ti o jẹ isoro pupo fun ajo to n mojuto eto eko  lati se ilana ti won lee tele lati mojuto awon
Ilé ẹjọ́ rán àwọn mérìndínlógún lẹ́wọ̀n gbére fún dídáná-sun Nusrat Ẹ wo ojú owó ìrẹ̀sì báyìí lẹ́yìn tí ìjọba ti ibodè pa Ilééṣẹ́ Google ṣe ìrántí Funmilayọ Ransome-Kuti!
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Oluwo Ìwo ṣ'àlàye lori oye Emir 1 Ìgbé 2018 Àkọlé àwòrán, Oluwo tilu Ìwo sọ pe òun fẹ di Ọba onilawani (Emir) ilẹ Yorùbá Oluwo ti ilu Ìwo, Oba AbdulRasheed Akanbi, ṣ'àlàyé nńkan to fáà to fi jẹ́ oye Emir.
Èyíkéyìí ninu wọn tí ó bá dáhùn, tí ó bá mú kí iná ṣẹ́, òun ni Ọlọrun.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Yoruba language: Ọdún 2020 to wọlẹ́ dé yìí á tu gbogbo wa lára Kini o ti ṣẹlẹ sẹyin?
) Bí ọkunrin onigbagbọ kan bá ní aya tí kì í ṣe onigbagbọ, tí ó bá wu aya rẹ̀ láti máa bá a gbé, kí ọkọ má ṣe kọ̀ ọ́.
Ọ̀pọ̀lọpọ̀ ìdí ló ń fa èyí, vaginismus kàn jẹ́ ọ̀kan lára wọn ni.
    “Ìwọ ọ̀rẹ̀ mi, díẹ̀ ló kù kí ikú bàbá mi sọ mi di wèrè; fún odidi ọ̀sẹ́ mẹ́ta n kò mọ̀ bí ayé ni mo wà bí ọ̀run ni.
Onisegun oyinbo ni: “Sise ayewo oju loorekoore se Pataki nitoripe arun ti eniyan ko ba tete mojuto maa n gbebo lowo eni lojo ola ni.
Ẹnikẹ́ni tí ó bá fi ọwọ́ kan òkè yìí, pípa ni n óo pa á.
₦500m lóṣù nìjọba Eko ń pa tẹ́lẹ̀ lọ́nà márosẹ̀ Lekki-Epe Oríṣun àwòrán, @TheLazyCheff O kere tan, ọjilenigba din mẹfa miliọnu naira ni ijọba ipinlẹ Eko ti padanu nitori awọn ẹnu iloro ti wọn ti n gba owo ibode to di titipa, lati igba ti iwọde End SARS bẹrẹ.
 Omotoso tẹ siwaju pe ""Agbofinro ti ọwọ ba tẹ pe o n ṣe iṣẹ ọkada tabi wa kẹkẹ ẹlẹsẹ mẹta lawọn ibi ti a ti fofin de, yoo foju wina ofin."
Àwọn ọlọ́pàá ti gbé Emia ìlú Kano, Lamido Sanusi kúrò ní ààfin rẹ̀ lẹ́yìn tí ìjọba rọ̀ ọ́ l'óyè Ìròyìn láti ìpínlẹ̀ Kano sọ wí pé àwọn agbófinró ti gbé Ẹmia Sanusi jáde láti ààfin rẹ niluu Kano.
"Tẹlẹtẹlẹ, awọn awakọ ero nipinlẹ Ọyọ lee sanwo fun irinajo kan ni ọna meji, orita bii mẹta si ni wọn yoo ti sanwo ita naa.
Saaju ọjọ idibo ni Ekiti, Ọ̀gá àgbà àjọ ọlọ́pàá Ibrahim Idris ti fi àwọn ọlọpáà ẹgbẹ̀rún lọ́nà ọgbọn sọwọ́ sí ìpinlẹ̀ Ekiti fún ààbò, to péye nínú ìdìbò tó ń bọ̀ lọ́jọ́ àbámẹ́ta nípìnlẹ̀ Ekiti.
 Aseyege fun ipo tuntun naaNigba ti asofin Ibrahaim n jabọ fun ile igbimọ  asofin,o sọ pe gbogbo awọn oruko  ti aare fi ranse lo yege lati odo awọn ajo eleto aabo, bakan naa ni  wọ yẹ fun ipo ti  wọn yan  wọn siAbẹnugan ile  igbimọ  asofin wa n ki awọn   igbimọ  tuntun naa ku ori-ire , o ni ile igbimọ  tete gba oruko  wọn wole , nitori  wọn jẹ alakinkanju.
Mahmood Yakubu , alaga ajo eleto idibo lorile ede Naijiria.
Asiko to n sisẹ ni ile iwe awọn agbẹjọro ni Naijiria ni o fẹ iyawo rẹ, Bisi Cole, ti wọn si bi ọmọ mẹrin.
-Taiwo Oyebola Agbona Àwọn sẹ́nétọ̀ Nàìjíríà fa ìbínú yọ 'torí N2Miliọ̀nù owó àjẹmọ́nú Kérésì tí wọ́n fún wọn Iyanifa Agwu sọrọ lori bi oun ṣe ba Ifa dida nile nitori pe Oluwo ni baba rẹ to bii nigba ti iya ẹ jẹ Iyanifa pẹlu Ilẹ̀ ifẹ̀ ní ìran Ìgbò tí ṣẹ wá kìí ṣe ilẹ̀ Juu - Ọọni Àǹfàní dé fún ọ láti lo internet lọ́fẹ́ Díẹ̀ lára àwọn ìṣẹ̀lẹ̀ tí yóò mi ìgboro tìtì l'ọ́dún 2020 rèé Lord Lucifer ni ó kọkọ ni ènìyàn mílíọnù kan to wòó lóri Youtube- Yekini Bakare Ella mẹnuba irufẹ awọn eniyan orilẹ-ede bii Brazil, Jamaica, Trinidad, Tobago, Ukraine atawọn orilẹ-ede ilẹ Adulawọ mii.
Lori isọrọ odi, Kawu kilọ f'awọn ile-isẹ igbohunsafẹfẹ lati sọ'ra lati maa gbe ọrọ odi s'ori afẹfẹ, eleyi ti o sọ wipe o le e da ija silẹ lorilẹede Naijiria.
Aliko Dangote: Mo gbà $10m ní bánkì kí o lè dami loju pé lòótọ́ ní mò lowo
com/yoruba/afrika-46577202 #67yearoldmother: Mo kojú ọ̀pọ̀lọpọ̀ àìsàn fún ọdún 35 lẹ̀yín ìgbéyàwò Àkọlé àwòrán, #67yearoldmother: Mo kojú ọ̀pọ̀lọpọ̀ àìsàn fún ọdún 35 lẹ̀yín ìgbéyàwò Iyi ati idunnu nla ni o maa n jẹ fun obinrin lati ṣe igbeyawo ki o si lọmọ.
 oyin adéjọbí náà ṣe fíìmù kan tí ó pè ní  orogún adédigba "" ní ọdún 1995 ."
Ọ̀nà rẹ̀ tura pupọ,alaafia sì ni gbogbo ọ̀nà rẹ̀.
O sọ èyi lọjọ Ru nigba ti wọn gbe ẹjọ agbejọrò abilekọ ti wọn tún ni o gé ǹkan ọmọkunrin ọkọ rẹ̀ lẹ́yìn tó pa á, wà si ilé ẹjọ́.
Toyin Abraham funra rẹ naa ki ara rẹ ku oriire pẹlu adura pe.
Nígbà tí ó ṣí i, ó rí ibi tí a gbé kọ ọ́ pé,
"Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Awọn oluwọde ENDSARS ba BBC sọrọ ""Eyi ni wọn n da ọmọ mi lẹjọ fun o leyi to si jẹ pe ohun to maa n wu u lati ṣe latinu ọkan rẹ ni o ṣe yii""."
Ọọni pe fun ifọwọsowọpọ Naijiria Ọọni kọ́lé fàwọn ọmọ òrukàn ní Ibadan Ọba Adesoji Aderemi, Ọọ̀ni Ifẹ̀ tó gba ipò ọba mọ́ tòṣèlú Àwa ọba alayé ń wọ́nà láti ṣẹ́ eegun ẹ̀yin ọ̀daràn Fulani - Ọọ̀ni Arole Oodua ni ko ni ṣeeṣẹ fun Naijiria lati tun koju ogun abẹlẹ bii ti Biafra to kọja lọ.
Nígbà tí wọn ń jáde lọ, wọ́n rí ọkunrin kan ará Kirene tí orúkọ rẹ̀ ń jẹ́ Simoni.
"Waziri funrarẹ ni ""bí wọ́n ṣe yìnbọn lù mí lójú gbàrà, ẹ̀rù kọ́kọ́ bà mí pé ṣe bó ṣe máa rí nìyìí""."
Ile iṣẹ to ni ọkọ ofururfu ti Naira Marley lo lọ si Abuja lọ fi kọrin lasiko isede Coronavirus ti tọrọ aforijin.
Losu kẹwaa ọdun ni yoo tẹwọ gba ami ẹyẹ naa nilẹ Géési nibi ti yoo ti ka apilẹkọ rẹ.
O wa gba awọn obi nimọran lati maa tete gbe awọn ọmọde ti wọn ba kẹẹfin pe o n hu ikọ lọ sile iwosan fun itọju, ki aisan naa to bọwọ sori.
" Wọn fi kun ọrọ wọn pe, gbogbo ìlú ni yoo mọ abajade iwadii naa.
Ayo Salami, to ti fi igba kan jẹ aarẹ ile ẹjọ kotẹmilọrun lo dari igbimọ oluwadii naa.
Nítorí náà, lọ, n óo sì wà pẹlu rẹ, n óo sì máa kọ́ ọ ní ohun tí o óo sọ.
Ọtí náà wọ́pọ̀ ní mímu nígbà òtútù ọ̀gìnìntìn ní orílẹ̀ Jamini àti káàkiri Úróòpù.
Èyí tí yóó yà ọ́ lẹ́nu jùlọ ni mo fẹ́ẹ́ sọ fún ọ yìí.
A kò lè lo è̩tó̩ yìí fún e̩ni tí a bá pè lé̩jó̩ tó dájú nítorí e̩ s̩è̩ tí kò je̩ mó̩ ò̩rò̩ ìs̩èlú tàbí ohun mìíràn tí ó s̩e tí kò bá ète àti ìgbékalè̩ Ajo̩‐ìsò̩kan orílè̩‐èdè àgbáyé mu.
aare Omar al-Bashir yoo maa lo fun eto ijoba re , ni won ti so pe, won ti sun
Àlá àwọn òjíṣẹ́ Olúwa tó fẹ́ jẹ ààrẹ Nàíjíríà leè má ṣẹ lógún ọdún - Abiara Aarẹ Buhari wa gbadura pe ki Eleduwa tubọ fi okun, ilera to peye ati ẹmi gigun jinki olori orilẹede Naijiria tẹlẹ ri.
Ọ̀pọ̀ eniyan bá wá péjọ sibẹ, wọ́n pọ̀ tóbẹ́ẹ̀ gẹ́ẹ́ tí ó fi jẹ́ pé ati inú ilé, ati ẹnu ọ̀nà ni ó kún.
Wọ́n rí kinní kan ní abẹ́ ẹsẹ̀ rẹ̀ tí ó dàbí pèpéle tí a fi òkúta safire ṣe, ó mọ́lẹ̀ kedere bí ojú ọ̀run.
Ìgbà tí Dókítà pàtàkì bá sùn ní òru tàbí babaláwo àtàtà, àwọn alátùn-únṣe wọnyí á fò lọ, wọn a lọ kọ ọ sí agbárí wọn.
Ọ̀pọ̀ eniyan ń tẹ̀lé e nítorí wọ́n rí iṣẹ́ ìyanu tí ó ń ṣe lára àwọn aláìsàn.
Eyi jẹ pẹlu ida ogun ninu ọgọrun ipin idokoowo ileeṣẹ naa to jẹ tirẹ gẹgẹ bi atọna awọn ọlọrọ lagbaye, Bloomberg Billionaires index, se sọ.
 ) mo odi sí ; se ààbò fún ; wón mo odi fún ilé náà nítorí ìjà àwon òtá .
Àwọn obìnrin méjì yí da bi ẹni pe wọ́n tilẹ̀ fi ibẹ̀ ṣe ilé ni, ti wọ́n ń gbádùn nínú igbó ti wọ́n sí ń ṣe fáàrí bí ẹni pé wọ́n wà ni ààrin ìlú.
 wọ ́ n ń sọ àwọn èdè wọ ̀ nyí ní penisula balkan ( balkan penisula ) ní ìlà-oòrùn àríwá ilẹ ̀ asia .
Ẹ ṣọ́ra, kí ẹ má baà wí pé, ‘A ti di ọlọ́gbọ́n,Ọlọrun ló lè ṣe ìdájọ́ rẹ̀, kì í ṣe eniyan.
Aafa Akeugbagold ni apẹẹrẹ were diẹdiẹ ni ọrọ ẹgbẹ ''Association of Stingy Men'' ti awọn kan n sọ.
Ó rọ́ àwọn ẹṣin náà lẹ́sẹ̀, ṣugbọn ó dá àwọn kan sí fún ọgọrun-un (100) kẹ̀kẹ́ ogun.
Wo oríṣìí oúnjẹ márùn ún tó lè dẹ́kun ikùn yíyọ àti ara àsanjù Wo àwọn oúnjẹ márùn ún tó ń mú kí àtọ̀ ọkùnrin dára síi Ìdí rèé táwọn àkàndá ẹ̀dá fi dí iwájú iléeṣẹ́ ìjọba ìpínlẹ̀ Oyo pa l'Agodi n'Ibadan Ìjọba àpapọ̀ ti kéde àdínkù owó epo bẹntiróòlù sí N162.
O sì níláti máa rú ẹbọ ìmúkúrò ẹ̀ṣẹ̀ fún pẹpẹ náà nígbà tí o bá ń ṣe ètùtù fún un, ta òróró sí i láti yà á sí mímọ́.
O wa rọ awọn ọmọ ikọ Bokoharam ati awọn ti wọn ji gbe ti wọn wa ni ipamọ lati jọwọ ara wọn fun awọn ọmọ ogun.
Ronke sọ lori oju opo Instagram rẹ pe inu oun ko le sọ bi inu oun ṣe dun to lori ọmọ tuntun ti Eleduwa fi ta idile oun lọrẹ.
Àwọn ọmọ ilé ìgbìmọ̀ aṣòfin náà ni ti Akpabio ba tó bẹ́ẹ̀, ti ǹkan to n sọ sì dáa'lójú kó kọ gbogbo àwọn iṣẹ́ kọngila ti àwọn gbà síta, kí àwọn àjọ tó n'mójú to ìwà àjẹbánu láwùjọ sì ṣe ìwádiìí tọ yẹ lórí rẹ̀.
Òtítọ́ ni pé a kàn án mọ́ agbelebu ní àìlera, ṣugbọn ó wà láàyè nípa agbára Ọlọrun.
O ni ki awọn eeyan maa fi ara balẹ gbe ọrọ kalẹ nitori gbogbo bi awọn ṣe n nawo ni akọsilẹ wa fun.
Ilé ẹjọ́ fún Sẹ́nétọ̀ Adeleke lọ́jọ́ mẹ́rin láti pèsè ìwé ẹ̀rí Fásitì
Gbìyànjú láti gun ọ̀kadà wálé láti Europe Wọn kédé Narendra, oludije ẹgbẹ́ BJP ni India pẹ̀lú ariwo ńla Mohammed Adamu ti di Ọ̀gá ọlọ́pàá Nàìjíríà tuntun Fayemi ṣetán láti ṣáájú àwọn gomina láti mójútó ètò ààbò Bakan naa lo sọrọ oko rẹ àti iṣẹ aladani ti oun n pada si ni kete to ba ti kuro nijọba ati pe ọrọ oṣelu ko ṣee kọ̀ silẹ.
Kii ṣe pe gbogbo Ekiti ko ni baba nile, wọn wa n wa baba lọ sode.
Oríṣun àwòrán, EPA Àkọlé àwòrán, Irufẹ baalu to wa ninu aworan yi lo jabọ Àti kúrò l'ẹ́wọ̀n Fayoṣe kò tíì lójútùú Ọ̀pọ̀ ń dárò Tony Anenih tó rèwàlẹ̀ àsà lẹ́ni ọdún 85 Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, #67yearoldmother:ọ̀pọ̀ gbà pé àdúrà ló gbà lóri tọkọtaya Otubusin Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Mike Ifabunmi: Òrìṣà ló gbè wà jù ni Brazil Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Wọ́n tún ti pa ọmọbìnrin míì lásìkò ìbálòpọ̀ tipá nílùú Ibadan Wàhálà tí àwọn ẹgbẹ́ òkùnkùn àt'àwọn ẹgbẹ́ ìjayà míràn ń dá sílẹ̀ láwọn ọgbà fásitì Nàìjíríà Irú kí lèyì!
O salaye pe ''ninu awọn akẹkọ wọn yi ni awọn ti yoo jẹ adari awujọ lọjọ iwaju yoo ti jade, ti a ko ba dẹkun iwa ibajẹ fun wọn nisinyii, kini ka ti wi ti o ba di ni ọla?
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ẹ sọ ìwé kíkà di dandan fún ẹ̀yà Fulani - Oluwo rọ ìjọba àpapọ̀ Òpin ọ̀ṣẹ̀ dé, ẹ jẹ́ ká jọ fi àwòrán aláyọ̀ ṣararindin Buhari gbà wá, àwọn àjèjì ti gbàkóso ilẹ̀ Yorùbá - Ọọ̀ni figbeta Afọnja, ẹni tó finú wénú ní Ilọrin, àmọ́ tó jẹ iwọ Àwọn ìròyìn BBC tó tayọ lọ́sẹ̀ yìí O tun fikun pe, laipẹ ni oun ati Salawa Abẹni yoo dijọ se awo orin jade, koda, ọmọ awọn to n kọ orin takasufe, Big Chef, ti oun gan yoo se awo orin naa papọ pẹlu awọn mejeeji.
O ni gbogbo ọjọ aye oun lohun yoo fi tun ohun toun ti bajẹ ṣe ti oun si fẹ ko mọ pe oun ko ni aburu lọkan rara ninu nkan ti oun ṣe.
Solomoni náà ranṣẹ pada sí Hiramu, 
“Gbogbo àwọn àkọ́bí eniyan tabi ti ẹranko tí àwọn ọmọ Israẹli bá mú wá fún mi, tìrẹ ni.
ni isẹ ohun osi pelu isoro airisẹ fun awon odo yoo di afiseyin ti eegun n fi aso.
Idi ni pe alaga ajọ alaanu kan, HANHF, Asofin Abayomi Fagbenro to se abẹwo si ọdọ iya Barakat lati baa kẹdun, ti pasẹ pe ki wọn bẹrẹ si se atunse ilegbe mọlẹbi naa.
Bi a ba ṣi eyi si owo Naira ti orilẹede Naijiria, owo irinna baluu ọhun jẹ laaarin ẹgbẹrun lọna ogoje naira (N140,847.
O ti hàn gbangba pé àwọn arúgbó lọ fara kasa nínú aarun yìí julo.
Nínú ìgbẹ́jọ́ ìgbìmọ̀ ẹlẹni mẹ́ta sàlàyé pé, ilé ẹja gíga kùnà, bi ó ṣe kọ̀ láti gba ẹrí tí wọ́n mú wá sílé ẹjọ́.
A ti sọ òtítọ́ inú wa fun yín, ẹ̀yin ará Kọrinti.
Iroyin ti o n tẹ wa lọwọ ṣalaye pe ni owurọ Ọjọbọ ni awọn oṣiṣẹ ajọ EFCC naa ya bo ileegbe awọn akẹkọ fasiti kan to wa lagbegbe Oke Baalẹ ni ilu Osogbo ti wọn si ko awọn akẹkọ kan nibẹ.
Ọjọgbọn Akindele ti beere fun eto ajọro bun mi-n-bun ọ ti oloyinbo n pe ni 'plea bargaining' lẹyin ti o ti gba pe oun jẹbi ẹsun naa.
Ajọ naa sọ pe aisan naa maa n wọpọ ni asiko ẹẹrun nitori bi oju ọjọ ṣe ri.
“Awon igbimo ti fenuko lori iye ti ekunwo yoo je nibi ipade ti won se kẹyin.
Ojisẹ Ọlọrun naa tun rọ Tinubu lẹẹkan si lati gbagbe erongba rẹ naa, ko ma si sopo daba lati dije fun ipo aarẹ rara nitori ala ti ko le sẹ lo rawọ le.
Ó tẹ àwọn ọ̀run ba, ó sì sọ̀kalẹ̀;ìkùukùu tí ó ṣókùnkùn sì wà ní abẹ́ ẹsẹ̀ rẹ̀.
Nigeria: Ọwọ tẹ afurasi mẹrin lori iku ọga SARS
Alukoro igbimọ amuṣẹya lori ọrọ ayika Adebayo Taofik lo sọ fun BBC Yoruba pe ọga ọlọpaa yi wọ gau lẹyin ti o gba owo lọwọ awakọ naa to rufin lagbegbe Lekki Ajah.
Bashir Ahmad oluranlowo si Aare lori ibanisọrọ ayẹlujara lo fi iroyin lede loju opo twita re.
PDP: A ò fẹ́ ẹ̀jẹ̀ Buhari gẹ́gẹ́ bí alábojútó ìbò kíkà INEC: Àìmọ̀kan-mọ̀kàn ló ń ṣe àwọn tó ń sọ̀rọ̀ tako ìyànsípò Amina Zakari Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Amina Zakari: Ojúṣe mi kìí ṣe láti ka ìbò Ọpọlọpọ awuyewuye lo wa lori iyansipo Amina Zakari,ẹni ti iroyin sọ wi pe o jẹ ibatan aarẹ Buhari, amọ Zakari sọ wi pe oun ko tan mọ aarẹ Buhari lọna kankan.
Bẹ́ẹ̀ ni Heburoni di ilẹ̀ ìní Kalebu, ọmọ Jefune, ará Kenisi títí di òní olónìí, nítorí pé ó fi tọkàntọkàn tẹ̀lé OLUWA Ọlọrun Israẹli.
Àmọ́ tí ó bá tayọ ọjọ́ kan péré, owó ọ̀hún di ọ̀lẹ̀lẹ̀ tó wọnú ẹ̀kọ nìyẹn.
Muslim High School, Ede, ni ipnle Osun fi si silẹ ni ile-ẹjọ.
Aarẹ orilẹede Naijiria tẹlẹ, Goodluck Jonathan lo yan an sipo gẹgẹ bii kọmiṣọna lajọ eleto idibo Naijiria, INEC ṣaaju idibo apapọ lọdun 2015.
Bo tilẹ jẹ pe baba Olajide ni awọn obi ko ri owo tọ ọ kọja ile iwe alakọbẹrẹ, o tiraka lati sọ ara rẹ di akọṣẹmọṣẹ ninu iṣẹ awakọ lai mọ wi pe eyi yoo sọ oun di mọlumọka to di lonii.
Ewe, idije naa yoo bere lonii ti n se ojo ketadinlogbon, si ojo keta osu kesan odun ti a wayii.
Eko Bridge Lagos Island / Lagos Mainland 37.
ile idọti ti won yoo maa da awon nnkan ti ko wulo sii.
Iṣẹ́ sí Àwọn tí ó Gbàgbọ́.
 Àìsàn naa ló n fa àìlèríran daadaa awọn eniyan tó lé diẹ ní miliọnu 2.
Ó lọ sí ilé-ẹ̀kọ́ Pọ́ọ̀lù mímọ́ ní Ayétòrò.
73 PMF Squadron, ni agbegbe Magumeri.
Ọlọrun bá fi àṣírí náà han Daniẹli ní ojúran, lóru.
Wọn ti gba ami ẹyẹ láti ọ̀dọ ajọ ìṣọkan agbayé Ọkùnrin mẹ́ta ni wọ́n ti fẹ́ rí Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Yellow Fever in Nigeria: Àrún ibà pónjú ti pa ènìyàn 172 ni Nàìjíríà - WHO5 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Adolf Hitler: Kíni ẹ̀yin rántí tàbí mọ̀ nípa Adolf Hitler yìí?
Kọmiṣọna fun eto ohun alumọni ilẹ ni ipinlẹ Ondo, ọgbẹni Rasheed Badmus sọ fun ileeṣẹ BBC wipe ni kete ti ijọba ti gbọ ọrọ nipa erin ti wọn pa yii, ni ijọba ti gbe awọn ọlọpa, aṣọgbo ati awọn eleto aabo abẹle jade lati ṣe awari ọdẹ naa.
Nípa igbagbọ ni Abrahamu fi Isaaki rúbọ nígbà tí Ọlọrun dán an wò.
BBC ti ba Kabiyesi Ọba Akadir Momoh, Olukare ti ilu Ikare sọrọ lataari iṣẹlẹ maalu to ku ni ilu Ikarẹ, ni Ipinlẹ Ondo.
26 Agẹmo 2020 Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí kan sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
” Ni ó bá jáde lẹ́sẹ̀ kan náà.
Bẹ́ẹ̀ ni a kò ní mu omi kànga yín.
Ta ba si fẹ kiyesara nipa arun naa, o yẹ ka mọ ohun kan tabi meji nipa rẹ ati awọ̀n ọna ta lee gba dena rẹ.
Asiko ni yi fun wa lati bọ si gbangba.
Samsoni bá sọ fún wọn pé, “Ẹ jẹ́ kí n pa àlọ́ kan fun yín, bí ẹ bá lè túmọ̀ àlọ́ náà láàrin ọjọ́ meje tí a ó fi se àsè igbeyawo yìí, n óo fun yín ní ọgbọ̀n ẹ̀wù funfun ati ọgbọ̀n aṣọ àríyá.
nígbà tí Ọlọrun dìde láti gbé ìdájọ́ kalẹ̀,láti gba gbogbo àwọn tí à ń nilára láyé sílẹ̀.
 Àkọ ́ kọ ́ ni Ṣódaa bẹ ́ ẹ ̀ .
Àwọn ọmọ Lefi nìwọ̀nyí: Geṣomu, Kohati ati Merari.
Àwọn ọ̀nà tí obìnrin fi le gbádùn ìbálòpọ̀ To ba n pẹ jẹun alẹ́, o le ni jẹjẹrẹ ọyan àti asétọ̀ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Ògidì ọmọ Yorùbá ni mí, kò sí ọ̀rọ̀ tí n kò lè túmọ̀' Awọn dokita lati ilẹ Amẹrika naa fikun wipe o seese ki igbẹ ọmọde jẹ ọna abayọ si gbogbo aarun ti n pa awọn eniyan lai to ọjọ.
Aworan bi Mamoudou Gassama se yara gun ile alaja merin lati gbemi omode naa la ni awon oluworan gbe kaakiri  sori ero ayelujara, bi awon eniyan se n pe odomokunrin omo odun mejilelogun naa ni alantakun okunrin.
Ní ọdún kejidinlogun ìjọba Jeroboamu ni Abija jọba ní ilẹ̀ Juda.
Hawkins ni orilẹ-ede India ni ọmọ wọn a pọju ti wọn bi ẹgbẹrun mẹtadinlaadọrin ikoko, o le ni irinwo din ni mẹẹdogun nigba ti China a bi ẹgbẹrun mẹrindinlaadọta o le ni ọọdunrun din ikan.
Wọn yóo wá gba ẹ̀bi nítorí wọ́n ti kọ ẹ̀jẹ́ wọn àkọ́kọ́ sílẹ̀.
Adeboye: Ìkìlọ̀ mẹ́ta tí àgbà ìjọ fi síta nínú ìwàásù f'áwọn Pásítọ̀ ọ̀dọ́
Àwọn alásẹ South Sudan ti ti ilé isẹ́ rẹ́díò BBC tó wà ní olú ìlú orílẹ̀èdè náà, Juba àti ní Wau pa.
Jẹ́ kí ẹ̀mí ọba ó gùn;kí ó pẹ́ láyé kánrinkése.
Ètò àbò, ètò ẹ̀kọ́, gbégbá orókè nínú àbádòfin 2019 Triliọnu kan naira n'ipinlẹ Eko yoo naa ni 2018 Ààrẹ Buhari yóò gbé ìgbìmọ̀ kalẹ̀ lórí ẹ̀kúnwó owó oṣù tuntun f'òṣìsẹ́ 'Ìlànà ọgbọ́n ni ètò ìsúná tí Ambode gbé síta' - Onímọ̀ nípa ètò ìsúná Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Bode George s'ọrọ lori abadofin tuntun ipinlẹ Eko Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Gẹgẹbii ọrọ rẹ, igba ọdun ni awọn obinrin orilẹede Naijiria fi n rakoro lẹyin gbogbo iran yooku gẹgẹbii iwadi naa ti se sọ.
Opó kan wà ninu ìlú náà tíí máa lọ sí ọ̀dọ̀ adájọ́ yìí tíí máa bẹ̀ ẹ́ pé, ‘Ṣe ẹ̀tọ́ fún mi nípa ọ̀rọ̀ tí ó wà láàrin èmi ati ọ̀tá mi.
Idasefiema Ibimina, Chinonso Cecelia Ndukwe ati Odelusi Bunmi Joy jẹ mẹta lara àwọn ti Blankson to doloogbe lẹyin to gba awọn ero ori omi là kọ̀ lati jẹ ki ikú rẹ̀ ja si asan.
JP Clark, àgbà ọ̀jẹ̀ òǹkọ̀wé dágbére fáyé lẹ́ni ọdún 85!
Shina Rambo fi aye rẹ jin Ọlọrun, Obadare gbadura fun, to si yi orúkọ rẹ pada si Oluwafemi, asiko ti Oloye Olusegun Obasanjo n dari orile-ede Naijiria si lo fun Shina Rambo ni idande kuro lọgba ẹwọn.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Arun iba ọrẹrẹ Lassa: dokita kan jalaisi nipinlẹ Kogi 23 Sẹ́rẹ́ 2018 Àkọlé àwòrán, ogunlọgọ awọn eniyan lo ti doloogbe nipasẹ arun iba ọrẹrẹ Ijọba ipinlẹ Ondo ti n lọgun bayi pe eniyan marun ti jalaisi lati ipasẹ arun iba ọrẹrẹ ati wipe eniyan mejilelogun miran ti wa labẹ itọju ni ipinlẹ naa.
Zambia Rats Video: Fọ́nrán fídíò èkúté ní ilé ìwòsan jẹ́ ìdójútì fún ìjọba -Mínísítà ìlera
O ni minisita fun ajo Niger Delta, alufa Usani Uguru Usanini yoo je alaga ipade naa, ti akowe agba Aminu Aliyu yoo si maa dari awon eto lolokan-o-jokan.
2020 Africa Prize:Ẹ wo àwọn ọ̀dọ́mọdé Naijiria tó ń ṣe bẹbẹ níní iṣẹ́ aládaní
Inú káàdì ìránti tí mo rí he ní mó tí rí fọ́tò ìhòhò Salawa, mó kàn fẹ́ gbà owó díẹ̀ ni- Afurasí Fájìn ni àbúrò mi ti wọn fipá bálopọ̀ nínú sọ́ọ́sì, tí wọ́n sì tún fọ́ lórí"" Olorì Anu Adeyemi ń ṣe ọjọ ìbí, ẹ gbọ́ ǹkan tò sọ sí Kábíyésì Jesu Oyingbo rèé, pásítọ̀ tó láṣẹ ìbálòpọ̀ lóri ọmọ ìjọ obìnrin Iye awọn to ti ri iwosan ti jẹ 3007, ti awọn to si ti ku nitori arun naa lorileede Naijiria ti jẹ 287."
Gba owó ètùtù lọ́wọ́ àwọn eniyan Israẹli, kí o sì máa lò ó fún iṣẹ́ ilé ìsìn àgọ́ àjọ, kí ó lè máa mú àwọn ọmọ Israẹli wá sí ìrántí níwájú OLUWA, kí ó sì lè jẹ́ ètùtù fún yín.
Bákan náà, aṣọ tí o óo ta sí ẹ̀gbẹ́ àríwá àgbàlá náà yóo gùn ní ọgọrun-un igbọnwọ, àwọn òpó ti ẹ̀gbẹ́ náà yóo jẹ́ ogún bákan náà, pẹlu ogún ìtẹ́lẹ̀ tí a fi idẹ ṣe, ṣugbọn fadaka ni kí o fi ṣe ìkọ́ ati òpó wọn.
Tunji sọ pe yatọ si pe ko ṣi ẹnikẹni to mọ pe igbakeji gomina yoo yọju sibi adura naa, wọn gbiyanju lati pe igbakeji gomina naa pada, ṣugbọn o ti kuro nibi ti iṣẹlẹ naa ti waye.
Nigba ti wọn n sọrọ nibi ifọrọwerọ pẹlu awọn akọroyin ni ipinlẹ naa, wọn ni awọn ti ṣeto biara ilu ṣe le maa gba ori afara naa lasiko atunṣe ọhun.
Ọ̀nà kan wà tí ó dàbí ẹni pé ó tọ́ lójú eniyan, ṣugbọn òpin rẹ̀, ikú ni.
 dida ara wa ni ida 65 % ninu awọn eniyan ti o ni irufẹ ẹjẹ 4 pẹlu itọju laarin Ọsę mejidinlaadọta .
Aṣe jijuwọ pe o dabọ, o ya nile ni aarẹ ju si awọn ọmọ Naijiria.
Lọdọọdun ni aarun iba ma n pa eeyan to to ẹgbẹrun lọna irinwo le marundinlogoji ti ọpọ wọn si jẹ ọmọde.
”Dafidi dáhùn pé, “Bẹ́ẹ̀ ni, oluwa mi.
 O ni, “bo tilẹ jẹ pe eleyii ki I ṣe ojuṣe aṣofin kan lati maa fun awọn ara ilu ni awọn ohue eelo ironilagbara bayii, sibẹ ninu apo awọn aṣofin yii ni wọn ti n na owo lati le jẹ ki awọn ara ilu mọ riri ijọba tiwantiwa yii”.
O pa oju fonran naa re ni ibere ose yi leyin ti awon olopa fi oro wa lenu wo.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Iléeṣẹ́ ọmọogun Nàìjíríà ní fídíò tó ti pẹ́ ní fídíò ọmọogun tí kò fẹ́ kojú Boko Haram 31 Ọ̀pẹ̀̀ 2018 Oríṣun àwòrán, Twitter Àkọlé àwòrán, Fidio naa ti n ja rainrain lori ẹrọ ayelujara Ileeṣẹ ọmọogun Naijiria ti fẹsi si fọnran fidio kan to gbode lori ayelujara nibi ti ọmọogun kan ti n fapa janu lori aisi nkan ija lati koju ikọ Boko Haram.
Àkọlé àwòrán, Ile miran tun wo l'Eko Wọn ní ní kété tí ẹni tó ní ilé náà ṣe gbó pé ìjọba tí yaa soto láti wòó ni ó fi kú àwọn tí yóò bá ṣe iṣẹ́ ilé Wiwo náà.
Ṣugbọn nígbà gbogbo kí ẹ máa lépa nǹkan rere láàrin ara yín ati láàrin gbogbo eniyan.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Dan Foster: Gbajúgbajà sọ̀rọ̀sọ̀rọ̀ orí rédíò Dan Foster ti dágbére fáyé 17 Òkùdu 2020 Oríṣun àwòrán, Facebook/Dan Foser Àkọlé àwòrán, Amẹrika ni Dan Foster wà tẹ́lẹ̀ kó tó wá sí Nàìjíríà Gbajugbaja sọrọsọrọ ori redio, Dan ti dagbere faye.
Ọjọ kọkanlelogun oṣu kẹjọ ọdun 1984 ni wọn ṣe ifilọlẹ rẹ Èèyàn 221 ló forí kó Covid -19 ní Nàìjíríà lọ́jọ́rú Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'ìjà ṣẹlẹ̀ láàrín èmi àti ọ̀gá mi ní Lebanon tórí mi ò lè dá N300K padà' Iṣọri kẹrin ni igbogun tiwa ajẹbanu ati didoju ọrọ aje Naijiria bolẹ: Ofin yii lo n gbogun ti iwa dida owo ilu sapo ara ẹni ati híhu awọn iwa to le ṣe akoba fun ọrọ aje wa.
O tẹsiwaju pẹ digbi ni oun wa lẹyin ofin ijọba ipinlẹ Benue ti o lodi si fifẹran jẹ kaakiri lalai bikita.
Ilẹ̀ tí ó fún Abrahamu, níbi tí Abrahamu ti jẹ́ àjèjì yóo sì di tìrẹ.
    “Ṣe ló déédéé ṣe tí a gbọ́ tí ẹnìkan ń polówó ọjà tí o ń ké lóhùn rara báyìí pé: ‘Ará ìgbó, èrò ọ̀nà, ẹ wá bámi rà á ooo, ọjọ̀ mi pọ̀, owó kékeré ni: wárapá, pọ́nùn mẹta; ṣọpọ̀nná pọ́nùn méjì; ẹ̀tẹ̀, pọ́nùn mẹ́rin; wèrè, pọ́nùn mẹ́fà; orí fífọ́, sílè mẹ́wàá; ẹsẹ̀ dídùn, ṣílè mẹ́fà; oówo, ṣílè kan ; inú rírun, ṣílè mẹ́wàá; sòbìà, pọ́nùn kan; òtútù, tọ́rọ́; làkúrègbé pọ́nùn kan; ìgbẹ́ ọ̀rìn , pọ́nùn kan-àbọ̀; ifọ́n, sísí, kúrúnà tọ́rọ́; ìkọ́, pọnùn kan; ibà, ṣílè méjì; òkè ilọ̀, pónùn méjì; aràn, ṣílè mẹ́ẹ̀dógún abbl.
Orukọ baba ati iya rẹ ni Fẹmi ati Feyi Adegoke.
Bakanna lo jẹ goolu meji lọjọ Kẹtadinlọgbọn, oṣu Kẹjọ nigba ti Tottenham koju Manchester United ti wọn si pegede pẹlu goolu 3-0.
Kamaru Usman: Ǹ jẹ́ o mọ ìlú akẹ̀ṣẹ́ UFC yìí ?
Ẹgbẹ oṣelu PDP, lo fi lede bẹẹ nibi ti wọn ti n dun inu wi pe ẹgbẹ oṣelu PDP jawe olubori ni ipinlẹ Edo.
Gomina Yahaya Bello ti Kogi àti David Lyon ti Bayelsa gba ìwé ẹ̀rí INEC Ẹgbẹ́ òṣèlú AA kò gbọdọ̀ kópa nínú ìdìbò gómìnà ní Kogi, Bayelsa - Ilé ẹjọ́ Kò sí aàyè fún ìbò rírà àti títà ni Kogi àti Bayelsa- IGP Ogun Cholera: Ọdọọdún ni àrùn onígbá-méjì máa n ṣọṣẹ́ ní Nàìjíríà -NCDC Yàjóyàjó: Èsì ìdìbò Kogi tó gbé Yahaya Bello wọlé rèé Saaju idibo loni, ẹgbẹ oselu PDP ti kọ iwe ipẹjọ si ajọ INEC pe ki idibo naa waye, lẹyin ti wọn tako esi idibo ti INEC gbe jade pẹlu ẹsun pe ọpọlọpọ esi idibo naa waye ni awọn agbeegbe ti rogbodiyan ti ṣẹlẹ.
Alukoro ileeṣẹ naa, Sunday James ni meji pere ninu awọn dokita wọnyi lo ni iwe aṣẹ irinna iyẹn fisa.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ilé ẹjọ́ kéde Ademọla Adeleke gẹ́gẹ́ bíi gómìnà ìpínlẹ̀ Ọṣun Ìyá àgbà Ọlayinka, arúgbó tó ń ṣoge bí omidan Baṣọ̀run Gáà, tó yan ọba mẹ́rin, pa ọba mẹ́rin àmọ́ ọba karùn-ún ló pa á Àràmọ̀ǹdà!
Awọn obinrin meje ti orukọ wọn pada wọnu iwe awọn tile igbimọ n ṣayẹwo fun ni: 1) Pauline Tallen: Labẹ ijọba Oluṣẹgun Obasanjọ, Baba Iyabọ ni arabinrin Pauline ti kọkọ ṣiṣẹ pọ.
Makiri fẹ́ iyawo kan ará Hupi, ati ọ̀kan ará Ṣupimu.
Tani otutu ma n mu ju laarin Ọkunrin ati Obinrin?
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ọbasanjọ: N kò ní dẹ́kun láti máa tako Buhari 5 Ẹrẹ̀nà 2019 Oríṣun àwòrán, @NGRPresident Àkọlé àwòrán, Ọbasanjọ ti kọ lẹta si Buhari eleyi to di gbajugbaja kaakiri agbaye Aarẹ tẹlẹri lorilẹede Naijiria, Olusegun Obasanjo ti ni, idi ti oun fi n tako Aarẹ Buhari ni wi pe isejọba tiwantiwa fayegba ki eniyan o sọrọ nipa ijọba to wa lode.
Mú kí ife kíkorò yìí kọjá kúrò lórí mi.
“Majẹmu tí mo bá ọ dá kò yẹ̀ rárá: O óo jẹ́ baba ńlá fún ọpọlọpọ orílẹ̀ èdè.
Amuwa sọ pe niwọn igba ti ọlọpaa ba ti gbaṣẹ lati yẹ eeyan wo, ẹni naa ko nilo lati kọkọ yẹ ọlọpaa wo ṣugbọn o ni lati fu ra ki wọn maa ba fi nnkan to le ṣakoba si i lapo.
Yahaya tun kẹkọọ nipa imọ ẹsin Islam, o si sọ pe baba oun lo kọ oun gẹgẹ bii Shaykh.
Mo ro nkan ti awọn eniyan yoo sọ nipa mi, to fi mọ iru oju ti wọn yoo fi wo ọkọ mi.
Africa ni iṣẹju kẹtadinlọgbọn ifẹswọnsẹ naa ki South Africa naa  to da ami ayo naa pada ni iṣẹju kárùndínlọ́gọ́rin ,nigba ti Bongani Zungu fori kan bọọlu sawọn iko agbabọọlu ti orile ede Naijiria.
Ọjọgbọn yi tun tẹ siwaju lati kawe sii, ni University College, ilu Ibadan, laarin 1960 si 1961.
Àwọn ọ̀dọ́ Benue fọnmú nítorí ìkọlù darandaran ''Èkó àti àwọn Ìpínlẹ̀ miran náà yóò sì bẹ̀rẹ̀ láàárín ọ̀sẹ̀ títi di ọjọ́ ìsinmi tó ń bọ̀'' Lójú òpó twitter ní ṣe làwọn olùwọ́de ń fi àwọ̀ran ìwọ̀de hàn.
Ó fọ́ wọn túútúú, ó sì fọ́n wọn ká sórí ibojì àwọn tí wọn ń sìn wọ́n.
Orilẹede Russia ati ilẹ Amẹrica wa wọya ija gidi gan gẹgẹ bi wọn ṣe n yara ko awọn ikọ ogun wọn sita.
Iko agbaboolu Lazio naa gbo ewuro soju Salzburg pelu ami-ayo merin si meji(4-2), beesin iko agbabolu RB Leipzig fagbahan Olympique de Marseille pelu ami-ayo kan sodo(1-0).
 Igbakeji Agbenusọ Ile, lati ẹkun idibo
Bẹ́ẹ̀ náà ni oyún; tí ènìyàn bá lọ ní in ní àsìkò tí kò dára, ó di epo tí ó dà síni láṣọ nìyẹn, kàkà kí a jẹ óúnjẹ pàtàkì tí a fẹ́, tí ó sì máa ṣe wá ní oore, á di ohun ìbànújẹ́ fún wa.
BBC Nigeria 2019: Ọ̀rọ̀ àwọn olóṣèlú, tásìkò bá tó, akólòlò á pe baba
Dá mi lóhùn, OLUWA, dá mi lóhùn; kí àwọn eniyan wọnyi lè mọ̀ pé ìwọ OLUWA ni Ọlọrun, ati pé ìwọ ni o fẹ́ yí ọkàn wọn pada sọ́dọ̀ ara rẹ.
” Manoa kò mọ̀ pé angẹli OLUWA ni.
Ààrẹ Obama ti ṣe ìkéde nípà ìṣẹ̀lẹ̀ náà.
Lasiko naa ni ibọn pa ‘afurasi’ mẹrin loju ẹsẹ, ninu eyi ti ọlọpaa mẹta ati araalu kan wa, ti awọn mẹrin miran si fara gba ọgbẹ ibọn, awọn meji mii si di awati.
Oríṣun àwòrán, others Igbimọ oluwadii naa ni irọ to jinna si ootọ, ti ko si lẹsẹ nilẹ ni awọn ẹsun naa, ti wọn si dibo pe awọn ọmọ ile asofin nipinlẹ Eko si ni igbẹkẹle kikun ninu olori wọn naa.
com/pEQ6lcpXSOOgbeni Keyamo  naa ti fi si ori ero ayelujara  twitter  re nipa atunto ti o de ba ile-ise to n sakoso
Alaga igbimo egbe Mo Ibrahim, Salim Ahmed Salim so pe, “Ellen Johnson-Sirleaf gbakoso orile-ede Liberia nigba ti ogun abele ti baa je tan, ni eyi ti o gbe igbese ati fopin si aawo ti mu idagbasoke ba orile-ede naa ati eto ijoba tiwa-n-tiwa.
kí o sì dàgbà bí irúgbìn oko.
O ti mú kí arabinrin rẹ dàbí olódodo lẹ́gbẹ̀ẹ́ rẹ, nítorí pé nǹkan ìríra tí o ṣe pọ̀ pupọ ju tirẹ̀ lọ.
Nítorí náà Saulu ọba ranṣẹ pe Ahimeleki ati gbogbo ìdílé rẹ̀, tí wọ́n jẹ́ alufaa ní Nobu, wọ́n sì wá sọ́dọ̀ rẹ̀.
Ìyàwó ààrẹ Nàìjíríà náà sọ pé gbogbo òṣìṣẹ́ tí wọ́n bá ká àìṣe dédé mọ́ lọ́wọ́ yó fojú winá òfin.
1 sẹ ́ yìn , tàbí ní òpin pliocene àti ìbẹ ̀ rè pleistocene sẹ ́ yìn ; Àsọyépọ ̀ fihàn pé ó jẹ ́ ìràn ènìyàn ti ìgbà ìsìsìyí .
Gbogbo eewọ idile ati ounjẹ wọn ni ẹbi ọkọ a ṣalaye fun iyawo tuntun ki wọn to wa bu omi tutu sii lẹsẹ wọle ki ẹsẹ ọsingin le dara lọọdẹ ọkọ rẹ.
Ọsẹ yii ni wọn yọnda Angel lati kuro ni ileewosan ọhun to n bẹ lapa ariwa ilu Libreville.
O ní òun ni lati gbé ǹkan kana kí àwọn ọmọ fi ọkan si pé ounjẹ n bọ, sùgbọ́n ìrètí oun ni pe, wọ́n o sùn lọ.
Ajọ NCDC tun kede pe awọn ti ayẹwo tun ti fihan pe o ti larun naa ni ọjọ Aiku ni ipinlẹ si ipinlẹ niwọnyii.
Ninu ifọrọwanilẹnuwo pẹlu BBC Yoruba, o ni ọrọ naa dabi ka ni ọlọja gbe ọja silẹ, to si n wa awọn ti yoo ra lowo to peye ni.
Ṣugbọn ohun ti mo le sọ bayii ni pe mo la awọn iṣoro yii kọja, bo tilẹ jẹ pe wọn ṣakoba fun mi ninu ero mi.
Sereṣi iyawo rẹ̀ ati àwọn ọ̀rẹ́ rẹ̀ sọ fún un, pé, “Lọ ri igi tí wọn ń gbé eniyan kọ́, kí ó ga ní ìwọ̀n aadọta igbọnwọ.
Wòlíì Kasali ní Dolapo Awosika kò lé ìyàwó òun jáde Bakare tun wa bu ẹnu atẹ lu irinajo ti oludije fẹgbẹ oselu PDP naa rin lọ silẹ Amẹrika, pẹlu afikun peeyi gan lo jẹ logun.
Ó wá sọ fún àwọn ìgbìmọ̀ pé, “Ẹ̀yin ọmọ Israẹli, ẹ ṣọ́ra nípa ohun tí ẹ fẹ́ ṣe sí àwọn ọkunrin yìí.
Ti a ko ba gbagbe, ijọba apapọ ti pe ẹgbẹ Ipob ni ẹgbẹ agbesunmọmi, ti wọn si fikun wipe awọn yoo fi panpẹ ọba mu enikẹni to ba n sọ kaakiri wipe ọmọ ẹgbẹ naa ni oun.
À ti jọ máa sọ ọ̀rọ̀ dídùndídùn pọ̀ rí;a sì ti jọ rìn ní ìrẹ́pọ̀ ninu ilé Ọlọrun.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Lizzy Anjọrin: Inú mi dùn láti di Bọ̀rọ̀kínnì Àdínnì 16 Sẹ́rẹ́ 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 17 Sẹ́rẹ́ 2019 Yoruba ni oniruuru ọbẹ laa ri lọjọ iku erin, bẹẹ ni ọrọ ri lasiko ti ilumọọka elere tiata lobinrin kan, Alhaja Aisha Lizzy Anjọrin se iwuye oye ẹsin Bọrọkinni Adinni ti wọn fi jẹ.
Ṣugbọn bí ó bá ń hu ẹ̀gún ati igikígi, kò wúlò, kò sì ní pẹ́ tí Ọlọrun yóo fi fi í gégùn-ún.
 Muhammadu Buhari fun aseyọri  rẹ lati jawe olubori ninu  eto idibo aarẹ to waye lorile ede yii.
O si tun ni ki obinrin tete bimọ le ran lọwọ.
OLUWA, o ti yọ mí kúrò ninu isà òkúo sọ mí di ààyè láàrin àwọn tíwọ́n ti wọ inú kòtò.
Lanre Onilu to jẹ akọwe ipolongo ẹgbẹ naa ni ''Atiku n ṣe iranra ni'' Ninu atẹjade kan ti o fi sita lọjọru lorukọ ẹgbẹ,Onilu sọ pe awọn ba Atiku kaanu bi awọn ọmọ Naijiria ti ṣe fi ibo wọn da sẹria fun.
Kí ó kọ etí rẹ̀ sí ẹni tí ó fẹ́ gbá a létí,kí wọ́n sì fi àbùkù kàn án.
Gbogbo àwọn tí ó kú ninu yín kò kú ikú idà,bẹ́ẹ̀ ni wọn kò kú lójú ogun.
Nibayii ileeṣẹ ọlọpaa ti jẹ ko di mimọ fun araalu pe ẹnikẹni to ba kofiri rẹ ko fi to ileeṣẹ ọlọpaa to ba wa lagbegbe rẹ leti.
Níwájú ẹnu ọ̀nà ìhà àríwá, ni ẹnu ọ̀nà gbọ̀ngàn inú wà bí ó ti wà níwájú ẹnu ọ̀nà ti ìlà oòrùn.
Ewe, pasi-paaro owo dollars kan si owo Naira din die nirinwo ni ojo-Isegun, latodo awon onisowo aladani oja owo ile-okeere.
O jẹ akọroyin to n ṣe oniruuru nkan pọ ni iha ilaoorun ilẹ Afirika ti o si ti ṣe ifọrọwanilẹnuwo fun ọpọ awọn gbajugbaja oloselu ati awọn ilumọọka miran ni Kenya.
”Idije Uefa Champions League ko ni se pelu, bi iko agbaboolu se dara si tabi se kopa si, bi ki ba a se esi ifesewonse ti o ba waye leyin saa ifiigagbaga mejeeji,”Ni bayii, iko agbaboolu Real madrid yoo gbalejo Juventus ni papa isere Santiago, bee si ni, Bayern Munich yoo gbalejo Sevila ni papa isere Alliance Arena.
Ṣugbọn n óo mú ìdájọ́ wá sórí orílẹ̀-èdè náà tí wọn yóo sìn.
Nípa igbagbọ ni ó fi jẹ́ pé bí ó tilẹ̀ ti kú, sibẹ ó ń sọ̀rọ̀.
Àtẹ ìfẹ́kà rẹ̀ ń bẹ lọ́wọ́ rẹ̀.
Bakan naa ni Odunlade tun gbe beba ninu eyi ti wọn kọ oriṣiiriṣii nkan si bii ''ọlọpaa, ẹ dẹkun ifiyajẹni, ipaniyan, ẹ ṣe atunṣe ileeṣẹ ọlọpaa,'' ati bẹẹ bẹẹ lọ.
nomba odidi ( integer ) je gbogbo awon nọ ́ mbà àdábáyé alapaotun { 1 , 2 , 3 .
Ami ayo mẹrin sodo ni Manchester United fi ṣagba Chelsea nigba ti wọn kọkọ jọ waako ni ibẹrẹ saa bọọlu yii.
Ọga ọlọpaa ni ileeṣẹ awọn ni ifarajin si igbesẹ atunṣe ti ijọba apapọ n ṣe lọwọlọwọ ni Naijiria.
Eto idibo yii ni yoo je akoko
’ Nígbà tí ó débẹ̀, ó rí i pé ibẹ̀ ṣófo, ati pé a ti gbá a, a sì ti tọ́jú rẹ̀ dáradára.
Riri to ri ẹyẹ meji ti wọn gbe sibẹ - to ti ku, to ki ẹnu bọ ara wọn l'ẹnu, pẹlu iyẹ wọn to fọn kaakiri ilẹ, o ro ninu ara rẹ pe, a jẹ pe ẹyẹ lo n ba ara wọn ja.
Iwadii naa ni laarin ọdun mẹta yii, ni awọn alakatakiti ẹsin Islam Boko Haram ti pa eniyan 5,598, ti ija awọn daradaran si pa eniyan to din diẹ ni ẹgbẹrun marun un (4,917).
Oríṣun àwòrán, Getty Images Arabinrin naa se akawe awọn ami ti o ma n safihan wi pe o seese ki okunrin naa ko wuwa ipa si obinrin ti o ba fẹ ẹ si ile.
Àwọn ọmọ Israẹli di ẹni ilẹ̀ patapata, nítorí àwọn ará Midiani.
Olukuluku a máa mú ohun tí wọ́n bù fún un wá sí ibi tí wọ́n ti nílò rẹ̀.
Nítorí èyí ni ọkunrin yóo ṣe fi baba ati ìyá rẹ̀ sílẹ̀, yóo wá fi ara mọ́ iyawo rẹ̀; 
Tesiwaju si, jijawe olubori ninu ifesewonse mejeeji naa lofun Brazil lanfaani lati pegede sipele ti o kan, ti won yoo si lo koju orile-ede Belgium nilu Kazan lojo Eti(Friday).
Oríṣun àwòrán, Instagram/bukunmioluwasina/ Aṣẹyinwa aṣẹyinbọ, Bukunmi tọrọ aforijin lọdọ awọn eeyan ti onikaluku naa si ki tọkọtaya tuntun naa ku ayọ igbeyawo.
"Ni asiko yii, a n gbadun adun aye, a si wà pẹlu awọn ti a fẹran.
Awọn to gba tọwọ rẹ ku - 117 Ipinlẹ Iye awọn to laarun covid-19Awọn to wa nibudo iyasọtọ Awọn to ti gbadun Awọn to ti ku Lagos 1,667 1,186 448 33 Abuja FCT 336 292 40 4 Kano 547 509 20 18 Gombe 110 100 10 0 Borno 142 128 0 14 Ogun 113 81 28 4 Katsina 137 120 9 8 Edo 67 51 12 4 Osun 38 4 30 4 Kaduna 95 79 14 2 Bauchi 117 110 6 1 Sokoto 93 80 4 9 Oyo 59 43 14 2 Akwa Ibom 17 5 10 2 Kwara 24 15 9 0 Ekiti 12 7 4 1 Ondo 15 9 6 0 Taraba 15 15 0 0 Delta 17 11 3 3 Rivers 21 15 4 2 Jigawa 83 82 0 1 Benue 2 2 0 0 Anambra 1 0 1 0 Zamfara 65 62 0 3 Abia 2 1 1 0 Enugu 10 8 2 0 Niger 6 4 2 0 Adamawa 15 15 0 0 Plateau 15 14 1 0 Imo 3 2 1 0 Bayelsa 5 5 0 0 Ebonyi 7 7 0 0 Kebbi 18 18 0 0 Nasarawa 25 24 0 1 Yobe 13 12 0 1 Bi Coronavirus se n tan kiri Naijiria ti awọn orileede agbaye miranon mii si n ka iye awọn to gba tọwọ rẹ ku to fi mọ awọn miran to n ko lojumọ,ipinlẹ meji kan ni Naijiria wa ti ko ti d'ọdọ wọn.
Aafin Ọba ilẹ Gẹẹsi, Buckingham palace lo kede eyii.
Kí ẹ jẹ ohunkohun tí ẹ bá rà ní ọjà láì wádìí ohunkohun kí ẹ̀rí-ọkàn yín lè mọ́; 
Mallam Tunde Kazeem, to je oludari ere idaraya fun ipinle Kwara ni won ko awon akonimoogba meta naa pelu won.
Ǹjẹ́ ewu wà nínú lílò ẹ̀rọ FaceApp?
Nítorí pé mo ti fi ara mi búra, èmi OLUWA ni mo sọ bẹ́ẹ̀, pé Bosira yóo di àríbẹ̀rù ati ohun ẹ̀gàn, ahoro ati ohun àmúgégùn-ún; àwọn ìlú rẹ̀ yóo sì di ahoro títí lae.
Ó kí àwọn tí wọn ń kórè ọkà, ó ní, “Kí OLUWA wà pẹlu yín.
Ṣugbọn OLUWA wí fún Samuẹli pé, “Má ṣe wo ìrísí rẹ̀ tabi gíga rẹ̀, nítorí pé, mo ti kọ̀ ọ́.
Nítorí gbogbo àwọn yòókù mú ọrẹ wá ninu ọ̀pọ̀ ohun tí wọ́n ní; ṣugbọn òun tí ó jẹ́ aláìní, ó mú gbogbo ohun tí ó fi ẹ̀mí tẹ̀ wá.
Odidi ọdun kan ni Naijiria fi ṣe eyi ki wọn to wa pinu lati dara pọ.
Inú mi yóo ru sí wọn ní ọjọ́ náà, èmi náà óo kọ̀ wọ́n sílẹ̀, n óo mú ojú mi kúrò lára wọn, n óo sì pa wọ́n run.
Orile-ede America so lojo-Bo pe, won yoo da owo-ori fun ile-Europe  duro fun igba die, eyi ti o je alajosowopo re ti o tobi julo, ati fun orile-ede Argentina, Australia, Brazil, Canada, Mexico ati South Korea, ni won yoo da owo ori naa duro fun titi di ojo kinni osu karun odun 2018, ki ijiroro lori oro ohun to tesiwaju.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ọ̀rọ̀ ń bọ́ lóríi fídíò Codeine 'Kọ́ ọgbà fún ẹran ọ̀sìn rẹ' Òǹyẹ̀ kò leè yẹ èlé owó osù - Ẹgbẹ́ òsìsẹ́ Akọ̀ròyìn BBC bá ìkọlù Afghanistan lọ ÀJẸPỌ́NNULÁ Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Awọn ọlọpa mu afunrasi janduku merinlelaadota n'ipinlẹ Ọyọ 30 Sẹ́rẹ́ 2018 Oríṣun àwòrán, AFP Àkọlé àwòrán, Lasigbo waye l'ọjọ aje nigba laarin awọn ẹgbẹ Oodua Peoples Congress, OPC Ọwọ ọlọpa ti tẹ awọn afunrasi janduku mẹrindinlaadọta to ni ibasepọ pẹlu laasigbo to waye l'Oke-Ado ni ilu Ibadan, nipinlẹ Ọyọ.
Produced b: Yemisi Oyedepo ati Bayo Odukoya Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí kan sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Nigeria Election 2019:Awọn wò ní Gómìnà El Rufai n ba wi pẹlu ihalẹ 'body bag' 6 Èrèlè 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 7 Èrèlè 2019 Oríṣun àwòrán, @elrufai Àkọlé àwòrán, Gomina El Rufai ko ṣẹṣẹ ma sọ ọrọ to ma n fa awuyewuye 'Onwoye kankan lati ilu okere to ba n bọ lati dasi idibo Naijiria ko ni fara re pada sile.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Lábẹ́ odò!
Àwọn amòfin ati àwọn Farisi bẹ̀rẹ̀ sí bá ara wọn sọ pé, “Ta ni eléyìí tí ó ń sọ̀rọ̀ àfojúdi sí Ọlọrun báyìí?
O kéré tan ènìyàn mọ́kàndínlọ́gbọ̀n ló ti pàdé ọlọjọ wọn níbi ìkọlú ti àwọn Boko Haram tun ṣe ní ìlú kan ní Maiduguri lánà òde yìí.
Lẹ́yìn náà, ó wí fún Uraya pé, “Máa lọ sí ilé rẹ kí o sì sinmi fún ìgbà díẹ̀.
Ṣaaju nigba ti iroyin yii bẹrẹ si ni tan kalẹ ni BBC kan si olubadamọran Aarẹ Buhari lori ọrọ iroyin, Garba Shehu ko le fiidi ọrọ na mulẹ tabi bẹẹkọ.
Ìdíje tó bẹ́rẹ̀ ni ọjọ́ kọkànlélógun oṣù kẹfa ọdún yìí ní bi ti àwọn orílẹ̀-èdè Afíríkà mẹ́rìnlélógun tí ń fi igagbága.
Melaye fẹ̀yìn Smart Adeyẹmi janlẹ̀ Àwọn àwòràn àyàbá tójú wa rí lọ́jọ́ ìdìbò Sẹnetọ Bukọla Saraki lo sọ bẹẹ ninu atẹjade kan ti, Yusuph Ọlaniyọni to jẹ amugbalẹgbẹ fun un lori ọrọ iroyin sita.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Arẹgbẹṣọla: 'Lóòtọ́ ni mo jẹ gbèsè l'Ọṣun ṣùgbọ́n gbèsè ayọ̀ ni' Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Arẹgbẹṣọla: 'Lóòtọ́ ni mo jẹ gbèsè l'Ọṣun ṣùgbọ́n gbèsè ayọ̀ ni' 29 Ògún 2018 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 31 Ògún 2018 Ogbẹni Rauf Arẹgbẹṣọla ni àǹkóò fáwẹ̀ẹ̀lì ni ọrọ gbese jijẹ!
Ṣugbọn ki se gbogbo ọmọ ẹgbẹ lo tẹlorun wi pẹ ki Buhari nikan du ipo aarẹ labẹ asia ẹgbẹ.
Khadijat Oluboyo: Ilé ẹjọ́ sọ ọ̀rẹ́kùnrin rẹ̀ sí gbaga
Wike to sọrọ ọhun nipasẹ kọmiṣọnna eto iroyin ati ibaraẹnisọrọ, ṣalaye pe lotitọ ni o dara lati ṣeto owo oṣu tuntun fawọn olukọ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Onímọ: Bo bá ṣe le è ṣùn tó, ni ẹmí rẹ yóò ṣe gùn sí 18 Ẹrẹ̀nà 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images To ba fẹ ni ẹmi gigun, ati ilera to peye, o ko gbọdọ yan oorun lodi rara, o si gbọdọ maa ba oorun sisun se ọrẹ ni."
Ohun tí olúkúlùkù bá gbìn ni yóó hù jáde fún un.
Ẹbọ ohun jíjẹ tí ẹ óo máa rú pẹlu wọn ni ìyẹ̀fun tí a fi òróró pò, ìdámẹ́wàá lọ́nà mẹta òṣùnwọ̀n efa fún akọ mààlúù kan, ati ìdámárùn-ún òṣùnwọ̀n efa kan fún àgbò; 
Bí ẹnu ti ń ya gbogbo eniyan sí gbogbo ohun tí Jesu ń ṣe, ó sọ fún àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ pé, 
Àkọlé àwòrán, El Rufai: A ti mú àdínkù ba kóníléógbélé Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
UFC248: Israel Adesanya ti fi ẹ̀ṣẹ́ yanjú Romero ní ìjà ẹ̀ṣẹ́ kíkàn
Ó ní, “Ẹ fún mi ní irú àṣẹ yìí kí ẹni tí mo bá gbé ọwọ́ lé, lè gba Ẹ̀mí Mímọ́.
"Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Awọn ẹya Fulani to ngbe pẹlu awọn Yoruba Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Awọn ẹya Fulani to ngbe pẹlu awọn Yoruba 30 Sẹ́rẹ́ 2018 ""Emi ti mo n sọrọ yi, ọmọ Yoruba ni iyawo mi."
Wọn bii ni ọjọ kejidinlọgbọn, oṣu kọkanla ọdun 1955.
 Gbogbo eniyan ni won feran awon ere to ba dari nitori pe kii se ole rara.
Ọmọ Yahoo Plus: Wọn ní kí ń pa ìyá mi, kí ń lè lówó si ni
Atẹjade naa fikun wi pe awọn ọmọ ogun yoo bẹrẹ iwadii lori ẹnikẹni ti ko ba ti ni Iwe Idanimọ rẹ ni agbegbe naa.
Igbimọ amuṣẹya naa sọ pe ki awọn ileeṣẹ baalu to n rinrinajo lọ silẹ okeere, ati awọn alaṣẹ papakọ ọk ofurufu bẹrẹ igbaradi fun ṣiṣi irinajo silẹ okeere.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Florida: Ọ̀ọ̀nì àléègbà dé ba Mary lálejò lọ́gànjọ́ òru Bakan naa ni a ni awọn ẹyẹ idì bii Super Eagles ti Naijiria, The Eagles ti Mali ati Carthage Eagles ti Tunisia.
Ní ọdún 1965 ní àjọ̀dún yìí kọ́kọ́ bẹ̀rẹ̀.
Dafidi kọjá sí òdìkejì àfonífojì ní orí òkè níbi tí ó jìnnà díẹ̀.
’’Aare wa ro awọn ijọba ibilẹ lati seto iranwo fun awọn ti ijamba ina yii sẹlẹ si.
Ìpínlẹ̀ Jigawa Ìpínlẹ̀ yìí nítirẹ̀ ni nítori ọ̀rọ̀ corornavirus ni òun ṣe gbe ilẹ̀kun ilé-ẹ̀kọ́ tì, bótilẹ̀ jẹ́ pé ààlà àwọn àti ìpínlẹ̀ Katsina náà súnmọ ara wọ́n.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ijinigbe: BBC ṣe ìwádìí bí ikọ̀ IRT ṣe ń gbéjà ko awọn ajinigbe lójú Ko da, o kan Ife, Ilorin to fi di wi pe ọta wa pọ to fẹ doju ija kọ ilu Ibadan.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ìtàn ayé Henry Fajemirokun, olówó tó fi owó mọ Olúwa àti ènìyàn Ọ̀fọ̀ ńlá ṣẹ̀ ní Ivory Coast, Olóòtú ìjọba, Amadou Gon Coulibaly jáde láye Tó o bá fẹ́ wọ bàálù lásìkò yìí, wo òfin tuntun tó tẹ̀lé Ọwọ́ ọlọ́pàá ìpínlẹ̀ Oyo ti tẹ àwọn aṣekúpani tó ń ṣọṣẹ́ ní Akinyele Ìpínlẹ̀ Eko kéde ọ̀nà àbáyọ sí súnkẹrẹ-fàkẹrẹ ọkọ̀ lásìkò àtúnṣe afárá Third Mainland Wo ìgbẹ́sẹ̀ méjọ tí ilé aṣòfin ìpínlẹ̀ gbọdọ̀ tẹ̀lé láti yọ igbákejì gómìnà Ilé aṣofin Ondo fọwọ́ òsì júwe ilé fún aṣòfin mẹ́ta pé wọ́n tàpá sí òfin ilé Bakan naa ni wọn salaye pe, wọn ti gbe oku awọn eniyan naa lọ si ibudo igbokusi ni Sapele, ti wọn si ti fi isẹlẹ naa to awọn ẹbi ati ara wọn leti.
Bẹ́ẹ̀ni àwọn ọmọdé a máa ṣeré ká nígbàmíràn pẹlú ajáa wọn.
”Aare Buhari seleri lojo abameta(Saturday) pe, oun yoo ri daju pe gbogbo abawole awon omo ogun olote ohun ni won di patapata.
Arabinrin Aisha Buhari ni gbogbo eeyan lo mọ pe Naijiria ko ni abo labẹ iṣejọba ọkọ ohun, ṣugbọn o da oun loju pe asiko to lati mu nnkan bọ sipo fun awọn ọmọ orilẹede Naijiria.
 Èdè igbìrà Èdè yìí jẹ ́ ọ ̀ kan lára àwọn èdè naìjírìà .
Kódà, ọ̀rọ̀ náà kò tíì tán lójú òpó BBC Yoruba, nibiti àwọn èèyàn ti ń gbáà ọrọ náà mọ ara wọn lọ́wọ́, bíi ẹni gba igba ọtí.
Koda, Alaafin adeyẹmi lo gbe ade le gbogbo wọn lori nilu ẹnikọọkan wọn O ma n bu ẹnu ẹtẹ lu ijọba ti ko se daadaa Oríṣun àwòrán, @alaafinofoyo Ọjọ ti pẹ ti Alaafin Adeyẹmi ti n kọ lẹta lati bu ẹnu ẹtẹ lu awọn igbesẹ ijọba ti ko dara, koda ko to o jẹ ọba.
Muka, ti ọpọ eeyan tun n pe ni Apasẹ tiata, tun salaye siwaju pe, ọpọ awọn oṣere tiata to dudu bíi koro isin tẹlẹ ni wọn ti bora, ti wọn si pọn roboto, ki awọn oṣere lee maa pe wọn lati kopa ninu ere.
Awọn ọlọpaa Dubai ni wọn ba ogoji miliọnu dọla, ọkọ bọginni mẹtala to to miliọnu meje dọla din ni igba, kọmputa mọkanlelogun, foonu mẹtadinlaadọta ati awọn nkan mii mọ Hushpuppi lọwọ.
Bí ẹ ti ń lọ, ẹ máa waasu pé, ‘Ìjọba ọ̀run súnmọ́ tòsí!
Ẹ kò gbọdọ̀ gé ẹsẹ̀ irun orí yín tabi kí ẹ gé ẹsẹ̀ irùngbọ̀n yín.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Obateru Akinruntan: Wíwá ohun tá jẹ títí láé ló gbé wa kúrò nílé Ife O ni ida mẹẹdọgbọn ninu ida ọgọrun ni agbara ti ijoba apapọ ni, ile igbimọ asofin ati ẹka idajọ lo ni eyi to pọju lọ.
Lati le e wa ojutu si ọrọ naa, awọn aṣojuṣofin ti wọn ṣẹṣẹ bẹrẹ iṣẹ lorile-ede Naijiria ti pinnu lati tọ pinpin bi ijọba to ti kọja laarin ọdun 1999 si 2007 ṣe na biliọnu mẹrindinlogun dọla.
    Èṣù dìde, Adéforítì náà tẹ̀lé e, àwa náà tẹ̀lé wọn.
Ẹwẹ, olori ẹgbẹ alatako ni Zambia, Hakainde Hichilema naa kẹdun pẹlu fasiti Copperbelt lori iku Matfishi.
Ni saa keji yii ẹru ọrun rẹ ti rọrun diẹ nitori aarẹ Buhari ti yọ ileeṣẹ kan kuro ni ileeṣẹ mẹta ti o n mojuto tẹlẹ.
Wọn á ranti pé Ọlọrun ni àpáta ààbò wọn,ati pé Ọ̀gá Ògo ni olùràpadà wọn.
Ọba mẹrin dojú kọ ọba marun-un.
Nigba to gba ipe naa tan, o ni oun n lọ ba wọn ṣugbọn arimọ wọn la ri o!
Wọn sin sinu agboole rẹ ti wọn n pe ni Brazillian Barracoon nilana ẹsin Musulumi.
Nígbà tí gbogbo àwọn eniyan rí i, wọ́n fi ìyìn fún Ọlọrun.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ohun tó yẹ kẹ́ẹ mọ nípà olùdíje mèjì tó lágbára nínú ìdìbò Ghana rèé 3 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Awọn eto oludije Tẹ aworan oludije ki o le mọ si nipa wọn ati ohun ti wọn fẹ ṣe John Mahama Nana Akufo-Ado John Mahama National Democratic Congress John Dramani Mahama jẹ oloṣelu ilẹ Ghana, sọrọsọrọ, ati olukọtan ti wọn bi si idile oloṣelu lọjọ kọkandinlọgbọn oṣu kọkanla ọdun 1958.
Trikytee ni olukópa kẹrinla ti yóò kúrò nínú ilé BigBrother Ebuka ni, ààyà wà fún ẹnikẹni tó bá fẹ́ dìbò fún ẹnikẹ́ni láti jáwe olúbori pẹ̀lú mílíọ̀nu márundìndinláàdọ́run náírà le bẹ̀rẹ̀ láti alẹ́ òní títí di ọjọ́ Eti tọ n bọ̀.
"Oríṣun àwòrán, Majeobaje ""Awọn janduku agbebọn ti gba ẹkun ariwa Naijiria kan, Awọn Fulani darandaran n sa fun asalẹ, awọn eeyan to n fori sọta ọsẹ Boko Haram n wa aabo."
Atiku fẹ́ fa Lauretta Onochie, amúgbálẹ́gbẹ́ Buhari, lọ silé ẹjọ́ fún ọ̀rọ̀ orí Twitter, ó tún bèèrè fún N500m
Ní ọdún kẹrinla tí Hesekaya jọba ní Juda, ni Senakeribu, ọba Asiria, gbógun ti àwọn ìlú olódi Juda, ó sì ṣẹgun wọn.
Ẹbi ati ara ati ọrẹ a jijọ jẹun alẹ ọjọBọ yii papọ pẹlu ayọ, wọn yoo dupẹ gbogbo oore ti wọn ti gbadun sẹyin.
Sọ àsọtẹ́lẹ̀ orílẹ̀èdè tí yóò borí ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ t'òní Biodun Fatoyinbo fi ipò sílẹ̀ lorí ẹ̀sùn ìfipábánilòpọ̀ Ta ni awàdà rẹ̀ wú u yín lórí jù ní Yollywood?
O tun maa n ran iya rẹ lọwọ nidi akara dindinta ko too tun maa ba awọn onibara rẹ so bata wọn to ba ja nigbogbo igba ti oju n pọn ọn.
Ọkan nínú wọ́n to jẹ́ ìgbákeji ààrẹ nigbà kan ri, Joe Biden, ti ròó pin ki o to gbe igba oroke ni South Carolina lọ́jọ́ Satide.
Oríṣun àwòrán, Biodun Fatoyinbo/Facebook Àkọlé àwòrán, Fatoyinbo kọ̀ láti yọjú ni ìwáàdí ò ṣe parí FRSC dá N443,180 padà fún ẹbí ẹni to ní ìjàmbá mọ́tò Ọlọ́pàá Germany ń wádìí àfurasí mẹ́rin nínú àwọn tó kọlu Ekweremadu ni Germany Ọwọ́ ti tẹ ọlọpàá mẹ́rìn to pa afurasí Nǹkan kò ṣẹnuure fáwọn obìnrin nínú ìgbìmọ̀ ìṣèjọba Buhari Awọn ajọ tó ń rí sí ọ̀rọ̀ ilé ìjọsìn pẹntikọsita ní Nàìjíríà (PFN) ti so pe iwadi ajọ naa si ẹsun ifipabanilopọ ti Busola Dakolo fi kan oludasilẹ ijọ Commonwealth of Zion Assembly (COZA), Pasitọ Biodun Fatoyinbo ko pari.
Ṣugbọn ọmọ ogun Siria kan déédé ta ọfà rẹ̀, ọfà náà sì bá Ahabu ọba níbi tí ìgbàyà ati ihamọra rẹ̀ ti pàdé.
Fayoṣe vs EFCC: Agbẹnusọ Fayoṣe ní àwọn ti pèsè ohun gbogbo tó yẹ Oríṣun àwòrán, Lere Olayinka Àkọlé àwòrán, Ọ̀sán ọjọ́ Aje ni Fayoṣe kérò l'ọ́gbà ẹ̀wọ̀n Ikoyi, ní ìpínlẹ̀ Eko.
Wọ́n run àwọn ati àwọn ìlú wọn patapata.
Wọ́n ní ẹ́gbẹ́ àwọn wà ní ipò tó dára láti mú orílẹ̀èdè Nàìjíríà tẹ̀ síwájú.
Security Meeting: A fẹ́ àgbékalẹ̀ ọlọ́pàá agbègbè láti pèsè ààbò tó rinlẹ̀
Eyi ko ṣẹyin bi Oyakhilome ṣe sọ ninu fidio kan to kari ori ayelujara pe coronavirus ni nkan ṣe pẹlu idasilẹ irinsẹ ayelujara 5G, ati wi pe ara imọ lati da ilana igbe-aye tuntun 'new world order' silẹ ni.
Awọn to fẹ lo Amọtẹkun lati fi maa kọrin ẹlẹyamẹya yoo kan idin ninu iyọ.
Bẹẹni, ko si ẹni to n gba owo to to Ibrahim Salisu Iriyos ni Gano, ijọba ibilẹ Dawakin Kudu ni ipinlẹ Kano, ninu awọn agbabọọlu to wa nibẹ.
Oga agba awọn ọlọpaa lorilẹ-ede Naijiria, Mohammed Adamu ko fi ọkan pe meji, to ti tẹ'kọ leti de ilu Eko lati kilọ fawọn agbofinro.
Òfò ṣ'ẹ̀dá: Ẹ̀fọn Norwich já bàálùu Man City Ronaldo, Messi ẹ yàgò lọnà fagbábọ́ọ̀lù Nàìjíríà tó n gbowò julọ!
Saworo Idẹ: Saworo Idẹ dabi ilu gangan sugbọn, wọn ṣe ni ọṣọ pẹlu awọn agogo keekeeke.
Muhammadu Buhari ti fiwe ikẹdun ransẹ si ẹbi awọn   to padanu ẹmi wọn, ile wọn ati ohun ini wọn
Ṣugbọn Jerusalẹmu ti òkè wà ninu òmìnira.
Bi ọjọ ti ṣe n gori ọjọ naa ni ilera pipe n sun mọ ọ.
Gbé e kọ́ sórí òpó igi akasia mẹrin, tí ó ní ìkọ́ wúrà.
Bakanna lo kopa nigbati Naijiria se ipo kẹta nibi idije African Nations Championship (CHAN) ni ọdun 2014 ni South Africa.
won si maa gba iwa  imẹlẹ laaye .
Nítorí náà, ẹ dúró ṣinṣin kí ẹ sì máa ṣe gbogbo nǹkan tí a kọ sinu ìwé òfin Mose.
 Nitori naa, tire-tibi lo wa nibi lilo  imo ero.
Kí ló dé tí àwọn orílẹ̀-èdè yóo fi máa sọ pé,“Níbo ni Ọlọrun wọn wà?
Baruku bá ṣe gbogbo ohun tí Jeremaya wolii pa láṣẹ fún un lati kà lati inú ìwé ilé Oluwa.
Ahmad ṣalaye pe laarin ọdun 2015 si 2018, aimọye biliọnu owo naira lo jade lati ilu Kano nikan nibi ọgbin irẹsi.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Ifẹsẹwọnṣẹ naa gbóná sii ni apa keji nigba ti olootu ọjọ naa ran Didier Drogba lọ ile nitori wi pe o gba Nemanja Vidić leti ni bii iṣẹju mẹrin si ipari ifẹsẹwọnṣẹ.
Iroyin taa gbọ ni wipe wọn ko jẹ ki arakunrin naa tẹ ita fun ọdun meje.
O ni adanu nla ni iku mama Oyediran jẹ fun ẹbi, atawọn ọrẹ rẹ to fi mọ ile iwe iroyin Tribune.
Sugbọn Ọlọrun nikan lo mu mi darapọ mọ wọn , ati pe emi ni mo n soju 'awọn ti a'.
naa tun so pe“Ajo naa yoo polongo esi idanwo naa, nigba ti o ba jade.
Adájọ́ ẹ tú wa ká, ìyàwó mi n gbé ààlè wá sórí ibùsùn wa- Ọkọ ìyàwó Pope Francis wọ́gilé òfin tó n dáàbò bo àlùfáà tó bá bá ọmọdé l'òpọ̀ Ààrẹ Muhammadu Buhari ti buwọ́lu owó ìṣúná ọdún 2020 Ẹ̀wọ̀n tí mo lọ ni ẹ̀san ìwà tí mo hù gẹ́gẹ́ bíi olórí ológun- Buhari Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Oluwo Divorce: ko si ẹni ti kò mọ pé ọmọ ilẹ̀ òkèrè ni mó fi ṣe aya Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Fídíò, Ondo election 2020: Àwọn ara ìpínlẹ̀ Ondo ránṣẹ́ sí Akeredolu ohun ti wọ́n ń retí ní báyìí12 Ọ̀wàrà 2020 Fídíò, Wole Soyinka sọ ìdí tó fi ni òun a fi màálù Fulani ṣe súyà fáwọn èèyàn abúlé23 Owewe 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
5M El-Zakzaky Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ìnú mi kìí dùn nígbà trí mo ń ṣiṣẹ́ ni bánkì tó ìgbà ti mo bẹ̀rẹ̀ mẹkáníìkì Oluṣakoso mẹta ní wọn sì ti rán lọ sí ẹwọn fún ọjọ máàrún ati mẹwaa lórí ìṣẹlẹ náà.
Sowore: olùdíje Ààrẹ tó loun fẹ gbà Nàìjíríà padà fún àwọn ọdọ
24 Agẹmo 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 26 Ọ̀wàrà 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, ọpọlọpọ gbagbọ pe arogun n mu lọkọlaya gbadun ara wọn daadaa Ko si ẹri pé oriṣi ounjẹ kan ṣoṣo n mu ibalopọ dun laarin ololufẹ.
Ijebu sàlàyé pé Fọ́nran ati fóto tó safihan ìyàwó tuntun àti òun, sùgbọ́n ọ̀rẹ́ ọkọ ìyáwó lásán ni òun jẹ́.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Òǹtàjà aṣọ ni mí tẹ́lẹ̀, ọ̀dá owó ló sọ mi di alábárù Osuolale ni ifẹ ilẹ̀ bàbá rẹ pupọ, ìdí si rèé tó fi pinnu láti má ṣe jókòó silu ọba, àmọ́ ó padà wá sile láti wá da ẹ̀ka isẹ agbẹjọro tiẹ̀ si orílẹ̀ èdè Nàìjíríà èyí tó pe orúkọ rẹ ní Akinjide & Co.
" Ni Ajegunlẹ, wọn dana sun ọfiisi ijọba ibilẹ Ajeromi Ifelodun ti wọn si tun ba awọn dukia jẹ nibẹ.
Wọ́n sọ fún wa pé tí o bá ti mu òògùn náà, ẹ̀rù kò ní bà ọ́ ma, ó ní agbára àti okun síi.
Koda, o ri lọ si Fasiti ijọba apapọ to wa ni Akọka nilu Eko.
Ilé ẹjọ́ yẹ àga mọ́ Ọba Ìkirè nìdí lẹ́yìn ọdún 27 lórí ìtẹ́ Ọlọ́pàá Ondo: Ètò ààbò kò mẹ́hẹ ní ọ̀nà Akure sí Ikere Bàbá Aláàfin ìlú Ọ̀yọ́, Elérúwà àti àwọn Ọba Ilẹ̀ Yorùbá míràn tí wọ́n rọ̀ lóyèỌba Falabi si lo gba ile ẹjọ giga lọ lati beere fun ìtumọ̀ idajọ ile ẹjọ to ga julọ naa, eyi to mu ko nira fun gomina ana nipinlẹ Osun, Rauf Aregbesola lati yọ nipo Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Gómìnà ìpínlẹ̀ Benue, Samuel Ortom ti parí ìjà láàrin akọ̀ròyìn Channels TV, Pius Angbo àti Ifeyinwa Angbo, ìyàwó rẹ̀ 8 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Oríṣun àwòrán, Twitter Arabinrin Ifeyinwa Angbo, to fi ẹsun kan ọkọ rẹ to jẹ akọroyin Channels Television, Pius Angbo, pe o lu oun ni ilukulu, ti sọ pe ki awọn eeyan ma gbadura fun idile oun.
Eyi tun jẹ iṣẹ to ran si awọn ọkọ obinrin to ba gba ẹsin yala ti Musulumi tabi ti Kristiẹni tabi ti ẹlẹsin abalaye lati maa pese iranlọwọ ati atilẹyin to yẹ fun wọn.
Gege bi agbenusoro papako ofurufu naa, Birendra Prasad Shrestha,” Ni bayii, awon ti o farapa si n gbatoju lowo.
Ajo INEC yoo se atundi idibo , nibi ti o ba ti yẹ ati awon ibi ti awuye-wuye ko
El Rufai sọ pe awọn ti n wọna lati pa eto alimajiri yi rẹ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Working religious women: Ẹ̀lẹ́hàá kìí ṣe ọ̀lẹ- Aminat Adegoke Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Working religious women: Ẹ̀lẹ́hàá kìí ṣe ọ̀lẹ- Aminat Adegoke 24 Agẹmo 2020 Mo kọkọ gba iyọnda lọwọ ọkọ mi ki n to lọ kọ iṣẹ bata ṣiṣe- Elẹhaa Amina Elehaa Amina Adegoke to n ṣe bata ni BBC lọ ba lalejo lati jẹ ki awọn ọdọ wa paapaa awọn obinrin to gba ẹsin ri awokọṣe rere lasiko yii.
''Bawo ni Gomina ṣe fẹ na aduru owo yẹn nigba to ṣe wi pe ọmọ igbimọ lasan ti aarẹ gbe dide lọ si Egypt ni?
O ni ẹgbẹ agbabọọlu Super Eagles gbiyanju ninu idije AFCON 2019, lẹyin ti wọn gba ami ẹyẹ baba(Bronze) tii ṣe ipo kẹta.
OLUWA ní ilẹ̀ Hadiraki yóo jìyà, bẹ́ẹ̀ náà sì ni ìlú Damasku.
Wọ́n fi igi olifi gbẹ́ ẹ̀dá abìyẹ́ meji tí wọn ń pè ní Kerubu, ọ̀kọ̀ọ̀kan wọn ga ní igbọnwọ mẹ́wàá, wọ́n kó wọn sinu Ibi-Mímọ́-Jùlọ náà.
Nígbà tí ó bá san owó ilé náà pada, ilé yóo di tirẹ̀.
Ẹni ìríra ni àwọn alágàbàgebè lójú OLUWA,ṣugbọn àwọn tí ọ̀nà wọn mọ́ ni ìdùnnú fún un.
Kí ló mú ọmọ Nàìjíríà mẹ́sàn án forí la ikú nínú ìkọlù Libya?
Ronaldo ní Tottenham yóò jẹ moyó ìyà lọ́wọ́ Liverpool N kò lẹ́bi pé ejò kó ₦36m owó àjọ JAMB mì -Philomina NURTW l‘Abuja yóò kàn sí Makinde láìpẹ́ lórí bó ṣe fòfin dè wá l‘Ọyọ - Ejiogbe Ni ipari, wọn fẹnuko pe ki gbogbo ori ade tuntun ti Amosun gbe ọpa aṣẹ le lọwọ ko to lọ pada si ipo ti wọn wa tẹlẹ.
Eliabu ọmọ Heloni ni yóo jẹ́ olórí láti inú ẹ̀yà Sebuluni.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Jumoke Odetola: Ọ́pọ̀ òṣèré koro ojú sí àṣehàn lásán lẹ́yìn ikú akẹẹgbẹ́ wọn, Williams Aanuoluwapo, Kumbalee 18 Ògún 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 19 Ògún 2020 Oríṣun àwòrán, https://www.
Tẹ́ ò bá gbàgbé àjọ agùnbánirọ̀ sọ nínú oṣù keje pé àwọn ti bẹ̀rẹ̀ ìwádìí tí adarí ẹka igbọ́rọ̀ sáfẹ́fẹ́ àjọ náà Adenike Adeyemi si sọ pé abájade ìwádìí náà ti wa ní ile iṣk ọ̀dọ́.
Ọgagun Ibrahim Babangida lo fi lede bẹẹ loju opo Twitter rẹ, lẹyin ti awọn ipinlẹ kaakiri orilẹede Naijiria n koju rogbodiyan lasiko ifẹhọnuhan tako ifiyajẹni awọn ọlọpaa lorilẹede Naijiria.
N óo sọ iná sí ìlú Gasa, yóo sì jó ibi ààbò rẹ̀ ní àjórun.
Ẹ wo ẹkunrẹrẹ fidio yii fun awọn ohun miran ti ọmọ Abacha sọ nipa baba rẹ.
Lọjọ Iṣẹgun ni Gomina ipinlẹ Kaduna, Mallam Nasir El-Rufai yan an gẹgẹ bi ọkan lara awọn ajọ to n ri si ọrọ karakata ni ipinlẹ Kaduna,(KADIPA).
N óo la ẹnu mi tòwe-tòwe;n óo fa ìjìnlẹ̀ ọ̀rọ̀ àtijọ́ yọ,
ilẹ̀ mì tìtì, ọ̀run pàápàá rọ òjò,níwájú Ọlọrun, Ọlọrun Sinai,àní, níwájú Ọlọrun Israẹli.
Àfikún ìdìbò ààrẹ yóò wáyé lọ́jọ́ kẹsàn án oṣù kẹ̀ta Kamaru Usman: Ọmọ Áfíríkà àkọ́kọ́ tó gba ìgbànú ẹ̀yẹ ẹ̀ṣẹ́ kíkàn Ogun: Amosun, ẹgbẹ́ òṣìṣẹ́ NLC fẹ́ forígbárí l'Ógùn Ìjọba pàṣán ni ìjọba Buhari yóò jẹ́ fún Nàìjíríà ní sáà kejì- Ṣoworẹ Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Ninu ìparun ati ìyàn,o óo máa rẹ́rìn-ín,o kò ní bẹ̀rù àwọn ẹranko ìgbẹ́.
Ó bá bu burẹdi náà, ó fi fún àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ kí wọn pín in fún àwọn eniyan.
Láti ilé ìwòsàn ni mo ti n bẹ̀bẹ̀ ki dókítà ṣe ǹkan ti o le ṣe titi a fi dé ilé igbóku sí, pẹlu ìgbàgbọ́ pé, òó tilẹ̀ gbé apá rẹ.
Ọmọ ipinlẹ Ogun ni, ere ọlọsọọsẹ ori mohunmaworan ti wọn n pe ni 'Ẹrin keeke' ni o gbe Ọpẹbẹ saye ni ọdun 1987 lori ikanni mọhunmaworan Channel 8.
Titi di asiko ti a ko iroyin yii jọ, ile ișẹ ọlọpaa ipinlẹ Oyo ko ti se alaye bi Sunday se bọ mọ wọn lọwọ ni ahamọ.
Bí Ẹ̀mí Mímọ́ Ti Ṣe Dé.
25 Bẹ́ẹ̀ni, òun ti sọ fún wọn: Ẹ tàn jẹ kí ẹ sì dúró ní ìkọ̀kọ̀ láti mú, kí ẹ lè pa run; kíyèsíi; èyí kìí ṣe ìbàjẹ́.
Ni kete ti wọn ti sọ niwaju ileẹjọ naa pe awọn ko jẹbi ẹsun ni adajọ ti gba oniduro awọn mẹta pẹlu Sẹnetọ Adeleke.
O ni  a dupẹ lọwọ gbogbo awọn to ti ṣe akitiyan lori ọrọ yii."
Oríṣun àwòrán, Faceboo/Frscedo Edo SEctor Command Eeyan mẹrin lo dero ọrun ninu ijamba ọkọ to ṣẹlẹ lopopona Ọrẹ si ilu Benin ninu eyi ti awọn mẹrin miiran ti farapa.
O tẹsiwaju wi pe awọn ọta itẹsiwaju ti n lepa lati mu ki oun padanu oju rere gomina ipinlẹ Ọyọ, Onimọẹrọ Ṣeyi Makinde.
2 251 Orilẹede Grenada 1 0.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ìjọ Àgùdà: Kò dára ká máa ké gbàmí-gbàmí kiri lójoojúmọ́ Gẹgẹ bii ajọ to n gbogun ti ajakalẹ arun lorilẹede Naijiria, CDC ṣe sọ, ko din ni ẹgbẹrun mẹta iṣẹlẹ arun onigbameji to ti waye, ti o si tun ti gba ẹmi awọn eeyan kaakiri orilẹede Naijiria, paapaa lawọn ipinlẹ kan lẹkun ila oorun ariwa bii Borno, Adamawa ati Yobe.
ó sì pàṣẹ pé kí wọ́n kọ́ àwọn eniyan Juda ní orin náà.
Ta ló lẹ̀bi ọ̀rọ̀ lórí awuyewuye ayédèrú ìwé ẹ̀rí NYSC Adeosun?
O fi kun un pe eto ilera ofe fawon arugbo, ọmọ wẹwẹ, ati aboyun Àkọlé àwòrán, #BBCOGUNDEBATE: O ṣe pataki láti yan àwọn akanda ẹda si ipò kọmisọna.
Ó gbọdọ̀ káwọ́ ilé rẹ̀ dáradára, kí àwọn ọmọ rẹ̀ máa gbọ́ràn sí i lẹ́nu tọ̀wọ̀tọ̀wọ̀.
Àwọn ènìyàn ti o fẹ́ràn àlàáfíà, ìfẹ́ àti ìrẹ́pọ̀ láàárin onílé àti àlejò sì ni wọ́n pẹ̀lú.
Bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé mo ti kọ́ wọn ni àkọ́túnkọ́, wọn kò gba ẹ̀kọ́.
idibo fun ajo INEC funipinle Oyo kede pe:APC- 357,982PDP- 515,621Iye ibo to yege: 916,860Iye ibo ti won di: 937,545Ademola Adepoju.
Ìgbáyé-gbádùn ọmọ Nàìjíríà ní South Afrika ló jẹwá lógún- Buhari O ni o yẹ ki ijọba kọkọ tun awọn ọna to ti baje ṣe ki wọn to bere owo oju opopona.
Wo bí ètò ìsìnkú Isa Funtua ṣe wáyé ní ìlú Abuja Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Ti a o ba gbagbe pe, aare ni o fe side awon opopona oko ati awon ise akanse omi ni igberiko ati olu-ilu naa, bakaa naa ni aare yoo tun maa se ifilolo ile-ibuje eran to wa ni Birni – Kudu ati awon ile-itoju alaisan bi i ogorin ati igbimo ti yoo maa ri si itoju awon ara ilu.
Sugbọn ẹyin lohun, to ba ti jabọ, ko tun se ko mọ, awọn ọmọ orilẹede yii ti n sọ ero ọkan wọn lori ọrọ ti ohun ti aarẹ ẹgbẹ akẹkọ ilẹ wa naa sọ.
Nigba ti alaga naa yoo wa siwaju ilke ẹjọ, inu aga awọn abarapa ti ko le rin lo ti wa sile ẹjọ.
Nítorí pé ó ti ṣe ohun tí ó dára, tí ó sì tọ́, yóo yè.
Abiodun wa kẹdun iku ologbe naa, to si sọ pe ijọba rẹ ko ni fọwọ yẹpẹrẹ mu eto abo ẹmi ati dukia awọn eeyan ipinlẹ Ogun.
Ẹ jẹ ki a jijọ ṣagbeyẹwo diẹ́ lara awọn ibeere to jẹyọ.
Amọ lati igba tokuro ni Arsenal lọ si Man United ni nnkan to ti rọgbọ mọ.
Wọn ni eleyi jẹ ọna pajawiri lati koju aisan Coronavirus to n ja kaakiri ilẹ naa.
Sisa, ọmọ Ṣifi, ọmọ Aloni, ọmọ Jedaaya, ọmọ Ṣimiri, ọmọ Ṣemaaya.
Isaaki, baba rẹ̀ bi í pé, “Ìwọ ta ni?
O ni titi di igba ti ayipada yoo fi de ba ofin naa, ẹṣẹ nla ni fun awọn ajeji lati maa ta ọja worobo lorilẹede Ghana.
Mikaaya bá dáhùn pé, “Bí o bá pada dé ní alaafia, a jẹ́ pé kì í ṣe OLUWA ló gba ẹnu mi sọ̀rọ̀.
Electoral Commission, INEC) ati   awon ile-ise
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Oyo Fire: Dukia ṣófo, ọmọ ọdún mẹ́rìnlá faragbọta níbí iná tó jó ọjà Akesan Ṣaaju ki ọrọ yii to ṣẹlẹ, tọkọ taya yii ti ni aawọ lori tani yoo maa ṣakoso ijọ gẹgẹ bi iwe iroyin Daily Nation ṣe sọ ọ.
 wọ ́ n sìnkú rẹ ̀ sí ẹ ̀ gbẹ ̀ ọkọ rẹ ̀ ní ikenne ní ojọ ́ karún oṣù kẹsán Ọdún 2015 .
Kìlómítà márùn là ń rìn ká tó rí omi mu’ Ṣe ko si ewu láti ni ìbálòpọ̀ lásìkò Coronavirus yìí?
Ó bá ki obinrin ọkunrin náà mọ́lẹ̀, ó tì í sí wọn lóde.
Àwọn ọmọ Jẹriko jẹ́ ojilelọọdunrun ó lé marun-un (345).
Koda, o ni oṣiṣẹ to to mejila to n ba oun ṣiṣẹ iru bayii.
" Ṣaaju ni iwe iroyin naa ti jabọ pe Gomina Obaseki ti ṣe ìpàdé kan pẹlu alaga igbimọ awọn Gomina labẹ ẹgbẹ naa Aminu Tambuwal ati alaga ẹgbẹ Uche Secondus l'#Ojọru.
Ekinni dàbí kinniun, ó sì ní ìyẹ́ bíi ti idì.
To si jẹ pe nigba ti wọn ba gba wọn siṣẹ tan, ni wọn to n fi iwa wọn han.
Oríṣun àwòrán, Twitter  Wúńdíá ni aburo mi lẹni ọdun mejilelogun, ko ni ibalopọ rí."
Ṣugbọn o kò gbọdọ̀ fọwọ́ kan igi olifi ati ọtí waini.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Amaju Pinnick di ààrẹ àjọ NFF tuntun NFF sadehun pẹlu Dennerby fun Falcons Super Eagles: Asọ idije ife ẹyẹ agbaye jade Victor Moses, Oshoala gba ami ẹyẹ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ìwádìí Anas: $1000 ni rìbá tí akọ́ni-mọ̀ọ́gbá Super Eagles gba Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
O ni South Africa ko ri iṣẹ pupọ pese mọ fawọn eniyan ni eyi to hande ninu eto ijajangbara fawọn agbejọro to n mojuto pẹlu.
Abenugan ni ipade naa tun da
" Bo tilẹ jẹ pe Odumakin sọ pe Afẹnifẹre ko fẹ ki Naijiria tu ka, ṣugbọn o ni erongba ẹgbẹ ọhun ni ki atunto de ba eto ijọba Naijiria.
Ẹ máa lépa alaafia lọ́dọ̀ gbogbo eniyan pẹlu ìwà mímọ́.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Maina dákú fún ọ̀pọ̀ ìṣẹ́jú, iléejọ́ sáré so ìjókòó rọ̀ Wo ìròyìn tó pọ̀ jùlọ táwọn èèyàn ń wá ní Google lọ́dún 2020 Obasanjo àti Gani Adams tẹ́ mi pẹ̀lú bí wọn ṣe tahùn síra wọn - Adebanjo Buhari le sọ ipò ààrẹ́ nù tí kò bá yọjú sáwọn aṣòfin - Amòfin Ẹgbẹ́ òṣèlú alátakò takú láti gba èsì ìbò ààrẹ ní Ghana Ọ̀pọ̀ nkan tó n ṣẹlẹ̀ kò jẹ́ kí n gbàgbọ́ pé Naijiria wà ní abẹ́ ìdarí ẹnikẹ́ni - Wole Soyinka Ọmọ ẹgbẹ́ òkùnkùn ṣoro ní Ijebu Ode, ọ̀pọ̀ ẹ̀mí sọnù Iroyin naa ni onikẹkẹ Maruwa naa lo fi aake kọri lati fun ọlọpa kan to wa loju popo ni ọgọrun naira, eyi to bi ọlọpaa naa ninu, to si da ibọn bo o.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Jesu Oyingbo rèé, pásítọ̀ tó láṣẹ ìbálòpọ̀ lóri ọmọ ìjọ obìnrin Alabi Pasuma Ọ̀gáńlá pé ẹni ọdún 51 Ọ̀pọ̀ ló ṣì n ṣelédè lẹ́yìn Barrywonder!
Awọn oju opo ikansira ẹni lori itakun agbaye ti kun pitimu nipa ero araalu lori abẹwo aarẹ Muhammadu Buhari si ilu Eko.
Mo fi asiko yii dupẹ lọwọ gbogbo ọmọ Naijiria fun adura ati ọrọ ikini wọn nigba ti mo lọ fun itọju."
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ẹmi mejila ṣofo ninu ijamba ọkọ l'ondo Ijamba m‘ẹmi akẹkọ mọkanlelogun lọ ni Kano 'Ori kó awakọ̀ àti ọmọ mẹta yọ nínú ìjàmbá ọkọ' À ń wo àtubọ̀tán APC níbáyìí tó gba àkóso ilé aṣòfin - PDP Saaju ni awọn ti ọrọ naa soju wọn kan ti ni o to eeyan mẹẹdogun ti o ku ninu iṣẹlẹ yi.
Ó ju ẹ̀kejì èyí bá mi ni iwájú n kò sọ̀rọ̀.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Coronavirus: Fífi nkan bo ìmú rẹ kò tòó dènà kíkó coronavirus Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Coronavirus: Fífi nkan bo ìmú rẹ kò tòó dènà kíkó coronavirus 25 Ẹrẹ̀nà 2020 Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí 2 sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 2:23 Fídíò, Water Generator: Ó leè ṣiṣẹ fún wákàtí mẹfà, kó tó sinmi, Duration 2,2310 Òkùdu 2020 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
Owo ipolongo lasiko idibo ko pọ rara bii ti isejọba aarẹ ti o nilo ọpọlọpọ owo lati se ipolongo, eleyii ti o n mu ọpọlọpọ oloselu jale lati di ọjẹlu.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Man City gòkè padà nínú ìdíje Premier League Salah gba àmì ẹ̀yẹ̀ agbábọ́ọ̀lù Afirika BBC lẹ́ẹ̀kejì Àpótí ìkẹ́rùsí jálu ọkọ̀ méjì lórí l'Eko Man United ko tii na Liverpool mọle fun ọdun marun un sẹyin bayii.
Àjọ INEC ní, mílíọ̀nù méje ni káàdì ti awọ̀n eeyan ko tii wa gba, atipe, ìpínlẹ̀ Èkó làwọn tí kò tíì gba káàdì náà pọ̀ sí jùlọ.
Bẹẹ si ni ni awọn apa ibomiiran, yinyin ti wọn yoo foju ri yoo le gan.
UK Covid Vaccine: Abẹ́rẹ́ àjẹsára Covid-19 yóò dé sí Nàìjíríà nínú oṣù kíní ọdún 2021
"Inira gba a ni asiko naa jẹ fun mi, paapa bukaata awọn ọmọ.
Agbẹnusọ fun ileeṣẹ ọlọpaa FCT Abuja, Anjuguri Manzah, sọ pe iwadii n lọ lọwọ lori iṣẹlẹ naa.
Adúmáadán gidi ni nítorí pé dígí ni wọ́n fi ṣe iwájú àti ẹ̀hìn rẹ̀, wọ́n wá fi irin alárà yí i po.
Queen Salawa to sọrọ naa ninu ifọrọwerọ rẹ pẹlu BBC Yoruba lọjọ Ẹti ṣalaye pe, to ba tiẹ jẹ pe oloogbe Alhaji Sikiru Ayinde Barrister gan an lo da Fuji silẹ, o yẹ kawọn eeyan fi Barrister silẹ lati sun nibi to wa.
Oríṣun àwòrán, AFP Àkọlé àwòrán, Abdullahi gba fun Naijiria ninu idije awọn ọdọ ti ọjọ ori wọn ko kọja ogun ọdun nilẹ Turkey lọdun 2013 Abdullahi sọ fun BBC Sport pe Mo dupẹ lọwọ Anorthosis Famagusta fun irinajo mi pelu wọn, inu mi si dun lati je ọmọ ẹgbe agbabọọlu Bursaspor "" Ni ọdun to pari adehun rẹ pẹlu ẹgbe naa ni ilu Cyprus, iroyin gba'le kan pẹ o se e se ki o darapọ mọ Birmingham City sugbọn o yi ọkan pada lati gba fun ẹgbe to lorukọ ki o baa lee ribi wa lara awọn ti yoo kopa ninu idije bọọlu agbaye."
Awọn mejeeji ọhun, ti wọn pe orukọ wọn ni Foluṣọ Ajayi, Vosco pẹlu ọdọmọdekunrin kan ti inagijẹ rẹ n jẹ Alhaji ni wọn gba fun iṣẹ agbaṣe kan ni ileto ọhun.
Minisita feto ilera pẹlu ti fi idi rẹ mulẹ nibi ifọrọwerọ to ṣe pẹlu awọn oniroyin ni ọsan oni.
Ọ̀nà tí a fi mọ ìfẹ́ nìyí, pé ẹnìkan fi ẹ̀mí rẹ̀ lélẹ̀ fún wa.
Ní ọjọ́ keje kí alufaa yẹ̀ ẹ́ wò, tí àrùn náà bá ti bẹ̀rẹ̀ sí tàn káàkiri ara rẹ̀, kí alufaa pe ẹni náà ní aláìmọ́; àrùn ẹ̀tẹ̀ ni.
Ehuriah parọwa pé ki wọn sa fun ọrọ ikorira ki wọn si fọwọsowọpọ pẹlu aarẹ Buhari ninu iṣejọba tuntunt yii.
Yóo jọba, yóo hùwà ọlọ́gbọ́n, yóo sì ṣe ẹ̀tọ́ ati òdodo ní ilẹ̀ náà.
Nítorí pé iná ni OLUWA yóo fi ṣe ìdájọ́,idà ni yóo fi ṣe ìdájọ́ fún gbogbo eniyan;àwọn tí OLUWA yóo fi idà pa yóo sì pọ̀.
Lalekan Are dagbere faye lẹni ọdun marunlelọgọrin.
Ní ọdún kẹẹdogun tí Ọba Tiberiu ti wà lórí oyè, nígbà tí Pọntiu Pilatu jẹ́ gomina Judia, tí Hẹrọdu jẹ́ baálẹ̀ Galili, tí Filipi arakunrin rẹ̀ jẹ́ baálẹ̀ Ituria ati ti agbègbè Tirakoniti, Lusaniu jẹ́ baálẹ̀ Abilene; 
Ṣugbọn ó kọ̀, kò mu ún; kàkà bẹ́ẹ̀, ó tú u sílẹ̀ gẹ́gẹ́ bí ẹbọ fún OLUWA.
Lọjọ idibo waye, ọpọ igba ni iroyin ti jade nipa bi awọn janduku oloṣelu ṣe yabo ibudo, ti wọn yoo si ji apoti ibo salọ.
Ipele àwọn wọnyìí ninu ìgbìmọ náà ní àwọn amúludùn 1.
Wo àwọn Ṣọ́ọ̀ṣì Nàìjíríà àti l'Áfíríkà tó ń wólẹ̀ àdúrà kí Trump lè wọlé ìbò ààrẹ America Wo àfiwé owó oṣù Ọlọ́pàá Nàìjíríà pẹ̀lú akẹgbẹ́ wọn lókè òkun Wo awọn iroyin manigbagbe to waye ni ọsẹ yii Orúkọ àwọn tó yege láti darapọ̀ mọ́ ikọ̀ Amotekun ní ìpínlẹ̀ Oyo ti jáde Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ogbomsho shooting, End Sars, End SWAT: Isiaka fi ọmọbìnrin kan àti ìyàwó tó lóyún sínú síl Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí 2:08 Fídíò, John Amanam: Ìfẹ́ tí mo ní sí àbúrò mi ló sọ mi dí ẹni tó ń ṣe 'Prosthetic' báyìí, Duration 2,081 Bélú 2020 Fídíò, Soyinka Cancer: Àṣe ara mi ni iso ti n run gbogbo bí mo ṣe n ṣèrànwọ́ lórí jẹjẹrẹ27 Bélú 2019 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Àwọn ọmọ wọn yóo rí bí wọn ti rí ní àtijọ́,àwọn ìjọ wọn yóo fi ìdí múlẹ̀ níwájú mi.
Oríṣun àwòrán, @Albert Àkọlé àwòrán, Ọpọ ile lo dawo ti opọlọpọ dukia si bajẹ ni Ghana O le lẹgbẹrun kan ile to ti da wo silẹ ti ọpọ eeyan ko si nile lori mọ ni ẹkun yii Ẹru n ba awọn alaṣẹ Ghana pe ki oku ma lọ pọ sii ju bayii lọ, ti awọn ti wọn ko nile lori naa si n pọ sii.
Wọ́n bá sọ fún un pé, “Alàgbà, máa fún wa ní oúnjẹ yìí nígbà gbogbo.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Aisha Abimbọla gba ẹ̀yẹ ìkẹyìn ní Nàìjíríà Ologun Nigeria gbakoso ibuba Boko Haram ‘Itusilẹ yoo wa fawọn onde Boko Haram’ Boko Haram kọlu abule Kofa ni Maiduguri Ìròyìn tó tẹ BBC Yorùbá lọ́wọ́ sọ pé ẹ̀rí Amnesty International dá lórí ìfọ̀rọ̀wánilẹ́nùwò ti wọn ṣe fún àwọn àádọ́talénígba eniyan ní budo àwọn tó sá fun ìkolù Boko Haram tí wọn ṣe láàárin ọdún 2016 sí 2018.
Saaju ifigagbaga olorejore ti iko agbaboolu Spain yoo gba pelu Germany lojo Eti(Friday), atamatase iko ohun, Adrie Iniesta ti kede pe oun ko ni kopa fun iko naa mo leyin idije boolu agbaye todun yii.
Ti o ba ṣetan lati kopa ninu eto igbanisiṣe naa, kan si oju opo yii ki o si fi orukọ rẹ silẹ bi o ti yẹ: Ẹ tẹ ni ori ẹrọ ibanisọrọ yin: www.
Ti eroja asaraloore probiotics ti wọn n fi si inu awọn ounjẹ ipapanu bii yogọọti gẹgẹbi eroja asaraloore ba wa ni ara eniyan, yoo seese fun ounjẹ lati da ni inu eniyan fun sise ara loore.
Ṣaaju idibo orilẹede Naijiria ni ọjọ Kẹrindinlogun loṣu Keji, ikọ ayẹwo oluwadi fun ileesẹ BBC, (BBC reality Check) gbe awọn ohun tawọn eeyan n sọ lori bi eto abo ṣe ri lorilẹede Naijiria.
Nípa ṣíṣe bẹ́ẹ̀, ẹ ti di ọmọ Baba yín tí ń bẹ ní ọ̀run.
72 Ìrìbọmi ni a nílati ṣe àkóso rẹ̀ ní ọ̀nà tí a là sílẹ̀ yìí fún gbogbo àwọn wọ̃nnì tí wọ́n ronúpìwàdà—
1 Olúwa sì wí fún mi pé: Jòhánù, àyànfẹ́ mi, kín ni ìwọ nfẹ́?
Josaya run gbogbo àwọn ère oriṣa tí wọ́n wà ní gbogbo ilẹ̀ Israẹli, ó sì mú kí àwọn ọmọ Israẹli sin OLUWA Ọlọrun wọn.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Nigerian Navy Ondo: Ikọ̀ ọmọogun orí omi fi páńpẹ́ mú olè mẹ̀rìnlélógún tó ń jí epo rọ̀bì wákàtí 4 sẹ́yìn Oríṣun àwòrán, Google Ileeṣẹ ọmọogun oju omi ni okeere tan awọn ti fi panpẹ ọba mu awọn ole mẹrindinlogun nibi ti wọn ti n ji epo rọọbi ji nipinlẹ Ondo.
Nígbà tí ó yá, Elikana bá Hana lòpọ̀, OLUWA sì gbọ́ adura rẹ̀.
Iyawo, Basirat Adeyoyin lo gbe ọkọ rẹ, Adeyoyin Niyi lọ sile ẹjọ, to si fi ẹsun kan an pe o fẹ fi oun ṣe oogun owo.
Àwọn ìgbà tí ìmọ̀ràn Pásítọ̀ Adeboye lóri igbéyàwó ti fa àríyànjiyàn Àwọn ọba tó wà lábẹ́ mi ń talẹ̀ nítàkutà- Oluwo Oyè Ibadan kò sí fún títà - Otun Olubadan, Lekan Balogun Ibrahim Magu sọ wi pe iwa jẹgudujẹra lo fa Coronavirus lasiko ti awọn ọmọogun ajọ EFCC n ṣe ayẹyẹ ikẹkọjade ni ileewe ọmọogun Naijiria to wa ni ipinlẹ Kaduna.
Àṣepọ̀ ni ó ṣe ọ̀pá fìtílà ati ẹ̀ka ara rẹ̀ ati ìrudi abẹ́ wọn; ojúlówó wúrà tí wọ́n fi òòlù lù ni ó fi ṣe wọ́n.
Ninu atẹjade kan ti ẹgbẹ oṣelu PDP fi sita, o ni asiko to fun aarẹ lati jẹwọ smọluwabi ti o n pe ara rẹ nipa fifaaye gba iwadi ti ko lọwọ ijọba ninu lori ẹsun iwa ibajẹ laarin awọn ọmọ igbimọ rẹ.
N óo fi ìwọ̀ kọ́ ọ lẹ́nu, n óo sì jẹ́ kí àwọn ẹja inú odò Naili so mọ́ ìpẹ́ rẹ; n óo sì fà ọ́ jáde kúrò ninu odò Naili rẹ pẹlu gbogbo àwọn ẹja inú odò rẹ tí wọn óo so mọ́ ọ lára.
Olólùfẹ́ méjì jábọ́ láti àjà kẹsàn án lásìkò tí wọ́n n ṣe kerewà Wò ó ọ̀nà láti mú ara rẹ dé ibi tó ga jùlọ nínú ìbálòpọ̀ pẹ̀lú ìlànà Tantra Akomolede: Bolaji Faleke ni Olùkọ́ tó ń kọ́ wa ní àṣà oge ṣiṣe lórí BBC Yorùbá Ìwọ tó ń ṣí ara sílẹ̀ lọ ṣọ́ọ̀ṣì, ṣé apàyàn kọ́ ni ẹ́ báyìí?
Social Media Bill: Sowore fàáké kọ́rí, ó ní àbádòfin láti ṣàmójútó ayélujára kò lè fẹsẹ̀ múlẹ̀ láéláé
Ní ọjọ́ kan tí Eliṣa pada lọ sí Ṣunemu, ó wọ inú yàrá náà lọ láti sinmi.
NBC fọwọ́ sí ìdásílẹ̀ ilé iṣẹ́ Fulani Radio
ọrọ ti awon kan n sọ lasiko ti oun n dupo abenugan nile igbimo asoju pe, ibo ti
Akọwe iroyin fun Saraki, Yusuph Olaniyonu, ninu atẹjade kan to fisita salaye pe Bukola Saraki ko mọ Hushpuppi ri, bẹẹ ni ko ni ajọsepọ kankan pẹlu rẹ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Chelsea kéde Frank Lampard gẹ́gẹ́ bíi olùkọ́ni tuntun 4 Agẹmo 2019 Oríṣun àwòrán, chelseafc.
Koda, wọn si gba awọn eniyan ti o ba n ṣe aarẹ lati joko sile wọn, nitori ẹni to ba lugbadi arun Coronavirus yoo se akoba fun awọn ti wọn ba jọ rinrinajo, o le jẹ ọmọde tabi agba.
"Wo àwọn ohun tó yẹ kí o mọ̀ nípa àrùn Coronavirus àti ìbálòpọ̀ akọ àt'abo Kunle Afolayan, òṣìṣẹ́ báńkì tẹ́lẹ̀ kó tó di gbajúgbajà òṣèré Njẹ o mọ oju yi ni ""Yollywood""?"
NLC, TUC, ULC yóò ṣe ìwọ́de l'ónìí NLC, TUC: Àwa ò gba owó lọ́wọ́ Fayose ooo Ojú ń kán wa, a fẹ́ gba àfikún owó osù tuntun- NLC Lẹyin opọlọpọ ijiroro nibi ipade naa ni minista fun ọrọ awọn oṣiṣẹ ni Naijiria, Chris Ngige sọrọ ni aarọ yii pe awọn ti sun akoko ipade mii si aago meje alẹ oni, ọjọbọ.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Nise ni Breazeale sun gbalaja silẹ ti ko si le e dide si pipe ago Amọ, Wilder yoo koju ipẹjọ Ajọ to n risi ere idaraya ifẹsẹkubiojo nitori o sọ wi pe gbagede ifẹsẹkubiojo nikan ni eniyan ti le paniyan, ti a si lo ni idare.
Lẹ́yìn náà, OLUWA á gbé àwọn adájọ́ kan dìde, àwọn adájọ́ náà á sì gbà wọ́n lọ́wọ́ àwọn jàǹdùkú ọlọ́ṣà tí ń kó wọn ní nǹkan.
" Oríṣun àwòrán, Oba Adeyeye Ogunwusi Ọba Ogunwusi fikun pe, awọn isẹlẹ kayeefi to n waye lẹnu lọọlọ yii nilẹ Yoruba jẹ ajeji si wa, a si gbọdọ sisẹ tọ ọna lati lati mu ki alaafia jọba lawujọ wa, awọn eeyan ko gbọdọ maa gbe ninu ibẹru bojo ati ifoya sugbọn wọn gbọdọ ni ominira lati ls si ibi to ba wu wọn.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Awọn Obinrin Dahomey: Awọn obinrin ilẹ Afirika ti wọn yii itan pada re e Igbeyawo ati ọsan aye Oyinkan Abayomi: Yoruba maa n ni ilẹ obìnrin kii pẹ su, igba ara si la n bura, Oyinkan ṣe igbeyawo pẹlu agbẹjọro kan, Morohunfolu Abayomi lọjọ Kẹwaa, osu Karun un, ọdun 1923.
Nígbà tí ọba Jehoiakimu ati àwọn ọmọ ogun rẹ̀, ati àwọn ìjòyè gbọ́ ọ̀rọ̀ rẹ̀, ọba wá ọ̀nà láti pa á.
Afo-Addo ti kọkọ dije fun ipo aarẹ labẹ asia ẹgbẹ oṣelu NPP lọdun 2008 ati 2012 ṣugbọn o fidi rẹmi lẹẹ mejeeji.
Ẹsẹ mi ti bọ́ sí pàkúté, ń kò lè fà á yọ, n kò sí le ké nítorí ojú ń ti mi.
Lasiko abẹwo naa, Aarẹ Buhari ṣalaye pe aisi amojuto to peye fun awọn ọlọpaa lo fa aijafafa wọn lẹnu iṣẹ wọn eyi ti o ni o mu ki awọn ologun maa ti oju bọ iṣẹ amojuto ofin ati abo laarin ilu jakejado orilẹede Naijiria.
N óo gba ẹ̀jẹ̀ ati ohun ìríra kúrò ní ẹnu rẹ̀, àwọn tí yóo kù ninu wọn yóo di ti Ọlọrun wa; wọn yóo dàbí ìdílé kan ninu ẹ̀yà Juda, ìlú Ekironi yóo sì dàbí ìlú Jebusi.
Nigba to n fi idi isẹlẹ naa mulẹ, ẹgbẹ oselu PDP ni, awọn ẹlẹri to le ni irinwo lo ti wa nilẹ bayii lati tako Buhari ati ẹgbẹ oselu APC lori esi ibo aarẹ to kọja.
’ rèé Ìgbín ní èmi àti ìyá mi máa ń he kiri, ká tó lee jẹun - Lizzy Anjọrin Àwọn ọmọ Iyabọ Ojo rí Bàbá lẹ́yìn ọdún mẹ́fà Ọdun 2018 ni iroyin gba igboro pe, gomina ipinlẹ kan nilẹ Yoruba to jẹ ololufẹ ikọkọ Mercy, lo ra ile ti oṣere tiata naa fi aworan rẹ sita, fun.
Ẹ̀kúnrẹ́rẹ́ ọ̀rọ̀ rẹ̀ lójú òpó twitter rèé: Amọ titi di akoko yii, oloye Bola Ahmed Tinubu, ti ọrọ Tunde Bakare da le lori ati awọn ohun ti Fani-Kayode fi fesi pada, ko sọ ohunkohun lori awọn isẹlẹ naa.
Lẹ́yìn ọdún méjìlá, mo gun òkè fún ọjọ́ márùn-ún kí ń tó rí ìyá mi"" Ṣé ìwọ leè wa kẹ̀kẹ́ lórí ìgò?"
lati fi gba wọn wọleLẹyin eyi ni Agbẹnusọ Ile naa
Gómìnà Zulum ní àwọn abanijẹ́ ló ń ṣe kèéta ìjọba àpapọ̀ Oríṣun àwòrán, Getty Images Gomina ipinlẹ Borno, Ọjọgbọn Babagana Zulum ni gbigbogun ti iwa awọn adunkukulajamọni bii Boko Haram ni Naijiria ko lee tan ayafi ti ijọba ba gbogun ti iwa biba ti ọmọlakeji jẹ.
OLUWA yóo jẹ Joabu níyà fún àwọn eniyan tí ó pa láìjẹ́ pé Dafidi baba mí mọ ohunkohun nípa rẹ̀.
Ẹ̀rù bà mí, mo sì sọ pé,“A lé mi jìnnà kúrò ní iwájú rẹ.
Wọn dibo ijọba ibilẹ ni Kano Inec yoo bẹrẹ iwadi lori oludibo Kano Kano gbalejo igbeyawo ọmọ gomina Ọyọ Sùgbọn nigbà tó ń ba àwọn akọ̀rọ̀yìn sọ̀rọ̀ ni l'Abuja, Ganduje sọ wipe fídíò náà kíì ṣe ògidì.
Nigba tó ń sọ̀rọ̀ lórí ajọṣepọ rẹ pẹlu olóògbé Sikiru Ayinde Barrister àti Oloye Bola Tinubu lórí eto ohun.
 ní ọdún 2010 ó ṣe òkùnfà ikú ènìyàn tó tó 1200 , èyítí ó wálẹ ̀ láti 2000 ní ọdún 1990 .
Pẹlu iye awọn eeyan tuntun yii, o ti pe 87,510 eeyan to ti ni arun naa ni orilẹede Naijiria bayii.
Àjọ tó n mójútó ètò ìlera ní àgbáyé, WHO, ní wọ́n fi ilé ìwòsàn ti wọn ti n gba itọju sílẹ̀ lẹ́yìn tí àwọn mọ̀lẹ́bí wọn ní àwọn gbọdọ̀ gbé wọn lọ sí ṣọ́ọ̀ṣì.
Dokita yọ góòlù àti owó ṣílè nínú obìnrin kan Etí ìjọba Buhari di sí ìmọ̀ràn àwọn ará ìlú -Jiti Ogunye Ẹ ṣọ́ra fún ìròyìn ẹlẹ́jẹ̀ lórí ètò ààbò - Ọlọ́pàá Pẹlu esi yii, ipo kẹrin ni Arsenal wa lori tabili liigi ilẹ Gẹẹsi bayii pẹlu ami mọkanla.
a le rí ẹ ̀ sìn ìgbàgbọ ́ gẹ ́ gẹ ́ bí àpéjọpọ ̀ àwọn onìgbàgbọ ́ .
Awọn ara ilu Ọwọ ti ge gbogbo igi nla ti won n pe ni igi ọja to wa ni aafin lati ke si awon ara ilu wi pe oba wọn ti waja ni ilu Ọwọ.
"Onímọ̀ nípa ẹṣin Islam náà wá tún woye pe, bóyá àwọn agbebọn ọ̀hún kàn ń wá ohun tí wọ́n yóò jẹ, ní wọn ṣe wá gbé ìbejì òun, ó ní, ibi tí eto ààbò orílẹ̀ èdè yìí dé dúró nìyẹn.
Oríṣun àwòrán, Twitter/Funso Dove O ni ṣọọṣi ti oun n lọ ni Sabo, Yaba naa n gbadura fun oun.
BBC Yoruba gbiyanju lati ba agbẹnuso fun ile isẹ ọmọ ogun ori ilẹ ọgagun John Chukwu sọrọ sugbọn o ni oun ko ti le fesi sọrọ naa.
Kí ẹnikẹ́ni má ṣe fi àbùkù kàn án.
Ta ló lè fi kòtò ọwọ́ wọn omi òkun?
Sunday Igboho fikun pe, lootọ ni awọn agbaagba kan nilẹ Yoruba n ri jẹ ninu eto aabo to mẹhẹ yii, amọ agba to ba setan lati fi atunbọtan rere silẹ de ọmọ, ko gbọdọ dalẹ iran Yoruba.
Ijọba Buhari ti ya owo pupọ lati ọdọ orile-ede China lati le ṣe akanṣe iṣẹlẹ lori ileeṣẹ ọkọ oju irin Naijiria.
ati Judasi Iskariotu ẹni tí ó fi Jesu fún àwọn ọ̀tá rẹ̀.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Iṣẹ nla niṣẹ abiyamọ kaakiri agbaye Wo àwọn òṣèré Yorùbá tí Aisha Buhari yàn fún ìpolongo ìbò Dino: Olúwa, ṣe sí àwọn ọ̀tá mi bí o ṣe ṣe sí Egypti 'Buhari, ṣé ìkíni ọdún níyìí tàbí ìpolongo ìdìbò?
ipinnu ti ijoba apapo ati igbimo ipinle se lori ẹgbẹrun mẹ́tàdínlọ́gbọ̀n naira je iyanilenu fun
Bakan naa ni idibo sile aṣofin yoo waye, fun gbogbo ijoko ile 435 nile igbimọ asoju-sofin, marundinlogoji ninu ọgọrun un yoo si waye nile aṣofin agba.
Eleyi bọ si àsikò ti ọkọ rẹ Philips pé ọgọrundinmarun ọdún.
O sì tún sọ fún Ọba pé òun ni òun yẹ fún ọlá tí Ọba dá Ìgbín torí pé òun ni òun pa abuké Ọba.
Ṣugbọn Ẹ̀mí fúnrarẹ̀ a máa bẹ̀bẹ̀ fún wa lọ́dọ̀ Ọlọrun lọ́nà tí a kò lè fi ẹnu sọ.
”Ewe, iroyin fi mule pe, eyi kii se igba akoko ti awon ondije asoju orile-ede Cameroon yoo  sonu ninu irufe idije bayii, lodun 2012, ondije marun-un ninu ifigagbaga ija (five male boxers), agbaboolu obinrin kan (female footballer) ati oluwe okunrin kan (male swimmer) ni won di awati nilu London.
Pasitọ ni kii se iru ọmọ mi nikan lo wa ni agbaye, iru awọn eeyan to ni nkan ọkunrin ati obinrin sun janti rẹrẹ, kii si se iwa ẹsẹ mi lo mu ki n bi ọmọ naa.
Nigba aye rẹ oniruuru awuyewuye lo wọ tọọ lẹyin: Ẹsun pe Abba Kyari gba abẹtẹlẹ lọwọ ileeṣẹ ibanisọrọ MTN Lọdun 2016 lẹyin ti ajọ to n ṣakoso ẹka ibanisọrs lorilẹede Naijiria, NCC paṣẹ ki ileeṣẹ ibanisọrọ MTN o san owo itanran fun bi o ṣe kuna lati ys gbogbo nọmba ibanisọrọ awọn eeyan ti ko ṣeto iforukọsilẹ awọn nọmba ibanisọrọ wọn gẹgẹ bi ofin ṣe laa kalẹ.
O fi kun un pe igbaradi ti wa fun ṣiṣe ayẹyẹ ọjọ ibi ọdun mokanlelaadọta oun ni orilẹ-ede Canada."
12 Àti oníwàásù àkọ́kọ́ ti ìjọ yìí fún ìjọ, àti níwájú ayé, bẹ́ẹ̀ni, ní iwájú àwọn Kèfèrí; bẹ́ẹ̀ni, àti bayìí ni Olúwa Ọlọ́run wí, wòó, wòó!
Ninu abala keji yii, ida meji ninu mẹta ni yoo ṣafihan boya wọn yoo le Trump kuro lori alefa patapata.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Adeola Smart and Malivehood Wedding: Diamond kún ara aṣọ ìyàwó, Cake jẹ́ alájá 16 11 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Oríṣun àwòrán, Istagram/malivelihood Ọpọ eeyan to peju sibi igbeyawo Adeola Smart, tii se ọmọbinrin Senatọ Smart Adeyemi ati ọkọ rẹ, Olusola Awujoola ni ko ni gbagbe aramọnda igbeyawo naa laelae.
O tenumo pe, awon omo ogun je ipago ohun run patapata lai ku enikan soso.
Awon agbegbe ti ile-ise wa ni yoo awon ile gogoro, ti yoo je agun ni apapo, ni eyi ti a o ti ri ile ti o ga ju nile Afrika, ti yoo to iwon bata bi irinwo 385.
Kì báà dúró, kì báà sì ṣubú, ọ̀gá rẹ̀ nìkan ni ìdájọ́ tọ́ sí.
    Nígbà tí o ṣe o ń bọ̀ lápá ọ̀dọ̀ mi, nígbà tí o sì de ibẹ̀, ó wo ìsàlẹ̀, o wo abẹ́ ìtàkùn, ó wo òkè, ṣùgbọ́n kò rí mi lábẹ́ ewé o sì kọja sí apá ẹ̀yìn mi, o lọ.
Bakan naa ni ilana tuntun fun eto isinku yii pọn ọn ni dandan fawọn mọlẹbi to n sinku lati fi ọrọ to ọga ọlọpaa to wa lagbegbe naa leti nipa sjs ati ibi ti wọn ti fẹ sinku ati pe oṣiṣẹ ijsba ibilẹ to n mojuto ọrọ ajakalẹ arun ni o gbọdọ lewaju eto isinku bẹẹ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Àwọn ọ̀dọ́ ẹ̀yà Hausa kan àtàwọn ọmọ ẹgbẹ́ òkùnkùn 'Awawa boys' da ìgboro Eko rú 18 Ògún 2019 Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Àwọn ọ̀dọ́ ẹ̀yà Hausa kan àtàwọn ọmọ ẹgbẹ́ òkùnkùn 'Awawa boys' da ìgboro Eko rú Wahala nla kan ti bẹ silẹ laarin awọn ọdọ kan lagbegbe Oke Odo ni ipinlẹ Eko.
Chelsea kọ́ láti fìyà panu bíi Arsenal àti Man U 22 Ìgbé 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Goolu mẹrin laarin iṣẹju mẹẹdọgbọn ni Chelsea ati Burnley jẹ ninu ifẹsẹwọnsẹ́ wọn lalẹ ọjọ aje.
Eleyi ṣẹlẹ bi ibẹru-boju ṣe gbalẹ saaju idibo gbogbogbo nilẹ naa.
Amọ Tedros Adhanom Ghebreyesus ni pipe arun naa ni ajakalẹ aarun ko tu mọ si pe ko ni si ọna abayọ lati kapa aarun naa.
Facebook gbégilé àwọn ojú òpó ayédèrú Kí lo mọ̀ nípa Eniọla Badmus?
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Lola Omolola FIN: A gbọ́dọ̀ dìde láti ran àwọn obìnrin tó ń la ìwà ipá nínú ìdílé lọ́wọ́ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Lola Omolola FIN: A gbọ́dọ̀ dìde láti ran àwọn obìnrin tó ń la ìwà ipá nínú ìdílé lọ́wọ́ 30 Ọ̀wàrà 2019 Iwa ipa to n wọpọ lawujọ si atọmọde ati agba obinrin lo ti di irawọ ọsan to n bawọn agba lẹru bayii, eyi to yẹ ki gbogbo wa dide lati mojuto.
"Oríṣun àwòrán, @Opetuyii ""Oniruuru ọna ni eto aabo fi mẹhẹ, paapa nipinlẹ Ondo, to si tun jẹ ohun ibanujẹ nla yika orilẹede Naijiria, nitori naa, igi gogoro ma gun mi loju, ati okeere laa ti lọọ, idi si ree taa fi gbọdọ gbe igbesẹ pajawiri lati rẹyin aifararọ eto aabo naa."
 lúwà àti Àlárẹ ̀ bí ọmọkùnrin kọ ̀ ọ ̀ kan .
Báńkì ìdàgbàsókè Áfríkà yóò bẹ̀rẹ̀ àkọ̀tun ìwadìí lórí Olùdarí báńkì náà, Akinwumi Adesina Obìnrin Nàìjíríà tí wọ́n lù aago gbà njo lé lórí ní Lebanon sọ pé òun kò wá sílé mọ́ Wo àwọn gbajúmọ̀ òṣèré Yorùbá tí kìí ṣe ọmọ káàárọ̀ oòjíire Ènìyàn 350 ló ní àrùn Coronavirus ní Naijiria ní Ọjọ́bọ̀ Ọrọ yii ni wọn n gba mọ ara wọn lọwọ ni aarọ ọjọ Ẹti, idi si ree ti BBC Yoruba fi n beere lọwọ onimọ kan nipa ẹṣin Islam pe ki ni itumọ Alhaji ati Alhaja pẹlu awọn oye apemọ orúkọ miran to wa ninu ẹsin islam.
Shehu sọ fun ile isẹ iroyin News Agency of Nigeria pẹ ina naa sẹyọ latara irin igbomikana (boiling ring) ni nkan bi agogo mọkanla alẹ lọjọ abamẹta ọgunjọ osu yi.
fiwe ranse si ile igbimo asofin ni ojo kẹ́jọ, osu kárùn ún, odun 2019 (May 8, 2019) , ti ile igbimo asofin si ri iwe naa gba ni
Nítorí náà inú wa dùn nígbà tí àwa bá jẹ́ aláìlera, tí ẹ̀yin sì jẹ́ alágbára.
Ẹ ranti pé ninu ẹ̀wọ̀n ni mo wà.
Ninu alaye rẹ, dokita Adepoju ni oju buluu Risikat atawọn ọmọ rẹ ko nilo itọju rara nitori abimọ lo jẹ fun wọn.
Fulani kò leè dúró, táa bá lo ohun ta jogún lọ́dọ̀ àwọn bàbá wa - Sunday Igboho Kí ni ó gbé ọlọ́pàá dé ibi àjọ̀dún ọjọ́ ìbí i Bobrisky?
Bada ni Abiola Ajimobi ri aye gbe, to si fi aye rẹ sin iran ọmọniyan, to si gbadura pe ki Ọlọrun gba abọ rẹ, ko si dari awọn ẹsẹ rẹ jin.
Ogunlọ́gọ̀ àwọn tí kìí tíí bìkítà fún mi ni wọ́n ń dọ̀bálẹ̀ tí wọn ń wí pé, ‘kẹ́ ẹ pẹ́, kẹ́ ẹ pẹ́, tí èmi náà sì ń kí wọn, tí mò ń ṣe, ‘ọọkú’ bí àgbàlagbà.
Ta ni yóo mú mi lọ sí Edomu?
Ilé ìsìn náà ga sókè sooroso tóbẹ́ẹ̀gẹ́ , àwọn ará ìlú míràn lè ríi lókèrè.
OLUWA yóo san ẹ̀san gbogbo ohun tí o ti ṣe fún ọ.
O s'afikun wipe eleyii yoo dẹkun ija laarin agbẹ oloko ati darandaran Fulani to n fojojumọ waye.
Bakan naa ni awọn ẹgbẹ bii awọn Fulani daran-daran naa ti sọrọ tako eto naa.
Ó jìn ju isà òkú lọ, kí lo lè mọ̀ nípa rẹ̀?
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Adeleke Vs Oyetola: Òní ni ilé ẹjọ́ tó ga jù lọ yóò kéde ìdájọ́ lórí èsì ìdìbò gómìnà ìpínlẹ̀ Ọṣun 4 Agẹmo 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 5 Agẹmo 2019 Àkọlé àwòrán, PDP àti APC Osun Ọjọ a da ti pe.
"€10,000, ara owó tí wọn fi ra Ighalo pòórá, Ilé aṣòfin Osun bẹ̀rẹ̀ ìwádìí Ìwádìí BBC rèé lórí ẹ̀sùn gbájuẹ̀ $120,000 tí wọ́n fí kàn igbákejì olórí òṣìṣẹ́ ìjọba l‘Osun PDP àti APC fi ìbọn dárà l'Ondo, ọ̀pọ̀ èèyan farapa, àìmọye dúkìá ṣòfò ""Dípò ìnákúnàá lórí ìgbéyàwó ọmọ mi, mo lò owó fún ìgbéyàwó ọmọ òrukàn mẹ́tàlá"" Àwàdà kẹríkẹrì nígbà táwọn olùdíje ààrẹ́ Amerika méjì kọjú ìjà síra wọn Ìjọba àpàpọ̀, jọ̀ọ́ máṣe yẹ̀ lórí àdéhùn rẹ fẹ́gbẹ́ òṣìṣẹ́ - Ile aṣojú-ṣòfin Ọgọ́rin arìnrìnàjò tó padà wá sí Nàìjíríà ló ní Coronavirus - PTF Awọn ikede wọn yii, yala lati ọdọ ileeṣẹ ọlọpaa ati awọn ijọba ipinlẹ, lawọn eeyan ti n ṣe eemọ si ṣugbọn ti awọn onwoye ni ko ba ofin mu."
Mo ké pe Ọlọrun fún ìrànlọ́wọ́,mo kígbe pe Ọlọrun kí ó lè gbọ́ tèmi.
Awọn ipinlẹ to ku ni Kaduna-27 Oyo-12 Rivers-6 Katsina-5 Ogun-3 Kwara-2 Edo-1 Kano-1 Apapọ awọn to ti ni jẹ 66,607, ti 62,311 si ti ri iwosan.
Minisita fun eto irinna ofurufu ni Naijiria, Hadi Sirika lo kede rẹ loju ọpọ ikansiraẹni Twitter rẹ.
Ileeṣẹ Ọlọpaa ni ipinlẹ Ondo ti ni aigbọran awọn eniyan lati ma ṣe rin irinajọ lasiko arun Coronavirus yii lo fun awọn ajinigbe lagbara lasiko yii.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Abiola Ajimobi: APC àti ALGON ti mú àbá tuntun jáde lórí ọ̀rọ̀ gómìnà Ọyọ àná 5 Òkùdu 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 23 Òkùdu 2020 Oríṣun àwòrán, Abiola Ajimobi Ẹgbẹ oṣelu All Progressives Congress, APC ni ipinlẹ Oyo ati ẹgbẹ awọn alaga ijọba ibilẹ, ALGON, ẹka tipinlẹ Oyo, ti bẹrẹ eto aawẹ ati adura fun ilera adele alaga ẹgbẹ oselu APC nipinlẹ Oyo, Abiola Ajimobi.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ sí: Ìpàdé ìtagbangba Ọṣun kò lọ́la ọjọ́ Ẹtì ‘PDP kò mọ̀ nìpa Femi Otedola tó ń dupò gomina’ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ọmọdé tó ń fi ọpọ́n àyò gba ipò Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Ninu osu keta, iko lati Ajo to n risi idagbasoke ni apa guusu ile Afirika ati Ajo isokan ile Europe  se abewo lotooto lati se iwadi lori eto=idibo naa to n bo lorile-ede naa.
 / https : / / en.
A padà san owó ìtanràn fáwọn ajínigbé kí wọ́n to fi àwọn mẹ́tẹ̀ẹ̀ta sílẹ̀- Ẹbí Ṣé Van Dijk lè borí Ronaldo àti Messi nínú ìdíje UEFA?
Oríṣun àwòrán, Others O dun mi pe n ko le ni anfaani lati juwọ si pe o digbose ko to gbẹmi mi, o si se ni laanu pe a padanu rẹ.
naa tun so pe pupo ninu awon orile ede lo n koju wahala  oju-ọjọ sugbon ti o je pe wahala ati isoro
Gbogbo ilẹkun to wọ ile igbimọ asofin naa ni wọn ti ti bayii, ti awọn asofin ko si le e jade.
Baalẹ ilu Dapchi wa nijoko nibi.
Ó ní kí wọ́n pọn ẹ̀kún ìkòkò omi ńlá mẹrin, kí wọ́n dà á sórí ẹbọ ati igi náà, wọ́n sì ṣe bẹ́ẹ̀.
Jesu Bá Obinrin Ará Samaria Sọ̀rọ̀.
Yóo sì fi bẹ́ẹ̀ di ẹni ègún láàrin àwọn eniyan rẹ̀.
Omijé ń dà lójú mi pòròpòrò,nítorí pé àwọn eniyan kò pa òfin rẹ mọ́.
Wo àwọn ọ̀tá tó ń da orílẹ̀èdè Nàìjíríà láàmú Bauchi State: Okú 596 ló ṣì ń gba owó oṣù 'Kò bá má dùn mí tó báyìí bí mi ò bá k'àwé', pé mò ń nu bàtà f'óúnjẹ òòjọ́' Irú kí lèyì!
"Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Mo fẹ́ ọkọ mi torí bó se ń kọrin, kìí se torí owó - Ìyàwó Aràrá Mo fẹ́ kí àyẹyẹ ìgbeyàwó mi dùn ni mo se bú sẹ́kún - Ọkọ ìyàwó ẹlẹ́kún Samuel Ladoke Akintọla jẹ́ Agbẹjọ́rò àti Akọ̀ròyìn tí ọ̀rọ̀ dá lẹ́nu rẹ̀ Hubert Ogunde rèé, baba àwọn òsèré tíátà Ìyàtọ̀ wà nínú ìlépa àwọn òṣèré tíátà ayé àtijọ́ àti ìsisìnyí-Papalolo Iléesẹ́ ológun ń retí bàálù 18 látọ́dọ̀ Amẹrika fi kojú Boko Haram Aláàfin ń se ọgọ́rin ọdún, àwọn àwòrán mánigbàgbé Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fọ́nrán ohùn, Alaafin Ọyọ: Asiri agbara bibi ibeji lọpọ igba ""Eyi to gboye imọ ijinlẹ to kere ju lọ ni iwe ẹri agba nileewe gbogboniṣe, Higher National Diploma (HND)."
ohun tí ó fa ìjà tí Ògúndélé àti jinádù ń jà ni pé Ògúndélé tí ó jé alágbẹ ̀ dẹ rọ kọ ́ kọ ́ rọ ́ kan fún jìnádù ní múrí mẹ ́ ta ( # 60 ) , jìnádù san múrí kan ( # 20 ) níbẹ ̀ ó ku múrí méjì ( # 40 ) .
Oríṣun àwòrán, @nassnigeria Àkọlé àwòrán, Ojuṣe awọ̀n agbofinro ni lati ṣe iwadi ipilẹ ẹni to fẹ di ipo ilu mu O ni lootọ ọpọ igba lawọn aṣofin maa n nii lskan pe ko si bi ẹni ti wọn pe fun ipo to gaa lawujọ lee wa lai ni awọn iwe ẹri to yẹ, ṣugbọn nitori ki ọrọ o ma baa ba ẹyin yọ ni eyi ṣe pọn dandan.
Lo ba di ofin lorilẹede Botswana!
Bi o ba se wi pe ki ẹ jijọ maa se bojuboju tabi sise ipade ranpẹ lori oun tẹ ẹ fẹ se ni ojumọ kọọkan lẹ ba yan laayo, ko si ọna ti ẹ yan ti ko ni jẹ ki ẹ gbadun isẹ yin lati ile.
 Ònà tí ó máa ń gbà déédé ni lati mombasa , kenya salalah , oman , si djibouti , padà sí mombasa .
Se bi irin ba kanrin , o
Ohun ti a gbọ ni pe ileewe alakọbẹrẹ ẹgbẹrun le ni mẹtadinlogun(1017) to jẹ ti ijọba ipinlẹ Eko ko tii wọle.
"Eyi nii ṣe pẹlu bi gulegule idukukulaja mọni awọn darandaran Fulani ti ṣe wa n di lemọlemọ bayi loju awọn opopona marosẹ gbogbo ni ilẹ Yoruba.
Lẹyin atotonu awọn agbẹjọro mejeji, adajọ Bode Adegbehingbe ni ẹri fi han pe Kingsley jẹbi ẹsun ti wọn fi kan an, lẹyin naa lo ni ko lọ faṣọ penpe roko ọba titi lai.
Bí ó ti ń súre fún wọn, bẹ́ẹ̀ ni ó ń gòkè lọ kúrò lọ́dọ̀ wọn, ni a bá fi gbé e lọ sí ọ̀run.
Boya igbesẹ ọlọpaa ba ofin mu tabi ko ba ofin mu, jọwọ ara rẹ silẹ fun wọn lai fa wahala rara.
Naijiria le ọmọ Cameroon mejila UN: Orilẹ́èdè Nigeria dalẹ̀ Cameroon Igí wó pa akẹ́kọ̀ọ́ Nàìjíríà ni Cameroon Àwọn míràn tí wọ́n tún yàn fún àyẹ̀wò fún isẹ̀ náà ni: Balógun ikọ̀ agbábọ́ọ̀lù Cameroon tẹ́lẹ̀rí, Rigobert Song; akọ́nimọ̀ọ́gbá ikọ̀ agbábọ́ọ̀lù Super Eagles nígbàkan rí, Philippe Troussier; àti akọ́nimọ̀ọ́gbá égbẹ́ agbábọ́ọ̀lù ilẹ̀ Faransé tẹ́lẹ̀ rí, Raymond Domenech.
Nigba ti mo ri i pe mo loyun, mo gbiyanju lati sọ fun, ṣugbọn mi o ri nitori pe o tun ti kuro niluu."
Aare ile-ejo ajo ECOWAS, adajọ Edward Asante lo pe ipe naa nilu Abuja, lasiko idanileko ti won pe akori re ni “gbigba dukia eni pada fun ni” eleyi ti ile-ise to n gbogunti iwa-ibaje nile Afrika(Inter-governmental Action against Money Laundering), GIABA se agbekale reEto idanileko olojo merin in ohun ni won sagbekale re lati ro awon osise naa lagbara si lojuma ati wani ibamu pelu ilana ajo isokan lagbaye.
Ìtàn Mánigbàgbé: Kuti ni akọni Obìnrin Ẹ̀gbá tó di àwòkọ́ṣe rere f'áwọn ọ̀dọ́bìnrin ìwòyí
"Àwọn Olúkọ ìpínlẹ̀ Oyo fakọyọ lórí ètò Akọ́mọlédè àti Àṣà púpọ̀ Diẹ lara awọn ibi ti o ko gbọdọ gbe ọkọ rẹ si boya wọn gbe akọle "" No Parking"" sii tabi bẹẹkọ niwọnyi- - Orita tabi iwọn mita mẹwaa to jẹ ẹṣẹ bata mejilelọgbọn."
Ẹgbẹrun meji o le lawọn to n reti iku lọgba ẹwọn Naijiria
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Yoruba culture: Adelé Olúbọ̀rọ̀pa ní ọmọ ọdún 16 ni òun jẹ́ Adelé, kó tó lọ sí Fáṣítì 2 Òkùdu 2020 Oríṣun àwòrán, Instagram/officialoluboropa_of_iboropa Adelé Olúbọ̀rọ̀pa tilu Bọ̀rọ̀pa, Ọmọọba Tinuade Babalola Adejuyigbe ti koro oju si bi ko ṣe si itọju gidi fun awọn ọba alaye ati awọn Adelé.
jẹ́ ẹgbaa mẹtalelogun ó lé ẹẹdẹgbẹta (46,500).
Ní orílẹ̀-èdè Nàìjíríà, àyẹwo ti wọ́n ń ṣe kò tó odidi kan nínú ẹgbẹ̀run kan, Mẹ́wàá ní Ghana, mẹ́tà ni Kenya.
Nígbà tí OLUWA bá sì bukun ọ, jọ̀wọ́ má ṣe gbàgbé èmi iranṣẹbinrin rẹ.
Kanye West ti bẹ̀rẹ̀ ìpolongo àti díje dupò aàrẹ ilẹ̀ Amẹrika Akanbi mi, má fọ̀ ọ́, mo wà pẹ̀lú ẹ; ẹni tó ṣe ìgbéyàwó olórùka ló l'ọkọ- Lizzy Anjorin Ó yẹ kí ìjọba gbé ilé ìwé tì pa títí di ọdún 2021- ASUU Oloye Sọbaloju ti ilu Ẹdẹ wa ṣalaye pe nigba ti owo ba tan ni irufẹ awọn eeyan yii dabi eṣú ti wọn maa n yalọ laisko ẹrun ninu oko.
Lọna ati ni imọ to peye nipa fifun ọmọ lọyan, o se pataki lati maa lọ fun idanilẹkọ lọdọ awọn eeyan to loye nipa rẹ.
Igba mẹta ọtọọtọ ree ti Naijiria ti fi ilana gbigbẹsan yi ba awọn orile-ede miran ṣe papọ latẹyin wa.
Nígbà tí wọ́n jẹun yó tán, wọ́n da ọkà tí ó kù sinu òkun láti mú kí ọkọ̀ lè fúyẹ́ sí i.
Egbe naa so pe awon se idalilekoo yii fun awon eniyan ti yoo kopa  lati mojuto  eto idibo, ni pataki julo ni igberiko ati ni ipinle to wa lorile ede Naijiria.
Ẹ̀rín pa wọn díẹ̀ ṣùgbọ́n kò sí ẹni ti kò dá àwọn ará ilé Òmùgọ́parapọ̀ lẹ́bi fún ìwà òmùgọ̀ tí wọn hù, àwọn ni wọn fi ọwọ wọn fa ìjàngbọ̀n tí wọ́n bá ìjàngọ̀n pàdá tí wọ́n sọ ènìyàn di màlékà tí wọn gbàgbé pé ẹlẹ́ran ara ni àwọn ara ilé Wọ̀bìáparapọ̀ i ṣe.
Ẹ̀ẹ̀kan lọ́dún mẹta ni àwọn ọkọ̀ náà máa ń dé; wọn á máa kó wúrà, fadaka, eyín erin, ati oríṣìíríṣìí àwọn ọ̀bọ ati ẹyẹ ọ̀kín wá sílé.
Amọ, ayẹwo fihan wi pe o din ni ipinlẹ kan ninu mẹta to n wo iye awọn obinrin si ọkunrin to wa ni ile iwe alakọbẹrẹ.
Ati pe ko si ohun to le mu ki Tinubu sọ iru ọrọ yii nitori oun ati Buhari ko si ninu ẹgbẹ oṣelu kan naa, bẹẹ ni wọn o si nija ara wọn ninu,'' Ọgbẹni Rahman lo woye bẹẹ.
Ìwọ̀nyí ni orúkọ àwọn ọmọ ati àwọn ọmọ ọmọ Israẹli tí wọ́n lọ sí ilẹ̀ Ijipti, Jakọbu ati àwọn ọmọ rẹ̀: Reubẹni, àkọ́bí rẹ̀, 
Ẹ̀bùn Èdè Àjèjì ati Ti Ìsọtẹ́lẹ̀.
ati Afirika , ni eyi ti o fi ran won lowo lati le je ki won samulo ohun ti won
Nígbà tí àwọn ọmọ Israẹli tí wọn ń gbé àfonífojì Jesireeli gbọ́ pé àwọn ọmọ ogun ti sá lọ, ati pé Saulu ati àwọn ọmọ rẹ̀ ti kú, wọ́n sá kúrò ní ìlú wọn, àwọn ará Filistia wá wọ́n sì ń gbé ibẹ̀.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ààrẹ Muhammadu Buhari Gẹgẹ bi idibo ọdun 2019 ṣe balẹ biba, Aarẹ Buhari n ja fita fita lati dupo yii lẹẹkan sii.
Obìnrin olówònààbì ta ọmọ rẹ̀ oṣù mẹ́rin ní N300,000 Egbìnrìn ọ̀tẹ̀!
Ká tó máàkì, Ká tó gbésì ìdánwò wa sí gbangba.
Nítorí ẹ̀yin fúnra yín mọ̀ pé onigbagbọ níláti rí irú ìrírí yìí.
Nígbẹ̀yìn ṣa, Ìṣubú fẹ́ ọmọbìnrin kan tí orúkọ rẹ̀ ń jẹ́ Ìbànújẹ́-òde.
Iwà burúkú wọnyi, pàtàki laarin àwọn Olóri ilú tàbi alágbára ló fa ti ta ara ẹni lẹ́rú si Òkè-Òkun, ogun abẹ́lé àti òwò ẹrú ti ayé òde òni ṣi wà.
Àpẹẹrẹ ni èyí fún gbogbo yín, ẹ̀yin ènìyàn wa.
Ta ló sì mọ̀ pé bí ẹ̀rù rẹ ti tó bẹ́ẹ̀ ni ibinu rẹ rí?
“Ìdáhùn tí wọ́n fún wa ni pé: ‘Iranṣẹ Ọlọrun ọ̀run ati ayé ni wá.
Oríṣun àwòrán, Toyin Abraham Ẹwẹ, Gbajugbaja Oṣere Tiata, Toyin Abraham naa ti da si ọrọ arun coronavirus to gbode kan bayii.
Ki wọ́n tó dá àwọn ipinlẹ̀ pọ̀, àwọn ipinlẹ̀ ndàgbà sókè gẹ́gẹ́ bi ohun ti ó ṣe kókó fún wọn.
Ọ̀rọ̀ ìfẹ́ ti wọn fi ń lọ̀ mí lágbo àmúlùúdùn ni ìṣòro kan tí mo ní - Lizzy Jay ọmọ Ibadan Borussia Dortmund ká eyín ọ̀ọ́kań Schalke 04 bí Líìgì ilẹ̀ Germany ṣe padà bẹ̀rẹ̀ 'Èèwọ̀!
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Mi ò ní ìyàwó nílé, àmọ́ mo ní ọmọ tó pọ̀-Saheed Oṣupa Atiku fẹ́ fa Lauretta Onochie, amúgbálẹ́gbẹ́ Buhari lọ ilé ẹjọ́ Àìgbọ́ran sí igbákejì ààrẹ Yemi Osinbajo lẹ́nu ló fa ìdàmú mi-Okorocha Gẹgẹ bi ohun ti a ri ka loju opo Facebook ajọ to n gbogun ti iwa jẹgudujẹra ni Naijiria, EFCC, ẹsun mọkanla ni wọn fi kan Azeez Adeshina, ti gbogbo eeyan mọ si Naira Marley.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Àwọn afurasí tí ọlọ́pàá ká orí èèyàn mọ́ lọ́wọ́ ní ìlú Akure ti fojú balé ẹjọ́ Olumide Owaduge BBC Yoruba, Lagos 26 Èbibi 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 9 Òkùdu 2020 Oni ni igbẹjọ awọn afurasi ti ileeṣẹ ọlọpaa ka ori eeyan mọ lọwọ ní agbègbè Imafon ni Ipinle Ondo.
wọ ́ n bị ́ adam abdullah al-ilory ní wasa ní apá gúsù orílẹ ̀ èd ̀ e benin , ẹni tí ìyá rẹ ̀ jẹ ́ ọmọ benin tí bàbá rẹ ̀ sì jẹ ́ ẹ ̀ yà yorùbá ọmọ orílẹ ̀ èd ̀ e nàìjíríà .
Bẹ́ẹ̀ náà sì ni àkọ́já ewébẹ̀ wa, ati àkọ́bí àwọn ẹran ọ̀sìn wa.
Ẹ óo mọ̀ pé èmi ni OLUWA; nítorí pé ẹ kò rìn ninu ìlànà mi, ẹ kò sì pa òfin mi mọ́, ṣugbọn ẹ ti gba àṣà àwọn orílẹ̀-èdè tí wọ́n yi yín ká.
” Bẹ́ẹ̀ ni orí kò lè wí fún ẹsẹ̀ pé, “N kò nílò yín.
Nàìjíríà bá RCCG, ìyá Folu Adeboye yọ ayọ̀ 70 INEC: Èsì ìdìbò Ekiti lẹ́kùnrẹ́rẹ́ Atọmọde ati agba jade fun idibo ni Ekiti Saraki ṣe àdúrà fún Fayẹmi Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ekiti Election: Kọmísánà fétò ìdìbò ní jàǹdùkú já àpótí gbà ní wọ́ọ́dù mẹ́fà Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Igba akọkọ ti wọn n kopa ninu idije AFCON tilẹ Adulawọ ni ti 2019 to n lọ lọwọ ni Egypt.
Asepati marosẹ Ibadan si Eko lewu - Fasọla Gani Adams gb'oriyin fun'pinlẹ Eko Bayọde, to kawe fun nnkan bi wakati mejilelọgọfa, o si simi fun wakati meji-meji ninu wakati mẹrinlelogun kọkan.
O salaye lori isele ojo-Eti pe, ara to san laarin awon akekoo ni agbegbe naa, eyi ti o seku-pa enikan ninu won.
Awọn agbegbe to bajẹ julọ ni bii abule Lading-Lading, ilu Mataram, ati àwọn agbegbe miran ni ariwa Lombok.
Kayọde Fayẹmi jẹ́ kó dí mímọ̀ wí pé bí wọn ṣe lérò rẹ̀ náà ni ó ṣe rí.
2018 , latari pe ko ni iwe-ẹri to koju osuwon lati dije fun ipo gomina.
Owo ori ti wọn n san ko yatọ si eyi ti onikaluku n san lori owo to wọle fun lọdun.
Amọ, agbẹjọrọ awọn ti wọn fi ẹsun kan naa, Ibrahim Omachi, ni awọn mejeeji ti wa ni ọgba ẹwọn fun ọsẹ mẹrin ati wi pe igba akọkọ ni yii ti wọn yoo jẹjọ ẹsun kankan.
Jesu tún lọ sí ìlú Kana ti Galili níbi tí ó ti sọ omi di ọtí ní ìjelòó.
7 28124 Orilẹede Cuba 162 1.
Ẹ tún fẹ́ràn kí eniyan máa ki yín láàrin ọjà.
World tour- Jessica Nabongo ni obìnrin akọkọ nilẹ Africa tí yóò rin àgbaye tan
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Alao Akala:Èmi àti Ajimọbi kò ṣe ìlérí kankan fún ara wa Dubai, UAE: Lootọ ni ilu Dubai ti goke agba ṣugbọn ilu naa si tun fofin to de ọkunrin ati obinrin.
òróró ìtànná, àwọn èròjà fún òróró ìyàsímímọ́ ati fún turari olóòórùn dídùn, 
Lati ibẹrẹ eto naa ni ọpọ awọn ololufẹ eto BBNaija ti fẹran Laycon to fi di oni ti eto naa yoo pari.
Nigba to n sọ ero kan rẹ lori isẹlẹ yii, Aarẹ Muhammadu Buhari ni inu oun dun si bi wọn se yan oun ni alaga ajọ Ecowas.
Ọmọ ọdun mẹtalelọgọrin, 83 ni ki o to jade laye.
Bi awon ifesewonse opin ose yii yoo se lo:Liverpool v Norwich CityA.
 bakanna rubin de ipo world no.
fi aaye sile fun won rara.
Lójijì, bí wọ́n ti wò yíká, wọn kò rí ẹnìkankan lọ́dọ̀ wọn mọ́, àfi Jesu nìkan.
Aworan naa ṣafihan Dele to n fi itanna ẹrọ ipọwo ATM ṣe iṣẹ amurele rẹ lalẹ ọjọ kan.
Ipinlẹ̀ Ìwọ̀-Oòrùn, ti ẹ̀yà Yorùbá ngbé, ni ìgbéga ni abẹ́ Olóri Òṣèlú Ipinlẹ̀, Olóògbé́ Olóyè Ọbáfẹ́mi Awólọ́wọ̀ àti ẹgbẹ́ Òṣèlú rẹ.
"Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Winnie Madikizela-Mandela kú lẹ́ni ọdún mọ́kànlélọ́gọ́rin Buhari tún ṣe àpèjúwe Winnie Madikizela-Mandela gẹgẹ bíi ""Obìnrin tí ìfọkànsìn, ìdúróṣinṣin àti ìfaradà rẹ̀ kò lẹ́gbẹ́; tó gbé ọ̀págun ìjìjàgbara sókè téńté, kódà nígbàtí ọkọ rẹ̀ wà ní àhámọ́."
O ni: “Eto idanilekoo yii yoo tesiwaju ni ki idagbasoke file ba ise awon odo to nife si ere sise ati ise gbogbo to ro mo gbigbe fiimu agbelewo sita”.
Ati wolii, ati alufaa, ìwà burúkú ni wọ́n ń hù,ní ilé mi pàápàá mo rí iṣẹ́ ibi wọn,èmi OLUWA ni mo sọ bẹ́ẹ̀.
” (Àkókò náà sì jẹ́ àkókò àkọ́so àjàrà.
O ni diẹdiẹ ni awọn agbabọọlu naa n kuro nile itura ti wọn wa nitori ọtọọtọ ni wọn de si France ati pe ọtọọtọ nibi ti wọn n lọ.
Igbakeji aarẹ Yemi Osinbajo lo fọwọ si isunsiwaju yi lẹyin ipade kan to waye laarin oṣẹ gẹgẹ biatjade kan ti o tẹ ile iṣẹ BBC Pidgin lọwọ.
Timoti mi ọ̀wọ́n, pa ìṣúra tí a fi fún ọ mọ́.
Wọn bẹrẹ́ si ni tako ara wọn lori tani yoo wọle ninu ẹgbẹ oṣelu APC tabi PDP ni Naijiria.
" Wọn gboriyin fun eto riran araalu lọwọ, pe o n mu adinku ba ìṣẹ́, ṣugbọn titẹsiwaju ninu rẹ yoo ni ipa to l'agbara ninu eto inawo ijọba.
Ohanaeze ni adura nikan kọ ni ọrọ Naijiria gba bayii, nitori ijọba gbọdọ wa ọna abayọ si iṣoro ipaniyan awọn Fulani darandaran laarin awọn iṣoro ti Naijiria n koju.
Ni Oṣu Kejila, ọdun 2019 ni wọn gbe ẹjọ naa kuro ni ileẹjọ gbogboogbo lọ si ileẹjọ awọn ọmọ ogun, ti awọn araalu ko si lẹtọ si igbẹjọ naa mọ.
Mose sọ ọ̀rọ̀ wọnyi fún àwọn eniyan Israẹli, ṣugbọn wọn kò fetí sí ohun tí ó ń sọ, nítorí pé ìyà burúkú tí wọn ń jẹ ní oko ẹrú ti jẹ́ kí ọkàn wọn rẹ̀wẹ̀sì.
Amosa, lapapọ, ni egbẹrun mọkanlelọgbọ̀n pọun iyẹn ….
O sàn ká wà láyé láì lówó lọ́wọ́ ju ká ya sinimá, ká kó Coronavirus lọ - Latin pariwo fáwọn òṣèré tíátà Ọwọ́ ọlọ́pàá tẹ 'ọba alayé' àti ọmọ rẹ̀ tó fi ipá bá ọmọ ọdún mẹ́rìnlá lòpọ̀ l'Ọ́ṣun Ọrọ yi buso sini lẹnu to tun bu yọ sii bayii ti onikaluku ti n da ọmu iya rẹ gbe nitori itankalẹ arun coronavirus.
3 Kíyèsíi, oko náà ti funfun tán fún ìkórè; nítorínáà ẹnikẹ́ni tí ó bá fẹ́ láti kórè, ẹ jẹ́ kí ó fi dòjé rẹ̀ pẹ̀lú ipá rẹ̀, àti kí ó kórè ní ojú ọjọ́, kí ó lè kó ìgbàlà àìlópin pamọ́ fún ọkàn rẹ̀ nínú ìjọba Ọlọ́run.
Ó ní ọmọkunrin kan tí ń jẹ́ Saulu.
Bẹẹ naa ni Jaiye Kuti fesi lori fọnran ti wọn fi sita lati dupẹ fun igbesẹ wọn bi oun naa ṣe ti gbiyanju ranpẹ tirẹ.
 nígbàtí làìbéríà di alómìnira ní 1847 , roberts jẹ ́ dídìbòyàn bíi ààrẹ àkọ ́ kọ ́ , ó wà lórí àga títí di 1856 .
Wọ́n tọ́jú àwọn òkúta onikisi, wọ́n jó wọn mọ́ ojú ìtẹ́lẹ̀ wúrà, wọ́n kọ orúkọ àwọn ẹ̀yà Israẹli sí ara wọn, bí wọ́n ti máa ń kọ orúkọ sí ara òrùka èdìdì.
N óo dá ire Juda ati ti Israẹli pada, n óo sì tún wọn kọ́, wọn yóo dàbí wọ́n ti rí lákọ̀ọ́kọ́.
Ọga ileeṣẹ Reckitt Benckiser, ti wọn n ṣe rọba idaabobo Durex ti sọ pe awọn eeyan ko saa ba ni ibalopọ pẹlu ara wọn lasiko ajakalẹ aarun covid-19 yii.
Ìwọ lè sọ̀rọ̀ jù n kò rí àyè tó bí i tìrẹ wọn-ọnnì, ìba ni nǹkan ń mọ.
Ìwọ óo fi ọ̀pá irin fọ́ wọn,o óo sì fọ́ wọn túútúú bí ìkòkò amọ̀.
''Ibi ti mo ti n sun niyi fun ibi ọdun marun un nitori mi o rowo ile san lẹyin ti okowo mi dẹnu kọlẹ, o ku diẹ kaato.
Ikoro ṣalaye pe Iwadii ṣi n lọ lọwọ lori iṣẹlẹ naa, bo tilẹ jẹ pe a ko tii le fidi rẹ mulẹ pe ọmọ ẹgbẹ okunkun ni ọkunrin naa tabi awọn ọmọ ẹgbẹ okunkun lo ṣekupaa."
Murphy Elégungun Rọba: Mo fẹ́ di ẹnití egungun rẹ̀ rọ̀ jùlọ ní àgbáyé
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Wo oríṣìí àrùn márùn ún tí ìgbéyàwó láàrin ìbátan si ìbátan máa ń fà Ǹjẹ́ ó ṣeéṣe kí ìyáwò rẹ gbé ọmọ àlè wá sílé láì mọ̀?
Ìjọba Ọyọ ti ọjà Ṣáṣá pa ní Ibadan torí ìjà láàrin ẹ̀yà Hausa Saaju la ti kọkọ mu iroyin wa fun yin pe, ijọba ipinlẹ Ọyọ ti paṣẹ wi pe ki awọn agbofinro sọ agadagodo si ẹnu ọna abawọle ọjọ Ṣaṣa to n bẹ ni agbegbe Moniya niluu Ibadan nitori rogbodiyan to bẹ silẹ laarin awọn ẹya Hausa to n taja nibẹ lọjọ Ẹti.
Láti Diboni Gadi wọ́n lọ sí Alimoni Dibilataimu.
Boeing 737 naa ni iroyin ni pe o nilati pada wa si Eko lẹyin iṣẹju mẹwaa to gbera.
Fake News: Ayédèrú Dino fẹ́ fún èèyàn mẹ́wàá ní mílíọ̀nù mẹ́wàá náírà tí Atiku bá wọlé
Ó pàṣẹ pé, “Ẹ ya ọjọ́ kan sọ́tọ̀ fún ìsìn Baali,” wọ́n sì kéde rẹ̀.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ondo Kidnapping: Egbìnrìn ọ̀tẹ̀ ni ọ̀rọ̀ àwọn ajínigbé ní ìpínlẹ̀ Ondo 17 Ọ̀pẹ̀̀ 2018 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 18 Ọ̀pẹ̀̀ 2018 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ọ̀pọ̀lọ̀pọ̀ ìgbà ni ìjínigbé ti wáyé ní ojú ọ̀nà ìlú Ọ̀wọ̀ sí Ìkàrẹ́-Àkókó.
Obinrin náà dáhùn pé, “Ta ni kí n pè fún ọ?
Kété tí àjọ elétò ìdìbò INEC kéde iròyìn àṣeyọrí rẹ̀ nínú ìdíje ọ̀hún ni àwọn olólùfẹ́ rẹ̀ bẹ̀rẹ̀ sí ní jó tí wọ́n sì ń kọrin.
iru rẹ ti yoo waye lasiko aare Cyril Ramaphosa,ti o dipo aare ana Jacob Zuma ti
sibẹ ẹ̀ ń sọ pé, ‘Ọwọ́ wa mọ́;dájúdájú, OLUWA ti dá ọwọ́ ibinu rẹ̀ dúró lára wa.
Popoola Kayode lo pe orukọ ọga yi to si ni ọkan lara awọn ọmọ igbimọ amuṣẹya lori gbigbogun ti iwa to lodi si ofin irina nii ṣe.
Amo, Freddie Ljungberg to je igbakeji akonimoogba ni yoo ma sakoso fun igba yii naa.
Nígbà tó ń ṣàlàyé ibi tó yẹ kí àwọn ọlọkada maa sanwó oọjọ wọn sì, Folaranmi ni àwọn alákòóso àgbà, táa mọ sí Consultant ńìjọba Ọ̀yọ́ ni kí àwọn máa sanwó fún.
Nígbà náà ni Dafidi wí fún Gadi pé, “Ìdààmú ńlá dé bá mi, jẹ́ kí n ṣubú sí ọwọ́ Ọlọrun, nítorí àánú rẹ̀ pọ̀; má jẹ́ kí n bọ́ sí ọwọ́ eniyan.
Sagamu: Ìkọlù ń wáyé bí ará ìlú ṣe gbéná wòjú ọlọ́pàá torí ikú agbábọ́ọ̀lù Elédùmarè ló rán mi sí gbogbo Ọba Yorùbá - Oluwo Ààrẹ Buhari ti ṣàlàyé ìdí tí kò ṣe tíì ṣí ibodè tó tì pa Fasiti UI forin tàkasúfèé wá ojúùtú si ìṣòro ẹ̀kọ́ iṣirò Otedola Bridge: Àwọn ẹ̀ṣọ́ ojú pópó ti gbé Ọkọ̀ agbépo tó dànù kúrò lọ̀ná Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Àwọn olúlùfẹ́ fí ìbòjú fi ẹnu ko ara wọn ní Philippine O fi eyi ran ara rẹ leti ohun ti iya rẹ la kọja.
Fake News: BBC Kò ṣe ètò ìrànwọ́ ìwé kíkà lásìkò yìí 'Ohun tó ṣẹlẹ̀ sí Ezekwesili kò le ṣẹlẹ̀ sí mi' #BBCNigeria2019 Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Obìnrin ló ni ilé àti àdúgbò fún ìdí èyí wọ́n lè ṣe ìlú dáadáa' Iṣana pẹlu awọn ohun ti ẹgbẹ oselu PDP pin fun awọn eniyan saaju idibo gbogboogbo lọdun 2015.
Tẹ́tí rẹ sílẹ̀ kí o gbọ́ ọ̀rọ̀ ọlọ́gbọ́n,kí o sì fi ọkàn sí ẹ̀kọ́ mi,
Ẹka ti o n ri si eto aabo ti sọ ṣaaju pe, arakunrin naa yin ibọn naa ni kete ti awọn ọmọ ogun mura ogun.
Ọlọrun bojú wo àwọn eniyan Israẹli, ó sì rí irú ipò tí wọ́n wà.
Láìpẹ́ arakunrin rẹ̀ náà wálẹ̀, pẹlu òwú pupa tí wọ́n so mọ́ ọn lọ́wọ́, wọ́n bá sọ ọ́ ní Sera.
Ẹni tí ó jẹ́rìí sí nǹkan wọnyi sọ pé, “Bẹ́ẹ̀ ni, tètè máa bọ̀.
Awọn ẹgbẹ osisẹ naa wa kesi ijọba apapọ lati da owo epo pada si iye to wa tẹlẹ bibẹẹ kọ, awọn yoo korajọ lati fi ẹhonu to lagbara han ni Naijiria.
 O wa seleri lati fowosowopo pelu awon to n gbe ni gberiko.
Ẹni to bori: Namibia Burundi vs Morocco.
Tunde Kelani ni ko si ẹni ti ko mọ pe oloogbe naa lo jẹ igi lẹyin ọgba fun ẹgbẹ osere Ayinla Omowura, Oniluola yii si lo ni ẹbun ilu lilu julọ ni agbaye.
nítorí angẹli Oluwa a máa wá lẹ́ẹ̀kọ̀ọ̀kan láti rú omi adágún náà pọ̀.
Lọwọ yii, iye awọn eeyan to laarun Coronavirus lorilẹede Naijiria ti le ni ẹgbẹrun bayii ti ijọba apapọ ti kede.
Ó bá dá wọn lóhùn, ó ní, “Ẹ kó àwọn oriṣa mi, tí mo dà, ẹ mú alufaa mi lọ; kí ni ó kù mí kù.
Àwọn olórí tí wọ́n jẹ́ akọni ati àwọn olùrànlọ́wọ́ wọn yóo máa sọ nípa wọn ninu isà òkú pé, ‘Àwọn aláìkọlà tí a fi idà pa ti ṣubú, wọ́n ti wọlẹ̀, wọ́n sùn, wọn kò lè mira.
Bẹ́ẹ̀ sì ni, bí àwọn arakunrin wa ti rí ni àwa náà rí, àwọn ọmọ wa kò yàtọ̀ sí tiwọn; sibẹsibẹ, à ń fi túlààsì mú àwọn ọmọ wa lọ sóko ẹrú, àwọn ọmọbinrin wa mìíràn sì ti di ẹrú pẹlu bẹ́ẹ̀ sì ni kò sí nǹkan tí a lè ṣe láti dáwọ́ rẹ̀ dúró, nítorí pé ní ìkáwọ́ ẹlòmíràn ni oko wa ati ọgbà àjàrà wa wà.
 olúìlú rẹ ̀ ni jakarta .
Oríṣun àwòrán, Tiannahsplacempire Àkọlé àwòrán, Ọkan tún rèé ẹ gbà yí yẹ̀wò Àkọlé àwòrán, Tiwa Savage lásìkò tó ń gba àmi ẹyẹ MTV Àkọlé àwòrán, Guguru ní wọn fi ṣe aṣọ yìí, o rẹwa púpọ̀ Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Ṣugbọn, ọga agba to n mojuto iṣẹ akanṣe naa, Ogbeni Popoọla ṣalaye pe didun lọsan atunṣe naa yoo so fawọn olugbe ipinlẹ Eko.
Kí ló dé tí àwọn akọni yín kò lè dúró?
Gbogbo nǹkan ní ń kó àárẹ̀ bá eniyan, ju bí ẹnu ti lè sọ lọ.
"Oríṣun àwòrán, @DavidOyedepoMin Oyedepo ni ""Akoko to buru ju ninu itan orilẹ-ede yii ni ọdun marun un ṣẹyin, ti wọn n pa eeyan ni ipakupa."
A óo máa pèsè burẹdi ìfihàn ati ẹbọ ohun jíjẹ ìgbà gbogbo, ẹbọ sísun ìgbà gbogbo, ẹbọ ọjọ́ ìsinmi, ati ti oṣù tuntun fún àwọn àsè tí wọ́n ti là sílẹ̀, ati fún gbogbo ohun mímọ́, fún ẹbọ ìmúkúrò ẹ̀ṣẹ̀ láti mú ẹ̀ṣẹ̀ Israẹli kúrò, ati fún gbogbo iṣẹ́ ilé Ọlọrun wa.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ajibade Babalade: Àwọn ọmọ Naijiria ṣèdárò gbajúgbajù agbábọ́ọ̀lù Super Eagles tó dolóògbè 5 Owewe 2020 Oríṣun àwòrán, Others Awọn ọmọ Naijiria ti n ṣedaro gbajugbaja agbabọọlu Naijiria, Ajibade Babalade to se alaisi ni ẹni ọdun mejidinlaadọta.
Bakan naa ni adari ajọ naa tuntun ti wọn ba yan yoo ni lati pẹtu saawọ idokowo laarin Amerika ati China.
Akeredolu ninu atẹjade to fi lede sọ wi pe adura nikan lo le sẹgun eto aabo to mẹhẹ lorilẹede Naijiria, eleyii ti o ti jasi iku awọn ẹlomiran ni awujọ.
Wọn fura si wi pe o wa lara owo ti ọgagun Sani Abacha ji laarin ọdun 1993 si 1998 Aare Muhammadu Buhari mu gbigba owo yi pada gẹgẹ bi koko ileri rẹ lasiko ipolongo ibo lọdun 2015 Ile isẹ eto idajọ, Banki agbaye ati orileede Switzerland fi ọpọ asiko jiroro lati se agbekalẹ eto fun dida owo naa pada fun orileede Naijiria Ijọba orileede Switzerland ti da ẹ̀ẹ́dẹ̀gbẹ̀rin milionu dollar pada ninu owo naa laarin ọdun mẹwa sẹyin Milionu ọ́ọ́dúnrún le méjilelogun dollar ($320million) ni owo to sẹku ti wọn da pada Kini owo naa le se fun ara ilu.
Lakotan, Kabiyesi Uba ni oun n gbero lati pe awọn gbajugbaja oṣere tiata wa si ilẹ Uba, lati le wa dokoowo ki awọn araalu si jẹ anfaani rẹ.
Joṣua dá wọn lóhùn pé, “Ẹ yí òkúta ńláńlá dí ẹnu ihò náà kí ẹ sì fi àwọn eniyan sibẹ, láti máa ṣọ́ wọn.
O ni agbegbe naa wu awọn baba nla wọn ni wọn fi tẹdo sii.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Irinajo Libya: Ọmọ Naijiria mọ́kàndínláàdọ́jọ pada sile 23 Ẹrẹ̀nà 2018 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ọmọ Naijiria mọ́kàndínláàdọ́jọ pada sile lati Libya Ile-iṣẹ to n risi iṣẹlẹ pajawiri ni orile-ede Naijiria (Nema) ti tẹwọ gbamọ orilẹede Naijiria arinrinajo mọ́kàndínláàdọ́jọ lẹyin ti wọn ronu lati pada wa sile lati orilẹede Libya.
Wọ́n wọ aṣọ ọ̀gbọ̀ onílà tẹ́ẹ́rẹ́tẹ́ẹ́rẹ́, wọ́n ń fi ìlù, hapu ati dùùrù kọrin; pẹlu ọgọfa alufaa tí wọ́n ń fi fèrè kọrin, 
bí ẹ bá ń fi adura yín ràn wá lọ́wọ́.
"Ọrọ yii si ni wọn fi maa n sa obinrin naa pe ""Ṣe bo ti mọ, Ẹlẹwa Ṣapọn""."
Ìjọba wá rọ àwọn ọmọ Nàìjíríà láti nigbagbọ nínú ìjọba, nítorí owoya náà ní wọn yóò lo fún àwọn àkànṣe isẹ tó yẹ fún.
Gege bi agbenusoro fun ile ise ohun, ogbeni Sunday James so pe, won mu asofin Melaye gege bi ase lati enu awon torokan gbangban.
Bakan naa ni ọgọọrọ eniyan ni ilu Abuja parapọ lati se ifẹhọnu han pe ki ijọba orilẹede Naijiria ri wi pe wọn gba itusilẹ Leah Sharibu ni kiakia.
Ninu ibinu ati ìrúnú mi, n óo gbẹ̀san lára àwọn orílẹ̀-èdè tí wọn kò pa àṣẹ mi mọ́.
Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Fídíò, Natalia Mufutau ìyá Yakub, Kamil àti Adam sọ̀rọ̀ lórí bí wọ́n ń sọ èdè mẹ́rin pàpọ31 Ògún 2020 Fídíò, Wole Soyinka sọ ìdí tó fi ni òun a fi màálù Fulani ṣe súyà fáwọn èèyàn abúlé23 Owewe 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Ní ọjọ́ kan, Dafidi bèèrè pé, “Ǹjẹ́ ẹnikẹ́ni kù ninu gbogbo ìdílé Saulu tí mo lè ṣoore fún nítorí Jonatani?
O ni idi ti awon se dawo ise duro fun igba die ni lati se atunse si awon oju irin to nilo atunse.
Ó máa ń jẹ́ kí eré tó ṣáájú ìbálòpọ̀ ni mí lára, ó mí kanlẹ̀.
Lórí gbogbo ìwọ̀nyí, èmi, Ìrìnkèrindò, tí o di ọkọ Ìfẹ́pàtàkì lónìí, bẹ gbogbo yín, kí ẹ bá mi gbádùrà pé ẹrù ńlá tí mó tẹ́ orí gbà lónìí, kí Olódùmarè bá mi gbé e; kí Ọlọ́run bá mig bé e; kí Ẹlẹ́dàá mi bá mi gbé e, kí ọba Àìkú bá mi gbé e, kí ọba Àìrí bá mi gbé e, kí ọlọ́jọ́ òní bá mi gbé e, kí ọba Alèwílèṣe bá mi gbé è, kí Alákòóso ayé àti Alákòóso ọ̀run bá mi gbé e, kí àwọn ogun ọ̀run sì máa bá mi gbé e titi láéláé.
Ajọ naa lo n ṣewadi ẹsun ifipabanilopọ mi i ti wọn fi kan aarẹ nigba kan ri ọhun.
” Aare tun tesiwaju pe, gbogbo ohun elo idibo loti wa nile ni se
Ẹ̀yin ẹ wo ọjà kan ní Lọndọn tí àwọn èèyàn wá ń ná (àwọn àwòrán nísàlè)
Adari ẹka ẹgbẹ Agbẹkọya Peace Movement naa to ni awọn ko lee da nkankan se lai si iranwọ ijọba, wa parọwa si ijọba lati pe ipade gbogboogbo ti awọn adari ijọba ibilẹ, gomina yoo kopa ninu rẹ, ti awọn yoo fi le lo ọgbọn inu awọn lati fi ran ijọba lọwọ.
Ṣugbọn agbẹjọro fun Olubadan, Adeniyi Adewọle,sọ pe gomina ko lágbara lati s'epade pẹlu awọn ọba alaye.
Iyawo mẹta ni Oloogbe Shehu Shagari fẹ: Amina, Aishatu ati Hadiza Shagari.
O ni ti irufẹ ẹni bẹẹ ko ba dẹkun aawẹ naa nigba ti gbogbo eroja ara ko ba le gba mọ, o ṣeeṣe ki ẹmi bọ lara iru ẹni bẹẹ lairo tẹlẹ.
Nítorí ní àkókò náà, kí ìkún-omi tó dé, ńṣe ni wọ́n ń jẹ, tí wọn ń mu, wọ́n ń gbé iyawo, wọ́n ń fi ọmọ fọ́kọ, títí ó fi di ọjọ́ tí Noa wọ inú ọkọ̀.
Baba Suwe: Ilé iṣẹ́ aṣọ́bodè kò fún bàbá mi ní kọ́bọ̀, igbákejì Ààrẹ kàn tọrọ àforíjìn ni
Ta ló gbọ́ irú èyí rí?
Amọ ṣa ki o to le jẹ awọn anfani wọn yi, awọn nkankan wa ti o gbọdo ṣe.
Iroyin so pe, O ku si enu ise re lojo Aje(Monday).
O ní kóda kó ṣe fíìmú àgbéléwo, irú rẹ̀ kò le wáyé, ko si si ààyè l'ágàbá SDM.
Ìsẹ̀lẹ̀ jákèjádò orílẹ̀èdè àgbáyé láàárín ìṣẹ́jú kan
Eyi ni idije kẹta sẹyin ti ẹgbẹ agbaọọlu Arsenal ti fidirẹmi sẹyin ni eyi ti akọnimọọgba wọn ni o fihan pe iṣẹ pọ niwaju wọn lati ṣe ni.
" pẹ ̀ lú ìrírí àti ẹ ̀ kọ ́ tó kọ ́ ní "" london ' àti "" germany ' ó di ọmọ ẹgbẹ ́ tí a mọ ̀ sí "" overseas broadcasters ' association ' ."
Ṣugbọn lawọn ileewe kan, niṣe lawọn akẹkọọ tu yahaya tu yahaya wọle pada sile iwe.
BBC Yorùbá fẹsẹ̀ kan débẹ̀, tó sì sọ fún wa pé isẹ́ Onímọ̀ ẹ̀rọ ni òun fẹ́ se.
Asuba (ati Jeriotu) ni aya Kalebu yìí, Asuba bí ọmọkunrin mẹta fún un: Jeseri, Ṣobabu, ati Aridoni.
Fún ẹbọ àgbò, yóo wá ìdámárùn-ún òṣùnwọ̀n efa ìyẹ̀fun kíkúnná tí a fi ìdámẹ́ta òṣùnwọ̀n hini òróró kan pò wá, 
Kí wọ́n kó wọn lẹ́rúkí wọ́n tẹ̀ wọ́n mọ́lẹ̀ bíi ẹrọ̀fọ̀tí à ń tẹ̀ mọ́lẹ̀ níta gbangba.
Ibi tí wọ́n sì kó ẹ̀bùn sí tóbi ju Gbọ̀ngàn-ìṣeré-òmìnira ti ìlú Ìbàdàn lọ.
Ní ọjọ́ kẹwaa oṣù karun-un, ní ọdún kọkandinlogun tí Nebukadinesari ọba Babiloni jọba, Nebusaradani, olórí àwọn tí ń ṣọ́ ọba Babiloni, wọ ìlú Jerusalẹmu.
Ó fi ìṣẹ́gun ńlá fún ọba rẹ̀,ó sì fi ìfẹ́ rẹ̀ tí kì í yẹ̀ han ẹni àmì òróró rẹ̀,àní Dafidi ati ìrandíran rẹ̀ títí lae.
Mo ti sọ fun yín láti ọjọ́ pípẹ́:kí wọn tó ṣẹlẹ̀, mo ti kéde wọn fun yín,kí ẹ má baà sọ pé, ‘oriṣa wa ni ó ṣe wọ́n,àwọn ère wa ni ó pàṣẹ pé kí wọn ṣẹlẹ̀.
"willard carroll "" will "" smith jr ."
Ibo Sierra Leone: Awọn alabojuto ibo pinu ibo to yanranti
 Die lara awon to fakoyo ninu idije naa ni Fahd Moubeti, Danladi Ibrahim, Ayiah- Toku ati Arhin.
 awon aralu to po ni be je igbo ( 95 % awon onibugbe ) .
A mú ìmọ́lẹ̀ kúrò lọ́dọ̀ àwọn ẹni ibi,a sì ká wọn lápá kò.
Ní ọjọ́ kẹta a dé Puteoli.
Atamatase iko agbaboolu Barcelona, Lionel Messi se gudugudu meje ohun yaya mefa lati ran iko re lowo sipele ti o kan ninu idije UEFA Champions League to n lo lowo.
Ọ̀pọ̀lọpọ̀ mọ̀ ọ́ sí Ronke Oshodi Oke.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ètò ìsìnkú Abba Kyari tako ìlànà ìjìnàsíraẹni lórí ààrùn covid-19- Àwọn ọmọ Nàìjíríà yarí Bakan naa ni ijọba FCTA ti lọ fin kokoro apako ati apa kokoro aifojuri kaakiri itẹ oku to wa ni agbegbe Gudu nilu Abuja lati dẹkun itankalẹ arun coronavirus.
ECOWAS: Orílẹ̀èdè 15 tó wà nínú àjọ ECOWAS yóò bẹ̀rẹ̀ sí níì ná owó kan nàá l'ọ́dún 2020
Wọn ni ko si ẹni ti ko ni ku, ọba Eshinlokun waja, ti ọmọ rẹ, Idewu Ojulari si rọpo rẹ, amọ oun naa ko pẹ lori itẹ, to fi darapọ mọ awọn baba nla rẹ.
Bi iye awọn eeyan to ṣẹṣẹ ko arun naa nipinlẹ kọọkan ni Naijiria ṣe lọ ree: Lagos-713 Plateau-273 FCT-199 Kaduna-117 Oyo-79 Enugu-58 Ondo-53 Kano-49 Sokoto-43 Ogun-37 Osun-37 Nasarawa-36 Rivers-28 Benue-24 Delta-24 Niger-24 Gombe-18 Edo-15 Taraba-12 Bayelsa-10 Ekiti-9 Borno-6 Zamfara-2 Jigawa- 1 Eeyan 107,345 lo ti larun covid-19 lapapọ kaakiri orilẹede Naijiria bayii, eeyan 84,535 lo ti ri iwosan nigba ti ti 1,413 ti ba arun coronavirus lọ.
”Ogbeni Kator Hule to je oludari egbe YET-P ni won ti rii pea won obinrin lo po julo ninu agbe ni Naijiria sugbon won ko ri ona taara si awon ohun ti won nilo fun idagbasoke won lenu eto ogbin.
Mẹ̀kúnnù tí ó ní iṣẹ́, tí ó tún gba ọmọ-ọ̀dọ̀ó sàn ju ẹni tí ó ń ṣe bí eniyan pataki, ṣugbọn tí kò rí oúnjẹ jẹ lọ.
Nígbà tí ìfẹ́kúfẹ̀ẹ́ bá lóyún, á bí ẹ̀ṣẹ̀; nígbà tí ẹ̀ṣẹ̀ bá gbilẹ̀ tán á bí ikú.
 a le lo àjẹsára náà láti ṣàkóso ìtànkiri àrùn náà .
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Human traffiking: Òyìnbó kòráà, amòfin kan wọ gbaga òfin fún títa obìnrin kan sóko ẹrú 10 Sẹ́rẹ́ 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 12 Sẹ́rẹ́ 2020 Oríṣun àwòrán, Omolola Ajayi Àkọlé àwòrán, Òyìnbó kòráà, amòfin kan wọ gbaga òfin fún títa obìnrin kan sóko ẹrú Ọwọ ofin ti tẹ ọmọ orilẹede Lẹbanon kan torukọ rẹ jẹ Wasit Muhammad pẹlu awọn eeyan meji miran ti wọn lo lọwọ ninu tita arabinrin kan, torukọ rẹ n jẹ Ọmọlọla Ajayi si oko ẹru ni orilẹede Lebanon.
Àwọn ìlú tí ó run jẹ́ ogún.
Nígbà tí Dafidi ati àwọn ọkunrin rẹ̀ pada dé Sikilagi ní ọjọ́ kẹta, wọ́n rí i pé àwọn ará Amaleki ti gbógun ti Nẹgẹbu ati Sikilagi, wọ́n ṣẹgun Sikilagi, wọ́n sì sun ìlú náà níná; 
Olori ile asofin kekere nilẹ Amẹrika, Nancy Pelosi si ti rinrin ajo lọ si orilẹede Ghana fun ayẹyẹ irinajo irinwo ọdun ti awọn ẹru akọkọ to jẹ adulawọ gunlẹ si orilẹede Amẹrika.
O ni: “Aare tii pase fawon omo ogun atawon osise eleto aabo gbogbo lati morile ile iwe Government Girls Technical College, Dapchi, nipinle Yobe ki won si maa fun oun nifitonileti to ye lasiko.
Dasofunjo ni ibanujẹ ọkan lo jẹ fun oun nigba ti oun gbọ nipa iku ọrẹ oun yii, nitori ko dagba debi to yẹ ko ku lasiko yii.
Irọ́ ni ò, kìí ṣe àwọn afẹ̀họ́núhàn EndSars ló tú àwọn ẹlẹ́wọ̀n sílẹ̀ ní Benin- Oby Ezekwezili Ọpọlọpọ awọn ọmọ Naijiria lo ti bẹrẹ si ni fi ero wọn han lori bi awọn ẹlẹwọn ṣe tu jade kuro ni ọgba ẹwọn to wa ni ilu Benin.
Gbogbo àwọn opó bá yí i ká, wọ́n ń sunkún, wọ́n ń fi àwọn ẹ̀wù ati aṣọ tí Dọkasi máa ń rán fún wọn nígbà tí ó wà láàyè han Peteru.
"Oju n ti mi, maa duro lati ki awọn miran ninu wọn gan-ko tilẹ rọrun lati ba wọn jiroro nitori pupọ ninu wọn lo jẹ pe ati abule ni wọn ti wa lai ni imọ ẹkọ kankan.
Ibrahim ni awọn ko fẹ ki wọn sọ ẹsọ alaabo Amotekun di ẹgbẹ ọmọbibi ilẹ Oodua, OPC, o si yẹ ki wọn gba awọn ọmọ ẹgbẹ Miyetti Allah sinu ikọ Amọtẹkun naa, ko lee fidi mulẹ bo se yẹ.
Ṣugbọn nígbà tí àwọn ẹran tí kò lókun ninu tóbẹ́ẹ̀ bá ń gùn, kì í fi àwọn ọ̀pá náà siwaju wọn, báyìí ni àwọn ẹran tí kò lókun ninu di ti Labani, àwọn tí wọ́n lókun ninu sì di ti Jakọbu.
Faisiti agbelegboye ti orilẹede Naijiria, National Open University lo si lọ lati lọ kọ nipa eto alaafia ati ipẹtu si aawọ Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Lẹyin ọsẹ diẹ ni awọn ọga ile iwe naa pe Miche si inu oọfisi ọga ile iwe naa ti wọn si sọ fun un wi pe nise ni wọn ji i gbe ni ọmọ ọwọ ni ile Iwosan ti wọn ti bii, Groote Schuur ni Cape Town.
Aare Buhari, ti o wa ni irinajo ọlọjọ kan lọ si ilu Eko ti o jẹ olu-ilu eto ọrọ aje ati eto okoowo  lorile ede Naijiria, ni yoo tun pada wa si ilu Abuja lọjọ kan naa lati lọ se ifilọlẹ awon ise akanse  ti ijoba ilu Eko ti gbe se.
Ẹ kò lè dá ohunkohun ṣe lẹ́yìn mi.
Ọlọrun, olùpèsè ibùjókòó fún àlejò tí ó nìkan wà;ẹni tí ó kó àwọn ẹlẹ́wọ̀n jáde sinu ìdẹ̀ra,ṣugbọn ó sì fi àwọn ọlọ̀tẹ̀ sílẹ̀ ninu ilẹ̀ gbígbẹ.
Nígbà tí Solomoni tají, ó rí i pé àlá ni òun ń lá, ó bá lọ sí Jerusalẹmu, ó lọ siwaju Àpótí Ẹ̀rí OLUWA, ó sì rú ẹbọ sísun ati ẹbọ alaafia sí OLUWA.
Tinubu naa dupo gomina ipinlẹ Eko fun saa keji lọdun naa labẹ asia ẹgbẹ oṣelu AD ninu eyi to ti jawe olubori.
Daniẹli dá ọba lóhùn, ó ní, “Jẹ́ kí ẹ̀bùn rẹ máa gbé ọwọ́ rẹ, kí o sì fi ọrẹ rẹ fún ẹlòmíràn.
Gbọ́nmi sí I, omi ò tó o .
Rohr so eyi di mimo fun awon akoroyin ni ipago iko ohun ni Essentuki.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ayédèrú Jẹẹsí Nàìjíríà ń tà wàràwàrà lọ́jà Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Super eagles fi ijó bẹ́ẹ lẹ́yìn tí wọ́n ta òmì pẹ̀lú Uganda Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Bẹ́ẹ̀ ni ọkùnrin yìí padà wá sí ilé pẹ̀lú ẹ̀bùn ńlá yìí tí ó sì ń bá ìyókù ìgbésí ayé rẹ̀ lọ láì fi ìdí àṣírí náà han ẹnikẹ́ni.
Kì í ṣe pé ìwà wa ni ó dára tóbẹ́ẹ̀ tí ó fi pè wá.
Ilé rẹ̀ fẹ̀gbẹ́kẹ̀gbẹ́ pẹlu ilé ìpàdé àwọn Juu.
Soworẹ ni ki awọn ọmọ Naijiria ma gbaradi nitori ijọba pasan ni wọn dibo fun ti gbogbo wọn yoo si ni ipin ninu rẹ.
Omo odun metalelogun naa je akekoo isegun oyinbo ni fasiti Cape Town.
gbagbe pe akasọ igbimo Olubadan ni oun naa tọ ko to de ipo Olubadan to wa lonii,
Katsina United 16:00Rivers United FC ?
Ní ọjọ́ kan, àwọn mejeeji ń bá ara wọn jà ninu pápá, kò sì sí ẹnikẹ́ni nítòsí láti là wọ́n, ni ọ̀kan ninu wọn bá lu ekeji rẹ̀ pa.
 Minista tun tesiaju pe“ E je ki eleyii wa ninu akosile pe, nigba ti  won yan wa sipo egbe JOHESU so fun wa pe awon ni adehun pelu ijoba apapo, sugbon ohun ti a ri ni pe ko si adehun Kankan laarin awon ati ijoba apapo”.
eO ni: “Irin ajo afe ti yato si ti tele, o ti di ohun to n mu owo goboi wole kaakiri agbaye, Lati 2006 nise ti bere lori nini akosile to ye lori awon ibudo irin ajo afe Naijiria, idi niyi ti a se gba iranlowo eka irinajo afe ninu ajo isokan agbaye ki o le yori si rere.
Ẹnikẹ́ni tí ó bá fara kan irú nǹkan bẹ́ẹ̀, tabi irú ẹni bẹ́ẹ̀, yóo jẹ́ aláìmọ́ títí di ìrọ̀lẹ́; kò sì ní jẹ ninu àwọn ohun mímọ́ náà títí tí yóo fi wẹ̀.
Awọn akẹkọ, paapa julọ awọn ti wọn ma n kọ idanwo igbaniwole sile Ẹkọ fasiti eleyi ti ajọ eleto idanwo Jamb n dari,a maa ke irora bi idanwo naa ṣe le si ti awọn miran a si ma ni ibẹrubojo ọkan.
O sọ isepataki sisan owo ọun ninu eto kan ti ajọ to n samujo awọn aririnajo lọ silẹ mimọ gbe kalẹ fun awọn ti wọn n gbero lati rinrinajo lọdun yii.
Àwọn tí oro naa soju wọn sọ pé àwon mẹ́rin ni ile naa wolu lásìkò tí wọn ń gbìyànjú láti ṣe àwo pale rẹ.
Mo sì máa ń ṣe àkíyèsí gbogbo oun tí ń lọ ní àyíká mi.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, EndSARS protest in Nigeria: Mr Macaroni, Falz, Wizkid, Tiwa Savage àtàwọn míì ṣe ìwọde Adari ijọ naa ni: ''Ni asiko yii, awọn eniyan ti gbọnju ti wọn si mọ ọna lati ja fun ẹtọ wọn ni ọna igbalode lorilẹede Naijiria.
AFCON 2019: Ìjà ẹlẹyẹ méjì láàrin Nàìjíríà àti Tunisia Ẹgbẹ agbabọọlu Naijiria ati ti orilẹede Tunisia yoo jọ ta kanungbọn lalẹ Ọjọru lati ja fun ipo kẹta ninu idije AFCON 2019 lorilẹede Egypt.
“Meṣeki ati Tubali wà níbẹ̀ pẹlu ogunlọ́gọ̀ àwọn eniyan wọn.
Nípa igbagbọ ni a fi mú Enọku kúrò ní ayé láìjẹ́ pé ó kú.
Inú àgọ́ rẹ̀ ṣókùnkùn,a sì ti pa àtùpà ìgbèrí rẹ̀.
kódà ki wọ́n fi àlà mítà àádọ́ta jìnà sírawọn, ìsun téré tó n kan ẹnìkọ̀ọ̀kan tó láti jẹ́ kí wọ́n ni ààrùn naa, nítorí naa bi a ṣe n padà sẹ́nu iṣẹ́ àwọn ilé iṣẹ́ kan yóò ní láti ṣe àtúnṣe Àwọn ọ́fíìsì ti kò ní ibi tí atẹ́gùn le gbà wọlé léwu gidigidi, Bromage ṣàpèjúwe pé ìdá mẹ́rìnleláàọ́run ninu òjìlénígba o dín mẹ́rin ọ́fíìsì ló ni ààrùn Coronavirus ni orílè èdè South Korea, ọ̀pọ̀ sì jẹ́ àwọn to wà nínú ọ́fíìsì kàn náà tó tẹ́ gbayawu ṣùgbọ́n tí àtẹ̀gùn rẹ̀ kò to ǹkan."
 nígbà èwe rẹ ̀ , ó ma ń yọ ́ kúrò nílé láti lọ wo ìran ọdún ìbílẹ ̀ yorùbá .
Election 2019 Updates: Atiku ní ìbò 18m ni mo ní, Buhari sì ní ìbò 16.
O gbọdọ gba Islam ni akata Boko Haram ki wọn to le fẹ ọ ni iyawo.
Igba to pada de si orilẹede Naijiria ni 1950, o ṣiṣẹ pẹlu ileeṣẹ to n pawo wọle fun ijọba, Inland Revenue titi di ọdun 1952.
Ṣugbọn wọn fidirẹmulẹ pe o jẹbi, wọn si dajọ ẹwọn ọdun mẹfa fun, botilẹjẹpe wọn yii pada si owo itanran.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Rwanda Sex: Wo bí àwọn obìnrin yìí ṣe máa ń gbáradì ojú abẹ́ wọn fún ìbálòpọ̀ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Rwanda Sex: Wo bí àwọn obìnrin yìí ṣe máa ń gbáradì ojú abẹ́ wọn fún ìbálòpọ̀ 12 Agẹmo 2020 Ni orilẹede Rwanda, wọn maa n ṣe igbelarugẹ ibadọgba akọ ati abo ninu ọpọlọpọ nkan bii oṣelu, eto ẹkọ atawọn ọrọ to kan araalu.
Nígbà náà, àwa eniyan rẹ,àní, àwa agbo aguntan pápá rẹ,yóo máa dúpẹ́ lọ́wọ́ rẹ títí lae;a óo sì máa sọ̀rọ̀ ìyìn rẹ láti ìran dé ìran.
#NotTooYoungtoRun: Gbájú-ẹ̀ ni Saraki lò fún wa
Baana, ọmọ Huṣai, ni alákòóso agbègbè Aṣeri, ati Bealoti.
Pupọ ninu wọn ni o n kabamọ lilọ si ilẹ naa nibi ti iroyin ti ni awọn kan ti n lo wọn nilo ẹru.
Ìtàn ìgbé ayé Abdulrahman Abdulrazak, gómìnà Kwara Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
 abúlé kòòkan ni ó sì ní baálè tirè , àwon alálè ni wón sì máa ń bo bíi olórun ti won .
Àwa meji péré ni a wà ninu ilé, kò sí ẹnìkẹta pẹlu wa.
Ọ̀daràn tó wà lẹ́wọ̀n tún wọ́'ke $100miílíọnu - EFCC Nínú kó o fi omi fọ ìdi tàbí lo tííṣù fi fá a, Èwo ló rọrùn?
Saraki di gomina ipinlẹ Kwara labẹ ẹgbẹ oṣelu PDP ni ọdun 2003, lẹyin ti o koju ajagun-fẹhinti Mohammed Lawal ninu idibo gomina lọdun naa, to si fi ẹyin Lawal janlẹ siyalẹnu àwọn eniyan.
Ninu ọrọ rẹ, aṣofin to gbe aba naa silẹ, Ọgbẹni Sarki ni iwadii fihan pe aarun arunmọleegun ti wa nilẹ Afirika fun bi ẹgbẹrun un mejila ọdun, eleyi ti ilẹ Adulawọ ko si tii ṣe nnkan gbogi lati dẹkun rẹ.
Nínú àtẹjáde kan ti àwọn aláṣẹ ìrìnà ọkọ̀ òfurufú (NCAA) fi sójú òpó twitter rẹ̀, ló ti sàfihan ìlànà ìrìnà tuntun ti wọ́n fẹ́ gùnlé.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù TSAIGUMI, ọmọ tuntun ileesẹ ọmọogun ofurufu Naijiria 16 Èrèlè 2018 Oríṣun àwòrán, @NigAirForce Àkọlé àwòrán, TSAIGUMI, idagbasoke ọtun ni ẹka ijagun ofurufu ni Naijiria Ni ọjọọbọ ọjọ kẹẹdogun osu keji ọdun 2018 ni aarẹ orilẹede Naijiria, Muhammadu Buhari si asọ loju baluu adanikan fo ti ileesẹ ọmọogun ofurufu orilẹede Naijiria ti wọn da orukọ rẹ pe ni Tsaigumi.
Bẹ́ẹ̀ ni Ọlọrun ṣe parí dídá ọ̀run ati ayé, ati gbogbo ohun tí ó wà ninu wọn.
Toyin Abrahams to gba ami ẹyẹ oṣere to gbamuṣe julọ lobinrin lagbo ere tiata nibi ami ẹyẹ AMVCA laipẹ yii tun fi fidio ilanilọyẹ kan lori bi a ṣe lee tọju imọtoto ara ẹni lasiko yii.
Ṣugbọn Jakọbu dáhùn pé, “Rárá o, jọ̀wọ́, bí mo bá bá ojurere rẹ pàdé nítòótọ́ gba ẹ̀bùn tí mo mú wá lọ́wọ́ mi, nítorí pé rírí tí mo rí ojú rẹ tí inú rẹ sì yọ́ sí mi tó báyìí, ó dàbí ìgbà tí mo rí ojú Ọlọrun.
Police Brutality: A yìnbọn lu Precious láti dáa dúró ni, akò mọ̀ pé o máa kú- Ọlọ́pàá Oríṣun àwòrán, others Ileeṣẹ Ọlọpaa ti ni lootọ ni awọn yinbọn fun ọmọ Naijiria ti orukọ rẹ n jẹ Precious ni agbegbe Gomoa Buduburam ni orilẹ-ede Ghana.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù L'Ọ́ṣun, àwọ̀n oníròyìn meji di tíṣà ọ̀sán gangan 15 Ìgbé 2018 Oríṣun àwòrán, Niyi Folorunso Àkọlé àwòrán, Àwọn oníròyìn náà kún ara ọ̀ọ́dúnrún òṣìṣẹ́ tí ìjọba dá padà sí kíláàsì Àwọn oníròyín méjì ni ìròyìn ti fihàn pé wọ́n wà nínú nǹkan bíi ọ̀ọ́dúnrún àwọn òṣìṣẹ́ ìjọba ìpínlẹ̀ Ọ̀ṣun tí wọ́n gbé lọ káàkiri àwọn iléèwé nípínlẹ̀ náà báyìí.
Oga agba fun ile-ise omo ogun oju ofurufu, Sadiq Abubakar ti sabewo sile-eko igbaradi ati ile iwosan iko omo ogun oju ofurufu ohun(403 Flying Training School (403 FTS)ati 465 Nigerian Air Force Hospital (465 NAFH), ti o wa nipinle Kano, eka ila oorun orile-ede Naijiria.
Kí ni àìsàn ìtọ̀ ṣúgà àti ọ̀nà tí o leè gbà dènà rẹ̀?
Agbẹnusọ fun ileeṣe ọlọpaa Abimbola Oyeyemi ṣalaye pe awọn ẹbi awọn mẹrin naa ko san kọbọ fawọn ajinigbe ọun.
Maa da idọti ile rẹ nu kiakia sinu àgbá ilẹ to ba ni ideri.
OLUWA ni ààbò ẹ̀mí mi,ẹ̀rù ta ni yóo bà mí?
Jesu Wẹ Ẹsẹ̀ Àwọn Ọmọ-ẹ̀yìn Rẹ̀.
 Ìgbàgbọ ́ nínú ohun tí jésù jẹ ́ tàbí tí ó ṣe nígbà ayé rè lọ ́ bí ìlànà tàbí èkó tí ìjo kọ ̀ ọ ̀ kan ń té lè ninu ẹ ̀ sín ìgbàgbó .
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Zainab Aliyu: A kò mọ́ pé wọ́n kẹ́ òògùn olóró sí àbúrò mi l'ọ́rùn- Hajara Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Zainab Aliyu: A kò mọ́ pé wọ́n kẹ́ òògùn olóró sí àbúrò mi l'ọ́rùn- Hajara 1 Èbibi 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 2 Èbibi 2019 Lẹyin ti iroyin jade pe wọn ti fi Zainab Aliyu si ẹwọn ni Saudi Arabia, ni awọn kan bẹ̀rẹ̀ iwọde ati ipolongo pe ki wọn o tu u silẹ.
Àkọlé àwòrán, Fayẹmi ko dahun ibeere awọn oniroyin nibi abẹwo naa.
isoro eto aaboMinisita fun oro abele , Abdulrahman Dambazau so pe ijọba n mu ohun amayederun lokunkundun,lati fi koju isoro airise ati eto aabo lorilẹ ede  Naijiria.
 Bio tile jepe, opo lo so pe, Ma a ma beru, sugbon mo ri ija ohun pelu oju miran pe, A o jo waako ninu ifigagbaga ohun ni.
A óò bẹ̀rẹ̀ sí san 30,000 owó oṣù òṣìṣẹ́ tó kéré jù lóṣù yìí- Fayemi Adekanmbi tẹsiwaju pe, o ti wa ni akọsilẹ pe Ajimọbi gbaradi ko to gba akoso ipinlẹ Ọyọ lọdun 2011, to si fi ipilẹ rere lelẹ nipa mimu idagbasoke ba awọn ohun amayedẹrun.
Mo rò pe ó yẹ ki n fi ìyókù di ọ̀la.
Atiku mu akawe bi awọn orileede miran nilẹ Yuroopu ti ṣe ti n ti bode wọn pẹlu ilẹ Gẹẹsi lọna ati kọdi itankalẹ ẹda Covid-19 kan to n ja rainrain ni ibẹ.
lowo awon to ko ipa Pataki lori  aseyori eto
Àmọ́ àwọn ọmọ Naija náà kó díẹ̀ nínú ẹ̀bi o.
Bi ẹ ko ba gbagbe, ọjọ diẹ sẹyin ni wahala bẹ silẹ lagbegbe Iwo Road niluu Ibadan latari iwọde EndSARS ti gomina Seyi Makinde si lọ ṣabẹwo sibẹ.
Ní ọjọ́ kinni, ẹ níláti ní àpèjọ, ẹ kò gbọdọ̀ ṣe iṣẹ́ tí ó bá lágbára.
Ọkan ninu awọn akanda ẹda to se ara ọtọ ni Murphy jẹ, nitori bi Oluwa se fi egungun to rọ bii rọba jinki rẹ.
Ìtàn míràn sọ fún wa pé ọmọ ìyá ni agígírì àti ajíbógun ni ilé-ifẹ ̀ .
9 457625 Orilẹede Bangladesh 7862 4.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù FA CUP FINAL 2020: Lacazette ṣàlàyé ìdí tí Arsenal ṣé gbọ́dọ̀ fìdí Chelsea rẹmi ní àṣekágbá 1 Ògún 2020 Oríṣun àwòrán, Getty Images Idojuti nla ni yoo jẹ ti a ko ba le gba ife ẹyẹ FA Cup tori naa, tọkan tọkan laa fi n reti ifẹsẹwọnsẹ wa pẹlu Chelsea ninu aṣekagba idije FA Cup ti yoo waye loni.
Àwọn àgbààgbà mẹrinlelogun tí wọ́n jókòó lórí ìtẹ́ wọn níwájú Ọlọrun bá dojúbolẹ̀, wọ́n júbà Ọlọrun.
Mose ati Aaroni bá jáde kúrò níwájú Farao, Mose gbadura sí OLUWA pé kí ó mú àwọn ọ̀pọ̀lọ́ náà kúrò, gẹ́gẹ́ bí òun ati Farao ti jọ ṣe àdéhùn.
 Àmọ ́ , ní ọdún 1973 ìjọba ilẹ ̀ nàìjíríà fòté lé wípé kí àwọn akẹ ́ kọ ̀ ọ ́ gboyè ilé ẹ ̀ kọ ́ fásitì àti pólì ilẹ ̀ nàìjíríà ó ma kópa nínú iṣẹ ̀ agùnbánirọ ̀ ní ikẹ ̀ nàìjíríà fún ọdún kan péré .
Alaafin ni inu awọn ọba alaye yoku nilẹ Yoruba ko dun si bi Fayemi se yan ọba kekere gẹgẹ bii alaga igbimọ lọbalọba ati ijoye nipinlẹ Ekiti, to si gbe lori awọn ilana to wa nilẹ́ tẹlẹ Idi ree tawọn ọba alaye naa fi panu wọn mọ, ti wọn si fi ọrọ naa sikun bii agba.
OLUWA sọ fún Aisaya pé, “Lọ bá Ahasi, ìwọ ati Ṣeari Jaṣubu, ọmọ rẹ, ní òpin ibi tí wọ́n fa omi dé ní ọ̀nà àwọn alágbàfọ̀.
Lẹyin naa ni Messi sọ fun Barca pe asiko ti to lati fi ikọ Barca silẹ.
Bí onílé bá ti ń náwó púpọ̀ jù ó yẹ kí àlejò máa múra àtilọ.
Onisegun oyinbo to n se itoju oju nile iwosan ijoba apapo National Hospital nilu Abuja,  Dokita Habibat Daromosu ti salaye kikun lori arun glaucoma to n yo oju lenu lasiko yii pe oun ni arun keji to n fa ifoju ni gbogbo agbanla aye.
Àwọn ará Jabeṣi bá sọ fún Nahaṣi pé, “Jẹ́ kí á jọ dá majẹmu, a óo sì máa sìn ọ́.
Lati igba ti arun Coronavirus ti bẹ silẹ lorilẹ-ede China lọdun 2019, arun naa ti tan de o orilẹ-ede to le lọgọrun un, eyi si ti mu kin wọn wọgile oriṣiriṣi apero ati ipade kaakiri agabye.
Oríṣun àwòrán, OTHER Ṣugbọn awọn miran n ro ninu ọkan wọn pe, agbo to fi ẹyin rin lọ ni ọrọ ẹgbẹ okunkun one million boys yii lee jẹ, o ṣee ṣe ki wọn lọ tun agbara mu wa.
Bakan naa ni ere tiata maa n se agbelarugẹ asa, ise, ede ati idaabo bo awọn ohun adayeba wa, eyi ti ko fi ni parun, ti yoo si tun maa fi isẹlẹ nipa awọn ohun to ti waye saaju kọ awọn iran ode iwoyi atawọn to n bọ.
4 3770 Orilẹede Trinida and Tobago 122 8.
Nítorí náà, ẹ̀yin tí à ń fi ìyà jẹ, ẹ gbọ́ èyí;ẹ̀yin tí ẹ ti yó láì tíì mu ọtí,
“Bí ọkunrin kan bá rí ọmọbinrin kan, tí kì í ṣe àfẹ́sọ́nà ẹnikẹ́ni, tí ó kì í mọ́lẹ̀, tí ó sì bá a lòpọ̀, bí ọwọ́ bá tẹ̀ wọ́n, 
michael clarke duncan ( december 10 , 1957 - september 3 , 2012 ) jẹ ́ òṣèré ará amẹ ́ ríkà .
OLUWA ló ṣe èyí;ó sì jẹ́ ohun ìyanu lójú wa.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù ENDSARS Protest Update: Iyabo Ojo ní ìpolongo tàbí ìbò dídì fáwọn olóṣèlú APC, PDP di eewọ f'óun 26 Ọ̀wàrà 2020 Oríṣun àwòrán, Instagram/iyaboojofespris Awọn oniruuru gbajumọ osere tiata atawọn ilumọọka lawujọ, ni wọn ti n ṣe ipinnu ọtun tori rogbodiyan to waye lasiko iwọde ENDSARS.
O ni Ajimọbi ro pe ti Shittu ba di gomina, oun a ran Ajimobi lọ si ẹwọn ni 'Ó ku Shittu, ó ku Ọlọ́run lórí ohun tó fẹ́ fi san ẹgbẹ́ APC l'ẹ́san' Ilẹ ẹjọ fagilé ìbò ọmọ ẹgbẹ́ APC nípinlẹ̀ Ogun pè kí àtúndì ìbò wà Akitiyan ìjọba láti mú kí àwọn ọmọ Nàìjíríà san owó orí Ronaldo, Messi ẹ yàgò lọnà fagbábọ́ọ̀lù Nàìjíríà tó n gbowò julọ!
O ni titi di igba ti awọn orilẹ-ede to yi Naijiria ka yoo fi tẹle ilana ti ajọ ECOWAS gbe kalẹ lori owo ṣiṣe lati orilẹ-ede kan si omiran.
Agogo tí ó wà ní òkè tí gbogbo ènìyàn máa ń kọ́kọ́ rí nìkan ni wọn kò da ojú rẹ̀ bo ògiri.
Ṣugbọn ṣa, eniyan 12,373 ti ri iwosan, awọn 684 si ti ku.
Nígbà tí a fúnrúgbìn nǹkan ẹ̀mí fun yín, ṣé ó pọ̀jù pé kí á kórè nǹkan ti ara lọ́dọ̀ yín?
Ibẹ̀ ni wọn yóo kọ́ ilé wọn sí, ibẹ̀ ni yóo sì jẹ́ ilẹ̀ mímọ́ fún ibi mímọ́ mi.
04 trn), owoona lori sisan gbese (Debt Servicing N2.
Estonia jẹ orilẹ-ede ti wọn ti goke agba ninu ọna igbalode nipa ṣiṣe gbogbo nkan inu eto ọrọ aje wọn ni eyi ti wọn fi n lo ayelujara pupọ.
Elédùmarè ló rán mi sí gbogbo Ọba Yorùbá - Oluwo Ọjọ́ burúkú, èṣù gbomi mu ní Ṣagamu nígbà tí agbábọ́ọ́lù kan dèrò ọ̀run Ẹ̀ṣẹ́ ju ẹ̀ṣẹ́ lọ!
Yóo gbà ọ́ lọ́wọ́ àwọn ẹlẹ́gàn,o kò ní bẹ̀rù nígbà tí ìparun bá dé.
Jesu ń kọ́ àwọn eniyan lẹ́kọ̀ọ́ ninu ilé ìpàdé kan ní Ọjọ́ Ìsinmi.
Ijọba ni awọn gbe igbesẹ ọhun lẹyin toun ti fikunlukun pẹlu awọn eeyan ati ẹka ti eto ẹkọ gberu.
Ẹnikẹ́ni tí ó bá ń sọ̀rọ̀ ẹnìkejì rẹ̀ níbi,n óo pa á run,n kò sì ní gba alágbèéré ati onigbeeraga láàyè.
Àwọn mẹrin ni ọmọ Isakari: Tola, Pua, Jaṣubu ati Ṣimironi.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Osun Supreme: Àwọn èèyàn Ọṣun rọ Oyetọla láti jẹ́ kí àsìkò rẹ̀ tú aráàlú lára Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Osun Supreme: Àwọn èèyàn Ọṣun rọ Oyetọla láti jẹ́ kí àsìkò rẹ̀ tú aráàlú lára 5 Agẹmo 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 6 Agẹmo 2019 Lẹyin idajọ ileẹjọ to ga julọ nilẹ wa pe, gomina ipinlẹ Ọṣun, Adegboyega Oyetọla ni ojulowo gomina fun ipinlẹ naa, BBC Yoruba fẹsẹ kan de ilu Ẹdẹ ati Osogbo lati gbọ ero awọn araalu nipa isẹlẹ naa.
Ibi ni wọ́n fí ń san oore fún mi,ìkórìíra ni wọ́n sì fi ń san ìfẹ́ tí mo ní sí wọn.
Mexico: Ounjẹ ati papanu ni ẹyin kokoro jẹ lorilẹede Mexico.
Kò sí wàhálà lórí ìkọlù Iran, lákọ ni america wà- Trump Ilé ìwòsàn l'Àbuja ti ya àwọn ìbejì tí wọ́n sọpọ̀ láyà lọ́fẹ̀ẹ́ Gómìnà mẹ́ta àtí ènìyàn 1,242 ló kó sí panpẹ EFCC ni ọdún 2019 Ẹ́ gba fóónù, ẹ pe ẹbí yín pé a fẹ́ dáná ṣun yín - Aráàlú sọ fún adigunjalè méji Ọdun 2019 ni wọn jawe lọ gbele ẹ fun awọn oṣiṣẹ to le ni ẹgbẹrun kan nile iwe naa, leyi to fa ọpọlọpọ awuyewuye.
Bakan náà ni àwọn ọmọ Naijiria ní kóòtu twitter ti bẹ̀rl si ní dájọ bóya ẹni náà jẹbi Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Oríṣun àwòrán, royzkingin / Twitter Se lawọn ọdọ naa da ina igi soju popo naa, ti wsn si gbe apẹ kana, bẹẹ ni wọn fọ irẹsi nu soju titi naa.
Gege bi aare ajo NFF, Amaju Pinnick se so, O ni ipade asale igbami-eye ohun ni lati sajoyo pelu awon agbaboolu Naijria ti o kopa ribiribi, fun gbogbo atileyin won lati mu idagbasoke ba boolu afesegba ni Naijiria.
Ń ṣe ni mo pariwo mọ́ ọn, tí mo ní kó mọ̀ pé òníni ọjọ́ ìsinmi ni àti wí pé àti bàbá àti ìyá wa ni inú wọn kò dùn.
Ọọ̀ni Ifẹ̀ la mọ̀ bíi olórí ọba Yorùbá, kí Aláàfin ya ṣo ewé gbéjẹ́ mọ́wọ́ - Ọ́ba Ekiti fárígá Saaju la ti sọ pe Alawe ti ilu Ilawẹ Ekiti, Ọba Adebanji Ajibade Alabi, Afuntade Kinni, ti ba BBC Yoruba sọrọ lati salaye idi to fi kọ lẹta kan si Gomina ipinlẹ Ọyọ, Seyi Makinde lori ọ̀rọ̀ Alaafin tilu Ọyọ.
”Aare Buhari fi mule pe ise si po ti isejoba re ni lati se bi o ti le je pe a ti pese ipile ti o dara sile lati sise le lori.
Oríṣun àwòrán, others Ilé asofin àgbà tí wá rọ àwọn igbimọ ilé to wà feto ibaraẹnisọrọ, ìmọ̀ sayẹnsi, ẹ̀rọ itakun àgbáyé pẹ̀lú eto ìlera láti ṣe ẹ̀kúnrẹ́rẹ́ ìwádìí lórí ẹ̀rọ alatagba 5G, ká lee mọ àǹfààní àbí àléébù ẹ̀rọ alatagba náà Ẹgbẹ́ àwa dókíta ló ra ìbòmú fúnra wa- Alága NMA Ogun Iye ìgbà tí Sani Abacha tí fi owó ransẹ si Nàìjíríà láti ọrun Wo àwọn bẹbẹ tí Umar Musa Yar'adua ṣe lórí àlééfà Coronavirus: Kíni àwọn àmì tuntun tó n fihàn?
" Ìdí òtítọ ́ rẹ ̀ ni pé èdè ifẹ ̀ "" ilẹ ̀ ẹ ́ fẹ ̀ "" hàn nínú orúkọ tí wọn sọ ìlú náà tí í ṣe ilẹ ̀ ifẹ ̀ tí ó di ilé-ifẹ ̀ ."
 Àkọtọ rómàniù ni wọ ́ n fi ń kọ èdè náà .
Ẹ mọ̀ pé n kò dánu dúró láti sọ ohunkohun fun yín tí yóo ṣe yín ní anfaani; mò ń kọ yín ní gbangba ati ninu ilé yín.
"Imam Ahmad gba ẹgbàwá ọrọ wá pé: Anabi ni: ""Ọlọrun máa ń fi àwọn tó lọ sí Arafa yangàn lójú àwọn tó wà lọrun."
Wọn yóo sì gba ilẹ̀ wọn, ohun tí yóo dé bá wọn nìyí nítorí ìgbéraga wọn, nítorí pé wọ́n ń fi àwọn eniyan èmi OLUWA àwọn ọmọ ogun ṣe yẹ̀yẹ́.
21 Kíyèsíi, èmi ni Jésu Krísti, Ọmọ Ọlọ́run.
Lẹyin eyi, wọn a maa fi okiti tita da awọn eniyan laraya lawọn ile ọti t'ilẹ ba ti ṣu.
Ní ọjọ́ kọkanla ni Pagieli ọmọ Okirani, olórí àwọn ẹ̀yà Aṣeri mú ọrẹ tirẹ̀ wá.
O si wa lara awọn akọṣe iṣẹ BBC News Yoruba ti o fọn rere rẹ kari aye.
" Ó jẹ ́ ọ ̀ gágun nígbà ogun àgbáyé kejí , tí ó jẹ ́ ìkan lára "" Àwọn díẹ ̀ "" ní "" ogun gẹ ̀ ẹ ́ sì "" , tí wọ ́ n ti paálára lójú ogun ."
Nitorinaa ki koowa o tẹle awọn ilana gbogbo to wa fun didena itankalẹ aarun naa.
Super eagles lo kọkọ gba ayo wọle lati ẹsẹ Samson Siasia ki Claudio Canigia to gba goolu meji wọle pada fun Argentina.
Nígbà tí àwọn ọmọ-ẹ̀yìn mẹ́wàá yòókù gbọ́, inú bẹ̀rẹ̀ sí bí wọn sí Jakọbu ati Johanu.
Oríṣun àwòrán, @CAF Àkọlé àwòrán, FIFA ni wọn ko fẹ magomago ni CAF lo n bi ofin ayeraye wọnyii Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Àwọn olólùfẹ́ Arsenal ní kí Emery kọ̀wé fipò sílẹ̀ Eji Gbadero, ọmọ Ibadan àti jayé-jayé ọmọ ónílẹ̀ ti wọn yẹgi fun l'Eko Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí 6:18 Fídíò, Natalia Mufutau ìyá Yakub, Kamil àti Adam sọ̀rọ̀ lórí bí wọ́n ń sọ èdè mẹ́rin pàpọ, Duration 6,1831 Ògún 2020 Fídíò, Yoruba Language: Akomolede ati Asa Yoruba tọ̀sẹ̀ yí rèé lẹ́nu olùkọ́ wa30 Ògún 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Oṣu keje 2018: Igbimọ oluwadii ti ijọba Malta gbe kalẹ ti agbẹjọro kan si dari ni adari ijọba ati iyawo rẹ ko jẹbi ẹsun jẹgudujẹra ti Daphne Caruana Galizia fi kan wọn.
Pasitọ sọ ojuṣe tirẹ gẹgẹ bii ilana ofin Naijiria.
Wọ́n pè é ní “adarí ayérayé tó ga jù”.
Ọpọlọpọ awọn ẹlewọn naa lo tun maa n sọ pe, bi ko ba ṣe awọn ohun ti awọn kọ bi iṣẹ ọwọ ati iwe ninu ọgba ẹwọn, ti awọn ba jade, awọn kò ba pada si ẹnu iwa janduku ni.
Coronavirus in Nigeria: Gómìnà àná ní ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́, Abiọla Ajimọbi ránṣẹ́ ìkíni sí Seyi Makinde lórí àrùn COVID-19 Oríṣun àwòrán, Seyi makinde Ni ọjọ Aje ni gomina ipinlẹ Ọyọ, Onimọẹrọ Ṣeyi Makinde kede pe oun pẹlu ti fara kaasa arun Coronavirus ati pe oun ti fi ara oun si igbele.
" lati igba orundun keta io ( ce ) , ijoba iran gupta samojuto igba ti a mo bi ancient "" igba oniwura india ayeijoun "" ."
Mo pe ẹ̀yin ọmọ ogun Israẹli níjà lónìí, ẹ yan ọkunrin kan, kí ó wá bá mi jà.
Oluwo ni kii ṣe pe o wu ohun lati ma tahun si awọn ọba wọnyii ṣugbọn nigba ti wọn ba ti n tẹ ẹtọ awọn ara ilu mọlẹ nipa tita ilẹ lọna ti ko tọ, ohun ko ni le dakẹ.
OLUWA àwọn ọmọ ogun ti búra, ó ní,“Bí mo ti rò ó bẹ́ẹ̀ ni yóo rí;ohun tí mo pinnu ni yóo sì ṣẹ.
À ń ṣiṣẹ́ pẹlu ọkàn kan; pẹlu ọgbọ́n ati sùúrù, pẹlu inú rere ati ẹ̀bùn Ẹ̀mí Mímọ́, pẹlu ìfẹ́ tí kò lẹ́tàn.
Iko mokanla ti yoo koju SerbiaFrancis Odinaka Uzoho ( GK)Tyronne EbuehiBrian IdowuWilliam Troost-EkongKenneth OmeruoJoel ObiWilfred NdidiOgenyi Onazi ( C)Alex IwobiAhmed MusaVictor Moses.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Florida: Ọ̀ọ̀nì àléègbà dé ba Mary lálejò lọ́gànjọ́ òru Sugbọn Sarafadeen Alli ko yọju sibi ibura naa.
Ọkunrin tabi obinrin kankan kò gbọdọ̀ mú owó tí ó bá gbà ní ibi àgbèrè ṣíṣe wá sinu ilé OLUWA láti san ẹ̀jẹ́kẹ́jẹ̀ẹ́ tí ó bá jẹ́, nítorí pé, àgbèrè ṣíṣe jẹ́ ohun ìríra níwájú OLUWA Ọlọrun yín.
Agbẹnusọ àjọ náà Peter Afunaya tó fìdí ọ̀rọ̀ náà múlẹ̀ sàlàyé pé Abdullahi lo yìnbọ, ọmọ àjọ àwọn sì ni, àti pé àwọn ti ṣetan láti dá sẹríà tó tọ́ fún.
"Lara awọn afurasi miran ti awọn ọlọpaa naa ni awọn n wa ni Alhaja Sekinat, ti wọn n pe ni ""Iyalaje ilu Oyo"" ati Sunkanmi Onikoko ti Ile-Ife."
O ni otitọ ibẹ ni pe nṣe ni okuta iyebiye Dayamọndi naa n pese iṣẹ fun awọn orilẹede okeere ti awọn eeyan orilẹede naa kan joye awakusa lasan.
Ẹ máa súre fún àwọn tí ó ń ṣe inúnibíni yín, kàkà kí ẹ ṣépè, ìre ni kí ẹ máa sú fún wọn.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù 2019 Budget: Ètò àbò, ètò ẹ̀kọ́, gbégbá orókè nínú àbádòfin N8.
Awọn oṣiṣẹ aṣọde ni iwadii ṣi n lọ lọwọ lori iṣẹlẹ naa.
Èyí ni yóo fún ọ láyọ̀, nítorí wọn kò lè san án pada fún ọ.
Ó sọ̀kalẹ̀ lọ sinu odò, ó sì pọnmi.
Fadaka ati wúrà ni ère tiwọn,iṣẹ́ ọwọ́ eniyan ni wọ́n.
Ẹ wo àwọn 'kọ̀ndísàn' tí ìlànà tuntun fún Covid-19 tí Sanwo-Olu kéde fún ìpínlẹ̀ Eko bá de Ọmọ Ọba Dubai yóò san owó ìtọ́jú ọmọ Nàìjíríà tó bí ìbẹrin sí Dubai tí kò sí rówó san Ìjọba àpapọ̀ kéde ọjọ́ tí ìdánwò NECO, NABTEB àti BECE yóò bẹ̀rẹ̀ Iroyin yi jẹ eleyi to dun mọ ọpọ ọmọ Naijiria ninu ti awọn miran si ti bẹrẹ si ni beere pe ṣe Naijiria ti re kọja ewu arun yi ni.
Afihan ifiga-gbaga fun idije ami ẹyẹ agbabọọlu alapẹrẹ to fakọyọ julọ, ikẹfa iru rẹ to waye laarin saa idije bọọlu alapẹrẹ fọdun 1997 si 1998 si wa ninu fọnran akojọ aworan fun akanse eto naa.
Àwọn àgbààgbà ati àwọn eniyan ńláńlá tí wọn ń gbé ìlú náà ṣe bí Jesebẹli ti ní kí wọ́n ṣe ninu ìwé tí ó kọ ranṣẹ sí wọn.
Ṣugbọn bí eniyan bá da omi lé èso náà lórí, tí apákan ninu òkú wọn sì já lé èso náà, ó di aláìmọ́ fun yín.
Ẹ lọ́ra pupọ láti gba ọ̀rọ̀ tí àwọn wolii ti sọ!
Ìgbà tí ó sì jẹ́ pé ọba kò dákẹ́, ìjà tún bẹ̀rẹ̀ lẹ́ẹ̀kẹta, obìnrin yìí tún yí ọba mọ́lẹ̀.
Nítorí náà, ọ̀kan ninu àwọn alufaa tí wọ́n kó wá láti Samaria pada lọ, ó sì ń gbé Bẹtẹli, níbẹ̀ ni ó ti ń kọ́ àwọn eniyan náà bí wọn yóo ṣe máa sin OLUWA.
Kò sí ẹni tí ó ronú wò, tabi tí ó ní ìmọ̀ tabi òye, láti wí pé: “Ìdajì igi yìí ni mo fi dáná tí mo fi se oúnjẹ, tí mo sì fi se ẹran tí mo jẹ.
Ifẹsẹwọnsẹ ọhun gbona girigiri nitori Man City ni lati jawe olubori ki wọn le lanfaani lati gba ife ẹyẹ Premier League Beckham, àgbábọ́ọ́lù tẹ́lẹ̀ rèé tó ń sọ èdè Yorùbá Napoli Vs Arsenal: Àwọn olólùfẹ́ Arsenal ń gara pẹ̀lú àṣeyọrí Europa Omotola Jalade ní Nàìjíríà dàbí ọ̀run àpáàdì lábẹ́ ìjọba Buhari Ẹlẹ́wọ̀n bí ìbejì làǹtì lànti!
Wọ́n jíṣẹ́ fún un pé Balaki ní, “Mo bẹ̀ ọ́, má jẹ́ kí ohunkohun dí ọ lọ́wọ́ láti wá sọ́dọ̀ mi.
Ẹwẹ, awọn naa ni ohun amuyangan lagbaye, Azarenka agbabọọlu ẹlẹyin tẹniisi to ṣoriire ju lorilẹede naa.
"Lara awọn fiimu to ti kopa ninu rẹ ni ""Diamonds are Forever,"" ''Hunter for red'' , ''October'', ''Indiana Jones'' , ''Last Crusader'' ati ''Rock''."
Sugbọn bi Oyenusi se daamu awọn olugbe ipinlẹ Eko to yii, ina papa dilẹ lẹyin asunsunjẹ rẹ naa ni.
0 40 Erekusu Kitts and Nevis 0 0.
Bakan naa, awọn olori ẹsin kristẹni ati musulumi le sọ fun awọn ọmọ lẹyin wọn lati maa dibo fun iru oludije bẹẹ.
O sọ siwaju sii pe, oun yoo dẹkun ati maa lo agbo naa ki oun to poora nitori bi oun ṣe n yọ jo naa ko tẹ oun lọrun.
Ọkan lara awọn osisẹ ibi igbafẹ yii, Stephen Boboly ni oun ti gba ẹmi ọpọ eniyan la ninu okun lati bii ọsẹ mẹta bayii.
Ṣugbọn ẹ kò gbọdọ̀ jẹ àwọn ẹyẹ wọnyi: ẹyẹ idì, igún ati idì tí ń jẹ ẹja, 
Nibi tajọ Unicef ti ni o jẹ ọkan lara awọn agbegbe to lẹwu lati bimọ si lasiko yii.
 kò tún sun inú ihò mọ́;
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Àgbálùmọ̀, ohun mẹ́fà tó ń ṣe lára tí o kò mọ̀ 1 Èrèlè 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 2 Èrèlè 2019 Àkọlé àwòrán, Àgbálùmọ̀ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Àgbálùmọ̀ àti ìwúlò rẹ̀ Bii ti awọn eso miiran ti ẹ mọ, agbalumọ ni ọpọlọpọ nkan to fi n se ara loore.
OLUWA yóo mú gbogbo àrùn kúrò lọ́dọ̀ yín, kò sì ní fi ẹyọ kan ninu gbogbo àwọn àrùn burúkú ilẹ̀ Ijipti, tí ẹ mọ̀, ba yín jà.
Ronkẹ ni oun gbagbọ pe okunrin to lee ṣe awọn ojuṣe ti awọn ọkunrin maa n ṣe laye atijọ ṣọwọn laye ode oni.
Kì í ṣe pé mo pa oore-ọ̀fẹ́ Ọlọrun tì.
A wà ninu oyún, ara ń ro wá,a ní kí a bí, òfo ló jáde.
Adekomi ni ẹgbẹrun lọna mẹtalelọgbọn (33,000) Naira ni igbimọ ti ijọba gbe kalẹ bu ọwọ lu lasiko ipade wọn , ki wọn to lo o gbe e fun ijọba apapọ lati fi ontẹ lu u.
O si wa ni ipo naa di ọdun 1956.
Bi o tilẹ jẹ wi pe ileewe giga fasiti ibadan ti bọ sita lati kede pe akẹkọjade ileewe naa ni, sibẹ igbimọ kotẹmilọrun ti ẹgbẹ oṣelu AOC gbe kalẹ lori eto ayẹwo naa pẹlu fọwọ si igbesẹ igbimọ ayẹwo naa.
” Hana bá dúró ní ilé, ó ń tọ́jú ọmọ náà.
Ẹ wo àwòrán àti ọ̀rọ̀ ìrántí àwọn akẹ́kọbìrin Chibok
Yorùbá bọ̀ ó ni “…ogún ọdún ń bọ̀ wá d’ọ̀la”.
Ojumọ kan ko nii mọ ki ileeṣẹ BBC ma gbe iroyin bo ba ṣe n lọ nipa Coronavirus sita, bẹẹ naa ni wọn n ṣe idanilẹkọ fun awọn eeyan nipa bi wọn ṣe le dabo bo ara wọn, bi wọn ṣe le ṣe imọtoto ara ati bẹ bẹ lọ.
Ọlọpaa ri awọn ohun ara meriri ni yara Taiwo Lasiko tawọn ọlọpaa sayẹwo ile rẹ, wọn ba igba meji, ti ọkan ni ori oku ninu, nigba ti igba keji kun fun agbo dudu.
Nítorí náà Farao ní kí wọ́n tọ́jú kẹ̀kẹ́ ogun òun, ó sì kó àwọn ọmọ ogun rẹ̀ jọ.
Lasiko ti Ọga agba ileewe naa ti wọn yọ nipo n sọrọ, o ni ọgbọn ọdun niyii ti oun ti n sisẹ ni ileewe naa ni ipo kan tabi omiran, nitori naa wọn ko le dede yọ oun bii jiga.
Oríṣun àwòrán, Sunday Igboho Atẹjade kan ti Igboho fisita fun awọn akọroyin nilu Ibadan salaye pe awọn gomina ilẹ Yoruba fi ohun kansoso sọrọ fun igba akọkọ lori agbekalẹ eto Amọtekun, idi si ree ti oun yoo fi sa ipa oun lati sugba eto naa.
Bakan naa ni alaga igbimọ naa, Danladi Umar to ka idajọ sita sọ pe ki Onnoghen fi ipo rẹ gẹgẹ bi alaga Igbimọ Idajọ ni Naijiria, CJN, to fi mọ Alaga ajọ to n mojuto ọrọ awọn oṣiṣẹ lẹka idajọ.
Bakan naa lo tun tenumo pe ijoba orilede yii ni lati gbe
Oun si ni ọmọ kẹrin ti iya rẹ bi ninu awọn mẹfa ti iya rẹ bi ninu ile olorogun, ti iya rẹ ti jẹ iyawo akọkọ.
Àánú rẹ pọ̀, OLUWA,sọ mí di alààyè gẹ́gẹ́ bí òtítọ́ rẹ.
Kò bèérè ijọ́ tí a o dé?
"Ohun mẹ́wàá tó yẹ kóo mọ̀ nípa Kunle Afod Fasiti Kaduna ni ki olùkọ́ lọ rọọ́kún nílé látààrí ẹ̀sùn pé ó ń dúnkookò mọ́ akẹ́kọ̀ọ́ Ìlé ẹjọ́ ti pàṣẹ pé kí ilé iṣẹ́ ọ̀lọ́pàá dá ìgbaniwolé dúró Iléeṣẹ́ Instagram wọ́gilé App ""Augmented Reality filters"" lórí ẹ̀rọ rẹ̀ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Yoruba Culture: ọjọ́ méje ni wọ́n fí n rẹ ẹ̀kú Danafojura kó tó jáde Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!"
Ìjọba Oyo fẹ́ mọ ikú tó pa akẹ́kọ̀ọ́ UI níléeṣẹ́ tó ń ṣe ọṣẹ Àwòkọ́ṣe ìwà ìrẹ̀lẹ̀, òtítọ́ àti olùfẹ́ mẹ̀kúnnù ni Ayo Fasanmi - Ìjọba Osun Afurasi yii ṣalaye lede abinibi rẹ, Hausa pe lati igba toun ti bẹrẹ, ọkunrin mẹta ati obinrin meji ni ẹmi wọn ti tọwọ oun bọ.
GomaGege bi awon osise ile –iwosan
Díẹ̀ lára àwon oúnjẹ ìbílẹ̀ wa tó tin ń di àwátì báyìí
Mi o kọkọ mọ itumọ rẹ fun igba diẹ, sugbọn lẹhin ti mo ri aworan kokoro aarun Ebola , o ye mi kedere wi pe Arabinrin Dokita Stella Folashade Adadevoh ni wọn n se iranti rẹ.
Inú ọkùnrin yìí dùn ó sì múra lọ́jọ́ kan ó lọ sí oko náà ó dá ẹmu ó sì so àwọn akèǹgbè wọn-ọnnì mọ́ orí ọ̀pẹ nírètí pé nígbà tí ó bá di ọjọ́ kejì tí òun bá dé òun óò bá ẹmu nínú àwọn àkèǹgbè wọn-ọnnì òun óo sì tà á, òun àti olówó náà yóó jọ pín owó tí ó bá ti ibẹ̀ wá ní dọ́gbadọ́gba.
Wo ohun tí Adájọ́ ṣe sí àṣùwọ̀n ìfowópamọ́sí Wòlíì Sotitobire Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Akure Kidnap: E túbọ̀ ní sùúrù, a máa wá ọmọ náà rí- Alukoro ọlọ́pàá Oludari ẹka idajọ ni ileeṣẹ to n ri si ọrọ idajọ, Grace Olowoporoku lo n lewaju ifarahan fun olupẹjọ nigba ti Agbẹjoro Olusola Oke ati Akinyemi Omoware n duro fun olujẹjọ.
Kí ẹ ranti pé ẹ̀yin náà ní Ọ̀gá kan ní ọ̀run.
ipade ajọ ilẹ Afirika niluu Nairobi ko to ṣagbako iku ojiji ninu ijamba oko
Oríṣun àwòrán, Getty Images Akano ni ẹmu fún ara ni Iodine, Zinc àti magnesium láàgọ́ ara Oríṣun àwòrán, Getty Images Ẹmu àti àìsàn Jẹjẹrẹ Akano sàlàyẹ síwájú sí pé, ẹmu ni àwọn èròjà kan tó máa n dènà àìsàn jẹjẹrẹ tó tí n ṣe ẹ̀mí àwọn ènìyàn légbodò tó sí n pa àwọn sẹ́ẹ̀lì ara Nítorí náà, ẹmu dára púpọ̀ láti dènà ààrùn jẹjẹrẹ Àpẹrẹ to dara jù ni tí Vitamin B2 to jẹ́ Ribovlavine, èyí maa n ràn ara lọ́wọ́ láti gbógun ti àwọn èròjà tó n Cancer Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ondo Land Death: Opó àti àbúrò olóògbé ní aáwọ̀ ilẹ̀ ló fá ikú òjijì fún Olayinka Olabode Se Ọtí máá ń fa Jẹjẹrẹ ọmú Àwọn ènìyàn ń bèrè ìbérèè nípa ẹmu.
Gbèsè tí Buhari ń jẹ bójúmu, isẹ ìdàgbàsókè ló fi ń ṣe
Premier League: Salah, Mane fi àmì tuntun lélẹ̀
Bí wọ́n ti ń lọ láti ìlú dé ìlú, wọ́n ń sọ fún wọn nípa ìpinnu tí àwọn aposteli ati àwọn àgbààgbà ní Jerusalẹmu ṣe, wọ́n sì ń gbà wọ́n níyànjú pé kí wọ́n pa wọ́n mọ́.
Ẹ fi ara yín fún OLUWA, kí ẹ wá sí ibi mímọ́ rẹ̀, tí ó ti yà sọ́tọ̀ títí lae.
wọn dabi ọlọpaa ti wọn n ṣọ bi ijọba ipinlẹ yii ṣe n nawo ilu.
Mo fẹ́ kí ẹ mọ̀ dájúdájú pé àwọn kan wà láàrin àwọn tí ó dúró níhìn-ín, tí kò ní kú títí wọn óo fi rí Ọmọ-Eniyan tí yóo máa bọ̀ wá gẹ́gẹ́ bí Ọba.
Àwọn tí wọ́n jẹ́ olórí ninu àwọn ẹ̀yà Israẹli nìwọ̀nyí, láti inú ẹ̀yà Reubẹni: Elieseri, ọmọ Sikiri ni olórí patapata.
Ẹ̀yin ọ̀tá mi, ẹ lọ dì mọ́ òpò ina lọ́dún 2020- Ayodele Fayose Akinyibi rọ àwọn awakọ̀ láti maa ṣe àmojuto ọkọ wọ́n, ki wọ́n si yee sáré àsápajudé, ki wọ́n si yée rin ìrìn oru.
Ọba Siria yóo ṣe wọ́n bí ó ti fẹ́ láìsí àtakò, yóo dúró ní Ilẹ̀ Dáradára náà, gbogbo rẹ̀ yóo sì wà ní ìkáwọ́ rẹ̀.
Ó fi agbára ńlá rẹ̀ hàn nígbà tí ó mú wọn jáde kúrò ní Ijipti.
Dafidi tún bèèrè lọ́wọ́ Ahimeleki pé, “Ǹjẹ́ o ní ọ̀kọ̀ tabi idà kí o fún mi?
FIFA U-20 World Cup: Amẹrika dá sẹ̀ríà fún Nàìjíríà nínú ààwẹ̀
–Dá mi lóhùn, mo ní ìwọ yìí tó ọ̀rọ̀ i sọ?
Kí ló dé t'awọn Gómìnà Nàìjíríà fẹ̀ yá N17trillion nínú owó ìfẹ̀yìntì òṣìṣẹ́?
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Kidnapped Girl: Iyá Ikimot ní lẹ́yìn ọ̀pọ̀ ìdààmú àti owó láti wá ọmọ náà, òun sọ ìrètí nù Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Kidnapped Girl: Iyá Ikimot ní lẹ́yìn ọ̀pọ̀ ìdààmú àti owó láti wá ọmọ náà, òun sọ ìrètí nù 27 Ẹrẹ̀nà 2019 Isẹ Oluwa, awamaridi ni ọrọ ijinigbe ati ipadawale ọmọdebinrin kan, Ikimot jẹ nilu Eko.
Ẹni to bori: Tunisia Tunisia Awọn ọmọ orilẹede Tunisia ti wọn bi lọdun 2017 ni ireti wa pe wọn yoo lo ọdun mejidinlọgọrin laye - mẹtadinlaadọrin ninu wọn yoo ni ilera to peye.
Promise ni o jẹ adari ikọ ọmọ Naijiria ninu idije ti ọjẹwẹwẹ ilẹ Afrika ni ọdun 2005 ni Orilẹ ede Benin.
ganfe ati ipanle, Amofin Falana rọ Ile Igbimọ Aṣofin yii lati jẹ ki awọn
@zhurg_ sọpe igbesẹ ajọ NAFDAC ku diẹ kaato nitori yoo só ọpọlọpọ di alainiṣẹ.
Vaccination: Kí ní ìdí tí àwọn ènìyàn kìí ṣe fọ́kan tan abẹ́rẹ́ àjẹsára ?
Nibayii, wọn ti gbe ọkọ naa to di oju ọna kuro laarin ọna, ti awakọ rẹ si ti di ero ileewosan.
 nínú ọ ̀ pọ ̀ àwọn àpẹrẹ nínú abala yìí àwọn olùsọdipúpọ ̀ jẹ ́ nọ ́ mbà odidi .
"Ọpọlọpọ eeyan lo ti kọwe fi isẹ wọn silẹ ni ireti wi pe ọrọ peace corps yii yoo tete jasi nitori ohun ti wọn sọ fun wa ni wi pe wọn ko ni pẹ buwọluu sugbọn ọdun meji lawa yii ti wọn ko tii buwọlu ki aarẹ tilẹ to wa sọ wipe ọrọ o lee ri bẹẹ mọ bayii.
Díẹ̀ lára àwọn ìṣẹ̀lẹ̀ tí yóò mi ìgboro tìtì l'ọ́dún 2020 rèé Rárá o, ẹ kò gbọdọ̀ sìnkú akẹ́kọ̀ọ́ LASU tí wọn fi ṣe òògun owó - Ìjọba Eko yarí Wọ́n ti so ìsìnkú Ọ̀gàgún Iran Qasem Soleimani rọ̀ lẹ́yìn tí èèyàn 35 kú Ìwà ọ̀dàlẹ̀ ni bí ẹ kò bá gbé iléèwé ìkọ́ṣẹ́ olùkọ́ni kalẹ̀ sí ìlú Ìwó- Oluwo Ìròyìn sọ pé, àwọn ará àdúgbò ọhun pà imọ̀ pọ̀ láti dána sún àwọ́n afurasi adigunjale naa nítori bi àwọn olè ṣe n já ládúgbò láti ìgbà díẹ̀ sẹ́yìn.
Mílíọnù ènìyàn ló ń jẹ Núdùlù lágbàyé lójoojúmọ́ Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, O rọrùn, ó rẹwà, pàtàkì jùlọ koi wọn rara bákan náa[ló ti di awo máleeló lágbàyé Lẹ́yìn ọgọ́ta ọdún ti Ando ṣe àwári Núdùlù, ó kéré tán ènìyàn tó dí díẹ̀ ní ẹgbẹ̀rún lánà sọ̀dúrún ló ń jẹ Núdùlù lójoojúmọ lágbàyé, gẹ́gẹ́ bi ẹgbẹ àwọn oni Nudulu ṣe sọ.
 o je pipe bi  oba orin calypso "" fun imugbajumo iru orin caribbean kakiri aye ni ewadun 1950 ."
O rawọ ẹbẹ wi pe ki ijọba tun ero rẹ pa.
Ṣugbọn bí ẹ bá tún ṣe nǹkan burúkú, yóo pa ẹ̀yin ati ọba yín run.
Eyi ni marun ninu awọn aarẹ ti wọn ti fi tipatikuuku mu kọwe fipo silẹ ni ilẹ Afirika.
Ẹnikẹ́ni kò sì dí i lọ́wọ́.
Àwòrán àwọn ìsẹ̀lẹ̀ lọ́ sẹ̀ yìí: ‘First Lady’ wọ asọ 1.
Hẹrọdu fẹ́ mú Peteru wá siwaju gbogbo eniyan fún ìdájọ́ lẹ́yìn Àjọ̀dún Ìrékọjá.
Awọn dokita to n ba awọn to n lo oogun oloro sọrọ ni Ojuẹlẹgba naa mẹnuba ọna abayọ.
Jọ̀wọ́ fún wa ní ààyè láti lọ gé igi ní etí odò Jọdani láti fi kọ́ ilé mìíràn tí a óo máa gbé.
Ọlọrun Ẹlẹ́dàá kò ní dójú tì wọ́n.
Nítorí OLUWA a máa gbọ́ ti àwọn aláìní,kì í sìí kẹ́gàn àwọn eniyan rẹ̀ tí ó wà ní ìgbèkùn.
"Atẹjade kan ti ileeṣẹ eto ẹkọ ni ijọba ipinlẹ Eko, fi sita ṣalaye pe kọmiṣọna eto ẹkọ nipinlẹ Eko Arabinrin Fọlaṣade Adefisayọ lo kede eyi ni ""ibamu pẹlu aṣẹ ati idari ijọba apapọ ati ọwọja ọwọ keji ajakalẹ aarun COVID-19 to n ja lọwọlọwọ."
Pottery: Àwọn onímọ̀ nípa amọ̀ wúlò púpọ̀ ju ike àbí irin lọ
Gẹgẹbii itan ti Baba sọ lọjọ naa, wọn ni lati ori Olori agba laafin titi dori awsn olori yooku, awọn ko kọ ẹnu si obinrin kọkan ri.
Iyapa ti o ba egbe oselu alatako leyin iku akikanju oloselu, ti o tun je olori ijoba teleri Morgan Tsvangirai,yoo je anfaani fun egbe oselu ZANU-PF.
Òun ni Ọlọrun pè ní olórí alufaa gẹ́gẹ́ bíi ti Mẹlikisẹdẹki.
Awon dokita tabi osisẹ ile iwosan gbọdọ sọra gidigidi, ki wọn si lo ibọwo tabi iboju ti wọn ba n toju ẹni to n se aisan.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ikú Dagunro: Sajẹ ní èèyàn tó ṣe gbáralé ni Dagunro, ọ̀pọ̀ èèyàn ló dìde láti ara rẹ̀ 13 Òkùdu 2019 Oríṣun àwòrán, Sajetiologa Awọn agba ọjẹ ninu isẹ tiata ni ẹka ti Yoruba ti n sọrọ nipa gbajugbaja osere tiata, Fasasi Ọlabankẹwin, ti gbogbo eeyan mọ si Dagunro.
Mo lọ̀ wọ́n lúbúlúbú bí eruku tí afẹ́fẹ́ ń gbá lọ,mo dà wọ́n nù bí ẹni da omi ẹrẹ̀ nù.
Wahala to bẹ silẹ lasiko idibo Gomina naa ni o mu ki Inec so idibo si ipo Gomina ati ti ile aṣofin rọ lọjọ kẹwa Oṣu kẹta ọdun 2019 .
Obitibiti ero kora jọpọ lati kẹdun nile alaga NURTW ẹkun gúúsù -ìwọ̀-oorunTọtun tosi ni igbe ẹkun ati idaro ti n sọ lasiko ti ẹbi, ara, ọrẹ, ojulumọ ati awọn alabaṣiṣẹ pọ kora jọpọ, lati kẹdun nile alaga ẹgbẹ awọn awakọ NURTW ipinlẹ Ọyọ, Alhaji Taofeek Oyerinde Fẹlẹ, to padanu ẹmi rẹ sọwọ aisan kidinrin lọjọ isẹgun.
11 Ògún 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Arsenal fi Newcastle sẹ̀sín, o dà òkùtà sí wan nígbá Ẹgbẹ́ agbábọọ̀lù Arsenal náà ti darapọ̀ mọ Machestger City, Liverpool àti Tottenham nínú ìdíje Premiere League tuntun sáà yìí to ṣẹ̀ṣẹ̀ bẹ̀rẹ̀.
O ni irọ ni ahesọ pe APC n gba kaadi idibo lọwọ awọn olokowo ti wọn n fun ni 'trader money'.
Lẹyin ti wọn fi ọrọ wa awọn ti ọrọ ṣ'oju wọn lẹnu wo, awọn ọlọpaa fidirẹmulẹ pe niṣe ni awọn ololufẹ naa n ba ara wọn lopọ lori ferese naa nigba ti wọn jabọ.
N kò lẹ́bi níwájú rẹ̀,mo sì ti yẹra fún ẹ̀ṣẹ̀ dídá.
O fi kún-un pé, òun pẹ̀lú kò faramọ́ ìwà ti ọgbẹ́ni Baban Gona hù pàápàá nílànà ẹ̀sìn.
Yorùbá sọ wi pé “Ìṣe ilé ló mbá ni dode”.
Ko sí ẹni náà tí ó lé mọ Davidson ní àkókò tí o fì ń ṣe Olùdánwò ti o n yí ilé ìwé kékeré kirir tí yóò rí i pé ó dé ipò ńlá yìí lónìí ti ẹnu lè yà.
Jákèjádò ilẹ̀ náà, ìdá meji ninu mẹta àwọn eniyan náà ni wọn yóo kú, a óo sì dá ìdá kan yòókù sí.
Ẹ wo irú ìwà tí ẹ hù ninu àfonífojì,kí ẹ ranti gbogbo ibi tí ẹ ṣebí ọmọ ràkúnmí tí ń lọ, tí ń bọ̀;tí ń tọ ipa ọ̀nà ara rẹ̀.
O so pe, bi eto ibanisoro ba fidimule daradara tan, yoo mu adinkun ba ebi, besini yoo tun pese ise fun awon odo lawujo.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Mo kọ̀ láti yí ọ̀rọ̀ mi padà lórí ètò ẹ̀kọ́ ọ̀fẹ́ - Gómìnà Dapo Abiọdun 'Operation Rewire' EFCC / FBI sèso owó tó lè ní mílíọ̀nù N153 Ìdá 90% nínú àwọn olówó Naijiria lo n lọ ilé babaláwo- Mr Latin Ọbasanjọ ni ọmọ òrùkàn tó di olóri orílẹ̀èdè lẹ́ẹ̀mẹ́ta ọ̀tọ̀ọ̀tọ̀ Obasanjo ni awọn eeyan jankan ti oun fiwe pe lati awon orilẹ-ede miran lagbaye wa sibi ayẹyẹ naa, bii aarẹ orilẹ-ede Sierra Leone tẹlẹ, Bai Koroma, aarẹ Liberia ana Ellen Johnson-Sirleaf, atawọn mii ni ko lee wa sibi ayẹyẹ ọhun, nitori ibẹru arun Coronavirus.
, John Marshal Law School, Chicago (Law, 2000) B.
Awọn iroyin ti ẹ lee nifẹẹ si: Ọsinbajo se‘dana ọmọbinrin rẹ nile ijọba Naijiria lewaju ninu ibọn rira Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí kan sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
Labẹ ofin, Gboluga ṣi lẹ́tọ̀ọ́ lati wa ni ipo titi ti ile ẹjọ kotẹmilọrun ati ile ẹjọ to gajulọ ba da ẹjọ naa.
Lẹyin ti wọn ba ti fi ontẹ lu abẹrẹ ajẹsara naa, ni wọn ṣẹṣẹ le gbe lọ si awọn orilẹede to wa lagbaye.
"Abẹwo Aarẹ Buhari si Plateau Buhari dasi ipaniyan Benue Gẹgẹ bi ẹnikan tisẹlẹ naa soju rẹ ti wi, "" Ohunto bani ninujẹ pupọ ni isẹlẹ yii nitori a sẹsẹ n palẹmọ lati sin awọn oku ti wọn kọkọ pa ni."
Mose sọ fún Aaroni pé, “Sọ fún gbogbo ìjọ eniyan Israẹli pé, kí wọ́n súnmọ́ tòsí ọ̀dọ̀ OLUWA, nítorí pé ó ti gbọ́ gbogbo kíkùn wọn.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Aarẹ orilẹede mẹrin lo parapọ si papa isere Eagles Square lati ba Naijiria dse ayẹyẹ ọjọ ominira June 12 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ọsẹ yii bakan naa ni Sẹnatọ Ahmed Lawan di Aarẹ ile igbimọ Asofin Agba lorilẹede Naijiria lẹyin ti awọn asofin naa di ibo yan awọn adari tuntun.
’ rèé Afọnja, ẹni tó finú wénú ní Ilọrin, àmọ́ tó jẹ iwọ Ẹfunsetan Aniwura, obìnrin tó ju ọkùnrin lọ Ọ̀rọ̀ǹpọ̀tọ̀niyùn, Aláàfin obìnrin àkọ́kọ́ rèé, tó ní nǹkan ọkùnrin Lẹyin eyi lawọn Gomina ẹkun Guusu-Iwọ Oorun eyi to ko awọn ipinlẹ Yoruba pọ sọ pe ko sewu loko longẹ awọn ki awn Fulani to ba wa lagbegbe ma foya ati sa lọ.
Mo gbọ́ tí ọ̀kan ninu àwọn ẹ̀dá alààyè mẹrin wí pẹlu ohùn tí ó dàbí ààrá, pé, “Wá!
Buhari tun tenumo awon ise akanse pataki ti orile-ede Naijiria yoo ri daju lati
Ibi ti a ti gbiyanju lati pe fóònù rẹ ni awọn ara sọọsi ti pe wa lati wa a wo, nitori awọn o mọ nkan ti wọn ṣe fun.
"Fun apẹẹrẹ, akọle kan loju ewe iwe iroyin Punch nilẹ Naijiria lo kede pe ""To ba fẹ bọ lọwọ arun Coronavirus, ge irungbọn rẹ, CDC sekilọ"" Irọ ni."
Ǹjẹ́ ẹni tí ó kórìíra ìdájọ́ ẹ̀tọ́ lè jẹ́ olórí?
"O ni ""Lai ṣe aniani, ijọba to wa lode yii ṣe afikun iṣoro awọn ọmọ Naijiria eyii to jugunba lọwọ ijọba ana ni, koda, ijọba Buhari n ṣapẹrẹ pe awa akẹkọọ ni lati pada si bi aṣe maa n fa 'aluta' laye atijọ."
Kaakiri Naijiria ni iwọde ti n waye lọjọ keji ti ijọba lawọn tu ikọ ọlọpaa FSARS ka.
Arabinrin naa, ti orukọ rẹ lori ayelujara njẹ Mwandu Chibwe kọ iwe kan si Kunle Afọlayan loju opo instagram rẹ, nibi to ti n fi ẹsun kan Mike.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Lekan Kingkong: Níbikíbi tí mo bá wà, màá gbé àṣà Yorùbá ga Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Lekan Kingkong: Níbikíbi tí mo bá wà, màá gbé àṣà Yorùbá ga 6 Bélú 2018 Ọlalẹyẹ Ọlalekan tabi Agba Inaki n gbe ni orilẹ-ede South Afrika, amọ ko gbagbe ile bi o tilẹ n gbe ni ajo.
0 25 Orilẹede Geenlande 0 0.
Láti inú ẹ̀yà Nafutali, ẹgbẹrun (1,000) ọ̀gágun wá, ọ̀kẹ́ meji ó dín ẹẹdẹgbaaji (37,000) ni àwọn ọmọ ogun tí wọ́n wà pẹlu wọn; gbogbo wọn ní apata ati ọ̀kọ̀.
Oríṣun àwòrán, authenticmuy Òṣèré Tíátà Yorùbá yìí la orí mọ́lẹ̀ nígbà tó ń ya sinimimá lọ́wọ́ Oríṣun àwòrán, mydemartins Gbajugbaja osere tiata Yoruba Mide Martins ti n ke irora bo ti ṣe fori janlẹ lasiko to n ṣe ere sinima kan lọwọ.
Won fi esun  kan Nacima Qorane pe.
Lẹ́yin náà ni ó tún gbéra lọ ilé ìfowópamọ́ UBA gẹ́gẹ́ bí adarí owó lati òkèèrè.
Akeredolu - BBC News Yorùbá BBC News, YorùbáFò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Coronavirus: Ẹ̀yin tí ẹ lọ ra aṣọ Okirika l'Ọjà Ọba Akure, ẹ lọ ṣàyẹ̀wò àrùn Coronavirus - Akeredolu 7 Òkùdu 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 9 Òkùdu 2020 Oríṣun àwòrán, @RotimiAkeredolu Gomina ipinlẹ Ondo, Rotimi Akeredolu ti rọ awọn eeyan to lọ ra aṣọ aloku ni Ọja Oba ilu Akure laipẹ yii lati lọ ṣe ayẹwo arun Coronavirus.
Gbogbo ẹ̀yin àyànfẹ́ Ọlọrun tí ẹ wà ní Romu, ẹ̀yin tí a pè láti jẹ́ eniyan ọ̀tọ̀.
agbesunmomi ati adigunjale da loro lorile ede yii.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, International Day Against Drug Abuse and Trafficking: ìdí ti mo fi ń mu oògùn olóró Lara awọn ololufẹ rẹ sọ wi pe nitori nigba ti Shah Rukh Khan de agbo osere Bollywood ni bi ọgbọn sẹyin ni ohun gbogbo yipada fun ẹka fiimu awọn India.
N ṣe ni wọn so ado oloro mọ ara ketekete kan, ti wọn si kẹ si oju ọna ti ọkọ Gomina Zulum gba kọja.
Ṣé òògùn Chloroquine lè dènà ààrùn Coronavirus bí?
Nataniẹli bi í pé, “Ṣé nǹkan rere kan lè ti Nasarẹti wá?
Arabinrin Stella Adedeji lati ile iwe CAC Grammar school ni ilẹ Olujii ni ipinlẹ Ondo to wa ni iwọ oorun guusu Naijiria ni olukọ wa fun toni.
Baba Legba: Foluke Daramola ní òun kò ní gbàgbé àdúrà òwúrọ̀ tó máa ń gbà fún òun
Oòrùn ló ràn lókè ọ̀dọ̀ tèmi.
Ẹni tí ó pín Òkun Pupa sí meji,nítorí pé ìfẹ́ rẹ̀ tí kì í yẹ̀ wà títí lae;
Ọjọ manigbagbe si ni ọjọ Satide, ọjọ Karun osu Kejila ọdun 2020 naa ti eto igbeyawo ọhun, ti wọn pe ni igbeyawo ọmọ ọba waye.
Chelsea kọ̀ láti fìyà panu bíi Arsenal àti Man U Ọna ki wọn ma ni ijakulẹ ninu idanwo bi Jamb,Waec tabi Neco lọpọ a ma sare titi ti wọn yoo fi tẹri sinu aburu ṣiṣe magomago.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù DR Congo: Ọ̀pọ̀ ẹmí lo ti sọ́nù ninú ìjàmbá ọkọ̀ òfurufú tó wáyé lóòní 24 Bélú 2019 Oríṣun àwòrán, Reuters Àkọlé àwòrán, Oko ofurufu naa ba nkan jẹ púpọ̀ O kéré tan ènìyàn mẹ́tàdinlógójì ló ti jẹ́ Ọlọrun nípe lónìí nígba ti ọkọ̀ ofúrúfú kan já ni ilú Goma ni ilà-òòrun DR Congo gẹ́gẹ́ bi àwọn aláṣẹ́ ṣe sọ.
Oun kan naa lo gba ileeṣẹ ilẹ okeere kan lati ilẹ America, fun atunṣe si oju ti awọn eeyan fi n wo Buhari ṣaaju eto idibo.
Lẹ́yìn ò rẹyìn, ilé ìwé di ṣíṣí padà ní ìpínlẹ̀ Oyo Oríṣun àwòrán, @OfficialSeyiMakinde Awọn alaṣe ni ẹka eto ẹkọ ni ipinlẹ Oyo ti gbaradi fun aṣẹ ijọba lati jẹ ki awọn akẹkọọ pada si ileewe, lẹyin ti wọn ti ileewe nitori arun Coronavirus.
Nítòótọ́ Ọlọrun óo bá ọ kanlẹ̀,yóo gbá ọ mú, yóo sì fà ọ́ já kúrò ninu ilé rẹ;yóo fà ọ́ tu kúrò lórí ilẹ̀ alààyè.
Tẹ ba wo Lizzy lasiko to ba n polowo ọja rẹ, ẹ mọ pe isẹ aje le.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Naira Marley: Adọ́jọ́ ṣún ìgbẹ́jọ́ síwájú di oṣù kejì ọdún 20202 Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
ASP Tijani Olatunji ati Insipẹkitọ Gboyega Oyeniyi.
Ile Igbimọ Aṣofin Ipinlẹ Eko ki Eleko ti Eko, Ọba Rilwan Babatunde Akiolu ku oriire ọdun kẹẹdogun ti wọn gori apere awọn baba-nla wọn.
Òun wò mí ó bú si ẹ̀rin, emi náà sì wò ó ẹ̀rín ti ẹ́nu èmi náà jáde.
Nígbà tí ó di aadọta ọdún tí Asaraya jọba ní Juda, ni Pekahaya, ọmọ Menahemu jọba lórí Israẹli, ní Samaria, ó sì wà lórí oyè fún ọdún meji.
Akowe ajọ naa lorilẹede Naijiria, Dudu Emeka lo fi ero rẹ han lasiko to n sọrọ lori idi ti awọn fi tako agbo lati orilẹede Madagascar ti ijọba Naijiria sọ wi pe awọn ti fẹ gba lati koju arun Coronavirus.
Kò sí àní àní pé, ti à bá ti ń sọ̀rọ̀ iromi Moshood Kasimawo Olawale (MKO) Abiola to n jo lori omi, à máa gbúròó Kudirat Abiola, akọni obinrin tó jẹ onilu to ń lu ilu fun lábẹ omi.
Ko dun mọ mi ninu rara, mo si ti pe awọn adari ile asofin apapọ lori rẹ.
Àkọlé àwòrán, Akala sọ pé oun ko nii maa gbe iṣe ti awọn ara Ọyọ le ṣe fun awọn ara ita.
ilera ati oju popo ni ipinle naa.
O fikun oro re pe, lataari bi won se n wa ketekete lati ra lorile-ede China, eyi ni o sokunfa bi won se n ta ketekete si oke okun lati ile Afrika ti o fi mo orile-ede Naijiria.
Majek Fashek fẹ Rita to si bi ọmọ mẹrin fun un ki wọn to kọ ara wọn silẹ .
Aare Buhari de si orile Amerika ni ọganjọ ojo Aiku .
 ní ilẹ ̀ amẹ ́ ríkà iye owó wọn jẹ ́ 25 sí 50 usd .
Ó bá dá wọn lóhùn pé, “Mò ń sọ fun yín pé, bí àwọn wọnyi bá dákẹ́, àwọn òkúta yóo kígbe sókè.
Ida mẹwa ninu ọgọrun ọmọ Naijiria nikan ni o yẹ ko maa lọ si ile iwosan ikọsẹ iṣegun, ṣugbọn wọn ko ni ifọkanbalẹ lori iwosan alabọde mọ.
awon eniyan bi ọgbọ̀n si farapa yẹlẹyẹlẹ.
2bn fún Obanikoro Ẹ̀ṣọ́ tó pa Ọ̀gágun Ethiopia tí a sọ pé ó kú, kò kú mọ́!
Osise agba ile-ise akanse ile-kiko ti ijoba so lojo-Aiku pe, ile-ifowopamo lorile-ede China yoo pese iko marundinladorun ninu  ida ogorun owo 85 %, ti iye re to bilionu meta dollars $3 billion, ti won niloo fun ise-akanse ile-kiko olu-ilu orile-ede Egypt tuntun, eyi ti ile-ise ijoba fun ise-akanse ohun n ko lowo.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Omi ìṣẹ̀ńbáyé tó ń dà ní Ówù rèé, èyí tó ga jùlọ ní Afirika Akẹ́kọ̀ọ́ tó gbèlé kàwé pegede wọ fásítì lọ́mọ ọdún méjìlá Ẹgbẹ́ òṣèlú AA kò gbọdọ̀ kópa nínú ìdìbò gómìnà ní Kogi, Bayelsa - Ilé ẹjọ́ Ẹ̀kun omi wo ògiri ọgbà ẹ̀wọ̀n, ẹlẹ́wọ̀n 150 sálọ Obinrin to ba BBC sọrọ lo wa ni iru ipo taa darukọ yii, eyi ti ko jẹ ki igbeyawo rẹ tọjọ nigba ti ọkọ rẹ ko ri ẹjẹ ibale lara rẹ.
” Mose bá lọ sọ ohun tí àwọn eniyan náà wí fún OLUWA.
6 12501 Orilẹede Vietnam 35 0.
’’ Ipade naa yoo tun maa wo”Bi ibasepo to wa laarin Europe
Rotimi Amaechi - Minisita fun igbokegbodo ọkọ Mohammed Maigari (Sokoto) - Minisita fun ọrọ ọlọpaa Onimọẹrọ Saleh Maman - Minisita fun ipese ina ọba Abubakar Aliyu - Minisita Abẹle fun iṣẹ ode ati ile gbigbe Sadiya farouq - minisita fun iṣẹlẹ pajawiri.
Ṣùgbọ́n bí mo ti sùn lóru ọjọ́ náà nínú àgọ́ tí àwọn ọdẹ ṣe fún mi, ni èmí náà déedée wọlé tí ó jí mi.
"Mi o ni i lero lati ri Biṣọpu naa fin, tabi kan an ni abuku, ti mo si kabamọ itumọ ti awọn kan fi n tumọ fidio naa.
Olóògbé náà tó jẹ́ akẹ́kọ̀ọ́ ni ìròyìn sọ wí pé ó ń bọ̀ láti Olupọnna, ìlú kan tí kò jìnà sí Iwo níbi tí ó ti ṣagbákò ikú ọ̀sán gangan.
”Ewe, o fikun un oro re pe,
Njẹ́ ẹ mọ̀n pé kòsí ẹni fẹ́ lọ.
Ohun naa lo si ti mu ayipada ba eto ẹkọ, irin ajo afẹ ati awọn nkan ọlọdọọọdun miran kaakiri agbaye Oríṣun àwòrán, @folastag Àkọlé àwòrán, Kò ní sí ayẹyẹ ọdún Ojúde Oba lọ́dún yìí- Awujale ilẹ̀ Ijebu Oba Adetona lo kede pe Covid 19 yii ko ni jẹ ki ọdun yii waye ninu atẹjade kan ti Ebumawe ti Ago-Iwoye, Oba A.
Olubadamọran fun aarẹ lori ọrọ iroyin, Garba Shehu lo ṣalaye ọrọ yii lori ohun to pe ni omilẹgbẹ ibeere awọn oniroyin lori bi Aarẹ Buhari ṣe gbalejo Adekunle Akinlade ti gomina Amosun mu lọ baa niluu Abuja lẹyin ti o ti kọkọ gbalejo Dapọ Abiọdunti Oloye Oluṣẹgun Ọṣọba mu wa baa ṣaaju.
Bàbá mi sá ju ú lọ púpọ̀, kò ṣàì tì bí ọmọ!
1980s Ibraheem Zakzaky ló dá ẹgbẹ́ ẹlẹ́sìn Islamic Movement in Nigeria (IMN) sílẹ̀.
Aare egbe osise lorile ede Naijiria, ojogbon Biodun Ogunyemi lo soro yii pelu awon akoroyin, leyin ipade alati-lekun-mori ti won se niluu Abuja, pe ijiroro si n lo lowo.
Nítorí Ọlọrun yóo fọ́n egungun àwọn ọ̀tá rẹ̀ ká;ojú óo tì wọ́n, nítorí Ọlọrun ti kọ̀ wọ́n.
sanwo fun agbasese lati ko awon idoti wonyii, bẹẹ gege ni o tun ran ara ilu
Gege bi iwe atejise ohun se so, ” lataari kikowe fise sile igbakeji aare CAF, ogbeni Kwesi Nyantakyi ati leyin gbogbo ijiroro ati ipade ti o waye laarin aare ajo CAF ati awon toro kan gbongbon, a ti panupo lati yan ogbeni Amaju Melvin Pinnick gege bi igbakeji aare ajo yii.
Ta ló fa Jakọbu lé akónilẹ́rù lọ́wọ́,ta ló sì fa Israẹli lé àwọn ọlọ́ṣà lọ́wọ́?
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ooni of Ife: Ọ̀wọ́ Ọlọ́pàá ti tẹ arákùnrin tó fi tipá wọ ààfin Ọ̀ọni ilé ifẹ̀ 4 Agẹmo 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 21 Èbibi 2020 Oríṣun àwòrán, Amiloaded media hub Ni alẹ ọjọ Iṣẹgun ni awọn eeyan ilu Ile ifẹ ni awọn gbọ iro ibọn ni kikankikan ni ile Oodua tii ṣe aafin Ọọni ile ifẹ, Ọba Adeyẹye Ogunwusi eleyi to mu ki ọpọlọpọ awọn eeyan ilu iṣẹmabaye naa o maa ko aye soke lori alaafia Ọọni Adeyẹye Ogunwusi ni.
Ẹni tó bá ń bínú kàn ń bínú lásán ni- Oyedepo Ọmọwe Adojutẹlẹgan n fapajanu pe iwe oruks awọn aṣojudibo ti wọn lo lasiko idibo abẹlẹ ẹgbẹ oṣelu naa ti wọn ti yan Akeredolu lati dije lorukọ ẹgbẹ oṣelu naa tako abala ikẹtadinlaadọrun iwe ofin idibo orilẹede Naijiria naa ati iwe ofin ẹgbẹ oṣelu APC.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Buhari: Ọwọ́ fẹ́rẹ̀ tẹ àwọn agbébọn lókè Ọya 15 Ògún 2019 Oríṣun àwòrán, @GarShehu Irọ ati arumọjẹ ni gbogbo awọn agbebọn ti wọn n paayan tan, ti wọn wa n pariwo Allahu Akbar n pa.
BBC Yoruba wa gbadura pe Ọba oke yoo dẹ ilẹ fun oloore to lọ.
Bi mo sẹ de ibudokọ, mo ba Maruwa yẹn, ṣugbọn ko ti to iṣẹju kan ti mo wọ inu rẹ, ti mo fi gbọ 'gba!"
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù EFCC: Ọwọ́ pálábá àwọn ọmọ China méjì tó fẹ́ fún ọ̀gá EFCC ní àbẹ̀tẹ́lẹ̀ N100m ségi 30 Ògún 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 12 Èbibi 2020 Oríṣun àwòrán, Faceboo/EFCC Ajọ to n gbogun ti iwa jẹgudujẹra lorileede Naijira EFCC ti sọ iwọ sodo ti o si ti mu ẹja nla pẹlu awọn ọmọ ilẹ China meji kan to gbiyanju lati fun ọga ajọ naa kan ni ọgọrun miliọnu Naira lowo abẹtẹlẹ.
Wọn tilẹ ran ijọba leti wi pe ko ranti ipinnu rẹ lati ta awọn ọkọ baalu yii, ki ijọba le e ri owo fi pese awọn ohun amayedẹrun fun ijọba.
O kọlu gbogbo àkọ́bí wọn ní ilẹ̀ Ijipti,àní, gbogbo àrẹ̀mọ ninu àgọ́ àwọn ọmọ Hamu.
Ikọ France ti di olori Group A bayii ninu idije ife ẹyẹ agbaye awọn obinrin, FIFA Women's World Cup lẹyin ti wo-mí-ngba-si-ọ ti adari ifẹṣẹwọnsẹ naa fun Wendie Renard lati gba ni ẹẹmeji.
Pilatu bi wọ́n pé, “Ohun burúkú wo ni ó ṣe?
Igbesẹ naa bi awọn ara ilu ninu gidi.
Àkọlé àwòrán, Fayẹmi ti kọkọ jẹ gomina ipinlẹ Ekiti laarin ọdun 2000 si 2014 Kódà wọn yọ àwọn alatilẹyin wọn, ti wọn fi ẹsun kan pe wọn n ṣe ti iṣakoso Fayose, kuro.
Nígbà tí àwọn ọmọkunrin Ọlọrun fẹ́ aya láàrin àwọn ọmọ eniyan, àwọn ọmọ tí wọ́n bí ni àwọn òmìrán wọnyi.
OLUWA ní kí ẹ ṣọ́ra fún ẹ̀mí yín, ẹ má máa ru ẹrù ní ọjọ́ ìsinmi, ẹ má gbé ẹrù wọ ẹnubodè Jerusalẹmu ní ọjọ́ ìsinmi mọ́.
Àwọn àlejò meji yi ṣe ìlérí pé kò si nkan ti yio ṣẹlẹ̀ ti àwon bá jẹ Igún, nitori eyi wọn fi ojú di èèwọ̀ ilú Ayégbẹgẹ́.
Ọmọ bibi ilu Ago Iwoye nipinlẹ Ogun ni Oloye Abdul Tawab Olaitan Ile-Aje Adeniyi.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù 2020 Events: Àwọn ìròyìn tó yẹ kẹ máa fojú sọ́nà fún rèé lọ́dún yìí 7 Sẹ́rẹ́ 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 8 Sẹ́rẹ́ 2020 Oríṣun àwòrán, Getty Images/Instagram Ọdun 2020 yii jẹ ọdun ti awọn eniyan kan ti n pariwo rẹ, ti wọn si ti ni afojusun fun lati ọjọ pipẹ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Akomolede ati Asa: Mọ̀ si nípa àwọn ọ̀nà tí Yorùbá ń gbà ran ara wọn lọ́wọ́ O fikun pe, Ile asofin yoo tun saayan lati ri daju pe aba ofin to n se atunto si eto idibo nilẹ wa dohun, lọna ti pese idibo to mọyan lori ni Naijiria.
Ẹ̀yin tí ẹ̀ ń pa àwọn ọmọ yín láàrin àfonífojì,ati ní abẹ́ àpáta?
Lọdun to kọja, awọn alaṣẹ l'orilẹ-ede Ghana kilọ fun awọn alaboyun lati dẹkun lilo oogun ibora to ni eroja antioxidant glutathione.
Mú ẹ̀gàn tí ń bà mí lẹ́rù kúrò,nítorí pé ìlànà rẹ dára.
Kí olukuluku ṣọ́ra lọ́dọ̀ aládùúgbò rẹ̀,kí ó má sì gbẹ́kẹ̀lé arakunrin rẹ̀ kankan.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Toyin Atoyebi mechanic: Ẹ wo Toyin, ọmọbinrin ọdún 16 tó ń tún skadà àti gẹnẹrátọ̀ ṣe ní Ifẹhonuhan lori afikun owo epo ọdun 2003 Ẹgbẹ apapọ oṣiṣẹ, NLC labẹ olori rẹ nigba naa, Adam Osiomole gunle iyanṣẹlodi pẹlu iwọde lẹyin ti ijọba aarẹ Naijiria tẹlẹ ri, Olusegun Obasanjo ṣe afikun owo epo bẹntiro lati N26 naira lọ si N40.
Babalawo ni agbara ti Eleduwa fun iran Yoruba ni Magun: Akoda Awo ṣalaye pe, ti awọn akọ ati abo to ba lẹpọ lasiko ibalopọ, bi awọn agba ko ba ṣe ẹ̀rọ̀ rẹ fun wọn lasiko, afaimọ ki ọkan tabi awọn mejeeji ma jade laye.
Nítori àwọn àtúgbẹ́yẹ̀wò, o níra láti ṣe àkójọpọ fún àwọn ọkọ́ naa Orisun: Johns Hopkins University atawọn ajọ eto ilera ilu Iye akọsilẹ to waye gbẹyin 7 Oṣù Ọ̀pẹ̀ 2020 14:22 WAT+3 Gomina Makinde ni ida aadọta awọn arun coronavirus to n waye ni ipinlẹ Ọyọ ko ṣẹyin ileewosan nla UCH ni ilu Ibadan.
Ọ̀ràngún ti Ila: Èdè àti àṣà Yorùba ní láti jọ wá lójú
O ni lati igba ti wọn ti lọ fun awọn ajinigbe naa ni owo, ni awọn darandaran naa ti kọ lati ba awọn sọrọ mọ, ti awọn ko si gburo Chris Sodje to jẹ ẹni ọdun mọkanlelogoji titi di asiko yii.
Ọmọ tí ó ṣe àfojúdi sí ìyá rẹ̀ ti lu òfin karùn-ún Olódùmarè, eléyìínì wọ ẹ̀wù ìjàngbọ̀n sí àtàrí, ó sì fi aṣọ ìparun bora.
Nígbà náà ni Jakọbu ati Johanu, àwọn ọmọ Sebede, wá sí ọ̀dọ̀ rẹ̀, wọ́n wí fún un pé, “Olùkọ́ni, a fẹ́ kí o ṣe ohunkohun tí a bá bèèrè lọ́wọ́ rẹ fún wa.
Ní ọdún kẹtadinlogoji tí Joaṣi jọba ní Juda ni Jehoaṣi, ọmọ Jehoahasi, jọba lórí Israẹli ní Samaria.
Ajọ EFCC gbe Olisah Metuh lọ sile ẹjọ giga kan nilu Abuja fun gbigba irinwo miliọnu naira lọwọ ọfiisi alamojuto abo lorilẹede Naijiria lọdun 2014.
Wọn kọ ọ dagba nile igbagbọ to si n kọrin laarin awọn ẹgbẹ akọrin ṣugbọn nigba to ya, Soyinka pada di alailẹsin kankan ti ko gbagbọ ninu Ọlọrun.
O ni lootọ wọn ti wa ki awọn sile, ṣugbọn akẹẹgbẹ aburo rẹ ko tilẹ fun wọn lẹnu ọrọ rara.
Ọna yoowu ti a ba lee gba lati se iranwọn ni a o se.
Uraya bá dúró ní Jerusalẹmu, ní ọjọ́ náà ati ọjọ́ keji.
Ondo Election 2020: Mo ṣèlérí N500 lóṣooṣù fún gbogbo ọmọ tuntun
Èyí tún túmọ̀ si pé, àwọn ènìyàn kò ni máa rajà láti ọ̀nà jínjìn mọ nítori owó ati fí ránṣẹ́ yóò ti pọ̀ jù.
" Ọsẹ mẹta sẹyin ni awọn to n tu ọkọ ṣe ri oku ọmọ okunrin jojolo kan ti wọn ju sori aatan ni adugbo Elechi, ni agbegbe Diobu yii kan naa.
Mo bèèrè pé, “Kí ni èyí?
Àkọlé àwòrán, Tìbọn-tìbọn ni àwọn ọmọ ogun dúró.
SERAP ati awọn ti wọn jijọ pe ẹjọ yii ni awọn fẹ ki ile ẹjọ f'ọwọ rọ afikun owo epo ati ina ọba sẹyin."
2 mílíọ́nù owó ìtanràn Ìjọba Nàìjíríà ti gbà láti san N30b owó àjẹmọ́nú fún ASUU Àjẹ́ àti Aṣẹ́wó ní ìyá Rainbow - Òjòpagogo Ẹwẹ agbarijopo ẹgbẹ àwọn Gomina ariwa Naijiria ti ni awọn ko lodi si ikọ SARS.
Eyi lo mu ki minisita feto irinna lorilẹede yii, Rotimi Amaechi to fi n salaye fawọn ọmọ Naijiria lori idi ti ijọba apapọ se fẹ gba owoya lọwọ ilẹ China.
won di tẹlẹ ati ninu atundi ibo to tun waye.
Gani Adams: Inú ìpèbí ni Ọ̀yọ́mèsì ti pàṣẹ kí n yan olóyè mi
Jeieli, baba Gibeoni, ń gbé ìlú Gibeoni, Maaka ni orúkọ iyawo rẹ̀.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Joshua to ti gba ami ẹyẹ to ga ju lagbo ere idaraya ẹṣẹ kikan lagbaye lẹẹmẹta ọtọọtọ fidirẹmi, to si jẹ iya ajẹbolori lọwọ ẹni ti ko to o, Andy Ruiz lasiko ti wọn koju ara wọn ni Madison Square Garden.
OLUWA sì ṣe ohun tí Mose bèèrè, ó mú kí ọ̀wọ́ eṣinṣin náà kúrò lọ́dọ̀ Farao ati àwọn ẹmẹ̀wà rẹ̀ ati àwọn eniyan rẹ̀.
Nítorí o ti jẹ́ kí ọmọ eniyan dàbí ẹja inú òkun, ati bí àwọn kòkòrò tí wọn ń rìn nílẹ̀, tí wọn kò ní olórí.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ọgbà ẹ̀wọ̀n ni wọ́n ti já àbálé Esra lábẹ́ àwáwí àyẹ̀wò wúndíá Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Jẹ́ kí àwọn yòókù pada sí ilé wọn.
Ahimaasi dáhùn pé, “Mo ṣá fẹ́ lọ ni, ohun yòówù tí ó lè ṣẹlẹ̀.
Kí ẹ wá kó ọkà jọ sinu abà mi.
Lẹ́yìn ikú Simiri àwọn ọmọ Israẹli pín sí ọ̀nà meji.
“Kí ni ẹ rí tí ẹ fi ń pa irú òwe yìí nípa ilẹ̀ Israẹli, tí ẹ̀ ń sọ pé,‘Àwọn baba ni wọ́n jẹ èso àjàrà tí ó kan,ni eyín fi kan àwọn ọmọ?
Ijọba ipinlẹ Kano labẹ isejọba Gomina Abdullahi Ganduje ti fi ontẹ lu abadofin to fọwọ si pe ki wọn pin Kano si ọna mẹrin, ki Emir mẹrin le maa jẹ.
“Ní ọjọ́ kẹwaa oṣù keje yìí, ẹ óo máa ní àpèjọ mímọ́, ẹ kò gbọdọ̀ jẹ ohunkohun bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò gbọdọ̀ ṣe iṣẹ́ kankan.
Vice Presidential Debate: Osinbajo,Peter Obi ko yọju ‘ASUU da ìyanṣẹ́lódì dúró' Obasanjo, Osinbajo, Shonekan àtàwọn èèkàn ọmọ Ogun nínú ìṣèjọba Nàìjíríà.
5 223,812 Bosnia and Herzegovina 4,411 132.
Ileeṣẹ ọlọpaa ipinlẹ Katsina ṣalaye pe ni aago mọkanla aabọ alẹ ọjọ Ẹti lawọn gbọ pe awọn janduku pẹlu ibọn AK47 lọwọ wọn yabo ileewe girama to wa ni Kankara.
ati pé, ẹ kò gbọdọ̀ bá èyíkéyìí ninu àwọn tí wọn ń gbé ilẹ̀ yìí dá majẹmu kankan, ẹ sì gbọdọ̀ wó gbogbo pẹpẹ wọn lulẹ̀.
WÈRÉDÌRAN TÍ Ń GBÉ ILÉ ÒMÙGỌ̀PARAPỌ̀
Bí mo bá ti jí, tí mo pàrọ̀ aṣọ, máà gbé orin sí i, iṣẹ́ lílọ ara bẹ̀rẹ̀ nìyẹn.
Tẹ́ bá fẹ́ lo ìwọ́de láti gba àkóso ìjọba, wọn yóò dá yín lẹ́kun - Tinubu Oríṣun àwòrán, @AsiwajuTinubu Gomina tẹlẹ nipinlẹ Eko ati asiwaju ẹgbẹ oṣelu APC, Bola Ahmed Tinubu, ti sọrọ nipa iwọde ENDSARS to gbode jake jado Naijiria.
Ẹ ṣeun o ẹ̀yin ènìyàn rere wọ̀nyí.
Attah ni paapaa julọ nipa itẹsiwaju ẹkọ wọn pẹlu ileri pe nibayii, ileeṣẹ ọgba ẹwọn lorilẹ-ede Naijiria ni yoo maa gbọ ilaji bukata owo ileewe ẹlẹwọn yoowu to ba fẹ kẹkọ lasiko to ba wa lẹwọn.
Wọ́n fi ibi san oore fún mi,ọkàn mi sì rẹ̀wẹ̀sì.
Oríṣun àwòrán, Others Àkọlé àwòrán, Gbajugbaja Osere tiata ti orukọ rẹ n jẹ Taiwo Akinwande, ti wọn n pe ni Yetunde Wunmi ni Ajọ NDLEA mu ni Osu Kẹwaa, ọdun 2006 fun ẹsun gbigbe oogun oloro ni papakọ ofurufu Murtala Muhammed International Airport (MMIA), Ikeja, ni ilu Eko.
Nítorí pé òfin tí a bá kọ ní orúkọ ọba, tí ó sì ní èdìdì ọba, ẹnikẹ́ni kò lè yí i pada mọ́.
"Ẹni ti iya ba jẹ ko ni dakẹ, mo ti sọ funle ẹjọ pe ko se ẹtọ ati igbesẹ to daa lori iya ti Oluwo fi jẹ mi, amọ to pada sọ pe ko si ija kankan laarin wa.
Ondo 2020: Tani ìgbìmọ̀ tó ń sàyẹ̀wò olùdíjẹ lábẹ́ APC nípínlẹ̀ Ondo yọ kúro gan-an?
Johnson Suleiman Oríṣun àwòrán, OFM/ Stephanie Otobo Alufaa yii, to jẹ olori ijọ Omega Fire Ministries International ti oriko rẹ wa ni Auchi nipinlẹ Edo, wọnu iroyin ni ọdun 2017 nigba ti arabinrin kan ti orukọ rẹ n jẹ Stephanie Otobo fi ẹsun kan wipe o fun oun loyun, o si ja oun silẹ.
Olufọkansin ni ọpọ lara awọn ọlọpaa Naijiria, to si n fi ara ṣiṣẹ lati pese aabo fun ẹmi ati dukia ni Naijiria, ao si ni dawọ atilẹyin wa duro ki wọn o le ṣe iṣẹ wọn."
Ó dójúti àwọn olóyè,ó tú àmùrè àwọn alágbára.
"Loni, inu mi dun pupọ pe mo fẹ ọrẹ mi lati igba ewe.
Àtéjáde náà to ka báyìí pé,  Ìjọba ìpínlẹ̀ Eko ti buwọ́lu ki àwọn akẹ́kọ̀ọ́ padà sí ilé ìwé yálà nilé ìwé alákọ̀ọ́bẹ̀rẹ̀ ni tàbi aládàni jákèjádò ìpińlẹ̀ Eko lọ́jọ́ keji, Osu kọkanla, sùgbọn àwọn tó ń gbe ilé ìwé le wọle ni ọjọ́ Aiku, ọjọ kini oṣu Kọkanla."
Wọn mẹnuba oriṣii ọna ti onikaluku wọn n gba lo oogun oloro ati orukọ irufẹ eyi ti wọn n mu.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Yaara ikẹkọọ nileewe ti wọn ti ji awọn ọmọ gbe nipinlẹ Katsina Oun lo mu ki awọn eeyan o ma a sọ fun ijọba lati ṣe atunto ilana eto aabo.
Wahala de ba gbajumọ osere tiata yii, ti oju rẹ si ri mabo ni ahamọ awọn asọbode.
Akọroyin naa tẹsiwaju pe ọkọ awọn sẹri pada sinu ilu Erinmọ lati duro diẹ ki isẹlẹ naa fi rekọja lọ, ki awọn to tun mu ọna ajo awọn pọn.
Láti ọ̀nà jíjìn réré ni mo ti ké pè ọ́,nígbà tí àárẹ̀ mú mi.
 Ó ti di bárakú tàbí àṣà fún wa pé a gbọ ́ dọ ̀ kọ ́ ọmọ tí a bá ṣẹ ̀ ṣẹ ̀ bí ni èdè .
 ni ìfá bá relé olókun kòdé mọ ́ .
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Mr Macaroni sọ nípa eré tí Fraky freaky, Sugar Daddy, You are doing well, freaky spicy fẹ́ Oṣere Allwell Ademola ni oun gbadura pe ọkan awọn oṣere ẹgbẹ oun a tubọ balẹ.
Nigeria Air Force recruitment 2020: Ilé iṣẹ́ ọmọogun Nàìjíríà ti ṣí ojú opó rẹ̀ fún ìforúkọ silẹ̀ àti ọ̀nà ti ó le gbà ṣe ìfọ̀rọ̀wánilẹ̀nuwò orí ayélujára fún iṣẹ́ náà
Abramu mú Sarai iyawo rẹ̀, ati Lọti, ọmọ arakunrin rẹ̀ lọ́wọ́ lọ, ati gbogbo ohun ìní wọn ati gbogbo àwọn eniyan tí wọ́n jẹ́ tiwọn ní Harani.
1 828295 Orilẹede Ukraine 14208 32.
Awọn nkan wọn yii lo si ṣe e ṣe ko sọ bi isejọba rẹ yoo ṣe jẹ itẹwọgba.
Ọ̀wọ́ EFCC tẹ ayédèrú Babaláwo pẹ̀lú òògùn abẹnugọ̀ǹgọ̀ Davido lẹjọ ro lórí àwọn obìnrin tó sọ panpẹ sí lọ́wọ́ - Ọlọ́pàá Àwọn ọkùnrin tó wà nínú ayé wa gbúdọ̀ bọ̀wọ̀ fún wa - Olùdásílẹ̀ FIN Àjẹ́ àti Aṣẹ́wó ní ìyá Rainbow - Òjòpagogo Jean-Marie Misago ṣalaye fun BBC pe olukọ naa to ẹgba si ọrun ati ẹsẹ Nishimwe debi wi pe, o n yọ ẹjẹ ni imu ati eti rẹ.
Opolopo lo fi Mohammed Salah ṣe apẹẹrẹ ninu idije yii nitori oun kọ lo pada gbogo fun Egypt.
Ka to wi ka to fọ, yoo pari ẹkọ rẹ ti yoo si mọ nipa Quran ati ẹsin Islamu daadaa'' Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Kí ni ìtumọ̀ àwọn alárùn covid-19 tí wọ́n ń pè ní ''Asymptomatic'' ?
Aminu Kano International Airport, nipinle Kano lonii ojoAje(Monday).
    Mo bá bi ọkùnrin kan báyìí kí ó sọ fún mi orúko ọkùnrin tí ó ná irú owó yìí, ẹni tí mo bi léèrè wí fún mi pé òun ni ọ̀gbẹ́ni Wèrédiran ti ń gbé ilé Òmùgọ̀parapọ̀.
Agbẹnusọ ile naa sọ pe, “Asiko Ramadan jẹ igba ti o yẹ ki a fifẹ han sira wa, ki a si sunmọ Olorun julọ, ki a jẹ ki ajọṣepọ wa dan mọran.
Tamari lọ, ó bá Amnoni lórí ibùsùn níbi tí ó dùbúlẹ̀ sí.
“Fi igi akasia tẹ́ pẹpẹ kan, tí wọn yóo máa sun turari lórí rẹ̀.
Oluwo ni ''Ọba kii pe meji laafin, mi o le jẹ ọba ki n tun maa fori balẹ fun nnkan mii laafin.
Bákan náà ni Jesu, ó jìyà lẹ́yìn odi ìlú kí ó lè sọ àwọn eniyan di mímọ́ nípa ẹ̀jẹ̀ òun tìkararẹ̀.
Ọkùnrin Lebanese tó lu ọmọ Nàìjíríà ní gbàǹjo lórí Facebook ti kó sí páńpẹ́ ọlọ́pàá Ọmọ orilẹede Lebanon, Wael Jerro to lu ọmọ Naijiria ni gbanjo loju opo Facebook rẹ ti wa ni gbaga ọlọpaa.
Àjẹsára hib àkọ ́ kọ ́ ni a ṣe jáde ní ọdún 1977 , èyí tí a rọ ́ pò pẹ ̀ lú àgbéjáde mìíràn tí nṣiṣẹ ́ dáradára jùú lọ ní àwọn ọdún 1990 .
egbe , Adamu Fanda ati adari awon abarapa , Misbau Lawal Didi.
Nígbà tí ó parì ọ̀rọ̀ yìí Ìjànbáforrítì dìde dúró láàrin wa ó bẹ̀rẹ̀ sí ọ̀rọ̀ í sọ, ó ní: Ẹ̀yin ẹgbẹ́ mi gbogbo, ẹ wò mí dáadáa, èmi, Ìjànbáforítì baba erin.
Ìgbà míràn ẹ̀wẹ̀, wọ́n a gbé gálọọnù jáde bi pé èpo ló wà nínú rẹ̀, wọ́n a wá sọ fún wa pé tí ako ba gba Islam àwọn ó dáná sún wa, ìdí nìyí ti àwọ́n míràn fi gba ẹ̀sìn.
pada sugbon omi po ju oka lo.
Inu mi dun bi aare se gba mi towo-tese, maa si tun mu awon imoran ti o gba mi lo.
Orin ni o, ìròhìn ní o tàbí ìwé àfetígbọ́, gbogbo ìgbà ni èmi máa ngbọ́ nkan ní tèmi.
Igbimọ to n gbẹjọ awuye-awuye lori eto idibo to wa niluu Abuja  tun tesiwaju pe ki ajo INEC kede Ademola Adeleke ti Peoples Democratic Party , gege bi gomina ipinle Osun ati pe  ko yẹ  ki ajo INEC kede Gboyega Oyetola , gẹgẹ bi gomina ipinle Osun.
Awọn ọlọpaa ilẹ South Africa ni ọwọ awọn ti tẹ eniyan mọkanlelogoji ti wọn ni i ṣe pẹlu ohun to n ṣẹlẹ yii.
Nitorinaa, ohun to ba gba laa fun lati daabo bo ileto wa, awọn oko wa.
Lere Ọlayinka to jẹ agbẹnusọ fun Gomina Ayọdele Fayose lo sọ bẹẹ fun BBC.
” Ni wọ́n bá gòkè lọ sọ́run ninu ìkùukùu, lójú àwọn ọ̀tá wọn.
Ṣé o kò fẹ́ kí òfin máa já ọ láyà?
Nígbà tí a dé ọ̀hún a kò bá ẹbọra náà ní ilé ṣùgbọ́n a ránńṣẹ sílẹ́ dè é wí pé bí ó bá padà dé ilé ki wọ́n jíṣẹ́ wa fún un.
ẹ ṣe ọ̀nà títọ́ fún ara yín láti máa rìn, kí ẹsẹ̀ tí ó bá ti rọ má baà yẹ̀, ṣugbọn kí ó lè mókun.
Iya Ewe, tun mu ẹnu ba iwa ipa sáwọn obinrin ninu idile tun mẹnuba ọpọlọpọ idi ti iyawo fi maa n duro sinu idile bẹẹ yatọ si itọju ọmọ.
Bí mo bá ń sọ òtítọ́, kí ló dé tí ẹ kò fi gbà mí gbọ́?
Nígbà tí ó dé èjìka rẹ̀ ó dúró kò sì lọ mọ́.
 15 : 40 ] eusebius mọ ipo rẹ nikan bi iha ariwa oke sioni , eyiti o ni ibamu pẹlu awọn aaye imọran ti o ni imọran julọ julọ ti igbalode .
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ẹrin Ijesa, Ọ̀ṣun Oṣogbo, àwọn ibùdó ìgbafẹ́ tí ó níi ṣe pẹ̀lú omi ní ilẹ̀ Yorùbá Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
OLUWA sì fi ìlú Libina ati ọba rẹ̀ lé Israẹli lọ́wọ́.
A kò mọ̀ọ́mọ̀ pa ọlọ́pàá mẹ́ta, aráàlú kan, ó ṣèèsì ni, ajínigbé la pè wọ́n - Iléeṣẹ́ ológun Òṣùká kékeré kò rẹrùn àgbà, orílẹ́èdè Nàìjíríà ṣòro púpọ̀ láti darí - Ibrahim Babangida A ò ní fààyè gba pípa ọmọ Naijirià nípakúpa ní South Africa mọ- Abike Dabiri Fídíò àwọn obìnrin tó n jó ní ìhòhò nígboro gbé Tekno dé àgọ́ ọlọ́pàá Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Omiyale Ile Ife: Dukia sọfọ, awọn eniyan si tun farapa O fikun wi pe awọn n kaakiri lati se idanilẹkọ ati ilanilọyẹ fun awọn ara ilu lori ibi ti ko yẹ ki wọn kọ ile si ati lori ibi ti ko yẹ ki wọn ma a da ilẹ si ki omiyale ma ba a waye ni ipinlẹ naa.
Nítorí bí ó ti jẹ́ pé nípasẹ̀ Adamu ni gbogbo eniyan ṣe kú, bẹ́ẹ̀ náà ni ó sì jẹ́ pé nípasẹ̀ Kristi ni a sọ gbogbo eniyan di alààyè.
Àwọn akẹ́kọ̀ọ́-bìnrin Naijiria fẹyin US ati China gbolẹ nidije ìmọ ẹrọ 'Obinrin lo mu mi fẹran orin kikọ' ‘Ẹsẹ kikan kọ mi lati di alagbara’ Nigba ti Sekinat wa ni ọmọ ọdun maarun ni oun ati Baba rẹ jijọ nasẹ lọ si papa iṣere naa ti o si ri awọn to n ja ẹṣẹ.
Ilé ẹjọ́ wọ́gilé ìgbẹ́jọ́ Olalekan 'Woodberry' Pọnle Òru òní ní ìjọba á ti afárá 'Third Mainland' ní Eko; Wo àwọn ọ̀nà míràn tí o leè gbà lẹ́yìn tí wọ́n bá tìí Ọlọ́lá jù lọ Terry Waya ni Bàbá Terseer Kiddwaya tó ń kópa nínú BBNaija 2020 Wo ohun tí Adájọ́ sọ nípa ìgbẹ́jọ́ Wòlíì Sotitobire l'Ondo Ọga agba patapata awọn ọlọpaa lo paṣẹ pe ki wọn ṣe iwadii lẹyin ti fidio bi awọn ọlọpaa yii ni iha Guusu-Ila Oorun Naijiria ṣe ṣe obinrin kan baṣubaṣu gba ori ayelujara kan to si ni ki wọn fi panpẹ ọba mu awọn oniṣẹ laabi naa.
Abraham, tó ń sisẹ́ gẹ́gẹ́ bíi Olùkọ́ni lérée bọ́ọ̀lù lẹ́yìn tó gba oyè kún oyè nílé ẹ̀kọ́ fásitì Gloucestershire ní ìlú ọba ni wọ́n sekúpa ní ìlú London lọ́jọ́ Àìkú.
Iṣẹlẹ naa mu ki igbakeji gomina ipinlẹ ọhun kede igbele oni wakati mẹtalelọgbọn ni ilu Jalingo.
Mú wàrà sísè mẹ́wàá yìí lọ́wọ́ fún olórí ogun ikọ̀ wọn, kí o sì bá mi wo alaafia àwọn ẹ̀gbọ́n rẹ, kí o gba nǹkankan bọ̀ lọ́dọ̀ wọn tí yóo fihàn mí pé alaafia ni wọ́n wà.
Ó sọ pé, ‘Wá ba mi ṣépè lé Jakọbu,kí o sì fi Israẹli ré.
Nitori naa, latari ifẹhonu han awọn araalu tọrọ kan nile igbimọ aṣofin ipinlẹ Eko lodi si yiyọ gomina Akinwumi Ambode lo mu ki awọn ọmọ ile igbimọ wọ inu ipade pajawiri lọ kanmọ kanmọ lẹyin ifẹhonu han naa.
ati àwọn tí wọ́n wà ní Aroeri, Sifimoti, ati ní Eṣitemoa; 
Nigeria 2019 Elections: Amòfin, àwọn òṣèré Tíàtà jà f'ẹ́tọ̀ọ́ àwọn olùdìbò àti òṣìṣẹ́ pàjáwìrì
Èémí ihò imú rẹ mú kí omi gbájọ,ìkún omi dúró lóòró bí òkítì,ibú omi sì dì ní ìsàlẹ̀ òkun.
Bí ẹnìkan bá rò pé òun jẹ́ olùfọkànsìn, tí kò bá kó ahọ́n rẹ̀ níjàánu, ó ń tan ara rẹ̀ jẹ ni, asán sì ni ẹ̀sìn rẹ̀.
Àkọlé àwòrán, Pẹlu ilu ati ijo ni wọn fi gbe aṣa laruge Àkọlé àwòrán, Orukọ mi ni ẹlẹrin ẹyẹ.
Osinbajo, ẹni to fi atẹjade sita loju opo Twitter rẹ lọjọru lẹyin ọjọ kan ti isẹlẹ naa waye ni orilẹede Naijiria yoo gba idajọ ododo fawọn oluwọde EndSARS to kagbako iku ojijij naa.
Ọpọ nnkan ti Sowore n sọ ninu awọn ifọrowanilẹnuwọ jọ bi ẹ ni wi pe ti oba de ori alefa,yoo gba gbogbo awọn agbagba oloselu si ẹgbẹ kan ti yoo si fi isejọba ọdọ rinlẹ.
Iya ọrẹ mi ba pe e pe ko ma pẹ wọle o to si da a lohun pe maami mo ma ti wa nile ọkọ kẹ.
 Aare awon omo ile igbimo Asofin agba, Onisegun oyinbo Bukola Saraki lo side eto naa pelu ileri pe gbogbo omo ile igbimo lo n fe satileyin to ye fun kiko iroyin lori awon abajade ninu ile igbimo.
Iná sọ nínú ilé Big Brother tó ń lọ lọ́wọ́ ní Cameroon Buruji Kashamu jẹ́ ènìyàn tó nífẹ̀ aráàlú- Gómínà Dapo Abiodun Iná jó àwọn ènìyàn 10 tó ń gbà ìwòsàn arùn Coronavirus níbùdó ìtọ́jú Baba Obasanjọ kò ní àrùn Coronavirus- NCDC NCDC kéde èèyàn 437 míràn tó ṣẹ̀ṣẹ̀ lùgbàdì Covid-19 ní Nàìjíríà, 142 gbàwòsàn Ileeṣẹ BBC ti ko gbogbo ohun eelo ilera ti a ra lati fi gba awọn oniṣẹ ibi yii mu pada si ile iwosan nlanla gẹgẹ bii ẹbun.
egbe to n ri si eto ile –kiko ati eto iwadii se ayẹyẹ ogoji odun ati ifilole
N óo mu ẹbọ nǹkan mímu wá fún OLUWA,n óo sì pe orúkọ rẹ̀.
Báyìí ni ẹbọra náà sọ bàbá mi kò sì bínú mọ́ òun àti Èṣù-kékeré ki ara wọn, wọn bọ ara wọn lọ́wọ́, olúkúlùkù sì kọjú si ibi tí ó ń lọ, ṣùgbọ́n gẹgẹ bi ìṣẹ̀dálẹ̀ wa, ìjà kì í lọ lásán kí oníjà ma ni ìfarapa rẹ̀ ya, ó sọ oògùn kan pàtàkì nù, ìkòkò tábà rẹ̀ sì dá.
O sọ nipa idanilẹkọ oriṣiriṣi ti wọn ṣe ki awọn eeyan to di SARS ati paapaa ofin alakalẹ iwa ọmọluwabi ti wọn fi kọ awọn agbofinro to darapọ mọ SARS nigba naa.
iyẹn, Ki o to di asiko yii o.
Kii ṣe gbogbo eniyan ni yoo ni anfaani si abẹrẹ ajẹsara yii lẹẹkan naa.
A Akinruluyọ tó wà ní Bárékè Rukuba sàlàyé bí wọn ṣe rí sààré náà pẹ̀lú ìrànwọ àwọn ajá ọlọpa tí maa ń fimu fílẹ̀ Ibi ti wọn ti rí sààré náà gẹ́gẹ́ bí ìròyìn ṣe sọ kò ju kìlómítà kan lo sí etí títì márosẹ̀ ní ibi tí wọn ti rí sàárè rẹ̀ Alkali ní olúdarí àti alábojúto àwọn osíṣẹ̀ ní ilé iṣẹ́ ọmọogun.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù LAUTECH Crisis: Makinde ní kí ìpínlẹ̀ Ọyọ gba àkóso fásitì náà ni ọ̀nà àbáyọ 26 Bélú 2019 Oríṣun àwòrán, Seyi Makinde Gomina ipinlẹ Ọyọ, Onimọ ẹrọ Seyi Makinde ti se abẹwo sile ẹkọ imọ ẹrọ fasiti Ladoke Akintola LAUTECH to wa nilu Ogbomoso ni aarọ ọjọ Isẹgun.
Láti orí 'Our Mumu don do' sí 'Revolution Now' Ìwọ́de #RevolutionNow forí ṣánpọ́n ní Ibadan, àgbófinró gbàkóso ojú pópó Bí ọdún Ọ̀ṣun Oṣogbo ṣe bẹ̀rẹ̀ rèé àti pàtàkì rẹ̀ fún Nàíjíríà Saudi ṣàtúnṣe lílẹ òkò mọ́ Asitani láti dẹ́kun títẹra-ẹni-pa Ìjọba Buhari ń wùwà bíi ìjọba Abacha lórí ọ̀rọ̀ Ṣoworẹ- Ṣoyinka Èmi kò gbé pọ̀ pẹ̀lú Kollington Ayinla àmọ́ ọjà t'ọ́mọ ti wọ̀ lọ̀rọ̀ àwa méjééjì - Salawa Abẹni Wọnyi ni diẹ lara aworan to ṣapejuwe bi eto naa ṣe lọ niluu Kabba nipinlẹ Kogi Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Wí fún wọn pé, ‘Èmi OLUWA Ọlọrun sọ pé àsọtẹ́lẹ̀ yìí ń bá àwọn olórí Jerusalẹmu ati àwọn eniyan Israẹli tí ó kù ninu rẹ̀ wí.
A sì ti múra tán láti jẹ gbogbo aláìgbọràn níyà, nígbà tí ẹ bá ti fi ara yín sábẹ́ wa.
@dbola01 lero tiẹ ni ọjọ p ti Aisha ti n pariwo pe kii se Buhari lo n se akoso ijọba, to si darukọ Mamman Daura.
ko fẹsẹ  mulẹ ni awon igbimo oba n sọ, niwon
gomina ipinle Oyo, Otunba Moses Adeyemo, akowe agba fun ijoba ipinle Oyo,
O ti wa di igba marundinlogun ọtọọtọ ti yoo gba ife ẹyẹ gboogi ni gọọfu bayii.
Nígbà tí àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀, Jakọbu ati Johanu, rí i, wọ́n ní, “Oluwa, ṣé o fẹ́ kí á pe iná láti ọ̀run kí ó jó wọn pa?
N ko le gba ko maa tabuku baba mi Oyedepo, se o ni baba bi?
orile-ede Isreal tuntun si Naijiria, ogbeni Shimon Ben-Shosan, lojoBo(Thursday),
Ó bá pada lọ sọ fún Eliṣa pé ọmọ náà kò jí.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Mo ń ṣa ike jọ láti san owó ilé iwé ọmọ mẹ́ta' Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Ileya: Saraki, awọn gómìnà rọ aráàlú láti máse sọ ìrètí nù
(Mines & Steel Development) márùndínlógójì  ) Sen.
Iyawo aarẹ naa dupẹ lọwọ awọn obinrin ati ọdọ fun atilẹyin wọn lasiko idibo naa.
Minimum wage tuntun kò túmọ̀ sí pé #30,000 ni yóò gun owó oṣù rẹ
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Kí ló mú kí ọkọ̀ kan tó jóná ráùráú lórí afárá Ojuelegba?
Mo kórìíra làálàá tí mo ti ṣe láyé, nígbà tí mo rí i pé n óo fi í sílẹ̀ fún ẹni tí ń bọ̀ lẹ́yìn mi.
Ẹ bọ́ aṣọ ẹrú rẹ̀ sílẹ̀, kí ó wà ní ilẹ̀ yín, kí ó sì máa ṣọ̀fọ̀ baba ati ìyá rẹ̀ fún odidi oṣù kan.
Bakan naa ni wọn ni awọn ri owo apapọ Naira ati dọla to le ni miliọnu mẹtalelaadọjọ gba pada lọwọ wọn, iyẹn $169,000 àti N92, 000, 000.
Bakan naa ni BBC Yoruba kan si Oloye Sẹgun Oni, lati fidi isẹlẹ yii mulẹ, o ni lootọ ni amugbalẹgbẹ oun nigba kanri naa ti jalaisi, ti iku rẹ si ka oun lara pupọ, amọ oun ko tii lee sọrọ kankan lori isẹlẹ yii.
Adeleke: Ajayi Shuaib tí wọ́n ní ó pe Adeleke lẹ́jọ́ ní irọ́ ni wọ́n pa mọ́ òun
Wọ́n ń gbé ìgbé-ayé wọn pẹlu ìbẹ̀rù Oluwa, wọ́n sì ń pọ̀ sí i nípa ìrànlọ́wọ́ Ẹ̀mí Mímọ́.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Oba Adedokun Abolarin ti Oke Ila: Ó ya ọ̀pọ̀ tó súnmọ́ mi lẹ́nu bí mo ṣe ń kọ́ Àwọn olóṣèlú, àti àwọn Ọba n gbàbọ̀dè fún ìpínlẹ̀ Ekiti lórí ọ̀rọ̀ àwọn tó n fi ipá bánilòpọ̀- Kọmísọ́nnà ètò ìdájọ́ Kọmísọ́nnà ètò ìdájọ́ nípìnlẹ̀ Ekiti fi ẹ̀sùn kan àwọn olóṣèlú, àti àwọn Ọba pé wọ́n ń di ìgbógunti ìfípábánilòpọ̀ lọ́wọ́ Agbẹjọro Agba, to tun jẹ kọmisanna fun eto idajọ, fun ipinlẹ Ekiti, Ọgbẹni Olawale Fapohunda, ti fẹsun kan awọn kan ni Ekiti.
Oríṣun àwòrán, @IsiakaAdeleke1 Àkọlé àwòrán, Meji ninu awọn ti wọn n jẹjọ naa ni wọn fi pamọ si ahamọ ọgba ẹwọn Adeleke yóò jẹ́jọ́ lẹ́yìn ìdìbò Osun - Ọ̀gá ọlọ́pàá Oríṣun àwòrán, @IsiakaAdeleke1 Àkọlé àwòrán, Senator Isiaka Ademola Adeleke Aarẹ Muhammadu Buhari ti pasẹ fun Ọga Agba Ọlopaa, lati ti ọwọ ọmọ rẹ bọ asọ lori iwe ipẹ̀jọ ti wọn fi n pe oludije si ipo gomina labẹ ẹgbẹ oselu PDP ni ipinlẹ Osun.
Nígbà tí ó rí Peteru tí ó ń yáná, ó tẹjú mọ́ ọn, ó ní, “Ìwọ náà wà pẹlu Jesu ará Nasarẹti.
Àkọlé àwòrán, Ara wa kii ṣe nkan iṣere yin, a kọ ifipabanilopọ Àkọlé àwòrán, Tọkunrin-tobinrin lo pejọ sibi iwọde naa Àkọlé àwòrán, Iwọde naa fa sunkẹrẹ-fakẹrẹ ọkọ loju ọna Mobolaji Bank Anthony, Ikẹja nibi ti ijọ COZA wa l'Eko Àkọlé àwòrán, Obinrin yii n sọ pẹlu akọle ọwọ rẹ pe 'ẹ maa gba awọn obinrin gbọ Àkọlé àwòrán, 'Adura ko le pa ifipabanilopọ rẹ.
Lero ti olori ile asoju sofin nilu Abuja, Yakubu Dogara, lasiko ipade akọroyin to se lori ikede naa ni, o se ni laanu pe eto iselu alagbada wa ti bọ sọwọ olori apasẹ waa.
Saraki sẹ́ pé àjẹmọ́nú Sẹ́nétọ̀ yóò di ₦15m 'Tattoo’ ara mi kò tí ì pọ̀ tó, mà á sì se si’ Owó oṣù tuntun kò le jẹ́ sísan, àfi.
” (Nítorí ọ̀rọ̀ yìí ni wọ́n ṣe ń pè é ní Edomu.
“Nítorí náà, sọ fún àwọn ọmọ Israẹli pé èmi OLUWA Ọlọrun ní kí wọn ronupiwada, kí wọn pada lẹ́yìn àwọn oriṣa wọn, kí wọn yíjú kúrò lára àwọn nǹkan ìríra tí wọn ń bọ
Ṣugbọn, oun kan naa ni orilẹede nibi ti ilaji awọn to n gbe ninu rẹ si n gbe ninu ìṣẹ́ ati òṣì- ìdá ọgọta ninu wọn ni ko si le gba ile gbigbe to dinwo julọ.
O ni baba n dana ifẹ yá oun ju bi awọn ọdọmọkunrin ṣe le ṣe lọ.
Ogunye ninu ọrọ rẹ sọ wi pe ofin nikan kọ lo sakoso Ile Igbimọ wọn yii, amọ asa ati ise ti wọn la kalẹ ni wi pe ẹgbẹ to ba ni asojusofin to poju lo ma n fa ẹni to ma a se Aarẹ Ile Igbimọ Asofin kalẹ.
Nínú ìkíni rẹ̀ si ọmọbinrin rẹ̀ Fridous Inumidun Adebayo bí ó ṣe ń ṣe ọjọ́ ìbí ọdún mẹ́ẹ̀dógún lónìí, mo gbàdúrà pé Ọlọrun yóò fún ọ ni ẹmi gígún àti àlàfíà tó pọ̀ fún ọ.
Eyi jẹ ara ọna lati daabo bo obinrin ati ọmọ inu rẹ lasiko oorun ọsan gangan.
Àgbàrá omíyalé ba ilé 500 jẹ́ ní Nàìjíríà Ẹ̀ẹ́dẹ́gbẹ̀ta ile lo ti lugbadi iṣẹlẹ omiyale to ṣẹlẹ ni ipinlẹ Katsina.
Ìgbé ayé Abiola Ajimobi nínú àwòràn pẹ̀lú àwọn ǹkan tó ṣẹlẹ̀ Ìgbà mẹ́jọ tí awuyewuye wáyé lórí ìṣèjọba Ajimobi Pẹlu ibasepọ tuntun yi, awọn ololufẹ wa yoo laanfani lati maa gbadun iroyin to ta leti ọhun nigba to ba wu wọn, lalẹ tabi lọsan gangan.
Nípa agbára rẹ̀, ó mú kí òkun parọ́rọ́,nípa ìmọ̀ rẹ̀, ó pa Rahabu.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Mọ ẹ̀tọ́ rẹ gẹ́gẹ́ bíi ọmọ Nàìjíríà gidi Ibà yọ Serena Williams ní Madrid open Bàtà àti aṣọ tú àṣírí afurasí adigunjalè Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Ẹ rò pé mò ń fi ọ̀rọ̀ ṣòfò lásán ni?
 Èyí lè jẹ ́ kí ìrònú àti àwọn oríṣiríṣi ìwà wáyé .
Ikú ti pa ọ́ tán báyìí, nítorí pé obinrin tí o mú sọ́dọ̀, aya aláya ni.
CAN ko lee sọ pe ẹ gbe owo eleyi kalẹ tabi ki ẹ maa gbe tọhun kalẹ.
Iwọ Oorun Gusu orilede yii tun jẹ ọna kan pataki ti yoo le gbogun ti awọn ipenija yii, O wa rọ ijọba apapọ lati ri daju wipe eto aabo to
Rí i dájú pé o ṣe gbogbo rẹ̀ pátá bí mo ti fi hàn ọ́ ní orí òkè.
Ọ̀sanyìn ẹlẹ́sẹ̀ kan lọ sí oko, ó pa itú ọwọ́ rè ó sì mú bàntẹ́ wá sí ilé.
Ìparun wa súnmọ́lé,ọjọ́ ayé wa ti níye,nítorí ìparun wa ti dé.
Ẹ tún wá fẹ́ kó tọkunrin tobinrin Juda ati Jerusalẹmu lẹ́rú.
Lasiko to n ba BBC sọrọ lori aseyọri rẹ yii, Tani salaye pe inu mọto oun ni oun ti bẹrẹ si ta ayo Chess, ti oun si gbaradi fun idije naa, nipa lilo awọn ohun eelo ere Chess igbalode to wa fawọn ọmọde.
Lara awọn jankanjankan to tun wa nibi ayẹyẹ yii ni Olori ọmọ ẹgbẹ to pọ ju ninu Ile Igbimọ Aṣojuṣofin orilẹ-ede Naijiria, Aṣofin Fẹmi Gbajabiamila, Agbaninimọran lori ọrọ ofin si ẹgbẹ Oṣelu All Progressives Congress (APC), Aṣofin Babatunde Ogaia; Olori ẹka obinrin ẹgbẹ oṣelu APC ni apa Iwọ-oorun Gusu orilẹ-ede yii, Arabinrin Kẹmi Nelson, Ajafẹtọ-ọmọniyan, Amofin Fẹmi Falana, Akọwe Agba si ijọba Ipinlẹ Eko, Ọgbẹni Tunji Bello, pẹlu awọn lọbalọba ati awọn eniyan pataki miiran.
1 7160 Orilẹede Chad 110 0.
“Ọjọ́ meje ni ẹ gbọdọ̀ máa fi se àsè àjọ̀dún àgọ́ nígbà tí ẹ bá kó ọkà yín jọ láti ibi ìpakà, tí ẹ kó ọtí waini yín jọ láti ibi ìfúntí.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Kọmísọ́nnà ètò ìdájọ́ nípìnlẹ̀ Ekiti fi ẹ̀sùn kan àwọn olóṣèlú, àti àwọn Ọba pé wọ́n ń di ìgbógunti ìfípábánilòpọ̀ lọ́wọ́ 26 Bélú 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 27 Bélú 2020 Oríṣun àwòrán, Twitter/olawala fapohunda/kayode fayemi Agbẹjọro Agba, to tun jẹ kọmisọnna fun eto idajọ, fun ipinlẹ Ekiti, Ọgbẹni Olawale Fapohunda, ti fẹsun kan awọn kan ni Ekiti.
Nígbà náà ni ọba na ọ̀pá àṣẹ wúrà sí Ẹsita.
Tori eyi, awọn agba a maa gba awọn alaisan foniku fọla dide nimọran ki wọn tete fẹ ọkọ tabi iyawo ki wọn le tete bi ọmọ saye tori ti wọn o ba ku.
sọ pe,  egbe APC lo jawe olubori ninu eto
Adari ikọ naa ni ipinlẹ Ondo, Adetunji Olu-Adeleye ni wọn bẹrẹ igbesẹ lati maa gba awọn eeyan naa siṣẹ lẹyin ti gomina ipinlẹ naa, Rotimi Akeredolu fọwọ si agbekalẹ ikọ alabo ọhun.
9 Àti nísisìyí, Oliver Cowdery, èmi bá ọ sọ̀rọ̀, àti bákannáà sí David Whitmer, nípa ọ̀na àṣẹ; nítorí, kíyèsíi, mo paáláṣẹ fún gbogbo ènìyàn níbigbogbo láti ronúpìwàdà, àti pé mo wí fún yín, àní bíi sí Paul Àposteli mi, nítorí a pè yín àní pẹ̀lú ìpè kan náà pẹ̀lú èyítí a fi pè òun.
MC Oluomo: Àánú ni mo rí gbà láti di alága NURTW Eko
Wọ́n ti fi òkú àwọn iranṣẹ rẹfún àwọn ẹyẹ ojú ọ̀run jẹ;wọ́n sì ti sọ òkú àwọn eniyan mímọ́ rẹ di ìjẹfún àwọn ẹranko ìgbẹ́.
Asoju ọhun ,soro yii lasiko to
Nítorí ó ti dájọ́ fún gbajúmọ̀ aṣẹ́wó náà, tí ó fi àgbèrè rẹ̀ ba ayé jẹ́.
“Ẹ sá kúrò láàrin Babiloni, ẹ jáde kúrò ní ilẹ̀ àwọn ará Kalidea, bí òbúkọ tí ó ṣáájú agbo ẹran.
’ Bẹ́ẹ̀ ni kíkí ń pe kíkí, tí àdúrà ń pe àdúrà níjà.
Ṣugbọn nígbà tí wọ́n dé ibùdó-ogun náà, àwọn ọmọ ogun Israẹli kọlù wọ́n, títí tí wọ́n fi sá pada; wọ́n sì ń pa wọ́n ní ìpakúpa bí wọ́n ti ń lé wọn lọ.
Awon ise akanse wonyii je ona idagbasoke si agbegeb Abuja ki okan awon eniyan le tubo bale loju popo.
Koju oṣu meji ti Leujoe bẹrẹ isẹ, lo lọ ba ọga rẹ pe ko fun oun lara owo oṣu oun fun oṣu Kejila.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, '500 level'' ni mo wà nígbà tí mo di adélé Ọba' Olukemi Olufunto Adegoke Badenoch Oríṣun àwòrán, kemi badenoch Àkọlé àwòrán, Ko si nkan ti ọkunrin n ṣe ti obinrin ko le ṣe Ni oṣu, keje ọdun 2019 ni Olootu ijọba ilẹ Gẹẹsi, Bori Johnson yan arabinrin Olukemi Olufunto Adegoke Badenoch gẹgẹ bii minisita abẹle fun ọrọ awọn ọmọde ati idile.
Nítorí ariwo kan ti gba gbogbo ilẹ̀ Moabu kan,ẹkún náà dé Egilaimu,ìpohùnréré náà sì dé Beerelimu.
Òun náà sì ni ó nta oúnjẹ àti nkan mímu níbẹ̀.
Kidnappings in Nigeria: Ajínigbé ń bèèrè fún epo, iṣu àti ọ̀tí Schinap àti owó ìtanràn
Coronavirus: Ohun tó ṣì ṣókùnkùn sí ìgboro ayé nípa àrùn Covid-19
Nítorí náà, Israẹli wà ní alaafia,àwọn ọmọ Jakọbu sì ń gbé láìléwu,ní ilẹ̀ tí ó kún fún ọkà ati ọtí waini,tí ìrì sì ń sẹ̀ sórí rẹ̀ láti ọ̀run wá.
Àwọn mìíràn rò pé Alẹkisanderu ni ó dá gbogbo rẹ̀ sílẹ̀, nítorí òun ni àwọn Juu tì siwaju.
Sotitobire Church: Òótọ́ àti irọ́ tó wà nínú iṣẹ̀lẹ̀ náà
NAFDAC ti parí ìwádìí lórí codeine Àbádòfin ọ̀hún ń wá ojúùtú sí òfin ìjọba Nàíjíríà ti ọdún 2004 tó de oúnjẹ, àti àwọn ǹkan tó jọ mọ́ òògùn, Òfin náà tí Betty Apiafi ( PDP Rivers) ṣe onígbọ̀wọ́ fún tún ń wá àtúnṣe sí ìjìyà tí yóò ṣe é gbọ́ nílé ẹjọ́ gíga àpapọ̀ àti ti ìpínlẹ̀ Àbádòfin òhun ṣe àlàkalẹ̀ ìjìyà ẹnìkọ̀ọ̀kan láti orí ẹ̀ẹ́dẹ́gbẹ̀ta náírà, ẹ́wọ̀n ọdún méjì tàbí owó ìtanran àti ẹ̀wọ̀n papọ, tí ilé-iṣẹ́ àti gbogbo àwọn lọ́ọ̀gálọ́ọ̀gá ibẹ̀ yóò jẹbi ẹ̀sùn gẹgẹ bíi pé àwọn gan ló ṣẹ̀.
Ìmọ̀ràn mi fún ọmọ ènìyàn ni èyí pé, kí olúkúlùkù tọ́jú òbí rẹ̀, ìba díẹ̀ ló lè ṣe bíi bàbá àti ìyá fún ni, ìgbà tí àwọn òbí bá ti fi ẹ̀hin sílẹ̀ tán, ó ku olúwaarẹ̀ pẹ̀lú Ọlọ́run.
Semi Ajayi (Rotherham United, England)Awon agbaboolu
 a máa ń lo akan fún àwọn èdè tí ó fara pera wọ ̀ nyí ashante , fante àti iwì tí àwọn tó ń sọ wọ ́ n gbọ ́ ara wọn ní àgbóyé dáàyè kan ṣùgbọ ́ n tí wọ ́ n kà sí èdè òtọ ̀ ọ ̀ lọ ̀ nítorí àṣà àti ọ ̀ nà ìgbà kọ nǹkan sílẹ ̀ wọn tí kò bára mu .
OLUWA wí fún Joṣua pé, “Má bẹ̀rù wọn, nítorí pé mo ti fi wọ́n lé ọ lọ́wọ́.
Ṣugbọn ṣa, o ṣeeṣe ki idije AFCON 2021 ni ipa lara idije Champions League nitori awọn agbabọọlu ilẹ Africa bi i Sadio Mane, Mohammed Salah, ati awọn miran to le fẹ gba bọọlu fun orilẹ-ede wọn.
‘Irọ́ ni pé Ọmọ ọdọ̀ Ọpẹ Bademosi kú’ Ọjọ kẹta lẹyin ti wọn gba Sunday Anani, si iṣé ni o fi ọbẹ gun ọga rẹ pa ti o si ko awọn dukia ọga rẹ salọ.
Ewe, afojusun ijoba yii bayii ni lati pese ise fun awon odo wa jakejade orile-ede yii.
Igbesẹ eyi ni Abdullahi sọ pe oun ni igbagbọ pe yoo yọri, nitori pe awọn pasitọ gan an n ṣe awuyewuye pe eto aabo ko fararọ ni Naijiria.
Mẹ́wàá ninu àwọn ọdọmọkunrin tí wọn ń ru ihamọra Joabu bá yí Absalomu po, wọ́n sì ṣá a pa.
Rex Tillerson: Amẹrika yoo ṣe'ranwọ owo tuntun fun Afirika
Síbẹ̀síbẹ̀ náà, n kò gbọdọ ṣáì sọ nǹkan tí ó sẹlẹ̀ sí mi ní ìlú tí à ń pè ní Ìtànjẹ-ènìyàn.
Ṣe ni iroyin sọ pe aarẹ Alexander Lukashenko lo tun jawe olubori ninu idibo ọjọ Aiku pẹlu ibo to le ni ida ọgọrin.
Nígbà tí gbogbo àwọn ọmọ Israẹli ń kọjá lọ lórí ilẹ̀ gbígbẹ, àwọn alufaa tí wọ́n ru Àpótí Majẹmu OLUWA dúró lórí ilẹ̀ gbígbẹ láàrin odò Jọdani, títí tí gbogbo àwọn eniyan náà fi la odò Jọdani kọjá.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ejo abami to n mu owo ni ajọ Jambu Agbowo ileefiweranṣẹ naa ko owo ti arakunrin yii mu wa pẹlu awọn owo miran to wa ni aapo ileeṣẹ naa.
Fà mí mọ́ra, jẹ́ kí á ṣe kíá,ọba ti mú mi wọ yàrá rẹ̀.
Nígbà tí ó pẹ́ mo bẹ̀rẹ̀ sí gbọ́ agogo, eléyìínì sì fi hàn mi pé àwọn ẹeranko parí ìpàdé wọn.
Mama Odegbami lasiko to n ba awọn oniroyin sọrọ wi pe ọmọ ọrẹ oun ti oun de si ọdọ wọn ni Amerika lo mu oun mọ Beyonce.
Ojú alágbe ni wọ́n fi ń wo alága ìdúró- Ayo Oladokun Zoe ati Maria si ti n saayan siwaju lati se afikun imọ loju opo Pussypedia, ko lee wa ojutu si isoro ti awọn obinrin n koju lati ni imọ nipa ẹya ara wọn atawsn ohun to rọ mọ.
Awọn oludije lati ẹgbẹ oselu APC, ADP, ADC ati SDP fi ero wọn han lasiko ipade itagbangba ti Ile-Ise Iroyin BBC News Yoruba gbe kalẹ saaju ọjọ idibo si ipo goimna ti yoo waye ni Ọjọ Kejilelogun, Osu yii.
Obinrin ará Samaria náà dá Jesu lóhùn pé, “Kí ló dé tí ìwọ tí ó jẹ́ Juu fi ń bèèrè omi lọ́wọ́ èmi tí mo jẹ́ obinrin ará Samaria?
Bakan naa ni ajọ EFCC si n sọ pe : owo to wọle lati ara igbani sisẹ naa ko ba ofin mú.
Báwo ni wàhálà ṣe bẹ̀rẹ̀ fún Shittu?
Ni ìjọ bá pinnu pé kí Paulu ati Banaba ati àwọn mìíràn láàrin wọn lọ sọ́dọ̀ àwọn aposteli ati àwọn alàgbà ní Jerusalẹmu láti yanjú ọ̀rọ̀ náà.
Oriṣiriṣi ẹ̀ṣọ́ ara ni awọn obinrin ati ọkunrin iran Yoruba maa fi n dárà si agọ ara wọn.
ti pe ipade pajawiri, ni eyi ti won yoo ti jiroro lojo Ẹti nipa gbedeke ti won
Ni ọjọ kẹwa oṣu karun un ọdun 2019 lawọn oṣiṣẹ ajọ EFCC mu Naira Marley niluu Eko.
O ni idi iya naa to maa n ji nigbakugba to ba n rin lo mu ki oun ma lee mu ara duro mọ ti oun si fi lo ipa fi baa lo.
Wọn kò ranti OLUWA Ọlọrun wọn tí ó gbà wọ́n kúrò lọ́wọ́ gbogbo àwọn ọ̀tá wọn ní gbogbo àyíká wọn.
Sugbọn ni agbegbe Meherpur ni iwọ oorun Bangladesh ni nkan ara ọtọ ti ṣẹlẹ.
Ẹnikẹ́ni kò rí i mọ́ nítorí pé Ọlọrun ti mú un lọ.
Ní àkókò yìí gan-an ni Saulu ń ti oko rẹ̀ bọ̀, pẹlu àwọn akọ mààlúù rẹ̀.
Nigba ti ikọ ọlọpaa debẹ, wọn ri i pe ko si ẹmi kankan lara rẹ mọ wọn si gbe e lọ si ile igboku si.
O mẹnuba awọn aṣeyọri ijọba rẹ ni saa to kọja (2015 si 2019).
" Orúkọ Burna Boy wọ àmì ẹ̀yẹ Grammy nítorí orin rẹ̀ 'Twice as Tall' Wo dókítà ọmọ Nàìjíríà tí àgbáyé ń wárí fún nítorí abẹ́rẹ́ àjẹsára COVID-19 Ìdí rèé tí ìjọba fi ń gbèrò pé kí àwọn tó ń gba 'minimum wage' má san owó orí mọ́ Ilé ẹjọ́ dájọ́ ẹgba mẹ́ẹ̀dóògún fún ọ̀daràn tó jí Iphone ní Kaduna Ǹkan tí ó yẹ ki o mọ̀ nípa Burna Boy Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Divorcee: Ó sàn kí wọ́n yàgò fúnra wọn ju ki wọ́n ṣe ara wọn léṣe- Fisayo Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Amos Dauda, Iphone: Ilé ẹjọ́ dájọ́ ẹgba mẹ́ẹ̀dóògún fún ọ̀daràn tó jí Iphone ní Kaduna25 Bélú 2020 Ondo Heardsmen vs Falae: Ilé iṣẹ́ ọlọ́pàá ìpińlẹ̀ Ondo ni Olóyè Falae kò tí ì mú ẹjọ́ wá si àgọ́ ọlọ́pàá kankan24 Bélú 2020 Jemila dáná sún ilé ọ̀rẹ́kùnrin rẹ̀ àti ọ̀rẹ́bìnrin tó bá nílé24 Bélú 2020 Helicopter crash in Lagos: Àbájáde ìwádìí ẹlikọ́pítà to já ni Opebi laipẹ yii ti jáde21 Owewe 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 3 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 5 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Ṣùgbọ́n ẹni tí ó ń na ọwọ́ rẹ̀ kò lè tó láéláé ìrù ló kù kí eléyìínì dì ọ̀bọ kí ó máa bẹ́ láti orí igi dé orí igi.
Oloogun ko ni ipa kankan lati ko ninu eto idibo Atiku ni o lodi si ofin ijọba tiwan-tiwa lati da awọn oloogun sita nigba idibo.
Lẹ́yìn ogún ọdún tí Solomoni fi kọ́ ilé OLUWA ati ààfin rẹ̀, 
com/4buxOhwjHd— 🇳🇬 Super Eagles (@NGSuperEagles) June 5, 2018Essentuki and it’s people turn up for @NGSuperEagles‘ first training ahead of Croatia #WorldCup clash #SoarSuperEagles #Team9jaStrong pic.
Mo fà wọ́n mọ́ra pẹlu okùn àánú ati ìdè ìfẹ́,mo dàbí ẹni tí ó tú àjàgà kúrò ní ẹ̀rẹ̀kẹ́ wọn,mo sì bẹ̀rẹ̀, mo gbé oúnjẹ kalẹ̀ níwájú wọn.
Oríṣun àwòrán, @semasir Dj Jimmy Jatt wa lara awọn to daro rẹ loni: K- Solo ni orin Dagrin ma n dabi ọtun leti oun nigbakigba ti oun ba ti gbọ.
Sotitobire Miracle Centre Ka ma gbagbe, iṣẹlẹ kan wa to ti bẹrẹ si ni gbode lati bii oṣu melo sẹyin ni ilu Akurẹ ipinlẹ Ondo ni ijọ Sotitobire Miracle Centre nibi ti ọmọ ọdun kan, Gold ti dede poora titi di akoko yii.
Gold Kolawole, ọmọ tó sọnù ní ṣọ́ọ́ṣì Sotitobire kò bá pé ọdún méjì lónìí Ninu atẹjade kan ti ẹgbẹ JOHESU kede iyanṣẹlodi ọhun ninu atẹjade kan to fi sita lọjọ Aiku.
”Gege bi Oba ilu Obolo Lopon tilu Ugep, Mo ti setan lati ni ibasepo pelu awon ile-ise ijoba kookan to mojuto yiyanju rogbodiyan laarin ilu tabi eya lorile-ede Naijiria.
Nibayii a o mọ ẹni ti yoo ṣalaye fun wa nipa rẹ."
Wọ́n gba ìwọ́ àbúrò rẹ ti wọ́n bi wọ́n sì lòó láti fi ṣe ìwòsàn rẹ̀.
N óo bù sí oúnjẹ rẹ̀ lọpọlọpọ;n óo fi oúnjẹ tẹ́ àwọn aláìní ibẹ̀ lọ́rùn.
M Atoyebi sọ fun wa pe lootọ lawọn kọ ìwé ipẹjọ yi akọ awọn yoo wọgile niwaju ileẹjo pada lọjọ Ẹtì nitori bi ọrọ naa ṣe n lọ.
Nítorí náà, nígbà tí wọ́n gbọ́ ìró àwọn ohun èlò orin náà, gbogbo wọn wólẹ̀, wọ́n sì sin ère wúrà tí Nebukadinesari, ọba gbé kalẹ̀.
Ileejọ tun ni ki se afikun abala ti yoo fun awọn eeyan to ni oju ara meji lanfaanin lati sọ irufẹ ẹda ti wọn jẹ.
Ọpọ ọmọ Naijiria lo ti n sọ lori ayelujara pe ileeṣẹ ọlọpaa dọgbọn sí aworan awọn ọdaran kan to wa loju opo rẹ lọjọ kinni, oṣu kejila, ọdun 2020 yii.
Ìdààmú-Ayé sí ni àrẹ̀mọbìnrin Olόyè Ògbójú, Mọ́gàjí Ilé-Ìkà ní Ìlú Ìbàjẹ̀-Ènìyàn.
” Satani bá kúrò níwájú OLUWA.
Lataari eyi ni awọn alaṣẹ mọṣalaṣi mejeeeji fi sọrọ loju opo facebook wọn ti wọn si ṣalaye ni kikun ohun to ṣokunfa igbesẹ yii.
Ní ọjọ́ kan, mẹta ninu àwọn ọgbọ̀n ọ̀gágun olókìkí lọ sọ́dọ̀ Dafidi nígbà tí ó wà ní ihò Adulamu, nígbà tí àwọn ọmọ ogun Filistini dó sí àfonífojì Refaimu.
1 16477 Orilẹede Ghana 325 1.
Ti a o ba gbagbe pe, gomina ipinle
22 Bélú 2020 Fídíò, Akomolede Yoruba: Kí ni ìdí tí aṣọ fi máa ń pọ̀ lára Egúngún ju Orò lọ́?
Ṣugbọn fún àwọn tí kò gbàgbọ́, gẹ́gẹ́ bí Ìwé Mímọ́ ti wí,“Òkúta tí àwọn mọlémọlé kọ̀ sílẹ̀,òun ni ó di pataki igun ilé.
Aare fi idunnu re han pelu iroyin ti asoju orile ede Poland Eric Adagogo Bell-Gam.
Ìbò 19,344 ni APC fi f'àgbà han PDP.
Nígbà náà, nípa ti ẹ̀dá ara, àwa náà wà ninu àwọn ọmọ tí Ọlọrun ìbá bínú sí, gẹ́gẹ́ bí àwọn eniyan yòókù.
Djxgee kede iku ara rẹ lori Instagram ko to gbe majele jẹ Adura gbogbo ọmọ Naijiria ni pe ki Ọlọrun da ẹmi awọn si lati se ọpọ ọdun laye ni kete taa wọ inu ọdun tuntun 2019.
 Àwọn tí wọ ́ n ń sọ ọ ́ jẹ ́ mílíọ ̀ nù kan .
Seyi Makinde: Àwọn ọba yoo ko ipa pataki lati gbogun ti aabo to mẹhẹ
Òní ni ọjọ́ àwùjọ àwọn ẹranko, níbi tí onírúurú ẹranko gbogbo péjọ sí tí wọ́n ń péré nípa ìgbésí-ayé wọn, ebi ní ń pa mi tí mo rọra yọ́ kẹ́lẹ́kẹ́lẹ́ láàárin wọn, nítorí bí ebi bá ti kúrò nínú iṣẹ́, iṣẹ́ bùṣe.
Ọkọ̀ akérò BRT gbiná lórí afárá 3rd Mainland Iṣẹ́ Kudirat Abiọla ṣì ń fọhùn síbẹ̀, lẹ́yìn ọdún 23 tó papòdà Mi ò gbè lẹ́yìn Naira Mailey fún ìwà ìbàjẹ́- Daddy Showkey Ilé alájà mẹ́ta wó pa onímọ̀ ẹ̀rọ́ tó ń kọ́ ọ lọ́wọ́ Air pollution: Nàìjíríà ni orílẹ̀ède kẹrin tí atẹ́gùn búburú ti ń pa ènìyàn jù làgbáyéé Olóri oṣisẹ̀ láàfin Emir, Munir Sanusi tó jẹ́ri si gbigba ìwé ẹsùn náà, sọ pe, ìjọba ní ki Emir fesi láàrin wákàti mẹ́rìnlélogun lóri ẹ̀sùn náà.
Awọn asofin naa ni: Adamu Aleiro, Bala Ibn Na-Allah, Aliyu Wamako, Ibrahim Gobir,  Kabiru Marafa,  Abu Ibrahim, Kabiru Gaya, Barau Jibrin, Abdullahi Gumel,  Shehu Sani ati Ahmed Lawan.
Awọn alaṣẹ agbabọọlu France paṣẹ ko ma kopa ninu ifẹsẹwọnsẹ mẹta tori pe o gba ololufẹ ere bọọlu kan lẹyin ti ẹgbẹ agbabọọlu Rennes na PSG bolẹ ninu aṣekagba idije Coup de France loṣu to kọja.
Ninu ọrọ to ba ileeṣẹ iroyin kan ni ilu Ọṣogbo sọ, alukoro fun ileeṣẹ ọlọpaa ni ipinlẹ Ọṣun, ASP Yẹmisi Ọpalọla, salaye wi pe darukọ arakunrin naa gẹgẹ bi Daramọla Wasiu.
 lafikun , arun fisera se e yẹwo nipa ayẹwo ẹjẹ .
Ninu idije Champions League ti yoo bẹrẹ loni yii ni ẹgbẹ agbabọọlu jankọ jankọ yoo ti gbena woju ara wọn.
Loṣu kejila ọdun 2019 ni wọn kọkọ foju ba ileẹjọ Majisireti Oke Eda niluu Akure.
Ijọba Naijiria ni Leah Sharibu ko tii ku -Garba Shehu.
Èyí jẹ́ kí n mọ̀ pé ìyá mi ti sọ ohun tí ó ṣẹlẹ̀ sí mi fún- un.
leyin iforowanilenuwon, won bere si n yin ibon pa ara won.
BBC ṣe iwadii odiwọn iye owo ti awọn eeyan fi ranṣẹ si ara wọn lọdun 2018 ati odiwọn iye to bọ sọwọ awọn alarinna oṣiṣẹ ti wọn n ṣeto fifi owo naa ranṣẹ.
Yóo fi àwọn kan ṣe ọ̀gágun fún ẹgbẹẹgbẹrun ọmọ ogun, àwọn kan yóo máa ṣe ọ̀gágun fún araadọta ọmọ ogun.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Gold coast 2018: Nàìjíríà ní góòlù mẹ̀sán láti dúró ní ipò kẹsán 15 Ìgbé 2018 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ipo kẹsan lori atẹ igbelewọn ami ẹyẹ ni Nàìjíríà wà nibi idije naa Bí ìdíje àwọn orílẹ̀èdè tó ti fìgbàkan rí wà lábẹ́ ìmúnisìn ilẹ̀ Gẹ̀ẹ́sì, Commonwealth ṣe ń wá sí ìdádúró lọ́jọ́ àìkú, orílẹ̀èdèNàìjíríà ti bọ́ sí ipoò kẹsán lórí atẹ ìgbéléwọ̀n àmì ẹ̀yẹ níbi ìdíje náà.
Nítorí n kò rí iṣẹ́ kan tí o ṣe parí níwájú Ọlọrun mi.
Buhari padà sí Naijiria lẹ́yìn tó lọ tọ́jú ara rẹ̀
Kì í ṣe iyawo ni ó ni ara rẹ̀, ọkọ rẹ̀ ni ó ni í; bákan náà ni ọkọ, òun náà kò dá ara rẹ̀ ni, iyawo rẹ̀ ni ó ni í.
Koda, Kevin ti ta awo orin to le ni miliọnu meji, ti eeyan to le ni biliọnu meji si ti gbọ awo orin rẹ lori YouTube.
Mo bá dọ̀bálẹ̀ gbalaja níwájú OLUWA bíi ti àkọ́kọ́, fún ogoji ọjọ́; n kò jẹ, bẹ́ẹ̀ ni n kò sì mu, nítorí gbogbo ẹ̀ṣẹ̀ tí ẹ ti dá, tí ẹ ṣe ohun tí ó burú níwájú OLUWA, tí ẹ sì mú un bínú.
Ọ̀rọ̀ Ìkìlọ̀ Ọmọ aráyé ẹ jẹ́ ká ṣọ́ra fẹ́nu Ẹnu ní í lani Ẹnu ní í pani Ẹnu ní jin ni sọ́fìn Ẹnu làá fi ń tún ènìyàn ṣe Ẹnu la fi ń bá ènìyàn jẹ Ẹnu wa ò ní pa wá Kí o tó fi ẹnu sọ ohunkóhun Ẹ jẹ́ ká ronú jinlẹ̀ Torí bí ọ̀rọ̀ bá ti balẹ̀ Kò ṣe dápadà mọ Wọ́n ni ká bọ eégún ilé A bọ eégún ilé Wọ́n ní ká bọ òrìṣà ọjà A Bọ òrìṣà ọjà Wọ́n ní ká bọ olúbọ̀bọ̀tiribọ̀ baba ẹbọ Ǹjẹ́ kí ni olúbọ̀bọ̀tiribọ̀ baba ẹbọ?
Ṣugbọn ìwọ eniyan Ọlọrun, sá fún nǹkan wọnyi.
 báyìí tí jìjì ti lanu fọhùn pé nǹkan tóun fẹ ́ ràn jù , tí ẹni náà sì mú un wá ; ọ ̀ rọ ́ ti bù ṣe .
'APC kò fẹ́ ire fún mi mọ́ nínú ìṣesí wọn' Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ogundiya: Àṣìṣe Dókítà ló sọ mi di aláàbọ̀ ara lórí kẹ̀kẹ́ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Bimpe: Èèyàn bíi tiyín ni àfín, ẹ dẹ́kun dídẹ́yẹsí àfín Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Trump ti gbé òdòdó ìrántí sójú oórì akọni lójú ìjà Nàìjíríà yóò dá ṣèríà fún Senegal lónìí- Balógun Flying Eagles Ikilọ: Awọn aworan to le bani lẹru han ninu fọnran yii.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Igbese ti ajo ERA gbe lati koju tita siga lagbegbe ile ẹkọ Senato Remi Tinubu, nigba to n ba ile igbimọ asofin agba sọrọ wipe, siga mimu le fa aisan jẹjẹrẹ ọna ọfun ati awọn aisan mii to le se ipalara fun ẹjẹ ati ọkan awọn eniyan.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ti ènìyàn bá n jẹ ǹkan ti orá ba pọju, o ṣeeṣe ki àwọn ǹkan to ba bàjẹ lára maa le ṣe atunse ara.
Adéọjọ: Ọmọkùnrin tí a bí tí ìyá rẹ̀ sì kú lọ́jọ́ náà tàbí kí a tó sọ ọ́ lórúkọ
”Ewe, bakan naa ni igbimo ohun tun gboriyin fun eto idibo aare ti o waye lorile-ede Mali, eleyi ti o lo nirowo rose, bee si ni won tun ki aare Ibrahim Boubacar Keita ku oriire iyansipo sori aleefa pada.
“Ẹnikẹ́ni kò gbọdọ̀ bá arabinrin ìyá rẹ, tabi arabinrin baba rẹ lòpọ̀, nítorí pé, ìwà ìbàjẹ́ ni láàrin ẹbí.
 Àwọn onímọ ̀ -ìjìnlẹ ̀ bẹ ̀ rẹ ̀ iṣẹ ́ -ìwádìí lóri kòkòrò-àrùn hvc ni ààrin ọdún 1970 , tí wọn sì fi ìdí rẹ ̀ múlẹ ̀ ní ọdún 1989 pé àrùn tí n jẹ ́ bẹ ́ ẹ ̀ wà .
Kò yé mí sùgbọ́n bóyá ó yé ẹlòmíràn, bóyá ìrònú tèmi nìkan ló gbà bẹ́ẹ̀ ni, mílíọ̀nú mẹ́rìndínlógun dọ́ọ́là tó láti fí gbogbo orilẹ̀-èdè Naijíríà,'' Aisha ló sọ bẹ́ẹ̀.
fun eto iroyin ati ikede, Femi Adesinalo soro yii lojo Eti:ALAGAAare  Muhammadu BuhariIgbakeji
Òmùgọ̀ nírètí ju ẹni tí yóo sọ̀rọ̀ sọ̀rọ̀,tí kò lè kó ara rẹ̀ ní ìjánu lọ.
Bí àpẹẹrẹ: Àíyá bẹ́ sílẹ̀ ó bé áré, 
Lọdun 2017, Ile ẹjọ giga ilẹ Egypt fi ẹsun kan an pe o pa awọn afẹhonu han wọn si tu u silẹ.
Ni ipari, o nijoba ko je awon oluko ni gbese kankan nitori owo osu won n lo deedee.
Sanwo-Olu pèsè ìpàgọ́ tó wà ní Igando fáwọn tí iná jólé wọn ní Abule Egba láti gbé Gomina ipinlẹ Eko, Babajide Sanwo-Olu ti paṣẹ ipese eto iranwo fun awọn olugbe agbeegbe ijọba ibilẹ Agbado/Oke Odo nilu Eko, lẹyin ti wọn lugbadi ọpa epo bẹntiroolu to gbina.
9 1175850 Ilu Ọba 61245 91.
Aarẹ tun sọ pe, oun yoo gbiyanju lati ri wi pe ile iṣẹ ọlọpaa ati ẹka eto idajọ gbopọn si ni saa keji ijọba oun.
“N óo ṣe ìlú Jerusalẹmu bí ife ọtí àmutagbọ̀n-ọ́n-gbọ̀n-ọ́n fún gbogbo àwọn orílẹ̀-èdè tí ó wà ní àyíká rẹ̀.
Ṣugbọn ní tèmi, OLUWA, ìwọ ni mò ń gbadura síní àkókò tí ó bá yẹ, Ọlọrun,ninu ọ̀pọ̀ ìfẹ́ rẹ tí kì í yẹ̀,ninu agbára ìgbàlà rẹ, Ọlọrun dá mi lóhùn.
To o ba n gba ₦50,000: Yoo gba sẹnatọ ni wakati meji at isẹju mọkandinlaadọta(49) lati pa iye owo to n pa losu.
Oríṣun àwòrán, @victoryomogiate Iha wo ni Cute Abiola kọ sawọn ẹsun naa?
Iroyin yii lo tubọ mu ifunra dani pe o ṣeeṣe ki aarin gomina Ambode ati ẹni ti ọpọ mọ si baba isalẹ rẹ, Oloye Tinubu ko gun mọ bayii.
Ìtànkálẹ̀ ààrùn Ebola ti ṣẹlẹ ní iwọ oórún àríwá orílèèdè DR Congo.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ekiti Decides: Buhari ni òun kọ́ ló rán àwọn darandaran nisẹ 10 Agẹmo 2018 Àkọlé àwòrán, Nibi asekagba ipolongo ibo to waye ni Ọjọ Isẹgun ni ilu Ado Ekiti, ni Chris Ngige ti sìsọ pe kí wọn dá Fayose padà sípò lọ́jọ́ Satide .
"Ohun ti mo fẹ lati ọdọ awọ opo wọnyi ni pe ki wọn maṣe ta awọn irinṣẹ ti a gbe le wọn lọwọ yii nitori eredi rẹ ni lati ṣan ọna atijẹ ati atimu funwọn, o si yẹ ki wọn loo bẹẹ gẹgẹ.
“Ẹ gbọ́ ọ̀rọ̀ OLUWA, ẹ̀yin ọba Juda ati ẹ̀yin tí ẹ̀ ń gbé Jerusalẹmu, OLUWA àwọn ọmọ ogun, Ọlọrun Israẹli ní òun óo mú ibi kan wá sórí ilẹ̀ yìí, híhó ni etí gbogbo àwọn tí wọn bá gbọ́ nípa rẹ̀ yóo máa hó.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Mama Rainbow pe 77 lónìí, àwọn òṣèré tíátà kọrin re kìí Ọrọ̀ ajé Nàíjíríà yóò forí ṣánpọ́n tá a bá san ₦30,000 fún òṣìṣẹ - Ìjọba Kò sí ìfoyà, mò ṣetán láti sàn jù ₦30,000 fáwọn òṣìṣẹ́ l‘Eko - Sanwo-Olu Àlá àwọn òjíṣẹ́ Olúwa tó fẹ́ jẹ ààrẹ Nàíjíríà leè má ṣẹ lógún ọdún - Abiara Bakan naa ni Adekanmbi tun rọ ijọba to n tukọ ipinlẹ Ọyọ lọwọlọwọ lati gbajumọ eto isejọba pẹlu gbogbo aayan to yẹ, nitori ni ilẹ toni to mọ yii, ijọba Ajimọbi nikan lo tayọ gẹgẹ bii ijọba to duro re ti yoo tukọ ipinlẹ Ọyọ lati ọdun 1976.
Gbogbo yín lè sọ àsọtẹ́lẹ̀, lọ́kọ̀ọ̀kan, kí gbogbo yín lè rí ẹ̀kọ́ kọ́, kí gbogbo yín lè ní ìwúrí.
Ambode: Ilé aṣòfin Eko ní kí gómìnà àná wá wí tẹnu rẹ̀ lórí owó ọkọ̀ BRT
Ẹni to bori: South Africa Morocco vs Egypt.
Ó bá kó àwọn ọba wọnyi jọ sí ibìkan tí ń jẹ́ Amagedoni ní èdè Heberu.
Ní ti ilẹ̀, inú rẹ̀ ni oúnjẹ ti ń jáde,ṣugbọn lábẹ́ rẹ̀, ó dàbí ẹnipé iná ń yí i po,ó gbóná janjan.
Àṣeyọrí míì tún dé lórí ìwòsàn Coronavirus Àlàyé rèé lórí bí agbẹjọ́rò tó ń ṣojú Hushpuppi nílé ẹjọ́ ṣe pegedé sí Oṣu kinni ọdu 2020 ni Omohtee ṣe iṣẹ abẹ kanti wọn n pe ni 'Liposuction' ti yoo jẹ ki ikun rẹ pẹlẹbẹ, bẹ lo tun fa ọra ikun rẹ, to si jan mọ idi rẹ ki idi ọhun lee tobi si.
2020 WASSCE: Àjọ WAEC sọ pé ìdánwò tó ṣẹ̀ṣẹ̀ parí nàá lọ ní ìrọwọ́-rọsẹ̀
Sáájú ni ìjọba Nàìjíríà ti fi owó kún owó físà fún àwọn ọmọ Amẹrika tó ba fẹ́ wa si Nàìjíríà, lẹ́yìn gbogbo àlàyé láàrin ìjọba Amẹrika àti Nàìjíríà ti kò kẹ́sẹ̀ jári.
Gege bi eto idibo odun 2019 se n sunmo etile ajo to n mojuto eto alaafia lorile ede Afirika West Africa Network for Peace building ati Ajo Afirika  ati ajo Ecowas ti se idanilekoo fun awon eniyan to le ni ogorin, paapaa julo awon ile-ise aladaani ti ki i se ti ijoba lati ko won lona ti won yoo fi le maa daabo bo ara won nigba ti ijamba ba waye lasiko eto idibo.
”Ará Kuṣi náà dáhùn pé, “Kí ohun tí ó ṣẹlẹ̀ sí Absalomu ṣẹlẹ̀ sí gbogbo àwọn ọ̀tá rẹ, ati gbogbo àwọn tí wọ́n dìtẹ̀ mọ́ ọ.
Yóo tún gbé e sókè bí ó ti ṣe ní Ijipti.
Sibẹsibẹ wọ́n tún dẹ́ṣẹ̀;pẹlu gbogbo iṣẹ́ ìyanu rẹ̀, wọn kò gbàgbọ́.
Ganduje sọ wi pe idi ti oun fi yapa kuro labẹ Kwankwaso ni pe o jẹ ẹni ti imọtara ẹni nikan n da laamu.
 Àpẹẹrẹ ni : Ẹ ̀ sìnmìnrìn , àti bẹ ́ ẹ ̀ bẹ ́ ẹ ̀ lọ .
 Lọwọ-lọwọ bayii, Will Smith ati aya rẹ, Jada Pinkett Smith ti pada di tọkọtaya, ti ifẹ wọn si n gbona gidigidi."
ba orile ede mejeji ohun , ni eyi ti orile ede mejeeji naa yoo se jẹ awokọse ni
Ẹgbẹ oṣiṣẹ NLC ti ni gbogbo ọmọ Naijiria ni yoo kopa ninu iyanṣelodi yii nitori gbogbo ọmọ Niajiria lo n jẹ irọra bi wọn ṣe fikun owo epo ati ina ijọba ni Naijiria.
láti inú ẹ̀yà Sebuluni, ó rán Gadieli, ọmọ Sodi; 
Mo fẹ́ kí o mọ̀ dájúdájú pé nígbà tí o wà ní ọ̀dọ́, ò ń di ara rẹ ni àmùrè gírí, ò ń lọ sí ibi tí o bá fẹ́.
Wọ́n ní, ‘Ó ní ẹ̀mí èṣù ni.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Coronavirus Update: WHO tí kéde pé Ó ṣeéṣe kí àrùn Coronavirus tànkálẹ̀ gba inú afẹ́fẹ 8 Agẹmo 2020 Oríṣun àwòrán, @FAAN Àkọlé àwòrán, WHO tí kéde pé Ó ṣeéṣe kí àrùn Coronavirus tànkálẹ̀ gba inú afẹ́fẹ Ajo Eleto Ilera lagbaye, WHO ti kede pe o ṣeeṣe ki arun Coronavirus tan kale lati inu afẹfẹ.
Won n sọrọ fidio rẹ ti wọn gba pe o dún pupọ ni eyi ti Meji Alabi dari rẹ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Russia in Africa: Ṣé òun ni alágbára ńlá ní Áfíríkà báyìí?
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìyá àkàndá ẹ̀dá: Àwọn ẹbí mi fẹ́ kí n pa ọmọ mi torí ó jẹ́ àkàndá ẹ̀dá Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Ìyá àkàndá ẹ̀dá: Àwọn ẹbí mi fẹ́ kí n pa ọmọ mi torí ó jẹ́ àkàndá ẹ̀dá 13 Ọ̀wàrà 2018 Ajọ to n ja fun ẹtọ awọn akanda ẹda lagbaye (Disability Rights International) sọ wi pe, ni orilẹede Kenya, Ida mẹrindinlaadọrin iya akanda ẹda lo ni, awọn mọlẹbi ati ara ma n gbe ẹmi awọn gbọna lati pa awọn ọmọ wọn to jẹ akanda.
Ọgbọ́n kì í jẹ́ kí ọlọ́gbọ́n yára bínú,ògo rẹ̀ sì níláti fojú fo ẹ̀ṣẹ̀ dá.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Busola Dakolo: Mílíọ́nù mẹ́wàá náírà tí a béèrè kì í ṣe owó gbà má-bínú 9 Owewe 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 10 Owewe 2019 Oríṣun àwòrán, BUSOLA DAKOLO Àkọlé àwòrán, Busola Dakolo: Mílíọ́nù mẹ́wàá náírà tí a béèrè kì í ṣe owó gbà má-bínú Agbẹjọro Busola Dakolo ti sọ pe, irọ balau ni pe onibara oun fẹ gba miliọnu mẹwaa Naira gẹgẹ bi owo gba ma-binu lọwọ oludasilẹ ijọ COZA, Biọdun Fatoyinbo.
Ẹni Mímọ́ ti Ọlọrun ni ọ́.
Obìnrin kan gbé ara rẹ̀ níyàwó Àyájọ́ ọmọbìnrin gba gbogbo ayélujára tán Ẹ̀mí mẹ́rin sọnù sínú ìjámbá ọkọ̀ n'Íbàdàn Kí lo fẹ́ mọ̀ nípa D.
Lọjọ kẹwaa oṣu yi ni Naijiria yoo pade South Africa ni ilu Cairo.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Lai Mohammed: Àtúntò yìí kò wà láti ga àwọn iléeṣẹ́ agbóhùnsẹáfẹ́fẹ́ lọ́rùn 24 Ògún 2019 Oríṣun àwòrán, @RadioToday Ààrẹ Muhammadu Buhari ti buwọlu àtúnto àwọn ilé iṣẹ́ ìròyin gbogbo lórilẹ̀-èdè Nàìjíríà, pàápàá jùlọ, lóri fífún àwọn ilé iṣẹ́ ìròyìn orí ayélújára ni ìwé àṣẹ́.
Àkọlé àwòrán, Oyedepo ni o dabi ẹni pe ẹmi eeyan ko tiẹ wa jọ awọn apaniyan yii loju mọ, ti wọn ko si bikita mọ rara lati da ẹmi awọn eeyan legbodo.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Onimọ nipa ihuwasi eniyan ati imọ ijinlẹ, Mark Vernon ni, eniyan le lo ibinu fun nkan to dara, ati wi pe o le mu ara ji pepe.
Bela bí ọmọ marun-un: Esiboni, Usi, Usieli, Jerimotu ati Iri.
Ninu atẹjade ti ajọ naa fi sita, wọn fidi iṣẹlẹ naa mulẹ ti wọn si ni awọn ko mọ eleyi ti o jẹ ninu awọn to wa ni ahamọ.
Botilẹjẹ pe Minisita fun eto ibaraẹni sọrọ ati eto ọrọ aje lori ayelujara Isa Pantami, sọ pe ki ileesẹ NIPOST, dawọ duro l'ori ofin naa, NIPOST kò ti i kede boya oun ti ṣe bẹ ẹ.
Oríṣun àwòrán, EDO STATE POLICE COMMAND Awọn ọlọpaa n'ipinlẹ Edo ni awọn janduku naa dana sun agọ olopaa, wọn ji ibọn ati ọta ko, wọn fipa ba awọn obinrin lo pọ l'awọn agbegbe kan, wọn pa ọlọpaa fọ ile onile ati ṣọbu oniṣọbu.
South) ati  Phillip Aduda (FCT), ni won
Amọ eewọ ni fun awọn obinrin oloyun, ki wọn ma ba a bi ọmọ ti ọpọn ori rẹ yoo jọ ti tata.
Bakan naa lo ni ẹbi ṣi wa ninu irora ati iyalẹnu pe ṣe gbogbo ẹ ti pari naa ni yẹn ni asiko yii.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Wòlíì Kasali sọ̀rọ̀ nípa awuyewuye pé ó lé ìyàwó rẹ̀ jáde nílé Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Wòlíì Kasali sọ̀rọ̀ nípa awuyewuye pé ó lé ìyàwó rẹ̀ jáde nílé 28 Ọ̀pẹ̀̀ 2018 Bi wọn ba ni ki pe eeyan to padanu oju ita wa ṣugbọn ti oju inu rẹ n rina daada wa,Woli Kasali nilu Ibadan jẹ irufẹ eeyan bẹ.
ìdajì àwọn ọmọ wọn ni kò gbọ́ èdè Juda àfi èdè Aṣidodu.
Ọ̀nà tí a fi lè mọ̀ pé a mọ Ọlọrun ni pé bí a bá ń pa àṣẹ rẹ̀ mọ́.
Àwọn ọmọ Imeri jẹ́ ẹgbẹrun ó lé mejilelaadọta (1,052).
Ní ọdún tó kọjá nìkan àwọn ènìyàn ọgọ́rùn bílíọ̀nù ní wọn jẹ núdùlù lágbàyé, ti méjìdínlógójì nínú rẹ̀ sí wáyé ní gbùngbùn China.
Solomoni bá gbadura, ó ní, “OLUWA, ìwọ ni o fi oòrùn sí ojú ọ̀run,ṣugbọn sibẹsibẹ o yàn láti gbé inú ìkùukùuati òkùnkùn biribiri.
 Ẹni tí ó bàv jẹ ́ Ààyàn tó bác yanjú yóò lè lo ìlù náà láti fibsọ ohun kóhun tó bá fẹ ́ .
Biotilejepe awọn ọmọ ile iwe Chibok ọgọrun ati meje ni wọn ti gbaalẹ ni panpẹ awọn ikọ Boko Haram lati bii ọdun mẹrin sẹyin, Aarẹ Buhari ni oun ko ni sinmi titi awọn ọmọ naa yoo fi pada sọdọ awọn obi wọn.
Oríṣun àwòrán, @dok Àkọlé àwòrán, Eyi ni lara awọn iṣẹ ti Oyedele n joko ti lati fi gbe awọn ọdọ sita Ni kete ti iroyin yii tan de ọdọ Aarẹ Trump ni oun naa ti da Oyedele lohun to gboriyin fun un pe, iṣẹ gidi lo ṣe.
Àpẹẹrẹ ni mo fi fun yín pé, gẹ́gẹ́ bí mo ti ṣe si yín, bẹ́ẹ̀ ni kí ẹ máa ṣe.
Wádìí mi, Ọlọrun, kí o mọ ọkàn mi;yẹ̀ mí wò, kí o sì mọ èrò ọkàn mi.
wa bẹnu atẹ lu ọwọ ti ijọba orilẹ-ede South Africa fi mu ọrọ naa,
Won yoo de Tachira, Tsonje, Adu, Tafan, Kukum Daji, Kukum Gida, Agban, A.
ati àṣá gidi, ati oríṣìíríṣìí àṣá mìíràn, ati igún gidi, ati àwọn oríṣìíríṣìí igún yòókù, 
"Itan mi kii ṣe itan ifẹ nikan.
Alhaji Lai soro ohun di mimo lasiko ipade apero idanileko awe Ramadan, eleyi ti o sagbekale re, ti o waye lojo Abameta(Saturday) nipinle Kwara, ipinle ti o kogun saarin gungun orile-ede Naijiria.
Ojoojumọ ni mò ń jókòó ninu Tẹmpili láti kọ́ àwọn eniyan.
Inu mi si dun fun igbese alaafia to n lo lowo ati awon nnkan to n pada bo sipo bayii.
Koda, a ti fi ọwọ si gbogbo iwe to yẹ lati gba oku naa sita fun sinsin, ki wọn tun to sọ fun wa pe asẹ kan to wa lati oke ni wọn ko gbọdọ gbe oku naa fun wa.
Ìjọba ìpínlẹ̀ Oyo kéde pé kí àwọn òṣìṣẹ́ ìjọba dáwọ́ iṣẹ́ dúró nítorí coronavirus Oríṣun àwòrán, Facebook/Seyi Makinde Ijọba ipinlẹ Ọyọ ti ti ilẹkun ileeṣẹ ijọba pa fun ọsẹ meji gbako nitori itankalẹ aarun coronavirus nipinlẹ naa.
Ẹ kò gbọdọ̀ ṣe iṣẹ́ kankan ní ọjọ́ náà, nítorí ọjọ́ ètùtù ni, tí wọn yóo ṣe ètùtù fun yín níwájú OLUWA Ọlọrun yín.
 awon akẹẹkọ ti o tun ti kuro nile –iwe .
Wọ́n ti kọ ọ̀rọ̀ OLUWA sílẹ̀,ọgbọ́n wo ni ó kù tí wọ́n gbọ́n?
Nise lo yẹ ki wọn o ma a kan sára si baba yẹn, nitori pe Naijiria i ba dara ka ni bi gbogbo awọn olori orilẹ-ede to ti jẹ tẹlẹ ṣe n ṣe niyẹn""."
to wa ni  Mainland ,ki o to lọ si ile-ẹkọ
 A wa nipinle Yobe bayii ki awon ebi awon toro kan le mo pe a mo ohun ti won n la koja pelu ileri lati sa ohin gbogbo to wa ni pa wa ki a le ri awon omo yii bi obinrin ti n wa nkan obe ri”.
Bákan náà ni àwọn òṣìṣẹ́ fẹ́ sọ èrò wọ́n lóri ìpèníjà ti àwọn òṣìṣẹ́ ilé ìwòsàn náà ń kojú lásìkò ààrùn Covid-19 yìí.
Latin lórí àìsàn Ogun Majek Coronavirus: Kíni àwọn àmì tuntun tó n fihàn?
Saaju ni alaga igbimọ ile to wa feto isuna nile asofin agba ilẹ wa, Sẹnetọ Barau Jibril ti kede pe ilana gbigbe aba isuna tọdun yioi kalẹ yoo yatọ si ti tẹlẹ nitori arun coronavirus to gbode kan.
Fi ìfẹ́ rẹ tí kì í yẹ̀ hàn mí, OLÚWA,kí o sì gbà mí là gẹ́gẹ́ bí ìlérí rẹ.
"Wo ọ̀rọ̀ ìkíni kú ọdún Keresi tí Sowore fi ránṣẹ́ lẹ́yìn ìtúsílẹ̀ rẹ̀ Tápà sí ìlànà tuntun CBN kí o fí owó ìtanràn ₦2m gbára Ọmọ ogún ọdún kan tún di àwátì nílùú Akurẹ nípìnlẹ́ Ondo- PPRO Bayìí ni àwọn ọlọpàá Akure ṣe ko àwọn ará ìlú ti o ji ẹrù ni sọọsi Sotitobirẹ Ikede Poopu tuntun Ni kete ti oludije kan ba ti ni ìdá meji ibo, wọn yoo beere lọwọ rẹ pe: ""Ṣe o faramọ iyansipo rẹ gẹgẹ bi poopu Alufaa to ga ju?"
Bí ẹ bá bínú, ẹ má jẹ́ kí ibinu mu yín dẹ́ṣẹ̀.
Ilẹ̀ karun-un tí wọ́n ṣẹ́ gègé lé lórí bọ́ sí ọwọ́ ẹ̀yà Aṣeri.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ọwọ tẹ afurasi mẹta ni Zamfara Ọmọ Nàíjíríà sọ̀rọ̀ lórí ìpànìyàn Zamfara Oloselu lo sokunfa bi ọlọpa ko se to ni Naijiria Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Àwọn ọ̀dọ́ kojú ààrẹ́ Buhari20 Ìgbé 2018 Ìtàn Mánigbàgbé: Kí lo fẹ́ mọ̀ nípa ‘Ajala Travels’?
 awọn ènìyàn zulu pin sí méjì !
Títí di àsìkò yìí a kò ti rí ẹni kankan lórí ìṣẹ̀lẹ̀ ti Mujeeb sùgbọ́n ọwọ́ ti tẹ ẹnikan nípa ti Azeezat.
7 103,127 North Macedonia 2,682 128.
Wo àwọn ìlérí tàwọn Gómìnà tuntun ṣe nínú ìbúra wọn Dapọ Abiọdun ree, ẹni tó dépò gómìnà ní àyájọ́ ọjọ́ ìbí rẹ̀ Ará ìlú dájọ́ oró fún ọkùnrin to bẹ́ orí ẹ̀gbọ́n rẹ̀ ní Cross River Rochas Okorocha, káàbọ̀ sí àwùjọ àwọn gómìnà tí EFCC ń wá - Fayose Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Makinde: Ẹgbẹ́ òṣìṣẹ́ faramọ́ wíwọ́gilé ₦3000 táwọn akẹ́kọ̀ọ́ girama ń san Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Oríṣun àwòrán, Reuters Ìwọ́de bẹ̀rẹ̀ ní Minnesota lórí àwọn ọlọ́pàá mẹrin to pa ọmọ adulawọ ni Amẹ́ríkà Oríṣun àwòrán, Getty Images Iwọde loriṣiriṣi ti n waye ni Minneapolis lorilẹede Amẹrika lori iku adulawọ kan, George Floyd.
Lẹyin to gbọ pe wọn ba ọmọ ọdun marun lopọ ni tipa, lo ba lo ileesẹ iroyin rẹ lati se ifilọlẹ eto ipolongo 'Black Tuesday' eyi to n se iwuri fun awọn obinrin lati wọ asọ dudu lawọn ọjọ Isẹgun to kẹyin osu, lọna ati fẹhonu han lori iwa ifipabanilopọ ati ilokulo ọmọbinrin ti ọjọ ori wọn ko tii to ọdun mejila.
Gege bi ile-ise aare South Korea se so, “Awon igbimo lati North Korea ti o darapo mo won nilu Pyeongchang  fun asekagba ayeye idije igba otutu, ti a mo si (Winter Olympics), sepade o ni bonkele pelu aare South Korea, Moon Jae-in  ni erongba lati sepade po pelu ijoba orile-ede Amerika,.
" alfred prufrock "" ( 1910 ) , "" ile ahoro "" ( 1922 ) , "" ese-orin merin "" ( 1945 ) ati ere ori-itage "" ipaniyan ninu soosi "" ( 1935 )."
Òkè òkè ní Barcelona lè téńté lórí àtẹ La liga Dangote: Mo ti gbà $10m ri ní bánkì kí n lè mọ bí o tí ṣé rí lójú Nàìjíríà ló wà nípò kẹfà nínú ewu ikú àìtọ́jọ́ l'ágbàáyé nítorí nkan mímú tó ní ṣúgà Ọkọ̀ ojú omi ''fẹri'' kọlu afárá, ọkọ̀ méjì já sódò Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Jawahir Roble:Hijab tí mò n lò kó jẹ́ kọ́kọ́ jẹ́ ìyàlẹ́nu fún àwọn agbábọ́ọ̀lù mi Ohun to n fa awuyewuye lori ayelujara bayii ni pe bo ya Kingston ni ajijakadi akọkọ ti yoo kọkọ gba ami ẹyẹ agbaye.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù GRIDCo: Àpọ̀jù iná mọ̀nàmọ́ná ló sọ Ghana sí òkùnkùn birimù 27 Bélú 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Ṣaadede ni awọn waya to gbe ina lọ si Mali bẹrẹ si ni gbona ti wọn si da ina ọhun pada si ori ibudo amunawa Ghana.
Ebi ló ń pami ti mo fi já sọọbu láti jí bisikitì- Afurasi Asuquo
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Akure Kidnap: E túbọ̀ ní sùúrù, a máa wá ọmọ náà rí- Alukoro ọlọ́pàá Bakan naa ni ile ẹjọ tun ti tẹwọ gba iwe iforukọsilẹ awọn ọmọde ni ileejọsin awọn ọmọde to wa ni ileejọsin fasiti Adura, Sọtitobirẹ gẹgẹ bi ọkan lara awọn ẹri niwaju ile ẹjọ naa.
Ẹranko tí ó ti wà láàyè rí, tí kò sí mọ́, ni ẹkẹjọ, ṣugbọn ó wà ninu àwọn meje tí ń lọ sinu ègbé.
Rutu bá lọ sí ibi ìpakà, ó ṣe bí ìyá ọkọ rẹ̀ ti sọ fún un.
O sọ pe 'awọn oloṣelu lo ni ẹbi rẹ.
"Tinubu ni ""a ni lati ṣe atunṣẹ si eto abo wa, awọn ọmọ ogun naa si ni lati ni afojusun tuntun lati dabo bo awọn ọmọ ile iwe ati awujọ wa lapapọ."
Ẹwẹ, alejo wa ki ẹnu bọ ọrọ lorii bi ẹ ṣe le gbadun ibalopọ, ohun to n jẹ ki ọkunrin wo ita, ohun to n jẹ ki obinrin di ọga ara rẹ tabi sa fun ibalopọ pẹlu ololufẹ rẹ.
“A bèèrè lọ́wọ́ àwọn àgbààgbà wọn pé, ta ló fun wọn láṣẹ láti tún tẹmpili yìí kọ́ ati láti dá àwọn nǹkan inú rẹ̀ pada sibẹ.
Josẹfu sọ fún àwọn arakunrin rẹ̀ pé òun ni Josẹfu.
Nígbà tí ó di ọjọ́ karun-un, ọkunrin náà gbéra ní òwúrọ̀ kutukutu láti máa lọ, baba ọmọbinrin náà tún rọ̀ ọ́ pé kí ó fọkàn balẹ̀, kí ó di ìrọ̀lẹ́ kí ó tó máa lọ.
O ni o maa n tu oun lara gan an ni Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Huda Shaarawi: Kò dára kí obìnrin sè’yàwó lọ́mọ ọdún mẹ́tàlá Yatọ si eleyi, ọna miran ti a le fi gbadun sise isẹ wa lati ile ni pe ki a wa awọn ere ti awa ati awọn mọlẹbi wa yoo jijọ maa se.
Bakan naa ni wọn si tun kede eto ilu o fararọ ọlọdun mẹta lati moju to ohun gbogbo to yẹ.
M Sani to ṣe idajọ naa sọ pe awọn mẹtẹẹta; ọmọ ilẹ okeere meji, ati ọmọ Naijiria kan, jẹbi ẹsun meji ti wọn fi kan wọn.
Ẹ kúàbọ̀ sí ọjọ́ ńla ọja òní lórílẹ̀èdè Nàìjíríà tíí ṣe ọjọ́ ìbúrawọlé fún ààrẹ Muhammadu Buhari àtàwọ́n adarí tí wọ́n yóò jọ tukọ̀ orílẹ̀èdè fún sáà mẹ́rin míìràn.
Ó wá láti ọ̀dọ̀ ẹgbaarun àwọn ẹni mímọ́,ó gbé iná tí ń jò lọ́wọ́ ọ̀tún rẹ̀.
Garlic, iyẹn ayuu ati awọn eso miran naa ni bii Vitamins C, E, B12, D ati zinc naa.
lorilẹ-ede Naijiria ati awọn koko ọ̀rọ̀ miiran nipa rẹ̀.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Wo àwọn ǹkan ti kò hàn síta púpọ̀ nípa Moses Bale kò le gba Real Madrid lọ́wọ́ ìyà Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ronke Oṣodi: òótọ́ ọ̀rọ̀ máa ń korò gan ni f'áwa èèyàn Ikọ agbabọọlu Spain lo kọkọ gbayo meji wọle Naijiria, awọn agbabọọlu Naijiria naa ta biọbiọ lẹyin ti wọn da ayo kan pada.
Lẹsẹkẹsẹ wọ́n bá fi àwọ̀n wọn sílẹ̀, wọ́n ń tọ̀ ọ́ lẹ́yìn.
Ó bá gbé òkú rẹ̀ nílẹ̀, ó gbé e sẹ́yìn kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ rẹ̀, ó sì lọ sílé rẹ̀.
"-Big Brother sọ fún Dorathy ""Ọlọrun lo sọ fun wa pe ka lo ohun gbogbo ta ba ri ko jọ lati inu owo to n wọle fun wa, fi mu igbe aye dẹrun fawọn eeyan to ku diẹ kaa to fun."
Ọlọ́pàá tó dá dókítà oníṣẹ́ abẹ dúró lásìkò ìséde, fa ikú alaboyún kan Ènìyàn 100 ló kó àrùn Coronavirus ní Nàìjíríà ní Ọjọ́ Aiku Wo ìdí tí wọ́n ṣe lé Erica dànù kúrò nílé BBNaija l'ọ́sẹ̀ yìí Kí ló ṣe Ibrahim Chatta tó fi dèrò ilé ìwòsàn?
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Pásítọ̀ ló sọ fún mi pé Ọlọ́run pè mí láti di Olokun tó ń bọ omi' Ki ni Funke Akindele se fun Bukunmi to fa ariwo?
Ẹ má bẹ̀rù, ẹ̀yin ẹranko inú igbó,nítorí ewéko gbogbo ni ó tutù,igi gbogbo ti so èso,igi ọ̀pọ̀tọ́ ati ọgbà àjàrà sì ti so jìnwìnnì.
O fikun pe, ni ọjọ diẹ lẹyin iṣẹlẹ yii ni awọn darandaran naa tun ṣẹ ikọlu si Idoani, nibi ti wọn ti gbe Adari ileewosan ijọba nibẹ pẹlu awọn eniyan miran lagbegbe naa.
Ninu ọrọ rẹ to fi kaṣẹ eto lalẹ ọjọ kinni apero naa, Michelle ni ''eeyan ko le fi makaruru ṣe iṣẹ aarẹ'' Bẹẹ naa lo fi kun ọrọ rẹ pe, eto ọrọ aje ti dẹnu kọlẹ fọjọ pipẹ nitori aarẹ fi ọwọ yẹpẹrẹ mu ajakalẹ arun Covid-19.
Ẹnu ya gbogbo wọn kọjá ààlà, wọ́n ń wí pé, “Ó ṣe ohun gbogbo dáradára: ó mú kí adití gbọ́ràn, ó mú kí odi sọ̀rọ̀.
Olódùmarè gbàwá láàyè yìí ká máa dárà bó ti wù wá ní ilé ayé.
A óo dá oko sórí àwọn ilẹ̀ tí wọ́n ti di igbó, dípò kí ó máa wà ní igbó lójú àwọn tí wọn ń kọjá lọ.
"Ọlọ́pàá wú òkú obìrin tó ń múra ìgbéyàwó lọ́wọ́ tí 'gate-man' rẹ̀ ṣekúpa ""A fẹ́ yọ ààrẹ ẹgbẹ́ Yorùbá YCE nípò torí àwọn ìwà tí kò bójúmu"" Wo àànfàní ‘Masturbation’, fífún ara rẹ̀ ní adùn ìbálòpọ̀ Ẹ fura o, Boko Haram ti pàgọ́ sí Abuja, yóò ṣe ìkọlù láìpẹ́ - Iléèṣẹ́ Aṣọ́bodè lọgun Lára àwọn tó fi èrò wọ́n sórí ayélujára ni Gbájúgbajà ọkùnrin to máa ń múra bi obìnrin Olarewaju Idris Okunneye ti gbogbo ènìyǹ mọ̀ si Bobrisky tó fi ìpè síta pé ki wọ́n bá òun fi nọ́mbà ìfówopamọ́ rẹ̀ ranṣẹ́ nítori òun fẹ́ ta lọ́rẹ."
"Iṣẹ́ fẹ́ bọ́ lọ́wọ́ ọlọ́pàá tó gba N100k lọ́wọ́ awakọ̀ tó gba""One way"" l'Eko Kíni àjọ ọlọ́pàá ń ṣe lórí bí agbófinró ṣe ń ṣèèṣì pànìyan lójoojúmọ́?"
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Wo bí Sunday Orimola ṣe gba ikú ẹranko kú ní Ifon ni Ondo lórí ọ̀nà àtijẹ Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Fídíò, Akomolede: Bolaji Faleke ni Olùkọ́ tó ń kọ́ wa ní àṣà oge ṣiṣe lórí BBC Yorùbá1 Owewe 2020 Davy dèrò ọ̀run nítorí 'Eré orí ẹní' ní ìlú Eko19 Ọ̀pẹ̀̀ 2018 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Kò sí ohun tí ó wà ní ilé ìṣúra mi tí n kò fihàn wọ́n.
Nisinsinyii gbogbo wa wà níwájú Ọlọrun láti gbọ́ ohun gbogbo tí Oluwa ti pa láṣẹ fún ọ láti sọ.
"a wa di pe ẹyin lẹ ma maa wa wọn kiri to dẹ jẹ pe awọn lo n lee yin kiri nigba ti wọn o tii debẹ""."
Ati pe ika to ba sẹ̀ ni ki agbara ofin maa ge lai bọwọ fun ẹnikẹni.
Ìgbà kẹta nìyíì ti yóò bí ìbejì l'ọ́dún 2018 nìkan ṣoṣo.
Idi ni pe laarọ oni yii ni ọwọ ileesẹ ọlọpa ipinlẹ Ondo tẹ ọkunrin kan to pe orukọ ara rẹ ni Elike Chibuzor, to ni oun loun ji Gold Kọlawọle gbe lọ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ileẹjọ f'ofin de ṣiṣe ọdun oro laigba'ṣẹ nipinlẹ Ogun 22 Èrèlè 2018 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Odun oro jẹ dun ti o wọpọ bi awọn ọdun egungun kan nipinlẹ Ogun Ile ẹjọ giga kan to n joko nijọba ibilẹ Ipokia nipinlẹ Ogun ti ni bi awọn oloro ṣe n pa ofin konileogbele fun awọn araalu Ipokia ko b'ofin mu.
si iroyin kankan nipa baalu to poora naa.
Baba wọn fún wọn ní ọpọlọpọ ẹ̀bùn: fadaka, wúrà ati àwọn nǹkan olówó iyebíye, pẹlu àwọn ìlú olódi ní Juda.
Ó fi ẹ̀mí ara rẹ̀ wéwu láti pa Goliati, OLUWA sì ṣẹ́ ogun ńlá fún Israẹli.
Nígbà tí wọ́n kan Jesu mọ́ agbelebu tán, àwọn ọmọ-ogun pín àwọn aṣọ rẹ̀ sí ọ̀nà mẹrin, wọ́n mú un ní ọ̀kọ̀ọ̀kan.
Lẹ́yìn tí ó bí Jaredi, ó gbé ẹgbẹrin ọdún ó lé ọgbọ̀n (830) láyé, ó sì bí àwọn ọmọ mìíràn lọkunrin ati lobinrin.
Ṣugbọn ní àkókò yìí, ọ̀nà tí Ọlọrun fi ń dá eniyan láre ti hàn láìsí Òfin, bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé àkọsílẹ̀ ti Òfin ati ti àwọn wolii Ọlọrun jẹ́rìí sí i.
Ọmọ Bàbá Sùwé - BBC News Yorùbá BBC News, YorùbáFò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Baba Suwe: Ilé iṣẹ́ aṣọ́bodè kò fún bàbá mi ní kọ́bọ̀, igbákejì Ààrẹ kàn tọrọ àforíjìn ni - Ọmọ Bàbá Sùwé 7 Sẹ́rẹ́ 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 17 Èbibi 2020 Oríṣun àwòrán, Bababsuwe/ instagram Àkọlé àwòrán, Oloogbe Muyideen Aromirẹ lo gbe sinima agbelewo akọkọ jade ni ọdun 1988 Ọpọ eniyan lo ti n ṣe aaro ilumọọka adẹrinposonu nni, Babatunde Omidina, ti ọpọ eeyan mọ si Baba Suwe nitori bi oju rẹ ṣe sọwọn lasiko yii ninu ọpọ ere sinima.
Niwọn igba to si jẹ́ pe ẹni nla, lo n ṣe ohun nla, lẹyin ile ẹkọ girama, Baba Oloye sọ ọmọ rẹ si ilu Ọba, nile ẹkọ Cheltenham College ni ilẹ Gẹeṣi ni ọdun 1979 si ọdun 1981 nibi to ti gba iwe ẹri girama miran.
O bẹrẹ si ni ṣe oṣelu lọmọdun mẹẹdọgbọn, nigba naa lo ṣe ipolongo fun oludije fun ipo aarẹ, Mallam Ibrahim Shekarau.
ASUU strike: Ìjọba Nàìjíríà ti gbà láti san N30b owó àjẹmọ́nú fún ASUU
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Fake News; Àwọn iròyin ẹlẹ́jẹ̀ márùn ún tó fẹ́ẹ̀ tú Nàìjíríà ká 21 Bélú 2019 Oríṣun àwòrán, others Àkọlé àwòrán, Fake News; Àwọn iròyin ẹlẹ́jẹ̀ márùn ún tó fẹ́ẹ̀ tú Nàìjíríà ká Ilé ìgbìmọ àṣòfin àgbà ní Nàìjíríà ti ká àbádofin tí yóò maa kó àwọn ènìyàn ní ìjánú láti gbé ìròyìn òfégè tàbí sọ ọ̀rọ̀ kòbákùgbé sí olésèlú lórí ayelujára fún ìgbà keji lánàá Abadofin náà ni wọn pé àkọlé rẹ̀ ni 'Protection from internet Falsehood and Manipulation Bill 2019, èyí ti sẹnatọ Muhammed Musa ṣe onígbọ̀wọ́ rẹ̀.
”Wọ́n dá a lóhùn pé, “Meje.
Àṣírí ígbèkùn nílé Olore n‘Ibadan kìí ṣe tuntun, ó ti kọ́ wáyé ní 2008 A ti mọ òbí 40 nínú 108 t'ọ́mọ wọn bọ́ ní ayédèrú ibùdó atúnwàṣe Ilorin - Ọlọ́pàá Kwara Àṣírí ilé ìmúni nígbèkùn míràn tú síta ní Ibadan Gbogbo ilé ọmọ aláìgbọràn nílẹ̀ Yorùbá, Ọlọ́pàá ń bọ̀ wá yẹ̀ yín wò Ẹ wó ilé amúninígbèkùn ti Olore tó wà ní Ojoo nílùú Ibadan - Seyi Makinde Oriṣiiriṣii ẹsun ni awọn ọdọ ti wọn ko sinu ile ibaniwi yii fi kan Aafa Olore atawọn to n tọju wọn nibẹ.
Igbimo Amusese tijoba apapo ni Naijiria ti fowosi gbigbe ise akanse  towo  e to bilionu meje owo dola din loodunrun sita fun sise oju ona oko oju irin lati ibadan nipinle Oyo si Kaduna.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Osun Election: Ìbò méje péré ni Adeleke fi fẹ̀yìn Adebiyi janlẹ̀ 22 Agẹmo 2018 Oríṣun àwòrán, Ademola Adeleke/Facebook Àkọlé àwòrán, Adeleke ni yóò kojú ọgbẹni Gboyega Oyetola ti ẹgbẹ òṣèlú APC nínú ìdìbò Gómìnà ìpínlẹ̀ Osun Sẹ́nétọ̀ Ademola Adeleke ni yóò máa ṣojú ẹgbẹ́ òṣèlú PDP nínú ìdìbò sípò Gomina tí yóò wáyé ní Ìpínlẹ̀ Osun.
Ṣugbọn nigba to n sọrọ, alukoro fun ileeṣẹ ọlọpaa nipinlẹ Osun, Opalola Yemisi, sọ fun BBC pe lootọ ni iṣẹlẹ naa waye, ṣugbọn ko si ẹni to jẹ ọba ninu awọn mejeeji ti wọn fi ẹsun kan.
kankan maa waye , ti a ba wo  bi awon agọ  idibo se pọ to lorile ede yii ati eto idibo ,
Bẹ́ẹ̀ sì nikú màjèsín ni í payítalẹ̀
4 Million), ati bilionu mẹ́sán án naira ( N9.
Iṣẹ́ aṣẹ́wó ni Tamari, opó ọmọ rẹ ń ṣe, ó sì ti lóyún.
gbese lati mu idagbasoke ba eto oro aje ipinle naa.
Bi o tilẹ jẹ wi pe ipinlẹ Eko ti dẹwọ ofin koni o gbele kaakiri gbogbo ọjọ to wa ninu ọsẹ, ofin konile o gbele ṣi n fidi mulẹ ni ipinlẹ Ogun ni ọjọ Abamẹta ati ọjọ Aiku.
"Klopp lasiko to n dahun ibeere lori boya Mane tabi Salah lee gba ami ẹyẹ agbabọọlu to gbayi julo lagbaye, Ballon d'Or, sowipe ""Afirika n reti ami ẹyẹ yii, orilẹede Germany pẹlu ti n reti rẹ fun ọpọlọpọ ọdun."
Mo ṣe bi ìyàwó mi ni.
Ìgbà míràn a dáhùn a ní, Ènìyàn-ṣe-pẹ̀lẹ́, pẹ̀lẹ́pẹ̀lẹ́ mà di ọwọ́ rẹ o.
Bí Jesu ti ń bá ìrìn àjò rẹ̀ lọ láti ìlú dé ìlú ati láti abúlé dé abúlé, ó ń kọ́ àwọn eniyan bí ó ti ń lọ sí Jerusalẹmu.
Ṣugbọn, ta ló lè farada ohun tí yóo ṣẹlẹ̀ ní ọjọ́ tí ó bá dé?
nítorí ó fẹ́ràn orílẹ̀-èdè wa, òun fúnrarẹ̀ ni ó kọ́ ilé ìpàdé fún wa.
CSKA Mosco ni Arsenal na pẹlu apapọ ayo mẹfa si mẹta, ti Athletico si gbo ewuro si oju Sporting Lisbon lati orilẹede Portugal pẹlu ami ayo meji si ẹyọ kan ṣoṣo.
ó ranṣẹ pè é, ó bi í pé, “Ṣebí o búra fún mi ní orúkọ OLUWA pé o kò ní jáde kúrò ní Jerusalẹmu?
”Nígbà tí ó bá mi sọ̀rọ̀ tán, mo tún lágbára sí i; mo bá dáhùn pé, “olúwa mi, máa sọ ọ̀rọ̀ rẹ lọ, nítorí ìwọ ni ó fún mi lágbára sí i.
Afẹ́fẹ́ òjò líle ṣọṣẹ́ ní ìlú Ìlọrin nípinlẹ Kwara
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Nnamdi Kanu: Ìdí tí mo fi sá ní Nàìjíríà Fayoṣe: Mi ò jẹ̀bi ẹ̀sùn kankan Oshiomole pajúdà sí àwọn olóyè ẹgbẹ́ APC Ninu ọrọ to ba BBC news sọ nilu Eko, sọ lori ibanisọrọ kan to sọ pe o waye laarin oun ati Nnamdi Kanu lori piparapọ lati le Buhari sita, eleyi ti ọkan lara awọn eekan ẹgbẹ IPOB ti jade lati sọ pe olori ikọ IPOB ko ba ẹnikẹni ni adehun ati le ẹnikẹni kuro ni ipo, oloye Fani kayọde ni ohun ko ni ero kankan lati doju ijọba tiwantiwa delẹ lọnakọna bikoṣe lati tubọ mu ki eto iṣejọba o tun gbilẹ daadaa ninu orilẹede Naijiria to wa ni isọkan.
Àwọn ohun ìkọ̀kọ̀ ọkàn rẹ̀ yóo hàn kedere, ni yóo bá dojúbolẹ̀, yóo sì júbà Ọlọrun.
Ajo to n ri si boolu afesegba lorile-ede Naijiria , NFF ti se kedun iku agbenusoro ajo ohun teleri, Austin Mgbolu.
Wọ́n rán àwọn alufaa ati àwọn kan ninu ẹ̀yà Lefi kí wọ́n lọ bi í pé “Ta ni ọ́?
Àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ wí fún un pé, “O rí i bí àwọn eniyan ti ń fún ọ lọ́tùn-ún lósì, o tún ń bèèrè pé ta ni fọwọ́ kàn ọ́?
Àwọn tí ń darí àwọn eniyan wọnyi ń ṣì wọ́n lọ́nà ni,àwọn tí wọn ń tọ́ sọ́nà sì ń já sinu ìparun.
Ṣe wọn si ni eeyan kan lo pari ni ilu ti wọn fi n pe gbogbo ilu ni apari.
O salaye pe, won se agbekale eto yii lati fi kase  ipari eto idanilekoo ati ibere idanilekoo miiran.
Awon kan tun daruko Humphrey Nwosu pe ki won ye oun naa si.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Igbákejì alága kú lẹ́yìn wákàtí díẹ̀ tó se ìbúra Márosẹ̀ Kaduna di ìbùba fáwọn ajínigbé Ilé aṣòfin Ọ̀yọ́ yan adarí ilé tuntun A gbọ pé alẹ́ ọjọ́ Ajé ni wọ́n ti gbé asaájú ẹgbẹ́ Shiite naa wá sí ìlú Kaduna, tí wọn sì fi pamọ́ sí ibití ẹnikẹ́ni kò mọ̀.
Ṣé a óo wá tẹ̀lé ìṣìnà yín, kí á sì máa ṣe irú nǹkan burúkú yìí, kí á sì máa fẹ́ àwọn obinrin àjèjì tí ó lòdì sí ìfẹ́ Ọlọrun wa?
ÒGÙN: Ògùn jẹ orukọ odo kan nilẹ Yoruba, o san lati ipinlẹ Ọyọ lọ si ilu Abẹokuta.
Serena funra rẹ gboriyin fun ọdọmọde Bianca, o ni: Inu mi dun fun Bianca, o ṣiṣẹ bi ọmọ akin nitootọ ninu idije yii.
Pupọ lara awọn ololufẹ rẹ lori ẹrọ ayelujara ti ko din nim ọgọta ẹgbẹrun lo kọ iwe ranṣẹ si lati dẹyin lẹyin rẹ ṣaaju akoko ti o fi tọrọ aforiji naa.
Ìlú náà kún fún ìṣúra,ati àwọn nǹkan olówó iyebíye.
Ó ya Ramoti sọ́tọ̀ ní Gileadi, fún ẹ̀yà Gadi, ó sì ya Golani sọ́tọ̀ ní Baṣani, fún ẹ̀yà Manase.
Nígbà tí wọ́n rí i, wọ́n bẹ̀ ẹ́ pé kí ó jọ̀wọ́ kí ó kúrò ní agbègbè wọn.
Eyi ko ṣẹyin ija ọrọ aje to n waye laarin orileede Russia ati Saudi to fi mọ airi ọja epo ta ti aisan corona virus naa ṣokunfa rẹ.
O si maa n nawọ ìrànwọ́ nípaṣẹ̀ ilé alaanu Oduduwà Foundation àti Hopes Alive Initiative to da silẹ.
“Dìde, lọ sí Ninefe, ìlú ńlá nì, kí o sì kéde iṣẹ́ tí mo rán ọ fún gbogbo eniyan ibẹ̀.
Kabir Rabiu to jẹ ọmọ ogun ọdun ni o ni oun jẹbi ẹsun ole ti wọn fi kan oun ati pe iṣẹ eṣu ni.
Àwọn ti ọ̀rọ̀ náà sojú wọ́n ṣàlàyé pé ẹni tí wọ́n gún pa yìí ti orúkọ rẹ̀ ń jẹ Ogbimi àti atún ọkọ̀ ṣe kan lọ gbé ọkọ kan ti ó dẹnukọlẹ̀ fún àtúnṣe.
Koda, àwọn ìlú Yorùbá gan o gbẹyin ninu idije ta lo n mu oogun Codeine yii.
ajo eleto idibo  ti ipinle naa omowe,Frankland
ilanilọye eto idibo fun awọn ara ilu, eleyii to nipa lara eto idibo naa
Ẹni tó bá bẹ̀rù OLUWA, yóo kórìíra ibi,mo kórìíra ìwà ìgbéraga, ọ̀nà ibi ati ọ̀rọ̀ ìbàjẹ́.
Bi bẹẹ kọ, ọkọ meje ni yoo ku mọ ọmọ naa lori, eyiun to ba jẹ obinrin, amọ ti ọmọ naa ba jẹ ọkunrin, aya meje ni yoo ku mọ ọmọkunrin naa lori to ba dagba tan.
Àwọn tí wọn ń fi òkùnkùn ṣe ìmọ́lẹ̀,tí wọn sì fi ìmọ́lẹ̀ ṣe òkùnkùn!
Alààyè, àní alààyè, ni ó lè máa yìn ọ́bí mo ti yìn ọ́ lónìí.
Ṣaaju ni agbẹjọro fun awọn olupẹjọ, Kayode Samson ati David Folalu ti sọ fun ile ẹjọ wipe awọn ti wọn fi ẹsun kan maa n ṣe ọdun oro wọn ninu igbo laarin oru.
Ọkàn rẹ̀ le bí òkúta,ó le ju ọlọ lọ.
Wò ó bí Alaafin àti aya àkọ́fẹ́ rẹ̀, Olorì Abibat ṣe pàdé ní èwe Mo ti gbà báyìí pé ohun gbogbo tó n dán kọ́ ni wúrà - Olori Badirat Adeyemi Tẹ o ba gbagbe, oṣu diẹ sẹyin ni iroyin sọ pe olori naa, ati gbajugbaja olorin Fuji, Wasiu Ayinde K1 n fẹ ara wọn.
Ọ̀pá ẹni tí mo bá yàn yóo rúwé; bẹ́ẹ̀ ni n óo ṣe fi òpin sí kíkùn tí àwọn ọmọ Israẹli ń kùn sí ọ.
Kò kúkú l'áàńṣàpèjúwèé kankan ẹ̀yin èèyàn mi.
Oríṣun àwòrán, @BUKOLASARAKI Àkọlé àwòrán, Buhari ati awọn gomina mejilelogun (22) ni wọn pe sibi igbeyawo ọmọ gomina ipinlẹ Ọyọ ati tipinlẹ Kano ninu osu kẹta Nibi igbewo yi Buhari lo se asoju ọkọ iyawo, Idris Ajimobi, to si san owo ori fun Asiwaju Bọla Tinubu, to ṣe asoju iyawo, Fatima Umar Ganduje.
Bakan naa lo sọ pe awọn oṣiṣẹ alaabo ti wa nilẹ lati mojuto awọn to n rinrinajo gba ipinlẹ Kaduna lati awọn ipinlẹ bi Eko, ati ilu bi i Abuja, Zaria, Kachia ati Jos.
akọ mààlúù kékeré kan, àgbò kan ati ọ̀dọ́ àgbò kan, ọlọ́dún kan, fún ẹbọ sísun; 
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, JusticeforBarakat: O lé lọ́mọ ọdún mọ́kànla kí n tó rí abúrò rẹ̀ bí lée Wayi o, orire oloogbe Barakat naa ti gbe alawore pade awọn ẹbi rẹ.
Oríṣun àwòrán, FRANCK FIFE Àkọlé àwòrán, ssi ko sí ninu awọn mẹta akọkọ Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Buhari ki Super Falcons kú oríire ife ẹ̀yẹ AWCON AFCON bọ́ mọ́ Cameroun lọ́wọ́ nítorí ìdí méjí-CAF Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ikọ̀ Super Falcons kijó mọ́lẹ̀ Kini ami ẹyẹ ballon d'Or da le lori?
O fi kun un wi pe wọn ti gbe iya rẹ naa lọ fun itọju pajawiri lẹyin ti ibọn ba a ni ikun ati ẹsẹ.
"Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Africa Eye: Wo ìtàn ìyá kan ìyá kan àtàwọn olè ajọ́mọgbé tó n ta ọmọ ní Kenya Ẹ wo o, emi ko kabamọ rara nitori pe mo yọ Sanusi loye Emir ti Kano"" Lasiko iṣejọba Rabiu Kwankwaso gẹgẹ bii gomina ipinlẹ Kano ni wọn fi Sanusi Lamido Sanusi joye Ẹmir ilu Kano ṣugbọn ni ọjọ Kẹsan an oṣu kẹta ọdun 2020 ni wọn rọọ loye."
Kò sí ẹni tíí fi ọtí titun sinu ògbólógbòó àpò awọ.
2018 FIFA U-20: Falconets Nàìjíríà kúrò ni France padà wálé
 Akeugbagold wa n beere pe Ṣe ẹṣẹ ni ki eeyan maa huwa rere si ọdọ to ni ọpọlọ lori amọ ti ko niṣẹ lọwọ bi?
2m ọmọdé kò ṣe lọ sílé ẹ̀kọ́ - SERAP ké tọ iléẹjọ́ àgbáyé Ọrọ̀ ajé Nàíjíríà tún leè dagun tí Buhari bá fi ìyànsípò àwọn mínísítà falẹ̀ si - Onímọ̀ Inu ọmọ ogun Bashir dùn lati ṣe ohun ti o tọ nipa jijẹ awokọṣe rere fun awọn ọdọ Naijiria.
Bẹẹ naa ni igbimọ amuṣẹya yi ni ki awọn ileewe wa ni titi pa fun oṣu marun naa.
eto oro aje ni ipinle Akwa Ibom.
Aare Buhari so pe: “Bi awon ti ikolu naa sele se n saapa won lati tun tesiwaju ninu aye won,  Emi ati ebi mi ati apapo ijoba orile-ede ati awon omo orile-ede yii kẹdun pelu aare Trump ati awon ti o fara kaasa isele ibi ohunt.
Bo tilẹ jẹ wi pe awọn eeyan ti o ba ikọ iroyin BBC News Yoruba sọrọ ko fẹ ki a gba ohun wọn silẹ, alaye wọn ni wi pe ọkan lara awọn aṣoju ẹgbẹ awakọ naa, Alhaji Mukaila Lamidi ti ọpọlọpọ eeyan mọ si 'Auxiliary' lo ko awọn ọmọ ẹgbẹ kan lẹhin lati tọpinpin aṣoju igun mii ninu ẹgbẹ naa, ti wọn pe inagijẹ rẹ ni 'Ajanaku' wa si ile rẹ to n bẹ l'agbegbe naa.
Ẹ má ṣe jẹ́ kí Hesekaya mú kí ẹ gbẹ́kẹ̀lé OLUWA, kí ó máa wí fún yín pé, ‘Dájúdájú OLUWA yóo gbà wá, ọba Asiria kò ní fi ogun kó ìlú yìí.
"Laipẹ yii a tun san owo ayipada kaadi idanimọ kan to jẹ ẹgbẹrun mẹwa naira.
Ẹ wo òtítọ́ ọ̀rọ̀ nàá Wo ìjìyà tó wà fún àwọn ọmọ Naijiria tí kò bá fi nọ́mbà NIN kún ìforúkọsílẹ̀ Siimu wọn láàrin ọ̀sẹ̀ méjì Wọn ni minisita naa n gba nnkan bii ẹgbẹrun mẹwaa owo orilẹ-ede ọhun lori ounjẹ ti eeyan kọkan n gba lati ọdọ ijọba.
Nínúu kẹ́ẹ kọ̀wé fipò sílẹ̀ tàbí kí ẹ gba ìdádúró, ẹ mú ọ̀kan - Ilé aṣòfin sí àwọn ọ̀gá àgbà ológun Wo bí ètò ìsìnkú Isa Funtua ṣe wáyé ní ìlú Abuja 'Adarí àjọ NDDC, Pondei ń ṣe àìsàn ló ṣe dákú lásìkó ìfọ̀rọ̀wánilẹ́nuwò' Alaafin Oyo kò dàgbà jù fún mi, ohun tó wù mí ní mo ṣe pẹ̀lú ayé mi- Olori Aanu O ba mi lojiji Reme sọ fun BBC."
03 million, nigba ti ile–ifowopamo  Fidelity se pasi-paro owo 20.
 lowolowo ohun ni aare orile-ede namibia .
4 8021 Orilẹede Guyana 170 21.
“N óo wá yí ọ̀rọ̀ àwọn orílẹ̀-èdè pada nígbà náà, yóo sì di mímọ́, kí gbogbo wọn lè máa pe orúkọ èmi OLUWA, kí wọ́n sì sìn mí pẹlu ọkàn kan.
’ rèé Olè wọ ilégbèé obìnrin ní fásitì Ibadan, àkẹ́kọ̀ọ́ méjì farapa Orí mi wú, Joke Silva kọ ewì ìfẹ́ lọ́jọ́ ìbí Olu Jacobs Ọkùnrin mẹrin wọ gàù torí ìgbéyàwó orí Facebook Ìgbín ní èmi àti ìyá mi máa ń he kiri, ká tó lee jẹun - Lizzy Anjọrin Odumakin salaye pe, obinrin ọhun ati awọn ọmọ ọdọ rẹ ni wọn n bọ lẹnu irinajo naa, asiko ti wọn de ikorita Ọrẹ si lawọn afurasi darandaran yii kọlu wọn, ti wọn si n yinbọn mọ wọn laibikita.
Ẹ níláti sin ín ní ọjọ́ náà, nítorí ẹni ìfibú Ọlọrun ni ẹni tí a bá so kọ́ orí igi, ẹ kò gbọdọ̀ sọ ilẹ̀ yín tí OLUWA Ọlọrun yín fun yín di aláìmọ́.
yìnyín a máa rọ̀ nígbàkígbà tí ó bá tutù tó nítorípé òtútù mú lókè àpáta ju pẹ̀tẹ́lẹ̀ lọ.
Eku àti ẹyẹ bínú si àdàn nitori ìwà àgàbàgebè ti ó hu yi, wọ́n pinu lati parapọ̀ lati dojú ìjà kọ àdán.
Lẹyin eyi ni wọn to le fun iru ọmọ bẹẹ ni awọn ounjẹ aṣaraloore miran.
ti salaye lẹẹkunrẹrẹ lori igbaradi fun eto aabo ti won  n se kaakiri orile ede Naijiria, ni eyi ti yoo
Ọrọ naa ya yin lẹnu bii?
Àkọlé àwòrán, Oyo NLC mú ìlérí rẹ̀ ṣẹ, ó bẹ̀rẹ̀ ìyanṣẹ́lódì Owó yii jẹ lara eyi to jẹ awọ̀n oṣiṣẹ ijọba ibilẹ bi i Lagelu, Ẹgbẹda, Ogbomọṣọ North, Ogbomọṣọ South, Surulere, ati Ibadan North West.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Coronavirus lockdown: Síńimá kòṣewòtán, Pásítọ̀ fo fẹ́ǹsì láti sá mọ́ Bi o tilẹ jẹ pe awọn ileejọsin kan tẹle ofin yii pe kawọn ileejọsin ileejọsin o maa ṣi ilẹkun wọn fun ijọsin, ọpọ awọn ile ijọsin miran lo keti ikun si aṣẹ naa.
Ní ọjọ́ kan, Jeroboamu ń ti Jerusalẹmu lọ sí ìrìn àjò kan, wolii Ahija, láti Ṣilo sì pàdé òun nìkan lójú ọ̀nà, ninu pápá.
Nigba tí àwọn ọmọ Israẹli gbọ́ èyí, gbogbo wọ́n bá péjọ sí Ṣilo láti lọ bá wọn jagun.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ṣé lóòtọ́, báwọn wọ̀nyìí ṣe sọ ọ́ ló rí fún gbogbo yín lọ́dún 2019?
Ṣaaju, ijọba ipinlẹ Oyo ati ẹbi oloogbe ti fi sita wi pe ilana Covid 19 gbaa ni awọn yoo tẹle fun eto isinku naa.
OLUWA Ọlọrun ní, “Ìwọ ọmọ eniyan, fi àsọtẹ́lẹ̀ bá Gogu wí, sọ fún un pé OLUWA Ọlọrun ní: ‘Mo lòdì sí ọ́, ìwọ Gogu, ìwọ tí o jẹ́ olórí Meṣeki ati Tubali.
Àwọn ọmọ Jedutuni jẹ́ mẹfa: Gedalaya, Seri, ati Jeṣaaya; Ṣimei, Haṣabaya ati Matitaya, abẹ́ àkóso Jedutuni, baba wọn, ni wọ́n wà, wọn a sì máa fi dùùrù sọ àsọtẹ́lẹ̀ ninu orin ọpẹ́ ati ìyìn sí OLUWA.
 phnom penh ni oluilu re ati ilu titobijulo nibe , ohun si tun ni gbanga fun okowo , aje , ile-ise ati asa ni kambodia .
Leyin osu die to sa kuro lorile ede naa, ni won ti n wa a kiri , ki o to di pe  ikolu yii waye.
Elisha Abbo ṣàlàyé ìdí tó fi lu obìnrin fún BBC Ẹ má bínú, mo kábàmọ́ pé mo na obìnrin -Elisha Abbo Èrò àwọn ọmọ Naijiria ṣọ̀tọ̀ọ̀tọ̀ lórí Tinubu àti Abbo Àwọn aṣòfin àgbà yóò wádìí ohun tó wáyé láàrín Sẹ́nétọ̀ Abbo àti obìnrin ilé ìtajà l'Abuja Eyi mu ki ọrọ naa de ileeṣẹ ọlọpaa, ti wọn si kọkọ gbe e lọ si ile ẹjọ majisireti kan ni agbegbe Zuba, nilu abuja.
Ọmọ a mẹ́ kìka kàn yan ẹsinsun t’ọrẹ
 Ẹnu ni a ń gbà fúnni ní àjẹsára náà , ènìyàn sì nílò ìwọ ̀ n egbògi náà méjì sí mẹta .
Education, didasilẹ Fafiti ile-eko awon oluko ti  ijoba apapo ni Zaria( Federal University of
Àwọn obìrin wọ̀nyí wà nínú ẹgbẹ́ MEX, ilé-iṣẹ́ tí a dá sílẹ̀ gẹ́gẹ́ bíi Ẹ̀ka Iṣẹ́ Àkànṣe LAM  Linhas Aéreas de Moçambique.
25 Owewe 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 26 Owewe 2019 Oríṣun àwòrán, @ Prof.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Àwọn ọmọ Nàíjíríà ló ṣiṣẹ́ takò mí ní Ireland kí ń má baà wọlé ìbò Káńsélọ̀ - Yemi Adenuga Láti January lọ, gbogbo ẹni tó bá ra ọjà lórí ayélujára yóò máa sanwó orí - FIRS Aṣojú Seyí Makinde lásan ní mo jẹ, òṣìṣẹ́ gbọdọ̀ bọ̀wọ̀ fún mi - Ọ̀dọ́mọdé Kọmísánà Èmi àti Bọla Tinubu fẹ́ lo ‘German Mercenaries’ láti gbé MKO Abiọla kúrò lẹ́wọ̀n - Dele Momodu Irọ́ ńlá!
Idi si niyii ti aisan itọ suga to waye nipasẹ ọjọ ori fi wọ́pọ̀ - ara to ti darugbo ko le ṣiṣẹ lori gbogbo awọn ounjẹ to wọ inu rẹ.
Manchester City vs Chelsea:Manchester City pàdí ọrẹ dà f'ogun ẹ̀yìn ja Chelsea
Dayọ Amusa ṣe bẹbẹ lati se ila alasepọ ni eyi to n da ọpọ eeyan lọfun tolo nibi.
Ati wi pe o maa n fi ọbẹ, igo ati awọn nkan oloro mi i dun kooko mọ ẹmi oun.
El Kanemi Warriors 16:00Go Round ?
eyi ti igbakeji aare orile ede Naijiria, ojogbon Yemi Osinbajo dari rẹ.
Ogagun Chukwu wa ro awon olugbe ipinle Yobe, paapaa julo agbegbe Katarko lati lo tesiwaju ninu ise ojo won, ki won maa si foya, sugbon ki won ri daju lati pe akiyesi awon agbofinro si ipa ese ti won ba fura si.
 orúkọ àbísọ lè tó láti mọ àwọn orí oyè , ṣùgbọ ́ n ìjọba wọn tí se pàtàkì jù , ẹ ̀ pọ ́ n wọ ̀ fun .
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Osinbajo: Ẹgbẹ̀rún mẹ́wàá náírà ni ọlọ́jà kọ̀ọ̀kan gbà 2 Èrèlè 2018 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 6 Bélú 2018 Oríṣun àwòrán, @profosinbajo Àkọlé àwòrán, Ẹgbẹrun mẹwaa ni o kan ontaja kọọkan Igbakeji aarẹ, Yẹmi Ọsinbajo se abẹwo si ipinlẹ Eko ni ọjọ Aje, lati pin owoya fun awọn ọlọja.
" Ikọ olupẹjọ náà ni, ẹsẹ kan ṣoṣo tí olóògbé náà ṣẹ àwọn awakọ èrò náà, tí wọ́n fi rán án sọrun ọsan gangan ni pé, ó sewuri fún àwọn onikẹkẹ Maruwa láti máa na Ayetoro, èyí tó ń mú adinku bá owó tí àwọn awakọ èrò ń pá.
Jesu wá tẹjú mọ́ ọn, ó fi tìfẹ́tìfẹ́ wò ó, ó wí fún un pé, “Nǹkankan ló kù kí o ṣe: lọ ta ohun gbogbo tí o ní, kí o pín owó rẹ̀ fún àwọn aláìní, o óo wá ní ọrọ̀ ní ọ̀run; lẹ́yìn náà wá, kí o máa tẹ̀lé mi.
Trump tọrọ aforiji lori asise rẹ Ààbọ̀ ìpàdé Bùhárí rèé pẹ̀lú Trump Mo ni ọwọ nla fun Afrika-Trump Iléeṣé MTN ti san bíliọnù N55 owó ìtanràn wọn tó kù -MTN Ninu abẹwo ọlọjọ mẹta yii ni Trump yoo ti ṣe ipade pọ pẹlu Theresa May to jẹ olootu to ti kọwe fipo silẹ bayii lori ọrọ ayipada oju ọjọ.
Báàgì, bàtà, aṣọ òjò, tampoli ti eeyan lee da bo ọkọ tabi ẹru ti ẹ o fẹ ki ojo pa wa lara ohun ti Olayemi n fi aloku ọra omi ṣe.
Nígbà tí Abimeleki dé ibi ilé ìṣọ́ náà, ó gbógun tì í.
Odò Jọdani ni ààlà ilẹ̀ wọn, ní apá ìsàlẹ̀ òkun Kinereti, lọ sí apá ìlà oòrùn, níkọjá odò Jọdani.
Ninu atẹjade kan ti awọn akọwe ẹgbẹ oṣiṣẹ nipinlẹ Ọyọ, Mohammed Ibrahim, fi sita ni Ọjọbọ, ni awọ̀n adari oṣiṣẹ ti paṣẹ fun gbogbo oṣiṣẹ lati joko sile wọn.
Láti inú ẹ̀yà Simeoni, ẹẹdẹgbaarin ó lé ọgọrun-un (7,100), àwọn akọni jagunjagun ni wọ́n wá.
Appendicitis Dokita Obinnaadigo ṣalaye pe àpẹẹrẹ akọkọ ti aisan appendicitis ma n fihan ni ki isalẹ inu o ma a dun eeyan.
Arun Coro"" ṣi n dọdẹ gidi gan ni Naijiria bẹẹ si ni lonii, iye awọn to lugbadi arun yii ti le ni ẹgbẹrun marun-din-lọgbọn bayii."
Oríṣun àwòrán, @vanguardngrnews Ninu atẹjade ti awọn obininrin na fi lede, wọn ki aya Ajimobi ku irọju ati afarada lẹyin iku ọkọ rẹ.
- Ìwádìí BBC Ẹ wo báwọn òṣèré tíátà kan yóò ṣe rí lọ́jọ́ ogbó Ọọ̀nì àléégbà dé bá ọ lálejò, kí ló máa ṣe?
Adonija lọ jíròrò pẹlu Joabu, ọmọ Seruaya, ati Abiatari alufaa, àwọn mejeeji tẹ̀lé ọ̀rọ̀ rẹ̀, wọ́n sì ràn án lọ́wọ́.
Wọ́n ń wí pé, “Níbo ni eléyìí ti kọ́ ẹ̀kọ́?
Ó ní kí ẹ sọ ohun tí ẹ ti gbọ́ fún ọba Juda tí ó ranṣẹ láti wá wádìí lọ́wọ́ OLUWA Ọlọrun pé, èmi OLUWA Ọlọrun Israẹli ní, 
tun je igbakeji alaga gbogbogboo fun egbe APC ni ila  ( Gusu ), Awon to tun wa ninu igbimo naa
Ninu atẹjade kan ti Adari eto Iroyin fun ileesẹ NNPC, Dokita Kennie Obateru fi sita lo ti salaye pe, isbugbamu ọpa epo naa waye lasiko ti wọn n ri opo ọpa epo mọlẹ.
Bí ó ti ń fúnrúgbìn lọ, díẹ̀ bọ́ sí ẹ̀bá ọ̀nà, àwọn ẹyẹ bá wá, wọ́n ṣà á jẹ.
Buhari, Obasanjo ṣe'pade nilu Abuja EFCC ń wádìí iléeṣẹ́ 'Bola Tinubu,' Alpha Beta Consulting Ltd' Lai Mohammed fèsì sí ọrọ Obasanjo Ẹ̀rò àwọn ènìyàn se ọ̀tọ̀ọ̀tọ̀ lórí lẹ́tà Ọbasanjo sí Buhari Obasanjo sọ pe oju ọrun to ṣu dẹẹdẹ yii, ojo iparun, ojo ajalu ati ojo ainiṣọkan ni yoo fi rọ ti ijọba ko ba wa nnkan ṣe si ọrọ eto aabo ni Naijiria.
Ẹ pa ara yín mọ́ ninu ìfẹ́ Ọlọrun.
NURTW: Ija ọmọ ẹgbẹ gbẹmi eeyan kan Ọlọpa mu asaaju ẹgbẹ NURTW NURTW yóò fikùnlukùn pẹ̀lú Gómìnà Makinde láìpẹ́ NURTW l‘Abuja yóò kàn sí Makinde láìpẹ́ lórí bó ṣe fòfin dè wá l‘Ọyọ - Ejiogbe Ẹ ranti pe ipinlẹ Ogun ati Oyo fofin de ẹgbẹ naa nitori ipenija si ọrọ eto aabo ti ija laarin awọn ọmọ ẹgbẹ naa maa n fa.
Là mí lóye, kí n lè máa pa òfin rẹ mọ́,kí n sì máa fi tọkàntọkàn pa wọ́n mọ́.
Titi funra rẹ n bẹ ni ẹsẹ kan aye, ẹsẹ kan ọrun nileewosan.
Nígbà tí ó bá yá, bí wọ́n bá fi tọkàntọkàn kọ́ àṣà àwọn eniyan mi, tí wọ́n sì ń fi orúkọ mi búra, tí wọn ń wí pé, ‘Bí OLUWA Ọlọrun ti wà láàyè’, bí àwọn náà ṣe kọ́ àwọn eniyan mi láti máa fi orúkọ Baali búra, n óo fi ìdí wọn múlẹ̀ láàrin àwọn eniyan mi.
Gẹgẹ bi iroyin abẹle ti a gbọ lati ibẹ, ko pẹ pupọ lẹyin ti ọwara ojo to balẹ lowurọ ọjọ Aje ni ilu Ibadan wawọ ro diẹ tan ni ọmọdekunrin naa ti orukọ rẹ n jẹ Mujeeb Trimisiyu pada lọ si ile awọn obi rẹ to wa lagbegbe Tose lagbegbe ijọba ibilẹ Akinyẹle lati lọ ree ṣe igbọnsẹ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ayodele Fayose and Seyi Makinde: Màá fidán han Seyi Makinde, tó bá yọjú sí Ekiti 12 Èrèlè 2018 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 10 Owewe 2020 O ti n rugbo bọ laarin awọn ọmọ ẹgbẹ oselu PDP lẹkun iwọ oorun guusu Naijiria, to si dabi pe wọn ti n bẹnu fun ara wọn.
Wọ́n ṣá Ṣobaki tí ó jẹ́ balogun wọn lọ́gbẹ́, ó sì kú sójú ogun.
Pẹ̀lúmi lu odindi ìlú kan ní jìbìtì ẹgbẹ̀lẹ́gbẹ̀ owó Ọ̀ọ̀ni kò láṣẹ láti yọ mí nípò, mi ò sì ní ááwọ̀ mọ́ pẹ́lú Aláàfin-Oluwo Nàíjíríà, ẹ fakọyọ lórí ìdènà Coronavirus àmọ ìròyìn òfegè léè ṣọṣẹ́ tẹ̀ bá ṣọ́ra - WHO Obasanjọ wa fi ewe ọmọ mọ awọn ọmọ aarẹ Naijiria, Muhammadu Buhari leti pe to ba kọti ikun si atunse ati atunto orilẹede wa lasiko yii, afaimọ ki omi ma ti ẹyin wọ igbin lẹnu, tori yoo lẹyin, bii oku iya jọjọ.
Nítorí pé Ọlọrun ní ń fun yín ní agbára, láti fẹ́ ṣe ìfẹ́ rẹ̀, ati láti lè ṣe ohun tí ó wù ú.
Àkókò wíwá nǹkan wà, àkókò sísọ nǹkan nù wà;àkókò fífi nǹkan pamọ́ wà, àkókò dída nǹkan nù sì wà.
Mo sì gbàgbọ́ pẹ̀lú pé, nínú ìpàdé oúnjẹ, iyàn á ṣe alága, àmàlà á ṣe igbákejì, ìrẹsì ni ìgbá kẹta, ẹ̀kọ ni aṣáájú, ó sì kẹ́ onírẹ̀lẹ̀, ṣùgbọ́n ọbẹ̀ ni ọlọ́pàá, òun ni atọ́kùn òkèlè, gbà tí iyán gbéyàwó, ọbẹ ilá ni ìyàwó, gbà tí àmàlà lóbìnrin, ewéédú lobìrin, ẹ̀fọ́ laya àkàṣù, mọ́ínmọ́ín arẹwà, olùfẹ́ ẹ̀kọ mímu, dodo náà kò rẹ̀yìn, baálẹ̀ ìgbèríko, dùǹdú kò kéré, ó jọba sí ìletò, kakaǹfòi níbẹ̀pẹ, ọ̀gẹ̀dẹ̀ wẹẹrẹ laṣipa, ìgbà tí gaàrí ń ṣọdún ó pe eja sípàdé, ó pe ẹran.
Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Fídíò, Azeezat Shomuyiwa : Oyún oṣù méje ló wà nínú Azeezat, kí wọ́n tó f'òkúta fọ́ ọ lórí pa9 Òkùdu 2020 Fídíò, CAN: ó pọn dandan kí wọn fágile ìdánwò ọlọ́pàá29 Èbibi 2018 Fídíò, CAN: ó pọn dandan kí wọn fágile ìdánwò ọlọ́pàá29 Èbibi 2018 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 3 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 5 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
" Lizzy fikun pe Baba oun Alaafin wa lootọ lati wa sure fun igbeyawo oun, to si beere lọwọ ọkọ oun pe baalu kekere ni ko san bii owo ori fun oun.
Ojú tì ọ́, ìwọ Sidoninítorí òkun ti fọhùn, agbami òkun ti sọ̀rọ̀, ó ní:“N kò rọbí, bẹ́ẹ̀ ni n kò bímọ;n kò tọ́ àwọn ọmọ dàgbà ríkì báà ṣe ọmọkunrin tabi ọmọbinrin.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Logo Benz: Ọba ìlú Benin kìlọ̀ fáwọn ọ̀dọ́ lórí ṣíṣe òògùn owó òjijì.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ondo Elections 2020: Ọgọ́rùn-ún ọdún tí a máa lò lórí oyè l'Ondo, ẹ ó rí àrà - Ojon YPP Ọpọ awọn osisẹ agbofinro si la gbọ pe wọn peju wamu wamu sile asofin apapọ naa, ti aarẹ Buhari ti n gbe aba isuna naa kalẹ.
Iṣẹlẹ ọhun waye lọjọ Abamẹta, ọgbọnjọ oṣu kẹjọ, ọdun 2020 nigba ti bireki ọkọ nla meji ọhun ja lori oke.
Ipò ètò ààbò ń já àwa gómìnà láyà, ó ń kọ wá lóminú - Àwọn gómìnà Ẹ má dá NEF lóhùn, kò síbi t'ọ́mọ Nàìjíríà kò lè gbé nílẹ̀ yìí - Buhari Kò lè ṣééṣe kí Ruga wà lápá gúúsù Nàìjíríà fáwọn Fulani- Ganduje O ni ki oun to lo ọgọrun ọjọ ni ijọba ipinlẹ naa ni awọn yoo bẹrẹ eto aabo to munadoko kaakiri ipinlẹ naa.
Ijọba Ghana yoo ṣe ijiroro pẹlu idile ọmọọba Osu to ta ilẹ naa lati yanju ọrọ to wa nilẹ yi.
Ijọba ti kọkọ ṣe edinwo epo bẹntiro lati naira marunlelogoje si naira marunlelọgọfa lọjọ kejilogun oṣu kẹta.
” Ṣugbọn ó ṣá tẹnumọ́ ọn pé bẹ́ẹ̀ ni ọ̀rọ̀ rí.
Oríṣun àwòrán, @rcgchristchurch O ti de si etigbọ̀ mi bayii pe awọn eeyan kan n lo fọto mi lara kalẹnda, iwe, ẹbun tẹ n pin ati ‘keyholder’."
22 Owewe 2020 Oríṣun àwòrán, @Oladapo Agba ọjọ ninu onkọwe lede Yoruba kan tun ti ki aye pe o digbose!
Gbogbo Orílẹ̀-Èdè ni yóo Wà lára Àwọn Eniyan Ọlọrun.
" Hubert Ogunde rèé, baba àwọn òsèré tíátà Ọọni, Aláàfin, Ojisẹ Ọlọ́run àti oniṣẹ ìwádìí fi Ògún gbari pé òògùn ìbílẹ̀ le wo Covid-19 Àlàyé rèé lóríi ìdí tí wọ́n fi ń pe aya ní ìyàwó Olorì Memunat Omowunmi Adeyemi, ṣe sadankata si ọkọ rẹ, Ọba Lamidi Olayiwola Adeyemi Kẹta, pe oun ni ọkọ to dara julọ ni agbaye.
Ọlọ́pàá ń wa Ọmọkùnrin tó pa ọmọ igbákejì Gómìnà Ondo gba ìdàjọ́ ikú Àwọn mọ̀lẹ́bí ajínigbé tó pàdánù ẹ̀mí l'Ondo kò tí ì yọjú Ọ̀gá àgbà iléèṣẹ́ ọlọ́pàá dín wákàtí iṣẹ́ ọlọ́pàá kù Bi a ko ba gbagbẹ,Ọwọ ọlọpaa nipinlẹ Ondo tẹ afunrasi naa ti wọn lo mọ nipa bi ina ṣe jo eeyan mẹsan mọle nilu Akure.
Simon Lalong: Gómìnà ìpínlẹ̀ Plateau ni ẹni tó bá fẹ́ ipò ní ìjọba òun gbọ̀dọ̀ yan ẹranko kan láàyò
Agbẹnusọ Ile Igbimọ Aṣofin Ipinlẹ Eko, Aṣofin
N24bn pọ̀ jù láti kọ́ ọ́fíìsì EFCC"" Ẹnu kò tí i sìn lára àjọ EFCC lórí iye tó lò láti kọ́ olú iléeṣẹ́ tuntun fún àjọ nàá."
Ẹ gbọ́ ọ̀rọ̀ OLUWA,ẹ̀yin ìjòyè Sodomu:Ẹ fetí sí ẹ̀kọ́ Ọlọrun wa,ẹ̀yin ará Gomora
Ẹ wo bi irinajo ọmọkunrin naa se lọ ati ohun ti oju rẹ ri ko to de ilu wọn.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Ta ló dà bíi Ọlọ́run Fayoṣe' lorin tó ń jáde nílé ẹjọ́ Ọjọru ni ileẹjọ naa kede fun gbigbọ ẹjọ lori ẹbẹ fun gbigba oniduro Ayọdele Fayoṣe, babi si ni yara igbẹjọ kun fun awọn agbẹjọro atawọn ololufẹ gomina ana ni ipinlẹ Ekiti ọhun to bẹẹ gẹẹ ti Onidajọ Olatoregun to n gbọ ẹjọ naa ni lati paṣẹ fun gbogbo awọn eeyan ti ko ba tii ṣe agbẹjọro ti wọn ko si ri aaye joko si lati jade sita.
Mo dúpẹ́ nítorí ó kà mí yẹ láti fún mi ní iṣẹ́ rẹ̀, 
Mo wá òkúta ńlá kan mo fi ṣe ilẹ̀kún mo sì lu ihò kéékèèkéé sí òkè ihò náà, mo fi àwọn wọn-ọnnì ṣe fèrèsé, nítorí bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé òkúta ni gbogbo ẹ̀gbẹ́ ihò mi yìí, síbẹ̀ apá kan orí rẹ̀ ni ó jẹ́ òkúta; apá kan tí ó sì jẹ́ erùpẹ̀ ni mo ṣe àwọn fèrèsé mi sí.
“Nítorí náà, nígbà tí ẹni tí ó ni ọgbà àjàrà bá dé, kí ni yóo ṣe sí àwọn alágbàro náà?
Gẹgẹ bi ọrọ ti ajọ NCDC fi lede loj opo Twitter rẹ lalẹ ọjọ Aiku, eeyan 1,024 tuntun miran lo tun fara kasa arun ọhun bayii.
Ade jake-jado ile kaaro- o- jire; Aare ona kakanfo ile yoruba, Otunba Gani
Rwanda Tẹlẹri, orilẹ-ede Rwanda ko ka awọn obinrin si.
Olè gbé òrùka ìgbéyàwó mì ní Eko Àwòrán àjọyọ̀ ìjọba ológun ní Sudan Wahala iyan rọ dẹdẹ sori South Sudan Àwọn òṣìṣẹ́ aláàbò kọlu àwọn tó n ṣe ìwọ́de ní Sudan Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
"Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ọkọ̀ rélùwéè 16 yóò ná Eko sí Ibadan láti oṣù tó ń bọ̀ lọ - Iléeṣẹ́ Rélùwéè kéde Géńdé agbébọn yabo àgọ́ ọlọ́pàá n‘Ibadan, ẹ̀mí ọlọ́pàá kan bọ́ Ọba Ilorin ló pàṣẹ pé kí ń padà sọ́dọ̀ ọkọ mi - Risikat olójú búlúù NCDC kéde èèyàn 340 míràn tó ṣẹ̀ṣẹ̀ lùgbàdì Covid-19 ní Nàìjíríà A fí ara mọ́ ìdájọ́ ikú Sharia tó tọ́ sí Olórin Yahaya- ẹgbẹ́ Amòfin Mùsùlùmí ẹ̀ka ìpínlẹ̀ Kano O ni ""Arun naa ni anfani lati maa fẹ loju si bi awọn eeyan ṣe n fara kanra, ṣugbọn a ni imọ ijinlẹ to dantọ lati koju rẹ."
"Ǹkan tí ó yẹ ki o mọ̀ nípa Burna Boy Ilé ẹjọ́ ju ọmọ ìjọ tó fi ìpá bá ọmọ pásítọ̀ rẹ̀ sùn ní ìpínlẹ̀ Ondo sí ẹ̀wọ̀n gbére Ìjọba ìpínlẹ̀ Osun tí búwọlù ìlànà àyẹyẹ Ọṣun-Oṣogboo ọdún 2020 Àwọn ẹgbẹ́ Tijjaniyya ti yọwọ́ kílàńkó Yahaya Sharif kúrò láwo ẹgbẹ́ wọn ní Kano ""Mi ò ní wọ Uber mọ́ tí wọ́n bá leè fi owó lée nítorí àfikún owó orí tí Sanwo Olu ṣe"" Mr Fabulous tun mẹnuba asiko to maa ṣe igbeyawo pe ko i to nitori oun ko ni obinrin afẹsọna rara."
Láìpẹ́ ni Wunmi Toriọla bá BBC Yoruba sọ̀rọ̀ lórí gbọ́nmi síì omi ò tó tó wáyé láàrin òun àti Toyin Abraham.
Ajọ WAEC ni awọn kii fun eniyan ni iwe ẹri lẹẹ meji ati pe gbogbo awọn ti iwe ẹri wọn ba sọnu pẹlu lanfani sii.
Awọn ẹsun ti ọlọpaa ka sii lẹsẹ ree: Umar kii ṣe ọgagun ninu Boko Haram nikan; adari ikọ adigunjale ni, bẹẹ si ni ẹgbẹgun rẹ maa n fọ ile ifowopamọ, ti o si jẹ onimọ ninu ṣiṣe ado oloro.
Brendan Rodgers di akọ́nimọ̀ọ́gbá Leicester Ó tó gẹ́, Atikulated àti àwọn àṣà ìpolongo tó gbòde lásìkò ìbò 2019 Àwọn aríran lórí ẹni tí yóò di ààrẹ Naijiria PDP pe ìpàdé pàjáwìrì lórí èsì ìdìbò ààrẹ l'Abuja O ti di ija mẹrinla bayii ti Usman ti ja lai fidi rẹmi ninu ọkankan ninu awọn ija ọhun.
Iwọde yii lo mu ẹmi opolopo eeyna lọ ati ti agunbanirọ Channels kan ati ọga agba ọlọpaa kan.
Ibo kika naa, to bẹrẹ ni bii aago mejila aabọ loru ọjọ Aiku, ni alamojuto eto idibo gomina ni ipinlẹ Ondo, Ọjọgbọn Idowu Olayinka, tii se ọga agba fasiti Ibadan, ṣide rẹ.
Oríṣun àwòrán, BBNaija/Twitter Loni ọjọ Aiku, ọjọ kẹsan an, oṣu kẹjọ yii ni ibeere nla ti gba ọkan awọn ololufẹ eto Big Brother Naija season five yii.
Dokita Sanusi Mohammed Bala ni irọ ni iroyin yii.
Ṣugbọn bí alufaa bá fi owó ra ẹrú fún ara rẹ̀, ẹrú náà lè jẹ ninu àwọn ohun mímọ́ náà.
Ẹ mú gbogbo ìdámẹ́wàá yín wá sí ilé ìṣúra, kí oúnjẹ baà lè wà ninu ilé mi.
 Èyí ló fà á ti wón fi ńpe ilé yìí ní ìlé ikú-kò-gbó-ìlèkùn .
 Ajo ilera agbaye, WHO, ti kede pe igbona ti n tankale sii lawon orile ede lohun.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ibadan: awon araalu figbe bonu pe ilu doti Gomina Seyi Makinde ti kọkọ se ipade lọsan ọjọ aje pẹlu awọn eeyan ti eto ipalẹmọ ẹgbin nipinlẹ Ọyọ gberu ati awọn ọmọ igbimọ alakoso fun ileesẹ to wa fun ipalẹmọ ẹgbin nilu Ibadan.
Ọlọrun rán ẹ̀mí ọmọ rẹ̀ sinu ọkàn wa, Ẹ̀mí yìí ń ké pé, “Baba!
South Africa: Kò pọn dandan fún mi láti tọrọ àforíjì lówọ Nàìjíríà
“Ṣé ìwọ ni ẹni kinni tí wọ́n kọ́ bí láyé?
Awon ti won kopa ninu ere naa ni: Boseman to je olu eda itan Black Panther, to pada wa sile gege bii Oba ile Wakanda, to huwa akoni gba ipo re pada lowo awon ota orile ede re.
O ṣiṣẹ pẹlu ẹgbẹ akọrin Barrister, Supreme Fuji Commander, laarin ọdun 1975 si 1978.
Ayẹwo ti fihan gbangba pe igbakeji aarẹ Naijiria, Yemi Osinbajo ko ni arun coronavirus.
6) Ki wọn maa lo gbagede fun awọn eto kọọkan dipo inu iyara ikawe tabi kilaasi.
Bákan náà ni yóo rí fún ìlú Ekironi, nítorí ìrètí rẹ̀ yóo di òfo.
inúu wa dùn nítorí wípé a fún àwọn ènìyàn mìíràn ní ìmísí ni.
Nígbà tí Abiatari, ọmọ Ahimeleki sá tọ Dafidi lọ ní Keila, ó mú aṣọ efodu kan lọ́wọ́.
" Àyọka Ìwé ìròyìn "" evening standard "" sọọ ́ di mímọ ̀ wípé ó ti ń wakọ ̀ fún ilé iṣẹ ́ fún ọdún mẹwa , ó sì ti ju ọdún méjì tí ó ti ní ìwé àṣẹ làti wa irú ọkọ bẹ ́ ẹ ̀ Ìkan lára àwọn tó ku , jẹ ́ ọmọ ọdún méjìdińlógún , tí ó sì lóyún ."
Bakan naa, ni adele akonimoogba iko agbaboolu Ivory Coast, Ibrahim Kamara kede Eric Bailly, Wilfried Zaha sara iko ti yoo koju Togo ati Moldova, bi o tile je pe, won sese pada sori papa latari ifarapa ti won ni.
Bi a ko ba ni gbagbe, ni ọdun meji sẹyin ni irufẹ iroyin bayii ṣẹlẹ eyi ti aje rẹ ṣi mọ agba olukọ kan ni fasiti naa, iyẹn ni ẹka imọ iṣiro owo lori.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ile ounjẹ igbalode bi ẹgbẹrun mẹtadinlọgbọn lo wa ni ilu New York Oṣu to kọja ni ijọba Saudi Arabia fi ofin de awọn arinrinajo ẹsìn lati ilẹ okeere pe, ki wọn o ma wa a si ilu Mecca ati Medina.
Dafidi Jọba lórí Israẹli ati Juda.
Ẹ máa gbadura fún àwọn tí wọn ń ṣe àìdára si yín.
js” charset=”utf-8″></script> Ti a o ba gbagbe pe  awọn  ọlọpaa  ti kọkọ pe Abẹnugan ile-igbimo asọfin Saraki lati wa salaye nipa ẹsun ti  wọn  fi kan an lori idigunjale to sẹlẹ niluu Offa, pe o je baba –isalẹ fun  awọn  adigunjale naa.
" fun apẹẹrẹ , awọn mejeeji ep sanders ati paula fredriksen ṣe atilẹyin fun itan itanjẹ agbelebu sugbon o ṣe jiyan pe jésù ko sọ asọtẹlẹ agbelebu rẹ ati pe asọtẹlẹ ti agbelebu jẹ "" ẹda ẹda "" ( p."
Ọ̀rọ̀ tí OLUWA sọ fún Jeremaya nípa ọ̀gbẹlẹ̀ nìyí:
Kemi Olunloyo rọ ìhà méèjèjì láti simi àgbaja kí wọn sì tẹ̀síwáju ninu ìrìnajo ayé wọ́n.
Naijiria gege bi won se n  se ni Orilede
" Osinbajò ní, ọ̀pọ̀ àwọn ìlàna àmúlò ìjọba ní ó dúrò lóri fifi àwọn òtòsì sọ́kàn, pẹ̀lú àfọkan si lóri ètò ọ̀gbìn àti láti máà gbe owoya fún àwọn àgbẹ, ki wọn lee ni aníto àti ànisẹkun.
Lẹ́yìn tí Gomeri gba ọmú lẹ́nu ‘Kò sí Àánú’ ó tún lóyún, ó sì bí ọmọkunrin kan.
Ẹẹmẹta ní ọdọọdún ni gbogbo ọkunrin yín níláti wá siwaju èmi OLUWA Ọlọrun yín.
Wọ́n mú ọrẹ wá tóbẹ́ẹ̀ tí àwọn tí wọn ń ṣe iṣẹ́ ibi mímọ́ náà tọ Mose lọ; 
Kò sí àyè fún fíìmù eré ìfẹ ṣíṣe ni Kannywood mọ́ Aisha Buhari ké gbàjare pé ètò ìjọba Buhari kò ṣànfàní f'óbìrin Ọ̀gọ̀rọ̀ èèyàn lórí ayélujára bú Dalung lórí owó IAAF NBC fọwọ́ sí ìdásílẹ̀ ilé iṣẹ́ Fulani Radio Bolanle Sarumi Aliyu sọ fun BBC Yoruba pé mọkan-mọkan loye n kàn, nígbà tó bá di àsìkò tèmi, èmi náà á dé 'bẹ̀.
Lati asiko yii lọ, mo paṣẹ gẹgẹ bii gomina wipe ki wọn wọgile sisan iru owo bẹẹ.
Báyìí ni ọ̀rẹ́ mi parí ìtàn yìí, ọkùnrin pàtàkì, ọ̀rẹ́ mi tòótọ́ Baba-onírùngbọ̀n-yẹ́úkẹ́, ẹni tí ń gbé ibi gegele  òkúta.
Nítorí ìfẹ́ àti fi orúkọ ẹni sí ipò iyì àti ẹ̀yẹ ni àwọn Yorùbá fi fi orúkọ wé ìjanu.
N óo dá ire wọn pada, n óo sì ṣàánú fún wọn.
Lara awon ti o gba iko Super Falcons wo ilu Abuja ni akowe agba ajo NFF, dokita Mohammed Sanusi, ati awon osise ajo NFF miiran.
bẹ́ẹ̀ ni kí o fi ìjì rẹ lé wọn,kí o sì fi ààjà rẹ dẹ́rù bà wọ́n.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù MaguEFCC: Omale ni orúkọ tí Magu ń lò.
Oògùn yìí wà wí pé kí n baà lè tètè sùn lálẹ́ àti wí pé bí mo bá sùn tán kí n má baà jí títí ilẹ̀ yóó fi mọ́ tí òun tìkaraarẹ̀ yóò jí mi.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Busola Dakolo: Ìdájọ́ ilé ẹjọ́ yàtò sí ǹkán tó sẹ̀lẹ̀ ní 14 Bélú 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 15 Bélú 2019 Oríṣun àwòrán, @BIODUNFATOYINBO/@BUSOLADAKOLO Àkọlé àwòrán, Pasitọ Biodun Fatoyinbo àti Busola Dakolo Agbẹjọro fun Busola Dakolo ti ni awọn n gbe Biodun Fatoyinbo lọ si ile ọjọ kotẹmilọrun lẹyin ti ile ẹjọ da ẹjọ ifipanilopọ to pe mọ danu.
ní ọ̀nà jíjìn, ní ìhà àríwá, ìwọ ati ọpọlọpọ orílẹ̀-èdè, gbogbo wọn lórí ẹṣin, ọpọlọpọ eniyan, àní, àwọn ọmọ ogun.
Kì í ṣe nítorí ìwà òdodo yín, tabi ìdúróṣinṣin ọkàn yín ni ẹ óo fi rí ilẹ̀ náà gbà; ṣugbọn nítorí ìwà burúkú àwọn orílẹ̀-èdè wọnyi ni OLUWA Ọlọrun yín fi ń lé wọn jáde fun yín, kí ó lè mú ìlérí tí ó fi ìbúra ṣe fún Abrahamu ati Isaaki ati Jakọbu, àwọn baba yín, ṣẹ.
Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí 6:18 Fídíò, Natalia Mufutau ìyá Yakub, Kamil àti Adam sọ̀rọ̀ lórí bí wọ́n ń sọ èdè mẹ́rin pàpọ, Duration 6,1831 Ògún 2020 4:42 Fídíò, Jude Chukwuka: Wọ́n yóò fi ojú ọlọgbọ́n wo akúrí tó bá sọ ojúlówó èdè Yorùbá, Duration 4,4222 Ògún 2020 Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí kan sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
Aare Muhammadu Buhari ti bowolu ẹ̀gbẹ̀rún lona ogbon naira(N30,000) gege bi  ẹkunwo  owo osu tuntun awọn osisẹ, eleyi opolopo awon osise ti n reti lojo pipe.
Òmùgọ̀ ọmọ lè kó ìparun bá baba rẹ̀,iyawo oníjà dàbí omi òjò tí ń kán tó, tó, tó, láì dáwọ́ dúró.
Ọ̀kùnrin ọdún 75 gbẹ́mìí mì nínú odò Ọ̀sà l'Eko Àwọn ohun tó yẹ kí o mọ̀ nípa igbákejì Jimi Agbaje ‘Afẹnifẹre lé Sẹnetọ Omisore nítorí kò finú hàn wọ́n’ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Òṣìṣẹ́ Bánkì ni mí l'Amẹ́ríkà kí n tó bẹ̀rẹ̀ Tíátà' Ninu lẹta ọhun to kọ, to si di kika ninu awọn iwe iroyin jakejado Naijiria, Iyabọ fi ẹsun wiwu iwa atobi ma ṣe e bawi, ti ki i gbọ imọran ẹlomii lori ohunkohun to ba fẹ ẹ ṣe.
Agbabọọlu fun orilẹ-ede Brazil tẹlẹ ri, ẹlẹsẹ ayo, Ronaldo ti inagijẹ rẹ n jẹ ''The Phenomenon'' ti sọ pe Liverpool yoo fagba han akẹgbẹ wọn, Tottenham ninu aṣekagba idije UEFA Champions League ti yoo waye lọjọ Abamẹta.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Èrò ọ̀pọ̀ èèyàn yàtọ̀ lórí lẹ́tà Alaafin Oyo sí Gomina Fayemi l‘Ekiti nípa ìyọnípò ọba N kò kọ̀ kí ń kú, ìfẹ́ tí mo ní sí Buhari ni mo ṣe sáré dì mọ"" Ẹ wo ìdí tí El Rufai kò fi leè fi Sanusi sílẹ̀ Láì lo Kakulétọ̀, mo ní ọpọlọ ìṣirò, tábìlì ìṣirò wà lórí mi - Human Calculator Amọ lara awọn ikinni to ya ni lẹnu julọ ni ti gbajugbaja osere tiata lobinrin kan, Ronkẹ Ojo Anthony, taa mọ si Ronkẹ Oshodi Oke, ẹni to gbe awo orin jade fun MC Oluọmọ."
Oluwo gboṣuba fofin ilana isinku Ogun.
Ṣé ẹṣin a máa sáré lórí àpáta?
Ọmọ ènìyàn dá mi lóhùn ni gbólohùn kan.
Oríṣun àwòrán, AFP Àkọlé àwòrán, Mo ku ti ni ọrọ Shekau Igba ikẹrin ti wọn ṣofọ Abubakar: Lọdun 2015 ni aarẹ orilẹ-ede Chad, Idriss Deby sọ pe o ti tan fawọn alakatakiti ẹsin Islam Boko Haram.
Èmi Paulu, iranṣẹ Kristi Jesu, ni mò ń kọ ìwé yìí.
Barrister ló sọ mí di èèyàn ńlá - Ayinla Kollington Èmi kò gbé pọ̀ pẹ̀lú Kollington Ayinla àmọ́ ọjà t'ọ́mọ ti wọ̀ lọ̀rọ̀ àwa méjééjì - Salawa Abẹni Ẹ wo àwọn ìròyìn tó ṣì ń gbóná fẹli fẹli lọ́sẹ̀ yìí Eleyi si ti n mu ki ọgọọrọ awọn eeyan maa beere pe, abi Ọba Waka ti pada sile Ọba Fuji bayii ni?
"Aarẹ ajọ IOC lagbaye, Thomas Bach ṣalaye pe, ""Ọmọ eniyan n la afonifoji dudu kọja lọwọ bayii, idije olympics yii si lee jẹ imọlẹ ti yoo tan lẹyin okunkun biribiri naa"" Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!"
"- Sanwo-Olu Ọtí tí wọ́n fi Sanitáísà àti Methanol pò pọ̀ ṣekú pá èèyàn 86 Láti 462 sí 386, àwọn tó ní àrùn Covid-19 já wálẹ̀ ní Nàìjíríà lọ́jọ́ Àbámẹ́ta Dúkìá àti ọjà jóná ráúráú lásìkò tí iná sọ ní ọjà Mushin ní Eko Ko si ẹni to ba n wo awọn ere ibilẹ Yoruba to kun fun aṣa, iṣe ati igbagbọ ẹya Yoruba ti ko ni mọ mama, Ọṣuntoun paapaa julọ nitori awọn ipa awọn ""ẹlẹmi agba"" to ko ninu awọn ere oloogbe Yẹkini Ajilẹyẹ."
Oríṣun àwòrán, Getty Images Fun apẹẹrẹ, ọpọ eeyan laagbọ pe o ṣeeṣe ko jẹ pe covid-19 lo pa wọn ṣugbọn ko si ayẹwo fun wọn.
Ṣùgbọ́n ìgbà tí Èṣù dé ibẹ̀ tí ó nawọ́ sókè báyìí, tí ó ní kí méjìlá nínú wọn jáde, ṣe ni a ri tí àwọn ẹranko wọ̀nyí yípadà tí wọ́n di ènìyàn.
Sugbọn, àwọn oṣiṣẹ ajọ LASTMA, ati FRSC wa nibẹ lati ma a dari.
Eto naa wa awọn to fẹ ẹ fi orukọ silẹ fun: Direct Short Service Commission' ati fun 'Short Service Combatant commission' .
Agbẹnusọ fun awọn obi naa, Manasseh Allen sọ fun BBC Yoruba wipe ọdun mẹta sẹyin ni ijọba fun awọn ni iroyin bii igbesẹ lati wa awọn ọmọ to ku si igbekun ṣe n lọ.
Ìgbìmọ̀ akẹ́kọ̀ọ́ sì ti ti ìyàrá ìpàdée wọn pa fún ìgbà díẹ̀, nítorí ọ̀rọ̀ àbò.
Jakọbu dá baba rẹ̀ lóhùn, ó ní, “Èmi Esau, àkọ́bí rẹ ni, mo ti ṣe bí o ti wí, dìde jókòó, kí o sì jẹ ninu ẹran ìgbẹ́ tí mo pa, kí o lè súre fún mi.
Fatima ni idi ti oun fi ya fidio naa ni lati jẹ ẹri fun ọjọ iwaju nitori awọn ko mọ oun ti Iyawo Aarẹ naa le ṣe si awọn, nitori ara rẹ gbona gidigidi.
Wúrà ni wọ́n yọ́ bo àwọn Kerubu náà.
Ṣugbọn wọn kò lè ṣe é ní àkókò rẹ̀ nítorí àwọn alufaa tí wọ́n ti ya ara wọn sí mímọ́ kò tíì pọ̀ tó, àwọn eniyan kò sì tíì péjọ sí Jerusalẹmu tán.
Àkọlé àwòrán, Ìtàn Manigbagbe: Àwọn àjakalẹ-àrun to ti wáyé rí ṣáájú Coronavirus E je ka ṣe àwọn ohun tó yẹ ká ṣe láti jajabọ lọ́wọ́ àrùn náà bii titakete sì ìpéjọpọ èèyàn, ká máa fọ ọwọ wa ni oorekoore, ká sì dúró sínú ilé wa.
O si tun kekọọ gboye ninu imọ ofin ni Fasiti Washington.
Aṣa irufẹ ounjẹ wa jẹ Yoruba logun pupọ.
Mo ti mọ ẹrù ńlá tí Ọlọrun dì ru ọmọ eniyan.
Ìyàwó wọ sòkòtò fún ayẹyẹ ìgbéyéwò rẹ̀, ní wáhálà bá bẹ́ sílẹ̀ Scotland ti di orílẹ̀-èdè àkọ́kọ́ tó bẹ́rẹ̀ si pínpín páàdì ǹkan osu fún gbogbo obìnrin lọ́fẹ̀ẹ́ Ó tó gẹ́!
Nígbà tí mo bá dé, n óo ṣe ètò nípa àwọn nǹkan tí ó kù.
Nígbà tí mo ṣàìsàn, ẹ wá wò mí.
Jeremaya wá bi Sedekaya ọba pé, “Ẹ̀ṣẹ̀ wo ni mo ṣẹ̀ ọ́, tabi àwọn ẹmẹ̀wà rẹ, tabi àwọn ará ìlú yìí, tí ẹ fi jù mí sẹ́wọ̀n?
Ajínigbé ń bèèrè fún epo, iṣu àti ọ̀tí Schinap gẹ́gẹ́ bí owó ìtanràn 'Ẹ má ṣi Fayemi túmọ̀ lórí àṣẹ tó pa nípa sísọ èdè Yorùbá' Wo ipò tí Buhari fún Faṣọla, Lai Mohammed, Saraki àti bẹ́ẹ̀ bẹ́ẹ̀ lọ Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
"Bi iṣẹ ṣe pọ fun un to, iyawo mi lo ṣi n da ina ounjẹ to si n bu ounjẹ ti mo n jẹ, koda o ṣi maa n ge eekana fun mi.
Amọ, O ni ohun ti oun gbọ ni wi pe ẹni ti o ba ni owo julọ ni Olubadan n fun ni oye, bi ko tilẹ ni orukọ rere.
se da duro funra won lori eto inawo lorile ede Naijiria , Presidential
Ẹ wá ń fi ìtara retí ìfarahàn Oluwa wa Jesu Kristi, 
Ninu ọrọ rẹ , o dupẹ fun aduroti ati amọran ti o n ri gba lọwọ onipo jipo awọn onibara rẹ.
Nítorí pé gbogbo rẹ̀ tòfin-tòfin ni,èyí òfin, tọ̀hún ìlànà.
Canada ń ṣọ́ ẹ o Olùdíje fún ipò aàrẹ (Republican) lọdun 2008 jáde láyé Cardi B ti pín yà pẹ̀lú ọkọ rẹ̀ Offset lẹ́yìn ọdún kan Èèyàn ogún bá ìjàmbá ọkọ̀ lọ Titi di isinyi, ko si ẹni to mọ idi to fi yinbọn pa ọlọpaa to da ọkọ rẹ duro ati awọn ero to wa nibẹ.
Wọn ti pari idibo lori awọn olugbe ile ẹlẹgbọn agba ti wọn le dibo lati yọ ninu abala idije naa ti a mọ si Big Brother Naija lockdown Season 5.
Bí ó ti ń lọ, àwọn ọmọdekunrin kan ní ìlú náà bẹ̀rẹ̀ sí fi Eliṣa ṣe ẹlẹ́yà; wọ́n ń wí pé, “Kúrò níbí, ìwọ apárí!
Ounjẹ ajẹju ko dara rara fun ọpọlọ eeyan: Gbogbo nkan lo ni iwọn-tun-wọn-si laye, eyi kọ yọ odiwọn ounjẹ ti eeyan n jẹ silẹ ati irufẹ ounjẹ ti eeyna n jẹ.
Kò fi ọ̀ràn mọ bẹ́ẹ̀; kò gba àwọn arakunrin tí wọ́n wá, àwọn tí wọ́n sì fẹ́ gbà wọ́n, kò jẹ́ kí wọ́n gbà wọ́n, ó tún fẹ́ yọ wọ́n kúrò ninu ìjọ!
CAN kò rán ẹnikẹ́ni lọ ṣọ́ọ̀ṣì COZA, iṣẹ́ ara wọn ní wọ́n lọ jẹ́ -Samson Ayokunle Ìdí rèé tí mi ò fi yọjú sí ìgbìmọ̀ àjọ PFN- Fatoyinbo Ronaldo, Messi ẹ yàgò lọnà fagbábọ́ọ̀lù Nàìjíríà tó n gbowò julọ!
Lasiko ti nnkan le koko fun Adegbọrọ, ti ko ri ba tise, ti ko ri ọna gbegba, ti isẹ n sẹ ẹ gidi, lo ba ronu jinlẹ lori ọna abayọ si ipọnju to ba a yii.
se ki egbe oselu ANC maa ni iye awon asoju , ki eleyii si jẹ ki won fidi rẹmi
Aṣẹ́wó, olè, gbájúẹ̀ ni 723 ọmọ Naijiria ta lé padà sílé - Ghana Oluwọde tako ele owo epo ni Ghana Saraki pe fun ajọṣepọ Ghana ati Naijiria 'Ileesẹ ọlọpa Ghana yoo ri atunto' Buhari fẹ ran Ghana lọwọ lori iwa ibajẹ Kojo Oppong Nkrumah to jẹ minista fun eto iroyin ati ifitonileti gbogbo ni Ghana ṣalaye pe, ọwọ agbofinro ti tẹ awọn afurasi oniṣẹ ibi naa.
Tọkunrin, tobinrin tọmọde tagba lo n wa si aafin wa ki awọn ẹbi ati Oloye ku ara fẹraku Kabiesi Adegbitẹ to lọ ba awọn baba nla rẹ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Hakeem: Mo lè sọ arúgbó dí ọmọge nígbà tó bá wù mí Dokita Hong ni awọn oyin mẹrẹrin ṣi wa laaye, ati pé wọn ti fi awọn oyin naa ranṣe si ile iṣẹ imiran ti wọn yoo ti ṣiṣẹ iwadii to peye nipa wọn nitori pe, igba akọkọ ni yii lorilẹ-ede Taiwan ti iru nkan bayii a ṣẹlẹ.
Ó gbé wọn kalẹ̀ sí ẹ̀gbẹ́ ara wọn ninu Ibi-Mímọ́-Jùlọ.
NFF fi #30,000 kún #10,000 owó ìrànwọ́ oṣooṣù fún ìyá Rashidi Yekini àti Samuel Okwaraji
Daniẹli dá ọba lóhùn pé, “Kò sí ọlọ́gbọ́n kan, tabi aláfọ̀ṣẹ, tabi pidánpidán, tabi awòràwọ̀ tí ó lè sọ àṣírí ìjìnlẹ̀ ọ̀rọ̀ tí ọba ń bèèrè yìí fún un.
ni ipinle Kwara,ni aarin gbungbun orile ede Naijiria.
Wọ́n ní kí ọ̀gá àgbà Ede Poly"" lọ rọ́kún nílé lórí ẹ̀sùn pé 'ó kan bẹ́ẹ̀dì sí ọ́fíìsì' Wo àwọn Adelé-Ọba aládé méje tó jẹ́ obìnrin nílẹ̀ Yorùbá Ṣé irúfẹ́ oúnjẹ tí ò ń jẹ́ lè jẹ́ kí o gbádùn ìbálòpọ̀ rẹ síi?"
Awọn adari mẹtalelaadorin naa parapọ si ààfin Burkingham lati leè jiroro lori ẹni ti yoo di ipo adari ajọ Commonwealth mú lẹyin Ọbabinrin Elizabeth ni ọjọ Ẹti.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ẹsa awọn aworan to rẹwaju kaakiri Arfika l'ọsẹ yii 24 Ẹrẹ̀nà 2018 Ẹsa awọn aworan to rẹwaju kaakiri Afrika ati ti awọn eeyan Afrika nibomiran lagbaye ninu ọsẹ yii.
Jẹ́ kí ọ̀run ati ayé kí ó yìn ín,òkun ati gbogbo ohun tí ó ń rìn káàkiri ninu wọn.
Bi awọn ipinlẹ to ni Coronavirus ṣe lọ ree: Eko-36 FCT-35 Oyo-29 Kaduna-10 Abia-9 Osun-5 Ogun-5 Enugu-5 Rivers-4 Nasarawa-3 Ekiti-3 Imo-3 Edo-2 Kwara-2 Katsina-2 Plateau-2 Niger-1 Èèyàn 125 míràn ṣẹ̀ṣẹ̀ kó COVID-19 ní Nàìjíríà Ajọ to n gbogun ti ajakalẹ arun lorilẹede Naijiria, NCDC ti kede afikun eeyan marundinlaadoje 125 pẹlu arun COVID-19 lorilẹede Naijiria.
BBC ṣe ìwadìí lórí bí ìrẹ̀wẹ̀sì ọkàn ṣe ń mú kí àwọn ọkùnrin lórílẹ̀èdè Kenya ó máa gb'ẹ̀mí ara wọn
Ìwọ́de EndSARS ti yíwọ́ pátápátá ní Ondo - Ọlọ́pàá Ẹ̀yin ọ̀dọ́ ti rí èrè ìwọ̀de yín lórí EndSARS àmọ́ ẹ ṣọ́ra, kẹ má baà sọ èrè náá nù - Tinubu Ẹni iyì àti akíkanjú tó ṣe gbẹ́kẹ̀lé làwọn èèyàn Akure, ilú ìyá mi - Seyi Makinde ''Ẹwa ede ni ki awọn eniyan lo gẹgẹ bi ọrọ asa(slang) lawujọ fun iwulo wọn'' Imọ wa ti ko pọ nipa ede lo jẹ ki a maa tẹmbẹlu rẹ'' Nibayii, sọrọ soke ti di akanlọ ede, eleyii to tumọ si wi pe awọn eniyan ti n lo o ju bi a ṣe mọ ọ si lọ Bawo ni aṣe le lo ''Sọ̀rọ̀ Sókè'' tí àwọn afẹ̀họ́núhàn EndSars ń lò káàkiri Ojọgbọn imọ Ede Yoruba, Bisoye Ẹlẹsin ni ''sọrọ soke'' bayii ti tunmọ si ki eniyan ṣe ohun to tọ lasiko laifaṣẹyin Ki eniyan dide ni kanmọ ko gbe igbeṣẹ to yẹ ṣiṣe ojuṣe gẹgẹ bi ijọba Awọn ọrọ to tun dabi rẹ ni gbohun soke, gbohun safẹfẹ- eleyii to tun mọ si pe atẹgun ni ọrọ, afẹfẹ lo n gbe kaakiri.
Oun si ni ẹni ti yoo maa ṣoju awọn ara ilu ninu igbimọ ẹlẹni meje ọhun Segun Awosanya Ọkan gboogi lara awọn to n ṣagbatẹru iwọde End SARS ni Segun Awosanya jẹ.
Bisọ́ọbu ni koda laipe ni ijọ Winners tun da ẹ̀ka okoo le ni ẹẹdẹgbẹta silẹ̀.
Akọroyin BBC to kọja lori afara naa ni opin ọsẹ ni nnkan ti yatọ si ti tẹlẹ gẹgẹ bi òun ti oju.
Ṣugbọn a kọ ìwọ̀nyí kí ẹ lè gbàgbọ́ pé Jesu ni Mesaya, Ọmọ Ọlọrun, ati pé tí ẹ bá gbàgbọ́, kí ẹ lè ní ìyè ní orúkọ rẹ̀.
Abala tí wọn sì túnṣe yìí jẹ́ ti obìnrin nígbàtí abala tí kò rí àtúnṣe náà jẹ́ ti ọkùnrin.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Bàtà àti aṣọ tú àṣírí afurasí adigunjalè Olórí alátakò ìjọba ní Mozambique kú Ohun t'ójú oníròyìn ń rí kúrò ní kèrémí Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Ṣugbọn nisinsinyii, mo ti parí iṣẹ́ mi ní gbogbo agbègbè yìí.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Aisha Buhari: Torí òtítọ̀ ni mo fi sọ̀rọ̀ tako ọkọ mi 16 Ìgbé 2018 Oríṣun àwòrán, @aishambuhari Àkọlé àwòrán, Aisha Buhari ní ìfẹ́ ìdájọ́ òdodo ti òun ní ló fàá tí òun fi ṣe bẹ́ Ìyàwó ààrẹ orílẹ̀èdè Nàíjíríà, Aisha Buhari ti sọ ìdí tó fi sọ̀rọ̀ tako ọkọ rẹ, Ààrẹ Mùhámádù Bùhárí̀ lórí ìṣèjọba rẹ̀ láwọn àkókò kan sẹ́yìn.
Ẹ wo àrà tí ''Ayo the Creator'' ń fi sinimá dá
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Inu ile pẹlu agbẹbi ni aboyun mii fẹran Ajọ UNICEF parọwa pe o yẹ ki a tubọ ṣiṣe sii ni Naijiria lati din iku awọn ọmọ ọwọ ku sii lasiko yii.
Solskjaer tun tẹsiwaju, o ni ''Van Persie gba aṣo igbabọọlu oun to ni nọmba ''20'', ohun kan to maa ri gba lọwọ mi niyẹn.
Oríṣun àwòrán, @joshua Àkọlé àwòrán, Ṣe ẹ ti gbọ́ ri?
Adonija, ọmọ tí Hagiti bí fún Dafidi, bẹ̀rẹ̀ sí gbéraga, ó ń wí pé, “Èmi ni n óo jọba.
Oríṣun àwòrán, @NGRPresident Àkọlé àwòrán, Ọbasanjọ ti kọkọ kọ lẹta si Buhari eleyi to di gbajugbaja kaakiri agbaye Ẹ̀wẹ̀, àjọ tó n jàfún àkóyawọ́ lẹ́ka ètò ọrọ̀ ajé, (SERAP), lọ́dún 2016 késí adájọ́ àgbà ní Nàìjíríà, Onídàjọ́ Walter Onnoghen, láti yan agbẹjọ́rò tí kìí sẹ tìjọba láti ṣe ìwádìí àwọn ẹ̀sùn ìwà ìbàjẹ́ tó jẹyọ nínú bí ìṣàkóso Oluṣẹgun Ọbasanjọ ṣe ná mílíọ́nù mẹ́rìndínlógún lórí iná ọba.
” Àwọn eniyan náà bá lọ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Internet: Ìpínlẹ̀ Oyo ni yóò kọ́kọ́ jànfàní òpó ìtàkùn àgbáyé 18 Sẹ́rẹ́ 2019 Oríṣun àwòrán, iStock Àkọlé àwòrán, Ina Ọba Ijọba apapọ orilẹede Naijiria ni awọn n pinu lati ya iye owo ọgọrun miliọnu dollar lati orilẹede India Owo yiio ni ijọba ni awọn fẹ lo fun idagbasoke itakun agbaye to fi mọ ẹrọ ayelujara ninu ilu ati lẹyin odi.
Mo ti fi ọba Ai, ati àwọn eniyan rẹ̀, ìlú rẹ̀ ati ilẹ̀ rẹ̀ lé ọ lọ́wọ́.
Ọ̀rọ̀ mi ati iwaasu mi kì í ṣe láti fi ọ̀rọ̀ ọgbọ́n tí ó dùn létí yi yín lọ́kàn pada, iṣẹ́ Ẹ̀mí ati agbára Ọlọrun ni mo fẹ́ fihàn; 
Osinbajo fárígá: Mò ṣetán láti wàákò pẹ́lù àwọn tó ń bàmí lórúkọ jẹ́!
O ti fi ọ̀rọ̀ gbé àwọn tí wọn ń ṣubú ró,ọ̀rọ̀ rẹ ti fún orúnkún tí ń yẹ̀ lọ lágbára.
Omowe Hamzat ni gbogbo iran Yoruba lo wa ninu igbekun yii laimọ nitori ko si ẹni ti ko le ṣẹlẹ si.
Ó wí fún wọn pé, “Kí ló dé tí ẹ fi ń kùn sinu?
Oríṣun àwòrán, Instagram Àkọlé àwòrán, Ọjọ Kini, Osu Kini bakan naa ni wọn bi Moyo Lawal ti o ti kopa ninu ọpọlọpọ awọn ere agbelewo.
Àkọlé àwòrán, Ilé ẹjọ́ gíga ti ìlú Eko Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ sí: Nnamdi Kanu: Ìdí tí mo fi sá ní Nàìjíríà Ǹjẹ́ ara rẹ ń kọ ìbálòpọ̀ bí?
Oríṣun àwòrán, others Yato sí pe siga mímú n koba ẹdọ fooro eniyan, o tún máa n mú kí ọpọlọ ma ṣiṣe to bo ti ṣe yẹ.
Ó wí fún un pé, “Samsoni!
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, JusticeforUwa:Awọn àkẹkọ̀ọ́ Uniben wọ́de ìfẹ̀hónú hàn nítórí Uwa tí wọ́n fipa bálòpọ̀ Wọ́n ní ìwà yìí pẹ̀lú kò mọ́ àsọ tí ènìyàn wọ tàbí ọjọ orí oní tọ̀hún.
“OLUWA wà láàyè,ìyìn ni fún àpáta ààbò mi.
Àyípadà tàbi Àtúnṣe yẹ ki ó bẹ̀rẹ̀ pẹ̀lú òṣiṣẹ́ Ìjọba, àwọn ti ó nta ọjà, ọ̀gá ilé-iwé àti àwọn ọmọ ilé-iwé, àwọn òṣiṣẹ́ ilé-ìwòsàn, ọmọdé àti àgbà ilú.
Ati pe, awọn dokita n fa omi si i lara ni gbogbo igba to fi wa nileewosan.
Awọn musulumi nipinlẹ Eko yoo laanfani lati kopa ninu irun Jimọ loni lẹyin nkan bi oṣu mẹrin ti ijọba fofin de akojọpọ lawọn ile ijọsin.
Ṣé ẹni ikú pa kọ́ ló d'óró fún
Mo ní ọ̀rọ̀ fún ẹ̀yin yòókù, (èrò tèmi ni o, kì í ṣe ọ̀rọ̀ Oluwa wa.
fihan pe ajo INEC ko bẹru  tabi gbe lẹyin
wákàtí 3 sẹ́yìn Oríṣun àwòrán, Getty Images Ibẹrẹ Anthony Joshua Wọn mọ ẹbi Joshua daadaa ni ilu Sagamu, ti wọn si mọ itan awọn baba nla rẹ daadaa.
ẹ̀yin tí ẹ̀ ń wí fún igi pé igi ni baba yín,tí ẹ sì ń sọ fún òkúta pé òkúta ni ó bi yín;nítorí pé dípò kí ẹ kọjú sí ọ̀dọ̀ mi,ẹ̀yìn ni ẹ kọ sí mi.
Dapọ Abiodun ni opin ti de ba inira ti awọn obi n koju lati le san owo ile iwe awọn ọmọ wọn.
aare si, won si tun ran aare leti nipa ileri ti o sẹ  fun awon obinrin lasiko eto idibo, , won wa ro
Nínú àlàyé rẹ, aṣáájú ikọ olupẹjọ, Arábìnrin C Rotimi-Odutola ṣàlàyé fun ilé ẹjọ́ pé ọ̀daràn náà ṣẹ ẹsẹ ọhun lọ́jọ́ kẹwàá oṣù kẹrin ni ìkòríta Gbara, Ayetoro ládùúgbò Ajegunle nílùú Eko.
Ààrẹ Túnisia kú sẹyin odi lẹ́ni ọdun mẹtalélọ́gọ́rin
Oríṣun àwòrán, Twitter/Pogba Àkọlé àwòrán, Idije Champions League Ifẹsẹwọnsẹ lọpọlọpọ ololufẹ ere bọọlu sọ pe o le julọ ninu gbogbo rẹ.
OLUWA gbọ́ adura rẹ̀ lórí ilẹ̀ náà, àjàkálẹ̀ àrùn náà sì dáwọ́ dúró ní ilẹ̀ Israẹli.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Donald Trump: ṣàbẹ́wò ọlọ́jọ́ mẹ́ta sílẹ̀ gẹ̀ẹ́sì 6 Òkùdu 2019 Wo àwọn àwòrán tó làmì-laaka nínú àbẹ̀wò Donald Trump àti Melania aya rẹ̀ wá sí ilẹ̀ Gẹ̀ẹ́sì lọ́sẹ̀ yìí.
Jeremaya kọ gbogbo nǹkan burúkú tí yóo ṣẹlẹ̀ sí Babiloni ati gbogbo àwọn ọ̀rọ̀ tí ó sọ nípa rẹ̀ sinu ìwé kan.
“Àwọn ọmọ ọba Siria yóo gbá ogun ńlá jọ, wọn yóo sì kó ogun wọn wá, wọn yóo jà títí wọn yóo fi wọ ìlú olódi ti ọ̀tá wọn.
"Awọn osere tiata tẹ ro pe wọn n ri owo pupọ lasiko yii ju asiko tiwa lọ, se inu isẹ tiata yii naa lẹ ro pe wọn ti n ri owo pupọ naa lati fi ra awọn ọkọ nlanla ati awọn ile awosifila tẹ ro pe wọn ni yii?
Ọba alaye naa, to ni awọn ko ni fi ọwọ yẹpẹrẹ mu isẹlẹ naa tun fikun pe ko yẹ ki irufẹ rogbodiyan bayii waye nitori gomina ipinlẹ Eko, Babajide Sanwo-Olu tete dide si ibeere awọn ọdọ naa.
Titi di osu Kẹrin, ko ju eeyan mẹsan an to gba ti ọwọ arun yi ku nibẹ.
Titi di bi a ṣe n ko iroyin yii jọ, ko tii si ẹni lee sọ ni pato ohun to ṣokunfa iku rẹ, ṣugbọn ohun ti a gbọ ni wi pe, ohun funra rẹ lo wa ọks lọ si ileewosan naa ni ọsẹ meji sẹyin fun ayẹwo ilera rẹ ti wọn si daa duro lati sinmi.
Abajade iru igbesẹ naa ni pe awọn eeyan kan yoo padanu iṣẹ wọn lasiko yii.
láti inú ẹ̀yà Nafutali, ó rán Nahibi ọmọ Fofisi; 
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Akẹkọ kan ku,ileẹkọ jona ninu ija akẹkọ fasiti Modibbo 5 Èrèlè 2018 Oríṣun àwòrán, Modibbo Adama University website Àkọlé àwòrán, Rogbodiyan ija ẹsin nileẹkọ naa se akoba fun idanwo asejade fawọn akẹkọ Ọrọ ti bẹyin yọ lori rogbodiyan to bẹ silẹ laarin awọn akẹkọ ileẹkọ fasiti imọ ẹrọ Modibbo Adama, to wa nilu Yola nitori awọn alasẹ ileẹkọ naa ti sọ agadagodo sẹnu ọna ileẹkọ ọhun.
 awọn mẹ ́ ta péré ló yè nínú àwọn tó yìnbọn mọ ́ .
Níbẹ̀ a lọ kí àwọn onigbagbọ, a sì dúró lọ́dọ̀ wọn fún ọjọ́ kan.
Agbẹjọro agba Livy Ozoukwu lo ṣoju Atiku Abubakar ati ẹgbẹ oṣelu PDP nibi igbẹjọ naa.
Wọ́n mú Paulu lóru lọ sí ìlú Antipatiri.
Wọ́n sì tọ́jú gbogbo nǹkan fún àsè Ìrékọjá.
 6 ni april 8 , 1996 , leyin igba to de ilajidopin ni open australia 1996 .
Awọn ẹsun onikoko mẹrin yii si lo kan ile asofin nipinlẹ Eko lara, eyi to mu ki wọn gbe igbimọ oluwadii ẹlẹni mẹsan kan kalẹ, ti Asofin Victor Akande ko sodi.
Nítorí náà, jọ̀wọ́ pada ní alaafia, kí o má baà múnú bí wọn.
Ẹni tí ó wí pé iṣẹ́ olùkọ́ kò wu òun mọ́ wí pé òun ń fẹ́ẹ́ ṣe akọ̀wé bá ara rẹ̀ ní ibi iṣẹ́ akọ̀wé nítòótọ́ ṣùgbọ́n nígbà tí ó kọ́ bẹ̀rẹ̀ iṣẹ́, ilé tí ó ti ń ṣiṣẹ́ kún fún ọ̀pọ̀lọpọ̀ ènìyàn, àwọn akọ̀wé jẹ́ ẹgbẹ̀rún bẹ́ẹ̀ ni òun sì ni ìkẹhìn gbogbo wọn; iṣẹ́ rẹ̀ kò lọ déédéé nítorí kò ní ẹ̀bùn iṣẹ́ tí ó wọ̀ ọ́ lójú yìí bẹ́ẹ̀ ni kò bá àwọn ọlọgbọ́n ibi iṣẹ́ yìí rìn ó ń ṣe bí àwọn ọmọ olówó láìní owó lọ́wọ́, àwọn tí kò gbẹ́kẹ̀lé owó oṣú nìkan tí wọ́n tún ń gba owó mìíràn lọ́wọ́ bàbá wọn bẹ́ẹ̀ ni onírúurú ènìyàn tí ó wà ní ibi iṣẹ́ yìí jẹ́ ìdánwò fún ọkùnrin náà, nígbà tí Aṣojú-Olódùmarè sì fi máa padà dé, inú gbèsè ni ó bá a.
Iṣẹ́ nṣẹ́ ‘Gún, Àwòdì ò bá ‘Gún ra.
Wọ́n pe Jesu ati àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ sí ibi igbeyawo náà.
Bàbá mi mi’rí, ó jù mí lọ́wọ́ sílẹ̀, ó sì wọ yàrá rẹ̀ lọ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Sotitobire church: Àwọn ọ̀dọ́ ilu dáná sun ilé ìjọsìn Sọtitobirẹ nílú Akure 18 Ọ̀pẹ̀̀ 2019 Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Sotitobire church: Àwọn ọ̀dọ́ ilu dáná sun ilé ìjọsìn Ileeṣẹ ọlọpaa ipinlẹ Ondo ti sọ pe ayederu iroyin ni pe wọn ba oku ọmọ kekere ninu ile ijọsin Sọtitobirẹ Miracle Centre, nilu Akurẹ.
Àwọn kan tilẹ ni emi ni o gbimọ lati pa iya mi tabi pe ohun lo fira rẹ wewu.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Àwọn ìgbà tí ẹ̀ṣọ́ aṣọ́bodè ti pànìyàn lọ́nà àìtọ́ Àjọ aṣọ́bodè gba Codeine N200m Iléeṣẹ́ aṣọ́bodè gba nǹkan ìjagun àìtọ́ Ẹ́ wo iye ààrẹ Nàíjíríà tó sọ̀rọ̀ ìjayà lásìkò ìbò INEC tako àṣẹ Buhari lórí pípa ẹni tó bá jí ìbò gbé Amọ nigba ti Asoju Ile Ghana ,Kwame Takyi n fesi, o ni awọn ti wọn le wale naa ni ilẹ Ghana fẹsun kan wi pe, wọn n se asemase bii hihu iwa ole, gbigbe ilu lọna ti ko bofin mu, sise isẹ asẹwo ati lilu awọn eniyan ni jibiti.
O ní ṣe pẹ̀lú gbogbo àwọn asoju .
Toyin Abraham bí ọmọkùnrin jòjòló Ariwo Allahu Akbar"" kò tọ́ sawọn Agbébọn àti Boko Haram - Buhari Facebook fi kọ́kọ́rọ́ ti àwọn ojú òpó ayédèrú ìròyìn léde Yorùbá àti Igbo Gẹgẹ bi igun olupẹjọ naa ti wi, awọn ipinlẹ mọkanla ọhun ti asise isiro esi ibo ti waye ni ipinlẹ Bauchi, Borno, Gombe, Jigawa, Kaduna, Kano, Katsina, Kebbi, Niger, Yobe ati Zamfara."
Sugbọn awọn agbẹnusọ fun aarẹ Buhari ko tii fesi pada lori ọrọ yi.
Akọroyin BBC News Yoruba to wa nibi idibo naa ṣalaye pe awọn aṣoju ọmọẹgbẹ gbogbo to fẹ dibo ni wọn ti wa nikalẹ ti wọn si n reti ki eto naa bẹrẹ.
 wọ ́ n fẹ àwòrán ti tẹ ́ lẹ ̀ tẹ ́ lẹ ̀ lọ ́ wọ ́ òkè ní ọrundún méjìdínlógún sẹ ́ yìn .
A pín iṣẹ́ fún àwọn ọmọ Amramu, ati àwọn ọmọ Iṣari, ati àwọn ọmọ Heburoni ati àwọn ọmọ Usieli.
Onnoghen lojo Eti ti n se osu keji ojo kerinla , odun 2019.
Wọ́n ń fi fèrè ati ìlù ati àwọn ohun èlò orin mìíràn kọrin ìyìn sí OLUWA pé:“OLUWA ṣeun,ìfẹ́ ńlá Rẹ̀ kò lópin.
Ijoba orile ede Gabon ti kowe fipo sile lojo Isegun leyin ti ile-ejo tu ile-igbimo asofin ka, ti ile-ejo naa tun pase fun awon adari orile ede naa lati fi ipo sile nitori pe won sun eto idibo siwaju.
Nípa igbagbọ ni Abrahamu fi gbà nígbà tí Ọlọrun pè é pé kí ó jáde lọ sí ilẹ̀ tí òun óo fún un.
Oríṣun àwòrán, Reuters Àkọlé àwòrán, Awọn molebi ati ara adugbo suru bo ọkọ ọlọpaa Osise ijọba kan, Jesus Santander, fidi ọrọ naa mulẹ pe ọlọpaa kan fara gbọta ninu isẹlẹ naa eleyi ti wọn ti dẹkun rẹ.
Ọlọrun gbọ́ igbe ọmọ náà, angẹli Ọlọrun bá ké sí Hagari láti ọ̀run wá, ó bi í pé, “Kí ni ó ń dààmú ọkàn rẹ, Hagari?
Awọn asoju pọ̀ ju ara wọ́n lọ ni àwọn ìpínlẹ̀.
Ju gbogbo rẹ lọ, itan manigbagbe yii kọ wa pe akọsilẹ awa ẹda, ko lee tase nitori aye ko lee pa kadara da, wọn kan lee fa ọwọ aago sẹyin ni, ko si si bo se buru fun wa to loni, igba to dara n bọ lọla.
Àwọn kan wá láti Teli Mela, Teli Hariṣa, Kerubu, Adani ati Imeri tí wọn kò mọ ìdílé baba wọn tabi ìran wọn, yálà wọ́n jẹ́ ọmọ Israẹli tabi wọn kì í ṣe ọmọ Israẹli àwọn nìwọ̀nyí:
 Ìtàn sọ fún wa pé , Ẹ ̀ pé , ní ẹ ̀ bá ìlú Òǹdó ni ó kọ ́ kọ ́ fi ṣe ibùgbé lẹ ́ yìn tí wọn kúrò ní ilé-ifẹ ̀ .
Ẹgbẹ́ Dókítà: A yóò máa kẹ́yin s'awọ̀n alárùn lassa
"Àkọlé àwòrán, Won so pe ina mọnamọna ijọba lo ṣe okunfa ijamba ina naa ""Mo gbọ pe ina mọnamọna lo fa ijamba yi, mo ti kìlọ fun gbogbo awọn ọlọja lati ma pa awọn ina ninu ṣọọbu wọn ti wọn ba ti taja tan ki wọn too lọ si ile wọn."
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ìdí rèé tí ẹ̀mí mi kò fi bọ́ sínú ìdìtẹ̀ gbàjọba tó pa Muritala Muhammed - Obasanjo Wọ́n gún ọkùnrin kan lọ́bẹ pa torí ó tako yínyin báńgà sínú Mọ́ṣálásí Ìjọba kéde ọjọ́ tuntun fún ṣíṣí afárá Third Mainland Bridge Àwọn àṣà tó milẹ̀ lọ́dún 2020 pẹ̀lú ìtàn lórí bí wọ́n ṣe jáde Kò bá wù mí kí n padà sí àwọ̀ tí Ọlọ́run dá mi, wàhálà ni ara bíbó - Bobrisky Nàíjíríà yóò gbóná janjan lẹ́yìn ìbò ààrẹ 2023 àyàfi.
iko naa ba pari idije EPL saa yii sipo kefa, won ko ni lanfaani ati kopa ninu
Ìdí rèé tí ìforúkọsílẹ̀ rẹ kò ṣè wọlé lójú òpó N-Power Ìdí tí lílọ Yúrópùù fi di èèwọ̀ fún Nàìjíríà àti àwọn orílẹ̀-èdè adúláwọ̀ míì Ojú Shagbada Erigga rèé lẹ́yìn tó pa ọ̀rẹ́bìnrin rẹ̀ l'Akinyele ní Ibadan Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Flood: Ọ̀pọ́ Dúkìá ló sọnù ní 2019 lásìkò tí ìjọba ṣí ’dáàmù Ọyan’ Ṣe iforukọsilẹ N-power ti ọdun 2020 ti bẹrẹ?
Bẹ́ẹ̀ sì ni kò mú ohunkohun lọ́wọ́.
OLUWA ní: “Àwọn ará Edomu ń dẹ́ṣẹ̀ kún ẹ̀ṣẹ̀, dájúdájú, n óo jẹ wọ́n níyà; nítorí wọ́n dojú idà kọ arakunrin wọn, láìṣàánú wọn, wọ́n bínú kọjá ààlà, títí lae sì ni ìrúnú wọn.
53 Ojúṣe olùkọ́ni ni láti ṣe àbójútó ìjọ nígbà gbogbo, láti wà pẹ̀lú wọn àti láti máa mú wọn lọ́kàn le;
Awọn oludibo ṣi n duro lati dibo ni wọọdu Okorocha to jẹ gomina ipinlẹ Imo.
awon olugbe ipinle  Zamfara, paapaa julo
 salaye pe ipade apero alakọọkọ waye ni
Ṣé yóo lọ sí ọ̀gbun àìnísàlẹ̀ ni?
(A ti tẹ Heburoni dó ní ọdún meje ṣáájú Soani ní ilẹ̀ Ijipti.
Ohun tí mo rí pé ó dára jù, tí ó sì yẹ, ni pé kí eniyan jẹ, kí ó mu, kí ó sì gbádùn gbogbo làálàá tí ó ń ṣe láyé, ní ìwọ̀nba ọjọ́ tí Ọlọrun fún un, nítorí èyí ni ìpín rẹ̀.
Àwọn ọmọ rẹ̀ mejeeji fẹ́ aya láàrin àwọn ọmọ Moabu, Iyawo ẹnikinni ń jẹ́ Opa, ti ẹnìkejì sì ń jẹ́ Rutu.
1–2, Apá Olúwa wà kárí gbogbo ilẹ̀ ayé; 3–6, Láti wàásù ìhìnrere àti láti gba àwọn ọkàn là ni ohun tí ó níye lórí jùlọ.
 A n ro ijoba orile ede Somaliland lati bowo fun ofin orile ede naa”.
Nibayii kọmiṣọna feto ilera nipinlẹ Eko, Ọjọgbọn Tunji Abayọmi ti wa ke si gbogbo awọn ero ọkọ baluu BA 75 to gunlẹ si ilu Eko ni ọjọ kẹtala oṣu kẹta ọdun 2020 lati joko jẹẹ sinu ile wọn ki wọn si ya ara wọn sọtọ fun ọjọ mẹrinla.
O lodi si oun ti Oloye Alao Akala sọ pe atari ajanaku ni ọrọ ipinl Ọyọ.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Agolo gáásì kéeké tó ń jò bú gbàmù l‘Eko, ẹ̀mí kan bọ́, mẹ́ta fara pa Aàrẹ Buhari buwọlu yíyí orùkó àwọn ibùdókọ ọkọ ojú ìrìn bíi ti Apapa padà fi sọrí àwọn èèkàn ìlú 'kò sí ẹ̀rí àrídájú níńu ọ̀rọ̀ Akpabio' Ìyá òòṣà fẹ̀sùn àjẹ́ kan ìyá ẹni ọdún 90, aráàlú bá sọ ọ́ lókò pa Nàìjíríà ṣí àwọn ilé ìwé padà; Ìdánwò WAEC á bẹrẹ lẹyìn ọdún Iléyá!
Tamari ni orúkọ ọmọbinrin yìí, ó sì jẹ́ arẹwà.
Ṣugbọn Jehoṣafati bèèrè pé, “Ṣé kò tún sí wolii OLUWA mìíràn mọ́, tí a lè wádìí lọ́dọ̀ rẹ̀?
Se ni awọn ọmọ Naijiria bẹrẹ si ni gba atẹjisẹ kan lati ileesẹ ibaraẹnisọrọ Kan, MTN lọjọ Satide pe, nibamu pẹlu adehun ti ileesẹ ibaraẹnisọrọ naa ati awọn banki ilẹ wa, oun yoo maa yọ owo ori lori awọn owo ti onibara kọọkan ba fi ransẹ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Eégun àti orò, bí wọ́n ṣe jọ bí Ẹ̀ṣà Egúngún nílẹ̀ Yorùba rèé Ǹkan mẹ́wàá tí ẹ ò gbọ́ rí nípa Israel Oladele, Woli ìjọ Genesis Global Israel Oladele Ogundipe (GENESIS) ni oludari ati alakoso ijọ Celestial Church of Christ, Genesis Global, ọkan ninu awọn ẹni ifami ororo yan tawọn ololufẹ rẹ n warii fun gẹgẹ bí ajinrere fun ijọ CCC lagbaye.
"Gomes fèsì lójú òpó Twitter rẹ, tó sì tẹpẹlẹ mọọ pé ẹsìn òun kìí ṣe ǹkan ti ó yẹ kí àwọn ènìyàn máa fọ̀rọ̀ jomitoro ọ̀rọ̀ lé lórí, pàápàá jùlọ nínú ìṣòrò ààùn Corornavirus yìí ati ìfẹhónúhàn ""ayé ènìyàn dúdú ṣe pàtàkì""(BLM) tó n jà ká gbogbo àgbáyé."
O ni NUPENG n fẹ ki ijọba Eko wa ọna abayọ si sunkẹrẹ-fakẹrẹ to n waye ni agbegbe Apapa ki ọkọ epo lee ri aye kọja.
Wo pàtàkì ayájọ́ ‘Má wọ kọ́mú’ tó kò lónìí Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Jawahir Roble:Hijab tí mò n lò kó jẹ́ kọ́kọ́ jẹ́ ìyàlẹ́nu fún àwọn agbábọ́ọ̀lù mi Igbaye mi ri boṣeyẹ ko ri, nitori pe aarun naa ko ni ipa lori bi mo ṣe fẹ gbe igba-aye mi.
Omíyalé àgbàrá ya ṣọ́ọ̀bù, ilé mẹ́ta wó, èèyàn mẹ́rin kú l'Eko Odunlade fijó bẹ́ẹ, Lizzy padà sọ́dún 2012, Toyin Abraham tọ̀ lẹ́ẹ̀mẹwàá Ìdí rèé tí mo fi ṣẹ̀ṣẹ̀ sọ̀rọ̀ lẹ́yìn tí wọ́n fipá bámi lopọ̀ lọ́mọ ọdún méje lọ́gọ́ta ọdún sẹ́yìn-Eli Toyin salaye siwaju pe ida ọgọjọ ninu awọn eeyan to kopa ninu sinima naa lo jẹ ọdọ ti ọjọ ori wọn ko ju ọdun mẹtadinlọgbọn lọ, ti oludari sinima naa si jẹ ọdun mẹrindinlọgbọn, ọdun mẹẹdọgbọn ati mẹrindinlsgbọn ni awọn olootu sinima naa, ti asaraloge oun si jẹ ẹni ọdun mẹtalelogun pere.
Koda ko tọ ki awọn kan ni ọmọ tabi iyawo latọdọ Ọlọrun.
Ni ọjọ kan to n tun yara mama to jẹ alagbatọ rẹ se nigba to wa lọmọ ọdun mẹtala, lo se alabapade lẹta kan ti iya to bi kọ si mama naa ni ọdun kan sẹyin.
" O so wi pe ''ti janduku ba wa ni igboro, a ko le tori pe a fe dibo ki olopaa wa ma wo wọn ni iran'' Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
ati pé kí wọ́n kéde rẹ̀ ní gbogbo àwọn ìlú wọn ati ni Jerusalẹmu pé, “Ẹ lọ sí orí àwọn òkè, kí ẹ sì mú àwọn ẹ̀ka igi olifi wá, ati ti paini, ati ti mitili, ati imọ̀ ọ̀pẹ, ati ẹ̀ka àwọn igi mìíràn láti fi pàgọ́, gẹ́gẹ́ bí ó ti wà ní àkọsílẹ̀.
Adelabu, loju opo ikansiraẹni Facebook rẹ kede pe akọsilẹ ayanmọ oun ninu itan ipinlẹ Ọyọ ko gbọdọ tase, ni oun se pinnu lati mase jami lori ẹjọ naa.
Awọn ọlọpaa ni oju ẹsun isekupani lawọn fi n wo iku Oluwatoyin ati ti Iya arugbo ẹni ọdun marundinlọgọrin ti wọn jijọri oku wọn.
Mo ní ọ̀rọ̀ pupọ láti sọ,Ṣugbọn ẹ̀mí tí ó wà ninu mi ló ń kó mi ní ìjánu.
Isṣẹlẹ yii ti pe akiyesi ọpọlọpọ awọn eniyan ilẹ naa si ni eyi ti Olootu Ijọba, Narendra Modi si ti fi si ori ẹrọ ayelujara ni ọjọ Aje ibi ti iṣẹ didoola ẹmi ọmọ naa de duro bayii.
Kò dùn mí pé mo sọ̀rọ̀ tako Buhari -Adedayo Festus
Wọ́n bá kúrò ní Ijipti, wọ́n pada sọ́dọ̀ Jakọbu baba wọn ní ilẹ̀ Kenaani.
Nigba ti wọn n ba BBC sọrọ, onisẹ ọna kan to n lo amọ lati fi mọ ere, Iyiọla Soẹtan kede pe lootọ ni isẹ amọ ti n parun lọ nitori ọpọ eeyan ko setan lati kọ isẹ naa tori pe o jẹ isẹ idọti.
“Ni ipinlẹ Eko, ayipada rere lo jẹ ifojusun ọrọ fun ijọba, boya ni ti ẹka amuṣẹṣe tabi ẹka aṣofin ijọba.
Omo ile igbimo asofin mẹ́jọ lati inu egbe APC lo fiwe lati yo gomina naa nipo, ranse si i.
Kí ló dé tí ẹ fi fẹ́ kú, ẹ̀yin ọmọ ilé Israẹli?
Bi ẹnikẹni ba fẹ jẹ iru anfaani yii naa, a ṣetan lati ṣe bẹẹ ti gbogbo eto ati adehun laarin wa ba ti wa ni ṣẹpẹ Ki ni kawọn ti ko ni owo wa ṣe bayi?"
lootọ kii ṣe orilẹede Libya ni wọn sọ fun un pe yoo lọ tẹlẹ, nigba ti ọrọ yoo fi foju han sii, oju ọna Libya lo ti ba ara rẹ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Àwọn nkan márùn ún tó gbajúmọ̀ nípa ìlú abínibí Buhari #BBCNigeria2019 24 Sẹ́rẹ́ 2019 Àkọlé àwòrán, Kẹtẹkẹtẹ jẹ ọkan lara àwọn nkan irinna to wọpọ ni Daura Ipinlẹ Katsina, ni ẹkùn Iwọ oorun Ariwa Naijiria ni ilu Daura wa.
Ogbẹni Akinọla Akinrọpo, to jẹ olukọni nipa itọju ọmọ laijẹbi ṣalaye pataki ipa obi ati alagbatọ lasiko yii pe: Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Parental Guidance: Ọdún méjì ni kí ẹ ti bẹ̀rẹ̀ kíkọ́ ọmọ nípa ìbálòpọ̀ Kí ló kàn olórí ọmọ ilé aṣòfin Osun pẹlú ìdájọ kòtẹ́milọ́rùn Sẹnẹtọ Adeleke?
Adajọ Okon Abang paṣẹ yii ti ajọ to n gbogun ti iwa ibajẹ lorilẹ-ede Naijiria, EFCC gbe e lọsi ile ẹjọ, bo tilẹ jẹ pe oni oun ko jẹbi ẹsun onikoko mejila ti wọn fi kan an.
Ìkébé mi tóbí ju ohun tí mo lè dọwọ́ bò lọ, n kìí fí ṣakọ- Nkechi Blessing Àwọn onílù mí ló ń tú àṣírí ìkà èèyàn tó bá wọ ààfin mi - Aláàfin Wò ó bí Alaafin àti aya àkọ́fẹ́ rẹ̀, Olorì Abibat ṣe pàdé ní èwe Oluwo kọ̀ láti sọ̀rọ̀ lórí àwọn afọbajẹ tó fẹ́ yọ ọ́ nípò, aráàlú fọ́n síta láti fẹ̀hónú hàn Ìdùnnú subú layọ̀ nípìnlẹ̀ Ọyọ́, àwọn tó dé láti Lebanon sọ ọmọ wọn ní Seyi Mo ṣetán láti ṣe Paulo Costa bí ọṣẹ sẹ ń ṣojú lọ́la- Israel Adesanya Èèmọ̀!
Oríṣun àwòrán, Twitter/PPPRA Epo bẹntiró ti di N121.
" Ko rọrun lati sọ fun ẹnikẹni nigba naa.
Iko omo ogun Naijiria ti se ikolu n la si ipago awon omo ogun olote Boko Haram lojo Aje(Monday), ti o wa lagbegbe Benisheikh, nipinle Borno.
Ní ọjọ́ kinni oṣù kẹwaa, wọ́n bẹ̀rẹ̀ sí ṣe ìwádìí lórí ọ̀rọ̀ yìí.
‘Báyìí ni ìtàn ìgbésí-ayé mi lọ, èyí tí mo sì kọ sílẹ̀ yìí yóó fi han àwọn ọmmọ mi lẹ́hìn ọ̀la irú ohun tí ojú mi rí kí ó tóó di pé mo fẹ́ ìyàwó mi àti èyí tí ojú mi rí lẹ́yìn tí mo fẹ́ ẹ tán kí n tóó di ẹni tí ó lè fi ojú rí ọmọ tí ó jẹ́ àkọ́bí mi.
Ọ̀rọ̀ Sotitobire tí a dá sí, àwọn aṣòfin àtàwọn àjọ kan ló fi lọ̀ wá- DSS George Floyd wọ káà ilẹ̀ lọ nílùú Houston l'Amẹrika Ẹ̀yin tí ẹ lọ ra aṣọ àlòkù ní Ọjà Ọba Akure, ẹ lọ ṣàyẹ̀wò Coronavirus - Akeredolu figbe ta Ṣé lóòtọ́ ni òjòjò dá Abiola Ajimobi wólẹ̀?
Koda, wọn maa n pa tabi pa awọn to ni ilẹ lara.
Oríṣun àwòrán, OYO STATE Àkọlé àwòrán, Ọgaagun Abdulsalami abubakar jẹ adari orilẹede Naijiria ni ọdun 1998 si ọdun 1999.
Ori oju opo Twitter kan to jẹ ti ẹgbẹ oṣelu APC nilẹ Gẹẹsi ni o ti jade pe awọn oluwọde lo n ji ẹru ko.
Wọ́n tì í láti inú ìmọ́lẹ̀ sinu òkùnkùn,wọ́n lé e kúrò láyé.
Àwọn Filistini dúró lórí òkè ní apá kan, àwọn Israẹli sì dúró lórí òkè ní apá keji.
Lai Mohammed lo sọ ọrọ naa nibi ipade awọn akọroyin kan to waye ni ilu Abuja, nibi to ti sọ iha ti ijọba apapọ kọ si iwadii CNN ọhun.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Májèlé olóró lẹ jí l‘Ekiti dípò èròjà oúnjẹ Covid-19 - Ariwo sọ lórí ayélujára Ẹ sọ́ra fún ìwà olè àti jàgídíjàgan nílẹ̀ Yorùbá-Sunday Igboho ₦147m la rí kójọ fún ìwọ́de, a kò fẹ́ owó mọ́, ìwọ́de ti parí - Feminist Coalition Sanwo-Olu kéde ìlànà ìséde tuntun l'Eko Ìjọba ìpínlẹ̀ Kwara sọ̀rọ̀ lórí bí àwọn kan se lọ pín CaCovid 19 Palliative"" ní Ilorin pé."
Má kọ̀wé fipò sílẹ̀, àwọn àgbààgbà Yorùbá sọ fún Osinbajo Ǹjẹ́ o mọ ohun tó ń fa súnkẹrẹ-fàkẹrẹ nílùú Eko Ẹgbẹ awọn agbẹjọro ni Naijiria atawọn ajafẹtọ miiran lawọn ṣetan lati da si ọrọ naa nibi ijiroro itagbangba ti yoo waye lọsẹ to n bọ.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ sí: Kí lo fẹ́ mọ̀ nípa D.
Ṣé o ranti pé, nígbà tí èmi pẹlu rẹ ń gun kẹ̀kẹ́ ogun lẹ́yìn Ahabu baba rẹ̀, OLUWA sọ ọ̀rọ̀ wọnyi nípa Ahabu, 
O ni iṣẹlẹ Coronavirus kọọkan yatọ sira wọn ati pe eto inawo itọju wọn yatọ si ara wọn.
"Mi o ni lọkan pe ma a ya fidio rẹ lọjọ naa, ṣugbọn bi mo ṣe n beere pe kilode to fi ṣe nkan ti mo ni ko gbọdọ ṣe, lo bẹrẹ si ni gba ori ara rẹ, to si n sọ pe, Ore, kilode ti o fi ṣe bẹ ẹ?
Ènìyàn 712 ló ní ààrùn Covid-19 ni Nàìjíria nínú èsì àyẹ̀wò tó jáde lọ́jọ́ ọdún kérésì Oríṣun àwòrán, NCDC Èsì àyẹ̀wò Coronavirus to jáde lọ́jọ́ kérésìmesì lórílẹ̀-èdè Nàìjíríà fi hàn pé, ènìyàn ẹ̀ẹ́dẹ́ẹ̀rin àti méjìlá ló tún ṣẹ̀ṣẹ̀ lùgbàdì ààrùn Covid -19 ni Nàìjíríà.
Bakan naa lọsẹ to kọja, ijọba ipinlẹ Ondo ti ni A kò ní fara mọ́ fífi àkókò ṣòfò lórí ẹjọ́ Sotitobire - Ìjọba Ondo Bí ìgbẹ́jọ́ wòlíì Sotitobire ṣe ń lọ lọ́wọ́ nílé ẹjọ́ lónìí rèé Ẹ tẹti leko lonii lori ikani yii, BBC Yoruba fun ẹkunrẹrẹ bo ba ṣe n lọ nile ẹjọ.
musulumi lati lo asiko Aawẹ Ramadan lati fi gbadura ki alaafia ati ifẹ le tẹ
Nígbà tí wọ́n dé Juda ati Jerusalẹmu, wọ́n pa gbogbo àwọn ìjòyè wọn, wọ́n sì kó gbogbo ìkógun wọn ranṣẹ sí Damasku.
Nítorí ìwọ OLUWA ni Ọ̀gá Ògo,o ju gbogbo ayé lọ,a gbé ọ ga ju gbogbo oriṣa lọ.
 Ṣe iwọ ti ri Iwo ri lori Google, Facebook, BBC,."
28 Òkùdu 2019 Oríṣun àwòrán, Oyo state government Ijọba ipinlẹ Ọyọ ti kede iyansipo ọga agba kan nileesẹ elepo rọbi Shell, gẹgẹ bii akọwe ijọba ipinlẹ Ọyọ.
"Àkàra tú s'épò, ICPC dárúkọ àwọn Fásitì tó ń tẹ́ abá isúná wọ́n nídìí 'Òní la máa mọ̀ bóyá Jonathan tako òfin PDP pé ó gbàlejò APC ní Bayelsa' Ọ̀daràn tó wà lẹ́wọ̀n tún wọ́'ke $100miílíọnu - EFCC Kìnìhún tí wọ́n mú l'Eko kìí ṣe ti orílẹ́èdè Nàíjíríà O ni ""ó dàbíi ká gbé ẹru wúwo léèeyàn lórí ni""."
Lo ba fi aworan ibi ti Sẹnetọ Omo Agege ti n jade bọ ti yoo si gba ọna ibi ti akọwe ile ti gbe ọpa aṣẹ dání.
Alao Akala tun ni arifin nla ni bawọn eeyan kan se npariwo pe oun n sisẹ fun Seyi Makinde to jẹ oludije gomina fẹgbẹ PDP.
Ìwọ tí o fi ẹ̀fúùfù ṣe iranṣẹ,tí o sì fi iná ati ahọ́n iná ṣe òjíṣẹ́ rẹ.
Ìyà ti ará ilú njẹ lọ́wọ́lọ́wọ́, ki i ṣe èrè iwà-ibàjẹ́ ọdún kan, ṣùgbọ́n  ti ọ̀pọ̀lọpọ̀ ọdún.
Naira Mailey sọ eyi loju opo ikansiraẹni Instagram lẹyin ti awọn eniyan bu ẹnu atẹ lu ọrọ to sọ lori igbesẹ ajọ EFCC lasiko ti wọn gbe lọ si ile ẹjọ lori ẹsun lilo gbajuẹ fi gba owo lọwọ awọn eniyan to ba ko si ọwọ ẹ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Ọwọ́ tó bá dilẹ̀ ni èṣù ń bl ní iṣẹ́kíṣẹ́' Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Naijiria ko ọmọogun ati ọkọ ogun ofurufu lati wa awọn ọmọ Dapchi 26 Èrèlè 2018 Oríṣun àwòrán, AFP/Getty Images Àkọlé àwòrán, Awọn akẹkọ sa asala fun ẹmi wọn ninu ikọlu Boko Haram ni Dapchi Orilẹede Naijiria ti kede wipe oun ti ko awọn ọmọ-ogun ati awọn ọkọ ofurufu sita lati wa awọn ọmọ ile-iwe to le lọgọrun ti awọn onijagidijagan agbesunmọmi Boko Haram jigbe ni ọsẹ to koja.
Ládugbó Amolaso, òpó ilé ìgbé lo wọ omí nígbà tí afárá kan ti wọn ṣẹṣẹ parí láì pé yí na já lulẹ̀.
Sara bá pe Abrahamu, ó sọ fún un pé, “Lé ẹrubinrin yìí jáde pẹlu ọmọ rẹ̀, nítorí pé ọmọ ẹrubinrin yìí kò ní jẹ́ àrólé pẹlu Isaaki ọmọ mi.
Ní ọjọ́ kẹta a dé Samosi.
 nitori pe ko lowo igbimo Olubadan ninu.
Kollington lasiko to n gba ijọba ilẹ wa ni imọran, gba awọn olori wa nimọran, lati maa ranti mẹkunnu, nipa ipese awọn ohun eelo amayedẹrun, papa atunse oju popo.
Ninu ìdílé Imeri: Hanani, ati Sebadaya.
Ẹgbẹ Oṣere oloogbe alagba Oyin Adejọbi ni baba wande ba ṣiṣẹ pọ fun ọpọlọpọ ọdun, ṣugbọn ninu ere 'Ti Oluwa ni ilẹ’ ti o jade ni ọdun 1993 ni Baba Wande ti di gbajugbaja ni Naijiria titi de oke okun.
Ko si pẹ si igba naa ni ijọba bẹrẹ si wadii rẹ fun iwa nina owo ilu fun igba keji.
Ta ló ń ru bí odò Naili yìí,bí odò tí ó kún bo bèbè rẹ̀?
Eyi ni awọn oṣere sinima ede Yoruba ti wọn ku ni ọdun 2018.
Bakan naa ni wọn ba ẹgbẹrun lọna ẹẹdẹgbẹta Naira ninu ọkọ ayọkẹlẹ Ọgagun AP Ubah.
Ikoumen Udoh lo gba ti ọkunrin ni abala yii ti Rasheedat Ajibade si gba ti obinrin.
Apapa - Ijora Link Bridge, Ijọba ibilẹ Apapa/Lagos Mainland 12.
“Nítorí náà, ẹ pa àwọn àṣẹ mi mọ́, kí ẹ má sì ṣe èyíkéyìí ninu àwọn ohun ìríra wọnyi, tí àwọn tí wọ́n ṣáájú yín ṣe, kí ẹ má fi wọ́n ba ara yín jẹ́.
Ọ̀kan ninu àwọn ọmọ ogun Dafidi rí i, ó bá lọ sọ fún Joabu pé òun rí Absalomu tí ó ń rọ̀ lórí igi Oaku.
Mo ní, “Ẹ̀yin obinrin, ẹ gbọ́ ohun tí OLUWA wí,ẹ gbọ́ ọ̀rọ̀ ẹnu rẹ̀.
Ninu àwọn ọmọ Josẹfu, Eliṣama ọmọ Amihudu ni yóo jẹ́ olórí láti inú ẹ̀yà Efuraimu; Gamalieli ọmọ Pedasuri ni yóo sì jẹ́ olórí láti inú ẹ̀yà Manase.
O sọ ọrọ yii lasiko ayẹyẹ ọjọ ibi ọgọrin ọdun Olu Bajọwa to waye ni ilu Igbotako, ni ijọba ibilẹ Okitipupa, ni ipinlẹ Ondo.
bi agbenusoro iko alaabo naa, Sutopo Purwo Nugroho,“O le pupo fun awon osise onisele
Èyí ni àkọsílẹ̀ àwọn olórí olórí ninu ìdílé wọn: Reubẹni, àkọ́bí Jakọbu bí ọmọkunrin mẹrin: Hanoku, Palu, Hesironi ati Karimi; àwọn ni olórí àwọn ìdílé ẹ̀yà Reubẹni.
Àwọn Afíríkà mẹ́tà to ṣe bẹbẹ nínú EPL sáà 2018/2019 Cardiff tí tiẹ̀ ti jóná kóná ìyà mọ́ Manchester United Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Lórí iṣẹ́ ikàn yìí, a ti kọ́ ilé, ọmọ ti lọ ilé ìwé' Amọ, fọnran naa gbe jade wi pe Gomina CBN, Godwin Emefiele pẹlu igbakeji ati adari eto isuna ni ẹka banki apapọ lori ọna ti wọn yoo gba fi di owo ti wọn ji ni apo ijọba ti ko ni fi ba eto ọrọ aje orilẹede Naijiria jẹ.
Bukola Saraki ti fi idunnu re han lori bi ọgọọrọ  awon eniyan  se jade lati dibo ni irọwọ ati irọsẹ.
Community policing: Ọ̀gá ọlọ́pàá Mohammed Adamu ní ètò ń lọ fún ọlọ́pàá agbègbè
Oloye Tinubu kede ọrọ yii lasiko to n ba awọn ọmọ ẹgbẹ oṣelu APC sọrọ nilu Eko lọjọru.
”Àwọn eniyan náà bá pada lọ jíṣẹ́ fún ọba.
Àwọn nǹkan tí obìnrin lè ṣe pẹ̀lú olólùfẹ́ oníwà ipá lásìkò ìgbélé Coronavirus yìí Ìyàwò kejì tó fi owú ré ọkọ bọ́ láti òkè pẹ̀tẹ́sì gba ìdájọ́ ikú Ẹ̀wọ̀n gbére ni fún ẹnikẹ́ni tó bá fipá bánilòpọ̀ ní ìpínlẹ̀ Ọ̀ṣun Lẹ́yìn tó ṣá Monisola aya rẹ̀ ládá, Oniya ní iṣẹ́ èṣù ni Iṣẹlẹ to ṣaaju ariwo ifipabanilopọ: Ojúmọ́ ọjọ́ kan lọ́sẹ̀ bíi méjì sẹ́yìn ni òkìkí kàn pé ọ̀dọ́mọbìnrin ẹni ọdun méjìlélógun kan Vera Omozuwa to jẹ́ akẹ́kọ̀ọ́ ni ilé iwé Uniben l'àwọn kan fipá bá lòpọ̀.
Èdè wa ò kópa kankan rárá nínú ìṣẹ̀dá rẹ̀.
Ó sì yin Ọlọrun ọ̀run lógo.
Gẹgẹ ba ti gbọ, afojusun ipade ọsan ọjọ Isinmi naa ni lati wa nnkan ṣe sawọn ẹdun ọkan tawọn ọdọ to n sewọde gbe siwaju ijọba, eyi to da lori ọna lati dẹkun iwa kotọ awọn ọlọpaa.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Peter Mutharika di ààrẹ ilẹ̀ Malawi lẹ́ẹ̀kejì 27 Èbibi 2019 Oríṣun àwòrán, AFP Àkọlé àwòrán, Ẹni tó ń ba ààrẹ du ipò Lazarus Chakwera tó se ipò kejì bu ẹnu àtẹ́ lu ìdájọ́ náà lórí ẹ̀sùn màgòmágó lásìkò ìdìbò.
O fikun pe, awọn gba ikọ ọtẹlẹmuyẹ DSS atawọn osisẹ aabo ara ẹni, laabo ilu, Civil Defence lati se ayẹwo awọn oludije naa, ki wọn lee yọ eepo kuro lara Alikama.
Orilẹede France wa laarin awọn orilẹede to n moke lagbo awọn orilẹede ti arun Coronavirus ti n ṣọṣẹ julọ pẹlu bi o ti ṣe jẹ pe ẹgbẹta o le mẹtala eeyan lo ti ko sọwọ arun naa ti eeyan mẹsan ti jade laye nitori rẹ.
Bi eto idibo se bẹrẹ ni pẹrẹu, ni aare Buhari  ati  iyawo rẹ naa lo sile idibo niluu Daura lati lo se ojuse wọn.
Ṣe emi ti mi o mọ bi nkan oṣu ṣe n ri?
Awọn iroyin ti ẹ lee nifẹẹ si: Ọmọbinrin Dapchi: Mi o lọ s'ile iwe mọ ‘Jibiti ni isẹlẹ Dapchi, kii se ootọ’ Biliọnu mẹtalelọgbọn ni iye owo ti wọn ni o koje.
Òkúta Agate ni n óo fi ṣe ṣóńṣó ilé rẹ, òkúta dídán ni n óo fi ṣe ẹnu ọ̀nà ibodè rẹ,àwọn òkúta olówó iyebíye ni n óo fi mọ odi rẹ.
iroyin se so, igba keyin ti orile-ede Egypt sagbateru idije Africa Cup of
Ibeere nla to wa nilẹ bayi ni pé: ki wa ni ijọba le se lati dẹkun ipenija Almajiri paapaa julọ lasiko ajakalẹ arun Covid-19 yi?
"Nàìjíríà ń ṣọ́ pápákọ̀ òfurufú tórí Ebola Ebola sẹ́yọ ní DR Congo ""Ààrùn Ebola ti 'wá ni kòkòrò ajokorun"" Àláìsàn Ebola sá kúrò níléwòsàn lọ sí ṣọ́ọ̀ṣì DR Congo rí owó ìrànwọ́ gbà lọ́wọ́ ilẹ̀ Gẹ̀ẹ́sì Loṣu keje, ọdun 2014 ni Naijiria kọkọ kagbako ọrọ arun Ebola."
Atamatase iko agbaboolu obinrin orile-ede Naijiria, Onome Ebi ti bowolu iwe-isise po iko agbaboolu Henan Huishang FC, ti o n kopa ninu idije orile-ede China.
Isẹ́ to se koko lati ṣe ni Hajj: 1)Wíwọ aṣọ Harami: Ihram ní wọn máa n pé aṣọ funfun ti awọn alalaaji máa n wọ lásìkò Hajj.
Ó tọ́, kí ó bọ̀wọ̀ fún àgbà onílàákàyè
O ni awọn nọọsi to wa nilẹ ko to fun iye awọn alaisan to nilo itọju, bẹẹ naa ni ko si ogun ati awọn ibusun ti alaisan le fẹyinle.
Ó yẹ kí a ṣe àkíyèsí fọláṣadé dáadáa nítorí pé òun ni Olófìn-íntótó ra otí fún ní ọjà tíó mu ìgò ọtí kan àbò.
Lórí gbogbo rẹ̀ ìdánwò ni owó-níní jẹ́ fún un bẹ́ẹ̀ ni ọkùnrin yìí kò ṣe dáadáa nínú ìdánwò náà, nígbà tí ó di olówó tán ó fẹ́ ogunlọ́gọ̀ obìnrin.
Ki lo de ti ilu Ondo ko ṣe gbudọ jẹ ẹran Okete?
N óo ṣàánú fún wọn bí baba tií ṣàánú fún ọmọ rẹ̀ tí ń sìn ín.
E gbe awọn nkan mẹ́sàn-án nipa atamatase Super Eagles ti ẹ le ma mọ wọnyi yẹ wọ: Ọdun mọkanla ni Moses wa ni ọdun 2001 nigba ti awọn obi rẹ ku ninu ija ẹlẹsin-mẹsin kan ni Ipinlẹ Kaduna.
2019 Budget: Á ò fọwọsi àbádafofin ìṣúna láìpẹ- Bukola Saraki
Ọ̀kan ninu wọn bi ẹni tí ó wọ aṣọ funfun, tí ó wà lókè odò pé, “Nígbà wo ni àwọn ìṣẹ̀lẹ̀ tí ń bani lẹ́rù wọnyi yóo dópin?
Níbẹ̀ ni kí ẹ ṣe ètò sí.
Nigba to pari ile iwe alakọbẹrẹ lawọn obi rẹ bẹrẹ si ni gbele kọ ni ẹkọ, lẹyin igba naa lo kọ idanwo ile ẹkọ girama WASSCE to si pegede.
Wọ́n ṣan ẹsẹ̀ wọn, wọ́n jẹ, wọ́n sì mu.
Alamojuto ajo INEC fun ikede ati
gl/SMHXRP Omowe Ahmed so pe “gbogbo odun ti adajo agba Akanbi lo lori eto idajo ati alaga ICPC  ni ko fi lowo ninu iwa ibaje,iwa akinkanju re lori eto ijoba rere ati itesiwaju ni agbegbe re ,ko ni pare ninu iwe itan orile ede  Naijiria.
Ṣugbọn Abimeleki kò tíì bá Sara lòpọ̀ rárá, ó bá bèèrè lọ́wọ́ OLUWA pé, “OLUWA, o wá lè pa àwọn eniyan aláìṣẹ̀ bí?
Lẹ́yìn ikú Joṣua, àwọn ọmọ Israẹli bèèrè lọ́wọ́ OLUWA pé, “Ẹ̀yà wo ni kí ó kọ́kọ́ gbógun ti àwọn ará Kenaani?
” Ó bá dìde, ó bá afẹ́fẹ́ ati òkun wí, ìdákẹ́rọ́rọ́ ńlá bá dé.
Nigba to ya ni awọn eebo amunisin fi jẹ ọba ilu Badagry lọdun 1913, ẹni to ba si de ile rẹ naa nilu Badagry, yoo ri aloku awọn ohun to fi n se ọla lasiko naa.
Gbogbo àwa yìí náà ti wà lára irú wọn rí, nígbà tí à ń ṣe ìfẹ́kúfẹ̀ẹ́ ara wa, tí à ń ṣe àwọn nǹkan tí ara bá fẹ́ ati àwọn ohun tí ọkàn bá ti rò.
Ìgbà tí ó maa tó agogo mẹ́ta a padà sí ilé tí a wọ̀ sí.
Ọkan lara awọn agbẹjọro fawọn ọlọpaa mẹrin naa lo fi lede pe, ẹrọ ayaworan to wa lara awọn ọlọpaa fihan pe, ọkan lara awọn ọlọpaa naa lo ni ki Floyd gbẹnu dakẹ.
Ṣébi tí èyàn bá nwá ìbọ̀sẹ̀ tàbí sòkòtò rà, èyí tó bá gùn délẹ̀ tàbí èyí to wọ̀’yàn lẹ́sẹ̀ l’èyàn nwá?
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, È gbọ òun ti ojú awọn ara ipinle Ogun rí lọwọ ìṣẹlẹ omiyale Akẹ́kọ̀ọ́ Ilaro Poly tó pegedé jù jẹ ẹ̀bùn iṣẹ́ ọ̀fẹ́ lọ́wọ́ Gómìnà Abiodun Ẹ gbà mi o!
Ẹ tọju iyara ijẹun ninu awon ile iwosan ko mọ toni toni.
Fi ọ̀dọ́ aguntan kan rúbọ ní òwúrọ̀, sì fi ekeji rúbọ ní àṣáálẹ́.
N óo jẹ àwọn ọmọ yín níyà, n óo fi ìgbẹ́ ẹran tí ẹ fi ń rúbọ kùn yín lójú, n óo sì le yín kúrò níwájú mi.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìsekúpani darandaran; ọlọ́pàá mẹ́rin forí káásà ní Benue 16 Ìgbé 2018 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Iroyin sọ pe awakọ ọmọ ọdun mẹrinlelọgbọn k'agbako nipinlẹ Ondo Ọlọọpa mẹrin ti papoda lẹyin ikọlu awọn agbebọn si ibudo awọn ọlọọpa ni ipinlẹ Benue, ti eniyan mọkanla si ti di awati.
Obasanjo n sọ̀rọ̀ lásìkò àbẹ̀wò rẹ sí gómìnà ìpińlẹ̀ Oyo, Seyi Makinde nílùú Ibadan, ní bi tó ti sàlàyé pé, ìfọwọ́sowọ́pọ̀ ará ìlú gan ṣe pàtàkì láti mójútó ìṣòrò tó wà nílẹ̀.
Wọ́n óo fi ọwọ́ wọn gbé ọ sókè,kí o má baà fi ẹsẹ̀ gbún òkúta.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Wo bí o ṣe lè kọ ẹ̀nu ìfẹ́ sí obìnrin pẹ̀lú ohun èlò orin yìí Awọn oṣiṣẹ baba rẹ to n kọwọ rin pẹlu rẹ ti ori yọ lo figbe ta si awọn araalu ti Oniroko ti ilu Iroko si tete ko awọn ọlọdẹ jọ.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Musa ni kete ti ọrọ yii to oun leti, ni oun ti pe Bello to jẹ ọga ọwọ karundinlaadọrin ileeṣẹ ologun (65 Battalion) to wa ni Bonny Camp, to si sọ fun oun pe ibọn ti ko ni ọta ninu, lawọn yin soke, kii ṣe ọta gidi.
Àwọn ohun ìjà wọ̀nyí ni wọ́n lò ní ogun àgbájé kìnní tí o wáyé ní Odun 1914 sí 1918 àti ti èkejì ní odún 1939 sí 1945 
Ṣugbọn ìfẹ́ tìrẹ ni kí o ṣe, kì í ṣe ìfẹ́ tèmi.
Awọon ibi abẹwo yii ni Odo Assal, ti o jẹ eyi ti o kere si ori ilẹ julọ ni ilẹ Adulawọ ti o si jẹ ikẹta iru rẹ ni agbaye lẹyin odo Galilee ati Okun pupa.
Joy Chioma je osise ile-itura CHESS-PUB to wa niluu
Ohun tí gómìnà Seyi Makinde fẹ́ ṣe lórí ìwọ́dé EndSARS lẹ́yìn ìpàdé rẹ̀ pẹ̀ láwọn tọ́rọ̀ọ kàn Gómìnà ìpínlẹ̀ Oyo, Seyi Makinde ti ṣe ìpàdé pẹ̀lú àwọn èèkàn ní Ìpínlẹ̀ náà lórí ọ̀nà àbáyọ sí ìfẹ̀hónúhàn #EndSARS àti nǹkan tó jẹyọ lórí ẹ̀.
 Ẹnikẹ ́ ni - àti ìwọ - lè di olóòtú wikipedia nípa ṣíṣe àtúnṣe tí wọ ́ n bá rí ohun tó ń fẹ ́ àtúnṣe .
dájúdájú , n ó fi ipò olorì Ọba dá a lọ ́ lá jọjọ .
Orúkọ ọkunrin náà ni Elimeleki, aya rẹ̀ ń jẹ́ Naomi, àwọn ọmọkunrin rẹ̀ sì ń jẹ́ Maloni ati Kilioni.
"ẹ pẹ laye lati ri orilẹede Naijiria bẹ ṣe fẹ ko ri"" Ṣugbọn ṣe ni awọn ọmọ ta gba igbakeji aarẹ lori ikini naa, ti wọn si n sọ oko ọrọ si pe ọrọ to sọ gbẹyin naa lo tabuku ikini rẹ si Soyinka naa."
O Samuel: Bakan naa ni Wolii Samuel ninu iran rẹ fun ọdun tuntun, ti sọ asọtẹlẹ lori rogbodiyan EndSARS.
Ni ipari, aare Buhari yoo kase
 Àwon tí ó ń so àwon èdè wònyí lé díè ní mílíònù méjì ( 2.
Sotitobire: Ojú àwọn Wòlí tó tí lọ sẹ́wọ̀n lórí ẹ̀sùn ọdaràn tẹ́lẹ̀ rèé Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Àwọn kan ṣónú bí wọ́n bá di gómìnà, ẹ fún wa láyè láti wá parí iṣẹ́ táa bẹ̀rẹ̀ - Akeredolu Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 3 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 5 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Ìgbátí tí ó ṣe náà fẹ̀ ní àtẹ́lẹwọ́ kan ati ààbọ̀.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ìtàn Olaniyi Balogun, ọ̀jọ̀gbọ́n tó fi Nàìjíríà sílẹ̀ lọ gba iṣẹ̀ àgbẹ̀ l'Ámẹ́ríkà Omọwe ni koda, Buhari kii da si ọrọ ẹgbẹ ni Daura to ti wa funra rẹ.
com Àkọlé àwòrán, Aarẹ Buhari ba Damilọla Osinbajo ati ọkọ rẹ sajọyọ Kii se ayẹyẹ igbeyawo yii nikan ni aarẹ Buhari yoo ti farahan, a ti ri aarẹ nibi awọn igbeyawo miiran laipẹ yii, bii igbeyawo laarin ọmọ Gomina Gunduje ati ọmọ Gomina Ajimọbi.
A wá lọ tààrà sí Kosi.
Ni ọdun 2018 lo darapọ mọ ẹgbẹ oṣelu ADP lati du ipo Sẹnetọ ki o to fidirẹmi.
Ẹni to bori: Guinea-Bissau Mali vs Morocco.
Tún mú wa bọ̀ sípò, Ọlọrun Olùgbàlà wa;dáwọ́ inú tí ń bí ọ sí wa dúró.
Ọ̀pọ̀ lo pe àṣeyọrí ìdìbò yìí ní ìdìbo fún ojú rere àti ìkáánú nítorí pé, ìdá méjìlélọ́gọ́ta àwọn tó díbò náà ló mú pé kí wọ́n máa ran aláìsàn lọ́wọ́ láti kú, yálà jú kí o máa jẹ ìrora lọ.
Ẹ má máa dẹ́rù bà wọ́n.
Idi ni pe eroja afaralokun to jẹ nijoko ẹẹkan ko gbọdọ tobi ju deede ẹsẹ ọwọ rẹ lọ nitori eroja Starch to wa nibẹ.
Bákan náà sì ni àwọn yàrá ẹ̀gbẹ́ rẹ̀, àtẹ́rígbà rẹ̀ ati ìloro rẹ̀ pẹlu àwọn yòókù.
Ero to wa jẹyọ ni pe ninu eyi to n ja rayin-rayin lọwọ lọwọ to ti di rangbọndan bayii ati awọn to ti waye tẹlẹ ri, ewo lo le ju?
Ìgbà tí ọba gbọ́ bẹ́ẹ̀ ó dáhùn pẹ̀lú ìbínú ó ni, ‘Bí ojú ba lè tìyìn kó máa tìyìn , bí ẹ kò bá ni bí ó ti ga sókè fíofío ni.
Ileeṣẹ amohunmaworan AIT wa lara awọn ileeṣe aladani akọkọ ni Naijiria.
Igba naa si ni awọn onibara ileefowopamọ kan ti n lo o.
“Ègún ni fún ọ ní ààrin ìlú, ègún ni fún ọ ní oko.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Musa olowo aye Bakan naa ni awọn oṣiṣẹ aafin rẹ, awọn sọja, awọn oniṣowo, awọn ti n wa kẹtẹkẹtẹ pẹlu ẹru kọwọ rin pẹlu Musa lọ si ilẹ mimọ.
“Ayeye odun Sallah ti waye o si ti lo, lai si wahala kankan bi o ti le wu ko mo, ka to wa so pe, ibugbamu ado oloro.
Ìdí rèé tí BBC Yoruba fi ṣe ìwádìí nípa àkójọ pọ àwọn owó yìí, àwọn orílẹ̀ èdè tó tú àṣírí owó náà, tí wọn sì fún wa àti ọjọ́ tí ìjọba àpapọ̀ tẹ́wọ́ gba owó náà.
12 Àti pé òun ti tún jí dìde kúrò nínú òkú, kí òun lè mú gbogbo ènìyàn wá sí ọ̀dọ̀ rẹ̀, lórí ìpinnu ironúpìwàdà.
"Xenophobic Attack:Àwọn ọmọ Naijiria sọ fun South Africa pé ""Ó tó gẹ́"""
Nígbà náà ni Saulu bèèrè lọ́wọ́ Jonatani pé, “Kí ló dé tí ọmọ Jese kò wá sí ibi oúnjẹ lánàá ati lónìí?
orile-ede mewaa yii: orile-ede Naijiria, Burkina Faso, Cameroon, Chad, The
Igbimo amuse-se egbe oselu ANC se ipade fun wakati metala gbako nile itura kan to wa leyin ilu Pretoria, latari ati fenu ko boya won yoo pe Zuma pada sori alefa gege bi Aare orile-ede naa.
Gambari ni ifọkansin ati igbarukuti oun ni Aarẹ Buhari nilo lati ṣe ijọba gidi fawọn ọmọ Naijiria.
Akọroyin BBC kan si alabojuto ẹkun Guusu-Iwọ Oorun Naijiria fun ajọ to n ri si iṣẹlẹ pajawiri, Ibrahim Farinloye ni ki awọn eniyan ṣaa bu omi suuru mu.
tí ẹ sì ń polongo ọ̀rọ̀ ìyè.
A fún un ní aṣọ funfun tí ń dán, tí ó sì mọ́.
pese owo fun igbimọ naa loorekoore, ti owo wọn yoo maa wa ninu iṣuna owona ọlọdọọdun
Ẹni tí ó rán iṣẹ́ abàmì ati iṣẹ́ ìyanu sí ilẹ̀ Ijipti,ó rán sí Farao ati gbogbo àwọn iranṣẹ rẹ̀.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fọ́nrán ohùn, Ìgbárùn ni ètò BB Naija kíì ṣe ìgbádùn - MURIC Naijiria ni ko jẹ ki Algeria le kopa ninu idije ife ẹyẹ agbaye nigba ti wọn ṣina fun kọlọkọlọ Algeria pẹlu ami ayo mẹrin si ookan ni papa iṣere ipinlẹ Eko.
Ṣugbọn ìbànújẹ́ kún ọkàn yín nítorí mo ti sọ nǹkan wọnyi fun yín.
Ǹjẹ́ ẹnìkan a máa fi igi rẹ̀ ṣe ohunkohun?
Ikede pe wọn fiṣẹ silẹ yii jade lorii tẹlifisan apapọ orilẹede naa nirọlẹ ọjọ aje.
Lootọ ni akọsilẹ wa lori itakun agbaye ajọ ọlọpaa ọtẹlẹmuyẹ ilẹ America, FBI, pe wọn ti tu ọmọ orilẹ-ede Naijiria, Hushpuppi ti wọn mu fun ẹsun jibiti, silẹ.
Ó sì tún rí i tí ṣiiri ọkà meje mìíràn yọ lẹ́yìn wọn, wọ́n tínínrín, wọn kò sì ní ọmọ ninu rárá, nítorí afẹ́fẹ́ ìhà ìlà oòrùn ti pa ọlá mọ́ wọn lára.
Ile isẹ ọlọpaa naa wa parọwa si awọn akẹẹkọ ti iru rẹ ba ti sẹlẹ si lati tẹsiwaju wa sọ fun wọn, ati wi pe aabo wọn daju.
yoo fi yanju isoro to n dojuko won.
O tun di ẹbi naa ru Aarẹ Muhammadu Buhari to yan Solomon Dalung sipo minisita.
Sarri ni lootọ l’oun fẹ ki Hazard duro ni Chelsea, ṣugbọn oun ko
Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Pigeon: Wo ìdí tí wọ́n fi ta ẹyẹlé kan ṣoṣo ní ₦893,000,00016 Bélú 2020 Yoruba World Assembly: Ìlú Ibadan ni wọ́n tí ṣe àgbẹ́kalẹ̀ ẹgbẹ́ ọmọ Yorúbá tuntun16 Bélú 2020 Lady Peller: Ọjọ́ ni ọjọ́ tí idán yíwọ́ fún ọkọ mi lẹ́yìn tó gé mi sí méjì, mo kú tán15 Bélú 2020 Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí kan sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
Ọjọ Kejilelogun, Osu Keje ọdun 2019, ni wọn yoo ma a kede ẹni to jawe olubori ninu idibo.
Ìpànìyàn, ìjínigbé ti gbàkóso ilẹ̀ Yorùbá, Buhari, tètè kéde pé ètò ààbò kò fararọ - Soyinka Pius Adesanmi: Awọn ọmọ Nàìjíríà ń ṣelédè lẹ́yìn akọni Ṣé o ti gbọ́ ohun ti Ọọni Ifẹ́ àti Soyinka parí ọ̀rọ̀ Yorùbá sí?
Iwadii ajọ WHO ni eniyan ẹgbẹrun lọna ẹẹdẹgbẹrun eniyan ti ko mu siga ṣugbọn to n gboorun eefin siga ni o n ku ni ọdọọdun.
O ni awọn ba ẹjẹ lẹnu rẹ nibi ti o lefo si ninu omi.
Ọjọ iṣẹgun, ọjọ keji oṣu kẹfa ni awọn amokun-ṣeka wọle tọ Barakat Bello lagbegbe Akinyele, ni ilu Ibadan, ti wọn si gbẹmi rẹ lẹyin ti wọn fi ipa baa lopọ tan.
lorile ede  yii fun igbimo asofin lojo
A ri ọrọ yi ka loju opo Twitter Ooni pẹlu ẹkunrẹrẹ alaye ati akawe oun to ṣẹlẹ ti o fi sọ bẹẹ.
Coronavirus wọ ìpínlẹ̀ Osun, èèyàn míì tún tí ni l'Eko, ó di èèyàn 46 tó níi ní Nàìjíríà ''Tí a bá ní káwọn èèyàn jókòó sílé nítorí coronavirus, ebi àti olè jíjà ma pọ̀'' Mò ti ya ara mi sọ́tọ̀ bí mo ṣe dé láti America nítorí coronavirus- Soyinka Ìjọba ìpínlẹ̀ Eko ti ni ki gbogbo ọjà wà ni títì pa, sùgbọ́n.
BBC ṣe ìwádìí lóri àbajade ìwádìí ti àjọ yiìí ṣe, láti le mọ àwọn ìgbéléwọ̀n ti wọn lò láti yọri si ohun ti wọn gbé jáde.
Haliu ni ikọlu naa waye ni awọn ile isẹ ajọ ọlọpaa lorilẹede naa ati olu ile isẹ ẹgbọ oselu (Amhara Democratic Party (ADP) to wa ni ijọba lorilẹede naa.
L'Ondo, àwọn agbébọn jí alága káńsù tẹ́lẹ̀ gbé
Jakọbu kìlọ̀ fún wọn, ó ní, “Mo ṣetán, mò ń re ibi àgbà á rè, inú ibojì tí wọ́n sin àwọn baba mi sí, ninu ihò òkúta tí ó wà ninu ilẹ̀ Efuroni, ará Hiti, ni kí ẹ sin mí sí.
”Ewe, lataari gbogbo atotonu lori esun ti won fi kan Nene ti o je okan gbogi lara awon to n sakoso isajoba aare Ramaphosa, eyi lo sokunfa ileri ti aare naa se lati fopin si iwa ibajẹ, bee si ni lati mu igberu ba eto oro aje lorile-ede South Afrika.
m lọjọRu yii , ni eyi ti o mu awon  ẹsọ eleto aabo duro soju gbogbo ọna ni ipinle
Bakan naa, ko si ajọsepọ mọ laarin rẹ ati awọn olori Alaafin to ku loju opo ayelujara, gẹgẹ bi wọn ti maa n se tẹlẹ.
Bakanaa ni ileeṣẹ aarẹ pẹlu ko tii sọ ohunkohun lori ọrọ naa.
lowo Allah fun bi o se mu won ri opin aawẹ yii .
Oludije fun ipo aare lorile ede Naijiria labe asia egbe oselu Save Nigeria Congress, asofin Ayo Da-Silva ti so pe asiko ti to bayii ti orile ede Naijiria nilo iyipada rere, ti won yoo si gba ara won kuro lowo ijoba amunisin.
“Ayọ̀ ń bẹ fun yín, tí wọ́n bá kẹ́gàn yín, tí wọ́n ṣe inúnibíni si yín, tí wọ́n bá ń fi èké sọ ọ̀rọ̀ burúkú lóríṣìíríṣìí si yín nítorí mi.
 wọ ́ n lo àkọsílẹ ̀ yìí láti ṣàlàyé pé ọkùnrin kan tí ń jẹ bàgódà ni ó kọ ́ kọ ́ jọba ní ìlú kano .
Ninu àwọn ọmọbinrin Kenaani ni Esau ti fẹ́ aya, ekinni ń jẹ́ Ada, ọmọ Eloni ará Hiti, ekeji ń jẹ́ Oholibama, ọmọ Ana tí baba rẹ̀ ń jẹ́ Sibeoni, ará Hifi.
Oríṣun àwòrán, Twitter/@AyindeBarrister Àkọlé àwòrán, Aworan yii ṣafihan Ayinde Barrister nibi ayẹyẹ to ti gba ade gẹgẹ bi olorin Fuji to dara julọ lọdun 1977.
Ẹwẹ, ẹgbẹrun mẹrindinlogun ati mọkanlelọgọta lawọn eeyan to ti ri iwosan gba ti wọn si ti ja ajabọ lọwọ ajakalẹ arun naa.
Àwọn kan ń bọ̀ láti ìhà àríwá, orílẹ̀-èdè ńlá, ati ọpọlọpọ ọba,wọ́n ń gbára wọn jọ láti máa bọ̀ láti òkèèrè.
Awọn agba oṣere apanilẹrin atawọn to n ṣafihan aṣa, oogun, agbara ati iṣe awọn akọni Yoruba naa tun maa n kọni lẹkọ lori amohunmaworan.
" Ọ ̀ rọ ̀ tí kò ní àyípadà kankan ní únjẹ ́ ọ ̀ rọ ̀ adúróṣinṣin , tàbí "" adúróṣinṣin "" lásán ."
 Mimu igberu ba ibasepo ti o wa larin wa tele     
O ni dida epo disu si oju popo yii maa ba iṣẹ akanṣe to n lọ lọwọ naa jẹ ni.
Ramadan 2018: Sultan rọ Mùsùlùmí láti gba àlààfía lááyè
Báyìí ni ìsìn ṣe lọ lónìí nílé ìjọsìn CCC Genesis Global Wo àwọn èèkàn, ìlúmọ̀ọ́ka olórin tó ṣàbẹ̀wò sí ijọ Celestial Church ti Genesis Global Seyi Makinde fún olórin Fuji Taye Currency lẹ́bùn ọkọ̀ bọ̀kìnnì Toyota Prado 2020 Ẹ jọwọ, ẹ ba mi bẹ ìyàwó mi kí ìgbéyàwó mi ma baà túká - 9ice Ọlọ́pàá fìyà jẹ mí lọ́dún 2014, mò wà lẹ́yìn àwọn ọ̀dọ́ lórí ìwọde EndSARS- Fayemi O ni Woli Genesis kan yẹra diẹ ni, ''ti akoko ba to, yoo wọle pada bi ole loru.
"Afurasí méjì fi áńbúláǹsì kó Tramadol N60m wọlé l'Apapa Ẹ padà sílé èyin ọmọ wa tó n ṣiṣẹ́ darandaran - NEF ti Fulani Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Fulani Heardsmen: Afenifere ní àṣẹ tó bá wu àwọn àgbàgbà agbègbè àríwá Nàìjíríà ni Bakan naa ni awọn kan ni gbogbo igba ni ikọ Super Eagles ma n se ipo kẹta, eleyii ti wọn tilẹ pe ni ""ogun ibi wa lorilẹede Naijiria""."
- Amẹ́ríkà fọnmú Iroyin naa ni, bi eeyan ba jẹ ori ahun, yoo papa bu sẹkun to ba ri ọwọja ikọlu ọhun bo se lagbara si, nitori awọn agọ ọlọpa ati baraki wọn, ọpọ ile ijọsin, ilegbe, to fi mọ ile ajagunfẹyinti Paul Tarfa, ni wọn jo kanlẹ.
Iya yi wọ inu iyara awọn ọmọ rẹ lọ nibi to ti ri Muhammad lori ọkan ninu awọn ọmọ rẹ́ to ti ràgà bòó mọlẹ sibẹ O figbe ta ti ọdaran naa si gbiyanju lati sa lọ sugbọn ọkọ arabinrin yi ati awọn araadugbo lee mu.
Bí ẹnikẹ́ni bá bi yín pé, ‘Kí ló dé tí ẹ fi ń tú u?
Nítorí láti ìbẹ̀rẹ̀ títí di àkókò yìí ni ẹ ti ń bá mi ṣiṣẹ́ pọ̀ ninu iṣẹ́ ìyìn rere.
" Mo dupẹ lọwọ gomina, fun bo ṣe fi aaye silẹ lati ba wa pari wahala yii.
Ewe, eyi ni ipo ate ATP ohun ni kikun ni itele n tele:Rafael Nadal (Spain)Roger Federer (Switzerland)Novak Djokovic (Serbia)Juan Martin del Potro (Argentina)Alexander Zverev (Germany)Marin Cilic (Croatia)Dominic Thiem (Austria)Kevin Anderson (South Africa)Grigor Dimitrov (Bulgaria)John Isner (United States) Tobi Sangotola.
Ààrẹ orílẹ̀èdè Nàìjíríà, Muhammadu Buhari ti fèsì sọrọ to n ja ràìnràìn nipa ẹ̀yáwó $328 million ti Nàìjíríà fẹ yà lọ́wọ́ orílẹ̀-èdè China.
Jesu pa òwe kan fún wọn láti kọ́ wọn pé eniyan gbọdọ̀ máa gbadura nígbà gbogbo, láì ṣàárẹ̀.
Bí ẹ óo ṣe máa ṣe ìdásílẹ̀ náà nìyí: ẹnikẹ́ni tí aládùúgbò rẹ̀, tíí ṣe arakunrin rẹ̀, bá jẹ ní gbèsè kò ní gba ohun tí aládùúgbò rẹ̀ jẹ ẹ́ mọ́, nítorí pé, a ti kéde ìdásílẹ̀ tíí ṣe ti OLUWA.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ọdún 1940 ni wọ́n ti ń sin ọ̀ọ̀nì ilé Delesolu ní Ìbàdàn Ṣoyinka ati Arole Oodua ni o n dun awọn gidi pe iṣọkan ati ẹmi irẹpọ to wa ni gbogbo ẹkun Naijiria tẹlẹ ti n di ohun igbagbe.
Bakan naa ni gomina Sanwo-Olu kede awọn ilana tuntun fun awọn akẹkọọ ti o fẹ wọle pada ni Ọjọ Ajẹ, Ọjọ Kọkanlelogun, Oṣu Kẹsan, ọdun 2020.
43  si idokowo oja pasi-paro naa.
A ko mọ bi ẹda kokoro yi se lagbara sí sugbon a gbodo gbe gbogbo igbesẹ tó yẹ ní kíákíá lati dẹkun rẹ pẹlu bi a ti ṣe n fun awọn eeyan labẹrẹ ajẹsara"" Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Kollington ṣàlàyé bí orin Fuji ṣe bẹ̀rẹ̀ gan an ní Nàiìjíríà Ọjọgbọn Alan McNally, to jẹ akọṣẹmọṣẹ ni fasiti Birmingham, ni laarin ọsẹ bi meloo to kọja lawọn laabu ilẹ Gẹẹsi kẹfin kokoro tuntun yi."
"A nilo ilana adehun tuntun pe a fẹ yọwọ-yọsẹ.
Bí ó bá sì jẹ́ pé obinrin ni ó kọ ọkọ rẹ̀, tí ó fẹ́ ọkọ mìíràn, òun náà ṣe àgbèrè.
Ṣugbọn àwọn eniyan náà kò gbọ́, wọ́n sì ń tẹ̀lé ìwà àtijọ́ wọn.
káàkiri àgbáyé , ó tó 80 miliọnu àwọn eniyan tó ní àìsàn náà lára .
Wọ́n dúró ní ààyè wọn, wọ́n sì ka ìwé òfin OLUWA Ọlọrun wọn fún bíi wakati mẹta lọ́jọ́ náà.
 Gbogbo iranlowo yii fihan pe laipe a ko ni nilo lati maa ko iresi wole mo lati ile okeere ni Naijiria”.
Eyi lo mu ki amugbalẹgbẹ fun gomina ipinlẹ Ondo lori ọrọ akanṣe iṣẹ, Ọmọwe Doyin Ọdẹbọwale ati ikọ amuṣẹya ijọba o fọn si igboro lati rii daju pe awọn ileejọsin tẹle aṣẹ yii.
Ṣugbọn sa, itẹwọgba àti ìdíyelé rẹ da lori iye ti awọn eeyan ba pinnu lati rà tàbí tà á.
laarin awon odo, ti o si tun ro won lati samulo awon ohun amusagbara eto ogbin
Ninu fidio yii to jẹ akanṣe fọnran ẹka ileeṣẹ BBC to maa n tu aṣiri aidaa lawujọ, BBC Africa Eye, arabinrin kan to jẹ akọroyin ati aṣefiimu lọ sinu yara ibimọ nile iwosan kan lati lọ ya fiimu bi obinrin naa ṣe n bimọ lọwọ lọwọ.
Ẹ kó wọn sí ẹ̀yìn odi kí wọn má baà sọ ibùdó yín di aláìmọ́ nítorí pé mò ń gbé inú rẹ̀ pẹlu àwọn eniyan mi.
Oríṣun àwòrán, @tostvnetwork Agbẹnusọ fun ẹgbẹ IMN atawọn ọmọlẹyin Shiite ni Naijiria, Ibrahim Musa ṣalaye fun BBC pe awọn ọlọpaa lo yinbọn pa mẹta ninu awọn ọmọlẹyin Shiite naa nilu Kaduna Lónìí ni Ajimobi yóò mọ bó ṣe ń lọ pẹ̀lú ẹjọ́ kòtẹ́milọ́rùn tó pè Ìdúnàdúrà ṣì n lọ láti dóòlà ọmọ Ọffa mẹ́fà lọ́wọ́ ajínigbé- ODU Ó lé ní ẹ́gbẹ́ta àwọn ọmọ Naijiria tí wọ́n ti ṣetàn láti padà sílé!
rara, eleyi ko si loruko meji ju iwa ibaje lo, “aare ko ni fayegba enikeni lati lo ipo
NFF ṣalaye loju opo wọn pe agbabọọlu Naijiria tẹlẹ ri naa ku lẹyin aisan ranpẹ.
Inú Ẹrú bàjẹ́, ṣùgbọ́n o ni ki Ẹrú má bẹ̀rù, Ẹrú na a ṣe ìlérí lati fi tọkàn-tọkàn tọ́jú ohun ti Bàbá fi silẹ̀.
Nígbà tí ó bá di ọjọ́ keje, kí alufaa yẹ ẹni náà wò.
Eyi waye nitori kii ṣe igba akọkọ niyii ti wọn fi iru fọto bẹẹ sita.
Wọn fi silẹ lẹyin oṣu mẹfa, o si pada tẹdo si Sagamu.
Nibayii, erongba orilẹede Indonesia ni pe Minisita feto abo ni ilẹ Gẹẹsi, Jim Mattis yoo lee se atọna bi okun ajọsepọ laarin orilẹede naa pẹlu ilẹ Amẹrika.
O ti fihàn gbangba pé, àwọn ọ̀gágun ati ọmọ ogun rẹ kò jẹ́ nǹkankan lójú rẹ.
Gẹgẹ bi alaye to wa ninu iwe to tẹ BBC lọwọ lati ọwọ agbẹjọrọ orile-ede Naijiria kan, Adetokunbọ Eribake Esq, ọrọ ile ẹjọ yii le tumọ si nkan meji: O ni: 'O le tumọ si pe awọn iha mejeeji n sọrọ lori bi wọn o ṣe yanju ẹjọ naa lai lọ ile ẹjọ, ki ijọba si wọgile ṣiṣe ẹjọ pẹlu Woodberry.
Gẹgẹ bi iroyin ti a gbọ ṣe sọ, nṣe ni wọn fi iwe pe Sẹnetọ Ekweremadu si ibi eto nla kan ti awọn ọmọ ẹya Igbo to n gbe ni ilu Nuremberg gbe kalẹ.
 O fikun pe, ireti aare Buhari ni lati ri pe, oruko Naijiria goke agba, kii orile-ede ohun si fakoyo ninu idije naa.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: A kò fipá mú ẹnikẹ́ni láti dá Ruga, aàgọ́ Fulani sílẹ̀ -Iléeṣẹ́ aàrẹ Ìpínlẹ̀ Oyo àti Eko kò nífẹ̀ẹ́ láti gba 'Ruga Settlement' láyè Ẹ̀mí ogójì ṣòfò, ọgọ́ta míràn farapa nínú ìjàmbá ọkọ̀ epo tó jóná 'Èèyàn mi mẹ́ta ló wà nínú ọkọ̀ ojú omi tó dà nù l'Eko!
A bí Samuel Okwaraji ní ọdún 1964 sí ìdílé ọgbẹ́ni David Okwaraji àti Janet Okwaraji, ó sì lọ ilé ìwé WTC practicing ní Enugu fún iwé alákọbẹ̀rẹ̀ àti Ezeachi fún grammer, bákan náà ló lọ sí Federal Government College ni Orlu ni ìpínlẹ̀ Imo.
Oun nikan lo le dan iru rẹ wo.
'Irọ́ ni o, Ọlọ́pàá 167 tó fẹ́ koju Boko Haram kò sá lọ' 'A ti pa Boko Haram run patapata' Àkójọpọ̀ àwòrán ọdún Kérésìmesì lágbáyé Òṣìṣẹ́ ẹka arinrinajo ọkọ̀ òfúrufú Nàìjíríà fẹ́ gún lè iyanṣẹlodi Eleyi ṣẹlẹ lẹyin igba ti ileeṣẹ ọmọogun ni awọn ti ra nnkan ija fun awọn ọmọogun Naijiria.
Ṣebí àtíbàbà Moleki ni ẹ gbé rù,ati ìràwọ̀ Refani oriṣa yín,àwọn ère tí ẹ ṣe láti máa foríbalẹ̀ fún?
Elihu, ọmọ Barakeli, ará Busi, ní ìdílé Ramu bá bínú sí Jobu, nítorí pé ó dá ara rẹ̀ láre dípò Ọlọrun.
Nítorí èmi ni OLUWA Ọlọrun rẹ,Ẹni Mímọ́ Israẹli, Olùgbàlà rẹ.
Èèyàn 5 farapa, ọ̀pọ̀ ọkọ̀ jóná nínú ìjàmbá iná márosẹ̀ Ibadan sí Eko Ta ni Babajide Sanwo Olu, gomina tuntun l‘Eko?
Báwo ni eniyan ṣe lè sọ fún Farao pé,“Ọmọ Ọlọ́gbọ́n eniyan ni mí,ọmọ àwọn ọba àtijọ́.
6 Ṣùgbọ́n lẹ́hìn ríronúpìwàdà, àti rírẹ ara rẹ̀ sílẹ̀ nítòótọ́, nípasẹ̀ ìgbàgbọ́, Ọlọ́run ṣe iṣẹ́ ìránṣẹ sí i láti ọwọ́ ángẹ́lì mímọ́ kan, ẹnití ìwò ojú rẹ̀ dàbíi mọ̀nàmọ́ná, àti ẹnití àwọn aṣọ rẹ̀ jẹ́ mímọ́ àti funfun ju gbogbo fífunfun míràn lọ;
Jẹ́ kí ó wà lọ́dọ̀ rẹ bí alágbàṣe tabi bí àlejò; kí ó máa ṣiṣẹ́ fún ọ títí di ọdún jubili.
 TomTom je elerindodo ti o se Pataki fun iko Super Eagles.
Ọwọ́ tẹ àwọn ọlọ́pàá tó fìyà jẹ obìnrin kan lọ́nà àìtọ́ n'Ibadan Ọlọ́pàá kan sọ pé òun ní láti ṣàyẹ̀wò ìlédíìí ǹkan oṣù Arabìnrin kan kó tó lè kọjá Obìnrin àti ọmọdé tó há sábẹ́ ilé tó wó ní Ebute Meta ti ń gba ìtọ́jú, LASEMA ń ṣàyẹ̀wò ilé náà lọ́wọ́ Kí ní 'Economy' ní èdè Yorùbá?
N óo fún wọn ní ọkàn ati ẹ̀mí kan, kí wọn lè máa bẹ̀rù mi nígbà gbogbo, kí ó lè dára fún àwọn ati àwọn ọmọ wọn lẹ́yìn wọn.
Àti pé, wọn yóò ṣi maa lo olú iléeṣẹ́ àtijọ́ tó wà ní agbègbè Adetokunbọ Ademọla, ní ìlú Abuja.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù June 12: Ọjọ́ tí ọ̀pọ̀ ẹ̀yà, èdè àti ẹlẹ́sìnjẹ̀sìn tó wà ní Nàíjíríà papọ̀ di ọ̀kan 12 Òkùdu 2019 Oríṣun àwòrán, @mko_abiola Ọjọ nla, ọjọ manigbagbe ni ọjọ Kejila osu Kẹfa ọdun 1993, ti gbogbo eeyan mọ si June 12 jẹ ninu itan orilẹede Naijiria.
Ọgbẹni Adesina ni awọn ọmọ ẹgbẹ IPOB ko ni ohun kan ṣe pẹlu Aarẹ Buhari lati igba to ti de si ilu Yokohama lorilẹede Japan.
igbo nla ni ila Ariwa iwo oorun ati aarin gbungbun Ariwa wa , nitori idi eyi a
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Abdurasheed Maina: Adájọ́ ní kí ọ̀gá àjọ tó rí sí owó ìfẹ̀yìntì tẹ́lẹ̀ sí wà látìmọ́lé 25 Ọ̀wàrà 2019 Oríṣun àwòrán, Facebook/Abdulsheed Maina Ile ẹjọ giga ijọba apapọ l'Abuja ti paṣẹ pe ki ọga ile isẹ to n risi owo awọn osisẹfẹyinti (pension) tẹlẹri, Abdurasheed Maina wa ni atimọle.
O ni lootọ ni iwọọde naa n lọ lọwọ lasiko ti a fi n ko iroyin yii jọ ṣugbọn awọn oṣiṣẹ ileeṣẹ naa to jẹ ọmọ ẹgbẹ ileeṣẹ to n pin ina ọba lorilẹede Naijiria ko jade lati kopa ninu iwọde ọhun.
, Aare Paul Kagame to n tuko orile ede Rwanda lowo fi aidunnu re han lori bi ina idagbasoke Ile Adulawo se n jo ajoreyin.
Kọmisọna ileeṣẹ yii lo tu kẹkẹ ọrọ kalẹ to si ṣalaye bi gbogbo nkan ṣe ri gan.
Kí ló ṣokùnfà afárá tó já tó pa ènìyàn kan ní Ilorin?
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ọpọ ẹmi lo ti sun ninu ikọlu awọn darandaran nipinlẹ Plateau Iroyin naa ni awọn Fulani darandaran ni wọn fura si pe o gbẹmi awọn eeyan mẹẹdọgbọn naa, to fi mọ awọn ọmọde mẹta ati obinrin meji ni abule Dundu nijọba ibilẹ Bassa.
Kì í ṣe pé dandan ni fún mi pé kí eniyan jẹ́rìí gbè mí.
Ẹ máa rìn níwọ̀n ìgbà tí ẹ ní ìmọ́lẹ̀, kí òkùnkùn má baà bò yín mọ́lẹ̀.
Wọn ni ọpọlọpọ awọn to n tẹle wọn lori Facebook ati Twitter ṣugbọn wọn ko reeyan kankan tẹle wọn lọ sile baba wọn pe o fẹ fẹ wọn gẹgẹ bi ọkọ tabi aya.
Maa kan mi nibadi ki n to deleee.
Babájídé/ Babátúndé/ Babárìndé/ Babáwándé: Ọmọkùnrin tí a bí ní kété tí bàbá rẹ̀ kú.
Ninu ọrọ tirẹ, Akọda Awo ṣalaye pe awọn obi, ori, olodumare ni iṣẹṣe ati pe aimọkan lo n ṣe awọn to n ro pe idibajẹ ati iwa okunkun ni.
Lara awọn ẹsun ti Abiọla Ajimọbi fi kan Kọla Balogun naa ni aiṣe eto idibo abẹnu ninu ẹgbẹ oṣelu PDP ki o to dije, ṣiṣẹ amulo awọn janduku lati ji apoti ibo gbe, titọwọ bọ akọsilẹ ẹsi ibo ati bẹẹ bẹẹ lọ.
28 Òkùdu 2020 Oríṣun àwòrán, Nigeria Defence News/Twitter Naijiria ti di orilẹede akọkọ ni Afirika ti yo maa lo ẹrọ abaniṣiṣẹ rọbọọti ni papakọ ofurufu gẹgẹ bi ẹka iroyin ileeṣẹ ologun Naijiria ṣe sọ ọ.
Láti Miletu, Paulu ranṣẹ sí Efesu kí wọ́n lọ pe àwọn alàgbà ìjọ wá.
Anwar lo soro yii ninu atejade kan lati pase fun ajo to n ri si sise owo ilu
 leventis je ọ ̀ jọ ̀ gbọ ́ n àgbà ní ilé ẹ ̀ kọ ́ cambridge university ní greek culture nígbà tí wọ ́ n oèé ní ọ ̀ jọ ̀ gbọ ́ n àṣà a.
Ijọba ipinlẹ Ọyọ ni oun ti gbẹsẹ le asa gbigba owo lawọn ileẹkọ alakọbẹrẹ ati girama to jẹ ti ijọba lasiko ti wọn se ibura fun oun.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Lọjọ Aiku, awọn alatilẹyin ẹgbẹ alatako nilẹ Congo ni wọn mu igbe bọnu lọjọ ajọdun ominira to waye lolu ilu Congo, Kinshasa Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Iwọde oselu miran lo tun n waye yii ni Omdurman, lorilẹede Sudan, ti oluwọde kan si n kesiawọn ologun lati fi ori apere silẹ Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Iwọde yii kọja bẹẹ.
Sùgbọ́n akọ́nimọ̀ọ́gbá fun ikọ alátakò Bayern Munich, Jupp Heynckes ti sọ pé, àwọn yóò ṣe àtúnse aṣiṣe tí àwọn ọmọ ẹgbẹ́ agbábọ́ọ̀lù se lọ́sẹ̀ tó kọjá.
Ilé ẹjọ́ wọ́gilé ìgbẹ́jọ́ Olalekan 'Woodberry' Pọnle
O ni mi o lo #EndSars, ẹ bu mi, mo tun lo o, ẹ tun n kun sinu""."
Lizzy gbe ọrọ coronavirus si ẹgbẹ kan papaa julọ bi o ti n palẹmọ fun ayẹyẹ ọjọ ibi rẹ.
Ṣé àwọn òṣìṣẹ́ elétò ìlera Ghana yóò ya Aarẹ Akufo-Addo sọ́tọ̀ lẹ́yìn tó dé láti ilẹ́ Yúròòpù?
Ofin CAMA naa to ti wa nilẹ tẹlẹ, sugbọn ti wọn ṣẹṣẹ ṣe afikun rẹ, ti o si kan awọn ijọ nlanla lo fa gbọnmisi omi o to laarin adari ijọ ọhun ati agbẹnusọ aarẹ Buhari.
Olórí àwọn tí wọn ń ṣọ́ ọba Babiloni mú Seraya olórí alufaa, ati Sefanaya igbákejì alufaa, ati àwọn aṣọ́nà mẹta.
Tó bá di àkókò náà, yóo dúró lórí òkè olifi tí ó wà ní apá ìlà oòrùn Jerusalẹmu; òkè olifi yóo sì pín sí meji.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù U.
Eni afunrasi miiran ti o ti na papa bora, ni won fi si ewon gbere leyin re, nigba ti eniketa naa tun jebi esun ti won fi kan-an yoo faso penpe roko oba fun odun meta gbako.
Yahaya Bello lẹ́ẹ̀kan síi ni APC ṣe ní ìdìbò abẹ́lé ní Kogi 'Òṣòkòmọlẹ̀' ní ẹjọ́ láti jẹ́ lórí owó Káńsù l'Ekiti Bakan naa ni ijọba Naijiria wa gbe e jade pe awọn ti mu ẹdinku ba owo irinna fun awọn ọmọ ilẹ Amerika naa.
 Ninu eyi ni wọn ti n yan akoṣẹmọṣẹ Onimọ iṣiro owo gẹgẹ bi akọwe-agba fun ile-iṣẹ ijọba yii.
Ile naa eleyi to ni oun fun Bunmi Ninalowo jẹ eleyi tiileeṣẹ kan fun un.
N kò lẹ́bi,sibẹ n kò ka ara mi kún,ayé sú mi.
Ajọ to n gbogun ti itankalẹ ajakalẹ aarun ni Naijiria, NCDC lo kede rẹ loju opo Twitter rẹ.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Igbẹjọ awọn afunrasi Boko Haram bẹrẹ lojo aje Akọroyin BBC, Ishaq Kalid sọ wipe awọn afunrasi ti o le lẹgbẹrun naa ti wa latimọle fun ọpọlọpọ ọdun, ati wipe adajọ mẹrin ni yoo gbọ igbẹjọ naa ti yoo waye ni ile-igbẹjọ tiwantiwa ti kii se ti awọn ologun.
Botilẹ jẹ wi pe awọn onimọ kan ko faramọ eyi.
Ṣugbọn nkan to mu ko yatọ ni bi o ṣe n mu ki aarẹ ko mu awọn eniyan, ati iye eniyan to ti pa.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Wo àwọn àdúgbò tí ìpínlẹ̀ Eko ti fòfin de ọ̀kadà àti Marwa Àwa ò ri lẹ́ta kankan gbà láti ọ̀dọ̀ Malami lóri ọ̀rọ̀ àwọn alága Kansu - Makinde Àwọn nkan tó yẹ kí o mọ̀ nípa ìgbẹ́jọ Trump tí yóò blrẹ̀ l'ọ́dọ̀ àwọn Sẹ́nétọ̀ Mí ò le nífẹ̀ẹ́ obìnrin Nàìjíríà kankan mọ lẹ́yìn ti mo ti tọ́ obìnrin òyìnbó wò- Issa O wa rọ aarẹ Buhari lati maṣe faye gba idasilẹ ikọ alaabo Amọtẹkun tawọn Gomina ipinlẹ Kaarọ o jiire dasilẹ.
Ajọ Amnesty sọ pe awọn alaṣẹ orilẹede Yuroopu ni aiṣedeede pẹlu awọn aṣikiri ati awọn asasala ni Libya.
Lẹyin igba ti wọn de Spain ni wọn sọ fun wọn pe, wọn yoo ma sisẹ nabi lati le da owo irinna wọn pada.
Bẹ́ẹ̀ ni iná yóo jáde láti ara àwọn ará ìlú Ṣekemu ati ti Bẹtimilo, yóo sì jó Abimeleki run.
Ó ṣe àlàyé fún wọn pé, “Bí ọba yín yóo ti máa ṣe yín nìyí: Yóo sọ àwọn ọmọkunrin yín di ọmọ ogun, àwọn kan ninu wọn yóo máa wa kẹ̀kẹ́ ogun, àwọn kan yóo wà ninu ẹgbẹ́ ọmọ ogun tí ń fi ẹsẹ̀ rìn, àwọn kan yóo máa gun ẹṣin níwájú kẹ̀kẹ́ ogun rẹ̀.
Ko yẹ ki nnkankan ya wa .
Èyí ni bí gómìnà Babajide SanwoOlu ti ìpínlẹ̀ Eko ṣe kó COVID-19 Wo àwọn Ọba aládé méje tó jẹ́ obìnrin nílẹ̀ Yorùbá Kí làwọn nǹkan tó lè rán ọkùnrin sí ọ̀run alákeji lásìkò ìbálòpọ̀ pẹ̀lú obìnrin?
Rabuṣake gbọ́ pé ọba Asiria ti kúrò ní Lakiṣi láti lọ jagun ní Libina, ó sì lọ sibẹ láti lọ rí i.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Coronavirus Updates in Nigeria: Òṣìṣẹ́ ètò ìlera méjì ló wà nínú àwọn tó lùgbàdì àrùn Coronavirus ní Ekiti 3 Òkùdu 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 4 Òkùdu 2020 Oríṣun àwòrán, Others Àkọlé àwòrán, Àjọ NCDC ṣàlàyé ní kíkún pé ènìyàn 348 ló lùgbàdì àrùn Coronavirus ní Naijiria ní Ọjọ́ọ̀rú nìkan ṣoṣo.
Nígbà tí wọ́n pada wọ inú ilé, àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ ń bi í nípa ọ̀rọ̀ náà.
OLUWA, mo mọ̀ pé ìdájọ́ rẹ tọ̀nà,ati pé lórí ẹ̀tọ́ ni o pọ́n mi lójú.
Oyindamola sọrọ lori awọn ami ẹyẹ ti oun ti gba ati awọn aṣeyọri to ti ni lẹnu yiyan iṣẹ yii laayo.
3 Ìgbé 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 8 Ìgbé 2019 Ẹ̀rín kèé-kèé ni báwọn èèyàn ṣe fi àmì sórí ọ̀rọ̀ 'Ayekofẹnifọrọ' Ami ori ọrọ ṣe pataki ninu ede Yoruba, o si yẹ ka maa kọ ara wa, tabi ran ara wa leti.
Jiti Ogunye: Ọ̀jẹ̀lú ni àwọn tó ń fi APC sílẹ̀ fún PDP
Àkọlé àwòrán, Zhang ni oludasilẹ ile iṣẹ to n pese omi mumu O le ni ẹgbẹrun marun un ọmọ orileede China to n gbe ni Kano.
Bí Janesi ati Jamberesi ti tako Mose, bẹ́ẹ̀ ni àwọn ọkunrin wọnyi tako òtítọ́.
Mo ṣetán láti kú nítorí rẹ.
Ẹsun pe o fẹ doju ijọba bo lẹ ati pe of fẹ da alaafia ru kaakiri orilẹede Naijiria ni wọn fi kan an.
Ninu ọrọ to fi sita, Ọọni ile ifẹ ti ṣe akawe ọrọ ọhun gẹgẹ bii eyi ti ko fidimulẹ.
Bakan naa ni iṣẹlẹ awọn ajafẹtọ to n gbe ẹbọ ka iwaju ile aṣofin naa pẹlu ti n waye lati tako iwa ijẹkujẹ ati aisi iṣẹ fun awọn ọdọ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Àsìkò Amojúẹ̀rọ Seyi ni ló fi wọlé l'Oyo, kìí ṣe àsìkò èmi Omobolanle' Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Super Eagles - BBC News Yorùbá BBC News, YorùbáFò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù AFCON 2019: A bọ̀wọ̀ fún orílẹ̀èdè wa ju àwọn ikọ̀ míì tí à gba fún - Super Eagles Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ AFCON 2019: A bọ̀wọ̀ fún orílẹ̀èdè wa ju àwọn ikọ̀ míì tí à gba fún - Super Eagles 1 Agẹmo 2019 Adari ikọ́ agbabọọlu Super Eagles, Genort Rohr atawọn ikọ agbabọọlu rẹ sọ ero wọn lori bi wọn ṣe ṣe e ti Madagascar mu wọn kọ oju awn ara Naijiria soorun alẹ.
Lati igba naa ni ati adari ati akọwe rẹ ti wa ni iyasọtọ.
O si daju pe aye ti ẹsin Oba Adeniran Adeyemi ko jẹ, ti wọn fi yọwọ rẹ ninu awo, ni iru idi rẹ, tii se ọmọ rẹ n jẹ lori aleefa.
Dasofunjo ni wọn gbe Majek digbadigba lọ si ileewosan UCH ni Ibadan, nigba ti aisan rẹ fẹ bọwọ sori amọ ẹpa ko boro mọ.
Àmọ́ ń jẹ ó ṣeé ṣe kí wọn tún ṣe àfikún àkókò òfin to de oko-owo ọtí líle, to tí wáyé ṣáájú fún ọ̀sẹ̀ márùn-ún tẹ́lẹ̀, síwájú sí, lẹyin ọgbọnjọ oṣù kẹrin tó yẹ kí òfin náà kasẹ nlẹ?
Ẹya Fulani lo pọ ninu awọn darandaran lorile-ede Naijiria.
Orisi ẹsun ni awọn ara ilu fi kan awọn agbofinro yii kaakiri Naijiria ati ni ilẹ okeere nibi ti iwọde ti waye kaakiri.
Wọ́n bá gé orí Ṣeba, wọ́n jù ú sí Joabu láti orí odi.
Bakan naa, ajọ naa wa ke si awọn ọmọ Naijiria pe ki wọn ma mikan nitori awọn ko ni fi ọrọ akọsilẹ wọn lede afi ti o ba niise pẹlu eto aabo lorilẹede Naijiria.
Ilẹ Gẹẹsi Wọn gbe ere Edward Colston to wa ni ilu Briston kuro.
Nígbà tí wọ́n pe Paulu, Tatulu bẹ̀rẹ̀ sí rojọ́.
Iṣẹ́ ẹ̀mí ẹ̀tàn ló bàlemi lasiko tí mo sọ àṣọtẹ́lẹ̀-Simeon Ononogbu Mo gbàgbé sùnlọ sìnú ọkọ̀ òfurufú, ẹ̀rù ikú bà mí -Tiff Ìdí tí ilé fi wó lu ènìyàn méjì ní Oshodi -LASEMA Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Tomomewo Favour: olóṣèlú kìí ṣe ọ̀daràn tàbí alágbèrè Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Ekwo nibiti awọn mẹrẹẹrin ti ni awọn ko jẹbi ẹsun mẹrẹẹrin ti wọn fi kan awọn.
Ibrahim Kalin  salaye fawon oniroyin pe ewu nla n be loko longe ti awon omo ogun Syria ba tun gbiyanju iru igbese yii leekan sii lati wonu Afrin.
 Ibasepo to wa laarin ilu Eko ati orile ede Britain bere lati opolopo odun seyin.
Ipade awọn akọroyin to waye ni nkan bi ago mẹwa owuro lỌjọbọ ni ile itura Gomina Ben Ayade ni Cross River ni iṣẹlẹ naa ti waye.
Àkọsílẹ̀ ìran Ṣemu nìyí: ọdún keji lẹ́yìn tí ìkún omi ṣẹlẹ̀, tí Ṣemu di ẹni ọgọrun-un (100) ọdún ni ó bí Apakiṣadi.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ondo Murder: Awọn ọlọ́pàá kò tíì mọ ibi tí wọn sin òkú ọmọ náà sí 27 Ògún 2019 Oríṣun àwòrán, sunshinetruth.
Ọpọ ọkunrin ni ololufẹ wọn maa n fi agidi mu lati ni ibalopọ lasiko ti iru ọkunrin bẹ ẹ ba ti mu ọti yoo.
" Ó pe ibẹ ̀ ní "" Àkún rẹ ́ ' nítorí ìtumọ ̀ "" gé ' ni "" rẹ ́ ' ní èdè Àkúrẹ ́ ."
 Osu keje odun 2018 ni aare Muhammadu
Olayanju fi idi ọrọ naa mulẹ lasiko to n ba BBC Yoruba sọrọ, eyi to fi n fesi lori bi awọn ọdẹ ibilẹ to fẹ kopa ninu ikọ Amotekun ṣe tako igbesẹ fifi orukọ silẹ lori ayelujara.
Iná yóo tún jó o ní àjórun,nítorí alágbára ni Oluwa Ọlọrun tí ó ti ń ṣe ìdájọ́ fún un.
OLUWA bá sọ fún un pé, “Mo múra tán láti ṣe nǹkankan ní Israẹli, ohun tí mo fẹ́ ṣe náà yóo burú tóbẹ́ẹ̀ tí yóo ya ẹnikẹ́ni tí ó bá gbọ́ lẹ́nu.
Ìdájọ́ m bọ̀ fún ọ̀rẹ́kùnrin Khadijat Oluboyo Alábaṣiṣẹ́ ọkùnrin tó kú sínú odò Ọ̀sà sọ bó ṣe rí Nigba ti BBC Yoruba ba ile iṣẹ Ọlọpaa sọ̀rọ̀, wọn ni lootọ ni Aisha mu majele.
Wo díẹ̀ lára àwọn ọ̀rọ̀ ìkẹyìn ti Alexander Akinyele fi léde kó tó papódà Olùdíje 24 ni yóò kópa ní ìdìbò Kogí Ọlọpàá gba owó ilé ìwé #150,000 lọ́wọ́ akẹ́kọ̀ọ́ DELSU kan Ẹ̀rù kò bà mí láti padà sí Bolivia- Evo Morales Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
OLUWA dá a lóhùn pé, “Ta ló dá ẹnu eniyan?
Ni eyi ti ogbontarigi oṣere Fathia Williams fi ni o tẹ oun lọrun lati jẹ oṣere ju olootu lọ nitori ko rọrun lati ko oriṣiriṣi ori jọ ninu sinima.
Fatima sọ eyi lasiko ti o n fesi si fidio ti o ja ranyin lori ẹrọ ayelujara ni ọṣẹ to kọja lorilẹ-ede Naijiria.
Atiku ni Aarẹ Buhari n tapa ṣofin orilẹede Naijiria, bẹẹ lo si n o ṣe awọn ẹka ijọba bi o ṣe wu u lati le tẹ ara rẹ nikan lọrun.
"Ìpinu mi ni láti dá fóònù náà padà lọ́jọ́ kejì ti mo bá ti lọ si ọ̀dọ̀ aṣerulóge mi, sùgbọ́n àwọn ọlọ́pàá ti tọpasẹ̀ fóònu náà wọ́n si mú mi.
O ṣalaye pe, bi eeyan ba ni dọla bayi, ki o ṣọra lati naa.
Gbà mí lọ́wọ́ àwọn aṣebi,kí o sì yọ mí lọ́wọ́ àwọn apànìyàn.
'Obinrin jẹ amuludun' Awọn kan gba pe asiko ti to ki Naijiria fawọn ọdọ laaye lati dupo aarẹ ki akukọ tuntun le kọ fun igbadun ara ilu.
O tun sọ nipa pataki ki ọmọ ni idanimọ ninu aye ki o le kọ iwa ọmọluwabi bi o ṣe yẹ.
Bayii ni Daniel Olutope ti ṣe gomina ipinlẹ Ekitit fun wakati meloo kan.
Ọmọwe Baruwa, ọkan lara awọn olugbe agbegbe naa pe ijọba Ipinlẹ Eko lati wa ona abayọ si awọn idoti bayii ti o fẹ maa ba ipinlẹ Eko jẹ ni lọwọlọwọ yii”.
TOT vs CHE:Lampard tẹ ojú ọ̀gá rẹ̀ mọ́lẹ̀, ayò meji sodo ló kó lé Mourinho lọ́wọ́
Ọkọ náà kọsẹ̀ nínú yàrá ìgbàlejò, ó sì kú, ebí sì ṣe wẹ́rẹ́ pa ìyàwó sí orí ibùsùn.
Inú mi dùn púpọ̀ nígbà tí mo gbọ́ ìròyìn ikú mi nítorí ó ṣe àfihàn bí mo ti ṣe gbajúmọ̀ tó ni."
Ẹ jí, ẹ̀yin ohun èlò orin, ati hapu,èmi alára náà yóo jí ní òwúrọ̀ kutukutu.
Osisẹ Ajọ to n risi ọrọ pajawiri naa, Hussaini Ibrahim, ni bi awọn eniyan se n bẹ igi ni igbo naa n se okunfa omiyale nitori igi maa n gba omi sara, sugbon awọn olugbe orilẹ-ede Naijria ma n bẹ igi ni igbo lati fi dana tabi ta a lati fi ko ile.
Abíọ́dún/ Abọ́dúnrín/ Abọ́dúndé: Ọmọ tí a bí lásìkò ọdún pàtàkì kan- Ó le ṣe ọdún ẹ̀sìn tàbí ọdún ìlú
Ǹjẹ́ ẹ lè dárúkọ àwọn mẹ́rẹ̀rin tí ó wà nínú àwòrán yìí.
Ẹ máa fi ṣe ọ̀rọ̀ sọ,gbogbo ẹ̀yin tí ẹ̀ ń gun kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ funfun,gbogbo ẹ̀yin tí ẹ̀ ń jókòó lórí ẹní olówó iyebíye,ati gbogbo ẹ̀yin tí ẹ̀ ń fi ẹsẹ̀ rìn.
tọwọ ́ ọmọdé nìkan ló ha ń gbà nì ?
Kùmọ̀ dàbí koríko lára rẹ̀,a sì máa fi ẹni tí ó ju ọ̀kọ̀ lù ú rẹ́rìn-ín.
Bí Jesebẹli ti gbọ́ pé wọ́n ti sọ Naboti lókùúta pa, ó sọ fún Ahabu pé, “Gbéra nisinsinyii, kí o sì lọ gba ọgbà àjàrà tí Naboti kọ̀ láti tà fún ọ, nítorí pé ó ti kú.
Eleasa bí Sisimai, Sisimai bí Ṣalumu; 
Ehanire ni ise iwadii ti bere bayii ni eka ile ise ijoba lati tubo wadii sii nipa isegun ibile.
Nígbà tó ń fi ẹ̀mí imoore rẹ hàn sí Ọlọ́run lójú òpó Instagram rẹ, Olatunji mú ọjọ́ tó kọ́kọ́ pàdé osere-binrin náà wá sí ìrántí, èyí tó bẹ̀rẹ̀ lórí ẹ̀rọ ibaraẹnisọrọ.
Agbẹjọro naa ni Arisekọla Alao kii se Ọlọrun sugbọn akanda eniyan ni.
Akọroyin BBC to wa nipinlẹ Enugu ni oriṣii ẹ̀ka meji ni awọn oludibo pin si ni awọn ibudo idibo abẹlẹ to n lọ lọwọ.
Ẹni to bori: Senegal Nigeria vs Benin.
Coronavirus in Nigeria: Ènìyàn márùn ún bọ́ lọ́wọ́ ìgbèkùn àrùn Coronavirus ní ìpínlẹ̀ Èkó Oríṣun àwòrán, Getty Images Eniyan marun un miran tun ti gba iwosan lẹyin ti wọn gba itọju fun arun coronavirus.
Oríṣun àwòrán, @dino_melaye Àkọlé àwòrán, Òwúrọ̀ Ọjọ́rú ni Melaye padà sí ilé aṣòfin lẹ́yìn rògbòdìyàn tó wáyé láàrin òun àti àwọn ọlọ́pà Senato Dino ni, kò yá òun lẹnu pé àwọn tí Ààrẹ je oga fún kọ láti yọjú sí ilé ''Fèré ti olówó wọn n fọn sinu wọn, ni wọn n fọn sita.
Wọn ti ri pupọ ninu awọn eero baalu na yọ jade, ti ọpọ ninu wọn si ti di eero ile iwosan nitori bi wọn ṣe fi ara pa.
isiporopo waye ni irowo-rose ni ojo kokandinlogbon osu yii.
Juda dàbí kinniun, tí ó bá pa ohun tí ó ń dọdẹ tán,a sì tún yan pada sinu ihò rẹ̀.
Pásítọ̀ Adeboye ṣelérí àti fojú aṣebi hàn lórí ikú Omozuwa, Amnesty International pẹ̀lú kọminú Ènìyàn 307 ló lùgbàdì àrùn Coronavirus ní Ọjọ́ Aiku Mo parí iṣẹ́ àṣepatì 239, iṣẹ́ 236 míì ń lọ lọ́wọ́- Seyi Makinde Kàyééfì BBC News Yorùbá gbé òtítọ́ òògun owó yẹ̀wò Nǹkan oṣù obìnrin le jáde ní imú tàbí ìdodo yàtọ̀ sí ojú ara - Dókítà Ẹ̀dínwó epo bẹntíró tí NNPC kéde kò kan ará ìlú Ọ̀pọ̀ ọmọ Nàìjíríà ló ti gbàlù gbájó lẹ́yìn ti wọ́n gbọ́ ìkéde pé ilé iṣẹ́ to n rí si epo rọ̀ọ̀bì ni Nàìjíríà (NNPC) tí mú àdínkù bá owó epo rọ̀ọ̀bì.
Ni ọdun to koja, agbajọ awọn orilẹede alawọfunfun f'ẹnuko lati pese iranlọwọ fun ile-isẹ to n seto ibodeti ilu Libya, lati da ọkọ oju omi ti o gbe awọn aṣikiri ati awọn asasala lọ si orilẹede Italy.
Ọrọ kan to jade nigba ti Chelsea ba Arseal gba ninu Europa League ni wipe amule Chelsea nigba kan ri Petr Cech yoo pada wa gẹgẹ bii oludari pataki.
) Wo esi Tun fọnran wo Pín in lori opo ayelujara WhatApp Facebook Twitter Awọn ileeṣẹ panapana: Onkaa wọn: Iwọn ilẹ: Wo Naijiria lerefee Asiko ibi ti o jìnà jùlọ ni Naijiria Gabu Bekwarra eyi to jẹ 6 hours, 58 minutes, 32 seconds lati ibudo awon panapana ati 7 hours, 5 minutes, 3 seconds ni ọjọ ti súnkẹrẹ-fàkẹrẹ ọkọ ba mọ niwọ́n Abia Abia Adamawa Adamawa Akwa Ibom Akwa Ibom Anambra Anambra Bauchi Bauchi Bayelsa Bayelsa Benue Benue Borno Borno Cross River Cross River Delta Delta Ebonyi Ebonyi Edo Edo Ekiti Ekiti Enugu Enugu Abuja Abuja Gombe Gombe Imo Imo Jigawa Jigawa Kaduna Kaduna Kano Kano katsina Katsina Kebbi Kebbi Kogi Kogi Kwara Kwara Lagos Lagos Nasarawa Nasarawa Niger Niger Ogun Ogun Ondo Ondo Osun Osun Oyo Oyo Plateau Plateau Rivers Rivers Sokoto Sokoto Taraba Taraba Yobe Yobe Zamfara Zamfara Awọn ileeṣẹ panapana: Onkaa wọn: Iwọn ilẹ: Iye ileeṣẹ to wa 1 2 3 4 > 4 Awọn ileeṣẹ panapana kaakiri Naijiria Lagos 20 Kano 4 Osun 4 Oyo 4 Adamawa 3 Ogun 3 Katsina 2 Rivers 2 Anambra 2 Akwa Ibom 2 Jigawa 2 Niger 2 Abuja 2 Cross River 2 Kwara 2 Borno 2 Ekiti 2 Abia 2 Sokoto 1 Ondo 1 Taraba 1 Nasarawa 1 Yobe 1 Kogi 1 Kebbi 1 Zamfara 1 Bauchi 1 Imo 1 Gombe 1 Enugu 1 Edo 1 Ebonyi 1 Delta 1 Benue 1 Bayelsa 1 Plateau 1 Kaduna 1 Ṣafihan awọn ipinlẹ Awọn ileeṣẹ panapana kaakiri awọn ilu pataki lagbaye London 103 New york 254 Tokyo 81 Akọroyin BBC Yoruba to wa nibi isẹlẹ naa jabọ pe deede aago mẹwa aarọ, lasiko ti awọn eeyan kan ti wa nile ijọsin ni ọpa to n pin afẹfẹ gaasi sadede bu gbamu, ti ina si sọ.
Ìyá àkàndá ẹ̀dá: Àwọn ẹbí mi fẹ́ kí n pa ọmọ mi torí ó jẹ́ àkàndá ẹ̀dá
Bí wọ́n ṣe ń ka gbogbo àwọn ẹ̀sùn náà ni Ayo fayose ń dáhùn wí pé òun kò jẹ̀bi ẹ̀sùn kankan; Agbẹjọ́rò: Ẹsun pe Ọgbẹni Ayọ Fayoṣe ati Ọgbẹni Abiọdun Agbele ti ajọ naa sọ pe o ti na papa bora gba N1.
PDP vs Tinubu: Aṣíwájú Tinubu lọ́ra láti fi wá kọ́ èébú
Novak Djokovic fi ini didun re han leyin ti o jawe olubori ninu ifigagbaga pelu Damir Dzumhur lojoBo(Thursday), lati pegede sipele keta si asekagba idije boolu afowogba Paris Masters to n lo lowo.
Wọ́n tu ọkọ̀ lọ sí ilẹ̀ Ofiri, wọ́n sì kó wúrà tí ó tó okoolenirinwo (420) ìwọ̀n talẹnti bọ̀ wá fún Solomoni ọba.
Fasoranti: Ẹ̀mí àwọ̀n darandaran Fulani kò dè mọ́ ní Gúsù Nàìjíríà, kí wọ́n padà sókè ọya ní kíákíá
Nise ni àwọn ajijagbara ti ji ọpọlọpọ olukọ gbé, wọn lu wọn, wọn si tun pa àwọn kan.
Mo fẹ́ kí ẹ mọ̀ dájúdájú pé ẹni tí ó bá gbàgbọ́ ní ìyè ainipẹkun.
Illegal Rehab Centre: A le ni ogójì tí wọ́n n kó sinú ìyará kékeré kan níle Ọlọrẹ
Lọjọ kini, oṣu kẹrin ni sẹnetọ to n ṣoju ila oorun ipinlẹ Kogi, Dino Melaye ke gbajare loju opo Twitter nipa ete ti awọn kan n pa lati yọ adajọ agba ipinlẹ naa nipo.
A fẹ́ lo ẹ̀jẹ̀ àwọn èèyàn tó ye àrùn Coronavirus láti fi ṣe ìwòsàn fún àwọn tó wà lórí àárẹ- UK Àwọn èèrò ìwòran ní kóótù gbalé ẹjọ́ dọ́gbà ẹ̀wọ́n l'Ọṣun Ìgbẹ́jọ́ ti bẹ̀rẹ̀ lórí àwọn afurasí tó pa ọmọ Fasoranti, Funke Olakunrin Ilé ẹjọ́ ní kí ìmáámù 15 tó rú òfin ìṣéde ní Kano san owó ìtanràn Ọpọ obinrin maa n lo ẹṣọ ara lati fi ṣafikun ẹwa wọn, fun idanimọ bii ilẹkẹ ayaba, ọmọ Oba ati bẹẹ bẹẹ lọ.
Mò ń wò ó títí tí ìyẹ́ rẹ̀ fi fà tu.
di oju popo pa, ti won n sun taya, ti won si tun n korin eebu  kaakiri  ni Khartoum to je  olu-ilu Sudan.
Wo àwọn ohun tó yẹ kóo mọ̀ nípa ajọ àwọn gomina Naijiria
    Nígbà ti ọjọ́ lílọ pé gọngọ sọ ní ìlú wa, kí ìlẹ̀ to mọ ni gbogbo ènìyàn ti ń wọ́ jáde ti wọ́n sí ti dúró sí ààrinn ọjà dè wá.
Gomina ipinle Osun, ogbeni  Rauf Aregbesola ti ni bi awon omo egbe kan se n yapa kuro nin u egbe APC lo sinu egbe miiran ko le dena aseyori egbe yii lati tun maa jawe olubori inu eto idibo  gomina ti yoo waye ni  lojo kejilelogun osu kesan an  odun yii.
A máa da ète àwọn alárèékérekè rú,kí wọn má baà lè yọrí ètekéte wọn.
Bakan naa lo tun rọ awọn akẹẹgbẹ rẹ ninu iṣẹ tiata, lati maa pe awọn agba ọjẹ oṣere to ti darugbo si iṣẹ, eyi ti yoo mu ki ẹmi wọn gun, ti gbogbo aye yoo si tun mọ pe wọn wa laaye, ti wọn ko si ni jẹ ohun elo alopati.
Ìwọ̀n tí wọn ń lò ní ibi mímọ́ ni wọ́n fi wọ̀n wọ́n.
“Ṣugbọn àwọn alufaa ọmọ Lefi láti ìran Sadoku, tí wọn ń tọ́jú ibi mímọ́ mi nígbà tí àwọn ọmọ Israẹli ṣáko lọ kúrò lọ́dọ̀ mi, àwọn ni yóo máa lọ sí ibi pẹpẹ mi láti rúbọ sí mi.
Wo àwọn ìlérí tàwọn Gómìnà tuntun ṣe nínú ìbúra wọn Rochas Okorocha, káàbọ̀ sí àwùjọ àwọn gómìnà tí EFCC ń wá - Fayose Kàyééfì: Deji pa èèyàn mẹ́sàn án nítorí ìfẹ́ Ará ìlú dájọ́ oró fún ọkùnrin to bẹ́ orí ẹ̀gbọ́n rẹ̀ ní Cross River Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí kan sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Widows Day 2019: Mo máa ń sá kiri wá owó ilé ni -Opó Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Ẹ kó ara yín jọ, kí ẹ gbìmọ̀ pọ̀, ẹ̀yin orílẹ̀-èdè tí kò ní ìtìjú.
Ninu ilé ìṣúra ààfin ọba ni kí wọ́n ti mú owó kí wọ́n fi san owó iṣẹ́ náà.
Owo ti awọn aṣofin naa yoo gba gẹgẹ bii owo ikinikaabọ bọ si N9,926,062.
"Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Àwọn aránṣọ yarí pé gbogbo ẹ̀bi kìí ṣe tàwọn, díẹ̀ wà lọ́wọ́ àwọn oníìbárà náà ""Mo kan fẹ ran wọn lọwọ nipa ipalẹmọ ọdun Keresi ni'' Bi mo ti ṣe n wo wọn, mo ri pe wọn mọ iṣẹ yi ṣe ju mi lọ."
PDP: Ọjọ́rú la máa mọ̀ bóyá Jonathan ṣelòdì sí PDP ní ìdìbò Bayelsa
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ta ni Ọgágun àgbà Lamidi Adeosun tó ṣẹṣẹ gba ìgbéga?
OLUWA sì kó wa jáde, kí ó lè kó wa wá sí orí ilẹ̀ tí ó ti búra láti fi fún àwọn baba wa.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Aṣọ òkè: Alákọ̀wé ní ọ̀nà láti wá oúnjẹ fáwọn tó ń ṣe aṣọ òkè ló ṣún òun débẹ̀ Ọwọ sinkun awn ọlọpa yii ba awọn ole naa, ti wọn si ba ibọn ilewọ kan, ada ati ọpọ ẹrọ ibaraẹnisọrọ alagbeka lọwọ wọn.
ojogbon Yemi Osinbajo yoo lọ si orile Amerika, United States nibi ti yoo ti maa
 Awon apero yii ni lati wa ona irorun si awon ofin tuntun meta tile ise ijoba apapo pa lase.
”Minista ni ijoba FCT ti fi bilionu meje kale fun awon agbasese to n sise lori oko irinna oju irin ni Abuja kise le bere lori abala akoko ki o le see lo titi osu kinni odun 2018.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Mo máa n forin mi kìlọ̀ ìwà ìbàjẹ́ láwùjọ ni -Hameen Aarẹ Buhari ni ki ọjọgbọn Sambo maa ba iṣẹ lọ titi ti wọn yoo fi yan igbimọ miran fun ajọ adojutofo ilera NHIS.
Gomina ipinlẹ Oyo, Seyi Makinde, Kayode Fayemi ti Ekiti, Gomina Rotimi Akeredolu lati ipinlẹ Ondo, to fi mọ minisita fun ina mọnamọna, Babatunde Fashola, minisita fun ọrọ awọn ọdọ ati idagbasoke ere idaraya, Sunday Dare.
"Iṣẹ́ fẹ́ bọ́ lọ́wọ́ ọlọ́pàá tó gba N100k lọ́wọ́ awakọ̀ tó gba""One way"" l'Eko Wo ọ̀nà tí ọrọ̀ ajé Naijiria tó dẹnu kọlẹ̀ gba kàn ọ Jemila dáná sún ilé ọ̀rẹ́kùnrin rẹ̀ àti ọ̀rẹ́bìnrin tó bá nílé Ileeṣẹ apogun ni Amẹrika ni, Pfizer kede ṣaaju loṣu kọkanla pe iwadii latara abẹrẹ ajẹsara rẹ fihan pe o n ni eso to dara."
Wọn pe fun ifipo silẹ Fatoyinbo.
Aarẹ ọna kakanfo Yoruba marun to jẹ kẹyin
 gúsù ilẹ ̀ italy ni naples wà .
Ẹdawọ naa yẹ ko jẹ aṣoju awọn ikọ elegbejegbẹ ati awọn aṣoju ijọba,
Ẹni tí ó bá ń ṣọ́nà ṣe oríire, tí olúwarẹ̀ wọ aṣọ rẹ̀, kí ó má baà sí ní ìhòòhò, kí ojú má baà tì í níwájú àwọn eniyan.
O ni ẹ̀rí wà lorisirisi láti gbé ọ̀rọ̀ yìí lẹ́yìn pe irọ ni Dabiri-Erewa n pa.
O ya, ẹ jẹ ka wo bi ayẹyẹ ipejọpọ gbogbo awọn Arugba se lọ nilu Oṣogbo lasiko ọdun Ọṣun Ọṣogbo fun tọdun yii.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Ní báyìí iyed ènìyàn to ti lùgbàdì ààrùn cororvirus ni Nàìjíríà tí lé ni mẹ́tàlélọ́gọ́rin (83,576) nígbà ti àwọn to ti rí ìwòsàn gbà ti lẹ́ ni àádọ́rin (70,495).
Ẹ ranti OLUWA tí ó tóbi tí ó sì bani lẹ́rù, kí ẹ sì jà fún àwọn arakunrin yín, ati àwọn ọmọkunrin yín, àwọn ọmọbinrin yín, ati àwọn iyawo yín, ati àwọn ilé yín.
Gbogbo ẹni tí ó bá ń dẹ́ṣẹ̀ ń rú òfin, nítorí rírú òfin ni ẹ̀ṣẹ̀.
Nítori náà ó kó kuro lọdọ̀ àwọn mọlẹbi rẹ, nítori pe ó ni ìgbàgbọ pe èwu ńla ni ti òun ba si ń gbe pẹ̀lú wọn nítori wọn lẹ lọ ọmu ọmọ oun láì gba aṣẹ.
Òróró ìkunra rẹ dára ju turari-kí-turari lọ.
Ṣé àwọn ọmọ rẹ lè sọ Yorùbá tó àwọn ọmọ Amẹrika yìí?
Wọn a máa fi ata sí oúnjẹ dáadáa bíi tiwa.
Ẹ̀rù OLUWA ati ti Samuẹli sì ba gbogbo àwọn eniyan náà.
O ni oun wa lara awọn ti inu n bi, ti ẹgbẹ APC ti sẹ, ti wọn si gbọdọ tu ninu pẹlu aafikun pe, ti igbimọ fidihẹ naa ko ba dẹkun ojuse aitọ to n se, oun yoo gbe wọn lọ sile ẹjọ.
8 6833 Orilẹede Somalia 121 0.
Gomina ipinlẹ Ondo, Rotimi Akeredolu lo fọrọ yii lede lati ẹnu oludamọran rẹ lori ọrọ aabo, Alhaji Jimoh Dojumo.
O ni awọn aṣojuṣofin la nilo lati ṣe agbẹkalẹ awọn ofin to yẹ ni Naijiria kii ṣe awon sẹnetọ rara.
Jakọbu gbé ọ̀wọ̀n kan nàró lórí ibojì rẹ̀, òun ni wọ́n ń pè ní ọ̀wọ̀n ibojì Rakẹli, ó sì wà níbẹ̀ títí di òní.
Ṣugbọn bí ẹ kò bá lé gbogbo àwọn ará ilẹ̀ náà kúrò, àwọn tí ó bá kù yóo di ẹ̀gún ní ojú yín ati ẹ̀gún ní ìhà yín, wọn yóo sì máa yọ yín lẹ́nu lórí ilẹ̀ náà.
Ní ọjọ́ náà, a óo gbé ẹrù tí ó dì lé ọ lórí kúrò, a óo sì fa àjàgà rẹ̀ dá kúrò lọ́rùn rẹ.
Eyi jẹyọ ninu esi ti ajọ NCDC fi sita ni alẹ ọjọ Aiku.
Dẹ etí sí mi, yára gbà mí.
Bákan náà ni àwọn yàrá ẹ̀gbẹ́ rẹ̀, àtẹ́rígbà rẹ̀ ati ìloro rẹ̀ rí pẹlu àwọn yòókù, ó sì ní fèrèsé yíká.
Oluwateru:Oju bọrọ kò ṣé gbọmọ lọ́wọ́ ekurọ South Afrika lori Xenophobia Airiṣẹṣe, ìṣẹ́ ati òṣì naa wa ninu nkan to n ṣokunfa ikọlu sawọn ajeji gẹgẹ bi Sharon Ekamaram to n ṣamojuto ọrọ awọn aṣatipo se sọ.
Láti ayébáyé ni mo ti ṣètò rẹ̀,pé kí o wó ìlú olódi palẹ̀,kí ó di òkítì àlàpà.
Ọ̀ràn náà le gidigidi, bí kò sí àánú Ẹlẹ́dàá mi ni, igi ìbá ti dá pa mí - Ọlọ́rùn tóbi lọ́ba.
Kanran salaye lasiko eto naa pe rẹrẹ ti rún bi ile oun ṣe kọkọ jona lati oke delẹ pẹlu gbogbo dukia ti òun ti fi ọpọ ọdun ṣíṣẹ fun , kò tá síbẹ , o ni ti iyawo ati awọn ọmọ si sa fun oun pẹlú.
Ẹ dáríjìn mí, gbogbo ẹ̀yin tí mo ti ṣẹ̀, Ayo Fayose tọrọ àforíjìn Má ṣe fi ọkọ̀ rẹ gbé àgùnbánirọ̀ lẹ́yìn aago mẹ́fà ìrọ̀lẹ́- FRSC Lẹyin to lo ọpọlọpọ ọsẹ ni ọdọ awọn ajọ EFCC ni ile ẹjọ gba oniduro rẹ.
Nínú àwọn fọ́nrán àti fọ́tò tó jẹyọ lojú òpó twitter rẹ̀, Mr Macaroni ni, ìròyìn tó tẹ òun lọ́wọ́ ni pé, àwọn ọlọ́pàá tún pa ẹnìkan ni ìpińlẹ̀ Delta níbí ti wọ́n ti ń ṣe ìwọ́de ENDSARS.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Adajọ yì ìgbẹ́jọ rẹ̀ padà lóri àtúndi ìbò Adamawa 26 Ẹrẹ̀nà 2019 Àkọlé àwòrán, Gbágbáàgbá ni àwọn òṣìṣẹ́ ètò àábò dúró ní ibi tí wan ti n pín òhun èlò ìdìbà nàá Ajọ eléto ìdìbò INEC ti pari ètò láti ṣe àtúndi ìbò gómìnà ní ìpínlẹ̀ Adamawa lọ́jọ́bọ ti ṣe ọjọkejidínlógbọn osùn yìí.
Solomoni sì tún ní ọ̀kẹ́ mẹrin (80,000) ọkunrin tí ń fọ́ òkúta ní agbègbè olókè; ati ọ̀kẹ́ mẹta ó lé ẹgbaarun (70,000) ọkunrin tí ń ru òkúta tí wọ́n bá fọ́.
2 1318295 Orilẹede Spain 53079 113.
Bí wọn ti sun turari níbi òkú àwọn baba rẹ, ati níbi òkú àwọn ọba tí wọ́n ti kú ṣáájú rẹ, bẹ́ẹ̀ ni wọn yóo sun turari níbi òkú ìwọ náà.
Ẹgbẹ́ Urban Study ti ṣe àgbékalẹ̀ ìwọ́de àti àkójọ àwọn ènìyàn tí yóò fi ẹ̀hónú àdàwólulẹ̀ wọ̀nyí hàn.
O ni ijọba yoo sa ipa gbogbo to yẹ lati mu itura ba araalu nitori, gẹgẹ bi ọrọ rẹ, ko si aniani lori pe ọwọja arun naa yoo ṣe ọpọ akoba fun ọrọ aje awọn eeyan.
Gomina ipinlẹ Katsina to tẹwọgba awọn ọmọ naa, Aminu Bello Masari, ki awọn ọmọ naa ku ajabọ, to si ṣapejuwe nkan to ṣẹlẹ si wọn gẹgẹ bi sababi.
N óo rán angẹli mi ṣáájú yín, n óo sì lé àwọn ará Kenaani ati àwọn ará Hamori, àwọn ará Hiti, ati àwọn ará Perisi, àwọn ará Hifi ati àwọn ará Jebusi jáde.
Gẹgẹ bi o ṣe sọ, awọn eroja ado oloro pẹlu awọn ibọn atamatase AK47 ni wọn fi fọ ẹnu ọna banki naa wọle.
Lọ́jọ́ ajé, ọ̀gá àwọn ọ̀mọ̀ ogun Nàìjíríà sèbẹ̀wò síbẹ̀ láti fi kún ìgbésẹ̀ àbò.
Mo wo ọjọ́ iwájú rẹ,mo sì rí ẹ̀yìn ọ̀la rẹ.
Eni to gba ami eye ohun  keyin ni Justin Trudeau ti o je adari ijoba orile ede Canada.
Ọga agba awọn oṣiṣẹ aṣọbode Badri Daher sọ pe awọn ti ke gbajare ki wọn wa gbe kẹmika to bu gbamu naa kuro laimọye igba ''ṣugbọn wọn ko wa'' O ni awọn yoo ma reti ababọ awọn onimọ nipa ohun to ṣẹlẹ gaan.
Kìí ṣe ebi, ìyà tàbí ìṣẹ́ ló mú kí wọ́n yabo àwọn ilé ìkẹ́rùsí - Femi Adeshina Ìpínlẹ̀ Ogun náà ti ilé ìwé títí dí ọjọ́ Ajé tó m bọ̀, kò ní sí lílọ bíbọ̀ ọ̀kádà fún wákàtí 24 Ẹ wo ojú àwọn jàndùkú tí ọwọ́ ọlọ́pàá tẹ nígbà tí wọ́n lọ kó ọjà ọlọ́jà ní Shoprite Ilorin Wo ìgbésẹ̀ mẹ́ta tí Gómìnà Obiano gbé lórí ọ̀rọ̀ SARS ní Anambra Awọn ileeṣẹ iroyin abẹle kan n sọ pe ọmọdekunrin naa wa lara awọn janduku to kọlu agọ ọlọpaa Ọba market, lẹyin ikọlu naa si ni o gbe aṣọ iṣẹ sajenti naa wọ to si n.
" Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Gbogbo ayé ń dúró dé ìkéde INEC lórí ìdìbò Ọṣun Ilé ẹjọ́ yọ ìbò 2,029 nínú ìbò APC, 1,246 nínú ibò PDP l'Ọṣun APC, PDP di ẹgbẹ́ aládúrà nítorí ìdájọ́ èsì ìdìbò Ọṣun Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí kan sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
Àkọlé àwòrán, Oro wa ko kuku dọgba ni adura ọpọ ero Ohun to kọ iwaju si ẹnikan, ẹyin lo kọ si ẹlomii, awọn miran ni Seyi Makinde lo kọkọ gbe iru igbesẹ bayii ninu itan ipinlẹ Oyo pe: Awon kan tun ni o ti ṣe ju ohun ti awọn to n gbogunti iwa ibajẹ miran ko ṣe paapaa.
Opọ awọn akọṣẹmọṣẹ oniṣegun lo sa kuro ni Naijiria lọ si UK, Canada àti Saudi.
Ile-ẹjọ giga naa sọ pe oun gbẹsẹle asẹ ijọba naa fun ọjọ mẹrinla ti igbẹjọ yoo fi waye lori ẹjọ naa.
omo egbe  ati alatileyin wa ati awon
Fún wa ní irúgbìn, kí á lè wà láàyè, kí ilẹ̀ yìí má baà di ahoro.
Bẹẹ ba gbagbe, ọpọ ẹnu lo ti n kun oju opo Facebook latẹyinwa pe o nkopa ninu itankalẹ awọn ayederu iroyin ati ọrọ ikorira lawọn oju opo rẹ.
ki lo n jẹ bẹẹ, mi o ni gba, Igba yii gan la ṣẹṣẹ maa jade, bo ba wu wọn ki wọn pa wa."
Ẹ kọ́ àwọn ọmọ yín obinrin ní ẹkún sísun,kí ẹ sì kọ́ aládùúgbò yín ní orin arò.
O ti mú kí ilẹ̀ mì tìtì;o ti mú kí ó yanu;dí gbogbo ibi tí ilẹ̀ ti ya, nítorí pé ó ń mì.
Àwọn kan láti inú ẹ̀yà Juda ati ti ẹ̀yà Bẹnjamini wá sọ́dọ̀ Dafidi níbi ààbò.
Nígbà tí Ahabu lọ jẹun, Elija gun orí òkè Kamẹli lọ, ó wólẹ̀, ó dojúbolẹ̀, ó sì ki orí bọ ààrin orúnkún rẹ̀ mejeeji.
Ǹ jẹ́ bí bàbá ṣe gbé ẹran nílẹ̀ tó gbé e lérí ní àwọn àwòdì méjì fò bàràbàrà tí wọ́n ya lu inú ọpọ́n ẹran bàbá.
Ko si ẹnikẹni to ri oku ẹbi wọn gba bayii lẹyin ti mwọn sọ fun wọn o kere tan o maa to oṣu mẹfa ki onikaluku to le da oku ẹbi wọn mọ.
Ní ọjọ́ tí a óo bá mọ odi ìlú yín, ẹ̀yin ará Jerusalẹmu, ọjọ́ náà ni a óo sún ààlà yín siwaju.
Ijoba orile ede Niajiria ti ya
Àwọn Àwo tí Ó Kún fún Ibinu Ọlọrun.
 Òun ni obìnrin àkọ ́ kọ ́ tí wọn yóò dìbò yàn gẹ ́ gẹ ́ bí olórí ìjọba ( president ) ní ilẹ ̀ argentina .
Agbébọn jí Alága Káńsù tẹ́lẹ̀ gbé l‘Ondo Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Àwọn oṣiṣẹ feyinti ni Osun ṣé iwọde Ọpọ awọn olugbe ilu Maiduguri ni wọn ni lati fi ẹsẹ rin lọ si ibi iṣẹ wọn.
Nítorí o ti ṣe ohun tí kò tọ́, kò sì buyì kún ọ lọ́dọ̀ OLUWA Ọlọrun rẹ.
Gbogbo igbiyanju wọn lati doola ẹmi rẹ nile iwosan lo pada ja si pabo.
“Igbesẹ naa yoo nilo ifọwọsowọpọ gbogbo
Oríṣun àwòrán, @HonZakari Àkọlé àwòrán, Zakari Mohammed naa ti fi iwe ferongba sowo si oul ile ẹgbẹ PDP labuja Bi a ko ba gbagbe, olori ile asofin ipinlẹ Kwara Ali Ahmad naa ti saaju kede erongba rẹ lati du ipo Gomina ipinlẹ Kwara labẹ asia PDP.
" Bakan naa lo ni ọkọ meji mii naa fi awakọ toun se awokọse, tawọn naa si fi ere sẹri pada wa si aarin ilu loju ibọn, lẹyin isẹju mẹwa ti ọkọ tiwa ti moribọ.
Orisun: World Happiness Report 2018 Awọn orilẹede apa iwọ oorun ilẹ Afrika kan ko fi bẹ ẹ ṣe daada ninu igbelewọn naa.
aare Buhari kii se iyalenu rara  fun awon
Nínú àbá ìṣúná 2020, ìjọba Ọyọ fẹ́ gba 500 òṣìṣẹ́ ìlera pẹ̀lú ọ̀pọ̀ olùkọ́ Ẹyin naa ẹ gbiyanju rẹ wo!
 Ọmọ yorùbá ni Ọmọ-ọba abẹ ́ òkúta ni .
Lọna ati gbe eto iṣejsba ro, a ni lati ṣe ohun gbogbo to tọ.
Nitori eyi si ni aarẹ Naijiria ṣe paṣẹ pe ki wọn o din iye ti wọn n ta jaala epo ku.
Ijọba ti kọ kede pe wọn yoo san owo ajẹmọnu awọn oṣiṣẹ fẹhinti naa ninu ọdun yii, amọ ti wọn ko ti i ri i gba titi di asiko yii.
Ọmọ a mú gbìrín eó b’ọ̀dìdẹ̀
Wọ́n fi igi akasia ṣe àwọn ọ̀pá ìdábùú mẹẹdogun, marun-un fún àwọn àkànpọ̀ igi tí wọ́n wà ní ẹ̀gbẹ́ gúsù, 
Spaghetti, mílíìkì, Chivita àti Àǹkàrá sọ Rabiu dèrò ẹ̀wọn ni Eko Ṣé Van Dijk lè borí Ronaldo àti Messi nínú ìdíje UEFA?
Agbẹnusọ fun Aarẹ Buhari, Garba Shehu lo fi lede ni oju opo ikansiraẹni Twitter wọn.
 agbègbè náà tóbi tó 71 km ² , tí àwọn ènìyàn inú rẹ ̀ sí jẹ ́ 106,586 nígbà ìkànìyàn ọdún 2006 .
Jonatani pe Dafidi ó sì sọ gbogbo ọ̀rọ̀ náà fún un.
ati gbogbo ìlú Sihoni ọba àwọn ará Amori, tí ó jọba ní Heṣiboni, títí kan ààlà àwọn ará Amoni; 
fun igba keji jẹ igbekele ti awon omo orile ede Naijiria ni ,ninu ijoba aare Buhari,
Lara awon asofin egbe alatako ,PDP ti o fenuko lati yan Ahmad lawan gege bi abeniugan ni  Ekweremadu,  adari igbimo asofin to kere ju teleri, Emmanuel Bwacha,lati ila Gusu Taraba ; Theodore Orji, lati  aarin gbungbun Abia ; Chukwuka Utazi, lati Enugu ; Enyinnaya Abaribe, lati Gusu Abia ;  Dino Melaye,lati  Kogi; James Manager, lati ila Gusu Delta ; Peter Nwaoboshi,  lati ila oorun Delta ; Gershom Bassey,lati ila Gusu  Cross River ati Uche Ekwunife,lati aarin gbungbun Anambra ati awon asofin miiranLara awon omo
Alhaji Pasuma ṣalaye pe idi ti oun ko tii fi ni iyawo lọwọ yii naa ni pe oun fẹ ṣe ohun gbogbo bi o ti yẹ ko le baa ri bose yẹ ko ri.
Tí o wa nǹkan ọ̀ṣọ́ wúrà sára?
Lara awọn iṣẹlẹ to mi ilu titi to waye ni ọṣẹ yii naa ni bi minisita fun ọrọ ịṣẹ ati ibugbe, Fashola ṣe ṣọ wi pe ohun ri fidio bi iṣẹlẹ ipaniyan to waye ni Lekki toll gate ṣe ṣẹlẹ.
#U20WC: Flying Eagles fìyà ṣínu ààwẹ̀ lórílẹ́èdè Poland Fasiti Ahmadu Bello ti Zaria ni o ti kẹkọọ gboye onipele ikinni ati ikeji.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Harry and Meghan: Olóòtú Canada ní ọ̀rọ̀ gbọ́dọ̀ wáyé nípa ìgbésẹ̀ wọ̀n 13 Sẹ́rẹ́ 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 14 Sẹ́rẹ́ 2020 Oríṣun àwòrán, PA Media Àkọlé àwòrán, Ọbabinrin Elizabeth ti Ilẹ Gẹẹsi ní òun faramọ́ èròńgbà Harry ati Meghan láti fi ipò ọba sílẹ̀.
Ẹ ̀ kẹ ́ ta gbògíì nínú ohun tí ó ṣe okùnfà irú ìgbé ayé tí luiz gama gbé ni títà tí bàbá rẹ ̀ tàá sí oko ẹrú .
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù End SARS Protest: Babangida ní ejò lọ́wọ́ nínú lórí ìsẹ̀lẹ̀ rògbòdìyàn tó ń wáyé káàkiri Nàìjíríà 17 Ọ̀wàrà 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 22 Ọ̀wàrà 2020 Adari orilẹede Naijiria labẹ ijọba ologun nigba kan ri, Ọgagun Ibrahim Babangida ti ni ko si rogbodiyan kankan to le bẹ silẹ ju wakati mẹrinlelogun lo ti ko si ọwọ ijọba nibẹ.
Kí ẹ̀yà Sebuluni pàgọ́ tẹ̀lé ẹ̀yà Isakari.
Nígbà tí àwọn baba ńlá wa wà ní Ijipti,wọn kò náání iṣẹ́ ìyanu rẹ,wọn kò sì ranti bí ìfẹ́ rẹ tí kì í yẹ̀ ti pọ̀ tó.
Mo ti fọ̀ ọ́ mọ́,ṣugbọn kì í ṣe bí a tií fọ fadaka,mo dán yín wò ninu iná ìpọ́njú.
O bomi rin poro oko rẹ̀ lọpọlọpọ,o ṣètò àwọn ẹsẹ̀ rẹ̀;o rọ òjò tó mú kí ilẹ̀ rọ̀,o sì mú kí ohun ọ̀gbìn rẹ̀ dàgbà.
Àjogúnbá Ìṣẹ̀lẹ̀ Àtẹ̀yìnwá ọ̀rọ̀ tí ò jẹ́ mọ́ nǹkan
Àwọn orílẹ̀-èdè wọnyi yóo sì sin ọba Babiloni fún aadọrin ọdún.
Ṣugbọn wọ́n pa á, wọ́n sì tú gbogbo àwọn tí ó ń tẹ̀lé e ká.
Oríṣun àwòrán, NDLEA/Twitter Àkọlé àwòrán, Garba ní àjọ ọ̀tẹlẹ̀mú tí àwọn jọ ń ṣiṣẹ́ pọ̀ ló ta àjọ òhun lólobó nípà òògùn Tramadol tó fẹ́ wọlé Ó sàlàyé pé, àjọ NDLEA ti gbésẹ̀lé kílò òògùn olóró mẹ́tàdínláàdọ́rún-ún láàárín oṣù kínní ọdún sí oṣù kẹrin ọdún yìí.
Khafi wọ gàu lẹ́nu iṣẹ́ lórí ẹ̀sùn ìbálòpọ̀ ní BB Naija Seyi Awolowo, ọmọ-ọmọ Awolowo, kí ló ń wà lórí ètò BB Naija?
Lẹ́yìn náà, ó kó àwọn eniyan rẹ̀ jáde bí agbo ẹranó sì dà wọ́n láàrin aṣálẹ̀ bí agbo aguntan.
Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Yoruba film: Irú ẹ̀ṣẹ̀ wo ni gbajugbaja òṣèré, Nkechi Blessing ṣẹ Toyin Abraham tó fi ní kó jèbùrẹ́?
Ọba dá a lóhùn pé, “Máa pada lọ sí ilé rẹ, n óo mójú tó ọ̀rọ̀ náà.
Àwọn ọmọ Ladani jẹ́ mẹta: Jeieli tí ó jẹ́ olórí, Setamu ati Joẹli.
A pinnu láti fojú rira, ìrísí Toyin lọ́jọ́ taa kọkọ rira dàbí tí gbajumọ osere ti ko sí lójú ọpọn mọ, ẹni tí ipenija ayé àti ibalorukọjẹ lorisirisi tí sọ di idakuda, kódà, kò jọ gbajumọ osere rárá.
Bẹẹ gan an lọrọ ri fun ẹgbẹ agbabọọlu Aston Villa to kọ lẹta si iya lọwọ Chelsea.
Lẹyin naa lo gba ajọ WAEC atawọn ijọba ipinlẹ ni imọran lati ma ṣi awọn ile iwe lasiko yii nitori o lewu lati ṣe bẹẹ.
Oríṣun àwòrán, LASG Ninu ọrọ ti ẹ, Alagba Fatomilola sọ pe, ọba ti ko ba ri ọ̀pá àṣẹ dabi pe ọba naa ti sọ ipo rẹ nu ni, ọgbẹni lasan si ni.
bakan naa ni wọn ti ba a wi fun awọn aṣemaṣe mii.
Bakan naa ni ọrọ ṣe ri ni agbegbe Alausa nilu Eko.
Kọmisọnna naa ni awọn ti gbe igbesẹ lati ri wi pe eleyii wa si imuṣẹ.
Gẹgẹ bi alukoro ileeṣẹ ọlọpaa nipinlẹ Ogun, Abimbola Oyeyem, ṣe sọ fun BBC, awọn alaṣẹ TRACE sọ pe awọn deede ri ọkunrin naa to joko sinu ọgba ajọ naa ni.
Amọ ileeṣẹ aarẹ ṣalaye pe dida ti wọn da awọn oluranlọwọ Osinbajo duro nii ṣe pẹlu igbiyanju ijọba apapọ lati din owo ti ijọba n na fun iṣejọba ku.
Ninu ilẹ̀ ẹ̀yà Reubẹni, wọ́n fún wọn ní: Beseri, Jahasi, 
m ni ojú mi déédé fọ́ níbi tí mo ti ń darí ọkọ̀ ni Ọrẹgun Ikẹja -LASTMA Yesufa Wòlíì Kasali ní Dolapo Awosika kò lé ìyàwó òun jáde Wòlíì míì, tún wọ gàù lẹ́yìn tó tàpá sí ìlànà béèlì tí wọ́n fún un nílé ẹjọ́ Iyawo lo maa n fi ilẹkẹ da ara to ba wu lati fi se baagi, bata, apamọwọ, apẹ fulawa ati bẹẹ bẹẹ lọ, ti ọkọ rẹ yo si kiri awọn ọja naa lọ sawọn ọọfisi ati sọọbu.
OLUWA àwọn ọmọ ogun bá Jeremaya wolii sọ nípa Elamu ní ìbẹ̀rẹ̀ ìjọba Sedekaya, ọba Juda.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Akẹ́kọ̀bìnrin Chibok kan tó ráàyè sálọ kàwé gboyè l'Amẹrika 18 Èbibi 2019 Oríṣun àwòrán, PIUS UTOMI EKPEI Ọkan lara awọn akẹkọbinrin Chibok to bẹ silẹ ninu ọkọ lati jajabọ lọwọ ikọ agbasunmọmi Boko Haram ti kẹkọ jade ni ileewe kan l'Amẹrika.
Ṣugbọn Jehoaṣi ọba ranṣẹ pada pẹlu òwe yìí: Ó ní, “Ní ìgbà kan ìtàkùn ẹlẹ́gùn-ún kan tí ó wà ní Lẹbanoni ranṣẹ sí igi kedari ní Lẹbanoni pé, ‘Fi ọmọbinrin rẹ fún ọmọkunrin mi ní aya.
Àwọn iyawo rẹ ṣe oríire; bẹ́ẹ̀ náà sì ni àwọn iranṣẹ rẹ wọnyi tí wọn ń wà lọ́dọ̀ rẹ nígbà gbogbo, tí wọn ń gbọ́ ọ̀rọ̀ ọgbọ́n rẹ!
Ìbá ṣe pọ̀ laarin Yorùbá àti Ìlú-Ọba ti lé ni igba ọdún nitori òwò Òkè-òkun, pàtàki òwò ẹrú àti fún ẹ̀kọ́ ni ilé iwé giga.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ọgbà ẹ̀wọ̀n ni wọ́n ti já àbálé Esra lábẹ́ àwáwí àyẹ̀wò wúndíá Ileeṣẹ ọlọpaa ni ipinlẹ Ọyọ, la gbọ pe o ti fi idi iṣẹẹ idigun jale naa mulẹ ti wọn si ni iwadii ti bẹrẹ.
Odò Orisun Rẹ ni mí, máṣe jẹ́ n gbẹ
Dájúdájú ìwọ dáràn lónìí, ìwo gun igi kọja ewé, ìwọ já láti òkè bọ́ sínu kànga, ìwọ jẹ májèlé àìròtẹ́lẹ̀, ìwọ rí oko tí ó kún ìwọ gbin ẹ̀pà sí i.
women’s world XI) – Sari Van Veenendaal; Lucy Bronze, Nilla Fischer, Kelley
Tori naa, awọn ile iṣẹ to n ja fun ẹtọ ọmọniyan ti ni akọsilẹ gbogbo eyi loṣu keji ọdun 2018 ti wọn si n gbe igbesẹ pẹlu ifọwọsowọpọ ijọba orilẹede Venezuela.
À kò gba owó kankan lọ́wọ́ àwọn ẹgbẹ́ agbésùmọ̀mí ISWAP- MURIC Olóyè Gani Adams ni ìlanilọ́yẹ ni àkọ́kọ báyìí láti ṣe fún àwọn ènìyàn àti àwọn lọ́balọ́ba láwọn agbègbè náà.
Ohun to bani ninu jẹ pupọ ni pe awọn akẹkọọ pupọ bayii padanu ẹmi wọn, ṣugbọn sibẹ a dupẹ lọwọ Ọlọrun, a si ki ijọba ipinlẹ Eko atawọn alaṣẹ ileewosan Lagos Island General Hospital ku iṣẹ, lori iṣẹlẹ naa."
Kekere ni wọn ti fa Zarka le ọkọ rẹ lọwọ ni paṣiparọ ọkan lara awọn aburo ọkọ rẹ to jẹ obinrin, ṣugbọn lẹyin to de ile ọkọ naa tan lo to ri pe ilu bara ni ọkọ naa maa n na awọn obinrin.
Gbogbo àwọn eniyan ń gbadura lóde ní àkókò tí ó ń sun turari.
OLUWA Ṣe Ìlérí láti Gba Àwọn Eniyan Rẹ̀ Là.
Nibi ibi iwe kika kan to waye nilu Ibadan ni aṣoju ajọ to n ri si iwọle wọde lorilẹede Naijiria ti fi ọrọ lede.
"O ni ""Gẹgẹ bi gbogbo yin ṣe mọ, emi naa jẹ ọkan lara awọn eeyan to ni arun Covid-19, ti mi o si ṣafihan apẹrẹ arun naa."
kia lawa na bẹrẹ iwaadi ti a si pada wa ri i wi pe kii ṣe Dino Melaye gangan lo fi ikede yi sita.
Ìyàwó náà fi ojú rẹ̀ rí nǹkan: kò gbọ́ràn kò bìkítà, a máa ro ẹjọ́ lójoojúmọ́, ìgbà tí ó bá wù ú ní ó ń jáde nínú ilé ìgbà tí ó bà sì wù ú ni ó ń padà bọ̀ bẹ́ẹ̀ ni òun ni ẹni tí ń pa àṣẹ fún ọkọ.
Agbenuso naa tun salaye pe, ere isuna owo odun 2018 ohun ti safihan pe, ile-ise ti o n pawo sapo ijoba ipinle naa bi won se fako yo ninu ojuse won.
Àpẹẹrẹ àwọn ilà tí a ń kọ rèé
Iseju kẹrin ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ náà ni Chelsea ti jẹ pẹlu bi Eden Hazard ṣe gbà bóòlù sí Fabregas to si fi ẹsẹ òsì gbà wò inú ilé Swansea.
Igbakeji aarẹ ile aṣofin naa, Sẹnetọ Ovie Omo-Agege sọ pe, oun gbagbọ pe iwadii ti ileeṣẹ BBC ṣe yoo ṣe atilẹyin fun aba ọhun.
"O ni ""Oyetola, o ti ja awọn eeyan ipinlẹ Osun ti o n ṣejọba le lori kulẹ lẹyin ti awọn janduku kọlu awọn to n ṣe iwọde."
Gẹgẹ bi iwe iroyin Daily Trust ṣe jabọ, ọjọ Ẹti ni iṣẹlẹ naa waye.
Wọ́n ń sọ̀rọ̀ burúkú sí wa, ṣugbọn àwa ń sọ̀rọ̀ ìwúrí.
Ọpọ lo ti bu ẹnu ẹtẹ lu Chelsea lẹyin ti Man U ka ayo mẹrin ọtọọtọ lewọn lọwọ ti wọn ko si le da ọkankan pada.
Ohun tí ó bẹ̀rẹ̀ lórí àgọ́ àjọ, ati àpótí ẹ̀rí ati ìtẹ́ àánú tí ó wà lórí rẹ̀, ati gbogbo àwọn ohun èlò àgọ́, 
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Blind DJ: Etu Omotayo kò ríran àmọ́ ó le to irinṣẹ́ eléré pọ̀ láti kọrin láì sí ìrànwọ́ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Blind DJ: Etu Omotayo kò ríran àmọ́ ó le to irinṣẹ́ eléré pọ̀ láti kọrin láì sí ìrànwọ́ 17 Ògún 2020 Yoruba ni ba o ku, ise ko tan, ẹni to ba si ti ku laye, nikan ni tiẹ ti tan, nitori ireti si wa fun igi ti a bẹ lori.
Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Lateef Adedimeji: Adebimpe Oyebade kọ́ ni àfẹ́sọ́nà mi, ọ̀rẹ́ lásán la jẹ́15 Sẹ́rẹ́ 2021 Nollywood: Gbajugbaja òṣèré ''Toromagbe'' nínú fíìmù ''Arelu'' ti jáde láyé30 Bélú 2020 Nigeria Oscars commitee : Ìdí tí sinimá Genevieve kò fi mókè ní Oscar Award5 Bélú 2019 Yollywood: Ǹjẹ́ ìwọ mọ àwọn ẹbí òṣèré sinimá Yorùbá yii?
Àwọn Juu Pa Àwọn Ọ̀tá Wọn Run.
Ó ní ìṣẹ̀lẹ̀ tí ọkùnrin kan pa ẹ̀gbọ́n-ọn rẹ̀ ọkùnrin ní ìta gbangba ní ojúu títì pẹ̀lú ọbẹ̀ ìwọ̀n ínṣì mẹ́sàn-án tí ó wọ inú ẹ̀dọ̀ fóró ẹ̀gbọ́n-ọn rẹ̀ lọ.
LASTMA: Ẹ̀sùn àgbèrè la gbọ́ pé ó fá ìjà, tó já sí ikú náà
Oríṣun àwòrán, Babajide Sanwo-olu Dokita Alfa Saidu ti ọpọ n foju wo gẹgẹ bi eekan ati ogo iṣẹ iṣegun oyinbo kaakiri agbaye jade laye ni opin oṣu kẹta nipasẹ ikọlu arun COVID-19 lẹyin to ti fi ogoji ọdun ṣe iṣẹ iṣegun.
Wọn fi ẹsun pe o ṣekupa arabinrin Funmilayọ Ọladeji kan an.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, COZA: Ọpọ èrò ló jáde ṣe lòdì sí ẹ̀sùn ìfipábánilòpọ̀ Fatoyinbo Adajọ Ojukwu ni ko si ohun to kan Pinnick ati awọn mẹrin naa ni Egypt nitori awọn kọ ni agbabọọlu ti yoo pa itu nibẹ awọn si kọ ni awọn oṣiṣẹ ikọ naa ti yoo kọ wọn ni are bọọlu gbigba.
O fikun pe alaafia orilẹ-ede yii lo jẹ oun logun, eyi ti oun n tiraka fun ni gbogbo igba, bẹẹ si ni wolii Ọlọrun alaaye ni oun bi o tilẹ pe awọn woli eke wa, to fara jọ woli Ọlọrun.
naa ni iye agọ idibo to wa ni ipinle naa jẹ mẹ́rìndínláàdọ́rùn ún (86) bo tilẹ jẹ pe won fagile awon ibo kan ni awon apa
 líló kòkòrò tí a gbà pé ó ń ṣe ìwòsàn lè ṣe ìrànlọ ́ wọ ́ .
Simoni ará Kenaani ati Judasi Iskariotu, ẹni tí ó fi Jesu fún àwọn ọ̀tá rẹ̀.
Ẹ mú kọ́kọ́rọ́ ìmọ̀ lọ́wọ́, ẹ̀yin fúnra yín kò wọlé.
Wọ́n dè é, wọ́n bá fà á lọ láti fi lé Pilatu, gomina, lọ́wọ́.
Gbajumọ oṣere tiata lobinrin, Sola Kosoko Abina ti sọ fun araye pe, baba oun, Jide Kosoko, ti oun naa jẹ agba ọjẹ osere tiata, lo ṣe agbatẹru bi oun ṣe de idi isẹ naa.
 Ṣùgbọ ́ n ohun ti wọ ́ n sabàá máa ń lò ni ( i ) yíyí padà kúrò ni ọ ̀ rọ ̀ ìse tàbí kí wọ ́ n lo aux àsèrànwọ ́ ìṣe ( 2 ) use of special words ( particles ) ( 3 ) use of cleft-types constructions fún àpẹẹrẹ nínú èdè ejaghan .
Nígbà tí Seti di ẹni ọdún marundinlaadọfa (105), ó bí Enọṣi.
Awọn eniyan jankan-jankan miran to jade laye lọdun 2020 ni ọgagun Emmanuel Nworah, Paul Efemini Poli (aka Decure), Sẹnatọ Saidu Umar ati Minisita tẹlẹri, Kumo Tonye Graham-Douglas.
"Funrarẹ naa lo fi n fọwọ sọya ara rẹ pe ""olootọ eeyan ni Adekunle Adeleye jẹ to jẹ pe to ba sọ bẹẹ, o maa n ri bẹẹ""."
Gẹgẹ bi ọrọ ti Aarẹ Muhammadu Buhari sọ, ara ilu mọkanlelaadọta, ọlọpaa mọkanla ati ọmọ ologun meje ni ẹmi wọn sọnu nitori ifẹhonuhan naa.
OLUWA, àwọn ọ̀tá mi pọ̀ pupọ!
Igba akọkọ kọ niyii ti ẹnu ti kun Olamide Baddo lori awọn orin rẹ.
"Èdè shíkọmọ "" ( shikomor ) "" tàbí èdè kòmórò ni èdè tó gbalẹ ̀ jùlọ ní ní kòmórò ( àwọn erékùṣù olómìnira ní Òkun Ìndíà , nítòsí mòsámbíkì àti madagáskàr ) àti ní mayotte ."
Kí ìràwọ̀ òwúrọ̀ rẹ̀ ṣókùnkùn,kí ìrètí rẹ̀ fún ìmọ́lẹ̀ àfẹ̀mọ́júmọ́ já sí òfo,kí ó má rí ìmọ́lẹ̀ òwúrọ̀ mọ́;
Ẹni tí ó dúró ṣinṣin lórí òdodo yóo yè,ṣugbọn ẹni tí ó bá ń lépa ibi yóo kú.
"Litireṣọ alohun ati apilékó tun jẹyọ pẹlu awọn apẹẹrẹ to yẹ ni a gbe yẹwo Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Bí ẹ ṣe mọ̀wé tó, ẹ wá dánrawò níbí pẹ̀lú ""Àpólà Ọ̀rọ̀ Orúkọ - Noun Phrase Arabinrin Adeyẹmọ lati Oke Ira Junior High school yannana Isọri Orọ Yoruba."
IRememberWhen: Àràmànda ni ǹkan ti ẹlọmiran ń ránti
“OLUWA, o ti gba ìjà mi jà,o ti ra ẹ̀mí mi pada.
Awuyewuye yii laarin awọn oloṣelu ṣeeṣe ko ta ba ọrọ aje orilẹ-ede naa.
Club/ RD Congo), Kabongo Kasongo (Zamalek/ Égypte), Chikito Lema Mabidi (Raja Casablanca/ Maroc), Bobo Beaudrick Ungenda Muselenge (Primeiro do Agosto/ Angola), Ricky Tulengi Sindani (DCMP/ RD Congo), Ben Malango Ngita (TP Mazembe/ RD Congo), Aaron Tshibola (Kilmarnock FC/ Écosse), Nelson Munganga Omba (AS V.
"Iroyin ni orile-ede India ni ọga agba fun ileesẹ ọlọpaa, Udayshankar Ghosh sọ pe: ""A n fura wi pe ọrọ naa ni bayo-bayo ninu."
 Lara awon ohun ti ile- ise oloopa ri gba lowo awon
Nítorí ẹni tí ó kéré jùlọ ninu yín, òun ló jẹ́ eniyan pataki jùlọ.
Menahemu ọmọ Gadi lọ sí Samaria láti Tirisa, ó pa Ṣalumu ọba, ó sì jọba dípò rẹ̀.
Ajo isakan agbaye ti yan minisita to n mojuto eto irinna lorile-ede Naijiria, ogbeni Rotimi Amaechi, sara igbimo awon olugbani-nimoran ajo to n mojuto eto irinna lagbaye United Nations Road Safety Trust Fund (UNRSTF), eyi ti o waye nile ajo ohun niluu Geneva, lorile-ede Switzerland.
Wọn ṣe aajo ki wọn ri ina tan lẹyin igba ti ina ọba lọ, lọrọ ba di mo ha mọ.
Oríṣun àwòrán, SIA KAMBOU Pasuma kìí ṣe ọkọ mi o!
Ile ẹjọ giga ni Kano dajọ ki wọn yegi fun, titi ti ẹmi yoo fi bọ lara rẹ.
O ni o tun wa n fẹ ẹ loju lori ẹrọ ayelujara bẹẹ si ni awọn eeyan ko mọ pe tori Gida lo ṣe n ṣe eyi.
Àtẹ̀jáde ọ̀hún fí kún pé sẹ́nátọ Dino Melaye àti àwọn ìsògbè rẹ̀ jọ fí ọwasowọ́pọ̀ láti yìnbọn pa Sajẹnti Danjuma Saliu tó wà lẹ́nu iṣẹ́ rẹ̀ ní ìpínlẹ̀ Kogi nínú oṣù keje ọdún 2018.
"Itunu kan ti mo ni niyẹn"" O fi kun un pe, Sẹnetọ Ajimọbi mu iṣẹ iriju rẹ laye ṣẹ."
Ọdun meji ati aabọ ni Mourinho fi tukọ ẹgbẹ agbabọọlu Man U ko to gbawe gbele ẹ lọjọ Iṣẹgun.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ọmọkùnrin kan sin Baba rẹ̀ láàyè torì pé ó gbàgbọ́ pé oṣó ni!
Ṣaadede ni ipinlẹ Oyo toun na jẹ ọkan lara ibi to ti n waye gba a mọ ipinlẹ Edo lọwọ.
Nítorí náà, láti ọjọ́ náà lọ ni wọ́n ti ń pe Gideoni ní Jerubaali, ìtumọ̀ rẹ̀ ni pé, “Ẹ jẹ́ kí Baali bá a jà fúnra rẹ̀,” nítorí pé ó wó pẹpẹ rẹ̀ lulẹ̀.
Iniesta, ti gba ifesewonse mẹ́tàlélọ́gọ́fà fun Spain bayii, sugbon ti koi ti ba  tawon asaaju re ti won ti feyinti bi: Andoni Zubizarreta, Xavi, Sergio Ramos ati Iker Casillas.
Wọn kì í ṣe ti ayé, gẹ́gẹ́ bí èmi kì í tíí ṣe ti ayé.
‘Buhari ti wọnu ẹmi lọ’ Ẹ̀rò àwọn ènìyàn se ọ̀tọ̀ọ̀tọ̀ lórí lẹ́tà Ọbasanjo sí Buhari 2019 Election: Bí Buhari ba le lọ Kóòtù ní ẹ̀ẹ̀mẹ́ta- Obasanjo Ẹ gbọ ohun to sọ nipa aarẹ''a ko ni igbagbo pe ẹni ti ori rẹ pe yoo fi owo ara ilu ra ọkọ baalu fun ara rẹ lasiko ti ko tilẹ le san owo osu oṣiṣẹ ijọba lẹlẹkaa jẹka ijọba'' Agbẹnusọ ọlọpaa Esther Katongo fidi ọrọ naa mulẹ.
Oríṣun àwòrán, YASUYOSHI CHIBA Ni ọdun 2017, bakan naa ni Ọga Ọlọpaa tẹlẹ, Ibrahim Idris fi opin si ki ọlọpaa ma a da awọn eniyan duro wi pe wọn fẹ wọ ohun ti wọn gbe.
ọkọ̀ ojú omi tuntun bẹ̀rẹ̀ iṣẹ́ Ta ni Sadiya Umar Farouq tí ìròyìn ẹlẹ́jẹ̀ ń gbé pé òun ló fẹ́ dí ìyàwó tuntun Buhari?
Akosemose lori itoju eti, ofun ati imu, Onisegun oyinbo Abdulwahab Anas se ikilo fawon eniyan lori fifi igba gbogbo ko okun amohundun gbamu seti nitori pe o maa n fa ewu igbonran feti ni to ba pe sii.
Sugbọn niagbo oselu Naijiria nilẹ toni to mọ yi, awọn oloselu ko fi tẹgbẹ se.
Ọ̀pọ̀ tilẹ̀ ni pé isó inú ẹ̀kú ni ọ̀rọ̀ náà, nítorí náà kò to sí Abike Dabiri láti sọ ǹkan tí ojú rẹ̀ bá rí lọ́wọ́ ìjọba yìí.
19 Owewe 2020 US election 2020: Olórí àwọn òṣìṣẹ́ Trump sọ pé ìjọba ilẹ̀ America kò le kápá coronavirus26 Ọ̀wàrà 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Èrò àwọn ènìyàn nípa ikú Khadijat Olubọyọ 'Óṣeéṣe kí ọ̀rẹ́kùnrin Khadijat fẹ́ fi ṣowó' ‘A bá òkú ọmọ igbákeji gómínà tẹ́lẹ̀rí nílé ọ̀rẹ́kùnrin rẹ̀’ Nílé ẹjọ́ ní Akurẹ Adajo ni ki wọn gbe Adeyemi pada siwaju ile ẹjọ ni ọjọ kẹrinlelogun oṣu to m bọ.
Àwọn olóṣèlú kọ̀ọ̀kan ti fipá mú ààrẹ Obama pé kó tiraka láti yí òfin náà pádà, kí wọ́n fi lè dẹ́kun àwọn íṣẹ̀lẹ̀ wọ̀nyí nítorí kìí ṣe àkọ́kọ́ rẹ̀ nìyí.
Isiaka Busari, Mighty Joe tó jẹ́ adigunjalè tó rọ́pò Ọyenusi lẹ́yìn tí wọ́n pa á Ọmọ Nàìjíríà kan gbé Fásitì Oxford lọ sílé ẹjọ́ tàko oríkí ọrọ 'Mortgage' nínú ìwé àtúmọ̀ ọrọ Ọwọ́ ọlọ́pàá tẹ àwọn olè tó kó góòlù àti ẹgbẹ̀lẹ́gbẹ̀ mílíọ̀nù lọ nílé MKO Abiola l'Eko Gbajabiamila balẹ̀ sí Ghana láti pẹ̀tù sááwọ̀ láàrin Nàìjíríà àti Ghana Ìgbà mẹ́ta ọ̀tọ̀ọ̀tọ̀ tí ìjọba Nàìjíríà ti gbẹsan lára orilẹ-ède mí tó dẹ́yẹsí i Minisita feto ọkọ ofurufu Naijiria Hadi Sirika lo fi ọrọ yi lelẹ lasiko ti igbimọ to n koju arun Covid-19 n jabọ fawọn akọroyin ni Abuja.
Lẹyin to gba ilẹ naa, Moi ta ilẹ naa fun ileeṣẹ Rai Plywood kan to n ta igi gẹdu.
Oríṣun àwòrán, Kwara APC Information Center Àkọlé àwòrán, APC ni ayederu aworan ni awọn alatako fi sita nipa Yahaya Seriki 'Dìbò ko sebẹ̀' tún gbòde ní àtúndì ìbò Kwara Saaju ni iroyin ti gbode lori ẹrọ ayelujara wi pe awọn ọ̀dọ́ nílùú Ekan meje ní ìjọba ìbílẹ̀ Oke-Ero, tí kọjú ìjà sí ọkan nínú àwọn oludije tẹlẹ tó feròngba han láti díje dupò gómìnà ninu ẹgbẹ APC nipinlẹ Kwara, Abdulfatah Yahaya Seriki Gambari, tí ìjọba ìbílẹ ìlà-oòrùn Ilorin.
Lẹ́ẹ̀kan sí i, ohun tí ó sọ ní ibí yìí ni pé, “Wọn kò ní wọ inú ìsinmi mi.
Gege bi alaga iko agbaboolu Dream
Mo ti mú sùúrù, ó ti sú mi.
Ana alana ni ile ẹjọ ṣi sọ pe ki wọ́n jami lori ẹjọ yii na.
Lọjọ Iṣẹgun ni ikede yi jẹ yọ lati ọdọ Femi Adesina oludamọran pataki fun Aarẹ Muhammadu Buhari.
Ṣugbọn kí ayé lè mọ̀ pé mo fẹ́ràn Baba ni mo ṣe ń ṣe bí Baba ti pàṣẹ fún mi.
Wọn ni nitorinaa, awọn yalaṣ to tọ lawn ipinlẹ yoo koro oju si aibọwọ fun ẹtọ awn araalu eyi ti ik Amotẹkun kankan ba ṣe si wọn.
17 Ẹrẹ̀nà 2018 Oríṣun àwòrán, Twitter.
Pupo ninu awon to n wa gusa ni ekun naa lo ti jawo ise , nitori opo emi to n sonu nibi ijamba ile-riri yii.
Ohun akọkọ ti gomina wọgile ni igbesẹ sisan ẹgbẹrun mẹta naira, ti awọn ọmọ ilẹ ẹkọ girama n san nipinlẹ Ọyọ.
Ẹẹmeji pere ni Alagba maa n jẹun laarin oṣu kan kii sii sunmọ ẹnu ibode ọgba rẹ ayafi bo ba fẹ mu omi.
Yatọ si eyii, lara awọ nnkan ti awọn eeyan korira nipà Trump ni bo ṣe sọ pe oun fẹ kọ odi, eyii ti yoo dena mọ awọn to n wọle sorilẹ-ede naa lọna aitọ.
Bi wọn ṣe gbéra ni ileẹkọ awọn osisẹ asọbode to wa ni Gwagwalada nilu Abuja niṣẹlẹ naa ṣẹlẹ.
Ìwọ gan-an ni kòríkòsùn àrin òru
BBC Yoruba ba ọkan ninu awọn ọdọ yii sọrọ sugbọn a fi orukọ boo laṣiri.
 lẹ ́ yìn ìgbẹ ́ jọ ́ ó tó oṣù mọ ́ kànlá , ilé-ẹjọ ́ dá awólọ ́ wọ ̀ àti àwọn ọmọ ẹ ̀ gbẹ ́ òṣ ̀ èlú rẹ ̀ méjìdínlọ ́ gbọ ̀ n ( èjìlẹ ̀ wá sẹ ́ jọ ) lébi èsùn ìdìtẹ ̀ , wọ ́ n sì rán wọn lẹ ́ wọ ̀ n ọdún mẹ ́ wàá.
'Mi o fọ́wọ́ sí bí ọmọ mi, Kiddwaya ṣe lọ fún BBNaija - Terry Waya Ìbéèrè àti ìdáhùn pẹ̀lú Seyi Awolowo ti BBNaija lórí BBC Yorùbá Àwọn akópa tó ti jáwé olúborí ní BBNaija sẹ́yìn àti ibi tí wọ́n wà báyìí Oríṣun àwòrán, Twitter Wo nkan to yẹ ki o mọ nipa wọn Wathoni Florence Wathoni Anyansi jẹ ẹni ọdun mọkandinlọgbọn, o si jẹ oniṣẹ adani ni ẹka oge ṣiṣe.
Ìkíni kú oríire ti ya bo Funke Akindele àti ọkọ rẹ̀ JJC Skillz
19 Ẹrẹ̀nà 2018 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Èyí ni òfin tí ó jẹ mọ́ àwọn ẹranko ati ẹyẹ ati àwọn ẹ̀dá alààyè tí wọn wà ninu omi ati àwọn ẹ̀dá alààyè tí wọ́n ń fi àyà fà lórí ilẹ̀, 
“Ọpọlọpọ ìgbà ni wọ́n ti ń pọ́n mi lójú láti ìgbà èwe mi,sibẹ, wọn kò borí mi.
APC: O jẹ́ tètè jẹ́wọ́ àwọn tó rán ọ níṣẹ́ torí àwa kìí fún apààyàn lówó
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Yoruba World Assembly: Ìlú Ibadan ni wọ́n tí ṣe àgbẹ́kalẹ̀ ẹgbẹ́ ọmọ Yorúbá tuntun 16 Bélú 2020 Oríṣun àwòrán, Google Olufilọlẹ ẹgbẹ ọmọ Yoruba tuntun, Comrade Victor Taiwo ti ni awọn gbe ẹgbẹ Yoruba World Assembly silẹ lati wa ọna abayọ si aisi ifẹ ati ifimọsọkan laarin awọn ọmọ Yoruba.
OLUWA nìkan ni a óo gbéga ní ọjọ́ náà,
ẹgbẹ oṣelu PDP Ọgbẹni Babatunde Aleshinlọyẹ ni ẹgbẹrun
Jesu bá gun orí òkè lọ, ó jókòó níbẹ̀ pẹlu àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀.
Brigade naa so pe opolopo irinse ija ogun ati awon ohun ijamba ni awon gba lowo
Eẹkan ṣoṣo ti Algeria tii gba ife ẹyẹ yii ri ni ti idije ọdun 1990 ti wọn ti na Naijiria ni orilẹ-ede wọn.
Awọn ọmọ Naijiria, ẹgbẹ awọn agbẹjọro fi ẹhonu wọn han wipe, igbesẹ̀ aarẹ naa ko tọ́na.
Ọjọru ọsẹ yii, to jẹ ọjọ kẹrindinlogun, oṣu kẹwaa, ọdun 2019 ni Jumoke pe eni ọdun mẹrindinlogoji laye.
Oju  Oja kan soso ni apa ila-oorun ati apa guusu ile Africa , Ajo isokan ile Africa (AU), ati igbimo Pan-African wa lara awon alejo ti won fi iwe pe pelu Ajo awon orile-ede lagbaye (Commonwealth).
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ogun kidnap: Àwọn ajínigbé gbé ọkọ̀ ojú omi ọlọ́pàá lọ lẹ́yìn tí wọ́n dóòlà ẹ̀mí ọmọ Ìmáàmù 18 Ògún 2019 Oríṣun àwòrán, Facebok/Bashi Makama Ileeṣẹ ọlọpaa ipinlẹ Ogun ti sọ pe o didan awọn gbọdọ gba ọkọ oju omi agbera pa awọn pada lọwọ awọn ajinigbe.
A ni ki awọ́n eeyan wọ aṣọ dudu, ẹgba ọwọ rọba dudu tabi ohunkohun lati fi han pe a n ṣe ọfọ.
RCCG: Ọlọ́pàá Ogun dóòlà àwọn ọmọ ìjọ Redeem mẹ́rin tó kù!
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Teslim Folarin: Ọwọ́ tẹ àwọn tó kó nkan tówó rẹ̀ tó N200m nílée Sẹ́nétọ̀ tó n ṣojú Oyo Cental 24 Ọ̀wàrà 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 25 Ọ̀wàrà 2020 Oríṣun àwòrán, @BolanleCole Ọwọ sinkun ọba ti tẹ lara awọn to ṣe ikọlu silee Sẹnetọ to n ṣoju ẹkun arin gbungbun ipinlẹ Oyo nile igbimọ aṣofin, Teslim Folarin, Lasiko ikọlu naa pẹlu afihan fọnran to gba ori ayelujara kan, ọpọlọpọ nkan ti ko lonka ni awọn afurasi janduku naa ji ko.
•Ti awọn eniyan ba n tọkasi oju opo rẹ pe o lewu, wọn le e gbegile fun igba diẹ, ki wọn fi ṣe iwadii boya lootọ ni awọn nkan ti eniyan n gbe jade loju opo ikansiraẹni rẹ lewu fun awujọ.
'Mo ni lati mura si' Frederick l'orukọ ọmọ naa, o si jẹ ọkan lara ogunlọgọ awọn ọmọ t'oun tiraka lati j'eeyan lai si oluranlọwọ.
Aare kẹdun pelu aare Trump ati awon eniyan ti o fara kaasa ikolu ohun lataari ibajẹ ti ikolu naa ti sokunfa lorisirisi.
Abọ iwadi naa fihan pe ogún ninu mẹtalelogun awọn ileeṣẹ to n ṣe oogun oyinbo ti wọn ṣe ayẹwo si lo jẹbi ọrọ naa.
"' Awọn miran gba pé ohun ti aya aarẹ fẹ jẹ ni o n fọgbọn wa pe Bẹẹ lawọn mii ni ṣebi aṣọ to kangun si egun ni wọn n pè ni jẹ̀pẹ̀, niṣe lo yẹ ki Aisha ba ọkọ rẹ sọ ododo ọrọ ninu iyara ko le gbọran daadaa ""Àlùfàá méjì wà lára àwọn mẹ́rin tó fi ipá bámilòpọ̀"" Orúkọ àwọn Super Falcons 23 tó ń lọ France ti jáde Wo àwọn míniístà mẹ́fà tí ẹnu ń kùn jùlọ ‘Bi Gomina Ajimobi se yan adarí òsìsẹ́ tuntun ní Oyo kò dí wa lọ́wọ́’ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Jiti Ogunye: Ìjọba àkóbá lológun gbé kalẹ̀ ni 1999 Loju àwọn ọmọ Naijiria omiran, aarẹ Buhari ti n kuna lati gbọ oo) tọ nkan to n ṣẹlẹ nitori pe awọn alatẹnujẹ kan ti rọgba yi aarẹ ka."
Oludari kata-kara awọn agbabọọlu ni Barcelona, Txiki Begiristain ti de si ilu Barcelona lati duna dura lori ati ra Messi lọ si Man City.
Pàṣán ati ìbáwí a máa kọ́ ọmọ lọ́gbọ́n,ọmọ tí a bá fi sílẹ̀ yóo dójúti ìyá rẹ̀.
6 Nísisìyí, bí ìwọ ti béèrè, kíyèsíi, mo wí fún ọ, pa àwọn òfin mi mọ́, kí o sì lépa lati mú jáde wá ati lati ṣe àgbékalẹ̀ ipa ọ̀nà Síónì.
1 10316 Orilẹede Trinida and Tobago 130 9.
Iroyin ohun waye lojoBo(Thursday), leyin ti pasipaaro Dola si Naira je ọ́ọ̀dúnrún o leni mọ́kàndínlọ́gọ́ta Naira(N359).
Nítorí ìlera mi ni mo ṣe ní ìbànújẹ́ lọpọlọpọ;ìwọ ni o dì mí mú,tí n kò fi jìn sinu kòtò ìparun,nítorí o ti sọ gbogbo ẹ̀ṣẹ̀ mi di ohun ìgbàgbé.
O ja fun ẹtọ ẹranko, o ni ko tọ ki wọn maa fi awọn ẹranko ṣe ounjẹ gẹgẹ bi wọn ti ń ṣe lorilẹede Burundi.
N óo sì yan ẹnikẹ́ni tí ó bá wù mí láti máa ṣe àkóso ibẹ̀; nítorí ta ló dàbí mi?
Eto idibo June 12: Igba keji ti isọkan ati ifẹsẹmulẹ Naijiria yoo mi pupọ nilẹ ni asiko ti ijọba ologun Ibrahim Badamosi Babangida wọgile eto idibo aarẹ ta di lọjọ kejila osu Kẹfa ọdun 1993.
Jesu bi í pé, “Kí ni o fẹ́?
OLUWA tún bá Jona sọ̀rọ̀ nígbà keji, ó ní: 
Baba iyawo rẹ̀ bá bá a wí pé, “Ohun tí ò ń ṣe yìí kò dára.
Mo gba àṣẹ lọ́wọ́ ọkọ, kí ń tó má ṣeré ìfẹ́ pẹ̀lú ìyàwó rẹ̀ - Àlè kan jẹ́wọ́ Ẹ̀mi arákùnrin yìí kò gbé e, ó bá aláṣẹ́wò lò dórí ìgbà ìkéje ló bá ré sálákeji Ohun tó yẹ kóo mọ̀ nípa Fásitì Babcock rèé Ìyàwó mi rẹ̀wa gidigidi-Oluwo Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí kan sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
OLUWA àwọn ọmọ ogun sọ pé, “Ní gbogbo ibi tí ó ti di ahoro yìí, tí eniyan tabi ẹranko kò gbé ibẹ̀, àwọn olùṣọ́-aguntan yóo sì tún máa tọ́jú àwọn agbo ẹran wọn ninu gbogbo àwọn ìlú ibẹ̀.
Ko pẹ si akoko to wọm ile iwe naa ti wọn le oun atawọn eeyan mọkanlelọgọta miran kuro nile iwe naa lẹyin ti wọn dari ifẹhonuhan kan lọdun na lọhun, ki oloye Gani Fawehinmi to gba ẹjọ wọn ro.
"Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù MKO Abiola: Buhari ní Abiọla kò bá dènà ìṣòro ẹ̀sìn àti ẹ̀yá ní Nàíjíríà 30 Agẹmo 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images ""To ba jẹ pe Abiọla wa laye ni, ọrọ aawọ ẹlẹsinjẹsin tabi ẹlẹyamẹya ko ba ti sẹlẹ lorilẹede Naijiria lasiko yii, paapa to ba jẹ pe wọn gbaa laaye lati jẹ aarẹ Naijiria ni."
“Lẹ́yìn náà, àwọn ọ̀gágun yóo wí fún àwọn eniyan náà pé, ‘Ǹjẹ́ ọkunrin kan wà ninu yín tí ó ṣẹ̀ṣẹ̀ kọ́ ilé titun, tí kò tíì yà á sí mímọ́?
Ọmọ naa jabọ lẹyin Ọmọyẹ, to si fi ori gba ilẹ.
fifi oju sile mo bi nkan se n lo layika won gbogbo, paapaa julo lasiko odun yii.
eniyan naa ba pari isẹ wọn.
bruce alan beutler ( ojoibi december 29 , 1957 ) je aseoroajesara ati aseiseabinimo ara amerika .
Jọ̀wọ́ máa gbọ́ adura tí èmi iranṣẹ rẹ bá gbà nígbà tí mo bá kọjú sí ilé yìí.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Yoruba film: Irú ẹ̀ṣẹ̀ wo ni gbajugbaja òṣèré, Nkechi Blessing ṣẹ Toyin Abraham tó fi ní kó jèbùrẹ́?
Ọmọ bibi ipinlẹ Edo ni gbajumọ oṣere tiata naa, to tun jẹ oludari ere sinima ati gbajugbaja oloko-owo.
Akotun igbese yii waye, leyin won se fi owo sinkun ofin mu Julius Ayuk Tabe, ti o n dari ekun naa tele, ni awon alase orile-ede Nigeria fi Tabe ati awon merindinladota le ijoba orile-ede Cameroom lowo, leyin ti won fi owo sinkun ofin mu won nile itura kan nilu Abuja ni osu kinni odun 2018.
Àwọn ìròyìn mìíràn tí ẹ lè nífẹ̀ẹ́ sí: Kìnìún tí wọn ń sìn yarí, ó pa olówó ati ọmọ olówó rẹ̀ Kí ló yẹ ká se sí ẹkùn tó pa ènìyàn márùń?
Ìdí nìyí tí wọ́n ṣe máa ń sọ pé
Gbogbo awọn agbegbe ti ina ikọlu yii ti n ru ni a ti fi awọn agbofinro ransẹ si lati seto alaafia.
Mo ti lu bàtá wọ Dubai, Abidjan, Turkey.
Iru ọmọ bẹẹ a ti ro ara rẹ pin'' Dokita Olaniyi sọ pe kaka ki awọn obi da iru ọmọ bẹẹ lẹkọ tabi ki wọn ṣe iwuri fun, niṣe ni wọn a maa ko iporuru ọkan ba wọn.
Bẹ́ẹ̀ ni wọn óo ṣe máa pèsè aguntan ati ẹbọ ohun jíjẹ ati òróró láràárọ̀, fún ẹbọ ọrẹ sísun ìgbà gbogbo.
O salaye pe, “mo ro awon odo orile-ede Naijiria lati wa ni igbaradi ati lati tesiwaju ninu iwa omoluabi ni iyanju ati le fako yo, ki o si ni okan rere lati mu ayipada rere ba isakoso ijoba”.
Òkìkí rẹ̀ kàn ká gbogbo agbègbè náà.
 “Igbimo yii tun dari ile –ise olopaa
Ni ipele kini ifẹsẹwọnsẹ naa ni aṣiṣe David Luiz ti kọkọ ṣakoba fun Arsena nigba to fara gbe bọọlu to yẹ ko gba danu sọwọ Raheem Sterling agbabọọlu Manchester city ti tọun si kanra gba bọọlu naa sawọn.
Ẹwẹ, Abdulrahman Dambazu to jẹ minista fun ọrọ abẹlẹ ni Naijiria kede pe ko ni si iṣẹ ni ójọ kókanlelogun ati ọjọ kejilelogun, oṣu kẹjọ, ọdun 2018 fun sisami ọdun Ileya.
Gbogbo ibi ìrúbọ tí Hesekaya, baba rẹ̀ ti wó lulẹ̀ ni ó tún kọ́.
Ǹkan kò bá má burú tó báyìí ká ní Aàre Buhari tètè bá àwọn ọmọ Nàìjíríà- PDP Oríṣun àwòrán, Pdp/apc Egbe oselu PDP lorileede Naijiria ti ni aare Buhari to dake lo fa rogbodiyan to gbode kan lorileede Naijiria.
Ẹni to bori: Senegal Morocco vs Angola.
Ilé ẹjọ́ gba béèlì Dino Melaye
Mo kábàámọ̀ pé n kò kàwé, kí n tó bẹ̀rẹ̀ iṣẹ́ tíátà - Sanyeri Àwọn òṣèré tíátà Yorùbá tó bá 2018 lọ Iya Rainbow, Jide Kosoko, Ọga Bello, yóò polongo Buhari fún 2019 'Mí ò sí lára awọ̀n aṣòfin tó bú Buhari'' Nigba to n ba BBC Yoruba sọrọ, Baba Suwe ti ohun rẹ ko fi bẹẹ ja gaara ni oun dupẹ lọwọ Ọlọrun pe o da ẹmi oun si ninu ipenija ara ti oun la kọja.
Ó pé Ogún ọdún lónìí tí àwọn ológun gbé ìjọba fún alágbádá ní Orílè-èdè Nàìjíríà.
Eyi ti fa sunkẹrẹ fakẹrẹ ọkọ lori afara naa.
Ọkan lara awọn ọdọmọkunrin naa ni Wọle, to jẹ ẹni ọdun mẹtalelogun.
bí kò bá bá wọn jẹ ẹbọ lórí àwọn òkè, tabi kí ó bọ àwọn oriṣa ilé Israẹli; tí kò bá bá aya aládùúgbò rẹ̀ lòpọ̀, tabi kí ó bá obinrin lòpọ̀ ní àkókò tí ó ń ṣe nǹkan oṣù rẹ̀ lọ́wọ́; 
Ọgbẹni Bitok sọ pe ọkunrin naa ku lasiko to n gba itọju nileewosan.
Bakan naa ni adinku ba owo ori to fa laasigbo naa, tijọba si tun pinnu lati mase lo awọn afipa gba owo ori mọ.
Lara awon ti o tun tele aare
O ni ọpọ igba ni ikọlu si awọn ọmọ Naijiria ti n waye ni South Africa ṣugbọn bayii, o to gẹẹ ni.
 wọn máa ń pín ara wọn sí ẹlẹ ́ gbẹ ́ jẹgbẹ ́ láti ṣe iṣẹ ́ ìlú láti jọ kẹ ́ gbẹ ́ àjùmọ ̀ ṣe lẹ ́ nu iṣẹ ́ àti oríṣìíríṣìí ayẹyẹ nílùú pẹ ̀ lú .
Ìgbà kan tí mo wí pé ẹmu ń wù mi mu wéré ni mo rí ẹmu ògidi níwájú tí ó ru pàtà.
Ṣugbọn ọkunrin náà jáde lọ, ó bẹ̀rẹ̀ sí sọ fún ọpọlọpọ eniyan, ó ń rán ọ̀rọ̀ náà mọ́ ẹnu, tóbẹ́ẹ̀ tí Jesu kò fi lè wọ inú ìlú ní gbangba mọ́, ṣugbọn ó lọ sí ẹ̀yìn odi ìlú níbi tí kò sí eniyan.
Tèmi ni Gileadi, tèmi sì ni Manase.
Oṣu kọkanla ọdun yii ni ajọ eleto idibo INEC ni eto idibo gomina nipinlẹ Kogi yoo waye.
Òṣèrébìnrin tí wọ́n bá fi ìbálòpọ̀ lọ̀ 'torí ìṣẹ́, kó bọ́ síta láti sọ̀rọ̀ - Kunle Afod Saraki àgbà ló kọ́ ilé yìí fáwa arúgbó kìí ṣe Bùkọ́lá- Arúgbó Ilọrin Àwọn fóònù wọ̀nyìí kò ní lè ṣe WhatsApp láti ọdún 2020 Wo àwọn èèyàn jáńkán tí yóò ṣe ọdún tuntun ní ọgbà ẹ̀wọ̀n Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí 2 sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 2:23 Fídíò, Water Generator: Ó leè ṣiṣẹ fún wákàtí mẹfà, kó tó sinmi, Duration 2,2310 Òkùdu 2020 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
Iru isẹlẹ yii ko si le mai waye nilẹ Afirika, ti itọju ati imọ ẹrọ ko ti kun to.
Ẹgbẹ agbesumọmi Islamic State IS, fi fọran kan lede, nibi ti wọn ti pa awọn Kristẹni mọkanla lorilẹ-ede Naijiria.
Atẹjade kan lati ọdọ agbẹnusọ rẹ, Lere Olayinka ni ''lẹyin igba ti Buhari da ọrọ naa wo ni o to o gbera lati lọ si awọn ipinle naa.
₦35,000 ni mò ń gbà bíi Adelé ọba, kò sí ọkọ̀ ayọ́kẹ́lẹ́ - Adelé Olúbọ̀rọ̀pa Ìrántí Sani Abacha, apàṣẹ wàá tó tún kó owó Nàìjíríà mì Àwọn 'ẹ̀bùn' tí ikú George Floyd fún àgbáyé Àwọn ọba Yorùbá kan rèé tí wọ́n rọ̀ lóyè, tí ọba míràn jẹ lójú ayé wọn Ìtàn ayé Taiwo Oredein rèé, ó kọ́ wa láti máa ni ìtẹ́lọ́rùn Sanusi Adebisi Idikan rèé, olówó tó ń san owó orí fún gbogbo ọkunrin ilẹ̀ Ibadan Gẹgẹ bi a ṣe ka a loju opo itakun agbaye ati ninu awọn iwe itan lorisirisi, ọba ilu Oyo ni Alaafin Aole, Afonja si ni aarẹ ọna Kakanfo rẹ, ohun to si fa aawọ laarin awọn mejeeji, ti Aole ṣe binu ṣẹ epe ree: Ija Alaafin Aole ati Afonja: Ni igba ijọba Oyo ijọhun, asẹ ti Alaafin ba pa laarin ilu, abẹ lo gee nitori lẹyin asẹ Ọba, ko si ọrọ miran mọ, Ọba lo ni ilẹ, Ọba lo ni ohun gbogbo.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Widows Day 2019: Mo máa ń sá kiri wá owó ilé ni -Opó Durojaye ni oun to ku ti iran Yoruba fẹ lasiko yii ni pe ki wọn gbajumọ iṣoro to n koju eto aabo Naijiria.
Nítorí Ọlọrun lawọ́, kì í sìí sìrègún.
Oga agba oniroyin náà padà sí Ethiopia leyin ti asoju ijoba Ahmed Abiy gorí alefa lodun 2018 lásìkò tí wọn tú òpó àwọn tí wọn mu nítorí oselu silẹ.
Ẹgbẹ Amnesty ni iwadii oun lori isẹlẹ naa lati ipasẹ awọn fidio to jade, ọrọ awọn ti isẹlẹ naa soju wọn ati abẹwo sile iwosan lo fidi isẹlẹ naa mulẹ.
Ọkùnrin kan pa ara rẹ̀ sínú ọgbà àjọ TRACE tó n mójútọ ìrìnnà ọkọ̀ nípìnlẹ̀ Ogun A yìnbọn lu Precious láti dáa dúró ni, akò mọ̀ pé o máa kú- Ọlọ́pàá Kí ló dé tí ìjọba ìpínlẹ̀ Oyo kéde fífagilé Sáà ètò ẹ̀kọ́ kẹta fún àwọn akẹ́kọ̀ọ́?
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù World Malaria Day: Ǹjẹ́ o mọ ohun tó ń mú àìsàn ibà pànìyàn?
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Adeola Smart and Malivehood Wedding: Diamond kún ara aṣọ ìyàwó, Cake jẹ́ alájá 16 11 Ọ̀pẹ̀̀ 2020, 13:45 WAT Oríṣun àwòrán, Istagram/malivelihood Ọpọ eeyan to peju sibi igbeyawo Adeola Smart, tii se ọmọbinrin Senatọ Smart Adeyemi ati ọkọ rẹ, Olusola Awujoola ni ko ni gbagbe aramọnda igbeyawo naa laelae.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù BUSA 2019: Aisha Buhari ń hù ìwa ipá sí wa!
Ẹ pín ilẹ̀ náà sí agbègbè mẹta, kí ẹ sì la ọ̀nà mẹta wọ inú àwọn ìlú náà.
 Gbogbo àwọn olórí bàbá Aláàfin ni n kò ní àǹfààní láti pàdé wọn tẹ́lẹ̀ ayafi ìgbà tí mo jẹ oyè Mayegun ilẹ̀ Yorùbá.
Ọgbẹni Adegunwa sọ pe Ile-iṣẹ Rite Foods ti na nnkan bii ọgbọṇ miliọọnu naira (N30Million) lori awọn ohun jijẹ ati ohun mimu ti wọn pese fun awọn elere idaraya yii, eyi ti o ni awọn fi n ṣe atilẹyin fun idagbasoke ere idaraya ni orilẹ-ede Naijiria ati ilẹ Afirika lapapọ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Wọ́n ti gbé Emir Kano tẹ́lẹ̀, Sanusi Lamido kúrò ní Nasarawa lọ síbi tẹ́nìkan kò mọ̀ Ọjọ Aje ni gomina ipinlẹ Kano rọ Emir Sanusi l'oye, ti wọn si tun le kuro nilu Kano lọ si Nasarawa.
“Ní ọjọ́ náà, ẹ kò ní bi mí léèrè ohunkohun.
Ondo Mortuary: Pàǹtí ni òṣìṣẹ́ Mọ́ṣúárì dà sínú pósí dípò òkú ọmọ
Ninu fidio ti aṣoju fi lede loju opo Instagram rẹ, Uzoma ni asiko ree lati ṣe ayẹyẹ awọn aṣeyọri Majek Fashek ati gbogbo nnkan to ṣe fun Naijiria ati ilẹ Afirika lapapọ.
Awọn onimọ sọ pe ibugbamu yii yoo ṣi fun Lebanon, orilẹede to ṣi n tiraka pẹlu ọrọ aje mọ ẹgbẹ kan ti awọn ọmọ ọdọ yoo si ni lati fara mọ atunbọtan rẹ.
Ṣé ẹ fẹ́ kí n pa yín run, kí ẹ di ẹni ẹ̀sín láàrin gbogbo orílẹ̀-èdè ayé ni ẹ ṣe ń ṣe báyìí?
Awọn to ni ipenija ara sọ pe awọn lo sun mọ oṣi ati iṣẹ ju awọn abarapa eeyan lọ.
"Ìjà d'ópin, fún ìgbà àkọ́kọ́, bàálù gbéra láti Israel lọ sí UAE Ṣé Nàìjíríà lẹ́mìí nkan tí Ghana ń ṣe fáwọn akẹ́kọ̀ọ́ ""Secondary"" tí yóò wọlé ní October yìí?"
Orile ede Garbon ni epo robi, ohun alumooni ile ati igi gedu , owo to si n wo apo orile ede naa le ni ilopo merin orile ede miiran.
kí àwọn arọmọdọmọ yín lè mọ̀ pé, inú àgọ́ ni mo mú kí àwọn ọmọ Israẹli máa gbé nígbà tí mo kó wọn jáde wá láti ilẹ̀ Ijipti.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Àwọn ọkùnrin tó wà nínú ayé wa gbúdọ̀ bọ̀wọ̀ fún wa - Adarí FIN To ba jẹ tori ibalopọ ni, mo ṣe iṣẹ abẹ l'ọdun 2018, eyi ti yoo mu ki o ṣeeṣe fun mi.
6 Owewe 2020 Awọn eeyan kii ṣaba sọrọ nipa fifun ara ẹni ni adun ibalopọ, paapa ni gbangba.
”Ni bayii, Chelsea yoo lo koju Southampton ninu ifigagbaga ipele keji si asekagba idije FA lojo Aiku(Sunday).
Akitiyan ọmọ'ṣẹ́ mi tó wà lára àwọn tó jí ìbejì mi gbé kò kéré nígbà tí á n wá wọn- Akeugbagold Wo ìgbà márùn ún tí àwọn ọmọ ọ̀dọ̀ ti gé ẹ̀mí ọgá wọn kúrú Wo ìgbà márùn ún tí àwọn ọmọ ọ̀dọ̀ ti gé ẹ̀mí ọgá wọn kúrú Àgbo Madagascar ti wà ní Nàìjíríà ṣùgbọ́n kìí ṣe ọ̀fẹ́, a ní láti sanwó-Mínísítà Nibayii, iye awọn to ti ri iwosan gba ti le ni ẹẹdẹgbẹsan(1734), ti eniyan mejilelaadọwa si ti ri ku nitori arun naa.
Òkítì òkúta náà sì wà níbẹ̀ títí di òní olónìí.
14 Ògún 2020 Kano lack of burial ground: Àìtó ibójì ti ń fa awuyewuye ní ìpínlẹ̀ Kano- Àwọn òṣìṣẹ́ ibojí13 Ògún 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Loni ilọpo meji ọwọja ṣiṣe igbọnsẹ sitagbangba lawọn ilu nlanla lo n waye lawọn igberiko bayii, amọṣa ọwọja rẹ a maa pọ lawọn ilu ti eeyan pọ si, eleyi ton kọni lominu nipa awọn ipinlẹ bii Eko.
" wọ ́ n máa ń pè wọ ́ n ní "" epics / historical films "" ."
 irú ìtẹ ́ wẹ ́ gbà báyìí sì máa ń mú kí ọ ̀ sèré túbọ ̀ ṣe eré tí ó dára lójú agbo .
Nitori naa,ni temi,igbese pajawiri ti a n gbe nipa eto idibo 2019 to n bo yii, ko yẹ rara, ohun ti o n komi lominu niyi.
Amọ o ni ọrọ ọhun yi pada nigba ti oun de ọhun nitori nibẹ ni o ti lu si oun leti pe, wọn ti gba owo oku ati aye oun.
” Secondus wa ro ajo eleto idibo iyen, Independent National Electoral Commission (INEC) lati ri i pe eto idibo odun to n bo, lo ni irowo irose , ni eyi ti yoo fi ife orile ede han.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Badagry Historical Wells: Omi inú kànga Wawú ló ń kó ọpọlọ àwọn ẹrú lọ Bawo ni Giadom ṣe di adari ẹgbẹ oṣelu APC?
David Adeleke, ti gbogbo eeyan mọ si Davido ti kede pe, Oluwa ti fi ọmọkunrin kan lanti-lanti da oun ati aya oun, Chioma, lọla.
Joe Biden ni awọn ko ni tọ ipasẹ Donald Trump, awọn yo ran orilẹede China lọwọ lori ọrọ aje wọn ati lati mu ibasepọ to dan mọran waye laarin awọn orilẹede mejeeji.
"Ikọ̀ mi n f'oju wina ikọlu, nitori pe a n ṣe iṣẹ́ wa.
Kò sí ẹni tí ó lè ra ohunkohun tabi kí ó ta ohunkohun àfi ẹni tí ó bá ní àmì orúkọ ẹranko náà tabi ti iye orúkọ rẹ̀ lára.
iru iwa ibajẹ naa lojo iwaju.
 Mó fẹ fi asikò yìí gbóríyìn fún àwọn adájọ kóòtù fún ìgboya wọn láti ṣe ohun tó tọ, èyí jẹ igbéṣẹ̀ akọkọ nínu ìlana òfin ti ó si mú ìwúrí ba àwọn eniyan lati ni igbagbọ nínú ìgbẹjọ Nàìjíríà."
Èyí ni a fi ronú pé, bí ẹnikẹ́ni bá tilẹ̀ sọ bẹ́ẹ̀ sí wa, tabi sí àwọn ọmọ ọmọ wa ní ọjọ́ iwájú, a óo lè wí pé, ẹ wo irú pẹpẹ OLUWA tí àwọn baba ńlá wá tẹ́, kì í ṣe pé wọ́n rú ẹbọ sísun lórí rẹ̀, tabi ẹbọ mìíràn.
Agbẹnusọ ọlọ́pàá ní ìpínlẹ̀ Kano, DSP Adbdullahi Haruna sàlàyé pé, ìwádìí ń lọ lọ́wọ́ lóri ọ̀rọ̀ náà.
Ọpọ ni ko si mọ pe laarin agbo tiata ni eekan oṣere tiata yii ti yan aayo tirẹ pẹlu.
Àwọn ìkìlọ̀ tí ọ̀gá àgbà ọlọ́pàá là kalẹ̀ lórí ìpànìyàn Eko Kílódé tí ìjọba Nàíjíríà kò fòpin sí lílo ike rọ́bà lẹ́ẹ̀kan?
Ẹ wo fidio yii fun alaye ni kikun.
Ni ọjọ kan, Ọrunmila, ti oun naa jẹ arẹwa ọkunrin pinnu lati lọ silu Iwo, ko lee fi Wuraọla se aya, amọ ko to gbera kuro ni ile, lo ti kọkọ beere lọwọ Ifa atun ori ẹniti ko sunwọn se, lati beere pe bawo ni ọhun yoo ti ri.
Àwọn aṣòfin ìpínlẹ̀ Ogun pariwo sí Gómìnà wọn Ọpọlọpọ iwe lo ti jade to jẹ akagbadun ti awọn eeyan n ka fi kọ ẹkọ ṣugbọn ti awọn marun un ti a n gbe yẹwo loni yatọ.
Lójú rẹ̀, ẹni tí ó bá ṣìṣe ni ìṣòro wà fún.
Ìgbìmọ̀ ìgbẹ́jọ́ wọ́gilé ẹ́jọ tó takò iyansipo Sanwo Olu Ṣé kìí ṣe pé ọlọ́wọ́ idán Houdini ti bómilọ nínú odò?
Pẹlu gbogbo igbesẹ ti ẹgbẹ oṣelu to wa nijọba n gbe, ti a si ti ri, ko si aridaju pe wọn ṣetan lati ṣeto idibo ti yoo kẹsẹ jari'' Atiku ni ohun to ṣẹlẹ ninu awọn atundi ibo to ti waye labẹ iṣakoso ẹgbẹ APC to ṣafihan bi APC ṣe fi awọn agbofinro dun kukulaja mọ awọn oludibo n tọka si ohun ti oun n sọ.
Tí ọ̀rọ̀ náà ba ti wá n ri bẹ́ẹ̀ fún ìgbà pípẹ́, ẹ ó gba pé wọ́n tí gba ẹmi ara wọ́n, Dókítà Baka lo sọ bẹ́ẹ̀.
Nítorí rẹ̀ ni a ṣe waasu ìyìn rere fún àwọn òkú, pé bí wọ́n bá tilẹ̀ gba ìdájọ́ bí gbogbo eniyan ti níláti gbà ninu ara, sibẹ wọn óo wà láàyè ninu ẹ̀mí nípa ti Ọlọrun.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Cancer: Àṣe ara mi ni iso ti n run gbogbo bí mo ṣe n ṣèrànwọ́ lórí jẹjẹrẹ Amọ, o ṣeeṣe ki Ilẹ Gẹẹsi kọkọ fun awọn agbalagba ati awọn ti wọn tete n ko arun Coronavirus yii nitori ailera ara wọn.
”Amugbalegbe Pataki ohun wa ro awon
kí ó tó já Àwọn olùgbé Fiditi pé fún ìrànlọ́wọ́ lórí àwọn òrùlé tí atẹ́gùn ojó ṣí lọ Kolade Johnson; Iléeṣẹ́ ọlọ́pàá ní ọwọ́ ti tẹ àwọn afurasí ọlọ́pàá tó ṣekúpaá Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ogunlọgọ awọn ọmọ orile-ede Algeria lo kopa ninu iwọde lati jẹ ki aarẹ Bouteflika fipo silẹ Akọroyin BBC Ahmed Rouba jabọ pe ọpọ ọmọ orile-ede Algeria lo gbagbọ pe alaafia aarẹ naa ti dẹnu kodo debi pe awọn kan lo n loo lati ṣe ijọba ti awọn wọnyi ko si fẹ fi ijọba kalẹ.
eka ilaniloye ati ikede ni ile-ise INEC to wa ni Anambra, lo so eleyii lojoBo,
Mo pa wọ́n mọ́, ọ̀kan ninu wọn kò ṣègbé àfi ọmọ ègbé, kí Ìwé Mímọ́ lè ṣẹ.
3 Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold 4 Kí ló ma n fa Àkúfà nílẹ̀ Yorùbá, àti ọ̀nà àbáyọ?
Bákan náà, òfin àkóso ajakalẹ-arun náà ni yóò rọ́pò òfin iyasọtọ lásìkò ajakalẹ-arun, tí wọn pé ní National Quarantine Act.
Orlando Owoh fun mi ni okiki pupọ nigba aye rẹ- Christiana Iya Orlando Owoh Mo mọ bi Orlando ṣe jiya bẹrẹ iṣẹ orin ṣugbọn nkan pada yipada si rere ki ọlọjọ to de- Lola Okoh to jẹ aburo Orlando Owoh Kìí ṣe gbogbo ohun tí dókìtà ni kí n má jẹ torí àìsàn jẹjẹrẹ ni mo tẹ̀lé- Soyinka Ẹ dẹ̀kun lílo Sniper àti Dichlorvos fún ìtọ́jú oúnjẹ- NAFDAC kìlọ̀ Wo ọ̀nà àbáyọ fún àwọn akẹ́kọ̀ọ́ tí àjọ WAEC gbẹ́sẹ̀ lé èsì ìdánwò wọn ''Àjọ NERC ti fún Disco láṣẹ láti padà sí owó tàríìfù tuntun iná mọ̀nàmọ́ná'' EFCC bẹ̀rẹ̀ ìwádìí lórí ẹ̀sùn ìwà jẹgúdújẹrá tí wọ́n fi kan Fowler tó jẹ́ Alága iléeṣẹ́ FIRS tẹ́lẹ̀ Èmi àti Oladipupo Owomoyela jọ lọ ẹ̀wọ̀n Alágbọn- Caroline Owoh, aya Orlando Owoh Sunny Ade maa n ko 'Gloves' ti Orlando Owoh fi n ja ẹṣẹ tẹlee ni nigba aye rẹ - Folarin Ogunmolawa aburo Orlando Owoh Caroline Owomoyela to jẹ aya Orlando ni: A jọ lọ ẹwọn ni alagbọn a tun jọ de pada de sile ni Koda a ko gbagbọ pe Orlando Owoh ku, a fi bii ala.
Kà nípa ìròyìn mánigbàgbé tí BBC News Yorùbá ṣe láàárín ọdún kan Ọba Adesoji Aderemi, Ọọ̀ni Ifẹ̀ tó gba ipò ọba mọ́ tòṣèlú Pope Francis wọ́gilé òfin tó n dáàbò bo àlùfáà tó bá bá ọmọdé l'òpọ̀ Ẹ̀wọ̀n tí mo lọ ni ẹ̀san ìwà tí mo hù gẹ́gẹ́ bíi olórí ológun- Buhari Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, '500 level'' ni mo wà nígbà tí mo di adélé Ọba' Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Oríṣun àwòrán, Olayomi Koiki Se emi nikan ni ọmọ Naijiria ni, se emi nikan ni ọmọ Yoruba ni?
Àwòrán ayẹyẹ ajọ̀dún ìlù nílú Abẹ́òkúta Àjọ̀dún ìlù bẹ̀rẹ̀ nílú Abẹ́òkúta Ninu ọrọ to sọ ṣaaju ki ajọdun ọlọjọ mẹta naa to bẹrẹ l'ọjọ kẹẹdọgbọn, oṣu Kẹrin, Gomina Amosun sọ pe yatọ si ipinlẹ mẹrindinlọgbọn ni Naijiria ti yoo kopa nibi ajọdun naa l'ọdun yii, orilẹede ilẹ Afrika mọkanlelogun, to fi mọ orilẹede UK ati China ni yoo kopa.
(Ní àtijọ́, ní ilẹ̀ Israẹli, ẹnikẹ́ni tí ó bá ń lọ wádìí ọ̀rọ̀ lọ́wọ́ Ọlọrun, yóo wí pé, òun ń lọ sí ọ̀dọ̀ aríran; nítorí àwọn tí àwa ń pè ní wolii lónìí, aríran ni wọ́n ń pè wọ́n nígbà náà.
Nigba ti BBC Yoruba kan si alukoro Ọlọpaa ipinlẹ Oyo, Olugbenga Fadeyi sọ pe ootọ ni wọn fi okuta fọ ọ lori.
Iná Ibadan: Gbogbo dúkìá tó wà lókè ilé alájà kan náà ló jóná tán
”Lẹ́yìn náà, wọ́n sin OLUWA níbẹ̀.
Ọsinbajo kó Ambọde, Sanwo-Olu lẹ́yìn láti pín owóyàá l‘Eko Ile-igbinmọ aṣoju naa ti gba Aare Muhammadu Buhari nimọran pé ki o da ọga NEMA, Maihaja duro lẹnu iṣẹ, pé ki o fun awọn agbofinro to n gbogun ti iwa ibajẹ n'ilu laṣẹ lati foju wọn ba ilé ẹjọ bi o ti yẹ.
Làá hàn mí dé, ètò tó ń ṣàlàyé ohun tó yẹ ká ṣe láti dènà àrùn Coronavirus Mi o tíì rí olórí tó fẹ́ràn Naijiria tó Baba Obasanjo- Yoruba Council of Elders Ṣe ọmọ inu alaboyun lee ko arun coronavirus yii?
O ni fun iwosan ni wọn n lo igbo fun, ko si yẹ ki wọn maa lo o ni ilokulo.
Tọju ara rẹ dáadáa, jẹun dáadáa, mumi dáadáa, feyinti kí inú rẹ sì máa dùn pé ó ní oyún.
A kọ orúkọ wọn sinu ìwé gẹ́gẹ́ bí ìdílé wọn, ní agbègbè wọn.
''Mo kọ lati ni ibalopọ pẹlu rẹ mọ lẹyin ti mo ti ko arun naa lara rẹ, ti mi o si fẹ ko ṣẹlẹ mọ.
Pẹlu ọpọlọpọ irú òwe bẹ́ẹ̀ ni Jesu fi ń sọ̀rọ̀ ìyìn rere fún wọn, gẹ́gẹ́ bí òye wọn ti mọ láti lè gbọ́.
Aare Buhari tilẹ sọ wi pe igba ọtun lo de ni Naijiria, ati wi pe gbogbo ileri ti awọn ti ṣe ni awọn yoo mu ṣẹ.
Coronavirus tún ti ṣe ọṣẹ́ lórí iṣẹ́ líla ojú ọ̀nà relùwe láti Eko sí Ibadan - Ìjọba àpapọ̀ Àrùn Coronavirus fa'lẹ̀ya láwọn ìletò aláwọ̀dúdú ní Amẹ́ríkà Coronavirus: Ààrẹ ẹgbẹ́ dókítà ní Nàìjíríà covid-19 lè tara òkú Abba Kyari ran àwọn tó péjú síbi ìsìnkú rẹ̀ Oríṣun àwòrán, Bashir ahmad Ewu n bẹ loko lọngẹ, longẹ gan an ewu!
5m owó oúnjẹ El-Zakzaky lè bọ́ ẹlẹ́wọ̀n 208 ní oṣù kan Fayoṣe gba ibi ìjàmbá ọkọ̀ dé ìpolongo ìbò Atiku Ẹ lọ gbé Diezani láàárín ọjọ́ méta - Iléẹjọ́ pàsẹ fún EFCC,DSS Lọjọ Ẹti ni awọn ọmọ ẹgbẹ ẹlẹsin Islam Movement of Nigeria, ti awọn eniyan tun mọ si awọn ọmọ ẹgbẹ Shiite, tun fẹ ẹ ṣe iwọde ifẹhonu han miran niluu Abuja, nitori ẹsun ti wọn fi kan an pe awọn ọmọ ogun pa awọn ọmọ ẹgbẹ naa l'oṣu Kẹwa, ọdun 2018.
Ta ni ó gbìmọ̀ irú èyí sí Tire,Ìlú tí ń fún àwọn ọba ìlú yòókù ládé?
O ni: mi o kọkọ fọwọ si iṣẹ orin ti Orlando n kọ nibẹrẹ ṣugbọn inu mi dun si okiki to mu wa fun mi ati ogo gbogbo idile.
ẹni kan ninu eniyan meje maa nilo itọju ile iwosan bayii End of Gbogbo nkan nipa coronavirus Ilera Mi Ibeere yin Skip Ilera Mi Bawo ni ikọlu coronavirus ṣe buru to fawọn to ni ikọ séèmí-séèmi Lati ọwọ Lesley- Anne ni Faikirk Micchelle Roberts Adari iko eleto iroyin ilera ni BBC Imọran Uk fawọn to ni ikọ séèmí-séèmí ni ki wọn tẹsiwaju lati maa lo oogun to yẹ lojoojumọ to n dena ikọlu gẹgẹ bi dokita wọn ṣe sọ fun wọn.
Fún ìgbà kẹ́ta láàrín oṣù mẹ́ta, àrá tún sán pa àwọn màlúù Fúlàní.
Lockdown updates: Naira Marley gbóríyìn fún Jude Chukwuka pẹ̀lú míliọnù kan Náírà
Iṣẹ́ tí SIM Card nṣẹ ni pé òun ló jẹ́ nkan ìdánimọ̀ nínu ẹ̀rọ yìí.
Nítorí n óo wà pẹlu rẹ.
Edotimi ni NAFDAC ti ṣetan lati ṣe iforukọsilẹ fun awọn ibudo ti ipesẹ awọn ogun ibilẹ naa yoo ti maa waye.
Bí àlejò kan bá wọ̀ sí ilé yín, tí ó bá sì fẹ́ bá yín ṣe àjọ̀dún àjọ ìrékọjá, ó gbọdọ̀ kọ gbogbo àwọn ọkunrin inú ìdílé rẹ̀ ní ilà abẹ́, lẹ́yìn náà, ó lè ba yín ṣe àjọ̀dún náà, òun náà yóo dàbí olùgbé ilẹ̀ náà, ṣugbọn ẹnikẹ́ni tí kò bá kọ ilà abẹ́ kò gbọdọ̀ jẹ ninu àjọ ìrékọjá náà.
Hesekaya ní ọpọlọpọ ọrọ̀ ati ọlá.
Idẹ dídán ni Huramu fi ṣe gbogbo wọn fún Solomoni ọba, fún lílò ninu ilé OLUWA.
“Ìgbàwo ni o óo sinmi ẹjọ́ tí ò ń tò yìí?
Yatọ si ọkunrin to kú, ọkunrin mẹta miran tun farapa, ti wọn si ti n gba itọju nileewosan.
6 mílíọ̀nù ni-APC Ilé ẹjọ kò pàṣẹ dá kíkà èsì ìbò ìpínlẹ̀ Rivers dúró-INEC Ajọ INEC ni ireti wa pe gbogbo ohun to n ja ranyinranyin lori eto idibo lawọn ipinlẹ wọnyii yoo jẹ rodo lọ mumi lọjọ abamẹta.
Nígbà tí Jesu wọ inú ilé, tí ó ku òun ati àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀, wọ́n ń bi í pé, “Kí ló dé tí àwa kò fi lè lé ẹ̀mí náà jáde?
Fún odidi ọjọ́ kan, tọ̀sán-tòru, ni mo fi wà ninu agbami.
Àmọ́ ṣe ẹni tó béèrè ọrọ, lo fẹ́ ìdí rẹ gbọ, nínú ìwádìí ikọ ìròyìn BBC Yoruba, ìjọba àpapọ̀ ti ṣàlàyé pe, oun fẹ́ gba owó náà lati fi mú kí ọrọ aje Nàìjíríà gbéra lásìkò ajakalẹ àrùn Covid-19 yìí, tí epo rọbi kò ta mọ ni ọjà àgbáyé, ti ọ̀rọ̀ aje àgbáyé si dẹnu kọlẹ.
Oríṣun àwòrán, Others O tẹsiwaju pe, oniṣowo ọhun ṣe iforukọsilẹ ilẹ naa pẹlu ileeṣẹ ijọba to n ṣamojuto ọrọ ilẹ, to si sọ pe oun ti bun gomina ana miran nilẹ ọhun.
OLUWA ní,“Ẹ má kọ́ àṣà àwọn orílẹ̀-èdè mìíràn,ẹ má sì páyà nítorí àwọn àmì ojú ọ̀run,bí àwọn orílẹ̀-èdè mìíràn tilẹ̀ ń páyà nítorí wọn,
Gónìmà Abdulfatah náà yóò káwọ pọ̀nyin rojọ́ lọ́dọ̀ àjọ EFCC lẹ́yìn to ba pari sáà rẹ̀, Abdulrahaman Abdulrazak ti wọn ṣẹ̀ṣẹ̀ dìbò yàn náà ti ni gbogbo kúlẹ̀ kúlẹ̀ gómìnà ni òhun yóò tú wo ní kete to ba ti kúro lóri oyè.
Aṣe orogun wọn, Manchester United ti wọn jọ wa ni ilu kan naa yoo fidi rẹmi bi tawọn naa.
Ilẹ Faranse n dari apa kan nigba ti ilẹ Gẹẹsi n dari apa keji labẹ akoso Naijiria.
Rep) ni iwe moyege ti awọn naa ni deede aago meji osan oni ọjọBọ, ọjọ kẹ́rìnlá, osu keta, odun  2019.
Ṣùgbọ́n ìrírí ayọ̀ ni tiwa ní ilẹ̀ Yorùbá ni ti ẹlẹ́sìn dé o.
Ilẹ̀ keji tí wọ́n ṣẹ́ gègé lé lórí bọ́ sí ọwọ́ ẹ̀yà Simeoni, ilẹ̀ tiwọn bọ́ sí ààrin ìpín ti ẹ̀yà Juda.
Mo sì tún bú ẹ̀rín, mo ni,Ìjàǹbáforítì baba erin, òun náà sì súnmọ́  mi, ó ní, Èmi nìyí lọ́wọ́ rẹ.
 kòkòrò ìbà pọ ́ njú-pọ ́ ntọ ̀ ni kòkòrò ènìyàn àkọkọ ́ tí a kọ ́ kọ ́ ṣàwarí .
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Fayose: Ẹ yee ta dukia ti EFCC gba ni kọọrọ 22 Èrèlè 2018 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ajọ to n gbogun ti sise owo ilu basubasu lorilẹede Naijiria, EFCC ti gba ọpọlọpọ dukia lọwọ awọn to jẹbii ẹsun iwa ibajẹ lorilẹede Naijiria Gomina Ayọdele Fayose ti ipinlẹ Ekiti ti ke si ijọba apapọ orilẹede Naijiria wipe asiko to lati kede iye awọn dukia ti ajọ to n gbogun ti ṣiṣe owo ilu baṣubaṣu lorilẹede Naijiria, EFCC ti ri gba pada lọwọ awọn eniyan ti ọwọ ṣinkun ajọ naa ti ba lori ẹsun ṣiṣe owo ilu baṣubaṣu.
Oun naa ti jẹ ẹbun owo to le ni miliọnu mẹta Naira, N3,572,000.
Igbimọ alaṣẹ NLC buwọlu igbesẹ igbimọ amuṣẹya ẹgbẹ naa lati bẹrẹ iwọde kaakiri orilẹede Naijiria lọjọ Aje to n bọ.
Ó sì pe orúkọ ọmọ náà ní Jesu.
Bakan naa ni Ọgbẹni Abe beere iranwọ Naijiria ninu ero rẹ lati di ipo olori mu lagbaaye.
23 Kọ́ ẹ̀kọ́ lọ́dọ̀ mi, kí o sì tẹ́tísí àwọn ọ̀rọ̀ mi; rìn nínú ìwà pẹ̀lẹ́ ti Ẹ̀mí mi, ìwọ yíò sì ní àlàáfíà nínú mi.
Isaaki bá bi wọ́n pé, “Kí ni ẹ tún ń wá lọ́dọ̀ mi, nígbà tí ó jẹ́ pé ẹ kórìíra mi tóbẹ́ẹ̀ tí ẹ lé mi kúrò lọ́dọ̀ yín?
A si le sọ pe Ọba Lamidi Olayiwola Adeyemi ti sisẹ pọ pẹlu awọn gomina to to mọkanlelogun lati ri si idagbasoke ipinlẹ Ọyọ.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Murphy Elégungun Rọba: Mo fẹ́ di ẹnití egungun rẹ rọ jùlọ ní àgbáyé Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Snake Market: Àwọn òńtàjà ẹran ejò ní ẹran ejò dùn ju ẹran adìẹ lọ Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
bi won se n jabo ise won kookan si lojuna ati wa ni ibamu pelu ofin ati ilana isakoso
Awọn oṣiṣẹ nipinlẹ Eko ti gbaradi lati ṣewode ati iyanṣẹlodi kaakiri ipinlẹ naa loni, amọ awọn adari wa ti gbabọde fun wa.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù EndSARS Protest Update: Ẹgbẹ́ àgbà Yorùbá ní ọwọ́ alágbarà ẹ̀yìn odi ló wà nídi ìkọlù tó wáyé l'Eko 18 Ọ̀wàrà 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 23 Ọ̀wàrà 2020 Oríṣun àwòrán, @_el_aaameen/via reuters Aṣiwaju ẹgbẹ Yoruba lagbaye, Yoruba World Congress, YWC, Alagba Banji Akintoye, ti koro oju si bi aarẹ Muhammadu Buhari ṣe foju rena iṣẹlẹ to waye ni Lekki.
Ìhòòhò ni àwọn akọni láàrin àwọn ọmọ ogun yóo sálọ ní ọjọ́ náà.
Ó sàn kí eniyan ní nǹkan díẹ̀ pẹlu ìbàlẹ̀ àyàju pé kí ó ní ọpọlọpọ, pẹlu làálàá ati ìmúlẹ̀mófo lọ.
Nílé Orímóògùnjẹ́ níbití wọ́n ti ń ṣe ìwádìí, Ọlọ́fìn-íntótó rí ẹ̀já òwú kan tí ó wà lára ọ̀kan nínú àwọn ojú kéékèèkéé inú séèfù ó sì mú un.
Ọfà ìbò Jerusalẹmu yóo bọ́ sí ọwọ́ ọ̀tún rẹ̀.
Mo ti fi idà tí ń dán lélẹ̀ fún pípa eniyan, ó ń kọ mànà bíi mànàmáná, a sì ti fi epo pa á.
Bí o bá pinnu láti lọ dandan (nítorí mo wòye pé ọ̀ràn náà wà lọ́kàn rẹ púpọ̀).
Kì í ṣe èyí tí ẹ óo jẹ ní ọjọ́ kan, tabi ọjọ́ meji, tabi ọjọ́ marun-un, bẹ́ẹ̀ ni kì í ṣe fún ọjọ́ mẹ́wàá, tabi fún ogúnjọ́.
Kí ó yọ àkàrà kọ̀ọ̀kan kúrò lára ẹbọ kọ̀ọ̀kan, kí ó fi rúbọ sí OLUWA; yóo jẹ́ ti alufaa tí ó wọ́n ẹ̀jẹ̀ ẹran ẹbọ alaafia náà sára pẹpẹ.
-Olorì Aláàfin, Memunat Adeyemi Kókó ohun tó wà nínú àbọ̀ ìwádìí Orosanye, tó le gba iṣẹ́ lọ́wọ́ òṣìṣẹ́ Buhari pàṣẹ lílo àgbo tí orílẹ̀-èdè Madagascar ṣe fún coronavirus fún ìtọ́jú ọmọ Nàìjíríà Koda, lara awọn ọdọmọde ayaba naa la ti ri awọn bi ibeji, ibẹta fun ọba Adeyemi, ti ọjọ ori rẹ ti le ni ọgọrin ọdun.
Retirement Benefits: Èyí ni mùdùnmúdùn tó wà nínú owó ifẹ̀yìntì àwọn Gómìnà tẹ́lẹ̀ ní Nàìjíríà
 síse ẹran dáradára àti wíwọ aṣọ tó yẹ láti dáàbòbo ara nígbàtí a bá npa tàbi kun ẹran lè ṣe ìrànwọ ́ , bákan náà sì ni wíwọ aṣọ tó yẹ láti dáàbòbo ara àti fífọ ọwọ ́ nígbàtí a bá wà ní àyíká ibi tí ẹnití ó ní àrùn náà wà .
Amọ wọn ni ko si ẹni to ni ẹri to daju to le fihan pe alufaa Babatunde jẹbi ẹsun ti wọn fi kan an.
Ó wọ Tẹmpili lọ láti lọ ṣe ìfilọ̀ ọjọ́ tí àkókò ìwẹ̀nùmọ́ wọn yóo parí, tí òun yóo mú ọrẹ ti ẹnìkọ̀ọ̀kan wọn wá.
Oniṣegun iwosan: Eefin oluṣosun lewu pupọ fun ilera awọn olugbe
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Òṣèré tíátà Yorùbá mẹ́ta gbàmì ẹ̀yẹ pé wọ́n pegedé Òkú ṣùn nínú ìbúgbàmú tó wáyé l‘Eko Àwọn kókó ohun tó wà nínú lẹ́tà tí Aláàfin kọ sí Fayemi rèé N kò ní ìjà pẹ̀lú Fayemi, ipò mi bíi aláàbò àṣà Yorùbá ní mó ṣe kọ lẹ́tà sí gómìnà Ekiti - Aláàfin Wò ó ọ̀nà láti mú ara rẹ dé ibi tó ga jùlọ nínú ìbálòpọ̀ pẹ̀lú ìlànà Tantra Ọ̀sẹ̀ yìí laá gbàwọn ẹ̀sọ́ Amotekun sísẹ́, ìparí oṣù kẹta ni iṣẹ́ yóò bẹ̀rẹ̀ - Akeredolu Ìpele tuntun ló kàn nínú ìrìnàjò ayé mi, ń kò pe ẹjọ́ lóri ìrọ̀lóyé - Sanusi Eniyan to le ni ẹgbẹrun meji ati ẹẹdẹgbẹrin lo ti ni aarun Coronavirus nilẹ America, ti awọn mẹrinlelaadọta si ti ku.
Ẹ ṣọ́ra fún àwọn oníṣẹ́ burúkú.
Gẹ́gẹ́ bi Sanwo-Olu ṣe sọ gbogbo ọlọ́pàá tó bá ń ṣiṣẹ́ ní ìpínlẹ̀ Eko yóò ni ètò adójútòfò ẹ̀mí (Life Insurance).
Dafidi dáhùn pé, “Ó dára, o óo sì rí ohun tí èmi iranṣẹ rẹ lè ṣe.
Ninu àwọn ọmọ Satu, Ṣekanaya, ọmọ Jahasieli, ni olórí;orúkọ ọọdunrun (300) eniyan ni wọ́n kọ sílẹ̀ pẹlu rẹ̀.
Oríṣun àwòrán, Others Amọ, akọroyin BBC ni ọrọ awọn aṣọna ṣọọṣi naa ti n yatọ si ohun ti wọn kọkọ n sọ tẹlẹ pe eniyan kọ lọ wa gbe ọmọ naa.
Obinrin náà lọ sinu ilé rẹ̀ pẹlu àwọn ọmọ rẹ̀, wọ́n sì ti ìlẹ̀kùn wọn; ó bá bẹ̀rẹ̀ sí da òróró náà sinu àwọn ìkòkò náà bí àwọn ọmọ rẹ̀ ṣe ń gbé wọn wá.
Ninu iwadii ni wọn ti rii pe ohun to wa ninu iwe ẹri ọjọ ibi Zephany kii ṣe otitọ rara nitori pe wọn ko ri akọsilẹ rẹ ni ile iwosan Retreat Hospital ti wọn ni wọn bii si.
Àwọn ọmọ Reueli ni Nahati, Sera, Ṣama, ati Misa.
kele-kele lasiko re lojuna ati tete wa woroko fi sada lori oro isuna naa,
 mo wá ń fa oorun ọ ̀ ún fin-ìn bi igbà tí ẹ ̀ fọn bá mùjẹ ̀ .
Olori Zynab kí Yeyeluwa tuntun ti Ile ifẹ kú oríire Oríṣun àwòrán, @oloriofficia Àkọlé àwòrán, Olóri Ìlé-Ifẹ tẹlẹ̀rí dáwọ ìdúnú pẹ̀lú Ọ̀ọ̀ni Olorì Ile -Ifẹ tẹ́lẹ̀ri Zynab- Otiti Wuraola Obanor to jẹ́ olori láàfin tẹ́lẹ̀ri fun Ọba Adeyeye Ogunwusi tí gba ojú òpó instagram rẹ̀ lọ láti kí olori tuntun láàfin Kabiyesi, olori Shilekunola Monronke Oluwaseyi kú oríire.
awon mejeeji lori oro ile gbigbe ati  oro
”O wa ro  oludibo ti ko ba
Bakan naa ni orilẹede Uganda ti paṣẹ ki ọkọ ofurufu kankan maṣe wọle si orilẹede naa lati dẹkun itankalẹ arun naa.
Mọ̀ síi nípa ìtàn ojúbọ̀ nàá O ni nigba mii, ẹni to kọkọ ku le jẹ pe oun ni okun to so ẹbi ro, ti iran yoo si jade si ẹbi naa pe ki wọn o sẹ etutu ki okun ẹbi naa ma ja.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Nigeria Police recruitment 2020: Ṣé àbáwọle sójú òpó NPF policerecruitment.
O gboriyin fun wọn gẹgẹ bi akọni loju ija to n san ẹbọ alaafia.
Ó jẹ́ eléré àwàdà tí ó mọ ohun tí ó máa ń wu ọmọdé, tí ó sì máa ń mú inú ọmọdé dùn.
"Dokita Anthony ṣalaye pe kẹmika to wa ninu ogun apẹfọn ti orukọ rẹ n njẹ ""Organophosphate"" buru pupọ ti o si ma n ṣe akoba fun ẹni to ba ba ṣe alabapade."
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù BUSA19: Bí ètò ìgbéyàwó ààrẹ Buhari kò bá ṣe lọ rèé -àwọn ènìyàn Nàíjíríà 11 Ọ̀wàrà 2019 Oríṣun àwòrán, @others Àkọlé àwòrán, Lẹyin to ti hande pe iroyin ẹlẹjẹ ni igbeyawo aarẹ Buhari ti awọn eeyan n pariwo lori ayelujara; sibẹ ọpọ aworan to panilẹrin fun ipalẹmọ lo kun ayelujara bayii Oriṣiiriṣi aworan ati akọle to pani lẹrin lo ti kun ori ayelujara ni eyi ti awọn eniyan fi n ṣeto ipalẹmọ igbeyawo ofege ti wọn ni o yẹ ko waye laarin Aarẹ Buhari ati Hajiya Sadiya Umar Farouq.
Nítorí náà mo fẹ́ kí àwọn opó tí wọ́n jẹ́ ọ̀dọ́ tún lọ́kọ, kí wọ́n bímọ, kí wọ́n ní ilé tiwọn.
Ọjọ kẹ̀wá, Osù Kẹfa ní wọn fí panpẹ́ ọba mú Hushpuppi ní United Arab Emirates lórí ẹ̀sùn lilọ gbajuẹ pẹlu ẹrọ ventilator to le ni $35million.
” Ki aare to de si Hague ni asoju orile ede Naijiria ti ba awọn akoroyin soro pe bo tile je pe awọn kan n tako ile-ejo agbaye to n ri si iwa odaran sibe aare Buhari nigbagbo pe isẹ ti  ile-ẹjọ  agbaye naa  n se yoo dekun awọn iwa odaran lorile ede agbaye.
Wolii naa ni ọgbọn iṣeju ti awọn kan fi wa lori obninrin ni awọn miran fi n ka owo gọbọi.
Oríṣun àwòrán, Pastorfoluadeboye Bí ẹgbẹ́ One Million Boys ṣe bẹ̀rẹ̀ rèé àti ọṣẹ́ tó ṣe n'Ibadan Ọlọ́pàá tún dé o!
Oríṣun àwòrán, Gold Eniola Bayii, ninu hilahilo ni awọn obi ọmọ naa wa, ti awọn onisegun oyinbo si n fa omi si iya ọmọ naa lara ni ile iwosan kan ni ilu Ondo.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ṣeyi Makinde ṣèdánrawò fún ayẹyẹ ìbúra Bidemi Kosọkọ di ìyá ìkókó Ọ̀tá Nàíjíríà ni Saraki àti Dogara - Buhari Awọn eeyan yoku ni akẹkọ mẹjọ, ti wọn n gba idanilẹkọ lọwọ lasiko ti awn osisẹ EFCC wọ ileẹkọ Yahoo naa.
Ilẹ̀ bá hu koríko jáde, oríṣìíríṣìí ohun ọ̀gbìn ati ewéko tí ń so ati oríṣìíríṣìí igi eléso tí ó ní irúgbìn ninu.
Isẹlẹ banujẹ lo waye ni ile Igbakeji Gomina Ipinle Ondo tẹlẹri, Alhaji Lasisi Olubọyọ, nigbati wọn ba oku ọmọ rẹ, khadijat ni ile ọrẹkunrin rẹ, Adeyemi Alao ni Akure, ní ipinlẹ Ondo, lẹyin ti wọn ti n wa ọdọbinrin naa lati bi osẹ diẹ sẹhin.
Kano Supplementary Election: Àwọn ẹgbẹ́ òṣèlú 42 tàpá sí èsì ìbò àtúndì Kano
Nítorí pé a ti ń fún un l'ésì fún ọdún pípẹ́.
Jesu tẹjú mọ́ wọn, ó wí pé, “Kò ṣeéṣe fún eniyan, ṣugbọn ti Ọlọrun kò rí bẹ́ẹ̀, nítorí pé, kò sí ohun tí Ọlọrun kò lè ṣe.
O níláti kíyè sára gidigidi, nítorí ẹ̀rù àwọn aládùúgbò rẹ ń bà mí.
Haṣemu, ará Gisoni, ati Jonatani, ọmọ Ṣagee, ará Harari; 
"Lẹyin naa ni wọn yẹ inu igbo ti afurasi naa sa wọ daadaa, nibi ti ọwọ ti tẹ ẹ.
N650,000 péré ni mò ń gbà gẹ́gẹ́ bíi owó oṣù -Gomina Ọyọ A padà san owó ìtanràn fáwọn ajínigbé kí wọ́n to fi àwọn mẹ́tẹ̀ẹ̀ta sílẹ̀- Ẹbí Spaghetti, mílíìkì, Chivita àti Àǹkàrá sọ Rabiu dèrò ẹ̀wọn ni Eko Amẹ́rika dá akẹ́kọ̀ọ́ padá nítori Facebook Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, U.
Ọlọrun kì í ṣe eniyan bíì mi,tí mo fi lè fún un lésì,tí a fi lè jọ rojọ́ ní ilé ẹjọ́.
Afurasí afipábánilópọ̀ kàgbákò, obìnrin tó jà lólè fi eyín gé nǹkan ọkùnrin rẹ̀ jábọ́ lásìkò ‘Blow Job’ Àwọn ọba alayé, Mínísítà àti gómìnà nílẹ̀ Yorùbá ṣèpàdé pẹ̀lú ìjọba àpapọ̀, àbọ̀ rèé Iná ṣẹ́yọ nílé ìtajà aya Ajimobi lẹ́yìn ọjọ́ mẹ́ta tó jáde opó Awọn apoogun naa ni awọn ti lo abẹrẹ ajẹsara naa ni ara eniyan bii ẹgbẹrun lọna mẹtalelogoji ni orilẹede mẹfa, ti ko si ni ipalara kankan fun wọn.
Lara awọn ohun to wa ninu iwe naa ni iṣẹ iwadii, ati mimu awọn afunrasi.
Gẹ́gẹ́ bí olùṣọ́-aguntan rere, mo ṣetán láti kú nítorí àwọn aguntan.
Oyo Politics: Onímọ̀ nípa òṣèlú ní kí 'Gomina Makinde má polongo ọ̀rọ̀ àwọn aráàlù
Tí ọ̀rọ̀ bá sì ti rí bẹ́ẹ̀, ó ti pọndandan ki ènìyàn dáàbò bo ẹmi ara rẹ náà.
O tẹsiwaju wi pe, ohun to maa n gbẹyin ọrọ lọpọ igba ni ki awọn ọmọ onilẹ naa gba owo ibọbẹ lẹyin idunkukulaja wọn, ṣugbọn airi owo gba lọdun yii lo da gbọmi si omo o to silẹ."
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù English Premier League: Arsenal jẹ́ọ́ àgbò tó tàdí mẹ́yìn fún Aston villapẹ̀lú àmì ayò mẹ́ta sí méjì 22 Owewe 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Ori lo ko Arsenal yọ lọwọ Aston Vila ni idije Premiership to waye ni papa iṣire Emirates.
Iroyin salaye pe, awon ipinle ti o n san owo kekere ju fun awon olokada ni ipinle Bauchi N65.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Sunday Igboho: Ẹ fi Ògún búra fún wa láti jà fún ilẹ̀ Yorùbá láì gbé Amotekun sábẹ́ ìjọba Bakan naa ni ẹgbẹ salaye lọjọ isẹgun pe, ilana sisan owo oṣu awọn oṣiṣẹ fasiti (UTAS) ti wa nilẹ bayii, lati tan imọlẹ si owo oṣu oṣiṣẹ sisan ti ijọba apapọ beere fun.
O ke gbajare pe ki awọn obinrin maa daa ninu ile naa bi wọn ṣe n daa lorii ẹrọ ayelujara.
ipade apero kewaa igbimo awon alase to n mojuto ijoba ibile lorile-ede
Canada Visa Application: Canada bẹ̀rẹ̀ iṣẹ́ lórí fọ́ọ̀mù àwọn tó fẹ lọ sí orílẹ̀-èdè náà
Satide ọjọ kẹrindinlogun oṣu keji odun yii lo ti yẹ ki eto idibo naa waye ṣugbọn ajọ INEC sun eto naa siwaju nitori awọn kọkọrọ kan to ba eyin aja jẹ nipasẹ imurasilẹ ajọ naa.
bale ẹjọ fun awon iwa  titẹ ẹtọ ọmọniyan
Nítorí náà, wọ́n fi Daniẹli ati àwọn ẹlẹgbẹ́ rẹ̀ sí ọ̀dọ̀ ọba ní ààfin.
9 Èmi nsọ̀rọ̀ sí ẹ̀yin tí a yàn nípa ohun yìí, àní bíi ẹnìkan, kí ẹ̀yin baà lè wọ inú ìsinmi mi.
 láìsí lára àwọn ènìyàn , àwọn ẹyin lè pẹ ́ tó oṣụ ̀ mẹ ́ ta .
Moscow Plane Crash: Ìjàmbá ọkọ̀ bàálu pa arìnrìǹàjò 41
Ganiyu, ti o jẹ olori ẹka ti Sango Ota naa wa rọ awọn ọlọkọda lati maa lo koto-adabori ki wọn si maa din ere sisa ku lati dẹkun gbigba ori mọlẹ.
Nisinsinyii, gẹ́gẹ́ bí Ẹ̀mí ti darí mi, mò ń lọ sí Jerusalẹmu láì mọ ohun tí yóo ṣẹlẹ̀ sí mi níbẹ̀, 
Baba a máa kọ́ àwọn ọmọ rẹ̀, nípa òdodo rẹ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Natalia Mufuta ìyá Yakub, Kamil àti Adam sọ̀rọ̀ lórí bí wọ́n ń sọ èdè mẹ́rin pàpọ Ipinlẹ Ogun ati Ekiti nikan kọ lo ni ero yii lori wiwọle pada awọn akẹkọọ.
 O so pe : “Ojuse ajo NCC ni lati daabo bo awon
Wo ohun tí yóò ṣẹlẹ̀ ní ìpàdé àwọn èèkàn Yorùbá láti mú kẹ́ẹ dìbò fún Tinubu ní 2023 Ìròyìn ayọ̀!
Amọ niwọn igba to jẹ pe yeye ọmọ nii gba ọmọ, iya rẹ, Abigail Ajike ṣe atilẹyin alailẹgbẹ fun nidi iṣẹ naa, ti Olusola si dara pọ mọ ẹgbẹ oṣere tiata Akin Ogungbe to wa nilu Abeokuta lọdun 1959, lẹyin to pari ẹkọ girama.
Bí ẹnìkan bá fọ́ eniyan lójú, kí wọ́n fọ́ ojú tirẹ̀ náà; bí ẹnìkan bá ká eniyan léyín, kí wọ́n ká eyín tirẹ̀ náà, bí ẹnìkan bá gé eniyan lọ́wọ́, kí wọ́n gé ọwọ́ tirẹ̀ náà, bí ẹnìkan bá gé eniyan lẹ́sẹ̀, kí wọ́n gé ẹsẹ̀ tirẹ̀ náà.
Bàbá ẹni ọdún 71 fi ẹ̀ṣẹ́ rán ìyàwó rẹ̀ lọ s'ọ́run àpàpàǹdodo ní Ìdànrè Sunday Igboho rán agbénipa sí mi láti gb'ẹ́mi mi-Auxilliary Èèyàn 20 mííràn tún ti lùgbàdì ààrùn Coronavirus ní Naijiria Òfìfo ṣọ́ọ̀ṣì pa aṣọ dà fún àwọn Páṣítọ̀ Nàìjíríà Ninu ọrọ ti ẹ, Harbimoo Ola sọ pe ki aarẹ Buhari o ma ṣe fi ọjọ kun isede ọlọjọ mẹrinla to wa ni ipinlẹ Eko, Ogun ati ilu Abuja.
Dokita naa ni kii ṣe ohun to bojumu ki awọn eeyan jade lọ sita lati ko arun ba awọn mọlẹbi ti wọn fi silẹ ninu ile.
Amọ, wọn fikun pe, ti ko ba ṣeeṣe nitori awọn ọmọ to ni ipenija ẹkọ, ki wọn tẹlẹ gbogbo ofin to ku bi lilo oogun apakoko kaakiri agbeegbe naa, ki wọn si maa fọ ọwọ wọn loore-koore.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Nibo ni awọn owo wọnyii ti n wa?
O ṣe àpèjúwe olóògbé náà bíi èèyàn rere àti ẹni apọnle bí ó tilè jẹ́ pé èrò àwọn nínú òṣèlú ṣe ọ̀tọ̀ọ̀tọ̀.
Ẹgbẹ naa ni ijọba ko ni ẹri to daju rara lati ba oludije aarẹ tẹlẹ naa se ẹjọ lori ẹsin idaluru ti wọn fi kan.
Agbẹnusọ fun Aarẹ Buhari, Garba Shehu ṣalaye pe Buhari nikan lo le sọrọ lori ohun to n da yiyan minista tuntun duro.
Ko si bii eeyan yoo se sọ itan Ẹgba, ti a ko ni darukọ Lisabi Agbongbo Akala.
Justice for Jubril: Ọwọ́ ọlọ́pàá ìpínlẹ̀ Kebbi tẹ bàbá àti ìyàwó rẹ̀ méjì fún pé wọn so ọmọ pọ̀ mọ́ ewúrẹ́ fún ọdún méjì
"Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ẹ wá gbọ òwe lẹnu ọmọ Igbo bíi àgbà ilẹ Yoruba ""Awọn afurasi naa ti wa ni ileesẹ ọlọpaa Katwe, ẹsun iwa to le mu ki aarun Covid-19 pọ si lao si fi kan wọn""."
Ìlùi ìbẹ̀ǹbẹ́ àti bàtá, ṣẹ̀kẹ̀rẹ̀ àti kìibótó, gòjé àti bóló,àti onírúurú àwọn ìlù míràn àti ti ènìyàn dúdú àti ti ènìyàn funfun; gbogbo ìwọ̀nyí ni ó pé sí ibi àríyá náà, ọjọ́ ńlá ni.
Ṣugbọn kàkà kí ó sàn, ńṣe ni àìsàn náà túbọ̀ ń burú sí i.
Nígbà tí Jesu rí i inú bí i: ó wí fún wọn pé, “Ẹ jẹ́ kí àwọn ọmọde wá sí ọ̀dọ̀ mi, ẹ má dá wọn dúró, nítorí ti irú wọn ni ìjọba Ọlọrun.
Ẹyin le jẹ ki eroja ara ji pepe, ki atọ ara ọkunrin le ṣiṣẹ dara dara.
Bi Joshua ti n leri leka naa ni Ruiz Jr ko dakẹ, O ni digbi loun n duro de Joshua ninu ija ọjọ Satide.
'IBB tẹ ń pariwo pé ó kú, kò kú o, Ko ko ko lara ọta ń le!
'Mo kan sara sawọn ayasọlo' Kingston lọmọ Áfíríkà tó gba ohun tí Hulk Hogan kò rí gbà Àwọn ọmọ Iyabọ Ojo rí Bàbá lẹ́yìn ọdún mẹ́fà Ọ̀pọ̀ òṣèré tíátà tó ń sàìsàn ni kò ṣe dáadáa fẹ́gbẹ́ - Jide Kosọkọ Hakeem ṣalaye fun BBC Yoruba pé idán lásán ni ṣugbọn ọpọ rẹ n bani lẹru.
Nigba ti akọroyin BBC Yoruba ba ẹgbọn oloogbe sọrọ, Adesewa Gbadebo ni irọ gbaa ni iroyin to n tan kalẹ pe ileeṣẹ naa fun awọn ni owo.
ó tọ ọkunrin náà lọ ninu àgọ́ rẹ̀, ó sì fi ọ̀kọ̀ náà gún òun ati obinrin náà ní àgúnyọ.
Ninu awọn olori ọkunrin orile-ede bii Brazil, Israel ati Hungary, a ti ri pe wọn di ẹbi asise wọn ru ara ita ti wọn si ni awọn eeyan ilẹ miran lo ko arun naa wọ ilẹ wọn.
Ogún jẹ ami isiro, ti onka rẹ bẹrẹ lati ookan de ogun, eyi si ni ara onka ni ede Yoruba.
Saaju ni Frey ti sọrọ lasiko to n ba awọn oniroyin sọrọ to sì salaye pe iṣẹlẹ naa bani lọkan jẹ gidi.
Igba ti yoo fi bọ sipo pada, Ruiz tun ti fi ẹṣẹ mi doju rẹ bolẹ.
Ṣugbọn ẹ̀ ń bèèrè pé, ‘Báwo ni a ti ṣe lè yipada?
Ìlú kò mọ ohunkóhun nípa iṣẹlẹ màálù tó kú nilu Ikarẹ- Oba Olukarẹ Ìdí tí mo ṣe fẹ́ yọ ayédèrú ìdí ńlá tí mo ní- Sophie Ìgbà tí òògùn ẹ̀jẹ̀ ríru lè ṣiṣẹ́ jù rèé- Onímọ̀ Mo pàṣẹ pé kí ọ̀gá owó ìfẹ̀yìntì tẹ́lẹ̀, Maina sì wà látìmọ́lé- Adájọ́ Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Kí wọn baà lè la ojú sílẹ̀ṣugbọn kí wọn má ríran;kí wọn gbọ́ títíṣugbọn kí òye má yé wọn;kí wọn má baà ronupiwada,kí á má baà dáríjì wọ́n.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ẹni ti ko riran to nlọ'ta ni Mushin Ọmọ ọdọ Oloye Opeyemi Bademosi dẹmi rẹ legbodo ni Parkview Estate Ile alakọpọ Parkview Estate naa ni isẹlẹ miran tun ti waye.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Nigeria swearing-in 2019: Wo àwòrán tó jẹ ojú ní gbèsè nípa ìbúra ààrẹ àtàwọn gómìnà 29 Èbibi 2019 Àkọlé àwòrán, Gele mi ga ju tiẹ lọ lawọn obinrin fi ibura se ni Naijiria E wo akojọpọ awọn iroyin to lamilaaka nipa ibura awọn gomina ati aarẹ: Olu-ilu Naijiria, Abuja: Àkọlé àwòrán, Igba ọtun wọle de, ọmọ Naijiria, Aarẹ Muhammadu Buhari lo sọ bẹẹ bo se n bẹrẹ saa keji pẹlu iburawọle Oríṣun àwòrán, VON Àkọlé àwòrán, Igbakeji aarẹ Yemi Osinbajo naa se ibura Àkọlé àwòrán, Oye naa tun ko sile wa lẹẹkeji.
Koda, o ni ọwọ oun ti tẹ awọn miran ti oun mu mọlẹ nibẹ.
O ni iṣẹ ilu ati awọn ti a yan sipo ni lati daabo to peye bo ẹmi ati dukia awọn eniyan abẹ wọn.
Awọn mejeeji ni awọn ko mọ nipa ẹsun ti wọn fi kan awọn.
Ṣaaju ni Kọmiṣọna to n risi ọrọ ayika ati ipese omi ni ipinlẹ Eko, Tunju Bello ti kilọ pe ki awọn eeyan mura silẹ fun ojo arọrọda to ṣeṣe ko yọri si ikun omi lọdun yii.
ireti pe bi awon se sọ ẹkunwo ọgbọ̀n  egberun naira owo osu awon  osise di ofin, yoo wu won lori  lati maa se ojuse won nipa minu idagbasoke ba
NNPC pàṣẹ fáwọn òǹtàjà epo pé owó epo bẹntiróòlù kò gbọdọ̀ lé ní N145
Gbogbo igba lo maa n la ala ifiyajẹni to n waye lojojumọ ni ọgba ẹwọn naa.
Ẹgbẹrun mẹtalelọgọta o le marundinlgọta (63,055) lawọn ti ara wọn ti ya nigbati aarun naa si ti gbẹmi awọn ẹgbẹrun kan ati mejilelaadọjọ (1173) eeyan.
Èwo ninu àwọn angẹli ni ó fi ìgbà kan sọ fún pé,“Jókòó ní ọwọ́ ọ̀tún mi,títí n óo fi ṣe àwọn ọ̀tá rẹ ní àpótí ìtìsẹ̀ rẹ?
Bakan naa ni kii lọ si ipade kankan ti ijọba ba pe lai si arigbamu idi ti ko fi lọ si ipade.
Nítorí náà, gbadura fún àwọn eniyan wa tí wọ́n kù.
Ṣugbọn àwọn eniyan burúkú dàbí ríru omi òkun,nítorí òkun kò lè sinmi,omi rẹ̀ a sì máa rú pàǹtí ati ẹrẹ̀ sókè.
 Àwọn okùnfa míràn ní ìsanrajù àti ẹsẹ ̀ wíwú , àti dídàrúgbó .
Oríṣun àwòrán, @dayoamusa Àkọlé àwòrán, Dayo Amusa Dayo Amusa Temidayọ Amusa jẹ́ ọmọ ìpínlẹ̀ Ogun tí a bí ní ìlú Eko, akọ́bí ọmọ márùn-ún ni.
Awọn ọlọpaa ni ko tii si ẹni to lee sọ pato ohun to ṣẹlẹ tawọn eeyan fi da ina sun awọn mejeeji yii.
Àwọn tó mọ̀ nípa ìpànìyàn Lekki yóò fojú winá òfin - Sanwo-Olu sí Becky Anderson Bode George jẹ ko di mimọ pe bi Tinubu ṣe n ri gba nibẹ lo ṣe jẹ pe ọmọ rẹ nikan ṣoṣo naa lo n ṣe akoso gbogbo nkan bii ina to wa nibi agbegbe ti wọn ni ki wọn pa ina ibẹ.
Àwọn elétò ààbò fẹ́sùn kan àwọn Shia tí wọ́n gba ìgbòrò kan fún ọjọ mẹ́ta ni ìlú Abuja pé wọ́n gbe ado olro àtí àwọn ǹkan ìjà olóró míràn.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Oyo NLC: A kò bẹ̀rẹ̀ ìyanṣẹ́lódì láti d'ẹ́rù ba ìjọba tuntun 27 Èbibi 2019 Àkọlé àwòrán, Oyo NLC mú ìlérí rẹ̀ ṣẹ, ó bẹ̀rẹ̀ ìyanṣẹ́lódì Ẹgbẹ oṣiṣẹ ijọba nipinlẹ Ọyọ, NLC, ti so iyanṣẹlodi rẹ rọ.
In his message to the nation on the beginning of the Ramadan, the president says fasting is not just merely meant to stay hungry or thirsty, but an opportunity to strive for inner purification and self-accountability.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ogun COVID-19 test: Ìjọba kéde ìlànà tuntun fún ìwọlé àwọn akẹ́kọ̀ọ́ tó fẹ́ ṣe ìdánwò àṣejáde 2 Ògún 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 3 Ògún 2020 Oríṣun àwòrán, @dabiodunmfr/theencounter.
Ni ọdun mẹta sẹyin lo fi ilu rẹ ni Katsina silẹ wa si ilu Abuja fun igbe aye to larinrin sii.
Orile ede Russia ti seleri lati tubo tepele mo ibasepo re pelu orile ede Naijiria lori eto oro aje ati okoowo.
Wọn kan n foju ara ilu gbolẹ nikan ni.
Hajj: Ǹjẹ́ o mọ pàtàkì Ọjọ́ Àràfá fún àwọn mùsùlùmí?
Igbimọ gbogboogbo ti orilẹ-ede agbaye (UN) ti o n ri si eto irinajo lo sọ bẹẹ.
Garba kede pe ijọba yoo pese gbogbo awon nkan aabo ti won yoo nilo, bii iboju ati 'hand sanitizer' ti won yoo lo.
Gbogbo ohun aláìmọ́ tí wọ́n rí ninu tẹmpili OLUWA ni wọ́n kó sí àgbàlá ilé náà.
Yóo fọ́ àwọn òpó ilé oriṣa Heliopolisi tí ó wà ní ilẹ̀ Ijipti, yóo sì dáná sun àwọn ilé àwọn oriṣa ilẹ̀ Ijipti.
Ailera yii tumọ si ki eeyan o deede ni ipaya pe ewu wa fun oun lasiko to tọ, ati asiko ti ko tọ ọ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Afro Brazilians: ìlú Rio ni a máa kọ ilé ìṣẹmbáyé náà sí Kabiesi ni oju kii pọn iṣin ki ọmọ inu ẹ ma là, o di dandan ki ori awọn ogo wẹẹrẹ yii kan oke.
ọmọ Meliki, ọmọ Adi, ọmọ Kosamu, ọmọ Elimadamu, ọmọ Eri, 
Aare Buhari soro yii ni idahun ibeere si oro ti gomina
Olufunmilọla Babayẹmi ni obinrin opó lati ọdun mẹrinla sẹyin ti o ṣalaye iriri rẹ lati tọ ọmọ rẹ mejeeji gẹgẹ bi opó.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Rape: Bàbà ọmọ ọdún márùndínlọ́gọ́rin kó HIV ran ọmọ ọdún mẹ́rìnlá lẹ́yìn tó fi ipá báa lò 30 Ògún 2019 Baba ọmọ ọdun marundinlọgọrin kan ti ko kokoro arun HIV ran ọmọ ọdun mẹrinla kan lẹyin to fi ipa ba a lo ni ipinlẹ Rivers.
Laarin ọsẹ kan, eniyan mẹtalelọgọta ni awọn aṣekupani da ẹmi wọn legbodo ni Guusu Kaduna.
Peter Aho to ṣẹṣẹ pe ẹni ọdun mẹrindinlogun lo gba bọọlu wọnu awọn ti wọn fi bori ifẹsẹwọnsẹ ti wọn fi jawe olubori patapata.
Biku lo loko ni, bi pakute ni, ipade di papa
Nítorí náà, OLUWA pa á, ó sì gbé ìjọba rẹ̀ fún Dafidi, ọmọ Jese.
Sẹnetọ naa ti awọn eniyan ti mọ fun bi o ṣe maa n fi ijo dabira, fi ẹsẹ rajo ranpẹ nibi ipolongo naa.
25 àárọ̀ ni olùkọ́ fi tipá bá akẹ́kọ̀ọ́ náà lòpọ̀ nínú ọọ́fìsì
Waziri sọ pe, ni igba ti oun n gbe ero ọkọ kan lọ si agbegbe Papa Ajao, to wa ni Mushin, ni nkan bi aago mẹjọ aṣalẹ ni iṣẹlẹ naa waye.
O ni èyi ṣe pàtàkì gẹ́gẹ̀ bi ọ̀nà láti da ìtànkalẹ̀ àrun náà dúro nitori oun gbòrò si ni ojoojumọ ni, eyti yoo si ṣe ilu lánfani ti gbogbo ènìyàn ba fi ọwọsọwọpọ.
Ile-ise ti o n samoju to awon etikun lorile-ede Nigeria ati ijoba ipinle Eko ni won je ile-ise ijoba ti won jo n fowosowopo, ojuse ijoba ni lati wa ni aisegbe niru ise-akanse ti o tobi bayii, eyi ti o se pataki julo ni lati pese ayeka to dun wo fun awon onile-ise aladani”.
Lẹsẹkẹsẹ ẹsẹ̀ rẹ̀ ati ọrùn-ẹsẹ̀ rẹ̀ bá mókun.
Ninu atẹjade ti NDCD fi lede loju opo Twitter rẹ, o ni wọn yoo ṣe ipade ita gbangba kan lori ayelujara lati jiroro lori bi ipagọ naa yoo ṣe lọ laisi ibẹru pe awọn agunbanirọ yoo lugbadi arun Coronavirus.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Jude Chukwuka: Wò ó bí òwé Yorùbá ṣe yọ̀ lẹ́nu ọmọ Igbo Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Obasanjo: Ìpasẹ̀ ìparun ni Nàíjíríà ń tọ̀ lábẹ́ Buhari12 Òkùdu 2019 Baba Obasanjo: Àwọn ọ̀rẹ̀ sàpèjúwe Baba Obasanjọ ní ọjọ́ ìbí 83 wọn5 Ẹrẹ̀nà 2020 Ìjọba Naijiria: Ọ̀rọ Olusẹgun Ọbasanjọ kò jọ wá lójú mọ́12 Ọ̀pẹ̀̀ 2018 Fídíò, Olusegun Obasanjo: Màá fi ìyókù ayé mi sin Ọlọ́run áti ènìyàn28 Agẹmo 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 3 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 5 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Bí a bá yẹ àṣà yìí wò, ó fi ara jọ ìṣamì àwọn ẹlẹ́sìn Krístì.
Gómìnà Kẹsan – Ọ̀gá Michael Ọ̀tẹ́dọlá – Gómìnà fún ọdún kan àti oṣù mẹwa – ọdú́n márùndinlọ́gbọ́n titi di ọdún mẹ́rinlélógún sẹhin
NWC fi lede wi pe ni itẹle idajọ Ileejọ Kotẹmilọrun lo mu ki awọn gbe igbesẹ naa lọna to ba ofin ẹgbẹ mu.
Jeremiah Addo: Ọmọ ọdún méjì tó ṣeeṣe kò mọ̀wé jù l'ágbàáyé
Èèyàn mẹ́sàn-án ti kú ní ilé alájà tó wó l'Eko Live: Ìjọba ìpínlẹ̀ Èkó bẹ̀rẹ̀ ilé wíwó ní Lagos Island Live:Àwòrán bí ìjọba ìpínlẹ̀ Èkó ṣé n wò ile ládugbó Lagos Island Oríṣun àwòrán, Facebook/Lagos State Ministry of Health Àkọlé àwòrán, Jide Idris ni awọn dupẹ lọwọ gbogbo eeyan to kopa ninu idoola ẹmi awọn eeyan Ikede iye eeyan to ku yi jẹ ohun ti awọn ara ilu ti n reti lati igba ti iṣẹlẹ naa ti waye ti awọn kan si n ro wi pe iye eeyan ti ijọba kede kere si iye ti o ku.
farajin lati se ise pelu won  tun  gbena wo iko  olote Boko Harama ni agbegbe Mboa, Mboa-Kura,
Ìbáwí ní gbangba sàn ju ìfẹ́ kọ̀rọ̀ lọ.
 O tun wa ro aare Buhari lati mojuto eto eko ati ilera lorile ede
Wọ́n mú Ẹsita lọ sọ́dọ̀ ọba Ahasu-erusi ní ààfin rẹ̀ ní oṣù Tebeti, tíí ṣe oṣù kẹwaa, ní ọdún keje ìjọba rẹ̀.
Nítorí pé a ti pèsè iná ìléru sílẹ̀ láti ìgbà àtijọ́ fún ọba Asiria;iná ńlá tí ń jó pẹlu ọpọlọpọ igi.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Orlando Owoh: Èmí àti Oladipupo Owomoyela jọ lọ ẹ̀wọ̀n Alágbọn- Caroline Owoh, aya Orlando Bakan naa ni wọn kọlu ọfiisi Ọga Agba ileewe naa, ati ti awọn olukọ.
Wọn kò ṣe ọ̀kan kan ninu gbogbo ohun tí o pàṣẹ fún wọn láti máa ṣe; nítorí náà ni o ṣe mú kí gbogbo ibi tí ó ṣẹlẹ̀ sí wọn bá wọn!
oba Edmund Daukoru, Mingi XII, Amanyanabo ti 
Àwọn olórí náà rú ẹbọ fún ìyàsímímọ́ pẹpẹ ní ọjọ́ tí wọ́n ta òróró sí i, láti yà á sí mímọ́.
Botilẹjẹ pe awọn obi ati aburo rẹ ko le sọrọ, o ni oun nifẹ ẹbi naa, ati pe oun yoo ṣetọju awọn obi naa ti ọna ba ti la fun oun lọjọ iwaju.
gomina Ambode wa dupe pupo lowo iyaafin Adesoye fun ise takun-takun re fun
Wọ́n sọ pé àwọn ọ̀tá náà ti dé Hasasoni Tamari, (tí a tún ń pè ní Engedi).
Tọ̀sán-tòru ni wọ́n ń yí orí odi rẹ̀ ká;ìwà ìkà ati ìyọnu ni ó sì pọ̀ ninu rẹ̀.
"Àwọn orílẹ̀-èdè China ló kọ̀kọ̀ bẹ̀rẹ̀ abẹ́rẹ́ ajẹsára ní ọọrundunrun kẹwàá, wọ́n n pe ǹkan ni ""Variolation"" èyí túmọ̀ sí tísù àwọ̀n ènìyàn ti ará wọ́n lé han si èpo tó maa ǹ wà lóju egbò ti àìsàn kan ba fà á láti mú ìdàgbàsókè ba àwọ́n àfani tó ń ba ààrun ja lára."
Awon osise orile-ede Mozamdique so pe, orile-ede Mozambique  ti da awon omo orile-ede Ethiopia bi aadota  ti won wo orile-ede ohun lona aibofin-mu pada si orile-ede won bayii, leyin irinajo bi ose mefa ti won rin wa si orile-ede naa.
towo-tese ti iko naa ba fun oun laaye ati darapo mo won fun ibasise po olojo
Èyí ni ọ̀nà tí àwọn obìnrin n gbà kó ara wọn sí wàhálà nítorí ara bíbó Ṣé o ti gbọ́ ohun ti Ọọni Ifẹ́ àti Soyinka parí ọ̀rọ̀ Yorùbá sí?
Baba Obasanjọ kò ní àrùn Coronavirus- NCDC NCDC kéde èèyàn 437 míràn tó ṣẹ̀ṣẹ̀ lùgbàdì Covid-19 ní Nàìjíríà, 142 gbàwòsàn Iná jó àwọn ènìyàn 10 tó ń gbà ìwòsàn arùn Coronavirus níbùdó ìtọ́jú Eric ati Tochi ni wọ́n lé kúrò nílé ẹlẹ́gbọ̀n àgbà BBNaija lọ́sẹ̀ yìí Iroyin ni eleyii ti fun Dieziani Alison-Madueke ni anfaani lati le bọ lọwọ ajọ EFCC to n ṣewadii rẹ lati igba to ti wa ni ilu London fun ọdun mẹrin bayii.
Oríṣun àwòrán, Temilolu Akinboola Adele naa sọ pe Ọba Aroloye wa lori itẹ nigba ti awọn janduku naa n na oun ninu aafin rẹ.
Wayi o, alaga ajọ amusẹya lori itankalẹ arun Coronavirus, Boss Mustapha ti kede peajakalẹ arun naa ti koba ọrọ aje awọn idile eyi to n fa arun ọpọlọ, asilo oogun ati iwa ipa ninu idile.
Wọn se lo kọ lati gbọ ti Ọba Akanbi ti o si ti i kuro lọna.
Gomina ni: Awọn ọdọ yii ti fi ohun marun un ti wọn fẹ ranṣẹ si ijọba, funra mi ni mo fi jiṣẹ fun aarẹ Buhari ni Abuja, Mo ti tu gbogbo awọn ti wọn mu satimọle nitori iwọde silẹ, mo ti ri owo igba milionu naira fun awọn opo ati ẹbi awọn ti wọn pa.
“Ohunkohun tí o bá kọ́ kórè ninu oko rẹ, ilé OLUWA Ọlọrun rẹ ni o gbọdọ̀ mú un wá.
Ijamba ọkọ ran eeyan mẹjọ lọ srun lopopona marosẹ Ibadan si Eko
kan lati fowosowopo pelu ile-ise olopaa ati ajo eleto aabo , ki eto idibo ohun
Ìyàlẹnu ni ó jẹ́ fún mi ní ọjọ́ kejì tí bàbá mi pè mí tí ó kí mi, tí ó sì fún mi ní owó fún orííre pé mo di obìnrin, tí ó sì ní kí n mú owó náà fún ìyá mi, kí ó sì fi se óúnjẹ fún mi.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù BBC sọ̀rọ̀ lórí òfin tí Burundi fi dè é 4 Èbibi 2018 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Burundi kò fẹ́ BBC fún ìgbà díẹ̀ Ilé iṣẹ́ BBC ṣe ìwádìí àṣẹ ti Ijọba Burundi pa pé kí wón dẹ́kun iṣẹ́ láti Ọjọ́ Keje oṣù Karùn ún ọdún 2018 Ìjọba orílẹ̀-èdè Burundi kéde òfin pé kí ilé iṣẹ́ BBC lọ rọọ́kún lati ọjọ́ Ajé to ń bọ̀ lataari pé ominú kọ wọ́n lórí ètò kan ti BBC ṣe sita.
 O ni bi won se yo ekun guusu kuro ninu ise akanse fun todun 2016 si 2018 naa ku die kaa to.
    Adéfirítì múra àtí lọ wa lébìrà dandan ó sì wí fún wa kí a múra di ọjọ́ kejì kí a ba òun lọ kí àwa náà tilẹ̀ wo bí ọ̀run Àpáàdì ti rí.
Gbogbo ìwọ̀n yẹtí wúrà tí ó gbà jẹ́ ẹẹdẹgbẹsan (1,700) ṣekeli, láìka ohun ọ̀ṣọ́ ati aṣọ olówó iyebíye tí àwọn ọba Midiani wọ̀, ati àwọn nǹkan ọ̀ṣọ́ tí ó wà lọ́rùn àwọn ràkúnmí wọn.
Ààrẹ Buhari fi kún sàá Muhammad Tanko nípò adelé adájọ́ àgbà Onnoghen gba ìwé ìfisùn míràn látọ̀dọ̀ ìgbìmọ̀ NJC UNO bẹnu àtẹ́ lu ìdàdúró Onnoghen A ti wọ́gilé ìwọ́de lórí COZA tí a fẹ́ ṣe tẹ́lẹ́ nítorí.
Oríṣun àwòrán, Abiola Ajimobi O wa fi kun un pe bi obinrin ba ka ọkọ rẹ mọ ale yiyan, ko daarijii ko si gbagbe ni o.
Bakan naa  ni won tun mu awon afurasi mẹ́rìndínlógún ati awon
Kí á tó dá ayé ni a ti yan Kristi fún iṣẹ́ yìí.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Aṣíwájú ni Nàíjíríà nínú ìdènà Coronavirus, ohun márùn-ún rèé tí àgbáyé ń kọ́ lára wa Ọ̀gá àgbà ọlọ́pàá, DSS, ẹ fún Sanusi lómìnira àti rìn fanda padà - Iléẹjọ́ pàṣẹ Ọkùnrin tó bẹ́ sì òdò ọ̀sà pa ọ̀rẹ́bìnrin rẹ̀, lòun náà fi fẹ́ kú - Iléeṣẹ́ ọlọ́pàá Kò sẹ́ni tó fẹ́ pa Buhari o, ọkùnrin tó pakuru mọ́ ààrẹ kàn fẹ́ bọ̀ọ́ lọ́wọ́ ni - Femi Adesina Yorùbá rẹwà, kọ́ nípa àwọn ọ̀rọ̀ tí ìró ẹnu wọn jọra àmọ́ tí ìtumọ̀ wọn yàtọ̀ Pẹlu ikede yii, ẹyọ eniyan kan pere lo ni arun Coronavirus ni Naijiria, to n gbe iwosan ni ile iwosan ajakalẹ arun ni agbeegbe Yaba ni ipinlẹ Eko.
BÍ ÈDÈ YORÙBNÁ SE DI KÍKỌ SÍLẸ̀
Ta ni ẹni náà tí ó lè gbọ́ kí Olọ́wọ̀ sọ èdè Gẹ̀ẹ́sì tí kò ní rò pé ó ti jáde ní fásitì tàbí pé wọ́n bíi sí ilẹ̀ Gẹ̀ẹ́sì ni?
Mo fẹ́ kí ẹ mọ̀ dájúdájú pé, wọ́n ti gba èrè wọn ní ẹ̀kúnrẹ́rẹ́.
Awọn janduku naa lo ṣe ikọlu sibẹ lasiko ti ijọba bẹrẹ si ni pin awọn ohun iranwọ naa fun awọn eniyan to wa ni agbegbe naa.
Sáájú ni ìjọba ti ní àwọn akẹ́kọ̀ọ́ yóò padà sílé ìwé ni ọjọ́ kejìdílógun, oṣù kíní ọdún 2021, sùgbọ́n ojoojúmọ ni ààrùn Coronavirus n péleke sí.
Amojúẹ̀rọ tó ń nu bàtà fi wá oúnjẹ òòjọ́
Àpò 65 là fi gbé owó N1.
je pe ohun ti ẹ ni ko pọ sibẹ ,ti ẹ  ba
Aṣẹ yii ko tumọ si pe wọn ti bẹrẹ si ni i lo chloroquine fun itọju coronavirus, ṣugbọn wọn ti ṣe ọpọlọpọ ogun naa pamọ lati lo, ti awọn ọpọ eeyan ba ko aarun naa.
” Aare tun wa ro iko agbaboolu
’’Minisita wa rọ awon igbimo naa lati  tete wa  ilana ti ajo tuntutn naa yoo maa tẹle lati bẹrẹ isẹ wọn , ni eyi ti yoo fi mu ipinnu omo orile ede Naijiria sẹ.
Coronavirus ló lé mi kúrò níléèwòsàn UCH n'Íbàdàn- Ogun Majek Gbogbo alaye akọroyin ileeṣẹ BBC lati jẹ ki o di mimọ fun ẹni ti awọn oṣere onitiata yan gẹgẹ bi aarẹ TAMPAN naa mọ pe ara ojuṣe ti ileeṣẹ iroyin lee ṣe fun pipe akiyesi iranwọ fun itọju agba oṣere naa lo bọ sẹyin eti rẹ to si ni oun ko lọrọ lati sọ nipa rẹ.
Awọn alẹnulọrọ ati awọn ẹlẹgbẹjẹgbẹ gbogbo ni wọn pariwo sita lati ke si ileesẹ ọtẹlẹmuyẹ apapọ orilẹede Naijiria, DSS wipe ko tu ọgbẹni Toni Ezimakor, akọroyin agba ni ọfiisi ileesẹ iroyin Independent Newspapers nilu Abuja ti wọn ti fi si ahamọ lati ọjọọru ọsẹ to kọja.
Saulu bá ní, “OLUWA Ọlọrun Israẹli, kí ló dé tí o kò fi dá iranṣẹ rẹ lóhùn lónìí?
Nigba to n kede isẹlẹ naa loju opo Instagram rẹ, ilumọọka osere tiata mii, Ibrahim Chatta fi tẹdun tẹdun daro awakọ to jẹ Ọlọrun nipe naa, ẹni to pe orukọ rẹ ni Juwọn.
Ó tún lò ninu wọn, ó fi ṣe ohun èlò orin tí wọ́n ń pè ní hapu ati gòjé fún àwọn akọrin rẹ̀.
'Ẹ bá wa sọ fún Sanwoolu kó dárí jì wá o, ìpinú tí wọ́n ṣe l'Eko kò m'ọ́gbọ́n wá rárá' Ọwọ Gómìnà Makinde làṣẹ wà bóyá a ó fí òfin dé Okada ní Oyo -OYRTMA A kò ní jẹ́ k'ẹnikẹ́ni tó láàrùn Coronavirus wọlé sí Nàìjíríà- Àjọ tó ń rí sí ìwọléwọ̀de Ìyàwó ilé lu ọmọ ọkọ rẹ̀ pa ní ìpínlẹ̀ Ogun Ni ti pe awọn ti ko ba forukọ silẹ fun kaadi idanimọ ọhun bakan naa yoo san owo itanran ẹgbẹrun lọna ọgọrun un naira, o ni ajọ naa ko tii gbe aṣe lati ṣe bẹẹ jade.
"Lójú òpó Instagram rẹ̀ ló ti kọ́ ọ pé ""Jayden Oluwatobiloba, ìwọ ni ǹkan to dára jùlọ tó ti ṣẹlẹ̀ si mi láyé"" ""mo dúpẹ́ bi ó ṣe mú kí ayé mi ni ìtumọ̀ láti ọjọ́ ti ó di dáye"" Femi Adebayo Oríṣun àwòrán, Others Femi Adebayo náà kò gbẹ́yìn níńu àwọn ti ọmọ wọ́n ń se ọjọ́ ibí fún ọmọ wọ́n lóri ayélújára."
Ti ọdun ba si ti n lọ sopin ni orin naa maa n gbalẹ kan , eyi tawọn eeyan n lo lati se adura funra wọn.
Toni Iwobi, yii ti lo odun mejidinlogoji to di asojusofin akoko to je eniyan dudu ti yoo koko jawe olubori gege bi asojusofin leyin to ti sise fun opolopo odun gege bi adari eka kan ni ile ise to n risi igbokgbodo awon arinrinajo fun League Party.
Láti inú ilẹ̀ ni ẹ̀jẹ̀ àbúrò rẹ ti ń kígbe pè mí.
Nígbà tí ó kù díẹ̀ kí á dé ìlú náà a bẹ̀rẹ̀ sí gbọ́ igbé onírúurú àwọn ẹyẹ àti àwọn ọ̀kẹ́rẹ́.
Wòlíì Kasali ní Dolapo Awosika kò lé ìyàwó òun jáde 'Alífábẹ́ẹ́tì Ohùn Oduduwa di ìtẹ́wọ́gbà ni Ajaṣẹ' Ṣẹ gbọ́ nípa Alájọ Ṣómólú, tó ta mọ́tò ra kẹ̀kẹ́?
Mo ní ìrètí ati wá sọ́dọ̀ yín, kí á baà lè jọ sọ̀rọ̀ lojukooju, kí ayọ̀ wa lè di kíkún.
”Lasiko yii ni mo da egbe Yoruba sile nile Amerika, egbe naa kiise fun omo Yoruba nikan, mo da egbe yii sile lati maa ran awon omo Naijiria to ba wa siluu Oyinbo lowo, nipa fifun won nile, ise ati pipese eto iranwo miiran fun won titi di igba ti won yoo fi ri iwe igbelu  gba.
Awon agbateru ni: “A pe Saraki lodun yii gege bi eni kan ti yoo se alejo Pataki nibi odun naa gege bii ise wa lodoodun ni.
Nitori naa, ki a maa hu iwa aito nitori pe o je obinrin , ko dara rara.
Lara awọn ẹsun tawọn asofin ilu Nairobi fi kan gomina Sonko ni pe o lo owo ilu lati ran ọmọbinrin rẹ lọ silu New York lorilẹede Amerika lọdun 2018.
Oríṣun àwòrán, Bimbo Oshin Nǹkan mẹ́sàn án tí Mùsùlùmí gbọdọ̀ ṣe nínú oṣù Dhual- Hijjah Alága àjọ EFCC Ibrahim Magu yóò tún bẹ ìgbìmọ̀ olùwádìí Aàrẹ wò lónìí Ilé ẹjọ́ wọ́gilé ìgbẹ́jọ́ Olalekan 'Woodberry' Pọnle Òru òní ní ìjọba á ti afárá 'Third Mainland' ní Eko; Wo àwọn ọ̀nà míràn tí o leè gbà lẹ́yìn tí wọ́n bá tìí Bakan naa ni ileeṣẹ kan yaa lẹnu pẹlu ẹbun bantabanta lọjọ naa.
Nígbà náà ni Peteru mú un, ó bẹ̀rẹ̀ sí bá a wí.
Day 18: Ṣé o fẹ́ mọ òtítọ́ nínu ọ̀rọ̀ ìpolongo àwọn oludije sípò aarẹ Naijiria?
Ipade ohun waye labe ajo ti o n ri si eto oro aje  fun ile Africa ninu ajo isokan orile-ede agbaye eyi ti akori re dale: “Ayipada: ipade eto oro aje ati idokowo ile Africa”.
Gbogbo àwọn tí wọn ń gbé inú ayé tí a kò kọ orúkọ wọn sinu ìwé ìyè bá ń júbà rẹ̀.
Bí àwọn ọmọ Israẹli bá pa òfin mi mọ́, tí wọ́n sì tẹ̀lé gbogbo ìlànà ati ìdájọ́ mi tí mo fún wọn láti ọwọ́ Mose, n kò ní ṣí wọn nídìí mọ́ lórí ilẹ̀ tí mo ti yàn fún àwọn baba wọn.
" Ọjọ mẹjọ ni ọmọ tuntun naa fi gba itọju nileewosan, ki ara rẹ to ya.
Ṣùgbọ́n bí ó bá jẹ ìbejì, ẹ̀ẹ̀mẹ́jọ ni.
Ẹ gbàgbé àpáta ìgbàlà yín,ẹ gbàgbé Ọlọrun tí ó da yín.
Ọ̀kan ninu àwọn meji tí ó gbọ́ ọ̀rọ̀ Johanu, tí ó tẹ̀lé Jesu ni Anderu arakunrin Simoni Peteru.
Nítorí ìfẹ́ rere rẹ tí kì í yẹ̀.
Eli ti di arúgbó gan-an ní àkókò yìí.
O wa tesiwaju pe,baalu ogun ofurufu orile ede Naijiria ati ISR ti orile ede Niger lo jumo fi ado oloro se ikolu si awon iko olote Boko haram ni Tumbum rago.
Ilẹ isinku apapọ fun awọn ọmọ ologun to wa nilu Abuja ni eto isinku naa ti waye.
iwa ọdaran to waye ni awon  ile- ijọsin
Nígbà tí Ojó Oba yìí dalé gbèrégbèré tí ó kíyèsi pé àwon asáájú gàpère rè ti n séwó sí i, ni ó bá pe àwon jèpé eégún tirè (tí wón kángun sí i), ó sàlàyé wí pé láti pínnísín ni Àyìnlá olórí erú òun ti n sin òun tèmítèmí láì rojú tàbí puró Nítorí náà, kí won ó jé kí omobìnrin òun ó mú òkan péré nínú dúkìá òun kí gbogbo ìyókù pátá ó sì jé ti olórí erú òun.
Ọjọ́ mẹfa ni kí ẹ máa fi ṣiṣẹ́, ọjọ́ keje jẹ́ ọjọ́ ìsinmi tí ó lọ́wọ̀, èyí tí ó jẹ́ mímọ́ fún OLUWA.
Ti a ba n sọrọ ki eeyan dantọ, ọga ni Okonkwo ninu ṣiṣe alaye ohun to n lọ lori papa ere bọọlu Awọn kọmẹntatọ miran ninu itan Naijria ti wọn pegede ti wọn fi gbọrọ jẹka ni Isola Folorunsho Kelvin Ejiofor Yinka Craig Sabastine Ofurum Emeka Odikpo Fabio Lanipekun Walter Oyatogun Àìsàn ìtọ̀ súgà kò túmọ̀ sí pé èèyàn ti gba ọjọ́ ikú- Dókítà Wilson Góòlù pọ̀ ní ìlú Madaka ṣùgbọ́n wọn kò ní ọ̀nà fún ọgọ́rùn ún ọdún Àwọn ọmọ Nàìjíríà bu ẹnu ẹ̀tẹ́ lu NTA lórí ìgbóhùnsáfẹ́fẹ́ ìdíje bọ́ọ̀lù Ilé ẹjọ́ ni agbábọ́ọ̀lù ọmọ Nàìjíríà, Dickson Etuhu jẹ́bi ẹ̀sùn títa ìdíje Sweden Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
O ni ohun ti Aarẹ ana, Goodluck Jonathan pẹlu ṣe ni.
Amọ ó ni ṣe tori pe o kan jẹ Abiola ni wọn ṣe pada yẹ ẹ sì.
Orilẹede Kenya ni tiẹ ti fagile saa eto ẹkọ ọdun 2020 yii.
Amọ awọn alasẹ ti sẹ pe irọ ni ọrọ naa, tijọba Ogun si fi ọrọ lede lori Twitter rẹ pe irọ̀ọ ni ọrọ naa.
Ìpín ti ẹ̀yà Juda tóbi jù fún wọn, nítorí náà ni ẹ̀yà Simeoni ṣe mú ninu tiwọn.
Ọ̀rọ̀ àlùfànṣá tí ó dá lórí ìtako àjọ̀dún Òyìnbó ti gba ẹ̀rọ-alátagbà ìlú China kan, èyí mú kí yíyan ayẹyẹ Kérésìmesì láàyò le koko fún àwọn tí ó rò wípé ní ìkọ̀kọ̀ ni ayọ̀ àwọn gbọdọ̀ wà.
Nígbà tí mo bá wà láàrin àwọn tí ó gba ètò ti Òfin Mose, èmi a máa fi ara mi sábẹ́ Òfin Mose, kí n lè jèrè àwọn tí ó gba ètò ti Òfin, bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé n kò gba ètò ti Òfin Mose fúnra mi.
Ninu awọn nnkan ti wọn ko si ibudo ise nkan isembaye lọjọ si naa, lo ni awọn nnkan to tọka si awọn orisa Yoruba, to fi mọ Ogun, IIfa ati Esu wa.
OLUWA yọ sí wọn láti òkèèrè.
Ile iṣẹ amohunmaworan orilẹ-ede Egypt ni o kọkọ daku nile ẹjọ ni ki ọlọjọ to de.
Ọ̀rọ̀ náà kúrò l’ẹ́nu bàbá mi títí, ó sọ ọ́ títí ó fi bí wa, láti ọjọ́ náà wá ni ó sì ti pa á láṣẹ pé, kí ẹnikẹ́ni má ṣe bú ẹnìkejì rẹ̀ lẹ́hìn mọ́, nítorí nínú gbogbo ọmọ ènìyàn tí ń bẹ lórí ilẹ̀ ayé, kò sí ọ̀kan ṣoṣo tí ó pé nínú wọn.
Diamond lo gba ami eye lara “Bongo Flava” to se.
Ko tan sibẹ o, Ọgbẹni Mustapah tun kede pe awọn eero ọkọ baalu labẹle le ma a de si papakọ ọkọ ofurufu ni wakati kan ataabọ ṣaaju irinajo wọn, dipo wakati mẹta ti ijọba kede tẹlẹ.
Talaka tí ń ni aláìní láradàbí òjò líle tí ó ba nǹkan ọ̀gbìn jẹ́.
Ní ọdún tí ń bọ̀ pẹlu, ohun tí ó bá lalẹ̀ hù ni ẹ óo máa jẹ bákan náà.
Mo mú ọ wá láti ṣépè lé àwọn ọ̀tá mi, ṣugbọn ò ń súre fún wọn.
Lẹ́yìn ìdásílẹ̀, Alaa ṣì tún ní láti sun ọrùn alẹ́ nínú àgọ́ ọlọ́pàá ìbílẹ̀ẹ rẹ̀ fún “ọdún márùn-ún”.
Ìrẹ̀wẹ̀sì yóo dé bá àwọn ará Ijipti,n óo sọ ète wọn di òfo.
Àwọn aláboyún f'ẹ̀hónú hàn lórí owó ìgbẹ̀bí ní ìpínlẹ̀ Òǹdó
Bakan naa lo gba imọran pe ki awọn eeyan maa lo ọkọ oju omi bii lati Ikorodu si Mile 2 ati bẹẹ bẹẹ lọ.
Adele alukoro ile iṣẹ ologun Naijiria tun rọ awọn ọmọ-ogun pe ki wọn wa lojufo lai bikita ohun tawọn to n da rogbodiyan silẹ n ṣe.
 O wa gba awọn eeyan nimọran pe lootọ ni ko si ohun to buru ninu ki eeyan gba aawẹ lati fi wa oju Ọlọrun amọ ẹnikọọkan gbọdọ mọ iye aawẹ ti ara rẹ lee gba lai fa akoba si agọ ara, o si lee jẹ ọjọ kan, ọsẹ kan abi ju bẹẹ lọ, ti okun ara rẹ ba ti gbe."
agbaboolu PSG ati AC Milan, George Weah ti o je aare orile-ede Liberia bayii.
Ọlọrun Súre fún Jakọbu ní Bẹtẹli.
Ara mi kò lè balẹ̀ títí yóo fi kọjá.
nígbà tí mo bá ń pada bọ̀, lẹ́yìn tí mo bá ti ṣẹgun wọn tán, ẹnikẹ́ni tí ó bá kọ́kọ́ jáde láti wá pàdé mi láti inú ilé mi, yóo jẹ́ ti ìwọ OLUWA, n óo sì fi rú ẹbọ sísun sí ọ.
 Mo ti kede lọjọ Kẹjọ osu Kinni ọdun 2019 pe mo n se iranti mama mi, lọjọ kẹtala ni mo joye ẹsin, ọjọ Kẹrinla osu Kẹrin ni mo se ọjọ ibi, ti ọmọ mi si se ọjọ ibi tiẹ ni ọjọ Kẹfa osu Kẹfa, bẹẹ ni mo si ile tuntun lọjọ Kọkanla osu Keje, ams ko si ibi ti Toyin Abraham ti ba mi yọ rara lasiko awọn ayẹyẹ naa.
Ko si ti i si ẹnikẹni to kú.
Mo gbàgbé sùnlọ sìnú ọkọ̀ òfurufú, ẹ̀rù ikú bà mí -Tiff Ejò lé ààrẹ Liberia kúrò ní ọ́fíìsì Mọ̀ síi nípa ǹkan tí o lè ṣe láti dènà ibà Lassa Ọrọ yi to de'ti igbọ Minisita feto ilera, Chilatu Chilufaya, ti mu ki o ṣabẹwo pajawiri sile iwosan naa.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ààwẹ Ramandan àti irú ouńjẹ tí o lè jẹ Àìsàn jẹjẹrẹ mú ẹ̀mí Aisha Abimbọla lọ Saraki: Ẹ gbà mi, ọ̀gá ọlọ́pàá fẹ́ kó bá mi Bákanaa ni Aarẹ Muhammadu Buhari rọ gbogbo Musulumí pe kí wọn ránti láti ran àwọn tí kò rí jẹ tó lọ́wọ́.
Ẹ gbọ́ ohun tí OLUWA, Olùràpadà Israẹli, ati Ẹni Mímọ́ rẹ̀, sọ,fún ẹni tí ayé ń gàn,tí àwọn orílẹ̀-èdè kórìíra,iranṣẹ àwọn aláṣẹ,ó ní, “Àwọn ọba yóo rí ọ, wọn óo dìde,àwọn ìjòyè yóo rí ọ, wọn óo sì dọ̀bálẹ̀.
    Èmi ni mo wí fún yín, ẹ̀yin ọ̀rẹ́ mi, lọ́jọ̀ tí mo ti dé inú ayé n kò rí ìlú tí ó jẹ́ ìlú eléèérí bi ìlú yìí rí.
Banki Nàìjíríà, CBN ṣàlàyé nípa àwọn tó máa rí gbà nínú owó ìrànwọ́ N75b tíjọba gbé kalẹ̀ Mọ̀ sí i nípa àwọn ọmọ Nàìjíríà mẹ́sàn-án tó ń díje nínú ìdìbò ilẹ America lọ́jọ́ Ìṣẹ́gun Ẹ dẹ̀kun lílo Sniper àti Dichlorvos fún ìtọ́jú oúnjẹ- NAFDAC kìlọ̀ Wo ọ̀nà àbáyọ fún àwọn akẹ́kọ̀ọ́ tí àjọ WAEC gbẹ́sẹ̀ lé èsì ìdánwò wọn ''Àjọ NERC ti fún Disco láṣẹ láti padà sí owó tàríìfù tuntun iná mọ̀nàmọ́ná'' EFCC bẹ̀rẹ̀ ìwádìí lórí ẹ̀sùn ìwà jẹgúdújẹrá tí wọ́n fi kan Fowler tó jẹ́ Alága iléeṣẹ́ FIRS tẹ́lẹ̀ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, EndSars, EndSwat Protest: Òbí agbábọ̀ọ̀lù Gbenga Tiamiyu Kaka àtàwọn míì tí ọlapàá pa sọ̀r Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Fídíò, Akomolede àti Asa lórí BBC Yorùbá: Mọ̀ síi nípa ẹ̀kún ìyàwó níbí3 Bélú 2020 Fídíò, Soyinka Cancer: Àṣe ara mi ni iso ti n run gbogbo bí mo ṣe n ṣèrànwọ́ lórí jẹjẹrẹ27 Bélú 2019 Australia: Igbe ayekòótọ́ sàànfàní, ó kó olówó rẹ̀ yọ lọ́wọ́ ikú gbígbóná4 Bélú 2020 Ibadan: Oluwapọ̀nmile sọ ìrírí rẹ̀ lọ́wọ́ àwọn sójà tó fìyàjẹ́ ní Ibadan3 Bélú 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 3 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 5 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Àwọn ni yóo máa ṣe ìtọ́jú àwọn igi àkànpọ̀ ibi mímọ́, ati àwọn ọ̀pá ìdábùú rẹ̀, àwọn òpó rẹ̀ pẹlu àwọn ìtẹ́lẹ̀ rẹ̀, ati gbogbo àwọn ohun èlò rẹ̀, ati gbogbo iṣẹ́ tí ó jẹ mọ́ wọn; 
Amọ nitori ofin iṣẹẹ tiwa, kii ṣe gbogbo ọrọ lo ṣee sọ sita tori oniruuru eeyan lo n ka iroyin wa tabi wo fọnran ti a ba fi sita, bẹẹ si ni a gbudọ jẹ ki ohun gbogbo dọgba fun awọn ololufẹẹ wa.
Ṣugbọn Fatima ni Buhari ati baba oun Daura wọnu nitori pe wọn jọ dagba papọ ni ti ọrọ wọn si ye ara wọn ni eyi ti ko dun mọ Aisha ninu lẹyin ti Buhari ti di Aarẹ .
Wọ́n rí Elija pẹlu Mose tí wọn ń bá Jesu sọ̀rọ̀.
Kọmiṣọnna naa pari ọrọ rẹ pe ki awọn eeyan joko sile to ba ṣeeṣe ki ọkọ le dinku loju popo lasiko atunṣe afara naa.
Cristiano Ronaldo lo kọkọ fori gbe bọọlu wọ le Ajax ki Ajax to dayo naa pada.
Aare Buhari wa ba awon eniyan ipinle Kwara ati gbogbo awon omo ilu Ilorin kedun iku oloogbe naa.
O salaye pe o yẹ ki wọn gbosuba kaare fun ikọ Amọtẹkun ni pẹlu bi wọn ti se doju ija kọ awọn ọdaran ni lawọn ijọba ibilẹ mẹrin.
Àwọn ọmọ Reubẹni tún àwọn ìlú wọnyi kọ́: Heṣiboni, Eleale, Kiriataimu, 
Wo àwọn oúnjẹ tí àṣẹ Buhari leè mú kó gbówó lórí Bi o ba tun se n lọ, a m aa mu iroyin naa wa fun yin.
Wo àwọn ibùdó ìtàn Mánigbàgbé ni Ìbàràpá méjèèje Bakare tun gba ijọba Naijiria ni imọran lati tubọ mojuto irinajo afẹ ni Naijiria bii ti awọn orilẹ-ede ilẹ okeere O ti lé ni ọdún kan ti mo ti n jí pátá l'ádugbò- Chukwajekwu Eziigbo Lord Lucifer ni ó kọkọ ni ènìyàn mílíọnù kan to wòó lóri Youtube- Yekini Bakare Mo fi iṣẹ́ agbẹjọ́rọ̀ sílẹ̀ lọ bẹ̀rẹ̀ Ifá dídá ní ìlú òyìnbó- Ella Popoola Ọlọ́pàá Uganda rí ohun ìpara olóró nínú ‘baby’ tí ẹnìkan pọ́n sẹ́yìn bí ọmọ Mubaraq mẹnuba awọn ami ẹyẹ to ti gba ati awọn iṣẹ to ti ṣe to lami laaka Àwọn ọjọ́ ìsìnmi tó máa wà nínú ọdún 2020 ní Nàìjíríà Ìjọba Nàìjíríà ti rí obìnrin tó wà l'óko ẹrú ní Lebanon gbà Ẹ̀bùn ọdún tuntun tó yááyì ni ikọ̀ Amotekun - Soyinka Ariwo kò jẹ́!
ate ayelura ti egbe PDP fun ẹri won ,bakan naa ni igbimo naa tun kọ jalẹ
Awọn nnkan ti ile asofin ti ba de ibi to lami Lọjọ kọkandinlọgbọn, oṣu kẹta ọdun 2018, ile asofin Naijiria kede awọn aba ti wọn ti ṣiṣẹ lori tabi ti wọn buwọlu lati igba ti wọn ti bẹrẹ saa kẹjọ lọdun 2015.
Oríṣun àwòrán, Vanguard Ramatu ni oun naa lo anfaani akoko keresi yii lati tan ọrọ ifẹ, alaafia, irẹpọ ati ipamọra kalẹ ni.
Nigba to n bawọn akọroyin sọrọ lẹyin ipade naa, aarẹ apapọ fun ẹgbẹ osisẹ NLC, Ayuba Wabba ati akẹẹgbẹ rẹ fun TUC, Kaigama Bobboi, sọ fun awọn akọroyin pe lootọ ni ilọsiwaju wa nipa aawọ to wa nilẹ.
Jesu bà lọ sí ilé Farisi yìí lọ jẹun.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù French Open: Serena kò gbọdọ̀ wọ aṣọ 'Black Panther' mọ́ 25 Ògún 2018 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Serena Williams ti gba ife ẹ̀yẹ French Open lẹ́ẹ̀mẹ́ta ọ̀tọ̀tọ̀ 'Aṣọ Black Panther ti mo wọ kii ṣe fún oge tabi igberaga' Awọn alaṣẹ idije French Open ti paṣẹ fun agbaọjẹ agbabọọlu tẹnisi, Serena Williams, wi pe ko gbọdọ wọ aṣọ dudu to dabi ti inu fidio 'Black Panther' mọ lọjọ iwaju ninu idije naa.
Iroyin sọ pe El-Rufai duna duna fun ipo olori awọn oṣiṣẹ ni ọdun to kọja, amọ ileeṣẹ BBC ko ni ẹri to fi idi iroyin yii mulẹ.
Ṣugbọn àwọn ọmọ ogun Kalidea lé wọn, wọ́n bá Sedekaya ní pẹ̀tẹ́lẹ̀ Jẹriko; wọ́n mú un lọ sí ọ̀dọ̀ Nebukadinesari ọba Babiloni ní Ribila ní ilẹ̀ Hamati, ó sì dá Sedekaya lẹ́jọ́.
Peller gbé 'gbá ìbò fún 2019 Iroyin iku wọn naa ti da ọgbẹ ọkan silẹ fun awọn ara Tanzania, ti ọpọlọpọ wọn si n kẹdun iku wọn nitori wọn fẹran awọn ibeji naa lọpọlọpọ.
Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Lagos Tanker Accident: Ìjàmbá ọkọ̀ agbépo mú ẹ̀mí èèyàn kàn lọ ní Èkó, awakọ̀ tírélà f'ẹsẹ fẹ́ẹ Ajọ LASEMA ni ladugbo Mile 2 ni iṣẹlẹ naa ti waye ni owuro ọjọ Ẹti ti igbbiyanju ṣi n lọ lọwọ lati gbe kuro lọna.
Bẹẹ ba gbagbe, igbakeji gomina naa lo ti kuro ninu ẹgbẹ oselu APC lọ si PDP, ti ọrọ si ti n lọ kaakiri pe o seese ko gbe igba ibo gomina bii oludije fun ẹgbẹ oselu PDP naa.
Dipo bẹẹ wọn tun n tẹra mọ ọ sii ni paapaa bi ijọba ṣe fi ikọ SWAT dipo SARS.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Wo àwọn gbajúmọ̀ òṣèré Yorùbá tí kìí ṣe ọmọ káàárọ̀ oòjíire Afipábánilòpọ̀ méjì tún ṣọṣẹ́ lára ọmọ ọdún 17 l'Ekiti Ènìyàn 350 ló ní àrùn Coronavirus ní Naijiria ní Ọjọ́bọ̀ Adigunjalè pa ọlọ́pàá mẹ́jọ àti obìnrin kan ní Kogi Sugbọn ilẹ America lo n ṣe agbatẹru ipolongo fun wiwadii rẹ, nitori pe wọn fura si pe o n kowo jẹ, o tun n yan awọn ọmọ Naijiria nikan si awọn ipo nlanla ni banki naa.
Awọn obi kan l'orilẹede Kenya maa n pa aṣiri aarun HIV wọn mọ titi wọ saare, ti wọn si maa n fi awọn ọmọ wọn sinu okunkun ati ailera.
Ọrọ mi si gbogbo awọn to n tiraka lọwọlọwọ bayii ni pe: iranlọwọ ti wa lọna.
Ìyàwó mi ṣẹ̀ṣẹ̀ bímọ tuntun, kò si oúnjẹ fún wa torí ìgbélé Coronavirus- Yakubu Ewu ń bẹ!
Ijakulẹ ọrọ aje Naijiria di dandan Onimọ nipa eto ọrọ aje ọmọwe Chijioke Ekechukwu ni iru nkan bayi ko ṣẹṣẹ ma ṣẹlẹ.
Nígbà tí wọ́n gbó n kò jẹ wọ́n mo tọ́jú àwọn àgbàdo ńlá méjì náà títí wọ́n fi gbẹ bẹ́ẹ̀ ni ọ̀pọ̀lọpọ̀ ọmọ ló wà lára àgbàdo náà.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù South Africa: Ọlọ́pàá South Africa rí ẹ̀wọ̀n ọgbọ̀n ọdún he torí ikú ọmọ Nàìjíríà 2 Ọ̀pẹ̀̀ 2019 Oríṣun àwòrán, @others Àkọlé àwòrán, Ọlọ́pàá South Africa rí ẹ̀wọ̀n ọgbọ̀n ọdún re torí ikú ọmọ Nàìjíríà Austin Reynold ni agbofinro ọmọ orilẹ-ede South Africa to ṣẹṣẹ ri ẹwọn re bayii nitori pe wọn ni o ṣe iku pa ọmọ Naijiria kan.
52 Nínú gbogbo ojúṣe wọ̀nyí, àlùfáà níláti ṣe àtìlẹ́hín fún alàgbà bí ó bá yẹ láti ṣe bẹ́ẹ̀.
Ti o ba n ṣe e ni gbogbo igba, n ṣe ni o n sọ fun ọpọlọ rẹ pe ọna kan ṣoṣo (masturbation) to wa niyẹn lati ni itura ibalopọ.
Gẹ́gẹ́ bí ìfẹ́ Ọlọrun ati ètò tí Ọlọrun ti ṣe tẹ́lẹ̀, a fi í le yín lọ́wọ́, ẹ jẹ́ kí àwọn aláìbìkítà fún Òfin kàn án mọ́ agbelebu, ẹ sì pa á.
Dárúkọ àwọn tọ ń gbaṣẹ́ lọ́wọ́ NDDC tàbí kí o fojú winá òfin- Gbajabiamila sọ̀kò ọ̀rọ̀ sí Akpabio Isa Funtua, Abba Kyari àti Zulaihat Buhari jẹ́ àwọn tó súnmọ́ Aàrẹ tó papòdà láìpẹ́ Ọkùnrin kan pa ara rẹ̀ sínú ọgbà àjọ TRACE tó n mójútọ ìrìnnà ọkọ̀ nípìnlẹ̀ Ogun Wo àwọn tí Pondei fara jọ pẹ̀lú ààrẹ̀ níwájú ijẹ́jọ́ Oṣu Karun ni orilẹ-ede Madagascar fi agbo na, Covid-Organics ranṣẹ si Naijiria, ati awọn orilẹ-ede ilẹ Africa kan, ṣugbọn Aarẹ Muhammadu Buhari sọ pe oun ko ni fi ọwọ si lilo agbo naa ni Naijiria titi di igba ti awọn alaṣẹ eto ilera ba buwọlu u.
koju iko agbaboolu Seychelles ninu ifesewonse keyin ipegede fun idije AFCON
Ẹ fi ìfẹnukonu ìfẹ́ kí ara yín.
Ní ọjọ́ kẹtadinlọgbọn oṣù keji ni ilẹ̀ gbẹ tán patapata.
Amọ, baba Elubuibọn ni iṣẹ kan kii ṣẹ lasan, ti ko ba si nidi obinrin kii jẹ ikumolu.
        “A n gbiyanju lati mojuto  odi ilu wa.
“Bẹ́ẹ̀ ni yóo rí fún ẹni tí ó to ìṣúra jọ fún ara rẹ̀, tí kò ní ọrọ̀ lọ́dọ̀ Ọlọrun.
Ó bá tún dúpẹ́ lọ́wọ́ mi lẹ́ẹ̀kan síi, kó tó máa rọra rìn lọ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Promise Akinlade: ọmọ ọdún mọ́kànlá tó ń fi ìlù dárà bíi àgbàlagbà sọ̀rọ̀ nípa tálẹ́ǹtì rẹ Victoria ni oṣerekunrin ti ka mi mọ inu yara nile itura ri nibi tawọn ti n ṣere, ṣugbọn ọgbọn ni oun fi le e jade.
Arábìnrin lẹ̀dì àpò pọ̀ pẹ̀lú ọ̀rẹ́kùnrin rẹ̀ pé kó ó jí òun gbe, ọ̀rẹ́kùnrin gba 700k tán ló bá sálọ Wo àwọn oúnjẹ márùn ún tó ń mú kí àtọ̀ ọkùnrin dára síi Kí làwọn nǹkan tó lè rán ọkùnrin sí ọ̀run alákeji lásìkò ìbálòpọ̀ pẹ̀lú obìnrin?
Ẹni ti wọn ṣẹṣẹ kede naa wa lara awọn ti wọn fi sabẹ ahamọ ayẹwo ni ipinlẹ Ogun.
Ẹsẹ̀ wọn tọ́, àtẹ́lẹsẹ̀ wọn sì dàbí pátákò mààlúù, ó ń kọ mànà bíi idẹ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Police Ondo: Láìpẹ́ ni ọwọ́ yóò tẹ àwọn agbébọn tó wa òṣìṣẹ́ wa 6 Ògún 2019 Oríṣun àwòrán, @PoliceNG Awọn gende agbebọn ti yinbọn pa osisẹ ọlọpa kan ti wọn pe orukọ rẹ ni Lasisis lasiko to wa loju popo se ayẹwo ọkọ lopopona Isua-Ise-Akoko nipinlẹ Ondo.
 kí wọn tó lọ , wọ ́ n pín ẹrù tàbí ohun ìní bàbá wọn líifi nǹkan kan sílẹ ̀ fún àbúro wọn - ajíbógun .
12 Agẹmo 2020 Oríṣun àwòrán, Others Ti ijakadi kọ, baba ni ba n jẹ ni rọ ri fun ọmọ Naijiria, Kamaru Usman lẹyin to lu Jorge Masvidal ni alubami lati di Ami Ẹyẹ UFC Welterweight Champion rẹ mu.
A o lee fọwọ kọ gbogbo orin ti oloogbe ilumọọka olorin ọmọ Yoruba, Olayiwola Fatai Olagunju, Fatai Rolling Dollar tí ọpọlọpọ si mọ si Baba 70 kọ.
 springbok yìí ma ń ní ojú funfun , ìlà dúdú láti ojú dé ẹnu , àwọ ̀ pako fẹ ́ ẹ ́ rẹ ́ fẹ ́ tí ó pupa díẹ ̀ láti apá iwájú dé íbubu ìha ìdí rẹ ̀ .
BBC ko tii le fidi ohun to n ṣẹlẹ ni pato mulẹ.
Wọ́n sá wọ inú igbó lọ,wọ́n gun orí òkè lọ sinu pàlàpálá òkúta;gbogbo ìlú sì di ahoro.
    Báyìí ni ọba sọ, mo sì fetísílẹ̀ mo gbọ́ gbogbo ọ̀rọ̀ náà tán pátápátá, nígbà tí ó parí ọ̀rọ̀ rẹ̀, mo dáhùn mo ni:
Adegboyega ti ọpọ mọ si John Boyega yan laayo.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Working religious women: Ẹ̀lẹ́hàá kìí ṣe ọ̀lẹ- Aminat Adegoke Wọn ko ṣẹkẹṣẹkẹ si obinrin naa ti orukọ rẹ n jẹ Towobola lọwọ, wọn ṣe fidio rẹ bi wọn ṣe n bere ọrọ lọwọ rẹ lori ibalopọ oun ati afurasi ọdaran ti wọn fẹ mu.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Cow rustlers caught: Ọwọ́ tẹ́ àwọn ọkùnrin mẹ́ta tí wọ́n jí Màálù kó ní Ogbomọṣọ- Àjọ NSCDC 28 Agẹmo 2020 Oríṣun àwòrán, @IndependentNGR Ajọ aabo ara ẹni laabo ilu ti a mọ si Nigeria Security and Civil Defence Corps (NSCDC) ti mu awọn ọkunrin mẹta ti wọn ji Maalu meji ko ni Ogbomọṣọ ni ipinlẹ Oyo to jẹ Guusu Iwọ oorun Naijiria.
"Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, CAN ni gbigba awọn osisẹ tuntun fun ipo adari lẹka abo yoo mu iran tuntun ba ọrọ abo ""A ko faramọ aato igbimọ eleeto abo to gaju lorilẹede Naijiria lọwọlọwọ yiieleyi to fi si ọdọ awọn ẹlẹsin kan ati ẹya kan lorilẹede yii."
Nípa ti pé a óo jí àwọn òkú dìde tabi a kò ní jí wọn, ẹ kò ì tíì kà ninu Ìwé Mose, níbi ìtàn ìgbẹ́ tí iná ń jó, bí Ọlọrun ti wí fún Mose pé, ‘Èmi ni Ọlọrun Abrahamu ati Ọlọrun Isaaki ati Ọlọrun Jakọbu?
Brown Ideye di aayo fẹgbẹ agbabọọlu Malaga West Brom nsewadi awọn agbabọọlu rẹ Karakata Agbabọọlu: Bi o se nlọ Super Falcons: Wọn nfi ilọkulọ ibalopọ lọ wa Bi ẹ ko ba gbagbe, o ti le ni oṣu mẹwaa ti Iheanacho ti gba ami ẹyẹ goolu sẹyin ti ko si ri bọọlu kankan gba si awọn.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Awọn ẹgbẹ Democrat nikan kọ ni yoo koju ipenija yii, Ẹgbẹ Republican naa yoo ni lati ṣe iṣẹ takuntakun ki awọn eeyan ba le tubọ dibo wọle fun wọn pada ninu idibo to n bọ lọna.
O dabi ẹni pe ọgbẹni Siddiqi ko sọ fun awọn iyawo rẹ pe oun fẹ ẹ fẹ ẹlomiran le wọn, awọn ẹbi iyawo tuntun ko si mọ pe ọkọ ọmọ wọn ti ni iyawo miran titi di igba ti iyawo rẹ akọkọ tu aṣiri nibi ayẹyẹ igbeyawo to waye nilu Karachi.
Ṣugbọn ninu àpò awọ titun ni à ń fi ọtí titun sí, ati ọtí ati àpò yóo wà ní ìpamọ́.
Nítorí dídì tí wọ́n di Ṣadiraki, Meṣaki ati Abedinego, wọ́n ṣubú lulẹ̀ sí ààrin iná náà.
ẹ ṣọ́ra, kí ẹ máa tẹ̀lé gbogbo ìlànà ati òfin tí mo fi lélẹ̀ níwájú yín lónìí.
ati kíndìnrín rẹ̀ mejeeji pẹlu ọ̀rá tí ó bò wọ́n.
n fori-kori pelu awon  asofin  APC , lari ri i pe ohun ti o sẹlẹ lọdun  2015 ko tun pada sẹlẹ mọ ọn.
"Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Oníkẹ̀kẹ̀ NAPEP: Àwọn ọlọ́pàá ń gba owó kòtọ́ lọ́wọ́ wa 30 Agẹmo 2018 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ọpọ awọn olugbe ilu Maiduguri ni wọn ni lati fi ẹsẹ rin lọ si ibi iṣẹ wọn Awọn onikẹkẹ NAPEP ni ilu Maiduguri, tii ṣe olu ilu ipinlẹ Borno, ya bo awọn opopona marosẹ to wa nilu naa ni owurọ ọjọ aje lati fi ẹhonu han lori ohun ti wọn pe ni ""bi ọlọpa ṣe n fi awọn jẹun"" Awọn opopona to lorukọ bii opopona Baga, opopona Maiduguri si Damaturu, ati agbegbe Lagos street, ni wọn fi kẹkẹ wọn di pa lagbegbe ileeṣẹ awọn ọlọpaa nibẹ."
Irọ funfun balau ni iroyin to tan kalẹ kaakiri lori ayelujara pe Gomina ipinlẹ Edo, Godwin Obaseki ti darapọ mọ ẹgbẹ oṣelu PDP.
Nígbà tí ó yọjú wo inú rẹ̀, aṣọ funfun tí wọ́n fi wé òkú nìkan ni ó rí.
" Lootọ ni Chidozie ti n gba itọju nileewosan miran, sugbọn dokita to n tọju rẹ nileewosan tuntun ti wọn gbe e lọ, sọ fun pe akọ iba ati iba jẹdọ-jẹdọ lo n ṣe e.
Ilé ìtàjà ìgbàlóde Shoprite tí agbègbè Lekki ní ọmọbinrin kan ti gbe ìwé iléwọ láti bu ẹnu àtẹ́ lu ìwá akọlu ti àwọn South Africa n ṣe si awọn ọmọ Nàìjíríà.
Ní ọdún tí ó ṣẹgun wọn, wọ́n fún un ní ọgọrun-un (100) ìwọ̀n talẹnti fadaka, ẹgbaarun (10,000) ìwọ̀n kori alikama ati ẹgbaarun (10,000) ìwọ̀n kori ọkà baali.
Sotitobire: Ẹlẹ́rìí mẹ́rìn ló tẹ̀lé Alfa Babatunde wá síwájú ilé ẹjọ́ Ohun tí ilé ẹ̀jọ́ rí rèé tí kò fi gba Béélì Hushpuppi Àlàyé rèé lórí bí wọ́n ṣe pa Ebila, olórí àwọn One million boys"" n'Ibadan Háà, àṣé Pastor Adeboye kò léè dá èékánná ara rẹ̀ gé, àwọn ọmọ Nàìjíríà kan pariwo Abajade ipinlẹ kọọkan ninu esi tuntun naa re e: Eko -128 Kwara-92 Enugu-39 Delta-33 Edo-29 Plateau-28 Kaduna-23 Oyo-15 Ogun-14 Osun-14 FCT-12 Ondo-9 Rivers-9 Abia-8 Bayelsa-5 Ekiti-3 Borno-2 Ààrùn Coronavirus tún ti ran ènìyàn 595 l'órílẹ̀-èdè Nàìjíríà Àpapọ̀ àwọn tuntun to ṣẹṣẹ lugbadi ààrùn Coronavirus ní Nàìjíríà jẹ 595 ní 13/07/2020 Ninu ikede ti ajọ NCDC fi sita ni Ọjọ Aje lo ti fojuhan pe , awọn to ti ni aarun naa ti pe 33,152 bayii."
7 Kíyèsíi, kò tíì yé ọ; ìwọ ti ní èrò pé èmi yíò fi í fún ọ, nígbàtí ìwọ kò ní èrò inú bíkòṣe pé kí o beèrè lọ́wọ́ mi.
Wo àwọn ohun márùn ún tó yẹ kí o mọ̀ nípa Sanusi Coronavirus: Kí ni àwọn àpẹrẹ àrùn náà?
Àwọn oníkẹ̀kẹ̀ 'Napep' tí wọ ilẹ Gẹ̀ẹ́sì Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ẹwa Agọnyin jẹ aayo ounjẹ Badagry Ọrọ ounjẹ jijẹ kii ṣe ohun afi ọwọ yẹpẹrẹ mu rara, nitorina ni ọpọ to fẹ ṣe ayẹyẹ ṣe maa n wa awọn alase ounjẹ to mọ iṣẹ lati se awọn ounjẹ fun awọn alejo wọn.
Awọn agbofinro ni lasiko ti ijọsin Sabbath wọn n lọ lọwọ lo kọju ibọn sawọn olujọsin naa.
Fun apẹẹrẹ, boya oludije kan ko ida mọkandinlọgọrun un tabi mọkalelaadọta ibo ni ipinlẹ Carlifornia; Oludije naa ni yoo ko gbogbo ibo awọn ọmọ igbimọ agbaọjẹ oludibo maraarundinlọgọta to wa nibẹ.
Ìbọn ọlọ́pàá ló pa èèyàn, ẹgbẹ́ wa kìí lo ìbọn - Shiite fárígá.
Lọjọ kẹsan an oṣu kejila ọdun 2016 ni Akufo-Addo tun gbegba ibo aarẹ ninu eyi to ti fẹyin aarẹ Johna Mahama to wa lori oye gbalẹ ti o si wọle.
"Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: SERAP gbé ìjọba àpapọ̀ lọ ilé ẹjọ́ àgbáyé ICC lọrí ẹ̀sùn ìpànìyàn ""Jàǹdùkú gún ẹ̀gbọ́n mi lọ́rùn, jó ilé àti mọ́tò wa méjì, kòròfò la wà"" Olùwọ́de 12 kú ni Lekki, 38 lapapọ kú lọ́jọ́ Isẹ́gun, 56 ni àròpọ̀ àwọn tó bá ìwọ́de lọ - Amnesty International Osinbajo gbarata lórí ìṣẹ̀lẹ̀ Lekki, ó ní ìdájọ́ òdodo yóò wà Ooni Ogunwusi àti Wole Soyinka kòrò ojú sí ìṣẹ̀lẹ̀ Lekki Tollgate Ọ̀rọ̀ Nàíjíríà kúrò ní sinimá àwòrẹ́rìn-ìn, Buhari gbé ìgbésẹ̀ bíi òbí àti olórí - Obasanjo gbarata Ilẹ̀ Amẹ́ríkà wà lẹ́yìn àwọn olùwọ́de, Buhari dẹ́kun ìpànìyàn - Joe Biden Mọ̀ nípa DJ Switch, akíkanjú obìrin sàfihàn fídíò ìpànìyàn Lekki bó ṣe ń wáyé Oke, ẹni ti ọrọ iku rẹ n ja rainrain lori ayelujara lọwọ lọwọ, lo jade laye lẹyin to fi ọrọ kan siju opo Twitter rẹ pe ""Ko ni tan fun Naijiria."
Ẹ padà sílé èyin ọmọ wa tó n ṣiṣẹ́ darandaran - NEF ti Fulani Ẹyẹ j’ẹyẹ lọ!
Àwọn ikọ̀ kan wá sí ọ̀dọ̀ Sedekaya, ọba Juda, ní Jerusalẹmu, láti ọ̀dọ̀ ọba Edomu ati ọba Moabu, ọba àwọn ọmọ Amoni, ọba Tire, ati ọba Sidoni wá, rán wọn pada sí àwọn oluwa wọn, 
Ṣugbọn kùmọ̀ ni Bẹnaya mú lọ́wọ́ lọ bá a, ó gba ọ̀kọ̀ tí ó wà lọ́wọ́ rẹ̀, ó sì fi pa á.
Sùn un re o, baba Oríṣun àwòrán, @Ladapo Àjànàkú sùn bí òkè,Erin ṣubú kò leè dìdeLáwuyì ònígègé àràSùn-ùn-re o!
Oríṣun àwòrán, Anja Barte Telin Àkọlé àwòrán, Orisirisi ounjẹ aramanda lo wa ni China.
Àwọn akẹ́kọ̀ọ́ bẹ̀ ìjọba láti ṣ'íléèwé fún ìdánwò WAEC, ìpinnu ìjọba ilẹ̀ Yorùbá rèé Ọrọ ṣiṣi ileewe ni orilẹede Naijiria ti fa ariyanjiyan nitori awọn ijọba ko fi ọjọ ti awọn akẹkọọ yoo pada si ileewe lede.
Ati wi pe oloogbe Olakunrin ni ibọn ba lara awọn eniyan to wa ninu ọkọ meji ti wọn da duro.
Bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé Jesu ti ṣe ọpọlọpọ iṣẹ́ ìyanu lójú wọn, sibẹ wọn kò gbà á gbọ́.
Kí àwọn orílẹ̀-èdè múra láti gbógun tì í,kí àwọn ọba ilẹ̀ Media múra, pẹlu àwọn gomina wọn,ati àwọn ẹmẹ̀wà wọn,ati gbogbo ilẹ̀ tí ó wà lábẹ́ wọn.
 Komisona fun eto ilera nipinle Eko, Onisegun oyinbo Jide Idris ninu oro tire gboriyin fun ijoba Eko fun ife ti won fihan loni.
"Inú mi dùn pé Coronavirus jẹ́ kí wọn ti iléèwé pa.
Nígbàtí mo dé iwájú ilé gogoro náà, tí mo rí bó ṣe ga tó, kàkà kí n yin ọmọ ènìyàn, Elédùà ni mo kí kú iṣẹ́ ìyanu.
A ti ń sin òkú méjì sínú ibójì kan náà nítorí ọ̀wọ́ngógó ibojì ìsìnkú"" Ẹ̀gbọ́n àti àbúrò wà ní ilé ẹ̀jọ́ lórí ikú Tolulope Arotile Awọn wo ló lè gbe ibọn ni Naijiria labẹ ofin?"
Isoro oju ọna to di pa naa waye nitori bi ileesẹ Berger to n se atunse abala kan ni opopona Marosẹ Ibadan silu Eko, se tun ti abala kan oju ọna naa pa, eyi to lọ si Ibadan lati Eko.
 O ni o ṣe pataki lati ṣegbe fun lilo awọn ohun eelo onike, ti a le tun ṣamulo lọpọ igba, ki adinku le ba awọn idọti bayii lawujọ.
BBC: Ṣe ẹ ro pé bi Baba Obafemi Awolowo gan ba wa laye, ṣe wọn a nifẹ si ki ẹ lọ sori eto BBNaija Seyi: Bẹẹ ni o da mi loju nitori idi pataki to mu mi lọ fun eto naa.
Gómínà ìpínlẹ̀ Eko Babajide Sanwo-Olu kéde ọ̀rọ̀ yìí lọ́sàn ọjọ Abamẹta, nílé ìjọba tó wà ni Marina.
Nígbà tí nǹkan fi ń dára fún Jerusalẹmu, tí eniyan sì pọ̀ níbẹ̀, ati àwọn ìlú agbègbè tí ó yí i ká, ati àwọn ìlú ìhà gúsù ati ti ẹsẹ̀ òkè ní ìwọ̀ oòrùn; ṣebí àwọn wolii OLUWA ti sọ nǹkan wọnyi tẹ́lẹ̀?
Mo pàdánù ọkọ méjì láàrin ọdún kan lórí Facebook 'BBC Yoruba gan gan lara' Ijọba Ondo n wa ọdẹ aperin Ọgbà ẹ̀wọ̀n ni Naira Marley yóò ti wo ìbúra Buhari ní May 29 Awọn mẹwaa to tẹlẹ wọn ni Selena Gomez, Dwayne 'The Rock' Johnson, Beyoncé, Taylor Swift, Neymarda ati Justin Bieber.
O ni aimọkan lo n jẹ ki awọn eeyan kan maa ro pe arumọjẹ ni arun Coronavirus, ijafara si lewu fun agbalagba to ba ni arun miran lara tẹlẹ, to ba tun ni arun Coronavirus.
Lẹ́yìn ọjọ́ díẹ̀ tí Fẹliksi ti dé pẹlu Durusila iyawo rẹ̀ tí ó jẹ́ Juu, ó ranṣẹ sí Paulu láti gbọ́ ọ̀rọ̀ nípa igbagbọ ninu Kristi Jesu lẹ́nu rẹ̀.
Gbogbo ìgbésẹ̀ Aláàfin láti jí mi gbé ló já sí pàbó, n kò le panumọ́ - Olori Anu Kí ló ń ṣẹlẹ̀ láàfin Oyo táwọn èèyàn fi ń ki Alaafin ní mẹ́sàn án mẹ́wàá?
alase egbe  oselu All Progressives Congress, APC ati egbe oselu People’s
Ṣugbọn ṣá o, ranti mi nígbà tí ó bá dára fún ọ, jọ̀wọ́, ṣe mí lóore kan, ròyìn mi fún Farao, kí Farao sì yọ mí kúrò ninu àhámọ́ yìí.
’’o ni ohun yoo tun tepele mo idagbasoke
Ojú yóo ti gbogbo àwọn ọ̀tá mi;ìdààmú ńlá yóo bá wọn,wọn óo sá pada,ojú yóo sì tì wọ́n lójijì.
Alupupu rẹ ti o gbe wa si ibiṣẹ ni ọjọ naa wa ni ẹgbẹ kan ti o gbe e kalẹ si.
Lara awon ti o wa lati wa jeri
 inú Ọ ̀ rúnmìlà dun nítorí ìwà Ààbò àti ori re tí ó ko ran-an .
Ní àkókò náà, àwọn Juu tí wọ́n jẹ́ olùfọkànsìn ti gbogbo orílẹ̀-èdè ayé wá, wọ́n wà ní Jerusalẹmu.
Pakistan ti ń sún kẹ́rẹ́ ní ti ìgbé ayé Abódiakọ-akọ́diabo.
Kí ni ò ń bi mí sí?
Sáájú ni àjọ ọlọ́pàá lórílẹ̀-èdè Nàìjíríà ti ṣàlàyé pé kò si ọlọ́pàá tó ni àṣẹ láti maa yẹ fóònù ẹnikẹ́ni wò lójú pópó láì ni ìwé àṣẹ ìjọba.
Tí olúwarẹ̀ bá ko Ebola, tí kò bá ṣe àfira wá nkan ṣe, ṣàngbà fọ́ nìyẹn – ó di gbére.
Lẹ́yìn èyí ni ó tún jókòó sínú igbó fún odidi ọdún kan, níbẹ̀ ni ó sì ti rí abàmì ìjímèrè kan tí o fi onírúurú ewé hàn án, tí ó sì kọ ọ ni ìlò wọn.
O ni eto aabo ilẹ Yoruba ṣe pataki si awọn gomina naa, eyi lo si ṣe atiwaye ifilọlẹ Amọtẹkun.
ohun yoo ri i pe ile-ise olopaa fi idi otitọ mulẹ lori iwadii naa, ni eyi ti
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Omi ìṣẹ̀ńbáyé tó ń dà ní Ówù rèé, èyí tó ga jùlọ ní Afirika Mo kan wàhálà lálẹ ọjọ ìgbeyàwó torí ìbálé mi kò ṣe ẹjẹ - Ìyàwó ọ̀sìngín Akẹ́kọ̀ọ́ tó gbèlé kàwé pegede wọ fásítì lọ́mọ ọdún méjìlá Ẹgbẹ́ òṣèlú AA kò gbọdọ̀ kópa nínú ìdìbò gómìnà ní Kogi, Bayelsa - Ilé ẹjọ́ Ẹ̀kun omi wo ògiri ọgbà ẹ̀wọ̀n, ẹlẹ́wọ̀n 150 sálọ Owo yii ni Ijọba lo wa fun ẹnawo atigbadegba awọ̀n ileewe naa fun taamu akọkọ ninu saa eto ẹkọ ọdun 2019 si 2020, ti wọ̀n si ti pasẹ fawọn ọga agba ileẹkọ alakọbẹrẹ ati girama naa lati lọ si apo asuwọn owo ni banki ki wọn lee gba owo naa ni kiakia.
nítorí náà, n óo nawọ́ ìyà sí wọn, n óo pa àwọn ọmọ Kereti run, n óo pa àwọn tí ó kù sí etí òkun rẹ́.
Ẹnu ọ̀nà kan wà ní ìhà gúsù gbọ̀ngàn inú.
Ọmọ Yahoo fẹ́ pa ìyá rẹ̀ ṣ'owó l'Eko Òbí tó n fa sìgá n fi ọmọ rẹ̀ sínú ìdè àìsàn l'ọ́jọ́ iwájú Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ayefẹlẹ: Orí ìkúnlẹ̀ ni ìyàwó mi wà, tó ń bẹ gómìnà, láti 11pm si 4am Nínú èsì rẹ̀, Olasunkanmi ní aláwọ dúdú ni wa, à kó lee da ǹkankan se bí àwọn oyinbo tí máà ń ṣe, bi wọn tilẹ̀ tí wa mọ inu yàrá kan fun odidi ọdun kan.
Eto oro-aje ipinle Benue n wa lati awon igberiko ti won n pese ounje, eso ati ewe-be, eyi ti won n je ki o sofo danu, latari aini imo a n ko ounje pamo”.
Donal Trump ń kó àwọn ọmọ ogun IS tó burù julọ kúrò ní Syria nítorí ìkọlù ọmọ ogun ilẹ̀ Turkey A ó máa tẹ àwọn afipábánilòpọ̀ lọ́dàá ni báyìí - Ìjọba Ekiti Àwọn èrò nígboro Eko fẹ́ lu obìnrin kan pa, pé ó mú nǹkan ọmọkùnrin pòórá Ǹjẹ́ o mọ ẹni tó ran àjọ ọ̀tẹlẹ̀mùyẹ́ CIA lọ́wọ́ láti rí Bin Laden mú?
Gbogbo ohun tí o ti gbà lọ́wọ́ àwọn ẹlòmíràn ni n óo gbà pada lọ́wọ́ rẹ; a kò sì ní gbọ́ ohùn àwọn iranṣẹ rẹ mọ́.
O ni ni bayi ti oun ti ṣetan ni ile ẹlẹbọn agba BBNaija bayii, oun n lọ gbaju mọ ileeṣẹ itọju ara ti oun da silẹ ni ati pe oun yoo tun mojuto eto ẹkọ ohun.
Josẹfu rí ìran kẹta ninu àwọn ọmọ Efuraimu.
Ijamba ọkọ naa la gbọ wi pe o ṣẹlẹ ni ibudo iwọkọ Ilasamaja loju ọna marose Apapa-Oshodi nigbati ọkọ akero ajagbe kan kọlu katako ipolowo nla kan, eyi ti o wo lu ọkọ akero kan.
Police Brutality: Ọlọ́pàá ìpínlẹ̀ Kwara lé ọlọ́pàá mẹ́rin kúrò lẹ́nu iṣẹ́ fún ẹ̀sùn ìwà ìbàjẹ́
 Ki o to ku lo sakosile si oju iwe re ni ero ayelujara pe: Allhamdulilahi fun Olorun, mo dupe fun oun ti o ti se.
bẹ́ẹ̀ ni kò sí ohun tí kò ní, tí a óo sọ pé kí eniyan fún un, nítorí òun fúnra rẹ̀ ni ó ń fún gbogbo eniyan ní ẹ̀mí, èémí ati ohun gbogbo.
Ní ẹ̀ẹ́dẹ́gbẹ̀wá ọdún ó lé mẹ́rìnlélógójì,
”Ó dáhùn pé, “N kò lọ sí ibìkan kan.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù New Covid-19 Strain UK : Atiku ní kí ìjọba dì ìrìnnà ọkọ̀ òfurufú láàrin ilẹ̀ Gẹ̀ẹ́sì sí Nàìjíríà kú nítorí Covid-19 15 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 21 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Oríṣun àwòrán, @Atiku Ina esisi ko gbọdọ tun jo wa lẹẹkan si, ẹ ti papakọ ofurufu ki Covid-19 ma baa yọ wọle lẹẹkeeji.
Àwọn ọkunrin kan láti Tire pàápàá tí wọn ń gbé ààrin ìlú náà mú ẹja wá ati oríṣìíríṣìí àwọn nǹkan títà, wọ́n sì ń tà wọ́n fún àwọn eniyan Juda ati ni Jerusalẹmu ní ọjọ́ ìsinmi.
Ki kó olú ilú kúrò ni Èkó kò din èrò ti o nwọ Èkó kù, ilú Èkó ngbòrò si ni, ṣùgbọn bi èrò ti npọ si, Ijọba àpapọ̀ kò ran Eko lọwọ nipa ipèsè owó tó tó ni àsikò fún ohun amáyédẹrùn.
Oríṣun àwòrán, Facebook/LBSL BBC Yoruba kan si ọga agba ileeṣẹ ọkọ akero BRT ipinlẹ Eko, Ọgbẹni Idowu Oguntona lori ọrọ yii.
" Agba Inaki wa gba awọn eeyan to ba n gbero lati rinrin ajo kuro ni Naijiria lọ soke nimọran pe, ki wọn ni ara wọn na, ki wọn to sọ pe awọn ni eeyan, tabi gbara le ẹnikẹni fun iranwọ loke okun.
“Bí ẹnìkan bá gbá ẹrukunrin tabi ẹrubinrin rẹ̀ lójú, tí ojú náà sì fọ́, olúwarẹ̀ yóo dá ẹrú náà sílẹ̀ lọ́fẹ̀ẹ́ láìgba ohunkohun lọ́wọ́ rẹ̀, nítorí pé ó ti fọ́ ọ lójú.
Nínú àtẹjade kan ti Gomina ìpínlẹ̀ Kwara Abdulrahman Abdulrazaq fọwọ́ si lo ti sàlaye pé botill jẹ́ pé ìpínlẹ̀ Kwara ko tii gba nipa ẹnikẹni to ni à[run náà sibẹ̀, iná ko se fi sori orule sùn.
Òun náà ló tẹ́ òfurufú léwa lórí.
Ninu atẹjade kan ti oludamọran aarẹ lori ọrọ iroyin, Femi Adesina fi sita loju opo Facebook rẹ, Buhari ni titi laelae ni orilẹede Naijiria yoo maa ṣe iranti iṣẹ ribiribi ti Babangida ṣe, nigba to fi wa lori aleefa.
O ni iru orin to yẹ ko maa jade ni pe gomina o, a dupẹ lọwọ yin o, ẹ n gbiyanju o, kẹẹ 'se daadaa si ni o""."
isipo-rọpo fun gomina tuntun ti yoo gba ipo lọwọ rẹ.
Premier League yóò bẹ̀rẹ̀ padà lóṣù kẹfà 11 Èbibi 2020 Oríṣun àwòrán, Twitter/Liverpool FC Gbogbo eto ti to bayii lati bẹrẹ idije Premier League lọjọ kinni oṣu kẹfa ọdun yii lẹyin to ti wa nin idaduro nitori ajakalẹ aarun coronavirus.
Ní tèmi, n kò ní ṣẹ̀, nípa aigbadura sí OLUWA fun yín.
Ọba lókè ló lè șẹ̀san olùkọ́, Ẹ jẹ́ ká kó yẹ̀yẹ́ dànù.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Coronavirus: Orílẹ̀èdè Cameroon ti ní alárùn àkọ́kọ́ 6 Ẹrẹ̀nà 2020 Orilẹede Cameroon ti fi lede pe awọn ti ni ẹni akọkọ to ni aarun Coronavirus ni orilẹede wọn.
Àkọlé àwòrán, Moshood Adeoti naa ti kọwe fi ẹgbẹ oṣelu APC silẹ lori ẹsun to fi ara jọ ti Akinbade, to si gba ẹgbẹ oṣelu APD lọ Ṣaaju ni akọwe ijọba ipinlẹ naa tẹlẹ, Moshood Adeoti naa ti kọwe fi ẹgbẹ oṣelu APC silẹ lori ẹsun to fi ara jọ ti Akinbade, to si gba ẹgbẹ oṣelu APD lọ.
Èyí ni bí ogun abẹ́lé Biafra ṣe bẹ̀rẹ̀ ní Nàìjíríà Wo ipa tí Mayegun yóò ma kó ní ilẹ̀ Yoruba!
Atundi idibo ohun waye laarin Maada Bio ati oludije labe egbe oselu to wa lori alefa Samura Kamara, eto idibo ohun lo ye ko waye lojo-Isegun amo, ti won tun yi asiko naa pada, leyin awuye-wuye awon eniyan pe, mago-mago wa ninu eto idibo alakoko, eyi ti won so pe, o wa latowo omo-egbe oselu All People’s Congress ti Kamara n dije labe re.
"Oríṣun àwòrán, Others ""Ni bayii, o le ni awọn ile ẹru mejila to wa nilẹ lọja agbaye to kun fun agba epo rọbi, ti ko ri ẹni yọwo rẹ nitori wahala arun Coronavirus to n ja rain nilẹ, eyi ti ọwọja rẹ tun ti tan de awọn ẹya ẹka epo rọbi miran."
Iroyin ọhun sọ pe lakoko ti awọn janduku bẹrẹ si ni lọ ji nkan ko nile awọn oloṣelu atawọn eekan lawujọ, wọn yabo ile SOB wọn si ko awọn nkan iranwọ Covid-19 to wa nibẹ.
Bí ó ti sọ báyìí tán ni ọ̀kan ninu àwọn ẹ̀ṣọ́ tí ó dúró níbẹ̀ bá gbá Jesu létí, ó ní, “Olórí Alufaa ni o dá lóhùn bẹ́ẹ̀!
Ẹ gbọdọ̀ ranti pé ẹ̀yin náà ti jẹ́ ẹrú rí ní ilẹ̀ Ijipti, OLUWA Ọlọrun yín ni ó rà yín pada; nítorí náà ni mo fi ń pàṣẹ fun yín lónìí.
Nígbà tí mo parí ọ̀rọ̀ mi, ọba náà tún sọ̀rọ̀ dáadáa nípa wa, lẹ́yìn èyí, a múra à ń lọ.
fa ile-ise naa le ile akede Naijiria, Voice of Naijiria lọwọ jẹ,ala to wa si
"Ijọba ipinlẹ ni yoo maa s'akoso ohun alumọọni ""Ọrọ awọn osisẹ to fi mọ awọn ẹlẹgbẹjẹgbẹ olokoowo, ibasepọ laarin awọn osisẹ ati agbanisisẹ, ilana isọwọsisẹ, aabo lẹnu isẹ ati eto idẹrun osisẹ to fi mọ yiyanju aawọ, ati agbekalẹ ilana owo osu to kere julọ ati yiyanju aawọ osisẹ ati awọn agbanisisẹ lo yẹ ko wa labẹ awọn ofin atigbadegba""."
Ede aiyede naa bẹrẹ lasiko ti Gomina Abiọla Ajimọbi mu ayipada ba ilana jijẹ oye Olubadan lọdun 2017, to si sọ awọn ijoye mọkanlelogun di ọba alade.
Ni bayii mẹrindinlogun ninu awọn mejilelogun to ti ni arun yii lorilẹede Naijiria ni wọn wa lati ipinlẹ Eko, mẹta lati olu ilu Naijiria, Abuja, meji lati ipinlẹ Ogun, Ẹyọkan lati ipinlẹ Ekiti.
Sibẹ ẹ ṣeun tí ẹ bá mi pín ninu ìpọ́njú mi.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Auxiliary ní òun yóò lé àwọn ọmọ ẹ̀yìn òun tó ń hùwà tọ́ọ̀gì dànù 20 Èrèlè 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 4 Òkùdu 2020 Oríṣun àwòrán, The park Management Oyo State Alaga igbimọ to n ṣe akoso gareeji ọkọ nipinlẹ Oyo, Alhaji Mukaila Lamidi, ti ọpọ eeyan mọ si Auxiliary ti fi ewe ọmọ mọ awọn ọmọ igbimọ rẹ leti, lati yago fun iwa tọọgi ati idaluru.
Mo dúró ní ẹnu ọ̀nà, mò ń kan ìlẹ̀kùn.
 Godswill Obot Akpabio – Akwa Ibom, Minisita fun agbegbe Niger Deltamẹ́rin ) Chris Ngige – Anambra, Minisita fun ọrọ oṣiṣẹ ati igbanisiṣẹ (Labour & Employment)márùn ún) Sharon Ikeazor – Anambra, Minisita abẹle fun ọrọ ayika ni ijoba ipinle (Environment), Statemẹ́fà) Adamu Adamu – Bauchi, Minisita fun eto ẹkọ  (Education)méje) Amb Maryam Katagum – Bauchi, Minisita Abẹle fun ọrọ ileeṣẹ, idokoowo, ati karakata(Industry, Trade and Investment), Statemẹ́jọ) Timipre Silva – Bayelsa, Minisita abele fun oro epo rọbi (Petroleum), Statemẹ́sán án) Sen.
"Lero ti Agba Amofin Adeniyi Akintọla, ""General lo yẹ ka maa pe Aminat Abiọdun, ko se fi ọwọ rọ sẹyin lawujọ."
Nítorí pé Kristi yìí ni alaafia wa.
Washington ló ni ibi ti o tóbi jùlọ ti wọ́n ti n pèsè Apple ni Amẹrika lóniruuru, sùgbọ́n àwọn èyí ti wọ́n ń pè ni Golden Delicious àti Red Delicious ti n ri ìpèníjà pẹ̀lú Pink Lady àti Royal Gala.
Ọjọ kẹrindilogun, Oṣu Kẹta, ọdun 2020 ni ọjọgbọn naa wọ Naijiria lati ilẹ Amerika, to si fi ara rẹ pamọ fun ayẹwo coronavirus lẹyin irinajo ọhun.
Oríṣun àwòrán, Nigeria Police Àkọlé àwòrán, Awọn mẹrin ti wọn mu fun iku alufaa John Adeyi Ni Ọjọru ni adajọ kan ni ile ẹjo kan ni Markudi dajọ iku fun awọn méji lara wọn.
 O tẹ siwaju pe Ijọba yii ko tii gbe agadagodo sẹnu ile iroyin kankan, bẹẹ ni ko gbẹse le iwe iroyin kankan.
A kò ní fi ẹnikẹ́ni sórí oyè, ṣe ohunkohun tí o bá rò pé ó dára.
Amnesty International fẹ́ tú Nàìjíríà ká —iléesẹ́ ológun Amnesty: Ọmọ ogun Nigeria ko naani ẹmi 'Ìrọ́ ni àjọ Amnesty International ń pa o' Ìyá ọmọ tí ó kú yóò fojú bale ẹjọ Nigba ti BBC kan si oludari IRT, Abba Kyari, o ni irọ ni gbogbo ẹsun na a.
 a maa ń gbé bv àti àkóràn vaginal tàbí àkóràn trichomonas síra wọn láìmọ .
Ṣugbọn nisinsinyii inú rẹ ti ru sí ẹni àmì òróró rẹ;o ti ta á nù,o sì ti kọ̀ ọ́ sílẹ̀.
Ó fẹ́ mọ òtítọ́ ẹ̀sùn tí àwọn Juu mú wá nípa rẹ̀.
Ó ti pèsè ohun ìjà ikú sílẹ̀,ó sì ti tọ́jú ọfà iná.
Ṣugbọn kí ẹ dá àwọn obinrin ati àwọn ọmọ wọn sí, ati àwọn ẹran ọ̀sìn wọn, ati gbogbo dúkìá yòókù tí ó wà ninu ìlú náà, kí ẹ kó gbogbo rẹ̀ gẹ́gẹ́ bí ìkógun fún ara yín, kí ẹ máa lo gbogbo dúkìá àwọn ọ̀tá yín tí OLUWA Ọlọrun yín ti fun yín.
Mountain- Waje ati Lira Waje ni ọmọ Naijiria, Lira wa lati South Africa.
Andile Ramaphosa, omo aare orile-ede South Africa Cyril Ramaphosa, ti bale si papako ofurufu Entebbe International Airport pelu erongba re lati lo denu ife ko omo adari ijoba  orile-ede Uganda teleri, Amama Mbabazi leni  ti o tun fe dije dupo aare bayii.
Joẹli ni ó bí Ṣemaya, Ṣemaya bí Gogu, Gogu bí Ṣimei; 
Bi a ko ba gbagbe, akọkọ goolu mẹta ti Loucas Moura jẹ ni Yuroopu waye ni Ọjọ Kẹtala, Oṣu Kẹrin, ọdun 2019 ninu ipade Tottenham ati Huddersfield.
Aare tesiwaju lati ro awon omo orile-ede Naijiria lati maa polongo igbe aye alaafia nibikibi ti won ba ti bara won.
Lasiko yii bakan naa lo jẹ gomina fun Banki Agbaye ati ọmọ igbimọ ajọ to ayanilowo lagbaye, International Monetary Fund (IMF).
"Dokita Kate O'Brien to jẹ adari eto gbigba ati pipese abẹrẹ ajẹsara ni ajọ WHO sọ fun BBC pe ""Iṣẹlẹ manigbagbe ni eyi jẹ fun abẹrẹ ajẹsara,kikoju aarun iba ati ilera ara ilu'' Gẹgẹ bi ohun ti a ri ka iye awọn ti aarun iba n ba finra n peleke si juti tẹlẹ lọ-eyi ti mu ki awọn alaṣẹ́ ma jaya lori ọrọ naa."
" Àjèjì yìí kò fèsì ju pé "" Ìjà dà ?"
Nítorí Dafidi sọ nípa rẹ̀ pé, ‘Mo rí Oluwa níwájú mi nígbà gbogbo,ó wà ní ọwọ́ ọ̀tún minítorí náà ohunkohun kò lè dà mí láàmú.
Ṣugbọn nigba ti yoo fi di owuro ọjọ ọdun ileya ni ariwo sọ lasiko ti ọmọde kan fẹ lọ ṣe igbọnsẹ nibi odo nla kan to n bẹ ni adugbo naa.
Iroyin to n tẹ wa lọwọ ni yajoyajo sọ pe wọn tun ti fipa ba akẹkọọbinrin miiran lọpọ lagbegbe Akinyele niluu Ibadan, wọn si tun ṣeku pa a.
Amosa, pupọ owó tó bá wọlé nígbà náà lọhun, ọwọ oga orin lo máa ń lọ táwọn ọmọṣe elegbe kan máa ń rí taataata.
3 Owewe 2020 Oríṣun àwòrán, Getty Images Ilumọọka onilu nilẹ America ati nilẹ Afrika, Babatunde Olatunji ti tako ofin ẹlẹyamẹya ni ọdun mẹta saaju ki Rosa Park to tako ofin ẹlẹyamẹya ninu ọkọ igboro lorilẹ-ede America.
“Ọba mìíràn yóo jẹ lẹ́yìn rẹ̀, yóo sì rán agbowóopá kan kí ó máa gba owó-odè kiri ní gbogbo ìjọba rẹ̀; ní kò pẹ́ kò jìnnà, a óo pa ọba náà, ṣugbọn kò ní jẹ́ ní gbangba tabi lójú ogun.
Ọrọ igbesẹ lati fa ilẹ Gẹẹsi jade kuro ninu ajọ orilẹede Yuroopu, EU eleyii ti wọn da pe ni BREXIT lo n fun un ni ẹfọri julọ bayii.
Nínú ọ̀rọ̀ rẹ̀ Asuquo to n síṣẹ́ àtunṣe ọpa ẹ̀rọ omi (plumber) sọ lẹ́yìn ti ọ̀wọ́ tẹ̀ẹ́ lo ti sàlàye pé ọwọ́ ebi lo bá oun ti oun fi lo já sọ́ọ̀bù láti ji ẹlẹ́rìndodò àti bísikítí.
N óo wọ́ ìwọ ati ìyá tí ó bí ọ jù sí ilẹ̀ àjèjì, tí kì í ṣe ibi tí wọ́n bí ọ sí, ibẹ̀ ni ẹ óo kú sí.
”“Bakan naa, ijọba apapo ati ijọba ipinle Plateau ni lati fowosowopo , ki won si wa ona lati mu eto aabo le koko ni ipinle naa.
Ti ile aṣofin ko ba ni dibo yọ Trump,ki wa lo mu wọn bẹrẹ igbesẹ iyọni nipo yi gaan fun?
Nígbà tí mo parí ọ̀rọ̀ tèmi, èmi àti Ikú kí ara wwa, a kò bọ ara wa lọ́wọ́ bẹ́ẹ̀ nì ẹni kan kò sì dọ̀bálẹ̀ fún ẹnì kejì ṣùgbọ́n dípò wọn-ọnnì, a mi orí sí ara wa, lẹ́hìn náà a sì kí ara wa ó dìgbòóṣe, kí Ọlọ́run jẹ́ kí á fi ire pàdé lọ́la.
Ọ̀pọ̀ àwọn ọmọ Olateru-Olagbegi sì lo wa ni àwọn ẹ̀ka isẹ aayan láàyò loniran nran bíi ẹ̀ka eto ẹ̀kọ́, idajọ, àkóso owó, ilé ifowopamọ, imọ isegun àti bẹẹ bẹẹ lọ.
Abiy ni yoo je olotu ijọba akọkọ ọmọ ẹya Oromo lati ọdun mẹtadinlọgbọn ti EPRDF ti wa ni ijọba.
Ilẹ̀ yín yóo bẹ̀rẹ̀ láti aṣálẹ̀ Lẹbanoni, ati láti odò Yufurate títí dé Òkun tí ó wà ní ìhà ìwọ̀ oòrùn.
" 'Dokita ilé ìwòsàn ló gba ẹsẹ̀ lọ́wọ́ mi' Mo lè sọ arúgbó dí ọmọge nígbàkúgbà - Hakeem Effect Ọkan lara awọn oṣiṣẹ to sẹ pataki ninu sinima ṣugbọn ti kii ṣe oṣere ni Hakeem Effect to n fi awọn oṣere pa idan to ba wuu.
Ẹni ti wọn fi ẹsun kan naa, to n gbe agbegbe Itowo ni Oke Sopen ni Ijebu Igbo, ni o fi idi ọmọ rẹ jọ sitoofu ẹlẹtiriki nitori o ji ẹja jẹ.
Eyi ni awon ifesewonse ti yoo maa waye ninu idije orile-ede Naijiria NPFL leeni:Warriors ?
O ni wọn kò ni faaye gba àwọn ti won maa n gberò láti da eto idibo rú rara.
Niluu rẹ, Daura nipinlẹ Katsina ni Aarẹ Buhari ti sọdun Ileya.
Abọ akọsilẹ naa fihan pe awọn to ti bọ lọwọ aarun coronavirus ti tun pọ sii lagbaye.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Naira Marley: Wo àwọn ìṣẹ̀lẹ̀ tó mú Naira Marley di òrìṣà àkúnlẹ̀bọ lọ́dún 2019 12 Ọ̀pẹ̀̀ 2019 Oríṣun àwòrán, NAira Marley/ instagram Azeez Fashola ti ọpọ mọ si Naira Marley jẹ gbajugbaja akọrin taka sufe lorilẹede Naijiria.
 irisi ọbẹ yi maa n ki , yo si ma yọbọlọ ti a ba njẹ yala pẹlu ṣibi tabi pẹlu ọwọ wa .
4 Nítorí, bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé ènìyàn lè ní ọ̀pọ̀lọpọ̀ ìfihàn, àti agbára láti ṣe ọ̀pọlọpọ̀ iṣẹ́ títóbi, síbẹ̀ tí ó bá ńṣògo nínú ipá ti ara rẹ̀, tí ó sì ka awọn ìmọ̀ràn Ọlọ́run sí asán, tí ó sì ńtẹ̀lé àwọn èrò ti ara rẹ̀ àti ìfẹ́ ti ẹran ara, òun gbọdọ̀ ṣubú kí ó sì gba ẹ̀san Ọlọ́run òdodo sí orí rẹ̀.
Saulu bá pe gbogbo olórí àwọn eniyan náà jọ, ó ní, “Ẹ jẹ́ kí á wádìí ohun tí ó fa ẹ̀ṣẹ̀ òní.
Satguru Maharaj Ji: Lẹ́yìn tí wọ́n fi kakata hú gbogbo iṣú àti ẹ̀gẹ́ mí, wọ́n tún ṣá àwọn ọmọ mi ládàá
Tí wọ́n bá kó ara wọn jọ sí mi, wọn óo run mí tilé-tilé.
Laarin ọdun 2000 titi di iwoyi, bi biliọnu kan eniyan ni ajọ naa ni o ti bọ lọwọ iṣẹ ni agbaye, ṣugbọn o jọ bi ẹni pe, ni Afrika, iṣẹ ati iya ni pọ si ni.
Bẹẹ ni ẹlomiran tun fesi pe ki lo kan an niwọn igba ti Atiku funra rẹ kii ṣe ọmọ orilẹede Naijiria.
Ni ipinlẹ Oyo, Họnọrebu Adebo Edward Ogundoyin ti ẹgbẹ oṣelu Peoples Democratic Party to n ṣoju ẹkun idibo Ila Oorun Ibarapa nipinlẹ Oyo lo bori.
 ilé sagbá : nínú ìwádìí , mo rí i dájú pé omùtí ni enitó pèsè ilé yìí .
Abadofin yii ti aṣofin Wilfred Onyema da laba da lori ṣiṣe agbekalẹ Fasiti ti orukọ rẹ wa loke yii lati pese ohun to tọ fun awọn alaṣẹ rẹ.
Ọdun to kja ni oludije fu ipo aarẹ labẹ asia ẹgbẹ oṣelu African Action Congress, Omoyele Sowore naa da aba fifọwọ si ofin ti yoo gba tita igbo lọ silẹ okere lati Naijiria dipo ki wọn maa jo oko ọgbin Igbo.
Eekan inu ẹgbẹ NURTW, Alhaji Abideen Olajide (Ejiogbe) to ba BBC Yoruba sọrọ ṣalaye pe ohun ti ijọba ko ran Auxiliary n ṣe kaakiri ipinlẹ Oyo.
Ohun to tẹ le fidio niroyin taa gbọ pe ọlọpaa yii atawọn akẹgbẹ rẹ ni wọn ṣadeedee bẹrẹ si ni yinbọn nitori wọn mu ọmọ ''Yahoo'' kan.
Amotekun kò tọ́ lábẹ́ ìjọba, ẹ búra fún wá, ká bọ́ sígbó láti ṣeré ọwọ́ pẹ̀lú ọ̀daràn - Sunday Igboho Mama Arsenal ṣeé débi èrè, ẹgbẹ́ kan ti fún màmá l'ẹ̀bùn owó Atorí ìkan ṣèkan l'Ọlọ́run!
Àwọn ọmọ Dafidi tí a bí fún un ní Heburoni nìwọ̀nyí, bí wọ́n ṣe tẹ̀lé ara wọn: Aminoni tí Ahinoamu ará Jesireeli bí fún un ni àkọ́bí rẹ̀, lẹ́yìn rẹ̀ ni Daniẹli, ọmọ Abigaili ará Kamẹli.
Àwọn Òfin tí Ó Jẹmọ́ Ohun tí a fi fún OLUWA.
Àfilé iye owó náà ti dá awuyewuye sílẹ̀.
23 Njẹ́ èmi kò ha sọ̀rọ̀ àlàáfíà sí ọkàn rẹ nípa ohun náà?
Ṣugbọn bí a bá fi ṣẹ́kẹ́ṣẹkẹ̀ dè wọ́n,tí ayé wọn kún fún ìpọ́njú,
L'oju òpó Twitter, nise ní àwọn iriwisi oríṣiríṣi lórí aṣemáṣe awọn eranko wọn yi ti n wáyé.
Adari LASEMA, Oke Osanyintolu to ko awọn oṣiṣẹ pajawiri lọ ibi iṣẹlẹ naa ni wọn n ṣe atunṣe bonkẹlẹ lori ile naa ki ileeṣẹ to n gbogun ti awọn ile àlàpà (LASBCA) ma baa wa wo o ni.
Odò Mayo Selbe ninu aworan yii lo gbe awọn agunbanirọ lọ.
Níbẹ ni Yunusa ti ki mọlẹ to si fun ni oyun, to sọ di iyawo rẹ lalai gba iyọnda awọn obi rẹ.
Àkọlé àwòrán, Ibadan Gomina Abdulfattah Ahmed ti ilu Ilorin ti wa nikalẹ ni olu ilu ipinlẹ̀ Kwara.
Olivier Giroud lo kọkọ ṣide eto nigba to rẹyin awọn Man United nigba to ku diẹ ki abala akọkọ ifẹsẹwọn ọhun wa sopin.
Ó fi igi kedari bo ara ògiri rẹ̀,ó wá fi ọ̀dà pupa kùn ún.
Ó bá bá wọn lọ sí Nasarẹti, ó sì ń gbọ́ràn sí wọn lẹ́nu.
Ohun nikan soso ni ọmọ ilẹ adulawọ to ti gba ami ẹyẹ FIFA gẹgẹbi agbabọọlu to pegede julọ lagbaye to fi mọ ami ẹyẹ Ballon d'Or lọdun 1995.
Ó ní, “Kabiyesi, jọ̀wọ́ má dá mi lẹ́bi, má sì ranti àṣìṣe tí mo ṣe ní ọjọ́ tí o kúrò ní Jerusalẹmu, jọ̀wọ́ gbàgbé rẹ̀.
”Awon alejo naa wa ro awon
Ipinnu ijoba yii ni lati mu eto idagbasoke ba ohun amayederun , eto eko ati ilera , paapaa julo  fun awon akusẹẹ.
Ó ní, “N óo ṣe yín bí ohun èlò ìpakà titun,tí ó mú, tí ó sì ní eyín,ẹ óo tẹ àwọn òkè ńlá mọ́lẹ̀, ẹ óo rún wọn wómúwómú;ẹ óo sì sọ àwọn òkè kéékèèké di fùlùfúlù.
(Gbogbo nkan to bá nṣẹlẹ̀ ní àríwá ilé-aiyé, ìdàkejì rẹ̀ ló ma nṣẹlẹ̀ ní gusu.
5 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 7:03 Fídíò, Olumuyiwa Bolade Adedeji Military Bruitality: Bí arákùnrin onípèníjà ara tí sọ́jà lù ṣe dé, Duration 7,035 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Fídíò, EndSARS: Olatunde Abolarinwa London Tailor ní òun á ṣe baba fún mi, kò tilẹ̀ dúró ṣe bàbá àwọn ọmọ tirẹ̀ tóríi ìwà Ọlọ́pàá Mopol5 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Busari fi idi ọrọ yii mulẹ lasiko to n ba ikọ BBC sọrọ lori ẹrọ ipanisọrọ rẹ.
Ninu ilẹ̀ ẹ̀yà Aṣeri, wọ́n fún wọn ní: Miṣali, Abidoni, 
O ni ilana ofin ominira fun oro siso to wa ni Naijiria je anfani fun awon eniyan ti enikeni ko gbodo silo rara lasiko yii ni Naijiria.
“Ẹ lọ káàkiri ibùdó, kí ẹ sì pàṣẹ fún àwọn eniyan náà, pé kí wọn máa pèsè oúnjẹ sílẹ̀, nítorí pé láàrin ọjọ́ mẹta wọn óo la odò Jọdani kọjá láti lọ gba ilẹ̀ tí OLUWA Ọlọrun wọn fún wọn.
TEKELI, a ti wọ̀n ọ́ lórí ìwọ̀n, o kò sì kún ojú ìwọ̀n.
Olopaa Ipinlẹ Taraba ti ni awọn jaguda ti pa fada ti o n lọ lati pẹtu si ija laarin ẹya Tifi ati Jukun ni ipinlẹ Taraba.
Sunday Igboho dá sí ọ̀rọ̀ ìbejì Akeugbagold tí wọ́n jí gbé Ohun tí a mọ̀ nípa ikú ọ̀wọọ̀wọ́ ní Kano nìyí Aláàfin pín oúnjẹ́ fárá Ọ̀yọ́ Alága ẹgbẹ́ NURTW tó gún ọlọ́pàá pá, gba ìdájọ́ ikú Dokita Adegbenro ni awọn gomina ipinlẹ gbogbo lorilẹede Naijiria ti fi ero wọn han fun Aarẹ pe ohun ti wọn fẹ ni ki ijọba apapọ o ti gbogbo ipinlẹ pa lorilẹede Naijiria.
Awọn orukọ obinrin ọgọrun fọdun 2019 la to si isalẹ yii gẹgẹ bi orukọ wọn ti lọ, isẹ ti wọn yan laayo, orilẹede wọn ati itan igbe aye wọn.
Lara awọn ile-iṣẹ ijọba Ipinlẹ Eko ti wọn ṣoju fun ninu ipade itagbangba awon alẹnulọrọ naa ni Ile-iṣẹ ijọba fun eto Ẹkọ; Ile iṣẹ ijọba fun Iṣuna-owo ilu, ẹka Idajọ, ile-iṣẹ ijọba fun iṣẹ Pataki ilu, ati awọn miiran.
 Àṣakẹ ́ ni ó bíí yàtọ ̀ sí Àkàngbé orímóògùnjẹ ́ , yéwándé nìkan ni ó tún máa ń mu owó nínú séèfù .
Yàtọ̀ sí ọpọlọpọ ẹbọ sísun, wọ́n fi ọ̀rá rú ẹbọ alaafia ati ẹbọ ohun mímu fún ẹbọ sísun.
Ta ló ṣe ìdíwọ̀n rẹ̀–ṣebí o mọ̀ ọ́n, dá mi lóhùn!
Ọlọrun kan fẹ ki iru nnkan bayii sẹlẹ ni, ki Alhaji Wasiu ma baa se iru nnkan bayii mọ.
”Batiṣeba bi í pé, “Kí ni?
Oríṣun àwòrán, Instagram Ni ti Arẹmọ Malik Ado Ibrahim to jẹ ọmọ Ọba Ohinoyi ti ilẹ Ebira, wọ bi i ni Naijiria ṣugbọn ilu UK ati US lo ti lọ kawe.
Ṣé yóo bá ọ dá majẹmu,pé kí o fi òun ṣe iranṣẹ títí lae?
Ninu ọrọ ti ẹ, gomina ipinlẹ Ondo ti o tun jẹ alaga agbarijọpọ awọn gomina ilẹ Yoruba, Rotimi Akeredolu ni ifilọlẹ Amọtẹkun jẹ nnkan ayọ fun gbogbo awọn gomina ẹkun iwọ oorun guusu Naijiria.
Ọlọ́pàá rí òkú ọ̀gá àgbà iléèṣẹ́ ńlá kan tí wọn ń wá, lójú omi l‘Eko A gbé òfin 1960 jáde, màálù tó bá jẹ oko àgbẹ̀, tí olówo rẹ̀ kò sanwó, títà ni - Buhari Ìjọba fẹ́ kọ́lé 300,000, pẹ̀lú ìrànwọ́ fún àgbẹ̀ 4m láti mú àdínkù bá ìṣẹ́ - Osinbajo Wò ó bí Alaafin àti aya àkọ́fẹ́ rẹ̀, Olorì Abibat ṣe pàdé ní èwe Adari ileeṣẹ Petroleum Products Pricing Regulatory Agency, PPPRA, Abdulkadir Saidu ni lati igba yii lọ, bi awọn eniyan ṣe n ta epo sii ati iye ti wọn ta epo rọbi lagbaye, ni yoo ma sọ iye ti awọn elepo yoo ma ta lita epo.
of Road Transport Workers, NURTW), eleyi
O ni awọn ọlọpaa mu awọn janduku naa, lẹyin ti wọn ya bo ibùba awọn janduku to wa ni awọn opopona to wa kaakiri ipinlẹ Osun.
 Abenugan ile igbimo asofin, Bukola Saraki lo ka iwe ti aare fi ranse naa nile
Ewe, lasiko igbami-eye naa, Pinnick fi anfani ohun gboriyin fun akonimoogba agba iko agbaboolu Super Eagles, Gernot Rohr latari ise takuntakun re ninu iko naaBakan naa, O tun gbosuba fun awon ti o sagbateru igbami eye ohun ati awon omo egbe ajo NFF fun ifowosowopo won patapata ni ona lati mu igberu ba ere boolu afesegba lorile-ede Naijria.
Nígbà tí wọ́n wo inú ibojì, wọ́n rí ọdọmọkunrin kan tí ó jókòó ní apá ọ̀tún wọn, tí ó wọ aṣọ funfun.
Ṣùgbọ́n lẹ́ẹ̀kọ̀ọ̀kan ó ṣe kókó kí a gbìyànjú ẹ̀.
Ẹ sọ fún Akipu pé kí ó má jáfara nípa iṣẹ́ tí ó gbà láti ọ̀dọ̀ Oluwa, kí ó ṣe é parí.
Awọn alaga ọhun fi sinu atẹjade pe ijọba ipinlẹ Oṣun ni yoo san owo fisa, owo baalu ati ile itura ti wọn yoo de si lorilẹede UAE.
Ile ise ijoba apapo to n mojuto oro awon ekun ti a ti n wa epo robi ni Naijiria ti a mo si: The Niger-Delta Development Commission (NDDC) ni oun ti gbe ise akanse to din die ni egberun kan fawon agbasese nipinle Bayelsa ni eyi ti odiwon iye owo ti won ti na sori won din die ni bilionu mokandinlogoji ni eyi to iye to din die ni ojilenigba ti pari ti won si ti si won fawon ara ilu.
Titi di akoko yii, Yetunde Ogunsola sì n kopa ninu ere tiata lorisirisi, oun naa si ti di Ajihinrere.
 ni 1990 , o je titundasile bi kroatia , o gba sistemu egbe oloselu pupo ati okowo oja ainidekun mu ( free market economy ) .
 to sneak , to skulk .
Nígbà tí àwọn òjíṣẹ́ Ọlọ́run aláwọ̀ funfun tó wá wàásù nípa kírísítì ṣe àkiyèṣí pé èdè wọ́n bá ara wọn mu ni wọ́n bá pè wọ́n ní Yorúbà tàbí Yóòba.
Lootọ lo dara lati ri akọṣẹmọṣẹ nipa ipenija yii, sugbọn o le ṣe diẹ fúnra rẹ : o le kọ awọn nkan to n ja ọ laya si ibi kan, ati idi ti o fi n jaya, ati bi o ṣe ni imọlara si.
Oríṣun àwòrán, Super eagles Àkọlé àwòrán, Awọn olorin ò gbẹ́yìn nínú ríra aṣọ Super Eagles ti a n wi yìí Ibi Ami ẹyẹ AMVCA A tún ṣe alábapàdé awọn imura tó yani lẹ̀nú lásíkò amì ẹ̀yẹ fún àwọn oṣèré jákèjádo Afíríkà.
Wo bí ilé ìwòsàn LUTH ṣe ń gba owó ibùsùn lọ́wọ́ àwọn aláìsàn, tí àwọn míràn sì ń sun ìta Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ìgbátí ìgbámú àná látọwọ́ sọ́jà obìnrin ti bá arákùnrin náà dé iléèwòsàn Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Military Bruitality: Sójà obìnrin lù mí lálù bami nílùú Ibadan4 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Nigerian Recession: Ọ̀rọ̀ ajé Naijiria tó dẹnu kọlẹ̀ yóò kan gbogbo èèyàn23 Bélú 2020 Lagos Senatorial Elections: Abiru ṣ'àbẹ̀wò sí Tinubu lẹ́yìn tó wọlé àtúndi ìbò Sẹnẹtọ ìlà oòrùn ìpínlẹ̀ Eko7 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 #EndSars Lagos Judicial Panel: Iléeṣẹ́ ológun ní òtítọ́ làwọn sọ́jà gbé ìbọn tó lọ́ta gidi nínú lọ sí Lekki Toll Gate22 Bélú 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Intersex: Abiyamọ ní dókítà kò leè sọ bóyá akọ ni ọmọ òun àbí abo
Nígbà tí wọ́n dé orí òkè tí Eliṣa ń gbé, Gehasi gba àwọn ẹrù náà lórí wọn, ó gbé wọn sinu ilé, ó sì dá àwọn iranṣẹ Naamani pada.
Nítorí náà ni wọ́n ṣe ń pe ibẹ̀ ní àfonífojì Akori.
Akase so wí pé lẹ́hìn tí àwọn darandaran náà ṣọṣẹ́ tán ní ilé ìjọsìn náà, wọ́n tún sọ iná sí ilé bíi àádọ́ta ní ìlú náà, kí wọn tó sa lọ.
súlfúrù je elimenti kemika kan to ni ami-idamo s ati nomba atomu 16 .
Ìwọ ìyá mi, bíỌlọ́run kò ti fi ọ́ sílẹ̀ ni ayé bẹ́ẹ̀ náà ni kò ni i fi ọ́ sílẹ̀ ní ọ̀run.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Murphy Elégungun Rọba: Mo fẹ́ di ẹnití egungun rẹ rọ jùlọ ní àgbáyé Àwọn ipò òṣèlú mìíràn tó dìmú lẹ́yìn èyí rèé: Kọmíṣọ́nà fún ètò ìsúná Kọmíṣọ́nà fún ọrọ̀ ajé Kọmíṣọ́nà fún ìdásílẹ̀ àtí ìtọ́ni Oríṣun àwòrán, Lagos State Government Ní ọdún 2016, Gomina Akinwunmiu Ambode yàn án gẹ́gẹ́ bíi adarí iléeṣẹ́ ìjọba Ìpínlẹ̀ Eko tó ń ṣàkóso àwọn ilé kíkọ́.
Orúkọ ìyá rẹ̀ ni Hamutali, ọmọ Jeremaya, ará Libina.
Wọn ṣe ipinu yii lasiko ijoko ile kan nibi ti ọmọ ile to n ṣoju ipinlẹ Borno sọ aba kan lorii iṣẹlẹ bi Boko Haram ṣe ṣekupa awọn agbẹ onirẹsi mẹtalelogoji nipinlẹ rẹ.
Aarẹ ti wọn yan yii dupẹ gidi lọwọ awọn onimọ Sayẹnsi atawọn aṣewadii to ṣiṣẹ takuntakun lai kaarẹ.
Ó bá dáhùn pé, “Ẹ lọ sí ọ̀dọ̀ ọkunrin kan báyìí nígboro kí ẹ sọ fún un pé, ‘Olùkọ́ni ní: Àkókò mi súnmọ́ tòsí; ní ilé rẹ ni èmi ati àwọn ọmọ-ẹ̀yìn mi yóo ti jẹ àsè Ìrékọjá.
“Ẹ gbọdọ̀ jẹ́ ẹni tí a yà sọ́tọ̀ fún mi, nítorí náà, ẹ kò gbọdọ̀ jẹ òkú ẹran tí ẹranko bá pa ninu ìgbẹ́, ajá ni kí ẹ gbé irú ẹran bẹ́ẹ̀ fún.
 ""O tiẹ wa yani lẹnu pe Festus Keyamo, tii se agba amofin nilẹ Naijiria, to tun wa lara ikọ agbẹjọro Buhari, yẹ ko nimọ ju bayi lọ, ti ko si yẹ ko maa lọwọ si idi fifi ọwọ bo otitọ loju, eyi to foju han fawọn ọmọ Naijiria pe Atiku Abubakar lo jawe olubori ninu ibo aarẹ to kọja."
Nigeria Army: àṣírí àwọn ajínigbé kò bò mọ́ ni Ondo àti Ekiti
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Oyo state paternity leave: Ìjọba ìpínlẹ̀ Oyo bẹ̀rẹ̀ ìgbésẹ̀ lórí bí àwọn ọkùnrin ṣe leè máa gba ìsinmi ìtọ́mọ (Paternity leave) 20 Ògún 2020 Oríṣun àwòrán, others Ijọba ipinlẹ Ọyọ ni igbesẹ ti bẹrẹ igbesẹ lati rii pe awọn ọkunrin ti iyawo wọn bimọ naa n gba isinmi itọju ọmọ ti oyinbo n pe ni Paternity leave.
Awon ibudo ọkọ, oja ati awon
 Àyajọ ́ ọdún ààrùn ẹ ̀ dọ ̀ àgbayé ó maa ń wáyé lọ ́ dọọdún ní july 28 láti mú kí àwọn ènìyàn mọ ́ ọ ̀ ààrùn ẹ ̀ dọ ̀ líle .
Awọn agbofinro ni o di dandan ki o foju ba ile ẹjọ laipẹ.
"Nkan bi ọsẹ kan si asiko ti isẹlẹ na sẹlẹ ni wọn ti ko awọn ologun kuro nilẹ, laarọ yii si ni wọn sẹsẹ sọ funmi wipe ileesẹ ọmọogun n sọ wipe awọn ko figba kankan ko ọmọogun kuro nilẹ.
Oríṣun àwòrán, Others Àkọlé àwòrán, Ẹlẹdaa fi ọpọ awọn akọni nla jinki ilẹ Yoruba laye atijọ.
Awọn asofin agba naa lo ni Sonko jẹbi ẹsun mẹrin ọtọọtọ ti wọn fi kan, paapaa julọ, iwa titapa si ofin, asilo ipo, hihu iwakiwa atawọn iwa ọdaran miran labẹ ofin.
Ilé ẹjọ́ sún ẹjọ́ Sẹ́nétọ̀ Abbo síwájú pẹ̀lú béèlì mílíọ̀nù márùn-ún Ṣé o ti gbọ́ ohun ti Ọọni Ifẹ́ àti Soyinka parí ọ̀rọ̀ Yorùbá sí?
Lórí òkè yìí, OLUWA yóo fa aṣọ tí a ta bo àwọn eniyan lójú ya, àní aṣọ tí a dà bo gbogbo orílẹ̀-èdè mọ́lẹ̀.
Ọ̀rọ̀ ti ara rẹ̀ ní ń sọ.
Ó sọ fún àwọn eniyan rẹ̀ pé, “Kí OLUWA pa mí mọ́ kúrò ninu ṣíṣe ibi sí oluwa mi, ẹni tí OLUWA ti yàn gẹ́gẹ́ bí ọba.
Ẹ yìnbọn pa ọ̀daràn tí ẹ bá rí níbi kíbi, Buhari pàṣẹ fáwọn ológun Oríṣun àwòrán, Twitter/Nigerian Presidency Àkọlé àwòrán, Ọrọ eto aabo Naijiria Aarẹ Muhammadu Buhari ti paṣẹ fawọn ologun pe ki wọn yinbọn pa ọdọran kọdaran to ba n ṣagbatẹru rogbodiyan tabi ikọlu kaakiri orilẹede Naijiria.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Corornavirus: Kini Gómìnà ìpínlẹ̀ Ekiti ṣe fun baba tọ ni ọmọ òun ko gbọdọ tèlé oun déle nitori o ṣẹ̀ṣẹ̀ de lati Eko?
Àwọn méèjèjì ṣì ṣe pinu lati gbá bọ́ọ̀lù sáwọn tí wọn ba pàdé Tottenham Hotspur ninu aṣekagba Champions League ti yoo waye ní ọjọ kini osù kẹ́fà.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Egypt President: Aàrẹ Morsi torílè-èdè Egypt dákú,ó gba ibẹ̀ derò alákeji 17 Òkùdu 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 18 Òkùdu 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Iku mu Aarẹ Egypt tẹlẹ lọ Ta ni Mohammed Morsi to ku nile ẹjọ Egypt?
Andriy Yarmolenko lo kọkọ gba goolu alakọkọ wọle fun Westham ki Aaron Cresswell to fọba lee nigba ti ifẹsẹwọnsẹ naa wọ iṣẹju kẹrinlelọgọrin.
Tí a fiṣọwọ́ ní 11:43 11 Òkùdu 201911:43 11 Òkùdu 2019 Ààrẹ ilé ìgbìmọ̀ aṣòfin àgbà Nàìjíríà tuntun BBCCopyright: BBC Ahmad LawanImage caption: Ahmad Lawan Article share tools Facebook Twitter ṢàpínlòView more share options Share this post Copy this linkKà síwájú síi nípa àwọn ìtọ́kasí wọ̀nyí.
Eeyan melo ni ijọba apapọ ti gba siṣẹ labẹ asia N-Power ṣaaju?
lakoko ifehonu han ti o waye niluu Tsafe, nipinle  Zamfara lana ”.
Ó yan Dafidi iranṣẹ rẹ̀;ó sì mú un láti inú agbo ẹran.
 Mo mọ̀ọ́mọ̀ dá €37,000 ti mo rí he padà ni -Ọmọ ogun Bashir Èèmọ̀!"
Àwọn jàndùkú dáná sun àwọn arìnrìnàjò lásìkò tí wọ́n sùn nínú ọkọ ní Borno Ìjọba Borno bẹ àwọn ọgbọ̀n Alfa Saudi lọ́wẹ̀ láti rẹ́yìn Boko Haram Gbàjarè!
Boko Haram: Buhari yoo gba itusilẹ gbogbo onde
Eliṣa pe ọ̀kan ninu àwọn ọmọ àwọn wolii, ó sọ fún un pé, “Ṣe kánkán, kí o lọ sí Ramoti Gileadi pẹlu ìgò òróró yìí.
Oríṣun àwòrán, Olu Alebiosu Àkọlé àwòrán, Wundia ni o maa n ru igba etutu ọṣun Itan naa tẹsiwaju pe, Ọṣun to jẹ oriṣa omi yii lo yọ si Olutimẹhim ti o si ke si oun atawọn eeyan rẹ pe ki wọn sun si apa oke diẹ, iyẹn nibi ti a n pe ni ilu Oṣogbo loni yii.
Nígbà tí Ṣefataya, ọmọ Matani, ati Gedalaya, ọmọ Paṣuri, ati Jukali, ọmọ Ṣelemaya, ati Paṣuri ọmọ Malikaya gbọ́ ọ̀rọ̀ tí Jeremaya ń sọ fún gbogbo àwọn eniyan pé, 
 Ẹni tí kò kọ ojú ewé ni ó lè yọọ ́ .
"Ju eyi lọ, a tun ro o wi pe o ṣe pataki fun awọn orilẹede agbaye lati ri i pe Naijiria n woye pe wọn ni imọlara oun ti a n la kọja ki wọn si da si ọrọ naa ki wọn ba wa yanju iṣoro yii tori o da bii wi pe iṣoro yii ti tayọ ijọba atawọn oṣiṣẹ alaabo orilẹede yii""."
Ajọ naa ni ṣiṣe ere idaraya ni gbogbo igba, jijẹ ounjẹ aṣaraloore, lai mu siga ṣe pataki.
Láti mú kí ó rọ̀rùn fún yín láti rí bí a ṣe ń lo àwọn ìlànà ìlànà ní yàrá ìkóròyìn jọ wa, a ti kọ gbogbo àwọn ǹkan ti yóò wúlò fún yín sí ipele yìí.
Ẹ óo jẹun, ṣugbọn ẹ kò ní yó, ebi yóo sì túbọ̀ máa pa yín, ẹ óo kó ọrọ̀ jọ, ṣugbọn kò ní dúró lọ́wọ́ yín, ogun ni yóo sì kó ohun tí ẹ kó jọ lọ.
Gẹgẹ bii alakoso iṣẹ rẹ ṣe sọ, Majek Fashek fọwọ rọri ku ni ni ilu New York lorilẹ-ede Amẹrika.
"Ààrẹ Buhari buwọ́lu gbígbé ìṣàkoso nọ́mbà ìdánimọ̀ (NIMC) lọ sí ẹ̀ka ìjọba tó ń rí sí ìbáraẹnisọ̀rọ̀ Wọ́n ti sún ìdájọ́ àwọn sójà tó pa ìyá àti ọmọ ní ọdun 2018 sí oṣù tó m bọ̀ Ìjà d'ópin, fún ìgbà àkọ́kọ́, bàálù gbéra láti Israel lọ sí UAE Iléẹjọ gíga jùlọ da ẹjọ́ SDP àti PDP nù, wọ́n ní Yahaya Bello ló wọlé ìbò gómìnà Kogi Yàtọ̀ sí Eko, wo ohun t'áwọn ìpínlẹ̀ meje míràn ń sọ nípa ìwọlé àwọn akẹ́kọ̀ọ́ Onitọhun sọ pe ""Stanley (ti wọn pa) lọ ọ fi ẹjọ sun iya Arinze pe Adekunle n yan iyawo ọmọ rẹ, Chisom, ni ale."
Obi awọn akẹkọ Dapchi nbeere ọmọ wọn Arsenal ja bi ẹlẹṣẹ - Wenger Ilu naa ti ṣaaju ṣe agbekale ofin pajawiri ọlọsẹmeji pe ki awọn eniyan ma ṣe mu ọti lẹyin igba ti wọn ṣe akiyesi bi iwa ipa to tati ọwọ ọti mimu ti ṣe peleke ni ilu Tenant Creek.
sugbon awon to n gbe ni agbegbe naa so pe won ti gbe Mdude Nyagali lo sile
Oríṣun àwòrán, Getty Images Ajọ ere bọọlu ilẹ Yuroopu ti rọ awọn ajọ to n ṣakoso liigi orilẹede kọọkan lati fun wọn ni asiko diẹ ki wọn fi yanju ọrọ lapa ọdọ tiwọn.
Ẹsita bá dá a lóhùn pé, “Ọlọ̀tẹ̀ ati ọ̀tá náà ni Hamani eniyan burúkú yìí.
Iyabo Ojo gé okùn àjọṣepọ̀ rẹ̀ pẹ̀lú olóṣèlú nínú ẹgbẹ́ APC ati PDP Ẹni tó jí ọ̀pá aṣẹ ń bọ̀ wá túbá fúnrarẹ̀, mo fi dáa yín lójú gẹ́gẹ́ bí ìyá - Erelu Kuti Ìró ìbọn dún lákọ ní Iwo road n'Ibadan, Seyi Makinde yọjú síbẹ̀ Gomina Ṣeyi Makinde ti yọju si Iwo Road lorii rogbodiyan to n ṣẹlẹ nibẹ.
Ìdí nì yí tí ó fi jí owó rẹ̀ gbé.
Wọ́n wọ gbọ̀ngàn ní ààfin pẹlu àwọn ọ̀gágun ati àwọn eniyan jàǹkànjàǹkàn ní ìlú.
Jẹ́ kí ó ṣẹ, kí á rí i!
Ọlọ́pàá SARS bíi ọgọ́fà fẹ́ sá kúrò ní Èkó Ìjọba Eko fòfin de àgbò títà lójú pópó f‘ọ́dún Ileya Ọlọ́pàá Sars bíi ọgọ́fà fẹ́ sá kúrò ní Èkó Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ronke Oṣodi: òótọ́ ọ̀rọ̀ máa ń korò gan ni f'áwa èèyàn Ogungbile fi ilu Eko silẹ lọ si Abeokuta, lẹyin to riṣẹ kan pẹlu ijọba ipinlẹ Ogun.
Bi awọn ọmọ ogun naa, ti wọn jẹ ẹṣọ to n tẹle ọkọ agboworin, ṣe ri aaye gbe owo naa salọ, ko sẹni to mọ.
Òun pàápàá sì ti yí ìrìn ẹsẹ̀ rẹ̀ padà, ẹ̀ẹ̀kọ̀ọ̀kan ni òun ń gbé ẹsẹ̀ bíí mààlúù tí ń jẹ koríko, bẹ́ẹ̀ ni òun kò hùwà bí ènìyàn kékeré mọ́, ó ń hùwà bí ìyàwó ènìyàn jàǹkàǹjankan.
O ni awọn oyinbo lo mu àṣà iyawo kan, ọkọ kan wa pẹlu ẹṣin Kristẹni.
Kí ni ẹ̀ṣẹ̀ tí ó ṣẹ̀?
9 45004 Orilẹede Slovakia 1122 20.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Wo àwọn ohun tó yẹ kóo mọ̀ nípa ajọ àwọn gomina Naijiria 23 Èbibi 2019 Oríṣun àwòrán, Twitter/Kayode Fayemi Àkọlé àwòrán, Ẹgbẹ awọn gomina Naijiria Gomina Ipinlẹ Ekiti, Ọmọwe Kayode Fayemi ni alaga tuntun awọn gomina lorilẹ-ede Naijiria bayii.
    Ẹnì kẹta tí o tún jẹ́ pàtàkì tí a rí mú bọ̀ ni ẹni tí oríkọ rẹ̀ ń jẹ Ayédèrú-ẹda ti o ń gbé ìletò kan lẹ́bàá ìlú wa, òun ni o ń fẹ́ obìnrin kan báyìí ti ó ń jẹ Inúdiméjì tí i máa ń gbé ilé Ìbẹ̀rù parapọ̀.
Tí ọ̀kan nínú wọn bá sì wàjà, ón ni ogún ti wọ́n máa ń jẹ lọ́dọ̀ ara wọn bí aya, ẹrú àti ẹrù.
Ile ti wọn wo naa jẹ eyi ti wọn n kọ lọwọ fun awọn oṣiṣẹ rẹ, ati awọn aṣoju ilẹ okeere to ba wa si ọfiisi naa.
"Bi ẹya kọskan ba pin kuro lara Naijiria, ẹ ma gbagbe pe a si tun jẹ alamuleti ara wa, tawọn araalu yoo si nilo lati maa ba ara wọn se.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Àwọn aránṣọ yarí pé gbogbo ẹ̀bi kìí ṣe tàwọn, díẹ̀ wà lọ́wọ́ àwọn oníìbárà náà Ṣugbọn, ipolowo ọja lo mu ki Baba Keresimesi ode-oni o gbajumọ.
Ẹ̀kọ́ kejì ni pé kò dáa tó kí ọba alaye lọ́wọ́ nínú òsèlú, àbùkù àti ẹṣin lo ń kó bá wọn.
Bí o kò bá ṣọ́ra, a óo ṣe sí ọ ju bí a ti fẹ́ ṣe sí wọn lọ.
Ṣugbọn wọn óo dáhùn fún ìwà wọn níwájú ẹni tí ó ṣetán láti ṣe ìdájọ́ alààyè ati òkú.
Eleyii jẹ iye oju owo fun owo isunna Naijiria ni ọdun 2017, triliọnu meje naira o le ni o ma a jẹ iye owo Naijiria.
Nígbà tí ó na ọkọ rẹ̀ tán, ó wá sí ibojì olùfẹ́ rẹ̀ yìí ó ké bí í tí í máa ké wí pé, Ọ̀rẹ́ mi ayé, ọ̀rẹ́ mi ọ̀run, ọjọ́ wo ni ìwọ ń bọ̀ wáá rí mi?
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Yewande Oyediran: Kò sí ohun tó burú nínú bí Ajimobi ṣe dá Yewande tó pa ọkọ rẹ̀ sílẹ̀ 22 Agẹmo 2019 Oríṣun àwòrán, @others Àkọlé àwòrán, Oro lọkọlaya ko yẹ ko maa gba ẹmi ni ọpọ n wi lasiko yii Yewande ni obinrin ti wọn fi ran lọ sẹwọn pe o pa ọkọ rẹ ni Ibadan tẹlẹ.
Ọmọbìnrin tó tayọ nínú ìdànwó WAEC ọdún 2019 pẹ̀lú A1 méje ti kú Ohun mẹ́wàá pàtàkì nípa Maradona àti ìbáṣepọ̀ rẹ̀ pẹ̀lú ẹlẹ́sẹ̀ ayò Diego Costa rèé Ganiyat tó fi irin gbígbóná àti àdá ya ara ọmọ àbúrò ọkọ rẹ ti dèrò àgọ́ ọlọ́pàá l' Ogun Akọwe agba naa ni: O ti di ẹsẹ bayii labẹ ofin fun ẹnikẹni, boya ẹbi, òbí, aladugbo, tabi olori ilu kankan, lati ba ẹni ti ọwọ tẹ fun ifipabanilopọ."
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ààrẹ Buhari fí mí jẹ olùrànlọ́wọ́ pàtàkì lóri epo rọ̀ọ̀bì- Guru Maharaji Ọba Adesoji Aderemi, Ọọ̀ni Ifẹ̀ tó gba ipò ọba mọ́ tòṣèlú Air pollution: Nàìjíríà ni orílẹ̀ède kẹrin tí atẹ́gùn búburú ti ń pa ènìyàn jù làgbáyéé Gẹ́gẹ́ bóṣe sọ, ìpedè Buhari yii jẹ́ èyí to le dá wàhalà sílẹ̀ láàrin ìlú, ó wa ke pe Buhari láti tọrọ àforijì lọ́wọ́ àwọn ọmọ Naìíjríà fún irú èdè bẹ́ẹ̀.
Ranti mi sí rere, Ọlọrun mi.
Lara awon akonimoogba miiran ti won ro pe won kaju osuwon lati tuko ohun ni: Antonio Conte ati Claudio Ranieri.
Lẹ́hìn èyí ló tún gbéra o kọrí sí ilé-ìwé alákọ̀ọ́bẹ̀rẹ̀ tí ìyá rẹ̀ ti jẹ́ olùkọ́.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Sri Lanka attack: Orílẹ̀èdè mẹjọ, yàtọ̀ sí Sri lanka ló pàdánù èèyàn wọn nínú ìṣẹ̀lẹ̀ náà 22 Ìgbé 2019 Oríṣun àwòrán, Reuters Àkọlé àwòrán, Ile ijọsin mẹta ni wọn ṣe ikọlu si ni ọjọ Ajinde Àwọn to gbẹmii mi ninu ikọlu ado oloro to ṣẹlẹ ni awọn ile ijọsin mẹta ati awọn ile igbafẹ kan ni Sri Lanka ni ọjọ Ajinde, ti di ọọdunrun o din mẹwaa bayii.
Wọn ni o ṣe eyí kí ojú má baa tii nígbà tó rí pe ogún náà tí dojúrú mọ òun lọ́wọ́ Oríṣun àwòrán, Other Ìtàn sọ pé Kurunmi ro ó pe, ki lo tún kù tí òun fẹ́ máa mú láyé mọ nígbà tí ọmọ rẹ maraarun tó bí sáyé, tí bá ogun lọ, tó si gba ẹ̀mí ara rẹ.
“Ìwọ ọmọ eniyan, sọ àsọtẹ́lẹ̀ fún àwọn wolii Israẹli.
Orilẹ-ede France ti kogoja lati kopa ni ipele aṣekagba idije ife ẹyẹ agbaye FIFA to n lọ lọwọ lorilẹede Russia.
Chris Kwakpovwe Oríṣun àwòrán, Manna Prayer Mountain Ministry Biṣọọbu ijọ Manna Prayer Mountain Ministry yii lo n kọ iwe Our Daily Manna.
”Ṣugbọn irú ẹ̀mí tí Kristi ní ni àwa náà ní.
Níbẹ̀ ni n óo ti máa pàdé rẹ; láti òkè ìtẹ́ àánú, ní ààrin àwọn Kerubu mejeeji tí wọ́n wà lórí àpótí ẹ̀rí ni n óo ti máa bá ọ sọ nípa gbogbo òfin tí mo bá fẹ́ fún àwọn eniyan Israẹli.
Bí ẹ bá ń gbọ́ lásán, ara yín ni ẹ̀ ń tàn jẹ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù David Bello-Monerville ni ọkùnrin kẹta nínú rẹ̀ tí wọn yóò pa ní London 22 Òkùdu 2019 Oríṣun àwòrán, Met Police Àkọlé àwòrán, David Bello-Monerville died after reports of a fight on Welbeck Road in Barnet on Tuesday night Ọkunrin kan ti wọn gun pa ni apa ariwa London ni Ilẹ Gẹẹsi ni awọn agbofinro ti ni orukọ rẹ n jẹ David Bello-Monerville.
Super Eagles f'ìyẹ́ bo Carthage Eagles Tunisia mọ́ 'lẹ̀
Ní ti àwọn èdè àjèjì wọn yóo di ohun tí a kò gbúròó mọ́.
Gbogbo ẹranko tí ó wà láyé, gbogbo ẹyẹ, gbogbo ẹja tí ń bẹ ninu omi, ati gbogbo ohun tí ń rìn káàkiri ni yóo máa bẹ̀rù yín, ìkáwọ́ yín ni mo fi gbogbo wọn sí.
Eyi tunmọ si pe ẹ̀ẹ́dẹ́gbẹ̀wàá naira 1,900 ni ijọba n na lori ọmọ orileede Naijiria kọọkan lori ilera wọn Naijiria wa lara awọn orileede 52 ti wọn pinu lọdun 2001 lati mu alekun ba owo ti wọn n na lori eto ilera si ida mẹẹdogun 15%.
Agbẹjọro fun Oloye Ogundokun, Opeyemi Adewale Esq.
mo ké sí àwọn akẹ ́ kọ ̀ ọ ́ àti olùkọ ́ láti ran ara wọn lọ ́ wọ ́ nínú ẹ ̀ kó yorùbá .
Ṣaaju akoko yii ni Shelly-Ann ti kopa ninu awọn idije agbaye miran bii; idije Olympic ti Beijin lọdun 2008, idije agbaye Berlin lọdun 2009, idije Olympic ti Londo lọdun 2012, ati bẹẹbẹẹ lọ.
Oríṣun àwòrán, OTHERS Bakan naa lo yẹ ka kọgbọn pe ko si ohun gbogbo taa fi ọna eru ko jọ, ti yoo ba ni kalẹ nitori ibukun Oluwa nii mu ni la, laifi laalaa kun.
 “Mo gbosuba kare lai fun ijoba apapo lataari atileyin won lolokan-o-jokan  fun iko yii.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Shiite: Ìjọba Kaduna ní òun yóò pe ẹjọ́ láti tako El-Zakzaky tó fẹ́ gba ìtọ́jú ní India 8 Ògún 2019 Oríṣun àwòrán, Shuhaila El-Zakzaky Ijọba ipinlẹ Kaduna ti kede pe oun ko faramọ asẹ ti ileẹjọ pa pe ki wọn fun olori ijọ Shiite, Ibrahim El Zakzaky ati iyawo rẹ ni aaye lati lọ gba itọju loke okun.
ti apapo esi ifesewonse ohun si je ami ayo marun un si meta(2nd leg, aggregate score(3 – 5)Ogbontarigi atamatase agbaboolu eyin fun iko Real Madrid,
Olusola jẹ ọkan lara awọn agba ọjẹ oṣere tiata to da ẹgbẹ awọn oṣere taa mọ si ANTP silẹ lọdun 1976, to si jẹ akọwe owo akọkọ fun ẹgbẹ naa laarin ọdun 1976 si 1989, bẹẹ lo tun gbe ọpọ ere jade ni ede Yoruba.
Ṣé o rò pé ìsọkúsọ rẹ lè pa eniyan lẹ́nu mọ́ ni?
Nígbà tí a bá ti dárí àwọn nǹkan wọnyi ji eniyan, kò tún sí ìrúbọ fún ẹ̀ṣẹ̀ mọ́.
''O gbiyanju lati ge ọmu apa ọtun obinrin naa eyi ti ọpọ gbagbọ pe o fẹ fi ṣe oogun ni, ṣugbọn aṣiri tu lẹyin tawọn to wa nile itura naa gbọ ariwo obinrin ọhun lati inu yara,'' agbẹnusọ ọlọpaa ṣalaye.
Àwọn ọmọ Peresi ni Hesironi ati Hamuli.
Kin lo de ti ikọ ẹlẹsin Hakika fi yatọ ?
 Ẹni àkọ ́ kọ ́ tí ó dé póólù gúsù .
Lẹ́yìn náà Mose ati àwọn aadọrin olórí náà pada sí ibùdó.
Gbogbo wọn jẹ́ ọtalelẹgbẹta ó dín mẹjọ (652).
Nígbà tí a kò lè yí i lọ́kàn pada, a bá dákẹ́.
Ko ti daju iye ọjọ ti aarẹ yoo fi wa ni iyasọtọ ṣugbọn idibo aarẹ Amẹrika ku oṣu kan bayi.
Nígbà tí wọ́n dé ọ̀dọ̀ àwọn eniyan, ọkunrin kan wá sọ́dọ̀ Jesu, ó kúnlẹ̀ níwájú rẹ̀.
Àwọn akọ mààlúù ni wọ́n kọ́kọ́ pa, àwọn alufaa gba ẹ̀jẹ̀ wọn, wọ́n dà á sára pẹpẹ.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Turkey n jẹ igba aya ati ọmu akukọ.
Ninu ọrọ rẹ, Oluwo tilu Iwo, Ọba Abdulrasheed Akanbi kọminu lori aigbọraẹniye to n waye laarin awọn ọbalaye ni ilẹ Yoruba, pẹlu ipe si alaafin latinbẹrẹ igbesẹ iṣọkan awọn ọbalaye ki ilẹ Yoruba lee pada si ipo ọlanla rẹ lawujọ agbaye.
world class training on arms and civility 3.
O tesiwaju pe  awọn  ala to wa lorilẹ ede  Naijiria ko dara rara , nitori eto ti ajo ECOWAS se lati fun  awọn  eniyan ni anfaani lati  maa wole-jade bo se wu won.
Mo wá gbégbá ọpẹ́, mo r’íbà k’íbà ṣẹ
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Jàǹdùkú jó agboolé Sanwo-Olu, Iléeṣẹ́ Channels ń kógbá wọlé Ọ̀kan lára olùwọ́de tó fara gbọgbẹ́ ní Lekki jáde láyé - Sanwo-Olu Kò sí olùwọ́de tó kú ní Lekki - Sanwo-Olu N kò lọ́wọ́ nínú ìpànìyàn, kò dáa bí wọn ṣe lo ọta ìbọn ní Lekki - Tinubu Ọjọ́ Ìsẹ́gun di ọjọ́ ìbànújẹ́ fún ọ̀pọ̀ ìdílé ní Nàíjíríà torí òkú tó ṣùn Ọ̀dọ́ 30 ń gba ìtọ́jú lọ́wọ́ nílé ìwòsàn torí ọ̀gbẹ́ ìbọn ní Lekki - Sanwo-Olu ṣàlàyé Àwọn ṣọ́jà ṣíná ìbọn bolẹ̀ ni Lekki Tollgate Àwọn ọlọ́dẹ darapọ̀ mọ́ ìwọ́de #EndSARS l'Osogbo, wọ́n ní kò sáyè fún jàǹdùkú mọ́ Bode George woye ọrọ yii nigba to n fesi si isẹlẹ isekupani to waye ni Lekki lọ̀jọ Isẹgun.
Nigba naa lọhun a ti ni ọga mii, Ibrahim Gusau to lọ ba minisita.
Ó kó gbogbo wúrà, fadaka ati àwọn ohun èlò tí ó wà lábẹ́ ìtọ́jú Obedi Edomu ní ilé Ọlọ́run.
    Bí àwọn iwin méjì yìí ti ń súnmọ́ wa ni ìmọ́lẹ̀ ńlá náa ń bá wọn bọ̀ lọ́dọ̀ wa.
Ẹni to bori: South Africa Madagascar vs Côte d'Ivoire.
Gbọningbọnin ni olódodo yóo dúró,ṣugbọn ẹni ibi kò ní lè gbé ilẹ̀ náà.
Ẹgbẹ́ IPOB ò tako Ààrẹ Buhari ní Japan- Iléeṣẹ́ Ààrẹ Òfin nìkan ló lè gbadé lórí àwa Ọba ìlú lbadan- Oba Lekan Balogun Irọ́ ló pa, a kò mọ̀ ọ́ rí tàbí fún ọ ní ₦13m - APC tako afurasí ajínigbé O fí kún pé àwọn atúnṣe kan to yọjú tí ẹgbẹ́ òṣìṣẹ́ ń gbíyànjú láti ṣe àtúnto rẹ, ló fa ìdádúró sísàn owó náà.
Igbakeji aarẹ tẹlẹ ri ati oludije fun ipo aarẹ lẹgbẹ oṣelu PDP lọdun 2019 fesi loju opo Twitter rẹ pe oun gba iroyin ibanujẹ pe aarẹ Donald Trump bẹgi dina wiwa awọn ọmọ Naijiria si orilẹede Amẹrika.
Bóyá yóo tilẹ̀ dá ibinu rẹ̀ dúró, kò sì ní pa wá run.
"‘Patience Jonathan yoo yọju sileẹjọ’ EFCC ń wádìí iléeṣẹ́ 'Bola Tinubu,' Alpha Beta Consulting Ltd' 'Operation Rewire' EFCC / FBI sèso owó tó lè ní mílíọ̀nù N153 Fayose ke s'ijọba lati kede dukia ti EFCC gba Jonathan sọ nigba naa pe oun yọ Waziri nipo ""lati le mu atunṣe ba gbigbogun ti iwa ibajẹ ni Naijiria""."
Awọn ẹlẹsin Coptic jẹ irufẹ ẹya kristẹni kan to gbalẹ ni iha Ila Oorun ilẹ Afrika, paapa ni orilẹede Egypt.
Ẹ wo adúrú ẹnu tí mó n bọ́ - Jaiye Kuti Wo orílẹ́èdè tí wọ́n tí ń dáwó ìsìnkú ara wọn pámọ́ Ayédèrú Ọ̀ṣun ni wọ́n ń bọ lónìí, kìí ṣe ojúlówó - Bàbá Ọlọ́ṣun tún figbe ta ''Àwọn ọmọ wa ma ń wọ ọkọ̀ ojú omi láìsí ẹ̀wù ìdàábòbò nítorí àti kàwé'' Tinubu ní kò jẹ́ kí àwọn ọmọ bíbí Eko gbérí nínú òṣèlú Amaechi ni ọrọ sisan owo osu naa ti yẹ ko bẹrk tipẹ, to si n rọ ijsba lati tete fẹnu ọrọ jona lori rẹ, ki wọn si san ajẹsilẹ owo osu tuntun naalsna ati dena ifẹhonuhan miran latọdọ awọn osisẹ.
Ida bi aadọrin ninu ọgọrun ni Kroenke nikan ni ninu awọn to ni Arsenal nigba ti Alisher Usmanov to jẹ ọmọ orilẹ-ede Russia si ni ida ọgbọn.
Iji naa si n fi alaga ẹgbẹ oṣelu naa lakalaka lọwọlọwọ.
Ṣugbọn ṣa, lati bi ọdun 1999 ni ijọba oloṣelu to n jẹ ni Ekiti ti sọ ọrọ Pelupelu di ọrọ oṣelu.
Lẹ́yìn náà, wọ́n wọ inú ibi mímọ́ Baali lọ, 
Nítorí náà ni Solomoni ṣe tún ìlú náà kọ́.
Olufon ti Ifon Murder: Àwọn agbébọn tó pá Olufon ti Ifon ti ṣe ohun èèwọ̀ ní ilẹ̀ Yoruba
"Eyi to wa buru ju nibẹ ni pe igbimọ lọbalọba nipinlẹ Ọyọ ko tii se ipade kankan lati ọdun mẹrin nibiti o ti jẹ alaga wọn, eyi ko si sẹyin bo se nira fun lati jẹ ki alaafia, isọkan ati irẹpọ waye laarin awọn ọba alaye nipinlẹ naa.
Gbogbo awọn osisẹ to yẹ ko wa lẹka eto ilera gan an ni wọn ti salọ tan."
Ọlọrun dá Mose lóhùn pé, “ÈMI NI ẸNI TÍ MO JẸ́.
Takyi tun fikun pe, ọgọrin ninu awọn ọmọ Naijiria ti wọn le naa n se gbajuẹ ni ilẹ naa ni Osu Kinni ọdun 2019 ati bẹẹ bẹẹ lọ.
Wéré ni tọ́mọ́ndé tàgbà ń rún orógbó lẹ́nu bí i gúgúrú, tí wọ́n sì ń jẹ obì bí ẹní jẹ̀pà.
    Kí n ma sà bá ọ̀rọ̀ gùn lọ títí, èmi náà fèsì ìwé tí Ìfẹ́pàtàkì kọ, nǹkan tí mo sì kọ ni èyí: 
MI ní 'Òjíṣẹ́ Satani' ni pásítọ̀ kan; ni ìjọ Satani bá da lóhùn
Leyin ti adari igbimo asofin Bukola Saraki ka oruko awon eniyan marun un  naa, o wa foruko won ranse si igbimo to n ri si ile-ifowopamo ati ajo ma –da-mi-dofo fun ayewo finni-finni.
Ẹgbẹ́ òṣèlú PDP sún ìdìbò abẹ́nú Edo síwájú síi Oríṣun àwòrán, Seyi Makinde/Twitter Lórí ṣíṣí iléèwé pàda, Makinde ní ó yá ní ìpínlẹ̀ Oyo, Cross River ní kò sóhun tó jọọ́ Ijọba ipinlẹ Ọyọ ti paṣẹ ki awọn ileewe gbogbo ni ipinlẹ naa o di ṣiṣi pada ni ọjọ Aje, ọjọ kọkandinlọgbọn oṣu yii, amọ ijọba ipinlẹ Cross River ti fi ọsẹ meji kun iwọle awọn akẹẹkọ.
Ó sọ fún àwọn ọmọ-ẹ̀yìn pé, “Ẹ jókòó níhìn-ín, èmi ń lọ gbadura lọ́hùn-ún nì.
 Ilé aṣòfin ìpínlẹ̀ Ondo yan olórí tuntun Oríṣun àwòrán, DailypostNigeria Àkọlé àwòrán, Nigba ti awọn akọroyin bere idi ti o fi ti ile pa, aṣofin Oloyelogun ni ofin ilana ile fun oun laṣẹ lati ṣe bẹẹ.
Ó gbìn ín bí wọn tíí gbin igi wilo.
wọ́n gba orí alagbalúgbú omi kọjá lọ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Mayowa Omoniyi: Kò sí orin Obey, Sunny Ade abí tàkasúfèé tí ń kò le ta gìtá sí Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Nigeria 2019 election: Jàndùkú yìnbọn f'ọ́mọ ọdún mọ́kànlá lẹ́sẹ̀
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Awọn asofin ni k'ijọba apapọ o dawọ owo ori ọja lati okeere duro 15 Èrèlè 2018 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Awọn asofin agba orilẹede Naijiria ni afikun owo ori ọja to n wọle lati ilẹ okeere n se akoba idagbasoke Ile asofin agba orilẹede Naijiria ti ke si ijọba apapọ lati so ọwọ rẹ kọ lori igbesẹ afikun owo ori ọja to n wọle lati ilẹ okeere.
Àwọn kọ ̀ mpútà alásopọ ̀ nodes ló ún ṣe ìjẹ ́ ẹ ̀ rí àwọn ìdúnàádúrà tó únṣẹlẹ ̀ pẹ ̀ lú ìṣeàmìkíkọpamọ ́ tí wọ ́ n jẹ ́ kíkọ sínú ìwé-àkọọ ́ lẹ ̀ pípínkiri tó hàn sí gbogbo ènìyàn tí à ún pè ní blockchain .
 Gbogbo won fi eto ti won gbekale yii fi la awon akoroyin lobinrin ati gbogbo ero lori ohun to ye ni mimo lori arun jejere.
Ami ori rẹ jọ ti onka ogún amọ itumọ rẹ yatọ pupọ.
Olukuluku wọn náà bá gé ẹrù igi kọ̀ọ̀kan, wọ́n tẹ̀lé Abimeleki.
Ṣugbọn Deji Adeyanju ninu ọrọ tiẹ pẹlu BBC sọ pe Charly Boy ja oun kulẹ.
"Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Mí ò ya wèrè, mí ò burú, ọ̀nà àtijẹ là ń wá' Lizzy ni: ""Mo kọkọ fẹ fi ile yii pamọ ni ko to di pe mo niran pe, inu osu kẹfa si ikeje ni awọn ile ti mo ba n kọ maa n pari."
ki lotun ku ti mo n fẹ?
maa se ipade pọ pẹlu igbimo alasẹ lori ọrọ to jẹ mọ ti ilẹ okeere lojo Aje ni
    Àwọn mẹ́tẹ́ẹ̀ta jùmọ̀ kúrò ní ilé, an rìn títí wọ́n fi dé oríta mẹ́ta kan báyìí.
Kola Olubiyo to jẹ oludari ajọ to n ja fun ẹtọ araalu lẹka ohun amuṣagbara woye si ọrọ yii, to si ni labẹ ofin karakata ina ọba, ko si ohun to buru ninu iru adehun bẹẹ.
Ọwọ́ Interpol àti ọlọ́pàá Nàìjíríà ti tẹ ọmọ Nàìjíríà mẹ́ta tó lu èèyàn 50,000 ní gbájúẹ̀ Kílódé tí Ọọni Ife, Oba Ogunwusi kò fi gbọdọ̀ rí ọmọ rẹ̀ tuntun ti Olorì Naomi bí títí di bíi ẹ̀yìn oṣù mẹ́fà?
O sọ nipa iṣẹ agbẹjọrọ to fi ọdun mọkanla ṣe ko to pada wa gbọran si Ifa lẹnu ko to maa ṣe iṣẹ Ifa dida.
 lóòótọ ́ , àwọn ìlú tí a dárúkọ bí ìlú tí a ti ń sọ ẹ ̀ ka-èdè Ìgbómìnà máa ń gbọ ́ ara wọn ni àgbọ ́ yé bí wọ ́ n ba ń sọ ̀ rọ ̀ síbẹ ̀ oríṣiríṣi ni ẹ ̀ yà ẹ ̀ ka-èdè Ìgbómìnà tí wọn ń sọ láti ìlú kan sí èkejì .
Àwọn maraarun wà fún àwọn ìlú olódi àwọn ọba Filistini, pẹlu àwọn ìletò kéékèèké wọn, tí kò ní odi.
kí ẹ máa retí ọjọ́ Ọlọrun, kí ẹ máa ṣe akitiyan pé kí ó tètè dé.
ifigagbaga ohun bere  lati di Ife Ẹyẹ WBC
Ìgbà tí ó tún ṣe, àfi bí mo tti ri omi gbígbóná tí ó ń rọ́ láti òkè lu ọkùnrin náà tí ara rẹ̀ sì bó fẹ́lẹfẹ̀lẹ; bí omi yìí sì ti ddáwọ́ dúró ni ẹ̀wọ̀n kan wá láti òkè tì ó dè é, inú èyí ni a sì fi í sí títía fi jáde nínú ilé ẹ̀dá tì kò ní ìtìjú, Ikú ẹni tí ń gbé agbedeméjì ayé òun ọ̀run.
Awọn ọmọbinrin naa yoo wa l'ẹwọn titi ti ile ẹjọ yoo fi gbọ ẹjọ wọn.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Sekinat Quadri ọmọ ọdun meje ajẹsẹ to fẹ dabi Anthony Joshua Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Obinrin Akansẹ: Ẹsẹ kiku bi ojo kọ mi lati di alagbara ''Lẹyin igba naa mo rin lọ si ibi ti awọn ẹru mi wa ninu agbepọnyin mi ti o si wa fi ọwọ kan ibadi mi nibẹ naa.
NÍ KÍÁKÍÁ Ní dédé àsìkò yìí, ní dédé agogo 3:00 òwúrọ̀ kùtùkùtù, ìgbìmọ̀  láti àjọ Amúninípá dé ilé oníròyìn àti ajà-fún- ẹ̀tọ́ọ ọmọ ènìyàn Luis Carlos Díaz, tí ó ti di ẹni àwátì láti agogo 5:30 ìrọ̀lẹ́ .
Atẹjade náà ni owó tuntun yìí, tí àpapọ̀ rẹ jẹ bílíọ̀nù lọ́nà mejidinlọgọfa náírà, (N118bn) tún yàtọ̀ sí aadọsan mílíọ̀nù dọla ó dín mẹta ($167m) tí ìjọba ilẹ̀ UK àti Faranse gbé ẹsẹ le, tó fi mọ mílíọ̀nù mejilelaadọjọ dola ($152m) miran ti wọn n bá ìjọba UK ṣe ẹjọ́ le lori.
Ìfihàn tí a fi fún Wòlíì Joseph Smith ní Fayette, New York, 6 Oṣù Kẹrin 1830.
Ologbondiyan sọ fún BBC pé àwọn n fi ẹ̀hónú hàn nítorí ìhùwàsí àjọ INEC lórí ọ̀nà tó gbà ṣètò ìdìbò gómìnà tó wáyé ní ìpínlẹ̀ Ọṣun.
Adolf Hitler: Kíni ẹ̀yin rántí tàbí mọ̀ nípa Adolf Hitler yìí?
INEC ko figba kan sọrọ si awọn iwe ti aar Buhari lẹ mọ awọn iwe ẹri rẹ.
Mo gbọ́ tí ó ń sọ̀rọ̀, ṣugbọn ohun tí ń sọ kò yé mi.
Sẹnẹtọ Abudulahi ṣalaye pe gẹgẹ bi akọsilẹ ajọ iṣọkan agbaye, orilẹede Naijiria ni awọn eeyan to ni irẹwẹsi ọkan ti pọ ju lọ nilẹ Afirika, bakan naa ni akọsilẹ ọhun to fihan pe Naijiria ni iṣẹlẹ ipara ẹni ti pọju ṣikarun un lagbaye.
Adesina sọ ọrọ náà lásìkò tó ṣe ìfọ̀rọ̀wánilẹ́nuwò ni orí móhùmáwòràn kan pé, kí a maa lọ ẹbi àti ìyà mọ bí wọ́n ṣe ń já sọ́ọ̀bù, dàbí ẹni pé ènìkàn sọ pé ìwà adigunjalè dára ni.
Kí ó jẹ́ àmì ní ọwọ́ rẹ, ati ohun ìrántí láàrin ojú rẹ, kí òfin OLUWA lè wà ní ẹnu rẹ, nítorí pé pẹlu ipá ni OLUWA fi mú ọ jáde láti ilẹ̀ Ijipti wá.
Ẹ kí Andironiku ati Junia, àwọn ìbátan mi tí a jọ wà lẹ́wọ̀n.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Itan Ilu gangan Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
"Ó fi ọ̀rọ̀ náà léde lójú òpó twitter rẹ̀ pẹ̀lú àfikún pé, òun ṣẹ̀ṣẹ̀ parí ìtàkurọ̀sọ pẹ̀lú Tunde Bakare àti Mogaji Gboyega Adejumọ, tó jẹ agbẹ̀nusọ fún ẹgbẹ́ ọmọ Yorùbá ti wọn ń pè ni ""Yorùbá Summit Group"" Gẹ́gẹ́ bí ó ṣe sọ, ó ní , a ti yánju gbogbo ọ̀rọ̀ tó wà láàrin wa, a si ti fi gbogbo ọ̀rọ̀ náà sẹ́yìn bí eegun ṣe n fi asọ."
Awọn ọlọpaa ipinlẹ Kaduna fidi ẹ mulẹ pe eniyan mẹfa lo ti jalaisi bayii ninu iṣẹlẹ naa ti awọn miran ṣi wa nile iwosan.
"Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Wo àwọn ọ̀nà tí o lè gbà láti di ọjọ́ ogbó pẹ̀lú olólùfẹ́ rẹ O ni ""Emi ko le darapọ mọ ẹnikẹni lati gba ẹmi ọpọ ero, lai lai."
 Ó maa ń sábà ran ẹsẹ ̀ tí ara bá lè bó .
Dandan si ni kirẹẹditi ninu imọ ìṣirò ati èdè Gẹẹsi.
2019 Election: Àwọn oloṣelu tó yege àti àwọn to fidirẹmi Ohun márùn-ún tí Atiku ń bèrè lọ́wọ́ Buhari níbi ìpàdé rẹ̀ pẹlú Abdulsalam, Kukah APC pàṣẹ lọ rọ́ọ́kún nílé fún Amosun, Okorocha Àwọn ohùn tó ṣé kókó tó yẹ ká mọ ṣáájú ìdìbò 2019 Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Yinka Ajia: ìbẹ̀rù Ọlọrun ni mo fẹ́ fi tukọ̀ Kwara ti mo ba wọlé Take it Back Awọn ọdọ Naijiria ni wọn ni aṣa yi ti Omoyele Sowore ti ẹgbẹ AAC ṣagbatẹru rẹ.
Bí ó bá jẹ́ pé ti ayé yìí ni ìjọba mi, àwọn iranṣẹ mi ìbá jà; àwọn Juu kì bá tí lè mú mi.
Ó jẹ́ kí á mọ àṣírí ìfẹ́ rẹ̀, gẹ́gẹ́ bí ètò tí ó kún fún oore-ọ̀fẹ́ tí ó ti ṣe ninu Kristi.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Yomi Fabiyi: Èmi ti dáríjì ẹ́, kí ìwọ náà jọ̀wọ́ dáríjì mí 3 Sẹ́rẹ́ 2019 Oríṣun àwòrán, Instagram Àkọlé àwòrán, Ìjà yíí bẹ̀rẹ̀ ní ǹkan bí ọdún díẹ̀ sẹ́yìn lẹ́yìn tí Yomi Fabiyi pe Toyin Abraham ní alágàbàgebè nítorí ìjà pẹ̀lú Mercy Aigbe.
Lati ọjọ kọkanla oṣu Kọkanla ni Adoke ti wa ni ahamọ ni Dubai nigba ti agbẹjọro rẹ Mike Ozekhome sọ fawọn akọroyin pe o lọ gba itọju.
Ṣugbọn Dafidi dáhùn pé, “Ẹ̀yin arakunrin mi, ẹ ẹ̀ gbọdọ̀ ṣe bẹ́ẹ̀, nítorí gbogbo ohun tí OLUWA fifún wa.
 Bi o ṣe bori yii kii ‘se fun emi nikan bikose fun gbogbo wa ni Ekiti.
Oluranlọwọ agba fun aarẹ lori iroyin ati ipolongo, Garba Shehu sọ ninu atẹjade kan pe ọrọ oṣelu ni bi awọn kan ṣe n bu aarẹ nitori pe ko ti i ba awọn ọmọ Naijiria sọrọ lori amohunmaworan.
gbagede Ile Igbimọ Asọfin naa ni ilu Ikẹja, Agbẹnusọ Ile Igbimo Asọfin Ipinlẹ Eko, Aṣofin
Ta sì ni adití, bíkòṣe ẹni tí mo rán níṣẹ́?
Ẹ jẹ́ kí á lọ gbé àpótí ẹ̀rí tí ó wà ní Ṣilo wá sọ́dọ̀ wa, kí ó lè máa bá wa lọ, kí ó sì gbà wá lọ́wọ́ àwọn ọ̀tá wa.
4 Àti pé dájúdájú olúkúlùkù ènìyàn gbọ́dọ̀ ronúpìwàdà tàbí kí wọn ó jìyà, nítorí èmi, Ọlọ́run, mo jẹ́ àìnípẹ̀kun.
Ìgbé ayé Abiola Ajimobi nínú àwòràn pẹ̀lú àwọn ǹkan tó ṣẹlẹ̀ Àlàyé rèé lórí ikú tó pa Ogun Majek Eji Gbadero, ọmọ Ibadan àti jayé-jayé ọmọ ónílẹ̀ ti wọn yẹgi fun l'Eko Ọrọ ipari rẹ ninu lẹta naa ni wi pe o ti tan fun Tinubu ninu oṣelu orilẹede Naijiria, oun ti o ku ni ki o lọ rọkun nile, ki o si ma a sinmi.
ibi n sekupa awon afin, lati lo eya ara won fi se ogun owo.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Oluwo of Iwo: Nàìjíríà, sọ́ra, ogun ń sọ ilé ọlá di ahoro!
Àwọn ẹgbẹ́ mẹtẹẹta fọn fèrè wọn, wọ́n sì fọ́ ìkòkò tì ó wà lọ́wọ́ wọn.
Baba-onírùngbọ̀n-yẹ́úkẹ́ ṣe é fún wa púpọ̀.
Rabiu Adamu to jé akọwé ile isẹ to n ri si ètò ẹ̀kọ́ nínú àtẹjáde rẹ̀ to fọwọ́si ṣàlàyé pé ènìyàn mẹrinla lo ni ààrun covid-19 lọ́jọ́ kan soso nípinlẹ̀ náà, nítori náà wọ́n kéde pé ki àwọn obi lọ mu ọmọ wọ́n láwọn ilé ìwé ti ọmọ ń gbe lọ́jọ́rú ki àwọn akẹ́kọ̀ọ́ tó n lọbọ̀ náà si dúro sílé.
Lara awọn amuyẹ ti iyawo ti baba fẹ ẹ fẹ gbọdọ ni, ni pe yoo ti to ẹni ọgọta ọdun tabi ju bẹẹ lọ, kii sii ṣe nitori ọmọ bibi mọ.
Lẹ́yìn tí ó ti lo ọdún 5 nínú ẹ̀wọ̀n, akọbúlọ́ọ̀gù ọmọ Íjípìtì àti ajàfúnẹ̀tọ́ Alaa Abd El Fattah yóò gba ìdásílẹ̀ nínú ẹ̀wọ̀n ní ọjọ́ 7, oṣù Ẹrẹ́nà, ọdún 2019.
" Maurice Iwu ni àwọn ewéko náà tí òun ṣe àwárí wọn náà, ní àwọn ọmọ ilẹ̀ China tí lo fún ìwòsàn àrùn Coronavirus yìí kan náà.
''Mi ò ṣe àrífín Sultan àmọ́ mi ò lè bẹ̀rẹ̀ àwẹ̀ láì fojú r'óṣù' Ọlọ́pàá Sharia Kano mú èèyàn tó lé ní 80 tori oúnjẹ nínú ààwẹ̀ Wo àwọn orílẹ̀èdè tí wákàtí ààwẹ̀ wọn gùn ju ti Nàìjíríà lọ ìjọba Nàìjíríà ti kéde ìsinmi lọ́jọ́ Ìṣẹ́gun àti Ọjọ́rú Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Omar Al-Bashir ti wọ́n gbajọba lọ́wọ́ ẹ ló di wàhálà Ninu atẹjade kan eleyi ti ajọ to ga julọ fun ẹsin Islam lorilẹ-ede Naijiria, NSCIA fi sita ni wọn ti sọ eyi.
Àwọn eniyan náà sin OLUWA ní gbogbo àkókò tí Joṣua ati àwọn àgbààgbà tí wọ́n kù lẹ́yìn rẹ̀ wà láàyè, àwọn tí wọ́n fi ojú rí àwọn iṣẹ́ ńlá tí OLUWA ṣe fún Israẹli.
Ẹlẹ́wọ̀n: Ọgbà ẹ̀wọ̀n ni mo ti kàwé yege ní ìdánwò Jamb
Pẹlu bi oniruuru eeyan yoo ṣe maa gbe ibomu tiwọn ran bayii, bawo la ṣe ayederu mọ ati pe ṣe gbogbo awọn ibomu wọnyii ni yoo le ṣiṣẹ idaabobo lọwọ arun yii?
Iranṣẹ mi yóo ṣe àṣeyọría óo gbé e ga, a óo gbé e lékè;yóo sì di ẹni gíga,
Ibẹ̀ ni wọn yóo sì ti máa ṣe burẹdi fún ẹbọ ohun jíjẹ, kí wọn má baà kó wọn jáde wá sí gbọ̀ngàn tí ó wà ní ìta, kí wọn má baà fi ohun mímọ́ kó bá àwọn eniyan.
Wọ́n bá fà á lé Gedalaya ọmọ Ahikamu, ọmọ Ṣafani lọ́wọ́, pé kí ó mú un lọ sí ilé rẹ̀.
Fẹmi ni ti kii ba se ere, kin ni oun ko ba jẹ yo, debi ti oun yoo maa gba baba oun leti pẹlu afikun pe gẹgẹ bii osere tiata to dantọ, ojuse ti wọn gbe le oun lọwọ ninu ere ni eyi, oun si gbọdọ see ni.
Èwo ni ó ṣe pataki jù!
Olusegun Obasanjo: Ibrahim Ibuoye, ẹni ọgọ́ta ọdún dèrò ilé ẹjọ́ nítorí ó wọ inú oko Obasanjo láì gba àṣẹ
Mose kó àwọn ọmọ Aaroni, ó wọ̀ wọ́n lẹ́wù, ó sì dì wọ́n ní àmùrè, ó dé wọn ní fìlà, gẹ́gẹ́ bí OLUWA ti pàṣẹ fún un.
Ohun tí wọ́n sọ fún mi kò tó ìdajì ọgbọ́n rẹ, ohun tí mo rí yìí pọ̀ ju ohun tí wọ́n sọ fún mi lọ.
Gbogbo aiṣododo ni ẹ̀ṣẹ̀, ṣugbọn ẹ̀ṣẹ̀ mìíràn wà tí kò jẹ mọ́ ti ikú.
Ogun tún bẹ́ sílẹ̀ láàrin àwọn Filistini ati Israẹli.
Orúkọ Aisha Yesufu náà wọ inú BBC 100 Women tí a fi ń sọri àwọn obìnrin tó pegedé ní 2020 Ọ̀rọ̀ àsọkẹ́yìn Diego Maradona ìlúmọọká agbábọ́ọ̀lù rèé kó tó dágbére f'áyé Omotara kan ìdin nínú iyọ̀, àwọn ọmọ ilẹ̀ Faranse náà bínú síi nítorí alágbe tó fi ṣe yẹ̀yẹ́.
 Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ibadan Murder: Oyún oṣù méje ló ń bẹ nínú Azeezat, kí wọ́n tó f'òkúta fọ́ ọ lórí Kini Esabod sọ nipa iwa ipa ninu idile?"
Ó lọ kọ orúkọ sílẹ̀ pẹlu Maria iyawo àfẹ́sọ́nà rẹ̀, tí ó lóyún, tí ó sì fẹ́rẹ̀ bímọ.
Kí ló dé tí ẹ̀yin eniyan mi fí ń sọ pé,‘A ti di òmìnira, a lè máa káàkiri;a kò ní wá sí ọ̀dọ̀ rẹ mọ́?
Ó ti yipada kúrò lẹ́yìn mi, kò sì pa òfin mi mọ́.
Ọgọsan ifẹsẹwọnsẹ ni Cazorla gba fun Arsenal pẹlu goolu mọkandinlọgbọn.
Lábẹ́ ìlànà tuntun yìí ni ìjọba yóò ti máa gba 45,250 kwanzas fún ìwé ìwọ̀lú ìdúró-sí-ìlú; 21,350 fún ìwé ìwọ̀lú ìrìnàjò-afẹ́; 36,500 fún ìwé ìwọ̀lú àgbàníbodè; 38,125 fún ìsúnsíwájú ìwé ìwọ̀lú iṣẹ́; 15,250 fún ìwé ìwọ̀lú ọ̀rọ̀ ìlera ara; àti 30,500 fún ìwé pélébé ìgbélùú.
"Fun awọn eeyan to san ẹgbẹrun lọna aadọta naira bata tapa sẹgun ti wọn fi n sisẹ wa nibẹ sugbọ fun awọn to san ẹgbẹrun lọna ogoji, ko si bata yii nibẹ.
O ni nibi ti awọn orileede miiran ti n ṣi ileeṣẹ aṣoju kaakiri, o jẹ ohun ibanujẹ pe Naijiria n ti awọn tiẹ pa.
Bẹ́ẹ̀ ló ṣe fi ọwọ́ mú Juda ati Bẹnjamini.
Eruku ẹjọ́ tún sọ lórí ìgbéyàwó Toyin Abraham àti Adeniyi Johnson tó forí ṣánpọ́n Ẹ wo bí ìpínlẹ̀ Eko, Ondo àti Oyo yóò ṣe dá ilé ìjọ̀sìn padà Ìtàn ìgbésí ayé Oshodi, ọmọ Tápà léǹpe tó di akọni ní ìlú Eko Àjọ NAFDAC ti bẹ̀rẹ̀ àyẹ̀wò àgbò mẹ́rin tí wọ́n ṣe ní Nàìjíríà fún Covid-19 Balogun ikọ awọn obinrin yi, Somaya Faruqi ni '' Ori mi wu lati wa lara awọn ikọ to n se ohun to n se iranwọ fawọn osisẹ ilera wa.
Didaabo bo iyi ati ẹyẹ ilu Kano Ijọba sọ ninu atẹjade to fi sita pe oun rọ Emir Sanusi l'oye lati le pa aṣa, iṣe ati awomọni ọrọ ẹsin Kano to ti wa lai mọye ọdun mọ kuro lọwọ yẹyẹ.
Ko din ni eniyan  mefa ti won ti gbemi mi ,ni Migori lorile ede Kenya .
Wo àwọn Adelé-Ọba aládé méje tó jẹ́ obìnrin nílẹ̀ Yorùbá 'Ẹ̀ṣọ́ ọgbà ẹ̀wọ̀n bọ́ mi sí ìhòhò, ó ki ìka rẹ̀ bọ ìdí mi látẹ̀yìn' Nítorí kò sí ọ̀nà àbáyọ nínú ìṣẹ́ ní mo ṣe fẹ́ ta ọmọ mi- Sarah ọmọ òrukàn Ogun abẹ́lé tó ń ja Akeredolu l'Ondo, òní la ó mọ̀ bóyá yó borí rẹ̀ Ìjọba Amẹrika yọ orúkọ Sudan kúrò nínú ìwé orílẹ̀-èdè tó ń ṣagbátẹrù ẹgbẹ́ agbésùnmọ̀mí Ilé mi túká, àyọ mi sọnù, ìdúnnú dàwátì, ọkọ pè mi ní àgbàná, ará ilé pè mi ní emere, Ogbanje nítorí ọmọ bíbí Èyí ni bí èèyàn 538 ṣe ń yan ààrẹ lé èèyàn mílíọ̀nù 331 ní Amẹ́ríkà Ìjọba ìpínlẹ̀ Zamfara ti gbé iléèwé mẹ́wàá tìpa lkyìn tí wọ́n jí àwọn akẹ́kọ̀ọ́ iléèwé Kankara gbé Kollington Ayinla ti sọ ẹni tó dá orin Fuji sílẹ̀ gan an ní Nàiìjíríà Ṣé ìwọ́ mọ Àrànmọ́ Fáwẹ́ẹ̀lì Yorùbá dáadáa?
Sisa ti wọn sa yii fi opin si ijoko ati ijiroro to n lọ lọwọ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Mo máa n forin mi kìlọ̀ ìwà ìbàjẹ́ láwùjọ ni -Hameen Eyi fi han pe o jẹ alagbara ọmọ to si tayọ awọn ẹlẹgbẹ ni gbogbo ọna.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Falana: Awọn to n dije dupo ìdìbò 2019 fẹ́ fa ogun si Naijiria Lasiko ipade itagbangba nigba ti ifọrọwerọ naa bẹrẹ, awọn ọrọ kanka kanka n jẹ jade ninu awọn ọrọ ti awọn oludije sọ ti ọpọlọpọ ko si ni gbagbe.
Nigba ti ifẹsẹwọnsẹ naa yoo fi pari ni papa iṣire agege, goolu meji lawọn ikọ Obasa All Stars fi gbẹyẹ mọ iks Ogogo lọwọ o.
Eyii lo mu kii Aarẹ Buhari ṣe ifilọlẹ igbimọ kan, eyii ti yoo ṣabojuto bi ọrọ aje Naijiria yoo ṣe gberasọ pada ko to di ọdun 2050.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Nigeria movie industry: Àgbà òṣèré, Lere Paimo ní àìgbọràn ló ń da ọ̀pọ̀lọpọ̀ àwọn òṣèrè sinimá láàmú Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Nigeria movie industry: Àgbà òṣèré, Lere Paimo ní àìgbọràn ló ń da ọ̀pọ̀lọpọ̀ àwọn òṣèrè sinimá láàmú 1 Òkùdu 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 11 Ọ̀wàrà 2020 Agba oṣere lagbo tiata ati sinima ni Oloye Lere Paimọ, MFR tiọpọ mọ si 'Ẹda onile ọla', orukọ rẹ ko si lee parun ninu itan sinima ati tiata ni ilẹ Yoruba.
Àṣé àṣírí wà nínú Hijabu tí Aisha Yesufu ń wọ̀ lọ ìwọ́de Àwọn ìṣẹ̀lẹ̀ mánigbàgbé tó wáyé nibi ìwọ́de ENDSARS Nàìjíríà Mo ṣèlérí láti ṣe ju ohun tí mo ti ṣe lọ fún ẹbí àwọn tó kú torí EndSARS - Seyi Makinde Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Àwọn jàndùkú ṣe yabò àwọn olùwọ́de #ENDSARS ní Alausa l'Eko O ni iru ẹ ti waye ri.
Jọ̀wọ́ tún yipada, Ọlọrun àwọn ọmọ ogun!
Ní ọjọ́ kan, ó bèèrè lọ́wọ́ Amnoni pé, “Ṣebí ọmọ ọba ni ọ́, kí ló dé tí ò ń rù lojoojumọ?
O sọ pe ilana tuntun naa jẹ ọna lati ri i pe eto iforukọsilẹ rọrun fun awọn oṣiṣẹ ajọ NIMC ati awọn to fẹ fi orukọ silẹ.
amulo iṣuna owo ọdun 2018 naa.
Mummy Calm Down di aṣojú iléeṣẹ́ ńlá kan l'Abuja Ọkùnrin tó dàgbà jù lágbàyé jáde láyé lẹ́ni ọdún 116 Ta ni Lisa Hanna, arẹwà obìnrin tí àwọn ọmọ Nàìjíríà fẹ́ kó di àárẹ wọn?
“Wọ́n pa èèyàn tó tó 1700, bẹ́ẹ̀ ni wọ́n sì ń fi ipá lé àwọn ẹlòmíìn, wọ́n ń fi ipá bá wọn ní ìbálòpọ̀, wọ́n ń fi ìyà jẹ wọ́n, wọ́n ń tì wọ́n mọ́lé, bẹ́ẹ̀ ni wọ́n sì ń dẹ́rùba àìmọye àwọn mìíràn”.
Muhammadu Buhari  ti fi orile ede
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ondo Kidnap: Afurasí ní òun kàn fẹ́ fi ọmọ tó sọnù gba owó lọ́wọ́ Sọtitobire 20 Sẹ́rẹ́ 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 21 Sẹ́rẹ́ 2020 Oríṣun àwòrán, Others Àkọlé àwòrán, Arabinrin Olawole to jẹ́ iyá Gold Kolawole lo gbe ọmọ rẹ̀ lọ si sọọsi awọn ọmọde nile ijọsin, tí ọmọ sì di awátì lẹ́yìn ẹ̀sìn.
Fi yà wọ́n sí mímọ́, kí wọ́n lè jẹ́ mímọ́ patapata; ohunkohun tí ó bá kàn wọ́n yóo sì di mímọ́.
Àwọn ibudo máun péré ni Naijiria ni láti mojúto ààrun náà, o yẹ ki wọ́n náwọ ìrànwọ si àwọn ìpínlẹ̀."
Ìtàn Mánigbàgbé: Baṣọ̀run Gáà jẹ́ àgbà ìjòyè tó le è yípadà sí ẹranko tó bá wù ú
Ogundamisi ni ko si nkan to buru ninu rẹ nitori ko si wi pe awọn eniyan n dibo pẹlu ipaya pe, laasigbo tabi wahala le bẹ silẹ lawujọ.
O ni ohun ti awọn ọmọ Naijiria nilo bayii igbesẹ kiakia lati rẹyin aarun yii, pẹlu afikun wi pe iṣegun ibilẹ ni ọna abayọ.
18 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Oríṣun àwòrán, @Reuters Ikọ ajijagbara ẹsin Islam ni Iwọ Oorun Afrika, Boko Haram sọ pe, oun lo wa nidi bi wọn ṣe ji ogunlọgọ akẹkọọ gbe ni Iwọ oorun Ariwa Naijiria.
Titi di igba ta fi n ṣe akojọ iroyin yi, a ko ti fidi ọrọ mulẹ lori ohun to fa ina naa.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Akomolede ati Asa lori BBC: Olùkọ́ Kikelomo Ogunboye tan ìmalẹ̀ sí ìwà olè ọ̀gá ọlọ́pàá Oloye Ọbafẹmi Awolowo: Ni ọdun 1962, oloye Obafemi Awolọwọ to jẹ olotu akọkọ fun ijọba iwọ oorun Naijiria nigba naa pẹlu koju ẹsun ikowojẹ.
Nítorí náà ọkàn mi rẹ̀wẹ̀sì;ọkàn mi sì pòrúúruù.
1 52274 Orilẹede Zimbabwe 291 2.
Lara awọn ohun to wa ninu ofin naa ree: 1.
Ọ̀kan ni èmi ati Baba mi.
Ṣe akiyesi ẹni pípé;sì wo olódodo dáradára,nítorí pé ìgbẹ̀yìn ẹni tí ń wá alaafia yóo dára.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Libya Explosion: Èèyàn 44 ló bá ìṣẹ̀lẹ̀ náà rìn lápapọ̀ 5 Agẹmo 2019 Oríṣun àwòrán, Reuters Àkọlé àwòrán, Ajọ iṣọkan agbaye sọ pe ado oloro naa jabọ latoju ofurufu le ibudo ti eniyan to le ni ọgọrun wa Ọmọ orilẹede Naijiria mẹsan an lo wa lara awọn to ku sinu ikọlu ado oloro to waye ni ibudo ifiniwọ kan ni Libya.
Josaya ọba fún gbogbo àwọn tí wọ́n wà níbẹ̀ ní ẹran fún ẹbọ Ìrékọjá.
OLUWA sọ nípa Kedari ati àwọn ìjọba Hasori tí Nebukadinesari ọba Babiloni ṣẹgun pé,“Ẹ dìde kí ẹ gbógun ti Kedari!
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Child Engineer: Olamide Odukọya ní òun fẹ́ ṣe ohun kan tí yóò wúlò fún gbogbo àgbáyé Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Child Engineer: Olamide Odukọya ní òun fẹ́ ṣe ohun kan tí yóò wúlò fún gbogbo àgbáyé 4 Owewe 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 7 Owewe 2019 Ọmọ ti yoo ba jẹ Aṣamu, kekere ni yoo ti maa jẹnu ṣamu-ṣamu.
Awọn iroyin ti ẹ lee nifẹẹ si: Ijamba baalu Syria: Ẹmi ọmọ Russia mejilelọgbọn sọnu Osisẹ Jamb: Ọga mi lo mi 36m, kii se ejo Ọpọ igba si ni Iwobi ti maa npolongo pẹlu asaaju ẹgbẹ oselu naa, Matteo Salvini pe iwa kawọn ajeji maa wọ orilẹede Italy lọna aitọ ti mu ki iwa ẹlẹyamẹya pọ si lorilẹede naa.
Ọmọ Yorùbá mẹ́wàá tó jẹ́ àmúlùúdùn ní Amẹ́ríkà àti Yúróòpù Ta ni Yusuf Satia ti iku mu lọ?
Koda, wọn fidiẹ mulẹ pe nigbakugba ti Kabiyesi yoo ba fẹ ki agbaye ri oju Arẹmọ, oun funrarẹ ni yoo fi aworan naa sita gẹgẹ bi i baba ọmọ.
Baraki lépa àwọn kẹ̀kẹ́ ogun ati àwọn ọmọ ogun Sisera títí dé Haroṣeti-ha-goimu, wọ́n sì fi idà pa àwọn ọmọ ogun Sisera láìku ẹyọ ẹnìkan.
Òdodo ọ̀rọ̀ nìyí: bí ẹnikẹ́ni bá dàníyàn láti jẹ́ olùdarí, iṣẹ́ rere ni ó fẹ́ ṣe.
Oríṣun àwòrán, Twitter Lẹyin to kawe gboye tan, o ṣiṣẹ gẹgẹ bi olutaja fun ileeṣẹ Bestman Games, Ikoyi, nilu Eko bakan naa.
Wọ́n súre fún Rebeka, wọ́n wí pé, “Arabinrin wa, o óo bírún, o óo bígba.
Oríṣun àwòrán, Oluwo Nigba to n fesi lori ọrọ ti Oluwo sọ pe, awọn ọba kan lo kan oro oun sinu, ti wọn n binu oun nitori pe oun n sakọ, Ọrangun ni se Oluwo nikan lo n wọ asọ ni tawọn yoo fi maa binu rẹ, abi ọba wo lo ri to n rin ihooho, bo ba si se wu, lo se lee lo owo rẹ.
Ẹ ya ara yín sọ́tọ̀ kúrò lọ́dọ̀ àwọn eniyan náà ati kúrò lọ́dọ̀ àwọn obinrin àjèjì.
Ẹsun keji ni pe iyawo olori ile asofin nipinlẹ Eko naa n gba miliọnu mẹwa naira ni osoosu lati owo ile asofin naa.
Ọmọbinrin to ba jabọ lẹyin iya rẹ yoo ri iku ọkọ ni ẹẹmeje.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Akomolede àti Aṣa: Ọ̀rọ̀ Ẹ̀yán ni Bunmi Femi Amao ń kọ́ wa lórí ètò Akọ́mọlédè àti Àṣà lóri BBC Yoruba Iya ilumọọka olorin kan, Fela, eyiun Funmilayo Ransome Kuti la gbọ pe o se agbatẹru ifẹhonu han naa fawọn obinrin ti wọn le ni ẹgbẹrun lọna ogun.
Tukur sọ̀rọ̀ yìí lásìkò tí àjọ tó ń rí sì ìrìn-àjò ìgbàfẹ́ sabewo sii.
Ijamba ohun ni yoo je elekeji iru re ti yoo waye, leyin ijamba akoko ti o gbemi eniyan merinlelogun.
Awọn ọlọpaa ati oṣiṣẹ pana-pana ti wa ni ibi ti ijamba naa ti waye.
Láti inú agbo ẹran tirẹ̀ ni ó ti mú ẹgbaa mẹẹdogun (30,000) aguntan ati ọmọ ewúrẹ́, ati ẹgbẹẹdogun (3,000) mààlúù fún wọn.
se nitori wahala to bẹ sile ni awon agbegbe kan ni ipinle naa.
A si le ni orukọ yii mọ lara nitori arẹwa ati ọmọde ni laarin awọn ayaba lode Ọyọ, to si jẹ aayo Alaafin laarin awọn ayaba.
Brighton vs Arsenal: Ọmọ Otedola bú sẹ́kún lẹ́yìn tí Brighton tún d'ẹrù ìyà lé Arsenal lórí
Ìjà Awolọwọ, Akintọla àti ogun 'Wẹtiẹ', ẹ̀kọ́ wo ló kọ́ wa?
”Wọ́n bá dá a lóhùn pé, “Èwo ló kàn wá ninu rẹ̀?
Ẹwẹ awọn akẹkọ kan ti fi atilẹyin wọn han si Gomina Ganduje pẹlu bi wọn ti ṣe gbe iwe ifẹhonuhan niwaju ile asofin Kano.
Gẹ́gẹ́ bí ìtàn ṣe lọ, àìsàn nawọ́ gán ọ̀kan nìnú àwọn ọ̀rẹ́ méjéèjí yìí, ikú foní kà sílẹ̀, ó mú onínúure lọ; ó wá jẹ́ pé ọ̀rẹ́ tí inú rẹ̀ mọ́ sí ọ̀rẹ́ kejì ni àìsàn kì mọ́lẹ̀, inú àìsaṅ náà ló kú sí.
O ni iye awọn eniyan naa npọsi, ti ẹka ajọ to nseto iranwọ labẹ ajọ isọkan agbaye sọ wipe ewu pọ fun awọn obirin ati ọmọ wẹwẹ laarin awọn eeyan to wa se atipo naa.
‘Mu ọti nilu Ilọrin, ko ri ẹwọn he’ Ara san pa eeyan 16 ninu ṣọọṣi ni Rwanda Ìgò ọtí méje àti sìgá ṣokùnfà ẹjọ́ ikú Rex Tillerson ṣe'pade pẹlu Aarẹ Buhari Ọjọgbọn Anne Charlton kọ itan pé Christopher Columbus tó jẹ ọkan lara awọn oyinbo alawọ funfun akọkọ to kọkọ ri bi wọn ṣe n lo taba fun iwosan.
Ọ̀rọ̀ náà kò dùn mọ́ Samuẹli ninu, pé àwọn eniyan náà ní kí ó fi ẹnìkan jọba lórí wọn.
Ẹlẹsin ibilẹ, Yemi Elebuibọn lo sọ bẹẹ nigba to ba BBC Yoruba sọrọ lori iṣẹlẹ ọhun.
That was both touching and assuring, but I decided that, tempting and assuring as the offer was, I would not take it.
Àwọn òkú tí wọ́n kú ninu Oluwa láti àkókò yìí lọ ṣe oríire.
Lasiko ta n wi yi, ara ẹni naa ti bẹrẹ si ni kọsẹ ti iku ko si nijina si mọ.
Ṣugbọn ẹ máa fẹ́ràn àwọn ọ̀tá yín; ẹ ṣoore.
Ńṣe ni mo fi gbogbo rẹ̀ ṣe ìran wò.
Oríṣun àwòrán, Twitter/deeper life bible church Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Kumuyi Bible: Ọdún mẹ́ẹ̀dógún ni òun àtàwọn onímọ̀ Yorùbá fi ṣe ìwádìí nípa Bíbélì náà29 Agẹmo 2020 Rape cases in Nigeria: Ẹ sọ ìlò afẹ́fẹ́ aláta àti ìbọn ònírọ́bà di òfin fáwọn obìnrin - Oluwo7 Òkùdu 2020 Mummy calm down: Oreoluwa di 'Ambassador' ilésṣẹ́ tó ń ṣòwò ilẹ̀ àti ilé23 Ògún 2020 Rape: Ọmọ tí wọn ń fipá bá lòpọ̀ yóò máa ní ìrora ọkàn nígbà gbogbo26 Ẹrẹ̀nà 2019 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 3 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 5 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
– Kí obìnrin má a na olúwarẹ̀ lójóojúmọ́ báyìí!
Ati pe obinrin yoo tun ni agbara sii lati gbe igbesẹ to ba wuu.
Oríṣun àwòrán, @NGRPresident Bakan naa, Obono-Obla yoo tun jẹjọ lori awọn ẹsun to jẹ mọ sise ayederu iwe ẹri ati ẹsun iwa ajẹbanu lọkan o jọkan eyi ti wọn fi kan-an.
Nígbà tí ó dé ní alẹ́, o béèrè bí olóko ti wí, wọ́n ní olóko ti ránṣẹ́ sí àwọn àna rẹ̀, àwọn tí ó fi ọmọ fún, kí wọ́n wá bá a ya àgbàdo náà.
Ẹ máa fi ìtara lépa àwọn ẹ̀bùn tí ó ga jùlọ.
Agba oṣelu naa ni o yẹ ki ojuṣe gbigba owo ori lori ọja (Stamp duty) ati ibudo igbafẹ (Tourism tax) jẹ ohun tawọn ijọba ipinlẹ yoo maa gba.
Ẹni to bori: Madagascar Madagascar Ni Osu Karun ọdun 2019, iyara kankan intanẹti Madagascar jẹ mẹgabaiti 28.
Rakẹli bá sọ pé, “Ìjàkadì gidi ni mo bá ẹ̀gbọ́n mi jà, mo sì ṣẹgun,” ó sì sọ ọmọ náà ní Nafutali.
Ara riro,ọfun didun ati ori fifọ naa le waye sugbọ́n kii se dandan.
Fúnra mi ni n óo rí i,ojú ara mi ni n óo sì fi rí i,kì í ṣe ti ẹlòmíràn.
ko  ikọ orile ede Naijiria lo si orile
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Elisha Abbo: Ẹ̀sìn àti ẹ̀kọ́ ilé tí mo ní kò gba ká na obìnrin 3 Agẹmo 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 4 Agẹmo 2019 Oríṣun àwòrán, @ElishaCliff Sẹnetọ Elisha Ishaku Abbo, ti fidio ori ayelujara kan gbe jade pe o na obinrin abilekọ kan nile itaja ti tọrọ aforijin lọwọ awọn orilẹede yii, awọn abiyamọ, ati obinrin to na pe ki wọn fi ori jin oun, oun ko ni hu iru iwa aidaa bayii mọ.
Lọjọ Aje tii ṣe ọjọ keji, oṣu Kejila ni ẹka ajọ EFCC to wa nilu Ilorin gba idajọ lọdọ adajọ Ridwan Aikawa pe ki Saraki jọwọ ile naa fun ijọba tori pe ọna aitọ lo gba kọ ọ.
Àwọn ìtàn àtẹnudẹ ́ nu tí a gbọ ́ nípa ìṣẹ ̀ dá yàtọ ̀ sí ara wọn díẹ ̀ díẹ ̀ .
Leyin naa lo ni awọn Osise LASEMA dide si didẹwọ ina naa.
Mongonu (APC-Borno), wa ro gbogbo omo ile igbimo asoju lati tẹle ilana  ti egbe la silẹ.
Idijẹ ti pọẹ́ nínú ere sinimá Yorùbá, nínú eré náà ló sì ti rí ìnagijẹ rẹ̀.
Gbogbo ìkòkò tí ó wà ní Jerusalẹmu ati ní Juda yóo di mímọ́ fún OLUWA àwọn ọmọ ogun.
Idowu Olakunrin: Kò sí ẹni tó lé è dí àlàfo tí Funke fi sílẹ̀
” Jakọbu kò mọ̀ rárá pé Rakẹli ni ó jí àwọn ère oriṣa Labani kó.
Kí ló mú kí Adájọ yin ìbọn lu ará rẹ láyà nílé ẹjọ́?
Ẹ Ronupiwada, Bí Bẹ́ẹ̀ Kọ̀ Ẹ Óo Ṣègbé.
Òkú wọn yóo wà ní títì ìlú ńlá tí a ti kan Oluwa wọn mọ́ agbelebu.
Bí Dafidi bá pè é ní ‘OLUWA’, báwo ni Mesaya ti ṣe jẹ́ ọmọ rẹ̀?
yii ni wọn yoo fi ṣatunṣe si abala mejilelogun ninu ofin naa, ti wọn yoo
Awọn Ibẹẹta pẹlu ọmọ iya wọn jona mọle ni jigawa
Ọpọlọpọ awọn awakọ ati awọn eeyan to n fi ẹsẹ rin lo lọri pada si ibi ti wọn ti n bọ lati ti ọrọ naa di wọlukọlu.
Ọ̀pọ̀ olùgbé ìlú Ìlọrin ní ìpínlè Kwara, ẹkùn ààrin-gbùngbùn orílèèdè Nàìjíríà ni wọ́n ń kérora ọṣétí ìjì náà ṣe.
Oṣu to lọ ni ọlọpaa bẹrẹ iwadii lori ọrọ naa wipe Linda to jẹ ẹni ọgọta ọdun ati Mary-Beth to jẹ ọdun mẹtalelọgọta lo pa baba wọn, ọdun mẹta lẹyin ti wọn pe ọlọpaa wipe baba wọn ṣa deede dakẹ ninu ile.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ilé-ẹjọ́ ìlú Èkó fi Nwaoboshi sátìmọ́le fún ìkówójẹ 25 Ìgbé 2018 Oríṣun àwòrán, Nwaoboshi /twitter Àkọlé àwòrán, Ilé ẹjọ́ fi Peter Nwaoboshi sátìmọ́lé di òpin ọ̀sẹ̀ Ilé-ẹjọ́ ìjọba àpapọ̀ tí Ìlú Èkó tí sọ Sẹ́nétọ̀ Peter Nwaoboshi tíì ṣe ọmọ ẹgbẹ́ People's Democratic Party tó ń soju fún ẹkùn Delta North sewon.
O sọ pe amọ o ṣeni laanu pe inu ibanujẹ ni awọn alejo to yẹ ko wa ba oun yọ ayọ igbeyawo ọmọ oun wa bayii.
Sebi o wu ni ka jeran lenu ko pe, amo onfa ona ofun iyen koje rara, iku doro, iku sẹka.
Jẹ́ ki n sọ fún ọ, òun pàápàá ti wọ ẹ̀wọ̀n lẹ́ẹ̀méta, ọ́jọ̀ kẹta tí ó jáde lẹ́wọ̀n ẹ̀ẹ̀kẹta ni mo fẹ́ ẹ, ó wù mi gan-an ni.
Minisita fun ọrọ iroyin ati eto aṣa, Lai Mohammed sọ pe awọn ọmọbinrin marunlelọgọrun ati ọmọdekunrin kan ni wọn gba ominira lọwọ Boko Haram.
"Nigba ti ẹgbẹ PDP wa ni iṣakoso, ẹsun kan naa ni ẹgbẹ oṣelu APC fi kan INEC pé a n ṣe atilẹyin fun wọn, ṣugbọn ni bayii ti APC naa ti wa nipo, PDP naa tun n sọ ẹsun kan naa.
Ẹni tí kò fi ahọ́n rẹ̀ sọ̀rọ̀ eniyan lẹ́yìn,tí kò ṣe ibi sí ẹnìkejì rẹ̀,tí kò sì sọ ọ̀rọ̀ ẹ̀gàn nípa aládùúgbò rẹ̀.
ASUU ni ipò tí kò dára táwọn fásitì wa lawọn ń jà fún Apapọ ẹgbẹ́ awọn olukọ ni fasiti jakejado Naijiria, Academic Staff Union of Universities, ASUU, ti kede iyanṣẹlodi alainigbedeke ni gbogbo ẹka wọn.
Iléẹjọ gíga jùlọ da ẹjọ́ SDP àti PDP nù, wọ́n ní Yahaya Bello ló wọlé ìbò gómìnà Kogi Ààrẹ Buhari buwọ́lu gbígbé ìṣàkoso nọ́mbà ìdánimọ̀ (NIMC) lọ sí ẹ̀ka ìjọba tó ń rí sí ìbáraẹnisọ̀rọ̀ Èèyàn mẹ́tàlélógóje míì ṣẹ̀ṣẹ̀ kó COVID-19 ní Nàìjíríà Ajọ to n gbogun ti ajakalẹ aarun lorilẹ-ede Naijiria, NCDC ti kede eeyan mẹtalelogoje miran to kun iye awọn to ti ni aarun COVID-19 lorilẹ-ede Naijiria.
Àwọn òṣìṣẹ́ rẹ tí wọ́n wà lọ́dọ̀ rẹ nígbà gbogbo tí wọn ń gbọ́ ọ̀rọ̀ ọgbọ́n rẹ náà ṣoríire.
Aṣofin ilẹ̀ Gẹẹsi kan, Nicky Morgan sọ pe ó ṣe pàtàkì láti kọ àwọn olùkọ náà nítori wọn ní ipa pàtàkì láti kó.
ipinle Osun, Gboyega Oyetola; igbakeji gomina Ondo, Ekiti, Ogun ati Eko;
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Rape cases in Nigeria: Ọmọ ọdun 5 àti 14 ni Kalu wà nígbà tí obìnrin fipá ba lòpọ̀ Minisita Agba ni ohun to n ṣẹlẹ si ọrọ aje agbaye lọwọlọwọ yoo jẹ ki owo to n ba ọja wọle si Naijiria gberu sii.
Bianca Andreescu jẹ ọmọ ọdun mọkandinlogun lati orilẹ-ede Canada lo koju agbaọjẹ Serena Williams ọmọ ọdun mẹtadinlogoji naa ninu idije aṣekagba.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ghana elections result 2020: Èsì ìdìbò tó gbé aàrẹ tuntun wọlẹ́ ní Ghana rèé.
Samsoni bá sọ fún wọn pé, “Bí ó bá jẹ́ pé bí ẹ óo ti ṣe nìyí n óo gbẹ̀san lára yín, lẹ́yìn náà, n óo fi yín sílẹ̀.
Kaakiri loju opo ayelujara lawọn eeyan ti n fi iyalẹnu han lori ohun to le mu ki awọn akẹkọ wọnyi hu iru iwa bẹẹ.
e ma pon ikuna le mo, ikuna ko ni oruko miiran, ikuna naa ni… eyin ti e je onisowo, okoowo yin ko ba ti dara ju bayii lo, ti a ba ni ijoba ti o ja fafa,to koju osuwon,to si n se ohun to ye ki won se.
Yemisi Oyedepo Broadcast Journalist 8 Ògún 2019 Àkọlé àwòrán, Àwọn ọ̀nà ti ẹ lè gbà kojú omí yale àgbára ya sọọbù Omí yale àgbàrá ya sọ́ọ̀bù jẹ́ ìsòrò kan gbòógí tó máa n ba ilé jẹ, ba ọ̀nà jẹ, ǹkan ìní yóò sòfò kọ́dà ẹmi a máa báa lọ ni ọ̀pọ̀ ìgbà.
A gbọdọ ṣe amulo wọn fun idagbasoke ileeṣẹ lorilẹede Naijiria.
Lọdun 2015, o tun kopa ninu idibo, to si wole lẹẹkan si.
Amọṣa ọrọ naa di ti sinima awodamiẹnu nigba ti pasitọ ijọ naa gbiyanju ati fo fẹnsi lọna ati sa mọ awọn ikọ amuṣẹya naa lọwọ.
nínú àwọn eukarioti , àwọn krómósómù nínú kóróonú jẹ ́ dídìpọ ́ látọwọ ́ àwọn proteínì sí àdìmú kíkipọ ̀ kan tó únjẹ ́ kromatínì .
A lè fi òwe Yoruba ti o ni “Bi ojú bá mọ́, Agbe á yalé Aláró, Àlùkò á yalé Olósùn, Lékeléke á yalé Ẹlẹ́fun” bá ilú, agbójúlógún àti ọ̀lẹ enia wi.
Níbayìí orílẹ̀-èdè mẹ́ta ló tí wọ ipele ẹlẹ̀ni mẹ́rìndínlógun, tí Nàìjíríà sì jẹ́ orílẹ̀-èdè àkọ́kọ́ to kọ́kọ́ pegedé, Egypt àti Algeria pẹ̀lú ojú àmì mẹ́fà.
Oriṣiriṣi nkan lo maa n fi iṣo ati owu ṣe.
Dokita Olagbe fikun pe lẹyin spọ ẹbẹ si awọn alasẹ ati iwọde lọ si ọọfisi gomina, gbogbo ileri ti akọwe ijọba ipinlẹ naa, Ifedayo Abegunde ati oludamọran gomina feto ilera se, lo ja si pabo.
Àwọn orílẹ̀-èdè ti aàrùn náà pọ̀ si jù ni Afíríkà ni South Africa àti Egypt.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Èéfín gẹnẹratọ: Iléẹjọ́ ní kí ayálégbé san ₦2m owó ìtanràn 6 Bélú 2018 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Kii ṣe ẹẹkan tabi ẹẹmeji, ni iroyin ti gbe e pe eefin ẹrọ amunawa ṣekupa mọlẹẹbi ni Naijiria.
ibilẹ Ibadan Southwest, naa ti gunlẹ ni ibudo idibo ladugbo Ring Road, ni olu
Èyí ni oúnjẹ tí ó ti ọ̀run sọ̀kalẹ̀, kì í ṣe irú èyí tí àwọn baba yín jẹ, tí wọ́n sì kú sibẹsibẹ.
Awọn gomina ọhun sọ pe 'owo oṣu tuntun naa ko le rọrun lati san, ayafi ti wọn ba da awọn oṣiṣẹ kan duro.
Nígbà tí a dé ilé mo pinnú láti bẹ̀ ẹ́ mo sì bẹ̀ ẹ́ dára-dára, mo wí pé n kò ní í lè padà dé ilé Ikú mọ́ àri pé kí ó jọ̀wọ́ bá mi ṣe ọ̀nà rẹ̀ tí n kò ní í fi tún padà lọ mọ́.
odun meta ati aabọ, ti mo ti n ba aare se ise papo , mo wa ri i pe ,iwa ibajẹ ni
Gani Adams ni ojuse oun ni lati lọgun faraye nipa awọn ọṣẹ táwọn agbébọn naa n ṣe nilu Kishi ati lagbegbe Oke Ogun lapapọ.
Ẹni tó gbọ́ ìbáwí rereyóo wà láàrin àwọn ọlọ́gbọ́n.
Kò sí ẹnikẹ́ni ní ọ̀run, tabi lórí ilẹ̀ tabi nísàlẹ̀ ilẹ̀ tí ó lè ṣí ìwé náà tabi tí ó lè wò ó.
“Ẹ̀yin arakunrin, ìran Abrahamu, ati ẹ̀yin tí ẹ̀ ń sin Ọlọrun, àwa ni a rán iṣẹ́ ìgbàlà yìí sí.
“Ọpọlọpọ èso ni ẹ óo máa gbìn sinu oko yín, ṣugbọn díẹ̀ ni ẹ óo máa rí ká, nítorí eṣú ni yóo máa jẹ wọ́n.
 O gba ijoba nimoran nipa gbigbogun ti  iwa jegudu-jera to ti di alaborun bi ewu fun
 ) ( sand is finer than gravel .
Ewe, Uzoho koni kopa fun ose merin gbako lojuna ati lo gba itoju.
Dá mi lóhùn, bí o bá mọ àwọn nǹkan wọnyi.
Àwọn abọ́ wọnyi ni wọ́n fi ń bu omi láti fọ àwọn ohun tí wọn ń lò fún ẹbọ sísun.
Nígbà tí Omawumi gbá àmì ẹyẹ obìnrin tó ní ohun tó dùn julọ ninu orin rẹ 'Butterfly'.
Garba Shehu to jẹ oludamọran aarẹ lori ọrọ iroyin ni o fesi yi ni idahun si ọrọ ti Obasanjo sọ pe Naijiria ti pin yẹlẹyẹlẹ labẹ ijọba Buhari.
Oríṣun àwòrán, Channel Koda, awọn afẹhonu han ọhun la gbọ pe wọn ti gbe igi da sna to wọ papakọ ofurufu ilu Abuja, tawọn arinrin ajo ko si le wọ baalu.
Ile igbimọ aṣofin l'Abuja ti sọ pe oun yoo tẹsiwaju ijiroro lori aba naa lọsẹ to n bọ.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ìpàdé ìtagbangba ní Ọṣun, ṣẹ́ ti fi orúkọ sílẹ̀ ?
Ó bá tún wọ ààfin lọ, ó bi Jesu pé, “Níbo ni o ti wá?
 nítorí ewu tó lè wáyé , a kò gbani nímọ ̀ ràn láti lòó fún àwọn ọmọ-ọwọ ́ tí ìfun wọn ti lọ ́ pọ ̀ rí .
Mahmood soro yii lasiko to n ba
ofurufu Umaru Yar’adua niluu Katsina laago mewa aabo owuro(10:47am) lo silu
Olori awọn oṣiṣẹ alaabo ni ileeṣẹ aṣoju Naijiria nibẹ, Emmanuel Kabutey sọ fun Joy FM pe, ọkunrin naa sọ pe awọn ni atilẹyin ileeṣẹ alaabo Ghana, nitori naa ẹni to ba sun mọ awọn yoo fara gba ọta.
Wọn fi si ẹwọn oṣu mẹfa lẹyin ti ajo EFCC fi ẹsun aadọrin to ni se pẹlu ikowojẹ kan an.
Kaka bẹẹ o ni ki awọn tọrọ kan kọkọ ṣe atunṣe ofin to ni ṣe pẹlu gbigbogun ti iwa jẹgudujẹra na, ki wọn wa gbe igbesẹ lati pa ofin naa ki wọn lee ri ofin ti i lẹyin.
Ninu awọn to kopa ni Hollywood to si jẹ ọmọ kaaro o jiire, ogbontarigi ni Adewale Akinnuoye-Agbaje.
Kí ẹ jọ wà ní alaafia ní ipò tí Ọlọrun pè yín sí.
Ọga INEC, Ọjọgbọn Ibrahim Magawata ṣalaye pe ibo naa ko fẹnu ko sibi kan nitori ajọ naa ti wọgile esi ibo ni ibudo idibo marun un.
O ṣalaye pe ọjọ ti ọwọ ba ti tẹ afipabanilopọ tabi gbe wọn lọ sile ẹjọ, ni awọn ọba, oloṣelu, ati awọn eeyan pataki mii lawujọ, ti ma n bẹ oun lati jawọ ninu ẹsun naa.
Aluko, nígbà tó ń dáhùn ìbéèrè lórí ìdí táwọn ọ̀dọ́ kò se kópa nínú ìbò gómìnà ní Èkìtì, tún sàlàyé pé àwọn ọ̀dọ́ gbọdọ̀ ní ìrírí, kí wọn tó leè díje fún ipò gómínà.
O fi kun un pe ka ni ileewosan ti wọn gbee lọ ni ohun elo iranwọ fun eemi, o ṣeeṣe ki Oloogbe Oriṣabunmi ṣi wa laye.
Bakan naa lo ṣalaye pe iroyin ti awọn akẹkọ naa n fi to oun leti ni pe nnkan bi akẹkọ ọgbọn si marundinlogoji ni awọn oṣiṣẹ EFCC naa ko nibẹ.
Kayode lo apẹrẹ epo ọfẹ fun gbogbo araalu nitori wi pe o ri i pe ko si ẹni ti ọrọ epo ko kan lorilẹede Naijiria, yala wọn jade nile tabi agbẹ ni wọn, bi owo epo ba lọ soke tabi wa silẹ, yoo kan alata, onidiri tabi oniṣẹ ọba."
Ile ẹjọ kotẹmilọrun ti da ẹjọ ti Adajọ Agba Walter Onnoghen pe tako ijọba apapọ.
Wo àwọn ẹranko tí wọ́n máa figagbaga ni Egypt nínú AFCON 2019 Ìdíje ife ẹ̀yẹ láàrin orílẹ̀èdè Áfíríkà 2019 Nigeria 1 - 0 Guinea Ere pari Alaye kikun lori ere Awọn agbabọọlu ti wọn yan Alaye ni soki lori ere bọọlu Ẹkunrẹrẹ Ilana ere bọọlu Nigeria (4-2-3-1) Guinea (4-2-3-1) Ẹkunrẹrẹ 27 - Falette 0 - 0 62 - Musa 0 - 0 65 - Seka 0 - 0 71 - Naby Keita                                                                          down Lass                                                                      up 0 - 0 73 - Dyrestam                                                                          down Sidibé                                                                      up 0 - 0 73 - Omeruo football 1 - 0 78 - Iwobi                                                                          down Chukwueze                                                                      up 1 - 0 82 - Kamano                                                                          down Koita                                                                      up 1 - 0 88 - Ighalo                                                                          down Paul Onuachu                                                                      up 1 - 0 90 - Peter Etebo 1 - 0 94 - Simon                                                                          down Kalu                                                                      up 1 - 0 Alaye ni soki lori ere bọọlu Nigeria Guinea Bọọlu wa nikawọ mi 48.
n óo mú kí ẹ̀fúùfù mẹrin láti igun mẹrẹẹrin ojú ọ̀run kọlu Elamu; n óo sì fọ́n wọn ká sinu ẹ̀fúùfù náà, kò sì ní sí orílẹ̀-èdè kan tí àwọn ará Elamu kò ní fọ́n ká dé.
Wọ́n fi òògùn tọ́jú òkú rẹ̀ kí ó má baà bàjẹ́, wọ́n sì tẹ́ ẹ sinu pósí ní ilẹ̀ Ijipti.
Àwọn ìlú náà yóo jẹ́ ti àwọn ọmọ Lefi, wọn óo máa gbébẹ̀.
Ẹni tó bá kàwé dé ipele girama leè di Ààrẹ, dandan kọ́ ni ìwé ẹ̀rí Ilé ẹjọ́ Divorcee: Ó sàn kí wọ́n yàgò fúnra wọn ju ki wọ́n ṣe ara wọn léṣe- Fisayo Olùdíje 24 ni yóò kópa ní ìdìbò Kogí Ìdí tí ètò ìdìbò ìpínlẹ̀ Kogi fi yàtọ̀!
 Sale Mamman – Taraba, Minisita fun ipese ina ọba(Power) méjílélógójì ) Abubakar D.
Ninu fidio naa lo ti ṣalaye pe dokita ni oun, amọ lati ọdun mẹfa ti oun ati Pius ti ṣegbeyawo,ni ko ti si alaafia ninu igbeyawo naa.
Ni ọjọbọ, igbimọ naa tun sọ pe igbakeji aare Naijiriya Yẹmi Ọṣinbajo naa fi ọwọ si milionu naira mẹfa-din (N5.
Oríṣun àwòrán, Sanwol-olu/instagram Lẹ́yìn olóògbé Barrister àti Kollington, èmi làgbà kàn nínú iṣẹ́ orin Fuji- Obesere yarí Building Collapse: Iléèwé míràn tún dàwó ní ìpínlẹ̀ Eko Yatọ̀ sí pé ó ṣe sọ́jà, tó tún jẹ́ ọkọ Oriṣabunmi, wo àwọn nkan tí o kò mọ̀ nípa Jimoh Aliu Facebook mú àyípadà bá àtẹ̀jíṣẹ́ síra ẹni lórí òpó Instagram, wo àwọn ǹkan tó kàn ọ níbẹ̀ Ó ní àwọn àkẹ́kọ̀ọ́ tó wà ni ipele, kẹta àti ìkaarún ní ilé ìwé girama nìkan ni ààyè wà fún láti padà sí ilé ẹ̀kọ́ ni ọjọ́ ajé, ọjọ́ kọkàlélógún, oṣù yìí.
6 40037 Orilẹede Norway 382 7.
Ibẹ́ lo ti subú lulẹ̀ tó sì kú.
Chima si ku lasiko ti awon ẹka Eagle Crack fi iya jẹ.
" Nibẹ lo ti sọ fun awọn ọmọ ijọ rẹ pe, ki wọn ma ṣe maa da si ọrọ ti ko kan wọn, ki wọn si ma ṣeyọnu nipa ẹni ti ko ba fẹran wọn.
Ìkúnlẹ̀ abiyamọ, ìkókó mẹ́jọ kú nílé ìwòsàn lálẹ́ ọjọ́ kàn Oríire dé!
Jonatani dá a lóhùn pé, “Kí á má rí i, o kò ní kú.
Wọ́n sọ fún un pé, “Abrahamu ni baba wa.
Bawo wa ni o ṣe jẹ pe ojọba faaye gba a?
Ọkan lara awọn olugbe ilu naa, Mallam Ibrahim Usman Fulani sọ pe Fulani daran daran ni mi, ṣugbọn igba ti mo gbọ iroyin irọloye Sanusi, ni mo pada wa si ilu."
Eyi ti sun iye awọn to ti lugbadi arun naa siwaju di ẹgbẹrunleọkandinlọgọrun un.
Koda, awọn ọmọbibi ilu ati awọn ajeji to ba n gbe ninu ilu, to n jẹ ounjẹ wọn, to si n mu omi wọn, ni okun ibeji abi ibẹta wa ninu rẹ.
Àwọn ìròyìn mìíràn tí ẹ lè nífẹ̀ẹ́ sí: R Kelly sunkún lóri Tẹlifísàn nípa ẹ̀ṣùn ìbálòpọ̀ Ọmọbíbí ìlú Benin di ìlúmọ̀ọ́ká akẹ̀ṣẹ́ lágbàáyé Ní'lùú Ilọrin, èèyàn méjì fara gbọta ìbọn Ọ̀rẹ́ la mọ ṣe!
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Èmi ni afunfèrè àkọ́kọ́ lágbo eré KWAM 1 ní 1983' Obama ni, pẹlu iriri oun lasiko ti oun wa nipo aarẹ, oun gba pe lootọ ni iwa ẹlẹyamẹya wa, to si wọpọ ni orilẹede naa, amọ o ni ilẹ naa si lee ni agbega siwaju si, tawọn oniruuru ẹya ba gbagbọ ninu ẹya wọn, ti wọn ko si gba kamu.
Tí kò bá sí ọ̀fọ̀ tí ó ṣẹ̀ wá ni, irú àsìkò báyìí , ilé- ìwé ni èmi, ẹ̀gbọ́n àtí àbúrò mi ìbá wà ṣùgbọ́n wọn kò jẹ́ kí á lọ sí ilé- ìwé.
Agogo wúrà kan, àwòrán èso pomegiranate kan, bẹ́ẹ̀ ni kí o tò wọ́n sí etí ẹ̀wù àwọ̀kanlẹ̀ efodu náà.
Iranṣẹ rẹ̀ náà bá dá a lóhùn, ó ní, “Obinrin ará Moabu, tí ó bá Naomi pada láti ilẹ̀ Moabu ni.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fọ́nrán ohùn, Ètò Atiku ló bá èròngbà Yorùbá mu Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fọ́nrán ohùn, Sẹ́nẹ́tọ̀ Femi Okunronmu sọ pé Atiku ló le tún Nàìjírìa ṣe Bakannaa Sẹnẹtọ Femi Okunronmu naa sọrọ, to si fa komookun rẹ yọ pe, ibi ti Obasanjọ lọ gan an l'oun n lọ lori ọrọ ibo Aarẹ lọdun 2019.
Ẹ bèèrè òjò lọ́wọ́ OLUWA ní àkókò rẹ̀, àní lọ́wọ́ OLUWA tí ó dá ìṣúdẹ̀dẹ̀ òjò; Òun ló ń fún eniyan ní ọ̀wààrà òjò, tí àwọn ohun ọ̀gbìn fi ń tutù yọ̀yọ̀.
Minisita sọ ọrọ yii lasiko ti igbimọ to n mojuto itankalẹ aarun Covid-19 n ba awọn akọroyin sọrọ lọjọru, ọjọ kẹtadinlọgbọn, oṣu Kẹta.
Ó bá bí àkọ́bí rẹ̀ ọmọkunrin, ó fi ọ̀já wé e, ó tẹ́ ẹ sí ibùjẹ ẹran, nítorí kò sí àyè fún wọn ninu ilé èrò.
Adarí iléeṣẹ́ wa ni, Irina Reyder
kò mọ nǹkankan; Jonatani ati Dafidi nìkan ni wọ́n mọ ìtumọ̀ ohun tí ó ń ṣẹlẹ̀.
Gideon sọ wipe ìgbésẹ náà wáyé nítorí ìpeníjà ààbò ẹmi Seneto Dino.
Igbà ti Agígírì kò rí Lúmọ̀ogun, ominú bẹ̀rẹ̀sí í kọ́ ọ́, bóyá ó ti sọnù tàbí ẹranko búburú ti pá jẹ.
Nítorí náà, OLUWA Ọlọrun ní, “Mo fi ara mi búra, n óo gbẹ̀san ìbúra mi tí kò náání lára rẹ̀, ati majẹmu mi tí ó dà.
Nigba ti o wa ni ẹgbẹ agbabọọlu Borussia Dortmund, a ma saba fi awọ oju Batman ati eyi keyi miran to ba wa si lọkan dawọ idunnu lẹyin to jẹ goolu.
Koda Gomina fikun ọrọ re pe, oun ṣetan lati lọ jẹjọ niwaju ajọ to n gbogun tiwa ajẹbanu ti ẹnikẹni ba f'ẹsun iwa ibajẹ kan oun.
Ṣókí ìròyìn kayefi yíi ree láti orileede Kenya níbi tí Gómìnà Alfred Mutua ti agbegbe Machakos àti àwọn akoroyin méjì, tí wọn já sodo nigba ti afárá tí Gómìnà wa se ìfilọ́lẹ̀ rẹ já.
 Èyí ló mú kí wọn di kòrí-kòsùn ara wọn láti kékeré wá , wọn kí í sì í yara wọn bí ó ti wú kí ó rí .
"Ọbasanjọ tun kabamọ lori ikuna awọn asaaju ni Afrika ""To ba jẹ pe wọn si wa loke eepẹ ni, ori wọn ko ba maa wu nipa awọn aseyọri mi yii ni."
Ileeṣẹ ologun orileede Naijiria ti ti ile iroyin Daily Trust pa nilu Maiduguri ati ilu Abuja.
Agbenuso kan fun minisita fun eto ilera so pe, won gbe awon ti o kagbako ijamba naa lo si awon ile-iwosan fun itoju to peye.
Ija ọhun bẹrẹ ni igba ti Lizzy Anjorin fi fidio kan sita l'oju opo instagram rẹ, nibi ti o ti fi ọpọlọpọ eebu ranṣẹ si Toyin.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ọ̀ṣun Oṣogbo 2018: Ulrich Salazar wálé ọdún láti New York Koda o tun gbe iṣẹ ogun jija rẹ ipinlẹ ti o n jẹ Edo lonii.
Bi ẹ ko ba gbagbe ninu oṣu kẹrinla ọdun to kọja, awọn igun kan ninu ẹgbẹ naa to wa lẹyin gomina ipinlẹ Edo, Godwin Obaseki jawe lọ simi nile fun Oshiomole eyi ti wọn pohun pọ ṣe.
, Afojúsùn rẹ sì ni láti wá ọna ti ìṣọ̀kan àti irẹpọ yóò fi padà silẹ Yoruba, Nibẹ sì ni wọn ti fẹnu ọrọ jóná pé, kí gbogbo ìlú nilẹ Yoruba máa san isakọlẹ wọn fún ìlú Oyo tuntun lábẹ́ Aláàfin Atiba, tó jọba lẹ́yìn ogun Fulani.
Wọn óo máa fọ́ ọ lórí,ìwọ náà óo sì máa bù wọ́n ní gìgísẹ̀ jẹ.
"O ni kii ṣe bi awọn okele nla nla ti a da bii okuta""."
Bẹ́ẹ̀ ni eniyan ṣe tẹ ara rẹ̀ lórí batí ó sì rẹ ara rẹ̀ sílẹ̀.
O kere tan, ẹgbẹ̀ta ohun ija, bii ibon abbl, ni o di awatii ni ipago iko omo ogun  United Arab Emirates-ti o wa laarin gungun orile-ede Somalia, ni won pate re bayii fun tita ni olu ilu orile-ede ohun ti n se Mogadishu.
”Ó ní, “Kígbe pé, koríko ṣá ni gbogbo eniyan,gbogbo ẹwà sì dàbí òdòdó inú pápá.
Oríṣun àwòrán, Others Àkọlé àwòrán, Rashidi Yekini ṣi ni aṣiwaju atamatase agbabọọlu fun ilẹ Naijiria ninu itan.
musulumi ododo lati maa  kaare ni rere sise
Nítorí ìdí ẹ̀yí ni wọ́n fi má ń tún ara wọ́n ṣe ní alẹ́.
oga agba Idris so pe: “Ki Igbakeji oga agba ile-ise olopaa to n dari eka agbegbe zone 7 ni olu ile-ise naa, Taiwo Lakanu ko awon omo ogun alaabo lo silu Kaduna lati lo bere ise akanse tuntun ti yoo mu igbe-aye alaafia tun joba pada nipinle Kaduna ati agbegbe re gbogbo.
(Àwọn Sadusi ni wọ́n sọ pé kò sí ajinde.
"m ni ojú mi déédé fọ́ níbi tí mo ti ń darí ọkọ̀ ni Ọrẹgun Ikẹja -LASTMA Yesufa Mo ti kó kúrò nílé Olu Jacobs rí lẹ́ẹ̀mejì- Joke Silva ""Mo fẹ́ pa ara mi torí ojú àbùkù tí wọn ń fi wò mí pé mo fi iṣẹ́ abẹ bímọ"" Èmi àti Saheed kìí ṣe ọmọdé, a ti jọ ṣe Sinimá papọ̀, èyí túmọ̀ sí pé ìjà ti parí - Fathia Balogun Ọmọge ti ifa ba si mu yii ko gbọdọ tii mọ ọkunrin, yoo si se isẹ naa titi ti yoo fi wọ ile ọkọ ni."
Alaga ile ẹjọ naa, Adajọ Danladi Umar gba si agbẹjọro Onnoghen lẹnu, o gba oniduro rẹ, o si fagi le iwe 'farahàn-tipátipá' ti wọn ti gbe jade tẹlẹ.
Lẹyin naa ni ijọba ipinlẹ ọhun kede konile-o-gbele tuntun fun wakati mẹrinlelogun.
Akinwumi Adesina jáwé olúborí gẹ́gẹ́ bí adarí Báńkì AFDB Iroyin to n tẹ wa lọwọ ni wipe wọn ti tun Akinwumi Adeshina yan gẹgẹ bii adari Banki Idagbasoke ilẹ Afrika, AFDB.
Àwọn oníṣẹ́ ibi ni ó ń bẹ̀rù àwọn aláṣẹ.
Ọjọ́ òkùnkùn ni, kì í ṣe ọjọ́ ìmọ́lẹ̀.
Àtíkù ní sé Ọbásanjọ́ jẹ́ Ọlọ́run ni?
Bakan naa ni agbẹnusọ fun Aarẹ Muhammadu Buhari, Garba Shehu sọ pe, ayederu iroyin ni ẹgbẹ oṣelu PDP n fi sita lori ọrọ naa.
Kọmiṣọnna fun ayika Aliyu Mohammed ni kọmiṣọnna ti yoo maa tukọ ile iṣẹ ijọba to n mojuto ọrọ ayika nipinlẹ Kwara.
, Duration 8,0016 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 5:57 Fídíò, LASTMA Yesufa: Àwọn dókítà gbìyànjú lórí ojú mi ṣùgbọ́n.
Diẹ re e lara awọn ibeere ti o fakọyọ nipa arun Coronavirus Coronavirus: Wo ohun tí o ní láti ṣe láti dáàbò bo ara rẹ Ǹjẹ́ mo tílẹ̀ ti ní àrùn Coronavirus?
Ní ọdún kẹtalelogun tí Joaṣi, ọmọ Ahasaya, jọba ní Juda ni Jehoahasi, ọmọ Jehu, jọba lórí Israẹli ní Samaria, ó jọba fún ọdún mẹtadinlogun.
Oríṣun àwòrán, Femi Adesina Èyí ní àtúpalẹ̀ ètò ìṣúná fọ́dún 2021 Aarẹ Buhari, lasiko to n gbe aba isuna naa kalẹ salaye pe gbogbo awọn akanse isẹ to n lọ lọwọ nijọba yoo sa ipa rẹ lati pari lọdun 2021, to fi mọ awọn oju popo ati oju irin.
Wọ́n dúró títí tí agara fi dá wọn.
Èmi OLUWA ni n óo jẹ́ Ọlọrun wọn; Dafidi, iranṣẹ mi ni yóo sì jẹ́ ọba láàrin wọn, èmi OLUWA ni mo sọ bẹ́ẹ̀.
Ó kọ sínú ìwé ìròyìn ìbílẹ̀ẹ Bhorer Kagoj:
Nígbà tí ó pẹ́,ọ̀sanyìn ẹlẹ́sẹ̀ kan yọjú síta, ó sọ pé òun yóò mú bàntẹ́ wá sí ilé.
Ṣé mo lè mọ̀ dájú pé baba mi fẹ́ pa ọ́, kí n má sọ fún ọ?
Ẹ wò ó, mo ní àwọn ọmọbinrin meji tí wọn kò tíì mọ ọkunrin, ẹ jẹ́ kí n kó wọn jáde fún yín, kí ẹ ṣe wọ́n bí ó ti wù yín, ẹ jọ̀wọ́, ẹ fi àwọn ọkunrin wọnyi sílẹ̀, nítorí pé inú ilé mi ni wọ́n wọ̀ sí.
A gbọ pe ọpọ orisa bii Ọbaluaye, Ọbatala, Ọsun, Sango ati Igùn lo wa labẹ Olumọ ti wọn n bọ sugbọn orisa Igùn ni ọba gbogbo wọn.
Oríṣun àwòrán, Instagram Àkọlé àwòrán, Doris Simeon to jẹ oṣere to gbajugbaja ni wọn bi ni ọjọ kẹrinlelogun,Osu Keje ni agbeegbe Ọjọta ni ipinlẹ Eko.
“Àlá náà nìyí; nisinsinyii, n óo sọ ìtumọ̀ rẹ̀ fún ọba.
Kí ló dé tí o fi jìnnà réré, OLUWA,tí o sì fara pamọ́ ní ìgbà ìpọ́njú?
Iyana-Ipaja Bridge, Ijọba ibilẹ Agege / Alimosho 2.
Buhari, ó yá, tètè kọ̀wé fipò sílẹ̀ - Oyedepo Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Sunday Adelaja: Tẹ́tẹ́ làwọn pásítọ̀ tó ń gba owó ‘ìserere’ ń ta Wọn ni ọmọ ti yoo ba jẹ asamu, kekere ni yoo ti maa jẹnu samu-samu.
Owo iṣejọba awọn amofin ko pọto ti isejọba aarẹ.
Ohun tí a mọ̀ nìyí nípa gbọ́nmi síi omi ò tó lórí ọ̀rọ̀ oyè Babaloja-General ní ìpínlẹ̀ Oyo Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Wo bí Sunday Orimola ṣe gba ikú ẹranko kú ní Ifon ni Ondo lórí ọ̀nà àtijẹ Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Coronavirus in Nigeria: Èèyàn mẹ́jọ kú, 1,024 míràn tún lùgbàdì ààrùn náà ní Nàìjíria11 Sẹ́rẹ́ 2021 Fídíò, Akomolede: Bolaji Faleke ni Olùkọ́ tó ń kọ́ wa ní àṣà oge ṣiṣe lórí BBC Yorùbá1 Owewe 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Ìdáhún àtàwọn ìbéèrè míì Ẹ̀yin obìnrin tẹ́ẹ fẹ́ wá bímọ ní America, ọ̀nà ti tì pa látònì!
Ọjọ karundinlọgbọn oṣu kẹjọ ọdun yii lo yẹ ki idije paralympics to wa fawọn akanda ẹda naa bẹrẹ tẹlẹ, ohun naa yoo wa bẹrẹ ni ọjọ kẹrinlelogun oṣu kẹjọ si ọjọ karun oṣu kẹsan ọdun 2021.
India: Ọkùnrin kan yọ kindinrin ìyàwó rẹ
Wọn óo máa bọ̀ lórí ẹṣin, lórí kẹ̀kẹ́-ogun, lórí kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́, ati ràkúnmí, wọn óo máa wá sí ìlú Jerusalẹmu, òkè mímọ́ mi, bí àwọn ọmọ Israẹli yóo ti máa mú ẹbọ ohun jíjẹ wọn wá sí ilé OLUWA, ninu àwo tí ó mọ́.
Aisha Buhari, Dubai trip: Ṣé lóòtọ́ ni pé Aisha Buhari ti kó lọ sí Dubai?
Ṣé ẹ óo máa parọ́ ní orúkọ Ọlọrun ni,kí ẹ sì máa sọ̀rọ̀ ẹ̀tàn ní orúkọ rẹ̀?
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Lekki Shooting: Ohun tó ṣẹlẹ̀ kò sí nínú ìlànà ológun, Buhari gbọ́dọ̀ ṣèwádìí 20 Ọ̀wàrà 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 21 Ọ̀wàrà 2020 Oloye Ọlabọde Ibiyinka George to jẹ ajagunfẹyinti, oloṣelu ati alakoso to lorukọ nilẹ yii, ti ke si aarẹ Buhari lati gbe iwadii kalẹ lori iṣẹlẹ ipaniyan Lekki.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù YCE: Ìpínlẹ kọ̀ọ̀kan ní àṣẹ láti dá ààbò bo àwọ̀n ènìyàn wọn 14 Sẹ́rẹ́ 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 15 Sẹ́rẹ́ 2020 Àkọlé àwòrán, Ìpínlẹ kọ̀ọ̀kan ní àṣẹ láti dá ààbò bo àwọ̀n ènìyàn wọn Ẹgbẹ to n risi idagbasoke ilẹ Yoruba, Yoruba Council of Elders ti bu ẹnu ẹ̀tẹ́ lu ohun ti agbejọro ijọba sọ lori idasilẹ ikọ Amọtẹkun to wa fun eto aabo ilẹ Yoruba.
Jesu bá wí fún wọn pé, “Ẹ wá máa tẹ̀lé mi, èmi yóo sọ yín di ẹni tí ó ń fa eniyan bí a ti ń dẹ ẹja ninu omi.
Gbogbo ẹ̀dá alààyè tí ń mí lórí ilẹ̀ ayé patapata ni wọ́n kú.
Lóòótọ́ ni, OLUWA, pé àwọn ọba Asiria ti pa gbogbo orílẹ̀-èdè run tàwọn ti ilẹ̀ wọn, 
Fun awọn to ni aisan ọgb inu, Oluwatobi ni awọn eso to ni oro ninu ko dara fun wọn lati fi ṣinu tori naa, o yẹ ki wọn ri onimọ nipa ounjẹ ti yoo ya atẹ ounjẹ fun wọn ki wọn to maa yan ounjẹ ti wọn yoo fi ṣinu ati iye akoko to yẹ ki wọn fi gbawẹ.
Ileeṣẹ ologun ofurufu ni Naijiria ni ọrọ gbogbo wa lọwọ awọn agbofinro bayii lati ṣe ohun to tọ lẹyin iwadii gbogbo.
 Àwon iní ìhun béẹ ̀ lè kún fún àwon èròjà wọ ̀ fún tí ó wọnú ara won .
Ati pé o ní iwe àṣíri níkawọ lọ́nà àìtọ ní èyí to lè gbógunti ààbo, àláàfíà tó tun le dá rògbòdiyan sílẹ̀ lórílẹ̀-èdè yìí ni àwọn fi kan an.
Ní ipò àìlórúkọ, ó jẹ́rìí sí ìyàsọ́tọ̀ ẹ̀yà tí ó rí láàárín ọdún mẹ́rìnlélógún tí ó fi ṣiṣẹ́ ológun:
S Embassy Bàbà ọmọ ọdún 75 kó HIV ran ọmọ ọdún 14 lẹ́yìn tó fi ipá báa lò Gbogbo ọjà di títì pa nílùú Akure, ṣugbọ́n nítorí kí ni?
Ìrètí wo ni ẹni tí kò mọ Ọlọrun ní nígbà tí Ọlọrun bá pa á run,tí Ọlọrun sì gba ẹ̀mí rẹ̀?
Idahun rẹ ni pe ara oun rẹwa lo jẹ ki oun maa ṣi ara mi silẹ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Lagosians: Eni tó ní owó ló ń kọ Will Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ọ̀tá Nàíjíríà ni Saraki àti Dogara - Buhari Olùdásílẹ̀, akẹ́kọ̀ọ́ iléẹ̀kọ́ Yahoo-Yahoo wọ gàù EFCC Igun ẹgbẹ́ NURTW tó bá da ayẹyẹ ìbúra mi rú, yóo rugi oyin - Seyi Makinde Ọgaagun awọn ọmọogun ori omi naa wa fikun wi pe, aarẹ Buhari rọ gbogbo awọn ti ọrọ naa kan lati ri daju pe wọn se ohun gbogbo to yẹ lati mu eto aabo gboro si lorilẹede Naijiria.
Minisita ètò ìbáraẹnisọ̀rọ̀ kò ní lé kópa nínú ìdìbò abẹ́lé APC nítorí ìwé ẹ̀rí àgùnbánirọ̀
"Ko si ẹni to da na biliọnu mẹjọ naira.
Àwọn ará Hiti dá Abrahamu lóhùn, wọ́n ní, 
Oríṣun àwòrán, Other Àkọlé àwòrán, Azeez Adeshina Fashola ti wọn n pe ni Naira Mailey ni Ajọ EFCC mu lori ẹsun jija ole lori ẹrọ ayelujara.
Kí ẹ lè máa ranti àwọn òfin mi, kí ẹ máa pa wọ́n mọ́, kí ẹ sì jẹ́ ẹni ìyàsọ́tọ̀ fún Ọlọrun yín.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Olaitan Olamide: mò lè má nílò ìwé ẹ̀rí mi tí mo bá parí ní LASU Alága ìgbìmọ náà, Adamu Gumba lásìkò to n ba àwọn oníròyìn sọ̀rọ̀ lóri abájade ìwádìí ìgbìmọ̀ rẹ̀ lọ́sàn òní ló fi ọrọ yii lede.
Àwọn ará Bẹtẹli ati Ai jẹ́ mẹtalelọgọfa (123).
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Agolo gáásì kéeké tó ń jò bú gbàmù l‘Eko, ẹ̀mí kan bọ́, mẹ́ta fara pa Ewé ṣunko!
7 1725 Orilẹede Olominira Congo 94 1.
Wolii kan tí orúkọ rẹ̀ ń jẹ́ Elija, ará Tiṣibe, ní Gileadi, sọ fún Ahabu pé, “Bí OLUWA Ọlọrun Israẹli, tí mò ń sìn ti wà láàyè, mò ń sọ fún ọ pé, òjò kò ní rọ̀, bẹ́ẹ̀ ni ìrì kò ní sẹ̀ fún ọdún mélòó kan, àfi ìgbà tí mo bá sọ pé, kí òjò rọ̀, tabi kí ìrì sẹ̀.
Ki gaan lo n mu Amẹrika jaya nipa Huawei?
Mo gba gbogbo ohun tí ó wà ninu ìwé Òfin ati ninu ìwé àwọn wolii.
Kayode Williams ọmọ lẹyin Oyenusi, ògbóǹtarìgì adigunjalè tó ń fi àyípadà rẹ̀ ran àwọn ẹlẹ́wọ̀n lọ́wọ́ Ìjà d'ópin, fún ìgbà àkọ́kọ́, bàálù gbéra láti Israel lọ sí UAE Iléẹjọ gíga jùlọ da ẹjọ́ SDP àti PDP nù, wọ́n ní Yahaya Bello ló wọlé ìbò gómìnà Kogi Ìjọba Ghana ṣí iléeṣẹ́ àwọn ọmọ Nàìjíríà padà.
Abari Abari jẹ ọkan lara awọn ounjẹ ilẹ Yoruba to gbajumọ laye nigba kan ri.
Nítorí náà ni àwọn ọmọ Lefi fi tọ́jú tiwọn, tí wọ́n sì tọ́jú ti àwọn alufaa, àwọn ọmọ Aaroni.
 Sugbon loju omo orile ede Naijiria , pelu bi igbimo ijoba  se foju lameeto wo o, ojo kejila osu kefa je ojo to lapere , to tun je malegbagbe lorile ede yii, ju ojo kokandinlogbon ati ojo kiini, osu kewaa lo.
Minimum wage: NLC ló ń fa ọwọ àfikún owó òṣìṣẹ́ sẹ́yìn!
Ẹ má parun nítorí ìjìyà ẹ̀ṣẹ̀ Babiloni;nítorí àkókò ẹ̀san OLUWA nìyí,yóo sì san ẹ̀san fún Babiloni.
Ni bayii ti ise ti bere, a ro awon ero oko fun ifarada won.
Oríṣun àwòrán, others Bakan naa o ni wọn ti tẹra mọ akitiyan lati mu awọn meji to ku.
2 Bélú 2020 Child Right Act: Àwọn ìpínlẹ̀ mọ́kànlá tí kò tíì ṣàmúlò òfin ẹ̀tọ́ àwọn èwe láti 2003 ní Nàìjíríà rèé10 Bélú 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Ọpọ lọ n ke si ijọba kí wọn ba awọn tó ń tà ọjà ṣọrọ kí wọn sì ni aṣẹ lori bí wọn ṣe ń gbowó lórí ọjà nitori pe nkan ti àwọn n ra ni eedegbeta Naijiria ti di egbeunnkannabo ládùúgbò báyìí.
Yóo jẹ́ ibi mímọ́ tí a ó ti máa sun turari olóòórùn dídùn níwájú rẹ̀.
Mo gbé ìgò ọtí kalẹ̀ níwájú àwọn ọmọ Rekabu, mo kó ife tì í.
Ṣebí Damasku ni olú-ìlú Siria, Resini sì ni olórí Damasku.
Ojú ń pọ́n mi, mo sì ń jẹ̀rora;Ọlọrun, jẹ́ kí ìgbàlà rẹ gbé mi lékè!
Oríṣun àwòrán, Toyin Abraham Gbajúmò óṣeré tíátà lóbìnrin, Toyin Abraham tí kéde pé, ilé ọkọ tí òun wa ti mú àyípadà rere bá igbe ayé òun.
O ni gbogbo nkan ti oun ṣe lásìkò ti òun jẹ alága ẹgbẹ́ APC lo tẹ oun lọrun ati pe, òun sì wà lẹ́yìn ìjọba ààrẹ Muhammadu Buhari lọ́jọ́kọ́jọ́.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Eruku ìjà sọ lálá lórí ayelujára láàrin Oyedepo àti Daddy Freeze Mo fòpin sí àjẹbánu lórí owó ìrànwọ́ epo àti iná ọba, ní èlé ṣe wáyé - Buhari Ọlọ́pàá tó dá dókítà oníṣẹ́ abẹ dúró lásìkò ìséde, fa ikú alaboyún kan Wo ìdí tí wọ́n ṣe lé Erica dànù kúrò nílé BBNaija l'ọ́sẹ̀ yìí Kí ló ṣe Ibrahim Chatta tó fi dèrò ilé ìwòsàn?
Amọ Adesina ni jẹ iyalẹnu lo jẹ fun oun pẹlu oun ti wọn wa n sọ nisinyii'' Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fọ́nrán ohùn, Ruga settlement: YCE ní ìjọba àpapọ̀ ko tó bẹ̀ẹ́ láti kọ́ àgọ́ Fulani sílẹ̀ Yoruba O fikun pe ''akọsilẹ wa pe awọn Gomina kan ni ọna abayọ niyi, ti wọn ba wa n tapa si, ọna abayọ miran wo ni wọn fẹ ka lo?
Alábòyun ṣe iṣẹ́ abẹ pẹ̀lú abẹfẹ́lẹ́, ó gbé ọmọ jádé nínú ara a rẹ̀ Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: SARS tó bá hùwà àìtọ́ á jẹyán ẹ̀ níṣu ni!
Nigeria v Argentina (0-0) Oríṣun àwòrán, 11v11.
Ijọba Zimbabwe gbe orukọ awọn to kowo ilu pamọ jade
Fake Kidnap: Ọlọ́pàá Eko ń wá arákùnrin tó parọ́ gba owó ìjínigbé 700k lọ́wọ́ mọ̀lẹ́bí ọ̀rẹ́bìnrin rẹ̀
A kò tíì fi ìdí ẹ̀ múlẹ̀ pé ògùn Dexamethsaone ń ṣiṣẹ́ fún àrùn coronavirus- WHO Ọmọ ọdún méjìlá ni mo ti ń ṣe bàálù, ọkọ̀, ilé àti ọkọ̀ ojú omi - Ọdọ́mọdé ‘Engineer’ A maa n ṣere tabi idije nipa ọrọ akọnilẹnu ki awọn eniyan le kọ sii nipa ede Yoruba ati fun idanilaraya ni.
Bakan naa lo bu ẹnu atẹ lu igbesẹ ijọba to fi owo kun owo epo ati owo ina lasiko arun Coronavirus ti awọn orilẹede miran n ṣe iranwọ fun awọn araalu.
O ni igbimọ amuṣẹya ipinlẹ Osun se idanilẹkọ yii, ki wọn baa le dẹkun itankalẹ arun Covid-19.
 Àtúnse gbọdọ̀ bá bí EFCC ṣe ń gbógun tí ìwà ọ̀daràn - Ọọ̀ni Ṣé àwọn ọmọ rẹ lè sọ Yorùbá tó àwọn ọmọ Amẹrika yìí?"
Saaju, akowe agba fun ijoba apapo, ogbeni Mustapha so pe, isakoso isejoba aare Buhari sagbekale awon ilana ti o pese ojutu lati mu ileri re se fun awon ara ilu.
 Ṣùgbọ ́ n , àwa ènìyàn lápapọ ̀ mọ ìwúlò ìbágbépọ ̀ .
No doubt, his generous assistance to my family while I was a political prisoner makes me forever indebted to him.
N óo ba yín dá majẹmu ayérayé,ìfẹ́ mi tí kì í yẹ̀ tí mo ṣe ìlérí fún Dafidi.
‘‘Mo ki o ku oriire iyansipo gege bi asoju ile Isreal si
Ti a o ba gbagbe pe ,Mọ́kàndínláàdọ́fà (109)
" Ki wa ni esi Iran?
Ẹsin kii ṣe ohun elo oṣelu.
CAMBODIA: O gbọdọ fi iwe aṣẹ igbelu rẹ han ni kete ti o ba ti n balẹ si ilu naa lẹyin ọgbọn ọjọ.
Kò si ẹni to yé ìdí ti ìjọba fi gbé ìgbésẹ̀ yìí ṣugbọn wọ́n si kọ̀ láti sọ ǹkankan lée lóri bí gbogbo ènìyàn ṣe ń bẹnu ẹ̀tẹ́ lùú.
O ni awọn ọmọ ogun ilẹ ti fi da aarẹ Buhari loju pe awọn oniṣẹ ibi boko Haram to ṣiṣẹ yii a jẹ iyan wọn ni iṣu laipẹ.
yálà kíkọ tà gẹ ́ gẹ ́ bí alágbe tàbí ìfẹ ́ láti máa kọrin lásán .
Ọjọgbọn Ibrahim Agboola Gambari sọ pe oun yoo fi gbogbo agbara oun sin aarẹ Muhammadu Buhari.
, eyi ni ibeere ti awọn mọlẹbi maa n ti si ọkọ."
idibo naa , ki o lee lọ ni irọwọ-irọsẹ.
 A ko won ni lilo awon irin ise igbalode fun aso riran ni eyi ti yoo je ki won le maa se aso lopo yanturu.
Dokita Tsafe sọ pe o le ṣe ere idaraya yii laarin iṣẹju aaya mẹta si marun, sinmi, ki o tun bẹrẹ pada.
Oríṣun àwòrán, AFP Àkọlé àwòrán, Ami oju ọta ibọn ti apaniyan yi fẹ fi pa awn eniyan O farahan pe o se afojusun ẹnikẹni ti o dabi pe wọn wa lati ilẹ Afirika.
Kí ló dé tí ara rẹ kò fi balẹ̀ ninu mi?
O fi kun ọrọ rẹ pe ẹru kọkọ n ba anti òun lati gbe igbesẹ, sugbọn o bori ẹru.
Ẹni to bori: Nigeria Algeria vs Ghana.
“Ọjọ́ mẹfa ni kí ẹ fi ṣe iṣẹ́ yín, ní ọjọ́ keje ẹ gbọdọ̀ sinmi; kì báà ṣe àkókò oko ríro, tabi àkókò ìkórè, dandan ni kí ẹ sinmi.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, E kọọ Lórílẹ̀-èdè Brazil Ẹja ní ọkúnrin máa ń fí wá ojú obínrin Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Sọọ́ pẹ̀lú ẹja Ní abúlé kan tí wọn ń pé ní Mehinaku, ní gbùngùn Brazil, àwọ obìnrin ibẹ̀ ti wá ọ̀nà àbáyọ láti mọ ìyàtọ̀ láàrín àwọn tó ńkọ ẹnu ìfẹ́ sí wọn.
Ó tó bí ibùsọ̀ meje sí Jerusalẹmu.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Àjọ NIDCOM rọ àwọn òbí láti má ran ọmọ lọ kàwé ni Northern Cyprus mọ́ 25 Ògún 2020 Oríṣun àwòrán, Abike Dabiri/Instagram Àjọ to n ri sí ọ̀rọ̀ ilẹ̀ òkèrè, ti rọ àwọn òbí ni Naijiria láti yé ran àwọn ọmọ wọn láti lọ kàwé ni Àríwá Cyprus mọ́ nítóri ìkú àìnídìí ti àwọn ọmọ Nàìjíríà ń kú níbẹ̀.
Afẹnifere: Omisore kò jẹ́ ká mọ ìgbésẹ̀ rẹ̀ nínú ìdìbò Oṣun
"Gẹgẹ bo ṣe sọ, o ni ""emi ni adari ati alaṣẹ lori gbogbo oriṣa ilẹ Yoruba ati kaakiri agbaye."
Minisita fun eto ẹkọ lorile ede Naijiria  Adamu Adamu ti rọ eni ti yoo gba ipo
Naama ará Amoni ni ìyá rẹ̀.
Èyí tí ẹ ṣé lórí iṣẹ́ àgbàṣe ₦67bn Ibadan Lagos Bye Pass-Makinde Adajọ naa tẹsiwaju pe, kete ti ajọ ti o n ri si eto ibo ati ẹgbẹ oṣelu ba ti fọwọ si ẹnikẹni pe o kunjuuwọn, ko si idaduro mọ fun iru ẹni bẹẹ.
Mo dupẹ lọpọlọpọ,'' Taye Currency lo sọ bẹẹ.
Nígbà ti wan sọkalẹ tan ni o wá sọ fun wan pe awako ofurufu lọ yọ orukọ wan kuro ninu irinajo náà.
Ẹ wo fidio yii fun ẹkunrẹrẹ.
Agbenuso fun orile-ede Faranse  Benjamin Griveaux so pe, “ile-Europe ti fi erongba re han lori laasigbo eto kara-kata ohun, o je ohun ti o dun mo wa ninu pe, Aare Trump yi ipinnu re pada lori owo ori naa”.
Àwọn ẹ̀bùn wọnyi wà fún lílò láti mú kí ara àwọn eniyan Ọlọrun lè dá ṣáṣá kí wọ́n lè ṣe iṣẹ́ iranṣẹ, ati láti mú kí ara Kristi lè dàgbà.
 a kò mọ ̀ bí àrùn náà ti ntàn káàkiri .
Wọn á gbé e lé èjìká wọn,wọn á gbé e sípò rẹ̀, á sì dúró kabẹ̀.
Arabinrin Faithe marere da lohun pada ti o si darukọ awọn ile itaja ti o jẹ ti South Afrika, to yẹ ki awọn ọmọ Naijiria dẹyẹ si.
Ká tó kọ nóòtì sójúu bọ́ọ̀dù, Ká tó buwọ́ lu ișẹ́ akẹ́kọ̀ọ́.
Mansa Musa: Ó lówó, ó ní dúkìá rẹpẹtẹ àmọ́ kò pẹ́ láyé
” Gbogbo wọn súnmọ́ ọn, wọ́n sì yí i ká.
Kẹ́kẹ́ ni mo ṣá Tí Mo mú ṣẹ èwe tí Àpínni; Àbàjà ni mo bù, Tí Mo mú ṣẹ èwe tí Àgùrè; Gọ̀mbọ́ ni mo wà, Tí Mo mú ṣẹ èwe tí Ògbórí.
Niṣe ni mo la ẹnu silẹ, ti mi o le pade, nitori pe mi o gbagbọ pe ọkọ mi le ṣe iru nkan bẹ ẹ.
Alamojuto eto idibo fun ajo INEC, Ojogbon Oluwatoyin Ogundipe
Nígbà tí a rìn díẹ̀ a bẹ̀rẹ̀ sí rí ọgbà tíàwọn ejò ṣe gbogbo, nínú èyí tí wọ́n kó àwọn ọ̀pọ̀lọ́ púpọ̀ sí tí wọ́n ń tọ́jú wọn.
Lásìkò táwọn aláṣẹ pe ìpàdé àwọn oníròyìn, ìjọba Trump sọ pé, òfin náà yóò múlẹ̀ títí di òpin ọdún 2020, èyí yóò sì kan àwọn ènìyàn tó lé ní ẹgbẹ̀rún lọ́nà márùnẹ̀ẹ́dẹ́gbẹ̀ta lé márùn dínlọ́gbọ̀n tí ó fẹ́ gba ìwé ìgbélùú.
                                                                                                                                               Aare ni ‘‘Ni bayii, a ti n ri bi awon eniyan se n lo imo ero igbalode lati fi se ayeduru eto idibo , ni eyi ti o tako ẹtọ ọmọniyan , ti o si tun  maa n da rogbodiyan silẹ laarin ilu.
Ambode ní kò sí gìrì, eré ọwọ́ lásán ni EFCC ń ṣe EFCC ń wádìí iléeṣẹ́ 'Bola Tinubu,' Alpha Beta Consulting Ltd' Agbẹjọro to n ṣoju Ọgbẹni Nolan ati Ọgbẹni Quinn ti pe ẹjọ kotẹmilọrun pe awọn ko jẹbi ẹsun ti ajọ EFCC fi kan an.
Maaka, ọmọ Absalomu ni Rehoboamu fẹ́ràn jùlọ ninu àwọn iyawo rẹ̀.
  Òkondoro ọ̀rọ̀ gidi ni eléyìí jẹ́ tí ènìà bá ṣe àgbéyẹ̀wò ìgbésí aiyé àwọn àgùntàn wọ̀nyìí!
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Akinwumi Ambode: Ilé aṣòfin Eko ṣèpàdé pàjáwìrì 'tórí Ambode 31 Sẹ́rẹ́ 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Gomina Ambode Ile igbimọ aṣofin ipinlẹ Eko ti ni ayafi dandan ki gomina Akinwumi Ambode atawọn komiṣana rẹ ti wọn pe fara han niwaju wọn wa ṣe alaye bi wọn ṣe ṣe owo ilu.
Kò ní sá àsálà, nítorí pé kò náání ìbúra ó sì da majẹmu, ati pé ó ti tọwọ́ bọ ìwé, sibẹsibẹ, ó tún ṣe gbogbo nǹkan tí ó ṣe.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Euthanasia in New Zealand: Kìí ṣe New Zealand nìkan ni òfin yìí yóò ti kọ́kọ́ wáye, Canada àti àwọn orílẹ̀-èdè míì rèé 30 Ọ̀wàrà 2020 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àwọn ènìyàn New Zealand ti dìbò láti sọ ìpolongo pé kí ìjọba gba àwọn ilé ìwòsàn láàyè láti fòpin si ayé aláísàn tó kù díẹ̀ fún láyé rẹ̀ di òfin.
Orí òpó igi kedari, tí wọ́n na ọ̀pá àjà igi kedari lé, ni wọ́n kọ́ ọ lé.
Eyi ko daju nitori pe, ti o ba ja kulẹ ninu idibo naa ni ọjọ Isegun, o gbọdọ sọ fun awọn aṣofin ni ọjọ Aje to tẹle oun ti o n gbero lati ṣe.
Wo oríṣìí oúnjẹ márùn ún tó lè dẹ́kun ikùn yíyọ àti ara àsanjù Akukọ naa ti orukọ rẹ n jẹ Marcel lagbegbe Ardeche, ni arakunrin naa yinbọn pa nitoeipe o n fi ariwo dii lọwọ.
Àpàlà jẹ ẹ ̀ yà orin , tí a múwá láti ọ ̀ dọ ̀ àwọn .
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Obìnrin gbọdọ̀ ṣe ara wọn lọ́kan láti gba ara wọn sílẹ̀ lọ́wọ́ ìfìyàjẹni - Olùdásìlẹ̀ ẹgbẹ́ FIN Davido lẹjọ ro lórí àwọn obìnrin tó sọ panpẹ sí lọ́wọ́ - Ọlọ́pàá Ọ̀pọ̀ ewébẹ̀ àti èso aṣaralóore tó wà ní àyíká àmọ́ tí ẹ kò kà kún rèé Ṣọ́ra fún ìgbín inú omi, àrùn ‘Schistosomiasis’ ti ń bá ìjọba ìbílẹ̀ mẹ́fà l‘Eko jà Àwọn ajínigbé jí adájọ́ gbé, ẹ̀mí ọlọ́pàá tó ń ṣọ ọ́ lọ sí i Gbogbo awọn adajọ mejeeje naa lo wọgile awọn ẹri ti Atiku ko wa siwaju wọn, ti wọn si ni ofuutu fẹẹtẹ, aasa ti ko ni kaun ni wọn.
Ninu atẹjade ti wọn fi lede ni Adari ikọ ọmọogun ofurufu Naijiria, Ọgagun Sadique Abubakar ni iku arabinrin naa jẹ manigbagbe.
Àwọn nkan tí Ẹlẹ́dàá ṣe, àwá ọmọ ènìyan pẹ̀lú, Ó ti fi ìbáṣepọ̀ sáàrin wa pé kí a jẹ́ aláànfàní arawa, kí a sì máa ṣe arawa lóore.
Hanan Buhari wedding: 'Cartoon' tí Bulama yà nípa ìgbéyàwó ọmọ mi kò bójúmu tó
Oríṣun àwòrán, @Alhaja Adeola Agoro Àwọn jàǹdùkú ya bo àfin Ọba ní Alade Idanre, wọ́n lu Adele ní ìlù bàrà Sanwo Olu àti Okowa dẹwọ́ ìséde ní Eko àti Delta pẹ̀lú àlàyé tuntun Ọ̀pọ̀ ẹ̀mí ló ṣòfò nibi ìjàmba tó wáye ni Akungba nìpińlẹ̀ Ondo England kéde ìséde ọ̀sẹ́ mẹ́rin míràn láti dẹ́kun ìtànkálẹ̀ Covid 19 Èèyàn 162 ló kó àrùn Coronavirus ní Nàìjíríà lọ́jọ́ Ajé Wolii Olapade Agoro jẹ ẹni ọdun mejidinlọgọrin ki ọlọjọ to mu u lọ.
Ò bá kúkú ní kí n dìde fún un lórí ìtẹ́ tí mo wà yìí.
Sugbọn nkan ti a ṣakiyesi ni pe, gbogbo awọn alaga ajọ EFCC to ti jẹ, lo maa n koju awuyewuye kan, tabi omiran.
 nínú ọ ̀ kọ ̀ ọ ̀ kan àwọn ìtàn wọ ̀ nyí , a rí abala tí ó fará pẹ ́ òtítọ ́ , a sì rí èyí tí kò fi gbogbo ara jẹ ́ òtítọ ́ .
Oríṣun àwòrán, @ChibuikeAmaechi Ọna oju irin naa wa lara ọna reluwe ti ijọba apapọ dawọle, eyii ti yoo so ipinlẹ Eko mọ Calabar atawọn ipinlẹ miran ni iha guusu-ila oorun Naijiria.
“iwe yii je akosile itan nipa agbegbe, asa ati ise abalaye ati igba ọlaju.
Báyìí lo ṣe salaye ọrọ naa loju opo Twitter rẹ pe ijọba yoo pese ohun gbogbo ti wọn nilo lati tẹlẹ aṣẹ igbogunti itankalẹ ajakalẹ arun Covid 19.
Dípò kí ó tọ́jú wọn, pípa ni yóo máa pa àwọn tí ó sanra jẹ, tí yóo sì máa fa pátákò wọn ya.
Ó sọ fún wọn pé, “Ohun tí OLUWA pàṣẹ pé ẹ gbọdọ̀ ṣe nìyí.
Egbe osise tun faake kori pe
Oluwa, irú èyí kò ní ṣẹlẹ̀ sí ọ.
Nítorí náà mo fi àwọn eniyan ṣọ́ gbogbo ibi tí odi ìlú bá ti gba ibi tí ilẹ̀ ti dà gẹ̀rẹ́gẹ̀rẹ́, mo yan olukuluku ní ìdílé ìdílé, wọ́n ń ṣọ́ odi ní agbègbè wọn pẹlu idà, ọ̀kọ̀, ati ọrun wọn.
O sọ fun BBC pe o yatọ si iru ọna ti awọn olori bi Aarẹ Trump ti ilẹ Amẹerika tabi Jair Bolsonaro ti Brazil ti se n se ijọba to n jiyan pe ko si ohun to jọ Coronavirus nita.
Ẹ̀ṣọ́ tó pa Ọ̀gágun Ethiopia tí a sọ pé ó kú, kò kú mọ́!
Gèlè wọn ati ìlẹ̀kẹ̀ ẹsẹ̀ wọn, ati ìborùn, ìgò ìpara wọn ati òògùn, 
orúkọ àwọn ọmọ rẹ̀ ni, Elifasi, tí Ada bí, ati Reueli, tí Basemati bí.
Kínni ó ń ṣokùnfà aigba kaadi awọ̀n oludibo ?
Bí ẹni tí a bọ́ṣọ rẹ̀ ninu òtútù,tabi tí a da ọtí kíkan sójú egbò rẹ̀,ni ẹni tí à ń kọrin fún ní àkókò tí inú rẹ̀ bàjẹ́.
” Ó bá pàṣẹ pé kí wọ́n máa ṣọ́ Paulu ní ààfin Hẹrọdu.
Ọrọ orin naa rinlẹ, to bẹ to mu ni ranti iku oloogbe Ibidunni Ighodalo arẹwa obinrin aya Pasitọ ijọ Trinity House to jẹ Ọlọrun nipe ninu oṣu kẹfa nigba to ku jọ di ko pe ogoji ọdun.
PDP sọ lori atẹ Twitter rẹ wipe igbesẹ aarẹ bu ẹtẹ lu iwe ofin Naijiria.
"Trump ni ohun to jẹ iṣoro gan an ni ọrọ ti ẹgbẹ oṣelu Democrat sọ lasiko ifẹhonuhan ""Black Lives Matter"" lọdun 2020."
Ìtàn sọ fún wa pé ní àgbáyé Kwa ní èdè Yorùbá bátan; kwa jẹ́ iyè kan ní Niger Congo.
Àwọn ará Jerusalẹmu sì pa majẹmu OLUWA Ọlọrun àwọn baba wọn mọ́.
Lọwọlọwọ ni awọn eniyan Naijiria n pariwo ninu iwọde kaakiri pe ki ijọba fofin de awọn ọlọpaa kogberegbe SARS ati pe ki atunto wọ igbesẹ bi ọlọpaa ṣe n yinbọn ni aarin iluÌgbà wo ni àjọ ọ́lọ́pàá yóò káwọ́ SARS?
Atẹjade kan ti igbimọ amusẹya ọhun fisita salaye pe, awọn igbesẹ naa pọn dandan nitori bi wọn tun se kẹẹfin ọwọja arun Coronavirus nile ẹkọ giga kan nipinlẹ naa.
Akọ mààlúù kékeré kan, àgbò kan, ọ̀dọ́ àgbò, ọlọ́dún kan, fún ẹbọ sísun, 
Ilé ẹjọ́ pàṣẹ, EFCC mú u ṣẹ, Ìjọba gbẹ̀sẹ̀ lé ilé Saraki ní Ilorin Kí ni pàtàkì ọ́fíìsì agbègbè fún aṣòfin?
Wo àwọn àwòràn tó làmìlaaka nílẹ̀ Adúláwọ̀ lọ́sẹ̀ yìí
Bẹ́ẹ̀ gan-an ni Oluwa pàṣẹ pé kí àwọn tí ó ń waasu ìyìn rere máa jẹ láti inú iṣẹ́ ìyìn rere.
Olori awọn ẹlẹsin ibilẹ Osugbo-Remo in Sagamu, Ifasola Opeodu sọ wi pe, lootọ ni iṣẹlẹ naa waye, ti o si sọ idi ti awọn fi kọkọ gba oku naa.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Aeroplane House: Látọdún 1999 ni mo ti bẹ̀rẹ̀ kíkọ́ ilé yìí fún ìyàwó mi ọ̀wọ́n Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Aeroplane House: Látọdún 1999 ni mo ti bẹ̀rẹ̀ kíkọ́ ilé yìí fún ìyàwó mi ọ̀wọ́n 13 Bélú 2019 Said Jamal jẹ oniṣẹ ile kikọ.
Kó wọn lọ sí etí odò, n óo sì bá ọ dán wọn wò níbẹ̀.
Ọbásanjọ́: Ojú bọ̀rọ̀ kọ́ lẹgbẹ́ alájùmọ̀se yóò fi gba ìjọba
Ní àtètèkọ́ṣe, ní ìbẹ̀rẹ̀ ayé pátápátá, ní àkókò ìgbà tí Èṣù ṣubú ní òde ọ̀run, tí Ọlọ́run sì fi ààlà sì agbedeméjì ọ̀run rere àti ọ̀run búburú, igi kan wà ní etí ọ̀gbun àìnísàlẹ̀ tí ó jẹ́ ààlà ní ààrin ọ̀run rere àti ọ̀run búburú, àwọn ará ọ̀run gbogbo a sì máa pe igi náà ní Tèmi-nìkan.
Ṣugbọn Obaseki ni ohun ko ni pe ẹjọ kotẹmilọrun lori igbesẹ igbimọ naa.
Ó wá pe àwọn eniyan jọ, ó sọ fún wọn pé, “Ẹ gbọ́, kí ó sì ye yín.
 láti fi hàn pé òun kò bá ogun wá .
26 Èbibi 2019 Oríṣun àwòrán, Aisha Buhari Àkọlé àwòrán, Aisha Buhari: Aya ààrẹ orilẹ̀-èdè Naijiria ke gbàjare lori eto ijoba Buhari Aya ààrẹ orilẹ̀-èdè Nàìjíríà Aisha Buhari ni àwọn eto oṣelu ti ijoba Muhammadu Buhari ṣe ni sáà àkọ́kọ́ rẹ̀ kò ṣe ànfani fún àwọn obinrin ní ìhà Aríwá orilẹ̀-èdè Naijiria.
Ọpọlọpọ eniyan lo padanu ẹmi wọn sinu ogun naa.
Jean Adukwei Mensa jẹ agbẹjọro ọmọ ilẹ Ghana oun si ni alaga ajọ eleto idibo il naa.
gbadura pe awon omo orile ede Naijiria yoo yan adari rere ninu eto idibo to n bọ,
Bẹ́ẹ̀ ni Isaaki ṣe rán Jakọbu jáde lọ sí Padani-aramu lọ́dọ̀ Labani, ọmọ Betueli, ará Aramea, arakunrin Rebeka, ìyá Jakọbu ati Esau.
SERAP fún àwọn aláṣẹ fásitì méjèèjì ní gbèdéke ọjọ́ méje làti fi dá owó ilé ìwé náà padà sí iye tó wà tẹ́lẹ̀.
O tun fi kun wipe, awọn gun le iyanselodi naa lati fi ehọ́nu wọn han, ati lati duro sinsin pẹ́lu awọn Igba o lẹ̀ mẹ̀rindinlọ̀gọ̀ta osise, ti wọn le kuro lẹ̀nu isẹ́ ijọba ni ipinlẹ́ naa.
 ní òpin ọdún 2012 , hollaway wà ní ipò kejìlá ní gbogbo àseyege ní bethany ( .
Ballon D'or: Ronaldo wà lára agbábọ́ọ̀lù tí wọ́n yàn fún àmì ẹ̀yẹ Agbaọjẹ agbabọọlu Cristiano Ronaldo wa lara awọn agbabọọlu ti wọn f'orukọ wọn lede ninu awọn ti wọn yoo gba ami ẹyẹ Ballon D'or ti ọdun 2018.
“Mo bẹ OLUWA nígbà náà, mo ní, 
" Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Naming of Railway stations in Nigeria: Afenifere, YCE, Akitoye, Fani-Kayode ní ẹ̀tanú Obasanjo ni Buhari ṣe28 Agẹmo 2020 Fídíò, Gani Adams: Ẹni ba fe pẹ laye, maa ra aye gbe ni20 Èrèlè 2018 Buhari: Òpùrọ́ àti òjòwú ni Olusegun Obasanjo21 Sẹ́rẹ́ 2019 Fídíò, Obasanjo: Eré ìtàn nípa ìbí, àti jéèyàn pẹ̀lú ìpèníjà Olusegun Aremu Obasanjo5 Ẹrẹ̀nà 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Ki ni awọn talẹnti ti iwọ naa ro pe o ni?
Bí ẹ bá fi òkúta tẹ́ pẹpẹ fún mi, ẹ má lo òkúta tí wọ́n bá gbẹ́, nítorí pé bí ẹ bá fi ohun èlò yín ṣiṣẹ́ lára òkúta náà, ẹ ti sọ ọ́ di aláìmọ́.
Ẹwẹ, Awosanya ni bi wọn ṣe f'oju wọn han sita fun gbogbo eniyan lori ẹsun pe wọn fura siwọn ko b'ojumu.
Àwọn ẹyẹ wọ́nyí ń dán, wọ́n pupa bíi góòlù, àyà wọn funfun bíi fàdákà, bẹ́ẹ̀ ni ẹnu wọ́n dàbí eyín erin.
Osinbajọ ni ọrọ naa gba ero ati atunṣe, eleyii ti aarẹ Buhari sọ wi pe awọn yoo wa ọna abayọ fun iṣekupani awọn ikọ ọlọpaa yii.
”O ti gba ami eye lorisiirisii bii osere lobinrin to mere se julo.
Bákan náà ni àwọn olórí alufaa pẹlu àwọn amòfin ń fi ṣe ẹlẹ́yà láàrin ara wọn, wọ́n ń wí pé, “Àwọn ẹlòmíràn ni ó le gbà là, kò lè gba ara rẹ̀ là.
O ni ''Lọdun to kọja, agbẹjọro ọlọpaa to joko lati gbẹjọ mi loni fọ mi leti lẹẹmẹrin ni ile iṣẹ ọlọpaa ọtẹlẹmuyẹ SCIID to wa ni Panti.
Madaki ni gbogbo ile idibo to
 Ẹnu rẹ ̀ ni wọ ́ n ti gbọ ́ pé bínpé àbúrò fìlísíà fẹ ́ ṣe ìgbéyàwó ní gbọ ̀ ngán .
Ọba aláde o gbọdọ kọ aya rẹ̀ sílẹ̀
SERAP gbé ìjọba àpapọ̀ lọ ilé ẹjọ́ àgbáyé ICC lọrí ẹ̀sùn ìpànìyàn Jàǹdùkú gún ẹ̀gbọ́n mi lọ́rùn, jó ilé àti mọ́tò wa méjì, kòròfò la wà"" Olùwọ́de 12 kú ni Lekki, 38 lapapọ kú lọ́jọ́ Isẹ́gun, 56 ni àròpọ̀ àwọn tó bá ìwọ́de lọ - Amnesty International Osinbajo gbarata lórí ìṣẹ̀lẹ̀ Lekki, ó ní ìdájọ́ òdodo yóò wà Ṣugbọn pupọ awọn ọmọ Naijiria lo n sọ pe, ohun ti awọn n reti pe ki Aarẹ sọ, kọ lo ba awọn sọ."
Wọ́n bi í pé, “Sọ fún wa irú àṣẹ tí o fi ń ṣe àwọn nǹkan wọnyi; ta ni ó sì fún ọ ní àṣẹ yìí?
Àwọn ni wọn yóo tò sẹ́yìn patapata.
 Ayeye ranpe ohun lo waye nile ise ijoba Ipinle Oyo ti o
Ó kó gbogbo àwọn ère oriṣa Aṣera tí ó wà ninu ilé OLUWA lọ sí àfonífojì Kidironi lẹ́yìn Jerusalẹmu.
''Mo ti wa Maruwa lẹyin baba mi ri ṣugbọn wọn o mọ pe emi ni.
Naijiria yoo maa waako pelu Burundi,
”Wọ́n sì ṣí kúrò níbẹ̀ lọ sí aṣálẹ̀ Matana.
Aare Buhari so pe owo ti orile ede Paris ati owo miiran ti ijoba apapo fun awon gomina ipinle ni lati fi san awon owo osu osise ti won je won, o ni lilo owo yii lona aito je iwa to buru jai, si awon osise.
Èròngbà àwọn t’ọ́n kọ́ ọ síbẹ̀ ni pé kó kàn wà níbẹ̀ fún bí ọdún kan sí méjì.
Mo tún gbadura pé kí ẹ lè kún fún èso iṣẹ́ òdodo tí ó ti ọ̀dọ̀ Jesu Kristi wá fún ògo ati ìyìn Ọlọrun.
 Àròsọ ni olófin-íntótó àti ilésanmí ti wokò .
Tesiwaju si, aare yoo tun lo
Abẹ́rẹ́ àjẹsára àkọ́kọ́ tó n dènà ibà yóò dì mímú lò ní Malawi
 Mo fi akoko yii dupẹ lọwọ awọn ara ilu fun atilẹyin ati adura wọn lori ijọba yii.
Ṣé Ọlọrun yóo kọ̀ wá sílẹ̀ títí lae ni;àbí inú rẹ̀ kò tún ní dùn sí wa mọ́?
Ghana Election Special Voters list 2020: Báyìí ni àwn òṣìṣẹ́ tó dá yàts ṣe ní ọjọ́ ìdìbò tiwọn lọ́tọ̀
Lẹ́yìn náà ó mọ odi ìta sí ìlú Dafidi, ní apá ìwọ̀ oòrùn Gihoni, ní àfonífojì, ati sí ẹnubodè ẹja; ó mọ ọ́n tí ó ga yípo Ofeli.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù #FIFAWWC: Amẹ́ríkà to pàṣán má r'ágbà fín sí ìdí Thailand 12 Òkùdu 2019 Oríṣun àwòrán, fifa.
Ile ẹjọ giga ti da ẹjọ iku fun ọkunrin kan, Lekan Shonde to lu iyawo rẹ Ronkẹ pa, ni bii ọdun mẹta sẹyin.
"Ilé iṣẹ́ ọmọogun kò sọ fún mi pé ọkọ mi kú fún ọdún kan- Iyawo soja Iran ní àwọn kò mọ̀ọ́mọ̀ ju irínṣẹ́ ìbúgbàmù ""missile"" lu bàálù Ukrain tó já Wo Sultan Qaboos bin Said, ẹni tó gbàkóso ìgbé ayé òṣèlú Oman fún àádọta ọdún Ẹ́ gba fóónù, ẹ pe ẹbí yín pé a fẹ́ dáná ṣun yín - Aráàlú sọ fún adigunjalè méji Eto igbanisiṣẹ sínu ikọ Amọtẹkun Oyeleye jẹ ko di mimọ pe lara awọn to n ṣiṣẹ ninu ikọ Amọtẹkun yii wa latara awọn ẹgbẹ alaabo kọọkan to wa nikalẹ tẹlẹ tori gbogbo ipinlẹ lo ni awọn to n mojuto aabo wọn tẹlẹ."
Gbogbo ohun tí ọba ṣe patapata ni ó dùn mọ́ àwọn eniyan.
Ṣugbọn bí ó bá jẹ́ pé mààlúù yìí ti máa ń kàn tẹ́lẹ̀, tí ẹni tí ó ni ín kò sì mú un so, yóo fi mààlúù mìíràn rọ́pò èyí tí mààlúù rẹ̀ pa, òkú mààlúù yóo sì di tirẹ̀.
Iko agbaboolu 3SC ilu Ibadan, lojo isegun(Tuesday) fagbahan Crown FC ilu Ogbomosho, ninu asekagba idije AITEO, eyi ti I o waye ni papa isere Adamasingba nilu Ibadan.
Bi itan igbe aye rẹ si se lọ ree: Ta ni Isọla Oyenusi?
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Mudasiru Obasa: Òṣìṣẹ́ tó tú àṣírí ilé asòfin rugi oyin 7 Òkùdu 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 9 Òkùdu 2020 Oríṣun àwòrán, Facebook/Musasiru Obasa Laipẹ yii ni iroyin kan jade lori ayelujara, to si n fi ẹsun orisirisi kan olori ile asofin nipinlẹ Eko, Mudasiru Obasa.
O wa ro gbogbo awon ololufe iko ohun lati pa okan won po sojukan, bee si ni ki won mase wo bi iko naa se kopa ninu olokan-o-jokan ifesewonse olorejore won,“Asiko ise ni a wayii, bee si ni a gbodo pa okan wa po ti a ba fe ri esi ti o dara leyin awon ifesewonse wa.
’Gbogbo àwọn tí ń bá a bínúyóo pada wá sọ́dọ̀ rẹ̀ pẹlu ìtìjú.
Oríṣìíríṣìí ibi ati wahala ni yóo bá wọn, tóbẹ́ẹ̀ tí wọn yóo máa wí ní ọjọ́ náà pé, ‘Ǹjẹ́ nítorí pé kò sí Ọlọrun wa láàrin wa kọ́ ni gbogbo ibi wọnyi fi dé bá wa?
Àpanisáyé ni ẹ̀wà tí wọ́n n fí 'sniper' sí Ikú ni fífi oògùn 'Paracetamol' bọ ẹran tàbí se ẹ̀wà- Iléeṣẹ́ ìlera Èèmọ̀ rèé!
Idà ni wọn óo fi pa àwọn tí wọ́n bá sá lára àwọn ọmọ ogun rẹ̀, a óo sì fọ́n àwọn tí wọ́n bá kù ká sí gbogbo ayé, ẹ óo wá mọ̀ pé èmi OLUWA ni mo sọ̀rọ̀.
Kí ló dé tí mò ń ṣọ̀fọ̀ kirinítorí ìnilára ọ̀tá?
Bí ó bá jẹ́ pé obinrin náà ti ṣe alaiṣootọ sí ọkọ rẹ̀, tí ọkunrin mìíràn bá ti bá a lòpọ̀, omi náà yóo korò ninu rẹ̀, yóo sì mú kí inú rẹ̀ wú, kí abẹ́ rẹ̀ sì rà.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, World Diabetes Day: Ọdún kọkandinlogun ti mo ti wà lẹ́nu itọ ṣúgà nìyí O sọ pe, ẹni to ba ni aisan yii le jẹ iru ounjẹ ti ẹni ti ko ni aisan naa n jẹ, ṣugbọn, ko jẹ ẹ ni iwọntuwọnsi.
Nítorí OLUWA ní,“Bí ìwẹ̀fà kan bá pa ọjọ́ ìsinmi mi mọ́,tí ó bá ṣe ohun tí mo fẹ́,tí ó sì di majẹmu mi mú gbọningbọnin,
Ó ba ayé mi jẹ́ ní gbogbo ọ̀nà,ó sì ti parí fún mi,ó fa ìrètí mi tu bí ẹni fa igi tu.
Oríṣun àwòrán, Screenshot Kókó ohun tí ìràn Yorùbá ń fẹ́ lọ́dọ̀ ìjọba àpapọ̀ nìyí Oríṣun àwòrán, @BashirAhmaad Awọn agbaagba nilẹ kaarọ oojire, ninu eyi ti awọn gomina ipinlẹ Oodua mẹfẹẹfa wa, ti se ipade pẹlu ijọba apapọ nilu Abuja lọjọ Aiku.
Ǹjẹ́ irú ọkunrin yìí ni ó yẹ kí ó wá sinu ilé mi?
Bí wọn ṣe ti wá jan ofin tuntun ọhun lóntẹ ti ìjọba Abdullahi Umar Ganduje si ti fọ́wọ́ si i lójọ́ru to kọjá, ọjọ kẹjọ ọsù karun ọdún 2019, ìjọba Emir to ti wá láti igba ọdún sẹyin ní ìpínlẹ̀ Kano tún ti bẹ̀rẹ̀ ìtàn túntún báyìí.
Àkọlé àwòrán, Igba n lọ, igba n bọ, aye ko duro si oju kan.
Awọn ohun pataki nipa Ọọni Luwooo Gbagida: Ọmọ Ataataa lati Idile Owode ladugbo Okerewe, to si fẹ Oloye Ọbalọran ti Ilode lọkọ Akoko saa onka ẹẹdẹgbẹfa ọdun, eyiun 1100 AD ni Luwoo Gbagida jẹ Ọọni tilu Ile Ifẹ, to si di olori awọn ẹlẹsin ati alakoso asa fun ilẹ Yoruba.
“Lẹ́yìn náà, kọjú sí Jerusalẹmu, ìlú tí a gbógun tì, ká aṣọ kúrò ní apá rẹ kí o sì sọ àsọtẹ́lẹ̀ sí i.
yii ko se dun lori bi ekunwo owo osu won se n fa bi igbin, egbe awon osise
BUSA 2019: Aisha Buhari ń hù ìwa ipá sí wa!
iroyin ati ikede, ogbeni Garba Shehu lo soro yii ninu atejade kan, ti o
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Joshua Beckford: Ọmọ ọdún mẹ́rìnlá kàwé gboye jáde ni Fasiti Oxford 29 Ògún 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 30 Ògún 2019 Àkọlé àwòrán, Ṣe ẹ ti gbọ́ ri?
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Àjẹ́, eégún, kí ni wọn ò pè mí tán tórí Vitiligo lára mi' O ni nigba ti awọn fi ọrọ wa Eze lẹnu wọ, o ni ọmọ naa funra rẹ, lo gba fun oun.
Eyi ribẹ lẹyin ti ajọ NCDC tun kede eniyan 649 to tun ṣẹṣẹ ni aarun naa.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Operation Velvet: Ilé ẹjọ́ alágbéèká bẹ̀rẹ̀ láti fìyà jẹ́ awakọ̀ tó bá r'úfin Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, #Adetutu Alabi OJ: Mo ti gba kámú lórí ilà ojú mi Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
O ni pe Hajar lọ sile iwosan lọ ri dokita rẹ nigba ti ẹjẹ n ya lara rẹ ni ko to di pe wọn fi ọwọ ofin muu pe o ṣẹyun lai ti i ṣe igbeyawo.
Ọkọ̀ akérò BRT gbiná lórí afárá 3rd Mainland Mi ò gbè lẹ́yìn Naira Mailey fún ìwà ìbàjẹ́- Daddyshowkey Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'A fẹ́ kí àwọn sẹ́nétọ̀ gba ẹlòmíì láàyè' Kini idi ti wọn fi fẹ fofin de lilo nylon ni Naijiria?
- Sanwo-Olu Ọtí tí wọ́n fi Sanitáísà àti Methanol pò pọ̀ ṣekú pá èèyàn 86 Láti 462 sí 386, àwọn tó ní àrùn Covid-19 já wálẹ̀ ní Nàìjíríà lọ́jọ́ Àbámẹ́ta Àlàyé rèé lóríi àjọṣepọ̀ tó wà láàrin èmi àti MC Oluomo - Ronke Oshodi Oke O ni oun mọọmọ paṣẹ fun awọn ẹṣọ oun lati maṣe fi ọwọ kan ẹnikẹni ni ni kete ti oun ri bi nnkan ṣe fẹ maa lọ nigba naa.
Igbimo so pe, won ti pinnu lati bura fun igbakeji aare Cyril Ramaphosa gege bi aare tuntun lorile-ede naa.
kì í ṣe pẹlu ìfẹ́kúfẹ̀ẹ́ ara bíi ti àwọn abọ̀rìṣà tí kò mọ Ọlọrun.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Idije ife ẹyẹ tilẹ Adulawọ laarin awọn agbabọọlu alafẹsẹgba ti bẹrẹ ni ana.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù John Onaiyekan: Ìtìjú ni fún mi láti rí àwọn ọmọbìnrin Nàìjíríà tó ń ṣe aṣẹ́wó ní Italy 6 Èbibi 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ọpọ awọn to n fi orilẹede Naijiria silẹ ni wọn wa lati agbegbe gusu ipinlẹ Edo Biṣọbu agba ijọ aguda nilu Abuja, ti ṣekilọ fun awọn adari orilẹede Naijiria pe awọn gan ni wọn n sọ orilẹede Naijiria di koṣeegbe fun ọpọlọpọ awọn ọdọ eyi to si n mu wọn maa tẹ ọkọ leti roke okun.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Yahoo Yahoo: Ọkùnrin kan rí ẹ̀wọn ọdún kan àbọ̀ he lẹ́yìn tó lu obìrin ní jìbìtì ìfẹ́ lórí ayélujára 10 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Oríṣun àwòrán, Succo Ile ẹjọ kan nipinlẹ Eko ti ran ọkunrin kan lẹwọn oṣu mejidinlogun lẹyin to jẹbi ẹsun lilu obinrin ni jibiti ifẹ lori ayelujara.
Yahaya Bello, Gomina ìpínlẹ̀ Kogi kéde Onoja ní ìgbákejì tuntun Ẹgbẹ́ òṣèlú AA kò gbọdọ̀ kópa nínú ìdìbò gómìnà ní Kogi, Bayelsa - Ilé ẹjọ́ Irọ́ ni pé wọ́n sèkọlù sí Gómìnà Seyi Makinde - Ọlọ́pàá Kogi INEC mo ko dé, ẹ̀rí rè é to ṣàfihàn èrú ìbò ní Kogi - Dino Melaye Àjọ INEC sún ìdìbò gómìnà ìpínlẹ̀ Kogi àti Bayelsa síwájú Oríṣun àwòrán, Inec Àkọlé àwòrán, INEC fun David Lyon to dije dupo gomina labe APC Bi ajọ eleto idibo INEC ṣe n fun Gomina Yahaya Bello ati Onoja igbakeji rẹ ni iwe ẹri o yege naa ni wọn n fun David Lyon ni Bayelsa.
“Ìwọ ọmọ eniyan, ààyè ìtẹ́ mi nìyí, ati ibi ìgbẹ́sẹ̀lé mi.
Awọn oluwadi naa tun fi kun un pe, o tun le sọ iru awọn ọmọ bẹẹ di ẹni ti yoo fi aisan l'ogba nigba ti wọn ba d'arugbo.
Nítorí a kò lè ṣe nǹkankan tí ó lòdì sí òtítọ́, àfi òtítọ́.
Ẹni tí ó bá ti kú, Ọlọrun pàápàá kì í tún gbé e dìde mọ́, ṣugbọn kabiyesi lè wá ọ̀nà, láti fi mú ẹni tí ó bá sá jáde kúrò ní ìlú pada wálé.
OLUWA bá yí afẹ́fẹ́ líle ìwọ̀ oòrùn pada, ó bá bẹ̀rẹ̀ sí fẹ́ àwọn eṣú náà lọ sí inú Òkun Pupa, ẹyọ eṣú kan ṣoṣo kò sì kù mọ́ ní gbogbo ilẹ̀ Ijipti.
ni yoo yọ arabinrin Zainab Habibu Aliyu kuro ninu atimọle ati ẹsun ti ko mọ idi
" ''Eyi kii ṣe ọrọ ofin rara.
Biden ti ni irs ni ẹsun naa ti ikọ olupolongo ibo rẹ si ti fi ọrọ sita pe: eyi ko ṣẹlẹ rara ati rara""."
Bótilẹ̀jẹ́pé àwọn èèyàn wa tí wọ́n fi ìlú Lọndọn ṣe ibùgbé pọ̀ bí ilẹ̀ bí ẹní, pàápàá ní agbègbè Hackney gan-an, àwọn ọmọ Yoòbá tó yọjú síbẹ̀ lè má ju mẹ́wàá lọ.
Asiwaju Tinubu ni iku wa ajọku, awẹ wa ajọgba ni ọrọ Oshiomole nitori ẹgbẹ lo yan an sipo to wa.
O ni idanwo ohun to maa buru jai ni ti ijọba ba le sun idanwo WAEC awọn ti ọdun 2021.
Ní àkókò yìí baba Pubiliusi ń ṣàìsàn: ibà ń ṣe é, ó sì ń ya ìgbẹ́-ọ̀rìn.
“Ní ọjọ́ náà, a kò ní dójútì yín nítorí ohun tí ẹ ṣe, tí ẹ dìtẹ̀ mọ́ mi; nítorí pé n óo yọ àwọn onigbeeraga kúrò láàrin yín, ẹ kò sì ní ṣoríkunkun sí mi mọ́ ní òkè mímọ́ mi.
 ile yi siwaju esin imale , besini gege bi asa islam , ile akoko nibe wa latowo abraham .
ohun tí a ti gbọ́ tí a sì ti mọ̀,ohun tí àwọn baba ńlá wa ti sọ fún wa.
Bákan náà, a gbo̩dò̩ rí àwo̩n ìgbésè̩ tí ó lè mú ìlo̩síwájú bá orílè̩‐èdè kan s̩os̩o tàbí àwo̩n orílè̩‐èdè sí ara wo̩n, kí a sì rí i pé a fi ò̩wò̩ tó jo̩jú wo̩ àwo̩n òfin wò̩nyí, kí àmúlò wo̩n sì jé̩ káríayé láàrin àwo̩n ènìyàn orílè̩‐èdè tó jé̩ o̩mo̩ Àjo̩‐ìsò̩kan àgbáyé fúnra wo̩n àti láàrin àwo̩n ènìyàn orílè̩‐èdè mìíràn tó wà lábé̩ às̩e̩ wo̩n.
Buhari yọ adájọ́ àgbà Onnoghen, PDP so ìpolongo ìbo rọ̀
Wọn ni Alaga Apapọ ati awọn ọmọ igbimọ oludari nikan lo lẹtọ lati pe iru ipade bẹ ẹ.
Gbogbo ìlú bú sẹ́kún bí àwọn eniyan náà ti ń lọ.
Iroyin sọ pe lati igba ti ọmọ rẹ Hanan ti ṣe igbeyawo, ni Aisha Buhari ti kuro ni Naijiria.
Eyi lo faa to fi jẹ pe oludije kan lee padanu ibo apapọ araalu jakejado orilẹ-ede naa ṣugbọn ko si di aarẹ bi o ba jẹ pe ida to pọ julọ laarin awọn igbimọ naa ni wọn dibo fun un.
O ni bi kaṣan to n gbe ẹjẹ ko ba lagbara to, ti ẹjẹ baa n gba inu rẹ lasiko ibalopọ, o le dipọ ti eyi yoo si ṣakoba fẹni naa.
Nígbà náà ni OLUWA wí fún Joṣua pé, “Fi akọ òkúta ṣe abẹ, kí o sì fi kọ ilà abẹ́ lẹẹkeji fún àwọn ọmọ Israẹli.
Ni bayi, atamatase agbaboolu afigigba omo orile-ede Serbia, Djokovic ti bere igbaradi ni kikun pada lati bi osu merin-in seyin ti o ti farapa, leyi ti o si se ise-abe lati fi pada bo sipo.
Bí atẹ́gùn bá fẹ́ wá láti gúsù, ẹ máa ń sọ pé, ‘Ooru yóo mú,’ Bẹ́ẹ̀ ni yóo sì rí.
“Nígbà tí ẹ gbọ́ ohùn láti inú òkùnkùn biribiri, tí iná sì ń jó lórí òkè, gbogbo àwọn olórí ẹ̀yà yín ati àwọn àgbààgbà wá sọ́dọ̀ mi; 
Wọ́n fi àwọn ọmọkunrin ati ọmọbinrin wọn rú ẹbọ sísun sí oriṣa, wọ́n ń ṣe àyẹ̀wò lọ́dọ̀ àwọn abókùúsọ̀rọ̀ ati àwọn alásọtẹ́lẹ̀, wọ́n sì fi ara wọn jì láti ṣe nǹkan tí ó burú lójú OLUWA, wọ́n sì fi bẹ́ẹ̀ rú ibinu rẹ̀ sókè.
2 1844 Orilẹede Maldives 47 9.
Arábìnrin lẹ̀dì àpò pọ̀ pẹ̀lú ọ̀rẹ́kùnrin rẹ̀ pé kó ó jí òun gbe, ọ̀rẹ́kùnrin gba 700k tán ló bá sálọ Wo oríṣìí oúnjẹ márùn ún tó lè dẹ́kun ikùn yíyọ àti ara àsanjù Rògbòdìyàn bẹ́ sílẹ̀ láàrin àwọn ọlọ́kadà àti àwọn òṣìṣẹ́ ọgbà ẹ̀wọ̀n ní Ibadan Wo àwọn oúnjẹ márùn ún tó ń mú kí àtọ̀ ọkùnrin dára síi Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Promise Akinlade: ọmọ ọdún mọ́kànlá tó ń fi ìlù dárà bíi àgbàlagbà sọ̀rọ̀ nípa tálẹ́ǹtì rẹ Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí SERAP ké sí ààrẹ Buhari lórí èròngbà àwọn NCC àti NIMC lórí ìforúkọsílẹ̀ NIN20 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Commonwealth scholarship 2020/2021: Wo ìlànà ìforúkọsílẹ̀ fún ẹ̀kọ́ ọ̀fẹ́ Ph.
Olori to n de ade laafin ko gbọdọ jẹ ọdalẹ,'' Oluwo lo sọ bẹẹ.
Nítorí dandan ni kí nǹkan wọnyi kọ́kọ́ ṣẹlẹ̀.
Akonimoogba agba iko agbaboolu Super Eagle, Gernot Rohr ti pe asole iko agbaboolu Enyimba, Theophilus Afelokhai lati ropo Francis Uzoho ti o fara pa lasiko ti o sole fun iko agbaboolu re nile okere.
" jẹ ́ díẹ ̀ lará èdè ènìyàn tí wón sì ní àwọn ìyàtọ ̀ wọn , nínú ohun tó ṣe kókó báyìí , fífún àwọn ọ ̀ rò aṣẹ ̀ dá ọ ̀ rọ ̀ asẹ ̀ dá bí ị Ọ ̀ pÒ "" Ø role ' , àwon ipò onítumọ ̀ gírámạ ̀ , abbl ."
Nígbà tí ó di ọ̀gànjọ́ òru, Boasi tají lójijì, bí ó ti yí ara pada, ó rí i pé obinrin kan sùn ní ibi ẹsẹ̀ òun.
Siasia tun ti wa kepe ijọba apapọ atawọn ẹlẹyinju aanu ọmọ Naijiria pe ki wọn ran oun lọwọ pẹlu owo ki oun le yọ orukọ oun ninu ẹsun jibiti ti wọn fi kan oun.
nipa ijiroro ti won n se pelu igbimo ijoba apapo .
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ọlọ́pàá Ondo: A ó ṣe àfihàn ọ̀rẹ́kùnrin Khadijat l'Ọjọ́rú 8 Agẹmo 2018 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 10 Agẹmo 2018 Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fọ́nrán ohùn, Àwọn ilé iṣẹ́ ọlọ́pàá Ìpínlẹ̀ Ondo sọ pé àwọn yóò ṣe àfihàn ọ̀rẹ́kùnrin Khadijat l'Ọjọ́rú.
Elomiran ni Oloye MKO Abiola ti ijọba gbe ẹsẹ le beba itẹwe to fẹ ko wọle lati oke okun fun Ileesẹ itẹwe iroyin rẹ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Police: Mo réèmọ̀ nígboro ayé, adigunjalè dìhámọ́ra lọ ja àgọ́ ọ́lọ́pàá lólè 19 Òkùdu 2020 Oríṣun àwòrán, Getty Images Bi ole ba ja eeyan lawujọ, ibi ti eeyan kọkọ n morile naa ni agọ ọlọpaa nitori pe ẹni to ba to nii gba lo yẹ ka fọrọ lọ.
 tí ó sì ń ṣiṣẹ ́ gẹ ́ gẹ ́ bí olùkọ ́ àti adarí fún ìpele àpilẹ ̀ kọ ́ eré orí ìtàgé eré oníṣe abáwùjọ mu ní agbọ ̀ n theatre arts ti ilé-ẹ ̀ kọ ́ gbogbo-nìṣe ti ìlú Ìbàdàn , níbi tí ó ti kọ ọ ̀ pọ ̀ lọpọ ̀ àpilẹ ̀ kọ fún ṣíṣe ní orí pẹpẹ , amóhùn-máwọ ́ rán , àti ọ ̀ pọ ̀ sinimá tó ti dàgbéléwò .
Nítori àwọn àtúgbẹ́yẹ̀wò, o níra láti ṣe àkójọpọ fún àwọn ọkọ́ naa Orisun: Johns Hopkins University atawọn ajọ eto ilera ilu Iye akọsilẹ to waye gbẹyin 7 Oṣù Ọ̀pẹ̀ 2020 14:22 WAT+3 Èèyàn 91 míràn tún ti ní àrùn Coronavirus ní Nàíjírìa Eeyan mọkanlelaadọrun miran ni ayẹwo tun ti fihan pe o ni arun Coronavirus bayii lorilẹede Naijiria.
GUINEA - Iwọ Oorun Afrika ni ilu yii wa ti ko nilo aṣẹ iwe igbelu, GUINEA BISSAU - Oṣu mẹta pere ni aigbawe aṣẹ ilu yii ti o si wa ni Iwọ Oorun Afrika.
Gomina to ń bọ̀ lọna ni Ipinlẹ Oyo, Seyi Makinde ní ẹru n ba oun lori bi Gomina Abiola Ajimobi ṣe n na owo lẹnu ọjọ mẹta yii.
Ọ̀pọ̀lọpọ̀ òkú ẹyẹ igún ré bọ́ lọ́jà Eke-Ihe Àrá sán pa màálù 23 l'Ekiti Maalu ko jẹ ki baalu balẹ l'Akurẹ Ilé ìwòsàn New Jersey ṣ'àṣìṣe ṣiṣẹ́ abẹ kìndìrín fún aláìṣàn l'Amẹrika Laipẹ yi ni ẹranko inu omi kan ti wọn n pe orukọ rẹ ni ''dugong'' ti kọkọ ku lataari idiwọ ti rọba to jẹ n ṣe fun un ninu ikun rẹ.
Community of West African States,)tun ni won tako iwa ifipagbajoba to kunna ni
" Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Funke Akindele jẹ àkàndá ẹ̀dá - Adaku Olatunji salaye pe: Mo kọ́kọ́ fẹ́ kọ láti bàa ṣiṣẹ́ àmọ́ ẹ̀mí mímọ́ sọ wípé kí n gba, tí ìtọ́ni sì wá fún mi lórí ohun tó yẹ ká ṣe láti mú àyípadà rere bá ayé rẹ.
re legbodo lasiko ti eto idibo n lo lowo ni ijoba Ibile Lagelu.
Òdodo yín yóo máa tàn níwájú yín.
“Èmi OLUWA àwọn ọmọ ogun, Ọlọrun Israẹli ní, ‘Bí mo ti bínú sí àwọn ará Jerusalẹmu, tí inú mi sì ń ru sí wọn, bẹ́ẹ̀ ni n óo bínú si yín nígbà tí ẹ bá dé Ijipti.
Nigeria governor's Forum: Kò sí Móṣáláṣí lórí ilẹ̀ náà, kòròfo ilẹ̀ lásán ni
Igba ta de inu yara naa, lawọn osisẹ civil defence ri pe o ti fa sokoto rẹ ya, o so mọ irin kan, to si ti pokunso ninu yara to wa."
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Akinwunmi Ambode: Ìsúná 2019 fi N1trn kéré sí ti 2018 5 Èrèlè 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 6 Èrèlè 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Adarí Ilé Asòfin, Modashiru Obasa ní inú òun dùn báyìí pé Gomina Ambode gbé àbá ìsúná 2019 sílẹ̀.
Ẹwẹ, ohun to mumu lookan aya ẹgbẹ Democrat bayii ni boya Harris yoo jẹ oluranlọwọ fun Biden lati jawe olubori.
Jọ̀wọ́ ṣọ́ra kí igi má baà gbá ọ lórí, kí igi má baà lù ọ́ ní ìpàkọ́, kí egungun orí rẹ má baà fọ́, ki ìmùdùnmúdùn orí rẹ má baà jáde, kí ìwọ má baà ṣe bẹ́l di èrò ọ̀run.
Bi orilẹede Naijiria se n sun'mọ asiko eto ipolongo idibo fun ọdun, orisirisi awọn ẹgbẹ oselu lo ti n jade lati polongo fun awọn eniyan lati kopa ti o peye ninu eto ijọba awarawa lorilẹede.
Professor Ayo Akinwale: Iṣẹ́ rẹ ń tọ̀ ọ́ lẹ́yìn
OLUWA, àwọn jàǹdùkú eniyan kó ara wọn jọláti pa mí lára, láìṣẹ̀, láìrò.
Ẹ wo àwọn gbajúmọ̀ òṣèré tíátà tó jogún eré ṣíṣe lọ́dọ̀ òbí wọn Owó gọbọi wá nídìí oko-owo igbó gbingbin, Ìpínlẹ̀ Ondo kò ní pẹ gba àṣẹ láti gbin - Akeredolu Èèyàn 195 míràn tún ti ní àrùn Coronavirus ní Nàíjírìa Òṣìṣẹ́ ààfin mi tí kò bá lo ìbòmú yóò pàdánù i'sẹ́ rẹ̀-Oluwo O ni toun ti pe aarẹ ni wọn yoo dẹwọ ofin konile o gbele ni Abuja,Eko ati ipiinlẹ Ogun,ileesẹ eto Eko ko ti le sọ ọjọ ti awọn ileeẹkọ yoo bẹrẹ pada jakejado Naijiria.
Tí a fiṣọwọ́ ní 10:14 29 Èbibi 201910:14 29 Èbibi 2019 Alaafin ilu Ọyọ de sibi iburawọle gomina Ọyọ BBCCopyright: BBC Ọba Lamidi Adeyẹmi Kẹta nibi ayẹyẹ iburawọle fun Seyi MakindeImage caption: Ọba Lamidi Adeyẹmi Kẹta nibi ayẹyẹ iburawọle fun Seyi Makinde Article share tools Facebook Twitter ṢàpínlòView more share options Share this post Copy this linkKà síwájú síi nípa àwọn ìtọ́kasí wọ̀nyí.
Jona bá jáde kúrò láàrin ìlú náà, ó sì lọ jókòó sí ìhà ìlà oòrùn ìlú náà.
OsunDecides: Adeleke kò jáwọn olólùfẹ́ tó fẹ́ wòran ijó rẹ̀ kulẹ̀
Buhari ba Aarẹ China yọ Àwọn òṣìṣẹ́ gbọ́dọ̀ jẹ aáyán fún ìjìyà ẹ̀ṣẹ̀ wọn À lágbára láti san gbogbo gbèsè tá jẹ Emir ilu Kano, Muhammad Sanusi ṣalaye pe idi ti oun fi fi oye da Zhang lọla ni pe o ni ipa rere laarin igba ti o lo ni ipinlẹ naa.
Gẹ́gẹ́ bí ọkan lára àwọn tórí kọ́yọ nínú ìṣẹ̀lẹ̀ náà ṣe sọ, Abatcha Umar àwọn okú tí òun rí kà tó mọkàndílogun tó fi mọ àbúrò òun nàá.
Amọ Michel ko gbagbọ, o tilẹ ba wọn jiyan wi pe ile iwosan Retreat Hospital ni wọn ti bi oun, nibi ti ko jina si ile iwosan ti wọn sọ wi pe wọn ti bii.
ni ipinle Oyo, ni eyi ti o si so  eso rere to si mu ki gbogbo gomina ekun Gusu
Awọn adari ile ẹkọ naa tẹsiwaju wi pe, ijọba ipinlẹ Ọyọ tun ti paa laṣẹ fun wọn lati maa ko awọn akẹkọọ naa si ita gbangba, fun bii ọgbọn iṣẹju.
" Ọjọ kọkanla, oṣu kẹjọ, ọdun 1960 ni Chad gba iyọnda lọwọ France to n mu wọn sin.
Àwọn àwo orin to ṣe jáde ko to jade laye ni Fatai Rolling Dollar Returns lọdun 2010 ati Better Life ni 2011.
Oríṣun àwòrán, ODSFA Àkọlé àwòrán, Ijọba ipinlẹ Ondo ni laipẹ loun yoo se agbekalẹ awọn igbimọ elere idaraya tuntun Nínú ọ̀rọ̀ rẹ̀, O wípé láìpé yìí làwọn yóò dà oniruuru ẹlẹgbẹjẹgbẹ ere idaraya tuntun sílẹ̀, tí yóò ri dájú wípé eré ìdárayá nidàgbàsókè nípínlẹ́ náà.
Eyi ni yoo jẹ ibẹẹrẹ abẹwo rẹ akọkọ si ilẹ Afirika nibi ti o ti n reti ati fi idi ajọṣepọ okoowo mulẹ lẹyin ti ilẹ Gẹẹsi ja ara rẹ kuro ninu ajọ ilẹ Yuroopu eleyi ti wọn n pe ni BREXIT.
Yuletide: Epo ò wọ́n sùgbọ́n ǹkan gbówó lórí Njẹ ẹ mọ pẹtẹsi akọkọ ni Naijiria?
Wọ́n mú wa lọ sọ́dọ̀ ẹni tí a óo dé sí ilé rẹ̀, Minasoni ará Kipru kan báyìí tí ó ti di onigbagbọ tipẹ́tipẹ́.
ó sì rọ̀jò ẹran sílẹ̀ fún wọn bí erùpẹ̀ ilẹ̀;àní, ẹyẹ abìyẹ́ bíi yanrìn etí òkun.
Tí ó bá wá bẹ̀rẹ̀ lọ́dọ̀ wa, báwo ni yóo ti rí fún àwọn tí kò gba ìyìn rere Ọlọrun gbọ́?
Oríṣun àwòrán, NGFSecretariat Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ìgbátí ìgbámú àná látọwọ́ sọ́jà obìnrin ti bá arákùnrin náà dé iléèwòsàn Oríṣun àwòrán, NGFSecretariat Bunmi Ogunkolade to jẹ olori ẹka iroyin ẹgbẹ oṣiṣẹ fẹyinti Nigerian Union of Pensioners ṣalaye si pe ''pupọ awọn ijọba ipinlẹ ni ko da si owo ifẹyinti oṣiṣẹ'' .
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ode/Isinigbo land Crisis: Ìjọba ìpínlẹ̀ Ondo kéde òfin konile-o-gbele ní Ode ati Ishinigbo 11 Ọ̀pẹ̀̀ 2020, 10:59 WAT Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn wákàtí 3 sẹ́yìn Oríṣun àwòrán, Paradisenews Ijọba ipinlẹ Ondo ti kede ofin konile-o-gbele oni wakati mẹrinlelogun ni ilu Ode ati Ishinigbo, to wa ni ijọba ibilẹ Ariwa Akure.
Aarẹ ọmọ ọdun mẹ́rìndínlọ́gọ́rin ni Naijiria dibo yan, Muhammadu Buhari si ni orukọ rẹ.
Igbimo ohun bowolu sise agbekale ile-iwe fafiti naa lasiko ipade apero awon torokan gbangban ti o waye lojoRU(Wednesday), eyi ti igbakeji aare omowe Yemi Osinbajo dari re.
Ẹ fi 'alarm' si ori ẹrọ ilewọ yin ti yoo ma ji yin ni wakati mẹta si ara wọn lati lọ ma a ṣe igbọnṣẹ tabi lọ tọ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù SARS Operation in Nigeria: Òṣèré tíátà ń fẹ́ kíjọba pa ẹ̀ka ọlọ́pàá tó ń gbógun ti ìdigunjalè jẹ́ 3 Owewe 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 29 Agẹmo 2020 Oríṣun àwòrán, Instagram/dayoamusa Gbajugbaja oṣere-binrin, Dayo Amusa, ti pe fun fifi òpin si ẹka ọlọpaa to n gbogun ti idigunjale, SARS.
Má ṣe àìnáání ẹ̀bùn tí Ẹ̀mí Mímọ́ fún ọ nípa àsọtẹ́lẹ̀ nígbà tí àwọn àgbà ìjọ gbé ọwọ́ lé ọ lórí.
8 % ) ati china ( 3.
Oríṣun àwòrán, PIUS UTOMI EKPEI/Getty Ipade wọn yii jẹ eleyi to lamilaka nitori oun lo se okunfa bi Dokita Adadevoh ti se di ilumọka gẹgẹ bi ẹni to kọdi itankalẹ aarun ebola ni orileede Naijiria.
 lóde òní , ewì ayaba ti ń wáyé nínú ayẹyẹ tó jẹ ́ ti ìdílé ọba .
Igbimọ igbẹjọ lori idibo Gomina ipinlẹ Eko ti fagile ẹjọ ti ẹgbẹ oṣelu Alliance for Democracy, AD ati Labour Party, LP gbe wa siwaju rẹ.
CAN: Ipenija aabo ni Naijiria n fẹ ẹjẹ tuntun lawọn ileeṣẹ alaabo
Ajọ WAEC ni esi idanwo naa ko ba ti jade tẹlẹ ṣugbọn rogbodiyan to ṣẹlẹ lẹyin ifẹhonuhan #EndSARS lo ṣe idiwọ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ethiopia: Bíi ti Zimbabwe, àdó olóró mìíràn bú ní Ethiopia 24 Òkùdu 2018 Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ikọ̀ BBC tó wà ní'bi ìwọ́de naa rí bó ṣe ṣẹlẹ̀ Àwọn alaṣẹ orilẹede Ethiopia ni eniyan meji ni o ku ti awọn ogunlọgọ si f'ara pa lẹyin ti ado oloro kan bu gbamu nibi iwọde fun olori orilẹede naa tuntun, Abiy Ahmed.
''Owo ti awọn ti ẹ wa sọ gọbọi.
Àwọn ọ̀nà tí obìnrin fi le gbádùn ìbálòpọ̀ Ọwọ́ tẹ Dókítà tó ṣe iṣẹ́ abẹ ìdí ńlá f'óbìnrin tó kú Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Oúnjẹ ibìkan jẹ́ èèwọ̀ ibòmíì ni ọ̀rọ̀ ọmú ńlá' Awọn gbajugbaja ilumọọka adanilaraya ni wọn saaba n ṣee ti o fi n di itẹwọgba kaakiri agbaye bayii.
Awọn ọmọ ile aṣofin to jẹ ọmọ ẹgbẹ Democrat ni, ipe ori ago naa eleyi ti eeyan kan tu asiri rẹ ṣe pataki, nitori o tan imọlẹ si bi aarẹ Trump ṣe n ṣe pẹlu awọn olori orileede miran.
Ẹ o ri i pe ijọba gan ko ja iyan rẹ."
Awon agbaboolu ohun so pe, iko Super Eagles gbodo tara giri, ki won si tun se awari ipo ti o fakoyo eyi ti won ba a bo tele, eleyi ti o mu iko ohun pegede fun idije agbaye naa, bi iko ohun ba fe de ipele ti o lapere ninu idije naa.
Coronavirus in Nigeria: Èèyàn 325 ló ti ní àrùn Coronavirus ní Naijiria báyìí Àkọlé àwòrán, Èèyàn 5 mííràn tún ti lùgbàdì ààrùn Coronavirus ní Naijiria Ènìyàn márùn míràn ni àyẹwò NCDC fi han pe o tu ti ni ààrun Coronavirus lórílẹ̀-èdè Naijiria bayii.
#Sima Sarkar 'Yorùbá gbà pé òrìṣà bí ìyá kò sí!
Wo fọ́tò àrà MC Oluomo, Pasuma àtàwọn òṣèré tíátà míì níbi ìṣílé Iyabo Ojo Wo àwọn òṣìṣẹ́ kólẹ̀-kódọ̀tí tó ń fi ẹ̀mí wọn wéwu kí Abuja leè mọ́ tónítóní Àwón Oníbúrẹ́dì ń gbé ìgbésẹ̀ láti fi kún owó Búrẹ̀dí ní Nàìjírià Wo ìyá ọlọ́mọ mẹ́ta tó ti pé ọdún 48 tó ń ṣe ìdánwò WAEC, kó le di nọ́ọ́sí Ṣaaju ni ọkan lara awọn ọmọ oṣere naa, Priscilla, ti kọkọ kede lori ayelujara pe iya oun ti di onile niluu Eko, eyii to mu ki ọpọ awọn eeyan kii ku ori ire.
fihan Iko gbabọọlu ti orile ede Tunisia pe , aba nikan n da, ti won si juwe ile
n óo kó àwọn àjèjì wá bá ọ; àwọn tí wọ́n burú jù ninu àwọn orílẹ̀-èdè, wọn óo sì gbógun tì ọ́, wọ́n yóo sì ba ẹwà ati ògo rẹ jẹ́, pẹlu ọgbọ́n rẹ.
Dokita Tedros wa ṣe ikilọ pe, ko si idaniloju kankan to fi idi rẹ mulẹ pe, ọwọja arun Coronavirus yii ko tun ni gbalẹ ni ẹẹkan si bi awọn orilẹ ede ba dẹ okun ofin konile o gbele.
Ṣugbọn gomina Ajimọbi ti wa fesi pada pe, oun to ba wu ẹlẹnu lo le fi ẹnu rẹ sọ, nitori pe, oun ṣi ni di ọjọ Kọkandinlọgbọn oṣu Karun-un ọdun 2019 lati ṣe ijọba.
O ni awọn agbofinro ikọ Operation Burst fẹ lọ doola eeyan kan tawọn ọmọ ẹgbẹ okunkun naa kan ji gbe ni wọn fi fija pẹẹta ti itaporogan ibọn si waye leyi to ṣeku pa Ebila tawọn miran si tun fara gbọta.
O Abiọla kú fún June 12 sùgbọn kìí ṣe òun nikan ló kú, ọ̀gágùn Sani Abacha náà kú ikú tó ya ni lẹ́nu ni June 8, 1998.
Ṣugbọn yóo ku ẹ̀yà kan sí ọwọ́ Solomoni, nítorí ti Dafidi, iranṣẹ òun, ati nítorí Jerusalẹmu, ìlú tí òun yàn fún ara òun ninu gbogbo ilẹ̀ Israẹli.
” Ṣugbọn ọkàn Farao le, kò sì fetí sí ọ̀rọ̀ wọn gẹ́gẹ́ bí OLUWA ti sọ tẹ́lẹ̀.
Ni ile iwosan ti wọn sare gbe e lọ lo ti gbẹmi mi.
Sani Zangon Daura: Minisita fun iṣẹ agbẹ ati idagbasoke igberiko laarin ọdun 1999 si 2000, ati Minisita fun ayika lọdun 2000 si 2001.
Ẹ fi ìṣoore fún àwọn onigbagbọ kún ìfọkànsìn, kí ẹ sì fi ìfẹ́ kún ìṣoore fún àwọn onigbagbọ.
Nkan ko daa to fun obinrin yii lasiko naa, to si ta ile kan soso to ni, ni ẹgbẹrun lọna ogun naira lọdun 1994, to si lọ ya ile gbe.
Akọ̀ròyìn Morocco, Hajar gbà ìdájọ́ ẹ̀wọ̀n lórí ẹ̀sùn àgbèrè àti pé o ṣẹ́yún 2.
Bí wọ́n ti tú àpò wọn, olukuluku bá owó rẹ̀ lẹ́nu àpò rẹ̀.
Nígbà tí yóo fi di oṣù keje, àwọn ọmọ Israẹli ti wà ní àwọn ìlú wọn.
Lọ́wọ́ àwọn ta ni àwọn ọba ayé ti ń gba owó-orí tabi owó-odè?
Wọ́n dá a lóhùn pé, “Dákẹ́, pa ẹnu rẹ mọ́, kí o sì tẹ̀lé wa, kí o jẹ́ baba ati alufaa fún wa.
Gomina ipinle Eko, Babajide Sanwo Olu fi orukọ awọn eniyan mẹẹdọgbọn ranṣẹ sile igbimọ aṣofin nipinlẹ Eko.
Ìbẹ̀rù OLUWA ni ìbẹ̀rẹ̀ ìmọ̀,ṣugbọn àwọn òmùgọ̀ a máa pẹ̀gàn ọgbọ́n ati ẹ̀kọ́.
Ooni Tadenikawo Adesoji Aderemi ni o jẹ Ooni ikọkandinlaadọta ni Ile Ife.
 “Ni gbagede naa, awon alejo yoo lanfaani lati ri orisirisi atejise awon ololufe iko agbaboolu orile-ede méjílélọ́gbọ̀n  ti o wa kopa fun idije naa.
Diẹ lara awọn ti kii ṣe ọmọ Yoruba ninu awọn oṣere naa ree: Faithia Williams: Oríṣun àwòrán, Faithia Williams Faithia Williams tawọn eeyan mọ si Faithia Balogun tẹlẹ ni oju rẹ wọpọ ninu ere tiata Yoruba.
Kí igi kọ̀ọ̀kan ní àtẹ̀bọ̀ meji, tí wọ́n tẹ̀ bọ inú ara wọn, bẹ́ẹ̀ ni kí o ṣe gbogbo àwọn igi tí wọ́n wà ninu àgọ́ náà.
Iléèṣẹ́ tẹlifísàn AIT, Arise TV àti Channels wọ gàù àjọ NBC nítorí ìpànìyàn Lekki Àṣírí tó ń bẹ láàrín Oluwo àtàwọn ọ̀dọ́ Iwo tí wọ́n fi fi ẹ̀mí wọn lélẹ̀ dáàbò bo ààfin rẹ̀ Olubadan ti Ibadan Oríṣun àwòrán, Olubadan/Guardian Lọjọ karun oṣu kẹta dun 2016 ni Olubadan to wa lori oye bayii, Oba Saliu Akanmu Olasupo Adetunji, Aje Oguguniso I gba ọpa aṣẹ.
Ó sọ fún wọn pé, “Ẹ múrasílẹ̀ di ọ̀tunla, ẹ má ṣe súnmọ́ obinrin láti bá a lòpọ̀.
Aaye atupa naa ni ori iru Telifiṣọn yii nigba naa Oríṣun àwòrán, @others Àkọlé àwòrán, Nọ́mbà 8: Nigba ti igba kan amohunmaworan yii, iyara awọn 'Big boys' lo ti wọpọ lọdun naa ti wọn fi n mu ọmọge!
Ajakalẹ arun Covid-19 ti baba fọwọ fa iṣẹlẹ ti wọn n fi ofin idibo to le ni irinwo yanju ẹ dani lawọn ipinlẹ mẹrinlelogoji.
Ipá ati agbára, pẹlu ibinu ńlá, ati ìrúnú gbígbóná ni n óo fi ba yín jà.
Ogbontarigi ayaworan ati olukọni iṣẹ ori-itage, Tunde Kelani ṣe idaro ọjọgbọn Akinwunmi Ishola ninu ifọrọwanilẹnuwo pẹlu ileeṣẹ BBC Yoruba.
Àkọlé àwòrán, Awọn eniyan parọwa si ijọba lati pesẹ agba ti awọn eeyan le ko ilẹ ati idọti si.
Ṣugbọn Jakọbu kò jẹ́ kí Bẹnjamini, arakunrin Josẹfu bá àwọn arakunrin rẹ̀ lọ, nítorí ẹ̀rù ń bà á kí nǹkankan má tún lọ ṣẹlẹ̀ sí òun náà.
NLC: Ìpàdé ọjọ́ Ajé ni yóò sọ bóyá á yansẹ́ lódì
ati gbogbo agbègbè Araba ní apá ìlà oòrùn odò Jọdani títí dé Òkun Araba, tí à ń pè ní Òkun Iyọ̀, tí ó wà ní gẹ̀rẹ́gẹ̀rẹ́ òkè Pisiga.
Aarẹ Trump yọ Rex Tillerson kuro nipo
Adesina so pe “ Aare Buhari ti se gudugudu meje ,yaya mefa lati mu idagbasoke ba eto oro aje ati ohun amayedun lorile ede yii.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Amotekun: Ẹgbẹ́ fijilanté pariwo síta lórí ìlànà ìgbanisíṣẹ́ ikọ̀ Amotekun ní ìpínlẹ̀ Oyo 5 Ògún 2020 Oríṣun àwòrán, Western Nigeria security network Adari ẹka abo oju lalakan fi n ṣọri ni Naijiria, Vigilante Group of Nigeria, VGN, ẹka ti ipinlẹ Ọyọ, Ọgbẹni Ọladeji Olowolafẹ ti ke gbajare sita lori eto abo ẹkun iwọ orun gusu orilẹede Naijiria ti a mọ si Amọtẹkun.
Ọga akọrin RCCG : Fẹla lo ṣe iwuri fun mi Adari Ijo RCCG naa wa rọ gbogbo ọmọ orilẹ-ede Naijiria lati gba kaadi idibo wọn ki wọn le se ojuse wọn ninu idibo gbogboogbo ti yoo waye ni Osu Keji, ọdun to n bọ.
“Ní ọdún keje-keje ni kí ẹ máa ṣe ìdásílẹ̀.
Nibayii wọn ti gbe oku rẹ lọ si ile iwosan Adeọyọ niluu Ibadan fun ayẹwo ohun ti o ṣokunfa iku rẹ.
Kogi Coronavirus Status: Kìí ṣe ààrùn Covid-19 ló pa adájọ́ àgba ìpínlẹ̀ Kogi-Kọmísọ́nà ìlera
Wọ́n ń bá ara wọn sọ pé, “Bí a bá sọ pé, ‘Láti ọ̀run ni,’ yóo bi wá pé, ‘Kí ló dé tí ẹ kò fi gbà á gbọ́?
Bi awọn kan ṣe lero pe oyẹ ki awọn ọmọ Naijiria ma san owo 'Toll gate' yii, awọn miran ni asiko ko ti to fun owo oju opopona.
Nigba ti BBC Yoruba kan si alaga ẹgbẹ oṣelu PDP nipinlẹ Ọyọ Alhaji Yemi Mustapha, o jẹ ko di mimọ lodi si awọn iroyin mii to sọ pe olori ọdọ ẹgbẹ lo ku pe irọ ni.
Jakọbu bá fa aṣọ rẹ̀ ya láti fi ìbànújẹ́ rẹ̀ hàn, ó fi aṣọ ọ̀fọ̀ bora, ó sì ṣọ̀fọ̀ ọmọ rẹ̀ fún ọpọlọpọ ọjọ́.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fọ́nrán ohùn, Fásitì OAU ní ohùn ọ̀jọ̀gbọ́n Richard Akindele ni wọ́n ká sílẹ̀ Agbẹjọro Ọjọgbọn Akindele, Francis Omotosho ni ki adajọ fi oju aanu wo ọjọgbọn naa ṣugbọn adajọ kọ jalẹ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Certificate Forgery: Ọmọ oyè yí ìwé ẹ̀rí láti dupò Oluwoye ti ilú Iwoye 26 Èrèlè 2020 Oríṣun àwòrán, other Àkọlé àwòrán, Certificate Forgery: Ọmọ oye ìwé ẹri láti dupo Oluwoye ti ilú Iwoye Ilé iṣẹ́ ọlọpàá nipinlẹ Ogun ti fi ọwọ òfin mu ọmọ oye kan to n dupo ọba to si ṣilẹ̀ ni Iwoye, Ilaro nijọba ibilẹ Yewa South ìpínlẹ̀ Ogun lori lilo ìwé ẹri ayederu.
''Aláàfin kìí ṣe ọkùnrin tí wàá jẹ lásán, tó sì wá sálọ - Aráàlú fèsì fún Olorì Anu Ọ̀dọ́mọdé olówó, ẹni ọdún 36 sọ̀rọ̀ sílẹ̀ pé aṣọ funfun ni kí wọn fi sìnkú òun Ta ni olóògbé Jerry Rawlings, tí wọ́n fún ní àlàjẹ́ 'Junior Jesus' Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Gbọ́, Idanre kings: Ọba Aroloye ko rán ẹnikẹ́ni si Temilolu, awọn ọ̀dọ́ ìlú ló ń bínú11 Bélú 2020 EndSARS Protest Updates: Feminist Coalition sọ fáwọn ọ̀dọ́ láti fòpin sí ìwọ́de23 Ọ̀wàrà 2020 US presidential election 2020: Kíni Kọ́lẹ̀jì ìdìbò, àwọn ìpińlẹ̀ tó le gbé olùdíje wọlé àti àwọn ǹkan ti o yé kí o mọ̀ nípa ìdìbò ilẹ̀ Amerika.
Ògo ilẹ̀ Ibadan míì lọ, Pàràkòyí Olóyè Bode Akindele dágbére fáyé Ìjọba àpapọ̀ fẹ́ f'òfin dé irina ọkọ̀ akero jakejado Nàìjíríà Ibi ọ̀rọ̀ dé dúró lórí ṣíṣí àwọn ilé ìwé padà ní Naijira rèé àti nílẹ̀ Afrika Kìí ṣe ààrùn Covid-19 ló pa adájọ́ àgba ìpínlẹ̀ Kogi-Kọmísọ́nà ìlera Boss sọ pe idẹwọ isede yi yoo waye fun oṣu mẹrin pẹlu iyipada diẹ si eyi to wa nilẹ tẹlẹ.
Gẹgẹ bi iroyin to tẹwa lọwọ, ile mọkandinlogun ni yoo fara gba ninu igbesẹ yi lara awọn ile ogoje ti wọn ti fagile pe awọn yoo wo.
Ègbé ni fún wọn,nítorí pé àwọn ni wọ́n mú ibi wá sórí ara wọn.
    Àti ọjọ́ yìí ni ọmọ náà ti máa ń wa kí bàbá rẹ̀ ti o n ṣe bí ọba tí inú bàbá rẹ̀ sì ń dùn, ṣùgbọ́n ibi ti o tì ń wá ṣókùnkùn lójú ẹnikẹ́ni.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Babangida si Buhari: bọọlẹ k'awọn ewe bọ sipo Ẹ̀mí márùń bá ìjà àwọn jàǹdùkú lọ ní Ìjẹ̀bu A kò fẹ́ bàbá àgbà mọ́ nípò ààrẹ - Fayose Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
A mọ ìgbátí yíká òkè àwọn ìtẹ́lẹ̀ náà, tí ó ga sókè ní ààbọ̀ igbọnwọ, ìgbátí yìí wà ní téńté orí àwọn ìtẹ́lẹ̀ náà.
"Loju opo Twitter ajọ naa ni wọn ti kede eyii lalẹ ọjọ Aje pe ""Ni ọjọ kọkanlelọgbọn oṣu kẹjọ ọdun 2020, eeyan mẹtalelogoje lo tun ṣẹṣẹ ko aarun naa ṣugbọn ko si akọsilẹ iku kankan lorilẹede Naijiria."
Tottenham na awọn ọmọlẹyin Jose Mourinho pẹlu ami ayo meji si odo ni papa isere Wembley, bẹẹni awọn ikọ agbabọọlu Bournemonth fi'ya jẹ Chelsea pẹlu ami ayo mẹta si odo ni papa isere Standford Bridge.
Awọn ọlọpaa ti gbé ìgbésẹ lẹyìn tí àwọn fidio tí o ṣafihàn bíi wọn ṣe n fí igbanu da seriya fun oṣiṣẹ náà tí o sí tún n mu omi tó jọ ito jade.
 smith ti je yiyan fun ebun golden globe marun ati ebun akademi meji , be sini o ti gba ebun grammy merin .
Nibẹ ni a ti ri Deji Adenuga ti awọn agbofinro n gbe lọ sile ẹjọ fún pe o dáná sun ọmọ meje ati iyawo rẹ ati ọkọ ẹgbọn iyawo rẹ mọle.
Olori ijoba orile-ede Ethiopia titun ti daruko igbimo amusese re ninu eyi ti mefa ninu won je omo igbimo amusese teleri ,ti merindinlogun si je awon ti won seese bo  sipo.
ṣugbọn ní tiwa, àwa ń waasu Kristi tí wọ́n kàn mọ́ agbelebu.
Ní Kaduna, wọ́n ti sin ọmọógun11 tí àwọn ọ́lọ́ṣà pa
Aṣọ títa ti iwájú àgọ́ náà, ní apá ìlà oòrùn gùn ní ìwọ̀n aadọta igbọnwọ.
N sẹ ní Jesse Duplantis ya foto lẹgbẹ awọn bàálù to ti ra tẹlé.
Nítorí pé èròńgbà Akọ̀ròyìn obìnrin yẹn ni láti wo bí wọ́n ṣe ń tọ́jú owó bí wọ́n bá gbé ọkọ̀, a nílò láti bá aṣojú iléeṣẹ́ tó ń ṣètò ìrìnnà-papọ̀-wa-ọkọ̀-kí-n-wa-ọkọ̀ kan sọ̀rọ̀ (bẹ́ẹ̀ ni, nítorí àlàkalẹ̀ ètò náà ni, kì í ṣe nítorí àìfẹ́dọ̀ọ́gba akọ àtabo, ó ní láti jẹ́ ọkùnrin).
    Àwọn ọkùnrin mẹ́ta kan wà orúkọ ẹnì kín-ín-ní a máa jẹ́ Owólayémọ̀, orúkọ ẹ̀kejì ni Afẹ́ayé, ẹ̀kẹta sì ni ọ̀kánjúwàfẹ̀yìntì.
Obìnrin to n sọ ede Yoruba bii ẹni layin naa si lo ti gba ami ẹyẹ lọpọlọpọ lori sinima to ṣe ni ede Yoruba.
"Ninu fidio kan to ṣafihan awọn ẹgbọn iyawo, Damilola ati Joshua , to sọrọ nipa bi aburo wọn ṣe fi to wọn leti pe Lawrence dẹnu ifẹ kọ oun, awọn mejeeji sọ pe ""iṣẹ iranṣẹ orin kikọ ni Lawrence wa a ṣe lọdọ wọn, lo gba ibẹ dẹnu ifẹ kọ Darasimi""."
Won yoo sun oku re, won yoo si fon idaji eeru re ka sori odo ni Danish ti won yoo si fon idaji to ku ka si oko etile ni aafin Fredensborg gege bi o se fe ni ariwa Copenhagen to ku si.
Lórí òrùlé nìkan, àwọn tí wọ́n wà níbẹ̀ tó ẹgbẹẹdogun (3,000) eniyan, lọkunrin ati lobinrin tí wọn ń wo Samsoni níbi tí ó ti ń dá wọn lára yá.
 O ni, ijoba yoo ri daju lati mo ohun ti o sokunfa ibugbamu naa.
Ọba ilẹ̀ Yorùbá ni olùṣàkóso gbogbowọn, tí wọ́n sì nsan ìsákọ́lẹ̀ fún àwọn Ọba olókìkí náà.
Ẹ wo àwọn gbajúmọ̀ òṣèré tíátà tó jogún eré ṣíṣe lọ́dọ̀ òbí wọn Ààrẹ Buhari yan Ibrahim Gambari gẹ́gẹ́ bíi olórí àwọn òṣìṣẹ́ lọ́fíìsì Ààrẹ Mo bí ìyá mi padà lẹ́yìn tó yọ sí mi lójú oorun- Iya Yetunde Àrà méèrírí, ọkùnrin kan ń fi ìyarun fọn fèrè tó ń dún bíi gìtá Àwọn alárùn coronavirus ṣe ìwọ́de ní Gombe, wọ́n ní ìjọba n febi pa wọ́n Aláàfin gbé àṣẹ kalẹ̀ láti dènà àtúnṣẹ̀ ìṣẹ̀lẹ̀ 'Soka'nílùú Ọ̀yọ̀ Muka Ray wa rọ ijọba Naijiria lati maa seto iranwọ, nipa amulo awọn dukia ijọba pẹlu owoya, fun awọn oṣere tiata, eyi ti yoo mu ko rọrun fun wọn lati ṣe eré to ni èrè, ti yoo si pawo gidi wọle fun ijọba.
Wo ìdí tí àwọn obìnrin kan fi n yọ ilé ọmọ wọn kúrò Iwadii ti Thomas Crowther atawọn ẹgbẹ rẹ ṣe yii lo jẹ ki a mọ pe o le ni ida ọgọta igi ti wọn jọ n ni ibaṣepọ pẹlu ara wọn ninu igbo.
Aba naa ti olori ọmọ ẹgbẹ to pọju lọ nile Faruq Musa Dosara ṣe agbekalẹ rẹ ni o sọ pe yoo dina owo to to ẹẹdẹgbẹrin miliọnu tawọn Gomina n gba lasiko tara ilu n kerora.
Boko Haram n fipá bá mi lòpò ní òpò ìgbà léyìn tí wọn kọlu ìlú wa- Omọbinrin náà
Ó mẹ́nu bàa pé Auxiliary gan fúnra rẹ̀ ló wá sí àdúgbò náà, láti wá mojuto bí àwọn ọmọlẹ́yìn rẹ̀ ṣe ń ṣe àwọn ọlọkada tí kò sanwó ojúmọ́ bí ọṣẹ ti ń ṣe ojú.
Ṣugbọn yatọ fun eyi, aimọye ọrọ mii to wa nilẹ to pọ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Nigeria Army: Bàbá Adamu tó jẹ́ ọmọ ogun Nàìjíríà tó dàgbà jùlọ jáláìsí 2 Sẹ́rẹ́ 2020 Oríṣun àwòrán, @Nig Army Àkọlé àwòrán, Bàbá Adamu tó jẹ́ ọmọ ogun Nàìjíríà tó dàgbà jùlọ jáláìsí Lọdun 1918 ni wọn bi Adama Aduku labule Abejukolo-Ife ni ijọba ibilẹ Omaha ni ipinlẹ Kogi ni aarin gbungubn Naijiria.
Kí ni ohun tí ẹ dá ní, tí kò jẹ́ pé ọwọ́ Ọlọrun ni ẹ ti rí i gbà?
O kan saara si iṣejọba Trump pe o ṣe nkan sọrọ awọn ileeṣẹ to n pese rọba idaabobo atawọn to n ṣẹ oyun lawọn orilẹede Afirika.
Hesekaya gba ìwé náà lọ́wọ́ àwọn ikọ̀ ọba Asiria, ó kà á.
Eruku sọ lálá níbi ayẹyẹ ìgbéyàwó Lizzy Anjorin, àwòrán àti fídíò nìyíì Orin ìsìn ọjọ́ ìbí àṣẹ̀yìndè Ibidunni Ighodalo yóò wáyé, Tope Alabi, Kenolly àtàwọn míì tí yóò kọrin níbẹ̀ rèé Wo bí ètò ìsìnkú Tolulope Arotilẹ yóò ṣe lọ nílùú Abuja lọ́sẹ̀ tó ń bọ̀ Nínú èèyàn 600 tó ní coronavirus lọ́jọ́ Ẹtì, 275 ló wá láti agbègbè ilẹ̀ Yorùbá Iṣẹ ọhun ni wọn gbe fun ileeṣẹ agbaṣẹṣe ilẹ China, CCECC lasiko iṣejọba ọmọwe Goodluck Jonathan.
Mo ri ọ̀pọ̀lọpọ̀ ìjàpá ṣùgbọ́n n kò rí àwọn ìgbìn jù bẹ́ẹ̀ lọ, inú sì ń bí mi nítorí ìgbín tóbi ju ìjàpá nínú Igbó Olódùmarè ṣùgbọ́n àwọn ìjàpá ibẹ̀ kéré ju irú ìjàpá tí a máa ń rí lọ.
Àwọn lọ́ba lọ́ba kò gbẹ́yìn níbi ìdíje náà nítórí wọ́n lòdì sí ìparun èdè Yorùbá.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù George Floyd: Àwọn ọlọ́pàá darapọ̀ mọ́ àwọn olùwọ́de lórílẹ̀èdè Amẹ́ríkà Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ George Floyd: Àwọn ọlọ́pàá darapọ̀ mọ́ àwọn olùwọ́de lórílẹ̀èdè Amẹ́ríkà 2 Òkùdu 2020 Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí 3 sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
Ìgbà tí a bá sì wò bí ojú Yorùbá ti là tó kí Gẹ̀ẹ́sì tilẹ̀ tó gòkè, tí ó sì jẹ́ pé kò sí ẹ̀yà kan ní nàìjíríà tí ó lè wí pé òun lajú ju Yorùbá lọ títí di òní olónìí, ẹ ó ríi pé bí a bá lè mú irú àbàwọ́n báyìí kúrò lára wa ìlọsíwájú wa yóò máa ya gbogbo ara ayé lẹ́nu ni.
Sola Ibidokun to jẹ obi fun awọn omo ile iwe lo sọ bẹẹ fun BBC Yoruba.
OLUWA àwọn ọmọ ogun ní ibi yóo máa ṣẹlẹ̀ láti orílẹ̀-èdè kan dé ekeji, ìjì ńlá yóo sì jà láti òpin ayé wá.
Wọn ni ninu awọn tawọn ri, awọn ọlọpaa ati ọmọ ogun wa ninu wọn.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Awọn ọdọ agbebọn lẹkun naa ti kọkọ bẹrẹ ikọlu awọn ibudo ipọnpo lẹkun naa ki alaafia ranpẹ to jọba Ajọ naa ni ko si ootọ ninu ariwo ti ileesẹ ipọnpo Shell ati Eni n pa pe gbogbo ipa awọn lawọn n sa lati rii wi pe epo rọbi ko fọnka kiri lagbegbe naa ati pe fun ọpọlọpọ osu ni wọn kii fi da si ipe lori ifọnka epo rọbi lagbegbe naa.
Ajọ to n mojuto iṣẹlẹ pajawiri nipinlẹ Eko LASEMA ni awsn ti gbe gbogbo igbesẹ to yẹ ni gbigbe lati dẹkun wahala to le fẹ sọ nibẹ.
APC kẹ̀yìn sí ìdájọ́ ilé ẹjọ, Ó ní ẹjọ́ kòtẹ́milọ́rùn ló kan Ẹwẹ, Ẹgbẹ oṣelu APC ti kede wi pe idajọ ti ile ẹjọ gbe kalẹ, eyi to kede Sẹnetọ Ademọla Adeleke gẹgẹ bii gomina ti ilu dibo yan nipinlẹ Ọṣun, ko ni pẹ jẹ rodo lọ ree mu omi nitori pe awọn n gba ile ẹjọ lọ.
 Bẹẹ bi ọmọ ko ba ba itan, o di dandan ko ba arọba to jẹ baba itan.
Kí irú ẹni tí ń gbọ́ ọ̀rọ̀ majẹmu má baà dá ara rẹ̀ lọ́kàn le pé ‘Kò séwu, bí mo bá fẹ́ mo lè ṣe orí kunkun kí n sì máa tẹ̀lé ìmọ̀ ara mi.
Ìyìn rere yìí ti dé ọ̀dọ̀ yín gẹ́gẹ́ bí ó ti dé ọ̀dọ̀ gbogbo aráyé, ó ń so èso, ó sì ń dàgbà.
 Gege bi awa, ti oro naa kan gbongbon, okan gbogi lara ojuse wa ni lati ri daju pe aabo ti o peye ati iranlowo wa ni irowoto awon omode ti o ba fara kaasa ifipabanilopo.
"Adebanjo ni ""Obasanjo fún ra rẹ lo mu ọjọ toun ati Gani yoo wa lati wa pari aawọ to wa laarin wọn, awọn mejeeji si wa lati yanju ọrọ naa"" Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ọ̀pọ̀ nkan tó n ṣẹlẹ̀ kò jẹ́ kí n gbàgbọ́ pé Naijiria wà ní abẹ́ ìdarí ẹnikẹ́ni - Wole Soyinka Ọmọ ẹgbẹ́ òkùnkùn ṣoro ní Ijebu Ode, ọ̀pọ̀ ẹ̀mí sọnù Àlàyé rèé lórí ìdí tí mo fi lọ sílé Tinubu - Rashidi Ladoja ‘Sim Card’ títà àti ìforúkọsílẹ̀ rẹ̀ dèèwọ̀ ní Nàíjíríà - NCC Ààrẹ Akufo-Addo la Mahama mọ́lẹ̀ wọlé ìbò ààrẹ Ghana fún sáà kejì Ẹ̀yin tí ẹ máa ń bú àwon tó sanra ni ẹ ń jẹ́ kí wọ́n ronú pa ara wọn - Eniola Badmus Ṣé lóòtọ́ ni tírélà ti gba ààrín Ronke Odusanya àti bàbá ọmọ rẹ̀, Jago?"
ninu idije Afcon 2019 to n waye ni  orile
Gbogbo àwọn ọ̀tá rẹ ń fi ọ́ ṣẹ̀sín,wọ́n ń pòṣé,wọ́n ń fi ọ́ ṣe ẹlẹ́yà.
"Ọkan lara awọn baba awọn ti wọn fipabalopọ sọ pe ""mo funpe si ijọba ki wọn jọwọ bojuto iṣẹlẹ naa ki wọn si ri i daju pe awọn to ba rufin foju wina ofin niruu iṣẹlẹ bẹẹ ki ijọba si rii pe wọn gbe igbesẹ kiakia."
 ) ( he fortified the wine with alcohol .
Ẹmẹrin ọtọọtọ ni wọn ri ijọba gba, ti awọn ologun ba ri ijọba Omar al-Bashir gba de lẹ, yoo di igba karun un ti ologun ri ijọba gba lorilẹede Sudan.
Òwìwí mu àbẹ̀tẹ́lẹ̀ wá, o ní kí a bá òun ṣe e, ìgbà tí a bá ṣẹ́gun àwọn tán òun kò fẹ́ kí àdán bá òun rìn ní òru mọ́.
Iye awọn eeyan to ṣẹṣẹ ko arun naa ni ipinlẹ kọọkan ree: Eko-195 FCT-50 Kano-42 Kaduna-27 Edo-26 Oyo-22 Imo-21 Gombe-17 Benue-12 Enugu-12 Delta-11 Anambra-11 Ebonyi-10 Nasarawa-9 Ogun-9 Bauchi-8 Kebbi-4 Akwa Ibom-3 Jigawa-3 Katsina-3 Yobe-2 Borno-2 Kwara-1 Ondo-1 Èèyàn 627 ló lùgbàdì àrùn Coronavirus ní Naijiria ní Ọjọ́ Ẹtì Eeyan 627 tuntun mii lo ṣẹṣẹ lugbadi aarun Coronavirus ni Naijiria.
Adajo teleri lorile ede Najiria, Alfa Blegore wa gbosuba fun aare nipa  bi o se n dari oko orile ede yii, o wa ro aare lati tesiwaju ninu iyanju re lati mu orile ede yii de ile –ileri.
Deede aago mẹsan aarọ lawọn dokita ti oju wọn ko rẹrin naa ti pejọ sibẹ, ti wọn si gbe oniruuru akọle lọwọ, ninu eyi ti wọn kọ awọn ohun to n jẹ wọn lọkan si.
Ninu ọrọ to fi si oju opo Instagram rẹ lọjọ Abamẹta, Bobrisky ni o wu oun lati ṣe ju bẹẹ lọ sugbọn agbara ku diẹ kaa to fun oun.
Ó sọ fún ìyá rẹ̀ pé, “Wọ́n gbé ẹẹdẹgbẹfa (1,100) owó fadaka mọ́ ọ lọ́wọ́ nígbà kan, mo sì gbọ́ tí ò ń gbé ẹni tí ó gbé owó náà ṣépè, ọwọ́ mi ni owó náà wà, èmi ni mo gbé e.
Ko si si ayipada gboogi kankan lati igba naa.
Ara bíbó èrè wo ni àwọn eeyan n rí níbẹ̀?
Gbogbo àwọn tí wọ́n bá Jakọbu lọ sí Ijipti, tí wọ́n jẹ́ ọmọ tabi ọmọ ọmọ rẹ̀ jẹ́ mẹrindinlaadọrin, láìka àwọn iyawo àwọn ọmọ rẹ̀.
Ile iwosan naa kọ lati fi orukọ awọn mejeeji sita.
O tun wa jẹ igbakeji Adjutant-General ti olu ile iṣẹ First Infantry Division lati 1971 si 1972.
Àti baálé àti baálẹ̀ ni wọ́n nyọ̀mọ́ ọn.
Irú olórí alufaa bẹ́ẹ̀ ni ó yẹ wá.
18 Sẹ́rẹ́ 2020 Oríṣun àwòrán, davido/twitter Ariwo ta ni owurọ ọjọ Abamẹta lori ayelujara nigba ti awọn eeyan bẹrẹ si ni gba a bi ẹni n gba igba ọti pe gbajugbaja akọrin takasufe, Davido ati iyawo rẹ ti kẹyin sira wọn lori ikanni Instagram.
Ní bayìí ilé iṣẹ́ ọlọpàá ti kó ọmọ ijọ méje àti àwọn ènìyàn mẹ́wàá mìíràn ti wọ́n ba níbi ti wọ́n ti n kó àwọn nkan to jóná kù.
Serena Williams s'ọrọ yii ninu ifọrọwerọ kan pẹlu BBC.
Àǹkóò àrùn coronavirus dé orílẹ̀èdè Togo Coronavirus ti di àjàkálẹ̀ àrùn káàkiri àgbáyé- WHO Àlárùn Coronavirus di 7000 lágbàyéé, ìjọba Nàíjíríà kọjú oro sí ọjà China tó jẹ́ ẹbu Èyí ni ohun tí a mọ̀ nípa afurasí aláàrùn coronavirus nípìnlẹ̀ Enugu Nàìjíríà bèèrè ìrànwó lọ́wọ́ àjọ àgbáyé láti kápá Coronavirus Minisita fun eto ilera l'orilẹ-ede Turkey, sọ pe yara ọtọọtọ ni wọn fi ẹnikọọkan wọn si fun iyasọtọ, ni ankara ati ni ẹkun Konya to wa ni tosi.
Oṣu Kẹjọ, ọdun 2020 ni iroyin nipa igbeyawo rẹ pẹlu Alaafin jade sita, bo tilẹ jẹ pe o ti n gbe ni aafin tipẹ, to si ti bi ọmọkunrin kan fun baba.
Vice Presidential Debate: Osinbajo,Peter Obi ko yọju Buhari ba osinbajo sayẹyẹ igbeyawo ọmọ rẹ Day 23: Ikẹnnẹ ṣááju àti lẹ́yìn ìwọlé Ọṣinbajo sípò #BBCNigeria2019 Ààrẹ ní kí wọ́n wádìí oun tó fa ìjàmbá bààlú Osinbajo ‘A ó ran àwọn tó lùgbàdì omíyalé ìpínlẹ̀ Kogi lọ́wọ́’ O ni awọn oloṣelu ti wọn jẹ ọ̀jẹ̀lù yii ti ba owo Naijiria jẹ debi pe o ti àkísà lawujọ owó ni agbaye àti pe ọpọ ẹmi ati dukia lo n sọnu nigba ti ijọba ko gbe awọn igbese to yẹ ni gbigbe fun ilọsiwaju.
Ṣugbọn lọdọ obinrin adajọ Sharia akọkọ lorilẹ-ede Malaysia ọrọ yii ko ri bẹẹ.
Nígbà tí Aṣojú-Olódùmarè padà dé òde ayé, ó lu agogo káàkiri òde, wwí pé kí olúkúlùkù wáá pàdé òun.
Ṣewadii nipa ọkọ ati ile itura ti o fẹ de si: O ṣe Pataki ki o ṣewadii ibi ti o ma a desi ati iru ọkọ ti o fẹ wọ ni asiko irinajo rẹ.
Bẹrẹ lati ori baba rẹ, Ayoola Adeleke, to jẹ Sẹnẹtọ ni saa isejọba oselu ẹlẹkeji, ẹgbọn rẹ naa, Isiaka Adetunji Adeleke, ti ọpọ eeyan mọ si ''Sẹrubawọn'' jẹ Gomina akọkọ lẹyin ti wọn da ipinlẹ Osun silẹ.
Àjọ NCDC kéde ènìyàn 195 míràn tó ní ààrùn Covid-19 l'órílẹ̀-èdè Nàìjíríà Àwọn ọmọ Nàìjíríà 256 tó há sí ìlú Dubai ti gúnlẹ̀ sí Nàìjíríà Auxiliary ń ní wá lára pẹ̀lú gbígba owó aitọ, a ń ko ọkọ̀ wa kúrò lójú pópó - Awakọ èrò Ayẹwò kò dáwọ́ dúro botílẹ̀ jẹ́ pé èròjà ayẹwò (Reagents) kò si mọ́ Ọgbẹni Musa Lawan, oludari agba ileeṣẹ to n ri si idunadura epo lorilẹede Naijiria, PPMC, ti atẹjade naa kede o fi ọrọ naa sita nio igbesẹ adinku owo epo lawọn ibudo ijapo gbogbo naa yoo mu ki wọn lee tete ta omilẹgbẹ biliọnu jala epo ti waọn ni kaakiri aka wọn sita lowo ti ko ga ju ara rọ fawọn onibara rẹ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Small Doctor: Mi ò fi igbò tàbí sìgá kọrin rí Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Small Doctor: Mi ò fi igbò tàbí sìgá kọrin rí 17 Agẹmo 2018 Ní ìgbà tí ó bẹ̀rẹ̀ orin kíkọ, Small Doctor jk kó di mímọ̀ pé kò dẹrùn.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù BBNaija: Kayọde Ogundamisi ní akọ́nilọ́gbọ́n, amúlùúdùn ni BBNaija, kìí ṣe òṣèlú 7 Ọ̀wàrà 2019 Oríṣun àwòrán, @BBNaija Eto BBNaija ti wa, to si ti lọ amọ ariyanjiyan nipa pataki eto naa sawọn ọmọ Naijiria ko tii buse.
Ǹkan tí a mọ̀ nípa kọ́lẹ̀jì olùdìbò tó ń fìdì ẹni ti yóò jẹ ààrẹ ilẹ̀ Amérika múlẹ̀ Aàbò tó péye yóò wà fún àwọn tí yóò kópa nínú ìfẹsẹwọ̀nsẹ̀ Naijiria àti Sierra Leone ní Benin - Obaseki Wo iye owó tí ìjọba Amẹrika ń na sí ìdìbò Ààrẹ àti ibi tí owó náà ti ń wá Biden gẹgẹ bi oloṣelu: Ọgbẹni Biden du ipo aarẹ lọdun 2008, ninu ẹgbẹ oṣelu Democrat, ko to o di pe o dije pẹlu Obama, gẹgẹ bi igbakeji rẹ.
BBC Yoruba naa wa n gbadura pe ki Ọlọrun dẹ ilẹ fun Fasasi Ọlabankẹ, ti gbogbo eeyan mọ si Dagunro.
Ọpẹ́ tí ò ń ṣe lè dára ṣugbọn kò mú kí ẹlòmíràn lè dàgbà.
Alufaa Adeboye ti kọkọ sọ siwaju pe oun mọ pe Ibidunni ti wa nibi to dara bayii.
Salim, ti ra ilẹ̀ náà láti fi kọ́ ilé alájà tó pọ̀ sí ibùdó náà.
Nadal, siwo lati tesiwaju ninu idije Australian Open ninu osu kinni odun yii latari ifarapa ti o ni.
Ma binu, fọnran ti o n lò ko le ṣiṣẹ fun un Nipa irinṣe ajumọlo wa,yan ikọ ti o wu ọ lọkan ninu awọn ti a ṣe aṣayan wọn ki o ṣi ṣe alabapin rẹ pẹlu awọn ọrẹ rẹ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Mọrèmi: Ọọ̀ni ní láìsi Mọrèmi, kò leè sí ilẹ̀ Yorùbá Àwọn asa ati ise ti obinrin ko gbọdọ gunle nilẹ Yoruba: Eewọ ni ki obinrin wọ igbo oro - Igbagbọ Yoruba ni pe obinrin ko gbọdọ mọ oro, kii oro ma baa gbe.
Laipẹ yii ni Gomina Ondo, Rotimi Akeredolu, Gomina Ebonyi David Umahi ati awọn miran lugbadi aarun naa.
"A ṣi ni ifarajin si awọn alakalẹ ati afojusun ẹgbẹ YWC gẹgẹ bi Ọjọgbọn Banji Akintoye ṣe ntukọ rẹ fun ayipada iran Yoruba ati lati ni ireti ọjọ iwaju rere fun awọn ọdọ.
” Ó ya Jese ati àwọn ọmọ rẹ̀ sí mímọ́, ó sì pè wọ́n síbi ìrúbọ náà.
Eto ilera ti yoo ṣeranwọ fun gbogbo eniyan paapaa julọ awọn obinrin to maa n fi bẹẹ ni nkan ṣe nile iwosan.
Wọ́n gé ọwọ́ wọn, ati ẹsẹ̀ wọn, wọ́n sì so wọ́n kọ́ lẹ́bàá adágún tí ó wà ní Heburoni.
Apapo awon agbaboolu ohun ni:Awon agbaboolu owo eyin(Defenders)Abdullahi Shehu, Leon Balogun, William Troost-Ekong and Brian Idowu.
Bakan naa lo sisẹ nile isẹ ijọba ọtẹlẹmuyẹ ilẹ America.
 Ọbàlùfọ ̀ n aláyémọrẹ ti jẹ oyè Ọọ ̀ ni kí Ọ ̀ rànmíyàn tó dé .
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Kayefi BBC Yorùba: Bàbá ọmọ, Mọ́ṣúárì, Ọlọ́pàá kẹ́jọ́ rò nípa òkú ọmọ tó pòórá Igbakuugba ti ogun ba de, ile logun ba a tori gudugudu ni ko figba kan turaa lẹ lati doju ija kọ ẹnikẹni to ba tọja rẹ kii sii kaarẹ afi to ba bori ija naa.
Ọpọ eeyan ni ko ri ere bọọlu ni Naijiria gẹgẹ ere idaraya to yẹ ki obinrin maa ṣe.
Ti irinwo akẹkọ ba wa nileewe kan, ta si n pese ẹgbẹrun kan naira fun itọju akẹkọ kọọkan, a jẹ pe ijọba yoo maa na miliọnu lọna irinwo naira ni taamu kan lawọn ileẹkọ girama."
“Lóòótọ́, mo mọ̀ pé bẹ́ẹ̀ ni ọ̀rọ̀ rí,ṣugbọn báwo ni ẹlẹ́ran ara ṣe lè jẹ́ olódodo níwájú Ọlọrun?
Oludari ijoba orile-ede Libya Fayez al-Sarraj yoo sabewo sile
“Mo fún ọ ní gbogbo èso àkọ́so tí àwọn ọmọ Israẹli ń mú wá fún mi lọdọọdun, ati òróró tí ó dára jùlọ, ọtí waini tí ó dára jùlọ, ati ọkà.
" Runsewe ni ijọba Naijiria yoo ṣagbekalẹ eto miran ti yooo maa fọn rere aṣa ati iṣe wa fun iran to m bọ yatọ si ti BB Naija to n ṣafihan ibalopọ.
Oloye Tolulaṣẹ ni ilu Ajaṣẹ ṣalaye pataki ki iran Yoruba ni alifabẹẹti ara wọn lasiko yii ki awọn ọmọ to wa lẹyin odi lè mọ ede baba nla wọn daadaa.
Nínú ìkòkò dúdú ni ẹ̀kọ funfun ti ń jade Ìwà rere lẹ̀ṣọ́ ènìyàn Ojú tó rí ibi tí kò fọ́ ire ló ń dúró dè A kì í mọ̀ọ́ gún mọ̀ọ́ tẹ̀ kí iyán ewùrà má lẹ́mọ Ẹni tó láṣọ tí ò léèyàn ìhòhò ló wà Omi tó tán lẹ́yìn ẹja ló sọọ́ di èrò ìṣaasùn A kì í fi ọjọ́ kan bọ́ ọmọ tó rù.
Gomina ipinle Sokoto Aminu Waziri Tambuwal ti kede pe oun ti fi egbe oselu to n se ijọba lọwọ( All Progressive Congress,APC )sile lo sinu egbe  alatako ,(People’s Democratic Party PDP).
 malariae  maa ń sábà fa ibà tí kò lera ."
Ohun to ku bayi fun wọn ni ki wọn ma sare du ipo keji pẹlu Real Madrid ninu ifẹsẹwọnsẹ to ku.
Iṣuna to din diẹ ni triliọnu mẹsan naira ni aarẹ gbe kalẹ.
Wọ́n Fi Àmì Òróró Yan Dafidi lọ́ba.
Wo àwọn nkan tó yẹ́ kí o mọ̀ nípa 'Awawa Boys', ọ̀kan lára ẹgbẹ́ òkùnkùn tó n dá Eko rú 'Adarí àjọ NDDC, Pondei ń ṣe àìsàn ló ṣe dákú lásìkó ìfọ̀rọ̀wánilẹ́nuwò' Kùdìẹ̀kudiẹ wà nínú ìbò abẹ́nú APC tó yan Akeredolu, ṣùgbọ́n.
Oríṣun àwòrán, @Ọọniadimulaifẹ Àkọlé àwòrán, Ọọ̀ni ti Ifẹ déjú mọ́lé fún ọjọ́ méje Ọba Ogunwusi kí àwọn ará ìpínlẹ̀ Ọṣun kú oríire bí wọ́n ṣe hùwà dáradára sáájú, lákòókò àti lẹ́yìn ìdìbò tí wọ́n sì dúró lórí ṣíṣe ohun tó tọ́.
 awọn olùbágbè wọn ni mandika ati fulaní .
Ẹ yin orúkọ OLUWA;ẹ yìn ín, ẹ̀yin iranṣẹ rẹ̀,
“Ìwọ ọmọ eniyan, la ọ̀nà meji fún idà ọba Babiloni láti gbà wọ̀lú, kí ọ̀nà mejeeji wá láti ilẹ̀ kan náà.
’ Ó sọ fún un pé, ‘Gba ìwé àkọsílẹ̀ rẹ, kọ ẹgbẹrin.
Alexis Sanchez: Man Utd faramọ asorọ ẹwọn lori jibiti owo ori
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Child sexual abuse: Ìdí rèé tí mi ò fi sọ̀rọ̀ nígbà tí ìbátan mi fipá bá mi lopọ̀ l'ọdún 67 sẹ́yìn 12 Ọ̀wàrà 2019 Àkọlé àwòrán, Child sexual abuse: Ìdí rèé tí mi ò fi sọ̀rọ̀ nígbà tí ìbátan mi fipá bá mi lopọ̀ l'ọdún 67 sẹ́yìn Ifipabanilopọ lo yẹ ki tonile-talejo fọwọsowọpọ gbogun ti.
Bí ó bá dé ní ọ̀gànjọ́, tabi ní àkùkọ ìdájí, tí ó bá wọn bẹ́ẹ̀, wọ́n ṣe oríire.
Gedalaya bá búra fún wọn, ó ní: “Ẹ má ṣe bẹ̀rù nítorí àwọn olórí Kalidea, ẹ máa gbé ilẹ̀ náà kí ẹ sì máa sin ọba Babiloni, yóo sì dára fun yín.
Oríṣun àwòrán, NLC Àkọlé àwòrán, Lati ọdun 2011 ti ijọba to n kuro ni iṣakoso ti de ipo ni oun ẹgbẹ NLC ti jọ n fa awọn ọrọ kan, ti ko si yanju di asiko yii.
Wọn ní àwọn lòdì sí àbájáde ìdìbò náà èyí tí Seneto Ademola Adeleke jáwé olú bori.
“Kí ni èsì tí ó yẹ kí n fún àwọn tí wọ́n sọ fún mi pé kí n sọ àjàgà tí baba mi gbé bọ àwọn lọ́rùn di fúfúyẹ́?
Jẹ́ kí igbe mi dé ọ̀dọ̀ rẹ, OLUWA,fún mi ní òye gẹ́gẹ́ bí ìlérí rẹ.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Wo iye obìnrin tó bá Ginimbi ọ̀dọ́mọdé olówó kú àti obìnrin to ṣeéṣe kó jogún rẹ̀ Èlé owó epo míì dé!
"- CAN Ẹ wo àwọn ìlúmọ̀ọ́ká ọmọ Nàíjíríà tó jáde láyé lọ́dún 2020 Ìtàn ìgbé ayé Isola Ogunsola, akọni mánigbàgbé òṣèré tíátà, olórin àti onílù ""Ma a pa ara mi si Cute Abiola lọrun bo ṣe já mi silẹ tori afẹsọna miran"" ""Àwọn akẹ́kọ̀ọ́ àgbà fipá bá ọmọkùnrin mi lòpọ̀ níléèwé Deeper Life, mò ń fẹ́ ìdájọ́"" Wo ọ̀pọ̀ àsọtẹ́lẹ̀ igba tí Primate Ayodele gbé síta fọ́dún 2021 Wọ́n ni fóònù Android àti Iphone ti o jẹ́ pé àwọn èròjà àtijọ́ nìkàn ló ń lò, kò ni le ṣiṣẹ́ pẹ̀lú gbogbo ápùù ti Facebook bá ṣe."
Bakan naa ni agbẹnusọ fun aafin Ooodua ni ile Ifẹ, Kọmureedi Ọlafare pẹlu fi idi rẹ mulẹ pe awọn oloye lati Ile Ifẹ pẹlu ti kan si Arẹmọ ni kete ti iroyin naa kan Kabiyesi Ọọni lara.
A ti gbé kọ́kọ́rọ́ sẹ́nu ibodè Nàìjíríà kí ọrọ̀ ajé wa leè gbé pẹ́lí- ìjọba àpapọ̀ Ẹ dẹkun ere sísá lójú pópó láti dẹkun ìjàmbá- FRSC Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Ajọ naa wa n rọ awọn ọmọ Naijiria to rinrinajo pada wa sorilẹede Naijiria laarin ọjọ mẹrinla sẹyin si asiko yii lati fi ara wọn sabẹ igbele fun ọjọ mẹrinla lati mọ boya wọn ni arun naa tabi ara wọn da ṣaka.
Ẹ o ranti pe D'Tigress jẹwọ ara wọn nigba ti wọn lu ikọ orilẹede Turkey ni alubami ninu ifẹsẹwọnsẹ akọkọ wọn.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ìtàn ayé Henry Fajemirokun, olówó tó fi owó mọ Olúwa àti ènìyàn Tó o bá fẹ́ wọ bàálù lásìkò yìí, wo òfin tuntun tó tẹ̀lé Ọwọ́ ọlọ́pàá ìpínlẹ̀ Oyo ti tẹ àwọn aṣekúpani tó ń ṣọṣẹ́ ní Akinyele Ìpínlẹ̀ Eko kéde ọ̀nà àbáyọ sí súnkẹrẹ-fàkẹrẹ ọkọ̀ lásìkò àtúnṣe afárá Third Mainland Wo ìgbẹ́sẹ̀ méjọ tí ilé aṣòfin ìpínlẹ̀ gbọdọ̀ tẹ̀lé láti yọ igbákejì gómìnà Ilé aṣofin Ondo fọwọ́ òsì júwe ilé fún aṣòfin mẹ́ta pé wọ́n tàpá sí òfin ilé Coulibaly si sẹsẹ ti ilẹ Faranse de ni, nibi to ti lọ setọju aisan ọkan to n baa finra fun odidi osu meji gbako.
Aare orile-ede Liberia, eni ti o tun ti figba kan gba ami-eye agbaboolu ti o dara julo lagbaye ri, George Weah tun pada sori papa leyin ti o kopa ninu ifesewonse olorejore ti orile-ede Liberia padanu sowo iko agbaboolu Super Eagles pelu ami-ayo meji sookan(2-1) lojo isegun(Tuesday), niluu Monrovia.
Ọmọ ilẹ̀ Iran 82 ló kú nínú bàálù tó já lórílẹ̀èdè naa Oríṣun àwòrán, AFP Ọmọ orilẹ-ede Iran mejilelọgọrin lo ku ninu ọkọ ofurufu ilẹ Ukraine ti o jabo ni iṣẹju diẹ ti wọn gbera ni papakọ ofurufu Imam Khomeini, ni olu ilu Iran, iyẹn Tehran.
'Ọdún 2018, àwọn gbajúgbajà tó ti lọ sinmi' Goodluck Jonathan kí Ààrẹ Buhari kú ọjọ́ ìbí Ẹ wo àwòrán tó làmìlaaka níbi ọjọ́ ìbí Gomina ìpínlẹ̀ Ọyọ Sima Sarkar sọrọ lori bi oun ṣe maa n ṣiṣẹ ile ati iranlọwọ ti ọkọ oun n ṣe ki ọjọ ola Hridoy le dara lai naani pẹ akanda ẹda ni.
Ṣé ẹni tí ó dá etí, ni kò ní gbọ́ràn?
Kò sì sí ẹni tí ó sọ ìsọkúsọ sí àwọn ọmọ Israẹli.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ikọlu ẹgbẹ IPOB ati awọn ọmọ ogun Naijiria mu ọpọ ẹmi lọ Olori ẹgbẹ Shiite, Ibrahim El-Zakzaky, ti awọn ọmọ ogunmu lasiko naa wa lahamọ ajọ ọtẹlẹmuyẹ DSS fun ọdun meji o le tako asẹ ti ile ẹjọ pa wipe ki wọn o tuu silẹ lẹyẹ o sọka lọdun 2016.
Ọgbẹni James to ni darandaran Fulani lawọn afunrasi naa, ṣalaye pe nigba ti awsn n lọ lori ere ni awọn afunrasi mejeeji naa ys ada ti oun ti wọn ṣa oun lada yannayanna ki wsn to gbe ọkada oun sa lọ O ṣalaye fawọn oniroyin pe n ṣe ni wọn fi oun silẹ ninu agbara ẹjẹ ni kete ti wọn rii pe oun ti daku ki oun le gba ibẹ dero ọrun.
ro Mallam Kyari lati ri daju pe o sise papo pelu awon toro kan gbongbon
Ọlọ́gbọ́n a máa fi ìmọ̀ rẹ̀ pamọ́,ṣugbọn àwọn òmùgọ̀ a máa kéde agọ̀ wọn.
Won ti kede bakannaa ki awọn ara adugbo ma se jade sita.
Harry Kane fọ́ Ronaldo àti Juventus lẹ́nu pẹ̀lú góòlù àràmọ̀ndà Abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò dágbére fáyé lẹ́yìn ìjà rẹ Olè gbé òrùka ìgbéyàwó mì ní Eko Akọnimọọgba ẹgbẹ agbabọọlu Liverpool, Jurgen Klopp ti ni ko si n to o jọ rara pe oun fẹ ẹ ra Gareth Bale lati ọwọ Real Madrid.
Ìlú ń ké pe àwọn ọmọ rẹ̀ (àwọn ọmọ ìlú) láti dojú ìjà kọ ìwà elẹ́yàmẹyà àti ìtẹ̀mọ́lẹ̀ ní Russia òde-òní.
Wọ́n wá sọ́dọ̀ Mose ati Aaroni, wọ́n sì sọ fún wọn pé, 
Ẹdọ kan naa ati egungun aya kan naa ni wọn ni ṣugbọn a ti irinṣẹ kan wa ti a lo eyi to ran wa lọwọ gan lati din ẹjẹ ti yoo ṣofo ku ti yoo si mu iṣẹ naa pari laarin akoko kukuru.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Èmi gan máa ń béèrè lọ́wọ́ ara mi pé ta ni Wole Soyinka gangan' Funmilayọ jẹ ọkan lara awọn obinrin to lagbara ju ni Naijiria nigba aye rẹ.
Mercy Aigbe: Iṣẹ́ ọwọ́ mi ni mó n jẹ, gómìnà àbi ààrẹ kò gbọ́ bùkátà mi
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Building Collapse: Wọ́n yọ èèyàn mẹ́rin níbi ilé mííràn tó wó l'Eko 18 Ẹrẹ̀nà 2019 Àkọlé àwòrán, Ile to tun wo l'Eko Ile yii ti wá ní abé àwọn ile ti wọn ti pinu láti wo teletele kò tó di pé ó dawo ni ìrólé yii.
Gbogbo ọ̀rọ̀ náà tọ́ lójú ẹni tí ó mòye,wọn kò sì ní àbùkù lọ́dọ̀ àwọn tí wọ́n ní ìmọ̀.
Àwọn ni olórí àwọn ẹ̀yà Israẹli.
Eyi ni agbeyẹwo awọn eekan ti wọn ti fi ẹsun iwa ijẹkujẹ kan ti wọn si ti jẹbi.
Sex: Ìye ìgbà tóo ní ìbálòpọ̀ kọ́ ló ń jẹ́ kí abẹ́ obìnrin fẹ̀
L'Ọjọru ni Arsenal kọkọ fi iya ṣide idije naa lẹyin ti Premier League bẹrẹ lẹyin isinmi ọlọjọ gbọọrọ nitori coronavirus.
Awon osise ti kii se oluko nile eko-giga fafiti ti da eto iyanselodi won duro.
Ẹgbẹ́ kọ̀ọ̀kan a fẹ́ dárà jú àwọn ìyókù  lọ.
Ni ipari, latari iranlowo awon omo ogun ile Amerika ati awon ohun ija ofurufu won, awon omo ogun SDF ti gba isakoso egberun mewa kilomita agbegbe lowo awon omo ogun IS fun bi odun meta seyin.
ti dibo rẹ ni agboole  Olusomi, Ariwa Abeokuta, ni
si fowo mu igbese ti won gbe tele pe awon ko ni gba oruko awon iko mejeeji naa
Nilu Kano, igbimọ lọbalọba ipinlẹ naa lo yan awọn ọba mẹrin tuntun yii sipo.
Nítorí bẹ́ẹ̀ ni wọ́n ṣe inúnibíni sí àwọn wolii tí ó ti wà ṣiwaju yín.
Wọ́n ń ké pè mí, wọ́n ń wí pé, ‘Ọlọrun wa, àwa ọmọ Israẹli mọ̀ ọ́.
Àwọn ọmọ Israẹli pa pupọ ninu wọn, wọ́n gba ilẹ̀ wọn láti odò Arinoni lọ dé odò Jaboku títí dé ààlà àwọn ará Amoni.
Olufemi Lanleyin ti egbe oselu ADC ati asofin Monsura Sunmonu.
Nigba to n sọ iriri rẹ lasiko to wa nile iwe, ọba alaye lobinrin naa to ti lo ọdun marun lori itẹ tun salaye pe, oun kii pa idanwo ati kilaasi jẹ, ti awọn olukọ si da oun mọ pẹlu buba, Sokoto ati ilẹkẹ lọwọ ati lọrun.
Eto aba iṣuna ile iṣẹ banki apapọ, CBN le ni tiriliọnu kan naira fun ọdun 2020.
O Fagunwa, Adebayo Faleti, Akinwumi Iṣọla, Lawuyi Ogunniran àti Oladejo Okediji ṣiṣẹ silẹ ki wọn to lọ3 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Overweight and pot belly: Wo oríṣìí oúnjẹ márùn ún tó lè dẹ́kun ikùn yíyọ àti ara àsanjù8 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Death During Sex: Àwọn nǹkan mẹ́ta tó le ṣekú pa ọkùnrin lásìkò ìbálòpọ̀ rèé9 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Akomolede Oyo round up: Àwọn Olúkọ ìpínlẹ̀ Oyo fakọyọ lórí ètò Akọ́mọlédè àti Àṣà púpọ̀27 Bélú 2020 Èyí tí a wò jùlọ 5:03 Fídíò, Omolola Arohunmolase Welder: Mo ti fí iṣẹ́ 'Welder' gbayì láwùjọ, tó mo fi tọ́ ọmọ yanjú, Duration 5,039 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 5:39 Fídíò, Akomolede ati Asa lori BBC: Olùkọ́ Kikelomo Ogunboye tan ìmọ́lẹ̀ sí ìwà olè ọ̀gá ọlọ́pàá Audu gẹ́gẹ́ bí àwòkọ́ṣe àsìkò yìí, Duration 5,398 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 4:11 Fídíò, Oba Adeyeye Ogunwusi: Ojú mi ti rí lọ́pọ̀ lọpọ̀, ọ̀pọ̀ èèyàn ni kò tilẹ̀ gbàgbọ́ pé mo lè jọba- Ooni, Duration 4,117 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 4:43 Fídíò, Promise Akinlade: ọmọ ọdún mọ́kànlá tó ń fi ìlù dárà bíi àgbàlagbà sọ̀rọ̀ nípa tálẹ́ǹtì rẹ̀, Duration 4,437 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 0:59 Gbọ́, Ìsẹ̀lẹ̀ jákèjádò orílẹ̀èdè àgbáyé láàárín ìṣẹ́jú kan, Duration 0,59wákàtí 5 sẹ́yìn 7:03 Fídíò, Olumuyiwa Bolade Adedeji Military Bruitality: Bí arákùnrin onípèníjà ara tí sọ́jà lù ṣe dé, Duration 7,035 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 4:45 Fídíò, Yoruba Films: Ẹ̀ẹ́ bẹ̀ mi kúrò láyé ni, mi ò lè kú - Fadeyi Oloro, Duration 4,4526 Èrèlè 2020 2:48 Fídíò, Esther Ajayi: Èmi náà ti borí ìṣòro rí ló ń mu mi ṣojú àánú, Duration 2,481 Ògún 2019 6:08 Fídíò, Adebola Ademilua: Àìrísẹ́ ṣè lẹ́yìn ìwé kíkà ló sọ mi dí ìyá onírú, mo dúpẹ́ tèmi, Duration 6,0827 Bélú 2020 2:36 Fídíò, Sotitobire: Ìdájọ́ òdòdò ló fẹsẹ̀ múlẹ̀ lórí ọ̀rọ̀ Pásítọ̀ Sotitobire - Agbẹjọ́rò fún ìjọba, Duration 2,367 Ọ̀wàrà 2020 BBC News, Yorùbá Ìdí tí ẹ fi le è nígbàagbọ́ nínú ìròyìn BBC Ìlànà Lílò Nípa BBC Òfin Àṣírí Cookies Kàn sí.
Ninu leta  ikedun ti aare Buhari kọ si aare  orile ede Niger, Mahamadou Issoufou loruko
Òun ni àpáta mi, ààbò mi, odi mi, olùdáǹdè mi,asà mi, ẹni tí mo sá di.
Ṣugbọn Dafidi kò lè lọ sibẹ láti wádìí lọ́wọ́ Ọlọrun nítorí ó ń bẹ̀rù idà angẹli OLUWA.
Ààrẹ tẹ́lẹ̀, Olusegun Obasanjo kọ̀wé ìbánikẹ́dùn sí aṣíwájú Afẹ́nifẹ́re, Rueben Fáṣọ̀ràntì lórí ikú ọmọ rẹ̀
Àwọn baba wọn a máa pa òfin OLUWA mọ́, ṣugbọn ní tiwọn àwọn kì í pa á mọ́.
Kí ló ṣe ikú pa Adediwura Lateefat Bello lẹ́yìn ọ̀sẹ̀ méjì tí wọ́n ń wá a Afurasi tó fa ìpayà nílé ìwé Port Harcourt ti wọ gàù Àwọn bàbá ìsàlẹ̀ òṣèlú tó bá ìtìjú bọ̀ nínú ìbò Gómìnà rèé Ọ̀rọ̀ Aisha Buhari sí Ramaphosa wú ọ̀rọ̀ síta lẹ́nu àwọn ọmọ Nàìjíríà Ọjọ́ kẹtàlélógún, osú kárùn-ún, ọdún 1964 ni orílẹ̀-èdè Nàìjíríà kọ́kọ́ se ayẹyẹ àyájọ́ ọjọ́ àwọn èwe.
Awọn kan tilẹ ṣe iwọde lọ si ẹka ileejọsin COZA nilu Abuja ati Eko, pe ki Biodun Fatoyinbo kuro ni ipo Pasitọ ninu ijọ naa.
Èmi óo sì yìn ọ́ pẹlu hapu,Ọlọrun, Ọlọrun mi.
Ajọ FRSC naa wa tẹnu mọ ọ wi pe awọn ti bẹrẹ iwadii ni ẹka ajọ naa to wa ni ipinlẹ naa lati mọ ibi ti nọmba ọkọ ọhun ti ṣẹ wa.
Má jẹ́ kí wọ́n wí láàrin ara wọn pé,“Ìn hín ìn, ọwọ́ wa ba ohun tí a fẹ́!
Adari awọn akẹẹkọ fasiti naa, Ọlawale Ijanusi nigba to n ba BBC Yoruba sọrọ wi pe, igba akọkọ kọ niyi ti awọn ọlọ́pàá ọtẹlẹmuyẹ naa n lu awọn akẹẹkọ bi bara, ti wọn yoo si fi panpe ọba mu wọn lori ẹsun pe wọn wọ asọ ju, eyi to mu wọn fara jọ awọn ọmọ yahoo-yahoo.
Won tun pinnu lati maa gba iwa buburu ti o le je ki ikuna ba eto ijọba tiwa-n-tiwa ati eto aabo  lorile ede Naijiria.
O ni ijoba ipinle Ondo bere ajosepo pelu ijoba apapo lati ta awon odo ji sise agbe lati wa ojutu sisoro airisese ni Naijiria.
WHO so pe, eyi jasi pe, awon adari  niloo lati ri daju pe, gbogbo eniyan, nibi gbogbo gbodo ni anfaani si eto-ilera to peye, lai koju ipenija owo-goboi.
1 1684647 Orilẹede Russia 43122 29.
Gẹ́gẹ́ bí amúgbálẹ́gbẹ̀ẹ́, Abubakar ni ó ṣe bònkárí ìsọhun-ìjọba-di-àdáni àti títa ọ̀kẹ́ àìmọye ilé iṣẹ́ tí ó jẹ́ ti ìjọba tí kò pa owó sí àpò ìjọba.
pé kí ó sọ fún àwọn ọmọ Israẹli pé, “Ẹ ya ọjọ́ kinni oṣù keje sọ́tọ̀ fún ọjọ́ ìsinmi tí ó lọ́wọ̀.
Lẹ́yìn oṣù márùn ún, Buhari kọ̀ láti yọ ọ̀ga NHIS Ta ló gé orí ọkùnrin mẹ́ta ní Lekki?
15am today President @MBuhari signed the 2019 Appropriation Bill – Budget of Continuity – into Law.
Àpọ́nlé òògùn, là ń so ońdè mọ́wọ́
Ó ń bá àwọn ẹranko gbé inú igbó.
Oríṣun àwòrán, Mide Ọ̀kan nínú àwọn Kògbérégbè láàrín àwọn ọ̀dọ́ tí wọ́n jẹ́ obìnrin tí wọ́n ń ṣe sinimá àgbéléwò Yorùbá ni Mide Funmi Martins Abiodun tó jẹ́ ọmo fún olóògbé Funmi Martin, ó sì jé aya fún òṣèré Hafeez Owo.
”Òun ni ọ̀rọ̀ tí à ń waasu rẹ̀ fun yín.
Èmi kò forí ṣọta ìjàmbá ọkọ̀ òfúrufú kankan - Obasanjo Ẹ̀rò àwọn ènìyàn se ọ̀tọ̀ọ̀tọ̀ lórí lẹ́tà Ọbasanjo sí Buhari Ni gbọngan Trenchard ninu ọgba fasiti Ibadan ni aarẹ Obasanjo ti sọrọ naa, to si ni Adedibu ṣe bẹbẹ lasiko igbe aye rẹ.
Ibùsùn tí ẹni náà bá dùbúlẹ̀ lé lórí di aláìmọ́, ohunkohun tí ó bá sì fi jókòó di aláìmọ́ pẹlu.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, JAMB 2019: A ó fagi lé ìdànwò ẹni tó bá ṣe aṣemáṣe Iroyin kan tiẹ sọ pe ina mọnamona gbe awọn kan ninu awọn eeyan to ku nigba ti awọn mii si rì somi.
Ẹ̀rù ba gbogbo àwọn ará Filistia tí wọ́n wà ní ibùdó, ati àwọn tí wọ́n wà ninu pápá, ati gbogbo eniyan.
    Yóò yà yín lẹ́nu pé títí nǹkan bí oṣù mọ̀rin lẹ́yìn èyí, a kò tíì dé òkè Ìrònù rárá.
Ki baa jẹ ẹjọ to nii ṣe pẹlu owo, adajo Nenney Shushaidah ma n dajọ lori gbogbo wọn.
Ọkùnrin yìí tún wá ọ̀nà míràn ó rí owó ó tún ra àwọn akèǹgbè míràn ó sì pinnu láti rí nǹkan tí ó ń fọ́ akèǹgbè òun, nígbà tí ó dá ẹmu tán kò lọ sì ilé, ó gun orí igi kan lọ ó ń wo nǹkan tí yóó ṣẹlẹ̀ sí àwọn akèǹgbè òun, ó dúró títí ilẹ fi ṣú kò rí nǹkan kan òun náà kò sì lọ.
"Ọọni fi kun un wipe ""gbogbo wa la ni imọlara ibinu awọn ọdọ lasiko iwọde #EndSARS, a si gbudọ bẹrẹ si ni mu wọn kopa gidi bayii""."
Ọwọ awọn ajọ ati orisun to ṣe e gbẹkẹle bi WHO nikan ni iroyin nipa aṣeyọri lori itọju aisan naa, idena rẹ tabi ipolongo ati ikede, yoo ti jade.
Bí bẹ́ẹ̀ kọ́, àwa ni a óo pa ọ́.
Saulu bá kó gbogbo àwọn ọmọ ogun rẹ̀ jọ, ó ka iye wọn ní Telaimu.
Nítorí nígbà tí Ọlọrun ṣe ìlérí fún Abrahamu, ara rẹ̀ ni ó fi búra nígbà tí kò sí ẹnìkan tí ó tóbi bíi rẹ̀ tí ìbá fi búra.
Mama Abigail Makinde: Oríṣun àwòrán, @Makinde Mama Abigail Makinde ni iya gomina ipinlẹ Oyo, Seyi Makinde.
pé kí wọ́n gbadura sí Ọlọrun ọ̀run fún àánú láti mọ àlá ọba ati ìtumọ̀ rẹ̀, kí wọ́n má baà pa òun ati àwọn ẹlẹgbẹ́ òun run pẹlu àwọn ọlọ́gbọ́n Babiloni.
Ṣé lóòótọ́ ni Amcon gba ilé Toke Makinwa ti wọn ní bàbá olówó rà á fun?
Ẹwẹ, minisita fun iroyin, Lai Muhammed ni awọn ti nawo le ipolongo pẹlu awọn ileeṣẹ iroyin lati da awọn ọmọ Naijiria lẹkọọ.
Ẹwẹ, awọn oludije naa tun maa n na owo fun ipolongo lori ayelujara lati lee kan si awọn eeyan to wa lori itakun ikansiraẹni bii Twitter, Facebook, Instagram, ati bẹẹ bẹẹ lọ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Kókó ìròyìn t'òní: 'Ẹ ṣọ́ra ní London', ‘Ìkọlù darandaran pa èèyàn 2000’ 10 Ìgbé 2018 Eyi ni awọn akojọpọ iroyin ti toni.
- MC Oluomo Auxiliary korò ojú sí àwọn ọmọ ẹ̀yìn rẹ̀ tó ń dàlú rú A kò yan Auxiliary ni adarí gáréjì, ọjọ́ Ajé lá kéde orúkọ̀ àwọn alákòsóo tuntun - Ìjọba Ọyọ Jakejado awọn ipinlẹ to wa ni Naijiria ni NUTW ti n ṣiṣẹ ayafi ipinlẹ Oyo nikan ti wọn ti fofin de ẹgbẹ ọlọkọ ero naa.
Sùgbọ́n lánàá òde yìí ni ẹgbẹ́ àfẹnifẹre fi àtẹ̀jáde kan síta pé àwọ̀n kò ni péjú níbi ìpàdé àperò ọhun.
Otitọ kan ko si ninu ijọ mọ - Aribisala Aribisala sọ fun BBC Yoruba wi pe, ko si ootọ kankan ninu pe adanwo maa n tẹle awọn olori ijọ ju awọn ẹlomiiran lọ.
Ijamba baalu pa eeyan 66 ni Iran 'Awakọ̀ bàálù Ethiopia Airline tó já kò jẹ̀bi' Ìjàmbá ọkọ̀ bàálu gbẹ̀mí ọmọdé méjì àtàwọn arìnrìǹàjò míì 'Súnkẹrẹ-fàkẹrẹ ọkọ̀ ló kó mí yọ lọ́wọ́ ìjàmbá ọkọ̀ òfurufú' Ileeṣẹ ọkọ ofurufu Sriwijaya Air sọ pe awọn ṣi n ṣe akojọ iroyin nipa baalu naa.
Mo tún rí nǹkankan tí ó burú nílé ayé.
Ó sọ èyí lẹ́yìn ti ìròyìn jáde pé ọmọ ọdún méjìdínlógún kan tó ti ní àìsàn lára tẹ́lẹ̀ kú nítorí Coronavirus ni ilẹ̀ Gẹ̀ẹ́sì.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ṣọla Allyson: Obìnrin tí kò bá rẹwà ni yóò máa ṣí ara sílẹ̀ Ni tirẹ, Peter Okoye, MrP ti PSquare tẹlẹ ni 'awọn eeyan bii Elisha Abbo ko tọ lati di ipo ilu mu rara' .
Wo àwọn orilẹ́èdè àgbáyé tó ti sí pápákọ̀ òfurufú wọn fún ìrìnàjò Báwo ni Coronavirus ṣe n tànkálẹ̀ l'Afrika?
Gomina Ibikunle Amosun ti ipinle Ogun ti o baa won akoroyin ile –ise Aare soro fi idunnu re han lori iwe adehun naa meyi ti o se apejuwe re gege-bi ohun ti o se Pataki bayi.
Wọn muu ninu yara agbara to pams si ki wọn to ran an ls si ile ẹjọ agbaye to n gbọ ẹjọ iwa ibajẹ ẹda, ICC Abdelaziz Bouteflika of Algeria O joko si ipo aarẹ orilẹede Algeria fun ogun ọdun laarin ọdun 1999 si 2009.
Ni agbegbe ibudo idibo Gwamamaja, ṣe ni awọn janduku le awọn aṣoju ẹgbẹ oṣelu yooku danu.
Awọn ohun to yẹ ko mọ nipa Samuel Ladoke Akintọla Ọjọ Kẹfa osu Keje ọdun 1910, eyiun ọdun mejidinlaadọfa (108) sẹyin, ni Akinbọla ati Akankẹ bi Samuel Ladoke nilu Ogbomọsọ, to wa nipinlẹ Ọyọ bayii Ileẹkọ alakọbẹrẹ baptist day lolọ lọdun 1922, to si wọle sile ẹkọ girama lọdun 1925 O sisẹ bii olukọ fun igba diẹ laarin ọdun 1930 si 1942, ko to lọ sisẹ nileesẹ reluwe nibi to ti salabapade H.
Ó pé ọdún mẹ́rìnlélàádọ̀ta tí Akintola kú, ìdí abájọ ìja rẹ̀ pẹ̀lú Awolowo rè é Ìtàn Gbọnka àti Timi, akọni méjì tó borí Aláàfin Ṣango Obinrin naa salaye siwaju pe awọn ọmọ oun maa n kọ ọrọ wọn silẹ fun oun lati ka, ti ọkọ oun si maa n kọ tiẹ sinu foonu, ki oun lee mọ ohun to fẹ.
Ìjọba Buhari ń lo agbára láti jà ìjà ẹsìn- Jiti Ogunye Òwò ẹrú pé irinwó ọdún tó bẹ̀rẹ̀, àwọn Amẹrika tó jẹ́ dúdú wá sí Afirika láti bẹ ilé wò Fifun ọmọ lọyan le pupọ: Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Fifun ọmọ lọyan: Ireti ati otitọ ohun to n sẹlẹ Ọpọ ọmọ ni ebi maa n pa, ti yoo si maa sunkun lasiko to ba n mu ọyan, iya rẹ yoo ro pe ko fẹ gba ọyan ni laimọ pe ọyan naa ko se omi sẹnu ọmọ ọhun.
Igba marun un ọtọọtọ ni wọn ti gba ife ẹyẹ yii; AC Milan ati Real Madrid nikan lo gba ife ẹyẹ yii ju wọn lọ.
Dandan ni fun gbogbo ẹni to ba fi orukọ silẹ lati tẹ ìwé pelebe to ni fọto jade, lẹyin ti wọn ba kọ akọsilẹ sori fọọmu naa tan.
lati maa se awon eto ilana ti awon 
Ẹ ti mú kí ibinu mi máa jó bí iná, kò sì ní kú títí lae.
Kí ó gbọ́ igbe lówùúrọ̀,ati ariwo ìdágìrì lọ́sàn-án gangan.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ghana Witches: Wò bí wọ́n ṣe pa ìyá ẹni ọdún 90 tí wọ́n pè ní àjẹ́ 27 Agẹmo 2020 Oríṣun àwòrán, facebook/ AFia pokua Iya agba ẹni aadọrun ọdun kan, ni iya ooṣa kan atawọn aladugbo kan ti sọ lokuta pa lori ẹsun pe ajẹ ni.
Oun lo gba ami ẹyẹ akẹkọọ to tayọ julọ ninu idanwo WAEC lọdun 2019.
Àríwá Nàíjíríà, ẹ sọ ẹran jọ̀bọ̀-jọbọ nù pẹ̀lú Sanusi tẹ yọ lóyè - Soyinka gbarata Coronavirus tún ti bẹ́ gìjà sí Ghana àti Gabon Wọ́n ti wọ́gilé ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ Arsenal àti Brighton lẹ́yìn tí Mikel Arteta lùgbàdì àrùn Coronavirus Coronavirus ti di àjàkálẹ̀ àrùn káàkiri àgbáyé- WHO Àríwá Nàíjíríà, ẹ sọ ẹran jọ̀bọ̀-jọbọ nù pẹ̀lú Sanusi tẹ yọ lóyè - Soyinka gbarata A kò mọ ẹni tó pa ọlọ́pàá Ondo àti ìyàwó rẹ̀, òun kọ́ ló pa ara rẹ̀- ọlọ́pàá Ohun kan gbogi ti awọn ileeṣẹ iroyin naa n tẹnu mọ, ni bi eeyan ṣe le pa ara rẹ mọ nipa lilo ọṣẹ lati fọwọ ẹni ni igba de igba, atawọn nnkan miran to yẹ fun eeyan lati ṣe, ki arun naa le jinna si wa.
Láti àkókò yìí lọ, n óo mú kí ẹ máa gbọ́ nǹkan tuntun,àwọn nǹkan tí ó farapamọ́ tí ẹ kò mọ̀.
Agbẹnusọ ọlọpaa naa tun sọ pe gbogbo agbara ti ile iṣẹ ọlọpaa ni lawọn agbofinro yoo fi wa awọn ti wọn jigbe ọun.
Níbẹ̀, àwọn ẹlẹ́wọ̀n ń gbé pọ̀ pẹlu ìrọ̀rùn,wọn kò sì gbọ́ ohùn akóniṣiṣẹ́ mọ́.
'Ogún ọdún lẹ́yìn ikú Abiọla; ipa rẹ̀ ń yọ sílẹ̀ káàkiri'
Ṣugbọn ẹlòmíràn ni ó ń jẹ́rìí mi, mo sì mọ̀ pé òtítọ́ ni ẹ̀rí tí ó ń jẹ́ nípa mi.
“Ṣugbọn nígbà tí àwọn ará ìlú bá wá siwaju OLUWA ní àkókò àjọ̀dún, ẹni tí ó bá gba ẹnu ọ̀nà apá àríwá wọlé, ẹnu ọ̀nà gúsù ni ó gbọdọ̀ gbà jáde, ẹni tí ó bá sì gba ẹnu ọ̀nà gúsù wọlé, ẹnu ọ̀nà àríwá ni ó gbọdọ̀ gbà jáde.
Àwọn jàǹdùkú pa fadá ní Taraba-Iléeṣẹ́ ọlọ́pàá Ọkọ̀ òfúrufú ọlọ́pàá yóò bẹ̀rẹ̀ sí ní káàkiri Naijiria - Ọgá Ọlọ́pàá Opọ iṣẹlẹ lo ti ṣẹlẹ nipinlẹ Kano ti awọn eniyan ti pa ara wọn lori owo tabi ohun ti ko to nkan rara.
Wo awọn iroyin manigbagbe to waye ni ọsẹ yii Ìtàn Manigbagbe: Àwọn àjakalẹ-àrun to ti wáyé rí ṣáájú Coronavirus Ọwọ́jà coronavirus yóò ṣì wà pẹ̀lú àgbáyé fún ìgbà pípẹ́- Ngozi Okonjo-Iweala Ọba Lamidi Adeyẹmi, òṣìṣẹ́ adójútòfò àti Abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò kó tó jọba Olólùfẹ́ mi ṣèèsì fi ọkọ́ gbá mi sí gọ́tà, mo rò pé ọlọ́jọ́ dé ni - Iya Osogbo Awọn obi Oyinkansola, Ọlọla Kitoye ati Lucretia Olayinka Moore, ni tọkọtaya akọkọ ni Naijiria ti ilẹ Gẹẹsi yoo kọkọ fi oye 'Knight' da lọla.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Àìsàn jẹ́ kí àwọ̀ ara Amida dàbí ara ẹja O tun ni lara awọn minisita yii ti gba iwe ikede dukia bẹẹni awọn miran ko tii gba.
Ṣugbọn ọ̀kan ninu àwọn ọmọ ogun Siria déédé ta ọfà rẹ̀, ọfà náà sì bá Ahabu ọba níbi tí àwọn irin ìgbàyà rẹ̀ ti fi ẹnu ko ara wọn.
“Lọ kó gbogbo àwọn Juu tí wọ́n wà ní Susa jọ, kí ẹ gba ààwẹ̀ fún mi fún ọjọ́ mẹta, láìjẹ, láìmu, láàárọ̀ ati lálẹ́.
June 21 ni pápákọ̀ òfurufú márùn-ún yóò di ṣíṣí padà - Ìjọba àpapọ̀ Kí ni ìdí tí ilé ẹjọ́ tún ti sún ìgbẹ́jọ́ Alfa Babatunde Sotitobire síwájú Irú kí lèyì?
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Domestic Violence: Ìjà láàrin lọkọlaya sọ aya dèrò ọ̀run Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ejò Sebe, Ọká, òjòlá àti àkeèké jẹ́ alábagbé Phillipe Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Ejò Sebe, Ọká, òjòlá àti àkeèké jẹ́ alábagbé Phillipe 6 Ọ̀wàrà 2018 Ali àti Gator jẹ́ ìbejì ọọ̀nì ti Phillipe jọ wà ninu iyàrá.
 O ni lara awon ti o kopa ninu ipade ohun ni: oga agba fun ile-ise olopaa, Idris Ibrahim, oludari eka otelemuye, Yusuf Bichi.
Abdulsalam Aliyu lo gba ami akoko wole ni iseju kokanlelogun ifesewonse ohun, ti Dantani Kolo si gba ami miran wole ki ifesewonse saa akoko to pari.
 Ewe, ohun ti o ye ki won mi lokunkundun ni bi ilera ara re yoo se pe.
Gregory‘s College, Ọbalende Imọ nipa isẹ Amofin lo wu Lamidi lati kọ nile ẹkọ fasiti kan nilu oyinbo, o ku ọjọ meji ti yoo tẹ ọkọ leti ni wọn rọ baba rẹ loye, ti ko si lee lọ mọ Isẹ aayan laayo ti Lamidi kọkọ mu se nigba ewe rẹ ni isẹ adojutofo (Insurance), to si tun jẹ akọsẹ-mọsẹ abẹsẹkubiojo, bẹẹ si lo tun maa n se ere idaraya titi di akoko yii lai naani ọjọ ori rẹ Ki Ọlayiwọla to gun ori itẹ awọn baba nla rẹ, iyawo meji lo ni, eyiun Olori Abibat Adeyẹmi, ti wọn n pe ni iya Dodo ati Olori Rahmat Adedayọ Adeyẹmi, ti wọn mọ si iya Ile koto Orukọ Akọbi ọmọ Ọba Adeyẹmi ni Kudirat Akọfade Erediuwa, ẹni to ti jade laye bayii Eeyan mẹwaa lo du itẹ Alaafin pẹlu Lamidi Ọlayiwọla lẹyin iku Alaafin Bello Gbadegẹsin Ladigbolu keji Lara awọn to du ipo naa ni Arẹmọ Sanni Gbadegẹsin, Ọmọọba Ọlanitẹ Ajagba, Ọmọọba Afọnja Ilaka, Ọmọọba Sanda Ladepo Ọranlọla ati bẹẹ bẹẹ lọ Ọjọ Kẹrinla, osu Kinni, ọdun 1971 ni Ọba Lamidi Ọlayiwọla gun ori itẹ awọn baba nla rẹ, to si di Ọba Lamidi Ọlayiwọla Adeyẹmi kẹta Alaafin maa n sọla laarin awọn aya rẹ, paapaa awọn to jẹ ọdọ, ti wọn si tun jẹ oju ni gbese ni ọdẹdẹ, o si maa n mu wọn yangan lọ si ọpọ ibi to ba n lọ Lara awọn arẹwa aya Alaafin ni Olori Ola, Memunat, Badrat ati bẹẹ bẹẹ lọ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Eegunjobi Omotanbaje Ajobiewe- Èébú ní wọ́n kọ́kọ́ ń bù mí nígbà tí mo bẹ̀rẹ̀ ẹ̀ṣà pípé ní Ni ẹni ọdun mejilelọgọrin, Ọba Adeyẹmi ni okun ati agbara to ju tawọn ewe miran lọ, to si bi ibeji ni ẹẹmeji ati ibẹta Onkọtan, Onpitan ati ọlọpọlọ pipe ni Alaafin, ti ko si gbagbe ọpọ itan ilẹ Yoruba ati Naijiria lai naani ọjọ ori rẹ Lara awọn ọmọ Alaafin to gbaju-gbaja ni Amofin Babatunde, Ọmọọba Fọlasade, Taibat, Nurudeen Adesẹgun, Akeem Adeniyi (Skimmeh), Adebayọ Fatai ati bẹẹ bẹẹ lọ Awọn ọmọ Alaafin kan ti di ipo oselu mu sẹyin, ti awọn miran si tun wa nipo oselu.
Ṣe ni Funke Akindele funrarẹ ṣe ajọyọ pẹlu awọn ololufẹ rẹ pẹlu fidio bo ṣe n ṣe idupẹ lọwọlọwọ ninu ile rẹ tawọn eeyan si n ri i wo loju opo instagram rẹ ti wọn si n fi ọrọ ikini ranṣẹ si i.
2 Bélú 2020 5:55 Fídíò, Soyinka Cancer: Àṣe ara mi ni iso ti n run gbogbo bí mo ṣe n ṣèrànwọ́ lórí jẹjẹrẹ, Duration 5,5527 Bélú 2019 Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí kan sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
Ṣé kí n máa lọ, ṣé kòsí nǹkan?
Asiko yii naa tun ni ogun Agbekoya n waye nilu Ibadan eyi to bẹ silẹ nitori afikun owo ori tijọba ṣe fun awọn agbẹ.
Wọn kò rí ohun tí Ọlọrun ṣe ìlérí gbà, òkèèrè ni wọ́n ti rí i, wọ́n sì ń fi ayọ̀ retí rẹ̀.
Nígbà tí Huṣai, ará Ariki, ọ̀rẹ́ Dafidi pàdé Absalomu, ó kígbe pé “Kí ọba kí ó pẹ́!
Ile igbimo asofin ranse si oludari ile –ise ati ajo ti ijoba apapo lati wa salaye nipa ilana to ro mo dida awon osise ajo naa duro boya igbimo to n sako ajo naa ni agbara labe ofin lati awon oludari eka ajo mefa naa duro lenu ise.
Ajọ yii ko ni dẹ oju rẹ silẹ ki ẹnikẹni yi orukọ rẹ m'ẹrẹ nitori awọn idi b'adiyẹ da mi loogun maa fọ lẹyin' Àríyá ò lópin láti ìgbà tí Nàìjíríà ti júwe ilé fún South Africa Kí ló mú àwọn adarí Nàìjíríà tako ra wọn lórí ikú ọmọ alága ẹgbẹ́ Afenifere?
Aare Buahri soro yii nile ijoba l’Abuja lasiko to n tewogba leta iwole sise komisona fun orile ede Singapore wa si Naijiria, Ogbeni Lim Sim Seng lojo Bo.
Dálémoṣú ni mí ṣùgbọ́n ó ní ìdí
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: 'Ètò olóògùn ebi yóò tẹ̀síwájú bí PDP bá wọlé l'Ékìtì' Ọlọ́pàá jáwé ìkìlọ̀ fáwọn olóṣèlú l'Ékìtì ‘PDP yóò padà sí ìjọ̀ba Nàìjíríà ni 2019’ ‘PDP yóò padà sí ìjọ̀ba Nàìjíríà ni 2019’ Tani yóò darí Èkìtì lẹ́yìn Fáyóṣé?
Eri, àkọ́bí Juda, jẹ́ eniyan burúkú lójú OLUWA, OLUWA bá pa á.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Ẹni ọdun mejilelaadọta ni Evariste Ndayishimiye, aarẹ tuntun ti wọn yan ni Burundi ti ireti si wa pe wọn yoo bura wọle fun un lonii ọjọbọ ọsẹ.
Awọn eekan ẹgbẹ PDP kan, ti wa kesi igbimọ fidihẹ naa, ti gomina ipinlẹ Yobe, Mai Mala Buni ko sodi lati pe ipade apapọ ẹgbẹ oselu APC losu to n bọ, ki wọn le dibo yan awọn ọmọ igbimọ amusẹ tuntun.
Owo ni ibudó ìdìbò ìgbà àtí mẹ́rìnlélọ́gọ́ta tí wọ́n si ni ènìyàn ẹgbẹ̀rún lọ́nà ọgọ́fà dín díẹ̀ tó ti fi orúkọ sílẹ̀ fún ìdìbò tó n bọ.
Amọ nigba to n fesi si iwe ipe ileesẹ ọlọpaa naa ati ọrọ to wa ninu rẹ, Timi Dakolo sọ loju opo Instagram rẹ pe igbesẹ naa ko ba awọn lojiji nitori agbẹjọro awọn ti sin awọn ni gbẹrẹ ipakọ tẹlẹ pe iru isẹlẹ naa le waye.
Kì í ṣe pé a ṣẹ̀ṣẹ̀ fẹ́ fi agbára ti igbagbọ bọ̀ yín lọ́rùn ni, nítorí ẹ ti fẹsẹ̀ múlẹ̀ ninu igbagbọ.
Nígbà tí àwọn ará Filistia gbọ́ híhó tí wọn ń hó, wọ́n ní, “Irú ariwo ńlá wo ni àwọn Heberu ń pa ní ibùdó wọn yìí?
European Union pẹ̀lú United Nations tako ìgbésẹ̀ Nkurunziza fún sáà kẹ́ta, wọ́n sì béèrè fún ìdápadà ìlọdéédé kí àsìkò ìdìbò ó tó dé.
Gomina ipinlẹ Eko, ninu ifọrọwanilẹnuwo ọhun tun sisọ loju rẹ pe ijọba oun ti gbe igba miliọnu naira kalẹ bii owo gba ma binu fawọn eeyan to fori sọta iwọde EndSARS naa.
Sudan Protest: Àwọn òṣìṣẹ́ aláàbò kọlu àwọn tó n ṣe ìwọ́de ní Sudan
" Ẹwẹ́, ọ̀tọ̀ lójú ti ìjọba Kano fi wo ọ̀rọ̀ náà, nínú àtẹjáde kan ti wọn fi síta sọ pé ìdí ti àwọn fi pin ìjọba Emir Kano ni láti mú ki ọba súnmọ àwọn ara ilú ni ìgbèríko Ọ̀jọ̀gbọ́n náà fí kun pé òun ni ìgbàgbọ́ pé ìlànà tuntun yìí to ni Emir marún-ùn kàkà ti yóò fi jẹ ẹyọkan ko ni pẹ ti yóò fi doju, nítori pe gómìnà ìpínlẹ̀ Kano nígbà kan rí, Abubakar Rimi ti gbìyànjú rẹ̀ ni ọdún 1982 tí gbogbo rẹ̀ sì dàyàbolẹ̀ láàrín ọdún kan Ọ̀kan nínú àwọn olùgbé ìpínlẹ̀ Kano Zakari Mohammed sàlàyé pé láì bèrè nípa pe a tún ìtàn kọ, oun ni ìgbàgbọ́ pé ọnà túntun ni láti rii dáju pe àwọn ara ìlú yóò ni ànfani láti súmọ ìjọba àti àwọn aláṣẹ.
Yinka Ayefele ni ìkómọ àwọn ìbẹ́ta òun kò tíì lè wáyé báyìí àyàfi tí òun bá gba páálí wọn l'Ámẹ́ríkà
Bayii gan an ni ọrọ ṣe ri pẹlu ẹgbẹ agbabọọlu Manchester United ninu ọja kata-kara awọn agbabọọlu to kasẹ nlẹ lọjọ Aje ọjọ karun un oṣu kẹwaa ọdun 2020.
Lórí ọ̀rọ̀ àwọn ìbejì mí tí wọ́n jí gbé, ṣe ni mo finúwénú tí wọ́n fún mi ní iwọ jẹ-Akeugbagold Yoruba bọ, wọn ni bi iku ile ko ba pa ni, tode ko le pa ni nitori eyinkule ni ọta wa, inu ile lawọn aṣeni n gbe.
0 54730 Orilẹede United Arab Emirates 733 7.
”Ṣugbọn gbogbo wọn náà ni wọ́n ti fa àjàgà wọn dá,tí wọ́n sì ti kọ àṣẹ ati àkóso OLUWA.
Yahaya Bello: Iléẹjọ́ tó ga jùlọ fòǹtẹ̀ lu Yahaya Bello, wọ́n da ẹjọ́ PDP àti SDP nù
Oríṣun àwòrán, TWITTER Àwọn ọ̀dọ́ l'Eko yarí, ìwọ́de tó tako ọlọ́pàá SARS gbòde Awọn ọdọ ni ọgọọrọ ti korajọ lati fẹhọnuhan tako iṣekupani awọn ọlọpaa SARS lorilẹede Niajiria.
Àwọn ọba tí wọ́n jẹ ní ilẹ̀ Edomu, kí ọba kankan tó jẹ ní ilẹ̀ Israẹli nìwọ̀nyí: Bela, ọmọ Beori; orúkọ ìlú rẹ̀ ni Dinhaba.
Ebi pa mí, òùngbẹ gbẹ mí.
Aare Buhari soro naa di mimo lasiko to n gba iwe maa base re lo lati owo igbimo National Consolidation Ambassadors Network niluu AbujaIleri  
Mose lọ pàdé wọn, ó wólẹ̀ níwájú Jẹtiro, ó fi ẹnu kò ó lẹ́nu, wọ́n bèèrè alaafia ara wọn, wọ́n sì wọ inú àgọ́ lọ.
Àwọn oúnjẹ tó n gbayì níbi ayẹyẹ báyìí Omi ara Ọ̀pọ̀lọ́ jẹ́ ẹlẹ́rìndòdò tó ń mára jípépé, ẹ máa mú To ba n pẹ jẹun alẹ́, o le ni jẹjẹrẹ ọyan àti asétọ̀ Ajàfẹ́tọ̀ọ́ ẹni fẹ́ gbèjà ọmọ Naijiria tí ilé oúnjẹ China kò gba láàyè Ile ounjẹ Yoruba yii jẹ ọkan lara iṣẹ ọwọ awọn ọmọ Naijiria to n gbe ni ilu Egypt.
 Bee si ni omo re George Walker Bush, jawe olubori ninu eto idibo odun 2000, ti o si tuko ile Amerika ni odun 2001 si 2009.
Àwọn olùwọ́de ṣetán láti bá mínísítà FCT Abuja wọ̀ ṣòkòtò kan lórí àṣẹ má ṣe ìwọ̀de Oríṣun àwòrán, @FCT Aṣẹ ti Minisita olu ilẹ Naijiria, Mallam Mohammed Bello pa ti mu ki awọn oluwode bẹnu atẹ lu u, t'awọn kan si ni awọn o kọ lati gbe e lọ si ile ẹjọ.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Asisat Oshoala ni agbábọ́ọ̀lù tó pegedé jù nínú ìfẹ́sẹ̀wọnsẹ̀ náà Ifẹsẹwọnsẹ to kangun si aṣekagba keji fun toni yoo waye laarin South Africa ati Mali.
Mo gbàdura titi pẹlú ìgbàgbọ́ pé iṣẹ́ ìyanu ìkẹyin le ṣẹlẹ̀ Títí di olwúrọ̀ yìí mo si n gbàgbọ́ pe wọ́n o pè mi láti ilé igbóku pamọ́ sí pe o tilẹ̀ sín"" Omowumi Ajiboye Oríṣun àwòrán, Wumi/instagram Àkọlé àwòrán, Yewande bi'mọ tuntun jòjòló, Mercy pàdánù èèyàn rẹ, Toyin Abraham fèsì lórí ìi asoju NCDC Lágbo òṣèré bákan náà lọ́sẹ̀ yìí Omowumi Ajiboye aya Segun Ogungbe náà se ọjọ ibí ti ọ̀pọ̀ awọn akẹ́gbẹ́ rẹ̀ nínú eré tíatia si báa dáwọ idún pẹ̀lú àdúra lọ́tun lósì."
Ọkeke to jẹ ọmọ ọdun mejilelọgbọn ni awọn ajọ ọtẹlẹmuye mu pe o wuwa ibajẹ lori ẹrọ ayelujara ni ọdun 2015 si ọdun 2019.
A o da aba lati pa arakunrin naa, a kan fẹ ko dawọ duro, A ko fẹ ko maa fi ada le awọn eeyan kiri ni, a ko mọ pe iku lo maa ja si fun Precious.
Ọmọ Nahori ni Betueli jẹ́, tí Milika bí fún un.
Ó dẹ ojú ọ̀run sílẹ̀, ó sì sọ̀kalẹ̀ wá,ìkùukùu tó ṣókùnkùn biribiri sì wà lábẹ́ ẹsẹ̀ rẹ̀.
" Ọrọ yii lo ti ẹnu alagba Ahmed Lamidi, ẹni ọgọrin ọdun jade ninu ifọrọwerọ rẹ pẹlu BBC Yoruba ni aafin ọba ilu Ifọn orolu nipinlẹ Ọṣun.
Aṣamọ ọrọ yii gan an lo ṣakawe iroyin nipa Ọgbẹni Adeniyi Theophilous to gba iwe ẹri imọ ijinlẹ meji lasiko to fi wa lọgba ẹwọn.
Ti a ko ba gbagbe, Osu to kọja ni wọn sun idibo ti wọn sẹsẹ n ka siwaju nibiti PDP ati AAC pẹlu atilẹyin APC lo n figagbaga.
Wọn kò kà wọ́n mọ́ àwọn ọmọ Israẹli nítorí pé wọn kò ní ilẹ̀ ìní ní Israẹli.
Omo-egbe oselu alatako lorile-ede Kenya,  Miguna ni won tun ti da pada lorile-ede naa  bayii, latari iwadii to n lo lowo lori ilu ti o ti wa.
Omotola Jolaide ní Nàìjíríà dàbí ọ̀run àpáádì lábẹ́ ìjọba Buhari UEFA Champions League: Barca yọ Man U dànù bí ẹni yọ jìgá!
Bí wọ́n ti ń pa àwọn eniyan, tí èmi nìkan dá dúró, mo dojúbolẹ̀, mo kígbe.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Nigeria 2019 Elections: Ẹnikẹ́ni tó bá ṣáájú láti jì àpótí ìbò ẹ̀mí rẹ̀ ló fi ń ṣeré- Buhari 18 Èrèlè 2019 Oríṣun àwòrán, @BashirAhmaad Àkọlé àwòrán, Aarẹ Buhari ko fi ẹlẹ fi ikilọ rẹ ranṣẹ si awọn to n gbero lati da ibo ru Aarẹ Muhammadu Buhari ti fi ikilọ sita f'awọn to ba n gbero lati da ibo Aarẹ to n bọ lọna ru.
 Ògúǹ ̀ dé ṣe  jaiyesinmi "" , "" Àròpin n ' tènìà "" àti Àyànmọ ́ ."
Ati wipe ibeere ṣi wa lori igba ati akoko ti abẹrẹ ajẹsara naa yoo ṣiṣẹ da lara eniyan, ṣe ọdun kan ni abi oṣu melo?
Bí ó ti ń gbé ẹsẹ̀ kọ̀ọ̀kan ni àwa náà ń gbé ẹsẹ̀ pọ̀ lẹ́ẹ̀kan ṣoṣo tí a ń tẹ̀lé e tí a sì ń pa àtẹ́wọ́.
Tí a bá ní káwọn èèyàn jókòó sílé nítorí coronavirus, ebi àti olè jíjà ma pọ̀- Akọ́ṣẹ́mọṣẹ́ Mò ti ya ara mi sọ́tọ̀ bí mo ṣe dé láti America nítorí coronavirus- Soyinka Ìjọba ìpínlẹ̀ Eko ti ni ki gbogbo ọjà wà ni títì pa, sùgbọ́n.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Wùnmí Toríọlá: Toyin Abraham kìí se ọ̀gá mi nínú tíátà Bayi ni awọn mejeji yii si ṣe n ṣe pasiparọ rẹ lati igba ti ọrọ ija ti wọ aarin wọn.
Ó tún bèèrè pé, “Báwo ni à bá ṣe ṣe àlàyé ìjọba Ọlọrun, tabi òwe wo ni à bá fi ṣe àkàwé rẹ̀?
Ọgbẹni Balogun ni ọlọpaa ipinlẹ ni ọna abayọ si iṣoro eto aabo kaakiri orilẹede Naijiria.
Lati wa jẹ ki ero dinku, adajọ agba pasẹ pe ki awọn tọ́rọ̀ kan ma mu wa ju agbẹjọrọ marun un lọ.
Lopin igba ti awọn oludari ilana naa ba ti n se ileri ere tabua fun awọn eniyan, ọpọ ko ni sin lẹyin re.
Barrow tun  lo si ile-eko Rochas to wa niluu ( Rochas Foundation School) Owerri,ni ipinle Imo lojo kẹ́rin,Abameta ,nibi ti o ti ba awon akẹkọọ ati awon omo orile ede Gambia to wa lorile ede Naijiria sere papo.
Serena yoo waako pelu Kiki Bertens ninu ifigagbaga keji, ti o si tun mo pe, oun yoo tun koju aburo re Venus nipele keta.
Osteogenesis, aisan níní egungun tó rọ̀ ló ń ba Efia fínra Ìlàná ìṣúná tí yóò mú aráàlú kúrò nínú àìní bọ́ sí ọ̀pọ̀ là fẹ́ gbékalẹ̀ - Seyi Makinde Ikechukwu Wilson ló gba Àmì Ẹ̀yẹ 2019 BBC Pidgin Essay Competition Àṣírí ígbèkùn nílé Olore n‘Ibadan kìí ṣe tuntun, ó ti kọ́ wáyé ní 2008 Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Ǹkan tó jẹ́ kí iṣẹ́ ọ̀nà tèmi yàtọ̀ lágbàáyé ni ǹkan tí mò ń lò' Ninu ọkọ baalu ni ẹni ti wọn jọ joko ti sọ fun un pe eefin n yọ ninu baagi rẹ, ti o si salọ si inu yara igbọnsẹ, ki eefin naa to wa gbina.
Bí ẹnikẹ́ni kò bá gbọ́ ọ̀rọ̀ wa ninu ìwé yìí, ẹ wo irú ẹni bẹ́ẹ̀ dáradára.
Mú òṣùnwọ̀n tí a fi ń wọn nǹkan kí o fi pín irun tí o bá fá sí ọ̀nà mẹta.
Nitori naa, ki eto ọrọ okoowo ati ọrọ aje to le ni idagbasoke , ni ẹkun
Pẹlu iye awọn eeyan tuntun yii, o ti pe 103,999 eeyan to ti ni arun naa ni Naijiria bayii.
Hẹrọdu wá Peteru títí, ṣugbọn kò rí i.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Risikat Moromoke Azeez: Inú èmí àti Òbí mi dùn nígbà ti Risi bí ọmọ olójú búlù- Wasiu Itọpinpin ti wọn ṣe ṣaaju fihan pe baba Ahmed sọ pe oun ko jẹbi ẹsun naa nígbà ti ti wọn ti dajọ ẹwọn ọdun mẹta fun un.
Ọmọ ogójì ọdún ni ó jẹ́, a bí i ní ọjọ́ keje osù kẹ́san, ọdún 1977.
Ni abala awọn olukọni agbabọọlu, gernert Rohr to jẹ olukọni fun ikọ Super Eagles ati Thomas Dernnerby ti ikọ Super falcons pẹlu wa lara awọn ti wọn fa kalẹ fun olukọni to pegede julọ ni ipele awọn ọkunrin ati obinrin.
Inú OLUWA yóo wá dùn sí ẹbọ Juda ati ti Jerusalẹmu nígbà náà bíi ti àtẹ̀yìnwá.
Bí ẹ bá dán ọ̀rọ̀ kòbákùngbé wò - Lai Mohammed Mo kan wàhálà lálẹ ọjọ ìgbeyàwó torí ìbálé mi kò ṣe ẹjẹ - Ìyàwó ọ̀sìngín Awọn eso taa mẹnuba diẹ lara wọn yii wa larọwọtọ wa ati lawọn ọja wa gbogbo, nitori naa, ẹ maa ra wọn jẹ, kẹ si mase fi wọn sere rara.
O ni awọn ọmọ naa ti gbadun, iṣẹ abẹ ti pari, awọn ibeji si ti wa ni alaafia bayii lati lọ si ile.
Ṣugbọn nígbà tí wọ́n tún ké pe OLUWA, OLUWA gbé olùdáǹdè kan, ọlọ́wọ́ òsì, dìde, tí orúkọ rẹ̀ ń jẹ́ Ehudu, ọmọ Gera, ará Bẹnjamini.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ojúdé Ọba 2018: Asọ ń pe asọ ránsẹ́ Pé Ayefẹlẹ jẹ́ àkàndá kò fún láṣẹ láti rú òfin - Ajimọbi MM1: Òṣìṣẹ́ méjì dá báagi pada f'olóhun ní pápákọ̀ òfurufú Tìlù tìfọn ni wọ̀n kí Arsène Wenger kàábọ̀ sí Liberia Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí kan sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
Ènìyàn-ṣe-pẹ̀lẹ́ àti Ewédayépọ̀ tí wọn kò ti sanra tó mi ri ti tóbi jù mi lọ.
Ọba tí ó wá nínú ibojì tún ìbọn rẹ̀ ṣe dáadáa, nígbà tí ó rí i pé ó súnmọ́ òun tán àti wí pé òun rí ara rẹ̀ kedere, ó fi ìbọn se oókan-àyà rẹ̀ ó ṣá a, ìbọn dún, òkú alákọrí dún “gbìì” ní ilẹ̀, ó kú pàtàpàtà, kò tilẹ̀ lè mí ara.
Ọgbẹni Ajayi tun ṣeleri pe oun yoo bawọn eeyan ipinlẹ Ondo sọrọ lori ohun to n lọ laipẹ.
Abdullahi fi da awọn obi ati alagbatọ loju pe aabo awọn akẹkọọ lo ṣe koko si ijọba ipinlẹ to fi mu wọn gbe igbesẹ naa.
Ewe, eyi je igba karun-un ti Naijiria ati Ghana yoo lo soju ile-Afrika ninu idije naa.
Bíí ìgbà tí ara rẹ̀ kìí se tiẹ̀.
Àwọn olùdíje meji míràn tún ti jọ̀wọ́ àgá fún Akeredolu níbi ètò ìdìbò abẹ́lé APC ìpínlẹ̀ Ondo Oríṣun àwòrán, @ondoapc Ni kete to ku wakati diẹ ki eto idibo abẹle lati mọ ẹni ti yoo gbe apoti ibo sipo gomina ninu ẹgbẹ oṣelu APC ni ipinlẹ Ondo bẹrẹ, oludije meji miran tun ti yọnda aga fun gomina Rotimi Akeredolu.
"Femi Adebayo, Bimbo Akinsanya sọ ìdí tí wọ́n ṣe fi ìgbéyàwó wọn àkọ́kọ́ sílẹ̀ kó tó bọ́ sórí Ìdí tí Ààrẹ Trump fi dínà mọ́ Nàìjíríà àtí orílẹ̀èdè márùn ún míì láti má wọ Amẹ́ríkà Ní ìgbẹ̀yìngbẹ́yín, orílẹ̀èdè UK fi àjọ EU sílẹ̀ Ìdílé kan gbé ilé iṣẹ́ ọkọ̀ òfurufú lọ ilé ẹjọ́ lẹ́yìn tí wọ́n léwọ̀n dànù nínú ọkọ̀ pé ara wọ́n ń rùn Sinimá tí Lateef Adedimeji dá nikan jẹ́ òṣèré yóò jáde, Yemi Solade fi ọ̀pọ̀ fọ́tò ""dẹngẹ pó"" lọ́jọ́ ìbí rẹ̀ Gẹgẹ bi iroyin ti Sky Sports fi lede, ikọ Tottenham naa ti gbiynaju lati fa ọmọ ọgbọn ọdun ọhun mọra, ṣugbọn o kuna."
Ninu ifọrọwanilẹnu wo pẹlu BBC Yoruba, Helen ṣalaye bi awọn ara adugbo ṣe n fi alebu yii wo o ṣugbọn o bori gbogbo rẹ o si tun nigbagbọ pe ilakọja naa ko tii tan o, oun a si bori ohun gbogbo.
Kí Ó fi ìrẹ́pọ̀ sí ààrin orogún; kí Ó fi ilẹ̀ ọlọ́ràá fún àwọn àgbẹ̀, kí Ó fún àwọn tí ń ṣ’iṣẹ́ mìíràn ní iṣẹ́ rere ṣe; kí Ó fún àwọn aláìsan ní ìlera; kí Ó fi ọgbọ́n fún àwọn ọba, kí Ó fi òye fún àwọn ìjòyè, kí Ó fi ìmọ̀ fún àwọn ọmọ ilé-ìwé; kí Ó tọ́jú àwọn olùkọ wọn; kí Ó sì máa tọ́ àwọn alágbára sí ọ̀nà òtítọ́.
Ọ̀pọ̀ ìpayà máa ń kó ìrẹ̀wẹ̀sì bá eniyan,ṣugbọn ọ̀rọ̀ rere a máa mú inú eniyan dùn.
Iroyin to n tẹ wa lọwọ sọ pe, ile iṣẹ aarẹ yoo ṣepade nirọlẹ oni Ọjọru pẹlu awọn gomina mẹfẹẹfa lati beere idi ti wọn fi fẹ fi eto naa lọlẹ nilẹ Yoruba.
Ojú kò sì ní ti àwọn eniyan mi mọ́ lae.
Ìwọ tí o tẹ́ àjà ibùgbé rẹ sórí omi,tí o fi ìkùukùu ṣe kẹ̀kẹ́ ogun rẹ,tí o sì ń lọ geere lórí afẹ́fẹ́.
Ìjọba yóò lo BVN àtàwọn ọ̀nà méjì míràn láti pín owó ìrànwọ̀ fún aráàlú Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí kan sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Osinbajo Crisis: Ìbéèrè mẹ́rin ti Laolu Akande ń bèèrè lọ́wọ́ Festus Adedayo 13 Bélú 2019 Oríṣun àwòrán, @akandeoj Agbẹnúsọ fun ìgbákeji ààrẹ Ọjọgbọ́n Yemi Osinbajo, Laolu Akande ti ni àsìgbọ́ ọ̀rọ̀ ni o, Osinbajo kò gbàdúra ikú fún ààrẹ Muhammadu Buhari lásìkò to lọ ẹka ìjọ ìràpadà RCCG.
eto ironilagbara fun awon akoroyin  to wa
Bí wọ́n bá ti gbúròó mi ni wọ́n ń gbọ́ràn sí mi lẹ́nu;àwọn àjèjì ń fi ìbẹ̀rùbojo tẹríba, wọ́n ń wá ojurere mi.
O si fẹ ẹ ṣoju ipinlẹ Tennessee nile aṣofin agba lorilẹ-ede America.
Onobum ni biotilẹjẹpe oun ko ni ẹkunrẹrẹ iroyin nipa iṣẹlẹ naa, amọ awọn alaṣẹ ni ọgba ẹwọn naa ni awọn ti kapa awọn ẹlẹwọn naa.
Bọ́ọ̀sì ìrìnà 106 tuntun yóò máa ná Ibadan sí Eko àtàwọn ìpínlẹ̀ míì - Seyi Makinde Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Kété tí wọ́n bá ti báa yín sùn tàn torí pé ẹ tóbi, ẹ gbà pé ìfẹ́ yẹn ti parí - Auntie Remi Ọlọ́yàn ńlá Oríṣun àwòrán, Getty Images Ilé iṣẹ́ ọmọogun Nàìjíríà tú àṣírí ẹni tó rán wọn níṣẹ́ lọ kojú àwọn olùwọ́de EndSARS ní Lekki Tollgate Lẹ́yìn ọ̀sẹ̀ kan ti gbómi-si-omi- ò tó tí wáye lórii pé tani o pàsẹ fún àwọn ọmọgún orílẹ̀-èdè Nàìjíríà láti jáde sígborò tí àwọn olùwọ́de fí faragba ọ̀ta ìbọ̀n nibi iwọde EndSARS ti àwọn míràn sì gbà ibẹ̀ kú.
Àwọn Arakunrin Jesu kò gbà á gbọ́.
Àwọn eniyan jókòó yí i ká, wọ́n bá sọ fún un pé, “Gbọ́ ná, ìyá rẹ ati àwọn arakunrin rẹ ń bèèrè rẹ lóde.
Oríṣun àwòrán, Instagram/saheedosupa Sẹ Maiyegun Meji Lo Wa Ni Ilẹ Yoruba?
Alukoro ileeṣẹ naa, Olugbenga Fadeyi lo fidi ọrọ naa mulẹ fun BBC.
” Bẹ́ẹ̀ ni àwọn eniyan náà ṣe gba Jonatani kalẹ̀, tí wọn kò sì jẹ́ kí wọ́n pa á.
Ẹ ṣí fìlà, kí ẹ sì ṣí adé ọba kúrò lórí, gbogbo nǹkan kò ní wà bí wọ́n ṣe rí.
Aare Buhari wa ro awon alakoso
Nítorí náà, OLUWA àwọn ọmọ ogun, Alágbára Israẹli ní:“N óo bínú sí àwọn ọ̀tá mi,n óo sì gbẹ̀san lára àwọn tí ó kórìíra mi.
Gẹgẹ bẹẹ lọrọ Oluwatobiloba Nsikakabasi Owolola to jẹ ọmọ ọdun mejila ati Fathia Abdullahi t'oun naa jẹ ọmọ ọdun mejila ri.
Nigeria Customs Service: Kò sí ǹkan tó jọ tòmátò tó ní májèlé ní Nàìjíríà'
"Alhaja Kudirat Abiola: Odindi géńdé ọkunrin mẹ́fà ni wọ́n gbé iṣẹ́ ikú rẹ̀ fún ""Ẹ̀wọ̀n gbére leè jẹ́ ìjìyà fún afipábánilòpọ̀ bí àwọn gómìnà ṣe dìde si"" Sotitobire: Ìgbẹ́jọ́ Wòlíì Alfa Babatunde Sotitobire yòó tún tẹ̀síwájú lónìí Wolii ijọ Sọtitobirẹ Prayer Minisitry nilu Akurẹ, Alfa Babatunde, ti ọpọ mọ si Wolii Sọtitobirẹ yoo pada si ile ẹjọ loni, ọjọ Aje ọjọ Karundinlogun oṣu kẹfa."
Ẹgbẹ oṣelu alatako gboogi, Peoples Democratic Party, PDP, tilẹ n sọ pe awọn ọmọ ẹgbẹ́ awọn nikan ni Buhari doju ogun kọ, ti ko si gbe igbesẹ kan naa si ẹsun ti wọn fi kan awọn ọmọ ẹgbẹ́ All Progressives Congress to jẹ ti ẹ.
Àwọn ológun ṣ'àfihàn afurasí apànìyàn mẹ̀ta Trump seleri atilẹyin fun ilẹ Gẹẹsi Awọn ọmọ ìjọ sàtánì ń bínú sí Nàìjíríà Iléèṣẹ́ ọlọ́pàá: A ṣe nkan tó yẹ lórí ajínigbé tó tojú orun dójú ikú' Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Bi awọ ara awọn ọmọ Britain se ri nigba iwasẹ Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Bakan naa ni wọn fikun wi pe lati igba ti ijọba apapọ ti n gbimọ rẹ ni awọn ti bẹrẹ si ni tako igbeṣẹ naa.
 egbe oloselu swapo ti pohamba je olori gba 77.
 wón n pè wón ni Ìla-oòrun adamawá ( adamawa-eastern ) télè .
Oba Ogunwunsi ni oni ni a ri ko si ẹda to mọ ọla, o ni oun ko le dupẹ tan lọwọ ọlọrun.
Ṣe é ní ọjọ́ ìṣúdudu,ati òkùnkùn biribiri.
Ko si musulumi ododo kankan ti yo maa ke 'Allahu Akbar' ti yoo si maa pa awọn alaiṣẹ tabi ṣe ibi eyi ti Qur'an lodi si.
A mọ̀ pé, “Gbogbo wa ni a ní ìmọ̀,” bí àwọn kan ti ń wí.
Wọn ṣe awọn miiran fun lilo ninu oko ni'' Eefin ẹrọ amunawa Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ọpọ mọlẹbi ni efin ẹrọ amunawa ti to si inu ibanujẹ Carbon monoxide lorukọ ti awọn oloyinbo n pe eefin ti o ma n jade lati inu ẹrọ amunawa.
Ninu idajọ  ti dajọ Bode Rhodes-Vivour to je adajo  ile ẹjọ kotẹmilọrun so pe Gomina Gboyega Oyetola oludije fun ipo gomina labe egbe oselu APC ni o jawe olubori gege bi gomina ipinle Osun ninu eto idibo to waye ni ipinle naa.
Wọn á fi ẹ̀wọ̀n dè é lọ́wọ́, wọn á tún kó ṣẹ́kẹ́ṣẹkẹ̀ sí i lẹ́sẹ̀.
 Ṣùgbọ ́ n pẹ ̀ lú àwọn ànfàní tí ó kóra jọpọ ̀ sínú iṣẹ ̀ àgbẹ ̀ yí , àwọn ènìyàn sì kóòríra iṣẹ ́ àgbẹ ̀ síbẹ ̀ .
 mitochondrial dna ati eri adikuta ( fossil ) fihan pe awoneniyan oni berelati africa bi odun 200,000 seyin .
 Ó jẹ ́ ohun ti olùsọ gbà pé oùgbọ ́ kò gbọdọ ̀ bá òun sọ .
Page 1 nínú 2 rewind previous Navigate to the next page nextNavigate to the last page forward Padà sí òkè ÀkọléÀkọlé abala Àkọlé abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Rìn káàkiri BBC News Sport Weather Radio Arts Ìlànà Lílò Nípa BBC Òfin Àṣírí Cookies Ìrànlọ́wọ́ Ìwọlé Ìtọ́ni Òbí Kàn sí BBC Get Personalised NewslettersCopyright  2021 BBC.
Joṣua ati àwọn ọmọ Israẹli ṣẹgun àwọn ọba wọnyi, ní apá ìwọ̀ oòrùn odò Jọdani, wọ́n sì gba ilẹ̀ wọn, láti Baaligadi ní àfonífojì Lẹbanoni títí dé òkè Halaki, ní apá Seiri.
Bi o tile je pe iroyin so pe,won ti dekun ija won, sibe won o ti gbe igbese lati mu adehun ti won se nipa eto  alaafia sẹ, ni eyi ti o si n jẹ ki orile ede mejeeji naa si n gbona gidigidi.
Ọba bá tún rán ọ̀gágun mìíràn ati àwọn aadọta ọmọ-ogun rẹ̀ láti lọ mú Elija.
Eniyan á sọ òkùnkùn di ìmọ́lẹ̀,a sì ṣe àwárí irin,ninu ọ̀gbun ati òkùnkùn biribiri.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Atiku ṣetán láti pèsè isẹ́ mílíọ́nù mẹ́ta lọ́dọọdún PDP fà Buruji Kashamu kalẹ̀ bíi olùdíje Gómìnà l‘Ogun Ìdìbò 2019 ku ọgọ́rùn-ún ọjọ́, INEC kò rí owó ìsúná rẹ̀ gbà Hubert Ogunde rèé, baba àwọn òsèré tíátà Ayefẹlẹ bá BBC sọ̀rọ̀ lórí ilé orin rẹ̀ tí Ajimọbí ń tún kọ́ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, World Toilet Day: Aráàlú ní woléwolé yẹ kó bẹ̀rẹ̀ àyẹ̀wò ojúlé dé ojúlé Amọ, ọkan gboogi lara awọn igbimọ agba ni ilẹ Yoruba, Akin Oke, lero ti rẹ ni ilẹ Yoruba o setan lati gbẹkele ipolongo to nii se pẹlu atunse ile iwe ẹgbẹwa lọdọọdun.
Ẹgbọn rẹ, Tola Adeniyi lo kede rẹ fun aye pe o ti jade laye.
Aare so pe “ o seni laaanu pe ina jo gbogbo ὸόgùn ati isẹ ti awọn eniyan fi wahale se, lati fi ran ara wọn lowo.
Ọwọ́ ọlọ́pàá tẹ afurasí ọkùnrin tó gé akẹ́kọ̀ọ́ ọ̀rẹ́bìnrin rẹ̀ wẹ́lẹ́ wẹ́lẹ́ fún òògùn owó ní Ikorodu Wo àwọn báńkì tó wà lẹ́yìn àwọn olówó èlé bí MMM Ọlọ́jọ́ Festival 2020:Ọ̀ọ̀ni ti Ilé Ifẹ̀ tí wọ ìléèdí ọlọjọ méje tí kò ní rí ẹnikẹ́ni sójú Ajọ eleto idibo lorilẹede Naijiria, INEC lo kede Gomina Godwin Obaseki ti ẹgbẹ oṣelu PDP lo bori ninu idibo sipo gomina to waye ni ipinlẹ naa ni Ọjọ Satide.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: À ti fi àwọ̀n ọlọ́kadà 123 láti Jigawa sílẹ̀ -Ọlọpaa Orí mi wú pé àwọn àgbà ìjòyè kọ́wọ̀rín-ìn tẹ̀lé Olúbàdàn, ìjà parí - Makinde Ìdí ti àwọn kọmísọna ṣe to láti kí ìyáwó gómìnà tuntun káàbọ̀ EFCC gba ọkọ ayọ́kẹ́lẹ́ 30, òògùn ìbilẹ̀ àti ọ̀pọ̀ fóònù lọ́wọ́ àwọn gbájúẹ̀ Bakan naa ni wọn n beere fun ọkada wọn ati awọn ohun to jẹ ini wọn, ti ile-isẹ ọlọpaa ipinlẹ Eko gba lọwọ wọn lasiko ifọrọwanilẹnuwo.
  ‘‘A nigbagbo pe  ọmọ wa to jẹ aare Buhari , ti se gudu-gudu ,
Minisita fun eto aabo ti so pe leyin ọgbọ̀n
Olóyè Olu Falae kò tíì mú ẹjọ́ wá si àgọ́ ọlọ́pàá kankan- Agbenusọ ọlọ́pàá Rògbòdìyàn bẹ́ sílẹ̀ láàrin àwọn ọlọ́kadà àti àwọn òṣìṣẹ́ ọgbà ẹ̀wọ̀n ní Ibadan Wo bí o ṣe lè ṣe eré ìdárayá tí yóò fún ọ ní adùn àti okun fún ìbálòpọ̀ Omotara pàdánù isẹ́ olówó ńlá nítorí ó fi ọtí ẹlẹ́rìndòdò sódà lá ọmọ alágbe lójú Bakan naa ni adajọ sọ pe ki ẹni to se oniduro rẹ, asofin ile aṣojuṣofin apapọ to n soju Kaura-Namoda, Sani Umar Galadima yọju sile ẹjọ.
Oríṣun àwòrán, Femi Joseph@official Àkọlé àwòrán, Ajoji ni iru iṣẹlẹ yi jẹ fun wa nipinlẹ Ondo Alukoro ọlọpaa ni nnkan bi ago mọkanla owurọ ọjọbọ ni awọn gburo iṣẹlẹ naa ti o si ni ki awọn to gbe ọgbẹni Gabriel de ile iwosan, o ti dakẹ.
Gomina Sanwo Olu bẹnu ẹ̀tẹ́ lú iwa awọn ara South Africa si alejo ṣugbọn o tẹpẹlẹ mọọ pe ko dara lati fi oro ya oro.
45 Kíyèsíi, ọ̀pọ̀lọpọ̀ ohun ni a fín sí orí àwọn àwo ti Néfì èyí tí ó fúnni ní òye títóbi jù lórí ìhìnrere mi; nítorínáà, èyí jẹ́ ọgbọ́n nínú mi pé kí ìwọ ó túmọ̀ abala kìnní ti àwọn ìfín tí Néfì yìí, kí o sì rán jáde nínú iṣẹ́ yìí.
Àmọ́, to ba jẹ pe o ko lo nọ́mbà naa mọ, o nilo lati lọ si ọfiisi ajọ NIMC lati ṣe akọsilẹ nọ́mbà tuntun, ki o to le tẹsiwaju.
Ofin ọdọ o kere lati ṣejọba Ile igbimọ aṣofin gbe abadofin ọdọ o kere lati ṣejọba lọ siwaju Aarẹ Muhammadu Buhari, eleyi ti aarẹ buwọlu lọdun 2018.
Mo ṣe tán láti kú tọmọ taya bí wọn kò bá fi El-Zakzaky sílẹ̀ - ọmọ ẹgbẹ́ Shiite Ọmọ Yorùbá tó bá ti rú òfin, ẹ gbé e jàntò - Oluwo Bakan naa ni NAFDAC fi kun wi pe, awọn miran tun n gbe awọ maalu wọle si Naijiria lati orilẹede Turkey ati Lebanon ni ọna ti ko ba ofin mu.
 pàtàkì ohun tí ó jẹ ́ àkóónú fíìmù yìí ní bí àwọn ènìyàn ṣe máa ń hùwà sí àwọn tí ó ní àrùn éèdì .
Toke Makinwa fúnra rẹ ko ti i sọ boya otitọ tabi irọ ni iroyin naa.
Bo ṣe ri ọkọ ayọkẹlẹ mi, lo bẹrẹ si ni wa ọkọ rẹ salọ.
‘Ọ̀rọ Baba Ọbasanjọ kò jọ wá lójú mọ́’ Ilé ẹ̀kọ́ Poly di títì pa torí ìyansẹ́lódì olùkọ́ Pásítọ̀ fẹsẹ̀ fẹ lẹ́yìn tọ́mọ ijọ rì sọ́mi Ọmọ ọdun meje naa fikun wi pe oun itiju lo jẹ fun oun laarin awọn ẹgbẹ oun ladugbo wi pe awọn ko ni ile igbọnsẹ ti eyi si jẹ ohun itiju laarin agboole fun idile oun.
Àwọn òkè ńlá yóo yọ́ lábẹ́ ẹsẹ̀ rẹ̀, bí ìda tíí yọ̀ níwájú iná;àwọn àfonífojì yóo pínyàgẹ́gẹ́ bí omi tí a dà sílẹ̀ ní gẹ̀rẹ́gẹ̀rẹ́ òkè.
Ó tún sọ pé, “Ẹ bá àwọn eniyan rẹ̀ yọ̀, ẹ̀yin orílẹ̀-èdè.
By Pablo Uchoa BBC Brasil 21 Ìgbé 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 11 Èbibi 2020 Bi aarun coronavirus ṣe n gbilẹ si ni gbogbo aye, lo n ṣekupa awọn eniyan.
 Àwọn ààmì àìsàn bíi inú wíwú , inú rírun àti ìgbẹ ́ gbuuru lè tẹ ̀ lé èyí .
agbaboolu Leganes lati iko agbaboolu Chelsea
won sẹsẹ yan sipo ni ipinle Eko,ogbeni  Babajide Sanwo-Olu, ati igbakeji rẹ,ogbeni  Obafemi Hamzat .
Fadeyi tẹsiwaju pe ileeṣẹ ọlọpaa ipinlẹ Oyo ko ni sinmi titi di igba ti yoo fi oju awọn oniṣẹ ibi ọhun lede.
Awọn ẹsun bi iwa ijẹkujẹ, to fi mọ ṣiṣe mago-mago lasiko eto idibo ọdun 1983 ni wọn fi kan iṣakoso Sahgari.
Iléeṣẹ́ ológun òfurufú Nàìjíríà fa àwọn mẹ́ta tí ọwọ́ tẹ̀ lórí ikú Tolulope Arotile lé Ọlọ́pàá lọ́wọ́ Èèyàn 591 míràn tún kó COVID-19 ní Nàìjíríà l'Ọ́jọ́ Ẹtì Ọwọ́ tẹ àwọn ọlọ́pàá tó fìyà jẹ obìnrin kan lọ́nà àìtọ́ n'Ibadan Obìnrin àti ọmọdé tó há sábẹ́ ilé tó wó ní Ebute Meta ti ń gba ìtọ́jú, LASEMA ń ṣàyẹ̀wò ilé náà lọ́wọ́ Bayii, Gbenga Omotoṣo to jẹ kọmiṣọnna fun ifitonileti ti jade wa ṣalaye ohun ti ijọba ipinlẹ Eko n sọ lori bi wọn ṣe n na miliọnu kan lojumọ fun ẹni to ni Covid 19.
Àwọn ijọ Shiite le lòó láti dá wàhálà silẹ̀ nitori wọ́n fi wé pé ilẹ̀ Amẹrika ń ba àwọn musulumi Shiite ja ni kìì ṣe Iran gan ni wọ́n n ba jà Ati pé àwọn ọmọ lẹ́yin Shiite míràn pẹ̀lú àwọn musulumi miran to niṣe pẹ̀lú Iran ni ilẹ̀ Adulawọ yìí le fẹ́ maa gbẹsan láti ba ǹkan to ba jẹ́ ti ilẹ̀ Amerika jẹ́.
” Nítorí náà, wọ́n sọ ibẹ̀ ní Abeli Misiraimu, ó wà ní apá ìlà oòrùn odò Jọdani.
25 Òkùdu 2019 Oríṣun àwòrán, ETV Àkọlé àwòrán, Ẹ̀ṣọ́ tó pa Ọ̀gágun Ethiopia tí a sọ pé ó kú, kò kú mọ́!
Pabanbari rẹ tilẹ ni pe ọpọ awọn aṣofin ni ko tilẹ ni awọn ileeṣẹ wọnyii.
Kenyan: Èyí ni bí wọ́n ṣe n lo Facebook lati ṣekupa awọn oníjàgídíjàgan
Eyi waye lẹyin ti ẹgbẹ Shia se ifẹhọnu han lọ si Ile Igbimọ Asofin ni ilu Abuja, eleyii to fa yanpọn-yanrin laaarin Shia ati awọn ẹsọ alaabo Ile Igbimọ Asofin.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ado Bayero: Èyí ni àwọn ohun tó yẹ kí o mọ̀ nípa Emir ìlú Kano tuntun 10 Ẹrẹ̀nà 2020 Oríṣun àwòrán, Aminu Ado Bayero/Instagram Ijọba ipinlẹ Kano lọjọ Aje gbe igbesẹ meji eleyi ti ọkan ninu rẹ yẹ aga ipo Emir nidi ẹnikan ti o si gbe Emir mi si ori ipo.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Ẹgbẹ naa ni gbogbo ijiya yii latimọle ti jẹ ki El-Zakzaky ati iyawo rẹ ni aarun rọpa-rọsẹ lọpọ igba, eyi si n jẹ ki ẹru maa bawọn pe aarun yii tun le pada ṣe wọn.
Nígbà náà inú rẹ yóo dùn láti lọ sí ibi àsè náà.
Oniruuru iroyin lo tẹyin rẹ jade ti a ko si ri aridaju iru iku to paa, bi awọn kan se ni aarun coronavirus lo paa, ni awọn miran ni o ti ni arun ẹjẹ riru lo sokun fa rẹ.
Ẹ óo sì jìyà ẹ̀ṣẹ̀ yín fún ogoji ọdún.
Adanna ni irufẹ ẹran bayii ko ni jẹ ki ara sun soju kan naa eyi to le nu eeyan yọkun tabi sanra ju.
Ni ó bá kúrò níbẹ̀, ó wọ ilé ẹnìkan tí ó ń jẹ́ Titiu Jusitu, ẹnìkan tí ń sin Ọlọrun.
Awọn to ni covid 19 ni Sub Sahara Africa jẹ awọn ti ọjọ ori wọn din ni ẹni ọgọta ọdun ti ida ọgọrin ninu ọgọrun ko si ki n fi ami coronavirus han.
Lóri òpó twitter ilé iṣẹ́ ọlọ́pàá ni wọn ti kédé wọn ti wọn si ni wọn o fi wọn jófin lábẹ ìdájọ ododo.
Nítorí kì í ṣe àwọn ọmọ ni ó yẹ láti pèsè fún àwọn òbí wọn.
Nígbà tí àwọn ará ìlú náà bèèrè bí Rebeka ti jẹ́ sí i, ó sọ fún wọn pé arabinrin òun ni.
O sọrọ ninu eto ifọrọwanilẹnuwo kan to ṣe pẹlu oludasilẹ Ovation Dele Momodu nibi to ti sọ pe oun ko tilẹ mọ nipa eto agbelewo yii tẹlẹ oun ko si tete fi atilẹyin oun hannigba ti ọmọ oun fẹ lọ kopa.
Joseph ni 'ikọ ẹlẹni mẹta naa wọ ile itaja oogun kan ni ìlú Ọ̀wọ̀, nipinlẹ Ondo, pẹlu ibọn lọwọ wọn, sugbọn ti onile itaja oogun naa ti wọn fẹ ẹ jigbe tete pariwo ẹ gbami, to si gba ẹnu ọna mi i sa jade.
Kí ló dé tí ẹ fi mú àwọn eniyan OLUWA wá sinu aṣálẹ̀ yìí?
Nígbà tí wọ́n kó àwọn ọba náà dé ọ̀dọ̀ Joṣua, ó pe gbogbo àwọn ọkunrin Israẹli jọ, ó sọ fún àwọn ọ̀gágun tí wọ́n bá a lọ sí ojú ogun pé, “Ẹ súnmọ́ mi, kí ẹ sì fi ẹsẹ̀ yín tẹ ọrùn àwọn ọba wọnyi.
ebi awon oloogbe yii, mo tun fe so fun un yin pe ile-ise Ologun ofurufu ko ni
Lasiko yii, awọn eniyan Iṣaṣi, Denro, Akute, Ibọkọ ati bẹẹ bẹẹ lọ ni omiyale ti le kuro ninu ile wọn ti ọpọ si ti padanu iṣẹ rẹ nitori pe wọn ko le jade.
Ṣugbọn ẹnìkọ̀ọ̀kan wa ti rí oore-ọ̀fẹ́ gbà gẹ́gẹ́ bí ìwọ̀n ẹ̀bùn tí Kristi fi fún wa.
Èyí jẹ́ ọdún kẹfa tí Hesekaya jọba, ati ọdún kẹsan-an tí Hoṣea jọba.
Ṣugbọn ọ̀gágun Lisia wá fi ipá gbà á kúrò lọ́wọ́ wa, ni ó bá mú un lọ.
Àtẹnudẹ́nu àtìrandéran ni àwá ń ṣe ní àtètèkọ́ṣe.
Ki ṣe gbogbo èèmọ̀ ni ó dára, fún àpẹrẹ, ni igbà kan ri èèmọ̀ ni ki èniyàn bi àfin, tàbi bi ibeji nitori eyi, wọn ma npa ikan ninú àwọn meji yi ni tàbi ki wọn jù wọn si igbó lati kú, ṣùgbọ́n láyé òde òni àṣà ji ju ibeji tàbi ibẹta si igbó ti dúró.
C Amedu ti ile iṣẹ agbẹjọro Ikeh Sunday, Ibadan, ninu iwe ipẹjọ fẹsun kan ile iwosan UCH pe, wọn jẹ ki aworan ipọkaka iku Sugar lu sita lasiko to wa gba itọju lọdọ wọn.
Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Fídíò, Obasanjo: Atiku kìí se Áńgẹ́lì, àmọ́ yóò se dáadáa ní ìlọ́po méjì ju Buhari lọ22 Sẹ́rẹ́ 2019 Fídíò, Olusegun Obasanjo: Màá fi ìyókù ayé mi sin Ọlọ́run áti ènìyàn28 Agẹmo 2020 Fídíò, Obasanjo: Eré ìtàn nípa ìbí, àti jéèyàn pẹ̀lú ìpèníjà Olusegun Aremu Obasanjo5 Ẹrẹ̀nà 2020 Buhari: Òpùrọ́ àti òjòwú ni Olusegun Obasanjo21 Sẹ́rẹ́ 2019 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 3 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 5 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Inú mi dùn nígbà tí Stefana ati Fotunatu ati Akaiku dé, nítorí dídé tí wọ́n dé dí àlàfo tí ó ṣí sílẹ̀ nítorí àìsí yín lọ́dọ̀ wa.
- Amina Zakari Dino Melaye ṣubú lulẹ̀, ó d'èrò ilé ìwòsàn Ọ̀sẹ̀ méjì péré la fẹ́ kí iṣẹ́ reluwe Eko sí Ibadan parí - Amaechi Àwọn òṣèré tíátà Yorùbá tó bá 2018 lọ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ìgunnukó: Àwọn Tápà gbà pé ẹni tó bá ń sin Ìgunnukó kò ní ráùn ohun rere Amọ wọn fikun pe ipade miran ti yoo waye lọjọ Aje ni yoo sọ boya ẹgbẹ osisẹ yoo tẹsiwaju pẹlu iyansẹlodi to fẹ gunle lọjọ Isẹgun abi bẹẹ kọ.
Ẹgbẹlẹgbẹ awọn eniyan ni wọn wa ṣe idaro gbajugbaja olorin n ni DJ Arafat.
Ori ayelujara bi i Facebook, WhatsApp, Twitter, Instagram, ati bẹẹ bẹẹ lọ si ni wọn ti ma n fa oju awọn eeyan mọ́ra lati dokowo Bitcoin.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Plane Crash: Ọkọ̀ báàlù ṣìnà, ó já wọ ilé onílé Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Plane Crash: Ọkọ̀ báàlù ṣìnà, ó já wọ ilé onílé 28 Ọ̀pẹ̀̀ 2019 Àfi kí elédúwà máa kó wa yọ lọ́wọ́ bí ọkọ bàálù ṣe máa ń já káàkiri àwọn orílẹ̀èdè.
Nítorí pé wọ́n ti ṣe ohun burúkú lójú òun, wọ́n sì ti mú òun bínú láti ìgbà tí àwọn baba ńlá wọn ti kúrò ní Ijipti, àní títí di òní olónìí.
Aago méjìlá ọjọ́ Ẹti ni ìséde yóò bẹ̀rẹ̀ ṣáájú ìdìbò náà Ọjọ́ kejilelogun, oṣù kẹsan an (ọjọ Abamẹta to m bọ) ni ètò ìdìbò náà yóò wáyé.
Nítorí náà, bí iná tíí jó àgékù igi kanlẹ̀,tíí sìí jó ewéko ní àjórun;bẹ́ẹ̀ ní gbòǹgbò wọn yóo ṣe rà,tí ìtànná wọn yóo sì fẹ́ lọ bí eruku.
Gẹ́gẹ́ bí ó ṣe sọ ọ̀rọ̀ ètò ààbò kìí ṣe èyí tí à ń fi àsìkò lé lórí, àsìkò tó bá tó ni ìyanjú ni, pẹ̀lú ìgbyànjú gbogbo ìgbà.
Salah to jẹ ọmọ ọdun mẹrindinlọgọn gba ami ẹyẹ naa mọ Medhi Benatia, Kalidou Koulibaly, Sadio Mane ati Thomas Partey lọwọ.
Yóo gbé ọwọ́ lé orí òbúkọ yìí, yóo sì pa á níbi tí wọ́n ti máa ń pa ẹran ẹbọ sísun níwájú OLUWA; ó jẹ́ ẹbọ ìmúkúrò ẹ̀ṣẹ̀.
Òtítọ́ rẹ dàbí òkè ńlá;ìdájọ́ rẹ sì jìn bí ibú omi.
Koda awọn eniyan ni awọn ilu bi Stockholm ni Sweden, Honk Kong, ati Singapore ti ijọba ko ti ṣe ofin ijina sira ẹni láwùjọ, awọn eniyan n din irinajo wọn ku.
Oríṣun àwòrán, @NLCHeadquarters Gomina ipinlẹ Kaduna, Mallam Nasir El-Rufai, tii se alaga igbimọ amusẹya fun igbimọ to wa fọrọ aje lo gbe aba naa siwaju awọn gomina, eyi ti wọn yara fontẹ lu.
Oye yii ni gomina maa n fun eeyan, lati ma a mojuto ọrọ to ba ni i ṣe pẹlu awọn ibi tí wọn n sin oku si nipinlẹ naa.
Wọn kò ní èrò ibi lọ́kàn, ní tiwọn, wọn kò sì mọ ohun tí ó wà lọ́kàn Absalomu.
Botswana: Ìdí tí erin àti òkúta Dáyámọ́ǹdì yóò fi leè sọ olúborí èsì ètò ìdìbò ààrẹ
Ní bàyìí ìwọde ti bẹ̀rẹ̀ ni ilé ìtaja ìgbàlode ti Ikeja náà.
Nígbà tí n kò jẹ́wọ́ ẹ̀ṣẹ̀ mi,ó rẹ̀ mí wá láti inú,nítorí kíkérora tí mò ń kérora ní gbogbo ìgbà.
Ó sì tún fi han gbangbagbàngbà pé Beijing ni a ti ṣe ọtíi wáìnì náà tí ó ní ìdá 64 iye ọtí-líle nínú tí ó sì ti wà nílé ìtajà fún ọdún mẹ́tadínlọ́gbọ̀n.
Òun ati obìnrin yìí sọ̀rọ̀ sí ara wọn ní èdè tì n kò gbọ rí, lẹ́yìn náà ni iwin tii ṣe alákòóso filà yìí bẹ̀rẹ̀, tí o ní ki n jókòó lé òun lẹ́yìn, nígbà tí mo sì ṣe bẹ́ẹ̀, wéré ni mo bá ara mi ni ofuurfú tí o ń fò lọ pẹ̀lú mi.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Women's state of origin: Obìnrin lè jànfàní nípìnlẹ̀ bàbá àti ọkọ 8 Èbibi 2019 Oríṣun àwòrán, Google Àkọlé àwòrán, Awọn obinrin aṣofin Naijiria Ajafẹtọ obinrin to tun jẹ amofin, Abiade Olawanle Abiola ti yin ile igbimọ aṣofin fun abadofin ti wọn fọwọ si eyi to faaye gba awọn abilekọ lati yan ipinlẹ to ba wu wọn lati lo ninu ti baba tabi ọkọ wọn.
Amọ to wa nibẹ ni pe laarin wakati ki konileogbele to bẹrẹ ni wọn le fi rinna.
Onigbowo iko agbaboolu Super Eagles, ile-ise epo robi Aiteo ti fi idunnu re han fun eto ati ipalemo olokan-o-jokan ti ajo to n ri si boolu afesegba ni Naijiria, NFF ti n pese sile saaju idije boolu agbaye to n bo lona lorile-ede Russia.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Àwọn aláìsàn rawọ́ ẹ̀bẹ̀ sí ẹgbẹ́ JOHESU Ọpọlopo lo bu ẹnu ẹ̀tẹ́ lu ọrọ ọjọgbọn to ti tukọ fasiti Ibadan nibi ti sanmọnti gbe dunlẹ fun ọpọlọpọ ọdun ko tẹ jẹ minista yii.
Bẹ́ẹ̀ ni èmi rọra jókòó ní tèmi, tí mo ń wo ojú ayé, ti mo ń ronú nípa àwọn ọmọ ènìyàn, nítorí onírúurú ènìyàn ni mo ti bá gbé pọ̀ rí; àkókò ìgbá mo sì ń sọ̀rọ̀ yìí, àkókò pàtàkì ni ó jẹ́ ní ìgbésí-ayé mi, nítorí ìgbà náà ni bàbá mi pa ojú dé, tí ó rékọjá òkè odò, ti ó kí ayé pé ó dìgbòóṣe, tí àkùkọ kọ l’ẹyìn  ọkùnrin.
Ilé iṣẹ́ BBC ni Fayẹmi kọ́kọ́ bá sọ̀rọ̀ gẹ́gẹ́ bíi gómìnà tí Ekiti yàn Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí kan sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
Ìpínlẹ̀ Ogun, Eko ti gbáradì fún ẹ̀kún omi yalé Ogun: Amosun, ẹgbẹ́ òṣìṣẹ́ NLC fẹ́ forígbárí l'Ógùn Ilẹ ẹjọ fagilé ìbò ọmọ ẹgbẹ́ APC nípinlẹ̀ Ogun pè kí àtúndì ìbò wà Ààrẹ Buhari wọ́gilé kí àwọn òṣìṣẹ́ ìjọba máa wọ ọkọ̀ bàálù olówó gọbọi Gomina Abiodun ti ipinlẹ Ogun fi eyi lede nibi ajọdun ikẹkọjade ogoji ọdun ti ile iwe giga naa lọjọru ọsẹ.
Sìgá mímu ń di èèwọ̀ oògùn ìlera pípé lagbaye Rochas Okorocha, káàbọ̀ sí àwùjọ àwọn gómìnà tí EFCC ń wá - Fayose Ṣeyi Makinde fòfin de ẹgbẹ́ NURTW Ọyọ, ó gbàkóso gáréjì ọkọ̀ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ondo: Dejí sun ọmọ méje àtagbalagba meji mọ́lé nítorí pé ó ń bínú Ronaldo de Lima gba bọọlu fun ikọ agbabọọlu Real Madrid fun ọdun marun un ṣugbọn ko ri ife ẹyẹ Champions League, ko da o tun ṣoju Barcelona naa fun ọdun kan.
Akpan ni ẹgbẹrun mejilelọgbọn (32,000) naira ni wọn n san tẹlẹ, amọ bayii awọn akẹẹko n san laaarin ẹgbẹrun lọna aadọta (150,000) si ẹgbẹẹrun lọna igba (200,000) naira gẹgẹ bi owo ile iwe.
Wo nnkan tawọn eeyan sọ lori rẹ.
 jagúnjagun gan-an sì ni akẹsin tó jẹ ́ olórí wọn .
Ìdí tí mo fi gún olólùfẹ́ mi tẹ́lẹ̀ pa - Jacinta Igboke Ìjọba korò ojú sí bí Islamic State ṣe bẹ́ àwọn Kristiẹni mẹ́wàá lórí ní Bornu Ṣé ẹ ti gbọ́ ọ̀rọ̀ lẹ́nu Wolii Sọtitobire fúnra rẹ̀?
Yàtọ̀ sí ẹbọ sísun ati ẹbọ ohun mímu ojoojumọ yìí, ẹ óo tún fi òbúkọ kan rú ẹbọ ẹ̀ṣẹ̀ sí OLUWA.
Ni bayii a ti mọ pe ko lee ṣe awọn nnkan pẹ-pẹ-pẹ bii ko dana fun ara rẹ ati ko ge eekanna rẹ.
Pẹlu iye awọn eeyan tuntun yii, o ti pe 57, 849 eeyan to ti ni arun naa l'orilẹede Naijiria bayii.
Maryam Sanda: Femi Adebayo, Bimbo Akinsanya sọ̀rọ̀ lórí ohun tó ń kóbá ìgbèyàwó
Ayọ̀ ń bẹ fún ẹni tí ó bẹ̀rù OLUWA,tí inú rẹ̀ sì dùn lọpọlọpọ sí òfin rẹ̀.
Ó di àjàrà, ó yọ ẹ̀ka, ó sì rúwé.
la, pe awon lo jawe olubori ninu eto idibo aare to  waye lorile ede Naijiria lodun 2019 .
Àgbo Covid-19 Madagascar kò ṣiṣẹ́, àwọn ènìyàn tí bẹ̀rẹ̀ sí ní kú níbẹ̀ Ọ̀rọ̀ ìtàjẹ̀sílẹ̀ ní Nàìjíríà yìí tí ń kọ àwa Oṣo àti Àjẹ́ lóminú, a fẹ́ wa ǹkan ṣe síi Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ìdílé tí ọkọ da ọmọ síta tóríi ojú Búlùú tí wọ́n ní bá BBC sọ̀rọ̀ Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí The Church of Beer: Ìnira nlá ni òfin tó dé kátà-kárà ọtí líle lásìkò Covid-19 jẹ́ fún ilé ìjọsìn wà5 Ògún 2020 WASSCE time table 2020: Àwọn akẹ́kọ̀ọ́ da ìdánwò WAEC rú ni Ghana, wọn gún infijilátọ̀9 Ògún 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
OLUWA jẹ àwọn ará ìlú Aṣidodu níyà gidigidi, ó sì dẹ́rùbà wọ́n.
Jesu bá tún kígbe tòò, ó mí kanlẹ̀, ó bá dákẹ́.
Awọn onileesẹ to n se ipese ounje agolo, nkan mimu bii tii, omi inu ike ati omi inu ọ̀rá to ba tete san owo ori saaju ọjọ kọkanlelọgbọn, osu kẹjọ yoo ri ẹbun ida aadọta gba ninu owo ori wọn.
Ko tii si iwosan tabi itọju fun arun naa, bẹẹ si ni ẹbu iroyin naa lo n salaye nipa bi omi ọbẹ alata naa se lee se iwosan Coronavirus.
Olóríi gbọ̀gán àdúrà abúlé l’ó dárúkọ rẹ̀ tí àwọn ará abúlé sí fi ìyà jẹ́ ẹ.
”’“Lati le se aseyori nipa awon eto idagbasoke  wonyi, ajo agbaye bi  I ile ifowopamo agbaye, ile ifowopamo ti orile ede Afirika  ati awon ile-ise miiran ti setan lati seto iranlowo fun awon orile ede yii, ti won ba lee fowosowopo lati le gbokun ti awon isoro to n doju kọ won.
Iroyin naa wipe awọn ọmọogun mọ̀kandinlogoji lo padanu ẹmi wọn, eyi to yatọ si iroyin akọkọ to wipe eniyan mejilelọgbọn lo padanu ẹmi wọn.
Ohun kín-ìn-ní tí a kọ́ ṣe ni pé a wá ọ̀pọ̀lọpọ̀ ọkọ́ àti àdá pẹ̀lú àáké a kó o fún wọn kí wọ́n bẹ̀rẹ̀ si i ṣe iṣẹ́ àti tún ìlú ṣe.
Van Persie vs Solskjaer: Ole bínú tán, ó lóun ò mọ Van Persie rí, bẹ́l kò lẹ́tọ̀ọ́ láti sọ̀rọ̀ s'óun
Bẹẹ ba si gbagbe, ọpọ lẹta ni Alaafin maa n kọ si awọn adari to ba wa nipo boya labẹ ijọba apapọ ni abi lawọn ipinlẹ.
won tẹle oludije fun ipo aare ohun si.
" Ọba alaye náà wá ń rọ àwọn oniṣẹ ìwádìí ni Nàìjíríà àti ní àgbáyé, láti fi àmúlò oogun ìbílẹ̀ yìí mọ Isegun òyìnbó.
Dìde, OLUWA, lọ sí ibi ìsinmi rẹ,tìwọ ti àpótí agbára rẹ.
Akewugbagold sọ pe ''ẹni to jẹ ọkọ ni ko ri owo na fun un yii, bẹẹ ale si ni o nawo fun obinrin yii, awọn kan wa ni awọn ni ọmọ ẹgbẹ ''Association of Stingy Men.
11 Ọ̀wàrà 2020 Fídíò, Wole Soyinka sọ ìdí tó fi ni òun a fi màálù Fulani ṣe súyà fáwọn èèyàn abúlé23 Owewe 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Onisegun oyinbo Aliyu Daware ti gba awon eniyan niyanju lati teramo jije eso ati ewebe ki oju won le riran daadaa lojo ogbo won.
Ọ̀dọ̀ fásitì jànkàn Oxford ló ti jáde Kanye West ti bẹ̀rẹ̀ ìpolongo àti díje dupò aàrẹ ilẹ̀ Amẹrika Ètò ìdìbò abẹ́lé sípò gómìnà APC ni ipinlẹ Ondo ti bẹ̀rẹ̀ ní pẹrẹwu Adelé Ọ̀gá Àgbà àjọ NDDC dákú rangbọndan lásìkò tí ìwádìí n lọ lórí ẹ̀sùn ìnákúnàá Lara awọn aṣeyọri ti Laycon ti ṣe sẹyin ni orin rẹ Fierce,"" eyii to wa loke tente ninu awọn orin mẹwaa to lamilaaka ju lori ikanni MTV BASE fun oṣu mẹfa gbako."
Olórí ilé asoju-sofin fúnra rẹ, Femi Gbajabiamila sì lo gbé àbá òfin náà kalẹ, èyí to ni yóò mú kó seese fún ìjọba àpapọ̀ láti dènà ajakalẹ-arun.
Lasiko ti akọroyin BBC kan de awọn mọṣalaaṣi bi ti Ikoyi ati Lekki lati kirun, titi pa ni awọn ilẹkun ibẹ wa lai si irun Jimọ.
daran-daran ati agbẹ  niluu Abuja se, ni
Bí mo bá wà ní ọ̀dọ̀ gbogbo yín, yóo mú ìlọsíwájú ati ayọ̀ ninu igbagbọ wá fun yín.
Bí ó ti ń kú lọ, àwọn obinrin tí wọn ń gbẹ̀bí rẹ̀ wí fún un pé, “Ṣe ọkàn gírí, ọkunrin ni ọmọ tí o bí.
Ẹ kò sì rò ó lọ́kàn yín, kí ẹ wí pé:‘Ẹ jẹ́ kí á bẹ̀rù OLUWA Ọlọrun wa,tí ó ń fún wa ní òjò lákòókò rẹ̀,ati òjò àkọ́rọ̀ ati àrọ̀kẹ́yìn;OLUWA tí ó ń bá wa mú ọjọ́ ìkórè lọ́wọ́,tí kì í jẹ́ kí àsìkò ìkórè ó yẹ̀.
Awọn ọlọpaa ko sọ bi o ṣe pa ọkunrin naa, ṣugbọn wọn ni o fi oku ọkunrin naa se irẹsi ti o si fi fun awọn oṣiṣẹ kan ti o wa ni agbegbe naa jẹ.
Samuel Ogundipe: Níní ìwé àṣíri ìjọba lọ́wọ́ lọ́nà àìtọ́ ni ẹṣẹ rẹ̀
Ṣugbọn Jesu kọ̀ fún un, ó ní, 
Ọjọ́ ọdún ni ọjọ́ òní, nítorí náà jẹ́ kí àwọn ọmọkunrin yìí rí ojurere lọ́dọ̀ rẹ.
Ó bá sáré lọ sọ́dọ̀ Simoni Peteru ati ọmọ-ẹ̀yìn tí Jesu fẹ́ràn, ó sọ fún wọn pé, “Wọ́n ti gbé Oluwa kúrò ninu ibojì, a kò sì mọ ibi tí wọ́n tẹ́ ẹ sí.
Ẹ̀rù kò ní bà wọ́n mọ́, wọn kò ní fòyà, ọ̀kankan ninu wọn kò sì ní sọnù, èmi OLUWA ni mo sọ bẹ́ẹ̀.
tun wa gbosuba fun ajo eleto idibo INEC  fun ise ribi-ribi ti won n se.
Bí ara bá tu ẹ̀yà kan, gbogbo àwọn ẹ̀yà yòókù ni yóo máa bá a yọ̀.
Liverpool lo si wa loke tente, awọn nikan si ni ikọ agbabọọlu ti ko ti fidi rẹmi ninu ifẹsẹwọnsẹ kankan ni saa bọọlu yii.
Aare gbadura pe, Olorun yoo bukun fun ogagun Onoja pelu emi gigun ati agbara lati tun bo ma lowosi idagbasoke orile-ede yii.
Ẹ jẹ́ kí á lọ sọ fún àwọn ará ilé ọba.
Nítorí pé ẹ̀ ń fi ẹ̀gbẹ́ ti àwọn tí wọn kò lágbára sọnù, ẹ sì ń kàn wọ́n níwo títí tí ẹ fi tú wọn ká.
Họnọrabu Lasun Yusuff ni ohun to lee ko ẹgbẹ oṣelu APC yọ naa ni ki àwọn eekan ẹgbẹ oṣelu naa o pe aro ati ọdọfin wọn jọ lati pari gbogbo ariyanjiyan ti n bẹ láàárín agbo wọn.
Moesha Boduong ní ètò ọrọ̀ ajé burú jáì ní orílẹ̀èdè náà tó bẹ́ẹ̀ tó fi jẹ́ wípé wọ̀n fi ipá mú u ní àjọsepọ̀ pẹ̀lú odidi baálé ilé kan kó lè báà r'ówó ná.
Ko tan sibẹ, Oyinkan tun jẹ aarẹ ẹgbẹ apapọ fawọn obinrin, National Council Of Women Societies ati aarẹ ayeraye fun ẹgbẹ Girls Guides lọdun 1982.
Adeleke bii jiga lati maa dije fun eto idibo  gomina  to waye ni ojo kejilelogun, osu kesan an, odun
Gẹ́gẹ́ bíi àlàyé wọn, ìlànà tí wọ́n fi ń se òdiwọ̀n èlé owó orí ọjà fihàn pé, owó ọjà lọ sókè lósù kẹta ọdún 2018.
Ojú òpó ajàfẹ́tọ̀ọ́ ẹni: Àádọ́ta lọ́yà ló wà ń bẹ̀ láti jà fún ọ
Akọwe ẹgbẹ oṣelu PDP, Kola Ologbondiyan lo sọ ọrọ yii lasiko to n ba BBC Yoruba sọrọ.
O ni aare ni ipinnu lati mu orile ede Naijiria de
Ẹẹdẹgbẹta ẹrọ yii ni awọn eeyan du ra, eyi to pa miliọnu mẹtadinlogun ati aabọ dọla wọle.
Falana ṣalaye pe Buhari kan naa to sọrọ lọdun 1984 pe awọn ile iwosan to wa ni Naijiria ko ju ibi tawọn eeyan kan ti n ri awọn dokita lasan lọ, oun naa si ni aarẹ Naijiria lonii ti awọn iwosan ti di mọṣuari.
 He was heard on tape claiming to have spent N300m-400m per state x 36 states.
Ọrọ to sọ ninu fidio naa fihan wipe, ohun ti abiyamọ to lu naa sọ ni wipe, ko fi ara balẹ nigba to n pariwo, ni inu ba bi.
National Electoral Commission) ti  bẹrẹ lati maa ka abajade esi ibo  gomina  ipinlẹ Rivers  ni olu-ilu naa to wa ni Port Harcourt.
Ṣugbọn ẹ lè jẹ gbogbo àwọn ohun tí ó bá ní ìyẹ́, tí wọ́n sì mọ́.
22 Èbibi 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ile igbimọ asojusofin lorilẹede Naijiria ti fi ontẹ lu abadofin to fopin si lilo rọba tabi nylon ni Naijiria.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Burundi: Wọ́n búra fún Evariste Ndayishimiye bii Ààrẹ Burundi 18 Òkùdu 2020 Oríṣun àwòrán, Getty Images Gẹgẹ bii aarẹ to jẹ saaju rẹ, eyiun Ọgbẹni Nkurunziza, Ọgagun Ndayishimiye bori ikọlu ti wọn ṣe sawọn akẹkọọ to jẹ ẹya Hutu ninu ọgba ile ẹkọ fasiti naa, to wa ni olu ilu tẹlẹ fun orilẹ-ede Burundi, Bujumbura.
Ìpinlẹ Òsun pé ọmọ ọduń méjìdínlógbọn, àsantán owó osù ti bèrè!
Buhari di alága àjọ Ecowas Gomina Sokoto náà fi APC sílẹ̀ lọ PDP Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Olóṣelú máa ń wá ẹgbẹ́ ti wọn lè lò láti mu ìpinu wọn ṣẹ Ti a ko ba gbagbe, Osu Kẹsan, ọdun to kọja ni Aarẹ Buhari lọ irinajo si ilẹ Gẹẹsi lati lọ se ayẹwo ara rẹ.
officiel @eaguingamp @olympiquedemarseille @chelseafc @shanghaishenhua @galatasaray @impactmontreal @phxrisingfcA post shared by  didierdrogba (@didierdrogba) on Nov 21, 2018 at 2:22pm PSTGege bi o se so: “Ti mo ba ro igba ti mo wa lomo ogun odun ninu ere boolu afesegba, lati maa wo aworan yii ki se ohun ti o wu mi lori, bi kii baa se aseyori lolokan-o-jokan eyi ti mo ti se gege bi agabboolu, eleyi ti o si tun ron mi lowo lati di okunrin.
Wọ́n fi àkọlé kan kọ́ sí òkè orí rẹ̀, wọ́n kọ ẹ̀sùn tí a fi kàn án sibẹ pé, “Eléyìí ni Jesu ọba àwọn Juu.
Ọjọ́ meje kọjá, lẹ́yìn tí OLUWA ti fi ọ̀pá lu odò Naili.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Chelsea vs Crystal Palace: Chelsea bínú gbẹ̀san ìyà Tottenham lára Crystal Palace 3 Ọ̀wàrà 2020 Oríṣun àwòrán, Getty Images Akọnimọọgba ẹgbẹ agbabọọlu Chelsea, Frank Lampard ti fi idunnu rẹ han pẹlu bi wọn ṣe na Crystal Palace lalubami pẹlu ami ayo mẹrin si odo.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Lockdown updates: Naira Marley gbóríyìn fún Jude Chukwuka pẹ̀lú #1 míliọnù Ninu ifọrọwerọ pẹlu ileeeṣẹ iroyin abele kan, aarẹ ASUU, Ọjọgbọn Biodun Ogunyemi ni o yẹ ki Naijiria kọgbọn lara ilẹ Kenya to tilẹkun awọn ile iwe rẹ titi di ọdun 2021 nitori ilera ara ilu lo jẹ ẹ logun.
“Ijiroro si n lọ lọwọ bayii
Gbogbo igbinyanju BBC lati ba awọn alakoso PPMC sọrọ nipa ikede yi ko ti seso re.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Èlé owó iná ọba kọ́ ló kàn, ẹ kọ́ ṣàtúnṣe sí ìlànà àdánú tẹ́ ń ṣe fún wa - Iléeṣẹ́ apínná sọ fún ìjọba Àdínkù bá owó ojúmọ́ ọlọ́kadà l‘Ọyọ láti ₦200 si ₦100, owó gbígbà bẹ̀rẹ̀ lónìí A fẹ́ ìtọ́jú fún Boko Haram tó bá ronúpìwàdà, ẹ dá iléeṣẹ́ sílẹ̀ fún ìtọ́jú wọn - Ilé aṣòfin Olùkọ́ tó fi tipá gba ìbálé akẹ́kọ̀ọ́ tó fẹ́ wọ fásitì rí ẹ̀wọ̀n ọdún 21 he Fayose, o kò ní àmúyẹ gidi láti di ọmọ ẹgbẹ́ wa, àyè kò sí fún ọ - APC Ekiti Oloye Elebuibon ni awọn oyinbo alawọ funfun lo ma n ṣe iru nnkan bẹẹ, ati pe ko si ninu aṣa ilẹ Yoruba.
Gẹgẹ bi iwadii kan eyi ti Journal of Epidemiology and community health gbe jade lọdun 2018, eeyan ẹgbẹrun kan ati mẹrindinlaaọjọ (1,146) ni ẹmi wọn ti ọwọ ọlọpaa bọ lọdun 2015 ti ẹgbẹrun kan o le mejidinlaadọfa (1, 092) miran si tun ku lọwọ ọlọpaa lagbaye lọdun 2016.
” Nígbà tí wọ́n gbọ́ pé àpótí ẹ̀rí OLUWA ni ó dé sí ibùdó àwọn Heberu, 
Lẹ́yìn náà ni gbogbo àwọn igi sọ fún igi ẹ̀gún pé kí ó wá jọba lórí àwọn.
'Ìdí rèé tí mo fi ṣẹ̀ṣẹ̀ sọ̀rọ̀ lẹ́yìn tí wọ́n fipá bámi lopọ̀ lọ́mọ ọdún méje lọ́gọ́ta ọdún sẹ́yìn' Bó tilẹ̀ jẹ́ pé ìròyìn òfegè ni pé Buhari fẹ fẹ́ Sadiya, síbẹ̀ àwọn ọmọ Nàìjíríà ń ṣètò ìyàwò náà lórí ayélujára 'Títẹ àwọn afipábánilopọ̀ lọ́dàá kọ́ ni ọ̀nà àbáyọ sí ìwà ìfipábánilopọ̀' Ọpẹ́ o!
Ìwà òmùgọ̀ ni èyí tí o hù yìí; nítorí pé láti ìsinsìnyìí lọ nígbàkúùgbà ni o óo máa jagun.
DC - BBC News Yorùbá BBC News, YorùbáFò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù COVID-19 variant tó wà ní Nàìjíríà tún yàtọ̀ sí ti UK - NCDC 22 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 25 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Oríṣun àwòrán, Getty Images Ajọ to n ri si igbogun ti aisan lorilẹede Naijiria, NCDC ni irufẹ arun Covid-19 ti wọn ṣẹṣẹ ri lorilẹede Naijiria ko fara jọ awọn eyi to ṣí wọ orilẹede UK ati South Africa.
Tí ó bá di ìgbà náà, ẹ̀ka igi OLUWA yóo di ohun ẹwà ati iyì.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Ẹni bá láyà kó wá wọ̀ọ́!
Tunde Bakare, ẹni to tun kesi awọn ọmọ ogun orilẹede Naijria lati dẹkun yiyaju sawọn araalu, tun rọ wọn lati maa se isẹ wọn tọwọ tọwọ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù UK Parliament on Nigeria: Geoffrey Onyeama ni aṣofin UK kò lágbára láti sọ̀rọ̀ lórúkọ ìjọba UK 24 Bélú 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 26 Bélú 2020 Oríṣun àwòrán, @Geoffrey Minista fun ọrọ ilẹ okeere ni Naijiria, Geoffrey Onyeama ti fesi pada fun awọn aṣofin United Kingdom pada lori ọrọ idajọ ifiyajẹni lasiko iwọde EndSars ni Naijiria.
Ninu oro re, eleyi ti agbenusoro ile-ise aare, Garba Shehu fi sita lojo Aiku(Sunday), O so pe, isele naa ba aare Buhari ninu je pupo, eleyi ti o gba emi eniyan, ti o si tun ba dukia awon eniyan je lopolopo.
Awọn agbẹjọro ati awọn osisẹ ileẹjọ to ti yẹ ki adajọ joko gbọ ẹjọ laarọ oni, lo fidi isẹlẹ naa mulẹ pe awọn ajinigbe ti ji adajọ lọ.
Nítorí a kò gbọdọ̀ gba Èṣù láyè láti lò wá, nítorí a kò ṣàì mọ ète rẹ̀.
Amọṣa titi di bi a ṣe n sọrọ yii, diẹ lara awọn ti a mọ nipa iṣẹlẹ iku rẹ niyi: Awọn ẹbi oloogbe naa ṣalaye pe, ni iwoye wọn ọrọ iku rẹ, bi iku ile ko ba pani tode ko lee pani ni ọrọ ọhun.
 irinse àwọn ọdẹ , àwọn ọ ̀ mọ ̀ lé àwọn alágbẹ ̀ dẹ ló ń rọ gbogbo rẹ ̀ .
Eyi ko ṣẹyin bi ọpọ ṣe ni wọn ko mu ileri ti wọn ṣe lasiko ipolongo ibo ṣẹ.
Ibeere fun ogunbanjo: O ni ko ni iriri oselu ogun.
Saaju, adari egbe oselu EFF Julius Malema ti pe fun titu ile-igbimo asofin ka.
Èmi wá ní orúkọ Baba mi, ẹ̀yin kò gbà mí.
Ẹni tí ó bá bèèrè nǹkan lọ́wọ́ rẹ, fi fún un.
Oríṣun àwòrán, @aireyys Awuyewuye waye nipa iṣẹlẹ yii ṣugbọn Mike ni awọn pada yanju rẹ.
A lérò wi pé àwọn oníwà ìbàjẹ́ ti ó jẹ́ Olóri Òṣèlú ilẹ̀ Alawo dudu ti ó n ja ilú lólè lati kó irú, ọrọ̀ ilú lọ pamọ́ si àwọn ilú ti o ti dàgbà sókè yio ronú pìwàdà.
Mo bi Ọlọrun, àpáta mi pé,“Kí ló dé tí o fi gbàgbé mi?
Oru ọjọ Iṣẹgun ni ajọ naa kede bẹẹ loju opo Twitter rẹ.
Fi aṣọ aláwọ̀ aró, ati ti elése àlùkò, ati aṣọ pupa ya àwòrán èso pomegiranate sí etí ẹ̀wù àwọ̀kanlẹ̀ náà nísàlẹ̀, sì fi agogo ojúlówó wúrà kéékèèké kọ̀ọ̀kan la àwọn àwòrán èso pomegiranate náà láàrin, yípo etí àwọ̀kanlẹ̀ efodu náà, nísàlẹ̀.
Nítorí náà ni mo fi fi ibinu búra pé,wọn kò ní wọ inú ìsinmi mi.
Lo ba deede yinbọn pa agbofinro to kọkọ da ọkọ rẹ duro ko too tun kọju ibọn sawọn ero atawọn awakọ nibẹ.
Ohun kan ṣoṣo tí ó lè mú kí ọ̀rọ̀ náà ṣeéṣe ni pé kí ẹ̀yin náà dàbí wa, kí gbogbo ọkunrin yín kọlà abẹ́.
Bí ìjà bá wà láàrin èmi àti Olubadan, a ó yanjú ẹ ní pẹ̀lẹ́kùtù, ọ̀rọ̀ bàbálọ́jà kò lè dìjà Àwọn ará ìlú Ikarẹ Akoko ń ṣọ̀fọ̀ Ọba Adegbite, Ọwá Ale Ikarẹ tó wàjà Ọba Saudi Arabia yọ ọmọ rẹ̀ àti àbúrò rẹ̀ kúrò nípò nítorí ìwà àjẹbánu lórí owó tó yẹ fún ààbò ìlú Ìjàmbá ọkọ̀ tó ṣẹlẹ̀ sí Adams Oshiomole kìí ṣe ojú lásan, àwọn kan ló fẹ́ pa á- APC Sinimá àwòdamiẹnu, Ẹ̀fáńjẹ́líìsì jìyà àjẹmumi nílé aṣẹ́wó l'Ejigbo ní ìlú Eko Iléeṣẹ́ ìròyìn Daily Trust gbọdọ̀ san N6 bilion nítorí ìbanilórúkọjẹ́- Femi Fani Kayode Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí NUJ ìpínlẹ Oyo bà àwọn ọmọ ẹgbẹ́ tó lọ ìpàdé tí Femi Fani Kayode pè ní Ibadan wí7 Owewe 2020 12:41 Fídíò, Baby abandoned on dunmpsite: Mo ti bímọ mẹ́rin tẹ́lẹ̀ fún bàbá méjì nínú òṣí- Dupe Ogbomọṣọ, Duration 12,414 Owewe 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Nítorí pé òun ni ó ni àwọn ìpìlẹ̀ ayé,òun ni ó sì gbé ayé kalẹ̀ lórí wọn.
Olootu ijọba ilẹ naa, Shinzo Abe kede iranwọ owo ọhun fun ẹka eto aabo ati ilera lorilẹede Naijiria nibi ipade to sẹ pẹlu Aarẹ Muhammadu Buhari ni ilu Yokohama.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Cosmic Crisp apple: kò le bàjé nínú ẹ̀rọ amúǹkan tutù fún ọdún kan Apple tuntun ọ̀hún ni wọ́n n pè ni Cosmic Crisp, èyí ti wọ́n fi àdàpọ oyin àti òwò ṣe, pẹ̀lú fasiti Washington ni wọ́n ti bẹ̀rẹ̀ si ni gbìn láti ọdun 1997 Àfilọ́lẹ̀ èso ẹlẹ́rindòddò yi gba mílíọnù mẹ́wàá dọ́là.
Ta ni ń wá ọ̀nà láti pa ọ́?
Rabiu Yusuf, ìgbákejì ọ̀gá àgbà ọlọ́pàá Nàìjíríà (AIG) lẹ́kùn Katsina jáde láyé Wo ọ̀rọ̀ tí gbogbo agbàyé fẹ́ràn jùlọ lójú òpó Twitter Irọ́ ni, kò sí olóyún nínú àwọn tí Tírélà pa ní Ondo ṣùgbọ́n awakọ̀ ti sá lọ- Ọlọ́pàá Ondo Ẹ̀fọn Arsenal já bàálù Liverpool lulẹ̀ ní Wembley ní ìrìn-àjò sí Community Shield Wo ọ̀nà márùn ún tí o lè gbà dáàbò bò ara rẹ lọ́wọ́ ìjàmbá láì gbé ìbọn!
ifesewonse ohuti akọnimọọgba Pep Guardiola gbe wọ gba pẹnariti ṣugbọn ẹsẹ goli
kí ẹ má baà darapọ̀ mọ́ àwọn orílẹ̀-èdè tí wọ́n ṣẹ́kù láàrin yín, kí ẹ má baà máa bọ àwọn oriṣa wọn, tabi kí ẹ máa fi orúkọ wọn búra, tabi kí ẹ máa sìn wọ́n, tabi kí ẹ máa foríbalẹ̀ fún wọn.
Àwọn àjàgà wọn nìwọ̀nyí, ati àwọn igi ìpakà tí o lè lò fún igi ìdáná.
O ni igbagbọ oun ninu wiwa imọ kun imọ lo ṣokunfa bi oun ṣe pada si ileewe.
Mo fẹ́ fi hàn wípé àpẹẹrẹ ni Inal jẹ́; ọ̀pọ̀ ọmọ ‘Inal’ ni ó ti wà ní Mauritania.
to je adari iko NNS Thunder lo soro yii lojo Aiku pe oko naa ti gunle si ebute
Bi awọn ipinlẹ to ni Coronavirus ni Ọjọ Iṣẹgun ṣe lọ ree: FCT-40 Eko-34 Plateau-26 Enugu-14 Delta-12 Ogun-12 Ondo-9 Oyo-8 Ekiti-6 Ebonyi-4 Adamawa-2 Nasarawa-2 Kwara-2 Rivers-2 Edo-1 Osun-1 Bauchi-1 Ènìyàn 296 ló kó àrùn Coronavirus ní Nàìjíríà ní Ọjọ́ Ìṣẹ́gun Ajọ to n gbogun ti ajakalẹ arun lorilẹede Naijiria, NCDC ti kede pe eeyan 296 miran ti lugbadi arun Covid-19 ni Naijiria.
Ṣugbọn ọpọ ọmọ Naijria ni ko mọ nipa aṣeyọri awọn aramọda obinrin wọn yii.
Oríṣun àwòrán, Others Nibayii, awọn oṣiṣẹ pajawari n ṣiṣẹ lati ri wi pe wọn tete ri awọn to sọnu naa.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Nigeria Air: Ilé iṣẹ́ ọkọ̀ òfúrufú tuntun ṣí'wọ́ iṣẹ́ 18 Agẹmo 2018 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 19 Owewe 2018 Oríṣun àwòrán, @Bashir Ahmad Àkọlé àwòrán, Ijọba Naijiria sọ nigba ti wọn kede idasilẹ ileeṣẹ naa pe ojú ọnà mọ́kànlélọ́gọ́rin ni ọkọ òfurufú náà yóò ma rin Mínístà fún ètò ìrìnàjò ọkọ̀ òfurufú Hadi Sirika ti kẹde pe wọn ti so ileesẹ ọkọ ofurufu Naijiria tuntun, Nigeria Air rọ bayi.
Ikọlu wáyé láàrin àwọn ọmọ ogun Nàìjìríà àti Shiite
Cafra Caino, ti igbakeji rẹ , ogbeni Jagaba Kutara,soju fun, dupẹ lọwọ ajo
asia egbe All Progressives Congress (APC), ni ajo INEC kede pe o jawe olubori
Eyi to mu ko jẹ akọbi awọn obi rẹ.
Wọ́n sì jíṣẹ́ Hesekaya ọba fún Aisaya pé, “Ọba sọ pé òní jẹ́ ọjọ́ ìrora, wọ́n ń fi ìyà jẹ wá, a sì wà ninu ìtìjú.
O ya mi lẹnu, o si mu oun kan ti ọrẹ mi kan sọ fun mi wa sọkan mi.
Ọjọ́ Ajé, ọ̀sẹ̀ yìí ní ìjọba ìpínlẹ̀ Kano yọ Sanusi Lamido ní orí oyè gẹ́gẹ́ bí Emir ìpínlẹ̀ Kano.
Nígbà tí Ahabu rí Elija, ó bi í pé, “O tún ti rí mi kọ́, ìwọ ọ̀tá mi?
" Sanyeri tun salaye pe awọn obi òun ko nifẹ si ere ori itage, amọ oun ko sọ fun wọn pe oun ti n ṣe tiata.
Ṣugbọn ẹni tí ó ń pèsè irúgbìn fún afunrugbin, tí ó tún ń pèsè oúnjẹ fún jíjẹ, yóo pèsè èso lọpọlọpọ fun yín, yóo sì mú kí àwọn èso iṣẹ́ àánú yín pọ̀ sí i.
“Bí ẹnìkan bá rí ọmọge kan, tí ó jẹ́ àfẹ́sọ́nà láàrin ìlú, tí ó sì bá a lòpọ̀, 
Eyi fihan pe ohun ti awọn oniṣowṣo epo ba ra ni ọja epo agbaye ni wọn yoo fi ṣe odiwọn iye ti wọn yoo taa lọja abẹle fun awọn ọmọ orilẹede Naijiria.
Ahabu ọba Israẹli ati Jehoṣafati ọba Juda lọ gbógun ti Ramoti Gileadi.
Ètò yìí ni ó wá hàn kedere nisinsinyii nípa ìfarahàn olùgbàlà wa Kristi Jesu, tí ó gba agbára lọ́wọ́ ikú, tí ó mú ìyè ati àìkú wá sinu ìmọ́lẹ̀ nípa ìyìn rere.
Obedi Edomu ati Jehaya pẹlu ń ṣọ́ ẹnu ọ̀nà ibi tí wọ́n gbé Àpótí Majẹmu sí.
Bat: Kìí ṣe ènìyàn nìkàn ló ń ṣe òfin ìyàsọ́tọ̀ lásìkò àìsàn ẹranko kan rèé tó ń ṣe bẹ́ẹ̀
Lara awon ti o wa sibi apeje ohun ni: igbakeji aare, ojogbon Yemi Osinbajo, alaga egbe osleu APC, Odigie Oyegun, adari egbe naa, Bola Ahmed Tinubu, adari egbe ohun ti eka awon ipinle ti o kogun si iwo oorun, Bisi Akande, awon minisita ati gomina awon ipinle lorisirisi naa ko gbeyin, ti o fimo awon ti o dije dupo ohun méjílélọ́gbọ̀n ninu egbe oselu naa nipinle Ekiti.
Mo da aba, ẹwọn ọdun mẹẹdọgbọn.
Gomina Simon Lalong ti wa paṣẹ pe ofin konile o-gbele naa yoo wa lati aago mẹjọ alẹ, ki awọn eniyan ba le raye lọ si ibi iṣẹ wọn lai si idaduro lori rẹ.
Hon Temitope Sugar lo dije fun ipo asofin agba ni ekun idibo Aarin
Wọ́n sá níwájú àwọn ọ̀tá wọn nítorí pé, wọ́n ti di ẹni ìparun.
Dokita yọ góòlù kílò kan àtààbọ̀ àti owó ṣílè nínú obìnrin kan
Bakan naa ni ipolongo idibo naa ti o ṣe ni Charleston ko fi idi rẹ mulẹ boya lootọ ni o fẹ fi gbogbo ara dije dupo naa tabi ofege ni.
Sọ àsọtẹ́lẹ̀ nípa ikọ̀ tí yóò gba ife ẹ̀yẹ àgbáyé 2018 pẹ̀lú eré ìdárayá tuntun ti BBC
Ijọba South Africa ṣe agbekalẹ ofin to de karakata ọti lilẹ lati mu adinku ba iye awọn eeyan to n lọ si ile iwosan.
Jesu kìlọ̀ fún wọn pé kí wọn má wí fún ẹnikẹ́ni.
Ó bá lọ sí àgọ́ àwọn ọmọ-ogun, ó lọ ròyìn fún Paulu.
se, nitori pe ,o ni se pelu  eto ilana
O fikun un pe mama oun lo kọ oun bi eeyan se lee fi ara pamọ si abẹ ẹru nla lasiko ti ojo ba n rọ lọwọ,.
Ibanuje d'orí agbà k'odò, Ruiz fi ẹ̀ṣẹ́ sọ Anthony Joshua di ọmọ ológo àná Sẹ́nétọ̀ Dino Melaye kéde láti dupò gómìnà Kogi Sìgá mímu ń di èèwọ̀ oògùn ìlera pípé lagbaye 'Ọmọ SS 1 mu èso olómi, ṣùgbọ́n ilé ìwé wa kọ́ ló kú sí' Aawẹ Ramadan jẹ ọkan lara opo marun un ẹsin Islam.
Gómìnà Kẹrinlá – Ọ̀gbẹ́ni Akínwùnmí Ambọde – Gómìnà lọ́wọ́lọ́wọ́ lati ọdún meji titi di òni
 títí di ọdún 2013 kò sí àjẹsára kankan tó nṣiṣẹ ́ .
Ẹni tí wọ́n bá yàn sí ipò olórí alufaa lẹ́yìn Aaroni ninu àwọn ọmọ rẹ̀ ni yóo máa rú ẹbọ yìí sí OLUWA gẹ́gẹ́ bí ìlànà títí lae, gbogbo ìyẹ̀fun náà ni yóo fi rú ẹbọ sísun.
Ìró ilu maa n jẹ ọna ibaraẹnisọrọ laarin eniyan meji tabi ju bẹẹ lọ, bi ẹrọ ibaraẹnisọrọ ṣe ri l'ode oni.
Oríṣun àwòrán, Reuters Awọn ololufẹ rẹ ni o ṣeeṣe, ki o fi lede pe oun fẹ dije dupo nitori a ti ta awọn orin tuntun ti o fẹ gbe jade.
Marun un pataki ninu iran ti Alufaa Olukọya gbe kalẹ fun ọdun 2019 ni: 1) Ọdun ara ọtọ ni ti o si nilo adura ọtọ.
Drug Law Enforcement Agency NDLEA) lati tu asiri awon ọdaran  to gbe oogun oloro sinu ẹru arabinrin Zainab
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Gómìnà Sanwo Olu ní òun kò sanwó ẹbùn N41.
Laipẹ laijinna, Ọba oke bukun Adegbọrọ, to si ra ọmọlanke bii meje kun eyi to ni.
Ẹgbọn Tolulope, Damilola Adegboye ni awọn ko gba iroyin pe ọkọ to rin wa ṣẹyin lo pa a.
Otti wipe Kọmisona fun awọn ọlọpa, Imohimi Edgar ti paṣẹ fun ile iṣẹ ọlọpaa lati gbe ọkunrin naa lọ si ile ẹjọ nitori iwadi ti awọn ọlọpaa ṣe ati ayẹwo ti awọn dokita ṣe fun awọn oloogbe naa.
nipa eto irinna oko ofurufu nile Afirika to waye niluu Abuja, ti ile-ise to n
Oríṣun àwòrán, others Amọ, Odame ko sọ ibi ti ibọn naa ti ba a nitori o le dabaru ayẹwo ti wọn ṣe fun un lẹyin iku rẹ.
Ras Mubarak tó n ṣojú ẹkùn Kumbungu nílé àṣòfin àgbà ni Ghana n béèrè bóyá wọn yóò fí Aarẹ Akufo-Addo sí àhámọ́ lọ́tọ̀.
Nígbà tí wọ́n jáde kúrò ninu odò.
Bakan naa ni wọn fi ami ẹyẹ Industry Merit Award da a lọla, fun awọn aṣeyọri to ti ṣe gẹgẹ bi oṣere, nibi ayẹyẹ fifunni ni ami ẹyẹ Africa Magic Viewers Choice Awards.
Àwọn ọmọ ogun yòókù láti inú ẹ̀yà Bẹnjamini kó ara wọn jọ sẹ́yìn Abineri, wọ́n sì dúró káàkiri lórí òkè, pẹlu ìmúra ogun.
Ìdìbò ti parí ní ìpínlẹ̀ Kogi àti Bayelsa tí ìbò gómìnà ti wáyé Messi gọ̀ láti sọ fun akọ́nimọ̀ọ́gbá Brazil pé kó gbẹ́nu dákẹ́- Thiago Silva Afunrasí jàǹdùkú 22 lọ́wọ́ ọlọ́pàá ti tẹ̀ lórí wàhálà ìdìbò ní Kogi-Iléeṣẹ́ Ọlọ́pàá Ikú ni fífi oògùn 'Paracetamol' bọ ẹran tàbí se ẹ̀wà- Iléeṣẹ́ ìlera Oun naa ni ọmọ to ni ipenija ẹsẹ lati igba ibi rẹ ti wọn si ti sọ fun un pe wọn gbudọ ge ẹsẹ naa.
Ṣùgbọ́n ó dùn mí láti wí pé ibẹ̀ ni Àgùntàn-ìnàkí tí sọ ẹ̀mí ara rẹ̀ nú.
Ìjọba Nàìjíríà ti rí obìnrin tó wà l'óko ẹrú ní Lebanon gbà Ẹ̀bùn ọdún tuntun tó yááyì ni ikọ̀ Amotekun - Soyinka Imam tó fẹ́ ọkùnrin míì níyàwó forí kó ìjìyà òfin Owó orí VAT di 7.
Awọn orilẹede mẹtalelọgbọn ti awọn eniyan wọn ku nibẹ ree: Kenya (32), Canada (18), Ethiopian (9), China (8), Italy (8), American (8), French (7), British (7), Egypt (6), Netherlands (5), UN passport (5), India (4), Russia (3), Morocco (23), Israel (2), Belgium (1), Uganda (1), Yemen (1), Sudan (1), Togo (1), Mozambique (1), Norway (1), Nigeria (1) Oríṣun àwòrán, FlightRadar24 Àkọlé àwòrán, Irinajo ọkọ naa re ninu ẹrọ FlightRadar 24 Awọn oṣiṣẹ aranilọwọ ti ijọ aguda mẹrin naa wa ninu ijamba naa.
Kí ló dé tí o fi kó àwọn eniyan wọnyi gòkè odò Jọdani láti fà wọ́n lé àwọn ará Amori lọ́wọ́ láti pa wọ́n run?
Ninu atejade kan ti akowe agba egbe awon osise naa, NLC ati Trade Union Congress TUC, dokita Peter Ozo-Eson ati ogbeni Ozigi bowolu, egbe naa fi mule pe ki gbogbo omo egbe re patapata bere iyanselodi lai fi oro naa fale rara lataari aikobi ara ijoba lati joko jiroro lori afikun owo osu awon osise.
Alágbàṣe tí kì í ṣe olùṣọ́-aguntan, tí kì í sìí ṣe olówó aguntan, bí ó bá rí ìkookò tí ń bọ̀, a fi àwọn aguntan sílẹ̀, a sálọ.
Lasiko ọkan ninu awọn iwọde yii, awọn osisẹfẹyinti kan ba BBC Yoruba sọrọ nipa ohun ti wọn n la kọja, ẹ gbọ wọn: Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Àwọn oṣiṣẹ feyinti ni Osun ṣé iwọde Atunse Ile Ekọ: Lọpọ igba ni ijọba ipinlẹ Ọsun labẹ Arẹgbẹsọla ati ẹgbẹ oselu rẹ, APC, maa n tọkasi ọpọ iyipada rere to de ba awọn ile ẹkọ nigba ti Aregbesola ṣe ijọba.
Awọn ọlọde to n koju awọn agbesunmọmi pelu awọn ologun jẹ ologun abẹlẹ to n ran awọn ọmọogun Naijiria lọwọ lati koju ikọ agbesunmọmi.
Lẹ́yìn náà, ní àkókò ìjọba Atasasesi, ọba Pasia, ọkunrin kan wà, orúkọ rẹ̀ ń jẹ́ Ẹsira, ọmọ Seraaya, ọmọ Asaraya, ọmọ Hilikaya, 
Ninu ẹri ti wọn jẹ niwaju igbimọ naa, wọn sọ pe awọn ologun ko yinbọn lu oluwọde, bi kii ṣe pe awọn yin ibọn ti ko ni ọta soke, lati fi tu wọn ka.
Ìwọ ṣá ti múra, kí o ṣe ọkàn gírí, kí o sì rí i dájú pé o pa gbogbo òfin tí Mose, iranṣẹ mi, fún ọ mọ́.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Àjọ onísirò Nàíjíríà: Àdínkù bá owó ọjà si ìdá mẹ́tàlá 12 Ìgbé 2018 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Àdínkù ti bá owó ọjà lábẹ́lé sí ìdá mẹ́tàlá lósù kẹta ọdún 2018.
Ni bayii, o ti di i mọ orilẹede meje ti ọpọ wọn si jẹ ilu ti Musulumi ti pọ ju.
Àkọlé àwòrán, Ṣáájú iyànsípò rẹ̀ gẹ́gẹ́ bíi olórí ilé aṣòfin ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́, òhun ni igbákejì akójánu ilé náà Ó ní wọn pinnu ìgbésẹ̀ yìí láti mọ ohun gan an tó ṣokùnfà ikú rẹ̀.
O ní àwọn fàyàwọ́ ọmọnìyàn ti kojú bọ ilé ìwé òhún láti máa kó àwọn ọmọ lọ sí ilẹ̀ òkèèrè.
Afẹ́fẹ́ lásán ni àwọn mẹ̀kúnnù;ìtànjẹ patapata sì ni àwọn ọlọ́lá;bí a bá gbé wọn lé ìwọ̀n, wọn kò lè tẹ̀wọ̀n;àpapọ̀ wọn fúyẹ́ ju afẹ́fẹ́ lọ.
Ọ̀mì ni ìjà 'arọ' méjì já sí ní Old Trafford Ilé yá!
Iléeṣẹ́ Twitter tí ojú òpó Ààrẹ Donald Trump lórí ẹ̀rọ rẹ̀ pa Àbẹ́wò ọlọ́jọ́ mẹ́ta Trump sí UK nínú àwòrán Buhari, Trump yóò ṣèpàdé l'Ámẹ́ríkà Niba yii, aarẹ Trump yoo foju wina igbẹjọ lọdọ awọn asofin agba, to ba si jẹbi, a jẹ pe wọn yoo fofin de e lati kopa ninu oselu titi aye.
Àwọn ọmọ Paroṣi jẹ́ ẹgbaa lé mejilelaadọsan-an (2,172)
Ọba ni ojiji Ọlọrun Ọba lórilẹ̀ ayé nítori náà ko yẹ ki Ọba maa bọ oriṣà Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Kò sí ǹkan tó ń jẹ́ ọ̀rọ̀ ìgbàgbọ́ tàbí ìmọ̀le nínú àgbékalẹ̀ Amotekun - Alake ti Egba Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Orúkọ ìyá rẹ̀ ni Naama, ará Amoni.
Alukoro fun igbimo yii , mallam Yunusa Abdullahi lo so eleyii di mimo ninu atejade kan lojobo ni ipinle Kaduna.
Ninu atẹjade ti ile iṣẹ DSS fi sita, eyi to si loju opo Twitter ajọ INEC, DSS ni ko si otitọ kan ninu iroyin miran to tun sọ pe ajọ na mu oṣiṣẹ INEC meja, wọn si fiya jẹ wọn fun ọjọ mẹta ki wọn le jẹwọ bi ọrọ naa ṣe jẹ gan an.
 O ni lara ibere ẹgbẹ awọn dokita ọhun ni pe ijọba maa san owo oṣu wọn papọ pẹlu awọn oṣiṣẹ to ku."
O salalye pe,ipinle ohun yoo pin apoti ero igbalode naa fun awon ti o ku die kaato fun ni awon igberiko.
Báyìí ni gbogbo àwọn ènìyàn wọnn-ọnnì bẹ̀rẹ̀ sí béèrè ohun  tí wọ́n ffẹ́, nígbà tí ó ṣe, Aṣojú-Olódùmarè wí fún wọn pé kí olúkúlùkù máa ṣe ìbéèrè nípa àìsàn rẹ̀ ṣùgbọ́n ó sọ fún wọn pé ẹni tí ó ba fẹ́ láti fi àìsan kan silẹ̀ níláti béèrè òmíràn dípò rẹ̀ tí wọ́n fi ara wé ara wọn nípa ibi tí wọ́n ń ṣe.
'Mẹ́ẹ̀dógún lókù láàyè nínú àwọn ọmọ Chibok' Njẹ ọrọ awọn akẹkọbirin Dapchi jọ ti Chibok ?
Idunu subu layo, lati ri omode-binrin re ti o je okan lara awon akekoo binrin adofa ti won ji gbe lojo kokandinlogun osu kejo odun 2018, ti pada layo ati alaafia, eyi ti o simi nile bayii.
Ojogbon Yemi Osinbajo to je Adele aare Naijiria bayii ti tewogba eto isuna fun odun 2017 kuro lowo awon omo ile igbimo Asofin agba l’Abuja.
Lẹyin ọ rẹyin, ile ẹjọ dajọ ẹwọn ọdun meje fun akọwe ẹgbẹ oṣelu PDP tẹlẹ.
adéolókun gbá fún leinster nígbà èwe rẹ ̀ .
Won gboriyin fun un gẹ́gẹ́ bii ogidi ọmọ Ogun to tẹpa mọsẹ Oríṣun àwòrán, OGIRS Ijọba ipinlẹ Ogun se sadankata Lekan pe omọ to se e fi yangan ni fun awọn ọdo asiko yii, Koda, won ti ranṣẹ ikini ku orire si 'ọmọ ologo' Laycon, to jẹ owo ati ẹbun BBNaijia to kasẹ nilẹ lọjọ Aiku.
Sani Bouajla – The Blessed Vost
N óo mú Israẹli pada sí ibùjẹ rẹ̀, yóo máa jẹ oúnjẹ tí ó bá hù lórí òkè Kamẹli ati ní agbègbè Baṣani, yóo sì tẹ́ ìfẹ́ ọkàn rẹ̀ lọ́rùn lórí òkè Efuraimu ati òkè Gileadi.
Gbogbo ọmọ ìgbìmọ́ aláṣẹ ìjọba ìpínlẹ̀ Oyo ló ṣe àyẹwò ààrùn Covid-19 Sùgbọ́n.
Igbakeji akọnimọọgba fẹgbẹ agbabọọlu Togo, Amelete Abalo naa figbe ta pe ọta ibọn ba oun, Amelete pada ku lẹyin ti ọta ibọn ba a tan.
Baba Jeremiah sọ fun BBC pe nitori pe awọn ko ni owo lọwọ, ọmọ naa ko fi ina mọna-mọna sun ri, tabi wo ẹrọ amohunmaworan ri.
Aarẹ ṣapejuwe rẹ gẹgẹ bii ọdọ ti ko wọpọ lasiko yii, to jẹ awokọṣe rere to ni ootọ inu.
Ọmọ ọdun mẹtalelọgọta ni Larisa bẹrẹ iṣẹ arinrin oge rẹ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Sekinat Quadri ọmọ ọdun meje ajẹsẹ to fẹ dabi Anthony Joshua Ninu aworan naa la ti ri Badirat ati ọba alaye naa, ti wọn wọn aṣọ oke kan naa lori ijokoo, ti wọn si n tẹ sọrọ, ori awọn mejeeji lo fẹẹ sun mọ ara wọn pẹki pẹki.
Johanu sọ fún un pé, “Ọ̀gá, a rí ẹnìkan tí ń fi orúkọ rẹ lé àwọn ẹ̀mí èṣù jáde.
Ẹni tó bá ń bínú kàn ń bínú lásán ni 12 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 14 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Oríṣun àwòrán, Facebook/Bishop David Oyedepo Oludasilẹ ijọ Living Faith ti ọpọ mọ si Winners, Biṣọọbu David Oyedepo tun ti sọ pe oun ko le toṣi laelae!
“Ṣebí Ọlọrun wà lókè ọ̀runÓ ń wo àwọn ìràwọ̀ nísàlẹ̀àní àwọn tí wọ́n ga jùlọ,bí ó ti wù kí wọ́n ga tó!
Toufah Jallow, to ti n gbe ni orilẹede Canada bayii sọ pe, oun sa kuro ni Gambia lẹyin ti Jammeh fi ipa ba a ni aṣepọ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Akomolede ati Asa lori BBC: Olùkọ́ Kikelomo Ogunboye tan ìmalẹ̀ sí ìwà olè ọ̀gá ọlọ́pàá Eyi waye nibi ipade igbimọ alaṣẹ ẹgbẹ naa to waye lori ayelujara nipasẹ Zoom ni ile aarẹ, Aso Rock niluu Abuja.
Asiko ti to ki igbẹjọ maa lọ bi o ti yẹ lai segbe fun ẹnikẹni ni Naijiria mọ́.
Gbogbo Israẹli gbọ́ pé Saulu ti ṣẹgun ọ̀wọ́ ọmọ ogun Filistini ati pé àwọn ọmọ Israẹli ti di ohun ìríra lójú àwọn ará Filistia.
" Ko si epo kankan ninu ọkọ náà ńgbà ti ìṣẹ̀lẹ̀ yìí ṣe, bákan náà ni abẹ̀bẹ̀ orí rẹ̀ dúró déédé lásìkò àbẹ̀wò lẹ́yìn ìṣẹ̀lẹ̀ ọ̀hún.
Adari ijọ mosalasi naa, Sheik Abdulwaheed Sulaiman  dupẹ lọwọ  Olorun Allah bi eto idibo se waye ni
Ewe, Aikhali Bangoura gba ami-ayo kerin wole, kii Plateau United o to taraji lati gba ami kan wole pelu boolu agbesile gba, besini Tosin Omoyele gba ami-ayo miran wole ki ifesewonse ohun o to wa si ipari.
Aare Buhari tun towobo iwe lati bowo fun awon akoni naa ninu iwe alejo,  ti o si lo oro Shakespeare’s ‘Julius Caesar  :”Iwa buruku ti awon eniyan ba wu, maa n tele won;sugbon iwa rere maa n wonu eegun lo.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ọ̀rọ̀ lórí Brexit Mọ síi nípa àwọn ti wọn n dupo Theresa May: Sam Gyimah jẹ ọkan lara awọn mọkanla naa bo tilẹ jẹ pe iran rẹ tan mọ orilẹ-ede Ghana.
Góòlù kan ní abala kíni ati meji ni abala keji ni won fi pá enu Liverpool mọ tí o sí jọ bí ẹni pé kikopa nínú asekagba ko ní yẹ fún wọ Ní sáà àkọ́kọ́ láàrin iṣẹju péréte ni Suarez ṣe gbá bọọlu sáwọn ilé Liverpool, Sùgbọ́n Lionel Messi ko sàànú ẹni kankan nígbà to ju góòlù èèkeji àti ẹkẹta sáwọn Liverpool Sùgbọ́n ni gba to di sáà keji, gbogbo ìgbìyànju Liverpool pàbó lo jási, se ti eni ti bọọlu wà ni ìkáwọ rẹ̀ jùlọ ni ka sọ ni tàbí ní ti gbigba bọọlu sile, ǹkan to ṣeni láànu jùlọ ni pé èyi ko ṣe pàtàki bii ki a wọn gbà bọọlu sáwọn.
Bí mo bá bà yín ninu jẹ́, ta ni yóo mú inú mi dùn bí kò bá ṣe ẹ̀yin kan náà tí mo bà ninu jẹ́?
Ẹ tún ń dá àwọn tí ó fẹ́ wọlé dúró!
Iwọde ọhun pa eto ọrọ aje lara ni opopona Ahmadu Bello, o si tun fa sunkẹrẹ fakẹrẹ ọkọ.
APÁ KÌNNÍ ÍN: ÌGBÀGBỌ́ ÀWỌN YORÙBÁ NÍPA ORÚKỌ
kí ẹ lè ní agbára, pẹlu gbogbo àwọn eniyan Ọlọrun, láti mọ bí ìfẹ́ Kristi ti gbòòrò tó, bí ó ti gùn tó, bí ó ti ga tó, ati bí ó ti jìn tó; 
”  Kò si owó, ọlá, ipò, agbára ti èniyàn ni, ti kò si ẹni tó ni ri tàbi ti ẹni ti ó mbọ̀ lẹhin kò lè ni.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Amẹrika: Ipa ti idẹnukọlẹ isejọba ni lori araalu 22 Sẹ́rẹ́ 2018 Àkọlé àwòrán, White House Ọjọ manigbagbe ni ọjọ ẹti, ọjọ kọkandinlogun osu kinni ọdun yii jẹ fun orilẹede Amẹrika nitori bi ẹnu awọn asofin lorilẹede naa ko se ko lori aba ilana owona fun ilẹ naa.
 Igbimo asofin wa fenuko lati yan igbimo tẹẹkoto pelu igbimo asofin agba lati se iwadii lori isele to waye  lojo Isegun nigba ti awon osise ile igbimo asofin faake kori lati maa jẹ ki awon asofin  mejeeji wọle si ile igbimo asofin.
Ní ìparí ọdún kẹrin, Absalomu tọ Dafidi lọ, ó ní, “Kabiyesi, fún mi láàyè kí n lọ sí Heburoni.
Nigba ti o n gbalejo minisita fun oro ile okere lorile-ede Tunisia, Boukekri Rmilli nile-ise Aare lojo-Isegun nilu Abuja, Aare Buhari so pe, isakoso oun yoo se alekun atileyin fun eto ogbin, ti o je ona kan gboogi lati pese ise.
Sẹnẹtọ Saniu fikun ọrọ rẹ pe onirẹlẹ eniyan ni Yar'Adua jẹ, bakan naa lo gbadura pe ki Eleduwa Alijana ṣẹsan 're fun un.
INEC kede ọjọ tuntun naa lori opo ayelujara Twitter rẹ.
Amọ eyi ko mu kawọn ọdọ naa dẹkun iwọde ọhun, ti wọn si n gbe idi dina lati dena lilọ bibọ ọkọ ati ero, titu ọgba ẹwọn silẹ, kikọlu awọn osisẹ ọlọpaa, ti wọn si tun n kslu awọn ileesẹ ati dukia ijọba gbogbo.
Kàkà bẹ́ẹ̀ ẹni tí ó bá jẹ èso àjàrà kíkan,òun ni eyín yóo kan.
 “A o gbiyanju lati mu iyipada ba eto ati ilana ti awon oloye egbe naa se.
Bi o tilẹ jẹ wi pe afunrasi alangana naa sa lọ ni kete to ṣiṣẹ ibi rẹ tan, ọwọ awọn ọlọpa tẹẹ lagbegbe ileto Agodo.
''Ohun to n ṣe oyinbo loyinbo n kojọ ninu fiimu, ki lo de ti a wa naa ko gbe tiwa jade faraye gbọ?
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ẹ wo fidio bi oṣiṣẹ Jamb ṣe sọ wipe ejo gbe 36m naira mi Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Ẹ wo fidio bi oṣiṣẹ Jamb ṣe sọ wipe ejo gbe 36m naira mi 15 Èrèlè 2018 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 16 Èrèlè 2018 Laipẹ yi ni Philomena Chieshe sọ fun awọn oloyẹwe owo wo to wa sisẹ ni ọọfisi ajọ Jamb to wa nilu Makurdi, nipinlẹ Benue pe ejo abami kan lo gbe owo to to miliọnu mẹrindinlogoji naiara mọ oun lọwọ.
O sọ itan aye rẹ àti bi oun ṣe pinnu pe oun ko ni jẹ ki aabọ ara oun sọ oun di ẹni ti yoo maa tọrọ kiri.
Agbegbe kan ti wọn n pe ni Gaa Eleesun nibi ti awọn darandaran Fulani n gbe ni iṣẹlẹ yii ti waye ni irọlẹ ọjọ Ẹti lẹyin ti awọn darandaran naa ti papa ijẹko de lati sinmi fun iṣẹ ọjọ naa gẹgẹ bi a ṣe gbọ.
Awon iko South Korea ko soro lori ipade naa sugbon won gba pe yoo bi awon ijiroro niran fun idagbasoek ati irepo.
 nígbà mìíràn , Èṣù jẹ ́ olùrànlọ ́ wọ ́ fún ifá .
 Ó ṣakitiyan fún ìbáradọ ́ gba àwọn ọmọ african-american , ó ṣe aṣíwájú fún civil rights movement ní 1960s .
lowo ninu sise pasi-paro ami idanimo awon eniyan ni ona atilu awon omo ile
Safiya Umar to jẹ ọga patapata fun ẹgbẹ naa sọ fun BBC pe awọn ko ni la oju silẹ ki awọn ọmọbinrin naa maa ṣe boṣe wu wọn.
Ẹ̀yin amòfin ati Farisi, alaiṣootọ; nítorí ẹ̀ ń jẹ ilé àwọn opó run; ẹ̀ ń fi adura gígùn ṣe ìbòjú.
''Ìdí tí mo fi rin ìrìn 800 metres'' Ọ̀gá DSS tẹ́lẹ̀ rí Daura kúrò l'àhámọ́ Bi ìdibò wọ́ọ̀dù APC ṣe lọ kákàkiri rèé Yar'Adua: Ọmọ Naijiria ránti ààrẹ àná Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Obasanjo: Atiku kìí se Áńgẹ́lì, àmọ́ yóò se dáadáa ní ìlọ́po méjì ju Buhari lọ 4.
Ẹfanjẹliisi Mathew yii ni wọn ni pe o n pariwo 'ẹ yi pada kuro ninu gbogbo iwa ọwọ yin' Gẹgẹ bi ọrọ ti ọkan lara awọn ti iṣẹlẹ naa ṣoju rẹ sọ, wahala naa bẹrẹ nigba ti ẹfanjẹliisi naa duro niwaju ilumọọka ile itura kan to wa ni Ejigbo to si bẹrẹ iwaasu fun awọn olowo nọọbi naa atawọn onibara wọn pe ki wọn fi awọn iwa ẹṣẹ ọwọ wọn gbogbo silẹ.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Laycon ni ọmọ ológo tó jáwé olúborí ní ètò BBNaija season 5 'Lockdown' Kí ló wà láàrin Olorì Badra àti Bobrisky, tí ọ̀rọ̀ wọn fi wọ̀?
SAFA tesiwaju pe, “Stuart Baxter yoo kede awon agba-boolu re ti yoo koju iko egbe agba-boolu orile-ede Naijiria lojo karundinlogbon osu karun un odun yii.
Àwọn eniyan sì jẹ́ ẹgbaajọ (16,000), ìpín ti OLUWA jẹ́ mejilelọgbọn.
Idajọ yi wa ni idahun si ẹbẹ ti agbẹjọro rẹ Nkem Okoro gbe lọ si iwaju adajọ N.
Kí Ọlọrun Olodumare jẹ́ kí ọkunrin náà ṣàánú yín, kí ó sì dá arakunrin yín kan yòókù ati Bẹnjamini pada.
“Ní apá ìhà ìlà oòrùn, ààlà náà yóo lọ láti Hasari Enọni tí ó wà láàrin Haurani ati Damasku, ní ẹ̀gbẹ́ odò Jọdani tí ó wà láàrin Gileadi ati ilẹ̀ Israẹli, títí dé òkun tí ó wà ní ìlà oòrùn, yóo sì lọ títí dé Tamari.
O ṣalaye pe ohun yii yoo si ma pe awọn orukọ adugbo lede wọn gangan eyi ti awọn Naijiria yoo gbọ́.
Ẹ̀mí Ọlọrun bà lé wọn, wọ́n sì ń sọ àsọtẹ́lẹ̀.
Ọjọ́ mẹfa ni ẹ óo fi jẹ burẹdi tí kò ní ìwúkàrà ninu, ní ọjọ́ keje, ẹ óo pe àpèjọ tí ó ní ọ̀wọ̀, ẹ óo sì sin OLUWA Ọlọrun yín.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Lagos 2019: Àwọn ọmọ ẹgbẹ́ awakọ̀ èrò ṣíná ìbọn níbi ìpolongo ìbò Sanwo-Olu l'Eko 8 Sẹ́rẹ́ 2019 Oríṣun àwòrán, PMnews Àkọlé àwòrán, Gómìnà Ambọde ni ó ń sọ̀rọ̀ nígbà tí wàhálà náà bẹ́ sílẹ̀ Oniroyin mẹta lo faragbọta nibi ipolongo idibo oludije ipo gomina ipinlẹ Eko labẹ aṣia ẹgbẹ oṣelu APC, Babajide Sanwo-olu nilu Eko ni ọjọ iṣẹgun.
Ìwọ̀n wúrà tí ó lò fún ọ̀kọ̀ọ̀kan jẹ́ ẹgbẹta (600) ṣekeli.
Richard Akinjide: Ìtàn igbe ayé Richard Akinjide, agbẹjọro àti olóṣèlú tó moye
lati maa se iwasu fun awon ọmọ ijọ wọn nipa ifẹ, alaafia, ni eyi ti yoo fi din
Mo pe e ni nkan bi aago kan ọsan ọjọ naa lati ki i, nitori pe o ṣẹṣẹ dee lati ipinlẹ Katsina pada si Kaduna, nibi ti wọn ti lọ kọjú ija si awọn agbebọn ni."
" Ẹ wo ìdí tí ẹ gbọdọ̀ fi gba abẹ́rẹ́ àjẹsára fún ọmọ yín!
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fọ́nrán ohùn, Ọlọ́fà tí Ọffà:Mo kí Ọ̀ọ̀ni kú iṣẹ́ ribiribi fún ìdàgbàsókè ilẹ̀ Yorùbá Ǹkan márùn-ún tó yẹ ko mọ̀ nípa Ọba Adeyeye Ogunwusi Ó ṣe pàtàkì kí à sọ àwọn ǹkan tí ọ̀pọ̀ ènìyàn kò mọ nípa rẹ̀ gẹ́gẹ́ bí ọba yìí ṣe jẹ́ ọkan gbòógì nínú àwọn ọba aláde nílẹ̀ káàrọ̀-òòjíre.
asia egbe oselu National Rescue Movement (NRM) ti jawe olubori nibe.
Atiku ni kò tíì dópin fún Adeleke, PDP ni àwọn gba idájọ́ wọlé Àlàyé rèé lórí ìdí tí ìyá mi fi sọ fáráyé pé mo ti kú Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Àjẹ́, eégún, kí ni wọn ò pè mí tán tórí Vitiligo lára mi' Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí 4:32 Fídíò, Fulani Kidnapping: Owó púpọ̀ la san kí wọ́n tó fi mi sílẹ̀ lẹ́yìn ọjọ́ mẹ́fà, Duration 4,328 Agẹmo 2019 Èyí ni ìdí tí àwọn obìnrin kan to n ṣe nkan oṣù fi n yọ ilé ọmọ wọn kúrò ní India7 Agẹmo 2019 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Osusan Oluwatobi tricycle accident: 'Ìgbà tí mo máa fi lajú sáyé padà, ọ̀fọ̀ ikú mi ní wọ́n ń kígbe' Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Osusan Oluwatobi tricycle accident: 'Ìgbà tí mo máa fi lajú sáyé padà, ọ̀fọ̀ ikú mi ní wọ́n ń kígbe' 24 Ògún 2020 Ki n ma fi kun un ki n si ma yọ kuro, ko tii to iṣẹju kan ti mo wọ inuu kẹkẹ, afi gbaa!"
Ní ọjọ́ keji, ẹ̀mí burúkú láti ọ̀dọ̀ Ọlọrun bà lé Saulu, ó sì ń sọ kántankàntan láàrin ilé rẹ̀.
Bakan naa, awon orile-ede ti Naijiria yoo maa waako pelu ninu idije boolu agbaye to n bo lona, Argentina, Croatia ati Iceland wa ni ipo karun-un, ipo kejidinlogun ati ipo kejilelogun ni itele n tele.
da awon omo ipinle naa loju pe awon odaran naa ko ni lọ laijiya labẹ ofin ati
E ku oge; E ku ẹwà, ẹ ku iṣẹ ati bẹẹ bẹẹ lọ ni a n gbọ, Wọn gba a, ṣugbọn o ni ijinlẹ ikini fun awọn ti wọn n di irun eeyan nilẹ Yoruba yatọ si eyi.
Baaṣa gorí oyè dípò Nadabu, ó sì di ọba ilẹ̀ Israẹli.
 Ó ti yá òpòlopò ènìyán kówó .
Bakan naa ló ni ki wọn má tíì sin òkú Otike, gẹgẹ bi wọn ṣe pinnu lọjọ Bọ tẹlẹ, ṣugbọn ki wọn duro ki iwadii fi parí ki wọn to sin in.
com/5mjAdaCEPSBakan naa oga agba ile-ise olopaa Mohammed Adamu jabo fun akoroyin ile ise aare wipe, o se pataki fun awon bayii lati mu igberu ba eto aabo layika awon opa epo robi ati awon ohun amayederun miiran lati dekun iwa ibaje ni awon agbegbe naa.
Ipaniyan naa waye ni ilu Koshebe nijọba ibilẹ Mafa ni ẹkun Ila Oorun-Ariwa ipinlẹ Borno eyi to jẹ ibi ija igba de igba ikọ Boko Haram.
Ohun ti wọn sọ fun baba ọmọ yii ni pe Chadia tapa si ofin kan to de awọn akẹkọọ ninu yara ikawe rẹ.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Bi o tilẹ jẹ pe ko ba ofin mu ki awọn eniyan ma a ta ọja ni ẹgbẹ ọna ni ipinlẹ Eko, awọn ọlọja nitori iya ati isẹ ma n tiraka lati duro si ẹgbẹ oju ọna lati ta ọja wọn.
Báyìí ni ìtàn náà párí – eléyìí ni ìtàn kẹta tí a gbọ́ nínú ilé Òpìtánparapọ̀.
 quechumaran fúnrarè náà jé omo egbé fún àwon èdè andea-equatorial .
Ninu atẹjade kan, olubadamọran Gomina lori eto ẹkọ alakọbẹrẹ ati ileewe Girama ni ipinlẹ Ogun, arabinbrin Ronke Soyombo ni awọn gbe igbesẹ ayẹwo yi lati dena itankalẹ arun Covid-19.
Àkẹ́kọ̀ọ́ gboyè ìmọ̀ ẹ̀rọ ni YabaTech ọun ni òun ri fótò ìhònhò náà nínú káàdì ìránti kan ní ìlẹ̀ẹ́lẹ̀ nílé iwé òun ní ínu ọsù kọkanlá ọdun 2019 ní.
 O ni Oba Adedapo feran alaafia ati idagbasoek ekun re nipa reran awon eniyan re leti nigba  gbogbo lori ifarada ati ife ilu.
” Saulu bá wí pé, “Ìwà ọ̀dàlẹ̀ ni ẹ hù yìí.
Báwo ló se sẹlẹ̀ Àkọsílẹ̀ láti ilé isẹ́ ìjọba àpapọ̀ tó ń rísí ọ̀rọ̀ isẹ́ òde, iná mọ̀nàmọ̀nà àti ilégbèé nílu Àbújà fihàn pé, Ibùdọ Amúnáwá da isẹ́ sílẹ̀ láàrín ọjọ́ kejìlá sí ọjọ́ kẹrìnlá, osù kẹrin ọdún yìí, èyí tó sì ń dààmú ìpèsè iná títí di ìsinyìí.
Èyí jẹ́ ìpínlẹ̀ Guus- ìwọ̀ -òorun akọkọ tí yóò gbé ìgbesẹ̀ yìí.
lati fi satunse si awon ile ti won won yoo gbe maa  se ayẹwo  niluu Abuja.
Ọpọlọpọ awọn eeyan gbagbọ wipe Amala ati ọbe Ilasa ti awọn eeyan ilu naa kundun lo n ṣokunfa ibeji ati ọmọ to ju meji lọ, bẹẹ sini awọn ẹlomii ri iṣẹlẹ naa gẹgẹ bi ohun ti o ti ọwọ Ọlọrun wa.
” Nítorí àpótí Ọlọrun ń bá àwọn ọmọ ogun Israẹli lọ ní àkókò náà.
''Gbogbo ẹ̀yin tí ẹ lọ sí ibi ìpàdé PDP ní Ibadan, ẹ lọ yara yín sọ́tọ̀ fún àyẹ̀wò coronavirus'' Ọgọrọ eeyan lo dẹnu bo Gomina Seyi Makinde lori ayelujara lẹyin to ṣagbatẹru ipade itagbangba ẹgbẹ oṣelu PDP niluu Ibadan l'Ọjọru.
Ẹ gbọdọ̀ fún un ní ẹran ọ̀sìn lọpọlọpọ ati ọkà láti inú ibi ìpakà yín, ati ọtí waini.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Wole Soyinka: Pańpẹ́ ọba lọ̀nà àbáyọ sí ìwà ìbàjẹ́ 15 Èbibi 2018 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, 'Àwọn asèbàjẹ́ gbọ́dọ̀ fi ẹ̀wọ̀n ju 'ra' Ọjọgbọn ati onkọwe ni, Wọle Soyinka ti sọ wi pe ayafi ti awọn asebajẹ ba bẹrẹ si ni fi ẹwon ju 'ra, ko le e si opin si iwa ibajẹ lorilẹede Naijiria.
Melo la fe ka leyin adipele.
Awọn miran tilẹ tun fi orukọ gbogbo awọn ti ọrọ naa kan sita lori ẹrọ ayelujara, bi iwadi wa ba si se n lọ lori isẹlẹ yii, BBC Yoruba yoo maa mu wa fun yin.
Pẹlu ikede tuntun yii, ẹni to ba fẹ ẹ gba nọmba NIN ti le lọ si ileeṣẹ ibaraẹnisọrọ MTN, Glo, Airtel, ati 9mobile, lati fi orukọ silẹ, ati gba nọmba naa.
Àwọn ọmọ ogun Israẹli pe àwọn ọkunrin Israẹli jáde láti inú ẹ̀yà Nafutali, ati ti Aṣeri ati ti Manase, wọ́n sì bẹ̀rẹ̀ sí lé àwọn ará Midiani lọ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Tortoise surgery: Àwọn dókítà fi wákàtí mẹ́fà ṣiṣẹ́ abẹ dóòlà ẹ̀mí ìjàpá tí ọkọ̀ gbá 10 Owewe 2020 Oríṣun àwòrán, Others Dokita kan to jẹ onimọ nipa itọju ẹranko, Nura Abubakar to n ṣiṣẹ nile iwosan itọju ẹranko nipinlẹ Sokoto, ti ṣalaye ni kikun bi iṣẹ abẹ ti wọn ṣe fun ijapa ti ọkọ kan tẹ, ti igba ẹyin rẹ si fọ, ṣe lọ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Agneroh: Ohun gbogbo tí ẹ bá rí lórí ẹ̀rọ ayélujára kọ́ ni òtítọ́ 13 Ọ̀wàrà 2018 Oríṣun àwòrán, CHRISTIAN SHABANTU MPENGA Àkọlé àwòrán, Arábìnrin Arlène Agneroh sọ ìrírí rẹ̀ lórí ẹ̀rọ ayélujáre lẹ́yín tò fi àwòrán ọ̀hún àti ọ̀rẹ́ rẹ̀ ọkùnrin tí wọ́n ti wọ asọ kan náà sórí afẹ́fẹ́.
''Pẹlu gbogbo ikede ti Ọga Agba ọlọpaa kede, o ṣi fihan gbangba pe, ikọ SARS ko jẹwọ ninu iwa buruku ti wọn n hu si awọn ara ilu.
Awọn ọlọpaa ni ipinlẹ Zamfara ko lee sọ ni pato iye awọn to fi ara kaaṣa ikọlu yii sugbọn awọn to se oju wọn ni sa dede lawọn ole aji maluu naa dabo ọkọ ọhun to n ko awọn oniṣowo lọ si ọja abule ti wọn n lọ.
O wa rọ awon omo egbe APC lati se isẹ wọn bi isẹ, ni
Ṣugbọn, ẹ̀yin ní tiyín, ẹ má ṣe bẹ̀rù, ẹ mọ́kàn le, ẹ má sì ṣe jẹ́ kí ó rẹ̀ yín, nítorí iṣẹ́ yín yóo ní èrè.
”Ṣugbọn kò sí ẹni tí ó gbà wọ́n,wọ́n ké pe OLUWA, ṣugbọn kò dá wọn lóhùn.
Idi ni wi pe ofin fi aye silẹ fun isọrọ gẹgẹ bi ẹtọ ọmoniyan.
O ṣeeṣe ki ẹ ma beere wi pe kini wọn ṣe Ọlọpa ko ka igbo mọ wọn lọwọ tabi ibọn ṣugbọn lọdọ awọn ololufẹ orin takasufe,wọn ti da ọran kabiti.
Dá ayọ̀ ìgbàlà rẹ pada fún mi,kí o sì fi ẹ̀mí àtiṣe ìfẹ́ rẹ gbé mi ró.
“Nítorí náà, wí fún wọn pé OLUWA Ọlọrun ní, Ẹ̀ ń jẹ ẹran pẹlu ẹ̀jẹ̀ rẹ̀, ẹ̀ ń bọ oriṣa, ẹ sì ń pa eniyan, ṣé ẹ rò pé ilẹ̀ náà yóo di tiyín?
COZA RAPE: Ilé ọlọpàá ìlú Abuja pé Fatoyinbo fún ìfọ̀rọ̀wánilẹ́nuwò
Bí wọ́n tilẹ̀ bímọ, n óo pa àwọn ọmọ tí wọ́n fẹ́ràn.
 a lè lo atóka ìyísódì kọ ́ tàbí kì í se .
 Zubairu Dada – Niger, Minisita abẹle fun ọrọ ilẹ okeere(Foreign Affairs), State mẹ́rìnlélọ́gbọ̀n ) Olamilekan Adegbite – Ogun, Minisita fun idagbasoke Irin tutu ati iwakusa.
O sọrọ ni kikun bo ṣe bẹrẹ irinajo rẹ ni ilẹ ajeji ni America ki ori to fi ọna iṣẹ aṣeyọri han an.
 Ṣugbọn titi di asiko yii, ko ti i
Ó jáde lọ sí ojú ogun, OLUWA sì fi Kuṣani Riṣataimu ọba Mesopotamia lé e lọ́wọ́, ó sì ṣẹgun rẹ̀.
Ọrọ naa da bi ẹni to maa ku pade ẹni to maa pa, nirori Joshua gan an funra rẹ ti sọ tẹlẹ pe o wu oun lati fija pẹta pẹlu akẹṣẹ to jẹ ọmọbibi ilẹ Afirika bi t'oun naa.
Ẹwẹ, ẹgbẹ awọn ọlọja naa ti kede pe awọn ti yan Yeye Justina Iyabode Ogundoyin lati ṣe adele iyaloja ipinlẹ Ọyọ ni kiakia.
Muhammadu Buhari ti fiwe ranse si ile igbimo asofin lorie ede Naijiria lati
Seidu Adeyemi to jẹ ọrẹkunrin Khadijat Oluboyo ni wọn fẹsun kan wi pe o pa a, ti o si tun riimọle si inu yara rẹ ni Aratusi, Oke-Aro ni Akure, nipinlẹ Ondo.
 Ṣé ọbẹ ̀ kì í mì ní ikùn àgbà , àgbà ilé sì ni láyọ ̀ ọ ́ nú , àgbà kì í sì í ba wao jẹ ́ .
Ẹgbẹ awọn ọmọ Sioni Ẹka yii ni ti iṣẹ iranṣẹ awọn obinrin inu ijọ.
PDP tá ko ìgbésẹ̀ Gómìnà Kwara lórí àwọn alága ìjọba ìbílẹ̀ O ni ṣugbọn gbogbo awọn ajọ agbofinro wọnyii lo lee da ọkọ duro loju popo, ṣugbọn idi ti olukaluku lee fi da ọkọ duro lo yatọ, to si ju ara wọn lọ.
"Ọpọlọpọ ni ko gba owo oṣu fun nnkan bi oṣu mẹwaa, awọn miran ko gba owo oṣu fun ọsu mẹrinla, wọn dẹ ni ẹbi sile, iya n jẹ wọn, sibẹ ijọba ko sẹtọju wọn.
Didier Drogba: Agbabọọlu to fí okiki dáwọ ìjà ogun abẹ́lé dúró n'ilẹ baba rẹ
Fadá méji, ọmọ ìjọ 13 kú nínú ìkọlù darandaran Póòpù rán aṣojú lọ́ fún ìsìnkú Benue Oríṣun àwòrán, Catholic Church Nigeria Àkọlé àwòrán, Àwọn fada naa lugbadi awọn ajinigbe nigba ti wọn n lọ ilu Ekpoma ni Ipinlẹ Edo fun ayẹyẹ kan Ewe,Komisana ọlọpa nipinlẹ Delta Mustafa Muhammed ni ọwọ awọn ti tẹ diẹ lara awọn afunrasi naa.
Bi o tilẹ jẹ pe ẹgbẹ yii ni ara ẹka ẹgbẹ ẹlẹsin musulumi Tijjaniyya ni oun wa, amọ awọn asaaju ẹgbẹ Tijjaniyya ti ta kete si ẹgbẹ Hakika yii, ti wọn si ni awọn ko ba wọn se rara.
Ó ń gbógun tì mí nígbà gbogbo,ó pakuuru sí mi bí ọmọ ogun.
Ọ̀kan yóo jáde lẹ́yìn wọn, tí yóo yàtọ̀ sí wọn, yóo sì borí mẹta ninu àwọn ọba náà.
Nítorí pé kò sí ẹni tí ó gbọ́ ohun tí ó ń sọ.
Bẹ́ẹ̀ ni wọ́n sì ṣe kó Juda ní ìgbèkùn kúrò lórí ilẹ̀ rẹ̀.
Ninu iye wọn o to ẹgbẹrun lọna ọgbọn ti awọn ololufẹ wọn pa ti awọn ẹgbẹrun lọna ọgun miran si pade ọlọjọ wọn lati owo awọn mọlẹbi.
O ni ipese eto ẹkọ to ye kooro ati igbaye gbadun awọn akẹkọọ ipinlẹ naa lo jẹ ijọba oun l'ogun julọ.
 Lati igba ti ati gba ami ẹyẹ akọkọ ninu fiimu ni mo ti mọ pe o to iṣẹ ti eeyan fi n jẹun”.
Sise alabapade awọn oludanilẹkọ wa, fifi eti silẹ si idanilẹkọ wọn, ati fifi ara kinra pẹlu awọn akọroyin tuntun miran ti yoo maa sisẹ papọ loju opo BBC Yoruba lẹyinọrẹyin, wu ni lori pupọ.
“Bí ẹnìkan bá jí ọ̀kan ninu àwọn ọmọ Israẹli ẹlẹgbẹ́ rẹ̀ gbé, tí ó sì ń lò ó gẹ́gẹ́ bí ẹrú, tabi tí ó tà á, pípa ni ẹ gbọdọ̀ pa olúwarẹ̀.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ọṣun State: Gboyega Oyetọla di Gómìnà Ọṣun 27 Bélú 2018 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 28 Bélú 2018 Ọ̀pọ̀lọpọ̀ mọ̀lúmọ̀ọ́ka ló péjú pésẹ̀ síbi ètò ìbúra wọlé fún Gómìnà Gboyega Oyetọla.
Sugbọn igbe aye ko ti i pada bọ sipo.
“Alufaa yóo rú ẹbọ ìmúkúrò ẹ̀ṣẹ̀ láti ṣe ètùtù fún ẹni tí wọ́n fẹ́ sọ di mímọ́, lẹ́yìn náà, yóo pa ẹran ẹbọ sísun náà.
Iwadii ko ti i fi han oun to fa ijamba naa gangan.
Adoramu ni olórí àwọn tí wọ́n ń kó àwọn eniyan ṣiṣẹ́.
Àjọ NSO ni a mọ̀ sí àjọ Director of State Service (DSS).
O ni o ti to eniyan marunlelaadọrin to ti gbẹmi mi latari iba Lassa lati igba to ti bẹrẹ.
Oríṣun àwòrán, Google Yakassai to fi lede loju opo Twitter rẹ pe aarẹ Buhari ko nifẹ araalu nitori naa ni ko ṣe sọrọ lori isekupani awọn eniyan lati ọwọ ọlọpaa.
Nítorí ó ti yẹ kí ẹ di olùkọ́ni ní ọjọ́ tí ó ti pẹ́.
Bí àwọnn baba ńlá wa bá jí ni isà òkú lónìí ki ni ìbá jẹ́ èrò wọn?
Ìpínlẹ̀ Oyo sọ àsìá Nàìjíríà kalẹ̀ láti dárò Abiola Ajimobi Oríṣun àwòrán, @seyiamakinde/twitter Aarẹ Muhammadu Buhari ti ṣapejuwe gomina ipinlẹ Oyo nigba kan, Abiola Ajimobi, gẹgẹ bi ẹni to ko ipa to jọju ninu idagbasoke Naijiria.
Fayose ni EFCC tun ti ile kan to wa ni adugbo Gana ni Maitama, Abuja.
Awa mọ pe igbesẹ to tọ ni ijọba Naijiria gbe pẹlu bi wọn se da oniwahala lẹkun lati mase fi tipa gba ijọba to ni atilẹyin ofin."
Kí ló dé tí o fi lù wá,tóbẹ́ẹ̀ tí ọ̀rọ̀ tiwa kọjá ìwòsàn?
 Ọ ̀ pọ ̀ lọpọ ̀ ogun ni wọn si ti sẹ .
Iroyin sọ pe ibalopọ tipa-tipa naa di oyun, eyi to mu ki baba rẹ lọ ọ fi ẹjọ sun ni agọ ọlọpaa.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Elon Musk, Ọ̀gá àgbà iléeṣẹ́ SpaceX, Tesla CEO ń bá Bill Gates du ipò ẹni tó lówó jùlọ ṣèkejì lágbayé 26 Bélú 2020 Oríṣun àwòrán, @Musk Ipin idokoowo Musk niileeṣẹ Tesla to n ṣe ọkọ ẹlẹntiriki l'Amẹrika lo sọ di olowo nla.
Lẹ́yìn náà Jesu ní kí wọn túká.
"- CAN Ẹ wo àwọn ìlúmọ̀ọ́ká ọmọ Nàíjíríà tó jáde láyé lọ́dún 2020 Ìtàn ìgbé ayé Isola Ogunsola, akọni mánigbàgbé òṣèré tíátà, olórin àti onílù Aráàlú dá iná sun èèyàn méjì n‘Ibadan, orí kó ẹni kan yọ ""Ma a pa ara mi si Cute Abiola lọrun bo ṣe já mi silẹ tori afẹsọna miran"" ""Àwọn akẹ́kọ̀ọ́ àgbà fipá bá ọmọkùnrin mi lòpọ̀ níléèwé Deeper Life, mò ń fẹ́ ìdájọ́"" Kí ló fa gbas-gbos láàrín Davido àti Burna boy lórílẹ̀èdè Ghana?"
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù AFCON 2019: Àwọn ọmọ Naijiria sọ̀rọ̀ lórí ìdíje Madagascar àná Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ AFCON 2019: Àwọn ọmọ Naijiria sọ̀rọ̀ lórí ìdíje Madagascar àná 1 Agẹmo 2019 Ọpọ n ṣaroye pe awọn ko ri iṣẹ Mikel ati John Obi rara ni papa iṣere Alexandra.
Ẹgbẹ al-Qaeda la le sọ pe o bẹrẹ ijijangbara ẹṣin Islam, lẹyin ti awọn ọmọ ogun America wọ orilẹ-ede naa lọdun 2003.
Nítorí pé, nígbà tí mo bá kó wọn wọ ilẹ̀ tí ó kún fún wàrà ati oyin, tí mo ti búra pé n óo fún àwọn baba wọn; nígbà tí wọ́n bá jẹ, tí wọ́n yó tán, tí wọ́n sì sanra, wọn óo yipada sọ́dọ̀ àwọn oriṣa, wọn óo sì máa bọ wọ́n.
O sọ pe Afees Ọwọ ti o wa di ilumọọka loni jẹ ọkan lara awọn to kọṣẹ sinima lọdọ ohun.
 Ipinle naa tun gba ami-eye Diamond fun ipinle to n sagbateru eto olokan-o-jokan fun idagbasoke ere-idaraya julo, besini won tun gba ami-eye akinkanju, onfarajin ololufe ere-idaraya lorile-ede yii.
Kini ohun ti o n rugbo lagbo oṣelu nipinlẹ Ondo?
Ramaphosa, aare ti o n bo naa ti n se ipade pelu Zuma, eni ti o ko lati fi alefa sile lati bi ose kan seyin.
"Ni bayii, a ti bẹrẹ iwadii ni kikun lati mọ boya awọn kan lo ran awọn ọdaran naa niṣẹ tabi iṣẹ ara wọn ni wọn n jẹ.
56k Ninu ọrọ rẹ, Gbajabiamila sọ pe eyin ati ahon a maa ba ara wọn ja nitori naa ede aaiyedeto n waye laarin Naijiria ati Ghana ko yẹ ko fa wahala.
Lẹ́yìn náà, ó wá sí Jerusalẹmu ó sì jọba lórí gbogbo Israẹli ati Juda fún ọdún mẹtalelọgbọn.
Minista fun eto iroyin, ifitonileti, irin ajo afe ati asa, Ogbeni Lai Mohammed lo ki awon meteeta loruko ijoba apapo pe won gbe ogo wa si Naijiria, ebi won ati iran won lapapo ga.
Oríṣun àwòrán, Facebook/Seyi Makinde O ni amulo ẹrọ ayaworan CCTV ni yoo fẹsẹ mulẹ, eyi ti yoo mu adinku ba eto aabo to n ba ilẹ Yoruba finra naa, ti yoo fi di afiẹyin ti eegun fi asọ.
Ipò wo wá ni àwọn ọlọ́gbọ́n wà?
Àwọn ọmọ-ogun bá lọ, wọ́n dá ekinni-keji àwọn tí wọ́n kàn mọ́ agbelebu pẹlu Jesu lójúgun.
Bí wọ́n ti ṣe ń gún iyán láti egbẹta ọdún sẹ́yìn la ṣe ń gún un lónìí, bí wọn ti ṣe ń rokà láti ẹ̀ẹ́dẹ́gbẹ̀fà oṣù sẹ́yìn la ṣe n ro ọka, bí wọn ti ń kọ ọ̀pẹ láti ìbẹ̀rẹ̀ ọpẹ kíkọ la ṣe ń kọ ọ̀pẹ, egbòogi tí wọ́n ti mọ̀ a kò mọ̀ ọ́ mọ́, ìgbéraga ti sọni di èrò ẹ̀yìn: ọmọdé ń sọ̀rọ̀ sàka sí àgbàlagbà, ọmọkùnrin kò ka bàbá rẹ̀ sí mọ́, ọmọbìnrin a ró aṣọ ìgbéraga sí igbá àyà, a ní ìyá òun kò jámó nǹkan kan – bẹ́ẹ̀ ni gbogbo ìwọ̀nyí àìrònú ni.
”Wọ́n dá a lóhùn pé, “Ó ti kú.
Àwọn òkú yòókù kò jí dìde títí òpin ẹgbẹrun ọdún.
Jonathan tun gbadura ilera, alaafia ati ayọ fun Babangida bi o ti n sun mọ bebe ọgọrin ọdun.
Gbogbo nǹkan tí o rí lánà-án wà lọ́wọ́ mi, ẹni tí o rò pé èmi ni kìí ṣe èmi o.
Nígbà tí ó yá, Adamu bá Efa, aya rẹ̀, lòpọ̀, ó lóyún, ó sì bí ọmọkunrin kan.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Coffee Painter: Adebukola ní kò sí ìrànwọ́ lẹ́yìn ẹ̀kọ́ girama lòun ṣe ń ya àwòrán 16 Ẹrẹ̀nà 2020 Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Coffee Painter: Adebukola ní kò sí ìrànwọ́ lẹ́yìn ẹ̀kọ́ girama lòun ṣe ń ya àwòrán Yoruba ni ori lo mọ isẹ asela, ki sba oke ma jẹ ka daamu, ka to ja ọna.
Igbakeji Gomina ipinlẹ Ondo, Agboola Ajayi tun fi ẹgbẹ oṣelu PDP silẹ.
obinrin- adari awon obinrin, Salamatu BaiwaIgbakeji oludari
J Omojuwa ní kìí ṣe EndSars ló wà nídìí àwọn ẹlẹwọn tó sálọ ní ilu Benin.
Ọmọ Naijiria tó lé ní 300 ti padà wálé láti South Africa Ọkọ̀ báàlù mi yóò ṣi padà lọ́ kó ọmọ Nàíjíríà tó kù sí South Africa - Alákoso Airpeace Àwọn ọmọ Nàìjíríà 320 yóò padà wálé láti South Africa lọ́jọ́rú - Adama Ọmọ Naijiria tó lé ní 300 ti padà wálé láti South Africa Bakan naa ni wọn sọ papa-iṣere bọọlu alafẹsẹgba ni Enugu, Fasiti Nnamdi Azikwe ni Awka, adugbo Nnamdi Azikwe ni orilẹ-ede Tanzania, ati bẹẹbẹẹ lọ.
Ẹbi rẹ n kọ ni imọ sayẹnsi ati iṣiro nitori pe wọn ni igbagbs pe yoo dagba, ti yoo si di ilumọọka onimọ sayẹnsi tabi imọ ẹrọ.
Amotekun: Ìdí táwọn àgbà Nàìjíríà fi ń forí gbárí àti ohun tó yẹ
OLUWA ni agbára ati orin mi, ó ti gbà mí là, òun ni Ọlọrun mi,n óo máa yìn ín.
Imọ ijinlẹ keji ati PHD ni gbogbo ẹka eto ẹkọ Awọn nkan miran ti olukopa ni lati mọ Oríṣun àwòrán, TWITTER/FEDERAL MINISTRY OF EDUCATION Ni wọn igba to jẹ pe awọn orilẹ-ede ti Naijiria ni adehun eto ẹkọ pẹlu kii sọ ede Gẹẹsi, olukopa ni murasilẹ fun ẹkọ ede ilẹ okeere fun ọdun kan gbako ni orilẹ-ede ti wọn ti fẹ ẹ kẹkọọ.
A o ki ẹni naa pe A kii ka o!"
Ilé Aṣòfin Àgbà fòǹtẹ̀ lu N30,000 owó oṣù òṣìṣẹ́ A gba ìwé ìpẹ̀jọ́ ₦200m lọdọ mọlẹbi Sugar - UCH Ko pẹ lẹyin rẹ ni wọn sọ pe afurasi naa tun ba ọmọbinrin keji lo pọ.
Iwobi fọwọsi adehun ọdun marun un pẹlu ẹgbẹ agbabọọlu Everton lẹyin ti wọn san miliọnu mejidinlọgbọn owo pọun fun Arsenal.
Aarẹ Buhari paṣẹ fun Minisita fun ọrọ ilẹ okeere, Geoffrey Onyeama lati tete jẹ iṣẹ naa fun orilẹede ọhun nitori ipe iranlọwọ pajawiri ti oun gba lati ọdọ ijọba wọn.
Lẹ́yìn ìgbà díẹ̀, Jehoṣafati, ọba Juda lọ darapọ̀ mọ́ Ahasaya, ọba Israẹli, tí ó jẹ́ eniyan burúkú.
Ọpọlọpọ ninu wọn wà títí di ìsinsìnyìí, ṣugbọn àwọn mìíràn ti kú.
"Ibi gbogbo ni awọn kanda inu irẹsi wa, kii ṣe ọdọ awọn nọọsi nikan ni, koda ko si iṣẹ oojọ ti ko ni iriri bayii.
Ko si ohunkohun ninu iwe ofin Naijiria to sọ wi pe ọmọ orilẹede Naijiria ti wọn bi si Naijiria, ti iya ati baba rẹ si jẹ ọmọ ilẹ Naijiria, ko ni asẹ lati dije dupo si Ile-Igbimọ Asofin Naijiria.
Ẹ tètè yára mú baba mi wá bá mi níhìn-ín.
Aare soro yii nigba to n gbawe ase lati odo asoju orilede Mali ni orile ede Naijiria,ogbeni Moustapha Traore nile -aare to wa niluu Abuja lojoBo ose yii.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Wo àànfàní ‘Masturbation’, fífún ara rẹ̀ ní adùn ìbálòpọ̀ Wo àwọn ìlànà tuntun ti o gbọdọ tẹlèé rèé ki ó to le wọkọ̀ òfurufú lọ sókè òkun Ìdí ti mo fi da sọ́ọ̀sì rú lásìkò ìgbéyàwó ìyáwó mi tó ló fẹ́ ọkọ míran- Osadebe Àwòráń ọdún Ashura àwọn ẹlẹ́sìn Shiite tí ọ̀pọ̀ ń sọ̀rọ̀ nípa rẹ̀ lórí ayélujára Risikat olójú búlù dí aya Wasiu ní ìlànà Islam, tẹbí tará péjú síbẹ̀ Ó ń bọ̀ lọ́nà!
Àwọn Asiria ti pinnu láti sọ Tire di ibùgbé àwọn ẹranko, wọ́n gbé àkàbà ogun ti odi rẹ̀.
Ẹṣin rẹ̀ óo pọ̀ tóbẹ́ẹ̀ tí eruku ẹsẹ̀ wọn yóo bò ọ́ mọ́lẹ̀ nígbà tí wọ́n bá dé ẹnubodè rẹ, ariwo àwọn ẹlẹ́ṣin rẹ̀ ati ti àwọn kẹ̀kẹ́ ẹrù ati ti kẹ̀kẹ́ ogun rẹ̀ yóo mi odi rẹ tìtì, nígbà tí wọ́n bá dé ẹnubodè rẹ, bí ìgbà tí àwọn ọmọ ogun bá wọ ìlú tí odi rẹ̀ ti wó.
ó rán àwọn iranṣẹ láti mú un.
Àkọlé àwòrán, Oriṣiriṣi ọna ni eto igbani wọle maa n gba ninu awọn ẹgbẹ okunkun Yatọ si pe wọn yinbọn lu ọmọkunrin naa nikun, wọn tun gba foonu ọwọ rẹ, ti wọn si tun soro fawọn aladugbo pẹlu.
O ni ọrọ aje to dẹnukọlẹ ni Niajiria wa lara oun to mu ki awọn eniyan ma a ja fun ẹya ti wọn.
Àlejò bẹ̀rẹ̀ si pọ̀ si ni ilú nlá ṣùgbọ́n ilé gbigbé kò kári.
 Èyí a má a bẹ ̀ rẹ ̀ lẹ ́ yìn ọ ̀ sẹ ̀ kan sí mẹta tí eṣinṣin náà bá ti gé ni jẹ .
Oniruuru ilana ẹsin ati ijọ lo ti wa kaakiri laye atijọ, ti ihuwasi ati isesi wọn si jẹ manigbagbe, eyi ti ijọ Jesu Oyingbo jẹ ọkan ninu wọn.
Ọjọ mẹrin ṣaaju iṣẹlẹ eleyi ni iroyin ti ọmọ ọdun mọkandinlogun kan, Barakat ti wọn fipa ba lo pọ ti wọn tun pa a ṣẹlẹ ni agbegbe Akinyele nilu Ibadan kan naa.
Lẹ́yìn osù méjì, kò sọ́nà àbáyọ sí ìyanṣẹ́lódì ASUU Ọmọ Nàíjíríà faraya lórí àìkópa Buhari àti Atiku nínú ìjíròrò 'Kò sí ìyàtọ̀ nínú ọ̀kùnrin olóòtọ́ àti èyí tí kò sòótọ́ mọ́' Nkan àrà ọ̀tọ̀ n ṣẹlẹ̀ ti wọn pè ni 'òṣùpá dẹ̀jẹ̀ tó lágbára' Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí kan sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
cs wa dopin die die , o si je pipare patapata ni january 1995 .
Funke Akindele fún mi lówó tí mo fi gba ilé, kò ra ilé fún mi o - Ajirebi Ikú Williams Aanuoluwa lágbo òṣèré hú ọ̀pọ̀ ọ̀rọ̀ síta ''Lẹyin naa ni mo sọ fun mọmọ mi lati lọ si ẹka ile ifowopamọ naa lẹẹkan sii pẹlu aburo mi ki wọn si mu ẹri bi banki naa ṣe jawo ninu apo ikowosi rẹ lọwọ,'' Oluwo lo sọ bẹẹ.
’ rèé Irufẹ isẹlẹ ki obi gbẹmi ọmọ rẹ bayii si to mẹtalelọgbọn ti wọn gbọ ẹjọ rẹ lọdun 2018 nikan ni orilẹede Russia, awọn eeyan to n sewadi iwa ọdaran si fi idi rẹ mulẹ pe ilọpo mẹjọ irufẹ ẹsun yii lo n waye lai jẹ pe o dele ẹjọ.
Adeleye ẹni ọdún mẹ́tàléláàdọ́rin bú sẹkún nilé ẹjọ pé oun tọrọ aforiji nítori pe àṣìṣe ni kìí ṣe pé oun mọ̀ọ́mọ́ pa ọmọ náà.
 A rọ gbogbo àwọn ilé epo aládani kí wọ́n ta ọjà wọ́n ni gbèdéke iye ti PPPRA pè é."
Philip Shuaibu, Julius Aghahowa ati Obafemi Martins.
 Èyí gbọ ́ dọ ̀ wáyé láàárín àkókò tí ènìyàn jẹ ́ ọmọ oṣù mẹ ́ ẹ ̀ sán sí mẹ ́ ẹ ̀ wá .
Oríṣun àwòrán, Twitter/globaltimesng Àwọn Ìpínlẹ̀ tí coronavirus kò tíì dé ní Nàìjíríà, àti ìgbésẹ̀ tí wọ́n ń gbé láti dènà rẹ̀ Nitorinaa, ko jẹ iyalẹnu pe ilana ijinasiraẹni yii wa lara awọn igbesẹ ti ijọba lẹkajẹka gbogbo ni orilẹede Naijiria tẹnpẹlẹ mọ julọ gẹgẹ bi ọna lati din ọwọja aarun naa ku nilẹ yii.
"Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: ""Ọ̀rọ̀ ẹ̀yìn ni ọ̀rọ̀ Trump nípa Ààrẹ Buhari"" Wo àwòrán ayẹyẹ ọjọ́ ìbí Olúbàdàn tilẹ̀ Ibàdàn Ogun Anglo àti Francophones Cameroon mú ẹ̀mí 23 lọ Orilẹ-ede South Africa, Nigeria ati Kenya ni olootu ijọba ilẹ Gẹẹsi naa yoo maa bẹwo pẹlu ireti ati tubọ fi idi iṣakoso rẹ mulẹ gẹgẹ bii olootu ijọba."
Bolu lọ si ile iwe Corona ni ilu Eko, lẹyin naa lo tẹsiwaju lọ kọ imọ ofin ni Fasiti kan ni ilu London, ni Ilẹ Gẹẹsi.
Ní ọdún kan náà, ní ìbẹ̀rẹ̀ ìjọba Sedekaya, ọba Juda, ní oṣù karun-un ọdún kẹrin, Hananaya wolii ọmọ Aṣuri, tí ó wá láti Gibeoni bá mi sọ̀rọ̀ ní ilé OLUWA lójú àwọn alufaa ati gbogbo àwọn eniyan pé, 
Mo ní ìtẹ́lọ́rùn pé mò ń waasu ìyìn rere lọ́fẹ̀ẹ́, n kò lo anfaani tí ó tọ́ sí mi ninu iṣẹ́ ìyìn rere.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Torí ₦300, awakọ̀ ojú omi ṣokùnfà ikú èèyàn méjìlá l‘Eko - Ọlọ́pàá Ìjọ́ mí ní Italy ni mo fi ń ṣèrànwọ́ fáwọn aṣẹ́wó ọmọ Nàíjíríà tó há - Taribo West Ààrẹ orílẹ̀èdè Mali, Boubacar Keita kọ̀wé fipò sílẹ̀ Inú mí dùn láti kọrin pẹlú Beyonce nílẹ̀ Amerika- Ìyá àgbà láti Nàíjíríà Àwọn òṣèré tíátà Yorùbá kọjú ìjà síra wọn lórí ìdárò akẹẹgbẹ́ wọn tó kú Ìpàkọ́ kò gbọ́ sùtì ní ọ̀rọ̀ ẹ̀yin tí ẹ̀ ń bú mi- Oyedepo Mo kọ̀ láti pín ọkọ mi pẹ̀lú ẹnikẹ́ni, nítorí náà ẹ tú wa ká- Abílékọ Idowu faraya ní kóòtù kọkọ-kọkọ Ogunyemi ni owo oṣu marun ni awọn olukọ fasiti ko tii ri gba ati pe, awọn ko ni ṣẹwele iyanṣẹlodi naa ti ijọba apapọ ba kọ lati se amuṣẹ adehun to ṣe pẹlu ASUU ni ọdun 2019.
Kwara bye election:Tá ní yóò borí ìbò láàrin APC àti PDP?
Wọ́n ń lọ sọ́dọ̀ àwọn eniyan tí kò lè ṣe wọ́n ní anfaani.
23 Òkùdu 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 13 Ògún 2020 Oríṣun àwòrán, @CryptographyAC_ Nigba mii, yiyan eeyan fun nkan maa n nidi.
Ó sàn kí eniyan jẹ́ onírẹ̀lẹ̀ pẹlu àwọn talakaju kí ó bá agbéraga pín ìkógun lọ.
N óo kọrin ìfẹ́ ati ìdájọ́ òdodo,OLUWA, ìwọ ni n óo máa kọrin ìyìn sí.
Àwọn Ìjẹ̀bú a máa kọ mẹ́ta-mẹ́ta tàbí mẹta lókè, mẹ́ta ní ìsàlè rè.
 Losu Kefa , odun to kọja ni
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ìlàná ìṣúná tí yóò mú aráàlú kúrò nínú àìní bọ́ sí ọ̀pọ̀ là fẹ́ gbékalẹ̀ - Seyi Makinde Ọmọ ogun Nàìjíríà mẹ́wàá dèrò ọ̀run lẹ́yìn ìkọlù ẹgbẹ́ Boko Haram A ó pe àjọ DSS lẹjọ́ tí wọ́n bá kọ̀ láti tú Sowore sílẹ̀ - Falana Ìyàwó mi kórira kí Odunlade Adekola máa bú mi nínú eré tíátà - Ijebu Àlàáfíà padà sí Ile Ife lẹ́yìn ikú awakùṣà méjì tó fa rògbòdìyàn Gẹgẹ baa se kaa loju opo itakun agbaye, taa si rii gbọ ninu itan atẹnudẹnu, a lee tọpasẹ itan Gbọnka ati Timi Agbale si ọdun 1500.
Ọjọ isinku ni Florence sọ ọrọ naa, lasiko ti igbakeji Makinde, lọ ọ ki ni ile fun iku ọkọ rẹ.
Bakan naa, ni Ọọni tun ke gbajare lori bi iwa ọdaran se peleke si ni ipinlẹ Ọsun, to si kesi awọn ọdọ lati jawọ ninu iwakiwa, bẹẹ lo tun kesi ajọ naa lati fi agbara kun bi wọn se n gbogun ti iwa ọdaran ni awujọ.
Àkọlé àwòrán, Lati alẹ́ ọjọ Ẹti lawọn ẹgbẹ́ alatilẹyin ikọ Super Eagles(Supporters Club) ti n fi orin ati ilu ṣatilẹyin fun ẹgbẹ agbabọọlu Nigeria ṣaaju ìfẹsẹwọnsẹ oni pẹlu Cameroon.
Ìròyìn ti tàn ká ibi gbogbo pé ẹ dúró ṣinṣin ninu igbagbọ.
O ni awọn wọnyi n gba itọju lọwọ ni ile iwosan .
Ọ̀tá kan kò ní lè borí rẹ̀,bẹ́ẹ̀ ni àwọn eniyan burúkú kò ní tẹ orí rẹ̀ ba.
Iyawo mẹrinla ni ó ní; ó sì bí ọmọkunrin mejilelogun ati ọmọbinrin mẹrindinlogun.
Ohun ti awọn eniyan mọ Hammed Ali si ni pe kii huwa jẹgudujẹra tabi lu owo ilu ni ponpo, ti o si ma n ṣọra ni ọdọ awọn ọrẹ rẹ.
Nítorí náà wọn kò ṣe àwọn eniyan wọnyi ní anfaani kankan.
Wọ́n dá ọba lóhùn pé, “Kò sí ẹni náà láyé yìí, tí ó lè sọ ohun tí kabiyesi fẹ́ kí á sọ, kò sí ọba ńlá tabi alágbára kankan tí ó tíì bèèrè irú nǹkan yìí lọ́wọ́ pidánpidán kan, tabi lọ́wọ́ àwọn aláfọ̀ṣẹ, tabi lọ́wọ́ àwọn ará Kalidea rí.
Ọkan ninu wọn ni Ọjọgbọn Joe Abah.
Mo mọ̀ pé Jesu tí wọ́n kàn mọ́ agbelebu ni ẹ̀ ń wá.
O ni ọpọ awọn eeyan to jẹ alatako eto Amotekun ni ko tako lori otitọ amọ wọn se bẹẹ nitoripe awọn alatako wọn ninu oselu lo daba eto naa ni, tabi tori pe wọn ko lee ri anfaani kankan jẹ ninu rẹ fun ara wọn ni.
Amọ, lero ti awọn eeyan kan, ijọba ni asẹ lati se ohun to ba wu u, nitori awọn to wa ni ẹgbẹ oselu APC naa jẹ alailotọ, nitori naa ni wọn se lọ mu Festus Adedayo.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Yorùbá dùn lédè, sáré pé gbólóhùn yìí wò tóo bá dá ara rẹ lójú Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Yorùbá dùn lédè, sáré pé gbólóhùn yìí wò tóo bá dá ara rẹ lójú 9 Owewe 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 18 Òkùdu 2020 Ọ̀bọ ń gbọ́bọ g'ọ̀pẹ - O yá, ìwọ naa gbiyanju ẹ wo f'awọn ọmọ rẹ.
Ẹ kò gbọdọ̀ wá ire wọn tabi alaafia, kí ẹ lè lágbára, kí ẹ lè jẹ èrè ilẹ̀ náà, kí ó sì lè jẹ́ ohun ìní fún àwọn ìran yín títí lae.
Mo ro o titi, ko kuro l'ọkan mi titi ti mo fi beere lọwọ rẹ laarin oru.
Àlàyé kejì fún ilà kíkọ ni pé bóyá àwọn ènìyàn Iwọ̀ Oòrùn níbi tí àṣà yí ti bẹ̀rẹ̀ rò pé yóò bùkún ẹwà ara wọn nípa ṣíṣe bẹ́ẹ̀.
Soyinka, ẹni to safihan ijakulẹ to ni nipa ohun to pe ni awọn asise afọwọfa ijọba Muhammadu Buhari , woye ọrọ yi nibi ipade kan to bawọn akọroyin se lori bi iwa ifẹhonu han se n gbinlẹ si jakejado orilẹede Naijiria, nitori ikọlu awọn darandaran agbebọn lawọn agbegbe ti awọn agbẹ tẹdo si.
"Fraternity ní ìtàn tirẹ̀ ó dẹ̀ lápẹrẹ oríṣirísi ṣùgbọ́n .
agbegbe naa ati awon ẹsọ alaabo.
Èyí ni ìfẹ́, pé kí á máa gbé ìgbé-ayé gẹ́gẹ́ bí àwọn òfin Ọlọrun.
Ẹru awọn ajọmọgbe naa ko tii kuro lara awọn ibeji yii, yatọ si pe wọn n sa fun mọto to ba wọle, igbe ma na ẹ, ma pa ẹ, ni wọn tun n kígbe, ti apa lorisirisi si kun ẹyin wọn, koda o le ni ọjọ mẹrin ki wọn to le rin daadaa lẹyin ta ri wọn, to si daju pe awọn ajọmọgbe naa n fi tipa fun wọn ni oogun oorun."
Oríṣun àwòrán, Others @EVheeky loju opo rẹ n beere pe ki lo de ti banki oun, Zenith fi ni ki ileesẹ ibaraẹnisọrọ MTN maa tun gba owo lọwọ oun, se oun lo fi wọn han ara wọn ni?
Josaya wó ilé oriṣa tí Jeroboamu ọba, ọmọ Nebati, ẹni tí ó mú Israẹli ṣẹ̀, kọ́ sí Bẹtẹli.
O farapa ni orunkun re ninu ifesewonse naa, leyi ti ko fun lanfaani lati kopa ninu ifesewonse pelu iko agbaboolu Serbia ati Mexico.
    Ẹni tí ń gbé ibi gegele òkúta,
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: ‘Buhari, kó ara rẹ ní‘jánu lọ́dọ̀ Trump’ 'Kọ́ ọgbà fún ẹran ọ̀sìn rẹ' Àjọ CAN bẹ̀rẹ̀ ìwọ́de L'òndó Ìmọ̀ràn Trump yìí wáyé lẹ́yìn tẹgbẹ́ àwọn ọmọlẹ́yìn Krístì nílẹ̀ Nàíjírià CAN, sọ pé kí àarẹ Buhari kọ̀wé fipò sílẹ̀ lórí ọ̀rọ̀ àwọn darandaran tó ń fẹ̀mí àwọn èèyàn ṣòfò.
Ọjọgbọn Garba Sheka ni 'Ti igbimọ baa de wọn yoo yọju si ọfiisi mi nibiti a o ti gbe iwe orukọ awọn oludibo le wọn lọwọ.
Ó bá pada wá siwaju ọba.
Ogunbayo tun gba awọn obinrin nimọran lati maa paarọ iledi wọn ni igba meji ni ọjọ kan, to si tun rọ ijọba lati pese paadi ni ọfẹ fawọn obinrin.
Nítorí náà, bí ẹ kò bá lè ṣe ohun tí ó kéré jùlọ, kí ló dé tí ẹ fi ń páyà nípa àwọn nǹkan yòókù?
Ẹni to bori: Mali Senegal vs Nigeria.
Ki o si tẹ 'pin', iyẹn numba mẹẹrin ti oun lo fun 'App' naa.
Ọmọwe Uba Adamu (1935-2020) Oríṣun àwòrán, family Olukọni ni Ọmọwe Muhammadu Uba Adamu lẹka imọ itan oṣelu ni ileeks gbogboniṣe poly ni ilu Kano ki o to fẹyiti lọdun 1995.
Bí àpẹẹrẹ, ǹ bá tí mọ ojúkòkòrò bí Òfin kò bá sọ pé, “Ìwọ kò gbọdọ̀ ṣe ojúkòkòrò.
Wọ́n tún gbádùn kí eniyan máa kí wọn ní ààrin ọjà.
Koda akọnimọọgba tuntun Ronald Koeman ti ṣe igbaradi akọkọ pẹlu awọn agbabọọlu Barca ṣugbọn Messi ko si nibẹ.
Eeyan mẹrin miran tun ti ruu la lọwọ arun Coronavirus.
E yé ṣíra yín s'íhòhò nínú fíìmù, àṣà burúkú ni- Efusetan kìlọ̀ fáwọn òṣèré Ìròyìn ayọ̀ tó wà nínú àrùn Coronavirus Ìjọba àpapọ̀ ní kí àwọn òṣìṣẹ́ grade 1 sí 12 jókòó sílé nítorí Corona Virus Ọmọde kan wà ní ẹsẹ̀ kan aye ẹsẹ kan ọ̀run lẹ́yìn ìṣẹ̀lẹ̀ ilẹ̀ rírì ní Croatia Okoto Akewi ọdọmọdebinrin yii sọrọ nipa ipa ti aṣa ati ori ẹni n ko ninu aye ẹni.
Ó jẹ́ ọjọ́ tí ẹ óo máa fun fèrè.
Bí Jakọbu bá lọ fẹ́ ọ̀kan ninu àwọn obinrin ará Hiti, irú àwọn obinrin ilẹ̀ yìí, irú ire wo ni ó tún kù fún mi láyé mọ́?
Bee farming: Oyin sínsìn lérè lórí ṣùgbọ́n ó tún gbé ikú karí
Ni ọ̀rọ̀ọ rẹ̀ alágbèékáa Jannat Ali ní:
O ni Ọba Ogunwusi nifẹ awọn aṣatipo naa ni ko ṣe ṣalai ranti wọn ninu ileedi to wa fun ayẹyẹ ọdun ọlọjọ lasiko yii.
Onílara ni ẹni tí inú rẹ̀ ń bàjẹ́ sí ìlọsíwájjú ẹlòmíràn, bí ènìyàn kan bá wà ní ipò olórí onílara a máa wá ọ̀nàkọ́nà láti fi hàn pé olúwaarẹ̀ kò tọ́ sí ipò náà òun a si gbàgbé pé ẹni tí Olódùmarè bá gbé ga kò sí ẹni tí ó lè rẹ̀ ẹ́ sílẹ̀ láéláé.
Olori ijoba orile-ede Britiko Theresa May so fun awon olori orile-ede naa wi pe oun gbagbo wi pe Ajo naa yoo tesiwaju ninu ojuse re ti yoo si so eso rere.
Awọn alabagbe obinrin naa sọ pe o fi aṣọ we ọmọ ọhun lori lẹyin to ṣe iṣẹ ibi naa ki awọn eeyan ma ba ri pe o ti ni ipalara.
' Ọga Agba ileeṣẹ ọlọpaa ni Naijiria, Mohammed Adamu, ti kilọ fun awọn oloṣelu ni ipinlẹ Edo ati Ondo, to n kopa ninu idibo si ipo gomina l'oṣu Kẹsan, ati ikẹwa.
Èèrù ina tó jó ọ̀pọ̀ ọkọ tó sì mú ẹmi lo nilu Eko tí n tútù ṣugbọn àrà àwọn ọmọ Nàìjíríà sí n gbóná lórí ìṣẹlẹ náà.
Nigba to ba BBC Yoruba sọrọ, Oluwo sọ pe ohun ko ni ọrọ kankan ti oun le sọ nipa ọrọ naa.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Tinubu parí aáwọ̀ Ambode àtàwọn aṣòfin ìpínlẹ̀ Eko #BBCNigeria2019 Sowore: olùdíje Ààrẹ tó fẹ gbà Nàìjíríà padà fún àwọn ọdọ SERAP gbé Fashola lọ sílé ẹjọ́ nítorí owó iná kíni ọ̀nà àbáyọ sí àìsàn Lassa Fever?
" Ile aye yii kere pupọ, o si yẹ ka maa ni ibẹru Ọlọrun ninu ohun gbogbo ta ba n ṣe, Ajimobi ti lọ lonii, iwa to ba si hu si ẹnikẹni ko ni ìtumọ mọ.
Ó gbọdọ̀ ṣe é jó sí, síbẹ̀ ó ní láti dùn ún ní etí àwọn ènìyàn tí yóò “mú wọn gbàgbé ara” ní orí ìtàgé, pẹ̀lú ọ̀rọ̀ orin tí yóò mú ayọ̀ jáde, èyí tí a mọ Ijó ìta-gbangba mọ́.
Nígbà tí àwọn ọkunrin náà lọ tán, Ahimaasi ati Jonatani jáde ninu kànga, wọ́n sì lọ ròyìn ohun tí ó ṣẹlẹ̀ fún Dafidi.
Ninu atẹjade ti adari ikọ naa ni ipinlẹ Oyo, Ajibola Kunle Togun, fi lede, o ni gbogbo awọn to forukọ silẹ si oju opo ti ijọba gbe kalẹ fun ikọ naa lati lọ wo orukọ wọn.
Àkọlé àwòrán, Ọwọ́ ọmọde ko to pẹpẹ, ti agbalagba ko wọ keregbe ni apero yii gba nilu Ibadan loni.
Àwọn ọlọ́pàá dá ìpàdé àwọn alátakò Tinubu dúró l'Eko Tinubu ti bẹrẹ isẹ ti Buhari gbe le lọwọ Tinubu parí aáwọ̀ Ambode àtàwọn aṣòfin ìpínlẹ̀ Eko #BBCNigeria2019 Tinubu gbéra lọ odidi Mecca láti lọ ṣàbòsí - PDP Loju opo itakun agbaye SEC ni wọn ti ṣalaye ni kikun awọn magomago ati aifootọ ṣe akọsilẹ loriṣiiriṣii ti wọn ri ni OANDO.
Awọn mejeeji ti n leri leka lati ọjọ yii wa, koda awọn alatilẹyin wọn naa ko gbẹyin nipa lileri ṣaaju ọjọ oni.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Day 16: Jimi Agbaje, iṣẹ́ rẹ̀ yàtọ̀ sí òṣèlú #BBCNigeria2019 Buhari gbọ́dọ̀ yọ àwọn mínísítà tí kò wúlò ní sáà kejì yí-Ogundamisi Ó tó gẹ́, Atikulated àti àwọn àṣà ìpolongo tó gbòde lásìkò ìbò 2019 Kamaru Usman: Ọmọ Áfíríkà àkọ́kọ́ tó gba ìgbànú ẹ̀yẹ ẹ̀ṣẹ́ kíkàn Agbẹnusọ fawọn akẹkọ naa ni ẹgbẹrun lọna ogun naira ni ijọba ipinlẹ Eko n san bii owo iranwọ eto ẹkọ fawọn akẹkọ rẹ, tijọba ipinlẹ Kwara ko si ranti awọn.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Grandma Maruwa: Ó yẹ kí obìnrin sisẹ́ láì wojú ọkọ kó tó jẹun Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Grandma Maruwa: Ó yẹ kí obìnrin sisẹ́ láì wojú ọkọ kó tó jẹun 7 Bélú 2018 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 11 Bélú 2020 Asamọ ọrọ kan lo ni, ‘isẹ ni isẹ n jẹ, ẹni to ba jale nikan lo ba ọmọ jẹ’.
“Ẹ má ṣe jẹ́ kí ọkàn yín dàrú.
Ní ọjọ́ kẹfa ni Eliasafu, ọmọ Deueli, olórí àwọn ẹ̀yà Gadi, mú ọrẹ tirẹ̀ wá.
Ewé igi náà wà fún ìwòsàn àwọn orílẹ̀-èdè.
“Lẹ́yìn tí ẹ bá ti kórè àwọn èso ilẹ̀ yín tán, láti ọjọ́ kẹẹdogun oṣù keje lọ, kí ẹ máa ṣe àjọ àjọ̀dún OLUWA fún ọjọ́ meje; ọjọ́ kinni ati ọjọ́ kẹjọ yóo jẹ́ ọjọ́ ìsinmi tí ó lọ́wọ̀.
Ṣugbọn ó mú Arimoni ati Mẹfiboṣẹti àwọn ọmọkunrin mejeeji tí Risipa, ọmọ Aya, bí fún Saulu; ó sì tún mú àwọn ọmọ marun-un tí Merabu, ọmọbinrin Saulu, bí fún Adirieli ọmọ Basilai ará Mehola.
Adamu sọ pe igbesẹ yi jẹ idahun si igbe tawọn ọmọ Naijiria n pa lori ikọ naa.
Ṣùgbọ́n ṣáá, ìdí tí a fi ń ṣe àṣà yìí ni láti jẹ́ kí ara ìkókó náà mọ omi tútù nítorí ìgbà tí ìyá rẹ̀ yóò máa gbé e kiri.
 tí wọ ́ n bá raá ojú ibẹ maa funfun ṣùbọ ́ n kò kìí rí báyìí ní gbogbo ìgbà .
Ṣugbọn lasiko yii, awọn obinrin to kawe to si n gbe ni awọn ilu nla ti bẹrẹ si ni kọju ija si aṣa naa.
Awọn eniyan ti o to ogoje ni wọn ti ko lọ si ile iwosan fun itọju.
Ó gbà mí ní wakàtí kan ó lé kí n tó pàpà ní ìmọ̀lára kiní yìí."
Wọ́n kọ OLUWA sílẹ̀, wọn kò sìn ín mọ́.
Ninu ọrs to sọ lẹyin ija naa, Adesanya ṣalaye pe ija naa ko rọgbọ, ṣugbọn gbogbo ohun to yẹ ki oun ṣe lati bori ni oun ṣe.
Eyi si maa n fi oju han pẹlu ọpọ ati oniruuru asọ ẹgbẹjọda ti ẹlẹgbẹjẹgbẹ maa n wọ lasiko ọdun Ojude Ọba.
”Gomino ipinle Osun, ogbeni Rauf Aregbesola wa lo anfani naa lati ki isejoba aare Buhari, fun mimu ileri won se lati se agbekale ero igbalode DSO naa.
 Àwọn oyè tó kù tó sì se pàtàkì ní apèènà , akẹ ́ rẹ ̀ , baàjíkí , baàlá , baàjítò , Ọ ̀ dọ ̀ fín àti lísa .
Arole Oduduwa ṣalaye pe inu oun dun lati gbalejo awọn ọdọ naa, ati pe o jẹ anfani nla lati ru awọn ọdọ ọhun soke ninu ijiroro wọn fun bi ọjọ ọla yoo ṣe dara.
Nítorí ní alẹ́ àná, angẹli Ọlọrun mi, tí mò ń sìn dúró tì mí, ó ní, 
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Mo kábàámọ̀ pé ń kò bẹ Baba Legba wò, nígbà tó pè mí - Foluke Daramola Aṣòfin méje yarí mọ́ Akeredolu lọ́wọ́ torí ọkọ̀ ayọ́kẹ́lẹ́ tí kò pín fún wọn Aya gómìnà Kwara gba ilé fún Risikat olójú búlúù àti ọkọ rẹ̀ Risikat, ìyá àwọn ọmọ olójú búlù tí bẹ̀rẹ̀ sí ní kọ́sẹ́ aṣojú lóge Àwọn ọ̀daràn tó jí ìbejì ọmọ Akeugbagold kó ti fojú ba ilé ẹjọ́ lòníì Àjọ ECOWAS yan Aàrẹ Ghana, Nana Akufo-Addo gẹgẹ bíi aàrẹ tuntun Orukọ wọn ni Mohammed Bashir, ẹni ọdun mẹtalelọgbọn, Oyeleye Opeyemi ẹni ọdun mẹẹdọgbọn, Olumide Ajala ẹni ọdun mẹrindinlogoji ati Taiwo Rildwan ẹni ọgbọn ọdun.
UEFA Champions League 2019: ilé ló máa bọ́sí fàwọn ọmọ Afrika loni
Ẹ fura, làásìgbò le wáyé ní ìjọba ìbílẹ̀ mẹ́fà yìí lásìkò ìbò gómìnà Ondo - YIAGA Wo ìṣẹ̀lẹ̀ márùn-ún tí kò bá pín Nàíjíríà sí yẹ́lẹ-yẹ̀lẹ Bọ́ síta láti ṣe ìwọ́de mọ́ ìjọba Nàìjíríà lónìí, ko rugi oyin - Iléeṣẹ́ ọlọ́pàá Ẹ̀yin ọlọ́pàá 10,000 tí ọ̀gá ọlọ́pàá gbà ṣíṣẹ́ ní 2019, ẹ padà sílé - Iléẹjọ́ pàṣẹ Ìjọba àpapọ̀ kéde ọjọ́ tí ìdánwò NECO, NABTEB àti BECE yóò bẹ̀rẹ̀ Saaju la ti sọ fun yin pe, ijọba apapọ ti kede pe idanwo aṣekagba ile iwe girama ti ajọ NECO n dari rẹ yoo waye laarin ọjọ karun un, oṣu kẹwaa si ọjọ kejidinlogun, oṣu kọkanla, ọdun 2020.
Ààrẹ àná, Goodluck Jonathan ló fún mi ní 'oògùn' tí mo fi yọ Sanusi nípò Emir Kano- Ganduje Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsèjẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọ Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 3 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 5 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
bi omo egbe PDP, mo fe ki egbe mi wọle, mo fe ki egbe oselu mi gba gbogbo ipo.
Ẹ jókòó sí ilẹ̀ yín gbogbo ẹ̀yín tó fẹ́ lọ sí Mecca Awọn ọmọ Naijiria to fẹ lọ si Mecca fun Hajj kekere,Unrah ni wọn ti sọ fun ki wọn joko si ile wọn ati orilẹede wọn.
Ki Ọlọrun Ọba alaanu ki o ba wa ṣe iku ni isinmi fun un.
Babajide Sanwoolu búrawọlé Eko BBCCopyright: BBC Idile Babajide SanwooluImage caption: Idile Babajide Sanwoolu BBCCopyright: BBC Idile Babajide SanwooluImage caption: Idile Babajide Sanwoolu Article share tools Facebook Twitter ṢàpínlòView more share options Share this post Copy this linkKà síwájú síi nípa àwọn ìtọ́kasí wọ̀nyí.
Ọmọ igbimọ meje dibo pe ki wọn yọ Ọjọgbọn Ogundipe nipo, nigba tawọn mẹrin dibo pe ki wọn fi i silẹ.
Drivers lincense renewal: Ẹgbẹ̀lẹ́gẹ̀ àwakọ ló ń lo iwé ìrinà ọ̀kọ̀ tí kò koju oṣùwọn- FRSC
Ife South Ọjọ Aje, 31/08/2020 15.
Wọ́n bẹ̀rẹ̀ sí bá ara wọn ṣàròyé pé, “Ta ni yóo bá wa yí òkúta kúrò ní ẹnu ibojì?
Gẹ́gẹ́ bí Baba ti fẹ́ràn mi, bẹ́ẹ̀ ni mo fẹ́ràn yín.
Wọn óo fà á lé àwọn tí kì í ṣe Juu lọ́wọ́ láti fi ṣe ẹlẹ́yà, láti nà ati láti kàn mọ́ agbelebu.
Tọkàntọkàn ni wọ́n fi ń sin Ọlọrun.
Bakan naa ni ọrọ kan itan ori oke kan lẹyin Odo Awaye nibi ti ẹbọra kan ti maa n lu agogo ni wakati wakati.
Bo ṣe de si Naijiria pada lo di adari ọ̀wọ́ kẹrin fun Ileesẹ ologun losu kẹjọ ọdun 1965, to si ni igbega diẹ diẹ siwaju di ọdun 1980, to gba oye Ọgagun, Brigadier General.
Ẹ gbọ naa, bawo ni ọbọ ṣe ṣe ori ti inaki o ṣe?
Peteru bá bi í pé, “Wò ó, àwa ti fi ilé ati ọ̀nà sílẹ̀, a wá ń tẹ̀lé ọ.
Ó bá bèèrè pé, “Ṣé kò sí wolii OLUWA kan níhìn-ín tí ó lè bá wa wádìí lọ́wọ́ OLUWA?
Ìkúnlẹ̀ abiyamọ, ìkókó mẹ́jọ kú nílé ìwòsàn lálẹ́ ọjọ́ kàn Mamman Daura rí ìjà ọmọ Nàíjíríà torí ó pè fún wíwọ́gilé pínpín ipò ààrẹ lẹ́lẹ́kùn jẹkùn Dayo Amusa gbarata lórí bí agbófinró ṣe ń pa ọ̀dọ́ láì nídìí Ẹyìn tí Hydroxychloroquine, Zinc ati Zithromax da lára yá,ẹ bọ síta wà jẹrìí mí-Dr Stella Emmanuel Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Oronpoto Animation: Akin Alabi ní kò dára bí eré aláwòrán fáwọn ọmọdé ṣe jẹ́ aláwọ̀ funfun Ìjọba àpapọ kéde ọjọ ìwọlé àwọn akẹkọọ onípele ìdánwò àsekágbá WAEC Ijọba ni eyi yoo fun awọn akẹkọọ onipele idanwo ni ọsẹ meji lati fi gbaradi de idanwo wọn.
CA Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Awọn oluwọde naa n ba awọn ọlọpaa sọrọ lọwọ lawọn oṣiṣẹ DSS naa ya bo wọn ti wọn si mu Ọgbẹni Ọlawale Bakare atawọn aṣiwaju ẹgbẹ naa kan ki awọn yoku to juba ehoro.
" awọn oniwe-orukọ gangan tumo si "" ọrun "" ."
Àwọn ará Róòmù ni wọ́n kọ́kọ́ kọ́ afárá náà ní nkan bi 2,000 ọdún sẹ́yìn.
Ohun ta gbọ ni pe ṣe ni awọn afunrasi to jin awọn alufaa na gbe fẹsẹ fẹ nigba ti wọn ko firi awọn ọlọpaa.
"Bakan naa pẹlu gbogbo ohun ti mo la kọja, o to ki eeyan fi sọkan pe igba mii ti ""Michelle Damsen"" ba tun jẹ jade ninu iroyin, iroyin naa ati ipa rẹ yoo rin jina gan."
Isele ibugbamu naa niroyin fi mule pe, awon meji padanu emi won, bee si ni eniyan mẹ́tàdínlógójì farapa yanana.
Ìbejì ọmọ ọdún méjì Mínísítà fún ọ̀rọ̀ omi bá odò lọ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Toma Unu: Ọmọbìnrin tó ń fi ẹsẹ̀ rẹ̀ ya àwọran nítori pe ó ni ìpènija ọpọlọ Ariwo aja yii si lo mu ki olowo rẹ o ṣawari ohun to n mu u gbo, to si ri ẹsẹ̀ ọmọ tuntun naa.
Ẹni to bori: Egypt Ìpele to kangun si aṣakagba Congo DR vs Nigeria.
 ní ilẹ ̀ kánádà àti amẹ ́ ríkà , àjẹsára èyí tó ń ṣiṣé fụn oriṣi mẹrin meningococcus ni wọ ́ n máa ń gbà fún àwọ ́ n ọṃọ tí kò tíì bàlágà àti àwọn tí ó láàńfàní jùlọ lati kó àrún yìí Ó tún pọn dandan fún àwọn tó ń lọ sí ilẹ ̀ mẹ ́ kà fún hajj .
Ọ̀pọ̀ ọmọ Nàìjíríà tó ló ṣe àtìlẹyìn fún àwọn ikọ agbábọ̀ọ̀lù Naijiria ní orílẹ̀-èdè Russia ní wọn kò le padà wále mọ, lẹ́yìn ìdíje ti orílẹ̀-èdè Nàìjíríà ti fìdí rẹmi.
25 Agẹmo 2020 Oríṣun àwòrán, others Àkọlé àwòrán, Ilẹ n jẹ eeyan!
Buhari gbekale lati dekun ebi ati paapaa julo lati se atileyin fun awon to
Wọn mú ọkọ rẹ̀ nígbà ti wọn rii pe oun ló ń jawé olúbori nínú ìdìbò àpàpọ̀ orílẹ̀-èdè Nàìjíríà lọdun 1993.
Ninu esi idibo ti ajo eleto
Agbẹnusọ fun aarẹ Buhari lori eto iroyin, Bashir Ahmad lo kede aseyọri nla yii loju opo Twitter rẹ.
Nibayii, Saheed gangan ti kede pe osu kẹta ọdun to n bọ, iyẹn ọdun 2020 lawọn fi oku Mama si o.
Ẹ̀sùn ìfipábánilòpọ̀: Wọ́n bá òkú afẹ̀sùnkan nínú ilé ìgbáfẹ́
(Star) Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Barcelona lo wu Neyman ko pada si.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù 2019 election: Bí wọ́n ṣe ń ta káádì ìdìbò ní Kano 21 Ẹrẹ̀nà 2019 Oríṣun àwòrán, EFCC Ni ọjọ Abamẹta to jẹ ọjọ kẹtalelogun oṣu kẹta ni ajọ eleto idibo INEC yoo ṣe eto ni awọn agbegbe kan ti wọn ti wọn ti fagile idibo ninu awọn ipilẹ kọkan ni orilẹede naa.
Ti a o ba gbagbe pe ni osu kerin odun 2017 ni aare Buhari ti koko foruko awon eniyan marun un naa ranse sile igbimo asofin  lati gbaa wole , sugbon ti won faake kori  nitori awuye-wuye to waye  laarin ile igbimo asofin ati ojogbon Yemi Osinbajo lasiko ti igbakeji aarei n dele fun aare , pe ile-igbimo asofin ko ni agbara lati fi onte lu Ibrahim Magu gege bi oludari ile-ise ajo  to n ri si sise owo ilu kumo-kumo (EFCC)Ni osu keta, odun yii ni ile-igbimo asofin fowo-wonu, ti won si fonte lu awon igbakeji adari ile-ifowopamo ti ijoba meji ati awon meta fun igbimo ti yoo maa sakoso eto inawo labe ile-ifowopamo naa.
OLUWA bá dáhùn pé, “Nítorí gbogbo ẹ̀ṣẹ̀ rẹ, n óo fi ọrọ̀ ati ohun ìṣúra rẹ fún àwọn tí ń kó ìkógun ní gbogbo agbègbè rẹ, láìgba owó lọ́wọ́ wọn.
ribiribi to wa laarin orilẹ-ede mejeeji.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 2020: Ọdun 2020 yii ko nìí nira fún àwọn tó bá bẹ̀rù Olorun Kini o ti ṣẹlẹ ṣeyin?
Africa in Pic: Àwọn àwòrán tó gbajúmọ̀ ní Afirika
bere lojo kokanlelogun osu kefa si ojo kokandinlogun osu keje(June 21 to July
Ki awọn eniyan ye e pe wọn lorukọ mọ tabi dẹyẹsi wọn.
Láti Abirona wọ́n lọ sí Esiongeberi.
- Mike Bamiloye Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Ọba Mohammed bin-Salman ti Saudi yọ ọmọ rẹ̀, Fahad, Abdulaaziz àti àbúrò rẹ̀, Ahmed kúrò nípò nítorí ìwà àjẹbánu3 Owewe 2020 6:18 Fídíò, Akomolede: Bolaji Faleke ni Olùkọ́ tó ń kọ́ wa ní àṣà oge ṣiṣe lórí BBC Yorùbá, Duration 6,181 Owewe 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
“Wọ́n gbé, nítorí pé wọ́n ti ṣáko kúrò lọ́dọ̀ mi!
Ibugbamu ibudo epo ni Ijegun Rẹ́rẹ́ rún níbi ìbúgbàmù l'Eko, ọ̀pọ̀ àwòrán rèé Àwòrán bí ìjàmbá iná ṣe lọ ní Ìjẹgun Olaleye ni lootọ ni pe koṣeemani ni lilo gaasi f'awọn ara ilu ṣugbọn ohun to ṣẹlẹ yi ti sọ di dandan ki ijọba mu opin ba tita afẹfẹ gaasi lẹgbẹ ibugbe awọn eeyan.
orile-ede Naijiria, fun odun 2019 yoo je ọgọ́rin le die bilonu owo dola(80.
Ayẹyẹ idana ọhun lo dun, to si larinrin, ti ọpọ eeyan si n ba yọ ayọ oriire naa, paapaa awọn akẹẹgbẹ rẹ ninu isẹ tiata.
Ṣugbọn ọwọ ọlọpaa tẹ afurasi mẹta lọgbọnjọ, oṣu Kẹrin, ọdun 2020, gẹgẹ bi nkan ti wọn sọ fun BBC.
Ta ló sì lè dúró ninu ibi mímọ́ rẹ̀?
’ rèé Laduntan Oyekanmi di ìyálóde tuntun fún ilẹ̀ Ibadan Orí mi wú, Joke Silva kọ ewì ìfẹ́ lọ́jọ́ ìbí Olu Jacobs Ninu ifọrọwerọ rẹ pẹlu BBC Yoruba, olori ẹgbẹ MURIC, Ọjọgbọn Ishaq Akintọla ṣalaye pe, gbogbo ọna to tọ lawọn ti gba lati yanju ọrọ naa ni tubinubi, ṣugbọn kaka ki ewe agbọn rẹ dẹ, pipele lo n pele sii.
Yemi sọ eleyii lasiko to n ba BBCYoruba sọrọ lori oun ti oju rẹ ri to di ilumọọka ni ẹka amuludun.
Akindele wọ wahala ni oṣu kẹfa ọdun 2018 nigba ti akẹkọọbirin rẹ kan Monica Osagie fi ẹsun kan an pe o n foro ẹmi oun lori pe o fẹ ba oun lo pọ lori maaki.
tun lo si ile-ẹkọ agbejoro to wa ni  Atlanta
A n bẹ Gomina ko ma wo ile arugbo'' Bi a ko ba gbagbe, fakinfa kan n waye lẹnu ọjọ mẹta yi laarin Ijọba Kwara ati aarẹ ile aṣofin agba tẹlẹ Bukola Saraki lori ilẹ ti Baba Saraki,Olusola Saraki kọ ile to pe ni ile arugbo le lori.
Nígbà tí ara rọ̀ mí,mo wí ninu ọkàn mi pé,kò sí ohun tí ó lè mì mí laelae.
Bákan náà ni ètò yìí yóò ná ìjọba ni bílíọ́nù méjìléláàdọ́ta náírà gẹ́gẹ́ bí owó oṣù osgún naira fún ẹni kọ̀ọ̀kan 774,000 Jobs: Ètò ìgbani sísẹ́ yìí yóò wà ni ìdádúró náà - Ilé ìgbìmọ̀ aṣòfin àgbà Oríṣun àwòrán, Others Ilé ìgbìmọ̀ aṣòfin Nàìjíríà ti kéde pé ki ìjóba dá iṣẹ́ ológun náìra oṣoosù ti ìjọba apapọ fẹ́ gbà àwọn èniyàn sí lábẹ́ àjọ tó ń gbani síṣẹ́ (NDE) láti mú ìrọ̀rùn bá ará ìlú nítori àarùn Covid-19 tó gba ayé kan.
Ó ní kí wọn ròyìn ohun tí ó ṣẹlẹ̀ fún Jakọbu ati fún àwọn arakunrin yòókù.
Lara awọn ohun ti Fabiyi tun mẹnuba pe ko dara ninu ere, eyi to ni kawọn osere tiata yee safihan rẹ mọ ninu fiimu ree: Iwa nina afurasi ni anadojubolẹ titi ti onitọun yoo fi gbe ẹmi mi lasiko ti afurasi ba wa ni ahamọ awọn ọlọpaa Fifi wọn jẹ irora nipa tita wọn ni ibọn lẹsẹ, abi dida egbo si wọn lara lasiko ti wọn ba n fi ọrọ wa afurasi lẹnu wo Iwa ika awọn ọlọpaa si afurasi bii fifi irin gbigbona abi ẹrọ ilọsọ jo wọn lara Mimu afurasi lọna aitọ lai ni iwe asẹ to bofin mu lati mu afurasi naa ayafi ti wọn ba mu onitọun nibi to ti huwa ọdaran gangan Iwa ọyaju si araalu bii lilu wọn lai sẹ ẹsẹ kankan tabi gbẹsẹ le dukia wọn lọna aitọ abi gbigba owo lọwọ wọn Asa titẹ ẹtọ ọmọniyan loju mọlẹ ni orisirisi ọna.
Igbo Olodumare rèé, níbi tí Ìgbín ti tóbi ju Ìjàpá lọ Agbébọn tún gbẹ̀mí àgbẹ̀ míì lọ́nà oko lágbègbè Ibarapa Titi di akoko ti a n ko iroyin yii jọ, ko ṣeni to tii le sọ iye awọn akẹkọọ to di awati ni pato.
Ibẹ̀ ni ọwọ́ wọn yóo ti tẹ̀ ẹ́, tí wọn óo sì fogun kó o.
Ẹ̀yin òbí, ẹ má ṣe mú àwọn ọmọ yín bínú.
Ẹni ti o fẹ ṣoniduro fun gbọdọ jẹ ẹni ti o mọ daadaa, dele dele, too mọ ọna rẹ.
Ile-igbimo asofin lorile-ede Nigeria ti ro Aare Muhammadu Buhari lati kede pajawiri ni eka eto ilera, lori ohun ti won sapejuwe bi awon ohun elo irin-ise ati awon ohun amayederun ni awon ile-iwosan se baje.
"Oríṣun àwòrán, daddyfreeze Amọ ọkunrin kan @jesusemmanuel_ty47, to farahan bii ọmọlẹyin David oyedepo, wa da Daddy Freeze lohun labẹ ọrọ to sọ naa bayii: ""Ẹ wo ọkunrin ti igbeyawo rẹ fori sanpọn to n gba ọkunrin ti igbeyawo rẹ ti le ni ọgbọn ọdun nimọran."
Aare soro yii nigba ti omo egbe All Progressives Congress, APC lati ipinle Benue, ni eyi ti asofin George Akume dari won , wa sile aare to wa niluu Abuja lojo Eti.
Segun Ogungbe: Oríṣun àwòrán, Muka ray Segun Ogungbé lọ jogún isẹ tíátà láti ọdọ bàbà rẹ , alàgbà olóògbé Akin Ogungbe, tó wá láti ilu Abeokuta nipinlẹ Ogun.
Boko Haram: Ẹ̀mí kan bọ́, èèyàn 16 míì farapa nínú ìṣẹ̀lẹ̀ àdó olóró ní Maiduguri
naa sekupa awon afehonu han nipinle Zamfara, o sapejuwe esun ohun gege bi iro
Ẹni tí ó bá kọ̀ yín èmi ni ó kọ̀.
Nítorí ẹ̀san OLUWA ni, ẹ gbẹ̀san lára rẹ̀; ẹ ṣe sí i bí òun náà ti ṣe sí àwọn ẹlòmíràn.
Wo àwọn irọ́ tí wọ́n ń pa fún ọ nípa àrùn Coronavirus Coronavirus: Wo ohun tí o ní láti ṣe láti dáàbò bo ara rẹ Kí ni ìtumọ̀ Pelúpelú, ìlànà àkàsọ̀ ọba tó fa wàhálà l'ọ́balọ́ba l'Ekiti Bí àjálù ìbúgbàmù tó gb'ẹ̀mí ọ̀pọ̀ nìlùú Eko ṣe wáyé nìyí Kọmiṣona ọrọ to n lọ, Gbenga Omotoso sọ fun BBC pe bo tilẹ jẹ pe ijọba ipinlẹ Eko ko laṣẹ lati gbẹsẹle ipejọpọ awọn ẹlẹsin, amọran naa ṣe pataki lasikjo yii.
9 4744 Agbegbe French Polynesia 126 45.
“Fi ojúlówó wúrà ṣe ọ̀pá fìtílà kan.
Fi ọkàn mi balẹ̀ ninu Kristi.
Gẹgẹ bi wọn ṣe sọ loju opo ikansiraẹni Twitter wọn pe Fọwọ́ kan obìnrin lọ́nà àìtọ́, kí o rẹ́wọ̀n ọdún mẹ́rìnlá he- Àwọn aṣòfin yarí Ọwọ́ ọlọ́pàá ìpínlẹ̀ Oyo tẹ àwọn afurasí lórí ìpànìyàn tó wáyé ní Akinyele Ó ṣeéṣe kí àrùn Coronavirus tànkálẹ̀ gba inú afẹ́fẹ́- WHO Bí àrùn Coronavirus ṣe dá gbogbo àgbáyé gúnlẹ̀ sójú kan náà nìyí Bawo ni ẹ ṣe maa fi orukọ silẹ?
Lówurọ̀ ọjọ iṣẹ́gun ni Jacinta Igboke gun Arinze Ani pa ni ṣọọbu rẹ̀ lọ́na opopona Ojo ni agbegbe Satellite Town lẹ́yin ti wọ́n ni gbolohun asọ kan.
Bíodun Fatoyinbo ti fojú hàn ní àgọ ọlọpàá Aṣojú Seyí Makinde lásan ní mo jẹ, òṣìṣẹ́ gbọdọ̀ bọ̀wọ̀ fún mi - Ọ̀dọ́mọdé Kọmísánà ‘Pussypedia’ rèé, ojú òpó tó ń mú àdínkù bá ìṣòro ìmọ̀ nípa ẹ̀yà ara obìnrin Eyi lo wa mu ka maa beere pe, se ẹ setan lati san gbese tiyin tii se ₦121,000?
Èmi kò mọ obìrin tí DSS mú rí —Aisha Buhari
Bí ẹni náà kò bá ra ilé náà pada láàrin ọdún kan, ilé yóo di ti ẹni tí ó rà á títí lae ati ti arọmọdọmọ rẹ̀; kò ní jọ̀wọ́ rẹ̀ sílẹ̀ bí ọdún jubili tilẹ̀ dé.
Oṣu Kinni ọdun 2019 ni ajọ CAF kede Egypt pe oun ni yoo gbalejo idije naa.
Nibayii, Ajọ naa ti wa paṣẹ ki awọn adari ni ajọ naa wa ni iyasọtọ bẹrẹ lati Ọjọ Iṣẹgun.
Oríṣun àwòrán, @Fayemi Alaye ti ọpọlọpọ ma n ṣe ni pe awọn ko fẹ ki orukọ ẹbi tabi ti ìlú àwọn ko ba jẹ.
5 Nítorínáà, bí ìwọ yíò bá kọ́ ìjọ mi lé orí ìpìlẹ̀ ìhìnrere mi àti àpáta mi, àwọn ẹnu ọ̀nà ọ̀run àpãdì kì yíò lè borí rẹ.
Oriṣiriṣi awọn ọrọ lo ti n jade lori pipa erin yii lori awọn opo ayelujara Facebook ati Twitter to fi mọ instagram.
“Olùkọ́ni, Mose kọ òfin kan fún wa pé bí ọkunrin kan bá kú, tí ó fi aya sílẹ̀, tí kò bá ní ọmọ, kí àbúrò rẹ̀ ṣú aya rẹ̀ lópó kí ó lè ní ọmọ ní orúkọ ẹ̀gbọ́n rẹ̀.
Ta ni ń fẹ́ ìyè ninu yín,tí ń fẹ́ ẹ̀mí gígùn,tí ó fẹ́ pẹ́ láyé?
Nítorí kì í ṣe ní kọ̀rọ̀ ni nǹkan wọnyi ti ṣẹlẹ̀.
Àwọn Ẹranko Tí Ó Tọ̀nà láti Jẹ.
Awon onise iwadii ti bere iwadii lori ohun to sokunfa ijamba yii.
bí ẹni pé mò ń ṣọ̀fọ̀ ọ̀rẹ́ mi, tabi arakunrin mi;mò ń lọ káàkiri, bí ẹni tí ń pohùnréré ẹkún ìyá rẹ̀,mo doríkodò, mo sì ń ṣọ̀fọ̀.
Bi kò bá ṣe ayẹyẹ igbéyàwó; á jẹ́ idúpẹ́ fun ikómọ/isọmọlórúkọ; ìsìnku arúgbó; ikóyọ ninú ewu ijàmbá ọkọ̀; iṣile; oyè gbigbà ni ilé-iwé giga tàbi oyé ilú; idúpẹ́ ìparí ọdún tàbi ọdún tuntun àti bẹ̃bẹ̃ lọ.
Àkọsílẹ̀ orúkọ wọn nìyí: Jaṣobeamu láti ìdílé Hakimoni ni olórí àwọn ọ̀gágun olókìkí mẹta.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Nigeria 2019 Elections: Eko, Anambra àti Rivers ló ṣeéṣe kí àtúnbì ìbò ti wáyé 24 Èrèlè 2019 Eto idibo aarẹ ati tawọn asofin agba to lọ nirọwọ rọsẹ lawọn agbegbe kan ni orilẹede naijiria, ni ko ri bẹẹ lawọn agbegbe miran, nitori isẹlẹ idaluru, jiji apoti ibo gbe ati itajẹsilẹ.
Agbẹnusọ fun ileeṣẹ ọlọpaa Naijiria, Frank Mba sọ fun BBC Yoruba wipe ootọ ni pe wọn ti gbe Shogunlẹ lọ Nkalagu nibi ti yoo ti maa ṣe ọga ọlọpaa (area commander) ni ẹkun naa.
Lọjọbọ ti ṣe ọjọ kẹrin oṣu Kẹrin ni Adeleke kọwe ẹjọ kotẹmilọrun ninu iwe ipẹjọ FCT/HC/BW/80/122/2018 lọ si ile ẹjọ giga Abuja.
Ó ṣe ohun tí ó dára lójú OLUWA, ó tẹ̀ sí ọ̀nà Dafidi, baba ńlá rẹ̀, kò sì ṣe nǹkankan tí ó lòdì sí àpẹẹrẹ tí Dafidi fi lélẹ̀.
Odun 1345 ni wọn pari kikọ ile ijọsin alarabara yii.
Ó ní, “Ọkunrin ọlọ́rọ̀ kan wà tí ìkórè oko rẹ̀ pọ̀ pupọ.
Ní àkókò yìí, ọ̀pọ̀ tí ẹ ní yóo mú kí ẹ lè pèsè fún àìní àwọn tí ẹ̀ ń rànlọ́wọ́.
Dafidi pàṣẹ fún àwọn ọmọ ogun rẹ̀, wọ́n sì pa Rekabu ati Baana.
Aàrẹ Marcelo Rebelo de Sousa ẹni ọdùn 71 bẹ́ sómi láti dóòlà obìnrin méjì tó fẹ́ rì sómi Ẹ̀rọ CCTV tú àsírí ọkùnrin ẹni ọgbọ̀n ọdún tó fi ipá bá ọmọ ọdún mọ́kànlá lòpọ̀ Nàìjíríà làwọn ní ìfẹ́ sí ìpèsè abẹ́rẹ́ àjẹsára Covid-19 tí Russia ṣe Òjò àrọ̀ọ̀rọ̀dá dá wàhálà sílẹ̀ l'Eko Idi ni pe iwa idọti, nnkan ti eeyan ko gbọdọ danwo, ni wọn ma n pe e.
Ìgbà náà ló bá nawọ́ sí àwọn kan tọ́n jòkó lókèrè.
Èèyàn mẹ́rin ló tí kú ninú otẹ́ẹ́li àyẹwò Coronavirus to dà wó ni China Akẹ́kọ̀ọ́ ọmọ Afíríkà kan tí lùgbadì ààrùn Coronavirus ní Fásitì China Coronavirus: Italy sọ àgádágodo sí ilé ẹ̀kọ́ alákọ̀ọ́bẹ̀rẹ̀ àti girama Ìjọba àríwá Italy fẹ́ dé èèyàn 16 mílíọ̀nù mọ́lé lórí àrùn Coronavirus Ẹwẹ, ajọ to n mojuto eto ilera nilẹ Gẹẹsi NHS ni awọn ti n ṣafikun agbara lati le ṣe ayẹwo fawọn eeyan pẹlu bi iye awọn to nko Coronavirus ṣe n pọ si.
Oluranwo aare tun so pe  ijoba ti egbe All Progressives Congress (APC) n sakoso re ko ni jawo lati maa tubo so nipa awon asise ijoba ana , bo tile je pe won  ko  je ki awon asesi yii di won lowo lati koju  awon ipenija to n koju orile ede  yii ,gege bi Obasanjo se so ninu oro re.
O so pe“ Ko ye ki aparo kan ga ju okan, lo, ko ye ki oju saaju wa, nipa ise akanse to ye ki won se si ila –oorun orile ede yiiGeeg bi o se so : “ Osu meelo kan seyin ,ni mo so pe won ko kobiara si awon  ise akanse ti won n se ni ila –oorun lori oro oju irin paapaa julo ise akanse ti won n se ni Port Harcourt-Enugu-Markudi  lo si Yola ati Maiduguri lo si Delta, Plateau  ati apa ibi kan ni ipinle  Nasarawa.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Sotitobire: Ọlọ́pàá ní ₦800,000 ní àfurasí náà ń bèèrè láti fi ọmọ tí wọn ń wá sílẹ̀ 17 Sẹ́rẹ́ 2020 Oríṣun àwòrán, Sotitobire Egbirin ọtẹ, ba ti n pa ọkan ni omiran n ru ni ọrọ ọmọdekunrin Gold Kọlawọle, ọmọ ọdun kan ti wọn ji gbe nilu Akurẹ ninu ile ijọsin Sotitobire.
Aworan Afrika: Adura ati ayẹyẹ Kíni ìdí tí àwọn ẹbí àwọn ọmọ Chibok fi ń tọ woli lọ?
Nígbà náà ni Jesu gbé àwọn ọmọde náà lọ́wọ́, ó gbé ọwọ́ lé wọn, ó sì súre fún wọn.
O bẹrẹ si nii ya aworan ni ọdun 2010 nigba ti o wa ni ile ẹkọ giga fasiti Michigan.
Ó fún Nàìjíríà l'èsì àwọn ẹ̀sùn tó fi kàn-án Ijọba Ghana wí àwíjàre rẹ̀ lórí àwọn ẹ̀sùn tí Nàìjíríà fi kàn-án Ijọba orilẹ-ede Ghana ti fesi si ẹsun ti ijọba Naijiria fi kan, pe wọn n fi iya jẹ awọn ọmọ Naijiria nibẹ.
Ninu ọrọ rẹ, Tinubu ni ta ni o ri awọn maalu tabi ẹran nibi ti ipaniyan naa ti waye?
Ẹ máa dúpẹ́ ninu ohun gbogbo nítorí èyí ni ìfẹ́ Ọlọrun nípa Kristi Jesu fun yín.
Lati paarọ adirẹsi rẹ, ẹẹdẹgbẹta Naira ni.
O ni ọrọ abo kii ṣe iṣẹ ọlọpaa nikan.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Nípínlẹ̀ Ògùn, Ọ̀gá ọlọpàá yìnbọn jẹ 19 Ìgbé 2018 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Àwọn ìdílé olóògbé náà kò mọ ìdí tí olóògbé Agholor fi gbé ìgbésè náà Ọ̀gá ọlọpàá kan tó ti fẹ̀yìntì tí orúkọ rẹ ń jẹ́ David Agholor, ti gb'ẹ̀mí ara rẹ̀ ní Ìjokò ní ìpínlẹ̀ Ògùn.
Wọn óo máa gbé ilẹ̀ wọn láìléwu, ẹnìkan kan kò sì ní dẹ́rù bà wọ́n mọ́.
Ibẹ̀ ni ẹ óo kú sí, ibẹ̀ ni wọ́n óo sì sin yín sí; àtìwọ, ati gbogbo àwọn ọ̀rẹ́ rẹ tí ò ń sọ àsọtẹ́lẹ̀ irọ́ fún.
Arabinrin yii ṣapejuwe ara rẹ bi ẹni ti ko lara rara ṣugbọn ti o kan fẹ ṣe afikun diẹ si ibi to ṣe pataki si i ninu ẹya ara rẹ yii.
Orilẹede Rwanda ni orilẹede ilẹ Afirika akọkọ to kede ofun gbele ẹ, ọsẹ meji ni ijọba fi kede ofin konile o gbele naa fi wa nilẹ.
Ọọ̀ni obìnrin, Lúwòó Gbàgídà rèé, akọni tó ń gun ọkùnrin ní ẹṣin rìn Wòlíì Kasali ní Dolapo Awosika kò lé ìyàwó òun jáde Àrà méèrírí!
Naijiria lu orilẹ-ede Qatar ni alubami ninu ifẹsẹwọnsẹ akọkọ ti wọn gba ninu idije FIFA U-20, ṣugbọn wọn fidi rẹmi ninu ere bọọlu keji lẹyin ti ikọ agbabọọlu Amẹrika la wọn mọ lẹ.
Nítorí náà, ẹ má fetí sí ọ̀rọ̀ àwọn wolii yín, ati àwọn awoṣẹ́ yín, àwọn alálàá yín ati àwọn aláfọ̀ṣẹ yín, ati àwọn oṣó yín, tí wọn ń sọ fun yín pé ẹ kò ní di ẹrú ọba Babiloni.
ÌTUMỌ̀: Ìṣẹlẹ̀ kìí dédé wáyé, ohun kan ló máa ń fà á wá
BBC Yoruba yoo kan sileesẹ ọlọpaa laipẹ lati mu ẹkunrẹrẹ iroyin wa fun yin nipa isẹlẹ naa.
Nítorí níwọ̀n ìgbà tí owú jíjẹ ati ìjà bá wà láàrin yín, ṣé kò wá fihàn pé bí ẹlẹ́ran-ara ati eniyan kan lásán ni ẹ̀ ń hùwà.
" Ṣugbọn o ni iwadii nikan ni yoo tu aṣiri nkan to ṣẹlẹ ni pato, awọn to hu iwa naa, ati idi ti wọn fi hu u.
Aarẹ Muhammadu Buhari soju abẹ niko lori iroyin kan to n tan kalẹ pe aarẹ n gbero lati lọ fun saa kẹta, ti saa keji rẹ ba pari.
Ẹ jẹ́ kí a jẹ́ ènìyàn ẹlẹ́ran ara, ohun tí ó dára jù ní ayé yìí nìyẹn.
Eniyan a máa tọ́jú ẹṣin sílẹ̀ de ọjọ́ ogun,ṣugbọn OLUWA ló ni ìṣẹ́gun.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ohun tawọn eeyan Kogi n sọ saaju idibo Gomina Esi idibo naa fun oludije lẹgbẹ oselu APC, Smart Adeyemi gẹgẹ bi ẹni to n le iwaju ninu eto idibo pẹlu ibo 89,153, nigba ti Melaye ti wọn jọ n figagbaga lati ẹgbẹ oṣelu PDP ni ibo 59,000 Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Kogi vs Bayelsa: Primate Ayodele sọ àsọtẹ́lẹ̀ Amọ Ajọ INEC gbẹsẹ le eto idibo naa nitori wọn wogile ibo 20,157 ti wọn di ni ibi ti iwa ipa ti waye, ti wọn si ni idibo naa kẹsẹjari.
Koda a ti ri awọn to lowo ti gbogbo aye si gba ti wọn bi MKO Abiola ti ko ri bi de ipo Aarẹ.
Gbogbo àwọn àgbààgbà Israẹli wá sí ọ̀dọ̀ ọba ní Heburoni, Dafidi ọba sì bá wọn dá majẹmu níbẹ̀ níwájú OLUWA.
Ní Zamfara àjọ EFCC ń sewadìí Yari fún dídari owo to tó biliọnu naira, Saááju ni ile ẹjọ kan l'Abuja ti gbésẹ̀ lé ẹ̀ẹ̀dẹ́gbẹ̀ta mílíọnù naira lọdun 2017, owo ti wọn ji ko ninu owo paris club ti ijọba apapọ fún àwọn ìpínlẹ̀ mẹ́rìndinlógóji Nàìjíríà.
Kò sí irú wọn rí ní gbogbo ilẹ̀ Juda.
Bí ènìyàn bá ń fẹ́ẹ́ ní ìyàwó ó yẹ kí olúwaarẹ̀ ronú dáradára kí ó sì bẹ Olódùmarè  kí Ó ṣe amọ̀nà òun, nítorí ìyá yátọ sí ìyàwó, bàbá yàtọ̀ sí obìnrin ẹni.
 Àwọn àjẹsára méjèèjì náà ti dẹ ́ kun àrùn rọpárọsẹ ̀ ní ọ ̀ pọ ̀ lọpọ ̀ orílẹ ̀ -èdè àgbáyé , wọ ́ n sì ti dín iye ènìyàn tó ń ní àrùn náà lọ ́ dọọdún kù láti iye tí a ṣírò sí 350,000 ní ọdún 1988 sí 359 ní ọdún 2014 .
Toyin Atoyebi mechanic: Ẹ wo Toyin, ọmọbinrin ọdún 16 tó ń tún ọ̀kadà àti gẹnẹrátọ̀ ṣe ní Wo ọ̀nà tí o fi lè dáàbò bo ọmọ rẹ lọ́wọ́ COVID-19 níléèwé Ìdùnnú subú layọ̀ nípìnlẹ̀ Ọyọ́, àwọn tó dé láti Lebanon sọ ọmọ wọn ní Seyi Akọ̀wé-owó wọ gàù ní iléẹjọ́ lórí ẹ̀sùn pé ó jí N500,000 lọ́wọ́ ọ̀gá rẹ̀ Ki lode to jẹ isinyii ni NLC fẹ ṣe ifẹhọnu han lẹyin ti awọn eniyan ti n ra ọwọngogo epo, ina ati ounjẹ?
Àwọn wundia òmùgọ̀ wá bẹ̀rẹ̀ sí bẹ àwọn ọlọ́gbọ́n pé, ‘Ẹ jọ̀wọ́ ẹ fún wa ninu epo yín, nítorí àtùpà wa ń kú lọ.
Ninu fọnran aworan yii, iya Gold salaye bi ko ṣe ki n fẹ fi ọmọ rẹ silẹ ati bi awọn ẹṣọ ijọ ṣe ni o yẹ ko maa gbe ọmọ rẹ lọ si yara ti wọn n ko awọn ọmọ wẹwẹ si.
awọn iroyin synoptics orisirisi awọn iṣẹlẹ iyanu nigba agbelebu .
Mo kí arakùnrin mi, Olúwó ti ìlú Iwò dáadáa, gẹ́gẹ́ bí èyí ṣe jẹ́ ìgbà àkọ́kọ́ rẹ̀ ní ààfin mi."
A n duro de igbẹjọ mii to tun n bọ lati pinu bi ẹjọ naa yoo ṣe yọri.
Ọ̀rọ̀ ojuṣaaju kò ní sí níbẹ̀.
Ní ọjọ́ iwájú, ọ̀pọ̀ tí àwọn náà bá ní yóo mú kí wọ́n lè pèsè fún àìní yín.
Oríṣun àwòrán, Reuters Ẹwẹ, lati nkan bi ọdun 1980 ni wọn ti ya apa ibikan sọtọ ninu iho naa to gun de ori-oke Sodom, to jẹ apata to gun julọ lorilẹede Israel.
Alákọrí kún inú ayé dé ẹnu, ẹ̀rù àwọn ẹlòmíràn ń bà mí, wọ́n á máa kígbe ọmọ-ọlọ́mọ káàkiri, wọ́n á kígbe ní ilé, wọ́n á kígbe ní oko, wọ́n á kígbe ní kọ̀rọ̀, wọ́n á kígbe ní gbangba, wọ́n á kígbe ní ọ̀ọ̀dẹ̀, wọ́n á kígbe ní yàrá, wọ́n dàbí ọkùnrin arẹwà tí ó dára lójú ṣùgbọ́n tí inú rẹ̀ kún fún jẹ̀díjẹ̀dí àti aràn, èérí ẹ̀dọ̀ àti èérí ìfun, àwọn wọ̀nyí kò ní gbòǹgbò rárá bẹ́ẹ̀ ni wọ́n ń kígbe kiri pé gbòǹgbò ẹlòmíràn kò tóbi, àfòmọ́ ń pẹ̀gàn ìrókò, ìtàkùn lásán ń pẹ̀ggàn awùsá, ìyẹ́ ń wi pé òkúta kò wúwo – bẹ́ẹ̀ ni ìyẹ́ ń bẹ lójú omi, òkúta ń bẹ ní ìsàlẹ̀ odò.
LAFIYA DOLE, soro naa di mimo fun awon akoroyin, niluu Maiduguri.
Àwọn ọmọ ti Sera ni Jeueli ati àwọn ìbátan rẹ̀, wọ́n jẹ́ ẹẹdẹgbẹrin ó dín mẹ́wàá (690).
"1 fm "" , níbi tí ó ti jẹ ́ ọ ̀ gá àgbà àwọn elétò ní ilé iṣẹ ́ ìgbóhùn-sáfẹ ́ fẹ ́ "" max fm "" tí ó ń jẹ ́ ( radio continental ) tẹ ́ lẹ ̀ ."
 Awon papako ofurufu ni awon atunse ti deba, eyi waye ni awon papako ofurufu ni Abuja, Ipinle Eko , Kano ati ipinle Enugu.
Se ohun to ba si ti ya kan, kii tun pẹ mọ, Aaya ti wa bẹ silẹ, o ti bẹ sare bayi, ijiroro ati iroyin nipa asa ati oselu ti wa gba ọna ọtun yọ bayi, ọpọn ti sun.
 nígbà tí òun náà dàgbà , ó dí ilé-ìfowópamó tí a ti lè máa yá àwon òtòsì lówó sílè .
Bí wọn sì ti dé ọ̀hún, wọ́n mu èso igi ìwòsàn, wọ́n fi si i ní imú, gbígbóòórùn tí Ẹwadapọ̀ gbóòórùn rẹ̀ báyìí, ṣe ló dìde gáú, ara rẹ̀ ti le.
7 27877 Orilẹede Cuba 136 1.
Oríṣun àwòrán, Twitter/Katung Aduwak O gba ẹbun owo ẹgbẹrun lọna ọgọrun un dọla ($100,000).
iye ibo to pọ ju awon alatako rẹ’’ .
    Ẹ bámi kí àwọn ọ̀rẹ́ yín dáadáa,
Ọlọrun jẹ́ kí àwọn nǹkan wọnyi ṣẹlẹ̀ sí wọn nítorí pé wọ́n ti kọ OLUWA Ọlọrun àwọn baba wọn sílẹ̀.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù SayNotoRape: Àlùfá tọ ba ọmọ ọdún méje sùn, wẹ̀wọ́n ọdún Márùn-un ni ìpínlẹ̀ Ekiti 16 Ògún 2019 Oríṣun àwòrán, Kayode Fayemi Àkọlé àwòrán, Fayemi fojú afípàbánilòpọ̀ síta ní Ekiti Ìjọba ìpínlẹ̀ Ekiti tí dí àkọ́kọ́ tí yóò bẹ̀rẹ̀ láti maa dárukọ ọ̀daran afipa banilòpọ̀ han àti láti maa doju ti wọ́n.
Awon kan n ni isoro leyin ibimo lo sokunfa iku re.
JOHESU so pe awon ko ni ba ijoba se iduna-dura  Kankan po moIgbakeji aare egbe JOHESU Ogbonna Chimela so pe“Ko si iduna-dura Kankan mo, nitori pe ijoba ti ba wa sadehun ti won towobo, ohun kan ti a n wo ni ona ti ijoba yoo se maa san owo ajemonu opolopo osu ti won je won, o  ti di odun  merub bayii, lati odun 2014”.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Anthony Joshua vs Pulev: Anthony Joshua rọ̀jò ẹ̀ṣẹ́ lu Pulev 13 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Oríṣun àwòrán, Reuters Nnkan yan lalẹ ọjọ Satide, ọjọ kejila oṣu kejila ọdun 2020 nigba ti awọn akanṣẹjẹun meji, Anthony Joshua ti ilẹ Gẹẹsi ati Kubrat Pulev ọmọ Bulgaria.
Ọsẹ keji ti ijọba dẹ isede lo n pari lọ bayii, ṣugbọn gomina sọ pe ọsẹ mẹfa ni yoo gba.
Akeem Pharm, Arabinrin Adenikẹ Ajayi-Bẹmbẹ, Ọgbẹni
Nǹkankan péré ni mo fẹ́ bi yín: ṣé nípa iṣẹ́ òfin ni ẹ fi gba Ẹ̀mí ni tabi nípa ìgbọràn igbagbọ?
4 25,368 DR Congo 628 0.
akọ mààlúù kékeré kan, àgbò kan, ọ̀dọ́ àgbò kan ọlọ́dún kan fún ẹbọ sísun; 
Ija lati oju ofurufu ni ileeṣẹ ologun Naijiria ṣaba n lo, lati ri aye wọ awọn ibudo awọn agbesunmọmi, to wa ninu igbo.
 Òrò atókùn àti apor ni a máa ń bá nínú àpólà atókùn ni a fa igi sí ní ìdí ní ( 38 ) .
‘Wàhálà yín pọ lórí Bayelsa ati Zamfara, àwa náà yóò ṣé àyẹwò ìdájọ tó gbé Buhari wọlé’ Ibi àyẹ̀wò mẹ́ta ló wà fún Coronavirus ní Naijiria Ọpọ awọn Naijriia lo ti bẹrẹ si n fi eroungba wọn lede loju opo Twitter lori iṣẹlẹ naa pẹlu ami #End SARS, pe ki ijọba gbẹsẹle ẹka ileeṣẹ ọlọpa to n risi ọrọ awọn adigunjale, iyẹn SARS.
Ìjọba Katsina ti gbogbo ilé ìwé tí àwọn akẹ́kọ̀ọ́ ń gbé pa lẹ́yìn àkọlù tó wáyé níbẹ̀ Gomina ipinlẹ Katsina, Aminu Masari ti paṣẹ pe ki wọn ti gbogbo ile iwe ti awọn akẹkọọ n gbe ni ipinlẹ naa pa.
Ann Chiejine, akonimoogba ti o darajulo“Coach of the Year (Women)’’, ti agbaboolu iko MFM FC, Sikiru Olatunbosun gba ami-eye ami ayo ti o darajulo “Goal of the Year’’ award.
Ó bá lọ, ó bẹ́ ẹ lórí ninu ilé ẹ̀wọ̀n.
OLUWA ní:“Ẹ kó ara yín jọ kí ẹ wá,ẹ jọ súnmọ́ bí,gbogbo ẹ̀yin tí ẹ kù ninu àwọn orílẹ̀-èdè.
ile-iwosan medical charity Medecins Sans Frontieres (MSF) ti orile ede  France  fi dawọ ise won duro losu to kọja.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Theresa May: A dúpé lọ́wọ́ Minisita fún isẹ́ tó se lásìkò rẹ̀ 9 Agẹmo 2018 Oríṣun àwòrán, PA Àkọlé àwòrán, Ìròyìn sọ pé ìkọ̀wéfipọ̀sílẹ̀ Boris Johnson tó jẹ́ Minisita fórọ̀ ilẹ̀ òkèèrè, ní Ilẹ̀ Gẹ̀ẹ́sì nííse pẹ̀lú 'Brexit'.
" Awọn ijọba ti gbe igbesẹ lori ohun to n ṣẹlẹ lagbegbe naa.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Codein lọ, DXM wọlé, kinni iyatọ?
Kí ó ṣe é pẹlu burẹdi tí a kò fi ìwúkàrà sí ati ewébẹ̀ kíkorò.
Kí lo mọ̀ nípa fẹntilétọ̀, ohun èlò aṣèrànwọ́ èémí Kí làwọn ìdàmú tí Coronavirus n mú bá àgọ́ ara?
Ẹ jókòó sí ilẹ̀ yín gbogbo ẹ̀yín tó fẹ́ lọ sí Mecca Igbákejì mínísíta fún ìlera ní Iran ti kó Coronavirus Kí ni ìjọba ń ṣe lórí ààrùn Coronavirus tó wọ Nàìjíríà?
Ìjàm̀bá Àwọn Ológun Mauritania 28 tí wọ́n pa ní ọjọ́ Òmìnira tí a kò sọ
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Iwo Kingmakers: Ìjọba Osun ní òun sí ń wo ọ̀rọ̀ Oluwo àtàwọn afọbajẹ lọ́wọ́ kó tó mọ ìgbésẹ̀ tó kàn 24 Owewe 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 28 Owewe 2020 Oríṣun àwòrán, Oluwo/instagram Yoruba ni agba kii wa lọja, kori ọmọ tuntun wọ, bẹẹ si ni agbalagba ti ko ba kẹu sọrọ, afaimọ ko ma kẹtan sare.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Oyo PDP: Olórí ọ̀dọ́ farapa ni, ẹni tó wa ọ̀kọ́ ló kú 20 Ọ̀pẹ̀̀ 2019 Oríṣun àwòrán, PolyIbada/Facebook Ọkọ to gbe awọn ọmọ ẹgbẹ oṣelu Peoples Democratic Party ipinlẹ Ọyọ to n bọ lati ibi idajọ ile ẹjọ giga julọ nilu Abuja eyi to gbe gomina Seyi Makinde leke ni ijamba, o mu ẹmi ọmọ ẹgbẹ kan lọ awọn mẹta mii si fara pa.
N óo mú ìpayà ati ìsọdahoro bá ọ,bí mo ṣe mú un bá Samaria, ẹ̀gbọ́n rẹ.
Gbójú sókè, kí o wò yíká,gbogbo àwọn ọmọ rẹ péjọ, wọ́n tọ̀ ọ́ wá.
Ṣugbọn Eliṣa dáhùn pé, “Mo fi OLUWA tí mò ń sìn búra pé n kò ní gba nǹkankan lọ́wọ́ rẹ.
Oriṣa ẹgbọ̀rọ̀ mààlúù kì í ṣe Ọlọrun, iṣẹ́ ọwọ́ eniyan ni, a óo sì rún ti Samaria wómúwómú.
Báyìí ni mo ṣe gbẹ̀san lára ọ̀rẹ́kùnrin mi tó kó HIV ràn mí
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Russia Shooting: Ọmọ ogun mẹjọ ni ilẹ Russia ni wọn ti ríkú òjiji he tí méjì míràn si farapa.
A ba onimọ ẹsìn,ọjogbọn Nasirudeen Bello sọrọ lórí àwọn nnkan to ye ki ẹ ṣé lati le ni láádá ati làádà to wa ninu oṣù náà.
Bakan naa ni aarẹ ẹgbẹ awọn oṣere sinima, TAMPAN, Bọlaji Amuṣan ti ọpọ mọ si Baba Latin pẹlu fi idi eyi mulẹ ninu ifọrọwerọ rẹ pẹlu ileeṣẹ iroyin abẹle kan.
Nítorí a kò mọ ohun tí ó tọ́ tí à bá máa gbadura fún.
Wọ́n bá mú un, wọ́n tì í jáde kúrò ninu ọgbà àjàrà, wọ́n sì pa á.
Ilé MKO Abiọlá di ibùgbé àwọ̀n asínwín Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Àwọn ṣajẹ tó gbayì jù láwùjọ O fi kun ọrọ rẹ pe awọn ọlọpaa yoo ṣe afihan afurasi naa l'Ọjọbọ.
#7000 sí #10000 ni owó àbẹ̀tẹ́lẹ̀ fún bẹẹdi ní ilé àwọn aláìsàn ọpọlọ Adeola ko ni iwe irinna kankan, amọ o ni awọn to mu ohun lọ sọ wi pe, Côte d'Ivoire ni wọn yoo ti se iwe irinna ọhun fun oun, ti wọ̀n si sekilọ fun pe ko gbọdọ fi ọrọ naa to ẹnikẹni leti, titi ti yoo fi lọ.
apejopo ohun, paapaa awon odo nija lati tele ipase Awolowo lati ri pe won sapa
Ta ni mo gba nǹkan lọ́wọ́ rẹ̀ tí mo níláti dá a pada fún un?
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Rape: ‘Uncle àti Granpa’ mi máa ń fi owó àti ẹ̀bùn fa ojú mi mọ́ra 3 Agẹmo 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Ọmọbinrin kan ti a fi orukọ bo ni aṣiri, ti ọjọ ori rẹ to ọdun mejilelogun bayii, ti sọ bi baba iya rẹ ṣe fipa ba lopọ fun ọpọlọpọ ọdun, lati igba to n gbe lọdọ baba naa ati iyawo rẹ, tii se iya iya ọmọ yii.
Wọn pari idanwo naa lọjọ Abamẹta dipo ọjọ Aiku ti wọn fisi tẹlẹ.
Your Premier League champions 2018/19 👏👏👏 pic.
Àwọn Ọmọ Israẹli La Odò Jọdani Kọjá.
Lẹẹkeji ohùn náà tún wá láti ọ̀run.
Ewe, Dokita Abari wa ro awon osise patapata lati se ojuse won bi o se to lojuna ati wa ni ibamu pelu erongba iyipada otun eleyi ti aare Buhari yan laayo fun ilosiwaju ati idagbasoke orile-ede Naijiria.
Toyin Abraham tú àṣírí ohun tí ọlọ́pàá Náìjíríà sọ mọ́lẹ́bí rẹ̀ kan dà Àwọn akẹ́kọ̀ọ́ 181 pẹ̀lú Olùkọ́ lùgbàdì Covid 19 níléèwé aláàdáni kan nípinlẹ̀ Eko Ìdí táwọn olùwọ́de EndSARS fi kọ oúnjẹ àti ọtí ẹlẹ́rìndòdò tí MC Oluomo gbé wá rèé Sọ̀rọ̀ sókè!
 Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Christmas: Ẹni ti ọdun ba ti bá láyé yẹ kó dúpẹ́ Shehu ni Sowore lo ipo rẹ gẹgẹ bi gbajumọ lati idoju ijọba bolẹ lori ẹrọ amohunmaworan ati ninu iwe iroyin rẹ lori itakun agbaye."
Kí inú ọ̀run kí ó dùn,kí ayé kí ó yọ̀,kí wọ́n sọ láàrin àwọn orílẹ̀-èdè pé “OLUWA jọba!
" Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Tóò bá fún ọkùnrinn lóúnjẹ́ tóo tẹ́ kiní yẹn sílẹ̀ fún un dáadáa.
Ko pé ni wọn deede gbọ ariwo rẹ to n ja sinu kọnga ti o jin to ọgọsan an mita silẹ.
Bi o tilẹ jẹ pe awọn akẹkọọ to wa ni kilaasi akẹkọjade nikan lo wọle pada, sibẹ awọn obin to ba BBC Yoruba sọrọ ni akoko ko ti to lati silẹkun ileewe pada.
O kò ka ìbúra mi sí, o sì ti yẹ majẹmu mi.
Níta gbangba, ogun ń pa mí lọ́mọ;bákan náà ni ikú ń bẹ ninu ilé.
Isiaka Busari, Mighty Joe tó jẹ́ adigunjalè tó rọ́pò Ọyenusi lẹ́yìn tí wọ́n pa á Minisita feto irinna ofurufu, Hadi Sirika lo fi eyi sita loju opo Twitter rẹ.
Ọkùnrin kan fipá bámi lòpọ̀ lọ́mọ ọdún mọ́kàndínlógún- Funke Oshonaike Ààrùn Coronavirus tún ti ran ènìyàn 595 l'órílẹ̀-èdè Nàìjíríà Ọlọ́pàá kọ́ lo pa olórí àwọn ''One Million Boys'' Ebila n'Ibadan- Ọ̀gá ọlọ́pàá Oyo Kí ló fa ìjà láàrin Wunmi Toriola àti Seyi Edun?
Awọn onimọ isẹgun a maa kilọ pataki ki eniyan maa mu omi, ati pe bi eniyan ko ba mu omi to, o le koba awọn eroja kan ninu ara.
Ìgbà tí o ba ṣe tí a bá wo òkè ọ̀wọ̀n yìí, a dàbí ojú ènìyàn.
Bi a ba mu adinku ba agbara awọn mẹkunu lati ra nnkan lọja, eyi yoo ṣe idiwọ fun idagbasoke ọrọ aje.
Nínú àtẹ́jáde náà, ìpínlẹ̀ Eko ló ń léwájú pẹ̀lú ènìyàn 104, ìpínlẹ̀ Kaduna tẹ̀lée pẹ̀lú 59, Abuja 50 nígbà ti Rivers 17 Ogun 16.
ÌP&ID: Ẹgbẹ́ àgbáríjọpọ̀ ajàfẹ́tọ̀ọ́ fẹ̀hónú hàn l'Abuja lórí ìdájọ́ tó gbẹ́sẹ̀ lé $9.
Ó dàbí ẹrú tí ń wá ìbòòji kiriati bí alágbàṣe tí ń dúró de owó iṣẹ́ rẹ̀.
Koríko a máa gbẹ,òdòdó a máa rẹ̀,
Oríta mẹ́ta kan ń bẹ lọ́nà àbáwọ igbó ńlá náà.
Ó ṣe òpó meji sí iwájú ilé náà, ọ̀kọ̀ọ̀kan rẹ̀ ga ní igbọnwọ marundinlogoji (mita 15).
Ẹ̀ṣọ́ tí ń ṣọ́ bodè gun orí odi lọ, ó dúró lé orí òrùlé ẹnubodè.
 Saraki tun ṣalaye siwaju sii wi pe ohun to ṣokunfa osi ati aini ni ilẹ Afirika ko ṣẹyin bi awọn orilẹede Afirika ṣe sọ ara wọn di orilẹede to n pese ohun eelo fun agbaye."
Oríṣun àwòrán, Bolaji Amusan Àkọlé àwòrán, Ìdá 90% nínú àwọn olówó Naijiria lo n lọ ilé babaláwo- Mr Latin O ní lẹ́yìn iṣẹ́ soja, iṣẹ́ ere ori ìtàgé tún ni o ni àṣà ìbáwi jùlọ, nítori náà gbogbo ǹkan ti àwọn ń ṣe, ìdánilẹkọ̀ọ́ lo wà fún.
Nígbà tí mo bá dójú lé wọn, ẹ óo wá mọ̀ pé èmi ni OLUWA.
Lẹyin ti China sọ pe oun ti padanu lara awọn ọmọ ogun ohun ni awọn ọgagun lati orilẹ-ede meji naa pe ipade alaafia.
Nígbà tó ń fèsì lórí ìbéèrè pé ìgbà wo ni olori tuntun yóò wọ ààfin rẹ lẹ́yìn tí aya rẹ tí kúrò ní ààfin, Oluwo ni àìmọye ọba míì tí wá nílẹ Yoruba ti wọn ṣẹ̀ṣẹ̀ ń wá ìyàwó, nígbà tó sì yá, wọn si ri ìyàwó, ó fikùn pé, kí àwọn èèyàn dúró de ìgbà tí Ọlọ́run bá yàn fún òun.
Ẹfunroye Tinubu - Ògbóǹtagí oníṣòwò, olówò ẹrú àti afọbajẹ Samuel Ajayi Crowther, òjíṣẹ́ Ọlọ́run tó gbé èdè Yoruba lárugẹ Mọrèmi Àjàṣorò, akọni obìnrin tó gba Ilé Ifẹ̀ sílẹ̀ lóko ẹrú Niwọn igba to si jẹ pe a kii mọ Alaja, ka na aja rẹ, eyi lo mu ki olu ileesẹ ajọ amunawa, IBDEC, to wa nilu Ibadan fi setan lati wa epo dẹkun fun awọn ọdọ to san iru asọ yii soro, lọna ati kọ ero ẹyin bii tiwọn lọgbọn.
Fun bi ogun ọdun sẹyin, awọn akẹkọọ Fasiti Copperbelt gbagbọ pe ẹja Mafishi maa n gbe ire ko wọn ninu idanwo.
14 Ògún 2019 Oríṣun àwòrán, Instagram/officialbroadwaytv Ọrọ ifẹ bi adanwo ni, oṣere tiata, Toyin Abraham ti sẹ ayẹyẹ adehun igbeyawo pẹlu oṣere miiran Kolawole Ajeyemi.
Ìgbà mìíràn alágàbàgebè a máa wá ọ̀nà àti pa ẹlòmíràn ṣùgbọ́n dípò onítọhùn òun pàápàá á lọ si àjùlé ọ̀run; ìgbà mìíràn abínúkú ọ̀rẹ́ a máa wá ọ̀nà àti pa ọ̀rẹ́ rẹ̀ ṣùgbọ́n dípò onítọ̀hún òun pàápàá á lọ sí àjùlé ọ̀run, ìgbà míràn olówó a máa wá ọ̀nà àti pa tálákà ṣùgbọ́n dípò onítọ̀hún òun pàápàá a lọ si àjùlé ọ̀run; ìgbà mìíràn ẹni kékeré a máa wá ọ̀nà àti pa ẹni ńlá ṣùgbọ́n dípò onítọ̀hún òun pàápàá a lọ si àjùlé ọ̀run.
Wo ìgbẹ́sẹ̀ méjọ tí ilé aṣòfin ìpínlẹ̀ gbọdọ̀ tẹ̀lé láti yọ igbákejì gómìnà Kòṣẹlẹ̀rí ni Hajj ọdún 2020, wo ìyàtọ̀ tó wà nínú rẹ̀ sí ti tẹ́lẹ̀ Nígbà ti àwọn amòokùnṣìkà yìí tún bẹ́ sílé àwọn Barakat Bello tí wọ́n fípa ba ọmọ ọdún méjìdínlógún ọ̀hún lòpọ̀ nínú balùwẹ̀ ilẹ́ wọ́n tí wọ́n sì tún pa a síbẹ̀.
Fún àpẹẹrẹ, ẹni tó bá ní ààsàn bí ikọ́'fe (Asthma), bóya ọmọdé tàbí àgbàlagbà.
Nígbà tí Rehoboamu kú, wọ́n sin ín sí ìlú Dafidi, níbi ibojì àwọn baba rẹ̀.
Lọdun 2019 ni ileeṣẹ ogun oju ofurufu ṣẹṣẹ fi ami ẹyẹ da Tolulope Arotile lọla gẹgẹ bi Ajagun-awakọ ofurufu obinrin akọkọ ti wọn ni.
Ìlẹ̀kùn tí ó bá ṣí, kò ní sí ẹni tí yóo lè tì í; èyí tí ó bá tì, kò ní sí ẹni tí yóo lè ṣí i.
igbagbe, ti orile ede Naijiria naa yoo si bere maa ko ounje lo si oke okun.
Ó ṣeni láàánú pé ti Carolina kún ìṣirò tí ó ti wà nílẹ̀, ọ̀pọ̀ ọ̀ràn báyìí ti wáyé kí tirẹ̀ ó tó ṣẹlẹ̀ tí àwọn ènìyàn gbọ́ sí, bẹ́ẹ̀ sì ni ẹgbẹẹgbẹ̀rún àwọn ọ̀ràn mìíràn tí àwọn èèyàn ò mọ̀ sí, ó jẹ́ ìṣòro kan tí ó ti wà níbẹ̀ lẹ́nu ọ̀nà níwájú wa.
Bí o bá ń bá aládùúgbò rẹ ṣe àríyànjiyànmá ṣe tú àṣírí ẹlòmíràn,
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Pool drown: Ìbejì ọmọ ọdún méjì Mínísítà fún ọ̀rọ̀ omi bá odò lọ 14 Èbibi 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 15 Èbibi 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Aworan yi la fi ṣe akawe iya to padanu awọn ọmọ rẹ Ina ọmọ ti jo Minisita fun ọrọ alumọni omi lorileede Uganda, Ronald Kibuule, pẹlu bi awọn ọmọ ibeji ọkunrin rẹ ṣe bodo lọ.
Àwọn ohun tí o gbọ́ láti ẹnu mi níwájú ọpọlọpọ ẹlẹ́rìí, ni kí o fi lé àwọn olóòótọ́ eniyan lọ́wọ́, àwọn tí ó tó láti kọ́ àwọn ẹlòmíràn.
Nítorí náà n óo lo agbára mi láti fi jẹ Ijipti níyà, ń óo sì ṣe iṣẹ́ ìyanu níbẹ̀, nígbà náà ni yóo tó gbà pé kí ẹ máa lọ.
2 Sẹ́rẹ́ 2020 Laago mẹrin idaji aarọ yii ni ijọba wa wo ile arugbo ti Bukola Saraki ni kí wọn ma wo tẹlẹ, ọrọ bẹ́yìn yọ.
Ẹwẹ, ṣaaju eyi, Ile Igbimọ Aṣofin naa ti kọkọ ṣagbeyẹwo awọn ọmọ ẹgbẹ Ile Igbimọ Aṣakoso Ile Igbimọ Aṣofin Ipinlẹ Eko, eleyii ti Gomina Akinwunmi Ambọde beere fun lati le da wọn pada sinu igbimọ naa.
Nítorí wọ́n kọ́ pẹpẹ ìrúbọ, wọ́n sì ri ọ̀wọ̀n òkúta ati ère oriṣa Aṣerimu mọ́lẹ̀ lórí gbogbo òkè ati lábẹ́ igi tútù káàkiri.
Tí o fi wá ń wádìí àṣìṣe mi,tí o sì ń tanná wá ẹ̀ṣẹ̀ mi?
Ṣé wọn yóo tún ìlú wọn kọ́ ni?
Ní òwúrọ̀ kutukutu ọjọ́ keji, Saulu pín àwọn ọmọ ogun rẹ̀ sí ọ̀nà mẹta, wọ́n kọlu ibùdó àwọn ọ̀tá wọn, wọ́n sì bẹ̀rẹ̀ sí pa wọ́n títí di ọ̀sán ọjọ́ náà.
Bakan naa ni wọn tun sọ pe dandan ni wiwọ ibomu fun awọn to fẹ ẹ fi orukọ silẹ.
Ebenezer Obey ń wá ìyàwó , wo àmúyẹ tí o gbọdọ̀ ní tí o bá fẹ́ ẹ́ di aya lọ́ọ̀dẹ̀ baba Awọn obi naa ti wọn ya bo ileewosan MTR Specialist Hospital nibi ti wọn ti ni ayẹwo naa yoo ti maa waye ni awọn ko gbaradi fun irufẹ owo bẹẹ ni sisan ati pe bawo lọbọ ṣe ṣori ti inaki o ṣe to fi jẹ wi pe awọn akẹkọọ ileewe aladani nikan ni yoo maa san owo ayẹwo nigba ti awọn akẹkọọ ileewe ijọba ko ni san kọbọ fun ayẹwo kokoro arun naa.
Diẹ to ninu nkan oni nkan, ẹ funra yin wo sii ki ẹ gbọ pabanbari ninu fidio to mbẹ loke iroyin yii.
Ǹjẹ́ ẹnìkan lè gbé iná ka àyà,kí aṣọ rẹ̀ má jó?
Ó dúró ní ibi tí ó ga lẹ́bàá ọ̀nà,ati ní ojú ọ̀nà tóóró,
Àwọn tí wọ́n gbọ́ ni wọ́n fún wa ní ìdánilójú pé bẹ́ẹ̀ ni ó rí.
” Nítorí náà, ó sọ ọmọ náà ní Dani.
Ọ̀rọ̀ lórí àwọn nǹkan tí ẹ kọ nípa rẹ̀, ó dára tí ọkunrin bá lè ṣe é kí ó má ní obinrin rara.
Àwọn ìlànà sí àtúnṣe ní a le ri ninu àwọn abala ilàna bí a ṣe ń kọ ìròyìn Ọ̀nà tí à n gbà ṣe ìwádìí ìròyìn wa gbọdọ̀ dá lóri òòtọ́, èyí ti o ṣe gbéléwọ̀n, tí a si kọọ́ sílẹ̀ ní èdè tó dántọ́ ati pe ko gbodo ni ìtúmọ míràn sí ohun ti a sọ.
Ẹwẹ, nigba ti BBC Yoruba kan si Sowore, o ni oun ṣẹṣẹ n gunlẹ lati irinajo kan ni pe oun yoo tun ba BBC sọ ẹkúnrẹrẹ ọrọ laipẹ ṣugbọn ni toun, oun ṣi ni alaga ẹgbẹ.
Jesu bi í pé, “Kí ni ó wà ní àkọsílẹ̀ ninu òfin?
O ni eniyan buruku ti o kan n lo orukọ Ọlọrun ni ọpọlọpọ wọn.
ṣugbọn yóo wà gẹ́gẹ́ bí ẹ̀rí, láàrin àwa pẹlu yín, ati àwọn ìran tí ń bọ̀ lẹ́yìn wa, pé àwa náà yóo máa sin OLUWA, a óo sì máa rú ẹbọ sísun ati ẹbọ alaafia níwájú rẹ̀.
Gassama so lori ero amaworan orile-ede Faranse p, nigba ti oun ri omode naa ti o ji diro-diro lori bakoni, mi o lero pe, mo gbemi omo naa la.
Jesu Oyingbo rèé, pásítọ̀ tó láṣẹ ìbálòpọ̀ lóri ọmọ ìjọ obìnrin Igbó mímu lè ṣe kóríyá, kò lé fi kún orín ẹnu òṣèré - 9ice Helen Paul: Ọmọ atàpáta dìde ni mí, ẹ má fójú ajẹbọ́ wò mí Ẹtahoro pere si ni awọn eeyan to mọ irufẹ ami to wa lori ọrọ naa, nigba ti awọn eeyan miran sọ di ẹrin keekee.
Nibi ipade ikowo jo kan, ninu eyi ti awon orile-ede bi adota ti kopa, ninu eyi ti a ti ri orile-ede America, Japan, ati Norway, ireti wa pe, ile-ise ologun orile-ede Faranse yoo ni atileyin to peye, latari ati faye gba lilo awon omo-ogun elekun-jekun, eyi ti won daba re ni nnkan bi odun merin seyin, lati bere ise-akanse ni kikun ni odun ti a wa yii.
Ìbàntẹ́ wo lo fi ń ṣe fáàrí?
Àwọn ẹranko ńláńlá mẹrin bá jáde láti inú òkun.
Nítorí náà, ẹ máa ranti pé OLUWA Ọlọrun yín ni Ọlọrun, Ọlọrun olótìítọ́ tíí pa majẹmu mọ́, tíí sì ń fi ìfẹ́ ńlá rẹ̀ hàn sí àwọn tí wọ́n bá fẹ́ ẹ, tí wọ́n sì ń pa òfin rẹ̀ mọ́, títí dé ẹgbẹrun ìran, 
Oyè Ibadan: Àwọn ọba 21 ní kí Olubadan yé fẹnu yẹpẹrẹ adé àwọn
   Awon mejo wa ni kilaasi ikinni, awon metadinlogun wa ni kilaasi ikeji alakobere, awon mejila wa ni kilaasi ipele iketa, awon ogoji wa ni kilaasi kinni ipele ikeji fawon akekoo girama agba, awon mokandinlogun wa ni kilaasi keji nigbati awon merinla wa ni kilaasi keta ipele keji patapata.
APC Primary: Wọ́n yọ Balogun Fulani gẹ́gẹ́ bí alága APC Ètò ìdìbò abẹ́lé ẹgbẹ́ òṣèlú All Progressives Congress n lọ jákè-jádò àwọn ìpínlẹ̀ ní Nàìjíríà yàtò si Eko, àti Imo.
Lati igba ti iroyin bi wọn ṣe n pa awọn agbẹ yii ṣe n tan ka orilẹede Naijiria ni ẹru ti n ba awọn ara agbegbe naa pe ko ma jẹ pe opin ti n de fun awọn.
Nibayii, eeyan 1,051 lo ti ba ajakalẹ arun naa lọ ni Naijiria.
Èèyàn 490 ló lùgbàdì àrùn Coronavirus ní Naijiria ní Ọjọ́ Ìṣẹ́gun A kọ̀ tíì fi ìdí ẹ̀ mule pe òògùn Dexamethsaone ń ṣiṣẹ́ fún àrun Coronavirus Alága méjì láàrín ọjọ́ kan, sinimá oríta láàrín àwọn adarí APC Àbúrò mi ni Babatunde Fashola- Naira Marley Seyi Makinde ṣí iléèwé padà ní ìpínlẹ̀ Oyo, Cross River pa ọ̀rọ̀ dà lórí ìwọlé akẹ́kọ̀ọ́ Ọlọ́run ló ní kí Abacha kú, àwọn àgbà Yorùbá púpò kò bá ṣòfò- Dele Momodu Premier League gbìnàyá padà, ọ̀gá àti ọmọṣẹ́ fìjà pẹ̀ta Ẹgbẹ awọn dokita ile ẹkọ iṣegun(NARD) ti kọminu lori bi awọn oṣiṣẹ eleto ilera ti n ko aarun ti ọpọ si n gba ibẹ ku.
Sisare sọrọ ninu orin ti wa di aṣa ninu idile wọn.
Má fà wá sinu ìdánwò,ṣugbọn gbà wá lọ́wọ́ èṣù.
 Múra síṣẹ́ Ọ̀lẹ́dàrùn wáṣẹ́ ṣe Ẹni tó ń ṣíṣẹ́ lọ́wọ́ ó múra ṣíṣẹ́ Ẹ̀dá tí kò ì rí kó má sọ̀rètí nù Iṣẹ́ takuntakun nii mú Kénìyàn ó le kẹ́sẹ́járí Iṣẹ́ nii múni gbọ́n Àìṣíṣẹ́ níí múni gọ̀ ju taṣutaṣu lọ Ẹni bá ṣíṣẹ́ á lówó lọ́wọ́ Múra ṣíṣẹ́ tó o bá nísẹ́ lápá Tẹra mọ́ṣẹ́ níbi o bá ti ráàyè Ìtẹramọ́ṣẹ́ níí mágbẹ̀ jẹun kánú Ìtẹramọ́ṣẹ́ níí sọmọ ẹ̀kọ́ṣẹ́ dọ̀gá Ìtẹramọ́ṣẹ́ níí fágbéga lẹ́nu isẹ́ Ìtẹramọ́ṣẹ́ níí mú màjèsín dé pò àgbà.
Aara ti san, atẹgun ti fẹ, koda, iji ti ja lorilẹede Naijiria, eyi to ti dunkooko mọ eto irẹpọ ati isọkan orilẹede yii, diẹ si lo ku ki orilẹede yii tuka.
Bẹ́ẹ̀ náà ni àwọn obinrin kan tí Jesu ti wòsàn kúrò ninu ẹ̀mí èṣù ati àìlera ń bá a kiri.
Bákan náà sì ni àwọn yàrá ẹ̀gbẹ́ rẹ̀, ati àtẹ́rígbà, ati ìloro rẹ̀ rí pẹlu àwọn yòókù, fèrèsé wà lára òun náà yíká ninu, bẹ́ẹ̀ náà sì ni ìloro rẹ̀.
Koda, wọn ṣe idasilẹ 'hashtag #BUSA2019' fun eto igbeyawo irọ naa.
Bẹẹ naa lo ni oun yoo gbe igbeṣẹ ti ri pe iru nnka nbẹẹ ko waye mọ.
23 Agẹmo 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 12 Òkùdu 2020 LASTMA gbiyanju pupọ fun mi -Yesufa.
Eyi ni esi ti wọn fi sita si iroyin ti awọn oniroyin kan Wall street Journal fi si oju opo wọn pe ile iṣẹ ogun yọlẹ sin oku ọpọlọpọ awọn ọmọ ogun ni saree ikọkọ wọn lati bo onka iye awọn to ku loju ogun pẹlu awọn agbesunmọmi mọlẹ.
Dafidi bá fi ṣe olórí àwọn tí ń ṣọ́ ọba.
Ṣùgbọ́n bí mo fẹ́ bí mo kọ̀ ọkùnrin náà yọ sí mi dandan; inú bí mi gidigidi, mò fa ojú ro bi ẹni tí ebi ń pa, mo ń pòṣé bí ẹni tí iyà ń jẹ, mo di ẹnu dudu bi ọmọ-ọ̀dọ̀ tí ó fọ́ àwo oúnjẹ, tí kò lè sọ fún ni, tí ó rìn káàkiri ẹ̀gbẹ́ ògiri, tí inu ọmọ náà si dàrú bi ìgẹ̀dẹ̀gẹ́dẹ̀ ìdí ẹmu inu ṣágo.
 Ìkejì , ó sì lè jẹ ́ àpólà kan nínú gbólóhùn bí àpólà orukọ ni a máa yí sódì .
Awọn oluwọde ni Briston ni tiwọn so okun mọ ere Edward Colston naa, wọn si tii ṣubu ki wọn to tii sinu agbami Avon.
Ó dá mọ́tọ̀ dúró ni kí ó tó lọ mú un Nígbà tí wọ́n dé ojà, dírébà jẹ ẹ̀bà, ilésanmí jẹ iyán ó sì ra òòyà ní irinwó náírà (400.
Ìwádìí ti fihàn pé Ajá n gbọ́ òórùn àìsàn ibà Kọmíṣọna fún ìrìnàjò afẹ́ sọ oun tí Èko ń ṣe nípa ilé oúnjẹ China Gbẹgẹdẹ gbiná ni Ghana, GFA gba rìbá!
T Cell jẹ́ èròjà kan to n dáàbò bo àgọ́ àra, iṣẹ́ to si n ṣe ni láti gbogun ti àwọn eroja àjòjì tó bá wọ inú ara.
OLUWA rán Mose pé, “Sọ fún Aaroni pé kí ó mú ọ̀pá rẹ̀, kí ó sì nà án sí orí gbogbo omi ilẹ̀ Ijipti, ati sórí odò wọn, ati sórí adágún tí wọ́n gbẹ́, ati gbogbo ibi tí omi dárogún sí, kí wọ́n lè di ẹ̀jẹ̀, ẹ̀jẹ̀ yóo sì wà níbi gbogbo jákèjádò ilẹ̀ Ijipti; ati omi tí ó wà ninu agbada tí wọ́n fi igi gbẹ́, ati tinú agbada tí wọ́n fi òkúta gbẹ́.
Gbogbo àwọn tí ó bá rí i yóo wá bẹ̀rẹ̀ sí fi ṣe yẹ̀yẹ́.
OLUWA ní, “Efuraimu darapọ̀ mọ́ àwọn eniyan tí wọ́n yí wọn ká, Efuraimu dàbí àkàrà tí kò jinná dénú.
Ó ṣe ohun tí ó tọ́ lójú OLUWA, gẹ́gẹ́ bíi Usaya, baba rẹ̀; àfi pé òun kò lọ sun turari ninu tẹmpili OLUWA.
Lowurọ ọjọru ni awọn agbofinro tu wọn silẹ lọwọ awọn to ji wọn gbe loju ọna Kaduna si Abuja.
Orile-ede Naijiria sajoyo ayeye odun ominira kejidinlogota lojo aje(Monday), ti n se ojo kinni osu kewa ti orile-ede ohun gba ominira lowo ijoba amunisin, eleyi ti o waye ni papa isere Eagle Square, niluu Abuja.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Coronavirus: Àwọn alárùn coronavirus ṣe ìwọ́de ní Gombe, wọ́n ní ìjọba n febi pa wọ́n 23 Ìgbé 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 6 Èbibi 2020 Oríṣun àwòrán, Twitter Nṣe ni awọn alarun coronavirus tu si ita ọkan lara awọn ibudo ti wọn ti n tọju aarun naa nipinlẹ Gombe lati fi ẹhonu han lọjọ Iṣẹgun.
Ẹni tí ń ṣọ́nà kígbe pé:“OLUWA mi, lórí ilé-ìṣọ́ ni èmi í dúró sí lojoojumọ,níbi tí a fi mí ṣọ́, ni èmi í sì í wà ní òròòru.
Sùgbọ́n kàyéfì ńlá ló jẹ́ wí pé ẹgbẹ̀fà Náìrà nìkan ni owó tí ikọ̀ aṣéwádìí yìí bá nínú ilé rẹ̀.
Ìbéèrè nípa èròjà ara ro gbógun ti aarun ṣe pàtàkì tí òye rẹ bá yẹ ni èyí sì ni yóò sọ nkan ti yoo sẹlẹ tí ẹni náà bá ní aarun.
EEMB : Ajọ to n ṣakoso eto idibo.
Ó yẹ kí Sotitobire gbọ́ ìdájọ́ lónìí ṣùgbọ́n ẹ wo bí ilé ẹjọ́ ṣe tún ṣe é Gẹgẹ bi igbejọ ṣi ṣe n lọ lọwọ lori ẹsun ti wọn fi kan oludasilẹ ijọ Sotitobire Praising Chapel l'Ondo, Wolii Alfa Babatunde atawọn ọmọ ijọ rẹ mẹfa tun ti farahan nile ẹjọ lonii lati lọ jẹwọ pe awọn sọ ọrọ ti wọn kọ silẹ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, The storm arrives in Luganville (footage courtesy ADRA Vanuatu via Reuters) Ki lawọn orilẹ-ede ti ko larun covid-19 le ṣe?
Rírí tí ó rí mi ni inú bí i tí o ń sáré bọ̀ wá pàdé mi.
A bí i ní ọjọ́ kẹtàdínlógún osú keje, ọdún 1974.
Bí Jesu ti ń jáde kúrò ninu omi, lẹ́sẹ̀ kan náà ó rí Ẹ̀mí Ọlọrun gẹ́gẹ́ bí àdàbà tí ó bà lé e.
Kí ni mo ṣàì  fi ẹnu mi jẹ tán ní ilé rẹ?
Mo gbàgbọ́ pé ọmọ mi kò kú, mo ṣì ń wá a - Bàbá Akẹ́ẹ̀kọ́ fásitì Akungba Ilẹ China ń sàmì àádọrin ọdun tí wọn gbòmìnira pẹ̀lú ìfẹ̀hònúhàn Nàìjíríà kò nílò sénétọ̀ kankan- Fayemi Wo àwọn orílẹ̀-èdè márùn ún tó fún àwọn obìnrin làńfàní tuntun sí ẹ̀tọ́ wọn Ninu oṣu karun un ọdun yii ni o ṣi ṣalaye fun ile iṣẹ BBC wi pe irin ajo kaakakiri yii ti jẹ ki oun mọ bi o ṣe ri lati gbe igbe aye alaini.
Manchester United vs Barcelona: Gbajúgbajà apanilẹ́rín, Wòlíì Àrólé ní ìrètí ṣì wà fún Man United ní Camp Nou
Kò sí ìdí láti tọrọ àforíjì lọ́wọ́ Nàìjíríà - Alákòso Johannesburg Nicolas Pepe gba gbeelẹ koo gba sile, pẹnariti wọle lẹyin ti awọn agbabọọẹu Aston Villa gbe Gendouzi, agbabọọẹu Arsenal lulẹ ninu oju iwọn alapoti Aston villa ko jẹ ko tutu ti wọn tun ti fi gba omiran wọle.
Fayemi: Ẹ̀sùn àjẹbánu àti lílo owó básubàsu la fi kàn wọn
Tambuwal sapejuwe Atiku gege bi adari rere ti yoo mu ife awon omo orile ede Naijiria se, paapaa julo nipa ironilagbara ati awon ohun miiran ti yoo je ki idagbasoke de ba orile ede Naijiria.
Amọ, ileẹjọ gba laaye lati rinrinajo lọ si Ilẹ Gẹẹsi lọ gba itọju, lẹyin to lugbadi arun Coronavirus, ti agbẹjọro rẹ si ni yoo pada si Naijiria lati pari igbẹjọ rẹ ni Osu Kini, ọdun 2021.
18 Òkùdu 2019 Insecurity: Ọọ̀ni ni báwọn ọba alayé ṣe lọ́wọ́ nínú àgbékalẹ̀ Amotekun, ni yóò ṣe tọ́jọ́13 Èrèlè 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
O óo jìyà ní àjẹtẹ́rùn,tóbẹ́ẹ̀ tí o óo máa fi àkúfọ́ àwo ìyà tí o bá jẹ ya ara rẹ lọ́mú.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù New Minimum wage: Ìjọba Eko bẹ̀rẹ̀ sísan N35,000 gẹ́gẹ́ bí owó oṣù tó kéré jùlọ fáwọn òṣìṣẹ́ 27 Bélú 2019 Oríṣun àwòrán, Twitter/Babajide Sanwo-Olu Igba ọtun de fawọn oṣiṣẹ ijọba niluu Eko, ijọba ipinlẹ Eko ti ṣetan lati maa san ẹgbẹrun un marun un le lọgbọn naira gẹgẹ bi owo oṣiṣẹ to kere julọ fawọn oṣiṣẹ ipinlẹ naa.
Nígbà náà ni àwọn olórí alufaa ati àwọn àgbà ìlú péjọ sí àgbàlá Olórí Alufaa tí ó ń jẹ́ Kayafa.
December 14, 2014 Àwọn ológun mú El-Zakzaky àti ìyàwó rẹ̀, Zeenat sí àtìmọ́lé ọlọ́pàá ìpínlẹ̀.
Oríṣun àwòrán, CockFM Radio Ọkẹ aimoye awọn ololufẹ rẹ ni wọn rọgba yii ka lasiko to fi lọ ki Alafin Ẹlẹpẹ ati Akarigbo ti ilẹ Rẹmọ ni aafin wọn.
Tunde lọ sile ẹkọ alakọbẹrẹ United nilu Ilorin laarin ọdun 1950 si 1952, o tun lọ si alakọbẹrẹ Okesuna ni 1953 si 1957, to si jade iwe mẹwa rẹ ni ile ẹkọ girama ologun laarin ọdun 1958 si 1962.
Bí a bá lo ‘ìwọ’ láti tọ́ka sí ẹnìkan nínú ọ̀pọ̀ ènìyàn, ẹni tí à ń báwí kò lè mọ ara rẹ̀ nítorí pé ‘ìwọ’ tọ́ka sí ẹni kọ̀ọ̀kan wọn ni.
 Òun si ni ètùtù ìlu wà ní ìkáwọ ́ rẹ ̀ .
Ẹ ranti pé ẹ ti jẹ́ ẹrú rí ní ilẹ̀ Ijipti, nítorí náà ni mo fi pàṣẹ fun yín láti ṣe èyí.
 Àjọ ̀ dún ìbílẹ ̀ tún lè wà fún ìrántí aṣááju tàbí akọni kan , bóyá tí ó tẹ ìlú kan dó , tàbí tí ó jagun kan láti gba àwọn ènìyàn rẹ ̀ sílẹ ̀ lọ ́ wọ ́ ọ ̀ tá tàbí lọ ́ wọ ́ ibi tàbí ìjàǹbá kan , tàbí tí ó ṣe ohun mánigbàgbé kan tí wọn fi ń ránti rẹ ̀ tàbí tí wọ ́ n fi ń ṣọpẹ ́ fún un , tí wọ ́ n sì tí ipa bẹ ́ ẹ ̀ sọ ọ ́ di òrìṣà tí wọn yóò máa bọ , tí wọn yóò sì máa ṣe ẹ ̀ yẹ fún lọ ́ dọọdún tàbí lóòrèkóòrè .
 Èyí lè la ṣíṣe ìtọ ́ jú gbogbo wọn lẹ ́ ẹ ̀ kan naa lọ , àní àpapọ ̀ awọn ènìyan tì a mọ ̀ pé àìsàn náà wọ ́ pọ ́ lára wọn jùlọ .
Lọjọ Aje ni wọn pese eto aabo fawọn to n ṣe iwọde Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ọpọ ero lo pejọ pọ ni Liberian City ti Monrovia.
Bí mo bá sì bi yín ní ìbéèrè, ẹ kò ní dáhùn.
Aṣofin Victor Akande naa ki Kabiyesi fun asiko pataki ti wọn wa si Ile Igbimọ Aṣofin yii ti wọn si mọ riri iṣẹ takuntakun awọn ọmọ ẹgbẹ Igbimọ Aṣofin yii, “eleyii jẹ ohun iwuri fun wa”.
Lẹ́yìn tí wọ́n ti gbààwẹ̀, tí wọ́n sì gbadura, wọ́n gbé ọwọ́ lé wọn lórí, wọ́n sì ní kí wọ́n máa lọ.
Ní ọjọ́ tí mo ké pè ọ́, o dá mi lóhùn,o sì fún mi ní agbára kún agbára.
Oriade naa ni inu ibudo igbalode nla to wa nilu Ifẹ́, Ifẹ Grand Resort, ti oun n kọ lọwọ ni wọn ti sawari omi ajeji naa, eyi ti ni awọ meje ninu eyi ti awọ buluu, eweko.
igbimo ipolongo fun eto aare  ati awon
Ìloro rẹ̀ kọjú sí gbọ̀ngàn òde, àwòrán ọ̀pẹ wà lára àtẹ́rígbà rẹ̀, àtẹ̀gùn rẹ̀ sì ní ìgbésẹ̀ mẹjọ.
Igba akọkọ si niyii ti Badirat sọ ni taara pe oun ti kuro ni aafin ilu Ọyọ.
Igbakeji gomina ipinlẹ Ondo, Agboọla Ajayi yoo maa wọ ṣokoto kan naa pẹlu kọmiṣọnna nigba kan ri fun eto idajọ ni ipinlẹ naa, Eyitayọ Jẹgẹdẹ atawọn eekan oludije miran.
Paulu kọjú sí àwọn ìgbìmọ̀, ó ní, “Ẹ̀yin ará, ní gbogbo ìgbé-ayé mi, ọkàn mí mọ́ níwájú Ọlọrun títí di òní.
Joṣua ati gbogbo àwọn ọmọ Israẹli kúrò ní Egiloni lọ sí Heburoni, wọ́n sì gbógun tì í.
Bí Dafidi bá kọlu àwọn eniyan rẹ, tí wọ́n sì pa díẹ̀ ninu wọn, àwọn tí wọ́n bá gbọ́ yóo wí pé wọ́n ti ṣẹgun àwọn eniyan Absalomu.
Alhaji Busari tun so pe “Eni kọọkan wa, gbodo rii pe
Nígbà tí àwọn ọmọ Israẹli yóo bá pàgọ́ wọn, kí olukuluku máa pàgọ́ rẹ̀ lábẹ́ àsíá ẹ̀yà rẹ̀, ati lábẹ́ ọ̀págun ìdílé rẹ̀.
Ẹni to bori: Côte d'Ivoire Algeria vs Benin.
#BBCNigeria2019 Kí ni àwọn olùdíje ìpínlẹ̀ Eko fẹ́ ṣe nípa ètò ìlera?
Aṣẹyin ni ọdun oro ni ọdun 2020 yii yoo wa fun adura lati le awọn ajinigbe kuro ni ayika wọn, ki ijọba Makinde le ni alaafia.
O ni wọn si le wọn jade sita, ṣugbọn o ni wọn pe awọn pada lẹyin ti fidio ohun ti oju wọn n ri lu jade lori ayelujara.
Ẹ ṣí ìlẹ̀kùn ibodè,kí orílẹ̀-èdè olódodo, tí ń ṣe òtítọ́ lè wọlé.
 O ni ile iṣẹmbaye naa ti wọn fẹ kọ yoo ṣafihan “igbe aye awọn eniyan Uganda ṣaaju ominira ati lẹyin ominira paapaa julọ lasiko ti wọn wa labẹ Idi Amin gẹgé bii olori wọn.
ẹ ya ìlú mẹta sọ́tọ̀ fún ara yín ní ilẹ̀ tí OLUWA Ọlọrun yín fun yín.
Joaṣi wà ní ìpamọ́ ninu ilé OLUWA fún ọdún mẹfa, Atalaya sì ń jọba lórí ilẹ̀ Juda.
Ẹ̀ka igi kankan kò dàbí ẹ̀ka rẹ̀,bẹ́ẹ̀ ni kò sí igikígi ninu ọgbà Ọlọrun tí ó lẹ́wà bíi rẹ̀.
Tàbí ẹni tí ó mọ̀ nípa ọkọ̀ lọ́pọ̀lọpọ̀ – ọkùnrin ni, kó má jẹ̀ ẹ́ obìnrin.
Ó kéré tán ènìyàn márùn ló bá ìṣẹ̀lẹ̀ náà rìn, tí ọ̀pọ̀ ǹkan ìní sì sòfò ní ọdún 2017 Àwọn ìlú méjì kan, Ifa Ikot Akpan ní ìjọba ìbílẹ̀ Uyo àti Ibiaku Ishiet ní ìjọba ìbílẹ̀ Uruan tí àwọn ọba ìlú méjèejì, Etteidung Edem Aniedi Ebong àti olóyè William Effiong Etim sì ń léwájú nínú ìjà ilẹ̀ láti ọdún mẹ́ta sẹ́yìn.
Pondei daku lasiko to n ṣalaye iye owo ti ajọ NDDC na labẹ iṣakoso rẹ.
Jehoramu jẹ́ ẹni ọdún mejilelọgbọn nígbà tí ó jọba, ó sì wà lórí oyè fún ọdún mẹjọ ní Jerusalẹmu.
ọ̀dọ́ 47,000 fẹ́ di Amotekun, agbófinró yẹ̀ wọ́n wò yẹ́bẹ́yẹ́bẹ́ Aáwọ̀ oyè PDP gbé Fayose àti Seyi Makinde kọlu ara wọn, ìjà ń bọ̀ Bàbálọ́jà márùn ún la ó ò ní l'Oyo tí Makinde bá lè buwọ́lu ìyànsípò YK Abass Awọn ikọ Nigerian Scrabble Federation naa pejọ pọ lati ranti ọ̀jọ ibi rẹ lori ẹrọ ayelujara ni ọjọ naa.
awọn agbesunmọmi wa ni agbegbe naa.
“Leyin gbogbo oro ti o so mo esun iwa ibaje yii, bee si ni fun isejoba rere.
Ni ọ̀kan ninu wọ́n bá ṣá ẹrú olórí alufaa kan, ó bá gé e ní etí ọ̀tún.
O ṣalaye pe ijọba ti n gbe awọn igbesẹ bi i ṣiṣe atunṣe si awọn nkan to n pawo wọle fun ijọba; Ikọgosi Warm Spring ati awọn ileesẹ ijọba mi i.
Ó ní: ‘N óo mú kí èémí wọ inú yín, ẹ óo sì di alààyè.
Oríṣun àwòrán, Ministry of Works Ta a ba pin triliọnu lọna mọkanla owo iranwọ epo yii si iye owo ti wọn fẹ fi kọ afara yii, yoo kọ to aadọta iru afara naa.
Deile fi kun ọrọ rẹ pe igbimọ naa maa ṣagbekalẹ ilana iṣiṣẹ, nigba ti
Ẹni ọdún mẹrindinlogun ni nígbà tí ó jọba, ó sì wà lórí oyè ní Jerusalẹmu fún ọdún mejilelaadọta.
N óo lé àwọn ẹranko burúkú kúrò ní ilẹ̀ náà, ogun kò sì ní jà ní ilẹ̀ náà.
O fi ń tù wọ́n lójú, kí wọ́n lè máa wá bá ọ ṣe àgbèrè láti ibi gbogbo.
Police Constable Grade Level 03 - N519, 525.
Losu Karun ọdun 2019 ni Gomina Abdullahi Ganduje ipinlẹ Kano buwọlu abadofin kan, to faaye gba iyansipo awọn ọba onipo kinni fawọn agbegbe mẹrin nilu ọhun.
com/pCtYfr4AQDNi bayii, ijoba n duro de ki ile-ise to n mujuto eto ibanirsoro lorile-ede Naijiria(Nigerian Communication Commission, NCC), lati fi awon nomba ipe ofe ranse ti awon ara ilu yoo maa pe lasiko isele pajawiri.
 bí ẹnìkan sì húkọ ́ lásán ní Ògìrììyàndá , gbogbo àwọn tó wa ní Ìlú lapá-edé ló máa gbọ ́ nípa rẹ ̀ .
Ewe, saaju oniruuru ifesewonse ti iko agbaboolu Super Eagles yoo maa gba fun igbaradi idije boolu agbaye to n bo lona lorile-ede Russia, agbaboolu merinla lo ti gunle si ipago iko ohun saaju ifigagbaga pelu iko agbaboolu Poland ti yoo waye lojo Eti(Friday), ni papa isere Municipal, Wroclaw.
Bakan naa, olori Ile Igbimo Asofin agba, Bukola Saraki, ti gboriyin fun BBC, fun fidio lori codeine naa, ninu agbejade kan ti agbenuso re fi ṣọwọ s'awọn oniroyin.
” Wọ́n bá dì mọ́ ọn lẹ́sẹ̀, wọ́n júbà rẹ̀.
"Ọmọ Ọba Dubai yóò san owó ìtọ́jú ọmọ Nàìjíríà tó bí ìbẹrin sí Dubai tí kò sí rówó san Aàre Donald Trump pàrọwà pé kí wọ́n sún ìdìbò Aàrẹ 2020 síwájú ní America Àwọn akópa tó ti jáwé olúborí ní BBNaija sẹ́yìn àti ibi tí wọ́n wà báyìí Ìtàn Ọba Yorùbá tí wọ́n yẹgi fún torí ó jí ọmọ gbé ṣe ètùtù ""Ọmọ mi kò tíì mọ̀ pé òun ti di ìlúmọ̀ọ́ká, ó ń wádìí bó ṣe ń rí ara rẹ̀ lórí ayélujára"" Ọmọ Baba Fasanmi salaye pe iboju oloke meji ni Baba ati aya re seto silẹ nigba aye wọn ni eyi ti wọ́n jọ fẹnuko pe ẹni to ba kọkọ lọ lo maa wa ni isalẹ ti eni keji ti ọlọjọ ba de fun a wa ni oke ninu iboji naa."
Ipinlẹ Eko Gomina ipinlẹ Eko, Babajide Sanwo-Olu lasiko to n ṣe ipade lori igbesẹ ti wọn n gbe lati koju arun Coronavirus sọ wi pe awọn ti ṣe ipade pẹlu awọn adari ile ijọsin ati awọn imaamu ni ipinlẹ Eko.
Ta ló gé orí ọkùnrin mẹ́ta ní Lekki?
Akani dá Joṣua lóhùn pé, “Lóòótọ́ ni mo ti ṣẹ̀ sí OLUWA Ọlọrun Israẹli.
Ni oorun oni to mọ, ọpọ ẹmi ati dukia lo ti ba ikọlu laarin Boko Haram ati ijọba Naijiria lọ.
Ṣugbọn ni bayii, awọn kọmisana ọlọpaa l'awọn ipinlẹ to wa lorilẹede yii ni yoo maa mojuto awọn ọlọpaa SARS.
Ó sọ nípa àwọn ẹranko, ati àwọn ẹyẹ, àwọn ohun tí ń fi àyà fà ati àwọn ẹja.
Idijẹ ṣe ìyá ìta tí kò gbàgbàkugbà nínú eré náà tí àwọn okùnrin sì mọ̀ ọ́ sí èyí.
Koda wọn a tun jọ mu aṣọ ankoo, ẹgbẹjọda papọ bii tolobinrin ile.
Ajọ Nibucaa ti awon kan da sile ni odun màrúndínlógún seyin, ni o ti di gbaju-gbaja kaakiri gbogbo agbaye.
Ibaṣepọ to wa laarin ajọ EFCC ati FBI ni Magu sọ pe o ti n so eso rere bayii.
Ọkunrin kan wà níbẹ̀ tí ọwọ́ rẹ̀ kan rọ.
Awọn kan ti ẹ tun sọ pe pupọ lara awọn ọmọ ẹyin rẹ lo jẹ àwọn ti ko rikan-sekan lẹyin ti gbajugbaja oloṣelu nilu Ibadan, Lamidi Adedibu, di oloogbe.
Orile-ede Germany, Faranse ati ile Biritiko so lojo-Eti pe, inu awon dun pe, Aare orile-ede Trump ti orile-ede America ti yi ipinnu re pada, latari ati gbe owo iyebiye lori owo-ori irin ti won ko wo orile-ede America lati ile Europe.
iṣẹ akanṣe sisọ ilu di tigbalode (Smart City) Nigba ti ti o n ṣe
Ki ẹ to ṣe haa, ẹ lọ ka ọpọ iyanu miran ti o wa ninu ọrs iyaafin ogunfunmilayọ ninu iroyin BBC News Yoruba yii: https://www.
Femi, ẹni tó ṣàlàyé bẹẹ lásìkò to ń kópa lórí ètò ileesẹ BBC Yoruba kan, tun fikun pé òun kò kabamọ pé òun fi iṣẹ agbejoro silẹ, máa ṣíṣẹ tíátà.
Amẹrika dá akẹ́kọ́ọ̀ Harvard pada sí orílẹ̀-èdè rẹ̀ nítori ǹkan ọ̀rẹ́ rẹ̀ kọ lóri ayálujára
Oṣù mẹ́ta àti ọjọ́ mẹ́wàá ni a fi wá ọkọ mi, ṣùgbọ́n pàbó ni ó já sí… Àwọn ẹ̀ṣọ́-ibodè sọ fún wa pé àìsàn ọkàn ló pa á, tí èyí kò sì jẹ́ òtítọ́.
"Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ẹlẹ́wọ̀n 200 sálọ lọ́gbà ẹ̀wọ̀n Benin lásìkò ìwọ́de EndSars Ìjọba da ológun sí Abuja láti dẹ́kun ìwọ́de Mo fura pé ẹ fẹ́ da Nàíjíríà rú, ń kò ṣe ìwọ́de mọ́ - Segalink, agbátẹrù ìwọ́de yọwọ́ Ìwọ́de EndSARS gboró n‘Ibadan, kò sẹ́ni tó le wọlé tàbí jáde ""Buhari, ìwọ́de yóò yíwọ́, tó gbá jẹ́ káwọn ológun bá bẹ̀rẹ̀ ‘Operation Crocodile Smile’ "" Ìjọba Eko pàdánù ₦234m láàrín ọ̀sẹ̀ kan torí ìwọ́de End SARS Bí o bá fẹ́ darapọ̀ mọ́ ikọ̀ ọlọ́pàá SWAT tí yóò rọ́pò SARS, wo àmúyẹ tí o gbọ́dọ̀ ní Aisha Buhari polongo àwo orin tó ní Nàíjíríà ń ṣun ẹ̀jẹ̀ lásìkò ìwọ́de Se ni awọn akẹkọọ pada sile ni lai le kẹkọọ tawọn ile iwe gbogbo si gbe ilẹkun wọn tipa, bẹẹ ni awn to yẹ ko joko sedanwo NECO, ko le wa sile iwe."
Oríṣun àwòrán, Getty Images Victoria Rubadir ọmọ Kenya ló gba àmì ẹ̀yẹ Komla Dumor BBC World News.
Ṣugbọn ayé yóo di ahoro nítorí ìwàkiwà àwọn tí wọn ń gbé inú rẹ̀; àní nítorí iṣẹ́kíṣẹ́ ọwọ́ wọn.
E jẹ́ kí àwọn ọdọ́mọdé tó ti rẹ̀ símí Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Àìsùn àti àìgbọràn láàárń àwọn ọdọ́ wọ́n jọ ń rìn ni Àwọn èròjà ara (hormone) máa ń pọ̀ síi nígbà t'ọmọ dé bá fẹ́ bàlàgà eléyìí tó ń máa ń dá owọ́ agogo dúró fún bíi wákàtí méjì.
Ìyẹn ló dífá fún àwọn aládìẹ díndín ‘yòókù, tí wọ́n dẹ́kun fífarawé KFC, tí wọ́n sì wá àwọn èròjà tiwọn lọ.
Bi wọn ba ti ṣetan, a o si fi ranṣẹ si wọn.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Bauchi Police: Ẹ wá wó arákùnrin tó pa ọmọ-ọmọ rẹ̀ tuntun jòjòló nítorí nípa ibálòpọ̀ ni wọ́n fi lóyún rẹ̀!
Awọn ọmọ orilẹede China mẹjọ, ọmọ Ghana kan atawọn ọmọ onilẹ mẹta ni ọwọ ikọ Amẹtẹkun ni ipinlẹ Ọṣun ba nibi ti wọn ti n wa kusa lọna ti ko bofin mu ni ipinlẹ naa.
Oríṣun àwòrán, @atiku Bi awọn to ta ko o ṣe n sọ tiwọn naa ni awọn mii n sọ wipe ki ba wu awọn ko jẹ pe lori eyi, aarẹ Buhari kọ ni aarẹ Naijiria.
Nigba wo ni a n sun ẹkun iyawo?
Gẹgẹ bi idajọ ti ijoko ẹlẹnimẹta ti Adajọ Stephen Adah ṣe adari rẹ pa, ile ẹjọ kòtẹ́milọ́rùn ni aṣẹ idaniduro ranpẹ̀ ti ile ẹjọ to n gbọ ẹsun iwa ibajẹ ati aṣemaṣe awọn to di ipo ilu mu, CCT pa, lodi si ẹtọ Onnoghen labẹ ofin.
 Inu wa dun pe orile ede Naijiria  ti tọwọbọ 
Aarẹ ni awọn gbajumọ ati ọmọwe maa n tako ijọba oun, lati le gba iyi lọwọ awọn ọmọ orilẹede Naijiria lasan ni.
Ogbeni Lucky Orimisan Aiyedetiwa to jẹ ọmọ bibi ilu Ilajẹ ẹsẹ odo ni ade naa ṣi mọ lori bayii.
ile-ise igbakeji aare so pe“ Igbakeji aare ojogbon Yemi Osinbaj yoo kọkọ
"láàrin ọdún 1982 sí 1984 láyé ìgbà ilé ẹ ̀ kọ ́ sẹ ́ kọ ́ ńdírì , ìfẹ ́ rẹ ̀ sí orin àti eré orí ìtàgè mú un darapọ ̀ mọ ́ àwọn tí wọ ́ n mọ ̀ ní ìgbà yẹn sí "" jesters international "" ( jacob , pápílolò àti adẹ ́ rùpọkọ ̀ ) ẹgbẹ ́ tí ó wà ní Ìbàdàn , ní ibẹ ̀ ni ó ti ní imọ ̀ àti ìrírí àkọ ́ kọ ́ nínú eré orí ìtàgé ."
Igahlo to ti jẹ olofẹ ikọ Manchester United tẹlẹ ni awọn adari ikọ naa lero pe yoo kopa ribiribi ninu awọn idije saa yii to n lọ lọwọ.
Wò ó, yóo lọ fẹ́ ọkà baali ní ibi ìpakà rẹ̀ lálẹ́ òní.
se isẹ lori atunse ofin naa, ki aare to bowolu iwe abadofin ohun.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, India: Ẹ wo bí àwọn ènìyàn ṣe dóòlà èmí erin tó jálulẹ̀ Idibo naa yoo waye ni awọn ijọba ibilẹ Epe, Ibeju Lekki, Kosofe, Somolu, ati Ikorodu.
Ẹnu ya gbogbo àwọn eniyan, wọ́n ń wí pé, “Ó ha lè jẹ́ pé ọmọ Dafidi nìyí bí?
Wọ́n ṣe àdéhùn ibi tí olukuluku yóo lọ wò ní gbogbo ilẹ̀ náà, olukuluku sì gba ọ̀nà tirẹ̀ lọ.
Àwọn ọ̀gá rẹ ní ìjọba ni mò ń bá se - Bobrisky fún ọ̀gá Arts & Culture lésì!
Àwọn ọmọ Nàìjíríà yarí lórí èròngbà ilé aṣòfin pé kí àjọ FRSC má a lo nkan ìjagun Sanwo-Olu buwọ́lu ìgbésẹ̀ ìjọba láti tún Eko ṣe lẹ́yìn rògbòdìyàn EndSARS 'Cartoon' nípa Anọbi Muhammed kó Ọ̀jọ̀gbọ́n kan sí ìyọnu ní Egypt Wo èèyàn ogún tí ilé ẹ̀jọ́ sọ pé kí CBN gbẹ́sẹ̀ lé àsùnwọ̀n wọn ní bánkì nítorí ìwọ́de ENDSARS Ọkọ̀ táńkà agbépo tó gbiná lójú ọ̀nà mọ́rosẹ̀ Eko sí Ibadan dá súnkẹrẹ fàkẹrẹ sílẹ̀ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Shomolu gbajúmọ̀ fún ìwé títẹ̀ Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Fídíò, Bose Okeowo: Àárẹ̀ kékeré ló sọ mi dí aláàbọ̀ ara yìí ṣùgbọ́n.
Ooni to bu ẹnu atẹ lu eto Big Brother Naija naa ni eto naa n fihan pe orilẹ-ede Naijiria ko ni awọn ọdọ to jẹ ọmọluwabi ati oninu irẹ.
Bí wọ́n ti ń ti ọ̀dọ̀ Farao bọ̀, wọ́n lọ sọ́dọ̀ Mose ati Aaroni tí wọ́n dúró dè wọ́n, wọ́n sì sọ fún wọn pé, 
Ohun tí a mọ̀ nìyí nípa ìròyìn Ajimobi kú, kò kú, táyé ń gbé kiri Èèyàn 745 ló lùgbàdì àrùn Coronavirus ní Naijiria ní Ọjọ́bọ̀ Fatima Ganduje, ìyàwó ọmọ Ajimọbi ní iró ni pé Bàbá ọkọ òun kú!
Ó sọ fún Jesu pé, “Ìwọ ni n óo fún ní gbogbo àṣẹ yìí ati ògo rẹ̀, nítorí èmi ni a ti fi wọ́n lé lọ́wọ́, ẹni tí ó bá sì wù mí ni mo lè fún.
LASEMA sọ pe eeyan mẹrinla ninu awọn mọkanlelogun to wa ninu ọkọ oju omi naa ni wọn ṣi n wa.
Ninu fidio kan to fi sita lọjọ Aiku, Akindele dupẹ lọwọ awọn ololufẹ rẹ fun atilẹyin ati aduroti wọn lasiko to fi la 'ewu' kọja.
Bí a bá ti ní oúnjẹ ati aṣọ, kí á ní ìtẹ́lọ́rùn pẹlu wọn.
"Abẹ́rẹ́ àjẹsára Covid-19 ti Pfizer ṣe yóò di lílò láti ọ̀sẹ̀ tó ń bọ̀ Ìdí tí mi ò fi lè parí ìjà pẹ̀lú Ààrẹ Ọ̀nà kakanfò, Gani Adams - Obasanjo COVID-19 gbẹ̀mí èèyàn kan lọ́jọ́rú, èèyàn 122 tún ti ní COVID-19 ní Nàìjíríà Wo dókítà ọmọ Nàìjíríà tí àgbáyé ń wárí fún nítorí abẹ́rẹ́ àjẹsára COVID-19 Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Ọkọ mi wa ọkọ̀ tẹ ""Poly Bag"" lásán, àfi gbùùàà!"
Iroyin kan tun ti kede pe se ni awọn eeyan lorilẹede South Africa tun n ja awọn sọọbu to jẹ tawọn ajeji, ti wọn si n ko wọn ni ọpọlọpọ ẹru tabi ba dukia wọn jẹ.
Wo orúkọ àwọn ẹ̀yà ara rẹ̀ ní èdé Yorùbá Àbá ìsúná N1.
Niti amala ati iyan gigun nibi ayẹyẹ, awọn kan gbagbọ pe eyi jẹ igbesẹ lati dena bi awọn alejo kan ṣe maa n fi ounjẹ ṣofo.
ilẹ̀ àwọn ará Keni, ti àwọn ará Kenisi, ti àwọn ará Kadimoni, 
Èyí ni pé, kì í ṣe àwọn ọmọ tí a bí nípa ti ara lásán ni ọmọ Ọlọrun.
Ewe, ireti wa pe, Ivan Rakitic, Mario Mandzukic, Luka Modric, Dejan Lovren ati Ante Rabic won ko ni bere ifesewonse naa.
Ọkan lara awọn ọmọ Oodua to gbe ogo iran wa ati orilẹede yii ga, to si n se abẹmi loke eepẹ lọwọlọwọ bayii ni Baba Michael Taiwo Akinkunmi.
Wọn kadi imọran yi pe ki a ri pe a ni eto ati ilana ta fẹ fi se isẹ wa lojojumọ.
Nítorí o ti ta àwọn eniyan rẹ nù,àní, ìdílé Jakọbu.
Mark so eyi ninu oro iranse re si awon omo orile-ede Naijiria fun ayeye odun ajinde, “A ni anfaani pupo ninu ibara eni gbe-po, gege bi eniyan ti a ni ayanmo kan naa”.
Mose bá tún yipada sí OLUWA, ó ní, “OLUWA, kí ló dé tí o fi ṣe ibi sí àwọn eniyan wọnyi?
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Abdulfatah Ahmed: Àwọn Kwara fẹ́ dán ilé ọkọ kejì wo ni lásìkò yí Fifi ipa ba awọn obinrin ati ọmọde lo pọ wọpọ ni Cameroon, ti awọn ti wọn fi ipa ba lo pọ kii ṣi jẹ ki ẹnikẹni mọ nipa rẹ.
Oríṣun àwòrán, @UNICEF_Nigeria Àkànṣe owó oṣù lá wa olùkọ́ ń fẹ́ yàtọ̀ sí tàwọn òṣìṣẹ́ ìjọba míì - NUT Ọjọ Karun osu Kẹwa ọdọọdun ni ayajọ ọjọ awọn olukọ lorilẹede Naijiria eyi to ko lọjọ Abamẹta.
12 Òkùdu 2018 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 24 Agẹmo 2018 Èsì ìwádìí àwọn Dókítà nípa ikú tó pá a fihàn pé kìí se àmúwá Ọlọ́run.
Ilé iṣẹ́ ọlọ́pàá ló sọ èyí lójú òpó twitter rẹ̀ lásìkò to n kàn si @officialnairam1 pé àwọn ti ṣetan láti ṣe ìpàdé pọ̀ pẹlú ilé iṣẹ́ ọ̀dọ́ àti àwọn míràn tí ọ̀rọ̀ kan ní Nàìjíríà láti wá ọ̀nà àbáyọ sí ìṣòrò náà.
Claritta O ku diẹ ki MMM o lana ni Claritta de.
O seese ki o jẹ idi ree ti Aisha Buhari fi n lọgun sugbọn a ko ti ridi ọrọ yi fi mulẹ.
Pataki jùlọ, o pa àwọn arakunrin rẹ, àwọn ọmọ baba rẹ, tí wọ́n tilẹ̀ sàn jù ọ́ lọ.
Àwọn eniyan wá bi í pé, “Kí ni kí a wá ṣe?
Yahaya Bello lẹ́ẹ̀kan síi ni APC ṣe ní ìdìbò abẹ́lé ní Kogi Ọwọ́ mi mọ́ lórí ọ̀rọ̀ owó Káńsù l'Ekiti - Ayodele Fayose Bakan naa ni ko wọpọ ki awọn ọlọpaa ni ilẹ Afirika ma a lo ọkọ ofurufu lati gbogun ti ijinigbe ati awọn iwa ọdaran ni awujọ, amọ wọn ma n lo o ni igba kọọkan.
, ni eyi ti o je ikesan an iru re ti yoo waye ni ọjọ kẹjọ si ọjọ kewaa .
Gẹ́gẹ́ bí ètò ìkànìyàn ọdún-un 2016, mílíọ̀nù èèyàn 1.
Yóo wí pé, “Mo ti fi ọba mi jẹ,ní Sioni, lórí òkè mímọ́ mi.
O tun sọ wi pe ẹsọ oju-popo ti o ba mu ju 500 naira lọwọ setan ati wọ wahala ijọba.
Tobaya kò sì dẹ́kun ati máa kọ lẹta sí mi láti dẹ́rù bà mí.
Akẹkọọ mẹrinlelaadọta ni a gbọ pe awọn janduku agbebọn ọhun ji lọ lọjọ Ẹti nileewe to wa ni kankara ni Katsina.
6 149815 Orilẹede Azerbaijan 1793 18.
Ohun tó yẹ kí o mọ̀ nípa OIC rèé Wo àwọn ìlérí tàwọn Gómìnà tuntun ṣe nínú ìbúra wọn Ara adugbo ti ọrọ naa ṣoju rẹ ni ṣe ni Obok pada de lati ode ti iyawo rẹ si gbe ounjẹ siwaju rẹ.
Wọ́n ti yìnbọn pa olórí ẹgbẹ́ jàndùkú ''One Million Boys'' ní Ibadan’ Covid19 Benefit: Inú mi dùn pé Coronavirus jẹ́ kí wọ́n ti iléèwé pa - Favour O ni bi ọwọ sinku awọn agbofinro ṣe mu Magu fihan pe ko si ẹni to kọja ofin ni Naijiria.
Iroyin to tẹ wa lọwọ sọ pe Ajeyemi naa lo ni oyun to wa ninu rẹ.
Lẹ́yìn ìgbà tí fídíò ọ̀hún gba kòbákùngbé ìjábọ̀ bíi “Kọ̀wé fipò sílẹ̀” àti “A kò fẹ́ àlọ́ atanijẹ mọ́” pẹ̀lú ọ̀pọ̀lọpọ̀ àìní ìfẹ́ràn ní ọjọ́ àkọ́kọ́ tí a gbé e sórí ayélujára, ìkànnì REAL TV ní oríi YouTube ti ìsọsí pa.
Ó wó àwọn òpó oriṣa Aṣera ati gbogbo àwọn ère tí wọ́n fi igi gbẹ́ ati àwọn tí wọ́n fi irin rọ.
Àwọn ìròyìn míì tí ẹ lè nífẹ sí Àgbedọ̀!
kí n má baà yó tán, kí n sẹ́ ọ,kí n wí pé, “Ta ni ń jẹ́ OLUWA?
Iwe ti mo kọ si Fayemi jẹ lẹta baba si ọmọ ni, mo si nigbagbọ pe awọn ohun to wa ninu iwe shun yoo ye yekeyeke.
Níbẹ̀ ni wọ́n ti rí ilẹ̀ tí ó ní koríko, tí ó sì dára fún àwọn ẹran wọn.
E je ki a gbadura lati fopin si iseku-pani, iparun, aisi aabo, oro-aje to le ikoko, iyan ati ebi, ise ohun osi ni ile wa.
Bi awọn kan ti n fi Arsenal ṣe yẹyẹ lori ayelujara ni awọn mii gab pe ojoojumọ kọ lọdun ni idije naa jẹ.
Wo ohun mẹ́wàá nípa gomina tuntun tí wọ́n dìbò yàn ní Bayelsa Wada: Alága àjọ ìdìbò INEC àti ọgá ọlọ́pàá, mò fà yín lè Ọlọrun lọ̀wọ́ Ohun mẹ́fà tó yẹ ní mímọ̀ nípa Yahaya Bello Adedimeji ní àdìtú layé, Toyin Abraham sọ pé kò sẹ́ni tó lè táyé lọ́rùn Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Àwa akódọ̀tí táà ń gba £1,500 lóṣù níbi sàn ju Sẹ́nétọ̀ lọ ní Nàìjíríà' Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, EkitiRapeCastration: ìgbésẹ̀ míì lè dẹ́kun ìwà ìfipábánilòpọ̀ Mo tun fi kun un pe awọn yoo ṣe agbekalẹ igbimọ alaṣẹ ti yoo mojuto ọrọ titete fi ọmọ lọkọ.
Ọrọ ti di iṣu ata yanan-yanan bayii lẹgbẹ oṣelu APC bayii pẹlu bi ẹgbẹ oṣelu naa ṣe n ni adele alaga apapọ meji laarin wakati diẹ si ara wọn.
” Àwọn náà dáhùn pé, “Kí OLUWA bukun ọ.
Bí ibi tí àrùn yìí wà bá bẹ̀rẹ̀ sí í pọ́n tabi, kí ó ní àwọ̀ bíi ti ewéko, kì báà jẹ́ aṣọ olówùú, tabi ti onírun, tabi kí ó jẹ́ awọ tabi ohunkohun tí a fi awọ ṣe, àrùn ẹ̀tẹ̀ ni; dandan ni kí wọ́n fihan alufaa.
Ọmọde yii moribọ nibi igbeyawo tipatipa ọhun, lẹyin naa ni baba rẹ tun fi fun ọkunrin mii to jẹ ẹni ọdun marundinlogoji.
Ọ̀dọ̀ rẹ ni gbogbo eniyan ń bọ̀,
Samir Azzimani Ọjọ ori: Ogoji Orilẹẹde: Morocco Ere idaraya: Cross-Country Skiing Samir Azzimani kọkọ kopa ninu ẹka ere ori yiyin ‘alpine skiing’ ki o to wa sun kuro lọsi idi ẹka ere  miran ti wọn npe ni ‘cross-country skiing.
AWỌN IROYIN TẸẸ LE NIFẸ SI NIPA RẸ Ibanuje d'orí agbà k'odò, Ruiz fi ẹ̀ṣẹ́ sọ Anthony Joshua di ọmọ ológo àná Mi ò ní gbà!
Iroyin sọ pe awọn ọlọpaa mu awọn oluwọde kan.
'Ẹ mu darandaran to n gbe'bọn' Darandaran pa ọlọ́pàá 4 ní Benue Soyinka s'ọrọ lori ipaniyan awọn darandaran Ọwọ ologun tẹ darandaran mẹwa ni Benue Awọn afurasi darandaran pa agbẹ l'Ekiti O ni ọfẹ ni NIS maa ṣe e fun koda awọn ti wọn ti wọle lọna aitọ ti wọn ko ni iwe irinna atiwọle to jẹ ootọ.
Ìpọ́njú olódodo a máa pọ̀;ṣugbọn OLUWA a máa kó o yọ ninu gbogbo wọn.
Awọn aṣofin bii meji kan beere ọrọ yii ti o si dahun pe ''awọn to n sọrọ nipa owo osu nipinlẹ Osun lasiko toun wa lori alefa kan n wi eleyi ti o wu wọn ni.
Ile-ise olopaa so pe awon afurasi mẹ́rìndínlọ́gọ́rùn ún ni awon ti fowo sinkun mu fun lilowo si ninu rogbodiyan ti o waye nipinle Kaduna, eleyi ti o gba emi opolopo awon ara-ilu, ti o si ba ohun ini awon miiran je nipinle naa.
Sugbọn ọpọlọpọ banki lo maa n gbẹsẹ le obitibiti owo to mu ifura dani, ti wọn ba ri i pe o ti pẹ ninu àsùnwọ̀n onibaara kan.
" Ẹgbẹ Ajafẹtọẹni naa wa n rọ awọn asaaju wa leti pe awọn ilana aatọ wa nilẹ to jẹ itẹwọgba lawujọ agbaye eyi to de sise amojuto agbegbe kọọkan, ti yoo si tun mu agbega ba idagbasoke aabo ati awujọ.
Da ìtìjú bò wọ́n,kí wọn lè máa wá ọ kiri, OLUWA.
Igbó wúlò fún ìwòsàn ara àmọ́ ẹ kọ́ iléeṣẹ́ tó le è fi ṣe òògùn - Ẹgbẹ́ Dókítà Ìwadìí ti bẹ̀rẹ̀ lórí àrá tó sán pa òṣìṣẹ́ FRSC mẹ́ta nípínlẹ̀ Ogun- Ọ̀gá àjọ FRSC Àwọn ohun tuntun tí a mọ̀ nípa ìgbẹ́jọ́ Wòlíì Sotitobire Gómìnà márùn ún tó fojú winá ìbínú bàbá ìsàlẹ̀ wọ̀n Ti ijo ti ilu ni wọn ọmọ ẹgbẹ oṣelu PDP fi ki Ọgbẹni Ajayi kaabọ sinu ẹgbẹ wọn.
Bí àrùn náà bá tàn káàkiri lára ògiri ilé náà, a jẹ́ pé àrùn ẹ̀tẹ̀ tí í máa ń tàn káàkiri ni; ilé náà kò mọ́.
Adebo bórí l'Oyo, Oluomo ní ìpínlẹ̀ Ogun gẹ́gẹ́ bí adarí ilé aṣòfin Ẹ̀mí 18 ṣòfò ní Òpópónà Akure sí Ọwọ Gómìnà ìpínlẹ̀ Osun wọ́gilé ìrìnàjò àwọn alága sí Dubai Ajọ UN ni oun tun ti fi awọn oluwadii nipa ẹtọ ọmọniyan ranṣẹ sijọba Mali ki wọn le pese iranlọwọ fun ijọba Mali ninu iwadii ti wọn n ṣe.
Alaye ti minisita keji fun ọ̀rọ̀ epo rọ̀bi, Ibe Kachikwu, ṣe nipe ijọba gbe igbesẹ naa lati fopin si ọwọn gogo epo bẹtiro to maa n waye.
Gẹgẹ bi atẹjade naa ṣe sọ, lootọ o le ni ẹgbẹrun kan ẹya kokoro arun naa to wa lode, ṣugbọn eyi to wa ni Naijiria, paapaa julọ ipinlẹ Ọṣun nitosi ibi ti ibudo iwadi naa kalẹ si yatọ si eyi.
Ìpínlẹ̀ mẹ́rìnlá lo ni ààrun náà.
Àwàdà kẹrí-kẹrì gbá à ni fídíò yìí.
Ṣugbọn àwọn ọmọ Lefi nìkan ni yóo máa ṣiṣẹ́ ninu Àgọ́ Àjọ, wọn óo sì ru ẹ̀ṣẹ̀ wọn.
O si beere fun omi, ṣugbọn o sọ fun un pe oun ko ni, nitori pe ejo kan fi inu kanga ti awọn n pọn ṣe ibugbe.
Àwọn kan gbèrò wọ́n fẹ́ gbé àjọyọ̀ Kérésìmesì fi ẹ̀gbẹ́ kan ẹ̀gbẹ́ pẹ̀lú ìrẹ̀sílẹ̀ ìlú tí ó wáyé ní 160 ọdún sẹ́yìn.
Eyi jẹ iyalẹnu fun awọn eniyan wọnyii ti ko mọ pe iru eto bẹ ẹ ti wa, ti o si ṣeeṣe ki wọn l'ero pe onijibiti ni ọkunrin naa.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Africa in Pic: Àwọn àwòrán tó gbajúmọ̀ ní Afirika 5 Agẹmo 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 6 Agẹmo 2019 Ni bayii ti opin ọsẹ wọle de, ẹ jẹ ka jọ fun oju ni ounjẹ lati ipasẹ awọn aworan isẹlẹ manigbagbe to waye nilẹ Afirika laarin ọsẹ to n pari.
Ilé ẹjọ́ sún ìgbẹ́jọ́ Sẹ́nétọ̀ Elisha Abbo tó lu obìrin Darandaran Fulani kìí lo ìbọn, 'pọ̀pá' la máa ń lò Ìlú ò rẹ́rìn ín rárá, Alaafin Adeyemi III fárígá fún Buhari nínú lẹ́tà tuntun 'Kò sí ohun tó burú nínú bí Ajimobi ṣe dá Yewande tó pa ọkọ rẹ̀ sílẹ̀' Femi Adesina ni ẹmi ọga ọlọpaa to sọnu sinu iṣẹlẹ iwọde yii to eyi to n gba ẹbọ lọwọ awọn oluwọde ṣugbọn oun ki awọn agbofinro fun gbigba alaafia laaye lai nii fiṣe ohun gbogbo to ṣẹlẹ.
Tí OLUWA yóo kó àwọn eniyan lọ sí ilẹ̀ òkèèrè, tí ibi tí a kọ̀tì yóo sì di pupọ ní ilẹ̀ náà.
com/iXqVVW53aiAARE BUHARI N TOWOBO IWE IBURAAdemola Adepoju.
Amọ, awọn miran ni awọn agbalagba bii Baba Obasanjo gan lo wa nidi iṣoro to ba orilẹede Naijiria, pe kii ṣe Buhari nikan ni o ba Naijiria de ibi ti o wa.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Tinubu: Emi ko mọ nipa ipẹtusaawọ APC ti Buhari ni kin se 6 Èrèlè 2018 Oríṣun àwòrán, @MBuhari Àkọlé àwòrán, Tinubu ni baba isalẹ fun Buhari lati di aarẹ lọdun 2015 Gẹgẹbi ara ọna lati da alaafia ati isọkan, to n dabi ẹni pe o n fi ẹgbẹ oselu APC silẹ, Aarẹ Muhammadu Buhari ti yan agba ọjẹ kan lẹgbẹ oselu, Asiwaju Bọla Ahmed Tinubu lati lewaju igbesẹ fun atunto ati isọkan l'ẹgbẹ oselu naa.
Bí òkè ńlá ti yí Jerusalẹmu ká,bẹ́ẹ̀ ni OLUWA yí àwọn eniyan rẹ̀ ká,láti ìsinsìnyìí lọ ati títí lae.
Lati igba naa ni awọn afẹhọnuhan EndSars ti bẹrẹ si ni lo ọrọ naa kaakiri, to fi mọ oke okun.
O ṣalaye pe, ida meji ninu ida mẹta ile aṣofin agba l'Abuja gbọdọ faramọ mọ na, ki wọn to le gbe adajọ lọ sile ẹjọ tabi siwaju igbimọ CCT lati jẹjọ.
Yahaya Abdullahi (Kebbi North), ti yoo maa 
 Ẹgbẹ awọn gomina lẹkun ariwa Naijiria naa wa n ke sawọn ọmọ Naijiria nile loko, lati tako awọn ọta orilẹede yii nipa sise atilẹyin fun aarẹ Buhari, ijọba apapọ ati eto ijọba alagbada."
Ni bayii, ati ijọba ataraalu ni wọn ti gba pe ki awọn iṣẹlẹ ile to n da wo lorilẹede Naijiria, paapaa julọ nipinlẹ Eko to lee di afisẹyin ti eegun n fiṣọ awọn igbesẹ gbogbo to yẹ gbọdọ waye.
Osun-Osogbo Festival 2020: Àwọn ẹlẹ́sìn àdáyébá rú òfin Covid-19 níbi àṣekágbá ọdún Osun Osogbo
Ọba bá pàṣẹ fún ọ̀kan ninu àwọn iranṣẹ rẹ̀ kí ó fún obinrin náà ní gbogbo ohun tíí ṣe tirẹ̀ pẹlu gbogbo ohun tí wọ́n ti kórè ninu oko náà, láti ìgbà tí obinrin náà ti fi ìlú sílẹ̀ títí di ìgbà tí ó pada dé.
Yoruba Language: Akomolede ati Asa Yoruba tọ̀sẹ̀ yí rèé lẹ́nu olùkọ́ wa
O salaye pe, “Ajo UNUCEF ni o se agbekale ise-akanse yii, eyi ti ajo EU satileyin fun, pelu erongba ati mu igbe aye irorun ba awon omo-wewe, nipa nini anfaani si omi-mimu ati imo-toto ayika ni awon ilu naa, ni eyi ti won ti se amulo iru ise-akanse bayii ni ipinle Adamawa, ekiti ati ipinle Plateau, ni ipinle Plateau lowo-lowo, a n se ise ni awon ijoba ibile bi: Shendam ati Riyom, a ti fowo siwe igbora-eni ye pelu ijoba ipinle Plateau lati pese, kanga-dero  ni awon ilu bi egbeta, amo ni bayii, a ti sise lori ipele kinni ati ipele keji, ninu eyi ti a ti pese kanga-dero ti o n lo bi irinwo ati ile-igbonse bi ogoji, a o bere ipele keta ninu osu karunodun ti a wa yii”.
"Makinde loun ní ìbéèrè láti bi Ajimobi lórí aṣemáṣe iṣẹ́ àgbàṣe, ni kọmíṣọ́nà Ajimobi kan bá gbarata Wo ìdí tí wọ́n fi ta ẹyẹlé kan ṣoṣo ní ₦893,000,000 Ṣaaju nigba ti ọrọ yii ṣẹlẹ̀, DPO ọlọ́pàá naa ju télọ̀ yii sátìmọ́lé, o tun gbé e lọ sílé ẹjọ́ n'Ibadan torí o ni ""ó ba aṣọ mi jẹ́''."
O ni o ṣeeṣe ko jẹ pe ede-aiyede lo mu ọlọpaa naa yinbọn.
Bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé òun ni ó kéré jùlọ ninu gbogbo irúgbìn, sibẹ nígbà tí ó bá dàgbà, a tóbi ju gbogbo ewébẹ̀ lọ.
Africa Eye: Olùkọ́ méjì ní fásitì Eko àti Ghana lùgbàdì ọ̀fíntótó BBC lórí ìwà ìbàjẹ́ Afurasi kan fipá bá akẹ́kọ̀ọ́ UNILAG lò pọ̀, ó tún jí pátá rẹ̀ - Iléeṣẹ́ ọlọ́pàá ‘Lóòótọ́ ni ọ̀jọ̀gbọ́n fẹ́ bá mi lòpọ̀’ OAU: Ohùn ọ̀jọ̀gbọ́n Richard Akindele ni wọ́n ká sílẹ̀ Fasiti Eko mẹnuba awọn ilana ofin ileewe giga naa lori ibalopọ ati iwa aitọ laarin akẹkọọ ati olukọ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Serena Williams: Wang tún da àlá Ife ẹ̀yẹ kẹrìnlélógùn fún Serena Williams rú 24 Sẹ́rẹ́ 2020 Oríṣun àwòrán, Getty Images Ọrọ Serena Williams, agbabọọlu ẹlẹyin ori papa ati ilepa rẹ lati gba ife ẹyẹ idije lawn tennis Grandslam fun igba kẹrinlelogun tun ti dete.
Ninu atẹjade ti agbẹnusọ ile iṣẹ ọlọpaa ipinlẹ Bayelsa, SP ASinim Butswat fi ranṣẹ si ile iṣẹ BBC o fi aridaju han pe lootọ ni wọn ji iya agbabọọlu ati akọnimọọgba Naijiria tẹlẹ ri, Samson Siasia gbe.
Ó sọ fún àwọn àgbààgbà pé, “Ẹ dúró níhìn-ín dè wá títí a óo fi pada wá bá yín.
Nisinsinyii mo bẹ̀ ọ́, arabinrin, kì í ṣe pé mò ń kọ òfin titun sí ọ, yàtọ̀ sí èyí tí a ti níláti ìbẹ̀rẹ̀, pé kí á fẹ́ràn ọmọnikeji wa.
Oríṣun àwòrán, @tosinsammy_s Alaga ẹgbẹ Miyetti Allah nipinlẹ Ogun, Abdulmumin Ibrahim sọ fawọn akọroyin pe ko yẹ ko jẹ ẹya Yoruba nikan ni yoo wa ninu ẹsẹ alaabo Amotẹkun niwọn igba ti yoo dojukọ aawọ to maa n waye laarin awọn agbẹ ati darandaran.
 Ọmọ ọkọ ni àwọn ọmọ ìlú Ìjẹ ̀ bú - jẹ ̀ ṣà ní tòótọ ̀ .
Ẹ̀rù àti oríkunkun ló mú kíjọba máa fi ọlọ́pàá, ológun halẹ̀ mọ́ aráàlú - Ṣoyinka Toyin Abraham kìí bá èmi náà yọ̀, ni kò jẹ́ kí ń gbé e lárugẹ fún ayọ̀ ọmọ - Lizzy Anjorin Iṣẹ́ ọpọlọ ló yẹ ká ṣe nínú tíátà, kìí ṣe àfihàn ara bíbó àbí ìhòòhò wa - Binta Mọgaji Èmi àti Saheed kìí ṣe ọmọdé, a ti jọ ṣe Sinimá papọ̀, èyí túmọ̀ sí pé ìjà ti parí - Fathia Balogun Ọ̀pọ̀ èèyàn bẹnu ẹ̀tẹ́ lu Mercy Aigbe lórí bó ṣe ki Adeniyi Johnson Koda iroyin naa ni Khafi le padanu iṣẹ lori ọrọ naa nitori iwa ibanilorukọ jẹ lo jẹ ati pe ileeṣẹ ọlọpaa ko fun laye lati lọ kopa ninu idije BB Naija.
Àwọn Ẹ̀bùn láti fi Kọ́ Tẹmpili.
Oríṣun àwòrán, Alawe of Ilawe Ekiti O fikun ọrọ rẹ pe, Ọọni Ile Ife, ni gbogbo lọbalọba gba gẹgẹ bi olori nilẹ Yoruba, kii ṣe Alaafin, yoo si dara ki oriade ilu Ọyọ lọ so ewe gbejẹ mọwọ.
Ilé ẹjọ́ tó ga jù dá Seyi Makinde láre gẹ́gẹ́ bíi gómìnà ìpínlẹ̀ Ọyọ Kò sí arúgbó ní Kano,Bàbá 74 gbé ìyá 84 ní ìyàwó Wọn pa ọlọ́pàá kan níbi tí wọ́n ti dáná sun ìjọ Sotitobire l'Akurẹ - Police PRO Èyí ni àwọn ìdí tí wọ́n fi fẹ́ ẹ̀ fi 37 Billion Naira tún ilé aṣòfin Nàìjíríà ṣe Ẹsun meji to da lori aṣilo ipo, ati ṣiṣe idiwo fun iṣẹ ile aṣofin-ni wọn fi kan Aarẹ Donald Trump .
Ajọ FBI ti ni awọn yoo ṣe iwadii iṣẹlẹ to waye lalẹ ọjọ aje.
gbigbẹmi ara eni se n gbilẹ lorile ede Naijiria.
Wo bi o ṣe le fi orukọ silẹ: Igbesẹ fun ẹnikẹni to ba nífẹ̀ẹ́ lati fi orukọ silẹ ni lati lọ si oju opo ayelujara recruitment.
Ta ló n darí ìkànì Twitter APC?
Adájọ́ pàṣẹ pé kí wọ́n o fi àwọn afurasí tó pa ọmọ Fasoranti sí ọgbà ẹ̀wọ̀n Àwọn àràmọ̀ndà ìbomú-bẹnu tó gbòde lásìkò Coronavirus yìí N kò jẹ Mayegun láti bùgá, mo wá tún ilẹ̀ Yorùbá ṣe ni - Wasiu Ayinde Wo àwọn nkan tí o le ṣe gẹ́gẹ́ bi aláboyún lásìkò àjàkálẹ̀ ààrùn Covid-19 Ṣugbọn bayii nnkan ti yi pada ni Naijiria, ati lawọn orilẹ-ede miran bi Egypt ati Saudi Arabia to jẹ olu ilu awọn Musulumi lagbaye.
Mo sì kìlọ̀ fún ọ pé, ní ọjọ́ tí o bá jáde, pípa ni n óo pa ọ́.
Àwọn ọmọ Nàìjíríà ṣe ìwọ́de l'Osogbo lórí àfikún owó epo bẹntiróò Ìjọba Nàìjíríà ti sún ọjọ́ tí ìrìnàjò bàálù sílẹ̀ òkèèrè yóò bẹ̀rẹ̀ padà síwájú Ìjọba kéde ọjọ́ míràn fún ìbẹ̀rẹ̀ padà ìrìnàjò bàálù sílẹ̀ òkèèrè Ijọba orilẹ-ede Naijiria ti sun ọjọ ti irinajo ofufuru silẹ okeere yoo bẹrẹ pada kuro ni ọjọ kọkandinlọgbọn, oṣu Kẹjọ, ọdun 2020.
4 Owewe 2020 Petrol Price Hike: Ilé aṣojú-ṣòfin dúró ìṣẹ́jú kan fún Buruji Kashamu àti Rose Okoh30 Owewe 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Oríṣun àwòrán, @GovKaduna Àkọlé àwòrán, Gomina Ipinlẹ Kaduna ati awọn olori ẹsin ti n ṣe ipade orisirisi Abájáde ìpàdé èètò ààbò naa ti Samuel Aruwan oluranlọwọ fun Gomina Kaduna lori ọrọ ibanisọrọ fi sita ṣe àlàkalẹ ètò kóníléógbélé naa.
O sọ̀kalẹ̀ sí orí òkè Sinai, o bá wọn sọ̀rọ̀ láti ọ̀run, o sì fún wọn ní ìlànà ati ìdájọ́ tí ó tọ̀nà ati àwọn òfin tòótọ́, 
Lọjọru to kọja ni dokita yii lọ ba awọn agbofinro to n ṣo ile aarẹ sọrọ.
Ni ayé igbà kan ri ki ṣe oye ọkọ, ilé gogoro, aṣọ àti owó ni ilé-ìfowó-pamọ́ ni a fi nmọ Ọlọ́rọ̀ bi kò ṣe pé oye Ẹrú, Ìyàwó, Ọmọ, Ẹran ọsin àti oko rẹpẹtẹ ni a fi n mọ Ọlọ́rọ̀.
Boyega je omo Naijiria ti a bi sile Geesi to n polowo fiimu re tuntun lati Hollywood, iyen Pacific Rim Uprising kaakiri lasiko yiiKini o fe se?
Nigba to n da si ọrọ naa, alaga igbimọ amuṣeya naa, to tun jẹ akọwe ijọba Naijiria, Boss Mustapha sọ pe, o yẹ ki awọn eeyan ṣora fun apejọpọ elero pupọ nitori Covid-19 ṣi wa lode.
Lẹ́yìn ọjọ́ mẹfa, Jesu mú Peteru ati Jakọbu ati Johanu arakunrin Jakọbu, wọ́n lọ sí orí òkè gíga kan; àwọn nìkan wà níbẹ̀.
 atọ ́ ka ibá-ìṣẹ ̀ lẹ ̀ yìí nínu Ẹi ni éé àti a ka .
Bi o ti n dahun awọn ibeere ti wọn bi i, bẹẹ naa lo n ṣe atupalẹ idahun rẹ si awọn ibeere naa.
Ogun flood: ọ̀pọ̀ àwọn olùgbé agbegbe yii ti fi iṣẹ́ sílẹ̀ nítorí wọn kò lè jáde
Ìtàn Àrọ̀gìdìgbà jẹ́ kí ń rò pé bàbá mi yan Yemọ̀ja ní àlè - Ọmọ Fagunwa Baṣọ̀run Gáà: Ó yan ọba mẹ́rin, tó sì pa ọba mẹ́rẹ̀ẹ̀rin àmọ́ ọba karùn-ún ló pa á Ọọ̀ni obìnrin, Lúwòó Gbàgídà rèé, akọni tó ń gun ọkùnrin ní ẹṣin rìn Sanusi Adebisi Idikan rèé, olówó tó ń san owó orí fún gbogbo ọkunrin ilẹ̀ Ibadan Ajakale àrùn miran ti àwùjọ agbaye kò leè gbàgbé ni àrùn onigbameji taa mọ sí Kọlẹra, èyí tó wáyé láàárín ọdún 1817 sí 1824.
Ènìyàn 653 míràn tún kún iye àwọn tó ní COVID-19 ní Nàìjíríà Ọlọ́paàá ní wọ́n ṣèèṣì yìnbọn pa ọmọ mi tó ń tọ́ ọmọ oṣù mẹ́rin lọ́wọ́ ni- Ìyá Kager Ẹ̀bi ta ni pé àwọn ọ̀dọ́bìnrin Nàìjíríà ń há sí Oman?
Nítorí náà, wọn óo dàbí ìkùukùu òwúrọ̀, ati bí ìrì tíí máa ń yára gbẹ, wọ́n óo dàbí ìyàngbò tí afẹ́fẹ́ ń fẹ́ kúrò ní ibi ìpakà, ati bí èéfín tí ń jáde láti ojú fèrèsé.
OLUWA àwọn ọmọ ogun, Ọlọrun Israẹli sọ nípa Moabu pé,“Nebo gbé nítorí yóo di ahoro!
Akọroyin wa to jabọ lati ilu Alexandria sọ pe niṣe ni wọn ni awọn ko foya lati koju ẹnikẹni to ba kan ninu idije naa.
Bí mo ṣe ń pada bọ̀, mo rí ọpọlọpọ igi ní bèbè kinni keji odò náà.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Àwọnn ǹkan tó yàtọ̀ nínú abá ìsúnà tí ọdún 2019 'Eré orí ẹní' rán Davy lọ sọ́run ní ìlú Eko Ajọ LASEMA sọ̀rọ̀ lórí okùnfà iná to jó l'Abule Ẹgba.
Sinima to gun ni ọrọ oṣelu Naijiria, ko fẹ ẹ ni opin Nibi ti ọrọ de duro yii, ko si ẹni to le sọ pe ibi kan ni yoo ja si nigbẹyin.
Ìgbín ní èmi àti ìyá mi máa ń he kiri, ká tó lee jẹun - Lizzy Anjọrin Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Kí ló máa ń wú ìyá Nike Davies lori láti wé gèlè ràbàtá?
Jumọkẹ Odetola ṣe ọjọ́ ìbí, Wumi Toriola bímọ, Ṣé ẹ fẹ́ tẹ̀lẹ́ Funkẹ Akindele lọ si Dubai?
3 trillion ni CBN gbé jáde fún ọdun 2020 Àráàlú yarí fún fásitì Babcock fún bo ṣe lé akẹ́kọ̀ọ́ tí wọn bá lòpọ̀ nínú fídíò Awọn agbofinro onijẹkujẹ: Bi o tile jẹ pe a ni ọpọlọpọ awọn oṣiṣẹ rere lawọn ajọ bii ileeṣẹ ọlọpaa, LATMA, bẹẹ naa ni a ni ọpọ to jẹ kọlọransi laarin wọn.
Díẹ̀ lára àwọn òṣèré Nollywood ti wọ́n ti ṣe ìgbéyàwó lẹ́ẹ̀kejì Ìdí tí a ṣe yọ ọwọ́ Naira Marley kúrò láwo Headies Award ọdún yìí rèé - HipTV Ìgbìmọ̀ ìgbẹ́jọ́ Kano: Ganduje ló pegedé nínú ìdìbò sípò Gómìnà Má ṣé tọrọ aforijin lọ́wọ́ Buhari lásìkò àbẹwò rẹ- South Africa Bakan naa lo ṣakawe awọn orilẹ-ede gbogbo ti wọn ti n san owo oju ẹnu ibode laarin ilu yii.
Èmi lérò pé bóyá Olúkòso ń bínú ni.
Iwadii fi han pe awọn eeyan bi igba lo gbe nnkan biliọnu kan dọla kalẹ fun idibo Aarẹ ọdun 2016.
Bakan naa ni wọn kesi Ile Isẹ to n gbogun ti lilo ogun oloro lorilẹede Naijiria, NDLEA lati da miliọnu mẹẹdọgbọn rẹ ti o yẹ pada fun lẹyin ọdun mẹjọ ti wọn ti fẹsun kan Baba Suwe wi pe o gbe ogun oloro cocaine, amọ ti gbogbo iwadii fihan wi pe ko se bẹẹ.
Ọba bá fi ọ̀rọ̀ náà lọ àwọn ọlọ́gbọ́n tí wọ́n ní òye nípa àkókò, (nítorí bẹ́ẹ̀ ni ọba máa ń ṣe sí gbogbo àwọn tí wọ́n mọ òfin ati ìdájọ́.
Wọn yóo ṣe gbogbo nǹkan wọnyi si yín nítorí tèmi, nítorí wọn kò mọ ẹni tí ó rán mi níṣẹ́.
“Nígbà tí ó di ààrin ọ̀gànjọ́, igbe ta pé, ‘Ọkọ iyawo dé!
Peteru ń tẹ̀lé Jesu, ó ń bọ̀ lẹ́yìn patapata, títí ó fi dé àgbàlá Olórí Alufaa.
Israẹli, wọ́n ti pa àwọn tí o fi ń ṣògo lórí àwọn òkè rẹ!
Kò lè ṣééṣe kí Ruga wà lápá gúúsù Nàìjíríà fáwọn Fulani- Ganduje Aarẹ Buhari pàṣẹ pé kí wọ́n ṣàwárí àwọn oníṣẹ́ ibi tó pa èèyàn 65 ni Borno 1.
Jẹ́ kí àwọn tí a lé jáde ní Moabu, máa gbé ààrin yín.
Tolani ti ba arun jẹjẹrẹ pòó, o si ti bori lo fi n figba gbogbo rọ awọn eniyan lati má sọ ireti nu laye.
Gẹgẹ bi iroyin ti ileeṣẹ L'Equipe gbe jade, iye owo ti wọn ra agbabọọlu naa lati ilẹ France lọ si iha 'Italian Serie A' le ni miliọnu mọkanlelọgọrin pọun.
O ni eyi lo mu ki gomina wo o pe dipo ki wọn maa reti ohun ti ko si rara, o ṣi gbiyanju lati gbe eto isuna sita.
Bí bàntẹ́ tí dáké orin, ni ọmọdé yìí fò sánlẹ̀ ó sì kú.
Ilana ti wọn lo yii mu ko jẹ pe Trump nikan ni ẹnu rẹ ṣe akoba fun - eyi to pada pé Biden.
ní ọ̀sán, yóo mú kí ìkùukùu bo gbogbo òkè Sioni ati àwọn tí ó ń péjọ níbẹ̀; ní alẹ́, yóo sì fi èéfín ati ìtànṣán ìmọ́lẹ̀ bò wọ́n.
Ẹ̀sun olè ní a fi kan Akoroyin Samuel Fayose: Kàkà kí n darapọ̀ mọ́ APC, màá.
to le mu wahala dani saaju akoko atundi  eto idibo ti yoo waye lọjọ Abamẹta, ki won
"Oun naa ti ni ile ẹkọ nipa ere ṣiṣe to pe ni ""Mercy Aigbe Gentry School of Drama""."
ti wọn maa n lo lati fi se ayẹwo ika ti oludibo fẹ lo, boya tirẹ ni tabi tirẹ
Gege bi aare Buhari; “Egbe yii lo fa mi kale, maa si dije.
Seyi Makinde vs ALGON: Àwọn alága káńsù ní ìpínlẹ̀ Oyo fẹ́ pẹjọ́ kòtẹ́milọ́rùn lórí bígómìnà Seyi Makinde ṣe yọ wọ́n nípò
Lẹ́yìn náà, yàtọ̀ fún gbogbo àwọn nǹkan tí mo ti pèsè fún Tẹmpili Ọlọrun mi, mo ní ilé ìṣúra ti èmi alára, tí ó kún fún wúrà ati fadaka, ṣugbọn nítorí ìfẹ́ mi sí ilé Ọlọrun mi, mo fi wọ́n sílẹ̀ fún iṣẹ́ ilé náà.
Ọkan lara awọn meje ọhun ni Robert to fẹ Yeta Odusanya lati ilu Sagamu kan naa, ohun si ni baba Anthony ati aburo rẹ, Janet.
Ẹni to bori: Cameroon Egypt vs Senegal.
Koda, awọn kan ni ipilẹ orilẹede naijiria ni wọn fi irọ mọ, tawọn kan si ni igbe aye ayederu gan ni Abike Dabiri n gbe funrarẹ.
Mercy ni igbagbọ pe iku ọkọ rẹ, Joe, yoo mu ki ijọba wa nkan ṣe si ibudokọ omi Abonnema, lati sọọ di ibi to pojuowo, ti yoo si ni awọn adoola ẹmi, iwe akọsilẹ orukọ awọn arinrinajo, ati awọn eroja mi i.
OLUWA tún sọ̀kalẹ̀ ninu ìkùukùu ó dúró níbẹ̀ pẹlu rẹ̀, ó sì pe orúkọ mímọ́ ara rẹ̀.
’Kò sí ẹni tí ó sọ ọ́, kò sí ẹni tí ó kéde rẹ̀;ẹnìkankan kò gbọ́ ọ̀rọ̀ rẹ̀.
 ogun Èkìtì parapọ ̀ bẹ ̀ rẹ ̀ ní ọdún 1877 , o sì perí ní ọdún 1886 .
Èmi àti Adewale Ayuba ò ja, Ọlọ́run ló fún mi lóhùn t'èmi - Ajebori Onifuji Táyà ọkọ̀ agbépo tó fọ́ fa ìjàmbá ọ̀kọ̀ l'Ékò, èèyàn kan farapa Boris Johnson àti ẹgbẹ́ rẹ̀ wọlé ìbò, Trump àtàwọn ààrẹ míì kíi kú oríire Ọdun ń lọ sópin, ariwo 'ń sọ̀ ní ilé ńlá l'Abuja Ẹjọ́ Sowore bọ́ sọnù lọ́wọ́ àjọ DSS Pa Kasumu ni oun wa ni ipagọ adura ile ijọsin kan nibi t'oun ti n gbadura fun iwosan agọ ara oun, o ni oun si maa wa nibẹ ti eto naa yoo fi pari.
Ọkàn ọ̀lẹ ń fẹ́ nǹkan, ṣugbọn kò ní rí i,ṣugbọn ẹni tí ń fi tọkàntọkàn ṣiṣẹ́ yóo ní ọpọlọpọ nǹkan.
to kere julo, ogbeni Gidion Gwani lati ipinle  Kaduna, adari aato, ogbeni Toby Okechukwu, lati
Ṣé lootọ ni pe alaboyun, alaarẹ, ọmọde tabi arugbo ko le fi ẹjẹ silẹ?
wa  niluu Eko nipa iwa ti ikọ agbofinro
Ọgbẹ́ mi ń kẹ̀, ó sì ń rùn,nítorí ìwà òmùgọ̀ mi,
Dafidi bèèrè lọ́wọ́ ọdọmọkunrin tí ó wá ròyìn fún un pé, “Níbo ni o ti wá?
Agogo igbeyawo nlu nile Ọsinbajo Kano gbalejo igbeyawo ọmọ gomina Ọyọ Oríṣun àwòrán, Twitter.
Bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé Olusiro owo agba naa ti pe ẹni ọgọ̀ta ọdun losu keje ọdun 2018, to si yẹ ko ti fi isẹ silẹ, sugbọn a gbọ̀ pe ijọba ipinlẹ Ọsun se afikun akoko to yẹ ko lo.
Ṣugbọn nígbà tí Jesu gbọ́, ó dá a lóhùn pé, “Má bẹ̀rù, ṣá gbàgbọ́, ara ọmọ rẹ yóo dá.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Adewole Oniluola: Tunde Kelani ni ikú àgbà Àyàn náà tún mú kí ilẹ̀ Yorùbá sọ ohun rere nù 30 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Oríṣun àwòrán, Sikiru Adepoju Gbajumọ ayan kan nilẹ Yoruba, to tun n lu ilu fun oloogbe Ayinla Omowura, gbajumọ akọrin Apala, ti jade laye ni alẹ ọjọ Isegun.
Ìpínlẹ̀ Eko ń bá àwọn iléètura sọ̀rọ̀ fún ìpèsè ibùsùn fáwọn aláàrùn Coronavirus Yàtọ̀ sí mímu, àǹfàní tó wà lára igbó pọ̀ jaburata- Akeredolu Ọlọ́run ló kọọ pé àwọn ọmọ mi yóò ṣiṣẹ tíátà, èmi kọ lo kàn-án nípa fún wọn - Ọga Bello Ẹ wo àwọn gbajúmọ̀ òṣèré tíátà tó jogún eré ṣíṣe lọ́dọ̀ òbí wọn Lasiko Coronavirus yii lagbaye, awọn oṣiṣẹ ẹka ilera naa lo n fara gba ọfa Coronavirus julọ.
Akọroyin BBC to wa ni ile ijọba ipinlẹ Katsina lọwọlọwọ, Khalifa Shehu Dokaji, sọ pe, ọpọlọpọ ọkọ bọọsi ni wọn fi ko awọn ọmọ naa pada.
Wo àwọn ohun tó yẹ kí o mọ̀ nípa àrùn Coronavirus àti ìbálòpọ̀ akọ àt'abo Wo bí wọ́n ṣe ń fín àyíká láti dènà Coronavirus Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí 3 sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
Ọkan lara awọn iyawo rẹ, Aishatu Shagari dagbere faye nileewosan kan nilu London lọjọ lẹrinlelogun, oṣu Kẹjọ, ọdun 2001 lẹyin aisan ra npẹ.
Ninu oro re ti won fi si ori ero ayelujara, Ikome Samuel ni ikawo re di adele Aare Federal Republic of Ambazonia, eyi ti o so pe, egbe ohun ti bere  igbese dida abo bo ara eni ati ekun won bayii.
Bakan naa lo jẹ ẹbun ohun elo inu ile, ounjẹ ọfẹ, aṣoju ileeṣẹ, ati ẹẹdẹgbẹta Dọla owo Bitcoin.
Ninu rẹ wọn ni wọn ko foju jọ alaarẹ amọ awọn mejeeji jẹ ẹni to ti n fa siga lọjọ pipẹ ti eleyi si ti mu ki ẹdọ foro wọn ma lagbara to bo ti se yẹ.
Usi ni alabojuto àwọn ọmọ Lefi tí wọ́n wà ní Jerusalẹmu.
Àwọn Agbejọrò wa kúnjú òsùwòn tí wón si dańtọ -Ọlọgbondiyan.
Ọpọlọpọ ọrọ ni wọn ti sọ lori ayelujara tako Festus ki aarẹ ile igbimọ aṣofin to wa yọọ kuro.
Abdul Aziz jẹ ọmọ orileede Afghanistan sọ pe nigba ti oun gbọ iro ibọn, oun mu ẹrọ igba owo pelebe (atm card) ti oun si lẹ mọ agbebọn naa.
Ikọ̀ aláàbò Nàìjìríà dojú kọ Shiite Ọlọ́pàá mú 115 ẹlẹ́sìn Shiite Àgùnbánirọ̀ akọ̀ròyìn Channels náà ti dágbére fáyé látààrí ìkọlù Shiite l'Abuja Dúkìá àti ọkọ̀ jóná, ọlọ́pàá mẹ́sàn-án fara gbọta lásìkò ìwọ́de Shiite Adamu fi da awọn eniyan loju wi pe awọn yoo ṣiṣẹ karakara lati ri pe eto aabo to muna doko wa fun awọn olugbe Naijiria.
Wọn kilọ pe àwọn kò ní fi àyè sílẹ̀ fún òṣèrè tíátà kankan láti dójú ti ẹgbẹ́ mọ.
Koda wọn ni oju ara nkan ọmọkunrin Kolade ni ibọn ikẹta ti ọlọpàa SARS naa yin ti baa ko to ku ki wọn to gbee de ilé iwosan #Mothersday2019: Àwọn ìpèníjà obìnrin láwùjọ Ṣé ìwọ mọ odò adágún Adó Àwáyè tí kò ní òpin ní ìsàlẹ̀?
Mose sọ gbogbo rẹ̀ fún àwọn ọmọ Israẹli gẹ́gẹ́ bí OLUWA ti pa á láṣẹ fún un.
Oríṣun àwòrán, other Agbẹnusọ ile iṣẹ ọlọpaa tun rọ ẹgbẹ OPC pe ki wọn ni suuru kọrọ naa maa ba di ija.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Natalia Mufuta ìyá Yakub, Kamil àti Adam sọ̀rọ̀ lórí bí wọ́n ń sọ èdè mẹ́rin pàpọ Iwadii naa fihan iru ibọn ti awọn soja naa lo, ati aṣọ awọn soja naa, to fi mọ bata ẹsẹ wọn ati bi wọn ṣe rọ ibọn lu iya ati awọn ọmọ rẹ.
Àbí ẹ rò pé lásán ni Ìwé Mímọ́ sọ pé, “Ẹ̀mí tí ó fi sinu wa ń jowú gidigidi lórí wa?
Gbogbo ìkọ wà lábẹ́ ó ṣe é ṣe kí àwọn ọ̀rọ̀ àdéhùn míràn tún wà.
Sibẹsibẹ, wọn kì í gbọ́ ti àwọn aṣiwaju wọn.
O ye mi yekeyeke bi ọpọ ọdọ orilẹede ni inu wọn ko dun.
Iroyin nii ọdun to m bọ ni fiimu naa a wọ Netflix.
Gbajugbaja onkọrin nì, Davido Adeleke, ti fìfẹ́ hàn sí olólùfẹ́ rẹ̀, Chioma Avril, lasiko to n ṣe ayẹyẹ ọjọ ìbí ọdún metalelogun laye.
Wo àwọn ohun tí Amotekun kò ní le è ṣe mọ́ ní ìpínlẹ̀ Oyo.
Awọn abẹrẹ wa taa le lo, ti a ba ti gun ibi isalẹ ibi ti irun ti n jade wn a si lẹ wọn mọ ibi tori ti n pa ti yoo si bọ si deede pada.
NIMC registration portal: Wo ọ̀nà tí o le gbà rí fọ́ọ̀mù ìforúkọsílẹ̀ fún NIN rẹ gbà àti àwọn ibùdó ìforúkọsílẹ̀ lágbáyé Ṣé lóòtọ́ ni ẹ̀yà kòkòrò àrùn COVID-19 ti wọ ìpínlẹ̀ Osun?
Gbogbo awọn ẹgbẹ ọdọ nilẹ Yoruba ni Aarẹ yoo kojọ tako idunkoko awọn ajeji.
Akẹkọ Dapchi 101 lo pada de Orilẹẹde 44 t'ọwọ bọ'we lori AfCFTA Ṣugbọn olugbe kan ni adugbo Ikosi, ti o kọ lati fun wa ni orukọ rẹ, sọ pe oun ko lee fi ile oun silẹ lọ si agbegbe miiran nitori iṣoro ati ri ile miran nilu Eko.
 o dubule si eba okun india , ni agedemeji aye , kẹ ́ nyà ni bode mo ethiópíà ( ariwa ) , sòmálíà ( ariwailaorun ) , tànsáníà ( guusu ) , Ùgándà ati lake victoria ( iwoorun ) , ati orile ede gúúsù sudan ( ariwaiwoorun ) .
Ṣugbọn yatọ si bo ṣe n waye tẹlẹ, ijọba ni awọn obi ati alagbatọọ awọn akẹkọọ to lẹtọ si ounjẹ ijọba naa, ni wọn yoo gbe fun.
Awọn aṣojuṣofin alawọ dudu mẹrin naa, Alexandria Ocasio-Cortez, Ilhan Omar, Ayanna Pressley ati Rashida Tlaib ti parọwa fawọn eniyan pe eyi ko di awọn lọwọ iṣẹ.
A ò sì gbọdọ̀ fi ẹhónú hàn…
Iye awọn to kọ̀ idanwo naa le ni miliọnu kan (1,459,463) kaakiri orilẹede Naijiria Adari eto iroyin ni ajọ WAEC, Demianus Ojijeogu, ni laipẹ laijina ni esi idanwo naa yoo jade fun awọn akẹkọọ lati mọ bi wọn se se daradara to ninu idanwo naa.
"O ni ""Wọn sọ fun mi pe mo ṣi maa ri ọmọ mi, nigba miran ti mo ba gbaawẹ ti mo si fẹ ṣinu, gari ati agbọn ni mo maa n fi ṣinu, gbogboẹ gbogboẹ ki n le ri ọmọ mi yii naa ni."
 káàkiri àgbáyé , ní ọdún 2010 , ó ṣe òkùnfà ikú àwọn ènìyàn tó tó 1,200 , èyí tó lọ sókè láti ènìyàn 700 tó kú ní ọdún 1990 .
" Awọn baba yin wa ninu itan, o si yẹ ki ẹ ju awọn baba yin lọ, iyẹn lemi n ṣe aridaju rẹ laye temi""."
Ajo kan ti o n ri oro ogbin lorile-ede Naijiria, ti a mo si Nigeria Agricultural Quarantine Service (NAQS) ti se ikinlo fun awon arinrinajo ati awon onifayawo, lati sora lori awon ounje ti won n je.
Duro Ladipọ, ìlúmọ̀ọ́ká òṣèré tíátà àti ọmọ àlúfà tí kò gbàgbé àṣà ìbílẹ̀ Hubert Ogunde rèé, baba àwọn òsèré tíátà Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
8 Bẹ́ẹ̀ni, ẹkún rẹ̀ fún Síónì ni èmi ti rí, èmi yíò sì mú kí òun máṣe ṣọ̀fọ̀ lórí rẹ̀ mọ́; nítorí ìgbà inú dídùn rẹ̀ ti dé sí ìmúkúrò àwọn ẹ̀ṣẹ̀ rẹ̀, àti àwọn ìfarahàn àwọn ìbùkún mi lórí àwọn iṣẹ́ rẹ̀.
Ìgbà lonígbà ń kà ni Irinajo Saraki lagbo oselu Naijiria Ni ọdun 2000, Saraki wọ agbo oṣelu orilẹ-ede Naijiria lẹyin ti Aarẹ ana, Oluṣegun Obasanjo yan-an sipo gẹgẹ bi oluranlọwọ pataki lori eto inawo.
Kí inú má baà bí Ọlọrun si yín, kí o má baà mú kí òjò dáwọ́ dúró, kí ilẹ̀ yín má sì so èso mọ́; kí ẹ má baà parun kíákíá lórí ilẹ̀ tí OLUWA fun yín.
eleyi ti o ran orile-ede naa lowo lati pegede fun idije 2019 AFCON ti yoo waye
Oríṣun àwòrán, AFP Àkọlé àwòrán, NEMA: Ǹkan méje ló ń fa omíyale ní orílẹ̀-èdè Nàìjíríà Bakan naa, ijọba Naijria gbọdọ fọwọsowọpọ pẹlu awọn orilẹ-ede to wa layika wọn, lati le fi aye gba ki omi o lo bi o se yẹ, ki awọn adagunodo maṣe ru soke ju bi o ti yẹ lọ.
Ò ń jọba lórí òkun tí ń ru;nígbà tí ìgbì rẹ̀ bá ru sókè, ìwọ ni ò ń mú kí ó rọlẹ̀.
Jose Mourinho: 3-2 ni Tottenham fi se àgbà fún West Ham
lápá kan , wọ ́ n ní ìtàn fiyeni wípé odùduwà jẹ ́ oníṣẹ ́ láti ìlú Òkè-Ọrà ìlú tí ó wà ní apá ìlà -oòrùn é-ifẹ ̀ .
Onnoghen: Adájọ́ àgbà ní òun kò jẹ̀bi ẹ̀sùn tí ìjọba fi kan òun
 Opọlọpọ ami ẹyẹ lo gba nigba aye rẹ bii ti Nigeria Music Awards ati Fame Music.
Awọn ọkọ yi jẹ ohun irinna pọọkulowo, ṣugbọn ipenija aabo jẹ iṣoro kan ti awọn eeyan maa n koju pẹlu wọn.
Ó wá jẹ́ pé gbogbo owó tí òun àti ọ̀rẹ́ rẹ̀ tó dolóògbé jọ ní nípàmọ́ kó tó kú tó lọ jí kó sápò ní ìrètí àti nìkan ná, ló dà sínú ibojì láì ku eépìnnì.
Àláfíà gbáà ni èyí jẹ́ fún mi.
Ṣugbọn o fẹ́ afẹ́fẹ́ lù wọ́n,òkun sì bò wọ́n mọ́lẹ̀,wọ́n rì bí òjé ninu ibú ńlá.
Bí Jakọbu ti gbé ojú sókè, ó rí Esau tí ń bọ̀ pẹlu irinwo (400) ọkunrin.
Adari ileeṣẹ naa lọdun naa lọhun, Moir Dem, sọ ninu atẹjade kan pe idi ti wọn ṣe ti ṣọọbu ọhunn ko sẹyin ọwọngogo iye owo ile itaja ati iṣoro pinpin ọja ka.
”Onisegun oyinbo yii gba awon eniyan nimoran pe ki won maa fiyesi itoju eya ara won kookan ki o to di pe o maa di aisan nla lara won.
Oríṣun àwòrán, @osunosogbo2019 O ni eyi yoo tubọ fa oju awọn eeyan mọra si jakejado agbaye, eyi ti yoo mu ki ọdun asa ibilẹ, irin ajo afẹ ati ogun abalaye wa naa se aseye, ti alakan n se epo lọdun 2019.
"Oríṣun àwòrán, Then Nigerian Senate Adewọle ni, ""Ero ti pọ ju ibi ti agbara awọn ile iwosan naa le gbe lọ."
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Akeugbagold Twins: Ilé ẹjọ́ fi afurasí méje pamọ́ sọ́gbà ẹ̀wọ̀n lórí ẹ̀ṣún ìjọmọ́gbe 7 Owewe 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 8 Owewe 2020 Oríṣun àwòrán, Akeugbagold/Facebook Ile ẹjọ Majisireti kan to kalẹ silu Ibadan ti paṣẹ pe, ki awọn afurasi mejeeje ti wọn fẹsun kan pe wọn ji ibeji Aafa Taofeek Akeugbagold gbe lọ fara pamọ sahamọ.
“Ògo fún Ọlọrun lókè ọ̀run,alaafia ní ayé fún àwọn tí inú Ọlọrun dùn sí.
Idije naa kọja ere bọọlu laarin ikọ agbabọọlu kan si ikeji, oju ọpọlọpọ lo maa wa lara awọn obinrin ti wọn nii ṣe pẹlu awọn gbajugbaja agbabọọlu ti wọn n kopa ninu idije agbaye ni Russia.
Ǹjẹ́ ó jẹ́ wá sí àjọ̀dún yìí?
O gboriyin fun gbogbo awon alatileyin lori eto yii, o ro awon obi ati a;agbato lati gbe omo won sita fun abere ajesara naa.
62 Àti pé àwọn àpéjọpọ̀ tí a sọ yìí ni yíò máa ṣe èyíkéyìí iṣẹ́ ìjọ tí ó bá yẹ ní ṣíṣe ní ìgbà náà.
Koda, opin ọsẹ to lọ ni ijba gbe ẹsẹ kuro lori ofin isede.
Gomina ipinlẹ Ondo, Rotimi Akereolu ti o jẹ alaga awọn gomina ilẹ Yoruba ni ireti wa wi pe yoo ṣi'ṣọ loju eto naa, ti yoo waye lọọfisi gomina nilu Ibadan.
Ayman Safadi to je minister fun ile okeere ni o bani lokan je pe Washington yowo iranwo ti won n pese fun Palestine sugbon o ni ijoba yoo tubo maa gbiyanju lati maa wa awon oluranlowo miran lati fopin si isoro ti ajo UNRWA n koju bayii fun owo nina.
O fi kun un pe ko si ẹri kankan lọdọ ọlọpaa to fidi rẹ mulẹ pe awọn darandaran fulani lo kọlu James Daniel, ọlọkada naa.
"Ẹ̀yin ọmọ Yorùbá lókè òkun, ẹ má bẹ̀rù mọ́ láti wálé - Akeredolu Ibadan Fire: Iná míràn tún ṣẹyọ nilú Ibadan Ọjọ keje, oṣu Kinni, ọdun 1970 si ni wọn ṣe ifilọlẹ ikọlu ikẹhun ti wọn pe ni ""Operation Tail-Wind""."
Gomina ipinle Plateau Simon Lalong, lo sọ eleyii di mimọ  nigba to n ba awọn oniroyin sọrọ niluu Abuja.
Àlejò àpàndodo ni Fayoṣe, a kò fìwé pèé - Afuye Ọkọ̀ òfúrufú ọlọ́pàá yóò bẹ̀rẹ̀ sí ní káàkiri Naijiria - Ọgá Ọlọ́pàá N650,000 péré ni mò ń gbà gẹ́gẹ́ bíi owó oṣù -Gomina Ọyọ Ṣe ẹ ti gbọ́ ri?
Ọlọrun ìbá ya ẹnu rẹ̀,kí ó sọ̀rọ̀ sí ọ.
Ranti mi, kí o sì ràn mí lọ́wọ́.
Ati lati mọ awọn to jẹ alatilẹyin wọn.
Ọsọọsẹ tabi osoosu ni Olotu ijọba isejọba amofin yoo ma jabọ fun awọn ara ilu, eleyii ti ko wọpọ ni isejọba aarẹ.
ABAJADE ESI IBO AARẸ TI ỌDUN 2019 Ademola Adepoju.
” Ṣugbọn wọ́n dáhùn pé, “Ó tì o!
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ondo: Dejí sun ọmọ méje àtagbalagba meji mọ́lé nítorí pé ó ń bínú Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Wo ìròyìn, àwòrán àti fídíò èké nípa ìwọ́de EndSARS Oríṣun àwòrán, Getty Images Owe Yoruba kan lo ni ọrọ okeere, bi ko ba lekan, yoo dinkan ni.
Ni Oṣu Keje, ọdun 2018 ni ijọba orilẹede Cameroon sọ wi pe awọn soja naa kii ṣe ikọ ọmọogun wọn, ati wi pe orilẹede Mali ni iṣekupani naa ti waye.
Ègún ọ̀dá owó yóò jà yín, tẹ́ ẹ̀ bá san ìdá mẹ́wàá - Oyedepo Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Daddy Freeze s'alaye n to faa ti oun fi n tako idamẹwa Ninu fidio naa, Freeze sọ pe ọmọ ale ni ẹnikẹni to ba sọ pe Jesu lọwọ nigba aye rẹ.
Lẹyin naa ni Emmanuel fi ọbẹ naa gun ara rẹ ni ikùn.
Amọ, awọn eeyan ti bu ẹnu ẹtẹ lu ofin naa pe o ti l'agbara ju, ati pe awọn awọ̀n alaṣẹ ijọba ko tẹle ilana to yẹ.
Lori eyi Lizzy ṣi tẹsiwaju lati maa tẹnu mọ ọ pe o da oun loju pe ile alagbo ọmọ lo bimọ si.
Oríṣun àwòrán, Musictori Àkọlé àwòrán, Ori pepele yii ni akọsilẹ itan miran yoo tun ti waye nigba ti Buhari ba ṣe ibura fun saa keji lori rẹ Oríṣun àwòrán, Musictori Àkọlé àwòrán, Ori pẹpẹ yii ni eto ibura yoo ti waye fun aarẹ Buhari lọla Oríṣun àwòrán, Musictori Àkọlé àwòrán, Alaga ọlọla ree fun awọn alejo pataki ti yoo peju sibi ibura aarẹ Muhammadu Buhari Oríṣun àwòrán, Musictori Àkọlé àwòrán, Ẹni atẹẹka to wọle sibi gbagede ibura ree ti aarẹ atawọn eeyan pataki miran yoo gba kọja Oríṣun àwòrán, Musictori Àkọlé àwòrán, Awọn ohun ase ibudo lọṣọ ti wa nikalẹ nibi ibudo ayẹyẹ ibura Oríṣun àwòrán, Musictori Àkọlé àwòrán, Ẹni ti yoo jẹun gbọin-gbọin yoo tilẹkun gbọin-gbọin lọrọ ipese eto aabo ni ibudo ibura ti yoo waye lọla Oríṣun àwòrán, Musictori Àkọlé àwòrán, Ilu Abuja ti dun wo pẹlu oniruuru aramọnda ọṣọ to gba oju popo kan BBC News, Yorùbá Ìdí tí ẹ fi le è nígbàagbọ́ nínú ìròyìn BBC Ìlànà Lílò Nípa BBC Òfin Àṣírí Cookies Kàn sí.
Ọjọ Satide, ọjọ kọkandinlọgbọn, oṣu Kọkanla, ọdun 2020 ni awọn ọmọ ẹgbẹ Boko Haram ṣekupa awọn eeyan mẹtalelogoji lagbegbe Marrabati ati Hammayya, lẹba ijọba ibilẹ Jere, ni ipi9nlẹ Bornu.
“Ẹni to jẹ ọkọ fun mi leni, Ọlọrun lo yan an fun mi bo tilẹ jẹ pe gbogbo ẹbi mi lo yari pe mi o le fẹ arara”.
Nítorí ọkunrin kò wá láti ara obinrin; obinrin ni ó wá láti ara ọkunrin.
Oríṣun àwòrán, Facebook Àkọlé àwòrán, Ni ọjọ keje, osu keje, ọdun 2013, Raji Fashola lasiko to si wa ni ipo gomina Eko lọ ra ọgẹdẹ sisun ti wọn n pe ni boli lasiko ipolongo.
Nígbà tí ó parí, ọ̀kan ninu àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ sọ fún un pé, “Oluwa, kọ́ wa bí a ti í gbadura gẹ́gẹ́ bí Johanu ti kọ́ àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀.
Wọ́n bi í pé, “Sọ fún wa, nítorí ta ni nǹkan burúkú yìí fi dé bá wa?
Ẹkẹta ń jẹ́ Basemati ọmọ Iṣimaeli, arabinrin Nebaiotu.
Ṣé lóótọ́ làwọn ìwà kan wà tó burú ju àlè yíyàn nínú ìgbéyàwó?
Obayi  n soro, o salaye pe o to  eniyan milionu merindinlogoji lo jẹ afoju lagbaaye
ibà zika , ( àrùn ibà zika ) tí a túnmọ ̀ sí àrùn àkóràn zika , jẹ ́ àìsàn tí Àkóràn zikańfà.
Osun Election 2018 : Ilé ẹjọ́ ní Adeleke kò lẹ́tọ̀ọ́ láti díje dupò gomina
O fikun ọrọ rẹ pe, ninu ọkọ itọju alaisan pajawiri taa mọ si ambulance lawọn afurasi meji ọhun kọkọ ko oogun naa si.
Ẹni tí kò náání ìbáwí tàbùkù ara rẹ̀,ṣugbọn ẹni tí ó bá gba ìmọ̀ràn yóo ní òye.
Lẹ́hìn tí àáké yìí dúró, mó tún rí ọwọ́ yìí, ó lọ ata ó sì mú ata náà ó ń fi ra ojú ọgbẹ́ ọkùnrin yìí, ọkùnrin náà sì tún ń sá kiri, àyà mi sì já tó bẹ́ẹ̀ tí mo fẹ́rẹ̀ sá jáde.
Ẹ yé irọ́ pa, mí o fún Super Eagles ní ẹbùn owó kánkan -Sanwo Olu Èyí ni ọ̀nà tí àwọn obìnrin n gbà kó ara wọn sí wàhálà nítorí ara bíbó Awọn miran n fi oju sunnukun wo ọrọ Remi Tinubu pe, ṣe o ṣeeṣe fun awọn aṣojuṣofin lati daabo bo ara wọn gẹgẹ bii ibeere Remi Tinubu Ni ipari awọn kan gba pe onile ni lọwọ, alejo naa di mẹru ni ọrọ awọn mejeeji Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Ọkan lara awọn oludije fun ipo gomina nipinlẹ Eko, Omolara Adesanya sọ pe ''oṣi to n ba wa finra, ko farapamọ rara.
Alukoro ileeṣẹ ọlọpaa ipinlẹ Ondo, Tee-Leo Ikoro, ti fidi rẹ mulẹ fun BBC Yoruba salaye pe, ilu Akure n gbona giri laarọ oni nitori awọn oluwọpde End SARS tó dí gbogbo oju ọna.
Àjọ NEMA fèsì ẹ̀sùn táwọn aṣòfin fi kan Ọṣinbajo Ọdún mẹ́tàlélógún lẹ́yìn ikú Ken Saro-Wiwa NAFDAC: Ẹ yàgò fún ẹwà ti wọn fi oògùn apakòkòrò sinu rẹ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Tony Elemelu Foundation: Gbogbo okòwò ló ní ìdojúkọ Banky W.
 O wa kere tan, o yẹ ki wọn le wa ni ipo Agbaninimọran Pataki fun Ijoba ‘(Advisory Capacity)’ ninu iwe-ofin.
Diẹ lara awọn obinrin naa ko tiẹ wa a gbadun nkankan mọ nipa ibalopọ.
Ifẹsẹwọnsẹ pẹlu Watford ati Newcastle ni mo gba kẹyin ninu oṣu Kejila, ti mo tun fi n ni inira.
Igbesẹ aarẹ lati buwọlu ''June 12'' waye ni ọjọ meji peri si ọjọ kejila oṣu kẹfa tii ṣe Ọjọru.
Wọ́n bá yan Juda tí à ń pè ní Basaba ati Sila, tí wọn jẹ́ aṣaaju láàrin àwọn onigbagbọ.
Igúnnugún tí í jẹun ẹbọ gbé
Nítorí ti ìrètí yìí ni a fi gbà wá là.
n ba awon oniroyin soro  yii, nile ise ajo
Lẹ́yìn náà, ṣe òrùka wúrà meji fún pẹpẹ náà, jó wọn mọ́ abẹ́ ìgbátí rẹ̀ lẹ́gbẹ̀ẹ́ kinni keji, àwọn òrùka náà ni wọn yóo máa ti ọ̀pá bọ̀ nígbà tí wọ́n bá fẹ́ gbé pẹpẹ náà.
Ekiti Oba Crisis: Ọọ̀ni ṣalàyé ìdí tí ààwọ̀ àwọn ọba Ekiti fi yàtọ̀ sí ti ẹ̀ẹ̀yà míràn
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Obateru Akinruntan: Wíwá ohun tá jẹ títí láé ló gbé wa kúrò nílé Ife Bawo ni awọn eewọ wọnyii ṣe kan Ọọni Ile ifẹ ati Arẹmọ rẹ?
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Pius Adesanmi: Òní ni ẹ̀bí akọni Pius Adesanmi n ṣètò ìkẹyìn fún ogbontarigi náà 26 Ọ̀wàrà 2019 Oríṣun àwòrán, @Pius Àkọlé àwòrán, Ilẹ n jẹ eeyan!
OLUWA, gbà mí lọ́wọ́ àwọn ẹni ibi;dáàbò bò mí lọ́wọ́ àwọn oníwà ipá;
Ninu atẹjade ti kọmiṣọna ọrọ to n lọ, Donald Ojogo fi ṣọwọ si awọn akọroyin, o ni gomina Rotimi Akeredolu ti dari awọn agbofinro lati bẹrẹ iwadii lori ohun to fa iṣẹlẹ naa.
Ohun Gbogbo ni Ó ní Àkókò Tirẹ̀.
Mo gbé àwọn nǹkan ribiribi ṣe: mo kọ́ ilé, mo gbin ọgbà àjàrà fún ara mi.
Kò sì sí èrè ninu pípa òfin rẹ̀ mọ́ tabi ninu rírẹ ara wa sílẹ̀ níwájú OLUWA àwọn ọmọ ogun.
13 Ògún 2019 Oríṣun àwòrán, @GboyegaOyetola Àkọlé àwòrán, Awọn kọmiṣọna labẹ iṣejọba ana lo n dele lawọn ileeṣẹ ijọba ni ipinlẹ Ọṣun.
Ko tii si ọna idani pada sipo ti a la kalẹ fawọn ti a n ko bọ lati South Africa - Abikẹ Dabiri.
Ó dàbí ọkunrin kan tí ó ń kọ́ ilé, tí ó wa ìpìlẹ̀ rẹ̀ tí ó jìn, tí ó wá fi ìpìlẹ̀ rẹ̀ lé orí àpáta.
Oluwo, Olúgbò àtàwọn Ọba alayé míì ṣàbẹ̀wò sí Gómìnà ìpínlẹ̀ Eko, Oba ìlú Eko àti Bola Tinubu
O sọ idi ti Oloye MKO Abiola fi fẹ jẹ aarẹ Naijiria nigba naa lọhun.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Iya Rainbow: Ó yẹ́ ká máa yẹ́ àwọn onítíátà sí ní ààyè, kìí ṣe òkú wọn 14 Ògún 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 16 Ọ̀wàrà 2020 Oríṣun àwòrán, Iya Rainbow Yoruba ni baa ku laa dere, eeyan ko sunwọn ni aaye.
N óo yí àsè àjọ̀dún yín pada sí ọ̀fọ̀, n óo sọ orin yín di ẹkún; n óo sán aṣọ ìbànújẹ́ mọ́ gbogbo yín nídìí, n óo sì mú kí orí gbogbo yín pá; ẹ óo dàbí ẹni tí ń ṣọ̀fọ̀ ọmọ rẹ̀ kanṣoṣo, ọjọ́ náà yóo korò ju ewúro lọ.
Orúkọ rẹ̀ wá di yẹ̀yẹ́ láàrin àwọn obinrin nígbà tí ìdájọ́ dé bá a.
Lọwọ-lọwọ bayii, ọpọ olugbe adugbo naa lo ti n ko ẹru wọn kuro ni adugbo naa, ta si tun kofiri ọkọ ofurufu to n paraaro adugbo ọhun, aibaamọ, isẹlẹ naa le tun fọn ina soju.
 Inu mi dẹ dun pe titi ti wọn fi papoda, n ko jinna si wọn, awọn naa ko si fi mi silẹ ninu gbogbo ipo akoso ti mo dimu, wọn maa n gba mi niyanju, ko dẹ si gbogbo ayẹyẹ ti mo ṣe nigba ti mo wa ni gomina, ti wọn kii wa.
 Timo Boll omo ile Germany wa ni ipo keji; Dimitrij Ovtcharov si bo sipo kerin loni itele n tele.
Kò sí ohun tí ó kù àfi kí ẹ kú lójú ogun,tabi kí ẹ ká góńgó láàrin àwọn tí wọ́n kó lẹ́rú.
Ayaba to ba si n lewaju awọn olori yoku ni yoo fi igba kekere, to dori kodo sinu omi siwaju.
Lẹ́yìn tórí yọọ́ nínú ìjambà ọkọ̀; Ọ̀jọ̀gbọ̀n Pius Adesanmi kú nínú ìjàmbá bàálù Ethiopia!
Moyo Onigbanjo Arabinrin Uzamat Akinbile-Yusuf, Ọgbẹni
Kọmisọna fun eto ẹkọ, imọ sayẹnsi ati iṣẹ ẹrọ, Olasunkanmi Olaleye ni awọn akẹkọọ ni ileewe Alakọbẹrẹ ati Girama ti wọn ti fẹ kẹkọ jade, yoo bẹrẹ ileewe pada ni oni, Ọjọ Aje, Ọjọ Kẹfa, Oṣu Keje, ọdun 2020.
Usaya bí Jotamu, Jotamu bí Ahasi, Ahasi bí Hesekaya.
Awọn wọnyii lo si ba wọn 'pe ejo naa jade' ninu awo iyagbẹ naa to wa.
Awọn agbofinro Paris ni iṣẹ iwadii ti bẹrẹ lori ohun to le fa ijamba ina naa.
O sàlàyé pé àwọn yárá fi afurasí ọ̀hun sọwọ́ sí olú ilé iṣẹ́ ọlọ́pàá ní Benin nígbà ti àwọ́n gbọ́ pe àwọn akẹgbẹ́ rẹ fẹ́ wá fípa gbà á kúrò ni agọ́ ọlọpàá.
“Nítorí náà, ohun tí OLUWA wí nípa ọba Asiria ni pé, ‘Kò ní wọ inú ìlú yìí, kò sì ní ta ọfà sí i.
O ni eyi ṣe koko ninu ẹkọ wọn ní ilé ẹ̀kọ́ ìgbáradì àjọ náà.
Ẹgbẹ agbabọọlu Man City lo jawe olubori ninu abala akọkọ ere bọọlu ọhun ni papa iṣere Santiago Bernabeu.
Wo ipa tí ìlànà tuntun tí ìjọba Eko gbé jáde lórí Covid-19 yóò nìí ní ìgbésí ayé rẹ Àrùn Coronavirus ti mú ẹ̀mí ẹni àkọ́kọ́ lọ nílẹ̀ Madagascar Ọwọ́ ọlọ́pàá tẹ 'ọba alayé' àti ọmọ rẹ̀ tó fi ipá bá ọmọ ọdún mẹ́rìnlá lòpọ̀ l'Ọ́ṣun Ta ló da 'ewé' bo N4.
Aṣofin Ọbasa wa pa a laṣẹ fun Akọwe-agba Ile naa, Ọgbẹni Azeez Sanni lati fi iwe ikini-ku-oriire ranṣẹ si Ọba Eleko ti Eko, Ọba Riliwan Babatunde Akiolu  fun ti ayẹyẹ ọdun kẹẹdogun wọn lori aleefa, lorukọ Ile Igbimọ Aṣofin Ipinlẹ Eko.
Super Eagles ti mbọ̀ wálé Micheal Jackson pàdánù bàbá rẹ̀ Oju àwọn tó gbẹ̀mí awọn olólùfẹ́ OOU rèé Wo bó se ń lọ nínú ìdíje Russia 2018 'Èmi ò kí ń lu ìyàwó mi' Mercy Aigbe: Èmi ni ìyá onílé tuntun Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí 2 sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 2:23 Fídíò, Water Generator: Ó leè ṣiṣẹ fún wákàtí mẹfà, kó tó sinmi, Duration 2,2310 Òkùdu 2020 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
O jẹ ẹrọ funra rẹ ti ọlọrun da.
Kòkòrò ti jẹ gbogbo aṣọ yín.
Gẹ́rẹ́ ti Ẹkùn tu Ọ̀bọ silẹ̀, ó lo agbára diẹ ti ó kù lati sáré gun ori igi lọ lati gba ara lowo iku ojiji.
Nkan gbona janjan bi amala gbigbona lasiko ti ẹgbẹ agbabọọlu Chelsea ati Arsenal koju ara wọn ni aṣekagba idije FA Cup.
Gbogbo aayan rẹ lati salaye bi owo naa ṣe jẹ si lo ja si pabo.
Peteru bá sọ fún Jesu pé, “Oluwa, kì bá dára kí á máa gbé ìhín.
Ṣé OLUWA ti jẹ wọ́n níyà bí ó ti fìyà jẹ àwọn tí ó jẹ wọ́n níyà?
Gege bi awon egbe oselu alatako se so, won ni erongba aare Macky Sall ni lati se adinku ati isakoso eto idibo to n bo lo na lodun 2019.
Abimeleki bá dá a lóhùn, ó ní “N kò mọ ẹni tí ó ṣe bẹ́ẹ̀, o kò sọ fún mi, n kò gbọ́ nǹkankan nípa rẹ̀, àfi bí o ti ń sọ yìí.
ile-ise  oloopa loju pe gbogbo ekun  Gusu yii ti setan lati fowosowopo pelu re ninu
Ageku ejo Boko Haram si n soro bii agbọn Nibo l'akẹkọbirin Dapchi to ku wa?
Nítorí Ọlọrun fẹ́ aráyé tóbẹ́ẹ̀ tí ó fi Ọmọ bíbí rẹ̀ kanṣoṣo fúnni, pé kí ẹnikẹ́ni tí ó bá gbà á gbọ́ má baà ṣègbé, ṣugbọn kí ó lè ní ìyè ainipẹkun.
Bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé ẹ ti mọ gbogbo nǹkan wọnyi, sibẹ mo fẹ́ ran yín létí pé lẹ́yìn tí Oluwa ti gba àwọn eniyan là kúrò ní ilẹ̀ Ijipti tán, nígbà tí ó yá, ó tún pa àwọn tí kò gbàgbọ́ run.
Ààrẹ Buhari ti fawọ kónile -ogbéle wálẹ díẹ̀ ní Eko, Ogun ati Abuja Mo ṣetán láti ta ilé tí mo ń gbé, kí n le rí àwọn ìbejì mi padà - Akeugbagold Kí ló fà ogun Ìjàyè àti ìṣubú Kurunmi, ìfẹ́ ìlú ni àbí orí kunkun?
ọgbọ́nb Olódùmarè ta ìmọ̀ ènìyàn yọ.
‘Wo ohun tó yẹ kóo mọ̀ nípa àrùn onígbá-méjì’ Èyí tí a wò jùlọ 5:03 Fídíò, Omolola Arohunmolase Welder: Mo ti fí iṣẹ́ 'Welder' gbayì láwùjọ, tó mo fi tọ́ ọmọ yanjú, Duration 5,039 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 5:39 Fídíò, Akomolede ati Asa lori BBC: Olùkọ́ Kikelomo Ogunboye tan ìmọ́lẹ̀ sí ìwà olè ọ̀gá ọlọ́pàá Audu gẹ́gẹ́ bí àwòkọ́ṣe àsìkò yìí, Duration 5,398 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 4:11 Fídíò, Oba Adeyeye Ogunwusi: Ojú mi ti rí lọ́pọ̀ lọpọ̀, ọ̀pọ̀ èèyàn ni kò tilẹ̀ gbàgbọ́ pé mo lè jọba- Ooni, Duration 4,117 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 4:43 Fídíò, Promise Akinlade: ọmọ ọdún mọ́kànlá tó ń fi ìlù dárà bíi àgbàlagbà sọ̀rọ̀ nípa tálẹ́ǹtì rẹ̀, Duration 4,437 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 0:59 Gbọ́, Ìsẹ̀lẹ̀ jákèjádò orílẹ̀èdè àgbáyé láàárín ìṣẹ́jú kan, Duration 0,59wákàtí 6 sẹ́yìn 7:03 Fídíò, Olumuyiwa Bolade Adedeji Military Bruitality: Bí arákùnrin onípèníjà ara tí sọ́jà lù ṣe dé, Duration 7,035 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 4:45 Fídíò, Yoruba Films: Ẹ̀ẹ́ bẹ̀ mi kúrò láyé ni, mi ò lè kú - Fadeyi Oloro, Duration 4,4526 Èrèlè 2020 2:48 Fídíò, Esther Ajayi: Èmi náà ti borí ìṣòro rí ló ń mu mi ṣojú àánú, Duration 2,481 Ògún 2019 6:08 Fídíò, Adebola Ademilua: Àìrísẹ́ ṣè lẹ́yìn ìwé kíkà ló sọ mi dí ìyá onírú, mo dúpẹ́ tèmi, Duration 6,0827 Bélú 2020 5:55 Fídíò, Soyinka Cancer: Àṣe ara mi ni iso ti n run gbogbo bí mo ṣe n ṣèrànwọ́ lórí jẹjẹrẹ, Duration 5,5527 Bélú 2019 BBC News, Yorùbá Ìdí tí ẹ fi le è nígbàagbọ́ nínú ìròyìn BBC Ìlànà Lílò Nípa BBC Òfin Àṣírí Cookies Kàn sí.
Òun ni ó rán sí wọn gbẹ̀yìn, ó ní, ‘Wọn yóo bu ọlá fún ọmọ mi.
"Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Murphy Elégungun Rọba: Mo fẹ́ di ẹnití egungun rẹ rọ jùlọ ní àgbáyé Onitọhun se haa, to si da Iyalufa lohun pe, ""ASỌ KO BA ỌMỌYẸ MỌ, ỌMỌYẸ TI RIN IHOOHO WỌ ỌJA."
’ rèé Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ọmọ ọdún méjìlá yìí sọ bó ṣe di téélọ̀ táwọn àgbà ń bẹ́rí fún Ninu oṣu kejila, ọdun 1962, Soyinka da ẹgbẹ awọn onimọ Tiata orilẹ-ede Naijiria silẹ.
Yollywood: Wo àwọn òṣèré Yoruba tí wọ́n bí ní ọjọ kan náà
Malami ti kọkọ sọ pe, eto Amọtẹkun tawọn gomina ipinlẹ Yoruba gbe kale ko si ninu iwe ofin Naijiria.
ó lè ṣe iṣẹ́ ìsìn rẹ̀ sí OLUWA Ọlọrun rẹ̀, gẹ́gẹ́ bí àwọn ọmọ Lefi ẹlẹgbẹ́ rẹ̀ yòókù, tí wọn ń ṣe iṣẹ́ ìsìn wọn níbẹ̀ níwájú OLUWA.
naa logun, nitori yala obinrin n bimo lera- lera tabi o tete n loyun tabi ti o
pé ẹ ti fi ẹ̀mí ara yín wéwu nítorí ìṣìnà yín.
daabo bo emi ati dukia tolori –telemu, omo bibi ati olugbe ipinle Oyo.
Nígbà tí o ṣe, wọ́n dé ibi odò kíkùn kan, ọmọ ọba gbé ẹrù kọjá sí òdì kejì, àfi bí ọmọ ọba náà bá tún gbé òun, ọmọ ọba ṣe bẹ́ẹ̀.
 Opo lara awon ti o ba isele ohun lo ni awon oluworan ololufe bolus,”  “A nigbagbo pe, omo ogun olote al Shabaab lo wa ni idi isele yii, bee si ni o farahan pe ero igbalode latona ti a mo si (remote control), ni won lo lati fi dari ado oloro naa,”  Omo ogun olote Al Shabaab lo n ja ijagbara lorile-ede naa lati da ijoba ti won sile, ni oye ti ti won ti won tunmo si ofin islam.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Naijiria: Ẹ wo iyé minisita tó ti kòwé fipò sílẹ̀ lásìkò Buhari 13 Ọ̀pẹ̀̀ 2018 Oríṣun àwòrán, @MBuhari Àkọlé àwòrán, Ní Ọjọ́ Kejila, Osù Kejila ni minisita fún ọ̀rọ agbèègbè fi ipò rẹ̀ sílẹ̀ láti lọ jẹ́ Emir tí ìlú Nazarawa.
wa ni ipinle naa  ni awon ti ko agbofinro
Hiramu ọba fi àwọn òṣìṣẹ́ rẹ̀ tí wọ́n mọ̀ nípa ọkọ̀ ojú omi, lé àwọn ọkọ̀ náà, ó kó wọn rán àwọn iranṣẹ Solomoni sí i.
Ni ileewosan ni wọn ti sọ fun pe, iṣẹ abẹ ni wọn o ṣe si ẹsẹ naa, nitori pe o kan kọja bo ṣe yẹ lọ.
Ikọ awọn odaran yi ni wọn tun fi ẹsun kan pe wọn n ji epo robi ta lọna aitọ.
CAN: ó pọn dandan kí wọn fágile ìdánwò ọlọ́pàá
Ayálégbé wa tó fi tipá já àbálé mi ṣe àkóbá fún ìgbé ayé mi - Foluke Daramola Ọmọ pupa làwọn olólùfẹ́ wa fẹ́ wò nínú fíìmù làwọn òṣèré tíátà fi ń bóra - Muka Ray Ìjà Awolọwọ, Akintọla àti ogun 'Wẹtiẹ', ẹ̀kọ́ wo ló kọ́ wa?
Ẹ̀rọ ayàwòrán ara ọlọ́pàá fihàn pé ìgbà ogún ni George Floyd pariwo, kó tó kú Iléesẹ́ rẹ́kọ́ọ̀dù tí mo ti bẹ̀bẹ̀ láti kọrin, padà di tèmi lónìí - Ebenezer Obey Ọ̀pá epo NNPC bú gbàmú ní Benin, òṣìṣẹ́ méje kàgbákò ikú òjijì Ọ̀fọ̀ ńlá ṣẹ̀ ní Ivory Coast, Olóòtú ìjọba, Amadou Gon Coulibaly jáde láye Ko pẹ to gbe igbesẹ yii ti awuyeweuye iyọnipo naa bẹrẹ, ti mẹrinla lara awọn aṣofin ile si gbe igbesẹ lati yọ igbakeji gomina ọhun nipo, ṣugbọn mẹsan an lara wọn ni wọn ko ni lọwọ sii.
pataki lowo awon eniyan ipinle Oyo fun bi won se fi ibo won gbee wole, O wa
Bakan naa ni ipinlẹ Bayelsa ati Imo kede lọjọ kẹrindinlọgbọn pe ki awọn ileewe di titi pa, wọn si tun fi ofin de ipejọpọ ọpọ eniyan to ba le ni àádọ́ta.
Ní ìgbà míràn àwọn òbí máa n gbìyànjú láti wo ààrun náà sàn, àwọn obi mi pẹ̀lú gbìyànju wọ́n a ma gún wọ́n ni abẹ́rẹ́ ti o tun le fa ààrun miran si ara ọmọ Liliya ni ioṣẹ́ oun lati maa ran àwọn ọmọ yìí lọ́wọ́ tí mu iwuri ba oun lati ma sisẹ iranwo amuludun.
Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Qdot: Ọ̀rẹ́ mi ni Funmi Awelewa, kò sí ọ̀rọ̀ ìfẹ́ láàrin wa- Fakoya Qudus Oluwadamilare28 Bélú 2020 Adeyeye Ile Ife: Kílódé tí Ọọni Ife, Oba Ogunwusi kò fi gbọdọ̀ rí ọmọ rẹ̀ tuntun títí di ẹ̀yìn oṣù mẹ́fà?
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ọ̀pọ̀lọpọ̀ àwọn tó kẹ́kọ̀ọ́ jáde ní fásitì ní Nàìjíríà lásìkò yìí ló n gba iṣẹ́ olùkọ́ nítorí àìríkan ṣèkan.
O ni ikọ alayẹwo arun ọpọlọ yoo maa ṣe iranwọ fawọn ti yoo ba gba iṣẹ labẹ SWAT.
Ọjọ kẹrinla, oṣu Kejila ni aṣẹ naa yoo bẹrẹ iṣẹ.
OLUWA bínú sí Israẹli, ó sì jẹ́ kí Hasaeli, ọba Siria, ati Benhadadi ọmọ rẹ̀ ṣẹgun Israẹli ní ọpọlọpọ ìgbà.
Àwọn eniyan ń ṣọ́ ìrìn ẹsẹ̀ wa,tóbẹ́ẹ̀ tí a kò lè rìn gaara ní ìgboro.
Ọga INEC sọ pe ajọ naa ko le kede ẹni to jawe olubori lawọn ipinlẹ tọrọ kan yii lai ṣe afikun idibo gẹgẹ bi ofin to de eto idibo ni Naijiria ti sọ.
Inú Tẹmpili ni wọ́n ń wà nígbà gbogbo, tí wọ́n ń fi ìyìn fún Ọlọrun.
Gígé ni yóo gé gbogbo ẹ̀ka ara mi tí kò bá so èso, ṣugbọn yóo re ọwọ́ gbogbo ẹ̀ka tí ó bá ń so èso, kí wọ́n lè mọ́, kí wọ́n sì lè máa so sí i lọpọlọpọ.
"Ẹwẹ, orin ti ọpọlọpọ pada fi n ranti rẹ ju naa ni eyi to kọ ko to ku, ""Wọn Kere si Number"" eleyii to fi ta sáwọn èwe to ba fẹ máa ruga si agba."
" O ṣalaye pe eroja ọbẹ̀ ọdun ni oun lọ ọ ra, ti ọmọ si ti di awati ki oun o to o de, botilẹjẹ pe oun ati awọn ọmọ miran lo jọ n ṣere niwaju ile.
N jẹ mo sọ fun yin bi wọn se n yẹyẹ mi si titi debi pe mo taku lati lọ sile ẹkọ Yunifasiti?
Ogoji ọdún ni o fi bọ́ wọn ninu aṣálẹ̀, wọn kò sì ṣe àìní ohunkohun, aṣọ wọn kò gbó, ẹsẹ̀ wọn kò sì wú.
”Jakọbu bá wí fún un pé, “Jọ̀wọ́, jẹ́ kí wọ́n súnmọ́ mi kí n lè súre fún wọn.
O tun ni wọn maa n ṣafihan awọn nkan to le fa wahala lawujọ ninu eto araarọ wọn ti wọn pe ni Kakaki Social.
N ṣe ni gbogbo ilu naa mi titi nitori ibugbamu ọhun, to bẹrẹ pẹlu ina ni ebute okun kan.
Ogundoyin wa fi asiko naa seleri lati bebe fun
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Àwọn ọmọ Nàìjíríà kan fẹ́ kí ilé ẹjọ́ ó fagilé orúkọ Buhari gẹ́gẹ́ bi olùdíje APC 29 Agẹmo 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Àwọn ọmọ Nàìjíríà kan fẹ́ kí ilé ẹjọ́ ó fagilé orúkọ Buhari gẹ́gẹ́ bi olùdíje APC Awọn ọmọ orilẹ-ede Naijiria mẹta kan ti pe ẹjọ tako Aarẹ Muhammadu Buhari nile ẹjọ to gaju ni Naijiria.
Kọmiṣọna ọlọpa ipinlẹ naa, Edward Ajogun lo fi ọrọ naa lede nigba to n ṣafihan owo ati oogun ọhun, ni olu ileeṣẹ ọlọpaa to wa ni Eleweran, nilu Abeokuta.
fun ila oorun Yobe ni ipinle Yobe ti di abenugan ile igbimo asofin agba kẹ́sán án.
Ọkan lara awọn ẹjọ to gbaju-gbaja nibi igbẹjọ naa ni ti ọkunrin alaabọ-ara kan ti wọn lo kopa ninu bi wọn ṣe ji awọn akẹkọbinrin to le ni igba gbe nilu Chibok, lẹkun ila-oorun ariwa lọdun 2014.
Ẹni ti itan sọ fun wa pe o ko ipa ribiribi nidi idagbasoke, alaafia ati ilọsiwaju awọn Ẹgba ati ilu Abẹokuta, bi o tilẹ jẹ pe kii ṣe oun lo da ilu naa silẹ, gẹgẹ bi awọn eeyan kan se lero Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ìtàn Gbọnka àti Timi, akọni méjì tó borí Aláàfin Ṣango Kíni ìwọ mọ̀ nípa Funmilayọ Ransome-Kuti?
Nítorí náà, ẹ pa òfin OLUWA Ọlọrun yín mọ́, nípa rírìn ní ọ̀nà rẹ̀ ati bíbẹ̀rù rẹ̀.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Pension: Ohun tí o ní láti ṣe kí owó ìfẹ̀yìntì rẹ̀ má wọgbọ́ 3 Ògún 2019 Àkọlé àwòrán, Àwọn òṣìṣẹ́ Ẹgbẹ awọn to ń ṣeto ifowopamọ owo ifẹyinti awọn oṣiṣẹ lorilẹede Naijiria ni awọn ati ri owo gba yoo nira fun awọn to n dawo sọdọ wọn bi wọn ba kọ lati ṣe iforukọsilẹ ori ẹrọ ayelujara.
Ènìyàn Third Mainland Bridge: Ìjọba ìpínlẹ̀ Eko kéde bí àtúnṣe afárá Third Mainland yóò ṣe wáyé Oríṣun àwòrán, others Àkọlé àwòrán, Ọdun 2018 ni wọn ti afara ọhun kẹyin fun ọjọ mẹta lọna ati ṣe iwadii awọn iha to ti n dẹnukọlẹ lori rẹ Ijọba apapọ ati ijọba ipinlẹ Eko ti kede ọna abayọ si sunkẹrẹ-fakẹrẹ ọkọ lasiko ti iṣẹ ba n lọ lori afara Third Mainland ti wọn fẹ tunṣe ni ilu Eko.
Ìwà ati ìṣe yín ni n óo fi da yín lẹ́jọ́.
Lara awọn eeyan to ba ikọ BBC Yoruba sọrọ nile oloogbe ni agbegbe ẹlẹbu nilu Ibadan, ṣe apejuwe ipapoda Alhaji Fẹlẹ gẹgẹ bii adanu nla fun ẹgbẹ NURTW ati ipinlẹ Ọyọ lapapọ.
 Bakan naa, ni igbimo ijoba apapo tun ya owo to
Àdáwọ́lé wọn lè yí wọn lọ́wọ́, wọ́n sì lè fi bẹ́ẹ̀ pàdánù ọrọ̀ wọn, tóbẹ́ẹ̀ tí wọn kò ní lè rí nǹkankan fi sílẹ̀ fún àwọn ọmọ wọn.
Ẹsun naa fa awuyewuye l'oriṣiriṣi jakejado orilẹede Naijiria.
Awọn aladugbo ti wọn ti gbiyanju lati la ija ki ọfọ naa to ṣẹ sọ wipe awọn gbiyanju lati gbe oloogbe naa lọ ile iwosan bi ẹjẹ ṣe n tu lara rẹ ṣugbọn o gbẹmii mi loju ọna.
Oríṣun àwòrán, Oluwo of Iwo Àkọlé àwòrán, Ọba Adewale Akanbi ti ma ń sọ̀rọ̀ nípa ìfìmọsọ̀kan àwọn ẹ̀yà tó wà lórílẹ̀èdè Nàíjíríà Yorùbá bọ wọn ní àrà kì tán ní ilé alárá.
Máfọ́ya, mo wà pẹ̀lú ẹ, Ajimọbi kàn sí Makinde lóri Coronavirus to ni Coronavirus: Àwọn ohun tí a kò tíì mọ̀ nípa àrùn Covid-19 Makinde jẹ ọkan lara awọn gomina mẹta to lugbadi aarun covid-19 ni Naijiria.
Nígbà tí mo jáde tán, mo simi díẹ̀.
Oríṣun àwòrán, Getty Images O ni Iboju to wa lọdọ wa bayii yẹ ko ti pari iṣẹ lati ọdun 2009, awọn kan yẹ ko ti pari iṣẹ lati 2013, ti awọn toku yoo kọṣẹ lọdun 2021, gẹgẹ bi akọle to wa lara rẹ."
BBC Africa Eye: Àwọn ajọ́mọgbé náà kò mọ̀ pé BBC ní wọ́n bá dòwò pọ̀ Ìpínlẹ̀ Eko ní èèyàn 136 nínú èèyàn 152 lápapọ̀ tó lùgbàdì àrùn Coronavirus ní Nàìjíríà Ọlọ́pàá fìyà jẹ mí lọ́dún 2014, mò wà lẹ́yìn àwọn ọ̀dọ́ lórí ìwọde EndSARS- Fayemi Awọn ọlọ́pàá gbòde kan ní Ajah, ọwọ́ tẹ àwọn afurasi tó ń jalè Awọn ololufẹ mejeeji si ku si inu ile ọrẹbinrin naa.
Ṣugbọn ẹni àgbéga títí lae ni ọ́, OLUWA.
FIFA fòfinde akoọ́nimọ̀ọ́gbá Super Eagles nigbakan ri Samson Siasia
Kí ni ìbéèrè rẹ, gbogbo rẹ̀ ni yóo sì tẹ̀ ọ́ lọ́wọ́, àní títí kan ìdajì ìjọba mi.
Ìríwísí àwọn aráàlú bí EFCC ṣe kó afurasí ọmọ yahoo 49 ní Ibadan Ọmọ ọdún mẹ́wàá ń jẹ ìrora lẹ́yìn tí ọ̀gá tì í sínú iná àrò búrẹ́dì Ọmọ ọdún márùn-ún, àgbà mẹ́rin ló bá ìṣẹ̀lẹ̀ ọ̀pá bẹntiróò tó gbiná ní Abule Egba lọ - LASEMA Lalong, Tambuwal, Ganduje ni ilé ẹjọ́ gíga jùlọ kéde bíi gómìnà ìpínlẹ̀ wọn Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Ọ̀rọ̀ tí Jeremaya wolii sọ fún Baruku ọmọ Neraya nìyí, ní ọdún kẹrin tí Jehoiakimu, ọmọ Josaya, jọba ní Juda.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Adeleke fọhùn, 'èmi ni gómìnà tí wọ́n dìbò yàn' Bakan naa, awọn ọmọ ẹgbẹ oṣelu All Progressives Congress to wa nilẹ Amẹrika fi ọrọ ikini wọn ránṣẹ si gomina Oyetola.
gègé ni wọ́n ṣẹ́ tí wọ́n fi yàn wọ́n, nítorí pé, bí àwọn alámòójútó ìsìn ati alámòójútó iṣẹ́ ilé Ọlọrun ṣe wà ninu àwọn ìran Eleasari, bẹ́ẹ̀ náà ni wọ́n wà ninu ti Itamari.
Adari ileeṣẹ ọhun, Beatrice Savadye ni wọn n gbiyuanju ati gba awọn eeyan naa la kurọ lọwọ iwa ipa ti wọn n dojukọ ninu ile wọn.
Ìrètí ń bẹ fún ọ lẹ́yìn ọ̀la,àwọn ọmọ rẹ yóo pada sí orílẹ̀-èdè wọn.
"Ọba Abdulrasheed tẹnu bọ owe lati fi bẹrẹ ọrọ o ni, ""Ọmọ ta o kọ lo n gbe'le ta a kọ ta""."
 ní agbègbè Àkókó , oríṣìíríṣìí èdè àdùgbò tó jẹ ́ ara ẹ ̀ yà èdè yorùbá ni a lè rí , nítorí ìdí èyí , ó ṣe é ṣe kí ọmọ ìlú kan máà gbọ ́ èdè ìlú kejì tí kò ju kìlómítà méjì sí ara wọn .
Muṣi ní ọmọkunrin mẹta: Mahili, Ederi, ati Jerimotu.
Mudasiru Obasa: Òṣìṣẹ́ tó tú àṣírí ilé asòfin rugi oyin
Yoo fa wahala silẹ bi wọn ba kan an ni dandan.
70 Olúkúlùkù ọmọ ìjọ ti Krístì tí ó bá ní ọmọ wẹ́wẹ́ ni ó níláti mú wọn wá sí ọ̀dọ̀ àwọn alàgbà níwáju ìjọ, àwọn tí wọn yíò gbé ọwọ́ lé wọn lórí ní orúkọ Jésù Krístì, tí wọn yíò sì súre fún wọn ní orúkọ rẹ̀.
Wayi o, idande awọn ọmọ ikọ Boko Haram yi lo se pẹkinpẹki pẹlu fọnran aworan tuntun kan ti ikọ Boko Haram fi lede, to se afihan awọn ọmọbinrin Chibok ti wọn ni awọn ko nife lati pada wale mo.
Mi o le fi silẹ, nitori pe ile ti mo ra fun awọn ọmọ mi ni.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Oluwo: Ọọni ran awọn eniyan lati yọmilẹnu 5 Èrèlè 2018 Oríṣun àwòrán, AFP Àkọlé àwòrán, Oluwo: 'Ọọni ran awọn eniyan lati yọmilẹnu' Ija ti o wa laarin Ọọni ti Ilẹ Ife, Oba Adeyeye Ogunwusi, Ojaja Keji ati Oluwo ti Iwo, Oba Abdurasheed Akanbi ti peleke si, lati igba ti wọn ti se'pade awọn Ọba ni Port Harcourt, ni'pinlẹ Rivers.
Lara awọn to wa nibi apero ọlọdọọdun ti Abiola Ajimobi naa ni Ọọni ile Ifẹ, Ọba Adeyẹye Ogunwusi ati Gomina Dapo Abiodun tipinlẹ Ogun.
O ni igbesẹ yii ni lati daabo bo Naijiria kuro lọwọ awọn agbesunmọmi, igara ọlọṣa, awọn onifayaywọ ati awọn to n ko nkan ija oloro wọle.
Dokita Jesuwale fikun wi pe, adiẹ to ba ti ni aisan naa, pipa ni wọn yoo pa wọn, ko ma baa ran awọn yoo ku.
Ó jẹ́ kí àánú wọn ṣe gbogbo àwọn tí ó kó wọn ní ìgbèkùn.
Oríṣun àwòrán, DESIGNED BY STUDIO Àkọlé àwòrán, Sanusi, Emir kẹrinla ilu Kano nibi ayẹyẹ kan Awọn agbẹjọro agba ti Sanusi bẹ lọwẹ ni; Ọjọgbọn Kanyinsola Ajayi, aarẹ ẹgbẹ awọn agbẹjọro Naijiria tẹlẹ ati Abubakar Mahmoud; aarẹ ẹgbẹ awọn agbẹjọro Naijiria bayii, Paul Osuro.
Dipo rẹ, wọn ma n dibọn bi ẹni to n gbadun rẹ.
O to ọgbọn iṣẹju ko too tu u silẹ.
Awọn iroyin ti ẹ lee nifẹẹ si: Aworan aṣa ati iṣe awọn ọmọ Yoruba Soyinka ni awọn ọdọ lokan lati ṣe'jọba Awọn ọdọ tileesẹ BBC ko jọ lati maa se bẹbẹ loju opo BBC Yoruba yi yaayi pupọ nitori wọn ni ọgbọn atinuda lati da ara.
Lẹ́yìn náà, pa akọ mààlúù náà níwájú OLUWA lẹ́nu ọ̀nà àgọ́ àjọ.
Sùgbọ̀n ẹyìn-ò-rẹ́yìn ìfẹsẹwọ́nsẹ Super Eagles pẹ̀lú Guinea eyí ti wọ̀n gbá àmi ayò kan si odo lẹ́yìn ti wọ́n sọ ọ̀pọ́ ànfani nu lóri pápá.
"ìwé À-kà-kọ ́ gbọ ́ n dèbó kọ ̀ tun Àbíkú "" Àròfọ ̀ òṣèlú nàìjíríà olówó ológun "" dá lé lórí àbíkú."
Èyí èkínní jókòó lórí àga didáda kan, ó wọ ẹ̀wù àrán àti ṣòkòtò àrán ó sì dé fìlà àrán tí ó dà bí adé bẹ́ẹ̀ ni bàtà ẹsẹ̀ rẹ̀ dà bí góòlù, ẹ̀wù pẹ̀lú ṣòkòtò rẹ̀ sì lẹ́wà púpọ̀, ọkùnrin náà dà bí ọba, ó sì yà mi lẹ́nu láti bá irú arẹwà bẹ́ẹ̀ nínú ilé òbùrẹwà ẹbọra.
Ṣefa ni akọ̀wé gbọ̀ngàn ìdájọ́ rẹ̀.
" Mo ri i tí wọ́n n dáná sun àwọn ṣọ́ọ̀bù kékèéké tó wà ní ẹ̀gbẹ́ ojú pópó.
Mo ti sọ̀rọ̀ ìṣípayá, mo ti gba eniyan là,mo sì ti kéde,nígbà tí kò sí Ọlọrun àjèjì láàrin yín;ẹ̀yin sì ni ẹlẹ́rìí mi.
OLUWA bi Abrahamu pé, “Èéṣe tí Sara fi rẹ́rìn-ín, tí ó wí pé, ṣé lóòótọ́ ni òun óo bímọ lẹ́yìn tí òun ti darúgbó?
Èéfín gẹnẹratọ: Iléẹjọ́ ní kí ayálégbé san ₦2m owó ìtanràn
Nígbà tó ń mẹnuba diẹ ninu ìṣòro tí Toyin tí là kọjá, alukoro àti Alakoso fún osere-binrin náà, Sam Olatunji kéde pé ọpẹ ló yẹ fún Ọlọ́run.
Gẹgẹ bi ọrọ rẹ, ohun kan to le mu ki ajọ naa o kẹsẹ jari lori eto igbaniwọle fawọn to ba fẹ ba a ṣiṣẹ ni lati ko awọn olori ikọ alaabo oju lalakan fi n ṣọri atawọn alaabo ibilẹ gbogbo lẹsẹ kuku mọra.
Minisita salaye pe, igberu ti o ba awon eka ti kii pese epo-robi gbe peeli bi 1.
fakere eleyi to maa n waye ni agbegbe Apapa ni ipinle Eko.
Buhari yoo se ifilọlẹ rẹ ni ile-ẹkọ
Ile-ise omo ogun ofurufu orile ede Amerika ni baalu meji.
Taiwo Akinkunmi, ọmọ Ibadan tó ya àsìá Nàíjíríà O fí kún un pé adarí àgbà NBC sí mínísità tẹ́lẹ̀rí lọna láti buwọlu lílo owó ìjọba láti maa sagbátẹru ilé iṣẹ́ aládanil.
 ""Lootọ ni ipo ti Naijiria wa bayii ko dun mọ mi ninu, amọ erongba mi ni pe alaafia nikan ni a le fi mu ki ayipada o wa."
Papapkọ ofurufu Muritala Muhammed ni Ikeja nipinlẹ Eko ni wọn maa balẹ si.
Ọlọ́pàá tó mú àwọn obinrin wọ gau -Ọ̀gá ọlọ́pàá Ọlọ́pàá yọ Yomi Shogunle kúrò ní adarí ẹ̀ka PCCRU Bournemouth fi àáké da Tottenham lágbo nù ní eré ìje fún Champions league Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí kan sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
Ikọ ọlọpaa si fikun wi pe ọlọpaa to ba ṣe aṣemaṣe yoo fi oju wina ofin laarin wakati mẹrindinlogun.
Hesekaya bí Manase, Manase bí Amosi, Amosi bí Josaya.
- Kemi Afolabi Akẹ́kọ̀ọ́ Ilaro Poly tó pegedé jù jẹ ẹ̀bùn iṣẹ́ ọ̀fẹ́ lọ́wọ́ Gómìnà Abiodun Mama Rainbow pe 77 lónìí, àwọn òṣèré tíátà kọrin re kìí Èmi àti Saheed kìí ṣe ọmọdé, a ti jọ ṣe Sinimá papọ̀, èyí túmọ̀ sí pé ìjà ti parí - Fathia Balogun Ta ni Funke Adesiyan?
Akonimoogba agba iko agbaboolu Super Eagles, Gernot Rohr ti safihan ohun pataki ti oun ri lara asole akoko iko ohun, Francis Odinaka Uzoho, ti oun fi yan gege bi asole iko ohun akoko, bee si ni O tun fi mule pe, iko Super Eagles ko ni isoro asole rara.
O ni laiku ẹgiri, ẹnikan kii fawọ rẹ ran gbẹdu ni ọrọ oun o.
Lọjọ Aje to ọsẹ to lọ, eeyan mẹta lo padanu ẹmi wọn nigba ti awọn ọmọ ilẹ South Africa n fi ẹhonu han ti wọn si ba ọpọlọpọ sọọbu to jẹ tawọn eeyan ilẹ okere jẹ.
Nígbà tí wọ́n bẹ̀rẹ̀ sí rú ẹbọ náà, àwọn akọrin bẹ̀rẹ̀ sí kọrin sí OLUWA pẹlu fèrè ati àwọn ohun èlò orin Dafidi, ọba Israẹli.
Lara awọn ẹjọ ti wn pati naa la ti ri eyi ti ileẹjọ giga ni ki wọn ṣẹṣẹ bẹrẹ igbẹjọ wọn lati ibẹrẹ pẹpẹ, ati eyi ti adajọ ni ki awọn igbẹjọ wọn tẹsiwaju ni ọdun to n bọ.
Èèyàn mẹ́rin péré ló ní àrùn Coronavirus ni Ọjọ́ Satidé Ajọ to n ri si igbogun ti ajakalẹ arun lorilẹede Naijiria, NCDC fi sita loju opo Twitter rẹ eniyan mẹrin lo lugbadi arun Coronavirus ni Ojọ Satide ni ilu Kano.
Ojisẹ Ọlọrun naa ni oludije fun ipo aarẹ mii lati ẹkun ariwa Naijiria ni Buhari yoo fa akoso Naijiria le lọwọ lẹyin ibo gbogbo gboo ọdun 2023.
Lasiko to n ba BBC Yoruba sọrọ, alukoro fun ileesẹ ọlọpa nipinlẹ Ọyọ, Olugbenga Fadeyi salaye pe ohun to mu ki awọn ọmọ onilẹ lọ si adugbo Soka lọjọ naa ko sẹyin ilakaka wọn lati fidi idajọ ileẹjọ to ga julọ mulẹ.
Nígbà tí ọkùnrin náà sì wí báyìí èmi náà kò tún sọ̀rọ̀ nípa ‘rùngbọ̀n onírùngbọ̀n mọ́, mo fi onírùngbọ̀n silẹ̀ kí ó máa gbé ‘rùngbọ̀n lọ.
Abdulfatah Ahmed: Àwọn Kwara fẹ́ dán ilé ọkọ kejì wo ni lásìkò yí
Bí o wí i ní burúkú, ayé á ní o kò wí i ní burúkú
 Ó yàtọ ̀ sí ṣẹ ̀ kẹ ̀ rẹ ̀ ti a kọ ́ kọ ̣ ́ sàlàyé rẹ ̀ nítorí pé a kìí lu aro , koso , àti bẹ ̀ mbẹ ́ síi .
Ọbasanjo ni ti ko ba fi ipọ rẹ silẹ, yoo soro lati ri osisẹ ajọ eleto idibo naa gẹgẹbi ẹni to kunjuwọn fun idibo ọdun 2019, ti kii si se wi pe ijọba to wa lode fẹ lo Amina Zakari lati da oju ibo ru lasiko ibo.
O fi kun ọrọ rẹ pe ki ẹgbẹ oselu APC mu ra silẹ fun ogun ninu idibo Aarẹ ọdun 2019.
Ṣugbọn nisinsinyii, ẹ̀ ń sin ère Sakuti, ọba yín, ati Kaiwani, oriṣa ìràwọ̀ yín, ati àwọn ère tí ẹ ṣe fún ara yín.
OsunDecides: Adeleke kò jáwọn olólùfẹ́ tó fẹ́ wòran ijó rẹ̀ kulẹ̀ Olùdíje fún igbákejì gómìnà fẹ́gbẹ́ ADC ní àwọn yóò pèsè ọ̀pọ̀ isẹ́ l'Ọ́sun Osun 2018: Àwọn aráàlú da ìbéèrè bo àwọn olùdíje ìpínlẹ̀ Ọṣun Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Osun Election 2018: A ti gbaradì de ìdìbò Ọṣun bí ó ti yẹ- Adeoye Eyi n waye gẹgẹbi ìgbáradì ilé isẹ́ ọlọ́pàá fún ètò ìdìbò sípò gomina tí yóò wáyé ní Satide.
Ọba Akanbi, lásìkò to ń bá BBC Yoruba sọ̀rọ̀ ni òun tún máa ń wọ agboolé lọ n'ilu Iwo láti fún àwọn arúgbó tí kò leè jáde nílé ní oúnjẹ.
Rebeka ati àwọn iranṣẹbinrin rẹ̀ bá gun ràkúnmí, wọ́n tẹ̀lé ọkunrin náà.
Arsenal àti Manchester United kọ́wọ̀ọ́ rìn lọ Europa Champions League: Ajax f'imú Tottenham fọn fèrè Ìyá 73 rọ ọmọ ní oúnjẹ dèrò ẹ̀wọ̀n l'Ámẹ́ríkà Man City ti gbayo mọkanlelaadọrun un sawọn ninu ifẹsẹwọnsẹ mẹtadinlogoji ti wọn ti gba ni saa yii nigba ti Liverpool gba goolu mejidindinlaadọrun sawọn.
Mo fẹ́ mọ̀ nípa àwọn ìwo mẹ́wàá orí rẹ̀, ati ìwo kékeré, tí ó fa mẹta tí ó wà níwájú rẹ̀ tu, tí ó ní ojú, tí ń fi ẹnu rẹ̀ sọ ọ̀rọ̀ ńláńlá, tí ó sì dàbí ẹni pé ó ju gbogbo àwọn yòókù lọ.
Lati ibẹ̀, O lọ si ile iwe giga ti Fasiti Ilu Eko nibi ti o ti gba iwe ẹri ikẹkọgboye imọ ijinlẹ Bachelor of Science (Honours) ni imọ ẹkọ idojutofo ni ọdun 1978.
Ọpọ eeyan si n tọ ọ wa pe ko sọ asiri owo rẹ fun awọn nitori awọn naa fẹ dabi rẹ, se aye ki bani ri wahala ẹni, sokoto to balẹ nikan ni ọmọ araye n ri.
Nibi to ti n gba itọju lo ba ri pe ileewosan ọhun ni afurasi to fi ipa balopọ naa wa fun itọju, lo ba bẹrẹ si ni pariwo pe ki wọn o ba oun mu u.
Ogúnpọlá: Ọmọ tí a bí lẹ́yìn tàbí lásìkò ogun.
Nigeria Looting: Àwọn jàǹdùkú dárà, ẹ wo àwòrán àwòdamiẹnu nǹkan tí wọ́n jí gbé
O gbọ̀nà, o lọ gbé òróró fún oriṣa Moleki,o kó ọpọlọpọ turari lọ,o rán àwọn ikọ̀ lọ sí ilẹ̀ òkèèrè,o sì ranṣẹ lọ sinu isà òkú pẹlu.
Ilẹ̀ tí wọn ń gbé bẹ̀rẹ̀ láti Meṣa, ní ìhà Sefari títí dé ilẹ̀ olókè ti ìhà ìlà oòrùn.
Fadaka ati wúrà wọn kò ní lè gbà wọ́n kalẹ̀ lọ́jọ́ ibinu OLUWA.
6 140516 Orilẹede Haiti 233 2.
Oriṣirisi ilu ti Yoruba ni pọ bii: omele, iya ilu, gangan, bata ati bẹẹ bẹẹ lọ.
Saraki ni eyi yoo wa ninu iwe itan, ṣugbọn awọn aṣofin dide lati gba ara wọn silẹ.
Bakan naa loun naa pe fun alaafia laarin awon Isreal ati Palestine ni eyi ti o ti seleri lati satileyin to ye fun Isreal.
Àbí irú mi ni ó yẹ kí ó sá lọ sinu tẹmpili kí ó lọ máa gbé ibẹ̀?
Ọjọgbọn Folashade Ogunsola lo gbegba oroke ninu gbogbo awọn ti wọn dibo yan eyi to waye larin awọn ile igbimọ aṣofin fasiti naa ti wọn fi yan adele.
Asofin Omisore fi kun oro re pe, ijọba oun yoo pese igbe aye irorun, bee si ni igberu yoo tun de ba eto oro aje ipinle naa, eleyi ti yoo fun awon olokoowo nile, loko ati leyin odi lanfaani lati wa da ile-ise sile nipinle naa.
Ṣugbọn awọn miran gbagbọ pe aṣiṣe nla ni yoo jẹ ẹ lati dibo fun Kanye West.
awon agbesunmọmi to n   da awon arinrinajo laamu ni won lee kuro loju
Nítorí nígbà tí èmi pàápàá lọ ṣe ọdẹ nínú Igbó Irúnmọ́lẹ̀ mo rí i pé òun kò gbé ilé ilẹ̀ bí i ti Igbó Olódùmarè mọ́, mo bá a lórí pẹ̀tẹ́ẹ̀sì mẹ́ta tí ó dúró lé orí ara wọn.
Ebi àti ìṣẹ́ kò sí ní Nàíjíríà, kódà a fẹ́ eré ìdárayá láti yọ́ ọ̀rá ara wa - Ìjọba àpapọ̀ Taló ya fídíò ibi tí Aisha Buhari ti ń bínú ní Aso Rock?
 agbara isofin wa lowo ijoba ati ile asofin .
Ó bá lọ sọ́dọ̀ rẹ̀, ó fi òróró ati ọtí waini sí ojú ọgbẹ́ rẹ̀, ó sì fi aṣọ wé e.
" O fi kun ọrọ rẹ pe awọn to wa ninu ile naa lasiko ikọlu ọhun fi ara pa, amọ ẹmi ẹnikẹni ko ba a lọ.
A kọ àwọn orúkọ ẹ̀yà àwọn ọmọ Israẹli mejila sí ara àwọn ìlẹ̀kùn mejila náà.
O ni itiju nla ni ki orilẹede Naijiria maa lọ si orilẹ-ede kekere bi Madagascar fun iwosan aarun coronavirus nigba ti awọn elegbo igi wa ni Naijiria.
Sotitobire: Iléẹjọ́ ṣún ìgbẹ́jọ́ síwájú di ọjọ́ kẹrìndínlógún oṣù Kẹta ọdún 2020
Bẹ́ẹ̀ ni mo kúrò ní ọ̀dọ̀ ọba náà mo sì wá sí ìlú mi.
Èyí wáye lẹ́yìn ti olùpẹjọ ní òun ko ṣe ẹjọ mọ.
Iru awọn iroyin ti ẹ le nifẹ si: Fọlọrunṣọ Alakija: Imọ ṣe koko 'Ara sisan kii ṣe arun' Abẹwo Aarẹ Buhari si Plateau Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Oríṣun àwòrán, APcNG Oluranlọwọ fun Aarẹ Buhari lori ọrọ iroyin, Bashir Ahmad lo fi ọrọ yii lede loju opo ikansiraẹni Twitter rẹ.
Corruption: Ọ̀gá àgbà àṣọbodè ní kíkọ rìbá ṣàfihàn aṣọ́bodè tó ti di àtúnbí
Ó pẹ́ díẹ̀ ni a tún rí àwọn mẹ́ta yìí tí àwọn mẹ́ta yìí tí àwọn jáde níbòmìíràn láti inú iyààrá kan ó sì ya ni lẹ́nu pé ẹni tí o ti kú tún dide, ṣùgbọ́n àti ìgbà tí a rí i tí ẹnìkan tún mú wọn tí ó sọ wọ́n sínú epo gbígbóná, lẹ́yìn èyí, Èṣù wí pé : wò ó àwọn ọlọ́sà jí owó olówó wọ́n yẹgi fún wọn nínú ayé, ìgbà tí wọ́n tún dé ọ̀dọ̀ mi mo sọ wọ́n sínú epo gbígbóná.
Ẹ ta àwọn ará Juda ati àwọn ará Jerusalẹmu fún àwọn ará Giriki, ẹ kó wọn jìnnà réré sí ilẹ̀ wọn.
 Minisita fun ọrọ awọn obinrin, Dame Pauline Tallen, ti amugbalẹgbẹ rẹ, ọmọba Dame Pauline Tallen ṣoju fun sọ pe kii ṣe akoko yii lo yẹ ki awọn dakẹ nitori awọn ohun to n ṣẹlẹ kaakiri agbaye."
‘Ẹ maa kọ ọmọ yin lede Yoruba’ Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí 2 sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
Ó gbà mí lọ́wọ́ ọ̀tá mi tí ó lágbára,ati lọ́wọ́ àwọn tí ó kórìíra mi;nítorí wọ́n lágbára jù mí lọ.
"Kate Evans tó wà lárá awọn to dari ọ̀gbìn Cosmic Crisp Apple ní olu ilu orilẹ-ede America sàlàyé pé ""Crisp apple le koko, o ni ọdiwọ̀n àdun àti ilera, bẹ́ẹ̀ lo ni omí dáradára"" Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ogun Cholera: Ọdọọdún ni àrùn onígbá-méjì máa n ṣọṣẹ́ ní Nàìjíríà-NCDC Kate fí kún un pé ara apple náà kìí tètè bàjẹ bákan náà ni gbogbo èròjà rẹ yóò pé si lára ti o ba wà nínú ẹ̀rọ amómitutu fún oṣù mẹwàá sí méjìlá."
'Budget Padding' Igba miran tun ni asiko ti Aarẹ Buhari atawọn aṣofin kọlu ara wọn ni lori aba owo iṣuna ọdun 2016.
Alárùn ọpọlọ lu àwọn nọ́ọ̀sì àti dókítà agba níléèwòsàn ní àlùdákú Dókítà ọmuti ṣe iṣẹ́ abẹ tó pa olóyún àti ọmọ rẹ̀ Akẹ́kọ́ọ̀ mẹ́tàdínlọ́gọ́ta ni wọ́n ti ko lọ sílé ìwòsàn Kenya Dokita àti Nọ́ọ̀sì fìyà jẹ mí lásìkò tí mò ń rọbí- Alaboyún Ìdí ti mo fi ṣe iṣẹ́ àmúrelé mi lábẹ́ ATM rèé - Dele Ipenija nla ni aisi oṣiṣẹ ilera to to nitori ajakalẹ arun Covid 19 lo ṣokunfa iṣẹlẹ yii.
Ninu iwadi kan to jadi ni ọdun 20117, wọn ni ọgbẹni Dewji ni ọdọmọkunrin tó lówó jùlọ ní Afrika.
Afolabi, ti gbogbo wọn jẹ agbẹjọro agba (SAN).
Ẹka ẹkunrẹrẹ rẹ nibi Ọjọ 26, Osu Keji Ile-isẹ ọmọogun Naijiria sọwipe kosi ootọ ninu ọrọ ti Ijọba ipinlẹ Yobe sọ nipa kiko awọn ọmọogun kuro ni oju poopo lọjọ ti isẹlẹ naa sẹlẹ.
Iko agbaboolu West Bromwich Albion ati Alan Pardew ti fenuko lati fopin si ibasepo won lojo aje(Monday), leyi ti o mu ki aaye akonimoogba iko naa sofo bayii.
 eni toun solori ijoba adajoba ni aunpe ni adobaje tabi oludajoba .
Ipinlẹ Ebonyi naa fi ofin de ipejọpọ ọpọ eniyan, lọjọ kẹtalelogun, ọsu kẹta.
Ẹlòmíràn kàn ṣeré wá láì ní ẹbí kankan tàbí ará nílùú ọba nì.
Yóo ṣa àwọn ọmọ Juda tí wọ́n fọ́nká jọ,láti orígun mẹrẹẹrin ilẹ̀ ayé.
Ẹ má fẹ́ràn ayé tabi àwọn nǹkan ayé.
Tí ó ba jẹ́ pé ìrú àṣìṣe bẹ́ẹ̀ kò yìí ìtumọ tàbí ǹkan ti ìròyín náà lòdí si ìlàna imúṣẹse wa bí àpẹrẹ (àṣìkọ orúkó) à ṣe àyípada lái pe àkíyèsí ẹnikẹni síi.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ó dèèwọ̀ láti sọ ilégbèé di iléèjọsìn l'Ékó Èèyàn mẹ́wàá kú nínú ìkọ̀lù tuntun ni Benue Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
lojuse isẹ won lọdun 2018, ni ami ẹyẹ pẹlu.
Ajọ naa fi kun un pe ko si ẹnikẹni to padanu ẹmi sinu ijamba ina naa.
Iroyin to tẹ BBC news Yoruba lọwọ ṣalaye pe nibi ijoko ile naa to waye ni ọjọ ẹti lawọn aṣofin mejidinlogun to wa nile aṣofin naa.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ìgbà tí Aisha Buhari ti f'ọ̀rọ̀ da ìgboro rú lórí ìjọba ọkọ rẹ̀ Àìle è ka kéú ló sọ mí di Krìstíẹ̀nì - Adewale Ayuba Mọrèmi Àjàṣorò, akọni obìnrin tó gba Ilé Ifẹ̀ sílẹ̀ lóko ẹrú Jesu Oyingbo rèé, pásítọ̀ tó láṣẹ ìbálòpọ̀ lóri ọmọ ìjọ obìnrin Aisha sọ ọrọ naa lọjọbo, ti oju opo Twitter si ti gbana jẹ lori rẹ.
Ọ̀lẹ ènìyàn ní í bẹ̀rù ìṣòro, ìṣòro kò sí níwájú alágbára ọkùnrin, àwọn ènìyàn pàtàkì wo ìdínà bí ẹni pé kò já mọ́ nǹkan rárá, bẹ́ẹ̀ ni òkè dà bí pẹ̀ tẹ́lẹ̀ níwájú àwọ alágbára.
Kí ó máa fi èdè àjèjì bá ara rẹ̀ ati Ọlọrun sọ̀rọ̀.
Posi ọkọ ọbọkun ọlọyẹ kan ree ti oku kan n ba lọ sọrun bii ibugbe ikẹyin.
Àwọn àgbà Yorùbá àtijọ́ a máà sọ̀rọ̀ kan.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Fulani Kidnapping: Owó púpọ̀ la san kí wọ́n tó fi mi sílẹ̀ Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
OLUWA mú kí àwọn eniyan rẹ̀ pọ̀ sí i,ó sì mú kí wọ́n lágbára ju àwọn ọ̀tá wọn lọ.
Ìwọ ọmọ eniyan, kígbe, kí o sì pohùnréré ẹkún,nítorí àwọn eniyan mi ni a yọ idà sí;ati àwọn olórí ní Israẹli.
Ẹ hó ìhó ayọ̀, ẹ̀yin ará Jerusalẹmu!
 ‘‘Inu mi  dun si ipa pataki ti e n ko lawujo , e je alagbara fun awon ti ko lagbara, mo gbadura pe ki Olorun san awon oore ti e n se wonyin fun un yin.
Awọn ọmọ meji ninu awọn mẹrin ti Olatunji bi, Folasade ati Modupe Olatunji ṣe apejuwe baba rẹ gẹgẹ bi akinkanju eniyan to si kọ awọn ọmọ rẹ ni ṣiṣe iṣẹ takuntakun lọna ati jẹ ki wọn jẹ akinkanju eniyan nibi gbogbo ti wọn ba de.
Ojemuyiwa wá sọ síwájú sí pé, àwọn yóò bun àwọn akọroyin gbọ padà, nípa ìgbésẹ tó kàn, tí àwọn yóò tún gbé lórí ọ̀rọ̀ náà Corornavirus: Ìjọba ìpínlẹ̀ Oyo ti pàṣẹ ki àwọn òṣìṣẹ́ láti ipele kẹtàlá padà sí ẹnu iṣẹ́ lọ́jọ́ ajé Oríṣun àwòrán, Others Àkọlé àwòrán, Corornavirus: Ìjọba ìpínlẹ̀ Oyo yóò pada si ẹnu iṣẹ́ lọ́jọ́ ajẹ́ Gómìnà ìpínlẹ̀ Oyo Seyi makinde ni àwọn òṣìṣẹ́ ìjọba láti ipele kẹtàlá sókè yóò pada ṣenu iṣẹ́ láti ọjọ́ ajé tọ n bọ, pàápàá jùlọ àwọn to bá dá ọfíìsì ni.
Èèyàn méjìlá míràn kó Coronavirus ní Nàìjíríà Máfọ́, mo wà pẹ̀lú ẹ, Ajimọbi kàn sí Makinde lóri Coronavirus to ni Ǹjẹ́ fífi omi àti iyọ̀ yọnu leè dènà àrùn Coronavirus?
Bí àwọn ènìyàn bá ka ìwé rẹ tí Ọlọ́run Ọba sì ti ibẹ̀ kọ́ wọ́n lọ́gbọ́n èyínì ni pé wíwá sí ayé rẹ ṣe ọmọnìkejì rẹ ní rere.
À ń bi gbogbo iyàn jíjà lórí èké ṣubú, 
"Nitori naa, ""sisun ni ihoho ma n mu ki ibalopọ o waye laarin tọkọ-taya Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?"
Ọkùnrin kan di èrò ọ̀run nítorí pé o fi ẹ̀sùn kan alájọgbélé rẹ̀ pé o n yan ìyàwó ẹnìkan lálè Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí 5:58 Fídíò, Akomolede ati asa Yoruba: Ẹ wá kọ́ nípa àpòtí ìṣura èdè wa lórí BBC Yorùbá, Duration 5,5820 Ògún 2020 6:10 Fídíò, Yoruba Language: Akomolede ati Asa Yoruba tọ̀sẹ̀ yí rèé lẹ́nu olùkọ́ wa, Duration 6,1030 Ògún 2020 Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí 2 sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
"Wo awọn Aàrẹ nílẹ̀ Áfríkà to ti gba oyè ""Field Marshal"" rí Àwọn àwòrán ìrántí tó ń sàmì ogójì ọdún tí Ọba Adesoji Aderemi jáde láyé Àjọ NCDC kéde ènìyàn 626 tó tún ṣẹ̀ṣẹ̀ ní Coronavirus ní Nàìjíríà Wo àdúgbò tó ń jẹ́ orúkọ èèbó amúnisìn tí yóò pa orúkọ dà l’Eko Oríṣun àwòrán, FAAN Airport reopening in Nigeria: Wo ohun tó yẹ kó o mọ̀ tó bá fẹ́ rìnrìnàjò pẹ̀lú ọkọ̀ òfúrufú ní Naijiria Minisita fun eto irinna ofurufu ni Naijiria, Hadi Sirika ti kede igbẹṣẹ tuntun ti awọn to n rinrinajọ gbọdọ tẹle ti wọn ba de papakọ ofurufu ni Naijiria."
Ògì ṣí ṣe fẹ ìmọ́ tótó, nitori eyi, lai si omi, Ògì kò lè ṣe é ṣe.
Nígbà tí wọ́n gbọ́ ohun tí ó bá wá, inú wọn dùn, wọ́n bá ṣe ìlérí láti fún un ní owó.
”Gbogbo àwọn eniyan hó ìhó ìyìn sí OLUWA, nítorí pé wọ́n fi ìpìlẹ̀ ilé OLUWA lélẹ̀.
Wọn a maa pe e ni alajẹ Ogedengbe Agbogungboro.
”Aare tun so pe Tunde Idiagbon kọ lati duro  si orile ede Saudi Arabia , gege bi oba orile ede naa se fun un ni anfaani pe ki  oun ati ebi re kuro ni orile ede Niajiria lati wa si orile  ede Saudi Arabia gege bi alejo pataki.
Amọ, Ajọ Eleto Ilera, WHO ti ke si awọn onimọ Sayẹnsi naa lati fi aaye silẹ fun iwadii kikun lori boya arun Coronavirus le tankalẹ ninu afẹfẹ.
Nítorí náà, ẹ ṣọ́ra kí ohun tí a kọ sílẹ̀ ninu ìwé àwọn wolii má baà dé ba yín:
Òun náà sì dáhùn ó ní, Èmi ni, èmi náà ni, èmi ọkùnrin náà nì.
Ìjànbáforítì tí ara rẹ̀ máa ń le koko ti di ẹni ti ara rẹ̀ rọ̀ tí ó sanra tí ó sì ń dán.
Ewe, awon osise alabo  ko fayegba ki awon asofin wa oko wole, leyin ti okookan won gbe oko sita ti won si fi ese won rin wole.
Awon agbe oniresi ni ijoba ibile Mani , nipinle Katsina ti gborinyin fun ijoba apapo fun ogbon atinuda re lori eto-ogbin, ni paapaa julo, idakoro eto eyawo, ti a mo si Anchor Borrowers Programme (ABP).
Hẹrọdu se àsè ọjọ́ ìbí rẹ̀, ó pe àwọn ìjòyè, àwọn ọ̀gágun, ati àwọn eniyan pataki ilẹ̀ Galili.
Àṣá ò pẹ́ lóko bẹ́ẹ̀ rí ọ̀nà ló pọ̀
A óo pín ọpọlọpọ ìkógun nígbà náà,kódà, àwọn arọ pàápàá yóo pín ninu rẹ̀.
N óo mú kí ọkàn àwọn ará Ijipti le, kí wọ́n sì tẹ̀lé àwọn ọmọ Israẹli wọ inú Òkun Pupa, n óo sì gba ògo lórí Farao ati àwọn ọmọ ogun rẹ̀, àwọn kẹ̀kẹ́ ogun rẹ̀, ati àwọn ẹlẹ́ṣin rẹ̀.
lu ẹgbẹrun lọna ọgbọn naira gẹgẹ bi owo oṣu oṣiṣẹ to kere julọ.
 lẹ ́ yìn èyí ni ó tẹ ̀ síwájú ní ilé-ẹ ̀ kọ ́ girama ti Ìkẹjà , tí ó wà ní oṣòdì , ó tún lọ sí ilé-ẹ ̀ kọ ́ girama Ẹ ̀ wù tun-tun tí ó wà ní máfolúkù ní ìpínlẹ ̀ Èkó àti iké-ẹ ̀ kọ ́ girama orímọládé ní ìpínlẹ ̀ Ọ ̀ ṣun .
82% ọkùnrin ní kó mọ̀ pé òun ní àìsàn jẹjẹrẹ asẹtọ ní Naijiria Mímu ọtí líle àti oúnjẹ oní sítáṣì le è fa àrùn jẹjẹrẹ ọyàn - Onímọ̀ To ba n pẹ jẹun alẹ́, o le ni jẹjẹrẹ ọyan àti asétọ̀ Ẹ fura o!
Atẹ́gùn òjò rán ọ̀pọ̀ lóko àdánù nílùú Ìbàdàn, aráàlú gbarata Wò ohun mẹ́ta tí a mọ̀ tí yóò mú ìjọba pàṣẹ kónílé-ó-gbélé lẹ́ẹ̀kejì ní ìpínlẹ̀ Èkó Àwọn nǹkan tí obìnrin lè ṣe pẹ̀lú olólùfẹ́ oníwà ipá lásìkò ìgbélé Coronavirus yìí Coronavirus: Ǹjẹ́ àwọn dókítà tó ń tọ́jú eyín ń ṣisẹ́ lásìkò pàjáwìrì?
Ninu iroyin ayederu naa, ''Aarẹ Magufuli'' sọ nipa aadọrin eeyan to wa ni orilẹede Tanzania ti awọn obinrin si miliọnu mẹwa ju awọn ọkunrin lọ Ṣugbọn ajọ iṣọkan sọ pe eeyan to wa lorilẹede Tanzania ko ju ọgọta miliọnu lọ, bẹẹ kosi iyatọ to pọ ninu iye ọkunrin ati obinrin Oju ayelujara ti iroyin ayederu naa ti jade le dabi gbajugbaja iwe iroyin Nipashe ni Tanzania.
”Nipa Olori tuntun Shilekunola Moronke:Olori tuntun Kabiesi Oba Enitan Ogunwusi je eni owo ati woli to n tuko ile ijosin En-Herald ti o fi iluu Akure, olu ilu ipinle Ondo se ibugbe.
Ijọba tí júwọlẹ̀ fún Amẹrika lóri iwé ìrìna!
Bukola Saraki: Kí ló dé tí Adams Oshiomole n fẹ́ kó gbé adé APC sílẹ̀?
Bẹẹ sini ṣaaju wọn ti ni Bukola Saraki kò kọjá òfin - EFCC.
Àwọn ògiri rẹ̀ jẹ́ igbọnwọ mẹta mẹta (mita 1½), ní ẹ̀gbẹ́ kinni ati ikeji.
Odumeje: Ǹkan mẹ́wàá ti o yẹ ki o mọ nípa Odumejeje Oríṣun àwòrán, OTHERS Àkọlé àwòrán, Gbajúgbajà Olùṣọ́ tó ń jẹ́ 'Liquid metal' Tí wọ́n ba ni ki awọn eniyan darukọ olusọaguntan ti o gbajugbaja ni Naijiria ni asiko yìí , ǹkan ti o ṣeeṣe ki wọ́n sọ náà ni Odumejeje.
Ajibola ni awọn ikunsinu to n waye ko ṣẹyin pe pinpin ipo oselu laarin ẹkun kan si omiran, fi si apa kan ni Naijiria.
O salaye pe, iwa ibaje yii je kokoro ajeniru ti o n di idagbasoke orile-ede lowo lati igba ti a ti gbominira.
Imam tó fẹ́ ọkùnrin míì níyàwó forí kó ìjìyà òfin Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ifa Priest: ọdún mọ́kànlá ni mo fi ṣe iṣẹ́ agbejọ́rọ̀ kí n tó gbọ́ràn si Ifá lẹ́nu Ẹwẹ, lẹyin iṣẹju diẹ ti igbẹjọ bẹrẹ ni ijoko ile ẹjọ dide nigba ti wọn n gbọ ariwo ero to wa ninu ile ẹjọ ti wọn ko si le kapa rẹ ti adajọ si sun un siwaju di ọjọ kẹrinla, oṣu kinni, ọdun 2020.
Àkọlé àwòrán, Orílẹ̀-èdè márùndínlọ́gbọ̀n tí ó ń wá òògùn ìṣẹ́yún jùlọ lórí goggle fún Misoprostol wá láti Afíríkà, mọ́kànlá nínú wọn wá láti ilẹ̀ Afíríkà tí àwọn mẹ́rìnlá tó kù sì jẹ́ Latin America.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Mother Language Day: Bàbá míì ní àìkọ́ ọmọ òun ní Yorùbá ló mú kò pàdánù iṣẹ́ olówó ńlá O ni ọgbẹ ọkan nla ti yoo wa titi aye ni isẹlẹ naa jẹ fun ọmọbinrin ọhun, eyi toun n gbadura pe ko san.
Bẹ́ẹ̀ náà ló kan gbogbo ohun tí ń hù lórí ilẹ̀, ati eniyan ati ẹran ọ̀sìn, ati gbogbo iṣẹ́ ọwọ́ eniyan.
dull : v ; ( the tablets they gave him dulled the pain for a while .
Ẹsẹ̀ Asaheli yá nílẹ̀ pupọ, àfi bí ẹsẹ̀ àgbọ̀nrín.
Ninu atejade kan ti Hafiz fi ranse  lojo KinnI Osu keje  si awon akoroyin  lojo Aiku , ni eyi ti o ko si gomina ipinle Kano, Abduallahi Umar Ganduje so pe “inu mi i ba dun pe ki a jo pari ipo oselu yii lati le mu ipinnu ati ileri awon omo ipinle Kano sẹ gege bi ipinnu wa lakooko eto idibo  lọdun 2015.
Ẹ lè mu ninu ife ìrora tí èmi yóo mu?
Iyabo Ojo Gbajugbaja oṣere tiata Yoruba, Iyabo Ojo ṣi ile tuntun laarin ọsẹ yii, nibi ti ọpọlọpọ awọn ẹbi, ọrẹ ati ojugba rẹ ninu iṣẹ tiata peju si.
Sùgbọ́n gẹ́gẹ́ bí ọkunrin mo ní ìmọ́kàn le díẹ̀ wà fún mi nígbà ti'mo gbọ́ ohùn rẹ̀.
Gomina ipinle Benue, Samuel Ortom ti fi mule pe oun si duro digbi labe asia egbe oselu ti o wa lori alefa lowo bayii, All Progressives Congress (APC).
gege bi ogagun ,ni o dari iko naa laarin odun 1980 si 1990.
MC Oluọmọ, fara gb'ọ̀bẹ níbi ìpolongo ìbò APC l'Eko O tun ṣalaye siwaju pe bi ọrọ NURTW ṣe ri ni awọn ipinlẹ ti awọn gomina ti fofin de ẹgbẹ naa yatọ si bo ṣe ri ni ipinlẹ Eko.
Nisinsinyii ni kí o fún mi, bí bẹ́ẹ̀ kọ́, n óo mú un tipátipá.
Ọrọ yii difa farakunrin ọlọpaa ilẹ Phillipines kan ti akukọ tawọn eeyan fi n ja ṣeku pa.
Wọn ni eyi lo fun awọn ologun ni anfaani lati fi okunkun boju, sisẹ ibi lọjọ Isẹgun naa.
"Awọn atipo naa nsa kuro ni guusu Cameroon nibi ti awọn soja tin gbogunti awọn ti wọn njija ọminira, lati da orilẹede ti wọn pe ni Ambazonia silẹ lawọn agbegbe ton sọ ede gẹẹsi nitọri ohun ti wọn pe ni ""isẹlu to fi sọdọ awọn eeyan to wa lagbegbe to nsọ ede Faranse""."
Ohun tí o bá ṣe, yóo pada sí orí ara rẹ.
Oríṣun àwòrán, Instagram/abiola ajimobi Ajimobi maa n fi ọwọ sọya ni ọpọlọpọ igba pe oun ni Gomina to tii ṣe aseyọri julọ ninu itan ipinlẹ Oyo, Ati pe oun tun ni gomina ti alaafia to peye ati eto aabo to pegede si jọba nipinlẹ Oyo lasiko isejọba rẹ.
Dan Ali to jẹ minista fun eto aabo.
Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Borno Zabarmani Rice Farmer Massacre: Àwọn àgbàgbà Òkè Ọya ní ẹ̀mí èèyàn kò níyì mọ́ lábẹ́ ìṣèjọba Buhari5 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Borno Zabarmani massacre: Ípànìyàn tó wáyé ní Borno fihàn pé omi n bẹ lámù fún ètò ààbò - Tinubu3 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Ere Boss ati Actor: Ọpọlọpọ awọn ọmọde ti wọn ba ti wo ere onija a bẹrẹ si ni ṣe awokọse fiimu ti wọn wo ,nipa yiyan ‘Boss’ to jẹ ole ati ‘Actor’ to jẹ bii ọlọpaa ti yoo si bori Boss ninu idije naa.
Ó ṣe nǹkan burúkú lójú OLUWA, ó tẹ̀lé àpẹẹrẹ burúkú Ahabu, baba rẹ̀, ati ti Jesebẹli, ìyá rẹ̀, ati ti Jeroboamu, ọmọ Nebati, àwọn tí wọ́n jẹ́ kí Israẹli dẹ́ṣẹ̀.
OLUWA bá pàṣẹ fún ẹja tí ó gbé Jona mì, ó sì lọ pọ̀ ọ́ sí èbúté, lórí ilẹ̀ gbígbẹ.
Eni ti o ti gba ife eye ohun ni eemejila otooto, lo ti fopin si irepo laarin oun ati awon akonimoogba re tele.
Lara awọn ohun ti wọn gbe kalẹ ni pe ki aarẹ Naijiria, Muhammadu Buhari o gba awọn ajagunta lati ṣe afọmọ aginju Sambisa ati agbegbe etido adagun omi Chad ki wọn koju awọn agbebọn to ti fi ibẹ ṣe ibuba.
Idije yii ko si fun oṣiṣẹ BBC kankan ati awọn ẹbi wọn rara.
Oríṣun àwòrán, Marta Moreiras Iyapa nla lo n waye laarin inu ile ati ita yii, nitori eyi ni nkan se pẹlu oju ti awọn eeyan fi n wo wọn bi o tilẹ jẹ pe iwadi mi fihan pe isẹ nla lawọn baba n se ninu ile nidi itọju ọmọ.
Ìyá dú ọmọ rẹ̀, o yíi láta, ó sì tún jòkó jẹ ẹ́ Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
ọkọ rẹ̀ àkọ́kọ́ kò gbọdọ̀ gbà á pada mọ́ nítorí pé obinrin náà ti di aláìmọ́.
Dorman Long Bridge Ijọba ibilẹ Surulere / Lagos Mainland 7.
Wòlíì Kasali ní Dolapo Awosika kò lé ìyàwó òun jáde Amọ ṣa bí ọjọ́ ṣe ń gorí ọjọ, tí ilé iṣẹ́ ọlọ́pàá si ń gbìyànjú láti mú sẹnatọ Dino Melaye si àhámọ́ wọn, àwọn ẹbi Dino ti ké gbàjare pé, ibi ti ọ̀rọ̀ ń lọ yii, ẹrú ilera Dino ń bà awọn lẹ́rù.
"gnu free documentation license ( gfdl ) ( "" Ìwé Àṣẹ aṣàlàyé Ọ ̀ fẹ ́ gnu "" ) jẹ ́ ìwé àṣẹ copyleft fún aṣàlàyé ọ ̀ fẹ ́ látọwọ ́ free software foundation ( fsf ) fún àwọn iṣẹ ́ ọwọ ́ gnu ."
Eto Amotekun yii naa ni awọn gomina lẹkun iwọ oorun Naijiria pawọpọ gbe kalẹ lai naani ẹgbẹ oselu ti wọn wa se, ilu Ibadan, tii se olu ilu ipinlẹ Ọyọ si ni eto ifilọlẹ naa ti waye.
Ajọ elere bọọlu ilẹ Portugal Portuguese Football Federation, FPF, lo fi ikede yi sita.
’ OLUWA sì tún tẹnu mọ́ ọn fún un pé, ‘Èmi fúnra mi ni n óo sọ ìdílé rẹ̀ di ìdílé ńlá.
" Ni ti Farida Adamu, o ni oun ko ni ba banki naa dowopọ mọ nitori bo ṣe fiya jẹ awọn olufẹhonuhan EndSARS lodi si ofin.
Ninu ikoko kinni, orile-ede France ti yoo sagbateru idije naa, yoo maa waako pelu Germany, Korea ati Japan.
Bẹ ẹ naa ni yoo sọ bi o ṣe gbadun oorun rẹ si.
Wo ǹkan tó yẹ kí o mọ̀ nípa Joe Biden, tó ń kojú Trump nínú ìbò America Ṣaaju ni Aarẹ Donald Trump ti kọkọ kede loṣu Kẹwaa pe jọba Amẹrika yoo yọ orukọ Sudan kuro lara awọn orilẹ-ede agbesumọmi naa lẹyin to ba ti san owo itanra $335 miliọnu fun awọn ẹbi atawọn eeyan to fara gba ninu akọlu ẹgbẹ al-Qaeda si ọọfisi ijọba Amẹrika lọdun 1998.
Aare Muhammadu Buhari ti ran awon asoju jankan-jankan lo si Dapchi, lati lo wo ohun ti o n sele nibe ati lati ba awon obi awon omode-binrin akekoo ti won jigbe, ti won si gba itusile lowuro ojo-Ru, ojo kokanlelogun osu keta odun 2018 yo ku oriire.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Seyi Makinde: Ìyàtọ̀ yóò dé bá àwọn òṣìṣẹ́ lásìkò yìí 29 Ògún 2019 Oríṣun àwòrán, Google Àkọlé àwòrán, Gomina Ìpínlẹ̀ Ọyọ, Seyi Makinde ti sọ wí pé ìgbáyé-gbádùn àwọn ènìyàn Ìpínlẹ̀ Ọyo ló jẹ́ ìjọba òun lójú.
Ju gbogbo rẹ lọ eyi ni awọn ohun marun ti awọn oniṣegun oyinbo ka silẹ gẹgẹ bi ọna abayọ, bi nnkan ọmọkunrin ati ọmọbinrin ba lẹpọ tabi ha sinu ara wọn, lasiko ibalopọ.
ti fun aya aare orile ede Niajiria , iyaafin Aisha Buhari  ati awon eniyan miiran lorile ede yii ni ami
‘Ẹ gbọ́, ẹ̀yin eniyan Israẹli, tí ẹ̀ ń lọ sí ojú ogun lónìí láti bá àwọn ọ̀tá yín jà, ẹ kò gbọdọ̀ jẹ́ kí àyà yín já, ẹ̀rù kò sì gbọdọ̀ bà yín, ẹ kò gbọdọ̀ wárìrì tabi kí ẹ jẹ́ kí jìnnìjìnnì dà bò yín.
Níbi ìgbẹ́jọ́ náà àwọn ti wọn jẹ́rìí pé àwọn ní àwọn pa Kudirat ni Sergeant Barnabas Jabila sọ pé àṣẹ Al-Mustapha ni àwọn tẹ̀lé.
Seyi Makinde: Ìrírí, ọ̀gbọ́n àti ìmọ̀ ìgbìmọ̀ yìí yóò ṣèrànwọ́ fún ìjọba mi
Àsíá ibùdó ẹ̀yà Efuraimu yóo máa wà ní ìhà ìwọ̀ oòrùn ní ìsọ̀rí-ìsọrí; Eliṣama ọmọ Amihudu ni yóo jẹ́ olórí wọn.
Iroyin lati ile ẹjọ to n gbọ ẹjọ ijinigbe ti wọn fi kan gbajugbaja iranṣẹ Ọlọrun kan niluu Akurẹ ẹni ti ọpọ mọ si Baba Sọtitobirẹ, Wolii Alfa Babatunde n jẹ ko di mimọ pe gbaragada ni iya ọmọ naa, arabinrin Modupẹ Kọlawọle bu s'ẹkun ni ile ẹjọ naa loni nigba to n jẹri lori ẹjọ naa.
Angẹli karun-un wá fun kàkàkí rẹ̀, mo bá rí ìràwọ̀ kan tí ó ti ojú ọ̀run já bọ́ sí orí ilẹ̀ ayé.
Se Tinubu ni yoo lọ maa bẹ awọn ọmọlẹyin rẹ tẹlẹ ti wọn ti jaa ju silẹ ni abi awọn lo maa bẹ Tinubu?
Eniyan meji padanu emi won lasiko ifehonuhan awon ara-ilu, ti awon márùndínlógójì miiran si farapa yanayana lakoko ifilole Amerika embassi nilu Jerusalem, eleyi ti o waye lenu ibode ilu Gaza lojo aje(Monday).
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Aládúgbò ti ọmọ Nàìjíríà jábọ́ látorí ilé alájà méjì 17 Òkùdu 2018 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 18 Òkùdu 2018 Àkọlé àwòrán, Wọ́n ti olólùfẹ́ eléré bọ́ọ̀lù ọmọ Nàìjíríà jábọ́ látorí ilé alájà méjì Àwọn olùgbé ilé kan ní àgbègbè Brusilov ní orilẹ̀èdè Russia kó sínú ìdàrúdàpọ̀ lọ́jọ́ àbámẹ́ta lẹ́yìn tí ẹnì kan ti ọmọ Nàìjíríà tó mu ọtí yó bọ́lẹ̀ láti orí ilé alájà méjì.
How to wear facemask: Wo bí o ṣe le wọ ìbomú-bẹnu láti dènà Covid-19
A le fi òwe yi tún gb́ àwọn obinrin ti ó kó gèlè aṣọ-ẹbí jọ ni ìyànjú pé ki ṣe bi gèlè ṣe pọ̀ tó ló mú kó yẹni.
Iroyin naa ṣalaye wi pe awọn mejeeji ti wọgi le orukọ arawọn loju opo ẹnikeji wọn.
Àwọn àsọtẹ́lẹ̀ tí ó ti ṣe sẹ́yìn Wọ́n ní òun ló sọ àsọtẹ́lẹ̀ pé Àarẹ orílẹ̀èdè Amerika, Donald Trump yóò borí nígba ìdìbò 2016.
”Ọlọrun dá a lóhùn pé, “Lọ bá wọn jà, n óo jẹ́ kí o ṣẹgun wọn.
Ó ti gba ìjọba náà kúrò lọ́wọ́ rẹ, ó sì ti fún Dafidi, aládùúgbò rẹ.
Èrò àwọn ọmọ Naijiria ṣọ̀tọ̀ọ̀tọ̀ lórí àwọn ti Sanwo Olu yàn sípò Ki èdè Yoruba ma le parun ni BBC Yoruba ṣe jade lọ ni kawọn eniyan lọkunrin lobinri fi ami si gbolohun yii.
Lati fi orukọ silẹ, ẹ lọ si oju opo ayelujara nyif.
Joabu balogun mi ati àwọn ọ̀gágun wà lójú ogun, níbi tí wọ́n pàgọ́ sí ní ìta gbangba, ṣé ó yẹ kí n lọ sílé, kí n máa jẹ, kí n máa mu, kí n sì sùn ti aya mi?
O si yẹ ko ye wa pe ohun aseyọri gbaa ni ki ọba alade kan lo aadọta ọdun lori oye, bẹẹ si ni ko si ni akọsilẹ pe Alaafin kankan lati ẹyin wa lo aadọta ọdun nipo.
Aarẹ yoo sọro lori atilẹyin Naijiria fun ICC ati igbese akin ti Naijiria n gbe lati gbogun ti iwa ibajẹ ni Naijiria.
Ọga ajọ LASEMA to n ri si iṣẹlẹ pajawiri niluu Eko, Ọmọwe Oluwafemi Oke-Osanyintolu ṣalaye pe awakọ nla naa fi ọkọ rẹ kọlu odi to wa laarin ọna.
Ohun tí ojú wa ń rí nìyí níbi ìbò abẹ́nú fún olùdíje gómìnà lẹ́gbẹ́ òṣèlú APC ní Edo Fayose dá sí àáwọ̀ igbákejì gómìnà àtí gómìnà Akeredolu l'Ondo Àwọn tó ní Covid-19 ní Nàìjíríà ti tayọ ẹgbẹrun lọ́nà ogún Wọ́n ti pàṣẹ lọ rọọ́kún nílé fún òṣìṣẹ́ káńsù tó lú obìnrin kan ní ìpínlẹ̀ Ogun Agbẹ lo wọpọ ni ilu naa wọn si ni awọn ko mọ ohun to n jẹ COVID-19.
Ǹjẹ́ o mọ̀ pé ètò ìdìbò kan wà tí erin àti òkúta Dáyámọ́ǹdì leè yí èsì rẹ̀ padà Ẹfunsetan Aniwura, ọmọ Ẹ̀gbá tó di akíkanjú obìnrin nílẹ̀ Ibadan Bakan naa, Oluranlọwọ fun Gomina Ipinlẹ Kwara fọrọ iroyin, Rafiu Ajakaye ti ni asọyepọ gbọdọ waye laarin ijọba ipinlẹ ati awọn osisẹ, ki awọn to le e gbe igbesẹ kankan lori sisan owo osu osisẹ tuntun.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ooni: Mo ti fi ọ̀rọ̀ obinrin tó ń parọ́ ìfẹ́ mọ́ mi sun agbófinró Ọba Maha Vajiralongkorn,ti ṣe ẹni ọdun mẹ́rìndínláàdọ́rindi ba lẹyin ti baba rẹ ti awọn ara ilu fẹran gidi gaan papoda lọdun 2016.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Nigeria Elections 2019: Ìjàmbá iná àti àwọn nkan mi i tó mú INEC sún ìdìbò 16 Èrèlè 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 17 Èrèlè 2019 Oríṣun àwòrán, InEC Alaga ajọ eleto idibo Naijiria, INEC, Yakubu Mahmood ti sọ wi pe kii ṣe aṣẹ ẹnikẹni lo mu ki ajọ naa sun eto idibo aarẹ ati ti ile aṣofin apapọ to yẹ ko waye lọjọ Abamẹta, ọjọ kẹrindinlogun, oṣu Keji siwaju.
Lori ọrọ ọkọ nini ọkọ tabi aya, ipenija kekere kọ ni awọn ti aisan yii ba mu ma n ni, paapa awọn obinrin.
Àwọn eniyan yóo máa kọ ọ̀rọ̀ yìí ní orin arò; àwọn ọmọbinrin ní àwọn orílẹ̀-èdè ni yóo máa kọ ọ́.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ekiti: Lẹ́yìn t'áwọn kan gba òmìnira, wọ́n tún jí òṣìṣẹ́ kánsù míràn gbé 8 Sẹ́rẹ́ 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Iru ijinigbe yii gbilẹ nipinlẹ Ondo to muleti ipinlẹ Ekiti ni 2018.
Àjọ NLC Naijiria : MTN kọ̀ jẹ́ kí òsìsẹ́ wọn darapọ̀ mọ́ àjọ òsìsẹ́
Ṣe lawọn ajinigbe n gba yiin ni ipinlẹ Eko.
Sara, tí ó ti di ẹni aadọrun-un ọdún ha tún lè bímọ bí?
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Badirat Ajoke sọ pé òun fínnú-fíndọ̀ fi ààfìn Oyo sílẹ̀ ni, wọ́n kò lé òun 9 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Oríṣun àwòrán, QueenOla2/Instagram Olori Alaafin ilu Oyo , Badirat Ajoke, ti sọ ni gbangba pe oun ti kuro ni aafin Ọba Lamidi Adeyemi III.
Sex: Ẹ̀ẹ̀méje ló gorí ọmọ alaṣẹ́wó, ni kò bá bọ̀ mọ́
Ọ̀run yóo parẹ́ bí èéfín,ayé yóo gbó bí aṣọ,àwọn tí ń gbé inú rẹ̀ yóo sì kú bíi kòkòrò;ṣugbọn títí lae ni ìgbàlà mi,ìdáǹdè mi kò sì ní lópin.
14 Nítorínáà, a pè yín láti kígbe ironúpìwàdà sí àwọn ènìyàn yìí.
Ṣebí etí a máa dán ọ̀rọ̀ wò,ahọ́n a sì máa tọ́ oúnjẹ wò?
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Búrẹ́dì tí wọn ó fi jẹ ẹ̀wà ni wọ́n lọ rà ni wọ́n pàdé ikú gbígbóná' Ẹ̀wẹ́, o ní kí olúkúlùkù pada si àwọn ìlàna orí ayelujara tabi rẹdíò ti wọ́n ń lò tẹ́lẹ̀ láti fún àwọn akẹ́kọ̀ọ́ ni ìmọ̀ títí di ìgbà ti ìjọba yóò ṣe ikéde tuntun.
Ní ọdún yìí, àwọn tí àìsàn-an ibàá kọlù tó bíi 7,179, àwọn - 2800 ní sáà kínní osùu Agẹmọ nìkan.
’ Kí o sì yára sá kúrò níbẹ̀.
Ó ṣeéṣe kí ilé ìjọsìn, mọ́sálásí àti ọkọ òfurufú ṣí, Ẹ wo àwọn ìlànà tuntun tí ìjọba là sílẹ̀ Awọn àkẹkọ̀ọ́ Uniben wọ́de ìfẹ̀hónú hàn nítórí akẹgbẹ́ wọ́n tí wọ́n fipa bálòpọ̀ Gómínà Kogi pàṣẹ kóníléógbélé ní ìjọba ìbílẹ̀ kan ní Kogi Ọwọ́ bàtá Auxiliary tó ń ró ní àrójù, leè ya láìpẹ́ - Ìjọba Oyo dúnkookò Ipinlẹ Eko lo ni eniyan to poju pẹlu eniyan 192 ni Ojo Aje nikan soso.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ibadan Obaship Tussle: Mọ́gàjí Ibadan ní ìjoba ló da ọ̀rọ̀ lọ́balọ́ba rú 26 Ògún 2019 Oríṣun àwòrán, Facebook/Olubadan of Ibadan O da bi ẹni pe awuyewuye lori awọn Ọba ilu ibadan ko tii loju tu, lẹyin ti ọkan lara wọn, Ọba Lekan Balogun ṣalaye fun BBC Yoruba wi pe ofin nikan lo le yọ awọn nipo gẹgẹ bi ọba ni ilu lbadan.
Lóri pe boya gomina Kogi Yahaya Bello ṣe dáradára ni ìpínlẹ̀ Kogi ni sáà tó n lò lọ yìí, Tinubu ni tí kò ba sí ìhà tó ń fapajánu, èyí tumọ si pe kò si ijọba àwa àrawa.
Nígbà tí baba iyawo Mose rí gbogbo ohun tí Mose ń ṣe fún àwọn eniyan, ó pè é, ó ní, “Kí ni gbogbo ohun tí ò ń ṣe fún àwọn eniyan wọnyi?
Ajafẹtọ ọmọniyan, Ọmọlolu Akinwale ti bu ẹnu atẹ lu igbesẹ awọn adari ni Naijiria ti wọn ma n lọ si oke okun lati lọ ṣe ipade ṣaaju idibo lorilẹede Naijiria.
wa niluu AbujaSymington so pe; “Eleyii yoo jẹ ohun iranti lasiko eto
Ẹ wo ìfọ̀rọ̀wẹ́rọ̀ pẹ̀lú Saheed Osupa
“ ‘Ẹni ìfibú ni ẹnikẹ́ni tí ó bá yẹ ààlà ilẹ̀ ẹnìkejì rẹ̀.
 ilé-ẹ ̀ kọ kékeré ni ó wà .
 láti lè jẹri sí òtítọ ́ àrùn náà , a ó ṣe àyẹ ̀ wò àwọn ẹ ̀ jẹ ̀ tí a gbà sílẹ ̀ fún àwọn èròjà agbóguntàrùn nínú ara tí n dójú ìjà kọ àwọn kòkòrò àìlèfojúrí afàìsàn , fún rna tí n dójú ìjà kọ àwọn kòkòrò àìlèfojúrí afàìsàn , tàbí fún kòkòrò àìlèfojúrí afàìsàn náà fúnraarẹ ̀ .
    Lẹ́yìn èyí, ọba ni kí wọ́n fún mi ni oúnjẹ, wọ́n sì fún mi.
Kàkà bẹ́ẹ̀, gbogbo nǹkan tí ń ṣe ni ó ń jẹ́ ìrànlọ́wọ́ fún ọ.
OLUWA Ọlọrun, ṣé o fẹ́ pa àwọn ọmọ Israẹli yòókù tán ni?
O fikun pe o ti di ẹsẹ fun ẹnikẹni lati ti oju popo pa nipinlẹ Ondo lai naani bi iru ẹni bẹẹ se kanka to lawujọ tabi iru ipo giga to di mu nitori ina lofin, ko mọ oju ẹni to daa.
Kiise pe wọn n ṣe isin adura lori ayelujara nikan, wọn tun n fun ijọba ati awọn ọmọ ijọ kọọkan ni owo.
Àbùkù ati ẹ̀gàn ni wọ́n láàrin yín.
Oríṣun àwòrán, Adejare Taofeek Àkọlé àwòrán, 'Awọn eniyan ipinlẹ Ọṣun kọ idajọ Jankara Nibi iwọde naa to waye nilu Oṣogbo ni awọn to wọde ti gbe oriṣiriṣi akọle dani lati fi sọ erongba wọn.
Àwọn ará Hiti, ará Jebusi ati àwọn ará Amori ń gbé àwọn agbègbè olókè.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Mo Salah ko ri bọọlu gba si àwọn Zimbabwe ninu idije iṣide AFCON Ẹkọ pataki ti awọn eniyan n sọ ni pe ki ikọ kankan ma gbojule ẹnikan ṣoṣo fun ogo idije wọn.
Ni ọdun to kọja, akọroyin marundinlọgọrun ni wọn pa, gẹgẹ bii ajọ awọn akọroyin lagbaaye, IFJ sọ.
Olórí ẹ̀yà Gadi sì ni Eliasafu ọmọ Deueli.
Iku ti pa ojú ilumọọka agba osere kan de, Fasasi Ọlabankẹwin, ti gbogbo eeyan mọ si Dagunro Alakija oogun Oríṣun àwòrán, Sajetiologa A gbọ pe irọlẹ ọjọbọ ni wọn yoo sinku agba osere to tẹri gbasọ naa ni ile rẹ ni Oṣogbo.
Aṣọ ń pe aṣọ ránṣẹ́ ni lásìkò ìbúra gómìnà àti ààrẹ Irọ́ ni o!
Ajo WHO náà sọ pé bótilẹ̀ jẹ́ pé ẹ̀rí wà pé àwọn tó ti pé ọgọ́ta ọdún ló ti kú ju àwọn ọmọdé lọ, àwọn ọmọdé naa le kú.
Oun kan naa lo gba goolu meji sawọn eyi to mu ki Arsenal gba ife ẹyẹ FA Cup loṣu yii ni Wembley lo ti ṣẹlẹ.
Ọ ̀ nà àkọ ́ kọ ́ tí àwọn ènìyàn ti máa n ṣe àgbákò àrùn hepatitis c jẹ ́ nípasẹ ̀ ẹ ̀ jẹ ̀ -kan-ẹjẹ ̀ ní ìgbà tí ènìyàn bá n gba ìtọ ́ jú fífa òògùn sínú isan ara , àwọn ohun èlò iṣẹ ́ ìlera tí a kò bọ ̀ lórí iná kí a tó lò wọn , àti nípa gbígba ẹ ̀ jẹ ̀ sí ara .
Oṣu Karun, ọdun 2020, ni ileesẹ ọlọpaa ti n wa Ebila, fun ipa to ko ninu iku to pa olori ẹgbẹ janduku miran, Moshood Oladokun 'Ekugbemi' l'oṣu Kẹrin.
Òwe Nípa Opó Kan ati Adájọ́.
 díámọ ́ ndì jẹ ́ ìkan nínú àwọn èròjà tó le jùlọ , nígbàtí gráfáìt jẹ ́ dídẹra dáadáa tó bẹ ̀ ẹ ̀ láti fi kọ ìwé .
    Kí ni mo máa rí, Òmùgọ́dimẹ́ta lọ ṣe ofin tí o fi hàn gbangba pé èmi àti àwọn ẹlẹgbẹ mí ni o ń fẹ́ ṣe ní ibi àwọn ofin náà ni ìwọ̀nyí:
 Ọ ̀ pọ ̀ egbògi aṣòdìsí ni a tún lè lò .
 cysticercosis tún má a nran àwọn ẹlẹ ́ dẹ ̀ àti máálúù ṣùgbọ ́ n wọn kìí sábà fi ààmì àìsàn kankan hàn nítorí pé ọ ̀ pọ ̀ lọpọ ̀ nínú wọn kìí gbé ilé-ayé pẹ ́ títí .
Oríṣun àwòrán, Empics Àkọlé àwòrán, Eyi ni yoo jẹ aṣekagba ipolongo idibo gomina fun ẹgbẹ oṣelu APC Oshiomole tẹsiwaju wipe awọn eeyan ipinlẹ Ọṣun ko nilo gomina to kundun ode owanbẹ, tabi ẹni to fẹran ile ijo.
 Ayefẹlẹ: Orí ìkúnlẹ̀ ni ìyàwó mi wà, tó ń bẹ gómìnà, láti 11pm si 4am Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ayefẹlẹ: Orí ìkúnlẹ̀ ni ìyàwó mi wà, tó ń bẹ gómìnà, láti 11pm si 4am Fidio oke yii lo n salaye ipade akọroyin ọtọọtọ, ti ijọba ipinlẹ Ọyọ ati Yinka Ayefẹlẹ se lori ileesẹ Fresh FM ti ijọba wo lulẹ lọjọ Aiku, amọ ti alaye igun kọọkan lori isẹlẹ naa tako ara wọn Ohun tó wà lórí ilẹ̀ Ayefẹlẹ́ ju àsẹ tó gbà lọ - Ìjọba Ọ̀yọ́ ."
A wá ọ̀pọ̀lọpọ̀ ọṣẹ àti kànìn kànìn fún wọn kí wọn fi wẹ̀, a sì ṣe òfin pé olúkúlùkù níláti fi ara hàn ni bí ó bá tì wẹ̀ tán.
“Ọlọrun nìkan ló mọ ọ̀nà rẹ̀,òun nìkan ló mọ ibùjókòó rẹ̀.
Bí wọ́n bá jẹ́ obìnrin, ọjọ́ karùn ún ni.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìjàǹbá ọkọ̀ ní Ìlasamàjà: Ẹ̀mí mẹ́ta bọ́, ọ̀pọ̀ farapa 4 Ìgbé 2018 Oríṣun àwòrán, LASEMA Àkọlé àwòrán, Wọn ti gbe awọn to farapa lo si ile iwosan Ìjàǹbá ọkọ̀ kan tó wáyé ní àárọ̀ ọjọ́rú ní Ìlasamàjà ní ìlú Èkó mú ẹ̀mí èèyàn mẹ́ta lọ, tí ọ̀pọ̀ míì sì tún farapa.
Awọn eniyan ni ki Naijiria fi ti Egypt kẹkọọ pé ko si ẹni ti ko le jẹ koriya fun awọn akẹgbẹ rẹ lasiko idije bii ti Sallah ti Liverpool.
Aarun Ebola maa n fa aarun igbẹ
Oríṣun àwòrán, @Haramain Àkọlé àwòrán, Sheik Khalid Al Muhanna to jẹ ọkan pataki lara awọn Aafa mọṣalṣi nla Wọ́n ti ṣí ilé oúńjẹ oní ọgbọ̀n náírà (N30) ní Kano ‘Jí foonu ọkọ rẹ̀ wò, kóo fi ẹ̀wọ̀n jura’ Wo àwọn orílẹ̀-èdè márùn ún tó fún àwọn obìnrin làńfàní tuntun sí ẹ̀tọ́ wọn Ìkọlù Syria- oun ti àwọn orílẹ̀èdè lágbàáyé n sọ Yatọ si iṣẹlẹ tọdun 2015, Lọdun 2011 ni ọkunrin kan tun deede yinbọn fun Sheik Juhany ti ọkunrin naa si bẹrẹ si ni pariwo ninu mọṣalaṣi mimọ naa.
Andy Ruiz já ìràwọ̀ Anthony Joshua2 Òkùdu 2019 Anthony Joshua vs Pulev: Anthony Joshua rọ̀jò ẹ̀ṣẹ́ lu Pulev13 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 RuizJoshua2: Anthony Joshua di akànṣẹ́ kẹrin nínu ìtàn tí yóò gba ogo rẹ̀ padà lẹ́yìn tó sọ ọ́ nù8 Ọ̀pẹ̀̀ 2019 Russia Boxer: Abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò dágbére fáyé lásìkó ìjà rẹ24 Agẹmo 2019 Anthony Joshua: Lẹ́yìn ìjà rẹ̀ pẹ̀lú Luiz, Anthony Joshua bẹ Ọba ìlú rẹ̀, Àkárìgbò wò20 Èrèlè 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 3 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 5 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé n kò ní fọ́nnu nípa ara tèmi ati nípa àwọn àìlera mi.
Ọmọbìnrin tó tayọ nínú ìdànwó WAEC ọdún 2019 pẹ̀lú A1 méje ti kú Orúkọ Aisha Yesufu náà wọ inú BBC 100 Women tí a fi ń sọri àwọn obìnrin tó pegedé ní 2020 Ọ̀rọ̀ àsọkẹ́yìn Diego Maradona ìlúmọọká agbábọ́ọ̀lù rèé kó tó dágbére f'áyé Omotara kan ìdin nínú iyọ̀, àwọn ọmọ ilẹ̀ Faranse náà bínú síi nítorí alágbe tó fi ṣe yẹ̀yẹ́.
    Ọkùnrin yìí bá bàbá rẹ ṣíré títí ilẹ̀ ọjọ́ náà fi ṣu, ìgbà ti ilẹ̀ ọjọ́ kejì sì mọ́ ó padà lọ sí ọ̀dọ̀ ìyàwó rẹ̀ ní ìsàlẹ̀ ilẹ̀.
"Iroyin tun sọ pe Makinde pe Arabinrin Florence Ajimobi, nigba to gbọ pe ọkọ rẹ kú, sugbọn ko tun gbe ìpè.
Àwọn aṣọ́nà tẹmpili kò kúrò ní ààyè wọn, nítorí pé àwọn ọmọ Lefi ti tọ́jú ẹbọ ìrékọjá tiwọn fún wọn.
Ijsba ipinlẹ Ọṣun ti kede ọjọ iṣẹgun tii ṣe ogunjọ oṣu kẹjọ ọdun 2019 gẹgẹ bi ọjọ isinmi lẹnu iṣẹ.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Aisha Abimbọla gba ẹ̀yẹ ìkẹyìn ní Nàìjíríà Àwọn ohun to yẹ ko mọ nipa Aisha Abimbọla ‘Tunde Kelani yan mi jẹ lori fiimu ‘Toluwanilẹ’ Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí kan sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
Omidan ti ko tii mọ ọkunrin, ti wọn n pe ni arugba, ni yoo ru igba naa, tawọn eeyan si maa n ri oun gangan bii orisa ti wọn yoo maa sọ isoro wọn fun, bo ba se n lewaju wọn ru igba to kun fun ohun etutu, lọ si ojubọ Ọṣun.
Bawo gan ni OPC ṣe ri wọn mu?
A wá sọ pé, “Èyí ni ẹ̀jẹ̀ majẹmu tí Ọlọrun pa láṣẹ fun yín.
Ṣé ẹ wá rí i pé nípa iṣẹ́ ni eniyan fi ń gba ìdáláre, kì í ṣe nípa igbagbọ nìkan?
Igbakeji Kọmisọnna ọlọpaa ni ipinlẹ Edo, Ayoola Ajala lo dari awọn ọlọpaa naa.
O ti n gbadura pe ki Ọgbẹni Trump fi ẹyin Joe Biden janlẹ ninu idibo oṣu kẹrinla o si ya akoko sọtọ lojoojumọ lati maa gbadura fun imularada aarẹ Trump laipẹ yii to wa nile iwosan tori aisan coronavirus.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Afẹ́fẹ́ òjò líle ṣọṣẹ́ ní ìlú Ìlọrin nípinlẹ Kwara 4 Ìgbé 2018 Oríṣun àwòrán, Abdul Momoh Àkọlé àwòrán, Afẹ́fẹ́ òjò líle ṣọṣẹ́ nípinlẹ Kwara Afẹ́fẹ́ òjò líle ṣọṣẹ́ ní ìlú Ìlọrin ní àṣàalẹ́ ọjọ́ ìṣẹ́gun.
Ìtàn ayé Shina Rambo, adigunjale tó fi oyún 27 gún ọṣẹ Ẹ wo ìrírí aláboyún tó ń rọbí lọ́wọ́ lásìkò ìbúgbàmù tó wáyé ní Lebanon Bí Gómìnà Obaseki ṣe yọ òrùlé ilé aṣòfin Edo lẹ́yìn tó fìjà pẹẹ́ta pẹ̀lú ọlọ́pàá Iru ọrọ ti ẹbi ati ọrẹ rẹ n sọ fun un gẹlẹ naa lo fi n huwa si iyawo ati awọn ọmọ ọhun Mallam Abdulwasiu lorukọ ọkọ rẹ n jẹ.
Niṣe ni iyawo funra rẹ ko ero sẹyin to gba agboole ọkọ rẹ lọ bẹrẹ eto igbeyawo ara rẹ.
Ó sọ fún Prince náà pé, àṣìṣe gbáà ni fún òun láti yan àn gẹ́gẹ́ bi ìgbákeji olórí ilé.
Sa gbogbo ipá rẹ láti ṣe ara rẹ ní ẹni tí ó yege níwájú Ọlọrun, gẹ́gẹ́ bí oníṣẹ́ tí kò ṣe ohun ìtìjú pamọ́, tí ó ń sọ ọ̀rọ̀ òtítọ́ bí ó ti yẹ.
Ile igbimo asofin lorile-ede Ethiopia ti fowo si Arabirin Sahle-Work Zewde lati di aare tuntun orile-ede naa.
Lara awọn akanṣe naa ni ibudo igbẹbi awọn oloyun ti wọn pe ni Ayinkẹ House to wa ni Ikẹja, Ibudo ere tiata to wa ni Ọrẹgun ati opopona olobiripo to wa ni Oshodi.
Nítorí OLUWA yóo ṣẹ́ apá eniyan burúkú,ṣugbọn yóo gbé olódodo ró.
Ẹlo ad blocker"" lati din awon ipolongo ku lori ẹrọ ayelujara."
Oriṣa Kemoṣi yóo lọ sí ìgbèkùn, pẹlu àwọn babalóòṣà ati àwọn ìjòyè rẹ̀.
” orile ede ti o n fowosowopo juloAlhaji Mohammed tun pupo ninu iroyin ni wọn ki I so lori  aseyori  ti ijọba yii ti se nipa Boko Haram.
miiran ti ile naa tun wo lu mọle .
Ṣé ìwọ jù ú lọ ni?
Ọna abayọ ni ki eniyan kọkọ ji lori ibusun, ko yi sẹ gbẹ, lẹyin naa ko joko, ko gbe ẹsẹ le lẹ, ki o to sẹṣẹ dide lori ibusun patapata Isubu ojiji: Ti eniyan ba subu lojiji, o le e ja si iku.
24 Ògún 2020 Oríṣun àwòrán, OTHERS Awọn agbẹ atawọn olugbe ilu Ikoyi Ile ni ijọba ibil Orire, ipinlẹ Oyo ti ni awọn yoo papa dide iranwọ fun ara awọn ni bi ijọba ipinlẹ Oyo ba kọ lati ṣe iṣẹ didaabo bo awọn.
’ Oríṣun àwòrán, Others Agbẹjọrọ Elizabeth ni: ‘Ki ni yoo ṣẹlẹ si obi to ba n gbe ni jina rere si ibi ti ọmọ rẹ ti n kẹkọ, ṣe iru awọn obi bẹẹ yoo tun fi oju wina ofin ti awọn ọmọ wọn ba ṣẹ?
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Eégun àti orò, bí wọ́n ṣe jọ bí Ẹ̀ṣà Egúngún nílẹ̀ Yorùba rèé Báwo ni yóò ṣe kan èmí àti ìwọ?
Ọrọ naa di gbọnmisi omi o too, ti awọn osisẹ ile-isẹ ijọba ibilẹ guusu Akurẹ si yabo ibi isẹlẹ naa.
Abajade ipinlẹ kọọkan ninu esi tuntun naa re e: Eko -152 Ebonyi-108 Edo-53 Ondo-46 FCT-38 Oyo-20 Kwara-19 Plateau-17 Osun-14 Bayelsa-14 Ekiti-14 Katsina-14 Akwa Ibom-11 Kaduna-11 Rivers-11 Niger-10 Ogun-7 Kano-6 Cross River-4 Bauchi-2 Àpapọ̀ àwọn tuntun to ṣẹṣẹ lugbadi ààrùn Coronavirus ní Nàìjíríà jẹ 664 ní 11/07/2020 Ninu ikede ti ajọ NCDC fi sita ni Ọjọ Abameta lo ti fojuhan pe , awọn to ti ni aarun naa ti pe 31,987 bayii.
Ẹnu àgbà ni obì ń gbó sí
Ijọba gbọdọ mu lọkunkundun lati kọ awọn araalu lọna ati daabo bo ara wọn.
Àwọn ọmọ Nàìjíríà ṣe ìwọ́de l'Osogbo lórí àfikún owó epo bẹntiróò Wo ohun tí ilé ẹjọ́ ní kí wọ́n ṣe fún Sunday Shodipe, afurasí ìṣekúpani l'Akinyele Èèmọ̀!
Obasanjọ-Kufuor: AU, ECOWAS gbọdọ̀ dá sí ọ̀rọ̀ Benin
bo tile jẹ pe orile ede Naijiria ni awon ipenija to n dojukọ sibẹ orile ede
Aarẹ Kenyatta ṣe'pade pẹlu olori alatako, Odinga
Nítorí náà, n óo bínú sí wọn, n kò ní fojú fo iṣẹ́ wọn, n kò sì ní ṣàánú wọn.
Lasiko ifẹhonuhan to ṣẹlẹ kaakiri orilẹede Naijiria yii, ọga agba ọlpaa ni agọ ọlọpa igba o le marun atawọn ibudo mii to fi mọ awọn nkan amayerọrun faraalu ni awọn kan lara awọn afhonuhan bajẹ.
Bakan náà ni àwọn ẹgbẹ́ agbábọọlu Kwara United náà ti kẹdun pẹlú Nasarawa United lori ikú Martins.
"Oríṣun àwòrán, @feminist_co ""Amọ nibi ti ọrọ de bayii, a gbọdọ daabo bo ẹmi ara wa ati tawọn ọmọ ẹgbẹ wa pẹlu."
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ọlọ́pàá Eko: A ti fi Tekno sílẹ̀ àmọ́ ìwádìí sì ń lọ lọ́wọ́ 7 Ògún 2019 Oríṣun àwòrán, Social media Ileeṣẹ ọlọpaa ti fi ọrọ wa gbajugbaja akọrin takasufe, Augustine Kelechi, ti awọn eniyan mọ si Tekno lẹnu wo, lẹyin to rin kiri igboro ilu Eko ninu ọkọ kan pẹlu awọn obinrin to wa ni ihoho.
Olayinka, eni ti o je olugbalejo agba lu Ajimobi lọgọ ẹnu
Aṣoju PFN naa sọ pe ohun to yẹ ki awọn ọmọlẹyin Kristi ṣe ni pe ki wọn gbohun adura soke ju ti atẹyinwa lọ.
Mo ti gbọ́ bí o ti lọ sókè sódò ni òde ayé yìí tí o ń wá ọgbọ́n kiri àtti pe bí o sì ti jẹ wí pé bàbá rẹ fẹ́ràn rẹ ti o sì tọ́jú rẹ bí bàbá tíí tójú ọmọ.
Bí ó bá ti ń sá fún idà,bẹ́ẹ̀ ni ọfà bàbà yóo gún un ní àgúnyọ-lódì-keji.
Pásítọ̀ ìjọ Sotitobire padà yọjú sílé ẹjọ́ lónìí, àbọ̀o rèé.
 “A gbudo sa ipa wa lati da oro ilu yii pada sibi ti o wa tele, yala lori epo robi, eto ogbin, eto irinna, ina abbl.
Yakubu Dogara gbo ikede abajade ibo ohun, o dupe pupo lowo awon eniyan ekun re
Inú káàdì ìránti tí mo rí he ní mó tí rí fọ́tò ìhòhò Salawa, mó kàn fẹ́ gbà owó díẹ̀ ni- Afurasí Ọwọ́ ọlọpàá tí tẹ ọ̀kan nínú àwọn ọ̀daràn tó ṣekú pa Uwaila Ohun mẹ́fà tí àgbáyé kò mọ̀ nípa Majek Fashek tó d'olóògbé nìyí ₦35,000 ni mò ń gbà bíi Adelé ọba, kò sí ọkọ̀ ayọ́kẹ́lẹ́ - Adelé Olúbọ̀rọ̀pa Ìròyìn sọ pé Alfa Babatunde àti àwọn tó kù ti padà sí inú ẹ̀wọ́n Olokuta ní Ondo láti tẹ̀síwájú ìgbẹ́jọ lọ́la Sáájú ni Temitope Kolawole tó jẹ́ bàbá ọmọ tó sọnù sọ fún ilé ẹjọ́ pé àwọn olólùfẹ́ Alfa Babatunde pébò òun ti wọ́n sì fa aṣọ òun ya kí òun tó sá lọ ba Deji Akure láti ṣe àwárí ọmọ òun.
Lẹ́yìn náà ó pàṣẹ fún Uraya alufaa, ó ní, “Máa lo pẹpẹ ìrúbọ tí ó tóbi yìí fún ẹbọ sísun àárọ̀ ati ẹbọ ohun jíjẹ ìrọ̀lẹ́, ati fún ẹbọ sísun ati ẹbọ ohun jíjẹ ti ọba, ati fún ẹbọ ohun jíjẹ ati ti ohun mímu ti àwọn eniyan.
Ẹni tí ó gbẹ́ kòtò ni yóo jìn sinu rẹ̀,ẹni tí ó bá já ọgbà wọlé ni ejò yóo bùjẹ.
Maria Magidaleni bá lọ sọ fún àwọn ọmọ-ẹ̀yìn pé, “Mo ti rí Oluwa!
O wa parọwa si ara ilu pe ki wọn má kaare ọkan nipa ijiroro eleyi ti yóò ''pé àkíyèsí sí bí wọn ti ṣe lè mú ìyípadà wa.
Lati kekere ni Majek Fashek ti ni ifẹ si orin kikọ; ifẹ to ni fun orin kiks naa lo mu ki o darapọ mọ ijọ aladura ti iya rẹ n lọ gẹgẹ bi akọrin.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Waris Kareem: Emmanuel Macron kan sáárá lórí àwòrán tó yà Igbimọ alakoso ileewe gbogboniṣe Igbajs ṣepade lori ọrọ naa nibẹ ni wọn si ti pinnu pe ki ọgbẹni Olugbenga Ọlaolu o fi ipo giwa ileewe naa silẹ.
Se afiwe iye owo re pelu: sẹnatọ kan iwọ Ọgbọn ọjọ Jẹ ka ri oun too gba Pin oju ẹrọ yii twitter facebook email Jẹ ka ri oun too gba Pin oju ẹrọ yii twitter facebook email Jẹ ka ri oun too gba Pin oju ẹrọ yii twitter facebook email Lati igba ti o ti wa loju opo yii O ti gba: Awọn to seto yii Olawale Malomo lo se eto yii, nigbati Manuella Bolomi ya atẹ yii Bi a se se eto yii A lo ọrọ ti ọkan lara awọn sẹnatọ orileede Nigeria, sẹnatọ Shehu Sani, lọjọ keje, Osu Kẹta, 2018.
AMAA 2018 Ami eye adari fiimu alalaye to dar julo
com Kayeefi ni ọrọ da ninu ọgba ileeṣẹ ajọ to n mojuto igbokegbodo ọkọ nipinlẹ Ogun, TRACE, lasiko ti ọkunrin kan gbẹmi mi sibẹ.
Olukuluku àwọn aṣọ́nà ni ó ní àkókò iṣẹ́ tirẹ̀.
Ṣugbọn àwọn ajá a máa jẹ ẹ̀ẹ́rún oúnjẹ tí ó bọ́ sílẹ̀ láti inú àwo oúnjẹ oluwa wọn.
Bí mo bá jáde lọ sí ìgbèríko,àwọn tí wọ́n fi idà pa ni wọ́n kún bẹ̀!
Amọ ibeere to wa n daamu ọ̀kan awọn eeyan ni pe o se jẹ pe akoko ti ipalẹmọ feto idibo Ọsun doju ọgbagade, ni Akintayọ sọ̀ pe oun ko sisẹ mọ.
Wọn ni ẹgbẹ ANC lọwọ ninu ikọle awọn ajoji.
Ta ni Mohammed Umar: Ṣaaju ki wọn to yan sipo, Umar Abba jẹ igbakeji Kọmisana ọlọpaa to si tun jẹ oludari gbogbo eto ni ajọ EFCC.
Awọn alajọgbele rẹ kan naa n lo awọn ọmọde fun iṣẹ naa.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìlú Igbo-Ọra: Ijọba ipinlẹ Ọyọ ṣe ayẹyẹ ọdun ibeji fún ìgbà àkọ́kọ́ 13 Ọ̀wàrà 2018 Àkọlé àwòrán, Awọn akọṣẹmọṣẹ nipa onka awọn eeyan ilu fidirẹ mulẹ wi pe ilu Igbo Ọra lo ni onka awọn ibeji to pọ julọ l'agbaye.
Amohunmaworan orileede náà ni Aare tí soro ni Ọjoru, èyí tó sì ni yóò bẹ̀rẹ̀ loni waransesa.
Àjọ NIMC ti gbé ìlànà tuntun jáde fún gbígba NIN lọ́nà ìrọ̀rùn Oríṣun àwòrán, NIMC Ajọ to n mojuto eto idanimọ lorilẹede Naijiria, NIMC, tun ti fi awọn ilana tuntun sita lori eto iforukọsilẹ fun gbigba nọmba idanimọ NIN.
Nítorí kì í ṣe àwọn nǹkan dúkìá yín ni mo fẹ́ bíkòṣe ẹ̀yin fúnra yín.
Arabinrin Abidemi ni  ”ero to ye kaadi wo naa n se ise dara-dara ni gbogbo ile-idibo to wa ni ayika oun.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, AFCON 2019: Ki akọnimọọgba Naijira bá wọn sọ̀rọ̀ kóríyá Ọmi ni ikọ agbabọọlu Tunisia ta ninu ifẹsẹwọnsẹ mẹta ti wọn kọkọ gba, ki wọn to na Ghana pẹlu wo mi ki n gba siọ ni ipele ẹlẹni mẹrindinlogun.
Ìlànà ojúlówó márùn ún tó dènà àrùn Coronavirus Kí lo mọ̀ nípa fẹntilétọ̀, ohun èlò aṣèrànwọ́ èémí Ìtàn Manigbagbe: Àwọn àjakalẹ-àrun to ti wáyé rí ṣáájú Coronavirus Ibadan ń tiẹ̀ ni Kurunmi, tii se Ààrẹ Ọ̀nà Kakanfo fẹ́ di Aláàfin, lo se n tako òun, òun náà kò si ní gbà kó di Aláàfin lẹ́yìn Atiba, torí Kurunmi yóò di olórí kunkun bii Afonja ni.
O le ni miliọnu mẹtadinlogun eeyan to maa dibo ni Ghana.
Iṣẹ́ Tí OLUWA Rán sí Àwọn Ọmọ Israẹli ní Ijipti.
" awon griiki ayeijoun n pe awon ara india ni "" indoi "" ( Ινδοί ) , awon eniyan indus ."
Sarkin Yara ‘A’ Ward ni agbole  re ni,Daura.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Akomolede ati Asa lori BBC: Olùkọ́ Kikelomo Ogunboye tan ìmalẹ̀ sí ìwà olè ọ̀gá ọlọ́pàá Bakan naa ni minisita naa sọ pe adinku to ba owo epo kii ṣe lati fi opin si amojuto ti ijọba n ṣe, nitori pe ko ni ipa lori eporọbi.
A ti di aláìníbaba, ọmọ òrukànàwọn ìyá wa kò yàtọ̀ sí opó.
Ile epo kan to wa ni agbegbe Akute ni Ipinlẹ Ogun wa lara awọn ile ti wọn ti pa naa.
Atamataṣe naa to jẹ goolu pupọ fẹgbẹ rẹ fifẹ han si pe oun fẹ ṣoju ẹgbẹ to wa ni ipele ikini.
Mo bẹ̀ yín pé kí ẹ ṣe ìtọ́jú ìjọ Ọlọrun tí ẹ wà ninu rẹ̀.
"Kabiyesi tẹsiwaju wipe, ọdun egungun kii ṣe fun ibọriṣa, bikoṣe fun igbelaruge aṣa ati ere idaraya.
lọwọ awọn ọmọ ijọ ti wọn n ṣẹsin ninu mọsalaṣi naa fun owo ti wọn
Toyin Abraham fi orin yẹ́ Iyabo Ojo sí níbi ìsìnkú ìyá rẹ̀, Falz di ẹni tí wọ́n fí òpópónà ṣọ orí rẹ̀ Látilẹ̀ ni mo ti fẹ́ràn orin ìjọ Kérúbù àmọ́ ẹlẹ́sìn mùsùlùmí àti krìstẹ́nì ni mí- Qdot Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Wọ́n rò pé mo ya wèrè ni Saudi lẹ́yìn ikú ọkọ mi Èmi kọ́ ló pàṣẹ fún àwọn sọ́jà láti máa pa èèyàn ní Oyigbo - Nyesom Wike Oríṣun àwòrán, @Wike Gomina Nyesom Wike sọ pé òun kọ́ ló rán àwọn sọ́jà láti má a pàáyàn ni Oyigbo Gomina ipinlẹ Rivers, Nyesom Wike, sọ pe oun kọ lo ran awọn sọja láti lọ paayan ni Oyigbo.
Wọn ko tii ri awọn ejo naa pa,"" Ọgbẹni Toby ni oju iho kekere kan ni wọn gba sa lọ."
" Ọgbẹni Loveday to kọ awọn ọrọ to ba ni lọkan jẹ ọhun sọ pe igbeaye ko le ri bakan naa mọ fun oun lẹyin iku arẹwa obinrin naa.
Alimi wa dupẹ lọwọ gbajugbaja agbohunsafẹfẹ nni, Funmi Iyanda, fun bo se gbaruku ti oun ninu irin-ajo aye rẹ.
Ẹ pa wọ́n, kí ẹ sì run wọ́n patapata.
Oríṣun àwòrán, Others Àkọlé àwòrán, Ajọ Niger Delta Development Commission ti kéde pe òwúrò Ọjọ́bọ̀ ní àdarí ẹ̀ka ètò ìṣúná yóò jáde láyé.
naa tun wa dari iko olopaa lati lo pese aabo to nipọn ni awon ibi ti alafo eto
Eekan amofin naa fi kun un pe, ọdaran ni ẹnikẹni to ba lọwọ ninu iṣẹlẹ idajọ ọwọ labẹ ofin.
Ni orilẹede Peru, omi ara ọpọlọ ti wọn ti rẹ ni awọn fi n se ara rindin, ti wọn si tun n ta a fun awọn eniyan gẹgẹbi omi ẹlẹrindodo to n mu araji pepe.
Kini Afẹnifẹre n sọ lori Amọtẹkun?
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Wole Soyinka: Ohun ìtìjú ni fún Naijiria bíí ìjọba se ti Sowore mólé 13 Bélú 2019 Oríṣun àwòrán, OTHERS Àkọlé àwòrán, Ọpọlọpọ awọn èniyàn ló ti bu ẹnu àtẹ̀ lu bí ìjọba se fi Omoyele Sowore sí àtìmólé Àjọ DSS.
Àdàbà mi, tí ó wà ninu pàlàpálá òkúta,ní ibi kọ́lọ́fín òkúta,jẹ́ kí n rójú rẹ, kí n gbọ́ ohùn rẹ,nítorí ohùn rẹ dùn, ojú rẹ sì dára.
Ayodele sọ fun iwe iroyin Tribune pe, oun kilọ fun Trump lati ṣọra ṣe lori ilana iṣejọba to n lo, ati ofin to n gbe jade, to ba fẹ ki wọn dibo yan oun lẹẹkeji.
Egypt ṣíná fún Zimbabwe, ẹ̀kọ́ mẹ́rin tó yẹ ní kíkọ́ Ẹyẹ ju ẹyẹ lọ, Super Eagles fi àmì ayò kan gbé ẹyẹ Swallow ti Burundi mì Wo àwọn ẹranko tí wọ́n máa figagbaga ni Egypt Wo ohun tuntun tó n ṣẹlẹ̀ lágboolé CAF Jane Nwaeze tó jẹ agbẹnusọ fawọn ọdọbinrin agbabọọlu Naijiria ṣalaye fun BBC pe irọ ni pe awọn Super Falcons n fẹhonuhan ni France.
Ẹ wá gba káàdì ìdìbò yín o!
Koda ajọ SERAP gan an ti fi sita pe eto aabo ti n gbẹbọ ni Naijiria bayii: Iku ọmọ olori afẹnifẹre yii lo ti n bi ige tai adubi pẹlu ọpọlọpọ ibeere lori iṣejọba aarẹ Buhari lasiko yii.
Kọmiṣọna ọlọpaa ni ipinlẹ naa, Austine Agbonlahor ni oun ko ti i gbọ nipa iṣẹlẹ naa.
Kiprotich pari ere ọun ti o jẹ ogoji ati meji kilomita ni iwọn wakati meji, isẹju mọkanla ati isẹju aaya mẹrin.
Ìyàwó mi yọ̀ púpọ̀, a ṣiré títí ilẹ̀ fi ṣú, a sì jẹun tí ó gbádùn nítorí mo mú ẹyẹ àparò bọ̀ gẹ́gẹ́ bí ó ti sọ fún mi nígbà tí mo fi í sí ibùdó ní Igbó Olódùmarè tí mo ń lọ ṣe ọdẹ.
Gómìnà tún kéde pé, ètò wà nílẹ̀ láti tún gbogbo àwọn àgọ́ ọlọ́pàá tí wọn ti dáná sun, tí wọn yóò sì ra ọkọ̀ míràn tí àwọn jàndùkú ti bàjẹ́.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ilé ẹjọ gíga India dajọ pé ìbálòpọ̀ ọkunrin sí ọkùnrin b'òfin mú 6 Owewe 2018 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Òfin to sì lòdì sí ìbálòpọ̀ láàrin ọkùnrin sí ọkùnrin yi ti wa tipe lorílèèdè India Ilé ẹjọ gíga l'orílẹ̀èdè India ti kede ìdájọ kan to ní ìbálòpọ̀ láàrin ọkùnrin sí ọkùnrin wa ni ìbámu pẹlú òfin orílèèdè náà.
Igba mii a dapọ mọ omi, awọn ounjẹ ti ko sẹrẹ ninu lee jade pẹlu ẹ.
Jagaban ti ilu Borgu lawọn miran fi n gbe ọkọ Olurẹmi larugẹ.
Bulama ni lilo awọn abanijagun ilẹ okere lasiko ogun maa n gbowo lori gan tori wọn maa n diidi ya owo gọbọi sọtọ lati gba wọn ni.
Coronavirus in Nigeria: Èèyàn 675 ló tún ti ní Covid-19 ní Naijiria
Ìwọ Jerusalẹmu, fọ ibi dànù kúrò lọ́kàn rẹ,kí á lè gbà ọ́ là.
ti ijọba orilẹ-ede South Africa fi mu ọrọ yii.
“Ẹ óo ka ọ̀sẹ̀ meje, bẹ̀rẹ̀ láti ọjọ́ keji ọjọ́ ìsinmi tí ẹ mú ìtí ọkà fún ẹbọ fífì wá fún OLUWA.
Oríṣun àwòrán, @TLA4_6 Bi o tilẹ jẹ pe lọdun 1966, eyiun ọdun mejilelaadọta (52) sẹyin, ni wọn gbẹmi Oloye Akintọla lojiji, ti ọpọ̀ ọdọ atawọn agbagba kan ko si baa laye, sibẹ o yẹ ka lee mọ iru isẹ́ ribiribi ti akikanju ọmọ Oodua yii se.
Ọjọ kinni, Oṣu Keji ọdun 2020 ni ijọba ipinlẹ Eko labẹ iṣakoso Gomina Babajide Sanwo-Olu gbẹsẹle ọkada ati kẹkẹ maruwa lawọn ijọba ibilẹ kan, leyi ti inu ọpọ awọn olugbe ipinlẹ naa ko dun si.
Barcelona Vs Liverpool: Barca sọ ara rẹ̀ di ìbákà, orin góòlù mẹ́ta ló kọ sí etíi Liverpool.
 Wo orílẹ́èdè tí wọ́n tí ń dáwó ìsìnkú ara wọn pámọ́ Ayédèrú Ọ̀ṣun ni wọ́n ń bọ lónìí, kìí ṣe ojúlówó - Bàbá Ọlọ́ṣun tún figbe ta Iṣẹ́ bọ́ lọ́wọ́ ọlọpàá mẹ́rìn to pa afurasí, wọ́n tún dèrò ẹ̀wọ̀n Ẹgbẹ́ Ilẹ̀ Yorubà gba Aṣíwájú tuntun!"
Ìdì abájọ mẹ́ta táwọn arẹwà fi ń gba ti Aláàfin Àjọ NAFDAC fọwọ́ sí pípo ògùn chloroquine fún àyẹ̀wò ìtọ́jú coronavirus Ṣé Ọ̀jọ̀gbọ́n Ibrahim Gambari ni yóò rọ́pò olóògbé Abba Kyari gẹ́gẹ́ bíi olórí àwọn òṣìṣẹ́ iléeṣẹ́ ààrẹ?
Ola Aina and Odion Ighalo combined on match-day one of the #TotalAFCON2019 to steal the spotlight and score a sublime goal.
Àwọn ojúlówó ǹkan ìṣeré ìbálòpọ̀, bí o bá ti gbé e lé ojú ara, yóò máamú ara rẹ wà lọ́nà láì kan ojú ara torí afẹ́fẹ́ ló ń lò kò si ni kanra.
Oríṣun àwòrán, Instagram/Okunnu ''Lati igba ti mo ti wa nile iwe alakọbẹrẹ ni mo ti bẹrẹ ere tiata ni ṣiṣe, ṣugbọn ko si ọkan ninu baba ati iya mi to fọwọ sii pe ki n ṣiṣẹ tiata,'' Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fọ́nrán ohùn, Sajẹ: Mo n rọ awọn akẹẹgbẹ mi lati se suuru de asiko Ọlọrun Ṣugbọn lẹyin ti baba mi papoda tan, mo beere iyọnda lọwọ mama mi pe, ki wọn jẹ ki n ṣe ere tiata.
Ẹni tí ń gun awọsanma lẹ́ṣin, àní awọsanma àtayébáyé;ẹ gbọ́ bí ó ṣe ń sán ààrá, ẹ gbọ́ ohùn alágbára.
Àwa, tí a wà nínú ìlú, ni a ó fi ààbò bò tí a ó sì ké pe àwọn aráa wa ní òkè òkun, kí àwọn náà ó ké gbàjarè, nítorí ìwé ẹ̀rí ọmọ-ìlú-fún-ìrìnnà ṣe kókó fún wọn.
Ọkunrin tí orúkọ rẹ̀ ń jẹ́ Ẹ̀ka ni yóo gba ipò rẹ̀, òun ni yóo sì kọ́ ilé OLUWA.
Àkọlé àwòrán, Àwọn oludije Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Reyder ń béèrè ìbéèrè ìkẹ́gàn náà lọ́wọ́ àwọn èèyàn-an rẹ̀.
O ni asiko ti to ki awọn adumaadan, ibadiaran, eyinfunjowo, aguntaṣọọlo obinrin Naijiria maa gbe ara wọn larugẹ.
Wo àwọn ǹkan ti kò hàn síta púpọ̀ nípa Moses Wo àwọn míniístà mẹ́fà tí ẹnu ń kùn jùlọ Shehu Abdullahi darapọ mọ Bursaspor Agbebọn pa eeyan 17 l'Amẹrika Papa iṣere yii ni wọn ti gba aṣekagba idije Europa League.
Ọjọ kẹtadinlọgbọn oṣu keji to lọ ni ajọ INEC kede pe, aarẹ Buhari lo jawe olubori ninu ibo aarẹ pẹlu ibo to le ni miliọnu mẹẹdogun, ti Atiku si se ipo keji pẹlu ibo miliọnu mejila o le diẹ.
Ṣimei, ará Rama, ni ó wà fún àwọn ọgbà àjàrà.
Soyinka tun wa ki Ṣowore pe o kaabọ si agbo awọn ti wọn ti fẹsun kan ri.
 Ó bá bàbá rẹ ̀ àti à ̀ ǹtí rẹ ̀ ṣe ìrìnàjò lọ sí ìlú Òyìnbó .
Nígbà tí ọba bá jókòó sórí ìtẹ́ ìdájọ́ rẹ̀,ojú ni yóo fi gbọn àwọn ẹni ibi dànù.
akede Najiria , Voice of Nigeria  soro lori ero ibanisoro ni ipinle Calabar,ti o
Ẹ kò ṣe fọwọ́ kàn mí?
Ó bá tú gbogbo ọkàn rẹ̀ palẹ̀ fún Delila, ó ní, “Ẹnìkan kò fi abẹ kàn mí lórí rí, nítorí pé Nasiri Ọlọrun ni mí láti inú ìyá mi wá.
Eeyan mẹrin ku ninu ijamba ọkọ l'Eko Ijamba ọkọ-ofurufu ologun pa 'yan mẹjọ Nigba to nfidi isẹlẹ naa mulẹ, oludari agba fun ajọ ẹsọ oju popo nipinlẹ Ogun, Clement Ọladele ni ẹmi meje lo bọ ninu isẹlẹ naa nigbati eeyan mejila si farapa .
Ajọ to n gbogun ti ajakalẹ aarun lorilẹ-ede Naijiria, NCDC ti kede pe eeyan 1,016 miran ti kun iye awọn to ti ni aarun COVID-19 ni Naijiria.
Kìí yọ àwọn kọ́kọ́rọ́ ojú kékeré séèfù yìí.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Davido, Simi,Omawumi gbégba orókè nínú ìdíje 2018 6 Èbibi 2018 Oríṣun àwòrán, Simi/Davido/Omawumi/Instagram Àkọlé àwòrán, Ọ̀kẹ́ àìmọye olórin lo kópa níbi igbami ẹyẹ 'Headies' elekeejila tí ọdún 2018.
Nígbà tí ó bá dé ilén óo jẹ́ kí wọ́n fi idà pa á.
Ọrọ wa lori ọrọ kobakungbe ko yi pada Oríṣun àwòrán, @inecnigeria Àkọlé àwòrán, Adele Ọga ọlọpaa tuntun ni iṣẹ nla niwaju pẹlu idibo 2019 to n bọ lọna Adele Ọga ọlọpaa tuntun lorileede Naijiria Mohammed Adamu naa ti da si ọrọ to wa nilẹ yii.
Àbúrò ìyàwó mi yìí bá wa kúrò ní odò Ìrántí, nítorí ó fẹ́ràn ìyàwó mi púpọ̀.
"Kò sí ọkùnrin tí yóò fún obìnrin tó halẹ̀ bíi tèmi lówó - Lizzy Anjorin Táyà ọkọ̀ agbépo tó fọ́ fa ìjàmbá ọ̀kọ̀ l'Ékò, èèyàn kan farapa Boris Johnson àti ẹgbẹ́ rẹ̀ wọlé ìbò, Trump àtàwọn ààrẹ míì kíi kú oríire Ọdun ń lọ sópin, ariwo 'ń sọ̀ ní ilé ńlá l'Abuja Ẹjọ́ Sowore bọ́ sọnù lọ́wọ́ àjọ DSS Ẹ́ wo ojú àwọn òṣèré tíátà tó péjú sí Ibadan fún ìpàdé ọlọ́dọọdún Òṣìṣẹ́ INEC méjì yóò ṣẹ̀wọ̀n ọdún 21 nítorí owó ẹ̀yìn N362m 'Penis Fish"", ẹ̀ja tuntun tó rí bí ǹkan ọmọkùnrin lùwẹ̀ jáde lórí òkun Joana to jẹ ọmọ ọdun mẹrindinlọgbọn ni kọmiṣọnna ti ọjọ ori rẹ kere julọ kaakiri orilẹede Naijiria bayii."
 ilé-ẹ ̀ kọ ́ náà kọ ́ kọ ́ gba àwón ọgọ ́ rùún ó lé mẹ ́ wàá akẹ ́ kọ ̀ ọ ́ wọlé nígbà àkọ ́ kọ ́ fún sáà ètò ẹ ̀ kọ ́ ọdún náà nígbà tí wọ ́ n ń pèsè ètò ẹ ̀ kọ ́ national diploma àti higher national diploma fún àwọn akẹ ́ kọ ̀ ọ ́ wọn gbogbo .
Everton já Manchester United sí ìhòhò lọ́jọ́ Àjíǹde Bakan naa, iroyin tun sọ pe awọn gomina gan an ko sai fọwọ si igbesẹ ile iṣẹ ọlọpaa ọhun.
Ewe, awon onidanilaraya yoo ni lokan pe, aare Macron ni yoo je aare akoko ti yoo nife lati sabewo sile igbafe ohun.
Adura ni ki a maa gba pe ki Olorun fun wa ni adari rere ,to ni iberu okan ni gbogbo eka ijoba orile yii.
Ajo FIFA so ninu oro re pe, olokan-o-ojokan ifesewonse olorejore ti o waye, wa lara ohun ti won se agbeyewo re fun abajade ipo ate tuntun naa.
Loni ọjọ Kẹtadinlọgbọn osu Kọkanla ọdun 2018 ni irinajo ijọba ọdun mẹjọ Gomina Rauf Arẹgbẹsọla dopin, ti ijọba tuntun ti Gboyega Oyetọla yoo si gberasọ.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: BBC yan agbábọ́ọ́lù 5 láti kópa nínú ìdíje ámì ẹ̀yẹ Buhari buwọ́lu owó oṣù tuntun fáwọn ọlọ́pàá Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Jide Kosọkọ: Isẹ́ tíátà yóò gòkè tíjọba bá gbówó kalẹ̀ láti seré Ẹgbẹ agbabọọlu Naijiria lo ṣe ipo keji ni isọri B lẹyin ti wọn jawe olubori ninu meji lara ifẹsẹwọnsẹ mẹta ti wọn gba ni ipele akọkọ, nigba ti Cameroon ṣi leke isọri A.
Nítorí náà, àwọn ni wọn yóo kọ́kọ́ lọ sí ìgbèkùn, gbogbo àsè ati ayẹyẹ àwọn tí wọn ń nà kalẹ̀ sórí ibùsùn yóo dópin.
Wọ́n bá já àwọn ìdákọ̀ró, wọ́n jẹ́ kí wọ́n rì sinu omi.
" Itumọ eyi ni pe, agbekalẹ oju opo BBC Yoruba ko rẹwa to bii ki awọn eeyan tẹwọ gbaa.
Ọlọrun, ìwọ ni ìyìn yẹ ní Sioni,ìwọ ni a óo san ẹ̀jẹ́ wa fún,
wọ́n sì bẹ̀rẹ̀ sí sọ̀rọ̀ sí Mose pé, “Ṣé kò sí ibojì ní Ijipti ni o fi kó wa kúrò láti wá kú sí ààrin aṣálẹ̀?
Ẹ pèsè ẹlẹ́rìí púpọ̀ bí bẹ́ẹ̀ kọ́, Sotitobire yóò jẹ́rìí fúnrarẹ̀ o!
 Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, #Queen Dihya: Obinrin tó gbógun tàwọn agbésùnmọ̀mí ni Algeria Ọpọ eniyan bi i Nadia lo wa ni Cameroon ti wọn ti fi ipa balopọ."
Ayédèrú Lọ́yà tó ń díbọ̀n gbowó lọ́wọ́ aráàlú bọ́ sí gbaga ọlọ́pàá Kílódé tí Ọọni Ife, Oba Ogunwusi kò fi gbọdọ̀ rí ọmọ rẹ̀ tuntun ti Olorì Naomi bí títí di bíi ẹ̀yìn oṣù mẹ́fà?
Tramadol: Ọwọ́ tẹ afurasí méjì tó kó òògùn olóró N60m wọlé l'Apapa
Urechis unicinctus ni eyi ti wọn ri ni Guusu Asia, ounjẹ adidun lo jẹ lawọn orilẹede bii South Korea.
Fún àpẹrẹ, Ìjẹ̀bú lè se ọbẹ̀ ẹ̀fọ́ rirò àti iyán dipò ìkọ́kọrẹ́ fún ọdún tàbi ki Èkìtì se ìkọ́kọrẹ́ fún ọdún dipò iyán àti ẹ̀fọ́ rirò àti bẹ́ ẹ̀ bẹ́ ẹ̀ lọ.
Àwọn àjẹsára àrùn rọpárọsẹ ̀ tí a fi kòkòrò tí a ti pa ṣe náà kò léwu rárá .
Adewole Oniluola: Tunde Kelani ni ikú àgbà Àyàn náà tún mú kí ilẹ̀ Yorùbá sọ ohun rere nù
Bí olùṣọ́-aguntan tií wá àwọn aguntan rẹ̀ tí ó bá jẹ lọ, bẹ́ẹ̀ ni n óo wá àwọn aguntan mi, n óo sì yọ wọ́n kúrò ninu gbogbo ibi tí wọ́n fọ́nká sí ní ọjọ́ tí ìkùukùu bo ilẹ̀, tí òkùnkùn sì ṣú.
O wa gba awọn awakọ ni imọran lati ya patapata kuro ni oju popo nigba ti wọn ko ba le tẹsiwaju mọ ninu irin ajo.
A wa sibi yii lati dupẹ lọwọ awọn eeyan Mali ni nitori isẹgun araalu ni eyi jẹ.
Ní ọdún kejila, ó bẹ̀rẹ̀ sí wó àwọn pẹpẹ oriṣa ní gbogbo ilẹ̀ Juda ati Jerusalẹmu.
“A wo awon ona miiran ti le gba mu okoowo ilu Aba lati lo fi je anfaani fun ipinle wa mejeeji.
Ènìyàn 284 ló ní àrùn Coronavirus ní Ọjọ́òrú ní Nàíjíríà Ènìyàn kán kú, méèje farapa nínú ìjàmbá afárá Otedola ní Eko Àjọ NAFDAC ti bẹ̀rẹ̀ àyẹ̀wò àgbò mẹ́rin tí wọ́n ṣe ní Nàìjíríà fún Covid-19 Ìjẹkújẹ àwọn adarí ìjọba ló sọ mí di alárìnkiri nílẹ̀ òkèèrè-Oluwo A o ranti pe afurasi obinrin naa, Rafiu Modinat, tii ṣe iyawo ọkan lara awọn afurasi yoku, Rafiu Mutiu, lo faake kọri lọdọ awọn ọlọpaa pe oun ko ba awọn afurasi yoku lọwọ ninu iwa ajọmọgbe naa.
Awọn abadofin ti wọn ko ba fẹnuko le lori ti wọn fi so ijokoo rọ yoo lọ soko igbagbe ni.
Ọ̀rọ̀ náà ló wà ní ìparí ìwé tó kọ níbi tí wọ́n ti ní kí òṣèré náà sàlàyé ohun tó fẹ́ nípa ti ìbálòpọ̀.
Partey to jẹ ọmọ ọdun mẹtadinlọgbọn kopa ninu ifẹsẹwọnsẹ liigi La Liga marun din logoji, o si gba goolu mẹta sawọn fun Atletico ni saa bọọlu to lọ.
"Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Bí ẹ ṣe mọ̀wé tó, ẹ wá dánrawò níbí pẹ̀lú ""Àpólà Ọ̀rọ̀ Orúkọ - Noun Phrase ""Idí ti a fi dá ẹgbẹ́ yìí sílẹ̀ ni, ìròyìn tó ni èdè Yoruba yóò parun láìpọ́ àti pé ètò ààbò ìràn Yoruba mẹ́hẹ."
Sibẹsibẹ, Jeroboamu, ọmọ Nebati, iranṣẹ Solomoni, ọmọ Dafidi, dìde, ó ṣọ̀tẹ̀ sí Solomoni, oluwa rẹ̀.
“OLUWA wí fún mi pé, ‘Kìlọ̀ fún wọn kí wọ́n má gòkè lọ jagun, nítorí pé n kò ní bá wọn lọ; bí bẹ́ẹ̀ kọ́ àwọn ọ̀tá yóo ṣẹgun wọn.
itesiwaju lenu ise naa lataari olokan-o-jokan ise ribiribi re eleyi to n gbese
Ẹ dáríjìn mí, gbogbo ẹ̀yin tí mo ti ṣẹ̀, Ayo Fayose tọrọ àforíjìn Ṣé lóòtọ́ ni pé wọ́n fi òfin de Uber àti Bolt ní pápákọ̀ òfurufú?
Oríṣun àwòrán, MUHAMMAD FUNTUA Ipinlẹ Zamfara ni wọn sun ni alẹ Ọjọbọ lẹyin ti wọn gba idande lọwọ awọn ajinigbe naa, lẹyin ọjọ mẹfa ni akata wọn.
Fúnra mi ni n óo fi wọ́n lé àwọn aláṣẹ ati àwọn ọba wọn lọ́wọ́.
Gómìnà ìpínlẹ̀ Kaduna fún Sanusi ní ipò tuntun Ẹgbẹgbẹrun eeyan ni wọn ti n gba itọju lọwọ, ṣugbọn o ṣeṣe ki awọn naa jẹ Ọlọrun nipe, to tunọ si pe iye awọn to gbẹmi mi nitori arun naa le ga ju iwọn to wa nilẹ lọ, bakan naa, iye eeyan naa tun le lọ silẹ ju bi awọn onimọ ṣe lero lọ.
Akọnimọọgba Senong ni Lesotho ko gbọdọ fun Osihmen ati Aribo laye, ti wọn ba fẹ bori Naijiria.
Lowuro Ọjooru, lẹgbẹ oselu PDP fi awọran Fayose sí ojú òpó Twitter rẹ pe, awon olópàá yín afẹfẹ tajutaju lù u.
Ṣugbọn Mata kò rójú nítorí aájò tí ó ń ṣe nípa oúnjẹ.
Ṣebí mo ti rí Jesu Oluwa wa sójú?
Ní ìrọ̀lẹ́ ọjọ́ náà ni àwọn angẹli meji náà dé ìlú Sodomu, Lọti sì jókòó ní ẹnubodè ìlú náà.
Davido je okan lara awon onkorin to ti daraba ni Naijiria lasiko yii paapaa ninu orin taka-sufe.
Ṣé àwọn ẹyẹ igún ṣùrù bò ó ni?
Lára èyí ni, ọmọbìnrin ogójì ọdún kan Kanya Devi rí ìkọlù tí a sì lù ú pa lẹ́yìn tí mọ̀lẹ́bíi rẹ̀ fi ẹ̀sùn kàn án ní agbègbèe Ajmer.
A óo máa ṣe ìdájọ́ ẹ̀tọ́ ní gbogbo ilẹ̀ náà,ìwà òdodo yóo sì wà níbi gbogbo.
Síwájú sí i, ó ní wípé ọjọ́ ìbíi Mao Zedong, bàbá ìsàlẹ̀ Ìlú-tí-kò-fi-ọba-jẹ ti Èèyàn-an China, ni ó yẹ kí a kà sí Kérésìmesì ìlú China:
Bakaana ni wọn ni ọmọ ogun mẹrin farapa ninu isẹlẹ naa to waye lalẹ ọjọ isẹgun.
“ O  wa ro awon eniyan ti wọn ko pada wa si orile
Ó fi òkùnkùn bo ara,ìkùukùu tí ó ṣókùnkùn,tí ó sì kún fún omi ni ó fi ṣe ìbòrí.
Ọmọbinrin Farao sọ fún ìyá ọmọ náà pé, “Gbé ọmọ yìí lọ, kí o máa bá mi tọ́jú rẹ̀, n óo sì san owó àgbàtọ́ rẹ̀ fún ọ.
Ṣugbọn ní ọdún kejidinlogun tí Josaya ti jọba ni àwọn eniyan ṣe Àjọ̀dún Àjọ Ìrékọjá fún ògo OLUWA ní Jerusalẹmu.
ẹni tí o ń wá ìgbéga fún ọmọnìkejì ko ní sí láàrin àwọn èrò ilẹ̀, ìkà kò lágbára níwájú Olóòótọ́, à ṣíírí Onígbèrága kìí bọ̀, ìṣubú onígbèrága dábí ìgbà tí ẹ̀fúùfù ńlá bá fẹ́ igi okó, tí ó wo ìrokò lulẹ̀, tí ó dá ẹka ìrókò, tí ewé ìrókò rẹ̀ sílẹ̀, ttí igi náà sì gbẹ; àsẹ̀yìǹwá àsẹ̀yìnbọ̀ Olú ń hù lára rẹ̀, ó di ààbò fún òkété, ibi ìṣiré àwọn ẹyẹ ibùgbé àwọn ejò, ibi tí aláǹgbá ti ń lé ara wọn kiri nítorí onígbèrága, kò fẹ́ ire ọmọ ẹlòmíràn, o ń fẹ́ kí a rí òun níkan ṣo ṣo.
Ọmọ Nàìjíríà ń retí ifẹ ẹ̀yẹ AFCON lọ́dọ̀ yín - Aarẹ́ Buhari Bí ìdíje láàrin Nàíjíríà àti South Afrika ṣe lọ sí Ta ni Ọgágun àgbà Lamidi Adeosun tó ṣẹṣẹ gba ìgbéga?
Mo ṣá rí kinní kan tí ó dúró;gbogbo nǹkan parọ́rọ́,nígbà náà ni mo gbọ́ ohùn kan tí ó wí pé,
Anthony Joshua vs Pulev: Anthony Joshua rọ̀jò ẹ̀ṣẹ́ lu Pulev
Wọn kò sì tíì gbé ẹ̀jẹ̀ rẹ̀ wá sinu ibi mímọ́, gẹ́gẹ́ bí mo ti pa á láṣẹ.
Niṣe lori ẹrọ ayelujara n du to to to leti eeyan ni gbogbo iṣẹju fun bi awọn eeyan ṣe n da si ọrọ̀ naa.
Dele: 'Oṣù mẹ́jọ ni wọ́n tí yọ ina wa ló jẹ́ kí Dele lọ ṣe iṣẹ́ àmúrelé nídìí ẹ̀rọ ATM
Orukọ Amutọrunwa ni eyi to maa n ṣapejuwe ipo ti ọmọ naa wa bi a ṣe bii ni eyi to fihan ohun ti ọmọ naa n ṣe lati ọ̀run ni ikùn iya rẹ wa sile aye.
Ohun mẹ́fà tí ọ̀pọ̀ kò mọ̀ nípa ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ Arsenal àti Machester City Koda, Baba awọn Marlians ni oun ti ṣe orin awọn bii QDot, Vector Tha Viper, Dagrin, 9ice ati awọn mii, kii ṣe ti Naira Marley nikan.
Iṣẹ́ bọ́ lọ́wọ́ ọ̀gá ilé iṣẹ́ ológun lórí ikú Fulani 134 A kò lè gba àwọn jandùkú Fulani láàyé nílẹ̀ Yoruba -Awọn gómínà Àwa ọba alayé ń wọ́nà láti ṣẹ́ eegun ẹ̀yin ọ̀daràn Fulani - Ọọ̀ni Ẹ padà sílé èyin ọmọ wa tó n ṣiṣẹ́ darandaran - NEF ti Fulani O ni ọgbọn ati da wahala silẹ lorilẹede Naijiria ni ipe yii ati pe ko si idi fun awọn ọmọ orilẹede yii lati ko aya soke lori rẹ.
Ẹ jáde kúrò ní Babiloni, ẹ sá kúrò ní Kalidea,ẹ sọ ọ́ pẹlu ayọ̀,ẹ kéde rẹ̀,ẹ máa ròyìn rẹ̀ lọ títí dè òpin ayé, pé“OLUWA ti ra Jakọbu iranṣẹ rẹ̀ pada.
Ọba Lamidi Adeyẹmi, òṣìṣẹ́ adójútòfò àti Abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò kó tó jọba MC Oluọmọ gbé ara rẹ̀ ṣépè nítorí ìwọ́de #ENDSARS Toyin Abraham tú àṣírí ohun tí ọlọ́pàá Náìjíríà sọ mọ́lẹ́bí rẹ̀ kan dà #EndSARS: Àwọn olùwọ́de kọ etí ikún sí àṣẹ ijọba, wọ́n tẹ̀sìwájú ìwọ́de l'Abuja Fulani sọrọ lori SWAT tuntun ti wọn yan pe SARS ko sọ ohun di ọlọrọ rara ṣugbọn o tẹ oun lọrun lati ni orukọ rere ju owo lọ.
Tori eyi wọn ni dandan ni ki aarẹ ṣe atunto ẹka abo ni Naijiria.
Alexis Sanchez lo fi góòlù alákọ̀ọ́kọ́ sọwọ sinu ile Tottenham, ki Ander Herrera naa tó gbá ẹlẹ́ẹ̀kejì wọle, lẹ́yìn tí Dele Alli ti kọ́kọ́ fi góòlù kan kí Man United káàbọ̀ sori pápá ni Wembly.
Máfọ́ya, mo wà pẹ̀lú ẹ, Ajimọbi kàn sí Makinde lóri Coronavirus to ni Coronavirus: Wo ohun tí o ní láti ṣe láti dáàbò bo ara rẹ Èyí ni àwọn tí òfin kónílé-ó-gbélé tí ààrẹ Buhari pa l'áṣẹ kò kàn ní Eko, Ogun àti Abuja Àjọ NAFDAC fọwọ́ sí pípo ògùn chloroquine fún àyẹ̀wò ìtọ́jú coronavirus Ṣaaju ni Salawa ti fi ọrọ kan lede loju opo Instagram rẹ, nibi to ti ṣafihan atẹranṣẹ ti ọkunrin naa, to pe orukọp ara rẹ ni Jason tẹ si.
" Àwọn ọ̀dọ́ Naijiria tun gbe aworan awọn agbalagba asofin Naijiria kọọkan nibi ti wọn ti nsun lẹnu isẹ́ jade lati beere wipe taa wa lọlẹ gan?
 bí wọ ́ n ba pe obìnrin ni dokọdọkọ .
Iye 'Calorie' to wa ninu nkan mimu ẹlẹrindodo Ni ọdun 2015, abajade iwadii kan ninu iwe imọ iṣegun oyinbo 'the Lancet', fihan pe awọn ọmọ orilẹede America n gba 'calorie' ti ko din ni mẹtadindinlọgọjọ sara ni ojoojumọ lati ara awọn nkan mimu to ni ṣuga ninu.
Boasi bá pe Rutu, ó ní, “Gbọ́, ọmọ mi, má lọ sí oko ẹlòmíràn láti ṣa ọkà, má kúrò ní oko yìí, ṣugbọn faramọ́ àwọn ọmọbinrin mi.
Ounjẹ ajẹju a máa ba ọpọlọ wa jẹ.
 àìbániláramu má ń ṣelẹ ̀ lẹ ́ ẹ ̀ ksn nínú mílíọ ́ nù kan .
Iwadi kan tiẹ ti safihan rẹ pe, ofin ibaradọgba yoo mu ki igbe aye idẹrun wa fun ti ọkunrin ati obinrin, ti wọn yoo si ni itẹlọrun pẹlu ipokipo ti wọn ba wa.
Ṣebí iranṣẹ ni wọ́n, tí ẹ ti ipasẹ̀ wọn di onigbagbọ?
 A o tun tẹpẹlẹ mọ awon ileri
O ni: Ïgbe sisun ati ile jijona maa n ba afefe je, bakan naa ni o maa n sakoba fun ile.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Pẹ̀lú gbogbo bùkátà, Bàbá 80 gboyè Masters Aarẹ Buhari ni mi o dẹru ba olu ilu yii o nitori bi mo da abo bo Abuja, ara mi ati igbakeji mi naa ni mo da abo bo""."
Olukuluku wọn jẹ́ iṣẹ́ tirẹ̀ bí Ọlọrun ti rán an.
Ilẹ Gẹẹsi ni orilẹ-ede ti agbabọọlu naa kọkọ gba bọọlu fun.
Gbogbo nǹkan yòókù tí Ela ṣe ni a kọ sinu Ìwé Ìtàn Àwọn Ọba Israẹli.
Eto IPPIS ni ijọba pese lati ma a san owo oṣu oṣiṣẹ lati inu apo isuna kan naa fun owo gbogbo oṣu oṣiṣẹ ijọba, eleyii ti Asuu ni eto isanwo yii yoo gba aṣẹ to gbe awọn duro lati le daduro lai si afikun ijọba lori eto isuna awọn.
gbogbo àwọn ìdílé yòókù ni wọn yóo ṣọ̀fọ̀ tiwọn náà ní ọ̀tọ̀ọ̀tọ̀, àwọn iyawo wọn náà yóo sì ṣọ̀fọ̀ tiwọn lọ́tọ̀.
Ọmọ mi ti bẹ̀rẹ̀ sí rìn dáadáa kí n tóó kí n tóó dé, àkọ́bí mi, àkàrà-oògùn, n kò si lè sọ bí ayọ̀ mi ti pọ̀ tó nígbà tí mo rí i.
Àwọn ọmọ Israẹli bèèrè lọ́wọ́ ọmọ Lefi náà pé, “Sọ fún wa, báwo ni nǹkan burúkú yìí ti ṣe ṣẹlẹ̀?
marundinlogun (15)ati awon nkan miran bii ero ilewo merin; ero igbalode
Lẹ́yìn tí wọ́n ti rìn jìnnà sí ilé Mika, Mika pe gbogbo àwọn aládùúgbò rẹ̀ jọ, wọ́n sì lé àwọn ará Dani bá.
” Ojogbon Yemi Osinbajo so pe, ilana ajo ohun ni “lati kopa ti o ye lakoko, besini lati safihan awon ohun ti a le gbese ati ipa wa fun agbaye, ati lati mu ilosiwaju ba oro oselu, asa ati awon ohun mere-mere ninu eto oro aje.
Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Grammy 2018: Wetin to expect28 Sẹ́rẹ́ 2018 Why rapper Cardi B surrender hersef give police afta strip club fight2 Ọ̀wàrà 2018 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Social Media Slay: Onílé kan bínú fi àwòrán iyàrá ayálágbé ré hàn lórí ayélujéra
Pasitọ̀ ijọ̀ RCCG marun bọ sọwọ awọn ajinigbe loju ọ̀na Ijẹbu Ode Oríṣun àwòrán, PAstor Adeboye/Facebook Àkọlé àwòrán, Pásítọ̀ ìjọ RCCG Ìròyìn tó tẹ̀ wa lọ́wọ́ ní wí pé àwọn ajínigbé ti gbé òṣìṣẹ́ ìjọ àti Pásítọ̀ ìjọ The Redeem Christian Church of God, tí gbogbo wọ́n jẹ́ márùn ún gbé ní ìlú Ijebu Ode.
Ikilo yi wa ye leyin ti awon omo ogun olote orile-ede South Sudan fi awon awako oju ofurufu omo orile-ede Kenya meji sile ,eyi ti won ti wa ninu ihamo  lati ojo keje osu kinni odun yi, ni agbegbe Akobo nitosi enu ibode laarin re ati orile-ede Ethiopia.
1–3, Jòhánnù àyànfẹ́ yíò wà láàyè títí tí Olúwa yíò fi dé; 4–8, Pétérù, Jamesì, àti Jòhánnù di àwọn kọ́kọ́rọ́ ìhìnrere mú.
Lẹyìn náà ni Gomina Ipinlẹ Eko lákòókò náà, BolaTinubu yàn án gẹ́gẹ́ bíi olùdámọ̀ràn pàtàkì lórí ọ̀rọ̀ àwọn iléeṣẹ́ àdáni lẹ́yìn tí wàhálà bẹ́ sílẹ̀ láàrin Pedro àti Tinubu.
Kò fi ìyàtọ̀ kankan sáàrin àwa ati àwọn; ó wẹ ọkàn wọn mọ́ nítorí wọ́n gba Jesu gbọ́.
Ileeṣẹ aarẹ sọ pe awọn ni imọlara ọpọ ohun tawọn araalu n sọ lori iṣẹlẹ to waye laipẹ yii laarin awọn olugbe ile aarẹ l'Abuja.
Olori orilẹede Tanzania faramọ nini ju'yawo kan lọ lati fopin agbere Oríṣun àwòrán, Zambian Observer Kinni iroyin naa?
Sibẹsibẹ, ó gbà wọ́n là, nítorí orúkọ rẹ̀;kí ó lè fi títóbi agbára rẹ̀ hàn.
- Primate Ayodele sọ àsọtẹ́lẹ̀ N kò tíì pa ọ̀rọ̀ ìfẹ́ tì, bí mo tilẹ̀ ti kúrò nílé ọkọ - Mercy Aigbe Bakan naa lo tun ni aawọ to maa n waye laarin awọn agbẹ ati darandaran yoo tubọ pọ si ninu ọdun 2021 ati siwaju si, jakejado Naijiria.
Àbùkù mi wà lára mi tọ̀sán-tòru,ìtìjú sì ti bò mí.
Lẹ́yìn náà ni n óo jáde lọ.
" nínú "" the bankers magazine "" wọ ́ n ṣe àtèjáde rẹ ̀ ní ọdún 1964 báyìí : "" jẹ ́ kí n sọ fún ẹ nípa òfin kòtò : tí o bá bá ara rẹ nínú kòtò , maa ṣe gbẹ ́ ẹ síwájú si "" ."
Ofin ti f'àyè gba ìbálòpọ̀ Akọs'akọ, Abos'abo ní Botswana Ileejọ Kenya wọgile ofin to ti tẹlifisan pa Ọwọ NAPTIP tẹ babalawo to n fọmọ sowo Àjọ ọlọpàá Eko kédé pé ìbalòpọ̀ nítà kò bójúmu Idi ti ọgba ẹwọn fi nkun akunfaya ni Naijiria 5) Lẹyin ibeere fun ayipada yii ni iru ẹni to le pa ololufẹ rẹ yii a bẹrẹ si ni mu gbogbo nkan le ninu ajọṣepọ naa.
Ipese Iṣẹ Ileri: Mimojuto idasilẹ miliọnu mẹta iṣẹ lọdun kan nipa dida ileeṣẹ silẹ, iṣẹ ijọba ati fifẹ iṣẹ agbẹ l'oju si i.
Yatọ si oṣere, a ni oludari, aṣaraloge, abaniwale, agbohunsilẹ, oni ina mọnamọna, ato itage, ọlọ́wọ́ idan ati bẹẹ bẹẹ lọ.
Ṣugbọn bí ọkunrin kan bá rò pé òun ń ṣe ohun tí kò tọ́ pẹlu wundia àfẹ́sọ́nà rẹ̀, tí wundia náà bá ti dàgbà tó, tí ọkunrin náà kò bá lè mú ara dúró, kí ó ṣe igbeyawo bí ó bá fẹ́.
Àwọn àdúgbò Ibadan gborúkọ tuntun látẹnu Ajimobi ‘Bi Gomina Ajimobi se yan adarí òsìsẹ́ tuntun ní Oyo kò dí wa lọ́wọ́’ Ọmọ atàpátadìde ni mí, télọ̀ ni bàbá mi- Abiola Ajimobi Ọlọ́pàá Nàìjíríà àti Ẹgbẹ́ IMN n ṣé fakinfa lórí ikú àwọn olùwọ́de ìdárò Ashura A gbiyanju lati ba awọn agbẹjọrọ ati alatilẹyin ẹgbẹ oṣelu APC sọrọ lẹyin idajọ naa, ṣugbọn pabo lo jasi.
9 48630 Orilẹede Zambia 527 3.
Ọmọwunmi ni orukọ iyawo rẹ keji.
” Ọba ṣe gbogbo ohun tí mo bèèrè fún mi, nítorí pé Ọlọrun lọ́wọ́ sí ọ̀rọ̀ mi.
Ó ṣe fún Arieli, Jerusalẹmu, ìlú tí ń jẹ́ pẹpẹ Ọlọrun!
O tun kọ wa pe ka maṣe pada lẹyin oloore wa ati iran rẹ nigba isoro.
Nibayii, giwa ileewe fasiti naa, Ọjọgbọn Eyitọpẹ Ogunbọdẹde ti kọ iwe ẹhonu si awọn agbofinro-ọlọpaa ati ileeṣẹ ọtẹlẹmuyẹ DSS lati ṣewadii ọrọ ọhun.
Bí ó bá ṣe pé wọ́n gbọ́n ni,tí òye sì yé wọn;wọn ì bá ti mọ̀ bí ìgbẹ̀yìn wọn yóo ti rí.
Boko Haram ṣíná fún àwọn tó lọ ìsìnkú, èèyàn 23 pàdánù ẹ̀mí wọn Èmi kò ní kí Shiite má ṣe ẹ̀sìn won o -Muhammadu Buhari 'Nàìjíríà, ṣọ́ra, ogun ń sọ ilé ọlá di ahoro!
"O sọ siwaju sii pe ""Afojusun wa ni lati pese idanilẹkọ to peye fun wọn, mo si rọ awọn ti ọrọ naa kan lati mu anfani yii ni ọkunkundun."
Minisita ni kilode ti ajọ IAAF ko ṣe mọ lẹsẹkẹsẹ pe awọn ti ṣi owo san fun Naijiria ti o fi wa jẹ pe lẹyin oṣu meji ni wọn ṣẹṣẹ mọ.
Dokita Faduyile tun sọ pe ọna miran lati daabo ara ẹni lasiko iwọde yii ni lilo ibomu.
lasiko eto idibo aarẹ, paapaa julo  bi
Ìtàn bi Ìjàpá ti fa Àkóbá fún Ọ̀bọ: Ẹ Ṣọ́ra fún Ọ̀rẹ́ Burúkú
Oludari ajọ to n ri si ọrọ awọn ọmọ́ Naijiria to wa nilẹ okere, Abike Dabiri-Erewa sọ fun ileeṣẹ BBC lọjọ Iṣẹgun ọsẹ pe orilẹede Uganda ti jawọ ninu ẹsun ti wọn fi kan wọn lẹyin ọjọ kan tawọn olorin yii farahan niwaju ile ẹjọ majisireeti Uganda.
Àpẹẹrẹ ni èyí fún ìwọ àti èmi, bí a bá fẹ́ kí orílẹ̀ èdè wa yìí máa ti ibi gíga dé ibi gíga a kò gbọdọ̀ sàìfi ara ti Ọlọ́run Ọba.
Ìdí rèé táwọn ọmọ Nàíjíríà kan ṣe ń tako ìdásílẹ̀ ‘Ruga Settlement’ Wọ́n lu àbúrò mi ló jẹ́ kí ń fi ìbínú lu òǹtàjà l‘Abuja - Sẹ́nétọ̀ tó lu obìnrin ṣàlàyé Jọ̀ọ́, má wé orúkọ mi mọ́ ìjákulẹ̀ tó bá ọ - Seyi Makinde kìlọ̀ fún Lanlẹ́yin Ẹ̀mí ogójì ṣòfò, ọgọ́ta míràn farapa nínú ìjàmbá ọkọ̀ epo tó jóná Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, A nilo agọ ọlọpa ni Orin Ekiti fún aabo wa -Falua Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
"Ìyàwó mi fi mí sílẹ̀ kó lọ sílé ọkùnrin míì nínú báráàkì kan náà, àmọ́ mò sí tún fẹ́ràn rẹ̀- Sọ́jà Wo àwọn ìṣesí ojoojúmọ́ mẹ́wàá tó le ṣàkóbá fún ọpọlọ rẹ Gomina Sanwo-Olu sún ọjọ́ ""ṣiṣẹ́ láti ilé"" síwájú fún àwọn òṣìṣẹ́ ìjọba Opral Benson, ẹni ti oge ṣíṣe sọ di gbajúmọ̀ àti Yeye Oge ìlú Eko Ti obinrin bẹẹ ba gbe ọmọ naa fun ọkọ rẹ gangan, to ba di ọjọ iwaju, ti ayẹwo DNA si waye lori ọmọ yii, iwadii fihan pe ayẹwo DNA ọmọ naa ko ni fihan pe ọmọ ale ni."
Eyi ni ibi ti awọn ibudo iforukọsilẹ fun NIN wa kaakiri orilẹede agbaye.
Angẹli náà sọ fún un pé, “Má bẹ̀rù, Maria, nítorí o ti bá ojurere Ọlọrun pàdé.
Obinrin náà bá fi ẹ̀wù rẹ̀ sọ́dọ̀ títí tí ọ̀gá rẹ̀ fi wọlé dé.
Ó bá bèèrè lọ́wọ́ mi pé, “Ṣé o kò mọ ìtumọ̀ wọn ni?
Ọjọgbọn Fagboungbe sọ pe o maa n ṣẹlẹ daada ti obinrin ti wọn hu iwa ipa si, tabi fi ipa balopọ yoo sọ pe oun ko ṣe ẹjọ mọ, lẹyin ti ọrọ ba ti de ileeṣẹ ọlọpaa lọ.
N óo máa gbé ààrin yín; ẹ óo sì mọ̀ pé èmi OLUWA àwọn ọmọ ogun ni mo ranṣẹ si yín.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Sowore, AAC ti yọ Leonard Ezenwa tó kéde ìyọnípò Ṣòwòrẹ́ Segun, Máàkì tóo ní kọ́ ni yóò ṣé atọ́nà oríire rẹ láyé Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Àwọn onímọ̀ ọpọlọ ní to bá gbé ìgésẹ̀ yí, aṣeyege dájú ní ìdánwò Ileeṣẹ ọlọpaa ti wa fi si oju opo Twitter rẹ, igbesẹ ti o yẹ fun araalu ni gbigbe lasiko ti awọn ọlọpaa ba fẹ mu wọn.
Iru awọn iroyinti ẹ le nifẹ si: Ara nni araalu Kini 'barber' ni Yoruba?
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ile igbimọ asofin Naijiria da ijiroro lori aabo duro 31 Sẹ́rẹ́ 2018 Oríṣun àwòrán, @NGRSenate Àkọlé àwòrán, Ile igbimọ asofin sun ijiroro lori aabo s'iwaju Ile igbimọ asofin agba ti orilẹede Naijiria ti da ipade ijiroro ọlọjọ meji lori ọrọ aabo duro.
Eree 'Ori' ni ọdun 2004 lo pokiki Muyiwa, lati igba naa wa ni o si ti n lọ siwaju lai kaarẹ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Asisat Oshoala: ìbẹ̀rẹ̀ mi kò rọrùn rárá nínú eré bọ́ọ̀lù Àkójọpọ̀ àwòrán ọdún Kérésìmesì lágbáyé Òṣèrébìnrin tí wọ́n bá fi ìbálòpọ̀ lọ̀ 'torí ìṣẹ́, kó bọ́ síta láti sọ̀rọ̀ - Kunle Afod Aisha Buhari, ohun mẹ́fà tò fi yàtọ̀ sí àwọn aya ààrẹ tó ti jẹ kọjá!
Ọjọ́ ìpalẹ̀mọ́ fún Àjọ̀dún Ìrékọjá ni ọjọ́ náà.
nigba ti awon oluko fafiti (Academic Staff Union of Universities,ASUU) naa bere
komon-komo lai fi ase mi fale, e lo foju wo awon kudie-kudie ti o wa ni awon
Ní gbogbo ìgbà tí ó bá jẹ́ Nasiri, kò gbọdọ̀ jẹ ohunkohun tí a fi èso àjàrà ṣe, kì báà jẹ́ kóró tabi èèpo rẹ̀.
" O wa gbadura pe ki Ọlọrun ko tu ọkọ, ọmọ, ẹbi ati ọrẹ oloogbe ninu.
Nígbà tí ó yá Ọlọrun lu Jeroboamu pa.
Ta ni ẹ óo sá tọ̀ lọ fún ìrànlọ́wọ́?
Ijamba: Ẹmi akẹkọ mọkanlelogun,olukọ meji bọ ni Kano
Idije boolu alafesegba naa yoo bere lojo kerinla osu kefa si ojo keedogun osu keje odun 2018 ni ilu mokanla.
Nítorí Banaba jẹ́ eniyan rere, tí ó kún fún Ẹ̀mí Mímọ́, tí ó sì gbàgbọ́ tọkàntọkàn, ọ̀pọ̀ eniyan ni ó di onigbagbọ.
ni ti awon omo ile igbimo asofin ba dibo yan oun gẹgẹ bi abẹnugan , oun yoo ri i
Amọ ko si ohun to tẹyin iwadi naa bọ to loju tu.
Mi o ni ṣe ohunkohun ti yoo pa oniroyin lara, nitori pe mo ti ja fun awọn oniroyin ni ọpọ igba."
Àwọn ẹgbọ̀rọ̀ kinniun ń bú fún ìjẹ,wọ́n ń wo ojú Ọlọrun fún oúnjẹ.
Eric Ayiah ati Emmanuel Toku, Patmos Arhin ni won ti fakoyo seyin lati je ki Ghana pegede bayii.
Lẹ́yìn náà, alufaa yóo gbé mààlúù yìí jáde kúrò ninu àgọ́, yóo sì sun ún bí ó ti sun mààlúù ti àkọ́kọ́; ó jẹ́ ẹbọ ìmúkúrò ẹ̀ṣẹ̀ fún gbogbo ìjọ eniyan náà.
Nígbà tí ó pẹ́ tí ọba yìí tí ń rìn káàkiri nínú òṣùpá báyìí ni ó déédéé rí ilé ńlá kan nínú èyí tí wọ́n tan iná sí.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Madagascar Covid 19 Update: Àgbo Covid-19 Madagascar kò ṣiṣẹ́, àwọn ènìyàn tí bẹ̀rẹ̀ sí ní kú níbẹ̀ 21 Agẹmo 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 14 Ògún 2020 Oríṣun àwòrán, AFP Àkọlé àwòrán, Ààrẹ orílẹ̀èdè Madagascar, fi ọwọ́ sọ̀yà lórí àgbo nàá, kódà, ó mu lára rẹ̀ lójú gbogbo ayé lórí tẹlifísàn Ileewosan lorilẹ-ede Madagascar ti n tiraka lati tọju awọn alarun Coronavirus nitori arun naa ti peleke si nibẹ.
Má sì bẹ̀ mí nítorí wọn, nítorí n kò ní gbọ́.
Ìgbà tí ó sì ṣe ni mo rí àbúrò ìyàwó mi ti o ń bọ̀ nínú aṣọ ìyàwó mi.
Àkọlé àwòrán, Ọ̀kan nínú àwọn to péju nibi ayẹyẹ náà rèé Àkọlé àwòrán, Obinrin kan rèé nínú àwọn to lọ si ibi ayẹyẹ Lagos Fashion show Àkọlé àwòrán, Awọn ìmúra tó dá orí ayélujára rú jùlọ lọ́dún 2018 Àkọlé àwòrán, Awọn ìmúra tó dá orí ayélujára rú jùlọ lọ́dún 2018 Ẹwẹ̀, kò tán síbẹ̀ oo, atún ri àwọn aṣọ míràn ti kò níṣe pẹ̀lú ayẹyẹ kankan sùgbọ́n tó jẹ́ àwòdami ẹnu.
Iya Leah Sharibu, Abilẹkọ Rebecca Sharibu nibi to ti n ba awọn oniroyin sọrọ ni ilu Abuja ni ki Aarẹ Buhari sa gbogbo ipa rẹ lati gba ọmọ oun lati ahamọ Boko Haram.
Iroyin ohun so pe, osise oko oju ofurufu Emirates ni o n palemo oko oju ohun lati gbera, ki isele yii to waye.
Oríṣun àwòrán, Thenationonline Àkọlé àwòrán, Wọn fi agidi mu awọn oṣiṣẹ ileefowopamọ lati ṣi ilẹkun rẹ, ṣugbọn owo ti wọn ba nibẹ ko jọ wọn loju rara.
Ní ọjọ́ kìíní, oṣù kaàrún ọdú un 1953 ni Elizabeth gorí oyè.
Aroko yii ni agbara pupọ nitori bi Aole ba kọ, to ṣe bii ojo lai si igba wo, awọn ọmọ ogun Afonja yoo papa pa a ni.
Agiripa Ọba Aláyélúwà, ṣé ẹ gba àwọn wolii gbọ́?
" Ọmọ yorùbá ni Ọmọ nàìjíríà àkọ ́ kọ ́ tí yóò di "" chief justice ' ilẹ ̀ nàìjíríà ni sir adétòkunbọ ̀ adémọ ́ lá ."
Soleimani ń gbìmọ̀ràn láti kọ lù wá l'Amerika la ṣe kọ́kọ́ yára mú u balẹ̀ - Trump Ìdí rè é tí a fí wó ìlè arúgbó ní ìdàjí -ìjọba ìpínlẹ̀ Kwara Àwọn fóònù wọ̀nyìí kò ní lè ṣe WhatsApp láti ọdún 2020 Ọgbẹni Oke-Osanyintolu sọ pe ọkọ to ko okuta ikọle ọhun ja si meji lẹyin to kọlu odi to wa laarin ọna, ti ori ọkọ naa si jabọ lati ori afara.
Ewe, Liverpool ni iko agbaboolu EPL akoko ti yoo pegede sinu asekagba idije UCL lati odun 2012 ti Roberto di Matteo akonimoogba agba iko agbaboolu  Chelsea teleri ti ran iko ohun lowo lati fagbahan Bayern Munich pelu boolu agbesile gba(penalties).
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Sogidi Lake: Kòṣẹja-kòṣèèyàn lá bá nínú adágún odò náà -Ojedele Lara awọn Sinima ti Ogunde gbe jade ni Aye ati Jayesinmi to si tun se awọn ere loniranran lori mohunmaworan nigba ti wọn si ileesẹ WNTV Ogunde lee kọrin bii ẹni layin, ohun rẹ̀ rẹ̀dòdò, to si se awo orin to le ni aadọrun jade ati ere ori itage to le ni aadọta.
Ẹ kò gbọdọ̀ jẹ burẹdi tabi ọkà, kì báà jẹ́ ọkà yíyan tabi tútù títí di ọjọ́ yìí, tí ẹ óo fi mú ẹbọ Ọlọrun yín wá, ìlànà ni èyí yóo jẹ́ fún ìrandíran yín, ní gbogbo ilẹ̀ yín.
Ogbeni Ayariga ;tun wa so pe  “Ayafi ti o ba jo omo orile ede ECOWAS ,ni o ni eto lati da ile-ise sile , lati lati lowo ninu okoowo siseni orile ede Ghana.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Sogidi Lake: Kòṣẹja-kòṣèèyàn lá bá nínú adágún odò náà -Ojedele Agbẹnusọ naa ni, ileesẹ ọlọpaa ipinlẹ naa yoo tubọ maa gbiyanju lati mu alaafia ati aabo duro ni ipinlẹ naa.
Ẹfunroye Tinubu - Ògbóǹtagí oníṣòwò, olówò ẹrú àti afọbajẹ Samuel Ajayi Crowther, òjíṣẹ́ Ọlọ́run tó gbé èdè Yoruba lárugẹ Mọrèmi Àjàṣorò, akọni obìnrin tó gba Ilé Ifẹ̀ sílẹ̀ lóko ẹrú Ọ̀rọ̀ǹpọ̀tọ̀niyùn, Aláàfin obìnrin àkọ́kọ́ rèé, tó ní nǹkan ọkùnrin Ṣé ìwọ mọ odò adágún Adó Àwáyè tí kò ní òpin ní ìsàlẹ̀?
Ó mú kí ẹ ṣe aájò mi.
 geza vermes tun wo ikun mọ agbelebu bi iṣẹlẹ itan ṣugbọn o pese alaye ti ara rẹ ati lẹhin rẹ .
ti won yoo fi lee maa se aseyori lori awon iko Boko Haram.
“Nítorí náà, ìwọ ọmọ eniyan, di ẹrù rẹ bíi ti ẹni tí ń lọ sí ìgbèkùn, kí o sì jáde ní ìlú lọ́sàn-án gangan níṣojú wọn.
Má jẹ́ kí ojú wọn dẹ́rù bà ọ́, nítorí pé ìdílé ọlọ̀tẹ̀ ni wọ́n.
Kedemotu, ati Mefaati pẹlu àwọn pápá ìdaran tí ó wà ní àyíká wọn, gbogbo wọn jẹ́ ìlú mẹrin.
O fikun pe agbara kan wa ti ko ni jẹ ki erongba Tinubu lati di aarẹ Naijiria jọ bi o tilẹ jẹ pe oke tente lo wa, wọn yoo kan erongba rẹ labuku, ti yoo si ja wa silẹ.
Bakan naa, ninu eka irin gbigbe tawon okunrin, Roland Ezuruike tuko  Naijira gba ami-eye goolu, leyin ti o gbe ikun irin iwon ti o le okòólénígba-mẹ́rìn Kilo (224.
jọ̀wọ́ gbọ́ láti ọ̀run, kí o dárí ẹ̀ṣẹ̀ àwọn ọmọ Israẹli, eniyan rẹ, jì wọ́n, kí o sì mú wọn pada sórí ilẹ̀ tí o ti fún àwọn ati àwọn baba wọn.
Wo ohun tó yẹ kí o mọ̀ nípa àwọn obìnrin méje ti Buhari fẹ́ yàn sípò minista Ajínigbé ń bèèrè fún epo, iṣu àti ọ̀tí Schinap gẹ́gẹ́ bí owó ìtanràn Ọ̀lẹ, aṣẹ́wó àti oníranù ni àwọn oní tíátà -Ìyá Rainbow 'Ẹ má ṣi Fayemi túmọ̀ lórí àṣẹ tó pa nípa sísọ èdè Yorùbá' Ọpọ nakn ti wọn mẹnuba jẹ édun ọkan onikaluku lasiko yii.
Wọn fi ọkọ ofurufu gbe awọn to fara pa lọ si ilu Zamboanga to sunmọ ibi iṣẹlẹ naa.
#EkitiDecides: Wọn gbe Fayoṣe digba digba wọ inu ọkọ alaarẹ
Àmọ́ṣá, ileeṣẹ ọlọ́pàá ilu Abuja ní àwọn afurasi ti wọ́n mú yóò fojú bá ile ejo ní kété ti àwọn ba parí ìwádìí.
“OLUWA gbọ́ ohun tí ẹ sọ, inú bí i, ó sì búra pé, 
Akure fire: Àwọn tó fara káásá ìjàmbá iná nílùú Akure d'ẹ̀bi ru panápaná
Itan ati ẹkọ nla miran lo rọ mọ bi Ayinla Ọmọwura se lọ si ọrun ọsan gangan lọjọ aipe ati ni ọna to jẹ iyalẹnu.
Àkọlé àwòrán, àwon òṣìṣẹ́ agbófinró Owó ọkọ̀ di gọbọi nígbà tí wọ́nti afara 3rd Mainland Awakọ ni oju ọna afara third mainland ni ilu Eko, Ọlamilekan Rafiu ti sọ wi pe gbogbo eniyan to wa ni ilu Eko ni yoo faragba ninu igbese ijọba ipinlẹ Eko ati ijọba apapọ lati ti afara kẹta to wa ni ilu Eko.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Blind DJ: Etu Omotayo kò ríran àmọ́ ó le to irinṣẹ́ eléré pọ̀ láti kọrin láì sí ìrànwọ́ Wọn gbe sinu awo amọ, wọn si lọ gbe si bebe odo.
Ọmọ́ Yorùbá korò ojú sí Buhari bí kò ṣe fi orúkọ Obasanjo sọ ibùdókọ̀ ojú'rin Ìjọba Nàìjíríà kéde ìsinmi ọlọ́jọ́ méjì f'ọdún Iléyá Irọ́ ni o, kò sí ẹ̀rí pé Hydroxychloroquine leè kojú àrùn Coronavirus - Ẹgbẹ́ àwọn adarí ilé ìwòsàn ní Naijiria Wọ́n kí irún Jimọ àkọ́kọ́ ní Hagai Sophia lẹ́yìn ọdún 85 ní Turkey Orukọ awọn afurasi ti NSCDC fi sita naa ni ẹya Fulani ni awọn mẹtẹẹta ati pe orukọ wọn ni: Aliu Beidu ẹni ogun ọdun to wa lati ipinlẹ Niger, Buba Bello, ẹni ọdun mẹẹdọgbọn to n gbe ni ipinlẹ Kwara ati Shatari Bello ẹni ogun ọdun lati Kwara.
“Ẹẹmẹta lọdọọdun, ni gbogbo àwọn ọmọkunrin yín gbọdọ̀ wá siwaju èmi OLUWA Ọlọrun, Ọlọrun Israẹli, kí wọ́n wá sìn mí.
 bí àbúrò olúbákin ṣe gun orí oyè kò ṣàìdá họ ́ ùhọ ́ ù àti yànpọnyánrin sílẹ ̀ láàárin àwọn méjèèjì .
Ko pe lẹyin naa ni Ojelarinaka naa di ero ọrun.
"Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Lere Ọlayinka: Ayo Fayose sí wà ní gbaga àwọn EFCC Fayose ko tilẹ jẹ ki wọn wa ki o to yọju si ile iṣẹ ajọ naa ni Abuja ti o si wọ aṣọ dudu ti wọn kọ akori ""EFCC I am here"" si."
Pataki ninu ifẹsẹwọnsẹ ti yoo waye loni ni laarin Manchester city ati Arsenal.
" Gomina Sanwo-Olu sọ pe ko si ẹni to fun awọn sọja to yinbọn mọ awọn oluwọde ni Lekki nipinlẹ Eko ni àṣẹ lati ṣe bẹ ẹ.
Funke Akindele, Toyin Abraham, Bimbo Oshin ṣe Kérésìmesì lọ́nà àrà Gómìnà Sanwo-Olu pàṣẹ pé kí wọn tú ẹléwòn 6 sílẹ lásìkò Kérésìmesì Bi àwọn kan ṣé n jẹ àsun ní àwọn míì n ṣeré lórí omí láti gbádùn Kérésì àná Èyí ni ìdí tí a kò fi yọ̀nda El-Zakzaky pẹ̀lúù Sowore àti Dasuki- Malami Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Boxing Day ko ni nnkan ṣe pẹlu ẹṣẹ kíkàn Ọjọ ọhun jẹ ọjọ ti awọn ẹru kii ṣe iṣẹ kankan, ti awọn olowo wọn si maa n fun wọn ni ẹbun ọdun Keresi ninu apoti.
”Eyawo fun awon oloja ti o bere ni Eko, Abia ati Kano ni yoo tan jake-jado orile ede Naijria.
 fifopin si iwa fayawọAare  Buhari wa benu ate lu iwa fayawọ ti o n sakoba
latin Ọpọ lo n ri awọn eekan ilu, paapaa awọn oṣere sinima gẹ¶gẹ bi awọn to ti ni gbogbo ohun ti wọn n fẹ tan.
 nígbà miran ẹ ̀ wẹ ̀ , Èsú sí dá bí ẹni tí ńfún ifá ni agbára .
Kii ṣe wahala kekere ni ọrọ abẹnu to waye laarin agbo APC ni ipinlẹ Zamfara ati Rivers ko ba ẹgbẹ oṣelu naa.
Nigeria 3 - 2 Cameroon Ere pari Alaye kikun lori ere Awọn agbabọọlu ti wọn yan Alaye ni soki lori ere bọọlu Ẹkunrẹrẹ Ilana ere bọọlu Nigeria (4-2-3-1) Cameroon (4-2-3-1) Ẹkunrẹrẹ 19 - Ighalo football 1 - 0 28 - Kunde 1 - 0 41 - Bahoken football 1 - 1 44 - N'Jie football 1 - 2 51 - Mandjeck 1 - 2 60 - Simon                                                                          down Chukwueze                                                                      up 1 - 2 62 - Mandjeck                                                                          down Zambo Anguissa                                                                      up 1 - 2 63 - Ighalo football 2 - 2 66 - Iwobi football 3 - 2 70 - Awaziem 3 - 2 70 - N'Jie                                                                          down Toko Ekambi                                                                      up 3 - 2 85 - Ighalo                                                                          down Paul Onuachu                                                                      up 3 - 2 87 - Kunde                                                                          down Zoua                                                                      up 3 - 2 91 - Iwobi                                                                          down Balogun                                                                      up 3 - 2 Alaye ni soki lori ere bọọlu Nigeria Cameroon Bọọlu wa nikawọ mi 38.
Kemi Afolabi: Dókítà ní ìrìnàjò wákàtí mẹ́jọ láti Mecca sí Medinah ló fa ibà
Ọ̀pọ̀lọpọ̀ ìnira lojú àwọn ọ̀dọ́ ilẹ̀ Áfíríkà t''o ń wá ìgbé ayé rere lọ sí Yúróòpù ń rí Ìtàn ìgbésí ayé Oshodi, ọmọ Tápà léǹpe tó di akọni ní ìlú Eko Eruku ẹjọ́ tún sọ lórí ìgbéyàwó Toyin Abraham àti Adeniyi Johnson tó forí ṣánpọ́n Ẹ wo bí ìpínlẹ̀ Eko, Ondo àti Oyo yóò ṣe dá ilé ìjọ̀sìn padà Nibayii, iye awọn to ti ri iwosan gba ti le ni ọgọtadinlẹdẹẹgbẹsan(1840), ti igba eniyan si ti ku nitori arun naa.
 15 : 21,29-30 ] ati ki o ṣe akiyesi lati diẹ ninu awọn ijinna kuro .
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Njẹ Chloroquine nipa kankan lati le koju Coronavirus Oyebamiji tẹsiwaju pe ijọba ipinlẹ ọhun yoo ṣe adinku si iye awọn eeyan ti ọkọ akero le gbe nigbakan ṣoṣo lọna ati dẹkun itankalẹ arun ọhun.
Oun ni balogun ikọ agbabọọlu Shooting Stars to kopa ninu ifẹsẹwọnsẹ aṣekagba idije Ife Ẹyẹ ilẹ Afirika lọdun 1984 ti o ti di African Champions League bayii.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù New Zealand mosques: Ẹmi 49 ló tí bá ìṣẹlẹ̀ iyìnbọn Christchurch lọ 15 Ẹrẹ̀nà 2019 Oríṣun àwòrán, TV NEW ZEALAND Àkọlé àwòrán, Awọn oṣiṣẹ alaabo n tọju awọn to faragbọta Awọn alaṣẹ lorileede New Zealand ti kede pe ọdọmọkunrin ọmọ ọdun mejidinlọgbọn ọmọ orileede Australia kan yoo foju ba ile ẹjọ lori ẹsun ipaniyan to ni ṣe pẹlu iyinbọn Christchurch.
Wọn kò ṣe ìdílé Gideoni dáradára bí ó ti tọ́, gẹ́gẹ́ bí ẹ̀san gbogbo nǹkan dáradára tí òun náà ti ṣe fún Israẹli.
Kí lo mọ̀ nípa fẹntilétọ̀, ohun èlò aṣèrànwọ́ èémí Akọrin tàkasúfé, Tommy Kuti tó ń forin ṣèkìlọ̀ COVID-19 lágbáyé 'Màálù tó bá tàsẹ̀ àgẹ̀rẹ̀ níwájú ilé mi, ó dẹran àsun!
Ṣugbọn kò sí ohun kan tí a fi aṣọ bò tí a kò ní ṣí aṣọ lórí rẹ̀.
Bi ọrọ naa ṣe wọwa Iroyin to mu arinyanjiyan yii waye ni eleyi ti a gbọ pe Sanwoolu ṣe ileri naa lasiko apejẹ kan lọjọ kejidinlogun oṣu karun nigba ti wọn ṣẹṣẹ dibo yan an gẹgẹ bii Gomina.
Kò sí ibìkan tí ó gbádùn ní gbogbo ara minítorí ibinu rẹ;kò sì sí alaafia ninu gbogbo egungun mi,nítorí ẹ̀ṣẹ̀ mi.
15 Bí ó bá sì rí bẹ́ẹ̀ pé ẹ̀yin ṣe làálàá ní gbogbo ọjọ́ ayé yín ní kíkígbe ironúpìwàdà sí àwọn ènìyan yìí, tí ẹ̀yin sì mú, bí ó ṣe ọkàn kan péré wá sí ọ̀dọ̀ mi, báwo ni ayọ̀ yín yíò ṣe pọ̀ tó pẹ̀lú rẹ̀ ní ìjọba Bàbá mi!
Mo ní àṣẹ láti yọ̀ǹda rẹ̀, mo ní àṣẹ láti tún gbà á pada.
Ẹ̀mí èṣù ni Coronavirus, kò leè ran ọmọ Ọlọrun - Ààrẹ Tanzania Ẹlòmíràn tún ti lùgbàdì àrùn Corona Virus nílùú Abuja àti Eko Àwọn jàndùkú jí agbábọ́ọ̀lù Nàìjíríà méjì gbé lópòpónà Owo sí Benin Covid-19 ti pa akọni afúnfèèrè Sax ilẹ̀ Africa Lásìkò to n ba àwọn onírolyin sọ̀rọ̀ ọgbẹni Zakari Aliyu to jẹ igbakeji alaga ilé igbé rẹ sàlàyé pé ko si ibẹru bojo nítori pe ẹbi ẹni ti wọ́n n sọrọ gan ko ni ààrun náà.
Láti ìgbà tí Ọlọrun ti dá ayé ni ìwà ati ìṣe Ọlọrun, tí a kò lè fi ojú rí ati agbára ayérayé rẹ̀, ti hàn gedegbe ninu àwọn ohun tí ó dá.
' Amọṣa ninu ọrọ to ba BBC News Yoruba sọ, alukoro ọlọpaa fun ipinlẹ Adamawa, Othman Abubakar ṣalaye pe lootọ ni awọn eeyan kan lati ijọba ibilẹ Maiha fi ẹjọ sun awọn pe eeyan kan to wa ni ahamọ ọlọpaa ti yirapada di ẹyẹ igunugun eleyii ti o n wa si ile ati ilu wọn lati da wọn laamu.
O tẹnumọ pe ohun tawọn bere kọ ni ijọba ṣe ati pe ijọba yi jẹ 1.
N óo sọ wọ́n di kékeré tóbẹ́ẹ̀ tí wọn kò ní lè jọba lórí orílẹ̀-èdè kankan mọ́.
O seese fun aarẹ CAF naa lati pe ẹjọ kotẹmilọrun si idajọ yii nile ẹjọ to wa fun igbẹjọ awọn elere bọọlu ati ere idaraya iyẹn: Court of Arbitration for Sport (CAS) laarin ọgọta ọjọ si asiko yii.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Parental Guidance: Ọdún méjì ni kí ẹ ti bẹ̀rẹ̀ kíkọ́ ọmọ nípa ìbálòpọ̀ Gomina Seyi Makinde to n ṣe ọjọ ibi pẹlu ìbí Jesu olugbala naa sọrọ akin ati ironupiwada bi a ṣe sami ayẹyẹ Keresi ọdun yii pe: Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Christmas:Ṣé ẹ ti ra fìlà ọdún?
Ile-ise omo ogun Naijiria ti tenumo ipinnu re lati gbogun ti iko
- Adelu Ayoade David 12APAAdeleke Adesoji M.
Ẹni ibukun jùlọ ni Jaeli láàrin àwọn obinrin,Jaeli, aya Heberi, ọmọ Keni,ẹni ibukun jùlọ láàrin àwọn obinrin tí ń gbé inú àgọ́.
S Embassy Iroyin ni kete to yinbọn fawọn ero tan lo fi ọkọ ara rẹ silẹ to ji ọkọ awọn to n gbe lẹta tó si salọ.
Gomina ipinle Ebonyi,David Umahi ti ro awon oloselu lati yago fun iwa bi-o- ba-paa, bi-o –ba-
ó lọ kó egungun Saulu, ati ti Jonatani, ọmọ rẹ̀, tí ó wà lọ́dọ̀ àwọn ará Jabeṣi-Gileadi.
Eto ẹkọ ọfẹ naa wa fun awọn to fẹ ẹ kẹkọọ gba oye imọ ijinlẹ akọkọ(undergraduate), ati awọn to ti gba iwe ẹri akọkọ ni awọn orilẹ-ede to ni ajọṣepọ eto ẹkọ pẹlu Naijiria.
Ó jẹ́ ohun ti Leanne ṣèrántí dáadáa: Dájú dájú, inú mi kò dùn sùgbọ́n ọpẹ́ fún ìgbádùn ìbálòpọ̀."
Oríṣun àwòrán, Seyi Makinde Awọn asaaju ẹgbẹ ọlọkọ ero naa, ninu eyi taa ti ri MC Oluomo tun n dunkooko pe awọn yoo ni kawọn awakọ ero dasẹ tilẹ tijọba Ọyọ ko ba tẹle ohun tawọn n fẹ laarin ọjọ meje.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Kí ló mú Obasanjo ti ilẹ̀kùn mọ́ ẹbí, òṣìṣẹ́, ojúlùmọ̀ ní ibi òkú àna rẹ̀?
Sibẹ, OLUWA ń rán àwọn iranṣẹ rẹ̀ ati àwọn wolii rẹ̀ kí wọ́n máa kìlọ̀ fún Israẹli ati Juda pé, “Ẹ kọ ọ̀nà burúkú yín sílẹ̀ kí ẹ sì pa òfin ati ìlànà mi, tí mo fún àwọn baba ńlá yín mọ́; àní àwọn tí mo fun yín nípasẹ̀ àwọn wolii, iranṣẹ mi.
ni Ile naa n gbero lati ṣe atunṣe rẹ si abala mejilelọgbọn to wa ninu ofin
Wọ́n dá a lóhùn pé, “A lá àlá kan ni, a kò sì rí ẹni bá wa túmọ̀ rẹ̀.
Gbogbo eniyan hó pé, “Kí ọba pẹ́.
    Ìgbà tí mo dé ilé mi, mo ṣe ìtọ́jú ara mi dáadáa, kí ilẹ̀ sì tó mọ́, ara mi ti le.
Ìyá: Ọmọ mi, ẹ̀bùn wo lo fẹ́ fún Kérésìmesì?
 iṣẹ ́ rẹ ̀ dá lórí ìmọ ̀ tó péye lórí ìrísí àti iṣẹ ́ macromolecular .
"Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ìró ìbọn dún lákọ ní Iwo road n‘Ibadan, Seyi Makinde yọjú síbẹ̀ ""7000 Jàǹdùkú ló fọ́ ọgbà ẹ̀wọ̀n Okitipupa, jó mọ́tò, tí wọn si se òṣìṣẹ́ léṣe"" Buhari kọ́ ni ìṣòro wa, bó ṣe wà láti láéláé rèé - Fr Mbaka Àwọn ọ̀dọ́ fi ọ̀nà àrífín pe Tinubu lórí aago àmọ́ ó ní òun kò mọwọ́-mẹsẹ̀ nípa ìpànìyàn Lekki Wo díẹ̀ lára dúkìá tí jàǹdùkú sun níná l‘Eko torí ìwọ́de EndSARS O ni ẹsun lasan ṣi ni awọn ọrọ to n kaakiri pe awọn ṣọja yinbọn pa awọn oluwọde kan, ati pe awọn akọṣẹmọṣẹ kan ti sọ pe, iroyin eke ni pe awọn ologun lo pa awọn to ku naa, kii ṣe ootọ."
Nítorí pé ó fọ́ ìlẹ̀kùn idẹ,ó sì gé ọ̀pá ìdábùú irin ní àgéjá.
Ọba Balogun kede pe ti ijọba yoo ba gbe iru igbesẹ naa, sebi o yẹ ko bun awọn ọba mọkanlelogun naa gbọ, ki awọn si dijọ se ipinnu lori rẹ amọ eyi ko ri bẹẹ.
Onimọ nipa ile kikọ Hermogene Nsengimana lo sọ bẹ, o ni awọn ibikan wa to jẹ pe awọn ohun elo ikọle ti ko lagbara nikan ni wọn maa n ta nibẹ.
Wọn ni oun to pa ree.
Ìyá Emir Sulu Gambari ti Ilorin dágbére f'áyé!
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Gani Adams: Àwọn agbébọn ń jí ọmọdé, àwọn obìnrin, ti wọn sì ń dúnkookò mọ ọrọ̀ aje Oke Ogun 25 Ògún 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 16 Owewe 2020 Oríṣun àwòrán, @OnwardNG Yoruba ni agbalagba to n lu irin loju kan ṣoṣo, o ni ohun to fẹ gba lọwọ irin ni.
Wọn sọrọ yi ninu atẹjade pe awọn adari nkan bii aadọta ẹlẹgbẹjẹgbẹ to parapọ di agbarijọ ẹgbẹ itẹsiwaju Yoruba lagbaye lo yan Ọjọgbọn Banji Akintoye gẹgẹ bi adari ẹgbẹ naa.
Lorile-ede Malaysia, ọtọọtọ ni bi wọn ti ṣe n lo Sharia lawọn ipinlẹ to wa nibẹ Adajọ Shushaidah ma n gbaruku ti ẹsin rẹ ti o si ni a ma ṣe deede.
Bi wọn ṣe sọ oju abẹ nikoo naa lo waye lasiko yii, ti ọpọ awọn orilẹ ede agbaye n dẹ okun lọrun ofin konile o gbele, tawọn asaaju orilẹ ede si n gbero lori akoko ati ọna ti wọn yoo gba ṣe agbende ọrọ aje orilẹ ede koowa wọn pada.
Ọlọ́pàá Amẹ́rìkà tún ti yìnbọn pa ọmọ Áfíríkà míì, bàbá ọmọ fárígá!
Lara ohun ti iwaadi naa daba ni pe ki ajọ to n ṣe iwadi iwa jẹ́gudujẹra ṣe iwadi aarẹ Olusegun Obasanjo ati Gomina ana ipinlẹ Ondo Olusegun Agagu lori ọrọ naa.
Àkọlé àwòrán, Ọlọ́pàá Ondo bá òkú ọmọ igbákeji gómínà tẹ́lẹ̀rí nílé Adeyemi Alao Fun idi eyi, o ni ki Adeyemi lọ rọọkun lẹwon titi ti ẹka to n ri si ipẹjo (DPP) yoo fi gba ile ẹjọ ni imọran lori ọrọ naa.
Ọjọgbọn Ishaq Akintọla ni ẹgbẹ MURIC ti ke sawọn musulumi kaakiri ẹkun iwọ oorun gusu orilẹede Naijiria, lati gunle iwọde alaafia lẹyin isin Jumat ni ọjọ ẹti pẹlu aṣọ funfun lati fi ẹhonu han lori iṣẹlẹ naa.
Ni igba naa,o ni awọn eniyan ma n lo ibinu ki a le ri wọn gẹgẹ bi ẹni iyi, ti o yẹ ki a bọwọ fun, ati ẹni ti o ma n lo ibinu lati jẹ ki awọn eniyan yi ọkan wọn pada, ati lati jẹ gaba lori awọn eniyan wọn.
Eyi lo mu ki awọn obi to jẹ ẹlẹsin Islam gbena woju awọn alakoso ile ẹkọ naa pẹlu alaye wi pe, awọn akẹkọ lẹtọ lati mura nilana ẹsin ti o ba wu ọkan wọn.
Oríṣun àwòrán, Twitter/miraclenaija Lẹyin o rẹyin Miracle Igbokwe lo pada gbe gba oroke, ti o si gba ẹbun owo tabua ọhun lọle.
Gẹgẹ bi o ṣe ṣalaye, nkan ti o wa nilẹ ni igbimọ kan to ja gbogbo ipinlẹ mẹfẹẹfa pọ ti adari tabi alamojuto ipinlẹ kọọkan yoo korajọ loṣooṣu lati ṣepade lori ilana iṣiṣẹ ikọ Amọtẹkun.
Bí mo ṣe bù ú jẹ ni adìẹ náà kàn ṣ’ọ̀rá sìnkìn sí mi lẹ́nu.
Ṣùgbọ́n nígbà tí a wo ààrin wa, a kò rí ọkùnrin kan báyìí tí o ń jẹ́ ìgbí-ènìyàn, ó jẹ́ ẹni tí kìí fi ìkánjú ṣe nǹkan kan rárá, bí ó bá ń rìn pàápàá náà báyìí, tẹ̀ǹkì-tẹ̀ǹkì ló máa ń rìn kiri ìgbà tí iwin náà gbé ojúayédùn dé nítorí òun ló gbé kẹ́yìn pátápátá, ó wi fún ni pé kò sí ẹnìkan lọ́hùn-un mọ́.
Àwọn ọmọ rẹ̀ a máa pè é ní ẹni ibukun,ọkọ rẹ̀ pẹlu a sì máa yìn ín pé,
Lẹyin igba ti wọn ji awọn akẹkọbirin Chibok gbe, ijọba dakẹ lai sọ nkankan.
Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Trump news: Biden tun fẹyin Trump gbolẹ ninu atunka ibo to waye ni Georgia20 Bélú 2020 US Elections 2020: Primate Ayodele ní òun ti sọ àsọtẹ́lẹ̀ pé Trump yóò fìdírẹmi, tí kò bá ṣọ́ra ṣe8 Bélú 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Jese ranṣẹ lọ mú un wá.
IINEC : Ajọ eleto idibo lorilẹ-ede NaijriaInconclusive election (Eto idibo ti ko ni ẹni to jawe olubori)
Ẹ gbọ́ ohun tí wọn sọ.
Yoruba Culture: àṣà ìkínni ṣe pàtàkì nílẹ̀ Oodua
Ojogbon Osinbajo soro yii ni Abagana ati Dauda ti won fi se atipo:”mo wa nibi yii gege bi asoju aare to wa sibi yii ni osu keta, oun naa lo so pe ki a lo se iwadii lori isele yii.
Ẹ le tẹle ni ori Twitter here.
O gba wọn nimọran lati ma fun ẹnikẹni lesi nipa iṣẹlẹ ẹsun yii.
Oríṣun àwòrán, Ademola adeleke Àkọlé àwòrán, Arakunrin Shuaib ni oun ko pe ki ẹnikẹni o lo orukọ oun lati pe ẹjọ.
Sowore: Èmi ṣì ni alága ẹgbẹ́, kò sẹ́ni tó yọ mí lóyè
Amosa,ofin yii ko ni bẹrẹ lati ori aare orile ede Faure
gbogbo àwọn orílẹ̀-èdè ni yóo máa bèèrè pé, ‘Kí ló dé tí OLUWA fi sọ ilẹ̀ yìí dà báyìí?
Nígbà tí wọ́n túká lọ, wọ́n ń waasu ní ibi gbogbo, Oluwa ń bá wọ́n ṣiṣẹ́, ó ń fi ìdí ọ̀rọ̀ ìyìn rere múlẹ̀ nípa àwọn iṣẹ́ àmì tí ó ń bá wọn lọ.
Ó wí fún wọn pé, “Ẹ máa tẹ̀lé mi, nítorí pé OLUWA ti fi àwọn ará Moabu, tíí ṣe ọ̀tá yín le yín lọ́wọ́.
OLUWA Ọlọrun ń ràn mí lọ́wọ́,nítorí náà ojú kò tì mí;nítorí náà mo múra gírí,mo jẹ́ kí ojú mi le koko,mo sì mọ̀ pé ojú kò ní tì mí.
Oríṣun àwòrán, ZAINAB BUHARI FANS/FACEBOOK Zulaihat (Nee) Buhari Awọn iroyin kan sọ pe o pẹ ki Aarẹ Buhari to turaka lẹyin iku ọmọbinrin rẹ, Zulaihat lọdun 2012.
Èyí tí ó yà mí lẹ́nu jùlọ ni pé àwọn ọlọ́pàá náà jọ ènìyàn díẹ̀, bí orí ènìyàn ni orí wọn rí ṣùgbọ́n ara ejò ni ara wọn.
 Iwọde alaafia tako iṣejọba ti ko dara tabi awọn igbesẹ ati ilana ijọba ti ko dara fun araalu, jẹ ọkan lara awọn ẹtọ ọmọniyan to ṣe koko, to si n mu ki eto iṣejọba awaarawa o dagba si.
Bakan naa lo tun tọrọ aforijin lọdọ ẹbi ọmọ naa ti o si bawọn kẹdun iku rẹ.
O ni o han pe ohun elo to to ko si fun awsn ologun nitori naa, titi digba ti ijọba yoo fi lee ra nnkan ija to to, mimu aba lori gbigba awọn ajagunta lo, ko buru ju.
Kosi ni baba Anubi ati Sobeba.
Yatọ si eyi, a tun ṣakiyesi pe imura rẹ ti yatọ si ti tẹlẹ, pẹlu awọn aworan to n fi sita bayii, nitori awọn asọ to fi bi igun ara rẹ se ri lo n wọ, ti ko we gele sori mọ gẹgẹ bi ayaba.
Paroparo ni ayika ile naa da lasiko ti a ṣe abẹwo sibẹ lọsan ọjọ Ẹti.
Nígbà tí Joabu rí i pé àwọn ọ̀tá yóo gbógun ti àwọn níwájú ati lẹ́yìn, ó yan àwọn tí wọ́n jẹ́ akikanju jùlọ ninu àwọn ọmọ ogun Israẹli, ó ní kí wọ́n dojú kọ àwọn ará Siria.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, ọ̀gá ọlọ́pàá sọ̀rọ̀ lórí SARS Ṣugbọn kii ṣe igba akọkọ ree ti Shogunle yoo fẹnu kọ lori Twitter.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Oladapo Adu: Nàíjíríà já mi kulẹ̀ torí wọn kò wá gbé mi Aṣẹyinwa-aṣẹyinbọ, Imaamu ni awọn ẹlẹsin ibilẹ beere owo, sugbọn awọn ko fun wọn, ati wi pe awọn ti sin okunrin naa ni ilana ẹsin Musulumi.
Ọlọ́pàá gbé àwọn tó yìnbọn lu olólùfẹ́ ní Ajegunle Àdúrà mi ni kò jẹ́ kí ìyà Manchester United ó pọ̀ jù lọ́wọ́ Barcelona- Wòlíì Àrólé Messi yẹyẹ aṣọle Man U fun goolu ẹlẹẹkeji to gba wọ le lẹyin ti David De Gea mu amubọ.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Àwọn tí wọ́n ń ṣe jáde nísisìyìí yàtọ̀ sí ojúlówó Lẹ́yìn ọdún méje, ó ṣì ń lo ǹkan ìṣeré ìbálòpọ̀ kan náà fún ìgbà díẹ̀ lọ́sẹ̀.
4 98859 Orilẹede Denmark 1720 29.
Alagba George ni ara ere ijọba awarawa naa ni ilana ipẹtu-saawọ dipo lilo ibọn.
Oríkì jẹ ikan ninú àṣà Yorùbá ti ó ti nparẹ́, nitori ọ̀pọ̀lọpọ̀ ọmọ Yorùbá bẹ̀rẹ̀ si kọ èdè àti àṣà wọn sílẹ̀ fún èdè Gẹ̀ẹ́sí.
Ṣé o lè fi ọ̀kọ̀ gún ẹran ara rẹ̀,tabi kí o fi ẹ̀sín àwọn apẹja gún orí rẹ̀?
Ó fún gbogbo eniyan ní ìsinmi, ó sì fún wọn ní ọpọlọpọ ẹ̀bùn.
Ní ọjọ́ Pẹntikọsti, gbogbo wọn wà pọ̀ ní ibìkan náà.
Àpẹẹrẹ ìdánilẹ́kọ̀ọ́ kan ni ìtúnsọ àlọ́ ‘Òwìwí àti Àgbọ̀nrín‘ àwọn aráa Kmhmu ní àárín gbùngbùn àti àríwá Laos.
Jẹ́ kí wọ́n yin orúkọ rẹ tí ó tóbi tí ó sì lẹ́rù,mímọ́ ni OLUWA!
Wọ́n ní, “Ẹ má fi àwa iranṣẹ yín sílẹ̀!
Ṣé ìwọ Ninefe sàn ju ìlú Tebesi lọ, ìlú tí ó wà ní ẹ̀gbẹ́ odò Naili, tí omi yíká, tí ó fi òkun ṣe ààbò, tí ó sì fi omi ṣe odi rẹ̀?
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Coronavirus:Ọmọ mi to ṣẹ̀sẹ̀ dé láti UK ko fi àmi Coronavirus han, sùgbọ́n.
Oun naa tun ba awon akoroyin soro leyin ipade ti o
Ọmọ mi, má bá wọn kẹ́gbẹ́,má sì bá wọn rìn,
Ni ṣoki, ohun to tun mọ si ni ''gba a pada''.
Ó ń yan kiri láàrin àwọn kinniun;nítorí ó ti di ọ̀dọ́ kinniun tí ó lágbára,ó kọ́ bí wọn tí ń ṣe ọdẹ,ó sì ń pa eniyan jẹ.
Ahitofeli jẹ́ olùdámọ̀ràn fún ọba, Huṣai ará Ariki sì ni ọ̀rẹ́ ọba.
Gbogbo àwọn ọmọkunrin tí a kà ninu ẹ̀yà Lefi láti ẹni oṣù kan sókè jẹ́ ẹgbaa mọkanla ó lé ẹgbẹrun (23,000).
Nibayii, eto idibo si n lọ ni irowo-irose ni ipinle Osun.
Ibinu pe wọn ko ri nkankan mu ninu ileefowopamọ naa ni wọn fi pa oṣiṣẹ banki mẹẹrin, to fi mọ ọga agba ileewe girama kan to wa gba owo, ati ọlọpaa kan.
Ọpọlọpọ eniyan lọ sọ́dọ̀ rẹ̀, wọ́n ń sọ pé, “Johanu kò ṣe iṣẹ́ ìyanu kankan, ṣugbọn gbogbo ohun tí ó sọ nípa ọkunrin yìí ni ó rí bẹ́ẹ̀.
Trump Ṣugbọn to wa nibẹ ni wo pe Trump to jẹ oludije ẹgbẹ oṣelu Rupublican ni Biden wọle ibo aarẹ nitori wọn ṣe eeru ninu eto idibo naa.
Bí bẹ́ẹ̀kọ́, ṣòkòtò gbọdọ̀ gùn délẹ̀ ni.
Oríṣun àwòrán, LASEMA Ajọ to ma n wadii ijamba ni Naijiria lo ṣawari apoti dudu, to wa ninu ẹlikọpita, to ja lulẹ ni agbegbe Ikeja, nipinlẹ Eko.
Nítorí èyí, bí ó ti ń rúbọ fún ẹ̀ṣẹ̀ àwọn eniyan, bẹ́ẹ̀ ni yóo máa rúbọ fún ẹ̀ṣẹ̀ ti òun alára.
bi tí àlejò mi sọ̀rọ̀ náà fún mi mọ lọ̀jọ̀ tí a tún kọ̀wé náà ni èyí, a bá dá ọwọ́ dúró lọ́jọ́ náà, a kí àwọn tí ó wá gbọ́ ọ̀rọ̀ wa pé kí wọ́n máa lọ sílé kí wọ́n tún padà lọ́jọ́ kejì.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù BBNaija 2020 Winner: Laycon ti gba sọ̀wédowó, ilé fúláàtì àti àwọn nkan míràn 27 Owewe 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 30 Owewe 2020 Oríṣun àwòrán, Big Brother Naija / Twitter Oludari Agba fun ileeṣẹ MultiChoice Nigeria, to jẹ ileeṣẹ to ṣe agbatẹru eto Big Brother Naija, John Ugbe, ti sọ pe, BBNaija ti ọdun 2020 lo ni idibo to ti i pọju lọ.
Èyí ni àwọn ìdí tí wọ́n fi fẹ́ ẹ̀ fi 37Billion Naira tún ilé aṣòfin Nàìjíríà ṣe N kò fẹ́ eégún onídọ̀tí ní ààfin mi - Oluwo Yàtọ̀ sí Olúwó, wo àwọn Ọba alayé tó ti kọ ìyàwó rí láìpẹ́ nílẹ̀ Oodua Ta lo pa Abimbọla ati Mubarak l'Ogun?
Ọlakunle Tẹjuoṣo mura ninu aṣọ Buba ati Sokoto rẹ, oun atawọn oṣiṣẹ rẹ si n sọrọ pọ bi wọn ṣe n tun iwe to wa lori awọn atẹ ifiwe si to.
Ọpọlọpọ igba ni orukọ alufa yii ti sun soke lori ayelujara to si tun jẹ ọkan lara awọn gbajugba ojiṣẹ Ọlọrun lagbaye amọ ọrọ tirẹ a maa fa ọpọlọpọ ọrọ jade lori ayelujara paapaa lẹnu awọn ọmọ Naijiria.
Aláàfin fẹ́ gba bàálù kékeré bíi owó orí mi, ọkọ mi ń gbọn kiri - Lizzy Anjorin Ronke-Oshodi sọ pe ọkọ oun ko mọ pe oṣere ni oun nigba ti awọn pade.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ìtàn Olaniyi Balogun, ọ̀jọ̀gbọ́n tó fi Nàìjíríà sílẹ̀ lọ gba iṣẹ̀ àgbẹ̀ l'Ámẹ́ríkà O ni ko ileeṣẹ ọlọpaa ko tii lee fi iroyin ti awọn eeyan kan n gbe kiri pe awọn ọmọ ẹgbẹ okunkun lo da ẹmi oloogbe ọhun legbodo mulẹ.
Oríṣun àwòrán, LASEMA O ni idi ni pe awọn fẹ kan si ẹni to ni ọkọ agbepo naa ki awọn to bẹrẹ si ni da epo inu rẹ kuro.
Pupọ eeyan lo ma n ro wi pe ti oun ba ti gba kaadi idanimọ E-Card ti NIMC n fun awọn eeyan,wọn yoo ti kọ NIN rẹ si lara.
Bakan naa ni ọgagun Sadique Abubakar to ṣoju adari wọn nibi eto naa fun Bashir ni lẹta o kare ọmọ ọdọ rere nitori iwa to hu yii jẹ ọpakutẹlẹ awọn ọmọ ogun ofurufu ni Naijiria.
Ẹnìkan ń bọ̀ lẹ́yìn mi, ẹni tí n kò tó tú okùn bàtà ẹsẹ̀ rẹ̀.
Irú ọlọrun bẹ́ẹ̀ kì í ṣe ọlọrun rárá.
Wọn ni, “bo ti wu ko ri, ṣaṣa ni awọn ọba lode oni ti ki i ṣe ọmọwe, bi a ṣe ri onimọ ẹrọ, la ri ọjọgbọn, onimọ-iṣiro owo, amofin, ati bẹẹ bẹẹ lọ laarin wọn.
Olóko ni o ma npèsè ibùgbé fún Alágbàṣe ti wọn bá gbà fún iṣẹ́ oko, nitori eyi, kò si pé àlejò gba ilé lati sanwó.
Ìtọ ́ jú pẹ ̀ lú egbògi clindamycin tàbi metronidazole .
 tí ẹní tí ó kọ ojú ewé kò bá gbà kí ó ni tí o kọ ́ , kí ó tẹ bọ ́ tìnì contest this speedy deletion tí ó wà lẹ ́ gbẹ ́ àmì píparẹ ́ láìrosẹ ̀ .
Nítorí náà, àwọn ọmọ Israẹli yóo wà fún ọjọ́ gbọọrọ láìní ọba tabi olórí láìsí ẹbọ tabi ère, láìsí aṣọ efodu tabi ère terafimu.
Increased DSTV tariff: MultiChoice ní àfikún owó epo, owó iná pẹ̀lú owó orí VAT ló jẹ́ káwọn fowó kún tàríìfù DSTV
ipinle Ekiti ti sagbekale igbimo ti yoo maa mojuto bi eto naa se n lo si.
"Àwọn Olúkọ ìpínlẹ̀ Oyo fakọyọ lórí ètò Akọ́mọlédè àti Àṣà púpọ̀ Ọkùnrin kan ""lu ìyàwó rẹ̀ pa"" nítorí ó lọ síbi ayẹyẹ ìsọmọlórúkọ Àwọn jàǹdùkú dojú ìjà kọ ọlọ́pàá, DPO faragbọta, ọlọ́pàá mẹ́rin di àwátì Abiru jáwé olúborí nínú àtúndi ìbò Sẹnatọ ìlàoorùn ìpínlẹ̀ Eko Olùdíje lábẹ́ òṣèlú All Progressives Congress (APC) fún ipò sẹ́nátọ̀ nínú àtúdi ibó Tokunbo Abiru ló jáwé olúborí."
Elija wí fún un pé, “Má bẹ̀rù.
’ Lẹ́yìn èyí ni Kùmọ́dìran ṣe ìbèérè tí ó ni, ‘Báwo ni ìjà náà tilẹ̀ ṣe bẹ̀rẹ̀?
Ààlà náà tún lọ sí apá òkè, sí àfonífojì ọmọ Hinomu ní apá gúsù òkè àwọn ará Jebusi (tíí ṣe ìlú Jerusalẹmu).
Nítorí náà, ẹ máa tu ara yín ninu, kí ẹ sì máa fún ara yín ní ìwúrí, bí ẹ ti ń ṣe.
Láìpẹ́, ọmọbinrin Farao lọ wẹ̀ ní odò náà, àwọn iranṣẹbinrin rẹ̀ sì ń rìn káàkiri etídò.
"Florence Ajimobi tahùn sí igbákeji gómìnà Oyo lórí ikú ọkọ rẹ̀, ""Gbogbo wa làó kú"" Àjọ NCDC kéde ènìyàn 490 tó tún ṣẹ̀ṣẹ̀ ní Coronavirus ní Nàìjíríà South Africa Bo tilẹ jẹ pe awọn obi ni ko yẹ ko ri bẹ, ọjọ kẹjọ oṣu Kẹfa ni ijọba South Africa ṣi awọn ile iwe rẹ pada."
" Oríṣun àwòrán, Facebook/Ekiti state government O ni ọpọ igba ti olori ileegbimọ aṣofin ile naa ti gbaa niyanju pe ko mojuto ifẹ awọn eeyan rẹ pẹlu itọju alaafia aara rẹ lo ti fi ẹyin ọwọ yi danu.
Gbajugbaja oniṣowo pataki ni Iyalode Abiodun nigba aye yẹ.
takun-takun ati ẹmi isọkan ti ikọ agbabọọlu naa fihan
Awọn iroyin ti ẹ lee nifẹẹ si: ‘Jibiti ni isẹlẹ Dapchi, kii se ootọ’ ‘Atunse ofin lo le dẹkun jẹgudujẹra’ Ajọ to n mojuto igbayegbadun awọn atipo lorilẹede Norway salaye wi pe, o din ni ilaji awọn eeyan orilẹede naa to ri awọn ohun elo iranwọ ti wọn nko ransẹ si wọn gba.
Awọn orilẹ-ede ti ko din ni ọgọrun un lo ti kede konile o gbele nigba ti yoo fi di ipari oṣu Kẹta, ọdun 2020, eyi to kan ọpọlọpọ biliọnu eniyan.
Iná ni a fi ń dán fadaka ati wúrà wò,ṣugbọn OLUWA ní ń dán ọkàn wò.
Alhaji Bayeri sọ wipe gbogbo Fulani to ba n daran lalẹ, afurasi ọdaran niru wọn.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Njẹ́ o dá ayédèrú ìròyìn mọ̀ tí o bá ri i?
Ipinlẹ mẹta ti ọwọja igbọnsẹ itagbangba wa ni Kogi, Plateau ati Benue nibi ti  o le ni idaji awọn eeyan ibẹ ko ti lanfani si ile igbọnsẹ lilo, iyẹn gẹgẹbi iwadii ajọ ilera agbaye ati ajọ idagbasoke eto ẹkọ awọn ewe lagbaye, UNICEF gbe kalẹ lọdun 2016/2017.
Ẹlẹ́wọ̀n Kirikiri tó ń wọ́ke, olùdarí ọgbà ẹ̀wọ̀n ló ṣe onígbọ̀wọ́ fun - EFCC Lasiko ti Ilẹ Gẹẹsi kọ Naijiria lẹru, ọ le ni ẹgbẹẹgbẹrun awọn ohun abalayẹ ti wọn ko lọ.
Síbẹ̀síbẹ̀ náà pẹ̀lú, àwọn wọn-ọnnì yan aṣojú tí yóò wáá ìròyìn bá wọn.
” Ó wólẹ̀, ó dojúbolẹ̀ níwájú ọba, ó sì wí fún un pé, “Ìyìn ni fún OLUWA Ọlọrun rẹ tí ó fún ọ ní ìṣẹ́gun lórí àwọn tí wọ́n dìtẹ̀ mọ́ ọba, oluwa mi.
I pray that the Almighty will grant you and the entire members of his family the fortitude to bear this irreparable loss.
Ṣugbọn bí olè ni ọjọ́ Oluwa yóo dé.
5 115471 Orilẹede Bosnia ati Herzegovnia 2952 88.
Ni bayii, Martial ti gba apapo boolu mewaa sagbon ni saa yii, ti
Oríṣun àwòrán, Reuters Àkọlé àwòrán, Awọn ti wọn s'ẹwọn tẹlẹ ri, wọn fẹ gun ọkọ nla kan lati ọgba ẹwọn Mpimba l'abala kan ninu aforoji ti aarẹ fun awọn ẹlẹwọn pipọ kaakiri, ni Bujumbura, Burundi.
Wọ́n sọ fún un pé ẹnì kan ń rọbí àti pé yóò nílò oníṣèẹ̀gùn.
Rélùwéè tẹ alágbe kan pa ní Eko Ètò ìdìbò gómìnà ìpínlẹ̀ Kogi àti Bayelsa m bọ̀ lọ́nà- INEC Wo bí o ṣe lè kọ́ ọmọ rẹ lẹ́kọ̀ọ́ ìbálòpọ̀ Kingston lọmọ Áfíríkà tó gba ohun tí Hulk Hogan kò rí gbà Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Parental Guidance: Ọdún méjì ni kí ẹ ti bẹ̀rẹ̀ kíkọ́ ọmọ nípa ìbálòpọ̀ Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Àáyá bẹ́ẹ́ lẹ̀, ó bẹ́ áré; Arsenal di ẹrù ìyà lé Fulham lórí Háà Ibadan!
Ajọ to n ri si ere bọọlu ni Naijiria lo kede iku Chiejine loju opo Twitter wọn lọsan Ọjọbọ.
Ẹ wo àwọn ìròyìn tó ṣì ń gbóná fẹli fẹli lọ́sẹ̀ yìí Barrister ló sọ mí di èèyàn ńlá - Ayinla Kollington OPC kò láṣẹ láti fipa lé ẹ̀yà kan nílẹ̀ Yorùbá lórí ọ̀rọ̀ ikú Olakunrin - Ọlọ́pàá Kọ̀lọ̀kọ̀lọ̀ Algeria là kìnìún Senegal mọ́ lẹ̀ lẹ́ẹ̀kejì gba ife AFCON Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, CAN: Samson ni ọrọ awọn ajinigbe ti gba àpérò ní Naijiria Ganduje sọ ninu ifọrọwanilẹnuwo pẹlu awọn oniroyin pe awọn ti n kọ ọgba nla nla fun awọn Darandaran ti awn si ti pe fun owo iranwọ latọdọ Banki Islam lati le pese okoojẹ fun awn maalu wọn.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Lẹyin igbẹjọ naa ni Adajọ Munta Abimbola da ẹjọ ẹwọn ọdun meje fun un, ninu eyi to ti lo ọdun meji.
Lara awọn ohun manigbagbe to nii se pẹlu owo ẹru to wa ni Badagry ni ọpọ kanga ti awọn ẹru gbẹ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Will: Àwọn olùgbé Eko ni ẹni tó ní owó, ló ń ṣe àkọsílẹ̀ ìlànà ogún pínpín Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Will: Àwọn olùgbé Eko ni ẹni tó ní owó, ló ń ṣe àkọsílẹ̀ ìlànà ogún pínpín 28 Èbibi 2019 Awọn ọmọ Naijiria ti fi ero wọn han lori ipa pataki ti kikọ ‘will’ nni lori igbe aye awọn eniyan.
Mo sì tún ṣe ìlérí pẹ̀lú pé kò sí ohunkóhun tí obìnrin yìí lè ṣe, tí n ó fi gbé ọwọ mi sókè lùú, ẹni tí ó bá lu ìyàwó rẹ̀, olúwarẹ̀ lu ohun ẹlẹgẹ Olódùmarè, ó mú ara rẹ̀ kúrò ni ipò ènìyàn, ó fi ara rẹ̀ sí ipò ajá tí ó ní dìgbọ̀lugi.
Ladugbo Ketu ni iṣẹlẹ yiti waye.
O ni títí di àsìkò yìí, kò sí ọ̀nà láti bá ẹgbọ́n àwọn sọ̀rọ̀.
Kí a sọkún kí ojú fọ́ kò kan ikú, kí á gbára sánlẹ̀ títí kò yíi lọ́kàn padà, kí á wọ aṣọ dúdú kò ṣe nǹkan fún un.
- Obasanjo gbarata Iyabo Ojo ṣílé, Toyin Abraham fẹ́ ṣílé iṣẹ́ f'ọmọ, àtàwọn nǹkan míràn lágbo òṣéré Wo fọ́tò àrà MC Oluomo, Pasuma àtàwọn òṣèré tíátà míì níbi ìṣílé Iyabo Ojo Wo àwọn òṣìṣẹ́ kólẹ̀-kódọ̀tí tó ń fi ẹ̀mí wọn wéwu kí Abuja leè mọ́ tónítóní Àwón Oníbúrẹ́dì ń gbé ìgbésẹ̀ láti fi kún owó Búrẹ̀dí ní Nàìjírià Wo ìyá ọlọ́mọ mẹ́ta tó ti pé ọdún 48 tó ń ṣe ìdánwò WAEC, kó le di nọ́ọ́sí Alhaji Bello Matawalle lo ti rinrin ajo lọ silu Abuja lati ọsẹ diẹ sẹyin, to si n pada bọ wa sipinlẹ Zamfara lọjọ naa.
Ni ojoojumọ, mo maa ni ireti wipe oun ti iya mi fẹmi rẹ lelẹ fun ni orukọ orilẹedemi yoo wa si imuṣẹ ni oju mi.
O Fagunwa kú, dúkìá rẹ̀ sì ń fọhùn síbẹ̀, ilé rẹ̀ rèé Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Ó ṣojú mi kòró, ẹ wọ bí ìgbà ayé Bàbá Fagunwa ṣe rí' Lara awọn iwe manigbagbe ti Fagunwa kọ ni Ogboju Ọdẹ ninu igbo Irunmọlẹ eyi to gbe jade lọdun 1938, Igbo Olodumare to tẹle lọdun 1949, Adiitu Olodumare, Ireke Onibudo 1949 lo gbe ohun naa jade baka naa ati bẹẹ bẹẹ lọ.
Ọwọ́ ọlọ́pàá tẹ ẹ̀gbọ́n tó dáná sun àbúrò rẹ̀ toyúntoyún nílùú Eko Ọwọ́ ọlọ́pàá tẹ ẹ̀gbọ́n tó dáná sun àbúrò rẹ̀ toyúntoyún nílùú Eko Ìmáàmù àgbà ilẹ̀ Egba Sheik Liadi Orunsolu ti jáde láyé lẹ́ni ọdún 98 'Ọkọ mi yọ kíndìnrín mi láti fi rọpò owó ori' Obinrin maa n ni arun ọpọlọ diẹ diẹ lasiko nnkan oṣu Igbagbọ karun nipa nnkan oṣu obinrin ti ko fidi mulẹ ni pe, awọn obinrin to n ṣe nnkan oṣu maa n ṣe gan gan gan fun isẹju diẹ lasiko nnkan oṣu wọn.
Wọn ṣe eyi nítori wọn fẹsun pe o kọ láti ṣe àgbékalẹ̀ ìgbìmọ̀ adójutòfò ohun amuludun àti ikowojọ kó si fi Frank Kokori, alaga nigba ti àwọn jànduku yabo awọn afẹhonuhan nile Minisita to wa ni Asokoro ṣe alaga.
O ya mi lenu pe, okan lara awon aare ana lorile ede yii, n gbenu re jo, pe awon na bilionu màrúndínlógún dola lori ina mona-mona lorile ede Naijiria, nibo ni ina mona-mona naa wa?
Ọ̀rọ̀ ajẹe tó dẹnukọlẹ̀ lọ́dún 2009 kíló ṣẹlẹ̀ nigba naa?
Laipẹ yii ni aarẹ orilẹede Madagascar polowo agbo kan pe o le wo aarun aarun coronavirus.
Mo fẹ́ràn OLUWA nítorí pé ó gbọ́ adura ati ẹ̀bẹ̀ mi.
Aṣofin Ọbasa sọrọ yii nibi ipade ijiroro Igbimọ Aṣofin naa pẹlu awọn ọgalọga lẹnu iṣẹ iroyin ati awọn ẹlẹgbẹjẹgbẹ kan, eleyii to waye gbagede Ile naa ni Alausa, ni ilu Ikẹja.
Bí o bá máa lọ, o níláti lọ gbé apo àlàáfíà ti ń bẹ ní iyààrá mi kí o fi pa ara, nítorí kí iná ọ̀run àpáàdì má ba le ṣe ọ ní nǹkankan, bí o bá sì fẹ́ mú àwọn ọ̀rẹ́ rẹ lọ, àwọn ènìyàn wọ̀nyí, o níláti fún olúkúlùkù wọn ní fìlà àírí ti ń bẹ nínú àpótí ńlá ní àbáwọ inú iyààrá mi kékeré, kí wọ́n dé e nítorí Èṣù kò gbọdọ̀ rí wọn, ṣùgbọ́n bí o tilẹ̀ jẹ́ pé ẹnikẹ́ni kò ni lè rí wọn bí kò ṣe ìwọ, síbẹ̀ àwọn náà níláti fi epo àlááfíà pa ara.
Awọn onimọ ni imọtoto ṣe pataki lawujọ ki arun gbogbo ma le ṣe akoba fawọn eniyan.
Carrington was devoted to something greater than he was.
Iwadii ti wọn ṣe ni orilẹede Amerika, Germany, Brazil, Argentina, South Africa ati Turkey fihan pe, laarin ọjọ meje ti wọn ba ti gba abẹrẹ ajẹsara keji naa ni arun naa yoo dopin lagọ ara ẹni to ba lo.
Oríṣun àwòrán, Ondostate house of assembly Àkọlé àwòrán, Olori tuntun ti wọn ṣẹṣẹ yan fun ile naa, Ọlamide George ni ilu Ibadan ni awọn sare wa fi ara pamọ si nitori abo ẹmi wọn Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Kí ló dé tí gómínà Akeredolu lé àwọn akọ̀ròyìn nílé ìjọba?
 Nigbati mo fẹ bẹrẹ sii kopa ninu eto oṣelu, awọn iya mi mejeji, iya Akurẹ ati iya Ibadan pe mi loru ọganjọ, wọn si kilọ fun mi lede Akure ati ni ede Ibadan pe, ti awọn oloṣelu ba fun mi ni ohun kohun, mi o gbọdọ gbaa."
Awọn obi rẹ ni Ọgagun agba Olufẹmi Olutoye to ti fẹyinti ninu iṣẹ ologun ati Ọjọgbọn Ọmọtayọ Olutoye to jẹ Ọjọgbọn akọkọ ninu ẹkọ imọ Yoruba.
 Àwọn òbinrin la ba máà pè ní ejò gẹ ́ gẹ ́ bí àgbékalẹ ̀ ifá .
Àkọlé àwòrán, Àwọn oṣìṣẹ́ ìrànwọ́ tí wọ́n jí gbé Ọgbẹni Sharibu mẹnu le ọrọ yii lẹyin ti awọn ọmọ Naijiria tu sori ayelujara lati fesi si fọnran kan ninu eyi ti ọkan lara awọn oṣiṣẹ iranwọ ti ikọ Boko Haram ji gbe laipẹ yii sọ.
Ọmọbinrin yii, Shiroma Pereira (ti a fi orukọ bo ni aṣiri), n mura fun ayẹyẹ igbeyawo rẹ.
Ṣugbọn kaka ki Eji fun wọn lesi, yiyan lo n yan kiri lori ilẹ naa, ti awọn ara abule naa ko si jẹ ki wọn tẹsiwaju lati san ilẹ ọhun mọ, Bẹẹ ni Gbadero ati awọn ọmọ ẹyin rẹ yi ẹsẹ pada, wọn kuro nibẹ, ti awọn ara abule si n pariwo le lori, bo ṣe n lọ.
Bẹẹ lọrọ ri pẹlu Ọmọtọlani Ekene, ẹni to salaye iru ipo idẹyẹsi to la kọja lọwọ awọn eeyan, tori pe o fi isẹ abẹ bimọ.
Ilu Eko ni wọn bi Jumoke si lọdun 1983.
“Bí ẹ bá ní òye, ẹ gbọ́ ohun tí mo fẹ́ sọ.
Ọkunrin tí ó ta ara rẹ̀ yìí yóo dàbí iranṣẹ tí à ń gbà lọdọọdun sí ẹni tí ó rà á; ẹni tí ó rà á kò gbọdọ̀ fi ọwọ́ líle mú un lójú rẹ̀.
Ìjọba da ológun sí Abuja láti dẹ́kun ìwọ́de Iroyin to n tẹ wa lọwọ ni yajoyajo ti kede pe ijọba apapọ ti fi awọn ọmọ ologun ransẹ si igboro ilu Abuja lati dẹkun iwọde EndSARS to n lọ lọwọ.
Ní 1995, ó bẹ̀rẹ̀ iṣẹ́ bíi ilé-iṣẹ́ ọkọ̀ òfuurufú aládàáni , Mozambique Express.
Nígbà tí ó parí ọ̀rọ̀ tí ó ń sọ, ó sọ fún Simoni pé, “Tu ọkọ̀ lọ sí ibú, kí o da àwọ̀n sí omi kí ó lè pa ẹja.
Ẹbí tàbi Ìdílé kan náà ni àwọn méjéèjì ti wá ṣùgbọ́n baba ni Elétùú Òdìbò jẹ́ sí Báálẹ̀, Elétùú Òdìbo ní í máa ń yan Báálẹ gẹ́gẹ́ bí aṣojú rẹ ní àárín ìlú.
'Ẹ má pè mí ní Kupe; DJ Copy l'orúkọ mi' Oríṣun àwòrán, Facebook Àkọlé àwòrán, Ilé isẹ́ ọlọ́pàá ní ìpínlẹ̀ Èkó ní Sunday Adefonou Anani jẹ́wọ́ lẹ́yìn tí ẹ̀rọ ìgbàlódé fihàn wí pé òun ló pa ọ̀gá rẹ̀.
 Ó gbé wọn dé màpó .
Ẹ má gba èlé lọ́wọ́ wọn mọ́, ẹ sì jẹ́ kí á pa gbèsè wọn rẹ́.
N óo fà wọ́n lé àwọn tí wọn ń wá ẹ̀mí wọn lọ́wọ́; n óo fà wọ́n fún Nebukadinesari, ọba Babiloni, ati àwọn ẹmẹ̀wà rẹ̀.
fun awon mọlẹbi rẹ pe ”Mo wa ninu ọkọ ofurufu kan to dabi ẹni pe
Àwọn ni baba ńlá àwọn tí wọn ń gbé etí òkun ati àwọn erékùṣù, tí wọ́n tàn káàkiri.
Mo wá rí àwọn ẹ̀mí burúkú mẹta kan, wọ́n dàbí ọ̀pọ̀lọ́ ní ẹnu Ẹranko Ewèlè náà, ati ní ẹnu wolii èké náà.
Àwọn ará ìlú Juda sì ń yọ̀,nítorí ìdájọ́ rẹ, OLUWA.
Kò yẹ kí ènìyàn ṣe ju ibi tí Ọlọ́run fún un ní ipá mọ.
Agbejoro agba fun ijoba ipinle, Tarek Saab so pe iwadii yoo bere ni pereu lori isele naa.
#BBCNigeria2019 Ààrẹ Buhari ti buwọ́lu òfin tí yóò dáàbò bo àwọn àkàndá ẹ̀dá Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí kan sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
Ọpọ eeyan si lo n fi oju wo eto atundi ibo naa gẹgẹ bii ija agba meji laarin aarẹ ile asofin agba ilẹ wa, Bukọla Saraki, tii se ọmọ bibi ipinlẹ Kwara ati aarẹ orilẹ́-ede yii, Mohammadu Buhari.
Bayii, ayipada ti n de ba ero ati ihuwasi awọn obinrin ẹkun yii.
A ti gbé kọ́kọ́rọ́ sẹ́nu ibodè Nàìjíríà kí ọrọ̀ ajé wa leè gbé pẹ́lí- ìjọba àpapọ̀ Ẹ dẹkun ere sísá lójú pópó láti dẹkun ìjàmbá- FRSC Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Wọ́n fẹ́ pa á ni ìròyìn bá kan ọ̀gá àwọn ọmọ-ogun pé gbogbo Jerusalẹmu ti dàrú.
Nigba ti BBC Yoruba kan si Oluwo lori aago, Ọba Oba AbdulRasheed Akanbi kọ lati sọrọ si aṣẹ ileẹjọ.
Nigba naa si ni Arsenal gba ife ẹyẹ idije Premier League kẹyin.
Àwọn èèyàn fi ìtara ba ilé ìjọsìn jẹ́ Ẹ gbà wá o!
    Bí a ti kúrò ni àjùlé ọ̀run tán tí a fi àgbègbè ibẹ̀ sílẹ̀ pátápátá tí a fi ẹsẹ̀ lé ọ̀nà ọ̀run Àpáàdì, nǹkan tí ó kọ́ yà mì lẹ́nu ni ẹbọ tí ó wà ni ojú ọ̀nà ní apá ọ̀tún àti apá òsì lọ, ogunlọ́gọ̀ wà nínú àpáàdì tí wọ́n ń bu epo sí, ìgbà mìíràn odidi màlúù wọ́n a kó ẹyọ owo sí inú àpáàdì wọ́n á bu epo sii, wọ́n a la ìfub adìyẹ wọ́n á rọ epo sii.
Ìró àwọn orílẹ̀-èdè dàbí ti omi òkun ńláṣugbọn OLUWA yóo bá wọn wí wọn óo sì sá lọ.
Dhikrulahi Sodo fi asiko naa ro ijoba Ipinle Oyo lati san owo osu tuntun yii
Bí ìbò rírà ṣe ṣákóbá fún iṣẹ́ ìwé títẹ̀ ní Nàìjíríà rèé Madam Sajẹ pé eni ọgọ́ta ọdún Ṣé ìgbé ayé rẹ dára ju bó ṣe wà lọdún mẹ́rin sẹ́yìn?
Balogun tí ó wà fún oṣù kẹwaa ni Maharai, ará Netofa láti inú ìran Serahi; iye àwọn tí wọ́n wà ninu ìpín rẹ̀ jẹ́ ọ̀kẹ́ kan ó lé ẹgbaaji (24,000).
Pasitọ Adeboye ni ipele kẹta awẹ naa yoo wa lati gba adura fun ijọ, idile ati ara wọn.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù AFCON 2019: Ki akọnimọọgba Naijira bá wọn sọ̀rọ̀ kóríyá Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ AFCON 2019: Ki akọnimọọgba Naijira bá wọn sọ̀rọ̀ kóríyá 17 Agẹmo 2019 Ọpọ tun yanana pé ki akọnimọọgba Naijiria ranti awọn aṣiṣe to ṣẹlẹ ninu idije to kọja.
Ẹ̀yin oluwa àwọn agbo ẹran, ẹ máa yíra mọ́lẹ̀ ninu eérú nítorí àkókò tí a óo pa yín, tí a óo sì tu yín ká ti tó, ẹ óo sì ṣubú lulẹ̀ bí ẹran àbọ́pa.
"Oríṣun àwòrán, @AsoRock ""Gbogbo awọn eeyan to jẹ pe iṣẹ ti wọn mọ ni ṣiṣe ko ju ki wọn pa eeyan lọ, ki wọn si maa pariwo ""Allahu Akbar"", n pa irọ ni nitori Ọlọrun o ṣe ibi."
Nígbà tí èmi àti ẹbọra náà kí ara wa tán tí mo sì béèrè ìyàwói mi, ó wí fún mi pé ẹ̀gbọ́n mi ti wá sí ibẹ̀ àti pé ó ti mú ìyàwó náà lọ sí ìlú wa nítorí pé wọn kò gbúròó mi.
Bákan náà ni àwọn ọmọ alufaa wọnyi: àwọn ọmọ Hobaaya, àwọn ọmọ Hakosi, ati àwọn ọmọ Basilai (tí wọ́n fẹ́ iyawo lára àwọn ọmọ Basilai ará Gileadi, ṣugbọn tí wọn tún ń jẹ́ orúkọ àwọn àna wọn.
Oúnjẹ koríko ni ìgbẹ́ eranko jẹ́ .
Tirẹ̀ ni ògo ati agbára lae ati laelae.
Ó ní Ijipti tí Hesekaya gbára lé dàbí kí eniyan fi ìyè ṣe ọ̀pá ìtẹ̀lẹ̀, ìyè tí yóo dá, tí yóo sì gún ẹnikẹ́ni tí ó bá gbára lé e lọ́wọ́.
WASSCE time table 2020: Àwọn akẹ́kọ̀ọ́ da ìdánwò WAEC rú ni Ghana, wọn gún infijilátọ̀
“mo ki ijoba yin ku ori-ire lati yanju ipenija to de  ba orile ede yin.
ọmọ Sufu, ọmọ Elikana, ọmọ Mahati, ọmọ Amasai, 
Awọn ajọ apinaka ni yoo fi iye owo ti o le ni naira meọ si merinla lori kilowati ina ti awọn olubara wọn ba n lo.
Orile-ede Naijiria pese ọgọ́rùn ún milionu owo dola($100 million), fun ise akanse naa.
Ìjọba ń ṣapá rẹ̀ lórí ìdènà Covid-19 àmọ́ àwọn awakọ̀ Eko ya aláìgbọràn - Ìjọba Gẹgẹ bi ikede ọhun ṣe sọ, eeyan mejila tuntun miran lo ku lọjọ Iṣẹgun nitori arun ọhun ni Naijiria.
Adebambo Olugbemigun n se kayefi lori bi o ti se jẹ Obasanjọ ni Afẹnifẹre lo ba ki wọn to le sọ ẹni ti wọ́n yoo gbaruku ti fun ipo Aarẹ lọ́dun 2019 Ero ọkan Adebambo se rẹgi pẹlu ti Abiodun Bamiduro Ko jẹ tuntun mọ pe Atiku Abubakar ati Muhammadu Buhari ni wọn jẹ oludije to lewaju lati du ipo Aarẹ lọdun 2019.
Awọn akiyesi ti a si ṣe ni pe Ronke ki Jago ku ayẹyẹ ọjọ ibi rẹ, lọjọ keji, oṣu Kọkanla.
ipinnu yin l, ki a jọ lee se isẹ yii papọ ati ni aseyọri.
lee se aseyori laisi ifowosowopo awon ara  ilu tabi orile-ede naa.
O ti dari awọn ọmọ ogun ilẹ lẹkun Keje ileesẹ ologun ilẹ wa, (7 Division), to wa ni Maiduguri, ko to tun di adari ajọ amusẹya Multi National Joint Task Force, ti ibujoko rẹ wa ni orilẹede Chad.
Soyinka ṣalaye pe ko si ohun kan to tumọ si iditẹ gbajọba ninu gbogbo ọrọ ti Sowore sọ.
Lati safihan mimu iko yii lokunkundun, paapajulo fun iko naa lati lo saseyori ninu idije yii, a ti san Ẹgbẹrun lọna ẹgbata owo dollar($600,000) ati millionu ti o leni Ẹgbẹrun lọna ọdunrun owo Naira(N320 million) lati pese awon ohun elo lolokan-o-jokan fun igbaradi ni kikun fun idije boolu agbaye yii.
Lẹyin ẹsun naa, Fatoyinbo ni oun yoo fesi si ẹsun naa nigba ti asiko ba to.
“Tabi bí ẹnikẹ́ni bá fi ọwọ́ kan ohunkohun tí ó jẹ́ aláìmọ́, kì báà jẹ́ òkú ẹranko tí ó jẹ́ aláìmọ́ ni, tabi òkú ẹran ọ̀sìn tí ó jẹ́ aláìmọ́, tabi òkú ohunkohun tí ń fàyà fà nílẹ̀ tí ó jẹ́ aláìmọ́, bí kò tilẹ̀ mọ̀, sibẹ òun pàápàá di aláìmọ́, ó sì jẹ̀bi.
Ọmọ kéékèéké 24 bá omi lọ!
O ni awọn alaṣẹ ileewe naa ti pinnu lati ṣe adinku owo ileewe lasiko yii nitori ai lanfaani lati maa kẹkọọ ninu yara ikawe nitori konile-o-gbele to wa nita nitori coronavirus.
Minisita fun eto aabo lorile ede Naijiria , Mansir Dan Ali ti pe fun ifọwọsowọpọ laarin akọroyin ati ajọ eleto aabo, ni eyi ti eto aabo
Ogagun to ti feyinti lenu ise naa, ni won ti n wa lati osu kesan an odun yii, leyin ti o kuro lati ilu Abuja lo si Bauchi sugbon ti ko de ibi to n lo.
Ọmọ náà kò ní í kú ní èwe bẹ́ẹ̀ ni kò ní í dàgbà sí ìyà, apà ọmọ aráyé kò sì ní í ká a.
Buhari so pe “O je adari rere tele, o tun je adari bayii ati ni ojo iwaju;wa a tun padabo sipo;mo gbadura fun o pe, ojo iwaju re yoo tun dara si I’’.
Wo àwọn Gómìnà Naijiria tí àrùn Covid-19 ti bá fínra Bàbá mi Aláàfin, ẹ ṣeun ẹ̀bùn owó tí ẹ fún èmí àti ọkọ mi- Lizzy Anjọrin Eyitayọ Jegede (PDP) ló máa gbéná wojú Rotimi Akeredolu (APC) nínú ètò ìdìbò Ondo tó ń bọ̀!
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù UK Covid Vaccine: Arábìnrin ẹni àádọ̀rún ọdún ló kọ́kọ́ gba abẹ́rẹ́ àjẹsára tí Pfizer ṣe síta 10 Bélú 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 8 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Arabinrin ẹni aadọrun ọdun kan ti di ẹni akọkọ ti yoo gba abẹrẹ ajẹsara Covid-19 tuntun ni ilẹ Gẹẹsi.
Ńṣe ni wọ́n ń fi Jesu rẹ́rìn-ín ẹlẹ́yà, nítorí wọ́n mọ̀ pé ọmọ náà ti kú.
ironilagbara ati lati wa ona miiran ti won yoo tun fi ran orile ede Naijiria
Ninu iwe akọranṣẹ kan ti igbakeji ọga ọlọpaa Yetunde Alonge buwọlu ni wọn ti ni ki olukọ naa yọju si agọ ọlọpaa, ẹka D10 CID to wa ni Yaba.
ko fi igba kankan kuro nibe lati maa se ojuse won lojuna ati ri daju pe 
Orilẹ̀ èdè Nigeria ti jẹ gbogbo ìyà àwọn ohun ti ó lè mú ki ọmọ rù yi, lọ́wọ́ Ìjọba Ológun àti Òsèlú fún ọ̀pọ̀ ọdún.
abadofin yii, ti awon igbimo tẹẹkotọ ba tete pari ise won ,ti won si gbee wa
Nítorí Ọlọrun níí jí òkú dìde.
Lára àwọn ọmọ Oholibama, aya Esau: àwọn tí wọ́n jẹ́ ìjòyè ni: Jeuṣi, Jalamu, ati Kora.
"níwọ ́ pọ ̀ , ààrùn yii maa ń múni nípa ìgéjẹ lọ ́ wọ ́ aabo ẹ ̀ fọn tí ó ní àkóràn "" anọfẹ ́ lísì "" ."
Coronavirus: Wo ohun tí o ní láti ṣe láti dáàbò bo ara rẹ Báwo ni o ṣe le mọ̀ pé o ní àrùn Coronavirus?
Àwọn àmúyẹ wo ni Ọ̀gá DSS tuntun, Yusuf Magaji Bichi ní ?
Ni afikun, FCTA tun fi atẹjade sita pe awọn ti da gbogbo awọn ti ọrọ kan mọ, awọn si ti fi ara balẹ wo iṣẹ ti wọn ṣe nibẹ ati ọna abayọ siṣoro to wa bayi FCTA ṣeleri pe lẹyin isinku Abba Kyari yii, awọn lawọn yoo maa ṣeto oku ẹnikẹni ti coronavirus ba tun pa ni Abuja.
Awọn kan sọ pe Sanwo Olu paapaa ko tii pade awọn miran ninu awọn kọmiṣọna naa ri rara Awọn miran gba pe agbara to ju agabra lọ lo yan awọn eeyan yii fun gomina.
Wọ́n bá mú un tọ Mose wá; orúkọ ìyá ọmọkunrin náà ni Ṣelomiti ọmọ Dibiri láti inú ẹ̀yà Dani.
Iku Daphne Caruana Galizia Oṣu kẹwaa 2017: Akọroyin oniwadii Daphne Caruana Galizia ku ninu ado oloro ti wọn fi sinu ọkọ.
( 2 ) Òrò àti Àpólà : Òrò ti a ba tòó pò ni ó ń di àpólà .
Orúkọ ìlú náà yóo máa jẹ́, “OLUWA Ń Bẹ Níbí.
Ninu isọri tawọn obinrin, Sharon Cherop ti oun naa jẹ ọmọ bibi ilẹ Kenya lo jawe olubori.
Ǹjẹ́ o mọ iye ẹ̀bùn owó tí olúborí BBNaija yóò gbà lọ́dún yìí?
O sọ eyi nitori o ni bi wọn ba lọ si ilu London, wọn ko lee ri owo ajẹmọnu ohun toju n ri lẹnu iṣẹ kankan gba lọhun tori naa wọn ko nilo lati lọ sọhun rara.
“Mo mú kí Farao dẹ́rù ba àwọn eniyan nígbà tí ó wà láyé.
Fọto ijapa ọhun ti kọkọ lu ori ayelujara pa, lẹyin ijamba ọkọ to ṣẹlẹ si i.
Nigeria Police: Ọ̀gá Àgbà Ọlọ́pàá ní kí àwọn ọlọ́pàá jà fún ara wọn
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Akọ̀wé àgbà ìgbìmọ̀ ilé ìwòsàn ìpínlẹ̀ Ondo sọ̀rọ̀ lórí ìkọlù ilé ìwòsàn àwọn alárùn ọpọlọ Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Nollywood Yoruba: Kìí ṣe sinimá ni mò ń ṣe, ìṣẹ̀lẹ̀ ojú ayé gangan ní sùgbọ́n.
Nígbà tí ìrì náà kásẹ̀ nílẹ̀, wọ́n rí i tí kinní funfun kan tí ó dàbí ìrì dídì bo ilẹ̀ ní gbogbo aṣálẹ̀ náà.
Agbára Oluwa wà pẹlu Jesu láti fi ṣe ìwòsàn.
Oju ọ̀nà titobi kan lọ tààrà sí iwájú, èyìínì ni pé ojú ọ̀nà tí bàbá mi ń tọ̀ bọ̀ túbọ̀ sí i.
“Mo ni lati tepamose ninu ipele ti o kan, nitori Petra Martic dara pupo ,”.
Isẹlẹ manigbagbe ti Abacha ṣe lori oye: Oṣu kẹsan-an ọdun 1994 ni Abacha kede pe ijọba oun ga ju aṣẹ ile ẹjọ lọ Abacha fragile ofin ologun 691 tọdun 1993, to si gbe ofin ologun miran kalẹ to fun ni agbara to ga julọ bii apaṣẹ waa, to si le ti ẹnikẹni mọle fun oṣu mẹta laisi gbe lọ sile ẹjọ Abacha sọ MKO Abiola si ẹwọn fun ẹsun iditẹ gbajọba tori pe Abiola pe ara rẹ ni aarẹ Naijiria, to si fiya jẹ ẹ titi ti Abiola fi ku O tun sọ Oloye Olusegun Obasanjo, Shehu Musa Yar'adua, Oladipupo Diya ati awọn eekan ilu miran si ẹwọn lori ẹsun igbidanwo iditẹ lati gbajọba.
Bẹ́ẹ̀ ni, mo mọ̀ nípa àyípadà tí ó wáyé nínú ìdarí iléeṣẹ́ yín lọ́dún tó kọjá.
Lọgan to kede aṣẹ yii naa ni awọn alaga ijọba ibilẹ ti ọrọ kan ti ṣepade, ti awọn naa si n leri peko si ẹnikẹni to le ṣi awọn nidi kuro ni ipo alaga.
Ọjọ buruku eṣu gbomi mu lọjọ Iṣẹgun jẹ fawọn mọlẹbi ati ọrẹ Richard Gbadebo, pẹlu bi iroyin iku rẹ ti ṣe kan wọn lara.
Sugbọn ti eeyan ba ni otutu igba aya ta mọ si pneumonia,omi ni yoo bẹrẹ si ni kun inu aaye atẹgun kekeeke wọn yi ti a si ma fa isoro fẹni naa lati ma mi daada.
Àwọn eniyan fetí sí ọ̀rọ̀ rẹ̀ títí gbolohun yìí fi jáde.
Oloogbe adajọ Kutigi feyin ti leyin àádọ́rin odun lenu ise ijoba, ni ogbon ojo osu kejila, odun 2009.
Akọroyin wa kan si ọkan lara awọn Pásítọ̀ tó ti gúnlẹ̀ síbi ètò náà, ó sì fi àrídájú hàn pé lóòtọ́ ni tórí adarí ìjọ náà, Pásítọ̀ Enoch Adeboye fúnra rẹ̀ sọ ọ́ lásìkò ìsìn kan lówùrọ̀ yìí, wọ́n sì ti pa ohùn pọ̀ gbàdúrà fún ìtúsílẹ̀ wọn.
Ẹ yin OLUWA, ẹ̀yin ẹ̀dá ayé,ẹ̀yin erinmi ńláńlá inú òkun ati gbogbo ibú omi;
Oríṣun àwòrán, Reuters Àkọlé àwòrán, Ina lagbara pupọ ko si nkan ti ko le jo Ilé ijọsin yii ti jona ri lọdun to ti pẹ ko to tun jona ti wọn fi tun un kọ laarin ọdun 1230 si 1240.
Wọ́n tún wà láàyè, wọ́n sì jọba pẹlu Kristi fún ẹgbẹrun ọdún.
Ẹni tí ó bá mu ọpẹ́ wá, tí ó fi rúbọ sí mi, ni ó bu ọlá fún mi;ẹni tí ó bá sì rìn ní ọ̀nà ẹ̀tọ́ ni èmi Ọlọrun yóo gbà là.
Yinka Ayefele ni alaga ati adari ile iṣẹ Iroyin Fresh FM ni ilu Ibadan.
Àwọn odi kọ̀ọ̀kan ní ààyè tóóró tí ènìà lè rọra rìn kọjá láì fo odi ọ̀hún, tí kò sì gba eranko kankan.
21 Bélú 2019 Arúgbó ṣe oge rí, àkísà lògbà rí lọ̀rọ̀ àwọn amóhùnmáwòrán wọ̀nyìí tí ọ̀pọ̀ àgbà ti wá owó kiri láti rà sílé nígbà náà!
O ṣe e ṣe ki awọn mii wa ti a ko mọ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ọlọ́fàiná, àgbà òṣèré sinimá ní ìfẹ́ owó, àti ṣekárími ló ń dá wàhálà sílẹ̀ láwùjọ Taiwo ní nítorí òfin ìgbéle COVID-19 ọ̀pọ̀ ló wà nílé, sáàjú ni àwọn ti gbọ́n pé àwọn One Million Boys ń bọ̀ láti kojú àwọn ará ilú, nítorí náà a kó ara wa síta láti gbèjà ara wa, sùgbọ́n nígbà tí o di ǹkan bíi aago mẹ́ta ọ̀sán mó rí Eze lórí ọ̀kadà pẹlú òkú èèyàn to sì gbékalẹ̀ sí Mosan lẹ́gbẹ̀ẹ́ afára aboru.
Gbàrà tí a wọ abà náà ni oúnjẹ́ ṣetán àti jẹ.
13 Ògún 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 3 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 5 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Nibayii, wọn ti yan Ọlamide George lati ẹkun ididbo ipinlẹ ti Akurẹ North gẹgẹ bii olori ile aṣofin naa nigba ti Abimbọla Fajolu lati ẹkun idibo Oluji/Okeigbo si bs si ipo igba keji.
Sugbọn ojiji ni aisan kọlu baba , eyi sọ di ẹni ti ko le gbe apa gbe ẹsẹ mọ.
Ninu iwadii kan ti ileeṣẹ BBC ṣe, a ṣe alabapade oju opo pupọ ti awọn obinrin ti n wa ọkọ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Itan Omi Erin Itan kan tun sọ wi pe lasiko ogun kan, wọn bẹ Ogedengbe lori ṣugbọn o fi agba han iku bẹẹ si ni ara rẹ rin lọ lati gbe ori rẹ pada to si gbe e le ọrun ara rẹ.
Lati orilẹede Japan, China ati Korea ni ajọ NAFDAC ni ẹja yii ti n wa si orilẹede orilẹede Naijiria.
Samuẹli dá a lóhùn pé, “Èmi aríran náà nìyí.
Yóo jẹ́ ọjọ́ ìrántí, ẹ óo kéde rẹ̀ pẹlu ìró fèrè, ẹ óo sì ní àpèjọ mímọ́.
Ọdun 1982 ni Ghana gba ife naa kẹyin.
Ẹ yìn ín fún iṣẹ́ ńlá rẹ̀;ẹ yìn ín nítorí pé ó tóbi pupọ.
Kọmiṣọnna fun eto ẹkọ ile iwe giga Saadat Modibbo Kawu ni kọmiṣọnna fun ile iṣẹ ijọba ti yoo maa ṣamojuto ọrọ eto ẹkọ ile iwe giga ni Kwara.
Àjọ ọlọpàá Eko kédé pé ìbalòpọ̀ nítà kò bójúmu 'Mo gbà kí baálé ilé f'ipá bá mi lò pọ̀' Èrò àwọn ọmọ Naijiria ṣọ̀tọ̀ọ̀tọ̀ lórí Tinubu àti Abbo Ọrọ yi ko ṣẹyin fọnran fidio kan to gbode lori ayelujara, nibi ti awọn obinrina kan ti ko wọ aṣọ tin jọ ninu ọkọ kan lopopona ibode Lekki si Ikoyi.
Bí ẹ bá ti wọ inú rẹ̀, ẹ óo rí kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ kan tí wọ́n so mọ́lẹ̀, pẹlu ọmọ rẹ̀.
Ati pe oun ti fi ẹjọ sun ni agọ ọlọpaa.
Yatọ si eyi, pupọ awọn nnkan to ma n kọ soju opo ayelujara, a ma fi adura to jọ ti Kristẹni sinu rẹ.
Saudi Arabia, Iran, Australia, Iceland, Peru, Costa Rica, Serbia, South Korea, Panama, ati Poland pẹlu awọn miran naa ti ja ninu idije.
Ó dá wọn lóhùn pé, “Òtítọ́ ni pé Elija yóo wá, yóo sì mú ohun gbogbo bọ̀ sípò.
Ó ń sọ ọ̀rọ̀ àfojúdi sí orúkọ Ọlọrun ati sí àgọ́ rẹ̀, ati sí àwọn tí wọ́n ń gbé ọ̀run.
 brasil je omoegbe oludasile awon orile-ede asokan , g20 , cplp , isokan latini , agbajo awon orile-ede iberia amerika , agbajo awon orile-ede amerika , mercosul ati isokan awon orile-ede guusu amerika , ati ikan ninu awon orile-ede bric .
Ṣugbọn Sadoku alufaa, ati Bẹnaya ọmọ Jehoiada, ati Natani wolii, ati Ṣimei, Rei, ati àwọn akọni Dafidi kò faramọ́ ohun tí Adonija ṣe, wọn kò sì sí lẹ́yìn rẹ̀.
Igbesẹ yii jẹ ọna lati le ri pe asẹyọri to ṣe lori ayẹwo iforukọsilẹ siimu to ṣe lọdun to kọja, ati lati mu nkan pada bọ sipo ni ẹka ibaraẹnisọrọ.
Nítorí pé, nígbà tí mo bá ń kọjá lọ, n kò fẹ́ kí ó jẹ́ pé mo kàn fi ojú bà yín lásán ni.
O ní ilé iṣẹ́ ilè òkèrè kan tí a ò fé dárúkọ ló sètò ìrìnà àlọ àtí ààbọ̀ wọn, sùgbọ́n ti wọ́n yọ owó náà pada kí àwọn tó dé pápákọ̀ òfurufú.
Tí ìjọba bá gbé òfin kónílé-ó-gbélé ọlọ́jọ́ pípẹ́ míì kalẹ̀ nítori Covid-19, ǹkan yóò bàjẹ́ ní Naijiria- Dokita OPC láwọn mú afurasí agbébọn ajínigbé mẹ́rin l'Oyo, ọlọ́pàá ní àpapọ̀ òṣìṣẹ́ elétò aàbò ló ṣiṣẹ́ náa INEC fún Obaseki ní ìwé-ẹ̀rí moyege gẹ́gẹ́ bí gómìnà tí wọ́n ṣẹ̀ṣẹ̀ dìbò yàn Wo bí ìwọ náà ṣe lè rí gbà nínú owó ìrànwọ́ tí ìjọba Nàìjíríà fẹ́ pín WASSCE: Ìpínlẹ̀ Delta fòfin de olùkọ́ 41 tó ṣe màgòmágó nínú ìdánwò Ifẹhonuhan lori afikun owo epo ọdun 2007 Ijọba Obasanjọ tun ṣe afikun owo epo bẹntiro lati N45 lọ si N70.
Lọjọ Iṣẹgun, ọjọ kẹrindinlogun, oṣu kéfa yii ni agbẹnusọ fun Senetọ Ajimọbi, Ọgbẹni Bolaji Tunji ti ba BBC Yoruba sọrọ ninu ifọrọwanilenuwo lori ohun to n ṣẹlẹ si Ajimọbi.
Ohun tí wọ́n yọ́ sọ fun yín, ẹ kéde rẹ̀ lórí òrùlé.
Nígbà tí ó gbọ́ pé Jesu ti dé sí Galili láti Judia, ó lọ sí ọ̀dọ̀ rẹ̀ láti bẹ̀ ẹ́ pé kí ó wá wo ọmọ òun sàn, nítorí ọmọ ọ̀hún ń kú lọ.
"Ẹranko náà gba ìwé ẹ̀rí lẹ́yín ọdún kan ètò ẹ̀ko Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Amiẹyẹ Fún ẹranko to ní ìgbpoya àti ìtẹramọ́ṣẹ́ lẹ́nu iṣẹ́"" láàrín àwọn ẹranko ọgbọ̀n to ti gba irú ami ẹyẹ yìí rí, "" Iyi nla ni fún wa ní a ṣe ri àmìẹ̀yẹ yìí gbà"" Olùdari Apopo Christophe Cox sàlàyé fún ilé ìròyìn Press Association News Agency."
A rí mọ̀lẹ́bí ẹlẹ́sìn Ìgbàgbọ́ àti Mùsùlùmí ní agbolé kannáà nítorí wọ́n a máa fẹ́ arawọn láì sí ìkórira kankan.
Nítorí pé ẹ̀ṣẹ̀ yín pọ̀ rékọjá ààlàni mo ṣe jẹ́ kí àwọn nǹkan wọnyi dé ba yín.
Ilé ẹjọ tún fi kún un pé ọ̀nà ti wọ́n gba san owó to kù náà fún ilé isẹ́ aládani tun ní kọlọfin nínú, wọ́n ní ẹ̀rí ìgbòkègbodo owó ti ko lọ ni ìlànà to yẹ tó ẹ̀ẹ̀mẹtà dín láàdọ́ta ti wọn san si awọn apo owo banki oniruuru láti ọdọ alága ilé iṣẹ Pinnacle Communications Olaoluwa ni kéte ti NBC san owo fún wọ́n.
Ṣugbọn o, ajọ naa ti sọ pe ibudo ayẹwo aarun naa ti pe mẹtalelọgọta jakejado Naijiria, ṣugbọn iṣoro kan to wa nibẹ ni pe awọn to n wa fun ayẹwo ko pọ to o.
Awọn agbofinro naa n gbe igbesẹ nipa ikọ ẹlẹsin Hakika Awọn agbofinro ti wa sọ fun BBC pe awọn ti n finmu-finlẹ nipa ikọ ẹ́lẹsin tuntun naa, tawọn si ti n dọdẹ wọn.
si jẹ  mẹ́fà , ọmọbinrin màrúndínlógún  , gbogbo iye won jẹ mọ́kàndínláàdọ́sàn án
Niṣe ni wọn maa n ti awọn Cardinal naa mọ ibi kan, ni olu ijọ Aguda, Vatican to wa ni ilu Rome l'orilẹ-ede Italy, Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Christmas:Ṣé ẹ ti ra fìlà ọdún?
Bakan naa, ibinu awọn ọmọ ẹgbẹ oṣelu APC, eto ati ilana ti awọn alaṣẹ naa n gba to eto ẹgbẹ oṣelu APC naa ko gbẹyin ninu awọn ẹsun ti wọn fi kan Adams Oshiomole.
” Wọ́n sì jáde pẹlu ọpọlọpọ ọmọ ogun ati agbára ogun láti lọ dojú ìjà kọ àwọn ọmọ Israẹli.
Goolu yii lo jẹ ki Rapinoe pada gba ami ẹyẹ ẹlẹsẹ ayo goolu ninu idije todun 2019 yii.
Awon olufesunkan ni aaye lati fi ohun to ba n dun won lokan han”.
Iya rẹ ni iyawo kẹta ninu iyawo mẹta ti baba rẹ ni Wo bí ìgbé ayé Richard Akinjide ṣe lọ gẹ́gẹ́ bí agbẹjọ́rò àti olóṣèlú tó mòye Àkójọpọ̀ fọ́tò ìsìnku Aisha Abimbola Pa Kasumu,gbajúgbajà òṣèré tíátà Yorùbá jáde láyé Auxiliary lo ń jà káàkiri ìlú Ibadan lọ́jọ́ Aje, ẹgbẹ́ ọlọkọ èrò NURTW kọ - Ejiogbe Baba rẹ jẹ oniṣowo rẹkọọdu orin, o si ni ile itaja kan, House of Nelly sounds, ni ibudokọ Meiran nigba kan.
O tun gbọdọ jẹ ọlọpọlọ pipe ti ko ni aisan opolo.
Fidio yii, koseemawo ni, ninu rẹ naa lẹ ti gbọ ohun ti awọn dokita atawọn ẹbi iyawo sọ nipa obinrin naa ati ọrọ ifẹ Tash ati Simon Young.
Kamaru Usman - Ninu ija mẹtadinlogun, o fidi rẹmi ninu ẹyọ kan Oríṣun àwòrán, Instagram/kamaru Usman Kamaru Usman naa, tii ṣe ọmọbibi orilẹede Naijiria, jẹ akọni abẹṣẹ ku bi ojo lagbo ija MMA.
Ewe, lara awon oloselu lorile-ede Naijiria naa so lori ero ayelujara won pe:Gege bi aare ile igbimo asofin, Dokita Bukola Saraki:” Ise takun-takun ni iko Super Eagles se.
Àwọn aláìlóye ọmọ,àwọn ọmọ eniyan lásán,àwọn tí a ti nà kúrò lórí ilẹ̀ náà.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Olamide Wonma nurse video: Nọ́ọ̀sì kan ní lóòótọ́ làwọn aláìsàn ń dẹnu ìfẹ́ kọ àwọn 5 Ògún 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 6 Ògún 2020 Oríṣun àwòrán, Olamide/Akintayo Blessing Olutọju alaisan kan to n ṣiṣẹ loke okun ti foju laifi wo oju aṣẹwo ti ọpọ eeyan fi n wo awọn nọọsi.
Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí US election 2020: What are primaries and caucuses and how do they work?
Ọkàn rẹ óo balẹ̀, nítorí pé o ní ìrètí,a óo dáàbò bò ọ́, o óo sì sinmi láìséwu.
A bi i ni ọjọ kọkandínlọgbọ̀n oṣù kẹsàn-an ọdún 1961 ní ilú Eko.
00 fun atunse ati dida ọda oju ọna onibeji Benin-Ofosu-Ore-Ajebandele-Shagamu Apapọ awọn owona wọnyii (16.
Gbogbo ara ni mo fi bá wọn ṣiṣẹ́ odi mímọ, sibẹ n kò gba ilẹ̀ kankan, gbogbo àwọn iranṣẹ mi náà sì péjú sibẹ láti ṣiṣẹ́.
Ọlọkan-o-jọkan awọn olorin bii Aṣa, Brymo ati Nneka ni wọn ti lọ ṣere nibẹ.
N óo fi ẹ̀rù mi sí wọn lọ́kàn, kí wọn má baà yapa kúrò lọ́dọ̀ mi mọ́.
  Bí ènìà dẹ̀ ṣẹ npàdé ehoro náà ni olúwarẹ̀ á máà rí onírúirú ẹiyẹ tí wọ́n nfò káàkiri láti igi sí igi inú igbó.
 ) ( my strength is flagging .
Ọdun 2016 ni ifasẹyin de ba eto ọrọ aje Naijiria kẹyin, iyẹn lasiko ti owo epo rọbi ja walẹ kaakiri agbaye.
Wọ́n fún Kalebu ní Heburoni gẹ́gẹ́ bí Mose ti wí, Kalebu sì lé àwọn ọmọ Anaki mẹtẹẹta kúrò níbẹ̀.
Ó tún lóyún, ó tún bí ọkunrin, ó ní, “Nítorí pé OLUWA ti gbọ́ pé wọ́n kórìíra mi ni ó ṣe fún mi ní ọmọ yìí pẹlu.
Iroyin sọ pe oloogbe naa lọ gba yara ni ile itura naa, Graceland Brothel to wa ni agbegbe Moshalasi ni Ejigbo lẹyin ti oun ati ọmọ alaṣẹwo kan jọ leri ẹgbẹrun lọna aadọta naira.
Bí mo bá kọ̀ wọ́n sílẹ̀, wọ́n gbé!
Ifesewonse naa waye lose melo kan ti o sayeye ojo ibi odun méjílélógójì laye, eleyi ti o mu ki orile-ede Liberia sagbateru ifesewonse olorejore ohun lati fi ka ese nomba ewu igbaboolu re, mẹ́rìnlá(number 14 jersey) kuro nile.
Nínú oṣù náà òpó iṣẹ ẹsìn àti itore a má wáyé.
Wọn ni ọrọ yi ko ri bẹ ati pe iye apapọ iye awọn ti ara wọn ya jẹ 364 ti wọn ba fi iye awn to gba itọju nile ni Katsina kun un.
Àwọn Farisi gbọ́ pé àwọn eniyan ń sọ ọ̀rọ̀ kẹ́lẹ́kẹ́lẹ́ báyìí láàrin ara wọn nípa Jesu.
Oríṣun àwòrán, others Gẹgẹ bi a ṣe gbọ, ni ọja Oke odo ni ija naa ti waye, bẹẹni ọpọ dukia lo parẹ sinu iṣẹlẹ naa ti ọpọ eeyan si fara pa pẹlu.
  Agbeyẹwo Iṣuna-Owo Ilu gbogboogbo wa ninu Ofin Iṣamojuto Iṣuna Owo Ilu“Abadofin
Ọ̀wọ́ keji àwọn tí wọ́n wá ṣe ìdúpẹ́ gba apá òsì, èmi náà sì tẹ̀lé wọn, pẹlu ìdajì àwọn eniyan, a gba orí odi náà lọ, a kọjá Ilé-ìṣọ́ ìléru, lọ sí ibi Odi Gbígbòòrò.
Ṣé wọn yóo tún máa rúbọ ni?
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Day 17: Àwọn olórí tó wà ní Kwara ń ṣe fún ara wọn nìkan ni #BBCNigeria2019 Idajọ naa tumọ si wi pe ile ẹjo to n gbọ ẹsun lori iwa ibajẹ le tẹsiwaju lati gbọ ẹjọ iwa ibajẹ ti wọn fi kan Adajọ Agba Walter Onnoghen.
Àwọn ọmọ Geriṣoni ni: Libini ati Ṣimei.
Ẹ óo sì ṣí àwọn ọ̀nà tí ó wọ ìlú wọnyi kí ẹnikẹ́ni tí ó bá ṣèèṣì paniyan lè tètè sálọ sibẹ.
 iye owó rẹ ̀ lójú pálí jẹ ́ 0.
Iran yii ko se wo rara, awọn obinrin, ọkunrin, ọmọde ati agba di ẹru diẹ lori, wọn n sa lọ, nigba to ya, wọn sọ ẹru ori wọn nu lati du ẹbi ara wọn ati ti ọmọ, amọ nigba to tun ya ni ọrọ di bi ina ba jo ni, to jo ọmọ ẹni, tara ẹni laa kọkọ gbọn.
Awọn alẹnulọrọ sọ wipe afurasi ọdẹ ti wọn pe ni Ajaja jẹ ẹni ti o ti pa erin miran ni ọdun mejila sẹyin.
Odunlade Adekola, Femi Adebayo, Jenifa ṣi aṣọ lójú àwọn fíìmù tuntun tẹ́ẹ ti ń retí Ẹ̀rọ CCTV tú àsírí ọkùnrin ẹni ọgbọ̀n ọdún tó fi ipá bá ọmọ ọdún mọ́kànlá lòpọ̀ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Àṣìṣe ọlọ́pàá àti Adájọ́ sọ mí di ẹni tí wọ́n dájọ́ ikú fún, ọpẹ́lọpẹ́ Fayoṣe tí ko buwọlu Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Ẹwẹ, oriṣi aawọ igbẹ lo wa: Eyi da lori irufẹ ounjẹ ti eeyan n jẹ o si n sọ nipa ipo ilera ẹni: Aawọ ewe - Ko dara Aawọ ewe to mọ lara - O dara Aawọ erupẹ - O dara Aawọ dudu - Tumọ si pe eeyan ti lo awọn oogun kan, tabi ẹjẹ dida nisalẹ ikun Igbẹ funfun - Nilo amojuto dokita kia kia Igbẹ pupa - Tumọ si pe o jẹ nkan ti awọ rẹ pupa, ẹjẹ dida ninu Igbẹ to ni ọra.
Abiola lo jawe olubori ibo naa, ṣugbọn Ọgagun fẹyinti Ibrahim Babangida wọgile esi idibo naa eleyi to da rogbodiyan silẹ kaakiri Naijiria nigba naa.
Ti a o ba gbagbe pe eto idibo gomina
 A ni igbagbo pe, won yoo satileyin fun wa nitori awon agbaboolu wa yii.
O ni ilẹ baba wa niyi, awọn agbẹ naa kii si se ajeji, nitori naa, ko si ohunkohun to yẹ ko maa dun mahuru mahuru mọ wọn lori ilẹ baba wọn.
Peter Okoye lóun ò ṣèlérí N60m fún Tacha, Zlatan gbórin tuntun jáde Ariwo sọ, wọ́n fọwọ́ òsì júwe ilé fún Tacha lórí ètò àgbéléwò BBNaija Kàyééfì rèé!
Igbà rẹ kò sì ní tọ lọ bíi orere, àwa sì laa borí rẹ, gẹgẹ báwọn ará ìgbàanì tí borí àjakalẹ-àrun to wáyé lasiko tiwọn.
Awon gomina ekun Gusu iwo-oorun orilede Naijiria, gbogbo
OLUWA bá sọ fún Aisaya pé 
Ìtàn tó rọ̀ mọ́ òwe ‘aṣọ kò bá Ọ́mọ́yẹ mọ́.
 ilé-ẹ ̀ kọ ́ náà ló wà ní Ìlọrin tí ọ ́ jẹ ́ olú ìlù ìpínlẹ ̀ náà .
O wa rọ awsn eeyan ipinlẹ Ọṣun lati fidimọle gẹgẹ bi aṣẹ ti ijọba pa lati lee wagbo dẹkun si wahala yii.
Ṣugbọn bí o bá wá rò pé àwọn wọnyi ni yóo jẹ́ kí ogun rẹ lágbára, OLUWA yóo bì ọ́ ṣubú níwájú àwọn ọ̀tá rẹ.
Ogbeni Rohr se ikede naa lojo
O so pe,“Eto ilera ofe yii waye lojuna ati tun
OLUWA fún Solomoni ní ọgbọ́n gẹ́gẹ́ bí ìlérí rẹ̀, alaafia sì wà láàrin òun ati Hiramu, àwọn mejeeji sì bá ara wọn dá majẹmu.
 bbhs wà ní ibùdó rẹ ̀ ní oke-saje .
Nítorí náà, OLUWA Ọlọrun ní, “N óo ṣàánú gbogbo àwọn ọmọ Israẹli n óo kó àwọn ọmọ Jakọbu pada láti oko ẹrú, n óo ṣàánú gbogbo àwọn ọmọ Israẹli, n óo sì jowú nítorí orúkọ mímọ́ mi.
 Ó tẹ̀síwájú pé, àwọn ǹkan wà ti ènìyà kò ni agbára lórí wọ́n, tí ènìyàn kò bá sì yí rí ojútùú ó tímọ̀ sí pé kò sí gbèdéke.
Dalung soro ohun di mimo lasiko ayeye odun ere-idaraya keji ipinle Akwa Ibom, 2nd Akwa Ibom State Youth Sports Festival ti o waye lojo isegun(Tuesday), ni  olu-ilu ipinle ohun,  Uyo.
Zubairu-Birnin-Daji soro ireti yii lasiko to n baa won akoroyin soro ni Zaria nipinle Kaduna pe: “O di dandan ki osan so didun leyin ti ijoba apapo ti pese owo yiya fawon agbe ologbin iresi lasiko yii.
" rántí ohun tí a rò nípa gírámà Àgbáyé , Èdè gẹ ̀ ésì , èdè Ìgbò , èdè "" eskimo ' , èdẹ ̀ "" japan ' ."
Obinrin kan tabi meji fún ọkunrin kọ̀ọ̀kan,ìkógun àwọn aṣọ aláró fún Sisera,ìkógun àwọn aṣọ aláró tí wọ́n dárà sí lára,aṣọ ìborùn aláró meji tí wọ́n dárà sí lára fún èmi náà?
Lasiko ti wọn ba n ṣe ajọdun Ṣango, paapaa lode Ọyọ, awọn oloriṣa Sango n maa yan Arugba pẹlu lati gbe igba iṣẹmbaye ti ipese fun ajọdun naa yoo wa wa si aafin.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Rape cases in Nigeria: Ọmọ ọdun 5 àti 14 ni Kalu wà nígbà tí obìnrin fipá ba lòpọ̀ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Rape cases in Nigeria: Ọmọ ọdun 5 àti 14 ni Kalu wà nígbà tí obìnrin fipá ba lòpọ̀ 21 Ògún 2020 Ni orilẹede Naijiria ati lawujọ agbaye patapata, isẹlẹ ifipabanilopọ ti di tọrọ fọn kale.
 Gbajabiamila  soro yii  lasiko  ayẹyẹ asalẹ apejẹ ti ijoba ipinle Eko se fun
 Atẹjade kan sọ pe “ lasiko iwadii ni  awọn  adigunjale marun un naa ti jẹwọ pe janduku oloselu ni  awọn  , ti oruko egbe  wọn  si n jẹ Youth Liberation Movement a.
"Ọmọ Nàìjíríà sọ òkò ọ̀rọ̀ sí Osinbajo lórí ìkíni rẹ sí Wole Soyinka Àlàyé rèé lórí bí wọ́n ṣe pa Ebila, olórí àwọn ""One million boys"" n'Ibadan Háà, àṣé Pásítọ̀ Adeboye kò léè dá èékánná ara rẹ̀ gé, àwọn ọmọ Nàìjíríà kan pariwo Sotitobire: Ẹlẹ́rìí mẹ́rìn ló tẹ̀lé Alfa Babatunde wá síwájú ilé ẹjọ́ lonìí Ṣé Akpabio ṣetán láti dárúkọ àwọn Aṣòfin tó gba iṣẹ́ àkànṣe lọ́wọ́ NDDC?"
Bí ó bá jẹ́ pé ti ayé ni yín, ayé ìbá fẹ́ràn yín bí àwọn ẹni tirẹ̀.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Arakunrin Fulani ni aigbede ara eni ni orisun ija pelu agbe Yatọ si ija ẹlẹyamẹya to n ṣẹlẹ leralera, lati ọdun 2012 ni wọn ti bẹrẹ ija ẹsin to ti mu ọpọlọpọ ẹmi lọ.
Nibayi, aṣa to n jẹyọ nibi ayẹyẹ ni pe awọn kan maa n gba awọn to ni ẹrọ ti wọn fi n lọ ata lati lọ iṣu iyan.
Mo kí yin mo tún yín kí, ẹ kú ìnáwo àáfin yìí, ẹ kú ìtọ́jú ìlú yìí, ìlú yìí jọ mi lójú, ẹ máṣe bínú sí mi àti àwọn ọ̀rẹ́ mi o, Kábíyèsí.
Mo sọ fun yín, n kò ní mu ọtí èso àjàrà mọ́ títí di ọjọ́ náà tí n óo mu ún pẹlu yín ní ọ̀tun ní ìjọba Baba mi.
Minisita fun ọrọ agbegbe, Ibrahim Jubril, ni minisita karun un ti yoo fi ipo silẹ lati ọdun 2015 ti wọn ti bẹrẹ isejọba Aarẹ Muhammadu Buhari.
Kelechi Iheanacho ẹlẹ́sẹ̀ ayò tún ti dábírà fún Leicester City
Ẹ jẹ́ kí a yé fi ojú tẹ́mbẹ́lú nkan tiwa n'tiwa.
Ayọ̀ ń bẹ fún gbogbo àwọn tí ó wá ààbò lọ sọ́dọ̀ rẹ̀.
Inú ọba ati àwọn ìjòyè dùn sí ìmọ̀ràn yìí, nítorí náà ọba ṣe bí Memkani ti sọ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Working religious women: Ẹ̀lẹ́hàá kìí ṣe ọ̀lẹ- Aminat Adegoke Koda, Gomina Rochas yan kọmiṣọnna ti yoo ma a dari rẹ.
O ṣalaye pe awọn ọmọbinrin tilẹ maa n bọ ara wọn si ihoho nile ijo, awọn si fẹ ẹ ri i daju pe ilu Abuja ni oṣuwọn iwa to tọ.
Nigba ti a beere lọwọ rẹ boya o le fẹ Adedimeji lọjọ iwaju, to ba dẹnu ifẹ kọ ọ, Adebimpe ni ọwọ Ọlọrun ni ohun gbogbo wa.
Ileeṣẹ ọlọpaa ipinlẹ ti fi ọwọ ofin mu Funke Akindele ati ọkọ rẹ lori ẹsun pe ohun ti wọn ṣe lodi si ofin konile-o-gbele to wa lode.
Aarẹ Buhari ti sọ tẹlẹ pe oun fẹ ki orilẹede Naijiria bẹrẹ si lo eto isuna ti yoo bẹrẹ ni oṣu kinni, ti yoo si pari ni oṣu kejila.
Esi ayẹwo ọhun to wa lati ipinlẹ mẹrindinlogun, ati ilu Abuja, lo ti i pọ ju lati oṣu diẹ sẹyin.
 irepo na , lomu pe kosese lati ma pe ilu meji , iworo to je awori po mo ajido to je egun , gegebi ikan , iworo-ajido .
Láti ibẹ̀ ni ó ti lọ sí Asiria, ó sì tẹ Ninefe dó, ati Rehoboti Iri, ati Kala, 
O soro lori ero ayelujara Tweeter, eyi ti o so lede Faranse amo ti won se itumo re lede geesi.
Nigba ti yoo si fi lo ọdun mẹrin nidi fifi ọkọ ko ẹru, Adegbọrọ tun ra ọkọ akẹru mẹfa sii, eyi to tun gba awọn awakọ si lati maa fi bawọn eeyan ko ẹru.
fun ipo aare ni igba kárùn
 Àwọn ààmì àìsàn a má a pọ ̀ síi pẹ ̀ lú iye aràn tó wà lára , lára irú àwọn ààmì bẹ ́ ẹ ̀ sì ni àìlèmíkanlẹ ̀ àti ibà ní ìbẹ ̀ rẹ ̀ àìsàn náà .
Nígbà tí àwọn ẹrú, ẹlẹgbẹ́ rẹ̀ yòókù rí ohun tí ó ṣẹlẹ̀, inú bí wọn pupọ, wọ́n bá lọ ro ohun tí ó ṣẹlẹ̀ fún olówó wọn.
'Ìdí tí pápákọ̀ ofurufú l'Ekiti kò fi m'ógbọ́n wá' Oṣiṣẹbirin ọkọ ofurufu jabọ latinu baalu Ọwọ tẹ agbofinro meji lori iṣowo ọmọniyan Ikọ iroyin BBC Yoruba ṣe abẹwo si papakọ ofurufu naa lati fi idi ọrọ mulẹ lori bi ọwọ iṣẹ ṣe n ya si ati lilọ-bibọ awọn arinrinajo ni papakọ ofurufu naa.
O ni bakan naa ni AIt kii bọwọ fun ofin igbohunsafẹfẹ.
”Nígbà tí aninilára kò bá sí mọ́ tí ìparun bá dópin,tí atẹnimọ́lẹ̀ bá ti kúrò ní ilẹ̀ náà.
Gbogbo ìgbìyànjú Newcastle láti gba ẹsan pàda, pabo ló jási oo Gbogbo àwọn ọmọ ti ikọ agbábọọlu Arsenal rà ni Chelsea naa kan ludo lónìí lái foya rárá, Alexandre Lacasete àti David Luis, bákan náà ni Pepe ti wọ́n rà láti France náà o gbẹ́yìn ninu ìdíje tònìí Ẹ̀wẹ̀, ẹnikan kò tẹ̀ fún ìkeji nínú ìfẹsẹwọnsẹ láàrin Leicester city àti Wolves.
“Ṣé koríko etídò le hù níbi tí kò sí àbàtà?
Lásán kọ́ ni pé alákùnrin yìí gbé ipò kíní, ìyẹn ni pé ó gba wúrà, ìwọ̀n ẹrù tó rí gbé sókè, kò tíì sí ẹni ẹgbẹ́ ẹ rẹ̀ kankan tó gbé ìwọ̀n wíwo báyìí rí!
Ṣugbọn ó tún ṣàǹfààní bí mo bá wà láàyè ninu ẹran-ara, nítorí tiyín.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ìdílé tí ọkọ da ọmọ síta tóríi ojú Búlùú tí wọ́n ní bá BBC sọ̀rọ̀ Ẹwẹ, ọkọ Risikat, Wasiu Dada ti jade lati sọ pe irọ ni o, kii ṣe torii oju buluu loun ṣe pa iyawo oun ti.
Kí ìjọ mi ní Sagamu le gbòòrò ni mo fi ń ṣiṣẹ́ ajínigbé pawó - Pásítọ̀ Bakan naa ni o sapejuwe ẹka eto idajọ ni Naijiria ti wọn ko naani ẹtọ awọn araalu afi awọn oṣelu ati awọn alagbara ti wọn le lo ọna magomago lati ri wi pe idajọ naa lo bi wọn ṣe fẹ.
Luminee wa sọ fun oun pe ki oun mase se aniyan lori rẹ rara nitori Ọlọrun yoo bu kun oun, ti yoo si ro oun ni agbara.
Baba ni oun ko bẹru iku nibi ti oun baa de lasiko yii, nitori naa Ṣaaju ni Baba ti ni oun ti gbadun aye oun daadaa nigba ti ahesọ jade nipa iku rẹ lọdun to kọja Nigba ti Akinyle pe ọdun kọkanleọgọrin ọdun lori oke eepẹ lo n fayọ rẹ han pe iya rere ni Juliana to bi oun Oríṣun àwòrán, @akinyele Àkọlé àwòrán, Kii ṣe nkan kekere lati di asiko yii laye, Akinyele dupe oore Oríṣun àwòrán, @akinyele Àkọlé àwòrán, Baba n ba awọn ololfẹ wọn sọrọ Oríṣun àwòrán, facebook/Alex Akinyele Àkọlé àwòrán, Akinyele jẹ ẹni to fẹran lati ma sọrọ lori ẹrọ ayelujara Akinyẹle tun ranti ajóṣepọ oun ati akọnimọọgba Clemens Westerhof ṣaaju iku rẹ Wo ohun tó yẹ kí o mọ̀ nípa Alex Akinyele minisita àná to dolóògbé Oríṣun àwòrán, facebook/Alex Akinyele Àkọlé àwòrán, Akinyele ni minisita tẹlẹri fun ọrọ iroyin lorilẹ-ede Naijiria tẹlẹ Wọn bi Alexander Opeyemi Akinyele lọjọ kẹrinlelogun, oṣu kẹrin, ọdun 1938, ni ilu Ondo, ni ipinlẹ Ondo.
Coronavirus: Ó dá mi lójú pé ìwá ìbàjẹ́ ló fa àrùn yìí - Ọ̀gá àgbá EFCC Ibà Lassa wọ ìpínlẹ̀ Èkó!
Mo yin Ẹni Gíga Jùlọ, mo fi ọlá ati ògo fún Ẹni Ayérayé.
nigba ti o ni iye ibo  17,248 lati gbomi
Logo Benz: Ọba ìlú Benin kìlọ̀ fáwọn ọ̀dọ́ lórí ṣíṣe òògùn owó òjijì.
Oríṣun àwòrán, OTHER Ariwo ayọ gba ilu kan pe eegun ẹyin ẹgbẹ okunkun naa ti ṣẹ, paapaa pẹlu olori rẹ to ku naa, ti awọn ọmọ ẹyin rẹ yoo si fi ẹsẹ fẹ.
Aarẹ Buhari kẹ́dùn ọ̀pọ̀ ẹ̀mí àti dúkìá tó jóná ni ọjà Onitsha Abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Patrick Day dèrò ọ̀run lẹ́yìn tó gba ẹ̀ṣẹ́ s'órí!
Ní ọjọ́ kan, ó lọ bọ Nisiroku, oriṣa rẹ̀, àwọn meji ninu àwọn ọmọ rẹ̀: Adirameleki ati Ṣareseri, sì fi idà gún un pa, wọ́n bá sá lọ sí ilẹ̀ Ararati.
Gomina Makinde ni gomina keji ti yoo bo lọwọ aarun coronavirus lẹyin ti gomina ipinlẹ Bauchi, Bala Mohammed naa ti gbadun.
Mo bẹ̀ ọ́ má dá mi lóró!
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Tani otutu ma n mu ju laarin Ọkunrin ati Obinrin?
O fikun un oro re pe, orile-ede Naijiria ti setan lati mu ayipada otun de ba ere idaraya ohun ati awon akonimoogba re lorile-ede yiiTesiwaju si, Ocheho so pe, idanileko naa yoo waye nipinle Eko, bee si ni iko obinrin yoo wa ni ipago won fun ose meji, ni ona lati tun maa samojuto awon olukopa saaju olokan-o-jokan idije to n bo lona.
Nígbà tí mo dé etí odo yìí, dípò ki ń dúró, ṣe ni mo bẹ́ si i, tí mo mòòkùn lọ, ìgbà tí mo sì maa jáde aarin omi ni mo jáde sí mo bá fi ìwẹ̀ si i, mo wẹ̀ já sí odì kejì odò.
wa, ni paapaa julo lori eto aabo,ọrọ aje ati gbigbogun ti iwa ibajẹ.
Yóo jẹ́ ìtùnú fún mi;n óo sì láyọ̀ ninu ọpọlọpọ ìrora,nítorí pé n kò sẹ́ ọ̀rọ̀ Ẹni Mímọ́.
” Ó fi ọwọ́ ọ̀tún rẹ̀ gbá Amasa ní irùngbọ̀n mú, bí ẹni pé ó fẹ́ fi ẹnu kò ó ní ẹnu.
Nígbà tí ó di òru, angẹli Oluwa ṣí ìlẹ̀kùn ilé-ẹ̀wọ̀n, ó sìn wọ́n jáde, ó sọ fún wọn pé, 
a la silẹ, o di dandan ki eto idagbasoke  de ba ina mọna-mọna lorile ede yii.
Lékeléke ló lẹfun, ki ráhùn ẹfun,
Nínú ọ̀rọ̀ tirẹ̀ Ayo Adebanjọ ni Tinubu kan dá si ọ̀rọ̀ náà nitori èròngbà rẹ̀ láti dupo ààrẹ ọdún 2023 ni.
Onilu ní láti ìgbà ti ẹgbẹ́ ò[sèlú PDP ti gbe APC lọ si ile ẹjọ ni òun ti mọ pé ẹ̀yìn igbá ni wan ń yín àgbàdo sí, nítori pé kò si àrigbámú kankan nínú ẹjọ́ ti wọ́n pé, pe ààrẹ kò ni ìwé ẹ̀rí tàbi ko lọ ilé iwé gíga.
Chutni sọ bí àìsí àtìlẹ́yìn tó késejárí ṣe mú u nira láti jà tako ìwà pálapàla yìí.
Aare ile-ejo agbaye ICC,adajo Chile Eboe-Osuji, ati igbakeji rẹ fun ile-ejo naa, Marc Perrin de Brichambut ati minisita fun oro ile okeere, Geoffrey Onyeama, ni wọn jọ lọ pade aare ni papa ofurufu naa.
Èmi ni àkọ́bí, ìgbà tí bàbá mi sì kú yìí ni mo tó wá mọ̀ pé ohun tí àwọn àgbà ń fi ara gbà kìí ṣe kékeré, àti pé ẹrù asáa’jú wúwo ju irin lọ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ondo Cow Death- Mùsùlùmí òdodo ni emi, mi ò kìí pa irọ́- Olu Ikare 25 Ọ̀wàrà 2019 Oríṣun àwòrán, @others Àkọlé àwòrán, Maalu mẹjọ di oku ni Ikarẹ / Akoko ni eyi ti Olukarẹ ni ko ni ọwọ ara ilu ninu Ó ṣeeṣe kó jẹ ohun tí wọn jẹ ló ṣekú pawọn ṣugbọn kìí ṣe ìlú lo pa wọn- Olukarẹ ti ilu Ikarẹ.
Awọn kan ni ọna ati pa ironu rẹ́ ni ìgbé ti awọn ọmọ orílèèdè Nàìjíríà n pa lójú òpó Twitter lẹyìn tí ìkọ Super Eagles fidiremi nínú ìdíje àgbáyé.
Gbogbo ohun tí ó ṣẹlẹ̀ sí wọn yìí jẹ́ àpẹẹrẹ fún wa.
Wòlíì Kasali ní Dolapo Awosika kò lé ìyàwó òun jáde 'Alífábẹ́ẹ́tì Ohùn Oduduwa di ìtẹ́wọ́gbà ni Ajaṣẹ' Ṣùgbọ́n àwọn èèyàn míràn ní, àwọn yóò mọ ìfìdírẹmi Bukọla Saraki lára, torí ọmọ ìpínlẹ̀ Kwara kò ní sí ní ipò kẹta mọ́ nínú àkóso Nàíjíríà.
Okòwò wo ni ẹ̀gbẹ̀rún mẹ́wàá tó ó ṣe?
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìjọba Naijiria: À ń se ìwádìí lórí àwọn oníwàásù Sokoto tó ń gbé ìbọ̀n 30 Bélú 2018 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ẹgbẹ́ agbébọ̀n náà wọ ìpínlẹ̀ Sokoto láti orílẹ̀èdè Niger tí wọ́n sì ń gbé ìjọba ara wọn kalẹ̀ lórí àwọn èèyàn agbègbè ọ̀hún Agbẹnusọ fun Aarẹ Muhammadu Buhari, Garba Shehu ti sọ wi pe ijọba apapọ yoo bẹrẹ iwadii lori awọn oniwaasu ti wọn lo n gbe oun ija kaakiri lagbeegbe kan ni Sokoto.
Iṣẹ ounjẹ tita naa ni arakunrin yii n ṣe gẹg bi iya rẹ ṣe fi to awọn oniroyin leti.
Ẹ̀yin ẹ̀dá ọ̀run, ẹ fi ògo fún OLUWA,ẹ gbé agbára rẹ̀ lárugẹ.
Iṣẹ pọ fun wọn lati ṣe nigba ti wọn ba koju France lalẹ ọjọ Aje.
Wọn ni o wa fun idagbasoke Naijiria ni ti ijọba ba lo owo ti wọn ba pa daadaa.
Gẹgẹ bi akọroyin wa, Chioma Obianinwa se salaye, awọn ọkunrin naa gba awọn irinsẹ akọroyin olowo iyebiye ti wọn gbe dani, ti wọn si dunkooko lati pa wọn danu nitori pe wọn ni wọn kọ 'awọn iroyin ti ko dara nipa Fada Mbaka'.
Kò sí àníàní, Coronavirus ló mú ẹ̀mí Ajimobi lọ - Ìjọba Eko Saaju la ti kọkọ mu iroyin wa fun yin pe ijọba ipinlẹ Eko ti kede pe arun Coronavirus lo mu ẹmi gomina ana nipinlẹ Oyo, Abiola Ajimobi lọ.
Aare ajo NFF, Amaju Pinnick se ifilole igbimo ti yoo maa samojuto wiwole ati bi owo se n jade ati igbimo isakoso miran ninu ajo ohun, lojo Isegun(Tuesday) nile ipade ajo ohun nilu Abuja.
Omar Conde naa ti ki aare Buhari ku ori ire fun jijjawe olubori gege bi aare
Onínúfùfù a máa hùwà òmùgọ̀,ṣugbọn onílàákàyè a máa ní sùúrù.
Àwọn ọkunrin tí ó wà ninu ìdílé tí OLUWA bá mú yóo wá ní ọ̀kọ̀ọ̀kan.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Rochas Okorocha: Fayose rọ Rochas Okorocha, Ibikunle Amosun láti jọ̀wọ́ ara wọn fún EFCC 30 Èbibi 2019 Oríṣun àwòrán, Twitter/Rochas Okorocha/Ayo Fayose Àkọlé àwòrán, Fáyòṣe ní kò yẹ kí ọ̀rọ̀ EFCC ó ya Rochas Okorocha lẹ́nu Gomina ipinlẹ Ekiti nigba kan ri, Ayọdele Fayoṣe ti ke si gomina to ṣẹṣẹ fi ipo silẹ ni ipinlẹ Imo, Rochas Okorocha pe, ko tete jọwọ ara rẹ silẹ fawọn oṣiṣẹ ajọ EFCC, to ba jẹ pe lootọ ni wọn wa lati muu.
Ṣugbọn àwọn ọkọ̀ mìíràn wá láti Tiberiasi lẹ́bàá ibi tí àwọn eniyan ti jẹun lẹ́yìn tí Oluwa ti dúpẹ́ lọ́wọ́ Ọlọrun.
Banzana Yusuf tó wá láti ìpínlẹ̀ Kano ní wọn sọ sẹwọn nitori pe, ó lọ́wọ́ nínú ìjínigbé àwọn akẹ́kọ̀ọ́ Chibok.
ti o ni agbara ju awon ẹsọ eleto aabo lọ.
Tesiwaju si, aare buhari wa ro awon omo orile-ede Naijiria lati maa fiyesi, ki won si tun maa samulo awon ilana ti o to ati ti o ye nipa idaabobo ara eni lenu ise, ni ona lati dena isele buruku.
Nítorí náà ẹ fi ògo fún OLUWA ní ìhà ìlà-oòrùn;ẹ̀yin tí ń gbé etí òkun,ẹ fògo fún OLUWA Ọlọrun Israẹli.
Sibaya tí ó wá láti ìlú Beeriṣeba ni ìyá rẹ̀.
Ojú n pọ́n ‘Gún, ẹyẹ- oko ò bá ‘Gún ṣe.
Àtẹ̀gùn pẹpẹ náà kọjú sí apá ìlà oòrùn.
9 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Oyo physically challenged protest: Ìdí rèé táwọn àkàndá ẹ̀dá fi dí iwájú iléeṣẹ́ ìjọba ìpínlẹ̀ Oyo pa l'Agodi n'Ibadan7 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Coronavirus: Ṣé ọtí leè dènà tàbí pa àrùn Coronavirus bi?
Rwanda ko faye gba ariwo irun pipe PDP tẹwọgba aabọ igbimọ to gbe kalẹ lati yanju aawọ Ijamba baalu to sẹlẹ kẹyin ni orilẹede Senegal ṣẹlẹ l'ọdun 2015, o si ṣe okunfa iku eeyan meje.
Ṣùgbọ́n ènià á kọ́kọ́ pọ́n òkè kékeré kan ná.
Kẹ̀kẹ́ náà ti gbajú-gbajà ní ìlú Èkó àti awọn ìlu nlá-nlá kọ̀ọ̀kan káàkiri Naija.
Eeyan mẹtadinlogun ni wọn pa loṣu karun ọdun 2020, ti mẹtalelogun miran si tun ku lọwọ awọn agbebọn ni ileto Gajihana, ni ijọba ibilẹ Magumeri.
Sugbon, diẹ́ lara awon osisẹ̀ ijọba lọ si ibi isẹ́ won, ti ọ́pọ́ si joko sile.
Ó bá sọ fún wọn pé, “Mo rí Satani tí ó ti ọ̀run já bọ́ bí ìràwọ̀.
“Kọ ìwé yìí sí òjíṣẹ́ ìjọ Efesu:“Ẹni tí ó di ìràwọ̀ meje mú ní ọwọ́ ọ̀tún rẹ̀, tí ó ń rìn láàrin àwọn ọ̀pá fìtílà wúrà meje wí báyìí pé, 
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Chow Chows Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Ìwọ OLUWA ni baba wa,Olùràpadà wa láti ìgbà àtijọ́, ni orúkọ rẹ.
Lẹ́yìn náà, OLUWA sọ fún Joṣua pé, 
Ọdun 1984 to gbe awo orin miran to pe ni Talazo'84, ni ogo rẹ fi bẹrẹ si n tan kalẹ.
Oríṣun àwòrán, CHISOM CHUKWUNEKE Àkọlé àwòrán, Bayii ni Chisom Chukwuneke ṣe ri lasiko to n gba itọju aisan jẹjẹrẹ inu ẹjẹ Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí World Cancer Day: Ènìyàn 26,000 ni àìsàn jẹjẹrẹ ń pa lóòjọ́4 Èrèlè 2019 Fídíò, Cancer: àpọ̀jù ṣúgà nínú ẹ̀jẹ̀ ń ṣàkóbá fún àgọ́ ara èèyàn1 Owewe 2019 Iléèṣẹ́ ọlọ́pàá mú ọkùnrin ẹni ọdún 55 tó gé ẹ̀yà ara èèyàn nílẹ̀ ìsìnkú ṣọ́ọ̀ṣì l'Ogun25 Bélú 2020 Ìbẹta, Oba Lamidi Adeyemi, Alaafin Oyo pé ọdún méjìlá; nkan tó yẹ kí o mọ̀ nípa wọn nìyíì26 Bélú 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 3 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 5 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Oríṣun àwòrán, @Naomi_Osaka_ Àkọlé àwòrán, Naomi fi aworan yan yio sita loju opo Twitter lati fi ki Baba rẹ ku ayajọ ọjọ ibi rẹ Akitiyan rẹ ko ipa ribiribi ninu igbesi aye ọmọ ati bi o ti se wa di ilumọka agbabọọlu Tennis loni.
"Mo si dupẹ pe mo yi ero mi pada.
Atiku n beere esi idibo ibo aarẹ orilẹ-ede Naijiria to waye ninu oṣu keji, ọdun 2019.
Kean ko se dáadáa ni saa akọkọ rẹ ni Premiership toun ti owó iyebiye tí wọn fi ra wa sí Everton lati Juventus,mílíọ̀nù meedogbon lè diẹ ní wọn rà tí kò sí ti gbá ju bọ́ọ́lù kan sáwọ̀n lọ ni sáà bọọlu yí.
O ni Auxiliary ko mọ iyatọ to wa laarin NURTW ati PMS.
Angẹli mìíràn tẹ̀lé ti àkọ́kọ́, ó ní, “Ó ti tú!
Nígbà tó bá yá, àwọn ọdọmọkunrin ati àwọn wundia yóo dákú nítorí òùngbẹ.
Mo ní ìdánilójú ninu Oluwa pé ẹ kò ní ní ọkàn mìíràn.
Lojiji ni ẹrọ ibanisọrọ mi dun, ọkan ni ninu awọn olukọ wa lo pe mo ba gbe ipe rẹ.
Ìdí tí Kristi fi kú nìyí, tí ó sì tún jí, kí ó lè jẹ́ Oluwa àwọn òkú ati ti àwọn alààyè.
láìka èyí tí àwọn oníṣòwò ati àwọn ọlọ́jà ń mú wá.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Bukola Saraki pe fun ajọṣepọ laarin Ghana ati Naijiria 6 Ẹrẹ̀nà 2018 Oríṣun àwòrán, AFP Àkọlé àwòrán, Orilẹede Naijiria ati Ghana ni ajọsepọ to fidi mulẹ Aarẹ ileegbimọ aṣofin agba lorilẹede Naijiria, Sẹnatọ Bukọla Saraki ti pe fun ajọṣepọ to gboopọn sii laarin awọn orilẹede lẹkun iwọoorun Afirika lati lee ṣi ilẹkun igba ọtun fun ilẹ Afirika.
Lọwọ-lọwọ bayii, pitimu nile ẹjọ kun fun awọn akọroyin, ero iworan, awọn agbẹjọro, igun olupẹjọ ati awọn ọmọ ijọ Sotitobire, ti wọn wa se atilẹyin fun asaaju ijọ wọn to n jẹjọ lọwọ, ki wọn si tun foju se mẹrin rẹ lẹẹkan si.
- Amina Zakari Kwara yóò gbàlejò BBC Yoruba Alao Akala ṣalaye pe, gba fun Raji nile lo maa n difa fun gbà fún Gbada lóko ṣugbọn ọmọ oko to fẹ jẹ Burẹdi ti ko fi èlùbọ́ ranṣẹ sile ti padanu ni ọrọ naa.
Coronavirus: Ìjọba ìpínlẹ̀ Eko rọ àwọn tó bá ọmọ Nàìjíríà tó k'árùn COVID-19 wọ bàlúù láti jókó sílé fún ọjọ́ mẹ́rìnlá
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Service Chiefs: Ilé aṣòfin ní kí àwọn ọ̀gá àgbà ológun kúrò lẹ́nu iṣẹ́ 21 Agẹmo 2020 Oríṣun àwòrán, NTA Awọn aṣofin orilẹede Naijiria ti funpe si awọn ọga agba awọn ologun ni ileeṣẹ ologun, ologun ori omi, ọlọpaa, ologun oju ofurufu, aabo, ati ileeṣẹ to n ri si ọrọ abẹnu lati fi ipo wọn silẹ.
Solomoni ọba fi igi alimugi náà ṣe òpó ilé OLUWA ati ti ààfin rẹ̀.
  Láàrin ìgboro kẹ̀, àwọn òṣìṣẹ́ ìjọba a máa fi ọkọ̀ akólẹ̀ kó wọn lọ dà sí ààtàn.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ǹjẹ́ o mọ gomina tuntun ní ìpínlẹ̀ Ọsun?
Iko asoju ijoba apapo kan, eyi ti minisita fun oro ile okere, Khadijah Abba Ibrahim dare re, ko awon omode-binrin naa le ijoba ipinle Yobe lowo.
'Niṣe ni wọn n ṣe ara wọn bi balogun, to maa n duro de ẹnikẹni to ba tile san owo isẹ wọn, lati gba ilẹ onilẹ pẹlu ipá.
Àwọn òbí rẹ̀ dáhùn pé, “A mọ̀ pé ọmọ wa nìyí; ati pé afọ́jú ni a bí i.
Bi o tilẹ jẹ pe awọn eeyan n sọ pe arun naa ko mọ oju sibẹ akọsilẹ n fihan pe ọwọja rẹ yatọ ni ileto si ileto.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Eeyan miliọnu 900 ni yoo kopa ninu idibo orileede India Amọ lọpọ igba ni awọn oludibo maa n koju iṣoro mimọ ami wọn yii nitori pe awọn ẹgbẹ oṣelu a maa dara pọ mọ ara wọn lasiko ibo ti awọn oludibo miiran kan si maa n koju ipenija dida ami wọn mọ.
Eyi lo mu mi tun ero ara mi pa.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù countries without coronavirus: Ọwọ́jà coronavirus yóò ṣì wà pẹ̀lú àgbáyé fún ìgbà pípẹ́- Ngozi Okonjo-Iweala 5 Èbibi 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 6 Èbibi 2020 Oríṣun àwòrán, Ngozi Okonjo-Iweala Minisita feto iṣuna lorilẹede Naijiria nigbakan ri, Ọmọwe Ngozi Okonjo Iweala ti ṣalaye pe ọwọja arun coronavirus yoo ṣi wa pẹlu gbogbo agbaye fun igba pipẹ ẹẹyin ti arun naa ba kasẹ n lẹ.
Bí o bá ń fẹ́ kí n máa bọ̀ lọ yí ọkọ rẹ padà sí ipò ènìyàn kí ó dà bí tí àtẹ́hhìnwá, oníbodè yóò ṣí ìlẹ̀kùn n ó sì wáá rí ọ.
Ní ọjọ́ keji, bí Jesu ti fẹ́ máa lọ sí ilẹ̀ Galili, ó rí Filipi.
Ni ọjọ buruku, eṣu gbomi mu ọhun, Mercy ni ọkọ oun sọ fun oun pe oun yoo gba ibi iṣẹ lọ si Bakana fun eto isinku.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù India election results 2019: Hema Malini, òṣèré Bollywood n léwájú nínú ìbò India 23 Èbibi 2019 Oríṣun àwòrán, Reuters Àkọlé àwòrán, Narendra Modi jáwé olúbori lẹẹkan sii ni India Wọn ti kéde Narendra Modi ti ẹgbẹ oṣelu BJP pé oun lo jawe olubori ni India.
Minisita ohun so lojo-Isegun lasiko abewo re si ilu Buea ti n se olu ilu ekun gusu iwo-orun  lojo-Isegun pe, “a le yanju oro naa laijo nnkankan, laijale, laiba nnkan j, ijoba ti setan lati sepade ijiroro pelu awon ti won n wa isokan ati alaafia orile-ede Cameroon”.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Nigeria ministers: Wo ohun tó yẹ kí o mọ̀ nípa àwọn obìnrin méje ti Buhari forúkọ wọn ránṣẹ 24 Agẹmo 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 21 Ògún 2019 Oríṣun àwòrán, others Àkọlé àwòrán, Wo awọn oju obinrin ti wọn le di minista lẹyin ayẹwo ile igbimọ aṣofin to n lọ lọwọ Bawo ni ayẹwo wọn ṣe waye: Lọjọ Iṣẹgun ni Aarẹ Mohammadu Buhari fi orukọ awọn minista mẹtalelogoji ranṣẹ sile igbimọ aṣofin ni AbujaDalung, Audu Ogbe, Shittu Adebayo àti Isaac Adewole kò wọlé.
Ọ̀sán ọjọ́ Aje ni Fayoṣe kérò l'ọ́gbà ẹ̀wọ̀n Ikoyi, ní ìpínlẹ̀ Eko.
Èkó kò ni bàjẹ́ o – ó bàjẹ́ ti.
Lẹ́yìn wọn ni àwọn ọmọ Kohati tí wọ́n ru àwọn ohun èlò mímọ́ tó ṣí.
Gẹgẹ bii Banki Agbaye ti wi, 2017, idamẹwa awọn eniyan to wa ni orilẹede lo n lo intanẹti.
Yàtọ̀ sí pé ọ̀jọ̀gbọ́n náà gbọ́n, ó tún kọ́ àwọn eniyan ní ìmọ̀.
Awọn Iroyin mii ti ẹ le nifẹ si Ìtàn tó wà nídi òwe ‘Sebótimọ Ẹlẹ́wà Sàpọ́n’ Ìtàn tó rọ̀ mọ́ òwe ‘aṣọ kò bá Ọ́mọ́yẹ mọ́.
Ọga ọlọpaa, Adamu n fi ẹsun sita pe awọn afẹhonuhan EndSARS ti ni i lọkan lati ṣe ibi sawọn ọlọpaa to si fi kun un pe ijọba ati ileeṣẹ ọlọpaa Naijiria yoo to ṣagbejade eto iranwọ fun idile awọn ọlọpaa to ku lasiko ifẹhonuhan naa.
Nàìjíríà kó 354 nínú ẹ̀ lọ́jọ́bọ̀ Ibí gbogbo làá tií dáná alẹ́ torí náà ẹ̀yin ọmọ Nàìjíríà, ẹ 'calm down'- Femi Adesina Ìjọba Nàìjíríà fi ọ̀sẹ̀ mẹ́rin kún ìséde ààrùn Coronavirus Àwọn agbófinró ti gbé Naira Marley lọ sílé ẹjọ́ fún ẹ̀sùn tí tàpá sí òfìn ìséde Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ohun tẹ́ẹ gbúdọ mọ nípa kókó orí ọyàn yín lásìkò fífọ́mọlọ́yàn Wolii Alfa Babatunde ti ọpọ mọ si Wolii Sọtitobirẹ n jẹjọ ẹsun ijinigbe lori ọmọdekunrin ọmọ ọdun kan to sọnu ni ijọ rẹ loṣu kọkanla ọdun 2019 lasiko ijọsin nibẹ.
Bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé mo ké pè é fún ìrànlọ́wọ́,sibẹsibẹ kò gbọ́ adura mi.
Ajọ EFCC ti fẹsun kan Ọga agba ẹka owo ifẹhinti lorilẹede Naijiria tẹlẹ, Abdulrasheed Maina pe o ra ile nla si orilẹede Dubai, Amẹrika ati awọn ile miran si agbegbe Jabi, ni ilu Abuja to to iye owo miliọnu meji dọla, owo ilẹ okeere.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù EFCC: Akinwumi Sorinmade ni orúkọ tí Aroke ń lo ni ilé ìfowópamọ 19 Bélú 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 20 Bélú 2019 Oríṣun àwòrán, Laailasnews Àkọlé àwòrán, Ọdaran tó wà lẹ́wọ̀n tún wóke $100miílíọnu níta-EFCC Olusegun Aroke tí àjọ tó n gbógun ti ìwà ìbàjẹ EFCC, jú ṣẹwọn ọdun mẹrinlẹ́logun ní ọgbà ẹwọn Kirikiri ní ìlú Eko ni wọ́n tún ń ṣe ìwadìí rẹ nitori pé oun ló tún wọké owó tó tó ọgọ́rùn mílíọnù naira laipẹ yìí.
Aré ti ń lọ fún ọjọ́ iwájú orílẹ̀ èdè Nàìjíríà
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Demilade Adepegba: Mo má a ń gbàgbé fèrè ni, tí mo bá wà nílé ìwé Adajọ Abiola Soladoye ti sun igbẹjọ naa siwaju di ọjọ kẹsan-an oṣu karun-un ọdun 2019, ti igbẹjọ yoo si tẹ siwaju.
Wo bí o ṣe lè mọ orúkọ àwọn afípabánilòpọ̀ ní Nàìjíríà Ìdí rèé tí mo fi ṣẹ̀ṣẹ̀ sọ̀rọ̀ lẹ́yìn tí wọ́n fipá bámi lopọ̀ lọ́mọ ọdún méje lọ́gọ́ta ọdún sẹ́yìn-Eli Wo bí àwọn obìnrin kan ṣe n sọ ara wọn di 'fágìn' lẹ́ẹ̀kejì Àwọn èèyàn kò fi bẹ́ ẹ̀ ní ìbálòpọ̀ lásìkò ìgbélé yìí - Iléèṣẹ́ kọ́ńdọ́ọ́mù Durex 'Àṣírí ọkọ mi tú sími lọ́wọ́, ṣé mo le dáríjì í?
Ìran tí Aisaya ọmọ Amosi rí sí Juda ati Jerusalẹmu nìyí, nígbà ayé Usaya, Jotamu, Ahasi, ati Hesekaya, àwọn ọba Juda.
Aare teleri oun fi ikominu han lori awon laasigbo ti o n waye kaakiri orile-ede Naijiria, ni eyi ti o so pe, o je idun-koko fun ojo-ola orile-ede yii.
Aidoo ni ireti wi pe ti arun Coronavirus ba ti kuro nilẹ, awọn yoo bẹrẹ si ni kọ awọn eniyan kaakiri agbaye bi awọn ṣe n ṣiṣẹ wọn.
Alukoro ileeṣẹ ọlọpaa ni ipinlẹ benue, Catherine Anene ṣalaye peawọn funra pe o ṣeeṣẹ ki o jẹ wahala to n bẹ silẹ laarin ẹya Ikurav ati Shitile ni ipinlẹ Benue lẹnu ọjọ mẹta yii.
Esi ifẹsẹwọnsẹ yii jẹ iyalẹnu fun ọpọlọpọ awọn ololufẹ ere bọọlu nitori ko si ẹni to le pe Man U le na Man City mọ le.
Àwọn iròyin ẹlẹ́jẹ̀ márùn ún tó fẹ́ẹ̀ tú Nàìjíríà ká Ìtọ́jú ara di ìrọ̀rùn!
Mose bá gbéra, òun ati Joṣua iranṣẹ rẹ̀, ó gun orí òkè Ọlọrun lọ.
Ti a ko ba gbagbe, Daddyshokey laipẹ yii ke si ajọ lati fi Naira Mailey lọrun silẹ nitori wi pe oun kọ lo n pa awọn eniyan lorilẹede Naijiria tabi ju ado oloro.
Bakan naa ni wọn ti ri iranlọwọ ẹrọ ibara ẹnisọrọ lori irin gba lọwọ ajọ UNDP O ni awọn ile iṣẹ ijoba ilẹ Gẹẹsi ni Mogadishu naa bawọn ṣeto iranlọwọ owo nipa ere idaji ni sisa.
Gbọ́ ìtàn bí ikọ̀ SARS ṣe dà bó ṣe dà láti ẹnu Ọ̀gá ọlọ́pàá tó dá SARS sílẹ̀ O sọ awọn iyatọ to wa ninu SARS ti oun da silẹ ati eyi to wa nigboro bayii.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Gbajugbaja eto BB Naija fun 2018 g'ori afẹfẹ 28 Sẹ́rẹ́ 2018 Oríṣun àwòrán, BBNaija Official Site Àkọlé àwòrán, Eto naa ti ọdun to kọja jẹ aseyọri nla Abala ikẹẹta gbajugbaja eto agbelewo to nipa ju nilẹ Afirika, Big Brother Naija ti bẹrẹ lonii ọjọ aiku, ọjọ kejidinlọgbọn osu kini pẹlu iside nla.
Fún odidi ọdùn kan gbáko èèso igi ni mo fi ṣe pàtàkì oúnjẹ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Oluwo: Ọ̀pọ̀ ọ̀dọ́ láwọn aṣíwájú orílẹ̀èdè Nàìjíríà ti fi ìwà àjẹbánu àti ìjẹkújẹ lé dànù sí òkè òkun 21 Èrèlè 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 20 Èbibi 2020 Oríṣun àwòrán, oluwo of iwo Oluwo ti ilu Iwo, Ọba Abdulrasheed Akanbi ni lootọ loun sa kuro lorilẹede Naijiria lọpọ ọdun, ṣugbọn iwa ijẹkujẹ to gogo lorilẹede Naijiria lo sọ oun di alarinkiri ni ilẹ okeere.
 ""O mọ iru isẹ ti mo n ṣe, idi ree ti ọwọ ọlọpaa ko fi tete tẹ mi."
Ninu ọrọ rẹ, ijọba ti gbe igbesẹ lati ri wi pe awọn ọmọ naa pada wale.
Mo fi ọ́ ṣe aláṣẹ lórí ìlú mẹ́wàá.
Adajọ naa kepe ajọ NBC, ileeṣẹ ijọba apapọ lori iroyin ati agbẹjọro agba ti Naijiria, lati farahan ki wọn si sọ idi ti ile ẹjọ ko fi gbọdọ da aṣẹ NBC lori ọrọ naa danu ni ọjọ kẹtala, oṣu kẹfa nigba ti wọn yoo tun gbọ ẹjọ naa.
Kola Ologbondiyan to j akọwe apapọ gb oṣelu PDP niPDP kọ ohun to pe ni idari lọna aitọ lati dena ipolongo.
lékèè gbogbo rẹ ̀ , ọ ̀ nà mẹ ́ rin pàtàkì nípa ìtàn ìṣẹ ̀ dálẹ ̀ ilé-ifẹ ̀ ni àwọn òǹkọ ̀ tàn ti kọ sílẹ ̀ tí wọ ́ n sì gbé yẹ ̀ wò .
"O ni ""Nnkan ti arakunrin yii ṣe ni wọn pe ni iwa ọdalẹ ni ilẹ Yoruba."
Ẹ kò gbọdọ̀ ṣe ohunkohun sí ọmọbinrin náà, kò jẹ̀bi ikú rárá, nítorí ọ̀rọ̀ náà dàbí pé kí ọkunrin kan pàdé aládùúgbò rẹ̀ kan lójú ọ̀nà, kí ó sì lù ú pa.
Kí Ọlọrun orísun alaafia mu yín ṣẹgun Satani ní kíákíá.
Bí ó ti wà yìí, ẹ̀yà pupọ ni ó ní, ṣugbọn ara kan ṣoṣo ni.
66 Ni igba yii, awọn ẹlẹsin Juu kan ti wọn n pe ni Essenes sọ tẹlẹ pe laarin AD 66 - 70, Jesu Kristi yoo pada wa lẹẹkeji aye yoo si pa aye rẹ.
Sẹnatọ Peter Nwaoboshi lo pe akiyesi awọn akẹgbẹ rẹ si isoro tawọn eeyan orilẹede Naijiria, paapaa julọ awọn mẹkunnu n doju kọ lori aisi owo ẹyọ fun wọn lati na pẹlu ọkan-o-jọkan iroyin to n sọ wipe banki apapọ orilẹede Naijiria ko tẹ awọn owo sile mọ.
Ní ọjọ́ keji, èyí àkọ́bí sọ fún àbúrò pé, “Èmi ni mo sùn lọ́dọ̀ baba wa lánàá, jẹ́ kí á tún mú kí ó mu ọtí àmupara lálẹ́ òní, kí ìwọ náà lè wọlé tọ̀ ọ́ lọ, kí ó lè bá ọ lòpọ̀, kí á sì lè bímọ nípasẹ̀ baba wa.
Ó bá lọ sọ́dọ̀ àwọn olórí alufaa ati àwọn ẹ̀ṣọ́ Tẹmpili láti bá wọn sọ̀rọ̀ bí ọwọ́ wọn yóo ṣe tẹ Jesu.
Ninu iwe ọrọ ibanikẹdun naa, ti alukoro agba Agbẹnusọ naa.
Ti a ba wa ri ẹnikẹni to ko o wọle, o tumọ si pe fayawọ lo ṣe.
Oríṣun àwòrán, others Ọrọ naa gba ibi ọtọ tun yọ pẹlu iroyin arakunrin kan ti orukọ rẹ n jẹ Sani Garba ti wọn ni o fipa ba obinrin ẹni ọgọta ọdun lopọ.
Àwọn eniyan náà a máa lọ kó wọn láàárọ̀, wọn á lọ̀ ọ́ tabi kí wọn gún un lódó láti fi ṣe ìyẹ̀fun.
A si nilo owo lati le ri ṣe'' Èèmọ̀ rèé o, Dókítà yọ eyín 526 lẹ́nu ọmọ ọdún méje Baṣọ̀run Gáà, tó yan ọba mẹ́rin, pa ọba mẹ́rin àmọ́ ọba karùn-ún ló pa á Ó tó gẹ́ẹ́!
Wo ojú ọmọbìnrin 5 tí afipa báni lòpọ̀ pa ní Nàìjíríà 'Àìjáfáfá àwọn panápaná ló mú kí ọṣẹ́ iná Akure pọ̀' Wọ́n ti gbé òkú Ibidunni Ighodalo sílé ìgbókúpamọ́sí l'Eko Wòlíì Sotitobire gúnlẹ̀ sí ilé ẹjọ́ ní ìtẹ̀síwájú ìgbẹ́jọ́ rẹ̀ 'Ọlọ́pàá ló ń pa wá, kìí ṣe coronavirus' Èèyàn 403 ló lùgbàdì àrùn Coronavirus ní Naijiria ní Ọjọ́ Isinmi Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí kan sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
 Òun ni bàbá fọ ́ kùnrin ; òun ni bàbá fóbìnrin .
Titi di bi a si ṣe n sọrọ yii, ọrọ naa ko tii tan nilẹ.
Lóri atéjiṣẹ Instagram rẹ̀ ni Bobrisky ti sàlàyé pé ìrìnajo oun láti yìí kuro ni ọkkunrin si obinrin to rẹwa, jẹ́ èyi to dun yùngbàyungba.
Ẹsun arabinrin naa tilẹ lagbara de bi pe, o ṣalaye bi alufaa naa ti maa n ba a lo pọ kakakiri gbogbo orilẹede ti wọn jijọ maa n rin irin ajo si.
O Shonibarẹ, Ayọ Akinsanya ati Ọlatunji Dosunmu.
Kini o fa igbesẹ Aarẹ Buhari yii?
James Omiyinka Olanrewaju gangan ni orukọ abisọ Baba Ijesha ṣugbọn ọpọlọpọ ni ko mọ ọ ju orukọ ori itage rẹ lọ.
Ó tun fi han ni pé obìnrin lè ṣe nǹkan ńlá; nítorí bí ó ti jẹ́ obìnrin yìí àwọn ọkùnrin ńlá gbogbo ń ṣiṣẹ́ lábẹ́ rẹ̀ dì bí a ti ń sọ̀rọ̀ yìí.
Òun ni yóo máa ṣe amọ̀nà wa títí lae.
Oshisko twins, àwọn 'ìbejì' tó ń dẹ́rìn ín p'òṣónú Ronaldo ya ẹro ibanisọrọ dokita lati yẹ oju rẹ wo Amnesty: Ọmọ ogun Nigeria ko naani ẹmi Oju àwọn tó gbẹ̀mí awọn olólùfẹ́ OOU rèé Adaku ni ẹnu araye lẹbọ ninu ọrọ igbeyawo nitori wọn a ni ki lode too ṣe sọrọ sita tabi o kuku ti n sọrọ ju.
26 Ògún 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 24 Ìgbé 2020 Oríṣun àwòrán, María Conejo/BBC Ti a ba n sọrọ nipa isẹda obinrin, a kii fẹ fi gbogbo ẹnu sọrọ nipa rẹ, nitori bi Ọba oke se obinrin ni ohun ọwọ ati ẹlẹgẹ.
Oke-ado niluu Ibadan ni ipinle Oyo to je  ekun Gusu, orile ede Naijiria .
À ń rí ohunkohun tí a bá bèèrè lọ́wọ́ rẹ̀ gbà, nítorí pé à ń pa àṣẹ rẹ̀ mọ́, a sì ń ṣe ohun tí ó dára lójú rẹ̀.
O sọ pe awọn kan wa to jẹ pe aisan diẹ ni yoo ṣe wọn ti wọn ba ni aarun naa, ti ara wọn yoo si ya.
" O wa gbadura fun Alaanu naa pe ko ni mọ inira nile aye rẹ.
Iwadii ti ileeṣẹ kan ṣe ti fi han pe, ileeṣẹ Facebook lee mọ igba ti awọn to wa loju opo ọhun ba n ni ibalopọ, paapaa julọ, awọn obinrin.
Ewe, Afghanistan ti kede ojo Aiku(Sunday) lati kedun iku awon omo-ogun ti o ba isele ikolu ohun lo, eyi ti ojo Aje(Monday) yoo si je ojo isinmi lati se-daro ati fifi ifehan si ebi, ara awon ologbe naa.
Ashade ti o je oga agba ile-ise African Prudential Registrar’s Plc ni o parowa yii lojo-Ru nibi ipade apero olodoodun fun ti odun 2018 ti a wa yii, eyi ti ile-eko awon akowe ati olutoju Institute of Chartered Secretaries and Administrators (ICSAN) ti o wa nilu Eko se agbateru re.
Nígbà tí mo wí báyìí tán ọkùnrin náà tún ń bá ọ̀rọ̀ rẹ̀ lọ, ó ní, Olówó-ayé, àwọn igi méjì tí iwọ rí wọn-ọnnì ènìyàn ni wọ́n jẹ́ rí.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Mo ń ṣa ike jọ láti san owó ilé iwé ọmọ mẹ́ta' Iroyin naa ti de agọ Ọlọpaa to wa ni Ipaja lati ile iwe Cedar College, Baruwa.
Ìdáhùn nìyíì Ṣẹ́ lóòtọ́ ní ginger àti garlic lè pa àrun Coronavirus?
DR Congo: Ọ̀pọ̀ ẹmí lo ti sọ́nù ninú ìjàmbá ọkọ̀ òfurufú tó wáyé lóòní
Gómìnà ìpínlẹ̀ náà Kayode Fayemi gbé jáde lóju opo twitter rẹ̀ lọ́sàn òní pé àsìkò ti tó láti máa fi oju hàn lásìkò to gbé àwòrán ẹni ọwọ Asateru Gabriel ti ìjọ St Andrew Anglican Ifinsin -Ekiti nígbà kan.
Kò yẹ kí ẹ má mọ̀, ará, pé ní ìgbà pupọ ni mo ti fẹ́ wá sọ́dọ̀ yín, kí n lè ní èso láàrin yín bí mo ti ní láàrin àwọn orílẹ̀-èdè yòókù, ṣugbọn nǹkankan ti ń dí mi lọ́wọ́ láti ṣe bẹ́ẹ̀ títí di àkókò yìí.
Lẹyin ti Aare Buhari wọle saa keji pẹlu ileri ati ṣẹgun wọn ikọlu awọn ẹgbẹ agbesunmọmi yii ko dẹkun.
Àwọn ìjọba tó n ṣe ìlànà ètò ẹ̀kọ́ (kòríkúlọ́ọ̀mù) kíì ṣe àwọn ohun tó yẹ́ tàbí pèsè àwọn ohun èlò.
Awọn olugbe ilu Kigali gẹgẹ bi iroyin naa ṣe sọ, tako erongba wọn lori igbesẹ naa.
Bush, ààrẹ Amerika tẹ́lẹ̀ ti jáde láyé lẹni ọdun mẹrinlelaadọrin Ọmọ rẹ, George W Bush, lo kede rẹ iku rẹ.
Ko ti daju ọna ti idiwọ yii yoo gba ṣugbọn lawọn orileede bi Iran, Libya North Kore ati Somalia ti Amẹrika ti gbe gi dina tẹlẹ, awọn alaṣẹ ati mọlẹbi wọn ko le gba awọn iwe irina 'visa' mọ lati wọ Amẹrika.
Níwájú gbogbo ìbátan wa, tọ́ka sí ohunkohun tí ó bá jẹ́ tìrẹ ninu gbogbo ohun tí ó wà lọ́dọ̀ mi, kí o sì mú un.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, June 12: Lekan Alabi ní kí ọmọ Naijiria rántí àwọn akọni ìjọba àwa-arawa Oloye Oluṣẹgun Obasanjọ lo kọ papa iṣere yii lasiko to n dari Naijiria labẹ ẹgbẹ oṣelu PDP.
Wọn yóo fi Ọmọ-Eniyan lé àwọn ẹlẹ́ṣẹ̀ lọ́wọ́.
Lai ni imọ eyi, Adediwura mori gba ọna agbegbe Abesan lọjọ naa ninu ojo, lori ọkada, to si ba ọlọjọ lọ nipasẹ agbara ojo to n ṣan.
Ọ̀nà wo ni a fi ba yín lò tí ó burú ju ti àwọn ìjọ ìyókù lọ; àfi ti pé èmi fúnra mi kò ni yín lára?
Oríṣun àwòrán, PA Àkọlé àwòrán, Loke okun ni igboro Dublin, orilẹede Ireland, ni ọmọ Somalia to jẹ ajafẹtọ Ifrah Ahmed (lapa alafia) ti duro ya foto pẹlu Aja Naomi King, to n kopa ninu fiimu kan gẹgẹ bi ajafẹtọ naa nipa ipolongo rẹ lori didẹkun didabẹ fun obirin.
Awuyewuye to waye laarin awọn ọmọ ẹgbẹ awakọ Ipinlẹ Eko ni iroyin ló ṣe iku pa ọkan lara wọn to gbẹmi mi ni ibudokọ Ọjọta.
Ẹ̀yin náà kúkú ti mọ irú ẹni tí a jẹ́ nítorí tiyín nígbà tí a wà láàrin yín.
Bákan náà, máa gba àwọn ọdọmọkunrin níyànjú láti fara balẹ̀.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Black women live matters: Ọdún 2015 ní àwọn ọlọ́pàá pa India Kager láìní ìdí- Gina Best Gbajabiamila fún Godswill Akpabio lọ́jọ́ méjì láti forúkọ àwọn aṣòfin tó gba iṣẹ́ lọ́wọ́ NDDC léde Agbẹnusọ ile igbimọ aṣoju-ṣofin, Femi Gbajabiamila ti fun Minisita fun ọrọ Niger Delta, Godswill Akpabio ni ọjọ meji pere lati darukọ awọn aṣofin ti ajọ NDDC n gbeṣẹ fun.
O ni fifi ẹmi ẹlomiiran wewu ni ṣiṣe ere idaraya pẹlu awọn mii tumọ sii lasiko yii.
Mi o ni ija tabi aawọ kankan bi o ti wulẹ o mọ pẹlu Gani Adams, ṣugbọn igbe aye rẹ atẹyinwa ti ko ba irinajo mi mu ni mo tako"" ""Bi ẹnikẹni ba lero pe mo ni aawọ pẹlu oun to nilo ka pari, irufẹ ipari ija bẹẹ ko lee waye nibomiran yatọ si ile mi ni Abẹokuta."
#AFCONU23Q: Nàìjíríà na Libya lálùdákú pẹ̀lú àmì ayò 4-0
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: ‘Èpè ni Toyin Abraham sẹ́ fún mi nínú ìgbìyánjú mi lórí ìgbeyàwó rẹ̀ tó dàrú’ Àwọn ọmọ Iyabọ Ojo rí Bàbá lẹ́yìn ọdún mẹ́fà Fídíò bí Ìwé títẹ̀ ní Sómólú l‘Eko se dára ju ti China lọ Atagitá Fẹ́mi Aníkúlápó-Kútì bá obìnrin lọ l‘Amẹ́rika Ikọ̀ ẹlẹ́sìn Hàkíkà rèé, níbití wọn ti ń pààrọ̀ ìyàwó láàrín ara wọn Òwò Àdìrẹ bùyààrì ní Abẹ́òkúta Justice Osei le dún bíi ẹranko 50 Túnbọ̀sún Ọládàpọ̀: Òǹkọrin ni etí Ọba láti sọ òdodo Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí kan sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
Nítorí ìkọlù àjòjì ní South Africa, èèyàn 5000 ló padánù iṣẹ́ wọn ní Nàìjíríà Ààbò tó péye wà fún àwọn okòwò ará South Africa ni Eko -Sanwo Olu Akeredolu ò ṣe ǹkan àrítọ́kasi ni Ondo- Komísọnà ọ̀rọ̀ to n lọ tẹ́lẹ̀rí Ọlabisi Ajala rèé, ó gun ọ̀kadà yíká àgbáyé, tó sì dé orílẹ̀èdè 87 Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
N óo jẹ́ kí ẹ máa gbé ní alaafia ati ní àìléwu.
Adajọ Sikiru Oyinloye tun paṣẹ fun Kolade Emmanuel Balogun pe ki o san ẹgbẹrun un lọna aadọta naira gẹgẹ bi owo itanran lẹyin to jẹbi ẹsun ti ajọ EFCC fi kan an.
Ajọ náà fi kún pé ti wọn ba fi le buwólu abadofin, owó ìfẹyin ti láílái yìí, ó túmọ si pe, ilé ìgbìmọ àsofin náà ti tàpá si òfin Nàijíría àti ti àgbáye.
N kò fẹ́ kí n sọ̀rọ̀ púpọ̀ jù nísisìyí, ìwọ ọmọ ènìyàn, mo kí ọ, o kú àbọ̀, mi sì kí ọ̀rẹ́ mi náà pé ó kú àléjò, ọ̀gbẹ́ni pàtàkì, Baba-onírùngbọ̀n-yẹ́úkẹ́, ẹni tí ń gbé ibi gegele òkúta.
 Palestine fe ila oorun Jerusalm gege bii olu ilu orile ede lojo iwaju bee Isreal ti kede gbogbo ilu Jerusalem gege bii olu ilu re.
Mo ti tẹ́ aṣọ fẹ́lẹ́fẹ́lẹ́ aláràbarà ti ilẹ̀ Ijipti sórí ibùsùn mi.
Ọlọrun, o ti kọ̀ wá sílẹ̀,o ti wó odi wa;o ti bínú, dákun, mú wa bọ̀ sípò.
Alukoro ọlọ́pàá ni àwọn oninure eniyan ti ń pe wọn fun itọni si awọn ole naa kaakiri ni eyi to ti ń bi èso rere bayii.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Àgùnbánirọ̀ mẹ́san pàdánù ẹ̀mí wọn Tọkọtaya lu ọmọ ni gbanjo fun 400k Irú ẹ̀dá wo ni aṣòfin Bukola Saraki jẹ́?
Ijoba ipinle Edo ti tenumo erongba re lati gba awon oludokowo niyanju, lati lo anfaani ilana ti won gbe kale lati mu igberu ba eto idokowo won ni ipinle naa.
Goolu méjídínlọ́gọ́fà lo gba wọ inu awn fun Manchester United ninu ifẹsẹwọnsẹ ọ́ọ̀dúnrún dín mẹjọ.
Ibi tí a ti ń yọ ayọ̀ yìí ni mo ti ń wo ọkùnrin kan báyìí tí ó ti bẹ̀rẹ̀ sí rẹ́rìn-ín láti ìgbà tí mo ti dé ọ̀dọ̀ àwọn àlejò wọ̀nyí, nígbà tí mo sì wò ó dára-dára mo rí í pé ẹni tí mo tí mọ̀ ni.
Fàyàwọ́ ọmọnìyàn kó ọmọ ilé ìwé ọgọ́rùn ún Ijamba ibọn Macerata s'afihan ẹlẹyamẹya Libya: Ọmọ Naijiria mejilelaadoje miran pada sile Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
 ní bíi 2014 , òṣùwọ ̀ n owó rẹ ̀ lójú pálí kúsí us $ 0.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Florida: Ọ̀ọ̀nì àléègbà dé ba Mary lálejò lọ́gànjọ́ òru Nitootọ ni ariwo ero pọ fun Mohamed Salah to n gba bọọlu fun Liverpool ṣugbọn o kan gbiyanju ti ara rẹ lasan ni.
Àkọlé àwòrán, Ọ̀pọ̀lọpọ̀ àwọn ẹlọ́wọ̀n ló n retí ìdájọ́ ikú láti ọjọ́ pípẹ́.
WAEC 2020 result checker: Wo nkan tí yóò ṣẹlẹ̀ sí àwọn akẹ́kọ̀ọ́ tí àjọ WAEC gbẹ́sẹ̀ lé èsì ìdánwò wọn
Ṣugbọn awọn ọmọ Naijiria miran lero pe titẹ okunrin lọdaa ki ṣe ọna abayọ si iwa ifipabanilopọ.
Andrew Johnson jẹ ọkan ninu wọn lọdun 1868, ti ẹnikeji si jẹ Bill Clinton lọdun 1998.
Láti ìgbà tí mo ti kó wọn wá láti Ijipti títí di òní ni wọ́n ti kọ̀yìn sí mi, tí wọ́n sì ń bọ oriṣa.
#Year end Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí 2 sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
"Ṣugbọn ""nigba to ya, o bẹrẹ si ni ba mi ja pe ki n ko awọn ọmọ meji ti mo bi fun ọkunrin keji pada si ọdọ baba wọn."
jise ikinni aare Buhari si Emir ilu Gusau ati apapo awon eniyan ipinle Zamfara,
Naijiria fi ìgbájú mẹ́ta lé Cameroon kúrò ní AFCON Ẹ yé irọ́ pa, mí o fún Super Eagles ní ẹbùn owó kánkan -Sanwo Olu Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, A ó jà fitafita láti ríi pé a ò já kulẹ̀ lónìí - Genort Rohr Ọdun 2018 ni wọn yan ọmọ ẹgbẹ agbabọọlu Naijiria tẹlẹri, Amuneke gẹgẹ bii akọnimọọgba ẹgbẹ agbabọọlu orilẹede Tanzania.
Alufaa yóo mú díẹ̀ ninu ẹ̀jẹ̀ ẹran ẹbọ ìmúkúrò ẹ̀bi yìí, yóo fi kan ṣóńṣó etí ọ̀tún, ati àtàǹpàkò ọwọ́ ọ̀tún ati àtàǹpàkò ẹsẹ̀ ọ̀tún ẹni tí wọ́n fẹ́ wẹ̀ mọ́.
Nígbà tí wọ́n bí Mose, nípa igbagbọ ni àwọn òbí rẹ̀ fi gbé e pamọ́ fún oṣù mẹta nítorí wọ́n rí i pé ọmọ tí ó lẹ́wà ni, wọn kò sì bẹ̀rù àṣẹ ọba.
bọya orukọ wọn wa ni pese, ati bi o ti yẹ.
Bakan naa, àwọn ọmọ Naijiria ti tú sí àwọn ojú òpó ayélujára láti bẹ̀rẹ̀ sí ni fi ọ̀pẹ́ fún ọlọ́run ti wọn si n gboriyin fun ijọba orilede Naijiria.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù NANS: Àwọn aráàlú ní se ló yẹ kí NANS bẹ̀bẹ̀ fún òpin ìyansẹ́lódì ASUU 5 Sẹ́rẹ́ 2019 Oríṣun àwòrán, @AsoRock Ọpọ ọmọ Naijiria lo ti n sọrọ lori fidio kan to n ja rainrain nilẹ pe aarẹ ẹgbẹ awọn akẹ́kọ ile ẹkọ giga nilẹ wa, NANS, Danielson Bamidele Akpan, sọ fun aarẹ Muhammadu Buhari pe, yoo ri ibo ogun miliọnu laarin awn akẹkọ ilẹ yii.
Ninu fidio kan eyi to fi ṣọwọ si BBC News Yoruba, Oluwo ti ilu Iwo rọ gbogbo awọn muslumi lati maṣe lọ si Mọṣalaṣi fun irun Jimọ ni ọjọ Ẹti.
Ebi kò ní pa wọ́n mọ́, bẹ́ẹ̀ ni òùngbẹ kò ní gbẹ wọ́n mọ́.
O sísọ loju rẹ pe, ilẹ obinrin kii pẹ su, bi oun ko ba si tete bi awọn ọmọ ti oun fẹ bi loju ọjọ, o ṣe e ṣe ki isoro wa lọjọ iwaju lati bimọ, bẹẹ si ni owo tabi okiki ti oun ni, ko lee ra ọmọ fun oun.
Oríṣun àwòrán, Omogoriola Hassan Olori kan ti mo ni ti to mi: Lori ọrọ awọn olori laafin, Oba ilẹ Uba ni oju kan lada ni lọrọ oun, o ni iyawo kan toun ni, ti tẹ oun lọrun.
Nítorí náà, a máa ranṣẹ pè é lemọ́lemọ́ láti bá a sọ̀rọ̀.
Láti ìgbà náà ni àwọn ọmọ ogun Dafidi ti búra fún un pé, “A kò ní jẹ́ kí o bá wa lọ sí ojú ogun mọ́ kí á má baà pàdánù rẹ, nítorí pé ìwọ ni ìrètí Israẹli.
Mi ò to iṣẹ́ Regina Daniels rárá kí n tó fẹ́ ẹ láàrin ọ̀sẹ̀ mẹ́ta, mo sì tún le fẹ́ ìyàwó míì - Ned Nwoko Ohun tó yẹ kẹ́ẹ mọ nípà olùdíje mèjì tó lágbára nínú ìdìbò Ghana rèé Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Favour Oladele: Bó ṣe kàgbákò ikú gbígbóná lọ́wọ́ ọ̀rẹ́kùnrin rẹ̀- Kayeefi10 Èbibi 2020 8:49 Fídíò, Coronavirus and Kayeefi: Òtítọ́ àti irọ́ wo ló wà nípa oògun owó àtàwọn ìṣẹ̀lẹ̀ kàyééfì míràn, Duration 8,4929 Èbibi 2020 Ìròyìn Kàyééfì BBC Yorùbá: Bí Ọba aládé ṣe jàjà bọ́ lọ́wọ́ àwọn afurasí ajínigbé28 Bélú 2020 15:39 Fídíò, Favour Oladele: bó ṣe kàgbákò ikú gbóná lọ́wọ́ ọ̀rẹ́kùnrin rẹ̀, Duration 15,3931 Sẹ́rẹ́ 2020 Èyí tí a wò jùlọ 5:03 Fídíò, Omolola Arohunmolase Welder: Mo ti fí iṣẹ́ 'Welder' gbayì láwùjọ, tó mo fi tọ́ ọmọ yanjú, Duration 5,039 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 5:39 Fídíò, Akomolede ati Asa lori BBC: Olùkọ́ Kikelomo Ogunboye tan ìmọ́lẹ̀ sí ìwà olè ọ̀gá ọlọ́pàá Audu gẹ́gẹ́ bí àwòkọ́ṣe àsìkò yìí, Duration 5,398 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 4:11 Fídíò, Oba Adeyeye Ogunwusi: Ojú mi ti rí lọ́pọ̀ lọpọ̀, ọ̀pọ̀ èèyàn ni kò tilẹ̀ gbàgbọ́ pé mo lè jọba- Ooni, Duration 4,117 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 4:43 Fídíò, Promise Akinlade: ọmọ ọdún mọ́kànlá tó ń fi ìlù dárà bíi àgbàlagbà sọ̀rọ̀ nípa tálẹ́ǹtì rẹ̀, Duration 4,437 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 0:59 Gbọ́, Ìsẹ̀lẹ̀ jákèjádò orílẹ̀èdè àgbáyé láàárín ìṣẹ́jú kan, Duration 0,59wákàtí 5 sẹ́yìn 7:03 Fídíò, Olumuyiwa Bolade Adedeji Military Bruitality: Bí arákùnrin onípèníjà ara tí sọ́jà lù ṣe dé, Duration 7,035 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 4:45 Fídíò, Yoruba Films: Ẹ̀ẹ́ bẹ̀ mi kúrò láyé ni, mi ò lè kú - Fadeyi Oloro, Duration 4,4526 Èrèlè 2020 2:48 Fídíò, Esther Ajayi: Èmi náà ti borí ìṣòro rí ló ń mu mi ṣojú àánú, Duration 2,481 Ògún 2019 6:08 Fídíò, Adebola Ademilua: Àìrísẹ́ ṣè lẹ́yìn ìwé kíkà ló sọ mi dí ìyá onírú, mo dúpẹ́ tèmi, Duration 6,0827 Bélú 2020 5:55 Fídíò, Soyinka Cancer: Àṣe ara mi ni iso ti n run gbogbo bí mo ṣe n ṣèrànwọ́ lórí jẹjẹrẹ, Duration 5,5527 Bélú 2019 BBC News, Yorùbá Ìdí tí ẹ fi le è nígbàagbọ́ nínú ìròyìn BBC Ìlànà Lílò Nípa BBC Òfin Àṣírí Cookies Kàn sí.
Sunday Igboho: Kò bójúmu bí wọn ṣe ní ká wá fi orúkọ́ sílẹ̀ bíi ọmọ ẹgbẹ́ Àmọ̀tekún lórí ayélujára
”Ipinnu wa ni lati mu  awọn  ileri ti aare Muhammadu Buhari se lasiko ipolongo rẹ lọdun 2015  wa si imusẹ.
, nitori naa, ki i se ẹbi yin.
Balogun sọ pe ko si ohun to buru nibẹ ti ẹgbẹ ba gbaruku ti Tinubu nitori o jẹ ọkan lara agba oṣelu nilẹ Afirika.
goal : n ; ( his goal is to go to college .
Kò ye yín pé kì í ṣe nǹkan tí ó bá wọ inú eniyan lọ níí sọ eniyan di aláìmọ́?
“O níláti fún mi ní àkọ́bí rẹ ọkunrin pẹlu.
Rwanda Sex: Ìṣòro mi ni pé mo tètè ṣe tàn, ṣùgbọ́n ó wù mí kí n ní ìbálòpọ̀ síi August Alsina ti fèsì sí ọ̀rọ̀ ìyàwó oníyàwó tó ń bálòpọ̀ Ọmọ Ibadan, Peace Busari tí wọ́n fẹ́ tà lórí Facebook ti dé sí Naijiria láti Lebanon Ààrùn Coronavirus tún ti ran ènìyàn 664 l'órílẹ̀-èdè Nàìjíríà Usman, ẹni dun mẹtalelọgbọn naa jẹ ọmọ Naijiria ati ti orilẹede Amerika naa.
Wọ́n kò pa ẹnikẹ́ni sí ààfin Ṣọun Ogbomosọ, òkú tí àwọn ọdọ́ gbé wa ni ọlọ́pàá wọ́ jáde- Agbẹnusọ Ṣọ̀un Wo ìgbà mẹ́rin tí ìjọba ti tú ikọ̀ ọlọ́pàá SARS ká sẹ̀yín ṣùgbọ́n.
2 447039 Orilẹede Pakistan 8653 4.
“Ọ̀rọ̀ ìkọkúkọ” náà ń ṣe àfihàn ìdúróṣánṣán ìjọba náà tí kò yẹ̀ àti ọ̀nà tí wọ́n ń gbà ṣe ẹ̀tọ́ọ wọn, títí mọ́ ṣíṣe ìgbéyàwó kànńpá fún àwọn tọkọtaya tí wọ́n ń gbépọ̀ láìṣe ìgbéyàwó ní 2017: ìfòfinlíle mú òwòo panṣágà àti agbe ṣíṣe.
Àwọn obìnrin ní n ṣíṣẹ́ líle àfi ẹ̀kọ̀ọ̀kan ni àwọn ọkùnrin ń ràn wọ́n lọ́wọ́ ṣùgbọ́n ìgbà tí àwọn obìnrin bá dé oko tán wọn á wá iṣu lé ọkọ wọn lórí, a rù ú bọ̀ láti oko.
Sùgbọ́n Àarẹ Trump sọ́ di mímọ̀ pé, ìjọba ilẹ̀ Amẹrika yóò ṣísẹ́ pẹ̀lú ìjọba Nàíjírià láti fòpin sí àkọlùkọgbà náà.
Eyi tumọ si pe, ẹni to n ṣowo epo pupa lọwọ yii n pawo wọle.
Nigba ti ọrọ yoo fi rọlẹ tan ọku mẹta ti sun ti awọn mii na si ti farapa.
Awọn ọlọpàá gbe ọmọ ọdun mọkanla naa ati iya rẹ lọ ile iwosan ṣugbọn iya rẹ kọ itọju; o sọ pe igbagbọ oun ko gba.
Àkọlé àwòrán, ` Wọn ni lẹyin asiko diẹ ni aburo ti o jẹ ọkunrin jade lọ ra nnkan ti o si ku oloogbe nikan sile.
"Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ọmọ Naijiria hú ẹ̀sùn ìfipá bánilòpọ̀ tí wọ́n fi kan Fatoyinbo síta lẹ́yìn tó lọ sí Shiloh Ìdí rèé tí mo fi yan ikọ̀ PMS rọ́pò NURTW nípìnlẹ̀ Oyo - Seyi Makinde Ìwọ́de ńlá yóò bẹ́rẹ̀ lọ́jọ́ táwọn gómìnà bá yá ₦17trn nínú owó ìfẹ̀yìntì òṣìṣẹ́ - NLC ""Buhari, Olóṣèlú àtàwọn òjíṣẹ́ Ọlọ́run ló mú àjẹbánu gogò ní Nàíjíríà"" Ooni Adeyeye ti Ile Ife fẹ sèrànwọ́ owó iléèwè fún akẹ́kọ̀ọ́ 5 mílíọ̀nù ní Nàìjíríà Ọkùnrin kan rí ẹ̀wọn he lẹ́yìn tó lu obìnrin ní jìbitì ìfẹ́ tí iye rẹ̀ tó $15,000 lórí ayélujára Àwọn jàndùkú ṣọṣẹ́ nílé aṣòfin ìpínlẹ̀ Ogun, wọ́n jí ọ̀pá àṣẹ gbé!"
'Ọdún méjì sẹ́yìn ni òbí àwọn ọmọbinrin Chibok gbọ́ láti ọ̀dọ́ ìjọba kẹ́yìn' Àwòrán àjọyọ̀ ìjọba ológun ní Sudan Kí ni arídájú pé ọmọ Cameroon ni Atiku?
    Eléyìí yà mi lẹ́nu lọ́pọ̀lọpọ̀, mo sì wí fún un pé kí o jọ̀wọ́ má ṣàì mú mi lọ.
OLUWA sì sọ fún Mose ati Aaroni pé: 
"A gbe ẹdun ọkan igun mejeeji yi yẹwo.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Coronavirus in Nigeria: Ìpínlẹ̀ Eko bẹ̀rẹ̀ fínfín àyíká nítorí Coronavirus Ṣaaju ni Minista ileeṣẹ ijọba apapọ to n risi eto ẹkọ ni Naijiria ti fi ilana aatẹle sita ṣaaju ki awọn ile ẹkọ to wọle pada.
Awọn nọmba ati lẹta naa ni yoo duro gẹgẹ bii 'apoti ifiweransẹ' ori ayelujara, ti Bitcoin yoo ma a wọle si.
Èyí tí a wò jùlọ 5:03 Fídíò, Omolola Arohunmolase Welder: Mo ti fí iṣẹ́ 'Welder' gbayì láwùjọ, tó mo fi tọ́ ọmọ yanjú, Duration 5,039 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 5:39 Fídíò, Akomolede ati Asa lori BBC: Olùkọ́ Kikelomo Ogunboye tan ìmọ́lẹ̀ sí ìwà olè ọ̀gá ọlọ́pàá Audu gẹ́gẹ́ bí àwòkọ́ṣe àsìkò yìí, Duration 5,398 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 4:11 Fídíò, Oba Adeyeye Ogunwusi: Ojú mi ti rí lọ́pọ̀ lọpọ̀, ọ̀pọ̀ èèyàn ni kò tilẹ̀ gbàgbọ́ pé mo lè jọba- Ooni, Duration 4,117 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 4:43 Fídíò, Promise Akinlade: ọmọ ọdún mọ́kànlá tó ń fi ìlù dárà bíi àgbàlagbà sọ̀rọ̀ nípa tálẹ́ǹtì rẹ̀, Duration 4,437 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 0:59 Gbọ́, Ìsẹ̀lẹ̀ jákèjádò orílẹ̀èdè àgbáyé láàárín ìṣẹ́jú kan, Duration 0,59wákàtí 6 sẹ́yìn 4:45 Fídíò, Yoruba Films: Ẹ̀ẹ́ bẹ̀ mi kúrò láyé ni, mi ò lè kú - Fadeyi Oloro, Duration 4,4526 Èrèlè 2020 7:03 Fídíò, Olumuyiwa Bolade Adedeji Military Bruitality: Bí arákùnrin onípèníjà ara tí sọ́jà lù ṣe dé, Duration 7,035 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 2:48 Fídíò, Esther Ajayi: Èmi náà ti borí ìṣòro rí ló ń mu mi ṣojú àánú, Duration 2,481 Ògún 2019 6:08 Fídíò, Adebola Ademilua: Àìrísẹ́ ṣè lẹ́yìn ìwé kíkà ló sọ mi dí ìyá onírú, mo dúpẹ́ tèmi, Duration 6,0827 Bélú 2020 5:55 Fídíò, Soyinka Cancer: Àṣe ara mi ni iso ti n run gbogbo bí mo ṣe n ṣèrànwọ́ lórí jẹjẹrẹ, Duration 5,5527 Bélú 2019 BBC News, Yorùbá Ìdí tí ẹ fi le è nígbàagbọ́ nínú ìròyìn BBC Ìlànà Lílò Nípa BBC Òfin Àṣírí Cookies Kàn sí.
Ìjọba rẹ̀ kò lè parun lae,àṣẹ rẹ̀ yóo sì máa wà títí dé òpin.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Coronavirus: Kíni àwọn àmì tuntun tó n fihàn?
Ìwádìí kan ti Young Scot ṣe fáwọ̀n akẹ́kọ̀ọ́ fi idí rẹ̀ múlẹ̀ ọkan nínú àwọn akẹ́kọ̀ọ́ mẹ́rìn ń tiraka lati ra ìléèdí ǹkan oṣù ni.
 Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Mama Arsenal: Màmá àgbà yìí máa ń lọ sí ìbùdó tí wọ́n ti ń wo bọ́ọ́lù láti wòran ""Lati ṣe eyi, to ba jẹ pe kikede konileogbele lọna abayọ, a o ṣe bẹẹ gẹgẹ."
Yéwándé náà kò sọ fún un.
Bí ó ti ń lọ, wọ́n ń tẹ́ ẹ̀wù wọn sọ́nà.
Ijọba ilẹ Saudi Arabia lo kede naa lati dẹkun aarun coronavirus to ti pa ẹgbẹgbẹrun eniyan kaakiri agbaye.
Nigeria Election: Kò sí ìwé ìrìnnà 'VISA' fáwọn ọmọ Naijiria tó hùwà àìtọ́ nígbà ìdìbò
"Àwa àti fijilanté pẹ̀lú ọdẹ́ ìbílẹ̀ ló dojú kọ adigunjalè ní First Bank Okeho - Iléeṣẹ́ ọlọ́pàá ""Ọmọ mi kò tíì mọ̀ pé òun ti di ìlúmọ̀ọ́ká, ó ń wádìí bó ṣe ń rí ara rẹ̀ lórí ayélujára"" Ìtàn ọba Yorùbá tí wọn yẹgi fún torí ó jí ọmọ gbé ṣe ètùtù Ẹ káàbọ̀ sọ́jọ́ Arafat, tí Ọlọ́run yóò fi ààwẹ̀ Mùsùlùmí pa ẹ̀ṣẹ̀ wọn rẹ́ Bakan naa, ileeṣẹ ọlọpaa to n mojuto ilu Abuja ti mu awọn afurasi mẹrinlelogun, ti wọn si ti gba orisirisi nnkan ija lọwọ wọn ṣaaju ọdun ileya to sunmọ yii."
Ijoba orile-ede Naijiria ti ya ojo merin soto lati fi sayeye ajodun eto ijoba tiwa-n-tiwa  ti odun 2018, eleyi ti yoo waye ni  ọjọ kárùndínlọ́gbọ̀n titi di  ọjọ kọ́kàndínlọ́gbọ̀n osu yii.
Ṣugbọn nítorí àgbèrè, kí olukuluku ọkunrin ní aya tirẹ̀; kí olukuluku obinrin sì ní ọkọ tirẹ̀.
Mose sọ fún àwọn eniyan náà pé, “Ẹ ranti ọjọ́ òní tíí ṣe ọjọ́ tí ẹ jáde láti ilẹ̀ Ijipti, láti inú ìgbèkùn, nítorí pé pẹlu ipá ni OLUWA fi mu yín jáde kúrò níbẹ̀, ẹnikẹ́ni kò gbọdọ̀ jẹ burẹdi tí wọ́n fi ìwúkàrà sí.
Òun náà ni Jesu Kristi Oluwa wa, 
Oṣiṣẹ meji tabi ju bẹẹ́ lọ lo n tọju oun nikan.
Idibo Burundi: Ijọba n yọ'wo osu oṣiṣe lati ṣeto l'ọdun 2020
EFCC: Ilé ẹjọ́ rán ọmọ ìjọ lẹ́wọ̀n lórí ẹ̀sùn pé ó jí ₦15m owo ìjọ
Nígbà tó ń dáhùn ìbéèrè lórí fìdío kan tó jáde sórí ayelujara laipẹ yii, ti ẹnikan tí ojú rẹ jọ tí ọba Akanbi tí ń we igbó, Oluwo ni òun kò ní ohunkóhun sọ lori rẹ, kí wọn mú ẹnu kúrò lórí ọ̀rọ̀ náà ni torí òun kò mọ ohun kohun nípa rẹ.
Àti àwọn ìbéèrè míràn Ṣugbọn adari ile tawọn obinrin Kenya le fori pamọ si julọ, Nana Sunnu ni wọn kole gba ẹnikẹni bayii nitori ajakalẹ arun to wa lode, ati pe ibi tawọn eeyan le gbe fun anfani idanikan wa ko to nkan.
ayika rẹ lati pese eto iranwọ fun wọn.
Balogun tí ó wà fún oṣù karun-un ni Ṣamuhutu, láti inú ìran Iṣari; iye àwọn tí wọ́n wà ninu ìpín rẹ̀ jẹ́ ọ̀kẹ́ kan ó lé ẹgbaaji (24,000).
''Buhari àti Tinubu ṣ'àdéhùn pé Yorùbá ni yóò jẹ́ olùdíje ipò ààrẹ APC lọ́dún 2023'' Ìjọba ìpínlẹ̀ Kaduna gbé iléèwé tì pa nítorí ọ̀wọ́ kejì àjàkálẹ̀ COVID-19 Ọkọ̀ àjàgbé agbépo kan tún dànù l'Eko Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Kollington ṣàlàyé bí orin Fuji ṣe bẹ̀rẹ̀ gan an ní Nàiìjíríà Ọmọ ile igbimọ aṣoju-ṣofin Naijiria tẹlẹ, Họnọrebu Rotimi Makinde lo fi ọrọ naa lede lorukọ ẹgbẹ South West Agenda 2023 eyi ti wọn pe ni SWAGA 23.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ṣọla Allyson: Obìnrin tí kò bá rẹwà ni yóò máa ṣí ara sílẹ̀ Ọrẹ wọn miran to wa si ibi igbeyawo naa, to ya awọn aworan lorisirisi lo fi si ori itakun rẹ ni Facebook.
O yẹ ki eto idibo  waye lọdun 2020.
Oríṣun àwòrán, Reuters Àkọlé àwòrán, Iyoku awon ẹru awọn ọmọ naa wa nile ẹkọ wọn Sugbọn ọkan lara awọn iwe iroyin lorilẹede Naijira, Daily Trust, sọwipe idaji awọn ọmọ naa ni awọn ajijagbara naa ti gbe kuro lorilẹede Naijiria lọ si orilẹede Niger to sun mọ Naijiria.
Gbogbo nǹkan yòókù tí Peka ṣe ni a kọ sinu Ìwé Ìtàn Àwọn Ọba Israẹli.
Cameroon wa ni ipo mẹrindinlọgọrun, Ghana wa ni ipo mejidinlọgọrun, Sierra Leone wa ni ipo mọkandinlaadoje, ti Liberia si wa ni ipo mọkanlelogoje.
Ayẹyẹ naa to jẹ akọkọ iru rẹ lo waye nipasẹ ajọsepọ laarin ẹka ile iṣẹ iroyin, aṣa ati irinajo igbafẹ nipinlẹ Ọyọ, ijọba ibilẹ Ibarapa, ẹgbẹ awọn ọmọ bibi ilu IgboỌra ati ajọ to n risi idagbasoke awọn ibeji l'agbaye.
O si siṣẹ olukọ lati ọdun 1953 di 1958 ni ẹkùn Sokoto.
Ta ni Ọlọrun bí kò ṣe OLUWA?
O ni igba ti akọrin naa wa sinu ẹbi oun, o dabi ẹni pe aisan n se e, to si nilo iranlọwọ, asiko yii naa si ni inu ile tawọn ko toro.
Kunle Afolayan, Tope Alabi, Fathia Balogun sọ̀rọ̀ lórí ikú Alabi Yellow Kí làwọn ìdàmú tí Coronavirus n mú bá àgọ́ ara?
Ibeere lórí oro iná, ti wọn si dahun pe àwọn idọti ni àwọn a maa lo láti mú ina wá Lori akanda eda, Akinlade ni oun yoo gbe ipin kan kale fun awon akanda lati gbadun awon eto ìjọba gbogbo.
Ondo election 2020: Igbákejì gómìnà Ondo, Agboola Ajayi ní lóòtọ́ lòun fẹ́ f'ẹgbẹ́ PDP sílẹ̀ láti jẹ́'pè aráàlú ṣùgbọ́n.
Nítorí pé, ẹ ti kọ OLUWA sílẹ̀, òun náà sì ti kọ̀ yín sílẹ̀.
"O sọ wipe: ""Ko si ipadi-apo-pọ kankan."
Èmi náà kò ní hùwà ìwọ̀sí, kí n dàbí ẹ̀gbọ́n tí ó ń hu ìwà aburo, tí ó sọ iò ara rẹ̀ nù tí ó ń bá rìkíṣí kiri.
O ni bi obinrin ba se aseyọri, ọkunrin fẹ maa n fa wọn sẹyin.
"Iku yoo pọ lati ipasẹ rogbodiyan nla kan to n bọ, mo si n rọ awọn ọdọ lati gbadura gidi lori isẹlẹ naa.
Agbẹnusọ fun Merkel ni kokoko lara rẹ le ati pe yoo tẹsiwaju pẹlu irinajo rẹ lọ si orileede Japan.
 A ro awon eniyan lati lo anfaani yii , ki won si lo foruko sile fun kaadi idbo won.
tun fi kun pe meji ninu egberun mewaa omode lorilede Naijiria lo foju nitori
Coronavirus tún ti ṣe ọṣẹ́ lórí iṣẹ́ líla ojú ọ̀nà relùwe láti Eko sí Ibadan - Ìjọba àpapọ̀ Àrùn Coronavirus fa'lẹ̀ya láwọn ìletò aláwọ̀dúdú ní Amẹ́ríkà Ìyá ìbejì tí di jánna-janna, ẹyin tẹ jí ìbejì mi gbé, mo bẹ yín, ẹ kàn sí mi ká sọ̀rọ̀ - Akeugbagold Oríṣun àwòrán, Akewugbagold Àkọlé àwòrán, Ìlànà IVF là fi bí ìbejì tẹ gbé lẹ́yìn idaduro ọdún méjìlá, ẹ jọ̀ọ́, ẹ tú wọn ṣílẹ̀ - Akeugbagold, aya rẹ bẹ̀bẹ̀.
Ilẹ̀ ti Manase bẹ̀rẹ̀ láti Aṣeri títí dé Mikimetati tí ó wà ní apá ìlà oòrùn Ṣekemu, ààlà rẹ̀ tún lọ sí apá ìhà gúsù ní apá ọ̀dọ̀ àwọn tí wọn ń gbé Entapua.
Mose ati Aaroni lọ dúró níwájú Àgọ́ Àjọ, 
3 trillion ni CBN gbé jáde fún ọdun 2020
O ti pa àwọn eniyan burúkú tì, bí ìdàrọ́ irin,nítorí náà ni mo ṣe fẹ́ràn ìlànà rẹ.
Oga olopaa naa ni oun ti gba awọn  akosilẹ lowo gomina Ayodele Fayose  ati oludije labe egbe oselu APC ,Kayode Fayemi ati gbogbo awọn  oga agba nile ise ijọba sile, bakan naa ni wọn  gbodo farahan ni deede aago mefa owurọ ni ile-ise olopaa to wa ni Ado –Ekiti lọjọ Abamẹta.
Iroyin sọ pe wọn sare gbe obinrin naa digba digba lọ si ileewosan UCH nilu Ibadan, ṣugbọn o pada gbẹmi mi.
'Lootọ iwa ọdaran to gogo ni ifipabanilopọ lorilẹede Naijiria, ṣugbọn ọwọ ti ijọba fi n mu u ko wuni lori rara' Justice for Uwa: Fájìn ni àbúrò mi ti wọn fipá bálopọ̀ nínú sọ́ọ́sì, tí wọ́n sì tún fọ́ lórí"" Oríṣun àwòrán, Twitter Àkọlé àwòrán, Ọjọru, ọjọ kẹtadinlọgbọn, oṣu Karùn-ún, ọdun 2020 ni àwọn kan fipá bá ọmọbìnrin ẹni ọdún 22 lopọ̀ nínú sọ́ọ́sì."
 “ Ohun ti o bojumu ni ki aare
A gbọ pe lasiko ija naa ni Emmanuel binu mu ọbẹ, to si fi gun Patricia ni itan, ko to o di pe Patricia raaye sa jade.
Oríṣun àwòrán, @Newsweek Bo tilẹ jẹ pe awọn ọlọpaa o tii fi ẹkunrẹrẹ sita lori bi ọwọ ṣe tẹ̀ wọn, Gomina Seyi Makinde gboriyin fun awọn ọlọpaa fun iṣẹ takuntakun ti wọn ṣe.
Hajara ni ijọba maa n ṣe bii pe awọn ko ṣe pataki.
Jakọbu ròyìn ohun gbogbo tí ó ti ṣẹlẹ̀ fún Labani.
OLUWA ti fi ọwọ́ ọ̀tún rẹ̀ búra,ó ti fi agbára rẹ̀ jẹ́ ẹ̀jẹ́,pé òun kò ní fi ọkà oko rẹ,ṣe oúnjẹ fún àwọn ọ̀tá rẹ mọ́;àwọn àjèjì kò sì ní mu ọtí waini rẹ,tí o ṣe wahala lé lórí mọ́.
O ni gbogbo eleyi nmu ifasẹyin ba ireti ilọsiwaju, aisi irẹpọ nilu ati aise eto oselu daradara to fi mọ aidọgba n ba wa gbe lọwọlọwọ bi ara ile ni.
O ti pe ẹni ọdun mejilelogun bayii, o si n ṣiṣẹ ipolongo igbogun ti aarun HIV pẹlu ṣọọṣi kan.
Wọ́n wà ninu ọkọ̀ pẹlu Sebede baba wọn, wọ́n ń tún àwọ̀n wọn ṣe.
Bakan naa ni iroyin mii sọ pe obinrin musulumi miran, Hajia Ramatu tun fi igi Keresi se ọsọ ni ile alaga ẹgbẹ awọn ọmọlẹyin Kristi CAN to wa nilu Kaduna, Ẹni-ọwọ Hayap.
Lara ijiya ti awọn aṣofin naa fọwọ si fun ẹnikẹni ti aje ọrọ naa ba ṣi mọ lori ni ẹwọn ọdun marun un si mẹrinla.
Awọn ijamba agbara ojo to ti ṣẹlẹ sẹyin Ni ọdun 2011, o to ọgọrun un eniyan ti ajọ Red Cross ni o padanu ẹmi wọn ninu agbara ojo ni ilu Ibadan.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ondo election 2020: Àwọn ara ìpínlẹ̀ Ondo ránṣẹ́ sí Akeredolu ohun ti wọ́n ń retí ní báyìí Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí End SARS protest: Lára àwọn ìlú tí ìwọ́de ti wáyé ní Ibadan, Ado Ekiti, Osogbo, Ado Ekiti ati Eko19 Ọ̀wàrà 2020 Fídíò, Wole Soyinka sọ ìdí tó fi ni òun a fi màálù Fulani ṣe súyà fáwọn èèyàn abúlé23 Owewe 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Kí oòrùn tó yọ, ẹni ibi a máa tutù yọ̀yọ̀,àwọn ẹ̀ka rẹ̀ a sì gbilẹ̀ káàkiri inú ọgbà rẹ̀.
Ole aji maluu pa eeyan marundinlogoji ni Zamfara
Bi o ba gba ki ọlọpaa naa o ṣe ayẹwo rẹ, beere fun iwe ofin to de ayẹwo naa.
Ilẹ̀ tí OLUWA yóo fún àwọn ẹ̀yà mẹsan-an ààbọ̀ yòókù.
Oloye Falae ni lẹyin iriri oun lọwọ awọn ajinigbe ninu igbo fun ọjọ mẹrin nibi ti wọn ti ṣa oun laakẹ, o ni o ṣe pataki lati wa nnkan ṣe si ọrọ eto aabo to mẹhẹ.
Àwọn aláìní yóo máa yọ̀ ninu Ẹni Mímọ́ Israẹli
Ireti si wa pe wọn yoo yọnda wọn kuri nileewosan l'ọsẹ yii.
Ile Olọmọyọyọ to jẹ agboole wọn ni BBC Yoruba lọ lati rii wọn ki a si mu oju aje kọ onisọ lati mọ okodoro ohun to ṣẹlẹ gangan Iya ati Baba Risikat naa sọ iha ti wọn kọ si ohun to ṣẹlẹ.
9 36096 Orilẹede Mali 305 1.
Ọrọ to niiṣe pẹlu awọn ile ẹkọ ti ẹgbẹ awọn oṣiṣẹ da silẹ, idunadura ati adehun laarin ẹgbẹ naa ati ijọba apapọ ni'bẹrẹ ọdun yii, ati bẹẹbẹẹ lọ ni ẹdun ọkan wọn.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Àwọn ọmọ Yorùbá àtàtà: Báwo lẹ se gbọ́ òwe sí ?
“Àbá tí wọn ń dá kò ní ṣẹ, ète tí wọn ń pa kò ní rí bẹ́ẹ̀.
Niṣe lo n beere bo ya oun gan an lounṣe okunfa bi Arsenal ṣe n daku daji tẹlẹ.
Amọ mo si jẹjẹ lati jẹ́ ki Naijiria gberasọ pada.
 harper fipòsílẹ ̀ nínú ẹgbẹ ́ rhodesian front ní ọdún 1968 , láìpẹ ́ sí ìgbà tí smith yọó lóyè nítorí wípé harper yànlè pẹ ̀ lú òṣìsẹ ́ gẹ ̀ ẹ ́ sì kan .
Eeyan marun-un, ninu eyi ti ọmọde mẹrin wa, lo ti di eero ileewosan nitori iṣẹlẹ naa.
Ẹsira, akọ̀wé, ni ó ṣáájú, àwọn eniyan sì tẹ̀lé e.
"Bakan naa lo ṣalaye pe: ""Mo maa mu ọrọ Big Brother Naija lọkunkundun""."
Alámì ẹ̀yẹ Scrabble Paul Sodje àti ọ̀rẹ́ rẹ́ kú lásìkò tó fẹ́ lọ́ sanwó ìdóòlà ẹ̀mí àbúrò rẹ̀, tí afurasí darandaran jí gbé Nitori eyi, eeyan mẹwa dipo mọkanla ni Chelsea fi gba ifẹsẹwọnsẹ naa ti eleyi si fun Liverpool lagbara lati wọle siwọn lara.
Ṣùgbọ́n ìyàtọ̀ ibẹ̀ ni pé bíótilẹ̀jẹ́pé mo rí àwọn ẹranko kọ̀ọ̀kan t’ọ́n ṣàjèjì sí mi, n kò fojú kan ẹbọra tàbí abàmì ẹdá kankan o 🙂 .
YPPNi lilo owo ori lona to tọ ati ona to yẹ yoo mu idagbasoke
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Money transfer: Òdíwọn iye owó tí èèyàn n fi rànṣẹ́ sílé ń dínkù púpọ̀ jù Onyema ṣalaye siwaju si pe awọn agbẹjọro oun ti wa lori ọrọ naa bayii ati pe oun o kowo lati Naijiria lọ si ilẹ okere lọna aitọ ri.
Gbade Ojo ni o le ni ọgbọn miliọnu Naira, ti ijọba Abiola Ajimobi fun awọn ẹbi fun isinku gomina tẹlẹri, Kolapo Ishola.
Ajo isokan UN ni awon ipago idaabobo mefa fun awon ara-ilu ti won kii se ologun jake-jado orile-ede naa Ronke Osundiya.
O ni JSS 3 loun wa nile iwe girama ki oun to kuro nile iwe, amọ o sọ pe oun o kaba Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
"Awọn ọlọpaa to yẹ ko ma a ṣọ ẹ̀mí ati dukia wa, ti di ẹni to n yinbọn mọ àwọn ọdọ wa, ti wọn si n pa wọn bo ṣe wu wọn, nitori pe wọn ro pe gbajuẹ ni wọn.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ọ̀rọ̀ Trump àti Russia kò yàtọ̀ pé àhesọ lásán ni èyí jẹ́ Ogunjọ oṣu kini ọdun yii ni Donald Trump yoo fi ipo aarẹ silẹ, ti Joe Biden yoo siwọle.
Ile ẹjọ kan ní ìpínlẹ Yola ní ìpínlẹ̀ Adamawa ti yí ìgbéjọ to ṣ tẹ́lẹ̀ pada pé àjọ elétò ìdìbò kò lẹtọ láti ṣe àtúndi ìbò gómìnà ní ìpínlẹ̀ náà.
Yatọ si eyi, o tun ti jẹ ẹbun ounjẹ fun oṣu mẹta, eroja fun inu ile fun ọdun kan, paali eroja iṣaraloge, ọ̀dà, irinajo si ilu Abuja ati orilẹ-ede Scotland, ati Dubai fun ayẹyẹ One Africa Music Fest.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Davido: Kí ló fa ariwo lórí ìdọ́rẹ́ òun àti Chioma aya rẹ̀ lójú òpó Instagram?
Àmọ́ mo wà ń rọ àwọn ènìyàn wá láti tẹle asẹ ìjọba tó nii ṣe pelu òfin ìtakété síra ẹni, fifi aṣọ bo imú, ki wọn maa fi ọ̀sẹ̀ fọ ọwọ, bẹ́ẹ̀ ni kí wọn jìnnà sí ibi tí èrò bá pọ si."
Ìkébé mi tóbí ju ohun tí mo lè dọwọ́ bò lọ, n kìí fí ṣakọ- Nkechi Blessing Ẹ̀yin òṣìṣẹ́, ẹ má ṣáì lọ síbi iṣẹ́ lọ́jọ́ Ajé, olórí àwọn òṣìṣẹ́ ní Nàìjíríà tako ìyanṣẹ́lódì Ọgbọ́n àti kówójẹ n'ìgbèsẹ̀ ìjọba láti ná $1.
Bí ọkàn wa bá tilẹ̀ dá wa lẹ́bi, kí á ranti pé Ọlọrun tóbi ju ọkàn wa lọ, ó sì mọ ohun gbogbo.
Bakan naa lo sọ pe ko si awawi kankan fun ijọba ipinlẹ lati ma san ẹgbẹrun lọna ọgbọ̀n Naira ti Aarẹ Muhammadu Buhari buwọlu laipẹ yii gẹgẹ bi owo oṣiṣẹ to kere ju.
Ẹ̀yin ọmọ ènìyàn, ayé ń lọ, ojoojúmọ́ ń mú ọjọ́ kan kúrò nínú ìgbésí-ayé olúkúlùkù, bẹ́ẹ̀ ni ọjọ́-ayé ọmọ ènìyàn kò ju kékeré lọ.
Lórí ọ̀rọ̀ Pásítọ̀ COZA àti Dakolo, Ìwadìí ń tẹ̀ síwájú, ṣùgbọ́n a kò mọ ohunkohun nípa rẹ̀ mọ́- Iléeṣẹ́ ọlọ́pàá Èkó
7 ni wọn ya sọtọ fun titọpinpin owo tawọn oloselu yoo na fun ipolongo ibo N149m ni owo to wa fun ipolowo ibo 2019 N125m ni Inec yoo fi se ifikunlikun pẹlu awọn onikọ-jikọ N94m lo wa fun fifi atẹjisẹ ransẹ lati ori ẹrọ ibaraẹni sọrọ N55m lo wa fawọn osisẹ to n seto ipalẹmọ fawọn irinsẹ idibo N50m ni owo ti wọn yoo fi tẹ ikede iwe lati wa gba isẹ (Tender) fawọn agbasẹse ti yoo nifẹ lati gba isẹ titẹ iwe idibo N1000 ni owo ti wọn yoo san lowo ajẹmọnu fawọn ọlọpa xxxxxxxxxxxxxxxxxxxxxxxxxxxxxxxxxxxxxxxxxxxxxxxxxxxxxxxxxxxxxxxxxxxxxxxxxxxxxxxxxxxxxxxx Ninu iroyin miran ẹwẹ, aarẹ Muhammadu Buhari ti pasẹ pe ki awọn ileese ijọba fi eto isuna wọn ranse ni kia kia si ile asofin, o pe tan, ọjọ Ẹti.
Wọ́n kojú pẹ̀lú àwọn ọmọ oogun ti wọ́n n gbé ǹkan ìjà lọ, èyí sì ló sokùnfà pípa àwọn ọmọ Shi'ite mẹ́ta.
Wọ́n ní “ọ̀rọ̀ púpọ̀, irọ́ ní í mú wá”.
Ogunjọ oṣu kẹta si ni aṣẹ naa yoo bẹrẹ iṣẹ.
Gbogbo àwọn ọ̀tá mi ti gbọ́ nípa ìyọnu mi;inú wọn sì dùn,pé ìwọ ni o kó ìyọnu bá mi.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Working religious women: Ẹ̀lẹ́hàá kìí ṣe ọ̀lẹ- Aminat Adegoke Sunday Dare ní òun ní ìgbàgbọ́ pé ètò náà yóò bẹ̀rl ni ọsẹ̀ àkọ́kọ́ nínú oṣù kẹ̀sán ọdún 2020 àti pé àfojúsùn ní láti ri ọ̀dọ́ to tó ẹ̀ẹ́dẹ́gbẹ̀ta láti fi orúkọ silẹ̀ fún ọdún àkọ́kọ́ .
Ọlọwọ: Olùdarí ètò ìṣúná àti àkóso ní Ondo ni Ogunoye tó di Ọlọwọ tuntun
Bí idà tí ń pa àwọn kan lójú pópó,bẹ́ẹ̀ ni ikú yóo di ẹ̀rù jẹ̀jẹ̀ láàrin ọ̀dẹ̀dẹ̀.
Ile gbigbe gẹgẹ bi odiwọn fun oṣi Bi ilaji awọn to n gbe ni Naijiria lo n gbe ni igboro - ọpọlọpọ awọn ile ti wọn ṣẹṣẹ kọ si awọn adugbo to joju ni gbese ni ilu Eko lo ṣófo, ti awọn adugbo ti ko ri bẹ si kun fọfọ.
''Ipade yii jẹ ibẹrẹ iṣọkan apa iwọ oorun gusu orilẹede Naijiria, ti a ba si ti wa ni iṣọkan lapa iwọ oorun gusu, Naijiria naa ti wa ni iṣọkan niyẹn,'' Gomina Makinde lo sọ bẹẹ.
Ẹwa Agọnyin yi, ti wọn mọ si ẹwa 'Tosẹ' laarin awọn Egun nilu Badagry ni ọpọ ọmọ Yoruba tun nifẹ si lati maa jẹ.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Awọn ọmọ ikọ ogun alaabo n ṣe ajọyọ pẹlu asia ati ami V for Victory.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Marie Bonaparte ko ni ẹnikan a n ba a ṣere nigba to wa ni ọdọ, o si tun jẹ alagidi ọmọ Lọjọ kan, ọkan lara awọn obinrin to n tọju rẹ ka a mọ ibi to ti n fun ara rẹ ni adun ibalopọ, eyi ti wọn n pe ni 'masturbation', ni ede Gẹẹsi.
O ni awọn alamojuto abo nibi ayẹyẹ taraalu n pe ni bouncers ni wọn kọkọ wa ba oun to si n halẹ pe oun yoo da sẹria fun oun lo fa wahala.
“Ẹ̀wù mímọ́ Aaroni yóo di ti arọmọdọmọ rẹ̀ lẹ́yìn ikú rẹ̀, àwọn aṣọ mímọ́ náà ni wọn yóo máa wọ̀; wọn yóo máa wọ̀ wọ́n nígbà tí wọ́n bá fi àmì òróró yàn wọ́n, tí wọ́n sì yà wọ́n sí mímọ́.
Ṣe ẹnu ibodè tí Buhari tì, ló ń mú kí èròjà oúnjẹ gbówó lórí?
Bakan naa ni Alaga fun Igbimọ Tẹẹkoto ti Ile gbe kale ti o n foju sunnukun wo ofin owo-ori ori ilẹ yii, Aṣofin Sikiru Oshinọwọ sọ pe o ti di aṣa fun Ile Igbimọ Aṣofin naa lati maa pe iru ipade itangbangba awọn alẹnulọrọ bayii lati ṣe ofin tabi abadofin kan.
Moabu ni ìkòkò ìwẹsẹ̀ mi;lórí Edomu ni n óo bọ́ bàtà mi lé;n óo sì hó ìhó ayọ̀ ìṣẹ́gun lórí Filistia.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ọmọbinrin Dapchi: Mi o lọ sile iwe mọ Ohun tawọn ọlọpaa sọ nipa iku Yusuf ni pe igba ti ikọlu waye ni o faragbọta.
Ọba Sedekaya rán Jehukali, ọmọ Ṣelemaya, ati Sefanaya, alufaa, ọmọ Maaseaya, sí Jeremaya wolii, pé kí ó jọ̀wọ́ bá àwọn gba adura sí OLUWA Ọlọrun.
Emi ni mo ṣi gbe ẹ de ibudokọ, nigba to n lọ si ibi'ṣẹ lọjọ naa, lai mọ pe igba ikẹyin ti ao rira niyẹn.
Nígbà tí ọjọ́ bá pé tí ó bá kú, tí a sin ín pẹlu àwọn baba rẹ̀, n óo gbé ọ̀kan ninu àwọn ọmọ rẹ̀ dìde, àní ọ̀kan ninu àwọn ọmọkunrin rẹ̀, n óo sì fìdí ìjọba rẹ̀ múlẹ̀.
Joe Biden náà ti gba abẹ́rẹ́ àjẹsara Covid-19 Kóníléógbélé ọlọ́sẹ̀ márùn ún gbáko ni ìjọba Nàíjíríà gbé kalẹ̀ fàwọn oṣìṣẹ́ lábẹ́ ìlànà Covid-19 tuntun Ìwádìí tú àṣírí Dókítà tó pa ìyàwó rẹ̀, ó fẹ́ pa ọmọ wọn méjì, òun fúnrarẹ̀ tún pokùnso Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Ọ̀lọ́pàá shátà mi láti Mowe dé Magboro dé Shagamu, wọ́n ní ṣé mi ò mọ̀ pé ìjọ́ba ni mo ṣiṣẹ́ fún' O ni beeyan ba n ṣiṣẹ bii ago ti ko sinmi, yoo pada dẹnukọlẹ ni.
Fọ́tò ló ṣàfihàn ibi tí ọmọ ti Nọọsi jígbé lódún 1997 wà Ebi ló ń pami ti mo fi já sọọbu láti jí bisikitì- Afurasi Asuquo Ó lé gba ìwé ìrìnnà (Visa) láti wá fẹ̀yìntì sí Naijiria Wo aṣọ òtútù tó wọ́n jùlọ ní àgbáyé!
5 8809 Orilẹede Lesotho 93 4.
fikun un oro re pe, “opo agbaboolu jankan-jankan miiran naa ni ko ni lanfaani lati kopa lataari ifarapa, bee si ni awon miiran n lo fun igba akoko, ti won yoo si maa nireti lati kopa daradara,”Ni bayii, Super Eagles yoo maa koju iko agbaboolu orile-ede DR Congo ninu ifesewonse olorejore ni papa isere Port Harcourt lojo kejidinlogon osu karun un odun ti a wa yii.
Nigerian Navy Ondo: Ikọ̀ ọmọogun orí omi fi páńpẹ́ mú olè mẹ̀rìnlélógún tó ń jí epo rọ̀bì
Arabinrin kan, Salma Ahmed sọ ninu ohun agbasilẹ kan to fi sori ikanni Whatsapp eleyii to ti gbalegbako ni ipinlẹ naa pe awọn gbe ọmọ lọ sawọn ileewosan ko si si eyikeyi awọn ileewosan ti wọn de ni ipinlẹ naa to tẹwọn gba ọmọ naa fun itọju, ki wọn si to gbe ọms naa de ileewosan nla Aminu Kano, ọmọ naa ti ku.
iṣuna owo Agba ni Ipinlẹ Eko ni wọn yoo yan lẹyin ti Igbimọ Alakoso Iṣẹ
Ní ìpalẹ̀mọ́ ìsààmì ọgbọ̀n ọdún tí ìṣẹ̀lẹ̀ ọjọ́ 4, ayàwòrán eré orí ìtàgé Deng Chuabin ti di ẹni tí ọ̀rọ̀ ìgò ọtí-líle 64 ń dá sẹ̀ríà fún lọ́wọ́lọ́wọ́.
Ẹni tí ó bá ní etí láti fi gbọ́ràn, kí ó gbọ́!
Àjàpadá aṣọdẹbóyèdé wá jẹ ́ ọba ìlú Àkúrẹ ́ kìíní , gbogbo ayé gbọ ́ , ọ ̀ run sì mọ ̀ .
com/v86a0Ym10NOpo lo sapejuwe aare Buhari gege bi eni ti o kun fun ogbon ohun imo ati oye, eni ti o ni iberu Olorun lokan, olooto, akinkanju eniyan, bee si ni adari ti eniyan n to ipase re.
Ni awon papa ofurufu yooku , opolopo atunse lo ti wa nibe lati je
O yanana ẹ pe a gbọdo gbe igbesẹ to yẹ lori ayẹwo gidi nipa odinwọn ki o to le di ohun tawọn le maa lo lorilẹ-ede Naijiria.
Nibayii, O ti le ni eniyan ọgọsan to ti ku nitori aarun Coronavirus ni ipinlẹ Eko nikan ṣoṣo.
40, ate ti o padanu julo.
Wọn óo da erùpẹ̀ sórí wọn,wọn óo yíra mọ́lẹ̀ ninu eérú.
Nítorí n óo fi àjàkálẹ̀ àrùn bá ọ jà n óo sì jẹ́ kí àgbàrá ẹ̀jẹ̀ máa ṣàn ní ìgboro rẹ.
com Àkọlé àwòrán, Ayipada ti de ba inawo ṣiṣe bayii Laipẹ yii ni gbaju-gbaja olorin Fuji, Wasiu Ayinde Marshal fi fidio kan sita loju opo ayelujara Instagram rẹ.
Loju awọn kan, Buhari lo fopin airotẹlẹ si iṣejọba alagbada.
"O ni ""mi o gbọ pe nkan bẹ sẹlẹ, ẹnikẹni ko si wa fi iru ẹjọ bẹ sun wa."
Asofin Ngige wa ro awon igbimo naa, pe ki won wo ife ti won ni si orile ede won , ki won si wa sibi ipade yii.
'Mo máa tó dìde lórí àìsàn', Muyiwa Ademola sọ̀rọ̀ látorí àkéte àìsàn rẹ̀ Wo ohun tí yóò ṣẹlẹ̀ ní ìpàdé àwọn èèkàn Yorùbá láti mú kẹ́ẹ dìbò fún Tinubu ní 2023 Ìjọba ìpínlẹ̀ Zamfara ti gbé iléèwé mẹ́wàá tìpa Ṣé lọ́òtọ́ ni ọlọ́pàá dàwátì torí àti dóòlà aráa India méjì tí wọ́n jígbé?
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Togo Elections: Ààrẹ Gnassingbe díje fún sáà kẹ́rin, òun àti bàbá rẹ̀ ti ṣèjọba Togo fún àádọ́ta ọdún lé 22 Èrèlè 2020 Oríṣun àwòrán, Getty Images Awọn ọmọ orilẹede Togo jade lonii ọjọ Abamẹta lati dibo yan aarẹ tuntun ti yoo tukọ ilẹ naa fun saa miiran Aarẹ Faure Gnassingbe to wa lori aleefa lọwọlọwọ n dije fun saa kẹrin lẹyin to di aarẹ ilẹ Togo lọdun 2005 nigba ti baba rẹ, Eyadema Gnassingbe aarẹ orilẹede naa tẹlẹ papoda.
wọ́n ní, “A kò ní fetí sì ọ̀rọ̀ tí ò ń bá wa sọ lórúkọ OLUWA.
“Ẹni tí ó bá ní etí kí ó gbọ́ ohun tí Ẹ̀mí ń bá àwọn ìjọ sọ.
Mo bẹ̀rẹ̀ sí gbadura, mò ń jẹ́wọ́ ẹ̀ṣẹ̀ èmi ati ti àwọn ọmọ Israẹli, eniyan mi, mo kó ẹ̀bẹ̀ mi tọ OLUWA Ọlọrun mi lọ, nítorí òkè mímọ́ rẹ̀.
Ninu ifọrọwanilẹnuwo pẹlu BBC Hausa, iyaafin Buhari ni lootọ oun lo wa ninu fidio naa toun n fi ibinu sọrọ.
fiwe ranse si awon adari orile ede agbaye lati wa nibi ayeye  eto ijoba tiwa-n-tiwa  ti yoo waye ni ojo kejila, osu kefa, odun
Mikel kéde ìfẹ̀hìntì fún Nàìjíríà Lori iṣẹlẹ yii, Pinnick ti fesi.
Abrahamu nawọ́ mú ọ̀bẹ láti pa ọmọ rẹ̀.
0 121253 Orilẹede Panama 3287 78.
Minisita fun eto ẹkọ, Adamu Adamu to ṣoju aarẹ Buhari, lo ka ikede naa jade fun awọn eniyan ni ibi ayẹyẹ ohun ni ilu Abuja.
Onitọun ni o ti pẹ ti awọn ẹbi rẹ ti n gbero lati rin irinajo si UK amọ ti Daura fi aake kọri pe oun ko lọ si ibi kankan nitori igbele Coronavirus to wa nita.
“Ṣugbọn, ìwọ Daniẹli, máa ṣe tìrẹ lọ títí dé òpin.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, John Amanam: Ìfẹ́ tí mo ní sí àbúrò mi ló sọ mi dí ẹni tó ń ṣe 'Prosthetic' báyìí Wo bí o ṣe le fi orúkọ sílẹ̀ láti gbà nínú N75b tí ìjọba fẹ́ ẹ̀ fún àwọn ọ̀dọ́ láti dá iṣẹ́ sílẹ̀ Ìjọba ti ṣí ojú òpó fún àwọn ọ̀dọ́ tó fẹ́ ẹ dá iṣẹ́ sílẹ̀ Ijọba Naijiria ti ṣi oju opo ayelujara silẹ fun awọn ọdọ orilẹ-ede naa lati fi orukọ silẹ fun owo iranwọ.
" Oyedepo wa leri leka pe, laipẹ ni oun yoo kede iye sọọsi ti wọn ti sọ ina si ni orilẹ-ede yii.
Kí àwọn ọmọ Lefi, tí wọn kò ní ìpín ati ohun ìní láàrin yín, ati àwọn àlejò, ati àwọn aláìníbaba, ati àwọn opó tí wọ́n wà ninu àwọn ìlú yín jẹ, kí wọ́n sì yó, kí OLUWA Ọlọrun yín lè bukun yín ninu gbogbo iṣẹ́ ọwọ́ yín.
Ẹ dúró ninu rẹ̀, kí ẹ má sì tún gbé àjàgà ẹrú kọ́rùn mọ́.
Bakan naa ni wọn pe de ibi ti wọn ti se igbaradi fun ifẹsẹwọnsẹ ti yoo waye ni oni.
Ṣé ìbẹ̀rù Ọlọrun kò tó ìgboyà fún ọ?
3 1787147 Orilẹede France 56940 87.
orile ede Naijiria fun atileyin won nigba ti o n se asekagba eto ipolongo fun
Dájúdájú o mọ̀, nítorí pé wọ́n ti bí ọ nígbà náà,o sá ti dàgbà!
Àwọn ohun ọ̀sìn tí wọ́n kó bọ̀ nìwọ̀nyí: ẹṣin wọn jẹ́ ẹẹdẹgbẹrin ó lé mẹrindinlogoji (736) akọ mààlúù wọn jẹ́ igba ó lé marundinlaadọta (245)
Mo ti sọ fawọn iyawo mi ati mọlẹbi mi pe ki wọn funemir tuntun ni ọwọ to yẹ'' Ni ọjọ Aje ni ijọba Kano yọ Sanusi kuro lori oye ti wọn si paṣẹ pe kio fi ilu silẹ lọ si ipinlẹ Nassarawa.
Ọpọlọpọ ileri ati ẹjẹ ni Buhari jẹ nigba naa ninu akọsilẹ to pe ni ''Majẹmu mi pẹlu awọn ọmọ Naijiria.
Gẹgẹ bi igbakeji adari ẹgbẹ, Akintola ko ṣiṣẹ ninu ijọba apa iwọ oorun Naijiria ti Oloye Awolowo jẹ alakoso rẹ.
Agbe kan ti isẹlẹ naa kan nilu Argungu, Sanusi Adamu, sọ fun BBC wipe bo tilẹ jẹ wipe ọrọ naa bẹrẹ lati nkan bi osu diẹ sẹyin, o buru pupọ l'asiko yii.
Ṣugbọn n óo dáàbò bo ilé mi, kí ogun ọ̀tá má baà kọjá níbẹ̀; aninilára kò ní mú wọn sìn mọ́, nítorí nisinsinyii, èmi fúnra mi ti fi ojú rí ìyà tí àwọn eniyan mi ti jẹ.
 Ó gbòòrò de apá àríwá àtiu gusu ní 1840 lábẹ ́ iiungo kablee .
ke si aare Muhammadu Buhari ko gba won sile lọwọ iko Boko Haram ati wahala to n
”Aare Buhari ni ko si egbe oselu ti oloye Anenih ko mo nipa re , o si tun je eni to ni ife si isokan orile ede yii.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ìyá Darasimi: Ọlọ́run fi ìbejì rẹ̀ mí lẹ́kún, lẹ́yìn ikú Darasimi tó mu sódà O ṣe alaye wipe gbogbo ẹni ti Eleduwa ṣẹgi ọla fun lo ni ojuṣe ati se iranlọwọ fun awọn eeyan to kudiẹ kaato fun.
Tí a bá tún wo àwọn oníṣòwò ńláńlá lóde òní nílẹ̀ Yorùbá jákèjádò, “Ọkan ni ṣànpọ̀nná kó láwùjọ èpè” ni ọ̀rọ̀ ti Ìjẹ̀ṣà.
Lati fi idi ilana naa mulẹ, awọn ijọba ipinlẹ bii Eko tilẹ fi ofin gbee lẹyin, ofin yii si wa lara eyi ti wọn gbe kalẹ ni ile ẹjọ lati fi gbajugbaja oṣere sinima, Funkẹ Akindele ati ọkọ rẹ j'ofin ni ọjọ Aje.
 wọ ́ n maa ń ta àwọn iṣẹ ́ tí o ṣe jáde ní ìlé ìtàjàrẹ ́ tí ẹ ̀ ka rẹ ̀ wà ní bí orílẹ ̀ èdè àádọ ́ ta .
Aarẹ Buhari ni kilaasi kan naa ni oun ati Ọgagun agba Shehu Musa Yaradua wa ni ile iwe alakọbẹrẹ ati girama ki wọn to darapọ mọ ileeṣẹ ologun.
Èmi ò lè ṣe kí ng má máa gbọ́ àgbọ́rìn o.
Calabar Killing: Àwọn ará ilú dáná sún èèyàn méji tí wọ́n furasí bíi olè
Bawo lo se fe see ti ikan ko fi ni ju ikan lo?
Oríṣun àwòrán, Getty Images Bawo ni awọn to ni ipenija titọsile ṣe le ran ara wọn lọwọ?
Òwe Yorùbá: Mélòó lo lè parí nínú òwe Yorùbá yìí?
Igba keji ree ni aarin osu kan ti ikede yoo waye pe ilumọọka osere tiata naa papoda, bẹẹ ni ọpọ eeyan to si gbọ ikede yii lo ka ọwọ sori pe ẹni re lọ.
ìgbì omi ìbá ti gbé wa mì.
Oríṣun àwòrán, @lasemasocial Bakan naa ni ajs naa tun ṣalaye pe awọn igi to wo ọhun tun wo lu awọn ọkọ ayọkẹlẹ kan ti wsn si tun da wahala irinna silẹ.
Ṣugbọn wọ́n ń wí pé, ‘Rárá o, OLUWA kàn ń sọ tirẹ̀ ni, tinú wa ni a óo ṣe, olukuluku yóo máa lo agídí ọkàn rẹ̀.
 sùgbọ ́ n síbẹ ̀ síbẹ ̀ a sì lè sàlàyé fún aláìgbàgbọ ́ nínú ẹ ̀ sìn ìgbàgbọ ́ ohun tí èsìn ìgbàgbọ ́ jẹ .
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ṣé òótọ ni pé èèyàn leè kó Coronavirus láti ara aṣọ tàbí bàtà?
Ajo ohun ti se akojopo iroyin owo-na ile-ise MTN lorile-ede Nigeria, eyi ti o gbegba oroke pelu awon onibara bi milionu mejileladota, nigba ti Bharti Airtel ati Globacom, gege bi awon ti o ni awon onibara to poju.
Olukúlùkù àtúntẹ̀ titun ti Ẹ̀kọ́ àti àwọn Májẹ̀mú ní àwọn àṣìṣe àtẹ̀hìnwá tí a ti túnṣe àti àfikún àwọn ọ̀rọ̀ ìwífúnni titun, pàápàá nínú àwọn abala onítàn ti àwọn àkọlé ìpín.
Díẹ̀ lára àwọn ìṣẹ̀lẹ̀ tí yóò mi ìgboro tìtì l'ọ́dún 2020 rèé Ilẹ̀ UAE ti n fún àwọn arìnrìnàjò ní ìwé ìrìnnà ọlọ́dún márùn ún Amotekun kò ní gbé ìbọn o!
Nítorí irú àwọn eniyan bẹ́ẹ̀ kì í ṣe iranṣẹ Oluwa wa Kristi, ikùn ara wọn ni wọ́n ń bọ.
Nígbà tí ẹ bá fẹ́ pe àwọn ọmọ Israẹli jọ ẹ óo máa fọn fèrè, ṣugbọn kò ní jẹ́ ti ìdágìrì.
 ' nísìsíìyí , arábìnrin adépèjì afọlábí tí ó jẹ ́ eléré àpíìrì ní Ìdó-Èkìtì ti mú ìlù bẹ ̀ mbẹ ́ àti àkúbà mọ ́ agbè àti agogo tí a ń lò tẹ ́ lẹ ̀ nínú eré àpíìrì .
Alfa Babatunde Sotitobire Ẹ má gbàbọ̀de kankan láti tú Wolii ìjọ Sotitobire sílẹ̀ o!
Ninu idahun rẹ lori ọrọ MI lori Twitter, ijọ Satani da si ọrọ naa.
 Àwọn ẹranko tí ó ń gbé ní àpáta dúdú maa n ní àwọ ̀ dúdú ju àwọn tó ń gbe ní orí iyẹ ̀ pẹ ̀ tí ó mọ ́ .
Ẹ̀wẹ̀, àtẹjáde láti ilé iṣẹ́ tó n ri si ọ̀rọ̀ ilẹ̀ òkèrè kò sọ ní pàtó pé iye báyìí ni owó físà náà.
Gbogbo wa sì máa dáhùn pọ̀ lẹ́ẹ̀kan náà wí pé, Ewédayépọ̀ gun òkè àjà lọ.
Nígbà tí mo kà á, ohun tí mo bá níbẹ̀ ni èyí:
Oríṣun àwòrán, Others Bẹẹ naa lo wa lara awọn to fi ẹgbẹ agbaagba Yoruba, Yoruba Council of Elders lọlẹ ni ọdun 1975.
Àkọlé àwòrán, Awo níì gb'áwo nígbọ̀wọ́ Àkọlé àwòrán, Ta ń lẹrù Àkọlé àwòrán, Bí ebi bá kúrò nínú ìṣẹ́.
ifesewonse ohun si lati ri Gomina ipinle Gombe, Ibrahim Dankwambo, alaga ajo to
Iroyin tun so pe aarẹ Trump fe ki baalu naa tun dabi tuntun”ko da a bi I ti Amerika’’ ko yi kuro ni eyi to da bi i ti” oda Jackie Kennedy’’; ni eyi ti Raymond Loewy  so pe o da bi “oko oju omi.
Lẹ́yìn tí Hananaya wolii bọ́ àjàgà kúrò lọ́rùn Jeremaya, tí ó sì ṣẹ́ ẹ, OLUWA sọ fún Jeremaya pé, 
Oluwa Ọlọrun tí ó mí sinu àwọn wolii rẹ̀ ni ó rán angẹli rẹ̀ pé kí ó fi àwọn ohun tí ó níláti ṣẹlẹ̀ láìpẹ́ han àwọn iranṣẹ rẹ̀.
Ẹ̀yin òṣìṣẹ́, ẹ má ṣáì lọ síbi iṣẹ́ lọ́jọ́ Ajé, olórí àwọn òṣìṣẹ́ ní Nàìjíríà tako ìyanṣẹ́lódì Ọgbọ́n àti kówójẹ n'ìgbèsẹ̀ ìjọba láti ná $1.
Ẹgbẹrun márùndínlọ́gọ́rin awọn ọdọ ti ko ni iṣẹ lọwọ ni yoo jẹ anfani eto ọhun.
O ni aba ni eyi, wọn ko le paṣẹ fun un rara.
'Iha kokanmi Buhari lewu fun Nigeria' 'Kristẹni lo n fara kaaṣa ikọlu fulani ju' Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Gọngọ sọ, ẹlẹ́há pàdé àwọn tó lùú ní jìbìtì nílùú Eko lọ́jà Ibadan Fani Kayode ni ki lo kan Lemọmu p\\elu itan aja ni ibeere Tinubu lori Evans ati ọmọ Baba Fasoranti Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, CAN: Samson ni ọrọ awọn ajinigbe ti gba àpérò ní Naijiria Bakan naa ni awọn miran ni oro to jade lẹnu Tinubu ko yẹ ko jade lẹnu rẹ gẹgẹ bi asaaju.
N1M ní iléẹ́jọ́ béèrè fún béèlì olùwọ́de EndSARS, Eremosele Adene Wo ìdí tí wọ́n fi ta ẹyẹlé kan ṣoṣo ní ₦893,000,000 Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Bí o bá bá ààrùn ìpẹ́pẹ́ gbígbẹ lára arẹwà obìnrin rẹ̀, kí loó ṣe?
Bẹẹni awọn tẹgbọntaburo a maa jọ tẹsẹ bọ ṣokoto kan naa.
Oríṣun àwòrán, @raufaregbesola Àkọlé àwòrán, Salinṣile ni bi oju ọrọ ti ṣe ri bayii, ko si idi fun ijọba ipinlẹ Ọṣun lati san aabọ owo oṣu mọ Ẹwẹ, ijọba ipinlẹ Ọṣun ti fi idi ọrọ naa mulẹ.
Kò sì sí ohun àṣírí tí a kò ní mọ̀.
5 15773 Orilẹede Guyana 154 19.
Àwọn aṣòfín ní ìpínlẹ̀ Edo ti yọ Abẹnugan Ilé, Francis Okiye bí jìgá Inú mi dùn sí iwọ́de EndSARS tàwọn ọdọ́ Nàìjíríà ń ṣè - Ooni Ogunwusi Àìbìkítà yíì gbọ́dọ̀ dópin, ìjọba gbọdọ̀ mú ẹ̀dùn ọkàn àwọn aráàlú lọ́kùnkúndùn- Agbẹjọ́rò Àgbà Wo àwọn kọ̀ndísàn tuntun tí àwọn olùwọ́de #ENDSARS gbé jáde lẹ́yìn tí wọ́n tú SARS ká Small doctor, Falz, Toyin Aimakhu, Wizkid, Tiwa Savage, Debo Macaroni atawọn miran gba Ibadan, Lekki, Ikeja, Agege ati bẹẹ bẹe lọ lati jẹ ki ijọba Naijiria mọ ohun to kan.
Ní ìgbà kan rí ẹ ní anfaani tó láti ṣe àwọn ohun tí àwọn abọ̀rìṣà ń ṣe.
Eyi ri bẹẹ nitori ẹsin musulumi ni o jẹ ẹsin kan gbogi ti ọpọ ọmọ orilẹ-ede naa n sin.
Ẹni tí ó bá sọ̀rọ̀ tí kò dára sí Ọmọ-Eniyan yóo rí ìdáríjì.
Bode Thomas di Minisita feto igbokegbodo ọkọ labẹ ofin Mcpherson lọdun 1951, to si n soju ẹkun iwọ oorun guusu Naijiria, ibẹ si lo ti n fọnrere fun agbekalẹ ijọba awa ara wa lorilẹ-ede yii , to fẹ ko bẹrẹ lọdun 1956 Nigba ti wahala suyọ lori ofin Mcpherson losu kẹta, ọdun 1953 ni Bode Thomas kọwe fi ipo minisita silẹ, amọ o pada wa di minisita fun isẹ ode lẹyin ipade apapọ lori atunse ofin to waye nilu London Itan fi ye wa pe bi Bode Thomas se jẹ ọlọpọlọ pipe ẹda to, naa lo ni ọkan giga to, eyi to mu ki ibasepọ oun ati awọn olori kan ma gun rara, to fi mọ Ọlọla Ahmadu Beloo ati Alaafin Adeyẹmi keji.
Oríṣun àwòrán, Western Nigeria security network Ni ọsẹ diẹ sẹyin ti Oludari fun ikọ Amotekun nipinlẹ Oyo, Ajagunfẹyinti Olayinka Olayanju ba BBC sọrọ lori igbesẹ yii, o ni o di dandan kawọn eeyan to ba fẹ dara pọ mọ ikọ Amotekun fi orukọ silẹ lori ayelujara.
Latori awọn ọkada tuntun ti iroyin ni o le ni ọọdunrun, firiiji, ẹrọ ilọta ati ọpọlọpọ nkan mii ti iye rẹ to ọpọlọpọ miliọnu naira.
2 % agbegbe ile ) .
Ọ̀kan ninu àwọn iranṣẹbinrin wá sọ́dọ̀ rẹ̀, ó ní, “Ìwọ náà wà pẹlu Jesu ará Galili.
Gẹgẹ bi iroyin to kan BBC Yoruba lọwọ, inu kilaasi ni Favour ati awọn akẹgbẹ rẹ wa ti wọn n duro de ẹkọ to kan nigba to mu eso olomi kan to si mu u.
Bẹ́ẹ̀ ni èmi OLUWA Ọlọrun sọ.
Ṣoworẹ sọ ọrọ yii ninu ọrọ to ba BBC Pidgin sọ lati fesi si bi NEDG ko ṣe fun l'anfaani lati kopa ninu ifọrọwerọ na 'Ó ku Shittu, ó ku Ọlọ́run lórí ohun tó fẹ́ fi san ẹgbẹ́ APC l'ẹ́san' Àjọ ọlọpàá Eko kédé pé ìbalòpọ̀ nítà kò bójúmu 'Ilé làbọ̀ ìsinmi oko fọ́mọ Yorùbá lórí Brexit' Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Sòwòrẹ́: Èmi kò leè bá jẹgúdújẹrá APC àti PDP se pọ̀ Oludije maarun pere ninu eyi ti Aarẹ Muhammadu Buhari ati alatako rẹ̀ gboogi, Atiku Abubakar, ni ẹgbẹ NEDG ati Ẹgbẹ agbohunsafẹfẹ, Broadcasting Organization, pe fun ifọrọwerọ laarin awọn oludije fun ipo aarẹ.
Ojo ori awon ti o kan julo ni omo odun mokanlelogun si ogoji odun awon mejidinlogun wa nile iwosan ijoba bayii ni Owo nigba ti awon merindinlogun wa ni Abakaliki ti awon marundinlogoji.
Oríṣun àwòrán, Instagram/Bashir Ahmad Ọgbẹni Iyaniwura sọ pe Buhari kan ṣa n kọwọbọ iwe lasan ni pẹlu ọpọlọpọ awọn olori orilẹ-ede nilẹ okeere, ṣugbọn ko tii so eso rere kankan.
Akande wa tesiwaju pe Osinbajo ba awon eniyan Adamwawa, ijoba,ebi ati ojulumo ti isele yii sele si kedun pupo.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ijamba ina Eko; Awakọ ni omi gọta lo yọ oun ninu ijamba ina Ọkọ̀ jóná lórí afárá 3rd mainland nilu Eko Eeyan mẹrin ku ninu ijamba afara to wo lulẹ Àyẹ̀wò DNA bẹ̀rẹ̀ lẹ́yìn ìjàmbá iná Eko Gbogbo awọn eeyan mejidinlogun ati awọn eeyan meji kan to n lọ ti wọn jẹjẹ lẹgbẹ titi ba isẹlẹ naa lọ.
Ní gbolohun kan, àwọn nǹkan mẹta ni ó wà títí lae; igbagbọ, ìrètí, ati ìfẹ́; ṣugbọn èyí tí ó tóbi jù ninu wọn ni ìfẹ́.
Bẹ́ẹ̀ bá gbàgbé, awọn ile igbimo aṣofin mejeeji l'Abuja ti ranṣẹ pe Ọga ọlọpaa Ibrahim Idris, fun ifọrọwanilẹnuwo lori eto aabo ilẹ Naijiria.
Àwọn ará Arabia náà sì mú ẹgbaarin ó dín ọọdunrun (7,700) àgbò, ati ẹgbaarin ó dín ọọdunrun (7,700) òbúkọ wá.
Oríṣun àwòrán, Emma Russell Mo ti pada si iwa ikiyesara ju bose yẹ lọ, fifọ awọn nkan ti mo ba ra ki n to o ko wọn sinu firiiji, fọfọ ọwọ laimọye igba, fifọ bata ti mo ba wọ jade; awọn iwa ti mo ro pe mo ti jawọ ninu rẹ.
Wọ́n bá mú imọ̀ ọ̀pẹ, wọ́n jáde lọ pàdé rẹ̀, wọ́n ń kígbe pé, “Hosana!
Lẹ́yìn tó ṣá Monisola aya rẹ̀ ládá, Oniya ní iṣẹ́ èṣù ni Ọ̀rọ̀ Sotitobire tí a dá sí, àwọn aṣòfin àtàwọn àjọ kan ló fi lọ̀ wá- DSS Ìyá àádọ́rin ọdún sọ bí ọkùnrin ọdún márùndínlọ́gbọ̀n ṣe fipá bá òun lòpọ̀ Esabod ni: N ko lee gbagbe ọjọ ti wọn n sọ kiri pe mo mu siga lori Facebook, oju ti mi, ẹṣin pọ ju fun mi."
26 Bélú 2020 Fatai Rolling Dollar: Baba 70 jayé kọjá 70 kó tó dágbére fáyé pé ó dìgbóṣe!
1 9434 Orilẹede Uganda 220 0.
MKO Abiola: Buhari ní Abiọla kò bá dènà ìṣòro ẹ̀sìn àti ẹ̀yá ní Nàíjíríà
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Biden has a lot of experience on the world stage Nipa Iriri gigun ti Biden ni Biden ti kopa ninu ọpọlọpọ nkan ro nii ṣe nipa awọn eto pataki ni ọpọlọpọ ọdun sẹyin ti awan ipinu yii si le maa fibẹẹ dun wo ninu oṣelu aye ode oni.
Iroyin sọ pe ori akete aisan lo wa nigba ti o gbọ pe iyawo rẹ fun ogun ọdun yoo ṣe igbeyawo pẹlu ọkunrin miran lọjọ kọkandinlọgbọn, osu kẹjọ, ọdun 2020.
 Eleyi safihan ore nla la ti oloogbe oloye MKO ati awon ebi re gbese lati ja fun sise ifilole isejoba tiwa-n-tiwa ti a n je anfaani re lorile-ede Naijiria bayii.
Lẹ́yìn tí ogun náà parí ni àwọn ọmọ ogun Israẹli tó pada sí ibi tí Eleasari wà, tí wọ́n lọ kó àwọn ohun ìjà tí ó wà lára àwọn tí ogun pa.
" O ni oun kẹdun pẹlu awọn ẹbi oluwọde to ku sinu iṣẹlẹ naa, o si gboriyin fun awọn ọdọ Naijiria fun bi wọn ṣe fi igboya ati iduro ṣinṣin polongo fun àtúnṣe nileesẹ ọlọpaa, ti aisi isejọba gidi ba jẹ""."
Wo bí ìwọ náà ṣe lè rí gbà nínú owó ìrànwọ́ tí ìjọba Nàìjíríà fẹ́ pín Ẹ yé parọ́ kiri!
Fájìn ni àbúrò mi ti wọn fipá bálopọ̀ nínú sọ́ọ́sì, tí wọ́n sì tún fọ́ lórí Olorì Anu Adeyemi ń ṣe ọjọ ìbí, ẹ gbọ́ ǹkan tò sọ sí Kábíyésì Ìnàkí bímọ lẹ́yìn tí ìfẹ̀tòsọ́mọbíbí pòfo!
11 Ọ̀wàrà 2020 Fídíò, Wole Soyinka sọ ìdí tó fi ni òun a fi màálù Fulani ṣe súyà fáwọn èèyàn abúlé23 Owewe 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 3 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 5 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Bakan naa lo tun dara fun eekanna wa, ta ba si tun jẹ, se ni a ya awọn idọti kuro lagọ ara wa.
Bi oloṣelu ba n ṣe awọn nkan to ṣe adehun rẹ nigba ipolongo, o yẹ ka lu wọn lọgọ ẹnu lootọ pe wọn ṣe daa ṣugbọn fun ẹni to ba ni arojinlẹ a mọ pe 'a fẹ kẹ ṣe saa kan sii' ko tii kan iyẹn rara.
Trump ni kaka ki FBI se eleyi, ileesẹ naa kan fi akọkọ s'ofo ni lori wiwa ẹri ti yoo fi han wipe Russia padi apo pọ pẹlu ẹto ipolongo - idigbọ oun.
”Adura I’tikaaf maa n waye ni ojo mewa ki awe Ramadan o to wa si ipari.
Philip Shekwo: Aága ẹgbẹ́ APC ní ìpínlẹ̀ Nasarawa tí àwọn agbébọn jí gbé ti kú
Bẹ́ẹ̀ sì ni ògo tíí ṣá ni.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ondo disability day: Ijọba ẹ gbà wá ní ariwo tí àkàndá ẹ̀dá ń pa Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Ondo disability day: Ijọba ẹ gbà wá ní ariwo tí àkàndá ẹ̀dá ń pa 18 Ọ̀pẹ̀̀ 2019 Folajogun Akinlami: Ko si idile ti ko ni akanda ẹda lọdọ Oriṣiriṣi ere idaraya lo waye nibi eto ti awọn ajọ ti kii ṣe tijoba ati ijọba ipinlẹ Ondo geb kalẹ fawọn akanda ẹda.
Bi Aarẹ Buhari ti ṣe n mẹnu ba awọn akanṣe iṣẹ ti ijọba rẹ ti gbeṣe ni 2018 ni asofin kan ti a ko ri oju rẹ bẹrẹ si ni pariwo ''irọ ni,kii ṣe ootọ ''Dino Melaye bẹnu àtẹ lù Buhari Ọ̀rọ̀ Buhari tó dá awuyewuye sílẹ̀.
O tẹsiwaju wi pe, yoo nira lati wa ojutu si ipenija eto aabo lai ṣe amulo awọn ẹrọ igbalode.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Akure okada attack: Ọlọ́kadà tí àwọn afunrasí darandaran ṣá ní Oyedepo: Òfin kẹ́lẹ́nu-ó-ṣọ́nu lórí ayélujára tíjọba ń gbèrò kò tọ̀nà fún Nàìjíríà Oríṣun àwòrán, David Oyedepo Ministries International Biṣọọbu David Oyedepo ti ṣe apejuwe ijọba to wa lorilẹede Naijiria bayii gẹgẹbi egun fun orilẹede Naijiria.
 awọn isẹ ́ ọna wọn màa ń rewà tó sì ma ń ní àmìn àti àwòràn àwọn asáájú nínú ẹ ̀ sìn musulumi .
Nígbà kan, ó mú kí ìyàn jà ní ilẹ̀ náà:ó ṣẹ́ ọ̀pá oúnjẹ mọ́ wọn lẹ́nu.
emewa re, alaga egbe oselu APC, ogbeni Adams Oshiomhole ati adari egbe APC
Oun nikan si lo ni aṣẹ lati wọ kaa awọn ayaba ninu aafin bo ṣe wu u, to si ma n ṣe atunse to ba yẹ sibẹ loore koore.
Fayemi, lọ so ewé agbéjẹ́ mọ́wọ́ lórí ọ̀rọ̀ àwọn ọba Ekiti!
Ki lo ṣẹlẹ nigba ti ina sọ?
Ọrọ yii waye nigba ti awọn ọlọpaa mẹta kan to n jẹri fun olupẹjọ ninu ẹjọ ti wọn pe awọn obinrin mẹrin kan ti wọn fi ẹsun kan pe wọn n ko ẹẹdẹgbẹsan o le mẹwaa idi ewe oogun oloro igbo ti wọn n pe ni 'Bhang' lọna ti ko ba ofin mu lati ilu Migori si Ukunda ni Kwale.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù AFCON 2019: Ẹgbẹ́ agbábọ́ọ́lù 24 ni yóò kópa nínú rẹ̀ 21 Òkùdu 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Niṣe ni eto aabo duro deede ni olu ilu Egypt, Cairo ni ọjọ Ẹti ti ayẹyẹ iṣide idije ilẹ Africa, AFCON 2019 bẹrẹ.
OLUWA, gbóhùn mi,dẹtí sí ohùn ẹ̀bẹ̀ mi.
O ti la ina yẹn kọja daadaa tori naa to ba tilẹ lẹbọ lẹru gẹgẹ bii oludije, yoo ti hande bayii.
68 Ojúṣe àwọn ọmọ ìjọ lẹ́hìn tí a ti gbà wọ́n wọlé nípa ìrìbọmi—Àwọn alàgbà tàbí àwọn àlùfáà nílati ní ànító àkókò lati sọ àsọyé ohun gbogbo nípa ìjọ ti Krístì bí ó ṣe yé wọn tó, saájú kí wọ́n ó tó jẹ oúnjẹ alẹ́ Olúwa, àti kí a tó fi ìdí wọn múlẹ̀ nípa gbígbé ọwọ́ léni lórí láti ọwọ́ àwọn alàgbà, kí á lè ṣe ohun gbogbo pẹ̀lú ètò.
Ọba Kosoko gbajumọ bii isana ẹlẹẹta fun owo ẹru ṣiṣe, ọpọ igba si ni awọn oyinbo ti ṣipẹ fun un ko pinwọ owo ẹru, Amọ ti ko dahun pẹlu awijare lọdun 1851 pe ayafi ti Oba Benin ba sinmi owo ẹru, ni oun naa yoo jami lori rẹ.
Lọ́dún yìí ni ọjọ́ kejìdínlọ́gbọ̀n, àwọn ọmọ Mauritania tí wọ́n jẹ́ aṣíkiri fi ẹ̀hónú hàn níwájú Ẹ́mbásì Mauritania ní ìlú Paris, ní orílẹ̀-èdè France, lórí àìfiyèsí ìjọba nípa ìṣẹ̀lẹ̀ oró yìí.
Ọlọrun sọ bẹ́ẹ̀ nítorí ó mọ̀ pé bí ẹ bá jẹ ẹ́, ojú yín yóo là, ẹ óo sì dàbí òun alára, ẹ óo mọ ire yàtọ̀ sí ibi.
Bí ẹ kò bá rọ́ àlá mi fún mi, ìyà kanṣoṣo ni n óo fi jẹ yín.
7 185424 Orilẹede Jordan 3250 32.
" Nigba ti BBC Yoruba beere iwulo eeyan to ni paali olukọni ṣugbọn ti ko fi ṣiṣẹ fun ọpọlọpọ ọdun fun idagbasoke eto ẹkọ, Ọgbẹni Ọmọtunde Young ni 'eto idanilẹkọ onísọyè' ti oloyinbo n pe ni [remedial course'yoo wa fun gbogbo wọn lati sọ iye wọn ji.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Onigbinde àti Owolabi: Ààrẹ NFF tuntun gbọdọ̀ sàwárí ọ̀jẹ̀ wẹ́wẹ́ agbábọ́ọ́lù Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Adeleke fọhùn, 'èmi ni gómìnà tí wọ́n dìbò yàn' Ọkan lara awọn to sọ pe Modric gan ni ika to tọ si imu ti wọn fi n rin imu ni akọnimọọgba Real Madrid tẹlẹ ri Zinedine Zidane.
Alamojuto  fun ajo INEC, Musa Jamtari ni eto idibo naa si
Wọ́n fi ìtara gbọ́ ọ̀rọ̀ náà.
''Mama mama mi kan ṣaadeede ṣakiyesi pe etutu n jade lati oju ara mi nigba ti wọn n wẹ mi, ṣugbọn wọn ko tiẹ lero wi pe bo ya ibatan wa lo ṣe okunfa rẹ.
Adari ẹgbẹ Labour lorilẹ-ede naa, Jeremy Corbyn ni oun ko ni dari ẹgbẹ oun ninu idibo miiran mọ, lẹyin ti ẹgbẹ Conservative fidi ẹgbẹ rẹ janlẹ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ondo Police: À ń wá Deji Adenuga tó dáná sun ènìyàn mẹ́jọ 24 Ìgbé 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Ileeṣẹ ọlọpaa nipinlẹ Ondo ti fidi rẹ mulẹ pe lootọ ni ọmọkunrin kan dana sun mọlẹbi ọrẹbinrin rẹ nigba kan.
O si rọ awọn eeyan lati pe eyikeyi ninu awọn nọmba naa ti wọn ba n ri apẹrẹ run naa bii, iba, inu riru, ẹfọri lile, iṣoro lati mi ati bẹbẹ lọ lara wọn tabi lara ẹnikẹni to ba sun mọ wọn.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Yóò nira láti lo òwú tí wọ́n fi ń dá ìsun ẹ̀jẹ̀ dúró Ọ̀rọ̀ náà ń fa ìpalára gan lórí àwọn ìbáṣepọ̀ Isley.
 Òun ni bàbá olówó , òun ni bàbá tálákà ; òun ni bàbá ọlọ ́ lá , òun ni bàbá àwọn mẹ ̀ kúnnù .
Agbẹnusọ Ileeṣẹ to n ri si iṣẹlẹ pajawiri ni ipinlẹ naa, LASEMA, Nosa Okubo sọ fun BBC pe eeyan meji lo ba iṣẹlẹ naa lọ ti ẹnikan si farapa.
Bí wọ́n bá fi mí ṣe adájọ́ ní ilẹ̀ yìí ni, bí ẹnikẹ́ni bá ní èdè-àìyedè kan pẹlu ẹlòmíràn, tabi tí ẹnìkan bá fẹ́ gba ohun tíí ṣe ẹ̀tọ́ rẹ̀, wọn ìbá máa tọ̀ mí wá, ǹ bá sì máa ṣe ìdájọ́ òtítọ́ fún wọn.
Ajọ to n risi eto ilera lagbaye, WHO ti fọwọsowọpọ pẹlu ijọba ilẹ naa fun alakalẹ lori bi abo to peye yoo ṣe wa fun awọn ọmọ ile iwe.
Oretoria to jẹ olu ilu South Africa naa wa nibẹ ni eyi to fi jẹ pe ẹkun yii ni ikọlu ti wọpọ si julọ.
Aye ti iṣẹ ba ti ṣi silẹ, awọn eeyan yoo sa lọ ibẹ ni, idi niyii ti ero fi pọ."
Wo àwọn míniístà mẹ́fà tí ẹnu ń kùn jùlọ Wo ohun tó yẹ kí o mọ̀ nípa àwọn obìnrin méje ti Buhari fẹ́ yàn sípò minista Faari Buhari Àwọn àwòrán mánigbàgbé nípa Ààrẹ Muhammadu Buhari Buhari gba ife ẹyẹ agbaye Ta ni Mamman Daura?
deede aago  mẹ́wàá ke isu mẹ́sán án (8:50am).
Peteru dúró fún ọjọ́ pupọ ní Jọpa, ní ọ̀dọ̀ Simoni, tí ń ṣe òwò awọ.
Ti ọdun 2019 naa ko yẹ pẹlu bi awọn olori ẹsin kan ti ṣe n jade pẹlu iran ti Ọlọrun fi han wọn fun ọdun 2019.
"Fẹmi ko sai fi kun pe ""ni kete ti oludari ere ni o to, ni mo yara dọbalẹ lati tọrọ aforijin lọwọ mi pe ko ma binu pe mo fọ oun leti."
“Ẹ gbọdọ̀ fi oko wọnjanwọnjan sí igun mẹrẹẹrin aṣọ ìbora yín.
Ọta le ni irinwo lekan(461) o lekan ninu wọn lo wa lati ipinlẹ Eko eyi to pọ julọ.
O gba ami ẹyẹ idije bọọlu Ilẹ Afirika gẹgẹ bi akọnimọọgba ni ọdun 2013, o si tun gbaa gẹgẹ bi agbabọọlu l'ọdun 1994.
tẹle aarẹ ni, minista fun ọrọ ilẹ okeere , Geoffrey Onyeama; oluranlowo aare
Làásìgbò òṣèlú wáyé nílùú Ondo, ọ̀pọ̀ èèyàn fara pa Ilu isẹyin ni wọn si bii si ni ipinlẹ Ọyọ.
Ẹ ṣe akiyesi àwọn òdòdó inú igbó bí wọ́n ti ń dàgbà.
Kí gbogbo èyí tó ṣẹlẹ̀, wọn yóo dojú kọ yín, wọn yóo ṣe inúnibíni si yín.
Mo bẹrẹ si ni lo oogun, ṣugbọn iya mi ko fi igba kankan sọ idi ti mo fi n lo awọn oogun naa fun mi.
Eeyan 55,160 ni apapọ ni wọn ti fara ko aarun Coronavirus, ti awọn 43,231 si ti ri iwosan gba lọwọ ajakalẹ arun ọhun.
Ọlọrun ní, “Mo kórìíra ọjọ́ àsè yín, n kò sì ní inú dídùn sí àwọn àpéjọ yín.
Ija pẹẹpẹpẹ to waye bẹrẹ si ni mu ki wọn ma bara wọn du obinrin,ipo,ọla,iyi ati atilẹyin awọn oloṣelu to bẹrẹ si ni lo awọn ọmọ ẹgbẹ okunkun lati doju ija kọ awọn alatako wọn.
Bí ẹnikẹ́ni bá fẹ́ pa wọ́n lára, iná ni yóo yọ lẹ́nu wọn, yóo sì jó àwọn ọ̀tá wọn run.
Ikechukwu Wilson ló gba Àmì Ẹ̀yẹ 2019 BBC Pidgin Essay Competition Ọmọ ogun Nàìjíríà mẹ́wàá dèrò ọ̀run lẹ́yìn ìkọlù ẹgbẹ́ Boko Haram A gbọ́dọ̀ ṣewàdìí ìròyìn ayélujára kí a tó pin in- OloriSuperGal Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Illegal Rehab Centre: A le ni ogójì tí wan n kó 'sinú ìyará kékeré kan níle Ọlọrẹ Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Okuwobi ṣiṣẹ fun ọpọlọpọ ọdun ko to fẹyinti ni ileeṣẹ to n ri si eto idajọ ti ipinlẹ Eko loṣu kinni, ọdun 2020, lẹyin to ti ṣiṣẹ fun ọdun mejilelogoji.
 Àwọn olóyè wọn wà lára àwọn Ẹ ̀ sọ ́ aláàfin láyé àtijọ ́ , àtipé àwọn olóyè yìí ló sá wá sí abẹ ́ òkúta lábẹ ́ olórí wọn tó jẹ ́ àbúrò ọba Ọ ̀ yọ ́ nígbà náà .
Mo rọ́ àlá mi fún un, mo ní: 
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Diẹ lára àwọn jẹsí tó mi ìgboro tìtì ní agbo bọ́ọ́lù 17 Ìgbé 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 17 Èbibi 2020 Asiko yii lọ́dọọdún ni awọn ẹgbẹ́ agbabọọlu maa n mura lati safihan àwọn aṣọ agbabọọlu wọn fun saa to n bọ.
Eliṣa tún ní kí ọba máa ta àwọn ọfà yòókù sílẹ̀.
Nígbà tí ilẹ̀ mọ́, obìnrin náà tọ bàbá rẹ̀ lọ ó sì sọ̀rọ̀ yyìí fún un.
Ni ipinlẹ Ọṣun nikan, apapọ iye awọn to ti ni arun naa bayii ti di ogun.
Ọ̀kan jẹ́ Farisi, ekeji jẹ́ agbowó-odè.
34 Àwọn ọ̀rọ̀ wọ̀nyí kìí ṣe lati ọ̀dọ̀ awọn ènìyàn tàbí láti ọ̀dọ̀ ẹnìkan; ṣùgbọ́n lati ọ̀dọ̀ mi; nítorí-èyí, ẹ̀yin yíò jẹ́rìí síi pé wọ́n wá láti ọ̀dọ̀ mi, kìí sìí ṣe láti ọ̀dọ̀ ènìyàn.
Ó rán marun-un ninu àwọn aṣọ títa náà pọ̀, ó sì rán marun-un yòókù pọ̀ lọ́tọ̀ọ̀tọ̀.
Ènìyàn 33,616 ló ti lùgbàdì ààrùn Coronavirus ní àpapọ̀ ní Nàíjíríà 'A ko lee fi ẹmi awọn nọọsi wewu' Awọn aṣoju ẹgbẹ awọn oṣiṣẹ ti sọ pe ko si ohun to buru ti wọn ba daṣẹ silẹ.
Lẹ́yìn ọdún meji gbáko, Farao náà wá lá àlá pé òun dúró létí odò Naili.
Nigba ti wọn bii wi pe asiko to fun aarẹ orilẹede Amẹrika, Donald Trump lati tọrọ aforiji fun ọrọ kobakungbe to sọ nipa awọn orilẹede Afirika, Ọgbẹni Rex Tillerson ni ipinu orilẹede Amẹrika ni lati ni ajọsepọ to dan mọran pẹlu awọn orilẹede gbogbo ni ilẹ Afirika.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ọṣun Decides: ADC, ADP, APC àti SDP soju abẹ níkòó lórí ìwà ìbàjẹ́ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Ọṣun Decides: ADC, ADP, APC àti SDP soju abẹ níkòó lórí ìwà ìbàjẹ́ 18 Owewe 2018 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 19 Owewe 2018 BBC Yorùbá ṣètò ìpàdé ìtagbangba fún marun un ninu àwọn oludije fun ipo gomina nipinlẹ Ọṣun.
Bi o ṣe kere to lo ṣe n ṣe iṣẹ nla fun ẹni ti ko ba fẹ bu sara.
Oríṣun àwòrán, @lauramilne Àkọlé àwòrán, Àwọn arinrinajo to wa ni Gili Trawangan Ọpọ àwọn to wa ni erekuṣu naa ni ebi n pa wọn nitori ko si omi to ṣee mu ati ohun jijẹ ni eyi ti awọn eniyan ti n fẹ huwa ipá.
Awọn alaṣẹ lagbegbe naa sọ pe ibugbamu alakọkọ waye ni nnkan bi ago mẹsan ku iṣẹju mẹẹdogun niile ijọsin Our Lady of Mount Carmel, ibi ti ikọlu ti waye ri tẹlẹ.
 fífún ni ní àjẹsára nígbàtí ènìyàn bá ní oyún lè dáàbò bo ọmọ inú oyún náà .
OLUWA bá dá Mose lóhùn pé, “Ẹnikẹ́ni tí ó bá dẹ́ṣẹ̀ sí mi ni n óo pa orúkọ rẹ̀ rẹ́ kúrò ninu ìwé mi.
'Koko pataki kan ni wi pe, kokoro arun tuntun yii n tan kalẹ, gbogbo eeyan lo si lee ko o.
NCDC ni lara awọn eeyan to ni arun ọhun sọ pe ipinlẹ Kogi ni wọn ti wa, eyi to da ariyanjiyan silẹ laarin ijọba ipinlẹ Kogi ati ajọ naa.
Bo tile je pe adajo Belgore so pe Aare tapa si ofin , bakan naa ni gbaju-gbaja agbejoro lorile ede Naijiria Femi Falana naa so pe, igbese ti aare gbe yii ,wa ni ilana ati ibamu ofin.
Wọ́n ń pa àwọn opó ati àwọn àlejò,wọ́n sì ń pa àwọn aláìníbaba;
“Mo ni igboya lori Francis Uzoho, bee si ni O se daradara ninu awon ifesewonse meta ti a gba seyin.
Bàtà yìí ni ó dàbí ẹ̀rí ati èdìdì láàrin ẹni tí ń ta nǹkan ati ẹni tí ń rà á, ní ilẹ̀ Israẹli.
Ọ̀rọ̀ OLUWA tí Aisaya sọ ní ọdún tí ọba Ahasi kú: 
Awọn ikọ agbabọọlu orilẹ-ede mejeeji yii jọ pegede ninu idije ẹlẹni mẹrindinlogun ti AFCON to n lọ lọwọ ni orilẹ-ede Egypt.
Akiṣi fún un ní ìlú Sikilagi, nítorí náà ni Sikilagi fi jẹ́ ti àwọn ọba Juda títí di òní yìí.
Ní àkókò kan, bí Jesu ti dúró létí òkun Genesarẹti, ọ̀pọ̀ eniyan péjọ sọ́dọ̀ rẹ̀ láti gbọ́ ọ̀rọ̀ Ọlọrun.
Awọn janduku oṣelu ji apoti ibo lawọn ibi kan, awọn eniyan kan si farapa.
Zakari lo soro yii lasiko ti awon akoroyin ile akede Naijiria Voice of Nigeria
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Mr Macaroni sọ nípa eré tí Fraky freaky, Sugar Daddy, You are doing well, freaky spicy fẹ́ Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Fídíò, Akomolede: Bolaji Faleke ni Olùkọ́ tó ń kọ́ wa ní àṣà oge ṣiṣe lórí BBC Yorùbá1 Owewe 2020 6:18 Fídíò, Natalia Mufutau ìyá Yakub, Kamil àti Adam sọ̀rọ̀ lórí bí wọ́n ń sọ èdè mẹ́rin pàpọ, Duration 6,1831 Ògún 2020 Fídíò, Yoruba Language: Akomolede ati Asa Yoruba tọ̀sẹ̀ yí rèé lẹ́nu olùkọ́ wa30 Ògún 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Ẹ wo ọmọ Yoruba, Adewale Adeyemo tí yóò jẹ igbákejì akọ̀wé akápò ní ilẹ̀ Amẹrika Bi agbaye ṣe n kọminu ti wọn si n daro lori iku awọn agbẹ onirẹsi tawọn agbebọn Boko Haram pa lọjọ Abamẹta, gomina ipinlẹ Borno, Ọjọgbọn Babangana Umara Zulum ti gbe opo mẹfa kalẹ to ni yoo lee dẹkun atunṣẹ irufẹ ifẹmiṣofo bẹẹ.
Nínú ṣí’se bẹ́ẹ̀ ọmọbìnrin náà lóyún, ó bí olójú-májèlé sílẹ̀.
Wọ́n bi Ìgbéraga si ilé olórogún, àwọn ìyàwó bàbá́ rẹ yoku ni ó tọ nitori ìyá rẹ kú nigbati ó wà ni kékeré.
O tẹsiwaju lati sọ pe awọn ṣe ayẹwo ilera fun gbogbo awọn to gba papakọ ọkọ ofurufu wọle.
"Sugbọn lẹyin ọpọlọpọ ijiroro,"" Ọlọrun sọ pe: mo n sọ isẹ ìranṣẹ rẹ di gbigbooroo, ki o le ṣe olùṣọ́ àgùntàn odidi orilẹ-ede."
Ìbálòpọ̀ ọkùnrin sí ọkùnrin kò lòdì s'ofin Ofin ti f'àyè gba ìbálòpọ̀ Akọs'akọ, Abos'abo ní Botswana Ọjọgbọn yii to jẹ olukọni ni ile iwe giga ti ipinlẹ Eko, LASU jẹ ko di mimọ pe awọn tọrọ ki iwa ibajẹ ma baa gbilẹ lawujọ jẹ lọkan lo kan si awọn kaakiri lati ba wọn gbe ohun soke pe ki ijọba fopin si eto naa.
níbẹ̀ gan-an, ọwọ́ rẹ ni yóo máa tọ́ mi,tí ọwọ́ ọ̀tún rẹ yóo sì dì mí mú.
Fi ìfẹ́ rẹ tí kì í yẹ̀ hàn lọ́nà ìyanu,fi ọwọ́ ọ̀tún rẹ gba àwọn tí ó gbẹ́kẹ̀lé ọkúrò lọ́wọ́ àwọn tí ó gbógun tì wọ́n.
Lati igba ti mo si ti paṣẹ yii naa, ko si ẹni to ko arun coronavirus niluu Iwo, amọ Ọlọrun ni ilu Iwo nikan ni Oun fun mi.
Joe Biden náà ti gba abẹ́rẹ́ àjẹsara Covid-19 Bí o bá rí Erin tí alùpùpù gbá lójú pópó, kí lo ó ṣe?
Ilu Ilorin ni wọn ti bi iya to bi lọmọ Alhaja Adeoti ti awọn eeyan a ma pe ni Iya Aminu ni Iya to bi Emir tuntun yi Iya yi fun ara rẹ jẹ ọmọ ọba Abdulkadir Dan Bawa to jẹ Emir Kẹjọ nilu Ilorin.
Ó sì ti kìlọ̀ fún mi pé kí n má bá àwọn eniyan wọnyi rìn, ó ní, 
Ọkọ mẹ́sàn-án tó forí-gbárí lórí afárá Otedola mú ẹ̀mí méjì lọ A kò mọ̀ bóyá a le è san owó osù tuntun fún òsìsẹ́ - Ìjọba Ondo, Oyo, Kwara jẹ́wọ́ Adeoye ni rogbodiyan bẹ silẹ lẹyin ti awọn awakọ kan kọ ki ajọ ọhun fi ọwọ ofin mu wọn, lẹyin ti wọn ru ofin oju opopona leyi to n fa sunkẹrẹ fakẹrẹ ọkọ lagbegbe ọhun.
"Okina ni, ""O maa n nawọ ọrẹ awọn nnkan eto ẹkọ si awọn ọdọ t'owa ni awọn ileewe ati awọn bareke to wa ni ipinlẹ Eko."
Níwọ̀n ìgbà tí a ti dá wa láre nítorí pé a gba Ọlọrun gbọ́, kò sí ìjà mọ́ láàrin àwa ati Ọlọrun: Jesu Kristi Oluwa wa ti parí ìjà.
Bi awọn kan ti ṣe ya sidi ijo ati orin lawọn mii fi asiko iwọde polongo ifẹ ti awọn mii tiẹ sokun ifẹ pọ.
Omokri wa kesi awọn ọdọ lorilẹ-ede Naijiria lati mọ daju wi pe awọn kọ́ ni ọ̀le, sugbọn Aarẹ Buhari ati awọn ẹgbẹ ipolongo rẹ ni ọ̀le.
"Orúkọ àwọn tó yege láti darapọ̀ mọ́ ikọ̀ Amotekun ní ìpínlẹ̀ Oyo ti jáde Wo ojú àwọn òṣèré yìí láì lo ""Make-up"" orí ìtàgé bó ṣe rí gẹ́lẹ́ Gbajúgbajà òṣèré tó ṣe fíìmù James Bond tí jáde láyé lẹ́ní ọdún 90 Wumi Toriọla ti sọ̀rọ̀ sóke láti fi idí rẹ̀ múlẹ̀ pé òun àti ọ̀rẹ́ òun níjà Ọjọ Iṣẹgun, Ọjọ Kẹtadinlọgbọn ni wọn ji arakunrin Walton gbe ninu ile rẹ ti ko jina si ibode Niger."
Ẹni tí ó dàbí eniyan bá tún fi ọwọ́ kàn mí, ó sì fún mi ní okun.
Awọn oluwadi se ayewo ibudo igbafẹ ẹranko naa, ti wọn si sakiyesi pe yatọ sawọn akojọpọ eweko,òkè ati pẹ̀tẹ̀lẹ̀ tun wa ninu igbo ọhun.
Bí ẹnikẹ́ni bá dá ara rẹ̀ lójú pé òun jẹ́ ti Kristi, kí ó tún inú ara rẹ̀ rò wò, nítorí bí ó ti jẹ́ ti Kristi, bẹ́ẹ̀ gan-an ni àwa náà jẹ́.
OLUWA tóbi ní Sioni,ó sì jọba lórí gbogbo orílẹ̀-èdè.
“Bí òwe bí òwe ni mo ti ń sọ àwọn nǹkan yìí fun yín.
“OLUWA nawọ́ sílẹ̀ láti òkè wá, ó dì mí mú,ó fà mí jáde kúrò ninu omi jíjìn.
Nibẹ wọn tẹpẹlẹ mọ ọrọ abo ni Naijiria eyi ti wọn ni o kan tolori tẹlẹ mu to fi mu ki awọn oriade dide lọ ba aarẹ ṣepade.
Bi wọn se pa ọga SARS Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Lush Beauties: Ẹ má jẹ́ k‘ójú tìyín torí pé ẹ sanra, ẹ jáde síta Awọn aṣẹ tuntun yii lo jẹyọ nibi ipade ijiroro kan ti igbimọ to wa fun atunto FSARS ṣe lọjọ Abamẹta.
Ó tẹ̀ sí ọ̀nà burúkú tí àwọn ọba Israẹli rìn, ó ṣe bí ìdílé Ahabu ti ṣe, nítorí pé ọmọ Ahabu ni iyawo rẹ̀.
Ilu Mayanmar ni Asia ni a ti ri irun ṣiṣe gẹgẹ bii ọkan lara ọna ti obinrin fi le pe ọkunrin.
ọlà ati aṣeyọri ninu igbagbọ Yoruba.
Bakan naa lo wọgile eto ayẹwo awọn oldije fun ipo gomina labẹ aṣia ẹgbẹ oṣelu APC ni ipinlẹ Edo.
Pásítọ̀ gún ìyàwó rẹ̀ lọ́bẹ nínú ṣọ́ọ̀ṣì, ló bá tì í bọ ara rẹ̀ náà níkùn Ènìyàn 241 tuntun ló ti lùgbàdì àrùn Coronavirus ní Ọjọ́ Ìṣẹ́gun ní Naijiria Oloye Obasanjo woye bẹẹ lasiko to n sọrọ níbi ifilọlẹ ọgbin ẹja naa eyi to waye nibudo iyawe kawe rẹ (OOPL) to wa nilu Abeokuta.
"Ninu ko fọwọ mu ki wọn yọ oyun ki wọn lee ṣe iṣẹ abẹ tori ko lee tilẹ lo oogun ara riro lasan lati din irora ku tori yoo pa ọmọ lara tabi ko fi oyun silẹ ko gbe ninu irora titi.
Ó tún bá wọn sọ̀rọ̀ pupọ, ó ń rọ̀ wọ́n gidigidi, pé, “Ẹ gba ara yín kúrò ninu ìyà tí ìran burúkú yìí yóo jẹ.
Bí ó ti bọ́ lu àgọ́ náà, ó wó o lulẹ̀, ó sì dojú rẹ̀ délẹ̀, àgọ́ náà sì tẹ́ sílẹ̀ pẹrẹsẹ.
Wo àwọn ọ̀tá tó ń da orílẹ̀èdè Nàìjíríà láàmú Irú kí lèyì!
Ẹ fi ògo fún OLUWA Ọlọrun yín kí ó tó mú òkùnkùn ṣú.
Ṣugbọn bí ẹ kò bá fetí sí ọ̀rọ̀ mi, tí ẹ kò ya ọjọ́ ìsinmi sí mímọ́, tí ẹ̀ ń ru ẹrù wọ inú Jerusalẹmu lọ́jọ́ ìsinmi, n óo ṣá iná sí ẹnubodè Jerusalẹmu, yóo jó àwọn ààfin rẹ̀, kò sì ní ṣe é pa.
Nigba ti a beere lọwọ rẹ boya awọn ọmọ Almajiri wa ni ipinlẹ Oyo, Nureni ni pe wọn wa, ṣugbọn ati Almajiri ati awọn miran ti ko lọ si ile iwe ni eto naa yoo ṣe lanfaani.
Òkú wọn dàbí pàǹtí láàrin ìgboro,sibẹsibẹ inú OLUWA kò rọ̀,bẹ́ẹ̀ ni kò sì dá ọwọ́ ìjà dúró.
Èèyàn 7 kú, 21 di àwátì lásìkò tí ọkọ̀ ojú omi dojúdé ní Eko àti Benue Oríṣun àwòrán, @lasemasocial Ajọ oṣiṣẹ pajawiri ni ipinlẹ Eko, LASEMA ti fi lede pe eniyan meje lo sọ ẹmi wọn nu lẹyin ti ọkọ oju omi danu ni opin ọsẹ.
Ṣugbọn ṣa, eniyan 12,795 ti ri iwosan, awọn 709 si ti ku.
Èyí sì jẹ́ ìkìlọ̀ fún àwọn ọmọ Israẹli pé ẹnikẹ́ni tí kì í bá ṣe ọmọ Aaroni kò gbọdọ̀ wá siwaju pẹpẹ OLUWA láti sun turari, kí ẹni náà má baà dàbí Kora ati àwọn ẹlẹgbẹ́ rẹ̀, gẹ́gẹ́ bí OLUWA ti rán Mose pé kí ó sọ fún Eleasari.
jẹ́ kí ọ̀tá ó lé mi bá,kí ó tẹ̀ mí pa,kí ó sì bo òkú mi mọ́ ilẹ̀ẹ́lẹ̀.
“Èmi ni OLUWA Ọlọrun yín, tí ó mu yín jáde láti ilẹ̀ Ijipti, ní oko ẹrú tí ẹ wà:
ki won jẹ eto ẹkunwo yii ju awon to wa loke lọ ”.
Patrick Pascal: Oliseh jẹ akọni ti ko gba gbẹrẹ Victor Moses, Oshoala gba ami ẹyẹ NFF Oríṣun àwòrán, Getty Images Bakannaa ni owo yii tun ju miliọnu mẹtadinladọrin ti ẹgbẹ agbabọọlu Liverpool fi ra Naby Keita lati ẹgbẹ agbabọọlu Red Bull Leipzig lọ.
Awọn ara ilu Eko si ti n ke gbajarẹ ki ijọba wa wọrọkọ fi ṣada lori ọju ọna yi.
Arinrin ajo lona aibofin mu omo orile-ede Mali ti o wo orile-ede Farance lona aibofin mu ni won n gboriyin fun latari bi o se safihan akoni lojo-Aiku.
Iléẹjọ́ fún Gómìnà Seyi Makinde láṣẹ láti yan alága tuntun ní ìpínlẹẹ̀ Oyo Inú mi dùn pé ẹni tó gbà ìjọba lọ́wọ́ mi ń san gbèsè tí mo fi kalẹ - Aregbesola Ibadan NURTW: Àwọn ti Auxilliary àtàwọn tí Ajanaku gangan ló ń dàgboro rú Ọkan lara awọn aworan yii ṣafihan bi alufa kan lorilẹede Kenyan sẹ sọ wi pe, oun ri Jesu to rin loju popo ni Kenya.
8bn naira) si yẹ ko jẹ fun sisan owo oṣu awọn osisẹ.
Máa gbé kẹ̀kẹ́ rẹ lọ, àwọn akọròyìn kọ̀ ìpàkọ́ sí Femi Fani Kayọde Músò Músò!
Ninu idamu lawọn igbimọ iṣakoso ẹgbẹ awakọ ero wa bayii lati lee ri owo ti awọn ajinigbepawo yii n beere fun itusilẹ akọwe wọn, to ti wa ninu idubulẹ aisan ṣaaju iṣẹlẹ yii.
Ibanujẹ dori agba kodo ni Fasiti Copperbelt nibi t'awọn akẹkọọ ti tan ina abẹla ti wọn si rin kaakiri ile ewe naa lati kẹdun ẹja Mafishi to jẹ Ọlọrun nipe.
OLUWA tún wí fún Gideoni pé, “Àwọn tí wọ́n ṣẹ́kù yìí pọ̀jù sibẹsibẹ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù #Sima Sarkar 'Yorùbá gbà pé òrìṣà bí ìyá kò sí!
Nítori àwọn àtúgbẹ́yẹ̀wò, o níra láti ṣe àkójọpọ fún àwọn ọkọ́ naa Orisun: Johns Hopkins University atawọn ajọ eto ilera ilu Iye akọsilẹ to waye gbẹyin 15 Oṣù Ṣẹ́rẹ́ 2021 20:44 WAT+3 Ìjọba àpapọ̀ ni àkànṣe isẹ mọkandinlọgọrun tó wà káàkiri àwọn ẹkùn idibo tí ń bẹ lorilẹede èdè yìí, làwọn yóò fi owóya náà gbọ bukata rẹ.
Ọmọ ọbabinrin fi aṣọ wúrà ṣọ̀ṣọ́ jìngbìnnì ninu yàrá rẹ̀,
Omoni sọ pe ni bi aago meje aarọ ọjọ kọkanlelogun, oṣu kẹjọ ni ọlọpaa yii ṣadeedee lọ si ile awọn Kote nibi to ti sọ wi pe oun fẹ ri i.
Seyi: A o tii ṣegbeyawo ṣugbọn mo ni 'Baby' kan ti mo nifẹ gan, ẹni bi ọkan mi ni mo si ti wa pa pẹlu ẹ.
Mo ti gbọ́ ìròyìn ibinu rẹ ati ìgbéraga rẹ,n óo fi ìwọ̀ kọ́ ọ nímú, n óo fi ìjánu bọ̀ ọ́ lẹ́nu,n óo sì fà ọ́ pada sí ibi tí o ti wá.
Messi ti gba goolu mẹtalelogoji sawọn ni saa ere bọọlu yii ni kan, eleyi to si tun jẹ ki awọn akẹgbẹ rẹ bẹru rẹ kaakiri ilẹ Yuropu.
 Ìyàwó rẹ ̀ kẹta , tí ó jẹ ́ ọmọ ọgbọ ̀ n ọdún jẹ ́ louisa thompson tí ó kú ní ọdún 1858 .
Atẹjade kan ti osisẹ alarina agba fun ileesẹ ọlọpa ilẹ wa, Frank Mba fisita ni ọjọ Ẹti salaye pe gbogbo ẹnu ni ọga agba ọlspa ilẹ yii fi koro oju sawọn isẹlẹ eto aabo to mẹhẹ to n waye lorilẹede yii.
 Ó tún jẹ ́ àṣà yorùbá òmíì kí wọn máa ṣú opó olóògbé fún àwọn àbúrò rẹ ̀ , láti fi ṣe aya .
Ko daju igba to bẹrẹ si ni tọju awọn agbalagba tabi boya o kẹkọ gboye nipa itọju awọn agbalagba ṣugbọn o sọ pe awọn agbalagba alarun Covid 19 to ni ipenija ilera bi aisan itọ ṣuga ati aisan ọkan wa lara awọn ti ohun ti tọju ti ara wọn si ti ya.
Ki onikaluku ja fun ẹtọ rẹ ninu ilẹ iran baba nla rẹ nitori oko kii jẹ ti Baba tọmọ ko ma ni ààlà.
”Lara awon to wa sibi ipde naa ni igbimo alase to ga ju, aare , akowe , akapo ati awon egbe aparapo awon osise lorile ede Naijriia.
Ọdún Ọlọ́jọ́ ń dùn mọ̀rànìn-mọran-in ní Ilé-ifẹ̀ Ariwo sọ, wọ́n fọwọ́ òsì júwe ilé fún Tacha lórí ètò àgbéléwò BBNaija Ọgọ̀rọ̀ èèyàn s'ayẹyẹ ọjọ́ ìbí ọgọ́rin ọdún fún Fẹla Atagitá Fẹ́mi Aníkúlápó-Kútì bá obìnrin lọ l‘Amẹ́rika Oun ni ọmọ ile iwe akọkọ to jẹ obirin ni ile iwe Girama to wa ni Abeokuta, eyi ni Abeoktuta Grammar School, oun naa tun ni obinrin akọkọ to kọkọ wa ọkọ ayọkẹlẹ lorilẹ-ede Naijiria.
OLUWA ní, “Nítorí náà, ẹ gbọ́, ẹ̀yin orílẹ̀-èdè,kí ẹ̀yin eniyan sì mọ ohun tí yóo ṣẹlẹ̀ sí wọn.
Bí ó bá sì wí pé, àwọn ẹran tí ó bá ní àwọ̀ tí ó dàbí adíkálà ni yóo jẹ́ tèmi, gbogbo ẹran inú agbo a sì bí ọmọ tí àwọ̀ wọn dàbí adíkálà.
Orin náà túmọ̀ pé kí Ọlọ́run dá ọba wọ́n sí o!
Pakistan Iku ni ere ẹnikẹni to ba ṣe ayipada lati akọ tabi abo si akọ lorilẹ-ede Pakistan tẹléri, sugbọn orilẹ-ede ọhun ti fun awọn irufẹ awọn eeyan bẹẹ lẹtọ labẹ ofin lọdun 2009.
Ọkan lara awọn atamatase to ti sọ awọn Arsenal di kọstọma daadaa, Ashley Barnes lo gba bọọlu naa wọle.
Nibayii, ẹgbẹ oṣelu PDP pẹlu ti da si ọrọ naa ti wọn si ti n ke si aarẹ Buhari pe ko rọ Adeọṣun loye; ko si ṣe iwadi rẹ pẹlu ijiya to tọ bi aje iwa ibajẹ naa ba ṣi mọọ lori.
7: Ile Aiye Dun Pupo / Love In Tokyo (India Sound) (1975) Vol.
A mọ̀ pé Ọlọrun kì í fetí sí ẹlẹ́ṣẹ̀, ṣugbọn a máa fetí sí ẹnikẹ́ni tí ó bá bẹ̀rù rẹ̀, tí ó bá ń ṣe ìfẹ́ rẹ̀.
Nítorí náà, àwọn ọmọ ogun náà dá àwọn tí wọ́n kó lẹ́rú ati ẹrù tí wọn ń kó bọ̀ sílẹ̀ níwájú àwọn ìjòyè ati gbogbo ìjọ eniyan Israẹli.
Ọjọ yii gan an ni Ọọni ana, Okunade Ṣijuwade Olubuṣe keji waja ti igbesẹ ati yan Ọọni tuntun bẹrẹ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Adebola Ademilua: Àìrísẹ́ ṣè lẹ́yìn ìwé kíkà ló sọ mi dí ìyá onírú, mo dúpẹ́ tèmi Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Adebola Ademilua: Àìrísẹ́ ṣè lẹ́yìn ìwé kíkà ló sọ mi dí ìyá onírú, mo dúpẹ́ tèmi 27 Bélú 2020 Àwọn ọ̀rẹ́ mi kọ́kọ́ sá fún mi nígbà ti mo bẹ̀rẹ̀ irú títà ṣùgbọ́n mo ti di ààyò ọ̀rẹ́ báyìí- Adebola Mo gba iwe ẹri America ati UK yatọ si ti Naijiria ṣugbọn idi iru ṣiṣe ni mo pari ẹ si nitori pe ko si iṣẹ ni igboro.
Nígbà tí gbogbo àwọn aguntan rẹ̀ bá jáde, a máa lọ níwájú wọn, àwọn aguntan a sì tẹ̀lé e nítorí wọ́n mọ ohùn rẹ̀.
Ile ọkunrin keji yii lo wa, ti baba ọmọ rẹ akọkọ tun fi n fẹ ko pada si ọdọ rẹ.
“Ǹjẹ́ ẹnikẹ́ni tíì sọ fún Ọlọrun pé,‘Mo ti jìyà rí, n kò sì ní gbẹ̀ṣẹ̀ mọ́.
Ògo tí o fi fún mi ni mo fi fún wọn, kí wọ́n lè jẹ́ ọ̀kan gẹ́gẹ́ bí àwa náà ti jẹ́ ọ̀kan; 
Ẹwẹ, igbakeji Gomina ti rọ gbogbo alabiṣiṣẹpọ rẹ lati da ohun ini ijọba Ondo to ba wa lakata wọn pada lati wakati mẹrinlelogun.
Ileeṣẹ ọlọpaa ni awọn yoo ṣalaye fun araalu ohun to fa iku awọn mejeeji ti iwadii ba ti pari.
Àwọn bísọ̀ọ̀bù Aguda rọ ààrẹ Buhari lati kọ̀wé fipò sílẹ̀
Ìjọba Nàìjíríà ti parí ìwádìí lórí àgbo Covid-Organics ti Madagascar kó ránṣẹ́ sí i Awọn alaṣẹ orilẹ-ede Naijiria ti sọ pe awọn ko ri ẹri tabi aridaju pe àgbo ti orilẹ-ede Madagascar ṣe fun iwosan coronavirus n ṣiṣẹ.
”Ewe, aare Buhari yoo lo darapo mo akowe agba ajo isokan agbaye, Antonio Guterres ati awon eniyan jankan-jankan miiran kaakiri agbaye lati jiroro lori awon ona ti yoo mu igbe aye alafia joba lorile-ede kookan.
 ami ti a fi n tokasi akojopo awon nomba odidi ni z ( tabi formula _ 1 , tabi unicode ℤ ) ti o duro fun  zahlen "" ( ti o tumosi nomba ni ede germani )."
Bakan naa lo rawọ ẹbẹ si ajọ agbaye, United Nations, lati finna mọ ijọba Naijiria, ko le ṣe iwadii iṣẹlẹ naa.
"Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Rogbodiyan NURTW: Ọlọpa gbe Ọlorunwa satimọle 16 Èrèlè 2018 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ọlọpa sọ pe afurasi yii jẹwọ pe oun gba ẹ̀gbẹ̀rún lọna ẹ̀ẹ́dẹ́gbẹ̀ta naira lati ṣe iṣẹ ibi naa Afurasi apaniyan kan ti orukọ rẹ njẹ Adeola Williams, ti inagijẹ rẹ n jẹ ""Ade Lawyer"", ti lu panpẹ ijọba ti o si ti wa ni ahamọ awọn ọlọpaa ti ẹka ọga agba ọlọpaa orilẹede yii."
Láìpẹ́, ayé kò ní rí mi mọ́, ṣugbọn ẹ̀yin yóo rí mi.
Ṣe mo lè fún ọmọ mi lọ́yàn lai fòyà?
Minisita fun ibaraẹnisọrọ ati irinajo, Dorcas Makgato ṣalaye lori iha ti ijọba orilẹede naa kọ si ijiroro idunadura pẹlu ileeṣẹ De beers.
 “Iku arakunrin yii je ofo ati ibanuje fun awon obi ati molebi re”.
O ni kii ṣe pe irinajo aarẹ lodi sofin nikan, ko fi iwa rere han.
Wọnyii ni awọn ohun to ṣẹlẹ lagbo awọn oṣere tiata Yoruba, Yollywood lọsẹ yii.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Nítorí owú jíjẹ, ọkọ Zarka gé imú aya rẹ̀ dànú!
Nígbà tí gbogbo àwọn ọmọ Israẹli ń kùn sí mi ní Meriba, ẹ kọ̀ láti fi títóbi agbára mi hàn níwájú àwọn eniyan náà.
“Ṣugbọn o gbójú lé ẹwà rẹ; o di alágbèrè ẹ̀sìn nítorí òkìkí rẹ, o sì ń bá gbogbo àwọn eniyan tí wọn ń kọjá ṣe àgbèrè.
Àkọlé àwòrán, Ibudo ayẹwo fun ikọni nipa itọju ẹranko ni Fasiti Pọta nipinlẹ Rivers Kikọ ni mímọ̀ ni ọrọ àwọn iṣẹ itọju ẹranko ni ayika to jẹ ki ẹkọ dun lati kọ.
Oríṣun àwòrán, AFP Àkọlé àwòrán, Orilẹede Naijiria wa lara awọn ti eniyan rẹ n pọ si ju lagbaye Banki agbaye paapa sọ pe orilẹede Naijiria lo ni awọn akuṣẹ julẹ ni agbaye bayii.
I pray God continues to direct you(Amen)Happy Birthday sir.
O ṣalaye pe awọn dokita sọ f'oun pe oun ni aarun rọpa rọsẹ eleyi to ṣakoba fun apa kan ara oun, ti o si tun ba oju oun.
Láàárin oṣù mẹ́ta yìí bàbá mi jẹun ó sanra, ẹ̀hin ọrùn rẹ̀ sì rì kọ̀- ǹgbẹ̀- kọǹgbẹ.
Àṣìṣe ló ṣẹlẹ̀ níbi ètò ìsìnkú Abba Kyari- FCTA Yewande bí'mọ tuntun jòjòló, Mercy Aigbe pàdánù èèyàn rẹ̀, Toyin Abraham fèsì lórí aṣoju NCDC Ìtàn Manigbagbe: Àwọn àjakalẹ-àrun to ti wáyé rí ṣáájú Coronavirus Nígbà tó ń fìdí ìṣẹ̀lẹ̀ náà múlẹ̀ fún BBC Yoruba, Alaga ẹgbẹ́ awakọ èrò ni Ipinlẹ Oyo, NURTW, tí ìjọba ti fofin de, Alhaji Abideen Olajide, tí gbogbo èèyàn mọ sì Ejiogbe, ṣàlàyé pé ẹgbẹ́ awakọ èrò kò lọ́wọ́ nínú rògbòdìyàn náà rara.
Obedi bí Jese, Jese sì bí Dafidi.
Nítorí Sẹ́nétọ̀ Adeleke, ìyá àti ọmọ gbé iléeṣẹ́ ọlọ́pàá lọ sílé ẹjọ́ Pọ̀nmọ́ olóró ni!
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Awọn ara orilẹede Sudan pe jọ niwaju olu ile iṣẹ awọn ologun lẹyin ti Minisita ọ̀rọ̀ abo, Ahmed Awad Ibn Auf kede pe oun fipo silẹ gẹgẹ bi olori ẹgbẹ ọmọ ogun to boju to gbigbe ijọba le ẹlomiiran lọ́wọ́ ni Khatourm, Sudan fun ajọyọ.
Kii ṣe pe boya tori o jẹ agbẹjọro tabi obinrin.
 gẹ ́ gẹ ́ bí ìtàn , obìnrin ni olówu .
Ọmọ́ Yorùbá korò ojú sí Buhari bí kò ṣe fi orúkọ Obasanjo sọ ibùdókọ̀ ojú'rin Irọ́ ni o, kò sí ẹ̀rí pé Hydroxychloroquine leè kojú àrùn Coronavirus- Ẹgbẹ́ àwọn adarí ilé ìwòsàn ní Naijiria Ìjọba Nàìjíríà kéde ìsinmi ọlọ́jọ́ méjì f'ọdún Iléyá Oríṣun àwòrán, others Àkọlé àwòrán, Rotimi Akeredolu sọ pé àṣìṣe nla ni yíyan Ajayi ní igbákejì òun Mo káàbámọ̀ pé mo yan Ajayi gẹ́gẹ́ bíi igbákejì mi- Akeredolu Rotimi Akeredolu sọ pé àṣìṣe nla ni yíyan Ajayi ní igbákejì òun Aṣiṣe nla gba a ti mo kabamọ ni bi mo ṣe yan Agboola Ajayi ni igbakeji mi.
entertain : v ; ( i don ' t entertain very oftern .
Ofin naa fihan pe, ojuṣe aigbọdọ ma se ni ki o maa ro eto idẹrun alajọgbepọ rẹ mọ ti ẹ.
O tenumo pe,“gbogbo ohun ti a ti se lo ti so eso rere bayii, ti o fi mo sise aseyori agbateru ipolongo iko agbaboolu Super Eagles ti yoo kopa ninu idije boolu agbaye, besini ti a tun ni iko agbaboolu meji ninu idije boolu afesegba tokunrin ati tobinrin torile-ede yii,” Ni ipari, alaga ayeye igbami-eye ohun, Philips Asiegbu so pe, titewo gba iko Super Eagles ati olokan-o-jokan atileyin ijoba ipinle naa ati awon ololufe re sokunfa sise aseyori ati jijawe olubori ninu ifigagbaga ipegede idije agbaye naa.
Iwadii BBC Yoruba fihan pe baba ọmọbinrin yii gan an ni pasitọ ṣọọṣi ọhun.
Laipẹ yi ni iṣẹlẹ kan waye nilẹ Gẹẹsi nibi ti ọmọ Naijiria kan ti fi ibinu fọ gilaasi ọkọ ileeṣẹ to n soju Naijiria nilẹ Gẹẹsi.
 baluclistan yìí ni ìpínlẹ ̀ ( province ) tí ó wà ní apá ìwọ ̀ -oòrùn jùní pakcstan .
"Ganduje àtàwọn èèkàn ìlú míì sàmì ogójì ọjọ́ tí Ajimobi dará ilẹ̀ ""Ìfẹ́ akọ sákọ àti abo sábo tó wọ́pọ̀ ní Àríwá Nàíjíríà ló fa ìbínú Ọlọ́run"" 'Àìjáfáfá àwọn panápaná ló mú kí ọṣẹ́ iná Akure pọ̀' Ó ṣe jẹ́ ṣọ́ọ́bù aláṣọ kanṣoṣo ni iná tí maa ń ṣẹ́yọ lọdọọ́dún lọ́jà Balogun?"
 ní àwọn ìgbà míràn , àwọn ènìyàn tí ó bá ní àìsàn ẹ ̀ dọ ̀ tí n jẹ ́ cirrhosis àìlera ẹ ̀ dọ ̀ parí-iṣẹ ́ , jẹjẹrẹ ẹ ̀ dọ ̀ , tàbí kí ó mú kí gògò-ń-gò àti ikùn wú bọ-bọ-ọ-bọ , èyí tí ó sì le yọrí sí sìsun ẹ ̀ jẹ ̀ tí ó mú ikú lọ ́ wọ ́ .
Bi o ti le je pe won
Ẹ jẹ́ ki a gbé oúnjẹ ilẹ̀ wa lárugẹ.
Wọ́n wá bi í pé, “Kí ló dé tí o fi ń ṣe ìrìbọmi nígbà tí kì í ṣe ìwọ ni Mesaya tabi Elija tabi wolii tí à ń retí?
A fẹ́ dá a lẹ́kun nítorí kì í ṣe ara wa.
O ni ko din ni ọlọpaa mẹtadinlọgbọn tawọn eeyan bii arabinrin Afọlakẹ ti kọlu lati igba ti ajakalẹ arun COVID-19 yii ti bẹrẹ, ọpọlọpọ ninu wọn lo si ti di ero ileewosan ninu eyi ti wọn ko tii bọ di bi a ṣe n sọrọ yii.
Nígbà tí àwọn àgbààgbà Israẹli lọ sọ fún Mose, 
Ẹnikan to ku jẹ ẹni to ko o lati ara ẹnikan to ti kọkọ ni i.
Ẹrúkẹ́rú tó bá ti dé ibùdó yìí kò tún padà sílé mọ́, ìpàdé di ọ̀hún ni.
Koda laarin eyi ọrọ igbimọpọ fẹ gbajọba eyi to n fa gbọnmi si omi o to laarin ijọba to wa lori oye ati ẹgbẹ oṣelu alatako, gbogbo eyi lo kun iṣoro orilẹede Zimbabwe.
Kii se igba akọkọ ree ti ẹnu yoo kun Sonko nitori ẹnu kii sin lara rẹ.
Oríṣun àwòrán, EPA Àkọlé àwòrán, Ọba Thailand n bu omi si ori aya'ba Suthida Niṣe ni wọn fi fọnran fidio igbeyawo wn han lori ẹrọ amohunmaworan orile-ede Thailand lọjọru nibi ti awọn ori ade ati ilẹkẹ peju sibẹ.
O ni ohun ibanujẹ lo jẹ fun oun wi pe awọn adigunjale gba ẹmi awọn eniyan aadọta to jẹ ọlọde, JTF.
" Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó Ọgbẹni Olaniyan ti sọ tẹlẹ ninu atẹjade kan ti oluranlọwọ rẹ lori eto iroyin, Omolere Omoetan fi sita pe, ojuṣe oun gẹgẹ bi igbakeji gomina ipinlẹ Oyo ni lati ṣiṣẹ pọ pẹlu Gomina Makinde.
Eyi ko sẹyin bi ikọ Liverpool ko se le e fakọyọ gẹgẹ bi ikọ ti wọn ko tii na fun igba mejidinlogun ni idije Premier League.
Ni owurọ ọjọ Aiku ni iroyin jade pe Seun da wahala silẹ nibi apejẹ kan lagbegbe Ikẹja to si tun fa ibọn yọ.
 Irọ́ ni Cameron pa mọ́ mi lórí ọ̀rọ̀ àwọn akẹ́ẹ̀kọ́ Chibok- Jonathan figbe ta Ìrọ̀rùn dé l'Ekiti!"
 ní àwọn agbègbè tí a tí ń fún àwọn ọ ̀ pọ ̀ lọpọ ̀ ènìyàn ní àjẹsára náà , ìwọ ̀ n ìtànkálẹ ̀ àrùn náà ti dínkù sí iye tó ju 90 % lọ .
    Nígbà tí ó dé tí ó jókòó lórí ìtẹ́, èmi wà lókèèrè nígbà tí ó jókòó tán, ó bẹ̀rẹ̀ ọ̀rọ̀ i sọ ó ni:
Tabi kí ni eniyan lè fi dípò ẹ̀mí rẹ̀?
Oríṣun àwòrán, iStock Àkọlé àwòrán, Àwọn ẹlòmíràn ò kí ń gbádùn ìbálòpọ̀ bí wọ́n ṣe fẹ́ pllú olólùfẹ́ wọn.
Kí oore-ọ̀fẹ́ Ọlọrun wà pẹlu yín.
Oríṣun àwòrán, Reuters Ẹni ti ko ni maa wa abala to jẹ buluu tabi pupa kiri ni orilẹede naa, amọ orilẹede Amẹrika nikan ni maa ma ri.
Mo sọ fun yín pé bí ẹ kò bá ronupiwada, gbogbo yín ni ẹ óo ṣègbé bákan náà.
Oríṣun àwòrán, Getty/AFP Àkọlé àwòrán, Ìrànlọ́wọ́ ti ń bọ̀ fún àwọn ti wọ̀n ha sínú ilẹ̀ níbùdó ìwakùsà Agbẹnusọ fún ibùdó ìwakùsà naa, James Wellsted sọ pe, ko si ẹ̀rí aridaju kankan pe ounkohun se ẹnikẹni ninu awọn awakusa naa, ati pe, wọn ti sagbékalẹ̀ ètò idanilẹ́kòó fun wọn ati awọn ẹbí onikaluku.
Mo tún rí angẹli mìíràn tí ń fò lágbedeméjì ọ̀run.
Ó ṣe fún gbogbo ẹ̀yin tí ẹ̀ ń gbé orí ilẹ̀ ayé nígbà tí kàkàkí tí àwọn angẹli mẹta yòókù fẹ́ fun bá dún!
Sugbọn ṣa, Islamic State tẹsiwaju lati da awọn ẹka silẹ ni India ati Central Africa.
Onímọ̀ kan ní fásitì Open University l'órílẹ̀-èdè Amẹrika, Ọ̀mọ̀wé Philip Seargeant, sọ pé ''ohun gbogbo ni àdínkù maa n dé bá pàtàkì rẹ̀ lórí ẹ̀rọ ayélujára.
Wọ́n pa ninu àwọn ọ̀gágun Dafidi, wọ́n sì pa Uraya ará Hiti náà.
7 2851670 Orilẹede Russia 63558 43.
Bí ọ̀sẹ̀ àkọ́kọ́ yóó ṣe rí rèé Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 3 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 5 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Lórí Covid-19, àdínkù iye àwọn tó lùgbàdì àrùn náà wáyé lọ́jọ́ mẹ́ta léra O ma tun ja wa silẹ ju ti tẹlẹ lọọ!
O ti to ọjọ mẹta bayii ti iporogan ti n waye laarin Oluwo tilu Iwo, Ọba Abduilrasheed Adewale Akanbi ati awọn afọbajẹ ilu naa.
Darma ni asiko re lati ṣe agbeyẹwo awọn afojusun Naijiria nipa iṣuna ọdun 2020.
Mo si setan lati lo ohun ati ipo mi lati ri pe, ko si omo ti won bi pelu aarun HIV lorile-ede Naijiria ti o ba fi maa di odun 2020”.
Owo iranwọ epo naa le kọ ibudo papakọ ofurufu to din diẹ niẹgbẹrin Ijọba apapọ fi to awọn oniroyin leti laipẹ yii pe wọn ti pinnu lati wo ibudo (terminal) papakọ ofurufu Murtala Muhammad to wa ni Ipinlẹ Eko.
O fi àwọn ẹṣin rẹ tẹ òkun mọ́lẹ̀;wọ́n tẹ ríru omi mọ́lẹ̀.
Adajọ naa ni pe orí àpèrè náà kò tọ́ síi.
Ìpín kan ti Sebuluni yóo wà lẹ́gbẹ̀ẹ́ ti Isakari, láti ìlà oòrùn títí dé ìwọ̀ oòrùn.
Ṣugbọn lọwọ yii, iye owo epo naa tun ti ja walẹ ju bi ijọba ṣe lero pe yoo ri lọ lati ọdun 2016.
Ibadan Tanker Fire Accident: Ṣúnkẹrẹ fàkẹrẹ gbalẹ̀ lẹ́yìn ìjàmbá ọkọ̀ epo
jẹ́ ọgbọ̀n ọ̀kẹ́ eniyan o le egbejidinlogun ó dín aadọta (603,550).
Bí ọwọ́ mi ṣe tẹ àwọn ìlú àwọn abọ̀rìṣà,tí oriṣa wọn lágbára ju ti Jerusalẹmu ati Samaria lọ,
Aare soro ohun di mimo ninu atejade ti amugbalegbe re pataki lori oro ifitonileti ati igbodegba, Garba Shehu gbe jade lojo abameta(Saturday), niluu Abuja.
Ẹgbẹ ọmọ Yorùbá kí Gomina Abiola Ajimobi kú oríire ọjọ́ ìbí
Àwọn tó wà níbi pàdé pàtàkì yìí tí wọ́n ṣe ní ìdákọ́nkọ́ ni Ààrẹ ẹgbẹ́ àwọn òṣìṣẹ́, ọ̀jọ̀gbọ́n Biodun Ogunyemi tó dári ikọ̀ náà.
Jesu dá a lóhùn pé, “Ẹ̀yin amòfin náà gbé!
Wo ọ̀nà tí o fi lè bọ́ lọ́wọ́ àrùn jẹ̀dọ̀-jẹ̀dọ̀ 'Hepatitis' Njẹ́ ẹ mọ̀ pé Trump kò tíì fi ìdí janlẹ̀ tán?
Oloye Obafemi Awolowo: Oloye Obafemi Jeremiah Oyeniyi Awolowo jọ ọkan pataki lara awọn to ja fitafita fun ominira orilẹ-ede Naijiria.
ilé ẹjọ́ tó ga jùlọ fòǹtẹ̀ lú gómìnà mẹ́rin Akẹgbẹ́ mi méjì kú, ọ̀pọ̀ farapa lọ́wọ́ agbébọn, orí ló yọ mi - Adebayor Makinde fẹ́ san ₦30,000 fáwọn òṣìṣẹ́ l’Oyo, yóò tún kọ́ ọjà ìgbàlódé sí Akẹ̀sán Iran ti jáwọ nínú ìlù ogun tó n lù -Trump Ikú òjijì kò jìnnà àmọ́ ọ̀nà méje rèé láti dènà rẹ̀ O ni bi oun ṣe n wo o, ọwọja ikọ alaabo naa yo rinlẹ daadaa paapaa julọ bi awọn ẹkun yoku ba lee wo awokọṣe rẹ.
Agbára ẹ̀rọ á sì máà dínkù síi titi agbára rẹ̀ ò fi ní ká iṣẹ́ tí a nfi ṣe dáadáa mọ́.
”Eleyii yoo waye lati din bi awon
ede Naijiria, se kuna  lati wa si ibi
Eni tii se alukoro ile iwosan UCH niluu Ibadan, Ogbeni Toye
Kí lo mọ̀ nípa fẹntilétọ̀, ohun èlò aṣèrànwọ́ èémí Èyí ni ìdí tí coronavirus ṣe n pa àwọn kan, tí kò sì pa àwọn kan Kínni ìtàkùn ayélujára 5G nííṣe gan na pẹ̀lú ààrùn coronavirus?
Tun yatọ si owo eyi, awọn alasẹ ilẹ Saudi tun sọ pe, aleekun ida marun yoo gori gbogbo nnkan ti awọn arinrinajo ba fẹ se lasiko Hajj ọun, sugbọn ti eyi ko mọ ounjẹ ati oogun rira.
ṣugbọn o kò gbọdọ̀ jẹ ninu èso igi ìmọ̀ ibi ati ire.
Eyi waye latari bi ijọba Naijiria ṣe ti sọ pe Amaju Pinnick ni oun da mọ ni Aarẹ ajọ to n mojuto bọlu gbigba ni Naijiria, NFF.
Wòlíì èké 'John of God' tó bá obìnrin 300 lò pọ́ gba ìdájọ́ ẹ̀wọ̀n ọ́dún 19 Ẹ má gbàbọ̀de kankan láti tú Wolii ìjọ Sotitobire sílẹ̀ o!
Ọba bá ranṣẹ pe Sadoku, alufaa, ati Natani wolii, ati Bẹnaya ọmọ Jehoiada, gbogbo wọ́n sì pésẹ̀ sọ́dọ̀ ọba.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Ìdáhùn àwọn olùdíje Ogun ṣọ̀tọ̀ọ̀tọ̀ lórí ẹ̀kọ́ ọ̀fẹ́' Kini o ṣokunfa igbeyawo awọn ọmọ ogun mejeeji?
Ẹ máa rìn bí ó ti yẹ láàrin àwọn alaigbagbọ, kí ó má sí pé ẹ nílò ati gba ohunkohun lọ́wọ́ wọn.
Orilẹ-ede China lo ti jade ni osu kejila, ọdun 2019 ti o si ti ran awọn eeyan to le ni miliọnu kan ati ẹgbẹrun lọna ọdunrun lọ sọrun.
Ẹ dúró jẹ́ẹ́, n óo sì fi ẹ̀sùn kàn yín níwájú OLUWA n óo ran yín létí gbogbo àwọn iṣẹ́ ìyanu ńlá tí OLUWA ṣe láti gba àwọn baba ńlá yín kalẹ̀.
O ni oun ṣe bẹẹ nitori bi ẹgbẹ́ agbesunmọmi to wa ni orilẹ-ede Naijiria, Boko Haram, ṣe ránṣẹ si oun.
Wọ́n gbé ibẹ̀ fún ọjọ́ bíi mélòó kan.
Iru awọn iroyin ti ẹ le nifẹ si: 'Fulani Ilorin l'ọkọ mi' ‘Ejo kọ lo mi 36m, Ọga mi lo gbaa’ Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí kan sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
Àwọn ìbejì Akeugbagold kò le rìn dáadáa mọ́ lẹ́yìn tí wọ́n dáwọn padà Ọọni, Aláàfin, Ojisẹ Ọlọ́run àti oniṣẹ ìwádìí fi Ògún gbari pé òògùn ìbílẹ̀ le wo Covid-19 Mo kábàámọ̀ pé n kò kàwé, kí n tó bẹ̀rẹ̀ iṣẹ́ tíátà - Sanyeri Ẹ wo àwọn gbajúmọ̀ òṣèré tíátà tó jogún eré ṣíṣe lọ́dọ̀ òbí wọn Nípìnlẹ̀ Rivers Kọmísọ́nà fún ètò ẹ̀kọ́ níbẹ̀ ọ̀jọ̀gbọ́n Kaniye Ebeku sọ fún BBC pé àwọn ò fi ọ̀rọ̀ ẹ̀kọ́ ṣeré rárá ìdí nìyí tí àwọn fi n ṣe ìdánilẹ́kọ̀ọ́ àpapọ̀ lórí redio àti telefísọ̀n fún akẹ́kọ̀ọ́ ipele kẹwàá àti àwọn tó fẹ́ kọ WAEC pẹ̀lú ìgbàgbọ́ pé Covid-19 ò ní pẹ́ kásẹ̀ nílẹ̀.
Ọjọ́ kẹtala ati ọjọ́ kẹrinla ni àwọn Juu tí wọ́n wà ní Susa pa àwọn ọ̀tá wọn, ní ọjọ́ kẹẹdogun, wọ́n sinmi, ó sì jẹ́ ọjọ́ àsè ati ayọ̀ fún wọn.
Àìbìkítà yíì gbọ́dọ̀ dópin, ìjọba gbọdọ̀ mú ẹ̀dùn ọkàn àwọn aráàlú lọ́kùnkúndùn- Agbẹjọ́rò Àgbà Wo àwọn kọ̀ndísàn tuntun tí àwọn olùwọ́de #ENDSARS gbé jáde lẹ́yìn tí wọ́n tú SARS ká Wo ìgbà mẹ́rin tí ìjọba ti tú ikọ̀ ọlọ́pàá SARS ká sẹ̀yín ṣùgbọ́n.
Nígbà tí wọ́n súnmọ́ Jerusalẹmu, tí wọ́n dé Bẹtifage ní Òkè Olifi, Jesu rán àwọn ọmọ-ẹ̀yìn meji lọ ṣiwaju.
Josẹfu sọ fún àwọn arakunrin rẹ̀ pé, “Àtikú mi kù sí dẹ̀dẹ̀, ṣugbọn Ọlọrun yóo máa tọ́jú yín, yóo sì mu yín jáde kúrò ní ilẹ̀ yìí, lọ sí ilẹ̀ tí ó ṣèlérí fún Abrahamu ati Isaaki ati Jakọbu.
Inu wa ko dun si eyi rara.
Ayọ̀ọlá: Á jẹ́ pé owó yín ti dé nì yẹn
Bakan naa ni Ọọni Ogunwusi tun ke sawọn agbaagba lorilẹede Naijiria lati ṣilẹkun silẹ fawọn ọdọ nitori, gẹgẹ bi o ṣe sọ, awọn lo ni orilẹede Naijiria.
Olorì Aláàfín tẹ́lẹ̀, Anuoluwapo Adeyemi gba àmì ẹ̀yẹ lórí ipa tó kó nínú oge ṣíṣe Wo iye ìgbà mẹ́rin tí ìtàkùn ìpínná ní Nàìjíríà ti dákú lọ́dún 2020 nìkan Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Yoruba Taboo: Èèwọ̀ ni fún ọba láti gbé Bibeli tabi Kurani dání dípò ifá- Elebuibon, Agẹṣin Àdìmúlà29 Bélú 2020 Yollywood: Lágbo tíátà lọ́sẹ̀ yìí, Toyin Abraham fi orin yẹ́ Iyabo Ojo sí níbi ìsìnkú ìyá rẹ̀, Òṣùpá fíi ìkíni ọjọ́ ìbí ránṣẹ́ sí Pasuma28 Bélú 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Nítorí nípa ìtọ́ni ọlọ́gbọ́n, o lè jagun,ọpọlọpọ ìmọ̀ràn níí sìí mú ìṣẹ́gun wà.
Ẹwẹ, oludije fun ipo aarẹ ẹgbẹ agbabọọlu Barcelona, Toni Freixa ti sọ pe ko si ṣiṣe ko si aiṣe, Messi o le duro mọ ni Barca.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Ìgbà tí mo máa fi lajú sáyé padà, ọ̀fọ̀ ikú mi ní wọ́n ń kígbe' Ṣaaju, ninu eeyan mẹẹdogun, Trichytee, Wathoni, Praise ati Vee ni ara ile mẹrin ti ibo wọn kere ju lati ita lọsẹ yii.
Ẹ ṣọ́ra kí omi maa gbẹ lára- Èyi láàrin ọjọ mẹ́ta si ọjọ Meje(Day 3-7) Bí ara ba ṣe ń gbàá pe ààwẹ ti n mọ oun lára, àwọn ọ̀rá ara a máá yíí si 'sgà inú ẹjẹ.
Kò náání ìgbì omi,kò bẹ̀rù bí odò Jọdani tilẹ̀ ru dé bèbè rẹ̀.
Ajọ Marie Stopes ni awọn n ṣiṣẹ papọ pẹlu ajọ NDA lati tete ṣe iwadii nkan to ṣẹlẹ si awọn ipele wọnyii ati ọna lati tun jẹ ki wọn daa sii.
Lẹ́yìn náà ni Riyad Mahrez gbábọ́ọ̀lù sí àwọn Watford.
Nítorí ọ̀ràn pé a kọlà tabi a kò kọlà kò jẹ́ nǹkankan fún àwọn tí ó wà ninu Kristi Jesu.
Baba wọn, Efuraimu, ṣọ̀fọ̀ wọn fún ọpọlọpọ ọjọ́.
"O ni ki wọn pe akọle eto tuntun naa ni ""The Big Nigeria Reality Show"" ''Eto naa yoo ma a ṣe afihan awọn ọdọ lorilẹ-ede Naijiria ti wọn n sisẹ ọwọ, awọn ọdọ akọṣẹmọṣẹ ati awọn oṣiṣẹ to wa ni awọn ẹka iṣejọba ni Naijiria, lọna ati le de ipele to gajulọ ninu iṣẹ ti wọn yan laayo."
Ìròyin sọ pe Aguti ni ọkùnrin to pọ̀ ninu àgbàlá náà sùgbọ́n o le gbogbo wọ́n nítori wọ́n o ni ìbáwí.
Iwe to fun mi jẹ alawẹ ọgọ́ta, ti wọn si pe akọle rẹ ni Ipagọ adura fun ọgbọn ọjọ.
Ẹjọ́ ẹ̀tọ́ níí dá fún talaka ati aláìní,ohun gbogbo sì ń lọ dáradára.
Awọn to n sọ ipinlẹ wọn di ogun ẹbi wọn Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Alapinni Oosa ṣàdúrà fún gogbo ọmọ kúoótù, oò jíire bí?
Àkọsílẹ̀ Àìsàn Pọ̀ Sí i Ní Osù Agẹmọ
Falowo gori itẹ gẹgẹ rẹ lọdun 2019 lẹyin ti baba rẹ papoda, oun ni yoo si wa lori oye titi ti awọn afọbajẹ yoo fi yan ẹni ti oye kan.
"Oríṣun àwòrán, Others Tí o bá ti ń gbọ́ tí ènìyàn ń sọ pé, ""ayé ti sú mi"" tabi Kí òpin ayé tíẹ̀ dá báyìí"", ara àmì pé ẹni náà le gba ẹ̀mi ara ẹni ni."
Ehín ẹnu rẹ̀ dà bí tí kìnnìún, ó ń pọ́n kankan: nítorí Ik’;u kò gbádùn iṣu bẹ́l ni kò gbádùn ọ̀gẹ̀dẹ̀, kò gbádùn ilé bẹ́ẹ̀ ni kò gbádùn ẹ̀fọ́, òun gbádùn ẹran ènìyàn ju ohun gbogbo lọ.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Omijé bọ́ níbi ìsìnkú Ogun Majek Eji Gbadero, ọmọ Ibadan àti jayé-jayé ọmọ ónílẹ̀ ti wọn yẹgi fun l'Eko Èyí ni àwọn arẹwà ‘ẹ̀lẹ̀ Daddy’, àfẹ́fẹ́ tí Aláàfin fi ń mí Mùjẹ̀-mùjẹ̀ ní Akinyele tún ti mu ẹ̀jẹ̀ obìnrin míràn lónìí Oyè adelé alága APC bọ́ lọ́wọ́ Ajimobi, Buhari fòǹtẹ̀ lu Giadom Ọkùnrin kan bá ọmọ oṣù mẹ́ta lòpọ̀, ìfun ọmọ tú jáde!
Èèyàn méjì kú, méjìdínlógóje míì ṣẹ̀ṣẹ̀ kó COVID-19 lọ́jọ́ Àìkú Ajọ to n gbogun ti ajakalẹ aarun lorilẹ-ede Naijiria, NCDC ti kede eeyam mejidinlogoje miran to kun iye awọn to ti ni aarun COVID-19 lorilẹ-ede Naijiria.
Nígbà tí ó jí ní òwúrọ̀ kutukutu ọjọ́ keji, tí ó sì fún irun aguntan náà, ìrì tí ó fún ní ara rẹ̀ kún abọ́ kan.
*Oṣu kẹfa, ọdun 2014: Nígbà tó tún di oṣù kẹfà, ọdún 2014 ni Lienchtenstein tún dá mílíọ̀nù lọ́nà okòólénígba àti méjì dọla ($227m) padà fún Nàìjíríà gẹ́gẹ́ bíi ara owó tí Sani Abacha jí kò lọ sókè òkun*Oṣu kẹjọ,ọdun 2014: Ileesẹ ètò ìdájọ́ ni orílẹ̀-èdè Amẹ́ríkà, ní ọjọ́ keje, oṣù kẹjọ ọdún 2014 kéde pé, owó tó tíì pọju nínú ìtàn orílẹ̀-èdè náà, tí àwọn yóò tíì dá padà ní mílíọ̀nù lọ́nà ọrinlenirinwo dola ($480m), Eyi tàwọn fẹ́ gbé fún ìjọba Nàìjíríà, tíì ṣe ara owó tí Sani Abacha fi ẹyin pọn wá si orílẹ̀ èdè awon*ọdún 2016: Orílẹ̀ èdè Switzerland náà fìdí rẹ múlẹ̀ pé, òun ti dá owó tó tó mílíọ̀nù lọ́nà okoolelẹẹdẹgbẹrin àti mẹta dọla ($723m) padà fún ìjọba Nàìjíríà lára owó tí Abacha jí kò, táwọn si gbé ẹsẹ le lọ́wọ́ mọlẹbi rẹ *Oṣu kejila, ọdun 2019: Oṣù Kejìlá, ọdún 2019 ni orílẹ̀-èdè Switzerland tún kéde pé, òun fe dá mílíọ̀nù lọ́nà Okoolelọọdunrun àti ẹyọ kan dọla ($321m) padà fún ìjọba Naijiria lati inu owó tí Sani Abacha ko lọ sókè òkun *Ọjọ karun un, oṣu karun un, ọdun 2020: Ìjọba Nàìjíríà kéde pé, òun tún ti gba owó tó lè díẹ̀ ni mílíọ̀nù lọ́nà okoolelọọdunrun ó dín mẹsan an dọla ($311,797,866m) míràn gba lọ́wọ́ ilẹ Amẹ́ríkà lára owó tí Sani Abacha ko lọ sókè òkun.
Ọbabinrin Ilẹ̀ Gẹ̀ẹ́sì àti Ọmọọba Harry yóò sèpàdé ní Ọjọ́ Ajé Naira Marley, Burna Boy àti Rema ló kó àmì ẹ̀yẹ tó pọ̀jù ló ni MVP Serena Williams gba ife ẹ̀yẹ àkọ́kọ́ láàrin ọdún mẹ́ta sẹ́yìn Wọ́n ti mu aṣojú ọmọ Britikó ní orílẹ̀-èdè Iran Kosọkọ tun rawọ ẹbẹ sijọba lati gbe owo kalẹ fawọn osere tiata.
Ki Ẹkùn tó bèrè ohun ti Ìjàpá nwa lo ti gbo oorun didun ohun ti Ìjàpá Ijapa gbe wa.
Àwọn tí kò ríṣẹ́ ṣe ló n ṣiṣẹ́ olùkọ̀ l'óde òní.
Ṣugbọn bí ó ti ń kìlọ̀ fún wọn tó, bẹ́ẹ̀ ni wọ́n ń ròyìn rẹ̀ tó.
A rán wọn láti ṣiṣẹ́ nítorí àwọn tí yóo jogún ìgbàlà.
Àwọn nǹkan mélòó kan wà tí ìrìn yẹ,àwọn nǹkan pọ̀ tí ìrìn ẹsẹ̀ wọn máa ń wu eniyan:
Wo ọ̀pọ̀ àsọtẹ́lẹ̀ igba tí Primate Ayodele gbé síta fọ́dún 2021 Gẹ́gẹ́ bí ìgbésẹ̀ tí àjọ CAN ń gbé, àwọn yóò fi àtẹjáde kan síta lónìí ọjọ́ ìṣẹ́gún láti sọ fún gbogbo àwọn ọmọ ẹgbẹ́ láti tẹ̀lé ǹkan ti ìjọba ìpínlẹ̀ wọ́n bá sọ.
Obìnrin mẹ́sà-án ní wọn ti fi tipá bálòpọ tí wọn sì fi ìyàwó àwọn Boko Haram séwọ̀n lọ́nà àìtọ́, pẹ̀lú ẹ̀rí pé àwọn márùn-ún àti ọmó wẹ́wẹ́ méjìlélọ́gbọ̀n ló ti kú.
@kingfreezy ni tirẹ fi aworan ọkunrin kan ti wọn fẹsun kan pe o fi ẹgbẹrun mẹwaa naira(10,000) ranṣẹ si ọrẹbinrin rẹ gẹgẹ bi owo ọkọ.
"Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fọ́nrán ohùn, iyonipo ""Oluwo yoo lọ pada sọ fun gbogbo agbaye to gbọ nigba to fiya jẹ mi pe asise gbaa ni oun se, oun si tuuba."
Ijẹgaba awọn eniyan Roshan ni wọn n ja lodi sí ninu ogun abẹle Sri Lanka.
Gbajabiamila sọ pe oun ba awọn mọlẹbi Ifeanyi kẹdun lori isẹlẹ naa.
Ẹgbẹ́ NLC n fẹ ki ijọba maa san ẹgbẹrun lọna ọgbọn naira gẹgẹ bi owo oṣiṣẹ to kere ju lọ, ṣugbọn awọn gomina sọ pe awọn ko le san ju ẹgbẹrun mejilelogun.
Ni gbogbo wọn bá ṣara gírí, àwọn náà bá jẹun.
Àwọn ọmọ ti Isakari ni: Tola, Pua, Jobu ati Ṣimironi.
Ijọba apapọ nipasẹ ileeṣẹ epo rọbi lorilẹede Naijiria, NNPC ti kede afikun owo epo lorilẹede Naijiria leyi to gbe owo ori epo bẹntiro soke sii.
Ordega ni mama oun sọ fun oun pe ko si ọkunrin to maa fẹ oun sile niwọn igba t'oun ba tẹsiwaju pẹlu bọọlu gbigba.
Olúkálukú ti mú àbùadà rẹ̀ lọ́wọ́ lọ ibiṣẹ́.
Bẹẹ si ni Iya Adodo ni ọpọ ojuse to n se ninu aafin, eyi ti asa Yoruba gbe le lọwọ.
Ọga ajọ INEC for eto idibo gomina ipinlẹ Edo, Ọjọgbọn kpofure Rim-Rukeh lo kede Obaseki gẹgẹ bi ẹni to wọle ibo ọhun.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Ọpọ awọn ọmọ ẹgbẹ oṣelu Republican gan an to jẹ ẹgbẹ oṣelu Trump papaajulọ awọn to kawe gan an ko nifẹsi si bi o ṣe n sọrọ sawọn ẹya mii yatọ si awọn alawọ funfun l'Amẹrika.
pelu won ati ile ise to n ri si eto ilera ati eto eko lorilede Naijiria , amosa
Nígbà tí ọkùnrin yìí di olówó tán ó pinnu àti máa fẹ́ obìnrin lé orí obìnrin, ṣùgbọ́n ìyàwó tí ó kọ́ fẹ́ kò lẹ́wà, ẹsẹ̀ rẹ̀ méjèèjì kò dára, arọ ni; ó fẹ obìnrin náà níttorí pé ọmọ ọba ní í ṣe bẹ́ẹ̀ ni ìlara obìnrin yìí ní ó pọ́ ju tí gbogbo obìnrin tí ńbẹ nínú ayé lọ.
Gbogbo ẹni tí ó bá wà láàyè, tí ó bá gbà mí gbọ́, kò ní kú laelae.
Abrahamu sọ fún iranṣẹ rẹ̀ tí ó dàgbà jù ninu ilé rẹ̀, ẹni tí í ṣe alákòóso ohun gbogbo tí ó ní, pé, “Ti ọwọ́ rẹ bọ abẹ́ itan mi, 
Ọkan lara wọn ni Babatunde Olatunji, eleyii ti Ajafẹtọ ọmọniyan, Opal Tometi to jẹ adari ikọ ''Black Lives Matter'' sọ wi pe wọn jẹ iwuri fun oun ni aye ode oni lati tako ẹlẹyamẹya ati ifiyajẹni nitori awọ ara eniyan.
Àwọn ẹni meji yóo wà ní oko, a óo mú ọ̀kan, a óo fi ekeji sílẹ̀.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ẹ̀mí sùn níbi ìkọlù Shiite àti ọlọ́pàá Bakan naa ni ọga ọlọpaa naa kilọ fun awọn ara ilu lati ye e gbe iroyin ofege, ti o le da ibaṣepọ ati alaafia orilẹ-ede Naijiria jẹ.
Ibadan-Ilesa Road: Àwọn olè Fulani ló ń jí ènìyàn, pànìyàn ní lọ́nà Ibadan sí Ileṣa
Ìgbà tí mo jí tí mo rọ́ àlá mi yìí fún àwọn ènìyàn mi, wọ́n ní àlá burúkú ni, wọ́n ní bí mo ti rí i tí a jọ ń gbé lójú àlá kò dára, èyí nì ni pé a kò ni jọ gbé pọ̀ bí tọkọtaya.
Nítorí bí a bá yí ètò iṣẹ́ alufaa pada, ó níláti jẹ́ pé a yí òfin náà pada.
Se ni òkìkí kàn pé ẹnìkan ti pa abukẹ́ Ọba.
Oríṣun àwòrán, Other Àkọlé àwòrán, Aworan aṣofin Braimoh lasiko ti Gomina Babajide Sanwoolu ṣabẹwo si mọlẹbi aṣofin agba Adebayo Osinowo to papoda Gẹgẹ bi mọlẹbi rẹ kan to fi idi isẹlẹ naa mulẹ ti wi, idaji aarọ ọjọ Ẹti oni ni asofin naa tẹri gbasọ, ko si tii si ẹni to lee fi idi ohun to ṣokunfa iku rẹ mulẹ.
Ejiogbe ni owo ẹgbẹ NURTW lawọn fi kọ ile ẹgbẹ NURTW ti ti Auxiliary n yi ọrukọ pada si PMS.
Wọn yabo ile naa lọna aitọ lọjọ Iṣẹgun nilu Abuja nigba ti Aarẹ Buhari wa ni orileede China .
Bí èmi ti rí i sí ni pé,ẹni tí ó kọ ẹ̀ṣẹ̀ mọ́ ebè,tí ó sì gbin wahala,yóo kórè ìyọnu.
Ọgbọ́n ni o fi dá gbogbo wọn.
Èmi ni mo dá ayé,tí mo dá eniyan sórí rẹ̀.
Nígbà náà ni n óo sọ ohun tí ó wà ní ọkàn mi.
Inu bi mi, nitori pe apejẹ naa ṣe pataki si mi pupọ.
aládùúgbò náà yóo lọ sí ilé Ọlọrun, yóo sì fi OLUWA ṣẹ̀rí pé òun kọ́ ni òun jí ẹran tí wọn fún òun sìn.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Rashidi Ladoja: Nígbà tí Ajimobi fìdí rẹmi ló ṣẹ̀ṣẹ̀ yan àwọn akọ̀wé Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Rashidi Ladoja: Nígbà tí Ajimobi fìdí rẹmi ló ṣẹ̀ṣẹ̀ yan àwọn akọ̀wé 16 Òkùdu 2019 Gomina ipinlẹ Oyo tẹlẹ ri Oloye Rashidi Ladoja ni nigbà tí Ajimobi ń lọ ló ṣẹ̀ṣẹ̀ kó àwọn akọwe tuntun jade fun ifẹ inu ara rẹ.
Pẹlu ọkọ oju omi ati ọkọ ofurufu ni awọn ologun bọ si igboro lati ran awọn eniyan lọwọ.
Ilé Israẹli tabi àwọn ọba wọn kò ní fi àgbèrè ẹ̀sìn wọn, ati òkú àwọn ọba wọn ba orúkọ mímọ́ mi jẹ́ mọ́.
orile ede Naijiria yoo ma se ayẹyẹ ajọyọ 
Ìdáhún àtàwọn ìbéèrè míì Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Mercy Aigbe, Lateef Adedimeji, Ayoola Ayolola kó sọ́wọ́ ìbéèrè kàbìtì, ó di gbọin!
Ìjọba Amẹrika fi ojú àwọn ọmọ Yahoo mẹ́fà léde, wọ́n gbẹ́sẹ̀ lé dúkìá wọn Gómìnà márùn ún tó fojú winá ìbínú bàbá ìsàlẹ̀ wọ̀n Ìdí rèé tí ilẹ̀ Afirika fi gbọdọ̀ kópa nínú dídán abẹ́rẹ́ coronavirus wò Ṣé lóòtọ́ ni Sẹ́netọ̀ Bayo Osinowo ní ìfura ikú ara rẹ̀?
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Nigerian Army: Awọn agbẹbọn pa ọ̀gágun tẹ́lẹ̀ Alex Badeh 19 Ọ̀pẹ̀̀ 2018 Oríṣun àwòrán, Nigerian Army Àkọlé àwòrán, Iku pa oga ologun Iku ogun nii pa akinkanju, iku odo ni pa omuwẹ.
Ọpọlọpọ irú nǹkan bẹ́ẹ̀ ni ẹ tún ń ṣe.
Awọn ọlọpaa ni Jardim Taquari fidi ọrọ naa mulẹ fun BBC wi pẹ wọn gun Sandra lọbẹ lọrun pa ni.
Gbogbo akitiyan wa lati ba minisita eto iroyin ati aṣa, Oloye Lai Mohammed sọrọ lo jasi pabo.
OLUWA da jìnnìjìnnì bo gbogbo àwọn orílẹ̀-èdè tí wọ́n yí Juda ká, wọn kò sì gbógun ti Jehoṣafati.
Ní ọjọ́ keji, wọ́n yípo ìlú náà lẹ́ẹ̀kan, wọn sì pada sinu àgọ́ wọn.
Atẹjade ọhun fikun pe aayan ti n lọ lati mu awọn afurasi ọdaran to sisẹ ibi ọhun.
Saulu sì rán wọn pé kí wọ́n sọ fún Dafidi pé, “Ọba kò bèèrè ẹ̀bùn igbeyawo kankan lọ́wọ́ rẹ ju ọgọrun-un awọ orí adọ̀dọ́ àwọn ará Filistia, gẹ́gẹ́ bí ẹ̀san lára àwọn ọ̀tá ọba.
Oun si ni ọmọ ilẹ America akọkọ to gba bọọlu sinu àwọn ni aṣekagba idije FA Cup.
"Ọjọ kọkandinlogun, oṣu Igbe (April), ọdun 2007 Ninu iwe rẹ ti akọle rẹ n jẹ ""The New Millenium"" eyi to kọ lọdun 1990, Pat Robbertson sọtẹlẹ pe ọjọ ikẹyin laye yii yoo jẹ ọjọ kọkandinlogun, oṣu kẹrin, ọdun 2007 ṣugbọn iyẹn gan an tun kuna."
Ile akede Naijiria (Voice of Nigeria) ni eka ede Yoruba ti bere igbohun safẹfẹ lati ilu Abuja.
Gege bi o se so,o ni lọdun to n bo orile ede naa lee foju wina ida mejo ninu ogorun lori  owo goboi ti awon eniyan yoo maa na lori eto oro aje ati okoowo.
Ìpàdé òru jẹ́ ìpèníjà f'àwa aṣòfin obìnrin -Hon Tomomewo School Boy ni oun fẹ dabi Davido ati Olamide ni.
Ṣé kò ní gbẹ patapata nígbà tí afẹ́fẹ́ ìlà oòrùn bá fẹ́ lù ú?
Marshall Islands Marshall Island to wa ni erekusu okun Pacific naa ko ni akọsilẹ aarun covid-19, bo tilẹ jẹ pe coronavirus ṣakoba fun ọrọ-aje ti wọn naa.
Emir ni iroyin kan lo gbe igbesẹ naa lati ipasẹ ẹgbẹ awọn ọdọ nilu Ilori, to da si aawọ naa.
” A wá pè é ní ọ̀rẹ́ Ọlọrun.
Ogun: Ọjọ kọkandinlogun ti ile igbimọ asofin ipinlẹ Ogun bẹrẹ asaro lori ikọ abadofin amọtẹkun ni wọn buwọlu.
 “Inu mi dun si awon ohun ti o n sele ni oja-idokowo lowo-lowo, eyi je anfaani nlanla fun awon oludokowo lati kowo lori oja idokowo naa.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Pius Adesanmi: Ìdílé ọ̀jọ̀gbọ́n tó kú níjàmbá Ethiopian Airlines ló ilé ẹjọ́ 8 Òkùdu 2019 Àkọlé àwòrán, Pius Adesanmi: Awọn ọmọ Nàìjíríà ń ṣelédè lẹ́yìn akọni Gbogbo ọmọ Naijiria ṣe ìdárò ọjọgbọn Adesanmi Idile oloogbe Pius Adesanmi, ọjọgbọn ọmọ Naijiria to ku sinu iṣẹlẹ ijamba ọkọ ofurufu Ethiopian Airlines (ET302) to waye ni oṣu kẹta ti gbe ileesẹ to n ṣe ọkọ ofurufu Boeing lọ ile ẹjọ.
Sikilagi, Beti Makabotu, ati Hasari Susa; 
Ẹ̀yin ará Media, ẹ múra ogun!
" Tinubu kò ṣékú, kò ṣé ẹyẹ, o n dibọn ní lórí ọ̀rọ̀ ikọ̀ Amotekun - Fani Kayode Àwọ́n kan ń ràgà bo Diezani nílẹ̀ Gẹ̀ẹ́sì láti jẹ́jọ́ ní Nàíjíríà àmọ́ á gbe wá - EFCC Sanwo-Olu pèsè ìpàgọ́ tó wà ní Igando fáwọn tí iná jólé wọn ní Abule Egba láti gbé Mọ̀ síi nípa ǹkan tí o lè ṣe láti dènà ibà Lassa Olori ikọ Dawn commission fikun pe, wọn yoo se idanilẹkọ fun awọn osisẹ Amọtẹkun, paapa ọna ti wọn yoo tete maa gba fura ati lori eto ibaraẹnisọrọ, isẹ ọtẹlẹmuyẹ, sise idamọ awọn agbegbe ti iwa ọdaran sodo si julọ ati itati were si iwa ọdaran.
Nígbà tí Dafidi gbọ́ ohun tí ó ṣẹlẹ̀, ó ní, “OLUWA mọ̀ pé, èmi ati àwọn eniyan mi kò lọ́wọ́ sí ikú Abineri rárá, ọwọ́ wa mọ́ patapata ninu ọ̀ràn náà.
o ṣalaye iru oju ti ọrẹ meji fi wo ọkunrin kan ti wọn pade ti ọkan fi oju tẹmbẹlu rẹ amọ oun gan lo pada n wa lati fa oju rẹ mọra tori owo Wo ìgbà márùn ún tí Buhari ti rìnrin àjò lọ sókè òkun fún ìtọ́jú ara rẹ̀ Mo ṣetán láti dojú ìjà kọ ẹnikẹ́ni tó bá fẹ́ bá ọ̀rọ̀ ajé Eko jẹ́- Sanwo Olu Sanwo-Olu buwọ́lu ìgbésẹ̀ ìjọba láti tún Eko ṣe lẹ́yìn rògbòdìyàn EndSARS Bí àwọn kan tí ń ní àtimọ̀lé tí wọ́n sọ olorin Nazir sí ní Kano ni ọwọ́ kan òṣèlù ní àwọn mii ní.
 Nibi akanṣe eto ṣiṣe afihan iṣẹ ọna ka to waye l'Eko, awọn ọdọ lo wọ pọ nibẹ to fi mọ ọmọ ọdun mẹrindinlogun kan ati awọn obinrin ti BBC Yoruba ba sọrọ."
Wọ́n ń lé wọn lọ tete títí dé Gidomu, wọ́n sì tún pa ẹgbaa (2,000) eniyan ninu wọn.
 ní ìgbà kàn-aǹ kàn a lè maa rí àmì .
Iyamọpo ni akinkanju obinrin to gba awọn eniyan Oyo silẹ lọwọ ogun fulani nigba naa.
41 Àti pé ẹ̀yin gbọ́dọ̀ wàásù fún ayé, ní sísọ pé: Ẹ gbọ́dọ̀ ronúpìwàdà kí a sì ṣe ìrìbọmi fún yín, ní orúkọ Jésu Krísti;
Wo iye àwọn tó ní ìbálòpọ̀ lórí ètò BBNaija 2020 tó n parí lónìí Oríṣun àwòrán, @BBNaija/twitter Oni lonii jẹ, ẹni a bẹ lọwẹ.
"Ninu idahuin rẹ si ibeere awọn eeyan lori eto naa, Kwam 1 ni ""Lati kekere ni mo ti n sapa lati ri pe Naijiria tẹsiwaju, bẹrẹ lati adugbo ti mo n gbe titi de ilẹ okeere, idi niyẹn ti mo ṣe n ba awọn oloṣelu ṣepọ, mo n bawọn sọrọ, wọn si n tẹti si imọran mi."
Nitori ajakalẹ arun coronavirus, ko si ẹyọ horo ololufẹ ẹgbẹ agbabọọlu naa kankan ni papa iṣire naa gẹgẹ bi o ti ṣe maa n ri.
N kò fetí sí ọ̀rọ̀ àwọn olùkọ́ min kò sì gba ti àwọn tí wọn ń tọ́ mi sọ́nà.
Adura mi ni pé kí àjọṣepọ̀ tàwa-tìrẹ ninu igbagbọ lè ṣiṣẹ́, láti mú kí òye rẹ pọ̀ sí i nípa gbogbo ohun rere tí a ní ninu Kristi.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù coronavirus: Ìdí tí obìnrin fi leè rù ú là ju ọkùnrin lọ 8 Ẹrẹ̀nà 2020 Oríṣun àwòrán, Getty Images O n dabi ẹni pe o ṣeeṣe fun ọkunrin lati ku lọwọ arun Coronavirus to n ja nilẹ bayii ju awọn ọkunrin lọ.
Lara awọn ilana naa ni pe, wọn gbọdọ fi eroja ti ko le jona kọ ibi ti wọn ba fẹ ẹ ko si, ko si gbọdọ si nkan to jọ gọta, ọpa to n gbe nkan, tabi awọn ọna miran ti o le ṣan si.
Ọkunrin kan wà tí orúkọ rẹ̀ ń jẹ́ Jobu; ó ń gbé ilẹ̀ Usi, ó jẹ́ olódodo ati olóòótọ́ eniyan, ó bẹ̀rù Ọlọrun, ó sì kórìíra ìwà burúkú.
O fẹ iyawo kan, o si bi ọmọ mẹrin.
Wọn yóo pe orúkọ mi, n óo sì dá wọn lóhùn.
Ade Love to ni awọn ọmọ bii mẹrin to n ṣe ere tiata bayii, Kunle, Aremu, Gabriel ati Moji Afolayan, lo gbe ọpọ sinima jade, ko to jade laye.
O fi kun un wipe ki gbogbo awọn oṣiṣẹ alaabo yii pata gba gbogbo igboro kan ki wọn si ri i daju pe alafia jọba lawọn ibi ti iṣẹlẹ idigunjale yii ti ṣọṣẹ.
Ohun tí a mọ̀ nìyí nípa àwọn tí yóò láǹfàní àti lọ sí Hajj lọ́dún yìí Ènìyàn 675 ni èsì àyẹ̀wò sọ pé ó tún ṣẹ̀ṣẹ̀ ní Covid-19 ní Nàìjíríà Ìjọba Nàìjíríà ránṣẹ́ pe aṣojú Ghana lórí ilé Nàìjíríà tí wọ́n wó lulẹ̀ ní Ghana Ìlú kan rèé l'Abuja tí kò mọ̀ rárá nípa Covid-19 Ni bayii, awọn olukọ nikan yoo wọle pada lọjọ kọkandinlọgbọn oṣu kẹfa nigba tawọn akẹẹkọ kan yoo wọlẹ pada lẹyin ọṣẹ kan tawọn olukọ wọn ba ti wọle tan.
Ejò lé àwọn aṣòfin ìpínlẹ̀ Ondo kúrò nípàdé Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Ṣílẹ̀kùn rẹ, ìwọ ilẹ̀ Lẹbanonikí iná lè jó àwọn igi kedari rẹ!
Ni afikun un si iku Khashoggi, ile Washington fesun kan awon asofin ile Amerika fun sise atileyin fun iko omo ogun ile Saudi Arabia ninu ogun ile Yemen.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Wọn o fi ọdun mẹwaa gbe ile aye síi ju awọn ti kii ba ṣe awọn nkan ti a ti mẹnu ba lọ.
”Lẹsẹkẹsẹ, ó fẹ́rẹ̀ ma tíì dákẹ́ ọ̀rọ̀ tí ó ń sọ, àkùkọ bá kọ.
Solar Power Naija: Ṣe lóòtọ́ ní ọmọ Nàíjíríà mílíọ́nù 25 yóò má ló ìná Solar látí Dec 1, 2020?
Ọkọ̀ aképo gbiná ní òpópónà Eko sí Badagry Ọkọ̀ ojú irin pa ènìyàn mẹ́rin ní Eko Lagos Building Collapse: Ìjọba ìpínlẹ̀ Eko gbé ìgbìmọ̀ olùwádìí kalẹ̀ O ṣalaye pe igbakuugba ti ojo ba ti rọ, adugbo naa kii ṣe ohun tẹnu le sọ rara nitori fọfọ ni gbogbo ilẹ yoo kun fun omi, ẹrọfọ ohun idọti to bẹẹ ti eeyan ko ni mọ ibi aa tẹsẹ bọ.
Nítorí náà, OLUWA Ọlọrun Israẹli ni ó gba ilẹ̀ náà lọ́wọ́ àwọn ará Amori fún àwọn ọmọ Israẹli.
Oríṣun àwòrán, @GovUmarGanduje Iroyin to tẹwa lọwọ so pe Oludasilẹ iwe Iroyin Daily Nigeria ọhun kọ lati jẹwọ ẹni to fi fidio owo gbigba naa sọwọ si i.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Yorùbá dùn lédè, sáré pé gbólóhùn yìí wò tóo bá dá ara rẹ lójú Lara awọn afurasi ti wọn fi orukọ wọn lede ni Richard Uzuh, ti wọn fẹsun kan pe o ma n kọwe ranṣẹ si awọn eeyan bi pe ọga ileeṣẹ nla kan lo n kọwe si wọn lọna ati gba owo lọwọ wọn.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Rape: Oluwaseun Osowobi ní Commonwealth fún lámì ẹ̀yẹ ọ̀dọ́ tó pegedé jùlọ ní 2018 Adajọ Samuel Bola sọ wipe, iwadi ti wọn se lara oku oloogbe naa fi han wipe, ọrùn ọmọdebirin naa ti wọ́ ati wipe olujẹjọ naa ti fi nkankan fọ ọ lori.
Wọ́n sọ fún un pé, “Ǹjẹ́ o mọ̀ pé Baalisi, ọba àwọn ọmọ Amoni ti rán Iṣimaeli, ọmọ Netanaya pé kí ó wá pa ọ́?
Bí ó bá jẹun mumi tán, á ní kó máa lọ
Ó dúró fún ẹ̀ṣẹ̀ àwọn eniyan jákèjádò ilẹ̀ yìí.
Oríṣun àwòrán, @olafare Àkọlé àwòrán, Bi a ba se ni looore, ọpẹ laa da nilẹ Oodua Wo ìdí tí àwọn obìnrin kan fi n yọ ilé ọmọ wọn kúrò Egypt dá akọ́nimọ̀ọ́gbá Aguirre dúró lẹ̀yìn ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ Èyí ni ọ̀nà tí àwọn obìnrin n gbà kó ara wọn sí wàhálà nítorí ara bíbó Àǹfàní n bẹ́ fun Naijiria nínú àdéhùn okòwò ní Afrika, AfCFTA ṣugbọ́n.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Taye Currency ní ọmọ ibàdàn tí Saheed Oṣupa jẹ́ kò lè já òun gbà lẹ́yìn Pasuma 29 Èrèlè 2020 Oríṣun àwòrán, Taye currency Ṣe ẹ mọ wi pe ọmọ ilu kan naa ni Saheed Osupa ati Taiwo Akande Adebisi ti ọpọ mọ si Taye Currency?
 ní orí kìn-ín-ní ni a ti sọ ìtàn orírun Ìṣẹ ̀ -Èkìtì .
Bi awọn ipin ipele komẹsẹ o yọ idije champions league fun saa 2020/21 yoo ṣe lọ niyi: Igba akọkọ niyi ti Messi ati Ronaldo yoo maa forikori lati igba ti Ronaldo ti fi Real Madrid silẹ lọ si Juventus.
O gba awon omo egbe n'iyanju pe ki won ma ba enikankan ja.
Ẹsun ti wọn fi n kan an ni pe, iṣẹkiṣẹ lo ṣe si ọyàn ati ìdí ti awọn ni ko ba wọn tun ṣe.
Abiramu àkọ́bí rẹ̀ ọkunrin kú, nígbà tí Hieli fi ìpìlẹ̀ ìlú Jẹriko lélẹ̀.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ifigagbaga fun ipo alaga gb oselu ANC kun ara ohun to fa ipinya laarin Ramaphosa ati Zuma Ni ọdun 1952 ni wọn bii ni Soweto ni ilu Johanesborg ki o to di wipe wọn fi si atimọle laarin ọdun 1974 sin ọdun 1976 fun oniruru ẹsun diditẹ mọ ijọba alawọ funfun.
Sugbọn ori baa se, iwa palapala yii ko se idiwọ fun ẹkọ rẹ, o gba oye imọ ijinlẹ akọkọ ati ikeji, to si tun ri isẹ gidi lorisirisi lati se, bẹẹ lo di akọsẹmọsẹ agbohunsafẹfẹ lori redio, Amọ oogun oloro to n mu yii lo papa le lẹnu isẹ nigba ti iwa rẹ ko ba taye mu.
Ìtàn tilẹ sọ pe adugbo Ajegunle nilu Eko ni awọn ọdọmọkunrin kan ti bẹrẹ ẹgbẹ naa lọdun diẹ sẹyin.
Ọkunrin ọhun ṣo pe ki Salawa fun oun lowo, bi bẹ kọ, oun yoo fi aworan ihoho Salawa lede fun gbogbo agbaye lati ri.
Agbábọ́ọ̀lù Super Falcons tẹ́lẹ̀, Chiejine jáde láyé lẹ́ni ọdún 36 FRSC dá N443,180 padà fún ẹbí ẹni to ní ìjàmbá mọ́tò Leon van Biljon dí èrò ọrun nípasẹ̀ Kìnìún rẹ̀ Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Akomolede ati Asa: Mọ̀ si nípa àwọn ọ̀nà tí Yorùbá ń gbà ran ara wọn lọ́wọ́ Ninu ọrọ rẹ, Iyalode Ogundoyin ṣe apejuwe Iyalajẹ to doloogbe naa gẹgẹ bi iya rere to duro ni ipo iya fun ọpọlọpọ eniyan.
Dafidi bá dáhùn pé, “Mo ti ṣẹ̀ sí OLUWA.
Bakan naa, minisita so pe aheso oro ni pe ijoba se adehun to monyan lori pelu egbe yii.
 teletele o je ibi-abo britani to unje beshuanalandi , botswana gba oruko tuntun leyin ominira ni ojo 30 osu kesan 1966 .
Ẹ ṣọ́ra fún ayédèrú ìròyìn, mi ò pe Buhari ní alákatakítí ẹ̀sìn láéláé- Tinubu ṣàlàyé Oríṣun àwòrán, Twitter/Muhammadu Buhari Ẹ ṣọra fun iroyin ofege, emi o pe aarẹ Muhammadu Buhari ni alakatakiti ẹsin, eekan ninu ẹgbẹ oṣelu APC, Bola Tinubu lo sọ bẹẹ.
N óo bínú sí Pelusiumu, ibi ààbò Ijipti, n óo sì pa ogunlọ́gọ̀ àwọn tí ń gbé Tebesi.
Ìta ni a óo gbé òkú rẹ̀ jù sí, oòrùn yóo máa pa á lọ́sàn-án, ìrì yóo sì máa sẹ̀ sí i lórí lóru.
Oun naa ni ko dara to bi ijọba Naijiria ba bu ẹẹkẹ diwọ nipa bi wọn se n kọlu awọn ọmọ Naijiria ni South Africa, to si n rọ awọn alasẹ wa lati tete sọrọ sita.
Ìgbà tí a dé aarin ọjà, gbogbo ìbẹ̀ ń rùn ni, kò dàbí ẹni pé ẹnikẹ́ni gba aarin ọjà náà rí.
Kíni ọ̀hún dàbí ìwé ṣùgbọ́n tí wọn kò kọ nkankan sí.
kí wọ́n baà lè pa ọ́ mọ́,kúrò lọ́dọ̀ alágbèrè obinrin,ati kúrò lọ́wọ́ onírìnkurìn pẹlu ọ̀rọ̀ dídùn rẹ̀.
"Ayefẹlẹ bá BBC sọ̀rọ̀ lórí ilé orin rẹ̀ tí Ajimọbí ń tún kọ́ Ajimobi fẹ́ di ‘Jagaban‘ tí ìpínlẹ̀ Oyo - Ladoja ""Mo máa wá nǹkan ṣe sí ilé Ayéfẹ́lẹ́ tí mo wó"" Ilẹ ẹjọ fagilé ìbò ọmọ ẹgbẹ́ APC nípinlẹ̀ Ogun pè kí àtúndì ìbò wà Sẹnetọ naa sọ ọrọ yi nigba ti o n ba awọn akọroyin sọrọ lẹyin aṣeyọri rẹ nilu Ibadan Saaju ni Ile ẹjọ to n gb'ẹsun idibo ni agbegbe Iyaganku niluu Ibadan ti wọgile ẹjọ ti gomina tẹlẹri ni ipinlẹ Ọyọ Ṣẹnetọ Isiaka Abiọla Ajimọbi."
Akọroyin mẹsan lo ku ni iṣẹlẹ kan ṣoṣo ni Kabul, lẹyin ti wọn lọ kọ iroyin nibi ti ado oloro kan ti bu gbamu.
Oríṣun àwòrán, Others O wa fikun pe Kọmisana ọlọpaa fun ipinlẹ Ogun, Edward Ajogun ti pasẹ pe ki wọn se ẹkunrẹrẹ iwadii nipa awọn afurasi naa.
Farao dáhùn, ó ní, “N óo fún yín láàyè láti lọ rúbọ sí OLUWA Ọlọrun yín ninu aṣalẹ̀, ṣugbọn ẹ kò gbọdọ̀ lọ jìnnà; ati pé, mo fẹ́ kí ẹ bá mi bẹ Ọlọrun yín.
Kọmisọnna fun eto ẹkọ nipinlẹ naa, Ọjọgbọn Badamasi Lawal lo sọ bẹẹ pe awọn ṣi n ṣe agbeyẹwo bi eto ẹkọ yoo ṣe ri ni Naijiria lasiko arun Coronavirus yii.
" bákan náà , èdè wọn hàn nínú orúkọ oyè ọba wọn "" Ọọ ̀ ni "" ."
Ẹyin ẹ tẹti leko o lori bi o ba ṣe n lọ ni ile ẹjọ naa loni.
Ninu ọrọ rẹ naa lo ti tẹsiwaju pe, ero orilẹ ede naa ni lati rii wi pe iwe ofin igbelu yoo fẹsẹmulẹ laipẹ ki opin le deba iwọlewọde lọna aitọ.
Nítorí ohun tí o wí nípa èrè iṣẹ́ ọwọ́ eniyan,mo ti yàgò fún àwọn oníwà ipá.
Ẹ̀wẹ̀, àwọn olùkọ́ni náà gbàgbọ́ pé ìpàdé mìí tí wọ́n yóò ṣe lọ́sl tó mbọ̀ yóò so èso rere eléyìí tí mínísítà fúnrarẹ̀ yóò wà níbẹ̀.
Ero wa gẹgẹbi osisẹ ileesẹ BBC Lasiko taa bẹrẹ si ni ko eroja jọ fun ifilọlẹ oju opo BBC, ohun kan to se pataki taa se akiyesi rẹ ni pe ara awọn araalu n ya gaga lati ba wa sọrọ nitoripe ileesẹ agbohunsafẹfẹ BBC la ti wa.
Ọpọ ọmọ Naijiria lo n na owo tarawọn lori ilera lawọn ile iwosan.
OLUWA ni ọba lae ati laelae.
’Gbogbo àwọn ọjà rẹati àwọn tí ń wa ọkọ̀ rẹ ti rì pẹlu rẹ.
Ogun naa bẹrẹ nitori ikunsinu lori ọrọ oṣelu, ọrọ aje, ẹya, àṣà, ati ẹsin to ti wa nilẹ ṣaaju ki orilẹ-ede Britain to o tu Naijiria silẹ l'oko ẹru lọdun 1960.
Òkúta mabu pupa ati aláwọ̀ aró ni wọ́n fi ṣe gbogbo ọ̀dẹ̀dẹ̀, tí gbogbo wọn ń dán gbinringbinrin.
Kano deaths: Èèyàn méjì míràn kú nítorí àrùn Coronavirus ní Kano Oríṣun àwòrán, Dr.
Àwọn tí wọ́n wà lọ́nà jíjìn réré sì gbúròó igbe ayọ̀ ní Jerusalẹmu.
Ta ló lè fìka wọn ojú ọ̀run,Kí ó kó erùpẹ̀ ilẹ̀ ayésinu òṣùnwọ̀n?
Láti inú ẹ̀yà Dani, a yan Buki ọmọ Jogili.
Ẹ ma si ṣe ṣalai wa ni irẹpọ pẹlawọn minisita ẹgbẹ yin.
Wọ́n fi ìwọ̀ kọ́ ọ nímú,wọ́n sì fà á lọ sí ilẹ̀ Ijipti.
fi ògágun murtala je alákoso orílè èdè yìí láti jé kí nàígíríà padà sí ìjoba alágbádá democracy .
Nítorí Johanu Onítẹ̀bọmi dé, kò jẹ, kò mu, ẹ sọ pé, ‘Ó ní ẹ̀mí èṣù ni.
Oríṣun àwòrán, @Lekan O jẹ ẹbun ẹkọ ọfẹ lọdun 1980 lati kawe nipa imọ ẹrọ fun ọkọ ayọkẹlẹ ni fasiti kan nilẹ UK, eyi to mu u kuro ni Naijiria.
Omi náà pọ̀ tóbẹ́ẹ̀ tí ó fi bo gbogbo àwọn òkè gíga tí wọ́n wà láyé mọ́lẹ̀.
Ẹnìkan kú ninu ọpọlọpọ ọrọ̀,nítorí pé ó wà ninu ìdẹ̀ra ati àìfòyà,
Bí ẹ bá rántí, D'banj pàdánù ọmọ ọdún kan rẹ̀ ní ọjọ́ kẹrìnlélógún oṣù kẹfà ni ọmọ náà fayé sílẹ̀ tí àwọn ènìyàn sì ń tàn án kálẹ̀ pé inú adágún omi ìgbafẹ́ tó wà nínú ilé D'Banj ni ọmọ náà kú sí.
O ni igbesẹ naa kan ti ọdun 2016, 2017 ati 2018.
wọ́n wọ ọkọ̀, wọ́n ń lọ sí Kapanaumu ní òdìkejì òkun.
Alix Fox: Oro ajakale aarun yìi tí ń mu kí òpó ènìyàn ronú bí wọn ṣe ni ìbálòpọ̀ tó dára ní òpò ìgbà àwọn miran ti wọn wa jí igbele gniyan láti kó leta ololufe sí ara wọn tí wón sì ni ìbálòpọ̀ tó dára lai fi ojú kan ara wọn.
Ìjọba àpapọ̀ fẹ́ f'òfin dé irina ọkọ̀ akero jakejado Nàìjíríà Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Láàrín ìdílé ẹlẹ́ni márùn ún yìí, ọmọ kan ṣoṣo ló léè sọ̀rọ̀ Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Naijiria, Independent National Electoral Commission, INEC lori bi won se sun  eto idibo ibo aare ati ile igbimo asofin
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ogbomosho shooting, End Sars, End SWAT: Isiaka Jimoh fi ọmọbìnrin kan àti ìyàwó tó lóyún sínú sílẹ̀ ló- Òbí Isiaka Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Ogbomosho shooting, End Sars, End SWAT: Isiaka Jimoh fi ọmọbìnrin kan àti ìyàwó tó lóyún sínú sílẹ̀ ló- Òbí Isiaka 17 Ọ̀wàrà 2020 Mo jiya pupọ lori Isiaka Jimoh ṣugbọn aye ko jẹ ki n jẹun ọmọ- Ramota, iya Isiaka Jimoh Nibi iṣẹlẹ iwọde End Sars / End SWAT to gba gbogbo igboro Naijiria kan yii ni aṣita ibọn ti lọ ba Isiaka Jimoh ni ilu Ogbomosọ ni ipinlẹ oyo to wa ni guusu ila oorun Naijiria.
Lọwọ-lọwọ bayii, wọn ti gbe baba Celestine lọ sile iwosan fun itọju, ti ko si si ẹni to lee sọ ohun ti yoo sẹlẹ sii nitori Paul, ọmọ baba naa lo n tọju rẹ lasiko ti awọn mejeeji wa lọgba ẹwọn.
 Ṣé tí ìwọ náà bá ti mú ọkùnrin kan wá , irú ọ ̀ rọ ̀ yìí ìbá má ti wáyé .
Kí ó san án pé pérépéré kí ó sì fi ìdámárùn-ún lé e, nígbà tí ó bá dá ohun náà pada fún olúwarẹ̀, ní ọjọ́ tí yóo bá rú ẹbọ ìmúkúrò ẹ̀bi.
Jesu bá sọ fún ọ̀gágun náà pé, “Máa lọ, gẹ́gẹ́ bí o ti gbàgbọ́, bẹ́ẹ̀ ni kí ó rí fún ọ.
Nígbà tí ó di ọjọ́ keji, Abimeleki gbọ́ pé àwọn ará Ṣekemu ń jáde lọ sinu pápá.
Àwọn ni wọn yóo máa san owó fún 
Ó bá dá Batiṣeba lóhùn, ó ní, “Jọ̀wọ́ bá mi bẹ Solomoni ọba, kí ó fún mi ní Abiṣagi, ará Ṣunemu, kí n fi ṣe aya.
 Ki wọn ri i daju pe wọn
Eniyan rere a máa rí ire nítorí ọ̀rọ̀ ẹnu rẹ̀,ṣugbọn ohun tí àwọn ẹlẹ́tàn ń fẹ́ ni ìwà jàgídíjàgan.
Èyí ni yóò fún aláìsàn ni àǹfààní láti bá aarun náà já títí tí ara yóò fi bọ̀ sípò.
Lateef Adedimeji Gbajugbaja ọdọ ni Lateef Adedimeji jẹ laarin awọn oṣere Yollywood bẹẹ si ni ko pẹ to dara pọ mọ awọn oṣere ti iṣẹ rẹ ti bẹrẹ si ni bu yọ.
Ọjọ Abamẹta, ọjọ kẹtadinlogun, osu Keji ọdun 2019 ni idibo aarẹ yoo waye.
Ó bá dìde láti ka Ìwé Mímọ́.
O jade laye ni oṣu kejila, ọdun 1996 lẹyin ti ọkan rẹ kọ iṣẹ.
Wọ́n ya ẹbọ sísun sọ́tọ̀ kí wọ́n lè pín wọn fún gbogbo ìdílé tí ó wà níbẹ̀, kí wọ́n lè fi rúbọ sí OLUWA gẹ́gẹ́ bí a ti kọ ọ́ sinu ìwé Mose.
abenugan pelu ẹni ti yoo gba ipo lowo re nigba ti awon ile igbimo asofin tuntun
Inú ọba Hiramu dùn pupọ nígbà tí wọ́n jíṣẹ́ Solomoni fún un.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, akeugbagold video Ọkan lara iru iṣẹlẹ bẹ ẹ to ti waye ni bi ọdun mẹta sẹyin, lasiko ti ọmọ ọdọ kan ji ọmọ mẹta ti awọn ọga rẹ bi lẹyin wakati mẹrinlelogun ti wọn gba a siṣẹ.
Rehoboamu jáde láyé, wọ́n sì sin ín sinu ibojì ọba, ní ìlú Dafidi.
Atẹjade kan ti gomina Sanwo-Olu fisita salaye pe alase yipo ni isede naa, ti yoo gba gbogbo ọjọ.
Oríṣun àwòrán, Reuters Àkọlé àwòrán, Wahala iyinbọn paniyan jẹ ipenija nla fun orile-ede Amerika Ọ̀pọ̀lọpọ̀ àwọn eniyan lo farapa nigba ti afurasi naa da ìbọn bolẹ nile ijọsin Sinagọọgu ti wọn n pe ni: 'Tree of Life' lọjọ Abamẹta to kọja.
Fayẹmi gba imoran yii lasiko ti o n sọrọ nibi apero lori eto ọrọ aje Naijiria ẹlẹẹkẹdọgbọn iru rẹ ti akori rẹ jẹ: Naijiria ni 2050: ki lo ku ni ṣiṣẹ yatọ?
 Èyí mú kí àrùn ascariasis jẹ ́ ẹ ̀ yà àkóràn aràn ajọ ̀ fẹ ́ nípasẹ ̀ iyẹ ̀ pẹ ̀ ilẹ ̀ tó wọ ́ pọ ̀ júlọ .
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ọkọ ìyàwó ẹlẹ́kún: N kò bá tí ba ẹnu jẹ́ lọ́jọ́ ìgbeyàwó, àwàdà ni mo se Ojuse alarina si ni lati mọ hulẹ hulẹ nipa itan idile obinrin naa ati iru aisan to n se wọn ninu idile wọn.
Deji ilu Akure - BBC News Yorùbá BBC News, YorùbáFò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Akure shooting: Àlááfíà ti padà sí ìlú Akure, ẹnikẹ́ni kò kú - Deji ilu Akure 7 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Oríṣun àwòrán, @Ondo Kò sí ẹnikẹ́ni tó kú níbi rògbòdìyàn tó wáyé lánàá - Deji ilu Akure Irọlẹ ọjọ Aiku, ọjọ kẹfa, oṣu kejila, ọdun 2020 ni iroyin gbode kan pe yinbọn lu eeyan kan ni Ọja Ọba, eyii to wa ni ilu Akure.
Ọjọ kẹjọ, oṣu Kẹfa ni ireti wa pe idije Premier League yoo tẹsiwaju, eyi to tumọ si pe awọn agbabọọlu gbọdọ pada si papa igbaradi lọjọ kejidinlogun, oṣu Karun.
Lára ilẹ̀ ìjọba rẹ̀ ni òkè Herimoni wà, ati ìlú Saleka, ati gbogbo Baṣani, títí dé ààlà ilẹ̀ àwọn ará Geṣuri, ati ti àwọn ará Maakati ati ìdajì Gileadi títí dé ààlà ọba Sihoni ti ìlú Heṣiboni.
Women's state of origin: Obìnrin lè jànfàní nípìnlẹ̀ bàbá àti ọkọ
Orílẹ̀-èdè kan ti dojú kọ ilẹ̀ mi,wọ́n lágbára, wọ́n pọ̀, wọn kò sì lóǹkà;eyín wọn dàbí ti kinniun.
Iwadii fihan pe, Ọgbẹni Atanda fi atẹjiṣẹ sọwọ si awọn eeyan lati maa fi owo bi ẹgbẹrun kan ati ẹgbẹrun un meji naira si akoto banki to fi ranṣẹ si wọn.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù 'Ìbí kò ju ìbí, Èèyàn bíi tiyín ni àfín, ẹ dẹ́kun dídẹ́yẹsí àfín' Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ 'Ìbí kò ju ìbí, Èèyàn bíi tiyín ni àfín, ẹ dẹ́kun dídẹ́yẹsí àfín' 9 Ògún 2018 Bí Ọlọrun ṣe dá ààwọ̀ ara wa nìyí, àfín kò yàtọ̀!
''Nigba ti awọn janduku naa n lọ si ile baba Sanwo-Olu, awọn ọlọpaa ko wọn lọna, ti wọn si yinbọn fun wọn, amọ wọn bori awọn ọlọpaa naa, ti wọn si salọ fun wọn.
Wọ́n ń bi mí pé,“Níbo ni gbogbo ìhàlẹ̀ OLUWA já sí?
Lọjọbọ, Minisita to n dari ileeṣẹ yi, Sadiya Umar sọ nibi apero kan to waye ni Katsina pe awọn ti yan awọn eeyan kan ti ijọba ipinlẹ yoo le ba ṣiṣẹ pọ lori awọn eto gbọnṣẹ gbọnyanu ijọba apapọ bi N-Power, Market-Moni ati Conditional Cash Transfer.
Bí mo bá mú kí ogun jà ní ilẹ̀ náà, tí mo sì pa eniyan ati ẹranko run ninu rẹ̀, 
Eyi ko sẹyin iku Ọba Ogunoye to gba ipo rẹ.
Ọ̀wọ́ngógó epo bẹntirò: NNPC ni ìròyìn ẹlẹ́jẹ̀' ni Oladejo Okediji àti ìgbé ayé ìtàn kíkọ rẹ̀ Àwòrán àjọyọ̀ ìjọba ológun ní Sudan Buhari ní òun kò gbàgbé àwọn ọmọ Chibok Ibẹrẹ kii ṣe oniṣẹ ni ọrọ ija naa jasi nitori pe Gastelum lo kọkọ n din dundun iya fun Isreal ki o to fi agbara kun agbara.
Omíyalé àgbàrà ti ya ṣọ́ọ̀bù ní Niger Kí ló ń fa ìjàmbá omíyale ní Naijiria?
Ẹlòmíràn lè gbé odindi garawa epo sílé!
"Igba ti akẹkọọbinrin naa ko le mu mọra mọ, lo pinnu lati sọ fun oludasilẹ ile ẹkọ naa.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ogungbinle: Àwọn onílé rò pé asẹ́wó ni mi 18 Ògún 2018 Àkọlé àwòrán, Ìdàmú àwọn obìnrin tí kò tíì lọ́kọ pẹ̀lú ilé wíwá Ọpọ onile lorilẹde Naijiria ni kii fẹ gba awọn obinrin ti kosi nile ọkọ sile, wọn maa n ro wipe aṣẹwo ni wọn.
Ilẹ̀ tiwọn ni Jaseri ati gbogbo ìlú Gileadi, ati ìdajì ilẹ̀ àwọn ará Amoni, títí dé Aroeri tí ó wà ní ìlà oòrùn Raba; 
Lẹ́yìn náà OLUWA Ọlọrun sọ pé, “Kò dára kí ọkunrin náà nìkan dá wà, n óo ṣe olùrànlọ́wọ́ kan fún un, tí yóo dàbí rẹ̀.
”Bakan naa, gege bi osise ijoba ti o sise ni agbegbe ohun, O ni, iko omo ogun Somalia miiran ti lo si awon agbegbe miiran ti o sun mo agbegbe naa lati daabobo awon ara ilu ati ohun ini won gbogbo lati deena iko omo ogun olote lati sekolu si won.
Ilé ìfowópámọ́ Access ti gbà láti dá owó àwọn oníbàráà wọ́n padà Kìí ṣe ààrùn Covid-19 ló pa adájọ́ àgba ìpínlẹ̀ Kogi-Kọmísọ́nà ìlera Ìgbà mẹ́jọ tí awuyewuye wáyé lórí ìṣèjọba Ajimobi!
Sera, ará Etiopia, gbógun tì wọ́n pẹlu ẹgbẹrun lọ́nà ẹgbẹrun (1,000,000) ọmọ ogun ati ọọdunrun (300) kẹ̀kẹ́ ogun.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Owó tí mo ń rí lórí Garri ni mo fi ń ran ọkọ lọ́wọ́' Ogagun Abubakar ni ikọ omo ogun oriṣi meji ti wọn kọkọ gbe kalẹ lati gbogun ti ijinigbe ni yoo jọ lo ẹro yii lati mu ayipada de ba eto aabo awọn eniyan ipinlẹ Ondo ati Ekiti Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, YSAN 2018: llú Ondo gbàlejò Àpérò Ẹgbẹ́ Onímọ̀ èdè Yorùbá Nàìjírìa Ileeṣẹ ọmọ ogun ilẹ ni aja iwoyi lo mọ ehoro iwoyii lé ni awọn fi ọrọ yii ṣe.
Báyìí ni Naomi ati Rutu, ará Moabu, aya ọmọ rẹ̀, ṣe pada dé láti ilẹ̀ àwọn ará Moabu.
O ni ki wọn pade oun ni ipebi ni ọjọ keje lati wa ri iran naa wo, to si bẹrẹ si ni wọ Agbada, buba ati sokoto bii ọkunrin lati igba naa lọ Ni ọjọ keje, ẹnu ya awọn Ọyọmesi ni Ipebi, nigba ti Ọ̀rọ̀ǹpọ̀tọ̀niyùn bọ ara rẹ silẹ fun wọn, ti wọn si ri pe ko si ọmu ni aya rẹ, bẹẹ si ni dipo nkan ọmọobinrin, nkan ọkunrin lo wa ni abẹ rẹ.
Southampton f’agbà han Huddersfield pẹ̀lú àmì ayò mẹ́ta soọ̀kan, ope pataki
Lanre Kuti ni mo fẹ́ - Jaiye Kuti Ṣé ẹ mọ̀ pé Ẹ̀wà Sóyà, Ẹja Puffer, àti ewébẹ̀ yìí lè ṣekú pa'ni kíákíá?
Lẹ́yìn tí ó ti wẹ ẹ̀ṣẹ̀ eniyan nù tán, ó wá jókòó ní ọwọ́ ọ̀tún Ọ̀gá Ògo ní ibi tí ó ga jùlọ.
Iwadii fihan pe, ọkan ninu awọn obinrin mẹrin l'Amẹrika lo ti gbero lati gbẹmi ọmọ wọn.
Oniduro ti ileeṣẹ ọlọpaa maa n waye lasiko ti awọn ọlọpaa ko ti i pari iwadi wọn lati mu ki ẹni naa duro fun afurasi ọdaran."
Gaali ọmọ Ebedi bá bèèrè pé, “Ta tilẹ̀ ni Abimeleki?
Wọ́n ti rí Kìnìún tó sá lọ́gbà ẹrankò lẹ́yìn tó pa gbogbo ewúrẹ́ jẹ tán Ipò aṣaájú ni Yorùbá yóò wà ní Nàíjíríà lásìkò tí mo jẹ Odole - Adebutu Egbìnrìn ọ̀tẹ̀!
Nítorí náà, ó bẹ̀rù Dafidi sí i, ó sì ń bá Dafidi ṣe ọ̀tá títí gbogbo ọjọ́ ayé rẹ̀.
Ẹ pa á tì, ẹ jẹ́ kí á lọ,kí olukuluku máa lọ sí ilẹ̀ rẹ̀;nítorí ẹjọ́ tí a dá a ti dé òkè ọ̀run,a sì ti gbé e sókè dé ojú ọ̀run.
Eto yii jẹ oni sogundogoji ti ọpọ eniyan jakejado agbaye, ti ko yọ awọn ọmọ Naijiria silẹ kopa ninu rẹ ti wọn si jẹ owo ti awọn mii padanu obitibi owo si MMM ti kógbá wọlé.
Ohun si ni iditi oludije alatako gangan, Svetlana Tikhanovskaya ṣe yari pe irọ ni esi idibo naa.
Nibayii, wọn ti gbe oku Ajibola fun ẹbi rẹ.
Kí OLUWA Ọlọrun rẹ gbọ́ ọ̀rọ̀ ẹ̀gàn yìí, kí ó sì jẹ àwọn tí wọ́n sọ ọ́ níyà.
Ó lé àwọn tí ń ta aguntan ati mààlúù jáde.
Bi Chelsea ko ba tilẹ le ra akọnimọọgba tuntun titi di 2020, o kere tan, agbabọọlu tuntun kan yoo wa nilẹ fun akọnimọọgba to ba wọle - Christian Pulisic, ti wọn ra pẹlu miliọnu lọna ọgọta o din meji Euro.
Lara awọn nkan ti wọn n fẹ ki ile ẹjọ o ṣe ni pe ko dajọ pe Buhari ko sọ otitọ fun ajọ INEC nipa iwe ẹri ileewe to lọ.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: INEC dá òsìsẹ́ lẹ́kọ̀ọ́ láti yọ Melaye Gẹ̀ẹ́sí gbé £1m kalẹ̀ láti tako Boko haram Ọbásanjọ́, Fálaè sè‘pàdé lóríi Bùhárí Iléeṣẹ́ ọmọogun Nàìjíríà ní sísọ̀rọ ̀ òdì sí àwọn ọmọogun yóò domi tútù sí wọn lọ́kaàn ni, yóò sì ṣílẹ̀kùn sílẹ̀ gbayawu fún àwọn ọ̀tá láti ṣe ọ̀pọ̀ ọṣẹ́ fún ètò àbò orílẹ̀èdè Nàíjíríà.
Oríṣun àwòrán, Instagram/currentalhaja Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Wọ́n ṣàn kọjá lórí òkèlọ sí inú àfonífojì,sí ibi tí o yàn fún wọn.
Mo ti lùgbàdì àrùn Coronavirus - Akeredolu figbe ta Arúfin ni Seyi Makinde pẹ̀lú bó ṣe gbà kí wọ́n sin Ajimobi sí GRA - Amòfin N-Power build nkọ?
Oríṣun àwòrán, EPA Àlàyé rèé lórí ohun tó ṣe okùnfà ibugbamu ní Beirut Inu ọfọ nla ni awọn eeyan orilẹ-ede Lebanon wa lẹyin ibugbamu nla to waye ni olu ilu orilẹ-ede naa, Beirut lọjọ Iṣẹgun.
OLUWA, tọ́ mi sọ́nà òdodo rẹ, nítorí àwọn ọ̀tá mi;jẹ́ kí ọ̀nà rẹ hàn kedere níwájú mi.
Ọdun 1997 ni Oyetola ti darapọ mọ sise oselu, ati wipe o pẹlu awọn to da ẹgbẹ oselu Alliance for Democracy AD silẹ ni ọdun 1998.
" Oríṣun àwòrán, @enso_uzor Atẹjade naa tun wa n dupẹ pupọ lọwọ awọn ẹlẹgbẹjẹgbẹ ajafẹtọ ẹni nilẹ yii ati loke okun, ati awọn ajafẹtọ ẹni lori ikanni ayelujara, fun bi wọn se gbe awọn iroyin to nii se pẹlu iwọde wọn sita lasiko ijagudu fun idajọ ododo naa.
ó bá rán ọdọmọkunrin mẹ́wàá lọ sí Kamẹli láti lọ rí Nabali, kí wọ́n sì kí i ní orúkọ òun.
Awọn alaga ẹgbẹ mejeeji ni o ti to ọdun mẹta ti wọn ti ṣe ìgbega lẹnu iṣẹ f'awọn ọmọ ẹgbẹ awọn to wa labẹ akoso NCAA.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Matthew (apa osi) ati aburo rẹ Paul n ṣe ipolongo lati gba idajọ fun iya wọn Ni aarin idile mi, igba miiran, a maa n sọrọ nipa bi a ko ṣe le ni suuru fu ki kawọ gbera awọn eniyan kan to wa ni ipo agbara.
 Laipẹ yii ni iroyin jade lori ayelujara pe, awọn ọdọ kan koro oju si Pasuma lasiko iwọde #ENDSARS."
Ẹ̀yin ọmọ ìlú mi, bí ẹ ti rí wa yìí, akìí ṣe òmùgọ.
O Fagunwa ti dara ilẹ, Ijọba ko fi bẹẹ se ohunkohun lati maa se iranti rẹ, tawọn ẹbi rẹ ko si ri ọwọ ijọba rara.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Coronavirus domestic violence: Àwọn nǹkan tí obìnrin leè ṣe pẹ̀lú olólùfẹ́ oníwa ipá lásìkò ìgbélé Coronavirus yí By Azeezat Olaoluwa Women's Affairs Reporter, West Africa 9 Èbibi 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 13 Èbibi 2020 Àkọlé àwòrán, Ti eeyan ba wa ninu igbeyawo oni jagidijagan, awọn iwa ipa naa ma n wa lemọ lemọ ni, bii eebu ati ilu bara Kaakiri ilẹ Afrika, ọpọ ijọba pẹlu awọn agbofinro ti sọ pe idjukọ awọn obinrin ninu igbeyawo wọn lasiko igbele Coronavirus n peleke sii.
O fi ku oro re pe, “won ti fi da awon ara-ilu loju pe, ile-ise ologun yoo sa gbogbo ipa re lati ri daju pe, alaafia joba ni ipinle Taraba, fun apere, awon odaran kan ge ori ogagun agba ile-ise ologun ni ojo kerindinlogun osu keta odun 2018, ni agbegbe Takum nipinle Taraba.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Gbajugbaja oṣere tiata, Bolaji Amusan fi hann wa bo se láyà to lori ètò ṣé o láyà.
O ni gẹgẹ bii ijọba to mọ ohun to n se, to si mu iwọde EndSARS lọkunkundun, a ko ni fọwọ lẹran, ki ilu dojuru mọ wa lọwọ.
Oríṣun àwòrán, The Punch Àkọlé àwòrán, Awọn ọlọpa hu oku arabinrin naa jade ninu ṣọọṣi Ṣugbọn nigbati o n sọrọ pẹlu awọn oniroyin, afurasi naa sọ pe oun kii ṣe oun ni o pa arabinrin naa, o sọ pe ẹlomiran ni o ṣe ọṣẹ naa.
Ìtùmò : nì àyé àtíjó àbikú ń da bàbá kan láàmu .
3 Sẹ́rẹ́ 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 6 Òkùdu 2020 Bi ẹ ba jẹ ẹni to n fi ọkan ba ere sinima lorileede Naijiria bọ daadaa, kete ti wọn ba ti darukọ Yemi My Lover, ko ni ṣe yin ni kayeefi.
Lanre Kuti ni mo fẹ́ - Jaiye Kuti Oúnjẹ márùn-ún tó lè ṣekú pa'ni kíákíá Ẹ yé parọ́ kiri!
Oṣiṣẹ ilu kan, Justus Kangwagye sọ fun iwe iroyin naa wipe awọn ileejọsin naa tapa si ofin eto aabo.
Oríṣun àwòrán, Google Àkọlé àwòrán, Ọrọ iku rẹ jẹ nnkan to ṣọkunkun titi di bi a ti ṣe n sọrọ yi.
Ó yà mi lẹnu bí bàbá rẹ ti ṣe ṣe bẹ́ẹ̀ kú nítorí ní kété ìgbà tí ó fi máa kú, ó wá sí ọ̀dọ̀ mi, ara rẹ̀ sì le dáadáa nígbà náà, a tilẹ̀ sọ̀rọ̀ tí ó pọ̀, àfi ìgbà tí ó sì tó ọjọ́ márùn-ún lẹ́yìn rẹ̀, tí wọ́n mú ọ̀fọ̀ rẹ̀ wá bá mi!
Nígbà tí àwọn ọmọ Israẹli pàgọ́ sí àfonífojì Ṣitimu, àwọn ọkunrin wọn ń bá àwọn ọmọbinrin Moabu tí wọ́n wà níbẹ̀ ṣe àgbèrè.
"Laarin ọsẹ yi ni Gomina lawọn yoo kede agbekalẹ igbimọ yi.
O ni ko si ipinlẹ kankan nilẹ Yoruba ti yoo da gbe igbesẹ kankan lori ọrọ ijọba apapọ ọhun.
Wọ́n wí fún un pé, “Nǹkan kan ni a fẹ́ bẹ̀ ọ́ fún, a sì fẹ́ kí o ṣe é fún wa: jọ̀wọ́, gbadura sí OLUWA Ọlọrun rẹ fún àwa ati gbogbo àwọn tí wọ́n ṣẹ́kù, nítorí pé a ti pọ̀ tẹ́lẹ̀ rí, ṣugbọn díẹ̀ ninu wa ni ó kù, bí ìwọ náà ti fi ojú ara rẹ rí i.
2 miliọnu owo itanran ni a gbe lọ fun awọn ajinigbe naa lẹyin ti a ba wọn duna dura tan, ko pẹ si asiko naa ti wọn tu wọn silẹ.
Ẹ lè fi ara yín ṣẹrú fún ẹ̀ṣẹ̀, kí ó fikú san án fun yín; ẹ sì lè fìgbọràn ṣọ̀gá fún ara yín, kí ó sì fun yín ní ìdáláre.
Ogun to fẹrẹ bẹ silẹ laarin orilẹede Iran ati Amerika Orilẹede Amẹrika ati Iran ti wọ iya ija lati ọdun 1979, lẹyin ti ijọba ti Amerika ṣe agbatẹru fun ni Iran forisanpọn nigba ti wọn gba ijọba lọwọ rẹ.
”Ewe, awon akonimoogba yooku ti yoo maa ran Dennerby lowo ni: Jorgen Petersson,  Olarenwaju Oni, Maureen Madu ati Tunde Omobolanle, besini O se ikilo fun won lati maa faye gba sise ole laarin agbaboolu Kankan ninu awon olokan-o-jokan igbaradi ti yoo maa wayeNi afikun, lara awon agbaboolu ti o kopa ninu ayeye isafihan akonimoogba naa, ni agbaboolu obinrin ti o darajulo nile Afrika, Asisat Oshoala ati akegbe re Onome Ebi.
Ṣugbọn nítorí pé o gbẹ́kẹ̀lé OLUWA, ó fún ọ ní ìṣẹ́gun lórí wọn.
Ìgbà tí a ni kò yẹ kí gbogbo ènìyàn  máa fara mọ ẹni tí ilẹ̀ẹ́gbóná b’’a ń ṣe bbí a ti ń rí wọn tí wọn ń ṣe wọ̀n-ọnnì, ó ní òun gan-an ló yẹ, ìgbà tí a wí pé èérí ìlú náà pọ̀ jù àti pé bí wọ́n ri ṣe n kọ́ ilé wọn ni o ń mú àìsàn dé bá wọn, ó ní irọ́ ni a ń pa.
Gbogbo awọn ohun eelo ounjẹ ti wọn ba n lo to fi mọ ike ti awọn eniyan nlo.
Gbogbo àwọn tí wọ́n fẹ́ obinrin àjèjì ni wọ́n kọ àwọn aya wọn sílẹ̀ tọmọtọmọ.
Akojọpọ iye awọn to ni niyii: Aarun naa ti pa eniyan 533, awọn 7,338 si ti ri iwosan.
Ó fún Nàìjíríà l'èsì àwọn ẹ̀sùn tó fi kàn-án Ará ìlú figbe ta bí wọ́n ṣe ní jálá epo bẹntiróò ṣe tún lọ sókè di ₦151.
 Kinni yoo sẹlẹ si ọba tabi ilu ti wọn ji ọ̀pá àṣẹ rẹ gbé salọ?"
" Ipinlẹ Plateau lo tun lewaju iye awọn to laarun naa lọjọ Iṣẹgun pẹlu eeyan mẹrindinlọgọfa (116), olu ilu ilẹẹwa Abuja eeyan mẹtalelọgbọn (33), ipinlẹ Eko eeyan mọkandinlogun (19), Ipinlẹ Ekiti mejila (12), ipinlẹ Kaduna eeyan mọkanla (11), ipinlẹ Ogun eeyan mọkanla (11), ipinlẹ Ebonyi eeyan mẹjọ (8) ipinlẹ Benue eeyan meje (7), ọkọọkan ipinlẹ Abia, ati Delta ni marun un (5), ipinlẹ Ondo mẹrin (4), ipinlẹ Edo eeyan mẹta (3), ipinlẹ Imo eeyan meji (2), ipinlẹ Ọṣun eeyan meji (2) Bauchi eeyan kan ṣoṣo (1).
Batiṣua, aya rẹ̀, ará Kenaani, bí ọmọ mẹta fún un: Eri, Onani ati Ṣela.
Lọjọ Abamẹta to kọja yii ni awọn alaṣẹ papakọ ofurufu Hong Kong gbẹsẹle apoti nla to kun fun ìwo Tuuku towo rẹ to miliọnu meji o le owo dọla ilẹ Amerika.
Wọ́n kan àwọn ìkọ́ kan tí ó gùn ní ìwọ̀n àtẹ́lẹwọ́ kan mọ́ ara tabili yíká ninu.
 Oríṣun àwòrán, Facebook/Genesis Global O tẹsiwaju pe ""alalubarika ọkunrin to mọ pe ọna oun jin ko ni maa dunu pe oun lo ọgbọn iṣeju lori obinrin."
 Iko agbaboolu Super Eagles fiya je Guinea, ope pataki lowo ami-ayo kan soso ti Kenneth Omerou gba wole, esi ifesewonse naa ni yoo mu ki Iko agbaboolu   Super Eagles duro digbi pelu ami mefa lori  oke tente tabili ohun.
Mú ìlérí rẹ ṣẹ fún iranṣẹ rẹ,àní, ìlérí tí o ṣe fún àwọn tí ó bẹ̀rù rẹ.
ilu Abuja( Federal Capital Territory ,FCT)  CP Bala Ciroma lati se iwadii lẹkununrẹrẹ ,
Ìgbà tí wọ ́ n dàgbà tán , tí ó di wí pé wọ ́ n ń wá ibùjókòó tí wọn yóò tẹ ̀ dó , àwọn méjèéji - agírírí àti ajíbógun yìí náà ló jìjọ dìde láti ilé-ifẹ .
Samsoni lọ sí Timna, ó rí ọ̀kan ninu àwọn ọmọbinrin ará Filistia níbẹ̀.
Oríṣun àwòrán, @Newsmongerng/Twitter Ti oṣu kẹta yẹ ko waye ni ogunjs oṣu kẹta si ọjọ kejilelogun oṣu ọhun ṣugbọn nitori ajakalẹ arun Coronavirus bayii, wọn ti sun un siwaju.
Iya rẹ ti ku lọdun marun sẹyin.
 Ọ ̀ gbẹ ́ ni ahmadu ali ló kọ ́ kọ ́ jẹ ́ adarí àgbà àkọ ́ kọ ́ fún àjọ náà títí di ọdún 1975 .
Wọ́n ń wí pé, OLUWA sọ báyìí, báyìí; bẹ́ẹ̀ sì ni OLUWA kò sọ nǹkankan.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ìtàn rèé nípa bí Ogbomoso ṣe pa ọba, yọ nǹkan ọkùnrin rẹ jó kiri ìlú Ìjàmbá iná míràn tún wáyé ní pápákọ̀ ojú omi Beirut Ẹ fi dókítà àgùnbánirọ̀ rọ́pò àwọn dókítà tó ń yanṣẹ́ lódì - Ìjọba àpapọ̀ pàṣẹ Afenifere fara ya lórí bí Tinubu ṣe jókòó kí Ooni Háà ilẹ̀ wẹ!
Ẹ óo wá mi láìsinmi,ṣugbọn ẹ kò ní rí mi.
Ó gbà, ó dìde nílẹ̀, ó sì jókòó lórí ibùsùn.
“Ìtàjẹ̀sílẹ̀ yóo pọ̀,n óo sì fi iná, ati òpó èéfín sí ojú ọ̀run,ati sórí ilẹ̀ ayé;yóo jẹ́ ìkìlọ̀ fun yín.
Orílẹ̀-èdè tí ó bá gbọ́ nípa àwọn ìlànà ati òfin wọnyi yóo wí pé, dájúdájú ọlọ́gbọ́n ati amòye eniyan ni yín.
Mo fẹ́ kí o mọ̀ dájúdájú pé, ìwọ kò ní jáde kúrò níbẹ̀ títí ìwọ yóo fi san gbogbo gbèsè rẹ láìku kọbọ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Sotitobire Church: Òótọ́ àti irọ́ tó wà nínú iṣẹ̀lẹ̀ náà Yemisi Oyedepo Broadcast Journalist 20 Ọ̀pẹ̀̀ 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 21 Ọ̀pẹ̀̀ 2019 Oríṣun àwòrán, ooniadimula Lẹyin ti ọpọlọpọ araalu ti ọrọ naa mu wọn lọkan ti da si i.
Obìnrin kan lu ọ̀gá ọlọ́pàá, ó tún gé ọmọ'ṣẹ́ ọlọ́pàá jẹ nítorí òfin ìséde ní Eruwa Oríṣun àwòrán, Getty Images Ọga patapata fun ileeṣẹ ọlọpaa lorilẹ€de Naijiria, Mohammed Adamu ti ke si araalu pe ẹnikẹni to ba ṣiwọ lu ọlọpaa to wa lẹnu iṣẹ rẹ yoo jẹ iyan rẹ niṣu ni.
Mikaaya bá dáhùn pé, “Mo rí àwọn ọmọ ogun Israẹli tí wọ́n fọ́n káàkiri gbogbo orí òkè, bí aguntan tí kò ní olùṣọ́.
O ni airi owo ẹgbẹrun marun un ti oun fi pamọ sinu ile loun fi fi iya jẹ ọmọ naa nitori pe igbagbọ oun nipe ọmọ naa lo mu u.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù O dun yin pe ọmọ Yoruba ko gba Oscars abi?
Ilé alájà mẹ́ta wó pa onímọ̀ ẹ̀rọ́ tó ń kọ́ ọ lọ́wọ́ Lẹ́yìn igbe Atiku, Ààrẹ Ilé Ẹjọ́ kòtẹ́milọ́rùn yọra rẹ̀ nínú ìgbẹ́jọ́ èsì ìdìbò ààrẹ Kò sí ààbò, kò síṣẹ́; Àwọn dókítà LUTH bínú tán Kíni o túmọ sí pé kí orílè-èdè rẹ má ní ilé iṣẹ tó n sójú rẹ n'ilẹ ókéré mìíràn?
"Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Shiite Movement: Shiite fèsì lórí àṣẹ ilé ẹjọ́ láti máa pé wọ́n ní ẹgbẹ́ agbésùnmọ̀mí 27 Agẹmo 2019 Oríṣun àwòrán, @SZakzakyOffice ""Mo lè kú tọmọ tọmọ bi ijọba ba kọ lati da adari wa, ElZakzaky silẹ""."
Engineering ati Construction ati ile ise to n ta –ra gaasi ati epo robi ri gba
#EndSARS: Pe nọ́mbà wọ̀nyìí láti fẹjọ́ ọlọ́pàá SARS sùn
Àwọn kan wà lẹ́yìn Tibini, ọmọ Ginati, pé òun ni kí ó jọba.
Moshood Kaṣimawo Olawale Abiọla Moshood Kasimawo Olawale Abiọla ti gbogbo eeyan mọ si MKO ni Aarẹ ọna kakanfo kẹrinla to jẹ.
Eṣúṣú bí ọmọbinrin meji, ó sì sọ àwọn mejeeji ni:“Mú wá, Mú wá.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Olólùfẹ́ méjì jábọ́ láti àjà kẹsàn án lásìkò tí wọ́n n ṣe kerewà 17 Agẹmo 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 18 Agẹmo 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Obinrin kan ti ku iku ojiji lẹyin to jabọ lati aja kẹsan ile kan lasiko ti oun ati ololufẹ rẹ n ṣe kerewa, ṣugbọn ololufẹ rẹ ọhun ye.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Akomolede ati Aṣa lori BBC: Kí ní ìtúmọ̀ Sílébù àti àmi ohun tó ń fún ni?
Kí àwọn ará ilé Aaroni wí pé,“Ìfẹ́ rẹ̀ tí kì í yẹ̀ wà títí lae.
Ǹjẹ́ ohun tí kò dùn ṣe é jẹláì fi iyọ̀ sí i?
Tabili meji meji wà ní ẹ̀gbẹ́ kinni keji ìloro ẹnu ọ̀nà náà, lórí wọn ni wọ́n tí ń pa àwọn ẹran ẹbọ sísun, ti ẹbọ ìmúkúrò ẹ̀ṣẹ̀, ati ti ẹbọ ìmúkúrò ẹ̀bi.
Iya yii n ta asun ẹja ni ọja ẹja oriṣirisi ni Nairobi.
Adehun naa faye gba Iran lati dawọ sise ado oloro tuntun duro Ti a ko ba gbagbe, ọpọ igba ni Aarẹ Donald Trump ti sọ wipe oun ko ni tẹsiwaju pẹlu adehun ti wọn se pẹlu Iran, eleyi ti yoo dopin ni Ọjọ Kejila, Osu Karun, Ọdun 2018.
 Ìgbà mìíràn màá dájọ ́ .
 Òun ni ó ṣe ìwádìí owó tí ó sọnù .
lojo Abameta nibi ti awon osise ile-ise naa ti n se atunse lori ọpa gaasi kan
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Bode George: òòtọ́ ni ìkìlọ̀ Obasanjọ ati Soyinka Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Bode George: òòtọ́ ni ìkìlọ̀ Obasanjọ ati Soyinka 25 Èbibi 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 26 Èbibi 2019 Bode George: Ọkanjua lo n yọ Tinubu lẹnu Agba ẹgbẹ oṣelu People's Democratic Party (PDP), oloye Bode George se ifọrọwerọ pẹlu awọn akọroyin nilu Eko.
59 Èmi ni ẹni náà tí ó sọ—Àwọn àgùntàn míràn ni emi ní tí wọn kìi ṣe ti agbo yìí—fún àwọn ọmọ ẹ̀hìn mi, àti pé ọ̀pọ̀lọpọ̀ ni wọ́n wà tí ọ̀rọ̀ mi kò yé.
We celebrate his life well spent in the service of humanity and we will continue to project his principles and values in contributing to governance, security and sustainable development of the African continent.
Nígbà tí OLUWA bá mú ìlérí rẹ̀ ṣẹ tí ó sì fi ọ́ jọba ní Israẹli, 
Ó wà nínú ìṣòro; ilée rẹ̀ ti wó.
Ìsọníṣókí Òní ọjọ́ kọkàndínlọ́gbọ̀n oṣù kárùn-ún ọdún 2019 ni ètò ìbúrawọlé ń wáyé lórílẹ̀èdè Nàìjíríà Láàrin ọdún 1999 sí ọdún 2019, ààrẹ mẹ́rin ló ti jẹ ní Nàìjíríà Ààrẹ Muhammadu Buhari ni ààrẹ ikeeje ati ikẹẹdogun ti orilẹede Naijiria Awọn gomina ti wọn dibo yan naa n bura wọle lonii Ko ni ju bayii lọ fun akojọpọ iroyin wa bo 'se n lọ lọwọ-lọwọ, ẹ 'seun ti ẹ ba wa kalọ Jíjábọ̀ ohun tí ń lọ lọ́wọ́ Nípasẹ̀ Yetunde Olugbenga àti Busayo Akogun Gbogbo àkókò tí a kọ jẹ́ ti UK Tí a fiṣọwọ́ ní 13:35 29 Èbibi 201913:35 29 Èbibi 2019 Ó dìgbà kan ná!
Ó ta àsíá, ó fi pe orílẹ̀-èdè kan tí ó wà ní òkèèrè;ó sì fọn fèrè sí i láti òpin ayé.
2 127786 Orilẹede Austria 4163 46.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Game of Thrones vs Ìrèké Oníbùdó: Ǹjẹ́ ìfarapẹ́ra wà nínú fíìmù méjèèjì?
” Wọ́n bá bù ú lọ.
Bakan naa lo bawọn eeyan sọrọ ko to wọ gbọngan ipade ọhun lọ.
Ní òru ọjọ́ keji, Oluwa dúró lẹ́bàá Paulu, ó ní, “Ṣe ọkàn rẹ gírí.
Ẹ̀yin tẹ́ẹ̀ ń fapá-jánú, ẹ bomi sùúrù mu - Buhari Oshiomole di alága àpapọ̀ APC 5000 ọlọ́pàà wà níkàlẹ̀ fún ìpàdé àpapọ̀ APC Bakan naa lo tun ni awọn aṣiwaju feto oṣelu ati eto karakata lagbo ẹgbẹ oṣelu APC , yẹ ko jumọ joko pọ lati gbe ilana ọtun kalẹ, eleyii ti yoo ṣe akawe ohun gan to n damu orilẹede yii to bẹẹ gẹẹ, ti awọn ọmọ Naijiria ko ni lee maa fi oju idẹyẹsi ẹsin, ẹya tabi ipo lawujọ, wo ara wọn mọ.
Ijọba kede pe ki wọn ti awọn ile kewu almajiri pa ni ipari osu Kẹta sugbọn nitori pe awọn ọmọ yi ko nii ri ibi kankan lọ, wọn si n tọrọ bara loju titi.
Asofin Nnena Elendu Ukeje ni tire ko gba abadofin naa wole nitori pe o gba pe o tako eto omoniyan awon agbefoba ati pe ko sibi tiru ofin yii ti n sise lagbaye.
Dokita yọ góòlù àti owó ṣílè nínú obìnrin kan Etí ìjọba Buhari di sí ìmọ̀ràn àwọn ará ìlú -Jiti Ogunye Wole Soyinka ni oun ko kọkọ gba ẹsun ti oun gbọ lori Soworẹ gbọ nibẹrẹ ṣugbọn nigba ti ọrọ naa di ootọ ni o di kọọ.
Nígbà tí àwọn ọmọ Reubẹni ati àwọn ọmọ Gadi, tí wọ́n ní ẹran ọ̀sìn pupọ, rí ilẹ̀ Jaseri ati ilẹ̀ Gileadi pé ibẹ̀ dára fún àwọn ẹran ọ̀sìn wọn, 
iwe adehun ti yoo mu idagbasoke ba eto ọrọ aje, a fẹ ki won ma jẹ irẹsi  Kebbi  ni gbogbo ilẹ Afirika.
Yatọ si eyi, ipinlẹ naa tun ti ṣi iwe kan si ori ayelujara nibi to ma n fi aworan ati orukọ awọn afipabanilopọ ti ọwọ ba tẹ nipinlẹ naa.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Coronavirus: Orílẹ̀-èdè Tanzania àti Somalia náà ti gbàlejò àrùn Coronavirus 16 Ẹrẹ̀nà 2020 Oríṣun àwòrán, Getty Images Minisita eto ilera orilẹede Tanzania, Ummy Mwalimu ti kede pe arun Coronavirus ti tan de orilẹede naa.
Adele akọwe ẹgbẹ naa Victor Giadom lo fidi ọrọ yi mulẹ ninu ifọrọwerọ pẹlu BBC.
Èdè wúlò fún kí a le bá ara sọ ọ̀rọ̀ léyìí tí ó máa ń fa àgbọ́yé àti àjọṣepọ̀
O ṣalaye pe eyi jẹ ọkan lara koko ohun ti oun le sọ nipatọ.
 Ìwọn yàtọ ̀ láàrín àwọn ẹ ̀ yà sí ẹ ̀ yà ní orílẹ ̀ èdè .
Lẹyin ti idibo ba ti waye tawọn oloṣelu to n du ipo gbogbo, ninu eyi ti awọn ipo ile aṣofin apapọ pẹlu wa ni wọn maa n dawati.
Akowe agba ninu ajo  naa, iya afin Esther Aluko  lo soju fun minisita ohun ninu ayeye naa.
Ileesẹ ijọba Ghana to n dari ọrọ ilẹ yoo wa fun wọn ni ẹkunrẹrẹ iwe aṣẹ lori ilẹ naa.
 Bakan naa, lo tun fi asiko ohun rawo ebe si ogagun Omozoje lati se
"Lasiko yii, ti awọn eniyan n w'oju ijọba tabi alufa lati mu ayipada ba awujọ, iwọ naa le ṣe iranlọwọ pẹlu nkan ti o ni, ni ibikibi ti o ba wa.
agbekale idanilekọọ fun awon oniroyin lati je ki gbogbo eniyan mo ipa pataki
Nígbà tí àwọn eniyan rí i pé Jesu ati àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ kò sí níbẹ̀, àwọn náà bọ́ sinu àwọn ọkọ̀ tí ó wà níbẹ̀, wọ́n bẹ̀rẹ̀ sí tọpa Jesu lọ sí Kapanaumu.
Lẹyin ti alaṣẹ ileeṣẹ baluu na ti ṣe apejuwe Naira Marley atawọn ikọ rẹ gẹgẹ bi awọn ọmọ alaiwulo kan, Naira Marley naa ti fesi si ọga agba ileeṣẹ baluu na bayii.
Emmanuel Enoidem, tii se oludamọran nipa ofin, to bawọn akọroyin sọrọ lorukọ ẹgbẹ oselu PDP nile ẹjọ naa sọ pe, ẹgbẹ oselu naa ati oludije rẹ ninu eto idibo aarẹ to kọja, Atiku Abubakar, ti gbe iwe ẹsun wọn kalẹ ni ibujoko igbimọ olugbẹjọ ibo aarẹ, to kalẹ silu Abuja.
RRe-run election (Atundi idibo) : Idibo yi ma n waye ti
Eto naa je ti ara oto tijoba gbe kale fun idagbasoke awon agbe ati ipese atileyin ti won nilo ki ebi ma pa ilu.
Ọlọ́pàá dóòlà àgùnbánirọ̀ 5 lọ́wọ́ ajínigbé Ìwọ́de nítorí Ochanya Ogbanje tí wọ́n fipá bá lò Gomina ipinlẹ Kaduna Nasir El Rufai fi ikede idapada ofin konileogbele yi soju opo Twitter rẹ lọjọ ẹti.
Iya rẹ, Abilekọ Babalọla lasiko to n ba BBC YORUBA sọrọ ni, ọmọ ọdun mẹrin ni ọmọ oun.
O le ni ẹẹdẹgbẹta awọn ọmọ ile iwe to kọ lati kọ idanwo naa, ṣugbọn ti wọn kọju ija si awọn infijilatọ ti ko jẹ ki wọn gbe iwe wọle si gbọgan idanwo.
 Gomina ipinlẹ Ondo tun salaye pe ijọba oun gba akanda ẹda marundinlogoji sẹnu isẹ, ti oun yoo si ṣe ju bẹẹ lọ fun wọn, ti oun ba pada sipo ni ẹkeji."
Mo bá gba ìwé náà ní ọwọ́ angẹli yìí, mo bá jẹ ẹ́.
Oríṣun àwòrán, @Love96047280 Ladugbo Lekki ni iroyin ti gbalẹ kan pe awọn araalu kan to n fẹhonu han ti ya bo ile itaja kan to wa nibẹ, ti wọn si n ko oniruuru ọja lati fi gbẹsan bi awọn ọmọ orilẹede South Africa se n kọlu awọn ọmọ Naijiria.
Àwọn kan wá láti Judia tí wọn ń kọ́ àwọn onigbagbọ pé, “Bí ẹ kò bá kọlà gẹ́gẹ́ bí àṣà ati Òfin Mose, a kò lè gbà yín là!
Ko si ẹni to mo ibi ti awọn aworan meji toku wa.
Nígbà tí ó bẹ̀rẹ̀ sí ṣírò owó, wọ́n mú ẹnìkan wá sọ́dọ̀ rẹ̀ tí ó jẹ ẹ́ ní ọ̀kẹ́ àìmọye.
Oríṣun àwòrán, @BokoHaramWatch Nigba to n sọ bo se de ahamọ Boko Haram, obinrin ẹni ọdun mẹẹdọgbọn naa ni, ọja ni oun wa ni Mubi, nigba ti Boko Haram wa ko awọn si ahamọ, ti wọn si fi tipa tipa sọ oun di ẹlẹsin Islam.
Ó bá dá wọn lóhùn pé, “Ẹ lọ sọ ohun tí ẹ rí ati ohun tí ẹ gbọ́ fún Johanu: àwọn afọ́jú ń ríran; àwọn arọ ń rìn, ara àwọn adẹ́tẹ̀ ń di mímọ́; àwọn adití ń gbọ́ràn, à ń jí àwọn òkú dìde; à ń waasu ìyìn rere fún àwọn talaka.
Bí ẹ bá sì kó ara yín jọ sinu àwọn ìlú olódi yín, n óo rán àjàkálẹ̀ àrùn sí ààrin yín, n óo sì fi yín lé àwọn ọ̀tá yín lọ́wọ́.
Ìṣẹ́jú mẹ́tàlá ló kù ki ìfẹsẹ̀wọ́nsẹ̀ parí láàrín Nigeria ati Angola ní National Stadium ìpínlẹ̀ Eko èyí ti yóò mú wọọn pegede fún ife ẹ̀yẹ FIFA.
Má sọ̀rọ̀ pẹlu ìgbéraga mọ́,má jẹ́ kí ọ̀rọ̀ ìgbéraga ti ẹnu rẹ jáde,nítorí Ọlọrun tí ó mọ ohun gbogbo ni OLUWA,gbogbo ohun tí ẹ̀dá bá ṣe ni ó sì máa ń gbéyẹ̀wò.
Ọọ̀ni Adeyeye Ogunwusi ló sọ ọ̀rọ̀ yìí níbi ìpàdé lọ́balọ́ba nípínlẹ̀ Ọ̀ṣun tó wáyé ní ààfin Odùduwà ní ìlú Ilé ifẹ̀.
Nígbà tí wọ́n dé ibi tí wọn ń pè ní Gọlgọta (ìtumọ̀ èyí tíí ṣe “Ibi Agbárí”), 
Jesu tẹjú mọ́ ọn, ó ní, “Ìwọ ni Simoni ọmọ Johanu; Kefa ni a óo máa pè ọ́.
Jesu Ni Ọ̀nà Dé Ọ̀dọ̀ Baba.
Laipẹ yi ni awọn ọkọ akero bẹrẹ si ni ko ẹgbẹẹgbẹrun awọn ọmọ ile Keu almajiri lati awọn ipinlẹ ti wọn wa ni agbegbe ariwa Naijiria pada lọ si ilu ti wọn ti wa ni ọrọ n bẹyin yọ.
Ami ayo si ọkan ni Naijiria fi ṣagba akẹgbẹ wọn lati tẹsiwaju lọ abala to kangun si aṣekagba.
o ti bọ́ sọ́wọ́ aládùúgbò rẹ.
O salaye pe, “owo ti o wole sapo ijoba fun odun 2018 je bilionu mokandinladorun, eyi ti o po ju ti odun 2017, ti o duro si bilionu mokanleladorin o-le, N71.
Nibayii, ijọba ti ni awọn ti ọwọ tẹ nibẹ yoo foju wina ofin, eleyii ti yoo ko awọn yoku lọgbọn.
Ìpàdé Buhari àti Trump: Ọ̀rọ̀ pọ̀ nínú ìwé kọ́bọ̀
 Odun yii je odun kewa ti a tin sise po pelu ajo NFF.
Ọgọrọ ọmọ ẹgbẹ oselu APC ati awọn eekan ẹgbẹ ni wọn pejo sibi ayẹyẹ naa Lọjọ Aje ni awọn aworan kan ti kọkọ jade sita, eyi to ṣafihan Godswill Akpabio pẹlu Asiwaju ẹgbẹ oṣelu All Progressives Congress, APC, Bola Tinubu.
won tun ri gba lowo awon odaran naa ni kẹkẹ atapupu  meta, ibon ilewọ meji ati isana meji.
Èyí ní ẹbi Adewura ṣe ti wọ́n fi rí òkú Adewura ní inú adágún omí ǹlá (Canal) ní àgbègbè Iyana Ipaja ni ipinlẹ Eko.
Oun naa ti jẹ ẹbun miliọnu meji aabọ Naira.
Oríṣun àwòrán, BBC Sport Àkọlé àwòrán, Awọn ololufẹ ẹgbẹ agbabọọlu Sfax n fi ina ṣere nigba ifẹwọnsẹ ẹgbẹ agbabọọlu naa pẹlu awọn agbabọọlu ilẹ Faranse ana lati ṣe ayẹyẹ aadọrun ọdun ẹgbẹ agbabọọlu ilẹ Tunisia naa ni papa-isere Mhiri in Sfax Oríṣun àwòrán, AFP Àkọlé àwòrán, Ọdọmọdekunrin apẹja ni Congo n tun awọn rẹ se ni eti omi-adagun Tanganyika ni Kalemie, ni orilẹede Ijọba-ara-ẹni Congo Oríṣun àwòrán, Reuters Àkọlé àwòrán, Nnkan ti iji Eliakim sọ aye da l'ẹgbẹ Manambonitra ni Madagascar, l'ọjọ Abamẹta.
Ijọba yoo paṣẹ fun awọn banki, ati ọja lati maa da awọn onibara to jẹ agbalagba lohun laarin aago mẹsan aarọ si mẹwa aabọ, ki wọn o to da awọn ọdọ lohun.
Àkọlé àwòrán, Aarẹ Trump ninu ọrọ rẹ fidiẹ mulẹ pe awọn Taliban ti ṣetan lati bawọn sọrọ bayii.
Taní Ibidunni Ighodalo tí gbogbo ọmọ Nàìjíríà ń selédè lẹ́yìn rẹ̀ Àjọ ọlọ́pàá, Ìjọba ìpínlẹ̀ Ọyọ jẹ́jẹ̀ẹ́ láti ṣàwárí òòsà tó ń mu ẹ̀jẹ̀ nílùú Ìbàdàn 'Ọlọ́pàá ló ń pa wá, kìí ṣe coronavirus' Èèyàn 403 ló lùgbàdì àrùn Coronavirus ní Naijiria ní Ọjọ́ Abámẹ́ta Awọn eeyan kan ti iṣẹlẹ naa ṣoju wọn ṣalaye pe ijamba ina naa ko ba ti jo ajopadukia run bẹẹ kani awọn oṣiṣẹ panapana naa tete de.
Àwọn kan sọ fún un pé, “Àwọn ọmọ-ẹ̀yìn Johanu ń gbààwẹ̀ nígbà pupọ, wọn a sì máa gbadura.
ati láti ọ̀dọ̀ Jesu Kristi, ẹlẹ́rìí òtítọ́, ẹnikinni tí ó jinde láti inú òkú ati aláṣẹ lórí àwọn ọba ilé ayé.
Adele oga agba eka oro iroyin nile ifowopamo naa, Isaac Okoroafor so ninu atejade kan nilu Abuja pe, CBN  fun awon ti o ni ase lati ta oja owo ile-okeere naa ni ogorun milionu $100 owo dollars .
Oríṣun àwòrán, @Osrt school Instagram Ẹwu nla n bẹ pẹlu bii awọn akẹkọọ ṣe pada si ileewe lasiko arun Coronavirus yii- Bisi Iyaniwura Onimọ nipa eto ọrọ aje ni Niajiria, Bisi Iyaniwura ti ni inu oun bajẹ pẹlu bii ijọba ṣe fun awọn ọmọ ileewe alakọbẹrẹ laaye lati pada si ileewe lasiko arun Coronavirus yii.
Nigbati Bàbá ti dàgbà, ó pe àwọn àgbà ẹbí lati sọ àsọtẹ́lẹ̀ bi wọn ṣe ma a pín ogún ohun lẹhin ti ohun bá kú nitori kò si iwé-ogún bi ti ayé òde oni.
O si tun ma n fi orin ki awọn gbajumọ ni awujọ.
OLUWA, fi ọwọ́ ara rẹ gbà mí lọ́wọ́ àwọn eniyan wọnyi;àwọn tí ìpín wọn jẹ́ ohun ti ayé yìí,fi ohun rere jíǹkí àwọn ẹni tí o pamọ́;jẹ́ kí àwọn ọmọ jẹ àjẹyó;sì jẹ́ kí àwọn ọmọ ọmọ wọn rí ogún wọn jẹ.
won ri opin aawẹ odun yii layo ati alaafia.
Abalọ ababọ, Ebenezer Obey pada gbe awo rẹkọọdi rẹ akọkọ jade labẹ ileeṣẹ naa, ti ọpọ rẹkọdi si pada tẹle.
Orile ede Zimbabwe ti gbẹsẹ le
Lampard to gba ife ẹyẹ European Champions League lọdun 2012 lo rọpo Maurizio Sarri lọdun yii gẹgẹ bi olukọni funn Chelsea.
O ni ko ṣeesẹ ki musulumi wa lọ gbadura nibi ti ko ba jẹ mimọ, bakan naa lawọn ọmọ lẹyin kristẹni.
Saaju asiko yi, ko si ẹni to le sọ pato boya yoo kowe fiṣẹ silẹ tabi yoo yi wa lori oye.
Wọ́n sọ fún wa pé àwọn ọ̀jọ̀gbọ́n onímọ̀ ilé-kíkọ́ kan ni wọ́n kọ́ ilé náà síbẹ̀.
Coronavirus extension in Nigeria: Ààrẹ Buhari leè pàṣẹ kónílé-ó'gbélé jákèjádò Nàìjíríà lọ́jọ́ Ajé-Kọmíṣọ́nà fétò ìlera ní ìpínlẹ̀ Ondo Oríṣun àwòrán, Twitter/Muhammadu Buhari O ṣeeṣe ki aarẹ orilẹede Naijiria o kede itẹsiwaju aṣẹ konileogbele to wa nilẹ ni awọn ipinlẹ bii Ogun, Eko ati Abuja.
Ọlọ́pàá ní kí n bọra sílẹ láti mọ bóyá obìnrin ní mí torí mo ní irùngbọ̀n ’Awọn sọja Cameroun tu mi sihoho' Ohun to ba wu ọ jẹ ninu oyun, to ba ti le ṣe ara rẹ loore dara ni jij.
Àwọn eniyan wọnyi yóo lọ máa bọ àwọn oriṣa tí àwọn ará ilẹ̀ náà ń bọ.
#EndViolenceAgainstWomen: Àwọn àmì mẹ́fà tó ń sàfihàn ọkùnrin tó ń hùwà ipá!
Ẹ gbé ọwọ́ tí kò lágbára ró.
Oko tí wọn ń kórè rẹ̀ yìí ni kí o kọjú sí, kí o sì máa tẹ̀lé wọn.
Ẹ wo bi iwọde naa ṣe n lọ.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Wọ́n sún ìsìnkú Abiola Ajimobi di ọ̀la Satide Ìtàn ìgbésí àyé olóògbé Isiaka Abiola Ajimobi Ìgbé ayé Abiola Ajimobi nínú àwòràn pẹ̀lú àwọn ǹkan tó ṣẹlẹ̀ Àlàyé rèé lórí ikú tó pa Ogun Majek Eji Gbadero, ọmọ Ibadan àti jayé-jayé ọmọ ónílẹ̀ ti wọn yẹgi fun l'Eko Lara awọn olujẹjọ naa si la ti ri aya olori ijọ Sotitobire, Arabinrin Abisola Alfa.
Níti pípa òfin rẹ mọ́, jẹ́ kí n pé,kí ojú má baà tì mí.
Ṣugbọn òpin kò níí tíì dé.
Mubarak gẹgẹ bi ọmọ ogun oju ofurufu Muhammed Hosni sọ wi pe ọjọ kẹrin oṣu karun ọdun 1928 ni wọn bi Mubarak ni Kafr-El Meselha ni iha ariwa Egypt.
Ṣugbọn kí ẹ máa kọ́kọ́ wá ìjọba rẹ̀, gbogbo nǹkan wọnyi ni yóo fun yín pẹlu.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Mistura Oseni Akintunde: Ara múmú kìí ṣe oríṣun ìfipábánilòpọ̀, ìran àwòjù ló ń fà á Bakan naa lo woye pe igbesẹ sise ipade apero miran tile asofin apapọ ilẹ wa n gbero kan wa lati fi akoko sofo ni.
Osun Coronavirus: Coronavirus ti gbẹ̀mí èèyàn mìí ní ìpínlẹ̀ Osun Oríṣun àwòrán, Adegboyega oyetola Eeyan kan ti jẹ Ọlọrun nipe nitori arun Coronavirus ni ipinlẹ Osun, nigba ti ẹni to kọkọ ni arun ọhun ati awọn oṣiṣẹ eto ilera mẹta mii ri iwosan gba.
Ẹ fi òtítọ́ ṣe ọ̀já ìgbànú yín.
Gẹgẹ bi iroyin ti ile iṣẹ iroyin NAN ti Naijiria fi sita lẹyin iwadii pe ibeere wọn tun yatọ lọtẹ yii.
Lawani yín gbọdọ̀ wà lórí yín; kí bàtà yín sì wà ní ẹsẹ̀ yín, ẹ kò gbọdọ̀ ṣọ̀fọ̀ tabi kí ẹ sọkún.
Ẹgbẹ olukọni nileewe giga fasiti Ọbafẹmi Awolọwọ, OAU nilu Ile ifẹ ti fọ si meji bayii.
Kódà nígbà ti mo mu ú tán, wéré ni mo tún rà'míì mu.
Ó ń ṣe báyìí fún ọjọ́ pupọ.
Nígbà tí ó dé ọ̀dọ̀ ìyá ọkọ rẹ̀, ìyá ọkọ rẹ̀ bi í pé, “Báwo ni ibẹ̀ ti rí, ọmọ mi?
Bí ó ti ń lọ lójú ọ̀nà, kinniun kan yọ sí i, ó sì pa á.
10 Ṣùgbọ́n rantí, aláànú ni Ọlọ́run, nítorínáà, ronúpìwàdà lórí ohun náà tí ìwọ ti ṣe èyítí ó lòdì sí òfin tí mo fi fún ọ, àti pé ìwọ náà ni a yàn síbẹ̀síbẹ̀, a sì tún ti pè ọ́ sí iṣẹ́ náà.
Wọn ni eyi yoo mu ki awọn ọdaran tete da awọn mọ, to si tun lee se okunfa iku ojiji fun awọn.
2019 Election: Ilé Asófin késí INEC láti fi N143bn sọwọ́ sí wọn lẹ́ẹ̀kan si
“ E fun wa ni iwe akosile ti e ni nipa  awọn  eniyan to lu yin ni jibiti , tabi ti wọn  gbe e yin lowo lọ, ki a le fiya to tọ jẹ wọn  lorile ede Naijiria.
Omah Lay ti fojú balé ẹjọ́ ní Uganda Oríṣun àwòrán, omah_lay Ileeṣẹ ọlọpaa Uganda ti gbe olorin takasufe ọmọ Naijiria, Stanle Didia, ti ọpọ awọn ololufẹ rẹ mọ si Omah Lay atawọn meji miran lọ sile ẹjọ.
Ní gbogbo àkókò tí ó fi ń sin Ọlọrun, Ọlọrun bukun un.
Gomina ipinlẹ Eko, Babajide Sanwo Olu jẹjẹ lati ri wi pe awọn ogiri to wo naa di titun kọ pada.
Ọba Ogunwusi seleri bẹẹ lasiko to n gbalejo awọn ọmọ igbimọ alasẹ ile iwosan naa, ti onisegun agba, Ọjọgbọn Jesse Abiodun Otegbayo ko sodi wa si aafin rẹ.
Oríṣun àwòrán, Other Àkọlé àwòrán, Àwọn ọmọ Naijiria to ti kú lóri pápá lásìkò ìfẹsẹwọ́nsẹ Emmanuel Ogoli: Ọmọ ẹgbẹ́ agbábọọlu Ocean Boys kan náà kú lori pápá, lásiko idije league, o si pada jẹ di oloogbe ni ilé iwosan.
Mo ti mú ẹ̀ṣẹ̀ rẹ kúrò, n óo sì fi aṣọ tí ó lẹ́wà wọ̀ ọ́.
Toò, kò kúkú yẹ kó yàmí lẹ́nu púpọ̀.
Idupẹ ni ọjọBọ ni oṣu kọkanla ni ọdọọdun ni orilẹ-ede America ṣe pataki pupọ sawọn eniyan ibẹ.
Minisita to n mojuto oro  ile okere, ogbeni Geoffrey Onyeama sapejuwe afojusun ajo AU gege bi, “Itosona ti o fayegba mimu igberu ba igbe-aye alaafia ati eto aabo, ti o fi mo idagbasoke eto oro aje.
) Daniele De Rossi45′52′Moussa Marega  2 – 155′   58′ 81′ 116′117′Alex Telles (pen.
Aare so pe, ”Mo dupe pupo fun akoko yin ti e n lo
3 8427 Orilẹede Sri Lanka 140 0.
Adajọ Gilbert wa paṣẹ pe ki Hushpuppi si maa naju lọ lọgba ẹwọn na, titi ti wọn yoo fi fi oju rẹ ba ile ẹjọ fun igbẹjọ to yẹ, eyi ti yoo bẹrẹ ni California, ki ọdun yii to pari.
Kí Ọlọrun, tí ó ń fún wa ní ìrọ́jú ati ìwúrí, jẹ́ kí ẹ ní ọkàn kan náà sí ara yín gẹ́gẹ́ bí ìfẹ́ Kristi Jesu, 
Bí mo tilẹ̀ kọ òfin mi sílẹ̀ ní ìgbà ẹgbẹrun, sibẹsibẹ wọn óo kà wọ́n sí nǹkan tó ṣàjèjì.
 Won ti fesun kan tele pe, o n dowobo awon ajakale aarun onigbameji to n sele ni orile-ede Ethiopia, sugbon awon to n se alatileyin re so pe iro pata ni esun naa.
Àwọn ará Beeroti ti sá lọ sí Gitaimu, ibẹ̀ ni wọ́n sì ń gbé títí di òní olónìí.
Samuẹli jẹ́ adájọ́ ní ilẹ̀ Israẹli títí tí ó fi kú.
Eniyan sá ni àwọn ará Ijipti,wọn kìí ṣe Ọlọrun.
Minisita fun ọrọ abẹle, Abdulrahaman Dambazau ni ọrọ naa ti di ti amukun ẹru rẹ wọ, o ni oke lẹ wo, ẹ o wo isalẹ.
OLUWA tún sọ fún Mose pé, “Ọjọ́ àtisùn rẹ kù sí dẹ̀dẹ̀.
Gbogbo eyi n waye, ki aṣiri kankan nipa idibo naa ma ba a tu sita lasiko to n lọ lọwọ tabi to ba pari.
Lọdun 2015 ni ajọ iṣọkan agbaye fẹsun kan ẹkun ọmọ ogun mejeeji pe wọn pa awọn eniyan lọna aitọ, ati pe wọn fipa ba wọn lo pọ.
ó sì sun turari olóòórùn dídùn lórí rẹ̀ gẹ́gẹ́ bí OLUWA ti pàṣẹ fún un.
"Obirin kan to jẹ ọkan lara awọn obi awọn ọmọ naa sọ wipe ""Ti mọ ba ranti wipe ki se l'ọrun lo wa ati wipe n ko mo iru ipo to wa, ti mo ba ronu bi wọn ti maa s'afihan aworan awọn ti wọn ji gbe, ma kan maa sukun ni lai dakẹ."
Fún àpẹrẹ, mo rí àwọn òdòdó kọ̀ọ̀kan tí wọ́n ṣẹ̀ṣẹ̀ ta, bótilẹ̀jẹ́pé ìgbà ìwọ́wé ni a wà yí.
Irina Reyder tí ó jẹ́ adarí iléeṣẹ́ BlaBlaCar ní Russia ní wọ́n fagi lé ìfìwépè òun sí ìfọ̀rọ̀wọ́rọ̀ kan pẹ̀lú iléeṣẹ́ amóhùnmáwòrán-an ti ìjọba, Channel One lẹ́yìn tí olóòtú náà rí i pé obìnrin ni òun.
Ẹsita dáhùn pé, “Bí ó bá tẹ́ ọba lọ́rùn, jẹ́ kí á fún àwọn Juu tí wọ́n wà ní Susa ní àṣẹ láti ṣe gẹ́gẹ́ bí wọ́n ti ṣe ní òní sí àwọn ọ̀tá wọn ní ọ̀la, kí á sì so àwọn ọmọ Hamani mẹ́wẹ̀ẹ̀wá rọ̀ sí orí igi.
Ancopss ni oun bawọn peju sibi ipade awọn eeyan ti eto ẹkọ gberu lọjọ Isẹgun to kọja, nibi ti gbogbo awọn ti fẹnu ọrọ jona.
Ilúmọ̀ọ́ká oníroyin Kemi Olunloyo ké sí Toyin pé ko lọ mu omi sùúrù o, nítori pé gẹ́gẹ́ bi abiyamọ tó jẹ, oun, lo nílo sùúrù jùlọ, Bakan náà lo ké si Lizzy pé, lábẹ́ àkoso bo ti wù kó rí pe, kìí ṣe ǹkan to tọ̀nà láti maa ṣepe fún ọmọ làkeji, pàápàá jùlọ ọmọ tuntun to ṣẹ̀ṣẹ̀ ń bọ wá sáyé.
ifẹhonuhan  to waye lojo Eti ni Algeria  je malegbagbe lorile ede naa.
Mo rí i pé ninu ayé yìí ibi tí ó yẹ kí ìdájọ́ òtítọ́ ati òdodo wà ibẹ̀ gan-an ni ìwà ìkà wà.
Theresia Mumbi sọ fun BBC pe, awọn ọlọpaa to n dari ọkọ ni Nairobi mu oun, ti wọn si ni ki oun bọra silẹ ki awọn ba le mọ boya lootọ obinrin loun.
Diẹ lara awọn eeyan naa ṣalaye fun BBC pe ita ni awọn sun mọju nitori wọn ko ni owo lati san fun ibusun nile iwosan ọhun.
Àwọn ọmọ ti Gadi ni: Sifioni, Hagi, Ṣuni, Esiboni, Eri, Arodu, ati Areli.
Ministerial Screening: Aregbesola, Fashola àti Gbemi Saraki wí tẹnu wọn
Fọ́tò ló ṣàfihàn ibi tí ọmọ ti Nọọsi jígbé lódún 1997 wà
Lagos-435 FCT-234 Oyo-103 Plateau-86 Rivers-71 Enugu-51 Nasarawa-41 Delta-39 Edo-39 Osun-33 Niger-31 Sokoto-23 Ondo-16 Taraba-13 Ebonyi-12 Kano-10 Abia-9 Bayelsa-8 Bauchi-7 Imo-5 Katsina-3 Gombe-1 Iye àwọn tó ń ní Covid-19 ti ń pọ̀ ju ilé ìwòsàn lọ, tó bá yá ọwọ́ wa ò ní ka mọ́ - NCDC Oríṣun àwòrán, @Chikwe_I Ajọ to n ri si igbogun ti ajakalẹ arun ni Naijiria, NCDC, ti sọ pe ọrọ Covid-19 ti n kọja oju ẹ, ati pe o ṣeṣe ki ile iwosan má le gba iye awọn to n lugbadi arun naa mọ bayii.
Ẹsira, alufaa, bá dìde, ó sọ fún wọn pé, “Ẹ ti ṣẹ̀ níti pé ẹ fẹ́ obinrin àjèjì, ẹ sì ti mú kí ẹ̀ṣẹ̀ Israẹli pọ̀ sí i.
Wo àwọn nǹkan to tún nílò NIN fún yàtọ̀ fún ìforúkọsílẹ̀ síìmù Ilé aṣòfin àgbà yọ gómìnà nípò, ẹni tó fi owó ìlú rán ọmọ lọ sí Amẹ́ríkà Amẹ́ríkà yarí pé àwọn agbégbọn tó jí akẹ́kọ̀ọ́ 344 gbọ́dọ̀ fojú winá òfin Ẹ̀ẹ̀kan láàrin ọjọ́ méjì là ń jẹun ní ìgbèkùn, ìyà jẹ wá - Akẹ́kọ̀ọ́ Kankara ṣàlàyé Sé Boko Haram ń pẹ̀ka kiri Nàíjíríà ní ìjínigbé ṣe burú báyìí?
Inú àgọ́ ni à ń gbé, a sì pa gbogbo àṣẹ tí Jonadabu baba ńlá wa fún wa mọ́.
Alukoro ọlọpaa ipinlẹ Rivers Nnamdi Omoni to fidi ọrọ yi mulẹ fun BBC sọ pe oro ọta ibọn lo ṣokunfa iku rẹ.
Láti ìrandíran rẹ̀, kò ní sí ẹnikẹ́ni tí kò ní kó àtọ̀sí, tabi kí ó ní àrùn ẹ̀tẹ̀, tabi tí kò ní jẹ́ pé iṣẹ́ obinrin nìkan ni wọn yóo lè ṣe, tabi kí wọ́n pa wọ́n lójú ogun, tabi kí wọ́n máa tọrọ jẹ.
Nítorí pé OLUWA sọ fún àwọn ará Juda ati àwọn tí wọn ń gbé Jerusalẹmu pé, “Ẹ tún oko yín tí ẹ ti patì tẹ́lẹ̀ kọ, ẹ má sì gbin èso sáàrin ẹ̀gún.
Amọṣa ẹsun mejeeji yii ko ni idajọ iku ninu.
Òṣìṣẹ́ àjọ FRSC méjì bọ́ sọ́wọ́ àwọn ajínigbé l'Ọsun Ọgbà ẹ̀wọ̀n ni Naira Marley yóò ti wo ìbúra Buhari ní May 29 Àtunbọ̀tán òjò òwúrọ̀ ọjọ́ ajé nílùú Eko Alukoro ẹgbẹ naa, Maxwell Dan ninu atẹjade naa wi pe ijọba aarẹ Buhari fi iwa ẹlẹyamẹya ba wọn lo.
Ijọba ipinlẹ Edo wa rọ awọn ara ipinlẹ Edo lati gba alaafia laaye , ẹmi ati dukia awọn eniyan le wa lalaafia kaakiri ipinlẹ naa.
Ireti awọn eniyan ni pe awọn agbegbe ti idibo yoo ti waye nikan lo yẹ ki wọn o ti pa iru aṣẹ bẹ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Restructuring: Àgbékalẹ̀ orílẹ̀èdè Nàìjíríà lọ́wọ́ yìí kò lè fàyè ìdàgbàsókè sílẹ̀ fún ẹ̀yàkẹ́yà-Ọ̀jọ̀gbọ́n Banji Akintoye Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Restructuring: Àgbékalẹ̀ orílẹ̀èdè Nàìjíríà lọ́wọ́ yìí kò lè fàyè ìdàgbàsókè sílẹ̀ fún ẹ̀yàkẹ́yà-Ọ̀jọ̀gbọ́n Banji Akintoye 19 Èbibi 2020 Ọjọgbọn Banji Akintoye ni aṣiwaju ẹya Yoruba lọwọ yii, nitorinaa obi ọrọ nipa bi idagbasoke ẹya Yoruba yoo ṣe kẹsẹjari gbo ni ẹnu rẹ.
O ni kii ṣe idagbasoke, iduroṣinṣin ati ilọsiwaju nikan ni asiko rẹ ti mu wọ ipinlẹ Ọyọ, amọ o tun mu ki iṣọkan, ifẹ ati ireti jọba ni ipinlẹ naa ati Naijiria lapapọ.
Gẹgẹ bii iwadii ajọ to n ṣewadi ati igbogun ti ajakalẹ arun lorilẹede Naijiria, eeyan eedẹgbẹta ati mọkanlelọgbọn ni wọn ti funra aisan iba Lassa si bayii lorilẹede Naijiria; mẹrinlelọgọrun ninu wọn ni wọn si ti fi idi rẹ mulẹ pe wọn ni aisan naa ti eeyan mẹfa si ti jade laye nipasẹ rẹ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Ìdáhùn àwọn olùdíje Ogun ṣọ̀tọ̀ọ̀tọ̀ lórí ẹ̀kọ́ ọ̀fẹ́' Lai Muhammed wa fikun wi pe awọn n sa gbogbo ipa awọn lati ri daju wi pe Leah Sharibu gba itusilẹ.
Minisita to n ri si oro ifitonileti ati Asa lorile-ede Naijiria, ogbeni Lai Mohammed so pe, latari akitiyan ati ipa lati samulo ero igbalode Digital Switch Over project, Naijiria yoo je orile-ede ti o tobi julo nile Afrika ti o fayegba wiwo ero igbalode amohunmawaron ofe, eyi ti a mo si Free To Air Television platform.
Alatako Boris Johnson ni oun gbagbọ pe iṣẹ akinkanju ti ko ni ja ilẹ Gẹẹsi kulẹ ni Boris a ṣe ni orilẹ-ede wọn.
Kanye West Breakdown: Ìpolongo ìdíje sípò aàrẹ Kanye ti gbéraṣo ní Charleston
Awọn asofin mẹwa latinu ẹgbẹ oselu Republican, tii se ẹgbẹ oselu Trump, lo darapọ mọ ẹgbẹ oselu alatako rẹ, Democrat lati yọ nipo.
Eniyan kò lè rí Ọlọrun, ṣugbọn ọmọ yìí ni àwòrán rẹ̀, òun ni àkọ́bí ohun gbogbo tí a dá.
Diẹ lara awọn ẹri ti wọn n fi kaakiri ori ayelujara niyi: Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, BIAFRA at 50: Ìhàlẹ̀ ológun ni Gowon ni ká kọ́kọ́ fi bẹ̀rẹ̀- Aladejẹbi Èyí ni bí ogun abẹ́lé Biafra ṣe bẹ̀rẹ̀ ní Nàìjíríà Ọ̀pọ̀ àwòrán tó ń ṣeni láàánú rèè nípa ogun abẹ́lé Nàíjíríà Àwọn ohun tó yẹ kí o mọ̀ nípa Gómìnà Imo tuntun Hope Uzodinma Irọ̀ ni ìjọba ń pa, Ikọ Amọtẹkun ba ofin Naijiria mu- Ìgbìmọ̀ Yoruba Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 3 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 5 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Ọrọ ariya naa si ni ọpọ eeyan n jẹ l'ẹnu lori ayelujara, pe o dara bi ijọba ṣe dawọn duro.
Jakọbu nífẹ̀ẹ́ Rakẹli, nítorí náà, ó sọ fún Labani pé, “N óo sìn ọ́ ní ọdún meje nítorí Rakẹli, ọmọ rẹ kékeré.
Ninu ipade apero mii to tun waye lọjọ Aje lori ifẹsẹmulẹ eto aabo to peye lẹkun iwọ oorun guusu Naijiria, ni wọn ti sisọ loju rẹ faraye pe ẹgbẹ akọya nilẹ Yoruba, OPC tii fi ẹnu ọrọ jona pẹlu ileesẹ ọlọpa ilẹ wa, lati ja ogun eto aabo to mẹhẹ naa nilẹ Yoruba.
South Africa: Iṣẹ́ bọ lọ́wọ́ adarí ile-ẹ̀kọ́ ìmọ̀ ìkọ́lé
Gege bi Liu se so lojo Aje(Monday) saaju agbekale ise akanse nla ohun nile igbimo asofin.
 Ó jẹ ́ olùdarí institute for bioengineering , biotechnology , àti quantitative biomedical research àti pé ó ti gba jẹ ́ olùṣèwádìí ti howard hughes medical institute ( hhmi ) lati ọdún 1986 .
Nkan tí a mọ nípa iṣẹ̀lẹ̀ náà Dornier-228 twin-turboprop ti ilé iṣẹ́ aládani kan Busy Bee ra ló dédé já lẹ́yìn ìṣẹ́jú kan to gbéra , èyí jẹ́ ǹkan ti ẹnikan sọ fun BBC ni pápákọ ofúrúfú Goma.
Ètò ẹ̀kọ́: Buhari dín owó fọ́ọ̀mù NECO, JAMB kù
Ṣugbọn ìwọ̀n ati òṣùnwọ̀n rẹ gbọdọ̀ péye, kí ọjọ́ rẹ lè pẹ́ lórí ilẹ̀ tí OLUWA Ọlọrun rẹ fún ọ.
Ìtàn Mánigbàgbé: Èyí ni àwọn Ọba ilẹ̀ Yorùbá mẹ́jọ tí wọn lé kúrò lórí oyè
Tinubu kọ lẹta si Odigie Ọjọ́ Sátidé lá fẹnu PDP gbolẹ̀ -Tinubu Ẹfunroye Tinubu - Ògbóǹtagí oníṣòwò, olówò ẹrú àti afọbajẹ Rochas Okorocha, káàbọ̀ sí àwùjọ àwọn gómìnà tí EFCC ń wá - Fayose Ajọ SEC tun fi ofin de igbakeji oludari ileeṣẹ Oando pẹlu pe iwa ti wọn hu na ko bojumu rara.
Nígbà náà ni ìyá àwọn ọmọ Sebede wá sọ́dọ̀ Jesu pẹlu àwọn ọmọ rẹ̀.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Imam tó ṣí Mọ́ṣálásì fáwọn Krístẹ́nì sọ ìdí tí kò fi lè ta wọ́n nù Alufa Wuye to fi ẹmi imoore han sọ pe, idunnu ati iyalẹnu ni ẹbun Tijjani jẹ fun oun, nitori pe oun ko gba iru ẹbun bẹ ẹ ri lọwọ obinrin Musulumi.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, AFCON 2019: Inú mi dùn pé mo jẹ́ ẹni àkọ́kọ́ tó ṣojú Nàíjíríà fún ìgbà 100 Lara awọn to maa gba bọọlu fun Naijiria ni Osinachi Ohale, Onome Obi, Rita Chikwelu, Francisca, Desire Oparanozie atawọn mii.
Ìjọba Ológun fi ibọn àti ipá gbé ara wọn si ipò Òṣèlú, wọn fi ipá kó gbogbo ohun amáyé-dẹrùn si abẹ́ Ìjọba àpapọ̀.
Lukaku wa lara awọn agbabọọlu ti Man U ko lo daadaa mọ ni saa bọọlu to lọ, Marcos Rashford lo maa n saa ba gba aye rẹ.
O gbe ẹni ati irọri lọ sori oke lọ gbadura fun arun Coronavirus lati dopin.
Nítorí pípé mi ati òdodo mi, pa mí mọ́,nítorí pé ìwọ ni mo gbẹ́kẹ̀lé.
Coronavirus in Nigeria: Wo àwọn ohun tó yẹ kí o mọ̀ nípa ọ̀nà láti dáàbò bo ara rẹ lọ́wọ́ Coronavirus
Nibẹ ni iyawo àti ọpọ awọn ọrẹ wọn n gbe ti wọn yoo si se ti ibilẹ ni india ninu oṣu kọkanla, sugbọn Coronavirus bẹ silẹ ti gbogbo nkan si daru.
Ó ga ní ọgọfa igbọnwọ (mita 54), ìbú rẹ̀ sì jẹ́ déédé ìbú tẹmpili.
O gba pé ilakaka oun yoo ja si ọpẹ ati ayọ ti ọmọ naa ba le da ṣe aye rẹ lẹyin iku oun.
" Ọrọ̀ aje to wa ninu wahala Laipẹ yii ni ọrọ aje Naijiria ṣẹṣẹ fi àpẹrẹ ipadabọ sipo han, lẹyin ti didojuru rẹ dopin lọdun 2017.
naa ,lo ti so pe awon atunse ti ile-igbimo asoju-sofin ,se si iwe abadofin eto
Àwọn ará Ijipti lo àwọn baba ńlá wa ati àwa náà ní ìlò ẹrú.
Awọn eeyan kan tilẹ tun pa aṣamọ rẹ pe awọn gan tun ni iyọ oṣelu.
Ijoba apapo orile ede Naijiria  ti n tepele mo ona lati tubo maa gbokun ti iwa ibajẹ.
Ṣùgbọ́n má ṣe ni èrò láé pé, ìwà ọ̀lẹ ni ó mú mi sọ irú ọ̀rọ̀ wọnyí, nítorí bí ìwọ bá ni èrò wọ̀n-ọnní, a jẹ́ pé èdè mi kò yé ọ: iwọ a sì da bi ẹni tí ó pe àgùntàn ní mààlúù, tí ó pe mọ́tọ̀ ní kẹ̀kẹ́, tí ó pé ayé ni ọ̀run alákeji.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fọ́nrán ohùn, Ilé iṣẹ́ FRSC àti àwọn agbófinró tóku yòó yẹ̀wé ọkọ̀ wò Oga agba FRSC kò ṣai fẹnu bá a pé, loorekoore ni wọn yóò máà ṣàyẹ̀wò sí àwọn ọmọ àjọ náà lójú pópó láti mu ẹ̀dínkù ba ìwà ìbàjé owó ẹyin gbígbà.
Ọmọ Nàìjíríà kan gbé Fásitì Oxford lọ sílé ẹjọ́ tàko oríkí ọrọ 'Mortgage' nínú ìwé àtúmọ̀ ọrọ Ojo sọ ipa ti Al-Mustapha kó fun oun nigba ti wọn jọ wa lẹwọn ati ajọ JLAA ati agbẹjọrọ Kingsley Ughe Esq tó pada kọwe si gomina Fayemi nigba to de ori aleefa.
Bi wọn se pa ọga SARS 'Àwọn SARS ló yìnbọn pa ìyá mi' #EndSARS: Pe nọ́mbà wọ̀nyìí láti fẹjọ́ ọlọ́pàá SARS sùn SARS já wọ ilé àwọn akẹ́ẹ̀kọ́ fásitì Akungba Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, SARS: Awọn ará ìlú fi ẹ̀rí síta nípa ìrírí wọn Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, SARS ti bẹ̀rẹ̀ ìgbésẹ̀ láti yọ àwọn ọ̀bàyéjẹ́ kúro Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Akọsilẹ ìtan tilẹ sọ pe Daura ni orisun ede Hausa ati awọn ẹya Hausa.
Kàkà bẹ́ẹ̀, Balaamu ọmọ Beori ará Petori, ní Mesopotamia, ni wọ́n bẹ̀ pé kí ó wá gbé yín ṣépè.
 Àwọn àmì yìí maa ń lo ọ ̀ sẹ ̀ díẹ ̀ , tí ìbẹ ̀ rẹ ̀ àkóràn yìí kíì sábà fa ikú .
Ṣé ẹni tí ń pa ẹ̀mí rẹ mọ́ kò mọ̀,àbí kò ní san án fún eniyangẹ́gẹ́ bí iṣẹ́ ọwọ́ rẹ̀?
Leyin iwadii ile-ejo naa, won yoo kowe iyoni kuro nipo sile-igbimo asofin, o seese ki olori ijoba gbe igbese yiyo Aare naa kuro nipo.
Fifopin si ìṣẹ́ àti òṣì ọgọrun un miliọnu eniyan ti wọn ba ni adari rere.
Ẹwẹ, minisita ere idaraya ni o da oun loju pe ikọ agbabọọlu Naijiria yoo tubọ fakọyọ ninu ifẹsẹwọnsẹ wọn toku.
Ẹnikẹni ti ara rẹ kii balẹ, to maa n re galegale, ti kii le duro si oju kan, tabi to jẹ oni iwanwara, to ba n jẹ ewe Lettuce, yoo ri pe irọrun ba agọ ara rẹ.
 tíí ṣe alákoso oòkà ́ n lé lógójí orílẹ èdè náà .
Nígbà tí ọ̀gá àwọn ẹ̀ṣọ́ ti Tẹmpili ati àwọn olórí alufaa gbọ́ ìròyìn yìí, ọkàn wọn dàrú; wọ́n ń ronú pé, irú kí ni eléyìí?
Ajọ WHO wa ke gbe amọran kalẹ pe yoo dara o ki gbogbo eeyan maa ṣe eto inawo ori ayelujara ti a mọ si Cashless policy bi wọn ba fẹ ra ohunkohun.
Ki n má fa ọ̀rọ̀ mi gùn bí ilẹ̀ bí ẹní, mo ní ayọ̀ láti sọ fún ọ pé, àti ìgbà tí ọkùnrin náà ti dé ni a ti ń ṣiré tí a ń gbádùn ara wa, níwọ̀n ìgbà tí ó si ti jẹ́ pé, ìwọ ọ̀rẹ́ mi, tí oj jẹ́ aládàágbò mi ni o tì ń ṣe ìtọ́jú mi ní mẹ́sàn-án mẹ́wàá kí òun tóó dé ìhín, mo tànmọ́ọ̀ pé ohun yíyẹ ni, ẹ̀tọ́ sì ni pẹ̀lú, wí pé kí èmi àti òun wá, kí àwa mẹ́tẹ̀ẹ̀ta fi ojú gán-ánní ara wa.
Oríṣun àwòrán, @RemoStarsSC ₦400 péré ni àfẹ́sọ́nà mi nílò, ìfẹ́ obìnrin yìí sì ló sọ mi di adigunjalè - Iṣọla Oyenusi Oluwo yí ìpinnu padà,Telu lóun yóò tẹlé àṣẹ lọ rọọ́kún nílé ṣùgbọ́n.
Amẹ́rika dá akẹ́kọ̀ọ́ padá nítori Facebook A ń fikunlukun pẹ̀lú FBI láti mú àwọn Yahoo Boys"" tó kù- EFCC Ijọba tí júwọlẹ̀ fún Amẹrika lóri iwé ìrìna!"
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Fídíò BBC ń fa gbùrù, gbùrù ń fa igbó ilé iṣẹ́ apoògùn 3 Èbibi 2018 Àkọlé àwòrán, Òkan lára àwọn ilé iṣẹ́ ti Fídíò BBC mẹ́nubà Ilé iṣẹ́ apoògùn Bioraj ni Ilọrin, ìpínlẹ̀ Kwara ti dá Baba Ibeji dúró Bí fídíò BBC lórí oògùn ikọ́ olómi ṣe ń gbilẹ̀ síi ni ó ń fa gbùrù fún ilé iṣẹ́ apoògùn àti ìjọba, bẹ́ẹ̀ náà ni gbùrù àwọn ilé iṣẹ́ apoògùn tí ń fa igbó àwọn òṣìṣẹ́ wọn Ile iṣẹ́ apoògùn Emzor ló kọ́kọ́ da òṣìṣẹ́ rẹ́ ti igbá ìwà ìbàjẹ́ yìí ṣi mọ́ lọ́wọ́ dúró.
gomina Orthom, nigba ti o ni iye ibo  345, 155 lati wa ni ipo keji.
Sibẹsibẹ, ìwọ Sedekaya, ọba Juda OLUWA ní wọn kò ní fi idà pa ọ́.
A gbo pe eeyan marun lara awọn ti o n tukọ ọkọ oju omi naa wa lalafia.
Ẹ káwọ́ lérí, kí ẹ káàánú nítorí àwọn oko dáradára,ati nítorí àwọn àjàrà eléso;
Bí ọwọ́jà ìjọba mi kò bá tíì dọ́dọ̀ yín, ẹ ṣe sùúrù pẹ̀lú wa- Ààré Buhari bẹ̀bẹ̀ Ìdí rèé tí Donald Trump ṣe fìdí rẹmi nínú ìbò ààrẹ Amẹrika ''Mi o le gbagbọ pe emi, to jẹ pe mi o rile gbe, ti awọn ọrẹ gba sile, lo wa di onile niluu London, ile ti kii ṣe ẹyọ kan amọ meji,'' Alimi lo sọ bẹẹ.
Saulu dáhùn pé, “Ọlọ́run yóo bukun ọ, ọmọ mi, o óo máa ṣe àṣeyọrí ninu gbogbo ohun tí o bá ń ṣe.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fọ́nrán ohùn, Ilé ẹjọ́ kòmítẹlọ́rùn yá lórí ìbò gómìnà Oṣun- PDP Ni ti Gomina Gboyega Oyetola oni nkan gan funra rẹ, ohun to sọ ko ju bayii lọ.
 Fun idi eyi a gbọdọ mu awọn iwa to le mu aawọ wa laarin ara wa kuro lọkan wa.
Adebisi Idikan: Òun ló gba Ìbàdàn sílẹ̀ lọ́wọ́ ìyà owó orí sísan
Ero amohunmaworan ile Syria lo safihan eefin ati ibugbamu ado oloro ninu ikolu naa.
" Lere Ọlayinka tó jẹ́ agbẹnusọ fún Gómìnà ìpínlẹ̀ Ekiti tẹ́lẹ̀ rí, Peter Ayodele Fayoṣe ti sọ wí pé gbogbo ìwé àti ẹ̀rí ni àwọn ti kó lọ síwájú ilé ẹjọ́ tí ilé ẹjọ́ sì ti rí àrídájú rẹ̀.
 ""Ko si igba ti wọn ba pe ipade apero ti ko ni la owo lọ"" Ọrọ Ajibola yii lo tun ṣe rẹgi pẹlu ti amofin James Ajibola to fi ilu Ibadan ṣe ibujoko."
Ṣugbọn àwọn olórí alufaa rú àwọn eniyan sókè pé Baraba ni kí ó kúkú dá sílẹ̀ fún wọn.
Nibẹ lo si ti ṣe ileri pe ijọba apapọ ko ni sun, bẹẹ ni ko ni wo titi ti yoo fi rẹyin ipenija aabo to mẹhẹ eleyi to n doju kọ orilẹ-ede Naijiria bayii.
Bótilẹ̀ jẹ́ pé Aisha Buhari ni kii ṣe pe ọmọ òun ni àpẹrẹ pé òun ni ààrun náà, sùgbọ́n àwọn kan gbọdọ tẹ̀lé òfin ti mínísita fi ilera àti NCDC là silẹ.
Buhari, máṣe gbá ìpànìyàn Lekki sórí ààtàn, kò yẹ́ kí ológun yin ọ̀dọ́ níbọn - Bode George Ilẹ̀ Amẹ́ríkà wà lẹ́yìn àwọn olùwọ́de, Buhari dẹ́kun ìpànìyàn - Joe Biden Ohun tí ojú ìyàwó mi rí lọ́wọ́ SARS kò ṣe é fẹnusọ- Poju Oyemade Ooni Ogunwusi àti Wole Soyinka kòrò ojú sí ìṣẹ̀lẹ̀ Lekki Tollgate Oríṣun àwòrán, Instagram Àwọn oníjàgídìjágan kọlu aàfin Oba ìlú Eko àti iléesẹ́ ìròyìn LTV Aisha Buhari polongo àwo orin tó ní Nàíjíríà ń ṣun ẹ̀jẹ̀ lásìkò ìwọ́de EndSars: Aisha Buhari kígbe kí ìjọba gba àwọn ará Àríwá lọ́wọ́ ètò ààbò tó mẹ́hẹ Iyawo aarẹ Naijiria, Aisha Buhari ti kesi ijọba lati gbe igbesẹ ni kiakia, nidi ipese eto aabo to mẹhẹ ni ẹkun iwọ oorun Ariwa orilẹede yii.
Oríṣun àwòrán, kano Àkọlé àwòrán, Sááju ààwẹ Ramadan Àwọn ọlọpàá Sharia n mú aṣewo àti ọdaràn nípìnlẹ̀ Kano Ipínlẹ̀ Kano jẹ ọkan nínú àwọn ìpínlẹ̀ Nàìjíríà to ń lo ofin Sharia ti Hasbah si dúro gẹ́gẹ́ bii ọlọpàá ẹsin fún ipinlẹ̀ náà.
Corornavirus: Lọ́jọ́ Ajé làwọn òṣìṣẹ́ ìjọba ìpínlẹ̀ Oyo láti ipele kẹtàlá padà sí ẹnu iṣẹ́ Awọn oṣiṣẹ ijọba ipinlẹ Ọyọ to n bẹ ni ipele ikẹtala soke ti wọle pada sẹnu iṣẹ lonii.
Àkọlé àwòrán, Caracas, Venezuela Bi lẹwọn ṣe n pọ sii ni El Helicoide ni awọn aṣọgba n wa ọna ati tun wa aaye sii.
Awọn igbimọ agba ọjẹ oludibo alaṣẹ ti wọn n pe ni Electoral College gan an lo lagbara ati yan aarẹ o.
Mo mọ̀ pé o kò jẹ́ gba àwọn eniyan burúkú mọ́ra.
Ọpọlọpọ eniyan lai yọ ọmọde tabi agbalagba silẹ lo ti ku iku ojiji nitori aiṣe akiyesi ara wọn.
O ní nínú àwọn ẹlẹ́wọ̀n méjìlá táwọn jọ se ìdánwò náà, òun ni òun léwájú gbogbo wọn pẹ̀lú máákì 248.
Alukoro fun ileeṣẹ ọlọpaa Eko, Bala Elkana, ninu atẹjade kan sọ pe iṣẹlẹ naa waye lasiko ti Ọga ọlọpaa kan, Inspẹkitọ Mohammed Akeem ati awọn ọmọ ikọ rẹ n mu olori ikọ janduku kan, Ikechukwu Monye lọ si ibi ti oun ati ikọ rẹ ma n ko awọn nkan ija oloro wọn pamọ si ko to di pe awọn ọmọ ẹgbẹ rẹ pade wọn lọna ni adugbo Ajisegiri, l'agbegbe Ilupeju.
Ìtìjú bá wọn tóbẹ́ẹ̀ gẹ́ẹ́ tí wọn kò lè pada sílé.
Yóo máa so ọmọ kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ mọ́ ìtàkùn àjàrà,yóo so àwọ́nsìn kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ mọ́ ìtàkùn àjàrà dáradára,bẹ́ẹ̀ ni oje àjàrà ni yóo máa fi fọ ẹ̀wù rẹ̀.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Coronavirus cases in Africa: Ijọba ipinlẹ Oyo ti kọ ẹgbẹsan irẹsi to jẹ iranwọ ti ijọba apapọ fi ransẹ si wọn.
Yíyọ àwọn ǹkan tó le ṣe àkobá fún ara kúrò ṣe pàtàkì nítorí kìí ṣe òunjẹ ọhun gan ni kò dára bi ko ṣe awọn èròjà kan lára rẹ̀.
Ọmọwe Babatunde ni nitori ki ọjọ iwaju awọn akẹkọọ to n kọ idanwo lọwọ, baa le dara, ni wọn ṣe n se iwọde.
Orúkọ ekinni ni Baana, ti ekeji sì ni Rekabu, ọmọ Rimoni, ará Beeroti, ti ẹ̀yà Bẹnjamini.
Idi ree ti awọn eeyan Naijiria ṣe n foju sọna lati mọ ẹni ti yoo di ipo aarẹ ile aṣofin agba mu labẹ saa kẹsan ile aṣofin Naijiria.
Amọ akọnimọọgba Barca fun ra rẹ, Quique Setien ni oun ko tii le sọ bo ya oun yoo fi ẹgbẹ agbabọọlu naa silẹ laipẹ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Osun governorship election: PDP àti APC fàdúrà jagun ṣáàjú ìdàjọ́ ìgbìmọ̀ tó n gbẹ́jọ́ ìdìbò Ọṣun 21 Ẹrẹ̀nà 2019 Oríṣun àwòrán, facebook Diẹ lara awọn ọmọ ẹgbẹ oṣelu All Progressives Congress (APC) ati Peoples Democratic Party (PDP), ti n ṣe eto aawẹ ati adura lati le ri ojurere gba lọdọ igbimọ to n gbọ ẹsun to jẹyọ lẹyin idibo gomina to waye nipinlẹ Ọṣun lọdun 2018.
Gẹgẹ bi ohun ti a ri ka ninu iwe iroyin Naijiria kan,The Cable, adajọ agba Onnoghen ''fi iwe ikọwefiposilẹ rẹ sọwọ si aarẹ Buhari ni ọjọbọ lẹyin ọjọ kan ti igbimọ to n risi ọrọ eto idajọ NJC fi abajade iwaadi wọn ranṣẹ si aarẹ Buhari.
ohun tí òfin ( 27 ) yìí ń so nip é tí a bá rí òrò-ìse kan , gégé bí elédè , a ó mo sàkáání ibi tí a ti lè bá a .
Ààrin àwọn kinniun ni mo dùbúlẹ̀ sí,àwọn tí ń jẹ eniyan ní ìjẹ ìwọ̀ra;eyín wọn dàbí ọ̀kọ̀ ati ọfà,ahọ́n wọn sì dàbí idà.
Nigba to n sọrọ pẹlu awọn akọroyin leyin ti ileeṣẹ apogun Pfizer kede abajade esi ayẹwo rẹ lori abẹrẹ ajẹsara naa, Dokita Ogbuagbu ni omi ṣi n bẹ laamu ati pe iṣẹ ṣi pọ ni ṣiṣe lati fi da awọn eeyan loju pe ko sewu pẹlu abẹrẹ ajẹsara naa.
" Nigba ti wọn bii pe iru aṣiṣe wo lo ju ale yiyan lọ, aya gomina ana nipinlẹ Ọyọ Abiọla Ajimọbi naa fesi pe ọpọ awọn obinrin lo n da ile kọ lẹyin ọkọ wọn, eyi buru pupọ.
Lati ibẹrẹ pẹpẹ ni mo ti n ṣatilẹyin fun awọn oluwọde naa, gẹgẹ bi akọrin Fuji, ọpọlọpọ awọn akẹẹgbẹ mi si lo ṣe bẹẹ."
Ilé isẹ́ tó ńrí sí ọ̀rọ̀ àbò ní orílẹ̀èdè Amẹ́ríkà sọ pé àwọn ìbúgbàmù náà ta bá báríkè àwọn ológun kan ní Damascus èyí tíí se olú ìlú orílẹ̀èdè Syria àtàwọn agbègbè méjì míì.
Oríṣun àwòrán, Others Ere ẹni to lagbara julọ(Thug of War): Bi o tilẹ jẹ pe awọn ọmọde ko mọ orukọ ti wọn n pe ere yii nigba naa, wọn ma n pin ara wọn si meji, ti ẹni to si lagbara julọ ni ikọ mejeeji yoo lewaju, ti wọn a si ma a fa okun ni ọna mejeeji.
 Àwon àbùdá àdámọ ̀ ti olùsọ èdè rẹ ̀ gbọ ́ dọ ̣ ̀ mọ ̀ ni àwon wònyí .
Ọ̀pọ̀ eniyan ni ó ń tẹ̀lé e tí ó sì wòsàn níbẹ̀.
Ileeṣẹ ologun Naijiria ti ri oku Ọgagunfẹhinti, Muhammed Alkali, ti wọn n wa, ni abule Guchwet nipinlẹ Plateau.
Wọ́n gé orí Orebu ati ti Seebu, wọ́n sì gbé wọn wá sí ọ̀dọ̀ Gideoni ní òdìkejì odò Jọdani.
O fikun un wi pe awọn Gomina ti awọn eniyan dibo yan lẹtọ lati pejọ, ki wọn wa ọna lati ri i wi pe aabo to daju wa fun awọn eniyan ilẹ ati agbegbe wọn.
Baba mi ni àgbẹ̀ tí ń mójútó ọgbà àjàrà.
Awa n kesi awọn eeyan to fori kata isẹlẹ aidaa yii lati bomi suuru mu.
Ìwé tí mo rà fún un ní àìpẹ́ yìí ó ti sọ ọ́ nù, ẹ̀wù tí mo rà fún ùn ní ijọ́sí ó ti fà á ya, ẹni tí ó jẹ́ alága ní ìdí ìrẹ̀sì, baálẹ̀ gaàrí, ọba nínú iyán, ènìyan pàtàkì ní ìdí ọbẹ̀, ẹni tí ì ṣe ọ̀rẹ́ oóúnjẹ, ọ̀tá ẹni tí ń ṣiṣẹ́, ọ̀rọ̀ ọmọ náà pọ̀ ju ohun kíkà lọ, nítorí náà, ìwọ ẹbọra òde ọ̀run, má ṣáí bá mi wá ibi tí n óò gbé ọ̀ràn yìí kà, ènìyàn rírọ̀ ló wù mi, n kò fẹ́ aláìgbọ́ràn ọmọ.
Nínú àtẹ̀jáde náà ni wọ́n ti kọọ́ wí pé, ṣaájú ìdìbò abẹ́lé ẹgbẹ́ òṣèlú All Progressives Congress ti yóò wáye ni ìpińlẹ̀ Ondo ní ogúnjọ oṣù kèje, ọdún 2020, lábẹ́ gómìnà ìpínlẹ̀ Yobe Mai Mala Buni tó ń jẹ́ adelé alága ètò àti ìpètù sááwọ̀ ẹgbẹ́.
Fi àwọn ọmọ rẹ, aláìníbaba sílẹ̀,n óo pa wọ́n mọ́ láàyè,sì jẹ́ kí àwọn opó rẹ gbẹ́kẹ̀lé mi.
Border Closure: Mínísítà fétò ìṣúná ní fún ìgbà díẹ̀ ni wọn yóò fi ti ẹnu bodè pa
(72) oludije fun ipo aare labe  egbe Peoples Democratic Party, PDP.
"Ibanijẹ lo jẹ fun wa nigba ti a gbọ iṣẹlẹ buruku yii, o si yẹ ki ijsba apapọ tete wa wọrọkọ fi ṣada ki irufẹ eyi ma baa tun waye mọ.
Peteru sọ fún un pé, “Wò ó ná!
Oríṣun àwòrán, @HistoryVille Àkọlé àwòrán, Wọn bi i ni ọjọ kẹrinla, oṣu kọkanla, ọdun 1864.
Eyi ti ko ba tun duro gẹgẹ bii itunu fun Chelsea ni igba ti alamojuto ere naa fun fere fun pẹnariti, iyẹn gbe e silẹ ko gba a si sawọn ṣugbọn igbo rere ni Barkley agbabọọlu Chelsea to gba a gba a si.
Rẹ́díò Fayose di títìpa l'Ekiti Bàbá ọlọ́mọ márùn-ún pokùn so ní Ekiti Ganduje pe awọn darandaran si Kano Ṣé Fulani daran-daran ni àwọn tó n jí ènìyàn gbé ní ìpínlẹ̀ Ondo?
Orúkọ àbísọ rẹ̀ ni Oluwaṣeyi Aletile.
Gẹgẹ bi asiko ti eso yii maa n jade ti de bayii, ọpọlọpọ fẹran lati maa gbadun aadun tabi kikan rẹ.
Olóòtú ìjọba Gẹ̀ẹ́sì yan ọmọ Yorùbá ní Mínísítà Àṣírí mẹ́wàá tí mo mọ̀ nípa Boko Haram-Naomi Adamu Agbẹjọrọ naa wa parọwa si ijọba lati jawọ nipa lilo agbara wọn laitọ, ti o si kesi awọn ara ilu naa lati ma a ṣe ifẹhọnu wọn ni ọna to ba ofin mu, ti ko si ni la ẹmi lọ.
Nítòótọ́ yóo tanná bí òdòdó,yóo yọ̀ ṣẹ̀ṣẹ̀, yóo sì kọrin.
Lọ, kí o sì mú Absalomu, ọmọ mi, pada wá.
Lára ilẹ̀ ẹ̀yà Sebuluni, wọ́n fún wọn ní Rimono ati Tabori, pẹlu àwọn pápá oko àyíká wọn.
Joẹli ni orúkọ àkọ́bí, èyí àbúrò sì ń jẹ́ Abija.
Awọn ọlọpaa ni iwadii ti bẹrẹ lori iṣẹlẹ naa Iṣẹlẹ idajọ ọwọ ti di eyi to n fi ojojumọ waye ni ipinlẹ Ọyọ bayii to si nkọ lominu nibẹ.
At'oun at'ọmọ ọdun mẹtalelogun lo bomi lọ ní igbiyanju wọn lati rekọja odo.
Ninu ọrọ ti wọn nibi ipade apero naa, Ọba Alajasa ti Ajasa, Ọba Sule Suberu ati awọn alẹnulọrọ miiran gboriyin fun akitiyan Gomina Akinwunmi Ambọde ati Aṣofin Bisi Yusuf ti o n ṣoju wọn ninu Ile Igbimọ Aṣofin Ipinlẹ Eko, paapaa fun awọn ọna mọkandinlogun ti wọn ṣẹṣẹ ṣi ni ẹkun idibo Alimọṣọ laipẹ yii, eleyii ti o ṣadinku sunkẹṛ-gbakẹrẹ ọkọ ni agbegbe naa.
Agbẹnusọ ile iwosan UCH wa ke pe ijọba lati ṣalaye ohun ti o fi miliọnu mejilelọgbọn ra gan an fun UCH.
, ẹgbẹ́ òṣèré tíátà pàṣẹ fún Lizzy àti Toyin Ọwọ́ sìkún ọlọ́pàá tẹ afurasí lórí ẹ̀sùn ìpaǹìyàn ni Port Harcourt Àjò ní ààrẹ Tunísia nígbà kan rí kú sí.
Duro Ladipọ, ìlúmọ̀ọ́ká òṣèré tíátà àti ọmọ àlúfà tí kò gbàgbé àṣà ìbílẹ̀ Hubert Ogunde rèé, baba àwọn òsèré tíátà Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí 2:07 Fídíò, Zainab Aliyu: Mo sọkún títí, ojé tán lójú mi ní àhámọ Saudi, Duration 2,0716 Èbibi 2019 Drivers lincense renewal: Ẹgbẹ̀lẹ́gẹ̀ àwakọ ló ń lo iwé ìrinà ọ̀kọ̀ tí kò koju oṣùwọn- FRSC16 Èbibi 2019 Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí 2 sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 2:23 Fídíò, Water Generator: Ó leè ṣiṣẹ fún wákàtí mẹfà, kó tó sinmi, Duration 2,2310 Òkùdu 2020 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
Awọn eeyan wọnyi naa ni iroyin tun fi kun un pe wọn n gbero ati lọ kọlu aafin kabiyesi Oluwo eleyi ti wọn ni awọn araalu gbọ ti wọn si fariga pe ko ni ṣẹlẹ.
A bá a kẹ́dùn ipò tí ó wà.
Ọdun 1925 ni wọn bi ẹlẹwa Ṣapọn sile aye.
Àwọn ọ̀dọ́ máa ń ṣe àjọyọ̀ àjọ̀dún Òyìnbó nítorí àríyá àti fún ayọ̀.
Mo fẹ́ kí ẹ mọ̀ pé ohun gbogbo tí ẹ ṣe wọn-ọnnì, èmi kọ́ ni ẹ ṣe é fún, ẹ ṣe fún Ọlọ́run Ọba.
com/VepYKaPTzz— Liverpool FC (@LFC) 3 May 2018Awon ololufe Liverpool ti iye won le ni ẹ̀gbẹ̀rún marun un ni papa isere Stadio Olimpico fi idunnu won han pupo leyin ti won gbo fere keyin oludari ifesewonse ohun, ti o fi mo awon miiran ti won ko lanfani lati lo wo ifigagbaga naa nilu Rome.
Ṣe aburu wa ninu wiwa ọkọ loju opo ayelujara?
Ó bi Solomoni pé, “Arakunrin mi, irú àwọn ìlú wo ni o fún mi yìí?
Oríṣun àwòrán, Ethiopian Airlines Àkọlé àwòrán, Ileeṣẹ baalu Ethiopia ṣe afihan aworan ibi ti ọga agba ileeṣẹ naa Tewolde Gebremariam ti lọ sibi ti baalu naa ti ja Baalu naa ko eero mọkandinlaadọjọ, to fi mọ awọn oṣiṣẹ baalu mẹjọ.
Laipẹ yii ni ileesẹ BBC Yoruba mu iroyin wa fun yin pe, ilumọọkaosere tiata naa ti segbeyawo pẹlu akẹẹgbẹ rẹ kan Kọ̀lawọle Ajeyẹmi, ti wọn si n reti ọmọ nitori Toyin ti di abarameji.
Ṣugbọn, aarin awọn mejeeji pada daru, ti Ọbasanjọ si jẹẹjẹ pe oun ko ni ṣatilẹyin fun ipinnu Atiku lati aarẹ Naijiria lailai.
Bakan naa lo ni Oriṣabunmi ṣẹṣẹ pari iṣẹ kan to lọ ya ni ilu Ẹdẹ ni ipinlẹ Ọṣun laipẹ yii ni pẹlu ti ko si si ohun kan to ṣe ilera rẹ.
Lẹyin naa ni wọn ri oku rẹ, ṣugbọn ti awọn ẹya ara rẹ kan ko si nibẹ mọ.
Àwọn tí ó ti ṣìnà ninu ẹ̀mí yóo ní òye;àwọn tí ń kùn yóo sì gba ẹ̀kọ́.
Orilẹ-ede Gẹẹsi ti yapa kuro ni EU lẹyin ibaṣepọ ọlọdun mẹtadinlaadọta ati lẹyin ọdun mẹta o le diẹ to ti n gbero ati fi ajọ naa silẹ.
Ọ̀kan ninu àwọn tí àwọn ọmọ Israẹli fi idà pa lójú ogun ni Balaamu, aláfọ̀ṣẹ, ọmọ Beori.
Biliọnu mọkanlelọgbọn naira ti wọn ya sọtọ fun isẹ yi ni 2015 ko ba gbọ gbogbo bukata atunse opopona naa.
Nigba ti ẹni to lowo ju l'Afrika, Dangote fẹ f'ọmọ rẹ l'ọkọ, Aarẹ Buhari lo ṣe asoju iyawo, to si gba owo ori lọwọ asoju ọkọ iyawo l'ọjọ Ẹti (Friday).
Ó ṣe wá jẹ́ pé ọ̀rọ̀ tìrẹ ni yóo kó ìbànújẹ́ bá mi?
Ọ̀rọ̀ǹpọ̀tọ̀niyùn, Aláàfin obìnrin àkọ́kọ́ rèé, tó ní nǹkan ọkùnrin Gómìnà Zamfara kò lágbára ní tòtọ́ọ́ lórí ọ̀rọ̀ ààbò- amòfin Ẹ yàgò fún ìwà adìẹ dàmí lóògùn nù, màá fọ lẹ́yin lásìkò ìjà - Buhari Dókítà yọ oyin mẹ́rin tó n gbé nínú ẹyinjú arábìnrin kán Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Hakeem: Mo lè sọ arúgbó dí ọmọge nígbà tó bá wù mí Diẹ lara awọn iwe ti oloogbe Okediji kọ nigba aye rẹ ni Aja Lo Leru, Rere Run, Agbalagba Akan, Atoto Arere, ati Karin Kapo.
Ó ní; “gbogbo ìwádìí tí wọ́n ṣe fi hàn pé àwọn ará Roma lọ́kùnrin lóbìnrin ni ẹ̀yà tí a yà sọ́tọ̀ jù lọ ní orílẹ̀-èdèe wa.
Igba akọkọ kọ niyii ti iru ijamba bẹ ẹ waye nipinlẹ Eko.
O ni: “Ẹyin olufẹ mi, omo
Ati pe nigba ti wọn si gbiyanju lati sọ fun un pe ko kuro ni ayika naa lo yọ nkankan jade ni apo, to si da a mu.
Ninu ọrọ rẹ, ogun ebi lawọn ọmọ orilẹede Naijiria ṣi n ba ja bayii, ko si daju pe orilẹede yii yoo lagbara lati koju ogun arun Coronavirus bi o ba di tọrọ fọnkale.
Awọn iroyin miran ti ẹ ni ifẹ sii: 'A sọ fún ọlọ́kadà pé omi kún, omi kún, ṣùgbọ́n ó kọ etí ikún' #Adewura Bidemi Kosọkọ di ìyá ìkókó Àkójọpọ̀ àwòrán láti ìpínlẹ̀ Ogun, Ọyọ àti Kwara fún ìbúra gómìnà tuntun Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí kan sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
Nígbà náà, mo rí àwọn Juu tí wọn fẹ́ iyawo lára àwọn ará Aṣidodu, àwọn ará Amoni ati ti Moabu, 
Lati igba ti wọn ti da a silẹ, Khorasan ti ṣe awọn ikọlu ado oloro to pọ ni awọn ibi kan ni Afghanistan, nípa lilo awọn asaadoku mọ́ra.
Wo àwọn to ti rí ìwòsàn lọ́wọ́ àrùn coronavirus àti ibi tí wọ́n ti wá káàkiri Nàìjíríà Mẹ́rin nínú àwọn mọ́kànlá tó ń bọ̀ láti Sokoto tí wón mú l'Oyo ló ní Coronavirus Iye ìgbà tí Sani Abacha tí fi owó ransẹ si Nàìjíríà láti ọrun Báyìí ni àwọn agbófinró ṣe dá ìrìnkèrindò ọkọ̀ dúró lẹ́nu ibodè Nasarawa sí Abuja Kókó tó wà nínú àbá àkóso ajakalẹ-arun: Ṣíṣe àyẹ̀wò ikú tó pa òkú kan Gbígba ọ̀rọ̀ tó ṣe kókó lẹ́nu mọlẹbí aláìsàn Fífi tipa gba òkú ẹni tó bá kú láti ipaṣẹ ajakalẹ-arun Àgbàra láti kéde ilé ẹnikẹ́ni bíi ibùdó iyasọtọ Àgbàra láti gbé ẹnikẹ́ni tó bá fẹ́ kó kúrò ní irú agbegbe iyasọtọ náà, fún ọlọ́pàá Abala kerinlelogun aba náà tún fún ọlọ́pàá lágbára láti gbé ẹnikẹ́ni tó bá ní arun si ahamọ Abala ogún òfin náà fún NCDC ni agbára láti dawọ ipejọpọ èrò dúró àbí ètò kan dúró lásìkò ajakalẹ-arun Abala kokanlelaadorin aba yìí fún ọga àgbà NCDC àtàwọn ọlọ́pàá abẹ rẹ lágbára, láti ni agbára gẹ́gẹ́ bíi Ààrẹ Nàìjíríà lásìkò ajakalẹ-arun, lai si ẹni ti yoo yẹ lọwọ wo, ohunkóhun tó bá ṣe lásìkò naa Abala karunlelaadota ro NCDC lágbára láti béèrè ìwé kiwe tàbí ohunkóhun pẹlu ipá lọ́wọ́ ẹnikẹ́ni tàbí fi ipá wọnú ilé kan lai gba àṣẹ lọ́wọ́ ọlọ́pàá Ẹgbẹrun lọ́nà ọgọ́rùn-ún náírà ni owó ìtanràn ẹnikẹ́ni tó bá ṣẹ lábẹ́ òfin naa tàbí kó lọ sí ẹ̀wọ̀n oṣù mẹ́fà Tí onitọun bá tún tún ẹsẹ náà dá, yóò san ẹgbẹ̀rún lọ́nà ìgbà náírà tàbí kó fi ẹ̀wọ̀n ọdún kan jura Èrò ọ̀pọ̀lọpọ̀ èèyàn tó tako aba náà sì ni pé, ó yí gbé agbára ńlá wọ ẹnikẹ́ni tó bá jẹ́ ọga àgbà fún àjọ NCDC, to di lee di apàṣẹ wàá, tàbí kó si agbára náà ló kọjá sísọ.
Irísí agba osere tiata naa jọ ti ẹni to ṣe àìsàn sùgbọ́n ọrọ ti awọn akẹẹgbẹ kan kọ sabẹ aworan ọhun mu ifura dani.
Ọmi ayo ni wọn jọ gba lọdun 1984 ati 1988 nigba ti wọn jọ pade ki Naijiria to bori pẹlu goolu kọju si goli koo gba a si awọn.
Nípasẹ̀ rẹ̀ ni a fi ní ìgboyà láti dé ọ̀dọ̀ Ọlọrun.
Wọn ko sọ pe dandan igba kan ni yoo jẹ amọ eleyi to fẹ sumọ igba ti yoo jẹ ni asiko tawọn aṣofin ba wole pada lẹyin isinmi loṣẹ keji inu oṣu kini ọdun to n bọ.
Ijọba tun ti dawọ fifun awọn ọmọ orilẹ-ede naa ni fisa.
Èèyàn 64 míràn tún ti ní àrùn Coronavirus ní Nàíjírìa Eeyan mẹrinlegọta miran ni ayẹwo tun ti fihan pe o ni arun Coronavirus bayii lorilẹede Naijiria.
Àwọn ẹ̀mí èṣù yìí bá bẹ Jesu pé kí ó má lé àwọn lọ sinu ọ̀gbun àìnísàlẹ̀.
4m Ìlú méjì kọjú ìjà síra wọn l‘Ondo torí aáwọ̀ ilẹ̀, ọba kan wà ní ‘Coma’, èkejì fo ògiri jáde Iroyin jade nirọlẹ Ọjọbọ ọsẹ kan naa pe awọn janduku yabo ile igbimọ aṣofin ipinlẹ Ogun, ti wọn si ji ọpa aṣẹ eyi tii ṣe ami agbara rẹ gbe lọ.
O óo jìyà nítorí ẹ̀ṣẹ̀ rẹ ati àwọn nǹkan ìríra tí o ṣe.
o sì ṣe iṣẹ́ àmì ati ìyanu, o fi jẹ Farao níyà ati gbogbo àwọn iranṣẹ rẹ̀ ati gbogbo àwọn ará ilẹ̀ náà, nítorí pé wọ́n hùwà ìgbéraga sí àwọn baba wa, o gbé orúkọ ara rẹ ga gẹ́gẹ́ bí ó ti wà lónìí.
”OLUWA dá wọn lóhùn pé kí wọ́n lọ gbógun tì wọ́n.
pẹlu burẹdi agbọ̀n kan, tí kò ní ìwúkàrà ninu, ati burẹdi aládùn tí a fi ìyẹ̀fun dáradára, tí a fi òróró pò ṣe, ati burẹdi fẹ́lẹ́fẹ́lẹ́ tí kò ní ìwúkàrà ninu, tí a ta òróró sí lórí, ati ẹbọ ohun jíjẹ, ati ti ohun mímu.
A ní ọ̀rọ̀ pupọ láti sọ fun yín nípa Mẹlikisẹdẹki yìí.
Nítorí pé ó gba ẹ̀mí aláìní sílẹ̀ lọ́wọ́ àwọn aṣebi.
Atẹjade kan ti alaga ẹgbẹ awọn gomina ipinlẹ, Kayode Fayemi fisita lẹyin ipade wọn lo sisọ loju ọrọ yii.
Èwo nínú ìlérí tí Buhari ṣe ní 2015 ló ti mú ṣẹ?
Gbogbo ère oriṣa rẹ̀ ni a óo fọ́ túútúú, a óo sì jó gbogbo owó iṣẹ́ àgbèrè rẹ̀ níná.
Awọn kan ti ẹ tun n fi fọto ihoho wọn sita pẹlu #BoobsOutForCardi.
JAMB 2019: JAMB ní ẹ̀rọ tó ń wo bó ṣe ń lọ ni ibùdó ìdánwò
 Ó ní nínú àlá tí òun lá , òún .
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ sí: Àwọn olórin Nàìjíríà kẹ́dùn ikú ọmọ DBanj Ẹ̀mí 86 ṣ'òfò ni ìkọlù Plateau Ìgbà wo ni Buhari yóò simi àwáwí?
Oloye Ọbasanjọ ni idi ni pe ko si igba kan yala latẹyinwa tabi nisinyi ti ija wa laarin oun ati Iba Gani Adams, nitori naa ko si idi lati maa pari ija ti ko si.
com/7l7wTfspfSBakan naa ikinni latowo aare ana, dokita Goodluck Jonathan naa ko gbeyin.
Oríṣun àwòrán, Emma Russell Eyi lo si ranmi lọwọ lati tete mọ nkan to yẹ lati ṣe niru asiko ajakalẹ aarun coronavirus, ti gbogbo eniyan ni ilana ti wọn gbọdọ pamọ.
Ojọgbọn Oye Taiwo to n dari ibi iṣẹ naa lọwọlọwọ ṣalaye kikun fun BBC lori irufẹ awọn akẹkọọ to n wa ati pataki eto ẹkọ yii.
Nígbà tí OLUWA bá ti fọ èérí Jerusalẹmu dànù, tí ó sì jó o níná tí ó sì mú ẹ̀bi ìpànìyàn kúrò níbẹ̀, nípa pé kí wọn máa ṣe ìdájọ́ òtítọ́, 
Awọn janduku ja iwọde alafia lati tako iwa kotọ awọn ọlọpaa SARS #EndSARS ti wọn si lo anfani naa lati kọlu awọn kọlu ọgba ẹwọn, agọ ọlọpaa, awọn ile ikonkan pamọ si ati bẹẹ bẹẹ lọ ni ipinlẹ naa.
A jọ ki ara wa ku ori-ire.
O parọwa si awọn alawọdudu lati fẹran ara wọn nitori awọn ara ilu ni o le yan eniyan ti yoo tukọ wọn lo si ilẹ ileri si ipo""."
Wọn óo wá, pẹlu ṣẹ́kẹ́ṣẹkẹ̀ lẹ́sẹ̀ wọn,wọn óo sì wólẹ̀ fún ọ.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ẹni kan kii jẹ awa de!
Ẹ má ṣe jẹ́ kí oríṣìíríṣìí ẹ̀kọ́ àjèjì mu yín ṣìnà.
O wa fi kun ọrọ rẹ pe, bi wọn ti se tọrọ aforijin yii ''jẹ ki o di mimọ pe idẹyẹsi eeyan yala nitori awọ ẹni naa tabi ẹya rẹ a maa tẹmbẹlu eeyan, ju orisi iwa abuku miran lọ'' O ti saaju sọ fun BBC pe, ojojumọ lawọn akẹẹgbẹ oun maa n fi oun se yẹyẹ.
Yinka Ayefele di bàbá ìbẹta Wá gbọ́ ìmọ̀ràn tí Jonathan fún Buhari lórí ọmọ Fasoranti tó kú!
"Ọmọ ti yoo ba jẹ Asamu, kekere ni yoo ti maa jẹ ẹnu samusamu, lati kekere ni mo ti nifẹ ede Yoruba, mo maa n beere ibeere pupọ, ti sisọ ati kika ede Yoruba si jẹ irọrun fun mi.
Àwọn ọmọ Israẹli gbéra lọ sí Bẹtẹli, wọ́n lọ wádìí lọ́dọ̀ Ọlọrun; ẹ̀yà tí yóo kọ́kọ́ gbógun ti ẹ̀yà Bẹnjamini.
Bi awọn esi ayẹwo naa ṣe lọ niyii: FCT -53 Lagos-48 Ogun-40 Akwa Ibom-20 Bauchi-9 Plateau-8 Kaduna-5 Kano-4 Benue-3 Jigawa-3 Nasarawa-3 Edo-1 Kwara-1 Àjàkálẹ̀ Coronavirus ran èèyàn 168 ní Naijiria, ó pa ẹnì kan ní 24/11/2020 Ajọ NCDC tun ti kede esi ayẹwo eeyan mejidinlaadọsan.
Samuẹli ń dàgbà sí i, ó sì ń bá ojurere OLUWA ati ti eniyan pàdé.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, DJXgee: DJSosogee, ọ̀rẹ́ DJXgee ṣàlàyé ìgbé ayé gbajúgbajà DJ to 'gbẹ̀mí ara rẹ̀' O fikun pe o fẹran lati maa 'fi ibanujẹ ara rẹ sẹgbẹ kan lati mu inu awọn eeyan ti o ba ba pade dun.
Lara imurasilẹ rẹ gẹgẹ bi ọpọ ṣe maa n ṣe ni South Asia, ni pe o pinnu lati bo ara rẹ ṣaaju ọjọ igbeyawo.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Bayelsa Electiions : Ile ẹjọ́ gíga jùlọ kọ ìpẹ̀jọ́ David Lyon àti ẹgbẹ́ òṣèlú APC 26 Èrèlè 2020 Oríṣun àwòrán, OTAHER Ile ẹjọ giga julọ ti ni gbọingbọin lawọn fi ẹsẹ mulẹ lori idajọ to waye lonii lori idibo gomina ipinlẹ Bayelsa.
Olóyè Andrew Ayọ̀délé ló jẹ Báálẹ̀ tí Elétǔ Òdìbò (Olóyè) Ìṣọ̀lá Bájùláyé Gbádéṣeré si fi oyè Báálẹ jẹ.
Ileeṣẹ Yeezy ti gbe awọn itẹlẹ kan jade, eyi tawọn eeyan kan sara si pe o dara pupọ.
Ṣugbọn ó ti kó wọn gun orí òrùlé rẹ̀, ó sì ti fi wọ́n pamọ́ sáàrin pòpórò igi ọ̀gbọ̀ tí ó tò jọ sibẹ.
 iṣẹ ́ àgbẹ ́ iṣu , gbágùúdá , àgbàdo àti ewé sìgá jẹ ́ lára àwọn iṣẹ ́ tó gbajúmọ ̀ jùlo ni Ògbómọ ̀ sọ ́ .
Odugbemi ni aare egbe olootu ere inu amohunmaworan ti won n pe ni Independent Television Producers Association of Nigeria laarin odun 2002 si 2006.
Coronavirus ti ba ìfinimọ̀ jẹ́ fún àwọn àgùnbánirọ̀ Nílé ijó Fẹla Anikulapo, àrùn Coronavirus dá fàájì dúró Wo àwọn irọ́ tí wọ́n ń pa fún ọ nípa àrùn Coronavirus Bí àjálù ìbúgbàmù tó gb'ẹ̀mí ọ̀pọ̀ nìlùú Eko ṣe wáyé nìyí Amọṣa ohun to wa ninu fidio yii nikan lawọn to n tako iranṣẹ Ọlọrun naa n wo, wọn ko wo ẹsẹ ọrọ rẹ to ti sọ wi pe, yatọ si pe Ọlọrun n ṣọ awọn tirẹ, gbogbo awọn eeyan lo gbọdọ tẹle ilana imọtoto to yanranti nitori imọtoto lo kangun si iwa mimọ.
Ipade to maa waye lọla, ọjọ kejidinlọgbọn, osu keje yii yoo mu awọn asoju ajọ idanwo NECO, NABTEB, NBAIS ati awọn to yẹ dani lati fẹnuko lori awọn ọjọ idanwo gbogbo Oríṣun àwòrán, others Oyo school reopening: Kí ló dé tí ìjọba ìpínlẹ̀ Oyo kéde fífagilé Sáà ètò ẹ̀kọ́ kẹta fún àwọn akẹ́kọ̀ọ́ Ijọba ipinlẹ Oyo ti buwọlu igbesẹ ti yoo mu ki gbogbo akẹkọọ pada si ileewe ni ipinlẹ naa.
Awọn ileesẹ miran ti isẹ wọn tun jọ ara wọn, ti igbimọ Orosanye dabaa pe ki wọn papọ ni ajọ Fiscal Responsibility Commission, ajọ Paṣẹrẹ ti wọn pe ni National Poverty Eradication Programme, Utilities Service Commission, National Economic Intelligence Committee, ajọ to n wa idẹrun ọmọlẹyin Kristi ni ilẹ mimọ, ti wọn n pe ni Nigerian Christian Pilgrim Commission ati ajọ alalaji ti National Hajj Commission.
Aa ti gbọ pe ọkọ mi n lọ sile aṣẹwo?
N óo tún fún un ní òkúta funfun kan tí a ti kọ orúkọ titun sí lára.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Òsìsẹ́ ìlera fẹ́ náa tán bíi owó pẹ̀lú ìjọba Johesu ń dí wa lọ́wọ́ isẹ́ nílé ìwòsàn Ifẹ̀ - Dókítà JOHESU yóò sèpàdé pẹ̀lú Sẹ́nétọ̀ Saraki Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Àwọn aláìsàn rawọ́ ẹ̀bẹ̀ sí ẹgbẹ́ JOHESU Iyanṣẹ́lódì Johesu ti pé ọ̀sẹ̀ mẹ́ta lbáyìí, bẹ́ẹ̀ bá sì gbàgbé, osu kẹwa ọdún tó kọjá ni awọn dókítà orileede Naijiria, sapèjúwe ẹgbẹ àwọn oṣiṣẹ ilera Johesu gẹgẹ bii ajo ti ko bofinmu""."
Àkọlé àwòrán, Gomina Abdulfattah Ahmed ati iyawo rẹ Emir ti ilu Ilorin, Alhaji Zulu Gambari wa nikalẹ ninu gbọngan iburawọle ni ilu Ilorin.
Ìró wọn dàbí ìró iná tí ń jó pápá,bí ìgbà tí àwọn alágbára ọmọ ogun múra fún ogun.
Oṣu kejila ọdun 2018 ni Aarẹ Buhari gbe abadofin naa lọ siwaju ile aṣofin, eyi to jẹ N8.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ajimobi Burial: Ẹbí Abiola Ajimobi kéde bí ètò ìsìnkú rẹ̀ yóò ṣe rí pé.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Lockdown updates: Naira Marley gbóríyìn fún Jude Chukwuka pẹ̀lú #1 míliọnù Bakan naa ni wọn fikun un pe Alaga ajọ NDDC ni Ile Igbimọ Aṣofin naa yọ ara rẹ kuro lasiko ifọrọwanilẹnuwo naa, amọ ki gbogbo eniyan mọ wi pe, gbogbo wọn ni yoo jiyin iṣe naa, paapaa ipa ti ẹni kọọkan ko lati lu owo ajọ naa ni ponpo.
Siwaju si, iko agbaboolu Brazil dipo keta mu pelu ami mọ́kàndínláàdọ́rin le lẹgbẹ̀jọ(1669 points), ti Croatia si dipo kerin mu pelu ami márùndínlógójì le lẹgbẹ̀jọ lori tabili(1635 points) saaju iko agbaboolu England ti won ni ami mọ́kàndínlógún le legbejo lori tabili.
Bí ó ti jé̩ pé àfi tí àwo̩n è̩tó̩ àti òmìnira wò̩nyí bá yé ènìyàn nìkan ni a fi lè ní àmús̩e̩ è̩jé̩ yìí ní kíkún,
Aarẹ fi orukọ Oloogbe Tobias Chukwuemeka Okwuru gẹgẹ bii ọkan lara awọn ọmọ igbimọ alakoso fun ajọ ijọba apapọ kan lẹyin oṣu meji to ti jade laye.
O jẹ senetọ ẹkun aarin gbungbun Kwara titi di ọdun 2011 nigba to dije dupo gomina ipinlẹ Kwara lẹyin ti Bukola Saraki ẹgbọn rẹ fipo naa silẹ.
Ní báyìí, àgbègbè méji ni Ebola n dà láàmú ni DR Congo, North Kiv àti Ituri, Goma ni olúlùú Kivu tó sì pààlà pẹ̀lú ìlú Gisenyi tó wà ni Rwanda.
    Nígbà ti wọ́n yọ sí ni, tí wọ́n dákẹ́ ìlù, wọ́n pejọ sí apá kan wọ́n sì wí fún mi ki ń yan ẹnìkan sí òde láàrin àwọn ènìyàn mi kí ó bá ẹnìkan nínú tiwọn jà.
 wọn ò tilẹ ̀ kárí ẹkù kan mọ ́ .
Ile-ise iroyin orile-ede Faranse s pe, awon obi omo naa ko si nile nigba ti isele naa waye.
Ile iṣẹ ìlera fìdí ìṣẹlẹ méjì múlẹ wọ́n sì sọ wí pé ènìyàn mẹ́tàdínlógún ti pàdánù ẹ̀mí wọn.
Wọn ni arun naa ti gba ẹmi ọpọ osisẹ eleto ilera, paapaa nitori aisi idaabo bo to yẹ fun wọn, ti Kọmisana feto ilera nipinlẹ naa si ti ba arun naa lọ.
Iroyin ti kọkọ jade pe, awọn ọlọpaa ti fi panpẹ gbe Tekno, ṣugbọn Ọgbẹni Elkana sọ pe, awọn kan pe e fun ifọrọwanilẹnuwo ni, ati pe fun ra a rẹ lo wa si agọ ọlọpaa lọjọ Iṣẹgun lati sọ tẹnu rẹ lori ọrọ naa.
“Nítorí náà, ìwọ ọmọ eniyan, sọ fún àwọn ọmọ Israẹli pé èmi OLUWA Ọlọrun ní Ọ̀nà mìíràn tí àwọn baba yín tún fi bà mí lórúkọ jẹ́ ni pé wọ́n ṣọ̀tẹ̀ sí mi.
Aago mefa irole ni won de Ado-Odo.
Bureau), ojogbon Muhammad Isa sọ fun aare Muhammadu Buhari pe o wa ni ilana
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù George H.
Alága àjọ EFCC Ibrahim Magu yóò tún bẹ ìgbìmọ̀ olùwádìí Aàrẹ wò lónìí Unai Emery, akọ́nimọ̀ọ́gbá Arsenal tẹ́lẹ̀ gba iṣẹ́ Villarael Wo ohun tí Adájọ́ sọ nípa ìgbẹ́jọ́ Wòlíì Sotitobire l'Ondo Ọmọ Yorùbá mẹ́wàá tó jẹ́ àmúlùúdùn ní Amẹ́ríkà àti Yúróòpù Afara yii lo gun ju nilẹ Adulawọ lasiko ti wọn ṣii, o bẹrẹ lati Oworonṣoki to ja si opopona Apapa-Oshodi ati opopona Eko si Ibadan pọ.
Ṣé lóòtọ́ ni pé fijilanté àti àwọn ọlọ́pàá ti mú Bobosky?
Amofin naa ni ''O fihan gbangba pe awọn kan ga ju ofin lọ ati wi pe, ofin orilẹede Naijria ko jọba lori gbogbo eniyan.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Russia 2018: Belgium ti gba ípò kẹ̀ta Ife Ẹyẹ Agbaye 14 Agẹmo 2018 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 15 Agẹmo 2018 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Bí England se jà fitafita tó síbẹ̀ wọn ri ipò kẹ́ta mú England ti fidi rẹmi nínú ife ẹ̀yẹ àgbáyé tó ń lọ lọ́wọ́ nígbati wọn wàákò pẹ̀lú Belgium ní ìrọ̀lẹ́ ọjọ Satide, ní St Petersburg.
"Ni òunjẹ ojoojumọ a máa n jẹ awọn ounje ti ọ́rá wọn pọ̀, eyi ti om si n ṣe akoba fun ara láti ṣe àwọn atunṣe to tọ si agọ ara fura rẹ "" Awọn ǹkan wọnyii ni ààwẹ maa ń ṣe lára ti yóò si ma mú gbogbo nkan bọ sipo"" "" Nítori náà ààwẹ máa n ṣe ara láàfàni, o maa n ṣe iwosan bákàn náà lo n dena àìsàn."
Adewuyi ni ifẹ maa n tan isoro, ẹkun, pẹlu isẹlẹ aidaa to ti waye sẹyin, ti yoo si tun mu ayọ̀, ibukun ati igbega wọnu ile wa.
 ni 2009 , o koja benjamin sheares lati aare ile singapore to pejulo lori ipo .
Ọpọ awọn adoola ẹmi lati ileeṣẹ LASEMA, ajọ panapana ati awọn ileeṣẹ mii lo yabo ibi ti iṣẹlẹ naa ti waye, lati wa ojutu si sunkẹrẹ fakẹrẹ ọkọ to ṣẹyọ lẹyin iṣẹlẹ naa.
"Ranti pe, iwọ kọ lo sọ mi di eeyan, nitori naa o o le ba temi jẹ.
Bí ẹnikẹ́ni bá ṣubú lu òkúta yìí, olúwarẹ̀ yóo fọ́ yángá-yángá, bí òkúta yìí bá sì bọ́ lu ẹnikẹ́ni, rírẹ́ ni yóo rẹ́ olúwarẹ̀ pẹ́tẹ́pẹ́tẹ́.
”Jehu sì dáhùn pé, “Ó sọ fún mi pé OLUWA ti fi òróró yàn mí ní ọba lórí Israẹli.
Sẹnẹtọ Abdullahi ni ile yoo ṣiṣẹ lori aba naa lati rii wi pe o jọ ohun tawọn ọmọ Naijiria n fẹ gan an.
Ọlọ́pàá àti Shiites tún fìjà pẹ́ẹ́ta
Kẹrẹ kẹrẹ, ifẹsẹwọnsẹ laarin ẹgbẹ agbabọọlu Naijiria, Super Eagles ati ti Cameroon ti n sunmọ.
Awọn ọmọ Naijiria ko jafara lati fọ esi fun wọn.
Bakan naa ni Aarẹ Trump ni awọn ti ran awọn dokita lati ilẹ America pẹlu iranwọ ounjẹ, omi mimu ati oogun oyinbo lati ran orilẹ-ede Lebanon lọwọ lasiko yii.
Wọ́n wá sí ọ̀dọ̀ àwọn ẹ̀yà Reubẹni, ẹ̀yà Gadi ati ìdajì ẹ̀yà Manase ní ilẹ̀ Gileadi, wọ́n sọ fún wọn pé, 
o tun wa ro won lati tun tesiwaju nipa ojuse won fun idagbasoke ile-ise naa.
Òun ni ó gba ọ̀rọ̀ ìyè láti ọ̀dọ̀ Ọlọrun tí ó fi fún wa.
Apapọ iye ibo ti wọn fi yọ aarẹ Trump nipo 232-197, eyi to tumọ si pe ibo awọn eeyan to fara mọ pe ki wọn yọ nipo jẹ ojilerugba o din mẹjọ nigba ti ibo awọn ti ko fara mọ igbesẹ yii jẹ mẹtadinnigba.
OLUWA rẹ Juda sílẹ̀ nítorí Ahasi, ọba Juda, nítorí pé ó hùwà ìríra ní Juda, ó sì ṣe aiṣootọ sí OLUWA.
Laipẹ yii ni ajọ LMC so idije liigi Naijiria NPFL rọ nitori ajakalẹ arun coronavirus.
(Ọba ti di arúgbó ní àkókò yìí, Abiṣagi ará Ṣunemu ni ó ń tọ́jú rẹ̀.
Nàìjíríà bá RCCG, ìyá Folu Adeboye yọ ayọ̀ 70 Kíni iyatọ tó wà láàrin FSARS àti SARS?
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Pussypedia: Ṣé gbogbo obìnrin ló ń damira lójú ara lásìkò tó bá fẹ́ rí ọkùnrin?
Bakan naa ni o gbọ wi pe iya rẹ to to tọ ọ dagba, Lavona Solomon wa ni panpẹ ọlọpaa, ti ọkan rẹ si daru pẹlu ibeere pe ki lo sẹlẹ, bawo lo se sẹlẹ?
N óo kó wọn pada sinu agbo wọn.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Demilade Adepegba: Mo má a ń gbàgbé fèrè ni, tí mo bá wà nílé ìwé Wọn máa ń san owó orí to ga gọbọi sùgbọ́n wọn ni ìgbágbọ́ nínú ìjọba wọn tó bẹ́ẹ̀, ti wọn fi n gbé ìgbé aye òmìnira, wọn ni ìfẹ́ ara wọn.
Ẹ jẹ́ kí owó oṣù yín to yín.
Ile awodamiẹnu, ile awosifila si ni Adegbọrọ kọ si adugbo ọja Ọba.
’ rèé Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Gẹgẹ bi a ti ṣe sọọ ṣiwaju, igba akọkọ kọ niyi ti awọn orilẹ-ede mejeeji yii yoo maa fi ori gbari ni idije naa.
Ọna lati dena iba Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, L'ọdun 2017, bi ilaji awọn to wa ni aye lo wa ninu ewu nini aisan iba.
Lẹyin iṣẹlẹ yii ni gomina ipinlẹ naa ti awọn ileewe ijọba gbogbo to wa lagbegbe naa pa.
Ilé ilé ẹjọ́ tó ń gbọ́ ẹjọ́ ìdìbò gómìnà ìpínlẹ̀ Ọṣun ti kede oludije fun ẹgbẹ oṣelu PDP, Ademọla Adeleke gẹgẹ bii gomina ti ilu dibo yan ni Ọ̀ṣun.
O ni ko mọgbọn wa ki papakọ ofurufu Ipinlẹ Ondo ti ko ri iṣẹ ṣe wa nibẹ, ki Ekiti naa tun ni awọn fẹ da tiwọn silẹ.
Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí 2 sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 2:23 Fídíò, Water Generator: Ó leè ṣiṣẹ fún wákàtí mẹfà, kó tó sinmi, Duration 2,2310 Òkùdu 2020 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Maryam Sanda: Toyin Abraham, Femi Adebayo, Tayo Sobola barajẹ́ lórí ìdájọ́ ikú 28 Sẹ́rẹ́ 2020 Idajọ iku ti ileẹjọ giga ilu Abuja da fun Maryam Sanda, to pa ọkọ rẹ ti n mu oniruuru ariwisi dani lati ọdọ awọn osere ori itage Nollywood.
Jiti Ogunye fesun kan pe ijọba Buhari gan an ni o n huwa bii agbẹsunmọni nitori awọn ṣoja pa awọn ọmọ ẹgbẹ Shia to to 360 ni ọdun 2015 gege bi oun se gbo Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Joke Silva: Olu, ó tó gẹ́ pẹ̀lú obìnrin yìí níkan tó ń ba ẹ ṣeré ìfẹ́ nínú sinimá Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
- arìnrìn oge Lẹ́yìn ìgbeyàwó ọdún mọ́kànlá àti ọ̀pọ̀ ìjà, Bọsẹ di èrò ọ̀run nílé Saidi Bakan naa lo sisọ loju rẹ pe loore koore ni oun n lọ wo ọmọ naa, ti oun si n ba sọrọ, o si ti foju han pe Mutallab ti kabamọ iwa to hu ọhun.
Minisita fere idaraya, Sunday Dare lo ti kọkọ keke isunsiwaju yii ko to di wi pe o tun fi kun un pe aarẹ Buhari funrarẹ kede rẹ.
Amọ, awọn oluwọde kan ti ko mọ ẹni to gbe ounjẹ ranṣẹ ti yara gba ounjẹ naa atohun mimu ti wọn si ti n da a si ọfun ki eeyan kan lara wọn to kigbe pe wọn lẹ orukọ mọ awọn abọ ounjẹ naa pe ọdọ MC Oluomo lo ti wa.
awon agbofinro , Mohammed Adamu ati awon oludari iko eleto aabo  kookan lorile ede yii lara won ni ajo eleto
Ṣugbọn bí apànìyàn náà bá rékọjá odi ìlú ààbò rẹ̀, 
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Àhámọ́ Leah àtàwọ́n ọmọbìnrin míì ṣì ń kọni lóminú 11 Ọ̀wàrà 2018 Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ǹ jẹ́ ó wù yín kí gbogbo ọmọ tí ẹ bí jẹ obìnrin?
sa ipa re lori eto aabo, idagbasoke eto ọrọ aje ati gbigbogun ti iwa ibajẹ.
Tribe ṣalaye pe ofin ilẹ Amẹrika ko gba ijọba laye lati fi ẹtọ awọn eeyan lati sọrọ dun wọn, ṣugbọn awọn ileeṣẹ opo ikansiraẹni bi Facebook ati Twitter le yọ ọrọ ti eeyan ba fi lede loju opo wọn kuro ti ko ba jẹ ootọ.
Bi o tilẹ jẹ wi pe, alaga ajọ INEC lo laṣẹ lati ṣeto iyansipo ajọ naa, ti o si jẹ pe oun lo ṣe eto iyansipo tuntun yii, aarẹ Buhari ko lagbara rẹ labẹ ofin lati yii pada.
Wọn ti fi ẹsun kan awọn pasitọ miran pe wọn n pin ayederu iroyin kiri, eyi to n di akitiyan lati kapa aarun naa lọwọ."
Oríṣun àwòrán, OTHERS Àwọn ìjọba ìpínlẹ̀ kéde ìwọlé fásitì, ASUU àti ìjọba àpapọ̀ ní kí wọ́n ṣọ́ra!
OLUWA tún pe Mose, ó ní, “Dìde kúrò níhìn-ín, ìwọ ati àwọn eniyan tí o kó wá láti ilẹ̀ Ijipti, ẹ lọ sí ilẹ̀ tí mo ti búra fún Abrahamu, ati fún Isaaki, ati fún Jakọbu pé n óo fún arọmọdọmọ wọn.
Ṣùgbọ́n wọ́n ayò Brighton yàtọ̀ si lẹ́yìn ìgba tí wọ́n fi atamátàsé Romania, Florin Andone, sínú eré tó sì bá wọn pa àmì ayò kan ré ní ìṣẹ́jú mẹ́rìndínláàádọ́rin (66) Pẹ̀lú èsì ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ náà Chelsea dúró sí ipò kẹẹ̀rin nígbà tí wà ní ipò kẹẹ̀tàlá.
Nígbà tí wọ́n la òkun já, wọ́n dé Genesarẹti, wọ́n bá gúnlẹ̀.
Ẹ ti yára pada lẹ́yìn OLUWA, ẹ kò sì tẹ̀lé e mọ́, nítorí pé ẹ ti ṣe oríkunkun sí OLUWA nípa títẹ́ pẹpẹ fún ara yín.
Gómìnà Makinde ní ìpínlẹ̀ Ọyọ́ lé sọ ìbòjú wíwọ̀ di ọ̀ranyàn nítorí Coronavirus Máfó, mo wà pẹ̀lú ẹ, Ajimọbi kàn sí Makinde lóri Coronavirus to ni Èèyàn mẹ́rin míràn kó àrùn Coronavirus Ó ṣe é ṣe kí o ti ní coronavirus kí ó má mọ̀ nítorí pé ó kò rí àpẹẹrẹ Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí 3 sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 2:23 Fídíò, Water Generator: Ó leè ṣiṣẹ fún wákàtí mẹfà, kó tó sinmi, Duration 2,2310 Òkùdu 2020 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
8 Àti pé nítorí tí ìwọ ti gbé àwọn ìwé náà lé e lọ́wọ́, kíyèsíi, àwọn ènìyàn búburú ti gbà wọ́n lọ́wọ́ rẹ.
Oṣiṣẹ ọgba iko-ẹranko-si naa ni Khun Sathan ational Park sọ pe o ti pẹ ti Igala naa ti n jẹ rọba ike ki o to wa ṣokunfa iku rẹ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Àṣà àti èdè Yorùbá dùn púpọ̀, o ní ìtumọ̀ kíkún Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àṣà àti èdè Yorùbá dùn púpọ̀, o ní ìtumọ̀ kíkún 31 Ògún 2019 Ṣé iwọ ti ri iru ọmọ bẹẹ ri?
Ẹmu máa ń fun ènìyàn ni okun ati agbára Omonhinmin tun sàlàyé pe, ẹmu ni èròjà tí à ń pè ni Carbohydrates ni èdè òyìnbó, àwọn èròjà inú ẹmu yìí lágbara gan láti fún ènìyàn lágbáre.
Aarẹ Buhari fi si oju opo Twitter rẹ pe oun gboriyin fun awọn ara ipinlẹ Osun ti wọn fi aaye gba idọgba labẹ ofin o si jẹjẹ atilẹyin iṣejọba rẹ fun un.
Ṣé o mọ iye òṣèré fíìmù Yorùba àti olórin tó bá ọdún 2020 lọ?
Mò ń tẹnu mọ́ ọn fún àwọn Juu ati àwọn Giriki pé kí wọn yipada sí Ọlọrun, kí wọn ní igbagbọ ninu Oluwa Jesu.
Ọna Abayọ Awọn mejeeji ti o ba BBC Yoruba ni o di dandan ki ijọba ma tẹle ilana to yẹ nigbakigba to ba fẹ gbani siṣẹ.
De Bruyne ni agbabọọlu ilẹ Belgium ti yoo gbami ẹyẹ naa lẹyin ti Vincent Kompany ati Eden Hazard kọkọ gba a siwaju.
Ìrètí irú èyí kì í ṣe ohun tí yóo dójú tì wá, nítorí a ti tú ìfẹ́ Ọlọrun dà sí wa lọ́kàn nípa Ẹ̀mí Mímọ́ tí ó fún wa.
O ni ko to bẹẹ nitori pe bi mi ba wa, ireti ṣi n bẹ.
Chelsea sáré kọjá kádàrá, góòlù kan ṣoṣo ní Vanlencia fi lù wọ́n Tani yóò gba ife ẹ̀yẹ UEFA Champions League ti saa yi?
Akomolede ati Asa lori BBC: Olùkọ́ Kikelomo Ogunboye tan ìmọ́lẹ̀ sí ìwà olè ọ̀gá ọlọ́pàá Audu gẹ́gẹ́ bí àwòkọ́ṣe àsìkò yìí
 egbé agbábóòlù wa rí àwòn méta .
Gbogbo orí wọn pá, wọ́n sì ti fá gbogbo irùngbọ̀n wọn.
Ọlọrun ní, Kí ẹnikẹ́ni má ṣe jiyàn, ẹ kò sì gbọdọ̀ ka ẹ̀sùn sí ẹnikẹ́ni lẹ́sẹ̀, nítorí pé ẹ̀yin alufaa gan-an ni mò ń fi ẹ̀sùn kàn.
Oríṣun àwòrán, @PoliceNG Àkọlé àwòrán, Beere fun idanimọ awọn ọlọpaa to wa mu ọ ati ibi ti wọn ti wa.
láti inú ẹ̀yà Juda, ó rán Kalebu, ọmọ Jefune; 
Ghana Witches: Wò bí wọ́n ṣe pa ìyá ẹni ọdún 90 tí wọ́n pè ní àjẹ́
Ní àkókò yìí, Dafidi ọba ti di arúgbó.
 Ítàn àwọn ọba tó ti jẹ rí .
Koda aifakọyọ naa ti gbomi loju ọkan lara awọn ololufẹ Arsenal Florence Otedola ti ọpọ mọ si DJ Cuppy.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Buhari fọwọsi aba igbimọ onidajọ lati yọ adajọ meji nipo 9 Èrèlè 2018 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ọjọ pẹ tẹnu ti n kun ọpọ adajọ Naijiria lori ẹsun iwa ibajẹ Aarẹ orilẹede Naijiria, Muhammadu Buhari ti buwọlu iwe asẹ ifẹyinti tipatipa lẹnu isẹ fun adajọ kan, ti wọn yoo si tun yọ ekeji nipo.
Lai mọ pe ọjọ ija kan n bọ lọna, Lisabi se idasilẹ ẹgbẹ awọn ọkunrin kan, eyi to dabi ẹgbẹ alafọwọsowọpọ silẹ Egbẹ yii ni ti wọn ti n pe ara wọn si oko aaro sise, nibi ti wọn yoo ti maa ran ara wọn lọwọ ni oko wọn Hubert Ogunde rèé, baba àwọn òsèré tíátà Kí lo fẹ́ mọ̀ nípa ‘Ajala Travels’?
naa  lati jawe olubori ninu idije to pọwọ
Bakan naa ni awọn ẹbi oloogbe naa ti wa nile ẹjọ.
Kí ló dé tí o fi kẹ́gàn ọ̀rọ̀ OLUWA, tí o sì ṣe nǹkan burúkú yìí níwájú rẹ̀.
Orílẹ̀-èdè Amẹrika kò ṣọ́ wọlé-wọ̀de mi àti ìdílé mi- Atiku fèsì Diẹ lara ohun ti wọn sọ ni yii; Oluwarotimi Akeredolu Oríṣun àwòrán, Alamy Iṣẹ pọ niwaju mi ti maa ṣe siwaju nigba tara ilu ba tun dibo yan mi ni eekeji, tori mo ṣẹṣẹ n mu ẹyẹ bọ lapo ni.
Oríṣun àwòrán, AfricanDrumFestival Àkọlé àwòrán, Ó lé ní ogún ìpínlẹ̀ tí yóò kópa níbi ayẹyẹ àjọ̀dùn ìlù nílẹ̀ Áfíríkà náà Ninu ọrọ ti wọn sọ nibẹ, awọn eekan ọbalaye meji nilẹ Yoruba, Ọọni ile Ifẹ, Ọba Adeyẹye Ogunwusi Ọjaja II ati Alaafin ti ilu Ọyọ, Ọba Lamidi Adeyemi III gba awọn to wa nipo aṣẹ lẹka iṣejọba gbogbo niyanju lati rii wi pe wọn n ṣe koriya fun igbedide aṣa ilẹ Yoruba.
Nígbà tí erin yìí mú Ìjàǹbáforítì ó sọ́ ọ́ sí orí igi kan, nígbà tí erin sì tún rí i pè ó wà lórí igi yìí ó hú igi náà, ìgbà tí igi tún máa wó, ó wó lu erin lórí, Ìjàǹbáforítì tún bọ́ sí orí erin, lórí erin yìí náà ló tún ti mú ọfà míràn láti inú apó tí ó tún fi gún un.
Inú tún bí OLUWA sí àwọn ọmọ Israẹli, ó sì ti Dafidi láti kó ìyọnu bá wọn.
NAFDAC: Fifi òògùn apakòkòrò 'Sniper' sinu ẹwà leè jásí ewu
Lojuna ati fopin si itankalẹ aarun Coronavirus ni ipinlẹ Kano, ijọba ti kede lọjọru pe oun wọgile gbogbo ayẹyẹ ọdun Eid-el-Kabir.
Ọdun 1957 ni wọn bi gbaju-gbaja akọrin Fuji, Olasunkanmi Wasiu Ishola Anifowoshe, ti ọpọ eeyan mọ ọ si Wasiu Ayinde.
Bakan naa lo sapejuwe Oke gẹgẹ bi eeyan daadaa.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Làá hàn mí: Ètò yìí ló ń kìlọ̀ fún wa láti mú ìmọ́tótó ní pàtàkì láti dènà Coronavirus Minisita eto ilera Somalia, Fowsiya Abukar sọ fun awọn akọroyin pe ọmọ ilẹ ọhun kan to ṣeṣe de lati oke okun lo ko arun Coronavirusa wọle.
 iṣẹ ́ àwọn ọkùnrin ni ẹmu-dídá tó tún ṣe pàtàkì tẹ ̀ lé iṣẹ ́ àgbẹ ̀ .
ijọba apapo ti bọwọlu owo to le ni biliọnu mẹ́rin
A gba owo lọwọ Banki apapọ lorilẹede Naijiria , CBN lati le ṣe igbese ina Solar naa fun awọn Niajiria'' Bí mo bá leè rí ọmọ alágbe t'áyé fẹnu sí pé mo fi ẹlẹ́rìndòdò lá lójú, máa kúnlẹ bẹ ẹ - Motara N81m pọ̀ lóòtọ́ láti fi gé koríko Stadium, Ọ̀gá Mínísítà,èló lẹẹ́ san fáwa ọ̀dọ́ láti gè e?
Ehudu bá jáde, ó sì fi kọ́kọ́rọ́ ti gbogbo ìlẹ̀kùn yàrá orí òrùlé náà.
Akẹkọ meje lo farapa ninu iṣẹlẹ yii, mẹfa ninu wọn lo jẹ ọmọde ti ọjọ ori wọn ko ju ọdun mẹsan lọ.
" Àwọn yorùbá ló ń pà á lówe pé , "" báyé bá ń yí ká báyé yí , bígbà bá ń yí ká bá ìgbà yí , ìgbà laṣọ , ìgbà lẹ ̀ wù , ìgbà sì ni òdèré ikókò nílè Ìlọrin ."
Wọn yoo si koju Norway, Korea ati France ni ipele akọkọ.
Ẹwẹ, bo ti ri ni ile ẹni kan, ko ri bẹẹ ni dandan ni ile ẹlomiiran; ṣugbọn fun ẹni ti ko tilẹ ni aáyan ati maa wọn ounjẹ ko to se e tabi to nilo iranwọ, oniruuru iwọn lo wa lode.
”Siwaju si i,aare dupẹ lọwọ  adari  egbe  All Progressives Congress APC, Bola Tinubu ati
Lasiko kan ninu ifẹhonu ija han yii ni wọn ra a mu ti wọn si gbe e lọ Ibadan.
Lẹyin naa ni gbajugbaja akọrin, Rema naa bọ si ori itage, to si kọ awọn orin rẹ, Beamer ati woman.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Buhari yarí, ó ní ẹni bá ń bínú ní APC leè lọ sílé ẹjọ́ Aregbesọla lọ àmọ́ ọ̀pọ̀ isẹ́ rẹ̀ ń fọhùn síbẹ̀ l‘Ọ́sun Ìpàdé ìjọba ati ASUU forí sánpọ́n Buhari buwọ́lu owó oṣù tuntun fáwọn ọlọ́pàá Àràbarà pósí rèé, ibùgbé ìkẹyìn tó jẹ ojú ní gbèsè Hubert Ogunde rèé, baba àwọn òsèré tíátà Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Jide Kosọkọ: Isẹ́ tíátà yóò gòkè tíjọba bá gbówó kalẹ̀ láti seré Ni ọjọ Isẹgun ni ẹni ti ajọ INEC Kede pe o bori ninu idibo sipo gomina ni ipinlẹ Ọsun, eyi to waye ni osu kẹsan ọdun 2018, iyẹn Ọgbẹni Gboyega Oyetọla yoo máa tẹwọ gba ọpa aṣẹ gomina lọwọ Rauf Aregbesola, to ti di ipo naa mu fún ọdun mẹjọ.
''Gbogbo wahala ti aarẹ koju pẹlu ile aṣofin ni saa to kọja ko ṣẹyin pe ẹnu ẹgbẹ ko ko.
 Àṣàkẹ ́ máa ń kanra mọ ́ ọmọdé .
Labare ree lori awọn igbesẹ ti o gbe lati mu ala rẹ ṣẹ.
Elkana ni awọn oun ti iwadii yoo fi han ree.
gboriyin fun Aṣagbeyẹwo iṣuna owo Agba ni ipinlẹ yii.
Ati pe, o san ki ẹni ti ko le mu ara duro ko lọ fẹ ọkọ opo miran lai gba ọkọ ọlọkọ.
Lẹyin naa ni Aarẹ Afẹṣẹkubiojo, Dana White wa kesi Masvidal boya o le ja ija naa.
” Ó bá súre fún Jakọbu níbẹ̀.
Afikun nba ikọlu wọn sugbọn ibudo afojusun wọn ko yatọ.
olubori lati gbomi ewuro si eni ti won jo n dupo , ti o jẹ igbakeji rẹ tẹlẹ pẹlu
Wọn yóo máa gbọ̀n, fún ẹ̀rù, nígbà tí OLUWA àwọn ọmọ ogun bá gbá wọn mú.
Iléesẹ́ Ọlọ́pàá: Ọwọ́ wa ti tẹ afurasí márùn-ún lórí ẹ̀sùn náà
Wọn kò sì mọ àṣírí agbára rẹ̀.
Dino Melaye ṣubú lulẹ̀, ó d'èrò ilé ìwòsàn Buhari nìkan kọ́ ni aṣíwájú táwọn èèyàn dẹ́yẹsí Àwọnn ǹkan tó yàtọ̀ nínú abá ìsúnà tí ọdún 2019 Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Kwara yóò gbàlejò BBC Yoruba Melaye sọ pe ''ko ṣeesẹ ki oun wa lara awọn aṣofin tó pariwo ẹlẹya le Buhari lori, nitpri pe oun ko si nibi eto ti Buhari ti gbe aba eto iṣuna naa kalẹ.
Àwọn tí wọ́n lè ṣiṣẹ́ ní ilé Ọlọrun láìka àwọn eniyan wọn ati àwọn olórí ìdílé wọn gbogbo jẹ́ ẹgbẹsan ó dín ogoji (1,760).
Ilé aṣòfin orílẹ̀-èdè UK ti faramọ́ fífí ìyà jẹ àwọn adarí Naijiria tọ lọ́wọ́ nínú rògbòdìyàn ENDSARS Jemila dáná sún ilé ọ̀rẹ́kùnrin rẹ̀ àti ọ̀rẹ́bìnrin tó bá nílé Adájọ́ Ibrahim Emmanuel dájọ́ pé ki wọ́n fún ni ẹgba mẹ́ẹ̀ddógún ki ó sì tóju àyíka ilé ẹjọ́.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù End SARS protest: Lára àwọn ìlú tí ìwọ́de ti wáyé ní Ibadan, Ado Ekiti, Osogbo, Ado Ekiti ati Eko 12 Ọ̀wàrà 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 19 Ọ̀wàrà 2020 Se ni eto okoowo dẹnu kọlẹ kaakiri awọn ipinlẹ to wa nilẹ wa Naijiria ati olu ilu ilẹ wa Abuja.
Igbakeji aare orile ede Naijiria Yemi Osinbajo yoo maa
enikeni ko da idoti tabi egbin soju popo.
Àgbékà mẹta ni àwọn yàrá náà, ọgbọ̀n yàrá ni ó wà lára ògiri ní àjà kọ̀ọ̀kan, wọn kò sì ní òpó bíi ti gbọ̀ngàn ìta, nítorí náà ni wọ́n ṣe sún àwọn yàrá àgbékà òkè kẹta sinu ju ti àwọn yàrá àgbékà kinni ati ti ààrin lọ.
Apapọ iye awọn ti arun naa ti fara kan labẹ ayẹwo lorilẹede Naijiria ti din diẹ ni ẹgbẹrun mọkandinlogoji.
Àkọlé àwòrán, Lara idi ti wọn tun fi n fẹhonuhan ni pe ki ijọba tu ajafẹtọ ati oludasilẹ ileeṣẹ iroyin Sahara reporters silẹ lahamọ ti wọn ti i mọ fun oṣu melo kan bayii.
Nibiti orilẹede kan ko ba ti gba ami ẹyẹ kankan, wọn yoo se igbelewọn rẹ nibamu pẹlu iye awọn elere idaraya to ko wa sibi idije ere idaraya Olympics lọdun to kọja.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: 'Mo lè fi ẹsẹ̀ mi jẹun, fọṣọ, mó tún lè fi gbá ẹni tó bá ṣẹ̀ mí létí' Àwọn ọ̀daràn náà lẹ orúkọ mi mọ́ báàgì ògùn olóró ni - Zainab Aliyu Ramadan:Àwẹ̀ àkọ́kọ́ gbà gbò mí jìgbì-jìgbì 'Ọmọ tó bá lanu gbàgà sọ̀rọ̀ sí àgbà, bàbá àti ìyá rẹ̀ ló ń bá wí' 'Ikàn táa fi ń ṣe pósí, òun náà la fi ń ṣe agbọ̀n fún ìgbéyàwó' Zainab Aliyu ti tààjò dé ariwo modúpẹ́ lọ́wọ́ Ọlọ́run ló ń ké 'Ọba tèmi ò ba lórí ohun gbogbo!
Nígbà tí Jesu dé agbègbè ìlú Kesaria ti Filipi, ó bi àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ pé, “Ta ni àwọn eniyan rò pé Ọmọ-Eniyan jẹ́?
Nítorí náà, ẹ yára dá ilẹ̀ náà pada ní alaafia.
  A ni láti ji giri si idojukọ wa.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: France Vs Nigeria: Super Falcons takú síbẹ̀, àmọ́ ẹ̀pa kò bóró mọ́ Ibéérè márùn ún tí Chelsea ní láti dáhùn lẹ́yin Sarri Ìdíje ife ẹ̀yẹ láàrin orílẹ̀èdè Áfíríkà 2019 Gani Adams: Iléèṣẹ́ ọlọ́pàá ti kàn sí OPC lórí ètò ààbò Ami ayo meji si odo ni wọn fi na South Korea, eyi to fun wọn lanfani ati duro mọ boya wọn yoo wa lara awọn ti ori yoo ko yọ lati kopa ni ipele to kan.
Ǹjẹ́ Olódùmarè fún ìwọ àti èmi ni ẹ̀mí yìí fún ìlò ara tiwa nìkan ni?
Mo ri ti ọpọ eeyan ya bo oju popo, o seese kẹ le da iwọde duro, amọ ẹ ko le da ijijagbara duro.
Gege bi ile-ise panapana se so lojo Aje(Monday), O ni, ijamba ina ohun bere loke ile itaja naa, ni ibi ekaa iworan amohunmaworan igbalode ti a mo si CINEMA ti awon omode ati odo posi.
Dafidi bá ojurere Ọlọrun pàdé; ó wá bèèrè pé kí Ọlọrun jẹ́ kí òun kọ́ ilé fún òun, Ọlọrun Jakọbu.
Ọmọ ọkùnrin kan ṣoṣo ni arákùnrin náà bí.
Wọn óo mọ̀ pé èmi, OLUWA Ọlọrun wọn, wà pẹlu wọn, ati pé àwọn ọmọ Israẹli sì ni eniyan mi.
- Kemi Afolabi Kíni ẹ mọ̀ nípa Mama Rainbow tó jẹ́ àgbà òṣẹ̀ré tíátà Yoruba?
Bee si ni, O kopa fun iko agbaboolu Manchester City ati Chelsea ninu idije ile geesi.
Yatọ si iriwisi lọdọ awọn amofin,ẹgbẹ alatako, Ile Asofin agba Naijiria ti ni awọn yoo ṣe ijoko pajawiri kan lati mẹnu ba ọrọ yi lọjọ iṣẹgun.
Ìwọ kò dà bí àwọn ẹlòmíràn tí ojú-inú wọ́n ti fọ́, nítorí bí ojú inú bá ti fọ́ bi olúwaarẹ̀ tilẹ̀ ń ṣe ibi kò ní i ríran rí i pé ibi ni òun ń ṣe.
'Ilé ìwòsàn ṣi abẹ́rẹ́ Formalin gún mí; n kò lè dá ìgbẹ́ àti ìtọ̀ dúró mọ́'
Bẹẹ ni ọrọ ri pẹlu iku gomina ana nipinlẹ Ọyọ, Sẹnatọ Abiola Ajimobi to papoda l'Ọjọbọ lẹni aadọrin ọdun.
 ) ( we folk , what are we going to do today ?
Ile ẹjọ giga apapọ kan nilu Abuja ti paṣẹ ki awọn agbofinro o fi panpẹ ofin gbe aarẹ ajọ ere bọọlu lorilẹede Naijiria, NFF, Amaju Pinnick atawọn oṣiṣẹ ajọ naa mẹrin miran wa siwaju oun.
Lati ọdun 1970 si 1971, Buhari jẹ Ọgagun gẹgẹ bi Major Commandant fun ikọ ogun Thirty-first Infantry Brigade.
Owó ìrànwọ́ Covid-19 dé, ìjọba fẹ́ san ₦75bn fún 54,000 olókoòwò Ìjọba ìpínlẹ̀ Eko ti iléèwé pa nítorí ìwọ́de #EndSARS Ìrẹ̀wẹ̀sì ń bá wa torí ìdánwò NECO tẹ ń ṣún síwájú lọ́pọ̀ ìgbà - Akẹ́kọ̀ọ́, ọ̀gá iléèwé Agbára ìgbìmọ̀ ìdájọ tí mo gbé kàlẹ̀ yóò dé ọ̀dọ̀ àwón ólọ́pàá tó ti kúrò lẹ́nu iṣẹ́ tẹ́lẹ̀- Sanwo Olu Sanow-Olu ni igbimọ ọhun ni aṣẹ lati ke pe ẹnikẹni ninu awọn ti ọrọ naa kan.
O ni:Öhunkohun to ba de ba oju ti de ba gbogbo ara, oju ni imole ara, jije eso ati ewebe dara pupo fun ago ara paapaa oju nitori awon ohun eelo asaraloore.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Gbajabiamila kéde èróńgbà rẹ̀ láti jẹ adarí ilé aṣojú ṣòfin l'Abuja Olùdíje mẹ́rin ti Gbajabiamila lẹ́yìn ṣáájú ìbò ilé aṣojú ṣòfin NASS 2019: Gbùngbùn Àríwá ní Agbẹnusọ kàn- Umar Bago ‘Jẹgúdújẹrá làwọn olórí tó ń lọ sókè òkun láti sèpàdé’ Kii ṣe akọkọ ree ti Gbajabiamila yoo du ipo olori ile Lọdun 2015,Femi Gbajabiamila koju Yakubu Dogara fun ipo olori ile amọ Dogara lo jawe olubori.
Ọ̀rọ̀ Coronavirus kì ń ṣe ṣeréṣeré o-K1 de Ultimate, Toyin Abraham kìlọ̀ Ǹjẹ́ òògùn vitamin C lè pa coronavirus?
Omisore ni, owo ti ijọ̀ba Ọsun ń gba lati ọ̀dọ̀ ijọba apapọ to lati fi san owo osu osisẹ, ti ko si si idi kankan fun ijọba Ọsun lati jẹ́ awọn osisẹ́ lowo osu.
Wọn ki awọn to le mọ pato iye ẹmi to nu ati awọn to fara pa, o di ti awọn ba ṣe ayẹwo to tọ, afiwe ati isiro to yẹ ki awọn ṣe.
Ọjọ́ orí mi kò tó nǹkan rárá, bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé ojú mi ti rí ọpọlọpọ ibi.
Wọ́n ti fi ìwà ìríra wọn ba orúkọ mímọ́ mi jẹ́, nítorí náà ni mo ṣe fi ibinu pa wọ́n run.
”Ó dá wọn lóhùn pé, “Bí mo bá sọ fun yín, ẹ kò ní gbàgbọ́.
Pauline Tallen ti  n je alaga igbimo ile-ise ti o n ri si oro aarun HIV/AIDS lorile-ede Naijiria (NACA) so pe, inu ile-ise NACA dun pupo lori b, Aisha Buhari se gba lati je asoju ajo UNAIDS.
Gomina Ambode jabo oro naa leyin ti igbimo amusese egbe oselu APC kede akegbe re ti won jo figagbaga, ogbeni Babajide Sanwo-Olu pe O jawe olubori.
Ó tan mànàmáná, wọ́n sì ń sá.
 Mo mo pe gbogbo awon olukopa ni won maa gbadun ara won ni Russia.
”Ni bayii, eto idibo tiwa ti pari, ti a si ti pese ondije dupo gomina, ohun ti o kan bayii ni ki, awon adari egbe oselu APC fowosowopo lojuna lati gbe egbe oselu APC jawe olubori ninu olokan-o-jokan eto idibo to n bo lona.
Mose ati Eleasari kó wúrà náà lọ sinu Àgọ́ Àjọ gẹ́gẹ́ bí ohun ìrántí fún àwọn ọmọ Israẹli níwájú OLUWA.
" Minisita ọhun fi kun un pe inu oun dun si iṣẹ to n lọ lọwọ loju ọna oju irin ọhun.
Bí wọ́n ti ń lọ, ìràwọ̀ tí wọ́n ti rí ní ìlà oòrùn bẹ̀rẹ̀ sí lọ níwájú wọn títí ó fi dúró ní ọ̀gangan ibi tí ọmọ náà wà.
funmilayo ransome kuti , mon ( Ọjọ ́ karùndílógún oṣù kẹwá ọdún 1900 abeokuta , nàìjíríà - ọjọ ́ kẹtàlá oṣù kẹrin ọdún 1978 Ìpínlẹ ̀ Èkó , nàìjíríà ) , jẹ ́ olùkọ ́ , olóṣèlú , ajàfẹ ́ tọ ́ ọmọ ènìyàn àti agbé ìṣẹ ̀ ṣe lárugẹ .
Bíbéèrè fún ìbálòpọ̀ gbogbo ìgbà sọ ìyàwó ilé dèrò ilé ìwòsàn Ẹ wo ìṣẹ̀lẹ̀ nípa ẹ̀sùn ìfipábánilòpọ̀ tí wọ́n fi kan D'banj ní sísẹ̀-n-tẹ̀lé 'Ẹwọn ọdun mẹẹdọgbọn ko pọ ju fun afipabanilopọ' Ìpínlẹ̀ Bauchi àti Kaduna láti máà tẹ àwọn afipábánilopọ̀ lọ́dàá Ó ti di ẹ̀ṣẹ̀ láti bẹ̀bẹ̀ fún afipábánilòpọ̀ nípìnlẹ̀ Ekiti- Ìjọba ìpínlẹ̀ Ekiti Grandpa àti Uncle mi, ń fipá bá mi lòpọ̀ láti ọmọ ọdún mẹ́rin"" Ijọba buwọlu ofin tuntun yii lẹyin awuyewuye to waye lẹyin ti awọn ọkunrin kan fi ipa ba obinrin kan lopọ nita gbangba nilu Lahore."
Gẹgẹ bi iroyin ṣe sọ, ọpọ ẹsun ti wọn ka si Magu lọrun ko sẹyin abajade iwadii agbejọro ijọba apapọ ati ajọ DSS lọ 2016, eyi ti wọn gbe fun ijoko ile igbimọ asofin agba lodun 2017.
" Arẹgbẹsọla, Gomina ipinlẹ Ọsun, iwọ oorun gusu orilẹede Naijiria.
Democratic Party, PDP) gbe lati tako abajade esi idibo aare to waye nile ẹjọ,
Lucky ti figba kan jẹ aṣoju ipinlẹ Ondo ninu igbimọ to n ṣamojuto idagbasoke awọn ipinlẹ ẹlẹpo rọbi ti a mọ si Niger Delta Development Commission (NDDC).
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù BBC: Iroyin yoruba yoo bẹrẹ ni pẹrẹwu 17 Èrèlè 2018 Oríṣun àwòrán, Channels TV Àkọlé àwòrán, BBC Yoruba yoo gbe iroyin jade lori ikanni agbaye bbc.
Ọpọ awọn oṣere lo fi ọrọ ibanikẹdun si oju opo wọn lati fi ṣe iranti agba ọjẹ adẹrinposonu yii.
Aarẹ ẹgbẹ osisẹ NLC nilẹ wa, Comrade Ayuba Wabba wa fewe ọmọ mọ awọn gomina lawọn ipinlẹ leti pe ki wọn rin jinna tefetefe si owo ifẹyinti naa, tori wọn ko ni asẹ lori rẹ.
James Park nirọlẹ ọjọ Aiku ninu idije Premier League Israel Adesanya fi ẹ̀ṣẹ́ mú ẹ̀jẹ̀ jáde nímú Whittaker láti gba àmì ẹ̀yẹ UFC Tottenham tasẹ̀ àgẹ̀rẹ̀ bí Tacha fara káásá ìyà lọ́wọ́ Brighton Ta ni yóò gba ₦60m lónìí láàrin olùdíje márùn-ún tó kù nílé BBNaija?
nigba ti awọn miran n ro pe wiwọ iboju maa n jẹ ki awọn eeyan miran ro pe awọn ti ri idaabobo gba kuro lọwọ arun coronavirus Rii pe o o tẹlẹ ofin to ba wa nita ni ẹkun rẹ bi apẹrẹ ni awọn orilẹ-ede bii Argentina, China, Italy ati Mexico to ti jẹ kan-n-pa fun ẹni to ba fẹ jade Kini ki n ṣe ti ṣe ti ẹni ti mo ba n ba gbe ba ni coronavirus?
orile ede Naijiria, Gernot Rohr ni ireti wa pe yoo tun lo ikọ agbaboolu mẹ́rìndínlógún to lo lati fiya jẹ iko agbaboolu orile ede Cameroon ninu
 Ọ ̀ pọ ̀ lọpọ ̀ ìyábọ ̀ ìròyìn jẹ ́ kó di mímọ ̀ wípé irú ìṣẹ ̀ lẹ ̀ bẹ ́ ẹ ̀ tó ṣẹlẹ ̀ kẹ ́ yìn wáyé ní ìgbà ogun barbary kejì ní ọdún 1815 , b ́ ótilẹ ̀ jẹ ́ wípé irú ìṣẹ ̀ lẹ ̀ bẹ ́ ẹ ̀ ti wáyé bí ọdún 1821 sẹ ́ yìn .
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Suicide attack: Ìlú Konduga Pàdánù ọ̀gọ̀ọ̀rọ̀ ènìyàn 17 Òkùdu 2019 Oríṣun àwòrán, @HQNigerianArmy Àkọlé àwòrán, Ipinlẹ Borno Iroyin to n tẹ wa lọwọ lati ipinlẹ Borno ni wi pe ọgọrọ eniyan ti dero ọrun nirọlẹ ọjọ aiku.
Staff Union of Polytechnics ,ASUP) bere iyanselodi lati osu kejila odun to koja
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù 2019 Election: Olasunkanmi Okeowo ní òun kò díje fun ipo ààrẹ mọ 24 Ìgbé 2018 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 21 Ògún 2018 Oríṣun àwòrán, Okeowo/instagram Àkọlé àwòrán, Orí àtẹ̀jíṣẹ́ ẹ̀rọ ayélujára rẹ̀ ló ti kéde pé òun yọ ọwọ́ àti ẹsẹ̀ òun lẹ́yìn tó sọ pé àwọn aláwọ dúdú ò lè ronú láti ṣẹ̀dá ohunkohun.
Máa ṣe sí àwọn ọdọmọkunrin bí ẹ̀gbọ́n ati àbúrò rẹ.
Police Checkpoint: Wo àwọn ìgbésẹ̀ tí ó lè gbé láti bọ lọ́wọ́ ẹ̀sọ́ ọlọpàá lóju pópó
Ọba bá pàṣẹ pé kí wọ́n lọ mú Daniẹli, kí wọ́n sì jù ú sinu ihò kinniun.
Sugbọn awọn ọrọ ti Alaafin sọ lasiko ayẹyẹ ọdun Sango naa si n ja rain-rain nilẹ.
Awon alatileyin re ri gege –bi Baba ijoba tiwa-n-tiwa.
Mo sọ̀rọ̀ nípa rẹ̀ ní ṣókí nínú móhùnmáwòrán tó wà lókè àkọslẹ̀ yìí.
Ìtàn Manigbagbe: Àwọn àjakalẹ-àrun to ti wáyé rí ṣáájú Coronavirus Àwọn Ìpínlẹ̀ tí coronavirus kò tíì dé ní Nàìjíríà, àti ìgbésẹ̀ tí wọ́n ń gbé láti dènà rẹ̀ Kí làwọn ìdàmú tí Coronavirus n mú bá àgọ́ ara?
Nígbà tí obìnrin yìí súnmọ́ ọ̀dọ̀ mi tí ó dé ibi tí kìnnìún idẹ nì wà, o dáhùn, ó sì wí pé: Ìwọ kìnnìún Ẹlẹ́dàá, kìnnìún idẹ, ìwọ tí a pàe fún láti máa ṣọ́ ẹnu ọ̀nà isà òkù, kúrò lójú ọ̀nà fún mi.
O kò gbọdọ̀ ṣàánú fún un, o kò sì gbọdọ̀ bò ó.
ẹ̀yin ọmọ Abrahamu, iranṣẹ rẹ̀,ẹ̀yin ọmọ Jakọbu, àyànfẹ́ rẹ̀.
Oga agba ọlọpaa Othman Abubakar, to tun jẹ alukoro ajọ ọlọpaa nipinlẹ Adamawa ni owo ti awọn fi n bọ igun yii ko ba pọ sii ka ni awọn ṣi fi si atimọle.
Bẹ́ẹ̀ náà ni Ọmọ-Eniyan yóo sì jìyà lọ́wọ́ wọn.
Bí ó ti jé̩ pé ó s̩e pàtàkì kí a dáàbò bo àwo̩n è̩tó o̩mo̩nìyàn lábé̩ òfin, bí a kò bá fé̩ ti àwo̩n ènìyàn láti ko̩jú ìjà sí ìjo̩ba ipá àti ti amúnisìn, nígbà tí kò bá sí ò̩nà àbáyo̩ mìíràn fún wo̩n láti bèèrè è̩tó̩ wo̩n,
”“Ti ijoba apapo ba kọ lati se ohun ti a fẹ , lojo Aje, ojo kefa, osu kokanla, ni a o gunle iyanselodi alailojo.
Whatsapp: Àwọn gbéwiri s'àtakò sí Whatsapp, yára ‘Update’ rẹ̀
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Lekki Shooting: Wole Soyinka ní ìnú òun dùn pé àwọn ọ̀dọ́ ń jà fọ́jọ́ ìwajú wọn lójú ayé òun 21 Ọ̀wàrà 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 22 Ọ̀wàrà 2020 Iroyin to n tẹ wa lọwọ ni pe ọgbà ẹ̀wọ̀n to wa ni Ikoyi n jona lọwọ.
Afirika yoo se maa na owo kan naa, ni eyi ti won yoo gbe abajade ise iwadii won
Idi ree ti awọn ọja ti mo n ta kii fi se iru wa, ogiri wa, wọn kii se gbarọ-gbudu.
Oríṣun àwòrán, ebalstv/facebook Àkọlé àwòrán, Owo ribiribi ti Gbajabiamila fi ra ọkọ ayọkẹlẹ ati aṣọ lasiko ayẹyẹ ọjọ ibi iyawo rẹ bi awọn eeyan ninu Ọrọ yii bi awọn eeyan ninu, ti Gbajabiamila si pada tọrọ aforijin pe oun ko ko iyan awọn ara ilu kere pẹlu rira ẹbun olowo iyebiye fun iyawo oun.
Nígbà tí àwọn eniyan rí ohun tí Paulu ṣe, wọ́n kígbe ní èdè Likaonia pé, “Àwọn oriṣa ti di eniyan, wọ́n tọ̀run wá sáàrin wa!
Nítorí pé ìjàyè ni olórí ogún wá, ọ̀pọ̀ èèyàn ló ń lọ tẹ̀dó si ilu naa, tó sì ń fẹ́ ju si lojoojúmọ́, tí wọ́n sì ń gbà ìlú náà lọ ṣe oko-owo ńlá.
'Kìí ṣe gbogbo ohun tí dókìtà ni kí n má jẹ torí àìsàn jẹjẹrẹ ni mo tẹ̀lé' Ẹni bá láyà kó fi àmì ohùn sí ọ̀rọ̀ Konko-jabele!
Àwọn tí Biliha, iranṣẹbinrin Rakẹli bí ni: Dani ati Nafutali.
Wọn ṣi aworan Obama ati Michelle Àwọn ìròyìn mẹ́wàá tó mí ilẹ̀ titi láàrin ọdún 2010-2019 Kanye West da àrínyànjiyàn silẹ́ nipa Trump Báwo ni Barack Obama, Bill Gates, Elon Musk, Jeff Bezos ṣe lùgbádì àwọn gbájúẹ̀ orí ayélujára?
Ìgbà náà ni mo sì tóó wáá ṣe àkíyèsí  wí pé púpọ̀ nínú wọn ni mo ti mọ̀ ní ilé, àṣé àwọn náà kò kọ́ wò mí dáadáa nii.
Ninu àwọn alufaa tí wọ́n wà ní ìlú àwọn ìran Aaroni ní ilẹ̀ gbogbogbòò ati ninu ìletò wọn, ni àwọn olóòótọ́ wà, tí wọ́n yàn láti máa pín oúnjẹ fún olukuluku ninu àwọn alufaa ati àwọn tí orúkọ wọn wà ninu àkọsílẹ̀ ìdílé àwọn Lefi.
Gbogbo àwọn tí a kà ninu ẹ̀yà Efuraimu jẹ́ ẹgbaa mẹrindinlogun ó lé ẹẹdẹgbẹta (32,500).
Lẹ́yìn èyí, a gba àwọn akópa ní ìyànjú láti so àlọ́ náà mọ́ ìdìbàjẹ́ àyíká ní ìlúu wọn.
O ni ọrẹ oun ni oloogbe botilẹ jẹ pe alatako oun ni lasiko idibo gomina lọdun 2019.
Ami ẹyẹ gbigba                Joël Tchédré ti gba ami ẹyẹ loriṣiriṣi yatọ si ni ilẹ Togo nikan.
Ipa ti o ko ninu sinima ‘Igbekun’ ti Kunle Afod ṣe, lo gbe han faye.
Ṣugbọn ẹ̀yin kò mọ ibi tí mo ti wá, bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò sì mọ ibi tí mò ń lọ.
Afe,  Kpam Jimin Sokpo, Robert Tyough, Soyinka
''Bakan naa ni a kesi ijọba apapọ lati jọwọ ran wa lọwọ lati wa ọna abayọ si ijinigbe yii.
Ooni Ile ife, Ààrẹ Gani Adams fárígá lórí ikú ọmọ Fasoranti Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Yinka Ayefele ni ìkómọ àwọn ìbẹ́ta òun kò tíì lè wáyé báyìí àyàfi tí òun bá gba páálí wọn l'Ámẹ́ríkà Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Yinka Ayefele ni ìkómọ àwọn ìbẹ́ta òun kò tíì lè wáyé báyìí àyàfi tí òun bá gba páálí wọn l'Ámẹ́ríkà 19 Agẹmo 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 20 Agẹmo 2019 BBC Yoruba ba gbajugbaja olorin nni to tun jẹ oludaleeṣẹ redio silẹ, Yinka Ayefẹlẹ sọrọ lati fi aridaju rẹ han pe ni bayi, o ti di baba ibẹta lootọ.
Assembly of the National Council of Traditional Rulers in Nigeria), NCTRN, niluu
Ijọba apapọ ni awọn fi ikilọ yii lede lẹyin ti Bobrisky da rogbodiyan kan silẹ ni papakọ ofurufu Nnamdi Azikwe ni ilu Abuja, nigba ti wọn ri i to n lo yara igbọnse awọn obinrin.
Wolii yìí rí ọkunrin mìíràn, o sì bẹ̀ ẹ́ pé, “Lù mí.
Dojú kọ wọ́n; là wọ́n mọ́lẹ̀;fi idà rẹ gbà mí lọ́wọ́ àwọn eniyan burúkú.
8 Èrèlè 2019 Lórí ètò ilèra Àkọlé àwòrán, #BBCGOVDEBATE: Kò sí ètò ilera ọfk fun àwọn obinrin- Ogunbanjọ Pasẹda ni eto ilera alabode ko si ni ipo to daara.
ascariasis jẹ ́ àrùn tí kòkòrò ajọ ̀ fẹ ́ tí a npé ní aràn alára rógódó  ascaris lumbricoides "" nṣe òkùnfà rẹ ̀ ."
Ọkan nínú àwọn ọmọbinrin tí wọn mú tó wà níbẹ̀ sàlàyé fún BBC pé, òun jáde nílé láti lọ kí ọ̀rẹ́ oun ní ǹkan bíi ààgo mẹ́sàn alẹ́ ní àwọn Hisbah ba mú òun sínú motò wọn.
Ìdáhùn tí ẹ fún mi nígbà náà ni pé, ohun tí mo wí ni ó yẹ kí ẹ ṣe.
Ileeṣẹ ọlọpaa ipinlẹ Kwara ni oun ti ri awọn ọmọ orilẹ-ede Turkey mẹrin ti awọn ajinigbe gbe pamọ ni ipinlẹ naa gba pada.
Ọdẹ ìbílẹ̀ ní Okeho pa adigunjalè mẹ́rin tó fọ́ báńkì, aráàlú dáná ṣun wọ́n Oríṣun àwòrán, @mosobaky Saaju la ti kọkọ mu iroyin wa fun yin nipa isẹlẹ kan to n ja rainrain lori ayelujara, eyi to ni awọn adigunjale mẹrin ni ọwọ palaba wọn segi ni Ọjọru nilu Okeho nipinlẹ Oyo.
Onimọ nipa ofin naa ko ṣai yannana rẹ pe, wahala iwọde #EndSARS to kọja laipẹ yii ti n fun awọn eeyan ni igboya lati hu awọn iwa kotọ.
A máa hun aṣọ funfun, a sì tà wọ́n,a máa ta ọ̀já ìgbànú fún àwọn oníṣòwò.
" Ẹgbẹ NMA ni asiko to fun ijọba apapọ lati jara mọ agbekalẹ eto ilera tẹru-tọmọ, Universal health coverage, ki eto ilera lee jẹ eyi ti yoo wa larọwọto gbogbo eniyan lorilẹede Naijiria.
21 Èrèlè 2018 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 3 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 5 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Olóòtú ìjọba Gẹ̀ẹ́sì yan ọmọ Yorùbá ní Mínísítà Afọnja, ẹni tó finú wénú ní Ilọrin, àmọ́ tó jẹ iwọ Mo ti kó kúrò nílé Olu Jacobs rí lẹ́ẹ̀mejì- Joke Silva Alábàárù ni mò ń ṣe lọ́jà Ketu àti Mile 12, kí ń tó bẹ̀rẹ̀ Fuji - Atawẹ́wẹ́ Ileẹjọ ṣi gba pẹlu awọn pe, awọn alaga ko le pada si ipo wọn, bẹẹ ni wọn ko le ṣe ohunkohun titi digba ti igbẹjọ yoo fi waye nibi oṣu meji si akoko yii.
bí ó bá lọ bọ oriṣa, kì báà ṣe oòrùn, tabi òṣùpá, tabi ọ̀kan ninu àwọn nǹkan mìíràn tí ó wà ní ojú ọ̀run, tí mo ti pàṣẹ pé ẹ kò gbọdọ̀ bọ; 
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Idajọ ileẹjọ lee mu ekuru gba ẹyin ni ifanfa fun ajọ EFCC Bakanna o ni agbeyẹwo iye ti a man gbe le owo iṣẹ amayedẹrun ni Naijiria ti wa di dandan bayi.
“Bí ẹnikẹ́ni tí ó jẹ́ olódodo, tí ó ń ṣe ohun tí ó tọ́, tí ó sì bá òfin mu; 
n óo sì fún wọn ní òye láti mọ̀ pé èmi ni OLUWA.
Nibayi ti gbogbo eeyan n ba Ajirebi yọ pe o ni ibi tuntun ti yoo maa gbe, awa naa n ba dawọ idunnu pe, o ku oriire.
Múra sí àfọ̀ṣẹ rẹ,sì múra si oṣó ṣíṣẹ́ jọ,tí o ti dáwọ́ lé láti kékeré,bóyá o óo tilẹ̀ yege,tabi bóyá o sì lè dẹ́rùba eniyan.
Dafidi sì tún kó ọpọlọpọ ìkógun mìíràn ninu ìlú náà.
Ẹ wo báwọn òṣèré tíátà kan yóò ṣe rí lọ́jọ́ ogbó Ẹ má dá NEF lóhùn, kò síbi t'ọ́mọ Nàìjíríà kò lè gbé nílẹ̀ yìí - Buhari Ta ni agbábọ́ọ̀lù tó fakọyọ jù lọ ní Afcon 2019?
Buhari at 76: Why We Love This President – THISDAYLIVE https://t.
Ó ní nínú àlá tí òun lá, òún.
Nígbà tí Jehoṣafati ọba Juda di ọlọ́rọ̀ ati olókìkí, ó fẹ́ ọmọ Ahabu kí ó lè ní àjọṣepọ̀ pẹlu Ahabu.
Ní ọjọ́ àbọlégùnún, ìlù Ọba Ìjẹ̀bu-Jẹ̀ṣà ni wọ́n máa n lù ní Ilẹ́ṣà fún gbogbo àwọn àgbà Ìjẹ̀ṣà làti jó.
Gbagede idanileko ohun nile ise to n mojuto oro ifitonileti ati imo ero National Information Technology Development Agency, NITDA se ifilole re, eleyi ti oludari agba ajo ohun, ojogbon Isa Patami  ti o fimo alaga awon alakoso ile-ise akoroyin VON, ogbeni Ibrahim Buba, oludari agba ile-ise VON ogbeni Osita Okechukwu ati awon osise tuko re.
 Oriade naa wa rawọ ẹbẹ sawọn ọmọ Naijiria lati yee na owo ribiribi lọ soke okun fun irinajo afẹ nitori ohun ti wọn n wa l si Sokoto, wa ni apo sokoto wọn nile."
Wọ́n ṣe aláìní pupọ, sibẹ wọ́n lawọ́ gan-an.
Sunny Ade ń se ọjọ́ ìbí, Obey kí i kú oríire Iléesẹ́ rẹ́kọ́ọ̀dù tí mo ti bẹ̀bẹ̀ láti kọrin, padà di tèmi lónìí - Ebenezer Obey Mi ò ní ìyàwó nílé, àmọ́ mo ní ọmọ tó pọ̀-Saheed Oṣupa Kí ló mú Olorì Badrat Ajoke kúrò ní ààfin Oyo lọ́jọ́ Iléyá?
Oríṣun àwòrán, Instagram/zanzeespabeautynstyle Iya alasọ tun ni a ba maa pe Mide lẹ́yin pe o jẹ́ osere tiata ti aye n gba tiẹ nitori ojoojumọ lo n polowo awọn asọ to n ta lori ayelujara.
Arabinrin Bunmi aya Femi Amao lati ile iwe Graceland Heights School ni agbegbe Wọfun, Olodo ni ilu Ibadan ni ipinlẹ Oyo ni olukọ wa fun toni.
Thelma Malaka, Akọwe eto ẹkọ nileewe girama naa sọ ninu fidio kan ti ijọ naa fi sita gẹgẹ bi atẹjade loju opo Instagram rẹ pe ọfiisi gomina ipinlẹ Akwa Ibom ti gbakoso iwadii lori isẹlẹ naa, ki akoyawọ le wa.
Wọn kì í gbèjà aláìníbaba,bẹ́ẹ̀ ni wọn kì í gba ẹjọ́ opó rò.
Lẹyin ti awọn ikọ Boko Haram tu awọn akẹkọ naa silẹ lọsẹ to kọja, ti wọn si foju kan awọn obi wọn, ni wọn tẹkọ leti lọ silu Abuja nibi ti wọn ti fojurinju pẹlu Aarẹ Muhammadu Buhari.
'Ninu ẹsin Islam, awọn ọmọbinrin to jẹ onirinkurin tabi oniṣekuṣe lo maa n fi ara wọn fun ọkọ lai jẹ pe awọn obi tabi alagbatọ wọn fi ọwọ si i.
Ó ṣe fún ìlú ńlá náà, níbi tí gbogbo àwọn tí wọn ní ọkọ̀ lójú òkun ti di ọlọ́rọ̀ nípa ọrọ̀ rẹ̀, nítorí ní wakati kan ó ti di ahoro!
Abẹ ìgbèkùn àwọn ọ̀gágun tí ó ti jagun fẹ̀yìntì àti àwọn asọ́mogbée wọn ni orílẹ̀-èdè Nàìjíríà wà.
Ijọ Anglican ni wọn ti ṣe igbeyawo lọdun 1977 nigba ti wọn ṣe ètò IVF naa nile iwosan kan nipinle Eko.
Lanre Kuti ni mo fẹ́ - Jaiye Kuti Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Ṣugbọn nígbà tí ó rí ọ̀pọ̀ ninu àwọn Farisi ati Sadusi tí wọ́n wá sọ́dọ̀ rẹ̀ pé kí ó ṣe ìrìbọmi fún wọn, ó bi wọ́n pé, “Ẹ̀yin ìran paramọ́lẹ̀, ta ni ó kìlọ̀ fun yín láti sá fún ibinu tí ń bọ̀?
abewo re n le pelu sise ipolongo eto idibo saa keji re ni gbegede pap isere Enyimba
₦750m ni Akeredolu ń gbà lóṣù fún ‘Security Vote’ àti ₦150m owó oṣù - Agboola Ajayi fèsì Agbẹjọ́rò fún Sotitobire yọ ọwọ́ nínú ìgbẹ́jọ́ rẹ̀ lónìí!
Orin náà ṣe àmúlò àti àfikún àwòrán ìlànà Ijó ìta-gbangba bí a ti ṣe mọ̀ ọ́ ni ìgbà-dé-ìgbà, fídíò orin náà túbọ̀ ṣe àfihàn ìdàgbàsókè orin soca láti ìpilẹ̀ṣẹ̀ tí í ṣe orin calypso.
Gbajabiamila kéde èróńgbà rẹ̀ láti jẹ adarí ilé aṣojú ṣòfin l'Abuja #Mothersday2019: Àwọn ìpèníjà obìnrin láwùjọ Ọ̀jọ̀gbọ̀n Pius Adesanmi kú nínú ìjàmbá bàálù Ethiopia!
Saulu ati Jonatani, ọmọ rẹ̀, pẹlu àwọn tí wọ́n wà pẹlu rẹ̀ pàgọ́ sí Geba ní agbègbè Bẹnjamini.
Gbèsè Nàìjíríà yóò di $50b tí wọ́n bá tún yáwó- Shehu Sani Imoran iya Bolu ṣe pataki si awọn ọdọ iwoyi pe ki wọn ṣọra fun aṣa kiko ọrẹ oriṣiiriṣii jọ laini idi gidi.
4 18613 Orilẹede Mauritania 396 9.
Oríṣun àwòrán, Postsubman Osun: Ilu Osogbo ni awọn aṣofin naa ti buwọlu abadofin ikọ amọtẹkun nipinlẹ Osun, bi o tilẹ jẹ pe o ni awọn atunṣe ti wọn ṣe nipa rẹ fun igba diẹ laarin igbimọ to gbe kalẹ ati abajade abadofin naa.
O ni Bibeli sọ pe paṣan lo tu were to wa laya ọmọde kuro, ṣugbọn o ni ẹgba tẹẹrẹ ko ran awọn ọmọkunrin mọ, igbaju igbamu lo yẹ wọn.
O wa ro ijoba lati tubo se iranwo fun egbe naa ,nipa kikopa  ni awon ipade ati idanilekoo isiro , ni eyi ti yoo je ki awon omo egbe naa tun ni imo- kun- imo.
Ọpọlọpọ ami idanilọla ni Ayinde Barrister gba fun iṣẹ orin kikọ.
Tí ń janu, tí ń ṣagbaja, tí ń tún minu
com/oGb8Mow4wq— 🇳🇬 Super Eagles (@NGSuperEagles) June 25, 2018Jijawe olubori ninu ifesewonse naa wa lara ohun ti o kun awon agbaboolu naa lowo lati tun bo tepamose won si.
nnkan fi le rọgbọ ni orilẹ-ede yii.
O tun fikun ọrọ rẹ kẹmika apakokoro naa yoo ṣe iranwọ nipa dibaabo bo ara ẹni lọwọ covid-19 lasiko yii.
Ipo keje ni ikọ Arsenal wa bayii ninu idije Premier League lẹyin ti wọn lu Newcastle mọle.
24 Bélú 2019 Oríṣun àwòrán, Okunoye facebook Àkọlé àwòrán, Àmúwá Ọlọ́run lásán ní ìṣẹ̀lẹ̀ tó wáyé ní Iba-Eburu Iba Oba Okunoye Ọba Eburù ti Iba ọba Adekunle Okunoye, ti fi ìdí ìṣẹ̀lẹ̀ to wáyé ni Iba múlẹ̀ nípa àwọn màálù Fulani to n gbé inú ìlú náà.
Láti ọjọ́ tí wọn ti tẹ ìlú yìí dó títí di òní, ni àwọn ará ilẹ̀ yìí tí ń mú mi bínú, tí wọn sì ń mú kí inú mi ó máa ru, kí n lè pa wọ́n rẹ́ kúrò níwájú mi, 
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Mama Rainbow: iṣẹ́ tíátà kò ta sánsán mọ́ bíi ti ayé àtijọ́ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Mama Rainbow: iṣẹ́ tíátà kò ta sánsán mọ́ bíi ti ayé àtijọ́ 21 Ògún 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 16 Ọ̀wàrà 2020 Laisi Oluranlọwọ, iṣẹ tiata kò ni pẹ parun - Idowu Phillips Ogbontarigi oṣere lati ọpọlọpọ ọdun sẹyin, Oloye Idowu Phillips ti gbogbo aye mọ si Iya Rainbow ti ke gbajere pe ki ijọba dide iranlọwọ.
Oríṣun àwòrán, @thenff Àkọlé àwòrán, Awọn agbabọọlu fẹyinti mọkanla gba amiẹyẹ pẹlu Bakanaa ni wọn tun fi ami ẹyẹ yii da Sẹgun Ọdẹgbami, Amiesimaka, Usiyen ati Mercy Akide-Udoh lọla.
"Pẹlu iwa irẹlẹ ni mo fi gba ipo minisita kekere ti wọn yan mi si.
Ile-ise aare so pe, ise akanse tuntun ti aare sese gbekale, ti o pe oruko re ni(Executive Order 6) (EO6),  ko waye lati koju ija si awon egbe oselu alatako, sugbon o je igbese ti o se pataki lojuna erongba ijoba lati gbogun ti iwa ibajẹ ti o joba lorile-ede NaijiriaAmugbalegbe pataki si aare lori oro ifitonileti ati igbodegba, Malam Garba Shehu, lo jabo oro ohun lojo Aiku(Sunday), niluu Abuja.
Ètò náà, tí wọn pè ní ìpàdé ìdókówò láàrin Amẹ́ríkà àti Nàíjíríà, ni iléesẹ́ asojú Nàíjíríà tó wà ní Amẹ́ríkà sètò pẹ̀lú léesẹ́ aládàání kan.
Fasiti ijọba apapọ ti Obafemi Awolowọ ni Ile Ifẹ ni ipinlẹ Ọṣun ni wọn fi sọ orukọ Awo ki a le maa ranti rẹ.
Bakan naa lo rọ awọn eeyan lati ko ayederu oogun kọlẹra ti wọn ba ri lọ si ile iṣẹ ajọ NAFDAC to ba wa ni tosi.
Wọn kì í sì í fi ìṣe wọn ati oríkunkun wọn sílẹ̀.
Ìṣẹ̀lẹ̀ Èkó: Aáwọ̀ Ọbàkan sọ ilé di áláwọ̀ méjì Ìfẹ̀hónúhàn àwọn aláboyún ní ìpínlẹ̀ Òǹdó Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Àwọn ìròyìn mìíràn tí ẹ lè nífẹ̀ẹ́ si: Fayemi: Gbèsè tí mo bá nílẹ̀ ni kò jẹ́ kí n ti yan kọmíṣọ́nà Ilé ẹjọ́ rán ọjọ̀gbọ́n fasiti OAU lọ sẹ́wọ̀n ọdún méjì Ile asofin fajuro si ọmọogun Cameroun to nwọ Naijiria laigbasẹ Gomina Fayemi jáwé lọ gbé ilé rẹ fún adarí fasiti Ekiti Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
ọdun Sallah , ni eyi ti akowe agba ile-ise olu ilu Abuja, ogbeni Chris Oha dari
Oríṣun àwòrán, Reuters Àkọlé àwòrán, Paul Pogba ba France fọba lee, o ṣeeṣe ki ife ẹyẹ lọ France ti Croatia kò ba ṣọra Lọwọlọwọ ayò ti di mẹrin si meji bi France ṣe n fagba han Croatia pe, a ju ara wa lọ.
Eyii to mu ki agbẹnusọ ile naa, Femi Gbajabiamila parọwa si awọn eeyan ọhun pe ko bojumu lati ke si Aarẹ lati wa tu aṣiri igbesẹ ti ijọba n gbe lori eto abo, nitori ko le so eso rere.
Ní báyìí orílẹ̀-èdeè Nàìjíríà ti ní èèyàn tó lé ni ẹgbẹ̀run mẹ́wàá tó ti ni ààrùn Covid-19 tí èǹiyàn to lé ni ẹgbẹ̀rún mẹ́ta ti móríbọ́ ti àwọn to lé ní igba sì ti báa lọ Ọ̀pọ̀ àwọn ọmọ Nàìjíríà fẹ́ kí Ààrẹ Buhari ṣí wọn sílẹ̀ kúrò lọ́wọ́ òfin kónílé -ó-gbélé President Buhari speech today: Ọ̀pọ̀ àwọn ọmọ Naijiria fẹ́ kí Ààrẹ Buhari ṣí wọn sílẹ̀ kúrò lọ́wọ́ òfin kónílé -ó-gbélé Oríṣun àwòrán, Others Nibayii, a n reti ohun ti aarẹ Buhari yoo kede lọni lẹyin ti Ajọ amuṣẹya aarẹ lori arun Coronavirus, PTF fi lede wi pe awọn ti jiyin fun aarẹ lori bo ṣẹ n lọ ni Naijiria ati amọran fun aarẹ Buhari boya ki ofin konile o gbele tẹsiwaju abi ko dopin.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Oríṣí ìjìyà ní àwọn bíi Gómìnà El Rufai àti Fayemi ń bèèrè f'àwọn afipábánilòpọ̀ Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Bakare tun gbadura pe, ko to di ọjọ Kẹrindinlogun osu Keji ọdun 2019, ki oluwa fi iji lile gba awọn ọta Naijiria kuro, ki omirira lee ba orilẹ́ede yii lọwọ awọn amunilẹru.
AfCFTA: Adùn wo gan ló wà nínú adehun okoòwò kan l'Áfíríkà?
Olówó rẹ̀ wá ṣàánú rẹ̀, ó bá dá a sílẹ̀, ó sì bùn ún ní owó tí ó yá.
Wo àwọn nkan tí ó yẹ kí o mọ̀ nípa Bitcoin, kí o tó ó dáwọ́ le e Taa ni Ebila One Million Boys"" àti Ekugbemi, olórí ẹgbẹ́ òkùnkùn míì tó da ìlú Ibadan rú?"
 igberiko damasku ni gomina bi olori toje yiyansipo latowo alakoso oro abele .
Ọrọ naa lagbara pupọ lasiko igba ti ọga ọlọpaa ana ,Ibrahim Kpotun Idris , wa nipo ọga ọlọpaa.
Ajo to n ri si oro ile okeere ni Naijiira The Nigerian foreign ministry soro ohun di mimo pe, oloogbe ohun ti oruko re n je Habibu Almu, ni o je olubasisepo ajo to n mojuto oro irin ajo “immigration attache”.
29 Nísisìyí, kíyèsíi, wọ́n ti pààrọ̀ àwọn ọ̀rọ̀ wọ̀nyí, nítorípé Sátánì wí fún wọn: Òun ti tàn ọ́ jẹ—àti pé báyìí ni ó pọ́n wọn sí ìṣìnà lati ṣe àìṣedéédé, láti jẹ́ kí ìwọ kí ó dán Olúwa Ọlọ́run rẹ wò.
Lasiko ifọrọwanilẹnuwo ni Kiddwaya sọ wi pe idaniloju ati ijọraẹniloju lo gbe oun de Big Brother Naija .
Lọjọ Abamẹta, awọn ọlọpaa yabo awọn ibudo ti wọn fura si pe wọn ti n ṣe ọti wọnyi ti wọn si mu eeyan marundinlọgbọn.
Wọ́n wá ṣe akiyesi ibìkan tí òkun ti wọ ààrin ilẹ̀ tí ó ní iyanrìn.
"Ẹni ti ọwọ tẹ yii lo kọkọ gbe ọkọ ayọkẹlẹ rẹ wọ inu ileefowopamọ wa nibi iṣẹju maarun ṣaaju ki iṣẹlẹ naa to o waye lati fi imu finlẹ lori bi ayika ṣe ri.
Saaju ko to di alaga,o lo ọdun mejidinlogun ni ileeṣẹ to n mojuto ọrọ aje,Institute of Economic Affairs (IEA) nibi to ti di ọga agba to si kopa ribiribi lati mu idagbasoke ba ijọba awarawa ni Ghana Jean Mensa kẹkọ nileewe girama St.
Bàtà tí bàbá mi fi sílẹ̀, mo ti pinnu àti fi ẹsẹ̀ mi sí i, ọ̀nà tí ó ti ń tọ̀ rí, mo ti pinnu àti máa tọ̀ ọ́, bẹ́ẹ̀ ni mo sì ti ṣu òṣùká bàrìbà sílẹ̀ tí n ó fi gbé ẹrù bàbá mi.
Oríṣun àwòrán, NAF Wo àwọn tí wòlíì ríran sí pé COVID-19 yóò pa ní ìpínlẹ̀ Edo l'óṣù kẹsàn án Alága àjọ EFCC Ibrahim Magu yóò tún bẹ ìgbìmọ̀ olùwádìí Aàrẹ wò lónìí Wo ohun tí Adájọ́ sọ nípa ìgbẹ́jọ́ Wòlíì Sotitobire l'Ondo Unai Emery, akọ́nimọ̀ọ́gbá Arsenal tẹ́lẹ̀ gba iṣẹ́ Villarael Òru òní ní ìjọba á ti afárá 'Third Mainland' ní Eko; Wo àwọn ọ̀nà míràn tí o leè gbà lẹ́yìn tí wọ́n bá tìí Wo bí ètò ìsìnkú Tolulope Arotile ṣe lọ nílùú Abuja Báyìí ni ètò ìsìnkú ọmọ ogun òfurufú náà ṣe lọ ní ìlú Abuja Eto ayẹyẹ ikẹyin ati isinku awakọ-ofurufu jagun obinrin akọkọ ni Naijiria, Tolulope Arotile, ti lọ nilu Abuja.
Aare ile Amerika, Donald Trump ti yan ogagun iko omo ogun orile-ede naa ti o ti feyin ti gege bi asoju ile Amerika si orile-ede Saudi Arabia, gege bi ilu Washington naa se n koju idojuko lataari iku akoroyin omobibi ile Saudi, Jamal Khashoggi ti o ku sipinle naa.
Lẹ́ẹ̀kan sí i, ọba rán ọ̀gágun mìíràn ati àwọn aadọta ọmọ ogun rẹ̀.
Gbogbo nǹkan wá wà ní ìṣọ̀kan, ìbáà ṣe nǹkan ti ayé tabi àwọn nǹkan ti ọ̀run.
Kùmọ̀ lásán ni Bẹnaya mú lọ́wọ́ tí ó fi dojú kọ ọ́, ó já ọ̀kọ̀ tí ó wà lọ́wọ́ ọmọ ogun ará Ijipti yìí gbà, ó sì fi pa á.
Ní gbogbo ìletò náà, kò sí alápatà kan (ẹlẹ́ran ní ń jẹ́ alápatà) ọkùnrin ẹlẹ́ran kan ní ń máa kiri wá sí ìletò náà.
Ara Ìwàrẹ̀fà mẹfà ni ògbóní méjèejì yí a ni Iléṣà ṣùgbọ́n ògbóni Ìjẹ̀bú-Jẹ̀ṣà ni aṣáájú àwọn ìwàrẹ̀fà náà.
tile je pe awon atunse ti ile igbimo asoju-sofin se si iwe abadofin eto isuna
Rehoboamu gbójú mọ́ àwọn eniyan náà bí ó ti ń dá wọn lóhùn, ó kọ ìmọ̀ràn tí àwọn àgbààgbà fún un, 
O fihan pe awọn ọdọ Naijiria ti dide, wọn ti ṣetan pẹlu itara ọkan pe ohun gidi yoo ti ara rẹ jade wa."
Asoju orile-ede Iran si orile-ede Nigeria, Morteze Rahimi Zarch, eni ti o soro yii di mimo nilu Abuja nibi ayeye  isami ayajo odun mokandinlogoji orile-ede Iran, eyi ti o fi kun oro re pe, orile-ede Nigeria je ore timo-timo fun orile-ede Iran.
Ṣaaju ọjọ Iṣẹgun ti orilẹ-ede Naijiria yoo pe ọdun mọkandinlgọta to di ilẹ olominira, igbakeji Aarẹ, Ọjọgbọn Yemi Oṣinbajo ati Aarẹ ologun tẹlẹ ri, ajagun fẹyinti Yakubu Gowon ti sọ pe ireti si wa pe nnkan yoo ṣẹnu 're fun Naijiria.
Adajọ tun pasẹ fun wọn lati san miliọnu mẹwaa Naira fun ikọọkan awọn ẹsun naa, lẹyin ti wọn gbà pe awọn jẹbi àwọn ẹsun ti wọn fi kan wọn.
Kò sí olódodo kan láyé tí ń ṣe rere, tí kò lẹ́ṣẹ̀.
"Amọ ti wọn ba ti sọ ọ, maa ni ẹ ṣeun.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Jangilofa epo mọtọ!
naa, nigba ti o gbọ nipa isẹlẹ ọhun lọsẹ keji to kọja.
A bi oṣere ọmọ Naijiria yii ni ọjọ kinni, oṣu kinni, ọdun 1978 lati ilu Benin, olu ilu ipinlẹ Edo.
Gbogbo àwọn ìjòyè bá rán Jehudi ọmọ Netanaya, ọmọ Ṣelemaya ọmọ Kuṣi pé kí ó lọ sọ fún Baruku kí ó máa bọ̀ kí ó sì mú ìwé tí ó kà sí etígbọ̀ọ́ gbogbo eniyan lọ́wọ́.
Oríṣun àwòrán, The Other Richard Àkọlé àwòrán, Bí o bá le bò awọ olóógbò, òó mọ bó ṣe rí fún ẹni tí kò fẹ́ kí ǹkan ọmọkùnrin wọ ara rẹ̀.
Minsita feto ọrọ abo abẹle Rauf Aregbesọla naa ti balẹ si ọgba ẹwọn naa.
Ninu ifẹsẹwọnsẹ naa to waye ni papa iṣere Stade du Hainaut ni Valenciene Cameroon ja fitafita ṣugbọn o jọ bi pe VAR pawọpọ pẹlu ikọ England lati ja ireti wọn kulẹ.
“Ṣé ìwọ ni ẹni tí ó ń bọ̀ ni, tabi kí á máa retí ẹlòmíràn?
Ṣugbọn ìwọ ati àwọn ọmọ rẹ nìkan ni yóo jìyà ẹ̀ṣẹ̀ tí àwọn alufaa bá dá.
Lẹyin naa ni oun ati awọn alajọṣiṣẹ rẹ lọ sile igbafẹ kan lati lọ ṣe ajọyọ ipari ìsìnrú'lú eyi ti ayeye rẹ yẹ ko waye loni (Ọjọ́bọ̀) jakejade orilẹede Naijiria.
ki won sora fun  iroyin ti won n fun awon
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, #Adetutu Alabi OJ: Mo ti gba kámú lórí ilà ojú mi Omiṣore bá APC lọ, ó gbà'lejò akọ̀wé ìjọba àpapọ̀ Oludije si ipo gomina ipinlẹ Ọṣun labẹ ẹgbẹ oṣelu PDP ti o n siwaju ninu idibo naa Ademola Adeleke ti sọ pe ata ika ti ko ran ikọ ni ọrọ ti oludije si ipo gomina labẹ asia ẹgbẹ oṣelu SDP Iyiọla Omiṣore sọ pe ẹgbẹ APC l'oun yoo satilẹyin fun ninu atundi ibo Gomina ipinlẹ Osun ti yoo waye l'Ọjọbọ.
 Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Njẹ ọ mọ̀ pé mímí afẹ́fẹ́ tí kò dára lè fa àìsàn?"
Ẹ jẹ́ kí áa máa ná owó nígbà tí owó bá lè gba ẹ̀mí wọn là.
'Shehu Shagari dáríji Buhari kó tó kú' Ṣé ìwọ ní ìpinnu ọdún tuntun?
Ẹnikẹ́ni tí ó bá ń hùwà ẹ̀ṣẹ̀, láti ọ̀dọ̀ Èṣù ni ó ti wá, nítorí láti ìṣẹ̀dálẹ̀ ayé ni Èṣù ti ń dẹ́ṣẹ̀.
Bakan naa ni Kabiyesi Uba ṣalaye pe, oye ti oun jẹ ko na oun owo bii ti wulẹ ko mọ.
Ni Shekau naa ba gba ori You tube ayelujara lọ lati ṣe afihan fidio pe lakọ ni oun wa.
ipinlẹ se pa ile iwosan abẹle ti sẹgbẹ kan lorile ede yii.
Àwọn ọmọ ti Aṣeri ni: Imina, Iṣifa, Iṣifi, Beraya, ati Sera arabinrin wọn.
OLUWA wà pẹlu Josẹfu, ninu ilé ọ̀gá rẹ̀, ará Ijipti, níbi tí ó ń gbé.
Wọ́n fi sí àtìmọ́lé,kí wọ́n má baà gbọ́ ohùn rẹ̀ mọ́ lórí àwọn òkè Israẹli.
Ahmed ni oun yi ẹrọ oun pada lori ati pa ara oun nitori ọmọ Buhari nitori ero naa ko dara rara, oun ko si ni ṣe iru rẹ mọ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Akomolede ati Asa lori BBC: Olùkọ́ Kikelomo Ogunboye tan ìmalẹ̀ sí ìwà olè ọ̀gá ọlọ́pàá 4) Elizabeth Olayinka Tolani Orogun: Elizabeth ni Adele Ọba ilu Akunu-Akoko, ni ipinlẹ Ondo.
Wọn óo hó lé Israẹli lórí lọ́jọ́ náàbí ìgbà tí omi òkun ń hó.
O ni obinrin naa ta oun ni ẹgbẹrun lọna ọtalelọdunrun o din mẹwa naira (₦350,000) fun ẹlomiran, Christiana Onuchukwu, to n gbe ni adugbo Fadeyi, to si n fi oun se isẹ agbara ati iya ajẹkudorogbo.
Aare Buhari soro naa di mimo lasiko igbode asoju ile igbimo fun eka guusu ipinle Bauchi ati sise afihan oludije dupo gomina labe asia egbe oselu APC, Gumau Lawal Yahaya, saaju eto idibo gomina ipinle Bauchi to n bo lojo kokanla osu kejo odun ti a wayii.
Ẹ̀yin ẹ padà wá ka apá kẹta ìtàn yìí láìpẹ́.
Ère kinniun wà ní ẹ̀gbẹ́ kinni keji ibi tí wọn ń gbé apá lé lára ìtẹ́ náà.
Ọsẹ to kọja ni ibanuje sọri agba Praise kodo, wọn ni ko kẹru rẹ kuro ninu ile Big Brother.
Èmi OLUWA ni mo sọ bẹ́ẹ̀.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Human trafficking in Libya: Ẹsẹ̀ bàtà àti èso kukumba ni wọ́n fi ń já àbálé àwọn ọmọ Nàìjíríà ní Libya-Yetunde, arìnrìnàjò sí Libya Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Human trafficking in Libya: Ẹsẹ̀ bàtà àti èso kukumba ni wọ́n fi ń já àbálé àwọn ọmọ Nàìjíríà ní Libya-Yetunde, arìnrìnàjò sí Libya 4 Èbibi 2020 Ohun taa jẹ, taa mu, taa fi r'ile aye gbe lo mu arabinrin yii kuro ni Naijiria lọ orilẹede Libya.
ile-ise olopaa ati adari awon agbofinro  lorile
Bakan naa o jẹ ko di mimọ pe awọn ikọ SARS kan ti ko lọwọ ninu iru ibajẹ yii atawọn ọlọpaa kan ti fifẹ han lati darapọ mọ iwọde naa.
Awọn ọlọpaa naa fin tajutaju lọna ati tu awọn afẹhọnuhan to pejọ si Power House ni Asokoro ka ni Ọjọ Aje.
Awọn kan tun n sọ pe Aphrodite to jẹ oriṣa ifẹ ni a bi lati inu ododo ifẹ ati foomu funfun ninu odo ni eyi to fi jẹ pe awọn ohun abẹmi inu odo maa n mu ki adun ifẹ pọ sii.
Ní ọdún kejidinlogoji tí Asaraya jọba ní Juda ni Sakaraya ọmọ Jeroboamu jọba lórí Israẹli, ní Samaria, ó sì wà lórí oyè fún oṣù mẹfa.
Saaju ni ileesẹ ọlọọpa ti fi iwe pe Sẹnetọ Adeleke lati wa kawọ pọnyin ro ẹjọ lori ẹsun sise magomago lasiko idanwo, iwa ọdanran, lilo oruko ti ki n se ti ẹ, ati sise onigbọwọ fun ọdaran.
Venezuela: Ọ̀pọ̀ ìdílé tí ebi ń pa, ti ń ta àwọn ọmọ wọn
Ọmọ Nàíjíríà fèsì lórí ààrẹ NANS tó ń sèlérí ìbò fún Buhari 'Mo máa ń parọ́ díẹ̀díẹ̀ ṣùgbọ́n kò pọ̀' Àwọn òṣèré tíátà Yorùbá tó bá 2018 lọ Eré Mọrèmi rèé, obìnrin tó gba Ilé-Ifẹ̀ là lọ́wọ́ ìparun Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí kan sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
kí ó má jẹ́ pé, nígbà tí ẹ bá jẹun, tí ẹ yó tán, tí ẹ ti kọ́ àwọn ilé dáradára, tí ẹ sì ń gbé inú wọn, 
Ati pé àwọn ọlọ́lá Juda ń kọ lẹta ranṣẹ sí Tobaya ní gbogbo àkókò yìí, Tobaya náà sì ń désì pada sí wọn.
 okowo awon ipinle aparapo ni okowo orile-ede to tobijulo lagbaye , pelu idiye gio 2009 to je $ 14.
Ọkọ̀ ojú omi ni OLUWA yóo fi ko yín pada sí ilẹ̀ Ijipti, níbi tí mo ti ṣèlérí pé ẹ kò ní pada sí mọ́ lae.
Ninu atẹjade kan ti ikọ Chelsea fi sita ni owurọ Ọjọbọ, oludari ẹgbẹ agbabọọlu Chelsea Marina Granovskaia ni: 'Inu wa dun lati ki Frank Lampard pada si Chelsea gẹgẹ bii olukọni agba.
Láti ìgbà àtijọ́, ẹnìkan kò gbọ́ rí, bẹ́ẹ̀ ni ẹnikẹ́ni kò tíì fi ojú rí Ọlọrun mìíràn lẹ́yìn rẹ,tí ń ṣe irú nǹkan wọnyi fún àwọn tí ó gbẹ́kẹ̀lé e.
Igbakeji Aare ni Naijiria, Ojogbon Yemi Osinbajo ti lo sabewo si awon ise akanse olopo bilionu naira tiijoba ipinle Kano n se loju ona Katsina to gba Kofarr Ruwa nitosi ibudo awon omo ogun ti Bukayo ki o le je ki irinajo nipinle naa tubo rorun sii.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Kid boxer: Ọmọọba 'The Buzz' Larbie rèé, ọmọ ọdún méje tó ń fi ẹ̀ṣẹ́ dá bírà tó ju ọjọ́ orí rẹ̀ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Kid boxer: Ọmọọba 'The Buzz' Larbie rèé, ọmọ ọdún méje tó ń fi ẹ̀ṣẹ́ dá bírà tó ju ọjọ́ orí rẹ̀ 23 Òkùdu 2020 Awọn agba bọ wọn ni ọmọ to ba maa jẹ aṣamu, kekere lo ti n ṣẹnu ṣamuṣamu; eyi ni itan Ọmọọba 'The Buzz' Larbie to n ti kekere ṣe ohun ti agba ko lee ṣe lagbo ẹṣẹ kikan.
Ajọ LASEMA ni awọn ṣiṣẹ lati alẹ Ọjọ Iṣẹgun ti ijamba ọkọ naa ti waye, titi di owurọ ọjọ keji.
Okediji naa maa n lo awọn ẹwa ede ati litireṣo alohun ninu agbekalẹ itan rẹ bii ti awọn agba onkọwe mẹrin to ku ti a n sọ nipa wọn yii ni.
Wọn ní ní kété tí ẹni tó ní ilé náà ṣe gbó pé ìjọba tí yaa soto láti wòó ni ó fi kú àwọn tí yóò bá ṣe iṣẹ́ ilé Wiwo náà.
Awọn meejeji yii ni wọn gbinmọpọ pẹlu ẹgbọn Charles, Henry Okah, tii se asaaju ẹgbẹ to nja fun ominira awọn eeyan Biafra tijọba ti fofin de, (Mend) ẹni toun naa ti gba idajọ tiẹ lori ẹsun yii saaju lorilẹede South Africa.
tabi pé ó rí nǹkan rẹ̀ tí ó sọnù he, tí ó sì ṣe bí ẹni pé òun kò rí i, tabi tí ó búra èké nípa ohunkohun, ẹ̀ṣẹ̀ ni ó dá.
Awon egbe alatako fe ki ofin yii bẹrẹ lati ori aare Gnassingbé sugbon
“Ẹnikẹ́ni tí ó bá kọ iyawo rẹ̀ sílẹ̀ tí ó gbé iyawo mìíràn ṣe àgbèrè.
Ọjọgbọn Campbell sọ pe ''imotomoto pọ fun awọn olori bi Trump ati Bolsonaro.
Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí EFCC gbé ọmọ ilẹ̀ Britain sẹ́wọ̀n lórí ẹ̀sùn ìkówójẹ22 Ọ̀wàrà 2019 EFCC ju akọwe ijọba Babachir silẹ24 Sẹ́rẹ́ 2018 EFCC: Akala se magomago biliọnu mọkanla at‘aabọ naira5 Ẹrẹ̀nà 2018 EFCC: A fẹ́ mọ bí Saraki ṣe gb'owó osù gómìnà, ààrẹ ilẹ́ asòfin13 Èbibi 2019 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Àkọlé àwòrán, Awọn ileewe pese ike omi ati ọṣẹ ifọwọ fawọn akẹkọọ Àkọlé àwòrán, Gbe ori rẹ wa ki n wo bi ara rẹ ti se gbona si Àkọlé àwòrán, Bi eeyan ba ti kọkọ wọle, ọwọ fifọ jẹ dandan Àkọlé àwòrán, Awọn akẹkọọ jinasirawọn bi wọn ti se joko ni kilaasi ti wọn si wọ ibomu Àkọlé àwòrán, Gbagada gbagada lawọn ileewe fi ikede sita lori ilana kikoju arun Covid-19 Àkọlé àwòrán, Awọn akẹkọọ to wa ni ipele ikẹkọjade ti bẹrẹ si ni kẹkọ pada Àkọlé àwòrán, Lati ẹnu ọna abawọle ni wọn ti n se ayẹwo fun olukọ ati akẹkọọ Àkọlé àwòrán, Ipinlẹ Oyo ni ipinlẹ akọkọ ti awọn akẹkọọ yoo wọle pada sile ẹkọ ni Naijiria Àkọlé àwòrán, Pupọ awọn obi lo pese awọn ibomu fawọn ọmọ to pada si ileewe.
Remi Tinubu, to jẹ sẹnetọ fun ẹkun Lagos Central, gẹgẹ bi Iwe Iroyin ori ayelujara, Motherhood-in-Style ṣe sọ, sọ lasiko ifọrọwanilẹnu wo kan to ṣe pẹlu ileeọẹ amohunmaworan TVC pe lasiko ti oun n da gbe pẹlu ọmọ meji lorilẹ-ede America ni oun di onigbagbọ.
Àwọn akẹ́ẹ̀kọ́ ni Ọ̀jọ̀gbọ́n tó ń bèèrè ìbálòpọ̀ lọ̀wọ̀ akẹ́ẹ̀kọ́ kò ṣẹ̀ṣẹ̀ máa ṣe bẹ́ẹ̀
Nígbà tí ó dé ilé baba obinrin rẹ̀ yìí, tí baba iyawo rẹ̀ rí i, ó lọ pàdé rẹ̀ tayọ̀tayọ̀.
 A gbodo gbaradi lawon aala ile wa ki won ma lo ko ebola wole lati ile okeere nipase oju irinna omi, ona ati t’ofurufu ki a le tete da eyi ti awon osise eleto ilera ba fura si mo lasiko.
 nítorí ìdí èyí , gbogbo ìlú Òyìnbó ni ó wá gbógun tì í kí àbá rẹ ̀ yìí má baà lè ṣẹ .
Yorùbá ni bi wọn ti ma a nka nkàn ki wọ́n tó bẹ̀rẹ̀ si ka a ni èdè Gẹ̀ẹ́sì.
Àwọn ọmọ tí OLUWA yóo jẹ́ kí obinrin yìí bí fún ọ yóo kún ilé rẹ fọ́fọ́, bí ọmọ ti kún ilé Peresi, tí Tamari bí fún Juda.
Olori Aanu ṣi n kawe lọwọ ni fasiti ọlọgba ẹranko nibi ti sanmọnti gbe dunlẹ ni ilu Ibadan UI nibi to ti n kọ imọ ijinlẹ nipa oṣelu.
lorile ede Naijiria Adams Oshiomole, ati awon asoju orile ede ile agbaye.
Olumuyiwa ni ṣe lawọn eeyan to jade n sọ fun oun pe bi oun ba mọ ioya ọmọ ti oun n bawi yii, yoo tẹ lọwọ rẹ o tori kii ṣe ẹran rirọ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Iya Woli: Ẹ̀mí ìjókíjó, Wòó, Ṣọ̀kí, Wojú, Ṣàkùṣákù, One Corner.
Orile ede Naijiria ni kokoro lati ni ibasepo pelu awon orile ede ni Afirika.
lo dibo yan enikeni ti won ba nifee si  lojuna
YCE: Ìpínlẹ kọ̀ọ̀kan ní àṣẹ láti dá ààbò bo àwọ̀n ènìyàn wọn
Láàrin òru gan-an, gbogbo ilé ní ìgboro ìlú a tanná kalẹ̀ gbòò.
O ni ọpọlọpọ eeyan ni ko ri ounjẹ jẹ ni Naijiria, ti ogunlọgọ awọn ọdọ ko si ri iṣẹ ṣe.
Won ni ayafi ti Yahaya ba je elesin omiran ti kii se musulumi ti wọ́n yoo fi Sharia da ejo rẹ.
Liverpool kọ ẹgbẹ agbabọọlu Arsenal lẹkọ ti wọn ko le gbagbe ni papa iṣere Anfield lọjọ Abamẹta.
Kò sí ìdí fún àjọyọ̀ lórí ọdún kan ìṣèjọba Fayemi - Ekiti PDP Kíni ẹ mọ̀ nípa Mama Rainbow tó jẹ́ àgbà òṣẹ̀ré tíátà Yoruba?
Aare Muhammadu Buhari seleri ohun lojoBo(Thursday), lasiko abewo igbimo ton ri si oro awon obinirin lorile-ede Naijiria (National Council for Women Societies) NCWS sile-ise aare, niluu Abuja.
Nítorí wọ́n ronupiwada nítorí iwaasu tí Jona wà fún wọn.
Bakan naa ni wọn n bere fun ki aarẹ gbekile ofin to de irinna lati ipinlẹ kan si omiran lorilẹede Naijiria.
Ajọ to n gbogun ti iwa ibajẹ, ti sọ idi ti awọn fi mu gbajugbaja olowo ori Instagram, Ismaila Mustapha ti wọn n pe ni Mompha.
Oríṣun àwòrán, @GOVUK Iwe ẹsun to ba ti ni ju ẹgbẹrun lọna ọgọrun eeyan to fọwọ si , ni ile aṣofin orilẹ-ede UK ma n jiroro le lori, iwe ẹhonu ENDSARS yii si ti le ni ẹgbẹrun lọna igba.
Àwọn akẹ́kọ̀ọ́ àgbà fipá bá ọmọkùnrin mi lòpọ̀ níléèwé Deeper Life, mò ń fẹ́ ìdájọ́ Wo ọ̀pọ̀ mílíọ̀nù fóónù tí Whatsapp kò ní bá ṣiṣẹ́ mọ́ lọ́dún 2021 Saheed tí wọ́n dáná sun ní OkeAdo, Ibadan, ajínigbé ni àbí àrìnfẹsẹ̀sí?
Coronavirus: Àwọn alárùn coronavirus ṣe ìwọ́de ní Gombe, wọ́n ní ìjọba n febi pa wọ́n
Ọlọrun, o ò bá àwọn ọmọ ogun wa jáde lọ sójú ogun mọ́.
Gbogbo wọn jẹ́ alabojuto àwọn ohun ìní Dafidi ọba.
Ahmad wa fi mule pe, oludije ti yoo ba dije dupo ohun, gbodo wa lati orile-ede ti o so ede geesi.
Ọkunrin kan ninu wọn tí ń jẹ́ Kalebu, ọmọ Jefune, ará Kenisi bá sọ fún un pé, “Ǹjẹ́ o mọ ohun tí OLUWA sọ fún Mose eniyan Ọlọrun ní Kadeṣi Banea nípa àwa mejeeji?
Loju opo Twitter ati Facebook, iroyin aṣeyọri Naijiria ti mu ki awọn ọmọ ile naa ati awọn akẹgbẹ wọn lati South Afrika ma fọrọwerọ.
Wọn ni ibi iṣẹ ni Isiaka ti n bọ nirọle o ku ọla to maa gba ominira lẹnu iṣẹ ina to n kọ ni Ogbomoso.
 Ohun ti a n se ni awon atunse ranpe, nitori pe ojo ko ni pe bere, nitori naa la se n tete sise lori oju ona agbara.
Ó jẹ́ ọ̀kan ninu ìgbìmọ̀ àwọn Juu.
 Awon ebi ati awon eniyan  lo ti n ko jade kuro ni olu-ilu naa to wa ni boulevards.
Nígbà náà, àkókò ìtura láti ọ̀dọ̀ Oluwa, yóo dé ba yín; Oluwa yóo wá rán Mesaya tí ó ti yàn tẹ́lẹ̀ si yín, èyí nnì ni Jesu, 
Omi bò mí mọ́lẹ̀,ibú omi yí mi ká,koríko inú omi sì wé mọ́ mi lórí.
oselu All Progressive Congress, APC, asofin Ahmad Alkali.
Òtítọ́ ni àlá yìí, ìtumọ̀ rẹ̀ sì dájú.
Pẹlu Heṣiboni ati àwọn ìlú agbègbè rẹ̀ ní ilẹ̀ tí ó tẹ́jú.
wan fi ifẹ han nípa idije yìí ati àwọn ǹkan míran náà, eyi si jẹ iwúri fún gbogbo wa.
" iṣẹ ́ rẹ ̀ tó dáyatọ ̀ nínú ìmọ ̀ síáyẹ ́ nsì ni ó jẹ ́ kì ó gba àmì ẹ ̀ yẹ ti "" l ' oreal-unesco ni odún 2013 ."
Israẹli, ọdọmọbinrin, ṣubú,kò ní lè dìde mọ́ lae.
Lẹsẹkẹsẹ ọkọ̀ sì gúnlẹ̀ sí ibi tí wọn ń lọ.
Iyawo rẹ , Aisha,naa ko gbeyin lati dibo nile idibo kan naa.
Ọkan lara awọn ti ọrọ ọhun ṣoju rẹ sọ fun BBC pe, ọna ile ijọsin ni oun wa fun adura owurọ nigba to oun gbọ orun gaasi.
Ipinlẹ Kaduna naa ti kọkọ kede iru aṣẹ yii, amọ nitori itankalẹ Covid-19 ni.
Ó bá jẹun, ara rẹ̀ bá tún mókun.
Báyìí ni ìyàwó mi náà sọ.
Bakan naa wọn fi ẹsun kan pe ile iṣẹ ko kede gbogbo iṣẹ ti wọn n ṣe fun ile iṣẹ to n ri si katakara lorilẹede Naijiria.
Alaafin of Oyo: Aláàfin pàṣẹ lórí ilẹ̀ tó ń dènà àbò fáwọn ará ìlú Ọ̀yọ́ Oríṣun àwòrán, Facebook/Alaafin Awọn onimọ kan ni wọn paṣamọ pe eeyan ti were ba lu iya rẹ pa, bo ba ri mọkaliiki ko ni duro.
Oríṣun àwòrán, others Ọkunrin lara awọn eeyan naa tilẹ ti di gbajumọ nitori bo ṣe maa n gbe asia naa to si ma n ju sọtun ati si osi.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Olapade Agoro: Olùdíje dùpo aàrẹ Nàìjíríà rí, Owatapa ti Itapa Ijesha, Wolii Olapade Agoro jáde láyé 1 Bélú 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 2 Bélú 2020 Oríṣun àwòrán, Others Olapade Agoro jade laye ni oru mọju ọjọ kinni, oṣu kọkanla, ọdun 2020.
Tí a fiṣọwọ́ ní 9:50 11 Òkùdu 20199:50 11 Òkùdu 2019 Kókó àfojúsùn mẹ́sàn án ni mo ní - Ndume Ninu ọ̀rọ̀ oludije Ali Ndume, o jẹ ko di mimọ pe koko afojusun mẹsan ni oun ni fun i'sejọba oun ti oun ba wọle gẹgẹ bi aarẹ ile igbimọ aṣofin @NgrSenateCopyright: @NgrSenate Ali NdumeImage caption: Ali Ndume Article share tools Facebook Twitter ṢàpínlòView more share options Share this post Copy this linkKà síwájú síi nípa àwọn ìtọ́kasí wọ̀nyí.
 nínú ọ ̀ rò - èdè tí ayé ( tí a gbé wọnú gírámà ) òrò ìse tó n darí àbọ ̀ apor rẹ ̀ fún ìdí èyí , ọ ́ n fún ní isẹ ́ ( ní báyìí , Ø role nìkan , àmó ó lè se àyànse àwon àwòmọ ́ mìị ́ ràn ) .
"Oríṣun àwòrán, Instagram/Muka Ray "" Iyabo Ojo ni iwa irẹlẹ pẹlu oju aanu, yatọ si pe mo jẹ ọga rẹ, ọrẹ mi ni ninu iṣẹ ta dijọ n ṣe."
Gege bi aare se sọ, o ni egbe
Ó jẹ́ arẹwà ènìyàn, ó ga, ó sígbọnlẹ̀, ó sì lágbára tó bẹ́ẹ̀ ti n kò tii gbọ́ pé ẹnìkan fi ẹ̀yìn rẹ balẹ̀ níní ìjàkadì rí.
Amọ ko bojumu to ki awọn asofin sọ ara wọn di abẹsinkawọ fun aarẹ, ki wọn si ma ni ọkan akin lati yẹ ohun to ba n se, ti ko dara wo.
O pari atẹjade ọhun pe iforukọsilẹ fun idanwo NECO ṣi n lọ lọwọ titi di ọjọ kẹwaa, oṣu kẹsan an, ọdun 2020.
Bi awọn eeyan ba gba abẹrẹ ajẹsara, yoo dẹkun arun yii, ki o to ran ka gbogbo awọn eeyan to n gbe lagbegbe naa.
Ìgbẹ̀hìn ni kí ìwọ máa wò, nítorí Olódùmarè ń bọ̀ wáá bẹ̀ wọ́n wwò àkókò ni kòì tí ì tó, ojú gbogbo wa ni yóó ṣe.
Ethiopian Airlines crash: Awakọ̀ òrúrufú pariwo 'lọ sókè!
Olùfẹ́ mi dàbí ìdì òdòdó igi Sipirẹsi,ninu ọgbà àjàrà Engedi.
 wọ ́ n mọ adomian fún ọ ̀ pọ ̀ lọpò.
Ajo isokan orile-ede agbaye UN so lojo-Abameta pe, Awon omo-ogun apetusaawo ajo UN  lorile-ede South Sudan ti pe eka ile-ise olopaa orile-ede Ghana kan ti won n sise idaabobo ni okan lara awon ipago naa, lori iwadii eyi ti o ni i se pelu esun pe, pupo lara won lowo ninu fifi ipa ba awon eniyan lo po.
Ṣadiraki, Meṣaki ati Abedinego dá ọba lóhùn pé, “Kabiyesi, kò yẹ kí á máa bá ọ jiyàn lórí ọ̀rọ̀ yìí.
Aṣo penpe funfun ati ṣokoto pelebe to ṣee sare 6.
Wọ́n kọ òfin mi sílẹ̀, wọn kò sì tẹ̀lé ìlànà mi.
Ilu Iwo ló yẹ kó kọ́kọ́ jẹ́ Sultan àkọ́kọ́ ní Nàìjíríà - Oluwo WAEC gbé èsì ìdánwò WASSCE jáde Etí ìjọba Buhari di sí ìmọ̀ràn àwọn ará ìlú -Jiti Ogunye Ṣé ẹ̀mí ilé aṣòfin lè gbé ṣíṣe ìwádìí 16 bn owó àgbàṣe iná ọba Nàìjíríà?
Iroyin naa tan kalẹ pe ajọ to n gbe ogun ti iwa jẹgudujẹra, EFCC ti ile Saraki to wa ni 15a, 15b ati 17 to wa ni agbeegbe MacDonald Road, Ikoyi, Lagos.
Oríṣun àwòrán, Screenshot Idile ọba Akinsemoyin sisọ loju rẹ pe, oun wa lẹyin iwọde EndSARS naa nibẹrẹ pẹpẹ lati tako ifiyajẹni ati ipani nipakupa latọwọ awọn agbofinro wa, toun si bu ẹnu atẹ lu ni gbogbo ọna.
“Ọkàn mi bàjẹ́, ọjọ́ ayé mi ti dópin,ibojì sì ń dúró dè mí.
Coronavirus Updates in Nigeria: Òṣìṣẹ́ ètò ìlera méjì ló wà nínú àwọn tó lùgbàdì àrùn Coronavirus ní Ekiti
Kí Kristi ọba Israẹli sọ̀kalẹ̀ láti orí agbelebu nisinsinyii, kí á rí i, kí á lè gbàgbọ́.
Ṣugbọn nisinsinyii, n kò ní ṣe sí àwọn eniyan yòókù yìí bí mo ti ṣe sí àwọn ti iṣaaju.
naa, lataari bi iko agbaboolu Wolves se gba aso lorun iko Arsenal, bi o ti le
”Wọn wa rọ awọn ara ilu lapapọ lati fi ẹmi iyin Oluwa si ọkan wọn nitori eleyii jẹ ohun eelo ti n mu idunnu ati ayọ wa si ọkan ẹda paapaa ni asiko iporuuru ọkan ati ipenija.
Ipinlẹ Ondo: Ni ọjọ kejidinlogun, osu keji ọdun 2020 ni ipinlẹ Ondo buwọlu abadofin naa.
Èmi kò yẹ ní ẹni tí ìwọ ìbá wọ ilé rẹ̀.
Bí àwọn ẹṣin ọ̀hún ati àwọn tí ó gùn wọ́n ti rí lójú mi, lójú ìran nìyí: wọ́n gba ọ̀já ìgbàyà tí ó pọ́n bí iná, ó dàbí àyìnrín, ó tún rí bí imí-ọjọ́.
Opọ ẹmi lo ti sọnu ti awọn eniyan si ti san owo to pọ gẹgẹ bi owo itanran kaakiri Naijiria lasiko yii.
” Itai ati àwọn eniyan rẹ̀, ati àwọn ọmọ kéékèèké, tò kọjá níwájú ọba.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Intersextuality: Dokita ni ká mu èyì tó wù wá nínú jíjẹ́ akọ tàbí abo Yara naa dọti de ibi pe awọn agbalẹ kọ ti wọn si fariga lati toju yara naa.
Àwọn eniyan tí ó kù, tí wọn kò kú ninu àjàkálẹ̀ àrùn yìí kò ronupiwada.
Lizzy Jay ọmọ Ibadan, lasiko to n ba BBC Yoruba sọrọ ni, oun kii ṣe ọmọ Ibadan rara, oun kan n ya ede Ibadan lo ni, lati ṣe awada.
Kò sí ẹni tí kò fẹ́ epo nínú ọbẹ̀, tí kì í rà á ní ọjà, ṣùgbọ́n tí epo bá lọ dà sí aṣọ mímọ́ pàtàkì olúwarẹ̀, kíákíá ni olúwa rẹ̀ yóò lọ fọ̀ ọ́ dànù’.
Wọn fi kun un wi pe bi o ṣe tun n peleke si i bayii nipinlẹ naa, awọn alaisan ti ipo wọn le atawọn to sunmọ ọ nikan ni wọn yoo maa tọju nibudo iyaraẹni sọtọ nigba ti wọn yoo ma tọju awọn ti ko safihan ami Covid19 tabi ti tiwọn ko fibẹẹ pọ nile wọn.
Ọtunba Alao Akala - ADP Àkọlé àwòrán, ìpàdé ìfọ̀rọ̀wérọ̀ BBC Yorùbá Pẹlu iwadii ati ibẹwo ti Akala ni awọn ṣe kaakiri wọn rii pe eto ilera ko koju osuwọn to.
Yìnyín ń bọ́, mànàmáná sì ń kọ yànràn ninu yìnyín náà.
Wọ́n kígbe pé, “Ẹ gbà wá o!
Ohun ti wọ́n ko jọ ni pé Amaechi dara pọ̀ mọ́ ẹgbẹ́ Boko Haram ni ọdun 2013.
Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Ẹgbẹ agbabọlu West Brom naa ti bẹrẹ iwadi tiwọn lori iṣẹlẹ ọhun to waye lọjọbọ.
Abramu ń gbé ilẹ̀ Kenaani, Lọti sì ń gbé ààrin àwọn ìlú tí ó wà ní agbègbè odò Jọdani, ó pàgọ́ rẹ̀ títí dé Sodomu.
Ẹwẹ, ọrọ naa ti wa ni ile ẹjọ lọwọ lọwọ ti eeyan ko si lẹtọ lati dede sọ ohunkohun pato nipa rẹ bo ṣe n lọ afi bi ile ẹjọ ba to fọhun lori rẹ.
Ijọba apapọ ni titpa lawọn ileewe yoo ṣi wa bayii nitori bi iye awọn to n ni arun naa ṣe n fojojumọ gogo sii lorilẹede Naijiria.
Ninu orukọ awọn minisita tuntun ti Buhari yan sipo, eeyan mẹrinla to ti ṣiṣẹ tẹlẹ bii minisitani saa akọkọ, lorukọ wọn wa ninu rẹ, amọ ti orukọ Shittu ko si lara wọn.
Wo àwọn ofin aatẹle ki o to le fo tabi wọle si Naijiria Arinrinajo gbọdọ ni iwe ẹri mo yege n ko ni coronavirus lọwọ Arinrinajo gbọdọ ṣe ayẹwo naa ni ọjọ mẹrin ṣaaju irinajo naa, o kere tan O ni iru awọn ile iṣẹ ayẹwo Covid 19 ti ijọba Naijiria a gba lọwọ awọn arinrinajo lati orilẹ-ede kọọkan.
Nítorí náà mo pada kábàámọ̀ lórí gbogbo ohun tí mo fi làálàá kójọ.
Bàbá mi náà si fèsì ó ní, Ó jọ bẹ́ẹ̀ lójú èmi náàm tàbí ilé yín ni ile tí ó wà ní ẹ̀hìnkùlé wa?
Jesu bá kìlọ̀ fún un pé, “Má ṣe sọ fún ẹnikẹ́ni, ṣugbọn lọ fi ara rẹ han alufaa, kí o ṣe ìrúbọ fún ìsọdi-mímọ́ rẹ, gẹ́gẹ́ bí Mose ti pàṣẹ.
Pasitọ Bakare ni pẹlu bi ọrọ ṣe ri yii, asiko to fun awọn ọmọ orilẹ-ede Naijiria lati dẹkun kikan sara sawọn ọta orilẹ-ede naa bayii.
kí ó lè gba iṣẹ́ yìí ati ipò aposteli tí Judasi fi sílẹ̀ láti lọ sí ààyè tirẹ̀.
"Mí ò tíí ní ìpinnu lóri ìdíje ààrẹ ọdún 2023 Ẹ ṣọ́ra fún ayédèrú ìròyìn, mi ò pe Buhari ní alákatakítí ẹ̀sìn láéláé- Tinubu ṣàlàyé Mi ò m'àwọn ẹgbẹ́ tó ń gbé ''Tinubu 2023'' kiri- Bola Tinubu Tinubu kìlọ̀ fún Buhari lórí ohun tó leè ṣàkóbá fún sáà kejì rẹ̀ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ìlú Eko ló jẹ gbèsè jù ní Nàìjíríà lẹ́yìn ìjọba àpapọ̀ ""Ti kii ba ṣe pe Tinubu jọwọ ara rẹ nigba naa, mo lero pe Kwakwanso ni ko ba gba tikẹẹti ẹgbẹ APC."
Ọlọrun fi gbogbo eniyan jìn ọ́, níbi yòówù tí wọn ń gbé, ati gbogbo ẹranko, ati gbogbo ẹyẹ, pé kí o máa jọba lórí wọn, ìwọ ni orí wúrà náà.
Ẹsun pe o gba miliọnu mẹẹdọgbọn Dọla, ninu miliọnu mẹtalelaadoje Dọla, ti wọn ni Minisita tẹlẹ fun epo rọbi, Diezani Alison-Madueke, ji ko, lo n jẹjọ le lori.
Meṣelemaya bí ọmọ meje, orúkọ wọn nìyí gẹ́gẹ́ bí ọjọ́ orí wọn, Sakaraya ni àkọ́bí, lẹ́yìn náà Jediaeli, Sebadaya, ati Jatinieli; 
Oríṣun àwòrán, Instagram/Telu1 O ni wọn pada tọju oun ni ileewosan ijọba to wa ni Asubiaro nilu Osogbo.
Ṣugbọn nígbà tí ó bá di ìrọ̀lẹ́, kí ó wẹ̀.
Ìtàn Mánigbàgbé: Ìdílé Mobee, Abass, Aniwura àtàwọn míràn rí owó tabua nínú òwò ẹrú
Ni ọjọru ni Liverpool tẹwọ gba igi ijakulẹ naa nigba ti wọn fara gba goolu mẹta ni ọwọ ikọ agbabọọlu Barcelona ti orilẹede Spain.
Ó fún ìgbín ni ẹṣin ńlá kan àti àwọn Onílù.
Wọ́n ṣe àyẹ́sí náà fun nítorí ipa ribiribi tó kó nínú ìdàgbàsókè èré ìdárayá ẹ̀ṣẹ kíkàn.
Buddy McGirt to n dari rẹ lo ni ki wọn fopin si ija naa ni ipele ikọkanla lọjọ Eti nigba ti Maxim ko lagbara mọ.
Ìwọ Kapanaumu, o rò pé a óo gbé ọ ga dé ọ̀run ni?
Àṣádì ni ó sì ṣe alága dípò rẹ̀.
Ọlọrun lo n fun ni, to si ngba a, fun idi eyi ko sẹni to lagbra lori aye ẹlomiran.
Femi Gbajabiamila, olùranlọ́wọ́ pàtàkì fún ààrẹ lọ́rí ọ̀rọ̀ ilé ìgbìmọ̀ aṣòfin Abdulrahman Sumaila, Ahmed Wase Muhammed Monguno àti àwọn míì.
A yìnbọn lu Precious láti dáa dúró ni, akò mọ̀ pé o máa kú- Ọlọ́pàá Iwadii naa bẹrẹ lẹyin ti awọn obi awọn obinrin ti nkan wọnyii ṣẹlẹ si lọ fi ẹjọ sun ni agọ ọlọpaa abi ti wọn ba ri awọn iṣẹlẹ bẹẹ lori ẹrọ ayelujara.
Oṣu Kinni, ọdun 2020 ni wọn fi ẹsun ibajẹ onigun mẹrindinlogun kan Adesina, amọ awọn alakoso banki naa fi ọwọ osi da ẹjọ naa nu wi pe ko si otitọ kankan nibẹ.
“Bí mo bá yọ̀ nítorí ìparun ẹni tí ó kórìíra mi,tabi kí inú mi dùn nígbà tí ohun burúkú bá ṣẹlẹ̀ sí i.
iroyin ni Aarẹ Bongo to bẹrẹ aarun rọpa rọsẹ ni Osu Kẹwa, ọdun to kọja, ti o si n gba itọju ni orilẹede Morocco.
Bẹ́ẹ̀ náà ni Asafu, Hemani, ati Jedutuni, aríran ọba.
Kì í ṣe ẹbọ sísun ati ẹbọ ìmúkúrò ẹ̀ṣẹ̀ni o ní inú dídùn sí.
Kì í yára bínú,Ó kún fún ìfẹ́ tí kì í yẹ̀,a sì máa dárí ẹ̀ṣẹ̀ ji eniyan.
Portharcout sugbon ti awon afurasi odaran yii dari oko ohun si opopona Ibadan
Ewe, ifigabaga naa nireti wa tele pe, yoo waye ni gbagede London’s O2 Arena lojo kerinla osu kerin-in odun yii, sugbon ni bayii yoo waye lojo ketalelogun inu osu kefa odun ti a wa yii.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Olórí ilé aṣòfin ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́, Michael Adeyemo jáde láyé 27 Ìgbé 2018 Oríṣun àwòrán, facebook/Michael Adeyemo Àkọlé àwòrán, LoOlori ile aṣofin ipinlẹ Ọyọ, Michael Adeyemo jade laye Iroyin ti sọ wi pe, aisan ọkan lo pa Olori ile aṣofin ipinlẹ Ọyọ, Aṣofin Michael Adeyemo.
Àwọn Juu ati àwọn tí kì í ṣe Juu pẹlu àwọn ìjòyè wọn dábàá láti ṣe wọ́n lọ́ṣẹ́, wọ́n fẹ́ sọ wọ́n ní òkúta pa.
Nítorí ó wà ní àkọsílẹ̀ pé Abrahamu ní ọmọ meji, ọ̀kan ọmọ ẹrubinrin, ọ̀kan ọmọ obinrin tí ó ní òmìnira.
awon ko ni pariwo eto ibura fun aare Buhari ti  saa keji yii, ni eyi ti  yoo maa waye ni ojo kọ́kàndínlọ́gbọ̀n ,osu karun un, odun 2019.
Aare Talon wa so pe“Bi iwa fayawọ  iresi se n koba eto ọrọ agbe lorile ede Naijiria , lo n se akoba fun eto ọrọ aje orile ede mejeeji yii,orile ede Naijiria si je orile ede ti a ko lee fọwọ rọ sẹyin.
Láti Inú Ikú sí Inú Ìyè.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Boko Haram: Ìjọba ṣetán láti ra irinṣẹ́, sanwó oṣù fún adúnkookò mọ́ni tẹ́lẹ̀ 23 Agẹmo 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 26 Agẹmo 2020 Oríṣun àwòrán, Others Awọn ikọ agbesunmọmi to to mọkanlelẹgbẹta ti wọn jọwọ ara wọn fun ijọba, ti kẹkọọ jade nile iwe.
“Yóo gba òbúkọ meji lọ́wọ́ ìjọ eniyan Israẹli fún ẹbọ ìmúkúrò ẹ̀ṣẹ̀, ati àgbò kan fún ẹbọ sísun.
"Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Akomolede ati asa Yoruba: Ẹ wá kọ́ nípa àpòtí ìṣura èdè wa lórí BBC Yorùbá ""Gbogbo wa la n waasu nipa bi aye se jẹ asan, sibẹ awa kan ni orisun isoro ara wa, o n waasu ifẹ, ti ikorira si gba ọkan rẹ kan."
Osun state lockdown update: Ìpínlẹ̀ Osun ṣòfin ẹ̀wọ̀n gbére fún ẹnikẹ́ni tó bá jẹ̀bi ẹ̀sùn ìfipábánilòpọ̀
Ọmọ ayo mẹrin mẹrin yoo si wa ninu koto kọọkan.
Ninu ọrọ tiẹ naa, Mama Ikimot salaye pe awọn ọrẹ Ikimot ti wọn dijọ n pada bọ lati ileẹkọ sọ pe, ipanu ‘Cheese ball’ ni obinrin kan fun Ikimot, to fi gbe sinu kẹkẹ Marwa.
Awọn iroyin ti ẹ le nifẹ si: NNPC n ronu afikun owo epo NNPC gbọdọ pese epo laarin ọjọ meje Naijiria bẹrẹ iwadi lori owo iranwọ epo Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Aláàfin tó rí ìbẹ̀rẹ̀ àti opin sáà gómìnà mọ́kànlélógún l‘Oyo14 Sẹ́rẹ́ 2021 Èyítí A Ń Kà Jùlọ 1 Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún un 2 Ọjọ́ orí wo ló yẹ kí ikùn ẹ̀dá bẹ̀rẹ̀ sí tóbi?
Bayii, ko tii si ẹni to mọ iye ẹmi to ti sọnu latari iṣẹlẹ naa ṣugbọn akọọlẹ wa pe, ọgọọrọ eru ati dukia lo ti ṣofo.
eto ilana ofin to fẹsẹ   eto idibo naa
Ọmọ ẹgbẹ́ APC mẹ́ta bá ìpolongo ìbò lọ l‘Eko BBC ṣèfilọ́lẹ̀ àmì ẹ̀yẹ 2019 Komla Dumor Award Ènìyàn 26,000 ni àìsàn jẹjẹrẹ ń pa lóòjọ́ kíni ọ̀nà àbáyọ sí àìsàn Lassa Fever?
Ẹ̀gbọ́n àti àbúrò wà ní ilé ẹ̀jọ́ lórí ikú Tolulope Arotile Oríṣun àwòrán, NAF Ẹgbọn ati Aburo, Nehemiah ati David Adejo lo ti lọ kawọ pọnyin rojọ bayii o lori iku to pa obinrin akọkọ ologun to wa ọkọ baalu awọn ajagun ofurufu, Tolulope Arotile.
Lẹyin eyi lo fi ara rẹ silẹ fun awọn ọmọ ogun Sri Lanka ti wọn ran lọ fun eto igbe aye ọtun ni awujọ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìtàn Mánigbàgbé: Baṣọ̀run Gáà jẹ́ àgbà ìjòyè tó le è yípadà sí ẹranko tó bá wù ú 20 Ẹrẹ̀nà 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 21 Ọ̀wàrà 2019 Oríṣun àwòrán, Steemit Ko fẹẹ si ọmọ Kaarọ o jiire ti ko gbọ orukọ Basọrun Gaa ri nitori odu ni, kii se aimọ fun oloko.
ede Niajiria ti dá èròǹgbà rẹ láti dá
Ààlà yín ní ìhà gúsù yóo jẹ́ láti òpin Òkun-Iyọ̀ ní ìlà oòrùn.
Bi fidio naa se lọ ree: Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Owo ori ti ko san yi wa lati ara owo adehun ti Sandes ri lori ẹtọ si aworan rẹ to se lọdun 2012 si 2013.
OLUWA tún rán Sakaraya kí ó sọ fún wọn pé, 
isele buruku to n waye lo faa ti awon se da iko omo ogun HARBIN KUNAMA III silẹ.
Jesu bá bá ẹ̀mí èṣù náà wí, ó wo ọmọ náà sàn, ó bá fà á lé baba rẹ̀ lọ́wọ́.
Awọn olupese: Isọri awọn eeyan yii ni awon to n fun awọn olufẹhonuhan ni ounjẹ ki wọn ba a le ni okun lati tẹsiwaju ninun iwọde ọhun.
Bẹ́ẹ̀ ní yóo rí ní ilẹ̀ ayé,láàrin àwọn orílẹ̀-èdèbí igi olifi tí a ti gbọn gbogbo èso rẹ̀ sílẹ̀,lẹ́yìn tí a ti kórè tán ninu ọgbà àjàrà.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí kan sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
Bẹ́ẹ̀ gẹ́gẹ́ ni ìmọ́lẹ̀ yín níláti máa tàn níwájú àwọn eniyan, kí wọn lè rí iṣẹ́ rere yín, kí wọn lè máa yin Baba yín tí ó ń bẹ lọ́run lógo.
Solomoni fi wúrà tí a fi òòlù lù ṣe igba (200) apata ńláńlá.
Àwọn ẹyẹ bá wá ṣà á jẹ.
Mo kí gbogbo yín láì ku ẹnìkan, o dìgbà díẹ̀ ná, onílé re ilé o.
Wọ́n ri yín, ọwọ́ sì tẹ̀ yín,nítorí pé ẹ yájú sí èmi OLUWA.
Wọ́n lè fà mí lé wọn lọ́wọ́, kí wọ́n sì fi mí ṣẹ̀sín.
Ọtí kan wà níbẹ̀ tí wọ́n npè ní mulled wine tó gbọ́nà fẹli-fẹli.
Ni ọdun 2015 ni aniyan ifẹ laarin awọn mejeeji yii kọkọ lu sita nigba ti awọn ayaworan kọkọ kofiri wọn pọ ni papakọ ofurufu ilu Los Angeles International Airport.
Máa gbé kẹ̀kẹ́ rẹ lọ, àwọn akọròyìn kọ̀ ìpàkọ́ sí Femi Fani Kayọde Ọkùnrin kan di èrò ọ̀run nítorí pé o fi ẹ̀sùn kan alájọgbélé rẹ̀ pé o n yan ìyàwó ẹnìkan lálè Èèyàn mẹ́tàlélógóje míì ṣẹ̀ṣẹ̀ kó COVID-19 ní Nàìjíríà Pẹlu eyi, ijọba ipinlẹ naa ti kede ọjọ kọkanlelogun, oṣu kẹsan an naa lati pari saa kẹta eto ẹkọ to n lọ lọwọ ki ajakalẹ arun COVID-19 loṣu kẹta ọdun 2020.
“Ẹbọ ohun jíjẹ tí o bá mú wá fún OLUWA kò gbọdọ̀ ní ìwúkàrà ninu, nítorí pé ìwúkàrà tabi oyin kò gbọdọ̀ sí ninu ẹbọ sísun sí OLUWA.
" Ìdí rèé tí mi ò fi yọjú sí ìgbìmọ̀ àjọ PFN- Fatoyinbo Ẹ yọjú sí FBI bí ẹ kìí bá ṣe ''yahoo boys'' - Abike Dabiri-Erewa Èmi àti Saheed kìí ṣe ọmọdé, a ti jọ ṣe Sinimá papọ̀, èyí túmọ̀ sí pé ìjà ti parí - Fathia Balogun Wọ́n ta ère Ọ̀ṣun Osogbo sí Togo - Bàbá Ọṣun figbe ta Ayédèrú Ọ̀ṣun ni wọ́n ń bọ lónìí, kìí ṣe ojúlówó - Bàbá Ọlọ́ṣun tún figbe ta Ọlọwọ tuntun yii, tii se amofin, la wa n gbadura fun pe igba rẹ yoo tu ilu Ọwọ ati ilẹ Yoruba lapapọ lara.
Lẹ́yìn náà, Aaroni kọjú sí àwọn eniyan náà, ó gbé ọwọ́ rẹ̀ sókè, ó sì súre fún wọn.
Iroyin naa ni Chris lo ransẹ pe Olamide pe ko wa sile oun, ti onitọun naa si wa pẹlu aburo rẹ obinrin, ẹni ọdun mejilelogun ati ọmọ rẹ mejeeji to bi fun Chris, ti wọn jẹ ọmọ ọdun meje ati mẹta.
O fi kun un pe bi iyanṣẹlodi awọn ko ba tu irun kan lara ijọba lori dida owo epo ati ina naa pada si bo ṣe wa tẹlẹ ri, a jẹ pe awọn yoo fi ida igba ninu ọgọrun un kun owo ori ọja ti awọn naa n ta ni o.
“Pada lọ sí ilé rẹ, kí o lọ ròyìn ohun tí Ọlọrun ṣe fún ọ.
Mose ṣá ti sọ pé, ‘Oluwa Ọlọrun yín yóo gbé wolii kan bí èmi dìde láàrin àwọn arakunrin yín.
Alaga ajọ Oyo SUBEB naa wa parọwa si awọn to n wa isẹ lati farabalẹ, ki wọn ma ba a lugbadi awọn onijibiti.
Bí ó ti ń ronú bí yóo ti gbé ọ̀rọ̀ náà gbà, angẹli Oluwa kan fara hàn án lójú àlá.
O ni ohun to dara ni ti awọn omuwẹ ba ni awọn ohun igbalode to dara.
Davido fi orúkọ bàbá rẹ̀, Adedeji, sọ ọmọ tuntun tó bí Oníbàárà tó bá fi owó ránṣẹ lórí ẹrọ ibaraẹnisọrọ yóò sanwo orí Health Talk: Onímọ̀ ìṣègùn ní àìsàn tó o ṣe l'óru yóò tètè sàn ju èyí tó o ṣe lọ́sàn-án lọ Osisẹ ile iwe naa parọwa si awọn obi wi pe awọn kan n woye boya paali naa yo dawọ asemase duro lasiko idanwo, eleyii ti awọn ọmọ ile iwe naa fi ọwọ si lati se e.
Mo kọ̀ ọ́ sílẹ̀ fún ìgbà díẹ̀,ṣugbọn n óo kó ọ jọ pẹlu ọpọlọpọ àánú.
O Fagunwa, Adebayo Faleti, Akinwumi Iṣọla, Lawuyi Ogunniran àti Oladejo Okediji ṣiṣẹ silẹ ki wọn to lọ3 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Seyi Makinde ṣèlérí owó oṣù kẹtàlá fáwọn òṣìṣẹ́ Amotekun l' Oyo10 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Fídíò, Soyinka Cancer: Àṣe ara mi ni iso ti n run gbogbo bí mo ṣe n ṣèrànwọ́ lórí jẹjẹrẹ27 Bélú 2019 Adeyeye Ile Ife: Kílódé tí Ọọni Ife, Oba Ogunwusi kò fi gbọdọ̀ rí ọmọ rẹ̀ tuntun títí di ẹ̀yìn oṣù mẹ́fà?
Ọjọ́ mẹfa ni kí o fi ṣe gbogbo làálàá ati iṣẹ́ rẹ; 
Mo ti ba awon egbe agbofinro,ile –ifowopamo, awon osise ijoba ati awon miiran  soro lati satileyin fun ijoba nipa gbigbogun ti iwa ibajẹ .
Nítorí ilé Israẹli ni ọgbà àjàrà OLUWA ọmọ ogun,àwọn ará Juda ni àjàrà dáradára tí ó gbìn sinu rẹ̀.
Bi esi ayẹwo naa ṣe lọ niyii: O ti pe ẹgbẹrun mẹta ati marundinlaadọjọ eeyan to ti ni aarun yii ni Naijiria.
Àsẹ̀yìnwá ni ó tó yé wípé ọkọ náà ni ó ṣe olùtọ́jú aya, ẹni tí ó arán ń ṣe.
A si le se apejuwe Ọba Lamidi Adeyemi bii oloriire, ti Ọlọrun gba fun, to si ri aanu pupọ gba.
  Leyin naa o se ipade pelu Aare Hosni Mubarak ki o to tun sabewo si Sultan Hassan ni mosalasi re.
Àwọn ọ̀tá rẹ̀ yóo pọ̀ bí iyanrìn,ogunlọ́gọ̀ àwọn aláìláàánú yóo bò ọ́ bí ìyàngbò tí afẹ́fẹ́ ń fẹ́ lọ.
Lẹ́yìn náà, ó mú ọmọ rẹ̀, ó sì jáde lọ.
Samuẹli gbé òkúta kan, ó rì í mọ́lẹ̀ láàrin Misipa ati Ṣeni, ó sì sọ ibẹ̀ ni Ebeneseri, ó ní, “OLUWA ràn wá lọ́wọ́ títí dé ìhín yìí.
Nítorí pé o óo bá àwọn Siria jagun ní Afeki títí tí o óo fi ṣẹgun wọn.
Ìbá dùn mọ́ ọn láti máa jẹ oúnjẹ tí àwọn ẹlẹ́dẹ̀ ń jẹ, ṣugbọn ẹnikẹ́ni kì í fún un ní ohunkohun.
Amọ, a ri awọn miran to sọ wi pe inu wọn dun si afara thrid mainland ti ijọba ti naa nitori ọpọlọpọ ileeṣẹ lo ti wa paṣẹ fun awọn oṣiṣẹ wọn lati ṣiṣẹ lati ile, eleyii to mu irọrun ba awọn eniyan.
Gbogbo àwọn arọmọdọmọ Obedi Edomu, ati àwọn ọmọ wọn, pẹlu àwọn arakunrin wọn, tí wọ́n yẹ láti ṣiṣẹ́ jẹ́ mejilelọgọta.
Tó o bá ṣàdéhùn ìfẹ́ tó ò mú u ṣẹ, ẹ̀wọ̀n lo fi ń ṣeré 'Eré orí ẹní' rán Davy lọ sọ́run ní ìlú Eko Oral Sex: Bóo bá ń gba ẹnu ní ìbálòpọ̀, wo àìsàn tóo lè kó lójú ara rẹ Àjọ ọlọpàá Eko kédé pé ìbalòpọ̀ nítà kò bójúmu Awọn obinrin to fi ẹsun naa kan an jẹ ẹni ọdun marundinlọgbon, ọgbọn ọdun, mẹtalelọgbọn ati mẹrindinlaadọta ọdun.
 labe isele deede , àwon atomu sulfuru unda horo oniatomumejo yiyipo pelu afida kemika s.
Bi ilu wọn ba gba wọn laaye daadaa ni, wọn ko ni kuro.
Ẹ gbadura sí oriṣa yín ṣugbọn ẹ má fi iná sí igi ẹbọ yín.
Aarẹ Buhari kẹ́dùn ọ̀pọ̀ ẹ̀mí àti dúkìá tó jóná ni ọjà Onitsha Ibẹrẹ aye Funke Adesiyan Funke Adesiyan bẹrẹ pẹlu iṣẹ arinrin oge ni ọmọ ọdun mẹtala, o bẹrẹ si ni ṣe okowo fun ra rẹ, nigba to pe ọmọ ọdun mẹrinla.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Akomolede ati Aṣa: Mọ̀ síi nípa ìró afárànma àti agbárànmọ́ fáwẹ́ẹ̀lì Yorùbá Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Jubril Martins-Kuye: Mínísítà lẹ́ẹ̀méjí, Jubril Martins-Kuye ti jáde láyéwákàtí 6 sẹ́yìn Inter-family marriage: Wo oríṣìí àrùn márùn ún tí ìgbéyàwó láàrin ìbátan máa ń fà17 Sẹ́rẹ́ 2021 Covid-19: Oluwo ní àṣẹ Ọlọ́run ni pé coronavirus ò lè wọ ìlú Iwo, àmọ́ òun ń wọ ìbòmú tórí olórí t'óun jẹ́wákàtí 6 sẹ́yìn Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Gege bi egbe ajafeto omoniyan ile okere, “Ejo naa dara lataari esun iseku pani, sugbon ile ejo o ba tun foju fo awon n kan miiran.
gẹ́gẹ́ bí ẹ ti mọ̀ pé bí baba ti rí sí àwọn ọmọ rẹ̀ ni a rí sí ẹnìkọ̀ọ̀kan yín; 
6bn ohun ìní Nàìjíríà A fẹ́ bẹ̀rẹ̀ òfin má lo fóònù mọ́ fàwọn ọmọ wa -Òbí Ìṣẹ̀lẹ̀ Bakana: àwọn tórí kó yọ fẹ́ bẹ̀rẹ̀ ètò ìrànlọ́wọ́ Gómìnà ìpínlẹ̀ Rivers, Wike pàṣẹ kí agbófinró mú kọngílá ilé tó wó ní Portharcourt Ọọni pe fun ifọwọsowọpọ Naijiria Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Jẹ ki ọrọ wa jọ ye ara wa lori mọṣalaṣi yii Gomina Wike salaye fun gbogbo awọn to kọwọrin pẹlu alaga ajọ awọn gomina ni Naijiria pe ko si ile tabi Mọṣalaṣi lori ilẹ naa lasiko to n mu Fayẹmi rin kaakiri ilẹ naa.
Oríṣun àwòrán, Google Àwọn ìgbésẹ̀ tóo lè fi so NIN rẹ̀ pọ mọ́ síìmù MTN, Glo, Airtel ati 9Mobile rẹ MTN, Glo, Airtel àti 9mobile ni àwọn síìmù ìbánisọ̀rọ̀ tó ṣe pàtàkì jùlọ tí àwọn ènìyàn ń lò ní Nàìjíría, nítorí ìdí èyí ni wọ́n ṣe fí àwọn ìlànà tí ènìyàn le gbà láti mọ́ NIN rẹ̀ lórí ìtàkùn wọ́n, pàápàá jùlọ tó bá jk nọ́mbà náà ni ènìyàn lò lásìkò tó forúkọ sílẹ̀ fún ìwé ìdánimọ̀.
Nítorí náà, mo di eniyan ńlá, mo ju ẹnikẹ́ni tí ó ti wà ní Jerusalẹmu ṣáájú mi lọ, ọgbọ́n sì tún wà lórí mi.
Ìjìyà rẹ nìyí, ó sì korò;ó ti dé oókan àyà rẹ.
Ẹni ọdún mejilelogun ni Amoni nígbà tí ó jọba, ó sì wà lórí oyè ní Jerusalẹmu fún ọdún meji.
Ìjọba orilẹ̀-èdè Nàìjíríà dojúkọ wọ́n nígbà ti wọ́n ni ìlànà òfin tí àwọn ni awọn yóò maa lò láì bọ̀wọ̀ fún òfin orílẹ̀-èdè Nàìjíríà, èyí ti ijọba si lòdì sí gede ń gbe Togo sòfin aago ti olùfẹ̀hónú han lè jáde àtí àsìkò tí ó wọlé Ẹ̀kúnrẹ́rẹ́ ìdí tí àwa Shiite fí ń fẹ̀hónúhàn ní Abuja -Zakariyah Sowore ṣèpàdé pẹ̀lú Nnamdi Kanu láti dojú ìjọba Nàíjíríà bolẹ̀ - Àjọ DSS Bí ọdún Ọ̀ṣun Oṣogbo ṣe bẹ̀rẹ̀ rèé àti pàtàkì rẹ̀ fún Nàíjíríà Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí kan sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
Ha ha ha ha"", Bamiloye rẹrin, o ni lootọ oun mọ pe iyawo oun rẹwa, ti awọn eeyan si maa n sọ ọ kan oun loju."
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: 'Èèkàn ìṣèjọba tiwantiwa ni Atiku Abubakar' Pín fídíò 'ayédèrú' kó o ríjà ológun Nàìjíríà Ilumọọka asọrọdorin, Rapper Falz ni wọn fun ni ami ẹyẹ olorin Rap ti o pegede julọ ni Afirika.
bí o bá wá ọgbọ́n bí ẹni ń wá fadaka,tí o sì wá a bí ẹni ń wá ìṣúra tí a pamọ́,
A gbọ wipe awọn iroyin ofege naa sọ wipe, Osinbajo ti fi ibinu kọwe fipo silẹ nitori wipe wọn ko pe e si ibi ipade kan ni ile ijọba.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ileejọ gbe asofin agba lẹyin lati tako iyansipo.
gọbọi ti won maa  n gba lori ọja dinku ,
Àwọn ọdọmọbinrin óo máa jó ijó ayọ̀ nígbà náà,àwọn ọdọmọkunrin ati àwọn àgbààgbà, yóo sì máa ṣe àríyá.
Ṣaaju ni fọnran yii ṣafihan eto isinku dokita akọkọ ti coronavirus pa ni Ghana.
Gbogbo àwọn tí wọ́n wà ní ibùdó Juda jẹ́ ẹgbaa mẹtalelaadọrun-un ó lé irinwo (186,400).
Oríṣun àwòrán, Reuters Iṣekupani yii ti jẹ bi irunu fun awọn ọmọ ilẹ Afrika to wa ni orilẹede Amerika ti wn ti lugbadi ki awọn ọlọpaa alawọ fun fun ṣe wọn basubasu.
Lẹ́yìn náà, ó wọ yàrá inú lọ, ó wọn àtẹ́rígbà ẹnu ọ̀nà, ó jẹ́ igbọnwọ meji (bíi mita kan), ìbú ẹnu ọ̀nà àbáwọlé náà jẹ́ igbọnwọ mẹfa (mita 3), ògiri ẹnu ọ̀nà àbáwọlé náà sì gùn ní igbọnwọ meje (mita 3½).
 Orile-ede yii kun fun awon odo ti o lebun ere boolu afesegba, sugbon ti won nilo iranwo lati saseyori.
Celina tun gba ami ayo miiran sagbon pelu boolu agbesile gba.
Awon ti yoo wa sibi ipade naa ni egbe awon osise, ile-ise aladaani ati ijoba apapo, bakan naa ni ijiroro yoo tun waye ni ojo Aje, ojo karun un osu kokanla ni ofiisi naa, lati tun jiroro  lori ekunwo owo osu awon osise orile ede yii.
Nigba to n salaye bo ṣe ṣe alabapade afurasi naa, to fi de ọdọ rẹ, Akeugbagold ni lati ipasẹ eeyan kan to ni orukọ rere laarin ilu, to si n ṣe daadaa ni oun ti mọ ọmọdekunrin naa.
Ọba Ọdẹdiran ni kayeefi pata gbaa ni o jẹ pe afurasi naa lee sa kuro ni ahamọ awọn pẹlupẹlu bi wọn ṣe ni ẹwọn wa lọwọ ati ẹsẹ rẹ nigba gbogbo.
 lẹ ́ yìn ìgbà tí ó ti di olórí ilẹ ̀ faransé tán ó tún fẹ ́ di olórí gbogbo ìlú Òyìnbó .
Lẹ́yìn náà, Josẹfu pàṣẹ fún àwọn iranṣẹ rẹ̀ tí wọn ń ṣiṣẹ́ ìṣègùn pé kí wọ́n fi òògùn tí wọ́n fi máa ń tọ́jú òkú, tí kì í fíí bàjẹ́, tọ́jú òkú baba òun.
Réṣẹ́ẹ̀lì Ọ̀ṣúnyọmí tí í ṣe ìyá mi jẹ́ obìnrin tí ó fẹ́ràn baálé rẹ̀ tí ó sì fẹ́ràn ọmọ, ọ̀spọ̀lọpọ̀ àánú ní ń bẹ ihò ojú ìyá mi.
Ọlọrun ti jókòó ní ààyè rẹ̀ ninu ìgbìmọ̀ ọ̀run;ó sì ń ṣe ìdájọ́ láàrin àwọn ẹ̀dá ọ̀run:
Ẹ̀kọ́ mẹ́jọ tó yẹ kí ilẹ̀ Afirika kọ́ lára àjàkálẹ̀ aàrùn coronavirus Kìí ṣe gbájúẹ̀ nìkan lọmọ Nàìjá ń ṣe lókè òkun!
"Wọn bọ mí sí ihoho"" Awọn akẹkọọ akẹgbẹ rẹ lo pada gbaa silẹ lọwọ wọn ti wọn si gbe e lọ si ile iwosan."
Jehoṣafati ọba Juda pada ní alaafia sí ààfin rẹ̀ ní Jerusalẹmu.
Bí ọkọ rẹ̀ bá lòdì sí ẹ̀jẹ́ náà, obinrin náà kò ní san ẹ̀jẹ́ náà.
O si jade laye ni irọlẹ ọjọ kọkandinlọgbọn, osu keje, ọdun 2020.
Nínú èyí, ó hànde wípé Adeleke forúkọ sílẹ̀ fún ìdánwò GCE C'O'Level lọ́dún 1981 sùgbọ́n ó fìdí rẹmi nínú èdè Gẹ́ẹ̀sì tí wọ́n sì kàá sí pé kò fara hàn nínú àwọn ìdánwò tó kù.
Ikilọ ti ijọba fi sita yii ko sẹyin ojo oniwakati mejidinlogun to ṣọsẹ nipinlẹ naa lopin ọsẹ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Abayọmi Aranmọlatẹ, Dr Laser: Vagino Plasty àti iṣẹ́ abẹ ẹwà Obìnrin ló jẹ mí lógún Wayi o, agbẹjọro agba fun Naijiria Abubakar Malami, to soju fun aarẹ Buhari nibi eto ti wọn fi n sami ayajọ olukọ naa, kede pe ijọba apapọ yoo fọwọ sowọpọ pẹlu ijọba ipinlẹ lati pese eto koriya fawọn olukọ, paapa awọn to wa lagbegbe igberiko.
Ẹni to bori: Congo DR South Africa vs Guinea.
"Oríṣun àwòrán, @NPF_NIGERIA Ileeṣẹ ọlọpaa sọ loju opo Twitter rẹ pe ""awọn ọmọ ogun yinbọn laimọye igba mọ awọn ọlọpaa naa, botilẹ jẹ pe o fojuhan pe ọlọpaa ni wọn, ti wọn si wa lẹnu iṣẹ ilu."
Níwọ̀n tí òun sì jẹ́ ọkọ Ìdààmú-Ayé, owó náà yόò di ti òun.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Kidnappings in Nigeria: Ajínigbé ń bèèrè fún epo, iṣu àti ọ̀tí Schinap àti owó ìtanràn 21 Ògún 2019 Àkọlé àwòrán, Orọ àwọn ajinigbe n gbẹnutan ni ariwo awọn eniyan bayii.
Oríṣun àwòrán, Arewa_ilorin_pple Ẹgbẹ alaanu naa, to pe ni Ajike Support Grouplo gba ile filaati oniyara meji fun idile naa laarin igboro ilu Ilorin.
Kiriati Baali (tí wọn ń pè ní Kiriati Jearimu), ati Raba, gbogbo ìlú ati ìletò wọn jẹ́ meji.
Ọjọ buruku, Eṣu gbomi mu naa bọ si ọjọ Aiku.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ó ti di ogún èèyàn tó kú ní ilé alájà tó wó l'Eko Ilé kẹta da wó l'Eko láàrin ọsẹ méjì Mìmì kan kò mì wá, Ẹlẹka yóò jíǹde bí i Lasaru inú Bíbélì -PDP Ekiti Obìnrin kan bí ibejì lẹ́yìn ọjọ́ 26 tó bí ọmọkùnrin '$800 ni Amẹ́ríkà ń fún ọmọ Yorùbá tó bá gba ìṣẹ́ ológun rẹ̀ lóṣooṣù' Ilé ẹjọ́ dajọ ikú fun ọkunrin tó pa olólùfẹ́ rẹ̀ Ẹ wo ọmọ ọdún méjì tó mọ orúkọ orílẹ̀èdè 40, àwọn ààrẹ l'ágbàáyé láì lọ síléèwé Ọmọkùnrin tó pa ọmọ igbákejì Gómìnà Ondo gba ìdàjọ́ ikú Wọ́n ta ère Ọ̀ṣun Osogbo sí Togo - Bàbá Ọṣun figbe ta Tinubu kìlọ̀ fún Buhari, Osinbajọ lórí àfikún owó orí ọjà VAT Kí ni àmì ohùn 'Aguntaṣọọlo'?
Man City sán bàntẹ́ ìyà fún Chelsea pẹ̀lú 6-0 Wàhálà bẹ́ sílẹ̀ níbi ìpolongo Buhari ní Abẹokuta Ẹwẹ, ẹgbẹ agbabọọlu Arsenal ti dupẹ lọwọ Ramsey fun akoko rẹ pẹlu ikọ naa loju opo Twitter rẹ Wọn ti ṣe ayẹwo ara fun Ramsey ninu oṣu kinni ṣaaju adehun rẹ pẹlu Juventus.
Wọ́n jáde kúrò níwájú ìgbìmọ̀, wọ́n ń yọ̀ nítorí a kà wọ́n yẹ kún àwọn tí a fi àbùkù kan nítorí orúkọ Jesu.
Nítorí náà, àwọn Yorùbá a máa dáàbò bo orúkọ rere wọn gẹ́gẹ́ bí wọn tí ń ṣọ́ra láti máa hùwà rere.
Mo sì fẹ́ kí ẹ ṣàkíyèsí pé òótọ́ ni gbogbo nǹkan ti w\\on s\\o nípa òunjẹ, o fi han ni pé nǹkan tí ènìyàn bá ń fẹ́ láti mọ, yóò mọ̀ ọ́, àwọn Èdìdàrẹ́ gọ̀ wọ́n bàjẹ́ ṣùgbọ́n wọ́n kọ́ ẹ̀kọ́ nípa oúnjẹ.
Kí wọ́n wí pé “OLUWA, dá àwọn eniyan rẹ sí,má sì sọ ilẹ̀ rẹ di ohun ẹ̀gàn ati ohun ẹ̀sín láàrin àwọn orílẹ̀-èdè yòókù.
ranse si aare Buhari lati ki Buhari ku ori ire fun jijawe olubori gege bi aare
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Africa Eye: Mo máá ń ṣàìsàn tí mi ò bá ṣiṣẹ́ òru Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Africa Eye: Mo máá ń ṣàìsàn tí mi ò bá ṣiṣẹ́ òru 7 Èbibi 2019 Ẹka ile iṣẹ BBC to n ṣe eto to maa n tu aṣiri awọn ohun to farasin, Africa Eye balẹ si ilu Luo ni orilẹede Kenya.
Nítorí èyí ni Ọmọ Ọlọrun ṣe wá, kí ó lè pa àwọn iṣẹ́ Èṣù run.
Kí a tó sanwó ajínigbé ní àwọn agbófinró dóòlà ọmọ Ọffa mẹ́fà -ODU Gbàgbé ẹ̀sọ́ ara $40m rẹ pátápátá - Ilé ẹjọ́ sí Dienzani Awọn esi iwadii yii lo maa n jẹ ki wọn lee sọ igba ti eeyan lee loyun ati igba ti nkan oṣu miran lee yọju.
Lẹyin gbogbo ifagagbaga, Argentina fagba han Super Eagles pẹlu ami ayo meji si ẹyọ kan.
Wọ́n fi iná ògùṣọ̀ wọn sí ọwọ́ òsì, wọ́n sì fi fèrè tí wọn ń fọn sí ọwọ́ ọ̀tún, wọ́n bá pariwo pé, “Idà kan fún OLUWA ati fún Gideoni.
Dokita onimọ nipa itoju pajawiri ni ile iwosan Cambridge Razeen Marhroof sàlàye pe àwọn anfani miran tun wá ninu ki ènìyàn máá gba ààwẹ.
Lẹ́yìn náà, gbé pẹpẹ wúrà turari siwaju àpótí ẹ̀rí náà, kí o sì ta aṣọ sí ẹnu ọ̀nà àgọ́ náà.
Àánú ṣe é, ó yára, ó dì mọ́ ọn lọ́rùn, ó bá fẹnu kò ó ní ẹnu.
Ṣàánú mi, OLUWA,nítorí ìwọ ni mò ń kígbe pè tọ̀sán-tòru.
Aarẹ ilẹ Amẹrika, Donald Trump ni orilẹede Amẹrika yoo kọwe bọwe adehun tuntun pẹlu ilẹ Gẹeṣi, lẹyin ti wọn ba dagbere fun ajọ EU tan.
" Dupe ati ọkọ rẹ yii ko rira fun bi ọdun kan aabọ, nitori pe onitọhun rinrinajo kuro niluuu.
Ara ló ń ta àwọn ẹgbẹ́ NURTW tó ń pariwo mi kiri, APC ni wọ́n bá lọ nígbà náà l'Oyo- Auxiliary Daniel Prude: Ìbòjú tí àwọn ọlọ́pàá New York fi bo ọkunrin ọhun ló ṣe ikú pà á Mo ṣetán láti fi ẹ̀ṣẹ́ dín dòdò ìyà fún Anthony Joshua- Efe Ajagba A kú oríire!
Jakande pé 90 láì gba àmì ẹ̀yẹ kankan ní Nàíjíríà -Osoba Jeremy Hunt ni òun gbà pé Boris Johnson á ṣiṣẹ́ dáadáa Èèmọ̀!
kí eniyan Ọlọrun lè jẹ́ ẹni tí ó pé, tí ó múra sílẹ̀ láti ṣe gbogbo iṣẹ́ rere.
Bí ó bá jẹ́ pé ó fẹ́ fi ẹran kan pààrọ̀ ẹran mìíràn, ati èyí tí wọ́n pààrọ̀, ati èyí tí wọ́n fẹ́ fi pààrọ̀ rẹ̀, wọ́n di mímọ́.
Awọn oluwadii kan nileewe giga fasiti ilu Geneva lo fidi rẹ mu lẹ gbigbọ orin maa ṣe atunṣe ọpọlọ awọn ọmọde.
Jesu dá a lóhùn pé, “Bí ó bá jẹ́ pé o mọ ẹ̀bùn Ọlọrun ati ẹni tí ó wí fún ọ pé, ‘Fún mi ní omi mu,’ Ìwọ ìbá bèèrè omi ìyè lọ́wọ́ rẹ̀, òun ìbá sì fún ọ.
Wọ́n dó ti ìlú náà títí di ọdún kọkanla ìjọba Sedekaya.
725trn) to wa lọdun 2017 si triliọnu mẹrinlelogun ati biliọnu lọna irinwo naira din diẹ ( ₦24.
O ni wọn tun sọ fawọn pe''awọn meji ti wọn jijọ n ṣiṣẹ ni wọn ri ẹjẹ lẹnu ẹrọ naa ti wọn si pakiyesi awọn eeyan to ku si pe eeyan kan ti ko si ẹnu ẹrọ.
Ilẹ̀ wọn yóo kún fún ẹ̀jẹ̀,ọ̀rá eniyan yóo sì mú kí ilẹ̀ wọn lẹ́tù lójú.
oun ni pe, ki eto idibo to n lọ lọwọ bayii jẹ ”Aseyori isipopada”.
 o jẹ oludari ile-iṣẹ meji : babiesessence , ti o n koni nipa bi a ṣe n gbaradi fun ọmọ tuntun jojolo ati nikktun , ile itaja ohun elo amaradan ati bẹ bẹ lọ .
Gbòngán ni fọláṣadé ìyàwó àfẹ́kẹ́yìn Orímóògùnjẹ́ ń gbé.
Ijọ Christ Embassy, to jẹ ti gbaju-gbaja pasitọ, Chris Oyakhilome, lo fa awuyewuye to mi ìlú julọ.
Lẹ́yìn náà, àwọn ọmọ Jakọbu wá kó gbogbo ohun ìní àwọn ará ìlú náà nítorí pé wọ́n ba arabinrin wọn jẹ́.
Ni bayi Naijiria yoo koju Algeria tabi Ivory Coast ninu abala to kangun si aṣekagba idije naa.
Igba ti wn tun pade nibi ere idaraya lorilẹede Cote Divoir, wọn tun ran wọ́n leti ti minisita ko si ri owo san.
 Lopin gbogbo ọrọ, Isa sọ pe irinajo ifẹ oun ati Janine jẹ ẹri pe ifẹ otitọ ṣi wa lori ayelujara, ti yoo si dara ti awọn eniyan ba 'gbiyanju aje' wo."
O ti fi ìkùukùu bo ara rẹ,tóbẹ́ẹ̀ tí adura kankan kò lè kọjá sọ́dọ̀ rẹ.
 oríṣìíríṣìí iṣẹ ́ ìwádii ni àwọn onímọ ̀ -èdè ti ṣe lórí àwọn ẹ ̀ ka-èdè yorùbá wọ ̀ nyí .
Sanwo Olu ni ijọba oun yoo jẹ eyi to n gbọ ọrọ awọn ara ilu to dibo yan oun.
Ọmọ ìlú tí ó lókìkí ni mí.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Nnamdi Kanu ti ṣàlàyé bí ó ṣe rìn lẹ́yìn ọdún kan tó dàwátì Amofin ṣalaye pe oriṣi oniduro meji lo wa.
má jẹ́ kí àánú rẹ kúrò ninu ilé mi títí lae.
#BBC Nigeria Decides: Akala darapọ̀ mọ́ APC fún ìbò gómìnà Ìdí tí mo fí kọ̀ èsì ìbò ààrẹ - Atiku ṣàlàyé Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Yinka Ajia: ìbẹ̀rù Ọlọrun ni mo fẹ́ fi tukọ̀ Kwara ti mo ba wọlé O ni ọ̀pọ̀lọpọ̀ àwọn ilanilọyẹ ni àjọ oun ti ṣe láti ri dáju pẹ ẹnikẹni ò tẹ ojú òfin mọ́lẹ̀, sùgbọn o ṣe ni láànú pé gbogbo rẹ̀ pàbó ló jási lásiko ìdìbọ ààrẹ tó wáye ní ọjọ kẹtàlélogun osu kéji.
Agbẹnusọ fun ileeṣẹ orilẹede Israel ni naijiria, ṣalaye fun BBC pe, ni ti awọn o, Kanu ko si ni orilẹede Israel.
John salaye fun BBC nipa igbiyanju rẹ lati maa pese ẹya ara atọwọda fun awọn alawọ dudu ni eyi to ba aawọ ara wọn mọ.
Iroyin wa sọ pe alaga ẹgbẹ alatako, Social democratic pary ni Kumba 3 Um Rufus gba afurasi naa mu pẹlu apoti idibo to kun fun iwe itẹka lati igba ti eto idibo ko tilẹ tii gberasọ.
 nínú ìtàn ìwáṣẹ ̀ , òrìṣà àti odù mẹ ́ rìndínlógún ni a gbọ ́ pé wọ ́ n rọ ̀ láti ìsálọ ̀ run wá sí ìsálayé ( abimbọla , w.
 jẹnotaipu 1 ni ó tún wọ ́ pọ ̀ jùlọ ́ ni gúùsù amẹrika àti ni ilẹ europe .
Ni bayii, ti Iniesta baa lanfani lati kopa ninu olokan-o-jokan ifesewonse olorejore fun Spain, eyi yoo mu saaju akegbe re teleri, Xavi leni ti o je eniketa ti o kopa julo fun iko agbaboolu Spain ki o to feyinti ni omo odun merinlelogbon.
Ilé ẹja náà lọ́ja ajé lásìkò ìjòkó rẹ̀ nílé ẹjọ ni ki wọ́n ti Maina mọ́ ọgbà ẹ̀wọ́n níwọ̀n ìgbà ti ko rí mú jáde lásìkò tó yẹ kó wá jẹ́jọ́ ìwà àjẹbánu tó ṣe lásìkò tó wà nípò.
Àṣé bí àwa ti ń ronú ikú ni Ènìyàn-ṣe-pẹ̀lẹ́ ti ń ronú ọ̀nà àtiyọ ó sì ti wá àyè rí àṣsírí ibẹ̀.
Ìtàn ikú wọn yìí gba ayé kan lákòókò náà Ọlọ́run Ọba sì yí àwọn méjèèjì padà sí igi méjì tí ìwọ ń wò ní, tí ewé wọn tutù bí ọ̀gẹ̀dẹ̀ etí odò tí òdòdó orí wọn sì ń mú òórùn d’;idùn jáde.
Bakan náà ni ọgá àgbà ọlọpàá Muhammed Adamu kédé rẹ nínú ìpàdé kan to pé fún àwọn ọgá ọlọpàá nílu Abuja níbi tó ti sàlàyé kíkún lóri fífòfin dé àwọn ọmọ egbẹ Shi'ite tó ń tèlé El-ZakyZakky, olori Islamic Movement in Nigeria (IMN).
1990 Ipele ẹlẹgbẹjẹgbẹ) Algiers Algeria 5-1 Nigeria 16.
” Bí ó bá sọ pé, “Rárá,” 
Ayé ò fún ni rí, kí á má fi òmíràn san
Ifẹ̀họ̀núhàn ń lọ lọ́wọ́ ní Belarus lẹ́yìn tí ìdìbò tùn gbé Ààrẹ̀ Lukashenko tó ti wà nípò fún ọdún 26 wọlé Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, BBC Africa Eye: ìwádìí ìkọ̀ks BBC fihàn pé àwọn kan ń jí ohun èèlò ìdáàbòbò ìjọba tà nígbo Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Bẹngeberi ni alákòóso ìlú Ramoti Gileadi, (ati àwọn ìletò Jairi, ọmọ Manase, tí ó wà ní ilẹ̀ Gileadi, ati agbègbè Arigobu, ní ilẹ̀ Baṣani.
Ẹsẹ̀ kan náà ni oró ejò mú ọkùnrin náà, kí á má fa ọ̀rọ̀ gùn lọ bí ilẹ̀ bí ẹni, ibẹ̀ ni Àgùntàn-ìnàkí sá parí ayé tirẹ̀ sí.
 Ni Ipinlẹ Eko lasan, ẹgbẹrun mẹrindinlogun tọọnu idọti ni wọn n da nu kaakiri lojoojumọ.
Aare ri i pe eni to jawe olubori ninu eto idibo abele ti egbe di lati fi yan oludije laarin awon eniyan to le ogbon , je idaniloju pe egbe APC ti gbaradi lati mu idagbasoke to monyan lori ba orile ede Niajiria.
Olùdásílẹ̀ Sotitobire Miracle Centre, Wòlìí Babatunde tí n lọ ilé ẹjọ bọ̀ láti bí ọdún kan nígbà ti ẹjọ́ náà bẹ̀rẹ̀.
Awọn miran tun dupẹ lọwọ Baba Olusegun Obasanjo pe otitọ ọrọ lo sọ lasiko ti Naijiria nilo ọrọ naa lasiko yii.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ẹfunsetan Aniwura, obìnrin tó ju ọkùnrin lọ Mọrèmi Àjàṣorò, akọni obìnrin tó gba Ilé Ifẹ̀ sílẹ̀ lóko ẹrú Ọ̀rọ̀ǹpọ̀tọ̀niyùn, Aláàfin obìnrin àkọ́kọ́ rèé, tó ní nǹkan ọkùnrin Ẹfunroye Tinubu - Ògbóǹtagí oníṣòwò, olówò ẹrú àti afọbajẹ Bi ọrọ se ri ree pẹlu akọni obinrin kan to n jẹ Lúwòó Gbàgídà,ẹni tii se akinkanju, olokiki, olowo, ọlọrọ ati aya ọba nigba aye rẹ, to si se gudugudu meje ati yayaya mẹfa, lati mase jẹ ki itan rẹ parẹ ninu itan Yoruba.
Nígbà tó ń sọ̀rọ̀ lórí ọpọ ọrọ kobakungbe tí àwọn èèyàn kan ń sọ nípa rẹ lórí ayélujára, Oluwo ni òun ń sanwó òkìkí ni ọ̀rọ̀ òun ti wọn n sọ, ẹni tó bá sì wà ipò, ó di dandan kí wọn sọ̀rọ̀ rẹ.
Ìkún omi wà lórí ilẹ̀ fún ogoji ọjọ́.
Ṣé ìwọ lọ̀ ń bẹ nínú ìtọ̀, ìwọ lọ̀ ń bẹ nínú itọ́
Gomina ipinlẹ Rivers, Nyesom Wike ninu ọrọ rẹ, dupẹ lọwọ awọn ọba naa fun isẹ takuntakun ti wọn n se lati ri i wipe orilẹede yi duro ninu isọkan ati ifọwọsowọpọ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Aṣọ òkè: Alákọ̀wé ní ọ̀nà láti wá oúnjẹ fáwọn tó ń ṣe aṣọ òkè ló ṣún òun débẹ̀ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Aṣọ òkè: Alákọ̀wé ní ọ̀nà láti wá oúnjẹ fáwọn tó ń ṣe aṣọ òkè ló ṣún òun débẹ̀ 18 Ẹrẹ̀nà 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 16 Èbibi 2020 Tunde Owolabi, tii se onisowo to n fi asọ oke se baagi ati bata salaye fun BBC Yoruba pe, lẹyin ti oun fẹyinti lẹnu isẹ lọdun marun sẹyin ni oun bẹrẹ isẹ naa.
Ẹ má fọwọ́ kan ohun àìmọ́,kí n lè gbà yín.
Ohun tí mo ti sọ fun yín tẹ́lẹ̀, ni mo tún ń sọ fun yín, pé àwọn tí ó ń ṣe irú nǹkan bẹ́ẹ̀ kò ní jogún ìjọba Ọlọrun.
Ọjọru ni wọn bẹrẹ iyanṣẹlodi naa, ti wọn si s pe yoo wa titi di igba ti ijọba yoo fopin si ifiyajẹni ti awọn ọlọpaa n ṣe si awọn ọmọ ẹgbẹ wọn lasiko ofin Konile-o-gbele.
Ṣugbọn, awọn mejeeji pada sọ pe, sinima kan ni wọn ya aworan naa fun.
Babalọla ni ofin ilẹ wa tọdun 1999 jẹ adina fun eto idagbasoke ati ilọsiwaju Naijiria taa ba wo ọpọ kudiẹ-kudiẹ to wa ninu amulo ati amusẹ rẹ.
Bangladesh: Orilẹ ede yii jẹ ọkan lara orilẹ ede ti o pọju lọ lagbaye.
Ṣugbọn wọ́n sọ ohun tí Esau, àkọ́bí Rebeka ń wí fún Rebeka ìyá rẹ̀.
Dida okoowo sileO tun so pe orile ede Britain ti setan lati ran ilu Eko lowo nipa eto okoowo ati pe orile ede Naijiria ni won ti se  aso jaketi( jacket) ti oun n wọ.
PDP: Ẹní ṣe nǹkan ètùfù ní kíyèsí ẹ̀hìnkùlé, ọmọ ẹgbẹ́ wà kò hùwà àìtọ́ lásìkò ìdìbò Wo ohun tó yẹ kí o mọ̀ nípa àwọn obìnrin méje ti Buhari forúkọ wọn ránṣẹ Kò lè ṣééṣe kí Ruga wà lápá gúúsù Nàìjíríà fáwọn Fulani- Ganduje Èmi kò ní kí Shiite má ṣe ẹ̀sìn won o -Muhammadu Buhari Garba Shehu ni lọwọlọwọ ni awọn ọmọ ogun ilẹ̀ ati ti ofurufu ti bẹrẹ igbesẹ lati ṣawari awọn oniṣẹ ibi yii pẹlu aṣẹ aarẹ Buhari.
Atẹjade kan ti ileesẹ ọlọpa fisita lori isẹlẹ naa salaye pe deede aago mẹta aabọ irọlẹ ọjọru ni isẹlẹ naa waye si ọkunrin kan, ti wọn pe orukọ rẹ ni Tobi Adebayo, ẹni ọdun mẹtadinlọgbọn to wa ninu ọkọ ayọkẹlẹ rẹ.
Bakan naa ni ẹlẹgbọn agba ṣalaye pe ikils naa kan gbogbo awọn olukopa nitori ofin igbele naa ko faye gba ija tabi iwa ipa yoowu.
nítorí pé mo sọ̀kalẹ̀ láti ọ̀run wá, kì í ṣe láti ṣe ìfẹ́ ti ara mi, bíkòṣe láti ṣe ìfẹ́ ẹni tí ó rán mi níṣẹ́.
Láti òdìkejì odò náà ni mo ti mú Abrahamu baba yín, mo sìn ín la gbogbo ilẹ̀ Kenaani já; mo sì sọ arọmọdọmọ rẹ̀ di pupọ.
Ọ̀gá ọlọ́pàá Adamu Pàṣẹ́ iṣẹ́ àkànṣe nílẹ̀ Yorùbá Ìtàn tó rọ̀ mọ́ òwe ‘aṣọ kò bá Ọ́mọ́yẹ mọ́.
O ni:  “Awon onise ona Naijiria miran ran mi lowo lori ise naa to to iwon mita ogofa.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Rape: Ọmọ tí wọn ń fipá bá lòpọ̀ yóò máa ní ìrora ọkàn nígbà gbogbo 26 Ẹrẹ̀nà 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Lojoojumọ ni iroyin ifipa ba ọmọde lopọ lorilẹede Naijiria ati kaakiri agbaye n peleke si, eyi to ti di irawọ ọsan, to n ba awọn agba lẹru bayii.
Ṣugbọn ṣa, ofin ṣi de ipejọpọ ọpọ eniyan, awọn ile ijọsin ati ileewe.
Amọ nigba to n polowo iwe rẹ lori redio lasiko to n se eto, o darukọ ara rẹ, ti baba rẹ si pe lẹyin ọjọ kẹta, ti wọn si sọrọ fun ọgbọn isẹju.
Lootọ Pẹlumi ko tii pe ọmọ ọdun mẹta nigba ti iya rẹ ti jade laye ninu ijamba ọkọ, bẹẹsi ni baba rẹ pẹlu ti sa fi ile silẹ, ṣugbọn iṣoro kan lo n bẹ loju ọna Pẹlumi bayii.
"Ninu fidio kan to ṣe afihan rẹ, a gbọ ohun to n dẹruba a pe ""jade wa tabi ka dana sun bọọsi yii."
Ko si akọsilẹ to so ojulowo orúkọ ati adirẹsi pọ.
Ọsẹ yii ni ọsẹ ayajọ awọn obinrin ni gbogbo agbaye.
" Òfin lè má mọ ògùn ṣùgbọ́n èmí gbàgbọ́ pé ǹkan wà nídìí bí wọ́n ṣe pa ọmọ mi - Baba Favour Ìjọba yóò ṣe ìwádìí ohun tí kò jẹ́ kí ìpínlẹ̀ Kogi àti Cross River tíì ní coronavirus- Mínísítà Ilé ẹjọ́ tó ga jùlọ ní Nàìjíríà wọ́gilé ẹ̀wọ̀n Orji Uzor Kalu, pàṣẹ ìgbẹ́jọ́ tuntun Àwọn Dókítà fárígá ní ìpínlẹ̀ Ondo, wọ́n ní kí Gómìnà san owó oṣù mẹ́ta tó jẹ wọ́n!
Ìgbọràn dára ju ẹbọ lọ, ìfetísílẹ̀ sì dára ju ọ̀rá àgbò lọ.
Oríṣun àwòrán, Alabi Rukayat Oyindamola Koda, ayẹwo oriṣiriṣi ni wọn ṣe fun ọmọ mi keji nigba ti mo bi silewoosan nitori oju naa, ṣugbọn wọn ko ri aisan kankan lara rẹ.
 bí àwọn ọmọdé ò ti ní àwọn ààmì àkóràn bẹ ́ ẹ ̀ wọ ́ n ṣì le koran ẹlòmíràn .
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Oyo Algon: Àlááfíà Ọyọ yóò dàrú, tí Buhari kò bá yanjú àáwọ̀ yìí 6 Òkùdu 2019 Oríṣun àwòrán, Oyo State Government Yoruba ni bi ọrọ ba se n pẹ nilẹ, yoo maa gbọn si ni.
Ọrọ bẹrẹ si ni ri bakan nigba ti oludari ifẹsẹwọnsẹ naa, Graham Scot ti ha sinu sunkẹrẹ fa kẹrẹ ọkọ ni opopona M40 eleyi to mu ki o pẹ de ibi ifẹsẹwọnsẹ naa.
Nígbà tí ó bá kù díẹ̀ kí ẹ dé ìlú náà, o óo pàdé ọ̀wọ́ àwọn wolii kan, tí wọn ń sọ̀kalẹ̀ bọ̀ láti ibi pẹpẹ tí ó wà ní orí òkè.
Eliṣa sọ fún Joramu ọba pé, “Lọ sọ́dọ̀ àwọn wolii baba ati ìyá rẹ.
Bí ọ̀kánjúwà sì ti ń ta gee, gee lọ ni afẹ́ayé tún ṣá ìbón tirẹ̀ sii, “wì” : Òkú Ọ̀kánjúwàfẹ̀yìntì ní ilẹ̀, ọ̀kájúwà kú.
Oorun díẹ̀, òògbé díẹ̀,ìkáwọ́gbera díẹ̀ láti sinmi,
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: 'Ológun kò ṣe àyọjúràn sí ìdìbò 2019' Kò sí ìwé ẹ̀rí fun olùdíje tí tó ba wóle lábẹ hílàhílo Bí Ganduje bá pàdánù ìdìbò gómínà, kí ni yóò ṣe?
Ilé iṣẹ́ náà ni àfurasi náà ti wà ni àhámọ àwọn bàyìí fun ìfọrọ̀wánilẹnuwò.
Lẹ́yìn náà, Ọlọrun kígbe sí mi létí, ó ní, “Ẹ súnmọ́bí, ẹ̀yin tí ẹ óo pa ìlú yìí run, kí olukuluku mú nǹkan ìjà rẹ̀ lọ́wọ́.
Ó bá da gbogbo wọn sinu ọgbà ẹ̀wọ̀n fún ọjọ́ mẹta.
Minisita soro yii lojo Isegun ,nigba ti adari ile akede orile ede Amerika, Amanda Bennet se ibẹwo si i ni ile-isẹ rẹ to wa niluu Abuja.
Oríṣun àwòrán, emperortelu1 Ọba Akanbi fesi bẹẹ loju opo Instagram rẹ eyi to fi n sọ ero rẹ nipa bi Awujalẹ ilẹ Ijẹbu ati Ọṣilẹ Oke ọna se n beere pe ki wọn se atunse si awọn asa ati ise wa kan to ti di ogbo.
Iṣuna Owo Ilu yoo fi kuro labẹ Ile-iṣẹ Ijọba fun Ọrọ Iṣuna Owo Ipinlẹ
Ilẹ̀ kan ń bẹ láàrin gbùgbùn Úróòpù tí ń jẹ́ Moravia.
Ọga agba to n ṣakoso ẹka iṣẹ apapọ gbogbo fun Ẹkun kẹta, Zone C ileeṣẹ aṣọbode orilẹede Naijiria, Ahmed Azarema ni wọn ti fi aṣoju ẹni to ni awọn ọja naa si ahamọ, ti iwaadi si n tẹsiwaju lori rẹ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ondo: Òjọ̀ àrọ̀rọ̀dà pa ènìyàn kàn, wó ìlé 50 ní Akure 20 Ẹrẹ̀nà 2020 Ojo tó ro ní ìlú Àkúré ni ọjọbo ọ̀sẹ̀ yìí dá ọ̀pọ̀lọpọ̀ rúgúdù sílè leyin ti o sí aimoye ilé tí ó sì wù pupọ nínú àwọn òpó iná ìjọba.
O ni ijọba ti gbẹsẹ le gbogbo ohun to jọ mọ irin ajo oke okun nilẹ naa fun ọsẹ meji gbako, bẹrẹ lati ọjọ kejidinlogun Oṣu Kẹta ọdun yii lati le dekun itankalẹ ajakalẹ arun naa.
Ajo eleto  idibo lorile ede Naijiria (Independent
Ọdun 2017 ni wọn sẹsẹ tun ri mu.
Nígbà náà kò sí ibi aláìsàn ò kí ń wá ìwòsàn dé.
Jagaban - BBC News Yorùbá BBC News, YorùbáFò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Lekki Toll gate: Àwọn ọlọtẹ̀ ló ń gbìyànjú láti dá ọ̀tá sílẹ̀ láàrin èmi àti ẹ̀yin ènìyàn mi - Jagaban 19 Ọ̀wàrà 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 26 Ọ̀wàrà 2020 Oríṣun àwòrán, ASIWAJU TINUBU Agba ẹgbẹ oṣelu All Progressives Congress, Asiwaju Bola Ahmed Tinubu ti ni gbogbo asiko iwọde EndSARS atohun to tẹyin rẹ wa to fi mọ iṣẹlẹ pipa awọn oluwọde kan ni Lekki Tollgate l'Eko kan tun n ba ọrọ jẹ fun oun ni.
Abíọ́nà: Ọmọ tí a bí lásìkò tí ìyá rẹ̀ wà lójú ọ̀nà sí ibì kan yálà ọ̀nà oko, ọ̀nà odò, ọ̀nà ọjà, ìrìn- àjò àti bẹ́ẹ̀ bẹ́ẹ̀ lọ
Eyi lo si mu ko pinnu lati ma lọ si ṣọọṣi naa mọ, nitori itiju.
Ìwọ̀n ọkà pẹlu iye ọ̀dọ́ aguntan tí ó bá lágbára ni yóo fi rú ẹbọ ọkà pẹlu ọ̀dọ́ aguntan.
Ní ọjọ́ náà, ẹ̀yin yóo mọ̀ pé èmi wà ninu Baba mi, ati pé ẹ̀yin wà ninu mi, èmi náà sì wà ninu yín.
 Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Oyenusi ló mú mi wọ ẹgbẹ́ adigunjalè kó tó di pé mo b'Ólúwa pàdé' Oun to ṣẹlẹ Lalẹ ọjọ ifẹhonuhan naa, wọn ri Kyle lori aworan CCTV nibi ti awọn eeyan kan ti n le e pẹlu ibọn ti oun naa si yinbọn lu ọkunrin to n le e ni ori."
Nígbà tí ó yá, àwọn ará Amoni gbógun ti àwọn ọmọ Israẹli.
Ẹ yẹra fún ohunkohun tí OLUWA ti yà sọ́tọ̀ fún ìparun, kí ẹ má baà di ẹni ègún nípa mímú ohun tí OLUWA ti yà sọ́tọ̀, kí ẹ má baà sọ àgọ́ Israẹli di ohun ìparun, kí ẹ sì kó ìyọnu bá a.
Ṣùgbọ́n wọ́n dá a dúró sí àsìkò tí olóògbè náà dákẹ́.
“Nítorí pé ọba Siria yóo tún pada lọ, yóo kó ogun jọ, tí yóo pọ̀ ju ti iṣaaju lọ.
Aare Buhari so pe oun ti n gbe igbese lati se atunse lori eto oro aje orile ede yii, ni eyi ti o si n so eso rere.
Ajọ to n gbogun ti iwa ibajẹ lorilẹ-ede Naijiria, EFCC ti sọ wi pe ẹniyan ẹgbẹ̀fà ati marundinladọta (1,245) ni awọn ti fi jofin iwa ibajẹ ni ọdun 2019.
Àwòran bó ṣe ń lọ káàkiri àwọn Yídì rèé Buhari ṣèlérí tuntun fún Nàìjíríà fún ìtúnu àwẹ̀ Ta ló fẹ́ ki bọwọ́bọwọ́ ọlọ́pàá agbègbè bọ Buhari lọ́wọ́?
 Àwọn ọ ̀ rọ ̀ ìpìlẹ ̀ kan wà tó jẹ ́ wí pé wọ ́ n ní ìtumọ ̀ ìyísódì nínú .
Ǹkan ìṣeré ìbálòpọ̀ ti ma ń ró kì lọ́kàn wa láti ìgbà ayé ọbabìnrin Victoria tí àwọn dókítà ṣe àgbéjáde rẹ̀ fún ìrànwọ́ àwọn obìnrin tí kò lè mára dúró.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Ọba Oke nikan si lo mọ idi taa fi wa papọ titi di oni, bi o tilẹ jẹ pe diẹ lo ku, ki iji da omi inu agbọn orilẹede Naijiria nu, paapaa lati ipasẹ ogun abẹle ta ja kọja.
O kò ní yé yí ọ̀nà títọ́ Oluwa po!
Olori Mujidat Adeyemi: Oríṣun àwòrán, Mujidat Adeyemi facebook Olori miran ti ko si lara awọn Ẹlẹ Daddy, amọ ti Ọba Adeyemi ko jẹ fi sere ni Olori Mujidat Adeyemi.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Nigerian schools resumption: ASUU ní kí ìjọba má tíì ṣí àwọn ilé ìwé nítorí Coronavirus 20 Agẹmo 2020 Oríṣun àwòrán, @MobseTheGambia/TWITTER Àkọlé àwòrán, Aarẹ ASUU ni o yẹ ki Naijiria kọgbọn lara ilẹ Kenya to tilẹkun awọn ile iwe rẹ titi di ọdun 2021 Ẹgbẹ awọn olukọ fasiti ni Naijiria, ASUU ti ke si ijọba apapọ lati gbe agadagodo sẹnu ọna awọn fasiti kaakiri Naijiria titi di ọdun 2021 lọna ati dena itankalẹ arun Covid-19.
Báyìí ni bàbá mi sọ, ó dúpẹ́ lọ́wọ́ olóore, inú onítọ̀hún sì dún wí pé òun kò ṣe oore fún aláìmoore, òun kò fi ẹ̀wù sányán bọ ẹlẹ́dẹ́ lọ́rùn, òun kò wọ ṣòkòtò fún ìnàkí, òun kò sán ìbàntẹ́ mọ́ obìnrin ni ìbàdi, òun kò fi àgàbàgebè ṣe olórí ẹgbẹ́, òun kò fi ọ̀bàyéjẹ́ ṣe alága nínú ìpàdé; òun kò ṣe ìtọ́jú ẹni tí kò yẹ.
Mathematics Education: Fasiti Ibadan f'orin tàkasúfèé wá ojúùtú si ìṣòro ẹ̀kọ́ ìṣirò
F Odunjo dibo, to si wọle sile asofin lẹkun iwọ oorun Naijiria, lẹyin naa ni wọn tun yan an gẹgẹ bii Minisita fọrọ ilẹ ati osisẹ J.
Dele, ọmọdé tó ń fi iná ẹ̀rọ ATM ṣe iṣẹ́ àmurelé sọ ìdí tó fi kára mọ́ ẹ̀kọ́ rẹ̀ fún BBC Yorùbá Elédùmarè ló rán mi sí gbogbo Ọba Yorùbá - Oluwo A ó fimú gbogbo ẹni tó lọ́wọ́ nínú ikú Tiamiyu Kazeem dánrin - Ìjọba ìpínlẹ̀ Ogun Ààrẹ Buhari ti ṣàlàyé ìdí tí kò ṣe tíì ṣí ibodè tó tì pa Iléeṣẹ́ ọlọ́pàá bẹ̀rẹ̀ ìwáàdí lórí ikú Tiamiyu Kazeem tí wọ́n ní SARS pa ní Sagamu Dokita Iṣọla Oyenusi waye amọ ko se aye re.
Kabiyesi, Ọba Akanbi Abdulrasheed ṣalaye pe iyatọ to wa laarin oun atawọn ọba alaye miran gbogbo ni pe oun ko ri ipo ọba gẹgẹ bi ipo lati jẹ gaaba le araalu lori tabi ko ọrọ ilu sabẹ, ṣugbọn oun ti lo asiko ti oun ti lo lori oye lati fi tan iṣoro araalu ati aini wọn.
Gomina ipinlẹ Ondo ni awọn kan lo kọ iroyin lati fi oun han gẹgẹ bi eeyan buruku.
Ṣá sọ gbolohun kan, ara ọmọ-ọ̀dọ̀ mi yóo sì dá.
Èmi náà yóo pa akọ mààlúù keji, n óo kó o sórí igi, n kò sì ní fi iná sí i.
Amọ iṣọ oru ni wọn yoo fi ṣe eyi ti yoo bẹrẹ lati ago mẹjọ alẹ si mejila oru gẹgẹ bi ijọ Trinity House ati ọkọ oloogbe to jẹ pasit ijọ naa ṣe fi si ori ayelujara wọn.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Drums musical instrument: Ka bí o ṣe le mọ èdè Àyàn àti àgbọ́yé ìlù 18 Ògún 2020 Oríṣun àwòrán, Others Ilu dabi ipilẹ lara elo orin ni ilẹ Yoruba, Ko si si ẹni to n kọ iyan rẹ kere to ba ti di asiko orin, bakan naa lo lara idi ti awọn eniyan fi maa n fẹran ayẹyẹ to nise pẹlu Yoruba.
Revolution Now: Lẹ́yìn ọdún kan, DSS tún ti mú Olawale Bakare tó jẹ́jọ́ pẹ́lúu Sowore l'Osogbo
26 Òkùdu 2019 Oríṣun àwòrán, others Àkọlé àwòrán, Ọmọọ̀dọ̀ tó ń se oúnjẹ fún Olóyè Ope Bademosi nígbà ayé rẹ̀ ni ilé-ẹjọ́ ní ó jẹ̀bi ẹ̀sùn pípa ọ̀gá rẹ̀.
 jìjì kò tí ì rí ẹni tó mọ nǹkan tó fẹ ́ ràn jù .
Nínú ọ̀rọ̀ rẹ̀, MURIC ní, Falz gbọ́dọ̀ yọ orin náà láfẹ́fẹ́ nítórí ó lè dá ìjà sílẹ̀ ati pé èèbú ni orin náà jẹ́ fún àwọn ẹlẹ́sìn Islam.
APC to wa niluu Abuja , leyin ti won kede rẹ gege bi aare orile ede Naijiria
Ekiti Election: INEC gbé èsì ìdìbò Ekiti síta lẹ́kùnrẹ́rẹ́
Oríṣun àwòrán, @jorowasinda Ileesẹ ọmọogun Naijiria ni awọn se bi akin, tawọn si wọya ija pẹlu awọn ikọ afẹjẹsofo naa, ti ibọn n dun lakọlakọ, amọ awọn olugbe ilu naa ni awọn ti tete kofiri awọn awọn ọmọ ikọ asẹrubalu naa lati okeere, tawọn si ta awọn ọmọ ogun lolobo.
Nítorí olóore ọ̀fẹ́ ati aláàánú ni OLUWA Ọlọrun yín, kò ní kẹ̀yìn si yín bí ẹ bá pada sọ́dọ̀ rẹ̀.
Wo ìdí tí àwọn obìnrin kan fi n yọ ilé ọmọ wọn kúrò Super Falcons: Wọn nfi ilọkulọ ibalopọ lọ wa Àráàlú yarí fún fásitì Babcock fún bo ṣe lé akẹ́kọ̀ọ́ tí wọn bá lòpọ̀ nínú fídíò Bíbéèrè fún ìbálòpọ̀ gbogbo ìgbà sọ ìyàwó ilé dèrò ilé ìwòsàn Ọga ajọ FCCPC, Babatunde Irukera, ti oun fun'ra rẹ jẹ amofin, ni yoo jẹ olori igbimọ ti yoo rojọ tako.
Iroyin fi idi rẹ mulẹ pe mẹta ninu awọn to wa ninu ọkọ oju omi to dojude naa ni wọn doola ẹmi wọn.
Lẹ́yìn-ọ̀-rẹyìn, bàbá ọgọ́rùn-ún ọdún gba ìdáǹdè l‘ẹ́wọ̀n Háà!
DSS ti fi ẹ̀sọ́ àbò abẹnugan ilé ìgbìmọ̀ asofin tó pa fẹ́ndọ̀ l'Abuja sátìmọ́lé Wo nkan tó sọ Woli ìjọ Genesis Global di ọmọ ìjọ Cele lẹ́yìn tó kúró nínú ìjọ C.
Bi ọdẹ bá ń wù ọ́ ṣe, gbé ìbọn kí o lọ máa ṣe ọdẹ nínu’igbó kí o sì máa padà wáá sùn ni ààfin.
25 Billion) ni iye owo irẹsi ti ijọba China fi ranṣẹ si ilẹ Niajiria fun awọn aṣatipo ni ariwa, wọn si sọọ di mimọ pe bii milionu aadọtalenirinwo naira ni wọn na lati gbaa ati lati tọju awọn irẹsi naa, kii ṣe ẹgbẹrin milionu naira bi igbimọ naa ṣe sọ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù New Zealand: Lateef Alabi ní òun kò lérò pé agbébọn leè kọlu mọ́ṣálásí ní New Zealand 17 Ẹrẹ̀nà 2019 Oríṣun àwòrán, @GbenroAdegbola A ṣe ọmọ Naijiria ni Imaamu agba fun mọsalasi kan ti agbebọn kan kọlu ni orilẹede New Zealand lọjọ Satide.
Ko lawọn eeyan gidi to yi i ka.
Aare orile ede Naijiria  Muhammadu Buhari  ti gba iroyin 
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, #Governorship Election: Òjò ni wá, a kò bẹ́nì kan ṣọ̀tá -Sanwo Olu Bakan náà ni àwọn ènìyàn lóri ayálujara náá ń banujẹ lóri akoni naa, to fi mọ Oby Ezekwesili.
Taiwo Akinkunmi, ọmọ Ibadan tó ya àsìá Nàíjíríà Iṣọla Oyenusi rèé, ẹnití ìfẹ́ obìnrin ṣun dé ìwà ìdigunjalè Ẹfunroye Tinubu - Ògbóǹtagí oníṣòwò, olówò ẹrú àti afọbajẹ Samuel Ajayi Crowther, òjíṣẹ́ Ọlọ́run tó gbé èdè Yoruba lárugẹ Iroyin sọ pe oludari ẹgbẹ OPC ni ipinlẹ naa Adedeji Aladesewa, ṣalaye pe ọmọ ẹgbẹ OPC nilu Ikire lo ṣaaju igbesẹ ọlọgbọn ti ọwọ fi tẹ ikọ ọdaran naa ati ẹni kan to jẹ bi ejika ti ko jẹ kaṣọ wọn o yẹ.
A gbọ́ pé àìsàn jẹjẹrẹ ọyàn tó ń bá Aisha fínra láti ọjọ́ díẹ̀ ló gba ẹ̀mi rẹ̀.
4 x Rocket Propelled Gun Tubes.
Gbogbo àwọn Juu ati àwọn Giriki tí ó ń gbé Efesu ni wọ́n gbọ́ nípa ọ̀rọ̀ yìí.
Ìbọn pa èèyàn mẹ́ta lásìkò ayẹyẹ Ọdun Oúnjẹ Inú mi dùn pé ẹni tó gbà ìjọba lọ́wọ́ mi ń san gbèsè tí mo fi kalẹ - Aregbesola EFCC: Àwọn ọba aládé àti olóṣèlú ṣé àpapín owó ìrànwọ́ N2bn ní Kwara Àṣírí mẹ́wàá tí mo mọ̀ nípa Boko Haram-Naomi Adamu Dokita naa fikun un pe, o seese ko jẹ pe irinajo tawọn eeyan to n sisẹ Hajj rin lati ilu Mecca si Medinah eyi to to wakati mẹjọ, lo fa sababi aisan osere tiata naa.
Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Royal baby: What is it like to have a home birth?
" Ẹgbe Arsenal ti le Unai Emery leyin osu mejilelogun, to gba ise.
Odun yii ṣe pataki ninu ọdun ti awọn ẹlẹsin Islam maa n ṣe ni eyi ti ọọ maa n sami kaakiri agbaye.
Buhari ti ba awon ẹbi eniyan to ku ninu ikọlu ado oloro to waye, lojo Aiku nile
Kí alufaa pè é ní aláìmọ́; kí ó má wulẹ̀ tì í mọ́lé, nítorí pé aláìmọ́ ni.
Oluwo: Àwọn baálẹ̀ tí a sọ dì ọba ló fẹ́ fí ọ̀pá fọ́ mi lójú Oyè Ibadan kò sí fún títà - Otun Olubadan, Lekan Balogun Yàtọ̀ sí eku gọ́tà tàbí èku inú ilé, kò sí eku téèyàn ò lè jẹ - Òǹtajà Eléwé ọmọ Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Àṣẹ yìí ni mo pa fun yín: ẹ fẹ́ràn ara yín.
Àwọn wọ̀nyí wọ aṣọ tí ó ń dán bí dígí tí n kọ mọ̀nàmọ̀nà bí ìràwọ̀ ojú ọ̀run, àwọn ẹnìkejì mi náà gun ẹsin tẹ̀lé mi lẹ́yìn, bí a ti ń kọjá ni àwọn tí ó dúró sí e’ti ọ̀nà wọ̀n-nnì bẹ̀rẹ̀ sí í kọrin, ohùn wọn dàbí ẹni pé ẹnìkan kọ́ ọ̀kẹ́ àímoye ẹyẹ ni orin kan náà ti ohìun wọn ń dún gooro.
Tinubu gbà pé ó ṣoro láti ko ìwo ẹkùn lé ajá lọ́wọ́ Adari ẹgbẹ oṣelu All Progressives Congress, APC, Bola Tinubu, ti fẹsun kan awọn kan lara awọn ọmọ ile aṣofin, pe wọn n gbero lati yọ Aarẹ Muhammadu Buhari l'oye.
Ní gẹ́rẹ́ tí Dafidi kọjá góńgó orí òkè náà, Siba, iranṣẹ Mẹfiboṣẹti pàdé rẹ̀, ó ń da àwọn kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ bíi mélòó kan bọ̀ tí ó di igba (200) burẹdi rù, pẹlu ọgọrun-un ṣiiri èso resini, ati ọgọrun-un ṣiiri èso tútù mìíràn ati àpò aláwọ kan tí ó kún fún ọtí waini.
 O pe osu meje Santos Aveiro.
Ìtakurọ̀sọ máa ń jẹ́ kí ìsọ̀ ìwé ìròyìn dùn
O ni eyi ri bẹẹ lataari pé imọ, ati awọn ohun eelo to wa nikawọ awọn eeyan nigba naa ko dabi ti isisnyi.
Àwọn eniyan tí wọn jẹun tó bí ẹgbaaji (4,000).
Ọpẹ́lọpẹ́ ẹni yìí ni a fi dá gbogbo ẹni tí ó bá gbàgbọ́ láre, àwọn tí Òfin Mose kò lè dá láre.
Oríṣun àwòrán, University of Texas Southwestern hospital O din diẹ ni ọọdurun biliọnu naira ti wọn fi pari ile iwosan naa.
Bí wọn tí ń lọ, ibikíbi tí ó bá wu àwọn Kerubu náà ninu ẹ̀gbẹ́ mẹrẹẹrin tí wọ́n kọjú sí ni wọ́n lè lọ láì jẹ́ pé wọ́n ṣẹ̀ṣẹ̀ yí ojú pada, nítorí pé ibikíbi tí èyí tí ó wà níwájú bá kọjú sí ni àwọn yòókù máa ń lọ.
Eyi ni ọ̀rọ̀ ọmọ ọba Dapo Adelegan tó jẹ́ oludije dupo gomina labẹ asia ẹgbẹ oṣelu African Democratic Congress (ADC).
Ṣugbọn ta ba wo bi Idiagbon ṣe gbe ọrọ Naijiria sori to, to si n lakaka fun orilẹede ti yoo goke agba, ipo ẹyin ti Naijiria wa nigba naa ko to lati pa ẹnikẹni lẹrin lootọ.
ko awon eniyan naa wa si orile ede Naijiria.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Abayọmi Aranmọlatẹ, Dr Laser: Vagino Plasty àti iṣẹ́ abẹ ẹwà Obìnrin ló jẹ mí lógún Ohun tawọn ọmọ Naijiria n sọ ni pe titu SARS ka nikan ko to bi kii ṣe pe ki ijọba ṣe atunto iṣẹ ọlọpaa.
Buhari: Ẹni ibi tí kò ṣeé má ní làwọn ará Abuja Oríṣun àwòrán, Presidency Àkọlé àwòrán, Aarẹ Buhari gbalejo awọn aṣoju ilu Abuja Lerefe ni aarẹ Muhammadu fi ọrọ ran Senator to n ṣoju olu ilu orilẹede yii, Phillip Aduda sí awọn ara ilu Abuja pe ẹni ibi ni wọn ṣugbọn oun ko le ṣai ma tọju ilu Abuja.
Ọdun 2012, 2016 àti 2020 ni John Mahama àti Nana Akufo-Addo ti jọ ń figagbága dupò aàrẹ Ghana Irọ́ ni pé mò kò Palliatives"" pamọ́ sí ilé mí-Abike Dabiri-Erewa Idi ti Odili fi gba ibi ìbálòpọ̀ lọ sí ọ̀run alákeji nílùú Port Harcourt Wo àwọn oúnjẹ márùn ún tó ń mú kí àtọ̀ ọkùnrin dára síi Ipinlẹ Niger jẹ ọkan lara ipinlẹ ti a da silẹ lọdun 1976."
N ò rí kí ojú bàbá mi pọ́n, kí ó sì rẹ̀wẹ̀sí báyìí rí.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ooni Ife ké sí olóòtú ìjọba Gẹ̀ẹ́sì tuntun pé kó má gbàgbé ìlérí tó ṣe fún gbogbo àgbáyé 26 Agẹmo 2019 Oríṣun àwòrán, Ile Oodua Ọọni ile ifẹ, Ọba Adeyẹye Ogunwusi ti fi ohun ranṣẹ si olootu ijọba tuntun lorilẹede Gẹẹsi, Boris Johnson pe ko ma ṣe gbagbe ileri to ṣe ninu ọrọ akọsọ rẹ gẹgẹ bii olootu ni ọjọru ninu eyi to ti ni ọwọ araalu ni agbara iṣejọba wa.
Olè yabo báńkì,fọ́n owó ká fáwọn èrò lẹ́yìn tó pariwo 'Merry Christmas' Àkójọpọ̀ àwòrán ọdún Kérésìmesì lágbáyé Ẹ ronúpìwàdà lásíkò ọdún, àti àwọn ìkíni mìrán tó jẹ yọ fún Kérésì Gómìnà Sanwo-Olu pàṣẹ pé kí wọn tú ẹléwòn 6 sílẹ lásìkò Kérésìmesì Ọjọ pipaarọ ẹbun 'Boxing Day' : ọjẹ kẹrindinlọgbọn, oṣu kejila Eyi ni ọjọ keji keresimesi ni gbogbo agbayeKí ló ṣẹlẹ̀ tí a fi ń pé ọjọ́ kejì Kérésì ní 'Boxing Day'?
Nígbà tí wọ́n wọ inú ilé, wọ́n lọ sí iyàrá òkè níbi tí wọn ń gbé.
Eleyi ni Aarẹ Muhammadu Buhari buwọ lu laipẹ yii.
Awọn ọmọ almijari yi lawọn ọmọ to wa lati idile ti o ku diẹ kaato fun lawujọ.
Orọ yii so ọlọgbọn kọ, o so were kọ ni awọn agbofinro Mozambique sọ.
Zakzaky ti wà láhàmọ́ àwọn ẹ̀ṣọ́ aláàbò ọ̀tẹlẹ̀múyẹ́ DSS, láti ọdún 2015.
Nígbà tí ó di òwúrọ̀ ọjọ́ keji, Dafidi kọ ìwé kan sí Joabu, ó sì fi rán Uraya.
Ǹjẹ́ o mọ àwọn òṣèré bí Oyin Adejọbi, Funmi Martins àtàwọn míì tó ti dágbére fáyé?
Koda, wọn ni awọn dokita naa ko ni lẹta lati ọdọ ileeṣẹ ilera tabi lati ọdọ ẹgbẹ onimọ iṣegun Naijiria.
Amọ, agbẹjọrọ to n soju Adeleke Nathaniel Oke bu ẹnu atẹ lu idajọ naa nitori adajọ naa tọ ọna ti ko ba ofin mu, ti o si da iwe ẹri WAEC to fihan pe Adeleke ni iwe ẹri WAEC rẹ.
Faithia Williams Ni ṣe lo dabi ẹni pe ọwọ jẹlẹnkẹ ni ọdun ọhun ba de fun Faithia Williams.
Lẹ́yìn náà ó fa ẹran ẹbọ sísun àwọn eniyan náà kalẹ̀, ó mú ewúrẹ́ ẹbọ ìmúkúrò ẹ̀ṣẹ̀ àwọn eniyan náà, ó pa á, ó sì fi rú ẹbọ ìmúkúrò ẹ̀ṣẹ̀ wọn, gẹ́gẹ́ bí ó ti ṣe ti ẹbọ ìmúkúrò ẹ̀ṣẹ̀ ti àkọ́kọ́.
Oríṣun àwòrán, others Àkọlé àwòrán, NFF, LMC Kwara United bá Nasarawa United kẹdun ikú Martins Agbabọọlu Kano Pillars, Dominic Dukudod subu ni papa isere kan naa ninu osu kejila odun 2018.
Boasi bá lọ sí ẹnu ibodè ìlú, ó jókòó níbẹ̀.
ṣíbí wúrà kan tí ìwọ̀n rẹ̀ jẹ́ ṣekeli mẹ́wàá, tí ó sì kún fún turari; 
#7000 sí #10000 ni owó àbẹ̀tẹ́lẹ̀ fún bẹẹdi ní ilé àwọn aláìsàn ọpọlọ Ẹ lọ fi òfin gbe ìdásílẹ̀ Amotekun lẹ́yìn - Ìjọba àpapọ̀ sọ fáwọn gómìnà Yorùbá Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Loju opo Twitter ile iṣẹ ọlọpaa, wọn ni oju awọn afẹhonu han naa gboro gan ṣugbọn awọn n ṣe iṣẹ awọn.
Mo bá wọlé láti wo ohun tí ó wà níbẹ̀.
Iberemi Osadebe da Gospel Salvation Christian Church rú lásìkò ìgbéyàwó ní Father's Church ni Eko
Ọrọ yi dagboro ru gan an ti awọn kan si bẹrẹ si ni ta aṣọ ti wọn kọ ọrọ yi silara ni witiwiti.
Ọpọlọpọ eniyan ati awọn nọọsi lo bu ẹnu atẹ lu igbesẹ ti Olamide gbe lori ayelujara, ni kete to jade sita, pẹlu #NursesAreNotSexualObjects.
adari ile ifowopamo ti ijoba apapo ti bere ise lori bi awon orile ede ile
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Idibo yan aarẹ tuntun ni orilẹ-ede Tunisia waye lọsẹ to kọja.
Ebola sẹ́yọ ní DR Congo DR Congo rí owó ìrànwọ́ gbà lọ́wọ́ ilẹ̀ Gẹ̀ẹ́sì Àláìsàn Ebola sá kúrò níléwòsàn lọ sí ṣọ́ọ̀ṣì Ọkan lara awọn dokita to n ṣiṣẹ lati gbogun ti arun naa, Pascal Vahwere sọ iriri rẹ fun BBC lasiko ti awọn ara abule kan ni Ariwa ẹkùn Kivu deede yi oun ati ikọ rẹ ka lasiko ti wọn fẹ fun awọn ara abule naa ni abẹrẹ ajẹsara.
Àwọn mejeeji wá dojú ìjà kọ Juda.
kí ó lè fihàn ní àkókò tí ó ń bọ̀ bí ọlá oore-ọ̀fẹ́ rẹ̀ ti tóbi tó, nípa àánú tí ó ní sí wa ninu Kristi Jesu.
Adewale Ayuba, lasiko to n kopa lori akanse eto ileesẹ wa BBC Yoruba, salaye pe ẹni ta ba laba, ni baba, lọrọ awọn to da orin Fuji silẹ, tii se Sikiru Ayinde Barrister ati Ayinla Kollington, ko si si ọrọ ansiyemeji nipa wọn.
Iroyin sọ pe wọn gbe iya arugbo naa lọ si ile iya olooṣa ọhun.
Ni ipinlẹ Osun, agbẹnusọ gomina, sọ pe awọn ti di gbogbo ọna to wọ ipinlẹ Osun lati awọn ipinlẹ miran.
Ọmọ ọdun mẹrindinlọgbọn ni Hauwa nigba ti wọn jii gbe.
O ti sọ pé ibẹ̀ ni àwọn eniyan yóo ti máa jọ́sìn ní orúkọ rẹ.
Tí ẹ bá gbádùn àwọn ìtàn mi, ẹ má ṣàìfi èsì sílẹ̀ fún mi.
Ati pe kii ṣe baba daada, nitori awọn ko jẹ anfaani rẹ gẹgẹ bi baba.
Ẹgbẹ oṣelu PDP wa pe fun iwadi iṣẹ ileeṣẹ eto iṣuna apapọ orilẹede Naijiria lasiko ti Kẹmi Adeọṣun fi jẹ minisita nibẹ lati lee ṣawari awọn iwa kots ti awọn agbẹyinbẹbọjẹ to wa ni iṣejọba aarẹ Buhari n ṣe titi to fi kan kiko owo epo rọbi sapo ara wọn pẹlu adinku owo to wa ninu aṣuwọn apapọ orilẹede yii nilẹ okeere Oríṣun àwòrán, @FinMinNigeria Àkọlé àwòrán, Adeọṣun pada sọrọ lori ẹsun ayederu iwe ẹri isinruulu NYSC ti wọn fi kan Kemi Adeosun: Ìdí tí mo fi kọ̀wé fipòsílẹ̀ gẹ́gẹ́ bíi mínísítà fétò ìṣúná Lẹyin nnkan bi osu meji ti awuyewuye lori ẹsun ayederu iwe ẹri isinruulu NYSC ti wọn fi kan an ti n ja ranyin ranyin,Minisita fun feto iṣuna lorilẹede Naijiria,Kemi Adeosun ti kọwe fi ipo silẹ.
Ìwọ Ọlọrun Olódodo, tí o mọ èrò ati ìfẹ́ inú eniyan,fi òpin sí ìwà ibi àwọn eniyan burúkú,kí o sì fi ìdí àwọn olódodo múlẹ̀.
Ijọba ibilẹ marun-un ni ẹgbẹ oselu PDP ti jawe olubori nigbati APC moke ninu ijọba ibilẹ mọkanla.
Bí apákan ninu òkú wọn bá jábọ́ lé orí èso tí eniyan fẹ́ gbìn, èso náà kò di aláìmọ́.
Ẹkunrẹrẹ fidio naa ree, ẹ woo: Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí 2 sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
Ó ku bí ọ̀sẹ̀ mẹ́ta kí Ijó ìta-gbangba ó wáyé, àwọn orin wọn mìíràn  tí ó ní akọrin obìrin Destra Garcia àti Patrice Roberts tí yóò mú ìdíje le fún àwọn ọkùnrin, àti bí àwọn akọrin soca ṣì ń gbé àwo orin tuntun jáde, ìfigagbága Ìwọ́de Ojúnà ọdún-un 2019 ṣì ń lọ lọ́wọ́.
Day 5: Nínú ilé yì o, APC lẹ gbúdọ̀ dìbò fún DBanj gbé àwo tuntun jáde lẹ́yìn ikú ọmọ rẹ̀ Ní Àwòrán: Ìsìnkú Winnie Mandela Obìnrin tó lágbára láti yan ìyàwó míì fún ọkọ 'Màálù tó bá tàsẹ̀ àgẹ̀rẹ̀ níwájú ilé mi, ó dẹran àsun!
Awọn akoko ti a lo jẹ (GMT+2), o si ṣeeṣe ko yipada.
7 Kíyèsíi, kò sí agbára míràn, àfi agbára Ọlọ́run, tí ó lè mú kí ẹ̀bùn Áárónì yìí wà pẹ̀lú rẹ.
Makinde sọ ọrọ yii ni Ọjọ Isinmi nibi ayẹyẹ iranti iya rẹ to doloogbe ni ile ijọsin Saint Paul's Anglican church, Yemetu, Ibadan.
Aare buhari so ninu oro re pe, isele ijamba ina ohun, je ohun ti o ba oun ninu je lopolopo, eleyi ti iroyin fi mule pe, isele buruku ohun gba emi eniyan mesan, ti o si ba ohun ini awon eniyan je.
Nisinsinyii, bí o bá pa àwọn eniyan yìí bí ẹni tí ó pa ẹyọ ẹnìkan ṣoṣo, àwọn orílẹ̀-èdè tí wọ́n ti gbọ́ òkìkí rẹ yóo wí pé; 
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù 9th Assembly: PDP ní láìpẹ́ làwọn aráàlú yóò mọ ìyàtọ̀ lórí àkóso ilé aṣòfin 11 Òkùdu 2019 Oríṣun àwòrán, @OfficialPDPNig Ẹgbẹ oselu alatako gboogi ni Naijiria, PDP, ti fesi lori bi idibo ile asofin agba ilẹ wa se lọ ni ọjọ Isẹgun.
Manchester United vs Manchester City: Ó ti di ìgbà mẹ́ta ní sáà yìí tí Man U dígbájú ru Man City.
Bẹ́ẹ̀ ni gbogbo wa sọ tí a sì fi ìpinnu sí wí pé kí Baba-onírùngbọ̀n ṣe àpèjúwe ọ̀nà fún wa àti wí pé a ó lọní ọjọ́ kejì lágbára Ọlọ́run.
Xenophobia: Àwọn ọ̀dọ́ kan ń ṣèwọ́de láti pè fún lílé àwọnjì kúrò ní South Africa
Davido tun fi asiko naa kedun pelu Dbanj olorin to padanu omokunrin re lojo Aiku.
ìbòrí tí wọ́n fi awọ ewúrẹ́ ati awọ àgbò ṣe tí wọ́n kùn láwọ̀ pupa, ati aṣọ ìbòjú inú àgọ́ náà.
Mo fẹ́rẹ̀ jẹ àwọn ìjọ mìíràn run, tí mò ń gba owó lọ́wọ́ wọn láti ṣe iṣẹ́ fun yín.
Abiyamọ ìyá olóògbé tí SARS yìnbón pá fàwọ́n lé kóòtù Olorun Magu,'estimated billing' àti àwọn ohun míràn tí ilé aṣòfin Nàìjíríà kò rí yanjú Ahmed Musa gbàmì ẹ̀yẹ agbábọ́ọ̀lù tó pegede ní ọdún 2018 O fi kún pe ọ̀pọ̀ àwọn ọmọ àkanda yìí kìí ni òòre ọ̀fẹ́ láti joko ju ìṣẹ́ju mẹ́ẹ̀dógun lọ láti kẹ́kọ̀ọ́ tabi ṣe iṣẹ́, sùgbọ́n, wọn jẹ onímọ gidigidi ti ènìyàn ba fi ara balẹ̀ fun wọn.
 Mo duoe lowo eyin ebi ati ore ati alatileyin mi gbogbo fun adura.
3 Gbigba bọọlu si oju ile 3 6 Gba bọọlu 15 16 kọna 4 6 Ṣẹ sofin 19 22 Ilana ere bọọlu Nigeria (4-2-3-1) Burundi (4-4-2) Ẹkunrẹrẹ 42 - Shehu                                                                          down Awaziem                                                                      up 0 - 0 58 - Mikel                                                                          down Musa                                                                      up 0 - 0 59 - Moustapha                                                                          down Kamsoba                                                                      up 0 - 0 63 - Shassiri Nahimana 0 - 0 73 - Paul Onuachu                                                                          down Ighalo                                                                      up 0 - 0 76 - Shassiri Nahimana                                                                          down Nduwarugira                                                                      up 0 - 0 77 - Ighalo football 1 - 0 92 - Berahino                                                                          down Mohamed Amissi                                                                      up 1 - 0 Awọn ti wọn o kọkọ bẹrẹ Nigeria 16 Akpeyi 2 Ola Aina 12 Shehu 5 Troost-Ekong 22 Omeruo 13 Chukwueze 10 Mikel 18 Iwobi 8 Peter Etebo 4 Wilfred Ndidi 14 Paul Onuachu Burundi 1 Jonathan Nahimana 8 Duhayindavyi 15 Moussa 19 Nsabiyumva 16 Nshimirimana 20 Moustapha 5 Bigirimana 17 Cédric Amissi 10 Shassiri Nahimana 18 Berahino 7 Abdul Razak Awọn iyipada 42 Shehu                                                                  down 42 Awaziem                                                              up 58 Mikel                                                                  down 58 Musa                                                              up 73 Paul Onuachu                                                                  down 73 Ighalo                                                              up 59 Moustapha                                                                  down 59 Kamsoba                                                              up 76 Shassiri Nahimana                                                                  down 76 Nduwarugira                                                              up 92 Berahino                                                                  down 92 Mohamed Amissi                                                              up Awọn ti wọn paarọ 21 Osimhen 23 Uzoho 1 Ezenwa 9 Ighalo 20 Awaziem 15 Simon 11 Onyekuru 6 Balogun 19 Ogu 7 Musa 14 Ngandu 21 Mohamed Amissi 23 MacArthur 13 Justin Ndikumana 4 Kwizera 3 Kamsoba 9 Mavugo 6 Nizigiyimana 22 Nduwarugira 2 Sabumukama 12 Shabani Bi Super Eagles ṣe bori yii ti mu ki o ṣeesẹ fun wọn lati wa ni oke tente ni aarin awọn ti wọn jọ wa ni isọri kan naa.
Oludari igbimo oludamoran fun ile ifowopamo First City
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Oronpoto Animation: Akin Alabi ní kò dára bí eré aláwòrán fáwọn ọmọdé ṣe jẹ́ aláwọ̀ funfun Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Lẹ́yìn èyí, ọmọ obinrin opó yìí ṣàìsàn.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Insecurity: Buhari ní ẹ̀ka aláàbò Nàíjíríà tiraka àmọ́ ó yẹ kí wọn ṣe jù bẹ́ẹ̀ lọ 18 Ògún 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 1 Ògún 2020 Oríṣun àwòrán, Others Aarẹ orilẹede Naijiria, Muhammadu Buhari ti kede pe awọn ọms Naijiria funra wọn mọ pe ijsba oun ti sa ipa rẹ lati gbogun ti aifararọ eto aabo.
ilọsiwaju eto oro aje orile ede naa nitori pe awọn
Ṣé Ẹni Mímọ́ Israẹli ni o ṣe irú èyí sí?
Kí ló ń ṣẹlẹ̀ nípa olùwọ́de EndSARS tí wọ̀n yìnbọ̀n lù ní Ogbomosho?
Aare tun so pe : ‘‘Inu
Nítorí ìyapa níláti wà láàrin yín, kí àwọn tí ń ṣe ẹ̀tọ́ láàrin yín lè farahàn.
Jehoiakini jẹ́ ọmọ ọdún mẹjọ nígbà tí ó jọba.
to wa niluu Abuja, lọjọ Ẹti.
 ní kùtù hàì ọjọ ́ náà , láfẹ ̀ mọ ́ jú ni oníṣẹ ́ ti kan ìdílé láṣòrè lára pé ẹnìkan tún ti fi ìpinnu rẹ ̀ hàn láti gbé jìjì níyàwó pẹ ̀ lú ohun tí jìjì fẹ ́ ràn jù .
Àwẹ̀ Ramadan wákàtí 22 lóòjọ́, ṣé ẹ̀mí rẹ gbà á?
naa ni gomina ipinle Ogun, Dapo Abiodun ati ogun ipinle Plateau, Simon Lalong.
 Àwọn èdè bú méjìlà mìíràn tún wà èyí tí avar àti armerican wà lára wọn .
Bill Gates ati aya rẹ ṣeleri lọdun diẹ sẹyin lati maa lo ọgọọrọ owo to ba n wọle fun wọn lati fi ṣaanu fun awọn to ba ku diẹ kaato fun lagbaye.
Aare ki ebi olojo ibi ku oriire pe Olorun fun iran yii ni wolii tooto, to n waasu ihinrere laisetan to n tuko ijo Irapada lati odun 1981 ni eyi ti ijo naa si ti kari aye di okan lara awon ijo ti omo ijo re poju lagbaye lasiko yi.
Ẹ̀wẹ̀, ẹlẹgbẹ́ ọlọ́pàá yìí kan sọ pé Ọgbẹ́ni Baba-Inna fẹ̀sẹ̀ múlẹ̀ pé òun kò lọ́wọ́ sí ẹ̀sùn yìí rárá wí pé òun kò gba owó kankan lọ́wọ́ ẹnikẹ́ni lórukọ ọ̀gá òun.
NAFDAC gbẹ́sẹ̀ kúrò lórí òfin tó fi de àwọn iléeṣẹ́ apòògùn
Olùfẹ́, ẹ jẹ́ kí á fẹ́ràn ẹnìkejì wa, nítorí ìfẹ́ ti ọ̀dọ̀ Ọlọrun wá.
Oriṣa ni wọ́n ń bọ nígbà náà.
Àwọn ẹni ńlá tí ó wá sí ìgbéyàwό yìí gbadun ara wọn pupọ̀.
ṣugbọn OLUWA ti sọ fún un pé aya Jeroboamu ń bọ̀ wá bèèrè ohun tí yóo ṣẹlẹ̀ sí ọmọ rẹ̀ tí ó ń ṣàìsàn, OLUWA sì ti sọ ohun tí Ahija yóo sọ fún un.
Ni bi a ṣe n sọrọ yii, ariwo to n ls loju opo ayelujara gbogbo bayii ni ibeere boya aarẹ yoo ṣi tun sun aṣẹ igbele tipatipa naa siwaju sii ni labẹ #lockdownextension Coronavirus Update: Ìséde káàkiri Nàìjíríà lọ̀nà àbayọ sí ìtànkálẹ̀ ààrùn coronavirus Onimọ nipa ajakalẹ aarun to ba BBC Yoruba ṣalaye pe iṣede kaakiri orilẹede Naijiria yoo ṣe iranwọ nipa gbogbogun ti itankalẹ aarun coronavirus.
Alaga ajọ eleto idibo ni ipinlẹ Ekiti, Ọjọgbọn Idowu Ọlayinka to ṣe ikede naa sọ wi pe Kayode Fayemi bori pẹlu ibo 197,459.
4bn ní rìbá táwọn agbẹjọ́rò fún adájọ́ láàrín ọdún mẹ́ta - ICPC Ìdí rèé tí ẹ̀mí mi kò fi bọ́ sínú ìdìtẹ̀ gbàjọba tó pa Muritala Muhammed - Obasanjo Wọ́n gún ọkùnrin kan lọ́bẹ pa torí ó tako yínyin báńgà sínú Mọ́ṣálásí Àwọn àṣà tó milẹ̀ lọ́dún 2020 pẹ̀lú ìtàn lórí bí wọ́n ṣe jáde Kò bá wù mí kí n padà sí àwọ̀ tí Ọlọ́run dá mi, wàhálà ni ara bíbó - Bobrisky N kò tíì pa ọ̀rọ̀ ìfẹ́ tì, bí mo tilẹ̀ ti kúrò nílé ọkọ - Mercy Aigbe Amọ nigba ti Victory ri ikede yii ka, lo ba kede loju opo Twitter rẹ pe @dysel pe Cute Abiola ti lu oun ni jibiti ara, ti ikede nini afẹsọna naa si fẹ da oun lori ru.
O ṣalaye wipe yatọ si papakọ Port Harcourt ati Kano to le ko to miliọnu kan lara ero naa lọdun, ko tumọ si wipe papakọ ofurufu Kano ati Port Harcourt naa n ṣiṣẹ debi to fi le pa owo lati fi maa boju to wọn wọle.
Mose bá gbé ọwọ́ rẹ̀ sókè sí ojú ọ̀run, òkùnkùn biribiri sì ṣú bo gbogbo ilẹ̀ Ijipti fún odidi ọjọ́ mẹta.
O tun ni  “Awon ekun Lake Chad gbodo le e  pese ohun amayederun, ise lopo janturu ati ise kikọ, lona ti yoo fi din wahala to n sele ni awon ekun naa ku.
Àti pàápàá, bàbá mi ti pàṣẹ bẹ́ẹ̀ fún mi kí ó tó kú.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Afcon2019: Egypt ni yóò gbàlejò Afcon 2019 8 Sẹ́rẹ́ 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Ajọ to n mojuto ere bọọlu nilẹ Afrika ti kede orileede Egypt gẹgẹ bi orileede ti yoo gbalejo idije Afcon 2019.
Agbẹnusọ fún àjọ tó ń kojú ìṣẹ̀lẹẹ̀ pàjáwírì ní Ipinlẹ Eko (LASEMA) Ọgbẹni Adebayo Kehinde, ni ọkọ̀ akérò mẹ́ta, àti àjàgbé mẹ́fa ni ó jóná nínú ìṣẹ̀lẹ̀ náà.
Dafidi dá Gadi lóhùn pé, “Ìdààmú ńlá ni ó dé bá mi yìí, ṣugbọn ó yá mi lára kí OLUWA jẹ wá níyà ju pé kí ó fi mí lé eniyan lọ́wọ́ lọ; nítorí pé, aláàánú ni OLUWA.
Awọn owo ori ti wọn n gba lọwọ ara ilu ti n pọ ju lai si ohunkohun ti wọn n fi se.
Ní oṣù Nisani, ní ogún ọdún tí Atasasesi ọba gorí oyè, mo gbé ọtí waini tí ó wà níwájú rẹ̀ fún un.
Opọ igba ni o maa n kọ nipa ìṣe ati irinsi awọn alatako.
 “A o ni jẹ ki wọn  lọ ni alaafia .
”  Umahi tun so pe, awon Ndi Igbo duro sinsin lati mu atipada otun de ba orile-ede ‘Naijiria,“A o fi oju sunukun wo ona ti a o gba lati tun mu ayipada otun de ba orile-ede Naijiria ninu ipade to n bo.
O ṣalaye pe, ijọba yoo wo iwe ọhun wo finni-finni ko to gbe igbesẹ kankan, ṣugbọn ni bayii, o ṣi n ṣagbeyẹwo rẹ ni.
Ikọ iroyin BBC Yoruba tun kan si olu ile isẹ ọlọpaa to wa ni ilu Akure, lati fi ọrọ wa wọn lẹnu wo lori ibi ti wọn ba isẹ de lori isẹlẹ naa.
Nígbà náà ni n óo dúpẹ́ lọ́wọ́ rẹ láàrin àwùjọ ọ̀pọ̀ eniyan;láàrin ọpọlọpọ eniyan ni n óo máa yìn ọ́.
Joṣua dáná sun ìlú Ai, ó sì sọ ọ́ di òkítì àlàpà títí di òní olónìí.
Mohammed Yusuf: Àwọn ohùn tó yẹ kí o mọ nípa olùdásílẹ̀ Boko Haram
Iroyin naa ni iru isẹlẹ bayii ko tii waye ri ni ile ẹkọ fasiti Howard tabi ni ile ẹkọ fasiti kankan ni orilẹede Amẹrika, awọn ọmọ Nigeria yii si ni oju gbogbo n wo nibi ayẹyẹ naa pẹlu itan ara ọtọ ti wọn fi lelẹ yii.
Agbẹnusọ Gomina Seyi Makinde lori ọrọ ẹrọ ayelujara Jide Ajani lo sọrọ yii, pẹlu bi awọn eeyan kan se n fi ẹsun kan Amotekun Oyo pe wọn n pa eeyan lainidi.
Awọn afẹhọnuhan naa ri iwọde ti wọn n ṣe gẹgẹ bi ọna lati fi opin si ifiyajẹni ati iṣekupani awọn ọlọpaa lorilẹede Naijiria.
Ninu atejade kan ti minista fun
Àbí ìrànlọ́wọ́ ìgbàlà rẹ wà ní ilẹ̀ àwọn tí a ti gbàgbé?
Awọn alaṣẹ Premier League fẹ bẹrẹ liigi ọhun pada lọjọ kẹjọ oṣu kẹfa, eyi ti wọn fẹ ko pari ninu oṣu keje ọdun yii.
Máa lọ ní alaafia, o kò ní gbúròó àìsàn náà mọ́.
Nítorí ẹni tí Oluwa bá fẹ́ràn ni ó ń tọ́ sọ́nà,ẹni tí ó bá gbà bí ọmọ,ni ó ń nà ní pàṣán.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Victor Agunbiade ni ojú àlá ni Ọlọrun ti yan iṣẹ́ ọmọ ogun ojú omi fún òun ní America Goolu meji ti atamatase ati Balogun ikọ naa, Pierre-Emerick Aubameyang gba wọ àwọ̀n Manchester City nigba ti ifẹsẹwọnsẹ naa wọ iṣẹju kejidinlogun ati ikọkanlelaadọrin.
Ninu atẹjade ti Ajọ LASEMA fi lede ni wọn ti sọ wi pe ajọ naa tete de ibẹ lati pa ina naa ki o tọ fa ijamba miran ni ibi iṣẹlẹ naa.
Ará Ijipti náà gbé ọ̀kọ̀ tí ó tóbi lọ́wọ́.
Oríṣun àwòrán, LASEMA Àkọlé àwòrán, Ara adugbo ati awọn arinrinajo pejọ nibi isẹlẹ naa Atẹjade naa wipe ọga agba ileeṣẹ to n risi iṣẹlẹ pajawiri ni ipinlẹ Eko (Lasema), Adebayo Tiamiyu n rọ̀ awọ̀n awakọ̀ lati ṣe jẹjẹ loju popo, ki wọn si bikita fun ere asapajude.
Diẹ lara awọn ami arun igbẹ ọrin to n tankalẹ yii ni igbẹ gbuuru, inu rirun, eebi bibi ati iba ti ara ko gbona pupọju.
Tọ̀sán tààjìn, Ni wọ́n fi ń tú ayé ọmọ ọlọ́mọ ṣe.
 #OoniOfIfe #OtiseseA post shared by  Ooni Adeyeye Enitan Ogunwusi (@ooniadimulaife) on Oct 18, 2018 at 3:05pm PDT“Eyi je ibere imo ati oye re lori ite oduduwa.
Ọmọ Ogun Naijiria - BBC News Yorùbá BBC News, YorùbáFò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù 'A ti pa Boko Haram run pataoata' - Ọmọ Ogun Naijiria 4 Èrèlè 2018 Àkọlé àwòrán, Ikọ̀ ọmọ ogun Naijiria ni ki awọn ti wọn wa ni kọrọ jade wa Ikọ̀ ọmọ ogun ilẹ Naijira ti sọ pe awọn ti lọ ikọ̀ Bokoharam ni àlọ̀mọ́lẹ̀ ti wọn n lọta o.
Awọn ọlọpaa mẹta ọhun ni Ken Olonde, Patrick Baya ati Sajẹnti Hamisi Kombo ti wọn fi ofin mu awọn afurasi obinrin naa.
”Awon akegbe re yooku ti won jo figagbaga du ami-eye ohun ni:David Silva, De Bruyne, Harry Kane Ninu ami-eye miran:Ami-eye agbaboolu odo ti o darajulo – Leroy SaneAsole ti o darajulo – David De GeaGege bi akonimoogba agba iko Manchester City, Pep Guardiola, O ni, bi won n ba n se agbeyewo ipa agbaboolu kookan ninu idije EPL saa yii, osuwon agbaboolu re Kevin de Bruyne ni o kun julo, ti o si leto si ami-eye ohun, yala nipa iranwo ami-ayo, tabi ka gba boolu sinu agbon.
Oríṣun àwòrán, Alamy Àkọlé àwòrán, Adebanji Akintoye fí ẹ̀yin Bola Ahmed gbálẹ̀ láti jẹ́ Aṣíwáju gbogbo ilẹ̀ Yoruba Bó tilẹ̀ jẹ́ pé Akintoye, ẹni ọdún mẹ́rìnlélọ́gọ́rin náà kò sí nínú ìpéjọpọ òhún síbẹ̀ wọ́n dìbò yàn-án gẹ́gẹ́ bi àsíwáju tuntun fún ilẹ̀ Yoruba.
Minisita naa fikun wipe, Ijọba apapọ tun pasẹ fun awọn ọkọ nla nla lati dari si papakọ to gba ọọdunrun ọkọ, ti wọn se lati dẹkun sunkẹrẹ ọkọ ni oju ọna marọse Oshodi si Apapa.
Faithia, tii ṣe iyawo gbajumọ oṣere miran, Saheed Balogun, ṣe jẹ agba ọjẹ oṣere to dangajia, naa lo tun jẹ adari ati Olootu ere sinima.
Lati igba ti wọn ti gbe Moshood Abiola ti mọle, pẹlu igboya ni Kudirat fi lọ pe fun itusilẹ ọkọ rẹ pẹlu bi ijọba ṣe n dunkooko mọ ẹbi ati awọn alatilẹyin rẹ to.
Still Water Runs Deep – Nigeria/USA
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Akeredolu, aya àti ẹbí rẹ̀ ló ń ṣèjọba ni mo ṣe fipò sílẹ̀ - Akọ̀wé ìjọba tẹ́lẹ̀ l‘Ondo Àlàyé rèé lórí ìdí tí Magu àti awọn alága EFCC míràn ṣe bá ìtìjú kúrò nípò Àwọn ẹlẹ́sìn ìbílẹ̀ ń bèèrè owó lọ́wọ́ àwọn Alfa lórí ìsìnkú ẹni tó pokùnso Hushpuppi di gbajúmọ̀ ẹlẹ́wọ̀n tó ní nọ́ńbà l‘Amẹrika, orúkọ̀ rẹ̀ wà lórí ayélujára Nǹkan tí ojú rí rè é bí pápákọ̀ òfurufú ṣe di ṣíṣí padà ní Nàìjíríà Ṣé lóòtọ́ ni Lateef Adedimeji àti Adebimpe Oyebade ṣe ìgbéyàwó?
Kọmisana feto ẹkọ, Olasunkanmu Aremu Olaleye lo sisọ loju ọrọ yii ninu atẹjade kan to fi ransẹ si awọn ọga ile ẹkọ naa ati awọn eeyan miran ti ọrọ eto ẹkọ gberu.
" wọ ́ n máa ń kó àwọn ẹ ̀ yà wọ ̀ nyí mọ ́ ìdílé "" microlophus "" ṣùgbọ ́ n ní ìgbà láéláè , wọ ́ n kó wọn pọ ̀ pẹ ̀ lú "" tropidurus "" ."
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù RUGA: Adeboye ní àsìkò tó láti wá nǹkan ṣe sí ọ̀rọ̀ ètò pápá ìjẹko RUGA pátápátá 1 Owewe 2019 Oríṣun àwòrán, PastorEAAdeboye Àkọlé àwòrán, RUGA: Adeboye ní àsìkò tó láti wá nǹkan ṣe sí ọ̀rọ̀ ètò pápá ìjẹko RUGA pátápátá Bi o tilẹ jẹ pe ijọba apapọ ni awọn ti ṣẹwe le eto idasilẹ papa ijẹko RUGA ni ọsẹ diẹ sẹyin awuyewuye lori eto naa ko dẹkun o.
Aarẹ Muhammadu Buhari lo n dari ipade naa eleyi ti yoo jẹ ẹlẹẹkẹta ti aarẹ Buhari yoo maa ko jọ lati ọdun 2015 to ti de ori ipo.
Aya Jeroboamu sì ṣe bí Jeroboamu ti wí.
Koda, ẹyin tutu ni wọn ju luu, wọn ko si tilẹ jẹ ko ri aaye wọle debi pe yoo roju raye ṣe alejo pataki ti wọn pee fun.
Mo wòkè títí ojú ń ro mí,ara ń ní mí, OLUWA, nítorí náà ṣe ààbò mi.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, End SARS, End SWAT: Ó pé mi bí SARS kò ṣe sọ mí dolówọ́- Fulani Kwajafa Ngige sọ pe lati bi ọsẹ kan ni ijsba ti n ṣiṣẹ lati fi opin si iyanṣẹlodi naa, to si sọ pe adura awsn ni pe ki ipade ti wọn ṣe naa so eso rere.
Kí àwọn alufaa, àwọn iranṣẹ Ọlọrun, sọkún láàrin ẹnu ọ̀nà àbáwọlé ati pẹpẹ ìrúbọ.
Bí ó ti nsún kẹrẹ ni ó nfà kẹrẹ.
Ṣugbọn nigba to di ọdun 2015 ni wọn kọrin mi o ṣe mọ, ti wọn si ta ileeṣe ̣hun fun Dangote patapata.
Germany football naked protest: Àwọn olùfẹ̀hónúhàn bọ́ra sí ìhòhò lórí pápá lòdì sí sísọ eré bọ́ọ̀lù di jẹunjẹun
Wọ́n gbọdọ̀ wó o lulẹ̀ ni, kí wọ́n ru gbogbo òkúta rẹ̀ ati igi tí wọ́n fi kọ́ ọ ati ohun ìrẹ́lé tí wọ́n fi rẹ́ ẹ jáde kúrò láàrin ìlú, lọ sí ibi tí kò mọ́.
Nítorí náà, olukuluku wa ni yóo sọ ti ẹnu ara rẹ̀ níwájú Ọlọrun.
December 2, 2016 Ile ẹjọ giga julọ ni Naijiria paṣẹ ki wọn tu adari ẹgbẹ naa silẹ latimọle ipinlẹ fun awọn ọlọ́pàá laarin wakati marundinlaadọta.
Ó ní ọjọ́ orí olóògbè n bẹ láàrin àádọ́ta ọdún sí ọgọ́ta.
Orile ede Naijria ti seranwo ẹ̀ẹ́dẹ́gbẹ̀ta owo dola fun Guinea Bissau lati fi ran won lowo lori eto idibo.
OLUWA fi ìlú Lakiṣi lé àwọn ọmọ Israẹli lọ́wọ́, wọ́n sì gbà á ní ọjọ́ keji.
Bariga-Ifako Bridge Ijọba ibilẹ Ikeja Somolu / Kosofe31.
Ọrọ yii jẹ ohun to mu iriwisi ọtọọtọ wa lati ọdọ awọn ololufẹ Seyi Edun ti pupọ si ni ki ẹni naa gbaju mọ ọrọ tiẹ.
Ṣugbọn ọpọlọpọ eniyan rí wọn bí wọ́n ti ń lọ, wọ́n mọ̀ wọ́n, wọ́n bá fi ẹsẹ̀ rìn, wọ́n sáré láti inú gbogbo ìlú wọn lọ sí ibi tí ọkọ̀ darí sí, wọ́n sì ṣáájú wọn dé ibẹ̀.
Àkọlé àwòrán, Ọpọlọpọ awọn ẹbi, ara, ọrẹ lo pejọpọ si ibi ayẹyẹ ọjọ ibi ti agbarijọpọ ẹgbẹ awọn ọmọ bibi ilẹ Ibadan, Central Council of Ibadan Indigenes(CCII) se fun Gomina ipinlẹ Ọyọ.
 Lara awon to n fesun kan Weinstein ni Lara Evans pe o fipa mu oun baa lopo lati enu lodun 2004.
Monatan - Olodo Road di Rashidi Ladoja.
Ìwọ ni olùrànlọ́wọ́ ati olùgbàlà mi,má pẹ́, Ọlọrun mi.
kí Ọlọ ́ run má fi wá sí kọ ̀ rọ ̀ ayé , ọ ̀ run náà mọ ̀ ni kọ ̀ rọ ̀ ; bẹ ́ ẹ ̀ -kí-í-ṣe , a à ní bá bẹ ́ ẹ ̀ lọ ́ wọ ́ rẹ ̀ ; bẹ ́ ẹ ̀ -ni-i-ṣe ò sin í í fi bẹ ́ ẹ ̀ sílẹ ̀ .
O maa n mu wahala ba bi ọkunrin ṣe le ṣe daada si lasiko ibalopọ, tabi ko maa ronu lati gba ẹmi ara a rẹ.
Ààbọ̀ ọ̀rọ̀ ni à ń sọ fún ọmọlúwàbí, tí ó bá dé inú rẹ̀ á di odidi.
Ọgá àgbà kan tí kò fẹ́ ki a dárukọ lásìkò tó ba akọròyìn Punch sọ̀rọ̀ sàlàyé pé ọgá àgbà pátápátá ti dári 93 Battalion láti sàwári ọ̀daràn náà, ó fi kún pé ìgbìmọ̀ tí wọ́n gbé kalẹ̀ láti ṣe ìwádìí ọ̀rọ̀ náà le ma ṣe ǹkankan to nitumọ àfi ti ọdún iléyá bá pari.
Absalomu wí fún àwọn iranṣẹ rẹ̀ pé, “Ẹ máa kíyèsí Amnoni, nígbà tí ó bá mu ọtí yó, bí mo bá ti fun yín ní àṣẹ pé kí ẹ pa á, pípa ni kí ẹ pa á, ẹ má bẹ̀rù; èmi ni mo ran yín.
Ìdí tí Gúúsù Akure, Owo àti ìwọ̀orun Ondo yóò fi sọ ẹni tí yóò jáwé olúborí nínú ìbò gómìnà Ondo Igbiyanju lati ṣe ibura wọle fun awọn aṣofin tuntun naa lo fori sanpọn, nigba ti awọn kan le wọn kuro ni Ile Igbimọ Aṣofin, lẹyin ti wọn ni wọn n tun ayika ati Ile Igbimọ Aṣofin naa ṣe lọwọ.
"Ìjà d'ópin, fún ìgbà àkọ́kọ́, bàálù gbéra láti Israel lọ sí UAE Wọ́n ti sún ìdájọ́ àwọn sójà tó pa ìyá àti ọmọ ní ọdun 2018 sí oṣù tó m bọ̀ Ààrẹ Buhari buwọ́lu gbígbé ìṣàkoso nọ́mbà ìdánimọ̀ (NIMC) lọ sí ẹ̀ka ìjọba tó ń rí sí ìbáraẹnisọ̀rọ̀ Ṣé Nàìjíríà lẹ́mìí nkan tí Ghana ń ṣe fáwọn akẹ́kọ̀ọ́ ""Secondary"" tí yóò wọlé ní October yìí?"
Bakan naa lo tun fi asiko naa rọ awon eniyan Ipinle Oyo lati fọwọsowọpọ pẹlu
    Ìgbà tí Ọkánjúwà fẹ́yìntì lọ tán àwọn méjì yòókù bẹ̀rẹ̀ síi ronúbí  ìbá ti dùn tó kí á wí pé àwọn méjì péré lorí owó náà, àpò mẹ́fà-mẹ́fà ni àwọn ìbá pín in.
fi kun ọrọ rẹ pe mọṣalaṣi Anọbi ni ilu Medina ṣe pataki nitori pe idanilẹkọkọ nipa orisun igbe aye
Iyawo rẹ̀ sì mọ̀ nípa rẹ̀.
 Àwọn ará ìlú aberdeen ni wọ ́ n ń pè ní aberdonian .
Nítorí náà, ẹ ṣọ́ra, kí ẹ má ṣe jẹ́ alaiṣootọ sí aya yín.
Lumumba ni awọn ṣi ṣe ipade pẹlu ijọba lọjọ meji ṣẹyin, ti wọn si ni igbesẹ yoo waye lati ṣatunṣe gbogbo ẹdun ọkan wọn.
Àwọn ọmọ Israẹli tún ṣe nǹkan tí ó burú lójú OLUWA, OLUWA sì fi wọ́n lé àwọn ará Midiani lọ́wọ́ fún ọdún meje.
" Bakan naa lo tun kan sara si aṣoju ijọba ilẹ Gẹẹsi lorilẹede Naijiria, Arabinrin Catriona Laing fun ilakaka rẹ lati rii pe ajọṣepọ to dan mọran wa laarin orilẹede Naijiria ati ilẹ Gẹẹsi.
Gbogbo ibẹ̀ rí ṣúkuṣùku ṣùkuṣuù, kò sí ọ̀nà kan tí ó gún gbogbo ọ̀nà rí wọ́gọwọ̀gọ.
OLUWA ní òun nìkan ni òun mọ ohun tí wọ́n ṣe; òun sì ni ẹlẹ́rìí.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Falconets gbo ewuro soju orilẹ ede Cameroon nínú ìdije eré ti ilẹ Afrika 30 Ògún 2019 Oríṣun àwòrán, FIFA.
Láti 462 sí 386, àwọn tó ní àrùn Covid-19 já wálẹ̀ ní Nàìjíríà lọ́jọ́ Àbámẹ́ta Akẹ́kọ̀ọ́ Babcock tí wọn bá lòpọ̀ nínú fídíò rí ẹ̀kọ́ ọ̀fẹ́ ní fásitì òkè òkun Ẹyìn tí Hydroxychloroquine, Zinc ati Zithromax da lára yá,ẹ bọ síta wà jẹrìí mí-Dr Stella Emmanuel O ni awọn ilana to rọ mọ ayewo yi ni pe ijọba ni yoo san owo ayẹwo f'awọn akẹkọọ ileewe ijọba.
Ẹwẹ Kabiyesi ni bí ẹnikẹni bá ti rú òfin, ko si iru ẹya to le jẹ, ẹ mọ̀ọ́ pa wọ́n, ẹ o ri i kò ní ṣẹlẹ̀ mọ́""."
Ó tún dáhùn pé “Kí ni o fẹ́ fi alaafia ṣe?
" Ajafẹtọ naa ni nitori pe awakọ oun ti lo ju ọjọ meji ni ahamọ, oun sọ fun awọn ọlọpaa naa pe ofin ko gbaa laaye ki wọn ṣi ti mọle.
oludije naa tun so pe, o daju
Isinku akẹkọọbinrin LASU ti wọn fi se oogun owo bẹrẹ l‘Eko Laipẹ yii la mu iroyin wa fun yin pe, awọn ẹbi, ọrẹ ati akẹẹgbẹ akẹkọbinrin ileeẹkọ fasiti Eko, LASU, Favour Daley-Oladele, ti iya ati ọmọ kan fi se ọbẹ alata fun oogun owo laipẹ yii, ni wọn ti n de si itẹ oku Atan ladugbo Yaba, nilu Eko.
Gbogbo àwọn ẹyẹ bá ń jẹ ẹran-ara wọn ní àjẹrankùn.
Ọba ní, “Rárá, ọmọ mi, bí gbogbo wa bá lọ, wahala náà yóo pọ̀jù fún ọ.
Aarẹ wa kilọ fawọn ọmọ ẹgbẹ osẹlu APC nibi ipade ọhun pe ẹgbẹ APC ko gbọdọ tuka lẹyin ti oun ba pari saa keji oun tan.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ẹ̀mí kan náà ló n darí ìrìnàjò wa táa fi jọ kọ́lé papọ̀- Ìbejì Marie Stopes bẹrẹ si ni gba awọn rọba idaabobo ti wọn ti pin yii pada lẹyin ti NDA kọwe si wọn lọgbọn ọjọ oṣu kẹwaa fi sọ pe ipele meji ninu awọn rọba idaabobo wọnyii ko ba gbendeke amuyẹ to yẹ ki rọba idaabobo n ni.
Lasiko to gbe awọn orin Pata ni Logo Benz jade, ọpọ eeeyan lo bu ẹnu atẹ lu u pe orin rẹ lo fa bi awọn kan ṣe bẹrẹ si ni ji pata obinrin lati fi ṣe aajo owo.
Ṣebí ìwọ ati ìdílé baba rẹ ni.
Wọn ṣi ile itura lorilẹ-ede Palau lọdun 1982 ki irin-ajọ igbafẹ to fẹsẹ rinlẹ, ṣugbọn lati igba naa, ọrọ-aje Palau ti gberasọ.
Tani fikun pe, lẹyin ti oun ba de lati ile iwe, ti oun si jẹun tan, to ba di aago meje, ni oun yoo ta ayo Chess fun wakati mẹta.
Mò ń sọ fún àwọn tí kò ì tíì gbeyawo ati fún àwọn opó pé ó dára fún wọn láti dá wà, bí mo ti wà.
Orisun: Banki Agbaye, (Ọrọ aje orilẹede), Dọla, ọdun 2017 Orilẹede wo ni ẹyawo rẹ nilẹ okeere kere julọ?
wọn ní ọjọ ́ tí a ò bá dá ni kì í pé .
Abẹwo Buhari si Taraba 'Gba Buhari ni'mọran ifẹyinti' Gẹgẹbii atẹjade kan to jẹyọ lati ileesẹ ọrọ okeere lorilẹede Naijiria se sọ, igbesẹ ati wọgile irinajo lati buwọlu adehun naa ko sẹyin bi aarẹ Buhari se n fẹ ki awọn alẹnulọrọ atawọn too niise pẹlu eto ọrọ aje, karakata ati ẹka miran lati da si ọrọ naa nitori aa pe gbọn ni.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Coronavirus updates and palliative: Gomina Dapo Abiodun ti APC kéde àdínkù owó orí nípinlẹ̀ Ogun 29 Agẹmo 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 9 Ògún 2020 Oríṣun àwòrán, others Gomina Dapo Abiodun to n tukọ ipinlẹ Ogun labẹ akoso ẹgbẹ oṣelu APC ti kede ẹdinku si awọn owo orí kan nibẹ.
Ọga ọkọ BRT ni awọn si n ri wi pe awọn ero wọ ibomu wọn, lo sanitisa sọwọ, bakan naa lawọn n yẹ ara wọn wo bo ya o gbona tabi ko gbona lati le mọ bo ya wọn ni covid-19.
ero ibanisoro Tecno k7 dudu kan.
Àjẹsára rotavirus jẹ ́ àjẹsára tí a fi ń dáàbò bo ara ẹni lọ ́ wọ ́ àkóràn kòkòrò àìlèfojúrí afàìsàn kan tí à ń pè ní rotavirus .
Lẹyin ti Everton pokọ iya fun Manchester United ni papa isẹre Goodison Park tan ni Crystal Palace ki Arsenal mọ lẹ nile wọn ti wọn si ki bẹndẹ siwọn ninu.
Pupọ ninu wọn lo n dije lati inu ẹgbẹ oṣelu Democrat, wọn si n du ipo ninu ijọba apapọ, ipinlẹ, ati ni agbegbe.
2 bílíọnù fi tún wáyà iná àti inú ilé Aso Rock ṣe- Buhari Oríṣun àwòrán, @Abujang Aarẹ Buhari ti gbe eto iṣuna ọdun 2021 lọ siwaju ile igbimọ asofin mejeeji ni Abuja.
Ẹ jọ̀ọ́, ẹ má jẹ́ kí ikú ọmọ mi lọ lásán - Ìyá Tiamiyu tí ọlọ́páà pa Wọ́n ti sin òkú Kazeem Tiamiyu tí wọ́n sọ pé SARS pa ní Sagamu ''Kazeem ṣèlérí pé oun máa mú mi lọ ìlú òyìnbó k'àwọn SARS tó pá á'' Bí èsì ìdìbò gómìnà ìpínlẹ̀ Ondo se ń jáde rèé.
Ewe, Hiddink soro ohun di mimo pe, afojusun re bayii ni lati ri daju pe iko naa pegede fun idije Olymipiki lọdun 2020.
Awọn akọsilẹ yii ko jẹ ki Biden o ba ẹgbẹ oṣelu Democrat ti ode oni mu.
Wọn kò ní ìmọ̀ tabi òye,wọ́n ń rìn kiri ninu òkùnkùn,títí gbogbo ìpìlẹ̀ ayé fi mì tìtì.
” “Won da igbimo ohun sile lati mu iyipada otun de ba eto irnna, pipese awon ohun elo ti o muna doko yala lati owo ijoba apapo lagbaye, ile-ise aladani abbl lojuna lati dena awon ijamba oju opopona.
Gẹgẹ bi iroyin ṣe fi idi rẹ mulẹ, lẹta ti wọn fi pe e pada sẹnu iṣẹ ni wọn fi ṣ'ọwọ si Minisita fọrọ ilera lọjọ isẹgun, ti Adewọle si sọ fun awọn oniroyin wipe, lootọ ni ohun gba lẹta lati da ọgbẹni Yusuf pada s'ẹnu iṣẹ.
Ṣugbọn nisinsinyii mò ń lọ sọ́dọ̀ ẹni tí ó rán mi níṣẹ́.
Atamatase agbaboolu owo eyin iko Super Eagles, Leon Balogun so pe, o je ohun iwuri pe awon akegbe oun ko ni ifarapa kankan saaju idije agbaye to n bo lona.
Kini ''Zoning'' ni se pẹlu ọrọ to wa nilẹ yi.
olopaa ni ekun rẹ, lati se ise won lona ti won ko fi ni tabuku ba ile-ise
bí gbogbo ìjọ eniyan Israẹli bá ṣẹ̀, láìmọ̀, wọn óo fi ọ̀dọ́ akọ mààlúù kan rú ẹbọ sísun, olóòórùn dídùn sí OLUWA, pẹlu ẹbọ ohun jíjẹ ati ẹbọ ohun mímu, ati òbúkọ kan fún ẹbọ ìmúkúrò ẹ̀ṣẹ̀ gẹ́gẹ́ bí ìlànà.
 olóde àti Àjànà darapọ ̀ wọ ́ n tẹ ibi tí à ń pè ní Ìta ajànà dó , èyí sì wà ni ìlú Ìjẹ ̀ bú-Òde títí di òní yìí .
Labẹ ofin idibo ile,idibo bonkẹlẹ alafihan(open secret ballot) ni iwe ofin la kalẹ.
Fọwọ́ kan obìnrin lọ́nà àìtọ́, kí o rẹ́wọ̀n ọdún mẹ́rìnlá he- Àwọn aṣòfin yarí Mi ò tíì gba ìwé ìfitónilétí pé wọ́n fẹ́ yọ mí nípò igbákejì gómìnà ìpínlẹ̀ Ondo- Agboola Ajayi Ìpínlẹ̀ Eko kéde ọ̀nà àbáyọ sí súnkẹrẹ-fàkẹrẹ ọkọ̀ lásìkò àtúnṣe afárá Third Mainland Ọwọ́ ọlọ́pàá ìpínlẹ̀ Oyo tẹ àwọn afurasí lórí ìpànìyàn tó wáyé ní Akinyele Ó ṣeéṣe kí àrùn Coronavirus tànkálẹ̀ gba inú afẹ́fẹ́- WHO Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Nigerian Celebrities: Ẹ wo àwọn ìlúmọ̀ọ́ká olórin, òsèré tó ti sàtìmọ̀lé rí!
Ẹwẹ, Tolanibaj, Nengi ati Brighto lo sọ fun Big Brother pe Praise lawọn fẹ ri akẹyinsi rẹ ko maa lọ ile.
O ni niṣe loun maa n gbe ounjẹ lọ fawọn ọmọ oun nile awọn obi iya oun ti wọn wa pẹlu rẹ.
Anthony Joshua vs Andy Ruiz: Págà!
Eagles kun lojo isegun(Tuesday), iko ohun bere igbaradi won ti ipele kinni
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Nkan ti awọn eeyan nsọ lori BBC Yoruba Owe yoruba kan lo ni: Gele ko dun, bii ka mọọ we, ka mọọ we, ko dabi pe ko yẹni, ko tun wa yẹ ni ,ko dabi pe ko jẹ tẹni."
    Ẹ̀yin ọ̀rẹ́ mi, n kò lè sọ bí inú mi ti dùn tó nígbà tí iwin náà jíṣẹ́ báyìí fún mi, oúnjẹ tí mo jẹ yàtọ̀ lọjọ́ náà, ara mi sì yà ju bí ti ń yá rí lọ.
O ní nítori àwọn ìṣèlẹ̀ yìí ni ẹgbẹ́ ṣe fi orúkọ silẹ̀ ni àwọn ilé iṣẹ́ adójutofò kan láti le jẹ ki àwọn òsèré le maa fi tọ́rọ́kọ́bọ̀ wọ́n síbẹ̀ titi di ọjọ́ ogbó ti wọn kò ni le ṣe iṣẹ́ mọ.
Ìfipábọ́mọlòò Kaduna: Ọlọ́ọ̀pá m'áwọn tó ń fipá bá èèyàn 500 àtàwọn ọmọdékùnrin lò pọ̀
Igbesẹ ati gba iwe ẹri pada lọwọ awọn oludije naa ko ṣẹyin aṣẹ ile ẹjọ.
Nnkan ko tii fi bẹẹ ṣe ẹnure fun Zidane lati igba ti o ti pada de lẹẹkeji gẹgẹ bii olukọni fun Real Madrid.
Ṣé mo ní ìyẹ̀fun tabi ọtí waini ni?
OLUWA bá dá Mose lóhùn pé, 
Jakọbu, baba ńlá wọn di arakunrin rẹ̀ ní gìgísẹ̀ mú ninu oyún, nígbà tí ó dàgbà tán, ó bá Ọlọrun wọ̀jàkadì.
Wole Soyinka: Ohun ìtìjú ni fún Naijiria bíí ìjọba se ti Sowore mólé
”Ó bá yọ àwọn fèrèsé sí i lẹ́gbẹ̀ẹ́.
Ọmọ Yahoo fẹ́ pa ìyá rẹ̀ ṣ'owó l'Eko Wọn ó sin ni Elebu, Ibadan láàrọ òní nílànà ẹ̀sìn Musulumi, Oyerinde dí alága ẹgbẹ́ awakọ ní 2011, ó bẹ̀rẹ̀ iṣẹ́ kọ̀ndọ́ bọ́ọ̀sì ní ọdún 1975, ó gba ìwé ọkọ ìrìnà ní 1979 nígbà to dí ọmọ ẹgbk tó fẹsẹ̀ rinlẹ̀ láti 'ọdun 1983 titi tó fi kú.
Eyi to wa jẹ oyin ninu rẹ ni igba ti wọn pin kaadi idamọ fun wa gẹgẹ bii osisẹ ileesẹ BBC, eyi lo wa fi idi rẹ mulẹ nitootọ pe osisẹ BBC ni wa.
Mo ré àwọn tí wọ́n jókòó lórí ìtẹ́ bọ́ sílẹ̀ bí alágbára ọkunrin.
”Ologbondiyan  tun so pe egbe PDP ni gbogbo awọn ibi ti wọn ti dibo fun un lọwọ, paapaa julo nibi ti egbe PDP ti ni ibo ju egbe APC lọ.
NURTW: Yasin ní àbẹ̀wò òun sí Makinde dá lórí ọ̀rọ̀ ẹgbẹ́ awakọ̀ èrò tó fòfin dè
Ọmọ mi, di ọgbọ́n tí ó yè kooro ati làákàyè mú,má sì ṣe jẹ́ kí wọn bọ́ kúrò lọ́wọ́ rẹ,
ipade naa siwaju lati lee se awon atunse miiran.
Nitori naa ere ati jawe olubori ni wọn sa wọ ifẹsẹwọnsẹ naa.
Ti iru isẹlẹ naa ba si waye fun ọmọ tuntun meji tabi mẹta, eyi le mu ki awọn agbẹbi gbe awọn ọmọ yii fun iya to ba wu wọn, ti iyawo yoo si gbe ọmọ ọlọmọ wale fun ọkọ rẹ laimọ.
Ipinlẹ Eko yan awọn aṣoju ti yoo dupo senetọ ni Abuja Àkọlé àwòrán, Bayo Oshinowo ní ìbò 247,743 nigba t Gbenga Ashafa ní ìbò 20,385 Alatako rẹ Bayo Oshinowo ní ìbò 247,743 nigba ti Ashafa ni ibo 20,385.
Dafidi bá sọ fún Ọlọrun pé, “Ṣebí èmi ni mo pàṣẹ pé kí wọ́n lọ ka àwọn eniyan?
”aare tun tesiwaju pe, pelu ifokansin, ko si ohun to soro se.
Ọgbọ́n ẹ̀tàn ni àwọn ọmọ Jakọbu fi dá Ṣekemu ati Hamori, baba rẹ̀ lóhùn, nítorí bíbà tí ó ba Dina, arabinrin wọn jẹ́.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ìdí tí mo fi pa irọ́ ìgbéyàwó lórí Facebook ‘Alẹ́ làwọn ọkùnrin fẹ́ bá mi jáde, torí mo kọ ilà’ Kí lo fẹ́ mọ̀ nípa D.
Ó dá wọn lóhùn pé, “Ta ni ìyá mi ati arakunrin mi?
omo bibi orile ede Kenya ni.
Tinubu lo fi ọrọ naa lede ninu atejade kan loju opo Twitter rẹ.
Oríṣun àwòrán, @raufaregbesola 2) Obitibiti Gbese: Ọpọ eeyan ati awọn ọmọ ẹgbẹ oselu alatako, to fi mọ awọn osisẹ ijọba ipinlẹ Ọsun lo n mu igbe bọnu lọpọ igba pe Rauf Arẹgbẹsọla jẹ gbese to pọ.
Fun awọn ọkunrin to ba ma n se e, o ṣe e ṣe ko bẹrẹ sini nira fun wọn lati pẹ lori ibalopọ pẹlu obinrin.
HAITI - Agbegbe Caribbean ni ilu yii wa.
Ẹni tí ó bá gbẹ́ kòtò, ni yóo já sinu rẹ̀, ẹni tí ó bá sì ń yí òkúta ni òkúta yóo pada yí lù.
( 2 ) Èdè nílò kíkọ ́ ọ fún ìgbà pípẹ ́ díẹ ̀ kí ènìyàn tó le sọ ọ ́ .
Peteru bá bi í pé, “Kí ló dé tí ẹ jọ fi ohùn ṣọ̀kan láti dán Ẹ̀mí Oluwa wò?
 “Ni bayii asiko ti to lati daabobo ara wa, lati odo ara eni titi de agbegbe, latari ati dekun iseku pani ati biba dukia je ni ekun Ambazonia”.
Lẹ́yìn náà, Solomoni ọba sọ fún Abiatari alufaa, pé, “Wá pada lọ sí orí ilẹ̀ rẹ ní Anatoti, pípa ni ó yẹ kí n pa ọ́, ṣugbọn n kò ní pa ọ́ nisinsinyii, nítorí pé ìwọ ni o jẹ́ alákòóso fún gbígbé Àpótí Ẹ̀rí káàkiri nígbà tí o wà pẹlu Dafidi, baba mi, o sì bá baba mi pín ninu gbogbo ìṣòro rẹ̀.
Ní ọjọ́ keji, Paulu mú àwọn ọkunrin náà, ó ṣe ètò láti wẹ ẹ̀jẹ́ wọn kúrò, ati tirẹ̀ pẹlu.
Nígbà tí oòrùn ń wọ̀ lọ, oorun bẹ̀rẹ̀ sí kun Abramu, ó sì sun àsùnwọra, jìnnìjìnnì mú un, òkùnkùn biribiri sì bò ó mọ́lẹ̀.
h jẹ ́ odidi láàárín 0-11 .
Ọgbẹni Yinka sọ fun BBC Yoruba pe aṣọgba ile naa lo fidi rẹ mulẹ fun awọn to jẹ ki wọn mọ pe lati orilẹede Cameroon ni ọga oun to jẹ ara ilẹ India ti ru Kinihun yii wọle wa si Naijiria.
Màrìwò ọ̀pẹ ni Ìnàkí-ìbẹ̀rù sán mọ́ ìdí.
1 Agẹmo 2019 Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Èèyàn mi mẹ́ta ló wà nínú ọkọ̀ ojú omi tó dà nù!
8 55135 Orilẹede Kyrgyzstan 1381 21.
Wọ́n sì gbé àgọ́ àjọ náà tọ Mose wá, àgọ́ náà ati gbogbo àwọn ohun èlò inú rẹ̀, àwọn ìkọ́ rẹ̀, àwọn àkànpọ̀ igi inú rẹ̀, àwọn igi ìdábùú inú rẹ̀, àwọn òpó rẹ̀, ati àwọn ìtẹ́lẹ̀ wọn; 
 Ó jẹ ́ onímọ ̀ -ẹ ̀ rọ àti onímọ ̀ nípa ìwọ ̀ n epo àti afẹ ́ fẹ ́ gáàsì ( fluid and gas metering ) .
Fọ́nran náà sàfihàn Gomes nibi to ti n ṣi ojú egbò rẹ̀ nínú ìjọ T.
Iya Oṣumare rọ ijọba lati gbe owo to to owo kalẹ si ẹka fiimu ṣiṣe ko ma baa parun.
Obinrin tí kò bá lọ́kọ tabi obinrin tí ó bá jẹ́ wundia yóo máa páyà nípa nǹkan ti Oluwa, yóo máa wá ọ̀nà tí yóo fi ya ara ati ọkàn rẹ̀ sọ́tọ̀ fún Oluwa.
Umahi to tun je alaga egbe awon gomina ni
Ìjọ eniyan náà bá rán ẹgbaafa (12,000) ninu àwọn jagunjagun wọn tí wọ́n gbójú jùlọ, wọ́n sì fún wọn láṣẹ pé, “Ẹ lọ fi idà pa gbogbo àwọn tí ń gbé Jabeṣi Gileadi ati obinrin wọn, ati àwọn ọmọ wẹ́wẹ́ wọn.
Àkọlé àwòrán, Abeokuta, Ogun Ati ni ipinlẹ Oyo, awọn ologun ko kẹrẹ rara.
Koda, ajọ iṣokan orilẹde agbaye, UN, ti sọ pe ajakalẹ arun kan ni ki obinmrin maa ni idojukọ ninu igbeyawo wọn, papa pẹlu ọkọ oniwa ipa.
OLUWA ní: “Ìwọ ọmọ eniyan, mú bulọọku kan kí o gbé e ka iwájú rẹ, kí o sì ya àwòrán ìlú Jerusalẹmu sórí rẹ̀.
Ọjọ́ kejì ni a sì tún múra ọ̀nà Òlè Ìrònù.
Ẹfunsetan Aniwura, obìnrin tó ju ọkùnrin lọ Ọjọ̀gbọ́n Mahmood Yakubu, alága INEC náà ti kédé pé, àwọn yóò ṣe ìpàdé pọ̀ pẹ̀lú ẹgbẹ́ ASUU.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Domestic Violence: Obìnrin kan wọ gàù lẹ́yìn tó kan ìṣó mọ́ ọmọ ọ̀dọ̀ rẹ̀ lórí ní Enugu 4 Agẹmo 2020 Oríṣun àwòrán, Wacol Àkọlé àwòrán, Nwata e kpọrọ ntu n'isi Ijọba ipinlẹ Enugu ti sọ pe oun ti bẹrẹ iwadii lori obinrin kan ti wọn fẹsun kan pe o kan iṣo mọ ọmọ ọdọ rẹ lori.
Labour Congress NLC, Trade Union Congress of Nigeria (TUC) ati  United Labour Congress (ULC)  ni  awon ko ni faramo ẹgbẹrun
A ṣe tán láti yọ ìjìyà ikú kúrò nínú àbá ọ̀rọ̀ ìkórìra- Sẹ́nẹ́tọ̀ Sabi Ki lo ti kọkọ ṣẹlẹ?
Nínú ìdíje ọjọ́ Àbámẹ́ta, Bernardo Silva gbá bọ́ọ̀lù mẹ́ta sí àwọ̀n nígbà tí àwọn ọmọ Pep Guardiola fárígá pẹ̀lú gbígbá bọ́ọ̀lù s'áwọ̀n tí wọ́n sì rí góòlù tó pọ̀ jù láti ìgbà tí olùkọ́ni náà ti darapọ̀ mọ́ ẹgbẹ́ náà ní ọdún 2016.
Oríṣun àwòrán, @NGRSenate Àkọlé àwòrán, Awọn ileesẹ ti ko se ayẹwo iwe owo wọn ko lee ni ipin ninu isuna ọdun 2018 Kini ohun ti awọn aṣofin agba sọ?
“Atarotu ati Diboni ati Jaseri ati Nimra ati Heṣiboni ati Eleale ati Sebamu ati Nebo ati Beoni, 
Aare orile-ede Naijiria,  Muhammadu Buhari ti kede ipo, ojuse ati
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Fi owo osu rẹ we ajẹmọnu Sẹnatọ re Ero ara ilu lori owo awọn sẹnatọ Naijiria EFCC kéde pé ilé ẹjọ́ ni yóò yanjú ẹ̀ Loju opo itakun agbaye, awọn eeyan ti bẹrẹ si ni so èrò ọkan wọn lai fepo-bọyọ.
Nítorí pé lẹ́yìn tí mo ṣáko lọ, mo ronupiwada;lẹ́yìn tí o kọ́ mi lọ́gbọ́n, ń ṣe ni mo káwọ́ lérí.
Ní tiyín, ẹ gbèrò ibi sí mi, ṣugbọn Ọlọrun yí i pada sí rere, kí ó lè dá ẹ̀mí ọpọlọpọ eniyan tí wọ́n wà láàyè lónìí sí.
Tìlù tìfọn ní Ọṣun fi kí Buhari káàbọ̀ l'Óṣogbo
kí ó sọ fún Aaroni ati àwọn ọmọ rẹ̀ ọkunrin, ati gbogbo àwọn eniyan Israẹli pé: “Nígbà tí ẹnìkan ninu àwọn eniyan Israẹli tabi àlejò tí ó wà láàrin wọn bá mú ohun ìrúbọ rẹ̀ wá, kì báà ṣe pé láti fi san ẹ̀jẹ́ kan ni, tabi gẹ́gẹ́ bí ọrẹ àtinúwá, láti fi rú ẹbọ sísun sí OLUWA, 
Eni keji jẹ ẹni ọdun mọkandinlaadọrin.
Ìpín Jakọbu kò rí bí àwọn wọnyi,nítorí òun ló dá ohun gbogbo,Israẹli sì ni ẹ̀yà tí ó yàn, gẹ́gẹ́ bí ìní rẹ̀;OLUWA àwọn ọmọ ogun ni orúkọ rẹ̀.
tuntun yii yoo tun tẹpẹlẹ mọ eto aabo, atunse oro aje ati gbigbogun ti iwa ibajẹ.
Ẹfunsetan Aniwura, obìnrin tó ju ọkùnrin lọ Ẹfunroye Tinubu - Ògbóǹtagí oníṣòwò, olówò ẹrú àti afọbajẹ Awọn yoku, bii 'Iwin' oloselu to maa n sori kunkun si awọn ẹgbẹ imulẹ taa mọ si mafia, to fi de ori awọn agbabọọlu ti wọn n dẹyẹ si tori pe wọn jẹ obinrin, gbogbo wọn lo n lo iriri wọn lati la ọnafun awọn to n bọ lẹyin.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Onnoghen: CCT ní Onnoghen kò gbọdọ̀ di ipò ìlú mú fún ọdún mẹ́wà 18 Ìgbé 2019 Oríṣun àwòrán, Nigeria Bar association Àkọlé àwòrán, Adajọ agba Onnoghen ni oun ko jẹbi Igbimọ to n gbọ ẹsun to ni i ṣe pẹlu ihuwasi lawujọ, CCT ti sọ pe, lootọ ni adajọ agba Naijiria nigba kan, Walter Onnoghen, jẹbi ẹsun ṣiṣe mago-mago ninu dukia rẹ to kede.
Nígbà tí Ahabu ti fẹnu kan “Arakunrin”, kíá ni wọ́n ti gba ọ̀rọ̀ yìí mọ́ ọn lẹ́nu, wọ́n ní, “Bẹ́ẹ̀ ni, arakunrin rẹ ni Benhadadi.
Aare Buhari so fun awon alakoso ijoba ibile ohun pata-pata pe, isakoso isejoba
Wọ́n ní ilé làá kọ́kọ́ wò.
Ọlọpaa sọ pe Umar lo dari ikọ to ṣe ikọlu si Nyanya ati Kuje ni Abuja ni ọdun 2015 ninu eyi ti ado oloro ti pa eniyan mọkanlelogun.
Ọgbẹni Bolaji tun ṣalaye pe ilana ẹsin Islam ni wọn yoo fi sin Ajimọbi ti wọn yoo si ki irun ikẹyin sii lara ni Mọṣalaṣi rẹ ni Oke Ado.
Kò ní sí ààbò mọ́ fún àwọn olùṣọ́-aguntan, kò ní sí ọ̀nà ati sá àsálà fún àwọn oluwa àwọn agbo ẹran.
WrestleMania 35: Kingston fẹnu ọmọ Amẹrika gbo lẹ̀ láti gbàmì ẹ̀yẹ
faa ti ile-iwosan naa se dẹnu kọlẹ .
Bẹ́ẹ̀ sì ni, ní tèmi, nígbà tí wọn ń ṣàìsàn,aṣọ ọ̀fọ̀ ni mo wọ̀;mo fi ààwẹ̀ jẹ ara mi níyà;mo gbadura pẹlu ìtẹríba patapata,
 orkney ni muir ti ṣe kékeré .
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Àjọ INEC ní mílíọ̀nù méje ni káàdì ti awọ̀n eeyan ko tii wa gba atipe INEC, ileeṣẹ́ ìbánisọ̀rọ̀ yóò ṣiṣẹ́ pọ̀ lórí Káàdì ìbò Àjọ elétò ìdìbò lórílẹ̀-èdè Nàìjíríà, INEC, yóò fọwọ́sowọ́pọ̀ pẹ̀lú àwọn iléeṣẹ́ ìbánisọ̀rọ̀ alágbèéká lórí ọ̀rọ̀ ìpèníjà àìwá gba káàdì ìdìbò àwọn olùdìbò.
"FUTA pàṣẹ lọ rọọ́kún nílé f'ákẹ́ẹ̀kọ́ méje tó lu akẹgbẹ́ wọ́n Àráàlú yarí fún fásitì Babcock fún bo ṣe lé akẹ́kọ̀ọ́ tí wọn bá lòpọ̀ nínú fídíò ""Ìfipábánilòpọ̀ tó ń gogò láwùjọ, ẹ̀yin aráàlú ló ń fàá"" Iṣẹlẹ naa waye lọjọ kẹrindinlogun oṣu Kọkanla ọdun 2019."
Ijọba apapọ ti sọ pe ko tii si iranlọwọ kankan fun awọn ọmọ Naijiria ti wọn n bọ lati South Afrika lọjọ ru.
Ajọ INEC sọ eyi lasiko ti wọn fi oye aṣoju ajọ naa da Yinka Ayefele lọla láti ẹnu igbakeji ẹka to n risi idanilẹkọ lori kaadi idibo, Abilekọ Lakunuya Dorothy Bello ni olu ilu Naijiria, Abuja.
Wolves bu Arsenal jẹ bí ajá Man Utd Vs Man City: Ọ̀rẹ́ dì ọtá, ọtá dì ọ̀rẹ́ torí ife ẹ̀yẹ Ìgbáju ìgbámú ni Leiscester city ǹko fún Arsenal, eyí ti ó si ń ṣe ọkàn láàrẹ pe sé ìrètí Arsenal ó ti ré bọ sinu omi báyìí?
Oríṣun àwòrán, Nigeria Bar association Àkọlé àwòrán, Adajọ agba Onnoghen ni oun ko jẹbi Adajọ agba orilẹ-ede Naijiria, Walter Onnoghen ti sọ pe oun ko jẹbi awọn ẹsun ti wọn ka si oun lẹsẹ lori kikede dukia rẹ.
Buhari búra láti bọwọ fún ofin Naijiria ni saa keji rẹ.
Ó pe ọ̀gágun, ó bèèrè bí Jesu ti kú tipẹ́.
 agbara iseoba wa lowo ijoba .
lati mọ ohun ti o fa ijamba ina afefe gaasi ohun ni ijoba ibile Oyibo ni ipinle
Oríṣun àwòrán, @google SWAT ni orúkọ tuntun ti SARS yóò máa jẹ́- IGP Adamu Ileeṣẹ ọlọpaa Naijira ti ni ki awọn oṣiṣẹ SARS ti wọn tuka yọju si Abuja lati wa ṣe ayẹwo ọpọlọ ṣaaju ki wọn to pin wọn si ẹka ileeṣẹ ọlọpaa mii.
mo mú wọn wá sinu ilé OLUWA.
Itàn yi lè nipá lóri irú iwà ti èniyàn yio hu si ẹni ti a bá pàdé.
Igboho, lásìkò to ń takurọsọ pẹ̀lú àwọn akoroyin kan lórí ìṣẹ̀lẹ̀ náà, rawọ ẹ̀bẹ̀ sáwọn agbofinro nipinlẹ Oyo, láti ṣíṣẹ kára, fi doola ẹ̀mí àwọn ọmọdé méjèèjì náà lọ́wọ́ ewu.
Olè gbé òrùka ìgbéyàwó mì ní Eko Agolo akẹ́rù Apapa kò pa ènìyàn ṣùgbọ́n ó ba ọ̀pọ̀ ọkọ̀ jẹ́- Ọ̀ga RRS Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ladoja Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
O ni ijọba ko ni da ọrọ naa dawọn ọlọpaa papaa julọ lori bi awọn janduku kan tun ti dana sun agọ ọlọpaa marun un.
Ẹ kọrin sí i, ẹ kọ orin ìyìn sí i,ẹ sọ nípa gbogbo iṣẹ́ ribiribi rẹ̀.
'Ọ̀fọ̀ ọkọ ló mú ìyàwó Ajimobi ṣe ohun tó ṣe sí mi, ṣùgbọ́n n kò bínú síi' Àgbáríjọ àwọn nọ́ọ̀sì fẹ́ gbé Olamide Baddo lọ sílé ẹjọ́ fún ìbanilórúkọjẹ́ Àbúrò mi ni Babatunde Fashola- Naira Marley Ìgbẹ́jọ́ Naira Marley sún síwájú bí àwọn agbẹjọ́rò ṣe ń jà sí àga ìjókòó Wo àwọn ìṣẹ̀lẹ̀ tó mú Naira Marley di òrìṣà àkúnlẹ̀bọ ní 2019 Kí ló dé tí Ilé ẹjọ́ sún ìgbẹ́jọ́ Naira Marley sí ọ̀la?
Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Coronavirus Ghana: Ààrẹ Nana Akufo-Addo ti wọ́lé ìyàsọ́tọ̀ ọlọ́jọ́ mẹ́rìnlá6 Agẹmo 2020 Ìsẹ̀lẹ̀ Ghana: Òògùn ẹ̀fọn pa ìbejì àti ẹ̀gbọ́n wọn24 Ìgbé 2018 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Garba Shehu tun tesiwaju pe “ Aare Buhari ti  se gudu, gudu meje yaya mefa lati je  ki okiki orile ede Naijiria tun tan kale ni
Cameroon ti ba aare orile ede Naijiria Muhammadu Buhari yọ ayọ pe o jawe
Skala wee tilẹ ni bi babalawo naa ba ni agbẹjọro to munadoko, kia ni yoo jaja bọ lọwọ EFCC.
Ni ọjọ Aiku ni Gomina ipinlẹ Ondo, Rotimi Akeredolu kede faye pe ọkan lara awọn afunrasi ọdaran ti wọn n pe lẹjọ lori iku ọmọbiinrin aṣiwaju ẹgbẹ Afẹnifẹre, .
Kiri Heresi tíí ṣe olú-ìlú wọn nìkan ni wọn kò pa run, ṣugbọn àwọn tí wọn ń ta kànnàkànnà yí i ká, wọ́n sì ṣẹgun rẹ̀.
O gba oyè nínú ààto ilú àti ètò bí aye se rí (Geography and Regional Planning) ní fásìti Eko, 1989 si 1995 sùgbọ́n ó ni ìdáduro ọdún meji nítori ìwà nítori ìwá Aluta.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ìwádìí ìwé ẹ̀rí àwọn olùdíje Ààrẹ lọ́dún 2019 Fayoṣe ti gba ìtúsílẹ̀ kúrò l'ẹ́wọ̀n Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, #Adetutu Alabi OJ: Mo ti gba kámú lórí ilà ojú mi Ewu wo lo wa ninu ki iroyin to wa lori oju-opo ayelujara ti pẹ?
Awọn kan sọ pe wọn fi asiko ti ọgbẹlẹ maa n waye fi sọri oṣu yi.
 oriṣiriṣi ẹ ̀ yá àjẹsára yìí lo ń ṣiṣé fún díẹ ̀ nínú tàbí gbogbo oriṣi meningococcus : a , c , w135 àti y.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Mò ń fi lẹ̀kẹ̀ ya àwọnran láti jèrè ǹkan méjì - Olaniyi Olaniyan Afojusun wọn nidi sise eyi ni pe, wọn yoo lo ohun awọn eeyan yii lati wa eekanna mọ awọn asaaju orilẹede agbaye lọrun, nibayi ti wọn n gbaradi lati gbe ipinnu kalẹ lori agbekalẹ apo asunwọn ẹdawo kan, eyi ti yoo maa gbogun ti aisan AIDS, ikọ ife, ati aisan iba.
''A ko le ma darukọ owo gọboi pe a fẹ fi ṣe isẹ agbaṣe.
Wọn kò gbọdọ̀ fọwọ́ kan àwọn nǹkan mímọ́ náà, ẹnikẹ́ni tí ó bá fọwọ́ kàn án yóo kú.
"À ń fojú sọ́nà fún ìpadé ti yóò mú àbájade rere jade wá "" Ẹwẹ̀, ìkéde pé àwọn yóò kopa yìí wáye lọjọ́ Jimọ, lẹ́yìn ìpàdé INEC àti ASUU."
"Onibara mi sẹsẹ fi ọrọ naa to mi leti ni, a si ti n fẹ gbe igbesẹ to tọ sofin lori rẹ, bi a ba si fẹ gbe igbesẹ ofin, ko yẹ ki onibara sọ ọrọ kankan lori ayelujara lori rẹ.
Adinku ti wọn kede ọhun ni lati naira márùndínláàdọ́jọ (N145) lita kan si naira méjìlélógóje N142 tabi ogóje naira N140 Aarẹ ẹgbẹ naa Chindeu Okoronwo to ba ikọ BBC Pidgin sọrọ sọ pe onagba lati mu idagbasoke ba Naijiria ni awọn fi ṣe bẹẹ.
Gbogbo àwòrán ẹbi tí ó wà ara ògiri ni wọ́n da ojú wọn kọ ògiri.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Coffee Painter: Adebukola ní kò sí ìrànwọ́ lẹ́yìn ẹ̀kọ́ girama lòun ṣe ń ya àwòrán Tinubu ṣalaye pe akoko ko tii to fun oṣelu ọdun 2023, o rọ awọn ọmọ ẹgbẹ APC lati gbaruku ti Aarẹ Buhari ko le ṣe aṣeyọri ninu ijọba rẹ.
O wa ro awon omo orile ede Naijiria lati sin
Èmi pàápàá ti pàṣẹ fún àwọn tí mo yà sọ́tọ̀,mo ti pe àwọn akọni mi, tí mo fi ń yangàn,láti fi ibinu mi hàn.
Coronavirus: Ọmọ márùn ún ni mo ní, ṣùgbọ́n kò sí oúnjẹ fún wa lásìkò ìgbélé yìí -Olùgbé ìlú Eko Ọ̀rọ̀ Coronavirus kì ń ṣe ṣeréṣeré o-K1 de Ultimate, Toyin Abraham kìlọ̀ Wọ́n ti gbé olóòtú ìjọba ilẹ̀ Gẹẹsi, Boris Johnson lọ sí wọ́ọ̀dù àìsàn tó lágbára Iyatọ gedegbe yii n fara han lawọn agbegbe gbogbo ni ipinlẹ nibi ti awọn eeyan alawọ dudu ti n ko ida mọkanlelogoji ninu iku gbogbo to lọwọ arun coronavirus ninu, ti o si jẹ pe ida mẹrinla awọn eeyan to n gbe ni ipinlẹ Illinois lo jẹ alawọ dudu.
- BBC News Yorùbá BBC News, YorùbáFò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Lagos VIO - Ǹjẹ́ o mọ ìyàtọ̀ ojúṣe ọlọ́pàá, VIO, FRSC àti LASTMA lójú pópó?
'Orúkọ pásítọ̀ ni Magu fi ra ilé N573 mílíọ̀nù sì Dubai - PCARA Ọmọdé méjì àtàgbà kan ló kú nílé alájà mẹ́ta tó wó l'Eko pátápátá - LASEMA Kí ló mú Obasanjo ti ilẹ̀kùn mọ́ ẹbí, òṣìṣẹ́, ojúlùmọ̀ ní ibi òkú àna rẹ̀?
” Àwọn mìíràn ń sọ pé, “Rárá o, ó jọ ọ́ ni.
 Èdè wọn ni oi maa wọ ́ n sì múlé gbe samburu , kikuyu , kamba , chaga , meru abbl .
Àwọn ọkùnrin nṣe iṣẹ́ agbára bi iṣẹ́ ọdẹ, alágbẹ̀dẹ, àgbẹ̀ tàbi iṣẹ́ oko (iṣẹ́ fún ji jẹ àti mimu ẹbí).
Ẹgbọn rẹ, Ojo Ọladele sọ fun BBC pe 'ibi ariya ni aburo oun(Wọle) dagbere pe oun n lọ ni alẹ ọjọ Abamẹta, ko to di wi pe awọn ọlọpaa mu u.
Ẹ̀yin tí ẹ̀ ń gbé Lẹbanoni,tí ẹ kọ́ ilé yín sí ààrin igi kedari.
Ahabu wí fún Jehoṣafati pé, “Bí a ti ń lọ sí ojú ogun yìí, n óo paradà, kí ẹnikẹ́ni má baà dá mi mọ̀.
kí ó má baà rò ninu ara rẹ̀ pé òun ga ju àwọn arakunrin òun lọ, kí ó má baà yipada sí ọ̀tún tabi sí òsì kúrò ninu òfin OLUWA, kí òun ati àwọn ọmọ rẹ̀ lè pẹ́ lórí oyè ní Israẹli.
Ọjọ kọkandinlogun, oṣu Kẹsan, ati ọjọ kẹwa, oṣu Kẹwa, ọdun 2020, ni idibo mejeeji yoo waye.
Ìgbéraga ní ń ṣáájú ìparun,agídí ní ń ṣáájú ìṣubú.
 Gege bi oro re, yoo ni: oselu se koko, bee si ni, ki awon ara ilu mase kuna lati darapo mo oselu,”Oloogbe Fela ni ijoba oloogun fi opolopo igba ti mo inu ahamo lodun 1970 ati 1980, ti o fi mo lasiko isakoso ijoba aare Buhari.
Ẹ ronú, kí ẹ sì máa ṣe dáradára.
Nítorí pé, o óo lóyún, o óo sì bí ọmọkunrin kan.
 Onwoye idibo abẹlẹ ati onwoye lati ilẹ okeere.
Coronavirus: Ìjọba àpapọ̀ fi Austria, Sweden kún àwọn orílẹ̀èdè mẹ́tàlá tí kò lè wọ Nàìjíríà
Pẹ̀lú ìdádúró ìrànlẹ́wọ̀n, àwọn mẹ́tẹ̀ẹ̀ta ṣì wà lábẹ́ ìṣọ́:
 Eyi ni esi ti gbajugbaja oṣere Nollywood, Toyin Abraham fọ, lẹyin ti awọn ololufẹ rẹ kan bu ẹnu atẹ lu bo ṣe polowo sinima rẹ, Fate of Alakada."
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Dókítà t'ọ́mọ kú lọ́wọ́ rẹ̀ bọ́ nínú ẹjọ́ ní Leicester 13 Ògún 2018 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 14 Ògún 2018 Àkọlé àwòrán, Dokita Hadiza Bawa-Garba gba ìdájọ́ ẹ̀bí lórí ikú ọmọ ọdún mẹ́fa kan ni 2015 Ìdájọ́ padà fojúhàn lẹ́yìn ọ̀pọ̀lọ̀pọ̀ ọdún Dokita ọmọ orilẹ-ede Naijiria kan to wa ni ilẹ Gẹẹsi ni ile ẹjo ti dajo pe ko jẹbi iku ọmọ odun mefa kan ti wọn fẹsun kan an pe o ṣekupa.
Ọba jó àwọn ohun èlò náà níná lẹ́yìn odi ìlú, lẹ́bàá àfonífojì Kidironi, ó sì pàṣẹ pé kí wọ́n kó eérú wọn lọ sí Bẹtẹli.
" Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ijọba apapọ àti ileegbimọ asofin agba ti nṣisẹ lati dẹkun iba lassa Minisita feto ilera ni, ifowosowopo pelu awọn ipinlẹ gbogbo se pataki lati kawọ arun naa nilẹ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Super Falcons: Iṣẹ́ ẹmí ẹtan ló bàlemi lasiko tí mọ so aṣọtẹlẹ̀ pé wọn ó wọ ipele aṣekágbá.
 kò sì fún un lésì kan gúnmọ ́ nígbà náà .
 Fani-Kayode fi kun ọrọ rẹ pe, ko tọ ọ láti maa fi ọrọ oṣelu bo ìtàn mọ́lẹ̀, nitori pe o yẹ ki wọn o bu ọlá fun ẹni to tọ si."
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Wo bí Sunday Orimola ṣe gba ikú ẹranko kú ní Ifon ni Ondo lórí ọ̀nà àtijẹ Lẹyin ọdun kan ti iwadii fihan pe awọn soja naa pa iya ati ọmọ rẹ ni agbegbe Zelevet, ni Ariwa orilẹede Cameroon ni igbẹjọ naa bẹrẹ.
Ẹni to bori: Nigeria Cameroon vs Mali.
Agba fun Ọrọ Abẹle ni Ipinlẹ Eko, Ọmọwe AbdulHakeem Abdulateef, ti o tun jẹ Imam Agba
bí ó ṣe jẹ ́ wí pé a lè pe àkíyèsí alátẹnumọ ́ sí olùwà nínu gbólóhùn , bẹ ́ ẹ ̀ náà ni a lè ṣe ìyísódì fún un .
Ẹni to bori: Egypt Ìpele to ṣaaju eyi to kangun si aṣekagba Tanzania vs Côte d'Ivoire.
Ẹyan Asapejuwe ni o maa n sọ fun wa sii nipa ọrọ orukọ.
Ṣugbọn Abrahamu sọ fún un pé, ‘Bí wọn kò bá fetí sí ohun tí Mose ati àwọn wolii kọ, bí ẹni tí ó ti kú bá tilẹ̀ jí dìde tí ó lọ bá wọn, kò ní lè yí wọn lọ́kàn pada.
Yẹra fún ibinu; sì yàgò fún ìrúnú.
Ọ̀rẹ́ a máa fẹ́ni nígbà gbogbo,ṣugbọn a bí arakunrin láti dúró tini ní ìgbà ìpọ́njú.
O ni gbogbo iṣẹlẹ a n ra ibo lasiko idibo, kii ṣẹlẹ tẹlẹ ni Naijiria, oni bi wọn ba mọ itan ni, itan atijọ lo yẹ ki wọn fi yanju isoro oni.
Awọn iroyin kan lo ni, awọn eeyan kan to n lu jibiti, ti wọn n pe ni ọmọ Yahoo, lo n ji pata awọn obinrin lati fi se oogun owo.
Jesu wí fún un pé, “Lọ pe ọkọ rẹ wá ná.
Tí a fiṣọwọ́ ní 7:28 9 Sẹ́rẹ́ 20217:28 9 Sẹ́rẹ́ 2021 Nígbà wo ni ìsìnkú Orisabunmi yóò wáyé?
“Mo wí fún ọ, dìde, gbé ibùsùn rẹ, kí o máa lọ sí ilé rẹ.
'Ọna aye atijọ ni wọn gba lati gbẹbi iyawo mi nitori ko si ohun elo kankan lati lo.
Alukoro fun ileesẹ ọlọpaa nipinlẹ Ọsun, Folasade Odoro rọ awọn ara ilu ninu atẹjade kan wipe, ki wọn ye gbe ahesọ ti ko fẹsẹ mulẹ sori ayelujara nipa bi ọrọ aabo ipinlẹ naa ṣe ri.
Nítorí pé àwọn ọ̀tá mi ń sọ̀rọ̀ mi,àwọn tí ń lépa ẹ̀mí mi ti pàmọ̀ pọ̀,
Bí ó ti sọ báyìí, bẹ́ẹ̀ ni Anania Olórí Alufaa sọ fún àwọn tí ó dúró ti Paulu pé kí wọ́n gbá a lẹ́nu.
Ile-ejo to ga julo lorile ede Kenya so pe  iwa ti awon osise ijoba hu si Miguna-Miguna to
Makinde, nigba to n kopa lori akanse eto to n sami ọdun kan ijọba rẹ lori aleefa, ni ijọba oun ti pari apapọ iṣẹ akanṣe ojilenigba o din ẹyọ kan tijọba ana fi silẹ ni ẹka eto ẹkọ.
Iranṣẹ yín ni a jẹ́, nítorí ti Kristi.
Oríṣun àwòrán, @aishambuhari Àkọlé àwòrán, Aisha Buhari ní ìfẹ́ ìdájọ́ òdodo ti òun ní ló fàá tí òun fi ṣe bẹ́ Aisha ṣalaye ninu fidio naa pe ''aṣeyọri iṣakoso ọkọ oun ko ba pọ ju boṣe wa lọ, ṣugbọn awọn alagbara mejeeji yii ni igi wọ́rọ́kọ́ to n da ina a ru.
Awọn akẹkọ obinrin naa, yoo gbinyanju lati ta ‘app’ wọn fun awọn oludokowo ni Silicon Valley nilu California.
Tilu, torin ati oniruuru asọ alarambara ni awọn ibeji, ibẹta, awọn obi, aṣoju ijọba ati awọn eeyan ilu peju pesẹ silu Igboọra nipinlẹ Ọyọ lọjọ Abamẹta fun ayẹyẹ ọdun awọn ibeji.
Adajo agba nile ejo giga ohun, adajo P.
Lẹyin eyi ni esi kan jade pe Họnọrebu ọhun ni awọn nkan ti wọn ji ko nile oun ni oun fẹ pin fun awn araalu lọjọ ibi rẹ eyi to jẹ ọjọ kẹẹdọgbọn oṣu kẹwa ọdun 2020.
11 Ní fífihàn sí ayé pé àwọn ìwé mímọ́ jẹ́ òtítọ́, àti pé Ọlọ́run sì nmísí àwọn ènìyàn Ó sì npè wọ́n sí iṣẹ́ mímọ́ rẹ̀ ní àkókò yìí àti ní ìran yìí, bẹ́ẹ̀ gẹ́gẹ́ bíi ní àwọn ìran tí ìgbàanì;
Gbogbo ọdún tí Mahalaleli gbé láyé jẹ́ ẹẹdẹgbẹrun ọdún ó dín marun-un (895) kí ó tó kú.
Kunle Afolayan: Òun àti Mike Ezuruonye ń gbéná wojú ara wọn lórí ayélujára
Bi o tilẹ jẹ pe Olori Badrat ati Wasiu Ayinde sẹ pe ahesọ ọrọ lasan ni iroyin naa, ofuutu-fẹẹtẹ, aasa ti ko ni kaun si ni pẹlu.
Àmọ́ omi’gbóná lèyí jẹ́ lẹ́sẹ̀ ọmọ Oòduà onílé.
Àwọn Juu náà gbè é lẹ́sẹ̀; wọ́n ní bẹ́ẹ̀ ni gbogbo ọ̀rọ̀ tí ó sọ rí.
Ti iku kọ, bẹẹ ni kii ṣe ti arun, ṣugbọn o ṣee ṣe ki iji aawọ to n waye laarin igbakeji gomina ipinlẹ Kogi, Simon Achuba ati Ọga rẹ, iyẹn gomina Bello o gbe igbakeji gomina naa lọ.
Ní ọ̀la, ẹ kógun lọ bá wọn; wọn yóo gba ibi gẹ̀rẹ́gẹ̀rẹ́ òkè Sisi wá, ẹ óo rí wọn ní òpin àfonífojì ní apá ìlà oòrùn aṣálẹ̀ Jerueli.
Mo ṣetán láti kojú Andy Ruiz ni Saudi lọ́jọ́ Sátidé- Anthony Joshua Ọjọ nii pẹ, ipade kii jina.
Ileeṣẹ Northrich to jẹ ti Maina ni ọkọ to le ni aadọta ti wọn fi n sisẹ akẹrọ kaakiri, ti wọn si tun ni ile nla ni Dubai.
oun naa se n wonu oko ayokele re lọ.
Wọn ma nrin lọ si Rio Naranja nibi ti omi isẹleru kan wa eyi ti o nsan jade latara odo Muassi tii se orisun omi kan soso ti awon ara abule Muassi npọn.
Gomina Ajimobi wa tenumo pe :’’ki eyan padanu ibo ko so pe ki irufe olori bẹẹ
 Èdè lárúbááwá ( arabic ) ni èdè ìjọba ní ibẹ ̀ .
ataabo seyin ni o tun buru sii, nigba ti awon igbimo olubadan fi esun kan
Oríṣun àwòrán, AFP Pẹlu gbogbo awọn ọna ti atẹgun oró fi n de inu agọ ara ọmọ Naijiria yii, awọn onimọ ti ke si ijọba ki wọn gbe igbesẹ gboogi lati dẹku iku to n pa awọn ọmọ Naijiria lati awọn ọna wọnyii.
Ogunlọgọ awọn eeyan to ti de sibi ipolongo ibo naa ni wọn wọ asọ ẹgbẹjọda ti wọn tẹ́ẹ ami idamọ ẹgbẹ oselu PDP si lara.
ENDSARS, End SWAT: Ààrẹ Buhari ló pa àṣẹ tó mú kí iléeṣẹ́ ọlọ́pàá ó dá ikọ̀ SARS sílẹ̀, Fulani Kwajafa tó dá SARS sílẹ̀ ṣàlàyé
Bí Eko ati Abuja ṣe rí rèé lọ́jọ́ àkọ́kọ́ tí wọ́n dẹ ọwọ́ igbele Coronavirus Ìjọba àpapọ̀ ti jẹ Sowore ní ₦1m Coronavirus: Kíni àwọn àmì tuntun tó n fihàn?
Òmíràn nínú àwọn obìnrin ilé wa tí wọ́n ń ta ọjà lóde a wá síwájú mi wọ́n á kúnlẹ̀ wọ́n á tú gèlè wọn, wọ́n á máa fi orí balẹ̀ wọ́n á máa yẹ́ mi sí.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ọmọọba Harry yóò gbéyàwó rẹ̀ lọlé lónìí Gẹ̀ẹ́sì ń rọ́ kẹ̀kẹ̀ fùn ìgbéyàwó Ọmọọba Ìjàmbá bàálù gba ọ̀pọ̀ ẹ̀mi ní Cuba Ẹ maa foya, apeja orukọ ọmọọba Harry ni Henry Charles Albert David ti ilu Wales, ṣugbọn orukọ ti gbogbo wa mọọ si ni Ọmọọba Harry.
ṣugbọn kì í ṣe òun ni yóo kọ́ ilé náà, ọmọ bíbí inú rẹ̀ ni yóo kọ́ ilé fún òun.
Kódà ó kojú àwọn jàǹdùkú kan tó fẹ́ fi tipátipá bá obìnrin kan lòpọ̀.
Ìdásílẹ̀ẹ rẹ̀ nínú oṣù Ẹrẹ́nà kì í ṣe ìsààmì òpin ìgbà Alaa ní ẹ̀wọ̀n, ṣùgbọ́n ìṣíkúrò sí ipò tí ó jẹ́ àṣekágbá àtìmọ́lée rẹ̀.
Ọmọ ẹgbẹ ́ ni èdè yìí jẹ ́ fún ẹgbẹ ́ èdè tí a ń pè ní turkic .
A padà san owó ìtanràn fáwọn ajínigbé kí wọ́n to fi àwọn mẹ́tẹ̀ẹ̀ta sílẹ̀- Ẹbí N650,000 péré ni mò ń gbà gẹ́gẹ́ bíi owó oṣù -Gomina Ọyọ Ta ni Ọjọgbọn Adebanji Akintoye tó borí Tinubu láti di olórí àwọn Yoruba?
Manchester city kọ lẹ́tà ìyà, Arsenal ló tẹ́wọ́ gbàá ní Etihad Iya o to 'ya afada pakun, ikun salọ ada tun sọnu ni ọrọ jẹ fun ẹgbẹ agbabọọlu Arsenal laṣalẹ ọjọru nigba ti wọn pada sori papa ni itẹsiwaju idije liigi premiership ilẹ Gẹẹsi ti wọn so rọ fun nnkan bii ọgọrun ọjọ nitori ajakalẹ arun coronavirus lagbaye.
Lẹnu ọjọ mẹta yii si ni iroyin ti n lọ lori ayelujara ati laarin ilu pe ẹya Yoruba yoo ya kuro lara orilẹ-ede Naijiria to ba di ọjọ kinni, oṣu Kẹwaa, ọdun 2020.
O gba ami ẹyẹ agbabọọlu to pegede julọ ldun 2017 ni Premiership.
Oke-Osanyintolu ni awọn to farapa ninu iṣẹlẹ ọhun si n gba itọju lọwọ nile iwosan.
fifi ona aito ba awon omobinrin ile America lajosepo lati ori ero ayelujara ni
Oríṣun àwòrán, CHESTER ZOO Àkọlé àwòrán, Igbo Gashaka Gumti wà lara awọn diẹ to sẹku ninu awọn igbo ẹranko lorilẹede Naijiria Erọ ayaworan ọhun ri ọ̀pọ̀ awọn ẹranko méríìrí lagbegbe yii, bii ìnàkí.
Ó ṣe àfikún pé gbogbo nǹkan tí òun ń ṣe lórí eré ìtàgé kìí ṣe ìwà òun ni.
“ Eyi fi han pe eto idibo to waye ni irọwọ-irọsẹ jẹ wa logun, eyi ti a tun fi n ṣiṣẹ bayii lojuna ati ṣaṣeyọri ninu eto idibo tọdun 2019 yii.
Omotoso, lasiko to n ba BBC Yoruba sọrọ kede pe lẹyin agbekalẹ Neighbourhood Watch, lawọn ipinlẹ yoku bii Oyo, Ogun ati Ondo gbe abadofin Ametekun lọ si ile igbimọ aṣofin ipinlẹ wọn.
Jẹfuta bá dá wọn lóhùn, ó ní, “Nígbà kan tí ogun bẹ́ sílẹ̀ láàrin àwọn ará Amoni ati èmi pẹlu àwọn eniyan mi, tí mo ranṣẹ pè yín, ẹ kò gbà wá sílẹ̀ lọ́wọ́ wọn.
Nígbà tí mo rò pé, “Ẹsẹ̀ mi ti yọ̀,”OLUWA, ìfẹ́ rẹ tí kì í yẹ̀ ni ó gbé mi ró.
Hofini ati Finehasi, àwọn ọmọ Eli, ni alufaa OLUWA níbẹ̀.
Nítorí fún àtikọ́ wa lẹ́kọ̀ọ́ ni a ṣe kọ ohunkohun tí a ti kọ tẹ́lẹ̀, ìdí rẹ̀ ni pé kí ìgboyà ati ìwúrí tí Ìwé Mímọ́ ń fún wa lè fún wa ní ìrètí.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Restructuring: Obasanjo gbóṣùbà fáwọn gómìnà ilẹ̀ Yorùbá lórí àgbékalẹ̀ Amotekun 1 Ẹrẹ̀nà 2020 Oríṣun àwòrán, Olusegun Obasanjo Aarẹ ana ni Naijiria, Oloye Olusegun Obasanjo ti kesi awọn asaaju lati tete tẹti si igbe ọpọ ọmọ Naijiria to n pe fun eto atunto orilẹede yii, ko to di pe wọn n se amusẹ rẹ funra wọn.
Bí Dáúdà ṣe jẹ́ ọmọdé tó yìí, ata ni, kò ṣeé fi sí ojú.
Wọn ti wo ẹnu odi to wọ ilu mi, ninu eyi ti awọn ọkunrin to sangun bii ọọdunrun wa, amọ ogun naa ba wa lojiji, laarin wakati mẹrin, sn ti jẹ ilu Osogun run.
ipinnu aare Muhammadu Buhari lati fi Abike
Ṣugbọn Joṣua dá Rahabu aṣẹ́wó sí, ati ilé baba rẹ̀, ati gbogbo àwọn eniyan rẹ̀, wọ́n sì ń gbé ààrin àwọn ọmọ Israẹli títí di òní yìí; nítorí pé, Rahabu ni ó gbé àwọn amí tí Joṣua rán lọ wo ìlú Jẹriko pamọ́.
O yẹ ka kọgbọn pe, lọpọ igba ko yẹ ka maa fi inu wenu, paapa pẹlu awọn ajeji, ka maa baa jẹ iwọ.
Oríṣun àwòrán, lasema Ikọlu naa si lo fa ina to jo.
Ọwọ́ ọlọ́mọ tuntun ki kúrò ni omi nitori omi ni wọn fi nto àgbo ti wọn nrọ ọmọ fún ìtọ́jú ọmọ tuntun.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Association of Stingy Men: Akeugbagold ní àpẹẹrẹ wèrè díẹ̀díẹ̀ ni k'ẹ́ni tó lówó láhun sí obìnrin wákàtí 9 sẹ́yìn Oríṣun àwòrán, Twitter/ITS DON JAZZY AGAIN Ẹ lọ ṣọra yin o, gbogbo ẹyin ti ẹ n pe ara yin ni ẹgbẹ awọn ọkunrin alahun, Association of Stingy Men.
 agbènọ ́ mbàga tó wà lórí ayípadà kan nínú ọ ̀ rọ ̀ kan làúnpè ní ìyí ayípadà náà nínú ọ ̀ rọ ̀ náà , ìyí ọ ̀ rọ ̀ náà yíò jé àròpọ ̀ àwọn ìyí àwọn àyípadà nínú ọ ̀ rọ ̀ náà , bẹ ́ ẹ ̀ sìni ìyí onírúiyepúpọ ̀ kan yíó jẹ ́ ìyí ọ ̀ rọ ̀ tí ìyí rẹ ̀ bá tóbijùlọ .
Nítorí náà, OLUWA, Ọlọrun Israẹli sọ nípa àwọn tí ó fi ṣọ́ àwọn eniyan rẹ̀, láti máa bojútó wọn pé, “Ẹ ti tú àwọn aguntan mi ká, ẹ ti lé wọn dànù, ẹ kò sì tọ́jú wọn.
Akintola ni kò sí ìwúri kankan fáwọn olùkọ tí ó le mú kí wọn ṣe iṣẹ́ wọn dáradára.
Ẹwẹ, dokita Tunde ni awọn ounjẹ afunilẹjẹ kan wa to le jẹ ki irun hu daadaa.
Ẹ jẹ́ kí wọ́n bu omi wá kí ẹ fi ṣan ẹsẹ̀, kí ẹ sì sinmi díẹ̀ lábẹ́ igi níhìn-ín.
Awọn ọmọbirin naa sọnu lẹyin ti awọn afurasi ikọ ẹgbẹ Boko Haram lọ si ile-iwe wọn ni Ilu Dapchi ni ipinlẹ Yobe lọjọ kọkandilogun oṣu keji ọdun 2018.
51 bn Ajọ to n ri si idagbasoke agbegbe North East - N29.
“A gbodo pari ona yii, ki a si sii lodun yii.
Alaafin gbadura pé gbogbo ohun ti iran Yoruba n fẹ ni ọwọ wọn yoo tẹ.
Omi ń bọ́ lójú àwọn tí à ń ni lára,Kò sì sí ẹnìkan tí yóo tù wọ́n ninu.
"Wo àwọn ọmọ Naijiria mẹ́ta tó jáwé olúborí nínú ìdìbò sílé aṣòfin ilẹ̀ Amẹrika 'Èmi Oluwatoyin Abosede Aya Kolawole Ajeyemi ń sọ fún yín pé mo ti dé ""bus stop"" sinimá lọ́dún yìí' US Election 2020: Nígbà wo laó mọ èsì ìdìbò àti pé ṣé ó ṣeé figagbága?"
"Ninu ifọrọwanilẹnuwo kan to jade laipẹ, Reade sọ pe ""awọn to bimọ fun un ti n sọ ọpọlọpọ ọrọ buruku lori ayelujara."
akoko ninu odun yii yato si Bbilioni mefa Naira ti ile ise naa pa ni saa ka nnaa
Aare soro naa di mimo lakoko to n se agbekale ami eye (2018 Nigeria National Order of Merit Award, NNMA) fun ojogbon Olufemi nile ise aare lojoBo(Thursday), niluu Abuja.
Alabi Pasuma Ọ̀gáńlá pé ẹni ọdún 51 Aláàfin yẹ́ Lizzy Anjọrin sí níbi ayẹyẹ ìwúyè rẹ̀ Saheed Osupa dá sí ọ̀rọ̀ Barrymade àti K1 Ẹ wo ìfọ̀rọ̀wẹ́rọ̀ pẹ̀lú Saheed Osupa 'Ọmọ tó bá lanu gbàgà sọ̀rọ̀ sí àgbà, bàbá àti ìyá rẹ̀ ló ń bá wí' Baba Alatika be gbogbo olorin Fuji lati jebure ki won fowo wonu.
Ọba rán ọkunrin kan ṣáájú láti lọ pa á, ṣugbọn Eliṣa sọ fún àwọn alàgbà tí wọ́n wà lọ́dọ̀ rẹ̀ pé, “Wò ó, ọmọ apànìyàn yìí ti rán ẹnìkan láti wá pa mí, ọba fúnra rẹ̀ sì ń tẹ̀lé e bọ̀ lẹ́yìn.
5m ẹnì kọ̀ọ̀kan lọ́dún 19 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Oríṣun àwòrán, Mofe Bamuyiwa Bi ori ba pẹ titi nilẹ, yoo pada di ire ni, ori ẹni si ni gbe alawore ko ni.
’ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Bisi Alimi: Ìyà mi rò pé n kò leè ṣe ni àmọ́ n kò ní ìfẹ́ abo ni mo ṣe fẹ́ akọ ‘O yẹ ki igbe aye awọn ipinlẹ to n pese ohun alumọni epo rọbi dara ju bo se wa lọ, amọ awọn adari ipinlẹ naa n lo owo ilu basubasu nipa didari owo si ibi ti ko yẹ.
naa,nitori ọwọn gogo ounjẹ ati owo lasiko ogbon odun ti Bashir ti lo lori ijoba
ǹ bá yára lọ wá ibi ààbòkúrò lọ́wọ́ afẹ́fẹ́ líle ati ìjì.
Ìrẹ̀wẹ̀sì ń bá wa torí ìdánwò NECO tẹ ń ṣún síwájú lọ́pọ̀ ìgbà - Akẹ́kọ̀ọ́, ọ̀gá iléèwé Ọ̀rọ̀ ajé dẹnu kọ̀lẹ̀ yíká Nàíjíríà, àkẹ́kọ̀ọ́, olókoòwò àti òṣìṣẹ́ ọba jókòó sílé Ọlọ́pàá fi afẹ́fẹ́ gáàsì tú àwọn olùwọ̀de #EndSARS ká ní Abuja Oríṣun àwòrán, Getty Images Namibia Ni ọjó kẹjọ, oṣu kẹwaa, ọdun 2020, awọn eeyan orilẹede Namibia ya wọ oju popo gbogbo lolu ilu orilẹede naa, Windhoek.
Si se ounjẹ rẹ daada ko to o jẹ ni anfaani pupọ.
Orile ede mejeeji yii,ni yoo tun maa towobo iwe igbọra-ẹniye  (ibasepọ)lori  eto aabo  ati idagbasoke.
kefa , osu kefa, odun 2018 ni aare Muhammadu Buhari so pe lati odun 2019 lọ ni
rọ awon to n kẹkọọ gboye jade naa pe awon lo wa nipo lati  lee mu iyipada rere ba orile ede agbaye,
n óo mú wọn wá sí orí òkè mímọ́ mi,n óo jẹ́ kí inú wọn máa dùn ninu ilé adura mi.
 Ó wà ní agbèègbè gowad-e-arabān nítòsí Šāh Čerāq mosque .
Ṣugbọn Man City ji loju orun pada, ti Bernardo Silva si da ayo
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Royal baby: Harry ní ojú gbogbo yóò rí ọmọọba tuntun ní ọjọ́ méjì sásìkò yí 6 Èbibi 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Michelle Obama rọọ lati ṣe ohun gbogbo ni wọntunwọnsi Ọmọọba Harry ni oun ati iyawo oun, Meghan ṣi n ronu lori orukọ ti wọn yoo sọ ọmọ wọn tuntun.
Yinka Ayefele ṣe ìṣirò owó tí Dino ná ní ìsìnkú ìyá rẹ̀
O ni bi bi o tilẹ jẹpe ọrẹ ni oun ati gomina, amọ ko ni ifẹ awọn eniyan oun rara, nitorina ko ni ifẹ oun tikalara niyẹn.
"Ìbọn ọlọ́pàá ló pa èèyàn, ẹgbẹ́ wa kìí lo ìbọn - Shiite fárígá Dalung, Audu Ogbe, Shittu Adebayo àti Isaac Adewole kò wọlé Ìtàn tó rọ̀ mọ́ òwe ""Ẹni tí kò ṣe bíi aláàárù l‘Oyingbo."
 Èyí kò jọ pé o ń ran ènìyàn .
Ó ti ṣiṣẹ́ gẹ́gẹ́ bí akọ́ni àti olùgbé-lárúgẹ ìdásílẹ̀ àyè ọ̀tọ̀ fún àwọn ará ìlú àti àwọn àkànṣe eto ìgbóhùn sáfẹ́fẹ́ tí kò lọ́wọ́ ìjọ̀ba nínú.
Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí 6:18 Fídíò, Natalia Mufutau ìyá Yakub, Kamil àti Adam sọ̀rọ̀ lórí bí wọ́n ń sọ èdè mẹ́rin pàpọ, Duration 6,1831 Ògún 2020 4:42 Fídíò, Jude Chukwuka: Wọ́n yóò fi ojú ọlọgbọ́n wo akúrí tó bá sọ ojúlówó èdè Yorùbá, Duration 4,4222 Ògún 2020 Èyí tí a wò jùlọ 5:03 Fídíò, Omolola Arohunmolase Welder: Mo ti fí iṣẹ́ 'Welder' gbayì láwùjọ, tó mo fi tọ́ ọmọ yanjú, Duration 5,039 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 5:39 Fídíò, Akomolede ati Asa lori BBC: Olùkọ́ Kikelomo Ogunboye tan ìmọ́lẹ̀ sí ìwà olè ọ̀gá ọlọ́pàá Audu gẹ́gẹ́ bí àwòkọ́ṣe àsìkò yìí, Duration 5,398 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 4:11 Fídíò, Oba Adeyeye Ogunwusi: Ojú mi ti rí lọ́pọ̀ lọpọ̀, ọ̀pọ̀ èèyàn ni kò tilẹ̀ gbàgbọ́ pé mo lè jọba- Ooni, Duration 4,117 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 4:43 Fídíò, Promise Akinlade: ọmọ ọdún mọ́kànlá tó ń fi ìlù dárà bíi àgbàlagbà sọ̀rọ̀ nípa tálẹ́ǹtì rẹ̀, Duration 4,437 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 0:59 Gbọ́, Ìsẹ̀lẹ̀ jákèjádò orílẹ̀èdè àgbáyé láàárín ìṣẹ́jú kan, Duration 0,59wákàtí 5 sẹ́yìn 7:03 Fídíò, Olumuyiwa Bolade Adedeji Military Bruitality: Bí arákùnrin onípèníjà ara tí sọ́jà lù ṣe dé, Duration 7,035 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 4:45 Fídíò, Yoruba Films: Ẹ̀ẹ́ bẹ̀ mi kúrò láyé ni, mi ò lè kú - Fadeyi Oloro, Duration 4,4526 Èrèlè 2020 2:48 Fídíò, Esther Ajayi: Èmi náà ti borí ìṣòro rí ló ń mu mi ṣojú àánú, Duration 2,481 Ògún 2019 6:08 Fídíò, Adebola Ademilua: Àìrísẹ́ ṣè lẹ́yìn ìwé kíkà ló sọ mi dí ìyá onírú, mo dúpẹ́ tèmi, Duration 6,0827 Bélú 2020 5:55 Fídíò, Soyinka Cancer: Àṣe ara mi ni iso ti n run gbogbo bí mo ṣe n ṣèrànwọ́ lórí jẹjẹrẹ, Duration 5,5527 Bélú 2019 BBC News, Yorùbá Ìdí tí ẹ fi le è nígbàagbọ́ nínú ìròyìn BBC Ìlànà Lílò Nípa BBC Òfin Àṣírí Cookies Kàn sí.
ó bá gbadura pé, “OLUWA, Ọlọrun Israẹli, kò sí Ọlọrun tí ó dàbí rẹ ní ọ̀run tabi ní ayé, ìwọ tí ò ń pa majẹmu mọ́, tí o sì ń fi ìfẹ́ ńlá han àwọn iranṣẹ rẹ, tí wọn ń fi tọkàntọkàn tẹ̀lé ìlànà rẹ.
Ati pe o wu oun ki oun maa kọrin yii kaakiri gbogbo agbaye ni.
Adari agba Ile ise ikole, BCC Tropical Nig.
òun kò le è yọ́ wá - Lekan Balogun Iléẹjọ́ gíga Akure kọ̀ láti gba onídùróó olórí ìjọ Sotitobire Ìjọba Eko sọ pé ká má tọrọ bárà mọ́, wọ́n tún fòfin de kẹ̀ẹ̀kẹ́ tá a fi n ṣiṣẹ́ - Àwọn àkàndá ẹ̀dá Mí ò bẹ̀bẹ̀ fún oyè igbákejì alága APC kí wọ́n tó ó fún mi - Abiola Ajimobi Saheed àti Fathia Balogun dìjọ ń ṣe ọjọ́ ìbí lónìí, ẹ wo àjọṣepọ̀ tó wà láàrin wọn Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Nígbà tí ó bá sọ̀rọ̀, irọ́ ni ó ń pa.
Ẹfunsetan Aniwura, obìnrin tó ju ọkùnrin lọ Hubert Ogunde rèé, baba àwọn òsèré tíátà Kí lo fẹ́ mọ̀ nípa ‘Ajala Travels’?
Gbogbo òkè ati erékùṣù ni wọ́n kúrò ní ipò wọn.
Adebayo Alao-Akala: 'Mo ti dàgbà ọ̀jẹ̀, n kò ní díje fún ipò gómìnà ìpínlẹ̀ Oyo mọ́'
Kẹẹ si maa wo o, wọn ri ẹja Penis yii gẹgẹ bi ounjẹ teeyan n jẹ́.
Human Trafficking: Iṣẹ́ tíṣà ni wọ́n sọ pé màá ma ṣe ní Dubai, oko ọmọ ọ̀dọ̀ ni mo ba ara mi ní Oman
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Owu Water Fall: Ọba Oyewole ni ibùdó ìrìn àjò afẹ́ gidi ni àmọ́ ọ̀nà ibẹ̀ burú jáì Ẹkọ ti itan yii kọ wa: Ẹkọ akọkọ ni pe ka maa tẹti silẹ lati gbọ alaye ara wa ko to di iporogan.
Ni gbogbo Naijiria, olu ilu Naijiria, Abuja nikan lawọn eeyan to n janfani omi ẹrọ ijọba ninu ile wọn ti pọ ju eeyan kan ninu mẹwa lọ.
Fọnran fidio ẹ to jade ni oṣu kẹwa ọdun yii lo tun sọ orin naa di kariaye nigba ti fidio naa ṣafihan Wizkid ati Tiwa Savage.
Wọn gbudọ ri i daju pe wọn forukọ silẹ loju opo ijọba ki wọn si ṣe ayẹwo ẹlẹẹkeji nigba ti wọn ba wọ orilẹede Naijiria.
Ẹ̀mí Ọlọrun bá bà lé Amasai, olórí àwọn ọgbọ̀n ọmọ ogun olókìkí, ó bá dáhùn pé,“Tìrẹ ni wá, Dafidi;a sì wà pẹlu rẹ, ọmọ Jese!
“Ìwọ, Eleasari ati àwọn olórí, ẹ ka gbogbo ìkógun tí ẹ kó, ati eniyan ati ẹranko.
Mose náà ni ó bá angẹli sọ̀rọ̀ ní òkè Sinai nígbà tí wọ́n wà ninu àwùjọ ní aṣálẹ̀, tí ó tún bá àwọn baba wa sọ̀rọ̀.
Mo sì ń bẹ̀bẹ̀ nígbà gbogbo ninu adura mi pé, ó pẹ́ ni, ó yá ni, kí n rí ààyè láti wá sọ́dọ̀ yín, bí Ọlọrun bá fẹ́.
Lẹyin ti aarẹ Muhammadu sọrọ tan, ọpọ awọn ọmọ Naijiria lo ti n fi ero wọn han lawọn oju opo ibaraẹnidọrẹpọ loju opo itakun agbaye.
PDP pè fún fífi Kemi Adeosun jófin Lẹyin ti minisita feto iṣuna, Kẹmi Adeọṣun kọwe fipo silẹ lọjọ ẹti lori ẹsun ayederu iwe ẹri agunbanirọ rẹ, ẹgbẹ oṣelu PDP to jẹ aṣaaju ẹgbẹ oṣelu alatako lorilẹede Naijiria ti beere fun fifi minisita naa jofin lori ẹsun ko ṣe eto isinruulu NYSC rẹ ti o si tun lọ lo ayederu iwe ẹri fun.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Amẹrika dá akẹ́kọ́ọ̀ Harvard pada sí orílẹ̀-èdè rẹ̀ nítori ǹkan ọ̀rẹ́ rẹ̀ kọ lóri ayálujára 28 Ògún 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Amẹrika dá akẹ́kọ́ọ̀ Harvard pada sí orílẹ̀-èdè rẹ̀ nítori ǹkan tó kọ lóri ayélujára Àwọn aláṣẹ ilẹ̀ Amẹríka tí lé ẹni ọdún mẹ́tàdílógun kan tí wọ́n ṣẹ̀ṣẹ̀ gbà wọlé sí ilé ẹkọ́ fásìtì Harvard pada sí orilẹ̀ -èdè rẹ̀ nítori ọ̀rọ̀ kan ti ọ̀rẹ́ rẹ̀ kọ sorí ẹ̀rọ́ ayelujara Facebook.
Lẹyin ifẹsẹwọnsẹ mẹfa ti awọn ẹgbẹ agbabọọlu ti gba, Liverpool nikan ni ko tii padanu ifẹsẹwọnsẹ kankan bayii.
O sọ pe wọn ni lati sọ iru eeyan wo ni wọn jẹ, bawo ni wọn ṣe de ibẹ, ati pe bawo ni wọn ṣe pẹ to nibẹ.
kí ó sì súre fún mi,nítorí pé ara rẹ̀ móorupẹlu aṣọ tí a fi irun aguntan mi hun,
Fìlà Olófìn-íntótó tilẹ̀ sí sọ̀nù ní ọ̀nà.
 Oríṣun àwòrán, @adedimejilateef Àwọn Kristiẹni tó ṣe ìwọ́de lórí ètò àbò ń tako ìjọba ni - MURIC Ṣíṣe iṣẹ́ ọlọ́pàá agbègbè láì gbowó, òfo ni - Onímọ̀ ètò ààbò Mímu ọtí líle àti oúnjẹ oní sítáṣì le è fa àrùn jẹjẹrẹ ọyàn - Onímọ̀ Àwọn òṣìṣẹ́ ọba ní Kwara sọ ara wọn sínú ààwẹ̀ àti àdúrà torí owó oṣù tuntun O tẹ siwaju pe Iya mi, iya Oluwasegunfunmi, mo ni ifẹ rẹ mama mi.
Tani Yorùbá máa ń kí báyìí 'Ẹ rìn wá'?
Asmaa James - Ajafẹtọ ẹni ati Akọroyin ni Sierra Leone Asmaa lo jẹ agbẹnusọ fun awọn obinrin lorilẹede Sierra Leone lati ipasẹ isẹ akọroyin ati osisẹ amayedẹrun to n se.
'Èrè tó tọ́ ni Jonathan, Ọbasanjọ jẹ lórí iṣẹ́ ọpọlọ jíjí' Kaka ki ewe agbọn Boko Haram dẹ Àwọn agbébọn kan tí wọ́n funrasí pé Boko Haram ní wọ́n ti jí ọmọbìnrin mẹ́ẹ̀dógún gbé ní agbègbè Diffa tó wà ni ilà oòrùn Gúsù orílẹ̀èdè Niger.
 wọ ́ n ń ṣe èyí kí àwọn ẹni tí ọba náà kọjá ni ìlú u wọn lè mọ ́ ẹni tí ń kọjá lọ .
Oju ọna to wa lati Iyana Oworo nikan lo wa ni ṣíṣí titi de Adeniyi-Adele, awọn ọkọ to ba n bọ lati ọna Iyana Oworo nìkan lo ni anfaani lati gba ori afara naa laarin aago mejila oru si aago kan ọsan.
Oyo Attack: Ilé ìwòsàn UCH ni Kọmíṣọ́nnà náà ti ń gba ìtọ́jú
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ọwọ́ ọlọ́pàá tẹ àwọn méji tó jẹ ẹran ara ọlọ́pàá tí wọ́n pa n'Ibadan 23 Bélú 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 24 Bélú 2020 Oríṣun àwòrán, others Ẹran ara ọlọ́pàá di èkìrí ẹran súyà, wo àwọn tó jẹ́ níbẹ́.
Ẹni tó ti ní àìsàn lára tẹ́lẹ̀ Àwọn àìsàn tó ti wà nínú àgọ́ ara tẹ́lẹ̀ náà wà lára nkan tó ń sọ ẹni tí yóò kù ú tàbí yè.
Elegee ara Lionel Messi lo fimu Man U danrin lẹyin to gba goolu meji sawọn labala akọkọkọ ifẹsẹwọnsẹ ọhun ni papa isẹre Nou Camp.
Idi ni pe gbogbo wa ko lee maa sisẹ ọpọlọ ni asiko kannaa.
Wọ́n bá kúrò ní ibojì náà, wọ́n pada lọ sọ gbogbo nǹkan tí wọ́n rí fún àwọn ọmọ-ẹ̀yìn mọkanla ati gbogbo àwọn yòókù.
Fayemi, tii ṣe alaga ẹgbẹ awọn gomina nilẹ Naijiria wa sisọ loju rẹ pe, ni ọpọ ipade ti awọn ti ṣe ni awọn ti fẹnu ko lori awọn igbesẹ kan, to fi mọ ofin pe irinke-rindo ko gbọdọ waye lati ipinlẹ kan si omiran.
naa,lati lee fi aaye sile fun awon oludibo lati yẹ orukọ won wo , ki won si
Ní ọjọ́ keji a dé Rodọsi.
Ṣé ìtùnú Ọlọrun kò tó fún ọ ni,àní ọ̀rọ̀ jẹ́ẹ́jẹ́ tí ó ń sọ fún ọ?
"Fulani darandaran méjì fojú balé ẹjọ́ 'Iha kokanmi Buhari lewu fun Nigeria' "" Bi a ba wo awọn ipinlẹ ti isẹlẹ ipaniyan wọn yii ti waye, awọn kristẹni lo pọ julọ nibẹ."
Olotu eto idajọ ni ipinlẹ Ondo ati kọmisọnna fun eto idajọ, Kola Olawoye ni igba akọkọ niyii, ti gbọgbọ ilẹ Yoruba yoo fi imọ sọkan lori itẹsiwaju awujọ wọn, lai si alatako laarin wọn.
Mo yẹ àwọn ilé tí ìporùrù ilẹ̀ ọ̀hún bà wò fínnífínní, mo sì rí àrító ohun tí ó ṣẹlẹ̀ níbẹ̀.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Promise Akinlade: ọmọ ọdún mọ́kànlá tó ń fi ìlù dárà bíi àgbàlagbà sọ̀rọ̀ nípa tálẹ́ǹtì rẹ Bakan naa, awọn gomina APC eyi ti alaga ẹgbẹ awọn gomina, Kayode Fayemi ati gomina ipinlẹ Yobe, Atiku Bagudu naa wa nibẹ lojukoroju.
Àlá tí wọn ń lá, fún ìbàjẹ́ ara wọn ni.
Ma ṣe ro ara rẹ pin ṣugbọn wa imọ kun imọ lori ohun to ba n yọ ẹ lẹnu gẹgẹ bii obinrin.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Atiku: Igun olùjẹ́jọ́ gan kò fèsì sí àṣìṣe ìṣirò tí ẹlẹ́rìí kan mẹ́nubà pé INEC ṣe 16 Ògún 2019 Oríṣun àwòrán, @atiku Ẹgbẹ oselu PDP ati oludije rẹ fun ipo aarẹ to kọja, Atiku Abubakar ti kasẹ atotonu wọn nilẹ niwaju igbimọ to n gbọ ẹjọ ẹhonu to suyọ lẹyin ibo naa.
EL-Zakzaky: DSS ti fi El-zakzaky sílẹ̀ láti lọ sí India fún ìwòsàn
    Mo gba oúnjẹ gbọ́, òun ni alákòóso ara, oúnjẹ didára mú ara dan, a máa mú egungun le, ẹ̀jẹ̀ a sàn ká koko, àìdára oúnjẹ ni ń fa àìsàn lẹ́sẹ̀, ìjẹkújẹ oúnjẹ, o ń sọ ara di arúgbó, èrẹ̀kẹ́ a di palaba, ojú á di foforo, imú á di tọgíla, ẹsẹ̀ a di tín-ín-rín, apá á di jawala, iwájú a di gọnbu, ìdí á di pẹlẹbẹ, gbogbo àwọ̀ ara a rí kùọ̀kuọ.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ẹ̀yin adarí Nàíjíríà, ẹ dẹ́kun àwáwí asán lórí ètò ààbò tó mẹ́hẹ - Ààrẹ àṣòfin àgbà Ẹ dákẹ́ àhesọ ọ̀rọ̀, ohun tó pa ẹ̀gbọ́n àti àbúrò Orisabunmi rèé - Mọ̀lẹ́bí gbarata Wo àdánù tó wà nínú gbígba ayédèrú áápù fún ìforúkọsílẹ̀ NIN lórí ayélujára Àmúlò ẹ̀rọ POS fun òwò ṣíṣe, ṣé ó tọ̀nà nínú Islam àbí bẹ́ẹ̀ kọ́?
Lori ayewo awon amoye meji naa,  osuwon eto oro-aje agbaye yoo wa ni iko meta-o-le 3.
Sugbọn, awọn eniyan ko faramọ ipinnu ijọba ipinlẹ naa, eleyi to mu ki ijọba naa din iye owo ori to yẹ ki wọn san ku.
‘Lóòótọ́ ni ọ̀jọ̀gbọ́n fẹ́ bá mi lòpọ̀’ Awọn ajafẹtọ naa gba ipinu yii wọle ti wọn si juwe rẹ bi igbesẹ pataki lati ni ẹtọọ akọs'akọ nilẹ adulawọ.
orile-ede, bi o ti le je pe, o je ona ti ko rorun rara.
Ṣugbọn mo sọ fun yín, Elija ti dé, ṣugbọn àwọn eniyan kò mọ̀ ọ́n; ohun tí ó wù wọ́n ni wọ́n ṣe sí i.
Ologbondiyan ni o jẹ iyalẹnu pe ijọba APC le gbe iru igbesẹ yi lasiko ti ara n ni awọn ọmọ Naijiria to si kesi ile aṣofin Naijiria lati da si ọrọ naa.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Alaafin Oyo: Olorì Anuoluwapo Adeyemi gba àmì ẹ̀yẹ lórí oge ṣíṣe 11 Bélú 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 1 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Oríṣun àwòrán, Royal Image Photography Aya Alaafin ilu Oyo tẹlẹ, Olori Anuoluwapo ti kede pe wọn ti fun oun ni ami ẹyẹ fun ipa ti oun ko nipa eto oge ṣiṣe.
Oloye Yemi Elebuibon sọ pe, o ti ṣẹlẹ ri, àmọ́ kii ṣe lati ọwọ awọn janduku.
Wọn si rọawọn to ba jade wa a woran iwọde naa lati ya ara wọn si ọtọ fun ọjọ mẹrinla.
Ni ọjọ Aje ni awọn agba oye to jẹ igbimọ Olubadan lọ ṣe baba kẹẹ pẹ si Olubadan laafin rẹ ni Popoyemọja nilu Ibadan, lasiko ayẹyẹ to fi n sami ọjọ ibi ọdun kọkanlelaadọrun rẹ loke erupẹ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Alaafin: Ẹ máa kọ́ àwọn ọmọ wa ní èdé àti àṣà Yorùbá 26 Ògún 2019 Oríṣun àwòrán, Alaafin Oba Adeyemi III Ọdun Sango , tii se ọdun isẹnbaye to maa n waye lọdọọdun, eyi ti Alaafin tilu Ọyọ, Ọba Lamidi Ọlayiwọla Adeyẹmi Kẹta maa n se agbatẹru rẹ, ti waye lọdun yii, to si ti lọ pẹlu.
Ó mú ju idà olójú meji lọ.
Oríṣun àwòrán, AFP Àkọlé àwòrán, Bring back our girls: Obi àwọn ọmọ Chibok 34 ló kú ní ọdún márùn ún Lasiko ayajọ ọdun karun un awọn ọmọ Chibok naa ni ijọba Aarẹ Muhammadu Buhari ṣalaye pe oun n sa ipa rẹ lati rii wi pe awọn to wa ni panpẹ Boko Haram naa gba itusilẹ laipẹ.
O ni oun ti bẹrẹ iṣẹ iwadii lori ninu awọn oku ti wọn ti ri yọ sita.
N óo ṣe àwọn nǹkan,n kò sì ní kọ̀ wọ́n sílẹ̀.
Ẹ óo kó wọn wá siwaju OLUWA, alufaa yóo wọ́n iyọ̀ lé wọn lórí, yóo sì fi wọ́n rú ẹbọ sísun sí OLUWA.
Akinwumi Adesina bọ́ lọ́wọ́ ẹ̀ṣùn jẹgúdújẹrá tí wọ́n fi kan - AFDB Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Hepatitis: A kò leè kóo nípa dídìmọ́ ara ẹni Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Mo kọṣẹ, mo si n ṣe iṣẹ mi.
Abineri ọmọ Neri, tíí ṣe balogun àwọn ọmọ ogun Saulu, gbé Iṣiboṣẹti ọmọ Saulu sá lọ sí Mahanaimu ní òdìkejì odò Jọdani.
Nitori naa ni awọn eniyan ṣe n woye pe ṣe aisan yii kii ṣe ohun ti eniyan gbọdọ bẹru lati ṣe.
Ọwọ Ọlọ́pàá tẹ afunrasi méjì tó mọ nípa ikú dókítà LUTH Ibi ibudo awọn ọlọpaa to n dari ọkọ ni popona Nyanya-Karshi ni bi aago meje aabọ ogunjọ oṣu kẹta ni iṣelẹ naa ṣẹlẹ.
Ìjà yìí pẹ́ ki ó tóó tán, nítorí kò sí ẹni tí ó máa mú àwọn oníjà yìí, àwọn tí ó sí dúró níbẹ̀ pẹ̀lú, wọn kò fẹ́ kí ìjà náà tètè pa’ri,nítorí aláràngbọ́ ni Àǹjànnú-ìbẹ̀rù ó sì ti tẹ́ lọ́wọ́ àwọn ẹgbẹ́ rẹ̀ gbogbo.
Bẹliti ọkọ di dandan lati wọ Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ẹni ti ko ba wọ bẹliti ọkọ rẹ yoo san owo ijiya Awọn to ṣe ọkọ fi aaye kalẹ fun wa lati lo bẹliti yi ni kete ti a ba ti ko si inu ọkọ.
Nínú ọ̀rọ̀ Florence Yaakugh, tó jẹ́ alákoso àwọn agùnbánirọ̀ ní ìpínlẹ̀ náà jẹ́rìsí ìṣẹ̀lẹ̀ náà, o ní ìwádìí ṣì ń lọ lọ́wọ́ pẹ̀lú àwọn àgbófinro àti àwọn òmùwẹ̀ ìlú nàá.
Nigba ti BBC Yoruba kan si Kọmiṣọna fun eto ẹkọ nipinlẹ Ọṣun, Ọgbẹni ọmọtunde Young lati mọ ohun gan to faa iṣinipo pada naa ni ẹka ileeṣẹ ijọba rẹ, o ni, ko si babara ninu iṣinipo pada naa nitori ijọba n wa awọn to ni iwe ẹri olukọni lọwọ ti wọn ko fi ṣiṣẹ olukọ lati da wọn pada si kilaasi.
OLUWA sọ fún Mose, pé, “Dá ọ̀pá Aaroni pada siwaju Àpótí Ẹ̀rí, kí ó lè jẹ́ àmì ìkìlọ̀ fún àwọn ọlọ̀tẹ̀ Israẹli, kí wọ́n sì lè dẹ́kun kíkùn tí wọn ń kùn sí mi, kí wọ́n má baà kú.
idoti bayii mọ” Bakan naa, ni o tun tenumo pe bo tile je pe ijoba n
Koda, ni irọlẹ Ọjọ Isẹgun ni iroyin gbalẹ pe gba Alagba ẹgbẹ oṣelu PDP ni ipinlẹ Kogi, Agbẹjọrọ Taiwo Kola-Ojo subu lulẹ, ni ibi ti o ti n gba bọọlu ẹlẹyin, lawn Tennis to si ku.
Ijọba ipinlẹ Ogun ninu ọrọ wọn ni awọn ti fi to ọlọpaa leti pe ọmọ marun un ti di awati ni ile ibugbe awọn ọmọ orukan naa.
Akindi jábọ́ ó sì fara pa sùgbọ́n ó ti wà nílé ìwòsàn báyìí tí ó sì ṣèse ní ẹsẹ̀ méjèèjì.
orile ede Naijiria ti  kẹdun pẹlu awọn  ẹbi  awon  meji , omo orile ede Naijiria ati  Biritiko ti won padanu ẹmi wọn nibi ikọlu to sẹlẹ
Tó bá dìgbà náà, àwọn eniyan kò ní máa wí mọ́ pé,‘Àwọn baba ni wọ́n jẹ èso àjàrà kíkan,àwọn ọmọ wọn ni eyín kan.
Kunle Afolayan, òṣìṣẹ́ báńkì tẹ́lẹ̀ kó tó di gbajúgbajà òṣèré Ilé ẹjọ́ kọ̀ láti tú Omoyele Soworẹ sílẹ̀ Ọwọ́ tẹ babaláwo àti adigunjalè márùń ni Imo - Olọpàá Àwọn mẹ́rin t'íjọba Buhari k'etí ikún s'àṣẹ òmìnira iléẹjọ́ lórí wọn rèé Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Intersextuality: Dokita ni ká mu èyì tó wù wá nínú jíjẹ́ akọ tàbí abo Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Àwọn ojú ewé ìwé àfọwọ́kọ wọ̀nyí ti sọnù ní ìpamọ́ Martin Harris, ẹnití a fa àwọn ewé ìwé náà lé lọ́wọ́ fún ìgbà díẹ̀.
Ní ìgbà keje tí ó pada dé, ó ní, “Mo rí ìkùukùu kan tí ń bọ̀ láti inú òkun, ṣugbọn kò ju àtẹ́lẹwọ́ lọ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, JAMB 2019: A ó fagi lé ìdànwò ẹni tó bá ṣe aṣemáṣe Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Isreal Adesanya fàgbàhàn Kelvin Gastelum ni Atlanta Adesanya ba gba ogo pẹlu 48-46 ni eyi ti yoo jẹ ko tun lọ koju Robert Whittaker ọmọ ilẹ Australia nipele idije ẹṣẹ kikan to tẹle eyi.
Nígbà tí Abramu wọ Ijipti, àwọn ará Ijipti rí i pé arẹwà obinrin ni aya rẹ̀.
 Ó ga tó iwọ ̀ n ẹsẹ ̀ bàtà mẹ ́ rin ó sì gùn gbọọgì .
tubo tesiwaju ninu ojuse won , o tun wa rọ awon ti ko ni anfaani lati gba ami
Ṣugbọn ẹni tí ó bá ń wá ògo ẹni tí ó rán an níṣẹ́ jẹ́ olóòótọ́, kò sí aiṣododo ninu rẹ̀.
'Soapy', àwo orin tuntun Naira Marley tó ń milẹ̀ tìtì
Ati pe yiyan tabi kikede Ojogbon Soyombo ko tẹle ilana to yẹ gẹgẹ bii adele Giwa fasiti Eko.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Arsenal vs Valencia: Arsenal gbẹ̀san fún Liverpool, Tottenham 3 Èbibi 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Chelsea ni tirẹ ta ọmi pẹlu Eintranct frankfurt ni orilẹede Germany Lẹyin idojukọ to de ba ikọ agbabọọlu Tottenham ati Liverpool ninu idije Champions league lọsẹ yii, orilẹede Gẹẹsi yi ipin rẹ pada ni idije bọọlu laaarin awọn ẹgbẹ agbabọọlu ni ilẹ Yuroopu pẹlu bi ikọ agbabọọlu Arsenal ati Chelsea ṣe gbo ewuro si oju awọn iks ti wọn ba gba bọọlu ni idije UEROPA ni ọjọbọ.
Nítorí pé, iranṣẹ mi ni àwọn ọmọ Israẹli jẹ́, iranṣẹ mi tí mo kó jáde láti ilẹ̀ Ijipti ni wọ́n.
O ṣalaye siwaju si pe, ile iṣẹ ọlọpaa ni irọ ni awọn ologun n pa pe o ṣeeṣi ni, o pari rẹ pẹlu aworan Aarẹ Muhammadu Buhari nibi to ti n ta eyin.
Àwọn àjèjì ni yóo máa ba yín bọ́ agbo ẹran yín,àwọn ni yóo sì máa ṣe alágbàṣe ninu ọgbà àjàrà yín;
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Caster Semenya: kíní ìdájó yìí dà fún obìnrin àti eré ìdáraya 1 Èbibi 2019 Àkọlé àwòrán, kíní ìdájó ti wọn dá fún Caster Semenya dà fún obìnrin àti eré ìdáraya Bí ọmọbinrin South Africa Caster Semenya to ń sáré ṣe fìdírẹmi lóri ẹsùn ìdẹ́yẹsini tó fi kan IAAF níle ẹjọ, BCC ń wo ohun to túmọ si fún àwọn obinrin àti eré ìdáraya.
O ni eleyi ṣe pataki paapaa julọ f'awọn to wa ni agbegbe ibi ti ikọlu ti'n waye.
Gómìnà ìpínlẹ̀ Eko Babajide Sanwo-Olu ló fi sọ̀wédowó òun lé àwọn ẹbí olóògbé náà lọ́wọ́ lásìkò ìpàdé ètò ààbò kan lọ́jọ́bọ, bákan náà ló sèlérí pé, kò ni si ààyè fún ìwà ọdaràn.
Kí alaafia kí ó wà pẹlu gbogbo ẹ̀yin tí ẹ jẹ́ ti Kristi.
Kí á má rí i pé o ṣe irú ohun tí ó jọ bẹ́ẹ̀!
 Tijoba ba le se eleyii opolopo alaisan ni won ko nii ku mo ni Naijiria.
Ó yára pe ọdọmọkunrin tí ń ru ihamọra rẹ̀, ó wí fún un pé, “Fa idà rẹ yọ, kí o pa mí, kí àwọn eniyan má baà máa wí pé, ‘Obinrin kan ni ó pa á.
Rhapsody Akọrin obinrin, Rhapsody naa fi ọrọ ṣe aisi nibẹ, lai ba wọn dasi.
Kí ó tó di àkókò náà, Eliaṣibu alufaa, tí wọ́n yàn láti máa ṣe àkóso àwọn yàrá ilé Ọlọrun wa, tí ó sì ní àjọṣe pẹlu Tobaya, 
O jẹ ọmọ ilu Udi, ni ipinlẹ Enugu, oun si ni abikẹyin iya rẹ.
Aare orile ede Naijiria Muhammadu Buhari ti so pe oro aje orile ede yii ti n burẹkẹ si I, o wa ro awon omo orile ede Naijiria lati ni afojusun  to dara ,nitori pe ojo iwaju orile ede yii dara .
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Àjọ NLC Naijiria : MTN kọ̀ jẹ́ kí òsìsẹ́ wọn darapọ̀ mọ́ àjọ òsìsẹ́ Bakan naa ni ileeṣẹ MTN ti darapọ mọ Nigeria Stock Exchange bayii to jẹ ọkan lara gbendeke ti ajọ NCC fun wọn nigba naa.
Anuolouwapo jẹ ọkan lara awọn Olori Alaafin ilu Oyo, Ọba Lamidi Adeyemi III, eyii ti awọn eeyan kan gbagbọ pe oun ni aayo Kabiesi.
N kò pàṣẹ fún wọn pé kí wọn máa ṣe bẹ́ẹ̀, n kò fún wọn ní irú ìlànà bẹ́ẹ̀; ohun tí ó jọ bẹ́ẹ̀ kò tilẹ̀ wá sí mi lọ́kàn.
Gẹgẹ bi alukoro fun ileeṣẹ ọlọpaa nipinlẹ Ondo, Femi Joseph ṣe sọ fun BBC Yoruba, awọn adigunjale naa ya bo ile ifowopamọ First Bank to wa ninu ilu Ido-Ani nijọba ibilẹ Ọ̀sẹ́ , ti wọn si gbiyanju lati ko owo lọ.
À ń fẹ́ àwọn òfin tí yóò dáàbò bò wá tí wọn yóò sì kún ojú ìwọ̀n, a fẹ́ àwọn ètò àmúlò gbogboògbò tí yóò mú àpọ́nlé wa lọ sí àwọn ìtàkùrọ̀sọ àti àwọn ìdásílẹ̀.
Aare  Muhammadu Buhari wa seleri pe ijoba oun yoo  tubọ maa gbiyanju lati gbogun ti iwa ibajẹ ati
Adajọ olupẹjọ, John Idoko fi ẹsun kan wọn pe wọn lọ yaworan nibẹ pẹlu awọn ọdọbinrin to fẹrẹẹ tu sihoho ti wọn si fi sita lori ayelujara eyi to lodi si igbagbọ ninu ẹsin ibilẹ ti wọn n ṣe ni Osun.
Àjàpadá gbáradì , ó kó àwọn ènìyàn rẹ ̀ , ó sì ṣe gẹ ́ gẹ ́ bí akíkanjú àti ògbójú ọdẹ.
Aburo ọkọ oloogbe to fi idi iṣẹlẹ naa mulẹ fun BBC Yoruba, Usman Ahmad Nuraini, sọ pe oloogbe Zainab lọ si ile iyagbẹ ni owurọ kutu ọjọbọ lati tura, lo ṣakiyesi pe nkankan ge e jẹ ni idi bo ṣe joko sori awo iyagbẹ.
Lẹ́yìn náà, wọ́n wá sọ fún Abrahamu pé Milika ti bímọ fún Nahori arakunrin rẹ̀.
lati gbokun ti iwa odaran , o tun wa ro won lati tepele mo ise naa, paapaa,
Ọmọ ọdún mẹ́rìnlá kàwé gboyè jáde ni Oxford N650,000 péré ni mò ń gbà gẹ́gẹ́ bíi owó oṣù -Gomina Ọyọ Van Dijk gbadé UEFA mọ́ Messi àti Ronaldo lọ́wọ́ Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Bí ó bá rí bẹ́ẹ̀, àwọn àjèjì tí èdè wọn yàtọ̀ ni OLUWA yóo lòláti bá àwọn eniyan wọnyi sọ̀rọ̀.
o yẹ ki igbimọ naa ni alaga kan ati ọmọ igbimọ mẹrin ti wọn jẹ akọṣẹmọṣẹ
 lakopo , awon planeti merin yi je pipe nigba miran bi planeti .
Ní ọjọ́ ajé ni wọ́n kéde ikú Winnie Mandela lẹ́ni ọdún mọ́kànlélọ́gọ́rin.
Ojo iranlọwọ to n rọ fun tọkọ taya Risikat ati Abdulwasiu Dada, ti iyawo rẹ jẹ oloju buluu ko tii dawọ duro.
A ti pèsè wọn sílẹ̀ fún wakati yìí, ní ọjọ́ yìí, ninu oṣù yìí, ní ọdún yìí pé kí wọ́n pa ìdámẹ́ta gbogbo eniyan.
Joṣua mú òfin tí Mose kọ tẹ́lẹ̀, ó dà á kọ sórí àwọn òkúta náà lójú gbogbo àwọn ọmọ Israẹli.
“Ti a ba ri awon ti won bu ọla fun  aare Buhari tabi ti won n yin in lori isẹ ribi ribi to n se lorile ede yii, awon orile ede ti won dariko yii ni.
Aṣọ́ bá ara jọ, ìlẹ̀kẹ̀ ṣe ìwọ̀n ọrùn, ẹsẹ̀ bá bàtà ṣe dọ́gbadọ́gba.
Bí ọgbẹ́ aṣekúpanini ẹ̀gàn àwọn ọ̀tá mi rí lára mi,nígbà tí wọn ń bi mí lemọ́lemọ́ pé,“Níbo ni Ọlọrun rẹ wà?
Ohun tí ẹ mọ̀ wọnyi, èmi náà mọ̀ ọ́n,ẹ kò sàn jù mí lọ.
 Oko yii yoo maa lo si ekun kookan loorekoore lati kan si awon alaisan ti won n ba arun jejere finra, ki a le fun won ni ireti pe gbogbo re ko tii pin.
Ogunleye sọ wípé ojú ẹsẹ̀ náà ni àsẹ tò tù awọn ìgbìmọ̀ náà ká bẹ̀rẹ̀ sí ní mulẹ, tó sì kìlọ̀ pé ẹnikẹ́ni kò gbọdọ̀ kede ara rẹ̀ gẹ́gẹ́ bíi alága ìgbìmọ̀ eré ìdárayá kankan.
wi pe ilera loro, ki won dakun ki won fowosowopo pelu wa ,ki a ma se ri awon
Lẹhin ìsìnkú, ìséde ọlọ́jọ́ meje yio bẹ̀rẹ̀ ni Ilé-Ifẹ̀ àti agbègbè rẹ lati agogo mẹrin ìrọ̀lẹ́.
Ohun kan to n tu u ninu nipe, iyawo rẹ wa laye, awọn mejeeji si nireti pe wọn yoo bimọ mii.
Ó ri àwọn òpó mejeeji yìí sí àbáwọ Tẹmpili, wọ́n ri ọ̀kan sí ìhà gúsù, wọ́n pe orúkọ rẹ̀ ní Jakini; wọ́n ri ekeji sí apá àríwá, wọ́n sì pè é ní Boasi.
Ire lójú owó ń rí, ire la ó máa rí o.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Secret Cult in Ogun: Iléeṣẹ́ ọlọ́pàá fojú afurasí ẹlẹ́gbẹ́ òkùnkùn hàn ní Ijebu Ode 11 Sẹ́rẹ́ 2021 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 13 Sẹ́rẹ́ 2021 Oríṣun àwòrán, Facebook/Nigeria Police Ileesẹ ọlọpaa ipinlẹ Ogun ti safihan awọn afurasi ọmọ ẹlẹgbẹ okunkun mọkanla, ti wọn lo gbẹmi awọn araalu mẹẹdọgbọn nilu Ijebu Ode nikan ati agbegbe rẹ.
Bákan náà, Akeugbagold, lásìkò to ń báwọn akọroyin sọ̀rọ̀ ni, lati igba ti iṣẹlẹ náà tí wáyé, òun kò tíì fi ojú kan oòrùn, tí òun sì ń retí kí àwọn ajọmọgbe náà pé òun lórí ẹ̀rọ ibaraenisoro.
Nígbà tí Dafidi rí i pé OLUWA ti gbọ́ adura rẹ̀ ní ibi ìpakà Onani ará Jebusi, ó bẹ̀rẹ̀ sí rú àwọn ẹbọ rẹ̀ níbẹ̀.
Seyi Makinde: Wo ìdí tí gómìnà Oyo fi pàṣẹ ìdádúró iṣẹ́ fún kọmíṣọ́nà rẹ̀
"Ìjọba àpapọ̀ jáwọ́ lórí àfinkún owó iná fún ìgbà díẹ̀ ""Ikọ́ lásán ló pa Orisabunmi"" A ti fòfin de Trump lórí Facebook àti Instagram lẹ́yìn ìkọlù ilé aṣòfin ní Capitol- Zuckerberg Ole Gunnar Solskjaer, akọnimọọgba Manchester United ni oinu oun dun pe adehun idunadura naa bọ si nitori pe: ""Ni igbagbọ oun, Diallo wa lara awọn ọdọ agbabọọlu taye n wari fun lọwọ lagbaye."
"Nitori naa, ẹ ma jẹ ki a foya rara""."
 Ewe, lataari pipegede iko agbaboolu orile-ede mejeeji, orisirisi atunse ni iko kookan se sinu iko re, leyin ti won se amulo awon agbaboolu miiran ti won koi ti lanfaani lati kopa seyin.
Bẹẹ ba gbagbe, Ọjọru ni ẹgbẹ awọn dokita nipinlẹ Ondo da isẹ silẹ nitori bi ọgọọrọ wọn se n ku nitori aisi aabo to peye fun wọn lọwọ arun Coronavirus.
O ní o mọ́, o kò ní ẹ̀ṣẹ̀,ara rẹ mọ́ o kò sì ṣe àìdára kankan.
Lati igba ti o ti jawe olubori ninu idibo, niṣe ni o mẹnumọ.
ìbá wúwo ju yanrìn etí òkun lọ.
Mo bi angẹli náà pé, “Níbo ni wọ́n ń gbé e lọ?
Mo tún lá àlá lẹẹkeji, mo rí ṣiiri ọkà meje lórí igi ọkà kan, wọ́n tóbi, wọ́n sì yọmọ.
Ìwọ ni o óo máa yá ọpọlọpọ orílẹ̀-èdè ní nǹkan, o kò sì ní tọrọ lọ́wọ́ wọn.
O ni ohun ti ko dara ni ki baba maa ba ọmọ rẹ lajọpọ, bakan naa ni ko bojumu ki obinrin maa ba obinrin bii tirẹ ṣere ifẹ tabi ki ọkunrin maa ni ibalopọ pẹlu ọkunrin akẹgbẹ rẹ.
Níbi ìpàdé kan tó wáyé lolu ilé ẹgbẹ náà labuja, Secondus àti àwọn ọmọ ìgbìmò amusẹya ẹgbẹ fikún-lukun pẹlú Oludije ẹgbẹ náà fún ipò Gómìnà l‘Ọ̀sun, Seneto Ademola Adeleke ati àwọn ọmọ ẹgbẹ míi ti wọn n fapa janu.
Pàtàkì ni afárá yìí jẹ́ ní Lọndọn.
Nicu ni orukó baba rẹ nigba ti iya rẹ n jẹ Maria.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Ṣugbọn Arsenal lo pada jawe olubori nigbẹyin gbẹyin lẹyin ti Joseph Willock gba goolu karun un wọle fun Arsenal.
Gawat Sinimá àwòòwòtán lẹ́gbẹ́ òṣèlú APC; tani alága APC láàrín Ajimobi àti Victor Giadom?
26 Owewe 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 27 Ìgbé 2020 Lẹyin Taye, Kehinde, Idowu, Alaba, o ni orukọ amutọrunwa pataki ti Yoruba a maa sọ ọmọ to ba tun waye lẹyin awọn wọnyii.
Iru iwuwasi ba yi lo jọ wi pe a ri apẹrẹ rẹ pẹlu awn lọkọlaya kan ti wọn ri oku wn lọjọ ti Zainab naa ku.
A óo kọlu Dafidi níbikíbi tí a bá ti bá a, a óo bò wọ́n bí ìgbà tí ìrì bá sẹ̀ sórí ilẹ̀; ẹnikẹ́ni kò sì ní yè ninu òun ati àwọn ọmọ ogun rẹ̀.
Ninu atẹjade ilana tuntun naa ti ijọba ipinlẹỌṣun gbe kalẹ, ko gbọdọ ju ogun eeyan ti yoo maa wa nibi eto isinku ti wọn si gbọdọ lo ibomu wọn ko duro deede.
US Equality Day: Obìnrin 140,000 kọ̀wé bèèrè àtìlẹyìn àwọn olórí orílẹ̀èdè àgbáyé
Wọn ní idanwo aṣekagba oni iwe mẹwaa yoo bẹrẹ ni ọjọ kẹtadinlogun, oṣu kẹjọ, ọdun 2020 ti a wa yii Oríṣun àwòrán, other Bi ẹ ko ba gbagbe ajakale arun coronavirus lo mu ki wón sun idanwo aṣekagba yii siwaju titi di asiko yii nitori pe awọn orilẹ-ede agbaye gbe awọn ile iwe ti pa ki ajakale arun naa ma ba a maa tan kalẹ.
Ibi tí o ti ń lé mi lọ àpò já láti èjìká rẹ̀ sílẹ̀, Ayédèrú-ẹ̀dá sá jáde.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Okùnrin SARS náà sọ pé òun máa pa èèyàn síbi ni- Aladugbo Ọrọ fifi ontẹ jan iyansipo Magu Titi di bi a ti ṣe n sọrọ yi, Ibrahim Magu ṣi n ṣe adele ipo alaga ajọ to n gbogun ti iwa jẹgudujẹra ni Naijiria EFCC.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Fulani Kidnapping: Owó púpọ̀ la san kí wọ́n tó fi mi sílẹ̀ O ni wọn gbe Ekpo pamọ sinu aja ilẹ to wa ninu ile ijọsin Paitọ naa ni Ogijo.
Oríṣun àwòrán, Nguher Gabrielle Zaki Lakotan YIAGA wa gba ajọ eleto idibo ni imọran pe, ki wọn ba awọn alẹnulọrọ sọrọ lọna ati jẹ ki ibo lọ ni irọwọrọsẹ.
Ẹ kò gbọdọ̀ jẹ ajá mọ́' Dandan kọ́ ni kí Ààrẹ Buhari wọ ìbòmú - ìjọba àpapọ̀ Adari awọn agboku naa, Benjamin Aidoo ni oun ko lerọ rara pe oun le e di ilumọọka, amọ inu oun dun gidigidi.
O ti àwọn ọ̀tá rẹ l'ójú
Ó ní ọ̀rọ̀ wọn yóo dàbí ẹni tí ó ja àjàbọ́, ṣugbọn yóo wà láàyè.
Jesu dá wọn lóhùn pé, “Bí ẹ bá wó Tẹmpili yìí, èmi yóo tún un kọ́ ní ọjọ́ mẹta.
"Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Àwòrán bí ìlú Ìwó se rọ̀sọ̀mù f’ọ́dún eégún N kò fẹ́ eégún onídọ̀tí ní ààfin mi - Oluwo ""Ohun tí ojú opó ń rí láwùjọ kò kéré"" Tanka epo tó jóná gbẹ̀mí àdájọ́, ọmọkùnrin rẹ àtàwọn míì Alárùn ọpọlọ lu àwọn nọ́ọ̀sì àti dókítà agba níléèwòsàn ní àlùdákú Ikọ̀ ẹlẹ́sìn Hàkíkà rèé, níbití wọn ti ń pààrọ̀ ìyàwó láàrín ara wọn Wo oríṣiríṣi ìgbádun ibálòpọ̀ láwọn orílẹ̀èdè mìíràn Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ìyá Darasimi: Ọlọ́run fi ìbejì rẹ̀ mí lẹ́kún, lẹ́yìn ikú Darasimi tó mu sódà Ajọ UN ni, ominu n kọ oun, ti aya oun ko si lelẹ mọ nitori awọn laasigbo yii ati awọn ohun miran to nii se pẹlu eto idibo gbogbo-gboo to n bọ, to fi mọ ọrọ aje ati igbaye-gbadun awọn araalu, ka ma sẹsẹ sọ boo ba o pa, boo ba, ko bu lẹsẹ, ti awọn agbẹ ati daran-daran n se."
O ni oun se eleyii lati je ki
Ajọ eleto ilera agbaye sọ pe ọunje ti ekute yagbẹ si tabi to tọ si a maa sokunfa itanka arun naa.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Àjọ iwádìí ọrọ̀ ajé, EIU ní nǹkan rọrùn ju bí ọ̀pọ̀ ṣe lérò lọ ni ilu Eko Karachi (Pakistan) ati ilu Eko ni wọn jijs wa ni ipo kẹfa ti Buenos Aires ni Argentina ati Chennai India si tun pin ipo keje.
to sun lo si ipinle Odisha ni aago mejo owuro.
Oluka ni àwọn jọ wá láti ìlú kan náà, sùgbọ́n òun mọ pé Aguti ni ọkùnrìn tó pọ̀.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ẹ gbà mí o!
Iṣẹ́ Tí Natani Jẹ́ fún Dafidi.
Ikú Olumegbon: Ọdún mọ́kàndínlọ́gọ́ta ló lò lókè èèpẹ̀, kó tó mí kanlẹ̀
Ó sọ fún Ọlọrun pé kí ó gba ẹ̀mí òun.
Bẹẹ lo tun sọ nipa orilẹ-ede Chad to dẹwọ bi awọn eeyan ṣe n lo ori ayelujara rẹ lati kapa ọrọ ikorira.
Baba gbogbo ilu Iwo ni mo jẹ, Ẹẹmẹta lsẹ la n pin ounjẹ fawọn ti ko ni lati jẹ.
Dafidi ọba bá wọlé, ó jókòó níwájú OLUWA, ó sì bẹ̀rẹ̀ sí gbadura pé, “Ìwọ OLUWA Ọlọrun!
Ó fi Sadoku, alufaa ati àwọn alufaa ẹlẹgbẹ́ rẹ̀ sí ibi Àgọ́ OLUWA ní ibi pẹpẹ ìrúbọ tí ó wà ní Gibeoni, 
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Marriage Certificate: Bí o ṣe lè mọ ìgbéyàwó tí kò bá òfin mu 27 Agẹmo 2019 Oríṣun àwòrán, OTHER Ibi ijọsin irinwo le mẹrinla (314) nikan lo niwe aṣẹ lati ṣegbeyawo ki wọn si fun ni ni iwe ẹri.
Ó wà ní àkọsílẹ̀ níbi tí ẹnìkan ti sọ pé,“Kí ni eniyan, tí o fi ń ranti rẹ̀,tabi ọmọ eniyan tí o fi ń ṣe ìtọ́jú rẹ̀?
ọ̀pọ̀ Onilé àti Abániwále bẹ̀rẹ̀ si lu jìbìtì nipa gbi gba owó lọ́wọ́ ọ̀pọ̀lọpọ̀ Agbalésanwó lóri ilé kan ṣoṣo, òmíràn ngba owó lóri ilé ti ki ṣe ti wọn.
Bí ọkunrin náà ti rọ̀ mọ́ Peteru ati Johanu, gbogbo àwọn eniyan sáré pẹlu ìyanu lọ sọ́dọ̀ wọn ní ọ̀dẹ̀dẹ̀ tí à ń pè ní ti Solomoni.
eto idibo ni ipinle Rivers nitori awon wahala to sẹlẹ ni ọjọ kẹ́sán án ,osu kẹ́ta
 O ti yẹ ki iru ipade yii waye ti pẹ”.
’ rèé Afọnja, ẹni tó finú wénú ní Ilọrin, àmọ́ tó jẹ iwọ Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Adeola Smart and Malivehood Wedding: Diamond kún ara aṣọ ìyàwó, Cake jẹ́ alájá 1611 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Ikú Djxgee: DJsosogee ní olóògbé fẹ́ràn ẹbí àti ọmọ3 Sẹ́rẹ́ 2019 2:23 Fídíò, Water Generator: Ó leè ṣiṣẹ fún wákàtí mẹfà, kó tó sinmi, Duration 2,2310 Òkùdu 2020 500 Teeth: Àgbọ̀n ọmọ náà tó wú làwọn obi rẹ̀ gbe lọ sí ilé ìwòsàn1 Ògún 2019 Ẹ wo fídíò bí eyín akọ̀ròyìn ṣe fò yọ lásìkò tó n ka ìròyìn lọ́wọ́ lórí tẹlifísàn19 Agẹmo 2020 Church of Satan: Báwo ni ìjọ́sìn ṣe n rí nínú ìjọ Sátánì?
Wọn fi ipa le Jammeh kuro nipo l'oṣu Kinni, ọdun 2017 lẹyin ti awọn alaṣẹ ẹkun naa ran awọn ọmọ ogun lọ si orilẹede Gambia nigba ti Jammeh kọ lati kuro ni iṣakoso.
Wọ́n bẹ̀rẹ̀ sí wá Jesu, wọ́n ń bá ara wọn sọ̀rọ̀ bí wọ́n ti dúró ninu Tẹmpili pé, “Kí ni ẹ rò?
Goolu mẹta ni Barcelona fi n lewaju lati abala kini ifẹsẹwọnsẹ wọn lọsẹ to kọja amọ Liverpool da goolu na pada ti wọn si tẹsiwaju lati bori Barcelona pẹlu ami ayo mẹrin si mẹta.
Bí ó ṣe gbé ojú sókè, ó rí ẹyọ ẹnìkan ṣoṣo tí ó ń sáré bọ̀.
Wọn o fẹran bi koṣe bawọn alawọ funfun wi nigba ti wọn ba ṣe aṣemọṣe.
Asofin naa wi pe ti wọn ba se eyi, yoo da eto ifowopamọ orilẹ-ede yi pada s'ipo.
O ni oun tun ṣiṣẹ apero sọkọ ati iṣẹ akọle, birikila ṣugbọn iṣẹ Fuji lo yọ ọpọ eeyan to n kọ Fuji loko ẹru.
Ọlọrun ti jẹ́ kí n gbẹ̀san lára àwọn ọ̀tá mi,ó ti tẹ orí àwọn orílẹ̀-èdè ba lábẹ́ mi;
Ọmọ ọgọ́ta ọdún ni Bàbá rẹ̀ nígbà tí ó kú.
Suliat Ogundele, to jẹ ọdọmọde akewi, to n fi ẹṣa egungun ki awọn eniyan lo ba BBC Yoruba lalejo.
Nítorí orúkọ rẹ ni a fi ń pè mí, OLUWA Ọlọrun àwọn ọmọ ogun.
Oríṣun àwòrán, @iKingMillie Millie ni ọsan ni oun n kiri lọ nigba ti oun wa ni kekere, ti oun si pada ọmọbinrin naa.
Unko Museum yìí n ran àwọn ènìyàn lọ́wọ́ láti rí ìgbọ̀nsẹ̀ bí nkan tó rẹwà
Dino: Àwòrán Omo Agege tí Dino fi síta ń fa àríyànjiyàn
Bakan naa lo ṣiṣẹ bii olori awọn obinrin fidiẹ fun ẹgbe APC lẹyin ti wọn darapọ lọdun 2014.
Ẹ̀yin ará Lakiṣi, ẹ de kẹ̀kẹ́ ogun yín mọ́ ẹṣin; ọ̀dọ̀ yín ni ẹ̀ṣẹ̀ ti kọ́ bẹ̀rẹ̀, tí ó sì tàn lọ sí ọ̀dọ̀ àwọn ará Jerusalẹmu, nítorí pé nípasẹ̀ yín ni Israẹli ṣe dẹ́ṣẹ̀.
Yoruba si ni bi iku ile ko ba pa ni, ti ode ko le pa ni, akọsilẹ si fihan pe, awọn ọmọ Adulawọ kan pẹlu idile wọn lo n ta awọn Adulawọ ẹgbẹ wọn fawọn oyinbo alawọ funfun, ti owo ẹru fi gbilẹ.
fun aare ana naa, fun ipa ribi-ribi ti o n ko lati mu idagbasoke ba orile ede
Adunni Oluwole, akọni obìnrin tó tako òmìnira Nàìjíríà, ó ní òyìnbó kò gbọ́dọ̀ lọ Kí ni apẹ̀rẹ̀ ikòlẹ̀sí Eko fi yàtọ̀ sí ti Ekiti tí ọ́ọ́físà mú wa mọ́lẹ̀?
Àwọn kan ń sọ pé, “Kí ni aláhesọ yìí ń wí?
”Danbatta tun so pe “Won ti gbe oku awon olote naa lo sile iwosan ijọba .
Ni aarin ọsẹ yii ni iroyin kan jade si igboro aye pe lori idubulẹ aisan ni gomina ana ni ipinlẹ Ọyọ ọhun wa ni ileewosan nla kan nilu Eko.
“O kò gbọdọ̀ lọ sí ilé tí wọ́n ti ń se àsè, má bá wọn jókòó láti jẹ tabi láti mu.
Yàrá pupọ ni ó wà ninu ilé Baba mi.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Forbes 2018 list: Àwọn ọmọ Nàìjíríà dẹ́bi àdínkù tó bá owó Dangote rú Ààrẹ Buhari 10 Sẹ́rẹ́ 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 11 Sẹ́rẹ́ 2019 Oríṣun àwòrán, ERIC PIERMONT Àkọlé àwòrán, Pupọ ninu owo Dangote wa lati idi ọja Dangote Cement rẹ Ilumọka oniṣowo ọmọ orileede Naijiria Aliko Dangote ṣi ni ẹni to lowo julọ nilẹ Afrika ṣugbọn o da bii wi pe adinku ti ba owo rẹ.
ṣé ẹni tí ń kọ ilẹ̀ tí ó fẹ́ gbin ohun ọ̀gbìnlè máa kọ ọ́ lọ láì dáwọ́ dúró?
Arabinrin Cheney to jẹ ọmọ igbakeji aarẹ Amẹrika tẹlẹ rí, Dick Cheney fi aake kọri, o ni oun yoo gbaruku ti Democrat lori àti yọ Trump nipo.
“Àwọn òfin tí OLUWA fún gbogbo yín nìyí, nígbà tí ẹ fi péjọ lẹ́sẹ̀ òkè, tí ó fi fi ohùn rara ba yín sọ̀rọ̀ láti inú iná ati ìkùukùu, ati òkùnkùn biribiri.
Mide Martins Mide Martins ati ọkọ rẹ, Afeez Owo lẹ pọ ninu sinima ti akori rẹ n jẹ ''SALAWA.
Lẹ́yin ti ile alaja kan wo lu eniyan meji ni adugbo Mafoluku ni Oshodi, Ipinlẹ Eko, ni ajọ to n koju isẹlẹ pajawiri ni Ipinlẹ Eko (LASEMA) sọrọ.
Laarin awọn eekan ilu bii olori ile asofin agba, Bukọla Saraki ati alaga ẹgbẹ oselu PDP lorilẹ-ede yii, Uche Secondus, ti wọn peju sibi asekagba eto ipolongo ibo ọhun, ni Adeleke ti gba ijo.
Lẹ́yìn tí ó ti ní kí wọ́n na Jesu tán, ó bá fà á fún wọn láti kàn mọ́ agbelebu.
Ìgbìmọ̀ sọ èyí nínú àtẹ̀jáde kan tí àwọn adarí ìgbìmọ̀ ẹlẹ́ni mẹ́ta ọ̀hún, Comrade Ayuba Wabba, Comrade BAla Bobboi Kaigama àti Comrade Joe Ajaero fọ́wọ́ sí.
 Àwọn náà ló gba Ẹ ̀ gbá kalẹ ̀ lọ ́ wọ ́ ìyà tí Ọlọ ́ yọ ̀ ọ ́ àti àwọn Ìlàrí rẹ fi ń jẹ wọn .
Igbimọ yii ni yoo ma a mojuto idanilẹkọ, atilẹyin ati imọra fun awọn ọlọpaa to ba n ṣe akaṣe iṣẹ.
Alapinni Ooṣa ṣalaye ipa pataki ti àwọn baba nla tiata bii Hubert Ogunde ko nigba aye wọn ni eyi ti o fi jẹ pe kikọ ni mímọ̀ ni wọn n fi ọrọ iṣẹ ere ori itage ṣe ni akoko naa.
Lẹ́yìn náà, OLUWA tún wí fún Mose pé, 
Wọn kii jagun tabi ba ara wn ja loṣu yi.
Ijamba ohun waye niwaju gbongan oko oju-irin ti o wa ni Kom Hamada.
Ọjọ meje ṣẹyin ni wọn gunlẹ iyanṣelodi lati pe akiyesi ijọba si awọn ohun to jẹ ẹdun kan fun wọn.
Wọ́n yan Filipi náà ati Prokoru ati Nikanọ ati Timoni ati Pamena ati Nikolausi ará Antioku tí ó ti gba ẹ̀sìn àwọn Juu.
Awọn ọmọ Naijiria ko fi ara ire gba imọran rẹ lori igbeyawo!
Lẹ́yìn náà, OLUWA fara han Solomoni lóru, ó ní, “Mo ti gbọ́ adura rẹ, mo sì ti yan ibí yìí ní ilé ìrúbọ fúnra mi.
Uganda faulty condom: Uganda kó rọ́bà ìdáàbòbò mílíọ̀nù kan kúrò ní ìlú
Maria Sharapova setan lati fopin si ibasepo oun ati akonimoogba re, Sven Groeneveld.
Ẹ kò rí bí ọkunrin yìí ti jẹ́ eniyan pataki tó, tí Abrahamu baba-ńlá wa fi fún un ní ìdámẹ́wàá àwọn nǹkan àṣàyàn ninu ìkógun rẹ̀.
Ikọ agbabọọlu Brazil ti kọkọ ta ọmi alayo kọọkan pẹlu Senegal l'Ọjọ ọsẹ to lọ nibu ifẹsẹwọnsẹ ọlọọrẹsọọrẹ.
 ohùn orin ni èkejì tí a máa ń bá pàdé nínú eré àpíìrì .
Bio tile jepe, iko agbaboolu CHAN Eagles torile-ede Naijiria sa gbogbo ipa won denu asekagba idije CHAN 2017 ti o waye lorile-ede Morocco, sugbon omi poju ooka lo ninu ifigagbaga ohun, leyin ti iko CHAN torile-ede Morocco ti o sagbateru idije naa gbo ewuro si iko ohun loju pelu ami-ayo merin sodo(4-0), ninu ifesewonse ti o waye ni papa isere Casablanca.
Yóo rẹ àwọn ọ̀dọ́ pàápàá, agara óo sì dá wọn,àwọn ọdọmọkunrin yóo tilẹ̀ ṣubú lulẹ̀ patapata.
Ẹwẹ, bi eto naa ṣe nlọ ni awọn to n wo o nile naa n fi iha ti o kọ si wọn ṣọwọ loju opo facebook bbcnewsyoruba.
Buhari ti buwọ́lu ẹ̀kúnwó sísan owó oṣù tuntun fáwọn òṣìṣẹ́ àpapọ̀ Super Eagles gba iṣẹ́ lọ́wọ́ Seedorf olùkọ́ni Indomitable Lions Cameroun Wá gbọ́ ìmọ̀ràn tí Jonathan fún Buhari lórí ọmọ Fasoranti tó kú!
Auxilliary : Sunday Igboho kìí ṣe ọmọ ìbàdàn, òun gan ló ń dá Ibadan ru
Ó sọ fún un pé, “Máa tẹ̀lé mi.
Àwọn tí wọ́n wò ó sọ àwọn nǹkan tí kò tẹ́ wọn lọ́run, wón sì tún pè fún àyípadà.
Ní ọdún keje Jehoiada alufaa mọ́kàn gírí, ó lọ bá àwọn marun-un ninu àwọn balogun dá majẹmu.
Wo ọ̀nà tí Yoruba ń gbà dá ọmọ àlè mọ̀ nínú ìdílé- Elebuibon Àlàyé rèé lórí bo ṣe le è dá Emèrè mọ̀ tàbí dara pọ̀ mọ́ ẹgbẹ́ wọn Afeez Ọwọ: Èmi kọ́ ni mo kọ́kọ́ làwòrán Orisabunmi, ẹ ti ṣe wá rangun mọ́ mi?
Lọwọ yii, olukọni ni ni ileewe ẹkọṣẹ olukọni agba, Adeniran Ogunsanya College of Education ni ilu Eko.
Ó wá sọ fún wọn pé, “Nígbà tí mo ran yín níṣẹ́ tí mo sọ fun yín pé kí ẹ má mú àpò owó ati igbá báárà lọ́wọ́, ati pé kí ẹ má wọ bàtà, kí ni ohun tí ẹ ṣe aláìní?
Tiffani Adams ni obinrin kan to fidi ẹ mulẹ pe ko si ohun tuntun labẹ ọrun mọ ni papakọ ofurufu Toronto Pearson.
Ohun tó ṣẹlẹ̀ ni wí pé, nígbà náà mi ò tíì máa fi ojú ara ṣe bíi ẹni tó nílò ìbálòpọ̀.
Itakun 5G yoo faaye gba keeyan maa gba fidio ati fifi fidio sita to fi mọ wiwo fidio to mọ gaara to si ja fafa, Tim Cook, oludari ileeṣẹ naa lo sọ bẹẹ.
Ṣaaju ni awọn afọbajẹ ọhun ti kọwe mọ Oluwo lọdọ gomina ipinlẹ Osun, iyẹn Gboyega Oyetola lọjọ kẹsan an, oṣu Kẹsan an, ọdun 2020.
Ori mi maa n wu ti mo ba ri awọn ọmọ to ni obi to fi ifẹ han wọn.
awon omo orile ede Naijiria bi won se gba alaafia laaye lasiko eto idiboohun.
Wo bí David Lyon ṣe fàgbà han Douye Diri ti ẹgbẹ́ PDP ní Bayelsa Ẹ máa retí láti ìpínlẹ̀ Kogi!
Ẹni tí ó bá wá sọ́dọ̀ mi, tí ó ń gbọ́ ọ̀rọ̀ mi, tí ó ń ṣe é, n óo sọ fun yín ẹni tí irú ẹni bẹ́ẹ̀ jọ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Akomolede àti Aṣa: Ọ̀rọ̀ Ẹ̀yán ni Bunmi Femi Amao ń kọ́ wa lórí ètò Akọ́mọlédè àti Àṣà lóri BBC Yoruba ''Ohun to buruju ni wi pe awọn oloṣelu to fi owo kun owo epo, ina ọba kii san owo kankan lati ra nkan wọnyii, ọfẹ ni wọn n rii lọ''.
Ọjọgbn ilẹ Amẹrika John Paden tẹnu bọ ibaṣepọ to wa laarin Buhari ati Daura o si ni o ti pẹ ti wọn ti jọ n ṣe nkan papọ.
Wo ìgbà mẹ́rin tí ìjọba ti tú ikọ̀ ọlọ́pàá SARS ká sẹ̀yín ṣùgbọ́n.
Oríṣun àwòrán, Facebook/Babajide Sabwo-Olu Taiwo sàlàyè pé lẹ́yìn ti gbogbo ǹkan tó wáyé sááju ọjọ náà, àga ọlọ́pàá ti wọ́n jó, pipa àwọn ọlọ́pàá,.
OLUWA bá kọ àwọn òfin mẹ́wàá tí ó kọ sí ara àwọn tabili àkọ́kọ́ sára àwọn tabili náà, ó sì kó wọn fún mi.
Nítorí náà ẹ má ṣe fi ara wé wọn.
“Pàṣẹ fún àwọn eniyan Israẹli pé kí wọn mú ojúlówó òróró olifi wá fún àtùpà ilé mímọ́ mi, kí ó lè máa wà ní títàn nígbà gbogbo.
Nebusaradani olórí àwọn ẹ̀ṣọ́ fi díẹ̀ ninu àwọn talaka sílẹ̀ ní ilẹ̀ Juda, ó sì fún wọn ní ọgbà àjàrà ati oko.
Ó fetí sílẹ̀, Ọlọrun ṣí i lọ́kàn láti gba ohun tí Paulu ń sọ.
orile-ede Brazil, Richalison lo gba lo gbayo akọkọ wọ le, niṣẹju die ti saa
Ninu awọn ipinlẹ ti yoo wọle pada ṣẹnu ẹkọ lọjọ Aje ni ipinlẹ Cross Rivers wa.
"Mo rọra bọ si inu ile kan to wa ni ẹgbẹ ileewosan Akala, ni Oke Elerin, nilu Ogbomọṣọ.
Lakọkọ bi ẹ ba wo o daadaa, o lee da ẹmi ọmọde legbodo."
Àmúwá Ọlọ́run lásán ní ìṣẹ̀lẹ̀ tó wáyé ní Iba-Eburu Iba Oba Okunoye Ènìyàn 27 lo ti bá iṣẹ̀lẹ̀ ọkọ̀ ofúrufú tó já rìnrìn ajò Atẹjade kan ti ẹgbẹ osisẹ nipinlẹ Ondo fisita ni irọlẹ ọjọ Ẹti, eyi ti wọn kọ si gomina Akeredolu, ti wọn si tun fi le awọn akọroyin lọwọ, lo sisọ loju rẹ nipa iyansẹlodi ti wọn fẹ gunle.
Rohr wa fi oro naa mule bayii pe, ko seese ki oun koyin si iko agbaboolu Super Eagles.
Lati ọjọ́ ti aláyé ti dá ayé ni Olówó tàbi Ọlọ́rọ̀ ti wà.
O ni ki awọn ọmọlẹyin Kristi fi asiko yii ṣe iranti iṣẹ igbala ti Jesu Kristi ṣe lataari bibi ti a bii sinu ibujẹ ẹran yii.
O ni ijọba Osun ṣetan lati tẹle gbogbo awọn ilana ti ijọba apapọ la kalẹ lori ṣiṣi ileewe lasiko yii.
Ẹ kúuṣẹ́, OLUWA óo fèrè sí i.
Lẹyin ipade igbimọ alaṣẹ ẹgbẹ naa ni wọn kede Egypt saaju orileede South Africa gẹgẹ bi orileede ti yoo gbalejo idije Afcon 2019.
Àwọn mejeeji na ìyẹ́ wọn tí ó fi jẹ́ pé ọ̀kan ninu àwọn ìyẹ́ Kerubu kinni kan ògiri yàrá ní ẹ̀gbẹ́ kan, ọ̀kan ninu àwọn ìyẹ́ Kerubu keji sì kan ògiri yàrá ní ẹ̀gbẹ́ keji.
Awọn orilẹde bi Kenya ati Somalia ti tilẹkun ibode rẹ mọ awọn eeyan lati ilẹ okere ti arun ọhun ti ṣọṣẹ julọ, bẹẹ lawọn orilẹede kan ti tilẹkun ile iwe atawọn ile ijọsin.
Ìjọba ìbílẹ̀ kan péré ló kù kí a pìn oúnjẹ tí wọ́n jí gbé fún ní Ilorin- Ijọba Kwara Oríṣun àwòrán, Abdulrahman Abdulrazaq Ijọba ipinlẹ Kwara bu atẹ lu awọn to ja ile igbeohun ini Covid-19 si Won ni: ''Ijọba ibilẹ kan lo ku ki a pin awọn ounjẹ iranwọ Covid-19 ti awọn eniyan jigbe lo fun'' Ijọba ipinlẹ Kwara ti ni iwa buruku ni awọn janduku to ja ile igbe ohun ini iranwọ Covid-19 si hu ni ilu Ilorin.
Lulu sọ pé ''ní kété tí mo fi ìwé ìpè ránṣẹ́, ni àwọn ènìyàn bẹ̀rẹ̀ sí pè mí pé taa ni ọkọ ìyàwó, ṣùgbọ́n mo sọ pé ìyàlẹ́nu ni mó fẹ́ fi ṣe fún wọn.
Àwọn wòòlí ń takora lórí ẹni tí yóò di ààrẹ láàrin Buhari àti Atiku
ati ìrètí ìyè ainipẹkun, tí Ọlọrun tí kì í purọ́ ti ṣèlérí láti ayérayé.
Agbaboolu owo iwaju iko Bordeaux, Samuel Kalu nireti wa pe yoo darapo mo awon akegbe re loni.
” Nítorí náà wọ́n jọ lọ sí Jẹriko.
Wike kìí ṣe dọ́là tí Ganduje leè kó sápò- Agbẹ́nuso ìjọba ìpínlẹ Rivers Ìfẹ̀hónúhàn l'Abuja lórí ìdájọ́ ilẹ̀ Gẹ̀ẹ́sì tó gbẹ́sẹ̀ lé $9.
O ni ti won ba gba abadofin naa wole, agbekale eka yii yoo so eto oro aje awon eniyan ipinle Eko ji, nitori pe ero pupo yoo maa wa kaakiri agbaye wa sinmi ni Eko ni.
Ẹwẹ, gbajugbaja ọjiṣẹ Ọlọrun nipinlẹ Enugu, Fada Ejike Mbaka sọ asọtẹlẹ nipari ọdun 2019 pe ki Gomina Ihedioha palẹ ẹru rẹ mọ nitori Uzodimma ẹgbẹ APC yoo di gomina ipinlẹ Imo lọdun yii.
Bí ó ti wọlé, ọba dìde, ó tẹríba fún ìyá rẹ̀, ó sì kí i tọ̀wọ̀tọ̀wọ̀, ó bá tún jókòó sórí ìtẹ́ rẹ̀, ó ní kí wọ́n gbé ìjókòó kan wá, ìyá rẹ̀ sì jókòó ní apá ọ̀tún rẹ̀.
Alamojuto ileeṣẹ rẹ, lo fi ọrs sita faraye gbọ.
”Ewe, bi o ti le je pe, ile ise akoroyin Reuters ti jabo isele ohun pe awon olopaa n se iwadii lowo lori isele naa, sugbon ti won ko so ni pato bi o se ku.
Awon osise CBN fikun un oro ohun pe, pataki adehun naa ni lati dekun fifi eyin ti owo dola, bee si ni lati mu adinku ba sise pasipaaro dola si Naira.
2bn Naira tó fẹ́ ẹ yá lọ́wọ́ Brazil Wo iye àwọn tí wọ́n ti gbà sí ikọ̀ SWAT báyìí àti òfin ti wọ́n fún wọn Ọ̀rọ̀ ìjókòó ìgbìmọ̀ ìwádìí #EndSARS náà dé ìpínlẹ̀ Ogun Àwọn ọ̀dọ́ dáná sun ọkọ̀ akérò tó ṣekúpa ọlọ́kadà ní Ibadan O fi kun pe awọn eeyan to maa n dana sun ọkọ n ru ofin to rọ mọ didana sun dukia.
Aisha Buhari ní ìfẹ́ ìdájọ́ òdodo ti òun ní ló fàá tí òun fi ṣe bẹ́ẹ̀.
AFCON 2019: Rohr já Iheanacho àti Semi jùú lẹ̀ lọ Egypt
Irú anfaani ńlá báyìí kò tọ́ sí mi láti ọ̀dọ̀ ọba, nítorí náà, n óo bá ọba gun òkè odò Jọdani, n óo sì bá ọ lọ sí iwájú díẹ̀ ni.
lasiko ipolongo idibo fun  aare to waye
Issa ti wọn ṣẹṣẹ yan si ipo alaga sọ pe lootọ ni o da ki oṣiṣẹ tete gba owo oṣu ''amọ ko tọ ki wọn ti gba owo iṣẹ ti wọn ko ti ṣe rara'' Àkọlé àwòrán, Ipade to waye laarin minisita fọ̀rọ̀ osisẹ́ ati ijọba apapọ fori sanpọn nitori igun mejeeji ko lee fi ẹnu ọrọ jona Nipa sisan owo oṣu fawọn oṣiṣẹ ni Kwara o ni ijọba ibilẹ ni wahala wa ti owo oṣu ko lọ deede.
Wọ́n kúrò ní Sukotu, wọ́n lọ pàgọ́ sí Etamu tí ó wà létí aṣálẹ̀.
mu idagbasoke ba awon to wa ni igberiko.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Àwọn agbébọn jí ìyàwó bàbá Sẹ́nétọ̀ Abbo tó lu obìnrin nílùú Abuja gbé ní Adamawa 13 Agẹmo 2019 Oríṣun àwòrán, Nigeria National Assembly Àkọlé àwòrán, Sẹnetọ Abbo sọ fun BBC news Yoruba pe iya oun gan ni wọn kọkọ n beere fun kí wọn to fi ipa ji iyawo baba oun to ṣẹṣẹ bimọ gbe Ṣe ẹ ranti Sẹnetọ Ishaku Abbo ti fidio fihan laipẹ yii nibi to ti n lu arabinrin kan nile itaja nilu Abuja?
"Wọ́n ní àwọn yóò fi ẹ̀mí wa ṣòfò, ni mo bá fi owó ránṣẹ́ sí àpò owó tirẹ̀ lórí ẹ̀rọ ayélujára kí wọ́n baà lè tọpinpin wọn""."
Ùgbà rẹ á tu ùlú Àkúrẹ́ lára (Àṣẹ)
Wọn si tun ma n bẹ wọn wo lẹyin rẹ.
gbọ́ láti ibùgbé rẹ lọ́run; kí o sì ṣe gbogbo ohun tí àjèjì náà bá ń tọrọ lọ́dọ̀ rẹ, kí gbogbo àwọn eniyan tí wọ́n wà láyé lè mọ orúkọ rẹ, kí wọ́n sì máa bẹ̀rù rẹ, bí àwọn eniyan rẹ tí ń ṣe, kí wọ́n lè mọ̀ pé ilé ìjọ́sìn ní orúkọ rẹ, ni ilé tí mo kọ́ yìí.
Ẹ sa ipá yín, níwọ̀n bí ó bá ti ṣeéṣe, láti wà ní ìrẹ́pọ̀ pẹlu gbogbo eniyan.
Gomina sọ pe, eto ironilagbara ti orukọ rẹ n jẹ Osun Youth Empowerment Scheme (OYES) ni ijọba fi kan si ọpọ araalu.
Òfín tuntun yìí rii dáju pé Emir ìlú Kano Alhaji Muhammed Sanusi Lamido Sanusi keji ti gbogbo ènìyàn mọ bi alágbára to si níkì láàrín àwọn ọba àti ẹlẹ́sìn ní orilẹ̀-èdè Naijirià ní wọn ti ìdá kan nínú ìdá márùn àgbára rẹ̀ sílẹ̀ fún, Wọn ṣe àgbákalẹ̀ àwọn ìjọba mẹ́rin míràn ti àwọn náà yóò si ná ààfin wọn.
 Ojogbon Osinbajo sọrọ yii nibi idanilẹkọọ ikẹkọọ-gboye awon akẹkọọ to waye
O ni iwa ti wọn hu lodi si ofin to rọ mọ iwa ọdaran ipinlẹ Ogun ti wọn gbe kalẹ lọdun 2006.
Laiko aarun Coronavirusw yii ni Oyedepo bu ẹnu atẹ lu ijọba aarẹ Muhammadu Buhari lori bi o ṣe gba ki ọja maa si , amọ ki awọn eniyan ma lọ si ile ijọsin.
Minisita to n mojuto eto iroyin ati asa lorile-ede Naijiria, Alhaji Lai Mohammed so pe eri to munadoko fihan-gbangba wipe egbe oselu alatako PDP ati awon emewa re n gbero lati ma jeki isakoso isejoba egbe oselu All Progressives Congress APC, eleyi ti aare Mohammadu Buhari n tuko re lojutu bi o se le wu komo.
Gẹ́gẹ́ bí òfin, ilé ẹjọ́ lé gbé ìgbésẹ̀ tí ó tako irúu ìdájọ́ báwọ̀nyí yálà láti ọ̀dọ̀ àwọn panchayat tí ìbó yàn àti panchayat ipò-ìsàlẹ̀.
Adebayọ Adelabu - APC Àkọlé àwòrán, ìpàdé ìfọ̀rọ̀wérọ̀ BBC Yorùbá Lori ọrọ eto ilera, Adelabu ni ilera jẹ ara ohun mẹta ti iṣejọba oun la kalẹ.
Kí sì ni ẹ̀ṣẹ̀ ilé Juda?
Ṣé o rí ohun tí olukuluku ń ṣe ninu yàrá tí ó kún fún àwòrán ère oriṣa?
Ohun ti awọn alaṣẹ idije naa n gbero ni lati gba gbogbo ifẹsẹwọnsẹ to ku tan laarin ọsẹ mẹfa ni kete ti idije naa ba ti bẹrẹ pada.
Èyí ni ẹ óo máa wọ̀, tí yóo máa rán yín létí àwọn òfin OLUWA, kí ẹ lè máa pa wọ́n mọ́; kí ẹ má fi ìwọ̀ra tẹ̀lé ìfẹ́kúfẹ̀ẹ́ ọkàn yín ati ìfẹ́kúfẹ̀ẹ́ ojú yín.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Snake Market: Àwọn òńtàjà ní àwọn ń sin ejò fún títà ni, wọn kìí ko nínú igbó Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Snake Market: Àwọn òńtàjà ní àwọn ń sin ejò fún títà ni, wọn kìí ko nínú igbó 5 Ògún 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 13 Bélú 2020 Ọpọ eeyan lo maa n sa fun ejo, ti wọ̀n kii si jẹ rara.
Ninu ọrọ tirẹ, Ọọni Ile Ife, Ọba Adeyeye Enitan Ogunwusi rọ awọn Mususlumi lati lo asiko fi dupẹ fun idasi ẹmi ati ojurere Allah si awọn ọmọ Naijiria.
nítorí pé àwọn eniyan yóo sá kúrò ní ààfin,ìlú yóo tú, yóo di ahoro.
Ibo Italy: Ọmọ Naijiria di asofin agba ni Italy
Fulani herdsmen: Mo ti Buhari lẹ́yìn ṣùgbọ́n ìjínigbé ìgbà gbogbo yìí náà ń kọmí lóminú
O jẹ ọmọ ọgọta ọdun oloṣelu lati ipinlẹ Plateau.
, ko si eni to gbọdọ fiya jẹ wọn ,nitori pe won fe gba esun lati ẹnu won,labẹ
 ni gomina Ajimobi tun se ifilole
Mo ranti orúkọ rẹ lóru;OLUWA, mo sì pa òfin rẹ mọ́:
"Iyalẹnu ni pe o ṣọ fun awọn eeyan rẹ to ri i pe oun kọ lo fun mi loyun.
Ifura ni oogun agba titi di aye ode oni, gbogbo igba ni ki a maa gbọ ohun ti ara ba n sọ fun wa.
Ó ṣe ohun gbogbo dáradára, ní àkókò rẹ̀.
Awọn ẹkọ ti owe yii kọ ree: Ka maa fi suuru lo ile aye Ka maa gbọ ibawi, ka si tun gbọrọ sawọn obi wa lẹnu Ka maa maa fi waduwadu gbọ ọrọ tabi gbe ọrọ kalẹ Ka maa maa fi ẹnà ba awọn ọmọ wa sọrọ, ka si maa jẹ ki alaye wa kun Ka mase dẹja ohun ti awọn agba ba pe ni eewọ nitori pe o lewu pupọ.
Awon agbofinro bẹrẹ si n ju ero
Àwọn ọmọ ilẹ Indonesia ṣe ìwọ́de lóri fífòfin de ìbalòpọ ṣáájú ìgbéyàwó 3.
Ṣaaju ni Sultan pàṣẹ fún àwọn mùsùlùmí láti ṣ'ọdẹ òṣùpá lónìí ṣugbọn bayii oun funra rẹ ti ri i o si ti kede rẹ.
awon omo ogun duro digbi fun oniruuru ikolu lati owo awon omo ogun olote,“Itoju ati igbardi ti o fi mo awon ohun
Wo fidio yii fun alaye kikun lori awọn ipenija ti abẹrẹ ajẹsara Covid-19 yoo dojukọ ati awọn ọna abayọ sii.
Ẹ óo jẹ ọ̀rá ní àjẹyó, ẹ óo sì mu ẹ̀jẹ̀ ní àmuyó ní ibi àsè tí n óo sè fun yín.
O fẹ́ràn òtítọ́ inú;nítorí náà, kọ́ mi lọ́gbọ́n ní kọ́lọ́fín ọkàn mi.
“Ìbẹ̀rù yí i ká,wọ́n ń lé e kiri.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ekiti: Ọwọ́ ọlọ́pàá tẹ afurasí tó pa ìyàwò lárìnlọọ̀dù lẹ́yìn tó fipá bá a lòpọ̀ 28 Ògún 2019 Oríṣun àwòrán, daily post Ọwọ ọlọpaa ti tẹ arakunrin ẹni ọdun mọkandinlọgbọn kan ti orukọ rẹ n jẹ Tunmiṣe Abraham ti wọn fi ẹsun kan pe o gbẹmi obinrin onile rẹ lẹyin to fi ipa ba a lo pọ.
Kano: Omidan, rìn jáde láago mẹ́jọ alẹ́ ko rẹ́wọ̀n he
fun awon iwa  titẹ ẹtọ ọmọniyan mọlẹ ati
Ṣugbọn Saulu gbọ́ nípa ète wọn.
Ṣugbọn o ni ilera ara oun ṣe pataki ju owo ti oun padanu lọ nitori igbesẹ ijọba to fofin de irin ajo sawọn orilẹede ilẹ okeere ti arun coronavirus ti ba wọn finra.
nítorí pé àwọn ará Edomu tún pada wá gbógun ti Juda; wọ́n ṣẹgun wọn, wọ́n sì kó àwọn kan ninu wọn lẹ́rú lọ.
Kàkà bẹ́ẹ̀, olukuluku ń ṣe ohun tí ó wà ní ọkàn burúkú rẹ̀.
''Ko tiẹ dabi ẹni pe Barrister tiẹ ku rara, nitori gbogbo igba laye si n gbọ orukọ rẹ,'' Obesere lo woye bẹẹ.
Ìjọba ń rọ àwọn olugbé etí odò láti kúrò níbẹ̀, gẹ́gẹ́ bi akọ̀ròyìn BBC, Ishaq Khalid ṣe sọ pé ìṣẹ̀lẹ̀ aburú yìí kárí Nàìjíríà ní sùgbọn ìpínlẹ̀ Niger ní àwọn ènìyàn ti kú jùlọ, ọ̀pọ̀ àwọn ìpínlẹ̀ tó wà ní ẹkùn aarin gbùngbùn Nàìjíríà lọ̀rọ̀ náà kàn.
Onírúurú ìròyìn ló ti tàn kálẹ̀ tí gómìnà ìpińlẹ̀ Eko sì ti jáde pé àwọn àgbára kan tó jú òun lọ ló ṣe ìṣẹ́ ibí náà, àti pé, gbogbo ìwádìí tó bá yẹ ni ìjọba yóò ṣe láti ríi dájú pé, ìdájọ́ òdodo jẹyọ fún àwọn tó pàdánù ẹ̀mí wọ́n tàbí tí wọ́n fara gbọgbẹ́.
Ẹgbẹ oselu meji ti o n koju aarẹ Ramophosa ti ANC ni Democratic Alliance (DA) ati Economic Freedom Fighters (EFF).
Ambode pe fun ijiya ẹwọn ọdun mẹẹdọgbọn fun afipabanilopọ
OLUWA, ranti ohun tí àwọn ará Edomu ṣenígbà tí Jerusalẹmu bọ́ sọ́wọ́ ọ̀tá,tí wọn ń pariwo pé,“Ẹ wó o palẹ̀!
“Mò ń ṣe ìdárò rẹ,Jonatani arakunrin mi;o ṣọ̀wọ́n fún mi lọpọlọpọ.
Ọkan lara awọn ọmọ ẹgbẹ Orange Movement sọ fun awọn oniroyin pe awọn ọlọpaa ni pe ẹgbẹ naa ko gbaaye lati ọdọ awọn alaṣẹ ki wọn to sẹ agbekalẹ eto ti wọn ṣe nibẹ.
Ileeṣẹ ọlọpaa Ipinlẹ Eko ni, ọrọ yii ki i ṣe lasan nitori wọn ti ba oku arakunrin naa ninu ile igbafẹ kan ni agbegbe Festac l'Eko nibi ti wọn ti funra pe o gbẹmi ara rẹ pẹlu oogun oloro Sniper ni.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ẹ̀mí márùń bá ìjà OPC lọ ní Ìjẹ̀bu Igbó A kò fẹ́ bàbá àgbà mọ́ nípò ààrẹ - Fayose Rashidi Ladoja: Kí Bùhárí gbé àpótí ìbò wò Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Ṣé ìjọba ìpínlẹ̀ Rivers wó mọsálásí tàbi wọ́n ò wóo?
Nnamdi Kanu: Ilé ẹjọ́ wọ́gilé béèlì Nnamdi Kanu
O ni ijọba to kọkọ ni Sunmọmi ni awọn Fulani ti wọn tun pada ko ọrọ wọn jẹ pe ọmọ Naijiria ni wọn ni wọn wa n pe awọn ti o jẹ ojulowo ọmọ Naijiria bayii ni ẹgbẹ sunmọmi.
miran ti won nifẹẹ lati dupo adari nile igbimo asoju-asofin ilu Abuja.
“A ni lati maa ṣeranlọwọ ninu ojuṣe awọn agbofinro
ó ní: “Ìwọ ọmọ eniyan, ǹjẹ́ àwọn ọmọ Israẹli, àwọn ọlọ̀tẹ̀ wọnyi kò bèèrè lọ́wọ́ rẹ pé kí ni ò ń ṣe?
Bo tile je pe orile ede naa n la awon ipenija kan koja, sibe o gba awon elewon to wa ni ahamo laaaye lati ri awon ohun amayederun kekere yii lo, bi iru eyi to wa ni Valencia.
Agbẹnusọ Ile Igbimọ Aṣofin Ipinlẹ Eko, Aṣofin Mudashiru Ọbasa ti pe fun ifẹ, iṣọkan ati adura awọn ọmọ orilẹ-ede Naijiria fun ilọsiwaju orilẹ-ede yii.
Ọlọrun tún ṣe bẹ́ẹ̀ ní alẹ́ ọjọ́ náà, nítorí pé, orí irun yìí nìkan ṣoṣo ni ó gbẹ, ìrì sì sẹ̀ sí gbogbo ilẹ̀.
World Food Day: Oúnjẹ àràmọ̀ǹdà mọ́kànlá tí wọ́n ń jẹ lágbààyé rèé
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Akomolede ati Aṣa lori BBC:Wo ìrúfẹ́ ìgbeyàwó méje tó wà nílẹ̀ Yorùbá àti ojúṣe Alárinà Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Ni bayii, iko agbaboolu Real Madrid yoo maa fojusona lati gba ife-eye idije Uefa naa ni igba keta lera won.
Họnọrebu Shina peller, Họnọrebu Akeem Adeniyi Adeyemi ati Alhaji Kunle Sanni ti o jẹ alaga awujọ awọn Musulumi ni fasiti ilẹ Ibadan naa ko gbẹyin ninu ipejọpọ awọn abanikẹdun ti o fi irobinujẹ wọn han lorii ipapoda gomina tẹlẹri nipinlẹ Ọyọ, Ishaq Abiọla Ajimọbi."
Bákan náà, àwọn àgbà obinrin níláti jẹ́ ẹni tí gbogbo ìgbé-ayé wọn bá ti ìsìn Ọlọrun mu.
Orukọ oogun naa- Dukoral Oral Cholera Vaccine/ Vaccin Oral contre le Cholera 2.
Ẹ́ kéde iye ọlọ́pá tó gba rìbá, kẹ tó máa yin ara yín - Aráàlú sọ fún ọlọ́pàá Ẹ wo ìgbà mẹ́jọ tí wọ́n fi àdó olóró já bàálù akérò lulẹ̀ bíì ti ìṣẹ̀lẹ̀ Iran Ìjọba Ondo, inú fìfo la fi ń ṣiṣẹ́, ẹ ṣan ọ̀pọ̀ owó oṣù tẹ jẹ wa - Àwọn dókítà fárígá Òyìnbó ẹni ọdún 46 wá ṣe mọ̀'mí n mọ̀ ọ́ ní Kano pẹ̀lú Isah olólùfẹ́ rẹ̀ Ọlatunji Sanusi to jẹ agbẹjọro ati ẹlomiran ti orukọ rẹ n jẹ Tunde, ni awọn meji ti ọwọ ba pẹlu Oyinbo koraa naa.
''Mi o le gbagbe ọjọ yii nitori pe mo ro pe ọlọjọ lo de ni.
Wọ́n fi okùn so ọwọ́ àwọn olórí rọ̀,wọn kò sì bọ̀wọ̀ fún àwọn àgbààgbà.
Wọ́n bá jáde láti inú ìlú lọ sọ́dọ̀ Jesu.
Bí ẹ̀gún tí ó gún ọ̀mùtí lọ́wọ́,ni òwe rí lẹ́nu òmùgọ̀.
 A nile ise lorisirisi lorile-ede yii, bee si ni a tun fojusona lati tun bo da awon ile-ise miiran sile si lorile-ede Naijiria.
Ati pé nígbà tí àwọn eniyan mi ń mọ odi, àwọn wolii wọnyi ń kùn ún ní ọ̀dà funfun.
Nítorí náà nígbà tí Esau jáde lọ sinu ìgbẹ́, 
Ẹ kò gbọdọ̀ jẹ ẹ̀jẹ̀, dídà ni kí ẹ dà á sílẹ̀ bí omi.
Aarẹ Kenyettasi lo bori ninu atundi idibo to waye losu kẹwa, sugbọn ọgbẹni odinga ko kopa ninu idibo naa.
pẹlu eto ilana ti igbimo alase ijoba apapo laa sile nipa eto ohun osin ati ohun
“omobinrin olote miiran kan ilẹkun ile kan , bi onile se fẹ si ilekun  , ti o ni ki oun tu ado oloro to wa lara re, ni o ba gbemi  ara re .
" Bakanaa ni Ọbasanjọ tun ge ika jẹ nipa ikuna awọn asaaju nilẹ Naijiria ati nilẹ Afrika, pẹlu afikun pe Ọlọrun ko da ipo ti ko dara mọ ilẹ Naijiria tabi Afrika.
Adura yin ni emi ati idile mi nilo lasiko yii."
Ajẹ́ pé àwọn ènìyàn nra epo pamọ́ silé.
Loju opo Facebook wọn ni wọn fi ọrọ yi si.
"A kọkọ rò pe ara rẹ ti ya tẹlẹ ni ṣugbọn yoo ṣe ayẹwo aṣepari ṣaaju idije naa pẹlu Russia""."
Wọ́n ní kí ó dúró láàrin wọn; 
Mo kọ oriṣa ẹgbọ̀rọ̀ mààlúù yín, ẹ̀yin ará Samaria.
APC mókè nínú ìbò gómìnà níjọba ìbílẹ̀ mẹ́sàn-án l‘Ondo, PDP gba mẹ́ta Ìdí márùn ún tí agbára Covid 19 ní ilẹ̀ Adúláwọ̀ kò fi tó tí àwọn ilẹ̀ àgbáyé míràn Nínú akànṣẹ́ mẹ́ta ọmọ Nàìjíríà tó dáńtọ́ lágbàáyé, Yorùbá méjì wà nínu wọn Ó sàn fún mi kí n máá tíì lọ́kọ báyìí ju kí n lọ́kọ ṣùgbọ́n.
Ni aipẹ yii ni iroyin gbee jade pe awọn ọlọpaa mu awọn olupẹjọ naa si ahamọ lori ẹsun pe baale wọn, to jẹ akọwe agba fun ileewe girama naa ṣe fun sẹnetọ Ademọla Adeleke ni iwe ẹri akẹkọjade ileewe naa.
Gbogbo eto lo ti to fun ifilọlẹ eto naa eleyi ti Gomina ipinlẹ Ondo, Oluwarotimi Akeredolu jẹ alaga rẹ.
Ọfiisi to yẹ ko ṣi silẹ gbaragada fun tẹrutọmọ ni.
Nípa ìnà rẹ̀ ni ẹ fi ní ìmúláradá.
Aare soro yii nigba to n ba awon omo orile ede yii soro lori ero mohun-maworan lati fi sayeye ajodun eto ijoba tiwa-n-tiwa , ni eyi to maa n waye ni ojo kokandinlogbon,osu karun un, lodoodun.
School resumption: Ilé aṣojú-ṣòfin l'Abuja dábàá kí ìjọba sún ìwọlé àwọn akẹ́kọ̀ọ́ síwájú pẹ̀lú oṣù mẹ́ta torí covid-19
Bí a bá fi ohunkohun rúbọ tí ó jẹ́ ìríra lójú àwọn ará Ijipti, ṣé wọn kò ní sọ wá ní òkúta pa?
"O ni iṣẹlẹ yii ti ba igboya ninu ara ẹni ti oun ni jẹ tori oun ko le sun, oun ko le jẹun pẹlu bi oun ṣe ni aisan ọgbẹ inu to nitori oun n woye bi ọmọ gan yoo ṣe ro o lọkan ara rẹ pe ""lootọ anti yii fun mi lowo ṣugbọn ṣe owo wa ni gbogbo nkan ni""."
Ṣé òótọ́ ni pé ìgbẹ́ erin le è wo arùn Coronavirus sàn?
egbe kankan, igbese  ti ajo INEC gbe nipa
Iná ṣẹ́ lára igi rẹ̀,ó sì jó gbogbo ẹ̀ka ati èso rẹ̀.
Bakan naa ni Gomina Sanwo-Olu kede pe ki ajọ amusẹya yọnda gbogbo ọkọ̀ to gbẹsẹ le lati ọjọ kinni, oṣu Kẹta.
    Nígbà tí ọkùnrin náà tún mu ewé yìí dé ọ̀dọ̀ baba rẹ̀ kò dákẹ́ ó tín bèèrè ohun mìíràn, o ní, ‘mo dúpẹ́ lọ́wọ́ rẹ, ọmọ mi.
Bakan naa lo ni awọn eniyan to ba Baba oun ṣiṣẹ ni asiko to wa lori oye sọ pe Baba oun ko lu owo ilu ponpo, ati wi pe ijọba baba oun ko gbogbo eniyan mọra.
Sùgbọn ni ti àwọn obí ọmọ mẹrinlélógun ile -iwe Kenba High School to padanu ẹmi wọn ni orilẹ-èdè Sudan ni ko ri bẹẹ fun.
Dangote: Mo ti gbà $10m ri ní bánkì kí n lè mọ bí o tí ṣé rí lójú Ṣé lóòótọ́ ni pé Buhari ló fa àdínkù owó Dangote?
Wọn yóo sì sọ fún àwọn òkè gíga pé kí wọ́n bo àwọn mọ́lẹ̀, wọn óo sì sọ fún àwọn òkè kéékèèké pé kí wọ́n wó lu àwọn.
Wọn bi oloye Akintọla Williams ni ọjọ kẹsan, oṣu Kẹjọ, ọdun 1919.
Uganda ti bẹrẹ ìgbésè láti fi ikú ṣefàjẹ fún ẹní bá ṣe ìgbéyàwó akọ si akọ ati abo si abo Olùkọ́ àgbà tó fipá bá ọmọ ọdún 13 lò yóò fojú ba ilé ẹjọ́ ni Benue Donald Trump ní àwọn ọmọ ogun IS yi wà lára àwọn tó burù julọ nínú ìkọlù A fẹ́ kí a máa tẹ àwọn afipábánilòpọ̀ lọ́dàá ni báyìí - Ìjọba Ekiti Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, David Adiatu oníṣẹ́ ọnà pẹ̀lú ìṣó àti òwú Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
wo àyíká nṣẹ ni wọ́n fán imíi màlúù yìí káàkiri gbogbo ilẹ̀ kí koríko fi lè hù dáadáa.
Alaga agbegbe idagbasoke Ikosi Isheri nilu Eko, Ọmọọba Samiat Abolade Bada ti wa n daro iku rẹ eyi to n fi idi iku oloogbe naa mulẹ fun ọpọ eeyan.
Ẹnikẹ́ni tí ó bá fara kan ẹni náà, kí ó fọ aṣọ rẹ̀, kí ó sì wẹ̀, yóo jẹ́ aláìmọ́ títí di ìrọ̀lẹ́.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Edo governorship election: Ẹ̀kọ́ márùn ún tí a rí kọ́ nípa eré tíátà tó ń wáyé l'ágbo òṣèlú ìpínlẹ̀ Edo 12 Òkùdu 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 21 Òkùdu 2020 Oríṣun àwòrán, Others Àkọlé àwòrán, Edo state news: Godwin Obaseki ti darapọ̀ mọ́ ẹgbẹ́ òṣèlú PDP Bi eeyan ba ti n fi ọkan ba awuyewuye to n waye lagbo oselu nipinlẹ Edo lorileede Naijiria lẹnu ọjọ mẹta yi, yoo ri pe ara ọtọ ni oselu Naijiria, ti o si gba ki eeyan fi ọgbọn ba awọn oloselu ibẹ lo.
Loju opo Twitter ọrẹ rẹ, @Mer_yherm jẹ ko di mimọ pe Aishat n ba oun sọrọ lọwọ lori Watsap lori eyi to ti fi lẹta idagbere to kọ kalẹ sọwọ si i ko to gbe majele jẹ.
Wọ́n yóo máa sin OLUWA pẹlu ẹbọ ati ẹbọ sísun; wọn óo jẹ́ ẹ̀jẹ́ fún OLUWA, wọn yóo sì mú ẹ̀jẹ́ náà ṣẹ.
Ọlọrun, àwọn orílẹ̀-èdè abọ̀rìṣà ti wọ inú ilẹ̀ ìní rẹ;wọ́n ti ba ilé mímọ́ rẹ jẹ́;wọ́n sì ti sọ Jerusalẹmu di ahoro.
Laipe yii ni ile-ifowopamo agba ko owo ti iye re n lo bi irinwo milonu dollars 355.
"A fun awọn to ti baba da ọjọ sọna si asiko yii lanfani lati yan eyi ti wọ́n ba fẹ.
” Saaju ninu oro Gomina Dickson nigba ti won n sibudo naa lo ni agbekale ibudo yii je imuse ileri fun awon oludibo ipinle Bayelsa.
LASTMA ni gbogbo awọn oṣiṣẹ ajọ pajawiri lo ti wa nibẹ lati tete bojuto awọn eniyan naa.
Bi awọn esi naa ṣe lọ niyii: Eko-97 Oyo-37 Kaduna -9 Bayelsa-3 Edo-3 Ekiti-3 Ondo-2 Osun-2 Plateau-1 Ìpínlẹ̀ Eko ní èèyàn 136 nínú èèyàn 152 lápapọ̀ tó lùgbàdì àrùn Coronavirus ní Nàìjíríà Apapọ awọn to ni coronavirus ni Naijiria ti pe 65,148 bayii.
”Gege bi aare Buhari se sọ,
Ṣé o lè máa fi ṣeré bí ọmọ ẹyẹ,tabi kí o dè é lókùn fún àwọn iranṣẹbinrin rẹ?
Se owo yi kere tabi o pọju?
Taxi Lady: Bùkátà pọ̀ lọ́rùn mi ní mo ṣe ń wa taxi akérò
O ni: “O kere tan oko mejo lo ha si aarin afara to ja naa, awon eniyan mejo ni a ti gbe lo sile iwosan fun itoju”.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Tinubu: Nítorí Tinubu, àwọn ọmọge Sanwo-Olu da ìlù bolẹ̀ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Tinubu: Nítorí Tinubu, àwọn ọmọge Sanwo-Olu da ìlù bolẹ̀ 30 Ẹrẹ̀nà 2019 Obinrin ni iyọ aye.
O ni yatọ si owo igbadegba ti ijọba ma n fun awọn ile ẹkọ fasiti,ile ẹkọ gbogboniṣe ati ile ẹkọ awọn olukọni,ijọba ṣe adehun lẹyin iwadi lori ipenija to n dojukọ idagbasoke fasiti lati san owo to le ni triliọnu kan naira laarin dun mẹfa.
 Àwon alágbède ló sì máa ńjé  eji "" Èyí ló fá a kíkì wón ní "" ejíwándá ará ìlágbède "" ."
Ibrahim Magu (2015 - 2020): Wọn ni o n dari owo ti EFCC gba lọwọ awọn ọdaran si ibomii, o n ba oniwa ibajẹ ṣe pọ, o si ni afojudi Oríṣun àwòrán, Others Laarin awọn alaga mẹrin to ti dari ajọ EFCC, Ibrahim Magu lo koju awuyewuye julọ.
”Ogbeni Moussa Faki wa se abewo olojo meji si orile-ede Naijiria, eleyi ti ipade yoo si waye laarin re ati aare Buhari lojoEti( Friday).
Immaculate Okochu to jẹ ọmọ ipinlẹ Delta n ṣiṣẹ gẹgẹ bi alamojuto ni ile itaja Cold Stone Creamery ni Apapa, Eko ṣaaju iku rẹ.
Bẹẹ si ni eniyan kọọkan lo gbọdọ ma a lo awọn ibi yii ni ọgbọn iṣẹju si ara wọn, ki wọn si fi ibẹ fun iṣẹju marundinlogun,ki ẹlomiran to lo.
''Ohun ti mo sọ ni pe mo maa ṣe agbeyẹwo ohun to n ṣẹlẹ l'Apapa laarin ọgọta ọjọ, mi o ni mo maa mu opin ba sunkẹrẹ fakẹrẹ to n waye nibẹ Awọn ẹri naa re e Akọkọ fọnran fidio ibi ti o ti seleri yi tọwọ wa tẹ ni ibi to ti n ṣe ifọrọwero niwaju awọn eeyan nibi ayẹyẹ wa wi tẹnu rẹ ti ile iṣẹ karakata ipinlẹ Eko ṣagbatẹru rẹ.
Minisita so pe o le ni aárùndínláàdọ́rinle ọ́ọ̀dúnrún ni awon asa to wa ni jake-jado orile ede Naijiria , iyen ni pe orile ede yii le e se asa kan lojumo kan, ni eyi ti yoo je ki idagbasoke ba eto igbafe ati oro aje orile ede yii.
Abadofin ti ile n jiroro le lori bayii ni won gba pe yoo je aabo pataki fawon omo onile ki awon to n ya ile won ma le se ibi fun won tabi ki won yan won je.
Nitori naa, ile-igbmo  asofin agba ni yoo maa sakoso ile-igbimo asofin kekere titi ti won yoo fi dibo .
"Jẹgẹdẹ ni ọrọ abo n kọ ẹgbẹ oun lominu torinaa ""a maa kọ agọ ọlọpaa, bareke awọn sọja sawọn ilu ti wọn ti n ji eeyan gbe."
Pẹlu iye awọn eeyan tuntun yii, o ti pe 85,560 eeyan to ti ni arun naa ni orilẹede Naijiria bayii.
O ni itara ijọba oun lori isẹlẹ yii gbopọn ju itara ijọba ana lọ lasiko tawọn Boko Haram ji awọn akẹkọ gbe lọ nilu Chibok, nipinlẹ Borno lọdun 2014.
O fẹ́ dá mi lẹ́bi kí á lè dá ọ láre?
Bẹ́ẹ̀ ni èmi OLUWA àwọn ọmọ ogun wí.
Bakan naa ni oṣere naa sọ pe oun ko ti lọ sile ọkọ, amọ oun ko wa ọkọ, ''ẹnikan si wa loju ọpọ bayii.
ṣaaju ni adajọ to n gbọ ẹjọ naa, Onidajọ Oluṣẹgun Oduṣọla ti kọkọkoro oju si bi awọn oṣiẹ ọgba ẹwọn ṣe pẹ ni gbigbe awọn afunrasi naa wa si ile ẹjọ.
Bakan naa ni aarẹ ṣalaye pe ijọba ko ni tori ajakalẹ arun naa gboju kuro lori ilakaka rẹ lati koju ija kọ awọn ikọ agbesunmọmi to n ṣigun si orilẹ-ede Naijiria.
Abenugan ana fun ile igbimo asofin ni ipinle  Osun, ogbeni Adejare Bello , ti o sese kuro ninu egbe PDP lati darapo mo egbe APC  naa jade lati wa dibo tire naa ni  Ward 3 Unit 4, Ologun Agba Akin, Ede North.
Ṣe latara awọn igi to wa labawọle igbo aginju ti ile rẹ wa ni ti awọn akọle awo bẹru wa.
Ẹ̀yin òǹkàwé, jagunlabí kò gba ibì kan lọ ju ibi tí òun àti ọ̀rẹ́ rẹ̀ tó dolóògbé fi owó pamọ́ sí.
‘Jobu ń sọ̀rọ̀ láìní ìmọ̀,ó ń sọ̀rọ̀ láìní òye tí ó jinlẹ̀.
Baluu adanikan fo Tsaigumi lee ri ohun to n sẹlẹ ni oke ilẹ ketekete lati inu ofurufu wa pẹlu ẹrọ iyaworan ti wọn pe orukọ rẹ ni 'infra-red camera system' Yatọ si fun jija ogun ofurufu, Tsaigumi tun wa fun sisẹ isẹ ọlọpaa, asiko ijamba tabi isẹlẹ pajawiri pẹlu sise eto abo fun awọn leekanleekan, sise amojuto agbegbe ori omi ati awọn ọpa epo to fi mọ didaabo bo aala ati ibode gbogbo.
O, Folu Adeboye bí ó ṣe jẹ àwokọṣe fún àwọn obinrin Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ sí: Yemi Osinbajo: Ìgbákejì Ààrẹ tó gbọ́ nípa ẹ̀!
wọ́n lọ bá Gedalaya ní Misipa.
😨 | Former @ManCity man Celina doubles @SwansOfficial’s lead!
Kí ó gbé e tọ àwọn ọmọ Aaroni, alufaa, lọ, kí alufaa náà bu ẹ̀kúnwọ́ kan ninu ìyẹ̀fun náà, pẹlu òróró ati turari tí ó wà lórí rẹ̀.
(Galatasaray SK, Turkey); Odion Ighalo (Shanghai Shenhua, China); Alexander
Nínú àtúntẹ̀ Ẹ̀kọ́ àti àwọn Májẹ̀mú ti 1981 ní Èdè Òyìnbó, àwọn àwẹ́ ìwé mẹ́ta jẹ́ fífikún fún ìgbà àkọ́kọ́.
Cece @Folasade_h sọ loju opo rẹ pe ko si ẹni ti inu rẹ dun si abẹwo aarẹ naa ju iya oun lọ, ti oun ko si mọ idi ti inu rẹ fi dun.
Awọn akẹẹgbẹ rẹ nigba kan to le ni ọgọrun lo ṣi wa ni ihamọ Boko Haram.
Josaya pinnu láti dá ogun Ijipti pada ní Megido, ṣugbọn ó kú lójú ogun náà.
Afẹnifẹre to jẹ ẹgbẹ ohùn iran Yoruba ti fi sita pe ki ẹni ti Amọtẹkun ko ba tẹ lọrun gba ile ẹjọ lọ.
Oloogbe Felicia to jk aya Oloogbe Ayo Fasanmi jade laye ni ọjọ kẹsan an, osu kẹwaa, ọdun 2014.
" Jọkẹ ni lati igba ti isẹlẹ yii ti waye, ni oun ti n fura pe wọn gba oun wo ni bi o tilẹ jẹ pe mama oun ni isọkusọ ni baba naa sọ, nigba ti oun bii leere ọrọ̀ naa nigba tawọn de ile.
Nígbà náà ni àká rẹ yóo kún bámúbámú,ìkòkò waini rẹ yóo sì kún àkúnya.
Nigba ti mo beere idi ti wọn ko fi tẹle ofin pe ki olukuluku gba adura nile rẹ, ọkan lara wọn dahun pe Bibeli gan an sọ pe nibi ti eniyan meji tabi mẹta ba pe jọ si, oun wa pẹlu wọn."
4 4922 Orilẹede South Sudan 62 0.
"Ẹbí Buhari lásán ni Mamman Daura kò nípò òṣèlú kankan ""Ọmọ Daura ti tàpá sí òfin ààbò Nàíjíríà, ó sì yẹ kí Buhari le è to ilé rẹ̀"" Ààrẹ Buhari wọ́gilé kí àwọn òṣìṣẹ́ ìjọba máa wọ ọkọ̀ bàálù olówó gọbọi Kò sí ìdí fún àjọyọ̀ lórí ọdún kan ìṣèjọba Fayemi - Ekiti PDP Ninu ifọrọwanilẹnuwo pẹlu BBC Hausa, iyaafin Buhari ni lootọ oun lo wa ninu fidio naa toun n fi ibinu sọrọ."
Bí a ti ń sọ̀rọ̀ yìí, wọ́n ti múra tán.
Ọ ̀ nà tí ó gbajúmọ ̀ tí wọ ́ n fi máa ń yi gbólóhùn sódì ni síse àtúnrọ àwọn ọ ̀ rọ ̀ ìse .
Sọ̀kalẹ̀ kí o jókòó ninu eruku, ìwọ Babiloni.
Wọn ni ajakalé arun naa ko tii lewu lasiko yii ṣugbọn ẹfọn, ayipada oju ọjọ ati ooru lee sọo di nla mọ agbaye lọwọ.
Ṣugbọn ó wí fún mi pé, n óo lóyún, n óo sì bí ọmọkunrin kan.
Lárà àwọn tí o ti tó ojọ́ mẹ́ta ti a ti rí ti wọ́n kópa ninú èré àgbéléwò ni Jimoh Aliu Abdulsalam Ishola Sanyaolu Segun Remi Jimi Solanke Dejumo Lewis Aráyé ẹ gbà mí, nǹkan ń ṣe mí, èyí tó ju àìsàn lọ - Kanran Iṣẹ́ ọpọlọ ló yẹ ká ṣe nínú tíátà, kìí ṣe àfihàn ara bíbó àbí ìhòòhò wa - Binta Mọgaji Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, ‘Tunde Kelani yan mi jẹ lori fiimu ‘Toluwanilẹ’ Jimoh Aworo Aliu Oríṣun àwòrán, Other Gbajúgbajà eléré orí ìtàgé ni Jimoh Aliu to sì ti n kópa nínú eré orí ìtàgé láti ọdún 1959 Àwọn ẹgbẹ́ Akin Ogungbe ni o bẹ̀rẹ̀ ré pẹ̀lú ni ọdún 1959.
"O nira ki oye rẹ to ye ni pe bawo ni iya to nifẹ ọmọ rẹ yoo ṣe wa lo si ile aladugbo rẹ lati pa ọmọ rẹ bi Regine Abanyuze ṣe sọ, òṣìṣẹ Never again"" ile iṣẹ ti kii se ti ijọba ti wọn si wà fún ipese alaafia ati ipẹtu sawọ."
Ẹni tí inú ń bí a máa dá rògbòdìyàn sílẹ̀,onínúfùfù a sì máa ṣe ọpọlọpọ àṣìṣe.
ọmọ Matatiya, ọmọ Amosi, ọmọ Nahumu, ọmọ Esili, ọmọ Nagai, 
Èrò rẹ̀ ni pé Ọlọrun lè tún jí eniyan dìde ninu òkú.
Láì tan ọ̀rọ̀ náà lọ títí, bí ó ti wù kí ó mọ, gbogbo yín ni ó bà ninu jẹ́.
Ọmọwe Ghali Kabeer Umar Ọga agba fasiti imọ ẹrọ Wudil Technical University to wa nipinlẹ Kano lo kede iku Ọmọwe Ghali Kabeerr Umar to wa lẹka ẹkọ imọ nipa aworan ile yiya.
 nẹ ́ ọ ̀ nù jẹ ́ aláìgbéra bíi kẹ ́ míkà , kò sì lè dá àdàpọ ̀ kẹ ́ míkà aláìní-àgbérù .
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ọlọ́wọ̀: Ayẹyẹ ìgbadé ń bọ̀ ní ọjọ́ mẹ́tàdínlógún sí àsìkò yìí 24 Ògún 2019 Oríṣun àwòrán, @juwon2017 Ori nii gbe ni, taa fi n dade owo, ori nii gbe ni, taa fi n tẹ ọpa ilẹkẹ, ori naa nii gbe ni taa fi n gori itẹ awọn baba nla ẹni.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, India: Ẹ wo bí àwọn ènìyàn ṣe dóòlà èmí erin tó jálulẹ̀ Nigba ti wọn n gbe wọn lọ si agọ ọlọpaa lawọn janduku kan dawọn lọna ti wọn si ji ọlọpaa mẹrin gbe'' O fi kun un pe: ''Wọn yinbọn lu DPO ti wọn si tu awọn afurasi ti ọlọpaa mu silẹ'' Oyeyemi wa pari ọrọ rẹ pe awọn ti doola ọlọpaa mẹta ti iwadii si n tẹsiwaju lati ṣawari awọn ti o ku.
O dẹ gboriyin fun iṣẹ iwadii awọn agbofinro to mu awọn ọdọmọkunrin alawọ dudu wọnyii.
Wọn gbe awọn igbesẹ ni kiakia.
Wọn yoo ti apa kan fun oṣu mẹta akọkọ ati apa keji fun oṣu mẹta miran.
Ó ní, “Ẹrù wúwo ni ẹ sọ pé baba mi dì rù yín, ṣugbọn èmi yóo tilẹ̀ tún dì kún un ni.
Ọlọ́pàá mu afẹ̀sùnkan ti wọn pè ni ọgá awọn ajínigbé
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Yemi Osinbajo: Ẹgbẹ́ àwọn àgbààgbà Yorùbá ní Osinbajo kò gbọdọ̀ kọ̀wé fipò sílẹ̀ 9 Bélú 2019 Oríṣun àwòrán, Twitter/Yemi Osinbajo Àkọlé àwòrán, Yemi Osinbajo: Ẹgbẹ́ àwọn àgbààgbà Yorùbá ní Osinbajo kò gbọdọ̀ kọ̀wé fipò sílẹ̀ Ọrọ n ba moko moro bọ lori aawọ to n ṣẹlẹ laarin igbakeji aarẹ, Yemi Osinbajo atawọn kan nile iṣẹ aarẹ Naijiria.
Ti ọpọlọpọ si n bu ẹnu ẹtẹ lu minisita naa pe irọ pipa rẹ ẹ ti pọju, ati pe ijọba to n ri owo fun ẹni kan ṣoṣo l'ounjẹ pẹlu miliọnu mẹta ataabọ Naira gbọdọ le ri ọgbọ̀n ẹgbẹrun Naira san gẹgẹ bi owo oṣu oṣiṣẹ to kere ju.
A tú ayaba sí ìhòòhò,a sì mú un lọ sí ìgbèkùn,àwọn iranṣẹbinrin rẹ̀ ń dárò rẹ̀,wọ́n káwọ́ lérí,wọ́n ń rin bí oriri.
"Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Igbakeji aarẹ, Yemi Osinbajo sọrọ lori anfaani ọlọpaa ipinlẹ kọọkan Gomina naa sọ siwaju wipe ''iye ọlọpaa ti o wa lorilẹede Naijiria kere si iye awọn eniyan ti o wa lorilẹede yii, eyi to s'afihan ailera awọn ọlọpaa lorilẹede yii""."
Marcus Rashford lo gbayo alakọkọ wọle fun Man United nigba ti ẹrọ VAR fun wọn ni pẹnariti.
Ọ̀pọ̀lọpọ̀ ènìyàn ló máa ń dá Ọgbọ́n jọ fún ìdàgbàsókè ìlú.
Kí ni olùfẹ́ tìrẹ fi dára ju ti àwọn yòókù lọ?
Trump: Bí ẹ bá ṣé ikọlù sí wá, nkán ìní yín 52 làá dojú ìjà kọ Ìjàmbá ọkọ̀ òfurufú dínkù lọ̀dún 2019 pẹ́lú ìdá àádọ́ta nínú ọgọ́rùn ún Obabinrin Elizabeth II ṣàfihàn àwòrán orí adé mẹ́ta tó lè jé lẹ́yìn rẹ̀ Ọ̀jọ̀gbọ́n Simon Mallam wa nínú àwọn mẹ́fà tó ti kú nínú ìjàmbá iná gáàsì- Ìjọba Kaduna Bakan naa ni Tunde sọrọ lori ìrírí to kọja ẹgbẹ́ abewú nìgbà akọkọ to gbe mọto wa sile lati Germany ti oun gba Turkey lọ si Niger si Sahara Desert si Kwara ko to dele ni Ondo.
Ṣugbọn Uraya kò lọ sí ilé rẹ̀, ó sùn sí ẹnu ọ̀nà ààfin pẹlu àwọn ẹ̀ṣọ́ ọba tí ń ṣọ́ ààfin.
O ni ẹgbẹẹgbẹrun un eeyan lawọn ajinigbe ti ṣe leṣe nitori ọrọ eto aabo to mẹhẹ ni Naijiria.
Àwọn ọmọ Lefi tí wọ́n mọ̀ nípa ohun èlò orin 
Makinde ni ''awọn eeyan kan ni ko yẹ ki PDP ṣe iru ipade itagbangba bayii lasiko ti coronavirus n tankalẹ yii, ṣugbọn ọkan lara awọn olori wọn lo sọ pe arun coronavirus ti wọ inu ẹgbẹ wọn, amọ awa mọ pe ko si ninu ẹgbẹ ti wa.
Johanu dá wọn lóhùn pé, “Omi ni èmi fi ń ṣe ìwẹ̀mọ́, ẹnìkan wà láàrin yín tí ẹ kò mọ̀, 
“Bí ẹ̀jẹ̀ bá ń dà lára obinrin fún ọpọlọpọ ọjọ́, tí kì í sì í ṣe àkókò nǹkan oṣù rẹ̀, tabi tí nǹkan oṣù rẹ̀ bá dà kọjá iye ọjọ́ tí ó yẹ kí ó dà, ó jẹ́ aláìmọ́ ní gbogbo àkókò tí ẹ̀jẹ̀ ń dà lára rẹ̀.
Àwọn ará Juda ti sọ ibi mímọ́ tí OLUWA fẹ́ràn di aláìmọ́; àwọn ọmọkunrin wọn sì ti fẹ́ àjèjì obinrin, ní ìdílé abọ̀rìṣà.
wọ ́ n bí gbémi ní ( july 18 , 1984 ) ní ìdílé Ọba Ọlágbẹ ́ gi ní ìlú Ọ ̀ wọ ̀ , ní ìpínlẹ ̀ Òndó .
Bákan náà ni àwọn ọgbà ẹ̀wọn ní kí àwọ́n ẹlẹ́wọ̀n tẹlé ìlànà ìmọ́tótó ki wọ́n tó wọ ilé ẹjọ́ tó fi mọ Alfa Babatunde.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Fídíò òògùn ikọ́ Codeine: Àpọ̀jù rẹ̀ ń ya ọ̀dọ́ ní wèrè Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Fídíò òògùn ikọ́ Codeine: Àpọ̀jù rẹ̀ ń ya ọ̀dọ́ ní wèrè 1 Èbibi 2018 Ọ̀pọ̀ ọ̀dọ́ ní orílẹ̀èdè Nàíjíríà ni ìwádìí abẹ́lẹ̀ tí iléesẹ́ BBC se ti fihàn pé ewu ńlá ń bẹ nínú mímu àpọ̀jù Òògùn ikọ́ olómi tó ní èròjà Codeine nínú.
Williams Akintọla ko ipa pataki ninu idasilẹ Ẹgbẹ awọn Oluṣiro owo ni Naijiria, Association of Accountants in Nigeria (AAN), l'ọdun 1960, pẹlu afojusun lati maa pese ẹkọṣẹ fun awọn oluṣiro owo.
Wo ìdí tó fi tọrọ àforíjì fún ọ̀rọ̀ ẹ̀gbin tó sọ sí Pásítọ̀ David Oyedepo Wo idi ti wọn fi fọwọ osi juwe ile fun Erica Oríṣun àwòrán, @BBNaija Twitter Wọn ti fi ọwọ osi juwe ile fun Erica, wọn si ti ni ko kuro ninu ile ẹlẹgbọn-ọn agba Big Brother Naija to n lọ lọwọ.
Kini ifarawe isẹlẹ yii ati ijinigbe awọn ọmọ ile-iwe Chibok?
Bo tilẹ jẹ pe o ṣe alaye yii, ọpọ to wo ifọrọwanilẹnuwo naa lo tẹnumọ pe oju rẹ jọ oju oloyun.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Omi ìṣẹ̀ńbáyé tó ń dà ní Ówù rèé, èyí tó ga jùlọ ní Afirika 'Ǹkan tó jẹ́ kí iṣẹ́ ọ̀nà tèmi yàtọ̀ lágbàáyé ni ǹkan tí mò ń lò' Mo ti sọ ìran nípa ọkọ aképo tó gbiná ní Onitsha kó tó ṣẹlẹ̀ - Primate Ayodele Àlá àwọn òjíṣẹ́ Olúwa tó fẹ́ jẹ ààrẹ Nàíjíríà leè má ṣẹ lógún ọdún - Abiara Ìbẹ̀rẹ̀ mi kò rọrùn rárá, omi máa ń bọ́ lójú mi tí mo bá rántí àkókò náà - Small Doctor Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
, ko si ẹni ti ko mọ gbajugbaja oloṣelu yii yika orilẹede Naijiria.
Gbogbo olukopa gbọdọ ni iwe ẹri ipele akọkọ '1st class, tabi ikeji '2nd class Upper Division'.
 Àwọn tí ó ń sọ abkhaz tó ẹgbẹ ̀ rún lọ ́ nà ọgọ ́ rùn-ún ènìyàn ní ìpínlẹ ̀ tí a ń pè ní abkhaz ní georgia .
Osun tribunal: Oyetọla ní òun kò bẹ̀rù ìdájọ́ ilé ẹjọ́ lórí èsì ìbò ìpínlẹ̀ Ọṣun
Kí Ọlọrun fún ọ ninu ìrì ọ̀runati ilẹ̀ tí ó dáraati ọpọlọpọ ọkà ati ọtí waini.
Ẹka ẹkunrẹrẹ rẹ nibi Ọjọ 27, Osu Keji Ijọba orilẹede Naijiria bẹrẹ iwadii lori bi isẹlẹ ijinigbe awọn akẹẹkọ aadọfa se sọnu.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Amos Dauda, Iphone: Ilé ẹjọ́ dájọ́ ẹgba mẹ́ẹ̀dóògún fún ọ̀daràn tó jí Iphone ní Kaduna 25 Bélú 2020 Oríṣun àwòrán, Getty Images Ọdọ́mọkunrin ẹni ogún ọdun kan, Amos Dauda ni ilé ẹjọ́ Májísíréétì ni ìlú Kaduna ṣe dájọ́ pe kí wọ́n fún ni kòbókò ẹgba mẹ́ẹ̀dógún nítorí o jí Iphone.
Ehonu marun un ni wọn gbe ka iwaju ijọba.
Nígbà náà ni ara mi yóo mọ́,n kò sì ní jẹ̀bi ẹ̀ṣẹ̀ ńlá.
"Ẹ̀yà kòkòrò Covid-19 míràn jáde ní ọgọ́ta agbègbè nílẹ̀ Gẹẹsi, àjọ eletò ìlera ni k'ára ìlú má fòyà Wọ́n ní kí ọ̀gá àgbà ""Ede Poly"" lọ rọ́kún nílé lórí ẹ̀sùn pé ó kan bẹ́ẹ̀dì sí ọ́fíìsì Ṣé lóòtọ́ ni Adajọ́ Àgbà Naijiria, Tanko Muhammad ti ní Covid-19?"
 O je agbaboolu ti o dara pupo.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Human Rights day: Aṣíwájú ajàfẹ́tọ̀ọ́ ní Àìbọ̀wọ̀ fẹ́tọ̀ọ́ ọmọnìyàn ló ń fa wàhálà ètò àbò Femi Adesina ni kete ti wọn ba ti ni ki eeyan gba oniduro ninu ẹjọ ṣugbọn ti igbẹjọ kotẹmilọrun ba dide ni ofin ti faye gba pe ki wọn ṣi fi ẹni naa si ahamọ titi yoo fi yanju.
Charlie boy lewaju iwọde lori ọwọngogo epo NNPC n ronu afikun owo epo Àkọlé àwòrán, Awọn ọmọ Naijiria pẹlu lọwọ ninu ọrọ naa Awọn ileeṣẹ apọnpo rọbi nlanla meji yii n jẹjọ lori ẹsunfifunni lowo riba, ati iwa ijẹkujẹ lasiko ti wọn fẹ fi ra oko ipọnpo kan lorilẹede Naijiria.
Ní ọjọ́ kẹtadinlogun oṣù keji ọdún tí Noa di ẹni ẹgbẹta (600) ọdún, ni orísun alagbalúgbú omi tí ó wà ninu ọ̀gbun ńlá lábẹ́ ilẹ̀ ya, tí gbogbo fèrèsé omi tí ó wà ní ojú ọ̀run ṣí sílẹ̀, 
" Eji Gbadero, ọmọ Ibadan àti jayé-jayé ọmọ ónílẹ̀ ti wọn yẹgi fun l'Eko Kọmíṣọ́nà mẹ́ta lùgbàdì àrùn Coronavirus l'Ọyọ Èyí ni àwọn arẹwà ‘ẹ̀lẹ̀ Daddy’, àfẹ́fẹ́ tí Aláàfin fi ń mí Ẹ wo ìṣẹ̀lẹ̀ nípa ẹ̀sùn ìfipábánilòpọ̀ tí wọ́n fi kan D'banj ní sísẹ̀-n-tẹ̀lé Ẹgbẹ oṣelu APC l'Eko Ẹgbẹ oṣelu All Progressives Congress, APC, nipinlẹ Eko naa ti darapọ mọ awọn to n daro iku Ajimobi.
Arábìnrin lẹ̀dì àpò pọ̀ pẹ̀lú ọ̀rẹ́kùnrin rẹ̀ pé kó ó jí òun gbe, ọ̀rẹ́kùnrin gba 700k tán ló bá sálọ Kí làwọn nǹkan tó lè rán ọkùnrin sí ọ̀run alákeji lásìkò ìbálòpọ̀ pẹ̀lú obìnrin?
Ipade naa ni yoo je eleekeji re, to waye laarin awon adari mejeeji yii.
Nígbà tí mo wí báyìí tán, Baba-onírùngbọ̀n rẹ́rìn-ín, ó ní, Ọ̀rẹ́ mi, mo ṣe bí ìwọ lo ń ṣe ìlérí níwájú ọk[]unrin náà nísisìyí tí ẹnu rẹ ń lekoko?
Oun lo maa n ṣe eto bi iṣẹ aarẹ yoo ṣe lọ lojoojumọ Amojuto ati ṣiṣeto gbogbo ipade ti aarẹ ba fẹ ẹ ṣe, to fi mọ ipade igbimọ alaṣẹ orilẹ-ede Naijiria tun jẹ alarina laarin aarẹ ati olu ileeṣẹ awọn ologun Naijiria Ṣiṣe agbeyẹwo ati atunṣe si ọrọ ti aarẹ ba kọ silẹ lati sọ ni gbangba Ṣiṣe amojuto apo asunwọn owo fun itọju aarẹ, ati fifi ontẹ lu lilo ọkọ ofurufu aarẹ fun awọn oṣiṣẹ ijọba Oun lo maa n fi erongba aarẹ to a Ohun kan to daju ni pe Aarẹ nikan lo le sọ bi ẹni naa yoo ṣe l'agbara to, ati pataki rẹ.
Ohun tí a mọ̀ nìyí nípa #IGotSurvivalFund owó ìrànwọ̀ Wo ohun tí Pasuma sọ nípa Opeyemi, ọmọ rẹ tó di ọmọ ogun orí omi l'Amẹrika Àṣírí tú!
Aare wa so fun won pe “Mo dupe bi e se wayii, wiwa yin tun ti fun mi ni okun ati agbara sii.
 O tun tesiwaju pe” Bi omi lake Chad se n dinku ko ran isẹlẹ yii lọwọ rara.
Wọ́n bá gbé e jáde, wọ́n sì sin ín sí ẹ̀bá ọkọ rẹ̀.
Èyí ni yóo jẹ́ ààlà ilẹ̀ náà ní apá ìwọ̀ oòrùn.
A ó ṣèwádíi òṣìṣẹ́ LASTMA tó ń ka owó àbẹ́tẹ́lẹ̀ nínú fídíò - LASTMA O ti le lọgọrun ọjọ bayii ti Naijiria ti ni ẹni akọkọ to ni arun Coronavirus bayii, koda itanka arun naa ti sun ọpọn de awọn ilu igberiko sibẹ, ṣe ni iye rẹ n goke sii lojojumọ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ọmọ Yoruba ni mi Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
ẹni tí ó bá wí pé òun ń gbé inú Ọlọrun níláti máa gbé irú ìgbé-ayé tí Jesu fúnrarẹ̀ gbé.
Iroyin naa ni ero ko pọ ninu baalu naa, fun idi eyi Tiffani nikan lo da joko si odindin ila kan ninu irirnajo ọhun.
Oríṣun àwòrán, Twitter/LASEMA Iṣẹlẹ ọkọ agbepo to dawo ni agbegbe ibi ti ileeṣẹ amohunmaworan AIT wa ni Alagbado, ipinlẹ Eko ti ni iyanju bayii.
Kínni ìlérí tí APC ṣe fún Omisore?
Ẹ jẹ́ kí ojú tì yín, kí ẹ sì dààmú nítorí ìwà yín, ẹ̀yin ọmọ Israẹli.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Obìnrin míràn gbẹ́mi mi torí pé o fẹ́ ki ìdí òun tóbi síi 5 Ọ̀wàrà 2018 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 19 Bélú 2018 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ìdí ti kò tẹ́ àwọn obìnrin lọ́rùn ń jẹ́ ki iṣẹ́ abẹ rán wọn sọrun.
“ ‘Bí ẹ bá tún ìrìn ẹsẹ̀ yín ati iṣẹ́ ọwọ́ yín ṣe nítòótọ́, tí ẹ bá ń dá ẹjọ́ òtítọ́, 
Nígbà tí ó yá, tí àwọn ọmọ-ẹ̀yìn Jesu ń pọ̀ sí i, ìkùnsínú bẹ̀rẹ̀ láàrin àwọn tí ó ń sọ èdè Giriki ati àwọn tí ó ń sọ èdè Heberu, nítorí wọ́n ń fojú fo àwọn opó àwọn tí ń sọ èdè Giriki dá, nígbà tí wọ́n bá ń pín àwọn nǹkan ní ojoojumọ.
Wọ́n bá bẹ̀rẹ̀ sí fi ẹ̀sùn kàn án pé, “A rí i pé ńṣe ni ọkunrin yìí ń ba ìlú jẹ́.
 O tun tesiwaju pe awọn agbofinro tun ran ajo eleto idibo lọwọ lati se mọndaru eto ibo nile ìka-ibo.
Lati ọsẹ to kọja ti Funke Akindele ti ṣe nkan ayọ onibẹta iyẹn ayẹyẹ ọdun igbeyawo oun ati ọkọ rẹ, ọjọ ibi rẹ bakan naa lo kede fiimu tuntun rẹ to gbe jade eyi to jẹ ipadabọ fiimu rẹ Omo Ghetto""."
O sọ iye ti ijọba ipinlẹ Eko n na lori ọkọọkan iṣẹlẹ coronavirus ti wọn ti tọju niyara iyasọtọ ati nile iwosan.
Yóo ṣẹgun àwọn ará Seiri tí wọ́n jẹ́ ọ̀tá wọn,yóo sì gba ilẹ̀ wọn.
N óo fi ọpẹ́ tí ó yẹ fún OLUWA nítorí òdodo rẹ̀,n óo fi orin ìyìn kí OLUWA, Ọ̀gá Ògo.
" Amotekun kò ní gbé ìbọn o!
Congress ti pe awon  ajo agbofinro ati alaabo
Amotekun: Kí ni iṣẹ́ tí Amotekun yóò máa ṣe gangan?
Ko si ohun ti a lee ṣe lati fi yọ majele yii kuro lara ẹjọ yii-boya sise e tabi kikoo pamọ sinu ẹrọ amohun tutu ko ran an.
Ibẹ̀ ni OLUWA ti fún wọn ní ìlànà ati òfin, ó sì dán wọn wò, 
Koda o fi kun un pe, lara awọn sinima tuntun tawọn ṣẹ tun gbe jade bii The train, Shackles, Abejoye ati bẹẹ bẹẹ lọ, orilẹede ọtọọtọ to ju mẹwaa lọ, ni wọn ti fẹ ṣe akọkọ wo rẹ."
Ninu lẹta kan ti SERAP kọ si agbẹjọro agba lorilẹede Naijiria, Abubakar Malami, lo ti pe ipe yii.
A ó máa tẹ àwọn afipábánilòpọ̀ lọ́dàá ni báyìí - Ìjọba Ekiti Ǹjẹ́ o mọ ẹni tó ran àjọ ọ̀tẹlẹ̀mùyẹ́ CIA lọ́wọ́ láti rí Bin Laden mú?
Èmi Ọba tí wọ́n ń kó jẹ nígboro- Oluwo ti ilú Iwo Wo bí ètò ìsìnkú Tolulope Arotile ṣe lọ nílùú Abuja Irubọ/Itọrẹ Nkan kẹta, o ṣe pataki lati ṣe itọrẹ aanu, eyi tọ sunnah Anabi Ibrahim (SAWA) ti Allah pa laṣẹ gẹgẹ bi adanwo lati fi ọmọ rẹ rubọ, o setan lati ṣe ki Ọlọrun to fi Agbo rọpo ọmọ rẹ.
Nígbà tí ó tọ́ ọ wò, ó kọ̀, kò mu ún.
Nítorí èyí, láti ìgbà tí mo ti gbọ́ nípa igbagbọ yín ninu Oluwa Jesu, ati ìfẹ́ yín sí gbogbo àwọn onigbagbọ, èmi náà 
Aaroni jẹ́ ẹni ọdún mẹtalelọgọfa (123) nígbà tí ó kú ní Òkè Hori.
Wọn sun ikede naa wa si waju lati ọjọru si ọjọ iṣẹgun.
Idanwo tọdun yii naa ni yoo waye lọjọ kẹsan si ọjọ kẹtadinlogun osu kẹta, ọdun yii.
gbadura pe olorun yoo kun lowo ninu gbogbo ohun ti o ba da owo re le.
O le fi ọkàn tan an tó bá jẹ́ àábọ̀ ìwádìí àjọ nla kan ni wan múlò.
Oríṣun àwòrán, @solaeleeka Àkọlé àwòrán, A ju ara wa lọ, ìjàkadì kọ́ lọrọ ìdìbò Ekiti maa n jẹ́ O ṣiṣẹ olukọni ninu imọ ijinle nipa ile kikọ ni Fasiti OAU ki wọn to yan an nigbakeji Gomina Ayodele Fayose lọdun 2014.
O ni ọrọ eto ẹkọ wa n fẹ amojuto paapaa ọrọ airiṣẹ ṣe awọn ọdọ.
Ejò lé àwọn aṣòfin ìpínlẹ̀ Ondo kúrò nípàdé Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Kayeefi: Facebook ni Wolii Arole Jesu fi tàn an wọ agbo, orí rẹ̀ ni wọ́n fi s'owó Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Inú wa dun tí a rii nítorí a n fẹ́ kí á tèlè rí ẹni tí yóò ba wa wọlé sọ fún ọba pé a ti dé.
“Mú igẹ̀ àgbò tí a fi ya Aaroni sí mímọ́, kí o sì fì í gẹ́gẹ́ bí ẹbọ fífì níwájú OLUWA, èyí ni yóo jẹ́ ìpín tìrẹ.
"Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Sunday Igboho: Fulani kò leè dúró, táa bá lo ohun ta jogún lọ́dọ̀ àwọ̀n bàbá wa ""Bi eeyan ba lowo laye, yoo lowo lọrun ni, bi eeyan ko ba si jẹ nnkan kan laye, ko lee jẹ nnkan lọrun."
Wọ́n sì kọ́ wọn pé, “Ẹ sọ pé, ‘Àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ wá lóru láti jí òkú rẹ̀ nígbà tí a sùn lọ.
Ẹ jẹ́ kí n kọrin kan fún olùfẹ́ mi,kí n kọrin nípa ọgbà àjàrà rẹ̀.
Bakan naa ni o fi n dani loju pe, ijoba ipinle Eko ti bere sise awon opopona  kaakiri ipinle naa, eyi ti yoo lo si awon agbegbe ile-ise fun irorun irin oko si awon agbegbe naa.
 lọ ́ pọ ̀ ìgbà , àwọn babaláwo ló ma ń báni ṣètùtù , àyàfi tí Ọ ̀ rúnmìlà bá fòté le wípé oníṣègùn kannpàtó ló gbọ ́ dọ ̀ rúbọ náà .
Wọ́n wí pé, “OLUWA Ọlọrun Israẹli, kí ló dé tí irú èyí fi ṣẹlẹ̀ ní Israẹli, tí ó fi jẹ́ pé lónìí ẹ̀yà Israẹli dín kan?
Angẹli náà wí fún un pé, “Má ṣe pa ọmọ náà rárá, má sì ṣe é ní ohunkohun, nítorí pé nisinsinyii mo mọ̀ dájú pé o bẹ̀rù Ọlọrun, nígbà tí o kò kọ̀ láti fi ọmọ rẹ kan ṣoṣo tí o bí rúbọ sí èmi Ọlọrun.
Ilu abinibi mi, Oṣogun lẹba ilu Ọyọ ni mo wa pẹlu awọn obi, ẹgbọn ati aburo mi lọkunrin ati lobinrin, taa si n gbadun aye wa nibẹ lai mọ pe ipinya sun mọ tosi, ti a ko si ni fi oju ri ara wa mọ.
Àwọn nǹkan yòókù tí Omiri ṣe ati iṣẹ́ akikanju tí ó ṣe ni a kọ sinu Ìwé Ìtàn Àwọn Ọba Israẹli.
Àwọn ni Simoni tí ó sọ ní Peteru ati Anderu arakunrin rẹ̀, Jakọbu ati Johanu, Filipi ati Batolomiu, 
Lodun 1998 ni tsunami ti sele ni apa ariwa Paupau New Guinea ni eyi ti odiwon re to ida meje ile riri ti eniyan to to igba le legberun meji si gbemi mi laataari isele naa.
òbúkọ kan fún ẹbọ ìmúkúrò ẹ̀ṣẹ̀.
Afurasi tó fa ìpayà nílé ìwé Port Harcourt ti wọ gàù Àwọn bàbá ìsàlẹ̀ òṣèlú tó bá ìtìjú bọ̀ nínú ìbò Gómìnà rèé Ọ̀gọ̀rọ̀ èèyàn lórí ayélujára bú Dalung lórí owó IAAF Ọ̀rọ̀ Aisha Buhari sí Ramaphosa wú ọ̀rọ̀ síta lẹ́nu àwọn ọmọ Nàìjíríà NBC fọwọ́ sí ìdásílẹ̀ ilé iṣẹ́ Fulani Radio Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
''Ijọba gbọdọ woye pe igba yii yatọ si ọgbọn ọdun sẹyin, ti ijọba le e ṣe ohun to wu wọn, ti ko si si ẹni ti yoo beere lọwọ wọn.
"Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, No reception wedding: Adewale ni àpèjẹ kò ṣe pàtàkì sí òun ""Lati igba ti a ti bẹrẹ igbẹjọ yii, ẹni ti wọn fi ẹsun kan ko yọju sile ẹjọ rara, nitori naa, titu ni ile ẹjọ yoo tu igbeyawo naa ka."
Nigeria 2019 Elections: Alága INEC, Mahmood Yakubu ní àṣẹ Ààrẹ Buhari lórí pípa ẹni tó bá jí ìbò gbé tako ohun tí òfin sọ
Wọ́n bá a tí ó dojúbolẹ̀ níwájú àpótí OLUWA.
O ni ọna abayọ ni ki gbogob ẹka eto idajọ ati agbofinro ati ara ilu dide papọ lati gbogun ti iwa buruku yii.
Sedekaya, o kò ní sá àsálà, ṣugbọn wọn óo mú ọ, wọn óo fà ọ́ lé Nebukadinesari lọ́wọ́, ẹ óo rí ara yín lojukooju, ẹ óo bá ara yín sọ̀rọ̀, o óo sì lọ sí Babiloni.
Ọ̀ṣun Oṣogbo: Èyí ni àwọn ayẹyẹ tí yóò wáyé ní ọjọ́ kọ̀ọ̀kan lásìkò ọdún Ọ̀ṣun Oṣogbo
Awon adari iko eleni merin ile Africa  fun amoju to eto idibo lagbaye, seleri lojo-Aje pe,awon  ko ni se oju-saaju, bakan naa ni won o ri daju pe, won yoo gunle igbese ilana ofin elekun-jekun ati ti orile-ede lagbaaye.
Lẹ́yìn ìsìnkú náà, wolii àgbàlagbà yìí sọ fún àwọn ọmọ rẹ̀ pé, nígbà tí òun bá kú, inú ibojì kan náà ni kí wọn ó sin òun sí, ati pé ní ẹ̀gbẹ́ rẹ̀ gan-an ni kí wọ́n tẹ́ òkú òun sí.
UK Election 2019: Boris Johnson kéde pé January ni UK yóò fi EU sílẹ̀
Ó ka ẹ̀gàn nítorí Mesaya sí ọrọ̀ tí ó tóbi ju gbogbo ìṣúra Ijipti lọ, nítorí ó ń wo èrè níwájú.
Nítorí èyí, òun ni alárinà majẹmu.
Lagos-Ibadan: Èèyàn mẹ́tàlá dèrò ọ̀run nínú ìjàmbá ọkọ̀ lọ́nà Ìbàdàn sí ÈKó
"Abuja ti rọ̀ṣọ̀mù fún ayẹyẹ ìbúra sáà kejì Buhari Ohun ìjà olóró kò gbọdọ̀ wọ Nàíjíríà mọ́ lọ́nà ẹ̀bùrú - Buhari Igun ẹgbẹ́ NURTW tó bá da ayẹyẹ ìbúra mi rú, yóo rugi oyin - Seyi Makinde Láti 1999 títí di 2019, wo àwọn ààrẹ tó jẹ ní Nàìjíríà Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Àgbà ni Obasanjo, oun tó ń sọ yé e, ìjọba ni kó tají - Wale oke ""Ẹkunrẹrẹ fọọmu ti idahun ti wa ninu rẹ ni Sarki Abba to jẹ oluranlwọ́ pataki fun aar lori ọrọ inu ile lorukọ aarẹ Buhari fi sọwọ si alaga ajọ CCB, Ọjọgbọn Mohammed Isa""."
Nítorí èyí ni ọpọlọpọ ninu yín ṣe di aláìlera ati ọlọ́kùnrùn, tí ọpọlọpọ tilẹ̀ ti kú.
Oun ti a sàkíyèsí ni pe, níse ni àsíá ẹgbẹ oselu APC to wà lori ikani ọun yípadà si ti ọ̀gbẹ́ni Sun yii, ti ó sì n kọ orisirisi nnkan nipa ijọba orilẹede Naijiria.
Ere naa to da lori ọmọ adari ilu to dagba ninu iṣẹ ati iya tori ohun to fa sababi ibi rẹ ni ọpọ eniyan atawọn ololufẹ rẹ naa ti n duro de.
Àánú arúgbó náà ṣe mí púpọ̀.
Adari ajọ to n gbogun ti iwa ibajẹ si ọmọde ni ijọba ibilẹ Oshodi-Isolo, Ebenezer Omejalile ni, afurasi naa wa ni ahamọ ileeṣẹ ọlọpaa Akinpẹlu, ni Oshodi bayii.
nítorí wọ́n mú Mose bínú,ọ̀rọ̀ tí kò yẹ sì ti ẹnu rẹ̀ jáde.
Awọn alaṣẹ n gbiyanju lati ko awoku afara naa kuro ninu omi.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Tọkọ-taya Aràrá: Àwọn èèyàn máa ń wò wá, ta bá fa ọwọ́ ara wa ní títì Iwadii fihan pe Naijiria lawọn to larun arunmọleegun ti pọju lagbaaye pẹlu miliọnu mẹta aabọ eeyan o le diẹ to larun naa.
Nitori naa lilo awọn ohun idaabobo araẹ̣ni bi iboju ṣ̣e koko, ati titẹle awọn ilakalẹ ti wọn gbe kalẹ.
Oyo SUBEB: Ayédèrú ní ìròyìn tó ní à ń gba ènìyàn sísẹ́
Facebook yóò bẹ̀rẹ̀ ìnáwó orí ayélujára Ọwọ́ ọlọ́pàá tẹ ọmọ Britain tó ń ta kẹ́míkà gẹ́gẹ́ bi omi ìyanu Wọ́n jí ọmọ yìí gbé láti máa fi tọrọ bárà l'Eko Lorilẹede Gẹẹsi, aisan jẹjẹrẹ to paniyan ju ni ti ọna ọfun ati ti isale ikun, ti aisan jẹjẹrẹ asẹtọ Ọkunrin si jẹ ikẹta ninu awọn aisan to paniju lọ ni ilẹ Geesi.
Ìwọ rí ojú ọkùnrin náà ó dà bí iná, ìwọ rí èékán rẹ̀ ó dà bí èékán ẹkùn, ìwọ wáá tún ń béèrè pé kí n sọ̀rọ̀ rere tàbí kí n má sọ̀rọ̀ rere, o kò mọ̀ pé bí mo fẹ́ bí mo kọ̀ mo níláti sọ nǹkan rere níwájú ọkùnrin náà ńdan?
O ni inu awọn yoo dun ti ijọba Buhari baa le sọ ''igbesẹ to ti n gbe lati kọdi awọn Gomina lati ma ṣe ya ninu owo yi laarin ọjọ mẹrinla tawọn fi iwe ranṣẹ sii'' SERAP wa sọ pe bawọn ko ba gburo esi kankan lati ọdọ ijba laarin ọjọ mẹrinla awọn yoo gbe igbesẹ nile ẹjọ lati jẹ ki ijọba ṣe ohun tara ilu n fẹ lori ọrọ yi.
Funke Adesiyan, òṣèré Yollywood tó di olùrànlọ́wọ́ aya ààrẹ, Aisha Buhari Aarẹ Buhari kẹ́dùn ọ̀pọ̀ ẹ̀mí àti dúkìá tó jóná ni ọjà Onitsha Abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Patrick Day dèrò ọ̀run lẹ́yìn tó gba ẹ̀ṣẹ́ s'órí!
Jẹ ki ọlọpaa mọ ipo ailera rẹ lẹyin ti wọn ba mu ọ.
Gbogbo ohun ta fi gbogbo ọjọ aye wa sisẹ fun, a ko si lee ko ohunkohun jade, bẹẹ ni emi ati awọn ọmọ mi ko nile lori mọ lati sun.
Eni ọdun ọgọta ni Salome Abuh.
 Awon odaran ohun ni won lowo ninu oniruuru iwa bii
iranwo ounje yii ko wa lati ọdọ ijoba sugbon lati apo awon to kora won jọ, ti
Tí a fiṣọwọ́ ní 14:14 16 Sẹ́rẹ́ 202114:14 16 Sẹ́rẹ́ 2021 Ààrẹ Yoweri Museveni tún borí ìdìbò ààrẹ ní Uganda lẹ́yìn ọdún 35 nípò Oludije fẹgbẹ oṣelu alatako Bobi Wine ni eeru pọ ninu eto idibo ọhun, ati pe niṣe ni wọn n yi ibo rẹpẹtẹ.
 kò sì sí ọ ̀ kan nínú ìṣọ ̀ rí iṣẹ ́ àgbẹ ̀ yí tí kò ní èrè tàbí ànfàní fún olórí-kò-jorí , fún àwùjọ , fun àwọn ilé-iṣẹ ́ àti fún orílẹ ̀ -èdè lápapọ ̀ .
Fayose koro oju si Buhari lori pipa awọn Fulani
Oluranlọwọ pataki fun ijọba lori eto ilera ni Ilẹ Gẹẹsi, Ọjọgbọn Chris Whitty ni, esi ayẹwo naa ṣe afihan iru agbara ti imọ sayẹnsi ni ati ifọkanbalẹ pe ọdun to n bọ yoo dara lati koju arun Coronavirus.
Koda, ẹkọ ti wọn mu jade nibẹ ko lakawe rara.
Ó lé e jáde, ó sì fi Kerubu kan sí ìhà ìlà oòrùn ọgbà náà láti máa ṣọ́ ọ̀nà tí ó lọ sí ibi igi ìyè náà, pẹlu idà oníná tí ń jò bùlà bùlà, tí ó sì ń yí síhìn-ín sọ́hùn-ún.
Àwọn ẹlòmíràn ń waasu Kristi nítorí owú ati nítorí pé wọ́n fẹ́ràn asọ̀.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Baby abandoned on dunmpsite: Mo ti bímọ mẹ́rin tẹ́lẹ̀ fún bàbá méjì nínú òṣí- Dupe Ogbomos Ki lo ti ṣẹlẹ sẹyin?
Kí àwọn tí wọ́n ń fi ọjọ́ gégùn-ún fi gégùn-ún,àní àwọn tí wọ́n lè fi àṣẹ rú Lefiatani sókè.
Arotile ti o wa lati agbegbe Iffe ni ijọba ibilẹ Ijumu ni ipinlẹ Kogi, lo ṣẹṣẹ pari akanṣe ẹkọ to lọ kọ ni Starlite International Training Academy, ni South Africa.
Nígbà tí ó rí i, ó mú un wá sí Antioku; fún ọdún kan gbáko ni àwọn mejeeji fi wà pẹlu ìjọ, tí wọn ń kọ́ ọpọlọpọ eniyan lẹ́kọ̀ọ́.
Aarẹ Buhari sọ eyi ni ọjọbọ nibi ipade to ṣe pẹlu awọn alẹnulọrọ kan ni ilu Jos ni ọjọ kinni abẹwo ọlọjọ meji ti o n ṣe si ipinlẹ Plateau.
Amọṣa, ọgangan ibi ti iṣẹlẹ naa ti waye ni wọn ti mu.
Wó ọkùnrin táwọn obìnrin fipá bá lòpọ̀ ní ẹ̀ẹ̀mejì O ni bi oun se gbọ nipa igbesẹ tawọn ọlọpaa n gbe lati doola ọkunrin naa, ni oun dara pọ mọ wọn lati wa itura fun ninu ile kan to wa nilu Rogo.
Nígbà tí ẹ̀ka rẹ̀ bá ṣẹ̀ṣẹ̀ yọ, tí ó rú ewé, ẹ mọ̀ pé àkókò ẹ̀ẹ̀rùn súnmọ́ ìtòsí.
- Amina Zakari INEC: Àìmọ̀kan-mọ̀kàn ló ń ṣe àwọn tó ń sọ̀rọ̀ tako ìyànsípò Amina Zakari Gẹgẹ bii iroyin ti o n tẹ BBC News Yoruba lọwọ ṣe sọ, laaarin awọn igun ẹgbẹ awakọ ero NURTW meji ni ina wahala naa ti suyọ ti wọn si bẹrẹ si nii yibọn fun ara wọn.
Ni ayé àtijọ́, kò si ohun ti ó njẹ́ Agbalésanwó nitori kò si ẹni ti kò ni ẹbi ti wọn lè bá gbé ni ọ̀fẹ́.
Ohun to sọ ni pe oun fẹ kawọn ọmọ oun ló sile iwe, ki wọn si di eeyan nla lawujọ.
Ẹwẹ, awọn oniroyin WSJ ni awọn ni aridaju orisun iroyin laarin awọn ologun Naijiria gan to fi mọ ọga kan lẹnu iṣẹ ọba.
" Sobola fikun pe Maryam gba ibinu lati gbakoso ọkan rẹ, ohunkohun si lo lee fa isẹlẹ yii, koda awọn ọkunrin lee ti obinrin debi pe yoo fi gbẹmi eeyan, bakan naa si lawọn obinrin kan ni aseju lọwọ, ti wọn si maa n se idajọ lọwọ ara wọn, eyi to maa n mu ki nkan polukumusu sii.
Friend of God, Sheu Usman Dan fodio, Òwe àti Ìtumọ̀ rẹ̀, Sàngbá fọ́, àti bẹ́ẹ̀ bẹ́ẹ̀ lọ.
Iyawo aarẹ orilẹede Naijiria ti ṣalaye bo ṣe mori bọ lọwọ ọkọ baalu to ri idamu loju ofurufu lasiko to n rinrinajo pada bọ wale lati ilẹ United Arab Emirates (UAE).
Ẹmi mi, ẹbi mi ati awọn aṣofin ẹgbẹ mi lo wa ninu ewu, idi si niyii ti a fi fi ilu silẹ wa fi ara pamọ si ilu Ibadan.
Ìwé èsì àyẹ̀wò arùn Covid-19 lè di kòṣeémàní fáwọn tí o bá fẹ́ rìnrìn àjò sí ilẹ̀ òkèèrè Àlàyé rèé lórí bo ṣe le è dá Emèrè mọ̀ tàbí dara pọ̀ mọ́ ẹgbẹ́ wọn Àwọn òṣèré tíátà Yorùbá kọjú ìjà síra wọn lórí ìdárò akẹẹgbẹ́ wọn tó kú Wo oríṣìí ìlù Yorùbá, ìwúlò wọn àti ba ṣe ń lò wọ́n Oloye Olusegun Obasanjo fi atẹjade sitra loni lati sọrọ lori igbesẹ Walter Carrington lasiko to n soju America ni Naijiria.
Ipade naa bẹrẹ lagogo mọkanla nile-ise aarẹ niluu Abuja.
spẹ ́ ktróskópì ni iwadi ibase larin ohun-elo ati okun-inu titanka .
Iroyin to tẹ wa lọwọ sọ pe awọn ọmọ ijọ Aguda kaakiri orilẹede Naijira yoo ṣe iṣọ oru lalẹ ọjọ naa.
Nítorí náà, nígbà tí mo rí ohun tí wọn ń ṣe, mo pa wọ́n run.
Ọ ̀ ràngún ilé Ìlá , onísábé ti ilẹ ̀ sábẹ ́ , olúpópó tí í ṣe ọba pópó àti Ọ ̀ rányàn .
Òṣèré tíátà Toyin Abraham daya Kolawole Ajeyemi Toyin Abraham rèé, ọmọ ìpínlẹ̀ Edo tó di àràbà nínú tíátà Yorùbá Obaseki, Ize-Iyamu àti Osagiobare ṣàlàyé ohun tí kóówá ní lọ́kàn fún ìpínlẹ̀ Edo lórí ètò BBC Iléeṣẹ́ ọlọ́pàá ní Kano tí ṣe àyẹ̀wò àwọn 13, 048 tó fẹ́ darapọ̀ mọ́ wọn Facebook mú àyípadà bá àtẹ̀jíṣẹ́ síra ẹni lórí òpó Instagram, wo àwọn ǹkan tó kàn ọ níbẹ̀ O lọ si ileewe gbogboniṣe poly ipinlẹ Ọṣun to wa nilu Iree ki o to kọri si ileewe gbogboniṣe Polytechnic Ibadan Eyi ni ohun marun un to duro laaye ọtọ laarin ogoji ọdun ti Toyin Abraham ti pe laye Oríṣun àwòrán, Instagram/toyin abraham Ọdun 2003 lo bẹrẹ iṣẹ sinima Ọdun 2003 lo bẹrẹ iṣẹ sinima lasiko ti Bukky Wright lọ ya iṣẹ sinima kan nilu Ibadan.
Eyi lo mu ki oṣere Wumi Toriola jawe s'obi ninu fọto to fi si oju opo Instagram rẹ.
Àní, kí n ṣá ti rí ojurere oluwa mi.
Nínú àtẹjjáde kan ti Gomina Bauchi fi sita láti ọwọ olùrànlọ́wọ́ pàtàkì rẹ lórí iròyìn Mukhtar Gidado, sàlàye pé àwọn jọ wó ọkọ ofurufu Aero Contractor ní to sì jẹ́ri si pé wọ́n jọ bọ́wọ lọ́ja náa.
fi kun oro re pe ofin tun gbodo faye sile fun ajo akole ile-sile iyen PSP lati
Ikinlo ohun wa latodo apapo ajo UN fun ise-akanse lorile-ede South Sudan , ti a mo si UN Mission in South Sudan (UNMISS) ati ofisi ajo ajafeto omo eniyan, High Commission for Human Rights (OHCHR).
Ẹni tí ń tà kò ní sí láyé láti pada síbi ohun tí ó tà ní ìgbà ayé ẹni tí ó rà á.
Won fi si ori oye yii gẹgẹ bi adari fun igba diẹ latari lile ti awọn olori agba egbe naa le awọn ti o wa nibẹ tẹlẹ kuro.
Ìdí rèé tí ilẹ̀ Afirika fi gbọdọ̀ kópa nínú dídán abẹ́rẹ́ coronavirus wò Nǹkan oṣù obìnrin le jáde ní imú tàbí ìdodo yàtọ̀ sí ojú ara - Dókítà Africans in China: Ọmọ Naijiria sọ bí wọ́n ṣe lé òun jáde kúrò nílé nítorí ó jẹ́ aláwọ̀dúdú Coronavirus and Kayeefi: Òtítọ́ àti irọ́ wo ló wà nípa oògun owó àtàwọn ìṣẹ̀lẹ̀ kàyééfì míràn Oríṣun àwòrán, Seyi Makinde Bakan naa lo fikun pe, ijọba oun tun ti da ọwọ le akanṣe iṣẹ miran ni ẹka naa to to mejidinlaadọrin pẹlu afikun pe oun lo ajakalẹ arun Coronavirus lati ṣe agbega ẹka eto ilera nipinlẹ Oyo ni.
Ẹni tí ń ṣe oríkunkun sí OLUWA ati ẹni tí ó ṣẹ́ṣó, bákan náà ni wọ́n rí; ẹ̀ṣẹ̀ ìgbéraga ati ẹ̀ṣẹ̀ ìbọ̀rìṣà kò sì yàtọ̀.
Wo ojú àwọn afurasí tó fipá bá Uwaila, akẹ́kọ̀ọ́ Uniben sùn tí wọ́n tún pa á sínúu ṣọ́ọ̀ṣì Ìtàn ayé Tunde Idiagbon, ọ̀gágun Kògbagbẹ̀rẹ́ tí kò ṣeé fowó rà Tarrant tó yìnbọn pa èèyàn 51 ní mọ́ṣálááṣí méjì gbà'dájọ́ ẹ̀wọ̀n gbére Àwọn òṣèré Nollywood tí wọn ò sí lóri amóhùmáwòrán mọ́ Òtítọ́ lékè!
Gbajue ń lọ orúkọ mi láti gba owó- Mama Rainbow Ọlọ́pàá bẹ̀rẹ̀ ìwadìí lórí ikú olùṣirò owo táwọn agbénipa pa ní Ikorodu Wo àwòràn ohun tó ṣẹlẹ̀ nílé ìjọsìn Sotitobire tí wọ́n sun ní àná Mí o mọ ǹkan kan nípa fọ́nran ìpolongo COZA- Davido Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Wọ́n ti run ọgbà àjàrà mi,wọ́n ti já àwọn ẹ̀ka igi ọ̀pọ̀tọ́ mi,wọ́n ti bó gbogbo èèpo ara rẹ̀,wọ́n ti wó o lulẹ̀,àwọn ẹ̀ka rẹ̀ sì ti di funfun.
Ahasaya jẹ́ ẹni ọdún mejilelogoji, nígbà tí ó jọba; ó sì wà lórí oyè fún ọdún kan ní Jerusalẹmu.
Nike Suliyat: Ọ̀dọ́mọdébìnrin akéwì tó n fi ẹ̀ṣà kìlọ̀ ìwá lásìkò yìí
Sir Ahmadu Bello: Wọn bi Sir Ahmadu Bello ni ọjọ kejila, oṣu kẹfa, ọdun 1910 ni Rabbah Sokoto.
Orúkọ àwọn baálẹ̀-baálẹ̀ náà nìwọ̀nyí: Elisuri ọmọ Ṣedeuri ni yóo jẹ́ olórí láti inú ẹ̀yà Reubẹni.
Liverpool lo kọkọ siwaju lẹyin ti James Milner gbayo wọle ni kete ti ifẹsẹwọnsẹ naa le diẹ ni wakati kan.
Fayẹmi bori ni ijọba ibilẹ mejila ninu mẹrindinlogun to wa ni ipinlẹ naa.
Ọkan lara awọn gbajugbaja elere tiata Yoruba, Dayo Amusa naa ba Pasuma yọ ayọ ọjọ ibi rẹ lori ẹrọ ikansiraẹni Instagram.
Ṣugbọn awọn oṣiṣẹ ileeṣẹ ọlọpaa, LASEMA, LRT, LRU PARAMEDICS, LRU FIRE, LASAMBUS, FRSC, RRS, LASTMA wa nikalẹ lati mu gbogbo nkan pada bọ sipo.
 friend of god , sheu usman dan fodio , Òwe àti Ìtumọ ̀ rẹ ̀ , sàǹgbá fọ ́ , àti bẹ ́ ẹ ̀ bẹ ́ ẹ ̀ lọ .
Awon ojuse miiran ni kiko iroyin sinu iwe iroyin olojoojumo, sise afihan lori ero amohun maworan ati fiforo wa awon eniyan lenu wo.
Bakan naa ni Alaaji Taiwo Akande Adebisi Taye Kọrẹnsi naa tun sọrọ lori bi o ṣe wakọ wọ agbami oṣelu, ọmọ rẹ, Yusuf Adebisi to jẹ ọkan lara awọn aṣofin ipinlẹ Ọyọ ati oniruuru iṣẹlẹ nipa igbesi aye rẹ.
Ọrọ naa lu sita lẹyin ti Trump fi atẹjiṣẹ sori twitter rẹ pe, oun ati iyawo oun ti lugbadi aarun Coronavirus.
Ṣugbọn yóo parun láìní ọwọ́ ẹnikẹ́ni ninu.
Ní oṣù Kisilefi, ní ogún ọdún tí Atasasesi jọba ní ilẹ̀ Pasia, mo wà ní Susa tíí ṣe olú-ìlú ilẹ̀ náà, 
Aisan ko ni jẹ ipin rẹ lailai."
Oríṣun àwòrán, Getty Images Lọjọ isegun ni o padanu emi rẹ ninu ìjà yọbẹ y'ada laarin awọn ẹgbẹ meji nilu naa.
Joshua Beckford: Ọmọ ọdún mẹ́rìnlá kàwé gboye jáde ni Fasiti Oxford
Atejade kan ti akọwe agba ileẹkọ naa, Alhaji Ibrahim Ribadu fisita ni ija ẹsin to bẹ silẹ laarin awọn akẹkọ Kristiẹni ati Musulumi lo bi aawọ naa, eyi to sokunfa bi wọn se pasẹ fawọn akẹkọ naa lati gba ọna ile koowa wọn lọ.
Àwọn ìròyìn mìíràn tí ẹ lè nífẹ̀ẹ́ sí: Ìyá Leah Sharibu ké gbàjarè sí ìjọba Buhari Boko Haram 113 dèrò ẹ̀wọ̀n nípínlẹ̀ Niger Ènìyàn márùn-ún kú nínú bàlúù ogun tó já ni Damasak Salkida ni ẹgbẹ naa ko sọ idi ti wọn fi yọ Abu Musab nipo ninu igbohunsilẹ ti wọn ti ṣe ikede naa.
O fikun wi pe awọn ko damu ara awọn lati mu asẹ ijọba ipinlẹ Kaduna se lori awọn ilakalẹ ti wọn fi le le lori irinajo El-Zakzaky lọ si India, nitori Ajọ DSS ti ni awọn yoo mu asẹ ile-ẹjọ sẹ.
Gomina ipinlẹ naa kede pe ijọba fun awọn arugbo, akanda ẹ̀dá ati awọn alaini ni oúnjẹ ọ̀fẹ́.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Saudi Arabia: Kíni ìdí ti àwọn ọmọ ogun fi n ṣọ́ àwọn Imaam ni Mecca?
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Boko Haram n fipá bá mi lòpò ní òpò ìgbà léyìn tí wọn kọlu ìlú wa- Omọbinrin náà 20 Òkùdu 2020 Oríṣun àwòrán, Others Àkọlé àwòrán, Ọ ṣòro fún mi láti foríjín ìbátan mi ọmọ ikò Boko Haram tó fipá bámi lòpò Mi o le fori jin ibatan mi ọmọ iko Boko haram to fipa bamilopọ Loni, ọjọ Kejidinlogun, oṣu Kẹfa, ti se ayajọ ti ajọ iṣọkan agbaye la kalẹ lati mu opin ba iwa ifipabanilopo lasiko ikọlu, Odomobirin kan ni Naijiria to ni ki BBC forukọ bo oun laṣiri sọrọ lori bi ibatan oun kan to jẹ ọmọ ikọ Boko Haram ati awọn miran ti ṣe fipa ba oun ati awọn ọmọbinrin miran lopọ f'un igba pipẹ ni ariwa Naijiria.
Ojú óo ti gbogbo wọn; gbogbo wọn óo sì di apárí.
" Ni bi a ṣe n sọrọ yii, eto ti n lọ ni pẹrẹ lawọn ibudo idibo abẹle lẹgbẹ oṣelu APC ni ilu Akurẹ.
Amọ BBC Yoruba wa n fi akoko yii ki iya Ibeji Alaafin ku oriire nipa ileesẹ aje tuntun rẹ, ta si gbadura pe aje yoo maa wọ igba.
Àwọn àjọ àgbáyé ti dẹ̀yìn kọ Òfin Ìṣíkúrò tí ó pàṣẹ àfilé ìdíyelé tí ó gbéra nílẹ̀ fìrì tí ó sì lọ òkè lálá.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ọrọ lori owo epo rọbi Ile ẹjọ kan lorilẹede Faranse ti sọ tẹlẹ pe, minisita tẹlẹ fun epo rọbi Dan Etete jẹbi ẹsun pe o kowo lọ silẹ okere, ati pe o fi owo ra ọkọ oju omi ayara bi aṣa lọna aitọ.
Aare tesiwaju lati tun gboriyin fun ise akinkanju ogagun Onoja lolokan-o-jokan eleyii ti o gbese lasiko to n si n ilu, ti O si tun gba lati je okan lara igbimo ajo to n mojuto eto oko irinna ofurufu ni Naijiria, “Federal Airports Authority of Nigeria, ile idanileko nipa oro ere idaraya National Institute of Sports, bee si ni fun ipa re ti ko se yesile ninu eto oselu bakan naa.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Njẹ́ ẹ ti gbọ́ nípa àríyá oníhòhò àti ìbálòpọ̀ tó fẹ́ wáyé ní Kaduna lásìkò ọdún?
Padà lẹ́yìn ẹni láàrín ín méjì
won ti gbagbe pe opolopo nnkan lo ti baje pupo, ki aare o to de ori aleefa.
O woye pe, ni ti Atiku, ko si ohun ti Atiku fẹ ṣe nibẹ ti Buhari ko ba si nibi eto naa, bo tilẹ jẹ pe o tọrọ aforiji pe, Atiku ko le kopa ninu ijiroro naa.
Ẹni tí kò bá gbọ́n níí jẹ́jẹ̀ẹ́,láti ṣe onídùúró fún aládùúgbò rẹ̀.
Siwaju si, asofin Dambaba to n soju fun ekun ila oorun ipinle Sokoto ro ile-igbimo naa lati pase fun igbimo to n ri si iwuwa si egbe nile igbimo asofin ohun lati sewadii idi ti igbimo to mojuto ile-ise omo ogun se kuna lati se ise won bose to ati bose ye.
Eto yii ni a o fi maa gbe àwọn iṣẹlẹ to gbẹnután, to ka ni láyà, to yanílẹnú wo káàkiri agbaye bẹrẹ lati Naijiria.
    N ó sọ nǹkan kan tí a rí ni òru ọjọ́ fún yín: ó ṣe ni, èmi tilẹ̀ sùn lọ, ni àwọn ènìyàn mi lú mi pẹ́pẹ́ láàrin òru tí wọ́n jí mi.
Oríṣun àwòrán, Others Àkọlé àwòrán, Primate Ayodele, Baba Adeboye àti Father Mbaka sọ àsọtẹ́lẹ̀ nípa ọdún 2020!
Àsìkò yí ni ìgbà ooru nré kọjá lọ, tí ìgbà òtútù nbọ̀ lọ́nà.
Osun after protest: Mo pinu látí dá Iphone ti mo mú padà, ṣùgbọ́n ọlọpàá mú mi- Afurasí
Ọ̀làjú sọ àṣà nù, wò ó báwọn obìnrin ṣe ń wà ọkọ kiri lórí ayélujára Wákàtí méjì àbọ̀ ní akẹ́kọ̀ọ́ yóò fi kẹ́kọ̀ọ́ lójúmọ́ - Ìjọba Oyo Bí pínpín owó ilù ṣe díjà sílẹ̀ láàrin àwa ìjòyè àti Oluwo rèé - Osa Iwo Ẹ wo àkọsílẹ̀ ọ̀pọ̀ ẹbùn tí ìkọ̀ọ̀kan olùdíje BB Naija tó kú nínú ilé, ti jẹ Kí ló mú kí ọkọ̀ kan tó jóná ráùráú lórí afárá Ojuelegba?
“OLUWA bá sọ fún mi pé, ‘Dìde, sọ̀kalẹ̀ kíákíá, nítorí pé àwọn eniyan rẹ, tí o kó ti Ijipti wá ti dẹ́ṣẹ̀, wọ́n ti yára yipada kúrò ní ọ̀nà tí mo pa láṣẹ fún wọn, wọ́n ti yá ère tí a fi iná yọ́ fún ara wọn.
Ohun tí a rí nílé Ajimobi rèé lẹ́yìn ìròyìn òfégè pé ó jáde láyé Godwin Obaseki ti darapọ̀ mọ́ ẹgbẹ́ òṣèlú People's Democratic Party Yẹ̀kínì kan kò lè yẹ ipinnu wa láti ṣí iléèwé pàda lóṣù yí - ìjọba ìpínlẹ̀ Oyo Gẹgẹ bi Dokita ọmọ Naijiria kan to tun wa ni ilu London fun imọ ẹkọ, Ogunboye Igbekele ṣe sọ fun BBC Yoruba, ọpọ nkan ni ẹ ti mọ tẹlẹ nipa awọn alaisan foniku fọla dide bii ki egungun maa ro wọn.
Ẹkunrẹrẹ bi iwọde naa ṣe lọ wa ninu fidio yii.
Wo àànfàní ‘Masturbation’, fífún ara rẹ̀ ní adùn ìbálòpọ̀ Wo àwọn ìlànà tuntun ti o gbọdọ tẹlèé rèé ki ó to le wọkọ̀ òfurufú lọ sókè òkun Ìdí ti mo fi da sọ́ọ̀sì rú lásìkò ìgbéyàwó ìyáwó mi tó ló fẹ́ ọkọ míran- Osadebe Risikat olójú búlù dí aya Wasiu ní ìlànà Islam, tẹbí tará péjú síbẹ̀ Ìdí ti mo fi da sọ́ọ̀sì rú lásìkò ìgbéyàwó ìyáwó mi tó ló fẹ́ ọkọ míran- Osadebe Ibrahim ni inu oun dun pe awọn ololufẹ oun pe oun lati mọ ohun to n sẹlẹ, to fi mọ aafin Oyo, to si n bu awọn akẹẹgbẹ rẹ ti ko wa ẹyin rẹ wo lati mọ boya ootọ lo wa lori akete aisan abi bẹẹ kọ.
Oshisko twins, àwọn 'ìbejì' tó ń dẹ́rìn ín p'òṣónú Ohun tí ojú opó ń rí láwùjọ kò kéré"" Ijọba Ondo n wa ọdẹ aperin Àwọn òṣèré, olórin Yorùbá gbàdúrà fún MC Oluomo Funmilola ni ariwo Oluwa jọọ da mi si ki n le sin ọ dopin ni igbe ti ọkọ oun ké ko too ku."
Dá mi sí gẹ́gẹ́ bí ìfẹ́ rẹ tí kì í yẹ̀.
"Ohun tẹ́ẹ gbúdọ mọ nípa kókó orí ọyàn yín lásìkò fífọ́mọlọ́yàn Ìyá àwọn ọmọ oní ""Blue Eyes"" n'Ilorin t'ọ́kọ dà síta bá BBC Yoruba sọ̀rọ̀ Ẹ́ wo bí sọ̀rọ̀sọ̀rọ̀ yìí ṣe ń fi ara rẹ̀ kọ́ àwọ́n òbinrin ní ìgbádùn ìbálòpọ̀ Bíbéèrè fún ìbálòpọ̀ gbogbo ìgbà sọ ìyàwó ilé dèrò ilé ìwòsàn Wò ó bo ṣe mú ara rẹ dé ibi tó ga jùlọ nínú ìbálòpọ̀ pẹ̀lú ìlànà Tantra Ilu London ni Yinka Ayanda wa to ti n ṣe iṣẹ to yan laayo lati maa ba awn kunrin ati obinrin sọrọ nipa gbigbadun ibalopọ ko da o ni eto lori ayelujara ti ọpọlọpọ maa n rọ bo lati wo olorin si ni pẹlu."
Wọ́n so ṣẹ́kẹ́ṣẹkẹ̀ mọ́ ọn lẹ́sẹ̀,wọ́n ti ọrùn rẹ̀ bọ irin,
Ó fí kún pé lẹ́yìn ti òun fi fótò náà si orí fóònù òun tàn, òun wá wá nọ́nbà Waka Quenn lójú òpó instagram rẹ.
France Vs Nigeria: Super Falcons takú síbẹ̀, àmọ́ ẹ̀pa kò bóró mọ́ Ọlọ́wọ́ idán Houdini kò yè é o, ó bómi lọ!
Coronavirus lè tara òkú Abba Kyari ran àwọn tó péjú síbi ìsìnkú rẹ̀- Ààrẹ ẹgbẹ́ dókítà ní Nàìjíríà Lórí ọ̀rọ̀ Ogun Majek, mi ò lọ́rọ́ láti sọ, ẹ lọ pe ẹni tára rẹ̀ kò yá- Mr.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ilé ẹ̀jọ́ tún pàṣẹ pé ẹnikẹ́ni tó bá nífẹ̀ẹ́ láti ra àwọn dúkìá náà gbọ́dọ̀ yọjú láàárín ọ̀sẹ̀ méjì péré 26 Ìgbé 2020 Oríṣun àwòrán, Others Àkọlé àwòrán, Ilé ẹ̀jọ́ tún pàṣẹ pé ẹnikẹ́ni tó bá nífẹ̀ẹ́ láti ra àwọn dúkìá náà gbọ́dọ̀ yọjú láàárín ọ̀sẹ̀ méjì péré Ilé ẹjọ́ gíga ìlú Abuja tí pàṣẹ pé àjọ tó ń gbógun ti ìwà ìbàjé, ICPC, gbé ẹsẹ lé àwọn dúkìá kan tó jẹ́ ti akọ̀wé tẹ́lẹ̀ fún àjọ JAMB, Ọjọgbọn Dibu Ojerinde.
Afeez Agoro: O ṣòro fún mi láti wọ Danfo jáde
Ó ṣá ti hàn si yín pé olóore ni Oluwa.
Lẹyin ọjọ mẹfa si i ni wọn ṣe awari oku rẹ lẹba ọna ni agbegbe ipinlẹ Eko.
Barakat, to jẹ akẹkọọ ile ẹkọ imọ nipa itọju ẹranko (Federal College of Animal Health and Reproduction) la gbọ pe o n gbe lagbegbe Akinyele nilu Ibadan, níbi ti awọn gende kan ti fipa baa lopọ, ki wọn to gbẹmi rẹ.
Kí ló dé tó jẹ́ sọ́ọ̀sì nìkàn ni ìjọba ń tìlẹ̀kùn mọ́ torí Covid-19?
Ẹ óo máa yá àwọn orílẹ̀-èdè ni nǹkan, ṣugbọn ẹ kò ní tọrọ lọ́wọ́ wọn.
" Oríṣun àwòrán, @asiwaju_ayobami O ni lẹyin eyi, awọn maa se atunse laarin awọn ọba ti Oluwo ti huwa abuku si kaakiri Naijiria, awọn yoo lọ ri wọn, pe ki wọn fiye denu, Oluwo naa ko si ni se bẹẹ mọ.
    Lẹ́yìn èyí ni mo ri i, tí ó dìde tí ó pa ilẹ̀ mọ́ tí ó di gbogbo ẹrù rẹ̀.
Oba Ogunwusi ti o jẹ alaga fun ajọ awọn ọba to wa lagbeegbe gusu Naijiria, sọ eyi nibi apejọ awọn lọbalọba to waye ni n'ilu Port Harcourt ni ipinle Rivers.
Yollywood: Àwọn ayé ló tú èmi àti Iyabo Ojo ká, wọ́n rò pé à ń fẹ́ ara wa ni- Muka Ray
Bí igbákejì ààrẹ, Yẹmí Osinbajo, ṣe ń lọgun pe owó tí èèyàn mẹ́ta lábẹ́ ìṣèjọba Aarẹ Goodluck Jonathan gbé lé ní bílíọ̀nù mẹ́ta náírà; bẹ́ẹ̀ gẹ́gẹ́ ni ẹgbẹ́ òṣèlú PDP pẹ̀lú ń pariwo pé ọ̀rọ̀ òṣèlú lásán ni wọ́n ń fi ṣe.
Abayomi Shogunle: Íjìyà tó tọ́ sí Charles Omotosho ni wọ́n dá fún un
Wọ́n sì kó òkúta jọ, wọ́n fi ṣe òkítì ńlá kan, gbogbo wọn bá jọ jẹun níbi òkítì náà.
Ọmọlẹyin gomina ana nipinlẹ Ọsun, Ọmọọba Ọlagunsoye Oyinlọla to tun jẹ agba ọjẹ lẹgbẹ oṣelu ADC ni ọpọ eeyan mọ aṣofin Oyeniran si.
O mẹnuba bi oun ṣe bẹrẹ pẹlu ijo ibilẹ nile iwe nibi ti oun ti rii pe ara oun ṣeé rọ́ si ipokipo tó bá wu oun.
Láti Bẹtẹli, ó lọ sí Lusi, ó sì kọjá lọ sí Atarotu, níbi tí àwọn ọmọ Ariki ń gbé.
”Nígbà náà ni olùdarí ìsìnkú yóo sọ pé, “Ẹ dákẹ́, ẹ ṣọ́ra, a kò gbọdọ̀ tilẹ̀ dárúkọ OLUWA.
Oríṣun àwòrán, LASEMA Àkọlé àwòrán, Eyi jẹ ijamba ibugbamu inọ epo ati gaasi ti yoo sẹlẹ nipinlẹ eko ninu osu yi Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Ó ṣe àwọn ohun ńlá tí ó kọjá òye ẹ̀dá,ati àwọn iṣẹ́ ìyanu tí kò ní òǹkà.
Awọn orilẹede to pẹlu Naijiria ni ni Eritrea, Sudan, Tanzania, Kyrgyzstan ati Myanmar ṣugbọn awn ọmọ orilẹede wọnyii kan ṣi le lọ ṣe ibẹwo nikan si Amẹrika.
Nítorí wọn kì í lè é sùn, bí wọn kò bá tíì ṣe ibi,oorun kì í kùn wọ́n, tí wọn kò bá tíì fa ìṣubú eniyan.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ìdí rèé tí mi ò fi yọjú sí ìgbìmọ̀ àjọ PFN- Fatoyinbo Ọ̀rọ̀ ìfipábánilòpọ̀ di kàyééfì lásìkò yìí; ọwọ́ tẹ àwọn kan ní Ekiti Obìnrin kan rèé tó sọ ìrírí rẹ̀ lẹ́yìn tí ọkùnrin mẹ́ta fipá báa lòpọ̀ Iyabo Ojo, Toyin Abraham, Mercy Aigbe, ta làwọn òṣèrébìnrin yìí gbè lẹ́yìn lórí ọ̀rọ̀ ìfipábánilòpọ̀?
Ní ọjọ́ 21, àwọn ọlọ́pàá sọ fún àwọn òbíi Deng láti máà gba agbẹjọ́rò fún un.
Oríṣun àwòrán, Reuters Iròyìn àyọ, àdínkù tún bá iye ènìyàn tó lùgbàdì Covid -19 ní Nàìjíríà lọ́jọ́ Àìkú Wo ojú àwọn tó na ìka máa lọ ilé sí Praise nilé ẹlẹ́gbọ́n àgbà BBNaija Owó dé!
Fún un ninu èrè iṣẹ́ ọwọ́ rẹ̀,jẹ́ kí wọn máa yìn ín lẹ́nu ibodè nítorí iṣẹ́ ọwọ́ rẹ̀.
Ọlọ́pàá kọlu àwọn ọmọ onílẹ̀, ní ìbọn àṣìyìn pa ènìyàn méjì Eèyàn 174,574 ló ti forúkọ sílẹ̀ fún ètò ìrànwọ́ ìjọba fáwọ̀n olókoòwò kéékèèké- Ìjọba Nàìjíríà Àwọn ọlọ́ṣà sùn lọ nínú ọkọ̀ tí wọ́n jí, lọ́wọ́ agbófinró bá tẹ̀ wọ́n Kò sí iléẹjọ́ tó le dá wa dúró, ìyanṣẹ́lódì yóò bẹ̀rẹ̀ ní Ọjọ́ Ajé - NLC Ẹ gbó òhun tí àwọn olùdíjé sípò gómìnà nípínlẹ̀ Ondo sọ nípa bàbá ìsàlẹ̀.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Orji Uzor Kalu: Ilé ẹjọ́ tó ga jùlọ ní Nàìjíríà wọ́gilé ẹ̀wọ̀n Orji Uzor Kalu, pàṣẹ ìgbẹ́jọ́ tuntun 11 Ọ̀pẹ̀̀ 2018 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 8 Èbibi 2020 Ile ẹjọ to ga julọ lorilẹede Naijiria ti wọgile idajọ ẹwọn ọdun mejila ati gbigbẹsẹle dukia ti ile ẹjọ gbe le gomina ipinlẹ Abia tẹlẹ Orji Uzor Kalu.
 nígbà tí ìyá rẹ ́ hajia asmah náà jẹ ́ gbajúmọ ̀ nípa kí á bọ ̀ wọ ̀ fún ọkọ nílé àti nìta .
Ṣé ìgbéyàwó òṣèré tíátà leè pẹ́?
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Zainab Aliyu: Orílẹ̀èdè Saudi túu sílẹ̀ lẹ́yìn oṣù mẹ́rin tó ti wà ní àhámọ́ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Zainab Aliyu: Orílẹ̀èdè Saudi túu sílẹ̀ lẹ́yìn oṣù mẹ́rin tó ti wà ní àhámọ́ 13 Èbibi 2019 Ọmọbinrin, ọmọ orilẹede Nàìjíríà, ẹni ọdún méjìlélógun ti wọn ṣẹ̀ṣẹ̀ fí sílẹ̀ ní àhámọ ni Saudi Arabia, Zainab Aliyu, tí balẹ̀ si ìlú Kano báyìí Ní kété tó balẹ̀, ẹkún ayọ̀ ló mu bọnu lẹ́yìn to rí àwọn mọ̀lẹ̀bi rẹ̀, bẹ́ẹ̀ ló ń kígbe Ọlọ́hun mo dúpẹ"", ""Ọlọhun mo dúpẹ́"", kò sọ ǹkankan ju ariwo Ọlọ́hun mo dúpẹ́ lọ."
Agbẹnusọ Obasanjo, Kehinde Akinyemi, lo fidi ọrọ naa mulẹ ninu ifọrọwerọ pẹlu BBC Yoruba.
"Àwọn tó jí ọmọ mi gbé nílé ìjọsìn ní ń kò gbọdọ̀ wa tàbí kí ẹ̀mí mi lọ si Ẹ dẹ́kun àbùkù tẹ fi ń kan Nàíjíríà, ẹ fi Sowore sílẹ̀ láhàmọ́ọ́ - Wole Soyinka ""Aug 2018 ni ìgbìmọ̀ aláṣẹ APC ti ṣe ìpàdé kẹ́yìn, Oshiomole ti kùnà"" Òbítíbitì ẹ̀gbin ti sọ ìlú Ibadan di ààtàn - Aráàlú figbe bọnu Samuel Kalu ati Victor Osinmhem lo gbeja ikọ Super Eagles, ti wọn si gba bọọlu meji sinu awọn Ikọ Benin Republic lati kẹsẹjari ninu ifẹsẹwọnsẹ naa."
Nígbẹyìn ó di omi ńlá, ṣùgbọ́n èmi di òòrùn, mo bẹ̀rẹ̀ síi ràn kíkan kíkan, àwọn ọdẹ di ẹye wọn n fo lo sori igi.
Ọjọ Kẹrinla, osu Kẹta, ọdọọdun si ni ayajọ Lasabi naa maa n waye nilu Abẹokuta.
koju Senegal ninu ifesewonse olorejore lojo kerindinlogun osu kefa saaju idje AFCON.
Ní ọjọ́ kan ni a gbọ́ pé ọwọ́ tẹ ọlọ́ṣà kan tí ó lọ jí ọkọ̀ àlùfáà ìjọ Ọlọ́run kan gbé.
Àkọlé àwòrán, Gbogbo awọn opo to janfani awọn ohun elo naa ni yoo wulo fáwọn lati da ileeṣẹ alabọde silẹ Gbogbo awọn opo miran nibi eto naa to janfani awọn ohun elo naa bii arabinrin Racheal Taiwo ati Kudirat Rufai ni awọn ohun elo iṣẹ kerejekereje ti wọn fun awọn 'yoo wulo lati da ileeṣẹ alabọde silẹ lati maa bọ ẹbi awọn.
Nítorí náà ó sọ fún wọn pé, “Ọkunrin ìjòyè pataki kan lọ sí ilẹ̀ òkèèrè, wọ́n fẹ́ fi jọba níbẹ̀ kí ó sì pada wálé lẹ́yìn náà 
Kí gbogbo wọn tóó túká ó wí fún wọn pẹ̀lú pé ìgbà tí ó bá di ọdún kẹrìnlá lẹ́hìn náà ni òun óò tún padà wáá bẹ́ wọ́n wò ní òde ayé kí òun wáá gbọ́ bí wọ́n tí ń gbádùn nǹkan tuntun gbogbo tí wọ́n béèrè sí.
 odùduwà ṣí adé , ó sì fi lé ọmọ náà lórí , ọmọ náà sì gbàgbé sùn lọ tòun tadé lórí .
- Aráàlú ń bèèrè Aarẹ Muhammadu Buhari tí bá àwọn ọmọ Naijiria sọrọ, bi orile-ede yii se n se ayẹyẹ ominira ọgọta ọdun.
Nítorí àwa fúnra wa ti gbọ́ ọ̀rọ̀ tí ó fẹnu ara rẹ̀ sọ.
" Ajọ Nimet salaye pe ooru to ndapọ mọ ọyẹ lagbegbe aarin gbungbun ariwa orilẹede yi lee sokunfa ojo nibẹrẹ ọdun.
Àkọlé àwòrán, Ẹgbẹ oselu marundinlogoji lo dije du ipo fun gomina ipinlẹ Ekiti ni ọdun 2018.
Emir of Kano: Gómìnà ìpínlẹ̀ Kaduna fún Sanusi ní ipò tuntun
Ṣùgbọ́n eyín rẹ̀ funfun ti n kò rí irú rẹ̀ rí, ó dára ó rí wẹẹrẹ.
 oríṣi kejì nit i àwọn ọkùnrin tí ó máa ń lu ṣẹ ̀ kẹ ̀ rẹ ̀ .
Nígbà tí ó rán ẹrú mìíràn lọ, pípa ni wọ́n pa á.
Lẹyin naa lo sọ pe iru igbesẹ bẹẹ yoo mu ko ṣoro fun awọn ọdọ, papa awọn ti ko lowo lati kopa ninu idibo ni Naijiria.
Ileesẹ itẹwe iroyin THE SUN lo ni fidio yi.
ekun orile ede yii  ,ti n se ayeye
Ọlọrun bá yí ọkàn rẹ̀ pada, kò sì ṣe ibi tí ó gbèrò láti ṣe sí àwọn eniyan náà mọ́.
Ìjàpá sọ fún ọba bí òun àti ìgbín ṣe jẹ́ ọ̀rẹ́ kòríkòsùn àti bí àwọn kì í ṣe fi nǹkan kan pamọ́ fún ara wọn.
“Kí ló dé tí o fi mú mi jáde láti inú ìyá mi?
Nigba to n sọrọ lẹyin ti wọn tọwọ bọwe adehun tan, alaṣẹ ati oludari ileeṣẹ ọhun, Ọgbẹni Akintayo Adaralegbe ni ọkan Akin ti Oreofeoluwa ṣe nigba ti iya rẹ fẹ da seria fun un lo jẹ ki ileeṣẹ naa nifẹ si i.
Àwọn olórí wọn ní Soani ti di òmùgọ̀,àwọn olórí wọn ní Memfisi sì ti gba ẹ̀tàn;àwọn tí wọ́n jẹ́ òpómúléró ní ilẹ̀ Ijipti ti ṣi Ijipti lọ́nà.
wọ́n to emeradi ati safire ati dayamọndi sí ẹsẹ̀ keji, 
Jesu wí fún wọn pé, “Bí ó bá jẹ́ pé ẹ fọ́jú, ẹ kò bá tí ní ẹ̀bi.
Jesu wí fún un pé, “Fún mi ní omi mu.
Àwọn ọmọ Israẹli tí wọ́n ba ní ibùba bá jáde kúrò níbi tí wọ́n ba sí ní apá ìwọ̀ oòrùn Geba.
Àtètèròtẹ́lẹ̀ ni wípé ní kété tí o bá ti pe obìnrin ní àjẹ́, o lè tẹríi rẹ̀ ba fún ìlòkulò.
Enìyàn mẹ́jọ ni àìsàn náà pa lákòókò náà.
Ilé ejọ́ Abuja ké si Fatoyinbo ati Busola Dakolo pé kí wọ́n yọjú.
 o pa nọmba nla ti awọn ọmọdebinrin ati awọn ọdọ ni ilu washington ni awọn ọdun 1980 ati ọdun 1990 .
Abewo ohun ni won se agbekale re lati lo se ipade po pelu aare orile-ede Togo, Faure Gnassingbe Eyadema nipinle naa.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Kano: Ọkùnrin mẹrin wọ gàù 'torí ìgbéyàwó orí Facebook 11 Agẹmo 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 12 Agẹmo 2019 Oríṣun àwòrán, AFP Àkọlé àwòrán, Ni kia ti iroyin naa jade ni awọn ọlọpaa sharia ti n wa Sanusi Abdullahi Awọn ọkunrin mẹẹrin ti 'wọ wahala' nilu Kano nitori pe wọn ṣe ayederu eto igbeyawo lori opo ibaraẹnidọrẹ Facebook.
Iṣé òòjọ́ wọn ni wọ́n ń ṣe.
Ìgbáyé-gbádùn ọmọ Nàìjíríà ní South Afrika ló jẹwá lógún- Buhari Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ogbologbo ijapa l'aafin Sọun Ajamu ṣalaye pe, idi ti wọn fi n pe ijapa ọhun ni Alagba jẹ nitori ọjọ ori rẹ.
Awon akoroyin ile akede Naijiria ,Voice of Nigeria , ti won wa ni ipinle
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: ‘Daily Trust fi àsírí ìgbógun tí Boko Haram jáde la se tì í’ Àwọn ológun gba ìjọba ilẹ̀ Gabon Ọmọ Nàíjíríà fèsì lórí ààrẹ NANS tó ń sèlérí ìbò fún Buhari Àwọn wòòlí ń takora lórí Atiku àti Buhari Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Alao Akala:Èmi àti Ajimọbi kò ṣe ìlérí kankan fún ara wa O fikun wi pe, idunnu lo jẹ fun awọn wi pe awọn ologun ko lu ẹnikẹni, bẹẹ si ni wọn ko pa ẹnikẹni lasiko ti wọn yabo ileeṣẹ naa.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Phone Battery: Wo bí o ṣe lè jẹ́ kí bátììrì fóònù rẹ pẹ́ síi 5 Ọ̀pẹ̀̀ 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 19 Èbibi 2020 Oríṣun àwòrán, @others Àkọlé àwòrán, Wo bí o ṣe lè jẹ́ kí bátììrì fóònù rẹ pẹ́ síi Ohunkohun ti ẹda ba n ṣe laye yii, o yẹ ki a fi tọkan tara ṣee ni- Ọjọgbọn Nigba ti ọjọgbọn Akira Yoshino bẹrẹ iṣẹ iwadii rẹ lori lilo batiri tuntun ti ẹmi rẹ yoo gun sii nibẹrẹ 1980; ko mọ pe pe iwadii naa maa di nla mọ oun lọwọ.
Bótilẹ̀ jẹ́ pé ìjọba ti wá ọna abayọ si sunkẹrẹ-fakẹrẹ ọkọ lasiko ti iṣẹ ba n lọ lori afara Third Mainland ti wọn fẹ tunṣe ni ilu Eko.
Bii ago meje abọ owurọ ni iṣẹlẹ yẹn ṣẹlẹ."
"Gẹgẹ bí ọ̀rọ̀ Bakare kọ si Odumakin, o ni ""Káàrọ̀ Yinka, mo ti ka ọ̀rọ̀ ti Femi Fani -Kayode kọ níbi ti ó ti dárúkọ rẹ̀ àti àwọn míràn."
Àwọn àgbààgbà ìlú yóo pe ọkunrin náà, wọn óo bá a sọ̀rọ̀, bí ó bá kọ̀ jálẹ̀, tí ó wí pé, ‘Èmi kò fẹ́ fẹ́ ẹ,’ 
Ẹ lè wá sọ pé, “Anfaani wo ni ó wà ninu èyí nígbà tí àwọn mìíràn ninu wọn kò gbàgbọ́?
Wọn ni o na ninu owo-ifilọlẹ apapọ nigba ti ko ri aṣe gba ni ile-igbinmo aṣofin lasiko naa.
A dupe lọwọ ikọ Amọtẹkun, ikọ ọlọpaa ati awọn ẹsọ alaabo ti wọn ri daju wi pe wọn gba awọn ohun ini yii pada''.
Ọdun mẹtadinlọgbọn ni yii ti Shah Rukh Khan to jẹ gbajugbaja oṣere to máa n dari bi fiimu ti bẹrẹ isẹ ni ẹka amuludun.
"Ìyàwó gómìnà tọ́jọ́ orí rẹ̀ kéré jù ní Nàìjíríà rèé, ohun tóo lè fẹ́ mọ̀ nípa rẹ̀ Ìyàtọ̀ wo ló wà láàrin Amotekun àtàwọn àjọ aláábò mìíràn Àṣìta ìbọn sọ́já pa ẹgbọn Kamsi tó pé sọ́ja kó wá fìyà jẹ aládùúgbò rẹ̀ ""Amọtẹkun ko ni gbe ibọn, ikọ alaabo sọ́ọ́ ni yoo jẹ ni ipinlẹ"" ""Iṣẹ Amọtẹkun ati ija ko jọ ara wọn rara o, Amọtẹkun ko ni jagun, ọrọ aabo ni iṣẹ tiwa""."
Gbogbo awọn to n ta ibo wọn ti wọn si tun n da wahala ati rogbodiyan oṣelu silẹ 11.
Awọn akọsilẹ kan ti ẹ sọ pe ko jina si opopona Adebipon, ti awọn ọmọ ẹgbẹ naa ti kọkọ fa wahala.
"- Amẹ́ríkà fọnmú Èmi àti Kolington kò fẹ́ra padà o, ọba Wákà kò fẹ́ ọba Fuji mọ́ - Salawa Abeni Èmi sì ní Oluwo tilẹ̀ Iwo, kò sí ìgbìmọ̀ ọba kankan tó lè ní kí ń rọ́ọ́kún nílé - Oluwo Toyin Abraham ọkọ rẹ̀ àti Ire ní London, Odunlade 'kòlábò' pẹ̀lú Mercy Aigbe Èlé owó iná ọba kọ́ ló kàn, ẹ kọ́ ṣàtúnṣe sí ìlànà àdánú tẹ́ ń ṣe fún wa - Iléeṣẹ́ apínná sọ fún ìjọba ""A mọ riri ileesẹ BBC News Yoruba fun ipolongo ede, aṣa ati ise Yoruba."
Buhari ti ro iko omo ogun ati apapo ile ise alaabo lati jara mose ki won si pese
Saulu bá ranṣẹ sí Jese pé kí ó fi Dafidi, ọmọ rẹ̀ tí ń tọ́jú agbo ẹran ranṣẹ sí òun.
Nígbà tí àkókò tí Jakọbu yóo kú súnmọ́ tòsí, ó pe Josẹfu ọmọ rẹ̀, ó wí fún un pé, “Wá, ti ọwọ́ rẹ bọ abẹ́ itan mi, kí o sì ṣèlérí pé o óo ṣe olóòótọ́ sí mi, o kò sì ní dà mí.
 bakanna ohun tun ni bisobu hippo regius .
Ènìyàn 643 ló tún ṣẹ̀ṣẹ̀ lùgbàdì ààrùn Coronavirus ní Nàíjíríà Ọkan lara awọn dokita to n ṣiṣẹ ni Port Elizabeth, John Black sọ pe ṣaaju arun Covid-19 ni awọn oṣiṣẹ wọn ko ti to n kan, arun naa si tun mu ki nnkan buru sii.
Ọba dáhùn pé, “Bí OLUWA kò bá ràn ọ́ lọ́wọ́, ìrànlọ́wọ́ wo ni èmi lè ṣe?
Ninu ọrọ to ba BBC News Yoruba sọ lasiko eto facebook live lori ikanni ayelujara facebook ni o sọrọ yii.
Kí ló wá kù kí á ṣe?
Ọlọrun bínú sí wọn;ó pa àwọn tí ó lágbára jùlọ ninu wọn,ó sì lu àṣàyàn àwọn ọdọmọkunrin Israẹli pa.
O ni eni to ba gba ise akanse ibi ti omi ba ti yale yoo foju wina ofinomi Gboyhega Nasiru Àkọlé àwòrán, #BBCGOVDEBATE: Ẹṣẹ Mẹ́ta ni ètò ìjọba fi lélẹ̀ ní Ogun Gboyega ni pipada si ileewe ekosẹ ọwọ yoo wulo pelu ìmọ ẹrọ pẹlu kikọ awon eeyan ni iwa Omoluwabi ati idapada aṣa yoo yanju wahala abo.
Wo nnkan ti yoo ṣẹlẹ si Ọba ti wọ̀n ba gbe ọpa aṣẹ rẹ lọ: Oríṣun àwòrán, LASG and Screenshot Ni Ọjọru ọsẹ yii ni awọn janduku kan ya wọ aafin Ọba Isalẹ Eko, Ọba Rilwan Akiolu, to wa ni adugbo lasiko rogbodiyan to ṣẹlẹ ni ipinlẹ Eko nitori iwọde EndSARS.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Àwọn aláboyún f'ẹ̀hónú hàn ní ìpínlẹ̀ Òǹdó NMA: Buhari ni iṣẹ ṣe lori ilera alabọde Ibugbamu afẹfẹ gaasi meji pa ọpọ eniyan nipinlẹ Eko Eyi kìí ṣe iyanselodi àkọkọ Losu kẹsán ọdún tó lọ, ní iyanselodi kàn wáyé lórí àfikún owó oṣù, ajemọnu, igbega ati àwọn ẹtọ míràn fún àwọn osíṣe ìlera lorileede Naijiria.
Wọn gbagbọ wi pe ile obi obinrin lo yẹ ki o ma a gbe titi yoo fi fẹ ọkọ.
O gbe pe eyi yoo mu idagbasoke ba eto ogbin orile ede yii ati ona adojutofo lati fopin si ise ati osi.
Aare soro yii  lọjọBọ lasiko ti awon adari egbe osise orile
Ipade awọn igbimọ ijọba apapọ pawọpọ fẹnuko pé ẹgbẹrun mẹtadinlọgbọn ni awọn yoo maa san fawọn oṣiṣe Naijiria.
A dàbí aboyún tí ó fẹ́ bímọ ṣugbọn tí kò ní agbára tó.
Gẹgẹ bii iwe adehun idunadura naa ṣe sọ, baba agbalagba, ọmọ ọdun marundinlọgọrin yii ni yoo maa ṣe kokari inawo fun itọju ọmọdebinrin ọhun titi di oṣu keji, ọdun 2020.
Sei Baba n bọ̀ l'Óṣogbo Èwo ló pàtàkì jùlọ nínú ẹ̀rọ ìbánisọ̀rọ̀ àti ilé ìgbọ̀nsẹ̀?
Mi o ni iru iriri yii ri.
Iroyin sọ pe ọgọrọ eeyan lo lu ile baba to wa ni Mobolaje niluu Oyo pa nipinlẹ Oyo lati kẹdun ẹni 're to lọ.
Èyí kún nkan tí ọwọ́ ìjọba ọ̀ fi lè kàn wọ́n rárá tí wọ́n sì fi jẹ́
Makinde fidi ọrọ naa mulẹ ni Ọjọru, lẹhin to bura wọle gẹgẹ bii gomina tuntun nipinlẹ Ọyọ, eyi to waye ni papa Iṣere Ọbafẹmi Awọlọwọ, tokalẹ si opopona Liberty niluu Ibadan.
kí n sọ pé:Abo kinniun pataki ni ìyá rẹ láàrin àwọn kinniun!
Ó yí òkúta tí ó wà lẹ́nu ibojì kúrò, ó sì jókòó lórí rẹ̀.
Kí ó yẹ àrùn ara aṣọ náà wò ní ọjọ́ keje, bí ó bá ti tàn káàkiri lára aṣọ tabi awọ náà, ohun yòówù tí wọ́n lè máa fi aṣọ náà ṣe, irú ẹ̀tẹ̀ tí ó máa ń ràn káàkiri ni; kò mọ́.
Bí ẹ ó ṣe jẹ ẹ́ nìyí: ẹ di àmùrè yín mọ́ ẹ̀gbẹ́ yín, ẹ wọ bàtà yín, ẹ mú ọ̀pá yín lọ́wọ́; ìkánjú ni kí ẹ fi jẹ ẹ́, nítorí pé oúnjẹ ìrékọjá fún OLUWA ni.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ sí: 'Àwọn SARS ló yìnbọn pa ìyá mi' Kíni iyatọ tó wà láàrin FSARS àti SARS?
O fikun wi pe, kii se pe agba lo de si ọrẹ oun nitori ọjọ ori rẹ ko tii to nnkan, amọ asiko ti to, ni Majek fi di ero ọrun.
O ni America ti n din ọmọ ogun to wa ni Afghanista ku diẹdiẹ àti pe ẹgbẹrun mẹtala ọmọ ogun lo ku nibẹ lọdun mejidinlogun lẹyin ikọlu ọjọ kọkanla, oṣu késan an, ọdun 2001.
Ìdajì tí ó kù lára ilẹ̀ àwọn ará Gileadi, ati gbogbo ilẹ̀ àwọn ará Baṣani tíí ṣe ìjọba Ogu, ati gbogbo agbègbè Arigobu, ni mo fún ìdajì ẹ̀yà Manase.
O sẹ pataki lati mọ pe ipolongo #ENDSARS ni akori ọrọ to leke kaakiri agbaye lori aye;ujara Twitter ni ọjọ akọkọ to bẹrẹ, to si jẹ ọkan lara akori mẹwa to leke julọ ni Twitter lati igba na.
Barcelona vs Bayern: Koeman di akọ́nimọ̀ọ́gbá Barcelona tuntun lẹ́yìn ìjàmbá Champions League
Bí ẹ bá fẹ́, tí ẹ sì gbọ́ràn,ẹ óo jẹ ire ilẹ̀ náà.
com/realyomifabiyi/ O fikun pe ko dara ki wọn maa pa awọn eeyan kan lẹnu mọ tabi sọ irufẹ ẹni ti yoo daro wọn leti iboji ki araye ba le mọ pe wọn mọ ọrọ sọ.
Ṣugbọn bí ó bá jẹ́ láti ọwọ́ Ọlọrun ni, ẹ kò lè pa wọ́n run, ẹ óo kàn máa bá Ọlọrun jagun ni!
Oríṣun àwòrán, others O ni ki ijọba pada si bi iṣejọba ṣe wa ni saa isejọba tiwantiwa akọkọ lorilẹede Naijiria, ti ẹkun kọọkan n bojuto iṣejọba ara wọn, eleyii to jasi idagbasoke fun ilẹ Yoruba nigba naa.
Oríṣun àwòrán, @IsiakaAdeleke1 Àkọlé àwòrán, Ile ẹjọ fi aaye gbigba oniduro rẹ silẹ nitori ipo rẹ lawujọ Nibayii, ile ẹjọ ti wa sun igbẹjọ si ọjọ kẹtadinlogun, ikejidinlogun ati ikọkandinlogun oṣu kejila.
Minisita naa ni ijọba ti gbẹsẹle iwe aṣẹ irinna ofurufu ileeṣẹ naa titi di ọjọ miran, ọjọ re.
Antigua and Barbuda Bahamas Barbados Belize Comoros Cuba Democratic Republic of the Congo Dominica Ethiopia Gambia Guyana Jamaica Lebanon Lesotho Qatar Saint Kitts ati Nevis Saint Lucia Saint Vincent ati the Grenadines Trinidad ati Tobago Uganda Zimbabwe.
Olusegun Obasanjo wá rọ àwọn ìjọba Áfíríkà láti bẹ̀rẹ̀ ọ̀gbìn oúnjẹ lọ́pọ̀ yanturu gẹ́gẹ́ bíi ọ̀nà láti dènà ebi lẹ́yìn àrùn Covid-19.
Ẹ ṣora fun oorun osan gangan, pelu aṣo to bo ara.
Alaga ajọ INEC, Ọjọgbọn Mahmood Yakubu ni ofin idibo lorilẹede Naijiria ti la ijiya to yẹ fun ẹnikẹni to ba tapa si ofin idibo nitori naa ajọ INEC ko lee faye gba ofin tabi aṣẹ miran to ba yatọ si ilakalẹ ofin yii.
" Momoh ni ijọba ipinlẹ Eko lo yẹ ko wa ojutu si awọn iṣoro ọhun, idi ree ti iyanṣelodi naa ṣe n waye ni ipinlẹ naa.
ipinlẹ yoo wa ona miiran ti owo yoo fi maa wọ apo ijọba lona ti ijọba yoo maa
Àlá àwọn òjíṣẹ́ Olúwa tó fẹ́ jẹ ààrẹ Nàíjíríà leè má ṣẹ lógún ọdún - Abiara Ìbẹ̀rẹ̀ mi kò rọrùn rárá, omi máa ń bọ́ lójú mi tí mo bá rántí àkókò náà - Small Doctor Ẹ̀kún omi lé ọ̀pọ̀ onílé ní àdúgbò Isheri ní Eko Kèǹgbè lílù ní Ilọrin rèé, orin ìgbéyàwó, àwàdà àti ẹ̀ẹ̀kẹ́ èébú Ọba Lamidi Adeyẹmi, òṣìṣẹ́ adójútòfò àti Abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò kó tó jọba Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 3 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 5 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
LazioSpanish LaLiga Santander February 10 13:00 Villarreal ?
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù World Economic Forum: A ò kópa mọ nínú àpérò ètò ọrọ ajé ní Cape town- Ìjọba Nàìjíríà 4 Owewe 2019 Oríṣun àwòrán, Presidency Àkọlé àwòrán, World Economic Forum: A ò kópa mọ nínú àpérò ètò ọrọ ajé ní Cape town- Ìjọba Nàìjíríà Ìjọba Nàìjíríà tí kédé pé òun ti yọwọ́ kúrò nínú ìpàdé àpérò ètò ọ̀rọ̀ ajé àgbáyé tí yòó wáye ni Cape Town lórí ọ̀rọ̀ àkọlù tí àwọn ọmọ orílẹ̀ èdè South Africa ń ṣe si àwọn ọmọ Nàìjíríà.
ọrọ idaniloju yii lojo Abameta lasiko ayẹyẹ ti igbimo  odo ati obinrin to sakoso eto ipolongo egbe (All
Ipinlẹ Eko ni awọn to ni i pọ si ju pẹlu eeyan mọkanlenigba, nigba ti eeyan méjìléláàdọ́fà ni ni Abuja, ti Kaduna atawọn ipinlẹ mejila miran si n tẹle lẹyin.
Kọmisọnna ọlọpaa nipinlẹ Osun Fimihan Adeoye ṣe abẹwo si Ọba ilu naa, Abdulrasheed Akanbi, ati awọn ẹbi to padanu ọmọ to padanu ẹmi rẹ ni Ileogbo ba wọn kẹdun, o si bu ẹnu atẹ lu bi awọn ọdọ ṣe lọ da ina sun agọ ọlọpaa naa.
Oyetola pari ọrọ rẹ pe ijọba oun wa lẹyin awọn oluwọde naa digbi lati igba ti wọn ti bẹrẹ fehonu han wọn.
Amọ awọn ọ̀rọ̀ to sọ si Aṣiwaju Tinubu lo n lọ niwaju ninu fidio yii.
Laarin awuyewuye yii ni El-Zakzaky funrarẹ ti gbe fidio kan sita, ninu eyi to ti sọ awọn ohun ti oju rẹ n ri lorilẹede India, bi o tilẹ jẹ wi pe ijọba apapọ naa ti sọrọ sita pe, ọrọ to sọ ko ri bẹẹ lọpọ igba.
Iroyin naa ni obinrin ọlọpaa ọtẹlẹmuyẹ ọhun lo fẹ baba yii bii ọkọ, lati ri idi agbara rẹ, eyi to mu ko rọrun lẹyin o rẹyìn lati mu Tafa Adeoye, lẹyin ti ogun naa wa sopin.
Òmíràn nínú wọn á ní ẹsè eyọ ìkan péré.
Won ro eyi nitori pe ipolowo ọja Coca Cola ni nkan bii ọdun 1030 lo sọ Baba Keresi di gbaju-gbaja.
Agbenuso fun ajo UN Farhan Haq so pe, awon meji ti won kagbako isele ohun je awon osise ajo kan ti ki I se ti ijoba orile-ede Faranse.
Inec ni esi idibo ijọba ibilẹ naa wa lọwọ rẹ, nigba ti awọn janduku agbebọn kọlu ọkọ to wa ninu rẹ.
Ibi gbogbo ni wọn ti n bi awọn ibeji to lẹpọ jakejado agbaye Bẹẹ ba gbagbe, nipinlẹ Bauchi yi kanaa lọdun meji sẹyin, mọlẹbi kan padanu ibeji to lẹpọ ni ẹsẹ mẹta nibi idodo wọn.
Bi aarẹ Trump ṣe n fẹsun kan awọn ileeṣẹ iroyin nilẹ Amẹrika wi pe awọn lo wa nidi iroyin ofege, Bakan naa ni awọn ileeṣẹ iroyin naa n kede pe awọn iroyin ti ko fẹsẹ mulẹ ni aarẹ Trump ma n kọ ibi ara si.
O ni eyi waye nitori pe igba akọkọ niyi ti Naijiria yoo gbalejo idije naa.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Police Brutality: Ọlọ́pàá ìpínlẹ̀ Kwara lé ọlọ́pàá mẹ́rin kúrò lẹ́nu iṣẹ́ fún ẹ̀sùn ìwà ìbàjẹ́ 22 Agẹmo 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 26 Agẹmo 2020 Ilé iṣẹ́ ọlọ́pàá ìpínlẹ̀ Kwara ti ni kí àwọn ọlọ́pàá mẹ́rin kan lọ rọ́kún nilẹ̀, nígbà ti àwọn mẹ́jọ mírà wà lábẹ́ ìbáwí fún onírúurú ẹ̀sùn ìwàbàjẹ́.
Gomina ipinlẹ Zamfara naa fikun wi pe agbara kaka ni awọn fi n san owo osu awọn osisẹ bayii, ti o si jẹ wi pe iranwọ ijọba apapọ lawọn fi n tiraka lati san owo osu ati ajẹmọnu awọn osisẹ.
O tẹsiwaju pe ijọ tun le pin isin si isọri ti eeyan ti yoo wa ni isọri kan ko ni pọ ju aadọta lọ.
 bakan naa ni ipade yii yoo tun pese eto iranwo fun awon ekun Ila -oorun Ariwa  lorile ede Naijiria ati apa ibikan lorile ede Niger, Chad ati Cameroon ti iko boko Haram ti sọsẹ si.
Ka nípa ọ̀nà tí agogo inú ara rẹ ń gbà ṣiṣẹ́
Túndé Atòpinpin máa ń lọ gbé ojà ní Èkó.
Nínú oṣù kínní ni wọ́n pa àwọn ológun Niger méje nígbà tí Boko Haram kolu ìlú Toumour.
rira awọn oka ti won yoo ko pamọ si ibi ikọjasi lorilẹ-ede Naijiria.
Neko ọba Ijipti mú Jehoahasi ní ìgbèkùn ní Ribila ní ilẹ̀ Hamati, kí ó má baà jọba lórí Jerusalẹmu mọ́.
YPPOludije fun igbakeji aare , fun egbe naa ni awon fara mọ
Wọn máa ń pín ara wọn sí ẹlẹ́gbẹ́jẹgbẹ́ láti ṣe iṣẹ́ ìlú láti jọ kẹ́gbẹ́ àjùmọ̀ṣe lẹ́nu iṣẹ́ àti oríṣìíríṣìí ayẹyẹ nílùú pẹ̀lú.
Olówó-ayé, Olówó-ayé, kùmọ̀ ńlá ń bẹ lápá ọ̀tún, ẹrù pàṣán ń bẹ lápa òsì, ìṣubú Àǹjànnú ń bẹ ní ibi gegele òkúta.
gbogbo ẹ̀dá yóo sì máa jẹ́wọ́ pé, “Jesu Kristi ni Oluwa,” fún ògo Ọlọrun Baba.
Nítorí náà, ‘Ẹ fetí sílẹ̀,kí èmi náà lè sọ èrò ọkàn mi.
Wọ́n kọ́ yàrá kan tí wọn ń pè ní Ibi-Mímọ́-Jùlọ, sí ọwọ́ ẹ̀yìn ilé ìsìn náà.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Oríire dé!
Oríṣun àwòrán, @others Àkọlé àwòrán, Nọ́mbà 13: Awọn oṣiṣẹ to wọ inu ajọ lọ ati awọn ti ọwọ wọn to ori ni ẹ maa ba iru telifiṣọn nile wọn lasiko yii nitori o jẹ ọkan lara awọn ti wọn ṣi n ṣakọ lara ogiri ile olowo lasiko yii Oríṣun àwòrán, @others Àkọlé àwòrán, Nọ́mbà 14: Eyi jẹ ọkan lara awọn to n lo oriṣiriṣi nkan bii ayelujara ati awọn nkan igbalode miran.
Amotekun: Ẹgbẹ́ fijilanté pariwo síta lórí ìlànà ìgbanisíṣẹ́ ikọ̀ Amotekun ní ìpínlẹ̀ Oyo
meje-le-okolenigba ati ookan (7,221) esi ibo.
Kí ló dé tí o ò ṣe nǹkankan?
Bi inira ba ba apa kan ara wọn,gbogbo ara ni yoo mọ inira rẹ'' Imam Gamal Fouda to ṣe waasi nibi irun Jimọ naa sọ pe ''agbebọn na da ọgbẹ si ọkan ọpọ eeyan jakejado agbaye.
Ṣugbọn lẹyin ọjọ mẹta, Zuma pada kọwe fipo sile ni tootọ.
Èyí yóo mú kí Aaroni máa mú orúkọ wọn wá siwaju OLUWA fún ìrántí.
Orin yìí dá lóríi agbègbè ayẹyẹ náà, àti ìrántí tí ó ti mú bá àwọn ayírapadà tí ó ti ń kópa láti ọdúnmọ́dún.
Nitori naa lo ṣe gbọdọ ri dokita ti o ba ṣe akiyesi naa to jẹ ajeji ni ara rẹ.
Ohun akọkọ ti a ṣe ni lati fun ijapa naa ni itọju ni kiakia, eyi to jẹ ki ara rẹ balẹ di ọjọ keji nitori o ni ipalara to pọ gan an ninu ijamba to ṣe e,"" Ẹwẹ, Sulaiman to ṣeesi fi ọkọ tẹ ijapa baba rẹ mọlẹ, wa fi idunnu rẹ han si bi iṣẹ abẹ ti wọn ṣe fun ẹranko naa ṣe yọri si rere."
Nigeria Independence Day: Aráàlú fa ìbínú yọ lórí ọ̀rọ̀ tí Buhari sọ fún àyẹyẹ òmìnira
idibo aare ati ile igbimo asofin, eleyi ti yoo waye ni gbongan akojopo ibo(International
Gege bi gomina Ambode se so, “Eyin eniyan ipinle Eko tooto, egbe oselu APC je egbe ti o tobi pupo, bee si ni ere ati ilosiwaju ipinle Eko lo je wa logun, ti o si gbodo mumu lookan aya wa.
 Àpeere irú gbólóhùn abode báyìí ni gbólóhùn alásínpò ìse .
Ìdájọ́ ńlá ń bẹ fún ayé, nítorí àwọn ohun ìkọsẹ̀.
Ipade naa waye lati jiroro lori aigbọra ẹni ye to n waye laarin awọn gomina ati ẹgbẹ osisẹ lori ọgbọn ẹgbẹrun gẹgẹ bi owow oṣiṣẹ to kere ju.
Iṣẹ́ tí OLUWA rán sí Israẹli nìyí, OLUWA tí ó ta ọ̀run bí aṣọ, tí ó dá ayé, tí ó sì dá ẹ̀mí sinu eniyan, ni ó sọ báyìí pé, 
"Ṣugbọn, iku mu u lọ lasiko to n ya ọkan ninu rẹ to pe akọle rẹ ni ""Olowo Ite""."
Mo bá tọwọ́ b'àpò mo kó gbogbo owó tí nbẹ níbẹ̀ fún arúgbó yìí.
INEC mo ko dé, ẹ̀rí rè é to ṣàfihàn èrú ìbò ní Kogi - Dino Melaye Láti ọdún 2025 lọ, to bá ṣe ìgbọ̀nsẹ̀ sigboro, o rugi oyin - Buhari Ọ̀nà láti bọ́ lọ́wọ́ àwọn olè nínú súnkẹrẹ fàkẹrẹ ojú pópó Lisabi Agbongbo Akala rèé, ẹni tó fi ìfẹ́, ìṣọ̀kan àti ìrẹ́pọ̀ gba ilẹ̀ Ẹ̀gbá lọ́wọ́ ìmúnisìn Opopona ti ko dara; Kii ṣe aniani pe ọpọ awọn opopona ni ilu Eko ni ko dara fun lilọ-bibọ ọkọ to ja geere.
Gege bi osise alamojuto eto ijoba nile funfun ohun se so lasiko to n ba awon akoroyin sori, O ni, aare Trump ti gba ninu ipade ti o waye lojo Isegun(Tuesday) lati fi awon omo ogun naa sile silu Syria fun igba die, amo ko so pato igba ti won yoo kuro.
Awọn ikọ agbabọọlu ilẹ Adulawọ ko tii rọwọ mu daadaa ninu idije ife ẹyẹ agbaye to n lọ lọwọ ni Russia yii.
23 Kí á lè kéde ẹ̀kúnrẹ́rẹ́ ìhìnrere mi láti ẹnu aláìlagbára àti òpè sí àwọn òpin ayé, àti níwájú àwọn ọba àti àwọn alakoso.
O ṣalaye pe iṣẹlẹ naa ko nii ṣe pẹlu idakureku ina ọba tabi kudiẹkudiẹ ajọ naa nitori ko wulẹ si ina lagbegbe naa tẹlẹtẹlẹ ṣaaju, lasiko ati lẹyin ijamba ina naa.
O ni oun yoo ṣe ipade pẹlu minista fun eto inawo lati yanju ohun gbogbo ti ASUU n beere nitowo.
Kí ni yóo sì jẹ́ àmì nígbà tí wọn yóo bá fi ṣẹ?
Ilẹ̀ yín yóo lọ títí kan Òkun Pupa, ati títí lọ kan òkun àwọn ará Filistia, láti aṣálẹ̀ títí lọ kan odò Yufurate, nítorí pé n óo fi àwọn tí wọn ń gbé ilẹ̀ náà le yín lọ́wọ́, ẹ óo sì lé wọn jáde.
Ọ̀gágun kan ní ẹrú kan tí ó ṣàìsàn, ó fẹ́rẹ̀ kú.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Àwọn wo ni gómìnà mẹ́rin tí yóò kojú àjọ EFCC lẹ́yìn tí wọ́n bá kúrò nípò?
Agbabọọlu iwaju fun orilẹede Naijiria, Victor Moses ti gba bọọlu s'inu awọn fun ẹlẹkeji lati igba ti ifẹsẹwọnsẹ Premier League saa yi ti bẹrẹ.
Àwọn náà ni wọ́n ni Nafati.
Ó mú ọ̀rá akọ mààlúù, ati ti àgbò náà, pẹlu ìrù wọn tí ó lọ́ràá, ati ọ̀rá tí ó bo àwọn nǹkan inú wọn, ati kíndìnrín ati ẹ̀dọ̀ wọn.
Wo àwọn èèkàn ìlú Kano tó kú láàrín ọjọ́ mẹ́rin sí ara wọn Orúkọ Abiku ni Okunnu tí mo ń jẹ nínú eré, inú orin Barrister ni mo sì ti ri - Wale Akorede Yàtọ̀ sí mímu, àǹfàní tó wà lára igbó pọ̀ jaburata- Akeredolu $30bn owoya ti Buhari fẹ́ gbà, kí ló wà fún?
Bàbá mi, ẹ yé fi mí gba ìràwọ̀, ọmọbìnrin Charly Boy, Dewy Oputa fárígá fún bàbá rẹ̀ Oladele sọ pe aṣiwere ni ọkunrin to ba n dunnu pe oun lo nnkan bi ọgbọn iṣẹju lati fi ba oninrin ni ibalopọ.
Ẹ óo kígbe pè mí,n óo sì dáhùn pé, ‘Èmi nìyí.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí:] Ọmọ Nàíjíríà faraya lórí àìkópa Buhari àti Atiku nínú ìjíròrò Omoyele Sowore: Èrù ló ń ba àwọn NEDG láti pè mí''Ìdí tí mo fi rin ìrìn 800 metres'' ''Ìdí tí mo fi rin ìrìn 800 metres'' O ṣalaye wipe, bo tilẹ jẹ pe awọn oludije to ku ti ni awọn le ṣe atilẹyin fun oludije ti aparapọ ẹgbẹ oṣelu ba fa silẹ, oun ko ro pe iru igbesẹ yii maa waye.
Olóòtú Ilẹ̀ Gẹ̀ẹ́sì, Boris Johnson ti kó àrùn Coronavirus!
Ajo to n samojuto eto ẹyawo lagbaaye
Àwọn ọmọ ogun bíi ẹgbẹta (600) wà ní ọ̀dọ̀ rẹ̀.
Lilọ Hajj O ṣe pataki lati lọ Hajj tabi Umurah.
"A fẹ́ gba ₦1bn lọ́wọ́ ìjọba Eko pé ó dẹ́yẹ sí wa - 123 Ọlọ́kadà Jigawa ""A kò ní ra ọjà South Africa mọ́, a ó gbẹ̀san oró tí wọn ń dá wa - Ọmọ Nàíjíríà fárígá"" Orí mi wú pé àwọn àgbà ìjòyè kọ́wọ̀rín-ìn tẹ̀lé Olúbàdàn, ìjà parí - Makinde Ìdí ti àwọn kọmísọna ṣe to láti kí ìyáwó gómìnà tuntun káàbọ̀ Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!"
Ọmọ bibi ilu Abẹokuta si ni.
Ẹwẹ, agbabọọlu Arsenal, Lucas Torreira lo rọpo Partey ni Atletico Madrid lẹyin to darapọ mọ wọn fun ọdun kan.
Awọn to ti figba kan wa lẹwọn yii tun sọ fun ile ẹjọ pe lọpọ igba lawọn ẹlẹwọn kii lanfani si awọn ohun ti wọn nilo bi ọṣẹ, ọṣẹ ifọyin atawọn nkan miran.
Ó lọ títí dé Sini, ó tún lọ sí apá gúsù Kadeṣi Banea.
Bakan naa ni o fi kun un pe iṣuna naa yoo da lori paṣiparọ owo ni naira marunlelọọdunrun si dọla owo ilẹ Amẹrika kan.
Àwọn ọlọ́rọ̀ yín kún fún ìwà ipá; òpùrọ́ ni gbogbo àwọn ará ìlú, ọ̀rọ̀ ẹ̀tàn sì kún ẹnu wọn.
Nígbà tí wọ́n dé, ẹ wẹ̀, ẹ kun àtíkè, ẹ tọ́ ojú, ẹ sì ṣe ara yín lọ́ṣọ̀ọ́.
Super Eagles kò ní já àwọn ọmọ Nàìjíríà kulẹ̀- Musa Wo ìdí tí àwọn obìnrin kan fi n yọ ilé ọmọ wọn kúrò Èyí ni ọ̀nà tí àwọn obìnrin n gbà kó ara wọn sí wàhálà nítorí ara bíbó Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Lati aimọye ọdun, nkan eewọ ni wọn ka nkan oṣu obinrin si ni orilẹ-ede naa, igbagbọ wọn ni pe awọn obinrin to ba n ṣe nkan oṣu ko mọ, wọn ki i si jẹ ki wọn o kopa ninu ayẹyẹ ati ọrọ ẹsin.
Bẹ́ẹ̀ ni Mẹfiboṣẹti, ẹni tí ẹsẹ̀ rẹ̀ mejeeji ti rọ ṣe bẹ̀rẹ̀ sí gbé Jerusalẹmu, ó sì ń jẹun lọ́dọ̀ ọba nígbà gbogbo.
Nígbà tí ọ̀sán pọ́n, wọ́n bẹ̀rẹ̀ sí kígbe, wọ́n ń sáré kiri bíi wèrè, títí tí ó fi di àkókò ìrúbọ ọ̀sán, ṣugbọn Baali kò dá wọn lóhùn rárá.
2 Àti nígbànáà, kíyèsíi, àwọn àkọsílẹ̀ mìíràn ni mo ní, tí èmi yíò fún ọ ní agbára pé kí ìwọ le ṣe àtìlẹ́hìn lati túmọ̀.
Wo ohun tó yẹ kí o mọ̀ nípa akínkanjú obìnrin alága àjọ elétò ìdìbò Ghana 2020 Buhari, pàṣẹ f'àwọn Gómìnà pé kí wọ́n jáwọ́ nínú èróǹgbà láti ná N17trillion owó ìfẹ̀yìntì òṣìṣẹ́ Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 3 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 5 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Tinubu sọrọ naa ni Ọjọru nibi ayẹyẹ igbaniwọle fun olori ọmọ ile to kere ju nile aṣofin agba Naijiria, Sẹnetọ Godswill Akpabio, to waye ni papa iṣere Ikot Ekpene, nipinlẹ Akwa Ibom.
Nígbà tí ó di ọjọ́ kan báyìí, mo gbé ojú sókè omi bọ́ lójú mi mo ké pe Ọlọ́run, mo ní, Ìwọ Ọlọ́run Ọba, má ṣàìkó wa yọ nínú ìhámọ́ yìí o.
 Mi o nife lati joko ma a wo awon aseyori mi, sugbon mo tun fe sise si lati tun fida miiran laale nniu idije Serie A.
Ẹrọ afunnilogun naa maa n fun awọn alaisan ti aisan wọn kii gb'ogun bọrọ ni anfani ati gba ogun laarin isẹju mẹta-mẹta, nigboro Alexandra, lorilẹede South Africa.
Báwo lẹ ṣe rí oúnjẹ wọn sí?
'Buhari ló lè sọ ìgbà tó máa yan minisita míì' Omoyele Sowore: Èrù ló ń ba àwọn NEDG láti pè mí 'Ó ku Shittu, ó ku Ọlọ́run lórí ohun tó fẹ́ fi san ẹgbẹ́ APC l'ẹ́san' Lẹyin ọpọlọpọ awuyewuye abẹnugan ile asofin, Họnọrabu Yakubu Dogara wa parọwa si awọn asofin wi pe ti minisita naa ba kọ lati tọrọ àforíjì ki o to di Ọjọ Isẹgun, ọsẹ to n bọ ni awọn yoo gbe igbese lori ọrọ naa.
Ko si ile ti ko fẹrẹ mọ Baba Suwe ni igba naa.
Kí oore-ọ̀fẹ́ wà pẹlu gbogbo yín.
 Bakan naa, @Benxta_ naa sọ pe Mi o lee gbagbọ pe Adeboye yoo joko o si wa ọna lati lo anfani ọjọ ibi iyawo rẹ fi sọrọ lori ara rẹ ati agbara to ni lori rẹ.
NURTW yóò fikùlukù pẹ̀lú Gómìnà Makinde láìpẹ́ Children's Day: Àwọn ọmọdé tó ń ṣe bẹbẹ láwùjọ Afíríkà Kini Pásítọ̀ Kumuyi fi ṣẹ ọmọ Naijiria?
yẹ ki awọn ọmọ orilẹ-ede South Africa loye ninu itan nipa ibaṣepọ
Lefi bá se àsè ńlá fún Jesu ninu ilé rẹ̀.
A gbọ́ pe awon òbí wọn ní wọn fin òògún náà silẹ, lati fi pa kòkòrò ẹ̀fọn ninu ile wọn.
Ilẹ̀ mì tìtì, nítorí angẹli Oluwa sọ̀kalẹ̀ láti ọ̀run wá.
Ẹ kò fẹ́ gbà pé ọjọ́ ibi ti súnmọ́ tòsí; ṣugbọn ẹ̀ ń ṣe nǹkan tí yóo mú kí ọjọ́ ẹ̀rù tètè dé.
Ó sì tún rí i pé Jakọbu gbọ́ ti baba ati ìyá rẹ̀, ó lọ sí Padani-aramu bí wọ́n ti sọ, 
 Ó kú ní orí òkè hor nígba tí ó di omo odún métàlélógófà .
Awujale ti ilu Ijebu, Ọba Sikiru Kayode Adetona ti ni gomina ipinlẹ Ogun, Ibikunle Amosun ko fẹran awọn ara Ijebu rara.
Olubadan to ye ko maa ko pa, to se koko ninu yiyan Mogaji ati Baale niluu
Wọn lọ fẹhonu wọn han lori idajọ ileejọ to fun ileeṣẹ Process and Industrial Development laṣẹ lati gbẹsẹ le ohun ini orilẹ-ede Naijiria to le ni biliọnu mẹsan an dọla.
OAU fẹ́ wádìí olùkọ́ tó fẹ́ bá akẹ́kọ̀ọ́ lò fún máákì Ẹgbẹ olukọni ya si meji ni fasiti Awolọwọ Ọ̀kan lara awon akekojade ileewe naa to ti keko jade ni nkan bii ogun ọdún sẹyìn ni igba ti awọn ti wa nileewe naa ni ojogbon yìí ti bẹrẹ.
Ọpọ ọmọ Naijiria le maa wo wi pe ki lorukọ aṣọ Tijanni Bande nile alaro Naijiria, Ta ni Ọ̀jọ̀gbọ́n Tijjani Bande tó di Ààrẹ ẹ̀ka Isọ̀kan Àgbáyé UNGA?
Iyẹ adiyẹ naa a ma a ri wuruwuru Ẹsẹ rẹ a ma a pọn bii igba ti ẹjẹ ba darogun sibẹ.
Ara àwọn ọrẹ rẹ̀ tún ni: àwo kòtò kan, tí wọ́n fi wúrà ṣe, tí ìwọ̀n rẹ̀ jẹ́ ṣekeli mẹ́wàá, tí ó sì kún fún turari; 
Asiko tiwa ni eleyii, ti a ba se ojuse wa lati satileyin fun aare Muhammadu Buhari.
Ninu ọrọ iyanju rẹ lati tubọ mu igberu ọrọ-aje orilẹ-ede yii, o ni a lo lati moju to eto ẹkọ, eto ilera ati pipese iṣẹ nipasẹ awọn eto to poju owo ati nina owo si awọn ẹka yii fun anfani ọpọ awọn ara ilu.
" bí àpeere , "" Ẹ ̀ wà "" ; èyí lè túnmọ sí ohun tí ó dára , bákan náà , ó tún túnmọ sí ẹ ̀ wà ( beans ) tí a máa ń jẹ ."
Ohun tó ba ni lọ́kan jẹ́ gbáà ni à si ba àwọn ẹbi tó pàdánù ẹmi àwọn ẹbi wọn nínú ìṣẹ̀lẹ̀ náà tó fi mọ àwọn àwọn òṣìṣẹ́ àjọ elétò ìdìbò àtí àwọn òṣìṣẹ́ elétò ààbò.
kò dì mọ́ ẹni tíí ṣe orí, tí ó mú kí gbogbo ara, ati iṣan, ati ẹran-ara wà pọ̀, tí ó ń mú un dàgbà bí Ọlọrun ti fẹ́.
 Ọ ̀ pọ ̀ lọpọ ̀ wọn a má a pèsè ààbò tó mọ níwọ ̀ n àti èyí tó lágbára púpọ ̀ fúnni lọ ́ wọ ́ ọ ̀ fìnkì ; ṣùgbọ ́ n , èyí a má a yàtọ ̀ láti ọdún dé ọdún .
Kii ṣe olè, ọlẹ ati gbajuẹ nikan ni ọmọ Naijiria paapaa Yoruba n ṣe loke okun.
Ariwo sọ, wọ́n fọwọ́ òsì júwe ilé fún Tacha lórí ètò àgbéléwò BBNaija Tacha tọrọ àforíjí, ó da gbogbo ẹ̀bi lé ara rẹ̀ lórí O tó gẹ́; A kò fẹ́ ìwòkuwò mọ́ ní Nàijíríà- Runsewe (NCAC) Khafi jẹ̀bùn ọkọ̀ ₦7.
Okunrin agbesunmomi ohun, ni iroyin so pe, O mu obe elenu sonso wo arin awon eniyan ti o n gbadura lowo ni mosalasi Malmesbury, ti o wa ni ila oorun ilu Cape Town, laago meta osan lojoBo(Thursday), ti o si gun awon eniyan meji pa.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Irú irun tí o bá n ṣe ni yóò sọ bí orí rẹ yóò ṣe rí 23 Ìgbé 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 24 Ìgbé 2019 Oríṣun àwòrán, Bandile Àkọlé àwòrán, Bandile ni ti oun ki i ba ṣe irun ni gbogbo igba ni, oun ko ba má pá lórí Lasiko igba ti o yẹ ki o ma fi irun ori rẹ da ara orisirisi, n ṣe ni arabinrin yi n wa ọna lati bo asiri ori rẹ to pa.
Amọṣa, BBC News Yoruba gbe ọrọ yii tọ awọn agbaagba ilẹ yii lọ.
Mose sọ fún Aaroni, ati àwọn ọmọ rẹ̀ meji, Eleasari ati Itamari pé, “Ẹ má ṣe fi irun yín sílẹ̀ játijàti, ẹ má sì ṣe fa aṣọ yín ya (láti fihàn pé ẹ̀ ń ṣọ̀fọ̀), kí ẹ má baà kú, kí ibinu OLUWA má baà wá sórí gbogbo eniyan.
Bello ti gbosuba fun ajo eleto idibo lorile ede Naijiria ( Independent National
Abẹwo yii ko yọ awọn minisita kan to jẹ ọmọ ilẹ Yoruba silẹ.
Kamaru Usman ti orukọ inagijẹ rẹ n jẹ Nigerian Nightmare ti di ọmọ ilẹ Afirika akọkọ ti yoo gba igbanu ẹyẹ fun ẹṣẹ kikan ti idije Ultimate Fighting Championship.
Enikan nínú ìdáhùn re ó ní 'A tẹ fóònù titi fóònù kú, Data Paapaa tán sugbon awon PHCN gbìyànjú díè.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Matuidi gbá góòlù kẹta sínú àwọ̀n Real Madrid lati sọ àpapọ̀ góòlù ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ wọn di mẹ́ta-mẹ́ta, 3-3 Alamójútó ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ naa Oliver lati ilẹ̀ Gẹ̀ẹ́sì pè fún gbé e siílẹ̀ ko gba sílé lẹ́yìn tí Benatia (Juventus) ti Vazquez (Real Madrid) lójú ilé Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Alamójútó ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ naa Oliver lati ilẹ̀ Gẹ̀ẹ́sì pè fún gbé e siílẹ̀ ko gba sílé lẹ́yìn tí Benatia (Juventus) ti Vazquez (Real Madrid) lójú ilé Alamójútó ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ naa Oliver lati ilẹ̀ Gẹ̀ẹ́sì lé aṣọ́lé Juventus, Gianluigi Buffon fun sísọ̀rọ̀ òdì sí alamójútó ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ naa Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Alamójútó ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ naa Oliver lati ilẹ̀ Gẹ̀ẹ́sì lé aṣọ́lé Juventus, Gianluigi Buffon fun sísọ̀rọ̀ òdì sí alamójútó ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ naa Ronaldo gbá bọ́ọ̀lú (penalty) wọlé Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ronaldo gbá bọ́ọ̀lú (penalty) wọlé Àwọn ẹgbẹ́ agbábọ́ọ̀lù tí yóò kópa ní ipele to kangun si aṣekagba Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Àwọn ẹgbẹ́ agbábọ́ọ̀lù tí ko leè kópa mọ́ ní ipele to kangun si aṣekagba Àwọn ẹgbẹ́ agbábọ́ọ̀lù tí opin de ba irinajo wọn Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Àwọn ẹgbẹ́ agbábọ́ọ̀lù tí opin de ba irinajo wọn Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 3 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 5 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
(Ègún ń bẹ lórí ẹni tí ó bá ń fi ìmẹ́lẹ́ ṣe iṣẹ́ OLUWA;ègún sì ń bẹ lórí ẹni tí ó bá sì kọ̀, tí kò máa fi idà rẹ̀ pa eniyan.
Laipẹ yii ni aarẹ orilẹede Amẹrika sọ oogun apakokoro pe o le wo aarun aarun coronavirus.
A ṣe ọ̀kọ̀ọ̀kan wọn bí ìgbà tí àgbá meji bá wọ inú ara wọn.
Jesu wí fún un pé, “Mo fẹ́ kí o mọ̀ dájúdájú pé ní alẹ́ yìí, kí àkùkọ tó kọ, ìwọ yóo sẹ́ mi ní ẹẹmẹta.
"Olùkọ́ fásitì méjì ń bèèrè ìbálòpọ̀ lọ́wọ́ akẹ́kọ̀ọ́ fún máákì ""Nína afurasí ní àhámọ́ nínú eré tíátà, bí àwọn ọlọ́pàá ti ń ṣe lójú ayé burú jáì"" Oloye Lekan Alabi ní àsìkò náà ni Olasope wa fún ìdánilẹkọọ nile iwe òun, sùgbọ́n isọrọ̀ si, ìrìn àti ìwọsọ bàbá naa lo jẹ ki òun bẹ̀rẹ̀ si ni fi èrò si láti yan iṣẹ́ iroyin láàyo."
Buhari ti gbo nipa isele buruku  to waye ni opolopo agbegbe to wa ni ipinle Plateau, lonii.
Idajọ iku ni wọn ma n da fun pupọ awọn ti ọwọ ba tẹ wi pe wọn gbe ogun oloro.
BBC tẹkọ leti lọ silu Ogbomọsọ, nipinlẹ Oyo, lati ba Dupe sọrọ, nkan to fa igbesẹ rẹ to sọ kọja bẹẹ.
26 Bélú 2020 Grammy awards 2021 - Burna Boy, Beyoncé, àti Dua Lipa, wà lára àwọn ti wọ́n fi orúkọ wọn sílẹ̀25 Bélú 2020 Amos Dauda, Iphone: Ilé ẹjọ́ dájọ́ ẹgba mẹ́ẹ̀dóògún fún ọ̀daràn tó jí Iphone ní Kaduna25 Bélú 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Igbaradi ti n rọ kẹkẹ ni gbagede Eagle square niluu Abuja atawọn ipinlẹ kọọkan.
Tani Ọ̀jọ̀gbọ̀n Ayodele Awojobi, onímọ̀ ẹrọ tí o ní kí wọ́n wọgi lè ìbò Ààrẹ Nàìjíríà?
Ikọ̀ BBC Yoruba ṣe àbẹ̀wò sí ilé Olóyè ìlú Ondo tí wọ́n furasí pé ọmọọ̀dọ̀ gún pa, fọ́fọ́ si ni ó kún fún àwọn abánikẹ́dùn.
“Ẹ̀yin eniyan mi, ẹ jáde kúrò níbẹ̀!
2bn naira ni owo ti wọn la kalẹ fun sisan owo oṣu awọn ọmọogun orilẹede Naijiria.
0 51 Orilẹede Laos 0 0.
Aare Muhammadu Buhari ti panupo pelu ogunlogo awon osere jakejade, ti o fi mo awon akoroyin, ki ogbontarigi, gbajugbaja osere, ayaworan, Tunde Kelanim ku oriire ayeye aadorin odun laye.
Wọn kò fi iyọ̀ pa ọ́ lára, wọn kò sì fi aṣọ wé ọ.
Wọn ní otubante ni aṣẹ yi jẹ ti ko si ba ofin Naijiria mu.
 o je oga omose agbogun naijiria lati july 1975 de october 1979 .
Ìṣòro yi jẹ ki ó ta gbogbo ohun ini rẹ ti ó fi nyangàn titi o fi di atọrọjẹ.
Awọn aṣofin Republican meji miiran, John Katko ati Adam Kinzinger sọ pe awọn ṣetan lati dibo yọ Trump nipo.
Ọlọrun, ìwọ ni Ọlọrun mi, mò ń wá ọ,ọkàn rẹ ń fà mí;bí ilẹ̀ tí ó ti ṣá, tí ó sì gbẹṣe máa ń kóǹgbẹ omi.
    Lẹ́yìn náà, okan Ayédèrú-ẹ̀dá, ìgbà ti ètè Ayédèrú-ẹ̀dà bbẹ̀rẹ̀ ọ̀rọ̀, kò sí ẹni tí àyà rẹ̀ kò já nínú wa.
26 Òkùdu 2018 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ahmed Musa lo gba ayo meji wọle fun orilẹede Naijiria nigba ti Argentina ati Naijiria pade ni ọ̀dun 2014 Ifẹsẹwọnsẹ idije ife ẹyẹ agbaye FIFA ti ọdun 2018 ni yoo jẹ igba kẹfa ti orilẹede Naijiria ati Argentina yoo maa waako ninu idije FIFA fun awọn agbalagba agbabọọlu lagbaye.
Oluwo tí sọ̀rọ̀ nípa awuyewuye láàrin rẹ̀ àti Agbowu tìlùu Ogbaagbaa
Ẹnikẹ́ni tí ó bá fọwọ́ kan ẹni tí wọ́n fi idà pa, tabi òkú, tabi egungun òkú tabi ibojì òkú ninu pápá yóo di aláìmọ́ fún ọjọ́ meje.
Stephen Romero ọmọ ọdun mẹfa ni ẹni ti wọn ri ti ẹmi rẹ kọkọ ba iṣẹlẹ naa rin.
O ni ojuṣe ọlọpaa SARS nigba naa ko ju mimu awọn adigunjale lọ, bẹẹni iwe ojuṣe ati ihuwasi wa fun gbogbo awọn ọlọpaa ikọ naa nigba naa.
Nígbà tí ó bá kúrò lọ́nà tán ni Ọkunrin Burúkú nnì yóo wá farahàn.
Adigunjalè méjì ko ìjàmbá ọ̀kadà lẹ́yìn ìṣẹ́ ibi n'Ibadan, ọ̀kan kú lójijì, aráàlú dáná sun èkejì Yoruba ni ọjọ gbogbo ni ti ole, amọ ọjọ kan soso pere ni ti olohun.
Ọkunrin kan wà ninu àwọn ìgbìmọ̀ tí ó ń jẹ́ Josẹfu.
Ẹwọn ọdun marundinlaadọta ni wọn ju Philippe si, lẹyin ti ile ẹjọ ri i pe o jẹbi ẹsun mẹfa to niiṣe pẹlu lilo ohun ija oloro - àtọ̀ ọmọkunrin rẹ lati ṣe iṣẹ ibi.
"O ni ""A wa nibi yii lati ba mọlẹbi oloogbe kẹdun, ati lati fi da wọn loju pe ijọba ti gbe igbesẹ lati ṣe iwadii ohun to fa iku ọdọmọdekunrin naa."
nítorí ìrúnú ati ibinu rẹ;o gbé mi sókè,o sì jù mí nù.
Ṣé ìjọba amúnisìn ni Róòmù jẹ́ nígbà náà, a jẹ́ pé títí dé ilẹ̀ Ígíbíìtì àti India ni òkìkí rẹ̀ kàn dé.
Mo jáde lọ ní kíkún, ṣugbọn OLUWA ti mú mi pada ní ọwọ́ òfo, kí ló dé tí ẹ fi ń pè mí ní Naomi, nígbà tí OLUWA fúnra rẹ̀ ti dá mi lẹ́bi, tí Olodumare sì ti mú ìpọ́njú bá mi?
Ẹkọ miran ta tun ri kọ ninu itan yii ni pe, igba ko tọ lọ bii orere, aye ko tọ lọ bii ọpa ìbọn, ohun gbogbo fun igba diẹ ni, ka lọ ni suuru ati ipamọra.
Ìdílé Elétù Òdìbò ni ó ń jẹ Báálẹ̀, àwọn sì ni wọ́n ń ṣe àkoso gbogbo ilẹ̀ Abúlé Ọjà àti ìdá kan nínú mẹ́ta ilẹ̀ Abúlé Ìjẹṣà.
Bí ó ti ń gun kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ rẹ̀ lọ, tí ó dé abẹ́ òkè kan, ó rí i tí Dafidi ati àwọn eniyan rẹ̀ ń bọ̀ níwájú.
"Lara awọn aṣofin naa ni Sẹnetọ Abdulfatai Buhari to n ṣoju ẹkun ariwa ipinlẹ Ọyọ, Oríṣun àwòrán, @Ajimobiinstagram ""Oyo North senatorial district"" nile igbimọ aṣofin agba, Họnọrebu Shina Abiola Peller, Họnọrebu Akeem Adeniyi Adeyemi ati Otunba Akin Alabi."
Ẹ óo ṣe gbogbo nǹkan wọnyi kí ẹ lè fi orí gba ẹ̀bi ikú gbogbo eniyan rere tí ẹ ti ta ẹ̀jẹ̀ wọn sílẹ̀; ohun tí ó ṣẹ̀ láti orí Abeli, ẹni rere títí fi dé orí Sakaraya, ọmọ Berekaya, tí ẹ pa láàrin àgọ́ mímọ́ ati pẹpẹ ìrúbọ.
Opolopo awon oloselu ati awon to wa woran lati gbo ohun ti won n sọ, ni
Lọjọ Abamẹta ni fidio kan to ṣe afihan awọn akẹkọọ kan to n lu akẹkọọ obinrin naa nilu bara lu sori ayelujara.
Ofin to n ṣe idajọ ẹ̀san fun abẹ̀mí gbogbo ni awọn eeyan gba pé o ṣẹlẹ ninu igbo Kruger National Park ni orilẹ-ede South Africa.
Pope Francis wọ́gilé òfin tó n dáàbò bo àlùfáà tó bá bá ọmọdé l'òpọ̀ Ẹ̀wọ̀n tí mo lọ ni ẹ̀san ìwà tí mo hù gẹ́gẹ́ bíi olórí ológun- Buhari Pervez Musharraf, Àarẹ ológun Pakistan nígbà kan rí gbọ́jọ́ ikú Hubert Ogunde rèé, baba àwọn òsèré tíátà Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ondo disability day: Ijọba ẹ gbà wá ní ariwo tí àkàndá ẹ̀dá ń pa Ẹsun aṣilo ipo ti wọn fi kan aarẹ Trump da lori ẹsun pe o gbiyanju ati fun orilẹ-ede Ukraine lokun lọrun ki o lee kede iwadii ọkan lara awọn alatako rẹ lẹgbẹ oṣelu Democrats, alagba Joe Biden.
Ohun tó yẹ kí o mọ̀ nípa ìbòmú tí ń lò yẹ́n O ya, ẹ wo o ki ẹ k'ẹkọ, ki ẹ rẹrin, ki ẹyin naa si gbiyanju u tiyin.
“Ní ìgbẹ̀yìn àwọn wundia yòókù dé, wọ́n ní, ‘Alàgbà, alàgbà, ẹ ṣílẹ̀kùn fún wa!
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Pásítọ̀ ló sọ fún mi pé Ọlọ́run pè mí láti di Olokun tó ń bọ omi' Kóníléógbélé ọlọ́sẹ̀ márùn ún gbáko ni ìjọba Nàíjíríà gbé kalẹ̀ fàwọn oṣìṣẹ́ lábẹ́ ìlànà Covid-19 tuntun Oríṣun àwòrán, PTF Ijọba Naijria ti kede konileogbele ọlọsẹ marun un gbako fawọn oṣiṣẹ ijọba apapọ lọna ati dẹkun itankalẹ Covid-19.
Pupọ ọmọ orilede Naijiria ni ko ni gbagbe minisita 'alaṣọ ankara' yii pẹlu gele 'ipakọ o gbọ ṣuti' rẹ.
Gẹgẹ bi ikede ti ọmọọmọ rẹ kan fi sita, Shagari ku lẹyin aisan ra npẹ sileewosan gbogboogbo to wa nilu Abuja.
Wọn kò gbójú lé Ẹni Mímọ́ Israẹli,wọn kò sì wádìí ọ̀rọ̀ lọ́dọ̀ OLUWA.
Àwọn fìtílà meje wọnyi ni ojú OLUWA tí ń wo gbogbo ayé.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Yemi Blaq: Ìyàwó mi lọ́wọ́ sí kí n fẹnuko obìnrin míì lórí ìtàgé Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Yemi Blaq: Ìyàwó mi lọ́wọ́ sí kí n fẹnuko obìnrin míì lórí ìtàgé 26 Ìgbé 2019 Adúmáadán ọkunrin òṣèré Tíátà tí àwọn ènìyàn fẹ́ràn ni Yemi Olatunji Blaq.
13 Bélú 2018 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 30 Èbibi 2020 Iwadii ti fihan wi pe awọn to n fẹsẹrin lo n koju ewu to rọmu mi mi afẹfẹ ti ko dara sinu.
Ojú ń kán wa, a fẹ́ gba àfikún owó osù tuntun- NLC Gẹgẹ bi o ṣe sọ, 'Aarẹ Buhari fi to wa l'eti wi pe ipo ti ọrọ aje Naijiria wa bayii ko dara.
A kò ní rí wọn níbẹ̀,àwọn tí a ti rà pada ni yóo gba ibẹ̀.
Aisha Buhari sọ wí pé òun kò ní ǹkankan ṣe pẹ̀lú ìwà jìbìtì tí ilé iṣẹ́ DSS ń ṣe ìwádí rẹ̀ lọ́wọ́.
Iye owo ti awọn sẹnatọ n gba losu ko han si awon ara ilu.
Gẹ́gẹ́ bi àgbà ninú Olórin ilẹ̀ Aláwọ̀dúdú Olóyè Ebenezer Obey (Fabiyi) ti kọ́ pé “Igbà mẹta ni igbà ẹ̀dá láyé, igbà òwúrọ̀, igbà ọ̀sán, igbà alẹ́, ki alẹ́ san wá ju òwúrọ̀ lọ”.
Eeyan 55,005 ni apapọ ni wọn ti fara ko aarun Coronavirus, ti awọn 42,922 si ti ri iwosan gba lọwọ ajakalẹ arun ọhun.
Aya rẹ yóo dàbí àjàrà eléso pupọ ninu ilé rẹ;bí ọmọ tií yí igi olifi ká,ni àwọn ọmọ rẹ yóo yí tabili oúnjẹ rẹ ká.
Nítorí náà, ẹ mọ́kànle, ẹ má bẹ̀rù.
Abidani ọmọ Gideoni, kó akọ mààlúù meji, àgbò marun-un, òbúkọ marun-un, ati ọ̀dọ́ àgbò marun-un, ọlọ́dún kọ̀ọ̀kan sílẹ̀ fún ẹbọ alaafia.
Kò ní bọlá fún àwọn alufaa wọn,kò sì ní fi ojurere wo àwọn àgbààgbà.
O ko nilo lati tẹ bọtini idaduro nitori, gẹgẹ bi ileeṣẹ twitter ṣe sọ eroja naa ni yoo funra rẹ daa duro ti yoo si tun bẹrẹ omiran lẹsẹkẹsẹ.
" Oríṣun àwòrán, @SkyebankNigeria O ni eyi ni yoo fun awọn onibara yii lati seto katakara wọn bo ti yẹ.
orile ede Sri Lanka kẹdun ajalu buruku yii , aare wa ro awon alasẹ orile ede
Okan lara ẹya litireṣọ Yoruba ni Ewi alohun ninu eyi ti ẹṣa ti awọn baba wa n kọ awọn ọmọ wọn lati iran de iran nilẹ Yoruba wa.
Mo fi Ọlọrun jẹ́rìí pé kò sí irọ́ ninu ohun tí mò ń kọ si yín yìí!
Nkan o fararọ laarin ẹgbẹ awọn olukọni nileewe giga fasiti Ọbafẹmi Awolọwọ, OAU nilu Ile ifẹ.
Oun ni yoo maa tukọ idari banki naa fun saa ọlọdun marun miran lẹyin ti iwadii ti fihan pe ko si kọnu n kọhọ kankan ninu saa iṣejọba rẹ akọkọ.
Igbesẹ keje: Tẹ ori akori Activate"" loju opo naa Igbesẹ kẹjọ: eleyii ni yoo gbe ọ wọle soju opo ibi ti ẹ o ti yan eyikeyi ibo ti ẹ fẹ yẹ esi ibo to wu yin wo."
Ninu ilẹ̀ ẹ̀yà Nafutali, wọ́n fún wọn ní: Kedeṣi ní Galili.
Wọ́n kọ̀wé sí ọba Pasia ní èdè Aremia, wọ́n sì túmọ̀ rẹ̀.
"Ero ilera pipe ni kiakia ni a n fi ranṣẹ si ọ-APC UK"" Ti wọn si tun fi fidio kan tii nidi."
"Wọn n wa ẹni ti yoo gbe wọn jade.
Ó wí fún mi pé ó yẹ kí a wa Filásayépọ̀ rí, nítorí bí a bá le ríi, iwin tíí ṣe alákòóso fìlà rẹ̀ yóò kó wa yọ.
Food Poison: Oúnjẹ márùn-ún tó lè ṣekú pa'ni kíákíá
 olùsọdipúpọ ̀ ọ ̀ rọ ̀ kan le jẹ ́ nọ ́ mbà yìówù láti inú àkójọpọ ̀ pàtó kan .
Nítorí ó wà ní àkọsílẹ̀ pé,“Ọlọrun wí pé, ‘Èmi óo pa ọgbọ́n àwọn ọlọ́gbọ́n run,n óo pa ìmọ̀ àwọn amòye tì sápá kan.
Buhari: Òpùrọ́ àti òjòwú ni Olusegun Obasanjo
Oba AbdulRasheed Akanbi gbadura pe ki Eleduwa ''ba wa le covid-19 wọlẹ lọ ni Naijiria.
Aàrẹ Ilé Igbimọ Aṣofin Agba, Bukola Saraki naa ke pe aarẹ Buhari lati yi igbesẹ rẹ pada lori Onnoghen.
Ninu ilana tuntun naa, wọn sọ pe wọn ko ni le lo owo to ba yẹ ki wọn fun awọn ijọba ibilẹ ninu akoto owo apapọ pẹlu ijọba ipinlẹ fun nnkan miiran.
Wọ́n jẹ́ ọba ẹ̀yà mejila, orúkọ wọn ni wọ́n sì fi ń pe àwọn ìletò ati àgọ́ wọn.
Ninu awọn to ti ṣedaro rẹ ni awọn adẹrin poṣonu bii Alibaba, Bovi, Seyi law, Ushbebe ati bẹẹ bẹẹ lọ.
Àwọn Aposteli yòókù Gba Paulu Bí Aposteli.
9 Ọ̀wàrà 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 11 Ọ̀wàrà 2020 Lẹ́yìn tí àwọn ènìyàn ìpínlẹ̀ Ondo dìbò tàn; èsì ìdìbò ti ń jáde báyìí.
''Ati ero inu ọkọ, ati ẹni to gun ọkada lo n bọọlẹ ti wọn si n fi ẹsẹ wọn rin lọ si ibi ti wọn n lọ.
Ẹwo diẹ ninu awọn awọran lati gbagede ijiroro naa Àkọlé àwòrán, Aliyu Tanko ti ileeṣẹ BBC àti Ngozi Alaegbu Àkọlé àwòrán, Ijiroro Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Ibihari ati Eliṣua, Nefegi ati Jafia; 
Ṣé o mọ àwọn òfin: má paniyan, má ṣe àgbèrè, má jalè, má jẹ́rìí èké, má rẹ́nijẹ, bọ̀wọ̀ fún baba ati ìyá rẹ?
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Shehu Abdullahi darapọ mọ Bursaspor ni Turkey 24 Sẹ́rẹ́ 2018 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Shehu Abdullahi je ami ayo meta ninu iwọnse mejidinlaadọta fun ẹgbẹ agbabọọlu Anorthosis Famagusta nigba to' ngba fun wọn Agbabọọlu ẹyin fun orilẹede Naijiria, Shehu Abdullahi ti fi ẹgbẹ agbabọọlu Anorthosis Famagusta ilẹ Cyprus silẹ lati darapọ mọ Bursaspor ilẹ Turkey fun ọdun meji ati abo.
Ohun kan tí a gbọ́dọ̀ mọ̀ nip é, kò ṣe é ṣe kí ẹ̀dá máa gbe ní ẹyọ kọ̀ọ̀kan.
Bẹẹ ba gbagbe, ọjọ aiku ní fọ́nrán kan gbòde níbi ti gómìnà ìpínlẹ̀ Kano, Abdulllai Ganduje, tí ń kó owó dọ́là sínú àpò agbádá rẹ̀ eyi tí Daily Nigerian gbé síta.
 Ìdẹ ́ kun ni nípa ìyẹra fún gígéje àwọn eṣinṣin .
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù US election 2020: Àlàyé rèé lórí bí èèyàn 538 ṣe ń yan ààrẹ lé èèyàn mílíọ̀nù 331 ní Amẹ́ríkà 15 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Awọn igbimọ agbaọjẹ oludibo alaṣẹ ni ilu Amẹrika, Electoral College ti buwọlu ibo to gbe Joe Biden ti ẹgbẹ oṣelu Democratic wọle gẹgẹ bi aarẹ.
Ile ẹjọ ni ki wọn gbee lọ si ahamọ.
Dókítà Alex George: Bí ó bá ní olólùfẹ́, tí ẹ jọ ń gbé tí ẹ sì jó ń ṣe pò ni agbègbè kan náà, èyí kò yẹ kí o yí onkohun padà.
Ni ekun idibo ti o wa ni apa iwo-orun orile-ede naa, awon oludibo yoo jade lati lo dibo yan omo ile-igbimo ti won ni ojo ketadinlogbon osu keta odun, tori pe, aworan oludije ekun naa ko si ninu iwe idibo.
Yatọ si Dele Giwa, awọn ilumọọka ọmọ Naijiria miran ti o kuku ojiji ti a ko le sọ awọn to pa wọn la ti ri awọn bii: Kudirat Abiola Bola Ige Harry Marshall Chuba Okadigbo Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Adebisi Olabode: Ìjọba ìpínlẹ̀ Oyo ti fòfin de oyè Ìyá àti Babalọja Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Saraki sọ ninu atẹjade kan lati ọwọ agbẹnusọ rẹ Yusuph Olaniyọnu l'ọjọ Abamẹta pe, ko da, miliọnu kan Oshiomhole ko le le oun kuro nipo.
Iyawo aarẹ ni, irọ ni pe oun fi ibinu fi ile ọkọ oun silẹ, o ni irinajo ti oun lọ wa lati lọ sinmi, ati pe ninu isimi naa ni oun ṣe aisan ranpẹ, ti dokita si gba oun ni imọran lati sinmi diẹ si.
Dájúdájú, kò lè jẹ́ Kristi, ẹni tí ó kú, àní sẹ́ ẹni tí a jí dìde kúrò ninu òkú, tí ó jókòó ní ọwọ́ ọ̀tún Ọlọrun, tí ó sì ń bẹ̀bẹ̀ fún wa.
O ni Ọfẹ ni owo ile iwe ati eto ilera ni Saudi, bakan naa ni ile iwe Ghana dara ju ti Naijiria lọ, idi ree ti awọn ọmọ ilẹ yii ṣe n kẹkọọ lọhun."
Mo ṣẹ̀ṣẹ̀ gba pe ikú ń dóró láì wẹ̀yìn wò
OLUWA a máa wó ilé agbéraga,ṣugbọn ó ṣe àmójútó ààlà opó.
Alufaa tí ó bá rú ẹbọ sísun fún eniyan ni ó ni awọ ẹran ẹbọ sísun náà.
ibugbe won, ti awon miiran si padanu ohun ini won ni agbegbe Puri, lorile-ede India
Eyi ya gbogbo àwọn ti ó pé jọ lẹ́nu pàtàki ọmọ Bàbá nitori ó rò pé Bàbá kò fẹ́ràn ohun.
Lẹ́nu ọlọ́gbọ́n ni ọ̀rọ̀ ìmọ̀ ti ń jáde,ṣugbọn òmùgọ̀ a máa sọ̀rọ̀ agọ̀.
 Ó jé kí nàíjíríà je ohun kìíní tí ó kà sí nípa ti ànfàní àti iye tí wón dálé epo ròbì .
Jesu dá a lóhùn pé, “Fi í sílẹ̀!
Bakan naa ni Ọgbẹni Muri-Okunola rọ awọn oṣiṣẹ lati fọwọ ṣowọpọ pẹlu ijọba Gomina Sanwo-Olu fun aṣeyọri ijọba rẹ.
Iwadii ti awọn dokita onimọ lati ilẹ Amẹrika fi sita ninu akojọpọ iwe Scientific Reports fihan wipe kokoro aifojuri kan wa ninu igbẹ awọn ọmọde ti o le pese eroja ara kan ti wọn n pe ni 'probiotic' ti wọn nilo lati koju aisan sisanra ju ati arun jẹjẹrẹ.
Níbẹ̀ ni yóo sì máa gbé títí tí olórí alufaa tí a fi òróró yàn yóo fi kú.
Awọn ajafẹtọ naa ni, eto idibo gomina to waye ni ipinlẹ Ọsun jìnnà sí ìlànà aatẹle fún idibo lagbaye ti won sì ke sí ẹka isedajo lati fi oju tó tọ wo awọn ẹhonu to ba tipasẹ idibo naa jade sí ọdọ wọn.
Beckham, àgbábọ́ọ́lù tẹ́lẹ̀ rèé tó ń sọ èdè Yorùbá ''Buhari, Zamfara là fẹ kí o lọ, kìí ṣé Jordan'' Ìjọba tí yòó ṣe àfikun yàrá ikérò si ọkọ ojú irin Dókítà yọ oyin mẹ́rin tó n gbé nínú ẹyinjú arábìnrin kán Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Hakeem: Mo lè sọ arúgbó dí ọmọge nígbà tó bá wù mí O fí kún un pe gbogbo àwọn ti ọ̀rọ̀ náà kan ni wọn ti foju kan mọ̀lẹ́bi wọn láyọ àti alááfíà.
Ẹ kò gbọdọ̀ sin OLUWA Ọlọrun yín bí wọn ti ń bọ àwọn oriṣa wọn nítorí oríṣìíríṣìí ohun tí ó jẹ́ ìríra lójú OLUWA ni wọ́n máa ń ṣe.
“Fun idi eyi, mo si le kopa daradara,” Kompany, leni ti iwe ibasisepo re pelu iko naa yoo pari ni saa to n bo, lo so oro ohun di mimo lori ero ayelujara iko naa.
Ẹ̀kọ́ mẹ́jọ tó yẹ kí ilẹ̀ Afirika kọ́ lára àjàkálẹ̀ aàrùn coronavirus Ọlọ́run ló ní kí Abacha kú, àwọn àgbà Yorùbá púpò kò bá ṣòfò- Dele Momodu Mo kọ̀ láti ṣe àpèjẹ 'Reception' lẹ́yìn ìgbéyàwó mi nítorí.
Àtìpó 161 míì dé padà láti Libya layajọ́ ominira Naijiria Lẹyin to gba ife ẹyẹ naa tan, o ni inu oun dun gidigidi.
Mo mọ̀ pé lẹ́yìn tí mo bá lọ, àwọn ẹhànnà ìkookò yóo wọ ààrin yín; wọn kò sì ní dá agbo sí.
Ní alẹ́ yìí ni a óo gba ẹ̀mí rẹ pada lọ́wọ́ rẹ.
Bí ètò ìjọba ò ṣe dántọ́ tó láti borí àjàkálẹ̀ àìsàn ibà tí ó gbòde yìí, àwọn ènìyàn ń gbẹ́kẹ̀le ẹ̀rọ-alátagbà láti fi sọ ẹ̀dùn-un ọkàn-an wọn, pín àlàyé nípa ìtànkálẹ̀ kòkòrò náà, àti ṣe ìkéde nípa bí àwọn ènìyán ṣe le dá ààbò bo ara wọn.
Bello Shinkafi  ti ile-ejo to wa ni Gusau,
Mínísítà ní ìwádìí sì n lọ lọ́wọ́ láti mọ ẹni tó wa ọkọ̀ òfurufú náà àti àwọn òṣìṣẹ́ tó wà lẹ́nu iṣẹ́ nílùú Eko àti ilú Abuja nígbà ti ọkọ̀ náà gbéra nílùú Eko àti ìgbà tó balẹ̀ ní Abuja Ẹ̀wẹ̀, mínísítà ni ìgbìmọ̀ amújṣẹ́se ìlú Abuja ni yóò le sọ irú ìjìyà ti wọ́n n fẹ́ fún naira Marley nitirẹ̀.
ó fún Nàìjíríà l'èsì àwọn ẹ̀sùn tó fi kàn-án Ni Oṣu Kẹjọ, ọdun 2019 ni ijọba orilẹ-ede Cameroon fi lede wi pe awọn ti bẹrẹ igbẹjọ awọn soja meje ti wọn furasi wi pe awọn lo ṣiṣẹ ibi naa.
Gẹ́gẹ́ bi àjọ tó n mójú tó ń àjàkálẹ̀ ààrùn ní Nàìjíríà (NCDC) se sọ lójú òpó twitter rẹ̀ lọ́ja àbámẹ́tà.
lo  yan Khayre sipo nigba to jawe olubori
Lẹ́yìn tí wọ́n ti ka Ìwé Mímọ́, láti inú Ìwé Òfin Mose ati Ìwé àwọn wolii, àwọn olóyè ilé ìpàdé àwọn Juu sọ fún wọn pé, “Ẹ̀yin arakunrin, bí ẹ bá ní ọ̀rọ̀ ìyànjú fún àwọn eniyan, ẹ sọ ọ́.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Oríṣun àwòrán, Getty Images Ọpọ awọn abanikẹdunn lo peju sibẹ.
Nahati bí Eliabu, Eliabu bí Jerohamu, Jerohamu sì bí Elikana.
Bayii, Ijọba Naijiria ti ya ọjọ kejila, oṣu kẹfa ọdun sọtọ gẹgẹ bii ayajọ ọjọ iṣejọba awa ara wa.
Bi iṣé abẹ ìdí ńlá ṣé n seku pá àwọn obìnrin Wọ́n ti rí ìbejì Taofeeq Akeugbagold tí wọ́n jígbé nílùú Ibadan Coronavirus ti gbẹ̀mí èèyàn mìí ní ìpínlẹ̀ Osun Iroyin sọ pe ọdun meje ni ifẹ fi wa laarin oun ati ọkunrin naa.
Awọn owó ori ayelujara to tun wa ni Ethereum, ati Litecoin.
Titi di asiko yii eyitayo Jegede ni meta nigba ti Akeredolu Rotimi ni mejila ninu ijọba ibilẹ mẹẹdogun ti wọn ti ka Bí èsì ìdìbò gómìnà ìpínlẹ̀ Ondo se ń jáde rèé.
Olùfẹ́ mi ti bọ́ sí ọwọ́ ẹranko búburú, kìnnìún ti fà á ya pẹ́rẹpẹ̀rẹ.
PDP wa rọ Buhari ati ẹgbẹ APC lati sinmi irọ pipa, iwa ibanilorukọjẹ ati ipolongo ẹtan, ki wọn si gbaradi lati koju igbẹjọ to wa nilẹ nipa esi ibo aarẹ to kọja.
Koda, Adeniyi Faleti, ọmọ baba Faleti to wa nile lasiko ti baba papoda ṣalaye fun ile iṣẹ iroyin Punch pe baba wẹ, o tọju ara rẹ daadaa lẹyin adura owurọ a-gba-papọ gẹgẹ bii ẹbi kan ti awọn ṣe tan.
Nigba to n salaye idi ti igbeyawo wọn se tọjọ di oni, Bamiloye ni awọn kii tasẹ agẹrẹ ko ipa ti ko yẹ ki awọn ti kii ṣe tọkọ taya ko ninu ere.
Dokita naa tun la mọlẹ pe, aloju oogun Tramadol maa n ge ẹmi kuru ni.
Fún mi ní ìṣù burẹdi marun-un tabi ohunkohun tí o bá ní.
 Àdúgbò yí di gbajú gbajà pẹ ̀ lú ilé ìgbé alákọ ̀ ọ ́ pọ ̀ tí wọ ́ n kọ ́ síbẹ ̀ láàrín ìgboro ìlú ìbàdàn lẹ ́ yìn ìgbòmìnira ilẹ ̀ nàìjíríà ní ọdún 1960 .
Olùfẹ́ mi ló ni mí,èmi ni mo sì ni olùfẹ́ mi.
“Irú eré báyìí ni mò ń sá tí mò fi ń lọ sí Damasku ní ọjọ́ kan, pẹlu ìwé àṣẹ láti ọ̀dọ̀ àwọn olórí alufaa.
PFN: Fatoyinbo kọ̀ láti yọjú ni ìwádìí wa kò ṣe parí Ajo awọn ẹni ẹmi ni Naijiria, eyi ti wọn n pé ni Pentecostal Fellowship of Nigeria (PFN), ti fi ọrọ lede pe awọn ko tii pari iwadii ti wọn n ṣe lori ẹsun ifipabanilopọ ti Busọla Dakolo fi kan Biọdun Fatoyinbo.
”Ọdọmọkunrin náà dáhùn pé, “Sísá ni àwọn ọmọ ogun Israẹli sá kúrò lójú ogun, ọpọlọpọ ninu wọn ni wọ́n sì ti pa; wọ́n ti pa Saulu ati Jonatani ọmọ rẹ̀ pẹlu.
“Ẹ wò ó, mo gbé ibukun ati ègún kalẹ̀ níwájú yín lónìí.
lakoko ipade naa, gbogbo awon oga agba, awon torokan gbangban ninu eto-abo nile Afrika ati loke okun ni yoo ye ipade ohun si lojo naa.
Hesekaya gba àwọn oníṣẹ́ náà ní àlejò.
Eyi waye lẹyin to pinnu lati rọ́pò ọkọ rẹ ti wọn mu si atimọle, ti wọn ko si jẹ ko fi orukọ silẹ lati díje.
Ki ni awọn apẹrẹ arun Coronavirus?
Gbogbo owo ti a na ni biliọnu mẹtalelogun naira koda ki Covid-19 to de, ida ọgọta aba eto isuna ajọ NDDC lo ba eto ilera lọ.
Ẹ̀wẹ̀, wọn tún kùdiẹ̀kudiẹ̀ pọ̀ níbẹ̀ lọ́wọ́ àjọ eléto ààbò àti ibudo ìbo, ó ni àwọn eléto ààbo ń dúnkoko mọ àwọn oludibo ní ìhà ibi ti ẹgbẹ PDP ti ni àwọn ènìyàn.
Tí a bá lo irú ìsọnkanlorúkọ yìí, a lè pèé ní “Ike Nkan
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Owanbẹ: Gari Ijẹbu, bọ̀ọ̀lì àtàwọn oúnjẹ lágbo ayẹyẹ 'owanbẹ' báyìí 29 Ẹrẹ̀nà 2019 Oríṣun àwòrán, www.
Naidoo pari ọrọ rẹ pe awọn ẹbi oloogbe naa ko gbagbọ pe arun Covid-19 lo mu ẹmi rẹ lọ.
"Oríṣun àwòrán, Instagram/gloriabamiloye Awọn ọrọ Bamiloye lori ayelujara to n da ariwo silẹ: Bamiloye ni oun le jẹ ""Old school"" ṣugbọn oun ni oun n tẹ foonu funrarẹ oun, ti oun si n kọ ọrọ sita lojoojumọ lati jiṣẹ Ọlọrun."
Ìyá àti bàbá , àti alásùn-ún-mọ ́ wọn lè fún ọmọ tàbí àwọn ọmọ ní orúkọ tóbá wù wọ ́ n.
Ewe, ami-ayo meji waye lati owo Zakaria Hadraf, besini Walid El Karti ati Ayoub El Kaabi gba ami-ayo kookan wole.
Kò sí àmì kan tí a óo fi fún un àfi àmì Jona wolii.
Bi ọpọ awọn aladugbo ṣe n sọ pe o jẹ mọ iṣẹ ọwọ awọn agbenipa to n fi eniyan ṣe oogun owo ni awọn miran ni o ṣeeṣe ko jẹ iṣẹ ọwọ awọn ọmọ ẹgbẹ okunkun.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Àtọ̀ ọmọkùnrin ti rógo o!
Ọgbẹni Abba ko ṣai fìdí rẹ mulẹ pe, ajakalẹ arun covid-19 ṣakoba fun ajọ EFCC lati ṣe ohun gbogbo to fẹ ṣe lọdun 2020.
Child sexual abuse: Ìdí rèé tí mi ò fi sọ̀rọ̀ nígbà tí ìbátan mi fipá bá mi lopọ̀ l'ọdún 67 sẹ́yìn
 O wa rọ ijọba lati wa wọrọkọ fi ṣada lori iṣorọ airiṣẹṣe ọpọ obinrin ni awujọ.
Ẹ ta kété sí àjọṣepọ̀ tí kò bá fún yín láyọ̀ torí ẹ̀mí kò ní ààrọ̀ - Àwọn òṣèré tíátà gbarata lórí ìdájọ́ ikú Ojora ń mú mi lọ́wọ́ lórí ìkọlù tó wáyé, ara mi kò tíì balẹ̀ - Toyosi Adesanya Bí Amẹrika bá dínà mọ́ Nàíjíríà láti wá sílẹ̀ wọn, ewu ń bẹ fún wa - Lai Muhammed Kalu fikun pe, ẹtọ araalu ni pe ki ijọba ti wọn dibo fun pese aabo to peye fun ẹmi ati dukia awọn araalu, ki awọn eniyan ma ba a ma gbe ninu ifoya.
Ileeṣẹ amohunmaworan Oaks lo fi fidio ipade oniroyin ti Mohammed ṣe pẹlu awọn akọroyin lẹyin ti ipade igbimọ alaṣẹ orilẹede Naijiria waye l'Ọjọru.
 Àwọn ìsí kejì sun mọ ìsàlẹ ̀ díẹ ̀ .
Ṣé ajá tí yόò sọnú kì-í gbọ́ fèèrè ọdẹ.
" Ṣugbọn ikọ olupejọ ni Amẹrika faake kọri lati gba ẹbẹ agbẹjọro naa pẹlu awijare pe Hushpuppi le salọ, ko si tun lọ lu jibiti miran lori ayelujara.
Èèyàn 290 míràn ló ṣẹ̀ṣẹ̀ fara káásá àrùn Covid-19 ní Nàìjíríà, 160 gbàwòsàn Wo bí ìgbéyàwó ọmọ bàbá olówó, Adama Indimi àti Prince Malik Ado ọmọ Ọba Ohinoyi ilẹ̀ Ebira ṣe lárinrin tó Asojú ìjọba orílẹ̀-èdè Lebanon ti kọ̀wé fipò silẹ̀ nítorí ìbágbàmù tó gbẹ̀mi ènìyàn 200 Ìyàwó Bukola Saraki fún tìyá-tọmọ olójú búlúù ní N250, 000!
Nisinsinyii, OLUWA Ọlọrun Israẹli, jẹ́ kí ìlérí tí o ṣe fún Dafidi, baba mi ṣẹ, pé, ìran rẹ̀ ni yóo máa jọba ní Israẹli títí lae, bí wọn bá ń tẹ̀lé ìlànà rẹ, tí wọ́n sì ń pa òfin rẹ mọ́ gẹ́gẹ́ bí Dafidi ti ṣe.
Ọ̀rọ̀ ẹnu ọlọ́gbọ́n a máa mú ìtẹ́lọ́rùn bá a,a sì máa jèrè iṣẹ́ ọwọ́ rẹ̀.
    “Ìwọ ọ̀rẹ̀ mi, nǹkan ti ń ó bá ọ sọ yìí, máṣe gbàgbé láéláé, fi í sí ìpamọ́, gbogbo nǹkan ti ń bẹ ní òde ayé gbáà ni ó ní ìgbẹ̀yìn wọn: ìgbẹ̀yìn òwúrọ̀ ni ọ̀sán, ìgbẹ̀yìn ọ̀sán ni alẹ́; ìgbẹ̀yìn ènìyàn ni ikú; ìgbẹ̀yìn oúnjẹ ni orí ààtàn; ìgbẹ̀yìn ìgbà òjò ni ìgbà ẹ̀ẹ̀rùn, ìgbẹ̀yìn odò gbogbo ti ń bẹ nínú ayé kò sí ju òkun lọ.
Àwọn Arakunrin Josẹfu Lọ Ra Ọkà ní Ijipti.
Pàápàá jùlọ àwọn ará ìlú Trinidad.
Ó sì mú ọ̀gágun tí ń ṣe àkóso àwọn ọmọ ogun, ati meje ninu àwọn aṣojú ọba tí wọn rí láàrin ìlú ati akọ̀wé olórí ogun tí ń kọ orúkọ àwọn eniyan sílẹ̀ fún ogun jíjà.
Sugbọn bi o ṣe n tan kaakiri agbaye, lo n nira lati koju rẹ.
Kani a mọ pataki idagbasoke aṣa si idagbasoke eto ọrọ aje wa, a o tẹpa mọ .
lorile ede Naijiria, Lai Mohammed, lo sọrọ yii fun awon akoroyin leyin ipade
Oríṣun àwòrán, Mike bamiloye/facebook Àkọlé àwòrán, Awọn ẹgbọn Darasimi mejeeji, ati awọn iyawo pẹlu ọmọ ọkan lara wọn Ibeji ni Lawrence, orukọ ibeji rẹ a si maa jẹ Godswill.
Bẹ́ẹ̀ ni kí o ṣe àwọn àkànpọ̀ igi mejeeji tí wọ́n wà ní igun mejeeji.
 eyí ni , ibi tí a ti ń ta ayò .
Toyin Ajamu, to jẹ akọwe agba ni Àafin Kabiyesi Ṣọun ti ilẹ Ogbomọṣọ sọ fun bi BBC pe, ijapa naa ti apele rẹ n jẹ Alagba jade laye lẹyin aisan ranpẹ.
Alága àjọ EFCC Ibrahim Magu yóò tún bẹ ìgbìmọ̀ olùwádìí Aàrẹ wò lónìí Ilé ẹjọ́ wọ́gilé ìgbẹ́jọ́ Olalekan 'Woodberry' Pọnle Òru òní ní ìjọba á ti afárá 'Third Mainland' ní Eko; Wo àwọn ọ̀nà míràn tí o leè gbà lẹ́yìn tí wọ́n bá tìí Wo ohun tí Adájọ́ sọ nípa ìgbẹ́jọ́ Wòlíì Sotitobire l'Ondo Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Working religious women: Ẹ̀lẹ́hàá kìí ṣe ọ̀lẹ- Aminat Adegoke Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Melaye ti n sọrọ loju opo ayelujara rẹ lati igba ti ajọ INEC ti kede Ọgbẹni Adeyemi gẹgẹ bi ẹni to jawe olubori ninu atundi ibo to waye lẹkun naa lẹyin ti Dino ti kọkọ wọle ki ile ẹjọ to wọgile eto idibo naa.
” Kò mọ̀ pé OLUWA ti fi òun sílẹ̀.
Ṣugbọn awọn akẹkọọ yoo pada si ẹnu ẹkọ wọn ọjọ kẹrin oṣu kinni, ọdun 2021 lati pari saa akọkọ eto ẹkọ ọdun 2020/2021 eyi ti yoo pari ni ọjọ kejilelogun, oṣu kinni, ọdun 2021.
Àwọn àjèjì láti inú orílẹ̀-èdè, tí ó burú jùlọ, yóo gé e lulẹ̀, wọn yóo sì fi í sílẹ̀.
Oríṣun àwòrán, Others Idi ree ti Ajimọbi fi beere pe ṣe Constituted Authority lẹ n ba sọrọ bayẹn?"
Ní ọjọ́ keje ni Eliṣama ọmọ Amihudu, olórí àwọn ẹ̀yà Efuraimu mú ọrẹ tirẹ̀ wá.
“Lẹ́yìn èyí, ninu ìran tí mo rí ní òru náà, ẹranko kẹrin tí mo rí jáni láyà, ó bani lẹ́rù, ó sì lágbára pupọ.
Ọlọrun ni ó mú kí á lè jẹ́ iranṣẹ ti majẹmu titun, tí kì í ṣe ti òfin tí a kọ bíkòṣe ti Ẹ̀mí.
Yẹni sọ pe oun ati ọgọrọ eeyan ko ni gbagbe Fẹla laelae.
Gẹgẹbi di lara awọn osisẹ ti isẹlẹ naa kan, amọ ti wọn fẹ ka fi orukọ bo wọn ni asiri ti wi, se fidi rẹ mulẹ, ọjọ ẹti ni wọn pin iwe maa rele rẹ naa fun awọn, lai mọ idi to fi ri bẹẹ.
 Àjọ náà ṣe iṣẹ ́ ìórẹ àánú púpọ lórúkọ rẹ ̀ nípa ríra àwon àwòrán olówó iyebíye tó ṣàfihàn àṣà àti ìṣẹ ̀ ṣe sínú ilé ìṣura ohun àbáláyé ilẹ ̀ cyprus , greec àti ọ ̀ pọ ̀ ilé ìṣura lágbàáyé lápapọ ̀ fún àǹfàní àwọn knìwàádìí ìmọ ̀ .
Minisita fun ọrọ eto isuna naa ni, fun igba diẹ ni ọrọ ibode ti awọn ti naa, lati dẹkun magomago ti awọn orilẹ-ede to sunmọ ibode Naijiria n se lati gbe ọja wọle ni ọna aitọ.
Ó bèèrè pé, “Èwo ni o fẹ́ yàn ninu mẹtẹẹta yìí, ekinni, kí ìyàn mú ní ilẹ̀ rẹ fún ọdún mẹta; ekeji, kí o máa sá fún àwọn ọ̀tá rẹ fún oṣù mẹta; ẹkẹta, kí àjàkálẹ̀ àrùn jà fún ọjọ́ mẹta ní gbogbo ilẹ̀ rẹ?
Modupe lowo gbogbo awon omo ile igbimo asofin agba ti won fi ara ji lati sise lori awon minisita to won ko si fi fale rara'' Òṣèré tíátà, Kemi Afolabi dùbúlẹ̀ àìsàn ní ìlú Mecca Ìjọba Buhari ń lo agbára láti jà ìjà ẹsìn- Jiti Ogunye Olóòtú ìjọba Gẹ̀ẹ́sì yan ọmọ Yorùbá ní Mínísítà Mohammed Yusuf: Irú èèyàn wo ní olùdásílẹ̀ Boko Haram?
Oun ni igbanu IBF, IBO, WBA ati WBO ''heavyweight'' wa lọwọ rẹ bayii.
O ba BBC Yoruba sọrọ nipa iriri rẹ ati awọn ipenija ara rẹ ati awọn adẹtẹ to ku ti wọn jọ wa nibudo.
Wọ́n bi í pé, “Níbo ni o fẹ́ kí á lọ ṣe ètò sí?
Awọn to ni aarun coronavirus ni Naijiria pọ si lọsẹ to kọja, pẹlu bi eniyan 2,558 ṣe ni aarun naa bayii, mẹtadinlaadọrun si ti ku.
” Lẹ́sẹ̀kan náà, iná wá láti ọ̀run, ó sì jó ọ̀gágun náà ati gbogbo àwọn ọmọ-ogun rẹ̀.
Bí a ti sọ gbogbo eniyan di ẹlẹ́ṣẹ̀ nítorí àìgbọràn ẹnìkan, bẹ́ẹ̀ náà ni a óo torí ìgbọràn ẹnìkan dá gbogbo eniyan láre.
0 17 Saint Pierre and Miquelon 0 0.
Iṣẹlẹ naa to waye lọjọ Ẹti to kọja fa awuyewuye laarin awọn ọmọ Naijria, koda Minisita fun ọrọ ilẹ okeere ni Naijiria, Geoffrey Onyeama ti sọ pe ijọba Naijiria koro oju si iṣẹlẹ naa.
Kọmisana fun eto ilera ni ipinlẹ naa Jide Idris lo fi idi ọrọ yìí múlẹ̀ ninu atẹjade kan , ṣungbọn ko sọ iye ọmọ wẹwẹ to wa ninu wọn.
Ọdun 2005 lo gori aleefa gẹgẹ bi aarẹ ilẹ Burundi, ipo aarẹ yii naa lo si dimu titi to fi jade laye.
Gbogbo àwọn ará Ijipti bẹ̀rẹ̀ sí gbẹ́lẹ̀ káàkiri yíká odò Naili, pé bóyá wọn á jẹ́ rí omi mímu nítorí pé wọn kò lè mu omi odò Naili mọ́.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Opo iya lo maa n jẹ abiyamọ lasiko irọbi nitori pe awọn Noosi ko ki n tete dahun Kini àwọn Nọọsi ri si ọrọ yii?
àwọn tí wọ́n ti ṣìnà kúrò ninu òtítọ́, tí wọn ń sọ pé ajinde tiwa ti ṣẹlẹ̀, tí wọn ń mú kí igbagbọ ẹlòmíràn yẹ̀.
Lẹ́yìn náà, àwọn eniyan yóo máa gbé Ijipti bíi ti àtijọ́.
 orìṣii ṣẹ ̀ kẹ ̣ ̀ rẹ ̀ mẹ ́ ta là ń lù si apiiri .
Lọdun 2007 ni ijọba sẹ ofin to ṣe agbekalẹ ẹka ijọba, NIMC lati maa bojuto ipese kaadi idanimọ fawọn ọmọ Naijiria.
Ọjọ́ mẹ́wàá òní ni ọjọ́ náà pé o!
Ọga agba ẹgbẹ awakọ, labẹ aburada NURTW, Alhaji Najeem Usman-Yasin ti ba gomina ipinlẹ Ọyọ ṣe ipade bonkẹlẹ lori ọrọ naa, ṣugbọn titi di asiko yii, aṣẹ naa ṣi duro digbi.
Mo gbudọ so ootọ pe o lagbara lati to ile rẹ paapaa bi o ko ba ni iyawo tabi ọkọ to ni oye kikun.
Oríṣun àwòrán, Reuters Àkọlé àwòrán, Ki lo n fa sababi isẹlẹ yi Ibo aadọta si mọkandinlaadọta ni wọn di lọjọ ẹti nile asofin naa, eyi to mu ko nira lati kede ẹni to bori pato.
Bi a ko ba gbagbe, laipẹ yi ni irufẹ idajọ bẹẹ waye nilu Ibadan, ti ile ẹjọ gba awọn ọba ti Gomina ana nipinlẹ Ọyọ, Abiola Ajimobi yan sipo nilu Ibadan.
"N kò jẹ Mayegun láti bùgá, mo wá tún ilẹ̀ Yorùbá ṣe ni - Wasiu Ayinde ‘Pussypedia’ rèé, ojú òpó tó ń mú àdínkù bá ìṣòro ìmọ̀ nípa ẹ̀yà ara obìnrin Ìgbẹ́jọ́ ti bẹ̀rẹ̀ lórí àwọn afurasí tó pa ọmọ Fasoranti, Funke Olakunrin Wasiu Ayinde ti ẹrọ̀fọ̀ dé ibi gíga, bí ikú bàbá rẹ̀ tiẹ̀ ṣèdíwọ́ láti lọ sílé ẹ̀kọ́ Aláàfin Ọyọ: Ọba tó bá n mú ọtí ní ìta kò yẹ ní ẹni tàá bọ̀wọ̀ fún Kwam 1 sọ síwájú pé ""Nígbà tí wọ́n ko ṣepe fún mi?"
'A máa ń bẹ́ orí ẹni tó bá gbé imọlẹ̀ ọdún ìjẹṣu tó bá ṣubú ni' Ṣe ẹ ranti ọdun ijẹṣu ni ilu Ilaramọkin, nibi ti awọn ọdọ ti n yọ pankẹrẹ ati atori si ara wọn lati fi sami ajọyọ ọdun ijẹṣu nibẹ.
Wọ́n para pọ̀ láti gba ẹ̀mí olódodo;wọ́n sì dá ẹjọ́ ikú fún aláìṣẹ̀.
Àwọn tafàtafà ta Josaya ọba ní ọfà, ó bá pe àwọn iranṣẹ rẹ̀, ó sì sọ fún wọn pé, “Ẹ gbé mi kúrò lójú ogun, nítorí mo ti fara gbọgbẹ́, ọgbẹ́ náà sì pọ̀.
Bí ó ti gbé ojú sókè, ó rí àwọn àlejò náà ní ìta gbangba láàrin ìgboro ìlú náà; ó sì bi wọ́n léèrè pé, “Níbo ni ẹ̀ ń lọ, níbo ni ẹ sì ti ń bọ̀?
Ṣùgbọ́n àwọn aláìgbọ́ràn ọmọbìnrin wọn-ọnnì hu ìwà tí Olódùmarè kò fẹ́, wọ́n kúrò ní ibi tí Ọlọ́run Ọba fi wọn sí ni òde ọ̀run wọ́n lọ ká èèso Tèmi-nìkan, nígbà tí wọ́n sì ká a tán wọ́n wá si inú ayé wọ́n fi í fún àwọn ọmọ ènìyàn jẹ àti ìgbà náà ni àwọn ọmọ ènìyàn sì tí ń hu ìwà àbòsí sí ara wọn tí ẹni kan kò fẹ́ kí ẹnì kejì ní ìlọsíwájú bí i tí òun mọ́ tí wọ́n ń kígbe ara wọn káàkiri inú ayé.
Gẹgẹ bi iwadi ti fi ye wa, lara awọn ohun to n mu ki obinrin maa wa ọkọ lori ayelujara tawọn kan sọ ni iwọnyii: Igbagbọ pe obinrin pọ ju ọkunrin lọ nitori naa ati ri ọkọ ṣoro diẹ Ailootọ awọn ọkunrin naa jẹ idi kan ti awọn obinrin mii fi sọ pe awọn n kan si oju opo lati mọ ẹni ti ko ni ṣaburu fun awọn Airaye ọpọ obinrin ode oni nitori iru iṣẹ ti wọn ṣe Onitiju lawọn obinrin mii ti wọn kii ṣaba ni ọrẹ pupọ Erongba lati fẹ ẹni to niṣẹ lapa, pupọ obinrin ni ko fẹ ọkọ ti ko ni le gbọ bukata wọn, ti eto alarina oju ayelujra yii si fun wọn lanfaani lati wa ẹni to niṣẹ lọwọ.
Eeyan ọọdunrun le mẹrinlelọgbọn lo gba iwosan lọwọ arun Covid-19 l'Ọjọru, ọjọ kejila, oṣu Kẹjọ, nigba ti awọn irinwo le mẹtalelaadọta miran tun lugbadi rẹ ni Naijiria.
Ipinlẹ Kwara làkọ́kọ́, lónìí sì ni yóò wáyé gẹ́gẹ́ bí BBC Yoruba ti ṣide ipade itagbangba naa, nibi ti eto ariyanjiyan yoo ti waye laarin awọn oludije latinu ẹgbẹ oselu marun un tawọn eeyan nifẹ si.
Ni ọjọ kẹrin, oṣu kẹsan an, ọdun 1964 ni wọn bi Ẹgbẹdokun ki o to darapọ pẹlu ileeṣẹ ọlọpaa ni ọdun 1990.
Wọn fi agidi mu awọn oṣiṣẹ ileefowopamọ lati ṣi ilẹkun rẹ, ṣugbọn owo ti wọn ba nibẹ ko jọ wọn loju rara.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Adetoun Ogunṣẹyẹ: ìrìnàjò ẹ̀kọ́ mi títí dé òkè kò rọrùn rárá Oun naa si tun ni ọmọ ilẹ Africa akọkọ to de ipo naa.
Di lara awọn ti wọn ku yi ni a fi sọwọ siyin.
Iná ni a fi ń dán wúrà ati fadaka wò,ìyìn ni a fi ń dán eniyan wò.
Kò sì sí ẹni tí ó lè gba àgbò náà lọ́wọ́ rẹ̀.
Nítorí náà, mo ti sọ ọ́ di ẹni ẹ̀gàn láàrin àwọn eniyan, ati ẹni yẹ̀yẹ́ lójú gbogbo orílẹ̀-èdè.
Sinimá àwòdamiẹnu, àwọn aṣẹ́wó dín dùǹdú ìyà fún Ẹ̀fáńjẹ́líìsì ní àbẹ́tẹ̀ wọn ní Ejigbo
Paulu Gbé Ẹjọ́ Rẹ̀ Lọ siwaju Ọba Kesari.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ooni Ile Ife: Ooni Adeyeye Ogunwusi àti Olòrì Naomi gbé Àrẹ̀mọ tuntun wọ ṣọ́ọ̀ṣì 8 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 21 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Oríṣun àwòrán, Ooniadimula Latari ayẹyẹ iwuye ọdun marun lori itẹ ti Ọọni Adeyeye Enitan Ogunwusi n ṣe, Kabiyesi ti fi idupẹ kadi ayẹyẹ naa nilẹ pẹlu lilọ si ile ijọsin lọ dupẹ lọwọ Oluwa.
Omotola Jalade ní Nàìjíríà dàbí ọ̀run àpáàdì lábẹ́ ìjọba Buhari Macron, aarẹ France ṣèlérí láti tún Notre-Dame kọ́ Ninu oṣu kẹrin ọdun 2019 ni Woli Arole bẹrẹ si ni ṣe agbejade ere agbelewo tuntun eyi ti o ko ọpọlọpọ gbajugbaja oṣere sinu ẹ.
ni awon iko omo ogun ofurufu ti won feyinti lenu ise laarin odun 2017 ati osun
Oríṣun àwòrán, AFP Àkọlé àwòrán, Awọn ọlọpa mu awọn eniyan kan lẹhin iṣẹlẹ naa ṣugbọn fi wọn silẹ nitoripe wọn se akiyesi pe awọn kọ ni wọn se ikọlu naa.
Ọdọọdún ni ìpàgọ́ fún ìpàdé àdúrà náà máa ń wáyé èyí tó ma ń kó gbogbo ọmọ ìjọ papọ̀ káàkiri àgbáyé.
Lẹ́yìn náà, Elikana pada sí ilé rẹ̀ ní Rama.
Nítorí ìfẹ́ rẹ̀ tí kì í yẹ̀ dúró laelae.
"Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Helen Paul sọ idi tó fi gba orúkọ ní kékere Kọmiṣonna ni ""oju n ti wa, nitori bi ifipabanilopọ ṣe ti pọ si."
Bakan naa, o jẹ adele adari ẹka irina ni olu ile iṣẹ ogun Naijiria.
Egbe oselu APC jawe olubori ninu abajade esi idibo
“Ẹ̀yin aguntan mi, aguntan pápá mi, ẹ̀yin ni eniyan mi; èmi sì ni Ọlọrun yín.
Ààlà ilẹ̀ náà yóo bẹ̀rẹ̀ láti ibi òkun títí dé Hasari Enọni, tí ó wà ní ìhà àríwá ààlà Damasku, ààlà ti Hamati yóo wà ní apá àríwá.
Wọn pada pari ọrọ naa ni tunbi n nubi ni.
Buhari yóò ṣèpàdé pẹ̀lú Ọba Morocco
Mahama naa lo tun fidi rẹmi bayii lẹyin nti Akufo-Addo wọle fun saa keji.
Wọn ti ṣagbekalẹ ẹrọ kan eleyi ti yoo dena titẹ ara ẹni nibi ti wọn ti ju oko mọ Asitani bẹrẹ lati ọdun 2019.
Báyìí ni àtúpalẹ̀ àwọn to ni ààrùn náà nípìnlẹ̀ kọ̀ọ̀kan ṣe lọ Lagos-130 Bauchi-36 FCT-25 Edo-17 Bayelsa-14 Ogun-14 Oyo-14 Anambra-13 Kaduna-12 Ondo-11 Abia-10 Osun-6 Plateau-5 Kwara-5 Kano-4 Ebonyi-3 Sokoto-2 Borno-1 Ipò ti ìpínlẹ̀ kọ̀ọ̀kan wà rèé lọ́wọ́lọ́wọ́ Definition of Coronavirus: NCDC kéde èèyàn 601míràn tó ṣẹ̀ṣẹ̀ lùgbàdì Covid-19 ní Nàìjíríà Àjọ tó ń gbogun ti àjàkálẹ̀ ààrùn lórílẹ̀-èdè Nàìjíríà ti kéde pé ènìyàn mọ́kànlélẹ́gbẹ̀ta ènìyàn ló tún ṣẹ̀ṣẹ̀ lùgbàdì ààrùn Covid -19 ni Nàìjíríà, bí ènìyàn to tó lé ni ẹgbẹ̀rún lọ́nà ẹgbẹ̀rin ṣe ti kú lágbàyé báyìí.
Bíótilẹ̀jẹ́pé òmìnira ọ̀hún gan-an ò péye, ìyẹn ni pé òmìnira ìjọba lásán ni kòsí òmìnira ọrọ̀-ajé di òní-olónìí.
", ẹgbẹ́ òṣèré tíátà pàṣẹ fún Lizzy àti Toyin Kemi Olunloyo dá sí ìjà Toyin Abraham àti Lizzy Anjorin Àwọn olólùfẹ̀ Toyin Abraham ati Liz Anjorin ti gbé ọ̀rọ̀ wọn rù sórí, ẹ wo òjò òkò ọ̀rọ̀ Àwọn òṣèré tíátà takò ìkọlù South Africa àti ìgbẹ̀san ọmọ Nàíjíríà Ọkọ Toyin Abraham pẹ́ ọ̀rọ̀ sọ lórí aáwọ̀ láàrin ìyàwó rẹ̀ àti Lizzy Anjorin ""Elo ni ọkunrin kan fẹ fun iru obinrin bi emi, ti yoo ka lẹnu?"
Wọ́n sì ń ta ọtí sílẹ̀ fún àwọn oriṣa láti mú mi bínú.
Atẹjade ti wọn fi sita sọ pe agbabọọlu ni dun marundinlogoji naa n ṣe daada ni iyasọtọ ti ko si ṣe afihan arun naa kankan Màmá Guardiola d'olóògbé lẹ́yìn tó lùgbàdì Coronavirus Wo agbábọ́ọ̀lù Super Eagles Nàìjíríà àkọ́kọ́ tó lùgbàdì coronavirus Zlatan: Èyí mo ṣé tó, àsìkò tó láti tèsíwájú nínú ìrìnàjò mi Real Madrid ń gbáradì láti ra Paul Pogba pẹ̀lúu £70m Awo lọ?
Abajade eto idibo si ipo Gomina ati Ile Igbimọ
Oluwa ni ó yọ mí ninu gbogbo wọn.
"Ọjọ naa yi pada lati di ọjọ afihan okun ọmọ iya to wa laarin ile yii ati awọn aṣoju-ṣofin, pẹlu bi awọn aṣofin naa ṣe dide lati gbaruku ti awọn aṣofin agba lati koju awọn to wọ ile naa.
Ní ọjọ́ kẹrinla, oṣù kinni ọdún tí ó tẹ̀lé e, àwọn Juu tí wọ́n pada láti oko ẹrú ṣe ayẹyẹ Àjọ Ìrékọjá.
Ọmọ ọdún mẹ́wàá ń fọn fèrè lágbo àríyá Ìlú mímọ́ nibí, wọn kò gbọdọ̀ bímọ, sin òkú àbí ẹran síbẹ̀"" Lẹ́yìn ìfẹ̀yìntì ọdún márùn-ún, báágì àti bàtà ló kàn Ọbasanjọ sọ àsírí sàgbàdèwe rẹ̀ Ka to wi, ka to fọ, ọwọja ina ọhun ti tan kaakiri adugbo yii, to si jo ọpọ ile ati sọọbu, ti ina ọhun si jo iya Dada kọja ala, to si wa ni ẹsẹ kan aye, ẹsẹ kan ọrun nile iwosan ijọba to wa ni Gbagada."
A óò bẹ̀rẹ̀ sí san 30,000 owó oṣù òṣìṣẹ́ tó kéré jù lóṣù yìí- Fayemi Kiki Osinbajo gbóṣùbà fún Seyi Awolowo, MC Oluomo tọrọ ìbò fún Mike ní BBNaija O fi kun wi pe Ile Arugbo naa ni wọn fẹ lo fun ile iwosan awọn oṣiṣẹ ati ile isẹ ijọba keji, ti ko si si ẹri pe ẹnikẹni san owo fun un.
bí ẹ bá gbọ́ ti OLUWA Ọlọrun yín, tí ẹ pa àwọn òfin ati ìlànà rẹ̀ mọ́ bí a ti kọ ọ́ sinu ìwé òfin yìí, tí ẹ bá sì yipada tọkàntọkàn.
3m) to duro fun ida mọkanlalaadọta o le diẹ (51.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Kogi, Bayelsa Governorship Elections: INEC kéde ọjọ́ tuntun 16 Èbibi 2019 Oríṣun àwòrán, INEC Ajọ eleto idibo Naijiria, INEC ti kede ọjọ tuntun fun eto idibo sipo gomina ti yoo waye nipinlẹ Kogi ati Bayelsa.
Lọ́sàn yìí ni àjọ tó rí sí ètò ìdìbò ní Naijiria (INEC) fi àtẹjáde kan síta pé, ìwé ìfitóniléti tí ẹgbẹ́ APC nípìnlẹ̀ Ondo kọ sí olú ilé iṣẹ́ ẹgbẹ́ náà l'Abuja láti pè òun fún ìdìbò àbẹ́nu wọ́n, kò kójú òṣùwọ̀n tó nítorí pé adelé akọwé àpapọ̀ ẹgbẹ́ APC ní Nìgeria níkan ló buwọ́ lu lẹ́tà náà.
Imam Fuad tako Oluwo lori wiwe lawani
Ìgbà wo ni n óo sì fara dà á fun yín dà?
    Ìgbà ó tó bí ọ̀sẹ̀ kan tí a ti de ibẹ̀ mo wí fún iwin ọ̀rẹ́ wa yìí pé a fẹ́ máa lọ sí ìrìnàjò wa.
Mose sì wí fún àwọn onídàájọ́ Israẹli pé, “Olukuluku yín gbọdọ̀ pa àwọn eniyan rẹ̀ tí ó lọ sin oriṣa Baali tí ó wà ní Peori.
Ori ko ọkan lara awọn ti àrá naa ba yọ, ṣugbọn wọn ti gbe oku awọn to ku lọ ile iwosan ijọba to wa nilu naa.
Asenati, ọmọ Pọtifera, babalóòṣà Oni, bí ọkunrin meji fún Josẹfu kí ìyàn tó bẹ̀rẹ̀.
Ayansike: SS3 ní mo wà báyìí, mo sì ti gba àmì ẹ̀yẹ̀ púpò nílé-lóko gẹ́gẹ́ bí onílù Oúnjẹ́ aṣaralóòre nìkan kò tó ò tí o bá n gbèèrò láti lóyún tàbí tí ó bá lóyún Èkúté tó sàwárí bọ́mbù ilẹ̀ gbàmi ẹ̀ye wúrà fúniṣẹ́ takuntakun Afẹ́fẹ́ gáàsì ṣe ìjàmba fún èèyàn 30, ilé 23,ọkọ 15 ní ìpínlẹ̀ Eko Amọ, ileẹjọ kan ni ilu Abuja ti pasẹ ki ẹgbẹ oṣiṣẹ dawọ iyanṣẹlodi wn duro titi di igba ti awọn ma a gbọ ẹjọ ti ajọ kan pe mọ ẹgbẹ oṣiṣẹ NLC.
 Ẹgbẹ ́ yìí fipá kó ọ ̀ pọ ̀ lọpọ ̀ ènìyàn lọ àti ìfipá kó akẹ ́ kọ ́ igba lé mẹ ́ rìndínlọ ́ gọrin kúrò ní chibok ní oṣù kẹrin Ọdún 2014 .
Budget 2019: Buhari fi ọ̀rọ̀ ẹ̀kúnwó owó tuntun òṣìsẹ́ sínú àbádòfin 2019
Obadiah Mailafia: DSS ti fi igbákejì gómìnà CBN tó ní gómìnà kan ní Àríwá Naijiria ní Ọ̀gá Boko Haram sílẹ̀
Àkọlé àwòrán, Buhari fun Abiola ni oye GCFR to ga julọ ni Naijiria lọdun 2018 Àwọn Gómìnà Gúúsù-Ìwọ̀ Oòrùn kéde June 12 Sáà kéji tọ́ sí Buhari - Asíwájú Bola Tinubu June 12 èso àwọn ohun málèègbàgbé nípa MKO Àwọn olùkòpá nínú ìdìbò June 12 1993 sọ ọ́ di mímọ̀ pé ó jẹ́ ìgbà àkọ́kọ́ tí ìdìbò lọ déédé láàrin Hausa, Igbo àti Yorùbá.
wọ́n ń sọ pé, “Ìwọ tí yóo wó Tẹmpili, tí yóo tún un kọ́ ní ọjọ́ mẹta, gba ara rẹ là.
Máa pada bọ̀, máa pada bọ̀, ìwọ ọmọbinrin ará Ṣulamu.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Agbekoya: Bí a bá na oògùn abẹnugọ̀ngọ̀ s'ókè, ìjínigbé á d'ópin!
Egbe to n wa ekusa lorile ede Naijiria ti koko  fi edun okan won nipa isoro ti egbe won n dojuko lati ri owo gba lati odo  Banki to n mojuto oro to je mo idagbasoke ise, ti o letoo lati fi owo ran won lowo fun idagbasoke ise won.
Olukọ wa kọ wa ni kikun nipa oriṣi isọri ounjẹ bii ounjẹ Oniyọ, ounjẹ Ẹlẹran/ Ọlọra, ounjẹ Asemiro, ounjẹ Afaralokun ati ounjẹ amaradan to wa.
Bi ọmọ kò bá ba ìtàn; ó máa n ba àrọ́bá ni, ọdún ìjẹṣu Ilara-mọkin kò déédé bẹ̀rẹ̀.
Ifiposilẹ Desalegn sokunfa ikede ilu o fara rọ ni Ethiopia Iyansipo ọgbeni Abiy tunmọ si pe ohun ni yoo bọ si ipo olootu ijọba lẹyin Hailemariam Desalegn to s'adede fipo silẹ losu to kọja.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Premier league: Manchester United jẹ àjẹkún ìyà góòlù méjì lọ́wọ́ Westham United 22 Owewe 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Ọwọ iya ba Manchester United ni ile Westham United ni ọjọ Aiku nibi idije Premiership ilẹ Gẹẹsi.
Oríṣun àwòrán, Abiola Ajimobi Amọ nigba to n ba BBC Yoruba sọrọ, agba oye kan nilẹ Ibadan, ti oun ati Ajimobi dijọ se ọmọde, Lekan Alabi ni iku oloogbe naa dun oun pupọ.
Exhibition Centre lọjọ keji, Isẹgun , osu kerin , odun yii.
Ni Ayé òde òni, njẹ́ ó yẹ ki a pọ́n Àṣà fi fẹ́ Iyàwó púpọ̀ lé ni Igbéyàwó Ìbílẹ̀ Yorùbá
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Saraki àti Buhari yóò jìjà àgbà nínú àtúndì ìbò Kwara Ayefẹlẹ bá BBC sọ̀rọ̀ lórí ilé orin rẹ̀ tí Ajimọbí ń tún kọ́ 'Tattoo’ ara mi kò tí ì pọ̀ tó, mà á sì se si’ Àmàlà ṣekúpa ènìyàn mẹ́rin ní Ilorin Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ayàwòrán Obama: Ọ̀pọ̀ ìgbà ni èmi àti ìyá mi pa èbi mọ́nú kí n tó jẹ́ èèyàn Nínú ìpádé ọ̀hún, eyi ti ààrẹ Muhammadu Buhari darí, ní mínísítà ti sàlàyé pé owó ìrànwọ ọhún ni láti mú àdínkù bá owó ìrẹ̀sì tó gbówó lórí gọbọi.
Ẹ̀mí ni Ọlọrun, àwọn tí ó bá ń sìn ín níláti sìn ín ní ẹ̀mí ati ní òtítọ́.
Igba kan ni wọn si maa n ṣe laarin oṣu kan.
ologun naa le kuro lori ipo latari aimọye ọpọlọpọ ifẹhonuhan to waye ni orile
Peteru dá a lóhùn pé, “O kò ní fọ ẹsẹ̀ mi laelae!
¨Ilana ẹsin Kristẹni ni mo fi tọ awọn ọmọ mi dagba, bo tilẹ jẹ pe orukọ Musulumi ni wọn n jẹ.
Àlọ́ mìíràn láti gúúsù Laos ní àwọn ìlànà tí ó kọ́ni nípa ìmọrírìi ìbójútó ọrọ̀ ìṣẹ̀dá:
Ó ṣeéṣe kí Ọlọrun ṣàánú, kí ó yí ibinu rẹ̀ pada,kí ó sì tú ibukun rẹ̀ sílẹ̀,kí ẹ lè rú ẹbọ ohun jíjẹ ati ẹbọ ohun mímu fún OLUWA Ọlọrun yín.
Nígbà tí ayé bá ń mì síhìn-ín sọ́hùn-ún,ati gbogbo àwọn tí ń gbé inú rẹ̀;èmi a mú kí òpó rẹ̀ dúró wámúwámú.
” Nítorí pé àwọn ọmọ Israẹli ti búra pé, “Ẹni ègún ni ẹnikẹ́ni tí ó bá fi ọmọ fún ará Bẹnjamini.
”Ó ní, “Ẹgbaagbeje,” Nítorí àwọn ẹ̀mí èṣù tí ó ti wọ inú rẹ̀ pọ̀.
Obìrin kògbérégbè mẹ́ta nínú òṣèré Yorùbá
Ìwọ ṣá ti múra, kí o sì ṣe ọkàn gírí.
O ni biotilẹjẹpe o lera fun awọn eniyan lasiko yii, awọn igbesẹ naa pọn dandan lati le mu itẹsiwaju ba orilẹede Naijiria, ati lati le mu ilọsiwaju ba ọrọ aje to dẹnu kọlẹ.
Gbogbo ẹ̀ṣẹ̀ tí eniyan lè máa dá kò kan ara olúwarẹ̀.
Nibi ayẹwo Minisita niwaju ile asofin Naijiria naa ohun ati awọn miiran bii Babatunde Fashola ati Gbemisola Saraki yọju siwaju ile lati wi tẹnu wọn.
Ṣugbọn, ko fun mi ni esi kankan fun bi i ọgbọn iṣẹju.
Ni oṣu kọkanla ọdun 2018, Aarẹ Muhammadu Buhari kede igbesẹ nnkan ko fararọ lẹka ipese omi ati imọtoto ti o si ṣefilọlẹ eto apapọ lori igbesẹ amojuto ilera ati imọtoto, WASH.
Oríṣun àwòrán, @Joe Eyi ko ṣẹyin bi awọn obinrin kan to jẹ oludibo ṣe n fi ẹsun kan an pe awọn ko nifẹ si bo ṣe maa n fi ọwọ kan wọn - àwọn kan ti ẹ tun fi àwọn fidio sita nípa rẹ.
Alhaji Mukaila ni awọn ara awọn ọmọ ẹgbẹ NURTW gan an ti bẹrẹ si ni darapọ mọ awọn ọmọlẹyin oun.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Awa Bike: Kẹ̀kẹ́ tiwa wà fún eré ìdárayá àti díndín èéfín agbègbè kù Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Awa Bike: Kẹ̀kẹ́ tiwa wà fún eré ìdárayá àti díndín èéfín agbègbè kù 23 Ògún 2019 Kẹ̀kẹ́ wíwà máa ń fún ni lẹmi gigun -Awa Bike.
" Olumide ni àwọn ọlọ́pàá ni kí òun máa parọ́ mọ́ ara òun pé 'Gay' ni òun kí òun sì máa dárúkọ́ àwọn ènìyàn síi tí oun bá ṣe e sí.
Ijọba Naijiria ti ṣetan lati ran oniṣowo ẹgbẹrun lọna ẹẹdẹgbẹta lọwọ jakejado Naijiria.
- Ẹgbẹ́ àgbẹ̀ kìlọ̀ Ọgbẹni Abdu Jinjiri fikun ọrọ rẹ pe awọn tọkọ taya naa ti n ni ede-ai-yede tẹlẹ ti wọn fẹ ara wọn fun ogunjo pere ki ṣaaju iṣẹlẹ naa.
Ẹ̀yin ará mi, èrè kí ni ó jẹ́, tí ẹnìkan bá sọ pé òun ní igbagbọ, ṣugbọn tí igbagbọ yìí kò hàn ninu iṣẹ́ rẹ̀?
Ṣugbon àwọn iranṣẹ rẹ̀ ati obinrin náà bẹ̀ ẹ́ kí ó jẹun.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù David Oyedepo pe Biodun Fatoyinbo si ìsìn Shiloh, ọmọ Nìíjíríà fárígá 11 Ọ̀pẹ̀̀ 2020, 10:45 WAT Oríṣun àwòrán, @biodunfatoyinbo Lẹyin ọdun kan, awọn ọmọ orilẹ-ede Naijiria tun ti hu ọrọ ẹsun ifipabanilopọ ti wọn fikan gbajugbaja pasitọ ijọ COZA, Biodun Fatoyinbo, sita.
Kí ló ń fa wàhálà láàrín Kunle Afolayan àti Mike Ezuruonye lórí ayélujára?
Awọn nkan mẹta ti awọn ọmọ Naijiria yoo ṣafẹri ninu ohun ti oludasilẹ ileeṣẹ iroyin Sahara Reporters Òun i ba sọ nibi ifọrọwerọ naa.
Adajọ naa ni won gbodo san owo itanran naa , ki o le dena
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, JAMB 2019: A ó fagi lé ìdànwò ẹni tó bá ṣe aṣemáṣe Iṣẹ ibi awọn alákatakítí ẹsin Isilaamu to n ju ado oloro kiri Koko ohun to n fa wahala ni pe odiwọn nọmba to ba wu ijọba ni wọn n pe lori awọn to farapa nibi ado oloro ti awọn alakatakiti ẹsin Islam n ju ni Somalia.
Jesu bá na ọwọ́ rẹ̀, ó fi kàn án, ó ní, “Mo fẹ́, kí ara rẹ di mímọ́.
Awọn mejeeji yoo maa patẹwọ ọwọ mejeeji, ẹni to ba ti kọkọ rẹ ni yoo kuna ninu idije naa.
Gauri Malar ati Roshan Jayathilake ni wọn ti di tọkọtaya pẹlu ikoko lọwọ.
Iṣẹ wọn ni lati maa ṣe iwadii lori ọrọ to niṣe pẹlu aabo kaakiri ilẹ Yoruba, bakan naa ni wọn le mu awọn ọdanran.
 Àwọn yorùbá tó sì wà ní orílẹ ̀ èdè benin pín sí méjì  ìdásà ' àti "" manígì ' ."
Mo dá jókòó nítorí àṣẹ rẹ, nítorí o ti fi ìrúnú kún ọkàn mi.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Ẹlẹ́ẹ̀kẹjọ t'óyún máà bàjẹ́ lára mi ni mo tó rí àànú gbà' Ẹgbẹ NAPS sọ pe awọn fi ọrọ lọ ijọba apapọ, nipasẹ igbimọ to wa fun fifi ẹsẹ eto ọrọ aje mulẹ ni Naijiria, ti igbimọ alasẹ naa si ti buwọlu u.
Oríṣun àwòrán, Facebook/Mwani Sparta Àkọlé àwòrán, Mwani Sparta fi aworan ara rẹ sori facebook pẹlu ibọn lọwọ pẹlu awọn ọmọ ẹgbẹ Gaza yoku Awọn aworan naa maa n fi oju ibi ti ibọn ti ba wọn han; bi agbari to fọ, ifun to tu jade, pẹlu ikilọ pe ohun ti yoo ṣẹlẹ si awọn ọdaran to ku naa niyẹn.
Nibayii, eeyan 996 lo ti ba ajakalẹ arun naa lọ ni Naijiria.
Ajọ naa sọ pe ki o to le laanfani ati jẹṣẹ ni California, o gbọdọ ''yoju siwaju ajọ naa nibi ti yoo ti fi han pe oun yoo wuwa ni ibamu pẹlu ofin wọn'' Amọ ṣa Pulev ti fi ọrọ sita loju opo Twitter nipa iṣẹlẹ naa.
Ẹbọ ọkà pẹlu àgbò yóo jẹ́ ìwọ̀n eefa kan.
Ó kọ́ pẹpẹ ìrúbọ oriṣa sinu ilé OLUWA, níbi tí OLUWA ti pàṣẹ fún àwọn ọmọ Israẹli láti máa sin òun.
Ìpele ikọ̀ mẹrindinlogun Uganda vs Tanzania.
" Bakannaa ni Aarẹ Buhari tun rọ awọn ti wọn fara kaasa ikọlu naa lati mase gbẹsan.
Kò sì sí òmíràn níbí lẹ́yìn rẹ̀.
Àwọn Juu tí a gé kúrò yóo tún bọ́ sí ipò wọn pada, bí wọn bá kọ ọ̀nà aigbagbọ sílẹ̀.
Fẹmi Fani-Kayode, tii se Minista fun eto irinna oju ofurufu nigbakan ri lorilẹede Naijiria naa dasi ọ̀rọ̀ yii.
Tom Waziri, to jẹ akẹkọjade Fasiti ipinlẹ Kogi to si n gbaradi lati lọ ṣe eto agunbanirọ ki iṣẹlẹ naa to ṣelẹ si i.
Kani wipe o ti bẹrẹ isẹ lati ọdun 1888, o ba ti maa gba iye owo wọn bayii Iye owo senato kan losu le ra apo iresi toto 866, nigbati iye owo osu rẹ yoo ra apo irẹsi mẹfa To o ba n gba ₦150,000: Yoo gba sẹnatọ ni wakati marun ati isẹju 37 lati pa iye owo to n pa losu.
Eni kan ti iroyin naa soju re so pe, nigba ti ipinnu lati pe Aare Zuma pada waye, oun ni igbimo egbe oselu naa koko fi to leti, oun wa so fun won pe, “ ki won se ohun ti won fe se naa”.
Baba mímọ́, fi agbára orúkọ rẹ pa àwọn tí o ti fi fún mi mọ́, kí wọ́n lè jẹ́ ọ̀kan, gẹ́gẹ́ bí àwa náà ti jẹ́ ọ̀kan.
Ṣugbn lai wo ipenija wọnyii, ọgọọrọ eniyan to ti n tẹle e lawọn oju opo ayelujara rẹ ko lonka.
Ẹ̀wẹ̀, lẹyin oṣu meji, ajọ IAAF kọwe si Naijiria pe a ṣi owo san fun yin o, ẹ da a pada""."
orile ede Naijiria,lakọọkọ, mo dupẹ lọwọ  Ọlọrun ti o da ẹmi  wa si lati foju ri aseyege  eto ijọba tiwa-n-tiwa lorilẹ ede Naijriia ati
Àwọn ẹgbẹ́ yìí máa ń dájọ́ àti fi ìyà jẹ ènìyàn tí kò sì sí ẹni tí ó ká wọn lápá kò.
Ile igbimo Asofin agba ni Naijiria ti bere ise iwadii lori asilo eto omoniyan to ye fun awon asatipo nibudo won kaakiri Naijiria.
Ninu ọrọ ikini ku ọdun Eid-el-Fitir rẹ to fi ransẹ si awọn musulumi lo ti kede eyi.
Uraya dá a lóhùn pé, “Àwọn ọmọ ogun Israẹli ati ti Juda wà lójú ogun, àpótí ẹ̀rí OLUWA sì wà pẹlu wọn.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Afeez Agoro: O ṣòro fún mi láti wọ Danfo jáde Vera ni eto aabo ati igbọraẹni ye yoo wa laarin wọn sii nidii ọja wọn nigba ti owo ibode, owo ori ọja ati owo ori ọlọja ba ti kuro nibẹ.
Irinajo Oselu rẹ Lọdun 2017 ti ẹgbọn rẹ, Isiaka Adetunji ku, anfaani si silẹ fun Nurudeen Ademọla lati wọ agbami oselu taara.
“Eleyii ni yoo je akọkọ lorile ede yii ti iru ipade naa yoo waye , ipade naa yoo fihan bi oro yii se ka awon alase igbimo awon osise lara to.
Wọ́n tilẹ̀ ṣe ju bí a ti lérò lọ, nítorí pé ara wọn pàápàá ni wọ́n kọ́ gbé bùn wá, tí wọ́n sì yọ̀ǹda fún Ọlọrun nípa ìfẹ́ rẹ̀.
Ọjọ kẹẹdọgbọn osu kẹfa ọdun 2020 si ni gomina ana naa dagbere faye nile iwosan aladani kan nilu Eko nibi to ti n gba itọju lori arun Coronavirus.
Ṣugbọn afurasi naa ti sọ fun ile ẹjọ pe oun ko jẹbi gbogbo ẹsun ti EFCC fi kan oun.
Mo ní, “Èmi óo máa ṣọ́ra,kí n má baà fi ahọ́n mi dẹ́ṣẹ̀;n óo kó ẹnu mi ní ìjánu,níwọ̀n ìgbà tí àwọn eniyan burúkú bá wà nítòsí.
Lẹyin naa ni won yoo pin heroin naa ka lo si Olu-ilu South Africa tii Johanesburg.
Lẹ́yìn ìfọ̀rọ̀wáni-lẹ́nùwò bíi wákàtí márùn-ún pẹlu ọ̀ga ọlọ́pàá, tí wọn sì yẹ ẹ̀rọ kọ̀mpútà àti ilé rẹ̀ wò, kò sí ohun kan tó ṣe àkóbá fún.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Professor Ayo Akinwale: Iṣẹ́ rẹ ń tọ̀ ọ́ lẹ́yìn 14 Owewe 2020 Oríṣun àwòrán, Etsu Muazu Idris/Facebook Ayobami Akinwale ọmọ agbo Sasa ọmọ agbo Yaya, Ọmọ Ibadan nile Oluyole, Omo ajẹgbin jẹ 'karahun .
Ẹwẹ, ninu awọn ifẹsẹwọnsẹ miran, Tottenham dawọọ papa iṣere tuntun lẹyin ti wọn na Crystal Palace pẹlu ami ayo meji sodo.
Ni kete to ba si n ti fi ẹnu kan an, ọrun laala o.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ilé ẹjọ́ gba béèlì Dino Melaye 16 Èbibi 2018 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ilé ẹjọ́ gba béèlì Dino Melaye Adájọ́ tó ń dá ẹ́jọ́ ẹ̀sùn tí wọ́n fi kan Sẹ́netọ̀ tó ń sojú ẹkùn ìdìbò Ìwọ̀-oòrùn ìpínlẹ̀ Kogi, Dino Melaye ti gba onídùró rẹ̀.
Mo wá ẹni tí ọkàn mi fẹ́,lórí ibùsùn mi lálẹ́,mo wá a, ṣugbọn n kò rí i;mo pè é, ṣugbọn kò dáhùn.
Ni ọjọ ẹti ni wọn yoo ṣe aṣayan awọn ẹgbẹ agbabọọlu to pegede wọ abal;a komẹsẹoyọ ati awọn ti wọn yoo ba ṣalabapade Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 3 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 5 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Bí ẹ kò tilẹ̀ mo gbogbo rẹ̀, ẹ kò rí aafin mi tí ó lókìkí jákèjádò ayó?
 o máa ń ṣẹlẹ ̀ níwọ ̀ nba ní àwọn orílẹ ̀ èdè tí o ti gbèrú níbi tí àwọn ọmọdé kòní àkóràn ní kékeré tí kòsí sí ìwọ ́ pọ ̀ ìfún lóògùn .
Andy Ruiz já ìràwọ̀ Anthony Joshua
Se ikọ agbabọọlu orile ede South
Nibo ni nkan yoo yọri si?
3b fún àkanṣe iṣẹ́ Nínú àtẹ̀jáde tí ilé iṣẹ́ ààrẹ gbé jáde lọ́sẹ̀ tó kọjá, wọ́n ṣàlàyé wí pé ó wà láàrin ilé iṣẹ́ Galaxy Backbone ti Nàìjíríà àti Huawei Technologies ti China fún ìdàgbàsókè ìbaraẹnisọ̀rọ̀ àti ìmọ̀ ẹ̀rọ gẹ́gẹ́ bí àlàkàlẹ̀ ètò ìṣèjọba ààrẹ Buhari.
Àwọn òsìsẹ yarí mọ́ báńkì Fidelity lọ́wọ́ ‘Èpè ni Toyin Abraham sẹ́ fún mi nínú ìgbìyánjú mi lórí ìgbeyàwó rẹ̀ tó dàrú’ Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí 2 sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
Bí irú mààlúù tí ó ti kan eniyan pa tẹ́lẹ̀ rí yìí bá tún kan ọmọ ẹnìkan pa, kì báà ṣe ọkunrin tabi obinrin, irú ẹ̀tọ́ kan náà tí a sọ yìí ni wọ́n gbọdọ̀ ṣe fún ẹni tí ó ni mààlúù náà.
Bi iye awọn to ni ni awọn ipinlẹ to ku ṣe lọ ni yii; Eko-163 FCT-76 Ebonyi-23 Rivers-21 Delta-8 Nasarawa-8 Niger-8 Enugu-6 Bauchi-5 Edo-5 Ekiti-5 Ondo-5 Gombe-5 Benue-4 Ogun-2 Osun-1 Plateau-1 Kogi-1 Anambra-1 Ènìyàn 241 tuntun ló ti lùgbàdì àrùn Coronavirus ní Ọjọ́ Ìṣẹ́gun ní Naijiria Ajọ NCDC ti kede eniyan 241 gẹgẹ bi apapọ eniyan to ni arun Coronavirus lorilẹede Naijiria ni Ọjọ Iṣẹgun lorilẹede Naijiria.
N óo ṣe é bí aṣálẹ̀, àní, bí ilẹ̀ tí ó gbẹ, n óo sì fi òùngbẹ gbẹ ẹ́ pa.
 A mọ pe oun ni Gomina Ipinlẹ
" Ibi ti mo ti n sare lọ ni mo ri i pe nkankan ba mi, nkan ti mo si mọ kẹhin naa niyẹn.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ọdunlade Adekọla gbóṣùbà fáwọn ọkùnrin tó ń ran ìyàwó wọn lọ́wọ́ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Fẹla Durotoye: ọ̀rọ̀ ìṣọ̀kan Nàìjíríà tó àpérò ọmọ eríwo Orí kó Ààrẹ yọ lọ́wọ́ àdó olóró Secondus pẹtu saawọ nínú PDP Ọ̀sun Fayose: Kàkà kí n darapọ̀ mọ́ APC, màá.
Àwọn ìròyìn mìírànm tí ẹ lè nífẹ̀ẹ́ sí: Ọwọ ọlọpa tẹ adigunjale ajọkọgbe nipinlẹ Ọsun Ilé ẹjọ́ pàṣẹ ki wọ́n sọ́ afurasí 5 sì àhámọ́ lórí ìdigunjalè Ido-Ani Ìjàmbá ọkọ̀ ojú'rin ní Agege, Eko Bi wọn se pa ọga SARS Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
O jókòó sibẹ, ò ń dá mi lẹ́jọ́ lórí Òfin, sibẹ o pa Òfin tì, o ní kí wọ́n lù mí.
Elieli, ará Mahafi, ati Jẹribai, ati Joṣafia, àwọn ọmọ Elinaamu, ati Itima ará Moabu; 
Arẹgbẹṣọla lọ àmọ́ ọ̀pọ̀ isẹ́ rẹ̀ ń fọhùn síbẹ̀ l‘Ọ́sun Gómìnà ìpínlẹ̀ Osun wọ́gilé ìrìnàjò àwọn alága sí Dubai Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Àwọn oṣiṣẹ feyinti ni Osun ṣé iwọde Rauf Arẹgbẹsọla ti o jẹ Gomina ipinlẹ Osun nigba kan ri ni wọn bo ti ṣe koju ipenija airi owo oṣu awọn oṣiṣẹ san ti o si fi gbese kalẹ nigba ti yoo fi kuro lori alefa.
N óo sì fún un ní àwọn ọgbà àjàrà rẹ̀ pada níbẹ̀, n óo sì sọ àfonífojì Akori di Ẹnu Ọ̀nà Ìrètí.
Ta ni ìwọ tí ò ń dá ọmọ-ọ̀dọ̀ ẹlòmíràn lẹ́jọ́?
Lockdown Extension: Kí ló le mú kí ìjọba Nàìjíríà ó dá òfin ìṣéde padà?
Ninu atejade kan lojo-Aje, olugbani-nimoran kan pataki fun Aare lori eto iroyin ati ona igbode gba, Femi Adesina ro awon ile-ise amohun-maworan ati radio jake-jado orile-ede Naijiria lati darapo mo ile-ise amohun-maworan ijoba NTA ati ero radio fun iroyin ohun.
Ṣugbọn ṣa ijọba ni ida meji awọn to ba yẹ ko wa ni aaye ijọsin naa ni awọn yoo faye gba lati jọsin.
Kìnìún mẹ́rìnlá bọ́ sígboro Àwà gómìnà PDP ṣetán láti san #30,000 owó oṣù fáwọn òṣìṣẹ́- Dickson Ilé ẹjọ́ ní kí NBC yí àṣẹ padà lórí DAAR Communications Wo àwọn agbábọ̀ọ́lù obìnrin ti wọ́n jọ máa figagbága ni France 2019 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
PDP tun bu ẹnu atẹ lu ijọba apapọ pe o n fi ọgbọ̀n-ọ̀gbọn pese owona fun ijọba ipinlẹ Ọsun lori eto idibo naa, pẹlu bo se ni oun da owo to le biliọnu mẹrindinlogun naira pada gẹgẹ bii owo to san le lori gbese Paris Club pada.
Bojúwò mí, kí o sì dá mi lóhùn, OLUWA, Ọlọrun mi.
Ọmọ China to ẹgbá sí ìdí ọmọ'ṣẹ́ rẹ tó pẹ́ ẹ́ dé ibi'ṣẹ́ Kenya rí akẹ́kọ̀ọ́ tó há sí Ṣáláńgá yọ Wọ́n ti búra wọlé fún Akinwunmi Adesina gẹ́gẹ́ bí ààrẹ Banki ilẹ̀ Afrika, AfDB Ileeṣẹ yi gan an ni wọn ni magomago ti waye nipa owo to yẹ ki wọn fi ra nkan eloo itọju alarun Covid-19.
Ibojì àwọn ọmọ ogun rẹ̀ sì tò yí tirẹ̀ ká.
Ṣugbọn ni kete ti o gunlẹ nibẹ bayii ni ariwo hee, hẹẹ ti bẹrẹ pẹlu oniruuru idẹyẹsi.
Javier Aguirre ni wọn ti ni ko maa lọ ni kete ti Bafanabafana ṣe ti gbo ewuro soju Egypt.
Aarẹ Ona Kakanfo ti ilẹ Yoruba naa wa parọwa si aarẹ orilẹede yii, Muhammadu Buhari lati rii daju wipe ọwọ sikun ọlọpa tẹ awọn apaniyan wọnyi.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Kí lo tíì rí nípa Amotekun?
lati gbaradi lati mu ipinnu awon ọrẹ wa ati agbaye wa si imusẹ.
Carlos to jẹ akẹgbẹ rẹ ni Real Madrid ati Brazil jẹri wi pe o nira fawọn ẹlẹsẹ ayo lati gba bọọlu sawọn nigba naa ju akoko yii lọ nitori iyatọ ti ba ofin ere bọọlu nisin yii.
Ní ọjọ́ karun-un, Ṣelumieli ọmọ Suriṣadai, olórí ẹ̀yà Simeoni mú ọrẹ tirẹ̀ wa.
Ibadan Poly: Àwọn aláṣẹ ní kí àwọn akẹ́kọ̀ọ́ fún ìsìnmi nítorí jàgídíjàgan
O ti se ọmọ ẹkọsẹ ri lọdo baba kan to n ṣiṣẹ awọ Ọmọ ọdun mọkandinlogun ni nigbati Ọlọrun ti fi han pe yoo jẹ woli ti ilu yoo mọka O fi iṣẹ isowo silẹ lọdun 2000 láti fi araji sinu iṣẹ iranṣẹ.
Ṣugbọn bí ó bá fún ọ̀kan ninu àwọn iranṣẹ ní ẹ̀bùn lára ilẹ̀ rẹ̀, ilẹ̀ náà di tirẹ̀ títí di ọjọ́ tí yóo gba òmìnira; láti ọjọ́ náà ni ilẹ̀ náà yóo ti pada di ti ọba.
Ooni wa ni ibeerẹ ohun rẹrẹ ni Naijiria ni iṣẹlẹ yi jẹ fun ara ilu ati awọn ọlọpaa naa.
 lára awon omo rè ni káyòdé , abósèdé , ségún , dàpò àti sèsan .
Lati igba naa ni ọrọ laarin ajọ naa ati Fayose ti di ikun n dẹ dẹdẹ,dẹdẹ n dẹ ikun.
 Ẹwẹ, nigba to n sọrọ lori awọn ohun ti oṣiṣẹ eto ilera sọ, akọwe agba ileeṣẹ to n ri si eto ilera ni iha ila-oorun Cape Town, Thobile Mbengashe sọ pe ootọ ni."
Sọ pé èmi, OLUWA Ọlọrun ní n óo da àwọ̀n mi bò ó níṣojú ogunlọ́gọ̀ àwọn eniyan; wọn óo sì fi àwọ̀n mi wọ́ ọ sókè.
Oluranlọwọ naa nigba to n ba BBC sọrọ sọ wipe nise ni awọn ọlọpaa ti i bọọlẹ ninu ọkọ ayọkẹlẹ ti wọn fi n gbe Melaye kuro ni Abuja losi Lọkọja lati lọ jẹjọ.
Àwọn Ohun Àìmọ́ tí Ń Jáde Lára.
Iroyin kan salaye pe, ó ti to ọdun mẹtadunlogoji ti laasigbo ti n waye lori ọrọ ọba ilu naa.
apapọ ko ni fi akoko sofo lati forukọ awon minisita ti yoo baa se isẹ papo si
7% ninu ida ogorun, eyi ti adinku ti ba ti o ba fi maa di odun 2020.
Ademola ni o yanilẹnu pe lẹyin aṣẹ ẹgbẹ yii ni awọn akọroyin miran gbẹyin lọ sibi ipade Femi Fani Kayode naa.
"Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Hepatitis: A kò leè kóo nípa dídìmọ́ ara ẹni ""Lẹyin ti a ba ti ṣe ayẹyẹ igbeyawo wa ninu oṣu Kẹta, ilẹ America ya niyẹn o."
Jesu bá sọ fún obinrin náà pé, “Igbagbọ rẹ ti gbà ọ́ là.
Wọ́n rán marun-un pọ̀ ninu àwọn aṣọ títa náà, lẹ́yìn náà ó rán mẹfa yòókù pọ̀.
 Ó pín sí ọnà ọgọ ́ òrún .
Igba kẹsan niyi ti awọn ọba ni gbogbo ẹkun orilẹede Naijiria yoo se ipade gbogboogbo, lati jijoro lori itẹsiwaju orilẹede yii.
Kaduna ati Plateau naa ko gbẹhin bi wọn ti 'ṣe ni eeyab 138 ati 80 eeyan to ko arun naa.
Ijọba Ghana ni wọn yoo gbe awọn afurasi naa lọ sile ẹjọ bi wọn ṣe n tẹwsiwaju ninu iṣẹ iwadii wọn.
Awọn amofin agba, SAN ti yoo lewaju ikọ rẹ ni Onyeachi Ikpeazu SAN, N.
Sibẹ wọn a máa hùwà ìgbéraga, wọn kìí sìí pa òfin rẹ mọ́, kàkà bẹ́ẹ̀ wọn a máa ṣẹ̀ sí òfin rẹ, tí ó jẹ́ pé bí eniyan bá pamọ́, ẹni náà yóo yè.
 Àwọn ipa mìíràn ni : ìráàyè sí omi tómọ ́ gaara àti sísẹ ́ omi bí kò bámọ ́ ́ .
Ọ ̀ kan pàtàkì lára àwọn èdè orílẹ ̀ èdè nàìjíríà ni èdè yorùbá .
"O ni: ""awa ọlọpaa ẹkun yii lo ṣokunfa bi wọn ṣe ri awọn eniyan yii gbe ṣugbọn a ko mọ nipa owo itanran rara""."
Opọ gba pe ti polongo ibo wọn pẹlu oniruuru agbọ-pọnula ileri fun araalu ba ti pari, ọpọ igba ni awọn oloṣelu kii boju wo ẹyin mọ titi di igba ti ọdun mẹrin miran ba ti pe ti wọn tun nilo ibo araalu.
Mo ti rán Tukikọsi lọ sí Efesu.
bí a ba wọ ilé àwọn babaláwo , a ó ri i wí pé ère Èsù kìí wọ ́ n nibẹ ̀ .
" Saraki, má gbé adé wa lọ sí ilé onílé - Oshiomole Irú ẹ̀dá wo ni aṣòfin Bukola Saraki jẹ́?
Ọgagun Olusegun Obasanjo, to pada di aarẹ Naijiria lo lewaju awọn ọmọ ogun to kọlu wọn.
Loju ti wọn, wọn gba pe ko yẹ ki ẹsun ifipabanilopọ jade ni ile ijọ Olorun rara.
Damilọla Ajayi: Ọ̀dá owó ló ṣún mi dé ìdí lílo ìyarun bíi fèrè
Kí ló wà ní ìdí igbá tí àwọn olorì Aláàfin máa ń tí lóde Ọ̀yọ̀ Lórí ọ̀rọ̀ àwọn ìbejì mí tí wọ́n jí gbé, ṣe ni mo finúwénú tí wọ́n fún mi ní iwọ jẹ-Akeugbagold Kíni ìjọba ń ṣe lórí ewu ẹkọ Almajiri àti covid 19 ní Nàìjíríà?
Tí a fiṣọwọ́ ní 6:196:19 Ìdí rèé tí mo fi yan ikọ̀ PMS rọ́pò NURTW nípìnlẹ̀ Oyo - Seyi Makinde Gomina Seyi Makinde ṣalaye idi to ṣe rọpo ẹgbẹ awakọ, NURTW to ti wa fun ọpọlọpọ ọdun.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Isreal Adesanya fàgbàhàn Kelvin Gastelum ni Atlanta 14 Ìgbé 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, A ju ra wa lọ , ijakadi nikan kọ Ninu idije oni ipele marun un ni Isreal Adesanya ti gbo ewuro soju Kelvin Gastelum.
Ṣugbọn lẹyin pe gbogbo nkan to n jade lati ọdọ awọn ti ọrọ kan fihan pe irọ to jina si ootọ ni iroyin ẹlẹjẹ naa; sibẹsibẹ ayelujara ti kun fun oriṣiriṣi aworan ati akọle to fihan pe apanilẹrin ni awọn eniyan Naijiria.
Bakanaa lawọn ololufẹ ẹgbẹ agbabọọlu Arsenal tun nse afiwe Wenger pẹlu aarẹ orilẹede Zimbabwe ti wọn yọ nipo laipk yii, Robert Mugabe.
Ai ni ìtẹ́lọ́rùn lè fà ikú ójiji nitori àìsàn ẹ̀jẹ̀-riru, irònú, ijiyà iṣẹ́ ibi, olè jijà, ija, gbigbé oògùn olóró, èrú ṣi ṣe,  àti bẹ́ẹ̀-bẹ́ẹ̀ lọ.
Àwọn ìlú tí ó wà ní ilẹ̀ náà ni: Jẹriko, Beti Hogila, Emeki Kesisi; 
Nígbà tí ó bá di ọjọ́ ajinde, iyawo ta ni obinrin yìí yóo jẹ́, nígbà tí ó jẹ́ pé àwọn mejeeje ni ó ti fi ṣe aya?
Tinubu sọrọ loju opo Twitter rẹ pe oun ko mọ ẹgbẹ naa ri, o ni pe wọn n ṣe ohun to wu wọn nitori oun ko ran wọn niṣẹ.
Máà se àyẹ̀wò ìṣàkóso Fayose - Fayẹmi ''Fayose yóò lọ ilé ẹjọ́ Supreme 'torí owó rẹ̀ Fayoṣe figbe ta pé wọ́n fẹ́ gbẹ̀mí òun O tẹsiwaju pe ijọba Fayose ko da bi Fayẹmi ti eru n ba lati koju igbimọ iwadi lẹyin to pari saa rẹ gẹgẹ bi Gomina.
Ninu atẹjade ti orilẹede Amerika fi lede, lati ọjọ kọkandinlọgbọn, Osu Kẹjọ ni afikun owo yoo ba iye owo ti awọn ọmọ Naijiria n san lati wọ ilẹ Amerika.
 Ó wọ ́ pọ ̀ ní ibi oorùn àwọn agbègbè gúúsù amẹ ́ ríkà àti Áfíríkà , ṣùgbọ ́ n kìíṣe ní Áṣíà .
Bi a ba fi koko pataki yii sọkan yoo jẹ ki a mọ bi nkan yoo ṣe lọ ninu idbo tọdun yii.
Bí ó bá sì jẹ́ obinrin ni, bákan náà ni kí ẹ ṣe fún un.
Àkọlé àwòrán, Caracas, Venezuela Ifiyajẹni Mo ti gbọ awọn ti wọn fi awọn nkan to lewu ba lo pọ pẹlu ipa.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Olópàá Nàíjíríà: A ti rí owó NNPC tí wọ́n kó sílé ìfowópamọ́ 13 Èbibi 2018 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 21 Owewe 2018 Oríṣun àwòrán, NNPC Àkọlé àwòrán, Mallam Kyari ni ọ̀gá àgbà fún ẹ̀ka tó ń rí sí káràkátà epo rọ̀bì ní àjọ NNPC Ajọ ọlọpaa ni orilẹ-ede Naijira ni awọn ti ri owó to le ni aadọrinlenirinwo billiọnu dọla to jẹ ti Ajọ Eleto Bẹntirol Lorile-ede Naijiria, NNPC.
Ẹwẹ, ẹgbẹ agbabọọlu Manchester United ti dero Europa League bayiilẹyin ti wọn ta ọmi alayo kọọkan pẹlu Huddersfield Town.
O fi kun ọrọ rẹ pe ijọba kan ti ọwọ bọ ọrọ naa ni, awọn ọba llu lbadan ko ṣetan lati gbe ade wọn silẹ.
Nítorí náà, Saulu wí fún un pé kí ó dáwọ́ dúró.
Papa isẹre to wa niluu Istanbul lorilẹede Turkey ni ifẹsẹwọnsẹ yoo ti waye.
30 Òkùdu 2018 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 15 Agẹmo 2018 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, England àti Croatia; ipade tun di ọdún míràn!
Bẹ́ẹ̀ ni kí ni gbòǹgbò ìgbéga ayé pátápátá?
Ní nǹkan bíi ọdún-un 1870 ni a kọ́ ilé náà tí ó fẹ́ẹ́ dà bíi ọkọ̀ ojú-omi, tí àwọn ọmọ ìbílẹ̀ ń pè ní “Jahaj Bari”, òun sì ni ilé àyágbé àkọ́kọ́ ni olú-ìlúu Bangladesh.
Lara ǹkan ti àwọn ọmọ Nàìjíríà ń sọ n rèé lójú òpó twitter wọ́n.
 Okonjo-Iweala ti sise pelu ile-ise Lazard Ltd, ile-ise to n mojuto oro isuna lagbaye, lọdun 2015.
Oríṣun àwòrán, MUHAMMADU BUHARI/TWITTER Àkọlé àwòrán, Muhammadu Buhari se ipade pelu awon eniyan lati Benue Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Nígbà tí wọ́n bá jáde sí wa láti bá wa jà bí i ti àkọ́kọ́, a óo sá fún wọn.
Sunday Igboho gba àwọn èèyàn Soka n‘Ibadan sílẹ̀ lọ́wọ́ àwọn ọmọ onílẹ̀ tó wá ṣọṣẹ́ Àwọn ọmọ onílẹ̀ lọ ṣe àmúṣẹ àṣẹ iléẹjọ́ ní Soka, làwọn ‘Jàǹdùkú’ fi dá wọn lọ̀nà - Iléeṣẹ́ ọlọ́pàá Ọyọ Lórí ìmọ̀ràn Sunday Igboho, Ẹlẹbubọn ní yóò dára kí Yorùbá padà sí àmúlò èròjà ìbílẹ̀ fún ààbò Amọ o daju pe Igboho ni awọn eeyan kan lọkan to n tahun si ninu fidi o.
nítorí náà OLUWA wí pé àwọn ọmọbinrin Selofehadi ní ẹ̀tọ́ láti fẹ́ ẹnikẹ́ni tí ó wù wọ́n, ṣugbọn ó gbọdọ̀ jẹ́ láti inú ẹ̀yà wọn.
 Iṣẹ ranṣọranṣọ ni iṣẹ Oluwatobi to si ni o wu oun lati kọkọ simẹdọ foju si iṣẹ ọhun daadaa na ki o to da kun bukata rẹ."
Ẹda fidio naa ti ileeṣẹ mohunmaworan ESAT TV fi han lai ṣe ayẹwo boya otitọ ni tabi ayederu, jẹ eyi ti wọn ti tọwọ bọ ti wọn si gbe agbasilẹ ohun awọn eeyan kan ti wọn pe ni awọn ọdọ ẹya Oromo ti wọn n pariwo le ori ohun tootọ to ba fidio naa jade.
Alaga awọn dokita naa, to ba BBC sọrọ, Dokita Oluwajimi Sodipo ṣalaye pe ọrọ aabo fawọn dokita to n tọju awọn alaarun covid-19, atawọn ajẹmọnu kan to fi mọ iyatọ to wa laarin awọn dokita to n ṣiṣẹ lawọn ile iwosan ijọba apapọ lawọn fẹ ki ijọba ipinlẹ Eko nkan ṣe si i.
“Igbimo mejeeji si gboriyin fun ilosiwaju lori gbigbogun ti iko olote boko haram, bee si ni won tun so ni pato bi ikolu omo ogun olote se n peleke si.
Àwọn eniyan tí ó jọba lé lórí pọ̀ tóbẹ́ẹ̀ tí wọn kò ní òǹkà; sibẹ, àwọn ìran tí ó bá dé lẹ́yìn kò ní máa yọ̀ nítorí rẹ̀.
Ṣugbọn igbesẹ to gbe lati gba ileeṣẹ alamojuto onkọrin to fi ilu London ṣebugbe, Dayo Adekunle Olomu, D.
O ni ṣe ni awọn to ma n pa wọn yii ma n po nkan pọ mọ ẹran ti wọn ti pa silẹ ati igbẹ wọn lati fa oju awọn Igunugun mọra ki wọn lee wa jẹ.
”Won yoo maa gbadura fun orile ede yii ati awon adari ni gbogbo ipele ijoba lojo Eti ni gbogan Mosalasi to wa niluu Abuja.
Iwadii BBC fihan pe ilana tuntun wọn yii ko sọrọ lori owo to ti wọnu MMM tẹlẹ ati ọna ti eeyan le fi rii gba pada.
Oríṣun àwòrán, Instagram/Tope Alabi O fikun pe o to ọdun meji ti oun ko ti lọ sile ijọsin Ajanaku mọ, ki ojisẹ Ọlọrun naa to jade laye pẹlu afikun pe, gbogbo aye gan lo mọ pe aarin oun ati Ajanaku ko gun mọ ki onitọun to jade laye.
Òun ni ìyàwó àfẹ́kẹ́yìn foún Orímóògùnjẹ́.
Ṣàánú wa, OLUWA, ṣàánú wa,ẹ̀gàn yìí ti pọ̀ jù!
Wo bí ètò ìsìnkú Tolulope Arotilẹ yóò ṣe lọ nílùú Abuja lọ́sẹ̀ tó ń bọ̀ Lizzy Anjori ṣèyàwó, àwọn òṣèré púpọ̀ ṣọjọ́ ìbí f'ọ́mọ lọ́sẹ̀ yìí 'Coro' wà 'Coro' ò sí o, èmi á lọ́ sókè òkún bí mo bá ríṣẹ́ - dókítà Nínú èèyàn 600 tó ní coronavirus lọ́jọ́ Ẹtì, 275 ló wá láti agbègbè ilẹ̀ Yorùbá Oríṣun àwòrán, Topealabi Oríṣun àwòrán, Topealabi Gẹgẹ bi a ṣe gbọ, lara eto ti wọn tun la kalẹ fun ayyẹ naa ni pe ajọ ti Ibidunni da silẹ ko to lọ iyẹn Ibidunni Ighodalo Foundation yoo ṣe onigbọwọ fun lọkọlaya ogoji tii ṣe dede iye ọdun to pe, lati lọ ṣe ayẹwo ati itọju iṣoro ibimọ.
Ẹni tí ó jókòó tí ó ń jẹun ni, tabi ẹni tí ó ń ṣe iranṣẹ?
Abiyamọ ni mi sùgbọ́n mo pa òbí àwọn ọmọ ọlọ́mọ lásìkò ìpìniyàn abéle Rwanda Kí ló ṣokùnfà afárá tó já tó pa ènìyàn kan ní Ilorin?
Ibatan rẹ ni iyawo akọkọ, Fatima.
N kò yàtọ̀ sí ẹni tí a pa tì sí apá kan láàrin àwọn òkú,mo dàbí ẹni tí a pa, tí ó sùn ninu ibojì,bí àwọn tí ìwọ kò ranti mọ́,nítorí pé wọ́n ti kúrò lábẹ́ ìtọ́jú rẹ.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, O kọ lẹta naa lẹyin ti Ọbasanjọ kọ lẹta kan si aarẹ tẹlẹ ni Naijiria, Goodluck Jonathan, lati bu ẹnu ẹtẹ lu iṣakoso rẹ.
Aare yoo tun maa lo anfaani naa lati ri arabinrin Fatou Bensouda to tun je agbejoro fun ajo ICC.
Ṣugbọn eyi ko tumọ si iyanṣẹlodi.
"''Ikú Abraham dùnmí jọjọ"" Baba Abraham, Asòfin Badru ní, ""ọmọ jẹ́ẹ́jẹ́, tó gbọ́ràn ni Abraham, tí kìí se ojo."
83 trillion tí Buhari gbé kalẹ̀ 19 Ọ̀pẹ̀̀ 2018 Oríṣun àwòrán, Bashir Ahmad Àkọlé àwòrán, Aarẹ Buhari ni abadofin oju awo lawo fi n gbọbẹ lawọn fẹ fi eto iṣuna ọdun 2019 ṣe Aarẹ muhammadu Buhari ti gbe abadofin iṣuna fun ọdun 2019 jade, o si ti gbe e kalẹ siwaju awọn aṣofin apapọ.
Wọ́n gé orí Saulu, wọ́n sì bọ́ ihamọra rẹ̀, wọ́n ranṣẹ lọ sí gbogbo ilẹ̀ Filistini, pé kí wọ́n kéde ìròyìn ayọ̀ náà fún gbogbo eniyan ati ní gbogbo ilé oriṣa wọn.
Tabi awọn igbo kijikiji ati igi gogogro to yi ọgba ile ọjọgbọn ka.
5 1399911 Orilẹede Peru 36499 114.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Òkìkí ìwà ìmúnilẹ́rú lórílẹ̀èdè Libya ti kárí ayé.
Àwọn ọmọ-ẹ̀yìn náà bá lọ, wọ́n wọ inú ìlú, wọ́n rí ohun gbogbo bí Jesu ti sọ fún wọn; wọ́n sì tọ́jú gbogbo nǹkan fún àsè Ìrékọjá.
Ariwo iranṣẹ Ọlọrun kan lo kọkọ gba ori afẹfẹ kan, ninu fidio kan ti o ti npe fun awọn ọmọ ijọ ti yoo fi owo dọla ilẹ Amẹrika silẹ, gẹgẹ bii eso fun Ọlọrun.
A kì í tún ṣe ọmọ-ọwọ́ mọ́, tí ìgbì yóo máa bì sọ́tùn-ún, sósì, tabi tí afẹ́fẹ́ oríṣìíríṣìí ẹ̀kọ́ àrékérekè àwọn tí wọn ń lo ọgbọ́n-ẹ̀wẹ́ láti fi tan eniyan jẹ yóo máa fẹ́ káàkiri.
Nígbà tí a ti ṣe é ní àṣepé, ó wá di orísun ìgbàlà tí kò lópin fún gbogbo àwọn tí wọ́n bá gbà á gbọ́.
6 569205 Orilẹede Bolivia 9008 79.
Nígbà tí Olú olùṣọ́-aguntan bá dé, ẹ óo gba adé ògo tí kì í ṣá.
Ijọba gbe igbesẹ naa ni ibi ipade ajọ amuṣẹya ti ipinlẹ ọhun to waye ni Ọjọ Iṣẹgun, lẹyin ti wọn ti ileewe pa nitori ajakalẹ arun Coronavirus.
Igbimọ amuṣẹya ijọba ti wọn gbekalẹ lọdun 2016 ṣe iṣiro pe ẹgbẹrun mẹtala naira pere ni iye ti wọn yoo na lati fun ọmọ kọọkan ni gbogbo abẹrẹ ajẹsara to yẹ ki o gba.
Nígbà tí wọ́n wọ ààrin ìlú, Iṣimaeli ọmọ Netanaya ati àwọn tí wọ́n wà pẹlu rẹ̀ pa wọ́n, wọ́n sì kó òkú wọn dà sí inú kòtò.
Ní títóbi, ìlú Ìjẹ̀bú - Jẹ̀ṣà ni ó pọwọ́lé ìlú Iléṣà ilẹ̀ Ijẹ̀ṣà, òun si ni olú ìlú fún ìjọba ìbílẹ̀ Obòkun ọ́un kí wọn tó tún un pín sí ọ̀nà mẹ́rin; síbẹ̀ náà òun ni olú ìlú fún ìjọba ìbìlẹ́ ààrin gùngùn obòkun.
Gege bi dokita Onu se so, O ni, poku lowo kemika epo robi, bee si ni o tun je ore ayika, yoo si tun mu adinku ba owo epo lawujo.
Ọba kò gbọ́ ti àwọn eniyan náà, nítorí pé ọwọ́ Ọlọrun ni àyípadà yìí ti wá, kí ó lè mú ohun tí ó ní kí wolii Ahija, ará Ṣilo, sọ fún Jeroboamu, ọmọ Nebati, ṣẹ.
Eyi si ti n mu ki awọn onwoye kan atawọn ọmọ ilẹ Yoruba kan o maa beere pe ṣe o lẹtọ ki aarẹ ọna kakanfo o yan ijoye fu ara rẹ.
Ọgbọ́n ga jù fún òmùgọ̀,kì í lè lanu sọ̀rọ̀ láwùjọ.
osise won yoo lo, lasiko idibo gomina ati ile igbimo asofin ipinle .
milionu mefa nibi ipate oja imo ero ati ise atinuda fun odun 2019, ni eyi to
A maa mu ẹkunrẹrẹ iroyin naa wa fun yin ni kete tijọba ipinlẹ Eko ba ti tan sọ ero ọkan rẹ nipa isẹlẹ yii.
Eyi ni ifẹsẹwọnsẹ meji ti Liverpool yoo maa bori laarin ọjs mẹrin si arawọn lẹyin to fagba han Chelsea lati gba ife ẹyẹ Super cup ni ọjọru.
 A rọ aarẹ Buhari lati maṣe daabo bo Adesṣun gẹgẹ bii iṣe rẹ nigbakugba ti awsn eeyan to sun mọọ tabi jẹ oṣiṣẹ rẹ ba ti ko sinu ọgbun ẹsun iwa kotọ Oríṣun àwòrán, @HMKemiAdeosun Àkọlé àwòrán, PDP ni pupọ awọn ọmọ igbimọ iṣejọba Buhari lo ni ẹsun iwa ibajẹ lọrun wọn Ẹgbẹ oṣelu PDP ni ọọyẹ to la lori ọrọ yii ti fihan pe ootọ n bẹ ninu awọn ọrọ ti ẹgbẹ oṣelu naa ti sọ ṣaaju pe, ibuba awọn agbalọwọ meri ati ọlọṣa to fi mọ awọn ti iṣẹ ọwọ wọn ko mọ ni iṣejọba aarẹ Buhari.
bẹ́ẹ̀ ni òṣì yóo ṣe dé bá ọ bíi kí olè yọ sí eniyan,àìní yóo sì wọlé tọ̀ ọ́ bí ẹni tí ó di ihamọra ogun.
Bakan naa ,ni ajo EFCC tun ri gbo pe Akeju tun lowo ninu
Iroyin to tẹ wa lọ́wọ́ ni wi pe alẹ ọjọru lawọn ajinigbe ọhun ya wọ ilu Daura ti wọ́n si bẹrẹ si ni yinbọn sinu atẹgun, awọn araalu sa asala fun ẹmi wọn.
 Ile igbimo asofin wa ro ijoba lati mu adehun ti won se pelu egbe osise fafiti sẹ, ni eyi ti yoo fi dena awon iyanselodi ti o maa n sele lorile ede yii.
Ninu ọrọ tiẹ, igbakeji ọga ọlọpaa agba, DIG Leye Oyebade to n ṣakoso iwọ oorun gusu rọ awọn ọlọpaa lati wa lojufo, ki wọn si ri pe alaafia jọba pada nipinlẹ Oyo.
Oríṣun àwòrán, Google Ṣẹ ẹ ranti apejuwe ''Nigeria score Nigeria!
8 129922 Orilẹede Nepal 1948 6.
Orileede Poland ni yoo gbalejo idije naa loṣu kaarun ọdun 2019.
Ọlọrun ti pinnu pé ìparun óo bá Ahasaya nígbà tí ó bá lọ bẹ Joramu wò.
Àwọn ohun tó yẹ́ kí o mọ̀ nípa Ọ̀gá DSS tuntun Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ọ̀rọ̀ Imam yìí ṣe kòńgẹ́ bó ti ń rí láàrin lọ́kọ láya Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
O si jina si pe wọn ti bori ikọ naa.
Wọ́n kọ OLUWA sílẹ̀, wọ́n gbójú kúrò lára ibùgbé rẹ̀, wọ́n sì kẹ̀yìn sí i.
Joẹli, ati Jehu, ọmọ Joṣibaya, ọmọ Seraaya, ọmọ Asieli.
Ajọ̀ to n ri si eto igbohunsafẹfẹ lorilẹ-ede Naijiria ni, bi gomina ipinlẹ Ekiti, Ayọdele Fayose se n kede awọn esi ibo ti ajọ eleto idibo ko fọwọ si, lo mu ki oun gbe igbesẹ naa.
Ojo ikini ku oriire ti n rọ lori ikọ agbabọọlu Flying Eagles naijiria lẹyin ti wọn pegede lati kopa ninu idije bọọlu agbaye fawọn agbabọọlu ti ọjọ ori wọn ko ju ogun ọdun lọ.
Ó fi agbára yìí hàn ninu Kristi nígbà tí ó jí i dìde ninu òkú, tí ó mú un jókòó ní ọwọ́ ọ̀tún rẹ̀ lọ́run.
Ojú àwọn mejeeji bá là, wọ́n sì mọ̀ pé ìhòòhò ni àwọn wà, wọ́n bá gán ewé ọ̀pọ̀tọ́ pọ̀, wọ́n sán an mọ́ ìdí.
Ile-ise International Breweries goke agba ninu ate ohun pelu N2.
“Fi igi akasia ṣe igi ìdábùú mẹẹdogun; marun-un fún àwọn àkànpọ̀ igi tí wọ́n wà ní ẹ̀gbẹ́ kinni àgọ́ náà, 
Koda Hazard lo gba ẹlẹsẹ ayo fun oṣu kẹsan an ninu idije Premier League yii.
Ida ọgọta ero nikan ni wọn yoo maa gbe sinu ọkọ wọn.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Àkókò tó láti gbẹ̀san lára ẹ̀fọ̀n mùjẹ̀mùjẹ̀ 20 Ìgbé 2018 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Àwọn eleyinju àánú ń gbèrò láti ṣe àgbékalẹ̀ dollar bilionu mẹta lé díẹ̀ Ọ̀nà àbáyọ tuntun láti gbẹ̀san lára ẹ̀fọn mujemuje tí yọjú.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Èyí ni àwọn arẹwà ‘ẹ̀lẹ̀ Daddy’, àfẹ́fẹ́ tí Aláàfin fi ń mí Ìhòhò ọmọlúàbí ni mo má a ń bá àwọn ọmọkùnrin mi wí - Elesho Onyeama, jọ̀ọ́ má bínú ìdẹ́yẹsí tá a ṣe torí pé o jẹ́ adúláwọ̀ - Ilé ẹ̀kọ́ Eton Abiola Ajimobi kò gbọdọ̀ kú, ẹ lọ wọlé àdúrà - APC Oyo pariwo Àlààyé rèé lórí ìdí ta fi gbé ìlẹ̀kùn olú iléeṣẹ́ APC tì pa l‘Abuja Ohun tí ọlọ́pàá ń ṣe rèé láti sàwárí àwọn ‘mùjẹ̀-mùjẹ̀’ ní Akinyele Wo bí ìpinu Amẹ́ríkà lórí gbígba físà ṣe kan ọ́ Ajiboye ṣalaye pe ijọba ipinlẹ Ondo ko sọ pe Agboola Ajayi kii ṣe igbakeji gomina mọ, ṣugbọn iwa ọdalẹ ni igbakeji gomina ọhun wu, bo ṣe fi ẹgbẹ oṣelu APC silẹ.
Oríṣun àwòrán, Twitter/iam_wandeyinka Ogbomosho Shooting: Irọ́ ni pé a yìnbọ̀n lú olùwọ́de EndSars - Ọlọ́páà Oju opo Twitter n gbana jẹ lori iroyin to gbode pe awọn ọlọpaa yinbọn lu arakunrin oluwọde kan lọjọ Abamẹta.
Oríṣìíríṣìí ni ẹ̀bùn Ẹ̀mí Mímọ́ ṣugbọn láti ọ̀dọ̀ Ẹ̀mí kan náà ni wọ́n ti ń wá.
OLUWA sì ń lọ níwájú wọn ní ọ̀sán ninu ọ̀wọ̀n ìkùukùu láti máa fi ọ̀nà hàn wọ́n, ati ní òru, ninu ọ̀wọ̀n iná láti máa fún wọn ní ìmọ́lẹ̀ kí wọ́n lè máa rìn ní ọ̀sán ati ní òru.
Bí àrùn yìí bá bẹ̀rẹ̀ sí tàn káàkiri lára olúwarẹ̀, kí alufaa pè é ní aláìmọ́; àrùn ẹ̀tẹ̀ ni.
" Gẹgẹ bii ajọ NAFDAC ṣe sọ ninu awọn ẹya ara ẹja naa bii ẹdọ, ifun ati awọ ara rẹ ni awọn majele fara sinko si.
Wo bí o ṣe leè lo èròjà agbohùnsílẹ̀ tuntun tí Twitter gbé dé Toyin Ibietan: Àlòkù táyà ọkọ̀ ló mú mi rí nǹkan ṣe lásìkò ìgbélé COVID-19 Gómìnà márùn ún tó fojú winá ìbínú bàbá ìsàlẹ̀ wọ̀n O fikun un pe ni ipinlẹ Ondo, ẹgbẹ oṣelu APC naa n koju aigbọraẹniye pẹlu bi igbakeji gomina ati gomina ipinlẹ naa ṣe n figagbaga lori ẹni ti yoo dije dupo nibẹ, Eleyii ti o fihan pe igbakeji gomina naa ti yapa kuro ni ẹgbẹ oṣelu APC, amọ ti ko i tii fi lede ẹgbẹ oṣelu ti o ti fẹ dije dupo gomina.
Kò sí àjòjì darandaran kankan ní Nàìjíríà -NIS Àti lọ s'Amẹrika ti yàtọ̀ báàyí US Shut down: iṣẹ́ ń lọ ní Abuja àti Eko Àwọn Ọba aládé ni ẹkùn Yorùbá ti dé síbi àpérò náà O salaye pe o ṣeeṣẹ ki awọn ma ti ma sọ fun awọn eeyan to fẹ wa gba iwe yi pe irufẹ anfaani bayi wa ṣugbọn ni bayi,awọn yoo ma tẹ mọ wọn leti.
Ninu atẹjade kan ti ajọ naa fi sita ni alẹ ọjọ abamẹta ni eyi ti jẹyọ.
Ọgbẹni Gbenga Fayẹmi lati ẹgbẹ oṣelu PDP ni ẹgbẹrun mẹta-le-ọgbọn
Gbìyànjú àwọn òwé Yòrúbà yìí wò Pàtàkì June 12 fún Nàíjíríà Iṣẹ́ Kudirat Abiọla ṣì ń fọhùn síbẹ̀, lẹ́yìn ọdún 23 tó papòdà Ọ̀nà márún-ún láti mú àdínkù bá dátà (Data) lílò rẹ Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí kan sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
Bàbá Aláàfin ìlú Ọ̀yọ́, Elérúwà àti àwọn Ọba Ilẹ̀ Yorùbá míràn tí wọ́n rọ̀ lóyè Ẹ wo bí Hushpuppi ṣe farahàn nílé ẹjọ́ l'Amẹrika fún ìgbà àkọ́kọ́ láti jẹ́jọ́ O ni Nnkan bii iṣẹju marun un ṣeyin ni mo ṣẹṣẹ baba sọrọ lori awuyewuye pe wọn papopda, ṣugbọn ko si nnkan kan to ṣe baba, alaafia ni wọn wa."
A óò wá àwọn ọmọ ilẹ̀ Turkey mẹ́rin tí wọ́n jígbé rí láàyè- Ọlọ́pàá Kwara Ọmọ Isaac Adewọle gba ìdáǹdè lọ́wọ́ ajínigbé Àwọn ajínigbé bèèrè N20m fún ìyàwó ọba Ẹni orí yọ, ó dilé!
Àwọn Filistini bá kì í mọ́lẹ̀, wọ́n yọ ojú rẹ̀, wọ́n mú un wá sí ìlú Gasa, wọ́n sì fi ẹ̀wọ̀n idẹ dè é.
Ṣugbọn alufaa Adeboye awọn ti wọn ba ni ibẹru Ọlọrun ko ni ipin ninu aarun naa mọ.
N óo wẹ̀ wọ́n mọ́, wọn yóo máa jẹ́ eniyan mi, èmi náà óo sì jẹ́ Ọlọrun wọn.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Presidential Candidates: Ọ̀rọ̀kọ́rọ̀ ni àbọ̀ EU lóri ìbò 2019 25 Òkùdu 2019 Àkọlé àwòrán, Ṣe ejò kò lọ́wọ́nú báyìí 60 oludíje dupò ààrẹ tako Atiku Olùdíje dupò ààrẹ to tó ọgọta nínú ìdìbò gbogboogbò ọdun 2019 ti bu ẹnu àtẹ lu ẹgbẹ́ òṣèlú People's Democratic Party, PDP, àti olùdije lábẹ́ àsíá ẹgbẹ́ náà, Atiku Abubakar, lóri ọ̀rọ̀ awuyewuye to n waye nipa oju òpó ayélujára àjọ elétò ìdìbò, èyí ti wọ́n sàpèjúwe pé, ọ̀rọ̀ ti kò nílári ni.
Bidemi Kosoko Oríṣun àwòrán, bidemi_kosoko Ile to kun fun awọn oṣere ni Bidemi Kosoko ti ṣẹ wa.
Ohun ni yoo mojuto eto idibo ti ikede ẹni to ba jawe olubori yoo si tẹnu rẹ jade ninu idibo ti yoo waye lọjọ Keje osu Kejila ọdun yi.
O ni awọn yoo kọkọ wo bi nnkan yoo ṣe lọ si lẹyin eto idanwo aṣekagba girama WASSCE ati JSSCE to n lọ lọwọ ba ṣe waye.
83 trillion kalẹ̀ Wo ǹkan mẹ́jọ tó yẹ kóo mọ̀ nípa Alex Badeh táwọn agbébọn pa Ekiti: Alágá ìjọba ìbílẹ̀ 16 gbàwé ìdádúró Aarẹ Buhari ni lootọ oun yoo ṣi gbe abadofin ranṣẹ sawọn aṣofin apapọ lori ilana owo oṣu tuntun fawọn oṣiṣẹ ṣugbọn nitori ati yago fun wahala ti o lee fẹ waye lori ipese owo fun ilana owo oṣu tuntun naa ni oun fi tete fi sinu abadofin iṣuna ọdun 2019.
"Wọn gbe ohun ija dáni, bi mo ṣe ń baa yín sọ̀rọ̀ yìí, ènìyàn mẹ́rin lo wa ni ile ìwòsàn yàtọ si àwọn ti ibọn ba "" Ó di dandan, à ó gbe ìgbésẹ̀ to nipọn, kàkà ki wọn dá ààbò bò wá, òun ṣe lòdi si wa."
Ṣugbọn a kò ka àwọn ẹ̀yà Lefi mọ́ àwọn ọmọ Israẹli, gẹ́gẹ́ bí àṣẹ tí OLUWA pa fún Mose.
Aarẹ Trump ti fọwọ sọya pe oun ni aarẹ to ṣe fun awọn alawọdudu to ti di ọmọ Amẹrika daadaa ninu itan paapaa lori ọrọ iṣẹ.
Oju opo ayelujara kan to maa n ṣe afihan fidio ibalopọ, Porn Hub, lo fi iroyin yii sita loju opo rẹ pe l'ọdun 2019, awọn ọmọ orilẹ-ede Naijiria lo wo fidio ibalopọ julọ lọdọọ wọn.
 Ewe, ti a ko ba gbagbe ni opin ose to koja ninu idije EPL, Liverpool dana iya fun iko agbaboolu Southampton ti Arsenal si fi aperin egbo diya loole fun iko agbaboolu Burnley pelu ami-ayo meji sookan.
Babatunde Faṣọla SAN Oríṣun àwòrán, @tundefashola Ni ọjọ kejidinlọgbọn ọdun 1963 ni wọn bi Babatunde Raji Faṣọla ni ilu Eko.
Wọ́n Gbé Àpótí Ẹ̀rí Wá sí inú Tẹmpili.
Lasiko awẹ yii, wọn ko gbọdọ jẹ ohunkohun to ba wa lati ara ẹranko.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ara: Láti kékeré ni mo ti ń lu ìlú pẹ̀lú ayọ̀ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Ara: Láti kékeré ni mo ti ń lu ìlú pẹ̀lú ayọ̀ 12 Owewe 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 16 Òkùdu 2020 Emi gangan ni Àrà -Aralola.
Ọmọde olorin, FJ Akinmurele to jẹ ẹni ọdun meje, lo jẹ ki Beyonce mọ arabinrin naa ati bi o ṣe darapọ mọ ṣiṣe awo orin tuntun ti Beyonce gbe jade.
” tí o kò sì ní gba olúwarẹ̀ sílẹ̀?
Premier League: Arsenal àti Man U dèrò Europa League
O ni awon  osisẹ yoo bẹrẹ si maa maa ẹkunwo owo  osu yii ni osu kárùn ún  ọdun  yii lati fi se ayẹyẹ ajọdun awon osise ti yoo
Mercy ló gbadé BBNaija ọdún 2019 Háà!
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Babcock Sex Video: Láti ìgbà tí fásitì ti lé àkẹ́kọ̀ọ́ náà ló ti dùbúlẹ̀ àìsàn amọ́ ara rẹ́ ti dá 20 Bélú 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 30 Agẹmo 2020 Oríṣun àwòrán, Babcock/Twitter Arabinrin akẹkọọ fasiti Babcock ti fidio ibalopọ rẹ pẹlu ọrẹkunrin rẹ lu sori ayelujara ni ọdun sẹyin yoo lọ kawe si ileẹkọ fasiti loke okun.
Àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ lọ jí i, wọ́n ní, “Olùkọ́ni, o kò tilẹ̀ bìkítà bí a bá ṣègbé sinu omi!
Ṣugbọn láti ọ̀dọ̀ Ọlọrun ni a ti ní gbogbo nǹkan ní ànító.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Chris Oyakhilome: Wọn tí fòfin de iléeṣẹ́ ìròyìn Chris Oyakhilome lẹ́yìn tó sọ pé 5G lọ ṣokùnfà Coronavirus 9 Ẹrẹ̀nà 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 18 Èbibi 2020 Oríṣun àwòrán, @lwsat Ijọba ilẹ gẹẹsi ti fofin de ileeṣẹ igbohunsafẹfẹ oluṣoagutan ijọ Christ Embassy, pasitọ Chris Oyakhilome lẹyin ti wọn fẹsun kan pasitọ naa pe o n waasu tako ilana ofin wọn.
Awọn idile Osu yii si ni idẹyẹsi wọn ma n pọju nitori orisa ti wọn ti fi awọn baba nla wọn rubọ si, ti wọn si n ṣe ẹru fun un.
Àmọ́ o, àwọn ilé itaja kan to ba ofin mu ti n faaye gba àwọn onibaara wọn lati fi owó Bitcoin ra ọja, tabi san owó fún iṣẹ́.
Ṣugbọn ẹni tí ó bá forí tì í títí dé òpin, òun ni a óo gbà là.
Isiraya sì bí ọmọ mẹrin: Mikaeli, Ọbadaya, Joẹli, ati Iṣaya; wọ́n di marun-un, àwọn maraarun ni wọ́n sì jẹ́ ìjòyè.
Ní ọdun tọ kọja, àwọn ènìyàn Finland ní inú wọn dùn julọ ni gbogbo àgbáyé, bàká náà ni inú àwọn àtìpó ibẹ̀ ló dùn jùlọ.
OLUWA Ọlọrun rẹ̀ wà pẹlu rẹ̀.
 kò sí abẹ ́ rẹ ́ -àjẹsára fún hepatitis c .
OLUWA sọ fún Jeremaya nígbà tí ó wà ní àtìmọ́lé ní gbọ̀ngàn àwọn tí wọn ń ṣọ́ ààfin ọba, pé, 
Kí ẹni tí ń jẹran má fi ojú tẹmbẹlu ẹni tí kì í jẹ.
Èmi kìí ṣe ọmọ eléégún ṣùgbọ́n mò ń pe kísà sí ẹ̀ṣà- Òkòtò akéwì Òkè Ìyámàpó ní ìlú Ìgbẹ́tì Alagba Ọjẹdele Adebayọ to jẹ alamojuto adagun odo Sogidi ni Aawẹ pa itan bi odo yii ṣe jẹ.
 ogójì aṣojú ni ó wà ní ilé ìgbìmọ ̀ aṣòfin , méjì láti ìjọba ìbílẹ ̀ kọ ̀ ọ ̀ kan ní Ìlú Èkó .
“Bí ẹnìkan ninu yín, tí ó jẹ́ arakunrin yín, bá jẹ́ talaka, tí ó sì wà ninu ọ̀kan ninu àwọn ìlú tí ó wà ninu ilẹ̀ tí OLUWA Ọlọrun yín fun yín, ẹ kò gbọdọ̀ dijú sí i, bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò gbọdọ̀ háwọ́ sí arakunrin yín tí ó jẹ́ talaka yìí.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Awọn ọmọbinrin Dapchi de s'Abuja, funpade pẹlu Aarẹ Buhari 22 Ẹrẹ̀nà 2018 Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ọmọbinrin Dapchi: Mi o lọ sile iwe mọ Ni bayi, awọn ọmọbinrin ile-iwe ti awọn Boko Haram tu silẹ ni Dapchi, nipinlẹ Yobe ti wa ni'lu Abuja lati pade Aarẹ Muhammadu Buhari.
Ọmọ Naijiria ni mi, agbẹjọro ni mi, àgbẹ̀ ni mi, emi kii se ọlẹ.
Ẹni tí yóo fọwọ́ kan ẹ̀gún gbọdọ̀ lo ohun èlò tí a fi irin ṣe tabi igi ọ̀kọ̀,láti fi wọ́n jóná patapata.
Pẹlu ibinu, ni mo fi fun yín ní àwọn ọba yín, ìrúnú ni mo sì fi mú wọn kúrò.
O tun jẹ ọkan pataki lara awọn ibi igbafẹ julọ ni ilẹ Adulawọ.
Àkọlé àwòrán, Kayode Fayemi ti ṣe gomina ipinlẹ Ekiti ri laarin Ọjọ kẹrindinlogun, osu kẹwaa, ọdun 2010 si ọjọ kẹẹdogun, osu kẹwaa, ọdun 2014.
Tẹgbọn-taburo se igbeyawo ni Anambra Mo kan wàhálà lálẹ ọjọ ìgbeyàwó torí ìbálé mi kò ṣe ẹ̀jẹ̀ - Ìyàwó ọ̀sìngín Ọ̀rọ̀ èmi àti Olorì Chanel Chin kò yé ara wa mọ́ nínú ilé- Oluwo Ta ni Sikiru Ayinde Agbéjélọlá Barrister?
Biodun Fatoyinbo: Mò ń gbé Busola Dakolo lọ ilé ẹjọ́
 A tilẹ ti fi awon kan
A si tun mọ ọ si ''Jẹlili'' nitori ipa to ko ninu ere rẹ ''Jẹlili''.
ipinnu aare Muhammadu Buhari, lati mu idagbasoke ba awon osise , ni eyi ti
Daurama lo bi awọn ọmọkunrin meje to pilẹ awọn ipinlẹ ẹya Hausa mejeeje - Bawo, Biram, Kano, Katsina, Zazzau, Gobir and Rano.
Kí àwọn olódodo máa ṣògo ninu ọlá;kí wọ́n máa kọrin ayọ̀ lórí ibùsùn wọn.
Àwọn ọmọ Israẹli bá yipada sí wọn, ìdààmú sì bá àwọn ọmọ Bẹnjamini nítorí wọ́n rí i pé ewu ńlá súnmọ́ tòsí.
Wo ọ̀nà àbáyọ sí bo ṣe ń han‘run Ọ̀làjú sọ àṣà nù, wò ó báwọn obìnrin ṣe ń wà ọkọ kiri lórí ayélujára Nínú akànṣẹ́ mẹ́ta ọmọ Nàìjíríà tó dáńtọ́ lágbàáyé, Yorùbá méjì wà nínu wọn Ọpọlọpọ ọmọ Naijiria lo fẹhọnu han lẹyin ti ajọ Amunawa lorilẹede Niajiria gbe owo le ina ọba, ti ẹkunwo naa si tun ba owo epo bẹntirol lasiko kan naa.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Isoro ipese isẹ fun awọn ọdọ kun ara ipeniuja iwaju aarẹ tuntun ni orilẹede South Africa Awọn ọgbun mẹrin naa.
Wo orílẹ́èdè tí wọ́n tí ń dáwó ìsìnkú ara wọn pámọ́ Olootu ijọba Japan tun sọ pe orilẹ-ede Japan yoo ṣatilẹyin fun Naijiria ninu eto idibo aarẹ igbimọ gbogboogbo ajọ iṣọkan agbaye ẹlẹẹkẹrinlelaadọrin iru rẹ.
Ẹ kí gbogbo àwọn aṣiwaju yín ati gbogbo àwọn onigbagbọ.
" A kò lọwọ́ sí ìwé ìpẹ̀jọ́ tó tako ìdásílẹ̀ ìgbìmò ìwádìí aṣemáṣe ikọ̀ SARS- ọlọ́pàá Nàìjíríà ''Abdulrasheed Maina yóò wà ní ọ̀gbà ẹ̀wọ̀n Kuje kó má ba tún sálọ'' Ṣé ẹ rántí àkọ́lé àwọn ìwé àkàgbádùn yìí?
Oríṣun àwòrán, Getty Images Ọkan pataki lara awọn to n pariwo lodi si alumajiri ni Emir atijọ fun ipinlẹ Kano ti Gomina Ganduje rọ loye, Lamido Sanusi Lamido.
nile-ise ogba ewon, paapaa julo lati tun fese ise rere, eto oniruuru to n
 Èyí lo ṣe okùnfa bíbá ọ ̀ pọ ̀ obìnrin pàdé ó ṣi fun ni àǹfáàní láti fẹ ìyàwó púpọ ̀ torí irúfẹ ́ isé ti ifá ń ṣe .
Awọn eroja yii lara awọn ọmọde maa n ṣiṣẹ ni kiakia ni; wọn a si maa jẹ iṣẹ kọja ibi ti wọn ba ran wọn de nigba miran.
Ìlànà tuntun yìí kìí ṣe láti mú kí nǹkan nira fún àwọn olókoòwò kéékèèké, sùgbọ́n láti mu ìdàgbàsókè bá wọn ni, yóò túbọ mú ki àwọn ti o ni nǹkan ṣe lé fa ojú àwọn oníbàárà wọ́n mọ́ra síi ni"" Ó ní ilé iṣẹ́ ìbáraẹnisọ̀rọ̀ àti ètò ọ̀rọ̀ ajé ló fún àwọn ni àsẹ fún ìlànà yìí, ti wọ́n si pee ni èyí to ṣe pàtàkì láti mójú tó, ki àwọn náà to gba láti kédé rẹ̀."
Saaju ojo naa ni baalu Ethiopia ti ko awọn  eniyan márùndínlọgọ́jọ wa si ilu Abuja ni ogunjọ osu keje.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù 2nd wave Coronavirus Update: England kéde ìséde ọ̀sẹ́ mẹ́rin níràn láti dẹ́kun ìtànkálẹ̀ Covid 19 1 Bélú 2020 Aṣoju ilẹ UK, Boris Johnson ti kede isede ẹlẹekeji ni England lati dẹkun itankalẹ ajakalẹ arun coronavirus.
Toyin Abraham Ara ọtọ ni ayẹyẹ ọdun keresi ọdun 2019 gba yọ lati ọdọ Toyin Abraham.
Lulu jẹ́wọ́ pé, òun gbé ìgbésẹ̀ ọ̀hún láti lé fi rú bàbá àti màmá rẹ̀, tó wà ní ìlú wọn ní Uganda, l'ójú ní, ṣùgbọ́n ó sọ pé, ayẹyẹ nàá ni ọ̀nà pàtàkì láti so òun àti ètò ẹ̀kọ́ rẹ̀ papọ̀.
Ọkọ baalu ile iṣẹ Aarẹ to gbe Buhari de balẹ si papakọ-ofurufu Nnamdi Azikiwe lalẹ ọjọ Satide l'Abuja.
Àwọn kọ́kọ́rọ́ àti agbára oyè àlùfáà ti Aarónì ni a fi lélẹ̀.
16 Bẹ́ẹ̀ni, mo wí fún ọ, kí ìwọ kí ó le mọ̀ pé kò sí ẹlòmíràn bí kò ṣe Ọlọ́run tí ó mọ àwọn èrò àti ète ọkàn rẹ.
Ṣugbọn boṣejẹ peko rọrun lati fidi erongba ọkunrin bẹ mulẹ nile ẹjọ, a jẹ pe o ku si ọwọ adajọ to fẹ ẹ gbọ ẹsun naa lati mọ bi yoo ṣe dajọ.
Ṣugbọn Ọjọgbọn Ihonvbere ṣalaye pe o kere tan eeyan to le lẹgbẹrun kan lo n larun naa lojoojumọ bayii ti ijọba paṣẹ pe kawọn akẹkọọ pada sile iwe lọjọ kejidinlogun oṣu kinni yii.
Iṣẹ́ ọwọ́ rẹ ni àwọn ọ̀run.
Leyin ti iko ohun fagbahan Connecticut lojo Eti(Friday) ninu ipele keji si asekagba idije naa, jijawe olubori lojo Aiku Sunday ninu asekagba idije naa je ohun iyalenu ti o si tun fitan bale ninu itan idije naa.
Wọn sare gbe e lọ si ile iwosan agba nilu Abuja sugbọn ẹpa ko boro mọ.
”Minisita fun oro epo rọbi ,Ogbeni  Gatkuoth,ni  gbogbo orile ede Afirika ni won ti n gbosuba fun aare Muhammadu Buhari nipa gudu-gudu meje  , yaya mefa to n ko lati gbokun ti iwa ibajẹ ati sise owo ilu kumo-kumo, o ni  eleyii lo mu ajo orile ede Afirika (African Union)  lati fi se asiwaju ninu gbigbokun ti iwa ibajẹ lorile ede Afirika.
Ninu gbogbo ipaniyan yii, ati ti iya mi, ko si ẹri wipe awọn ijọba n gbe igbesẹ kankan lati ran awọn to ṣiṣẹ naa lọ ẹwọn.
Wo àwọn tí Pondei fara jọ pẹ̀lú ààrẹ̀ níwájú ijẹ́jọ́ Wo àwọn òṣìṣẹ́ kólẹ̀-kódọ̀tí tó ń fi ẹ̀mí wọn wéwu kí Abuja leè mọ́ tónítóní Isa Funtua, Abba Kyari àti Zulaihat Buhari jẹ́ àwọn tó súnmọ́ Aàrẹ tó papòdà láìpẹ́ Ọkùnrin kan pa ara rẹ̀ sínú ọgbà àjọ TRACE tó n mójútọ ìrìnnà ọkọ̀ nípìnlẹ̀ Ogun Àwọn ìgba mẹ́rin t'áwọn èèkàn tí dùbúlẹ̀ àìsàn lásìkò tí wọ́n ń jẹ́jọ́ ìwà ìjẹkújẹ Ni ọjọ Aje, sinima awodamiẹnu kan ṣẹlẹ nibi ijoko iwadii itagbangba lori iṣuna ajọ idagbasoke agbegbe Niger Delta.
Ó ti pẹ́ tí irú ìṣẹ̀lẹ̀ ìjínigbé láti gba owó ní apá ìwọ̀ oòrùn ti máa ń sẹlẹ̀, sùgbọ́n irú èyí tó sẹ̀lẹ̀ ní Kaduna lọ́tẹ̀ yìí kò sẹlẹ̀ rí.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Omidan jáde láyé lẹ́yìn tí ìlú lù ú, jáa sí ìhòhò lórí ẹ̀ṣẹ̀ tí kò ṣẹ̀ Awọn ọmọde lee ko arun Coronavirus.
ile-eko won ati orile ede Naijiria, ki won si lo ọgbọn ati oye ti won ti kọ
Àwọn alufaa kò gbọdọ̀ sọ àwọn ohun mímọ́ àwọn eniyan Israẹli tí wọ́n fi ń rúbọ sí OLUWA di aláìmọ́.
Lapapapọ bayii eeyan 11516 ni ayẹwo fihan pe wọn ti ko arun yii lorilẹede Naijiria bayii.
Ninu atẹjade ti alukoro fun ajọ DSS, Ọmọwe Peter Afunanya fi sita lọjọ Aje, o ṣalaye pe iroyin ofege lawọn ileeṣẹ iroyin kan n gbe kiri lori ọrọ Magu Oríṣun àwòrán, Facebook/Ibrahim Magu Ọmọwe Afunanya sọ pe ajọ DSS fi atẹjade sita nitori ọpọ lo n pe wọn, lati mọ bo ya lootọọ ni wọn ti fi panpẹ ofin mu Magu.
Ko si idi meji gẹgẹ bi Ọba ilu Akurẹ ṣe sọ ju wi pe ni ọjọ Ẹti ni ayẹyẹ ọdun Amọle yoo waye nibẹ.
Ọ̀rọ̀ ìtàjẹ̀sílẹ̀ ní Nàìjíríà yìí tí ń kọ àwa Oṣo àti Àjẹ́ lóminú, a fẹ́ wa ǹkan ṣe síi Ìpànìyàn tún wáyé ní Akinyele, àwọn ará àdúgbò ṣe ìwọ́de Mọ̀ síi nípa Shina Rambo tó pàdé Jesu lọ́gbà ẹ̀wọn lẹ́yìn tó ti jalè Mi ò tí ì mọ obìnrin rí; kódà, mí ò ní 'Girlfriend'- Mr Macaroni Kọ́ńdọ̀mù tó bẹ́ gbé iléèṣẹ́ ìjọba àti aládáni kan dé ilé ẹjọ́ L'Ọjọbọ, ọjọ kẹtala, oṣu kẹjọ ni EFCC fi ẹsun onikoko kan ọmọkunrin naa pe purọ pe ara rẹ ni Ọgbẹni William Davis ti inagijẹ rẹ n jẹ Behemooth lati tan obinrin alawọfunfun kan jẹ lori ẹrọ ayelujara.
Lẹ́yìn náà, Joṣua pe àwọn ẹ̀yà Reubẹni ati ẹ̀yà Gadi ati ìdajì ẹ̀yà Manase, 
Ní ọjọ́ kẹrinla, wọ́n sinmi; ọjọ́ náà sì jẹ́ ọjọ́ àsè ati ayọ̀.
 iye owó tí a nílò láti dáàbò bo ara ẹni lọ ́ wọ ́ àrùn onígbáméjì jẹ ́ láàárín 0.
Lẹ́yìn tí ó parí ẹ̀kọ́ rẹ̀ ní ilé-ẹ̀kọ́ yìí ni ó kọjá sí Ìlaròó tí ó sì dá iṣẹ́ tẹ̀wétẹ̀wé sílẹ̀ ńbẹ̀ fúnrarẹ̀ ni ó ka ìwé gba ìwé-èrí G.
OLUWA pàṣẹ fún ọ̀kan ninu àwọn ọmọ ẹgbẹ́ wolii kan, pé kí ó sọ fún wolii ẹlẹgbẹ́ rẹ̀ kan pé kí ó jọ̀wọ́ kí ó lu òun, ṣugbọn wolii náà kọ̀, kò lù ú.
Eli mọ̀ pé wọ́n ń ṣe bẹ́ẹ̀ ṣugbọn kò dá wọn lẹ́kun.
8 Ọ̀wàrà 2020 Oríṣun àwòrán, Alamy Ìròyìn tó n tẹ́ BBC Yoruba lọ́wọ́ ni pé, àjọ LASEMA àti ilé isẹ́ panápana tí fòpin si jàmbá iná tó bẹ́ sílẹ̀ ní òwúrọ̀ òní ni agbègbè Ipaja ìpínlẹ̀ Eko.
Ilé ìgbìmọ̀ aṣòfin ikẹ̀jọ kógbá sílé l'Abuja Owó wọgbó!
Bakannaa ni wọn ni arakunrin to mu owo ọhun wa pẹlu ti poora lẹyẹ o sọka.
Daniel Lewis Lee, ẹni àkọ́kọ́ tí wọ́n yóò yẹgi fún ní US lẹ́yìn ìdádúró ọdún 17
Isele yii waye leyin osu meloo kan seyin, ti awon eniyan mokanlelogoji padanu-emi won ninu ijamba oko oju-irin kan ni ilu Alexandria ninu osu kejo odun to koja.
Ààrẹ Trump fi ofin de gbogbo irinajo ti ko ba ṣe koko lati ilẹ Yuroopu si America lọjọ kẹẹdogun, oṣu Kẹta.
Ògbójú ni wọ́n, ati onigbeeraga; wọn kò bẹ̀rù láti sọ ìsọkúsọ sí àwọn ogun ọ̀run.
Ó sì di àṣà ní ilẹ̀ Israẹli, 
Ẹni tí ó bá ń ka ọ̀rọ̀ àsọtẹ́lẹ̀ yìí ati àwọn tí ó bá ń gbọ́, tí wọ́n sì ń ṣe àwọn ohun tí a kọ, ṣe oríire.
O fi si oju opo twitter rẹ pe esi ayẹwo oun ti de ko si si ẹja n bakan kankan lori rẹ nitori ẹja lo ba de.
Sunday lo gbadura nibi ayeye naa a .
Nígbà tí Jehoṣafati bá àwọn eniyan rẹ̀ jíròrò tán, ó yan àwọn tí wọn yóo máa kọrin ìyìn sí OLUWA; tí wọn yóo wọ aṣọ mímọ́, tí wọn yóo sì máa yìn ín bí wọn yóo ti máa lọ níwájú ogun, wọn yóo máa kọrin pé,“Ẹ yin OLUWA!
Ní ọ̀gágun bá lọ bi Paulu, ó ní, “Wí kí n gbọ́, ọmọ-ìbílẹ̀ Romu ni ọ́?
"Ìdí rèé tí ilẹ̀ Afirika fi gbọdọ̀ kópa nínú dídán abẹ́rẹ́ coronavirus wò ""Ẹ̀wọ̀n gbére leè jẹ́ ìjìyà fún afipábánilòpọ̀ bí àwọn gómìnà ṣe dìde si"" Kíló fáà tí Póópù fi fẹnú ko ẹsẹ̀ àwọn olórí South Sudan?"
 Al Shabaab nikan ni ota ti a ni to n da wa laamu,”.
Nígbàtí ó n bá àwọn olólùfẹ́ rẹ̀ sọ̀rọ̀, Fáyẹmí ní gbogbo ìpínlẹ̀ Ekiti ló ní àṣeyọrí yìí.
Ẹni ẹ̀gàn ni mí láàrin gbogbo àwọn ọ̀tá mi,àwòsọkún ni mí fún àwọn aládùúgbò.
Àwọn ọmọ ogun Filistini kó ara wọn jọ sí Soko, ìlú kan ní ilẹ̀ Juda láti bá Israẹli jagun.
Ó sì kó àwọn ohun ọ̀ṣọ́ olówó iyebíye fún arakunrin rẹ̀ ati ìyá rẹ̀ pẹlu.
Ṣé nǹkan kékeré ni, pé Ọlọrun Israẹli yà yín sọ́tọ̀ láàrin àwọn ọmọ Israẹli láti máa ṣe iṣẹ́ ìsìn ninu Àgọ́ Àjọ OLUWA, ati fún ìjọ eniyan Israẹli?
 ní ìlú náà ẹrẹ ̀ ṣe ìdíwọ ́ fún àwọn jagunjagun Ọ ̀ yọ ́ ni wọ ́ n bá fi ń pe ìlú náà ni Ìjẹ ̀ bú - Ẹrẹ ̀ .
Lagos-49 FCT-34 Kaduna-34 Plateau-11 Oyo-7 Bayelsa-5 Taraba-4 Sokoto-1 Ẹgbẹrun mẹtadinlaadọrin o le ọtalelẹdẹgbẹta o din mẹta (67,557) eeyan lo ti ko aarun naa lorilẹede Naijiria lati igba ti wọn ti kẹẹfin ẹni akọkọ to laarun naa ni Naijiria ni oṣu keji ọdun 2020.
Olori gbogboogbo fun Ijọ Redeem Christian Church of God (RCCG) ni agbaye, Enoch Adeboye ti sọ wi pe ko si ohun to kan òun ninu didasi isejọba abẹlẹ ẹgbẹ oselu APC.
“Isakari dàbí kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ tí ó lágbáratí ó dùbúlẹ̀ láàrin gàárì ẹrù rẹ̀.
- Sanwoolu Ìjọba ìpínlẹ̀ Eko ti kéde orúkọ àwọn ọlọ́pàá tó fi ìyà jẹ àwọn olùwọ́de End Sars Toyin Abraham tú àṣírí ohun tí ọlọ́pàá Náìjíríà sọ mọ́lẹ́bí rẹ̀ kan dà Ìyá gómìnà Seyi Makinde dágbére fáyé lẹ́ni ọdún 81 Ṣugbọn awọn eeyan to n gbe ni agbegbe naa sọ pe isẹlẹ naa waye ni nnkan bii aago mejila abọ oru ọjọ Iṣẹgun.
Báwo ni àwọn kan yóo ṣe lọ kéde rẹ̀ láìjẹ́ pé a bá rán wọn lọ?
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Akomolede ati Aṣa lori BBC: Mọ̀ si nípa oríṣìí ẹ̀ka ìsọ̀rí ọ̀rọ̀ àti ìwúlò wọn Ki lo ti ṣelẹ sẹyin?
Ṣugbọn wọn kò lè máa bá irú ìwà bẹ́ẹ̀ lọ pẹ́ títí.
Alukoro ileesẹ ẹsọ oju popo nipinlẹ Ogun, Babatunde Akinbiyi salaye wipe, ina sẹyọ lara ọkọ agbepo ọhun ni kete ti ọkọ akẹru naa kọlu u.
Ọmọ Nàìjíríà yarí lórí àbá láti mójútó ayélujára, ilé aṣòfin láwọn ń tẹ̀síwájú lórí ẹ̀ Ọ̀nà kan ò wọjà fáwọn òṣèré tíátà, bí wọn ṣe ń ta ìpara ìbóra ni wọ́n ń ta aṣọ ẹbí Lisabi Agbongbo Akala rèé, ẹni tó fi ìfẹ́, ìṣọ̀kan àti ìrẹ́pọ̀ gba ilẹ̀ Ẹ̀gbá lọ́wọ́ ìmúnisìn Ẹ wo ìdí tí ẹ gbọdọ̀ fi gba abẹ́rẹ́ àjẹsára fún ọmọ yín!
Lara igbesẹ to si gbe naa ni fifi fofin de gbogbo ayẹyẹ aarin àdúgbò, kánífà òpín ọdún ati gbogbo ode faaji nitori ọwọja arun Coronavirus lẹẹkeji.
Ṣugbọn, awọn atọnisọna ere idaraya maa n gba awọn eniyan nimọran lati ma a bọ aṣọ ki wọn o to sun.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Taribo West: Agbábọ́ọ̀lù Nàìjíríà wọ gàu lọ́wọ́ ọmọ Náìjíríà lórí àsọtẹ́lẹ̀ pé Trump yóò wọlé ìbò ààrẹ Amerika 10 Bélú 2020 Oríṣun àwòrán, Taribo/twitter Taribo West wọ gàu lọ́wọ́ ọmọ Nàìjíríà lẹ́yìn tó sọtẹ́lẹ̀ pé Trump yóò wọlé ìbò ààrẹ Amerika.
Àwọn ni ọmọkunrin Manase, tíí ṣe ọmọ Josẹfu; wọ́n sì jẹ́ olórí fún àwọn ìdílé wọn.
 Igbimo Olubadan wa fi asiko naa ke si gbogbo  awon
Wọ́n fi ẹyin adìyẹ lé Ike Ekweremadu, kúrò níbi àṣeyẹ kan ní Germany
Nítorí pé ó fẹ́rẹ̀ kú nítorí iṣẹ́ Kristi.
Idi niyi ti a se gbodo se ara wa ni okan gege bi  osusu igbalẹ ati ri i pe gbogbo wa lowo si idagbasoke ipinle Ekiti.
Gẹgẹ bi iroyin ṣe sọ, ọlọkada naa ati obinrin ọhun n dunadura lori iye owo ni lasiko ti opo ina naa fi wo luwọn ni ina ara waya ori rẹ si pa wọn.
"obí yóò sọ irú ẹkọ ti oó kà ni ilé iwe gíga"" ""Wọ́n ko ni jẹ́ ki o mọ ìgbà ti o bá ń ṣe dáada ṣùgbọ́n wọ́n le sọ ǹkan ti wọ́n lérò pe o yẹ kí o maa ṣe."
Obìnrin Mùsùlùmí ṣe ilé àlúfà ní ọ̀ṣọ́ fún Kérésìmesì Àwọn gómìnà nílẹ̀ Yorùbá ti kùnà láti pèsè ààbò tó péye fún aráàlú - Ẹgbẹ́ Majeobaje Ọ̀fẹ́ ló bá dé, Boko Haram kọ́ ló jí akẹ́kọ̀ọ́ gbé, a kò san kọ́bọ̀ fún ìdáǹdè wọn - Masari Ṣé lóòtọ́ ni Bimpe Oyebade lóyún fún Lateef Oladimeji?
Ipa ti Boseman ko ninu sinima agbelewo to fọnrere agbara eeyan alawọ dudu ni, Black Panther lo sọ ọ di gbajugbaja.
    Lóòótọ́, àwọn ará ilé Wọ̀bìáparapọ̀ kó gbogbo àwọn obìnrin ilé Òmùgọ́dìran lọ sí ilé wọn, o sì de ọdún kan gbáko tí èyí ti sẹlẹ̀ gan-an ni èmi lọ kí Wèrédìran.
Bi eeyan ba fi ti wọn ṣe, ko ni fẹrẹẹ si ẹni ti yoo ba ara wọn ṣọrẹ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Dókítà yọ oyin mẹ́rin tó n gbé nínú ẹyinjú arábìnrin kán 10 Ìgbé 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Irufe awon oyin ti won feran ilaagun eniyan Arabinrin ọmọ ọdun mejidinlọgbọn kan ti wọn pé ni Ms He ni àwọn oyin mẹrin sọ ẹyinju rẹ di ibugbe.
Omoyele Sowore, ọmọ ọdun mẹ́tàdínláàdọ́ta to n du ipo Aarẹ lorileede Naijiria labẹ asia ẹgbẹ oselu African Action Congress (AAC) ni oludasilẹ ile iṣẹ iroyin naa.
Awa gan n fẹ idajọ to tọ, lọrọ ti agbẹjọro rẹ sọ.
Abegunde fi eyi lede ninu atẹjade kan to fi si oju opo ikansiraẹni Twitter rẹ.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, 'Mi o raaye to bi o ṣe yẹ nigba ti mo wa pẹlu ikọ Chelsea' Awọn agbabọọlu ni wọn maa n dibo lati yan ẹni ti wọn ba wo pe, o fakọyọ julọ laarin wọn.
N óo jẹ́ kí ó di igbó,ẹnikẹ́ni kò ní ro ó mọ́,wọn kò sì ní tọ́jú rẹ̀ mọ́.
tí kò bá mú un wá sí ẹnu ọ̀nà Àgọ́ Àjọ láti fi ṣe ẹ̀bùn fún OLUWA níwájú Àgọ́ mímọ́ rẹ̀, olúwarẹ̀ yóo jẹ̀bi ìtàjẹ̀sílẹ̀, ó ti ta ẹ̀jẹ̀ sílẹ̀, a óo sì yọ ọ́ kúrò láàrin àwọn eniyan rẹ̀.
Oladepo ni iku iyalọja naa ba wọn lọkan jẹ gidigidi, to si ba wọn lojiji.
Lara awọn to wo awokọṣe rẹ ni Apostle Sleman to nioun yoo san owo tikẹti eeyan ogun lati South Africa wa si Naijiria.
awon igbimo tuntutun naa, ti won je mẹ́rìndínlọ́gbọ̀n  sugbon awon ogun lo wa nibi ifilole naa.
Lizzy Anjorin vs Toyin Abraham: Wo àwọn òṣèré Tíátà t'ọ̀rọ̀ ìjà ta mọ́ etí aṣọ wọn tẹ́lẹ̀ rí
Ó sọ ọ́ di mímọ́ lẹ́yìn tí ó ti fi omi wẹ̀ ẹ́ nípa ọ̀rọ̀ iwaasu.
Ọsan oni, ni deede aago mejila ni ẹbi ara ati ọrẹ oloogbe Pius Adesanmi fẹ ṣeto isinku rẹ ni Ottawa, Ontario ni orilẹ-ede Canada.
"O ṣalaye pe igbesẹ naa ki yoo ni ipa kankan lara awọn ọmọ Naijiria, O ni ""kini anfaani adinku owo tí ko nipa lara awọn ara ilu."
Bí ó tilẹ̀ rí bẹ́ẹ̀ púpọ̀ nínú àwọn ìpín náà jẹ́ àwọn tí a darí wọn sí àwọn ọmọ Ìjọ Jésù Krístì ti Àwọn Ènìyàn mímọ́ Ọjọ́-ìkẹ̀hìn, àwọn ọ̀rọ̀ ìfiránṣẹ́, àwọn ìkìlọ̀, àti àwọn ìyànjú tí ó wà fún ire gbogbo aráyé ó sì jẹ́ ìpè sí gbogbo ènìyàn níbi gbogbo láti gbọ́ ohùn Olúwa Jésù Krístì, tí ó nsọ̀rọ̀ sí wọn fún wíwà ní àlàáfíà ti ara àti ìgbàlà ayérayé wọn.
”Lasiko to n gba asoju eka
Wákàtí mẹ́ta lo gbọ́dọ̀ ti dé pápákọ̀ òfúrufú bóo bá fẹ́ wọ bàlúù báyìí INEC yóò ṣàmúlò ẹ̀rọ ayélujára láti fi gba fọ́ọ̀mù àwọn olùdíje fún ìbò gómìnà Ondo àti Edo Ìtàn ìgbé ayé Isola Ogunsola 'I-sho Pepper', ògbóǹtagí òṣèré tíátà tó s'eré Yorùbá yíká Nàìjíríà Èyí ni ìdí tí Nàìjíríà kò fi ní f'òpin sí lílo hydroxychloroquine láì fi ìmọ̀ràn àjọ WHO ṣe Bẹẹ si ni ko si iṣẹ iwadii abi arigbamu ẹri kankan to fi idi rẹ mulẹ pe eroja nnkan osu obinrin lee wulo fun oogun owo.
Ṣugbọn ní tèmi, olùpọ́njú ati aláìní ni mí,yára wá sọ́dọ̀ mi, Ọlọrun!
O ni: o maa n yamilẹnu irufẹ ẹri ọkan ti awọn eniyan Naijiria ni, nigba ti iwọ ti o n sọ awọn eniyan sẹwọn ko tun le tẹle ofin.
Gbogbo àwọn ọkunrin tí a kà ninu wọn láti ọmọ oṣù kan sókè jẹ́ ẹgbaarin ó lé ẹgbẹta (8,600).
Ọjọ Satide ní àwọn mọ̀lẹ́bí rẹ̀ ní McCain pinnu láti máṣe gba ìtójú àìsàn jẹjẹrẹ mọ́ nítorí ọjọ́ orí rẹ̀.
Niyi Akintola, SAN - O yege 2.
Oríṣun àwòrán, Twitter/UEFA Champions League Àkọlé àwòrán, Idije Champions League ti saa 2019 Gbajugbaja agbabọọlu Brazil tẹlẹ ri, to tun figba kan gba bọọlu jẹun ni ikọ agbabọọlu Real Madrid ati Barcelona, Ronaldo de Lima sọ pe ko si ani-ani kankan pe Liverpool yoo gbẹyẹ lọwọ Tottenham pẹli ami ayo mẹta si ẹyọ kan.
Láti ọjọ́ tí obìnrin náà ti ṣe báyìí nu ó ti lọ wa ihò kan sí ààrin ilé tí ìwọ wà yìí, ó wa ihò náà ó jìn díẹ̀ ó sì gbé olúfẹ́ rẹ̀ tí mo bẹ́ lórí sínú rẹ̀.
Nigba to wa ni Man United, oun ni agbabọọlu to n gba owo ju lọ tii ṣe £400,000 lọsẹ.
”Amnoni dá a lóhùn pé, “Ìfẹ́ Tamari, àbúrò Absalomu, arakunrin mi, ni ó wọ̀ mí lọ́kàn tóbẹ́ẹ̀.
" Ipade ti aarẹ ṣe pẹlu Ọga Agba ọlọpaa waye lẹyin ọjọ meji ti awọn ọdọ bẹrẹ iwọde ojoojumọ lati ọjọru nipinlẹ Eko, ati awọn ipinlẹ miran ni Naijiria.
Boya ni wọn mọ wi pe adura wọn lẹyin ọjọ yii yoo kọja esi ayọ bikoṣe itusilẹ wọn kuro ninu ahamọ nitori ṣa dede ni awọn agbebọn kan lati ikọ boko haram ya wọ ileewe wọn ti wọn si ko awọn akẹkọbinrin ọrinlelugba o din mẹrin lọ.
Dokita onimọ ti sọ wi pe ki obinrin tete loyun , ki o si bimọ ni ọna abayọ si airọmọbi to le jẹyọ nitori nkan osu to kọ lati wa.
Jesu bi wọ́n pé, “Ẹ̀yin ọmọde, ǹjẹ́ ẹ ní ohunkohun fún jíjẹ?
Ohun to si fa aawọ aarin wọn ko ju bi alaga ẹgbẹ APC naa ṣe faake kọri pe oun ko ni fọwọ si eeyan ti wọn fa kalẹ gẹgẹ bi oludije awọn ipo oṣelu nibẹ lai yan ipo gomina silẹ.
Àwọn ni ọmọ Huri, àkọ́bí Efurata, tí ó jẹ́ baba Bẹtilẹhẹmu.
Nígbà tí ó dé ilé, ó mú ọ̀bẹ, ó gé òkú obinrin yìí sí ọ̀nà mejila, ó sì fi wọ́n ranṣẹ sí gbogbo agbègbè Israẹli.
Ẹ̀yin ará, mo fi orúkọ Oluwa wa Jesu Kristi bẹ̀ yín, gbogbo yín, ẹ fohùn ṣọ̀kan, kí ó má sí ìyapa láàrin yín.
Alaga ẹgbẹ́ awọn agbẹjọro obinrin l'orilẹ̀-ede Naijiria, ẹka ti ipinlẹ Oyo, Arabinrin Deborah Collins ti sọ fun BBC Yoruba pe ko si nkan to buru ninu igbesẹ ijọba.
Bí wọ́n ti ń sọ òkúta lu Stefanu, ó ké pe Jesu Oluwa, ó ní, “Oluwa Jesu, gba ẹ̀mí mi.
Ó kọ́ mi ní ogun jíjà,tóbẹ́ẹ̀ tí mo lè lo ọrun idẹ.
 ní 1960 àti 1970 , portugal kó ọ ̀ pọ ̀ lọpọ ̀ ọmọ ogun lọ sí mozambique láti bá àwọn tí ó ń jà fún òmìnira jà .
 Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, End SARS, End SWAT: Ó pé mi bí SARS kò ṣe sọ mí dolówọ́- Fulani Kwajafa 3."
Awọn kan lo n ko wọn wọle lọna ti ko ba ofin mu, ti wọn si n ta a ni ọja pade mi ni kọọrọ.
Kọmiṣọna feto iroyin nipinlẹ Ọṣun, Lani Baderinwa ni 'ijọba gomina Aregbeṣọla ko lee yẹ ipinnu rẹ lori alaafia awọn oṣiṣẹ' Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Kì í ṣe àpẹẹrẹ ti eniyan nìkan ni mo fi ń sọ nǹkan wọnyi.
Ohun tí ó rí, tí ó sì gbọ́ ni ó ń jẹ́rìí sí, ṣugbọn ẹ̀yin kò gba ẹ̀rí rẹ̀.
Àwọn iranṣẹ Dafidi lọ sọ́dọ̀ Abigaili ní Kamẹli, wọ́n ní, “Dafidi ní kí á mú ọ wá, kí o lè jẹ́ aya òun.
Ko pẹ ti ijamba yii ṣẹlẹ ni wọn ni awọn ajọ ẹṣọ alaabo oju popo (FRSC) ti de sibẹ lati pese iranwọ to yẹ.
o tun wa ro won lati maa se kaarẹ lati tubo maa gbogun ti awon iko olote Boko
Òun ní ó máa ń kọrin kan báyìí ń ilé wa pé:
ní àsìkò yìí ni àwọn ọmọ odùduwà ń jẹ ọba káàkiri ilẹ ̀ yorùbá .
Nígbà tí ó dé ọ̀dọ̀ ọba, ọba bi í pé, “Mikaaya, ṣé kí á lọ gbógun ti Ramoti Gileadi ni, àbí kí á má lọ?
Nisinsinyii ó túbọ̀ ní ìtara pupọ nítorí ó gbẹ́kẹ̀lé yín pupọ.
Abẹyin la ti bẹrẹ, mo si fẹ́ fun yin ni ọwọ rẹ.
Àkọ́bí rẹ̀ lágbára bí akọ mààlúù,Ìwo rẹ̀ sì dàbí ìwo mààlúù tí ó lágbára,tí yóo fi máa ti àwọn orílẹ̀-èdè títí dé òpin ayé.
Fi ààmì sórí 'Bobajiroro Awọn ọmọde ti a tu silẹ loni yoo jẹ anfani awọn eto ti yoo ṣe adapada wọn si igbe aye to boju mu, ti o si mu wọn ṣe awari ọna to tọ fun idagbasoke ati alaafia to peye wa si Naijiria gẹgẹ bii ọmọ orilẹede naa.
iṣẹ naa paapaa nipa sisan owo to yẹ loṣooṣu fu ikọ eṣọ LNSC yii.
Nípa bẹ́ẹ̀ o óo wa ẹ̀yinná lé e lórí, OLUWA yóo sì san ẹ̀san rere fún ọ.
Odumakin - BBC News Yorùbá BBC News, YorùbáFò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Fulani darandaran: Ẹ ma wa ija Yoruba - Odumakin Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Fulani darandaran: Ẹ ma wa ija Yoruba - Odumakin 25 Sẹ́rẹ́ 2018 Odumakin sọrọ lori ọrọ Fulani darandaran, o wipe ki wọn ma tẹ Yoruba loju molẹ.
Inú ihò kan báyìí ni mo fi ṣe ilé; nígbà tí ó sì pẹ́ díẹ̀ tí mo ti ń gbé inú ihò náà mo tún un ṣe dáadáa mo sì ṣe onírúurú yàrá sí í.
ni eyi ti orile ede Niajiria yoo maa jẹ anfaani rẹ.
 iṣẹ ́ àwọn oníṣègùn ni kí wọ ́ n tọ ́ jú aláìsàn pẹ ̀ lú oògùn ìbílẹ ̀ oríṣiríṣi tí wọ ́ n ti pèsè láti ara ewé àti egbò tí ó le wo àrùn tàbí àìsàn náà sàn .
Orin yii ṣi n ta ni ori You tube di isinyi.
Àjàkálẹ̀ àrùn burúkú náà yóo kọlu àwọn ẹṣin, ìbakasíẹ, ràkúnmí, kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ ati gbogbo àwọn ẹran tí wọ́n bá wà ní ibùdó ogun wọn.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Edo Election 2020: Ààrẹ Buhari, Atiku àti àwọn èèkàn ìlú míràn ti n kí Obáseki ku oriire 20 Owewe 2020 Oríṣun àwòrán, Obaseki/ Twitter Ààrẹ Muhammadu Buhari ti ránṣe kú orííre si Godwin Obaseki lẹ́yìn tó jáwé olúborí nínú ìdìbò gómìnà tó wáye lónìí nípìnlẹ̀ Edo.
40) fun irinna baluu ti yoo gbe ipapanu yii wa.
Ọkunrin yìí kò fẹ́ fọwọ́ kan èyíkéyìí ninu ẹran tirẹ̀ láti pa ṣe àlejò náà.
padanu awon ohun ini re sapo ijoba bi  irinwó
Ìlú kékeré kan wà, tí eniyan kò pọ̀ ninu rẹ̀, ọba ńlá kan wà, ó dótì í, ó sì mọ òkítì sí ara odi rẹ̀.
Mo kàn fẹ́ fi ọmọ tó sọnù gba owó lọ́wọ́ Sọtitobire ni - Afurasí Ọmọ ọdún márùn-ún, àgbà mẹ́rin ló bá ìṣẹ̀lẹ̀ ọ̀pá bẹntiróò tó gbiná ní Abule Egba lọ - LASEMA Atiku náà kéde àtìlẹ́yìn rẹ̀ fún ẹ̀ṣọ́ alábòò Amọtẹkun Ẹ má mu gaarí mọ́ nítorí ìbà Lassa- Dókítà Boniface Orilẹ-ede South Africa lo kọkọ sọ ni ilẹ adulawọ pe o ba ofin mu ki akọ fẹ akọ tabi ki abo fẹ abo.
Owó ìfẹ̀yìntì àwọn Gómìnà ní ìpínlẹ̀ Zamfara dì àlọrámirámi Àìsàn jẹjẹrẹ mú ẹ̀mí Aisha Abimbọla lọ Tí Mágà ẹ bá ti lè yó ìfẹ́, kò kọ̀ kí ọ́mọ tirẹ̀ kú - Yahoo Boy Ilé aṣòfin Amẹrika gbọnmú lórí ìtìmọ́lé Sowore, ó ní ìjọba Nàíjíríà tako òmìnira aráàlú Minisita fun eto isuna orilẹ-ede Naijiria, Abilekọ Zainab Ahmed lo sọ bẹẹ lẹyin ipade igbimọ alasẹ ti ijọba apapọ, Federal Executive Council ni ilu Abuja.
Àwọn ọmọ Seiri ará Hori, tí ń gbé ilẹ̀ náà nìyí: àwọn ọmọ rẹ̀ ni: Lotani, Ṣobali, Sibeoni ati Ana, 
Nítorí tí ó dára láti máa kọ orin ìyìn sí Ọlọrun wa;nítorí olóore ni, orin ìyìn sì yẹ ẹ́.
Eyi lo n jẹ ki wọn maa tiraka lati wa owó ti awọn aṣoju yii ba beere fun ti wọn si fi n ko sọwọ gbajuẹ.
àwọn ni wọ́n wá bá mi tí wọ́n ní, ‘Ṣe oriṣa fún wa tí yóo máa ṣáájú wa lọ, nítorí pé a kò mọ ohun tí ó ti ṣẹlẹ̀ sí Mose, tí ó kó wa wá láti ilẹ̀ Ijipti.
Koda, oṣiṣẹ ọba to ba pẹ de ibi iṣẹ yoo maa tọ bii ọpọlọ ni tabi ko jẹ koboko Sọja, bii ijiya ẹṣẹ rẹ.
Ohun ti ofin ẹgbẹ naa sọ ni pe, oṣu mẹfa pere ni saa igbimọ fidiẹ naa, to si gbọdọ ṣe ipagọ gbogboogbo laarin akoko naa, nibi ti wọn yoo ti yan awọn adari ẹgbẹ tuntun.
Awọn mẹta to ṣẹwọn ri yii ṣalaye pe iyipada ilẹ naa eyi ti wọn sọ pe o mu awọn lẹru, ati pe o tapa sofin ẹtọ ọmọniyan wọn.
Ọla ọjọ keje oṣu kejila ọdun 2019 ni atunja ija laarin Anthony Joshua ati Andy Ruiz Jr yoo waye lorilẹede Saudi Arabia.
B Joshua-Angel Gomes Elébi ní iléeṣẹ́ bàlúù yín - Naira Marley dapadà fún Executive jet Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Bakan naa ni a ti se eto pelu awon osise ile ise eto ogbin lati rii pe awon katakata wa fun awon agbe ki won le se oko lopo yanturu yato si ajile ti Gomina Ifeanyi Ugwuanyi ti ra fun lilo awon agbe tele.
“Ẹ kò gbọdọ̀ ta ilẹ̀ kan títí ayé, nítorí pé èmi OLUWA ni mo ni gbogbo ilẹ̀, ati pé àlejò ati àtìpó ni ẹ jẹ́ fún mi.
50 Ọrọ ẹsin, igbafẹ ati asa - 5,170,065,144.
Adejobi ni ohun to ṣẹlẹ ni wi pe araalu kan lo ji pe awọn ọlọpaa ni aago mẹrin owurọ lati agbegbe Agunfoye, Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ìjà àgbà méjì!
Àwọn òfin rẹ ni dídùn inú mi,àwọn ni olùdámọ̀ràn mi.
Idi si ree ti awọn ọmọ Naijiria se n beere pe, ki ni pataki eto BBNaija fawọn ọdọ, eyi to lowura ju eto iyansipo olori isejọba Naijiria lọ?
Awọn minisita mẹsan ati gomina mẹrin lati ẹgbẹ oselu PDP naa wa lara awọn adari osisẹ ijọba to tẹlẹ Aarẹ Buhari.
Ó mú ìṣàn omi jáde láti inú àpáta;ó sì mú kí ó ṣàn bí odò.
Agbẹnusọ fun ajọ , Bisi Kazeem ati agbẹnusọ ile iṣẹ ọlọpa ipinlẹ Oṣun, Folasade Odoro lo fi aridaju iṣẹlẹ naa han fun awọn oniroyin.
Iroyin ayọ miran ree lori ọwọja arun Coronavirus to n waye bayii.
Opolopo ile ijosin ni Isreal ni won nile ara won ni Jerusalem ni eyi ti won fi gba peofin bayii ko ni je ki won tete maa ri alabara fun ile won lasiko.
Angela Merkel ti Germany fún ìgbà èkejì, gbọ̀n pẹ̀pẹ̀ lóde
Dolapo aya Igbakeji aarẹ Naijiria, Osinbajo rre, to n kunle ki aarẹ Buhari nibi eto ijọba kan.
Pilatu bá jáde lọ sọ́dọ̀ wọn lóde, ó bi wọ́n pé, “Ẹ̀sùn wo ni ẹ fi kan ọkunrin yìí?
Àjẹsára ibà pọ ́ njú-pọ ́ ntọ ̀ jẹ ́ àjẹsára tí ń dáàbò bo ni lọ ́ wọ ́ ibà pọ ́ njú-pọ ́ ntọ ̀ .
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Obasanjo: Àwọn èèyàn ìpínlẹ̀ Ogun ní iṣẹ́ ṣì pọ̀ fún Ọbasanjọ láti ṣe fún mẹ̀kúnù Nàìjírìà O ni ọpọlọpọ igba ni Mallam Sanusi ti tako awọn agbekalẹ ofin to de oye jijẹ ni ipinlẹ naa eleyi to ni yoo ba iyi ilu Kano jẹ bi wọn ko ba mojuto.
bákan náà , àwọn fíìmù kan tún wà tí iṣẹ ́ pàtàkì tí wọ ́ n ń jẹ ́ níí ṣe pẹ ̀ lú àrùn tí ó bá ń kojú àwùjọ lásìkò kan kì í sẹ ní afrika nìkan ní irú fíìmù yìí ti ń jáde .
24 Èbibi 2020 10:43 Fídíò, Wole Soyinka sọ ìdí tó fi ni òun a fi màálù Fulani ṣe súyà fáwọn èèyàn abúlé, Duration 10,4323 Owewe 2020 Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí 2 sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
Ipaya wa lori fọnran ohun kan nilẹ Kenya: Lorilẹede Kenya, ijọba fi ikede sita pe pe irọ ni fọnran ohun ti wọn n pin kiri pe arun Coronavirus ti wọ orilẹede naa, eyi to ni awọn eeyan to ni arun naa to mẹtalelọgọta niye.
ọmọ Serahaya, ọmọ Usi, ọmọ Buki, 
Ó bá tú òróró yìí sí Jesu lẹ́sẹ̀, ó ń fi irun orí rẹ̀ nù ún.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Abẹ́rẹ́ àjẹsára tó dájú fún ìdènà àrùn Coronavirus ti jáde Awọn onimọ sayẹnsi ti gbe abẹrẹ ajẹsara ti yoo koju arun Coronavirus jade.
Ó dé adé tí ó ní ìràwọ̀ mejila.
Besaleli fi igi akasia àpótí ẹ̀rí náà, gígùn rẹ̀ jẹ́ igbọnwọ meji ààbọ̀, fífẹ̀ rẹ̀ jẹ́ igbọnwọ kan ààbọ̀, ó sì ga ní igbọnwọ kan ààbọ̀.
 tí wàhálà ẹ ̀ dọ ̀ tó-ṣíwọ ́ -iṣẹ ́ bá ṣẹlẹ ̀ , ọ ̀ nà-àbáyọ kan ṣoṣo náà ni gbígba-ẹ ̀ dọ ̀ -míràn .
CP Awosola Awotunde - CP Ebonyi Command xli.
Ken Saro-Wiwa wa lati ẹya Ogoni to pẹlu awọn ẹya to kere julo lorilẹ-ede Naijiria, amọ ti wọn ni epo rọbi lati ọdun 1950, ti o si n se ipalara fun awọn eniyan ati ohun ọgbin wọn.
Ni afikun, ki eeyan maa run bii ile ọti kii mu adun ifẹ pọ.
Sùgbọ́n oo, ti a ba le rẹ ẹ somi fún bii wákàti mejila kó to di sísè, àwọn kẹmika ara rẹ yóò pòórá.
Ìgbà tí ẹ̀dá náà dé ọ̀run, tí ó jísẹ́ wí pé àwọn ọmọ aráyé kò ní ìtẹ́lọ́rùn, Ọlọ́run rán an padà kí ó lọ béèrè ohun tí olúkúlùkù wọn ń fẹ́,kí Òun baà lè ṣe é fún wọn.
Zarka fun BBC laṣẹ lati ka bi o ṣ e n gbawosan silẹ, o si ṣalaye ohun ti oju rẹ ri nile ọkọ rẹ naa.
Bí Zainab ṣe dèrò ẹ̀wọ̀n Saudi lórí ẹ̀sùn ògùn olóró tí kò mọ̀ ''Ọrẹbinrin mi jẹ́ mí ní ₦20,000 ní mò fí dáná sún àwọn ẹbí rẹ'' Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ìbejì Àyànbìnrin tó ti ń di gbajúgbajà Awọn ti isẹlẹ naa ṣoju wọn ni kẹkẹ maruwa to ko awọn eniyan mẹrin to padanu ẹmi wọn naa n tiraka lati kọja loju irin ni ọkọ oju irin se ijamba fun wọn.
Bí ẹnikẹ́ni bá bi yín pé, ‘Kí ló dé tí ẹ̀ ń tú u?
  Wọ́n sì mọ gbogbo kọ̀ọ̀rọ̀ inú igbó náà pátápátá.
0 4 Orilẹede Samoa 0 0.
"Igbakeji aarẹ ni ""ninu gbogbo eyi, ijọba apapọ ko ni mu ipinlẹ kankan ni dandan lati pese ilẹ fun eyi"" Omotola Ekehinde, Ezekwesili, Funmi Iyanda dá sí ẹ̀sùn ìfipábánilòpọ̀ Fatoyinbo COZA: Mi ò fípá bá obìrin lò pọ̀ rí láyé mi - Pásítọ̀ Fatoyinbo Seyi Makinde yan obìnrin míràn sípò akọ̀wé ìjọba SSG Àwòrán apanilẹ́rìn-ín fún ọ̀sẹ̀ yìí, ìtọ́wò rèé Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!"
Ekiti APC Politics: Mo mọ̀ pé ọ̀rọ̀ ètè lásán lẹ̀ n sọ, ẹ ò lè yọ mí lẹ́gbẹ́
bi alaga egbe oselu APC, Adams
" awako ofurufu  tabi "" pade alamuleti "" je episodu awakofurufu ninu amohunmaworan amerika ."
Aarẹ Nana Akufo-Addo ati John Mahama lawọn oludije meji to jọ n figa gbaga ninu eto idibo naa.
OLUWA ní: “Ìwọ ọmọ eniyan, mú idà kan tí ó bá mú, lò ó gẹ́gẹ́ bí abẹ ìfárí, kí o fi fá orí ati irùngbọ̀n rẹ.
Iru nkan bayii ko dabi pe o ṣẹlẹ ri, aarun coronavirus to n ba gbogbo aaye finra lo fa a.
ede Naijiria lo si ni kọkọrọ idagbasoke orile ede Afirika lọwọ’,Osinbajo tun ni
Ilé iṣẹ́ márùn ún tí wọ́n dárukọ kìí ṣe túntun- Garba Sheu FRSC dá N443,180 padà fún ẹbí ẹni to ní ìjàmbá mọ́tò Ọwọ́ ti tẹ ọlọpàá mẹ́rìn to pa afurasí Ìjìyà ń bẹ fún àwọn ti adé ọ̀rọ̀ náà bá ṣí mọ́ lóri -Ọga àgbà FRSC Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
si ootọ ọrọ nibi esi abajade ibo naa.
Bakan naa, ajo to n ri si
Iroyin ni lẹyin ọjọ karun un ti wọn fi Temilolu jẹ adele ni awọn janduku kọlu afin rẹ ti wọn si luu ni ilu bara toun ti iya rẹ.
Lorumọju ọjọ naa ni wọn doloogbe ninu ooru to pọ de ida sẹntigireedi mẹrindinlaadọta lọjọ naa.
Sekyen Dadik to je alakoso ajo Africa Media Development Foundation (AMDF) to tun soju fun NURHI ninu oro iside re gba awon eniyan niyanju lori pataki ifetosomobibi fun iya ati gbogbo ebi lapapo.
Bakan naa ni Makinde tun ko awọn ikọ agbofinro Operation Burst si igboro lawọn agbegbe ti ina wahala ti n jo julọ lati mu ki alaafia jọba nibẹ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Mobile App: Àsìkò tó wu àwọn akẹ́kọ̀ọ́ ni olùkọ́ máa jáde wa kọ́ wọn láti inú fóònù wọn Ki lo ti ṣelẹ sẹyin?
Ohun ti ọpọ si n ke ibosi le lori naa ni pe, arabinrin Amina Zakari tan mọ aarẹ Muhammadu Buhari, ọkan lara awọn eeyan ti yoo dije fun ipo aarẹ lorilẹede Naijiria ni ọjọ kẹrindinlogun oṣu keji, ọdun 2019.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, SS3 ní mo wà báyìí, mo sì ti gba àmì ẹ̀yẹ̀ púpò nílé-lóko gẹ́gẹ́ bí onílù - Ayansike Wọn wa n rawọ ẹbẹ pe ko gba ade ọba lori Oluwo, nitori awọn iwa kobakungbe ti wọn fi kan an.
72 Ẹka eto ọgbin - 18,311,948,584.
Wo bí Sunday Shodipe ṣe pa Funmilayo tó pa kẹ́yìn l' Akinyele Ẹ̀yin òṣìṣẹ́ elétò ìlera, ẹ padà sẹ́nu iṣẹ́- JOHESU Bí PDP ṣe na APC lálùbami ní Edo, bẹ́ẹ̀ ni yóò ṣẹlẹ̀ ní Ondo- PDP Ọwọ́ ọlọ́pàá tẹ afurasí ọkùnrin tó gé akẹ́kọ̀ọ́ ọ̀rẹ́bìnrin rẹ̀ wẹ́lẹ́ wẹ́lẹ́ fún òògùn owó ní Ikorodu Cameroon Atrocity: Àwọn sójà náà ní ìyá àti àwọn ọmọ náà jẹ́ ikọ̀ Boko Haram Ikọ ọmọ ogun orilẹ-ede Cameroon marun un ni yẹ ki wọn gba idajọ loni lẹyin ti iwadii ile ẹjọ fihan pe wọn jẹbi ẹsun iṣekupani ti wọn fi kan wọn.
Bẹẹ bá gbàgbé, Gbenga Adeboye lo jáde láyé ni ọgbọnjọ oṣù kẹrin ọdún 2003, èyí tó pé ọdún mẹtadinlogun lonii Ọjọ́bọ.
Ohun ìjà olóró kò gbọdọ̀ wọ Nàíjíríà mọ́ lọ́nà ẹ̀bùrú - Buhari Ta ló ni $1.
Aare orile ede Naijiria  Muhammadu Buhari ti ni eto idagbasoke ati
” Mo bá pe ìpàdé ńlá lé wọn lórí, mo sọ fún wọn pé, 
Ẹgbẹ oselu PDP ni dipo aroye ti ijọba to wa lorilẹede Naijiria n ṣe bayii, asiko to lati dahun oniruuru awọn ibeere to nranju mọọ yi isẹlẹ naa ka.
Awọn ọdọ to jẹ akẹgbẹ oloogbe naa ti fi ibinu lọ ile oloṣelu kan ti orukọ rẹ njẹ Kunle Oluọmọ, ti wọn si jo awọn ọkọ nla ati ile to wa nibẹ.
Wákàtí méjì àbọ̀ ní akẹ́kọ̀ọ́ yóò fi kẹ́kọ̀ọ́ lójúmọ́ - Ìjọba Oyo Bí pínpín owó ilù ṣe díjà sílẹ̀ láàrin àwa ìjòyè àti Oluwo rèé - Osa Iwo Ẹ wo àkọsílẹ̀ ọ̀pọ̀ ẹbùn tí ìkọ̀ọ̀kan olùdíje BB Naija tó kú nínú ilé, ti jẹ Kí ló mú kí ọkọ̀ kan tó jóná ráùráú lórí afárá Ojuelegba?
Bí kò bá sí ẹni tí yóo gbà wá, a óo jọ̀wọ́ ara wa fún ọ.
com/WdaXp9NdJa— ITV Football (@itvfootball) June 26, 2018Atamatase agbaboolu owo iwaju fun Uruguay, Luiz Suarez lo gba ami-ayo kinni-in wole niseju mewa saa akoko ti ifesewonse naa bere.
Awọn ọna abayọ naa si ni akọkọ, ki wọn da owo epo pada si iye to wa tẹlẹ, iyẹn naira marundinlaadọjọ N145 lori jala kan; ikeji ki wọn si da owo ina pada si iye to wa tẹlẹ.
₦30,000 owó oṣù yòó bẹ̀rẹ̀ ní September - Alága ẹgbẹ́ òṣìṣẹ́ l‘Ekiti Láti January lọ, gbogbo ẹni tó bá ra ọjà lórí ayélujára yóò máa sanwó orí - FIRS Aṣojú Seyí Makinde lásan ní mo jẹ, òṣìṣẹ́ gbọdọ̀ bọ̀wọ̀ fún mi - Ọ̀dọ́mọdé Kọmísánà Èmi àti Bọla Tinubu fẹ́ lo ‘German Mercenaries’ láti gbé MKO Abiọla kúrò lẹ́wọ̀n - Dele Momodu Ti ọpọ orilẹede lagbaye ba sọ aba ibaradọgba awọn obinrin yii di ofin, o daju pe ọpọ anfaani ni gbogbo agbaye yoo ri ninu rẹ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Akure Kidnap: E túbọ̀ ní sùúrù, a máa wá ọmọ náà rí- Alukoro ọlọ́pàá Tipatikuku lawọn ọlọpaa kogberegbe ati oṣiṣẹ ileeṣẹ ẹlẹwọn fi tu awọn akọroyin ka lasiko ti wọn gbe Pasitọ Alfa Babatunde wa si ile ẹjọ majistereeti ladugbo Oke Eda nilu Akure.
Niṣe ni ọgọọrọ awọn olufẹhonuhan bọ soju oju ti wọn si tẹsiwaju pẹlu ifẹhonuhan wọn.
Ó sì pe orúkọ ibẹ̀ ní Masa ati Meriba, nítorí ìwà ìka-ẹ̀sùn-síni-lẹ́sẹ̀ tí àwọn ọmọ Israẹli hù, ati nítorí dídán tí wọn dán OLUWA wò, wọ́n ní, “Ṣé OLUWA tún wà láàrin wa ni tabi kò sí mọ́?
Yóo yí ọkàn àwọn baba pada sọ́dọ̀ àwọn ọmọ wọn, yóo sì yí ti àwọn ọmọ, pada sọ́dọ̀ àwọn baba wọn; kí n má baà fi ilẹ̀ náà gégùn-ún.
Nigba to n salaye iyatọ to wa laarin ṣíṣe isẹ Nọọsi ni Naijiria ati loke okun, Akintayo ni iyatọ nla lo wa laarin awọn oṣiṣẹ mejeeji.
Bẹ́ẹ̀ ni gbogbo ilẹ̀ Ijipti ṣe di ti Farao, 
Ó bá wo gbogbo wọn sàn.
Nibayi awọn ẹrọ abaniṣiṣẹ rọbọọti yii ti wa nilẹ digbi wọn si ti duro deede lati maa ṣe ayẹwo gbogbo arinrinajo ni papakọ ofurufu Naijiria lati asiko ajakalẹ arun COVID-19 yii.
"Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Fídíò, Soyinka Cancer: Àṣe ara mi ni iso ti n run gbogbo bí mo ṣe n ṣèrànwọ́ lórí jẹjẹrẹ27 Bélú 2019 Fídíò, Akinwumi Isola: Wo ohun tí Abeni fi ojú ọkọ rẹ rí tórí iṣẹ́ bọ́ lọ́wọ́ rẹ̀ nínú ìwé ""Nitori Owo""27 Ọ̀wàrà 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?"
Olusola Oke ní ìfẹnukò àwọn alátìlẹ́yìn òun ni yóò sọ ìgbésẹ̀ tó kàn lẹ́yìn ìdìbò abẹ́nú APC l'Ondo Oríṣun àwòrán, others Àkọlé àwòrán, Olusola Oke ní ìfẹnukò àwọn alátìlẹ́yìn òun ni yóò sọ ìgbésẹ̀ tó kàn lẹ́yìn ìdìbò abẹ́nú APC l'Ondo Lootọ lawọn aidọgba pọ nipa eto idibo abẹle APC to waye lana nipinlẹ Ondo, ṣugbọn n o tii le sọ igbesẹ to kan fun mi bayii- Olusola Oke.
Ní ọjọ́ kẹwaa ni Ahieseri ọmọ Amiṣadai, olórí àwọn ẹ̀yà Dani mú ọrẹ tirẹ̀ wá.
Lara awọn ti wọn wi ti wọn ni ikọ onwoye idibo abẹle kan lorileede Naijiria ti orukọ wọn n jẹ 'Watching the Vote'.
Bakan naa lo fi kun un pé ijọba ti fi ofin de wiwọ igbo naa lọ ṣodẹ laigba aṣẹ nitori iru iṣẹlẹ bawọn yii.
Ọgbọn ọjọ, oṣu Kinni, ọdun 2020 ni ẹgbẹ kan ti kii ṣe ti ijọba, Anti-Corruption and Accountability Coalition Against Corruption, fẹsun kan an, Wọn si kọwe mọọ lọdọ aare Muhammadu Buhari pe ayederu iwe ẹri lo fi n ṣiṣẹ.
Ẹ ṣọ́ra gidigidi, kí ẹ rí i pé ẹ kò bá àwọn tí wọn ń gbé ilẹ̀ tí ẹ̀ ń lọ dá majẹmu kankan, kí wọn má baà dàbí tàkúté tí a dẹ sí ààrin yín.
Wọ́n dáko, wọ́n gbin àjàrà,wọ́n sì kórè lọpọlọpọ.
“Ẹ ranti, ẹ má sì ṣe gbàgbé, bí ẹ ti mú OLUWA Ọlọrun yín bínú ninu aṣálẹ̀, láti ọjọ́ tí ẹ ti jáde kúrò ní ilẹ̀ Ijipti títí tí ẹ fi dé ibí yìí ni ẹ̀ ń ṣe oríkunkun sí OLUWA.
Ìpàdé àwọn orílẹ̀èdè G7:Trump lòdì sí àbájáde ìpàdé
Àwọn ọmọ Elifasi ni Temani, Omari ati Sefi; Gatamu, Kenasi, Timna ati Amaleki.
Mo fẹ́ ọkọ mi torí bó se ń kọrin, kìí se torí owó - Ìyàwó Aràrá Akẹ́kọ̀ọ́ LASU láàrọ́ọ̀, Mọkálíìkì lọ́sàn án, ẹni tó ń ṣe bàtà lálẹ̀ ní mí- Olamide Ọsán jáá!
E̩nì kò̩ò̩kan ló ní è̩tó̩ láti wá ààbò àti láti je̩ àn fàní ààbò yìí ní orílè̩‐èdè mìíràn nígbà tí a bá ń s̩e inúnibíni sí i.
Ní ọdún 2013 tó wọlé dé yìí, aríkọ́ṣe àti àwòkọ́ṣe ni ilẹ̀ Yorùbá jẹ́ fún gbogbo àgbáyé nípa ìrẹ́pọ̀ èsìn.
Ilé aṣòfin Ondo bẹ̀rẹ̀ ìgbésẹ̀ láti yọ igbákejì gómìnà nípò Kòṣẹlẹ̀rí ni Hajj ọdún 2020, wo ìyàtọ̀ tó wà nínú rẹ̀ sí ti tẹ́lẹ̀ Oba ọhun rọ awọn ara ilu lati tẹle gbogbo ilana ti ajọ NCDC gbe kalẹ bii ọwọ fifọ loorekoore ati ijinasiraẹni lawujọ lọna ati le arun naa lọ.
Oko àgùntan ni oko náà nṣe.
'Ìdùnnù wa kọ́ ni kí á má fún ọmọ Nàìjíríà ní 'Visa' Ǹjẹ́ o mọ̀ pé o le gba owó lára 'ATM' láì lo káàdì?
Mo ti fi ọ̀rọ̀ rẹ sọ́kàn,kí n má baà ṣẹ̀ ọ́.
O jẹ olukọ, ẹni to fẹran eto oṣelu ati ajijangbara fun ẹtọ awọn obinrin.
Ẹni tí ó bá ń rìn ninu òkùnkùn kò mọ ibi tí ó ń lọ.
"Oríṣun àwòrán, Instagram/Lady Peller ""Àwọn kan ni àwọn ò fẹ́ rí ǹkan kan míràn mọ́, wọ́n sì bínú lọ, lọ́jọ́ kejì, àwọn ènìyàn Lady Peller sa ni àwọn fẹ́ rí."
Ẹ máa gbé inú ìfẹ́ mi.
Ó ti tabili àwọn onípàṣípààrọ̀ owó ṣubú, ó da ìsọ̀ àwọn tí ń ta ẹyẹlé rú.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Bauchi Elections: Gómínà Abubakar ti kí Mohammed oludije PDP to jáwé olú borí 26 Ẹrẹ̀nà 2019 Oríṣun àwòrán, Bala Mohammed/facebook Gomina Mohammed Abubakar ti ki Sẹnetọ Bala Mohammed to jẹ oludije fun ipo gomina ipinlẹ Bauchi labẹ ẹgbẹ oṣelu PDP lẹyin ti ajọ eleto idibo INEC kede pe sẹnetọ naa gẹgẹ bi ẹni to bori ninu idibo gomina ipinlẹ naa.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Trump: Ìpàdé èmi àti Trump so èso rere 12 Òkùdu 2018 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ààrẹ orílẹ́èdè America ṣe ìpàdé fún ìgbà àkọ́kọ́ pẹ̀lú olórí orílẹ́èdè North Korea Aarẹ orilẹede America, Donald Trump sọ pe, ijiroro oun pẹlu olori orilẹede North, Korea Kim Jong-un yọri si rere.
” Kí wọ́n baà lè rí ẹ̀sùn fi kàn án ni wọ́n fi bèèrè ìbéèrè yìí.
Lẹ́yìn tí Rakẹli bí Josẹfu, Jakọbu tọ Labani lọ, ó bẹ̀ ẹ́ pé “Jẹ́ kí n pada sí ilé mi.
Ṣugbọn Ahimaasi ṣá tẹnu mọ́ ọn pé, “N kò kọ ohunkohun tí ó lè ṣẹlẹ̀, jọ̀wọ́ jẹ́ kí n sáré tẹ̀lé ará Kuṣi náà lọ.
O ṣalaye pe idi pataki ti oun ko ṣe ti i yan awọn kọmisana, to fi mọ awọn olubadamọran pataki ti yoo ba iṣakoso rẹ to ti pe oṣu meji ṣiṣẹ bayii, ko ṣẹyin ki oun le lanfaani lati san owo oṣu awọn oṣiṣẹ ijọba ipinlẹ naa.
 ní ọdún 2008 , ó kéré , àwọn orílẹ ̀ -èdè bíi 192 ni wọ ́ n ń fúnni ní ìwọ ̀ n egbògi náà méjì .
Oríṣun àwòrán, others Uzoma ni ko ba dara ki ijọba ranti ohun ipa ribiribi ti Majek Fashek pẹlu orin rẹ ki ijọba ṣi maa ṣe ayẹyẹ ni orukọ rẹ lọjọ keje oṣu kẹta to jẹ ọjọ ibi rẹ.
 nígbà tí ìtàn kejì sọ fún wa pé odùduwà àti àwọn ẹmẹ ̀ wà rẹ ̀ kúrò láti ìlú mẹ ́ kà .
Ó gun orí Kerubu, ó sì fò,ó fò lọ sókè lórí ìyẹ́ apá afẹ́fẹ́.
Ti mo ba ni kin sọ iye ọṣẹ ti a ra, yoo to ẹgbẹrun mẹwa.
Awọn ohun aramọnda to mu ki igbeyawo naa yatọ ree: Akara Oyinbo: Oríṣun àwòrán, Instagram/cakes_by_la Miliọnu mẹrin naira ni wọn fi se akara oyinbo naa gẹgẹ bi wọn se ni iyawo funra rẹ kede Osu mẹrin ni wọn fi gbaradi fun sise akara oyinbo naa Awọn onimọ nipa akara oyinbo mejidinlogun lo se akara oyinbo naa fun ọjọ marunlelaadọfa gbako Ile nla bii aafin ọba ni wọn fi akara oyinbo igbeyawo naa se O ga ni iwọn bata mejidinlaadọta Aja mẹrindinlogoji lo ni Iwọn ọgọsan kilogiramu suga ni wọn fi se akara oyinbo naa Ẹgbẹlẹgbẹ awọn ododo to jẹ kiki suga si lo wa lara rẹ.
Odunlade Adekola, Femi Adebayo, Jenifa ṣi aṣọ lójú àwọn fíìmù tuntun tẹ́ẹ ti ń retí Ẹ̀rọ CCTV tú àsírí ọkùnrin ẹni ọgbọ̀n ọdún tó fi ipá bá ọmọ ọdún mọ́kànlá lòpọ̀ Oríṣun àwòrán, @Mohammed Jagunma ati Gold Abdulrafiu Lawọn Aafa nlanla ba kuku so yigi Iya Kausara ati Baba Kausara o Ni awọn alarinna ba ṣetan ati yẹba fun tọkọ taya.
Àkọlé àwòrán, BBC Ninu awọn ti o n kopa ninu itako ọrọ naa lati ri oludije igbakeji Aarẹ awọn ẹgbẹ oṣelu bi PDP,Peter Obi, Yemi Osinbajo ti ẹgbẹ APC ,Shehu Gabam SDP ati Rabiu Ahmed Rufai AAC.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ṣọla Allyson: Obìnrin tí kò bá rẹwà ni yóò máa ṣí ara sílẹ̀ 51.
Agbábọ́ọ̀lù Brazil tẹ́lẹ̀, Ronaldinho gba ìtúsílẹ̀ kúrò lọ́gbà ẹwọ̀n, àmọ́.
" Oríṣun àwòrán, Sogo ọmọ Osun Atẹjade naa ni ijọba Osun mọriri bi Baba Fasanmi se fẹran ilu Osogbo, ẹni ti isẹ gbe wa silu naa lọdun 1951 gẹgẹ bii osisẹ apoogun amọ to gba lati gbe nilu naa titi di ọjọ iku rẹ.
Senator Elisha Abbo: Ọga àgbà ọlọ́pàá Nàìjíríà ti pàṣẹ ìwádìí sí ọ̀rọ̀ Sẹ́nétọ̀ Abbo tó lu obìnrin l'Abuja
Oyo: Bisi Ilaka ní ìdìbò àwọn alága ìjọba ìbílẹ̀ lòdì sófin
Kò sí èèyàn kánkan tó kù nílé tó wó ní Ibadan- NEMA Iyanrìn làwọn ẹbí olóògbé bàálù Ethiopia rí gbà dípò òkú Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí 2 sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 2:23 Fídíò, Water Generator: Ó leè ṣiṣẹ fún wákàtí mẹfà, kó tó sinmi, Duration 2,2310 Òkùdu 2020 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
Ẹwà rẹ̀ dàbí ti òkúta iyebíye tí ó mọ́lẹ̀ gaara.
mo pèsè igi ìrúbọ, ní àkókò tí ó yẹ ati àwọn èso àkọ́so.
DJ Switch ni Mo kabamọ pe a ṣe bẹẹ nitori ṣe ni awọn ọmọ ogun naa ko oku awọn eeyan naa sinu ọkọ, ti wọn gbe wa."
Ó pe gbogbo àwọn ọ̀rẹ́ rẹ̀ ati iyawo rẹ̀ tí ń jẹ́ Sereṣi, 
ó fi aṣọ ìbora rẹ̀ sílẹ̀, ó bá sálọ níhòòhò.
pe oko oju irin ti yoo maa ko awon ero je eyi ti gbogbo eroja rẹ wa lati orile
Àwọn igi tó hù níbẹ̀, ńṣẹ ni gbòngbò wọn lọ́pọ̀ mọ́n òkúta.
Àmọ́ ìyẹn lọ́dọ̀ tíwa lọ́hùún ni o.
Àwọn mìíràn ń sọ pé, “A ti fi ilẹ̀ oko wa yáwó, ati ọgbà àjàrà wa, ati ilé wa, kí á lè rówó ra ọkà nítorí ìyàn tí ó mú yìí.
8 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Ronke Oshodi-Oke: Ọkọ mi kò mọ̀ pé òṣèré ni mi nígbà tí a pàdé- Ojo8 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Gómìnà ìpínlẹ̀ Benue, Samuel Ortom ti parí ìjà láàrin akọ̀ròyìn Channels TV, Pius Angbo àti Ifeyinwa Angbo, ìyàwó rẹ̀8 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Borno Zabamari Massare: Àjọ NCC fẹ́ tú ìwé owó àwọn olúpèsè ìtàkùn ìbánisọ̀rọ̀ wo10 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 APC NEC Meeting: Ẹkúnrẹ́rẹ́ ọ̀rọ̀ ìkini PDP sí APC bí àwọn adarí ẹgbẹ́ lápapọ̀ ṣe túká rèé8 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Ọgbẹni Mustapha ni aarẹ Buhari paṣẹ pe ki awọn eleto ilera ṣe ayẹwo oogun naa finifini ki wọn to bẹrẹ si ni maa loo fawọn eeyan.
” Wọ́n bá bẹ́ sí ìgboro, wọ́n bẹ̀rẹ̀ sí pa àwọn eniyan láàrin ìlú.
Amọ, wọn ti sọ iwadii naa di ohun ibanilorukọjẹ fun adele ajọ naa, ti ko si mọ nkankan nipa ẹ.
Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí 3 sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
- Ìjọba Oyo Ẹgbẹ́ àwọn òṣìṣẹ́ elétò ìlera, JOHESU bẹ̀rẹ̀ ìyanṣẹ́lódì káàkiri Nàìjíríà Òní lòní ńjẹ́ nílé ẹlẹ́gbọ̀n-ọ́n àgbà BBNaija fún Dorathy, Prince, Kiddwaya, Ozo!
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Àwọn fíìmì òde òní ń kọ́mọ lólè àti ọ̀pọ̀ ìwà burúkú Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 3 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 5 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
O sọ pe ofin tuntun naa ni wọ̀n gbekalẹ lati sọ lilo rẹ di eewọ fun awọn ọmọde, ati lati di ọna mọ awọn janduku, ọdaran to fi n pawo sapo ara wọn.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Bó ṣe wa ni liki, naa lo wa ni gbanja.
Ojuti nla ni eyi jẹ fun ori ade naa, to si ro pe o seese ki Timi, ti wọn n pe ni Ẹlẹdẹ nigba naa wa doju ijọba oun bolẹ laipẹ.
Victor Moses, Oshoala gba ami ẹyẹ NFF
Baba arúgbó náà bá dáhùn pé, “Ṣé alaafia ni ẹ dé?
Ben Ali tó dari orílẹ̀-ede náà fún ọdún mẹ́talélógun, sùgbọ̀n gbogbo ìlú mọ̀ọ́ si ẹni to mu ìlọsíwáju ba ètò ọ̀rọ̀ ajé orilẹ̀-èdè náà.
Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Mùsùlùmí ni mí ṣùgbọ́n ìrírí àkọ́kọ́ mi rèé nípa ọdún Kérésìmesì ní Canada, Muhammad Hussain ṣàlàyé25 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Adultery/Adeboye: Agbẹjọró ní ìjìyà wà lábẹ́ òfin Naijiria fún pànságà nínú ìgbéyàwó30 Sẹ́rẹ́ 2020 Yoruba Films: Femi Adebayo sọ ẹran àgbò rẹ̀ lórúkọ tuntun, Bukky Wright ṣ'ọjọ ìbí5 Ìgbé 2020 Coronavirus prevention tips: Ọ̀nà àbáyọ fún olóyún lásìkò àjàkálẹ̀ ààrùn Covid-197 Èbibi 2020 Fídíò, Nike Suliyat: Ọ̀dọ́mọdébìnrin akéwì tó n fi ẹ̀ṣà kìlọ̀ ìwá lásìkò yìí24 Ẹrẹ̀nà 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Ile iṣe aarẹ ni Naijiria lo fi atẹjade kan sita tẹlẹ fi kede irinajo igbakeji aarẹ Naijiria lọ si New York.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Helen Paul sọ idi tó fi gba orúkọ ní kékere Aaringbungbun Gylfi Sigurdsson lo fọba lee fun Everton lẹyin to gba goolu keji wọ le lati ọna jinjin ti aṣole fun Man U, David De Gea si wo goolu naa wọ le.
Ninu atẹjade kan ti wọn fi sita, awọn alaṣẹ Shoprite sọ pe awọn n wa ẹni ti yoo ra ẹka to wa ni Naijiria.
Sé Nàìjíríà yóò gba lílo igbó láàyè?
 irú bánkì yìí ni í wá di community bank lóde òní mohammed yunus ló kókó dá a sílè .
Marichka kọ sori ayelujara Instagram rẹ pe oun ro pe awọn to n wo oun lori tẹlifisan ko ni mọ nkan to ṣẹlẹ.
Aarẹ orile-ede Naijiria, Muhammadu Buhari lọ sọ ọrọ yi di mimọ nibi ipade apero eto ọrọ aje l'agbaye ni ẹkun Middle East ati North Africa to n waye ni Amman lorileede Jordan.
Lọjọ kọkanla, oṣu kẹsan an, ọdun 2001 ni ọfọ ṣe ni amerika ti ọpọlọpọ ẹmi sọnu sinu ado oloro to dahun latọwọ awọn agbesunmọmi.
Gbogbo àwọn tí wọn ń gbé Ijipti yóo wá mọ̀ pé èmi ni OLUWA.
Ìtura gbáà ló jẹ́ nígbà ooru.
Leyin ti isele naa waye, ni awon olopaa lo irinse taju-taju lati fi le awon molebi awon eniyan naa kuro ni agbegbe naa.
eniyan lasiko ipolongo fun eto idibo.
O ni afaimọ ki iṣẹ ikọ Amọtẹkun ni ipinlẹ Ọyọ maa ja ireti ọpọlọpọ to n foju sọna fun un kulẹ.
Orí àwọn òkè ni ó ti ń rí oúnjẹ jẹ,níbi tí àwọn ẹranko ìgbẹ́ ti ń ṣeré.
Ajọ Eleto Idibo orilẹ-ede Naijiria (Independent Electoral Commission (INEC) ti ṣe ileri alekun awọn ibudo idibo kekere ni ipinlẹ Eko.
kíni wọn yóò máa ṣe ní ìpínlẹ̀ - DAWN Commission Wọ́n ti mu aṣojú ọmọ Britikó ní orílẹ̀-èdè Iran Obìnrin Kwara tí wọ́n tà sóko ẹrú ní Lebanon figbe ta, ọwọ́ tẹ èèbó kọ̀ráà tó ṣiṣẹ́ náà Ilé ẹjọ́ pàṣẹ kí wọ́n fi àwọn afurasí tó pa àkẹ́kọ̀ọ́ LASU sí ẹ̀wọ̀n Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Trump picture: ọjọ́ tí Trump kí mi kú iṣẹ́ lórí 'twitter' ní inú mi dùn jù- Oyedele Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Canada yóò bẹ̀rẹ̀ àyẹ̀wò f'áwọn ọmọ Nàìjíríà tó fẹ́ wọ Amẹrika
Àkọlé àwòrán, Àwọn ẹgbẹ́ òṣìṣẹ́ lábẹ́ àbùradà NLC àti TUC ẹ̀ka ti ìpínlẹ̀ Ọyọ ń ṣe ìwọ́de láti fẹ̀hónú hàn lórí owó oṣù òṣìṣẹ́ tí ó kéré jù.
 A de bi laago kan owuro, sibe awon eniyan si jade wa ki wa kaabo.
léhìn ìyapa pèlu bàba obama , ìya rè fé lolo soetoro , ọmọ ilé èkó gíga unifasiti láti orílè èdè indonesia .
Sugbọn nise ni Ronaldo nmi'ri rẹ.
Nígbà tí wọn rí i tí ó ń rìn lórí omi, wọ́n ṣebí iwin ni, wọ́n bá kígbe.
N óo bá wọn dá majẹmu alaafia, tí yóo jẹ́ majẹmu ayérayé.
0 41 Orilẹede New Caledonia 0 0.
Lopin eto idibo naa to waye niluu Ibadan, Bọlaji Amuṣan ti awọn ololufẹ rẹ mọ si Mr Latin, lo wọle gẹgẹ bi aarẹ ẹgbẹ, nigba ti awọn oṣere bi Ọdunlade Adekọla, Yọmi Fash-Lanso ati Fathia Balogun naa ri ipo di mu.
Kabiyesi, ṣebí abẹ́ ìwọ oluwa mi ni gbogbo wọn wà?
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Coronavirus Cases in Africa:Ẹ wo bí ìpínlẹ̀ Eko, Ondo àti Oyo yóò ṣe dá ilé ìjọ̀sìn padà 3 Ọ̀pẹ̀̀ 2018 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 20 Èbibi 2020 Oríṣun àwòrán, Twitter Àkọlé àwòrán, Ní Ọ̀jọ́ Ajé ni ìjọba orilẹ-ede Naijiria ti kede pe isede yoo tẹsiwaju fun ọsẹ meji miran lórílẹ̀èdè Naijiria.
Ahabu ní aadọrin ọmọkunrin tí wọn ń gbé Samaria.
Wọ́n pa àwọn ológun ọ̀hún ni lẹyín ìgbà tí wọ́n pa àwọn asáàjú àwọn ọlọ́ṣà kan ní ìpinlẹ́ Zamfara.
“OLUWA tún sọ fún mi pé, ‘Mo ti rí i pé olórí kunkun ni àwọn eniyan wọnyi.
Ijọba orile-ede Ghana ni bibọ ẹran pẹlu paracetamol iku ni!
Ìtara yín sì ti mú kí ọpọlọpọ túbọ̀ múra sí i.
Mashaba wi pe ko din ni millọnu mẹwa awọn ọmọ ilẹ naa ni ko niṣẹ latari ayederu eru ti wọn ko wọle lọna aitọ ti o si n ṣe akoba fun idagbasoke ile iṣe wọn.
Ẹni to bori: Cameroon Mauritania vs Côte d'Ivoire.
Ta ni ó sì mọ̀ bóyá ọlọ́gbọ́n ni yóo jẹ́, tabi òmùgọ̀ eniyan?
Bí ó bá dá egungun aládùúgbò rẹ̀, kí wọ́n dá egungun tirẹ̀ náà, bí ó bá fọ́ ọ lójú, kí wọ́n fọ́ ojú tirẹ̀ náà, bí ó bá yọ eyín rẹ̀, kí wọ́n yọ eyín tirẹ̀ náà; irú ohun tí ó bá fi ṣe ẹlòmíràn gan-an ni kí wọn fi ṣe òun náà.
Ẹ jẹ́ kí á yọ̀, kí inú wa dùn, ẹ jẹ́ kí á fi ògo fún un, nítorí ó tó àkókò igbeyawo Ọ̀dọ́ Aguntan náà.
 O ni, “gẹgẹ bi ipinrọ keji orin orilẹ-ede wa Nigeria, pe ‘kiṣe awọn akọni wa ko ma ṣe ja si ofo’ , eleyii lo ṣe jẹ ki a pe ipade yii, ki a le fi ero ti yin kun abadofin naa”.
“Má fọwọ́ kan èyí,” “Má jẹ tọ̀hún,” “Má ṣegbá, má ṣàwo?
Oríṣun àwòrán, Diane Reeve Emi nikan ni mo da lọ sile, mo si pinnu lati ya wo Philippe ti ara rẹ ko ya.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Àmì idanimọ St.
Mo bẹbẹ fẹ ni ọkọ iyawo atawọn ọrẹ rẹ n sọ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Natalia Mufuta ìyá Yakub, Kamil àti Adam sọ̀rọ̀ lórí bí wọ́n ń sọ èdè mẹ́rin pàpọ Ohun mẹ́fà tí ọ̀pọ̀ kò mọ̀ nípa ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ Arsenal àti Machester City Oke ti alagbara gun to mi hẹlẹhẹlẹ ni ikọ Manchester City jẹ fun ọpọlọpọ ẹgbẹ agbabọọlu ni idije premier league, FA Cup lorilẹede Gẹẹsi tabi idije miran kaakiri agbaye.
" ní ọdún 1947 , wọ ́ n pèé ní "" west african pilot "" pèé ní "" abo kìnìún ti lisabi "" fún ipa tí ó kó gẹ ́ gẹ ́ bí olórí àwọn obírin ní Ẹ ̀ gbá láti ríi wípé àwọn obìrin kò sanwó orí mọ ́ ."
”Samuẹli bá dáhùn pé, “Máa wí, OLUWA, iranṣẹ rẹ ń gbọ́.
Bayii ni ile iṣẹ ijọba Amẹrika to n fun arinrin ajo ni Naijiria niwe iriina ti fi léde pe iṣẹ n lọ ni pẹrẹwu nile iṣẹ wọn to wa ni Abuja ati ipinlẹ Eko.
yii,A ni lati dupe lowo ara wa fun aseyori yii, ki a si tun dupẹ lọwọ Ọlọrun
Ẹ kí Pirisila ati Akuila, àwọn alábàáṣiṣẹ́ mi ninu iṣẹ́ Kristi Jesu.
Kí wọ́n sì sọ ilé rẹ̀ di ààtàn.
Wọn yan an gẹgẹ bi igbakeji minisita fun iṣẹ Ọna, Aṣa, Sayẹnsi ati imọ Ẹrọ.
Sugbon lọjọ Aje yii ni Saraki sọ fun olusọ alaabo rẹ, Usman Dunguza lati gba iwe –ipe lati ile-isẹ  ọlọpaa  , ki oun lee tẹle igbesẹ ti  wọn  fẹ gbe lori isẹ iwadii ọhun.
Gẹ́gẹ́ bí wolii nì ti sọ:
Ṣùgbọ́n tí àwọn ìbejì náà bá jẹ́ ọkùnrin, ọjọ́ keje la ó sọ wọ́n lórúkọ.
Nigeria Independence Day: Wo ìlérí tí àwọn ènìyàn ṣe Buhari yóò rí ara rẹ̀ gẹ́gẹ́ bíi Mèsáyà yóò sì gbìmọ̀ràn sáà kẹta nípò-Dele Momodu Àwọn òbí ní lóòtọ́ ni àìsàn bẹ́ sílẹ̀ ní Queens College lèyín tí Ọmọ 85 dùbúlẹ̀ àìsàn Orìlẹ-èdè mẹrindínlọgbọn tí ọmọ Nàìjíríá lè wọ̀ láì ní àṣe ìwé ìgbélùú Fashola ni ijọba gbe igbesẹ naa lati pa owo wọle fun ijọba lati tun awọn opopona to ti bajẹ se kaakiri orilẹede Naijiria.
Ohun to ṣẹlẹ gan gan ree niluu Bujumbura tii ṣe olu ilu orilẹede Burundi.
Ìtàn Ọba Yorùbá tí wọ́n yẹgi fún torí ó jí ọmọ gbé ṣe ètùtù Kí ló mú Olorì Badrat Ajoke kúrò ní ààfin Oyo lọ́jọ́ Iléyá?
Gbogbo àwọn ilé tí wọ́n wà níbẹ̀ pátápátá ni wọ́n fi òkúta kọ́.
Òkan ò jòkan àdàpè ni àwon àgbà máa n fún olè wéwéèwé pèlú ìfojúsun òsunwon ohun tí eni náà gbé àti ònà tí ó gbà gbé e.
àjàkálẹ̀ àrùn yóo ti ọwọ́ òun OLUWA wá sórí gbogbo ẹran ọ̀sìn rẹ̀ tí wọ́n wà ní pápá, ati àwọn ẹṣin rẹ̀, ati àwọn kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ rẹ̀, ati àwọn ràkúnmí rẹ̀, ati àwọn agbo mààlúù rẹ̀, ati àwọn agbo aguntan rẹ̀.
Ààrẹ Ìgbìmọ̀ àwọn Inal-France, Youba Dianka, ṣàlàyé:
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ilé ẹjọ́ kòtẹ́milọ́rùn dín ẹ̀wọ̀n Joshua Dariye kù 'Mo mọ bí Boko Haram ṣe bẹ̀rẹ̀' Amọṣa, ọrọ yii pada lọjọ naa eleyi ti o yi itan igbe aye awọn akẹkọ, awọn olugbe ilu Dapchi ati orilẹede Naijiria lapapọ pada nigba ti awọn igara agbebọn kan ti wọn jẹ ọmọ ikọ Boko haram ya bo ileewe naa ti wọn si ko awọn akẹkọ naa lọ.
OLUWA yóo jọba títí lae ati laelae.
Ikọ Falconets kii ṣe ajeji si idije ife ẹyẹ agbaye, ṣugbọn ikọ yii ko tii fi igba kan pa idije yii jẹ lati igba ti o ti bẹrẹ.
Mekong jẹ́ ọ̀kan nínú àwọn odò ńlá Ásíà tí ó ṣàn gba orílẹ̀-èdè mẹ́fà: China, Myanmar, Thailand, Laos, Cambodia, àti Vietnam.
Mr Macaroni àtàwọn olùfẹ̀hónúhàn sun Alausa mọ́jú láti fòpinsí ìpànìyàn SARS N kò sọ fún ìyá mi kí ń tó lọ sílé BB Naija - Laycon Ẹ gbà mí o!
Ija naa waye ni gbagede T-Mobile Arena ni Las Vegas, orilẹede Amẹrika.
Ọpọlọpọ ninu àwọn ará Samaria tí ó wá láti inú ìlú gbà á gbọ́ nítorí ọ̀rọ̀ obinrin tí ó jẹ́rìí pé, “Ó sọ gbogbo ohun tí mo ṣe fún mi.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ẹ kọ́ nípa ohun tí Yorùbá ń pè ní Àrígiṣẹ́gi Ti a ko ba gbagbe, laipe yii ni Olubadan sọ fun awọn ọba yii wi pe ki wọn pada wa si aafin, amọ ki wọn ma de ade wa si aafin ti wọn ba n bọ.
Abigaili bá wólẹ̀ ó ní, “Iranṣẹ Dafidi ni mí, mo sì ti ṣetán láti ṣan ẹsẹ̀ àwọn iranṣẹ rẹ̀.
Ẹ sinmi ariwo Saraki, ẹnikẹ́ni ló le è di ààrẹ aṣòfin àgbà Àwọn olùgbé ìpínlẹ̀ Ọṣun ṣèwọ́de tako ìdájọ́ tó ní Oyetọla kọ́ ló wọlé sípò gómìnà Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Jeremiah Addo: Ọmọ ọdún méjì tó ṣeeṣe kò mọ̀wé jù l'ágbàáyé Gẹ́gẹ́ bí gómìnà ìpińlẹ Borno ṣe sọ, ó kéré tan, ọmọ ẹgbẹ́rún lanà mẹ́tàdínlógójì ni yóò jẹ anfani ètò ẹkọ yìí àti ààbo fún àwọn ọmọ wẹ́wẹ́ fún ọdún méjì ni ìjọba ibílẹ̀ Gwoza, Pulka àti Dikwa.
Southanpton ta putu diẹ da ayo kan pada nibi ọgbọn iṣẹju, ṣugbọn Ngolo Kante fọba lee fun Chelsea pẹlu goolu kẹta.
Iwe iroyin Zimbabwe Chronicle ni ile iwe Oxley State ni Brisbane ni orile ede Australia lo gbaa tele pelu eniyan mejidinlaadofa losu kokanla odun 2016.
Wò ó, obìrin ọmọ ọdún 92 èyí tí ilé rẹ̀ ti di ìlẹ̀ẹ́lẹ̀, ìrètí gidi wo ló tún wà fún un mọ́!
gbe jade lọjọ Aiku pe awon oloselu kan ti ko ni ipa lati koju aare lori awon
”Awon eniyan po ju ohun amayederun  to wa lo, ni eyi to tun je ki wahala ati ifehonuhan tun po si.
àwọn ọmọ Bakosi, àwọn ọmọ Sisera, ati àwọn ọmọ Tema,
"Ọwọ ṣikun awọn ikọ ọlọpaa ọtẹlẹmuyẹ tẹ ""Ade Lawyer"" nilu Akure lọjọbọ."
 díẹ ̀ péré lára àwọn àìsàn tí ó wọ aláìsàn náà lára ni ó máa n mú ibà-ọmọdé lọ ́ wọ ́ .
Gege bi alaga ajo NICOMSSAT,  ogbeni George Moghalu ,” A ti seyan lati fowosowopo pelu awon osise ni ona lati mu iyipada otun de bae to ibanisoro lorile-ede yii .
Orukọ awọn mẹwaa lara awọn to je ilumọọka ninu ẹgbẹ osere Nollywood, ti wọn jẹ ọmọ Yoruba ni yii: Odunlade Adekola Ọmọ bibi ilu Abeokuta nipinlẹ Ogun, to wa niwọ oorun Guusu Naijiria ni osere naa ise.
"Ọba Adeyemi ni "" Ń ko fi igba kankan kọnu ifẹ sawọn ayaba mi ri, ó wu wọn ni wọn pinnu pe awọn yoo duro ti mi tori emi ni mo n ran wọn lọ sile iwe."
Èkeje, má ṣe mọ ti ara rẹ nìkan, ìwọ nìkan kọ́ lo wà láyé, máa ran ọmọnìkejì rẹ lọ́wọ́.
Juventus n fi ami mefa saaju iko agbaboolu Napoli lori tabili idije ohun, pelu ifesewonse meji ti yoo ku fun iko kookan lati gba.
Bakan naa ni Gomina ipinlẹ Eko, Babajide Sanwo-Olu ti fun awọn Musulumi laaye lati bẹrẹ adura ojoojumọ pada ki iye awọn to fẹ kirun si pọ bi o ba ṣe wu wọn.
Vice Admiral Ibok-Ete tun so pe “ A
A fi àsìkò yìí kí gbogbo olólùfẹ́ ojú ìwé yìí kú ọdún
" Orin ó digberé gb'ọkàn àwọn èèyàn níbi ìsìnkú Abiola Ajimobi Oríṣun àwòrán, Oyo insight Iroyin to n tẹ wa lọwọ ni wipe wọn ti gbe oku gomina ana ipinlẹ Oyo, Sẹnetọ Abiola Ajimobi bọ ilẹ ni inu ọgba ile rẹ ni Oluyole, Ibadan.
Naamani bá ní, “Jọ̀wọ́ fún mi ní ààyè láti bu erùpẹ̀ ẹrù kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ meji lọ sílé nítorí láti òní lọ, iranṣẹ rẹ kì yóo rúbọ sí ọlọrun mìíràn bíkòṣe OLUWA.
fun igbakeji aare ninu egbe APC ati iyawo rẹ Dolapo
Wayi o, leyin ijiroro lori eto isuna naa, abenugan ile-igbimo asofin Bukola Saraki gbosuba kare lai fun awon akegbe re fun ise takun-takun won lojuna ati ri daju pe eto idibo gbo-gbo-gbo o ohun waye lai si idiwo kankan bi o ti le wu ko mo.
Mo fi wọ́n lé ọ lọ́wọ́,o kò ṣàánú wọn.
Nitori naa, awọn olori tuntun naa gbọdọ tun orukọ naa ṣe.
Ọlọrun maa n fi awọn Alhaji to wa ni Arafa yangan lọrun: Ọlọrun máa fi àwọn Alhaji tó lọ sí Arafat yangàn Arafat ní ọjọ yìí.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Àwòrán àwọn ìsẹ̀lẹ̀ lọ́ sẹ̀ yìí: ‘First Lady’ wọ asọ 1.
Awon gomina ni ekun Gusu orile
Gbenga Adeyinka: Àwọn Adẹ́rinpòṣónú Nàìjíríà lè di ààrẹ Ṣaaju ni Ọgbẹni Agada fi ikede kan sita pe lọgan ti ile aṣofin kẹjọ ba wa sopin ni aṣẹ ti awọn akọroyin n lo fi ṣiṣẹ nile aṣofin naa wa sopin, ati pe akọroyin to ba fẹ ẹ ṣiṣẹ nile aṣofin kẹsan an gbọdọ tun orukọ fi silẹ.
 Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Làá hàn mí: Ètò yìí ló ń kìlọ̀ fún wa láti mú ìmọ́tótó ní pàtàkì láti dènà Coronavirus Bello wa rọ awọn eeyan ipinlẹ Oyo lati ma foya nitori arun naa, ṣugbọn ki wọn ma ṣe awọn ohun to le mu arun jina si ayika wọn, bii wiwa ni nkan bii iwọn ẹsẹ bata mẹfa si awọn elomiran ati ṣisṣọra fun ibi ti ọpọ eeyan ba korajọpọ si."
Òun ni ó ń mú ohun gbogbo kún.
Banda so fun AFP pe “mo maa je oludije nibi ipade egbe” egbe to je gbaju-gbaja julo( PP,egbe alatako)O tun so pe “Awon eniyan lagbara lati yan eni ti yoo dije labe asia egbe won ati pe inu mi dun lati pe gbogbo awon to n bo fun ipade egbe naa.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Kini Yorùbá ń pe Necklace?
O ni  “ A fe atileyin ijoba apapo  loju popo ona to jẹ ti ijoba apapo  ni ipinle Anambra; Awon oju popo ti won se
Ipese ọpọn imọ yii ni wọn ni yoo mu ki eto ẹkọ wọn tubọ ja gaara sii, bi o tilẹ jẹ pe iroyin kan n ja ranin-ranin nigba kan pe awọn eeyan kan n fi apa janu pe owo ti wọn fi ra ọpọn imọ yii kọja sisọ, ti ko si tun sisẹ pẹ, ti wọn fi kọsẹ silẹ.
Aarẹ sọ eleyi nibi ipade to ṣe pẹlu awọn adari ile igbimọ aṣofin lalẹ ọjọbọ.
A o maa fi iroyin ohun to yin leti bi o ba se n lo….
Oniruuru ahesọ ọrọ lo ti n waye nipa ipa ti awọn oṣiṣẹ Amọtẹkun yoo maa ko gan ti ẹru si n ba ọpọ pe ṣe wọn ko ni tọ ipasẹ aṣiṣe ọlọpaa pẹlu.
Ọnà ara ilé náà kọjá àfẹnusọ tí a kò le è rí lára àwọn ilé mìíràn ní àwọn agbègbè àtijọ́ọ Dhaka.
Bẹ́ẹ̀ ni òdodo mi yóo jẹ́rìí gbè mí ní ọjọ́ iwájú, nígbà tí o bá wá wo ọ̀yà mi.
Ní ọdún 1999 ni òfin Sharia bẹ̀rẹ̀ lórílẹ̀èdè Nàìjíríà nígbà ti gómìnà ìpińlẹ̀ Zamfara nígbà náà lọ́hùún, Ahmed Sanni Yerima pè fún lílo òfin Sharia láwọn ìpińlẹ̀.
won se fun un lasiko to n dupo abenugan ile igbimo asoju.
“Ẹ fi àṣẹ Ọlọrun sílẹ̀, ẹ wá dìmọ́ àṣà eniyan.
Nígbà tí Jesu yipada, tí ó rí wọn tí wọn ń tẹ̀lé òun, ó bi wọn pé, “Kí ni ẹ̀ ń wá?
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ìsúná 2018 di òfin Ènìyàn 3 kú nínú ìjàmbá afárá l’Eko 'Ọmọ Naijria ń jẹ àpò ìrẹsì 190m l'ọ́dún' Ọlọpaa kan ti orukọ ré n jẹ Prakash Sonowal fidi ré mulẹ pe, ẹrọ naa ko ti i ṣiṣẹ fun ọjọ mejila.
Dokita Ikubese ṣalaye pe, iku awọn eeyan yii tun le jẹ awọn aisan ajogunba bi ẹjẹ riru ati itọ ṣuga, ṣugbọn ayẹwo oku naa lo le sọ nkan to jẹ.
Bakan naa, ni asiko aare lorile-ede france, aare lo se ikinni “e n le n beun”  si ogunlogo awon omo orile-ede Naijiria ti o fi ile France se ibugbe, nibi ti o ti se ileri titesiwaju lati maa pese awon ohun amayederun, bee si ni mimu igberu ba eto lorile-ede Naijiria.
H5N1 ni aisan lukuluku to wọpọ ju.
Asa ṣe ohun tí ó dára, tí ó tọ́, tí ó sì dùn mọ́ OLUWA Ọlọrun rẹ̀.
Ayọ̀ ń bẹ fún àwọn tí eniyan ń ṣe inúnibíni sí nítorí òdodo,nítorí tiwọn ni ìjọba ọ̀run.
Ó dára, bí o kò bá fẹ́ kí n lọ, n óo pada.
Agbegbe ibi to dagba si jẹ ibi ti awọn ti ko lowo pupọ n gbe, amọ pẹlu gbogbo ipenija to yi ka,Moura di ilumọka agbabọọlu.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Coronavirus: Ọjoọ́ mélòó ni Coronavirus ń lò lára kí ènìyàn tó gba ìwòsàn?
Ninu idibo yii, ọgọọrọ awọn ọmọ Amẹrika ti n dibo nitori arun coronavirus eyi to tumọ si pe o ṣeeṣe ki idiwọ wa ninu kika ibo naa.
Nítorí OLUWA fẹ́ràn ẹ̀tọ́;kò ní kọ àwọn olùfọkànsìn rẹ̀ sílẹ̀.
"Iye awọn eeyan to ṣẹṣẹ ko arun naa ni ipinlẹ kọọkan ree: Eko-200 Edo-119 Kaduna-52 FCT-52 Niger-32 Ogun-19 Ondo-16 Imo-14 Plateau-11 Abia-8 Oyo-8 Bayelsa-7 Katsina-6 Kano-5 Bauchi-3 Osun-3 Kebbi-3 Borno-2 Jigawa-1 Florence Ajimobi tahùn sí igbákeji gómìnà Oyo lórí ikú ọkọ rẹ̀, ""Gbogbo wa làó kú"" Ilé ìfowópámọ́ Access ti gbà láti dá owó àwọn oníbàráà wọ́n padà Ẹ wo àwòrán bí ìsìnkú Abiola Ajimobi ṣe lọ!"
"Gbájúgbàjà kàn nínú èrè ìdárayá Collin Udoh tí fi léde lóju òpó Twitter pé òun ti bá Samson Siasia sọ̀rọ̀ àtí wi pé Siasia ní "" mí o mọ ǹkan kan nípa ọ̀rọ̀ tó wà nílẹ̀ yìí."
Ninu ọrọ̀ ti oluranlọwọ agba fun aarẹ, Garba Shehu fi sita, o ni aarẹ Buhari dupẹ lọwọ rẹ fun iṣẹ isin rẹ si orilẹede o si gbadura ifẹyinti ayọ fun un.
Aworan ẹ́rọ̀ to n pọ owo naa tiẹ se afihan eku kan to ku sinu ẹrọ naa, ti àwọn owo beba to wa ninu ẹrọ naa si ti ya wẹlẹ́-wẹlẹ.
Àwọn ọkunrin tí wọ́n lọ sin òkú náà kò rí nǹkankan àfi agbárí, ati egungun ọwọ́ ati ti ẹsẹ̀ rẹ̀.
Nígbà náà ni ọpọlọpọ eniyan yóo ṣọpẹ́ nítorí ọpọlọpọ oore tí Ọlọrun ṣe fún wa.
Lasiko to n ba ile iṣẹ amounmaworan Naijiria Channels TV sọrọ, Mahmoud ni igbesẹ naa kọdi ẹtọ Sanusi labẹ ofin ati pe ti awọn ba fi le lọ si ile ẹjọ o di dandan ki adajọ yi aṣẹ naa pada.
Amọ ni Biden ati igbimọ rẹ wa ọna lati bori awọn ipenija oṣelu, wọn si jawe olubori.
Àkọlé àwòrán, Àwọn akẹ́kọ̀ọ́ kan dunnú, àwọn míràn fajúro si iyansẹlodi Asuu Awọn akẹkọ mii ṣe alaye wipe, ifasẹhin nla gbaa ni iyanṣẹlodi naa yoo jẹ fun eto ẹkọ wọn nitori wipe wọn tii n gbaradi fun idanwo ki ẹgbẹ awọn oluko to da iṣẹ silẹ.
Nítorí èyí, láti ọ̀dọ̀ ẹyọ ọkunrin kan, tí ó ti dàgbà títí, tí ó ti kú sára, ni ọpọlọpọ ọmọ ti jáde, wọ́n pọ̀ bíi ìràwọ̀ ojú ọ̀run, ati bíi iyanrìn etí òkun.
Ọba Ilorin ló pàṣẹ pé kí ń padà sọ́dọ̀ ọkọ mi - Risikat olójú búlúù Ìgbà mẹ́ta ọ̀tọ̀ọ̀tọ̀ tí ìjọba Nàìjíríà ti gbẹsan lára orilẹ-ède mí tó dẹ́yẹsí i Oríṣun àwòrán, Sunkanmi omobolanle Sunkanmi Ọmọbọlanle gbalejo ọmọ tuntun Eekan oṣere tiata, Sunkanmi Ọmọbọlanle, ọmọ gbajugbaja oṣere, Sunday Ọmọbọlanle ti ọpọ mọ si Pappy Luwẹ ti gbalejo ọmọ tuntun ni aarin ọsẹ yii.
Musa ṣalaye wi pe, awọn bẹrẹ si ni le ọkọ 'awọn afurasi ajinigbe' naa nitori wọn kọ lati duro ni ibudo ayẹwo mẹta, ti awọn ọmọ ogun ti da wọn duro.
Idi ni pe DNA baba to fun iya rẹ loyun ati baba to n pe ni baba rẹ jẹ nnkan kannaa tori ẹbi ni wọn.
Jẹ́ kí wọn mọ̀ pé ìwọ nìkan,tí orúkọ rẹ̀ ń jẹ́ OLUWA,ni Ọ̀gá Ògo lórí gbogbo ayé.
Ìbẹ̀rùbojo gba ọkàn àwọn olùgbé Eko àti Ogun nítorí adágún omi Ọ̀yan tí yóò di ṣíṣí láìpẹ́ Báwó ni òògùn dexamethasone ṣe ń ṣiṣẹ́ lára Ilé ẹjọ́ yẹ àga mọ́ Ọba Ìkirè nìdí lẹ́yìn ọdún 27 lórí ìtẹ́ Wo ọ̀nà tí àwọn ‘ẹ̀lẹ̀ Daddy’ gbà dé ààfin Ọyọ Ìjọba tó wà lóde yìí kò ní ìfẹ́ aráàlú la ṣe dá ẹgbẹ́ NCF sílẹ̀ - Femi Falana Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Láàrín ìdílé ẹlẹ́ni márùn ún yìí, ọmọ kan ṣoṣo ló léè sọ̀rọ̀ Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Kí ẹ rí i dájú pé, ẹ kò gbàgbé àwọn ọmọ Lefi níwọ̀n ìgbà tí ẹ bá wà lórí ilẹ̀ yín.
Agbẹnusọ ileeṣẹ ọlọpaa ni ipinlẹ Eko, Olumuyiwa Adejobi, ninu atẹjade to fi lede naa ni ikọ ọlọpaa to wa ni Ikorodu lo mu awọn ọdaran naa.
“Bẹ́ẹ̀ ni kí o ṣe sí Aaroni, ati àwọn ọmọ rẹ̀ gẹ́gẹ́ bí mo ti pa á láṣẹ fún ọ; ọjọ́ meje ni kí o fi yà wọ́n sí mímọ́.
Lẹyin igba naa ni awọn eniyan tun ni wọn ti gbe e lọ si Germany fun itọju.
"Awọn eniyan gbọdọ wa ọna lati daabo bo ara wọn, paapaa awọn ọmọde nipa fifa eefin naa.
Àwọn mìíràn ń bá aya baba wọn lòpọ̀, wọ́n sì ń fi ipá bá obinrin lòpọ̀ ní ìgbà tí ó ń ṣe nǹkan oṣù rẹ̀ lọ́wọ́.
Gomina ipinlẹ Ọyọ, Abiola Ajimobi ti parọ̀wa si gomina tuntun ti wọn sẹsẹ yan, Seyi Makinde lati sọra fun ọrọ kubakugbe nipa oun ati isejọba ọdun mẹjọ oun.
ẹsun meje ni wọn fi kan an pe o fẹ ditẹ gbajọba Naijiria.
Abọ́ kọ̀ọ̀kan sì wà lórí ìtẹ̀lẹ̀ mẹ́wẹ̀ẹ̀wá.
Kuṣi bí Ṣeba, Hafila, Sabita, Raama ati Sabiteka; Raama ni baba Ṣeba ati Dedani, 
Kí ni mo fi sàn ju àwọn baba mi lọ?
Nígbà tí Dafidi ati àwọn ọmọlẹ́yìn rẹ̀ dé, wọ́n rí i pé wọ́n ti dáná sun ìlú náà, wọ́n sì ti kó àwọn aya wọn ati àwọn ọmọ wọn lọkunrin ati lobinrin lẹ́rú.
ifehonu han ohun awon odo agbegbe naa ti won pe ni, Civilian Joint Task Force
Ṣugbọn iwe ilana ofin Naijiria ni abala 174 gbe agbara fun minista eto idajọ lati pese aabo to yẹ fun ilu ati ẹtọ ọmọniyan ni eyi ti awọn kan gba pe o fi le ṣi fi El Zakzakky atawọn miran si atimọle.
Ó ń wá ibi tí yóo fi ṣe ibùgbé, ṣugbọn kò rí.
Bi a ṣe n sọrọ yii awọn agbofinro ti gbẹsẹ le aṣuwọn ifowopamọsi Wolii Alfa Babatunde Sọtitobirẹ eleyi ti awọn agbẹjọro fun Wolii naa ti kọwe si ile ẹjọ naa lati tako o.
Kàkà bẹ́ẹ̀, ikú ọ̀dọ́ ni a óo máa pe ikú ẹni tí ó bá kú ní ẹni ọgọrun-un ọdún.
Oríṣun àwòrán, Abba kyari/facebook page Àkọlé àwòrán, Ikọ̀ yìí tun ti bẹrẹ iṣẹ lori idigunjale to waye nilu Ọffa Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ọ̀pá àṣẹ jíjígbé kìí ṣe tuntun ní Naijria Ọlọ́pàá mú Sẹnatọ Omo-Agege ‘Báwo ni iléesẹ́ òfúrufú se ná 462 mílíọ́nu dọ́là?
Ohun ti awọn eeyan n sọ ni wi pe, mimu ti wọn mu akọroyin yii nii se pẹlu iroyin kan ti o kọ eleyii ti o pe akọlee rẹ ni Chibok Girls: How Swiss-Mediated Deal Revived Boko Haram"" (Itumọ eyi to ja si, Awọn ọmọbinrin Chibok: Bi idunadura ti orilẹede Swizerland se agbatẹru rẹ se tun se agbedide agbara Boko Haram)."
Ọba bá pàṣẹ, ó ní, “Ẹ dá ọ̀kan ninu àwọn alufaa tí a kó lẹ́rú pada sí Samaria, kí ó lè kọ́ àwọn eniyan náà ní òfin Ọlọrun ilẹ̀ náà.
Olu ilu Naijiria Abuja lo ṣe ipo keji nibi ti igba eeyan o le mẹfa ti lugbadi coronavirus lọjọ Abamẹta.
Oríṣun àwòrán, @OfficialSeyiMakinde Minisita feto ẹkọ, Adamu Adamu , to soju aarẹ Buhari nibi eto ti wọn fi n sami ọjọ olukọ nilu Abuja, lo sisọ loju ọrọ yii.
Ṣugbọn ó kìlọ̀ fún wọn pé kí wọn má ṣe sọ ohun tí ó ṣẹlẹ̀ fún ẹnikẹ́ni.
Ni awon  ileto Sunke ni awon odaran naa ti padanu emi
Agbẹnusọ ile iṣẹ ọlọpaa KwaZulu Natal Thembeka Mbele sọ pe atẹgun ojo lile fẹ ni agbegbe naa lalẹ ọjọbọ.
" Bákan náà lo fikùn pé, òun ni ile kan ti òun fẹ́ fi ṣe ilé ẹ̀kọ́ fún àwọn tó bá nifẹ láti kọ orin àti bí wọn ṣe leè dàgbà nínú ẹ̀mí.
A tún fi ń ye yín pé kò bá òfin mu láti gba owó ìṣákọ́lẹ̀, tabi owó bodè, tabi owó orí lọ́wọ́ àwọn alufaa, tabi àwọn ọmọ Lefi, tabi àwọn akọrin, tabi àwọn aṣọ́nà, tabi àwọn òṣìṣẹ́ tẹmpili, tabi àwọn òṣìṣẹ́ mìíràn ninu ilé Ọlọrun.
 Ọ ̀ pọ ̀ lọpọ ̀ awọ tẹ ́ ẹ ̣ ́ rẹ ́ la fi ń fa awọ ojú rẹ ̀ méjèèjì pọ ̀ .
Ni bayii, Caroline Wozniacki, ti o je olukopa ti o n gbegba oroke lowolowo ninu ipo ate idije naa, yoo ni lati fagba han Elina Svitolina, leni ti ko I ti padanu ifigagbaga kankan lati ibere idije naa,  ti o ba fe daabo bo ife-eye idije ohun ti o wa lowo re.
Ẹ jẹ́ mọ̀n pé àwọn ibìkan ń bẹ tí oòrùn kò ní wọ̀ rárá lónìí?
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Iya jẹ Anthony Joshua l'Amẹrika Eddie Hearn to jẹ onigbọwọ Joshua lo sọ bẹẹ.
Ẹ lo ìfẹ̀họ̀núhàn #EndSARS lati fí tún gbogbo ohun tó bàjẹ́ ṣe ní Naijiria- Pásítọ̀ Sam Adeyemi Nibi tawọn eeyan ti n sa yi, awọn mii sọ foonu ati nkan ini wọn nuu.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Idije UEFA Champions League Milito ni Tottenham yoo ṣe ohun ti wọn fun Ajax fun Liverpool naa, o ni ami ayo meji sẹyọkan ni Tottenham yoo fi bori Liverpool.
OLUWA, OLUWA mi, alágbára tíí gbani là,ìwọ ni o dáàbò bò mí ní ọjọ́ ogun.
Ẹ̀yin ọmọ Yorùbá lókè òkun, ẹ má bẹ̀rù mọ́ láti wálé - Akeredolu Ọmọ ti lọ kí baba, Fayemi bẹ Aláàfin wo l‘Ọyọ, wọ́n jírórò lórí lẹ́tà Awọn akọsilẹ kan sọ pe awọn oyinbo amunisin, ati awọn ijọba ologun ati oloṣelu to ti jẹ ni Ekiti ti gba awọn ọba miran wọle si igbimọ Pelupelu.
Eyii ni igba akọkọ ti wọn yoo fi ede abinibi ṣe ifọrọwerọ bayii lorilẹede Naijiria.
26 Ọ̀wàrà 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 18 Òkùdu 2020 Òpópónà Mẹ́kà mọ́ roro; àwọn èèyàn ni wọ́n n tún un ṣe to fi n rẹwà síi bi o ṣe hànde ninu awọn aworan yii.
Ẹ kò jẹ́ kí ọ̀rọ̀ rẹ̀ gbé inú yín nítorí ẹ kò gba ẹni tí ó rán níṣẹ́ gbọ́.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Africa Events: Ilẹ̀ Afrika lọ́sẹ̀ yìí nínú àwòrán!
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ẹ wo bí Amotekun ṣe gba ilẹ̀ Yoruba silẹ̀ lọ́wọ́ agbéṣùnmọ̀ní ní igba ọdún sẹ́yìn Ọ̀daràn tó bá ta féle-fèle yóò bọ́ sọ́wọ́ Amọtẹkun - Ìjọ́ba Ekiti Agbábọ́ọ́lù alápẹ̀rẹ̀, Kobe Bryant àti ọmọ rẹ̀ dèrò ọ̀run nínú ìjàmbá ọkọ̀ òfurufú Àwọn àpọ́n ọmọ Yorùbá olówó Marun tí kò tíì laya Kò dín ní ọkùnrin márùndínlógún tó ń bá mi lò lójúmọ́ Maryam ati ibatan rẹ kan, iya ati alabasisẹpọ rẹ kan si ni wọn fi ẹsun kan pe wọn ba ẹri to daju jẹ, eyi to lee fidi rẹ mulẹ pe Maryam jẹbi ẹsun ti wọn fi kan.
Igba akọkọ ni ti igbeyawo to waye laarin gbajugbaja akọroyin kan, John Raymond, ati Judith Case, ọmọ gbajugbaja agbẹjọro.
” “laipe ti aawo naa bere ni iko omo ogun ijoba de, ti won si gbemi omo ogun olote metala.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ipaniyan Benue: Buhari sepade pẹlu awọn t'ọrọ kan 22 Sẹ́rẹ́ 2018 Ninu alaye ọrọ ti wọn fi lede lori itọna twitter lẹyin ipade naa, Aarẹ Orilẹ ede Naijiria, Muhammadu Buhari seleri lati se imusẹ ileri eto aabo to muna-doko fun gbogbo ọmọ orilẹ-ede Naijiria.
O ni ikede yii ni yoo sọrọ lẹkunrẹrẹ nipa bi isẹlẹ naa se waye.
Ọkọ̀ dáńfó tí mò ń wà ní mo fi kọ́lé, rán ọmọ mẹ́ta ní fásitì - Obìnrin àkọ́kọ́ tó ń wa dáńfó l‘Eko Olúbàdàn, ẹ bá wa bẹ́ Seyi Makinde kó tú wa sílẹ̀ - Oyo NURTW Lẹ́yìn ọdún mẹ́wàá, Tokyo àti Auxillary ṣèpàdé bòńkẹ́lẹ́ NURTW yóò fikùnlukùn pẹ̀lú Gómìnà Makinde láìpẹ́ Akẹ́kọ̀ọ́ fásitì Ebonyi ló kó iba Lassa wọ Eko Ìhàlẹ̀ lásán ní NURTW ń ṣe torí pé a dínà owó tí wọn ń kó sápò - Ìjọba Ọyọ Awọn onimọ iṣegun oyinbo lo Chloroquine fun itọju iba fun ọpọlọpọ ọdun, ki o to di pe oogun naa ko ran awọn kokoro to maa n fa aisan iba mọ.
Asa ọba bá kó gbogbo fadaka ati wúrà tí ó kù ninu ilé ìṣúra ní ilé OLUWA ati ti ààfin ọba jọ, ó kó wọn rán àwọn iranṣẹ rẹ̀ sí Benhadadi ọmọ Tabirimoni, ọmọ Hesioni, ọba ilẹ̀ Siria, tí ó wà ní ìlú Damasku.
Bẹẹ ni nilu Eko, Sẹ́nétọ̀ Gbenga Ashafa ti já kulẹ̀ nínú ìdíje abẹ́le ti ẹgbẹ oṣelu APC fun ipo aṣoju ẹkùn ilà oorùn Eko (Lagos East) ni Ilé Ìgbìmọ̀ Aṣòfin Àgbà.
àbá Chisom - BBC News Yorùbá BBC News, YorùbáFò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Chisom Chukwuneke jẹ ìrora jẹjẹrẹ inú ẹjẹ̀ lásìkò tó n ṣe ìdánwò WAEC - Bàbá Chisom 26 Bélú 2020 Oríṣun àwòrán, FELIX CHUKWUNEKE Iyalẹnu nla ni yoo jẹ fun ọpọ eeyan lati gbọ pe ọmọdebinrin ti wọn ba sẹ ajọyọ bo ṣe gba A1 meje ninu idanwo WAEC rẹ lọdun 2019, Chisom Chukwuneke, ti jade laye.
Arakunrin Bisi Babalẹyẹ ni ariwo rẹ gbode pe oun pẹlu fẹ jẹran sunkunsi akẹkọọ abẹ rẹ ni ẹka ẹkọ imọ ọrọ ilẹ Okeere, International Relations lọgba fasiti naa.
A nilo atunto to pegede ninu ẹka afẹfẹ gaasi lati yee fi wọn ṣofo."
Lẹyin naa ni wọn fi ranṣẹ si orilẹ-ede Amẹrika.
Ninu atẹjade kan to fi sita, Ọmọọba Famodun ni 'adura ṣe pataki lati wawọ awọn igbesẹ awọn ẹni ibi lori lori idajọ naa.
o je ko di mimo pe oniroyin lo le je ki gbogbo ara ilu, paapaa awon obi ati
Sanwo-Olu ni olori to ṣee fi ọkan tan ni mama nigba aye rẹ ati pe ẹlẹyinju aanu ati onirẹlẹ eniyan ni.
Nígbà tí wọ́n wọ inú ibojì, wọ́n kò rí òkú Jesu Oluwa.
Amọ titi di asiko yii, ko si ohunkohun to yi pada.
Ẹnikọọkan lo ko aarun ọhun lati ipinlẹ Katsina ati ipinlẹ Oyo.
Ajọ to n gbogunti ajakalẹ arun lorilẹede Naijiria, NCDC ṣalaye pe o ti di eeyan marundinlọgbọn to ti ni arun naa bayii.
Nígbà tí àkókò ọ̀fọ̀ rẹ̀ parí, Dafidi ní kí wọ́n mú un wá sí ààfin, Batiṣeba sì di aya rẹ̀.
Irú ikú bẹ́ẹ̀ ni ẹnikẹ́ni tí ó bá fẹ́ ṣe wọ́n ní ibi yóo kú.
Oríṣun àwòrán, Nairaland Àkọlé àwòrán, Gomina ipinlẹ Ondo pin burẹdi fun awọn eniyan saaju idibo sipo gomina ni ipinlẹ Ondo.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Irokotọla: Báwo ló ṣe rọrùn láti fi àmì sí ọ̀rọ̀ yìí, ‘Irokotọla’ Ki ni ọna lati koju ibẹru lasiko idanwo?
Ìṣòfin àìdájú àti àwọn gbólóhùn bíi “ìnira” tàbí “ìwọ̀sí” jẹ́ nǹkan tí a ní láti mójútó.
Ní ọdún kejila ìjọba Ahasu-erusi, Hamani pinnu láti yan ọjọ́ tí ó wọ̀, nítorí náà, ní oṣù kinni tíí ṣe oṣù Nisani, wọ́n bẹ̀rẹ̀ sí ṣẹ́ gègé tí wọn ń pè ní Purimu, níwájú Hamani láti ọjọ́ dé ọjọ́ ati láti oṣù dé oṣù, títí dé oṣù kejila tíí ṣe oṣù Adari.
" Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Sextuplet: Àdúrà Ìbùkún ló kú lẹ́yìn ọmọ mẹ́fà yìí- Ifeoma Thelma àti Onyemaechi Chiaka Ọọni ṣalaye pe: ''Eyi yoo fun awọn oluworan lanfaani lati le ma a ri wọn gẹgẹ bi awokọṣe ni awujọ.
Bí mo bá níláti fọ́nnu, n óo fọ́nnu nípa àwọn àìlera mi.
Ninu atupalẹ iye awọn to ko arun yi, ipinlẹ Eko lewaju pẹlu eeyan 459 ti Abuja si tẹle pẹlu 145.
Ninu atẹjade kan ti Oludari Agba fun ajọ naa, Captain Musa Nuhu fi ọwọ si, NCAA sọ pe dandan ni fun awọn baalu to ba wọ Naijria lati ilẹ okeere, lati pa gbogbo ilana aabo, idena ati amojuto aarun mọ.
Eyi si maa n mu ki ọpọlọpọ eniyan ma a kopa ninu eto idibo nitori ibẹru pe nkan buruku le ṣẹlẹ si wọn.
Nígbà tí wọn bá sì gbọ́ ohun tí o ṣe sí wọn, wọn yóo sọ fún àwọn eniyan tí ń gbé ilẹ̀ yìí.
O tun tesiwaju pe ipenija ati ikolu to n sele ni awon ekun Lake Chad nilo ki awon to wa ni ekun naa fori-kori lati lee yanju awon isoro naa papọ.
Ondo Election Tribunal: APC jáwé olúborí ní ìdìbò sílé asojúsòfin
Lootọ ni orilẹede Soviet Union laye igbakan ni ojuse to fidi mulẹ ni ilẹ Afirika tẹlẹ amọ ipa rẹ ni ẹka ọrọ aje ati oselu ti dinku lẹyin ogun abẹle keji.
 Èyí ló fi dàbí ìgbà pé won kò ní àbò .
Iradi bí Mehujaeli, Mehujaeli bí Metuṣaeli, Metuṣaeli bí Lamẹki.
Nile ijọsin taa n wi yi, igbagbọ wọn ni pe mimu ọti lamupara jẹ ọna kan gbogi tawọn fi le ba Ọlọrun sọrọ .
“A wa n se ayewo si awon iwe ti a ti fowo si naa, lati se akosile re, latari a ti ri daju pe, orile-ede Nigeria fako yo ninu awon iwe adehun ti won fowo si naa.
- Oshonaike Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Kí ni Yorùbá ń pe ọmọ tí wọ́n bí lẹ́yìn Àlàbá?
8 Àti pé bí ẹ̀yin bá ṣe àwọn òfin mi ìkẹ́hìn yìí, èyí ti mo ti fi fún yín, àwọn ẹnu ọ̀nà ọ̀run apáàdi kì yíò lè borí yín; nítorípé oore ọ̀fẹ́ mi tó fún yín, a ó sì gbé yín sókè ní ọjọ́ ìkẹhìn.
 záwiyyah yí sọ ọ ̀ pọ ̀ lọpọ ̀ àwọn mukadam láti ìgbà náà títí di óní tí wọ ́ n dipọ ́ pàtàkì mú nínú agbo tijaniyya .
Ipinlẹ Eko lo ṣi n le waju.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù ICPC: Ìwádìí ti pari lóri iwe ẹ̀ri ayéderú Kemi Adeosun 15 Owewe 2018 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 18 Owewe 2018 Oríṣun àwòrán, @HMKemiAdeosun Àkọlé àwòrán, Kemi Adeọṣun kọwe fipo rẹ silẹ Àjọ tó ń ri sí ìwá ajẹbanu àti jẹgúdújẹrá lórílẹ̀-èdè Nàìjiríà (ICPC) ní òun kò ṣe ìwadìí mọ lóri ọ̀rọ̀ ìwé ẹ̀rí NYSC ayédèrú tí ó fa awuyewuye fun mínísítà owó àti ìsuná Kemi Adeosun.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Papa iṣere Leicester City, King Power ni gbigba ami ẹyẹ naa yoo ti waye Bakan naa ni Hamza Choudhury, Youri Tielemans, Ben Chilwell, Demarai Gray, Marc Albrighton, Danny Ward, Harvey Barnes, Jamie Vardy, Andy King, Kasper Schmeichel, Christian Fuchs, Jonny Evans, Fousseni Diabaté ati James Maddison yoo kopa.
Àní sẹ́, Elédùà Apàṣẹwàá ló ní kí ayé gan-an máa pòyì ararẹ̀.
O pada gbe awọn rẹkọọdu mii jade labẹ ileeṣẹ African Songs Ltd, ko to o da ileeṣẹ ti ẹ, Silky-Oluyole Records, silẹ.
Ojogbon Adewole tun tesiwaju pe “Ohun ti won gbe sile ni iwe akosile ipade kan ti won se, ko si ijoba kankan ti ori re pe to lee gba iwe ipade gege bi adehun .
Ó wá sí ẹ̀bá ibi tí mo dúró sí.
Boya ijọba Buhari yoo tẹle awọn amọran ko tii di mimọ fun araalu.
Adajọ Anthony Ombwayo ni Moi ko mu ẹri kankan wa to fi han bi o ṣe ni onilẹ naa.
Fún ọjọ́ méjì gbáko ni àríyá yìí lọ.
Ó jẹ́ balogun ọ̀rún ti ẹgbẹ́ tí à ń pè ní Ẹgbẹ́ Ọmọ Ogun Itali.
Ọga agba ileeṣẹ Amazon (AMZN), Jeff Bezos ni eeyan to lowo julọ lagbaye bayii pẹlu ọrọ to to biliọnu mejilelọgọsan dọla ($182 billion).
Bẹẹ ni o rọ awọn obi lati ri i wi pe wọn toju wọn, ki wọn si mọ wi pe awọn ọmọ yii ni aṣẹ labẹ ofin lati ri i wi pe awọn obi wọn ko fi iya jẹ wọn.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù FG Covid Palliatives: Àjọ SERAP ń wá ìdájọ́ tó tọ́ lórí rògbòdìyàn jíjí ǹkan ìrànwọ́ Covid-19 16 Ọ̀wàrà 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 25 Ọ̀wàrà 2020 Oríṣun àwòrán, SERAP Ajọ ajafẹtọ ọmọniyan kan ní Naijiria, SERAP ti ke si ajọ to n ri si ọrọ iwa ibajẹ ICPC lati tu iṣu de isalẹ koko gbogbo rogbodiyan to rọ mọ ẹsun pe ijọba kọ lati pin nkan iranwọ Covid-19 fawọn araalu.
Ọrọ naa ṣebi fakinfa ti agbẹnusọ ileeṣẹ aarẹ Garba Shehu si pada ṣalaye pe awọn ko ni tii wọgile eto naa amọ awọn ko ni jẹ ki ohun to ba awọn ile ẹkọ Almajiri ti ijọba tẹlẹ da silẹ ṣẹlẹ sawọn naa.
Wọ́n ti nà mí nígbà pupọ jù wọ́n lọ.
Awon ti o kopa ninu ipade ohun ni: Alaga egbe oselu APC, ogbeni Adams Oshiomhole, adari egbe oselu naa, Bola Ahmed Tinubu, alaga egbe naa teleri, oloye Bisi Akande.
Nígbà tí wọ́n dé ọ̀dọ̀ rẹ̀, wọ́n bi í pé, “Olùkọ́ni, sọ fún wa, ṣé ó tọ̀nà pé kí á máa san owó-orí fún Kesari ni, àbí kò tọ̀nà?
Egbe oselu All Progressives Congress (APC) ti setan lati yan oludije dupo gomina egbe naa saaju idibo gomina ipinle Osun to n bo lona.
Ṣugbọn iyalẹnu lo jẹ pé ọpọlọpọ itan ati igbagbọ ati arosọ ti ko ni ootọ ninu lo rọ mọ fifi ẹjẹ silẹ lọna ti ko tọna.
Gẹ̀ẹ́sì gbẹ́sẹ̀ lé ₦82bn owó Abacha Kò gba ẹnu Buhari láti tàbùkù ará Abuja - PDP Iṣẹ́ Kudirat Abiọla ṣì ń fọhùn síbẹ̀, lẹ́yìn ọdún 23 tó papòdà Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Ṣé o rò pé lásán ni mo wá láti pa ilẹ̀ yìí run, láìsí ìrànlọ́wọ́ OLUWA?
Lásìkò tí Dino Melaye fi wà ni ilé ìgbìmọ̀ àṣòfin àgbà l'Abuja, oríṣiríṣi àṣọ àti ìmúra to pani lẹrin ló maa ń wọ wá si ìjòkó ilé.
O sọ eyi nigba to n sọ ọrọ akọsọ rẹ lẹyin eto ifilọọlẹ ile igbimọ aṣofin ikẹsan eyi to gbe e wọle.
Àwọn olóyìnbó a máa pè’yẹn ní “Burger”.
N kò ní bínú sí ọ, nítorí aláàánú ni mí.
Melo ninú ọmọ ayé òde òni ló ránti àwọn Ọlọ́rọ̀ ilẹ̀ Yorùbá ni aadọta ọdún sẹhin?
Eto igbaradi yii waye ni olu ileesẹ ọmọogun ilẹ Indonesia pẹlu ọpọlọpọ awọn igbaradi miran ninu eyi ti wọn ti fi asọ dudu bo oju ọmọogun kan pẹlu ibọn lọwọ lati yin si ohun kan ti wọn gbe si aarin ẹsẹ ọkan lara awọn akẹgbẹ rẹ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, jkkkkk O ni ofin orilẹ-ede Naijira sọ pe awọn ile itaja ko gbọdọ to iru ọja ti ọjọ ba ti n lọ lori wọn si ori atẹ fun tita.
Wọ́n dá a lóhùn pé, “Ti Kesari ni.
Nigba ti o ṣẹlẹ, BBC News Yoruba lo ṣaaju lati tu iṣu de isalẹ ọrọ naa.
OLUWA a máa san ẹ̀san rere fún àwọn tí wọ́n bá jẹ́ olóòótọ́ ati olódodo.
Ènìyàn 653 míràn tún kún iye àwọn tó ní COVID-19 ní Nàìjíríà Wo àwọn òṣìṣẹ́ kólẹ̀-kódọ̀tí tó ń fi ẹ̀mí wọn wéwu kí Abuja leè mọ́ tónítóní Mo ti bẹ̀rẹ̀ sí ń bá àwọn tí a jọ díje nínú ìdìbó abẹ́lé sọ̀rọ̀ kí àláàfíà léè jọba - Akeredolu Wo àwọn nkan tó yẹ́ kí o mọ̀ nípa 'Awawa Boys', ọ̀kan lára ẹgbẹ́ òkùnkùn tó n dá Eko rú 4) Henry Olusegun Adeola Samuel (Seal): Ọjọ Kọkandinlogun, oṣu Keji, ọdun 1963 ni wọn bi Henry Olusegun Adeola Samuel, ti ọpọ eeyan mọ si Seal nilu London.
Ṣugbọn nígbà tí ìyọnu dé, wọ́n yipada sí OLUWA Ọlọrun Israẹli.
Idowu-Fearon,je alaga rẹ ti yoju si awon agbegbe ti wahala ti bẹ sile lati pese
Ní ọjọ́ keje, alufaa náà yóo yẹ abirùn náà wò, bí àrùn náà kò bá tàn káàkiri ara rẹ̀, kí alufaa tún tì í mọ́lé fún ọjọ́ meje sí i.
Ọgbẹni Omtata pe ẹjọ lati da'wọn pada sori afẹfẹ lẹsẹkẹsẹ ati fun ijọba lati sanwo ti wọn ipadanu gege bi owo itanran.
O ní kí wọ́n lọ gba ilẹ̀ tí o ti ṣèlérí láti fún wọn bí ohun ìní wọn.
Nípa rẹ̀ ni ẹ óo lè fi pa iná gbogbo ọfà amúbíiná tí èṣù ń ta.
Àwọn ará ilé Ọ̀tẹ̀ mú ìjόkòό ńlá, Olόyè Àbòsí sì jόkòό ní agbo ènìyàn pàtàkì pẹ̀lú ọ̀rẹ́-ẹ rẹ̀ Àgàbàgebè.
Ọdun 2010 ni ijọba ipinlẹ Ondo lábẹ́ Gomina Segun Mimiko yọ ọba naa nipo lẹyin to lu iyawo rẹ ni ìlùkulù.
Wọ́n tì í mọ́lé títí tí wọn fi mọ ohun tí OLUWA fẹ́ kí wọ́n ṣe sí i.
Mikaya bá dáhùn pé, “Gbọ́ ohun tí OLUWA sọ!
Ero awọn eeyan nipa ila kikọ Ohun to kọju s'ẹnikan, ẹyin lo kọ s'ẹlomii ni ọrọ ila kikọ jẹ laaarin awọn ọmọ Yoruba, paapa lode oni.
Àkọlé àwòrán, Ènìyàn 5,162 ló ti ni ààrùn Coronavirus ní Nàìjíríà ti èèyàn 167 si ti bá ààrùn náà rìn.
gbogbo awon  iwaasu ati ẹkọ ti ẹ ti kọ lasiko
Onyema Nwachukwu sàlàyé pé ìgbìmọ ti ilé iṣẹ́ ọmọ ogun gbé kalẹ̀ ń tẹ̀lé ìlànà gẹ́gk bi ààrẹ ṣe pàṣẹ.
Babagana Kingibe Ipinlẹ Borno naa lo ti wa gẹgẹ bi oloogbe Abba Kyari,bẹẹ lo si ti di ipo mu ni awọn ẹka ijọba l'orilẹ-ede Naijiria.
Àwọn ọmọ-ẹ̀yìn Johanu ati àwọn Farisi ń gbààwẹ̀ ní àkókò kan.
Wo àwọn tó ti dákú bíi Maina níwájú ìjẹ́jọ́ Amọ, ẹni ti wọn jọ wa lori alapupu mori bọ lọwọ awọn janduku afẹmiṣofo naa.
2 162 Erekusu Virgin Island tilẹ Gẹẹsi 1 3.
Ọgbẹni Kalu Kalu Agu, Labaran Ismail ati Hassy Jyari El-Kunis lo gbẹjọ naa lọ siwaju ileẹjọ to ga julọ, lẹyin ti ileẹjọ kotẹmilọrun fi ontẹ lu bi Buhari ti jawe olubori ninu idibo aarẹ ọjọ kẹtalelogun, oṣu keji.
Ayọ̀ ń bẹ fún orílẹ̀-èdè tí ó ní irú ibukun yìí;ayọ̀ ń bẹ fún orílẹ̀-èdè tí OLUWA jẹ́ Ọlọrun wọn.
Wọ́n fún un láṣẹ kí ó lọ pa ilé rẹ̀ mọ́, wọ́n sí dá ọjọ́ pípa rẹ̀.
    Ẹ bá mi kí gbogbo àwọn ará ilé yín, ói dùn mi pé n kò lè rí bàbá ní ijọ́sí, kí ẹ kí wọn fún mi.
Bí wọ́n bá ká ẹran ọ̀sìn tí olè jí gbé mọ́ ọn lọ́wọ́ láàyè, kì báà ṣe akọ mààlúù, tabi kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́, tabi aguntan; ìlọ́po meji ni yóo fi san pada.
Eleyi dá ìbẹ̀rù silẹ̀ ni àgbáyé pàtàki ni àwọn ilú Òkè-Òkun bi Àmẹ́ríkà ti ó ka àwọn iṣẹ̀lẹ̀ wọnyi si àfọwọ́fà ọmọ ẹda.
Awọn oluwọde ọhun tun gbe ifẹhonuhan wọn han de ọfiisi awọn ọlọpaa SARS to wa ni Magbọn nibi a gbọ wi pe awọn ọlọpaa ti yinbọn soke.
Imam tó fẹ́ ọkùnrin míì níyàwó forí kó ìjìyà òfin Owó orí VAT di 7.
''ẹ kuku mọkan naa ni o'' ''Ọlọrun a wa pẹlu yin, a dile mu'' Coronavirus ti di ara wa, kò le è kúrò mọ láéláé - WHO Wo pàtàkì ayájọ́ ‘Má wọ kọ́mú’ tó kò lónìí Ẹgbẹ́ òṣìṣẹ́ ẹ múra sílẹ̀, ìjà ń bọ̀ lórí owó oṣù tuntun lọ́jọ́rùú - NLC kéde fáráyé Ìjọba àpapọ̀ kò leè ṣùn torí ìyanṣẹ́lódì òṣìṣẹ́ tó ń bọ̀ Odunlade fijó bẹ́ẹ, Lizzy padà sọ́dún 2012, Toyin Abraham tọ̀ lẹ́ẹ̀mẹwàá Kini ọgbọn ati oye to wa ninu ki a fi ọgbọn tufọ Lode oni, awọn ọna ibaraẹnisọrọ ti mu ki awọn eeyan maa fi ọrọ ranṣẹ yala nipa atẹjiṣẹ tabi lori foonu.
4 Bẹ́ẹ̀ni, ẹnikẹ́ni tí ó bá fi dòjé rẹ̀ tí ó sì kórè, ẹni náà ni Ọlọ́run pè.
 O ṣalaye pe awọn ẹṣo alabo ti mọ agbegbe ibi ti awọn ọmọ naa wa, ati pe awọn ọmọ Naijiria yoo gbọ iroyin ayọ nipa awọn ọmọ naa laipẹ."
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù BBC Women's Footballer of the Year 2019: Wo bí o ṣe lè dìbò yan ẹni ti o bá fẹ́ 18 Ìgbé 2019 Àkọlé àwòrán, Lucy Bronze ara England, ni ife ẹyẹ naa ṣi wa lọwọ ẹ bayii Wọn ti fi orukọ awọn oludije ife ẹyẹ BBC fun agbabọọlu obinrin to pegede ju lọdun 2019 hande o si lee dibo yan ẹni ti o f ko jawe olubori bayii.
Koda, ọpọ a maa fẹ wo àwọn ǹkan ti ọrẹ́ ti gbé sórí Snapchat, Instagram àti àwọn oríṣirísí èròjà tó wà lóri ẹ̀rọ ayélujara, sùgbọ́n ó ni láti ròó dáràdára kí o to tẹ̀síwáju nítori bi yóò ṣe maa jẹ dátà rẹ.
 Eyi tun mo si pe, eto idibo gbogbogbo-o ti a ti n reti, eleyi ti ajo eleto idibo.
Nigba to ba BBC Yoruba, Alawe ṣalaye gbogbo nkan to kọ sinu lẹta ọhun lẹẹkan si, to si ni pe, ọrọ lọbalọba ipinlẹ Ekiti ko le ye Alaafin laelae, nitorinaa ko maa da si ohun ti ko kan an.
Nítoríi fóònù ìbánisọ̀rọ̀, géńdé méjì kú sínú u kọ̀ǹga l'Ékìtì Òfin ṣì gbẹ́sẹ̀lé Ẹgbẹ́ awakọ̀ èrò NURTW ní ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́ Nítorí ìkọlù àjòjì ní South Africa, èèyàn 5000 ló padánù iṣẹ́ wọn ní Nàìjíríà Fayemi to jẹ gomina ipinlẹ Ekiti salaye pe ko si ohun to dara bii ki a ri aridaju ọrọ ki a to maa fi iru ahesọ bee sita.
Ó tó gẹ́, Atikulated àti àwọn àṣà ìpolongo tó gbòde lásìkò ìbò 2019 Ogun: Amosun, ẹgbẹ́ òṣìṣẹ́ NLC fẹ́ forígbárí l'Ógùn Kamaru Usman: Ọmọ Áfíríkà àkọ́kọ́ tó gba ìgbànú ẹ̀yẹ ẹ̀ṣẹ́ kíkàn Ogun: Amosun, ẹgbẹ́ òṣìṣẹ́ NLC fẹ́ forígbárí l'Ógùn Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Buhari gbọ́dọ̀ yọ àwọn mínísítà tí kò wúlò ní sáà kejì yí-Ogundamisi Abilekọ naa to ti fi igba kan jẹ asojusofin lorilẹ-ede Naijiria sọ ninu atẹjade wi pe, ''Next Level'' ni ipinlẹ Kwara n lo.
'Àìjáfáfá àwọn panápaná ló mú kí ọṣẹ́ iná Akure pọ̀' Wòlíì Sotitobire gúnlẹ̀ sí ilé ẹjọ́ ní ìtẹ̀síwájú ìgbẹ́jọ́ rẹ̀ Wọ́n ti gbé òkú Ibidunni Ighodalo sílé ìgbókúpamọ́sí l'Eko Kẹ ba le mọ bi igbe aye awọn ọmọbinrin ti wọn da ẹmi wọn legbodo lọjọ aipe yii ṣe ri, ni BBC Yoruba fi ṣe akojọpọ itan ranpẹ nipa aye wọn.
OLUWA ń bọ̀ ninu iná,kẹ̀kẹ́ ogun rẹ̀ yóo dàbí ìjì,láti fi ìrúnú san ẹ̀san,yóo sì fi ahọ́n iná báni wí.
Ṣugbọn nítòótọ́, Ọlọrun ti gbọ́;ó sì ti dáhùn adura mi.
Minisita tun so pe awon awako
Ile Igbimọ Aṣofin Ipinlẹ Eko ti fọwọ si Abadofin
Eyin eniyan mi lokunrin ati lobinrin lorile-ede NaijiriaOni je ayajo ayeye ijoba tiwa-n-tiwa odun kokandinlogun ati odun keta ti mo gori aleefa.
Yoòbá ẹnu ọ̀gbẹ́ni náà dùn léti bí orin ewì ni.
Bakan naa ni iroyin naa ni akanse eto yii yoo seranwọ lati sedamọ awọn ọmọ ikọ Boko Haram to n sa kuro lẹkun ila oorun ariwa Naijiria, lọ sáwọn agbegbe miran nitori báwọn ọmọ ologun ṣe n finna mọ wọn.
Ìjọba Ghana fún Nàìjíríà l'èsì àwọn ẹ̀sùn tó fi kàn-án Mo ti dàgbà ọ̀jẹ̀, n kò ní díje fún ipò gómìnà ìpínlẹ̀ Oyo mọ́ - Alao Akala Ọ̀fẹ́ ni China yóò kọ́ fásítì $50M ètò ìrìnnà sí Daura ìlú Ààrẹ Buhari- Amaechi Irọ́ ni, kò sí olóyún nínú àwọn tí Tírélà pa ní Ondo ṣùgbọ́n awakọ̀ ti sá lọ- Ọlọ́pàá Ondo Ọmọdebinrin yii lọ fọ aṣọ rẹ leti odo kan to wa lẹgbẹ ile baba rẹ ni nigba ti afurasi naa kii mọlẹ.
Ariwo to si pa lo mu ki awọn oṣiṣẹ ile to ku sa wọle, ti ọwọ fi tẹ ẹ.
Iwe orukọ ori ẹrọ ayarabiasa ni wọn gbe fun wa, oun naa ni awa pẹlu yoo gbe le wọn lọwọ pada.
Àwọn ọmọ rẹ̀ sì gbé ẹ̀jẹ̀ rẹ̀ wá fún un, ó sì ti ìka bọ̀ ọ́, ó fi kan ara ìwo pẹpẹ, ó sì da ẹ̀jẹ̀ yòókù sí ìdí pẹpẹ.
Orúkọ ẹni tí ó gùn ún ni Olódodo ati Olóòótọ́, nítorí pẹlu òdodo ni ó ń ṣe ìdájọ́, tí ó sì ń jagun.
2bn fún Obanikoro Sọ àsọtẹ́lẹ̀ orílẹ̀èdè tí yóò borí ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ t'òní Wo àwọn ẹranko tí wọ́n máa figagbaga ni Egypt nínú AFCON 2019 Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Mo máa n forin mi kìlọ̀ ìwà ìbàjẹ́ láwùjọ ni -Hameen Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Nígbà tí alákọri sì dé ilé tán ńkọ́, kò tilẹ̀ mọ fáàrí kan ṣoṣo í ṣe, kò bá ayé ìwóyí mu, aṣọ rẹ̀ kò dára tó, ìrìn ẹsẹ̀ rẹ̀ kò gbádùn, oúnjẹ rẹ̀ kò sì lọ dáádáá ni ọ̀nà ọ̀fun.
Iléèṣẹ́ ọlọ́pàá: A ṣe nkan tó yẹ lórí ajínigbé tó tojú orun dójú ikú' Tá ló pá olùrànlọwọ Segun Oni?
Ní àkókò kan, àwọn igi oko kó ara wọn jọ pé wọ́n fẹ́ ọba, wọ́n lọ sọ́dọ̀ igi Olifi, wọ́n wí fún un pé kí ó máa jọba lórí wọn.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Promise Akinlade: ọmọ ọdún mọ́kànlá tó ń fi ìlù dárà bíi àgbàlagbà sọ̀rọ̀ nípa tálẹ́ǹtì rẹ Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Overweight and pot belly: Wo oríṣìí oúnjẹ márùn ún tó lè dẹ́kun ikùn yíyọ àti ara àsanjù8 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Death During Sex: Àwọn nǹkan mẹ́ta tó le ṣekú pa ọkùnrin lásìkò ìbálòpọ̀ rèé9 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 FRSC No Parking: Wo ibi mẹ́rìnlá tí o kò gbọdọ̀ gbé ọkọ̀ rẹ sí lásìkò yìí.
ÓLUWA ní, “Ẹ gbàgbé àwọn ohun àtijọ́,kí ẹ sì mú ọkàn kúrò ninu ohun tí ó ti kọjá.
Oluwo: Ọ̀ràngún ní táwọn kò bá ní kí Oluwo sinmi nílé, kò ní ṣíwọ́ ìwà àbùkù tó ń ṣe
Tabi eniyan lè rìn lórí ẹ̀yinná,kí iná má jó o lẹ́sẹ̀?
Ó dìgbà, láti òní lọ, n kò wá sí ọ̀dọ̀ yín mọ́ ẹ máa ṣe ayé yín lọ, ènìyàn yàtọ̀ sí màlékà, ará ayé yatọ sí ará òde ọ̀run.
‘‘Aare ni orile ede Naijiria ba
Láti gba ẹ̀mí là, tabi láti pa á run?
Ẹ jẹki a se akawe awọn nnkan ti owo naa le se fun ara ilu.
Seyi: Bẹ ni mo ma n lọ si Ikenne daadaa.
” O fi kun oro re pe awon ti
OLUWA ní: “Nǹkan burúkú wo ni àwọn baba ńlá yín ní mo fi ṣe àwọn, tí wọ́n jìnnà sí mi; tí wọ́n fi bẹ̀rẹ̀ síí bọ oriṣa lásánlàsàn, tí àwọn pàápàá sì fi di eniyan lásán?
Ó ranti ìfẹ́ rẹ̀ tí kì í yẹ̀, ati òtítọ́ rẹ̀sí àwọn ọmọ Israẹli;gbogbo ayé ti rí ìṣẹ́gun Ọlọrun wa.
Wọ́n bá ké ìbòòsí láàrin gbogbo èrò, wọ́n sì dọwọ́ bo Paulu, 
Mo ní, ‘N kò ní yẹ majẹmu tí mo bá yín dá, 
Buhari tun sekilo lasiko to jabo oro re ninu ipade apero ajo UNGA74 wipe:“A n kilo gidigidi fun egbe oniwa ibaje nile okere,
A bi Kashamu ni ipinlẹ Ogun ni ẹkun guusu iwọ oorun Naijiria lọjọ kọkandinlogun, oṣu karun un, ọdun 1958.
Ìwọ ọmọ mi, mo gbọ́ pé ìwọ ti ní obìnrin, jọ̀wọ́ máa tọ́jú ìyàwó rẹ, ahọ́n àti enu a máa jà, bẹ́ẹ̀ ni a kò gbọ́ nígbà kan rí, wí pé ahọ́n lọ wí fún ojú àti imú kí ó wáá parí ìjà òun àti ẹnu.
Ṣùgbọ́n nígbà ti wọ́n rìn díẹ̀, obìnrin náà béèrè ó ní, Níbo ni à ń lọ gan-an?
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Eegunjobi Omotanbaje Ajobiewe- Èébú ní wọ́n kọ́kọ́ ń bù mí nígbà tí mo bẹ̀rẹ̀ ẹ̀ṣà pípé ní Ẹwẹ, ipade naa ni awọn faramọ aba lati ṣe agbekalẹ igbimọ iwadii ti yoo tọpinpin gbogbo aṣemaṣe ti SARS ti ṣe ati awọn ẹka ọlọpaa miran.
Ó bi Abrahamu pé, “Kí ni èrò rẹ gan-an, tí o fi ṣe ohun tí o ṣe yìí?
Nígbà tí Mose gbọ́, ó dojúbolẹ̀, 
Ẹ̀yin tí ẹ̀ ń gbé ẹ̀bi fún aláre, tí ẹ sì tẹ òdodo mọ́lẹ̀.
A dúró à ń wò, à ń retí, ṣùgbọ́n ọ̀sán tún pọ́n, ó fẹ́rẹ di ìrọ̀lẹ́ kí bàbá àti ìyá wa tó wọlé.
Gẹgẹ bi Ọgbeni Rene ti salaye fun ikọ iroyin BBC ,o ni oun, iyawo oun atawọn ọmọ fọ̀n ka, nigba tawọn soja Cameroon kolu abule wọn, ti wọn si se ibẹ sakasaka, bẹẹni wọn gbẹmi ọpọlọpọ eniyan Iyaw ore ati awọn ọmọ re se alabapade iranwọ lati ọwọ awọn enikan ti wọn gbe wọn lori alupupu fun wakati gbọọrọ.
Kò sí ohunkohun tí yóo pa yín lára.
Ọmọ aráyé kò ní pókìkí ẹ̀!
Paul Biya: Kìí ṣèpàdé pẹ̀lú àwọn mínísítà rẹ̀, ilé ìtura ní Switzerland ló ń gbé
Gẹgẹ bi ọmọ Baba Sala to kede iku oloogbe naa loju opo Facebook rẹ, Adejumọ Boisala Emmanuel ti wi, Baba Lẹgba maa n se babalawo ninu ere tabi ọlọpaa.
Aṣọ ọ̀gbọ̀ tí wọ́n ṣe iṣẹ́ ọnà sí lára láti ilẹ̀ Ijipti,ni wọ́n fi ṣe ìgbòkun rẹtí ó dàbí àsíá ọkọ̀ rẹ.
Ninu ilẹ̀ náà ni àwọn ìlú wọnyi wà: Helikati, Hali, Beteni, Akiṣafu.
Awọn ileeṣẹ ibaraẹnisọrọ yoo sọ fun gbogbo onibaara wọn lati fi nọmba NIN wọn kun akọsilẹ to wa nilẹ tẹlẹ nipa wọn fun siimu.
” OLUWA Ọlọrun ló sọ bẹ́ẹ̀.
FRSC: Èèyàn mẹ́jọ ló kù nínú ìjàmbá ọkọ̀ nípìnlẹ̀ Ògùn Wo àwòrán pápá ìṣeré MKO Abiola National Stadium Ghana ti mu àwọn afurasí ajínigbé ọmọ Naijiria mẹ́ta Buhari kò tíì ṣe to lóri June 12- NADECO Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Ó ti fi ọpọlọpọ akọ mààlúù, ati aguntan, ati àbọ́pa mààlúù rúbọ.
Bi èsì ibò ti jade, Olóri Òṣèlú Ilú-Ọba, David Cameron, jade lati bá ará ilú sọ̀rọ̀.
Ṣiṣi awon ileewosan alabode ti o wa ni titipa.
Ṣugbọn agbẹnusọ fawọn musulumi Shiite, Ibrahim Musa ni irọ ni ijọba n pa, o ni El-Zakzaky ko gbero lati lọ ṣatipo nilẹ okere.
Bí mo tí ń sọ àsọtẹ́lẹ̀ lọ́wọ́ ni Pelataya, ọmọ Bẹnaya, bá kú.
 Àwọn nǹkan tí adìẹ ń jẹ náà lati ṣàlàyé nínú ìmọ ̀ ẹ ̀ rọ àbáláyé .
ìbọ̀rìṣà, oṣó, odì-yíyàn, ìjà, owú-jíjẹ, ìrúnú, ọ̀kánjúwà, ìyapa, rìkíṣí; 
Bakan naa, ni gbagede owo oke ti afihan ife-eye ohun yoo ti waye, ajo FIFA yoo ya ibe soto lati fi safihan itan idije boolu agbaye.
Wọn tun sọ ninu atẹjade naa pe awakọ kan ku ninu ikọlu ọhun, bakan naa ni wọn ko ri awọn ti wọn n jọ n rinrin ajo.
Ọpọ awon eniyan lo ti wa
O kọ lati gbe ìpè rẹ lẹyin ti oun ati akọroyin BBC kọkọ fi atẹjisẹ ba ara wọn sọrọ lori oun ti o fẹ ba a sọ.
” “ọko oju omi naa je irinse nla lati fi koju
Ó ti fi kún ayọ̀ wọn;wọ́n ń yọ̀ níwájú rẹ̀, bí ayọ̀ ìgbà ìkórè.
Ọlọ́pàá kó àwọn ọmọ ẹgbẹ́ òkùnkùn Ẹiyẹ Confraternity ni Ikorodu Laycon ni ọmọ ológo tó jáwé olúborí ní ètò BBNaija season 5 'Lockdown' Èèwọ̀!
wọ ́ n mọ ebute metta sí ṣíṣètò oúnjẹ àti àwọn aṣọ .
Nígbà tí Ọlọrun sọ pé,“Mo búra pẹlu ibinu pé,wọn kò ní wọ inú ìsinmi mi.
Ìwà obinrin alágbèrè nìyí:bí ó bá ṣe àgbèrè tán, á ṣojú fúrú,á ní “N kò ṣe àìdára kankan.
“Ògo Lẹbanoni yóo wá sí ọ̀dọ̀ rẹ:igi sipirẹsi, igi firi, ati igi pine;láti bukun ẹwà ilé mímọ́ mi,n óo sì ṣe ibi ìtìsẹ̀ mi lógo.
Ẹ̀ ń wá inú Ìwé Mímọ́ káàkiri nítorí pé ẹ rò pé ẹ óo rí ọ̀rọ̀ ìyè ainipẹkun ninu rẹ̀.
Amugbalegbe pataki fun ile-ise aare lori eto iroyin ati igbodegba, ogbeni Garba Shehu, lo jabo oro naa fun awon akoroyin pe “oju lo mo n to yo nu”  ohun ti o wa nile ti foju han gbangba-gbangba saraaye.
Wakati mẹrinla ni wọn lo ko to di wi pe wọn lo ohun igbe nkan lati fi faayọ kuro ninu ihọ naa.
Ọjọ keji lo gbe jade wi pe oun ti ni aisan naa, to si ni ki awọn eniyan fi ọkan balẹ.
Lara awọn ipinlẹ to ti gbe igbimọ naa kalẹ ree: Ọ̀pọ̀ aráàlú ló ti pàdánù ọwọ́ àti ẹsẹ wọn sọ́wọ́ jàǹdùkú - Sanwo-Olu Ẹni iyì àti akíkanjú tó ṣe gbẹ́kẹ̀lé làwọn èèyàn Akure, ilú ìyá mi - Seyi Makinde Ìwọ́de EndSARS ló ń sọ pé inú ń bí àwọn ọ̀dọ́, ìjọba, ẹ náání wọn - Obasanjo Àrùn ń bẹ lóde, ẹ̀yin olùwọ́de EndSARS, ẹ ṣọ́ra fún Covid-19 - Ìjọba àpapọ̀ kìlọ̀ Eko Ọjọ kejidinlogun, oṣu Kẹwaa, odun 2020 ni gomina ipinlẹ Eko gbe igbimọ tirẹ kalẹ.
" Saaju asiko yii ni ibẹẹrẹ ọdun 2018 ni gomina ipinlẹ Ekiti, Ayọdele Fayose ti gbe isẹ le awọn ọlọdẹ lọwọ lati daabo bo ileto koowa wọn lọwọ gulegule ikọlu awọn darandaran fulani ni ipinlẹ̀ naa.
Harani bí ọmọ kan tí ń jẹ́ Gasesi.
 ohun nikan ni o gba ebun alafia nobel leyin to se alaisi .
Lọ kéde ọ̀rọ̀ yìí sí ìhà àríwá, kí o wí pé:‘Yipada ìwọ Israẹli alaiṣootọ.
Koda, ọjọgbọn Kehinde sọ pe awọn olukọ oni ipele mẹrindinlogun si mẹtadinlogun ni wọn yoo maa ṣamojuto wọn.
Ikọlukọgba wa pọ ni El Helicoide gẹgẹ bi ọkọ to kun fun awọn ẹlẹwọn ṣe n wọ ọgba ẹwọn lojoojumọ.
Àwọn ẹranko ńlá gbogbo ni ó ti ń gbé inú ihó yìí kì n dé ṣùgbọ́n nígbà tí mo ti dé ibẹ̀ ni wọ́ọ́n ti sá jáde fún mi.
Agba oṣere ni Baba Suwe jẹ to si ti dẹrin pẹẹkẹ ọpọlọpọ ninu awọn fiimu agbelewo to ṣe ko to di pe aisan da a lulẹ laipẹ to si ti n dara ya bayii.
Soaga to tun jẹ ọga agba ile isẹ amounmaworan Naijiria, NTA Katsina ni ẹgbẹ naa sọ ninu atẹjade pe ayẹwo fihan pe o ni Covid-19.
Aare Muhammadu Buhari to n tuko orile-ede Naijiria lowolowo ti buwolu abadofin ase Aare elekarun un lati fi mu igbelaruge ba awon ohun ti a n se nile yii ninu imo sayensi, imo ero ati ohun eelo ki idagbasoke le de ba eka kookan ninu eto oro aje Naijiria.
Bi ẹ ko ba ni gbagbe, lagbegbe Akinyẹle yii kan naa lawọn oniṣẹ ibi kan ti pa awọn omidan meji, Barakat Bello ati Grace Osiagwu lẹyin ti wọn fipa ba wọn lo pọ tan.
Oríṣun àwòrán, Twitter/Ministry of Humanitarian Affairs Bakan naa lo sọ pe o yẹ ki ijọba ṣeto fawọn agbẹ lati le maa rin lai si ẹni lai ni idiwọ lasiko igbele coronavirus yii.
Aare tun gbosuba fun Alaafin nipa imoran to n fun awon ijoba ,ile-eko giga ati ebi.
Tí Mo ba fi ẹnu kò ẹni tí mo ṣẹ̀ṣẹ̀ pàdé lenu tí ó wà padà rí àpẹẹrẹ aarun náà, kini kí n ṣe?
Adajọ tun sun igbẹjọ beeli awọn afurasi naa di ọjọ kẹtalelogun oṣu kẹfa yii kan naa.
Àwọn ìwàásù akọnilẹ́nu hàà tí Prophet Israel Oladele CCC Genesis Global ti ṣe rèé Wòlíì míì, tún wọ gàù lẹ́yìn tó tàpá sí ìlànà béèlì tí wọ́n fún un nílé ẹjọ́ CCC Genesis Global: Ǹkan mẹ́wàá tí ẹ ò gbọ́ rí nípa Israel Oladele, Woli ìjọ Genesis Global Ẹ̀tanú pé Olùṣọ́ Genesis kò fẹ́ Laide Williams-Oni ló ṣe rán an lọ́ sí ẹ̀wọ̀n ọdún kan - CCC Genesis Global Ẹgbẹ awọn woli ọkunrin ati obinrin Awọn wọnyii ni ariran, agbẹnusọ, iranṣẹ, oluṣọ.
Àjọ tó n rí sí ìsẹ̀lẹ̀ pàjáwìrì lorilẹ-ede Naijiria, NEMA ti sọ pe ọwọ wọn mọ lẹyin igba ti ile igbimọ-aṣofin kekere naa sọ pe ọga agba ajọ ọhun lọwọ ninu jibiti ti o to biliọnu mẹtalelọgbọn naira.
Amọ ṣa fọnran fidio yi gbode kan koda eeyan to le ni miliọnu mẹrinla lo ti wo loju opo Facebook ki wọn to yọ kuro.
O dára dára, o ò kù síbìkan,kò sí àbààwọ́n kankan lára rẹ.
” Nítorí pé wọ́n ti gba àpótí Ọlọrun ati pé baba ọkọ rẹ̀ ati ọkọ rẹ̀ ti kú.
A máa fi fadaka ṣe ilé ìsìn ti oriṣa Atẹmisi; èyí a sì máa mú èrè pupọ wá fún àwọn tí ń ṣe iṣẹ́ ọnà yìí.
Tottenham náà yóò kọ́kọ́ lọ Newcastle, kí wọ́n to lọ gba pẹ̀lú Fulham ní Wembley, nítorí bí pápá ìṣeré wọn tuntun se parí.
A óo kó wọn lẹ́rù lọ, a óo sì wó ilé wọn lulẹ̀.
Àjọ NCDC kéde èèyàn 248 míràn tó ni ààrùn Covid-19 lórílẹ̀-èdè Naijíríà Ta ló fipá bá Jennifer lò pọ̀?
Lẹ́yìn tí Bàbá àgbà Celestine ṣe ọjọ́ ìbí ọgọ́rùn ún ọdún l'ọ́gbà ẹ̀wọ̀n ni àwọn akọ̀ròyìn kọ nípa rẹ̀.
nítorí a lè sọ pé ó wà ní ara Abrahamu baba-ńlá rẹ̀ nígbà tí Mẹlikisẹdẹki pàdé rẹ̀.
 Gbógbo ohun tí aarẹ sọ ni àwa ń ṣe."
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Justice for Richard: Òbí àkẹ́kọ̀ọ́ tó kú síléeṣẹ́ ọṣẹ ń bèèrè fún ìdájọ́ lórí ikú ọmọ wọn Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Justice for Richard: Òbí àkẹ́kọ̀ọ́ tó kú síléeṣẹ́ ọṣẹ ń bèèrè fún ìdájọ́ lórí ikú ọmọ wọn 31 Agẹmo 2020 Ọlọrun ma jẹ ka foju sunkun ọmọ laye ni adura ti obi maa n gba sugbọn to ba ri bẹẹ, Ọba oke la gbadura si pe ko tu obi ninu.
Ṣé o mọ Ààrẹ Buhari délé délé?
Awọn orilẹ-ede mẹrinlelogun ni wọn jọ maa woju ara wọn ninu idije AFCON tọdun 2019 fun igba akọkọ.
" yálà kí á pe ewì yìí ní "" ewì ayaba "" tàbí "" orin olorì "" , sibẹ ́ iṣẹ ́ kan náà ni wọ ́ n ń ṣe láwùjọ yorùbá ."
Oríṣun àwòrán, AFP/GETTY IMAGES Àkọlé àwòrán, Olori alatako lorileede Zambia Hakainde Hichilema ki ṣe aimọ fun awọn alaṣẹ nitori bi o ti ṣe n tako ijọba Zambia Lọdun 2017,awọn ọlọpaa mu gbajugbaja olori alatako kan Hakainde Hichilema lẹyin igba ti wnni o da ọkọ aarẹ lọna.
Àwọn ọjọ́ ìsìnmi tó máa wà nínú ọdún 2020 ní Nàìjíríà Ṣé àsọtẹ́lẹ̀ ìjàmbá iná kò tíì máa ṣe báyìí?
Wọ́n tò bí àwọn tí ń lọ sójú ogun,wọ́n dótì ọ́, ìwọ Jerusalẹmu!
Ajayi sọ pe awọn obi ko le mọ nipa iru iya to n jẹ awọn ọmọ yii tori wọn ko wọ ibẹ.
DR Congo gba ami ayo kinni
Àwọn Arakunrin Josẹfu Pada Lọ sí Ijipti pẹlu Bẹnjamini.
Ẹgbẹ oṣelu PDP naa ti wa ṣe ipade tirẹ lọjọ Isẹgun, nibi ti gbogbo awọn ogunna-gbongbo ẹgbẹ PDP, to ni ọrọ kan tabi omiran sọ nipa idibo ti wọn sun siwaju ati ọrọ Buhari, ti ri aaye sọ tẹnu wọn.
Ijọba ti kéde pé àṣẹ kóníléógbélé tó wà ni aagoo mẹ́fà ìdájí sí aago mẹ́jọ alẹ́ tẹ́lẹ̀ yóò sún si aagoo mẹ́rin ìdájí sí aago mẹ́wàá alẹ́ Ó ṣeéṣe kí ọkọ̀ òfurufú alábẹ́lé ó bẹ̀rẹ̀ láti ọjọ́ kọ́kànlélógún oṣù kẹfà ọdún 2020, gẹ́gẹ́ bí a ọ̀e sọfún fún àwọn ẹka náà láti ṣètò ìlànà ti àwọn yóò maa tèlé.
Gbogbo ọkàn ni mo fi dúpẹ́ lọ́wọ́ rẹ, OLUWA, Ọlọrun mi;n óo máa yin orúkọ rẹ lógo títí lae.
Iyan South Sudan: Eeyan miliọnu mẹfa ni ebi nba finra
 Àwọn àgbà Ọ ̀ jẹ ̀ nìkan ni wọ ́ n lè mọ ẹni náà .
Buhari wa kede pe iku awọ̀n eeyan naa dun oun pupọ, to si ni irufẹ ajalu bayii ko yẹ ko waye rara, ti ko si nitumọ.
Ikilọ naa wa ninu atẹjade ti oludamọran pataki fun Aarẹ Ona Kakanfo, Kẹhinde Aderẹmi fi ranṣẹ s'awọn oniroyin, nibi ti o ti safiwe awọn darandaran to n paniyan gẹgẹ bii mujẹmujẹ.
Ọgbẹni Cruz ti jẹwọ wipe oun lo yin ibọn pa eeyan mẹtadinlogun ni agbegbe Parkland to wa ni ipinlẹ Florida.
Buhari sàlàyé pé ìmọ̀ tara ẹni nìkan, wọ̀bìa àti ìwà àjẹ́bánu ti gba ọkan àwọn ọmọ ènìyàn, to fi jẹ́ pé wọn ti kọ ẹsìn wọn sílẹ̀ láti máà lépa ìfẹ́ ọkan wọn.
Sábàbí ire ní ikú Barakat padà já sí - Ẹ̀bí fẹ̀mí ìmoore hàn sọ́mọ Nàíjíríà Magu gba ₦9.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo Awọn ọlọpaa sọ pe ko si ohun to jọ bẹ to ṣẹlẹ ti wọn si ni awọn kan mọọmọ tan iroyin ẹlẹjẹ yi ka ni lati le fi d'ẹru ba awọn ara ilu ṣaaju ki wọn to ṣigun wa.
Biṣọọbu agba tun ni igbesẹ yii wa lati fun'pe si ijọba lori ọ̀rọ̀ yii.
Àwọn ará Ọwọ gé igi Ọjà láti ṣe ìdárò Ọba Folagbade Ọlateru!
miran tun ni alakoso ile-eto idajo ana lorile ede Naijiria , Muhammad Uwais,
Bo tilẹ jẹ pe, ọmi ni awọn ẹgbẹ agbaboolu naa kọkọ gba ni ori papa Boubker Aamar ni ipele akọkọ ati ikeji ifẹsẹ wọn sẹ naa.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Babangida: Èròǹgbà ọmọ Nàíjíríà pọ̀ èyí tó ṣòro láti bá pàdé 8 Ògún 2019 Oríṣun àwòrán, Twitter/Presidency Àkọlé àwòrán, Ọrọ lori orilẹede Naijiria Olori orilẹede Naijiria tẹlẹ ri, ajagunfẹhinti Ibrahim Babangida ti ṣapejuwe Naijiria gẹgẹ bi orilẹede to ṣoro lati dari.
Ipa ti aisan naa yoo ni lori igbeaye ẹni to ba mu da lori awọn obi, awujọ ati ọlaju.
Ọ̀kọ̀ọ̀kan ninu wọn ní ìyẹ́ mẹfa mẹfa: ó fi meji bo ojú, ó fi meji bo ẹsẹ̀, ó sì ń fi meji fò.
Man City gba ife ẹyẹ Premier League pẹlu ami ayo mejidinlọgọrun un nigba ti Liverpool tẹle wọn pẹlu ami ayo mẹtadinlọgọrun.
 Àjẹsára náà a má a ṣiṣẹ ́ bó ṣe yẹ nínú gbogbo àwọn oríṣiríṣi àgbéjáde wọ ̀ nyí .
O ni eyi fihan pe awọn janduku ti sa asawọ wọnu iwọde naa, wọn si ti n lo anfani iwọde ọhun lati fi dana iwa laabi kaakiri ipinẹ Eko.
O wa gba àwọn aráàlú láti gba agbẹjọro, lásìkò tí wọn ba fẹ́ tá àbí ra ilẹ̀ ati ile, kò leè bá wọn ṣe ìwádìí nípa dúkìá náà lábẹ́ òfin, tí wọn yóò sì gba ojúlówó ìwé ilẹ̀ àbí ilé náà.
Ninu ohun ta ri ka nibẹ, Ọgbẹni Meng Wei Kun ati Xu Koi fẹ fun ọga EFCC agbegbe Sokoto ni owo abẹtẹlẹ aadọta miliọnu naira ti wọn ko wa ba eleyi to jẹ idaji ọgọrun miliọnu ti wọn fẹ fun ki o ba le mẹnumọ lori iwaadi kan tajọ naa n se lori ileesẹ wọn.
Òun pẹlu Jehonadabu bá wọlé láti rú ẹbọ sísun sí Baali.
Abọ iwadii kan fihan pe iye awọn eeyan ti ebi n pa lagbaye lee gbera lati miliọnu marundinlogoje lọ si ọtalelugba o din mẹwaa milọnu eeyan.
Nígbà tí àwọn tí ó wà ninu ilé ìpàdé gbọ́ ọ̀rọ̀ yìí, inú bí gbogbo wọn.
Igbesẹ yi ko sẹyin titẹle ilana titaketesiraẹni tuntun ti ijọba gbekalẹ, eleyi ti o mu adinku ba iye eeyan to le jọsin lẹẹkan naa ninu ile ijọsin.
Iroyin idajọ iku fun arabinrin Maryam Sanda to pa ọkọ rẹ nilu Abuja, to waye lọjọ Aje, tun jẹ ohun aritọkasi pe iru idajọ iku bayii ṣi n waye ni Naijiria.
Ọjọ́ méje ni ó fi gbé inú ihò ilẹ̀ nígbà tí ó gbé iwin kan ní ìyàwó kí ó tóó di pé wọ́n tún fi ara wọn sílẹ̀.
6bn ni wọn yoo fi tẹ iwe akọsil orukọ oludibo N972m lo wa fun titẹ iwe atọna feto idiboN840m lo wa fun rira awọn irinsẹ feto idibo N730m ni wọn ya sọtọ bii ẹnawo fun yara ti wọn yoo ti maa tọpinpin bi nkan se n lọ si lasiko iboN710m ni owo fun itaniji awọn oludibo N700m ni owo to wa fun ẹnawo awọn ọmọ ilẹ okeere ti yoo tọpinpin eto idibo 2019 N630m ni Inec yoo na lori titọpinpin awọn eto idibo abẹnu ẹlẹgbẹjẹgbẹ oselu saaju ibo 2019 N587m ni owo fun itankẹlẹ iroyin jake-jado Naijiria N495m ni wọn yoo fi seto iranwọ fawọn osisẹ ajọ Inec to n kopa ninu eto idibo N286m wa fun sise amojuto eto idibo N160.
Ìnákúnàá ni alásè, bẹ́ẹ̀ ni àbúrò-o rẹ̀ Àwìn lό wà ní ìdí ọtí.
"Ìgbìmọ̀ yìí sàlàyé nínú àbájáde ìwádìí rẹ̀ pé ìwádìí fìdí rẹ̀ múlẹ̀ pé lóòótọ́ ni ọ̀jọ̀gbọ́n Akíndélé jẹ̀bi ẹ̀sùn aṣemáṣe tí kò tọ̀nà tí wọ́n fi kàn án.
Nítorí ẹnikẹ́ni tí a bá yàn láàrin àwọn eniyan láti jẹ́ olórí alufaa, a yàn án bí aṣojú àwọn eniyan níwájú Ọlọrun, kí ó lè máa mú àwọn ọrẹ ati ẹbọ fún ẹ̀ṣẹ̀ wọn wá siwaju Ọlọrun.
 Ó wà níbẹ ̀ láti dá ayé ọfọ ̀ sílẹ ̀ , láti mọ àti láti tún ọ ̀ rò-sísọ mọ , láti fikún , láti yọ kúrò àti láti mú yẹ ní oríṣìíríṣị ọ ̀ nà .
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, '500 level'' ni mo wà nígbà tí mo di adélé Ọba' O ku ifẹsẹwọnsẹ kan ṣoṣo lo ku fun Chelsea bayii lati gba a ti msaa bọọlu yii yoo fi pari.
Àkọlé àwòrán, Awọn ọdọ ijọba ibilẹ Ọyẹ 06:46am Ni afẹmọju kaakiri oniruuru ijọba ibilẹ ati awọn ilu to wa ni ipinlẹ Ekiti, kedere ni oju awọn eniyan da ti wọn si n reti ki ajọ eleto idibo kede abajade esi ibo gomina lati mọ gomina wọn tuntun.
59 Síbẹ̀síbẹ̀, àwọn wà, lati ṣe ìkìlọ̀, sọ àsọyé, gbani níyànjú, àti kọ́ni, àti lati pè gbogbo ènìyàn wá sí ọ̀dọ̀ Krístì.
Syria: Ẹgbẹ IS ni ẹgbẹ alakatakiti to fẹṣẹ mulẹ julọ ni orilẹ-ede Syria, lẹyin Iraq.
“Igba otun ti de , awon eniyan orile-ede yi ti dibo si ona otito”Ogbeni Maada Bio ti o je omo odun metalelaadota je okan lara awon oloogun ti won gba ijoba lodun 1992 nigba ti o je omo ogun odun.
Lasema ni awọn eniyan ti wọn nilo iranwọ ni agbeegbe naa to ọọdunrun eniyan, ti awọn obinrin ati ọmọde si wa ni ara wọn.
Kọmiṣọna fun amojuto ijọba ibilẹ ati oye jijẹ, Bimbọ Kọlade lo ṣeto ibura naa nileeṣẹ ijọba ibilẹ Ogbomọṣọ North.
5m péré wá, ko kópa nínú ìbò abẹ́nú fún ipò gómìnà ní Ondo àti Edo - APC kéde Àwọn dókítà ìpínlẹ̀ Eko tó ń yanṣẹ́lódì ti padà s'ẹ́nu iṣẹ́ Ọkùnrin kan gbé ‘búrọ́ọ̀ṣì ìfọyín’ mì O ni ọpọ ninu awọn eeeyan to n yọlẹ rin irinajo lati Eko lọ ipinlẹ mii lo ma n parọ pe ile wọn ni wọn n lọ jẹ ko ṣoro lati mọ awọn to n lọ ipinlẹ mii.
Nile idibo to wa ni  oju popo Ifon ,gbogbo awon oludibo ni won yege lasiko ti won n fi ero ayewo kaadi, wo kaadi idibo won.
Ó ní, ‘Ẹ dìde kí ẹ gbógun ti orílẹ̀-èdè tí ó wà ní alaafia, ati láìléwu,ìlú tí ó dá dúró tí kò sì ní ìlẹ̀kùn tabi ọ̀pá ìdábùú ìlẹ̀kùn fún ààbò.
O parowa fun ijoba lati satileyin fawon agbe olowu atawon ile ise to n se aso kaakiri Naijiria ki idagbasoke le ba okowo naa ninu ile nitori pea won eniyan Naijiria po ti won nilo iranlowo lati sa ipa won fun idagbasoke eto oro aje Naijiria.
Awọn orukọ ẹgbẹ okunkun bi i Aiye, Eiye, Vikings, Black Axe, ati Buccaneers, jẹ gbajugbaja ni Naijiria.
Adari egbe oselu Democratic Alliance (DA) Mmusi Maimane so pelu egbe oselu alatako yoku fun awon oniroyin pe, “ a gbodo gbe igbese lati lati tu ile-igbimo asofin ka, ni afikun si eyi, a gbodo seto idibo ni kiakia”.
Ó mú ọ̀pá darandaran rẹ̀, ó ṣa òkúta marun-un tí ń dán ninu odò, ó kó wọn sinu àpò rẹ̀, ó mú kànnàkànnà rẹ̀ lọ́wọ́, ó sì lọ bá Filistini náà.
Ṣugbọn ó níláti máa ṣe jẹ́jẹ́ sí gbogbo eniyan, kí ó jẹ́ olùkọ́ni rere, tí ó ní ìfaradà.
Omi náà ṣàn sílẹ̀ yí pẹpẹ ká, ó sì kún kòtò tí wọ́n gbẹ́ yípo.
Ìwà burúkú ń bẹ lọ́wọ́ rẹ̀ ìwà wọ̀bìà ń be ní oókan-àyà rẹ̀, bẹ́ẹ̀ nni ọmọ òkùnkùn ni òun í ṣe.
 Asiko ni eroja idapadabọsipo ti a n lo julọ, a n fun wọn ni aaye yii bi o ti tọ ati bo tiyẹ titi ti wọn yoo fi wa jẹwọ nkan ti wọn ti ṣe gẹgẹ bi Grace Ndawanyi adari ọgba ẹwọn awọn obinrin ni Ngoma ni Rwanda."
Ondo Election 2020: Ẹ wo àwọn olùdíje sípò gómìnà nípínlẹ̀ Ondo tó takò bàbá ìsàlẹ̀
A óo máa kó wọn tọ àwọn alufaa lọ sí gbọ̀ngàn ilé Ọlọrun wa.
Igbeyawo tawọn eeyan n jẹ ọrọ rẹ lẹnu yi si ni ti Darasimi, ọmọ gbajugbaja oṣere, olukọtan Kristẹni, Mike Bamiloye pẹlu olorin Kristẹni, Lawrence Oyor.
Ni Colombia, numba kaadi idanimọ eeyan ni yoo sọ ọjọ ti yoo anfaani lati jade; ni Serbia, wọn ti ya asiko ti o le mu aja rin nigboro sọtọ.
Bakan naa, awon asofin naa tun benu ate lu iku Hauwa Leman, ti o je osise Red Cross, eleyi ti awon omo ogun olote boko haram sekupa.
"Jazz àtàwọn orin àtijọ́ tẹ́ ò mọ̀ pé ẹ ṣì lè rí gbọ́ Iléeṣẹ́ BBC fi ètò ""Aim High"" lọ́lẹ̀ fún àwọn àkàndá ẹ̀dá Fasiti Eko ti ""Cold Room"" ni Staff Club wọn pa látàri ìwádìí BBC lórí àwọn olùkọ́ kan Ìṣesí Kunle Ọlasọpe ni mo ṣe yan iṣẹ́ akọ̀ròyìn láàyò - Lekan Alabi Ọpọlọpọ awọn eniyan lo ti pe ile iṣẹ ipooogun yii lẹjọ lorilẹ-ede America."
Ní Nàìjíríà, fún àpẹẹrẹ, Àbádòfin Òmìnira Ọ̀rọ̀ fún ọmọ ìlú ní òmìnira láti béèrè fún ìwífun lọ́wọ́ àjọ ìjọba.
" Lootọlootọ ni Kọburu Adamu ba ki ibọn rẹ, to si yin mọ Sajẹnti Timothy, to si paa loju ẹsẹ, lọrọ ba di boolọ, koo yago fun mi.
Gẹgẹ bii iroyin ti o n tẹ wa lọwọ ni yajoyajo, loni ni Yinka Ayefẹlẹ tu iroyin ayọ yii fun awọn oṣiṣẹ ileeṣẹ redio rẹ.
O gbàgbé OLUWA ẹlẹ́dàá rẹ,tí ó ta ojú ọ̀run bí aṣọ,tí ó fi ìpìlẹ̀ ayé sọlẹ̀.
Ṣé Ọlọrun a máa yí ìdájọ́ po?
Ipolongo ibo wọn mi gbogbo ilu titi.
Ẹwẹ, ile iṣẹ Aarẹ ti fesi tẹlẹ pe Aarẹ orilẹede Naijiria ana, Olusẹgun Obasanjọ ati igbakeji rẹ Atiku Abubakar, yoo jọ padanu ninu idibo Aarẹ ọdun 2019 nigbati Aarẹ Muhammadu Buhari ba jawe olubori.
Iṣẹ́ tí ó kọ́kọ́ nṣe nígbà náà ni ìsirò.
Ìpín kan ti Gadi yóo wà lẹ́gbẹ̀ẹ́ ti Sebuluni, láti ìlà oòrùn títí dé ìwọ̀ oòrùn.
1 to wa ni ọdun maarun sẹyin.
Bí mo ṣe mórí bọ́ nínú ọkọ̀ bàálù tí kò bá já - Aisha Buhari Yusuf Buhari pada de lẹyin itọju lẹyin odi Mo sọ̀rọ̀ tako ọkọ mi torí òtítọ́ - aya Bùhárí Otitọ to wa ninu ọrọ naa ree: Oṣu Kẹsan-an ni Sahara Reporters sọ pe Aisha ti kuro ni Naijiria, ṣugbọn eyi kii ṣe otitọ rara.
O ni awọn mejeeji ni wọn yọ ọpọ olorin Fuji loko ẹru lonii.
aare se abewo si gomina ipinle naa, ogbeni Dave Umahi ti oun je okan lara egbe
Oga agba naa tun se abewo si ise akanse 21 QRW to n lo lowo ni Agatu, o fi idunnu re han lori ibi ti ise gbe duro , o pase pe ki ise naa tun tesiwaju si i.
a ti ni ibasepo pelu orile ede Naijiria lati ojo to ti pe, a si ni ireti lati tun tesiwaju pelu ibasepo naa lojo iwaju.
Nígbà tí ọ̀gágun tí ó dúró lọ́kàn-ánkán rẹ̀ rí bí ó ti dákẹ́ lẹ́yìn tí ó ti kígbe, ó ní, “Dájúdájú, ọmọ Ọlọrun ni ọkunrin yìí.
Aṣọ ọmọ iléèwé tó n fa jẹjẹrẹ wọ Nàìjíríà Ṣaaju iku rẹ, oun ni akọbi awọn obi rẹ.
Lọdun 2014 ni wọn ṣe igbeyawo.
OLUWA Pe Àwọn Eniyan Rẹ̀ Pada Sọ́dọ̀.
Bo tilẹ jẹ wipe BBC ko ti fi idi ẹsun ti ọmọge arẹwa naa sọ mulẹ, ṣugbọn oṣiṣẹ ijọba Gambia nigba kan, ti ko fi orukọ rẹ sita sọ pe, oun mọ pe awọn iṣẹlẹ ti ko bojumu maa n waye nile aarẹ.
INEC fagile lataari bi apapo ibo ohun se poju bi won se lero lo.
Ọ̀rọ̀ náà wà lórí bí àwọn èèyàn Kwara bá ṣe dìbò.
“Asán ati ìbàjẹ́ ni gbogbo nǹkan tí Efuraimu ń ṣe látàárọ̀ dalẹ́.
Agbẹjọro ni iṣẹ ti Fẹmi kọ jade ni fasiti ki o to gba ọna iṣẹ tiata lọ.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ọbasanjọ fèsì lórí $16bn owó iná ọba Ekiti 2018: Báwo ni yóò ṣe rí?
Lasiko to n da ẹjọ naa, Adajọ Agba Oathman Musa sọ wi pe iwadii fihan pe ọdun 1976 ni Adeleke wọ ile iwe girama, amọ ti ko si iwe ẹri to fihan pe o jade iwe mẹwaa ni ọdun 1980.
Kini awọn gomina iha aringbungbun guusu orilẹ-ede Naijiria, (South-South) sọ?
Arabinrin Funmilayo Taiwo ti ina naa ran ile itaja rẹ sọ wi pe oun ati awọn ara agbeegbe lo ja ilekun ile naa lati lọ pa ina naa ki awọn panapana to de.
Olùdásílẹ̀, Àgbékalẹ̀, Ọ̀nà tí à n gbà rí owó àti Ẹbun: Ilé iṣẹ́ BBC dádúro gedegbe kúrò ńinú ǹkan tó le ta ẹrẹ̀ bá àwọn àlàsílẹ̀ ìlàna ìròyìn ti à ń gbé jáde.
Oṣù tuntun ni yóo run àtàwọn, àtoko wọn.
”Wọ́n dáhùn pé, “Kò fi ìgbà kan sí aṣẹ́wó kankan ní àdúgbò yìí.
Lẹ́yìn rẹ̀, Abidoni, ọmọ Hileli, ará Piratoni, jẹ́ aṣiwaju ní ilẹ̀ Israẹli.
O tun je omo egbe igbimo to n sakoso ile-ise Standard Chartered plc lati odun 2017.
Mo gbé, nítorí mo fara gbọgbẹ́!
Makinde ko ṣalai ki aburo oloogbe, Dokita Dosunmu-Awolowo ati iyawo igbakeji aarẹ Dolapo Osinbaji pẹlu igbakeji Aarẹ rẹ ku ara fẹraku.
Bakan naa lo tun mẹnuba iwa aibikita awọn oludibo gẹgẹ bii idi miran to n fa bi awọn kaadi yii ko ti ṣe tii ri eeyan wa gba wọn.
COM Àkọlé àwòrán, Wọ́n fi ẹ̀sùn ìwà ìbàjẹ́ kan alága àjọ tó n mójútó bọ́ọ̀lù àfẹsẹ̀gbá ní Ghana.
Ní tèmi, èmi óo rí ojú rẹ nítorí òdodo mi,ìrísí rẹ yóo sì tẹ́ mi lọ́rùn nígbà tí mo bá jí.
“Mo fi ara mi búra pé, ẹ kò ní pa òwe yìí mọ́ ní ilẹ̀ Israẹli.
Manchester City jẹwọ pe ẹni a ba ni aba ni Baba fun Liverpool pẹlu bi wọn ṣe din dundun iya mẹrin si odo fun Brighton.
Àwọn obìnrin gba Naijiria lọ́wọ́ ìdójútì Asaba 2018 ‘A ti rí $470.
Ni igba to n sọrọ lori ijiroro naa, Sẹnatọ to n soju ẹkun aringbungbun Bauchi lo sọ ọrọ naa nigba to n dasi ijiroro lori isẹlẹ ikọlu naa.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Èyí ni àwọn ìdí tí INEC fi sún ìdìbò aarẹ síwájú Ẹnikẹ́ni tó bá ṣáájú láti jì àpótí ìbò, ẹ̀mí rẹ̀ ló fi ń ṣeré - Buhari Ihalẹ Buhari: PDP na ìká àbuku sí Buhari lẹyìn ìpàdé wọn O ṣeéṣe ki iṣẹ́ bọ́ lọ́wọ́ ọlọ́pàá inú àwòrán 4+4 APC, PDP, CUPP kọ etí ikún sí òfin INEC Ọjọgbọn Yakubu tọka si awọn idi kan, bii eto aabo to mẹhẹ, idiwọ fun pipin eroja idibo ati awọn nkan mi i gẹgẹ bi ohun to fa a ti INEC fi sun idibo siwaju.
Jesu bá kígbe pé, “Ẹni tí ó bá gbà mí gbọ́, kì í ṣe èmi ni ó gbàgbọ́ bíkòṣe ẹni tí ó rán mi níṣẹ́.
Ofin konile o gbele tumọ si wi pe ẹnikẹni gbọdọ joko si ile lai lọ si ibi kan.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, FUTA: Àwọn mẹ́jọ ló ṣíná ìyà fún Bolu ní FUTA Gẹgẹ bi ohun ti Minisita Amaechi sọ, aadọta miliọnu dọla tii ṣe biliọnu mejidinlogun Naira ni wọn yoo na lori kikọ fasiti yi.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Daura Ruler: Ọlọ́pàá ti gba àna ẹ̀ṣọ́ ẹ̀yin Buhari silẹ̀ lọ́wọ́ ajínigbé 2 Agẹmo 2019 Oríṣun àwòrán, IRT Àkọlé àwòrán, Musa Umar pẹ̀lú àwọn ọlọ́pàá lẹyin ti ọlọpaa gba silẹ Awọn ajinigbe ti da ana ẹsọ ẹyin Aarẹ Muhammadu silẹ lẹyin oṣu meji ati aabọ ti wọn gbe.
O ni Ọlọrun fun oun ni iran nipa Trump: O sọ fun mi pe oun n wa digbolugi, ọkurin to ni igboya tori awọn iṣẹ kan wa ti oniwapẹlẹ ko lee ṣe""."
Oríṣun àwòrán, @OfficialSeyiMakinde Bakan naa ni awọn akẹkọjade ni inu awọn dun lati pada si ileewe, bẹẹ si ni awọn akẹẹgbẹ awọn fi idunnu wọn han si pipada si ẹnu ẹkọ wọn.
O ni bi o tilẹ jẹ pe awọn ọba ilẹ Yoruba ko ni agbara bi oloṣelu mọ, ohun to yẹ ni lati bọwọ fun awọn ori ade nipa titẹriba lati ki ọba.
''Bi ọga ọlọpa ko ti se ni iroyin to peye lori Boko Haram, safihan bi darudapọ ti se gbode kan labe ijọba yi.
 Ìsòro yìí ní ṣe pẹ ̀ lú ọyún tàbí tí èyàn bá ní àkóràn mrsa tẹ ́ lẹ ̀ .
lọ fi ẹjọ́ sun Mose ati Eleasari alufaa ati àwọn olórí àwọn ọmọ Israẹli níwájú Àgọ́ Àjọ pé, 
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Nkán mẹ́rin ti wọn o fi yan olórí ilé aṣòfin orílẹ̀-èdè Nàìjíríà Ìtàn ọmọ Afirika tó ló lówó jùlọ lágbàyéé rèé Ajàfẹ́tọ̀ọ́ ẹni fẹ́ gbèjà ọmọ Naijiria tí ilé oúnjẹ China kò gba láàyè Yorùbá, ọmọ ọdún mẹ́jọ tà ọmọ òyìnbò yọ nínú ayò Chess l‘Amẹrika Àlàyé àwọn orilẹ̀-èdè yìí wà nínú àtẹjade ti àjọ ìṣọ̀kan orilẹede àgbáye (UN) gbé jáde ní àyájọ ọjọ́ òní, ogunjọ oṣù kẹta ọdun 2019.
Ìgbín gun orí ẹṣin, o sì ní kí àwọn Onílù ó máa lu ìlù tẹ́lẹ̀ òun báyìí pé: 
Nítorí bí ìjì ti rí lára ògiribẹ́ẹ̀ ni ibinu aláìláàánú rí;
Ṣugbọn wọn binu gbe oku ọkunrin naa ti wọn si kọri si agọ ọlọpaa.
" Orin naa ti n mi ori ayelujara titi, o da bi ọrọ ilu gangan to jẹ pe ibi to kọ s'ẹnikan, ẹyin lo kọ si ẹlomiran.
Oríṣun àwòrán, AFP Kọmisana fun iṣẹ ṣiṣe ninu ajọ naa, Alhaji Abdullahi Magaji Harwawa, sọ pe igbesẹ ti Saudi gbe ko ya wọn l'ẹnu, botilẹjẹ pe wọn ti n palẹmọ lati bi oṣu mẹta.
Ọ́pọ́ igba lo maa n jẹ pe awọn ti a ba gbọkan le kii gba eeyan duro nitori ibi ti a ba foju si, ọna le ma gba ibẹ lọ.
 Lọjọ ade ni afunrasi ọdaran yii ṣa dede wọ ileewe alakọbẹrẹ St."
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Èmí àti Ajimobi ni a ko jọ sin Naijiria ilẹ̀ bàbá wa ṣugbọn.
Orúkọ wọn, ati bí wọ́n ṣe tẹ̀léra nìyí: Eseri ni olórí wọn, lẹ́yìn náà ni Ọbadaya, Eliabu; 
Ìròyìn ti ó gbòde ni inu iwé ìròyìn  àti lori ayélujára fi han bi àwọn Olóri Òṣèlú, Aṣòfin àgbà nla àti kékeré, òṣiṣẹ́ Ìjọba àgbà àti àwọn ti ó wà ni ipó giga ni Nigeria ti lo ipò wọn lati fi ja ilu lólè.
À ń kọsẹ̀ lọ́sàn-án gangan,bí ẹni tí ó jáde ní àfẹ̀mọ́júmọ́a dàbí òkú láàrin àwọn alágbára.
Àwọn ọmọ Nàìjíríà bu ẹnu ẹ̀tẹ́ lu NTA lórí ìgbóhùnsáfẹ́fẹ́ ìdíje bọ́ọ̀lù Zlatan: Èyí mo ṣé tó, àsìkò tó láti tèsíwájú nínú ìrìnàjò mi Ilé ẹjọ́ ni agbábọ́ọ̀lù ọmọ Nàìjíríà, Dickson Etuhu jẹ́bi ẹ̀sùn títa ìdíje Sweden Àmì ayò 2-1 ni Naijiria fi ṣàgbà Benin Republic Rudurudu ati ailọ-deede eto naa lo n bi ibeere pe ṣe ileeṣẹ amohunmaworan Naijiria ko tilẹ ṣe igbaradi kankan ki wọn to bẹrẹ afihan ifẹsẹwọnsẹ naa ni?
Akọroyin ileeṣẹ BBC News Yoruba to wa nibi igbẹjọ naa ṣalaye pe ki awọn afunrasi naa to wọ ile ẹjọ ni wọn ti kọkọ ni ki wọn fọ ọwọ wọn gẹgẹ bi ohun ti o n lọ lode bayii pẹlu ajakalẹ arun Coronavirus.
Ninu ọrọ rẹ pẹlu awọn akọroyin,Onyeama ni aifẹ ki iya jẹ awọn ọmọ Naijiria lo mu ki ohun nawo nara lati ri pe wọn pada wa si Naijiria layọ ati alaafia.
Ko pẹ si asiko naa to darapọ ileeṣẹ to n gbe orin jade, Sony Music.
Amọ, ijọba ilẹ Paraguay si fi ofin de e wi pe ko gbọdọ jade nile.
Hesekaya ọba bèèrè pé, “Kí ni yóo jẹ́ àmì pé OLUWA yóo wò mí sàn, ati pé n óo lọ sí ilé OLUWA ní ọjọ́ kẹta?
Isaaki bá se àsè fún wọn, wọ́n jẹ, wọ́n mu.
Makinde sọ pe awọn oṣiṣẹ ti iṣẹ wọn jẹ koṣeemani nikan ni yoo ma lọ si ibi isẹ wọn.
Ni ipari, ajọ OXFAM rọ àwọn ìjọba láti sa ipa wọ́n gidi kí wọ́n kásẹ̀ àrùn Covid-19 kúrò nilẹ̀, Bákan náà ni wọn ni pe ki ijọba tètè kó ọ̀rọ̀ ebi àti ìṣẹ́ kúrò nilẹ̀ kí ikú tó ní i ṣe pẹ̀lú ebi máa baa gbòde kan lẹ́yìn ti Covid-19 bá kásẹ̀ nílẹ̀.
Ilẹ̀ Aláwọ̀dúdú kún fún ọrọ̀ oriṣiriṣi, ṣùgbọ́n, iwà àpà, ojúkòkòrò, ki kó ti ilé dà si ita, àti ìfẹ́ àjòjì ju ara ilé ẹni lọ, ló fa iṣẹ́ ti ó pọ̀ ni Ilẹ̀-Aláwọ̀dúdú.
Ṣugbọn nígbà tí o bá ń ṣe ìtọrẹ àánú, má tilẹ̀ jẹ́ kí ọwọ́ òsì rẹ mọ ohun tí ọwọ́ ọ̀tún rẹ ń ṣe; 
Manchester City dáná sun Brighton, gba Premier League
Abajade aṣeyọri Hajj ọdun naa si lo duro gẹgẹ bi osuwọn ti wọn fi n wo aṣeyọri irinajo Hajj ni Naijiria titi di oni.
"Kódà, wọn tún máa ń pariwo pé kò sì ohun tí ìjọba fe ṣe, kò sì ìjọba.
Ọwọ ṣìkún òfin ti tẹ Maina, alága àná fún ọrọ owó ìfèyìntì - DSS Ẹ tètè pè fún àjọ tó ní irònú pìwàdà kó tó pẹjù- NLC/TUC Abami Ẹda ni tirẹ ni iwa jibiti ni ijọba fẹ wu ni bi wọn ṣe fẹ bẹrẹ si ni gba owo oju opopona.
 Ẹni bá láyà kó fi àmì ohùn sí ọ̀rọ̀ Konko-jabele!"
Ewe, aare dahun si ibere awon akoroyin ti won bere pe, ipese wo lowa nile lati dekun iwa ipanle tabi rogbodiyan bi o sele wu ko mo, aare so pe: “Awon osise alaabo ni o lee dahun si ibere yii, nitori pe gbogbo ipese ati awon elo pata-pata ni a ti fun awon osise alaabo lati fi sise won bi o se to ati bi o se ye saaju idibo yii.
Nítorí náà mo bẹ̀ yín kí ẹ fi sùúrù gbọ́ ọ̀rọ̀ mi.
Ọpẹ́lọpẹ́ ọpọ́n-ìtẹ̀wé Yorùbá tó tún ń bẹ lórí ẹ̀, òun ni mo fi ń kàn sí ẹ̀yin olùkàwé mi gbogbo, yálà ní ìhà'hín ni tàbí lórí Twítà.
Àwọn Ìyá àwọn ọmọ Yahoo ti ń kórajọ láti dá ẹgbẹ́ sílẹ̀ - Magu Ẹlẹ́wọ̀n tẹ́lẹ̀ gboyè ìmọ̀ ìjìnlẹ̀ méjì lọ́gbà ẹ̀wọ̀n Òní ni ẹ̀bí akọni Pius Adesanmi n ṣètò ìkẹyìn fún ogbontarigi náà Wo àwòdamiẹnu àwòrán Mọ́ṣáláṣí Ànọ́bì ní Medina!
Revolution Now: NLC ní bí agbófinró ṣe mú Soworẹ àti àwọn yókù rẹ̀ sí àhámọ́ tẹ ẹ̀tọ́ ọmọnìyàn lójú
Shuaib ní wọ́n pa irọ́ mọ́ òun láti tako Sẹ́nétọ̀ Adeleke ní ilé ẹjọ́ Ori pepele mẹrin ni Adeleke gbe ipẹjọ kotẹmilọrun rẹ le eleyi to fi n ke si ile ẹjọ to ga julọ lorilẹede Naijiria lati da idajọ ile ẹjọ kotẹmilọrun to kede Gboyega Oyetọla gẹgẹ bii gomina ti ilu dibo yan nipinlẹ Ọṣun nu.
Ni wọ́n bá lọ, wọ́n rí ohun gbogbo bí Jesu ti sọ fún wọn.
Nítorí ẹni tí ó bá pa gbogbo òfin mọ́, ṣugbọn tí ó rú ẹyọ kan ṣoṣo, ó jẹ̀bi gbogbo òfin.
Bẹ́ẹ̀ ni Ọlọrun ṣe gba gbogbo ẹran baba yín tí ó sì fi wọ́n fún mi.
Oduala Olorunrinu kii ṣe ẹni to ga pupọ ṣugbọn bi eeyan ba foju di i, yoo kan idin ninu iyọ.
bibi (  170 ibusun ode oni fu alaboyun
Nítorí òkùnkùn yóo bo ayé mọ́lẹ̀,òkùnkùn biribiri yóo sì bo àwọn orílẹ̀-èdè mọ́lẹ̀,ṣugbọn ìmọ́lẹ̀ OLUWA yóo tàn sára rẹ,ògo OLUWA yóo sì hàn lára rẹ.
Ni ojo kokandinlogbon osu kesan, odun 2018, Makinde jawe olubori gege bi eni ti yoo dije fun ipo gomina legbe oselu Peoples Democratic Party, ninu idibo gbogbo gbo ti odun 2019 nipinle Oyo.
” Wọ́n bá lé wọn jáde kúrò níwájú Farao.
- Yinka TNT Ọtí tí wọ́n fi Sanitáísà àti Methanol pò pọ̀ ṣekú pá èèyàn 86 Láti 462 sí 386, àwọn tó ní àrùn Covid-19 já wálẹ̀ ní Nàìjíríà lọ́jọ́ àbámẹ́ta Èèyàn 462 míràn tún kó COVID-19 ní Nàìjíríà l'ọjọ́ Ẹtì Ó ṣeéṣe kí àrùn Coronavirus tànkálẹ̀ gba inú afẹ́fẹ́- WHO Yatọ si eyi, anfaani ti wa fun ipejọpọ ita gbangba bi ipade, lati gba to aadọta eyan, dipo ogún ti ijọba pa laṣẹ tẹlẹ.
Idi ree ti BBC Yoruba tun ṣe woju wo ẹyin lati ṣe akojọpọ idile marun nilẹ Yoruba, ti wọn kopa ninu owo ẹru ṣíṣe nigba atijọ.
O fihan wipe awọn ọmọ ogun Naijiria ko naani ẹmi awọn to yẹ ki wọn maa da abo bo.
Gomina ipinlẹ naa, João Doria, sọ pe oun ko ni i faaye gba ìwà palapala bẹẹ, ati pe iṣẹ́ ti bọ lọwọ ọlọpaa mejeeji.
Ni ejò yìí bá tú omi jáde lẹ́nu bí odò, kí omi lè gbé obinrin náà lọ.
ohun pàtàkì tí ó jẹ ́ ààrin gbungbun èsìn ìgbàgbó tí ó dàbí òpó tí ohun gbogbo dìrò mọ ́ ni jésù .
Ṣugbọn ọ̀gágun náà dáhùn pé, “Alàgbà, èmi kò yẹ ní ẹni tí ìwọ ìbá wọ inú ilé rẹ̀.
O salaye pe, erongba ipade apero ohun ni lati se alekun ikopa awon odo ninu isejoba nipa sise agbekale abadofin ti a mo si ‘ko kere ju lati dije’ eyi ti o n lo lowo ninu ile-igbimo asofin ijoba apapo.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ronaldo ya ẹro ibanisọrọ dokita lati yẹ oju rẹ to bẹjẹ wo lori papa 22 Sẹ́rẹ́ 2018 Oríṣun àwòrán, EPA Àkọlé àwòrán, Wọn gba Ronaldo nipa lẹgbẹ oju rẹ, o si bẹrẹ si ni sẹjẹ gan Ogbontarigi agbabọọlu ẹgbẹ Real Madrid, Cristiano Ronaldo ti ja abale airi ami ayo gba wọle rẹ lori papa nigba ti o se bẹbẹ lọjọ aiku.
nitori naa,awon obinrin gbọdọ se ojuse won lati ri i pe egbe oselu APC se aseyọri ni gbogbo ọna.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù SERAP gbé Fashola lọ sílé ẹjọ́ nítorí ìpèsè iná mànàmáná 3 Èrèlè 2019 Oríṣun àwòrán, @lagosstategov Àkọlé àwòrán, Ofin ọfẹ lohun, FOI ni SERAP n lo lati fi pe Fashola lẹjọ Ẹgbẹ ajafẹtọ kan, SERAP ti gbe minisita fun ipese ina ọba, iṣẹ ode ati ile gbigbe, Raji Fashọla lọ si ile ẹjọ lori ẹsun pe o kuna lati daruks awọn ileeṣẹ agbaṣẹṣe to ni o gba owo iṣẹ ipese ina manamana lọwọ ijọba lai ṣe iṣẹ naa.
Gbajugbaja oṣere Yoruba, Jaiye Kuti sọrọ lori pataki iṣẹ ti fiimu kọọkan n jẹ ni eyi to gba iṣẹ ọpọlọ.
Bi o ti le je pe, orisirisi ikolu waye lasiko itunyansipo aare Keita lose ti o koja laarin awon omo ogun olote ati awon daran-daran, eleyi ti o gba emi opolopo ara ilu.
Ti gbongan ibi iko ohun Iṣẹn baye si naa ko gbẹyin.
Ọfà mímú ni a óo ta yín,a óo sì dáná sun yín.
Oriṣii nkan ni àwọn eeyan gba pe o n jẹ kile iṣẹ aarẹ maa parọwa fun àwọn ọmọ ilé igbimọ lasiko yii bíi.
OLUWA jẹ́ kí ọwọ́ rẹ̀ tẹ Jehoiakimu ọba Juda.
Lagos State Task Force: Lóòótọ́, a tí mú Ọlọ́páà to f'ọ̀nà ẹ̀bùrú gba owó ẹ̀yìn N100k lọ́wọ́ awakọ̀
Ǹjẹ́ o mọ̀ pé Nàìjíríà kò pa ife ẹ̀yẹ àgbáyé jẹ rí?
Oríṣun àwòrán, Getty Images Bi o tilẹ jẹ pe ileeṣẹ akoroyinjọ Reuters ti gbee sita pe eeyan kan ti awọn fi oruks bo laṣiri ṣalaye fun awọn pe lootọ ni aarẹ Omar al-Bashir ti kọwe fi ipo silẹ gẹgẹ bii aarẹ orilẹede naa.
Koda awọn to ṣe ayẹyẹ ọjọ ibi wọn laarin awọn oluwọde wa.
"Ajafẹtọẹni ọhun tẹsiwaju pe ""Awọn eeyan n ṣe oriṣirisi ibajẹ lai lo ẹrọ ibanisọrọ, ko di igba ti wọn ba sọ pe eeyan kan ko gbọdọ lo ju simu mẹta lọ ki eto abo ilẹ wa to ṣenu ire."
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Oluwo ilu Iwo ba BBC Yoruba sọrọ lori awuyewuye pẹlu awọn Ọba Bakan naa ni Agbowu tun n fẹ ki ile ẹjọ ni ki Oluwo fun oun ni miliọnu kan Naira gẹgẹ bi owo ti oun fi pe lẹjọ.
Ṣugbọn Jerusalẹmu yóo yọ kedere láàrin àwọn ilẹ̀ tí ó yí i ká, láti ẹnubodè Bẹnjamini, lọ dé ẹnubodè àtijọ́ ati dé ẹnubodè Igun, láti ilé-ìṣọ́ Hananeli dé ibi tí wọ́n ti ń pọn ọtí fún ọba.
“Kí ni o fẹ́ kí n ṣe fún ọ?
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Lesbianism: Àwọn ará South-Africa yarí 'torí gbọ̀ngàn kọ̀ ìgbéyàwó abo-sábo 20 Sẹ́rẹ́ 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 21 Sẹ́rẹ́ 2020 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Àwọn ará South-Africa yarí 'torí gbọ̀ngàn kọ̀ ìgbéyàwó abo-sábo Awọn ọmọ ilẹ South-Africa kan ti kọ jalẹ lẹyin ti ile igbafẹ kọ lati fun wọn ni gbọngan igbalejo wọn lati fi ṣe iyawo abo si abo.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Victor Agunbiade ni ojú àlá ni Ọlọrun ti yan iṣẹ́ ọmọ ogun ojú omi fún òun ní America Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Kano lack of burial ground: Àìtó ibójì ti ń fa awuyewuye ní ìpínlẹ̀ Kano- Àwọn òṣìṣẹ́ ibojí13 Ògún 2020 Fídíò, Alaafin: Olori Aanu Adeyemi aya Oba Lamidi Adeyemi ti ìlú Oyo ní ohun tó bá kúkú wu ọmọ láti jẹ kìí.
Ninu atẹjade ti wọn fi lede naa ni wọn ti sọ aidunnu wọn lori rogbodiyan to bẹ silẹ ni ipinlẹ Edo, eleyii to ti da ipaya silẹ saaju idibo sipo gomina ti yoo waye nibẹ ni osu to n bọ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Abule Ado explosion: Irọ́ ńlá ní NNPC pa lórí ìbúghbàmù Abule Ado níbí tí ẹ̀mí èèyàn 23 Awọn ti iwadii naa kan ni Atiku Abubakar, Rukaiyatu Atiku Abubakar, Amina Atiku Abubakar, Massimo Del Celo, Uyiekpen Gboyega Giwa-Osagie ati awọn ileeṣẹ Tanjay ati ileeṣẹ GTCN.
Oríṣun àwòrán, Efem Àkọlé àwòrán, Ìdí ti àwọn kọmísọna ṣe to láti kí ìyáwó gómìnà tuntun káàbọ̀ Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Portugal naa si ti kede konile o gbele, bẹrẹ lati Ọjọru.
Bí Baba-onírùngbọ̀n-yẹ́úkẹ́ ti parí ọ̀rọ̀ rẹ̀ tán ni ìránńṣẹ́ rẹ̀ kan tí ìsàlẹ̀ ilé náà wá, ó wí fún un pé àwọn àlejò dá fún un, gbogbo wa si sọ̀kalẹ̀ láti lọ wo àwọn àlejò náà.
Bi o tilẹ jẹ pe ofin ilẹ wa ko gba awọn ọba alaye laaye mọ lati maa kopa ninu oselu, amọ o yẹ ki wọn fi igbe aye Ọba Adesọji Aderẹmi se awokọse rere.
Wọn lo atẹjade naa lati ki awọn ajafẹtọ ọmọmiyan, awọn akọroyin, ati gbogbo eeyan to gbaruku ti ẹgbẹ Shiite nigba ti wọn n ṣe iwọde lati beere idajọ otitọ fun El-Zakzaky ati iyawo rẹ atawọn ti awọn ologun pa niluu Zaria.
Afurasí márùn ún pa Memunat Ẹlẹ́ja àti ọlọ́kadà, wọ́n pín ẹran ara wọn sí yẹ́lẹyẹ̀lẹ Ṣaaju awọn onimọ yii ti kọkọ sọ ọ ti wọn si fi atẹjade sita ninu oṣu kẹjọ ọdun nigba ti wọn kọkọ ri i ṣugbọn awn eeyan ko fibẹẹ gbagbọ.
Won ni koda awọn pa awọn olori boko Haram miran sii labule Taye.
O rọ ile igbimọ aṣofin kẹsan an to sẹṣẹ bẹrẹ iṣẹ lati ya owo kan s'ọtọ gẹgẹ owo iranwọ fawọn ti ko rọwọ họri.
Ado-oloro ogun agbaye keji, World War II bomb ti awon omo-ogun sawari re ni papa-ko ofurufu lasiko ise ikole nilu London lojo isegun(Tuesday), ni won ti lo ju sinu agbami okun bayii.
“Àwọn ọmọ Israẹli yóo wá mi, n óo sì bú bíi kinniun; lóòótọ́ n óo bú, àwọn ọmọ rẹ̀ ọkunrin yóo sì fi ìbẹ̀rùbojo jáde wá láti ìwọ̀ oòrùn; 
O óo di arúgbó kí o tó kú,gẹ́gẹ́ bí ọkà tií gbókí á tó kó o wá síbi ìpakà.
Ewe, won bi Lassoued si United Arab Emirates, O si je iran Libya ati Tunisia, sugbon o gbe nilu Syria fun opolopo odun.
Coronavirus: Gbogbo ilé ẹ̀kọ́ alákọ̀ọ́bẹ̀rẹ̀ àti girama yóò wá ní titipá ní Italy
Ta ni ó dàbí OLUWA láàrin àwọn ẹ̀dá ọ̀run?
Amọ Alaafin ṣalaye pe awọn kan ti wọn n pe ara wọn lọba loun n sọ nipa awọn kii ṣe awọn ọba laye bi Ọọni Ile Ife, Awujalẹ ti ilẹ Ijẹbu, Owa Obokun Ileṣa, Alake ti ilẹ Ẹgba ati bẹẹ bẹẹ lọ.
Ni pataki, o ni ki a ma gbagbe pe mọlẹbi wa se pataki pupọ.
Sùn kalẹ̀, kí á sì tẹ́ ọ sọ́dọ̀ àwọn aláìkọlà.
Ẹ ti gbọ́ nípa Jesu, a sì ti fi òtítọ́ rẹ̀ kọ yín, 
Gbogbo agbára ni obìnrin náà fi ń ṣiṣẹ́ lọ́dọ̀ wa, bẹ́ẹ̀ ni ọ̀pọ̀lọpọ̀ ọmọ tí wọ́n bí lójú rẹ̀ tiwọ ilé ọkọ láti ọjọ́ pépẹ́ a kò gbọdọ̀ gbàgbé obìnrin yìí láéláé.
O óo wá mọ̀ nígbà náà pé èmi ni OLUWA,ojú kò ní ti àwọn tí ó bá gbẹ́kẹ̀lé mi.
Ẹ yọjú sí FBI bí ẹ kìí bá ṣe ''yahoo boys'' - Abike Dabiri-Erewa Amẹ́rika dá akẹ́kọ̀ọ́ padá nítori Facebook A kó dúkòkò mọ́ Ambode, isẹ́ wa là ń ṣe - Ilé Aṣòfin Eko Gómìnà mẹ́rin yóò jẹ́jọ́ lẹ́yìn sáà wọn - EFCC Oríṣun àwòrán, @FBI Friday salaye sii pe, iwadii ti wọn n ni lati mọ ibaṣepọ to wa laarin awọn afurasi ni orilẹ-ede yi ati awọn ojugba wọn to wa loke okun.
ati pé o tilẹ̀ ti yan àwọn wolii láti máa kéde nípa rẹ ní Jerusalẹmu pé, ‘Ọba kan wà ní Juda.
Ipo yìí ni ahọ́n èèmọ̀ yìí dúró sí fún ìyàwó mi, ahọ́n tí ó gbà lọ́wọ́ Àjàkálẹ́-àrùn ti i ṣe ìyàwọ mi, ahọ́n tí ó gbà lọ́wọ́ Àjàkálẹ́-àrùn ti i ṣe ìyàwọ Ikú lọ́jọ́ ìgbéyàwó wa.
Ẹ ṣe gáfárà fún ìwúkàrà àwọn Farisi ati Sadusi.
Jàǹdùkú ló fẹ́ pa mí, kìí ṣàwọn ọ̀dọ́ tó dìbò yàn mí bíi gómìnà - Oyetola Gomina ipinlẹ Osun, Gboyega Oyetola ti sọ pe, awọn janduku kan lo gbiyanju lati gba ẹmi oun, nibi rogbodiyan iwọde End SARS to waye ni ilu Osogbo lọjọ Satide.
Kìkì agbára ni ọrùn rẹ̀,ẹ̀rù jẹ̀jẹ̀ sì ń bẹ níwájú rẹ̀.
Ìtàn ayé Shina Rambo, adigunjale tó fi oyún 27 gún ọṣẹ Ipa tí Fathia Balogun kó nínú bí mo ṣe dèèyàn lágbo òṣèré fíìmù Yorùba rèé - Baba Ijesha Èèyàn 16 kú lẹ́yìn tí bàálù Air India já lulẹ̀ , tó sì kán sí méjì ní Kerala Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ohun tẹ́ẹ gbúdọ mọ nípa kókó orí ọyàn yín lásìkò fífọ́mọlọ́yàn Saheed Osupa ni oun ko ni lọkan lati se oselu bayii nitori oun jẹ olooto eniyan ti awọn eniyan fọkan tan.
ọmọ Iṣari, ọmọ Kohati, ọmọ Lefi, ọmọ Israẹli.
Ẹ fi àṣà ìbílẹ̀ yín yí ọ̀rọ̀ Ọlọrun po.
 Egbejule se pelu gomina naa kan si gomina naa
"Aisi isẹ nilu lo mu wa bẹrẹ isẹ abani fi nkan ránṣẹ.
Jẹ́wọ́ ohun tí o ṣe, má fi pamọ́ fún mi.
Igbeyawo ati Idile Wole Soyinka Iyawo aarọ Wole Soyinka, Barbara Dixon ti wọn si ni ọmọ̀kunrin kan, Olaokun Soyinka.
Ìgbà tí wọ́n ṣe àwọn méjéèjì ní ọ̀sọ́ báyìi’tán wọ́n gbé wọn sí inú kẹ̀kẹ́ wọ́n si ń yí wọn lọ.
Angẹli yìí tún sọ fún un pé, “Da aṣọ rẹ bora, kí o máa tẹ̀lé mi.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Àjẹ́, eégún, kí ni wọn ò pè mí tán tórí Vitiligo lára mi' Ọdun mẹta ni Frank Lampard lo ni Stamford Bridge, awọn alaṣẹ Chelsea si ti fi igbẹkẹle wọn han pe asiko to yẹ ẹ gan lo pada wa yii gẹgẹ bii oluksni wọn.
' Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí 6:18 Fídíò, Natalia Mufutau ìyá Yakub, Kamil àti Adam sọ̀rọ̀ lórí bí wọ́n ń sọ èdè mẹ́rin pàpọ, Duration 6,1831 Ògún 2020 Fídíò, Yoruba Language: Akomolede ati Asa Yoruba tọ̀sẹ̀ yí rèé lẹ́nu olùkọ́ wa30 Ògún 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Da Àgbàdo rẹ fún ọjọ́ mẹta ninú omi tútù tàbi omi gbi gbóná
 lẹ ́ yìn èyí , ó dá ilé iṣé ọnà sílẹ ̀ ní clifton park , new york ; àti new york city , níbi tí ó ti ń ṣe iṣẹ ́ ọnà pẹ ̀ lú ọ ̀ dà àti àwọn àwọ ̀ olómi lóríṣiríṣi .
Ọjọ kẹrindinlọgbọn, oṣu kan naa ni ijọba ipinlẹ Eko fi ọrọ lede pe arun Covid-19 lo da ẹmi gomina tẹlẹri naa legbodo.
Amọṣa, pẹlu bi ajakalẹ arun coronavirus ṣe kan ọrọ aje gbogbo aye, awọn ti jaa walẹ si ẹgbẹrun kan ati ẹgbẹrun mẹrin tabi mẹrin abọ.
ohun di mimo lasiko ti eni owo Ndudi Elumelu, ti o je oludari awon omo egbe keekeke
Dàkun máse gba àdúrà ìgbéga nítorí ẹ̀dá kan kò ní gòkè ọlà;
Khadijah lo yi aṣa yii pada pe oun fẹ ki awọn obinrin Bangladesh bọ ninu igbekun aṣa yii, paapaa awọn ti ololufẹ wọn ko yara ninu igbesẹ to yẹ fun iyawo.
Oríṣun àwòrán, Wolii arole O wu mi kì ń ṣe sinima àti show tèmi, kí n sì ni studio tèmi náà, Bẹ́ẹ̀ si ni èdè òyìnbó yọ lẹ́nu mi pẹ̀lú, bí mo ṣe leè ṣe awada ni ojúlówó èdè Yoruba náà ni awada tún dùn lẹ́nu mi ni èdè gẹ̀ẹ́sì, mo sì ni eto fún méjèèjì pẹ̀lú ni ọjọ́ iwájú."
5 27881 Orilẹede Malaysia 384 1.
Igbimo asofin Sudan to yẹ ki wọn se atunse lori ofin orile ede naa ti
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ìjọba àpapọ̀ ti ń wádìí #EndSARS 'Àwọn SARS ló yìnbọn pa ìyá mi' Ayefẹlẹ: Ìjọ̀ba ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́ kò fẹ́ òótọ́ ní wọ̀n ṣe fẹ́ wó iléèṣẹ́ rédíò mi Bákan náà ní ilé-iṣẹ́ ọlọpàá tun ni àwọn ń fọjú ẹ ba ilé ẹjọ nítorí pe àwọn tun fi ẹsun kàn-án pé ó tẹ ojú ofin láti tú àṣírí tí kò yẹ kó tú, pẹlú ṣíṣẹ̀ sí ofin ori ayélujara, ni èyi ti o ti jẹ́wọ si tí o si ti ṣetan láti jẹjọ.
Oríṣun àwòrán, Presidency Ọpọlọpọ aawọ lo ti waye laarin awọn oloye ẹgbẹ APC ati laarin awọn ọmọ ẹgbẹ APC lati igba ti ẹgbẹ yii ti bẹrẹ.
Lẹ́yìn náà, mo wo orí àwọn Kerubu, mo rí kinní kan róbótó róbótó, wọ́n dàbí òkúta safire, ìrísí wọn dàbí ìtẹ́.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Olaitan Olamide: mò lè má nílò ìwé ẹ̀rí mi tí mo bá parí ní LASU Osu Kẹjọ, ọdun 2018 ni awọn obi naa gbe awọn ọmọ naa wa si ile iwosan leyin ti wọn bi awọn ọmọ ibeji ọhun.
Lẹsẹkẹsẹ a tún gbé aṣọ náà lọ sókè ọ̀run.
Inú rẹ̀ dùn nítorí pé ó ti mu ọtí ní àmupara.
Lẹ́yìn ẹ̀fúùfù náà, ìṣẹ̀lẹ̀ kan ṣẹ̀, gbogbo ilẹ̀ bẹ̀rẹ̀ sí mì tìtì.
Oludije ninu egbe oselu alatako kan gboogi lorile-ede Sierra Leone, ti a mo si, Sierra Leone People’s party, Julius Maada ni o n gbegba oroke bayii ju Samura Wilson Kamara, ti o je oludije dupo egbe oselu to wa lori alefa, ti a mo si All People’s Congress.
 university of south alabama ní ilẹ ̀ amẹ ́ ríkà nígbà tí ó jẹ ọmọ ọdún mẹ ́ wàá àti oṣù mẹ ́ rin .
Mo tun kii  yin ku ori-ire pe, inu yin dun pe mo jawe
Juda bá bèèrè pé kí ni ó fẹ́ kí òun fi dógò.
Awọn eeyan miran gan san ẹgbẹrun lọna aadọta naira.
O ni orí àti ojú tí o dàbí ti ènìyàn gan-an, bí ènìyàn lo sì ṣe ń sọ̀rọ̀, ṣùgbọ́nláti èjìká sí isalẹ pátápátá, ti ìnàkí ni.
ijoba apapo ba fẹ  ki won da sii.
Awọn ero s'ọrọ lori ohun to ṣ'okunfa ijamba baluu Dana Ọkọ ofurufu Dana ya wọ'gbo ni papakọ ofurufu Port-Harcourt Wọn ti n ṣe iwadi lorin nnkan to ṣ'okunfa iṣẹlẹ naa, ti awọn iroyin to takorawọn si n jade nipa iṣẹlẹ naa.
Ajo Helpline foundation, Link for Help Foundation ati Empowerment Support Initiative seto iranwo to ye fun egbe ki eto yii le kogoja.
O tesiwaju pe, orile ede Naijiria ko gbọdọ  maa gba awon ọja wọle lai jẹ pe won lowo ninu iwadii lati mu idagbasoke ba imo sayensi ati eyi ti won yoo fi lee fẹgbẹkẹgbẹ pẹlu awọn orile ede lagbaaye.
“Bí mo bá gbójú lé wúrà,tí mo sì fi ojúlówó wúrà ṣe igbẹkẹle mi,
Ṣe iṣẹlẹ ifipagbajọba mii le waye?
Nígbà tí gbogbo àwọn ọmọ Israẹli rí i bí iná ati ògo OLUWA ti sọ̀kalẹ̀ sórí tẹmpili, wọ́n dojúbolẹ̀, wọ́n sin Ọlọrun, wọ́n fi ọpẹ́ fún un, “Nítorí pé ó ṣeun, nítorí pé àánú rẹ̀ wà títí lae.
O ni awon ti Mexico ati Zee World je awon ti o saaju ninu awon ti ko ni iwe ase ni Naijiria.
Nítorí náà, ẹ gbọ́ ète tí OLUWA pa lórí Edomu, ati èrò rẹ̀ lórí àwọn tí wọn ń gbé Temani.
(àwọn wọnyi ni ọmọ tí Rakẹli bí fún Jakọbu ati àwọn ọmọ ọmọ rẹ̀.
Elo gaan lo n gba losu?
A jọ ṣe ìyàwó pọ̀, a jọ bímọ ní ọjọ́ kan náà, a tún jọ máa ń ṣàìsàn pọ̀ ni Man U gbiyanju lati gbayo keji wọle, amọ Deli Alli sọ ere bọọlu ọhun di ọmi alayo kọkọkan.
Oríṣun àwòrán, Others Amọṣa, ohun ti ọkan lara awọn ọgagun agba kan fi to ileeṣẹ iwe iroyin abẹle kan leti ni pe, awọn agbebọn Boko Haram ni wọn de wọn l'ọna.
Mo si n bi ara mi leere pe Oluwatoyin ki lo de to n le òjìji aye kiri nigba to jẹ pe Ọlọrun lo ni aye rẹ?
Iṣẹ olukọ àwọn ewe ni Larisa Mikhaltsova n ṣe tẹlẹ ni eyi to ti ṣe fun odindin ogoji ọdun.
Bakan naa ni Ọjọgbọn Gambari ṣiṣẹ labẹ akọwe agba ajọ iṣọkan agbaye ninu ọrọ oṣelu laarin ọdun 2005 si ọdun 2007.
Eyi ni fidio ti Ọgbẹni Usman ya lẹyin ti wọn gbe ejo naa jade kuro nile iyagbẹ.
Àwa ọba alayé ń wọ́nà láti ṣẹ́ eegun ẹ̀yin ọ̀daràn Fulani - Ọọ̀ni Ẹ sọ ìwé kíkà di dandan fún ẹ̀yà Fulani - Oluwo rọ ìjọba àpapọ̀ Fulani nìkan kọ́ ló ń pa ènìyàn ní Naijiria -Tinubu Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Mo fi iṣẹ́ Banki silẹ̀ lọ bẹ̀rẹ̀ alápatà - Derin Bi ẹ ko ba gbagbe, maluu mẹrindinlogoji ni ara kọkọ san pa ni ilu Ijarẹ ni ipinlẹ Ondo lẹyin ti awọn adari ilu naa ni ori ilẹ aiwọ ni wọn ti ri awọn maluu naa ati pe titasẹ agẹrẹ wọn lo ṣokunfa iṣẹlẹ naa.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Champions League: Barca da yẹpẹ sí gaàrí Man U ní Old Trafford 10 Ìgbé 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 11 Ìgbé 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Champions League Aileja lojude ile baba mi ko debi.
Ninu ikede kan ti ijọba ipinlẹ Ekiti fi sori ayelujara Twitter rẹ, ni a ti ri ọpọ aworan to n safihan bi Alaafin se tẹwọ gba Fayemi tọwọ-tẹsẹ.
Insecurity: Àwọn aráàlú ní ìpànìyàn àti ìgbéṣùnmọ̀mí ni kò jẹ́ kí ẹnu sìn lára Buhari
Alufaa yóo fi wọ́n rúbọ: yóo fi ọ̀kan rú ẹbọ ìmúkúrò ẹ̀ṣẹ̀, yóo sì fi ekeji rú ẹbọ sísun.
OObjection : Eyi ni igbese kotẹmilorun ti awọn
” Ó bá lọ wádìí ọ̀rọ̀ náà wò lọ́dọ̀ OLUWA.
Aare Buhari lọ si ipinle Eko ,
Ilẹ̀ náà dàbí ọgbà Edẹni níwájú wọn,ṣugbọn lẹ́yìn wọn, ó dàbí aṣálẹ̀ tí ó ti di ahoro,kò sì sí ohun tí yóo bọ́ lọ́wọ́ wọn.
Sam Dede – In My Country
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Dino Melaye nánwó fún Ayefẹlẹ lójú agbo Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Saulu bá dá a lóhùn pé, “O ṣeun, jẹ́ kí á lọ.
O ní bi aṣé n sọ̀rọ̀ yìí kò si àwọn èròjà ìdáàbò ara ẹni to káári, bótilẹ̀ jẹ́ pé ìyaṣẹ́lódì yìí kò kan àwọn dókítà to n mójuto àwọn aláàrùn Covid-19.
To n tumọ si pe lapapọ, eeyan 11844 ni ayẹwo ti fihan pe wọn ti ko arun naa ni Naijiria.
Pa wọ́n run kí wọn má sí mọ́,kí àwọn eniyan lè mọ̀ pé Ọlọrun jọba lórí Jakọbu,ati títí dé òpin ayé.
Atẹjade kan ti adele akọwe ipolongo fẹgbẹ oselu APC, Yekini Nabena fisita, lo sisọ loju ọrọ yii.
Wọ́n ń ka ìdájọ́ Wòlíì Sotitobire lọ́wọ́ báyìí nílé ẹjọ́ l'Akure Ni yajo yajo bo ṣe n tẹ wa lọwọ lati ipinl Ondo ni pe agbẹjro Alfa Babatunde Sotitobire iyẹn Bayo Ayenakin ni oun yọ ọwọ ninu igbẹjọro to yẹ ko waye lonii.
“N óo jẹ́ kí àwọn eniyan wọnyi rí ojurere àwọn ará Ijipti, nígbà tí ẹ bá ń lọ, ẹ kò ní lọ lọ́wọ́ òfo, 
Ipele kinni lowa ni ile-ẹkọ girama agba (SS1).
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Building Collapse: Àlàyé rèé lórí bí ilé kẹ̀ta ti wó l'Eko Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Building Collapse: Àlàyé rèé lórí bí ilé kẹ̀ta ti wó l'Eko 18 Ẹrẹ̀nà 2019 Ile yii ti wá ní abé àwọn ile ti wọn ti pinu láti wo teletele kò tó di pé ó dawo ni ìrólé yii.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Àwọn afurasí ajínigbé tó tan oníṣòwò jáde ní ṣọ́ọ́sì wọ gàù Ọlọpaa Eré ìtàgé lórí ayélujára, àbíkẹ́yìn faraya pé iṣẹ́ ilé ń pá òun lórí, ó gbé òfin kalẹ̀ fún ẹbí Boko Haram 601 parí iléẹ̀kọ́, ìjọba yóò san ₦20,000 lóṣù fún ẹnì ìkọ̀ọ̀kan Aráàlú faraya torí èèyàn 63 tó dèrò ọ̀run ní Gúúṣù Kàdúná láàrin ọ̀sẹ̀ kan Hospital Wedding: Oṣù kan péré ni Tash fi ṣe ìgbéyàwó pẹ̀lú Simon kó tó kú Èèyàn 11 kú, èèyàn 438 míràn tún kó COVID-19 ní Nàìjíríà l'Ọ́jọ́ Àbámẹ́ta Lizzy Anjọnrin fẹ̀si fáwọn agbọ́yì-sọ̀yí lórí ìgbéyàwó rẹ̀, Madam Sajẹ dasójú ilé iṣẹ́, àti àwọn ǹkan míràn tó ṣẹlẹ̀ lágbo tíátà lọ́sẹ̀ yìí Ikọ ipolongo Obaseki da ẹbi rogbodiyan naa ru ikọ ẹgbẹ oṣelu APC, to jẹ alatako rẹ.
 Àwon náà bèrè sí í se ode .
yóo pa ọ̀kan ninu àwọn ẹyẹ náà sinu ìkòkò amọ̀ lórí odò tí ń ṣàn, 
Ibi orí ranni lọ làá lọ.
O ni ọdọ oun nikun wa, ko ni hande si ẹnikẹni.
Ìwọ kọ́ ni mo wá bá jà lákòókò yìí, orílẹ̀-èdè tí èmi pẹlu rẹ̀ ní ìjà ni mo wá bá jà.
Ó tó bí agogo mẹta òru kí Jesu tó máa lọ sọ́dọ̀ wọn.
Gbogbo ẹ̀yin tí ẹ̀ ń dáná,tí ẹ tan iná yí ara yín ká,ẹ máa rìn lọ ninu iná tí ẹ dá;ẹ máa la iná tí ẹ fi yí ara yín ká kọjá.
 wọ ́ n dáwà tàbí pẹ ̀ lú àwon Àjẹsára míràn .
Ẹ̀fúùfùlẹ̀lẹ̀ ni alàgbà yìí nígbà ayé rẹ̀, kìí ṣ'àmọ̀ fún olódò.
Bí ẹnikẹ́ni bá mú nǹkankan kúrò ninu ọ̀rọ̀ àsọtẹ́lẹ̀ ìwé yìí, Ọlọrun yóo mú ìpín rẹ̀ kúrò lára igi ìyè ati kúrò ninu ìlú mímọ́ náà, gẹ́gẹ́ bí a ti kọ ọ́ sílẹ̀ ninu ìwé yìí.
Giwa ile-ifowopamo ohun so fun CNBC pe, ipade ti won fi si ojo-Aje, ojo kokandinlogun titi di ogunjo osu keta ti a wa yii ni won yoo da duro fun bi ojo meje si mewaa, tabi o pe ju, inu ose kinni osu kerin odun ti a wa yii.
Nigba naa, gomina Zullum ṣe apejuwe awọn oṣiṣẹ naa gẹgẹ bi akinkanju Iye awon igba ti wọn ti kọlu Borno laarin ọdun sẹyin.
Eyi lo si mu ki Deji fi ibinu lọ dana sun ẹbi Titi mọle.
Bí ẹ bá wí pé, ‘Báwo ni a óo ṣe lépa rẹ̀!
Ṣugbọn Solomoni kò fi àwọn ọmọ Israẹli ṣe ẹrú.
 Àwọn àjẹsára tí ó wà ń dábòbò lòdì sí àwọn irúfẹ ́ bóyá méjì , mẹ ́ rin , tàbí mẹ ́ sàn ti hpv .
Aya oloogbe bẹ gbogbo agbaye lati dide idajọ siku ọkọ oun.
O fẹ́ràn òdodo, o sì kórìíra ìwà ìkànítorí náà ni Ọlọrun, àní Ọlọrun rẹ, ṣe fi àmì òróró yàn ọ́.
 President @MBuhari received Security briefing from Service Chiefs and other heads of security agencies today, at the State House, Abuja.
Awon alufaa ile ijosin Catholic ni Burundi ti bu enu ate lu erongba awon asofin lati se atunse si iwe abadofin ti o romo saa ti awon aare lorile-ede naa yoo maa lo lori aleefa.
Aarẹ Buhari lo n beere pe ki awọn aṣofin fọwọ si igbesẹ to fẹ gbe lat ya owo biliọnu ọgbọn dọla lati ilẹ okeere ko le fi ṣe awon iṣẹ aknṣe to pọ.
Oríṣun àwòrán, Odunlade Adekola Àkọlé àwòrán, Ọdunlade ọmọ Adekọla, agba n bọ wa kan ọ o Oríṣun àwòrán, Jide Kosoko Àkọlé àwòrán, Agba kii pẹ kan ni Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Sheffield faṣọ iyì ya mọ́ Chelsea lára lọ́nà ìrìnàjò sí Champions League Ọlọ́run ló yàn mí ti Arsenal, mi ò lè fi wọ́n sílẹ̀ láéláé- Mama Arsenal yarí Funke to ti ṣoju orilẹede Naijiria ninu idije ''Olympics'' ni igba mẹfa ọtọtọ pinnu lati sọ iriri rẹ lẹyin ti awọn kan fipa ba ọdọbinrin ọmọ ọdun mejilelogun, Uwa Omozua lopọ ti wọn si tun pa a niluu Benin.
UK ṣetán láti dá Adìyẹ 'Àkùkọ' Nàíjìrìa ti wọ́n gbé padà Oga mi lo gba 36m Jamb Ejò bu abóyún jẹ nílé ìyàgbẹ́, ó kú pẹ̀lú oyún oṣù mẹ́jọ ní Kaduna Ejò bu ìdí obìnrin kan jẹ nínú ilé ìgbọ̀nsẹ Kí ló yẹ ká se sí ẹkùn tó pa ènìyàn márùn ún?
Satani dáhùn pé, “Ṣé lásán ni Jobu bẹ̀rù ìwọ Ọlọrun ni?
Olorin naa wa rọ ile ẹjọ pe ki wọn gbe ẹjọ ati idajọ naa ti ile ẹjọ Sharia da fun un ti sẹgbẹ kan ki wọn si bẹrẹ ẹjọ eyi ti yoo ṣe oun loore.
Absalomu kórìíra Amnoni gan-an nítorí pé ó fi ipá bá Tamari, àbúrò rẹ̀, lòpọ̀, ṣugbọn kò bá a sọ nǹkankan; ìbáà ṣe rere ìbáà sì ṣe burúkú.
"Bi wọn ṣe n ṣe daadaa tẹlẹ ti gbogbo nkan n dan fun wọn ṣugbọn ti ọrọ wa di olowe pe ""O wa di akọ aja to n gbo lasan ninu ile""."
Oríṣun àwòrán, Reuters Àkọlé àwòrán, Niṣe ni awọn eeyan tu yaya lati wa kopa ninu irun Jimọ iranti lorileede New Zealand Ninu ọrọ rẹ to waye ṣaaju, arabinrin Arden ka ayọka lati inu Kurani eleyi to ti sọ pe ''awọn mumini ododo, bi wọn ba n fi oju anu han tabi bani kẹdun dabi ara kan,nnkan to ba ti ba oju fun wọn, dandan ni ki o ba imu .
Trump ti gbé òdòdó ìrántí sójú oórì akọni lójú ìjà Wọ́n ti ni kí àwọn alága ìjọba ìbílẹ̀ Ogun lọ rọọ́kún nílé Sìgá mímu ń di èèwọ̀ oògùn ìlera pípé lagbaye Nitori dukuu wọnyii, ipinlẹ mejeeji yii ni APC padanu.
Ajọ INEC kede aarẹ Buhari gẹg bi ajawe olubori plu ibo 15,191,847 eyi to fi fi ẹyin alatako rẹ, Atiku janlẹ to ni ibo 11,262,978 ṣugbọn ṣe ni Atiku kọjalẹ to si pe ẹjọ lori pe oun lo yẹ ko jawe olubori.
5 1040547 Orilẹede Spain 46252 99.
Ìdájọ́ ati Oore Ọ̀fẹ́ Ọlọrun .
Nígbà tí Moabu bá wá siwaju,tí ó fi gbogbo agbára gbadura ninu ilé oriṣa rẹ̀,títí ó fi rẹ̀ ẹ́,adura rẹ̀ kò ní gbà.
Báyìí ni a fi ààfin ọba àwọn Èdìdàrẹ́ sílẹ̀ tí a wa sí ibùdó wa.
Uganda ti bẹrẹ ìgbésè láti fi ikú ṣefàjẹ fún ẹní bá ṣe ìgbéyàmí ẹyà kannaa.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù FRSC No Parking: Wo ibi mẹ́rìnlá tí o kò gbọdọ̀ gbé ọkọ̀ rẹ sí lásìkò yìí.
Nígbà tí wọ́n ti parí ohun gbogbo tí ó wà ní àkọsílẹ̀ pé yóo ṣẹlẹ̀ sí i, wọ́n sọ̀ ọ́ kalẹ̀ láti orí igi agbelebu, wọ́n tẹ́ ẹ sinu ibojì.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ìgbésẹ̀ àti yọ Dino: Ìdí ìjákulẹ̀ rẹ̀ Dino Melaye bẹnu àtẹ lù Buhari Ilé ẹjọ́ ti gba onídùúró Dino Melaye Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Fi oúnjẹ ra àwa ati ilẹ̀ wa, a óo sì di ẹrú Farao.
Olùfẹ́ mi lẹ́wà pupọ, ó sì pupa,ó yàtọ̀ láàrin ẹgbaarun (10,000) ọkunrin.
O ní kò si oore kankan ti ìjọba ṣe fún ara ilú, nítori pé olúkúlúkù lo fi owó ara rẹ san owó ọkọ to fi wálé àti pé wọ́n ti sọ fún àwọn pé, ki olorí di ori rẹ̀ mú ni ti àwọn ba de ilú Abuja.
Ìkọlù Benue: Ọ̀dọ́, PFN, CAN tutọ́ sókè lórí ikú olùjọ́sìn
Ki lo de ti ijọba ko ṣe ran awọn elomiran lọwọ pẹlu iṣẹ ọwọ wọn, tabi okowo ti a mọ wọn mọ́ bi wọn ti ṣe fẹ ṣe fun awọn Fulani Awọn nkan ti a ka silẹ wọnyii wa lara awọn nnkan ti o n jẹ ki ọrọ Ruga yii ma fa awuyewuye.
Ìpolongo ìtakò Kérésìmesì ìlú China mú yíyan àjọyọ̀ le fún ọmọ-ìlú
Nigba to n sọ ero rẹ lori imọran naa, Ẹlẹbubọn ni ọrọ ti Sunday Igboho sọ ṣe pataki nitori ''igi kan ko le dagbo ṣe igbo, aja to ba si lẹni lẹyin ni p'ọbọ, ẹnikan ko le maa ṣe ohun kan, ko maa lawọn eeyan to n ti lẹyin.
Ẹ̀yin mọ́, ṣugbọn kì í ṣe gbogbo yín.
Bẹ́ẹ̀ ni aṣọ ìbora kò ní fẹ̀ tó eniyan bora.
 Ìròyìn ń jẹ́ ká mọ̀ wípé Ọ̀gbẹ́ni Olatoye Temitope Sugar kú láti ibo tí wọ́n yìn mọ
Gomina ipinlẹ Ekiti, Kayode Fayemi ni asiko ti to ka fopin si ipo awọn sẹnetọ ni Naijiria lasiko yii ki orilẹ-ede yii le ri owo na.
 eré àpíìrì kún fún ọ ̀ pọ ̀ lọpọ ̀ ìmọ ̀ àti òye tí ó fi ọgbọ ́ n , ìrònú , àkíyèsí , èrò , èèwò àti ìgbàgbọ ́ àwa yorùbá hàn .
Bakan naa ni awọn iṣoro miran to n waye nipa lilo awọn ajẹsara naa, lo n faa ti ọpọ fi n sare jina si abẹrẹ ajẹsara.
Amọ o ni ibọn ba ọmọbinrin kan to n kiri ila lọ loju popo, to se alabapade awọn ọlọpaa naa, ti ibọn si gba ẹmi rẹ.
Ajọ keji to n gbogbun ti iwa ibajẹ ni Naijiria, ICPC, sọ nigba naa pe oun n wadii Waziri fun iwa ibajẹ.
Alufaa yóo sì máa wọ́n ẹ̀jẹ̀ wọn sí ara pẹpẹ OLUWA lẹ́nu ọ̀nà Àgọ́ Àjọ, yóo sì sun ọ̀rá wọn bí ẹbọ sísun olóòórùn dídùn sí OLUWA.
8 Àti pé ẹnikẹ́ni kò lè ṣe ìrànwọ́ nínú iṣẹ́ yìí bí kò ṣe pé ó rẹ ara rẹ̀ sílẹ̀ kí ó sì kún fún ìfẹ́, pẹ̀lú níní ìgbàgbọ́, ìrètí, àti ìfẹ́ àìlẹ́gbẹ́, pẹ̀lú wíwà ní ìwọ̀ntún-wọ̀nsì nínú ohun gbogbo, èyíkéyìí tí a lè fi sí abẹ́ ìtọ́jú rẹ̀.
Èmi Dariusi ọba ni mo pa àṣẹ yìí, ẹ sì gbọdọ̀ mú un ṣẹ fínnífínní.
wa gbosuba kare lai fun ijoba to n sakoso lowolowo ati eleyi ti o gbejoba sile
6m lórí ètò BBNaija torí pó sọ̀rọ̀ ìwúrí nípa Nàíjíríà Omi ara Ọ̀pọ̀lọ́, ẹ̀jẹ̀ Ẹlẹ́dẹ̀ àti wáìnì tí wọn fi Èkúté ṣe ń mára jípépé, ẹ máa mú Bí mo ṣe dúró ti Toyin nílé ìgbẹ̀bí jẹ́ kí ń mọ̀ pé ó yẹ kí ọkùnrin máa bọ aya wọn - ọkọ Toyin Abraham Jackye ni tirẹ sọ pe, yoo jẹ didun inu oun to ba je pe Mercy lo maa jawe olubori ninu idije Big Briother naa.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Lebanon Explosion: Ibùdó tí igba èèyàn ti kú lóṣù kẹjọ ní iná míràn ti jó 4 Ògún 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 10 Owewe 2020 Ijamba ina alagbara miran tun ti waye ni papakọ oju omi to wa nilu Beirut lorilẹede Lebanon.
Arsenal fa Chelsea ya pẹ́rẹpẹ̀rẹ gba ife FA Cup 1 Ògún 2020 Oríṣun àwòrán, @Arsenal/twitter Ami ayo meji si odo ni ẹgbẹ agbabọọlu Arsenal fi ja ife idije FA Cup mọ Chelsea lọwọ.
Igbakeji aare orile ede Naijiria Yemi Osinbajo ti sedasile Eto eyawo fun awon ọlọja olokoowo keekeeke loja Uttako to wa niluu Abuja.
Wò ohun mẹ́ta tí a mọ̀ tí yóò mú ìjọba pàṣẹ kónílé-ó-gbélé lẹ́ẹ̀kejì ní ìpínlẹ̀ Èkó Ìtàn tó rọ̀ mọ́ òwe ‘aṣọ kò bá Ọ́mọ́yẹ mọ́.
Saaju ni Wike ti buwọlu àṣẹ kan, to fi fofin de ẹgbẹ IPOB nipinlẹ Rivers, to si pasẹ fun awọn alaga ijọba ibilẹ, ati awọn oṣiṣẹ eleto aabo lati wa gbogbo ọmọ ẹgbẹ IPOB nipinlẹ naa jade, lati fi oju wina ofin nile ẹjọ.
Bí inú ọkọ iyawo tuntun tíí dùn nítorí iyawo rẹ̀,bẹ́ẹ̀ ni inú Ọlọrun rẹ yóo dùn nítorí rẹ.
Èyí ni ohun tí ó dára lójú Ọlọrun.
Ọba bá gbé Ṣadiraki, Meṣaki ati Abedinego sí ipò gíga ní ìgbèríko Babiloni.
a ma dabi ẹni ti oyi oju nkọ.
Nigba ti BBC Yoruba kan si alukoro ile iṣẹ Ọlọpaa Kwara, Ajayi Okasanmi Jeffrey sọ pe awọn yoo ko awọn tara wọn ya fun awọn obi wọn.
ki yin ninu odun tuntun yii , mo tun fi n da a yin loju pe eto idibo odun 2019
Lojo Eti to koja ni won fi atejade oruko naa sita nilu Eko nibiti Munachi Abii to je arewa Naijiria tele ati osere Enyinnaya Nwigwe ti siso loju eegun re.
Ní ọjọ́ tí àwọn ọ̀tá ń kó ọrọ̀ wọn lọ,tí àwọn àjèjì wọ inú ìlú wọn,tí àwọn ọ̀tá sì ń ṣẹ́ gègé lórí Jerusalẹmu,ẹ dúró, ẹ̀ ń wò wọ́n;ẹ sì dàbí ọ̀kan ninu wọn.
OLUWA tóbi, ìyìn sì yẹ ẹ́ lọpọlọpọ;àwámárìídìí ni títóbi rẹ̀.
Wọ́n a sì máà yọ̀ mọ́ ọ tí wọ́n á máa báa rojọ́ dáadáa.
Ẹ óo parun láàrin àwọn orílẹ̀-èdè, ilẹ̀ àwọn ọ̀tá yín yóo sì gbé yín mì.
Ọ̀rọ̀ Buhari tó dá awuyewuye sílẹ̀.
Ileẹjọ Majisireeti gba beeli rẹ lẹyin ti adajọ wọgile aṣẹ ọlọpaa lati fi i silẹ latimọle lọjọ Iṣẹgun.
Afojusun wọn ni pe ki ọmọ to to ẹgbẹrun lọna ọgọfa ti ọjọ ori wọn ko ju ọdun meji lọ je anfaani rẹ.
Ràn wá lọ́wọ́, Ọlọrun Olùgbàlà wa,nítorí iyì orúkọ rẹ;gbà wá, sì dárí ẹ̀ṣẹ̀ wa jì wá,nítorí orúkọ rẹ.
“ ‘Ẹni ìfibú ni ẹnikẹ́ni tí ó bá bá ìyá aya rẹ̀ lòpọ̀.
”|Ipade naa waye lojo keji  ti awon to yapa lati inu egbe APC, da egbe won sile , the Reformed All Progressives Congress, RAPC ,ni eyi ti Buba Galadima to je alatileyin  ana fun aare Buhari dari re.
Abénugan to sàbẹ̀wò sí ilé iṣé wọ́n, ó sàlàyé fún wan pé, bí ìjọkó ilé yóò ṣe bẹ̀rl lọ́ja ìṣẹ́gun, àwọn yóò yẹ́ Ifeanyi sí nínú ìjókó àwọn Bákan náà ló sọ pé òun ti wọ́gilé gbogbo ètò tí òun ní nílẹ̀ tẹ́lẹ̀ láti ríi dájú pé, òun se ìdárò Ifeanyi dáadáa.
Àtúndì Ìbò Kwara: APC àti PDP ń sọ òkò ọ̀rọ̀ síra wọn Oríṣun àwòrán, @SKSolaKuti Iran yoo dun wo ni ipinlẹ́ Kwara loni ọjọ Abamẹta nigba ti ẹgbẹ oselu PDP ati APC yoo maa ti ẹsẹ bọ sokoto kan naa lati yan asoju-sofin tuntun ti yoo maa soju ẹkun idibo Irẹpọdun, Isin Ekiti ati Oke ẹrọ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Emir Sulu Gambari kú ara fẹ́rakù 4 Òkùdu 2019 Oríṣun àwòrán, @official_IYO Àkọlé àwòrán, Emir Ilorin Iya Emir ti ilu Ilorin, Alhaji Sulu Gambari, Alhaja Aishat Nma Sulukarnaini ti re ibi agba n re.
Ẹ̀yin tẹ̀ ń parọ́ ẹlẹ́yà-mẹ̀yà mọ́ Amotekun Oyo, Seyi Makinde lẹ̀ ń dojú ìjà kọ Oríṣun àwòrán, Twitter/seyi makinde Ijọba ipinlẹ Oyo ti bẹnu atẹ lu bawọn kan ti se n gbe irọ kiri nipa ikọ Amọtẹkun, lati le foju kere aseyọri wọn, ki wọn si fi da wahala silẹ nilu.
75 O ṣe ànfààní pé kí ìjọ máa pàdé papọ̀ lóòrèkóòrè láti ṣe àbápín ti àkàrà àti wáìnì ní ìrántì Olúwa Jésù;
”Ó dá wọn lóhùn pé, “Ó wà ninu àgọ́.
Opọlọpọ lo kọkọ dunnu pe ologun gba ijọba pẹlu ileri lati tete gbe igbesẹ lati daa pada fawọn alagbada.
Lẹ́yìn náà, Dafidi ọba gbógun ti àwọn ará Filistia, ó ṣẹgun wọn, ó sì gba ìlú Mẹtẹgi-ama lọ́wọ́ wọn.
Bí ayé n fẹ́ ọ loni, bí o bá lówó lọ́wọ́, ni wọn má a fẹ́ ọ lọla
àṣírí míì tú síta12 Agẹmo 2020 Maina N2bn Fraud: Agbẹjọ́rò Maina yọ ọwọ́ nínú ìgbẹ́jọ́, Ó lóun kò ṣé mọ̀25 Bélú 2020 Maina Arrest- DSS ti mú Maina àti ọmọ rẹ ní ile Itura kan l'Abuja3 Ọ̀wàrà 2019 Malabu Oil Scandal: Iléẹjọ́ ní kí àwọn ọlọ́pàá, Interpol gbé wọn níbikíbi tí wọn bá wà17 Ìgbé 2019 Mohammed Adoke: EFCC dájọ́ wíwà láhàmọ́ ọjọ́ mẹ́rìnlá fún Mínísítà ètò ìdájọ tẹ́lẹ̀21 Ọ̀pẹ̀̀ 2019 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 3 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 5 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Bí aya bá kọ ọkọ rẹ̀ silẹ̀, kó wà láì lọ́kọ̀' 7) Iru ẹni yii a wa bẹrẹ si ni ronu ọna ti yoo gba pa ololufẹ rẹ to ba kọ lati moju kuro.
Ó ń retí pé kí Jesu ṣe iṣẹ́ ìyanu lójú òun.
Premier League yóò bẹ̀rẹ̀ padà lóṣù kẹfà
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Impeached Kenya Governor: Sonko Mbuvi ní àwọn alájẹbánu tóun dí lọ́wọ́ ló yọ òun nípò 18 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Oríṣun àwòrán, Getty Images Gomina ilu Nairobi, tii se olu ilu Kenya, Mike Sonko Mbuvi ni wọn yọ kuro nipo lẹyin ti ile asofin agba orilẹede naa fi ontẹ lu iyọnipo tile asofin agbegba se.
Bẹ́ẹ̀ ni Aaroni yóo ṣe máa ru ìdájọ́ àwọn ọmọ Israẹli sí oókan àyà rẹ̀, nígbà gbogbo níwájú OLUWA.
Gomina fi kún un pe ẹgbẹrun meji ọlọpaa ni São Paulo, ni yoo ma fi ẹrọ ayaworan si ara bayii.
"Nigba ta beere lọwọ rẹ pe iyawo rẹ n kọ, ọkunrin naa ni iyawo oun akọkọ to bi Ibrahim fun oun, ti ṣe alaisi nigba ti iyawo keji to bi Zenab ti kọ oun silẹ.
Ewe, ojo kerinlelogun osu kewa je ojo ti ijoba ya soto lati fi sami-eye eto abere ajesara lagbaye(World Polio Day) lodoodun.
Akọ kinniun a máa fa ẹran yafún àwọn ọmọ rẹ̀,a sì máa lọ́ ẹran lọ́rùn pafún àwọn abo rẹ̀;a máa kó ẹran tí ó bá paati èyí tí ó fàya sinu ihò rẹ̀.
Ibú rẹ̀ sì jẹ́ igbọnwọ kan (idaji mita kan).
OLUWA ní kí Mose sọ fún àwọn eniyan Israẹli pé, 
Ipinlẹ Eko ni a ti bẹrẹ pẹlu awọn akọsẹmọṣẹ Olukọ lati ipinlẹ Eko Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ìtàn ọ̀rẹ́ tó fi ògùn gba ọkọ ọ̀rẹ́ rẹ̀ ni Akomolede BBC Yorùbá fẹ́ kọ́ wa lònìí Arabinrin Olaitan Zainab kọ nipa iwe: Ọrẹ Mi ninu ẹkọ oke yii.
OLUWA kì í jẹ́ kí ebi pa olódodo,ṣugbọn ó máa ń da ìfẹ́ ọkàn eniyan burúkú rú.
Alaga egbe osule naa omooba Gboyega Famodun war o awon omo egbe lati tun tesiwaju ninu iwa ifọkansin , o wa so pe egbe APC ni yoo tun jawe olubori ninu eto idibo to n bọ, bo tile je pe awon kan tile ti yapa lọ sinu egbe miiran.
Minista fun eto iroyin ati asa
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ogun robbery: Ọlọ́pàá ní àwọn afurasí adigunjalè náà ló ń ṣe ọṣẹ́ ní Abeokuta 30 Sẹ́rẹ́ 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 28 Agẹmo 2020 Oríṣun àwòrán, @PoliceNG Babalawo kan ati awọn afurasi adigunjale marun miran, to maa n da awọn eeyan agbegbe Osiele nilu Abeokuta riboribo, ni ọwọ palaba wọn ti segi.
Bo ṣe ṣẹlẹ si baba naa lo ṣelẹ si ọmọ Lamido Sanusi gori oye lọdun lọdun 2012 lẹyin ẹgbọn baba rẹ, Ado Bayero.
Ó ti àwọn ọ̀pá náà bọ àwọn òrùka tí wọ́n wà ní ẹ̀gbẹ́ kinni keji pẹpẹ náà láti máa fi gbé e; pákó ni ó fi ṣe àwọn ọ̀pá náà, wọ́n sì ní ihò ninu.
Nigeria, FAAN)la ti ri I pe won mojuto gbogbo awon ẹrọ ayaworan (CCTV cameras )
Ǹ bá rí ẹni gbọ́ tèmi!
ati pe  l'ọjọ kan ni ọmọ mi ọkunrin, Owen, gbe baagi rẹ pe oun n wa baba oun lọ si Bakana."
Ọ̀pọ̀ àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ wá sọ́dọ̀ rẹ̀ ati ọ̀pọ̀ àwọn eniyan láti gbogbo Judia ati Jerusalẹmu ati Tire ati Sidoni, ní agbègbè ẹ̀bá òkun.
Ibaraẹnisọrọ Tẹ ibi yii lati ṣe ibaraẹnisọrọ < Ẹ pada si orukọ awọn oludije Agbeyẹwo Ọrọ Atupalẹ yii yoo mu ki awọn eniyan kiyesi eto ilana oṣelu awọn oludije yatọ si ẹgbẹ oṣelu wọn.
O ni àfojúsùn àjọ to ń rí sì àkóso àrùn ni Naijiria ni lati ṣe àyẹ̀wò fún èèyàn mílíọ̀nù méjì láàárín oṣù mẹ́ta tó ń bọ̀, tí wọn sì nílò ibùdó iyasọtọ si.
ni ,“Inu mi dun lati ki
Nígbà tí àwọn baba yín ké pe OLUWA, OLUWA fi òkùnkùn sí ààrin ẹ̀yin ati àwọn ará Ijipti, ó sì mú kí òkun bò wọ́n mọ́lẹ̀.
ẹ gée wẹ́lẹ́wẹ́lẹ́ tàbí kí ẹ fi iná sun ún.
Mo bá gbọ́ tí pẹpẹ ìrúbọ wí pé, “Bẹ́ẹ̀ ni, Oluwa, Ọlọrun, Olodumare, òtítọ́ ati òdodo ni ìdájọ́ rẹ.
Ohùn Àgbáyé ṣe ẹ̀dàa ìròyìn náà ní abẹ́ ìtọwọ́bọ̀wé àjọṣe pọ̀ ìkóròyìnjọ.
Ohun ati iyawo rẹ ni wọn jijọ n rinrin ajo lasiko ti awọn ajinigbe naa ṣọṣẹ.
Yatọ si awọn ọọfisi ileeṣẹ ọlọpaa ti wọn dana sun, tun wo diẹ lara awọn ileeṣẹ miran ti awọn janduku ọhun tun ti ṣọṣẹ l'Eko.
Bẹẹ naa lo tun sọ pe kii ṣe ohun to bojumu ki ọkunrin jẹ alapa ma ṣiṣẹ ti yoo maa reti ki iyawo rẹ maa bọ ọ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Imo: Aléjò mẹ́wàá ṣòfò ẹmí níbi ayẹyẹ ìgbéyawó 11 Òkùdu 2019 Ìjàmba ṣẹ̀ ní ìpínlẹ̀ Imo lọ́jọ́ ajé lẹ́yìn ti alejò mẹ́wàá jẹ ọlọ́run nípe nípasẹ̀ èèfi ẹrọ amúna wá níbi ayẹyẹ ìgbéyàwó ìlànà ìbílẹ̀.
Ọkùnrin kan bẹ́ orí ẹ̀gbọ́n rẹ̀ ní Cross River, ni ará ìlú bá sin ín láàyè
o ba se n tewa lowo.
O ni ko lee si abo laisi iṣẹ.
akoto ti won maa n de sori won.
Ọrẹ ọmọ naa lo wa wọ ọmọ naa ,ti wọn si ri wi pe o ti daku, ko to di wi pe o gbe ẹmi mi ni ile iwosan.
Ọmọ orilẹ-ede Naijiria ni awọn obi rẹ, sugbọn wọn ti di ọmọ ilẹ America.
Eto ipolongo eto idibo bere ni pereu lorile-ede Sierra Leone, bi awon oloselu se n baa won oludibo soro lori eto idibo gbogbogbo ti o n bo lona nibi ti awon oludibo yoo ti dibo yan aare ati awon asofin ninu eto idibo ti yoo waye lojo keje osu keta odun ti a way ii.
Láti Makihelotu wọ́n lọ sí Tahati.
" Awọn gomina naa wa n beere fun agbekalẹ ajọ eleto idajọ ti yoo sewadi iwa idaluru ati ipaniyan to waye lasiko iwọde EndSARS.
Esau dá ara rẹ̀ lọ́kàn le ó ní, “Ìgbà mélòó ni ó kù tí baba wa yóo fi kú?
idi pataki ti a se nilo lati mu igberu ba eto ogbin, bee si ni akitiyan igbimo
Kò sì dá Jakọbu mọ̀, nítorí pé ọwọ́ rẹ̀ ní irun bíi ti Esau ẹ̀gbọ́n rẹ̀, ó bá súre fún un.
Nígbà tí Dafidi gbọ́, ó kó gbogbo àwọn ọmọ ogun Israẹli jọ, ó la odò Jọdani kọjá lọ sí Helamu.
‘Èmi ni OLUWA Ọlọrun yín, tí ó ko yín jáde láti ilẹ̀ Ijipti, ní oko ẹrú tí ẹ wà:
Àwọn ọkunrin náà ṣe gẹ́gẹ́ bí àṣẹ tí Joṣua pa fún wọn.
Nípa agbára rẹ, mo lè ṣẹgun àwọn ọ̀tá mi,mo sì lè fo odi kọjá.
Kò sí ọba ní ilẹ̀ Edomu.
Lẹyin ti wọn ọrọ tubi n nubi ati didi mọra ẹni gbagi, o de ibi kan ti ọeọ ti Neymar n gbe wa le to si wa fi ipa ba obinrin naa lajoṣepọ lọna ti ko nifẹ si."
Oyo Corornavirus: Gbogbo ìgbìmọ́ aláṣẹ ìjọba ìpínlẹ̀ Oyo ló ṣe àyẹwò àrùn Covid-19 Sùgbọ́n.
Mose bínú gidigidi, ó sì sọ fún OLUWA pé, “OLUWA, má ṣe gba ẹbọ àwọn eniyan wọnyi.
Lásìkò ti BBC News Yoruba ba alága NMA ní ìpínlẹ̀ Ogun náà sọ̀rọ̀ Dókítà Lawal Akinlade láti mọ ìdí ti irú ìgbésẹ̀ yìí fi wáyé ni àsìkò yìí tí gbogbo àgbáye n koju ààrun Corornavirus Dókítà Akinlade ni ọ̀rọ̀ to fa ìyásẹlódi ránpẹ yìí kìí ṣe ọ̀rọ̀ òní, sùgbọ́n èyí tó lágbára jùlọ níbẹ̀ ni pé, ko si àwọn èròjà ìdáàbò bo ara ẹni (PPE) tó kójú òṣùwọ̀n láti koju ààrùn Corornavirus.
Ẹ fi ìwọ̀ra pa á lára nítorí ìrora rẹ̀,bóyá ara rẹ̀ yóo yá.
Ìgbà tí ara bá ìgbẹ́ làá rí Eṣú.
Wọn kò ní náání pẹpẹ tí wọ́n fọwọ́ ara wọn tẹ́ bẹ́ẹ̀ ni wọn kò ní gbójúlé àwọn ère tí wọ́n fọwọ́ ara wọn ṣe, ìbáà jẹ́ oriṣa Aṣera tabi pẹpẹ turari.
Àwọn Olúkọ ìpínlẹ̀ Oyo fakọyọ lórí ètò Akọ́mọlédè àti Àṣà púpọ̀ Ṣé ẹ rántí àkọ́lé àwọn ìwé àkàgbádùn yìí?
Ninu ẹ̀yà Bẹnjamini ni wọ́n ti wá, wọ́n sì jẹ́ ìbátan Saulu.
" Ọrọ yii ti n ja ranyinranyin laarin awọn ololufẹ igun mejeeji at'awọn onwoye.
'Nàìjíríà kò sí lábẹ́ ìṣèjọba àwọn afagídíjayé' Àwọn ọmọ Nàìjíríà kan dín dùǹdú ìyà fún mi ní Spain-Rotimi Amaechi, mínísítà fétò ìrìnnà Ìbúgbàmú ọ̀pá epo béntíróò mú ẹ̀mí lọ ni Eko Uzor Kalu tó jẹ́ àṣojú láti ìpínlẹ̀ Abia rí ẹ̀wọ̀n ọdún méjìlá he O ni awọn kan ni ileeṣẹ aarẹ lo wa nidi iroyin ọhun lori ayelujara.
Arabinri Buhari tun wa ro egbe oselu APC lati tele ilana ti won la sile lati maa fun awon obinrin ni ipo márùndínlógójì ninu ogorun un , ki won tun lee tubo kopa ninu  eto oselu.
Ọkọ àtìyàwó tó sọ ọmọ wọn ni Adolf Hitler wọ wàhálà ní ilẹ̀ Gẹ̀ẹ́sì
Eyi ko ṣẹyin bo ṣe jẹ ọmọ bibi orilẹede Naijiria ti o si ṣe iṣẹ takuntakun nipa awari abẹrẹ ajẹsara akọkọ to ogun rẹ ṣe e fi gbari lorilẹede Amẹrika.
Ajọ naa ni ogun abẹle ọdun mẹrin to n waye nibẹ ko ran isẹlẹ naa lọwọ rara.
Ireti si wa pe laipẹ laijinna, irufẹ ode ijo bayii yoo tan kalẹ bii ọwara ojo yika gbogbo ilẹ Afirika, nibiti wọn yoo ti maa gbe awọn obinrin larugẹ bo se yẹ.
ti e ba n se ojuse yin ni awon ibi idibo pata-pata.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Makinde: Ẹgbẹ́ òṣìṣẹ́ faramọ́ wíwọ́gilé ₦3000 táwọn akẹ́kọ̀ọ́ girama ń san Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Jairi ará Gileadi ni ó di adájọ́ lẹ́yìn rẹ̀, ó jẹ́ aṣiwaju ní ilẹ̀ Israẹli fún ọdún mejilelogun.
Bakan naa o ni ile iṣẹ ti ko rọgbọku le ijọba eyi to fi n kọ awọn ọdọ niṣẹ ọwọ.
 Idi niyi ti a se gbọdọ fọwọsowọpọ lati le jọ koju aarun yii, ni eyi ti
eko gbogbonse sile, sugbon ijoba apapo si n reti, pe ki awon ile igbimo asofin
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Yoruba Culture: ọjọ́ méje ni wọ́n fí n rẹ ẹ̀kú Danafojura kó tó jáde Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Gẹ́gẹ́ bii ǹkan ti Abba Yusuf sọ, ó ni ọwọ́ Emir kò le wọ sọ̀ọ̀lọ̀ nítori pe kìí ṣe akápò tàbí akọwé fún ìgbìmọ ẹmireeti.
Sùgbọn bi ìlanilọye ṣe ń lọ lóri abẹ dida fún ọmọ obinrin, ó ṣeni láànú pé ènìyàn péréte ló mọ nipa ọmu lílọ nji eyi to yẹ ko ti dohun igbagbe nilẹ Afrika bayii Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Wọ́n nílò ìrànlawọ́ mi láti ṣèmọ́tótó ibi tí wọ́n ti ń tọ́jú àwọn tó ní Coronavirus Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
o si sekupa egberun meta eniyan ni awon agbegbe lorisirisi lodun 2018.
 lọ ́ pọ ̀ ìgbà ni ọ ̀ pọ ̀ ìgéjẹ gbọ ́ dọ ̀ wáyé ṣáájú kí àkóràn tó wáyé .
Ẹ o ranti wi pe ijọba ti kọkọ duro lori ẹsẹ rẹ tẹlẹ pe ki El-Zakzaky gba itọju nile iwosan to wa ni Naijia.
Chadwick Boseman wife: Simone Ledward ni ìyàwó Chadwick Boseman, wọ́n sì 'sègbéyàwó kó tó jáde láyé
N óo jẹ́ kí ogun pa àwọn tí wọ́n bá ṣẹ́kù lára wọn, Kò ní sí ẹyọ ẹnìkan ninu wọn tí yóo lè sálọ, bẹ́ẹ̀ ni kò ní sí ẹnìkan tí yóo sá àsálà.
Kòsí ẹni tí yóò rí Dáúdà ní àsìkò yìí tí ìrísí rẹ̀ kò ní pa á lẹ́rìn- ín.
Ṣaaju awọn ẹsun yii, ni Gistlover ti kọkọ kọ iroyin lọjọ karun-un, oṣu Kọkanla, pe aarin Ronke ati Jago ti daru.
wọ ́ n fọwọ ́ sí Àjẹsára jẹ ̀ dọ ̀ jẹ ̀ dọ ̀ b àkọ ́ kọ ́ ní ilẹ ̀ united states ní odún 1981 .
Nípa bẹ́ẹ̀ n óo fa ègún sórí ara mi dípò ìre.
Ṣugbọn lẹ́yìn ibùdó ni kí o ti fi iná sun ẹran ara rẹ̀, ati awọ rẹ̀, ati nǹkan inú rẹ̀, nítorí pé, ẹbọ ẹ̀ṣẹ̀ ni.
Agbẹnusọ ajọ LASBCA, Titi Ajirotutu ni awọn agbofinro ti fi alabojuto iṣẹ atunṣe ti wọn n ṣe lori ile to wo naa, Dada Olaniyi si ahamọ.
Dokita Onu soro naa di mimo lasiko abewo adele komisona ile Canada si Naijiria, Amy Galican sile-ise minisita ohun lana niluu Abuja.
Amọ ajọ eleto ilera ni agbaye, WHO ti wa sin gbogbo agbaye ni gbẹrẹ ipakọ pe, o see ṣe ki arun Covid-19 naa di baraku fun wa, ko ma si kuro laarin wa titi laelae.
   O tesiwaju pe, lati fi ami eye fun awon ti o
Ọgbẹni Akufo-Addo kii ṣe aimọ fuloko lagbo oṣelu orilẹede Ghana.
Kọmíṣọ́nà Ọlọ́pàá kó gbogbo ọlọ́pàá ẹkùn Ondo lọ fún àyẹ̀wò COVID-19 Àlàyé rèé lóríi ìdí tí wọ́n fi ń pe aya ní ìyàwó Ohun tí a mọ̀ tó lè mú kí ìjọba Nàìjíríà ó dá òfin ìṣéde padà nìyí Àjọ NCDC kéde ènìyàn 381 míràn tó ní ààrùn Covid-19 l'órílẹ̀-èdè Nàìjíríà Bi o tilẹ jẹ wi pe awọn alaṣẹ ti jẹ ko di mimọ pe ilu Abuja ni wọn yoo ko awọn eeyan wọnyii lọ, pupọ ninu wọn lo n faake kọri pe awọn ko mọ ẹnikẹni nilu Abuja ti awsn lee duro ti lẹyin ọjọ mẹrinla ti eto iyasọtọ kan n pa ti wọn fẹ fi wọn si ba pari.
Mo ṣebí ìṣe ẹ̀dá pàápàá kọ yín pé tí ọkunrin bá jẹ́ kí irun rẹ̀ gùn, ó fi àbùkù kan ara rẹ̀; 
Ni apa ila-oorun Afghanistan, akọroyin BBC, Ahmad Shah ku ninu awọn ikọlu to waye ni agbegbe Khost.
Èmi kò forí ṣọta ìjàmbá ọkọ̀ òfúrufú kankan - Obasanjo Ti ẹ ba ranti, ile ẹjọ giga ilu Abuja da ẹjọ lọjọ keji osu kẹrin ọdun 2019 pe, oludije fun ipo gomina ni ipinlẹ Ọsun fun ẹgbẹ oselu PODP, Sẹnetọ Ademọla Adeleke ko lẹtọ lati du ipo gomina nitori ko ni iwe ẹri iwe mẹwa.
Oúnjẹ ati ohun mímu kò dùn lẹ́nu mi mọ́.
Àní, ní òkè Horebu, ẹ mú kí inú bí OLUWA, tóbẹ́ẹ̀ tí ó fi fẹ́ pa yín run.
Bi o tilẹ jẹ pe igbesẹ ati aṣẹ ọhun ṣe ọpọlọpọ onwoye ere bọọlu afẹsgba ni haa-hinn, ajọ CAF ni bi eto ati ato gbogbo ṣe lọ si lasiko ifẹsẹwọnsẹ naa ku diẹ kaa to eyi lo si faa ti oun fi gbe igbesẹ atungba ifẹsẹwọnsẹ naa.
Ìwadìí ti bẹ̀rẹ̀ lórí àrá tó sán pa òṣìṣẹ́ FRSC mẹ́ta nípínlẹ̀ Ogun- Ọ̀gá àjọ FRSC Ohun tí a mọ̀ nìyí nípa ìròyìn Ajimobi kú, kò kú, táyé ń gbé kiri Invictus Obi, Hushpuppi, àwọn ọ̀dọ́ Nàìjíríà méjì tí ẹ̀sùn gbájúẹ̀ wà lọ́rùn wọn Ọ̀rọ̀ ńlá, àwọn adigunjalè ja àgọ́ ọ́lọ́pàá lólè 4.
E ka ekunrere re ni bii Awọn nkan miran ti ẹ ni lati mọ loni Ramadan 2018: Wákàtí àwẹ̀ káàkiri àgbáyé Kíni ẹ mọ̀ nípa àwọn gbajúgbaja Yollywood?
Ọlọrun ti fún wọn ní ìmọ̀ oríṣìíríṣìí iṣẹ́ tí àwọn oníṣọ̀nà máa ń ṣe, ati ti àwọn gbẹ́nàgbẹ́nà ati ti àwọn tí wọn ń ṣe iṣẹ́ ọnà sí ara aṣọ, ìbáà jẹ́ aṣọ aláwọ̀ aró, tabi ti elése àlùkò tabi aṣọ pupa tabi aṣọ funfun onílà tẹ́ẹ́rẹ́tẹ́ẹ́rẹ́ tabi oríṣìí aṣọ mìíràn, gbogbo iṣẹ́ ọnà ni wọn yóo máa ṣe; kò sì sí iṣẹ́ ọnà tí wọn kò lè ṣe.
Ogbeni Isa fikun oro re pe, igbakeji aare Yemi Osinbajo ti o je aare ati alaga igbimo ajo NEMA pase pipese isuna fun ile-ise naa, lai daruko re rara.
N óo pa gbogbo àwọn ará Aṣidodu run ati ọba Aṣikeloni; n óo jẹ ìlú Ekironi níyà, àwọn ará Filistia yòókù yóo sì ṣègbé.
 láàrin àwọn Ọ ̀ yọ ́ ni ewì yìí ti wọ ́ pọ ̀ jù lọ .
Ọdun 2013 ni wọn da ikọ ologun abẹle yi silẹ lati daabo bo awọn agbegbe lọwọ ikọlu.
9 188,969 Costa Rica 2,401 48.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ladoja: Àwọn èèyàn Oyo fì ìbò sọ̀rọ̀ pé ìjọba Ajimobi kò dára Awọn ilumọọka Sẹnẹtọ bi Tayo Alasoadura, Yele Omogunwa ti wọn ṣoju ipinlẹ Ondo pẹlu Godswill Akpabio lati ipinlẹ Akwa Ibom lo fidi rẹmi ninu ibo ile igbimọ aṣofin agba to lọ.
Lọdun 2016 ni Adebola, iya Adigun oniru bẹrẹ iṣẹ yii ṣugbọn o dupẹ pe oun ti di ẹni to n ko iru ranṣẹ si awọn ilu oyinbo bayii.
Lẹ́yìn náà jẹ́ kí á mọ ohun tí o fẹ́ kí á ṣe nípa ọ̀rọ̀ yìí.
Aarẹ ọna kakanfo Yoruba Yoruba l'ẹni akọkọ to kawe f'ọgọfa wakati ‘Ẹ maa kọ ọmọ yin l'ede Yoruba’ Idogbe ati Idoha lawon to tun tẹle Ibeji, Oyilaki, Ọba ọmọ,ti Yoruba gba pe wọn fẹsẹ meji bẹ kẹsẹ sile alakisa, ti wọn ọ alakisa donigba aṣọ.
26 Agẹmo 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Bi ọkunrin ba ni ibalopọ pẹlu obinrin lai gba aṣẹ lọwọ rẹ, ifipabanilopọ ni.
Tó bà á fi nọ́mbà ìpè rẹ sílẹ̀, ẹ̀wọn ọdún mẹ́ẹ̀dọ́ọ́gbọ̀n lo fi ń ṣeré - NCC Ajọ to n bojuto ẹrọ ibanisọrọ lorilẹede Naijiria, NCC, ti ni awọn ọmọ Naijiria ti wọn n lo ‘Sim Card’ ti ko ni iforukọsilẹ to miliọnu lọna ọgọrun.
 alákùnrẹ ́ sì jókòó gẹ ́ gẹ ́ bí olórí ìlú .
Bí ó bá sì bí yín nínú mo bẹ̀ yín kí ẹ dáríjì mí, kíi ẹ fi ara yín sí ipò mi.
Àràmọ̀ǹdà àwòràn láti ilẹ̀ àdúláwọ̀ lọ́sẹ̀ yìí Ajimobi tako àṣẹ iléẹjọ́ pẹ̀lu ìbò ìjọba ìbílẹ̀ tó ṣe - Ìjọba Ọyọ Kéré o!
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ sí: Ìpínlẹ̀ Oṣun kò nílò Gómìnà oníjó - Oshiomole Àgbárá òjò bà'lú jẹ́ n'Ípínlẹ̀ Ogun Ọ̀rọ̀ LAUTECH gba àpérò f'áwọn Olúdíje Ọṣun A kú ewu ọmọ Linda Ikeji ooo Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, OsunDecides: Omisore ní ẹni tó bá fẹ́ ra ìbò, àwọn yóò lọ lásọ mú ni Fayose wa fikun pe, ẹru ko bodo fun oun lẹyin ajọ to n gbogun ti iwa ibajẹ ati iṣowo ilu kumọkumọ ti fi orukọ oun ransẹ si ajọ aṣọbode lorilẹede Naijiria, lati maa ṣọ oun kiri, ki oun maa ba sa lọ nitori igbẹjọ rẹ pẹlu ajọ naa lori ẹsun iwa ajẹbanu.
Koda, orukọ minisita ọrọ obinrin tẹlẹ ri, Aisha Alhassan, to kuro ninu ẹgbẹ APC ati gomina tuntun ipinlẹ Ekiti, Kayode Fayemi, to jẹ minisita fun idagbasoke ohun alumọọni naa wa nibẹ.
Ta ni ó ti ṣẹgun ayé?
Mò ń gbadura pé, gẹ́gẹ́ bíi títóbi ògo rẹ̀, kí ó fun yín ní agbára Ẹ̀mí rẹ̀ tí yóo fún ọkàn yín ní okun; 
Ọga agba ileeṣẹ VIO ni ipinlẹ Eko, Abdulafeez Toriọla lo sọ eyi di mimọ, lasiko to n kopa lori eto ifọrọwanilẹnuwo ori ikanni ayelujara ileeṣẹ BBC News Yoruba.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Kano Emirate: Ṣé àwọn gómìnà ò máa tọwọ́ bọ àṣà lójú báyìi?
Ekiti: Lẹ́yìn t'áwọn kan gba òmìnira, wọ́n tún jí òṣìṣẹ́ kánsù míràn gbé
O n jẹ kí wọn jẹ ìrora fún ọpọ ọjọ́, títí tí wọn yóò fi mí kanlẹ.
Ogoji ọjọ́ gbáko ni àwọn oníṣègùn máa fi ń tọ́jú irú òkú bẹ́ẹ̀.
Nígbà tí Israẹli ń gbé ibẹ̀, Reubẹni bá Biliha, aya baba rẹ̀ lòpọ̀, Jakọbu sì gbọ́ nípa rẹ̀.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ọbasanjọ sọ àsírí sàgbàdèwe rẹ̀ Jesu Oyingbo rèé, pásítọ̀ tó láṣẹ ìbálòpọ̀ lóri ọmọ ìjọ obìnrin Igbó mímu lè ṣe kóríyá, kò lé fi kún orín ẹnu òṣèré - 9ice Ìtàn tó wà nídi òwe ‘Sebótimọ Ẹlẹ́wà Sàpọ́n’ Ọkan lara awọn ọba alaye ilu Igboọra, Ọba Adedamọla Badmus, tii se Olu-Aso ti Ibẹrẹkodo sọ fun ikọ BBC Yoruba pe, igbagbọ wa pe ọbẹ ilasa ati amala dudu lo n sokunfa okun ibi pupọ nilu ọhun.
Ó fún Nàìjíríà l'èsì àwọn ẹ̀sùn tó fi kàn-án Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Oyenusi ló mú mi wọ ẹgbẹ́ adigunjalè kó tó di pé mo b'Ólúwa pàdé' Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Fídíò, Wole Soyinka sọ ìdí tó fi ni òun a fi màálù Fulani ṣe súyà fáwọn èèyàn abúlé23 Owewe 2020 6:18 Fídíò, Akomolede: Bolaji Faleke ni Olùkọ́ tó ń kọ́ wa ní àṣà oge ṣiṣe lórí BBC Yorùbá, Duration 6,181 Owewe 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Ó di ìkọ̀sílẹ̀ ní ilẹ̀ rẹ̀,kò sì sí ẹni tí yóo gbé e dìde.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Akure Kidnap: Ilé ẹjọ́ fi Wòlíì Alfa sí ẹ̀wọn ọjọ́ mọ́kànlelógún 23 Ọ̀pẹ̀̀ 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 24 Ọ̀pẹ̀̀ 2019 Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Sotitobire Church: Ilé ẹjọ́ fi Wòlíì Alfa sí ẹ̀wọn ọjọ́ mọ́kànlelógún Bayii awọn agbofinro ipinlẹ Ondo ti foju awọn ara ìlú ti wọn kọlu ile ijọsin naa hanỌlọ́pàá Akurẹ kó àwọn ará ìlú tí wọ́n ni wọ́n jí ẹrù Pásítọ̀ Sọ titobi rẹ kó lọ sílé ẹjọ́ Wọn ko wọn wa sile ẹjọ ni Oke Ẹda ni Akurẹ nibi ti wọn ti fẹsun kan awọn mẹtala naa pe wọn pa ọlopaa, wọn ji ohun ini Wolii Sotitobire ko nile ijọsin ti wọn dana sun ati awọn ẹsun miran Ọlọ́pàá Akurẹ kó àwọn ará ìlú tí wọ́n ni wọ́n jí ẹrù Pásítọ̀ Sọ titobi rẹ kó lọ sílé ẹjọ́ Ọgbà ẹ̀wọ̀n ní Pásítọ̀ ìjọ Sotitobire yóò ti ṣe Kérésì Lowurọ oni ni ijọba ipinlẹ Ondo gbe Pasitọ Alfa Babatunde tii ṣe oludasilẹ ijọ Sotitobire ni Ondo lọ si ile ẹjọ.
Ẹsun jijale owo wa lara awọn ẹsun ti wọn fi kan ọpọ Naijiria to wa lara awọn afurasi naa.
tun fi mulẹ pe erongba lati sagbekalẹ awọn akanṣe ẹka ile-iṣẹ eleto aabo pataki jakejado apa
Esther Oyema fitan ba le lagbaye ninu ere idaraya irin gbigbe (Para powerlifter), O fitan ba le leyin ti o gba ami-eye goolu saaju awon akegbe re ti won jo kopa.
Ẹ má ṣe sọ̀rọ̀ ìṣubú wa ní ìlú Gati, ẹ má sọkún rárá; ẹ̀yin ará ìlú Beti Leafira, ẹ máa gbé ara yílẹ̀.
O ni bayii, ọna to yẹ ni ẹnikẹni to ba fẹ ko ọja wọ Naijiria gbọdọ gba koo wọle ki o si pa owo ori fun Naijiria.
Oríṣun àwòrán, oshodi Akitoye naa waja lọjọ Keji oṣu kẹsan-an ọdun 1853, ti ọmọ rẹ, Dosumu si jẹ ọba lẹyin rẹ, amọ sibẹ-sibẹ, ilu Eko ko fararọ laisi nile Kosoko.
Jonatani ọmọ Saulu ní ọmọkunrin kan, tí ó yarọ, orúkọ rẹ̀ ń jẹ́ Mẹfiboṣẹti.
Àkọlé àwòrán, Ti oku ba ti jẹra, o maa n ni ipa lori ayika to ba wa Sugbọn ohun ti wọn n fi oju awọn oku to wa ni oko oku yii ri kọja afẹnusọ, to si yatọ si itọju ti a maa n fun oku.
Wọn ni ta ba pin iye gbese yii le ori ọmọ Naijiria kọọkan, a jẹ pe gbese okoolerugba ati ẹyọ kan naira (₦121,000) lo wa lori ọmọ Naijiria kọọkan ti yoo san.
Àkọlé àwòrán, Ileeṣẹ BBC ṣe ifilọlẹ BBC Yoruba, Igbo ati Pidgin ni ipinlẹ Eko Àkọlé àwòrán, Ogunlọgọ awọn ara ati ọrẹ peju-pesẹ sibi ifilọlẹ naa to waye ni Ikoyi lọjọru Àkọlé àwòrán, Agbẹnusọ fun Aarẹ Muhammadu Buhari, Ọgbẹni Garba Shehu darapọ mọ awọn ololufẹ BBC Àkọlé àwòrán, Oga agba ileeṣẹ amohunmaworan Channels, John Momoh naa pẹlu nibi ayẹyẹ yi Oríṣun àwòrán, Taiwo Kola-Ogunlade Àkọlé àwòrán, Taiwo Kola-Ogunlade ati Dorothy, awọn oṣiṣẹ Google naa wa sibẹ Àkọlé àwòrán, Oluwo ti ilu Iwo, Oba Abdulrasheed Adewale Akanbi pẹlu olori rẹ Àkọlé àwòrán, Awọn oṣere tun ṣe bẹbẹ nibi ayẹyẹ yii pẹlu oriṣiriṣi ara dida Àkọlé àwòrán, Yoruba ree.
Iwe iroyin New York Times tun fi iroyin kan lede pe, olori aṣofin Republican nile igbimọ aṣofin agba, Sẹnẹtọ Mitch Mcconnell ti sọ fawọn to sún mọ ọ pe, inu oun dun pe ẹgbẹ oṣelu Democrat fẹ yọ Trump nipo.
Aare Muhammadu Buhari ti kedun iku Asoju-sofin John Shagaya to doloogbe.
 osìlè ni ọba wọn , oun ni igbákejì aláké .
Ni afikun, awon minisita mejeeji ohun seleri erongba ati maa gbogun ti awon adunkooko-moni, awon alakata-kiti ati pipolongo didekun  laasigbo nile Afrika.
Coronavirus lè tara òkú Abba Kyari ran àwọn tó péjú síbi ìsìnkú rẹ̀- Ààrẹ ẹgbẹ́ dókítà ní Nàìjíríà Ìdajì kutu òwúrọ̀ ọjọ́ Isẹgun ni ìròyìn tán kalẹ pé erin tí wó, akọni amofin tí lọ, bẹ́ẹ̀ sì lo yẹ ká mọ àkọsílẹ̀ àwọn ohun tó gbé ilé ayé ṣe.
Biden ni ibo awọn aṣoju 273 nigba ti Trump ni 214 eyi to fihan gbangba pe Biden lawọn ọmọ orileede Amẹrika lati tukọ ilẹ naa fun ọdun mẹrin tó n bọ.
Lati orúkọ Mohammed Buba Marwa tí ó jẹ́ gómìnà Èkó nígbàkan ni orúkọ kẹ̀kẹ́ yìí ti jẹyọ.
Nigeria Army: Ọmọ ológun gún awakọ̀ lọ́bẹ pa
Ṣebi Yoruba bọ, wọn ni ko si ẹni to mọ ibi ori n gbe e lọ.
O fikun wi pe ileri ati se atunsẹ ile iwe ko jọ awọn Yoruba loju nitori lati ọgbọn ọdun ni awọn ti n gbo ileri to jọ bẹẹ.
Ìwọ ẹbọra pàtàkí, Ikú, ẹni tí ilé rẹ̀ ń bẹ lágbedeméjì ayé òun ọ̀run, mo dúpẹ́ lọ́wọ́ rẹ.
Igba mejilelọgbọn ni Salah ti gba bọọlu wọnu awọn fun gbogbo ifẹsẹwọnsẹ to ti gba fun Liverpool ni saa yii.
Lasiko yii, ko si ọna fun awọn to n bọ lati Mainland lati gba ori afara.
Lẹyin naa ni wọn tu mi silẹ ni ogúnjọ, oṣu Karùn-ún, ọdun 2016.
Gẹgẹ bi ohun ti ijọba orilẹede naa sọ, arabin ọmọ ọdun mejilelogoji kan to jẹ olugbe ilu Lome tti ṣe olu ilu orilẹede naa lo ko arun naa.
Oríṣun àwòrán, Instagram Abhishek Bachchan ní òun àti ̀bàbá òun ti lọ si ilé ìwòsàn.
O ni lẹyin gbendeke yii ni wọn yoo maa ri ẹgbẹrun mejila gba titi wọn yoo fi pari paṣipaarọ odiwọn owo banki kọọkan.
Sibẹsibẹ ẹ̀ ń wí pé, ‘Irú ọ̀rọ̀ burúkú wo ni a sọ sí ọ?
 ""Wọn yoo maa fi ẹnu tẹnbẹlu isẹ asekara mi."
137 obìnrin ni ikú ń pa lójúmọ́ lágbàáyé Àwọn alábàágbé Kasali ní nígbà tí wọ́n ri pé arábìnrin náà ti kú, wọ́n so arákùnrin náà mọlẹ̀ titi ti wọ́n fi pe ọlọ́pàá tó wá mu.
A gbe eto ayẹwo iroyin yii kalẹ lati ya iroyin bi eto idibo yoo ṣe lọ sọtọ kuro lara oṣelu ẹgbẹ kan  lati mọ awọn ohun to ṣe koko nipa eto iṣejọba<br>lorilẹede Naijiria.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ọwọ ijọba ipinlẹ Ọyọ tẹ awọn eeyan mẹjọ kan to sọ ile ẹkọ ijọba di ileeṣẹ bulọku ati ile igbe 31 Ẹrẹ̀nà 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 6 Èbibi 2020 Awọn eeyan mẹjọ ọtọọtọ ti bẹrẹ sini fi oju wina ofin ijọba ipinlẹ Ọyọ nipasẹ lilo ayika awọn ile ẹkọ to jẹ ti ijọba lọna aitọ.
Ileeṣẹ iroyin City People lo fun Anuoluwapo ni ami ẹyẹ ọhun lọjọ Aiku, ọjọ kọkandinlọgbọn, oṣu kọkanla, ọdun 2020.
Awọn ọmọ Naijiria kan gba pe ohun ti awọn ọmọ ẹya Igbo yii ṣe ni Germnay ku diẹ kaa to: Awọn miran gba pe àṣìbí inú bíbí ni nitori Ekweremadu gbiyanju fun iran Igbo Bẹẹ lawọn miran n beere ibeere nla pe ki ni Ekweremadu lọ ṣe ọdun iṣu fun ni Germany laduru ọdun iṣu to wa ni Naijiria Bi awọn kan ṣe n bu igbakeji aarẹ ile igbimọ aṣofin Naijiria to kogba wọle pe ko si nkan ti Dauda rẹ da nigba ti o wa lori oye ati pe ikilọ leyi jẹ fawọn olori ti ko ba ṣe daadaa.
Idaduro lenu ise naa, waye leyin wakati meloo kan ti awon osise ajọ ile-ise otelemuye yawọ enu ona ile igbimo asofin  pelu aso iboju wọn.
Mi o ni sọ ohun ti a maa se bayii, sugbon mo fẹ fi daa yin loju pe,
Bakanna ni Osinbajo sọ pe oun ti paṣẹ fawọn agbẹjọro oun lati gbe igbesẹ didoju ija kọ awọn to wa nidi ọrọ naa ni ile ẹjọ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Zlatan: Ọ̀rẹ́ ni mo sìn lọ ‘studio’ tí mo fi bẹ̀rẹ̀ orin lẹ́yìn tí mo kùnà ìdánwò WAEC Ó tún ni àwọn rọ wọ́n kí wọ́n ṣe ìsìrìn náà sáájú àsìkò tí wọ́n maa n ṣee tẹ́lẹ̀ ki olúkúlùkù sì pàda síé wọ́n kí ilẹ̀ tó ṣú.
Oríṣun àwòrán, Instagram/ abiola ajimobi Abiola Ajimobi: Awuyewuye ń lọ lórí afẹ́fẹ́ nípa ipò ìlera gómìnà Ọyọ àná Gomina ana ni ipinlẹ Ọyọ ni Sẹnetọ Abiọla Ajimọbi, ko si si bi iru wọn yoo ṣe gbin ti gbogbo ilu ko ni ṣojojo.
Wá kẹ́kọ̀ọ́ nípa ègé ọ̀rọ̀ ohùn Yorùbá tí a mọ̀ sí Sílébù Báyìí ni Egúngún àti Orò ṣe jọ bí Ẹ̀ṣà Egúngún nílẹ̀ Yorùba Oríṣun àwòrán, others Awọn ire oko ilẹ Yoruba pọ, bẹẹ naa si ni irufẹ ounjẹ ti a le ri lara wọn kọ sisọ.
Elija bá na ara rẹ̀ sórí ọmọ yìí nígbà mẹta, ó sì ké pe OLÚWA, ó ní, “OLUWA Ọlọrun mi, jẹ́ kí ẹ̀mí ọmọ yìí tún pada sinu rẹ̀.
Àwọn ọbá aláye ilẹ̀ Yorùbá márùn-ún pẹ̀lú ọ̀pá àṣẹ wọn Eko, Kwara, Osun àtàwọn ìpínlẹ̀ míì tí àwọn èèyàn ti jí oúnjẹ ìrànwọ́ Covid-19 kó Wo ohun tí Fashola rí níbi ìṣẹ̀lẹ̀ Lekki Tollgate tó ń fa ariwo lórí ayélujara Ẹni tó jí ọ̀pá aṣẹ ń bọ̀ wá túbá fúnrarẹ̀, mo fi dáa yín lójú gẹ́gẹ́ bí ìyá - Erelu Kuti Ìjọba ìpínlẹ̀ Eko tí kéde ìlànà ìséde tuntun fún ará ìlú Ni gbogbo asiko yii, inu aafin ni Kabiyesi Oluwo wa ti o si ni, awọn 'ko mọ ohunkohun to n lọ nita' Ninu ọrọ to ba BBC News Yoruba sọ, Kabiyesi Oluwo ti ilu Iwo ṣalaye pe aṣiri to n bẹ laarin oun atawọn araalu Iwo ti wọn fi duro gba-gba-gba lati daabo bo ohun ko ju pe oun ti n sin wọn gẹgẹ bii baba ilu.
    Nígbà tí ó wí báyìí, èmi náà ba bẹ̀rẹ̀ sí ọ̀rọ̀ i sọ mo ní:
Ohun tí ó ṣe pataki ni ẹ̀dá titun.
Ọlà ati ọgbọ́n ati ìmọ̀ Ọlọrun mà kúkú jinlẹ̀ pupọ o!
 Àwọn náà kò kẹ ̀ rẹ ̀ nípa gbígba ẹ ̀ sìn Òkèèrè mọ ́ ra nígbà tí gbogbo ilẹ ̀ yorùbá mìíràn ń ṣe èyí .
Amọ iyatọ wa lori iye yii lẹlẹkunjẹkun.
ẹ má ṣe agídí, gẹ́gẹ́ bíi ti àkókò ìṣọ̀tẹ̀,ní àkókò ìdánwò ninu aṣálẹ̀,
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ìdí tí Buhari fi gbọ́dọ̀ buwọ́lu àbádòfin ìdìbò 2018 Èmi kò mọ obìrin tí DSS mú rí —Aisha Buhari Ladi ni olùdíje gómìnà wa l'Ogun —PDP Ọọni Ifẹ ni ko si ẹsin kan ti o ju ẹsin kan lọ nitori ninu ifẹ ati iṣọkan ni gbogbo ẹsin ti waye.
Akosile ajo WHO fihan pe o din die logorin lenigba o le ni egberun marun un nisele igbona to sele lekun yii lodun 2016 ni eyi to ti n lo ilopo merin bayii nitoripe ogun egberun lo ti sele ti eniyan marundinlogoji si ti gbemi mi.
Láti ìgbà náà ni ó ti di opó, ó sì tó ẹni ọdún mẹrinlelọgọrin ní àkókò yìí.
Bi a ko ba gbagbe, ọjọ kejila oṣu kẹjọ, ọdun 2015 ni wọn ji Eseoghene Rita Oruru gbe ni Bayelsa lọ si Kano.
 Ọ ̀ gá wọn ni lord nelson .
Ààrẹ Buhari tẹ́wọ́ gba ìwé ìrìnnà Nàìjíríà tuntun Òṣìṣẹ́ ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́ gúnle ìyanṣẹ́lódì Lórí ìdìbò 2019, kí ni Ọọ̀ni bá Atiku sọ?
“Bí ẹnikẹ́ni bá ṣèèṣì dẹ́ṣẹ̀ nípa pé kò san àwọn nǹkan tíí ṣe ti OLUWA fún OLUWA, ohun tí yóo mú wá gẹ́gẹ́ bí ẹbọ ìmúkúrò ẹ̀bi fún OLUWA ni: àgbò kan tí kò ní àbààwọ́n, láti inú agbo aguntan rẹ̀, ìwọ̀n tí wọ́n fi ń wọn fadaka ninu ilé OLUWA ni wọn yóo lò láti fi díyelé àgbò náà; ẹbọ ìmúkúrò ẹ̀bi ni.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: BBOG: Ọdún kẹrin kò láìrí áwọn ọmọ tó sọnù pé Madrid-Bayern, Arsenal-Athletico yóò wàákò Aláwàdà ni Buhari - Fáyóṣé Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Ninu atẹjade ti ileeṣẹ ologun ori ilẹ fi sita, wọn ni awọn sọja ṣetan lati lo gbogbo agbara wọn lati daabo bo ijọba awarawa orilẹede Naijiria.
Igboora: Wòlíì ni mí, ṣùgbọ́n àwọn ọ̀gá tó kọ́ mi níṣẹ́ òògùn owó ní kí n má dárúkọ
Nítorí èébì kún orí gbogbo tabili oúnjẹ,gbogbo ilẹ̀ sì kún fún ìdọ̀tí
Omi ara Ọ̀pọ̀lọ́ jẹ́ ẹlẹ́rìndòdò tó ń mára jípépé, ẹ máa mú Yaba Left: Àṣírí tú!
Abimbola ni ẹgbẹ oṣelu PDP ṣe iru ipade itagbangba ti ko waye ri ninu iwe itan.
Ki a to mọ ohun to ṣẹlẹ, wọn ko wa si ori ọkada, ti wọn si gbewa lọ si oko miran.
Lẹyin ile iwe girama, Funke kawe gboye OND ni ile ẹkọ akọṣẹmọṣẹ Moshood Abiola Polytechnic ninu imọ iṣẹ iroyin lẹyin eyi to tun kawe gboye ninu imọ ofin ni ile ẹkọ fasiti ilu Eko.
Àwọn tí ń wà ọ́ ti tì ọ́ sí ààrin agbami òkun.
Ninu atẹjade ile iṣẹ Aarẹ, wọn tẹnu mọ ọ pe itiju nla gbaa ni ọrọ ti Gbenga sọ o si buru jai.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Tope Alabi: Mo ti tọrọ aṣọ àti yẹtí etí rí, kí n tó leè ṣe àwo orin 29 Ìgbé 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 27 Ọ̀wàrà 2020 Oríṣun àwòrán, Tope alabi Ilumọọka olórin ẹ̀mí lóbìnrin nnì, Tope Alabi tí ṣàlàyé pé, láti ìbẹ̀rẹ̀ pẹpẹ tí òun ti ń kọrin ẹ̀mí ni òun ti ń lo yẹtí eti, tí òun sì ń wọ ṣòkòtò pẹ̀lú, èyí tó lòdì sí èrò àwọn èèyàn kan tó ní òun kii lo yẹtí tẹ́lẹ̀.
Bakan naa a gbọ latẹnu NEMA pe wọn ti pa ina ọhun wọn si ti gbe awọn to fara pa lọ si ile iwosan fun itọju.
Inú tún bí OLUWA sí Israẹli ó sì fi wọ́n lé àwọn ará Filistia ati àwọn ará Amoni lọ́wọ́.
Oludasilẹ ẹgbẹ 'Save Lagos Group' ni isọkusọ lasan ni ẹgbẹ awọn darandaran, Miyetti Allah Kautal Hore n sọ lẹyin ti sọ pe eto Amọtẹkun le dena ki ọmọ Yoruba jẹ aarẹ ninu ibo gbogbogbo ọdun 2023.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Awọn olugbe ilu Kigali gẹgẹ bi iroyin naa ṣe sọ, tako erongba wọn lori igbesẹ naa Iroyin naa ni awọn ṣọọṣi kan n ṣesin labẹ atibaba, ti wọn o si tun ni ibudo igbọkọ si to to fun awọn olujọsin, eyi ti o maa n mu ki wọn o wa ọkọ wọn gunlẹ si ẹgbẹ ọna, teyi si maa n fa sunkẹrẹ fakẹrẹ ọkọ.
Oríṣun àwòrán, Others Àkọlé àwòrán, Saaju idibo sipo gomina ni ipinlẹ Edo ati Ondo, ẹgbẹ oṣelu APC n koju rogbodiyan lori tani alaga ẹgbẹ oṣelu naa.
Nítorí pé mo ti bẹ̀rẹ̀ sí mú kí ibi ṣẹlẹ̀ sórí ìlú tí à ń fi orúkọ mi pè yìí, ǹjẹ́ ẹ lè lọ láìjìyà bí?
Ras Kimono Efe, aya olorin rege naa tẹlẹ ọkọ rẹ loṣu to tẹlee.
"Mo lero wi pe a n tẹsiwaju o ṣugbọn bayii kọ lo ṣe yẹ ko ri.
O ni ko si otitọ kankan ninu ọrọ to n kaakiri naa.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Mama Rainbow: Toyin Adegbola àti Razak Olayiwola ní ìyá rere àti àwòkọ́ṣe gidi ní O ti wa pe ọdun meji ati oṣu meje bayii ti Egbegbe lo lẹwọn Ikoyi niluu Eko ṣugbọn ti ko tii ri alagbaalẹ kankan ninu ẹbi tabi ara ti yoo gba beeli rẹ.
Gómìnà Kẹjọ – Ọ̀gágun Àgbà Rájí Ràsákì – Gómìnà fún ọdún mẹrin – ọdú́n mọ́kàndinlọgbọn di ọdú́n márùndinlọ́gbọ́n sẹhin
Comey ní Trump jẹ́ òpùrọ́ àti ẹni tó máa yí ìdájọ́ po pẹ̀lú àfikún pé òun kò fara mọ́ọ pé Trump kò pé tó ní ọpọlọ.
 “ Bi won se n se fayawo epo robi lo si orile ede miiran , je ohun to n ko ile ise NNPC lominu, eyi ti  o je akoba fun anfaani ti ijoba apapo n fun awon omo orile ede Naijiria  lori  iranwo owo ori epo robi lati maa ra jala  epo kan  ni N145 bo tile je pe alekun ba iye ti ijoba n ra   jala epo naa ni N171”.
O ni Cristiano Ronaldo lagbabọọlu to dantọ julọ laye ninu itan.
Access Bank: Babaláwo ní òun yóò t'ọwọ́ Ifá bọ̀ọ́, tí Access Bank kò bá dá owó ìyá òun pádà
“Ọpọlọpọ orílẹ̀-èdè ni yóo máa gba ìlú yìí kọjá; wọn yóo sì máa bi ara wọn pé, ‘Kí ló dé tí OLUWA fi ṣe báyìí sí ìlú ńlá yìí?
Ṣugbọn, gbogbo igbiyanju wa lati gbọ ọrọ lẹnu Adebayọ Shittu ni ko so eso rere, nitori pe pabo ni akitiyan wa ni gbogbo igba ti akọroyin BBC Yoruba pe e.
gbe  igbesẹ lati yanju wahala oselu to wa
ó wí fún wọn pé, “Ohun tí OLUWA wí nìyí, ‘Ọ̀la ni ọjọ́ ìsinmi tí ó ní ọ̀wọ̀, ọjọ́ ìsinmi mímọ́ fún OLUWA.
Secondus pẹtu saawọ nínú PDP Ọ̀sun Àwọn obìnrin gba Naijiria lọ́wọ́ ìdójútì Asaba 2018 Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ọmọ Yoruba ni mi Olùdíje gbé APC lọ sílé ẹjọ́ nítorí èsì ìbò Tọkọtaya lu ọmọ ni gbanjo fun 400k Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ṣé ẹ rántí orin - Má ṣe jẹ́jẹ́ ma wà mi lọ?
Awọn alaṣẹ ileewe giga Moshood Abiola Polytechnic, Abeokuta ni awọn yoo bẹrẹ si ni ta fọọmu Post-UTME fun awọn to fẹ wọlẹ si ileẹkọ wọn.
Nígbà tí àkókò oúnjẹ tó, Boasi pe Rutu, ó ní, “Wá jẹun, kí o fi òkèlè rẹ bọ inú ọtí kíkan.
Ṣugbọn ẹ̀yin, ní tiyín, ẹ ṣọ́ra.
“Èmi, OLUWA àwọn ọmọ ogun, Ọlọrun Israẹli ní, nítorí ìwé tí o fi orúkọ ara rẹ kọ sí gbogbo àwọn eniyan tí wọ́n wà ní Jerusalẹmu, ati sí Sefanaya alufaa, ọmọ Maaseaya, ati sí gbogbo àwọn alufaa, pé:
Ta ni kin wọlé tọ̀ kin jẹun!
Ṣébi min ò lóògùn, kédì ewé jíjá
”Ọkunrin náà ni, “Èmi gan-an ni.
Ẹbọra olójú kan yìí ni ó fún mi ní ìwé tí Baba-onírùngbọ̀n-yẹ́úkẹ́ kọsí mi, ohun tí ó sì wà nínú ìwé náà ni èyí:
Kayode Fayemi ni ó pegedé nínú ìdìbò náà gẹ́gẹ́ bí ó ṣe fi ìbò 197,459 ju olùdíje ẹgbẹ́ PDP, Oluṣọla Ẹlẹka tó ní ìbò 178,121 lọ.
Keshi di oloogbe l'ọjọ keje, oṣu kẹfa, ọdun 2016 ni ilu Benin ni ipinlẹ Edo.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Àtúntò FSARS: Àwọn ọmọ Nàìjíríà bẹ̀nu ẹ̀tẹ́ lu àtúntò FSARS 22 Sẹ́rẹ́ 2019 Oríṣun àwòrán, @OfficialSARS Àkọlé àwòrán, Àwọn aláṣẹ Iléeṣẹ́ ọlọ́pàá ní ìlànà iṣẹ́ ikọ̀ ọlọ́pàá kògbérégbè FSARS kò fi ààyè ìrégbè sílẹ̀ fún wọn Eero awọn ọmọ orilẹede Naijiria ṣọtọọtọ si bi ọga ileeṣẹ ọlọpaa Naijiria, Mohammed Adamu ṣe da awọn ọlọpaa FSARS pada, ti ọpọlọpọ si n fapa janu lori ẹrọ ayelujara.
Nígbà tí àwọn ọmọ Israẹli bá fẹ́ pọ́n ohun ìtúlẹ̀ wọn ati ọkọ́ ati àáké ati dòjé, wọ́n níláti lọ sí ọ̀dọ̀ àwọn ará Filistia.
Bo tilej jẹ pe 'jẹsi' naa fa àríyànjiyàn nigba naa, Southampton ati Coventry wa lara awọn ẹgbẹ́ agbabọọlu to pada wọ nkan to jọ aṣọ naa.
Ṣugbọn a ti gba kamu nitori owo tile ẹjọ ni ki Ileesẹ aṣọbode san fun baba mi gan an kere, si iye owo to fi tọju ara rẹ fun aisan loke okun."
Onísùúrù rí ìjà ó ta kété òmùgọ̀ ṣe bí ọ̀lẹ ni, ṣùgbọ́n nígbà tí onísùurù bẹ̀rẹ̀ ìjà, gbogbo àwọn òmùgọ̀ ń wó lulẹ̀ bí igi.
Ọṣinbajo ninu ọrọ to sọ nibi ipade apero ti ileeṣẹ BBC ṣe lati polongo tako ayederu iroyin, sọ pe diẹ lo ku ki ayederu iroyin da igbeyawo oun ru lasiko ti iroyin kan jade pe oun n ba awọn to maa n rin ihoho nile ijo d'ọrẹẹ.
Kọmiṣọna ọlọpaa ni ipinlẹ Ekiti, ọgbẹni Asuquo Mba ṣalaye pe, inu ile ijọsin kan ni ilu Akurẹ lọwọ ti ba Tunmiṣe lẹyin to kan si awọn mọlẹbi rẹ.
Enikeji ni Gomina Kaduna Nasir El Rufai to n tukọ ipinloẹ Kaduna bayii.
Bi o tilẹ jẹ pe atapata dide ni, o kawe gboye ni ileewe awọn ọmọ ogun il Egypt ldun 1949 ko to rekọja lọ si ileeṣẹ awọn ọmọ ogun ofurufu nibi ti wọn ti fi ẹsẹ rẹ mulẹ lọdun 1950.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Akomolede ati asa Yoruba: Ẹ wá kọ́ nípa àpòtí ìṣura èdè wa lórí BBC Yorùbá Bakan naa ni akọwe iṣakoso ileeṣẹ panapana ni ipinlẹ Ọṣun , Fatai Arẹmu pẹlu fi idi ijamba naa mulẹ to si tun ṣalaye pe awọn panapana ti bomi pa ina naa.
A rán an láti jẹ́rìí sí àwọn ọ̀rọ̀ tí Ọlọrun yóo fi fún un láti sọ ni.
Ni ọdun 2015, ajọ ilera agbaye, WHO fi sita pe 57 miliọnu awọn ọmọ Naijiria ni ko lanfani si omi to mọ gaara bẹẹni aadoje miliọnu ninu ọmọ orilẹede Naijiria lo n gbe ni ayika to dọti laisi eto imọtoto gidi.
Ṣugbọn nisinsinyii, Jakọbu,gbọ́ nǹkan tí OLUWA ẹlẹ́dàá rẹ wí,Israẹli, gbọ́ ohun tí ẹni tí ó dá ọ sọ.
Eyi ni yoo jẹ ifẹsẹwọnsẹ kẹjọ ti Arsenal yoo ti maa fidirẹmi ni ọdun 2018 nikan eleyi ti akọsilẹ fihan wipe ko sẹlẹ rii ti Arsenal yoo maa padanu ifẹsẹwọnsẹ mẹrin tẹlera.
Police Corporal Level 04 (1) - N536,586.
 Losu keta odun yii ni Moji Olaiya bi omo keji re ni Canada.
Oun lo ṣee ṣe ko gba ipo kẹrin lonii ninu awọn oludije marun un to ku nile Ẹlẹgbọn Agba.
Mo ní èmi OLUWA ni Ọlọrun yín.
Wọn ni eniyan meji ni ipinlẹ Kwara, méjì ní Edo, ẹyọ kọ̀ọ̀kan ní ipinlẹ Rivers àti Abuja.
ìlú Eko kọ́ ló léwu jùlọ láti gbé lágbàáyé- Ìjọba Eko Ìdí tí mo fi ṣàbẹ̀wò sí ilé ìjọ́sìn T.
Super Eagles f'ìyẹ́ bo Carthage Eagles Tunisia mọ́ 'lẹ̀ 17 Agẹmo 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Diẹ to ninu nnkan oni nnka, eyi lo difa fun ẹgbẹ agbabọọlu Naijiria, Super Eagles ti wọn ipo kẹta tawọn nnkan n pe ni golden bronze ninu idije AFCON 2019.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ìdílé tí ọkọ da ọmọ síta tóríi ojú Búlùú tí wọ́n ní bá BBC sọ̀rọ̀ Baba rẹ naa atawọn ọrẹ pẹlu aladugbo gan an gbarata, wọn daamu, ikun imu ọtun wọn bọ si toi si, amọ ofuutu-fẹẹtẹ, aasa ti ko ni kahun ni gbogbo wahala rẹ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Àyà mi kọ́kọ́ máa ń já nígbà ti mo ṣẹ̀ṣẹ̀ bẹ̀rẹ̀ -Alaga iduro ọkùnrin Ọgbẹni Salami ni ẹgbẹ alatako APC lo wa nidi ọrọ yii, ati wi pe APC ko ṣetan lati gba idajọ ododo laaye.
Gbogbo àwọn ìjòyè ati àwọn ará ìlú tí wọ́n dá majẹmu yìí ni wọ́n gbọ́ràn, tí wọ́n sì dá àwọn ẹrú wọn lọkunrin ati lobinrin sílẹ̀; wọn kò sì fi wọ́n ṣe ẹrú mọ́.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ọlọ́pàa dóòlà ẹ̀mí fadá mẹ́rin lọwọ àwọn ajínigbé 25 Agẹmo 2018 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 10 Bélú 2018 Àkọlé àwòrán, Awọn alagba ijọ aguda lorileede Naijiria ti pe fun iwọde lori ipenija ipaniyan to peleke Orin ọpe ti gba ẹnu awọn ọmọ ijọ Katoliiki ilu Edo ati Warri pẹlu iroyin to gbode pẹ awọn ọlọpaa ti ribi doola ẹmi awọn alufaa ijọ aguda mẹrin lọwọ awọn ajinigbe.
Àwọn eniyan náà sì ké tọ Mose wá fún ìrànlọ́wọ́.
Ọdun 2016 ni ọjọgbọn Yusuf bẹrẹ iṣẹ adari ajọ NHIS.
Conference Centre (ICC) to wa niluu  Abuja.
O si sọ pe oun fẹ lọ sinmi ati pe oun gbadura ki Ọlorun gbe eeyan mii dide to maa wa pari iṣẹ yii nibi ti oun ba a de.
Eyi tumọ si pe Constant Omari lati orilẹede DR Congo ati Faouzi Lekjaa lati Morocco yoo kuro ni ipo keji ati ikẹta bọ si oke.
Ogbeni Bayo Okeowo to jẹ ọkan lara awọn to n gbe agbegbe yii sọ ohun ti oju rẹ ri lẹyin to fi ọpọlọpọ owo oniru, owo oniyọ kọ ile nibẹ.
Oríṣun àwòrán, LASEMA Ọga ọlọpaa ni, awọn tọpasẹ awakọ naa ni awọn fi ri mu, sugbọn awọn yoo gbe lọ si ile ẹjọ laipẹ.
O kere tan ẹ̀gbẹ̀rún- le- nigba eniyan lo ti padanu emi won sinu orisirisi rogbodiyan ti  o ti n sele lati odun 2015 lakooko ti won n dupo  aare ohun fun saa re keta.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Kété tí wọ́n bá ti báa yín sùn tàn torí pé ẹ tóbi, ẹ gbà pé ìfẹ́ yẹn ti parí - Auntie Remi Ọlọ́yàn ńlá Gómínà Oyetola ṣàtúnṣe kónílé-ó-gbélé ní Osun Oríṣun àwòrán, @GboyegaOyetola Gomina ipinlẹ Osun, Gboyega Oyetola ti paṣẹ ki ofin konile o -gbele rọlẹ si nipinlẹ Osun.
Ní àkókò kan, Johanu bá Hẹrọdu baálẹ̀ wí nítorí ọ̀ràn Hẹrọdiasi, iyawo Filipi, arakunrin rẹ̀, tí Hẹrọdu gbà.
Loju ọpọ ọmọ Yoruba, eyi kii se lasan nitori o lọwọ aye ninu ati oogun abẹnu gọngọ, to si nilo ilana ibilẹ lati tu awọn ololufẹ meji naa silẹ.
Bi a ko ba gba wipe, ninu ifẹsẹwọnṣẹ akọkọ ti wọn gba ni papa
Èèyàn 56 ni Covid-19 ṣẹ̀ṣẹ̀ ràn ní Naijiria ní 23/11/2020 Itankalẹ coronavirus ni Naijiria ja walẹ lọjọ Aje, pẹlu bi esi ayẹwo ṣe fihan pe eeyan mẹrindinlọgọta pere lo ṣẹṣẹ ràn.
A ti ń sin òkú méjì sínú ibójì kan náà nítorí ọ̀wọ́ngógó ibojì ìsìnkú Ẹ̀gbọ́n àti àbúrò wà ní ilé ẹ̀jọ́ lórí ikú Tolulope Arotile Oba Ogunwusi wa rọ ijọba lati wa wọrọkọ fi ṣe ada nipa wiwa eto miran ti yoo safihan asa ati iṣe ni orilẹ-ede Naijiria ati awọn ihuwasi to buyi kun eniyan lawujọ.
Oniṣẹ abẹ agba to tun jẹ oludari ile iwosan FMC ni ilu Yola, Ọjọgbọn Auwal sọ pe iṣẹ abẹ naa jẹ aṣeyọri.
Agbẹnusọ iléeṣẹ́ ọlọ́pàá ní Ipinlẹ Ogun, Abimbola Oyeyemi sọ wipe Kasali jẹ́wọ́ wípé òótọ́ ni oun lu ìyàwó oun ni ọjọ́ Àbámẹ́ta tó kọ́já lórí ẹ̀sùn pé òun wó àwọ̀tẹ́lẹ̀ àṣẹ́wó kan to jẹ́ alábàágbé wọn.
Ó ti ẹsẹ̀ ara rẹ̀ bọ àwọ̀n,ó ń rìn lórí ọ̀fìn.
Lẹ́yìn náà ó lọ sí Antioku.
Maarun un ninu awọn adigunjale naa lo yọju siwaju adajọ lati jẹjọ lori ẹsun ti wọn fi kan wọn.
Ninu ipade apero olojo kan fun idanileko dida ara eni lokoowo, eleyi ti oga agba awon omo-ogun naa, ogagun Okwudili Fidelis Azinta seto re, O se lalaye pe  didawole eto ohun osin wa lara ona abayo ti yoo mu igberu ba eto oro aje orile-ede Naijiria.
Fadeyi ni oun ko ti gbọ ẹkunrẹrẹ alaye lori bi isẹlẹ naa se waye ati awọn eeyan to huwa ibi yii.
Oríṣun àwòrán, Other Eleyii lo bi awọn ọmọ Niajiria ninu ti wọn si pe fun itusilẹ Busari ati ki wọn fi panpẹ ọba mu Jerro to polowo rẹ lori ayelujara.
Èèyàn 176 ní àrùn Coronavirus tún ṣẹ̀ṣẹ̀ ràn ní Nàìjíríà ní Ọjọ́ Ìṣẹ́gun Ajọ to n gbogun ti ajakalẹ aarun lorilẹ-ede Naijiria, NCDC ti kede pe eeyan 176 miran ti kun iye awọn to ti ni aarun COVID-19 ni Naijiria.
Nítorí pé Mose fun yín ní òfin ìkọlà, ẹ̀ ń kọlà fún eniyan ní Ọjọ́ Ìsinmi.
Awon kan tile so pe egbe oselu
Bí OLUWA ti ṣe sí Sihoni ati Ogu, ọba àwọn ará Amori, tí ó pa wọ́n run tàwọn ti ilẹ̀ wọn, bẹ́ẹ̀ ni yóo ṣe sí àwọn orílẹ̀-èdè yìí.
Awọn ọlọpaa Plateau fi panpẹ ofin mu afurasi mẹrinlelaadọsan tuntun, eyii to ṣalekun iye eeyan ti wọn ti mu bayii si ọọdunrun o le meje lapapọ.
Gbogbo wa rọ bí ewé,àìdára wa sì ń fẹ́ wa lọ bí atẹ́gùn.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: ‘Ẹ Kéde darandaran bíi agbésùmọ̀mí’ Pápà mímọ́ gbarata lóríi ìpànìyàn Benue Ọwọ́ ọlọ́pàá tẹ àwọn olókoòwò nkan ìjagun O fikun ọrọ rẹ pe ọjọ naa tun ṣe pẹki pẹlu ayẹyẹ ọjọ ti Igbimọ Aṣofin Ipinlẹ Benue fọwọ si ofin to tako kiko ẹran jako ni gbangba ni Ipinlẹ naa.
Ní Bẹtani ni ó ń gbé, ní ìlú kan náà pẹlu Maria ati Mata arabinrin rẹ̀.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Rwanda ti ṣọọsi 700 pa lori ẹsun aṣemaṣe 28 Èrèlè 2018 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Rwanda ti ṣọọsi 700 pa lori ẹsun aṣemaṣe Awọn alasẹ orileede Rwanda ti gbelẹkun awọn ṣọọṣi to le ni ẹẹdẹgbẹrin ti panilu Kigali to jẹ olu-ilu orilẹede naa nitori wipe wọn ko koju oṣuwọn to lori ilana eto aabo ati ilera tijọba la silẹ fun wọn.
Nibẹ lo ti ṣe ayewo awọn ohun elo igbalode ti ijọba ipinlẹ Ọyọ ra sibẹ lati dẹkun itankalẹ aarun Coronavirus.
" Lizzy Jay ni ohun to kan fun oun bayii ni lati dara pọ mọ awọn elere tiata, ti oun si fẹ maa kopa ninu sinima ṣiṣe.
Iyawo mẹta ati ọpọlọpọ ọmọ lo gbẹyin rẹ.
Alaga egbe awon agbe oniresi ni orile ede Naijiria, Rice Farmers’ Association of Nigeria (RIFAN), eka ipinle Kaduna, Alhaji Junaidu Zubairu-Birnin-Daji, ti fireti egbe han lori igbiyanju awon agbe lati fopin si kiko iresi wo Naijiria.
Àwọn wo ló kó oníkẹ̀ẹ̀kẹ́ 'Napep' wọ ìgboro ìlú Liverpool?
O rọ awọn eeyan lati ma se fojudi anfani ibaraẹni sọrọ to ti wa tẹlẹ saaju ajakalẹ yi.
Ará, tí ó bá jẹ́ pé iwaasu pé kí eniyan kọlà ni mò ń wà, kí ló dé tí wọ́n fi ń ṣe inúnibíni sí mi?
Ati wi pe iwadii ti bẹrẹ lori ọrọ naa.
Àfi ìgbà tí mo bọ́ sọ́wọ́ ọ̀tá mí nínú ìrìnàjò ìfẹ́- Roshan Àròsọ àti ìgbàgbọ́ àwọn ènìyàn lórí gbígba ẹ̀jẹ̀ Ìṣẹ́ tó mu ọmọ Nàíjíríà lómi ti gba oorun lójú mi - Osinbajo Ayinla Ọmọwura, orin èébú àti oríyìn lo fi di ọ̀rẹ́ àwọ̀n obìnrin Adedayọ ṣo fun BBC pe inu oun ko bajẹ si igbesẹ aarẹ ile igbimọ aṣofin rara.
Oríṣun àwòrán, Ọjọgbọn Akin Ayọbami Ẹ mase bọ ẹnikẹni lọwọ, ẹ ma di mọ ẹnikẹni lasiko yii yatọ si mọlẹbi yin nikan, ẹ rin jinna bii ẹsẹ bata mẹta si ẹni to sun mọ yin."
Àfi díẹ̀ ninu àwọn ará Aṣeri, Manase, ati Sebuluni ni wọ́n rẹ ara wọn sílẹ̀, tí wọ́n wá sí Jerusalẹmu.
Apẹẹrẹ iru iṣẹlẹ bẹẹ ni bi mọlẹbi ẹnikan ti arun naa pa, ṣe kọlu awọn oṣiṣẹ eto ilera to n bawọn mojuto isinku ẹbi wọn naa.
Àwọn ẹlẹ́ṣẹ̀ pàápàá ń yá àwọn ẹlẹ́ṣẹ̀ ẹgbẹ́ wọn lówó kí wọn lè rí i gbà pada ní ẹ̀kúnrẹ́rẹ́.
Timothy Omotosho: Ó pàdánù ìwé ìgbélú ní South Africa t'orí ẹ̀sùn ìfipábánilòpọ̀
"Ọpọ isẹ ati igbaradi ni wọn se ki wọn to lee da ara ti wọn da.
Nígbà tí ó gbọ́, ó rán ikọ̀ lọ bá Hesekaya, ó ní: 
Loju opo BBC News Yoruba, niṣe lawọn kan n bẹnu atẹ lu igbesẹ rẹ, tawọn mii si ni o dara bo ti ṣe sa asala f'ẹmi ara rẹ.
Sugbọn ṣa, ajọ naa tun ti kede pe o nilo lati san owo fun àwọn ayipada kan nipa akọsilẹ rẹ lori kaadi NIN, botilẹjẹ pe ọ̀fẹ́ ni gbigba nọ́mbà NIN.
Papa isere Oluyemi Kayode ni olu olu- ilu ipinle Ekiti, Ado-Ekiti ni ipolongo ibo naa ti waye.
Nítorí pé àwọn arakunrin rẹ pàápàáati àwọn ará ilé baba rẹti hu ìwà ọ̀dàlẹ̀ sí ọ;àwọn gan-an ni wọ́n ń ṣe èké rẹ:Má gbẹ́kẹ̀lé wọn,bí wọ́n bá tilẹ̀ ń sọ̀rọ̀ rere sí ọ.
    Ọ̀rọ̀ ni ìwọ̀nyí, ẹ̀yin ènìyàn mi, àti pàápàá ẹ̀yin ọmọ ilé-ìwé, àti ẹ̀yin tí ẹ jẹ́ olúkọ́ wọn.
Bakan naa ni ajọ naa sọ pe awọn akẹkọọ meje ni wọn kọkọ fi ofin gbe, ko to o di pe wọn fi awọn mẹẹrin silẹ.
Nígbà tí ìyàwó Olówó-ayé àfẹ́sọ́nà tí ó ti sọ ara rẹ̀ di ẹyẹ náà ri èyí, ó yípadà ó ddi ènìyàn, ó mú oúnjẹ ni inú àpò ó fí í fún ọkọ rẹ̀ tuntun, ó si wí pé ‘Gba eléyìí, jẹun dáadáa, má ṣe jẹ́ kí inú run ọ́, ọkọ kì í ju ọkọ lọ.
Jeremaya dá a lóhùn, pé, “Rárá o, n kò sálọ sọ́dọ̀ àwọn ará Kalidea.
Kò tíì pẹ́ jù bí ìjọba bá leè sọ ẹni tó pa olóògbé Bola Ige- Gani Adams Wo ohun ti Esabod sọ nipa ọrọ alufanṣa to n sọ si awọn Ọba alaye kan:- Esabod, ẹni ti ọpọ eeyan mọ pe o maa n fi ede abuku sọrọ nipa awọn Ọba alaye nilẹ Yoruba, awọn agba oselu, olorin, oṣere tiata atawọn eekan ilu miran lori ayelujara, wa salaye pe, oun kii woju ẹnikẹni bii sọrọ-sọrọ, ti oun ba wa lẹnu iṣẹ oun O ni:  Ni ẹnu iṣẹ mi, n ko fẹ mọ iru ẹni to jẹ, amọ laisi lẹ́nu iṣẹ, maa kunlẹ fun Ọba; amọ, ki ni Ọba wa de ibi iroyin?"
Nigba ti Atiku naa ko gbe ẹnu rẹ fun alagbafọ, nise ni o da esi pada fun igbakeji Aarẹ Osinabjo Ọrọ naa ko ti tan nilẹ Ọ̀rọ́ PVC di kátàkárà, ará ìlú ń san tó N7,000 Ọjọ́ kọkanlelọgbọn, oṣù kẹjọ ní Àjọ eleto ìdìbò INEC kéde gẹgẹ bí gbendeke fún gbígba káàdì ìdìbò PVC.
" Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Igba mejila ni Moses o gba bọọlu sinu awọn lati 2012 to ti bẹrẹ.
Aabo fawọn olutọju alaisan Ilé ìwòsàn ṣàlàyé bí àgùnbánirọ̀ Linda ṣe ku Wo bí oògùn olóró ṣe ń fèèyàn dábírà!
” Wọ́n sì fi ọ̀nà náà hàn án.
Adajọ Binta Nyako tile ẹjọ giga ijọba apapọ to wa nilu Abuja lo pasẹ bẹẹ nigba ti asaaju ikọ agbejọrofun igun olupẹjọ to fẹsun kan Ipob, Shuaibu Labaran sọ wipe, bi Kanu ko se yọju sile ẹjọ nfa ifasẹhin fun igbẹjọ ati ilọsiwaju lori ẹjọ naa.
Bigsam pin oriṣiiriṣii fọto eto adehun igbeyawo ọhun laarin Toyin Abraham ati Kolawole Ajeyemi.
Ki Olorun ko dẹlẹ fun agba ọjẹ onkọwe yii ni adura BBC Yoruba Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Akomolede ati asa Yoruba: Ẹ wá kọ́ nípa àpòtí ìṣura èdè wa lórí BBC Yorùbá Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Fídíò, Akomolede: Bolaji Faleke ni Olùkọ́ tó ń kọ́ wa ní àṣà oge ṣiṣe lórí BBC Yorùbá1 Owewe 2020 Fídíò, Akomolede Yoruba: Ìtàn ọ̀rẹ́ tó fi ògùn gba ọkọ ọ̀rẹ́ rẹ̀ nílùú òyìnbó rèé15 Owewe 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Fayose: Ẹ yee ta dukia ti EFCC gba ni kọọrọ
Kàkà kí n wọ̀ ọ́ lẹ́wù  tàbí kí n tì í bọ́'nú àpò fún ìdáàbò bò ó, nṣe ni mo fi sílẹ̀ ní ìhòhò.
Oríṣun àwòrán, Oluwaseyi Makinde Àkọlé àwòrán, Day 20: Ìgbà mélòó ni Ṣeyi Makinde ti dupò rí?
    A ṣán igbó gbogbo tí ó wà ní ibi tí a o kọ́ ilé Ìgbéga-ọ̀run sí, a padà wá sí ibi ti à ń gbé.
Shehu ni lati igba ti aare ana ti kuro lori aleefa, ni o
Bí ènìyàn ba ń tọ odó náà lọ sí apá òkè, nígbà tí olúwarẹ̀ yóò bá fi rìn tó wákàtí mẹ́ta yóò kan odi ńlá kan tí ó dúró gẹ́gẹ́ bí ààlà láàrin ayé òun ọ̀run.
2 29570 Orilẹede Madagascar 267 1.
Nígbà tí ọkùnrin náà parí ọ̀rọ̀ rẹ̀ tán, dípò kí Ikú fèsì kúkúrú, ó fèsì tí ó gún gbọọrọ.
 Àwa náà sí mọ ̀ pé èdè yorùbá yìí kún , ó dùn , ó ṣe pàtàkì , ó sì jọjú gidigidi .
láti ṣe ìdájọ́ lórí gbogbo ẹ̀dá.
Olóòótọ́ ti tán lórí ilẹ̀ ayé, kò sí olódodo mọ́ láàrin àwọn eniyan; gbogbo wọn ń wá ọ̀nà ìpànìyàn, olukuluku ń fi àwọ̀n dọdẹ arakunrin rẹ̀.
Wọn óo wí pé, “Ẹ wá, ẹ jẹ́ kí á pada sọ́dọ̀ OLUWA; nítorí bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé ó ti fà wá ya, sibẹ yóo wò wá sàn; ó ti pa wá lára lóòótọ́, ṣugbọn yóo di ọgbẹ́ wa.
com/tocrSNqwe4Awon aworan ati fonran yii safihan bi ifigagbaga idije UEFA Champions League se lo laarin iko agbaboolu PSG ati Iko Manchester United.
Ṣe ẹni naa jẹ Ọlọrun ni, koda bo jẹ Ọlọrun, maa pe e maa ba a sọrọ̀ tori bo ṣe fi ọmọ ọdun mẹrin nikan silẹ ko dara"", iyẹn ni mo sọ o ti mo si fọwọ kan ọmọ ba a wi."
Ni bayii, Naijiria yoo koju Algeria tabi Ivory Coast ninu abala
O ni o pe awọn mọlẹbi rẹ pe, oun pa eeyan kan ni oun ko fi lee pada wa sile mọ o.
Nígbà tí mo ka ìwé yìí tán mo mí kanlẹ̀, inú mi bàjẹ́ ó rí rúdurùdu, n kò mo òsì tí n bá fún ẹni tí ó rán wá, mo wí fún un pé kí ó máa lọ, n ó fi èsì ránṣẹ́ nígbà tí ó bá ṣe.
Ohunkohun tí ó bá fihàn mí, n óo sọ fún ọ.
Ìdájọ́ àkọ́kọ́ kò tẹ́ mi lọ́rùn, mo tún tí gbé Seyi Makinde lọ silé ẹjọ́ - Bayo Adelabu Ìjọba Ìpínlẹ Ọyọ yọ̀ǹda pé kílé Ìjósìn má san owó orí mọ́ - Makinde Seyi Makinde, yé é sọ̀rọ̀ mi láìdà - Gomina Ajimobi Seyi Makinde, bàtà tí Ajimobi bọ́ sílẹ̀ ni ko tẹsẹ̀ bọ̀ fún àṣeyọrí Ọyọ - APC Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ladoja Eyi ni wi pe bo ba ṣe pe lootọ awọn araalu lo n kan sara si iṣẹ rẹ ti wọn si n pe e pe ko lọ fun saa keji ko buru nitori pe awọn oloṣelu lọpọ igba lo maa n fi ọgbọn fi iru ọrọ naa sita lati wo bi awn eeyan yoo ṣe gba a si.
Peteru sọ fún un pé, “Túmọ̀ òwe yìí fún wa.
Egbe oselu tuntun lorile-ede Zimbabwe ti a mo si New Patriotic Front (NPF) so lojo-Aje pe, ajagun feyinti kan ti o tun je alatileyin Aare teleri Robert Mugabe ti se idasile egbe oselu tuntun kan lati gbena koju Aare Emmerson Mnangagwa ninu eto idibo ti yoo waye ninu odun ti a wa yii.
Child Trafficking: Àwọn ọmọ ọdun mẹ́fà sí mẹ́wàá pọ̀ tí a ti tú sílẹ̀
Bí eléyìí ṣe n lọ lọ́wọ́ ní òmíràn tún ṣẹlẹ̀ ni ìlú Ibadan to tun di ariwo ikunlẹ abiyamọ.
Igbimọ amuṣẹya ti ijọba apapọ gbe kalẹ lori akoso arun Coronavirus, lo fidi ọrọ yi mulẹ pe awọn arinrinajo naa foju arun yii han, lẹyin ọjọ meje ti wọn pada de.
O ni: Ägbekale igbimo alamojuto yii dara pupo lasiko yii.
“Yato si awon to wa ni sinima ti won ni iwe ase  igbesita ni Naijiria, awon to ku to wa lori igba ko ni iwe ase rara.
Àwọn ọmọ Aaroni yóo sun wọ́n lórí igi tí ó wà ninu iná lórí pẹpẹ; ẹbọ sísun ni, tí ó ní òórùn dídùn, tí inú OLUWA sì dùn sí.
Oreoluwa tọwọ bọwe adehun ọlọdun meji pẹlu ileeṣẹ naa to n ṣowo ilẹ ati ile, ni olu ileeṣẹ rẹ to wa ni Abuja.
Ileeṣẹ MTN jẹ ọkan lara awọn ileeṣẹ to n ṣeto ibanisọrọ ni orilẹ-ede Naijiria yatọ si GLO, Airtel, Etisalat atawọn miran.
Àbí ẹ kó mọ̀ pé Tẹmpili Ọlọrun ni yín ni, ati pé Ẹ̀mí Ọlọrun ń gbé inú yín?
Ọmọbinrin naa, Elizabeth Oyeniyi, ninu fidio ifọrọwanilẹnuwo kan to ṣe pẹlu ajọ ajafẹtọ Dorothy Njemanze Foundation, sọ pe kọmisana naa ji oun gbe, to si tun lu oun nitori pe oun gba a nimọran pe ko tọju ẹbi rẹ.
Onigbagbọ kan tí ń jẹ́ Timoti wà níbẹ̀.
Bakan naa ni iroyin sọ pe awọn akẹkọọ tawọn obi wọn ko tii sanwo ileewe wọn ko ni lanfaani lati kopa ninu igbẹkọ naa lori ayeluajra.
”Àwọn tí a kàn mọ́ agbelebu pẹlu rẹ̀ náà ń bu ẹ̀tẹ́ lù ú.
Wọ́n ti sé ìlẹ̀kùn odi àwọn ìlú ilẹ̀ Nẹgẹbukò sì sí ẹni tí yóo ṣí wọn.
  Alákùrin àtijọ́ Robin Hood ni ìtàn kán sọ fúnwa pé ó fò láti igun sosoro ìkíní sí ìkejì ní ìgbésẹ̀ ẹyọọ̀kan soso!
oko ofurufu ,to sẹlẹ lojo Abameta niluu Kabba , ni ipinle Kogi.
Agbẹnusọ àjọ EU, Eric Mamer sàlàyé pe, àwọn ni ọ̀nà ti àwọn ń gbà láti mọ orílẹ̀-èdè tí yóò le gba arìnrìn àjò, ó fi kún pé, ìpinu àwọn dá lórí ìlànà ìjọba lórí ẹ̀ka ètò ìlera.
Oríṣun àwòrán, Facebook/Otuba Adebayo Alao-Akala ''Ko si ohun ti n ko mọ nipa oṣelu ipinlẹ Oyo, n o si ni erongba lati fa ẹnikan kalẹ lati dije fun ipo gomina lọdun 2023,'' Alao-Akala lo sọ bẹẹ.
Oríṣun àwòrán, @HQNigerianArmy Ó fi kún u pé, ọ̀rẹ́ wọn ọ̀hún kọ́kọ́ bẹ̀rẹ̀ sí mú díẹ̀ nínú wọn lọ, tí wọ́n sì ń rí N3,000 gbà ní gbogbo ìgbà tí wọ́n bá jà tábí tí wọ́n bá digun jale àbí tí wọ́n gba owó ìtúsílẹ̀.
Òwe: Kí ni ìtumọ̀ òwe ikú tó ń pa ojúgbà ẹni?
Mo dúpẹ́ lọ́wọ́ rẹ fún gbogbo ọ̀rọ̀ tí ó sọ n ó sì jíṣẹ́ rẹ fún àwọn ọmọ aráyé, n kò ní í fi ọ̀kan pe méjì, nítorí máà mo fẹ́ kí o yọ̀ọ̀da fún mi lónìí n óò tún padà wáá rí ọ lọ́la, nǹkan kan ni mo ń ṣe lọ́wọ́ tí mo fi sílẹ̀ tí mo ní kí ń yára wáá fi ojú gán-ánnní rẹ, nítorí náà ó dìgbà díẹ̀ nísisìyí ná, mo ń lọ sí ilé, lọ́dọ̀ ọ̀rẹ́ mi.
Wo ìdí tí àwọn obìnrin kan fi n yọ ilé ọmọ wọn kúrò Egypt dá akọ́nimọ̀ọ́gbá Aguirre dúró lẹ̀yìn ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ 2) O ṣe pataki fun ẹgbẹ agbabọọlu to ba fẹ ṣe aṣeyọri lati ni adilemu to gbounjẹfẹgbẹ gba awo bọ.
Opium ni o ṣeto iṣẹ iwadii naa lorukọ USwitch ni United Kingdom.
ijoba apapo lorile ede Naijiria, Boss Mustapha naa gbosuba fun oludari ile-ise
Oore-ọ̀fẹ́, àánú ati alaafia láti ọ̀dọ̀ Ọlọrun Baba ati láti ọ̀dọ̀ Jesu Kristi Ọmọ Baba yóo wà pẹlu wa ninu òtítọ́ ati ìfẹ́.
Enìyàn mẹ́ta kú nínú ìjàmbá ọkọ̀ ní'lù Abuja
Gege bi awon osise eleto ilera lorile-ede Democratic Republic of Congo, won fi mule pe eniyan meji miiran tun ti ba ikolu arun asekupani Ebola lo.
Ìwọ ni a fẹ́ kí o jẹ balogun gbogbo àwa ará Gileadi patapata.
Ìpìlẹ̀ àwọn yàrá ẹ̀gbẹ́ jẹ́ ọ̀pá kan tí ó gùn ní igbọnwọ gígùn mẹfa (mita 3).
Olorin takasufe ti ọpọ mọ si Marlian wi pe niṣe lo yẹ ki wọn ko awọn ọlọpaa SARS kuro loju titi.
A wà nínú igbó tí a ti ń wá àwọn arinrìnàjò mẹ́jọ láti Abuja sí Eko tí wọ́n jígbé lọ- Ọlọ́pàá Ondo Awọn oludije to n dije fun aṣia ẹgbẹ oṣelu APC lati dupo gomina ipinlẹ Ondo ni Gomina Rotimi Akeredolu, Chief Olusola Oke, Dokita Segun Abraham, Ọgbẹni Olaide Adelami, Ko yọ Bukola Adetula, Arabinrin Jumoke Anifowose, Ambasadọ Sola Iji, Ọgbẹni Isaac Kekemeke, Jimi Odimayo, Ọgbẹni Nathaniel Adojutelegan ati Awodeyi Akinsehinwa naa silẹ.
Ọjọ kẹta Ileya ni ọdun Ojude Ọba maa n waye: Ni ọjọ kẹta ọdun Ileya ni awọn ọmọ bibi ilẹ Ijẹbu yoo korajọ pọ lati se ayẹyẹ ọdun Ojude Ọba pẹlu awọn ọrẹ, ẹbi ara ati ibatan wọn.
Ni ojo Aiku Sunday Ogbeni Bio ati Ogbeni Kamara pelu awon aya won pade ni ile ijosin ni ilu Freetown ti n se olu ilu orile-ede na pelu erongba ibasepo to danmoran.
Bí mo ti bẹ̀rẹ̀ sí sọ̀rọ̀ ni Ẹ̀mí Mímọ́ bá bà lé wọn bí ó ti bà lé wa ní àkọ́kọ́.
wọ ́ n kọ ́ ibi ìwòràwọ ̀ àkọ ́ kọ ́ ní ọdún 1753 sí 1754 lórí òrùlé ìkan lára àwọn ilé tó wà ní yunifásitì yìí , tí emperor franz joseph i of austria pàṣẹ iṣàmúlò rẹ ̀ ní ọdún 1883 .
 Siwaju si, akonimoogba iko agbaboolu Liverpool, Juergen Klopp lo gba ami-eye akonimoogba ti o dara julo, ti akonimoogba orile-ede Amerika tiko obinrin, Jill Ellis si gba irufe ami-eye naa.
Stuart s èyí nítorí wí pé wọn ti ń ṣe é jáde gkgẹ́ bí ohun èlò ìgbádùn.
Ọba rán àwọn olórí ogun ati àwọn ẹlẹ́ṣin tẹ̀lé mi.
Ìjọba Ìpínlẹ̀ Osun ṣàlàyé pé, àwọn aráàlú yóò ní anfaani lati rin yíká ìpínlẹ̀ náà bẹ̀rẹ̀ láti aago mẹ́fà àárọ̀ si marun irọlẹ, láti ọjọ́ Ajé sì Ọjọ́bọ ọsọọsẹ.
Àròsọ àti ìgbàgbọ́ àwọn ènìyàn lórí gbígba ẹ̀jẹ̀ Gbogbo ènìyàn ló mọ pe owó dátà kò rọrùn rárá, àbí ẹ ẹ melo ní ẹ ti ròó pé ó yẹ ki àwọn Mààmí àti Bàámí ti fi kún owó àkosápò yín nítori ǹkan ti dátà ń gbà lọ ninu owó ti wọ́n ń fún yín Oríṣun àwòrán, Getty Images Sùgbọ́n ìfòyà kò sí mọ nítori Oluwakorede Cole gẹ́gẹ́ bi orúkọ rẹ̀ ti kó ire wọ̀lú.
Nígbà tí a dé ààfin ọba àwọn ejò yìí a bá a lórí ìtẹ́, o gúnwà gbogbo àwọn ìjòyè rẹ̀ sí kájọ yí i káàkiri.
Ọlọ́rọ̀ máa ń jọba lé talaka lórí,ẹni tí ó lọ yá owó sì ni ẹrú ẹni tí ó yá a lówó.
Ẹni tí ó lágbára gba ilẹ̀,ẹni tí ó lọ́lá sì ń gbé inú rẹ̀.
Nibayii, aago mẹrin irọlẹ si aago mẹfa aarọ ni ofin konile-o gbele naa yoo ma waye lati Ọjọ Kẹtadinlogun, Oṣu Kẹwaa fun ọjọ mẹta gbako.
Mo n ṣe iṣẹ mi gẹgẹ bi akọroyin ni.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Coronavirus Update: Omi mímu wọ́n ju owó ilé lọ nílùú yìí Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Coronavirus Update: Omi mímu wọ́n ju owó ilé lọ nílùú yìí 4 Ògún 2020 Omi jẹ ọkan pataki lara ohun ti eeyan nilo bi yoo ba duro sile gẹgẹ bi ijọba ṣe n paṣẹ isede, ibomu, fifọwọ, diduro sile lasiko ajakal arun Coronavirus yii.
aseyori ijoba aare Buhari, ti ajo to n mojuto iroyin ati asa se onigbonwo re.
Komisona to n mojuto ipese eto ilera nipinle naa, dokita Kabiru Getso, soro iyanju naa lasiko ayeye odun abere ajesara lagbaye ti o waye nipinle Kano, lojoBo(Thursday).
17 Nítorínáà, èmi Olúwa, ní mímọ àwọn ewu tí yíò wá sí orí àwọn olùgbé ilẹ̀ ayé, ké pe ìránṣẹ́ mi Joseph Smith, Kékeré, mo sì sọ̀rọ̀ sí i lati ọ̀run, mo sì fún un ní àwọn òfin;
Àwọn oluwádìí láti ilé iṣé ọlọ́pàá ti lọ sí ibi tí ìsẹ̀lẹ̀ náà ti ṣẹlẹ̀ láti lo ya àworán ibẹ.
Nígbà tí ó gbọ́ pé Jesu ará Nasarẹti ni ó dé, ó bẹ̀rẹ̀ sí kígbe pé, “Jesu!
Eleyi to buru julọ ṣẹlẹ lọdun 2008 nibi ti ọgọta ọmọ ilẹ okere ti padanu ẹmi wọn lorilẹede South Africa.
“Ìwọ ọmọ eniyan, mo ti ṣẹ́ Farao, ọba Ijipti, lápá, a kò sì tíì dí i, kí ọgbẹ́ rẹ̀ fi san, kí ó sì fi lágbára láti gbá idà mú.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ọlọ́jọ́ Festival 2018: Ayẹyẹ ọdún Ọlọ́jọ́ ti Ilẹ Ifẹ̀ á parí pẹ̀lú àyájọ́ òmìnira Nàìjíríà 24 Owewe 2018 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 27 Owewe 2018 Oríṣun àwòrán, AFP Àkọlé àwòrán, Kabiesi, ki ade pẹ lori O Ọjọ́ Iṣegun, ọjọ́ kejidinlogun, oṣu kẹsan an ni ayẹyẹ ọdun Ọlọ́jọ́ ti 2018 bẹ̀rẹ̀ pẹ̀lú ayẹyẹ àṣà Gbajure.
Gbogbo àkànpọ̀ igi yóo jẹ́ mẹjọ, ìtẹ́lẹ̀ fadaka wọn yóo sì jẹ́ mẹrindinlogun, meji meji lábẹ́ àkànpọ̀ igi kọ̀ọ̀kan.
Wo àwọn òfin tuntun tíjọba fí síta lórí lílọ ìrìnàjò sílẹ̀ òkèèrè Oríṣun àwòrán, Ethiopian Airline Ọ̀la òde yìí ni ìrìnàjò sí ilẹ̀ òkèèrè yóò padà bẹrẹ ní Nàìjíríà Ijọba apapọ ti kéde ọjọ karun un, oṣu Kẹsan an, ọdún 2020, gẹgẹ bí ọjọ ti irinajo ọkọ ofurufu si ilẹ okeere yoo bẹrẹ pada ni Naijiria.
Minisita to n ri si ere idaraya ati idagbasoke awon ni Naijiria, Solomon Dalung so pe, inu ijoba ko baje rara latari pipadanu ifesewonse olorejore keji sowo Serbia lojo Isegun(Tuesday).
Seyi Makinde: Ìyá Akurẹ àti Iya Ibadan kìlọ̀ fún mi lóru ọ̀gànjọ́ làti sọ́ra fún olóṣèlú
idibo ni ipinle naa, ọjọgbọn Adikwu ni iye awon oludibo ni ipinlẹ Kogi  jẹ 1,640,449, ti iye awon ti won yege lati
Nígbà tí ẹ̀ ń gbà fún àwọn àlejò, tí a kò kọ nílà abẹ́, ati ti ọkàn, láti máa wọ ibi mímọ́ mi nígbà tí ẹ bá ń fi ọ̀rá ati ẹ̀jẹ̀ rú ẹbọ sí mi, ibi mímọ́ mi ni ẹ̀ ń sọ di aláìmọ́.
láti jẹ́ iranṣẹ Kristi Jesu sí àwọn orílẹ̀-èdè tí kì í ṣe Juu.
Dayo Amusa: Ohun didun ni o fi n gbe awo orin jade Isẹ ori ran mi ni mo n se ni ọrọ Temidayo Amusa nitori ko ta igba abi awo rara, orin lo n mu kọ lẹyin isẹ tiata.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Agbenusọ fun ile isẹ ọlọọpa ni ipinlẹ Ondo ni iwadii ti bẹrẹ ni pẹrẹwu lori isẹlẹ naa.
Ó wá di ibi tí àwọn àǹjọ̀nnú ń gbé, tí ẹ̀mí Èṣù oríṣìíríṣìí ń pààrà, tí oríṣìíríṣìí ẹyẹkẹ́yẹ ń kiri.
"Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, World Radio Day: Àwọn aráàlú ní Rédíò ni àgbára àwọn, òògùn ẹ̀jẹ̀ rúru ni O fi kun un pe, ""ninu ipokipo ti o ba ba ara rẹ, ma jẹ ki ọkan rẹ ko daru""."
Bi o tilẹ jẹ pe irinajo arugba lọ si idi odo ni o gbajugbaja julọ laarin awsn eeyan sibẹ oniruuru ayẹyẹ lo maa n waye lasiko ọdun naa.
Oríṣun àwòrán, @BashirAhmaad Àkọlé àwòrán, Ogunlọgọ awọn eniyan tu jade si oju popo lati kii Aarẹ Buhari kaabọ si ipinlẹ Plateau lọjọ ọjọbọ.
 ilẹ russia kọ etí ikún sí àsẹ tí ilẹ ̀ germany lórí àsẹ yìí .
Jesu wò wọ́n lójú, ó sọ fún wọn pé, “Èyí kò ṣeéṣe fún eniyan; ṣugbọn ohun gbogbo ni ó ṣeéṣe fún Ọlọrun.
Àwọn ọ̀rẹ́ mi ń fi mí ṣe ẹlẹ́yà,mo sì ń sọkún sí Ọlọrun,
Nítorí ẹ̀ṣẹ̀ wa pọ̀ tẹ́lẹ̀, ọwọ́ ibinu OLUWA sì ti wà lára Israẹli.
O sọ̀ oe ibẹru lo mu ki ejo naa kọlu Arabinrin Richards, nitori pe o di ọna to yẹ ki ejo naa gba jade.
Nígbà náà ni Samuẹli mú ìgò òróró olifi kan, ó tú u lé Saulu lórí.
 ti díẹ ̀ ìkọ ́ jùjàsí pòorá ní àwọn oṣù sí ọdún bí kò básí pé ibà kọluni .
Chloroquine for coronavirus: Àjọ NAFDAC fọwọ́ sí pípo ògùn chloroquine fún àyẹ̀wò ìtọ́jú coronavirus ní Nàìjíríà
    Ìfẹ́pàtàkì nílá rí púpọ̀, àpẹẹrẹ pàtàkì ni ó jẹ́ fún àwọn ọmọge.
Ẹsun ìgbéjọ lori gbigba ifitonileti nipa awọn kan labẹlẹ laigba ọna to tọ ni olori ẹsun ti wọn fi kan aarẹ ana naa.
O ti le ni ọdun mẹẹdọgbọn ti Sara ti de orilẹede South Afrika gbẹyin, koda, ọmọ ọsẹ meje lo wa ti wọn fi gbe lọ silu ọba, ti ko si niran ohunkohun nipa orilẹede naa rara, koda igbe aye nilẹ Gẹẹsi gan ko dẹrun, nitori pe kii se alawọ funfun pọnbele, to si n tiraka lati farada igbe aye rẹ nilu Surrey, bẹẹ ni ko lee sọ oun to faa, ti iya rẹ fi kọ silẹ.
Akeredolu ni oun yoo si tete ṣe agbeyẹwo ọna abayọ ti ijiroro naa ba la kalẹ lati ri wi pe lilọ si ile ijọsin pada si awujọ wọn.
Ọlọrun Pàṣẹ fún Joṣua pé Kí Ó Fi Ogun Kó Ilẹ̀ Kenaani.
Ọlọrun tí ń lọ níwájú yín ninu ọ̀wọ̀n iná lóru, ati ninu ìkùukùu lọ́sàn-án, láti fi ọ̀nà tí ẹ óo máa tọ̀ hàn yín kí ó lè bá yín wá ibi tí ẹ óo pàgọ́ yín sí.
7 672886 Orilẹede Canada 17692 47.
Èkejì rèé losu kan tí nkan ń ṣẹlẹ̀ sàwọn òṣìṣẹ́ UN.
hifikepunye lucas pohamba ( ojoibi august 18 , 1935 ) je oloselu omo ile namibia .
Ẹ kò gbọdọ̀ jẹ ẹ́, kí ó lè dára fún ẹ̀yin ati àwọn arọmọdọmọ yín nígbà tí ẹ bá ṣe ohun tí ó tọ́ ní ojú OLUWA.
Nítorí pé ó mọ iṣẹ́ ọwọ́ wọn,á bì wọ́n ṣubú lóru, wọn á sì parun.
8 Bélú 2019 Oríṣun àwòrán, OTHERS Àkọlé àwòrán, Ẹni ti ọ̀rọ̀ náà sojú rẹ̀ ní ọmọbinrin kan ló mú fa Shisha, tí ó gbàgbé pa iná rẹ̀, kí ó tó wo inú ọkọ̀ ofùrufú.
19 Òkùdu 2019 Àkọlé àwòrán, Kíní abẹ́rẹ́ ajẹsára, báwo ni wọ́n ṣe n ṣiṣẹ́ àti pé kíní ìdí tí àwọn ènìyàn kìí ṣe fọ́kan tan?
eniyan gbodo foju sile, bee si ni ki won fi ejo enikeni ti won n ba n furasi
báwo ni n óo ṣe dúró níwájú Ọlọrun?
Kó ní sí ohun kan tí ẹ kò ní lè ṣe.
Àwọn ni ó ṣe ìlérí fún.
Wọ́n tó dé, wọn kò dé, a retí, retí, wọn kò dé.
Ẹgbẹ oṣiẹ ati ijọba apapọ ti fẹnuko lori adehun bi aba ofin ẹkunwo oṣu tuntun yoo ṣe de ọwọ awọn aṣofin apapọ.
Ìyá rẹ̀ jẹ́ Juu tí ó gba Jesu gbọ́; ṣugbọn Giriki ni baba rẹ̀.
bayii, a n foju sunukun wo ilana ajo eleto idibo, Independent National
Bẹ́ẹ̀ ni yóo rí nígbà ajinde àwọn òkú.
Iwaadi ti BBC Yoruba ṣe nipa rẹ tu aṣiri awọn nkankan nipa Dokita yi.
Kódà, lọdun 1997 nigbati àrùn ọhun gbóná jain-jain, èèyàn mílíọ̀nù mẹta àti aabọ lọ gba ẹ̀mí wọn lairo tẹ́lẹ̀.
Ìbálópọ̀ nínú ọkọ̀: Ọlọ́pàá ìpínlẹ̀ Eko tako ìsesí yìí
Codein lọ, DXM wọlé, kinni iyatọ?
Ọjọ́bọ̀ la ó mọ̀ bóyá a ní Coronavirus - Aṣòfin Ondo Àlàyé rèé lórí ikú tó pa Adegbenro, Kọmísánà l‘Ondo Wo àwọn gómìnà Nàìjíríà tó tí lùgbàdì Covid-19 àti ipò tí ìlera wọ́n wà Bẹẹ ba gbagbe, laipẹ yii Gomina Akeredolu kede ninu fọnran fidio kan pe, ohun ti lugbadi Covid-19.
''Ta lo mọ wi pe PDP le gba Bauchi, ta lo mọ wi pe PDP le gba Benue,ta lomọ wi pe PDP le gba Imo?
Ẹnikẹ́ni tí ó bá fara kan ohunkohun tí ó jẹ́ aláìmọ́, kì báà jẹ́ pé ó fara kan òkú ni, tabi pé ó fara kan ẹni tí nǹkan ọkunrin jáde lára rẹ̀, 
kí àwọn ọmọ Aaroni, alufaa, to igi sórí pẹpẹ náà kí wọ́n sì dáná sí i.
Bakan naa ni Gomina Akeredolu ta aarẹ Buhari lọrẹ pẹlu aṣọ ibilẹ ti wọn ṣẹ ni ipinlẹ naa fun igbelaruge ọrọ aje labẹle lorilẹede Naijiria.
Èmi Juda, iranṣẹ Jesu Kristi, tí mo jẹ́ arakunrin Jakọbu ni mò ń kọ ìwé yìí sí àwọn tí Ọlọrun Baba fẹ́ràn, tí Jesu Kristi pè láti pamọ́.
" Aàrẹ Buhari buwọlu yíyí orùkó àwọn ibùdókọ ọkọ ojú ìrìn bíi ti Apapa padà fi sọrí àwọn èèkàn ìlú Ìyá òòṣà fẹ̀sùn àjẹ́ kan ìyá ẹni ọdún 90, aráàlú bá sọ ọ́ lókò pa Nàìjíríà ṣí àwọn ilé ìwé padà; Ìdánwò WAEC á bẹrẹ lẹyìn ọdún Iléyá!
to farapa pe ki Olorun fun won ni alaafia to pe.
Nítorí àwọn olórí mẹrin wọnyi, tí wọ́n jẹ́ ọmọ Lefi, ni wọ́n tún ń ṣe alabojuto àwọn yàrá tẹmpili ati àwọn ilé ìṣúra tí ó wà ninu ilé Ọlọrun.
Game of Thrones ati Ireke Onibudo jẹ adakọ iwe.
Ẹni tí ó tẹmbẹlu aládùúgbò rẹ̀ kò gbọ́n,ṣugbọn ọlọ́gbọ́n a máa pa ẹnu mọ́.
Ishaq Abiola Ajimobi to wa ni Oke Ado, Ibadan.
Dominican Republic fi lede pe awọn arinrinajo gbọdọ ni kaadi eto ilera ti wọn yoo fihan awọn ẹsọ aṣọbode bi wọn ba ṣe n wọ orilẹede wọn lati Ọjọ Keji, Oṣu Keje.
Oríṣun àwòrán, Reuters Àkọlé àwòrán, Bayii lawọn musulumi ṣe ki rawọn ni Nairobi.
Oba Akinruntan ṣe apejuwe iṣekupani Oba Adeusi gẹgẹ bi ohun to bani ninu jẹ, ti awọn si tako patapata.
Àwọn tí wọn ń fi abọ́ mu ọtí, tí wọn ń fi òróró olówó iyebíye para, ṣugbọn tí wọn kò bìkítà fún ìparun Josẹfu.
Nítorí,“Gbogbo ẹlẹ́ran-ara dàbí Koríko,gbogbo ògo rẹ̀ dàbí òdòdó.
Pásítọ̀ Ofori dèrò ẹ̀wọ̀n lẹ́yìn tó yìnbọn pa ìyàwó rẹ̀ ní ìta gbangba Bí nǹkan ọkùnrin bá há sójú ara obìnrin, kìí ṣe Mágùn, ẹ má páyà Ẹ fún ọ̀já kó le, lítà epo kan le tó ₦250 àbí ju ₦300 lọ"" Wọ́n ti dáwọ́ ìdánwò àbẹ́rẹ̀ àjẹsára Oxford dúró lẹ́yìn ti olùkopa kan ṣàìsàn Ìdí tí mo ṣe se oúnjẹ nínú ilé ẹni tí mo lọ jà lólè rèé- Afurasí adigunjalè Wọn ni babalọja marun un nipinlẹ Oyo yoo ni ti Gomina Seyi Makinde ba fi le buwọlu iyansipo YK Abass."
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Èèwọ̀ méje tí kò fi ìdí múlẹ̀ nípa nǹkan oṣù obìnrin nílẹ̀ Yorùbá 28 Èbibi 2020 Oríṣun àwòrán, others Jakejado agbaye ni igbagbọ ti wa pe eniyan ara ọtọ ni awọn obinrin, akanṣe iṣẹ Olodumare si ni wọn pẹlu nitori iṣẹda wọn.
Nígbà tí ọba Aradi ará Kenaani tí ń gbé ìhà gúsù ní Nẹgẹbu Kenaani gbọ́ pé àwọn ọmọ Israẹli ń gba ọ̀nà Atarimu bọ̀, ó lọ bá wọn jagun, ó sì kó ninu wọn lẹ́rú.
"Oríṣun àwòrán, Lagos state government Àkọlé àwòrán, Ipinlẹ Eko wa lara awọn ipinlẹ ti o gbe ofin kalẹ lori ifipabanilopọ ati awọn iwa ipa miran labẹle ""Iwa ifipabanilopọ kii ṣe ohun to yẹ ki a fun ni ijiya yẹpẹrẹ."
Champions league draw: Kà bí Juventus àti Barcelona, PSG àti Man United, pẹ̀lú Bayern ati Athletico Madrid yoo ṣe dáná sun ara wọn ní Champions League tọdun yii
Orilẹ-ede Naijiria yoo koju Algeria loni ninu ifẹsẹwọnsẹ ipele to kangun si aṣekagba idije AFCON 2019 to n lọ lọwọ ni Egypt.
Koda awọn to mọ ọ daada ni, Ademọla a maa saba tele ẹgbọn rẹ lo si ibi ipolongo oselu, ni ibi ti awọn to mọ ọ daada ni a ma fi ijo da ara.
" Ó ní ìrírí òun pẹ́lú ìbálopọ̀ tipatipá gẹ́gẹ́ bíí ọmọde kò nípa lára òun, ti òun yóò fi wa má fi hùwa gẹ́gẹ́ bi àgbàlàgbà.
Ninu atẹjade kan lati ọọfisi agbẹjọro rẹ, ile ẹjọ naa ni oun ti gba awọn iroyin kan nipa awọn iṣẹlẹ ifẹmiṣofo to waye nibi iwọde ọhun.
O bẹrẹ oṣelu rẹ pẹlu ẹgbẹ PDP ko to ṣi lọ si ẹgbẹ oṣelu APC 2) Mariam Katagun: Mariam Katagun ti jẹ aṣoju Naijiria si ajọ iṣokan agbaye ni eto ẹkọ ati àṣà UNESCO.
Ó mú àwọn ọlọ́gbọ́n ninu àrékérekè wọn;ó sì mú ète àwọn ẹlẹ́tàn wá sópin.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, LASU Ritual: Àwọn akẹẹgbẹ́ akẹ́kọ̀ọ́ LASU tí wọn fi ṣowó sọ̀rọ̀ lórí ìgbé ayé olóògbé Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Igbiyanju BBC lati gbọ ọrọ lati ẹnu Gomina ipinlẹ Kogi ja si pabo.
Amọ ṣa ninu ifọrọwerọ kan ti BBC ṣe pẹlu aarẹ oṣere tiata labẹ asia TAMPAN Bolaji Amusan Mr Latin, ni Odunlade fi ọrọ naa lọ ohun lootọ ṣugbọn o ni ohun ko ti mọ boya ki ohun jẹ oba tabi ko ma jẹ.
Èyí tí ọ̀wọ́ àwọn eṣú ńláńlá jẹ kù,àwọn eṣú wẹẹrẹ mìíràn jẹ ẹ́,èyí tí àwọn eṣú wẹẹrẹ yìí jẹ kù,àwọn eṣú tí ń jẹ nǹkan run jẹ ẹ́ tán.
Kyari ti o fi mo awon oga agba osise alaabo loniiruuru.
Missing Child: Òbí àti asọ́nà ṣọ́ọ̀ṣì 14, lọ́ búra nì'dí imọlẹ̀ l'Akure Ìgbéyàwó mẹfa ní a ti ṣe lọ́dun yìí láàrin awọn oníkòkòrò HIV Sẹnẹtọ Melaye ni bi t'ọkunrin t'obinrin ṣe dibo fun oun fihan pe Eleduwa ṣi wa lẹyin oun gbọingbọin.
Mo ti rù láàrin ọ̀sẹ̀ kan, iṣẹ́ Eko kò dẹ́rùn - Sanwo-Olu Atẹjade kan lati ileeṣẹ igbakeji aarẹ ni wọn buwọ lu, bi wọn ṣe sun gbedeke naa siwaju ninu ipade kan pẹlu awọn ti ọrọ kan ni ibẹrẹ ọsẹ yii.
Ó ní ìjọba ló ni ìpinu ti wọ́n fi n lọ ará ìlú, àti pé òun gẹ́gẹ́ bi ẹni kan ko fi ara mọ ìgbélé míràn nítori èyí ti wọ́n ṣe kẹyin kò so èso rere kankan.
Àwọn Orílẹ̀-Èdè Tí Ó Ṣẹ́kù lórí Ilẹ̀ Kenaani.
Akah Nani – Banana Island Ghost
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Janduku yinbọn nilu Iwara Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Àwọn ọ̀dọ́ Nàìjíríà fohùn ránṣẹ́ sí ìjọ̀ba tí yóò wọlé Aarẹ Buhari ti o n dije fun ipo Aarẹ lẹẹkan sii labẹ asia ẹgbẹ naa ni oun ti paṣẹ fun awọn oṣiṣẹ aabo lorileede Naijiria lati toju bọ gbogbo ibi ti awọn ọdanran ba wa ṣaaju idibo naa.
Ó rí apẹ̀rẹ̀ náà láàrin koríko, ó bá rán iranṣẹbinrin rẹ̀ lọ gbé apẹ̀rẹ̀ náà.
ninu atejade kan ti alukoro ile –ise olopaa Emeka Iheanacho, to wa ni ekun naa,
Ẹ bèèrè, ẹ óo sì rí gbà, kí ẹ lè ní ayọ̀ lẹ́kùn-únrẹ́rẹ́.
Fasoranti ní àwọn wà lẹ́yìn PDP, SDP àti ADC.
’’ Oludari ile-ise ogba eranko  naa, Umar Yusuf Kachakobo naa fi ootọ ọrọ mulẹ 
ṣugbọn Joramu ọba ti lọ sí Jesireeli láti tọ́jú ọgbẹ́ tí wọ́n ṣá a lójú ogun Siria.
asofin tun pe akiyesi ijoba apapo si owo isuna ti won ya soto fun eto ẹkọ orile
Oríṣun àwòrán, @NANSNIG Ẹgbẹ akẹkọọ yii wa n kesi awọn ẹka ẹgbẹ naa to wa nipinlẹ Kogi, Ondo, Ekiti ati Osun lati jade wa se koriya fawọn akẹkọọ Fuoye, ti iya n jẹ.
Ìdílé ẹni ibi yóo parun,ṣugbọn ilé olódodo yóo máa gbèrú títí lae.
Ogbeni  Adesiyan ati Senator Akinlabi-Rasheed  wa ro awon ipinle yooku lati fi ipinle Osun se apejuwe , bi won se n  dibo won ni irowo –irose, ti won si n ba ara won se gege bi ebi kan, soso.
Ni bayii orilẹede kan ti ọwọja arun yii ti mulẹ bi ọwara ojo ni orilẹede Italy nibi ti omilẹgbẹ awọn eeyan ti ko arun yii ti ọpọ si ti ku nipasẹ awọn ohun to jẹyọ lẹyin arun naa.
Lisabi Agbongbo Akala rèé, ẹni tó fi ìfẹ́, ìṣọ̀kan àti ìrẹ́pọ̀ gba ilẹ̀ Ẹ̀gbá lọ́wọ́ ìmúnisìn Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Orílẹ̀-èdè Mauritania ti Ìwọ̀-oòrùn Ilẹ̀-Adúláwọ̀  jẹ́ ìdàpọ̀ àwọn Lárúbáwá àti àwọn aláwọ̀ dúdú, àwọn ẹgbẹ́ ajàfẹ́tọ̀ọ́ ọmọnìyàn sọ pé àwọn aláwọ̀ dúdú ti ń dojúkọ ìyàsọ́tọ̀ àti ìlòkulò fún ìgbà pípẹ́.
Pásítọ̀ Ofori dèrò ẹ̀wọ̀n lẹ́yìn tó yìnbọn pa ìyàwó rẹ̀ ní ìta gbangba Ìjọba, e yé dẹ́yẹ sí wa mọ́, àwọn ẹlẹ́sìn ìbílẹ̀ ṣèwọ́de n'Ibadan Ọkùnrin tí wọ́n fẹ̀sùn kàn pé ó jí ǹkan nílé ìjọsìn rí ẹ̀wọ̀n he!
Nítorí náà mo bẹ̀ yín, ẹ fi ìwà jọ mí.
oun faramo igbese ti ajo INEC gbe naa.
Ọpọlọpọ ẹmi ọlọpaa ati agbẹ pẹlu araalu lo si bọ sinu ogun Agbekoya naa, eyi to waye nitori ele owo ori lasan lasan.
OLUWA Ọlọrun ní, “Ohun kan tí n óo tún mú kí àwọn ọmọ Israẹli bèèrè lọ́wọ́ mi pé kí n ṣe fún àwọn ni pé kí n máa mú kí àwọn ọmọ wọn pọ̀ sí i bí ọ̀wọ́ aguntan.
Fiditi: Àwọn olùgbé rawọ ẹbẹ sí ìjoba lẹ́yìn tí ìjì ṣí òrùlé mọ́ wọn lórí
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Akomolede ati Asa lori BBC: Olùkọ́ Kikelomo Ogunboye tan ìmalẹ̀ sí ìwà olè ọ̀gá ọlọ́pàá Nnkan bii ẹgbẹrun lọna ọgọrun eeyan lo ti buwọlu iwe ifisun naa Ileẹjọ da ọkunrin naa lẹbi lori pe o hu iwa ika si ẹranko at'awọnẹsun miran bẹẹ.
Malabu Oil Scandal: Iléẹjọ́ ní kí àwọn ọlọ́pàá, Interpol gbé wọn níbikíbi tí wọn bá wà
sewadii isele naa, ti won yoo si mu awon odaran ohun.
Aare ni”A ti wa ni oju agbami ti oko omi orile ede
Mo tún fi omi tútù lé e.
Ara o r'okun ara o r'adiyẹ Kayode Eesuola ti o jẹ olukoni agba ni ẹka imọ eto ijinlẹ oṣeelu ile eko fasiti Eko ni bi wọn ṣe bẹrẹ APC ko le jẹ ki ọrọ wọn toro.
' Aruwan sọ wi pe awọn ọmọogun Naijiria naa yoo da abo bo awọn to wa ni agbeegbe na, ki alaafia o le pada si ilu.
Adamu fi kun un pe ni bayii, ko si igbakugba ti awon ko lanfani lati maa gbe alaboyun to ba fẹ rọbi tabi ni iṣẹlẹ pajawiri.
Gbogbo àwọn tí wọ́n kú sinu òkun tún jáde sókè.
olubori nigba marundinlogun ninu ifesewonse metadinlogun ti iko naa ti gba lori
Ayefele fi orin ẹ ṣeun sẹ́nu kí Ajimobi Àwọn àdúgbò Ibadan gborúkọ tuntun látẹnu Ajimobi Ayefẹlẹ bá BBC sọ̀rọ̀ lórí ilé orin rẹ̀ tí Ajimọbí ń tún kọ́ Lara awọn aseyọri Kosẹlẹri ti Ajimobi ṣe lori aleefa, ni agbekalẹ ofin atunto oye jíjẹ nilẹ Ibadan, to si fi ọba mọkanlelogun jẹ nilẹ Ibadan ni ọjọ kan ṣoṣo, Eyi ti okiki rẹ gbalẹ kan, ti awuyewuye igbesẹ rẹ yii ko si jẹ ki ilana oye jijẹ nilẹ ni ojutu titi di oni yii.
Arsenal rántí \Invincibles,\"" ó pé ọdún mẹ́rìndínlógún tí Arsenal gba ife Premier League"
 À ń ṣàpèjúwe bv pẹ ̀ lú àìdúródéédé microbiota òbò pẹ ̀ lú díndínkù iye lactobacilli .
Nítorí Èṣù ti dé sáàrin yín.
" Ọba Adeyemi tẹ siwaju pe, oun ti kẹkọọ pe oun gbọdọ ko ipa manigbagbe rere ninu aye awọn eeyan, ki oun si jẹ ki ero wọn nipa òun nigba akọkọ jẹ ero rere.
Àwọn òṣèré tíátà Yorùbá kọjú ìjà síra wọn lórí ìdárò akẹẹgbẹ́ wọn tó kú Walter Carrington ràn mí lọ́wọ́ kí ń lè sá àsálà lásìkò tí Abacha ń wá mí kiri- Obasanjo Mo kọ̀ láti pín ọkọ mi pẹ̀lú ẹnikẹ́ni, nítorí náà ẹ tú wa ká- Abílékọ Idowu faraya ní kóòtù kọkọ-kọkọ Inú mí dùn láti kọrin pẹlú Beyonce nílẹ̀ Amerika- Ìyá àgbà láti Nàíjíríà Ninu iwaasu ti Bisọọbu Oyedepo se nile ijọsin re lọjọ Isẹgun to pe ni: Titayọ kọja gbedeke ni eyi ti wọn gbe sita lori ayelujara ijọ naa lo ti fesi.
25 usd fún ìwọ ̀ n egbògi náà kanṣoṣo fún oríṣi tí à n gba ẹnu lò ní ọdún 2014 .
 Àpólà atókùn àti Àpólà Àpónlé : a ti menu bà apor àti apis .
Wọn ko tii fọ aṣọ naa lati ọjọ naa to ti wọ ọ gbẹyin titi di oni oloni.
Ọjọ mẹrin si ni aarẹ Buhari yoo lo lorilẹede Ethiopia, ko to pada wale.
Ní kété tí wọ́n wọ Samaria, Eliṣa gbadura pé kí OLUWA ṣí wọn lójú kí wọ́n lè ríran.
Àwọn pásìtọ tí wọ́n fẹ́sùn kan ní Favour David ati Favour Chimobi pẹ̀lú ìfọwọ́sowọ́pọ̀ Rukayat Folawewo àti Bunmi Joshua, láti maa ṣe ìṣẹ́ jìbìtì wọ́n.
Yara mi o jo ri, yara awọn ọmọ mi naa bakan naa.
Òkè Sioni, ní àríwá, lọ́nà jíjìn réré,ìlú ọba ńlá.
Tẹ́lẹ̀ rí, bí ẹ̀yà Efuraimu bá sọ̀rọ̀, àwọn eniyan a máa wárìrì; wọ́n níyì láàrin àwọn ẹ̀yà Israẹli yòókù, ṣugbọn nítorí pé wọ́n bọ oriṣa Baali, wọ́n dẹ́ṣẹ̀, wọ́n sì kú.
Bí ó ti wu OLUWA ni ó ń ṣelọ́run ati láyé,ninu òkun ati ninu ibú.
2 mílíọ́nù owó ìtanràn 16 Ọ̀wàrà 2020 Oríṣun àwòrán, @IAMSPonline Iyawo Alhaji Aliyu Mai-Yadi Charanchi ati ọmọ rẹ ọmọ ọdun mẹta ti gba ominira lọwọ awọn ajinigbe to ji wọn gbe ni ipinlẹ Katsina.
Wọ́n ń rún àwọn eniyan rẹ mọ́lẹ̀, OLUWA,wọ́n ń pọ́n àwọn eniyan rẹ lójú.
Ti arun naa ba ti wọ ara, ko si ọna lati pa a.
Akọroyin naa ni ko si oun to ṣe Abu Musab, ati wi pe o ṣi wa labẹ ISWAP bo tilẹ jẹ wipe wọn yọ ọ nipo.
Ọrọ yi ko jẹ tuntun lagbo oṣelu Naijiria ṣugbọn igba kigba to ba gbori sita, niṣe ni iriwisi ọtọtọ a ma tele.
Ó fi ayọ̀ kó àwọn eniyan rẹ̀ jáde,ó kó àwọn àyànfẹ́ rẹ̀ jáde pẹlu orin.
Diẹ bayi lo ku ki Fulham wọ ijakulẹ (relegation) bi o ṣe wa ni ipo mẹtadinlogun.
Bí ó ti wà ní àkọsílẹ̀ pé,“Lónìí, bí ẹ bá gbọ́ ohùn rẹ̀,ẹ má ṣe agídí gẹ́gẹ́ bíi ti àkókò ọ̀tẹ̀.
Gbogbo àwọn ọmọ Israẹli bá wá sọ́dọ̀ ọba, wọ́n sì bi í pé, “Kabiyesi, kí ló dé tí àwọn eniyan Juda, àwọn arakunrin wa, fi lérò pé àwọn ní ẹ̀tọ́ láti mú ọ lọ, ati láti sin ìwọ ati ìdílé rẹ, ati àwọn eniyan rẹ kọjá odò Jọdani?
Kabiyesi ba mẹnu ba ohun ti ijọba n sọ nipa ipaniyan lonii, ijinigbe lọla ni Naijiria.
Flying Eagles Naijiria jẹ goolu meji ni abala ikini ifẹsẹwọnsẹ naa lati ọwọ Maxwell Effiom to jẹ goolu akọkọ ni iṣẹju kejila.
Oríṣun àwòrán, Twitter/TemiOanu Lara iṣẹ igbimọ yi ni ki wọn ṣe akojọ ẹsun, fi ọrọ wa awọn eeyan lẹnu wo ki wọn si tun fi idi ododo mulẹ lori ifiyajẹni tabi ipaniyan.
Adigunjalẹ̀ fìbọn fọ́ ojú ọmọ tó fẹ́ lọ sìnrú ìlú nílùú Èkó 'Olùkọ́ kan tilẹ̀ sọ fún un pé ẹlẹ́sẹ̀ kan ni ẹ́, oò ní 'le ."
Nítorí ẹ̀yin ni a ṣe ìlérí yìí fún, ati àwọn ọmọ yín ati gbogbo àwọn tí wọ́n wà ní ọ̀nà jíjìn; a ṣe é fún gbogbo ẹni tí Oluwa Ọlọrun wa bá pè.
Ẹni tí ó ní òye yóo rí ojurere,ṣugbọn ọ̀nà àwọn tí kò ṣe é gbẹ́kẹ̀lé ni ìparun wọn.
Wọ́n pa Balaamu ọmọ Beori pẹlu.
N óo wá àwọn alágbára, àwọn tí wọ́n burú jùlọ láàrin àwọn orílẹ̀-èdè, n óo jẹ́ kí gbogbo wọn fi idà pa ogunlọ́gọ̀ àwọn eniyan rẹ.
Peteru dáhùn pé, “Lọ́wọ́ àlejò ni.
Agbábọ́ọ̀lù obìnrin wo ni yóò gba'dé?
 bákan náà ni ó lọ sí ilé-ẹ ̀ kọ ́ queens college , ní ìlú yábàá lẹ ́ yìnnèyí ninó lọ sí ìlé-ẹ ̀ kọ ́ àgbà oakland university , níbibtí ó ti gbọoyè àkọ ́ kọ ́ nínú iṣẹ ìròyìn , ìyẹ ́ n ( mass communication ) .
Ẹ̀mí Mímọ́ yìí jẹ́ onídùúró ogún tí a óo gbà nígbà tí Ọlọrun bá dá àwọn eniyan rẹ̀ nídè, kí á lè yin Ọlọrun lógo.
O ni : a ti paṣẹ fawọn oṣiṣẹ eleto aabo wa lati daabo bo gbogbo ohun ini awọn ara South Africa nipinlẹ Eko.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Siasia lè gba iṣẹ́ akọ́nimọ̀ọ́gbá égbẹ́ agbábọ́ọ̀lù Cameroon 24 Ìgbé 2018 Oríṣun àwòrán, Twitter/Siasia Àkọlé àwòrán, Samson Siasia wà lára àwọn akọ́nimọ̀ọ́gbá tí àjọ tó ń rí sí eré bọ́ọ̀lù àfẹsẹ̀gbá ní orílẹ́èdè Cameroon fẹ́ fọ̀rọ̀ wá lẹ́nu wò Akọ́nimọ̀ọ́gbá ikọ̀ agbábọ́ọ̀lù Super Eagles tẹ́lẹ̀ rí, Samson Siasia, wà lára àwọn akọ́nimọ̀ọ́gbá mẹ́tàdínlọ́gọ́rin tí àjọ tó ń rí sí eré bọ́ọ̀lù àfẹsẹ̀gbá ní orílẹ́èdè Cameroon fẹ́ fọ̀rọ̀ wá lẹ́nu wò láti tukọ̀ ikọ̀ agbábọ́ọ̀lù ilẹ̀ náà.
"Iroyin fi idi rẹ mulẹ wi pe ""eeyan kan lara awọn to n ṣe faaji ọdun ni aṣita ibọn ti awọn ọlọpaa yin si awọn ọdara naa ba, ti awọn ero to wa nibi ode ariya naa si bẹrẹ sini lẹ oko mọ awọn ọlọpaa naa""."
O f'ojuhan pe May n wa idaniloju ofin pe orilẹede UK ko ni forisanpọn ninu igbesẹ lati mu ki ohun ati orilẹede Northern Ireland maa lo adehun to faaye gba pe ko ni i si owo ori sisan lori ọja tabi ẹru to ba n wọ orilẹede kan lati ikeji.
Ṣé gbogbo ìgbà ni àwọn eniyan yóo máa bọ́ sinu àwọ̀n rẹ̀ ni?
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù OsunElectionUpdates2018: Ọ̀rọ̀ bẹ́yìn yọ fún PDP lórí ìbò ibùdó méje 28 Owewe 2018 Àkọlé àwòrán, Agbára jú agbára lọ ni ọ̀rọ̀ ìdìbò Ọṣun Àjọ INEC kéde pé Alhaji Gboyega Oyetola ti ẹgbẹ oṣelu APC ló jáwe olúborí nínú idibò Ọṣun.
Àwọn ọmọ ogun Ijipti kò ní lágbára láti dojú ìjà kọ ọ́, àwọn akikanju wọn pàápàá kò ní lágbára mọ́ láti jagun.
Awọn ijọba ibilẹ naa ni Ọwọ, Ọsẹ ati Iwo Oorun guusu Akoko.
Bode George gbe lẹyin awọn oluwọde pe ṣe ni wọn kan n bere fun ohun ti wọn fẹ lalafia.
E̩nì kò̩ò̩kan ló ní è̩tó̩ láìjé̩ pé a fi ipá mú un láti kópa nínú àpapò̩ ìgbé ayé àwùjo̩ rè̩, kí ó je̩ ìgbádùn gbogbo ohun àmús̩e̩ wà ibè̩, kí ó sì kópa nínú ìdàgbàsókè ìmò̩ sáyé̩n sì àti àwo̩n àn fàní tó ń ti ibè̩ jáde.
Kí ilẹ̀ náà má baà ti ẹ̀yin náà jáde nígbà tí ẹ bá bà á jẹ́, bí ó ti ti àwọn tí wọn ń gbé inú rẹ̀ ṣáájú yín jáde.
Ó ku ọ̀la kí Saulu dé ni OLUWA ti sọ fún Samuẹli pé, 
Lẹ́yìn ọjọ́ keje, ìkún omi bo ilẹ̀ ayé.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Àwọn ọ̀dọ́ Naijiria ti sọ̀rọ̀ síta lórí ohun ti wọ́n ń retí lọ́dọ̀ minista tuntun Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àwọn ọ̀dọ́ Naijiria ti sọ̀rọ̀ síta lórí ohun ti wọ́n ń retí lọ́dọ̀ minista tuntun 21 Ògún 2019 Ọpọ n reti ki aarẹ Buhari kede iṣẹ onikaluku ninu awọn minista tuntun ti ilé ṣe ayẹwo fun.
Ní ọdún kẹtadinlọgbọn tí Asa jọba ní Juda, Simiri gorí oyè ní Tirisa, ó sì jọba Israẹli fún ọjọ́ meje.
Ẹ má bẹ̀rù, ẹ má sì jáyà níwájú ọba Asiria ati àwọn ọmọ ogun rẹ̀ bí wọ́n tilẹ̀ pọ̀; nítorí agbára ẹni tí ó wà pẹlu wa ju ti àwọn tí wọ́n wà pẹlu rẹ̀ lọ.
Inú ìwọ̀nyí ni àìsàn dé bá a, nígbà tí ó sì pẹ́ àìsàn náà ṣe é dé ibi tí ọkàn rẹ̀ kò fi lù kìkì mọ́, èmi náà sì lọ mo mú un tọ Ẹlẹ́dàá mi lọ.
S - Ikorodu Baiyeku - Langbasa Ebute Ojo - Ibasa Ebute Ojo - Ijegun Egba Ebute Ojo - Irewe Ijegun Egba - Ibasa Liverpool - Five Cowries Marina/C.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Damasus, Omotola, Ezekwesili, Funmi Iyanda dá sí ẹ̀sùn ìfipábánilòpọ̀ Fatoyinbo 29 Òkùdu 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 30 Òkùdu 2019 Oríṣun àwòrán, @Omotolafans Àkọlé àwòrán, Nínú fídíò kan tó ń ja rànyìnrànyìn ni ẹ̀sùn ìfipábánilòpọ̀ yìí ti kọ́kọ́ gbèrú Ikanni ayelujara ṣi n rọ kẹkẹ bayii lori ẹsun ifipabanilopọ ti iyawo gbajugbaja onkọrinTimi Dakolo, Busọla Dakolo fi kan pasitọ agba ijọ COZA, Biọdun Fatoyinbo.
Kò fèsì sí àtẹ̀jíṣẹ́ tàbí iṣẹ́-ìjẹ́ oríi WhatsApp
Nígbà náà ni ẹ óo mọ̀ pé èmi ni mo pàṣẹ yìí fun yín, kí majẹmu mi pẹlu Lefi má baà yẹ̀.
Majẹmu tí ẹ bá ikú dá yóo wá di òfo,àdéhùn yín pẹlu ibojì yóo sì di asán.
Ọmọbìnrin tó tayọ nínú ìdànwó WAEC ọdún 2019 pẹ̀lú A1 méje ti kú Nàìjíríà fohùn ránṣẹ́ padà sílé aṣofin UK pé ọ̀rọ̀ EndSars kò sí lẹ́nú wọn láìgbọ́ ìwádìí tán!
Igbiyanju lati kan si Giwa ile iwe naa ko tii yọri si rere bo tilẹ jẹ wi pe awọn aṣoju alaṣẹ naa buwọlu iwe adehun naa nibi ipade to waye laarin wọn ati ẹgbẹ ASUP.
Lori ọrọ orukọ awọn oludari eto idibo lawọn ijọba ibilẹ ati ipinlẹ ti Inec fi sita, APC ni pupọ ninu wọn ni wọn jẹ ọmọ ẹgbẹ PDP ti wọn si parọwa si Inec lati gbe igbese atunṣe rẹ.
Ni ọdun 1952, mo wa ni ọmọ ọdun meje nigba ti mo n gbe pẹlu mama to bi mama mi ni abule wa.
Ọjọ Abamẹta ni ọkọ naa, Augusta AW139 ja lulẹ ti ori si ko Osinbajo, minisita kan ati awọn mẹwaa miiran yọ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Samo Baba: Eléréepá ní mi láti kékere, ẹjọ́ sí pọ̀ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Samo Baba: Eléréepá ní mi láti kékere, ẹjọ́ sí pọ̀ 17 Òkùdu 2019 Akẹkọgboye ni Samo Baba ninu imọ Eko Tiata eyi to n jẹ Performing Arts ni fasiti ilu Ilorin.
"Ẹsun naa ko lẹsẹ nlẹ rara.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Kano Emirs: Ilé ẹjọ́ wọ́gilé ìyànsípò àwọn Emir mẹ́rin tí Ganduje yan 21 Bélú 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 22 Bélú 2019 Oríṣun àwòrán, Others Àkọlé àwòrán, Asọ̀ ti ń waye tẹlẹ lori iyansipo awọn Emir mẹrin ti Gomina Ganduje yan loṣu kaarun ọdun yii amọ ile jọ ti da iyansipo naa nu.
Amọ loju ẹrọ ikansiraẹni Twitter, awọn elomiran n bere idi ti ijọba ṣe jẹki ofin konile-o-gbele rọlẹ nigba ti iye awọn to ti ni arun Coronavirus n peleke si ni Naijiria lojojumọ.
Aarẹ Jonathan ni aarẹ Nigeria akọkọ to pe alatako lati ki i ku orire aseyọri ninu idibo botilẹ jẹ wipe awọn kan sọ pe ijọba rẹ faye gba awọn aisedeede kan bi iwa ajẹbanu ati aidoju ija kọ awọn ikọ Boko Haram bo ti se yẹ.
#DaysOfRage: Sowore ní ìwọ́de náà kò ni gbèdéke ọjọ́ tí yóò parí
- ẹgbẹ́ àgbẹ̀ kìlọ̀Ọjọgbọn Charles Parry, to ń ṣe àfihàn bí òfin ti jọba fi dé oko-owo ọtí ṣe mú adinku bá iye èèyàn ti igbimọ oluwadi nípa ìwòsàn ni South Africa ń yẹ wo sọ pé, ipa tó ṣe pàtàkì ni eyi""."
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fọ́nrán ohùn, Ondo: Iya lu ọmọ pa nítori ẹgbẹ̀rún mọkànlélógun Naira Wọn ni awọn ikọ tijọba ṣagbekalẹ lati gbogun ti awọn ajinigbe ti bẹrẹ iṣẹ ni pẹrẹwu ni agbegbe yii.
Mo tún ń ṣe ère idaraya lásìkò yìí, a to èèyàn méjìdínlógún nínú ilé mi, a jọ n yín Ọlọ́run, gba àdúrà, tá sì tún jọ ń ṣiṣẹ nínú ilé, àmọ́ kò mọ mi lára láti máa sun oorun ọ̀sán, mo kan ń tiraka láti ṣeé ni O wa rọ àwọn olólùfẹ́ rẹ láti jókòó sile nítorí àrùn .
Ninu abajade wọn lẹyin ipade gbogboogbo naa, Alaga igbimọ tẹẹkoto ti o dari eto idibo naa, Agbẹnusọ Ahmed Guni ti Ipinlẹ Niger sọ pe leyin ijiroro kikun lori awọn ọrọ to ṣe pataki laarin ilu, wọn fẹnu ko lati tete ṣiṣẹ lori fifun awọn ile igbimọ aṣofin ni ominira kikun ninu ojuṣe wọn.
Ki o to de ori itẹ, o jẹ gbajugbaja oludaṣẹsilẹ ti itan tilẹ fi idi rẹ mulẹ pe ati ilu ẹkọ ni o ti bẹrẹ si ra ọwọ le okoowo ati idaṣẹsilẹ.
Mò ń fojú sọ́nà láti bá Emir àná, Sanusi kírun lọ́jọ́ Jímọ̀ - Aráàlú Awe Ọkan lara awọn iyawo Sanusi Lamido Sanusi, to jẹ Emir ana nilu Kano, ti ṣabẹwo si ni ilu Awe lẹyin irọloye rẹ.
Ó mú àwọn ọmọ-ẹ̀yìn mejila lọ sápá kan, ó sọ fún wọn pé, “Ṣé ẹ rí Jerusalẹmu tí à ń gòkè lọ yìí, gbogbo ohun tí àwọn wolii kọ nípa Ọmọ-Eniyan ni yóo ṣẹ.
Bakan naa ni Ọga Ọlọpaa naa fikun pe awọn sisẹpẹlu awon eto aabo kaakiri Naijira lati ri pe ifipabaniopo Wo ojú ọmọbìnrin 4 tí afipa báni lòpọ̀ pa ní Nàìjíríà Ojoojumọ ni akọtun iṣẹlẹ iwa ifipa bani lopọ ati isekupani n waye yika Naijiria, eyi to n mu omi loju ọpọ eeyan.
Ọkunrin náà lọ sí apá ìhà ìlà oòrùn, ó mú okùn ìwọ̀n kan lọ́wọ́.
Lootọ ní pé láàrin ìgbà tí oòrùn bá yọ sì ìgbà tí o bá wọ ní jíjẹ àti mímú dì èèwò fún àwọn Mùsùlùmí nínú oṣù Ramadan.
Johanu sọ gbogbo nǹkan tí ó rí nípa ọ̀rọ̀ Ọlọrun ati ẹ̀rí Jesu Kristi.
A fi ọwọ́ rọ́ ẹjọ́ ẹ̀tọ́ sẹ́yìn,òdodo sì takété.
Abrahamu yára wọ inú àgọ́ tọ Sara lọ, ó sọ fún un pé, “Jọ̀wọ́ tètè tọ́jú ìwọ̀n ìyẹ̀fun dáradára mẹta, bá mi yára pò ó, kí o fi ṣe àkàrà.
"Ọkan lara awọn ẹbi wọn ti ko fẹ fi orukẹ rẹ lede sọ pe ""₦1."
 Ki idagbsoke ba gbogbo wa ni tile –toko
O ṣe atunṣe si iṣẹ awọn ọmọ ogun Ethiopia ni eyi to gba pe o maa jẹ ojutu siṣoro to n koju eto aabo wọn O faragbọta pẹlu awọn ọmọ ogun kan ti wọn si sare gbe lọ sile iwosan fun itọju.
Gomina ipinlẹ Eko, Ọgbẹni Akinwunmi Ambode ti gbe eto isuna to to ọtalelẹgbẹrin o din mẹjọ biliọnu Naira (N852.
igbaye-gbadun awo omo orile ede Naijiria lo jẹ oun logun.
Ǹjẹ́ Mesaya tí à ń retí kọ́?
Ó pa gbogbo ibi tí wọ́n ti ń ṣe àwọn àjọ̀dún tí a yà sọ́tọ̀ run.
Nítorí náà sọ ohun tí o rò fún wa.
Wọ́n fi aṣọ funfun dáradára dá ẹ̀wù meji fún Aaroni ati fún àwọn ọmọ rẹ̀, 
 Won gab pe, ero asoromagbesi ni agbara lati koju idojuko awon igbagbo to n segbe fenikan.
Bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé igbó náà dí,nítorí pé igi ibẹ̀ pọ̀ bí eṣú, tí wọn kò sì lóǹkà.
Baba Adeboye ni ilẹ yoo lanu, bi iru eleyii ti ko i tii ṣẹlẹ ri lọdun 2020.
Ọdẹrinde ni bi ero ba se p si ni ori oun maa n wu, ere gbangba si ni oun maa n se.
igbalode fonran nipinle Kaduna(Command and Control Centre of the Kaduna State
Ajọ to n ri si idena ati amojuto arun ni Naijiria, NCDC, ti ṣa akọsilẹ awọn apẹẹrẹ ti aisan iba Lassa to tun ti gbode ni awọn ilu kan ni Naijiria, maa n mu jade lara ẹni to ba ni i.
awon alakoso ile akede Naijiria lati jẹ akinkinju lẹnu isẹ.
Mo roo wi pe ijiya kan naa lo yẹ ki a fi jẹ gbogbo wọn.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Cancer: Àṣe ara mi ni iso ti n run gbogbo bí mo ṣe n ṣèrànwọ́ lórí jẹjẹrẹ Ilé ẹjọ lé Ọba Èrúwà kúrò lórí Àpèrè lẹ́yìn ọdun 21 Missing Child: Òbí àti asọ́nà ṣọ́ọ̀ṣì 14, lọ́ búra nì'dí imọlẹ̀ l'Akure Aàrẹ Trump kọ̀ láti jẹ Tòlótòló ìsìn ìdúpẹ́ 2019 nílé, ó gba Afghanista lọ!
Ọjọ Kẹtala osu Kẹwaa ọdọọdun yii naa tun ni awọn obinrin lawọn orilẹ ede kan maa n lo, lati fi se eto ikowojọ fun awọn onimọ iwadi isegun oyinbo lati se awari oogun ti yoo wa egbo dẹkun fun arun jẹjẹrẹ ọyan.
Kò sí ogun mọ́ rárá títí tí ó fi di ọdún karundinlogoji ìjọba Asa.
Oríṣun àwòrán, Rotimi Akeredolu Aketi Ṣaaju idibo abẹle naa ni oriṣiriṣi nnkan ti n ṣelẹ ninu iṣejọba Akeredolu, akọkọ ni pe igabkeji rẹ, Agboola Ajayi fi ẹgbẹ APC silẹ, to si lọ darapọ mọ ẹgbẹ oṣelu PDP.
Awọn ẹgbẹ ọlọdẹ naa ni awọn ṣetan lati maa pese abo fun awọn to n wọde naa .
Akomolede ati asa Yoruba: Ẹ wá kọ́ nípa àpòtí ìṣura èdè wa lórí BBC Yorùbá
EFCC fi ẹsun iṣowo ilu to le ni biliọnu kan naira (N1.
”O wa ro awon arinrin-ajo naa lati gbagbe ohun yoowu ti won ba la koja lasiko irin-ajo naa, ki won si tesiwaju ninu aye won.
Bí fèrè ti ń dún kíkankíkan tí dídún rẹ̀ sì ń gòkè sí i, bẹ́ẹ̀ ni Mose ń sọ̀rọ̀, Ọlọrun sì ń fi ààrá dá a lóhùn.
ng Oṣu Kẹsan ọdun 1963 ni orekelẹwa Funmi Martins dele aye, to si papoda lọdun 2002 lẹni ọdun mọkandinlogoji.
Bí ọ̀pọ̀lọpọ̀ bá kú pọ̀ lẹ́ẹ̀kan ṣoṣo wọn á rọra gbé òkú wwọn sí àgbàlá wọ́n a máa jẹ ẹ́ díẹ̀díẹ̀.
Unicycle School: Olùdarí ibùdó ìkẹ́kọ̀ kẹ̀kẹ́ alájọwà ń fẹ́ ìrànwọ́ ìjọba
Ilé Aṣòfin: Buhari ni yoo dahun fun awọn to yan sipo
Ranti, Ọlọrun mi, nítorí pé wọ́n rú òfin àwọn alufaa, wọn kò sì mú ẹ̀jẹ́ àwọn alufaa ati ti àwọn ọmọ Lefi ṣẹ.
O àti lọ́wọ́ ẹni tí ó ti yáa, ó dárúkọ àwọn tí ọba gbà gẹ́gẹ́ bí ọ̀tá àti àwọn tí ó gbà gẹ́gẹ́ bí ọ̀rẹ́.
Inu mi dun pe mo ni akosemose minisita fun eto ilera lorile ede yii.
"Ninu atẹjade kan lati ọọfisi iyawo Aarẹ, o ni ""ojuṣe wa ni gẹgẹ bi ẹni to wa lori ipo adari lati gbaruku ti awọn obinrin ati awọn ọdọ fun igbedide alaafia lawujọ."
Lẹ́nu ẹlẹ́rìí meji tabi mẹta ni a óo sì ti mọ òtítọ́ gbogbo ọ̀rọ̀.
Ohun tí a tí ń bá ọ sọ ni kí o gbé yẹ̀wò,kí á lè sọ èyí tí a tún fẹ́ sọ.
O ni ootọ ni pe inu n bi gbogbo eniyan lọwọ ni Naijria ti ilu si n gbona janjan ati pe o n ya awọn eeyan lara lati sọ bi nkan ṣe ri lọkan wọn.
Gege bi ogbeni Prestige Ossy ti o sagbekale oro ohun, O ni, lati igbati won ti sefilole ile-ise oko ofurufu aladani logun odun seyin ni Naijiria, ile-ise Dana airline ko se dede mo latari orisirisi ijamba ti n kolu oko ofurufu won.
Ìran Iṣimaeli, ọmọ Abrahamu, tí Hagari, ará Ijipti, ọmọ-ọ̀dọ̀ Sara bí fún un nìyí: 
Ki ṣe gbogbo àwọn ará ilú wọnyi ló bá àpèjúwe yi mu.
Obinrin náà yóo sì tún jẹ́ iyawo rẹ̀, kò sì gbọdọ̀ kọ̀ ọ́ sílẹ̀ ní gbogbo ọjọ́ ayé rẹ̀.
Sweden Ohun to jọ bi ọwọ yẹpẹrẹ ti Sweden fi mu ọrọ Covid-19 yi ya ọpọ eeyan lẹnu.
Eyi waye ninu atejade kan, ti alukoro igbimo ajo naa, omowe Fabian Benjamin fowo siAjo ohun so pe, won koi ti gbesi idanwo awon akekoo ti iye won din die ni ogofa, 112,331 (One Hundred and Twelve Thousand, Three Hundred and Thirty-One)jade.
"Ko sija, ko si ikunsinu, gbogbo ẹ lọ ni irọwọrọsẹ ṣugbọn a o wa mọ bi ọrọ ṣe dẹnu akayin ti akara fi wa di egungun""."
Iraq to ṣe ipo keji foju wina ikọlu igbesunmọmi ẹẹdẹgbẹfa ati mọkanlelọgbọn 1131 to gbẹmi ẹgbẹrun kan ati mẹrinlelaadọta, 1054 eeyan.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Natalia Mufuta ìyá Yakub, Kamil àti Adam sọ̀rọ̀ lórí bí wọ́n ń sọ èdè mẹ́rin pàpọ Lati igba ti atẹjade ti a n sọrọ rẹ ọhun ti jade loju opo Twitter Chadwick Boseman ni irọlẹ ọjọ Ẹti, o din diẹ ni miliọnu mẹfa eeyan (6.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Tọkọ-taya Aràrá: Àwọn èèyàn máa ń wò wá, ta bá fa ọwọ́ ara wa ní títì Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Tọkọ-taya Aràrá: Àwọn èèyàn máa ń wò wá, ta bá fa ọwọ́ ara wa ní títì 3 Ọ̀pẹ̀̀ 2018 John Adewuyi, ẹni to jẹ arara, lasiko to n ba BBC Yoruba sọrọ ni, aye ti ro pe oun ko lee ri aya fẹ́, amọ oun dupẹ pe Ọlọrun fun oun ni aya rere, ti o n tọju oun daada.
 Mó kéré lásìkò náà àwọn òbí mi ǹkan yìí dára fún mi láti ṣe, ìṣòro pọ̀ gàn ni lágbàyé báyìí tó yẹ kí a mójú tó Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Aare Muhammedu Buhari ti setan lati yan ise fun awon minisita tuntun Ìjọba Buhari ń lo agbára láti jà ìjà ẹsìn- Jiti Ogunye Òpópónà márosẹ̀ Eko sí Ibadan tún dí pa lásìkò tí ọkọ̀ epo dànù A kò ní ṣe ìwọ́de mọ́ torí a ti gbé ìjọba lọ sílé ẹjọ́ - Shiite kéde fáráyé Ọkọ oju omi yii si lo gbe awọn ọmọ adulawọ to to ọọdunrun ati aabọ (350), ti wọn ko lati orilẹede Angola, ọpọ wọn lo ti ku lasiko irinajo naa nitori ipo inilara ti wọn la kọja.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ajá kìí rorò kó ṣọ́ ojú'lé méjì, kò tọ́ ọ́ sí Alaafin láti dásí ọ̀rọ̀ ọba l‘Ekiti - Peter Fatomilọla Àwọn kókó ohun tó wà nínú lẹ́tà tí Aláàfin kọ sí Fayemi rèé Ọmọ ti lọ kí baba, Fayemi bẹ Aláàfin wo l‘Ọyọ, wọ́n jírórò lórí lẹ́tà Ìlú ò rẹ́rìn ín rárá, Alaafin Adeyemi III fárígá fún Buhari nínú lẹ́tà tuntun Àwọn alálẹ̀ kò ní forí jìn mí tí ń kò bá ṣe ọdún Ṣàngó - Alaafin Bakan naa lo tun kede pe ko gbọọdọ si eto kankan mọ nigboro to nii se pẹlu ipejọpọ ero lọna ati dena itankalẹ ọwọja arun asekupani Coronavirus.
Ṣùgbọ́n tí ó pa ìdí ọ̀rẹ́ dá sí Yar'Adua lẹ́yìn ìgbátí ó bẹ̀rẹ̀ àìsàn tí kò sì gbé ètò ìṣe ìjọba fún igbákèjì rẹ̀ tii ṣe Goodluck Jónátánì.
Awọn eeyan naa ti gbogbo wọn jẹ okunrin ni wọn ji gbe ni ipinlẹ Bornu.
com Àkọlé àwòrán, Ayipada ti de ba inawo ṣiṣe bayii Ṣugbọn ṣaa, iyatọ ti n deba bi awọn alayẹyẹ ṣe n pese awọn ounjẹ kan fun awọn alejo wọn.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fọ́nrán ohùn, Dókítà: Kò dára ká sọ ìlò igbó fún ìwòsàn di òfin Sùgbọ́n onímọ̀ kan nípa ìdènà àwọn òògùn olóró ní orílẹ̀èdè Nàíjíríà, tó fẹ́ ka fi orúkọ bo òun ní àsírí sàlàyé pé kò sí ohun tó burú nínú àbá náà, orílẹ̀èdè Nàíjíríà ni yóò dènà irúfẹ́ àwọn èèyàn tí yóò ní ànfààní sí èròjà igbó.
Ninu lẹta kan ti o kọ si aarẹ Buhari, ajọ SERAP ni pẹlu fidio to n lọ kaakiri ninu eyi to ṣafihan gomina Ganduje nibi ti o ti n gbowo ẹyin yii, O di dandan ki aarẹ tete dari amofin agba orilẹede yii atawọn ajọ to n gbogun ti iwa ijẹkujẹ lati tete bẹrẹ iwaadi lori ẹsun naa.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Amosun ṣiṣẹ́ l'Ogun ṣùgbọ́n kí Dapo ma yà wá' Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Saaju ayeye odun ajinde, owon-gogo bi iko ogorun ninu ida ogorun 100%, ti ba owo-ori oja awon ounje bi: tomati, ata rodo, alubosa ni awon oja kaakiri ipinle EkoIwadii so lojo-Bo ni oja Mile 12, Ile-epo ati Oyingbo safihan pe, apere tomati, eyi won n ta ni egberun merin abo N4,500 tele ninu osu to koja, ti di egberun mesan abo  N9,500 bayii.
Ilu naa si la n pe ni ilu Ẹdẹ, eyi to wa titi di oni oloni Asiko ti Timi Agbale wa nibudo yii ni alaafia jọba lagbegbe naa, ti awọn agbesunmọmi ko si wa da agbegbe naa laamu mọ, eyi to mu ko ransẹ si Alaafin Sango pe se oun lee maa pada bọ wale Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Osteogenesis, aisan níní egungun tó rọ̀ ló ń ba Efia fínra Alaafin Sango ni ki Timi Agbale duro si agbegbe naa, to si tun fọwọsi i pe ko maa gba owo ẹyọ marun un bii owo ibode lawọn agbegbe yii, ko si maa mu isakọlẹ wa fun oun.
’ ” Gbogbo eniyan bá pé lé Jeremaya lórí ninu ilé OLUWA.
Nígbà tí Simoni rí i pé ọwọ́ tí àwọn aposteli gbé lé wọn ni ó mú kí wọ́n rí Ẹ̀mí gbà, ó fi owó lọ̀ wọ́n.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Olateru-Olagbegi II: Ìtàn ayé Ọba Olateru-Olagbegi Kejì, àkàndá ẹ̀dá tí kò ṣe fi ara wé 7 Èbibi 2020 Oríṣun àwòrán, @Omoola.
Primate Elijah Ayọdele sọ eyi ninu atẹjade asọtẹlẹ kan to gbe jade.
Nítorí náà, ó dára kí ìṣọ̀kan jọba ni àwujọ-ẹ̀dá.
Ìjèbú-Jèṣà je ilu ni ile Naijiria ati oluilu agbegbe ijoba ibile Oriade ni Ipinle Osun.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Arsenal tẹ̀síwájú nínú idije Europa 13 Ìgbé 2018 Oríṣun àwòrán, ALEXANDER NEMENOV/AFP/Getty Àkọlé àwòrán, Danny Welbeck ti je goolu mẹta bayi ninu ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ meji Ẹgbẹ agbaboolu Arsenal ti pegede lati tẹsiwaju nínú ìdíje Europa league pẹlu apapọ àmì ayo mẹfa si mẹta ti CSKA Moscow.
Kí àwọn tí ń ra nǹkan máa ṣe bí ẹni pé kì í ṣe tiwọn ni ohun tí wọ́n ní.
Ó ti fún un ní àṣẹ láti ṣe ìdájọ́, nítorí òun ni Ọmọ-Eniyan.
Ìtàn Mánigbàgbé: Diipọ Fagunwa ní a le è pe bàbá òun ní ‘osó’ ìtàn àkọsílẹ̀
Ṣé ó lẹ ́ ni tó n sọ mófíìmù tó dáwà tí wọn kìí sìí ṣe ọ ̀ rò fúnra wọn ?
7 370 Orilẹede Tanzania 21 0.
Lójú kan náà ó sì tún ríran, ó bá ń tẹ̀lé Jesu, ó ń yin Ọlọrun lógo.
OLUWA fúnra rẹ̀ ni ó sọ fún mi pé kí n wá pa ilẹ̀ yìí run.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Lateef Adedimeji: Nkan tí a mọ̀ nìyíì nípa ìgbéyàwó tí Lateef àti Adebimpe Oyebade 7 Agẹmo 2020 Oríṣun àwòrán, Instagram/adedimejilateef Àkọlé àwòrán, Ìgbà akọkọ kọ niyii ti aworan igbeyawo ti jade nipa awọn mejeeji Bẹẹni, bẹẹkọ lariwo to gba ori ayelujara lopin ọsẹ to kọja lori gbajugbaja oṣere tiata, Lateef Adedimeji pe o ti ṣe igbeyawo.
Tení Apata ti gbogbo ènìyàn mọ si Teni Entertainer lo maa n sere ati orin daadaa fun igbadun awọn ololufẹ rẹ sùgbọ́n ǹkan ti ọpọ n sọ nipa Teni ni o bi iroyin yii.
lasiko ti egbe oselu naa n se ipolongo fun gomina ti yoo dije fun  egbe oselu naa, Adekunle Akinlade ati awon
Nígbà tí ó pada dé, ó bá Balaki ati àwọn àgbààgbà Moabu, wọ́n dúró ti àwọn ẹbọ sísun náà.
Nígbà tí Abineri pada dé Heburoni, Joabu mú un lọ sí kọ̀rọ̀ kan, níbi ẹnubodè, bí ẹni pé ó fẹ́ bá a sọ ọ̀rọ̀ àṣírí, Joabu bá fi nǹkan gún un ní ikùn.
Bí mo bá ti ṣe èyíkéyìí ninu àwọn nǹkan wọnyi rí, mo ṣetán láti san ohun tí mo gbà pada.
Bẹ́ẹ̀ náà sì ni àwọn ìlú Tire ati Sidoni, bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé àwọn jẹ́ ọlọ́gbọ́n.
“Àwọn ọmọ Lefi yóo bẹ̀rẹ̀ iṣẹ́ ìsìn wọn ninu Àgọ́ Àjọ láti ìgbà tí wọ́n bá ti di ẹni ọdún mẹẹdọgbọn.
Sanwo Olu ni ọrọ yii ko yọ awọn olọpaa ti wọn ti gba iṣẹ lọwọ wọn silẹ.
Fásitì náà sọ pé, èèyàn tó kó ààrùn ààrùn Coronavirus lágbáyé ju eeypan 860,000 lọ, nígbà tí ààrùn ná ti pa èèyàn 42,354.
Ní aginjù yìí ni mo bá àwọn ẹranko, ibẹ̀ ni mo bá àwọn ẹyẹ, ibẹ̀ ni mo sì bá àwọn àǹjànnú ṣùgbọ́n gbogbo wọn ni mo lé lọ féfé tobẹ́ẹ̀ tí n kò ri ẹni kan bá gbé pọ̀ mọ́ tí mo wà ni èmi nìkan ṣoṣo tí mo ń jẹ́ ewéko inú igbó kiri.
”Aare Buhari fikun oro re pe, orile-ede Naijiria ti gbegi dina awon ikolu tabi idojuko ti o fe mu ipinya wa saarin awon omo orile-ede yii lojo pipe, bee si ni ko si ohun ti o le mu iyapa wo aarin wa.
 Besini, Mo lero pe Mo ni ebun ara oto lati koju re.
Jesu dá wọn lóhùn pé, “Àkókò náà dé wàyí tí a óo ṣe Ọmọ-Eniyan lógo.
Neri ni baba Kiṣi, Kiṣi ni ó bí Saulu, Saulu sì bí àwọn ọmọkunrin mẹrin: Jonatani, Malikiṣua, Abinadabu, ati Eṣibaali.
Titi di ba ti ṣe n sọrọ yi, ofin naa ko ti di amuṣẹ.
INEC kede Lalong gẹgẹ bi olubori lẹyin atundi ibo to waye ni ipinlẹ naa ni ọjọ Satide, ọjọ Kẹtalelogun oṣu Kẹta ọdun 2019.
"Oríṣun àwòrán, Ajimobi O tẹsiwaju wi pe, "" Emi ṣiṣẹ labẹ wọn gẹgẹ bii Kọmisana n'igba ti wọn ṣe ni ti alakọkọ."
Oríṣun àwòrán, @ngrpresidency Àkọlé àwòrán, Aare a ma yan awọn Minisita lati ba ṣíṣe Fún ipò Mínísítà, abala mẹ́tàdínláàdọ́jọ sọ pé ẹni bá fẹ di ipò Mínísítà mú ''gbọdọ ní ìwé ẹrí eléyìí tó ṣé dédé òun tí wọn fí n gbà aṣojú ilé aṣòfin àgbà wọlè.
Afurasí afipábánilópọ̀ kàgbákò, obìnrin tó jà lólè fi eyín gé nǹkan ọkùnrin rẹ̀ jábọ́ lásìkò ‘Blow Job’ Àwọn ọba alayé, Mínísítà àti gómìnà nílẹ̀ Yorùbá ṣèpàdé pẹ̀lú ìjọba àpapọ̀, àbọ̀ rèé Iná ṣẹ́yọ nílé ìtajà aya Ajimobi lẹ́yìn ọjọ́ mẹ́ta tó jáde opó O ni ipe yii di dandan nitori Naijiria kii ṣe ilẹ ta ti n tẹle ofin ẹsin tabi ilẹ to n tẹle ofin ẹsin Islam.
Ó fi aṣọ aláwọ̀ aró, ti elése àlùkò, ti àlàárì ati aṣọ ọ̀gbọ̀ onílà tẹ́ẹ́rẹ́tẹ́ẹ́rẹ́ ṣe aṣọ ìbòjú fún ibi mímọ́ jùlọ, ó sì ya àwòrán kerubu sí i lára.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ilé iṣẹ́ aṣọ́bode orílẹ̀-èdè Nàìjíríà ti ni kò si àjòjì darandaran kankan lórílẹ̀-èdè Nàìjíríà gẹ́gẹ́ àwọn ènìyàn ṣe ń sọ.
Wọn yóo wá mọ̀ pé èmi ni OLUWA, ati pé kì í ṣe pé mo sọ ọ́ ní ọ̀rọ̀ ẹnu lásán pé n óo ṣe wọ́n níbi.
Iko agbabọọlu Everton fẹyin Chelsea gbo lẹ ninu idije boolu
Ninu Kristi yìí ni a ti kọ yín nílà, kì í ṣe ilà tí a fi ọwọ́ kọ nípa gígé ẹran-ara kúrò, ṣugbọn ilà ti Kristi; 
Lẹyin naa lo tun gba oye ipele keji (Masters) ati ipele ikẹta (Ph.
Ijọba ipinlẹ Ekiti ni ayẹwo tuntun yoo tun waye fun arabinrin olutọju ọmọ ilẹ Amẹrika naa latọdọ ajọ NCDC.
Nígbà tí ó wá sọ́dọ̀ wa, ó mú ọ̀já ìgbànú Paulu, ó fi de ara rẹ̀ tọwọ́-tẹsẹ̀.
Oxfam: Ìjọba kìí gba owó orí púpọ̀ lọ́wọ́ àwọn olówó tàbí fìyà jẹ àwọn alájẹbánu
Oríṣun àwòrán, Twitter/Muhammadu Buhari O ni awọn eeyan kan ti wọn koriira Tinubu lo wa nibi iroyin ofege naa, bakan naa lo beere pe ki ẹnikẹni to ba mọ ibi ti Tinubu ti sọrọ naa wi pe ko wa sọ.
Bákan náà ni ó mú ife lẹ́yìn oúnjẹ, ó ní, “Èyí ni ife ti majẹmu titun tí a fi ẹ̀jẹ̀ mi dá.
Ṣé koríko tí afẹ́fẹ́ ń fẹ́ síhìn-ín, sọ́hùn-ún?
Amọṣa atundi ibo lawọn ipinlẹ marun ninu awọn ipinlẹ wọnyii yoo waye ni ọjọ abamẹta, ọjọ kẹtalelogun oṣu kẹta.
Bí Gideoni ti ṣaláìsí tán gẹ́rẹ́, àwọn ọmọ Israẹli tún bẹ̀rẹ̀ sí bọ oriṣa Baali, wọ́n sì sọ Baali-beriti di Ọlọrun wọn.
21 Àti pé ọkàn wọn ti bàjẹ́, ó sì kún fún búburú àti àwọn ohun ìríra; àti pé wọn fẹ́ràn òkùnkùn dípò ìmọ́lẹ̀, nítorí awọn iṣẹ́ wọn jẹ́ ibi; nítorínáà wọn kì yíò béèrè mi.
fẹ ́ mi fálànà san ( senior advocate of nigeria ) jẹ ́ agbẹjọ ́ rò àti ajàfẹ ́ tọ ̀ ọ ́ ọmọnìyàn ọmọ orílẹ ̀ èdè ̀ nàìjíríà tí wọ ́ n bí ní ọjọ ́ kẹẹ ̀ dógbọ ̀ n oṣu kejìlá , ọdún 1958 .
O óo fi òtítọ́ inú hàn sí Jakọbu, o óo sì fi ìfẹ́ tí kì í yẹ̀ hàn sí Abrahamu, gẹ́gẹ́ bí o ti búra fún àwọn baba wa láti ìgbà àtijọ́.
"O sọ pe ""mo mọ ọpọlọpọ obinrin paapaa ninu ere bọọlu to nfoju ri ilọkulọ ibalopọ sugbọn wọn o le sọ nitori ẹru nba wọn."
Gẹgẹ bii ohun ti BBC News Yoruba gbọ, ọjọru ni wọn gbe oku arabinrin kan ati ọmọde jojolo to ṣẹṣẹ bii ni abiku wa si ileewosan nla naa lẹyin ti wọn ku nigba ti obinrin naa n rọbi ni ileewosan awọn ọlọpaa to wa ni ilu Akurẹ kan naa.
Àìsí ìmọ̀ràn a máa mú kí ètò dàrú,ṣugbọn ọpọlọpọ ìmọ̀ràn a máa mú kí ó yọrí sí rere.
keji ,osu keta odun ti a wayii.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù CBN: Kò sí owó tó sọnù ní banki àpapọ̀ Naijiria 13 Èbibi 2019 Oríṣun àwòrán, WIKIPEDIA Àkọlé àwòrán, Fọnran kan fẹsun kan gomina banki apapọ Naijiria ati awọn alabasisẹ rẹ ti wọn n wa ọna lati bo 500bn Naira ti wọn ji.
Awọn eeyan ti ọjọ ori wọn wà laarin ọdun mẹtadinlogun mẹẹdọgbọn, ni eto naa wa fun.
Ẹ má purọ́ fún ara yín, nígbà tí ẹ ti bọ́ ara àtijọ́ sílẹ̀ pẹlu iṣẹ́ rẹ̀, 
Ṣugbọn OLUWA, èmi ń ké pè ọ́;ní òwúrọ̀ n óo gbadura sí ọ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ọkọ ìyàwó ẹlẹ́kún: N kò bá tí ba ẹnu jẹ́ lọ́jọ́ ìgbeyàwó, àwàdà ni mo se Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Ọkọ ìyàwó ẹlẹ́kún: N kò bá tí ba ẹnu jẹ́ lọ́jọ́ ìgbeyàwó, àwàdà ni mo se 2 Ọ̀pẹ̀̀ 2018 Ọkọ iyawo kan to bu sẹkun lọjọ ayẹyẹ igbeyawo rẹ, ti BBC Yoruba mu iroyin rẹ wa fun yin, Ọladapọ Ifẹoluwa ti salaye pe, oun mọọmọ fi adun sinu ayẹyẹ igbeyawo oun ni lati da awọn eeyan lara ya.
Euro Cup Idije ere idaraya miran ti oju tun wa lara rẹ ni Euro 2020, ti yoo waye l'oṣu Kẹrin bakan naa.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ààrẹ Buhari ṣí ilé iṣẹ́ àti afára ní ìpínlẹ̀ Ondo 25 Èrèlè 2020 Oríṣun àwòrán, Twitter Aarẹ orilẹede Naijiria, Muhammadu Buihari ati Gomina ipinlẹ Ondo, Oluwarotimi Akeredolu ti ṣe ifilọlẹ akanṣe iṣẹ ni ipinlẹ Ondo.
Awọn asaaju kan ninu ẹgbẹ Afenifere ti bu ẹnu atẹ lu asaaju ẹgbẹ oṣelu APC, Bola Tinubu lori bo se pe fun atunto ilana pinpin owo ajọni fawọn ipinlẹ ni Naijiria.
O ro awon eniyan lati ra awon ohun eelo agbelero nile wa ki a le begbe pe nitori ko si orile ede to le dagba nipa kiko nnkan wole latile okeere.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Miyetti Allah ní kí wọn wọ́gilé Amotekun, Sunday Igboho yarí Ẹ kíyèsára!
Iroyin sọ wipe akẹkọ ati olukọ ileewe girama ilu Misau lawọn to lugbadi ijamba mọto naa.
Ọjọ Kẹrinla, Osu Kẹrin, ọdun 2019 ni ọdun marun ti ikọ Boko Haram ti ji awọn ọmọ ile iwe Chibok gbe ni ile iwe wọn ni ọdun 2014.
Àwọn ọ̀tá yín ni yóo máa wá bẹ̀bẹ̀ fún àánú,ẹ óo sì máa tẹ àwọn pẹpẹ ìrúbọ wọn mọ́lẹ̀.
Fún ìfẹsẹ̀múlẹ̀ ẹ̀tọ́ àti imúdiṣíṣẹ ìbéèrè wọn lábẹ́ òfin, ìwọ́de Afẹ́ Abódiakọ-akọ́diabo wáyé ní Lahore, Pakistan, lọ́jọ́ 29 oṣù Ọ̀pẹ ọdún 2018.
Nigeria Swearing in 2019: Seyi Makinde di gómìnà tuntun
Ọpọlọpọ tí ó jẹ́ ará iwájú yóo di èrò ẹ̀yìn; àwọn èrò ẹ̀yìn yóo di ará iwájú.
MKO Abiola, iṣẹ́ aṣẹ́gità ló fi bẹ̀rẹ̀ okoòwò BBC Yorùba balẹ̀ bàgẹ̀ s'ílée MKO Abiola l'Eko #Democracy Day: Pápá ìṣeré Abuja di MKO Abiola Stadium Ààrẹ Buhari tún fún Abiola ati ẹbi rẹ̀ ni àmi ẹ̀yẹ ní Abuja, tí ìjọba tún tọrọ àforíjìn lọ́wọ́ ẹbí Abiọla lórí ìjájkulẹ̀ June 12.
Itura ni wọn gbé wa fun àwọn eniyan ìpínlẹ̀ Ogun Etò ẹkọ ọfe kò le ṣeeṣe bíkose se pe àtunto àwọn olùkọ gbọdọ jẹ koko.
Akọroyin kan lorileede South Africa Max du Preez gbosuba fun adajọ Steenkamp to si ṣe apejuwe rẹ gẹgẹ bi ''ọlọgbọn eeyan, alaanu, ti a le fi ọkan tan'' Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
'A máa bá àwọn èèyàn Ọṣun kọ́ ilé àkọ́tì wọn parí' A kò ní ǹkan ṣe pẹ̀lú ẹgbẹ́ òsèlú -Adeboye Gboyega Oyetọla APC Gboyega Oyetola lo n dije lẹgbẹ oṣelu APC, o ṣalaye nibi ipade ijiroro naa pé ijọba wọn ni igbimọ ti wọn ṣagbekalẹ rẹ ti o n ṣayẹwo iye owó to n wọle finifini.
Bakan naa lo àri kikọ awọn ibi kan ni ileeṣẹ ti wọn ti n wa irin tutu ni Ajaokuta.
Oríṣun àwòrán, Instagram/sanyeri12 Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Ṣíjuwádé tí ọkàn mi kò ń súre fún un.
Kíkọ́ ẹ̀kọ́ gboyè nínú iṣẹ́ ìṣègùn ìbílẹ̀ yóò pèsè ìtọ́jú tó péye fọ́mọ Nàìjíríà- Ẹgbẹ́ àwọn dókítà Wọ́n mú ọjọ́ ìgbẹ́jọ́ agbésúnmọ́mí 9/11 tó ṣẹlẹ̀ l'Amẹrika Ọwọ́ ọlọ́pàá ti tẹ ọkùnrin kan tó pa ọ̀rẹ́ rẹ̀ nítorí N40 ní Kano Ẹ yé gba owó orí níbi ìdána ìyàwó mọ́, sísọmọbìnrin s'óko ẹrú ni- Daddy Freeze Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Fela ni awokọse mi - Kunle Ajayi Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Bẹtilẹhẹmu ti Juda ni mo lọ, mo wá ń pada lọ sílé, nígbà tí a ti dé ìhín, kò sí ẹni tí ó gbà wá sílé.
Bakan naa lọdun 1967 ijọba Ọgagun Yakubu Gowon mu u si atimọle ọdun meji.
Àwọn odò Nimrimu di aṣálẹ̀,koríko ibẹ̀ gbẹ;àwọn ohun ọ̀gbìn tí ó ṣẹ̀ṣẹ̀ ń yọ jóná mọ́lẹ̀,bẹ́ẹ̀ ni ewé kò rú mọ́.
Ọlọrun pàṣẹ pé kí ilẹ̀ hu koríko jáde oríṣìíríṣìí ohun ọ̀gbìn ati ewéko tí ń so ati oríṣìíríṣìí igi eléso tí ń so èso tí ó ní irúgbìn ninu, ó sì rí bẹ́ẹ̀.
Giwa gba iṣẹ́ lọwọ Mohammed Sanusi, to jẹ akọwe agba fun ajọ NFF, ati awọn ọmọ igbimọ oluṣakoso mi i.
Nítorí bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé láti ara ọkunrin ni obinrin ti wá, láti inú obinrin ni ọkunrin náà sì ti wá.
Lagos-279 FCT-179 Plateau-62 Kaduna-54 Kano-52 Katsina-52 Imo-42 Jigawa-42 Rivers-38 Kwara-30 Nasarawa-19 Yobe-15 Ogun-13 Borno-10 Oyo-9 Niger-9 Ebonyi-6 Bauchi-6 Edo-5 Taraba-4 Sokoto-2 Cross River-2 Èèyàn mẹ́ta míràn kú, olú ìlú Nàìjíríà, Eko, Kaduna léwájú ìṣẹ̀lẹ̀ Covid-19 ní Naijiria Oríṣun àwòrán, Ncdc Esi ayẹwo coronavirus lati ipinlẹ mọkandinlogun ti ajọ NCDC fi sita ni ọjọ Iṣẹgun, ọjọ karundinlogun oṣu kejila ọdun 2020 fihan pe, eeyan ọtalelẹẹdẹgbẹrin o din meji, 758 lo tun ti ni aarun naa ni Naijiria.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Wunmi Toriola, Aisha Lawal, Sotayo àtàwọn ọmọge Yollywood mìí 18 Ọ̀wàrà 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 2 Ìgbé 2020 Oríṣun àwòrán, OTHER Àkọlé àwòrán, Wunmi Toriola, Aisha Lawal, Sotayo àtàwọn ọmọge Yollywood mìí Ọpọ loju teeyan mọ ninu awọn oṣere fiimu Yoruba ti a mọ si Yollywood ṣugbọn ẹni ti yoo yaayi loju ẹnikan yàtọ̀ sẹni ti yoo yaayi loju ẹlomiran.
Ami meji sodo ni Liverpool fi ṣagba Tottenham, ti wọn fi gba ife ẹyẹ naa fun igba kẹfa ninu itan ẹgbẹ agbabọọlu naa.
Ewe, ogbeni Agara wa ro awon ara ilu lati se gafara kuro nibi isele naa ki won si gba awon ti yoo mojuto bi isele ohun se n lo laaye lati se ise won.
"Ní ọdun 1798, èsí ìwádìí náà jáde ti wọ́n si pè é ni ajẹsára láti inu èdè Latin ""Vacca"" tí ó tumọ si (Cow) Màálu."
Ó gbé ère oriṣa tí ó gbẹ́ wá sí ilé Ọlọrun, ilé tí Ọlọrun ti sọ nípa rẹ̀ fún Dafidi ati Solomoni, ọmọ rẹ̀ pé, “Ninu ilé yìí ati ní Jerusalẹmu tí mo ti yàn láàrin àwọn ẹ̀yà Israẹli mejeejila ni wọn yóo ti máa sìn mí.
 Igbimo asofin tun fẹ mọ boya igbesẹ aare Buhari  ko tapa si ojuse ile igbimo asofin ni eyi ti
Eliṣama, ọmọ Amihudu, kó akọ mààlúù meji, ati àgbò marun-un, òbúkọ marun-un ati ọ̀dọ́ àgbò marun-un, ọlọ́dún kọ̀ọ̀kan sílẹ̀ fún ẹbọ alaafia.
Ẹ̀ṣẹ̀ ti obinrin ni pé, nígbà tí wọ́n kì í mọ́lẹ̀ láàrin ìlú, kò pariwo kí aládùúgbò gbọ́.
Wọn fi kun ọrọ wọn pe ki awọn gomina pada si ipinlẹ kaluku wọn, lati lọ duna-dura pẹlu awọn oṣiṣẹ wọn, kiiṣe ipinnu ajumọṣe.
O ni ẹẹdẹgbeje awọn eeyan lawọn ileeṣẹ eto ilera n wa bayii lori itankalẹ arun coronavirus ọhun.
Nígbà náà ni Hanani aríran, wá sọ́dọ̀ Asa, ọba Juda, ó wí fún un pé, “Nítorí pé o gbẹ́kẹ̀lé ọba Siria, dípò kí o gbẹ́kẹ̀lé OLUWA Ọlọrun rẹ, àwọn ogun Siria ti bọ́ kúrò lọ́wọ́ rẹ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Akomolede àti Asa lórí BBC Yorùbá: Mọ̀ síi nípa ẹ̀kún ìyàwó níbí Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Akomolede àti Asa lórí BBC Yorùbá: Mọ̀ síi nípa ẹ̀kún ìyàwó níbí 3 Bélú 2020 Koko wo lo wa ninu ẹkun iyawo?
Èmi Ọba tí wọ́n ń kó jẹ nígboro- Oluwo ti ilú Iwo Wo bí ètò ìsìnkú Tolulope Arotile ṣe lọ nílùú Abuja Ki laa ri ti aarẹ Buhari wọ ibomu fun igba akọkọ nita gbangba?
Gauri ni ojoojumọ ninu ẹgbọn oun maa n dun si Roshan nitori iwa irẹlẹ rẹ.
O Fagunwa; Ǹkankan máa ń darí wọn lọ ibi tí a kò mọ̀
Ẹgbẹ okunkun miran lo wa ba awọn ọmọ ẹgbẹ one million boys ja, ko si ẹni to laya ninu one million boys lati koju ẹgbẹ okunkun to wa bawọn ja naa afi Abiola Ebila, o jagun, to si segun, lati igba naa si ni wọn ti fi ṣe olori wọn.
Lẹ́yìn tí ẹ rí èyí, ẹ kò ronupiwada kí ẹ gbà á gbọ́.
Ó rán Mose, iranṣẹ rẹ̀,ati Aaroni, ẹni tí ó yàn.
Kẹti kẹti ni ero n tu ni gbagede Eagle Square ni olu ilu orilẹede yii, Abuja nibi ti eto naa ti n waye.
 Ọ ̀ nà apá ọ ̀ tún yẹn tí wọ ́ n ṣẹ ̀ ṣẹ ̀ ń ṣe ni a óò wá tọ ̀ dé Ìrè-Èkìtì , kìlómítà márùn-ún ibi tí a ti máa yà jẹ ́ sí ìlú Ìrè-Èkìtì .
O jẹ ọkan lara awọn ọmọ ẹgbẹ obinrin to ni irungbọn ni Kenya, ti wọn a si ma ba awọn obinrin sọrọ nibi ipade wọn.
Lẹ́yìn èyí ni wọ́n mórí lé ìloro ọgbà fásitì náà tí wọ́n sì fi ẹ̀wọn tìí, ṣùgbọ́n wọ́n fi ààyè ìrìnnà ẹsẹ̀ sílẹ̀.
Funke Akindele: Oríṣun àwòrán, funkejenifaakindele Jenifa baby, gẹgẹ bi ọpọ eeyan se maa n pe Funkẹ Akindele, naa ko gbẹyin ninu awọn oloriire to gba ami ẹyẹ nibi ayẹyẹ ifamiẹyẹ danilọla ti AMVCA7 naa.
Nisinsinyii, ìwọ Amasaya, nítorí pé o ti ṣẹgun Edomu, ọkàn rẹ kún fún ìgbéraga.
Ọlọ́pàá Amẹrika tún yìnbọn lu aláwọ̀ dúdú míì nígbà méje, ìwọ́de #BlackLivesMatter bẹ̀rẹ̀!
Oríṣun àwòrán, @BBNaija O fikun wi pe ọrọ ki ilu dara tabi ko gbooro ko nii se pẹlu ere idaraya, ati wi pe, a ko gbọdọ dina awon eniyan lati je ki won wo nkan to ma a mu inu wọn dun.
Ṣé aṣálẹ̀ ni mo jẹ́ fún Israẹli;tabi mo ti di ilẹ̀ òkùnkùn biribiri?
Tinubu kìlọ̀ fún Buhari, Osinbajọ lórí àfikún owó orí ọjà VAT Wo obìnrin tó ń múra bíi ọkùnrin láti leè ṣe 'iṣẹ́ ọkùnrin' Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Tinubu Colloquium: Ìṣẹ́gun APC ní ìdìbò 2019 ni ẹ̀bùn pàtàkì tí mo rí gbà fún ọjọ́ ìbí mi29 Ẹrẹ̀nà 2019 1:05 Fídíò, Neha Sharma: obìnrin tó ń múra bíi ọkùnrin láti leè ṣiṣẹ́ gẹrígẹrí, Duration 1,0531 Ẹrẹ̀nà 2019 Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí kan sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
Awon asoju ile-ẹjọ to n ri si ẹtọ
Akojọpọ awọn ipinlẹ ti esi tuntun naa ti wa niyii.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Duro Ladipọ, ìlúmọ̀ọ́ká òṣèré tíátà àti ọmọ àlúfà tí kò gbàgbé àṣà ìbílẹ̀ Ìtàn ìgbésí ayé Oshodi, ọmọ Tápà léǹpe tó di akọni ní ìlú Eko Ìtàn Manigbagbe: Àwọn àjakalẹ-àrun to ti wáyé rí ṣáájú Coronavirus Wo àwọn gbajúmọ̀ òṣèré Yorùbá tí kìí ṣe ọmọ káàárọ̀ oòjíire Ǹjẹ́ o mọ àwọn òṣèré bí Oyin Adejọbi, Funmi Martins àtàwọn míì tó ti dágbére fáyé?
Wọn ti rọ awọn ile-iṣẹ ara ilu ti wọn ni agbara lati maa nawo si ẹka ere idaraya nipa ifọwọsowọpọ awọn ara ilu loriṣiriṣi ni ẹka ere idaraya orilẹ-ede Naijiria.
Bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé ò ń rò pé o gbọ́n bí àwọn oriṣa, 
Coronavirus: Àwọn ọmọ Nàìjíríà n polongo pé ibìkan nàá ni kí olórí àti ọmọ ìlú ní Nàìjíríà ti gba ìtọ́jú
Wang gbo ewuro soju Serena eleyi to jẹ ipele to ya ju ti Serena ti jabọ ni idije Lawn Tennis lati ọdun mẹrinla sẹyin ti o ti ja kulẹ ni ipele yii kan naa nigba to koju Daniela Hantuchova.
’ Bí wọ́n bá ṣe inúnibíni mi, wọn yóo ṣe inúnibíni yín.
Àwọn ọkọ̀ ojú omi fò sókè roro,wọ́n sì tún já wá sílẹ̀ dòò, sinu ibú,jìnnìjìnnì bò wọ́n ninu ewu tí wọ́n wà.
Ṣugbọn kí ni ẹ jáde lọ wò?
Wo ohun tí àwọn ọmọ Nàìjíríà ń sọ lórí dájọ́ ikú Yahaya Sharif-Aminu tó gba ìdájọ́ ikú lórí ẹ̀sùn ọ̀rọ̀ òdì sí Ànọ́bì Orílẹ̀-èdè Chad pé ọgọ́ta ọdún, àwọn ara ìlú ń pariwo lábẹ́ Aàrẹ Deby tó gba 'Field Marshal' Dẹ́rẹ́bà kẹ̀kẹ́ Maruwa rí ẹ̀wọ̀n gbére he lẹ̀yìn tó fi ipá bá ọmọ ọdún mẹ́rìnlá lòpọ̀ ‘Àwọn òlóṣèlú kò ní ìwà ọmọlúwàbí ló jẹ́ kí wọ́n má a lọ láti ẹgbẹ́ òṣèlú kan lọ sí òmìràn’ San Louis ní wọ́n gba owó náà láti gba àwọn ọmọ Fulani kéékèké ti wọ́n n gbé ìhà Ìwọ̀ òòrùn-gúúsù Nàìjíríà.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Fury vs Wilder: Ìbínú ni Wilder fi kúrò níbí ìjà, tó sì ní síbẹ̀-síbẹ̀, akọni ni òun 23 Èrèlè 2020 Oríṣun àwòrán, @peluu_lovers Tyson Fury ti fagba han Deontay Wilder lẹyin to na jati-jati ninu idije ẹṣẹ kikan to waye laarọ ọjọ Aiku, ni gbọgan MGM, to wa ni Las Vegas.
CNN ni Minsita Lai Mohammed ko mu ẹri kankan wa lati fi han pe ayederu ni fidio awọn tabi pe awọn ọta ibọn naa kii se tawọn ọmọ ogun Naijiria.
to ba fẹ wọ ọkọ wọn, sugbon won gbodo lee fi kaadi idibo won han lati jẹ anfaani
Nígbà tí àwọn obìnrin mejì yìi’kọ́ tẹ̀lé bàbá mi wọ́n ṣe bí yóó tètè padà ni, wọn kò mọ̀ pé o ń lọ ṣe ọdẹ nínú Igbó Olódùmarè ni.
” Inú bí Samuẹli, ó sì gbadura sí OLUWA ní gbogbo òru ọjọ́ náà.
Awọn miran n sọ wi pe oye eniyan to ti lugbadi arun naa ju oye naa lọ.
Abenugan ile igbimo asoju-sofin lorile ede Naijiria, Yakubu Dogara ti so pe igbimo asofin yoo tubo tepele mo ojuse won lati ri i pe eto idibo odun 2019, lo ni irowo –irose.
N óo jẹ́ baba fun yín, ẹ̀yin náà óo sì jẹ́ ọmọ fún mi,lọkunrin ati lobinrin yín.
Eyi mu ki wọn tete gbe e kuro ni ile iwosan tiwọn si lọ si ile iwosan miiran ko to di pe Favour jade laye.
Ọrọ ìdánilójú rè láti ọdọ ẹgbẹ́ òṣèlú PDP sí gómìnà ìpínlẹ̀ Èkó Akinwunmi Ambode.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Boko Haram yóò dá Leah sílé Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Lagos- Ibadan Express: Kò sí ìfòyà lásìkò ọdún iléyá30 Agẹmo 2019 Tá láwọn ọba aládé àti olóṣèlú tí EFCC n wà lórí owó ìrànwọ́ N2bn ní Kwara?
Ajo to n koju arun Coronavirus ni Naijiria, NCDC to fi lede ni Ọjọ Iṣẹgun ni iye awọn to ti ni arun naa ti le ni ẹgbẹẹta ati irinwo(6401).
Otedola bridge fire: Ọkọ̀ akẹ́rù rí ìjánu rẹ̀ já ló kọlù ọkọ̀ agbépo tó fa ìjàmbá iná ní Otedola lópópónà Lagos-Ibadan- LASEMA
Ọlọ́run kò ní í jẹ́ kí ẹ fi irú rẹ̀ gbà á o.
Kùmọ̀ àti ọ̀gọ, ẹrù pàṣán àti ogunlọ́gọ̀ òkúta, egungun ènìyàn àti agbárí ẹranko, àgógó ẹnu ẹyẹ àti ọ̀ké àìmoye ìkarawun ìgbín ni ó yí Àǹjànnú-ìbẹ̀rù ká, ẹni tí i ṣe oníbodè Igbó Olódùmarè: iwin burúkú ni.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Oorun sisun kii se ka gbe ori le irọri nikan, tori kii se ọpọ eeyan lo lee tete sun lati ipasẹ eyi nikan Sugbọn awọn onimọ ni ta ba lee mu ayipada ba awọn iwa kan to ti di baraku fun wa, a maa sun bo se yẹ Bawo la se fẹ ri oorun gidi sun ni alẹ: Maa ji, ko si maa sun ni akoko kan naa lojoojumọ - To ba lee maa ji, ko si maa sun ni akoko kan naa lojoojumọ, eyi too ran ọ lọwọ lati maa mọ iye wakati to fi n sun, ti oorun yoo si maa kun ọ, ti akoko to yẹ ko sun ba ti ko.
O ṣeeṣe ki o gba iwe aṣẹ igbelu ṣugbọn pẹlu owo ti ko ga ju ara lọ, ṣugbọn ti ilẹ naa ni awọn ibi abẹwo to lọọrin.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Port Harcourt: Afurasí wà ní àhámọ́ ọlọ́pàá 20 Owewe 2019 Oríṣun àwòrán, Mustapha Dandaura/Facebook Àkọlé àwòrán, Ìpaǹìyàn ni Port Harcourt Ọwọ awọn agbofinro ti tẹ Gracious David West, ẹni ti wọn fura si pe o pa ọpọlọpọ obinrin ni ipinlẹ Rivers.
“yahoo boys” n hu ni agbegbe naa.
Koda, nitori ojojo to n se ọrọ aje wa yii, spọ ipinlẹ lo n lọ ya owo lati gbọ bukata sisan owo osu awọn osisẹ, ko to di ariwo.
Ẹgbẹ agbabọọlu ipinlẹ Osun ọhun, ti o n jẹ Prime FC, ni Ighalo ti gba bọọlu kẹyin ko to lọ si ilẹ okeere, nibi to ti darapọ mọ ẹgbẹ agbabọọlu Norwegian kan ni Lyn Oslo lọdun 2007.
” Israẹli bá rán an láti àfonífojì Heburoni lọ sí Ṣekemu.
O kasẹ ọrọ rẹ nilẹ pe, a gbodo rọra tufọ fun iyawo oloogbe tabi ọkọ oloogbe pẹlu afiwe iṣẹlẹ to n muni lọkan le ati suuru.
ti iko ohun gba omi ayo(0-0) pelu orile-ede Uganda niluu Asaba, ki won to
Ni apa ariwa, meji ninu marun ile to wa nibẹ ni ko ni anfani omi to mọ.
Ọkùnrin kan ati obinrin kan ni awọn ibeji naa, ti wọn jẹ akọbi awọn oṣere tiata mejeeji, ti awọn ọmọ naa ko si tii gba aburo di akoko yii.
Nítorí ó ń retí ìlú tí ó ní ìpìlẹ̀, tí ó jẹ́ pé Ọlọrun ni ó ṣe ètò rẹ̀ tí ó sì kọ́ ọ.
Aare Malawi ana, Joyce Banda ti o sese pada lati ibi ti o salo , leyin odun merin, ti kede lojo Aje lati dije fun ipo aare lodun to n bo labe  asia egbe re.
 Ètò ìkànìyàn 1995 sọ pé àwọn ènìyàn ibè jẹ ́ ẹgbẹ ̀ rún lọ ́ nà ojójì ó lé mẹ ́ ta ( 43 , 000 ) .
Angẹli kan yọ sí i láti ọ̀run láti ràn án lọ́wọ́.
Wọ́n lu òun lórí ní àlùbẹ́jẹ̀, wọ́n sì dójú tì í.
Iroyin taa gbọ ni wi pe ni ọjọ abamẹta ni wọn jii gbe nigba ti o n rin irinajo lati ls ki ẹbi rẹ nilu Eko.
Cazorla n fi Arsenal silẹ lẹyin ọdun mẹfa to lò nibẹ.
Ọdun 1985 ti ọgagun Babangida si gba oye aarẹ ati Kọmanda awọn ologun ni Naijiria, naa ni Abacha gba oye olori Ileesẹ ọmọ-ogun ori ilẹ, to si tun di Minisita feto aabo lọdun 1990.
Àwọn àgbá kẹ̀kẹ́ mẹrẹẹrin wà lábẹ́ àwọn ìtẹ́dìí yìí, àṣepọ̀ mọ́ ìtẹ́lẹ̀ ni wọ́n ṣe àwọn ọ̀pá inú àgbá kẹ̀kẹ́ náà.
Loṣu to kọja ni aarẹ Madagascar naa ni oun fẹ lọ lẹẹkeji ninu idibo to yẹ ko waye ni oṣu kẹta ọdun to m bọ.
Nígbà tí Joṣua ati àwọn ọmọ Israẹli rí i pé àwọn tí wọn farapamọ́ ti gba ìlú náà, tí èéfín sì ti yọ sókè, wọ́n yipada, wọ́n sì bẹ̀rẹ̀ sí pa àwọn ará Ai.
Oríṣun àwòrán, oyo insight Esi lẹta fun agbekalẹ Ileesẹ ọlọpaa kogberegbe naa silu Oyo lo de ni ọjọ kẹtala osu kinni ọdun 2020 pe ijọba ti fọwọsi pe ki wọn gbe Ileesẹ ọlọpaa kogberegbe naa silu Oyo ati ilu mẹfa miran ni Naijiria.
Awon orile ede bii UK, Romanina, Italy ati Ukraine ni igbona ti tankale julo.
N óo fọ́n àwọn ará Ijipti ká orílẹ̀-èdè ayé, n óo sì tú wọn káàkiri gbogbo ilẹ̀ ayé.
6bn ohun ìní Nàìjíríà ShopRite Ibadan gbé ìlẹ̀kùn tìpa torí ìkọlù àwọn tó ń fẹ̀hónú hàn OPC, Miyetti Allah, agbófinró yóò wà nínú ìgbìmọ̀ aláàbò nílẹ̀ Yorùbá Wike kìí ṣe dọ́là tí Ganduje leè kó sápò- Agbẹ́nuso ìjọba ìpínlẹ Rivers Nibayii, Wada ni yoo ṣoju ẹgbẹ oṣelu PDP ninu ibo gomina ti yoo waye lọjọ kẹriundinlogun oṣu kọkanla ọdun 2019.
Nípa bẹ́ẹ̀, bí ikú ṣe sọ ẹ̀ṣẹ̀ di ọba, bẹ́ẹ̀ ni ìdáláre náà ń fi oore-ọ̀fẹ́ Ọlọrun jọba, ó sì mú wa wọnú ìyè ainipẹkun nípasẹ̀ Jesu Kristi Oluwa wa.
Lara awon egbe oselu ti INEC tun foruko won sile ni: Alternative Party of Nigeria (APN), Change Nigeria Party (CNP), Congress Of Patriots (COP), Liberation Movement (LM), Movement for Restoration ati Defence of Democracy (MRDD), Nigeria Community Movement Party (NCMP), Nigeria for Democracy (NFD) ati  Peoples Coalition Party (PCP)Awon egbe oselu miiran tun ni:Reform and Advancement Party (RAP), Save Nigeria Congress (SNC), United Patriots (UP ), United Peoples Congress (UPC), We The People Nigeria (WTPN) , YES Electorates Solidarity (YES), Youth Party (YP), ati Zenith Labour Party (ZLP).
Saulu fẹ́ràn rẹ̀ gidigidi, ó sì di ẹni tí ń ru ihamọra Saulu.
Mohammed Adamu fi ọrọ naa lede lataari ikọlu to waye laarin awọn ọlọpaa ati awọn ẹlẹsin Shia, eleyii ti o mu ọpọ ẹmi lọ.
Ṣugbọn Valencia lo kọkọ gbayo sawọn Chelsea lẹyin ti Carlos Soler jẹ goolu akọkọ nigba ti ifẹsẹwọnsẹ ọhun di ogoji iṣẹju.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù International flights resumption: Bàálù ilẹ̀ òkèèrè bà l'Abuja léyìn ìṣéde oṣù márùn ún coronavirus 22 Ẹrẹ̀nà 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 8 Owewe 2020 Oríṣun àwòrán, others Lẹyin ti irin ajo ọkọ ofurufu silẹ okeere gberasọ pada ni Naijiria, baalu Ethiopia Airline lo kọkọ ba silu Abuja lati Addis Ababa, Ethiopia.
Wọ́n mú Peteru ati Johanu wá siwaju ìgbìmọ̀.
Nibi ọrọ yi ni awọn aṣa kan ti jẹyo eleyi ti o gba ori ayelujara kan.
Ninu esi rẹ ti oun pẹlu gbe soju opo ayelujara Instagram rẹ, Mike Ezuruonye laali Kunle Afọlayan pe, ohun to ṣe ku diẹ kaa to.
 Ó lóun mẹ ̀ làkátakàta .
Mo lè ṣá eniyan lọ́gbẹ́,mo sì lè wò ó sàn.
Ninu gbogbo bí mo ti ṣe ń bá àwọn ọmọ Israẹli kiri, ǹjẹ́ mo bèèrè lọ́wọ́ ọ̀kan ninu àwọn olórí wọn tí mo yàn láti jẹ́ alákòóso àwọn eniyan mi, pé, Kí ló dé tí wọn kò fi igi kedari kọ́ ilé fún mi?
Ramat Olowo fikun pe ẹya Ibariba, Fulani ati Gambari lo ko asa lilu Kengbe wa si Ilọrin amọ o ti yi wọnu asa Yoruba, ti ko si yẹ ko parun.
Aare ki igbimo NCWS lopolopo fun abewo won, O fikun oro re pe, ipese owo iya fun awon agbe lojuna ati mu igberu ba eto agbe jake-jado orile-ede yii ti gbale pupo.
Kíá ni ìjọba Naija náà fọhùn.
Gẹgẹ bi alukoro ile iṣẹ Ọlọpaa ipinlẹ Delta ṣe ṣalaye fun akọroyin BBC, Onovwakpoyeya Onome sọ pe lootọ ni o ṣẹlẹ ni agbegbe Abraka.
Ojú rẹ̀ sì já a pé àìgbọràn kì í bímọ rere.
Awọn ajafẹtọ ẹni bẹnu ẹtẹ lu iha ti awọn ọlọpaa kọ si iṣẹlẹ yii ati bi wọn ti ṣe ṣeku pa ana Mohammed Yusuf, iyẹn Baba Fugu Mohammed ni ipakupa.
 a fi oruko re sori eranko igbo ursula , omo re urs igbo ni swistzerland .
Àwọn Ìjẹ ̀ sà jẹ ́ alákíkánjú àti jagunjagun ènìyàn ọ ̀ pọ ̀ lọpọ ̀ ogun ní àwọn Ìjẹ ̀ sà ni pa nínú rẹ ̀ , ní àkókò ogun kariaye ilè yorùbá .
Pẹlu àtìlẹ́yìn OLUWA, Nimrodu di ògbójú ọdẹ, tóbẹ́ẹ̀ tí wọ́n máa ń fi orúkọ rẹ̀ súre fún eniyan pé, “Kí OLUWA sọ ọ́ di ògbójú ọdẹ bíi Nimrodu.
Awọn onimọ ilera ni bi Élẹda ṣe da ara ni lati tun ṣe igbọnsẹ lalẹ lasiko ti awọn eeyan ba n sun.
Loṣu kẹwaa, ọdun 2019 ni ajọ FIFA fẹsun kan Siasia pe o gba lati tẹwọ gba riba lati ṣe eeru ninu awọn ifẹsẹwọnsẹ kan to ti waye sẹyin.
Wọn ri atilẹyin ikọ agbesunmọmi lagbaye, Al Queda gba, tawọn naa si bẹrẹ si ni yin ado oloro kaakiri orilẹede Naijiria.
Lara wọn ni eeyan 44,152 ti gba iwosan, ti awọn 1,082 si ti ku.
Mo ṣàìsàn, mo wà lẹ́wọ̀n, ẹ kò wá wò mí.
Àkọlé àwòrán, Sekinat Quadri ''Mo sọ fun Mummy mi wi pe mo fẹ́ ma ja ẹṣẹ ṣugbọn wọn sọ wi pe rara.
Ali soro yii, lasiko to n ba awon akoroyin soro ni
"Nigeria Police recruitment 2020: Bí ó bá fẹ́ dara pọ̀ mọ́ ìṣẹ́ ọlọ́pàá, forúkọ́ sílẹ̀ níbí Ohun tí o kò mọ̀ nípa Ebila ""One Million Boys"" àti Ekugbemi, olórí ẹgbẹ́ òkùnkùn méjì tó da ìlú Ibadan rú Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!"
Bẹ́ẹ̀ ni, Baba, nítorí bí ó ti tọ́ ní ojú rẹ ni.
Ẹni miran lara awọn ololufẹ Toyin pa arọwa si i pe, ki o tiraka lati pari aawọ to wa laarin oun ati Lizzy.
Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Fídíò, D.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Saheed Oṣupa: Ọlọ́pọlọ pípé kò leè ṣe òṣèlú Nàìjíríà 17 Èbibi 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 8 Ògún 2020 Gbajugbaja olorin fuji lorilẹede Naijiria, Saheed Osupa ti sọ fun gbogbo awọn ololufẹ rẹ wi pe oun ko ni iyawo ni ile, amọ oun ni ọpọlọpọ ọmọ to jẹ ti ti oun.
Nígbà tí ó wí eléyìí, inu mi dùn bí inú ẹni tí wọ́n pè lẹ́jọ́ ẹ̀wọ̀n ṣùgbọ́n tí adájọ́ dá láre, nítorí mo rí ohun tí mo ń wá, mo ṣe alábàápàdé ohun tí ó wù mí, Olódùmarè fi bọ́tà sí búrẹ́dì fún mi; mo ki ọwọ́ bọ àpò nítòótọ́, mo sì rí ohun ìkọ̀wé kítikìti, mo bá dọ̀bálẹ̀ mo bẹ̀rẹ̀ si bá iṣẹ́ ọwọ́ lọ.
Gómìnà Dapo Abiodun fún Modupe Akintola n'íṣẹ́ ọ̀fẹ́
Nigba to n jabọ fun awọn akọroyin lori iṣẹlẹ naa, Kọmiṣọna ọlọpaa nipinlẹ Oyo, Joe Nwachukwu Enwowu sọ pe ọwọ tẹ Erigga lẹyin ti wọn fi ọrọ rẹ sun ni ẹka ileeṣẹ ọhun to wa ni agbegbe ̣Ojoo.
A mú gbogbo èrò ọkàn ní ìgbèkùn kí ó lè gbọ́ràn sí Kristi lẹ́nu.
" Oríṣun àwòrán, Others Nigba to n dahun ibeere lori boya ilọsiwaju ti wa fun ipese awọn ohun eelo eto ilera igbalode lawọn ile iwosan wa gbogbo ni Naijiria, Faduyile ni ipese awọn ohun eelo ilera kọ lo ja ju bikose ka tena itankalẹ arun naa, ko ma wọ Naijiria, ka si seto idanilẹkọ fawọn araalu.
Aare orile ede Naijiria ,Muhammadu Buhari ti ro adari awon elesin onigbagbo lati maa tan ihinrere kaakiri orile ede Naijiria nipa emi ifarada, ifẹ  ati isọkan.
Gbogbo ẹyin oniwa ibajẹ nilẹ Yoruba, ẹ bila!
Awọn to wa ni ipele A ni awọn ọba ti itan sọ pe wọn wa ninu igbimọ Pelupelu lati ibẹrẹ pẹpẹ, ati awọn miran ti ijọba ti fi kun wọn.
Ìrìnàjò mà ni Alákọ̀wé tẹsẹ̀ bọ̀ ní ọlọ́kanòjọ̀kan o.
O ní wọ́n wọ́gile ìwé ìrìnà Visa òun lẹ́yìn ti wọn wo ẹrọ iléwọ àtí kọmputa alágbéletan rẹ̀.
Igbimọ apapọ ti Ile Igbimọ Asofin lori ajọ INEC ti Sẹnetọ Suleiman Nazif jẹ adari fun, lo paṣẹ bẹ lẹyin ipade to ṣe l'ọjọ Aje ọ̀ṣẹ̀ yii, ti wọn si fi ikede rẹ sita lori ẹrọ ikansiraẹni Twitter.
Àwọn ọba mejeeji gúnwà lórí ìtẹ́ wọn, ní ibi ìpakà, ní àbáwọ bodè Samaria, gbogbo àwọn wolii sì bẹ̀rẹ̀ sí sọ àsọtẹ́lẹ̀ níwájú wọn.
Ẹfunroye Tinubu - Ògbóǹtagí oníṣòwò, olówò ẹrú àti afọbajẹ Samuel Ajayi Crowther, òjíṣẹ́ Ọlọ́run tó gbé èdè Yoruba lárugẹ Mọrèmi Àjàṣorò, akọni obìnrin tó gba Ilé Ifẹ̀ sílẹ̀ lóko ẹrú Ọ̀rọ̀ǹpọ̀tọ̀niyùn, Aláàfin obìnrin àkọ́kọ́ rèé, tó ní nǹkan ọkùnrin O jẹ ọkan lara awọn oṣere tiata to kọkọ ṣe ere itage lori amohumaworan pẹlu awọn gbajumọ oṣere tiata miran bii Hubert Ogunde, Baba Sala, Baba Mero, Kola Ogunmola, Oyin Adejobi, ati Adeyemi Afolayan.
Àsẹ̀yìnwá Àsẹ̀yìnbọ̀ o jẹ́wọ́ fún ọmọ rẹ̀ pé òun ti wádìí òun sì ti mọ ìdí rẹ̀, òun ti mọ ẹbọra tí o jókòó tì, ó sì rán an kí ó lọ bèèrè lọ́wọ́ ẹbọra ìyàwó rẹ̀, kí óo bá òun wá aṣọ títóbi kan tí ó jẹ́ pé bí ènìyàn bá ká aṣọ yìí tán tí dìí mọ àtẹ́lẹwọ́ kan ẹnikẹ́ni kò ní í rí ohun tí olúwarẹ̀ dì mọ́ ọwọ́, ṣùgbọ́n bí ènìyàn bá nà án tán, yóò bo gbogbo ìlú.
Oun lo kọkọ koju iṣoro ibeere ta ni adari ajọ NFF ni Naijiria?
Nígbà tí a gbọ́ ohun tí Agabu wí, àwa ati àwọn tí ó ń gbé ibẹ̀ bẹ Paulu pé kí ó má lọ sí Jerusalẹmu.
Ikolu iji lile naa ba opolopo nnkan je ni olu-ilu naa, paapaa julo ni awon igberiko ati aarin ilu.
Ó níláti gba ààrin ilẹ̀ Samaria kọjá.
Ìkòkò òkúta mẹfa kan wà níbẹ̀, tí wọ́n ti tọ́jú fún omi ìwẹ-ọwọ́-wẹ-ẹsẹ̀ àwọn Juu, ọ̀kọ̀ọ̀kan wọn gbà tó bíi garawa omi marun-un tabi mẹfa.
Àjọ ajàfẹ́tọ̀ọ́ ni ènìyàn 2000 ti kú nínú ìṣẹ̀lẹ̀ darandaran Ajọ ajafẹtọ kan lorilẹede Naijiria ti sọwipe o le ni ẹgbẹrun meji (2000) eniyan to ti ku ninu rogbodiyan laarin awọn darandaran ati awọn agbẹ lati bi Osu Mejidinlogun lorilẹede Naijiria.
Bagudu ti so pe orile ede  Naijria ko ni jẹ
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ọ̀pọ̀lọpọ̀ló ń fara pamọ́ mu igbò Laijẹ bẹẹ ko ni ṣanfaani, awọn eniyan yoo lo igbo ni ilokulo to ba pọ nilu."
Ọba ṣètò pé kí wọn máa gbé oúnjẹ aládùn pẹlu ọtí waini fún wọn lára oúnjẹ ati ọtí waini ti òun alára.
O sọ fun BBC Yoruba pe eyi ti ijọba kọ wayi tilẹ̀ dara ju ti eyi ti wọn wo lọ.
Ṣugbọn ṣa, eniyan 13, 103 ti ri iwosan, awọn 724 si ti ku.
Ọlọrun Israẹli ti sọ̀rọ̀,Àpáta Israẹli ti wí fún mi pé,‘Ẹni yòówù tí ó bá fi òtítọ́ jọba,tí ó ṣe àkóso pẹlu ìbẹ̀rù Ọlọrun,
Nígbà tí Josẹfu wọlé, wọ́n mú ẹ̀bùn tí wọ́n mú bọ̀ fún un wọlé tọ̀ ọ́ lọ, wọ́n sì wólẹ̀ fún un, wọ́n dojúbolẹ̀.
” Lẹ́yìn ìgbà tí ẹni náà bá sọ inú ẹ̀yà tí òun ti wá fún Absalomu tán, 
Cavani dèrò Man United, Arsenal bínú ra Partey ní £45m, Walcott padà sí ẹsẹ àárọ̀ Ìdájọ́ ẹ̀wòn gbére kò ní kí Wòlíì Sotitobire má lọ sí ilèẹjọ́ kòtẹ́milọ́rùn - Agbẹjọ́rò Pásítọ̀ Alfa Babatunde Sotitobire: Ojú àwọn Wòlí tó tí lọ sẹ́wọ̀n lórí ẹ̀sùn ọdaràn tẹ́lẹ̀ rèé MC Murphy ko sọ òótọ́ ọ̀rọ̀ to wà níbẹ̀, tó ba wùú kó sọ òótọ- Adebayọ 'N500 dé fún gbogbo ọmọ tuntun lóṣooṣù bí mo bá di gómìnà Ondo - Adeleye AAC Alabami ni ilẹ Faranse lu Ukraine ninu ere bọọlu naa lẹyin ti wọn gba goolu meje ọtọtọ wọle ti Ukraine si rapala da ẹyọkan ṣoṣo pada.
"' ""Ti kii ba ṣe Ọlọrun, nkan ta n wi yii kọ lao ba maa wi tori ọmọ to jana mọ ọkọ mi lẹnu yẹn ṣe e lojiji o si sunmọ gan""."
Lẹyin naa ni mo darapọ mọ Adebayo Salami lori awada kẹrikẹri fun bi ọdun meje.
A kò tíì le sọ nkan to fa ìjà yi pato sugbọn finfinfin t'awọn akọroyin lagbegbe naa gbọ ni pe, owo ẹbùn ọdun to to ẹgbẹrun lọna aadọjọ naira (N150,000) lo dá ìjà silẹ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Mistura Oseni Akintunde: Ara múmú kìí ṣe oríṣun ìfipábánilòpọ̀, ìran àwòjù ló ń fà á Eeyan meji lo wa ninu ọkọ ayọkẹlẹ naa nigba ti ijamba naa ti waye, eeyan kan ku, eeyan kan yoku si n gba itọju Ọkọ̀ tírélà 3 kọlu ọkọ̀ ìgboro, obìrin 2 kú, 6 farapa yánnayànna Oríṣun àwòrán, Lasema/Facebook Awọn obinrin meji to wa ninu ọkọ igboro ti padanu ẹmi wọn lasiko ti ijamba ọkọ waye ni agbegbe Anthony to wọ Gbagada ni ipinlẹ Eko.
Arabinrin Toyin Saraki to jẹ aya Aarẹ ile igbimọ Aṣofin agba ni Abuja tẹlẹ, Bukola Saraki naa ti fun tiya tọmọ oloju buulu ni ẹgbẹrun lọna igba ati aadọta owo naira lati fi tọju ara rẹ ati ọmọ rẹ.
Kí ló dé tí ẹ fẹ́ bá mi lọ?
Ènìyàn 749 míràn ló tún ṣẹ̀ṣẹ̀ lùgbàdì ààrùn Covid-19 ní Nàìjíria Oríṣun àwòrán, Ncdc Ajọ to n gbogun ti ajakalẹ aarun lorilẹ-ede Naijiria, NCDC ti kede pe eeyan 749 miran ti kun iye awọn to ti ni aarun COVID-19 ni Naijiria.
 a lè ṣe èyí nípa ṣíṣe àyẹ ̀ wò irú àwọn ẹranko bẹ ́ ẹ ̀ fún àrùn náà , pípa wọ ́ n , àti sísọ òkú wọn nù ní ọ ̀ nà tí ó tọ ́ bí a bá rí àrùn náà lára wọn .
Àwọn àmì tí yóo máa bá àwọn tí ó gbàgbọ́ lọ nìwọ̀nyí; wọn yóo máa lé ẹ̀mí burúkú jáde ní orúkọ mi; wọn yóo máa fi àwọn èdè titun sọ̀rọ̀; 
tí ó fi ìdí rẹ̀ múlẹ̀ fún Jakọbu gẹ́gẹ́ bí òfin,àní fún Israẹli gẹ́gẹ́ bíi majẹmu ayérayé,
Dokita Joe Okei-Odumakin ṣalaye wipe o yẹ ki opin de ba lilo awọn obinrin gẹgẹbii ohun elo amuludun nikan.
Ó bẹ̀rẹ̀ sí bọ Aṣitoreti, oriṣa àwọn ará Sidoni ati oriṣa Milikomu, ohun ìríra tí àwọn ará Amoni ń bọ.
O fidi rẹ mulẹ pe awọn ko tii ri awọn ajẹmọnu gba fun idije Afcon to n lọ lọwọ.
Oríṣun àwòrán, others Folarin Ademola sọ pe Obasanjo ko sọ pe oun naa ko da ẹṣẹ ri, ṣugbọn ti eeyan ba ri ootọ o yẹ ko le e sọ.
 adéolókun ló tún ń gbá rugby fún ikọ ̀ ( connacht ) ní pro14 .
Ki lo de ti ti Pasitọ Adeboye fi yatọ?
Ní ọdún náà, olukuluku yín yóo pada sórí ilẹ̀ rẹ̀ ati sinu ìdílé rẹ̀.
Abẹẹrẹ mi bọ sinu okun, Ọlọhuun yọ ọ pada fun mi.
Àwọn tí ń rìn ninu òkùnkùn ti rí ìmọ́lẹ̀ ńlá.
 fi aidunnu rẹ han lori bi
Gomina Ugwuanyi  so pe, irinajo ayipada si lilo ero igbalode ohun ko rorun to bee, amo a dupe pupo lowo ijoba apapo, ni paapaa minisita nipa erongba ati ifokan-jin won lori ise-akanse naa.
Irina ọfẹ oni wakati mẹta yii ti pari fun tonii ti wọn si ti bẹrẹ si ni gba owo pada ni apa afara Admiralty lagbegbe Ikoyi niluu Eko.
Ìwádìí fi hàn nínú àwọn tó ni, ní China àti Italy, àwọn orílẹ̀-èdè méjì tí aarun náà bá fà julọ.
    Lẹ́yìn èyí, mo pe iwin inú fìlà Fìlásayépọ̀ mo bẹ̀rẹ̀ si i ṣe ìbéèrè wọ̀nyì lọ́wọ́ rẹ̀: ‘Níbo ló wà nígbà tí ori i?
Nígbà tí ó yá, Dafidi ati àwọn ọmọ ogun rẹ̀ gbógun ti ìlú Jerusalẹmu.
End SARS, End SWAT: Ó pé mi bí SARS kò ṣe sọ mí dolówọ́- Fulani Kwajafa
Àwòrán mánigbàgbé BBC news Yorùbá fún ọ̀sẹ̀ yìí Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Kí ni àmì ohùn orí ''Aifagbafẹnikan' Lasiko eto isinku rẹ to waye ni gbọngan awọn lọbalọba nilu Ibadan ni ẹgbọ aṣofin naa Ọlajide Olatoye ti paroko ikilọ ranṣẹ si gomina Ajimọbi pe ko jawọ igbesẹ to ni o n gbe lati tu awọn afunrasi ti wọn mu fun iku ẹgbọn rẹ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Aeroplane House: Látọdún 1999 ni mo ti bẹ̀rẹ̀ kíkọ́ ilé yìí fún ìyàwó mi ọ̀wọ́n Nigba to pada dele, Oyinkan dara pọ mọ ẹgbẹ Girls Guides nilu Eko, to si n ṣiṣẹ kara lori eto ẹkọ ọmọbinrin, oun si tun ni obinrin akọkọ ti yoo wa ọkọ ayọkẹlẹ nilu Eko.
Alao Akala ni saa isejọba oun akọkọ ohun da awọn eto ilera alabode ẹsẹ kuku silẹ.
Bákan náà, ní ọdún 2010, ó gbé àpótí ibo láti dije fún gomina ipinle Osun labẹ ẹgbẹ oṣelu APC.
Nibayii, aarẹ Trump ti ko lara awọn ikọ ọmọogun orilẹede Amerika kuro ni Afghanistan, Iraq ati Syria.
Atẹjade kan lati aafin ọba naa lo fidi ọrọ yi mulẹ.
Lẹyin to ji owo rẹ tan, o tun gbe tẹlifisan, ati foonu, lo ba tun beere pe ko fi ẹnu fa nkan ọmọkunrin oun, irufẹ ere ibalopọ ti wọn n pe ni 'blow job'.
imo ijnle re ati iriri ti o ni ninu ere boolu afesegba, bee si ni a tun ni
Baba Ijeṣha ni Wọn pada ni ki oun kan duro soju kan lẹgbẹ Fathia Balogun to yẹ ko fọwọ leran lori itage, wọn ni ko ma sọ ọrọ kankan ko kan maa jo.
Wọ́n gba ilẹ̀ Samaria, wọ́n sì ń gbé inú àwọn ìlú rẹ̀.
Ẹ má ṣe di ẹrú eniyan mọ́.
Ọlọpa kan yinbọn mọ ọga rẹ nitori obinrin nipinlẹ Adamawa
Oba Folagbade Olateru-Olagbegi wàjà lẹ́ni ọdún 77 Ṣé ó tọ́ kí ilé asòfin buwọ́lù abàdòfin mẹ́fà tí Ààrẹ Buhari kọ̀ sílẹ̀?
Sadiq sọ pe “ijọba lagbara lati seto ofin ti yoo mu igbe aye idẹrun ba awọn  omo orile ede.
Ẹ dojú ìjà kọ Èṣù, yóo sì sálọ kúrò lọ́dọ̀ yín.
Oríṣun àwòrán, Facebook Àkọlé àwòrán, Toyin Abraham O ni to ba wa ni ẹnikẹni tabi eeyan keeyan to ba n binu tabi fapa jana, ki wọn o fi silẹ pe ki iru ẹni bẹẹ lee ri ogo Oluwa ninu aye ohun.
Èkínní ni pé ni ẹ̀gbẹ́ ògiri ilé náà ní apá ọ̀tún orúkọ gbogbo àìsàn tí ó lè pa ènìyàn ló wà nìbẹ̀ àti èyí tí ó kéré pátápátá lójú ẹni àti èyí ó ba ni lẹ́rù púpọ̀, gbogbo orúkọ wọn pé ṣánṣán sí ẹ̀gbẹ́ ògiri.
Àkọlé àwòrán, Ayelujara ti ẹnu kọlẹ ni Ethiopia Bakan naa ni ileeṣẹ Amẹrika sọ pe iroyin sọ pe iro ibọn n dun ni olu ilu Ethiopia, Addis Ababa.
Ọkan lara awọn ọrọ to fọnka ori ayelujara lẹnu ọjọ mẹta yii ni iroyin bi awọn ọdọ janduku kan ṣe ya wọ aafin Oba rilwan Akiolu ti ilu eko ti wọn si ji ọpa aṣẹ gbe lọ.
O ti le ni ọsẹ kan ti awọn ọdọ kaakiri Naijiria ti gunle ifẹhonuhan, lori bi awọn oṣiṣẹ ẹka to n gbogun ti iwa idigunjale ni ileeṣẹ ọlọpa, SARS, ṣe pa awọn eeyan lọna aitọ.
Deji Adenuga nigba ti o n ba akọroyin sọrọ ṣalaye pe nitori pe ọrẹbinrin oun gba ẹgbẹrun lọna ogun Naira lọwọ ohun ti o si kọ lati fẹ ohun loun ṣe dana sun ile pa awọn mọlẹbi rẹ.
Eyitayo ni awọn akanda to fẹ ṣe ere idaraya naa yoo ri iranwọ.
Ìfẹ́, ati ìkórìíra, ati ìlara wọn ti parun, wọn kò sì ní ìpín kankan mọ́ laelae ninu ohun tí ń ṣẹlẹ̀ nílé ayé.
Lóòtọ́ ni mo yìnbọn níbi yánpọnyánrin tó wáyé ládúgbò mi-Seun Kuti ''Buhari àti Tinubu ṣ'àdéhùn pé Yorùbá ni yóò jẹ́ olùdíje ipò ààrẹ APC lọ́dún 2023'' Àṣeyọrí Anthony Joshua fi hàn pé owó tí à ń ná lórí eré ìdarayá kò lọ lásán - Dapo Abiodun Ṣé lóòtọ́ọ́ làwọn ọlọ́ṣà tún gbẹ̀mí èèyàn kan ní Moniya, Ibadan?
Baba rẹ̀ bá a wí, ó ní, “Irú àlá rándanràndan wo ni ò ń lá wọnyi?
Bakan naa ni wọn ni awọn yoo pese abẹrẹ ajẹsara miliọnu aadọta ki ọdun yii to pari, ti awọn yoo si pese abẹrẹ ajẹsara biliọnu kan o le ni ọdun to n bọ.
Bí ẹnìkan ninu àwọn ọmọ Israẹli bá pa akọ mààlúù, tabi ọ̀dọ́ aguntan, tabi ewúrẹ́ kan ní ibùdó, tabi lẹ́yìn ibùdó, 
Solomoni kò wọn àwọn ohun èlò tí ó ṣe, nítorí wọ́n pọ̀ yanturu.
O ni igbesẹ yii yoo kọkọ bẹrẹ pẹlu papakọ ofurufu to wa ni ilu Eko ati Abuja.
Ní ọjọ́ kinni oṣù náà, gbogbo wọn pátá péjọ pọ̀ sí gbangba ìta níwájú Ẹnubodè Omi, wọ́n sì sọ fún Ẹsira, akọ̀wé, pé kí ó mú ìwé òfin Mose tí OLUWA fún àwọn ọmọ Israẹli wá.
Wọn gbọdọ ṣetan lati wa ojuutu si awọn iṣoro naa ki a lee kọ orukọ wọn sinu iwe iranti orilẹ-ede Naijiria.
Wọn gba pe abajade iwadii Anas ati BBC yoo ṣe atunṣe to yẹ si FIFA lagbaye ati ni ajọ ere bọọlu orile-ede kọọkan.
O sọ fun BBC ninu ifọrọwanilẹnuwo pe nigba ti wọn kọkọ mu Sarkin Waka nibẹrẹ ọdun yii, alaga ajọ to n fun awọn olorin ati elere ni lansẹẹsi ni ko si ọwọ oṣelu kankan ninu ohun to ṣe bikoṣe riru ofin.
ni ibeere ti o gba ẹnu awọn eeyan loju opo ayelujara Oríṣun àwòrán, Getty Images Diẹ lara ohun ti awọn eeyan n sọ re.
Olubadan ko jamo nkankan, awa naa le so pe Olubadan ko le ja mo nkankan lai si
O fi kun oro re pe, awon agbe ti iye won n lo bi egbefa ti won foruko sile lasiko ojo to koja, ni won janfaani orisirisi eso fun ogbin won.
Akanbi mi, má fọ̀ ọ́, mo wà pẹ̀lú ẹ; Ẹni tó ṣe ìgbéyàwó olórùka ló l'ọkọ- Lizzy Anjorin Ta ni Ebuka Obi-Uchendu tó ń gbàlejò BBNaija 2020?
Insurance Agency Bill, Nigeria Automotive Industry Development Plant Fiscal
Access Bank, dá ₦206,000 ìyá mi pádà lónìí, bí bẹ́ẹ̀ kọ́.
Lọjọbọ ni ẹgbẹ náà fi ọrọ yí síta lójú òpó Twitter wọn lẹyìn tí fónrán fídíò kan se àfihàn àwọn ọdọ tó n dunu níbi ayẹyẹ wọn ti Saraki ti kéde pé òun yóò dije ipò Ààrẹ Nàìjíríà Bukola Saraki fẹ́ rẹ ọmọ Nàìjíríà lẹ̀kún ní 2019 Buhari buwọ́ lu òfin ọ̀dọ́ leè dupò 'Èrò ọ̀dọ́ Kwara ṣọ̀tọ̀ọ̀tọ̀ lórí ọ̀rọ̀ Saraki' Ninu atejade naa, ẹgbẹ náà ni ojú gbà awon tí fún Saraki pẹlú bí ọ ti ṣe wù iru wa bẹẹ.
O súnmọ́ ọ̀dọ̀ mi nígbà tí mo pè ọ́,o dá mi lóhùn pé, ‘Má bẹ̀rù.
Ogbontarigi omo ogójì odun ohun, gba ami-ayo mẹ́rìnlélọ́gọ́jọ sagbon ninu ifesewonse mọ́kànlélọ́gọ́rin le lọ́ọ̀dúnrún(164 goals in 381 appearances) fun saa meji otooto ti o fi kopa fun iko agbaboolu Chelsea.
Àmì ohùn ṣe pàtàkì nínú èdè Yorùbá púpọ̀
Baaṣa kú, wọ́n sì sin ín sí Tirisa.
O ni ọwọ ko ni pẹ tẹ awọn janduku naa nitori iwadiii ti bẹrẹ lọgan ti iṣẹlẹ naa ṣẹlẹ.
Oniírúurú ènìyàn ní ń bẹ ní inu aayé, onígbèéraga kún inú ayé, ẹni tí kò ní owó ilé ilẹ̀ tí ó bẹ̀rẹ̀ pẹ̀tẹ́ẹ̀sì ti dé fìlà àimọ̀kan sí àtàrí.
“Nisinsinyii, OLUWA, jọ̀wọ́ jẹ́ kí ọ̀rọ̀ tí o sọ nípa èmi iranṣẹ rẹ ṣẹ, ati ti ìran mi lẹ́yìn ọ̀la, kí o sì ṣe bí o ti wí.
Ǹjẹ́ ọkunrin kan wà ninu yín tí ó ṣẹ̀ṣẹ̀ gbin ọgbà àjàrà, tí kò sì tíì jẹ ninu èso rẹ̀?
" Obinna Nwosu ni ti ẹ ni, ileeṣẹ NTA ko ni idagbasoke kankan lati ogun ọdun sẹyin.
Ilu Kabba nipinlẹ Kogi ni eto naa ti bẹrẹ lọjọ karun un oṣu kẹjọ, eto yii yoo tẹsiwaju di ọjọ kẹjọ oṣu kẹjọ ko to kasẹ nilẹ.
Buhari yóò báwọn ọmọ Nàìjíríà sọ̀rọ̀ lọ́la 'June 12' tí ṣe àyájọ́ ìjọba àwarawa Oríṣun àwòrán, Facebook/muhammadubuhari Aarẹ orillẹede Naijiria, Muhammadu Buhari yoo bawọn eeyan sọrọ lọjọ Ẹti, ọjọ kejila oṣu to ti di ayajọ ijọba awarawa bayii.
Nítorí náà, ọba kò gbọ́ ti àwọn eniyan náà, nítorí pé OLUWA alára ni ó fẹ́ kí ọ̀rọ̀ yìí rí bẹ́ẹ̀, kí ọ̀rọ̀ OLUWA lè ṣẹ, tí ó bá Jeroboamu ọmọ Nebati sọ, láti ẹnu wolii Ahija ará Ṣilo.
Ó dọ̀la o, kí Ọlọ́run jẹ́ kí a fi ire pàdé lọ́la.
Ọjọ nla ni ọjọ Kẹwaa, osu Kinni, ọdun 1949 nigba ti isẹlẹ nla kan waye nilu Efon Alaaye, to wa nipinlẹ Ekiti bayii Ọmọdebinrin kan to n jẹ Adediwura Ojo, tii se ọmọ ọdun kan ati osu mẹta, lo saadede poora ninu agbala baba rẹ to ti n sere.
Kí àwọn eniyan máa jáde lọ ní ojoojumọ, kí wọ́n sì máa kó ìwọ̀nba ohun tí wọn yóo jẹ ní ọjọ́ kọ̀ọ̀kan.
Jesu wí fún un pé, “O rí ilé yìí bí ó ti tóbi tó?
Joke Silva: Olu, ó tó gẹ́ pẹ̀lú obìnrin yìí níkan tó ń ba ẹ ṣeré ìfẹ́ nínú sinimá!
Joe Biden náà ti gba abẹ́rẹ́ àjẹsara Covid-19 Àwọn tó jí wa gbé fi tìpá-tìkúùkù bọ́ Hijab mi, wọ́n lù mí ní ìlù bàrà - ọmọ ọdún mẹ́rìndínlógún Kóníléógbélé ọlọ́sẹ̀ márùn ún gbáko ni ìjọba Nàíjíríà gbé kalẹ̀ fàwọn oṣìṣẹ́ lábẹ́ ìlànà Covid-19 tuntun Ìwádìí tú àṣírí Dókítà tó pa ìyàwó rẹ̀, ó fẹ́ pa ọmọ wọn méjì, òun fúnrarẹ̀ tún pokùnso Ṣé lóòtọ́ ni Bimpe Oyebade lóyún fún Lateef Oladimeji?
Oríṣun àwòrán, @others Àkọlé àwòrán, Aṣepari awọn iṣẹ akanṣe ti ijọba rẹ ti bẹrẹ tẹlẹ.
Khaffi a ma sọ ede maarun to fi mọ Yoruba ṣugbọn Yoruba rẹ ko dan mọran daadaa.
Sinimá tí Lateef Adedimeji dá nikan jẹ́ òṣèré yóò jáde, Yemi Solade fi ọ̀pọ̀ fọ́tò dẹngẹ pó"" lọ́jọ́ ìbí rẹ̀ Iṣẹ́ tíátà kìí jẹ́ kí obìnrin tètè rí ọkọ fẹ́, wọ́n maa n ro pé mo ti lajú jù - Aisha Lawal Ẹ wo àwòrán ìgbé àyé ààrẹ ilẹ̀ Kenya tẹ́lẹ̀rí, Arap Moi tó papòpà Àkọsílẹ̀ nípa okoòwò láàrin ilẹ̀ Áfíríkà àti UK Fídíò ìgbé ayé Arap Moi ree, olùfẹ́ aráàlú tó di òkúrorò aṣaájú ní Kenya Akọle ere ọhun ni Ọmọ Prime Minister."
alopo emeji dna double helix je gbigbero pelu ipa meji : awon ide haidrojin larin awon nukleotidi ati awon ibasepo ipele ipile larin awon ipilenukleu oloorundidun .
O sa kuro nile nigba ti o wa ni ọlọmọge pẹlu ireti wi pe yoo ri igbe aye to dun rọrun diẹ.
O ti to nnkan bi ọjọ mẹta kan ti eruku aawọ ti n waye laarin Oluwo ati awọn afọbajẹ naa to taku pe lilọ ni Oluwo gbọdọ lọ fun awọn.
Tabi, kí àwọn tí wọ́n wà níhìn-ín fúnra wọn sọ nǹkan burúkú kan tí wọ́n rí pé mo ṣe nígbà tí mo wà níwájú ìgbìmọ̀.
O ti ṣe agbekalẹ ile iṣẹ to n tale talẹ to si pe orukọ rẹ ni Lambo Homes.
Kii saba si iyatọ ninu bi pupọ awọn ipinlẹ to wa l'Amẹrika ṣe n dibo.
lo si abule Asola ti o wa nijoba ibile Tsafe Local Government Area (LGA), nibi
Aarẹ ẹgbẹ musulumi Shiite ni, ibanilorukọjẹ ni ọrọ ti ile iṣẹ ọlọpaa sọ pe Shiite lo ṣekupa ọga ọlọpaa Musa ati Owolabi.
Ẹ ranti ohun tí OLUWA Ọlọrun yín ṣe sí Miriamu nígbà tí ẹ̀ ń jáde ti ilẹ̀ Ijipti bọ̀.
Báyìí ni Jesu ṣe di onígbọ̀wọ́ majẹmu tí ó dára ju ti àtijọ́ lọ.
Awọn ẹṣọ aabo duro wamuwamu si ẹnu ọna ileeṣẹ ijọba ipinlẹ Ọyọ lati ṣe ayewo kaadi idanimọ gbogbo ẹni ti yoo lanfani lati ri aye wọlẹ si ofisi wọn.
olòṣì, ọ̀mọ̀we tàbi púrúǹtù ni kódà, àwọn ọmọdegan ń lòó.
Eyi si da awuyewuye to pọ silẹ lori ayelujara ti awọn eniyan si fọn foto naa ka sori ayelujara.
“Aare Muhammadu Buhari  ti pasẹ pe ki won gbe igbesẹ ni kiakia lori ọrọ
Tabi ki o tẹ iwe atẹjiṣẹ si adirẹsi yi loju opo ayelujara e-training@recruitment.
Èyí dín ewu kù púpọ̀ fún ẹni tí ń gun kẹ̀kẹ́ lójú títì.
“Alufaa yóo sì kó àwọn nǹkan wọnyi wá siwaju OLUWA, yóo rú ẹbọ ìmúkúrò ẹ̀ṣẹ̀ ati ẹbọ sísun rẹ̀.
Eji Gbadero, ọmọ Ibadan àti jayé-jayé ọmọ ónílẹ̀ ti wọn yẹgi fun l'Eko Ohun mẹ́fà tí ọ̀pọ̀ kò mọ̀ nípa ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ Arsenal àti Machester City Ènìyàn 653 míràn tún kún iye àwọn tó ní COVID-19 ní Nàìjíríà Afurasí tí Ọlọ́pàá ní ó pa Barakat, Grace àtàwọn míì l'Akinyele ti sọ̀rọ̀ pé.
Olódodo ni ọ́, OLUWA, ṣugbọn lónìí yìí ojú ti gbogbo àwọn ará Juda ati Jerusalẹmu, ati gbogbo Israẹli; ati àwọn tí wọ́n wà nítòsí ati àwọn tí wọ́n wà ní ọ̀nà jíjìn, níbi gbogbo tí o fọ́n wọn káàkiri sí nítorí ìwà ọ̀dàlẹ̀ tí wọ́n hù sí ọ.
Ìjàmbá iná míràn tún wáyé ní pápákọ̀ ojú omi Beirut Femi Fani-Kayode sọ̀kò ọ̀rọ̀ sí Tinubu tori kò dìde kí Ooni Ẹ fi dókítà àgùnbánirọ̀ rọ́pò àwọn dókítà tó ń yanṣẹ́ lódì - Ìjọba àpapọ̀ pàṣẹ Háà ilẹ̀ wẹ!
Ọlọrun yọ bí ọjọ́ láti Sioni,ìlú tó dára, tó lẹ́wà.
Iṣẹlẹ naa lo da jìnnìjìnnì bo awọn araalu naa, to si tun da omi alaafia ilu ru.
Loju awọn alatako rẹ, o jẹ oni gale gale eniyan to ko maa n sọ ọrọ to lee doju ti ni gidi gan atawọn ọr alufansa si eeyan (koda wọn ni o fẹran ko maa fa oorun ara irun obinrin simu).
Oríṣun àwòrán, Other Àkọlé àwòrán, Olorin takasufẹ Babalọla Falemi ti awọn eniyan mọ si Sinzu ni ijọba ilẹ Amerika ran lọ si ẹwọn dun meji lati ọdun 2016 si 2018 fun ẹsun ole jija, lẹyin to ji awọn kaadi ATM awọn eniyan, to si ji ọpọlọpọ owo ko to di wi pe ọwọ ba a.
 wọ ́ n kúkú ti sọ pé owó fúnni kò tó ènìyàn .
Bẹ́ẹ̀ ni wọ́n sì tí wọ́n sí tọ́jú bàbá mi tí wọ́n sì fi ìyàwó rẹ̀ tì í, tí wọ́n jọ ń gbé fún oṣù mẹ́ta kí ó tóó di pé ọba gbéyàwó fún wọn.
Bi Kìnìún ti lágbára tó ninú igbó, bi ó bá bú ramúramù, ohun gbogbo ninú igbó á pa kẹ́kẹ́ titi dé ori ẹranko yoku.
Nítorí omi ni Johanu fi ń ṣe ìwẹ̀mọ́, ṣugbọn Ẹ̀mí Mímọ́ ni a óo fi ṣe ìwẹ̀mọ́ fun yín láìpẹ́ jọjọ.
Ilẹ kaarọ oojiire ni awokọṣe fun gbogbo agbaye.
Ṣugbọn pupọ ninu wọn ni ko fi bẹẹ mọ awọn ore to n se fun agọ ara.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, N jẹ o ti jẹ ọkan ejo ri?
Ní àkókò náà, Jesu ń wo ọpọlọpọ eniyan sàn ninu àìsàn ati àrùn.
Mi ò gbèrò láti lọ fún sáà kẹ́ta gẹ́gẹ́ bí ààrẹ - Buhari Andrew Haruna: So-bàtà tó di ọ̀jọ̀gbọ́n fásitì tó tún jẹ́ ọ̀gá àgbà pátá (V.
3 billion lodun yii,ti owo ti won tun ya nibo miiran tun
Oríṣun àwòrán, Bola Tinubu 'Tinubu ta ẹmi rẹ, ta ọkan rẹ, to si ta gbogbo ilẹ Yoruba, to fi mọ Guusu ati Ariwa orilẹede Naijiria lati le ri wi pe oun mu gbogbo ero ọkan rẹ to kun fun ibi ṣẹ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Coronavirus in Nigeria: Ǹjẹ́ ṣé òògùn apakòkòrò le pa ààrùn coronavirus?
Yobo wa yanana idojuko ti iko ohun koju ni eka agbaboolu asole, pe iko naa yoo la idojuko ohun koja ti won yoo si fakoyo lorile-ede Russia.
Ní ọjọ́ keji, Mose wí fún àwọn eniyan náà pé, “Ẹ ti dẹ́ṣẹ̀ ńlá, n óo tún gòkè tọ OLUWA lọ, bóyá n óo lè ṣe ètùtù fún ẹ̀ṣẹ̀ yín.
Nígbà náà ni ẹ̀mí kan jáde, ó sì dúró níwájú OLUWA, ó ní, ‘N óo lọ tan Ahabu jẹ.
Nigba ti ẹgbẹ Congress ni ijoko mẹrinlelogoji pere lọdun 2014 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Mamata Banerjee to jẹ minista ẹkun iwọ oorun Bengal naa jẹ alatako gboogi fun Modi Oludibo miliọnu kan ni ọgọrin eeyan lo ni ẹtọ lati dibo lọdun yii ni India.
Rárá, àwọn tí wọ́n wà lórí odi náà wà lára àwọn tí mò ń bá sọ̀rọ̀.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, KHARTOUM, SUDAN - APRIL 13: Awọn eniyan korajọ lati ṣe ajọyọ niwaju olu ile iṣẹ awọn ologun lẹyin ti Minisita ọ̀rọ̀ abo, Ahmed Awad Ibn Auf kede pe oun fipo silẹ gẹg bi olori ẹgbẹ ọmọ ogun to boju to gbigbe ijọba le ẹlomiiran lọ́wọ́ ni Khatourm, Sudan.
Ìtẹ́ Ọlọrun ati ti Ọ̀dọ́ Aguntan yóo wà níbẹ̀.
Ni abule Udayankatu ti ijọba da silẹ fun eto ọgbin lẹyin ogun ni o ti pade ọkọ rẹ.
Géńdé agbébọn yabo àgọ́ ọlọ́pàá n‘Ibadan, ẹ̀mí ọlọ́pàá kan bọ́ Ọba Ilorin ló pàṣẹ pé kí ń padà sọ́dọ̀ ọkọ mi - Risikat olójú búlúù NCDC kéde èèyàn 340 míràn tó ṣẹ̀ṣẹ̀ lùgbàdì Covid-19 ní Nàìjíríà A fí ara mọ́ ìdájọ́ ikú Sharia tó tọ́ sí Olórin Yahaya- ẹgbẹ́ Amòfin Mùsùlùmí ẹ̀ka ìpínlẹ̀ Kano Coronavirus bí èso rere nílẹ̀ Adúláwọ̀, wo díẹ̀ lára èso náà.
Àní, kí ni ẹ lọ wò?
8 Ìgbé 2020 Oríṣun àwòrán, EPA Agbabọọlu Brazil tẹlẹ, Ronaldinho ti gba itusilẹ lọgba ẹwọn lorilẹede Paraguay.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìjọba Ọṣun: Ẹ sowọ́pọ̀ pẹ̀lú wa láti gbé Ọṣun Oṣogbo dé ibi gíga ní 2019 18 Òkùdu 2019 Oríṣun àwòrán, @osunosogbo2019 Ijọba ipinlẹ Ọsun ti fọwọ idaniloju sọya pe, didun ni ọsan yoo so lasiko ọdun Ọsun Osogbo ti yoo waye lọdun 2019 ta wa yii, ti ohun gbogbo yoo si lọ ni irọwọrọsẹ, eyi ti yoo jẹ iwuri fun gbogbo ọmọ orilẹede Naijiria.
Ó tún gbé igba ọdún ó lé meje (207) sí i láyé lẹ́yìn tí ó bí Serugi, ó sì tún bí àwọn ọmọ mìíràn lọkunrin ati lobinrin.
Ọjọ kẹwaa, oṣu kẹwaa, ọdun 2020 ni idibo sipo gomina ọhun yoo waye.
Ó sì mú Samuẹli lọ sí Ṣilo ní ilé OLUWA, ọmọde ni Samuẹli nígbà náà.
Ẹni tí ó bá ń hùwà burúkú, kí ó máa hùwà burúkú rẹ̀ bọ̀.
Bi o tilẹ jẹ wi pe wọn yoo ma a jabọ ohunkohun to ba n sẹlẹ lagbeegbe wọn fun Emir Sanusi, agbara kan naa ni wọn ni gẹgẹ bi Emir ilu Kano.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ladoja Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Koda, iwọde naa ko tu irun kan lara ijafafa iṣẹ ni ileeṣẹ yii nitori naa ko si ohun to jọ pe ina ọba yoo lọ kale-n-kako lorilẹede Naijiria loni.
Òkúta nlá yìí ní ibi méjì tí ó ga sókè jù ní igun méjéèjì.
Nígbà tí àwọn ará Aṣidodu rí ohun tí ó ń ṣẹlẹ̀, wọ́n ní, “Ọlọrun Israẹli ni ó ń jẹ àwa ati Dagoni, oriṣa wa níyà.
Wòlíì TB Joshua, Apostle Suleman, Wòlíì Odumeje, Pásítọ̀ D.
O ni awọn ko ba ma sọrọ lori iroyin ofege yi ṣugbọn awọn ṣe bẹẹ nitori ki akọsilẹ ba a le wa lọjọ iwaju.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Coronavirus: A kò nílò láti ti àwọn ilé ìwé àti ilé ìjọsin wa pa- Minista ètò ìlera 6 Ẹrẹ̀nà 2020 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, A kò nílò láti ti àwọn ilé ìwé àti ilé ìjọsin wa pa- Minista ètò ìlera Komiṣọnna fun eto ilera ni ipinlẹ Eko, Ojọgbọn Akin Abayomi ti kede iyasọtọ awọn mẹta miran lori iṣẹlẹ Coronavirus tuntun.
Yàtọ̀ sí Olúwó, wo àwọn Ọba alayé tó ti kọ ìyàwó rí láìpẹ́ nílẹ̀ Oodua Ààrẹ Muhammadu Buhari ti buwọ́lu owó ìṣúná ọdún 2020 Pope Francis wọ́gilé òfin tó n dáàbò bo àlùfáà tó bá bá ọmọdé l'òpọ̀ Wọ́n f'ẹ̀sùn ọkọ̀ jíjí kan Naira Marley; Ó ní òun ni Buhari yóò gbé ìjọba fún Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, '500 level'' ni mo wà nígbà tí mo di adélé Ọba' Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Eden Hazard wẹ̀ 'yan kàì-kàin níbi tí Chelsea ti na Brighton ní 1-2 16 Ọ̀pẹ̀̀ 2018 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Hazard jẹ bọ́ọ̀lù rẹ̀ kẹẹ̀jọ nínú ìdíje líígì Gẹ̀ẹ́sì níbi ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ pẹ̀lú Brighton Eden Hazard gbá bọ́ọ̀lù kan sí àwọ̀n ó sì ṣe sábàbí ọ̀kan yókù nínú ìfẹsẹ̀swọnsẹ̀ tí Chelsea ti na Brighton ní pápá ìṣeré Amex Stadium.
Agbekoya War: Ọta ìbọn kan ṣoṣo ló fa ogun tó fi ọ̀pọ̀ ẹ̀mí ṣòfò nínú ìtàn mánigbàgbé lẹ̀ Yorùbá
O sọ pe Oluwo kan tumọ ojuse olori ẹsọ Ọọni sodi lasan ni leyi to pọ̀n dandan fun un lati se fun ọga rẹ.
Egbẹ to ba maa bori lẹyọ kan tabi lafọwọsowọpọ gbọdọ ni ijoko ile mejilelaadọrin o le nigba ninu ọmọ ilé ti wọn jẹ mẹta le logoji o le ni ẹẹdẹgbẹrin.
Agbejọ́rò Dakolo:Mílíọ́nù mẹ́wàá náírà tí a béèrè kì í ṣe owó gbà má-bínú Irọ funfun báláwú ni, Boko Haram kò dawa lọnà rárá -Ọmọ ogun Naijiria Wike kò wó Mọṣáláṣi rárá o -Fayẹmi lórúkọ gbogbo Gómìnà Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Ijoba tun ti gbiyanju lati da awon eniyan yii pada si agbegbe won,nipa pipese ile-iwe,ile-iwosan , ile-itoju,ipese omi ati eto oro aje , ki won lee tete pada si ibugbe won.
Àwọn àgbààgbà bá dá a lóhùn pé, “Má dá a lóhùn rárá, má sì gbà fún un.
Soyombo ròyìn o fi ti, o ni ǹkan ti ẹni kan kò ba ti fẹ́ ki ekúte fẹnu kan ki olúwà rẹ o ma wulẹ̀ gbe e silẹ̀.
Àwọn èrò tí ń bọ̀ wá sì dá wọn lóhùn pé, “Jesu, wolii, láti ìlú Nasarẹti ti Galili ni.
2 9181 Orilẹede Cote d‘ivoire 133 0.
Omo ogun ofurufu Bashir Umar ni oṣiṣẹ alaabo to wa lẹnu iṣẹ lasiko ti ẹnikan gbagbe owo naa silẹ pẹlu awọn akẹgbẹ rẹ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Omolola Arohunmolase Welder: Mo ti fí iṣẹ́ 'Welder' gbayì láwùjọ, tó mo fi tọ́ ọmọ yanjú Bẹẹ lo tun sọ siwaju si pe ọpa aṣẹ naa ni ami atọna ninu ile aṣofin nitori oun ni abẹnugan maa n tẹle wọ inu ile, ati pe lẹyin ti ọpa aṣẹ naa ba ti joko tan ni awọn aṣofin yoo to gba pe ile naa ti joko.
Jiti Ogunye: Ìjọba àkóbá lológun gbé kalẹ̀ ni 1999
Sibẹ, awọn olori obinrin mi gba oriyin lọdọ awọn eeyan nitori pe wọn ko pẹ ọrọ sọ nipa ipenija to de bawọn fara ilu Angela Merkel ti Germany ko pẹ ọrọ sọ fara ilu pe ''ipenija nla ni arun naa jẹ'' Orile-ede rẹ se agbekalẹ aye ayẹwo ati iyasọ́tọ to tobi julọ ni gbogbo Yuroopu.
Jesu bá dáhùn pé, “Kìkì àwọn aguntan tí ó sọnù, àní ìdílé Israẹli nìkan ni a rán mi sí.
Lati ọjọ pipẹ, oogun to n gbogun ti aisan iba ni Chloroquine jẹ, botilẹjẹ pe awọn orilẹ-ede kan ti fi ofin de lilo rẹ.
Democracy Day: Àkójọpọ̀ àwòrán láti ìpínlẹ̀ Ọyọ, Ogun àti Kwara fún ìbúra gómìnà tuntun
Coronavirus in Africa: WHO ní ìwádìí ìmọ̀ ìjìnlẹ̀ yóò ṣèrànwọ́ láti pinwọ́ àrùn náà
OLUWA rán Balaamu pada sí Balaki pẹlu ohun tí yóo sọ.
Àyọrísí rẹ̀ ni pé ìmọ̀ tìrẹ mú ìparun bá ẹni tí ó jẹ́ aláìlera, arakunrin tí Kristi ti ìtorí tirẹ̀ kú.
"Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Black women live matters: Ọdún 2015 ní àwọn ọlọ́pàá pa India Kager láìní ìdí- Gina Best Yahaya Bello ni: ""A o tẹsiwaju pẹlu idibo abẹle yii."
 Ọjọ ́ tí kábíèsí dá ku oṣù kan péré .
Bisi Alimi: Ìyà mi rò pé n kò leè ṣe ni àmọ́ n kò ní ìfẹ́ abo ni mo ṣe fẹ́ akọ
Aare so pe: “Inu mi dun
Bakan naa lo parọwa pe ki gbogbo eeyan sọ ogun ayederu ẹda nkan ti a mọ si 'Piracy' di ogun àjùmọ̀jà.
Oríṣun àwòrán, @PastorEAAdeboye Bi o tilẹ jẹ pe awon kan dahun pe ṣaaju iṣejọba to wa lode bayii ni ijọ naa ti n seto awẹ ati adura ibẹrẹ ọdun.
"A ba gbogbo awọ́n to padanu eeyan lasiko iwde EndSARS kẹdun.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ẹ́ tú èékánná lọ́rùn Sowore, ẹ kò ní ẹ̀rí láti ba ṣẹjọ́ - Ẹgbẹ́ Amòfin Amẹ́ríkà Irú iṣẹ́ wo ní Funke Akindele rán sí Bukunmi Oluwasina, tó fa ariwo lórí ayélujára?
Àánú ati òtítọ́ a máa ṣe ètùtù fún ẹ̀ṣẹ̀, ìbẹ̀rù OLUWA a sì máa mú ibi kúrò.
Orísun: Unicef Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Yorùbá dùn lédè, ẹ máa sọọ́ Bẹẹ ba agbagbe, laipẹ yii ni ariwo sọ nigba ti Busọla sọ lori fọnran aworan kan pe Pasitọ Fatoyinbo ti ijọ COZA fi tipa ba oun ni ajọsepọ lọdun mẹrindinlogun sẹyin nilu Ilọrin lasiko ti oun si wa ni ọdọ.
 O tẹsiwaju pe irọ ni pe Ebenezer Obey wa ni ilu oyinbo."
Gẹgẹ bi gbogbo awọn ololufẹ Anthony Joshua naa ni amofin Keyamọ kii loju opo twitter rẹ, ṣugbọn kaka ki wọn dara pọ mọọ lati dawọ idunnu naa, ọrọ alufansa ni wọn fi daa lohun.
Ọkàn rẹ̀ tún le, kò sì jẹ́ kí àwọn ọmọ Israẹli lọ, gẹ́gẹ́ bí OLUWA ti sọ láti ẹnu Mose.
Oni lo di ọjọ kẹrin ti wọn ti n gbiyanju lati doola ẹmi ọmọde yii to ko si kanga.
Àkóràn to ń ṣòkunfà ààrùn yíì ni akọ ́ kọ ́ yàsọ ́ tọ ̀ ní ọdún 1947 .
Ibi tí ìjà náà ti bẹ̀rẹ̀ ni èyí: ìgbà tí kìnnìún bá béèrè nǹkan kan tí àgbọ̀nrín tí ó jẹ́ olórí agbáwo bá sì ń fi nǹkan náà fún un, a bẹ̀rẹ̀ si í ha àgbọ̀nrín ni èékán a sì máa fà á mọ́ra bí ẹni pé ó ń fẹ́ẹ́ pa á jẹ, a wí pé òun ń bá àgbọ̀nrín ṣiré; nígbà tí ó ṣe, ara àgbọ̀nrín kò gbà á mọ́ ó sì fi kìnnìún sun ọkọ ìyàwó, ọkọ ìyàwó sì bá alága náà wí.
Ireti wa pe aarẹ ati awọn isọngbe rẹ, ninu eyi ti a ti ri minisita fun ọrọ ilẹ okeere, Geoffrey Onyeama ati oludamọran pataki fun aarẹ lori eto aabo, Babagana Monguno yoo pada si orilẹede Naijiria lẹyin ayẹyẹ ọun lọjọ isẹgun.
Ẹ jí lójú oorun, ẹ̀yin ọ̀mùtí,ẹ sọkún tẹ̀dùntẹ̀dùn,gbogbo ẹ̀yin tí ẹ̀ ń mu waini,nítorí waini tuntun tí a já gbà kúrò lẹ́nu yín.
O ṣalaye pe lẹyin agbeyẹwo awọn ikọlu to waye lasiko iwọde naa lawọn ibikan nipinlẹ Eko ni wn se ipinnu ọhun.
Pásítọ̀ gún ìyàwó rẹ̀ lọ́bẹ nínú ṣọ́ọ̀ṣì, ló bá tì í bọ ara rẹ̀ náà níkùn Ènìyàn 544 ni èsì àyẹ̀wò fihàn pé ó tún ti ní ààrùn Coronavirus ní Nàìjíríà Mo ti bá ọmọ ọwọ́ mẹ́ta lòpọ̀ sẹ́yìn, ọmọ oṣù mẹ́ta ló ṣìkẹrin - Afurasí jẹ́wọ́ Obìnrin kan wọ gàù lẹ́yìn tó kan ìṣó mọ́ ọmọ ọ̀dọ̀ rẹ̀ ẹni ọdún mẹ́wàá lórí Gẹgẹ bi a se gbọ, ede aiyede na da lori iwa agbere, eyi to yọri si kiko ẹṣẹ bo ara ẹni.
eto ijoba tiwa-n-tiwa  ni ọjọ kọ́kàndínlọ́gbọ̀n,
Hram, oun lo n lọwọ ninu iwa ibaje, igbesunmomi , iwa adigunjale ati iwa
Ojú ọ̀run ti ṣí sílẹ̀, Ọlọrun sì ń tú ibinu rẹ̀ sórí gbogbo eniyan nítorí ìwà ẹ̀ṣẹ̀ ati ìwà burúkú tí wọn ń hù, tí wọ́n fi ń ṣe ìdènà fún òtítọ́.
Àwọtẹ́lẹ̀ ọkùnrin àti Ìdọ̀tí Kilo méje ṣekú pa Ìgalà Ẹ wo iye t'óúnjẹ dà báyìí lọ́jà lẹ́yìn tí ìjọba ti ibodè Ẹ̀wọ̀n oṣù mẹ́ta àti #3,000 ni awakọ̀ tí kò bá ní ‘speed limiter’ yóò fi jura- FRSC Missing Child: Òbí àti asọ́nà ṣọ́ọ̀ṣì 14, lọ́ búra nì'dí imọlẹ̀ l'Akure Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí 2 sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 2:23 Fídíò, Water Generator: Ó leè ṣiṣẹ fún wákàtí mẹfà, kó tó sinmi, Duration 2,2310 Òkùdu 2020 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
Nísàlẹ̀ àwọn yàrá wọnyi, ọ̀nà kan wà ní apá ìlà oòrùn bí eniyan bá ti ń bọ̀ láti ibi gbọ̀ngàn ìta.
Eyi difa fun pe wọn yoo yan ninu ijọba to n kọ nkan amayedẹrun ati ijọba to n ṣamojuto eto ọrọ aje.
Wọn mbẹ Oníṣègùn, wọn ò bẹ Aláìsàn
Ahọ́n iná kò ní jó ọ run.
Ọ̀rọ̀ tèmi kò jù báyìí lọ 
“Ìṣọdẹ-àjẹ́ kò jẹ́ tuntun ní Jharkhand,” Prem Chand, Olúdásílẹ̀ àti Alága Free Legal Aid Committee  ní Jharkhand, sọ nínúu ìfọ̀rọ̀wánilẹ́nuwò orí ẹ̀ro-ìbánisọ̀rọ̀ kan.
Góòlù pọ̀ ní ìlú Madaka ṣùgbọ́n wọn kò ní ọ̀nà fún ọgọ́rùn ún ọdún Ta ni ìgbẹ́jọ́ ìbò gómìnà Ondo yóó gbè nínú Akeredolu àti Jegede?
Dapo Abiodun wà lára àwọn tó ta ohun ìjà olóró fún mi - Amoṣun Buhari san lára owó àjẹmọ́nú Super Eagles!
Alukoro fun isẹ ọlọpaa ni ipinlẹ Kaduna, Muktar Aliyu salaye wi pe, 'A o mo ohun to fa ija naa sugbọn a ti dẹkun rẹ.
Bakan naa ni Oba Alowolodu Adeyemi Kinni, tii se baba fun baba Oba Adeyemi naa jọba laarin ọdun 1876 si 1905, to si lo ọdun mọkandinlọgbọn lori oye.
Pẹlu iye awọn eeyan tuntun yii, o ti pe 57, 437 eeyan to ti ni arun naa l'orilẹede Naijiria bayii.
Ó tún sọ bí òun tí ṣe ro ẹjọ́ òun níeájú àwọn ẹranko tí ó sì fi di pé wọ́n fún òun ní ẹ̀bún àti máa gbóhùn àwọn ẹranko àti àwọn ẹyẹ, àti bí wọ́n sì ti kìlọ̀ fún pé ní ọjọ́ tí òun bá sọ àṣírí náà fún ẹlòmíràn ni òun yóò kú.
Ẹni tí kì í báá yára bínú lóye lọpọlọpọ,ṣugbọn onínúfùfù ń fi ìwà òmùgọ̀ rẹ̀ hàn.
”Okan lara noosi ile iwosan so pe,“Gbogbo ero
Ọpọ awọn iwe iroyin abẹle lorilẹede Naijiria nigba naa ni wọn royin bi Abba Kyari ṣe n lo agbara aarẹ Buhari lati ti awọn ohun ti Oṣinbajo ba beere fun inawo si ẹgbẹ kan Awuyewuye pe Abba Kyari n toju bọ ọrọ to nii ṣe pẹlu abo orilẹede Naijiria.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Police Brutality: Ojú mi rí tó lọ́wọ́ ọlapàá nítorí Múrí màrùn ún- Adebayo Olaide Lara awọn ti wọn yi idajọ iku pada si ti ẹwọn gbere fun ni Muhammed Abdulkadir; Moses Akpan ati Sunday Okondo.
Awon gomina lorile ede Naijiria yoo tun sepade pọ, lonii yii to je ojo Isegun lati fohun-sokan lori ekunwo owo  osu awon osise.
Ilẹ̀ aṣálẹ̀ ni ó ń gbé títí di àkókò tí ó fara han àwọn eniyan Israẹli.
O si ti kọlu awọn oṣiṣẹ eto aabo, ileesẹ aṣoju orilẹ-ede ati ileesẹ iwe iroyin.
Bi o tilẹ jẹ pe mo lọ tikọ saaju lati gba fun, amọ nigba to ya mo fun ni nọmba mi, ta si bẹrẹ si ni sọrọ lọsan loru, to si n yọ mi lẹnu pe oun fẹ ba mi dọrẹ pọ.
Ṣé ogún mi ti dàbí ẹyẹ igún aláwọ̀ adíkálà ni?
Atamatase omo orile-ede Serbia ohun fagbahan akegbe re, leyin ti Dzumhur ko tesiwaju mo lataari ifarapa ti o ni lasiko ikolu awon mejeeji.
Ati igba naa ni oogun Tramadol ti n se isẹ ki sẹ lara rẹ.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ikọlu awọn ole aji maluu ti n di tọrọ fọnkale ni ipinlẹ Zamfara.
Ẹni tí ó bá wà lóko yóo kú ikú ogun.
Bí ẹ bá ti ká èso olifi yín, ẹ kò gbọdọ̀ pada sẹ́yìn láti ká àwọn èso tí ẹ bá gbàgbé.
O ni 'orilẹede Indian ati China ṣi n ṣe amulo awọn aṣa wọn, lai fi ohunkohun ti ẹnikẹni ba sọ ṣe.
Wo ọkùnrin tó fipá bá ìyá ọdún 60 lò nítorí 'ìkébè rẹ̀ tó ń mì Ìjọba ti wọ́gilé, ètò ìgbéyàwó tó le ni 4000 nítori Covid-19 Ẹwẹ, eeyan 18,203 lo ti ri iwosan gba ti wọn si ti ja ajabọ lọwọ ajakalẹ arun naa.
Bo tilẹ jẹ pe Toyin ti tuuba pe aimọkan lo faa, ati pe eeyan ẹlẹran ara ni oun, to si ti bẹrẹ si ni lo #EndSars loju opo Twitter rẹ, sibẹ eebu ni oun ati awọn ololufẹ rẹ kan ṣi n bu ara wọn lori ọrọ naa.
Ó wù mí kí ọwọ́ òsì rẹ̀ wà ní ìgbèrí mi,kí ó sì fi ọwọ́ ọ̀tún rẹ̀ fà mí mọ́ra.
Ó wá sọ fún wọn pé, “Ẹ̀yin ni ẹ̀ ń dá ara yín láre lójú eniyan, ṣugbọn Ọlọrun mọ ọkàn yín.
Obinrin yìí bí ọmọkunrin, tí yóo jọba lórí àwọn orílẹ̀-èdè pẹlu ọ̀pá irin.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ọ̀wọ́ngógó epo bẹntirò: NNPC ni 'ìròyìn ẹlẹ́jẹ̀' ni 14 Ìgbé 2019 Àkọlé àwòrán, Awọn eniyan yii n gba ọna ẹburu ta epo ni ilu Eko Ile isẹ to n pese epo bẹntiro lorilẹ-ede Naijiria, NNPC ti kesi awọn ọmọ Naijiria pe iroyin ẹlẹjẹ ni ọwọngogo epo lorilẹ-ede Naijiria.
Àkọlé àwòrán, Ṣọ́ọ̀bù àti ọkọ lóríṣiríṣi ni wọ́n bàjẹ́ lásìkò tí àwọn agbébọn naa kọlu àdúgbò náà Ọpọlọpọ ọkọ ati sọọbu lawọn janduku naa bajẹ.
 bí àkóràn àrùn náà bá ṣe òkùnfà àyípadà àwọ ̀ ẹni sí àwọ ̀ ìyeyè , tó bá ní ìkùnà kídìnrín , tó sí ń da ẹ ̀ jẹ ̀ lára , a ń pe èyí ní àìsàn weil .
Fún akiyesi, ilé iṣẹ́ ti ó n pèsè iná mọ̀nàmọ́ná, owó ti Ìjọba àpa-pọ̀ ba pin lati pèsè iná mọ̀nàmọ́ná fún gbogbo ará ilú, ọ̀gá ilé-iṣẹ́ á pin pẹ̀lú àwọn Ìjọba Ológun tàbi Òṣèlú Alágbádá.
Ikọ̀ naa yoo si maa ṣiṣẹ pọ pẹlu ileeṣẹ ọlọpaa, Ẹgbẹ awọn ọkọ akẹru, ati ajọ to n mojuto igboke-gbodo ọkọ̀ nipinlẹ Eko (LASTMA) lati ri i daju pe aṣẹ naa fidimulẹ.
ti Ipinle Oyo wa bayi dara ju bi isejoba oun se ba lọ.
Adari ipolongo Aarẹ Buhari, Festus Keyamo, fesi pe kii se asia ẹgbẹ APC ni o wa lori ẹrọ ayelujara, ati wi pe awọn alatako lo n tiraka lati ba isẹ awọn jẹ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Buhari: Màá sisẹ́ fún ààbò àti àgbéga ẹkùn wa 1 Ògún 2018 Oríṣun àwòrán, @BashirAhmad Àkọlé àwòrán, Kete ti awọn olori orilẹ-ede lẹkun iwọ oorun Afrika pari ipade ajọ Ecowas naa, ni wọn kede Buhari gẹgẹ bii alaga wọn tuntun.
Se Aarẹ Trump ni igbagbo ninu ayipada oju ọjọ (Climate Change)?
Niṣe ni awọn agbofinro mu Hajar Raissouni ati afẹsọna rẹ nigba ti wọn jade lati ile iwosan awọn alaboyun kan ni ilu Rabat loṣu Kẹjọ.
Àwọn Ohun Ìrúbọ Gbọdọ̀ Jẹ́ Mímọ́.
Bákan náà, yóo fi ìka wọ́n ẹ̀jẹ̀ náà siwaju Àpótí Ẹ̀rí nígbà meje.
Saaju ni ìgbìmọ aláṣẹ ìjọba ìpínlẹ̀ Kaduna ṣe ìpàdé kan ti igbimọ aláṣe si fẹnukò pé kí wọn mú àdínkù bá iye wákàti tí ètò kóníléógbélé yóò fi wà.
Yóo yọ gbogbo ọ̀rá ewúrẹ́ náà, bí wọ́n ti ń yọ ọ̀rá ẹran tí wọ́n bá fi rú ẹbọ alaafia, alufaa yóo sì sun ún níná lórí pẹpẹ gẹ́gẹ́ bí ẹbọ olóòórùn dídùn sí OLUWA.
Nígbà náà ni Maria dé, ó mú ìgò kékeré kan lọ́wọ́.
OLUWA Ọlọrun rẹ sì ti ṣèlérí fún ọ pé ìwọ ni o óo máa ṣe olùṣọ́ àwọn ọmọ Israẹli, eniyan òun, tí o óo sì jọba lé wọn lórí.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Police Recruitment: Ìlé ẹjọ́ ti pàsẹ pe ki ilé iṣẹ́ ọ̀lọ́pàá dá ìgbaniwolé dúró 24 Ọ̀wàrà 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Police Recruitment: Ìlé ẹjọ ti pasẹ pe ki ilé iṣẹ́ ọ̀lọ́pàá dá ìgbaniwolé Ilé ẹjọ́ gígá nílùú Abuja ti pàsẹ pe ki àjọ ọlọpàá dá ètò ìgbànisísẹ́ ẹgbẹ̀run mẹ́wàá ti wọ́n ń ṣe lọ́wọ́ dúró.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Yoruba Nollywood: Àgbà òṣèré tíátà, Musiliat Arikeusola 'Osuntoun' jáde láyé 2 Ògún 2020 Oríṣun àwòrán, OTHER Iku tun ti mu ọkan gboogi laarin awọn agba oṣere tiata Yoruba lorilẹede Naijiria, Alhaja Musiliat Arikeuọọla ti ọpọ mọ si Ọṣuntoun lọ.
"\""Next Level\"" Ààrẹ Buhari àti APC ló gbòde báyìí"
Wọ́n wá láti ilẹ̀ òkèèrè,láti ìpẹ̀kun ayé.
Oríṣun àwòrán, @dabiodunMFR Agbẹnusọ fun gomina ipinlẹ naa, Kunle Somorin lo kede bẹẹ ninu atẹjade kan to fi sọwọ si awọn akọroyin.
Awọn miran tilẹ se onkaa tiwọn lati ogun si mẹẹdọgbọn, eyi to mu ki ori ọpọ ọmọ Naijiria gbona.
Ó tún kí wọn pé, “Alaafia fún yín!
Mí o mọ ǹkan kan nípa fọ́nran ìpolongo COZA- Davido Wo àwòràn ohun tó ṣẹlẹ̀ nílé ìjọsìn Sotitobire tí wọ́n sun ní àná Ọlọ́pàá bẹ̀rẹ̀ ìwadìí lórí ikú olùṣirò owo táwọn agbénipa pa ní Ikorodu Gbajue ń lọ orúkọ mi láti gba owó- Mama Rainbow Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, '500 level'' ni mo wà nígbà tí mo di adélé Ọba' Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Kete ti wọn kede pe o ti di lilo ni awọn ile itaja kan ni agbegbe Newfoundland, bẹrẹ si ni ta a ni ọ̀gànjọ́ oru.
Diẹ ree ninu wọn: Minisita Amaechi ati ọrọ pe Naijiria fẹ jọwọ ominira fun China Nigba ti Minisita feto irina ni Naijiria Rotimi Amaechi n ṣalaye idi ti owooya lọwọ China ṣe ṣepataki si ọrọ kan lu ago leti awọn ọmọ Naijiria.
Alake fi orí oye rẹ silẹ, o tun fi Ẹ̀gbá silẹ.
BBC n gba awọn eeyan ni imọran lati ṣọra nipa pinpin iroyin ofege kaakiri.
7 174 Orilẹede Mongolia 2 0.
Nígbà tí mo pa gbogbo àkọ́bí ní Ijipti ni mo ti ya gbogbo àkọ́bí ninu àwọn ọmọ Israẹli sọ́tọ̀ láti jẹ́ tèmi.
Ọkùnrin kan kú lẹ́yìn tí wọ́n lù ú 'fún pé ó ní coronavirus' Iye nọmba yii kere si ti awọn ilẹ̀ nmiran bii Yuroopu, Asia, ati America nibi ti nọ́mba awọn miran si n pọ sii.
eleyi ti o sokunfa idi ti opo awon omo orile-ede Naijiria se n fojusona lati lo
Bakan naa ni iroyin lọ kaakiri nigba kan naa lorilẹede Naijiria to fẹsun kan Abba Kyari nigba naa pe o n lo anfani bi o ṣe sunmọ aarẹ Muhammadu Buhari lati maa fi jẹ gaba le igbakeji aarẹ, Yẹmi Oṣinbajo lori.
Oríṣun àwòrán, @PoliceNG Àkọlé àwòrán, Tubu (SARS) wà lára àwọn ọgbà ẹ̀wọ̀n tí wọn yóò wò.
Ni nkan bii osu kan sẹyin, ni lawọn ikọ Boko Haram ji awọn akẹkọ yii gbe nilu Dapchi nipinlẹ Yobe to wa lẹkun ila oorun ariwa orilẹede Naijiria.
Hẹrọdu ati àwọn ọmọ-ogun rẹ̀ ń kẹ́gàn rẹ̀, wọ́n ń fi í ṣe ẹlẹ́yà.
Ṣugbọn jẹ́ olóòótọ́ dé ojú ikú, Èmi yóo sì fún ọ ní adé ìyè.
Watch the #AFCON2019 live >> https://t.
Maṣẹ gbe ọrọ ọlọrọ lori Oríṣun àwòrán, Genesis Global Lara awọn iwaasu manigbagbe ti wolii Oladele ti ṣe ni bo ṣe maa n kọ awọn ọmọ ijọ rẹ lati foju si iṣẹ wọn, ki wọn si ma sọrọ ẹnikeji lẹyin.
Lára èyí ni gbogbo òfin tí ó de obìnrin ní ti ìbálòpọ̀ àti ẹ̀tọ́ ọmọ bíbí wà.
83 trillion kalẹ̀ Aarẹ Muhammadu Buhari gbe abadofin iṣuna ti o din diẹ ni triliọnu mẹsan naira kalẹ fun ọdun 2019.
Kí lo fẹ́ mọ̀ nípa D.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ronaldo Brazil làgbà gbogbo agbábọ́ọ̀lù, kì í ṣẹgbẹ́ ẹ Messi àti Ronaldo- Roberto Carlos 21 Èbibi 2020 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ronaldo Delima gba gbajugbaja ami ẹyẹ Ballon d'Or lẹẹmeji, o si tun gba ife ẹyẹ agbaye lọdun 1994 ati 2002.
Aretha Franklin: Gbajúgbaja olorin Amerika jáde láyé
,eyi ti awon omo ogun olote naa fi se ibudo leyin ti awon molebi won  san owo idasile eyi ti o to egberun lona aadofa owo dola.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Dele Momodu : Lẹ́yìn Buhari àti Atiku, èrò ọjà làwọn olùdíje yóòkù ní ìdìbò 2019 Ikede yii waye ni aadọta ọjọ lẹyin ti wọn ṣe ibura fún aarẹ Mohammadu Buhari.
Kolade Johnson; Iléeṣẹ́ ọlọ́pàá ní ọwọ́ ti tẹ àwọn afurasí ọlọ́pàá tó ṣekúpaá #EndSARS lu ayélujára pa lórí ikú Kolade Johnson SARS já wọ ilé àwọn akẹ́ẹ̀kọ́ fásitì Akungba Ninu atẹjade kan ti alukoro ile iṣẹ ọlọpaa nilu Eko,Bala Elkana fi sọwọ sawọn akọrọyin o salaye pe Adajọ ile ẹjọ kekere to wa ni Ebute Meta,Adajọ A.
O ni Trump n ṣi ipo rẹ lo, ti o si n ṣe atilẹyin fun awọn to n ṣe iwode tako iṣẹkupani Floyd bii aarẹ tẹlẹri, Barack Obama ṣe ṣe nigba ti o wa ni ipo.
Yatọ si ọgba fasiti naa ti yoo wa ni Daura, wọn yoo tun ṣe gabekalẹ fasiti miran si ipinlẹ Rivers tii ṣe ilu Minisita fetro irinna Naijiria lọwọlọwọ Rotimi Amaechi.
Alufaa yóo ṣe ètùtù fún gbogbo ìjọ eniyan Israẹli, a óo sì dáríjì wọ́n nítorí pé àṣìṣe ni; wọ́n sì ti mú ẹbọ sísun ati ẹbọ ìmúkúrò ẹ̀ṣẹ̀ wá fún OLUWA nítorí àṣìṣe wọn.
Premier League Top Scorer: Aubameyang, Mane àti Salah gba Golden boot
Gbọ́ OLUWA, nígbà tí mo bá ń kígbe pè ọ́;ṣàánú mi kí o sì dá mi lóhùn.
Nígbà tí ó dé ààfin Ọba, ó kí Ọba pẹ̀lú ìdọ̀bálẹ̀, ó sọ fún Ọba pé òun ni ó yẹ kí Ọba dá lọ́lá torí pé òun ni òun pa abuké Ọba.
Orúkọ ìnagijẹ mẹ́jọ tí wọ́n fi ń pe Abiola Ajimọbi nígbà ayé rẹ̀.
O yẹ kí gbogbo Ọba Alade fi òrìṣà silẹ̀ fún ará ìlú, Ọba to ba ti gbe Ade sori ko gbọdọ bọ oriṣa.
Tí a fiṣọwọ́ ní 18:37 4 Ọ̀pẹ̀ 202018:37 4 Ọ̀pẹ̀ 2020 Wo ọ̀nà tóo lé tọ̀ láti gba físà tóo bá fẹ́ ṣiṣẹ́ ní UK lábẹ́ ìlànà tuntun Ijọba UK ti gbe ilana tuntun jade lori bi awọn eeyan ṣe le gba iwe irinna ilẹ naa lẹyin to yapa kuro ni EU.
Gómìnà mẹ́rin yóò jẹ́jọ́ lẹ́yìn sáà wọn - EFCC Adari awọn to n ja fun idasilẹ orilẹ-ede Biafra naa fikun wi pe, ki ijọba apapọ ko ṣe ifẹ inu wọn o, ati wi pe ọmọbibi Ilẹ Gẹẹsi ni oun, ti ko si ẹ ni to le ṣe oun basubasu.
Nípa bẹ́ẹ̀ yóó la ifun ara rẹ̀ sí ìta.
Nígbà tí ọjọ́ meje náà fẹ́rẹ̀ pé, àwọn Juu láti Esia rí Paulu ninu Tẹmpili.
Drone àti CCTV ni yóò máa ṣọ́ ọ̀pọ̀ igbó tó wà nílẹ̀ Yorùbá - Ooni A kò ní ṣe ìwọ́de mọ́ torí a ti gbé ìjọba lọ sílé ẹjọ́ - Shiite kéde fáráyé Òpópónà márosẹ̀ Eko sí Ibadan tún dí pa lásìkò tí ọkọ̀ epo dànù Amọ agbẹjọro asofin naa, Olumide Ogunje ni awọn n lọ si ile ẹjọ kotẹmilọrun.
 nígbà tí àjẹsára yìí kò bá péye fún àwọn ọmọdé ní ọ ̀ pọ ̀ ìgba , ó ṣeéṣe kí àìsàn cogenital rubella pọ ̀ síi , pàápàá jùlọ bí àwọn obìrin bá ṣe ń bímọ síi láì jẹ ́ wípé wọ ́ n gba àjẹsára tàbí kó àrùn náà .
Amọ ti aarẹ ba buwọlu u yoo mu abadofin naa da ofin, nitori naa a le lo iwe lati fi se awọn ohun elo ti a le gbe nkan si inu rẹ.
 irúfẹ ́ ilé ìgbé méjì ni ó wà ní àdúgbò náà , àkọ ́ kọ ́ ni bódìjà ayé àtijọ ́ àti bódìjà tìgbàlódé , bẹ ́ è sì ni ó tún jẹ ́ ilé ìgbé fún ọ ̀ pọ ̀ lopọ ̀ ilé ìwé tí ó wà ní agbègbè náà .
Fún àwọn to sì fẹ wọ́ ilé Ẹ̀kọ́ gíga, ìdẹnukọlẹ ọ̀rọ̀ ajé yìí le jẹ́ ki wọ́n sún ìwọlé síwájú, nítori kò si owó ti wọ́n yóò fi ṣètò náà.
Amọ, Chelsea fakọyọ ni ti wọn lẹyin ti fagba han Crystal Palace pẹlu ami ayo meji sodo.
Bàbá ọmọ tí Mammadou Gassama dóòlà ẹ̀mí rẹ̀ rẹ́wọ̀n he ní France
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìjọ Hàkíkà: O leè sùn ti ìyàwó mi, kí ń sùn ti tìrẹ 31 Agẹmo 2018 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Asaaju ẹgbẹ Tijjaniyya ti ta kete si ẹgbẹ Hakika yii, ti wọn si ni awọn ko ba wọn se rara.
 Ó le ní ọgọ ́ ruǹ-ún aṣojú fún ìgbèríko kọ ̀ ọ ̀ kan .
Folúkẹ́ ní ojoojúmọ́ ni Ọ̀sányìnnínbí máa ń wá sọ́dọ̀ Orímóògùnjẹ́ nígbà tí Orímóògùnjẹ́ ń sàìsàn ó sì máa ń dúró di ìgbà tí wọ́n bá ń pèrun alẹ́ kí ó tó kúrò ní ọ̀dọ̀ rẹ̀.
Ni bayii, pipadanu ife-eye idije FA ohun sowo iko agbaboolu Chelsea, lo fihan pe, iko agbaboolu Manchester United pari saa yii lai gba ife-eye kankan.
Àwọn ni ó wu Ọlọrun pé kí wọ́n mọ ọlá ati ògo àṣírí yìí láàrin àwọn tí kì í ṣe Juu.
Kí ló fà ogun Ìjàyè àti ìṣubú Kurunmi, ìfẹ́ ìlú ni àbí orí kunkun?
Ònlo Weibo Long Zhigao ya àwòrán ìròyìn orí WeChat ti rẹ̀ ní orí Weibo ní ìfihàn àríyànjiyàn.
owo naira márùndínláàdọ́jọ (N145) si ogóje naira
Àwọn ọjọ́ Purimu wọnyi kò gbọdọ̀ yẹ̀ láàrin àwọn Juu, bẹ́ẹ̀ ni ìrántí wọn kò gbọdọ̀ parun láàrin arọmọdọmọ wọn.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ọmọge Campus fayé sílẹ̀ ní Canada 16 Èbibi 2018 Àkọlé àwòrán, Oniruuru ere ori itage ni Aisha Abimbọla ti se sita Gbájú-gbajà òsèré tíátà obìnrin, Aisha Abimbọla, tí ọ̀pọ̀ èèyàn mọ̀ sí ‘Ọmọge Campus’ tí jáde láyé ní orílẹ̀èdè Canada.
Angẹli OLUWA gbéra láti Giligali, ó lọ sí ọ̀dọ̀ àwọn ọmọ Israẹli ní Bokimu, ó sọ fún wọn pé, “Mo ko yín jáde láti ilẹ̀ Ijipti, wá sí ilẹ̀ tí mo ti búra fún àwọn baba ńlá yín pé n óo fún wọn.
Oríṣun àwòrán, @LagosSarsPanel Nigba ti alaga fun un laaye, lo ba kọju si ọkan lara awọn ọlọpaa to wa ni ijoko, Ọgbẹni Joseph Ebosereme pe o fiya jẹ oun lọna aitọ.
Irinajo ti ko lọpẹ ninu ni olukọni iks Manchester United, Ole Gunner Solkjaer ko awọn agbabọọlu rẹ rin lọ si papa iṣire.
Lẹ́yìn ìlú mẹfa yìí, ẹ óo tún fún wọn ní ìlú mejilelogoji pẹlu ilẹ̀ tí ó yí wọn ká.
Àkọlé àwòrán, Wọn ni ọwọ awọn panapana ti ka ina naa Lẹyin wakati mẹsan an ti ina naa ti n jo ni wọn ṣẹṣẹ n kapa ẹ.
Ọba sọ fún un pé, “Má wulẹ̀ san owó kankan, àwọn eniyan náà wà ní ìkáwọ́ rẹ, lọ ṣe wọ́n bí o bá ti fẹ́.
Amọṣa lẹyin o rẹyin ni iroyin jade pe ibọn ba Ifeanyi Okereke, ọkan lara awọn fẹndọ to n ta iwe iroyin ni sẹkitariati ijọba apapọ ni lu Abuja ti o si jade laye.
OLUWA Ọlọrun ní, “Ègbé ni fún àwọn òmùgọ̀ wolii tí wọn ń tẹ̀lé ìmọ̀ ara wọn láì jẹ́ pé wọ́n ríran rárá.
Bakan naa, ni o tun ti ran won
Yatọ si ipe, o tun le fi imeeli ranṣẹ si actu@nimc.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, AFCON 2019: Ọmọ Nàijíríà rọ Super Eagles lati tubọ sápa wọn pẹlú Madagascar Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
O salaye pe, ile-eko naa se olokan-o-jokan eto ati idanilekoo fun awon omo egbe re, awon akosemose ni eka gbogbo ati awon ti oro kan ni awon ile-ise ijoba.
Tàkúté yóo mú wọn, ọwọ́ yóo sì tẹ̀ wọ́n.
- Ààrẹ Akufo-Addo Gbajabiamila balẹ̀ sí Ghana láti pẹ̀tù sááwọ̀ láàrin Nàìjíríà àti Ghana Òtítọ́ ọ̀rọ̀ rè é lórí ilẹ̀ tó fa awuyewuye láàrin Ghana àti Nàìjíríà Ohun tó yẹ kí o mọ̀ nípa ìgbésẹ̀ tí Amẹ́ríkà fẹ́ gbé lórí Nàìjíríà nítorí ọ̀rọ̀ ẹ̀sìn Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Borno Zabamari Massare: Àjọ NCC fẹ́ tú ìwé owó àwọn olúpèsè ìtàkùn ìbánisọ̀rọ̀ wo10 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Andrew Haruna: So-bàtà tó di ọ̀jọ̀gbọ́n fásitì tó di ọ̀gá àgbà9 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Ooni Ile Ife: Ooni Adeyeye Ogunwusi àti Olòrì Naomi gbé Àrẹ̀mọ tuntun wọ ṣọ́ọ̀ṣì21 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Oríṣun àwòrán, Reuters Àkọlé àwòrán, Ọgbẹni Johnson ni esi ibo naa jẹ asẹ araalu fun oun lati tete ko wọn kuro ni EU Wo bí èsi ìdìbò UK ṣe fi hàn pé Boris Johnson ń gbégbá orókè lọ́wọ́ Gẹgẹ bi wọn ṣe n ka esi idibo ilẹ Gẹẹsi lọwọ yii, ẹkọ n foju minu han pe ẹgbẹ Conservative ni yoo jawe olubori ninu idibo naa.
Gẹgẹ bi akọsilẹ itan igbesi aye rẹ to wa lori ayelujara itakun agbaye ijọ naa, genesisglobal.
ati ọ̀kẹ́ mẹta (60,000) ẹlẹ́ṣin, ati ọ̀kẹ́ àìmọye àwọn ọmọ ogun tí wọ́n tẹ̀lé e láti Ijipti.
Yoruba ni ti ọkunrin kan ba gboju gboya lati gun le alaboyun kan, ti kii se iyawo rẹ, tabi ko jẹ pe oun lo pilẹ oyun naa tẹlẹ, iru ọkunrin bẹẹ yoo tosi ku ni.
Ojú wọn ti dá, ó le koko,wọ́n kọ̀, wọn kò ronupiwada.
Wọn yóo rán àwọn aṣọ mímọ́ náà fún Aaroni ati àwọn ọmọ rẹ̀ kí wọ́n lè máa ṣe iṣẹ́ alufaa fún mi.
“Ẹ yipada sí mi kí á gbà yín là,gbogbo ẹ̀yin òpin ayé.
Ọjọ́ náà pé lónìí wàyí, ti n ó lọ si ibi tí àwọn alágbára ń lọ, sí ibùgbé àwọn abàmì ẹ̀dá, sí ibi ti ó ṣókùnkùn dudu lójú mi, n ó fi àlàáfíà sílẹ̀ lẹhin, n ó wọlé tọ ijàngbọ̀n lọ, ṣùgbọ́n ìṣòro ni bàbá ìṣúra, orúkọ rere dára ju ìyàwó tuntun, bí mo bá fi ara da iṣòro ti òní, n ó rí ìṣúra ti ẹhin ọ̀la, bí mo bá ti igbó Olódùmarè dé tayọ̀tayọ̀, orúkọ mi yóò pẹ láyé gidigidi.
Lọjọ kejilelogun, oṣu kẹwaa, ọdun yii ni Gomina Okow kede isede latari biba nkan ilu jẹ nipinlẹ naa.
Ó sàlàyé pé òsìṣẹ́ Emzor tẹ́lẹ̀rì ni Madubuike tó sì ń ta òògùn náà lọ́nà àìtọ́ nítori pé ó lẹ́tọ̀ọ́ si láti ilé iṣẹ́.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Bukunmi Oluwasina: Ìmọ̀ràn ọkọ mi nínú eré tí mo bá kọ lo ń jẹ́ kí eré mi dáńtọ́ 17 Owewe 2020 Oríṣun àwòrán, Bunkunmi Oluwasina Gbajugbaja oṣerebinrin to ṣẹṣẹ ṣe igbeyawo, Bukunmi Oluwashina ti sọ pe o daju pe ẹbẹ ati aforiji ni oun yoo fi iyooku ọdun yii tọrọ lọwọ ọpọ eeyan, fun bi ko ṣe dajọ ayẹyẹ igbayawo rẹ fun wọn.
”Jeremaya dáhùn, ó ní, “Bẹ́ẹ̀ ni, ohun tí OLUWA sọ ni pé, a óo fi ọ́ lé ọba Babiloni lọ́wọ́.
Awọn iroyin ti ẹ lee nifẹẹ si: Ogun Anglo àti Francophones Cameroon mú ẹ̀mí 23 lọ Ìfọ̀rọ̀wánilẹ́nuwò ti BBC ṣe fún Baba Leah, Nathan Sharibu lánàá fi han pé ohùn ọmọ òhun ni ó wà nínú fọ́nran náà.
Khadijah, obìnrin àkọ́kọ́ tó dẹnu ìfẹ́ kọ àyànfẹ́ rẹ̀ South Africa: Báwo ni ìkọlù sáwọn àjèjì ṣe wọ́pọ̀ tó?
Ìhùwàsí búburú ati dídá wàhalá ati ìkọlura pẹ ̀ lú ìjayé fàmílétè-kí-n-tutọ ́ pọ ̀ lọ ́ wọ ́ ṣàngó g ̣ ẹ ́ gẹ ́ bí Ọba tó bẹ ́ ẹ ̀ títí ó fi di ọ ̀ tẹ ́ yímiká , èyí jásí wí pé tọmọdé tàgbà dìtẹ ̀ mọ ́ ọ .
Kí arakunrin tí ó jẹ́ mẹ̀kúnnù kí ó yọ̀ nígbà tí Ọlọrun bá gbé e ga.
Ẹhonu lai lo ibọn tabi ada lawa n ṣe.
 júpítérì je kikosoto bi omiran efuufu kan pelu satu , uranu ati neptu .
Mo mọ̀ pé ibi tó dára ni Ibidun Ighodalo wà báyìí- Adeboye Amọ, O fikun wi pe ti iwadii ba fidi ẹ mulẹ pe lootọ ara lo san pa wọn, oun ko le e ṣe ẹbo tabi ṣe etutu nitori ẹlẹsin Musulumi ni oun, oun ko si gbagbọ ninu rẹ.
Ó na ìhà àríwá sórí òfuurufú,ó sì so ayé rọ̀ sí òfuurufú.
Ẹ̀fúùfù fẹ́ títí mo fi fẹ́rẹ̀ ṣe àìsàn; bẹ́ẹ̀ ni òòrùn pa mi títí ara mi fi gbóná bí iná alágbẹ̀dẹ.
Bí ó ti rí wọn, wọ́n wọ̀ ọ́ lójú, ó bá rán ikọ̀ sí wọn ní ilẹ̀ Kalidea.
Awọn lo mn jẹ ki ẹni to n jẹjọ salọ.
com Àkọlé àwòrán, Ikọ Falconets gbo ewuro soju ojugba won ti ile Cameroon Ẹgbẹ agbaboolu ọjẹ wéwé orilẹ-ede Naijiria ti ọjọ ori wọn ko ju ogun ọdun lọ ni wọn ti fi agba han ojugbaa wọn ti ilẹ Cameroon.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Àlàyé rèé lórí bí wọ́n ṣe mú mi lẹ́rú ní 1837 - Ajayi Crowther Samuel Ajayi Crowther, òjíṣẹ́ Ọlọ́run tó gbé èdè Yoruba lárugẹ Èmi àti Bọla Tinubu fẹ́ lo ‘German Mercenaries’ láti gbé MKO Abiọla kúrò lẹ́wọ̀n - Dele Momodu Mo nífẹ̀ẹ́ Khafi torí kìí díbọ́n tàbí hùwà oníwà - Gedoni sọ̀rọ̀ ìdágbére Adehun naa lo fun wọn ni anfaani lati maa san owo to pọ ju eyi to yẹ lọ, to si lowura ju tawọn ẹgbẹ wọn lọ, ki wọn lee maa ri ina ọba lo laisẹju.
  Ìyá arúgbó kan ni ó ntọ́jú ilé ìtura yìí.
Ó ń rò lọ́kàn ara rẹ̀ pé, kò sí ohun tí ó lè bi òun ṣubú,ati pé ní gbogbo ọjọ́ ayé òun, òun kò ní ní ìṣòro.
"Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Anthony Joshua: Mí ò mọ̀ pé ọ̀rọ̀ ọlọ́pàá ni ìwọ́de #EndSars níṣe pẹ̀lú 26 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Oríṣun àwòrán, Anthonyjoshua/instagram Gbajugbaja abẹsẹ ku bi ojo Anthony Joshua ti tunu pé, lasiko ti iwọde #EndSars gbona janjan ninu oṣu kẹwaa ko ju ọrọ ""Virus"" ti wọn pè ni ""Severe Acute respiratory Syndrome ti age ku rẹ n jẹ́ ""SARS"" ni oun ro pe o jẹ."
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Àwọn to n bá ẹlẹkun sunkún ní Ghana Kii ṣe Gyan nikan ni ọrọ yi so si lẹnu to tun buyọ si.
Wahala ọpọ ọdun pẹlu ti ni ipa pupọ lori awọn ohun elo amayedẹrun to lee faye gba ipese omi to ja gaara ati ile igbọnsẹ, paapaa julọ lawọn agbegbe ni ẹkun ila oorun ariwa.
Ninu ọrọ to sọ nibi ayẹyẹ ipade igbimọ awọn ẹya ti ko ni aṣoju ninu igbimọ agbaye, aṣiwaju igbimọ Yoruba lagbaye naa sọ pe ohun ti oju ẹya Yoruba n ri nilẹ yii ko dẹrun rara.
”O seleri pe ile igbimo asofin yoo fowosopo pelu ajo eleto idibo la ti ri I pe won se aseyori lori eto idibo odun to n bo.
Nítorí kì í ṣe àgọ́ tí a fi ọwọ́ kọ́ ni Kristi wọ̀ lọ, èyí tíí ṣe ẹ̀dà ti àgọ́ tòótọ́.
oyún tí ó wà ninu rẹ, ọkunrin ni o óo fi bí, o óo sọ ọmọ náà ní Iṣimaeli, nítorí OLUWA ti rí gbogbo ìyà tí ń jẹ ọ́.
Ejò wo ló mi ₦118m láàrin UCH àti ìjọba Oyo?
 Ààrin ilẹ ̀ afíríkà ni ó wà .
Wọn yóo fà yín lọ sí inú ilé ìpàdé ati sinu ẹ̀wọ̀n.
OLUWA ní, “N óo pa gbogbo nǹkan tí ó wà lórí ilẹ̀ ayé run: 
Sunday Igboho sọ̀rọ̀ lórí ohun tó kan fún ilẹ̀ Yorùbá lọ́dún 2021 Pásítọ̀ Adeboye bú ẹnu àtẹ́ lú ìjọba tó fofin dé ìsìn ìrékọjá sí ọdún tuntun Àwọn ànfààní tó wà nínú ìbálọ̀pọ̀ fún ọkàn àti ara rẹ Bá wo ni òrékelẹ́wà Adedoja tó gbàmì ẹ̀yẹ ''Miss Oyo 2020'' ṣe jẹ́ sí Alaafin?
Ṣé ẹ̀ ń dìtẹ̀ mọ́ ọba ni?
Wá, n óo rán ọ sí Farao, kí o lè lọ kó àwọn eniyan mi, àwọn ọmọ Israẹli, jáde kúrò ní ilẹ̀ Ijipti.
N óo sọ wọ́n di ohun tí ó bani lẹ́rù fún gbogbo ìjọba ilẹ̀ ayé, nítorí ohun tí Manase, ọmọ Hesekaya, ọba Juda, ṣe ní Jerusalẹmu.
Akọroyin naa sọ fun BBC Yoruba pe ibéèrè òun ko ju pe gbogbo irinajo to n rin lọ si iha Guusu, taa gan lo n ṣe onigbọwọ rẹ tabi gbowoo lẹ.
Biden la Trump mọ́lẹ̀ wọlé ìbò ààrẹ orílẹ̀-èdè Amẹ́ríkà Oríṣun àwòrán, Getty Images Oludije ẹgbẹ oṣelu Democrat Joe Biden lo wọle ibo aarẹ orilẹ-ede Amẹrika.
 Èkejì nit i Ìwọ ̀ -oòrùn tí wọ ́ n gbé lé orí ẹ ̀ ka-èdè tí wọ ́ n ń sọ ní islanbul .
Peter ṣalaye pe ohun to sọ ni pe oun yoo ran Tacha lọwọ lati ṣiṣẹ ri owo to to ọgọta miliọnu naira.
Bí Demeteriu ati àwọn oníṣẹ́ ọnà tí ó wà pẹlu rẹ̀ bá ní ẹ̀sùn kan sí ẹnikẹ́ni, kóòtù wà; àwọn gomina sì ń bẹ.
Àrà rèé, ogbontarigi ayanbinrin ti gbogbo eeyan mọ pẹlu ilu lilu kaakiri agbaye.
si ile idibo ati bi awon irinse to n yẹ kaadi ibo se n se mọna-mọna ni awon
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Awọn ero n fi ehonu han lati pe fun idajọ lori iku akọroyin Malta Daphne Caruana Galizia Ki i ṣe awa nikan ni ọrọ yii wa lọwọ wa lati doju kọ ọrọ yii: awọn ẹbi, ara, ọrẹ ati awọn ololufẹ awọn akọroyin ti wọn ti pa tabi ti wọn gbe si atimọle.
Alabi ni bo tilẹ jẹ́ pé kìí ṣe abẹ rẹ tààrà ni oun ti ṣiṣẹ̀, síbẹ̀, ìgbé aye Olasope jẹ ǹkan ti eniyan ń tẹ̀le, ṣe ni ti èdè ni tàbí làákàyé?
'Ọṣinbajo jọmí lójú pẹ̀lú ìwà akin tó hù' Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ọ̀ṣọ́ Aṣọ Òkè ti kọjá lílo ìlẹ̀kẹ̀ níkan Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ogundiya: Àṣìṣe Dókítà ló sọ mi di aláàbọ̀ ara lórí kẹ̀kẹ́ Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
“Kì í ṣe pé ẹ pọ̀ ju àwọn eniyan yòókù lọ ni OLUWA fi fẹ́ràn yín, tí ó sì fi yàn yín.
Wọ́n pọ̀ púpọ̀ n kò sì rò pé ohun ẹlẹ́mìí ni wọ́n, nítorí pé wọn kò kúrò ní ibi kan, olúkúlùkù dúró sí ipò rẹ̀ ni.
Nigeria Stowaway: Baalu tó ń lọ Owerri ni Ọdọmọkunrin náà fẹ́ gán- Airpeace
Iha wo ni ijọba Oyo kọ si idajọ ọwọ to di lemọ-lemọ?
Nigba to n ba BBC News Yoruba sọrọ lori idajs naa, alaga ẹgbẹ awọn alaga Kansu ALGON ni ipinlẹ Ọyọ, Ọmọọba Abass Alẹshinlọyẹ ni bi igba ti eeyan fẹ mọọmọ fi ọwọ ọla gba awọn alaga kansu naa loju lọrs ọhun yii.
N óo jẹ́ kí díẹ̀ ninu wọn bọ́ lọ́wọ́ ogun, ati ìyàn ati àjàkálẹ̀ àrùn, kí wọ́n lè ròyìn gbogbo ohun ìríra wọn láàrin àwọn tí wọn óo lọ máa gbé; wọn óo sì mọ̀ pé èmi ni OLUWA.
Ifẹhonuhan lori awọn akọ to n ṣe ṣakọ ati abo sabo: Ohene lo ṣe ni laanu pe ọpọ lo sọrọ tako awọn akọ to n fẹ akọ ara wọn nigba ti wọn fi awọn to n fipa bawọn ọmọde silẹ.
Ogbeni Bala ropo Ahmed Ibeto, ti o je asoju teleri sugbon ti o kowe fise sile ninu osu keje odun ti a wayii, lati lo darapo mo egbe oselu Peoples Democratic Party PDP.
Aare  Buhari bu ẹnu atẹ lu isẹlẹ buruku ọhun ,o wa fi
Àwọn ìròyìn mìíràn tí ẹ lè nífẹ̀ẹ́ sí: Èèyàn 5 farapa, ọ̀pọ̀ ọkọ̀ jóná nínú ìjàmbá iná márosẹ̀ Ibadan sí Eko Ọja Alaba nilu Ekọ njona Ẹ̀mí 68 bọ́ nínú ìsẹ̀lẹ̀ iná ní Venezuela Tanka epo tó jóná gbẹ̀mí àdájọ́, ọmọkùnrin rẹ àtàwọn míì Ilé jóná ní Òkè Àdó Ibadan, ọ̀pọ̀ dúkìá ṣòfò Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí kan sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
Iwadii yii lo ṣafihan iye awọn to n ṣiṣẹ ni ajọ to n ṣakoso ọgba ẹwọn (NPS), abo ara ẹni ni aabo ilu (NSCDC), iwọle-wọde eniyan si Nigeria (NIM), panapana (FFS) ati awọn ajọ meji miiran.
Fatima, Ọmọ Mamman Daura ni pe oun lo ya fidio naa nigba ti o n ba akọroyin BBC sọrọ.
“Mo bá gbéra, mo sọ̀kalẹ̀ láti orí òkè pẹlu àwọn tabili òkúta mejeeji tí a kọ majẹmu náà sí ní ọwọ́ mi.
Èmi iranṣẹ rẹ yóo ti dúró pẹ́ tó?
Aawo Tinubu ati Odigie ko ṣẹṣẹ bẹrẹ Awọn amoye sọ wi pe o ti pẹ ti awọn mejeeji ko tii gbọrawọn ye lori didari ọrọ ẹgbẹ APC.
Ni ilú Èkó, lati Ọjọ́bọ̀ titi dé ọjọ́ Àikú ni enia yio ri ibi ti wọn ti ńṣe ayẹyẹ.
Ìyàn ati àjàkálẹ̀-àrùn yóo pa ẹni tí ó bá wà ninu ìlú.
Tí o sì kọ̀ wá sílẹ̀ fún ìgbà pípẹ́?
Àwọn eniyan mi ń ṣègbé nítorí àìsí ìmọ̀; nítorí pé ẹ̀yin alufaa ti kọ ìmọ̀ mi sílẹ̀, èmi náà yóo kọ̀ yín ní alufaa mi.
awon ebi ati agbegbe  ti won padanu awon
O óo kọlu àwọn ọmọ Israẹli, àwọn eniyan mi, bí ìkùukùu tí ń ṣú bo ilẹ̀.
Bi ọlọpaa ti n lọgun pe awọn agbebọn ni, wọn kii ṣe darandaran Fulani, lawọn apa kan araalu naa n pariwo pe rara oOoni Ile ife, Ààrẹ Gani Adams fárígá lórí ikú ọmọ Fasoranti, awọn Fulani lo ṣiṣẹ laabi yiiǸjẹ́ ẹ mọ ohun tí igbákejì ààrẹ Yemi Osinbajo sọ nílé bàbá Fasoranti .
Jẹ́ kí ògo rẹ hàn lára Ọmọ, kí ògo Ọmọ náà lè hàn lára rẹ.
Nǹkan àṣírí ni n óo sọ fun yín.
Bakan naa ni ki o ri i daju pe o tẹ ẹ̀dà (print) ohunkóhun ti kọmputa ba fi ránṣẹ si imeeli rẹ, nigba ti o ba fi orukọ silẹ tan.
"Loju opo Instagtam ni a ti ri oriṣiriṣi fọnran ati fọto ayẹyẹ igbeyawo ọ̀hún Ayẹyẹ igbeyawo naa bẹrẹ pẹlu aṣalẹ pataki ti wọn n pe ni ""Henan night"" ni ilu Maiduguri, ipinlẹ Borno lalẹ ọjọ ẹti ọjọ keje oṣu kẹjọ ọdun 2020."
Jakọbu bá dìde ní òwúrọ̀ kutukutu, ó gbé òkúta tí ó fi ṣe ìrọ̀rí nàró gẹ́gẹ́ bí ọ̀wọ̀n, ó sì da òróró sórí rẹ̀.
Iléèṣẹ́ ọlọ́pàá mú ọkùnrin ẹni ọdún 55 tó gé ẹ̀yà ara èèyàn nílẹ̀ ìsìnkú ṣọ́ọ̀ṣì l'Ogun
Oríṣun àwòrán, @others Àkọlé àwòrán, Lẹyin to ti hande pe iroyin ẹlẹjẹ ni igbeyawo aarẹ Buhari ti awọn eeyan n pariwo lori ayelujara; sibẹ ọpọ aworan to panilẹrin fun ipalẹmọ lo kun ayelujara bayii Ṣaaju ni iroyin ẹlẹjẹ ti gba ori ayelujara pe eto igbeyawo naa yoo waye laarin minista tuntun fun Abojuto lori ọrọ Ijamba ati Igbayegbadun ọmọniyan lorilẹ-ede ati aarẹ Naijiria.
Ṣugbọn ọmọbinrin yii, Maureen, ọmọ orilẹede Kenya, pinnu lati kekere lati maa tọju ẹranko igbo.
" Ni bayii, wọn ti gbe oku Razak lọ sile iwosan lati mọ ohun to paa, ti iwadi si n tẹ siwaju.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Alaafin Adeyemi: Lára àwọn òrékelẹ́wà ayaba náà ló dẹnu ìfẹ́ kọ Ọba Adeyemi fúnra wọn 2 Agẹmo 2020 Oríṣun àwòrán, Alaafin Oba Adeyemi 111 Facebook Ni ọjọ mẹta diẹ sẹyin, a mu iroyin kan wa fun un yin, ninu eyi ti Alaafin ti kede pe, oun kii dẹnu kọ obinrin, o wu awọn iyawo oun, ni wọn fẹ oun funra wọn.
Ó jọ pé kò mọ̀ pé ẹnìkan yóò wá ṣe ìrànwọ́ fún òun.
Tí Ọwá bá fẹ́ fi ènìyàn bọrẹ̀ láyé àtijọ́, Ọba Ijẹ̀bú-Jẹ̀ṣà gbọ́dọ̀ gbọ́ nípa rẹ̀.
Oriṣiriṣi ọna ni eto igbani wọle maa n gba ninu awọn ẹgbẹ okunkun.
Idibo abele awon ondije dupo gomina labe asia egbe APC, nireti wa tele pe yoo waye lojoBo(Thursday), ojo kokandinlogun osu keje odun yii, sugbon ti won sun siwaju di ojo Eti(Friday), ti n se ogunjo osu keje odun ti a wayii.
Ní ọdún kan, nígbà tí ó wa, o sọ ara rẹ̀ di arúgbó kù jù ọ̀, ó sì gbé erù lórí, ó dúró sí ẹ̀bá ìlú àwọn Èdídàrẹ́, nígbà tí ọmọ ọba ń lọ sí oko tí ó rí i, wọ́n kí ara wọn, arúgbó yìí sì wí fún un kí ó bá òun gbe ẹrù òun díẹ̀.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Enuduisu Odili sexual Port Harcourt death: Ọkùnrin kan gba ibi ìbálòpọ̀ jásí ọ̀run alákeji 6 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Oríṣun àwòrán, Naija info Ẹbi ọkunrin ẹni ogoji ọdun, Enuduisu Odili to ku ninu ile itura, otẹẹli lẹyin to ni ajọsepọ pẹlu obinrin kan ti n bere fun iwadii to yanranti lati ọdọ ọlọpaa.
Awon ti won tu sile ohun ni: okunrin meji ati obinrin meji ni abule Maima ti o wa nijoba ibile Ngala Local Government nipinle Borno.
vilma lucila espín guillois ( april 7 , 1930 - june 18 , 2007 ) je omo ile kuba be sini o tun je iyawo raul kastro aare ile cuba .
Lọjọ kẹrindinlọgbọn, oṣu keji, ọdun 2017 kan naa ni adajọ agba Oguntoyinbo dajọ pe wọn yoo san beeli miliọnu marun un naira pẹlu oniduro meji.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ṣọla Kosọkọ: ọlá bàbá mi ni mò n jẹ́ nínú iṣẹ́ tíátà Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Ṣọla Kosọkọ: ọlá bàbá mi ni mò n jẹ́ nínú iṣẹ́ tíátà 14 Ọ̀pẹ̀̀ 2018 O ni iṣẹ́ agbẹjọro gangan ló wu oun láti kà ni fasiti tẹ́lẹ̀, iṣẹ́ orí rán kaluku ló n ṣe.
O kọ ẹkọ nipa imọ Microbiology ni fasiti imọ ẹrọ, OSUSTECH, ni ipinlẹ Ondo kan naa.
Àwọn tó gboriyin àti àwọn tó gbàbuku lórí ìṣẹlẹ New Zealand Ọmọ Nàíjíríà tó jẹ́ Ìmáàmù mọ́ṣálásí tí wọn kọlù ní New Zealand ṣàlàyé ìṣẹ̀lẹ̀ Èèyàn 49 bá ìṣẹlẹ̀ iyìnbọn lọ ní Mọ́sálásí méjì ní New Zealand Nigba ti o n ba awọn eeyan orileede naa sọrọ, Jacinda Arden ni ''New Zealand n ba yin daro,ọkan ṣoṣo ni wa'' Aadọta eeyan lo padanu ẹmi wọn ninu iṣẹlẹ naa ti ọpọ eeyan si farapa.
Eyi si lo mu ki oju opo ayelujara maa gbona lori bi awọn ọmọ Naijiria se n gbarata, lori bi gbese tilẹ wa jẹ se n fi ojoojums fo lọ soke.
Lapaapọ eeyan 62,964 ni ayẹwo ti fihan pe wọn ti ko aarun corinavirus lorilẹede Naijiria.
Ile ẹjọ ni Chicago lo ti kọkọ foju han lọjọ kẹta, oṣu kejila lori ẹsun gabjuẹ.
Nítorí pé, Jonatani fẹ́ràn rẹ̀ bí ó ti fẹ́ràn ẹ̀mí ara rẹ̀.
Ile-ise Floor Mill lorile-ede Nigeria je ile-ise to pegede julo nipa sisan owo-ipin ori idokowo alakoko iru re, eyi ti ile-ise kan ti a mo si, Third Observers Nigeria Limited se agbateru re nipinle Eko.
Bẹ́ẹ̀ ni àwọn ọmọ Israẹli ṣe fún àwọn ọmọ Lefi ní gbogbo àwọn ìlú ńláńlá pẹlu àwọn pápá oko tí ó yí wọn ká.
 Àwọn ìlànà lílo polymerase ìtàgìjí àṣokunfà láti ṣàwarí kòkòrò náà dna ti di àgbékalẹ ̀ , ṣùgbọ ́ n a kí sábà lò ní àwọn agbègbè tí ibà ti wọ ́ pọ ̀ nítorí ọ ̀ wọ ́ n àti ipá gbòòrò líle wọn .
Bẹ́ẹ̀ ni ẹnikẹ́ni kò sì káàánú mi láàrin yín, kí ó sì sọ fún mi pé, ọmọ mi ń ran iranṣẹ mi lọ́wọ́ láti ba dè mí, bí ọ̀rọ̀ ti rí lónìí yìí.
Oríṣun àwòrán, Instagram/oluwoofiwoland Aarin awa ati Oluwo ko gun rara nitori naa la se n kọwe ẹhonu pe ki wọn yọ loye."
Bi awọn ipinlẹ to ni Coronavirus ṣe lọ ree: Eko-107 FCT-91 Plateau-81 Kaduna-32 Ogun-30 Kwara-24 Ebonyi-19 Ekiti-17 Oyo-8 Borno-6 Edo-6 Kano-4 Nasarawa-3 Osun-3 Taraba-3 Gombe-2 Bauchi-1 Irinwó lé méje èèyàn ló gbàwòsàn lọ́wọ́ Covid-19, 453 míì tún lùgbàdì rẹ̀ lọ́jọ́ Àbámẹ́ta Irinwo le meje eeyan lo gbowosan lọwọ arun Covid-19 lọjọ Abamẹta, nigba ti awọn irinwolelaadọta le mẹta miran tun lugbadi rẹ ni Naijiria.
Bo ba si se n jade, ni a maa mu iroyin rẹ wa fun un yin.
Nítorí pé ó ti jẹ́ kí n ṣẹgun gbogbo àwọn orílẹ̀-èdè yìí, ilẹ̀ náà sì wà lábẹ́ àkóso OLUWA ati ti àwọn eniyan rẹ̀.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Olusegun Obasanjo: Ọmú ìyá mi ti mo fi ń mùkọ ni kekere ló jẹ ki ń lókun Nigba ti iwadii wọn tẹsiwaju, paapaa lori awọn akinkanju oloogun to wa ninu ilu naa, ọwọ tẹ awọn Babalawo mẹta.
Bótilẹ̀ jẹ́ pé àwọn òṣìṣẹ́ pápákọ ofurufu náà ko le fi ìdí ti ọkunrin òhun ṣe gbe irú igbésẹ̀ bẹ́ẹ̀ ni kété ti ọ̀rọ̀ naáà ṣẹlẹ̀, ṣùgbọ́n ọwọ́ ti tẹ̀ẹ́.
Iroyin to lu oju ayelujara pa ni pe awọn oṣiṣe INEC fun oludije fun ipo aarẹ labẹ asia ẹgbẹ oṣelu PDP Atiku Abubakar lanfani lati ri awọn ohun elo idibo aarẹ lori ẹrọ kọmputa INEC.
O ni kii kiku ṣe wi pe oun fẹran lati maa ni ọkọ lori, ṣugbọn ọrọ yipada nigba ti Sholaye yọwọ iwa si oun.
Aaroni sì kú sí orí òkè náà, Mose ati Eleasari sì sọ̀kalẹ̀.
  Gbogbo wọn wá ń wò mí bàùn bí àguntàn Ìbàdàn.
Ẹ óo pa òmíràn ninu wọn, ẹ óo sì kan òmíràn mọ́ agbelebu.
Márosẹ̀ Eko sí Ibadan àti Ibadan sí Eko dí pa fún ṣúnkẹrẹ́-fàkẹrẹ ọkọ̀ Bakan naa lo sọrọ lori bi Baba ati Iya rẹ ṣe gba kamu lori ọrọ naa ti wọn si n pese atilẹyin to yẹ fun oun.
 Mo ro yin lati dibo fun mi ati oludije fun ipo gomina ninu egbe
Wọ́n gúnlẹ̀ sí ilẹ̀ àwọn ará Geraseni tí ó wà ní òdì keji òkun tí ó dojú kọ ilẹ̀ Galili.
Ninu ọrọ rẹ, Ọba Ajayi ni lootọ ni isẹlẹ naa waye pẹlu afikun pe asiko ọdun la wa yii, iru isẹlẹ bayii si maa n wọpọ.
Ko tan sibẹ o, nitori kii se igbeyawo nikan ni wọn fi n dẹyẹsi awọn ti wọn ba wa lati idile ẹru ni ẹya Igbo,lorilẹede Naijiria.
Iléeṣẹ́ Ọlọ́pàá ṣetán láti bẹ̀rẹ̀ ètò ìgbanisíṣẹ́ lákọ̀tun Ọ̀rọ̀ǹpọ̀tọ̀niyùn, Aláàfin obìnrin àkọ́kọ́ rèé, tó ní nǹkan ọkùnrin Masvidal gba lati ja, ti o si gbiyanju, koda o ru lara si pẹlu gbogbo akitiyan rẹ lati gbaradi fun idije naa laarin ọjọ mẹwaa.
Awọn wo ni igbimọ agba ọjẹ oludibo alaṣẹ ti wọn n pe ni Electoral College?
Nígbà tí ó yá, Lọti jáde kúrò ní Soari, nítorí ẹ̀rù ń bà á láti máa gbé ibẹ̀, òun ati àwọn ọmọbinrin rẹ̀ mejeeji bá kó lọ sí orí òkè, wọ́n sì ń gbé inú ihò kan níbẹ̀.
Awọn obi awọn akẹkọọ ileewe aladani ọhun ke gbajare sita lasiko iwọde kan ti wọn ṣe ni ilu Abẹokuta lọjọ Aiku nibi ti wọn ti ni ẹgbẹrun marundinlọgbọn naira ti ijọba ni ki awọn akẹkọọ ileewe aladani o san fun ayẹwo kokoro arun COVID-19 ko rọrun rara.
Gẹgẹbi ọrọ ọgagun agba ileesẹ ọmọogun ofurufu lorilẹede Naijiria se sọ, baluu adanikan foyii le da sisẹ ni ssan ati oru.
5 2246 Isle of Man 25 29.
orile ede Naijiria fun saa keji.
Idi ti isẹlẹ naa se waye ni bi Lizzy Anjọrin se n ba Ronkẹ Odusanya yọ pe o ku ayọ ọmọ tuntun to bi lẹyin ọjọ diẹ ti iroyin gbalẹ pe Toyin Abraham bi ọmọ tuntun.
Irinajo si orilẹ-ede South Africa Ni ibẹrẹ oṣu kẹwaa ni Aarẹ Buhari lọ si ilẹ South Africa nibi to ti ṣepade pẹlu Aarẹ Cyril Ramaphosa lẹyin iṣẹlẹ inunibini tawọn ọmọ orilẹ-ede naa ṣe si awọn ọmọ Naijiria to n gbe nibẹ.
Ọjọ́ ìsọmọlórúkọ ní ìdílé Ọlọ́fà tún yàtọ̀.
Pẹlu eniyan to le ni miliọnu meji ṣugbọn ti wọn ri iṣẹlẹ Coronavirus 1, 700 pẹlu eniyan ogoji to ti gbẹmi mi.
Ibeere to wa n gba ọkan awọn eeyan ni pe, ṣe iṣẹlẹ to waye l'ọdun 2016 yoo tun waye bi lọdun 2020?
ANCDC lofi ikede naa si oju opo ikansiraẹni Twitter rẹ, ti apapọ awọn eniyan to ti ni arun naa ti wa da 12801.
Yorùbá dùn Egypt: Bàálù méjì yóò kún tí ìjọba bá ṣèrànwọ́ láti kó wa kúrò ní Egypt
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Nigeria movie industry: Àgbà òṣèré, Lere Paimo ní àìgbọràn ló ń da ọ̀pọ̀lọpọ̀ àwọn Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Ondo Election 2020: Ẹ wo àwọn olùdíje sípò gómìnà nípínlẹ̀ Ondo tó takò bàbá ìsàlẹ̀26 Owewe 2020 Fídíò, Wole Soyinka sọ ìdí tó fi ni òun a fi màálù Fulani ṣe súyà fáwọn èèyàn abúlé23 Owewe 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Gege bi Yobo se so,“Mo ni igbagbo pe iko Super Eagles yii yoo fakoyo lorile-ede Russia,”O fikun pe, agbaboolu odo ti o po ninu iko naa yoo ran iko naa lowo lopolopo ninu idije naa.
“Ṣugbọn ní ti ọjọ́ ati wakati náà, kò sí ẹni tí ó mọ̀, àwọn angẹli kò mọ̀, Ọmọ pàápàá kò mọ̀, àfi Baba.
Mubarak goke lẹnu iṣẹ rẹ titi to fi di ọga ileewe awọn ọmọ ogun oju ofurufu ati ọga patapata awọn ọmọ ogun oju ofurufu lọdun 1972.
Mo ní ọ̀rọ̀ kan tí mo fẹ́ bá a sọ.
Jesu tí ẹ̀yin pa, tí ẹ kàn mọ́ igi, Ọlọrun àwọn baba wa jí i dìde.
"Gẹgẹ bo se wi, ""Chai, mo gbọdọ fun ọ loyun."
Kí ni eniyan jẹ́, tí o fi gbé e ga,tí o sì fi ń náání rẹ̀;
 Èyí ni ó ṣokùnfà gbígba àmì ẹ ̀ yẹ ìdánilọ ́ lá ilẹ ̀ faransé ìyẹn : ( french constantin award ) ní ọdún 2008 , nígbà ti wọ ́ n dìbò yàán gẹ ́ gẹ ́ bí ẹni àkọ ́ kọ ́ làárin àwọn olùdíje akọrin mẹ ́ wàá tó lẹ ́ bùn ọpọlọ jùlọ nílùú parisi .
Agbẹnusọ fun ile iṣẹ ọlọpaa ni, ayederu ile ọmọ alailobi nibi tawọn ti tu awọn ọmọde naa silẹ.
Idanre Kingship tussle:Adelé Ọba Idanre ní Ọba Aroloye wà lórí ìtẹ́ nígbà tí àwọn jàndùkú lù ú
Abilekọ Babalọla ni gbogbo igba ti oun ba ti fẹ fi iya jẹ ọmọ naa nitori o ṣe aṣemaṣe ni ọmọ naa ma n dapara, ti oun ko si ni lee naa mọ.
Àwọn okunrin tó bá mọ ohun ti wọn ń ṣe yóò gbé ẹja wa nínú ìgò wá gẹ́gẹ́ bí ẹ̀bùn.
Lẹnu ọjọ mẹta yii, niṣe ni iye awọn to n ku latari mimu gbarọgudu ọti naa n pọ sii.
Ọmọ Risikat olójú búlúù méjèéjì jẹ̀bùn oríire àti ìfà ńlá Òṣèré tíátà Yorùbá yìí la orí mọ́lẹ̀ nígbà tó ń ṣe sinimá lọ́wọ́ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Risikat Moromoke Azeez: Inú èmí àti Òbí mi dùn nígbà ti Risi bí ọmọ olójú búlù- Wasiu O ni minisita paṣẹ pe ki ikọ awọn ọmọ ogun ri i pe wọn doola awọn ọmọkunrin naa lai farapa ati ni kiakia.
Gomina Babajide Sanwó Olú, kò sai yàn àwọn ènìyàn láti ẹ̀yà mìíràn láti Gúúsù ìlà Òòrùn ilé yìí àti Ariwa Orílẹ̀ èdè yìí bakan naa.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Fake Facebook: Ọkùnrin kan dèrò iléejọ́ lórí ẹ̀sùn pé ó f'orúkọ Adeboye lu jìbìtì 4 Ìgbé 2019 Oríṣun àwòrán, Twitter/Adeboye/Olukoya/Joshua Àkọlé àwòrán, Ọkunrin kan fawọn ojiṣẹ Ọlọrun lo jibiti Ọwọ ti ba ọkunriun kan ti wọn fẹsun kan pe, o n fi orukọ Olori ijẹ Redeem, Enoch Adeboye, ati ti ijọ Mountain of Fire, Daniel Olukọya pẹlu Olori ijọ Synagogue, Temitọpẹ Joshua lo awọn eeyan ni jibiti.
”Ahabu bá dáhùn pé, “Ó ṣì wà láàyè?
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Goriola Hassan: ‘Tattoo’ tó wà lára mi, kò dí ọba jíjẹ lọ́wọ́, ara oge ṣíṣe ni 16 Sẹ́rẹ́ 2021 Oríṣun àwòrán, Instagram/goriolahassan Gẹgẹ bi aṣa ilẹ Yoruba, o ni awọn etutu kan ti ilu gbọdọ ṣe ati eyi ti ọmọ oye to ba fẹ jọba naa ni lati ṣe, ki o to le gori oye.
 Bi, sise okoowo tabi gbe ile-ise sile lai san owo ori fun odun meta latari olugbe ti o po yanturu lorile-ede yii, paapajulo ebun ti a tun ni.
5 90958 Orilẹede Costa Rica 1882 37.
awon opo eniyan se n gba ounjẹ, yoo beere pe ibo ni ounje yii ti n wa.
Awọn ọlọpaa ṣalaye fún ileẹjọ pe ẹrọ ti wọn máa fi n fọ nnkan ọga rẹ ni Danladi jigbe ti o si fẹ ta fawọn to n sa ilẹ kiri ki aṣiri rẹ to tu Wo bí iṣẹ́ abẹ wákàtí mẹ́fà, tí wọ́n fi dóòlà ẹ̀mí ìjàpá tí ọkọ̀ tẹ̀, ṣe lọ Kò sóhun tó ń jẹ́ ‘Captivus’ nílẹ̀ Oodua, mágùn ni mágùn ńjẹ́ - Babaláwo Wo àwọn obìnrin abúlé kan tó dáwó ra ọkọ̀ láti máa gbé aláboyún lọ ilé ìwòsàn Ẹ fi dókítà àgùnbánirọ̀ rọ́pò àwọn dókítà tó ń yanṣẹ́ lódì - Ìjọba àpapọ̀ pàṣẹ Ìtàn rèé nípa bí Ogbomoso ṣe pa ọba, yọ nǹkan ọkùnrin rẹ jó kiri ìlú Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Mayowa Omoniyi: Kò sí orin Obey, Sunny Ade abí tàkasúfèé tí ń kò le ta gìtá sí Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Fídíò, Akomolede: Bolaji Faleke ni Olùkọ́ tó ń kọ́ wa ní àṣà oge ṣiṣe lórí BBC Yorùbá1 Owewe 2020 Fídíò, Akomolede ati Aṣa lori BBC: Mọ̀ si nípa oríṣìí ẹ̀ka ìsọ̀rí ọ̀rọ̀ àti ìwúlò wọn8 Owewe 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 3 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 5 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
O ni ọkunrin kan, Agu Benson lo fi to awọn ọlọpaa leti ni Ogunjọ, Oṣu Kẹfa, ọdun 2020 pe oun ri oku eeyan ninu kanga ile rẹ.
Àwọn ni yóo máa ṣe iṣẹ́ iranṣẹ fún àwọn alufaa ati fún gbogbo ìjọ eniyan Israẹli níwájú Àgọ́ Àjọ bí àwọn alufaa tí ń ṣe iṣẹ́ níbi mímọ́.
Igba naa ni wọn sagbejade aisan to ń ṣe e gẹgẹ bii aisan jẹjẹrẹ ọna ọfun.
Ọ̀kan ninu àwọn eniyan náà wí fún un pé, “Ebi ń pa gbogbo wa kú lọ, ṣugbọn baba rẹ ti búra pé, ‘Ègbé ni fún ẹnikẹ́ni tí ó bá fi ẹnu kan nǹkankan lónìí.
Police Brutality: Ọlọ́pàá kan sọ pé òun ní láti ṣàyẹ̀wò ìlédìí ǹkan oṣù Arabìnrin kan kó tó lè kọjá
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ìpínlẹ̀ Ọ̀ṣun ń sàìsàn, òṣìṣẹ́ ọba ti pọ̀ jù - Oluwo Leah Sharibu ni wòlíì wa ní àgọ́ Boko Haram - Obìnrin tó jàjàbọ́ 2019 Election: Bí Buhari ba le lọ Kóòtù ní ẹ̀ẹ̀mẹ́ta- Obasanjo Baṣọ̀run Gáà, tó yan ọba mẹ́rin, pa ọba mẹ́rin àmọ́ ọba karùn-ún ló pa á Àràmọ̀ǹdà!
O wa rọ ijọba lati 'tun Naijiria ṣe' ki awọn ọdọ lee dẹkun sisa kuro lorilẹede Naijiria lọ soke okun.
Ṣugbọn ṣa, Gomina Sanwo-Olu sọ pe o ṣeeṣe ki isede miran tun waye, ti awọn araalu ko ba tẹle awọn ilana naa.
Pẹ̀lú ìfohùnṣọ̀kan ìbò, àwọn ènìyàn wọ̀nyí fi èrò ọkàn àti ìpinnu wọn hàn láti ṣe àkójọ, ní ìbámu sí àṣẹ Ọlọ́run (wo ìpín 20).
Nigba to n sọrọ lori arun Coronavirus to gbode, ati ipa ti ijọba rẹ n ko lati ṣẹgun arun naa, Fayemi ni ko si ẹni to le sọ pe oun ja ajasẹgun lori arun Coronavirus.
Hushpuppi: Ó di ẹlẹ́wọ̀n tó ní nọ́ńbà l‘Amẹrika, orúkọ̀ rẹ̀ wà lórí ayélujára
OLUWA, ṣe oore fún àwọn eniyan rere,ati fún àwọn olódodo.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ọwọ́ tẹ ọkunrìn tó n fi kẹ́míkà ṣe ìtọ́jú àìsàn jẹjẹrẹ àti ibà.
Ninu lẹta naa ti ajọ Hisbah kọ, o ni ọjọ Mimọ ni ọjọ Jimọ jẹ ninu ẹsin Islam, nitori naa pipe e ni ọjọ dudu jẹ nkan iwọsi.
Ọ̀rọ̀ tí a fi pẹ̀lẹ́ sọ dàbí igi ìyè,ṣugbọn ọ̀rọ̀ ẹ̀tàn a máa bani lọ́kàn jẹ́.
Ni iyawo rẹ̀ bá tún bẹ̀rẹ̀ sí sọkún títí gbogbo ọjọ́ mejeeje tí wọ́n fi se àsè náà.
ba gba eto idibo ti ko ni wahala tabi ojoro ninu laaye, ohun nikan ni ọna ti o
Àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ ń ṣe ohun tí kò tọ́ láti ṣe ní Ọjọ́ Ìsinmi.
Nígbà tí o bá jẹ eniyan níyàpẹlu ìbáwí nítorí ẹ̀ṣẹ̀,ìwọ á ba ohun tí ó ṣọ̀wọ́n fún un jẹ́ bíi kòkòrò aṣọ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Kenyan: Èyí ni bí wọ́n ṣe n lo Facebook lati ṣekupa awọn oníjàgídíjàgan 17 Ìgbé 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 1 Èbibi 2020 Ikọ kan ti wọn furasi pe o n sẹkupa awọn eniyan laarin awọn ọlọpaa orilẹ-ede Kenya, n lo Facebook lati mu ati lati pa awọn ọdọmọkunrin ti wọn gbagbọ pe wọn jẹ ọmọ ẹgbẹ onijagidijagan.
“Nítorí náà, sọ àsọtẹ́lẹ̀ nípa ilẹ̀ Israẹli.
Nitori naa ki ẹgbẹ oṣelu APC yee gbe iroyin sita lati ki ara rẹ ku oriirẹ ki wọn maa so ms ẹgbẹ wa lọrun.
Loju opo Twitter rẹ aarẹ funrarẹ kede ọrọ naa .
Fá gbogbo ọ̀rá tí ó bo ìfun, ati ẹ̀dọ̀ akọ mààlúù náà; mú kíndìnrín rẹ̀ mejeeji, ati ọ̀rá tí ó bò wọ́n; kí o sun wọ́n lórí pẹpẹ náà.
”Obinrin náà dáhùn pé, “N kò ní ohunkohun, àfi ìkòkò òróró kan.
ó ní: “Ẹ̀yin ni n óo fi ilẹ̀ Kenaani fún,yóo jẹ́ ìpín yín tí ẹ óo jogún.
Ajá tí ó yadi ni wọ́n,wọn kò lè gbó;oorun ni wọ́n fẹ́ràn.
Ohun to ba si sọ ni abẹ ge nigba naa nitori oun ni akọwe aato ẹgbẹ Ọlọpẹ, to si ni asẹ lati ni ki awọn to wa nipo asẹ wa kawọ pọnyin ro ẹjọ, ti ohun ti wọn se ko ba dara.
Gomina naa so pe ” leyin ijiroro pelu opolopo awon eniyan, mo pinnu lati darapo mo egbe oselu PDP’’.
 Ó pè é ní il popolo d ' italia .
Àkọlé àwòrán, Ajo INEC leyin idibo naa sọ wi pe idibo naa lọ ni irọwọrọsẹ laisi si ifarapa.
Nítorí Kristi ni ohun gbogbo, tí ó wà ninu ohun gbogbo.
A ti yanjú ìṣẹ̀lẹ̀ ìjàmbá ọkọ̀ agbépo tó dànù lágbègbè AIT, Alagbado - LASEMA Alagbado tanker overturned: Àjọ LASEMA láwọn ti yanjú ìṣẹ̀lẹ̀ ìjàmbá ọkọ̀ agbépo tó dànù lágbègbè AIT, Alagbado Oludari agba ajọ LASEMA ni awọn ti di gbogbo ibi ti iṣẹlẹ yii ti waye pẹluu kiki foomu ki iṣẹlẹ naa ma tun lọ bi omii.
”O ṣalaye pe ni ipele ijọba ipinlẹ, ko si ani ani pe awọn ara ilu ni  ipinlẹ Eko ti n jere  ijoba tiwantwa pẹlu awọn iṣẹ akanṣe loriṣiriṣi to n lọ laarin ilu ati awọn ohun idagbasoke miiran ti wọn n ṣe fẹni kọọkan pẹlu atilẹyin ofin to tọ.
Tí ó bá di ìgbà náà, àwọn ará Ijipti yóo di obinrin.
Gideoni bá fi wúrà yìí ṣe ère Efodu kan, ó gbé e sí ìlú rẹ̀ ní Ofira, gbogbo àwọn ọmọ Israẹli sì bẹ̀rẹ̀ sí bọ ère oriṣa yìí, ó sì di tàkúté fún Gideoni ati ìdílé rẹ̀.
Nimet: Ẹ ma tii dako nitori ojo akọrọ
Nigba ti amin ayo keji wọle nigba ti o ku iseju marun ki ere pari ti Bukayo Saka ṣokunfa wiwọ le bọọlu naa.
dọla lati fi pese ina mona-mona lati ibi oorun’’.
A gbọ́ pé Ras Kimono jẹ́ ènìyàn tí kíì mu ọtí.
Ti ẹ ko ba gbagbe, Mourinho ti ṣe akọnimọọgba ẹgbẹ agbabọọlu Chelsea fun igba meji ọtọọtọ.
Pasitọ Adeboye fọrọ yii lede loju opo Twitter nigba ti o n daro arẹwa to dagbere faye.
BB Naija: Ẹgbẹ́ MURIC figbe ta kí ìjọba dá a dúró lẹ́sẹ̀kẹsẹ̀
oríṣìíríṣìí ẹ ̀ bùn móríyá àti ìkansáárásí ni bámijí Òjó gbà nígbà tí ó wà lẹ ́ nu iṣẹ ́ ijọba .
Ìwọ lágbára lórí ẹranko ìgbẹ́ àti lórí ejò afàyàfà, kìnnìún àti ìmàdò, ìkòokò àti àjànàkú, òjòlá àti àwọn ejò gbogbo.
Oriṣa pataki ni Osun jẹ nilẹ Yoruba, kaakiri agbaye si ni awọn eeyan ti ma n wa fun ayẹyẹ ọdun Osun Osogbo lọdọọdun.
Gbogbo àwọn alufaa jáde wá láti ibi mímọ́, (nítorí gbogbo àwọn alufaa tí wọ́n wà níbẹ̀ ti ya ara wọn sí mímọ́ láìbèèrè ìpín tí olukuluku wà.
N óo fún ẹni tí òùngbẹ bá ń gbẹ ní omi mu láti inú kànga omi ìyè lọ́fẹ̀ẹ́.
A sì tún gba gbogbo àwọn ìlú wọn tí ó wà ní pẹ̀tẹ́lẹ̀, gbogbo ilẹ̀ Gileadi ati gbogbo ilẹ̀ Baṣani títí dé Saleka ati Edirei, àwọn ìlú tí ó wà ninu ìjọba Ogu, ọba Baṣani.
Nígbà tí mo wò, mo rí nǹkankan tí ó dàbí eniyan.
“Ọ̀rọ̀ ibi dùn lẹ́nu yín pupọ;ọ̀rọ̀ ẹ̀tàn sì yọ̀ létè yín.
Seyi Makinde fojú hàn n'íta lẹ́yìn tó ṣẹ́gun Coronavirus Coronavirus: Ọmọ márùn ún ni mo ní, ṣùgbọ́n kò sí oúnjẹ fún wa lásìkò ìgbélé yìí -Olùgbé ìlú Eko Máfọ́ya, mo wà pẹ̀lú ẹ, Ajimọbi kàn sí Makinde lóri Coronavirus to ni Makinde wọ igbele lọ lati ya ara rẹ sọtọ lẹyin ti ayẹwo fihan pe o ti ko arun Coronavirus.
“Tabi ọba wo ni yóo lọ ko ọba mìíràn lójú ogun tí kò ní kọ́kọ́ jókòó kí ó gba ìmọ̀ràn bí òun yóo bá lè ko ẹni tí ó ní ọ̀kẹ́ kan ọmọ-ogun lójú?
Ṣugbọn n kò fetísí ọ̀rọ̀ Balaamu; nítorí náà ìre ni ó sú fun yín, mo sì gbà yín kúrò lọ́wọ́ rẹ̀.
Fi ọkàn rẹ sí ẹ̀kọ́, kí o sì tẹ́tí sí ọ̀rọ̀ ìmọ̀.
Olufẹmi ni anfaani pupọ wa ninu iṣẹ agbẹ ni Naijiria nitori ilẹ to dara wa ni Naijiria ati oju ọjọ to sunwọn fun eto ọgbin.
Tí a fiṣọwọ́ ní 12:55 29 Èbibi 201912:55 29 Èbibi 2019 Ifeanyi Ugwuanyi ti Enugu rèé ní gbàgede ìbúrawọlé BBCCopyright: BBC Ifeanyi Ugwuanyi ti EnuguImage caption: Ifeanyi Ugwuanyi ti Enugu Article share tools Facebook Twitter ṢàpínlòView more share options Share this post Copy this linkKà síwájú síi nípa àwọn ìtọ́kasí wọ̀nyí.
Ewe, pelu esi ifesewonse naa, iko agbaboolu Super Falcons tun pegede fun idije boolu afesegba lagbaye(2019 World Cup) lọdun 2019.
Nítorí bí Jona ti wà ninu ẹja ńlá fún ọjọ́ mẹta tọ̀sán-tòru, bẹ́ẹ̀ ni Ọmọ-Eniyan yóo wà ninu ilẹ̀ fún ọjọ́ mẹta, tọ̀sán-tòru.
O fikun un pe ija ati asọ lo maa n waye lọjọọjọ ipade awọn obi naa, eleyii ti ko jẹ ki wọn fi imọ sọkan.
Ewe, opolopo eniyan lo ba aare ohun yaworan, ti o fi mo gomina ipinle Eko, onkorin Banky W ati omo oloogbe Kuti, Femi Kuti abbl.
Ní kéte ti pati pari, ti olúkúlùkù sì n jíròrò lọ́wọ́ nínú ilé ìdána, ni Erica ba tún ta mọ Laycon, bẹ́ẹ̀ lo ń pariwo fòò pé, ó maa n parọ fún Ebuka pé òun máa ń gbìyànjú láti fẹnukò òun lẹ́nu ní ẹ̀ẹ̀meeji ọ̀tọ̀ọ̀tọ.
Wọ́n run gbogbo ìlú tí ó wà ní agbègbè Gerari, nítorí pé ẹ̀rù OLUWA ba àwọn ará ibẹ̀.
ẹgbẹrin le mejilelaadota ati miliọọnu ọọdunrun le mẹrindinlogun naira (N852.
UK Covid Vaccine: Arábìnrin ẹni àádọ̀rún ọdún ló kọ́kọ́ gba abẹ́rẹ́ àjẹsára tí Pfizer ṣe síta
Kylie to n ṣe aṣọ jade ni ọkanlelogoje miliọnu eniyan (141 million followers) to n tẹle e, ti owo si n wọle fun atẹjisẹ to ba kọ si awọn ọrẹ rẹ, tabi awọn ti oun tẹlẹ e ni ori ẹrọ ayelujara.
Olùdìbò gé ìka ara rẹ̀ torí ó ṣèṣì dìbò fún ẹgbẹ́ mìíràn A kò mọmọ pá ọdọ́ kan tó kù ní Portharcourt - Ilé iṣẹ́ ọlọ́pàá Ejò lé ààrẹ Liberia kúrò ní ọ́fíìsì Sugbọn bayii, o fẹ lati gbe iṣẹ ọna fifi táyà ọkọ̀ gbẹ ere yii de ibi giga kaakiri agbaye.
Kini o mu ipinnu tuntun Aisha yii wa?
aare, niluu Abuja, eleyi ti aare Muhammadu Buhari tuko re.
 Ó sọ síwájú wí pé òun ń tẹ ́ ẹ lọ ́ rùn àti wí pé kò yẹ kí ó ba inújẹ ́ rárá níwọ ̀ n ìgbà tí oun ti ń ṣe bíi baba fun-un .
 kò sí ẹ ̀ dá alààyè tó dá wà láì ní olùbátan tàbí alájogbé .
"Mo fẹ sọ pe nkan ti awọn oniroyin gbe naa nipa mi kii se otitọ.
Ó ní, “Ìyìn ni fún OLUWA Ọlọrun Israẹli, tí ó mú ìlérí tí ó ṣe fún Dafidi, baba mi, ṣẹ, tí ó ní, 
Nibẹ lo ti dahun ibeere loriṣiiriṣii lori eto oṣelu Naijiria ati bi nkan ṣe ri lasiko yii ninu ẹgbẹ oṣelu PDP.
Ẹni yòówù tí ó bá gbégbá-orókè nínú ìdíje sí ipò ààrẹ ọdún 2019 ní iṣẹ́ ìmúgbòòrò ọrọ̀ Ajé, ààbò ní àárín ìlú, àtúntò agbára àti ìmúkárí agbára, àti ìṣèlú elẹ́yàmẹyà làti ṣe.
Nítorí ẹ mọ̀ pé kì í ṣe ohun tí ó lè bàjẹ́, bíi fadaka ati wúrà, ni a fi rà yín pada kúrò ninu ìgbé-ayé asán tí ẹ jogún láti ọ̀dọ̀ àwọn baba yín.
Oríṣun àwòrán, AFP Àkọlé àwòrán, Ile iṣẹ T-Mobile naka abuku si Huawei pe o ji awọn ni imọ tẹkinọlọgi Ile isẹ orileede Germany kan ti wọn jijọ n ṣiṣẹ pẹlu Huawei lawọn ko gba ọrọ yi gbọ.
Lẹ́yìn náà, ó fa àgbò keji kalẹ̀, èyí tí í ṣe àgbò ìyàsímímọ́.
Ọ̀kọ̀ọ̀kan ninu àwọn ìlú mẹtẹẹta tí ẹ yà sọ́tọ̀ gbọdọ̀ wà ní agbègbè kọ̀ọ̀kan.
Titi di bi ogoji ọdún sẹhin, ilé Bàbá Iyàwó tàbi ọgbà ẹbi ni wọn ti nṣe àpèjọ igbéyàwó.
Àwọn iranṣẹ rẹ̀ dìtẹ̀ mọ́ ọn, wọ́n sì pa á ní ààfin rẹ̀.
O fi kun pe oniruuru ibọn pẹlu ọkẹaimoye ọta ibsn ni wọn tun gba lọwọ awọn ọdaluru kan nipinlẹ naa.
Aṣẹ́wó, olè, gbájúẹ̀ ni 723 ọmọ Naijiria ta lé padà sílé - Ghana Bí Zainab ṣe dèrò ẹ̀wọ̀n Saudi lórí ẹ̀sùn ògùn olóró tí kò mọ̀ Ọmọ Nàìjíríà mẹ́jọ gba ìdájọ́ ikú ní UAE Kókó ìròyìn t'òní: 'Ẹ ṣọ́ra ní London', ‘Ìkọlù darandaran pa èèyàn 2000’ South Africa: Wọ́n jó ọmọ Nàíjììrà nína láàyè Ọjọ kẹẹdọgbọn, oṣu keje ni ijọba apapọ ya sọtọ lati ṣe agbeyẹwo ohun gbogbo to ni ṣe pẹlu awọn ọmọ Naijiria lẹyin odi.
Ẹwẹ, lẹyin ti Florence Otedola ti ọpọ mọ si Chelsea DJ kọ Arsenal silẹ pẹlu omije loju, o ti kede loju opo Twitter rẹ pe oun fẹran ohun ti oun ri lara ẹgbẹ agbabọọlu Chelsea.
Ẹ wò ó, ẹ̀yin ọmọ ilé Israẹli,mò ń mú orílẹ̀-èdè kan bọ̀ wá ba yín, láti ilẹ̀ òkèèrè,tí yóo ba yín jà.
Àwọn obìnrin ilé ìgbìmọ̀ aṣòfin Amẹrika fọnmú sí ọ̀rọ̀ Trump O dí gbére!
Arábìnrin lẹ̀dì àpò pọ̀ pẹ̀lú ọ̀rẹ́kùnrin rẹ̀ pé kó ó jí òun gbe, ọ̀rẹ́kùnrin gba 700k tán ló bá sálọ Wo oríṣìí oúnjẹ márùn ún tó lè dẹ́kun ikùn yíyọ àti ara àsanjù Rògbòdìyàn bẹ́ sílẹ̀ láàrin àwọn ọlọ́kadà àti àwọn òṣìṣẹ́ ọgbà ẹ̀wọ̀n ní Ibadan Wo àwọn oúnjẹ márùn ún tó ń mú kí àtọ̀ ọkùnrin dára síi Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Promise Akinlade: ọmọ ọdún mọ́kànlá tó ń fi ìlù dárà bíi àgbàlagbà sọ̀rọ̀ nípa tálẹ́ǹtì rẹ Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Sedekaya ṣe nǹkan burúkú lójú OLUWA, bí Jehoiakimu ti ṣe.
3bn Nàíjìrìà ti ṣe tán láti f'ẹjọ́ sun EU, UN lórí àwọn akẹ́kọ̀ọ́ tí Croatia le lọ sí Bosnia Ẹsun ti wọn fi kan Trump ni pe pe o gbiyanju lati fi dandan mu orilẹ-ede Ukraine ko lee kede iwadii ọkan lara awọn alatako rẹ lẹgbẹ oṣelu Democrats, Joe Biden ati ọmọ rẹ Hunter.
Mo ṣetán láti dojú ìjà kọ ẹnikẹ́ni tó bá fẹ́ bá ọ̀rọ̀ ajé Eko jẹ́- Sanwo Olu Sanwo-Olu buwọ́lu ìgbésẹ̀ ìjọba láti tún Eko ṣe lẹ́yìn rògbòdìyàn EndSARS Bí àwọn kan tí ń ní àtimọ̀lé tí wọ́n sọ olorin Nazir sí ní Kano ni ọwọ́ kan òṣèlù ní àwọn mii ní.
Atẹjade ajọ NCDC fihan pe eeyan to le ni irinwo lo ko coronavirus laarin ọsẹ meji nipinlẹ Oyo.
Èrò ọkàn yín kò ní ṣẹ: ẹ̀ ń gbèrò ati dàbí àwọn orílẹ̀-èdè mìíràn ati àwọn ẹ̀yà tí ó wà ní agbègbè yín, kí ẹ máa bọ igi ati òkúta.
Ipagọ ẹgbẹ to ni akoyawọ Nkan miran ti igbimọ oludari ẹgbẹ APC tun gbọdọ mojuto ni ṣiṣe ipagọ/ipade ẹgbẹ, ti ko ni mago-mago ninu.
Pasitọ ijọ Redeem, Akolade Arowolo to pa iyawo rẹ: Pasitọ awọn ọdọ kan ninu ijọ Redeem naa gba idajọ iku lori pe o pa iyawo rẹ, Titilayo to n ṣiṣẹ ni ile ifowopamọ kan.
Alaga ile-ise to n ri si isakoso eru ati pasipaaro nipinle ohun, Malam Musa Umar, lo so oro ohun di mimo lakoko iforowanilenuwo pelu awon akoroyinO fikun-un pe, ajo to n ri si iranwo eyawo fun awon agbe ni Naijiria,  Nigeria Incentive–Based Risk Sharing System for Agricultural Lending (NIRSAL), ni yoo pese isuna fun ise akanse ohun.
Ní ọjọ́ náà gan-an, Gadi tọ Dafidi lọ, ó sì wí fún un pé, “Lọ sí ibi ìpakà Arauna kí o sì tẹ́ pẹpẹ kan fún OLUWA níbẹ̀.
Titi di igba to wa kowe fipo silẹ, Adeọṣun ko sọrọ lori rẹ.
Ọrọ owo oṣu naa lo fa wahala laarin wọn.
Bakan naa ni asiwaju ninu ẹgbẹ APC ọhun fikun pe o yẹ kawọn ẹya Igbo dibo fun ẹgbẹ APC nitori ko si igba kankan ti ijọba APC fọwọ rọ wọn sẹyin tabi dẹyẹ si wọn ninu pinpin ere ijọba tiwantiwa.
Tẹ ipa mọ iṣẹ ọwọ rẹ lai ṣe ọlẹ.
Bawo ni o ṣe yẹ ki awọn adari ẹsin maa sọrọ nipa awọn adari oṣelu?
ninu abala kọkanlelogun ofin ọdun 1999 (gẹgẹ bi wọn ṣe ṣatunṣe rẹ) Gomina
Àwọn kan ń gbé tí wọ́n sì ń sọ ìtàn-an wọn tí wọ́n sì ń jà fún ẹ̀tọ́ọ wọn.
Ẹ jẹ ka bojuwo awọn iye igba ti Aisha ti sọrọ nipa ijọba ọkọ rẹ ni sisẹ n tẹle: Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ẹ má bẹ̀rù àgbára ìjọba àpapọ̀, ànàbolẹ̀ ni PDP yoo nà APC - Saraki Ohùn ìjálá lásán ni mo fi ń pa ẹran nínú igbó - Ọdẹ Oníjàálá Mo fẹ́ ọkọ mi torí bó se ń kọrin, kìí se torí owó - Ìyàwó Aràrá Mo fẹ́ kí àyẹyẹ ìgbeyàwó mi dùn ni mo se bú sẹ́kún - Ọkọ ìyàwó ẹlẹ́kún Samuel Ladoke Akintọla jẹ́ Agbẹjọ́rò àti Akọ̀ròyìn tí ọ̀rọ̀ dá lẹ́nu rẹ̀ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ìfipálówó: Bàbá ọmọ tí wọn gé lórí ní òun rán an láti l gbowó lẹ́nu ATM ni Awọn alagbara ti ja ijọba gba mọ ọkọ mi lọwọ Igba akọkọ ti Aisha Buhari kọkọ sọrọ to tako iṣakoso ọkọ rẹ, o sọ pe awọn alagbara ti gba iṣakoso mọ ọkọ oun lọwọ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Omidan jáde láyé lẹ́yìn tí ìlú lù ú, jáa sí ìhòhò lórí ẹ̀ṣẹ̀ tí kò ṣẹ̀ O ni idi niyi ti oun ko fi da si ija aarin awọn mejeeji.
Ninu atẹjade kan ti Ṣoworẹ fi sita ni ọjọ aje, o ni ẹgbẹ oṣelu naa ti kọkọ paṣẹ lọ rọọ kun nile naa fun ọgbẹni Leonard Ezenwa lori awọn ẹsun to rọ mọ ṣiṣe owo ẹgbẹ baṣubaṣu atawọn ẹsun ṣiṣe lodi si eto ẹgbẹ oṣelu naa.
Orúkọ tí a pe ọtí-líle náà ni “8 wine 64″.
Eeyan 4206 lo ti ri iwosan gba, nigba ti awọn 365 ti papoda nitori arun ọhun.
Ẹ ka nipa oun pẹlu nibi: https://www.
Morenike ṣalaye pe, bo tilẹ jẹ pe ijọba n fi iya jẹ awọn ọdaran lori ẹsun miran, eyi ko da iru iwa bẹ duro.
lati lee koju awon ipenija to n dojukọ wọn , paaapaa julo ni ona ati fẹsẹ eto
Mild symptoms of coronavirus : Kíni àwọn àmì nàá, àti ọ̀nà tí o le fi dáàbò bo ara rẹ?
Akeugbagold, nínú fídíò kan tó gbé soju òpó Facebook rẹ ni irọlẹ ọjọ́ Aiku, ní òun àti ìyá ìbejì tí wọn jì gbé lọ, tí ń rọ àwọn ajọmọgbe ọhun pé, kí wọn tú àwọn ìbejì àwọn silẹ.
Orúkọ ẹ̀yà mẹfa sára òkúta ekinni ati orúkọ ẹ̀yà mẹfa yòókù sára ekeji, kí o to àwọn orúkọ náà bí wọ́n ṣe bí wọn tẹ̀lé ara wọn.
Abule oloogbe naa, ti ọpọ eeyan mọ si Ogun Majek, to wa ni agbegbe Elesude, lọna Ọmi ni ilu Ibadan ni wọn yoo sin wọn si.
Super Eagles f'ìyẹ́ bo Carthage Eagles Tunisia mọ́ 'lẹ̀ Ẹ wo báwọn òṣèré tíátà kan yóò ṣe rí lọ́jọ́ ogbó Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Fulani Heardsmen: Afenifere ní àṣẹ tó bá wu àwọn àgbàgbà agbègbè àríwá Nàìjíríà ni Aarẹ Buhari ni iwe ofin orilẹede Naijiria, ijọba Naijiria ati isejọba Aarẹ Muhammadu Buhari yoo da abo bo awọn ọmọ Naijiria ni ibikibi ti wọn ba wa.
Aarẹ Muhammadu Buhari ti gbera kuro ni Naijiria lọsan ọjọ Aiku ni Abuja lọ si orilẹ ede Netherlands nibi ti yoo ti kopa ninu eto iranti ogun ọdun ti ajọ ofin ọdaran agbaye (International Criminal Court:ICC) bẹrẹ ti aṣẹ Roomu.
”Bákan náà ni gbogbo àwọn ọmọ-ẹ̀yìn yòókù sọ.
Ọlọrun bojú wo àwọn ọmọ eniyan láti ọ̀run wá,ó ń wò ó bí àwọn kan bá wà tí òye yé,àní, bí àwọn kan bá wà tí ń wá Ọlọrun.
Oríṣun àwòrán, Twitter Ni oju opo ikansiraẹni Gates Bill, nkan ti wọn ko si bẹ ni pe ti o ba fi $1000 sọwọ si mi, ma a fun yin pada ni $2,000.
Oga agba ile-ise olopaa, Mohammed Adamu, ti seleri lati koju awon idojuko to n koju eto aabo lorile-ede Naijiria.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Valencia vs Chelsea: Oró tó dá mi ni mo dá ọ ni Chelsea àti Valencia fi ṣe fún ra wọn 27 Bélú 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Aileja lojude ile baba mi ko de ibi.
Ẹ máse sọ pátá tí ẹ kò lò mọ́ sibi kan ṣáá.
n se olu-ilu ipinle Niger lojo Isegun(Tuesday).
EFCC ko darukọ ọba alade ti o bawọn pin ninu owo yi amọ ajọ naa ninu ọrọ oju opo wọn ni oludari ileeṣẹ to n risi awọn owo alabọde tawọn mu ti n wi tẹnu rẹ lọdọ awọn.
 champaigne ni oníṣẹ ́ ọnà tí wọ ́ n gbà láàyè loáti ya àwòrán richelieu tí wọ ́ n fi sàmì , tí ó ṣe ní ìgbà mọ ́ kànlá .
 O tun wa ro won lati maa se kaare lati tubo maa se atileyin fun ajọ Nibucaa, nitori  pe ise si tun n bẹ lati se.
Ohun ta gbero ni lati mu idẹkun ba awọn ọmọ Naijiria paapa jullasiko idibo yii."
Lẹ́ẹ̀kan sí i mo dúpẹ́ lọ́wọ́ rẹ fún wíwá tí o wá, bá mi kí ìyàwó rẹ kí o sì kí ẹ̀gbọ́n ọmọ náà fún mi.
Èyí ni ohun ti ìwádìí ìjìnlẹ̀ BBC kan tí wọ́n pè ní 'Beyond Fake News' fìdí rẹ̀ múlẹ̀.
“Ìwọ ọmọ eniyan, àwọn ọmọbinrin meji kan wà, tí wọ́n jẹ́ ọmọ ìyá kan náà.
"Ohun ti Badirat si kọ si abẹ aworan naa ni pe Alaafin n beere pe "" Ṣe o ko ni dẹkun lati maa rẹwa tabi dun wo ni?"
Kano Govnorship Re-run: Gómìnà Ganduje ní òun yóò fara mọ́bí èsì ìdìbò bá ṣe jẹ́
Ó jẹ́ òṣèré, olùdarí eré àti atọ́kùn pẹ̀lú tó máa ń fara hàn nínú eré lédè Yorùba, Igbo tó fi mọ́ Hausa.
Iye ènìyàn tọ gbọ̀dọ̀ péjú lẹ́ẹ̀kan kò gbọdọ jú ìdá ọgbọ́n lọ́, gbogbo àwọn ilé iṣẹ́ yìí si gbọ̀dọ gba iwé ẹ̀rí lọ́dọ̀ ìjọba ìpínlẹ̀ Eko kí wọn to bẹ̀rẹ̀.
O n lu ìlù èmi náà sì ń jó lọ.
Ẹ dìde kí á lè kọlù ú, lóru;kí á wó àwọn ilé ìṣọ́ rẹ̀ lulẹ̀!
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Minimum wage: Gbogbo ìpínlẹ̀ tó wà ní Nàíjíríà ní ìwọ́de NLC yóò ti wáyé 7 Sẹ́rẹ́ 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 8 Sẹ́rẹ́ 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ọ̀rọ̀ ẹ̀kúnwó oṣù tuntun ló ń fa èdèàìyedè láàárín ìjọba àpapọ̀ àti àwọn ẹgbẹ́ òṣìṣẹ́ lórílẹ̀èdè Nàìjíríà Ẹgbẹ oṣiṣẹ lorilẹede Naijiria ti kede pe lọjọ Isẹgun ni iwọde apapọ awọn oṣiṣẹ yoo bẹrẹ jakejado orilẹede Naijiria.
Ileeṣẹ ologun ṣalaye pe awọn ẹrọ ayaworan to n fo lofurufu yii ni awọn yoo lo lati ṣawari ibúba awọn ajinigbe lawọn ipinlẹ yii.
 nítorí owó tó ní yìí ni àwọn ènìyàn ṣe máa n pè é ní ajénifújà , alówó-lódù-bíi-ṣẹ ̀ kẹ ̀ rẹ ̀ .
Ẹfunroye Tinubu - Ògbóǹtagí oníṣòwò, olówò ẹrú àti afọbajẹ Samuel Ajayi Crowther, òjíṣẹ́ Ọlọ́run tó gbé èdè Yoruba lárugẹ Mọrèmi Àjàṣorò, akọni obìnrin tó gba Ilé Ifẹ̀ sílẹ̀ lóko ẹrú Ohun tó yẹ kí o mọ̀ nípa OIC rèé IRIRI DAPỌ LẸNU IṢẸ: Lẹyin ti Dapọ pari iwe lo di gbajugbajaolokoowo ati oloselu.
Biṣọọbu Oyedepo jẹ ọkan pataki lara awọn ojiṣẹ Ọlọrun ni Naijiria ti kii fi ọrọ sabẹ ahan sọ lori ojuṣe tabi aṣiṣe ijọba.
Olúwarẹ̀ ni Alátakò Kristi, tí ó kọ Baba ati Ọmọ.
Lock down: Wo ọ̀nà mẹ́ta tí ìjọba fẹ́ gbà pín owó ìrànwọ́ fún ọmọ Nàìjíríà lásìkò kónílé-ó-gbélé yìí Oríṣun àwòrán, Bashir ahmad Boo ba lẹbẹrun marun naira ni banki, gbagbe owo iranwọ latọdọ ijọba.
Nítorí ìdí èyí, mo bẹ̀ ọ nítorí Olódùmarè, tẹ́tí sílẹ̀ ki n bá ọ sọ̀rọ̀ méjì tàbí mẹ́ta: àwo ti ẹnikẹ́ni ko fọ̀ láti ayébáyé, máṣe fi mmu omi mọ́ gẹ́gẹ́ bí ìà rẹ àtijọ́, ọbọ̀ tí kò ni epo, tí kò ní iyọ́ m€tàdínlọ́gbọ̀n nínú ayé kò yẹ ọmọ ènìyàn, yé é bá àwọn ará ile Òmùgọ́ parapọ̀ tọ́ ọ wà, gẹ́gẹ́ bí ìwà wọn.
Adajọ mẹta lo jọ fẹnuko lati sọ ọdi ofin pe ki wọn fi aaye gba.
Tẹ́lẹ̀ rí, nígbà tí a ti ń ṣe ìfẹ́ inú wa bí ẹlẹ́ran-ara, èrò ọkàn wa a máa fà sí àwọn ẹ̀ṣẹ̀ tí Òfin dá wa lẹ́kun rẹ̀, láti tì wá sí ohun tí àyọrísí rẹ̀ jẹ́ ikú.
Oríṣun àwòrán, Olawale Abolade O ní kaadi ko le dede jona, awọn kan lo lọ fi ina sii.
Ìgbà tí èmi àti ọba sí wọlé, wọn kò dákẹ́ rárá, ẹnìkan kò tilẹ̀ sọ pé òun rí wa ṣùgbọ́n nígbà tí ọba kígbe sókè, tí ó dìde dúró, tí ó ní kí àwọn ka ìgbàgbọ́ nípa oúnjẹ, ṣe ni gbogbo wọn dákẹ́ minimini.
6m táwọn ọmọ ogun jí gbé sálọ nínú ọkọ̀ agbówórìn?
Nítorí pé, eniyan rẹ ni wọ́n, ohun ìní rẹ ni wọ́n sì jẹ́, àwọn tí o fi agbára ńlá ati ipá kó jáde.
Ẹwẹ, o ni idi to tun fi ṣe pataki lati ma a jẹ ounjẹ aṣaraloore ki oyun to o waye ni pe, ọpọ obinrin ni kii tete mọ pe awọn ti loyun, ni ọsẹ mẹjọ akọkọ, to si jẹ pe ko si atunṣe fun kudiẹkudiẹ to ba ti waye lasiko naa mọ.
Ambode salaye pe, ise-akanse yii je eri pataki ti o safihan ipinnu ijoba lati mu idagbasoke ba eto oro-aje ni ibamu pelu awon orile-ede yoku lagbaye.
 gẹ ́ gẹ ́ bí mo ti fẹnu bà á ní ọ ̀ rọ ̀ àkọ ́ sọ , ìbágbé pọ ̀ àwọn èèyàn ni ó mú eré àpíìrì tàn kálẹ ̀ ní Ìwọ ̀ oòrùn Èkìtì .
Aina òrósùn ni ọkan ninu awọn orukọ amutórunwa ti ọmọ Yoruba n jẹ bii oriki.
"Soyinka fikun pe, bi ijọba ṣe dakẹ lai fọhun lori ọrọ naa bi oun ninu, amọ ọpọ awọn ti inu n bi bii ti oun, ni ko fẹ sọrọ to le da nnkan ru.
Kàyééfì: Deji pa èèyàn mẹ́sàn án nítorí ìfẹ́ Top sticks Onilu gboriyin fún Baba rẹ pé oun ló n polowo iṣẹ oun julọ lati kekere.
Ajagunfẹyinti Olayanju tun sisọ loju rẹ pe awọn osisẹ Amotekun ko lee jẹ puruntu nikan nitori wọn gbọdọ mọ nnkan kọ tabi ka lati fi lo awọn ẹrọ igbalode kan feto aabo.
Koda ọpọlọpọ fidio lawọn ọmọ Naijiria fi ranṣẹ si Mama Adeboye gẹgẹ bi ikini ku ọjọ ibi to fi mọ awọn oṣere adẹrinpoṣonu gan atawọn ọmọ ijọ irapada naa.
 O je omoluwabi to sa ipa re fun idagbasoke ise ere onise ati fiimu agbelewo nile Geesi.
OLUWA ní:“Bí ó bá tilẹ̀ ṣeéṣe láti gba òǹdè lọ́wọ́ alágbára,tabi láti gba ìkógun lọ́wọ́ òkúrorò eniyan.
akọ mààlúù kékeré kan ati àgbò kan, ọ̀dọ́ àgbò kan ọlọ́dún kan, fún ẹbọ sísun, 
Ipo kan naa ni wọn ba Titilayo, ko si omi kankan lara rẹ.
Bákan náà ni ọmọ Lefi kan.
Idije Asaba 2018 bẹ̀rẹ Awọn kan lara awọn elere idaraya to fẹ kopa ninu idije ere idaraya laarin awọn orilẹ-ede nilẹ Afrika, All African Games, to n bẹrẹ ni ilu Asaba, ti se olu ilu ipinlẹ Delta, l'ẹkun aarin gbun-gbun Guusu Naijiria, ni ko ti i gunlẹ si ibi ti idije naa yoo ti waye, lai fi ti idije naa to yẹ ko bẹrẹ lọjọru ṣe.
Nítorí náà máa lọ sí ilé rẹ.
Aare yoo ba awon ti oro naa kan se ipade papo , lati fun won ni omi suuru mu , ki o si tun lee  dekun ona lati gbesan laarin awon agbe ati odaran .
Lọjo ti wọn pa, o jade pẹlu ọrẹkunrin rẹ.
Àbí ó lè máa kọ ebè lọ láì ní ààlà?
 Ẹ ̀ dà kóńsónáǹtì tí ènìyàn yóò mú lò dúró lóró fáwẹ ̀ lì tí kóńsónáǹtì náà yóò bá jẹ yọ .
Ó dá a lóhùn pé, “Tí wọ́n bá fi okùn titun, tí wọn kò tíì lò rí dè mí, yóo rẹ̀ mí, n óo sì dàbí àwọn ọkunrin yòókù.
Ara agbegbe Kirkissoye kan ni yi ni Niamey to n wo ile rẹ ti omi ya wọ ti ko si si nkan to le ṣe.
Kissit Golit osise ile-ise akoroyin Voice of Nigeria ti gba ife-eye idije boolu afibaati gba lori tabili ti iko obinrin (Women’s 2nd NUJ Chapel Table Tennis tournament).
Lẹyin ọ rẹyin Mercy lo jawe olubori lori eto ọhun, oun lo ẹbun owo ọgọta miliọnu naira lọ ile.
Wọn fi oṣu mẹfa kun saa ti wọn yoo lo.
Gẹ́gẹ́ bí Ọlọrun ti ṣe é gbẹ́kẹ̀lé, ọ̀rọ̀ wa pẹlu yín ti kúrò ní “bẹ́ẹ̀ ni” ati “bẹ́ẹ̀ kọ́.
Àwọn ọmọ Harimu jẹ́ ọọdunrun ó lé ogún (320)
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Serena Williams bí ọmọbinrin ti orúkọ rẹ̀ ń jọ́ Olympia lọ́dún 2017 Ṣugbọn aarẹ ajọ French Open, Bernard Giudicelli, ni ofin tuntun ko ni gba iru ẹ laaye mọ.
Ẹ yàgò fún ìwà adìẹ dàmí lóògùn nù, màá fọ lẹ́yin lásìkò ìjà - Buhari Tottenham na Man City bí olè tó jí ike owó Ọ̀rọ̀ǹpọ̀tọ̀niyùn, Aláàfin obìnrin àkọ́kọ́ rèé, tó ní nǹkan ọkùnrin Ètò ìdìbò gómìnà ìpínlẹ̀ Kogi àti Bayelsa m bọ̀ lọ́nà- INEC Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Lasiko naa Sheikh Abdulwahab n kẹkọ nigba naa ni.
Ìbànújẹ́ sọ ojú mi di bàìbàì,agbára káká ni mo fi lè ríran nítorí ìnilára àwọn ọ̀tá.
“Ní ọdún kẹtakẹta, tíí ṣe ọdún ìdámẹ́wàá, tí o bá ti dá ìdámẹ́wàá gbogbo ìkórè oko rẹ, kí o kó wọn fún àwọn ọmọ Lefi, ati àwọn àlejò, ati àwọn aláìní baba, ati àwọn opó, kí wọ́n lè máa jẹ àjẹyó ninu ìlú yín.
Olopaa ipinle Borno ti so pe awon olujosin meji ni won ku, ti awon eniyan mejo si farapa , nigba ti awon omobinrin meji  to di ado oloro mora kolu mosalasi kan, nibi ti won gbe n josin ni Bama.
O ni gbogbo akitiyan ajọ naa lati ko awọn awakọ Micra"" kuro ni ibudokọ ti wọn ti n ko ero ki ọna ọhun le ja gaara lo ja si pabo."
”Aare so pe ajo eto idajo je okan lara awon egbe ti awon eniyan n bowo fun lawujo, nitori naa , o ye ki awon naa le maa se idanilekoo fun awon eniyan.
Ó ní òun kò sì leè sọ ọpọ ohun tí ojú òun ti rí, kí òun tó já ojú ọ̀nà Okunnu ṣàlàyé pé ọ̀pọ̀ èèyàn ló ti kọkọ sina, kò tó jánà, tí yóò sì ti koko rìn àwọn irin kan, kí Ọlọ́run tó wà fi ọna hán-an.
won si ninu  osu kẹ́rin  ati ojo kárùndínlọ́gbọ̀n
Kí ẹ rí i dájú pé ẹ kò jẹ ẹ̀jẹ̀ rẹ̀ nítorí pé ninu ẹ̀jẹ̀ ni ẹ̀mí wà, ẹ kò sì gbọdọ̀ jẹ ẹran pẹlu ẹ̀mí rẹ̀.
 Ó tó miliọnu 130-170 káàkiri àgbáye tí wọn ní àrùn hepatitis c.
Iyẹn lo mu ki awọn ọlọpaa lọ pọ sii wa.
Bẹẹ ba wo awọn onimọ nipa ibalopọ jakejado agbaye, wọn o ki n fẹ keeyan maa ṣẹnu ku pe awọn ẹya ara to wa fun ilo ibalopọ lakọ labo.
Oríṣun àwòrán, @NGRPresident Àkọlé àwòrán, Ìpàdé FOCCAC yoo ma jiroro lori ọna ati tunbọ mu idagbasoke ba orileede Afrika ni ifọwọsowopọ pẹlu China Ipade oun to waye ni ile ise orileede Naijiria ni China ni akọkọ ipade Buhari lati igba to ti gunlẹ si China fun ipade ẹlẹẹkeje ti yoo waye ni ọjọ kẹta si ikẹrin ni Beijing.
Awọn ọlọpaa pada ri ageku okó naa to fi eyin ge jabọ, wọn si ti mu lọ sileewosan fun itọju.
6 Má ṣe kùn sínú, ọmọ mi, nítorí ó jẹ́ ọgbọ́n nínú mi pé mo ti hùwà sí ọ ní ọ̀nà yìí.
"Jegede kasẹ ọrọ rẹ nilẹ pe ""ni ti idibo to n bọ lọna yii, a o ni fi ọmọ ṣe""."
Lọdun 2013, Oprah Winfrey ṣabẹwo si ile iwosan rẹ nibi to ti ri to n ṣe iṣẹ abẹ lai lo irinṣẹ abẹ.
Ẹnikẹni to ba fẹ fọ ọwọ yoo lo ẹsẹ rẹ lati fi tẹ omi ati ọṣẹ jade ninu ẹrọ onaa lai fọwọ kan an.
– Kí ni ayé ọmọ ènìyàn já sí?
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ajọ SERAP sọrọ lori owo ifẹhinti awọn oloselu kan Ogagun Sadique ni ki olori ẹka aato ileeṣẹ ologun ofurufu, Kingsley Lar bẹrẹ igbesẹ lori eto idanilọla naa.
Ṣugbọn wọ́n gbàgbé OLUWA Ọlọrun wọn.
Ọgọọrọ ọmọ orilẹ-ede Naijiria lo ṣedaro Ọjọgbọn Pius Adesanmi to wa lara awọn to padanu ẹmi wọn ninu ijamba baalu Ethiopia to ja lulẹ lọna Nairobi.
Lionel Messi darapo mo awon akegbe re lojo Isegun(Tuesday) ni papa isere Manchester City lati gbaradi fun ifesewonse olorejore pelu iko agbaboolu Italy.
Ó dìgbà, ìyá mi, máa lọ sínú òkú; máa simi kúrò nínú làálàá ayé; kúrò nínú làásìgbò àwọn ọmọ ènìyàn, ni ọjọ́ tí ikú bá pa ojú mi dé, a ó máa fi ojú gán-ánní ara wa.
Eyi ni awon ifesewonse ti yoo waye ninu idije NPFL(Nigeria Professional Football League), lojo aiku(Sunday):Enugu Rangers ?
Ó ní èyí ni láti le máa dóòlà ẹ̀mí àwọn ènìyàn to ni ààrùn kan tàbi òmíràn.
Ni ọjọ Kẹta Oṣu keji ọdun 1976 ijọba ologun pin awọn ipinlẹ Ariwa yii si Bauchi, Borno ati ipinlẹ Gongola.
Sugbọn awọn ọmọ Naijiria ti n se eemọ lori igbese yi.
Oríṣun àwòrán, Instagram/djswitch_ Akinkanju obinrin naa pari ọrọ rẹ pe, oun ko faramọ bi awọn eeyan ṣe n jo awọn ọkọ akero, ṣugbọn oun yoo ṣi tun kopa ninu iwọde kannaa lọjọ iwaju.
Ó wà lára àwọn tí Nebukadinesari ọba Babiloni kó lẹ́rú láti Jerusalẹmu lọ sí ilẹ̀ Babiloni pẹlu Jekonaya, ọba Juda.
Kì í ṣe ohun tí ó jẹ́ anfaani tèmi ni mò ń wá, bíkòṣe ohun tí ó jẹ́ anfaani ọpọlọpọ eniyan, kí á lè gbà wọ́n là.
Oríṣun àwòrán, Presidency Ikọ olujẹjọ ni bi akojọpọ esi ibo aarẹ naa ba lọ bo se yẹ ko lọ, apapọ esi ibo to yẹ ki ẹgbẹ oselu PDP ati oludije rẹ fun ibo aarẹ gba ni 9,426,082, eyi ti wọn lo tayọ apapọ ibo Buhari ati APC tii se 9, 203,750.
Ewe, lasiko sise agbekale ewu igbaboolu iko Super Eagles fun oludari agba ile ifowopamo Zenith, ogbeni Peter Amangbo, gege bi ebun fifi ore han saaju atileyin ti o ran iko Super Eagles lowo lati pegede fun idije 2019 AFCON.
Gẹgẹ bi iṣe bi ọdun tuntun ba ti n wọle wẹrẹ ni awọn ojiṣẹ Ọlọrun, Alufaa, Imaamu atawọn olori ẹsin gbogbo yoo maa jade pẹlu ohun ti wọn ba ni Ọlọrun ba awọn sọ.
Fi wúrà tí wọ́n fi ọmọ owú lù ṣe Kerubu meji, kí ọ̀kọ̀ọ̀kan wà ní ẹ̀gbẹ́ kinni keji ìtẹ́ àánú náà.
Gbogbo àwọn tí wọ́n fi ọwọ́ kàn án ni ó mú lára dá.
Ẹ wo márùn ún lára àwọn tí ilé ẹjọ́ ti yọ kúrò nípò lẹ́yìn ìdìbò ọdún 2019 Àwọn ọmọ Naijiria ti ń wọ bàálù láti South Africa báyìí Kí a tó sanwó ajínigbé ní àwọn agbófinró dóòlà ọmọ Ọffa mẹ́fà -ODU Gbàgbé ẹ̀sọ́ ara $40m rẹ pátápátá - Ilé ẹjọ́ sí Dienzani O rọ awọn ololufẹ rẹ lati má ṣi oun mu mọ fun Àrá nitori ọtọ ni tọ́lú ọtọ dẹ ni tọ̀lù ni awọn mejeeji.
Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí 5:55 Fídíò, Soyinka Cancer: Àṣe ara mi ni iso ti n run gbogbo bí mo ṣe n ṣèrànwọ́ lórí jẹjẹrẹ, Duration 5,5527 Bélú 2019 11:51 Fídíò, EndSARS, EndSWAT Protests: Òbí agbábọ́ọ̀lù Kazim Tiamiyu Kaka àtàwọn míì tí ọlọ́pàá pa sọ̀rọ̀, omijé bọ́ lójú, Duration 11,513 Bélú 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
kaare lati tubo maa pese ina mona-mona fun awon omo orile ede Naijiria.
Nígbà tí ilẹ̀ mọ́, obinrin yìí bá lọ wó lulẹ̀ sì ẹnu ọ̀nà baba arúgbó náà níbi tí ọkunrin tí ó mú un wá wà, ó wà níbẹ̀ títí tí ilẹ̀ fi mọ́ kedere.
O ni ẹbi kan naa ni gbogbo ọmọ Naijiria, ko si si ọta kankan laarin wọn.
"Fasiti Kaduna ni ki olùkọ́ lọ rọọ́kún nílé látààrí ẹ̀sùn pé ó ń dúnkookò mọ́ akẹ́kọ̀ọ́ Seun Egbegbe lo ọdún méjì àti oṣù méje lẹ́wọ̀n láì tìí san béèlì rẹ̀ À ń gbé ìjọba ìpínlẹ̀ Ọyọ lọ si ilé ẹjọ- Ẹgbẹ́ Fulani darandaran Iléeṣẹ́ Instagram wọ́gilé App ""Augmented Reality filters"" lórí ẹ̀rọ rẹ̀ Bayii, sophie ti ronu ara rẹ pe, o dara ki eeyan maa gba bi ara rẹ ṣe ri ki o si maa fun ara rẹ ni iwuri."
Ẹ̀ẹ̀kejì, tí wọ́n bá pèsè epo-rọ̀bì tó káárí gbogbo gbòò, wọ́n á yéé gbé èpò sẹ́hìn ọkọ̀ rìn.
” Bí ó ti ń bá mi sọ̀rọ̀ lọ́wọ́, mo dìde nàró, ṣugbọn mo ṣì tún ń gbọ̀n.
Gege bi o se so, “O fihan gbangba-gbangba pe, opo egbe oselu ni o kuna lati se idibo abele, sugbon ti won gbaruku ti oludije ti o wa latowo gomina ti o wa lori aleefa, eleyi ti ko si ba ofin mu rara.
Ọmọ náà jọ ọ́ gidigidi, bí Adamu ti rí gan-an ni ọmọ náà rí.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Tani otutu ma n mu ju laarin Ọkunrin ati Obinrin?
Nàíjíríà yóò gba ife ẹ̀yẹ AFCON 2019 tí Super Eagles bá.
Amọ'sa, Okorocha ni esi ti oun fun Oṣinbajo nigba naa ni pe owo ti oun yoo fi ṣe eto ṣiṣi awọn akanṣe iṣẹ naa, oun yoo lo fi kọ kilasi miran sawọn ileewe.
Bakan naa, ajọ NJC ni ki adajọ agba tuntun Mohammed ti Aarẹ Buhari ṣẹṣẹ bura fun wa sọ tẹnu rẹ idi ti o fi gba iyansipo naa lai jẹ pe ajọ NJC fọwọ si.
" Awo ọrọ nipa iwe ẹri Ọgbẹni Akinọla Olugbenga Ọlaolu lu sita ni ọsẹ diẹ sẹyin nigbati iroyin tan pe iwe ẹri ti o fi gba iṣẹ gẹgẹ bii giwa ileeks gbogbounṣe ilu Igbajọ kii ṣe otitọ ati pe arakunrin naa ko kẹkọ gboye ọmọwe, PhD ni fasiti ilu Ibadan Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ojú mi ti rí lọ́pọ̀ lọpọ̀, àmọ́ mo dúpẹ́ pé mo ti pé ọdún márùn ún lórí oyé- Ooni O ṣalaye ninu iwe ifisun to kọ pe ajalu nla gbaa lo ṣẹlẹ si ẹbi oun o wa fi kun un pe ki wọn sọ ileto oun di ibudo ikonkan iṣẹmbaye si.
Alagba Rafiu Balogun toun pẹlu jẹ oṣere tiata, akọtan ati olotu ere ni ọkọ 'Madam ṣajẹ' Gẹgẹ bi a ti ṣe gbọ, o ti le ni ọgbọn ọdun ti awọn mejeeji yii ti pade ara ni ikorita irinajo ifẹ.
Popoola sọ pe ijọba ti ṣe atunṣe awọn ọna miran ti awọn eeyan le maa gba lasiko ti iṣẹ ba n lọ lọwọ lori afara Third Mainland.
'Kò tọ̀ọ́ kí olórí Nàìjíríà tó bá ní coronavirus gba ìtọ́jú ní ìlú tí kìí ṣe tirẹ̀' 4.
Ẹ kò gbọdọ̀ ṣe iṣẹ́ líle kan, ẹ sì níláti rú ẹbọ sísun sí OLUWA.
Kí alufaa pè é ní mímọ́.
Oríṣun àwòrán, @GovKaduna Lenu ọjọ mẹta yi,Gomina ipinlẹ Kaduna Ahmad El Rufai ti n ṣe ipade orisirisi pẹlu awọn olori ẹya ti ọrọ ija to bẹ silẹ yi kan.
Nígbà tí ó tó bí agogo mejila ọ̀sán, òkùnkùn bo gbogbo ilẹ̀ títí di agogo mẹta ọ̀sán.
Ṣugbọn a óo gé ọ lulẹ̀ pẹlu àwọn igi ọgbà Edẹni, a óo sì wọ́ ọ sọ sí ìsàlẹ̀ ilẹ̀.
Ọdún-un 1610 ni Dhaka di olú-ìlúu Bengal, ìyẹn ogójì ọdún sẹ́yìn.
Ninu fidio mii ti Lizzy gbe jade yii lo ti ni Ẹbẹ ti mo bẹ kii ṣe fun Toyin, sugbọn o wa fun awọn ẹbi ati awọn ololufẹ mi ni."
Nígbà tí kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ náà rí i, ó fún ara rẹ̀ mọ́ ògiri, ẹsẹ̀ Balaamu sì fún mọ́ ògiri pẹlu, Balaamu bá tún lù ú.
 “ Ẹ jẹ ki gbogbo wa
"Àwọn èèyàn fi ìtara ba ilé ìjọsìn jẹ́ Òbítíbitì ẹ̀gbin ti sọ ìlú Ibadan di ààtàn - Aráàlú figbe bọnu Àwọn ẹni òkùnkùn ló já ìṣẹ́gun mi gbà, mò ń lọ sílé ẹjọ́ tó ga jùlọ - Bayo Adelabu ""Aug 2018 ni ìgbìmọ̀ aláṣẹ APC ti ṣe ìpàdé kẹ́yìn, Oshiomole ti kùnà"" Nigba to n sọ bi isẹlẹ ọhun ti ka lara to, baba Eniola ni orisirisi ipe lo n wọle sori ẹrọ ibanisọrọ oun wipe, ti awọn ko ba jawọ ninu wiwa ọmọ naa, o seese ki ẹmi oun ati iya rẹ gan lọ si."
Orukọ wọn 'Coptic' tumọ si 'ọmọ Egipti', awọn kritiẹni to wa ni orilẹede Egypt si n pe ara wọn ni ẹlẹsin kristiẹni Coptic.
Lára ọ̀kan ninu àwọn ìwo mẹrin ọ̀hún ni ìwo kékeré kan ti yọ jáde, ó gbilẹ̀ lọ sí ìhà gúsù, sí ìhà ìlà oòrùn ati sí Ilẹ̀ Ìlérí náà.
Lẹ́yìn náà, ọkunrin náà mú mi gba ẹnu ọ̀nà ìhà àríwá wá siwaju tẹmpili; mo sì rí i tí ìtànṣán ògo OLUWA kún inú tẹmpili, mo bá dojúbolẹ̀.
Oríṣun àwòrán, Twitter/Mr_JAGss Ẹka ọgbin, irina, aabo ati ẹkọ naa ko gbẹyin ninu awọn ti yoo jẹ ninu mudunmudun iṣuna ọdun 2021 yii.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Coronavirus Updates in Nigeria: Baba Obasanjọ kò ní àrùn Coronavirus 9 Ògún 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 10 Ògún 2020 Oríṣun àwòrán, Kehinde Akinyemi Aarẹ orilẹ-ede Naijiria tẹlẹri, Oloye Oluṣẹgun Obasanjo ko ni arun Coronavirus.
Lọdun 2019 lo pe ogoji Ọdun.
Gideoni bá gba oúnjẹ àwọn eniyan náà ati fèrè ogun wọn lọ́wọ́ wọn, ó sì sọ fún wọn pé kí wọ́n pada sí ilé, ṣugbọn ó dá àwọn ọọdunrun (300) náà dúró.
Nígbà tí angẹli mi bá ń lọ níwájú rẹ, tí ó bá mú ọ dé ilẹ̀ àwọn ará Amori, ati ti àwọn ará Hiti, ati ti àwọn ará Perisi, ati ti àwọn ará Kenaani, ati ti àwọn ará Hifi, ati ti àwọn ará Jebusi, tí mo bá sì pa wọ́n run, 
Wọn ni niwọn igba ti awọn banki ba fi gbedeke ọjọ silẹ lasiko ti wọn n ṣe BVN, o ṣeeṣe ki awn naa ṣe bẹẹ fun eto yii.
ati àwọn ará Hori ní orí Òkè Seiri, títí dé Eliparani, lẹ́bàá aṣálẹ̀.
Gẹ̀ẹ́sì gbẹ́sẹ̀ lé ₦82bn owó Abacha BBC Yoruba ko fẹ ki èdè, àṣà ati ìṣe Yoruba parun ni a ṣe n gbe awọn ibeere yii wa.
L'Ọ́ṣun, àwọ̀n oníròyìn meji di tíṣà ọ̀sán gangan
 ni 1999 ati 2005 , o je didiboyan bi aare lisi alatako .
1, Elijah ni yíò fi oyè-àlùfáà hàn; 2–3, Àwọn ìlérí ti àwọn bàbá ni a gbìn sínú ọkàn àwọn ọmọ.
Ò ṣe f'ọ́mọ tí ń jeérú!
Mose fún Aaroni ati àwọn ọmọ rẹ̀ ní owó ìràpadà náà gẹ́gẹ́ bí OLUWA ti pàṣẹ fún un.
Kí ló dé, ọmọ mi,tí ìfẹ́ alágbèrè obinrin yóo fi wọ̀ ọ́ lọ́kàn,tí o óo fi máa dìrọ̀ mọ́ obinrin olobinrin?
Jotamu ọmọ rẹ̀ di alákòóso ìjọba, ó sì ń darí àwọn ará ìlú.
nina owo ile okeere , yala ti orile ede Amerika (dollar)tabi  owo orile ede South African (rand) ni lorile
8 25730 Orilẹede Belarus 1564 16.
 nítrójìn bíi ẹ ́ límẹ ̀ ntì jẹ ́ ẹ ̀ fúùfù átọ ̀ mùméjì aláilawọ ̀ , aláìlóòórùn , aláìní-ìtọ ́ wò àti aláìkópa ní ìgbà onídéédéé , tó jẹ ́ 78.
Ṣugbọn wọ́n ń gbọ́ pé, “Ẹni tí ó ti ń fìtínà wa tẹ́lẹ̀ rí ti ń waasu ìyìn rere igbagbọ tí ó fẹ́ parun nígbà kan rí.
Wo bí èsì ìdìbò ìpínlẹ̀ Edo ṣe ń jáde Èèyàn 189 ní àrùn Coronavirus tún ṣẹ̀ṣẹ̀ ràn ní Nàìjíríà Lẹ́yìn olóògbé Barrister àti Kollington, èmi làgbà kàn nínú iṣẹ́ orin Fuji- Obesere yarí ''Operation Burst'' ti mú Eji, tó gba ipò Ebila olórí ''One Million Boys'' ní ìpínlẹ̀ Oyo Ninu atẹjade naa ni wọn ti fikun un wi pe awọn ẹsọ alaabo ti wa ni pesẹ lati ri i wi pe ayẹyẹ naa lọ ni irọwọ-rọsẹ.
Midtjyland, Denmark); Kelechi Iheanacho (Leicester City, England); Samuel
Messi ati Tite tahun si ara wọn nigba ti ere bọọlu naa si n gbona girigiri, bo tilẹ jẹ pe Messi naa lo gba goolu kan ti ẹgbẹ agbabọọlu Argentina fi bori sawọn.
se pa oko naa ti si ebute omi to wa ni Onne ni ipinle Rivers.
Akuila ati Pirisila ati ìjọ tí ó wà ní ilé wọn ki yín pupọ ninu Oluwa.
Àwọn olóṣèlú, àti àwọn Ọba n gbàbọ̀dè fún ìpínlẹ̀ Ekiti lórí ọ̀rọ̀ àwọn tó n fi ipá bánilòpọ̀- Kọmísọ́nnà ètò ìdájọ́ Ọ̀rọ̀ àsọkẹ́yìn Diego Maradona ìlúmọọká agbábọ́ọ̀lù rèé kó tó dágbére f'áyé Orúkọ Aisha Yesufu náà wọ inú BBC 100 Women tí a fi ń sọri àwọn obìnrin tó pegedé ní 2020 Omotara ni: ''Mo kan fẹ tọrọ aforijin nitori gbogbo nkan to ṣẹlẹ kan n waye lera wọn ni.
Oríṣun àwòrán, Speaker media department Ìjọba ìpínlẹ̀ Kogi kéde ọjọ́ ìwọlé àwọn akẹ́kọ̀ọ́ padà sí iléèwé Ará ìlú figbe ta bí wọ́n ṣe ní jálá epo bẹntiróò ṣe tún lọ sókè di ₦151.
Sergio Aguero ati Bernado Silva lo gba bọọlu naa wọnu awọn, to si mu ki Manchester City bori ninu ifẹsẹwọnsẹ naa.
Ọlọ́pàá tó mú àwọn obinrin wọ gau -Ọ̀gá ọlọ́pàá Ọlọ́pàá yọ Yomi Shogunle kúrò ní adarí ẹ̀ka PCCRU Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Intersex: Kò dẹrùn láti sọ wí pé kòjako-kòjabo ni mí Gẹgẹ bi ile isẹ to n risi ọrọ ile gbigbe ati isẹ se sọ, ọdun 2014 ni wọn ti gbe isẹ naa fun wọn, ti o si jẹ pe mẹtala ninu mọkandinlogun isẹ ti wọn gba ni wọn se.
Oríṣun àwòrán, Google Owó Shile meji yii pọ ju oun ti awọn ẹlẹgbẹ rẹ maa n ni lọwọ nigba yẹn torinaa ni wọn ṣe kuku fi jẹ oye ẹni ti yoo maa yi owo ẹyọ onidẹ lasiko ti wọn ba fẹ gba eree bọọlu.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Àlá àwọn òjíṣẹ́ Olúwa tó fẹ́ jẹ ààrẹ Nàíjíríà leè má ṣẹ lógún ọdún - Abiara Ìjọba Buhari kò mọ̀ pé ìyà ń jẹ́ aráàlú ló ṣe ní ebi kò pa wá - Ọmọ Nàíjíríà Ọba Lamidi Adeyẹmi, òṣìṣẹ́ adójútòfò àti Abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò kó tó jọba Yatọ̀ fún orí ìtàgé, wo ohun tí o kò mọ̀ nípà Mr Latin Amọ nigba ti wọn n da si ọrọ yii, oniruuru ero ni awọn ọmọ Naijiria fi han nipa isẹlẹ naa.
com Àkọlé àwòrán, Kiprotich gba aadọta ẹgẹrun dọla gẹgẹ bi ẹbun fun sise ipo kíní Ayẹ̀yẹ̀ ti bẹ̀rẹ̀ ni pẹrẹu lẹyin ti awọn oludije ati awọn akopa miiran ti n de ibudo ayẹyẹ fun idije ọun ti awọn ti wọn jawe olubori si ti foju han.
Idibo ẹlẹẹkarun yoo waye ni oni laago mẹta abọ ọsan (15:30 BST) si aago marun un abọ (17:30).
Won gbe igbese yii nitori isele to waye lasiko eto idibo gomina  , nibi ti awon oludibo  ti n ta ibo won  ni ipinle Ekiti.
" Sheikh Taofeeq Akeugbagold tí wọn jì ìbejì rẹ lọ lọ́jọ́ Satide to kọjá, tí kọ́kọ́ kéde pé, Gẹ̀ẹ́sì tó yọ lẹ́nu bíi ti oyinbo ni àwọn ajọmọgbe tó bá òun sọ̀rọ̀ ń sọ lẹ́nu Akeugbagold ni èyí fihan pe àwọn akẹ́kọ̀ọ́ jáde Fáṣítì làwọn ajomogbe ọhun, to sì ń ké sí ìjọba láti tètè pèsè isẹ fáwọn ọdọ tí kò nise lọwọ.
Wúrà ni kí o yọ́ bo gbogbo òpó náà, kí wọ́n sì wà lórí ìtẹ́lẹ̀ fadaka mẹrin.
Ṣugbọn bí mo bá ń ṣe é, èmi kọ́ ni kí ẹ gbàgbọ́, àwọn iṣẹ́ tí mò ń ṣe ni kí ẹ gbàgbọ́.
Igi Kedari ni òpó ilé wa,igi firi sì ni ọ̀pá àjà ilé wa.
Bakan naa tun ni a ṣagbeyẹwo ohun ti o n fa ti iru iṣẹlẹ bayii ṣe wọ pọ nilẹ Afirika.
“Kí wọ́n fi igi akasia kan àpótí kan, kí ó gùn ní ìwọ̀n igbọnwọ meji ààbọ̀, kí ó fẹ̀ ní igbọnwọ kan ààbọ̀, kí ó sì ga ní igbọnwọ kan ààbọ̀.
Toò, ọ̀rọ̀ mi ò jù báyìí lọ.
Awọn kan laera awọn ọdọ naa gbe kẹkẹ, ọkada, ọkọ bọọsi lati fi ko awọn ounjẹ ti wọn n ji ko nibẹ naa.
Wọn kò wẹ egbò àwọn eniyan mi jiná, wọ́n ń kígbe pé: ‘Alaafia ni, alaafia ni’,nígbà tí kò sí alaafia.
Ilé ẹjọ́ tú Sowore sílẹ̀, wọ́n gba onídùúró rẹ̀!
Champions League Final: Liverpool dín dòdò ìyà ṣínu ààwẹ̀ fún Tottenham
Oríṣun àwòrán, @Julisco_ O ni bi ọwọja idẹyẹsi yii ti ṣe wa peleke bayi, ijọba Naijiria gbọdọ gbe igbese to le, ki South Afrika ba le mọ pe ko fi ọwọ yẹpẹrẹ mu ẹmi awọn ọmọ ilẹ rẹ lẹyin odi.
 Alhaji Lai tun ro awon ipinle miiran ti o n koju awon ikolu ohun lati fowosowopo koju awon isoro naa  Tobi Sangotola.
Coronavirus and OCD: 'Mo fi ogún ọdún gbáradì fún àjàkálẹ̀ ààrùn yìí' 'Èkúté jẹ oògùn olóró níbi tí wọn fi pamọ sí ní àgọ ọlọpàá Kíni ẹ̀yin mọ̀ nípa iṣẹ́ ọnà ti a fi ìṣó ṣe?
Iwọde to ti n waye lori ikede siso ijokoo ile rọ: Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Awa ko faramọ igbesẹ Boris yii nia riwo ti wọn mu bọ ẹnu Lọjọru ni awọn eniyan bẹrẹ iwọde niwaju English parliarment ni Westminster.
Amọ sa, ipadabọ mi jẹ pẹlu ọkan ọtọ Olukọni ikọ agbabọọlu Liverpool, Jurgen Klopp, ni inu oun dun fun anfaani lati jẹ olukọni fun Salah."
Ṣugbọn ṣa, minisita fun eto ilera ni Naijiria, Dokita Osagie Ehanire sọ fun BBC pe ọwọ araalu ni ọna abayọ wa, to fi mọ awọn olori ẹsin ati ileeṣẹ iroyin, lati maa la awsn eeyan lọyẹ pe fun anfaani ara wọn ni ofin ijọba.
Ṣugbọn inú bí Ọlọrun sí Usa, ó sì lù ú pa, nítorí pé ó fi ọwọ́ kan Àpótí Majẹmu, ó sì kú níwájú Ọlọrun.
Frapuccinno yìí, omi-dídì ni wọ́n fi nṣe é.
omo ile Igbimọ Asofin, awọn gomina kookan.
Ẹ̀rù ń bà mí pé kí ohun tí n óo bá láàrin yín má jẹ́ ìjà ati owú jíjẹ, ibinu ati ìwà ọ̀kánjúwà, ọ̀rọ̀ burúkú ati ọ̀rọ̀ ẹ̀yìn, ìgbéraga ati ìrúkèrúdò.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Akwa-Ibom:Mílíọ́nù mẹ́wàá Náírà ni ilé ẹjọ́ ni kí Kábíyèsí san gẹ́gẹ́ bí owó ìtaran ilẹ̀ tí ó gbà lọ́nà àìtọ́ 23 Bélú 2020 Ilé ẹjọ́ kòtẹ́milọ́run kan tó fi ìlú Calabar ṣe ìbùjókòó, ti dája lórí ẹja ilẹ̀ kan láàrín ìjọba ìbílẹ̀ méjì ní Akwa Ibom.
Abẹwo awọn aṣoju Naijiria si ibudo naa, Tajoura, lẹyin iṣẹlẹ naa to waye l'Ọjọru fihan pe, ọmọ Naijiria mẹsan an lo wa lara eniyan bi i mẹrinlelogoji to ku sinu isẹlẹ naa.
"O ni ""Gomina Ipinlẹ Oyo ko fi igba kankan pe oun lori aago tabi fi ọrọ itunu ransẹ fun osu kan ti ọkọ oun fi wa ni idubulẹ àìsàn, iru oselu wo wa nìyẹn?"
wọ́n jẹ gbogbo ewé tí ó wà ní ilẹ̀ wọn,ati gbogbo èso ilẹ̀ náà.
O fi ofin silẹ lati ma jẹ ki awọn eeyan rẹ ni anfani awọn nkankan bii gbigbọ rẹdio tabi wiwọ gilaasi oju koda to fi m yiyan ẹni ti wọn yoo fẹ funrawọn, ọrọ ileewe tabi bi wọn ba fẹ kuro lorilẹede.
‘Buhari kò bú àwọn ọdọ’ Buhari ṣ'eleri iṣẹ f'awọn ọdọ Buhari wa ẹnu si àwọn ọdọ Nàìjíríà ‘Irọ́ ni pé Ọmọ ọdọ̀ Ọpẹ Bademosi kú’ Ọdọ́bìnrin kan dáná sun ara rẹ̀ lórí ọ̀rọ̀ ìfẹ́ Awọn ọlọpaa ilẹ Mozambique ṣalaye pe, ọdọmọkunrin yii gbagbọ pe oṣó ni baba rẹ lo ṣe gbe e sin laaye.
Àwọn olùgbé Fiditi pé fún ìrànlọ́wọ́ lórí àwọn òrùlé tí atẹ́gùn ojó ṣí lọ Ìjí líle, Cyclone Fani, kọlu Ìlà-Oòrùn India Ìkìlọ̀ ẹ̀kun omi wáyé fún ìpínlẹ̀ méjìlá Àkójọpọ̀ àwòrán Òjò òwúrọ̀ Ọjọ Àjé l'Eko Ramla jẹ́ ọ̀dọ́mọbìnrin ajẹ̀sẹ́ àkọ́kọ́ ní Somalia Ọmọ ti o ba doju bolẹ nigba ti a bii ni iran Yoruba maa n pe ni Ajayi.
Awọn amugbalẹgbẹ ati ọrẹ rẹ kan to ba ikọ BBC sọrọ fi idi rẹ mulẹ, amọṣa wọn bu ẹnu atẹ lu iwa naa.
Psquare Peter Okoye, àbúro Linda, Laure Ikeji Kanu àti ọkọ rẹ̀ wà lára àwọn to wà níbi àpejẹ náà.
Wọn ni ohun ti Yahaya Sharif Aminu ṣe ti ileẹjọ Sharia fi ni ko gba idajọ iku nipasẹ isọrọ lodi si Anabi Muhammed ko ba igbagbọ ẹgbẹ ẹlẹsin Islam Tijjaniyya mu.
Bi ọrọ naa ṣe ri re nilu Kano nigba ti arakunrin ọmọ orileede China kan di akọkọ ọmọ orileede rẹ ti wọn yoo fi jẹ oye nipinlẹ Kano.
oselu APC gbodo pese oludari fun ile igbimo asofin mejeeji lataari bi awon se
Láyé òde òní, ìyípadà ti dé bá ọjọ́ ìsọmọlórúkọ.
Ọmọ Naijiria - BBC News Yorùbá BBC News, YorùbáFò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Russia 2018: Ọjọ́ 11 ní à ò fí jẹun tí kò rí ibi sùn - Ọmọ Naijiria 14 Agẹmo 2018 Oríṣun àwòrán, Yulia Siluyanova Àkọlé àwòrán, O ní nígbà ti ọ̀rọ̀ náà sẹlẹ̀ obinrin kan tó ń mójú to àwọn ti irú ìṣẹ̀lẹ̀ bẹ́ẹ̀ bá sẹlẹ̀ sí Yulia Siluyanova ló ti kọ̀kọ̀ bẹ̀rẹ̀ ìtọ́jú wọn kí ó tó pe òhun.
Ẹgbẹ oṣelu NNDP ni ajọsẹpọ pẹlu Northern People's Congress (NPC) to n ṣakoso ijọba apapọ nigba naa.
O ti bi ọmọ mẹrin tẹlẹ, fun ọkunrin meji.
Nígbà tí àwọn òkè ńlá rí ọ,wọ́n wárìrì;àgbàrá omi wọ́ kọjá;ibú òkun pariwo,ó sì gbé ọwọ́ rẹ̀ sókè.
Ni nkan bi ọdun 1820, ipolowo fun ẹbun ọdun Keresimesi bẹrẹ si ni tan kiri orilẹ-ede Amẹrika, nigba ti yoo si fi di ọdun 1940, Baba Keresi naa ti bẹrẹ si ni farahan daada ninu ipolowo ọja.
Oríṣun àwòrán, Bose Àkọlé àwòrán, Gbèdéke ọjọ́ méje ni wọ́n fún fásitì náà làti san owó orí ọ̀hun.
Pásítọ̀ Adeboye kéde ààwẹ̀ ọjọ́ 63 fọ́mọ ìjọ rẹ̀, ariwo sọ lórí ayélujára Báwo ni #stingymenassociation ṣe gba ojú òpó twitter kan?
#NotTooYoungToRun: Seun Fakorede ẹni ọdún 27 di kọmísánà l'Oyo
26 Bélú 2020 Elon Musk, Ọ̀gá àgbà iléeṣẹ́ SpaceX, Tesla CEO ń bá Bill Gates du ipò ẹni tó lówó jùlọ ṣèkejì lágbayé26 Bélú 2020 4:48 Fídíò, Akọ́mọlédè àti Àṣà lórí BBC Yorùbá: Kọ́ síi nípa iṣẹ́ tí oúnjẹ ń ṣe lára níbí, Duration 4,4824 Bélú 2020 Èyí tí a wò jùlọ 5:03 Fídíò, Omolola Arohunmolase Welder: Mo ti fí iṣẹ́ 'Welder' gbayì láwùjọ, tó mo fi tọ́ ọmọ yanjú, Duration 5,039 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 5:39 Fídíò, Akomolede ati Asa lori BBC: Olùkọ́ Kikelomo Ogunboye tan ìmọ́lẹ̀ sí ìwà olè ọ̀gá ọlọ́pàá Audu gẹ́gẹ́ bí àwòkọ́ṣe àsìkò yìí, Duration 5,398 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 4:11 Fídíò, Oba Adeyeye Ogunwusi: Ojú mi ti rí lọ́pọ̀ lọpọ̀, ọ̀pọ̀ èèyàn ni kò tilẹ̀ gbàgbọ́ pé mo lè jọba- Ooni, Duration 4,117 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 4:43 Fídíò, Promise Akinlade: ọmọ ọdún mọ́kànlá tó ń fi ìlù dárà bíi àgbàlagbà sọ̀rọ̀ nípa tálẹ́ǹtì rẹ̀, Duration 4,437 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 0:59 Gbọ́, Ìsẹ̀lẹ̀ jákèjádò orílẹ̀èdè àgbáyé láàárín ìṣẹ́jú kan, Duration 0,59wákàtí 5 sẹ́yìn 7:03 Fídíò, Olumuyiwa Bolade Adedeji Military Bruitality: Bí arákùnrin onípèníjà ara tí sọ́jà lù ṣe dé, Duration 7,035 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 4:45 Fídíò, Yoruba Films: Ẹ̀ẹ́ bẹ̀ mi kúrò láyé ni, mi ò lè kú - Fadeyi Oloro, Duration 4,4526 Èrèlè 2020 2:48 Fídíò, Esther Ajayi: Èmi náà ti borí ìṣòro rí ló ń mu mi ṣojú àánú, Duration 2,481 Ògún 2019 6:08 Fídíò, Adebola Ademilua: Àìrísẹ́ ṣè lẹ́yìn ìwé kíkà ló sọ mi dí ìyá onírú, mo dúpẹ́ tèmi, Duration 6,0827 Bélú 2020 2:36 Fídíò, Sotitobire: Ìdájọ́ òdòdò ló fẹsẹ̀ múlẹ̀ lórí ọ̀rọ̀ Pásítọ̀ Sotitobire - Agbẹjọ́rò fún ìjọba, Duration 2,367 Ọ̀wàrà 2020 BBC News, Yorùbá Ìdí tí ẹ fi le è nígbàagbọ́ nínú ìròyìn BBC Ìlànà Lílò Nípa BBC Òfin Àṣírí Cookies Kàn sí.
Gege bi iwe isiro ajo isokan agbaye
Ṣé ìwọ ní ìpinnu ọdún tuntun?
Kí ló dé tí orúkọ baba wa yóo fi parẹ́ kúrò ninu ìdílé rẹ̀ nítorí pé kò ní ọmọkunrin?
Wọn kò gbọdọ̀ gbé orí ilẹ̀ yín, kí wọ́n má baà mú yín ṣẹ èmi OLUWA; nítorí pé bí ẹ bá bọ oriṣa wọn, ọrùn ara yín ni ẹ tì bọ tàkúté.
Wo àwọn olorì àgbà mẹ́rin tí Aláàfin ń wárí fún Èèmọ̀!
Liverpool lu Chelsea lálùmọ́lẹ́ bíi bẹ̀m̀bẹ́ Nínú akànṣẹ́ mẹ́ta ọmọ Nàìjíríà tó dáńtọ́ lágbàáyé, Yorùbá méjì wà nínu wọn €10,000, ara owó tí wọn fi ra Ighalo pòórá, Ilé aṣòfin Osun bẹ̀rẹ̀ ìwádìí Ronaldo ati Messi yoo kojú ní Champions League tọdun yii Amọ, Frank Lampard ti rọ awọn agbabọọlu rẹ lati farabalẹ nitori ere ṣẹṣẹ bẹrẹ ni.
G Primary School, Beyerunka, Alafara Oje ni Temitọpẹ lọ.
Ọ̀rọ̀ ìjókòó ìgbìmọ̀ ìwádìí #EndSARS náà dé ìpínlẹ̀ Ogun Ijoko akọkọ igbimọ iwadii lori iwa ifiyajeni eyi ti ijoba ipinlẹ Ogun gbe kalẹ yoo bẹrẹ lọjọ karun un, oṣu Kọkanla tii ṣe ọjọbọ.
Nigba naa awọn ẹgbẹ figilante ilu Ikire ti dara pọ mọ Aladesewa ti wn si jọ lọ si ile ti awọn ọdaran to ku n sa pamọ si.
Dokita naa sọ pe ere idaraya le ran ọkunrin lọwọ lati fi opin si ti tete da 'ejaculation', aile ṣe deede ninu ibalopọ.
Kutukutu owurọ ọjọbọ lawọn oṣiṣẹ naa ti ya bo olu ileeṣẹ ọhun pẹlu awọn patako alakọle ti wọn kọ awọn ẹhonu wọn si.
Ọjọ́ ń gorí ọjọ́, sibẹ adájọ́ yìí kò fẹ́ ṣe nǹkankan nípa ọ̀rọ̀ náà.
Ati pe ẹgbẹ APC naa ṣi n woye bi nkan ṣe nlọ nile aṣofin.
O ti kọ òfin OLUWA sílẹ̀, OLUWA sì ti kọ ìwọ náà ní ọba Israẹli.
Samuel fikun pe inagijẹ Shagidon lo wu oun lati jẹ, ti oun si ge kuru si Brọda Shaggi.
Ile-ifowopamo agba lorile-ede Nigeria Central Bank of Nigeria (CBN) so pe, ohun ti se atunse si ilana ti awon agbe fi le ri eya-wo, eyi ti ko ni ere ninu.
Ile-ise Dangote Cement ja wale si N1 eyi ti o pajude si N259, nigba ti ba adinku ba oja idokowo ile-ifowopamo United Bank for Africa pelu 45k ti o si pajude si N12.
Wọ́n gbẹ́ ère oriṣa Aṣera, wọ́n sì ń bọ àwọn ohun tí ó wà lójú ọ̀run ati oriṣa Baali.
 Ìsòrí kọkànlá yìí ni ó ti hàn gbangba pé fọláṣadé , ọ ̀ kan nínú àwọn ìyàwó orímóògùn ni ó jí owó rẹ ̀ gbé .
O ni awọn orin ti Naira Marley n kọ ni imisi Eṣu ninu, eyi to le ṣakoba fun ọjọ iwaju ati ayanmọ awọn ọdọ ni Naijira.
N óo run àwọn ère ati àwọn òpó oriṣa yín, ẹ kò sì ní máa bọ iṣẹ́ ọwọ́ yín mọ́.
Kì í ṣe pé ó lókìkí nìkan ni, ṣugbọn òun ni ẹni tí gbogbo àwọn ìjọ yàn pé kí ó máa bá wa kiri nípa iṣẹ́ oore-ọ̀fẹ́ tí à ń ṣe fún ògo Oluwa ati láti fi ìtara wa hàn.
Ṣugbọn, gbogbo àwọn tí wọ́n bá jẹ yín run, ni a óo pada jẹ run.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Seriki Williams Abass: Ọba Badagry tó jẹ́ ẹrú, tó tún padà di olówò ẹrú 20 Ògún 2020 Oríṣun àwòrán, Others Arise ni arika, arika si ni baba iregun, ọpọ ohun ti a ba se ni oni, n bọ wa di itan to ba di ọla.
"Níbi ìpàdé àwọn oníròyìn tí wọn ti sàlàyé ọ̀nà tí wọn gba mú arábìnrin Mohammed ṣe ló kígbe pé ""irọ́ ní'' Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!"
nile ejo to ga julo lorile ede yii ati lati lee je ki won se isẹ lori ọkẹaimọye
Ìdí tí mo fi kọ ìwé sí yín ni láti fi dán yín wò, kí n lè mọ̀ bí ẹ bá ń gbọ́ràn sí mi lẹ́nu ninu ohun gbogbo.
Naijiria ti ro aare Muhammadu Buhari lati tubọ fun awon obinrin laaye sii dipo
Ṣugbọn ńṣe ni ó túbọ̀ ń kígbe pé, “Ọmọ Dafidi, ṣàánú mi.
Ibodè tí a tì ló fa ọ̀wọ́ngógó owó ọjà- Ìjọba Naijiria Ilé ìwòsàn New Jersey ṣ'àṣìṣe ṣiṣẹ́ abẹ kìndìrín fún aláìṣàn l'Amẹrika EFCC fẹ́ gbẹ́sẹ̀ lé ilé tí mo fi owó ìfẹ̀yìntì kọ́ nílùú Ilorin- Saraki Ẹ wo ìpínlẹ̀ táwọn gómìnà tẹ́lẹ̀ àti igbákejì wọn ń gba dúkìá ìfẹ̀yìntì tabua Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Àwọn mìíràn ti kùnà nípa irú èyí; wọ́n ti yipada sí ọ̀rọ̀ asán.
“Àwọn erékùṣù rí i, ẹ̀rù bà wọ́n,gbogbo òpin ayé gbọ̀n rìrì wọ́n ti súnmọ́ tòsí, wọ́n ti dé.
Ó rò pé, Beijing ló yẹ á bá wí.
Iwadii tiẹ tun fihan pe niṣe lawọn mii dana sun ara wọn ti wọn sì gba ibẹ dero ọrun.
Nígbà tí kò bá rí, á ní, ‘N óo tún pada sí ilé mi níbi tí mo ti jáde kúrò.
Liigi orilẹede Germany: awọn ẹgbẹ agbabọọlu ti pada si papa igbaradi ṣugbọn wọn ṣi gbe liigi orilẹede naa kọ di Ọgbọọjọ oṣu kẹrin.
Ọpọ onitiata to dudu si lo di pupa, ki wọn le maa lo wọn ninu ere.
sọ pe egbe  UfUK duro fun alaafia, ifẹ,
Aisha Buhari sàtìlẹyìn fáwọn ọ̀dọ́ tó fọnmú lórí ìyànsípò àwọn alátakò sínú ìjọba APC Àwọn àrùn aṣekúpani ti ń yọjú torí àìgba abẹ́rẹ́ àjẹsára Ẹ wo olùdíje mẹ́ta tó ń du ipò olótú ìjọba Gẹ̀ẹ́sì Ayinla Ọmọwura, orin èébú àti oríyìn lo fi di ọ̀rẹ́ àwọ̀n obìnrin O fikun wi pe, loore koore ni oun yoo ma a kan si awọn ọba naa, lati fun oun ni imọran ati ijiroro lori ọna abayọ si ipenija eto aabo.
mejeeji, bi o se pe awon mejeeji ti fi igba kan je oludari ijoba ologun, ki won
Omotosho ni o jẹ alaga igbimọ tẹẹkoto ti apapọ ẹgbẹ APC lawọn mọ ni Ekiti.
Ọgbẹni Tao Tofeek ti o jade sọrọ lorukọ Ẹgbẹ Awọn Oniṣẹ-ọwọ ati Olokoowo (Lagos State Council of Trade Men and Artisans (LASCOTA) ẹka ti agbegbe Agboyi-Ketu, lẹyin ti o gboriyin fun ijọba ipinlẹ Eko fun iṣẹ idagbasoke wọn gbogbo, o wa ke gbanjari si ijọba fun ipese iṣẹ fun awọn ọdọ nipa riro wọn lagbara imọ ati iṣẹ, ki wọn le ri iṣẹ ṣe lawujọ gẹgẹ bi ọna kan gbogii ti yoo le ṣadinku iwa ọdaran.
"Ohun to jẹ ki n gba lati dije bii igbakeji fun Buhari tẹlẹ ni eto atunto Naijiria to mu ni ọkunkundun nigba naa, eyi ti ileesẹ aarẹ ni ko se koko mọ̀ bayii.
Ìjọba kò là ṣe àyẹ̀wò ju ẹgbẹ̀rún márùn-rún lọ nínú iye mílílọ̀nù èèyàn to wà ní ìpínlẹ̀ Eko.
Okunrin kan kú lójijì lẹ̀yin ọjọ̀ díẹ̀ to jẹ milionu kan dọ́là Emma Shields to ṣaaju iṣẹ iwadii naa ni France ni wọn ṣee pẹlu o le ni ẹgbẹrun ọgọrun un eniyan ni eyi ti wọn ṣe odiwọn ọti ẹlerindodo ti wọn n mu.
Gomina sọ pe awọn ọlọpaa naa ti n koju igbimọ olubawi nileeṣẹ ọlọpaa ni kiakia.
Awọn ti Ambọde pe ko wa jẹjọ lori ọrọ naa bayii ni olori ile aṣofin ipinlẹ Eko, Mudashiru Ọbasa, akọwe agba ile aṣofin ipinlẹ Eko, A.
“Nítorí pé ó ga sókè fíofío, góńgó orí rẹ̀ wọ inú ìkùukùu lójú ọ̀run, ọkàn rẹ̀ sì kún fún ìgbéraga nítorí gíga rẹ̀.
O dá a, ipò rẹ̀ rẹlẹ̀ díẹ̀ ju ti àwọn angẹli lọ fún àkókò díẹ̀.
Orúkọ wọn tun jẹ jade lasiko isede coronavirus laarin oṣu Kẹrin si oṣu Karun un, ọdun 2020, fun pe wọn n ka àwọn eeyan mọ́lé lati ja wọn lólè nipinlẹ Eko.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ukraine President: Zelensky jẹ ààrẹ, ọ̀pọ̀ adẹ́ẹ̀rínpòṣónú Nàìjíríà kún ojú òṣùwọ́n jú àwọn adarí wa lọ 20 Èbibi 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 21 Èbibi 2019 Oríṣun àwòrán, Gbenga Adeyinka/instagram Agba ọjẹ adẹrinpoṣonu l'orilẹede Naijriia, Gbenga Adeyinka , ti sọ pe pupọ ninu awọn adẹrinpoṣonu ni Naijiria lo ni imọ, to si koju oṣuwọn lati di ipo oṣelu mu.
Àfonífojì ìpànìyàn ni a óo máa pè é.
Gbogbo àwọn orílẹ̀-èdè yóo kúrò lábẹ́ òjìji rẹ̀, wọn yóo sì fi sílẹ̀.
Akọroyin BBC to ṣe abẹwo si ile oloogbe to wa ni adugbo Idi Ishin nilu Ibadan jabọ pe ẹbi, ara, ọrẹ ati awọn olubanikẹdun ti n pejupesẹ si ile oloogbe naa.
9 768 Orilẹede Gilbraltar 5 14.
Wọ́n kó gbogbo wọn wá fún ọrẹ ẹbọ fún yíya pẹpẹ sí mímọ́, lẹ́yìn tí wọ́n ta òróró sí i.
Bi o tilẹ jẹ pe Toyin ko sọ pato ohun to n kọ ọ lominu to fi kọ awọn ikilọ yii sita.
Buhari ti be awon toro kan gbongbon ninu egbe oselu All Progressives Congress
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Erin fara gbọgbẹ̀, ó ṣekú pa ènìyàn méjì ni Liberia 18 Òkùdu 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Erin Erin kan to fara gbọgbẹ ti doju ija kọ awọn eeyan agbegbe ila oorun ariwa Liberia ti o si ṣeku pa eeyan meji.
Kọmiṣọna ọlọpaa nipinlẹ Eko, Edgal Imohimi lo fi afunrasi olorin naa han awọn oniroyin ni ọjọ Aje lori ẹsun nini ibọn lọwọ lai bá òfinmu ati gbigbimọran lati yinbọn lu ọlọpaa.
 Ààrẹ Ìṣọ ̀ kan , jefferson davis , àti ijọba rẹ ̀ tokú bá ẹsẹ ̀ wọn sọ ̀ rọ ̀ .
Napoleon paá láṣẹ fún àwọn ọ̀jọ̀gbọ́n àti onímọ̀ orílẹ̀èdè rẹ̀ pé kí wọ́n wá ọ̀na tí àwọn jagunjagun òun lè fi máa kàwé nínú òkùnkùn láì tan iná kalẹ̀.
atundi ibo to waye ni ọjọ kẹ́tàlélógún (23rd ) osu keta.
Ayederu Iroyin Awọn ayederu iroyin naa n mu ki awọn eniyan o ni igbagbọ pe, awọn oloṣelu n fi aarun Ebola pa owo si apo ara wọn."
Àdùnní: Òun ni ìyá Dúró Orímóògùnjé.
O ni ọjọ mẹwaa pọju fun aarẹ lati fi aga rẹ silẹ lọ lai fa ijọba le ọwọ ẹni kankan.
“Aare ran mi lati fi dayin loju pe, iru isele buruku yii ko ni waye mo rara, bee si ni ijoba yoo na owo iranwo si awon eniyan ti o fara kaasa isele naa.
Gíga ilé Ọlọrun náà gbọdọ̀ jẹ́ ọgọta igbọnwọ, (mita 27), kí ìbú rẹ̀ sì jẹ́ ọgọta igbọnwọ, (mita 27).
gege bi aare ati igbakeji ni deede aago meji osan lojoRu oni.
Àwọn aṣekúpani tún ti pa ọmọ ọdún 16 ní Akinyele nípìnlẹ̀ Oyo Gómìnà ìpínlẹ̀ Ekiti, Kayode Fayemi nàá ti ni aàrùn Coronavirus Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Funmi Adewara: Tele Medicine' ní a fi ń ṣàyẹ̀wò èèyàn ìdá ọgọtá láti dènà ìtànkálẹ̀ Covid Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Ṣọọṣi, mọṣalaaṣi ati gbogbo ile ijọsin ni yoo wa ni titi pa kaakiri orilẹede.
Oun ni ọmọ adulawọ akọkọ to ṣiṣẹ pẹlu ileeṣẹ Formula 1.
Àwọn ni Olori Badirat Ọlaitan Adeyẹmi tó bí ìbejì ọkùnrin nínú oṣù Kẹta.
Ni Rakẹli ati Lea bá dá a lóhùn pé, “Ǹjẹ́ ogún kan tilẹ̀ tún kù fún wa ní ilé baba wa mọ́?
yálà o lọ́wọ́ sí i tàbí o kò lọ́wọ́ sí i.
Ìjọba àríwá Italy fẹ́ dé èèyàn 16 mílíọ̀nù mọ́lé lórí àrùn Coronavirus Odunlade fẹ́ j'ọba, Bolanle Ninalowo fun ìyàwó rẹ̀ ni ẹ̀bun kanka, Pá Kasumu rebi àgbà ree Ìdá 90% nínú àwọn olówó Naijiria lo n lọ ilé babaláwo- Mr Latin Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, International Womens day: Àwọn obìrintọ́kasí pàtàkì ìbáraẹnidọ́gba láárin ọmọnìyàn Ha, adilemu Everton, Jordan Pickford ko tun ri nkankan 'piiki' o.
Ninu awọn to ni ka maa gbaa gbọ ni aarẹ Trump wa.
Mika ní ojúbọ kan fún ara rẹ̀, ó dá ẹ̀wù funfun kan, ó sì ṣe àwọn ère kéékèèké.
 láìpẹ ́ , wọ ́ n kàá sí wípé ó gbéléayé láàrin ọduń míliọ ́ ọ ̀ nù 3.
Ṣugbọn àwọn ẹrú tí ẹ fi owó rà, tí ẹ sì kọ ní ilà abẹ́ lè bá yín jẹ ẹ́.
Wọ́n ní, “O wọlé tọ àwọn eniyan tí kò kọlà lọ, o sì bá wọn jẹun!
Bẹ́ẹ̀ sì ni mo ti fi ojú rí Ọba, OLUWA àwọn ọmọ ogun.
Aworan wọnyii wa lati ileesẹ AFP ati EPA Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Nígbà tí Uraya gbọ́, ẹ̀rù bà á, ó sì sálọ sí ilẹ̀ Ijipti.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Chelsea vs Tottenham: Lampard àtàwọn agbábọ́ọ̀lù Chelsea dọ́wọ́jọ wó òrùlé Stamford Bridge lu Mourinho àti Tottenham 22 Èrèlè 2020 Oríṣun àwòrán, Getty Images Agbaọjẹ agbabọọlu Chelsea tẹlẹ, to ti di akọnimọọgba ẹgbẹ agbabọọlu naa bayii, Frank Lampard lo moke ninu ija oun ati ọga rẹ, Jose Mourinho ni papa iṣere Stamford Bridge lọsan ọjọ Satide.
O ni ẹgbẹrun kan Naira ni obinrin kọọkan labule naa fi bẹrẹ ẹdawo ọhun loṣooṣu.
A si gbodo tele eto ilana yii nitori pe , o ni i se pelu ofin eto ajo idibo orile ede Naijria.
A fún ìràwọ̀ yìí ní kọ́kọ́rọ́ kànga tí ó jìn tóbẹ́ẹ̀ tí eniyan kò lè dé ìsàlẹ̀ rẹ̀.
“Àwọn nǹkan àṣírí mìíràn wà, tí kò hàn sí eniyan àfi OLUWA Ọlọrun wa nìkan, ṣugbọn àwọn nǹkan tí ó fihàn wá jẹ́ tiwa ati ti àwọn ọmọ wa títí lae, kí á lè máa ṣe àwọn nǹkan tí ó wà ninu ìwé òfin yìí.
”Afọ́jú náà dáhùn pé, “Olùkọ́ni, mo fẹ́ tún ríran ni.
Amọ, onimọ ọrọ aje, Ọgbẹni Bisi Iyaniwura sọ pe irinajo Aarẹ Buhari silẹ okeere lati igba to ti dori aleefa lọdun 2015 ko tii nipa rere kan lori ọrọ-aje orilẹ-ede Naijiria.
Iṣẹlẹ naa ṣẹlẹ kete ti Buhari bẹrẹ abẹwo ọlọsẹ kan si ipinlẹ Katsina tii ṣe ipinlẹ rẹ.
Nígbà tí wọ́n dé ibi tí wọn ń pè ní, “Ibi Agbárí”, wọ́n kàn án mọ́ agbelebu níbẹ̀ pẹlu àwọn arúfin meji náà, ọ̀kan ní ọwọ́ ọ̀tún, ekeji ní ọwọ́ òsì.
"Mọ̀ síi nípa ìtàn ojúbọ̀ nàá Aya gómìnà Kwara gba ilé fún Risikat olójú búlúù àti ọkọ rẹ̀ Aṣòfin méje yarí mọ́ Akeredolu lọ́wọ́ torí ọkọ̀ ayọ́kẹ́lẹ́ tí kò pín fún wọn Risikat, ìyá àwọn ọmọ olójú búlù tí bẹ̀rẹ̀ sí ní kọ́sẹ́ aṣojú lóge Àwọn ọ̀daràn tó jí ìbejì ọmọ Akeugbagold kó ti fojú ba ilé ẹjọ́ lòníì Àjọ ECOWAS yan Aàrẹ Ghana, Nana Akufo-Addo gẹgẹ bíi aàrẹ tuntun Àrà mánigbàgbé tí Baba Legba dá lágbo tíátà rèé Ẹgbẹ́ akọ̀ròyìn NUJ ìpínlẹ Oyo bà àwọn ọmọ ẹgbẹ́ tó lọ ìpàdé tí Femi Fani Kayode pè ní Ibadan wí Fìdíhẹẹ́ ní Banji Akintoye nínú YWC, lílọ ni yóò lọ - Tola Adeniyi Amọ nigba to n fesi lori aworan naa, ati bi ọpọ eeyan se fi ifẹ han si, Chatta ni aworan naa lo fara jọ owe to ni "" Ẹ́ jẹ́ ka diju, ka se bi ẹni to ku, ka wo ẹni ti yoo sunkun ẹni."
Ninu ọrọ tirẹ, Kọmisọnnna ọlọpaa nipinlẹ Eko, Hakeem Odumosu ni iwadii ti bẹrẹ lori iṣẹlẹ naa, ati wi pe awọn ko ni fi aye gba iwa ipa ati iwa ọdaran kankan nipinlẹ Eko.
Africa Eye: Mo máá ń ṣàìsàn tí mi ò bá ṣiṣẹ́ òru
Láti àsìkò tí o bá jí ní òwúrọ̀, ni wàhálà orun ti ń máa kójọ pọ.
"Dìbò fún un níbí Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Osinbajo yẹ́ Woli Arole sí níbi ìṣíde ""The Call"" Awọn abadofin ti wọn buwọlu naa ni awọn abadofin to nii ṣe pẹlu epo bẹntiroo, ile isẹ irina lorilẹede Naijiria, ẹka iwosan, ajọ imọ sayẹnsi to n ṣe iwadii ati ajọ to n risi eto ọgbin lorilẹede Naijiria (Petroleum Industry Governance Bill, Stamp Duties Amendment Bill, National Instituete of Hospitality and Tourism Est."
"Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ẹ wo àwọn ìlúmọ̀ọ́ká ọmọ Nàíjíríà tó jáde láyé lọ́dún 2020 Ìtàn ìgbé ayé Isola Ogunsola, akọni mánigbàgbé òṣèré tíátà, olórin àti onílù Aráàlú dá iná sun èèyàn méjì n‘Ibadan, orí kó ẹni kan yọ ""Ma a pa ara mi si Cute Abiola lọrun bo ṣe já mi silẹ tori afẹsọna miran"" ""Àwọn akẹ́kọ̀ọ́ àgbà fipá bá ọmọkùnrin mi lòpọ̀ níléèwé Deeper Life, mò ń fẹ́ ìdájọ́"" Kí ló fa gbas-gbos láàrín Davido àti Burna boy lórílẹ̀èdè Ghana?"
Abubakar Malami ni kò si Gómìnà, yálà ẹyọ kan tàbi lápapọ̀, to ni ẹ̀tọ láti ṣe ìdásílẹ̀ àjọ kankan to níi ṣe pẹ̀lú èètò ààbo.
''Nibi ta ti n se iwadii la ti ri arabinrin kan to ni ẹjọ nile ẹjọ, ti afurasi yii si fi ọna eru gba ẹgbẹrun lọna ọọdunrun naira lọwọ rẹ pe, oun fẹ ba pari ilana beeli rẹ, ti ko si pada yọju si ile ẹjọ rara'' Abimbola ni nigba ti awọn ri ẹri to pọ gba nipa rẹ, lawọn mu ti awọn si bẹrẹ si ni fọrọ wa lẹnu wo.
O da mi loju pe wọn ko ni fi ina sori orule sun lọtẹ yi'' Amofin Adebayo tẹsiwaju pe esi abajade ibo yi yoo tubọ fi rinlẹ boya APC ṣetan lati di agbara mu ni gbogbo ẹka ijọba lalai fi ọkan jafara.
Ìdáhùn-ìbéèrè lórí bí a ṣe le tọ́ka ojúewé yìí
orile ede Sudan ju ẹrọ a-ta-ju lati fi le awon to n fi ehonu han ,ni eyi ti won
Alága àjọ náà, ọ̀gbẹ́ni Eze Duruiheoma ní, wọ́n ńní àfojúsùn wípé ó yẹ kí orílẹ̀èdè Nàìjíríá di ipò kẹta nínú àwọn orílẹ̀èdè tó pọ̀ jù lágbayé ní ọgbọ̀n ọdún sí ìsinsìyìí.
Wọ́n fẹ́ràn ipò ọlá nínú sinagọgu ati ní ibi àsè.
Láti ọjọ́ náà ni inúnibíni ńlá ti bẹ̀rẹ̀ sí ìjọ tí ó wà ní Jerusalẹmu.
“Bí aráyé bá kórìíra yín, kí ẹ mọ̀ pé èmi ni wọ́n kọ́ kórìíra ṣáájú yín.
Dùùrù, hapu, ìlù, fèrè ati ọtí waini wà níbi àsè wọn;ṣugbọn wọn kì í bìkítà fún iṣẹ́ Ọlọrun,wọn kìí sìí náání iṣẹ́ ọwọ́ rẹ̀.
- Mike Bamiloye Ọkùnrin kan da ṣọ́ọ̀ṣì rú lásìkò ìgbéyàwó, Ó ní òun lọkọ àárọ̀ ìyàwó tuntun Mi ò fẹ́ ìrànwọ́ ẹgbẹ́ òṣèré, àwọn kọ́ ló kóbá mi- Chief Kanran Arakunrin Jeremy to jẹ ẹni ọdun mẹtadinlaadọrin ti kopa ninu fiimu ibalopọ ta mọ si ''Blue film'' to ti le ni ẹgbẹrun ati ẹẹdẹgbẹrin (1700) lati igba to ti bẹrẹ ṣiṣẹ ere naa ni ogoji ọdun sẹyin.
Eyín akọ̀ròyìn fò yọ lásìkò tó n ka ìròyìn lọ́wọ́ lórí tẹlifísàn Wo àwọn Gómìnà Naijiria tí àrùn Covid-19 ti bá fínra A yìnbọn lu Precious láti dáa dúró ni, akò mọ̀ pé o máa kú- Ọlọ́pàá Ki lo ti ṣelẹ sẹyin?
Àwọn ìwàásù akọnilẹ́nu hàà tí Prophet Israel Oladele CCC Genesis Global ti ṣe rèé Ẹ̀mi arákùnrin yìí kò gbé e, ó bá aláṣẹ́wò lò dórí ìgbà ìkéje ló bá ré sálákeji Tohun ti pe awọn dokita sọ pe o le mu ki nkan ọmọ ọkunrin gbera daada, ko yẹ ki eeyan maa lo ni gbogbo igba to ba fẹ ni ibalopọ Eyi lo mu ki ọpọ awọn ọkunrin to ba ni aisan ọkan (pupọ ni kii mọ pe awọn ni gaan) maa ni ipenija lasiko ibalopọ ti eyi a si maa fa iku fawọn miran ti ọkan wọn ko ba gbe agbara oogun naa.
Wo oríṣìí oúnjẹ márùn ún tó lè dẹ́kun ikùn yíyọ àti ara àsanjù Rògbòdìyàn bẹ́ sílẹ̀ láàrin àwọn ọlọ́kadà àti àwọn òṣìṣẹ́ ọgbà ẹ̀wọ̀n ní Ibadan Wo àwọn oúnjẹ márùn ún tó ń mú kí àtọ̀ ọkùnrin dára síi Atẹjade naa tọka si awọn orilẹede bii Naijiria, to ba Amẹrika dọrẹ, gẹgẹ bi orilẹede to n kọ awọn eeyan lominu labẹ ofin ati ṣe ẹsin to ba wuni lagbaye ti won gbe kalẹ lọdun 1998.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Money transfer: Òdíwọn iye owó tí èèyàn n fi rànṣẹ́ sílé ń dínkù púpọ̀ jù Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Money transfer: Òdíwọn iye owó tí èèyàn n fi rànṣẹ́ sílé ń dínkù púpọ̀ jù 23 Bélú 2019 Ìwádìí BBC nípa fífí owọ ránṣẹ́ sílẹ̀ òkèèrè àti okòwò inú ìgbésẹ̀ náà Salma ara Tanzania n sọ dola mẹrinla nu loṣooṣu to ba ti fi igba dọla ranṣẹ sile!
"Owo osu lorilẹede yii ko le fi aaye silẹ fun ẹkunwo kankan lori epo.
Ó wí èyí nípa Judasi Iskariotu ọmọ Simoni, nítorí òun ni ẹni tí yóo fi í lé àwọn ọ̀tá lọ́wọ́.
Ìrìn ẹsẹ̀ òmùgọ̀ láàrin ìgboro ń fihàn pé kò gbọ́n,a sì máa fihan gbogbo eniyan bí ó ti gọ̀ tó.
Oluwo Divorce: Olúwòó ilú Iwo: Èèwọ!
Laipẹ yii, ija suyọ laarin oun ati akẹgbẹ rẹ ninu sinima Yoruba, Lizzy Anjorin lasiko ti Toyin Abraham sọkalẹ ayọ ọmọ tuntun, aawọ yii si hu ọpọlọpọ ọ̀rọ̀ sita.
Ẹ tún máa gbadura fún wa, pé kí Ọlọrun lè ṣí ìlẹ̀kùn iwaasu fún wa, kí á lè sọ ìjìnlẹ̀ àṣírí Kristi.
Gbogbo ohun tí ẹ pàdánùní àwọn ọdún tí àwọn ọmọ ogun mi tí mo rán si yín ti jẹ oko yín;ati èyí tí eṣú wẹẹrẹ jẹ, ati èyí tí eṣú ńláńlá jẹ,gbogbo rẹ̀ ni n óo dá pada fun yín.
Leyin ti won ti se ipade lori ise akanse won, awon olori iko  alamoju naa jiroro lori igbaradi fun eto idibo naa.
Serena Williams: Mọ̀ sínú, mọ̀ síkùn ni ìdí tí mo fi kọ̀
Baaṣa, ọmọ Ahija, láti inú ẹ̀yà Isakari, ṣọ̀tẹ̀ sí Nadabu, ó sì pa á ní ìlú Gibetoni, ní ilẹ̀ Filistia, nígbà tí Nadabu ati àwọn ọmọ ogun rẹ̀ gbógun ti ìlú náà.
Ṣe ni gbogbo ọmọde adugbo a maa yọju loju ferese wa wo ere bii Arelu ti wọn yoo maa bóyín gee lati ìta!
O ni bi oun ba n jo lati Osu Kinini ọdun wọ osu Kejila, o loju osere tiata ti yoo sọ pe oun ri oun, koda, awọn itan aye oun ti oun kọ lasiko ti oun n sile, lee gba omi loju ẹni to ba ti jẹ ori ahun, sugbọn sibẹ, diẹ ninu awọn osere yii lo da si ọrọ naa.
Nípa igbagbọ ó fi ìṣìnà aráyé hàn, ó sì ti ipa rẹ̀ di ajogún òdodo.
 Nipa oro eto oro aje, ise n lo lowo lati pari ise akanse lori eto irnna oko oju irin ati awon opopona ma ro se.
o abíọ ́ lá jẹ ́ ọmọ orílẹ ̀ èdè nàìjíríà .
Ọkan lára àwọn olólùfẹ́ wọn tilẹ̀ faṣọ mọ́ agbábọ́ọ̀lù wọn, Frank Ribery, lọ́rùn nígbà tí òmíràn ya fọ́tò pẹ̀lú ọmọ agbábọ́ọ̀lù alátakò Real Madrid lẹ́yìn tí ìfẹsẹwọnsẹ̀ náà parí Ìgbẹ́jọ́ náà yóò wáyé ní ọjọ́kọkànlélọ́gbọ̀n osù karùn ọdún yìí.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Èmi gan máa ń béèrè lọ́wọ́ ara mi pé ta ni Wole Soyinka gangan' Itan igbe aye Oshodi Tapa:Balogun Landuji Oshodi Tapa jẹ ọmọ ọba nilu Bida to wa nipinlẹ Niger bayii, eyi to fidi rẹ mulẹ pe ẹya Tapa ni, lọdun 1800 si lo dele aye.
Mo kan ṣa a gbọ ti ẹnikan lara awọn ọlọpaa na n sọ pe gbogbo eeyan, ẹ ma a salọ."
Bakan naa ni a gbọ pe ibọn ọlọpaa ran diẹ lara awọn adigunjale naa lọ sọrun, ti awọn yooku wọn si salọ.
Ki lo fa a ti iye ọṣẹ́ ti ajakalẹ arun Covid 19 ṣe ni Africa kò ṣe pọ?
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ondo: Dejí sun ọmọ méje àtagbalagba meji mọ́lé nítorí pé ó ń bínú Ṣe aṣẹ ẹgbẹ APC yoo ṣẹ lọtẹ yi?
Awọn eniyan ti n ṣe idaro Oloye Richard Akinjide to d'oloogbe.
Ọ̀rọ̀ ẹnu olódodo dàbí fadaka,ṣugbọn èrò ọkàn eniyan burúkú kò já mọ́ nǹkankan.
Ohun ti mo fe ni eto idagbasoke lori eto eko ati igbe aye iderun.
"O ni, ""Mo dupe lọwọ gbogbo eniyan to fẹ ijọba to dara fun iṣẹ takuntakun wọn."
Nítorí ẹni tí kò bá lòdì sí wa, tiwa ni.
Wọ́n á ní “Òkènísà orí ayó”.
orúkọ bàbá rẹ ̀ ni alhaji ahmad zaruq tí orúkọ ìyá rẹ ̀ sì ń jẹ ́ hajia asmah .
Mo kó àwọn baba yín jáde kúrò ní ilẹ̀ Ijipti.
ti won dibo yan, lati fowosowopo pelu ijoba oun ki won le wa ọkọ Ipinle Oyo de
Ejò lé àwọn aṣòfin ìpínlẹ̀ Ondo kúrò nípàdé Wo àwọn tí gómìnà ìpínlẹ̀ Oyo fi orúkọ wọn sílẹ̀ fún ipò kọmísánnà Agbébọ́n tún ṣoro ní márosẹ̀ Ibadan sí Eko, wọ́n jí èèyàn mẹ́ta gbé Àgùnbánirọ̀ akọ̀ròyìn Channels náà ti dágbére fáyé látààrí ìkọlù Shiite l'Abuja Ṣugbọn oludamọran lori ọrọ iroyin si Aarẹ Muhammadu Buhari, Garba Shehu to ba BBC sọrọ fidi rẹ mu lẹ pe ijọba ti bẹrẹ si ni ba awọn ajinigbe naa sọrọ lori bi wọn yoo ṣe dawọn silẹ.
Aare Muhammadu Buhari ti dari owo isuna naa ti n se òjìlénígba lé meji bilionu Naira(N242 billion) eleyi ti ajo INEC se asaaro re pe won yoo lo fun eto idibo naa lo sile igbimo asofin, ki won to bere isinmi olodoodun won ninu osu keje.
Ó bá sọ fún Jesu pé, “Ranti mi nígbà tí o bá dé inú ìjọba rẹ.
Ìdí ti àwọn ọlọpàá ṣe gbe àwọn ọ̀nà àbáyọ yìí kalẹ̀ kò yé ẹnikẹni sùgbọ̀n kò sàì rọ mọ fọ́nràn kan to n jà rainrain lóri ayelujara laipẹ yìí ni bi ti ọlọpàá kan ti ni dandan afi ki onu gba égbẹrun mẹrin naira lọ́wọ́ awakọ kan Ọlọ́pàá tó n gba rìbá sọ pé 'Ọlọ́run gan fara mọ́ olè jíjà' Ní ọ̀pọ̀ ìgbà irú àwọn ǹkan báyìí ti sọ awakọ miran di ero ọrun ní ki ọlọpàá yìbọn pa irú ẹni bẹẹ ti o ba kọ lati san irú owo bẹ́ẹ̀.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù ASUU Strike: Ìpàdé láàárín ẹgbẹ́ olùkọ́ fásitì àti ìjọba jásí pàbó!
O ni ṣugbọn oun gbagbọ pe o yẹ ki awọn Kristiẹni o ma a fi aaye gba awọn ilana tabi akiyesi tuntun to ba n jade ni ibamu pẹlu ẹkọ Bibeli yatọ si eyi to ti wa tẹlẹ ti ko si ẹni to le sọrọ tako o.
Nítorí náà, OLUWA Ọlọrun ní: “Ègbé ni fún ìlú tí ó kún fún ìpànìyàn yìí, èmi fúnra mi ni n óo kó iná ńlá jọ.
Ortom , to jẹ ọmọ ẹgbẹ oselu  Peoples
Ẹka naa fẹsun kan Ọgbẹni Onyema loju opo agbọrọkaye wọn pe gbe ogun miliọnu dọla lati orilẹ-ede Naijiria sawọn apo ikowosi kan l'Amẹrika.
Nítorí báyìí ni ọ̀rọ̀ ìlérí náà: “Nígbà tí mo bá pada wá ní ìwòyí àmọ́dún, Sara yóo ti bí ọmọkunrin kan.
Eyi ko ṣẹyin bi awọn soja ṣe da ibọn bo awọn afẹhọnuhan ni agbegbe Lekki, ni ilu Eko lasiko ti wọn ṣe ifẹhọnuhan lọwọọwọ tako ifiyajẹni awọn ọlọpaa.
ṣùgbọ́n kò dájú pé ǹkan yóò yàtọ̀ nítorí àtìlẹyin tó ti ni.
O ti wa farahan gbangba-gbangba bayii pe, asole iko agbaboolu Deportivo de La Coruña, Francis Uzoho ni yoo je asole kinni iko ohun fun idije agbaye naa, leyin  ti yoo tun sole ninu ifigagbaga naa.
Bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé lojoojumọ ni ó ń rọ Josẹfu, sibẹsibẹ, Josẹfu kò gbà láti bá a lòpọ̀, tabi láti wà pẹlu rẹ̀.
Àwọn ohun tó yẹ kí o mọ̀ nípa Ọ̀ọ̀ni Ilẹ̀ ifẹ̀ Ọọni pe fun ifọwọsowọpọ Naijiria Ilẹ̀ ifẹ̀ ní ìran Ìgbò tí ṣẹ wá kìí ṣe ilẹ̀ Juu - Ọọni Opolopo ẹbun ni awọn ọmọ ko lọ sile pẹlu idunnu lẹyin ti wọn ti yan bi ologun tan fun Oba atawọn alejo to wa nibẹ.
Orúkọ rẹ yóo sì lókìkí títí lae, gbogbo eniyan ni yóo sì máa wí títí lae pé, OLUWA àwọn ọmọ ogun ni Ọlọrun Israẹli.
O si gba awọn eeyan nimọran lati lati ye pa awọn eeyan nipa ọrọ ti wọn ba kọ lawọn oju opo itakun agbaye.
Awọn Banku music lo baa gbe Sample You bo sita ti ọgbẹni Eazi.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Africa Eye: Wo ìtàn ìyá kan ìyá kan àtàwọn olè ajọ́mọgbé tó n ta ọmọ ní Kenya Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Coronavirus in Lagos: Sanwo-Olu ti ilé ẹ̀kọ́ pa, fòfin de ayẹyẹ àdúgbò àti òde fàájì torí ọwọ́jà àrùn19 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 US election 2020: Àlàyé rèé lórí bí èèyàn 538 ṣe ń yan ààrẹ lé èèyàn mílíọ̀nù 331 ní Amẹ́ríkà15 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 New Covid 19 update: Ẹ̀yà kòkòrò Covid-19 míràn jáde ní ọgọ́ta agbègbè nílẹ̀ Gẹẹsi, àjọ elétò ìlera fọkàn ará ìlú balẹ̀15 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Fídíò, Fuji Music: Kollington Ayinla sọ ẹni tó dá orin Fuji sílẹ̀ gan an ní Nàiìjíríà16 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Oyo Coronavirus: Makinde ní kò sí ọwọ́jà Coronavirus ẹlẹ́ẹ̀kejì ní ìpínlẹ̀ Oyo14 Sẹ́rẹ́ 2021 Kankara Abduction: Àwọn ológun ṣàlàyé ìdí tí wọ́n fi yọ̀nda àwọn tó jí àwọn akẹ́kọ̀ọ́ gbé.
El- Zakzaky ṣe agbékalẹ̀ ofin, ilé ẹkọ, ilé ìwòsàn ni ìlanà ìgbàgbọ́ Shíà ní àwọn ìpínlẹ̀ Ariwa Nàìjíríà, tí orílẹ̀-èdè Iran àti Iraq sí ń ṣe agbátẹru wọ́n.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Divorcee: Ó sàn kí wọ́n yàgò fúnra wọn ju ki wọ́n ṣe ara wọn léṣe- Fisayo Wọ́n fi kún un pé ń ọ̀pọ ìgbà èyí a máa dá èdè àiyede sílẹ̀ láàrín àrá ìlú ti ó si máa n la ẹmí lọ nígbà míràn, tàbí kí o mú itẹsíwájú ǹkan rere nira.
Lẹ́yìn tí Lamẹki bí Noa, ó gbé ọdún marundinlẹgbẹta (595) láyé, ó sì bí àwọn ọmọ mìíràn lọkunrin ati lobinrin.
Àwọn ni wọ́n ń ṣe ìtọ́jú ibi mímọ́.
Ó jẹ́ àṣà tí ó burú jùlọ lọ́pọ̀lọpọ̀, láàrin àwọn orílẹ̀ èdè mìíràn, pé kí ẹni tí kò bímọ, rò pé ayé òun ti bàyẹ́, kí ó rrò pé fi òun ti parí, kí ó máa kábàámọ̀ pé, kí ni òun wá sí ayé ṣe, ènìyàn lè wà ní àìlọ́mọ, kí o ṣe ayé ní rereju ọlọ́mọ lọ, ènìyàn lè bímọ, kí o bí ìjàngbọ̀n sílẹ̀, kí o fi ọmọ rẹ̀ ṣe ayé ní ibi.
Ilú bẹ̀rẹ̀ si rù lati igbà ti Ìjọba Ológun àkọ́kọ́ ti fi ipá kó gbogbo ipinlẹ̀ Nigeria si abẹ́ Ìjọba-àpapọ̀ ni  ọdún mọ́kàndinlãdọta sẹhin .
Àwọn ọkunrin tí yóo máa ràn yín lọ́wọ́ gbọdọ̀ jẹ́ baálẹ̀ ní àdúgbò wọn.
Nítorí náà Ọlọrun kò tijú pé kí á pe òun ní Ọlọrun wọn, nítorí ó ti ṣe ètò ìlú kan fún wọn.
Ẹ̀gún yóo hù ninu ààfin rẹ̀,ẹ̀gún òṣùṣú ati ẹ̀gún ọ̀gàn yóo hù ninu àwọn ìlú olódi rẹ̀.
, sùgbọ́n nitori kò tẹ̀lé ìlànà tó yẹ ni wọ́n ó fi lọ síbẹ̀ tí o si ni kí ó kọ́ka pé olóri ọmo ologun pátápáta, Tukur Buratai O ní kóda gomina ko ni aago ìpè GOC bákan náà ni GOC ko ni ti Gómìnà ni àsìkò tí ìṣẹ̀lẹ̀ náà ṣẹlẹ.
Asiko yi ni olori ọmọ ile to kere ju labẹ ẹgbẹ Democrat Chuck Scumer beere fun.
Ẹ óo máa rú ẹbọ yìí yàtọ̀ sí ẹbọ sísun ati ẹbọ ohun jíjẹ ti ọjọ́ kinni oṣù, ati ẹbọ sísun ati ẹbọ ohun jíjẹ pẹlu ẹbọ ohun mímu ojoojumọ, gẹ́gẹ́ bí ìlànà wọn.
 cellulitis ní ọdún 2013 ṣe okùnfà ikú àwọn ènìyàn bíi ẹgbẹ ̀ rú mẹ ́ ta jákèjádò gbogbo àgbáyé .
"Iresi tá gba, a rí díẹ̀ nínú rẹ tí kò dáa, àmọ́ kò pọ rárá, wọn ní ká dá èyí tó ti bajẹ padà, ki wọn parọ́ rẹ fún wa.
Ọdọmọkunrin ọmọ Lefi náà gbà, láti máa gbé ọ̀dọ̀ Mika.
Wọ́n ní kí ọ̀gá àgbà Ede Poly"" lọ rọ́kún nílé lórí ẹ̀sùn pé 'ó kan bẹ́ẹ̀dì sí ọ́fíìsì' Kollington Ayinla ti sọ ẹni tó dá orin Fuji sílẹ̀ gan an ní Nàiìjíríà Kollington ṣalaye pe oun ko lero pe orin Fuji le di gbajugbaja orin bi o ti da lonii."
Sala Carrió ku si Manresa, niluu Barcelona lorilẹede Spain.
 Òun ni ọmọ ilẹ ̀ gẹ ̀ ẹ ́ sì àkọ ́ kọ ́ tí yóò lọ sí japan .
15 ti ohun naa si pajude si N 24.
Eto iṣide idije naa ni awọn eniyan gba pé o dun bii ti iṣide ife ẹyẹ agbaye Russia 2018 O fẹrẹ tó ẹgbẹrun lọna marundinlọgọrin ero ti wọn peju si papa iṣere ni Cairo wa wo idije iṣide naa.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Orúkọ ọmọ ni Yorùbá gbà pé ó máa ń ro ọmọ nílẹ̀ Oodua Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Ko yẹ ki iwọ naa o sọ pe o maa rọ awọn ọba loye.
Masari lo kede bẹẹ lẹyin ti awọn agbebọn kan ṣakọlu sile iwe awọn akẹkọọ to jẹ ọkunrin nikan loru ọjọ Ẹti, ti wọn si ji lara wọn gbe lọ.
Ṣùgbọ ́ n sá , àwọn ológun ojú omi ilẹ ̀ gẹ ̀ ẹ ́ sì lágbára gan-an ni .
Oyińdayépọ̀ wá lọ fẹ ìyá mi tí orúkọ rẹ̀ ń jẹ́ Ẹni-ayé tí wọ́n bí sí ilé àwọn Àkàrà-Oògùn.
Iyanṣẹlodi ko da iṣẹ duro Tóhun tí iyanṣẹlodi náà, àwọn aṣòfin tí kéde orúkọ àwọn ọmọ àjọ tí yóò mójú tó ètò gbogbo nílé aṣòfin Nàìjíríà.
Ìrísí rẹ̀ kò dára,ojú rẹ̀ kò fanimọ́ra,bẹ́ẹ̀ ni kò ní ẹwà tí ìbá fi wu eniyan.
Atiku soro yii, leyin ti o dibo
Yàtọ̀ sí ife ẹ̀yẹ AFCON, orílẹ̀èdè wo ló tún leè mókè lẹ́ka míràn l‘Afirika Amuneke fipò sílẹ̀ gẹ́gẹ́ bí akọ́nimọ̀ọ́gbá Tanzania Asamoah Gyan: O ṣeéṣe kí èyí jẹ́ ìdíje AFCON ìkẹyìn mi Èrò àwọn ọmọ Naijiria ṣọ̀tọ̀ọ̀tọ̀ lórí Tinubu àti Abbo Gba owó lọ́wọ́ àkẹ́kọ̀ọ́ ìjọba, ko rugi oyin - Seyi Makinde O ni awọn agbabọọlu Naijiria ko ro nnkan miiran bayii ju bi wọn yoo ṣe fiya jẹ South Africa lọ.
Orilẹ-ede Uruguay, ati Brazil ti yọ kuro ninu ipele yii nigba ti France ati Belgium ṣíná fún wọn.
Tẹẹ ba gbagbe, Ojilelẹẹdegbẹta ọmọ Naijiria, to jẹ isi kinni awọn ọmọ Naijiria to rinrin ajo lọ silẹ Libya, lo pada de si ilu Port Harcourt ni oṣu kinni ọ̀dun yi.
Àjọ elétò ìdìbò kéde ọjọ́ tí ìdìbò aàrẹ Nàìjíríà 2023 yóò wáyé MC Oluọmọ gbé ara rẹ̀ ṣépè nítorí ìwọ́de #ENDSARS Àbádòfin ìṣúná 2021 ré kọjá ìpele ìkejì nílé aṣòfin àgbà Ìjọba kéde ọjọ́ ìwọlé àwọn àgùnbánirọ̀ sí ìpàgọ́ lẹ́yìn Covid 19- Sunday Dare Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí 7:57 Fídíò, End SARS, End SWAT: Ó pé mi bí SARS kò ṣe sọ mí dolówọ́- Fulani Kwajafa, Duration 7,5717 Ọ̀wàrà 2020 Fídíò, Soyinka Cancer: Àṣe ara mi ni iso ti n run gbogbo bí mo ṣe n ṣèrànwọ́ lórí jẹjẹrẹ27 Bélú 2019 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Bakan naa lo jẹ wi pe Daura ti fẹhinti kuro lẹnu iṣẹ nileeṣẹ ajọ DSS, ko to di pe Buhari tun pe e pada.
Lẹ́yìn tí Saulu ti sọ àsọtẹ́lẹ̀ tán, ó lọ sí ibi pẹpẹ, ní orí òkè.
Ẹgbẹ agbabọọlu Manchester City naa yoo maa waako pẹlu Tottenham Hotspur ninu ifẹsẹwọnsẹ miran.
Lẹ́yìn náà, tí kò bá wù yín mọ́ ẹ níláti fún un láyè kí ó lọ sí ibikíbi tí ó bá wù ú, ṣugbọn ẹ kò gbọdọ̀ tà á bí ẹrú, ẹ kò sì gbọdọ̀ lò ó ní ìlò ẹrú, níwọ̀n ìgbà tí ẹ ti bá a lòpọ̀ rí.
"Tẹ ""Apply now"" lati fi orukọ silẹ fun SSC tabi DSSC gẹgẹ bi amuyẹ ti o ni."
Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Katsina Den: Ilé mìíràn tí wọn ti n fi ìyà jẹni ni Olọpàá ti rí17 Ọ̀wàrà 2019 Katsina Child sale: Obìnrin olówònààbì ta ọmọ rẹ̀ tuntun jòjòlò ní N300,0002 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Ẹ̀kùn omi Katsina: Omi gbé òpó àti ọmọ mẹ́ta lọ18 Agẹmo 2018 Katsina: Ó di ìgbàkẹ́tà l'óṣù kan tí àṣírí ilé ìmúni nígbèkùn yóò tú síta ní àríwá Nàìjíríà15 Ọ̀wàrà 2019 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 3 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 5 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Lara awọn ofin to wa nilẹ fawọn olukopa lati igba ti eto naa ti bẹrẹ wa ni pe wọn ko lee ni ajọṣepọ kankan pẹlu awọn to wa ni ita ile naa.
 Bakan naa lo menuba ise tijoba n se lori abadofin eto ilera kariaye ati awon igbese mii bii ti ayewo eroja ara bii Anti-Microbial Resistance (AMR) ati ise tijoba n se lori iko ifee atawon mii.
Ìgbà tí mo lọ sí aafin, ṣe ni mo bá gbogbo wọn tí wọn ń yọ̀, ìgbà tí mo sì bèèrè ìdí ayọ̀ lọ́wọ́ ẹnìkan báyìí ó ni, ‘Gbogbo wa ń yọ̀ nítorí ẹran dé, ìdí Òmùgọ̀diméjì rí bẹ̀ǹbẹ̀ bẹnbẹ, ìkùn rẹ̀ yọ bọ̀ǹbọ̀ bọ̀ǹbọ, òun pàápàá tóbi ó rí yọ̀kọ̀tọ̀ yọkọtọ, ẹran ìbàdí rẹ̀ kò ní ṣàì ṣe sínkín sí wa lẹ́nu.
Ọba bá dìde, ó lọ jókòó lẹ́bàá ẹnu ọ̀nà ibodè.
Laarin ọdun 2013 si asiko yii o ti le ni ọgọrun igba ti itakun ina pinpin lorilẹede Naijiria daku patapata.
Ati ẹ̀yin, ati àlejò tí ń gbé ààrin yín, òfin kan ṣoṣo ni ó de gbogbo yín.
Bẹrẹ lati oni lọ,bo lọ amerika tẹlẹ, boo lọ ri,afi ko yọju sileeṣẹ wọn ki wọn to le fun ọ ni iwe irina oke okun Wọn fi ikede yi soju opo wọn kan lori ayelujara ti awọn eeyan kan si ni awọn ri ikede yi loni ti awọn fẹ kowe gba iwe irina naa loni.
0 441399 Orilẹede Pakistan 8398 4.
Akọ̀wé àgbà fún ilé iṣẹ́ tó n ri si ọ̀rọ̀ ilẹ̀ okèrè Mustapha Suleiman, lo sáaju àwọn asoju ijọba, Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ladoja: Àwọn èèyàn Oyo fì ìbò sọ̀rọ̀ pé ìjọba Ajimobi kò dára Ààrẹ Muhammadu ni ìgbà ọtun yìí yóò fún orilẹ̀-èdè Nàìjíríà àǹfàní, láti pè fún ètò òṣèlú, ìgbáyegbadùn tó dára, eto ọ̀rọ̀ ajé to yanrantí àtí láti mu ọ̀rọ̀ àyíka tó n da gbogbo àye láàmu gbọ.
Lẹ́yìn eleyii gan, o ṣi yẹ ki wọn mu nkan bii miliiki ki wọn to wa jẹ iru ounjẹ ti wọn maa n jẹ tẹlẹ.
'Up Super' ''Triple Flaming''ati ''Gbogbo wa lọrẹ Adebajo'' Stationery Stores lawọn eeyan n kan sara si.
ko ni agbara lati fenuko lori ekunwo owo osu awon osise leyin ti igbimo elenu
láti orí ìtẹ́ rẹ̀ tí ó gúnwà sí,ó wo gbogbo aráyé.
Ko saye a n duro ninu ọkọ bọọsi akero ijọba BRT ati LBSL.
Soyinka: Buhari ti wọnu ẹmi lọ Idaamu Boko Haram: Igbẹjọ awọn afunrasi bẹrẹ ni gbangba loni Bakanaa lawọn asofin ọhun tun pinnu lati sagbeyẹwo elo gan an lowo ti orilẹede Naijiria n na, lati ipasẹ ileesẹ itẹwo rẹ, lati fi lati tẹ owo naira.
“Ta ló rí ohun ìdíwọ́ kan, ninu pé kí á ṣe ìrìbọmi fún àwọn wọnyi, tí wọ́n gba Ẹ̀mí Mímọ́ bí àwa náà ti gbà á?
Èyí tó kúrú, èyí tó ga, gbogbo wọn n’ọ́n péjọ sínú igbo, tí wọn ń jẹ́rìí sí agbára Ẹlẹ́dàá wọn.
Oríṣun àwòrán, AFP Àkọlé àwòrán, Amọ lorilẹede Kenya, ero ọkan awọn elere idaraya ni igbaradi fun idije ere idaraya Commonwealth ti yoo waye lorilẹede Australia losu Kẹrin.
Code of Conduct Tribunal: Adájọ́ Àgbà Nàíjíríà, Walter Onnoghen ní ẹjọ́ láti rò
Ẹ ṣe akiyesi ìṣe àwọn ọmọ Israẹli.
Titara titara si ni wọn n rin pẹlu ibọn Ak47, ti wọn si n fi ipa aba awọn obinrin wa lopọ, bẹẹ ni wsn n gbẹmi eeyan laibikita, koda, wsn ko tun bọwọ fun ẹmi eeyan, asa ati ofin pẹlu.
 Ile-ejo to  wa ni ipinle Zamfara ti adajọ Ijeoma Ojukwu
Ẹ óo rí i pé ìlú ọlọ̀tẹ̀ ni ìlú yìí.
Oríṣun àwòrán, WCS Nigeria Ajọ to n ṣakojọpọ owo fun itọju ohun adayeba lagbaye, WWF sọ pe, irufẹ awọn inaki ti wọn ri ni ipinlẹ Cross River naa lo ṣọwọn julọ lagbaye.
BBC sàbẹ̀wò sí ilé iṣẹ́ Hisbah lọ́jọ́rú láti rí àwọn ọmọbinrin kan tó ti ṣẹ̀ sí òfin yìí ní ọjọ́ ìṣẹ́gún, tí wọn sì sun ọgba Hisbah mójú.
Bí wọ́n ti ń gun òkè lọ láti wọ ìlú, wọ́n pàdé àwọn ọmọbinrin tí wọ́n ń jáde lọ pọn omi.
“Tó bá di ìgbà náà, wọn yóo kó egungun àwọn ọba Juda jáde kúrò ninu ibojì wọn, ati egungun àwọn ìjòyè ibẹ̀; ati ti àwọn alufaa, ati ti àwọn wolii, ati ti àwọn ará Jerusalẹmu.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Hibeethebarber: Kò sí ẹni tí mi ò lè firun èèyàn yàwòrán rẹ̀ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Hibeethebarber: Kò sí ẹni tí mi ò lè firun èèyàn yàwòrán rẹ̀ 26 Ìgbé 2018 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 24 Ògún 2018 Abdulrahman Ibrahim wípé irun gígẹ̀ kọjá orí fífá lásán.
Tí a bá yọwọ́ àwọn ọba alayé kúrò, kò ní sí Nàìjíríà mọ́- Alaafin Oyo Díẹ̀ ló kù kí ọjọ́ ìkúnlẹ̀ di ọjọ́ ikú fún ìyá mi lọ́jọ́ tó bí mi - Seyi Makinde Àwọn èèkàn ìlú péjú s'Ibadan níbi ìsìnkú màmá Omotola àkọ́bí obìnrin Awolowo tó wọ káà ilẹ̀ lọ Kò bá àṣà wa mu kí obìnrin máa kó ọmú síta!
iru iselu je ti opolopo egbe oloselu ti won yan awon asoju pelu aare abasewa nibiti aare ile benin , ti se yayi boni lowolowo bayi , je olori orile-ede ati olori ijoba .
" O fẹran awọn ọmọ rẹ, bi ẹ ba wo awọn oju opo ayelujara rẹ gbogbo, ẹ o ba aworan awọn ọmọ rẹ nibẹ, bẹẹ naa lo jẹ ẹni to fẹran ẹbi, iyawo ati ọmọ rẹ gidigidi.
Mo wá gbọ́ ohùn líle kan ní ọ̀run tí ó sọ pé, “Àkókò ìgbàlà nìyí ati ti agbára, ati ìjọba ti Ọlọrun wa, ati àkókò àṣẹ Kristi rẹ̀.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù World Cup 2018: France fàgbà hàn Croatia pẹ̀lú àmì ayò 4-2 10 Agẹmo 2018 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 15 Agẹmo 2018 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ìgbà kejì nìyí tí France yóò gba ife ẹ̀yẹ àgbáyé France ló gbé ife ẹ̀yẹ àgbáyé tọdún 2018 lọ!
Ta ni a fi agbára Oluwa hàn fún?
Ajọ to n gbogun ti ajakalẹ aarun lorilẹ-ede Naijiria, NCDC ti kede pe eeyan 213 miran tuntun mi ti darapọ mọ awọn to ti ni aarun COVID-19 ni Naijiria ni ọjọ kẹẹdọgbọn, oṣu Kẹsan-an.
Gbogbo àwọn tí ó bá gba Jesu gbọ́ yóo yege lọ́dọ̀ Ọlọrun láìsí ìyàtọ̀ kan.
Èyí ni yóo jẹ́ àmì fún wa, pé OLUWA ti fún wa ní ìṣẹ́gun lórí wọn.
Ṣebí èmi nìkan ni mo ṣẹ́kù,níbo ni àwọn wọnyi ti wá?
ó ní, “Kọ ohun tí o bá rí sinu ìwé, kí o fi ranṣẹ sí àwọn ìjọ ní ìlú mejeeje wọnyi: Efesu ati Simana, Pẹgamu ati Tiatira, Sadi ati Filadẹfia ati Laodikia.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Kogi alleged rape: Agbẹjọ́rò fún arábìnrin tó fẹ̀sùn ìfipábánilòpọ̀ kan kọmíṣọ́nà Kogi ní ó ṣeéṣe kí ìyípadà rẹ̀ lórí ẹ̀sùn náà ó lọ́wọ́ àwọn alágbára nínú 28 Èbibi 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 29 Èbibi 2020 Oríṣun àwòrán, Elizabeth adeniyi Ṣe ẹranti arabinrin kan to fi ẹsun ifipabanilopọ kan kọmiṣọna kan ni ipinlẹ Kogi ni oṣu diẹ sẹyin?
Ka to wi, ka to fọ, Phil Foden gba goolu keji wọle fun City, lo ba di ami ayo meji sodo.
Ojulowo Yoruba lo ma n sọ lẹnu.
N ó máa mú yín káàkiri ìlú yìí kí ẹ lè rí ìgbésí ayé ọmọ Yoòbá nílẹ̀ yìí.
Yóo dìde, yóo sì ràn yín lọ́wọ́.
Òkè ati ilé ìṣọ́ yóo di ibùgbé àwọn ẹranko títí lae,yóo di ibi ìgbádùn fún àwọn kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ ìgbẹ́,ati pápá ibùjẹ fún àwọn ẹran ọ̀sìn.
Alẹ́ ọjọ́ Aiku ni òfin konile ó gbélé to wá nilẹ yóò wa sopin Láti ọjọ́ Ajé, ọjọ́ kẹrin oṣù karùn-ún, ìjọba yóò dẹkùn lọrun àṣẹ konile ó gbélé, tí àwọn aráàlú yóò sì ní anfaani lati rin láàárín ìlú bẹ̀rẹ̀ láti aago mẹ́fà àárọ̀ si márùn-ún irọlẹ.
2 8782 Orilẹede Mozambique 133 0.
Eden Hazard lo kọkọ gba bọọlu s'inu awọn fun Chelsea ni isẹju marundinlọgbọn ti ifẹsẹwọnsẹ naa bẹrẹ, ti Victor Moses si fi ikeji s'inu awọn ki Hazard to tun fi ẹlẹẹkẹta s'inu awọn ni isẹjukanlelaadọrin.
Ni ilẹ to mọ loni yii ẹya epo rọbi Brent ti di dọla mọkanlelogun, iyẹn ẹgbẹrun mẹjọ o le bi igba naira lori agba epo rọbi kan nigba ti ẹda epo rọbi WTI ti di dọla mẹrindinlogun iyẹn ẹgbẹrun mẹfa o le ojilelugba ati naira marun lori agba kan.
Ni amẹrika, ipade adura yoo waye ni ijọ Society for Advancement of Judaism lẹyin ti adura jumaat ti waye lọjọ ẹti ni ibudo ẹsin islam to wa ni ilu New York.
O n ṣiṣẹ pẹlu ileeṣẹ Proton and Lotus to si ṣe ipo Lotus fun ijọba Malaysia lọdun 1999.
Bí o bá ti rí ọmọ kékeré o máa fọmọ kékeré mọ́ra
Ọmọ Israẹli ni èmi fúnra mi.
Ọpọlọpọ miliọnu Dọla si ni ileesẹ naa n pa lọdọdun.
Bundesliga, ki won to padanu eleyi.
Nítorí náà, ègún ati ìbúra tí Mose, iranṣẹ rẹ kọ sinu ìwé òfin ti ṣẹ mọ́ wa lára.
OLUWA bá mú àwọn tí Mose rán lọ wo ilẹ̀ náà tí wọ́n sì mú ìròyìn burúkú wá, àwọn tí wọ́n mú kí àwọn eniyan náà kùn sí Mose, 
san ida mewaa owo ti onile gba sapo ijoba ipinle eko gege bi owo ori fun ile.
Ní alaalẹ́, wọ́n ń tan fìtílà wúrà lórí ọ̀pá fìtílà rẹ̀; nítorí àwa ń ṣe ohun tí Ọlọrun wa pa láṣẹ fún wa, ṣugbọn ẹ̀yin ti kọ̀ ọ́ sílẹ̀.
Aisha ni ìròyìn gbalẹ̀ kan ní ààrọ̀ ọjọ́rú lórí ìtàkùn àgbáyé pé ó ti mí kanlẹ̀ lásìkò àìsàn ọlọ́jọ́ gbọọrọ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ekiti Election: Ǹkan méwàá tó yẹ kí o mọ̀ nípa Oluṣọla Eleka 9 Agẹmo 2018 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 13 Agẹmo 2018 Oríṣun àwòrán, @elekaolusola Àkọlé àwòrán, Ọọlọ pipe ati ọgbọn iwe naa wa lara amuyẹ ipò olori Oluṣọla Eleka tó ń díje fún ipò gómìnà Ekiti lábẹ́ asia ẹgbẹ́ oṣelu PDP.
Esther sọ pe Ni ṣe lo dabi ẹni pe mo wa nin u ẹwọn ti wọn fi irin yika ti mi o si le jade, o jẹ ohun to ṣoro funmi, bẹẹ naa ni mo tun n ro ti awọn ọmọ mi pẹlu."
Bi wọn ba si pe ọmọ ọmọ ni ọmọ ale, ile ti daru, tiru ọmọ bẹẹ yoo si di ọmọ ale titi ayeraye lai jẹ pe iya rẹ yan ale tabi gbe ọmọ ọba fun ọsun.
 Ki lo de ti ilana oye jijẹ nilẹ Ibadan ko se lee yatọ gẹgẹ bi awọn ilu miran nilẹ Yoruba.
Wọn tun fi ẹsun kan Magu pe, oun naa n dari owo ti EFCC gba lọwọ awọn ọdaran si ibomii, o n ba awọn oniwa ibajẹ ṣe pọ, ati afojudi si ọfiisi Agbẹjọro agba.
Àwọn Ìpínlẹ̀ tí coronavirus kò tíì dé ní Nàìjíríà, àti ìgbésẹ̀ tí wọ́n ń gbé láti dènà rẹ̀ Ìtàn Manigbagbe: Àwọn àjakalẹ-àrun to ti wáyé rí ṣáájú Coronavirus Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, libya O ní irú èrò báyìí ni o mú kí òun kọ irú ọ̀rọ̀ yìí si ta.
Àwa jẹ́ aláìlera, ẹ̀yin jẹ́ alágbára!
Sibẹ àwọn ọmọ Israẹli kò lé àwọn ará Geṣuri ati àwọn ará Maakati jáde; wọ́n ń gbé ààrin àwọn ọmọ Israẹli títí di òní olónìí.
"Wọ́n fún obìnrin kan lọrùn pa, awuyewuye ti ń wáyé Makinde fẹ́ fọwọ́ ọlá gbá wa lójú ni, a ò sì ní gbà-ALGON Oríṣun àwòrán, other ""Lẹ́yìn èyí ni àwọn ọlọ́pàá ṣe fídíò míì ti wọ́n sì gbé ìbọn si mi léti pé tí mo bá kọ̀ láti sọ ǹkan ti àwọn bá ṣọ àwon lé pa mi tàbi fi mi sí ẹ̀wọ̀n."
Ọwọ́ ọlọ́pàá tẹ afurasí olóògùn owó tó fẹ́ gé ọmú obìnrin kan nílé ìtura Àwọn èèyàn ìpínlẹ̀ Oyo gbarata lórí àlékún owó epo bẹntiróò E wo ọmọ Yorùbá àkọ́kọ́ tó jà fún ẹ̀tọ́ àwọn aláwọ̀dúdú ní America!
"Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Àwọn àpẹẹrẹ mẹ́sàn-án tí yóò fihàn pé o ti n darúgbó 26 Ọ̀wàrà 2018 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ìyá arúgbó ""Ko si nkankan ninu ara wa to n dara si bi a ba ṣe n dagba."
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Gomina Akeredolu n tọka si i pe ipinlẹ Ondo lo n gbin igbo julọ ni Naijiria, to si yẹ ki orilẹ-ede yii o lo anfaani naa fun awọn ọmọ Naijiria.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù 2019 Elections: Àwọn òṣèré Yorùbá tó wà nínú ìgbìmọ̀ ìpolongo APC 1 Sẹ́rẹ́ 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 2 Sẹ́rẹ́ 2019 Oríṣun àwòrán, Aisha buhari Àkọlé àwòrán, 2019 Elections: Àwọn òṣèré Yorùbá tó wà nínú ìgbìmọ̀ ìpolongo APC Lánàá òde yìí ní aya ààrẹ orilẹ̀-èdè Nàìjíríà Aisha Buhari yàn àwọn ti wọn yóò jọ kọ́wọ́ọ̀ rín láti ṣe ìpolongo ìdìbò Buhari ní elékejì.
Ati àwọn olùdámọ̀ràn rẹ,lẹ́yìn náà a óo máa pè ọ́ ní ìlú olódodo.
Sẹnetọ Lawan wa kede igbimọ ti yoo wadii iṣẹlẹ naa labẹ Sẹnetọ Sam Egwu gẹgẹ bii alaga ti Olurẹmi Tinubu, Mathew Rugide, Stellah Uduah, Dauda Haliru Jika, Danladi Sankara ati Mohammed Sani Musa yoo si jẹ ọmọ igbimọ naa.
- MC Oluomo Ìgbẹ́jọ́ Naira Marley sún síwájú bí àwọn agbẹjọ́rò ṣe ń jà sí àga ìjókòó Oríṣun àwòrán, OTHER Marlians Marlians Marlians!
Olumegbon jẹ́ àgba oyè ni ilu Eko nigba aye rẹ àti ọkan lara awọn afọbajẹ ilu Eko.
Akọwe agba ati alukoro ẹgbẹ oṣelu PDP ni kii ṣe nitori araalu ni wọn fi n ṣe ohun ti wọn n ṣe lori reluwee lọ si Niger.
Ẹ kò gbọdọ̀ fi kún òfin tí mo fun yín yìí, ẹ kò sì gbọdọ̀ mú kúrò ninu rẹ̀, kí ẹ lè máa pa òfin OLUWA Ọlọrun yín tí mo fun yín mọ́.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Alaafin: Olorì Folashade ní òun ni olorì àkọ́kọ́ tó bí ìbẹta nílẹ̀ Yorùbá 12 Owewe 2020 Oríṣun àwòrán, Alaafin_oyo Àkọlé àwòrán, Olori Folashade sọ pe ẹni ọdun mẹẹdọgbọn ni oun nigba ti oun pade Alaafin Ọkan pataki lara awọn 'Ẹlẹ Daddy', oxygen ti Alaafin ilu Oyo, Ọba Lamidi Adeyemi, fi n mi, ni Olori Aisha Folashade Adeyemi jẹ.
Fìlà kan ni ó fẹ́ rà o, ṣùgbọ́n bí á ti dé ibi ti wọ́n ti ń ta ọjà tí o ri arẹwà wúndíà tí wọn ń ta ọjà náà, ti wọn ń mì, ti wọ́n ń yan níwájú rẹ̀, tí wọn ń pọ́n oun náà, tí wọn ń fi ọjà gbogbo hàn án, ó bẹ̀rẹ̀ síí náwó, ó ra gbogbo nǹkan tí kò ní èrò àti rà tẹ́lẹ̀, ó ná gbogbo owo tan, bẹ́ẹ̀ ni àpò owó méjì ló gbé wá.
Aṣọ òde ni, nitori kò ṣe gbé wọ lójojúmọ́.
Ni ọdun 2016 ni Obaseki deede yoju si gbagede oṣelu Naijiria lẹyin ti Adams Oshiomole gbe e wa lati ilu Eko nibi ti o ti n ṣiṣẹ, ti ọpọ eniyan ko si mọ ọ ni gbagede oṣelu ipinlẹ Edo.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Seyi Makinde: ₦60m ní mo gbé kalẹ̀ fún ìtọ́jú àwọn akẹ́kọ̀ọ́ ìmọ̀ òfin fún ọdún kan 7 Ògún 2019 Oríṣun àwòrán, Seyi Makinde Àkọlé àwòrán, ‘Ẹnikọ̀ọ̀kan nínú àwọn 120 ọmọ ìpínlẹ̀ Ọyọ tó ń kẹ́ẹ̀kọ́ ìmọ̀ òfin yóò gba N500,000’ Gomina Ipinlẹ Ọyọ, Seyi Makinde ti buwọlu owo to to ẹgbẹrun lọna ẹẹdẹgbẹta naira (₦500,000) bii owo iranwọ eto ẹkọ, fun akẹẹkọ kọọkan to wa lati ipinlẹ Ọyọ, ti wọn n kọ ẹkọ imọ nipa ofin ni ileewe imọ ofin(Law School).
Nitori naa, ti awon kan ba so pe mo n gbe leyin awon eya tabi esin kan, ki onitohun gbiyanju lati se owo ilu basu-basu.
Kí ni n óo ti ṣe yín sí, ẹ̀yin ọmọ Seruaya, tí ẹ̀ ń ṣe bí ọ̀tá sí mi?
Báyìí ni ọ̀rẹ́ mi náà kọ̀wé sí mi, nígbà tí mo rí ìwé rẹ̀ àfi bí ẹni pé òun ni mo rí.
Ijọba Naijiria ti tẹwọ gba agbo ilẹ Madagascar ti wọn ni o lagbara lati wo ajakalẹ arun Coronavirus.
 America je orile ede to maa n se iranwo fun ile Adulawo lati ibere a maa n pese iranlowo fun orile-ede ile Adulawo ki awon naa le goke agba.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Super touch: Roller Blader ni mí láti ọdún mẹ́jọ sẹ́yìn Lẹ́yìn gbogbo ìgbìyànju ti ọmọ náà kò si jẹ́ rírí, Arabinrin Kolawole ni olùdásilẹ̀ ijọ náà ko gbe igbésẹ̀ kan to ṣe koko, èyí ló fàá ti òun fi ke gbajare sita ti Deji Akure si fi pa a láṣẹ̀ pé ki awọn wa bura.
Bí ó bá jẹ́ ẹran tí kò mọ́ ni, tí eniyan kò lè fi rúbọ sí OLUWA, kí ẹni náà mú ẹran náà tọ alufaa wá, 
Eto idibo ni gbangba : Eyi ni ọna ti awọn awọn oludibo n gba
Jediaeli, ọmọ Ṣimiri, ati Joha, arakunrin rẹ̀, ará Tisi, 
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Premier League: Ọ̀mì ayò kan ni Man U àti Liverpool gbá!
Benson Akinroluyi lo jabo oro naa fun akoroyin Voice of Nigeria lasiko
Ó to ìtẹ́lẹ̀ marun-un marun-un sí apá ìhà gúsù ati apá ìhà àríwá ilé náà, ó sì gbé agbada omi sí igun tí ó wà ní agbedemeji ìhà gúsù ati ìhà ìlà oòrùn ilé náà.
Oríṣun àwòrán, Others Lasiko isede coronavirus ni Naira Marley ati awọn kan fi ilu Eko silẹ pẹlu baalu aladani kan, ti wọn si lọ ọ ṣe ariya alẹ ni ile itaja nla Jabi Lake Mall, lọjọ kẹtala, oṣu Kẹfa, botilẹjẹ pe ofin de irinajo lati ipinlẹ kan si omiran.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Samuel Ogundipe: Níní ìwé àṣíri ìjọba lọ́wọ́ lọ́nà àìtọ́ ni ẹṣẹ rẹ̀ 15 Ògún 2018 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 16 Ògún 2018 Oríṣun àwòrán, Twitter/Samuel Ogundipe Àkọlé àwòrán, Akọròyìn Samuel Ogundipe wà ní ahámọ́ àwọn ọlọ́pàá Ilé iṣẹ́ ọlọpàá Nàìjíríà ní Samuel Ogundipe tí àwọn gbé lọ sí ilé ẹjọ́ ni àwọn fi ẹ̀sùn olè kàn.
Awọn ọmọ igbimọ maraarun naa fi ẹnu ko lori igbesẹ ọhun lati ma fi aaye gba ẹgbẹ oṣelu PDP ati oludije rẹ, Atiku Abubakar, nitori awọn nkan mii to tun ti kún ẹjọ naa nipa oju opo ayelujara INEC.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Wo ìdí tí wọ́n ṣe lé Erica dànù kúrò nílé BBNaija l'ọ́sẹ̀ yìí Kí ló ṣe Ibrahim Chatta tó fi dèrò ilé ìwòsàn?
Nígbà tí wọn bá mu yín lọ sí ibi ìdájọ́, ẹ má ṣe da ara yín láàmú nípa ohun tí ẹ óo sọ, ṣugbọn ohun tí Ẹ̀mí Mímọ́ bá fun yín ní wakati kan náà ni kí ẹ sọ, nítorí kì í ṣe ẹ̀yin ni ó ń sọ̀rọ̀ bíkòṣe Ẹ̀mí Mímọ́.
Ṣùgbọ́n kì í ṣe gbogbo àwọn ara ọ̀run Àpáàdì ló ń jẹ irú oró tí a sọ wọ̀nyío, àwọn tí wọn ń jẹ irú ìyà báwọ́nonnì ni àwọn tí wọ́n ti jẹ́ alágbára ní ìgbà ayé wọn ti wọ́n sì ti lo agbára wọn láti fi dá ọmọ ẹlòmíràn lóro irú èyí tí a dárúkọ gbogbo.
Èèyàn 300 míràn ló ṣẹ̀ṣẹ̀ coronavirus ní Nàìjíríà lọ́jọ́ Aiku Ajakalẹ aarun coronavirus tun ti gbera soke si ni orilẹ-ede Naijiria, pẹlu bo tun ṣe ran ọọdunrun (300) eeyan mii.
Codeine: Ijọba àpapọ̀ fòfin de oògùn ikọ́ tó ń dorí àwọn ọ̀dọ́ rú Oríṣun àwòrán, Frankieleon Àkọlé àwòrán, òpin dé bá lílo oògùn ikọ́ olómi Codeine àti Tramadol Ijọba àpapọ̀ f'òfin de títà àti rírà oògùn ikọ́ olómi to ni codeine lẹ́yìn ti BBC gbe fidio jade ti o fi ṣàfihàn ewu ńlá to wa ninu mímu àpọ̀jù iru oògùn ikọ́ báyìí.
ó sì wí pé, “Sún mọ́ mi níhìn-ín, n óo sì fi ẹran ara rẹ fún àwọn ẹyẹ ati ẹranko jẹ.
Nítorí náà, ọba bi mí léèrè pé, “Kí ló dé tí o fi fajúro?
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù World suicide prevention day: Iye àwọn tó ti gbẹ̀mí ara wọn rèé láàrin ọdún mẹ́rin ìjọba Buhari ní Nàìjíríà rèé 10 Owewe 2020 Oríṣun àwòrán, others Mẹwaa n ṣẹlẹ ní duniyan, ẹni to kan lo mọ o.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù AFCON 2019: Bí Nàìjíríà ṣe gbá eyí tó lọ, mi ò lè sọ àsọtẹ́lẹ̀ti tònìí Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ AFCON 2019: Bí Nàìjíríà ṣe gbá eyí tó lọ, mi ò lè sọ àsọtẹ́lẹ̀ti tònìí 6 Agẹmo 2019 Gẹgẹ bi awọn agbabọọlu Naijiria ṣe ti n gbara di fun ifẹsẹwọnsẹ wọn pẹ̀lú ikọ agbabọọlu ti Cameroon, ọkan awọn ọmọ Naijiria naa ti wa loke.
Bákan náà ni ọgágun náwọ́ ìwé ìpè apero yii sí ẹgbẹ́ Afẹnifere tí ó ń soju fún ẹ̀yà Yorùbá ìhà Guusu - ìwọ̀-òòrun Nàìjíríà.
Nígbà tí Ọlọrun gbé Ọmọ rẹ̀ dìde, ẹ̀yin ni ó kọ́kọ́ rán an sí, kí ó lè bukun yín láti mú kí ẹnìkọ̀ọ̀kan yín yipada kúrò ní ọ̀nà burúkú rẹ̀.
Kì í ṣe ẹ̀yin ni ẹ yàn mí.
BBCCopyright: BBC Ike Ekweremadu ati Ovie Omo-AgegeImage caption: Ike Ekweremadu ati Ovie Omo-Agege Article share tools Facebook Twitter ṢàpínlòView more share options Share this post Copy this linkKà síwájú síi nípa àwọn ìtọ́kasí wọ̀nyí.
''Aṣẹ Ọlọrun Ọba ni pe gbogbo arun bi coronavirus ko le wọ ilẹ Iwo, ohun lo jẹ ki sọ tẹlẹ pe covid-19 ko gbọdọ wọ ilu Iwo.
N30,000 ni mo gbà fún orí, ọwọ́ àti ẹran ara wòlíì Bosede - Kayeefi Pásítọ̀ bẹ́'rí ọmọ ìjọ ní ìpínlẹ̀ Ògùn Kini Pásítọ̀ Kumuyi fi ṣẹ ọmọ Naijiria?
Wọn á kú ikú ìtìjú,nígbà tí wọ́n wà ní èwe.
Gege bi o se so, “ireti wa pe awon olopaa ti iye won to ẹ̀gbẹ̀rún meji ti won ti gba eko ija loju
- Kemi Afolabi Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Mí ò ya wèrè, mí ò burú, ọ̀nà àtijẹ là ń wá' Sotayo Gaga Oríṣun àwòrán, Sotayo Gaga Sotayo Sobowale lorukọ rẹ ṣugbọn ti apele rẹ n jẹ Sotayo Gaga.
😁 | Walking into work after a Sunday evening win like… 🕺 @richarlison97 #MondayMotivation pic.
Arabinrin Raissouni n ba ile iṣẹ iroyin aladani kan ṣiṣẹ eleyi ti o saaba ma n bẹnu ẹtẹ lu awọn alaṣẹ.
Lori opo ayelujara ikansiraẹni Twitter ni Man U ti fidi ọrọ naa mulẹ lọjọ Aje.
Àwọn tí wọ́n súnmọ́ ọn ni: Kaṣena, Ṣetari, ati Adimata, Taṣiṣi ati Meresi, Masena ati Memkani, àwọn ìjòyè meje ní Pasia ati Media.
"- Ori afara to tinrin ti o dabi ẹsẹ o gbèjì fún mọ́tò Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ìgbátí ìgbámú àná látọwọ́ sọ́jà obìnrin ti bá arákùnrin náà dé iléèwòsàn - Opopona irinna reluwe ti ọkọ oju irin maa n gba kọja - Ibi ti wọn fa ila ami idanimọ "" Zebra Crossing"" si ni eyi to ṣafihan ila pẹlu awọ ofeefee pe awọn ẹlẹsẹ ero yoo maa gba kọja bọ si odi keji opopona."
Oríṣun àwòrán, felix chukwuneke Iroyin sọ pe irora ẹsẹ ni ọmọ naa kọkọ n pariwo fun awọn obi rẹ, amọ ayẹwo pada fihan pe aisan jẹjẹrẹ inu ẹjẹ lo ni.
Lasiko yii ni awọn awakọ yoo si maa gba abala ọna ori afara ọhun to wa lati Oworonsoki si Lagos Island, ni abala ọna naa to lọ si Lagos Island, lati aago mejila oru si aago kan ọsan.
Kì í ṣe ẹnìkan tí ó dẹ́ṣẹ̀ ni Ọlọrun ń wò kí ó tó ta àwọn eniyan lọ́rẹ.
Ọmọ alufaa lobinrin, tí ó bá sọ ara rẹ̀ di aláìmọ́ nípa ṣíṣe àgbèrè káàkiri, sọ baba rẹ̀ di aláìmọ́, nítorí náà sísun ni kí ẹ dáná sun ọmọ náà.
Bawọn kan ti ṣe n dawọọ idunnu lawọn miran n sọ pe ko si ipa to le mu ba Tottenham yatọ si eleyi to ti wa nilẹ tẹlẹ Bi iroyin naa ti ṣe lu sita Jose Mourinho ti da akọnimọọgba ẹgbẹ agbabọọlu Tottenham, lẹyin ti wọn yọ Mauricio Pochettino ni isẹ.
Gẹ́gẹ́ bí àwọn tí ọ̀rọ̀ náà ṣojú wọ́n ṣe sọ, àwakọ Benz tí nọmba ọkọ̀ rẹ̀ jẹ́ SRP 553 QG tí mu otí yọ tí ó sì ń sáre asápajúde ní ǹkan bi ààgo mẹ́fa ààbọ̀ ìdájí òní nígbà tó lọ kọlu àwọn awakọ̀ Maruwa náà.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Ohun tóo gbúdọ ṣe lọ́dún yìí bí o bá fẹ́ kí Ọlọ́run bá ọ rìn' Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Iroyin naa ni, isẹlẹ naa buru de bi pe o mu ẹmi akẹkọ kan lọ, ti wọn si tun sọ ina sinu gbọngan ikẹkọ nla kan atawọn ibudo mii ninu ọgba ile ẹkọ ọhun.
 lọ ́ tọ ̀ roof ní ẹ ̀ sùn ọ ̀ ràn ìpànìyàn mẹ ́ sàn ní ilé-ẹjọ ́ ìpínlẹ ̀ south carolina .
Ìjàmbá ọkọ̀ bàálu gbẹ̀mí ọmọdé méjì àtàwọn arìnrìǹàjò míì Ọlọ́pàá tó mú àwọn obinrin wọ gau -Ọ̀gá ọlọ́pàá Ààrẹ Buhari padà sí Nàìjíríà lẹ́yìn àbẹ̀wò sílẹ̀ Gẹẹṣi Ajimobi figbe ta, ó ní 'èmi kọ́ ló pa Ṣugar o!
Labẹ adehun ti ijọba Theresa May se - eyi ti ile asofin apapọ wọgile ni ẹẹmẹta ọtọọtọ - ilẹ Gẹẹsi ko ba wọnu eto ilana olosu mọkanlelogun ti wọn yoo tọ kuro ninu ajọ isọkan ilẹ Yuroopu.
Ọrọ yi di ootọ pẹlu bi ile iṣe ọlọkọ irina kan ti ṣe ṣe ifilọlẹ ọkọ akero 'Kẹẹkẹ Napep' fun awọn eeyan ilu Liverpool nilẹ Gẹẹsi.
"O ko gbọdọ ni ni ami kọkan lara tabi ya ""tattoo."
Ṣebí bí ìlú yín ti pọ̀ tó, bẹ́ẹ̀ ni àwọn oriṣa yín náà pọ̀ tó, ẹ̀yin ará Juda.
Ọjọ́ wíwó odi ìlú palẹ̀ati igbe kíké láàrin àwọn òkè ńlá.
Awon olori miiran fenuko lati se idasile ti won loto, pelu awon eniyan ti won le ni bilionu kan, amo,  awon orile-ede mokanla nile Afrika, lara eyi ti a ti ri orile-ede Naijiria, ti eto oro-aje won tobi julo, ati orile-ede South Africa ti ni igberu julo nile Afrika.
APC Adams Oshiomhole,oludari eto ipolongo egbe APC Rotimi Amaechi ati gbogbo omo
ṣugbọn kí wọn bẹ̀rù OLUWA Ọlọrun wọn, yóo sì gbà wọ́n lọ́wọ́ gbogbo àwọn ọ̀tá wọn.
kí ọ̀rọ̀ tí wolii ti sọ lè ṣẹ, nígbà tí ó sọ pé, “Bí òwe bí òwe ni ọ̀rọ̀ mi yóo jẹ́.
CBN: A ń pariwo tó lórí MMM fáwọn ọmọ Nàíjíríà Ọmọ ogun Nàìjíríà bẹ̀rẹ̀ lílo 'Drone' láti gbógun tàwọn ajínigbé ni Ondo àti Ekiti Jẹ́ kí a jọ sọ àǹfàní US fún Nàìjíríà -Osinbajo Báwo ni ọkùnrin tí ọlọ́pàá bá òkú rẹ̀ nínú àgbá ní Oyingbo ṣe kú?
Ṣoyinka sọrọ yii niluu Badagry nibi to ti lọ ṣi iṣẹ ọna kan to nii ṣe pẹlu ayajọ ọjọ ibi rẹ.
ninawo iwe kikopa si oludari ijoba orile-ede Israeli lati wa kopa lojo ayeye
Trump bu ẹnu atẹ lu FBI Agbebọn pa eeyan 17 l'Amẹrika O sọ fun awọn aṣofin naa lati maṣe bẹru kikoju ẹgbẹ to'n ja fun lilo ibọn lamerika (NRA).
Ọdun 2012, 2016 àti 2020 ni John Mahama àti Nana Akufo-Addo ti jọ ń figagbága dupò aàrẹ Ghana Ó tó gẹ́!
Ẹ óo máa ṣe àjọ̀dún ìrántí àjọ àìwúkàrà, nítorí ọjọ́ yìí ni ọjọ́ tí mo ko yín jáde kúrò ní ilẹ̀ Ijipti.
Àwọn Farisi wí fún un pé, “Wò bí wọn ti ń ṣe ohun tí kò tọ́ láti ṣe ní Ọjọ́ Ìsinmi!
gbogbo omo orile ede Naijiria fun ifẹ ti won fihan lati tu asiri iwa ibi ohun,
Eto iranwọ yii ni yoo tun je
Ileeṣẹ ọlọpaa nipinlẹ Nasarawa ti fidirẹmulẹ fun BBC pe o ku lẹyin ti awọn agbebọn ji i gbe lọjọ Satide.
Wọ́n ti hùwà aiṣootọ sí OLUWA; nítorí pé wọ́n ti bí ọmọ àjèjì.
Igbagbọ nigba naa ni pe Neymar yoo le mu ki PSG gba ife eye Champions League amọ loni yii, Moura ti wọn ta lọ si Tottenham lo pa iru itu yii.
Àwọn ọkunrin tí wọn ń ṣọ́ Jesu ń fi í ṣe ẹlẹ́yà, wọ́n sì ń lù ú.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Natalia Mufutau ìyá Yakub, Kamil àti Adam sọ̀rọ̀ lórí bí wọ́n ń sọ èdè mẹ́rin pàpọ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Natalia Mufutau ìyá Yakub, Kamil àti Adam sọ̀rọ̀ lórí bí wọ́n ń sọ èdè mẹ́rin pàpọ 30 Ògún 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 31 Ògún 2020 Ede Yoruba, Gẹeṣi, Polish ati Finnish ni awon ọmọ mẹtẹẹta n kọ- Adewumi Waliu Mufutau.
Seyi Makinde, bàtà tí Ajimobi bọ́ sílẹ̀ ni ko tẹsẹ̀ bọ̀ fún àṣeyọrí Ọyọ - APC Ṣe ẹnu ibodè tí Buhari tì, ló ń mú kí èròjà oúnjẹ gbówó lórí?
Nítorí náà, ẹ gbọ́ràn sí Ọlọrun lẹ́nu, kí ẹ má sì ṣe oríkunkun mọ́.
Bí ó bá rí bẹ́ẹ̀, kí ní ṣe tí ẹ fi fẹ́ dán Ọlọrun wò, tí ẹ fẹ́ gbé àjàgà tí àwọn baba wa ati àwa náà kò tó rù, rù àwọn ọmọ-ẹ̀yìn?
Má ta wá nù títí lae.
Ile yii ni agbaọjẹ oloṣelu to ti di oloogbe, Oloye Olusọla Saraki kọ fun ra rẹ, eleyi ti wọn maa n fi n ṣe iranwọ fun awọn eeyan ti ko ri ọwọ họri.
Ó sọ fún mi pé, “Ọmọ Eniyan, jẹ ohun tí a fún ọ; jẹ ìwé tí a ká yìí, kí o sì lọ bá ilé Israẹli sọ̀rọ̀.
 leventis ìyẹn ( foundation gallery ) níbi tí ọ ̀ pọ ̀ ihun ìṣura àbáláyé bí ère cypriot , terracottas , vases , jewelry àti coins tí a lè tọpasẹ ̀ rẹ ̀ padà sí ọ ̀ rùndún kẹrin àti ọ ̀ rùndún karùún ṣájú kí wọ ́ n tó bí jésù .
Kò sí aṣọ tí ó bò wá lójú.
Iṣọla Oyenusi rèé, ẹnití ìfẹ́ obìnrin ṣun dé ìwà ìdigunjalè Bala sọ pe, ẹni ọdun marundinlaadọta ọhun jẹ ọmọ ẹgbẹ ikọ̀ alagbara kan to maa n gba ilẹ onilẹ, to si tun n ṣiṣẹ agbanipa nipinlẹ Ogun ati Eko.
Oríṣun àwòrán, Fayose Àkọlé àwòrán, Iṣẹ oko ni ọpọ awọn olugbe Ipinlẹ Ekiti n ṣe Ojikutu ṣalaye wipe, awọn irinṣẹ to n juwe ọna fun ọkọ ofurufu jẹ oun to wọn.
Ọmọ Atapatadide ni Moura Lati kekere ni Lucas Moura ti bẹrẹ si ni gba bọọlu ni ilu Sao Paulo lorilẹede Brazil.
O kawe ni Adeen International School, Ogbomosho ati ile iwe girama ti awọn akẹkọbinrin, Federal Government College, Ogbomosho.
Kini awọn nkan to n fa aisan jẹjẹrẹ?
Bẹ́ẹ̀ ni iṣẹ́ ṣe parí lórí àwọn òpó náà.
O si han gbangba pe, Taiwo Olunaike ko kọja nile aye bii ejo ti ko ni ipa, o ko ipa tirẹ naa si idagbasoke ọmọ niyan, ko mu ọkanmọkan, ko ja ole nidi ajọ to gba, bẹẹ ni ko wa owo ojiji.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ifa Worshippers: Àwọn ẹlẹ́sìn ìbílẹ̀ ń fẹ́ kíjọba pín èrè òṣèlú alágbádá yíká gbogbo ẹ̀sìn Iwadii ṣi n lọ lọwọ lori iṣẹlẹ yii.
Orisun miran ni aṣọ Baba Keresi ode oni ti wa.
Mo fẹ́ kí ẹ mọ̀ dájúdájú pé, ẹnikẹ́ni tí kò bá gba ìjọba Ọlọrun gẹ́gẹ́ bí ọmọde, kò ní wọ ìjọba ọ̀run.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Parental Guidance: Ọdún méjì ni kí ẹ ti bẹ̀rẹ̀ kíkọ́ ọmọ nípa ìbálòpọ̀ Awọn mejeeji gbiyanju lati sọ Aisun alẹ Keresimesi di nkan ti gbogbo eniyan yoo wa lori ibusun wọn lati sun, dipo ayẹyẹ ati ariya ita gbangba.
Oríṣun àwòrán, @Alaafinofoyo Àkọlé àwòrán, kekere ni Lamidi Adeyẹmi wa to fi gori itẹ awọn baba nla rẹ, ti ade si yẹ ẹ Bi a se n ba Ọba Lamidi Adeyẹmi yọ pe o pe ọdun mejilelọgọrin loke eepẹ, BBC Yoruba se Kabiesi o, ki ade pẹ lori fun Alaafin, ki bata pẹ lẹsẹ, ki irukẹrẹ di abẹrẹ, ki ẹsin ọba jẹ oko pẹ.
” Àwọn ẹ̀yà Simeoni bá tẹ̀lé wọn.
Ipade naa de gongo nigba ti Alaga Ẹgbẹ awọn Amofin lorilẹ-ede Naijiria, ẹka Ikẹja ni Ipinlẹ Eko, Ogbẹni Adeshina Ogunlana binu jade pẹlu ikọ rẹ pe oun ti gba Ile Igbimọ Aṣofin naa nimọran tẹlẹ lati sun ipade yii siwaju nitori asiko ti wọn fun awọn tọrọ kan ko to rara ati pe wọn ko pese ẹda ofin tẹlẹ naa fun wọn lati ṣiṣẹ lori rẹ ki o to di ọjọ yii.
Àwọn ni wọ́n bá Mose ati Aaroni ṣe gbolohun asọ̀ nígbà tí Kora dìtẹ̀, tí wọ́n tako OLUWA.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù C.
Wọnpe irun Jimọ ni nnkan bi ago kan abọ ti gbogbo ile iṣẹ rẹdio ati amounmaworan si gbe si afẹfẹ.
“Nígbà tí ó yá, talaka yìí kú, àwọn angẹli bá gbé e lọ sọ́dọ̀ Abrahamu.
- Ọ̀gá àgbà ọlọ́páà Wo bí ìwọ náà ṣe lè rí gbà nínú owó ìrànwọ́ tí ìjọba Nàìjíríà fẹ́ pín ''Nisinyii ti ijọba n ṣe oju ọna reluwee lọ si Niger lati ran wọn lọwọ, iranlọwọ wo lawọn ọmọ Naijiria gan an tii riu lati ọdọ ijọba yii,'' Ologbondiyan lo sọ bẹẹ.
Nígbà tí ó bá di ọjọ́ keji, lẹ́yìn ọjọ́ ìsinmi, alufaa yóo fi ìtí ọkà náà rú ẹbọ fífì níwájú OLUWA, kí ẹ lè jẹ́ ẹni ìtẹ́wọ́gbà lọ́dọ̀ rẹ̀.
’ ” Àwọn eniyan Israẹli wólẹ̀, wọ́n sì sin OLUWA.
Awon egbe osere ni Naijiria tun sofo ogbontarigi mii ninu awon osere lataari iku Mojisola Olaiya, eni to je omo odun mejilelogoji.
Oríṣun àwòrán, Wiki Àkọlé àwòrán, Ìtàn Manigbagbe: Ẹ fokan balẹ, àwọn ajakale àrùn kan rèé to burú ju Coronavirus lọ A gbọ pé ìdá mẹ́ta èèyàn tó wà láyé ni òtútù àyà àbí ofinkin náà mú, tó sì lé ní eedegbeta mílíọ̀nù èèyàn tó fara kaasa ajakale arun aseku pani náà.
"Àsìkò tó láti fi ìwọ́de gba ara wa sílẹ̀ lọ́wọ́ ebi àti oko ẹrú - Sowore Yasin ni ""A kan ro pe awuyewuye ati aigbọra ẹniye lasan to maa n waye ni, sugbọn laarọ yii ni awọn ọdọ Hausa ati Yoruba bẹrẹ ija eyi to mu ki wọn ba ọpọ ọja jẹ nibẹ, tawọn eroja ounjẹ si bajẹ pupọ, bẹẹ ni o to ogun eeyan to fara pa yannayanna."
Jesu sọ fún wọn pé, “Ẹ kò ì tíì kà ninu Ìwé Mímọ́ pé, ‘Òkúta tí àwọn tí ń mọlé kọ̀ sílẹ̀,òun ni ó di pataki ní igun ilé.
Ogbẹni Uwauzor ṣalaye pe ile ẹjọ lo buwọlu awọn ohun ini Pan Ocean ti Amcon fofin de ni eyi ti kii ṣe pe Amcon kan deede gbe igbesẹ to wuu ni.
Awọn iroyin ti ẹ lee nifẹẹ si: Aworan aṣa ati iṣe awọn ọmọ Yoruba Kini 'pen' lede Yoruba?
Lootọ, Ọga agba ọlọpaa Naijiria, Ibrahim Idris kii ṣe oloṣelu ṣugbọn lọdun 2018, awọn kan gba wi pe iṣesi rẹ kan ko jẹ ki a fẹ mọ iyatọ laarin oun ati awọn oloṣelu.
Àkọlé àwòrán, fẹntilétọ̀, ohun èlò aṣèrànwọ́ èémí Ilé ìṣe ilé Geesi miran Gtech tí ṣe irú rẹ miran ti kí ni nílò afẹ́fẹ́ ile iwosan tí kò sì nílò iná mọ̀nàmọ́ná.
Ìgbà Marún-un ti Aisha Buhari ti tako ìjọba Buhari Aisha vs Garba Sheu: Igba Marún-un ti Aisha Buhari ti tako ìjọba Buhari Nidile mọlẹbi akọkọ orileede Naijiria,nkan ko fẹ ṣẹnu ree.
Tinubu ní kò jẹ́ kí àwọn ọmọ bíbí Eko gbérí nínú òṣèlú Ìgbà kò lọ bí òréré- Ó yá; ẹ fi àmì síi.
Art Exhibition: Ṣé ẹ láwọn ọ̀dọ́ kò mọ Àṣà ni, ẹ wo itú t'ọ́mọ ọdún mẹ́rìndílógún kan ń pa
“Ní ọjọ́ náà, n óo pe Eliakimu, iranṣẹ mi, ọmọ Hilikaya.
Ninu ifọrọwerọ pẹlu ikọ BBC Yoruba, ọkan lara awọn ontaja to wa nibi ọdun naa saroye pe aje ko bu igba jẹ lọdun yii, nitori pe witiwiti pọ lọdun to kọja ju ti ọdun yi lọ.
”O tenumo pe,“Aare gboriyin nla fun iko naa fun titepa mose, fifara jin ati akitiyan won lati pegede sinu asekagba idije naa.
Ṣugbọn ṣá o, ohun tí o fẹ́ ṣe yìí kò ní já sí ògo fún ọ, nítorí pé, OLUWA yóo fi Sisera lé obinrin kan lọ́wọ́.
6bn ohun ìní Nàìjíríà Iṣẹ́ ṣẹ̀ṣẹ̀ bọ́ lọ́wọ́ Seth Ator tó yìnbọn pa ọ̀pọ̀ èèyàn ní Texas ni- ọlọ́pàá A fẹ́ bẹ̀rẹ̀ òfin má lo fóònù mọ́ fàwọn ọmọ wa -Òbí Òní nilé ẹjọ́ tó ga jùlọ yóò gbẹ́jọ́ ẹ̀sùn ayédèrú sabuké tí wọ́n fi kan Buhari Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Aarẹ orilẹede South Africa tẹlẹri Jacob Zuma Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Orin idanimọ South Africa.
Aare Muhammadu Buhari ti ba awọn to padanu dukia wọn nibi ina to sẹlẹ lọja Jos ,ni eyi ti o jo ọja to le ni igba  lojo Abameta, osu keje, ojo kokanlelogun.
Kị́lá Akínlàdé lọ kàwé ní Yunifásítì Ifẹ̀ ní ilẹ̀ Nàìjíríà ó sì tún padà sí ẹnu iṣẹ́ ní ìpínlẹ̀ ìwọ̀-oòrùn Nàìjíríà.
Àmọ́ ṣá, oríṣìíríṣìí lojú rí níbẹ̀ o.
Ma ṣe gbogbo èyí láàrin ìṣẹ́jú kan péré.
 kò gbè ìyàwó , bẹ ́ ẹ ́ ní kò sì bí omo .
Wúrà tí wọ́n fi òòlù lù ni ó fi ṣe ìtẹ́lẹ̀ ati ọ̀pá ìgbámú rẹ̀, àṣepọ̀ ni ó ṣe é, pẹlu àwọn fìtílà rẹ̀, ati àwọn kinní kan bí òdòdó tí ó fi dárà sí i lára.
Olori egbe APC Bola Tinubu ro awon omo egbe pe ki won jade dibo fun Aare Muhammadu Buhari ni idibo ojo Satide.
Àwọn tí wọ́n mọ iyàn jà ní ayé yìí ńkọ́?
“Nígbà tí ẹrú náà jáde, ó rí ẹrú, ẹlẹgbẹ́ rẹ̀ kan tí ó jẹ ẹ́ ní eélòó kan.
Ẹjẹ ka tibi pẹlẹbẹ mu ole jẹ ninu APC to jẹ ẹgbẹ to wa lori ijọba.
“O ni itoju oju popo ati agbegbe je ijoba to wa lori aleefa bayii logun.
Stadium gege bi gbagede ipolongo ohun.
Wayii o, Didier Drogba gba ife-eye idije Premier League merin  ati ife-eye Champions League kan lodun 2012, bee si ni O tun gba ife-eye idije FA Cup merin ati ife-eye idije abele meta.
Ṣugbọn nigba ti mo pe ọmọ ọdun mọkanla, ọkunrin kan naa tun fipa bami lopọ!
Ó mú owó pupọ lọ́wọ́,kò ní dé títí òṣùpá yóo fi di àrànmọ́jú.
Àwọn alufaa wọ ibi mímọ́ lọ láti tọ́jú rẹ̀.
Iroyin sọ pe miliọnu mẹrinlelaadọta lo gba nigba to na Rafael dos Anjos loṣu kọkanla ọdun 2018, ṣugbọn ko si ẹni to mọ iye to gba ninu ija eleyi to ṣẹṣẹ ja yii.
O ni oun n yẹba kuro lori pẹpẹ iwaasu fun igba diẹ ni ibamu pẹlu imọran awọn agbaagba ijọ COZA ati ifẹ ti oun ni si iṣẹ Ọlọrun.
E̩bí jé̩ ìpìlè̩ pàtàkì àdánidá ní àwùjo̩, ó sì ní è̩tó̩ pé kí àwùjo̩ àti orílè̩‐èdè ó dáàbò bò ó.
Usi ni àkọ́bí, Busi ni wọ́n bí tẹ̀lé e, lẹ́yìn náà Kemueli tíí ṣe baba Aramu.
Bí ọba ìlú kan, tabi tí orílẹ̀-èdè kan, bá sọ pé o kò sí ní ilẹ̀ òun, Ahabu á ní dandan, àfi kí wọ́n búra pé lóòótọ́ ni wọn kò rí ọ.
Oríṣun àwòrán, @fkeyamo Àkọlé àwòrán, Awọn ọdaran kan lati inu ẹgbẹ PDP gbọna ẹburu wọ oju opo INEC Wọn fi ọrọ yi sita lẹyin ti ẹgbẹ PDP ti saaju fi iwe ehonu tiwọn naa ṣọwọ si igbimọ to n gbẹjọ ẹhonu to niṣẹ pẹlu idibo aarẹ nibi ti wọn ti ni ''awọn ni ẹri tawọn gba lati oju opo Inec to ṣafihan pe Atiku ri ibo 8,356,732 gba lati fẹyin Muhammadu Buhari to ni ibo 16,741,430 janlẹ.
Ṣugbọn Jesu wí fún wọn pé, “Kò sí wolii tí kò níyì, àfi ní ìlú ara rẹ̀, ati láàrin àwọn ará rẹ̀, ati ninu ẹbí rẹ̀.
Èèyàn 14 mííràn tún ti lùgbàdì ààrùn Coronavirus ní Naijiria Èmi náà ti hù ìwà tó burú ju àgbèrè lọ sí Abiola Ajimọbi -Florence Ajimọbi Òfìfo ṣọ́ọ̀ṣì pa aṣọ dà fún àwọn Páṣítọ̀ Nàìjíríà Afunrasí ẹ̀sùn jìbìtì ló ni iléeṣẹ́ tó ń ṣe ìwé àṣẹ wọléwọ̀de ní Nàìjíríà Aarẹ Buhari ṣalaye pe igbayegbadun awọn ọmọ orilẹ-ede Naijiria kii ṣe oun to ṣee dunadura le lori ṣugbọn igbesẹ aabo ati alaafia araalu ni ijọba lẹkajẹka n le.
Ọba pè wọ́n, ó dán wọn wò, ninu gbogbo wọn, kò sì sí ẹni tí ó dàbí Daniẹli, Hananaya, Miṣaeli ati Asaraya.
ifinijoye aare orile-ede South Africa, Cyril Ramaphosa ti yoo waye niluu.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ọgbà ẹ̀wọ̀n ni Naira Marley yóò ti wo ìbúra Buhari ní May 29 Èèmọ̀ rèé o!
APC ni aridaju akọsilẹ wa pe ni ọjọ kẹrindinlọgbọn oṣu kọkanla ọdun 1946 ni wọn bi Atiku Abubakar ni ilu Jada ni Adamawa, iha ariwa Cameroon.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù UK Recession: Ètò ọ̀rọ̀ ajé ilẹ́ Gẹ̀ẹ́sì ti dẹnukọlẹ̀ fún ìgbà akọ́kọ́ láti ọdún 2009: wo bí ipa tí yóò ní lórí rẹ̀ 12 Ògún 2020 Oríṣun àwòrán, Getty Images Fún ìgbà àkọ́kọ́ ní ǹkan bi ọdún mọ́kànlá sẹ́yìn orílẹ̀-èdè United Kingdom ti kédé pé ètò ọ̀rọ̀ ajé rẹ̀ ti dẹnukọlẹ̀.
Awọn to mọ sọ pe o fẹran lati ma para ile ẹjọ ti a si ma bu si ẹkun ti adajọ ba kọ lati da lare ninu ẹjọ.
Àwọn ìṣẹ̀lẹ̀ mánigbàgbé tó wáyé nibi ìwọ́de ENDSARS Nàìjíríà Kíni ìyàtọ̀ tí yóò wà láàrin SARS àti SWAT?
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Lamidi Adeyẹmi, Anthony Joshua: Ọmọọba mẹ́wàá ló du òyè pẹ̀lú Adeyẹmi, tó sì já mọ́ ọ lọ́wọ́ 26 Èbibi 2018 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 15 Ọ̀wàrà 2020 Oríṣun àwòrán, @Alaafinofoyo Àkọlé àwòrán, Ọba Adeyẹmi gbafẹ, o gboge, to si rẹwa lọkunrin Ọba Lamidi Ọlayiwọla Adeyẹmi Kẹta, ti pe ẹni ọdun mejilelọgọrin loke eepẹ bẹẹ lo ti lo ọdun mọkandinlaadọta lori itẹ awọn baba nla rẹ.
Ìwé Mímọ́ tún wí níbòmíràn pé, “Wọn yóo wo ẹni tí wọ́n fi ọ̀kọ̀ gún.
Ìbá sàn kí n ti kú,kí ẹnikẹ́ni tó rí mi.
Ẹ mú òun àti ìyàwó rẹ̀ àfẹ́sọ́nà lọ sí pẹ̀tẹ́ẹ̀sì dídára tí ń bẹ nínú ààfin mi lọ́hùn-ún nì, ibẹ̀ ni kí ó máa gbé, nígbà tí ó bá ṣe díẹ̀ sí i mò ń bọ̀ wàà gbé ìyàwó fún ọmọ akọ̀wédìran.
Jesu bá sọ fún wọn pé, “Gbogbo yín ni ẹ óo pada lẹ́yìn mi, gẹ́gẹ́ bí a ti kọ ọ́ pé, ‘Ọwọ́ yóo tẹ olùṣọ́-aguntan, àwọn aguntan yóo bá fọ́nká,’ 
Emir Muhammadu Sanusi II ti fèsì sí ẹ̀sùn Gómìnà Kano Ẹ̀mí 18 ṣòfò ní Òpópónà Akure sí Ọwọ Ìdílé Pius Adesanmi ti gbé Boeing lọ sílé ẹjọ́ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ondo: Dejí sun ọmọ méje àtagbalagba meji mọ́lé nítorí pé ó ń bínú Osinachi Ohale ti ẹgbẹ agbabọọlu Naijiria naa lo wa bọrọ jẹ patapata, ti o si gba bọọlu wọle si oju ile ara rẹ, eyi to mu ki ifẹsẹwọnsẹ naa pari si ami ayo mẹta si odo fun ikọ Norway.
Juda ati ilé Israẹli bá ọ ṣòwò: wọ́n ń kó ọkà, èso olifi, àkọ́so èso ọ̀pọ̀tọ́, oyin, òróró ati òrí wá láti fi ṣe pàṣípààrọ̀ àwọn nǹkan tí ò ń tà.
" ni ariwo ti ọkan lára àwọn ọmọlẹyìn agba oṣelu naa n pa ni gbagede ile oloṣelu naa lẹyin to gbọ iroyin ọhun.
  Ewu nbẹ fún onírìnsè lójú ọ̀nà yìí nítorípé àwọn
Nígbà tí mo bá wà láàrin àwọn tí kò gba ètò ti Òfin Mose, èmi a máa fi ara mi sí ipò wọn, bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé mo ka òfin Ọlọrun sí, pàápàá jùlọ òfin Kristi.
Koda, gomina Abiola Ajimobi lo gbé ijọba ipinlẹ Ọyọ lọ sile ẹjọ lori ọrọ ilẹ naa.
N kò fojú pamọ́ nítorí ẹ̀gàn,bẹ́ẹ̀ ni n kò gbójú sá fún itọ́ títu síni lójú.
Epe rabandẹ ni @legendarylekzzy fi ranṣẹ si awọn ọlọpaa, o ni Ọlọrun lo maa fiya jẹ wọn.
“A gbagbo pe, iko yii yoo se daradara, bee si ni o dami loju pe won yoo gbe orile-ede Naijiria laruge niluu Beijing.
 ipade naa da lori bi eto oro aje orile ede Naijiria yoo se ni idagbasoke nipa bi ojo ori  awon eniyan se n le si i lorile ede yii.
argentina nínú ètò ìkànìyàn 1995 , iye àwọn ènìyàn tí ó wà ní orílẹ ̀ -èdè ajẹntínà ( argentiana ) lé díẹ ̀ ní mílíọ ̀ nù mẹ ́ rìnlélógójì àti àti ààbọ ̀ ( 34 , 513 , 000 ) .
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Coronavirus Ghana: Ààrẹ Nana Akufo-Addo ti wọ́lé ìyàsọ́tọ̀ ọlọ́jọ́ mẹ́rìnlá 7 Èrèlè 2018 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 6 Agẹmo 2020 Oríṣun àwòrán, Facebook/Nana Akufo-Addo Aarẹ orilẹede Ghana yoo wa ni yara iyarasọtọ fun ọjọ mẹrinla lẹyin ti iwadii fihan pe o ti ni ipade pẹlu ẹni to ni arun Coronavirus.
Ni gbangba ati ni ikọkọ, May ni ipinnu oun dara ati wipe oun nikan ni ọna ti ilu ko fi ni bajẹ.
In 2008 Modise Mokwadi Fly, a Motswana, was hanged for killing his son.
Ẹ kò gbọdọ̀ ṣe iṣẹ́ kankan ní ọjọ́ náà.
- Amina Zakari Pásítọ̀ wọ gàù lórí ìran ikú, ọ̀dọ́ musulumi ya wọ ṣọ́ọ̀ṣì Àwọn àṣà àti ìse tó yọ obìnrin sílẹ̀ nílẹ̀ Yorùbá Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Rashidat Fawẹhinmi: Sísọ èdè Yorùbá kò leè ba Gẹ̀ẹ́sì jẹ́ lẹ́yìn odi Nigba to n sọrọ lori isẹlẹ ọtun to gba awujọ wa kan yii, Dolapo Badmos, tó jẹ́ agbẹnusọ iléeṣẹ́ ọlọpàá Ẹkun keji, to wa ni ipínlẹ̀ Eko ní, ó ṣéeṣe kí àwọn olè ajípáta naa jẹ́jọ́ ẹ̀sùn ìpànìyàn, tí ọwọ́ bá tẹ̀ wọ́n.
Ọba dìde ní òru ọjọ́ náà, ó sọ fún àwọn olórí ogun rẹ̀ pé, “Mo mọ ète àwọn ará Siria.
Orúkọ àwọn ìjòyè tí wọ́n ṣẹ̀ lára Esau nìwọ̀nyí, gẹ́gẹ́ bí ìdílé wọn ati ìlú tí olukuluku ti jọba: Timna, Alfa, Jeteti, 
 ( eyi yatosi nomba gidi ti won foriko si gbongbo alagbarameji 2 ) .
O fikun un pe, idi pataki ti oun se fe je ki, ifesewonse ohun ko waye nilu Abuja, ni lati fi ye iko Super Eagles si, saaju irin ajo iko ohun lo si orile-ede Russia fun idije agbaye to n bo lona, atipe boya aare Muhammadu Buhari yoo wa ye ifesewonse ohun si.
Ó ṣe pataki ki gbogbo ọmọ ilú pinu ni ikan kan lati ṣe àtúnṣe lati bọ́ lọ́wọ́ ìnira ti ó wà ni ilú lọ́wọ́lọ́wọ́.
Mo rí nǹkankan tí ó burú lọ́wọ́ àwọn wolii Samaria:Ẹ̀mí oriṣa Baali ni wọ́n fi ń sọ àsọtẹ́lẹ̀;wọ́n sì ń ṣi àwọn ọmọ Israẹli, eniyan mi, lọ́nà.
Lọjọ Abamẹta ni Liverpool gbo ewuro soju Arsenal ti wọn na wọn pẹlu ami ayo marun un sookan ni papa iṣere Anfield.
Ẹ ranti pé ẹni tí ó bá fúnrúgbìn díẹ̀, díẹ̀ ni yóo kórè.
Jesu sọ fún àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ pé, “A kò lè ṣàì rí ohun ìkọsẹ̀, ṣugbọn ẹni tí ó ti ọwọ́ rẹ̀ ṣẹ̀ gbé!
O fi iwe ikọsile naa ranṣẹ sawọn igbimọ Backbench 1922 gẹgẹ bi o ṣe fẹẹ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Oba Adedokun Abolarin ti Oke Ila: Ó ya ọ̀pọ̀ tó súnmọ́ mi lẹ́nu bí mo ṣe ń kọ́ Ó lọ sí ilé ìwé girama Corona ní Agbara, láti ibẹ̀ ló gbà lọ sí ìlú ọba níbi tó ti tẹ̀síwájú nínú ẹ̀kọ́ rẹ̀.
5million ) naira sọtọ fun rira ẹyẹ ati irinse ati
ẹ óo fún àwọn alufaa, ọmọ Lefi, láti inú ìran Sadoku, tí wọn ń rú ẹbọ sí mi, ní akọ mààlúù kan fún ẹbọ ìmúkúrò ẹ̀ṣẹ̀.
 umuahia ni oluilu re wa bo ti le je pe abá ni ilu gbangba fun aje .
Awọn ọmọ ijọ Sotitobirẹ pọ biba nile ẹjọ lati wa se atilẹyin fun asaaju wọn, ti awọn akọroyin naa ko si gbẹyin pẹlu awọn eeyan miran to wa woran, ti ọpọ ko si mọ pe wọn ti sun ẹjọ naa siwaju.
Jíjìn rẹ̀ mu ẹṣin dé ọrùn, ó sì gba ilẹ̀ lọ ní nǹkan bí igba ibùsọ̀.
Asiko iloyun tumọ si asiko ti ko si ẹni to le da obinrin lẹbi ti o ba n ṣa ounjẹ jẹ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù SARS: Ẹgbẹ́ agbábọ́ọ̀lù Remo Stars ní ikọ̀ SARS ló pa agbábọ́ọ́lú òun 23 Èrèlè 2020 Oríṣun àwòrán, @RemoStarsSC Ẹgbẹ agbabọọlu Remo Stars ti fẹsun ipaniyan kan ikọ ọlọpa to n gbogun ti iwa idigunjale, Special Anti-Robbery Squad, SARS, nipinlẹ Ogun.
Àkọlé àwòrán, Kilaasi kan ni yi ti wọn ti n kọ akẹkọọ ni imọ kẹmisitiri ni Fasiti Bayero nipinlẹ Kano Koda ko yọ àwọn ibi to yẹ ki akẹkọo ti kọ ẹko nipa afojuri iṣẹ silẹ.
Nigba miran, o si lee jẹ pe awọn orisa lo tako awọn iwa naa lati ọdọ awọn obinrin.
Pasito Ezekiel Odeyemi,igbakeji alakoso ile-ijosin ti irapada ,Redeemed Christian Church of God, , naa tun soro ninu iwasu re pe , o ye ki  a maa dupe lowo Olorun pe orile ede Naijiria si wa ni isokan.
awon ẹsọ eleto aabo yoo ri i pe won sa gbogbo ipa won, lati mu awon ọdaran , ki
oloselu ti won maa n sọ awọn  ahesọ ọrọ
O ni idije ti 2018 yii, ni amojuto rẹ ko dara rara lati igba ti oun ti n kopa ninu iru idije bẹẹ.
Ọrọ naa le koro leti ṣugbọn ootọ ibẹ ni wi pe: oselu Naijiria ko dẹrun lati kopa fun ẹni ti ko ba ni Baba isalẹ lẹyin tabi ti ko ni owo ti yoo fi du ipo.
Festac Explosion: Àwọn àwòràn tó ṣeni ní àánú níbi ìbúgbàmù Eko
Bí mo ti ń lọ lónìi’, jọ́wọ̀ jẹ kí n padà gẹgẹ bi ọkùnrrin, tó bẹ́ẹ̀ tí, bí ọjọ́ mi bá tilẹ̀ pé ti mo kú, àwọn ènìyàn kò ní le bi ara wọn léèrè lẹ́hìn mi pé ‘Tàbí a bí ọkùnrin náà rí ńdan?
Láti Kehelata wọ́n lọ sí Òkè Ṣeferi.
Iroyin ti a gbọ nipe Gomina Makinde yan an sipo naa nirori iṣe takun takun to ṣe ṣaaju ibo gomina ọdun 2019 to gbe e wọlẹ gẹgẹ bi gomina ipinlẹ Oyo.
Irú ẹni bẹ́ẹ̀ níláti jìyà ẹ̀ṣẹ̀ rẹ̀.
N óo máa kígbe fún ayọ̀,nígbà tí mo bá ń kọ orin ìyìn sí ọ;ẹ̀mí mi tí o ti kó yọ, yóo ké igbe ayọ̀.
Adájọ́ pàṣẹ kí wọ́n fi Naira Marley sí àhámọ́ ọgbà ẹ̀wọ̀n Bí àwàdà bí eré, apanilẹ́rìn yìí di ààrẹ Orílẹ̀-èdè!
Gbogbo nǹkan wọnyi ṣẹlẹ̀ nígbà ayé Joiakimu, ọmọ Jeṣua, ọmọ Josadaki, ati nígbà ayé Nehemaya, gomina, ati Ẹsira Alufaa ati akọ̀wé.
Ìgbà mélòó ni wọ́n ṣọ̀tẹ̀ sí i ninu ijù,tí wọ́n sì bà á lọ́kàn jẹ́ ninu aṣálẹ̀!
O tesiwaju pe , oun ti gbe igbese nipa didekun bi won se n se fayawo epo robi lo si awon orile ede to je amulegbe , ni eyi ti o fi je isoro lati le se amujoto awon epo robi ti won gbe kaakiri orile ede Naijiria.
Wọn sọ ẹlẹsẹ ayo Diego Costa to jẹ ọmọbibi orilẹede Brazil to n ṣoju Spain lorukọ Maradona.
Wọ́n tò lọ́wọ̀ọ̀wọ́,ẹnikẹ́ni kò sì yà kúrò ní ọ̀nà tirẹ̀.
Bí àìsàn yìí kòbá dé sí ọkùnrin náà ìjà ńlá kan ìbá bbẹ́ sílẹ̀ tí orílẹ̀-èdè yóó fi máa dìde sí orílẹ̀-èdè, tí ìjọba kan yóò fi máa dìde sí ìjọba kejì bẹ́ẹ̀ ni orí ọkùnrin yìí ní ìjà ìbá ti bẹ̀rẹ̀, orúkọ rẹ̀ ìbá sì bàjẹ́ láti ìrandíran.
Omotola wa pari ọrọ rẹ bayii loju opo Twitter, nigba ti o ki gbogbo awọn eeyan ti wọn ti dasi ọrọ naa.
Oun ni aye mọ ni agba ọjẹ ninu awọn orin ibilẹ ilẹ̀ Afirika (African Folk Music) ti wọn si tun mọ ọ ní ọkan ninu awọn ọba orin igbalode ni Iwọ-Oorun Afirika.
Oríṣun àwòrán, others Ijọba fikun un pe idanwo 'The Basic Education Certificate Examination' yoo waye ni Ọjọ Kẹwaa, Oṣu Kẹjọ.
Tabi kí eniyan jẹ́ mímọ́ níwájú Ẹlẹ́dàá rẹ̀?
“Èmi OLUWA kò gbàgbé ohun tí àwọn ọ̀tá wọn ṣe,ṣebí gbogbo rẹ̀ wà ní àkọsílẹ̀ lọ́dọ̀ mi?
O fi kun un pe ko si idi fun ileewosan naa lati maa gbarata pẹlu bi awọn eeyan ṣe n na ika si wọn.
Lọdun 2020, ijọba Saudi Arabia ko faaye gba ọpọ eeyan lati wa fun iṣẹ Hajj nitori ajakalẹ aarun covid-19, Eeyan to le ni 161,000 lo ti lugbadi aarun Coronavirusnaa nibẹ nigba ti awọn to ti ku ju 1,300 lọ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Oyo government: Kí ló dé tí ọ̀rọ̀ Ìyálọ́jà àti Babalọja ń fà awuyewuye?
Obasanjo: Mo lòdì sí ìgbé ayé tí Gani Adams ń gbé látẹ̀yìnwá, ṣùgbọ́n n kò bá a jà
ati oríṣìíríṣìí èròjà ati òróró ìtànná, ati ti ìyàsímímọ́, ati fún turari olóòórùn dídùn.
Aarẹ Buhari gbe igbesẹ yii lẹyin ti awọn agbabọọlu yii ko jalẹ wi pe awọn ko ni kopa ninu ifẹsẹwọnsẹ pẹlu Burundi ninu idije Afcon 2019 ti ijọba ko ba san awọn owo ajẹmọnu ti wọn jẹ wọn.
osu  to kere ju fun awon osise ipinle naa.
Ahmed Musa ló fakọyọ jùlọ láàrín àwọn agbábọ́ọ̀lù Nàìjírìa lọdún 2018
Ṣugbọn Gedalaya sọ fún Johanani, ọmọ Karea pé, “Má ṣe bẹ́ẹ̀, irọ́ ni ò ń pamọ́ Iṣimaeli.
Lọwọlọwọ, apapọ awọn to ti ni aarun naa ti pe 62,853, eyan 58,675 ti ri iwosan, 1,144 si ti ku.
Bawo lawọn ọmọ igbimọ amusẹya APC se kọja aaye wọn?
Wo bí ètò ìsìnkú Tolulope Arotile ṣe lọ nílùú Abuja Èmi Ọba tí wọ́n ń kó jẹ nígboro- Oluwo ti ilú Iwo Ìjọba ìpínlẹ̀ Kano tí wọ́gilé ayẹyẹ lẹ́yìn ìrun ọdún Iléyá!
Tí a fiṣọwọ́ ní 13:01 11 Òkùdu 201913:01 11 Òkùdu 2019 Wọn ti búrawọlé fún àwọn àdarí ilé aṣòfin àgbà BBCCopyright: BBC IburawọleImage caption: Iburawọle Article share tools Facebook Twitter ṢàpínlòView more share options Share this post Copy this linkKà síwájú síi nípa àwọn ìtọ́kasí wọ̀nyí.
Ajebori Onifuji - BBC News Yorùbá BBC News, YorùbáFò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Fuji: Èmi àti Adewale Ayuba ò ja, Ọlọ́run ló fún mi lóhùn t'èmi - Ajebori Onifuji Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Fuji: Èmi àti Adewale Ayuba ò ja, Ọlọ́run ló fún mi lóhùn t'èmi - Ajebori Onifuji 14 Ọ̀pẹ̀̀ 2019 Asimiyu Ajebori lorukọ tirẹ ti ọpọ mọ si Ọmọ gba Feeder""."
Russia 2018: Belgium ti gba ípò kẹ̀ta Ife Ẹyẹ Agbaye
Ninu ẹ̀yà Simeoni, àwọn tí wọ́n tó ẹni ogún ọdún, tí wọ́n tó lọ sójú ogun, gẹ́gẹ́ bí àkọsílẹ̀ wọn ní ìdílé-ìdílé 
Bẹ́ẹ̀ ni bí ìyàwó bá ti rí ọkọ fín, nǹkan báwọ̀nyí kò ní ṣàì máa ṣẹlẹ̀ láàrrin òun àti ọkọ.
Adajọ Taiwo ni oun fun ajọ DSS lasẹ lati fi Sowore si ahamọ ko fi pari iwadi rẹ to n se ni nitori ajọ naa nilo akoko si lati fi ẹnu iwadi rẹ jona.
 Àwọn ẹ ̀ ka èdè tí ó wà ní abẹ ́ rẹ ̀ ni okene ( hima , ihima ) igbara ( etunno ) ebira ní ìsupọ ̀ ẹ ̀ ka èdè , wọ ́ n ń lò ó ní ilé ìwé .
Ko ti han faye ọna ti Asiwaju Tinubu yoo gba mu isẹ yii se tabi awọn ti yoo ko mọra fun isẹ yii, sugbọn ohun ti awọn eeyan n sọ nipe eyiun bi awọn iroyin to n lọ kaakiri ba see gbagbọ, Tinubu funrarẹ naa ni awọn ẹhonu kan si ẹgbẹ oselu yii, tawọn eeyan si n beere pe tanni yoo tan ẹhonu tirẹ?
Oṣù mẹta péré lo fi jẹ gomina, tí ìjọba ológun Muhammadu Buhari gba akoso Nàìjíríà ni ọjọ́ Kọkanlelọgbọn, osu Kejìlá, ọdún 1983.
Ajọ JAMB ni ko tii si gbedeke fun ọjọ ti esi idanwo aṣewọle si ileewe giga UTME lọọkan.
O ni lẹyin ijiroro pẹlu awọn olugbani nimọran oun, oun ti ko gbogob ọrọ ti oun sọ si akọroyin naa nilu Calabar jẹ.
Ẹni tí ń ṣe ìmẹ́lẹ́ lẹ́nu iṣẹ́ rẹ̀,ẹgbẹ́ ni òun ati ẹni tí ń ba nǹkan jẹ́.
Ikede yi jẹ eyi ti ko dun mọ awọn oṣiṣẹ ninu ti wọn si ti tutọ soke foju gba a pe ki wọn maa dan wo rara.
Àwọn ìlú olódi tí ó wà ní ilẹ̀ náà ni Sidimu, Seri, Hamati, Rakati, Kinereti; 
Ẹ̀wẹ̀ àwọn elétò ìlera yóò tètè fún ẹni tó bá nira fún láti mi ni Fẹntílàtọ̀ kí a dinku máa bà bá afẹ́fẹ́ tó ń wo inú ara.
Kí ó kó wọn wá sọ́dọ̀ alufaa, kí alufaa sì fi ekinni rú ẹbọ ìmúkúrò ẹ̀ṣẹ̀.
Oríṣun àwòrán, Twitter/ Osagie Ize-Iyamu Lara ohun ti Ize-iyamu ni oun yoo ṣe ni lati jẹ ki eto aabo gbooro si ni ipinlẹ Edo ati lati pese owo iranwọ fun awọn ọdọ fun idokowo.
Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Fídíò, End SARS, End SWAT: Ó pé mi bí SARS kò ṣe sọ mí dolówọ́- Fulani Kwajafa17 Ọ̀wàrà 2020 Fídíò, Soyinka Cancer: Àṣe ara mi ni iso ti n run gbogbo bí mo ṣe n ṣèrànwọ́ lórí jẹjẹrẹ27 Bélú 2019 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 3 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 5 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Ajọ Nigerian Supreme Council for Islamic Affairs ti sọ wi pe awọn n rọ ijọba lati ri pe awọn n fin awọn ile ijọsin kaakiri ni ojoojumọ nitori awọn ile ijọsin ko ni owo lati se e.
”Alaga igbimo ati adari ẹka to n ri si idagbasoke imo sayensi ati ẹrọ,Ekanem Udoh, wa fokan minisita balẹ pe , igbimo naa ko ni pẹ gbe eto ilana  jade, ni eyi  ti yoo mu ipinnu awon omo orile ede Naijiria sẹ.
A gbọ pe awọn olubi wọn yi ṣina fun awọn ẹsọ alaabo ọhun ni orita Udege loju ọna Mararaban-Udege ni ipinlẹ Nasarawa ti wọn si ji eeyan mẹwaa gbe lọ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù EndSars Protest slang: Kíní ìtumọ̀ Sọ̀rọ̀ Sókè tí àwọn afẹ̀họ́núhàn EndSars ń lò káàkiri 20 Ọ̀wàrà 2020 Oríṣun àwòrán, Small Doctor Ojọgbọn imọ Ede Yoruba, Bisoye Ẹlẹsin ti salaye fun BBC idi ti ''Sọrọ Soke'' ṣe di akanlo ede lorilẹ-ede Niajiria lasiko ifẹhọnuhan tako ifiyajẹni ọlọpaa kaakiri orilẹede Naijiria.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Fire Eater: Azonto ní àfojúṣùn òun ni láti lọ fi idán iná yìí pa owó lókè òkun Amọ awọn gomina to wa nilẹ Yoruba ti wa sọ fawọn Fulani pe ibẹru wọn yii ko lẹsẹ nilẹ, ko si tọ, bẹẹ ni ko pọn dandan.
Naamani, Ahija ati Gera, tí ń jẹ́ Hegilamu, baba Usa, ati Ahihudu.
Ṣùgbọ́n bótiwù kí òde rẹwà tó, àsìkò yí ni àmì ìrẹ̀wẹ̀sì ọkàn máa ń ṣábàá bẹ̀rẹ̀ sí í farahàn lára àwọn ènìà.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Akomolede ati Aṣa lori BBC: Kí ní ìtúmọ̀ Sílébù àti àmi ohun tó ń fún ni?
Ẹ̀yin ni ara Kristi, ẹ̀yà ara rẹ̀ ni ẹnìkọ̀ọ̀kan yín.
Nítorí pé, OLUWA ti pàṣẹ fún mi pé n kò gbọdọ̀ fẹnu kan nǹkankan ati pé, n kò gbọdọ̀ gba ọ̀nà tí mo gbà wá pada.
Bi orin yii ṣe n lọ labẹlẹ fidio ti Bunkunmi fi sita n wu ni lori jọjọ eyito ṣalaye itan ifẹ to mbẹ laarin wọn.
Wo àwọn òṣìṣẹ́ kólẹ̀-kódọ̀tí tó ń fi ẹ̀mí wọn wéwu kí Abuja leè mọ́ tónítóní Mo ti bẹ̀rẹ̀ sí ń bá àwọn tí a jọ díje nínú ìdìbó abẹ́lé sọ̀rọ̀ kí àláàfíà léè jọba - Akeredolu Èèyàn 576 míràn tún kún àwọn tó ní àrùn COVID-19 ní Nàìjíríà Wo àwọn nkan tó yẹ́ kí o mọ̀ nípa 'Awawa Boys', ọ̀kan lára ẹgbẹ́ òkùnkùn tó n dá Eko rú Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Olofa ina: ẹ parí òwe yìí pé ìgbà tí ara bá tu ìgbẹ́ láà ri eṣú.
1 648 Saint Barthélemy 1 10.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ǹjẹ́ o tilẹ̀ mọ àwọn ọ̀gá àgbà tó ti jẹ rí ní DSS?
búkan ( persian : شارۆچکه ی بۆکان ; kurdish : bokan ; tun romanized bi būkān , bokan , ati bowkān ) je ilu kan ni ati olu ti búkan county , oorun azerbaijan ekun , iran .
Ó ní, “Baba, Baba, ohun gbogbo ṣeéṣe fún ọ.
Òṣìṣẹ́ ààfin mi tí kò bá lo ìbòmú yóò pàdánù isẹ́ rẹ̀-Oluwo Oluwo pàṣẹ fáwọn òṣìṣẹ́ ààfin rẹ̀ láti lo ìbòmú tàbí kí wọ́n pàdánù iṣẹ́ wọn Oríṣun àwòrán, Emperor Abdulrasheed Adewale Akanbi Telu 1 Oluwo ti ilu iwo, Ọba Abdulrasheed Akanbi ti leri leka pe lile loun yoo le oṣiṣẹ aafin rẹ ti ko ba lo ibomu gẹgẹ bi ijọba ipinlẹ Ọṣun ti ṣe paa laṣẹ.
Mo di ẹni ẹ̀gàn níwájú àwọn ọ̀tá mi,wọ́n ń wò mí ní àwòmirí.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Lagos Killings: Ọ̀gá àgbà ọlọ́pàá ṣèkìlọ̀ pàtàkì fún àwọn ọlọ́pàá 15 Ìgbé 2019 Àkọlé àwòrán, Ọga agba ọlọpaa, Mohammed Adamu Lataari ipaniyan to n waye ni lemolemo ni ipinlẹ Eko, ọga agba ọlọpaa ṣabẹwo ojiji.
Ẹnìkan tí ìṣẹ̀lẹ̀ nàá ṣojú rẹ̀ sọ fún BBC pé ìjà ọ̀hún bẹ̀rẹ̀ lásìkò tí àwọn ọmọ ẹgbẹ́ Shiite n rìnrìn àjò láti Nasarawa lọ sí ìlú Abuja, tí àwọn ọmọ ogun sì ''dí ọ̀nà mọ́ wọn, pé kí wọ́n padà sí ibi tí wọ́n ti n bọ̀.
Diẹ lara awọn minista ti awọn eniyan sọrọ julọ laida nipa wọn ni: Solomon Dalung- Minista fun ọrọ ọ̀dọ́ ati ere idaraya Oríṣun àwòrán, @solomon Àkọlé àwòrán, Oun lo kọkọ koju iṣoro ibere ta ni adari ajọ NFF ni Naijiria?
Lẹ́yìn wọn, Asaraya ọmọ Maaseaya, ọmọ Ananaya ṣe àtúnṣe ní ẹ̀gbẹ́ ilé tirẹ̀.
“Ṣugbọn ìwọ, ọmọ eniyan, fetí sí ohun tí mò ń sọ fún ọ.
OIC tun pinnu lati mu eto aabo lọkun-kundun ati lati lepa alaafia kaakiri gbogbo orilẹede ti ẹgbẹ naa wa.
 iṣé aseparí fun eko wọn ti ile-wosan ni o se ni ile-iwosan ti st.
'Wọ́n ní a kò lówó tó láti díje dupò ní Nàìjíríà' Báwo ni ìròyìn òfégè ṣe burú tó ní Afrika?
Àwọn olórí yín dàbí tata, àwọn akọ̀wé yín sì dàbí ọ̀wọ́ eṣú, tíí bà sórí odi nígbà òtútù, nígbà tí oòrùn bá yọ wọn a fò lọ; kò sì ní sí ẹni tí yóo mọ ibi tí wọ́n lọ.
Oliver Cowdery bẹ̀rẹ̀ iṣẹ́ rẹ̀ gẹ́gẹ́bí akọ̀wé nínú títúmọ̀ Ìwé Ti Mọ́mọ́nì, Ọjọ́ keje oṣù kẹrin 1829.
Ó sì mú kí Juda dẹ́ṣẹ̀ nípa pé wọ́n ń bọ àwọn ère rẹ̀.
Oun ni o dije labẹ ẹgbẹ oṣelu APC ni Osu Keji, ti ọdun 2019.
Afẹnifẹre ni Atiku se fọkan tan lẹni ti yoo mu atunto ba eto iṣejọba Naijiria.
Awọn ara agbeegbe naa wa rọ ijọba lati ba wọn wa atunsẹ si isẹlẹ omiyale to n sẹlẹ lati igba de igba ni ile Ile-Ifẹ.
- Olukoya ti ìjọ MFM Ẹ̀kọ́ ọ̀fẹ́, ètò ilera ọ̀fẹ́ àti iná ọba ló jẹ wá lógún- ọmọ Nàìjíríà Akíkanjú obìnrin Algeria tó kojú ogun Lárúbáwá fáwọn ènìyàn rẹ̀ Sheikh Samadaani gba awọn olori ni imọran lati ṣe ohun to dara ki ọkan awọn eniyan le balẹ.
Iwa ole jija Kabir yii tako ofin ipinlẹ Eko ti abala 287 tọdun 2015.
Ó ní ọdọmọkunrin kan, tí orúkọ rẹ̀ ń jẹ́ Mika.
Aadọta ojóbó ni kí o ṣe sí àránpọ̀ aṣọ kinni, lẹ́yìn náà ṣe aadọta ojóbó sí àránpọ̀ aṣọ keji, kí àwọn ojóbó náà lè kọ ojú sí ara wọn.
INEC: Kò sí ìká tí o kò lè fí dìbò, ṣáà tí tẹ̀ ẹ́ sójú ẹ dáadáa Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, APC jáwé olúborí nípínlẹ̀ Ekiti Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 3 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 5 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
’’Awọn asofin tun so pe  igbese ti ijọba apapo fẹ gbe yii yoo jẹ ikilọ fun awọn oniwa -ibajẹ, bakan naa ni yoo tun jẹ ki ofin iwa ibajẹ fese mule si lorile ede yii.
Ọjọ́ tí o bá jẹ ẹ́ ni o óo kú.
Ṣáájú ni àwọn eleri méjì tí sọ̀rọ̀ gbé sẹ́yìn Alfa Babatunde dípò àwọn mẹta tí ó yẹ kí o sọ̀rọ̀.
Aduku ni awọn oludije naa gbe igbesẹ ọhun lẹyin ti wọn se ipade apero nibi ti wọn ti gba awọn eniyan ni iyanju pe, ko pọn dandan ki gbogbo wọn dije dupo ninu idibo abẹle.
Awọn ara ilu pe jọ si ibi ti wọn ti ilu Agogo ati ilu Oyingbo ati Ugbama Olori, lẹyin naa ni wọn ti ọja ọba pa, ti wọn si ṣi ọja lọ si ibo miran.
Josaya wó gbogbo ibi gíga tí wọn tún ń pè ní òkè ìdíbàjẹ́, tí Solomoni kọ́ sí apá ìhà ìlà oòrùn Jerusalẹmu, ní ìhà gúsù Òkè Olifi, fún àwọn oriṣa Aṣitoreti, ohun ìríra àwọn ará Sidoni, ati Kemoṣi, ohun ìríra àwọn ará Moabu, ati fún Milikomu, ohun ìríra àwọn ará Amoni.
ero igbalode  ti yoo ni akoonu to pọ julọ
Ninu ọrọ rẹ, o ni eniyan ẹlẹran ara lasan niwọn ati wi pe, ọpọlọpọ olori ijọ kii ṣe eniyan Ọlọrun bi aye ṣe maa n sọ.
Ajo WHO salaye pe, awon omo egbe ajo-isokan orile-ede agbaye fenuko lati se aseyori lori eto-ilera lagbaye bi o ba fi maa di odun 2030, gege bi okan lara erongba elegberun odun naa.
Iroyin naa ni adajọ Abdul Dogo lo n bọ lati ilu Abuja nigba ti awọn ajinigbe naa da lọna, ti wọn si ji gbe lọ.
Eyi si lo mu ki Dupe ko pada si ile rẹ.
Eléyìí yà á lẹ́nu lọ́pọlọpọ̀ ó sì dùn ún gidigidi.
Kí ló dé tí ó fi pẹ́ tóbẹ́ẹ̀ kí á tó gbúròó ẹsẹ̀ àwọn ẹṣintí wọ́n ń wọ́ kẹ̀kẹ́ ogun rẹ̀?
Ni odun 2008, Modise Mokwadi Fly, ti o je omo Motwsana ni won yegi fun latari pe, o seku pa omo re.
Iwaju kootu ile ẹjọ to gha julọ ni Amerika ni wọn ti ya awọran naa ni Washignton DC to jẹ olu ilu America.
Ó yadi, ọwọ́ ni ó fi ń ṣe àpèjúwe fún wọn.
Aare tun wa fi okan gbogbo omo
Ó ń lọ ní òpópónà, lẹ́bàá kọ̀rọ̀ ilé alágbèrè obinrin náà,
Ita gbangba lórí ebutu ni won yóò sun si.
Oríṣun àwòrán, INSTAGRAM/HUSHPUPPI O si tun sowọpọ mọ ẹnikan to ni asunwọn meji nilẹ Yuroopu, pẹlu ireti pe ẹni kọọkan wọn yoo gba miliọnu marun un Pọun ($5.
Bi orile ede Britain se yapa kuro ninu egbe Europe tun je ki  idagbasoke tun de ba okoowo lagbaaye.
O ni owo oṣu dokita kan ni London lee san owo oṣu dokita Naijiria mẹrin si mẹfa.
O ni ko si ẹni ti ko mọ pe aṣaaju ni Alaafin ninu igbelarugẹ aṣa Yoruba nile, loko, lẹyin odi ati kaakiri gbogbo agbaye tawọn ọmọ Yoruba wa.
“Dípò bàbà, wúrà ni n óo mú wá.
Agbẹ́nusọ ẹsọ ìgbòkègbodo ọkọ náà (FRSC) Bisi Kazeem tó fidi ọ̀rọ̀ náà múlẹ̀ sàlàyé wọ́n ti gbé òkú ènìyàn mẹ́ta náà kúrò, nígbà tí wọ́n ti gbe àwọn tó farapa lọ si ilé ìwòsàn gbogbo níṣe Kubwa Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Àbẹ́wò ọlọ́jọ́ mẹ́ta Trump sí UK nínú àwòrán 'Ọmọ Naijiria 25,794 ló kú sí rògbòdìyàn láàrin ọdún mẹ́rin' Wo àwọn ìlérí tàwọn Gómìnà tuntun ṣe nínú ìbúra wọn Àrà kengé!
ó ní, “Bí ẹ bá farabalẹ̀ gbọ́ ohùn èmi OLUWA Ọlọrun yín, tí ẹ sì ṣe ohun tí ó tọ́ lójú mi, tí ẹ pa gbogbo òfin mi mọ́, tí ẹ sì tẹ̀lé gbogbo ìlànà mi, èmi OLUWA kò ní fi èyíkéyìí ninu àwọn àrùn tí mo fi ṣe àwọn ará Ijipti ṣe yín, nítorí pé, èmi ni OLUWA, olùwòsàn yín.
Wọn óo máa gbé ibẹ̀ láìbẹ̀rù; wọn óo kọ́ ilé, wọn óo sì ṣe ọgbà àjàrà, wọn óo máa gbé láìbẹ̀rù nígbà tí mo bá ṣe ìdájọ́ gbogbo àwọn tí wọ́n yí wọn ká, tí wọ́n sì ti kẹ́gàn wọn.
Bakan naa lo fikun pe awọn eniyan naa yoo bẹrẹ si ni koju awọn aṣekupani naa nitori ipaniyan naa ti pọ ju bo ṣe lọ.
Aṣọ kò gbó mọ yín lára, bẹ́ẹ̀ ni ẹsẹ̀ yín kò wú, fún odidi ogoji ọdún yìí.
Nítorí, gẹ́gẹ́ bí ẹ ti mọ̀, a kò wá pọ́n ẹnikẹ́ni, a kò sì wá ṣe àṣehàn bí ẹni tí ìwọ̀ra wà lọ́kàn rẹ̀.
Nígbà tó yá, ọba mìíràn tí kò mọ Josẹfu jẹ ní ilẹ̀ Ijipti.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, BBC Yorùbá: Temidayọ Ọlọfinsawo ní kò rọrùn láti darí òṣìṣẹ́ ọlọ́pọlọ pípé Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Bisọọbu Agba naa ni lọpọ igba ni oun ti ja fitafita fun awon ololufẹ to fẹ se igbeyawo, amọ ti awọn obi wọn ko fun won nitori ọkan lara wọn jẹ ẹru.
Lara iwadii ti ajọ LASSESSO ṣe, wọn ri i pe, arakunrin India yii n ṣiṣẹ pẹlu ileeṣẹ kan, Sterlin Global.
Mínísítà fétò ẹ̀kọ́ lórílẹ̀-èdè Nàìjíríà, Adamu Adamu, ló ṣàlàyé èyí níbi ìdánilẹ́kọ̀ọ́ lórí ààbò níléèwé tó wáyé nílùú Abuja.
''Ọ̀gẹ̀dẹ̀ tí kò pọ́n ni mo maa n fun un jẹ́, àwọn olùṣọ́ ọgbà ẹ̀wọ̀n naa si maa n fun ní òògùn.
Àwọn aríran lórí ẹni tí yóò di ààrẹ Naijiria PDP pe ìpàdé pàjáwìrì lórí èsì ìdìbò ààrẹ l'Abuja Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Jimi Agbaje: èmi kò faramó owó ẹnubodè Toll Gate Eko rárá Bakan naa ni aarẹ Muhammadu Buhari ti wọn ṣẹṣẹ yan fun saa keji naa sọ wi pe oun mọ ipa ribiribi ti awọn obinrin ati ọdọ ko lasiko idibo naa, nitori naa oun yoo yan awọn obinrin sipo lati ba oun ṣiṣẹ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù African Games: Àwọn akọni Nàìjíríà padà sílé pẹ̀lú àmì ẹ̀yẹ 121 láti Morocco 2 Owewe 2019 Oríṣun àwòrán, @others Àkọlé àwòrán, Olajide Omotayo, ọkan lara awọn akóni to gbogo fun Naijiria ni Morocco Awọn akọni to lọ ṣoju Naijiria ninu idije African Games ti orilẹ-ede Morocco gbalejo ẹ ti de pada sile pẹlu ariwa ayọ.
Minista yii lo kọkọ fi ọrọ ajọ to n mojuto eto ere bọọlu alafẹsẹgba ni Naijiria, NFF ṣide iṣẹ nigba to wọle.
ipade yii  nitori  pe  o se
" Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ìwà ipá nínú ìdílé máa ń bí ìgè àti àdùbí ni tó lè já sí ikú Nigba ti yoo dahun ibeere lori boya opin iyanṣẹlodi wọn wa nitosi, aarẹ apapọ ẹgbẹ olukọ fasiti lorilẹede Naijiria, ASUU ni ni bi ọrọ ṣe n lọ yii ko daju o nitori ijọba ko tii sunmọ ibeere adehun wọn.
Ile iṣẹ Google ti bẹrẹ si ni lo ohun Naijiria lati juwe ọna lawọn opopona ilẹ naa.
”Blatter, ti o je aare ajo FIFA lati odun 1998 si 2015, ko tewogba apapo sise agbateru idije boolu agbaye yii larin orile-ede meji, leyin eyi ti o ti waye lodun 2002 ni Japan ati South Korea, eyi ti o si je igba akoko re ti orile-ede meji yoo gbimopo lati sagbateru idije naa.
Ohun tí ó wí ni pé, “Bí mo bá fẹ́ kí ó wà títí n óo fi dé, èwo ni ó kàn ọ́?
Ninu iwadi ikọ iroyin BBC, a se awari rẹ pe kaadi idibo ni awọn eeyan naa mu dani, ti wọn fi n lọ gba ẹgbẹrun mẹrin naira ẹni kọọkan.
Kyari lo ṣaaju awọn aṣoju ẹkun ariwa Naijiria lọdun 1994 nibi apero National Constitutional Conference ki wọn to yan an gẹgẹ bii alaga igbimọ to n mojuto ọrọ eto aabo.
Fulani kò leè dúró, táa bá lo ohun ta jogún lọ́dọ̀ àwọn bàbá wa - Sunday Igboho Ǹkan mẹ́jọ tó máa kọ́kọ́ ṣẹlẹ̀ kí olólùfẹ́ méjì tó pa ara wọn Laipẹ́, ọmọ tí kò bá pé ọdún méjìdínlógún kò ní leè jáde girama l’Ọṣun Amọ, Adajọ Ahmed Mohammed ti ile ẹjọ giga l'Abuja tu ẹjọ naa ka lọjọ keji, oṣu karun un, ọdun 2019 lẹyin to sọ pe ko lẹsẹ nlẹ.
Ìdájọ náà wọgi lè ìdájọ kan to ti kókó ní irú ìwà bẹẹ o lòdì s'ofin labẹ abala 377 òfin ìgbà àwọn amunisin eléyìí tó ká ìbálòpọ̀ láàrin ọkùnrin sí ọkùnrin gẹgẹ bí ẹsẹ.
”Wọ́n bá dá a lóhùn pé, “Ó dára, lọ ṣe bí o ti wí.
Wo orúkọ àwọn ẹ̀yà ara rẹ̀ ní èdé Yorùbá Pneumonia: Dókítà ní kòkòrò àìfojúrí ló ń fàá òtútù àyà Burna Boy n gún òke àgbà, wọ́n fà á kálẹ̀ fún àmì ẹ̀yẹ̀ Grammy Garba ni awọn kọ idajọ ile ẹjọ, ati wi pe awọn Emir tuntun mẹrin naa duro gẹgẹ bi ọba ọlọla bii Emir Sanusi.
Buhari mórí lé ìlú London lẹ́yìn ìrìn-àjò lọ sí Saudi Arabia Báwo ni gbogbo alága kánsú Kwara ṣe de àhàmọ́ EFCC?
Saudi fẹ́ gbẹ̀mí 23 ọmọ Nàìjíríà tó gbé òògùn olóró Irọ́ ló pa, a kò mọ̀ ọ́ rí tàbí fún ọ ní ₦13m - APC tako afurasí ajínigbé Àlàyé rèé lórí bí wọ́n ṣe mú mi lẹ́rú ní 1837 - Ajayi Crowther Amọ sa, Fowler ni asẹ wa lọwọ ijọba apapọ ti igbesẹ gbigba owo lori awọn ọja ti wọn ba ra lori ayelujara naa, yoo ba di ohun.
Ẹni ọdún mẹẹdọgbọn ni nígbà tí ó jọba, ó sì wà lórí oyè fún ọdún mọkandinlọgbọn ní Jerusalẹmu.
Wọn si ṣeleri lati tubọ ṣe iwọde titi Boris a fi gbọ ohun ti wọn n fẹ.
Ẹ wá, ẹ jẹ́ kí á kọrin sí OLUWA;ẹ jẹ́ kí á hó ìhó ayọ̀ sí Olùdáàbòbò ati ìgbàlà wa!
Losu to kọja, Agbaarin fẹgbẹ agbabọọlu Real Madrid, Luka Modric san owo toto miliọnu kan Euro lati san owo ori nidi owo to ri latara ẹts si aworan rẹ to se.
Ẹ̀yin ará, ìdí rẹ̀ nìyí tí ẹ fi gbọdọ̀ túbọ̀ ní ìtara láti fi pípè tí a pè yín ati yíyàn tí a yàn yín hàn.
Gbogbo wọ́n bá túká pátá láìku ẹnìkan.
Àwọn ẹyẹ àwodì ti ṣe ìpàdé ní àìmoye ìgbà láti kó gbogbo ẹran orí bàbá alápatà yìí ní ìgbàkigbà tí àwọn bá péjú, torí ọ̀pọ̀ ìgbà ní bàbá sì ń kiri wọ inú ìletò tí àwọn àwodì yóò sì ti wá nǹkan jíjẹ, mímu wọn lọ.
Minisita tun so pe ,baalu orilẹ ede  Naijiria yoo tun je ki   awọn  onisowo tun nigbẹkẹle ninu orilẹ ede  yii.
waye lola ode yii fun awon omo orile-ede Naijiria.
Labẹ pe awọn oloselu ko bikita fun erongba tabi ilana yi naa la ti ri pe awọn ọmọ ẹgbẹ oselu PDP naa gba Obaseki tọwọ tẹsẹ, Koda, wọn si tun fi aaye awọn nkankan gba a, ki o ba le jẹ ẹni ti ẹgbẹ fẹ gbe asia le lọwọ lati du ipo.
Ojọgbọn Yemi Osinbajo lo n dije dupo igbakeji aarẹ pẹlu Buhari ni ẹgbẹ
 Ìjọba yìí ń gbòòrò láti upemba tí Í ṣe ààrin gbuńgbún lube .
Ọba to jẹ saaju Ọba Vajiralongkorn,Ọba Bhumibol Adulyadej lo àádọ́rin ọdun lori itẹ eyi to mu jẹ Ọba to pe lori oye julọ lagbaye.
Eyi si maa n mu ki wọn wa larọwọto ọpọlọpọ kokoro arun lasiko oyun yii.
Amẹrika ń gbẹ̀san lára Nàíjíríà, owó ‘Visa’ di ọ̀nà méjì láti wọ Amẹrika Ọkọ̀ akẹ́rù Dangote rọ́lu BRT lọ́nà Ikorodu, èèyàn kan kú, 59 farapa, ẹsẹ̀ dẹ́rẹ́bà gé Gẹgẹ bii alaye re, O ni, irọrun igi ilẹ Yoruba ni irọrun ẹyẹ ipinlẹ Osun, lojuna lati daabo bo dukia ati ẹmi awọn eniyan ilẹ Yoruba lapapọ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Coroavirus drugs: Àwọn aláṣẹ̀ America fọ́wọ́ sí lílo òògùn Ebola fí tọ̀jú Coronavirus 6 Èrèlè 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 2 Èbibi 2020 Oríṣun àwòrán, Getty Images Ileeṣẹ to n mojuto ipese ounjẹ ati òògùn nilẹ America, Food and Drug Administration (FDA), ti fọwọ si lilo òògùn ti wọn fi n tọju aisan Ebola fun itọju coronavirus.
Inú bí mi nígbà tí mo gbọ́ igbe wọn ati ohun tí wọn ń sọ.
Oríṣun àwòrán, Seyi Edun/Instagram Oríṣun àwòrán, others Ọ̀pọ̀ àwọn olólùfẹ́ Lizzy lágbo òṣèré ló ti ń kí i kú oríire.
A bá kígbe pe OLUWA Ọlọrun àwọn baba wa; ó gbọ́ ohùn wa, ó rí ìpọ́njú, ati ìṣẹ́, ati ìjìyà wa.
Human trafficking: Ọlọpàá Spain mú ènìyàn mọkànlá tó ń fi àwọn obìnrin Nàìjíríà ṣòwò aṣẹwó
Àmì tí àwọn ọmọ Israẹli ati àwọn tí wọ́n ba ní ibùba ti jọ ṣe fún ara wọn ni pé, nígbà tí wọ́n bá rí i tí èéfín ńlá yọ sókè ní Gibea, 
Irú àṣẹ tí mo gbà lọ́dọ̀ Baba mi ni n óo fún un.
Covid-19: Oluwo ní àṣẹ Ọlọ́run ni pé coronavirus ò lè wọ ìlú Iwo, àmọ́ òun ń wọ ìbòmú tórí olórí t'óun jẹ́
Abi ka sọ pe tori pe wọn gba awọn eeyan si ẹnu iṣẹ, ka fi wọn silẹ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Oyo Coronavirus: Makinde ní kò sí ọwọ́jà Coronavirus ẹlẹ́ẹ̀kejì ní ìpínlẹ̀ Oyo 14 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 14 Sẹ́rẹ́ 2021 Oríṣun àwòrán, Seyi Makinde/Facebook Gomina ipinlẹ Oyo, Seyi Makinde ti sọ pe akọsilẹ fihan pe ọwọja keji arun covid-19 ko tii wọ ipinlẹ naa.
Ìròyìn ikú Muhammad Ali ọmọ ọdún mẹ́rinlélaadọrin kàn ni oṣù kẹfa, ọjọ́ kẹta, ọdún Ẹgbàálémẹ́rìndínlógún.
Ìjọba ìpílẹ̀ Kaduna ti kọ́kọ́ séde ní ìlú tí ìjà náà ti kọ́kọ́ bẹ̀rẹ̀.
 Alakoso  ajo IMF fun ẹkun  Ariwa ati aarin gbungun Jihad Azour,lo soro yii
Oríṣun àwòrán, tokemakinwa O ni oun ko mọ nipa ile Toke Makinwa ti wọn n pariwo yii nitori oun ko le ṣo ni pato boya ile naa wa lara eyi ti ileeṣẹ Amcon gbesẹ le tabi boya ko si nibẹ.
OPC, Miyetti Allah, agbófinró yóò wà nínú ìgbìmọ̀ aláàbò nílẹ̀ Yorùbá Orí mi wú pé àwọn àgbà ìjòyè kọ́wọ̀rín-ìn tẹ̀lé Olúbàdàn, ìjà parí - Makinde A kò ní ra ọjà South Africa mọ́, á gbẹ̀san oró tí wọn ń dá wa - Ọmọ Nàíjíríà fárígá"" A fẹ́ gba ₦1bn lọ́wọ́ ìjọba Eko pé ó dẹ́yẹ sí wa - 123 Ọlọ́kadà Jigawa Ọrọ ti Andrew sọ yii lo fa ibinu awọn ololufẹ awọn ololufẹ Dayọ Amusa yọ, ti gbogbo wọn si n yọ suti ete si ọkunrin naa lara pe ko wii re rara, ti ọpọ wọn si n beere pe ki lo de ti awọn eeyan kii se bọwọ fun awọn gbajumọ lawujọ."
Absalomu dáhùn pé, “Ó dára, bí o kò bá lè lọ, ṣé o óo jẹ́ kí Amnoni arakunrin mi lọ?
Gomina Ibrahim Gaidam salaye ọrọ yii fun akẹgbẹ rẹ lati ipinlẹ Borno, iyẹn gomina Kashim Shettima lasiko to wa baa kẹdun.
Nitori naa, ẹni to ba fẹ ra ounjẹ lati ilẹ okeere gbọdọ ṣetan lati san owo lori rẹ.
Ìṣúra ti Ẹ̀mí ninu ìkòkò Amọ̀.
Nígbà tí Jesu gbé ojú sókè, ó rí ọ̀pọ̀ eniyan tí ó wá sọ́dọ̀ rẹ̀, ó wá bi Filipi pé, “Níbo ni a ti lè ra oúnjẹ fún àwọn eniyan yìí láti jẹ?
Mo dìde lọ́gànjọ́ láti yìn ọ́,nítorí ìlànà òdodo rẹ.
Ọ̀wọ́ngógó oúnjẹ, epò, iná ọ̀ba ti sọ owó oṣù N30,000 da N9 nitórí náà kò ní sí ọjà, epo, iléèwòsàn láti Ọjọ́ Ajé - NLC Ẹ yé parọ́ kiri!
O ni kia lawọn ti ṣe iwadii tawọn si ba owo naa lakoto rẹ.
Òun náà ṣe nǹkan burúkú lójú OLUWA, ó tẹ̀lé ìwà ẹ̀ṣẹ̀ Jeroboamu ọmọ Nebati, ẹni tí ó mú Israẹli ṣẹ̀.
Afẹ́fẹ́ ń fẹ́ lọ sí ìhà gúsù, ó sì ń yípo lọ sí ìhà àríwá.
Awọn ohun elo iṣegun oyinbo mẹtadinlọgbọn ti wọn ṣe lorilẹede China.
Nàíjíríà, ẹ fakọyọ lórí ìdènà Coronavirus àmọ ìròyìn òfegè léè ṣọṣẹ́ tẹ̀ bá ṣọ́ra - WHO Àfagbárawọ̀ ló jẹ́ fáwọn arìnrìnàjò láti wọ pápákọ̀ òfurufú Nàíjíríà torí Coronavirus!
Oya, jẹ ka ma mu wọn lọọkọọkan.
Isẹ nla ni ti ijba yoo ba ri owo osu tuntun san, ayafi ti atunto ba ba ẹka isẹ ọba.
Huṣimu náà bí ọmọkunrin meji fún un: Abitubu ati Elipaali.
Ní ọjọ́ tí ọba ń ṣe àjọyọ̀, àwọn ìjòyè mu ọtí àmupara, títí tí ara wọn fi gbóná; ọba pàápàá darapọ̀ mọ́ àwọn ẹlẹ́yà.
Gomina Fayẹmi to fi iṣẹ yii ran olori awsn oṣiṣẹ ijọba ni ipinlẹ Ekiti, Deji Ajayi fi kun un pe oṣu kejila ọdun yii ni ajọdun aṣa ipinlẹ naa yoo waye.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ààrẹ Buhari gbé àbádòfin N8.
Àwọn aguntan a máa gbọ́ ohùn rẹ̀, a sì máa pe àwọn aguntan rẹ̀ ní orúkọ, a máa kó wọn lọ jẹ.
 ilé kúògbó : Ìwádìí fi hàn mí pé arákùnrin tó pilèsè ilé yìí jé ìríjú gbogbo ìlú .
 Ṣùgbọ ́ n jù èyí lọ , iṣẹ ́ àgbé ti wà láti ìgbà tí ayé ti wà .
Solomoni ọba ní ẹgbaaji (4,000) ilé fún ẹṣin ati kẹ̀kẹ́ ogun, ó ní ẹgbaafa (12,000) ẹlẹ́ṣin.
O ni 'Mo fẹ fi asiko yii fi daa yin loju pe, ko si arun Coronavirus kankan ti yoo de ọdọ yin; nitori pe ẹ n gbe ninu ibi ikọkọ Ọga ogo.
Wọ́n lọ ṣùrù bo ilé Jasoni, wọ́n ń wá Paulu ati Sila kí wọ́n lè fà wọ́n lọ siwaju àwọn ará ìlú.
Bakan naa lo tun rọ awọn ọlọpaa lati rii pe gbogbo afurasi ti wọn ba mu de ọdọ wọn, ni wọn foju wina ofin.
Nigba to n ba BBC Yoruba sọrọ, alaga ẹgbẹ ọlọkọ ero nipinlẹ Ọyọ, Waheed Adeọyọ, ti gbogbo eeyan mọ si Ejiogbe, ẹni ti akọwe ẹgbẹ, Sunday Yeye gbẹnu rẹ sọrọ, salaye pe laipẹ ni awọn yoo pe ipade gbogbo ọmọ ẹgbẹ awakọ ero nipinlẹ Ọyọ, lati fi asẹ ijọba naa to wọn leti Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Seyi Makinde kò ní ẹ̀tọ́ láti yọ alága ìjọba ìbílẹ̀ tì kò yàn sípò - Amòfin Sìgá mímu ń di èèwọ̀ oògùn ìlera pípé lagbaye Ohun tó wù kí ileẹjọ́ kòtẹ́milọ́rùn sọ, Adeleke kò lè di gómínà Ọ́ṣun - APC Ejiogbe wa rọ awọn awakọ ero nipinlẹ Ọyọ lati mase fa wahala kankan nitori asẹ ijọba yii, amọ ki wọn maa ba isẹ oojọ wọn lọ nitori asẹ ijọba naa ko di awọn lọwọ lati sisẹ oojọ awọn, sugbọn awọn ọmọ igbimọ alasẹ ẹgbẹ ni asẹ yii ba wi.
Ìwọ ọmọkùnrin, Igbó Olódùmarè léwu gidigidi, ilé ìjàǹbà ni, igbó ìbanujẹ ni, bi ìwọ kò bá ṣọ́ra ìwọ yóò kábàámọ̀ lílọ rẹ, ṣùgbọ́n bu ìwọ bá gbá ìmọ̀ràn ìwọ yóò ni orúkọ rere lẹ́hìn ọ̀la, àwọn ọmọ ènìyàn kì í lọ si ibẹ̀ ki wọ́n padà bọ̀, ṣùgbọ́n bi Ẹlẹ́dàá ti mu kí ìwọ ṣe alábàápàdé wa yìí ńkọ́, ìwọ padà bí ìwọ bá gbọ́ràn si wa lẹ́nu.
O ni oun yoo ri daju pe gbogbo ilana ofin to yẹ ni wọn tẹle ki gbogbo awọn to lọwọ ninu rẹ si lee jẹjọ.
Oríṣun àwòrán, Facebook/Remi Oladoye Àkọlé àwòrán, Ohun ti yoo ba pa ni, to ba si ni ni fila, ka maa dupẹ lo tọ Awakọ keji naa si ni oun fi oju oun ri korokoro bayii, tawọn ajinigbe ọhun n ko awọn ero inu ọkọ ti wọn da duro wọnu igbo lọ, ki oun to bọ mọ wọn lọwọ.
eto igbafe ati eleyi ti yoo maa ri si oro olopaa (Special Duties and Intergovernmental Affairs, Humanitarian
Tottenham ni mẹrindinlọgbọn ti wọn si wa ni ipo keje.
Agbada náà nípọn tó ìbú àtẹ́lẹwọ́, etí rẹ̀ dàbí etí ife omi ati bí òdòdó lílì.
Ǹjẹ́ gbogbo ẹja tí ó wà ninu òkun tó fún wọn bí?
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Seyi Makinde: Gbogbo iṣẹ́ àgbàṣe tí Ajimọbi ṣe lẹ́yìn ìbò ní màá gbéyẹ̀wò 25 Ẹrẹ̀nà 2019 Oríṣun àwòrán, Engr Seyi Makinde Gomina tri ilu sẹsẹ dibo yan nipìnlẹ Ọyọ, Onimọ ẹrọ Seyi Makinde ko tii sinmi lori ariwo to n pa pe, gomina to wa nipo lọwọ, Abiọla Ajimọbi mọọmọ fẹ gbọn owo ilu gbẹ ni ki oun to gba ọpa asẹ lọwọ rẹ ni osu karun ọdun yii.
Kaka ki wọn bu ẹyẹ fun un gẹgẹ bi alejo pataki, nṣe ni wọn yẹyẹ aṣofin agba naa.
Mo ti mú kí orúkọ rẹ hàn sí wọn, n óo sì tún fihàn, kí ìfẹ́ tí o fẹ́ mi lè wà ninu wọn, kí èmi náà sì wà ninu wọn.
Ati òòró ati ìbú àwọn yàrá ẹ̀gbẹ́ náà jẹ́ igbọnwọ mẹfa mẹfa (mita 3).
Tí a kò bá gbàgbé, mínísítà méjì nínú ìjọba Ààrẹ Muhammadu Buhari ni wọ́n ti fi ẹ̀sùn kàn nípa ìwé ẹ̀rí ìsìnrú ìlú ètò àgùnbánirọ̀, NYSC.
 You are welcome home my beautiful and adorable queen.
Ati pe alase to ṣẹṣẹ gba sile lo ṣeku paa.
Mourinho ti kọ lati gba iṣẹ akọnimọọgba ni ẹgbẹ agbabọọlu Benfica ati ikọ agbabọọlu kan lorilẹede China.
Àwọn ará Hori ni wọ́n ń gbé òkè Seiri tẹ́lẹ̀ rí, ṣugbọn àwọn ọmọ Esau ti gba ilẹ̀ náà lọ́wọ́ wọn, wọ́n sì ti pa wọ́n run.
Lẹ́yìn náà, ọba pàṣẹ pé kí wọn sọ ọ́ lókùúta pa ninu gbọ̀ngàn ilé OLUWA.
Ṣe Ruga le dẹkun wahala laarin agbẹ ati darandaran?
Aare Muhhamadu Buhari wa ro won lati fi ogbon oloogbe Winnie Mandela ati awon aseyori re se awokose nipa fifopin si ogun eleyameya.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Promise Akinlade: ọmọ ọdún mọ́kànlá tó ń fi ìlù dárà bíi àgbàlagbà sọ̀rọ̀ nípa tálẹ́ǹtì rẹ O ni ileeṣẹ to n ri si ọrọ awọn obinrin labẹ oun yoo ṣe gbogbo ohun to yẹ lati ri pe alaafia wa lawujọ, o si jẹ eyii to ṣe é gbe fun gbogbo eeyan.
Ninu ìpọ́njú mi mo ké pe OLUWA,Ọlọrun mi ni mo ké pè.
Akẹkọọbinrin yii ni a gbọ pe o padanu mọmọ rẹ ni nnkan bi ọdun meloo sẹyin, bakan ni baba rẹ ti le ni ọgọta ọdun.
Ni bi aago mẹfa kọja ogun iṣẹju ni ọkọ baalu to gbe aarẹ balẹ si papakọ ofurufu Nnamdi Azikwe ni olu ilu orilẹede Naijiria, Abuja nirọlẹ ọjọ Aiku.
"Aole wa ni "" ki epe mi maa wa lori yin titi laelae ẹyin iran Yoruba ati arọmọ-dọmọ yin, fun iwa ailootọ ati aigbọran ti ẹ hu, awọn ọmọ yin yoo maa ṣe aigbọran si yin ni'."
Awọn ọmọ ilẹ Gẹẹsi to gba wọn loju okun naa si lo ta awọn adulawọ ọhun fawọn amunisin to wa ni Virginia.
 sùgbón ní báyìí , wón ti kó ilé yí ni wón wá ń pè ní elékùú sùgbón èyí kò túmò sí wí pé , àwon àdúgbò yí ló ni èkùú náà .
Joaṣi pàṣẹ fún àwọn alufaa pé kí wọ́n máa kó àwọn owó ohun mímọ́ tí wọ́n mú wá sí ilé OLUWA pamọ́: ati gbogbo owó tí àwọn eniyan san fún ẹbọ ìgbà gbogbo ati èyí tí wọ́n mú wá gẹ́gẹ́ bí ọrẹ àtinúwá.
Oludije lẹgbe oselu PDP wa ni ara lo n ta ẹgbẹ oselu APC ati wi pe agbẹjọrọ oun ni ẹlẹjọ wọn ni ile ẹjọ.
Èmi nìkan ni mo tẹ́ ojú ọ̀run,tí mo sì dá ilẹ̀ ayé tẹ́,
Oludije ipo aarẹ labẹ aṣia ẹgbẹ oṣelu Zenith Labour Party , Olusẹgun Mimiko ti dagbere fun idije ipo aarẹ lọdun 2019.
 a ṣe àkíyèsí onírúurú ìhun tí ìyísódì ti ń jẹ yọ nínu Ẹi .
Àṣírí pásìtọ̀ tó ń fí sọ́ọ̀si ṣe ọ̀gbà wèrè tú!
Ẹni ọdún mẹẹdọgbọn ni nígbà tí ó jọba, ó sì jọba fún ọdún mẹrindinlogun ní Jerusalẹmu.
Horamu ọba Geseri wá láti ran àwọn ará ìlú Lakiṣi lọ́wọ́, Joṣua gbógun tì í, ó sì pa òun ati gbogbo àwọn eniyan rẹ̀ láìku ẹyọ ẹnìkan ṣoṣo.
Gbogbo àwọn akikanju jagunjagun tí a kọ orúkọ wọn sílẹ̀ ninu àwọn ìbátan wọn ninu ẹ̀yà Isakari jẹ́ ẹgbaa mẹtalelogoji ó lé ẹgbẹrun (87,000).
Àkọlé àwòrán, Ni ipari ipolongo naa wọn gbe asia ẹgbẹ fun Gboyega Oyetọla Lara awọn eekan to ba wọn peju-lesẹ nibi akanṣe eto naa ni aare Muhammadu Buhari, adari ẹgbẹ oṣelu naa, Bola Ahmed Tinubu, Minisita fun ikansira ẹni, Adebayọ Shittu, minisita fun eto ilera Isaac Adewole, ati bẹẹbẹẹ lọ Àkọlé àwòrán, Bola Tinubu,Adams Osiomole ati awon eekan ẹgbẹ wa lara awọn to peju sibẹ .
Oríṣun àwòrán, Instagram Àkọlé àwòrán, Ọjọ Karun un, Osu Keji, ọdun 1969 ni wọn bi gbajugbaja oṣere Fathia Akorede Adunni Balogun ti wọn bi ni agbegbe Opara Oríṣun àwòrán, Instagram Àkọlé àwòrán, Bakan naa ni Saheed Akolawole Alabi Balogun ti o jẹ agbaọjẹ ninu ere amuludun ni Naijiria ni wọn bi ni ọjọ karun un, ọdun 1966 ni ipinlẹ Kwara amọ ti awọn obi rẹ wa lati ipinlẹ Oyo.
Ewe, aso tuntun ohun lo safihan ewu ti iko Super-Eagles wo ninu ifesewonse ipegede idije agbaye USA ’94.
’ rèé Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí kan sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
Osun Supreme: Àwọn èèyàn Ọṣun rọ Oyetọla láti jẹ́ kí àsìkò rẹ̀ tú aráàlú lára
Lẹ́yìn èyí, Jesu lọ sí òdìkejì òkun Galili tí ó tún ń jẹ́ òkun Tiberiasi.
O si ṣe pàtàkì ká fi igbe ayé aramọnda ọba yìí kọ ara wa ni ẹkọ, kò leè ye wa pé, ayanmọ ni kadara, ayé sì leè lè fa ọwọ aago sẹ́yìn ni, wọn kò leè pa kadara da.
Nígbà tí o bá jókòó láti bá ìjòyè jẹun,kíyèsí ẹni tí ó bá wà níwájú rẹ dáradára.
Mo mọ̀ dájú pé ǹkankan ń ṣẹlẹ̀ lẹ́yìn tí mo ní ọ̀rẹ́kùnrin àkọ́kọ́.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù NUJ ìpínlẹ Oyo bà àwọn ọmọ ẹgbẹ́ tó lọ ìpàdé tí Femi Fani Kayode pè ní Ibadan wí 25 Ògún 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 7 Owewe 2020 Oríṣun àwòrán, others Ẹgbẹ awọn akọroyin Naijiria, ẹka ipinlẹ Oyo ti pe awọn ọmọ ẹgbẹ to lọ sibi ipade ti Femi Fani Kayọde pe ni ilu Ibadan lati wa wi tẹnuwọn niwaju igbimọ to n ba ni wi ninu ẹgbẹ naa.
Ọba Babiloni sì pa wọ́n ní Ribila ní ilẹ̀ Hamati.
Agbẹjọro ijọba, ọgbẹni Lamido Sorondinki, so fun ile ẹjọ pe afurasi naa hu iwa ọdaran naa lọjọ kejila, oṣu Kẹfa, ọdun.
Wò ó, ẹni tí ó ju Jona lọ ló wà níhìn-ín.
Ajo UEFA ti ni atamatase iko agbaboolu Juventus, Cristiano Ronaldo yoo san owo itanran egberun lona ogun Euro(€20,000) sapo ajo naa latari bi o se yo-aayo ami ayo re ti o gba sagbon ninu ikolu pelu iko agbaboolu Atletico Madrid lona ti ko bofin ajo ohun mu.
Lọpọ igba, awọn oloṣelu máa n lo asiko idibo lati fi ara han awọn ara ilu gẹgẹ bi ẹni pe awọn naa jẹ ikan kan naa pẹlu wọn nipa ṣiṣe ohun aramanda.
Ìdí tí abiyamọ yìí kò fi jàǹfàní ètò ìlera ọ̀fẹ́ kí gómínà Makinde tó fún un ní N50,000 Kí ló dé tí Ilé ẹjọ́ sún ìgbẹ́jọ́ Naira Marley sí ọ̀la?
Sibẹsibẹ àwọn ọmọ Israẹli ń wí pé, ‘Ọ̀nà OLUWA kò tọ́.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Africa Eye: Coronavirus di adákẹ́jà ní Somalia, ikú ọ̀wọ́ọ̀wọ́ ń peléke si Wọn n digbaju luu, wọn yọ ẹgba ti i fun ọpọlọpọ igba, bi o ṣe joko sori ilẹ titi ti ẹlẹmi fi gba a.
Kí ni mo tún lè sọ?
Dúkìá àti ọjà jóná ráúráú lásìkò tí iná sọ ní ọjà Mushin ní ìpínlẹ̀ Eko
Ó sọ ìdí tí ó fi rọrùn fún erin láti máa gbé pẹ̀lú àwọn ènìyàn àmọ́, lẹ́yìn ọ̀pọ̀lọpọ̀ ìran, wọ́n gbàgbé ìpìlẹ̀ wọn, wọ́n lọ ń gbé nínú igbó.
 Ẹyin ọrẹ mi, lootọ ni aarun coronavirus wa.
Oríṣun àwòrán, others Àkọlé àwòrán, A ju ara wa lọ, .
lórí àwọn ìtẹ́dìí yìí ni ó ya àwòrán àwọn kinniun, mààlúù ati ti kerubu sí.
Ọkan lara awọn afurasi tọwọ tẹ, Friday Akpan, lo mu awọn ọlọpaa lọ si ibi ti wọn ti wu awọn oku naa jade ninu iboji kotopo kan ti wọn sin wọn si ninu igbo ladugbo Eleme, lọjọ kinni, oṣu Karun, ọdun 2020.
Amọ, ẹni ti ko ba kiyesara yoo padanu nkan ini rẹ sọwọ awọn ọmọ ẹgbẹ naa to darapọ mọ ero iworan.
Nigba ti wọn yoo fi pari iṣẹ aburu wọn, ẹmi meje lo ba iṣẹlẹ naa lọ.
N óo tẹ́ ìtẹ́ mi kalẹ̀ ní Elamu, n óo sì pa ọba ati àwọn ìjòyè wọn.
Leyin ọ̀pọ̀lọpọ̀ atotonu àwọn agbejoro fun wòlíì Babatunde Alfa Sọtitobirẹ ni ile ẹjọ́ àgbà tí ìpínlè Ondo to fikalẹ si ilu Akurẹ lọjọru, ilé ẹjọ́ gba ẹri àwọn agbofinro ọtẹlẹmuyẹ àjọ DSS wọlé pé, wọn fi ẹ̀sùn méjì kan àlùfáà náà tí ó dà lórí ijinigbe àti ifowosowopo láti ṣíṣe láabi náà Ẹlẹ́rìí àwọn àjọ DSS, Khadijat Oriyomi ṣàlàyé pé, ní ọjọ́ Kejìlá Oṣù Kejìlá Ọdún 2019, ní wón mú ọkàn lára àwọn afunrasi naa, arábìnrin Margaret Oyetola, tí ó sì kọ ìwé sílè pé Lóòótọ́ ni iṣẹlẹ náà ṣẹlẹ̀ ṣùgbọ́n tí kò ye ohun bóyá Lóòótọ́ ni àlùfáà náà jí ọmọ gbé ati pé lóòótọ́ ni ọkàn lára wọn, Peter Anjorin fò fóònù mọ́lẹ̀ èyí tí ó jẹ ti àlùfáà Babatunde níwájú àjọ náà.
Kí ló ṣẹlẹ̀ tí o fi pada sẹ́yìn, ìwọ Jọdani?
Oríṣun àwòrán, Instagram/officialyemielesho Adewale Elesho ni aikawe oun ṣakoba fun oun ninu ṣugbọn oun dupẹ lọwọ Eleduwa.
O wa pe orukọ ọmọ ọhun ni David Adedeji Ifeanyi Adeleke Jnr pẹlu afikun pe inu oun dun pupọ si iroyin ayọ naa.
Láti ọ̀dọ̀ èṣù baba yín, ni ẹ ti wá.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ramadan: ọmọ ọdún mẹ́wàá sọ ìrírí rẹ̀ pẹlú Àwẹ̀ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Ramadan: ọmọ ọdún mẹ́wàá sọ ìrírí rẹ̀ pẹlú Àwẹ̀ 14 Èbibi 2019 Awẹ, ọkọ ẹni tii gba ni awọn alaawẹ musulumi a ma wi.
13 Agẹmo 2020 Oríṣun àwòrán, Wumi toriola ati seyi edun Ni agbo ere tiata Yoruba, odu ni Wunmi Toriola ati Seyi Edun jẹ, wọn kii si ṣe aimọ fun oloko.
Pàápàá àwa ayàwòrán, inú wa a máa dùn tí a bá ti rí irú ọjọ́ báyìí.
Iléeṣẹ́ ológun bẹ̀rẹ̀ 'Operation Crocodile Smile' yíká Naijiria fún oṣù méjì Oríṣun àwòrán, Nigerian Army/ Twitter Ileesẹ ologun Naijiria ti kede pe oun fẹ gunle akanse eto operation Crocodile Smile fun ọdun 2020 jake jado orilẹede yii.
“Nígbà tí ẹ bá ń gbààwẹ̀, ẹ má máa ṣe bí àwọn aláṣehàn tí wọ́n máa ń fajúro, kí àwọn eniyan lè rí i lójú wọn pé wọ́n ń gbààwẹ̀.
Idunnu nla ni fun iya-iya Pẹlumi Akinṣọla akẹkọ girama kan ni ilu Ibadan fun ọpọlọ pipe ti Eledua fi taa lọrẹ.
Bẹ́ẹ̀ ni wọ́n máa ń ṣe sí gbogbo àwọn ọmọ Israẹli tí wọ́n bá wá rúbọ ní Ṣilo.
Mo ti buwọ́lu àdínkù owó orí nítorí ìrọ̀rùn àwọn èèyàn ìpínlẹ̀ Ogun lásìkò Covid 19- Dapo Abiodun Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Alaafin: Olori Aanu Adeyemi ṣàlàyé ìdí tó ṣe gẹ́ Oba Lamidi Adeyemi ti ìlú Oyo Agbẹnusọ fun ẹbi oloogbe to tun jẹ ọmọkunrin rẹ, Randy Fashek lo kede pe ilẹ Amẹrika ni awọn yoo sin Fashek si.
35, bakan naa ni alekun ba Redstar pelu 30k ti o si pajude si N6.
Irú ọjà wo ni wọ́n kò ti lè yan Ìyálọ́jà?
Jeieli, baba Gibeoni ń gbé ìlú Gibeoni, iyawo rẹ̀ ń jẹ́ Maaka, 
Oríṣun àwòrán, BUHARI/TWITTER Àkọlé àwòrán, Itusilẹ awọn ti wọn jigbe naa ko sẹhin ọpọlọpọ ifọrọwerọ tẹgbẹ Alagbelebu pupa, (International Committee of the Red Cross), seto rẹ 'Awọn alagbara lo wa lẹyin ikọlu Dapchi 'Naijiria k'ọmọogun lati wa'wọn ọmọ Dapchi Asoju ijọba Naijiria mi titun de Dapchi Aarẹ Buhari, lori itakun agbaye Twitter rẹ, fi lede wipe inu oun dun nitori awọn ti wọn jigbe naa, ti sọ ireti nu, ko to di wipe wọn ri wọn gba pada.
Igbesẹ ayipada rẹ yii pada ya pupọ ninu awọn ololufẹ rẹ lẹnu ti awọn miran bẹrẹ si ni kan saara si Lisa.
O ni dipo ki awọn maa gbadun, ẹbu ni lẹta ti ijọba gbe le wọn lọwọ nitori awn kan gba igbega lasan ninu iwe ni, awọn ko gba owo oṣu to yẹ ko ba a rin.
Gbogbo àwọn orílẹ̀-èdè yóo máa rìn ninu ìmọ́lẹ̀ rẹ̀.
Nígbà tí Isaaki di ẹni ogoji ọdún, ó fẹ́ Rebeka.
 Ọgbẹ ́ -inú kékeré kán náà lè wáyé , pẹ ̀ lú àpá díẹ ̀ lẹ ́ yìn tí ojú ibi abẹ ́ rẹ ́ náà bá jiná .
Iyé ènìà tó pé jọ fún ayẹyẹ náà lé ní 1,000,000!
OLUWA, yóo ti pẹ́ tó, tí n óo máa ké pè ọ́ fún ìrànlọ́wọ́; tí o kò sì ní dá mi lóhùn?
“Igi akasia ni kí o fi ṣe àwọn òpó àgọ́ náà, 
Ọdun Ajinde jẹ ọkan lara awọn ọdun pataki fun awọn ẹlẹsin Kristẹni.
O sọ nigba naa pe ọkọ akẹru kan lo n ko eroja ibugbamu lati ibi kan si ekeji.
Oríṣun àwòrán, Nff Àkọlé àwòrán, Samuel Okwaraji: Ó pé ọgbọ̀n ọdún tí lónìí ti akọni àgbábọ̀ọ̀lù papo dà Ọ̀pọ̀ ọmọ Nàìjíríà ló ti ń ṣelédè lẹ́yìn Okwaraji bí wọ́n ṣe n ṣe ayájọ́ ọgbọ̀n ọdún to ti papo dà, sùgbọ́n wọ́n fi ẹdùn ọ̀kan wọ́n hàn pé, NFF àti ìjọba ko ti ṣe tó: Àkọlé àwòrán, Samuel Okwaraji: Ó pé ọgbọ̀n ọdún tí lónìí ti akọni àgbábọ̀ọ̀lù papo dà Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 3 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 5 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Ẹ wá kiri, ẹ óo sì rí.
Jesu bá kìlọ̀ fún wọn pé, “Ẹ kíyèsára kí ẹ sì ṣọ́ra fún ìwúkàrà àwọn Farisi ati ìwúkàrà Hẹrọdu.
Àwọn ọmọ Sebuluni fi ẹ̀mí wọn wéwu dójú ikú,bẹ́ẹ̀ náà sì ni àwọn ọmọ Nafutali,wọ́n fi ẹ̀mí ara wọn wéwu ninu pápá, lójú ogun.
Ó ṣoríkunkun, ó sì kọ̀ láti yipada sí OLUWA Ọlọrun Israẹli.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ogun Suicide: Ẹ̀lẹ́sìn Islam àti tìbílẹ̀ fìjà pẹ́ẹ́ta lórí ìsìnkú ẹni tó pokùnso 22 Ẹrẹ̀nà 2018 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 8 Agẹmo 2020 Oríṣun àwòrán, Others Awọn adari ẹsin Musulumi ati ẹlẹsin Ibilẹ gbena wo oju ara wọn lẹyin ti Arakunrin kan gba ẹmi ara rẹ ni Sagamu ni ipinlẹ Ogun.
muna doko wa fun awọn ọmọ orilẹ-ede Naijria
Iru awọn iroyin ti ẹ le nifẹ si: Ipenija oju kii ṣe idena si atijẹ Kinni ohun to nmu idunnu ba ọkan re ?
Aarẹ ni ki awọn orilẹede agbaye maa gbọ ọrọ lagbọye ki wọn to maa gbe ọrọ kalẹ nipa orilẹede Naijiria.
gomina to wa nipo bayii ni yoo maa dari eto ni ipinle won.
O ni o tun le ṣe iranlọwọ lori iṣoro ti ọkunrin ba ni pẹlu ile itọ rẹ.
Tọ́ ọ wò, kí o sì rí i pé rere ni OLUWA!
O ní: ìyàlẹ́nu ló jẹ́ pé agbẹnusọ ọlọ́pàá padà sọ fún àwọn akọròyìn pé, wọ́n yin tájútaju sí wọ́n, èyí túmọ̀ sí pé ǹkankan wà níbl tí wọ́n kò sọ.
fun egbe APC ni yoo ma ran Hon.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Kylie Jenner ń pa $360m lọ́dún kan, tó sì ta adarí Facebook yọ 6 Ẹrẹ̀nà 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Atẹjade kan ti ajọ Forbes Billionaires fi lede wi pe, Kylie Jenner ni ọdọmọde olowo julọ ni agbaye.
Ó fà mí jáde láti inú ọ̀gbun ìparun,láti inú kòtò tí ó kún fún ẹrọ̀fọ̀;ó gbé mi kalẹ̀ lórí àpáta,ó sì fi ẹsẹ̀ mi tẹlẹ̀.
Mo sọkún títí àárẹ̀ mú mi,ọ̀nà ọ̀fun mi gbẹ,ojú mi sì di bàìbàì,níbi tí mo ti dúró, tí mò ń wo ojú ìwọ Ọlọrun mi.
Bí àkókò ṣe nlọ, Joseph Smith ni a mú kí ó ṣeéṣe fún nípasẹ̀ ìranlọ́wọ́ àtọ̀runwá láti túmọ̀ àti láti ṣe àtẹ̀jáde Ìwé ti Mọ́mọ́nì.
Ẹ̀mí kan kọjá fìrí níwájú mi,gbogbo irun ara mi sì dìde.
Wọn ni igbesẹ yii yoo mu adinku ba bi ijọba ṣe n na owo, paapaa fun awọn irinajo to ba iṣẹ lọ.
Wọ́n ti kó àgbò láti Sela, ní ọ̀nà aṣálẹ̀,wọ́n fi ranṣẹ sí aláṣẹ ilẹ̀ náà, ní òkè Sioni.
Ibi tí mo ti ń yí igbó kiri mo rí ọ̀pọ̀lọpọ̀ ìgbìn, ìkarawun wọn ni mo sì fi ń pọn omi tí mo wọ́n jọ lẹ́sẹẹsẹ sí inú ihò mi.
Ó kéré tán, ènìyàn mẹ́rìnlá tí kú nínú àjálù ọkọ̀ òfurufú tó já Èkìtì ṣé àgbéga àwọn Ọba Aládé mẹ́rìndínlógún Òṣèrébìnrin tí wọ́n bá fi ìbálòpọ̀ lọ̀ 'torí ìṣẹ́, kó bọ́ síta láti sọ̀rọ̀ - Kunle Afod Awakọ̀ Maruwa tó bá gbé okùnrin àti obìnrin papọ ní Kano yóò jẹ búlálà mẹ́wàá- Hisbah Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Mí ò ya wèrè, mí ò burú, ọ̀nà àtijẹ là ń wá' Ẹ̀wẹ̀, ilé iṣẹ́ Airpeace ni ọkùnrin náà jẹ́ ọkàn lára àwọn ti wọ́n máa ń tèlé ọkọ ofurufu sálọ si ilẹ̀ òkèrè.
Àwọn iranṣẹ mi yóo máa kọrin nítorí inú wọn dùn,ṣugbọn ẹ̀yin óo máa kígbe oró àtọkànwá;ẹ óo sì máa sọkún tẹ̀dùntẹ̀dùn, nítorí àròkàn.
Wọn kò ní fọ́ ọ mọ́, ẹnìkan kò sì ní wó o lulẹ̀ títí laelae.
Wo àwọn tó ń jí owó Covid-19 tí Ìjọba ní wọ́n yóò káwọ́ pọ̀nyìn rojọ́ Ìjọba ìpínlẹ̀ Kogi kéde ọjọ́ ìwọlé àwọn akẹ́kọ̀ọ́ padà sí iléèwé Sinimá àwòdamiẹnu, Ẹ̀fáńjẹ́líìsì jìyà àjẹmumi nílé aṣẹ́wó l'Ejigbo ní ìlú Eko Ki lawọn ọmọ Naijiria sọ si alekun yi?
Àwọn Òwu náà ń bu Àbàjà, wón sì ń bu Kẹ́kẹ́ pẹ̀lú.
Ǹkan tí a mọ̀ nípa kọ́lẹ̀jì olùdìbò tó ń fìdì ẹni ti yóò jẹ ààrẹ ilẹ̀ Amérika múlẹ̀ Wo iye owó tí ìjọba Amẹrika ń na sí ìdìbò Ààrẹ àti ibi tí owó náà ti ń wá Banki Nàìjíríà, CBN ṣàlàyé nípa àwọn tó máa rí gbà nínú owó ìrànwọ́ N75b tíjọba gbé kalẹ̀ Mọ̀ sí i nípa àwọn ọmọ Nàìjíríà mẹ́sàn-án tó ń díje nínú ìdìbò ilẹ America lọ́jọ́ Ìṣẹ́gun Ìbẹ̀rù-bojo gbalẹ̀ ní Oyigbo lẹ́yìn tí ọlọ́páà mẹ́ta àti sọ́jà kú nínú rògbòdìyàn EndSARS Ìbẹ̀rù-bojo gbalẹ̀ ní Oyigbo lẹ́yìn tí ọlọ́páà àti sọ́jà kú nínú rògbòdìyàn EndSARS Ninu ibẹru lawọn eeyan to n gbe ni ijọba ibilẹ Oyigbo nipinlẹ Rivers atawọn olokowo nibẹ wa bayii lẹyin eto aabo to mẹhẹ nibẹ.
Bi awọn kan ṣe n sọ pe awọn ti ohun to sọ lẹyin, ni awọn miran n sọ wi pe ta ni Igboho lati maa pa iru aṣẹ bẹẹ?
Gbogbo ọdún tí Enọku gbé láyé jẹ́ ọọdunrun ọdún ó lé marundinlaadọrin (365).
Lẹ́yìn náà wọ́n tọ́jú ẹ̀bùn Josẹfu sílẹ̀ di ìgbà tí yóo dé lọ́sàn-án, nítorí wọ́n gbọ́ pé ibẹ̀ ni wọn yóo ti jẹun.
Bí ẹ̀bi ẹ̀jẹ̀ ẹnìkan bá ń da eniyan láàmú,yóo di ìsáǹsá ní gbogbo ọjọ́ ayé rẹ̀,kí ẹnikẹ́ni má ṣe ràn án lọ́wọ́.
Ninu ipade apero kan ti o waye lorile-ede Saudi Arabia, aare Ismail Omar Guelleh ati aare Isaias Afwerki jo panupo bowolu ibasepo laarin orile-ede mejeeji.
NOPRIN naa sọ ninu atẹjade adari ajọ naa pe o fi han pe ootọ ni pe awọn ọlọpaa ti pa Adikwu si ihamọ bo tilẹ jẹ pe o ni oriṣiriṣi ọrọ lati sọ fun ile ẹjọ.
Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold Jubril Martins-Kuye ti jáde láyé Wo ìdí tí Oluwo fi ń wọ ìbòmú lẹ́yìn tó ní covid-19 ò lè wọ ìlú Iwo láéláé Covid-19: Ilé aṣojú-ṣòfin l'Abuja dábàá kí ìjọba sún ìwọlé àwọn akẹ́kọ̀ọ́ síwájú pẹ̀lú oṣù mẹ́ta Ọjọ Kẹtala, Oṣu Kini, ọdun 2021 ni awọn fi oju awọn ole naa han kaakiri ipinlẹ Ondo.
Wumi Toriọla ti sọ̀rọ̀ sóke láti fi idí rẹ̀ múlẹ̀ pé òun àti ọ̀rẹ́ òun níjà Ọlọ́pàááá!
Wọn gbé fídíò ìwádìí ọhun jáde lórí bí àwọn adarí eré bọ́ọ̀lù ṣe ń gba rìbá láti ṣe màgàmágó.
Mẹ́rìndínláàdóta nínú àwọn àbọ̀dé Libya náà ló jẹ́ obìnrin, méjì jẹ́ ọmọdé, tí mẹ́sán sì jẹ́ ọmọ ìkókó.
Nítorí pé lọ́la ni a óo kú.
oludari ajo INEC lorile ede Naijiria Mahmood Yakubu lo soro yii niluu Abuja, O ni awon yoo maa kede abajade esi idibo naa ni ola lọjọ kárùndínlọ́gbọ̀n, osu kéjì , odun 2019                      .
Kcee fí ọwọ́ Jóná lóri Liverpool Vs Barcelona Sàǹgbá fọ́!
Bẹ́ẹ̀ náà ni ìyẹ̀fun tí a kọ́kọ́ kù, ati ọrẹ wa, èso gbogbo igi, ọtí waini, ati òróró.
Òkú ṣùn nínú ìbúgbàmú tó wáyé l'Eko Saaju la ti sọ fun yin pe iroyin to n ja rainrain to n tẹ wa lọwọ bayii ti kede pe, ọpa epo miran tun ti bẹ lagbegbe Festac, ti ọrinrin rẹ si gbalẹ yika Eko.
Ẹ fi pẹ̀lẹ́pẹ̀lẹ́ gba ọ̀rọ̀ tí a gbìn sinu yín, tí ó lè gba ọkàn yín là.
Awọn iroyin ti ẹ lee nifẹẹ si: Trump tọrọ aforiji lori asise rẹ ‘ Awọn ọmọ Yobe’ Kini yoo pada jasi?
Bakan naa lo sọ fun BBC pe ọwọ ko ti i tẹ ẹnikẹni lori iṣẹlẹ naa, ati wi pe iwadii n lọ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ikú ọmọ D'banj: Àwọn mọ̀lẹ́bí sọ̀rọ̀ lórí ikú ọmọ rẹ̀ 25 Òkùdu 2018 Àkọlé àwòrán, Ẹbí D'banj kò fẹ́ sọ̀rọ̀ lórí ọ̀rọ̀ náà Àwọn ẹbí gbajúgbajà akọrin tàkasúfèé ọmọ orílèèdè Nàìjíríà, Daniel Oyebanjo tí gbogbo ènìyàn mọ̀ sí Dbanj sọ̀ pé àwọn banujẹ́ gidi gan lórí ikú ọmọ náà.
Àkọlé tí a kọ sára èdìdì tí ó wà lára rẹ̀ nìyí: “Ọlọrun mọ àwọn ẹni tirẹ̀,” ati pé, “Gbogbo àwọn tí ó bá ń pe orúkọ Oluwa níláti kúrò ninu ibi.
Baba Ijesha: Ọkan mi kan baa yin sọ̀rọ̀ nii Fathia: What for?
Sanwo-Olu sọ pe oun gbe igbesẹ naa lati le fi ran awọn onisẹ aladani lọwọ ati lati le fi sun ọrọ aje siwaju ni akoko idẹnukọlẹ ọrọ aje ati koni le gbele ti arun Coronavirus yii.
Igbesẹ naa lo jẹ ki ọkan akẹkọọ naa poruru papaa julọ bi awọn ẹbi rẹ ti sọ pe aafa fẹ fi ọmọ awọn ti ko ti i mọ ọkunrin ri ṣe oogun owo ni.
Ọ̀pọ̀ ẹ̀mí sọnù sínú ìjàmbá ọkọ̀ ojú'rin lásìkò tí wọ́n n wòran ọdún Eeyan 18 ku ni marosẹ Ibadan si Eko Iṣẹlẹ naa waye lẹyin ọjọ mẹta ti ajọ to n mojuto igbokegbodo ọkọ nipinlẹ Eko, LASTMA fi ikede kan sita loju opo Twitter rẹ pe awọn irin kan ti yẹ̀ kuro ni aaye wọn ni oju'rin ọhun, to si n fẹ atunṣe ni agbegbe Mangoro Ashade yii kan na.
Jazz music: Ayọ̀ tó ń bẹ nínú orin Jazz
Bungudu tun fi mule pe, ijoba ipinle Zamfara pelu ibasepo ajo to n pese eto ilera, ti bere olokan-o-jokan eto lati ro awon obinrin ipinle naa lagbara, papaajulo awon obi awon omo alabarapa.
Kì í ṣe ire yín ni àwọn tí wọn ń ṣaájò yín ń wá.
Ọjọ́ wo ni ẹ̀dá yóò sinmi ogun ní àgbáyé?
OLUWA, gbogbo ohun tí o dá ni yóo máa dúpẹ́ lọ́wọ́ rẹ,àwọn eniyan mímọ́ rẹ yóo sì máa yìn ọ́.
    Ẹni tí o dúró sí ipò kẹfà ni Kùmọ́dìran tí mo ti sọ̀rọ̀ rẹ̀ ní ìsáájú.
Lucy fi kun un pe ẹni to mu foonu rẹ nibi ti iṣẹlẹ yii ti waye lo pe oun lati sọ fun oun koun to sa lọ sileewosan ti Immaculate Okochu ku si.
Àtẹ ìdíje Premier League fun sáà 2018 sí 2019
Chinese restaurant: CDHR ní ìjọba Nàíjíríà ló fa ẹ̀gbin náà bá wa
Ati ajọ LASEMA ati ileeṣẹ panapana Eko ni wọn pawọpọ fun iṣẹ naa ti ikọ adoola si kan sinu omi naa lati maa wa awọn ọmọ to sọnu.
Lọkọọkan-ejeeji sini wọn duro gẹgẹ bi wọn ṣe n wo awọn ile naa pẹlu iyalẹnu.
Àkọlé àwòrán, Awọn alasọ ẹbi ẹlẹgbẹjẹgbẹ lawujọ ati ni ipinlẹ Ọyọ naa ko gbẹyin nibẹ.
Lonii yii orile ede Naijiria jẹ àádọ́wàá milionu eniyan.
Ṣẹ gbọ́ nípa Alájọ Ṣómólú, tó ta mọ́tò ra kẹ̀kẹ́?
Omo odun mẹ́rìnlélọ́gbọ̀n ohun gba apapo ifesewonse òjìlénígba lé mewaa fun iko agbaboolu Juve, bee si ni O gba ife eye idije Serie A fun igba meje otooto.
Àbí ẹ̀ṣẹ̀ ni, pé mo waasu ìyìn rere Ọlọrun fun yín láì gba nǹkankan lọ́wọ́ yín?
O wa ro awon oludibo ki won ni imo nipa awon ami idanimo wonyii, lasiko
Balaamu bá Balaki lọ sí ìlú Kiriati-husotu.
O ni awijare awọn agbofinro naa ni pe dokita obinrin yii ko mura bii alakọwe, o si seese ko jẹ pe oninabi ni.
Pásìtọ̀ ìjọ Sotitobire Alfa Babatunde padà s'ẹ́wọ̀n, Iléẹjọ́ sún ìgbẹ́jọ́ sí ọjọ́ Ajé tó ń bọ̀ Ìrántí Sani Abacha, apàṣẹ wàá tó tún kó owó Nàìjíríà mì APC ni Auxilliary ṣiṣẹ́ fún lásìkò ìdìbò gómìnà 2019 kìí ṣe PDP-Oyo NURTW Ṣé lóòtọ́ ni òjòjò dá Abiola Ajimobi wólẹ̀?
    Nígbà ti a dé ìgbìmọ̀ ní ọjọ́ náà, a bá àwọn ènìyàn ọ̀pọ̀lọpọ̀ tí wọ́n ń sọ̀rọ̀ tí wọn ń sá kiri nínú ilé náà.
ti o si le e gbegi dina ilosiwaju ati idagbasoke ilu, agbenusoro naa wa ro awon
Díẹ̀ díẹ̀ nimú ẹlẹ́dẹ̀ẹ́ fi ń wọgbà
Ẹ má ṣe gbàgbé ọ̀rọ̀ tí ẹ gba nípa ìwà ìrẹ̀lẹ̀.
" , "" awon afaso boju "" ."
Ẹni tí ó bá gba Ọmọ Ọlọrun gbọ́ ní ẹ̀rí yìí ninu ara rẹ̀.
iwe igbelu , ni eyi ti yoo bẹrẹ ni ojo kinni osu keje, odun 2019.
Oyinkan Abayomi, akọni obìnrin tó fi ìfẹ́ pa orúkọ ọkọ kejì dà sí ti ọkọ àárọ̀ Àlàyé rèé lóríi ìdí tí wọ́n fi ń pe aya ní ìyàwó Ẹ wo ẹyẹ ayékòótọ́ tó kó olówó rẹ̀ yọ lọ́wọ́ ikú gbígbóná Wo àwọn ọmọ Naijiria mẹ́ta tó jáwé olúborí nínú ìdìbò sílé aṣòfin ilẹ̀ Amẹrika Ọ̀rọ̀ ìjókòó ìgbìmọ̀ ìwádìí #EndSARS náà dé ìpínlẹ̀ Ogun A ti gbé ìwádìí dìde lórí ìpànìyàn tó wáyé lásìkò ìwọ́de EndSARS- Ilé ẹjọ́ àgbáyé, ICC Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Fídíò, Orlando Owoh: Ayé ti sú mi, àdúrà ikú ìrọ̀rùn ló wù mí- Christiana, Ìyá Orlando Owoh tó ti pé ọdún 1105 Bélú 2020 Fídíò, Soyinka Cancer: Àṣe ara mi ni iso ti n run gbogbo bí mo ṣe n ṣèrànwọ́ lórí jẹjẹrẹ27 Bélú 2019 Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
O fi kun un pe eyi yoo tun mu ki ifẹ to wa laarin ọkọ ati aya l'agbara sii.
 ) ( there are six exits in the departmental store .
'Ìjà fún ìdájọ́ òdodo lórí ìyá mi tí wọ́n ṣekú pa' ‘Gboingboin ni Ilẹ̀ Gẹ̀ẹ́sì wà lẹ́yìn ìgbógun ti Boko Haram’ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Kí ni àmì ohùn orí ''Aifagbafẹnikan' Awọn osisẹ pajawiri ni ojo lile ti sẹlẹ lawọn ibi kan, ti ọpọlọpọ orule si ti ba iji lile naa lo, amọ ko si ẹni ti o padanu ẹmi wọn.
 abẹ ́ ìrọ ̀ rí rẹ ̀ ni ó wà nígbà tí ó ń ṣàìsàn .
Àwọn èèkàn ìlú péjú s'Ibadan níbi ìsìnkú màmá Omotola àkọ́bí obìnrin Awolowo tó wọ káà ilẹ̀ lọ Wo dókítà ọmọ Nàìjíríà tí àgbáyé ń wárí fún nítorí abẹ́rẹ́ àjẹsára COVID-19 Nkechi Blessing vs Toyin Abraham: Nkechi tí tọrọ ìdáríjí ẹ̀ṣẹ̀ lọ́wọ́ akẹgbẹ́ rẹ̀, Toyin Abraham Omotara kan ìdin nínú iyọ̀, àwọn ọmọ ilẹ̀ Faranse náà bínú síi nítorí alágbe tó fi ṣe yẹ̀yẹ́.
Anine Lansari – The Blessed Vost (Les Bienheureux)
Donald Trump ní àwọn ọmọ ogun IS yi wà lára àwọn tó burù julọ nínú ìkọlù A fẹ́ kí a máa tẹ àwọn afipábánilòpọ̀ lọ́dàá ni báyìí - Ìjọba Ekiti Ǹjẹ́ o mọ ẹni tó ran àjọ ọ̀tẹlẹ̀mùyẹ́ CIA lọ́wọ́ láti rí Bin Laden mú?
Àwọn ọ̀dọ́ Akure faraya lẹ́yìn tí ọkọ̀ agbówórìn 'Bullion van' pa ẹnìkan Amọ lati ọdun 2018, eyiun ọdun meji sẹyin ni Nasreen ti n wọna nile ẹjọ lati da igbeyawo naa nu.
Owó orí gọbọi lori ọjà yii pẹlu iwa ipá ti awọn agbofinro n lò lati fagidi mu awọn ọlọja, di ẹru nla lori awọn obinrin.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Death During Sex: Àwọn nǹkan mẹ́ta tó le ṣekú pa ọkùnrin lásìkò ìbálòpọ̀ rèé 8 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 9 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Oríṣun àwòrán,  ROYALTY-FREE / CORBIS Lọpọ igba la maa n gbọ iroyin pe ọkunrin tabi obinrin re sọda di ero ọrun lasiko ibalopọ.
Kì yóo sí ìdí tí ẹnìkan yóo fi kọ́ aládùúgbò rẹ̀ tabi arakunrin rẹ̀, pé,‘Mọ Oluwa.
Ọwọ́ ọlọ́pàá ti tẹ afurasí mẹ́ta tó lọ́wọ́ nínú ìjínigbé alága Iganna l'Oyo Ileeṣẹ ọlọpaa ipinlẹ Oyo ti fi panpẹ wọn mu eeyan mẹta lara awọn ti wọn furasi pe wọn lọwọ ninu ijinigbe alaga kansu kan ṇi ipinlẹ Oyo.
 Ẹ ̀ ka-èdè wọn dọ ́ gba , orúkọ àdúgbò wọn tún bára mu , bákan náà ni ẹ ̀ sìn wọn tún dọ ́ gba .
Àjọ yii gba agbẹjọ́rò fún àwón ọmọ Naìjíríà ti wọn fi tipá mu fi ṣe iṣẹ́ aṣẹwó nilẹ̀ Yuroopu.
Wọn ni irọ́ pátápátá ní àwọn to fi ẹ̀sùn kan ń pa bíkò ṣe pé èdè aiyedè tó ṣẹlẹ̀ nínú ẹgbẹ́ ló faa àhesọ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Fulani Ilorin l'ọkọ mi' Bi ẹ ko ba gbagbe, laipẹ yii ni awọn agbebọn kan ti ọpọ furasi gẹgẹ bi awọn darandaran Fulani pa arabinrin Funkẹ Olakunrin.
Majistireti Oluwasanmi lasiko to n gbe idajọ rẹ kalẹ sọ pe iwa naa le dẹmi awọn eeyan legbodo nitori ewu to wa nita pẹlu Coronavirus.
Pásítọ̀ gún ìyàwó rẹ̀ lọ́bẹ nínú ṣọ́ọ̀ṣì, ló bá tì í bọ ara rẹ̀ náà níkùn Gẹgẹ bi a ti gbọ lati ẹnu awọn ẹbi oloogbe to ti de sitẹ oku naa, awọn alasẹ ileesẹ eto ilera nipinlẹ Eko lo pasẹ pe kawọn ẹbi naa ma ti gba oku akẹkọbinrin naa lọ sin.
Àwọn ni baálé baálé ní ìdílé wọn, ìjòyè ni wọ́n ní ìran wọn; wọ́n ń gbé Jerusalẹmu.
Awọn ti ọrọ naa ṣe oju wọn ni wn n sun ina ni ilẹ kan ni agbeegbe naa, ki o to di wi pe ina naa wa bẹrẹ si ni ran.
Ni kete ti abiyamọ ba ti bi ìkókó si ilé ayé ni ẹbi, ara ati ojulumọ a ti wa maa ki wọn ku oriire alejo tuntun ni ọọdẹ wọn.
Wọ́n ń yípo lábẹ́ ìtọ́ni rẹ̀,láti mú gbogbo àṣẹ tí ó pa ṣẹ, lórí ilẹ̀ alààyè.
Ọpọlọpọ awọn ẹgbẹ lo si ti kesi ipinlẹ Rivers, lati fi opin si isede ni Oyigbo, ki awọn eeyan le jade ra oúnjẹ.
Ọkunrin náà ní ọrọ̀ lọpọlọpọ; ó ní ẹgbẹẹdogun aguntan (3,000) ati ẹgbẹrun (1,000) ewúrẹ́, Kamẹli níí ti máa ń gé irun aguntan rẹ̀.
Wọn ji adari ẹka nile iṣẹ pana pana ipinlẹ Eko, Rashidi Musibau atawọn mẹfa mii ti wọn jọ n lọ gbe ni ọjọ abamẹta to kọja wọn si gbe wọn lọ si ibi ti wọn ko mọ.
wọ ́ n bí mozart ní 1756 .
Awọn iroyin ti ẹ le nifẹ si: Pasitọ Tunde Bakare: Akoko to fun Buhari lati lọ 'O yẹ ki dokita ọpọlọ yẹ ọpọlọ mi wo' Ọdalẹ ni Babangida ati Abacha - Ọmọ Abiola Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Ẹ máa gbadura fún èmi gan-an alára, pé kí n lè mọ ohun tí ó yẹ kí n sọ nígbà tí n óo bá sọ̀rọ̀.
Igba o le aadọta ẹgbẹrun ni iye ọlọpaa to wa ni Naijiria lọwọlọwọ.
Ta ni Chelsea le doju kọ?
Wọ́n pada tọ Joṣua wá, wọ́n sì wí fún un pé, “Má wulẹ̀ jẹ́ kí gbogbo àwọn eniyan lọ gbógun ti ìlú Ai, yan àwọn eniyan bí ẹgbaa (2,000) tabi ẹgbẹẹdogun (3,000) kí wọ́n lọ gbógun ti ìlú náà.
 O ni ki onikaluku sora fun iyepe, afefe lile ati iji lasiko oye yii kidoti ma baa ko si eyinju koowa.
OLUWA sọ fún Mose pé kí ó sọ fún àwọn alufaa, àwọn ọmọ Aaroni pé, “Ẹnikẹ́ni ninu wọn kò gbọdọ̀ sọ ara rẹ̀ di aláìmọ́ nítorí ikú àwọn eniyan rẹ̀.
Eyikeyi ninu gbogbo ika la le fi dibo.
Kì í ṣe ẹ̀bùn ni mò ń wá, ṣugbọn mò ń wá ọpọlọpọ èso fún anfaani yín.
Bi ọmọbinrin naa ṣe ge okó rẹ jẹ niyẹn o, ti ẹjẹ si bẹrẹ si ni i tu jade, eyi lo si mu ki afurasi naa sa jade ninu yara naa.
Adilemu fun Man U tẹlẹ ni Sheffield United gan an lo yẹ ko jawe olubori ninu ifẹsẹwọnsẹ alẹ ọjọ Aje nitori awọn lo fakọyọ julọ.
Ohun ti ko tilẹ ṣee gba lero ni nitori, bawo ni eeyan ti ọpọẹọ rẹ pe kan yoo ṣe gba ẹsun yii gbọ?
A kò fetí sí ọ̀rọ̀ àwọn iranṣẹ rẹ, àní àwọn wolii, tí wọ́n wá jíṣẹ́ rẹ fún àwọn ọba wa ati àwọn olórí wa, àwọn baba wa, ati fún gbogbo àwọn tí ń gbé ilẹ̀ náà.
N óo wá kọ́ àwọn ńláńlá mìíràn; níbẹ̀ ni n óo kó àgbàdo mi sí ati àwọn ìkórè yòókù.
Òbítíbitì ẹ̀gbin ti sọ ìlú Ibadan di ààtàn - Aráàlú figbe bọnu Ìbínú ẹlẹ́wọ̀n!
Ni lọọlọ yii, alaboyun lee wọ ilẹ Amẹrika koda titi di ọjọ ibimọ gẹgẹ bi ajọ aṣọbode ilẹ Amẹrika ṣe sọ ọ ṣugbọn irina ẹni to ti fẹẹ di abiyamọ kan le ri idiwọ ni bi wọn ba ri idi pe o ṣi fẹ duro si Amẹrika kọja iye akoko ti wọn fun un lori iwe aṣẹ irina rẹ tabi igbiyanju lati jẹ ki awọn to n san owo ori ni ilẹ Amẹrika ba a san owo ile iwosan to ti bimọ rẹ.
O fikun-un pe, o kere tan eniyan ti o leni ẹ̀ẹ́dẹ́gbẹ̀ta lo ti padanu emi won ninu ikolu ohun, ti awon miran si farapa yanayana.
Ayẹwo fihan l'ọjọ Aiku pe, ọkunrin naa ni i, ṣugbọn iyawo rẹ ko ni i.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Seyi Makinde: Ẹ̀kọ́ ọ̀fẹ́ tó pọn dandan ti bẹ̀rẹ̀ nílé ẹ̀kọ́ alákọ̀ọ́bẹ̀rẹ̀ àti girama ní Ọyọ 9 Agẹmo 2019 Oríṣun àwòrán, Seyi Makinde Ijọba ipinlẹ Ọyọ tun ti tẹnumọ pe ilana oun lati pese ẹkọ ọfẹ to pọn dandan nipinlẹ Ọayọ lawọn ile ẹkọ ijọba si tun n fẹsẹ mulẹ o Gomina ipinlẹ Ọyọ, Onimọ ẹrọ Seyi Makinde lo satẹnumọ ọrs yii latinu atẹjade kan ti olori osisẹ sba nipinlẹ Ọyọ, Arabinrin Ọlọlade Agboọla fisita.
O ṣiṣẹ gẹgẹ bi oluranlọwọ fun ile iṣẹ Kakawa Asset Management fun oṣu mẹta lati oṣu Kẹfa si oṣu kẹjọ ọdun 2008.
Aráàlú dá iná sun èèyàn méjì n'Ibadan, orí kó ẹni kan yọ Oríṣun àwòrán, @PoliceNG Eeyan meji ọtọọtọ l'awọn ero dana sun lagbegbe ASAS ni Molete ati Oke Ado ni ilu Ibadan lọjọ Aje.
UNMISS ti fi isele naa to olu ile-ise ajo UN to wa nilu New York leti, eyi ti won so pe, ki iwadii bere lori esun ohun, ko si anihani pe, iru iwa bayii maa n waye laarin awon omo-ogun naa”.
Ó wá wí fún wọn pé, “Nígbà tí òwe yìí kò ye yín, báwo ni ẹ óo ti ṣe mọ gbogbo àwọn òwe ìyókù?
Ahabu pe Ọbadaya, tí ó jẹ́ alabojuto ààfin.
Nígbà tí Sanbalati gbọ́ pé a ti ń kọ́ odi náà, inú bíi gidigidi, ó bá bẹ̀rẹ̀ sí bu ẹnu àtẹ́ lu àwọn Juu.
Lekki Shooting: Ohun tó ṣẹlẹ̀ kò sí nínú ìlànà ológun, Buhari gbọ́dọ̀ ṣèwádìí
"Ọga agba fun ajọ naa, Hameed Ali lo sọ ọrọ yii, nibi ifọrọwerọ kan pẹlu awọn oniroyin lori iṣẹ ti wọn pe ni ""Ex-Swift Response"" ni Abuja."
aare tun ro awon omo orile-ede Naijria lati tu yaya, tu yaya sita lola ojo Abameta(Satide)
Ẹ̀rẹ̀kẹ́ wa kún fún ẹ̀rín, a sì kọrin ayọ̀,nígbà náà ni àwọn orílẹ̀-èdè yòókù ń wí pé,“OLUWA mà ṣe nǹkan ńlá fún àwọn eniyan yìí!
O kan ṣaa jẹ ina ibọn to ya gan gẹgẹ bi ẹlomiran to ṣoju rẹ ṣe sọ ọ.
Minisita fun eto inawo lorile ede Naijiria  Kemi Adeosun, ti oun naa wa nibi ipade ohun so pe ijoba orile ede Niajiria n ba banki agbaye soro lori atileyin ti won yoo se  fun orile ede yii ,nipa ina mona-mona.
Adajọ tu Yunusa silẹ lori ẹsun kini ti wọn fi kan ṣugbọn o gba idajọ ẹwọn ọdun marun un lori ẹsun keji, meje lori ẹlẹẹkẹta, ẹlẹẹkẹrin ati ẹlẹẹkarun-un.
Ó sàn láti sá di OLUWA,ju ati gbẹ́kẹ̀lé àwọn ìjòyè.
Ojogbon Osinbajo soro yii nibi ipade ti awon olori elesin musulumi se nipa bi won  yoo se maa samulo ohun alumooni ilẹlona ti yoo se mu  idagbasoke ba orile ede Naijiria.
Wọ́n dàbí idẹ, páànù, irin, ati òjé tí ó wà ninu iná alágbẹ̀dẹ.
Bí ẹ ti ń ṣe ni kí ẹ túbọ̀ máa ṣe.
Gbogbo ọ̀nà eniyan ni ó mọ́ lójú ara rẹ̀,ṣugbọn OLUWA ló rí ọkàn.
EFCC ni àwọn ń ṣe ìwádìí wọ́n fún oníruuru ìwà ọdaran ori ayelujára àti kíko owó pamọ lọ́nà àìtọ́, àti pé ìwádìí fi han pé Olusegun Aroke lo ṣe agbódegbà fún olé ori ayelujara tó tó ọgọ́rún kan mílìọnù dọ́là bi o ṣe n ṣẹ̀wọ̀n rẹ̀ lọ́wọ́.
 oruko alaje re ni haeak tabi ilso .
Pẹlu ìgbéraga ni àwọn ẹlẹ́ṣin wọn máa ń gun ẹṣin wọn lọ.
Oríṣun àwòrán, Alaafin of oyo Irufẹ agba olori bẹẹ lee jẹ obinrin ti ọba to wa lori oye naa fẹ funra rẹ abi eyi to jogun lati ọwọ awọn ọba to ti waja, to si ba ninu aafin.
Ṣùgbọ́n àtẹ̀yìnwò ìgbéyàwó wọn kò ṣẹnure.
Gẹgẹbi awọn akọroyin BBC to tọpinpin bi eto idibo naa se lọ si yika orilẹede Naijiria ti wi, nkan ko fararọ lawọn agbegbe kan nilu Eko, Oyo, Ọsun, Rivers ati Anambra.
ipinle Kaduna je ipinle akoko ti yoo koko se iru ise akanse nla bayii ti isuna
Eyi mu ki ọpọ eeyan maa bere pe ki gan an lo wa laarin aarẹ ati ọjọgbọn Usman Yusuf?
Nigba to n ba wa sọrọ lori isẹlẹ naa lorukọ onibara rẹ, agbẹjọro fun Cute Abiola, Amofin Fatai Adebanjo ni ẹsẹ ofin ni awọn yoo fi yanju ọrọ naa.
Lẹ́yìn náà, yóo ṣe ètùtù fún un níwájú OLUWA.
Yorùbá dùn lédè, ẹ máa sọọ́ Awọn awakọ, ẹrọ to n naa popona naa sọrọ lori awọn ohun ti oju wọn n ri lasiko ti awon adigunjale ba n sọsẹ ni awọn ọna naa.
Oríṣun àwòrán, @Moneycentral4 Ajọ eleto idibo Naijiria, Independent National Electoral Commission (INEC) ti kede pe eto gbogbo ti to de eto idibo lati yan gomina tuntun ti yoo waye ni ipinlẹ Ondo lọjọ kẹwaa, oṣu kẹwaa, ọdun 2020.
Oríṣun àwòrán, Twitter/@eniola esan Ọmọwe Yemi-Esan rọ awọn oṣiṣẹ papaa julọ awọn to wa nipele kejila lọ soke atawọn oṣiṣẹ ko ṣee maa ni lati lọ sẹnu iṣẹ wọn lọjọ Aje.
Ó wá sí ìlú ara rẹ̀, ṣugbọn àwọn ará ilé rẹ̀ kò gbà á.
Dafidi tún tọ OLUWA lọ láti bèèrè ohun tí yóo ṣe.
Nígbà ti IMN sọ pé Abdullahi Muhammad Musa, sọ fún ilé ìròyìn Reuters pé àwọn ọlọpàá síná bolẹ̀ ti wọ́n sì pa ènìyàn méji láàrin àwọ́n afẹhonu han lágbà ti wọ́n ń fẹ wọ ilé ìgbìmọ aṣojúsofin ní ìrọ̀wọ́rọsẹ̀.
Ìgbà tí ó tó déédéé agogo mẹ́ta ni bàbá mi dé igbó tí ó kángun sí igbó Olódùmarè gan-an, orúkọ igbó náà a si máa jẹ́ Aginjù Ìdákẹ́rọ́rọ́: nítorí ibẹ̀ ni ó dákẹ́ jùlọ ni gbogbo abẹ̀ ọ̀run.
RuizJoshua2: Anthony Joshua di akànṣẹ́ kẹrin nínu ìtàn tí yóò gba ogo rẹ̀ padà lẹ́yìn tó sọ ọ́ nù
Aare panupo pelu ogunlogo awon ololufe iko agbaboolu Naijiria jake-jado lati ki won ku ori-ire aseyori naa.
Àkọlé àwòrán, Ijọba ni ile iṣẹ naa ko lẹtọ lati kọ apa ibi ti ijọba wo, lai ṣe ohun ti ijọba fẹ.
''A ti ṣe gbogbo ètùtu tó yẹ́, asì ti sàdúra tí yóò kó ààrùn Coronavirus kúrò nílùú.
Ó yé àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ nígbà náà pé nípa Johanu Onítẹ̀bọmi ni ó ń sọ fún wọn.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, EndSars, EndSwat Protest: Òbí agbábọ̀ọ̀lù Gbenga Tiamiyu Kaka àtàwọn míì tí ọlapàá pa sọ̀r Ajọ EFCC fi iwe pe arakunrin Fowler to tun jẹ adari ajọ to n risi ọrọ owo ori labẹle nipinlẹ Eko, ti oun naa si jẹ ipe wọn ni Ọjọ Aje.
Kí ló pa wá pọ̀ pẹlu ọmọ Jese?
Oríṣun àwòrán, Air Peace Àkọlé àwòrán, Air Peace ti setan lati maa ko awon omo Naijiria bo Aarẹ Muhammadu Buhari lo pasẹ yii nigba ti Aṣoju orilẹ-ede yii ni ilẹ South Africa, Ahmed Rufai Abubakar ṣe abẹwo si i lori iṣẹlẹ ikọlu si awọn ajoji ni outh Africa.
Ati ará Patia, ati ará Media ati ará Elamu; àwọn tí ó ń gbé ilẹ̀ Mesopotamia, ilẹ̀ Judia ati ilẹ̀ Kapadokia; ilẹ̀ Pọntu, ilẹ̀ Esia, 
Oríṣun àwòrán, Others Nínú ọ̀rọ̀ rẹ̀, Ọ̀jọ̀gbọ́n Folashade Tolulopẹ Ogunsola sàlàye fún BBC pé, wàhálà yìí kìí ṣe ǹkan ti ó ṣẹ̀ṣẹ̀ bẹ̀rẹ̀ ni àná bíkòṣe láti ọjọ́ tó ti pẹ́.
Abimeleki lé Gaali, Gaali sì sá fún un, ọpọlọpọ eniyan fara gbọgbẹ́ títí dé ẹnu ibodè ìlú.
"Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Watford b si ipo kọkanla lori tabili premier league Gracia, ti o rọpo Marco Silva ni osu to kọja, sọ fun BBC Sport wipe: ""O jẹ aseyọri ati iṣere nla fun awọn ẹgbẹ agbabọọlu Watford."
Awọn sẹnetọ meji naa ni Isah Misau ati Ben Murray-Bruce.
Kò yẹ mi ìdí tí Wasiu Ayinde fi hu ìwà àbùkù tó hù sí mí- MC Murphy Àdigunjalè báńkì ní Iyin-Ekiti fẹsẹ̀ fẹ, bí wọ́n ṣe rí wa - Iléeṣẹ́ ọlọ́pàá Ìlànà ‘Referendum’ nìkan la fi le gba orílẹ̀èdè Oduduwa, kìí ṣe ìwọ́de Awọn ẹbi ati ara awakọ naa lo pejupese si ibi iṣẹlẹ naa, ti wọn si n dupẹ pe awakọ naa ko ba iṣẹlẹ oun lọ.
Ó wá tún ku àwọ̀tẹ́lẹ̀ rẹ̀.
" Oun ti aburo mi sọ fun awọn aṣoju orilẹede Gẹẹsi kan ree nigba ti ṣi n ṣọfọ iya mi.
 “O digba ti a ba ni anfaani si awon ijoba ibile ati awon ile-iwosan kekeke wonyii, o soro fun wa lati so pe, aarun ropa-rose ti di ohun afiseyin teegun n fiso, a si ni isoro lati wo ijoba ibile Abadam, Marte ati awon agbegbe miiran bi: Bama, Dambowa, Ngala ati ijoba ibile Magumeri”.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Wọ́n nílò ìrànlawọ́ mi láti ṣèmọ́tótó ibi tí wọ́n ti ń tọ́jú àwọn tó ní Coronavirus Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Lẹyin ti gbajugbaja agbabọọlu ni , Christiano Ronaldo ti fi Real Madrid silẹ ni ọdun 2018 ni nnkan ti dẹnukọlẹ fun Real Madrid.
alexander babátúndé akínyẹlé , cbe ni wọ ́ n bí ní ( 5 september 1875 - 1 october 1968 ) je bíṣọ ́ ọ ̀ bù àgbà àkọ ́ kọ ́ ní ìjọanglican diocesan ní ìlú Ìbadàn , ní orílẹ ̀ èdè nàìjíríà.
'Gomina Makinde, àgbọ́gbọn'tí ni kẹ́ẹ gbọ́ àwọn ará Oyo o lórí sáà kejì 'torí.
yanju aawon ipenija to n dojuko eto irinna ofurufu ati lati yanju awon isoro
Ohun to yẹ ko mọ nipa Jesu Oyingbo: Emmanuel Olufunmilayọ Odumosu ni orukọ Jesu Oyingbo, Jacob Odumosu ni orukọ baba rẹ, ti baba baba rẹ, Joseph Odumosu si jẹ onisegun ibilẹ ni ilu Ijẹbu Ode Ọdun 1915 ni wọn bi Odumosu, o kọ isẹ Gbẹna-gbẹna ta mọ si Kafinta, to si tun sisẹ bii osisẹ lẹka to n ri si pinpin lẹta ati waya lasiko ogun agbaye keji sugbọn idaṣẹsilẹ nla to waye lọdun 1945 lo mu ko fi isẹ naa silẹ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Sogidi Lake: Kòṣẹja-kòṣèèyàn lá bá nínú adágún odò náà -Ojedele Emmanuel Odumosu pada si idi isẹ Kafinta, to si nira fun lati ri ọwọ mu lọ sẹnu, ti gbese jijẹ si di baraku fun.
Ṣugbọn OLUWA sọ fún wolii Ṣemaaya, eniyan Ọlọrun pé, 
Omotoso ni ti eto Amotekun ba fẹsẹ mulẹ tan, ẹṣọ alabo ipinlẹ Eko ko ni yi orukọ rẹ pada lati Neighborhood watch"" to n lo fun aabo agbegbe pada si Amotekun, nitori iṣẹ kan naa ni wọn n ṣe."
oorun ati aarin gbugbun orile ede yii.
Presidency: $500 mílíọ́nù ni a ti ná lórí nǹkan ogun nínú owó tí a gbà nínú àṣùwọ̀n àpapọ̀
OLUWA ti dá wa láre;ẹ wá, ẹ jẹ́ kí á lọ ròyìn iṣẹ́ OLUWA Ọlọrun wa ní Sioni.
"Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Akinwumi Isola: Wo ohun tí Abeni fi ojú ọkọ rẹ rí tórí iṣẹ́ bọ́ lọ́wọ́ rẹ̀ nínú ìwé ""Nitori Owo"" Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Akinwumi Isola: Wo ohun tí Abeni fi ojú ọkọ rẹ rí tórí iṣẹ́ bọ́ lọ́wọ́ rẹ̀ nínú ìwé ""Nitori Owo"" 27 Ọ̀wàrà 2020 Awọn iwe Ọjọgbọn Akinwumi Ishola jẹ ibi ikẹkọọ fun ọpọlọpọ gẹgẹ bo ṣe jẹ agba ọjẹ onkọwe lede Yoruba."
– Nítorí Ẹlẹ́dàá ń wo ẹ̀dá pẹ̀lú iṣẹ́ ọwọ́ ẹ̀dá, àti ìrìnkèrindò ẹ̀dá láàárin àwọn ẹ̀dá, bẹ́ẹ̀ ni Ẹlẹ́dàá kò ní ṣàìfi èrè iṣẹ́ ọwọ́ ẹ̀dá fún ẹ̀dá bíó ti wù tí àyípadà dé tó, yálà ní òde ayé tàbí ni òde ọ̀run.
The Adventures Of Supermama – South Africa
"Kristofer Hivju Oríṣun àwòrán, Kristofer Hivju Kristofer Hivju to jẹ ọkan pataki lara awọn oṣere to kopa ninu sinimọ 'Game of thrones"" naa kede pe oun pẹlu ti ko arun ọhun."
Ó lọ jókòó ní òkèèrè, ó takété sí i, ó tó ìwọ̀n ibi tí ọfà tí eniyan bá ta lè balẹ̀ sí, nítorí ó wí ninu ara rẹ̀ pé, “Má jẹ́ kí n wo àtikú ọmọ mi.
Àwọn ọmọ Lefi rẹ àwọn eniyan náà lẹ́kún, wọ́n sọ fún wọn pé, “Ẹ dákẹ́, nítorí pé ọjọ́ mímọ́ ni ọjọ́ òní, ẹ má bọkàn jẹ́.
Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó
Fasoranti: Dẹ́rẹ́bà tó wa ọmọ Fasoranti ṣàlàyé bí wọ́n ṣe pa Funke Olakunrin
Aare ajo UN, Maria Garces soro ohun di mimo fun awon
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Colorado ni Amẹrika àti Adò Awaye ní Naijiria nìkan ni àdágún órí àpáta ní gbogbo àgbáyé!
6 8200 Orilẹede Martinique 41 10.
Ẹwẹ, Jaiye ni iwa aidaa yii ko tọ niwaju eniyan ati Ọlọrun.
Nǹkan yìí ni Ọlọrun fi àṣírí rẹ̀ hàn wá nípa Ẹ̀mí.
Pẹpẹ náà wó lulẹ̀, eérú orí rẹ̀ sì fọ́n dànù gẹ́gẹ́ bí wolii náà ti sọtẹ́lẹ̀ ní orúkọ OLUWA.
Ninu ọrọ rẹ, o wipe mẹtala ninu awọn ile iwe Girama naa ni aṣemaṣe wọpọ si, ti o si fikun un wipe ijọba ipinlẹ naa yoo fikun ijiya awọn ile ẹkọ bẹẹ.
Agbẹnusọ Ile Igbịmọ Aṣofin Ipinlẹ Eko, Aṣofin Mudashiru Ọbasa ti fi da awọn ọmọ orilẹ-ede Naijiria loju pe ijọba to wa lori aleefa ni gbogbo ipele ti n sa gbogbo ipa lati tubọ mu igbe-aye rọrun fun awọn ara iluNinu ọrọ ikini ku ajodun ‘Ayajọ Ijọba Oṣelu Tiwantiwa’ (Democracy Day) agbẹnusọ Ile Igbimọ Aṣofin naa, eleyii ti Alukoro rẹ, Ọgbẹni Musibau Rasak fọwọ si, o gboriyin fun iwa igboya ati ifarada wọn, o wa fi da wọn loju pe, laipẹ laijina, wọn a bẹrẹ si ni jẹ ere ijọba paapaa lẹka ọrọ-aje ilu ti  atunṣe n de ba bayiiO ni, ”eleyii ni ọdun kẹta ti ijọba ẹgbẹ oṣelu All Progressives Congress (APC) bọ sori aleefa ni ipele ijọba apapọ ati ni awọn ipinlẹ pẹlu awọn ijọba ibilẹ kan.
Ọmọbinrin naa sọ pe ''wọn sọ fun wa pe ti a ko ba sọ pe lootọ la jẹbi, ọdọ awọn ni a o wa fun oṣu mẹfa.
 “Pupo ninu ijoba ipinle lo ti yan igbimo ti yoo maa jiroro pelu egbe osise won, , mo tilẹ gbọ pe ipinlẹ Akwa-Ibom ti fẹ bẹrẹ, lati jẹ ipinle akọkọ lati maa san ekunwo fun awon osise rẹ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Odion Ighalo: Ẹlẹ́sẹ̀ ayò Ighalo ń ronú láti padà sí Super Eagles láìpẹ́ 5 Òkùdu 2020 Oríṣun àwòrán, Getty Images Ẹlẹsẹ ayo ọmọ Naijiria to n gbabọọlu fun ikọ Manchester United, Odion Ighalo ti sọ pe oun n roo lọwọ lati pada si ẹgbẹ agbabọọlu Naijiria, Super Eagles.
Amofin agba Ipinlẹ New Jersey ti ṣalaye pe agbeyẹwo yoo wa fun ilana kan-an -nipa awọn ọlọpaa, eyi yoo si jẹ igba akọkọ laarin ogun ọdun.
Àwọn aṣòfin ìpínlẹ̀ Ogun pariwo sí Gómìnà wọn Àyà mi já nígbà tí Ganduje rọ Sanusi lóyè Emir Kano tó fi Bayero síi, ṣùgbọ́n.
Àgékúrú ( g12 , a3 .
Oríṣun àwòrán, Ọrangun ile Ila Kabiyesi ni awọn pe igbakeji ọga agba ọlọpa, AIG, ni Ọsun pẹlu awọn lọgalọga osisẹ ọba miran sibi ipade yii, Agbowu si lo kọkọ sọrọ nipa bi Oluwo se na oun lalubolẹ ni iwaju ọga ọlọpa, to si fi ọrun rẹ ti wọn we bandeji mọ, han awọn.
Ìgbà náà ni iwin náà tó rántí pé ó fi ohun ìkọ̀wé ránṣẹ́ sí mi pé bí mo ba fẹ́ kọ̀wé sí ẹnikẹ́ni lójú ọ̀nà ki ń máa lò wọ́n.
Eyi waye lẹyin ayẹwo atigbadegba kan ti ajọ to n mojuto ipese ounjẹ ati oogun lilo ni Naijiria, NAFDAC, ṣe.
ti se nipa gbigbogun ti iko ọlọtẹ ati iwa odaran ko kere.
O ni nitootọ iṣẹ yii pọ lati gbogun ti awọn ajinigbe ati agbesunmọmi, ṣugbọn eyi ti di ankoo fawẹẹli gbogbo agbaye.
"Wilfred Ndidi, ọmọ Nàìjíríà pa iná ògo Chelsea ní Stamford bridge Manchester United dáná sun Chelsea bi ẹràn àgbò iléyá ""Ojú wa rí tó ní Egypt, bí wọ́n ṣe ń tẹ̀ wá lọ́mú, ni wọ́n ń gbá wa ní ìdí"" Toyin Abraham kìí bá èmi náà yọ̀, ni kò jẹ́ kí ń gbé e lárugẹ fún ayọ̀ ọmọ - Lizzy Anjorin Ọ̀pọ̀ èèyàn bẹnu ẹ̀tẹ́ lu Mercy Aigbe lórí bó ṣe ki Adeniyi Johnson Ìdí rèé tí mi ò fi yọjú sí ìgbìmọ̀ àjọ PFN- Fatoyinbo Ṣugbọn Todd Cantwell dayo naa pada lẹyin iṣẹju mẹta mii lo ba di ọmi alayo kọọkan."
Nígbà náà, wọn yóo mọ̀ pé èmi ni OLUWA.
to kale si agbegbe Jericho niluu Ibadan, ni ipinle Oyo  to wa ni ekun Gusu orile ede Naijiria.
Saulu ti lé gbogbo àwọn abókùúsọ̀rọ̀ ati àwọn oṣó kúrò ní ilẹ̀ Israẹli.
Bẹ́ẹ̀ ni wọ́n ṣe ìsìn Àjọ Ìrékọjá ati ti ẹbọ sísun lórí pẹpẹ OLUWA ní ọjọ́ náà gẹ́gẹ́ bí àṣẹ Josaya ọba.
A ti gba onírúurú ìgbẹ́ tí a rí lọ́wọ́ Emmanuel Egbu lọ fún àyẹ̀wò -Ọlọ́pàá Oyo
Iṣẹlẹ naa to waye lasiko iji ojo lile to n waye lẹkun naa, ni deede aago meji abọ ọsan.
Awọn wo ni èèyan jànkanjakan ti wọ́n wà nibẹ̀ ti wọn si le jẹ́ri síí, Ki ni orúkọ wọ́n?
Ọkọ̀ agbépo tó da epo nù fa súnkẹrẹ-fàkẹrẹ lòpópónà márosẹ̀ Eko sí Ibadan Mo mọ àwọn mẹ́rin tó já fún ìtúsílẹ̀ Dasuki àti Sowore- Fani Kayode Èyí ni bí wọ́n ṣe n dìbò yan Póópù tuntun nínú ìjọ Àgùdà Olè yabo báńkì.
Ọga agba ọlọpaa ni ẹkun naa, Abdullahi Haruna ṣalaye pe Muhammad ti jẹwọ nipa awọn obinrin to to ogoji to ti fipa ba lo pọ ati pe agbara ofin yoo ṣe ohun to yẹ lẹyin iwadii Awọn eeyan ilu naa ni: ''O ti pẹ ti Arakunrin yi i ti maa n dẹruba awọn eniyan agbegbe Kwanar Dangora lori ọrọ ifipabanilopọ ṣugbọn ti onikaluku dakẹ ti wọn n fi mọra nitori eru to n ba wón.
Tottenham vs Ajax: Láti òní lọ,Lucas 'Miracle' lòó má jẹ!
N óo le yín kúrò níwájú mi, bí mo ti lé àwọn ọmọ Efuraimu, tí wọ́n jẹ́ arakunrin yín dànù.
Ajimọbi pegedé fún ìdíje ipò asòfin àgbà Gómìnà Ambode gbà pé òun fìdí rẹmi nínú ìdìbò abẹ́nú APC l'Eko 'Ẹ kò gbọdọ̀ fọwọ́ kan èsì ìdìbò gómìnà Osun' Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
 Bee si ni , Inu wa ko dun rara.
Oríṣun àwòrán, Abike Dabiri Erewa Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ìgbátí ìgbámú àná látọwọ́ sọ́jà obìnrin ti bá arákùnrin náà dé iléèwòsàn Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Alaafin Oyo: Oba Lamidi Adeyemi ní ''tí a bá yọwọ́ àwọn ọba alayé kúrò, kò ní sí Nàìjíríà mọ́6 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Harry Akande: Makinde, Dele Momodu ń ṣèdárò Àgbà Oyè Ilẹ̀ Ibadan, Harry Akande tó jáde láyé6 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Fídíò, Soyinka Cancer: Àṣe ara mi ni iso ti n run gbogbo bí mo ṣe n ṣèrànwọ́ lórí jẹjẹrẹ27 Bélú 2019 Fídíò, India: Ẹ wo bí àwọn ènìyàn ṣe dóòlà èmí erin tó jálulẹ̀6 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 3 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 5 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Pẹlu gbogbo nkan ti a ka kalẹ yi, eleyi ti ohun gangan kii ye sọ nipa rẹ ni pe, awọn obi rẹ kii se olowo ati pe, ohun t'apata dide ni ki ẹlẹda to wa kọdi ọla si ọdọ ohun.
Ẹ jẹ́ ká gbọ́ o, ẹ fèsì kalẹ̀ o.
Mudashiru Obasa wa rọ igbimo to n ri si ile igbimo asofin lati tun lọ jiroro
Medium ti ṣe àtẹ̀jáde ẹ̀dàa ìròyìn yìí ṣáájú èyí.
Ninu aba naa o ni awọn yoo doju kọ pipese ohun amayedẹrun ati mimu igbe aye rọrun fawọn ọdọ nipa awọn eto orisirisi.
" haram jẹyọ lati èdè lárúbáwá "" ḥarām "" , "" èèwọ ̀ "" ; tí ọ ̀ rọ ̀ hausa yìí "" boko "" [ tí àìránmúpè àkọ ́ kọ ́ gùn long , tí èkejì máa ń pe oùn ìsàlẹ ̀ ] , tí ó túmọ ̀ sí "" ẹbu "" , tí wọ ́ n fi ń pe ẹ ̀ kọ ́ ọ ̀ làjú ."
Aare Muhammad Buhari ti ba awon eniyan ti won farapa nibi ipolongo ti
Ni Jesu bá tẹnu bọ̀rọ̀, ó ní, “Ẹ ṣọ́ra, kí ẹnikẹ́ni má ṣe tàn yín jẹ.
Ṣugbọn kí ni Ìwé Mímọ́ wí?
Ìlànà ojúlówó márùn ún tó dènà àrùn Coronavirus Àwọn Ìpínlẹ̀ tí coronavirus kò tíì dé ní Nàìjíríà, àti ìgbésẹ̀ tí wọ́n ń gbé láti dènà rẹ̀ Kí ló ń ṣẹlẹ̀ láàfin Ọ̀yọ́?
Àkókò náà ni kí ìwọ wá ọ̀nà kí ìw\\o lè jáde.
bí ẹ bá ń wí pé, ‘Rárá o, a óo sá lọ sí ilẹ̀ Ijipti, níbi tí a kò ti ní gbúròó ogun tabi fèrè ogun, níbi tí ebi kò ti ní pa wá, a óo sì máa gbé ibẹ̀,’ 
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Messi fakọyọ pẹ̀lú àmìn ayò mẹ́ta nínú ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ tó wáyé láàrin Barcelona àti Deportivo Ìgbà kẹrìndínlọ́gbọ̀n nìyí tí Messi yóò gbá àmìn ayò mẹ́ta wọle nínú ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ kan ṣoṣo fún ikọ̀ ẹgbẹ́ agbábọ́ọ̀lu tí o'ń sojú àti orílẹ́-èdè rẹ̀.
Ọgbẹni Akorede ni lori wi pe Naijiria yoo dara naa ni baba to bi oun lọmọ ku si, Naijiria yoo dara naa lo jẹ ki oun ko idile oun lọsi oke okun.
Nígbà tí ó di oṣù kẹjọ ti mo dé inú igbó yìí, ẹ̀fúùfù ńlá kan fẹ́ lọ́jọ́ kan báyìí; ẹ̀fúùfù náà pọ̀ púpọ̀, ojú àwọsánmọ̀ sí kún fún ọ̀pọ̀lọpọ̀ ìpàǹtí.
O ṣalaye siwaju sii pe, aṣiri aṣeyọri oun ni iwa irẹlẹ ti oun ni ati bi oun ṣe mu iṣẹ oun lokunkundun.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: ‘Ìjàmbá iná Àbẹ́là kò ló pa ìyá Jimoh Ibrahim’ ‘Ìjàmbá iná Àbẹ́là kò ló pa ìyá Jimoh Ibrahim’ Ẹ̀rò àwọn ènìyàn se ọ̀tọ̀ọ̀tọ̀ lórí lẹ́tà Ọbasanjo sí Buhari Iléẹjọ́ òṣìṣẹ́ tún dáwọ́ ìgbẹ́jọ́ Onnoghen dúró lọ́dọ̀ CCT Ọbasanjọ: Ó yẹ kí Amina Zakari kọ̀wé fipò sílẹ̀ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Atiku ní òun kò dènà kí ọ̀dọ́ kankan dupò ààrẹ ní Nàìjíríà Ọga agba ile isẹ panapana naa wa tọka lẹsẹẹsẹ, awọn ohun to n se okunfa ijamba ina ninu ile ati awọn ọna abayọ si ijamba ina ninu ile naa: Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fọ́nrán ohùn, Ọ̀gá àgbà ilé isẹ́ panápaná ní Eko ti pàrọwà sí àwọn ènìyàn láti má se mu sìgá nínú ilé.
" Bakan naa ni oṣiṣẹ nọọsi naa fidi rẹ mulẹ pe lootọ làwọn alaisan maa n nawọ ifẹ sáwọn Nọọsi sugbọn eyi ko sọ gbogbo Nọọsi di aṣẹwo.
O fi ẹnu rẹ ṣèlérí, o sì ti fi ọwọ́ ara rẹ mú ìlérí náà ṣẹ lónìí.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Twins Festival: Asọ ń pe asọ ránsẹ́ lára àwọn ìbejì lásìkò ọdún wọn 13 Ọ̀wàrà 2018 Ẹsẹ̀ kò gbèrò ní ìlú Igbo ọrà lásìkò ọdún ìbejì àgbáyé tí ìjọba ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́ sètò.
Èèyàn mẹ́jọ jónà ráúráú nínú ìjàmbá ọkọ̀ akérò tó ṣẹlẹ̀ ní mọ́rosẹ̀ Eko sí Ibadan Ọlọ́jọ́ Festival 2020:Ọ̀ọ̀ni ti Ilé Ifẹ̀ tí wọ ìléèdí ọlọjọ méje tí kò ní rí ẹnikẹ́ni sójú Ìjọba Kaduna kéde ọjọ́ mẹ́ta fún ìdárò Emir Zazzau, Buhari, Tinubu, Babangida náà ń ṣèdárò Wo àwọn báńkì tó wà lẹ́yìn àwọn olówó èlé bí MMM Bakan naa, oo nilo nọmba BVN rẹ.
Bawo ni ọrọ̀ Omar al-Bashir ṣe pọ to?
Èmi ati àwọn ọmọ tí OLUWA fún mi, a wà fún àmì ati ìyanu ní Israẹli láti ọ̀dọ̀ OLUWA àwọn ọmọ ogun, tí ń gbé orí òkè Sioni.
Lara awon ipinle ti won se atunse lori naa ni Oyo, Kwara, Niger, Sokoto ati awon miiran.
Lẹyin to pari ẹkọ, girama, o tẹsiwaju lọ ilẹ ẹkọ fasiti Oxford nibi to ti kawe gboye imọ nipa imọ iwa ẹda, oṣelu ati ọrọ aje, iyẹn Philosophy Politics and Economics.
O ni niṣe lo joko le oun ni ikùn, to si tun gbiyanju lati fun oun ni ọrun pa.
Ibo naa ti yoo waye ni awọn ijọba ibilẹ kan ni guusu ipinlẹ naa jẹ eleyi ti wọn yoo fi yan asoju tuntun fun ẹkun idibo Irepodun/Oke-Ero/Isin/Ekiti .
Mo ti fọ́ bàbá mi, Ọ̀gá Bello létí rí - Fẹmi Adebayọ̀ Toyin Abraham kìí bá èmi náà yọ̀, ni kò jẹ́ kí ń gbé e lárugẹ fún ayọ̀ ọmọ - Lizzy Anjorin Oríṣun àwòrán, Damola oltunji Àkọlé àwòrán, Araye kìí gbọ́ ariwo àwọ̀n tó bá dúró fún ọ̀pọ̀lọpọ̀ ọdún.
”Wọn óo tún sọ pé, “A gbé!
Nígbà tí a ronú síi, a bá ríi pé kìí ṣe ẹ̀sìn Islam ni, ẹ̀tan lásán ni.
Abike Dabiri-Erewa: Ìròyìn òfégè ní pé mò kò \Palliatives\""pamọ́ sí ilé mí"
    Ìgbà tí ọba dé sí ààrin ọjà, a o gbọ́ ariwo ní ilé mi, ìgbà tí a bá sì gbọ́ ariwo ni àwa náà yóò tó dìde.
Ọwọ́ òsì rẹ ìbá wà ní ìgbèrí mi,kí o sì fi ọwọ́ ọ̀tún rẹ fà mí mọ́ra!
"Kí ni ""Future tense"" lédè Yorùbá?"
Bakan naa lo ni ki a dẹkun sisọ ara wa si oko ẹru awọn oloṣelu nitori owo ti ko tan iṣoro wa.
Kinni o sọ ọrọ yii si ni, iṣọrọ nigbesi ni ileeṣẹ FIRS fi ọrọ naa ṣe.
Ṣe ẹda fọọmu naa ko si tẹ iwe pelebe to jẹri sí pe o kan sí ojú òpó naa.
Oludije mẹrin lo yoju sibi ipade naa ti won si dahun awọn ibeere orisirisi to fi mọ ibeere lori bi won yoo ti se se eto ijọba ti wọn ba de ori oye.
àwọn ará Afa gbẹ́ ère oriṣa Nibihasi ati Tataki, àwọn ará Sefafaimu sì ń sun ọmọ wọn ninu iná fún Adirameleki ati Anameleki, àwọn oriṣa wọn.
Gbadura sí OLUWA kí ó mú ejò wọnyi kúrò lọ́dọ̀ wa.
O ni kii ṣe obi nikan lo n tọ ọmọ lawujọ, iṣẹ gbogbo eniyan ni, nitorinaa gbogbo wa lo jẹbi.
Awon adari orilede  Afirika ti ni awon ko ni faramọ ifipagbajọba
laaye lati maa dibo lasiko eto idiibo nibikibi ti won ba wa niluu okeere.
O wi pe ati oun ati awọn osisẹ Ajọ INEC ni ijọba ibilẹ mẹtalelọgbọn to wa ni ipinlẹ naa, lo koju isoro ibanilorukọjẹ, ìjínigbé, àti ìdúnkookò mọ́ni lásìkò ìbò, ti wọn si fẹ rẹ salọ kuro lẹnu idibo naa.
Iyawo Aarẹ, Hajia Aisha Buhari, ti rọ awọn aya gomina ni Naijiria lati ṣe koriya fawọn obinrin, ki wọn si fọwọsowọpọ pẹlu awọon ọdọ atawọn obinrin ẹgbẹ wọn ki alaafia le jọba ni Naijiria.
Òṣèré tíátà, Kemi Afolabi dùbúlẹ̀ àìsàn ní ìlú Mecca Àkúntúnkú, ìgbà márùn ún rè é tí Shekau kú tí wọ́n ní kò kú mọ Mohammed Yusuf: Irú èèyàn wo ní olùdásílẹ̀ Boko Haram?
Ṣugbọn gẹ́gẹ́ bí ẹni tí ó pè yín ti jẹ́ mímọ́, bẹ́ẹ̀ ni kí ẹ̀yin náà jẹ́ mímọ́ ninu gbogbo ìwà yín.
Ẹ wa kọ ẹkọ pupọ nipa asa ati ede wa, ko maa baa parun.
Ṣé ẹ̀ṣẹ̀ ni mo ṣẹ̀ tí mo fi ara mi sí ipò ìrẹ̀lẹ̀, kí ẹ lè ní ipò gíga?
  A fẹ eto idibo eleyii ti yoo lọ ni irọwọrọsẹ lorilẹede Naijiria, ti ifẹ awọn eniyan lori ẹni ti wọn fẹ ko ṣoju wọn yoo si leke.
Obabinrin Dihya gbèjà àwọn eniyan Algeria lai nani pe obinrin ni oun lasiko ti awujọ ko tii maa foju alakikanju wo ọmọbinrin.
Ladodo, lasiko to n sapejuwe isẹlẹ yii bii eyi to ya ni lẹnu to si n ba ni ninujẹ, tun salaye pe marun ninu awọn afurasi ọhun ti ọwọ tẹ, ti n ka boroboro fun awọn ọlọpa nipa isẹlẹ naa, ti aayan si ti n lọ lati mu awọn afurasi yoku ti wọn ti na papa bora, to fi mọ baba ọmọ tuntun naa.
Stan Kroenke , ti o je eni ti osuwon re po julo ninu awon toro kan gbangban ninu iko ohun, gboriyin bantabanta fun Wenger fun ise takuntakun re ti o ti n se lati eyin wa, bee si ni o fi da awon ololufe iko naa loju lati ropo re pelu akonimoogba miran ti o kaju osuwon bii ti re.
Ìbú pèpéle tí kò sí ohunkohun lórí rẹ̀ jẹ́ igbọnwọ marun-un (mita 2½) yíká.
Àwọn ti iṣẹ́lẹ̀ ajálù náà kàn jùlọ ni àwọn mẹ́sàn nínú ìdílé kan ti gbogbo wọ́n kú ni àgbègbè Mapendo.
Arinze to jẹ ọkọ iyawo, koju Adekunle, ni ọrọ naa si di ariwo nla ni adugbo ti gbogbo wọn jọ n gbe.
Bí ó ti ń sọ̀rọ̀ lọ́wọ́ iranṣẹ mìíràn dé, ó ní, “Iná Ọlọrun wá láti ọ̀run, ó jó àwọn aguntan ati gbogbo darandaran patapata, èmi nìkan ni mo sá àsálà láti wá ròyìn fún ọ.
Muhammadu Buhari ti dibo aare  odun 2019
Kenanaya ni a yàn láti máa darí orin àwọn ọmọ Lefi, nítorí pé ó ní ìmọ̀ orin.
Mose bá dá OLUWA lóhùn pé, “OLUWA, àwọn eniyan wọnyi kò lè gun òkè Sinai wá, nítorí pé ìwọ náà ni o pàṣẹ pé kí á pààlà yí òkè náà po, kí á sì yà á sí mímọ́.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Odebiyi: ìgbà gbogbo ni Bàbá mi ń polówó iṣẹ́ mi fáráyé Alaga NUJ ni oun gbagbọ pe awọn ọna miran wa to yẹ ki ajọ NBC gbe lati fidi ofin wọn mulẹ ju ki wọn ṣe oun to tabuku gbogbo ẹgbẹ.
Èyí ni ìgbà àkọ́kọ tí Oshiomhole yóò sọ̀rọ̀ láti ìgbà ti gbogbo ǹkan ti n rú gùdùgùdù nínú ẹgbẹ òṣèlú APC, eyi ti wọ́n sì fi yọ Oshiomhole kúrò nípò gẹ́gẹ́ bi alága.
Jeṣua ati àwọn ọmọ rẹ̀ pẹlu àwọn ìbátan rẹ̀, ati Kadimieli pẹlu àwọn ọmọ rẹ̀, ati àwọn ọmọ Juda ń ṣe alabojuto àwọn tí wọn ń kọ́ ilé Ọlọrun pẹlu àwọn ọmọ Henadadi, ati àwọn Lefi pẹlu àwọn ọmọ wọn ati àwọn ìbátan wọn.
O ṣi ṣeeṣe ki wọn yanju ohun ti o'n mu ki Gomina Amosun ṣọ wi pe oun ko ni gbe lẹyin oludije ẹgbẹ'' Bi a ko ba gbagbe,Gomina Ibikunle Amosun fi saaju fi àtẹ̀jáde kan síta nínú ìpàdé tó ṣe pẹ̀lú àwọn adarí ẹgbẹ́ káàkiri ìjọba ìbílẹ̀ pe oun yoo fi ẹgbẹ oselu APC silẹ.
ṣugbọn inú Ọlọrun kò dùn sí Kaini, kò sì gba ẹbọ rẹ̀.
” Lẹ́yìn ìgbà tí wọn ti wádìí, wọ́n ní, “Gideoni ọmọ Joaṣi ni ó ṣe é.
"Oríṣun àwòrán, Screenshot ""Nkan to buru pupọ ni awọn to ji ọ̀pá àṣẹ gbe ṣe, nitori pe ko yẹ ki a maa fi awọn ọba wa wọlẹ."
“Mi o figba kan ni ero meji si awon omo orile-ede Naijiria lati saseyori ti atileyin ba wa fun won,” Aare kase oro re nile lati tenumo ipinnu ijoba apapo nipa mimu idagbasoke ba ere idaraya jake jado orile-ede Naijiria.
Ọ̀pọ̀ oúnjẹ lo le sàkóbá fún ara wa ti a kò bá ṣe aáyan rẹ̀ bó ti tọ àti bo ti yẹ.
Idaamu darandaran: Ganduje pe awọn darandaran si Kano
Lamidi Adedibu: Èyí ní àlàyé bí akọni olóṣèlú nílẹ̀ Ibadan ṣe sẹ̀ wá
    Ọ̀kánjúwàfẹ̀yìntì ní tirẹ̀ náà ń kọ́ kẹ́, bí o ti ń lọ ni òun náà bẹ̀rẹ̀ sisi rọnú bí òun ìbá ti jẹ́ olówó tó kí á wí pé òun nìkan ;òun rí owó yìí.
Adari eka to  n ri si oro to je mo ile okeere fun ajo  ECOWAS , ogbeni.
Gbogbo olukopa fun eto ẹkọ imọ ijinlẹ keji ni Russia gbọdọ ti gba iwe ẹri imọ ijinlẹ akọkọ ni Russia, ki wọn si fi si ori ayelujara pẹlu: a.
2m dọlà ni ìgbàkúgbà tó bá kọ ǹkan sórí Instagram rẹ̀
Irọ́ ni pé Shonekan ti re'bi àgbà á rè Itumó ọrọ Segregation ni ede Yoruba ni: Iyasọtọ, iyọkuro, iyapa yatọ si awọn to ku.
O gbé ère oriṣa kalẹ̀ sí ẹ̀yìn ìlẹ̀kùn ati ẹ̀yìn òpó ìlẹ̀kùn.
Àwọn ará Midiani lágbára ju àwọn ọmọ Israẹli lọ tóbẹ́ẹ̀ tí àwọn ọmọ Israẹli fi ṣe ibi tí wọn ń sápamọ́ sí lórí àwọn òkè, ninu ihò àpáta, ati ibi ààbò mìíràn ninu òkè.
Ohun ti ọpọ lero ni pe awọn ẹgbẹ agbabọọẹu yoo jiroro lori boya ki wọn pada bẹrẹ ni ọgbọn ọjọ oṣu kẹfa ọdun 2020 ṣugbọn ilana ti wọn yoo fi to idije naa ni wọn jiroro le lori.
Ó la àpáta, omi tú jáde,ó sì ṣàn ninu aṣálẹ̀ bí odò.
Ọ̀rọ̀ tí OLUWA bá Jeremaya sọ nìyí, nígbà tí Nebukadinesari, ọba Babiloni, ati gbogbo àwọn ọmọ ogun rẹ̀, ati gbogbo ìjọba ayé tí wọ́n wà lábẹ́ rẹ̀, ati gbogbo àwọn orílẹ̀-èdè gbógun ti Jerusalẹmu ati gbogbo àwọn ìlú Juda.
Lẹ́yìn ìgbà tí wọ́n padà wá láti ìsimi ìdajì àsìkò, ìkanran Man City dínkù díẹ̀, ṣùgbọ́n Bernarndo Silva gbá bọ́ọ̀lù s'áwọ̀n ní ẹ̀mejì kí Kevin de Bruyne ó tó gbá ẹlẹ́ẹ̀kẹẹ̀jọ s'áwọ̀n.
Kàkà bẹ́ẹ̀, o pada, o jẹ, o sì mu ní ibi tí òun ti pàṣẹ pé o kò gbọdọ̀ fi ẹnu kan nǹkankan.
Dárí ẹ̀ṣẹ̀ wa jì wá,nítorí àwa náà ń dáríjì gbogbo ẹni tí ó bá jẹ wá ní gbèsè.
Awọn ololufẹ rẹ ya bo oju opo Instagram rẹ ti wọn si n fi adura ati ikini ranṣẹ sii.
Oríṣun àwòrán, @CAF Àkọlé àwòrán, FIFA ni wọn ko fẹ magomago ni CAF lo n bi ofin ayeraye wọnyii Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Ṣugbọn, o ti ye mi bayii pe o ṣeeṣe ki n ri iranlọwọ ka ni mo sọrọ sita nigba naa.
    Nígbà tí ó ṣe ni mo rí Ayédèrú-ẹ̀dá tí ó sá jáde ni abẹ́ ìtàkùn tí ó sá pamọ́ sí, nítorí Ẹlẹ́gbára ju kùmọ̀ sí ibẹ̀, Ayédèrú-ẹ̀dá wá ṣebí ó rí òun ni.
Oko òkú rèé, níbití òkú ti ń jẹrà mọ́lẹ̀ fún àyẹ̀wò Kàyééfì, oyún inú nínú ilé ìgbọ̀nsẹ ọkọ̀ òfurufú NFF sadehun pẹlu Dennerby fun Falcons Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
-Olorì Aláàfin, Memunat Adeyemi Àjọ NCDC kéde èèyàn 242 míràn tó ni ààrùn Covid-19 lórílẹ̀-èdè Naijíríà Buhari pàṣẹ lílo àgbo tí orílẹ̀-èdè Madagascar ṣe fún coronavirus fún ìtọ́jú ọmọ Nàìjíríà Kókó ohun tó wà nínú àbọ̀ ìwádìí Orosanye, tó le gba iṣẹ́ lọ́wọ́ òṣìṣẹ́ Ni ọjọ Aje ni Gomina El-Rufai fi ọrọ yii sita loju opo twitter rẹ ni idahun si fidio kan eleyi ti gbajugbaja adẹrinpoṣonu ni, Tẹju babayface fi sita loju opo twitter nibi to ti n fi ọrọ wa El-Rufai lẹnu wo lọdun 2010 ti o si ni oun ni akọwe ẹgbẹ awọn eeyan kukuru lorilẹede Naijiria.
Ìsọníṣókí Aráàlú yabo ọ̀pọ̀ ibùdó tíjọba kó èròjà oúnjẹ́ Covid-19 sí Buhari paṣẹ fáwọn àgbófinró láti fòpin sí ìwọ́de UN, Clinton, Biden, Ooni, Obasanjo ati Soyinka korò ojú síwà ìpànìyàn Àwọn sọja yibọn pa ọpọ ọdọ to n se iwọde ni Lekki Èrò ọ̀nà gbẹ̀bí aláboyún ìbejì, tìyá, tọmọ jáde láyé Adájọ́ rán bàbá ọlọ́mọ méjì tó fi ipá bá ọmọ ọdún mẹ́rin lò pọ̀ lẹ́wọ̀n gbére Àjọ DSS tú gbogbo pátá mi wò pé wọ́n ń wa ọmọ- Bisola aya Woli Alfa Wo fídíò bí àwọn jàndùkú ṣe yabò àwọn olùwọ́de #ENDSARS ní Alausa l'Eko Ìjàmbá ọkọ̀ akérò àti tírélà pa èèyàn mẹ́rin lọ́nà mọ́rosẹ̀ Ore sí Benin Jíjábọ̀ ohun tí ń lọ lọ́wọ́ Nípasẹ̀ Yetunde Olugbenga àti Yemisi Oyedepo Gbogbo àkókò tí a kọ jẹ́ ti UK Tí a fiṣọwọ́ ní 12:0012:00 Wo ìdí tí Oluwo fi ń wọ ìbòmú lẹ́yìn tó ní covid-19 ò lè wọ ìlú Iwo láéláé Oba AbdulRasheed Akanbi ni oun n wọ ibomu lati jẹ awokọṣe rere fawọn ọmọ Naijiria nitori ifẹ ti oun ni si wọn.
Dafidi wá mọ̀ pé, OLUWA ti fi ìdí òun múlẹ̀, gẹ́gẹ́ bí ọba Israẹli, ó sì ti gbé ìjọba òun ga, nítorí Israẹli, àwọn eniyan rẹ̀.
Nígbà tí ó di ọ̀sán ọjọ́ kejì tí a kúrò lọ́dọ̀ ọkùnrin náà ní nǹkan déédéé  agogo mẹ́ta ni a dé etí ìl’;u àwọn ejò níbi tí Òjòlá-ìbínú tí ń ṣe ọba wọn.
Awọn alaṣẹ sọ pe obinrin naa ge e afurasi naa jẹ, lẹyin to ti kọkọ fi ipa ni ibalopọ pẹlu rẹ, to tun wa a sọ pe ti ko ba fun oun ni 'blow job', oun ko ni i kuro ni ile rẹ.
“Ẹnikẹ́ni tí ó bá ṣépè lé baba tabi ìyá rẹ̀, pípa ni kí wọ́n pa á.
Ẹ̀yin ará, nígbà tí mo dé ọ̀dọ̀ yín, n kò wá fi ọ̀rọ̀ dídùn tabi ọgbọ́n eniyan kéde àṣírí Ọlọrun fun yín.
Akẹkọọ onipele kẹta ileewe giga gbogboniṣe Poly ipinlẹ Ọṣun ni Iree kan, Aminu Sheu, ni iroyin sọ pe o ku lẹyin to pari idanwo aṣewọ ipele aṣekagba ẹkọ rẹ ni ọjọ Ẹti nilu Iree nipinlẹ Ọṣun.
" Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Inu idaamu ni awọn obi wa, lati igba ti wọn ti gbọ pe wọn ji awọn ọmọ wọn gbe.
Gbogbo ẹ̀ka ìjọba pátá ní ọ̀rọ̀ naa kàn.
Nítorí náà, ẹ jẹ́ kí á tọ̀ ọ́ lọ lẹ́yìn ibùdó, kí á gba irú ẹ̀gàn tí ó gbà.
Ẹwẹ, D'Tigress ti sọ Argentina dero ile lẹyin iya ti wọn fi jẹwọn.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Sunday Igboho: Fulani kò leè dúró, táa bá lo ohun ta jogún lọ́dọ̀ àwọ̀n bàbá wa O ni ni kete tawọn ọmọ onilẹ foju kan oun ati Bako ni wọn fẹsẹ fẹ, eyi to mu kawọn doola ofo ẹmi ati dukia ti ko ba waye latipasẹ isẹlẹ yii.
 Awọn ọrẹ mi nileewe gan maa n mọọmọ wa nu bata bi bata wọn gan ko tilẹ dọti tori ki wn le fun mi lowo."
Omowe Bello  tun tesiwaju pe egbe naa ti n ba awon egbe miiran fowosowopo lati  maa se ohun iwuri nipa lilowo ninu ifigagbaga lori eko isiro,Adari egbe naa wa tepele mo oro re nipa sise ipolongo fun gbogbo omo orile ede Naijiria lati mo ipa pataki eko naa.
Ṣugbọn n óo pe àwọn iranṣẹ mi ní orúkọ mìíràn.
Afi ti ẹka yìí ko ba ni si mọ.
Àwọn ọlọ́pàá a sì máa gbe igi dínà tàbí kí wọ́n o kan ọgbà dí àwọn ọ̀nà kékèké kan tó bá gba àrin'lé ẹlòmíràn kọjá.
Amọṣa, ẹpa ko boro mọ fun un nitori pe ileewosan ọhun lo dakẹ si lẹyin wakati diẹ.
DSS ti fi El-Zakzaky sílẹ̀ láti lọ sí India- Femi Falana Àwọn agbébọn jí alága ẹgbẹ́ òsèlú PDP gbé ní Kogi Samuel Okwaraji: Ó pé ọgbọ̀n ọdún tí lónìí ti akọni àgbábọ̀ọ̀lù papo dà Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Kílò fa èdè àìyedè láàrin ìjọba àti àwọn ọmọ lẹ́yìn El-Zakzaky?
Owo to to le ni bilionu metadinlogota owo naira ni won san fun awon agbasese lori awon ise akanse ti won se lorisiirisi nilu Abuja ati agbegbe re.
 Iweala  so ninu oro re pe, “Anfaani n la lo je lati tun ba Bob sise po.
Ogunlọ́gọ̀ eniyan, pataki jùlọ ọpọlọpọ ninu àwọn tí wọn wá láti Efuraimu, Manase, Isakari ati Sebuluni, kò tíì ya ara wọn sí mímọ́, sibẹ wọ́n jẹ àsè Àjọ Ìrékọjá, ṣugbọn kì í ṣe ní ọ̀nà ẹ̀tọ́.
Itọju nile iwosan ni kete too ba ti kẹfin pe o fẹ ni arun yii ṣe pataki pupọ ni ayika rẹ.
osise ajo INEC se sọ fun won pe ko yinki(ink) ti won yoo maa lo lati tọ si ọwọ
Bí ọmọkunrin kan bá bá OLUWA jẹ́jẹ̀ẹ́ tabi tí ó ṣe ìlérí láti yẹra fún ohunkohun, kò gbọdọ̀ yẹ ọ̀rọ̀ rẹ̀, bí ó ti wí ni ó gbọdọ̀ ṣe.
Ẹni ti ọrọ naa soju rẹ, amọ ti ko fẹ ka darukọ rẹ sọ fun awọn akọrọyin ni ile Aarẹ wi pe, Aarẹ Buhari ti fi asẹ si pe, o di ẹyin idibo ki wọn to le fi iwe ipẹjo ransẹ si Sẹnetọ Adeleke.
Awọn alaṣẹ ti wọn darukọ ni aarẹ ile aṣofin agba,aare Buhari ati igbakeji rẹ tó fi mọ olori ile aṣojuṣofin.
tí kò ṣẹ ẹnikẹ́ni; tí Kì í gba ohun ìdúró lọ́wọ́ onígbèsè, tí kì í fi ipá jalè, ṣugbọn tí ń fún ẹni tí ebi ń pa ní oúnjẹ, tí sì ń da aṣọ bo ẹni tí ó wà ní ìhòòhò, 
Ki lẹ nilo lati forukọ silẹ?
Ètò yìí jẹ́ nkan ayọ̀ àti ìwúrí fún mi gidi gẹ́gẹ́ bí ọmọ Oòduà.
Wọn yoo gbe igbesẹ to yẹ nipa iwadii awọn ti ọlọpaa mu pe wọn lọwọ si wiwo apa kan ileesẹ orileẹde Naijiria ni Ghana.
O ni awọn ni lati wa ọna ara ọtọ lati ṣe iṣẹ iranṣẹ wọn paapaa fun awọn to ba nilo rẹ lọna ara ọtọ.
Ọkunrin naa ti orukọ rẹ n jẹ Yusuf Atanda, ni wọn fẹsun kan pe o ṣi oju opo ayederu Facebook fun awọn ojiṣẹ Ọlọrun mẹtẹẹta yii lati maa fi gba owo lọwọ awọn eeyan.
Igbakeji aarẹ ni wọn gba pe yoo pada si Naijiria lọjọbọ to m bọ.
Iyansipo Lawal Daura gẹgẹ bi ọga agba ajọ ọtẹlẹmuyẹ DSS lọdun 2015, mu awuyewuye dani.
Nǹkan mẹ́wàá tó yẹ kí o mọ̀ nipa George Floyd tí ọlọ́pàá fún lọ́rùn pa rèé Oríṣun àwòrán, Getty Images Lọjọ Iṣẹgun tii ṣe ọjọ kẹsan oṣu kẹfa ọdun 2020 ni George Floyd ti ọlọpaa ilẹ Amẹrika kan, Derek Chauvin fi ẹsẹ fun lọrun pa yoo wọ kaa ilẹ lọ.
Àtìwọ àtàwọn eniyan tí wọ́n wà pẹlu rẹ, ẹ óo pa ara yín; ohun tí ò ń ṣe yìí ti pọ̀ jù fún ọ, o kò lè dá a ṣe.
Nítorí ohun gbogbo tí Ọlọrun dá ni ó dára.
Ọrẹ tirẹ̀ ni: àwo fadaka kan tí ìwọ̀n rẹ̀ jẹ́ aadoje (130) ṣekeli, abọ́ fadaka kan tí ìwọ̀n rẹ̀ jẹ́ aadọrin (70) ṣekeli.
Ẹ̀gbọ́n rẹ̀ obinrin dúró ní òkèèrè, ó ń wo ohun tí yóo ṣẹlẹ̀ sí i.
Ṣugbọn ọrọ oloogbe David ti oṣẹṣẹ ku yii ju bẹẹ lọ.
Àdùnní ni orúkọ ìyá rẹ̀ òun nìkan ni ó sì bí fún bàbá rẹ̀.
Ajọ Amnesty international ni awọn yoo gbe abọ iwadi awọn kalẹ niwaju ijọba orilẹede Naijiria pẹlu ipe lati mu ki wọn tubọ tẹnpẹlẹ mọ ifidimulẹ awọn ofin gbogbo to de ẹka epo rọbi.
Celestine Egbunuche: Òun àti ọmọkùnrin rẹ̀ ti lo ọdún 18 l‘ẹ́wọ̀n, kó tó rí ìdáǹdè
Èyí ni ìbẹ̀rẹ̀ àwọn iṣẹ́ ìyanu tí Jesu ṣe ní Kana ti Galili.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Arakunrin Fulani ni aigbede ara eni ni orisun ija pelu agbe Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
“Èyí ni òfin ẹbọ alaafia, tí eniyan lè rú sí OLUWA.
Ni ọ̀gágun bá pàṣẹ pé kí wọ́n mú Paulu wọ àgọ́ ọmọ-ogun lọ.
Ibadan: Òkìtì iyanrìn wó pa Wale àti Adeyemi lágbègbè Ologuneru
Constituency office: Kí ni pàtàkì ọ́fíìsì agbègbè fún aṣòfin?
won to bẹrẹ si n lo lori omi lati bi ọsẹ kan.
Lọjọ Satide, ọjọ kejidinlogun, oṣu Kẹrin, ọdun 2020, ni ọpọlọpọ awọn olugbe ilu Akurẹ ati awọn agbegbe to sunmọ deede gbọ iro ariwo nla kan laarin oru.
Mose bọ́ aṣọ alufaa tí ó wà lọ́rùn Aaroni, ó gbé e wọ Eleasari.
dojuko eto aabo to mẹhẹ ni ekun  Gusu yii
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Èmi gan máa ń béèrè lọ́wọ́ ara mi pé ta ni Wole Soyinka gangan' Sinai: Sinai ni wọn n pe orúkọ ti awọn ajijagbara n jẹ lorilẹ-ede Egypt.
Aisha wa gbadura fun alaafia ati itẹsiwaju fun awọn orilẹede lagbaye.
Ko fi mọ ọ bẹẹ, Fayose tun naka abuku si agba oloselu PDP nii, Bode George, ati gomina ipinlẹ Oyo, Seyi Makinde pe awọn ni wọn de janduku to si fila lori oun nibi eto ipolongo idibo PDP l'Akure.
Kí ó tó rin ìrìnàjò lọ sí Canada ní ọmọ ọdún mọ́kànlá , Chemi Lhamo jẹ́ ẹni ogúnléndé tí kò rí ibùgbé kan gbé ní India.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Kí ni àmì ohùn 'Aguntaṣọọlo'?
Èmi mọ̀ ọ́n, nítorí láti ọ̀dọ̀ rẹ̀ ni mo ti wá, òun ni ó sì rán mi níṣẹ́.
Nígbà tí Esau gbọ́ ohun tí baba rẹ̀ sọ, ó fi igbe ta, ó sọkún kíkorò, ó wí pé, “Baba mi, súre fún èmi náà.
Itumọ yii si ni ọpọ fi n wo ohun ti Ruga tumọ si.
Ṣùgbọ́n kò gbọdọ̀ ju oṣù mẹ́sàn- án lọ tí baba rẹ̀ ki á tó bí i
Jẹ́ kí á fi àwọn onígbàgbọ́ ṣe àpẹẹrẹ.
láti fi wúrà ati fadaka ati idẹ ṣe oríṣìíríṣìí iṣẹ́ ọnà, 
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Mo kàn máa ń lọ́ ayẹyẹ kiri torí ijó láì ṣe pé wọ́n pe mí ló sọ mí di DJ olórin Fuji nìkan' Ti omi ko ba to lagọ ara, o ṣeeṣe ki eniyan maa dubulẹ aisan ni gbogbo igba nitori ko si nkan ti yoo ba awọn kokoro to n fa aisan ja.
Àwọn ọmọ Lefi tí wọn ń gbé Jerusalẹmu nìwọ̀nyí: Ṣemaaya ọmọ Haṣihubu, ọmọ Asirikamu, ọmọ Haṣabaya, lára àwọn ọmọ Merari; 
A si ma n pe ara wa ni ẹgbẹ ooṣa.
Oríṣun àwòrán, Screenshot Gomina ipinlẹ Eko wa rawọ ẹbẹ si awọn obi lati ba awọn ọmọ wọn sọrọ pe, ki wọn ma ṣe darapọ mọ awọn janduku to n ba dukia ijọba jẹ.
Mose wí fún wọn pé, “Kí ẹnikẹ́ni má ṣe ṣẹ́ ohunkohun kù di òwúrọ̀ ọjọ́ keji.
Nítorí náà ni ìṣubú rẹ̀ fi pọ̀, tí kò sì fi ní olùtùnú.
F Odunjo kọ ni Isẹ ni oogun isẹ, Tọju iwa rẹ ọrẹ mi ati akojọpọ ewi aladun, Ọmọ bẹẹrẹ, osi bẹẹrẹ, Owo Apekanuko, eyi ti gbogbo wọn jẹ ewi to gbe jade lọdun 1961 Lẹyin naa lo kọ awọn Alawiye Yoruba akọkọ fun awọn ọmọde nile ẹkọ alakọbẹrẹ lọdun 1943, eyi to gbajugbaja pupọ di oni Ọdun 1964 ni J.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Muhammadu Buhari: Iléẹjọ́ tó ga jùlọ bẹ̀rẹ̀ ìgbẹ́jọ́ ẹ̀sùn ayédèrú sabuké Buhari 2 Owewe 2019 Oríṣun àwòrán, Twitter/Presidency Àkọlé àwòrán, Muhammadu Buhari: Iléẹjọ́ tó ga jùlọ bẹ̀rẹ̀ ìgbẹ́jọ́ ẹ̀sùn ayédèrú sabuké Buhari Lẹyin ti wọn ti lọ ilẹ ẹjọ giga tẹlẹ, ẹjọ Buhari n bẹrẹ nile ẹjọ giga julọ ni Naijiria.
Amosa wahala ati ija ogun to si n waye ni agbegbe naa si n jẹ idena fun
Iwadii ti ile-isẹ iroyin Punch gbe jade sọ wi pe, ipinlẹ Eko, Osun, Ogun ati Ondo wa lara awọn ipinlẹ mẹsan, ti ko ni i pẹ ma a lo ẹrọ igbalode yii.
Láti Obotu wọ́n lọ sí Òkè Abarimu ní agbègbè Moabu.
Àbẹ́wò ọlọ́jọ́ mẹ́ta Trump sí UK nínú àwòrán Ganduje ń bèèrè bí Emir Sanusi ṣe se owó ìlú mọ́kumọ̀ku Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí kan sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
7 152 Erekusu Cayman Island 2 3.
Ijọba Babangida ko na Biliọnu kan naira tan to fi pari rẹ lẹyin ti awọn kan yọwọ ninu rẹ.
Awọn osisẹ ileesẹ ọrọ ayika nipinlẹ Eko naa ya bo ibudo idalẹsi to wa ni Olusosun ladugbo Ọjọta nipinlẹ Eko, lati wa mu asẹ ijọba sẹ pe ki wọn ti ibudo atọkọse to wa nibudo idalẹsi naa pa.
Akinwunmi Ambọde lati lo anfani ti wọn fun un lati wa ṣalaye ara rẹ lori
gomina naa lo fenuko lati jẹ ki ifẹ ipinle naa bori ju ifẹ ọkan won, ni eyi ti yoo
Ọlọ́run kò ní í fi irú bẹ́ẹ̀ sí sàkání yín mọ́.
Nítorí ìwọ, Ọlọrun, ti gbọ́ ẹ̀jẹ́ tí mo jẹ́;o ti fún mi ní ogún tí o pèsè fún àwọn tí ó bẹ̀rù orúkọ rẹ.
Àmọ́ ó kúkú ti mọ́n wọn lára ní ilẹ̀ yí.
"Oríṣun àwòrán, Twitter/seyi makinde ""A lee dena pipadanu ọmọ Naijiria bi a ba pe fun iranwọ""."
 Ẹbí yìí tóbi púpọ ̀ , lẹ ́ ẹ ̀ kọ ̀ ọ ̀ kan , wọ ́ n máa ń pín wọn sí àwọn mọlẹ ́ bí méjì , phasianinae , àti perdicinae .
Ẹẹmẹta ni ọkọ̀ ojú omi tí mo wọ̀ rì.
Ajọ UEFA ti fawọn alaṣẹ idije naa atawọn idije liigi bọọlu mii kaakiri ilẹ Yuropu di ọjọ kẹẹdọgbọn oṣu karun un lati ṣeto igba ti wọn fẹ bẹrẹ saa bọọlu yii pada.
Lẹyin ipẹtu saawọ ati idunadura naa, ijọba le awọn oṣiṣẹ ijọba ibilẹ to n ṣe akoso abule kọọkan kuro, to fi mọ awọn Bàálẹ́.
Ninu atẹjade kan ti alukoro ileeṣẹ ọlọpaa, DCP Frank Uba fi sita lọjọ Aiku, ileeṣẹ ọlọpaa awọn yoo ṣe agbeyẹwo fidio naa boya ayederu fidio ni.
 ìfi ojú sí ọ ̀ nà , híhàn , ìwò , ìrí si ìrètí ohun rere .
" Àbá àpérò 2014 CONFAB lojútùú sí àtúnṣe ìwé òfin Nàìjíríà- Afenifere sáwọn sẹ́nẹ́tọ̀ Kí ló mú àwọn adarí Nàìjíríà tako ra wọn lórí ikú ọmọ alága ẹgbẹ́ Afenifere?
Èro tó tò kalẹ̀ pé àwọn fẹ́ gùn ún ò l’óǹkà.
Kíní àwọn ohun tí ètò ẹkọ Nàìjíríà nílò Gẹ́gẹ́ bí ọgbẹ́ni Akintola ṣe sọ, ó rọ ààrẹ Muhammadu Buhari láti wá ojútu sí ìyanṣẹ́lódi ti ASUU gùnlé lọ́wọ́lọ́wọ́ báyìí nítori pé tí àwọn ọmọ náà bá parí ilé ẹkọ́ gíga náà ní wọn yóò wọ.
Agbẹjọro agba orileede naa ṣalaye pe awọn ọdaran ti wọn n ṣẹwọn lori ẹsun pẹẹpẹẹpẹ ati awọn obinrin wọn ni ọmọ lọwọ yoo wa lara awọn ti yoo gba itusilẹ.
Eyi ni ogbontarigi olorin takasufe ọmọ Naijiria, DBanj nigba to n ṣere ni ile iwe giga Brixton Academy ni London lọjọ Aiku.
Chioma ti wa nile iwosan, ohun ti a gbo lati ẹnu awon dokita ati osise ile
Lẹ́yìn tí wọ́n ti wo ilẹ̀ náà fún ogoji ọjọ́, àwọn amí náà pada.
 Lara awon to wa nibi eto ikabo
Máà se àyẹ̀wò ìṣàkóso Fayose - Fayẹmi Kia lawọn eeyan tun ti wa aworan miran to safihan Minisita feto irina Naijiria Rotimi Amaechi nibi ti oun naa ti n ba Felix Obuah bawọ.
dena  isoro airowo san, ijoba apapọ ati ijọba
Oríṣun àwòrán, Rochas Okorocha Àkọlé àwòrán, Ibo gomina ipinlẹ Imo Emeka Ihedioha oludije ẹgbẹ PDP lo jawe olubori ninu ibo gomina ipinlẹ Imo.
Ninu lẹta naa ti wọn kọ si Igbakeji Aarẹ ẹka ibanisọrọ ni CNN, Ọgbẹni Jonathan Hawkins lo sọ pe: A kọ lẹta yii lati fihan pe ẹbu ni iwadii ti ileeṣẹ amohunmaworan CNN sọ pe oun ṣe, to si fi sita fun aye ri lọjọ kejidinlogun, oṣu Kọkanla, ọdun 2020."
5m owó oyè tó gbà lọ́wọ́ òkú padà, àwọn ará ilé rẹ̀ ń bèèrè - Olúbàdàn Oyè Ibadan kò sí fún títà - Otun Olubadan, Lekan Balogun Owó àwọn aṣòfin kò pọ̀jù, iṣẹ́ kàbàtì tí wọn ń ṣe ju owó oṣù wọn lọ - Buhari Kò síbi tó dàbí ilé, tìlù-tìfọn ni wọ́n fi kí Anthony Joshua tó bẹ ìlú rẹ̀, Ṣágámù wò káàbọ̀ Àbòsí ló wà níbẹ̀ tí ìpínlẹ̀ Eko ò bá ṣe Amotekun- Bode George Kọmiṣọna feto ilera wa ṣalaye fawọn akọroyin lasiko to n ṣe ipade pẹlu wọn ni Ikẹja pe, awọn eeyan to ti ni ajọṣepọ pẹlu eeyan ọhun ni wọn ti fi si ahamọ fun itọju ati ayẹwo, lati rii pe wọn ko tii ko aisan naa.
 pada si Moshood Abiola, eni ti o jawe
kan gbongbon nile-ise olopaa pe mi, mo si salaye awon idojuko to n koju eto
Koda, ni alẹ ọjọ ti idibo ku ọ̀la, Arabinrin Tikhanovskaya, sọ pe awọn ọlọpaa mu olori ikọ ipolongo òun.
Nípa èyí tí o wí, kékeré ni èyí nì, ṣùgbọ́n jẹ́ ki a fi gbogbo ìyókù dọ̀la, nígbà tí ilẹ̀ bá mọ́ n ó mú àwọn ǹnka tí mo ffi ń kọ̀wé, n o sì kọ ohun tí o ba ń fẹ́ sílẹ̀ fún ọ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Iriwisi Lydia,oludokowo lori MMM Sogúndogójì ko le tan Akọsẹmọsẹ kan nipa eto idokowo, Rotimi Obende ni pẹlu bi nnkan ti se ri, ko daju wi pẹ awọn ọmọ orileede Naijiria yoo dẹyin lẹyin ilana sogúndogójì.
Àwọn ìròyìn mìíràn tí ẹ lè nífẹ̀ẹ́ sí: Ọmọ ìyá méjì gé orí ọmọ ọdún mẹ́wàá l'Eko Ta ló ji òṣìṣẹ́ kánsù gbé l'Ekiti?
Esau bá ní, “Jẹ́ kí n fi àwọn bíi mélòó kan sílẹ̀ pẹlu rẹ ninu àwọn ọkunrin tí wọ́n wà pẹlu mi.
O tun so pe “Eto ijọba tiwa-n-tiwa ki i se ere igbafẹ , o jẹ ilana, ti ilekun kan ba ti, opolopo omiran ni yoo tun si i, ti eniyan  ba dẹ oju silẹ , yoo rimu.
'Tattoo’ ara mi kò tí ì pọ̀ tó, mà á sì se si’ Ayefẹlẹ bá BBC sọ̀rọ̀ lórí ilé orin rẹ̀ tí Ajimọbí ń tún kọ́ Àmàlà ṣekúpa ènìyàn mẹ́rin ní Ilorin Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ayàwòrán Obama: Ọ̀pọ̀ ìgbà ni èmi àti ìyá mi pa èbi mọ́nú kí n tó jẹ́ èèyàn Wayi o, ẹgbẹ oselu APC ni ipinlẹ Kwara ti kede pe, ko si ootọ kankan ninu iroyin kan to gbode wi pe, ọmọ ẹgbẹ awọn kan n ṣe fakinfa pẹlu awọn ọ̀dọ́ nílùú Ekan meje ní ìjọba ìbílẹ̀ Oke-Ero, lasiko ti idibo atundi n waye nibẹ lọjọ Satide.
Ọgbọ́n ati òye tí n óo fún ọ yóo tayọ ti gbogbo àwọn aṣiwaju rẹ, ati ti àwọn tí ń bọ̀ lẹ́yìn rẹ.
Ilu Benin ni wọn gba wọle, ko to o di pe awọn ọmọ ogun da wọn duro ni ilu Ọrẹ lọjọ kọkanlelogun, oṣu Kẹjọ.
Ninu ọkàn mi, mo kórìíra àwọn àjọ̀dún oṣù tuntun yín, ati àwọn àjọ̀dún pataki yín.
kò sí irú orin tí mozart kò lè kọ .
Esi ayẹwo ti ajọ naa fi sita ni Ọjọbọ lati awọn ipinlẹ mọkanlelogun fihan pe: Lagos-113 Kaduna-49 FCT-33 Plateau-24 Kano-16 Edo-15 Ogun-14 Delta-13 Osun-10 Oyo-8 Ekiti-6 Bayelsa-6 Akwa Ibom-5 Borno-4 Enugu-4 Ebonyi-3 Rivers-2 Bauchi-1 Nasarawa-1 Gombe-1 Niger-1 Ẹ wo apapọ iye ti ipinlẹ kọọkan ni: Awọn to ni aarun Covid-19 ni Naijiria pe ẹgbẹrun mejidinlaadọta ati mẹrindinlọgọfa lọjọ kẹtala, oṣu Kẹjọ.
Awọn igbesẹ wo ni ipinlẹ pinlẹ Kwara ti gbé?
Won ni afi ki wọn fi ipo silẹ nitori awọn eto ti wọn fi kalẹ sinu iwe adehun ti wọn fi gba iṣẹ.
"Genevieve woye pe ""ẹni to ni Ibalopọ pẹlu rẹ le ma nifẹ rẹ, bakan naa ẹni to ni ifẹ rẹ denu le ma ni Ibalopọ pẹlu rẹ."
Translation: One who talks much is likely to make mistakes
Ijede Lagos Boat Mishap: Mi ò rí irí ìṣẹ̀lẹ̀ yìí rí láyé mi!
Lara ohun to n fa ija ni ọna ti wọn yoo gba lati di inu adagun odo naa ẹru si n ba orilẹ-ede Egypt pe akanṣe iṣẹ yii lee faaye gba ki Ethiopia maa dari odo yii to gun ju nilẹ Adulawọ.
Nitootọ ni awọn ibeji maa n jọ ara wọn nile aye ṣugbọn ti awọn wooli Olorun meji yii yatọ.
'Ileeṣẹ ọlọpaa ko mọ nkan to n ṣe' Agbẹjọro ọkan lara awọn ọdọmọkunrin naa, Ṣẹgun Awosanya, ti awọn eniyan tun mọ si Segalink, sọ fun BBC pe, ọrọ ọhun ko ye awọn ọlọpaa gan nitori sẹ ni awọn agbẹjọro wọn n jasi ẹni ti ẹjọ naa yoo ja mọ lọwọ ninu wọn.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ijamba baalu Ethiopia Bakan naa ni isin iranti isin iranti fawọn to ku waye loni niluu Nairobi nibi t'ọpọ eeyan ti ṣadura fawọn to doloogbe.
Shehu ni aarẹ ti gba imọran to daju nipa ohun ti ofin ilẹ wa sọ lori awọn isẹlẹ to n waye ninu ẹgbẹ oselu APC, to si fara mọ pe ẹyin Victor Giadom ni ofin gbe si.
”Dafidi bá tún bèèrè pé, “Ìlú wo ni kí n lọ?
Ninu alaye ti ajọ to n ṣakoso eto idanimọ ni Naijiria, NIMC ṣe, wọn ni ki awọn ọmọ Naijiria ṣa ti tẹ nọmba *346# lori foonu wọn lati ri nọmba yii.
Amọṣa, Ọọni ile ifẹ, Adeyẹye Ogunwusi ni ko sohun to jọ eyi ati pe awọn onijibiti kan ni wọn n lo orukọ oun lati lu awọn obinrin ni jibiti.
 Òrò-ìse ni ó máa ń so ohun tí apor se nínú gbólóhùn .
orile ede Naijiria lati pese eto alaafia ,nile agbaye ko kere rara.
"OPC, Miyetti Allah, agbófinró yóò wà nínú ìgbìmọ̀ aláàbò nílẹ̀ Yorùbá Orí mi wú pé àwọn àgbà ìjòyè kọ́wọ̀rín-ìn tẹ̀lé Olúbàdàn, ìjà parí - Makinde ""A kò ní ra ọjà South Africa mọ́, á gbẹ̀san oró tí wọn ń dá wa - Ọmọ Nàíjíríà fárígá"" A fẹ́ gba ₦1bn lọ́wọ́ ìjọba Eko pé ó dẹ́yẹ sí wa - 123 Ọlọ́kadà Jigawa O wa gba awọn ọdọ bii tiẹ niyanju lati mase kawọ gbera maa reti owo lasiko ti nkan ba safẹrẹ diẹ, nitori o yẹ ki wọn maa wa nkan se lati ri owo fi mu afojusun wọn sẹ."
Akọ̀wé gbogboògbò fún CNDD-FDD, Evariste Ndayishimiye ṣàlàyé ìdí tí orúkọ náà ṣe di ti Nkurunziza:
Yóo fi wọ́n ẹni tí ó fọwọ́ kan egungun òkú tabi tí ó fọwọ́ kan ẹni tí wọ́n pa, tabi ẹni tí ó kú fúnrarẹ̀, tabi ibojì òkú.
Osun State: Gómìnà Oyetola wọ́gilé ìrìnàjò àwọn alága sí UAE
Ernest Doku to jẹ akọṣẹmọṣẹ USwitch ni odiwọn iye ẹrọ alagbeka ti ti awọn akẹkọọ yii n muwa sile iwe kọja bẹẹ.
Baba rẹ, ọjọgbọn Theophilus Ogunlesi ni onimọ iṣegun akọkọ to gba oye ọjọgbọn nilẹ Naijiria.
Rutu bá dáhùn, ó ní, “O ṣàánú mi gan-an ni, oluwa mi, nítorí pé o ti tù mí ninu, o sì ti fi sùúrù bá èmi iranṣẹbinrin rẹ sọ̀rọ̀, bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé n kì í ṣe ọ̀kan ninu àwọn iranṣẹbinrin rẹ.
the Nigerians in Diaspora Commission) paapaa
Ó wá ọ̀nà títí kò rí.
Marcus Rashford ti ikọ Manchester United lo koko gba bọọlu sinu awọn, ki saa kini ifẹsẹwọnsẹ naa.
Lana ni iroyin naa jade pe wọn ji wọn gbe ti Ọ̀gá àgbá ọlọ́pàá pàṣẹ pé kí wọn ṣàwárí àwọn pásítọ̀ tí wọn jí gbé.
(Nítorí pé irú nǹkan báwọ̀nyí ni àwọn alaigbagbọ ayé yìí ń dààmú kiri sí.
Bí ẹ bá ń lo òótọ́-inú, Olódùmarè yóò dúró tì yín bí òkè ńlá, ẹni tí ó bá sì kọlù yín yóò rí ìpalára.
Nígbà tí ó tú èdìdì karun-un, ní abẹ́ pẹpẹ ìrúbọ, mo rí ọkàn àwọn tí a ti pa nítorí ọ̀rọ̀ Ọlọrun ati nítorí ẹ̀rí tí wọ́n jẹ́.
Bẹẹ ba gbagbe, ọjọ Abamẹta ni ọmọ aarẹ naa se igbeyawo pẹlu ọkọ rẹ nilu Abuja.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ile asofin agba si ọmọ Naijiria: Ẹ sọra fun owo bitcoin 30 Sẹ́rẹ́ 2018 Oríṣun àwòrán, Reuters Àkọlé àwòrán, Awọn asofin agba ilẹ Naijria nfẹ ipolongo lori ewu to nbẹ ninu idokoowo owo ori afẹfẹ Bitcoin Ileegbimọ asofin agba lorilẹede Naijiria ti ke gbajare sita wipe ki awọn araalu sọra fun owo ori afẹfẹ, Bitcoin eleyi ti wọn sọ pe o ti n di tọrọ fọnkale bayii.
Iṣẹlẹ yii waye nigba ti ogiri wo pa wọn nile ijọsin ti wọn ti n kopa ninu ijọsin ọjọ ọjọbọ mimọ rere lasiko ọdun ajinde.
Ni aago 0707 GMT,  ni okoowo di  14.
Babatunde Fowler, tii se alaga fun ajọ FIRS lo kede ọrọ yii nibi ipade apero kan to waye nilu Abuja.
Ninu idahun Ujah, o ni pe ''gbogbo Naijiria lo yẹ ki ọrọ yi ka laya, kii ṣe NMA nikan.
Ninu amọran wọn miran ni pe, ki awọn eeyan yii gbiyanju lati mọ ẹni ti wọn ba ṣalabapade daadaa nipa ibeere ati itọpinpin to peregede.
Kí ni ó mú ọ ṣe iyè meji?
Àwọn míràn tilẹ̀ sọ pé, ijọba lo ọ̀rọ̀ àwọn ọdọ́mọkurìn Kankara láti gbayì kúnra wọn ní, nítori tí kò bá rí bẹ́ẹ̀, kí ló dé ti wọ́n ko ti gba àwọn ọmọ Chibok àti Dapchi tókù wálé.
"O ni, ""gbogbo ẹni to ri taje ṣe lo yẹ ki o ṣe awokọṣe ajọ ẹleyinju aanu yi, ki aye le dẹrun fun gbogbo eyan ti ara n ni."
PasitoTunde Bakare: Aago Nàìjíríà ti kún àkúnwọ́sílẹ̀
naa, a wa rọ gbogbo omo ipinle Rivers , paapaa julọ awon oludibo  lati gba eto alaafia laaye titi ti a o fi
Ṣaaju eyi ni ẹgbẹ naa kopa ninu ipolongo ti Ajọ Aṣamojuto Aabo Awujọ ni Ipinlẹ Eko’ (Lagos State Environmental Protection Agency (LASEPA)’ ṣe lati fi saami Ayajọ Aaabo Awujọ Lagbaaye ti ọdun 2018, eyi ti akori rẹ da lori ‘Fifopin Si Ewu Idọti ohun Eelo onike si Awujọ’ lati fi rọ awọn ara ilu ọna to yẹ lati maa ṣamulo awọn idọti bayii ati lati gba awọn onileeṣẹ to n pese awọn ohun eelo onike yii ni imọran lori awọn ọna miiran ti wọn yoo fi maa pese awọn eelo oriṣi miiran, ti yoo le mu adinku ba ohun eelo onike yii.
" Gígé tí a ń gé ní ọjọ́ náà kìí ṣe fún amóhùmáwòrán, o gbóná gan ni lọ́jọ́ náà, mó lọ mi o le pada lọ́jọ́ ti a ń wí yìí, títí ti ètò náà fi pari.
Sún mọ́ mi, rà mí pada,kí o sì tú mi sílẹ̀ nítorí àwọn ọ̀tá mi!
Òṣèré tíátà, Kemi Afolabi dùbúlẹ̀ àìsàn ní ìlú Mecca Jesu orí ayélujára kan rèé tó ń ṣèlérí iṣẹ́ ìyanu l‘Afirika Tinubu gbéra lọ odidi Mecca láti lọ ṣàbòsí - PDP Èèkànlú ní ìpínlẹ̀ Ogun lọ kí Buhari l‘Abuja torí ẹ̀yẹ tó fi dá Abiọla lọ́lá Awọn meji lara awọn eniyan to ku ọhun, ọkunrin kan ati obinrin kan wa lati ipinlẹ Katsina.
ṣugbọn ìdí pataki tí òun fi jẹ́ kí wọ́n wà láàyè ni láti fi agbára òun hàn Farao, kí wọ́n lè máa ròyìn orúkọ òun OLUWA káàkiri gbogbo ayé.
Oríṣun àwòrán, Policeofficial Àkọlé àwòrán, Ilé iṣẹ́ ọlọ́pàá ti dárúkọ àwọn SARS to pa Kolade Abiyamọ ìyá olóògbé tí SARS yìnbón pá fàwọ́n lé kóòtù Olorun Obi Kolade Johnson ti SARS yìnbọn pa ni ìpínlẹ̀ Eko ti ké gbàjarè pé kijọba ṣe ohun tó yẹ́ fún SARS tó gbẹ̀mí ọmọ wọn.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Àpótí ìkẹ́rùsí jálu ọkọ̀ méjì lórí l'Eko Ṣẹ̀ s’ófin ìrìnà l‘Eko, ko fi ẹ̀wọ̀n ọdún mẹ́ta jura - Ìjọba Eko Buhari ní Nàìjíríà ti bẹ̀rẹ̀ ìgbẹ́sẹ̀ ìmúṣẹ àdéhùn Paris 2020 Má ṣe fi ọkọ̀ rẹ gbé àgùnbánirọ̀ lẹ́yìn aago mẹ́fà ìrọ̀lẹ́- FRSC Sikiru Ayinde bẹrẹ iṣẹ orin kikọ gẹgẹ bii Aji wéré tabi a ji sààrì laisko aawẹ Ramadan awọn ẹlẹsin musulumi.
O kẹkọ gboye meji ni fasiti Eko.
Ajínigbé kọlu òṣìṣẹ́ FRSC, èèyàn méjì kú, mẹ́rin farapa, mẹ́wàá di àwátì Ojú àwọn tọ́wọ́ ti tẹ̀ lára àwọn tó jí 'tíá rọ̀bà ọ̀kadà', fíriìjì, ẹ̀rọ ata kó nílée Sẹ́nétọ̀ Teslim Folarin rèé Iléeṣẹ́ ọlọ́pàá ṣàfihàn ojú àwọn afurasí tó se ẹran ara ọlọ́pàá jẹ ní Ibadan Kílódé tí Ọọni Ife, Oba Ogunwusi kò fi gbọdọ̀ rí ọmọ rẹ̀ tuntun ti Olorì Naomi bí títí di bíi ẹ̀yìn oṣù mẹ́fà?
Awọn obinrin ti wọn ti hu iru iwa yii si ṣalaye pe igbesẹ ayẹwo gbogbo ara eeyan yii maa n jẹ ki o dabi ẹni pe wọn kii ṣe eniyan, abi eniyan ti wọn ko bikita fun ni awujọ.
Koda Okoye sọ pe ẹni to ba ni ẹri to daju, oun ṣetan lati fun ẹni naa lẹbun miliọnu mẹwaa naira.
Ìgbà tí ó di ọjọ́ kejì mo kó ẹrù mi mo kọjú sí ojú ọ̀nà, mo n lọ.
Nítorí pé ọfà rẹ ti wọ̀ mí lára,ọwọ́ rẹ sì ti bà mí.
OLUWA wí fún oluwa mi, ọba, pé,“Jókòó sí apá ọ̀tún mi,títí tí n óo fi sọ àwọn ọ̀tá rẹdi àpótí ìtìsẹ̀ rẹ.
”Imam  Shehik Mayaleke benu atẹ lu bi awọn olowo
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Moscow Plane Crash: Ìjàmbá ọkọ̀ bàálu pa arìnrìǹàjò 41 6 Èbibi 2019 Oríṣun àwòrán, AFP Àkọlé àwòrán, Ọkọ baalu gbina ni papakọ ofurufu Moscow Eniyan mọkanlelogoji lo ti re salakeji lẹyin ti ọkọ baalu kan ṣaa dede gbina lẹ́yìn to gunlẹ pajawiri ni papakọ ofurufu Sheremetyevo ní ilẹ̀ Moscow.
Ijọba ipinlẹ Oyo fikun wi pe awọn ọkọ naa yoo mu igbeyagbadun ba awọn eniyan, ti ilọsiwaju yoo fi ba wọn.
Ọjọ kẹrinla, oṣu keji, ọdun 1942 ni wọn bi Bloomberg ni Brighton, Massachusetts, lorilẹ-ede Amẹrika.
bi awọn kan ṣe n gbosuba fun, lawọn miran n bẹnu atẹ lu Koda, Bashir Ahmad to jẹ oluranlọwọ aarẹ Buhari wa lara awọn to sọ oko ọrọ si Ezekwesili.
Oyebode, ti o je akoroyin tele ri, O ti sise gege bi adari eka iroyin sile ise gomina ni saa akoko gomina Fayemi, bee si ni O tun sise gege bi olugbani-nimoran pataki si gomina lori eto iroyin fun gomina Fayemi lasiko re gege bi minisita.
Awon osise eleto ilera lo so oro ohun di mimo, bee si ni, won fi mule pe, ifehonuhan ohun waye lojo kannaa ti Isreal pe àádọ́rin odun.
Abike Dabiri Erewa to jẹ ọga agba NIDCOM sọ pe kete ti wọn ba ti gba iwe ẹri ibi ati awọn iwe mii fun ọmọ naa,oun ati iya rẹ yoo pada wa sile.
Oladimeji Shotunde, to gba apapọ maaki to ga julọ nile ẹkọ fasiti ipinlẹ Eko, LASU ni akẹkọọ akọkọ ti yoo gba iru maaki to ga bẹẹ ninu itan ileẹkọ naa.
Bi o ti le je pe iko naa ko
Ogbeni Ogehena ti o soju ajo to n mojuto oro ayika ati imo ijinle lorile-ede Naijiria, (Nigerian Meteorological Agency), (NIMET ) ti so asotele pe, o seese ki ojo ro lopo yanturu jakejado orile-ede yii, eleyi ti o si le sokunfa ikolu omiyale.
Buhari ti ni oun kaaanu lori isẹlẹ to waye paapaa julo ni ile-ise awon ọlọpaa to
Pẹlu owo osu rẹ, yoo gba ọ ni ọdun 86, ati osu mẹjọ lati gba iye owo ti sẹnatọ kan n gba lọdọọdun.
Ó tún jáde lọ ní agogo mẹsan-an òwúrọ̀, ó rí àwọn mìíràn tí wọn dúró ní ọjà láìṣe nǹkankan.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Covid-19 vaccine: Abẹ́rẹ́ tí àjẹsára Pfizer ṣe yóò di lílò láti ọ̀sẹ̀ tó ń bọ̀ ní UK 2 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Oríṣun àwòrán, @thehill Orilẹ-ede United Kingdom ni orilẹ-ede akọkọ lagbaaye ti yoo buwọlu lilo abẹrẹ ti ileeṣẹ apoogun Pfizer/BioNTech ṣe fun iwosan coronavirus.
Orúkọ OLUWA àwọn ọmọ ogun ni wọ́n fi ń pe àpótí ẹ̀rí náà, ìtẹ́ rẹ̀ sì wà lórí àwọn Kerubu tí ó wà lókè àpótí náà.
Minisita f'eto ilera wipe ni awọn ipinlẹ ni iṣẹ lati ṣe lori iba lassa
Àwọn olórí orílẹ̀ èdè afipá ṣe ìjọba máa ń ṣe ìtakùrọ̀sọ pẹ̀lú àwọn ilé ìgbéròyìn jáde ní èèkàn l'ọ́dún tàbí kí ó kéré jù bẹ́ẹ̀ lọ.
O ni Kọmiṣọnna ileeṣẹ ọlọpaa ipinlẹ Oyo fẹ fi to awọn eeyan leti pe ẹgbẹrun lọna ẹẹdẹgbẹta naira ni ileeṣẹ naa yoo fun ẹni to ba le e ran an lọwọ lati ri afurasi naa mu."
ti isakoso ijoba re mu wa si ipari.
Díẹ̀ nínú àwọn àǹfàní tọ́n hàn sí mi nìwọ̀nyí:
 o budo si ilaorun etiokun awon ipinle aparapo , isupoile to sunmo julo ni cape hatteras , north carolina , bi si iwoorun-ariwaiwoorun .
#EndSARS: Ìbọn ba Kolade Johnson níbi tó tí ń wo bọ́ọ̀lù
Ibùgbé rẹ lẹ́wà pupọ, OLUWA àwọn ọmọ ogun,
" Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ǹjẹ́ bákan náà ní ǹkan rí ní gbogbo àgbáyé?
Nítorí mo fẹ́ kí ẹ mọ bí mo ti ń ṣe akitiyan tó nítorí yín ati nítorí àwọn tí ó wà ní Laodikia ati nítorí àwọn tí kò mọ̀ mí sójú.
Nígbà tí o bá ń lọ, wọn yóo máa tọ́ ọ,bí o bá sùn, wọn yóo máa ṣọ́ ọ,bí o bá jí, wọn yóo máa bá ọ sọ̀rọ̀.
Viemens Bamfo: Ọmọ ọdún méjìlá tó gbèlé kẹ́kọ̀ọ́ dì àpéwò bó tí ṣé wọ ilé ẹ́kọ́ fásítì Ghana
Ajax vs Chelsea: VAR ṣ'ègbè lẹ́yìn Chelsea f'ogun ẹ̀yín ja Ajax mọ́lé
Ọpọlọpọ àwọn eniyan wá láti agbègbè ìlú Jerusalẹmu, wọ́n ń gbé àwọn aláìsàn ati àwọn tí ẹ̀mí burúkú ń dà láàmú wá; a sì mú gbogbo wọn lára dá.
Agbegbe Farm Arena ni Atlanta ni Georgia lo ti fagbahan Kelvin nibi idije UFC 236.
Wọn óo wá mọ̀ pé èmi ni OLUWA!
N óo dẹ́rùbà wọ́n; níwájú àwọn ọ̀tá wọn, ati níwájú àwọn tí ń wá ọ̀nà ati pa wọ́n.
Àjọ JAMB kéde ìlànà ìgbà ni wọlé tuntun fún àwọn ilé ẹ̀kọ́ gíga Mi ò gbọdọ̀ má ní ìyá, kí n tún má gbádùn nílé ọkọ ni mo ṣe fẹ́ Alaafin- Olori Aanu Belarus tó ń gbóná lọ́wọ́ torí ààrẹ tó ti lo ọdún 25 lórí oyè, nkan márùn ún tí o kò mọ̀ rèé Ọwọ́ ọlọ́pàá ìpínlẹ̀ Kebbi tẹ bàbá àti ìyàwó rẹ̀ méjì fún pé wọn so ọmọ pọ̀ mọ́ ewúrẹ́ fún ọdún méjì Ọwọ́ ọlọ́pàá ìpínlẹ̀ Kebbi tẹ bàbá àti ìyàwó rẹ̀ méjì fún pé wọn so ọmọ pọ̀ mọ́ ewúrẹ́ fún ọdún méjì Àmọ̀tẹ́kùn gbéra!
Èdè kan ni eléyìí lára àwọn èdè tí a ń pè ní abkhazo-adyghian tí àwọn wọ ̀ nyí tún jẹ ́ ọmọ ẹgbẹ ́ fún àkójọpọ ̀ èdè tí a ń pè ní caucasian ( kọ ̀ kọ ́ síànù ) .
Ikú Ààrẹ KurunmiBí ó tilẹ̀ jẹ́ pé kò sí ẹni tó mọ ikú tó pa Ààrẹ Kurunmi, akọni, jagun-jagun alagbara àti Ààrẹ Ọ̀nà Kakanfo nígbà náà, àmọ́ ìròyìn kan ni, ó gbé majele jẹ n.
“Gomina ọlọ́lá jùlọ, Fẹliksi, èmi Kilaudiu Lisia ki yín.
Lara wọn gbagbọ pe Buhari ti dagba kọja ẹni to yẹ ko wa lori aga iṣakoso.
Dalung so oro ohun di mimo lasiko to n ba osise ile-ise akoroyin VON soro, Rafat Salami  ni papako ofurufu Nnamdi Azikiwe niluu Abuja.
Ẹkunrẹrẹ data Sun atẹ wa silẹ tabi oke lati ri ẹkunrẹrẹ akọsilẹ *Iye awọn to tọwọ aisan ku ni isọri eeyan ẹgbẹrun lọna ọgọrun Gbe e yẹwo: Àgbáyé Orilẹede Afrika Ariwa Amẹrika Apa Latin Amẹrika ati Caribbean Ilẹ Asia Ilẹ Yuroopu Agbegbe Middle East Erekusu Oceania Iye to ti ku Iye awọn to ku %* Apapọ awọn iṣẹlẹ arun Akọtun arun yii 0 10 100 1000 10000 ** Orilẹede Amẹrika 387741 118.
Oríṣun àwòrán, @MubailuG O ni ebi n pa awọn ọmọ Naijiria, ati pe ijọba ko faye ilọsiwaju silẹ fawọn ọmọ Naijiria, o sọ pe asiko ti to fawọn ọmọ Naijiria lati gbara wọn silẹ loko ẹru ati airiṣẹṣe.
Àwọn aláṣẹ iléese ọlọ́pàá ṣe agbekale iko SWAT eyi to tumọ si Special Weapons and Tactics Unit ni ọjọ kẹtala, oṣu kẹwaa, ọdun 2020 lati fi rọpo ikọ SARS.
Ọkan lara igba ti wọn dẹyẹ sii rẹ ni ita gbangba naa ni asiko kan ti o lọ si ibi ipadeeto ọrọ aje agbaye, World Economic Forum, (WEF) ni Davos nigba ti o fi ẹsun iroyin ofege kan awọn oniroyin.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ẹ̀mí sùn níbi ìkọlù Shiite àti ọlọ́pàá Omo ọdun mẹtalelogun naa to n sin ilẹ baba rẹ pẹlu ileeṣẹ Channels pada dagbere faye lataari ọgbẹ naa.
Ṣugbọn Absalomu dáhùn pé, “Ẹ pe Huṣai wá, kí á gbọ́ ohun tí òun náà yóo sọ.
Àwọn ọmọ Manase ni: ìdílé Makiri, Makiri bí Gileadi.
Àpérò àwọn àjẹ́ kò gbọdọ̀ wáyé - Àjọ PFN Ṣé ẹ mọ̀ pé Ẹ̀wà Sóyà, Ẹja Puffer, àti ewébẹ̀ yìí lè ṣekú pa'ni kíákíá?
''Ọrẹbinrin mi jẹ́ mí ní ₦20,000 ní mò fí dáná sún àwọn ẹbí rẹ'' Duro Ladipọ, ìlúmọ̀ọ́ká òṣèré tíátà àti ọmọ àlúfà tí kò gbàgbé àṣà ìbílẹ̀ Ẹwẹ, oluranlọwọ pataki fun aarẹ naa fi ikede itusilẹ rẹ sita loju opo Twitter rẹ.
A maa wa wọn kan, ti ọwọ wa yoo si tẹ wọn, wọn si gbọdọ finmu ko ata ofin pẹlu, ti ẹlẹsẹ wọn ko si ni lọ laijiya.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù 2019 Elections: Ìpàdé ìtagbangba BBC Yorùba ń ṣẹlẹ̀ ní gbọ̀ngàn fásitì ìlú Ilorin 3 Sẹ́rẹ́ 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 10 Sẹ́rẹ́ 2019 Àkọlé àwòrán, Ipade itagbangba Nibayii ti eto idibo gbogbo gboo n kanlẹkun gbọn-gbọn ni orilẹ-ede Naijiria, oniruuru aayan ni ileesẹ BBC Yoruba ti n ṣe lati rii daju pe awọn araalu ni anfaani lati yan aarẹ, awọn gomina ati awọn aṣofin to pegede, fi gbọọrọ jẹka.
Ọba wí fún un pé, “Bá mi kálọ sí Jerusalẹmu, n óo sì tọ́jú rẹ dáradára.
Ọwọ́ tẹ Julian Assange lẹ́yìn ọdún méje Awọn ologun da ibọn bolẹ lati fi fopin si iwọde ti awọn eniyan Sudan n ṣe yii.
Gbogbo àwọn tí wọ́n lè fi fadaka ati idẹ tọrẹ fún OLUWA ni wọ́n mú wọn wá, bẹ́ẹ̀ ni gbogbo àwọn tí wọ́n ní igi akasia, tí ó wúlò náà mú wọn wá pẹlu.
Eyi lo mu BBC kan si Mallam Aaron Musa, to jẹ ọga agba adari ọkan lara awọn banki olokowo Naijiria, iyẹn Guarantee Trust Bank (GTB) lori koko yii.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ọjọ́ ìbí bàbá mi ni aàrùn ọkàn ṣekúpa màmá mi lójijì- Davido Ìjọba Kwara kéde ọjọ iwọlé àwọn akẹkọọ lẹyìn ìséde Covid 19!
Ogun gbóná gidigidi ní ọjọ́ náà.
Amọṣa, ọga ọlọpaa, Ẹlkana ko sọ ni pato awo iroyin to lu si wọn lọwọ naa.
Ṣugbọn bí aboyún náà bá kú tabi bí ó bá farapa, kí wọ́n pa ẹni tí ó ṣe é léṣe náà.
Ṣugbọn ẹ ní àṣà kan, pé kí n dá ẹnìkan sílẹ̀ fun yín ní àkókò Àjọ̀dún Ìrékọjá.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù African Drum Festival 2019: Ẹ wo àwòrán tó làmìlaaka níbi Àjọ̀dún Ìlù Ọdún 2019!
Olorun wo gbogbo won san “Mo mọ pe ijoba ipinle Borno ,
Ẹ pàtẹ́wọ́, gbogbo ẹ̀yin orílẹ̀-èdè;ẹ kọ orin ayọ̀, ẹ hó sí Ọlọrun.
Bí a bá jọ bá Jesu kú, a ní igbagbọ pé a óo jọ bá Jesu yè.
Ojú àwọn tọ́wọ́ ti tẹ̀ lára àwọn tó jí 'tíá rọ̀bà ọ̀kadà', fíriìjì, ẹ̀rọ ata kó nílée Sẹ́nétọ̀ Teslim Folarin rèé 'Ó ku ọ̀la kí Isiaka ṣe 'Freedom' ní àṣìta ìbọn bà á ní Ogbomọshọ ' Mo ṣèlérí láti ṣe ju ohun tí mo ti ṣe lọ fún ẹbí àwọn tó kú torí EndSARS - Seyi Makinde Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí 2 sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
Nítorí ìrètí wa pé àwọn òkú yóo jí dìde ni wọ́n ṣe mú mi wá dáhùn ẹjọ́.
Ohùn tó yẹ ní mímọ nípa òfin ojú pópó Gbèsè Nàìjíríà yóò di $50b tí wọ́n bá tún yáwó- Shehu Sani Aàrẹ Trump kọ̀ láti jẹ Tòlótòló ìsìn ìdúpẹ́ 2019 nílé, ó gba Afghanista lọ!
Ṣugbọn ṣebi ti ko ba nidi, obinrin kii jẹ kumolu.
Ó bẹ̀rẹ̀ eré Tíátà rẹ̀ nínú eré 'Ìsẹ̀ṣe Làgbà' sùgbọ́n eré tó ti bẹ̀rẹ̀ sí ní di mọ̀lúmọ̀ká ni 'Ìwàkiwà'.
Sugbọ̀n ọpọ èèyàn k'ọti ikùn sí àṣẹ yi.
Naijiria gbọdọ kẹyin si irẹpọ pẹlu South Africa Igbakeji Aarẹ orilẹede Naijiria ki kesi awọn adari lorilẹede South-Africa pẹlu ibanujẹ ọkan lati dẹkun ipaniyan nitori ẹya to n lọ lọwọ lorilẹede South Africa.
Ikú Aráàlú 51, ọlọ́pàá 11, Sọ́jà 7 tó kú lásìkò ìwọ́de EndSARS dùn mí - Buhari Oríṣun àwòrán, @MBuhari Aarẹ Muhammadu Buhari ti fidi rẹ mulẹ pe, ẹmi eeyan mọkandinlọgọrin lo sọnu nitori rogbodiyan to waye ninu iwọde EndSARS kaakiri Naijiria.
 pínpín wọn lò lè ṣe okunfa ewu àisàn hcv .
De Bruyne gba àmì ẹ̀yẹ Premier League mọ́ Henderson lọ́wọ́ Ìjọ́ mí ní Italy ni mo fi ń ṣèrànwọ́ fáwọn aṣẹ́wó ọmọ Nàíjíríà tó há - Taribo West Ààrẹ orílẹ̀èdè Mali Boubacar Keita kọ̀wé fipò sílẹ̀ Àwọn òṣèré tíátà Yorùbá kọjú ìjà síra wọn lórí ìdárò akẹẹgbẹ́ wọn tó kú Koeman gbabọọlu fun ikọ Barcelona laarin ọdun 1989 si 1995, o si gba ami ẹyẹ La Liga mẹrin ati ife ẹyẹ kan ni Yuropu.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, UNICEF ni awọn ọmọ tuntun ti a maa bi ni Naijiria a tó ìdá meje ninu ọgọrun un gbogbo ikoko ti a maa bi lagbaye Aṣoju UNICEF ni o le ni ẹgbẹrun lọna irinwo awọn ikoko ọmọ Naijiria lo ni awọn alaboyun n bi ku lọdọọdun ni Naijiria.
Ènìyàn 296 ló kó àrùn Coronavirus ní Nàìjíríà ní Ọjọ́ Ìṣẹ́gun Wò ó bí Alaafin àti aya àkọ́fẹ́ rẹ̀, Olorì Abibat ṣe pàdé ní èwe Coronavirus ti fa ọ̀wọ́ngógó oúnjẹ ní ìpínlẹ̀ Eko, Kano, Rivers àti Abuja- NBS Àwọn èrò yarí lórí sísan owó àyẹwò covid-19 bí bàálù ilẹ̀ òkèèrè ti ba s'Abuja lẹyìn oṣù márùn ún Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Mayowa Omoniyi: Kò sí orin Obey, Sunny Ade abí tàkasúfèé tí ń kò le ta gìtá sí Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí BBNaija 2020: Terry Waya ní torí ìfẹ́ tí Erica ní sọ́mọ òun ló fi ní ọ̀pọ̀ ìṣòro9 Owewe 2020 Fídíò, Akomolede ati Aṣa lori BBC: Mọ̀ si nípa oríṣìí ẹ̀ka ìsọ̀rí ọ̀rọ̀ àti ìwúlò wọn8 Owewe 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Elisha Abbo ṣàlàyé ìdí tó fi lu obìnrin fún BBC Ilé iṣẹ́ ọlọ́pàá ti bẹ̀rẹ̀ ìwádìí sí ọ̀rọ̀ Sẹ́nétọ̀ Abbo Ilé ẹjọ́ sún ẹjọ́ Sẹ́nétọ̀ Abbo síwájú pẹ̀lú béèlì mílíọ̀nù márùn-ún Èrò àwọn ọmọ Naijiria ṣọ̀tọ̀ọ̀tọ̀ lórí Tinubu àti Abbo Lori ẹsun lilu eeyan lọna aitọ pẹlu aridaju ni wọn fi gbe sẹnetọ Elisha lọ siwaju ile ẹjọ.
Katsina kidnap: Ìyá àti ọmọ ọdún mẹ́ta gba òmìnira lọ́wọ́ ajínigbé lẹ́yìn tí wọ́n san ₦1.
Ilé ìgbìmọ̀ Aṣòfin Nàìjíríà kó igbá wọlé l'Abuja nítorí coronavirus Wo bí àwọn ará Ibadan ṣe ń ṣe lásìkò Coronavirus yìí 'Ẹ dárí ẹ̀ṣẹ̀ mi jìnmí, àmọ́ èmi nìkan kọ́ ló ṣẹ̀,' Ajimobi bẹ ọmọ ẹgbẹ́ APC l'Oyo Oyo APC Crisis: Gómìnà Oyo tẹ́lẹ̀, Ajimobi tọrọ àforíjì lọ́wọ́ àwọn ọmọ ẹgbẹ́ APC l'Oyo Abiola Ajimobi ni ''a kii mọọ rin, k'ori o ma mi,'' o ni oun gba pe oun ṣe awọn aṣiṣe kan ṣugbọn oun tọrọ aforiji lọwọ gbogbo ọmọ ẹgbẹ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Yoruba-Hausa clash: Ọlọ́pàá mú èèyàn márùn ún lórí ìjà tó bẹ́ sílẹ̀ láàrin Hausa àti Yorùbá l'Eko 19 Ògún 2019 Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Àwọn ọ̀dọ́ ẹ̀yà Hausa kan àtàwọn ọmọ ẹgbẹ́ òkùnkùn 'Awawa boys' da ìgboro Eko rú Ileeṣẹ ọlọpaa ipinlẹ Eko ti mu eeyan marun un lori wahala nla to bẹ silẹ laarin awọn Hausa ati Yoruba lọja Ile-epo lọjọ Aiku.
Ṣugbọn angẹli OLUWA kan pàṣẹ fún wolii Elija, ará Tiṣibe pé, “Lọ pàdé àwọn oníṣẹ́ ọba Samaria, kí o sì bèèrè lọ́wọ́ wọn pé, ‘Ṣé nítorí pé kò sí Ọlọrun ní Israẹli ni ẹ fi ń lọ wádìí nǹkan lọ́dọ̀ Baalisebubu, oriṣa Ekironi?
Ǹjẹ́ ẹ mọ àwọn olórí Nàìjíríà dada
Ẹnikẹ́ni tí kò bá gba ọ̀rọ̀ mi, tí yóo máa sọ ní orúkọ mi, èmi fúnra mi ni n óo jẹ olúwarẹ̀ níyà.
Ẹ má bẹ̀rù rárá, ẹ má sì ṣe jẹ́ kí àyà fò yín; nítorí pé, OLUWA Ọlọrun yín ń ba yín lọ.
Ọmọkùnrin kan sin Baba rẹ̀ láàyè torì pé ó gbàgbọ́ pé oṣó ni!
Pẹlu bi eto idibo apapọ se ku osu diẹ, ohun ti o han gbangba ni wi pe awọn alasẹ ijọba ko ni fẹ iforigbari pẹlu awọn ẹgbẹ osisẹ .
Gege bi alakoso iko to n soju Cameroon ninu idije naa, ogbeni Victor Agbor Nso, se so lasiko to n ba awon akoroyin CRTV soro lojo Isegun(Tuesday), Nso so pe, ondije ninu irin gbigbe, Olivier Matam, oluja Ndzie Tchoyi ati Simplice Fotsala ni won ye kan figagbaga lojo Isegun(Tuesday), sugbon ti won ko ri won.
 O ni gbogbo awọn ẹlẹwọn atawọn oṣiṣẹ ọlọpaa ikọ kogberegbe SARS to muu ni wọn ti bẹrẹ si ni mojuto lati mọ boya wọn ti ti ara rẹ ko arun naa."
wipe, ojoBo(Thursday) ni aare Buhari teko leti lo si sorile-ede Saudi Arabia
"O da wa loju pe Oloye Gani Adams kaato lati se ojuse Aarẹ Ọna Kakanfo la se sugba rẹ lati jẹ oye naa, ti yoo si se aseye, ti alakan n se epo, nitori ilẹ Yoruba ko ni faaye gba kawọn ajoji gba ilẹ wa mọ wa lọwọ.
Bakan naa ni gomina sọ pe ijọba ti n ṣiṣẹ lori ki awọn ileewe girama, ati alakọbẹrẹ naa le wọle pada, to ba ṣe e ṣe lati ọjọ kọkanlelogun, oṣu Kẹsan-an, ọdun 2020.
Ṣugbọn OLUWA yóo gba gbogbo ohun ìní Tire, yóo kó gbogbo ọrọ̀ rẹ̀ dà sinu òkun, iná yóo sì jó o ní àjórun.
n beere fun iranwo yin, lori eto idibo to n bọ yii, ki o waye ni irọwọ ati
Coronavirus: Ǹjẹ́ àwọn dókítà tó ń tọ́jú eyín ń ṣisẹ́ lásìkò pàjáwìrì?
 battambang , ilu titobijulo ni apaiwoorun kambodia , ggbajumo fun ogbin iresi re , sihanoukville , ilu leba odo ni ebute alakoko ati ibi igbadun eti odo .
 ogbón , ìmò , àti òye tí olódùmarè fi fún ifá ló fún ifá ní ipò ńlá láàrin àwon ìbọ ní ile yorùbá .
Gomina Akeredolu ṣalaye pe gbogbo eto lo ti to bayii lati gbe fọọmu naa sita.
Akeredolu, tó ò bá fa àkóso Ondo lé mi lọ́wọ́ láàrin ọjọ́ 21, o tàpá sófin - Igbákejì gómìnà Ọ̀pọ̀ ìgbà ní Hushpuppi àtàwọn èèkàn PDP ti ya fọ́tò ní Dubai, EFCC ẹ wádìí wọn - APC ń lọgun Irọ́ ni o, Ebenezer Obey ò kú!
Ọ̀pọ̀lọpọ̀ òkú ẹyẹ igún ré bọ́ lọ́jà Eke-Ihe Mo mọ̀ọ́mọ̀ dá €37,000 ti mo rí he padà ni -Ọmọ ogun Bashir Ìlú ò rẹ́rìn ín rárá, Alaafin Adeyemi III fárígá fún Buhari nínú lẹ́tà tuntun Bi o tilẹ jẹ pe sẹnetọ naa ti tọrọ aforiji fun iwa rẹ, awọn ọmọ Naijiria ni afi ki wọn fi jofin.
Awọn naa ni Ọgbẹni Ọlawale Mọgaji, Ọgbẹni Balogun Afọlabi, Arabinrin Ajọkẹ Riskat ati Ọgbẹni Bode Tawak, ti wọn jẹ ọmọ ẹgbẹ igbimọ naa tẹlẹ.
Aare orile ede Naijiria Muhammadu Buhari yoo yoju si aare orile ede Amerika Donald Trump nile aare White House lonii yii to je ojo Aje .
Ọkan gboogi ni Baba Fasanmi ninu ẹgbẹ Afẹnifẹre ki wọn to yapa - Odumakin Bakan naa, ẹgbẹ ọmọ Yoruba, Afẹnifẹre ti kẹdun ọkan gboogi lara wọn, Baba Ayo Fasanmi to papoda ni ẹni ọdun merinlelaadọrun.
Aláàfin pín oúnjẹ́ fárá Ọ̀yọ́ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Kí ni Yorùbá ń pe ọmọ tí wọ́n bí lẹ́yìn Àlàbá?
Ìṣọ̀rí Amotekun táa pè ní 'Irúnmọlẹ̀' ní yóò máa gun ọ̀kadà kiri láti pèsè ààbò - Àjọ Dawn Olori ajọ to n se akoso ikọ alaabo Amotekun fun ẹkun iwọ oorun guusu Naijiria, ti wọn n pe ni DAWN Commission ti salaye pe, kii se pe wọn gbẹsẹle isọwọsisẹ ikọ Amotekun lẹyin ti wọn sefilọlẹ rẹ tan, lo se lọ jai diẹ fawọn araalu lati kofiri rẹ nita gbangba.
Ilé ẹjọ́ kòmítẹlọ́rùn yá lórí ìbò gómìnà Oṣun- PDP Kíni ìlànà tí o dé yíyọ adájọ ilé ẹjọ kánkan ní Nàìjíríà?
’ Èyí yóo kó ìparun bá gbogbo yín, ati àwọn tí wọn ń ṣe ibi ati àwọn tí wọn ń ṣe rere.
Eko, Ondo, Ekiti, ati Oyo .
Aṣoju ẹṣọ aabo oju popo ni agbegbe naa, Arabinrin Uche Chukwurah fi idi ọrọ mulẹ pe ni agbegbe Idi-Apẹ ni rogbodiyan naa ti ṣẹlẹ.
Àáyá bẹ sílẹ o bẹ sáré,wábiwọ́sí ìyá ni Flying Eagles fi bẹrẹ fún Qatar Kíni ìtumọ̀ oyè Balógun káàfàtà tí wọ́n fí Asamoah Gyan jẹ?
Mustapha woye ọrọ naa lasiko to n bawọn akọroyin sọrọ nilu Abuja, toun naa si fi ibẹru han lori bi ọwọja arun naa se n peleke si.
17 Àti sí àwọn ará Néfì, àti àwọn ará Jákọ́bù, àti àwọn ará Jósefù, àti àwọn ará Sórámù nípasẹ̀ ẹ̀rí àwọn bàbá wọn—
Wo àwọn ojúṣe àti èèwọ̀ fún ikọ̀ ọlọ́pàá SWAT tó gba iṣẹ́ lọ́wọ́ SARS Ọlọ́pàá mú afurasí 31 tó ń dúnkokò máwọn ọmọdé lórí ayélujára Pásítọ̀ Enoch Adeboye darapọ̀ mọ̀ #ENDSARS, ó fún ìjọba Nàìjíríà ní ìmọ̀ràn ọ̀nà àbáyọ Mọ̀ nípa iPhone 12, fóònù ológo 5G tí kìí lo Charger” tó ṣẹ̀ṣẹ̀ jáde Ẹ̀yin olùwọ́de, ẹ lọ kọwọ́ ọmọ yín bọṣọ, bí bẹ́ẹ̀ kọ́."
Ó dára, ó sì dùn pupọ,bí àwọn ará bá ń gbé pọ̀ ní ìrẹ́pọ̀.
    Nísisì yìí tí a ti kọjá odò Ẹ̀jẹ̀ ní ẹ̀ẹ̀kejì, àwa náà mọ̀ pé à ń súnmọ́ Igbó Elégbèje.
Ọlọrun Ṣèlérí Ọmọkunrin Kan fún Abrahamu.
G Gwynne- Jones ni ọ̀gá Ile Ẹ̀kọ́ gíga ti ìjọba ní Ìbàdàn tí wọ́n ti ń kọ́ àwọn ènìyàn ní iṣẹ́ olùkọ́.
Ti a ba fun ẹnikan lowo loni, ẹlomii yoo tun wo awokọṣe naa lati ji ẹlomiran gbe.
Commission ,INEC) ti kede ẹgbẹ  oselu (People’s
Leyin eyi ni ijọba aarẹ Buhari ṣeto ipagọ idanilẹkọọ ọlọjọ meji fawọn ti wọn fẹ yan naa.
Abenugan naa , tun soro lori aseyori eto idibo to waye lọdun 2015, o tun wa  ro ajo naa lati tun tesiwaju lori aseyori yii.
Àwọn ni àgbèrè, ìwà èérí, wọ̀bìà; 
Ààrẹ Muhammadu Buhari gbé ìpolongo ìbò dé ìlú Eko Leah to jẹ ọmọ ọdun mẹẹdogun pẹlu awọn ọmọ to le ni ọgọrun ti Boko Haram jigbe lati ile iwe Dapchi ni ipinlẹ Yobe lọdun to kọja.
Ǹjẹ́ ó yẹ kí òṣìṣẹ́ ìjọba ó ṣe ìmúdàgbà àwọ̀-ara tí ó ní ipọn?
Gẹgẹ bi wọn si ti sọ, ẹbun ti iye owo rẹ to miliọnu marundinlaadọrun naira, N85m ni olubori nibi eto naa yoo fi ṣara rindin.
 Awon alakoso idije naa sagbekale ifigagbaga ohun lati fi gbaradi fun idije (2019 Africa U-20 Cup of Nations), ti yoo waye lorile-ede Tanzania bere lojo keji si ojo ketadinlogun osu keji, odun 2019.
Ní òru, mọ́jú ọjọ́ tí Hẹrọdu ìbá mú Peteru wá fún ìdájọ́, Peteru sùn láàrin àwọn ọmọ-ogun meji, wọ́n fi ẹ̀wọ̀n meji dè é; àwọn ọmọ-ogun kan sì tún wà lẹ́nu ọ̀nà, tí wọn ń ṣọ́nà.
Ṣugbọn ìwọ ni o gbà wá lọ́wọ́ àwọn ọ̀tá wa,o sì dójú ti àwọn tí ó kórìíra wa.
won di mora gba lowo awon obinrin asekupani yii.
Sofari dáhùn pé,“O sọ wí pé,‘Ìṣàn omi a máa gbá àwọn ẹni ibi lọ kíákíá;ìpín tiwọn a sì di ìfibú ninu ilẹ̀ náà,ẹnikẹ́ni kìí sì í lọ sinu ọgbà àjàrà wọn láti ṣiṣẹ́ mọ́.
Ta ni Van Dihk ti oju wa lara rẹ yii?
Okowo Bitcoin kii fun ni ni èlé bi ìpín idokowo ni banki tabi ileesẹ.
Wo àwọn tí wòlíì ríran sí pé COVID-19 yóò pa ní ìpínlẹ̀ Edo l'óṣù kẹsàn án Nǹkan mẹ́sàn án tí Mùsùlùmí gbọdọ̀ ṣe nínú oṣù Dhual- Hijjah Alága àjọ EFCC Ibrahim Magu yóò tún bẹ ìgbìmọ̀ olùwádìí Aàrẹ wò lónìí Ilé ẹjọ́ wọ́gilé ìgbẹ́jọ́ Olalekan 'Woodberry' Pọnle Ẹgbẹ oṣelu APC ni Yakubu Dogara kọkọ wa ko to ṣi lọ si ẹgbẹ oṣelu PDP lasiko ti oun ati aarẹ ile igbimọ aṣofin tẹlẹ, Bukola Saraki jẹ adari awọn aṣofin.
Oríṣun àwòrán, facebook Àkọlé àwòrán, Sophie yi ọkan rẹ pada lori iṣẹ abẹ idi ṣiṣe Kini idi ti Sophie ṣe fẹ yọ ayederu idi naa lẹyin ọdun marun un ti o ti fi si?
ṣe ẹni tí o ba n rí èmi àti òun bí a ti jọ n rìn, kò ni sàì ní èrò pe a n bẹ̀rẹ̀ ọ̀rẹ̀.
V Herklots jẹ́ obìnrin tí o mọ ìwé lọpọlọpọ.
Ninu awọnti wọn fẹsun kan ni a ti a ri ọmọ Naijiria mẹtadinlọgọrin ninu wọn.
Bí ẹnìkan bá ṣèèṣì pa aládùúgbò rẹ̀ láìjẹ́ pé wọ́n ti ń bá ara wọn ṣe ọ̀tá tẹ́lẹ̀, bí ó bá sálọ sí èyíkéyìí ninu àwọn ìlú náà, yóo gba ẹ̀mí ara rẹ̀ là.
Ajọ UNICEF gba pe airitọju to peye fun awọn alaboyun lo maa n fa iku ọmọ tuntun.
EndSARS Protest Update: Ọwọ́ pálábá àwọn tó fọ́ ShopRite fún ìgbà kejì ségi
Ipinlẹ Oyo Àkọlé àwòrán, Onimọẹrọ Ṣeyi Makinde ati igbakeji rẹ, Rauf Olaniyan ti bura wọle gege bii gomina ati igbakeji gomina ipinlẹ Ọyọ Àkọlé àwòrán, Gomina tuntun naa nipinlẹ Oyo ni oun ni imọ rere fun awọn ara ilu Àkọlé àwòrán, Igbakeji gomina Oyo, Rauf Aderẹmi Ọlaniyan ree to n se ibura niduro pẹlu aya ati ọmọbinrin rẹ Àkọlé àwòrán, Ẹgbẹ olorin ni ipinlẹ Ọyọ fi ijo ati ayẹ̀yẹ pada gomina tuntun ni ipinlẹ naa.
Ejogbe ni ohun ti ijọba ni ki Auxiliary maa ṣe ni pe ko maa pa owo si apo ijọba, ko si maa jawe fawọn awakọ lawọn ibudokọ.
Àwọn ẹ̀dá ojú ọ̀run yóo fò, wọ́n óo sì jóná.
Aarẹ Iṣẹṣe ti ipinlẹ Ọyọ, Oloye Omikẹmi Egbẹlade ni iṣejọba gomina Abiọla Ajimọbi ti ja awọn oniṣẹṣe ni tanmọn ọn nipa kikọ lati kede isinmi lẹnu iṣẹ fun sisami ayajọ ọdun iṣẹṣe lagbaye.
Dafidi bá ranṣẹ sí Joabu, pé kí ó fi Uraya ará Hiti ranṣẹ sí òun, Joabu sì fi ranṣẹ sí Dafidi.
Wo ohun tí Adájọ́ sọ nípa ìgbẹ́jọ́ Wòlíì Sotitobire l'Ondo Wo àwọn ọ̀nà míràn tí o leè gbà lẹ́yìn tí wọ́n bá ti afára Third Mainland Afárá Third mainland gba ẹ̀gbọ́n Ìgbésẹ̀ wo ní aláboyún lé gbé láti dẹ́kun ìjẹkújẹ nínú oyún?
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Yemen Water Child: Ọmọdé 44 ni Sọ́jà pa, tí 100 míì sì kú látọwọ́ ohun ìjà olóró Ẹ̀yin òṣìṣẹ́, ẹ má ṣáì lọ síbi iṣẹ́ lọ́jọ́ Ajé, olórí àwọn òṣìṣẹ́ ní Nàìjíríà tako ìyanṣẹ́lódì Olori awọn oṣisẹ lorilẹede Naijiria, Ọmọwe Folasade Yemi-Esan ti rọ awọn oṣiṣẹ jake jado Naijiria pe ki wọn ma ṣalai lọ sibi iṣẹ lọjọ Aje.
Bẹẹ ba gbagbe, ọjọru ni aarẹ Buhari kede pe oun ti ṣe ayipada orukọ ileeṣẹ to n mojuto ọgba ẹwọn, Nigeria Prisons Service si Nigeria Correctional Service, eyi ti yoo maa tọ awọn to ba wa ni ahamọ sọna.
Omo ogun ile Amerika merin lo ti padanu emi won sinu ijamba oko oju-ofurufu ti o waye ni aarin guusu California.
Oríṣun àwòrán, FemiGbajabiamila/FACEBOOK Àkọlé àwòrán, Femi Gbajabiamila ati Ahmad Lawan aarẹ ile aṣofin Naijiria ti wọn ṣẹṣẹ yan Femi Gbajabiamila ni aṣofin to da ọrọ ofin pajawiri kan silẹ, eyi to faye gba ki igbakeji aarẹ laṣẹ lati dari ijọba, nigba ti aarẹ ko ba lagbara lati dari ijọba.
Ilu Mamu Ijẹbu lo wa labẹ Agbegbe Idagbasoke Ijọba Ibilẹ Agọ-Iwoye ni ni Ipinle Ogun lapa Iwọ-Oorun Gusu orilẹ-ede Naijiria.
Ṣugbọn, o ṣeeṣe ki ọpọ eeyan ma mọ iyatọ to wa laarin awọn ẹgbẹ mẹtẹẹta.
Ọmọ ọkunrin ọhun di gbajumọ lẹyin ti fidio ibi to ti n bẹ iya rẹ pe ko farabalẹ lẹyin to ṣaṣemaṣe kan ti ẹnikẹni ko mọ jade lori ayelujara.
Joshua tun ni ilumọọka abẹṣẹ ku bi ojo to ti fẹyin ti, Wladimir Klitschko tiẹ gba oun ni imọran pe k'oun ma ṣe lo ẹrọ ibanisọrọ rara ti ija naa yoo fi waye.
Agbabọọlu iwaju Leroy Sane fọba lee fun ikọ Man City pẹlu goolu keji nigba ti o ku iṣẹju kan ki ipele akọkọ pari.
“OLUWA Ọlọrun, fi ojurere wo àwa iranṣẹ rẹ, àní àwọn ọmọ Israẹli, eniyan rẹ, kí o sì gbọ́ adura ati ẹ̀bẹ̀ wọn nígbàkúùgbà tí wọ́n bá ké pè ọ́ fún ìrànlọ́wọ́.
Akọsilẹ to peye ni wọn n ṣe fun ohun to nilo ati awọn to yẹ fun ipese fawọn to lugbadi omiyale.
Awọn janduku maa n jẹ lọdọ Adedibu nigba aye rẹ.
Bí ó bá jẹ́ pé o gbọ́ tirẹ̀ ni, nisinsinyii ni OLUWA ìbá fìdí ìjọba rẹ múlẹ̀ lórí Israẹli títí lae.
Kí ló dé tí o fi sọ àsọtẹ́lẹ̀ ní orúkọ OLUWA pé ‘Ilé yìí yóo dàbí Ṣilo, ati pé ìlú yìí yóo di ahoro, ẹnikẹ́ni kò sì ní gbébẹ̀ mọ́?
Lori ọrọ ayẹwo yii, awọn arinrinajo ti n bẹnu atẹ lu eto ti ijọba gbe kalẹ nipa owo gọbọi tawọn n san ṣugbọn ti ayẹwo naa ko munadoko.
Ayédèrú-ẹ̀dá jẹ́ ẹnikan tí a lè wí pé ó ti kọ́ ilé fún rìkíṣí ni agbárí, tí ó ti fún àgàbàgebè ní iyààrá, tí òun àti wọ̀bíà jọ ń fi ọwọ́ kọ́ ọwọ́ rìn kiri.
kí á lè mọyì ẹ̀bùn rẹ̀ tí ó lógo tí ó fi fún wa lọ́fẹ̀ẹ́ nípasẹ̀ Kristi àyànfẹ́ rẹ̀.
Lasiko ti o fi n ba awọn akọroyin sọrọ ni Aarẹ Akufo-Addo ṣalaye ọrọ yii.
Ẹbi ti kò bá ni owó, kò ni lè lọ nitori kò ni ri iwé irinna gbà.
Wò bí wọ́n ti ń tàbùkù mi, tí wọn ń fín mi níràn.
Ẹ máa dúpẹ́ lọ́wọ́ Ọlọrun Baba nígbà gbogbo fún gbogbo nǹkan ní orúkọ Oluwa wa Jesu Kristi.
Bẹ́ẹ̀ ni kí OLUWA ṣe sí àwọn ọ̀tá mi,àwọn tí ń sọ̀rọ̀ ibi nípa mi!
Goodluck Jonathan lo yan ogbeni Godwin Emefiele gege bi  adari ile ifowopamo ti ijoba apapo lodun 2014
"A n lo ọdun naa lati fi sopọ mọ awọn aṣẹda wa ni lati ipasẹ ohun ti aṣẹda da, eyi ti yoo wo aye san, paapaa lasiko ajakalẹ arun Coronavirus yii.
Mark Krikorian, tó jẹ́ ọ̀gá àgbà àti adarí àjọ tó n rí sí ìmọ̀ nípa ìwọlé àti ìjáde àlejò nílẹ̀ Amẹrika sọ fún ilé iṣẹ́ ìròyìn AP pé  Èyí jẹ́ ìgbésẹ̀ tó lààmì-laaka nínú àwọn ìpinu ìjọba ààrẹ Trump, nípa fífún àwọn ọmọ ilẹ̀ Amẹrika ní iṣẹ́ òòjọ́."
Abiola ran Dele lọ ilu Oyinbo, Austria fun ayẹyẹ ami ẹyẹ kan ti Oloye Fawehinmi n gba nibẹ.
Alhaji Mukaila ko ṣai fikun ọrọ rẹ pe oun naa lẹtọ si ohun ini ẹgbẹ NURTW nitori ọkan lara ọmọ ẹgbẹ naa loun n ṣe tẹlẹ.
Oríṣun àwòrán, TWITTER Ni bayii, EFCC ni Mompha ti jẹwọ wi pe lootọ ni oun se gbajuẹ ẹsun meji ninu mẹrin ti wọn fi kan an, ti wọn si ba aago ọwọ marun un lọwọ rẹ, ti iye rẹ si jẹ ogun miliọnu Naira (N20,000,000.
 fleurbaey ati awọn alakọwe rẹ dagbasoke awọn ariyanjiyan ni ojurere fun awọn apejuwe miiran .
Àwọn nǹkan tí obìnrin lè ṣe pẹ̀lú olólùfẹ́ oníwà ipá lásìkò ìgbélé Coronavirus yìí 'Pọ́ńbélé Yorùbá ni mí, n ò sì ní tijú rẹ níbikíbi' 'Èmi lòdì sí kí àwọn kan máa pe iṣẹ́ ọwọ́ọ N20,000 ní N5,000' Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí 2 sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 2:23 Fídíò, Water Generator: Ó leè ṣiṣẹ fún wákàtí mẹfà, kó tó sinmi, Duration 2,2310 Òkùdu 2020 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
Nínú àwọn ìtàn òkè yí àwọn méjì ló sọ bí a ṣe sọ ìlú náà ní Ijẹ̀bú ṣùgbọ́n ó dàbí ẹni pé a lè gba ti irúfẹ́ èyí tí ó sọ pé Ìjẹ̀bú – Òde ni Ọba Ijẹ̀bú Jẹ̀ṣà ti mú orúkọ náà wá ní eléyìí ti ó bójú mi díẹ̀.
Ẹni tí ó bá ní ẹ̀bùn ìkọ́ni, kí ó lo ẹ̀bùn rẹ̀ láti kọ́ni lẹ́kọ̀ọ́.
Àkọlé àwòrán, Sìgá mímu ń di èèwọ oògùn ìlera pípé lagbaye Wọn tun n lo taba ti wọn po pọ mọ ṣọ́ọ́kì lati fi fọ ẹyin ni agbegbe to di Venezuela lonii.
Ó yan àwọn aṣọ́nà sí oríṣìíríṣìí ẹnu ọ̀nà gẹ́gẹ́ bí Dafidi eniyan Ọlọrun ti pa á láṣẹ.
”Wọ́n dá a lóhùn pé, “Láti ilẹ̀ Kenaani ni, oúnjẹ ni a wá rà.
Ṣe ẹ ranti bi Ọmọ ọba William ati aya rẹ Catherine ṣe n jade lati ile iwosan St Mary's niluu London?
Ìgbà tí ènìyàn bá rí ìṣòro kan ṣoṣo nígbà míràn a dà bí ẹni pé kí olúwaarẹ̀ kú lẹ́sẹ̀ kan náà.
Ilẹ Asia lo ni iye awọn obinrin ti awọn ololufẹ wọn tabi mọlẹbi pa to poju lọdun 2017 pẹlu ẹgbẹrun lọna ogun.
Òjò àrọ̀ọ̀rọ̀dá: Àwòrán káàkiri ìlú arómi-sá-lẹ̀gbẹlẹ̀gbẹ
Ọ̀wọ́ngógó búrẹ́dì gbòde kàn lẹ́yìn tí àwọn oníbúrẹ́dì da iṣẹ́ sílẹ̀ Sudan tí bẹ̀rẹ̀ ìjìròrò lórí bí US yóò ṣe yọ òrúkọ̀ wọn kúrò nínù ikọ̀ agbẹ́sùnmọ̀mí àgbáyé Èèyàn mẹ́jọ jónà ráúráú nínú ìjàmbá ọkọ̀ akérò tó ṣẹlẹ̀ ní mọ́rosẹ̀ Eko sí Ibadan Ọlọ́jọ́ Festival 2020:Ọ̀ọ̀ni ti Ilé Ifẹ̀ tí wọ ìléèdí ọlọjọ méje tí kò ní rí ẹnikẹ́ni sójú Ìjọba Kaduna kéde ọjọ́ mẹ́ta fún ìdárò Emir Zazzau, Buhari, Tinubu, Babangida náà ń ṣèdárò Ọpọ awọn onkọwe lo n ṣe idaro Baba Lawuyi Ogunniran ti ọpọ n pe ni Eegun Alare re ibi agba n re lẹni ọdun marunlelọgọrin.
Lootọ ni Olori Badirat Ajoke ṣi n wọ oruka si ọwọ, ṣugbọn o dahun ibeere ololufẹ rẹ kan to beere nipa rẹ pe kii ṣe oruka igbeyawo lo wa ni ọws oun.
Trump: Bí ẹ bá ṣé ikọlù sí wá, nkán ìní yín 52 làá dojú ìjà kọ Ìjàmbá ọkọ̀ òfurufú dínkù lọ̀dún 2019 pẹ́lú ìdá àádọ́ta nínú ọgọ́rùn ún Obabinrin Elizabeth II ṣàfihàn àwòrán orí adé mẹ́ta tó lè jé lẹ́yìn rẹ̀ Ìjọba Gomina Raman Razak padà wólé arúgbó ní Ilọrin!
Ni eyi to mu ki oun ati awọn agbẹjọro rẹ gba ile ẹjọ giga ipinlẹ lọ, pe idajọ ile ẹjọ to ga ju naa ko sọ pe ki oun kuro lori oye.
Nígbà tí ó yá, Jakọbu sọ fún Labani pé, “Fún mi ní aya mi, kí á lè ṣe igbeyawo, nítorí ọjọ́ ti pé.
Aṣojú Seyí Makinde lásan ní mo jẹ, òṣìṣẹ́ gbọdọ̀ bọ̀wọ̀ fún mi - Ọ̀dọ́mọdé Kọmísánà Èmi àti Bọla Tinubu fẹ́ lo ‘German Mercenaries’ láti gbé MKO Abiọla kúrò lẹ́wọ̀n - Dele Momodu Irọ́ ńlá!
Ajọ to n gbogun ti iwa jẹgudujẹra lorilẹ-ede Naijiria, EFCC, ni awọn yoo bẹrẹ iwadii ohun to fa ina to sọ ni ọọfisi wọn kan lAbuja.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Minimum Wage: Saraki dúpẹ́ lọ́wọ́ àwọn òṣìṣẹ́ fún sùúrù wọn lórí owó oṣù tuntun 14 Ẹrẹ̀nà 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 19 Ẹrẹ̀nà 2019 Oríṣun àwòrán, Senate President Ile Igbimọ Aṣofin Agba orilẹede Naijira ti bu ọwọ lu abadofin kan to ni ẹgbẹrun lọna ọgbọn naira ni yoo jẹ owo oṣu to kere ju ni orilẹede yii.
Ni ọjọ karun oṣu kẹjọ ọdun 1974 ni wọn bi Fatoumatta Bah-Barrow ni ilu Banjul tii ṣe olu ilu orilẹede Gambia.
Ile iwe Gbagada Girls Junior school ni olukọ wa ti wa.
Asiko ifilọlẹ ofin WAI yii naa ni wọn ju gomina tẹlẹ nipinlẹ Kano, Alhaji Barkin Zuwo si ẹwọn ọtalerugba o din mẹwa ọdun lori iwa ajẹbanu.
Ajafẹtọ ọmọniyan Kayode ni igbesẹ naa dun mọ awọn ara ilu ninu ati wi pe Aarẹ Buhari naa ko binu si igbesẹ naa nitori o mọ wi pe nkan to tọna ni awọn asofin naa se.
Ojú olè rèé, Ọwọ́ tún tẹ lára olè Ọffa Ọ́lọ́pàá mú 'Rambo' ní àríwá Naijiria Wo ikọ̀ ọlọ́pàá tí àwọn ọ̀daràn ń sá fún Olórí IRT fi atẹjade sita ní ọjọ́ Abamẹ́ta, ti wọn fi kede awọn oniṣẹ ibi to pa ololufẹ mejeeji.
1 Bélú 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 2 Bélú 2020 Oríṣun àwòrán, Getty Images Ọjọ kẹ̀ta, oṣù kọkànlá, ọdún 2020 ni ìdìbò ààrẹ ilẹ̀ Amẹrika yóò wáyé, sùgbọ́n , ó ṣee ṣe kí ẹni tí ó ni ìbò tó pọ̀jù lọ lásìkò ìdìbò gbogboogbo má wọle gẹ́gẹ́ bi ààrẹ.
Lábẹ́ rẹ̀ ni mo ti kọ́ ṣe iṣẹ́ olùkọ́ kékeré; ṣùgbọ́n láìsí ìmọ̀r[sn ọkùnrin yìí, láìsí ìwé rẹ̀ tí mo yá tí mo kà, láìsí àtìlẹ́yìn rẹ̀, n kò lè tó ẹni ti ó ń wọ Ilé Ẹ̀kọ́ Gíga ní òde Ọ̀yọ́; láìsí dé ilé ẹ̀kọ́ yìí, n kò lè tó ẹni ti ń kọ́wé fún enikẹ́ní láti kà rárá.
Ilé tí ó kọjú sí àgbàlá Tẹmpili ní apá ìwọ̀ oòrùn fẹ̀ ní aadọrin igbọnwọ (mita 35), ògiri ilé náà nípọn ní igbọnwọ marun-un (mita 2½) yíká, òòró rẹ̀ sì jẹ́ aadọrun-un igbọnwọ (mita 45).
"Wọn ko fi ọrọ naa lọ igbimọ lọbalọba ipinlẹ Kano, nitori pe Emir Sanusi ni alaga igbimọ naa.
 astronomer sì ni pẹ ̀ lú .
Mílíọ́nù mẹ́wàá Náírà ni ilé ẹjọ́ ni kí Kábíyèsí san gẹ́gẹ́ bí owó ìtaran ilẹ̀ tí ó gbà lọ́nà àìtọ́ Ìjọba Naijiria faraya nínú lẹ́tà tó kọ sí CNN lórí ìwádìí rẹ̀ nípa ìṣẹ̀lẹ̀ Lekki Toll Gate Omotara pàdánù isẹ́ olówó ńlá nítorí ó fi ọtí ẹlẹ́rìndòdò sódà lá ọmọ alágbe lójú Wo bí o ṣe lè ṣe eré ìdárayá tí yóò fún ọ ní adùn àti okun fún ìbálòpọ̀ Ilé aṣòfin orílẹ̀-èdè UK n gbèrò fífí ìyà jẹ àwọn adarí Naijiria tọ lọ́wọ́ nínú rògbòdìyàn ENDSARS Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Akọ́mọlédè àti Àṣà lórí BBC Yorùbá: Kọ̀ síi nípa iṣẹ́ tí oúnjẹ ń ṣe lára níbí Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Ooni of Ife: Àwòrán ọmọ mi kọ́ lẹ ń rí lórí ayélujára o, ọmọ ọ mi ń ṣètùtù lọ́wọ́- Ọba Adeyeye Ogunwusi24 Bélú 2020 UK Parliament on Nigeria: Geoffrey Onyeama ni aṣofin UK kò lágbára láti sọ̀rọ̀ lórúkọ ìjọba UK26 Bélú 2020 Jemila dáná sún ilé ọ̀rẹ́kùnrin rẹ̀ àti ọ̀rẹ́bìnrin tó bá nílé24 Bélú 2020 Fídíò, The New Pandemic: Kíni àwọn onímọ̀ sáyẹ́ńsì ń sọ nípa rẹ̀?
Wákàtí márùn ún márùn ún ní wọ́n ń fipá bá obìnrin kàn lò pọ̀ ní Nàìjíríà- Ọga Ọlọpaa Gbajugbaja oṣere tiata naa fikun un pe, ti eeyan ba mọ inu ro, oye aye yii yoo han si wa kedere pe igba diẹ ni aye Amọ, a kan n sare le awọn ohun to wa lonii, ti ko ni si mọ ni ọla, pẹlu ireti pe yoo wa titi laelae.
O ni lootọ ni edeaiyede waye laarin oun ati dokita agba nileewosan nla UCH, ṣugbọn awọn ti pari rẹ.
Akọroyin BBC, Aaron Akinyemi ni ọdun mẹta saaju Rosa Park ni Babatunde Olatunji ti bẹrẹ ijijagbara fun ẹtọ awọn ọmọ ilẹ Afrika gẹgẹ bi eniyan bi i alawọfunfun ni ilẹ America.
Milioni Meje Naira; Apo Sugar; Awon aso aloku (Tokunbo) ti owo ori won
 Àmì àrùn lè má sí rárá , wọ ́ n lè wà níwọ ̀ nba , bíi orí-fífọ ́ , ẹran ara dídunni , àti ibà ; wọ ́ n sì lè nira púpọ ̀ ẹ ̀ dọ ̀ fóró tí nṣẹ ̀ jẹ ̀ tàbí meningitis .
Ọ̀rọ̀ ijinlẹ àti Òwe Yorùbá wà lati fi kọ́ ọgbọ́n àti imò bi èniyàn ti lè gbé igbésí ayé rere.
Wo àwọn olórí ní ilẹ̀ Israẹli tí wọ́n wà ninu rẹ, olukuluku ti pinnu láti máa lo agbára rẹ̀ láti máa paniyan.
Ìlú tí ń ta ẹ̀jẹ̀ sílẹ̀ gbé!
Lẹ́yìn ọpọlọpọ ọjọ́, a óo fìyà jẹ wọ́n.
Atẹjade kan ti agbẹnusọ Seyi Makinde, Dọtun Oyelade fisita salaye pe, se ni ijọba Ajimọbi n fi iwanwara gbe awọn isẹ agbase kan jade pẹlu ọkẹ aimọye biliọnu naira, to si mu ifura dani.
Wò ó, mo rí i tí wọn ń kó àwọn obinrin tí wọ́n wà ní ààfin ọba Juda jáde lọ sọ́dọ̀ àwọn ìjòyè ọba Babiloni, wọ́n sì ń wí pé,‘Àwọn ọ̀rẹ́ rẹ tí o fọkàn tán tàn ọ́,wọ́n sì ti ṣẹgun rẹ;nisinsinyii tí o rì sinu ẹrẹ̀,wọ́n pada lẹ́yìn rẹ.
Niger/Ghana/SenegalSaaaju eyi,ni  aare Mahamadou Issoufou ti orile ede Niger,to
Sibẹsibẹ, ẹ̀ ń gbéjú gbéré bí aṣẹ́wó,ojú kò sì tì yín.
“Èmi, Nebukadinesari wà ninu ìdẹ̀ra ní ààfin mi, nǹkan sì ń dára fún mi.
Bí Rebeka ti fún un ní omi tán, ó ní, “Jẹ́ kí n pọn omi fún àwọn ràkúnmí rẹ pẹlu, títí tí gbogbo wọn yóo fi mu omi tán” 
com/Y9jShu5xpH “Inu mi dun lopolopo lati kopa ninu ifesewonse
O ni a ṣi n ṣepade lọwọ ako si tii pari ipade na, ṣugbọn a o fi esi ababọ ipade wa lede fun gbogbo eeyan titi ipari ọsẹ yii."
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù ALGON Oyo: Ìjọba ní àlá lásán tí kò le è dòhun ni ìlàkàkà àwọn alága APC láti padà sí káńṣù 22 Èrèlè 2020 Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fọ́nrán ohùn, Oyo local government: ALGON, Makinde sọ ọ̀rọ̀ ọ̀tọ̀ọ̀tọ̀ lórí ọ̀nà àti Awọn alaga kansu nipinlẹ Ọyọ ti sọ pe, igbesẹ ti ijọba ipinlẹ Ọyọ n gbe lori ọrọ aawọ laarin awọn ati ijọba, kii ṣe eyi to lee mu alaafia waye bọrọ.
Gege bi ogagun Benson, o ni,
Ibojì titun kán wà ninu ọgbà náà, wọn kò ì tíì sin òkú kankan sinu rẹ̀ rí.
Bakan naa ni ẹgbẹ naa tun tako igbesẹ ile igbimọ aṣoju-ṣofin l'Abuja lati jiroro lori aba ti yoo fun ijọba apapọ lagbara lori alumọọni inu omi kaakiri orile-ede Naijiria.
Ó wí fún mi pẹ̀lú pé ẹsin ni a o jọ gùn lọsí Ìgbìmọ̀ náà láti ilé òun; nítorí òun ṣẹ̀ṣẹ̀ ra ẹsin méjì náà òun yóò sì kọ̀ gún ọ̀kan lọ́jọ́ tí a bá máa lọ kí èmi náà gun èkejì.
Iroyin to tẹ wa lọwọ sọ pe lojuna oko ni wọn ti ji i gbe nilu Iroko nitosi Fiditi, ipinlẹ Ọyọ.
Ohun tí mò ń sọ ni pé Kristi ti di iranṣẹ fún àwọn tí ó kọlà, láti mú òtítọ́ Ọlọrun ṣẹ, kí ó lè mú àwọn ìlérí tí Ọlọrun ṣe fún àwọn baba-ńlá ṣẹ, 
Uraya, ará Hiti, ati Sabadi, ọmọ Ahilai, 
Nibayii, gbogbo eniyan lo kawọ gbera ti wọn n reti boya lootọ lootọ aye yoo ṣi parẹ ni 21/10/2017 ti Camping sọ.
Onome Ebi  ti o gba ife-eye idije African Women’s Championships (AWC) ni igba meta otooto ti pada sori papa bayii, leyin ifarapa ti o ni ninu asekagba idije AWC  lodun 2016 pelu iko agbaboolu orile-ede Cameroon.
 O ni; “ O jẹ ẹni ti o maa n  wa alaafia, ọlọgbọn eniyan, ti o maa n wa rere fun eniyan ẹgbẹ rẹ pẹlu idagbasoke ipnlẹ rẹ ati orilẹ-ede lapapọ.
Ta ni agbábọ́ọ̀lù tó fakọyọ jù lọ ní Afcon 2019?
Ẹ̀ ń bèèrè pé, “Kí ló dé tí kò fi gbà á?
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Èrè ti Nàìjíríà yóò jẹ nínú ọ̀rọ̀ Iran àti US O tún ni ìgbòkègbodo àwọn agbésùmọ̀mi yóò tun pọ si ni ìhà ìwọ̀-òòrun ilẹ̀ Afirika, pàápàá jùlọ ni Chad Basin.
End SARS protest: Lára àwọn ìlú tí ìwọ́de ti wáyé ní Ibadan, Ado Ekiti, Osogbo, Ado Ekiti ati Eko
O ni ọna atiṣejọba ni wn fi kọ oun lẹkọọ kii ṣe ka kan maa ṣe oṣelu.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ó tó gẹ́ẹ́!
nígbà náà ni inú yín yóo máa dùn láti sin èmi OLUWA,n óo gbe yín gun orí òkè ilẹ̀ ayé,n óo sì mu yín jogún Jakọbu, baba ńlá yín.
Orukọ rẹ wa lara awọn orukọ mẹta ti gomina Seyin Makinde fi sọwọ si ile igbimọ asofin ipinlẹ Ọyọ.
Ẹfunsetan Aniwura, obìnrin tó ju ọkùnrin lọ Hubert Ogunde rèé, baba àwọn òsèré tíátà Akọroyin BBC kan ba arakunrin kan ti iṣlẹ naa ṣoju rẹ Bekele Gutema to wa ni agbegbe naa nigba sọ wipe: ''Ibugbamu to lagbara kan ni a gbọ ti ina si sọ, o pọ to bẹẹ ti a ko le sun mọ ibẹ.
Kò sí ẹ̀ṣẹ̀ nínú ìbálópọ̀ nínú ọkọ̀ - Ọlọ́pàá Igbakeji Kọmisana Ọlọpaa (ACP), Abayọmi Shogunlẹ lo kede loju opo ikansira ẹni Twitter rẹ pe kii se ẹsẹ rara fun awọn akọ ati abo lati ni ibalopọ ninu ọkọ nita gbangba.
Idi ni pe Aarẹ Muhammadu Buhari ti kede pe ẹni to yẹ nipo igbakeji alaga fun ẹgbẹ oselu APC ni igbakeji alaga ẹgbẹ tẹlẹ, Victor Giadom.
Ẹyọ òkúta kan ṣoṣo kò ní ṣẹ́kù sórí òkè náà.
Lateef Jakande, Bola Tinubu, Babatunde Raji Fashola ati Akinwumi Ambode.
Nigba ti igbẹjọ ọhun waye ni Ọjọbọ, Agbẹjọro agba ati Kọmisana feto idajọ nipinlẹ Ondo, Adekola Olawoye, lo soju ijọba ipinlẹ Ondo lori ẹjọ naa.
Àbáwọlé ẹnu ọ̀nà ẹ̀bá ìloro tí ó kọjú sí tẹmpili jẹ́ ọ̀pá kan.
Ẹ ti gbọ́ ọ̀rọ̀ àfojúdi tí ó sọ sí Ọlọrun nisinsinyii.
Akọwe ẹgbẹ Afẹnifẹre, Yinka Odumakin, lasiko to n ba BBC Yoruba sọrọ ni Baba Fasanmi jẹ akinkanju eniyan to si ni ifẹ awọn ọmọ kaarọ-ojiire.
Botilẹjẹ pe awọn ọkunrin meji mi i wa ninu ile naa nigba ti ijamba yii waye, wọn ko fi ẹsun kan wọn.
"NURTW l‘Abuja yóò kàn sí Makinde láìpẹ́ lórí bó ṣe fòfin dè wá l‘Ọyọ - Ejiogbe Òfin ṣì gbẹ́sẹ̀lé Ẹgbẹ́ awakọ̀ èrò NURTW ní ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́ Ohun tí o kò mọ̀ nípa Ebila ""One Million Boys"" àti Ekugbemi, olórí ẹgbẹ́ òkùnkùn méjì tó da ìlú Ibadan rú Ta ló leè rò pé ọmọ mẹ̀kúnnù bí èmi leè dé ipò alága NURTW?"
Gẹgẹ bi atẹjade ti Forbes fi lede, idiyẹle Kanye West ko din ni biliọnu kan ati ọọdunrun miliọnu dọla, ṣugbọn West yari pe oun niye lori ju bẹ lọ.
Ìfọwọ́sowọ́pọ̀ nìkan ni ọ̀nà abáyọ sí ìṣòro Nàìjíríà- Olusegun Obasanjo Ìtura ìgbà díẹ̀ ni bọ́dà tí ìjọba ṣí padà, kò lóòre nínú - Onímọ̀ ọrọ̀ ajé Wo ìdí tí ààrẹ Buhari kìí fi ṣe ẹ̀dà Jubril láti Sudan Ni Iwọ oorun Ariwa Naijiria, gbogbo igba ni awọn eeyan n ku ipinlẹ Zamfara, Katsina ati Kaduna, nitori ija oṣelu ati janduku.
"lẹ ́ yin tí ó gbé àwo náà tí ó là á jáde tí ó pe àkọ ́ lé e rẹ ̀ ni "" the uncomfortable truth "" pẹ ̀ lú ilé iṣẹ agbó rinjáde yo mama ' s , níbi ìgbé -kiri orin ẹ ̀ fún ìgbà àkọ ́ kọ ̀ ló ti kọrin pẹ ̀ lú atrice bart williams nínú oṣù kẹrin , odún 2005 , ní àwọn ìlú bíi germany , austria àti switzerland ."
Arabinrin Titilọpẹ Akosa lati ajọ ti wọn pe ni ‘Centre for 21st Century Issues’ rọ Ile Igbimọ Aṣofin naa lati tubọ sapa ki awọn ara ilu le maa kopa ninu awọn ilana ṣiṣe ofin wọn nipa ti tete maa pe awọn alẹnulọrọ lori abadofin bẹẹ.
O ni gbogbo ẹda alaaye lo ni ẹgbẹ ọrun kan tabi omiran ti wọn n ṣe, o si tẹnu mọ ọ pe, mimọ ẹgbẹ ẹni daadaa ati ṣiṣe ifẹ inu wọn, maa n ran irinajo ẹda laye lọwọ.
Igi rẹ̀ tí ó lágbára gbẹ, iná sì jó o.
Ileeṣẹ ọlọpaa ipinlẹ fidi iṣẹlẹ naa mulẹ fun akọroyin BBC Yoruba niluu Ibadan lọjọ Abamẹta.
O ni nkan bii aago mẹjọ kọja ogun iṣẹju ni wọn ji awọn obinrin naa gbe bi wọn ṣe kuro ni iyara ti wọn de sí.
"Ọpọlọpọ nkan lati n ṣe bayii lati ri i pe ọrọ ijinigbe di afisẹyin ti eegun n fiṣọ.
Lọsan Ọjọru ni yoo ṣe igbaradi akọkọ pẹlu awọn agbabọọlu ẹgbẹ naa lalai fi asiko falẹ.
Oníbodè kò ṣí ìlẹ̀kùn, ó pa ìlẹ̀kùn ọ̀run dé mọ́ mi o.
Seyi Makinde fún olórin Fuji Taye Currency lẹ́bùn ọkọ̀ bọ̀kìnnì Toyota Prado 2020 Ọlọ́pàá fìyà jẹ mí lọ́dún 2014, mò wà lẹ́yìn àwọn ọ̀dọ́ lórí ìwọde EndSARS- Fayemi Ìbọn ń dún kíkan n‘Ibadan, àwọn òǹtàjà ti ṣọ́ọ́bù pa Ẹ jọwọ, ẹ ba mi bẹ ìyàwó mi kí ìgbéyàwó mi ma baà túká - 9ice Èyí ni bí wọ́n ṣe pín fásitì LAUTECH láàrín ìpínlẹ̀ Oyo àti Osun Ọkùnrin tó pe ìyàwó rẹ̀ lájẹ̀ẹ́ tì í mọ́lé fọ́dún mẹ́rin, fún un lóyún nígbà mẹ́ta!
Ìgbẹ́jọ́ Naira Marley sún síwájú bí àwọn agbẹjọ́rò ṣe ń jà sí àga ìjókòó Ohun mẹ́wàá tó yẹ kóo mọ̀ nípa Kunle Afod Seun Egbegbe lo ọdún méjì àti oṣù méje lẹ́wọ̀n láì tìí san béèlì rẹ̀ Fasiti Kaduna ni ki olùkọ́ lọ rọọ́kún nílé látààrí ẹ̀sùn pé ó ń dúnkookò mọ́ akẹ́kọ̀ọ́ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ogun flood: ọ̀ps àwọn olùgbé agbegbe yii ti fi iṣẹ́ sílẹ̀ nítorí wọn kò lè jáde Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Isede wa lasiko yi nitori Coronavirus.
Nígbà tí ilẹ̀ mọ́, àwọn àgbààgbà ati àwọn olórí alufaa ati àwọn amòfin péjọ, wọ́n fa Jesu lọ siwaju ìgbìmọ̀ wọn.
Lara awsn oṣere to wa ninu sinima yii ni Toyin Abraham, Dele Odule, Desmond Elliot, Seyilaw, Gbenga Adeyinka 1st, Woli Agba, Arole, Papi Luwe, Aisha Lawal, Rachael Okonkwo and Razak Olayiwola aka ojopagogo, and Bolanle Ninalowo.
èmi, Daniẹli bẹ̀rẹ̀ sí ka ọ̀rọ̀ OLUWA, mò ń ronú lórí ohun tí Jeremaya, wolii sọ, pé Jerusalẹmu yóo dahoro fún aadọrin ọdún.
 lóòótọ ́ ni Ọ ̀ rànmíyàn jẹ ọba ni Òkò , tó tún wá sí ilé-ifẹ ̀ .
gbogbo àkọ́bí ní ilẹ̀ Ijipti ni yóo sì kú.
Onyema loun ko jẹbi gbogbo ẹsun ti ẹka idajọ ilẹ Amẹrika fi kan oun, o ni oun ko tii ṣe jibiti ri pẹlu owo ti oun n ṣe.
Osinbajo ni olori ebu ni ojuse tire bee si ni ojuse ijoba  apapo ni lati mojuto eto ilera ati eto ẹkọ.
Botilẹ jẹ pe ijọba ilẹ Amerika ko dárúkọ awọn ti ọrọ naa kan, sugbọn o ni igbesẹ awọn ni lati tubọ mu eto iṣejọba awa ara wa ni Naijiria gbopọn sii Ẹwẹ atẹjade naa fi ku pe, awọn eniyan kan ni ifofinde yii n ba wi kii ṣe awọn ọmọ Naijiria lapapọ Afurasí kan yin Oloruntoba níbọn nítorí èdèàìyedè nílé oní Sharwama Wọ́n ti ní kí Jolaosho ""TBlak"" wá káwọ́ pọ̀nyìn r'ojọ́ ìdí tó fi ya ""Blue Film"" nínú igbó Osun Osogbo Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Aràrá bíi tèmi, kó má rò pé kò sì ǹkan tó lè ṣe láyé ju iṣẹ́ agbe lọ' 'Ẹ ki ọwọ́ ọmọ yín b'ọṣọ lásìkò ìdìbò gómìnà Edo àti Ondo, bíbẹ̀ẹ́ kọ́."
Hamu, baba Kenaani, rí baba rẹ̀ ní ìhòòhò, ó lọ sọ fún àwọn arakunrin rẹ̀ mejeeji lóde.
Oríṣun àwòrán, InSTAGRAM/MCOLUOMO Alaga ẹgbẹ ọlọkọ ero ni Eko tun fikun pe, inu iya oun ko dun pe oun n ṣe kọndọ, ti wọn si fẹ mu oun lọ sile ọmọ alaigbọran, ti wọn n pe ni welfare, amọ oun sa mọ wọn lọwọ, ti oun si n sun ita.
Ẹ jọwọ, ẹ ba mi bẹ ìyàwó mi kí ìgbéyàwó mi ma baà túká - 9ice Àwọn ìwàásù akọnilẹ́nu hàà tí Prophet Israel Oladele CCC Genesis Global ti ṣe rèé Báàgì Ghana Must Go pàwọ̀dà, ó di ohun táwọn ránsọ ránsọ fi ń dárà orísirísi Wòlíì míì, tún wọ gàù lẹ́yìn tó tàpá sí ìlànà béèlì tí wọ́n fún un nílé ẹjọ́ Gẹgẹ bi awọn onimọ nipa eto ọrọ aje ṣe sọ, ti ọrọ aje orilẹ-ede ba ti ja walẹ lere-lera laarin abala meji ọdun kan, o n tumọ si pe ifasẹyin ti de ba ọrọ aje irufẹ orilẹ-ede beẹ niyẹn.
Ọkunrin yìí ń ṣiṣẹ́ lọ́dọ̀ gomina ilẹ̀ náà, tí ń jẹ́ Segiu Paulu.
Pasitọ Adeboye ni atunto Naijiria gbọdọ waye laipẹ, ki ipinya ma ṣẹlẹ ni Naijiria.
"O dara ki ijọba maa gbe eto ilera ati iwosan oju wa si ẹsẹ pupu nitori aisi owo ati bi itọju aisan oju ṣe di ọwọngogo lo n fa ọpọ oju to n fọ laarin awọn ọmọ orilẹede Naijiria.
Coronavirus: Àwọn ìpèníjà márùn ún tó wà lórí pínpín abẹ́rẹ́ ajẹ́sara àrún Coronavirus
Àkọlé àwòrán, Akaara oyinbo ti wọn fi ohun elo orin bii gangan ati sẹkẹre se naa o gbẹyin Àkọlé àwòrán, Awọn adari ile ijọsin ati awọn Alfa ati imamu naa wa ba Gomina Abiọla Ajimobi se ẹyẹ ọjọ ibi.
'Mi o ti jingiri' Lẹyin ọdun mẹta, Okina to jẹ ẹni ọdun mejidinlogun ti o ti di akẹkọọ nipa amojuto okoowo ni fasiti ilu Calabar bayii ti gba gbogbo ọna lati ri owo ti awọn okoolerugba din maarun awọn ọmọde yoo fi kawe, o si tun ni aadọta eniyan ti o yọ nda ara wọn.
Èyíkéyìí tí kò bá jẹ́ dúdú ninu àwọn aguntan, tabi ewúrẹ́ tí àwọ̀ rẹ̀ kò bá ní dúdú tóótòòtóó tí o bá rí láàrin àwọn ẹran mi, a jẹ́ pé mo jí i gbé ni.
Fifi akukọ ja jẹ nkan ti ijọba fofin de lasiko Coronavirus yi.
didi - BBC News Yorùbá BBC News, YorùbáFò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù AFCON 2019: Èmi ò lè fi dáa yín lójú pé a máà bórí o - Ndidi Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ AFCON 2019: Èmi ò lè fi dáa yín lójú pé a máà bórí o - Ndidi 6 Agẹmo 2019 Oni loni n jẹ!
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Covid-19: Oluwo ní àṣẹ Ọlọ́run ni pé coronavirus ò lè wọ ìlú Iwo, àmọ́ òun ń wọ ìbòmú tórí olórí t'óun jẹ́ wákàtí 6 sẹ́yìn Oríṣun àwòrán, Instagram/oluwoofiwoland Oba AbdulRasheed Akanbi, Oluwo ti ilẹ Iwo ti sọ idi to fi n wọ ibomu lẹyin to ti sọ tẹlẹ pe arun coronavirus ko le wọ Iwo laelae.
Eeyan kan ni ẹka ọtẹlẹmuyẹ ileeṣẹ ọlọpaa ni awọn gba ipe pajawiri pe ọmọ kan sọnu lootọ lati agbegbe Masaka, iyẹn apa gusu ilu Kampala to jẹ olu ilu orilẹede naa.
re soro n salaye lori awon ewu to n pagidina idagbasoke orile-ede Naijiria ni
Eyi to le da alaafia ilu ru.
Wọ́n bi í pé, “Ta ni ọ́?
A ti gbé ìwádìí dìde lórí ìpànìyàn tó wáyé lásìkò ìwọ́de EndSARS- Ilé ẹjọ́ àgbáyé, ICC A kó ní sanwó oṣú ASUU láìjẹ́ pé wọ́n gba IPPIS- Ìjọba Àpapọ̀ Oṣú mẹ́fà ni òṣìṣẹ́ ìjọba tó bá bímọ yóò máa lò nílé kó tó wọṣẹ́ padà- Seyi Makinde Gomina Fayemi ni o ṣeni laanu wi pe awọn to n gba owo oṣu yii ko le e sọ pato ohun ti wọn n fi owo oṣu naa ṣe.
Ọmọ bibi agboole Lagunna ladugbo Agunpopo nilu Ọyọ ni Olori Abibat, kii si se ajeji rara si AafinỌyọ.
Nigba ti awọn kan lara awọn ọdaran yii jẹwọ ẹṣẹ wọn, awọn kan ni awọn o jẹbi ẹsun naa.
Adebanji Stephen Akintoye lọ sile iwe Emmanuel Primary school Ado Ekiti, ati Christ's School ni Ado Ekiti laarin ọdun 1951 si 1955.
Wákàtí díẹ̀ sẹ́yìn, Soto túwíìtì pé àwọn ti ń wá Luis Carlos Díaz fún wákàtí márùn-ún:
Ọjọ aiku, ọjọ karundinlọgbọn osu keji ọdun 2018, si ni Ayaba Badrat bi ibeji ọkunrin mejeeji naa.
Zainab lọ si orileede Saudi lati lọ ṣe Umrah ṣugbọn ko rii ṣe nitori ọjọ to de ibẹ naa ni wọn mu u.
Nítorí bí àṣẹ ọba ti le tó, ati bí adágún iná náà ti gbóná tó, ahọ́n iná tí ń jó bùlàbùlà jó àwọn tí wọ́n gbé Ṣadiraki, Meṣaki ati Abedinego sinu rẹ̀ ní àjópa.
Oríṣun àwòrán, Instagram/iyaboojofespris Wọn ko tiẹ se ayẹwo kankan fun mi, wọn kan gba owo lọwọ mi ni, ti wọn si fi ẹrọ yẹ ara mi wo bo se n gbona si."
O ni ati ẹyẹ igun, ati ẹni ti wọn n pe o yirapada sii ni wọn jijọ wa ni atimọle bayii.
Ta ni yóo bá mi dìde sí àwọn eniyan burúkú?
Mọrèmi Àjàṣorò, akọni obìnrin tó gba Ilé Ifẹ̀ sílẹ̀ lóko ẹrú Aarẹ ọna kakanfo Yoruba Kíni ìwọ mọ̀ nípa Funmilayọ Ransome-Kuti?
Mike Zhang fi da awọn ara ipinlẹ Kano loju wi pe oun yoo rii daju wi pe ibaṣepọ to nipọn wa laarin awọn ara Kano ati awọn ara orilẹede China.
Lẹyin iku Abubakar Audu to dupo labẹ APC ni APC fa Yahaya Bello kalẹ ti wọn si kede Yahaya Bello lọjọ kejilelogun, oṣu kọkanla.
ArabinrinArabinrin naa ti wọn pe orukọ rẹ ni Ganiyat Ganiyu dero agọ ọlọpaa ni ọjọ Aje.
Ẹ takò ó pẹlu igbagbọ tí ó dúró gbọningbọnin.
Ṣugbọn ní ọdún keje, Jehoiada ranṣẹ pe àwọn olórí ogun tí wọn ń ṣọ́ ọba wá sí ilé OLUWA pẹlu àwọn olórí ogun tí wọn ń ṣọ́ ààfin.
Bo tilẹ jẹ pe ileeṣẹ ọlọpaa sọ pe wọn ko lọwọ ninu iku arakunrin ọhun, ṣugbọn wọn ni wọn fi pampẹ ofin mu u nitori o wọ aṣọ ologun, ti kii sii ṣẹ ọmọ ogun Naijiria.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ganduje ń bèèrè bí Emir Sanusi ṣe se owó ìlú mọ́kumọ̀ku ‘Buhari gbà wá o, Seyi Makinde n fi jàǹdùkú halẹ̀ mọ́ wa láti kúrò lọ́ọ́fìsì’ Ilé ìgbìmọ̀ aṣòfin ikẹ̀jọ kógbá sílé l'Abuja Buhari, fí mí jẹ olùrànlọ́wọ́ pàtàkì fépo rọ̀bì- Guru Maharaji Aisha, bá ọ̀kọ̀ rẹ sọ̀rọ̀ ní yàrá lórí ìpèníjà ètò ààbò - Obasanjo Saraki wa lara awọn aṣofin ti ko ni pada fun saa tuntun mọ ni ile aṣofin apapọ orilẹ-ede Naijiria ti yoo bẹrẹ saa kẹsan an ni ọjọ kọkanla, oṣu kẹfa, ọdun 2019.
O ni abala labala ni won yoo seto abere ajesara naa fawon omode.
Mo sọ fún wọn nípa bí Ọlọrun ṣe lọ́wọ́ sí ọ̀rọ̀ mi ati nípa ọ̀rọ̀ tí ọba bá mi sọ.
Ṣugbọn gbogbo àwọn ará Israẹli ati Juda ni wọ́n fẹ́ràn Dafidi, nítorí ó jẹ́ olórí tí ń ṣe àṣeyọrí.
Ewe, orile-ede Tunisia ni o wa loke julo saaju orile-ede miran nile Afrika, leyin ti won di ipo kerinla mu lagbaye, ti Senegal ati DR Congo si di ipo méjídínlọ́gbọ̀n ati ipo méjídínlógójì ni itele n tele.
Gbogbo nǹkan wọnyi yóo ṣẹ patapata bí ẹ bá pa òfin OLUWA Ọlọrun yín mọ́.
Àwọn ẹ̀ṣọ́ ọ̀hún bá dáhùn pé, “Ẹnikẹ́ni kò sọ̀rọ̀ bí ọkunrin yìí rí!
Kiní ọ̀hún jọ iyọ̀, àmọ́ dídùn rẹ̀ yàtọ̀ sí ti iyọ̀, ó jọ ti oyin àti ìrèké.
Gbogbo àwọn tí a kà ninu ẹ̀yà Nafutali jẹ́ ẹgbaa mejilelogun ó lé egbeje (45,400).
Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí 3 sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 2:23 Fídíò, Water Generator: Ó leè ṣiṣẹ fún wákàtí mẹfà, kó tó sinmi, Duration 2,2310 Òkùdu 2020 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
kí alufaa yẹ̀ ẹ́ wò, bí ọ̀gangan ibẹ̀ bá funfun díẹ̀ tí ó dúdú díẹ̀, ara olúwarẹ̀ kàn fín lásán ni, ó mọ́.
O to ẹgbẹrun mẹwa ololufẹ rẹ to wo ija kan, koda awọn kan rinrinajo lọ wo o.
Èyí ni àwọn aṣíwájú ìjọba tí ajé ìwà ìjẹkújẹ ti ṣí mọ́ lórí láàrin ọdún 1960 sí àsìkò yí Ara mi rẹwà ló jẹ́ kí n máa ṣí ara sílẹ̀- Victoria Kolawole Àrẹ̀mọ Ooni Adeyeye Ogunwusi ti wọ Ààfin Ile Ife fún ìgbà àkọ́kọ́ Ẹ̀yin tí ẹ máa ń bú àwon tó sanra ni ẹ ń jẹ́ kí wọ́n ronú pa ara wọn - Eniola Badmus Kí làwọn nǹkan tó lè rán ọkùnrin sí ọ̀run alákeji lásìkò ìbálòpọ̀ pẹ̀lú obìnrin?
agbofinro ti ipinle Kano, DSP Abdullahi Haruna  ti so pe, ni kete ti awon  gbo iroyin naa ni awon ti bẹrẹ isẹ iwadii, ni
Davido lo fi ọrọ naa sita loju opo Instagram rẹ, nibi to ti ṣalaye pe bi oun ṣe de lati America laip yii, naa ni afẹsọba oun, Chioma de lati ilẹ Gẹẹsi pada si Naijiria.
Tọkọ taya kú lọ́jọ́ kan náà l'Abeokuta lẹ́yìn ìgbéyàwó ọdún méjìléláàdọ́rin 72 'Ṣọ́ọ́ṣì ni mọ ti ń bọ̀ kí n tó pàdé àwọn sójà tó fi abẹ gẹ irun fún mi' US Election 2020: Nígbà wo laó mọ èsì ìdìbò àti pé ṣé ó ṣeé figagbága?
AbdulQudus Bello ṣàlàyé bí òun ṣe dí aláàbọ̀ ara nítorí pọpọ́ọ̀fù àti ìbínú jàǹdùkù àdúgbò Àwọn ìṣẹ̀lẹ̀ mánigbàgbé tó wáyé nínú oṣù Kẹ́wàá ọdún 2020 Wo ìgbà márùn ún tí Buhari ti rìnrin àjò lọ sókè òkun fún ìtọ́jú ara rẹ̀ Buhari, dẹ́kun à ti máa lọ sókè òkun fún ìtọ́jú, tún ilé ìwòsàn Aso Rock ṣe- Sẹ́nátọ̀ Odunade ni iwadii fihan wi pe ko si ohun ti ileẹjọ le ṣe mọ, afi ki wọn tu igbeyawo naa ka nitori arabinrin Adebimpe naa buwọlu igbesẹ naa.
Funmilayọ tun tesiwaju lori ijajagbara fun ẹtọ awọn obinrin kaakiri ilẹ Adulawọ lọ si Ghana, Sierra-Leone ati bẹẹ bẹẹ lọ.
Lẹ́yìn tí wọ́n fi kakata hú gbogbo iṣú àti ẹ̀gẹ́ mí, wọ́n tún ṣá àwọn ọmọ mi ládàá-Guru Maharaj Ji Àwọn aṣekúpani tún ti pa ọmọ ọdún 16 ní Akinyele nípìnlẹ̀ Oyo Ìyá Barakat fi ẹ̀mí ìmoore hàn sí gbogbo àwọn tó nawọ́ síi lẹ́yìn ikú ọmọ rẹ̀ Mọ̀ síi nípa Shina Rambo tó pàdé Jesu lọ́gbà ẹ̀wọn lẹ́yìn tó ti jalè Bẹẹ naa ni Barakat Bello, ọmọbinrin ọdun mejidinlogun, ti wọn fi ipa balopọ, ki wọn o to o pa si ile awọn obi rẹ.
Abẹwo Aarẹ Buhari si Plateau Buhari ṣ'eleri iṣẹ f'awọn ọdọ Iroyin f'idi rẹ mulẹ wipe ọdẹ yi na papa bo'ra lẹyin iṣẹlẹ yi to waye ninu aigbo ọba.
Lẹyin eyi lo da ileeṣẹ iṣiro owo ara rẹ, Akintọla Williams & Co.
uhari - BBC News Yorùbá BBC News, YorùbáFò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù RUGA: Gbogbo ọmọ Nàìjíríà ló lásẹ láti gbé ìlú tó bá wù ú - Buhari 18 Agẹmo 2019 Oríṣun àwòrán, Google Àkọlé àwòrán, Àjọ Northern Elders Forum (NEF) láìpé yìí késí àwọn darandaran Fulani kí wọ́n padà sókè ọya ní kíákíá.
Bẹẹ ni ọrọ ri pẹlu awọn ọmọ ẹgbẹ Revolution Now to n se iwọde lati beere fun ijọba to duro re ni orilẹede Naijiria, nigba ti wọn pinnu pe awọn ko jade mọ fun iwọde ita gbangba ti wọn bẹrẹ lọjọ Aje.
Èèyàn 16 míràn tún ti ní àrùn Coronavirus ní Naijiria Ajọ to n risi idẹkun itankalẹ arun lorilẹede Naijiria, NCDC ti kede pe eniyan mẹe miran tun ti ni arun Coronavirus lorilẹede Naijiria.
#FreeSowore: Àwọn ọmọ Nàìjíríà fi gbe ta lórí Sowore tí DSS mú Ori ẹrọ ayelujare Twitter n gbona jainjain lẹyin ti iroyin sọ pe awọn olopaa ọtẹlẹmuyẹ(DSS) lorilẹede Naijiria ti ṣigun bo ile ọkan lara awọn oludije si ipo aarẹ lọdun 2019, Omoyele Sowore ni oru moju mọ Ọjọ Satide.
Ṣugbọn, adajọ ile ẹjọ naa, Abdullahi Ilelah, wọgile ẹjọ naa, lẹyin ti Abbo kọwe pe oun ko ni ẹjọ kankan latiu jẹ.
“ A o ni ona miiran ti a le gba ju, ki a maa pin ina yii si ara won lo, nitori pe afefe gaasi ni ina mona-mona n lo lorile ede Naijiria.
"Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Sunday Igboho: Ẹ fi Ògún búra fún wa láti jà fún ilẹ̀ Yorùbá láì gbé Amotekun sábẹ́ ìjọba SERAP ni ""Abala ti ko tọ rara ninu ofin naa ni agbara ti ijọba gbe fun ajọ CAMA lati maa dari awọn ileesẹ ti kii se tijọba naa."
Gẹgẹ bi awọn Dokita ti ṣe sọ, meji ninu awọn ọmọ yii ni wọn bi ni oku ọmọ nitori pe ko si awọn nọọsi ti yoo gbẹbi awọn awọn nọọsi da iṣẹ silẹ.
Koda a tun ma kan pe ki wọn se itọju nipa sise iranwọ atẹgun ọxygen fun ara ẹni naa.
Lẹyin naa, ti gbogbo awọn olukopa to wa nile wọle lọ ọ sun, ni awọn mejeeji jọ wa pọ lori ibusun kan naa.
Gbogbo àwọn eniyan ni ó fẹ́ràn wọn.
OLUWA, mo ké pè ọ́, tètè wá dá mi lóhùn,tẹ́tí sí ohùn mi nígbà tí mo bá ń ké pè ọ́.
Akintọla ni igbakeji gbajugbaja oloṣelu ni, Oloye Awolọwọ lẹgbẹ oṣelu Action Group.
Bakan naa ni awọn eniyan kan ni Ilẹ Gẹẹsi n sọ wi pe wọn ti wọgile bii Ilẹ Gẹẹsi se fẹ kuro ninu ajọ isọkan ilẹ Yuroopu ati bẹẹ bẹẹ lọ, ti wọn si n beere pe ki awọn eniyan mu eleyii to ba jẹ April Fool ninu rẹ.
    Bí Ọ̀kánjúwàfẹ̀yìntì ti dé owólayéemọ̀ gbé ìbọn ttì í ní ookan àyà tí ó yìn ín.
Ìyàwó mi ṣẹ̀ṣẹ̀ bímọ tuntun, kò si oúnjẹ fún wa torí ìgbélé Coronavirus- Yakubu Coronavirus ló lé mi kúrò níléèwòsàn UCH n'Íbàdàn- Ogun Majek Ta a ni yóò rọ́pò Abba Kyari gẹ́gẹ́ bi olórí òṣìṣẹ́ Buhari?
ti egbe  Peoples Democratic Party (PDP)gẹgẹ bi gomina  to jawe olubori ninu eto  idibo gomina to waye ni ipinlẹ Ọsun lodun
Ile iṣẹ iroyin naa ni ẹkun Oromia ni orilẹede Ethiopia ni wọn ti ya fidio naa nibi ti ikolu lile ti n waye laarin ẹgbẹ meji ninu ọdun yii.
Nípa ti àwọn kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ tí wọ́n sọnù láti ìjẹta, ẹ má da ara yín láàmú, wọ́n ti rí wọn.
Ogbeni Chen, leni ti o tuko
Ogun abẹ́lé tó ń ja Akeredolu l'Ondo, òní la ó mọ̀ bóyá yó borí rẹ̀ Ìjọba Amẹrika yọ orúkọ Sudan kúrò nínú ìwé orílẹ̀-èdè tó ń ṣagbátẹrù ẹgbẹ́ agbésùnmọ̀mí Èyí ni bí èèyàn 538 ṣe ń yan ààrẹ lé èèyàn mílíọ̀nù 331 ní Amẹ́ríkà Wo àwọn Adelé-Ọba aládé méje tó jẹ́ obìnrin nílẹ̀ Yorùbá Rògbòdìyàn bẹ́ sílẹ̀ láàrin àwọn ọlọ́kadà àti àwọn òṣìṣẹ́ ọgbà ẹ̀wọ̀n ní Ibadan Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Africa Eye: Wo ìtàn ìyá kan ìyá kan àtàwọn olè ajọ́mọgbé tó n ta ọmọ ní Kenya Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Ondo politics: Ilé ẹjọ́ da ìpèjọ́ pé Akeredolu kọ ló wọlé ìdìbò ìpińlẹ̀ Ondo nù16 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Kankara Abduction: Àwọn ológun ṣàlàyé ìdí tí wọ́n fi yọ̀nda àwọn tó jí àwọn akẹ́kọ̀ọ́ gbé.
 Àwọn ààmì wọ ̀ nyíi maa ń sábà bẹ ̀ rẹ ̀ ní ọjọ ́ mẹ ́ wà tàbí mẹ ́ ẹdógún lẹ ́ hìn ìgéjẹ .
Fun iyalẹnu gbogbo wọn, wọn ri asọ ibusun wa to kun fun ibale mi.
Nígbà tí àwọn ará Filistia gbọ́ pé wọ́n ti fi Dafidi jọba Israẹli, gbogbo àwọn ọmọ ogun wọn jáde lọ láti mú un, ṣugbọn Dafidi gbọ́ pé wọ́n ń bọ̀ wá mú òun, ó bá lọ sí ibi ààbò.
Nítorí bí ó ti ń ṣe yìí, gbogbo àwọn ọmọ Israẹli ni wọ́n fẹ́ràn rẹ̀.
Ègún OLUWA wà lórí ìdílé ẹni ibi,ṣugbọn a máa bukun ibùgbé àwọn olódodo.
Ọ̀kan ninu wọn tí ń jẹ́ Sedekaya, ọmọ Kenaana fi irin ṣe ìwo, ó sì wí fún Ahabu pé, “OLUWA ní kí n wí fún ọ pé, ohun tí ìwọ óo fi bá àwọn ará Siria jà nìyí títí tí o óo fi ṣẹgun wọn patapata.
Oríṣun àwòrán, @MBuhari O ni awọn ilana ti Buhari n gba yanju ọrọ eto aabo gẹgẹ bi Oludari gbogbo ileeṣẹ aabo, kii ṣe nkan ti gbogbo aye gbọdọ mọ.
Oríṣun àwòrán, BBC Tamil Àkọlé àwòrán, Baba rẹ ni ohun ti bẹrẹ si ni ko ile igbọnse naa, ati wi pe ohun ko le e pẹ kọ tan.
Ọlọrun ni olùgbàlà mi, n óo gbẹ́kẹ̀lé eẹ̀rù kò sì ní bà mí,nítorí pé OLUWA Ọlọrun ni agbára mi, ati orin mi,òun sì ni Olùgbàlà mi.
''Nigba ti iṣẹlẹ yi yoo fi ṣẹlẹ kii ṣe oṣiṣẹ wa mọ, fun ara rẹ lo kowe pe oun ko ṣiṣẹ mọ ṣugbọn a kan fun laaye ko ma gbe ibẹ ni tori pe oju lo n roju ṣaanu'' Ogbẹni Tunji Oladejo fidi ọrọ mulẹ pe awọn mọlẹbi oloogbe naa ti sin oku rẹ si iboji oku to wa ni Akinyele.
Faruk ati awon adari miiran kookan.
Ko si pẹ rara lẹyin eyi, wọn ti bẹ̀rẹ̀ si ni ṣe àwo orín fun ilé isẹ Philips West Africa Record ti wọn si ti fi orúkọ ẹgbẹ́ rẹ silẹ láti ṣeré lọjọ òmìnira orílẹ̀èdè Naijiria lọdun 1960.
Bí mo bá leè rí ọmọ alágbe t'áyé fẹnu sí pé mo fi ẹlẹ́rìndòdò lá lójú, máa kúnlẹ bẹ ẹ - Motara Oríṣun àwòrán, Twitter/Governor Borno Ṣaaju ni aarẹ ile aṣofin agba, Ahmed Lawan ti ba awọn eeyan ipinlẹ naa kẹdun lorukọ aarẹ Muhammadu Buhari ni aarẹ ti paṣẹ fawọn ologun lati tubọ mu gbigbogun ti awọn agbebọn Boko Haram lọkunkundun, paapaa julọ nipa gbigbe ija naa tọ wọn lọ si ibuba wọn.
Wọ́n sọ èyí di mímọ̀ lójú òpó Twitter wọ́n.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Maradona ba ọwọ pẹlu aṣọle ilẹ Gẹẹsi Peter Shilton ni abala to kangun si aṣekagba idije ife ẹyẹ agbaye lọdun 1986 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Goolu ti Mardona fọwọ jẹ ati eleyi to lamilaka to fi de a'\\seyọri Argentina lori England Oríṣun àwòrán, Rex Features Àkọlé àwòrán, Maradona lagbabọọlu ti o pegede julọ nidije agbaye ọdun 1986 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Mardona gba ife Uefa Cup lọdun 1989 ati ife liigi meji ni Napoli.
N kò ní mójú fo ọ̀rọ̀ wọn, n kò sì ní ṣàánú wọn.
 Ọgbẹni Musibau Rasak fọwọ si, o ni iroyin naa ba oun lojiji, o si ba jẹ ohun ibanujẹ nlanla fun oun ati awọn ọmọ ẹgbẹ Ile Igbimọ Aṣofin Ipinlẹ Eko lapapọ.
Má Ṣe Dá Ẹnìkejì Rẹ lẹ́jọ́.
Bí ìwọ bá ní igbagbọ ní tìrẹ, jẹ́ kí igbagbọ tí o ní wà láàrin ìwọ ati Ọlọrun rẹ.
 27 : 39 ] [ mii .
Cornavirus: Makinde tọrọ aforiji fun ìpàdé ìta gbangba ẹgbẹ́ PDP tó wáyé nílu Ibadan
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ọmọ ilẹ̀ Kenya gbé ‘búrọ́ọ̀ṣì ìfọyín’ mì nígbà tó ǹ fọyín 6 Ìgbé 2018 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 21 Èbibi 2020 Oríṣun àwòrán, AFP Àkọlé àwòrán, Bawo ni burọsi ifọyin se le de ikun eniyan?
Lẹ́yìn ìgbà tí ìjọba rẹ̀ ti fẹsẹ̀ múlẹ̀, ó pa gbogbo àwọn tí wọ́n pa baba rẹ̀.
so nipa awon omo orile ede Naijiria to n gbe inu ilu naa.
A gbọ́ pé ọwọ́ tẹ̀ ẹ́ nígbà tí àwọn ojúlówó agbẹjọ́rò tó wà nínu ilé ẹjọ́ nígbà tí ó ń sọrọ níwájú adájọ funra pé kò kàwé.
Kò sí iléẹjọ́ tó le dá wa dúró, ìyanṣẹ́lódì yóò bẹ̀rẹ̀ ní Ọjọ́ Ajé - NLC Wo iye ìgbà tí ẹgbẹ́ òṣìṣẹ́ àtàwọn ọmọ Nàìjíríà ti ṣèwọ́de lórí àfikún owó epo bẹntírò Ìbúgbàmù gbogbo ìgbà nílù ú Èkó, kí ló ń ṣokùnfà rẹ̀?
"Ọgbẹni Lukashenko ti sọ ọ jade lẹnu ri pe ẹnikẹni to ba dara pọ mọ ifẹhonuhan alatako gẹgẹ bii adunkoko mọni, ""a o yin in lọrun bii ti pẹpẹyẹ ni""."
Apakiṣadi ni baba Ṣela, Ṣela sì ni baba Eberi.
Amọṣa, diẹ ninu wọn ni ọwọ awọn ko tii tẹ eku ida eto ẹkọ nitori naa awọn n pada lọ si ile ẹkọ lati lọ kẹkọ.
OLUWA ní, “Ẹ̀yin ni ẹlẹ́rìí mi,ẹ̀yin ni iranṣẹ mi tí mo yàn;kí ẹ lè mọ̀ mí, kí ẹ sì gbà mí gbọ́,kí ó sì ye yín pé, Èmi ni.
Ó dá wọn lóhùn pé, “Bẹ́ẹ̀ ni, Elija ni ó níláti kọ́ dé láti mú ohun gbogbo bọ̀ sípò.
Olórí ilé aṣòfin ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́, Michael Adeyemo jáde láyé
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Botswana: Ìdí tí erin àti òkúta Dáyámọ́ǹdì yóò fi leè sọ olúborí èsì ètò ìdìbò ààrẹ 22 Ọ̀wàrà 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Orilẹede Botswana yoo ṣeto idibo apapọ rẹ lọjọ kẹtalelogun oṣu kẹwa, bẹẹni eto ifọrọwerọ ti BBC World Questions debate gbe kalẹ ti ṣe awari rẹ ni ilu Garborone pe ipa diẹ kọ ni okuta iyebiye Dayamọndi ati erin lee ko ninu esi idibo naa.
Ọdun 2017 ni Sẹnetọ Dino Melaye to wa lati ipinlẹ Kogi kọkọ gbe aba ofin naa kalẹ niwaju ile igbimọ aṣofin.
Ninu odò yìí ni o óo ti máa bu omi mu, mo sì ti pàṣẹ fún àwọn ẹyẹ ìwò kan pé kí wọ́n máa gbé oúnjẹ wá fún ọ níbẹ̀.
N kò fẹ́ dá irú ẹjọ́ bẹ́ẹ̀.
Isọri keji awọn ọmọ Naijiria to de lati ilẹ Gẹeṣi balẹ si papakọ ofurufu Murtala Muhammed (MMIA), niluu Eko Ṣaaju ni awọn mii ti rinrin ajo wale lati Dubai lorilẹede United Arab Emirates (UAE) Lẹyin ti wọn ṣe ayẹwo bi ara wọn ṣe n gbona si ni wọn fi ọkọ ko wọn lọ si ibudo iyatọ ti wọn ti pese silẹ fun wọn.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù World Menopause Day: Ǹkan osù tó ń se ségesège jẹ́ àmì 18 Ọ̀wàrà 2018 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 19 Ọ̀wàrà 2018 Àkọlé àwòrán, Dokita onimọ nipa obinrin ni irinwo ẹyin lo wa lara obinrin ati wi pe osoosu si ni ẹyin naa n dikun lasiko ti wọn ba n se nkan osu.
Ẹ máa gbé ìgbé-ayé yín pẹlu ọgbọ́n níwájú àwọn alaigbagbọ.
Ẹ jẹ ki a wo awọn ifẹsẹwọnsẹ iṣaaju ti awọn ikọ mejeeji yii ti pade Argentina v Nigeria (2-1) Ni ọdun 1994 ni ikọ Super Eagles orilẹede Naijiria ọkọ farahan ni idije ife ẹyẹ agbaye ti FIFA, ifẹsẹwọnsẹ keji ti wọn si gba nigba naa jẹ pẹlu ikọ Argentina, eleyi ti gbajugbaja agbabọọlu ni, Diego Maradona ko sodi gẹgẹ bii Balogun.
Awon oga agba amunidara miran to wa nibe ni Bridget Awosika, Emmy Kasbit, Gozel Green, GREY, IAMISIGO, Kenneth Ize, Maxivive, Mo Agusto, Onalaja, Orange Culture, Re, Sisiano, Style Temple, Sunny Rose ati Tsemaye Binitie.
Okpe sọ pe: Awọn mẹtadinlogoji ni ijamba naa kan, okunrin ogun, obirin mẹẹdogun ati ọmọde meji.
Kidnapping: ASUU kọminú lórí ọwọ́jà ìjínigbé, pè fún àbò fáwọn olùkọ́ fásitì
Koda, ileeṣẹ ologun ni a\\won ọmọ ogun Naijiria fakọyọ ti wọn si kọlu awọn oniṣẹ ibi yii pupọ.
Kò ní pa iná tí ó ń jó bẹ́lúbẹ́lú,títí ìdájọ́ òdodo rẹ̀ yóo fi borí.
Amotekun: Àwọn èèyàn sọko ọ̀rọ̀ sí Tinubu lórí ìkéde rẹ̀ nípa Amotekun
“Kí ni mo fi ṣe yín rí, ẹ̀yin ilẹ̀ Tire, ati ilẹ̀ Sidoni ati gbogbo agbègbè Filistini?
Ni bayi ohun ti wọn n sọ ni pe ẹṣọ naa ko ku mọ ati pe o n gba itọju lọwọ nile iwosan ni.
 ìṣètò aromatic nlá bíi pentacene tún ṣeéṣe .
Yoòbá bọ̀ wọ́n ní “Ajá ìwòyí là ń lé sí ehoro ìwòyí”.
gomina ipinle Zamfara, ogbeni Sanusi Rikiji ati awon omo egbe igbimo isakoso re
Mike Tyson vs Roy Jones: Ìjà Mike Tyson pẹ̀lú Roy Jones Jr kò ní wáyé mọ́ lóṣù tó ń bọ̀- The Ring
"Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ọlọ́pàá dóòlà ọkùnrin kan tí wọn so mọ́lẹ̀ fún ọdún mẹ́ẹ̀dógún ""Àwa Emèrè Onítẹ̀síwájú la ṣèpàdé nílé Elebuibon, kìí ṣe Oṣó àti Àjẹ́"" Nǹkan wọ̀lú!"
 bó bá tilẹ ̀ ṣe orúkọ ló yípadà , àwọn ọmọ Ọkànbí ni ọba méje pàtàkì ni ilẹ ̀ yorùbá tí kò sí Ọbàlùfọ ̀ n nínú wọn .
Òun ni yóo kọ́ ilé fún mi, n óo sì rí i dájú pé ìran rẹ̀ ni yóo máa jọba títí laelae.
Wọ́n ní tí ẹ bá dé ibi sẹ́lẹ̀ru Sulis, tí ẹ ju owó sínú ẹ̀, ẹ di olóríire nìyẹn.
Nígbà tí Ahasaya rí ohun tí ó ṣẹlẹ̀, ó sá gba ọ̀nà Beti Hagani lọ.
Awon agbofinro ni orile-ede Dubai ti pari ejo ti won n se lori iku ogbontarigi osere omo India to ku si Dubai, iyen, Sridevi Kapoor.
Ẹ jẹ́ kí á wá siwaju rẹ̀ pẹlu ọpẹ́;ẹ jẹ́ kí á fi orin ìyìn hó ìhó ayọ̀ sí i.
Lóri ọ̀rọ̀ àwọn àgbà nínú òṣèrè ti wọ́n ku ti ọ̀pọ̀ wọ́n si n ṣe àìsàn, Mr Latin ní, ẹgbẹ́ ń ṣe ìwọ̀n to lè ṣe, sùgbọ́n ìhà ti ẹgbẹ́ yóò ko si irú ẹni bẹẹ ti wà lori irú ìhà ti ẹni náà kọ si ẹgbẹ́ nígbà ti ara rẹ̀ ji pépé.
Òun ló gbá ìkùukùu jọ láti òpin ilẹ̀ ayé,ó fi mànàmáná fún òjò,ó sì mú afẹ́fẹ́ jáde láti inú ilé ìṣúra rẹ̀.
 bijuga , budjago , bugago .
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Buhari yóò ṣèpàdé pẹ̀lú Ọba Morocco 9 Òkùdu 2018 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Èyí yòó wáyé lẹ́yìn ìpàdé tí wọ́n ti kọ́kọ́ ṣe l'óṣù Kejìlá, ọdún 2016, lásìkò tí Ọba nàá ṣàbẹ̀wò sí Nàìjíríà.
naijiria ni orile-ede kejo ti o ni awon eniyan topojulo laye .
” Dafidi bá rán oníṣẹ́ lọ sọ́dọ̀ rẹ̀ láti tù ú ninu, nítorí ikú baba rẹ̀.
Bakan naa lo ti kọ lẹta si Aarẹ Muhammadu Buhari lori eto aabo nilẹ Yoruba, ninu eyi to ti sọ fun aarẹ pe ko fi opin si bi awọn kan ṣe n kọlu ilẹ Yoruba.
to n ba ijoba aare  Ramaphosa  wọya ija lọwọ -lọwọ  bayii, ni eyi ti aare naa ti seleri lati wa
Ǹjẹ́ yóo máa ké pe Ọlọrun nígbà gbogbo?
Water Resources Bill: Wo ohun tó wà nínú òfin nípà àbádòfin lórí omi tí ìjọba rẹ́ buwọ́lù
Alaga fun ile-isẹ to n risi ọrọ owo to n wọle labẹle ni ipinlẹ Ondo, Tolu Adegbie nigba to n ba BBC sọrọ wipe igbesẹ ijọba ipinlẹ naa ni lati pese ohun amayedẹrun fun awọn ara ilu nipa pipa owo wọle labẹle lọna ti ko ni pa awọn ara ilu lara.
“Ìwọ ọmọ eniyan sọ fún àwọn àgbààgbà Israẹli pé, OLUWA Ọlọrun ní, ‘Ṣé ẹ wá wádìí ọ̀rọ̀ lọ́wọ́ mi ni?
 ashe , tí ó jẹ ́ ọmọ afrika ameríkà , tún jẹ ́ riranti fun akitiyan re fun ilosiwaju awujo .
gbọ́ adura tí wọ́n bá gbà, ati ẹ̀bẹ̀ tí ẹnikẹ́ni tabi gbogbo Israẹli, àwọn eniyan rẹ, bá bẹ̀, nítorí ìpọ́njú ọkàn olukuluku wọn.
Wo bí bàbá ẹni ọdún 67 yóò ṣe tún lo ọdún 25 ayé rẹ̀ lẹ́wọ̀n Ẹ wo ọ̀nà márùn ùn tí ọkùnrin ṣì fi ń jẹ gàba lé obìnrin lórí 'Fáàbàdà!
EFCC: Ààrẹ Buhari ní gbogbo àwọn aṣèbàjẹ́ ni wọn yóò fojú winá òfin
Orúkọ wọn ni Mahila, Noa, Hogila, Milika, ati Tirisa.
Eyi yoo mu ko fi ẹyin minisita fun okoowo l'orilẹ-ede South Korea, Yoo Myung- he, ti wọn jọ de ipele to kẹhin.
Ó wí fún baba rẹ̀ pé, “Bẹ́ẹ̀ kọ́, baba, eléyìí ni àkọ́bí, gbé ọwọ́ ọ̀tún rẹ lé e lórí.
Àwa pàápàá délé, ṣùgbọ́n ìyá mi àti bàbá mi kò sí ní ilé; wọ́n ti lọ sí ilé- ìsìn mǐràn tí wọ́n pè wọ́n sí.
Fọnran kan to jade laipẹ yii nibi eto ti Foluke Daramola ṣe lo ṣafihan bi Pa Kasumu ti ri nitori aisan to ti n ba a finra lati ọjọ pipẹ.
Nígbà tí ó ń wo Ijipti lókèèrè, ó sọ fún Sarai aya rẹ̀ pé, “Ṣé ìwọ náà mọ̀ pé arẹwà obinrin ni ọ́, 
Ọmọ Yoruba lati ipinle Ogun lawọn obi rẹ.
 Ó jẹ ́ ìwé ìtàn tí a kọ ́ kọ ́ kọ ní èdè yorùbá , tí ó sì jẹ ́ ìkan lára ìwé ìtàn tí a má a kọ ́ kọ ́ kọ ní èdè Àfíríkà .
Nigba to n sọrọ lori ayipada ile ọhun, oṣiṣẹ ijọba Turkey kan sọ pe awọn eeyan ṣi le maa ṣabẹwo si ile ọhun bo tilẹ jẹ pe o ti di Mọṣalaṣi bayii.
2 Bélú 2020 Fídíò, Soyinka Cancer: Àṣe ara mi ni iso ti n run gbogbo bí mo ṣe n ṣèrànwọ́ lórí jẹjẹrẹ27 Bélú 2019 Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
O ni nnkan bii agogo mẹrin abọ irọlẹ ni wọn gbe e de ti awọn oṣiṣẹ iṣegun oyinbo to wa nibẹ si sa ipa wọn lati doola ẹmi rẹ ṣugbọn to ja si pabo.
Amir Hatami ti o je minisita to n mojuto eto aabo lorile-ede Iran lo jabo oro naa fun awon akoroyin lasiko ipade re pelu aare orile-ede Syria Bashar al-Assad ati minisita to n mojuto eto aabo, Ali Abdullah Ayyoub lorile-ede naa.
”Má fi ibinu lé èmi iranṣẹ rẹ kúrò,ìwọ tí o ti ń ràn mí lọ́wọ́,má ta mí nù, má sì ṣá mi tì,Ọlọrun ìgbàlà mi.
“Ó bá pe ọ̀kọ̀ọ̀kan ninu àwọn tí ó jẹ ọ̀gá rẹ̀ ní gbèsè.
Ni ṣe ni o'n sọ ọrọ yi nipa NRA lati igba ti iṣẹlẹ iyinbọnpaniyan ti waye ni ile ẹkọ kan lọjọ kẹrinla oṣu keji ọdun yii ni Parkland, nilu Florida.
Ẹwẹ, ọpọ lo gboṣuba fun Onyema ninu oṣu kẹsan an lẹyin to lo baalu ile iṣẹ rẹ lati gbe awọn ọmọ Naijiria ti wọn ha si orilẹede South Africa lasiko ikọlu awọn ọmọ ilẹ naa sawọn ọmọ Naijiria lọfẹẹ.
” Mo bá dáhùn pé “Mo rí ìwé kíká kan tí ń fò ní òfuurufú.
Ọdun 1666 Lẹyin adanwo ati ina nla to ja ni ilu London eyi to pa ọpọ eeyan lọdun naa ẹgbẹ ẹlẹsin kan to jẹ iran to n dari sọ pe ọdun yẹn ni aye yoo parẹ ṣugbọn ko ri bẹẹ.
Jesu tún sọ pé, “Mo fẹ́ kí ẹ mọ̀ dájúdájú pé, èmi ni ìlẹ̀kùn àwọn aguntan.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ohun marun t'ejo n jẹ 13 Èrèlè 2018 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Oṣiṣẹ ile iṣẹ ajọ JAMB sọ pe ejo gbe owo mi Ejo jẹ ẹranko to maa n faya wọ, lati ẹka ẹranko to maa n jẹran nikan, ti o si le jẹ ajo bi ara rẹ.
OLUWA Ọlọrun ṣe ọgbà kan sí Edẹni, ní ìhà ìlà oòrùn, ó fi eniyan tí ó mọ sinu rẹ̀.
Ìkìlọ̀ Ìkẹyìn Tí Dafidi ṣe fún Solomoni.
Ibi ààbò ni Dafidi wà nígbà náà, bẹ́ẹ̀ ni àwọn ogun Filistini sì ti wọ Bẹtilẹhẹmu, 
Iroyin ni, Joel jẹ atipo lati orilẹede Cameroon ti ijọ kan ran lọwọ nigba to kọkọ wọ Naijiria.
Ninu Atẹjade, Oluwo ṣalaye pe lilo ibomu yoo pinwọ itankalẹ arun Coronavirus ni ipinlẹ Ọṣun ati jakejado orilẹede NAijiria.
Oríṣun àwòrán, AFP Àkọlé àwòrán, Ọkọ-akẹru yii da bii ẹni pe ọkan rẹ balẹ lẹyin igba ti agba gbe danu nilu Isinya, to to ogoji mẹli si olu ilu Kenya, Nairobi.
9m kalẹ̀ fún owó oṣù òṣìṣẹ́ ní Kwara ‘Irọ́ ni, Saraki kò kí alátakò rẹ̀ kú oríire’ Irú ẹ̀dá wo ni aṣòfin Bukola Saraki jẹ́?
'Tinubu ta ẹmi rẹ, ta ọkan rẹ, to si ta gbogbo ilẹ Yoruba, to fi mọ Guusu ati Ariwa orilẹede Naijiria lati le ri wi pe oun mu gbogbo ero ọkan rẹ to kun fun ibi ṣẹ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Adamawa: Ọlọ́pàá mú ẹyẹ igún sí àtìmọ́lé ní ìpínlẹ̀ Adamawa 24 Èbibi 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ileeṣẹ ọlọpaa ni awọn ṣi n ṣewaadi ẹsun ti wọn fi kan ẹyẹ igunnugun naa Ile iṣẹ ọlọpaa ni #30, 000 ($86, £67) ni awọn fi bọ igun naa ati olowo rẹ laarin ọjọ mẹfa to fi wà ni atimọle.
Senegal  bo si ipele kerin, ti won yoo si maa koju Latvia, USA ati China.
Elioenai bí ọmọ meje: Hodafaya, Eliaṣibu, Pelaaya, Akubu, Johanani, Delaaya ati Anani.
Ọlọ́pàá Adamawa ni #30,000 ni wọ́n fi bọ́ igún látìmọ́lé Wo àwọn míniístà mẹ́fà tí ẹnu ń kùn jùlọ Lasiko to n sọrọ lori owo oṣu oṣiṣẹ to kere ju, Makinde ni lọwọlọwọ bayii, ipinlẹ Ọyọ ko lee san ẹgbẹrun lọna ọgbọn naira fawọn osisẹ.
Àwọn jàndùkú agbébọn''jí akẹ́kọ̀ọ́ lọ nílé ìwé girama Katsina'' lẹ́yìn tí Buhari gúnlẹ̀ sí bẹ̀ Yoruba bọ wọn ni ọmọ ẹni ku san ju ọmọ ẹni nu lọ, eyi lo difa fun Gomina ipinlẹ Katsina to bẹ sẹkun gbaragada lẹyin tawọn janduku agbebọn yabo ileewe girama kan to wa ni Kankara, nipinlẹ Katsina nibi ti wọn ti ji ọpọ akẹkọọ lọ.
"Ileewe ẹkọ imọ ilera ati iṣegun ni ọgba fasiti naa ni ọjọgbọn Adegbẹhingbe ti n ṣiṣẹ.
Yomi Fabiyi, ẹni to se apejuwe iwa titẹ ẹtọ ọmọniyan loju ti awọn agbofinro lorilẹede Naijiria n se gẹgẹ bii iwa asiwere, tun kede pe awa ọmọ Naijiria kii se ẹranko, yoo si dara ki wọn dẹkun iwa ailaju naa.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Mummy calm down: Ìyá Ore sọ pé gbogbo ìgbà tí óun bá n bá a wí ló ma n ṣe àwàdà Ninu ọrọ to ba awọn oniroyin sọ, igbakeji alaga ẹgbẹ awọn obi ati olukọ PTA ni ipinlẹ Ogun, Alagba Kẹhinde Sanwo ṣalaye fawọn oniroyin pe ko yẹ ki ijọba maa dẹyẹsi awọn akẹkọọ ileewe aladani ati si awọn akẹkọọ ileewe ijọba nitori pe ọmọ ipinlẹ Ogun naa ni gbogbo wọn.
Alukoro ọlọpaa wa pari ọrọ rẹ pe, wọn ti gbe lọ si ẹka ọtẹlẹmuye fun ẹkunrẹrẹ iwadii .
12 Àti, ní ọ̀nà yìí, Sátánì ti lépa lati gbé ète àrékérekè kan kalẹ̀, kí òun lè pa iṣẹ́ yìí run.
Bo ṣe oke ọya ni bo si ṣe ilẹ Igbo tabi Hausa, ọna gbogbo ni awọn ọkọ Ibadan maa n rin.
Àwọn tó ní ààrùn Coronavirus ní Nàìjíríà ti pé 29,789 Ti ẹ ko ba gbage, ninu oṣu kẹjọ ọdun 2018 ni ijọba apapọ ti afara Third Mainland fun ọjọ mẹta fun ayẹwo.
 Oríṣun àwòrán, others Àkọlé àwòrán, Obinrin kan to sọ pe oun ni iyawo Asif da ayẹyẹ igbeyawo naa ru."
Ẹ gbọ́, ẹ̀yin eniyan mi, nígbà tí mo báń kìlọ̀ fun yín,àní kí ẹ fetí sílẹ̀ sí mi, ẹ̀yin ọmọ Israẹli!
àwọn ará Arifadi, àwọn ará Semari ati àwọn ará Hamati.
Ṣugbọn arabinrin aboyun naa lo funra rẹ bu ekiri ẹran ati pe aṣọ inuwọ lasan lo kan beere lowo oun lati fi yi wọn pamọ.
O kawe ni ile ẹkọ gbogbo niṣẹ ikọni niṣẹ imọ ẹrọ ti Yaba College of Technology, ni ipinlẹ Eko.
Suarez ni Liverpool kii ṣe ẹran rirọ nigba kugba ti wọn ba n koju ẹgbẹ agbabọọlu miran ni papa isẹre Anfield Suarez gba goolu kan sawọn nigba ti Messi jẹ goolu meji ninu abala akọkọ ifẹsẹwọnsẹ yii to waye ni Camp Nou.
Ìlérí Pé Oluwa Yóo tún Pada Wá.
O gbọdọ dara si awọn ẹbi rẹ ki o si ra aṣọ tuntun fun wọn ti o ba lagbara rẹ, ki wọn si lọ yidi pẹlu awọn obinrin.
Oríṣun àwòrán, OTHER Idahun: 'Irọ́ ni o, àò pinnu láti kógbá Shoprite wọlé ní Nàìjíríà' Awọn alaṣẹ ile itaja nla Shoprite ti sọ pe awọn ko gbeero lati fi opin si okoowo wọn ni orilẹ-ede Naijiria.
Kí o máa rí ire Jerusalẹmuní gbogbo ọjọ́ ayé rẹ.
O sọ pe awọn olootu ere tiata laye igba naa maa n kọ ẹnu ifẹ si awọn arẹwa obinrin laarin awọn oṣere.
Orílẹ̀èdè Canada fọwọ́ sí kí wọ́n máa fi igbó sararindin
Sera bí ọmọ marun-un: Simiri, Etani, Hemani, Kalikoli ati Dada.
Ààbò tó péye wà fún àwọn okòwò ará South Africa ni Eko -Sanwo Olu Akeredolu ò ṣe ǹkan àrítọ́kasi ni Ondo- Komísọnà ọ̀rọ̀ to n lọ tẹ́lẹ̀rí Ọlabisi Ajala rèé, ó gun ọ̀kadà yíká àgbáyé, tó sì dé orílẹ̀èdè 87 Ẹ máṣe gba ààwẹ̀ dójú ikú, ẹ gba iye tí agbára yín gbé - Dókítà Wọn tun maa n jẹ gbolohun alọ́niláhọ́n to jẹ pe o maa n gba ero ati ifarabalẹ ki eeyan to le gba a daadaa.
Ninu oro re gege bi abẹnugan tuntun, Alhassan Rurum, wa seleri lati maa se isẹ rẹ  lona to tọ ati lona to yẹ ati lati maa jẹ ki awọn Igbimọ mọ nipa igbese to ba fẹ gbe.
Ṣugbọn, nitori eto lati gba awọn ọmọ ogun l'ọkunrin ati l'obinrin si ileeṣẹ ologun ori ilẹ, oju ofurufu ati ori omi, lo mu ki ileeṣẹ eto aabo fẹ ẹ yi ofin naa pada.
Ọlọpaa ni wọn pa baba wọn nitori wipe o kọ lati lọ gbe ile awọn arugbo nibi ti wọn fẹ ko lọ ku si.
Ninu awọn origun ijọsin musulumi,awẹ gbigba ninu oṣu Ramadan jẹ ọkan gbogi.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ifesewonse ìkẹta lera rèé ti wọn yóò pokọ iya fún Arsenal 28 Ìgbé 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 29 Ìgbé 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ifesewonse ìkẹta lera rè ti wọn yóò tí pokọ iya fún Arsenal Ìgbà kẹta rèé léra wọn ti ìyà ń ba ìyà fún ìkọ ẹgbẹ́ àgbabọọlu Arsenal, èyí sì mú wọn to sẹ̀yìn Chelsea ti yóò koju Manchester United ní old Trafford Nínú ìfẹsẹwọnsẹ tó tún wáyé lónìí láàrin Leicester City àti Arsenal ní wọn ti gbẹwuro àmi àyó mẹ́ta si òdo fún Arsenal.
Nígbà wo ni a rí ọ níhòòhò tí a daṣọ bò ọ́?
Ohun tí mo ti pinnu nípa gbogbo ayé nìyí,mo sì ti na ọwọ́ mi sórí orílẹ̀-èdè gbogbo láti jẹ wọ́n níyà.
Ko yẹ ki iran ode oni ma mọ itan igbe aye Ayinla Ọmọwura rara, nitori odu ni fun oloko lawujọ awọn olorin.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìtàn Mánigbàgbé: Bí Ẹfunroye Tinubu ṣe di ilú Ẹ̀gbá mú, ló ń pàṣẹ ní Eko 12 Èrèlè 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 5 Ìgbé 2020 Oríṣun àwòrán, @pin_africa Ti a ba n sọrọ awọn akọni obinrin nilẹ Yoruba, ti a ko ba ti darukọ Iyalode akọkọ nilẹ Ẹgba, Ẹfunroye Tinubu, a jẹ pe itan naa ko ti kun ni.
Cedrick Bakambu gba ami ayo keji
Wọn ra aṣọ, wọn si se gbogbo eto to yẹ ni ireti ọmọ tuntun to n bọ, ṣugbọn ko sẹni to ranti nipa aisan ailera to le ṣẹyọ lẹyin ibimọ.
Orísìírísìí ẹ̀yà oúnjẹ yìí ni ó wà.
majẹmu tí ó bá Abrahamu dá,ìlérí tí ó fi ìbúra ṣe fún Isaaki, 
Ìtàn ìgbé ayé Bamidele Olumilua, àgbà òṣèlú tó jáde láyé Wọ́n tún ti pa ọmọbìnrin míì lásìkò ìbálòpọ̀ tipá nílùú Ibadan Wàhálà tí àwọn ẹgbẹ́ òkùnkùn àt'àwọn ẹgbẹ́ ìjayà míràn ń dá sílẹ̀ láwọn ọgbà fásitì Nàìjíríà Irú kí lèyì!
Ogidi ọmọ Kaarọ Oojiire ni Adebisi Ogundeji, tii ṣe iya Seal, nigba ti baba rẹ, Francis Samuel, jẹ alawọ dudu ọmọ orilẹ-ede Brazil.
Èmi ni OLUWA, Ẹni Mímọ́ yín,Ẹlẹ́dàá Israẹli, Ọba yín.
Àsọtẹ́lẹ̀ Fada Mbaka, tó yẹ àga mọ́ gómìnà Imo nídìí rèè Wo ipa tí Mayegun yóò ma kó ní ilẹ̀ Yoruba!
Wọn kò wẹ egbò àwọn eniyan mi jinná, wọ́n ń kígbe pé, ‘Alaafia ni, alaafia ni,’bẹ́ẹ̀ sì ni kò sí alaafia.
"josephine baker ( june 3 , 1906 - april 12 , 1975 ) je onijo , akorin ati osere omo amerika ara fransi to je mimo kaakiri bi "" black pearl "" , "" bronze venus "" ati "" creole goddess "" ."
Ó rí egungun páárì ẹ̀rẹ̀kẹ́ kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ kan tí wọ́n ṣẹ̀ṣẹ̀ pa, ó mú un, ó sì fi pa ẹgbẹrun ninu àwọn ará Filistia.
Bi o tilẹ jẹ pe ijọba fi katakata wo ajaalẹ naa mọlẹ, to si run womuwomu, sibẹ ọpọ eeyan lo n fi ẹnu kun ijọba Ajimobi pe ko fi ẹnikẹni jofin lori isẹlẹ naa.
'Títẹ àwọn afipábánilopọ̀ lọ́dàá kọ́ ni ọ̀nà àbáyọ sí ìwà ìfipábánilopọ̀' Àwọn àmì tó fi mọ̀ pé wọn ń fipá bá ọmọdébìnrin rẹ lòpọ̀ Ó rẹ ẹni ọdún 49 tó ri ẹ̀wọ̀n ọgọ́ta ọdún he lẹ̀yìn tó bá ọmọ ọdún méjì lòpọ̀ Nigba to n salaye ohun ti iwe akọsilẹ naa wa fun awọn awọn igbesẹ to rọ mọ lilo rẹ, oludari fun ẹka eto itaniji fun araalu labẹ ajọ Naptip, Arinze Orogwe salaye fun BBC Yoruba pe eto yii lo jẹ eyi to kan tọmọde tagba lorilẹede Naijiria.
Ó bá wí fún un pé, “Pada lọ sùn.
Níbẹ̀ ni Balaki ti fi akọ mààlúù ati aguntan ṣe ìrúbọ, ó sì fún Balaamu ati àwọn àgbààgbà tí wọ́n wà pẹlu rẹ̀ ninu ẹran náà.
”Eto iranwo ounje je eyi ti
Oni lo pe ọdun mejila ti Orlando Owoh, agba ọjẹ onkọrin ni di ara ọrun.
 A ti kogbon lopolopo seyin, a si ti pinnu lati ma fayegba asise ti a se lodun 2015 bi o se le wu ko mo.
Increment in bread price: Ọ̀wọ́ngógó búrẹ́dì gbòde kàn lẹ́yìn tí àwọn oníbúrẹ́dì da iṣẹ́ sílẹ̀
Bamidele dara pọ mọ ẹgbẹ oselu Ẹlẹsin SDP ni saa isejọba alagbada kẹta, to si dupo wọle gomina nipinlẹ Ondo ijọun ni oṣu Kinni ọdun 1992.
Gomina Makinde tun sọ pe ki wọn gba awọn oṣiṣẹ eleto abo megaadi ẹgbẹjọ.
Bẹ́ẹ̀ ni igi náà ga, bí ènìyàn bá ń wò mí ní ìsàlẹ̀ n kò ju kékeré lọ.
Ilé ìwòsàn l'Àbuja ti ya àwọn ìbejì tí wọ́n sọpọ̀ láyà lọ́fẹ̀ẹ́ Ọmọ ilẹ̀ Iran 82 ló kú nínú bàálù tó já lórílẹ̀èdè naa Gómìnà mẹ́ta àtí ènìyàn 1,242 ló kó sí panpẹ EFCC ni ọdún 2019 Díẹ̀ lára àwọn ìṣẹ̀lẹ̀ tí yóò mi ìgboro tìtì l'ọ́dún 2020 rèé Amọ ṣa, ileeṣẹ iroyin Gulf n sọ pe awọn ẹri kan jade pe orilẹede naa yoo fi aaye gba awọn to ba ni iwe irinna ọlọdun marun un lati lo to oṣu mẹfa lẹẹkan naa to ba wu wọn.
Bo tilẹ jẹ pe Biden ti pẹ ninu isejọba ilẹ America, àwọn nkankan wa to le ta ko o.
Ṣugbọn ọ̀pọ̀ ninu àwọn tí ó gbọ́ ọ̀rọ̀ náà gbàgbọ́, iye wọn tó ẹgbẹẹdọgbọn (5,000) eniyan.
Ijaw ni ede ti wọn n sọ julọ nibẹ.
Gẹ́gẹ́ bí ìwé ìròyìn NAN ṣe sọ ọ, Salinsile ló ń rọ́ pò Alhaji Oyetola Gboyega tó ti di oludije fun ipò gomìnà lábẹ́ àsía ẹgbẹ́ òṣèlú APC níbi ìdìbò tí yóò wáye lọ́jọ́ kejìlélógun oṣù yìí nípìnlẹ̀ Oṣun.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Olusegun Obasanjo: Ọmú ìyá mi ti mo fi ń mùkọ ni kekere ló jẹ ki ń lókun Isẹlẹ yii soju ẹbi rẹ to gbe ounjẹ wa, ta si kesi awọn ọlọpa lati wa dasi isẹlẹ yii.
Yomi ni yala awọn ba ara wọn ṣe tabi awọn ko ba ara wọn ṣe, daadaa yoo ya lọdọ onikaluku torinaa o tọrọ aforiji lọwọ to ba ti fi ihuwasi rẹ ṣẹ o si wa alafia.
Yóo ti pẹ́ tó kí ẹ tó mójú kúrò lára mi?
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ẹkún àti ìbànújẹ́ láwọn mọ̀lẹ́bí fi sìnkú ọmọ méje ní Kumba, Cameroon lónìí 5 Bélú 2020 Oríṣun àwòrán, Joel Kouam Ẹkun oun ibanujẹ l'awọn molebi fi n sinku awọn ọmọ wọn meje to kagbako iku ni ilu Kumba lorile-ede Cameroon.
“Tèmi ni àwọn ọmọkunrin mejeeji tí o bí ní ilẹ̀ Ijipti kí n tó dé, bí Reubẹni ati Simeoni ti jẹ́ tèmi, bẹ́ẹ̀ náà ni Manase ati Efuraimu jẹ́ tèmi.
Lekki Toll gate: Àwọn awakọ̀ Lekki sọ èrò wọn nípa ìrìnà ọ̀fẹ́ ní ibodè Lekki
Lásìkò Ramadan, wo àwọn orílẹ̀èdè tí wákàtí ààwẹ̀ wọn gùn ju ti Nàìjíríà lọ Ààwẹ Ramandan àti irú ouńjẹ tí o lè jẹ Ramadan 2018: Wákàtí àwẹ̀ káàkiri àgbáyé Akọroyin BBC,Mansur Abubakar jabọ lati ilu Kano nibi ti o ti ba awọn musulumi ti wọn kii bẹrẹ awe bi wọn ko ba foju ri oṣu fun ara wọn.
Ṣalumu ọmọ Jabeṣi dìtẹ̀ mọ́ ọn, ó pa á ní Ibileamu, ó sì jọba dípò rẹ̀.
Idije Commonwealth Games yii, ni yoo di igba ketala ti Naijiria yoo kopa ninu re lati odun 1950.
Beti Lebaotu ati Ṣaruheni, gbogbo ìlú ati ìletò wọn jẹ́ mẹtala.
Dájúdájú, OLUWA yóo fọ́ orí àwọn ọ̀tá rẹ̀;yóo fọ́ àtàrí àwọn tí ń dẹ́ṣẹ̀.
Ọ̀rọ̀ yìí ń lọ bẹẹ títí di ìgbà tí Aláàfin Atiba waja lọ́dún 1859, tí Ibadan sì tún yari pé ọmọkùnrin Atiba, tí orúkọ rẹ ń jẹ Adelu, ni yóò gùn orí itẹ àwọn baba ńlá rẹ, lai tẹle ìlànà oyè jíjẹ nílùú Ọ̀yọ́.
Ọ̀pọ̀ igbà, lai pàdé enia ri, ẹlòmiràn lè ni lọ́kàn pe ẹni burúkú tàbi ẹni rere ni ohun pàdé nitori itàn ti ó ti gbọ́.
Nigeria 2019 Elections: Issa Onilu ní APC kò ní fi èrú gba ìbùkún lásìkò ìbò
Ọmọ: Èmi ò ní ṣe àjọyọ̀ àjọ̀dún Òyìnbó kì í ṣe àjọ̀dún ìlúu China.
"Njẹ ẹyin ko mọ wipe ana mi ni Omiṣore?
O ni oun di eti oun si ariwo ọja awọn eniyan ni bi awọn ero lori papa naa ṣe n pariwo orukọ Serena ki oun to le bori.
Akeredolu tún ṣàlàyé pé, òun fẹ́ràn ìpínlẹ̀ òun àti ìlú Ọwọ, tíì ṣe ìlú abinibi oun, ní òun ṣe dù ipò gomina, àwọn ará ìlú Ọwọ sì lo wà bẹ òun n'ilu Ibadan, láti wá dù ipò náà.
Àbúrò Sàká ni Dáúdà jẹ́ ṣùgbọ́n, Kúnlé ni ó jẹ àgbà wọn.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Amotekun: Àwọn èèyàn sọko ọ̀rọ̀ sí Tinubu lórí ìkéde rẹ̀ nípa Amotekun 22 Sẹ́rẹ́ 2020 Ṣaaju ki Asiwaju ẹgbẹ oṣelu All Progressives Congress Bola Ahmed Tinubu to sọrọ nipa idasilẹ ikọ alaabo Amọtẹkun, n ṣe lawọn eeyan n dẹti lati gbọ ọrọ rẹ.
Matthew's Primary School, Ikere-Ekiti (1972-1978) ati Annunciation School, Ikere-Ekiti (1978-1983).
Ìwádìí BBC rèé lórí ìjà APC tó fẹ́ gbẹ̀mí Sẹ́nátọ̀ l‘Osun Ìlú tuntun tó kún fún ohun àdáyébá láìsí ọkọ̀ tàbí òpópónà ń bọ̀ ní Saudi Arabia Mo ti gba ọmọ Igbo tó ń wá bàbá rẹ̀ bí ọmọ, kó má ba à pa ara rẹ̀ - Iba Oluyole Lẹ́yìn ọgọ́rùn ún ọjọ́ tí wọn ti Lekki Toll Gate pa, ẹ wo owó gọbọi tíjọba Eko ń pàdánù Ẹ́ ràgà bo ìṣọ̀kan Nàíjíríà, ìyàpà le mú ìṣẹ́ àwọn akọni wa já sásán - Osinbajo Orí kó Sẹ́nátọ̀ Orilowo yọ lọ́wọ́ ikú lọ́jọ́ Àìkú Kí ló ń pa ẹbí Orisabunmi lọkọ́ọ̀kàn, àkúfà ni àbí àmúwá Ọlọ́run?
Kan siwa lori opo ikan ayelujara wa to fi mọ Facebook ati Instagram lori opo bbc.
Òun náà ni ó lọ rọ kọ́kọ́rọ́ lọ́dọ̀ bàbá àgbẹ̀dẹ tí Àṣàkẹ́ fi dán séèfù wò.
Ẹ̀yin tí a gbé Jesu Kristi tí wọ́n kàn mọ́ agbelebu sí níwájú gbangba!
Ọkunrin kan wà tí orúkọ rẹ̀ ń jẹ́ Siba, tí ó ti jẹ́ ọ̀kan ninu àwọn iranṣẹ Saulu nígbà ayé rẹ̀.
Ọọni naa ti wa di eyi ti awọn babalawo ati oniṣegun n mu adìyẹ to tobi wa fun wa fi tọrọ nkan ati lati wa dupẹ fún.
Ọwọ́ ọlọ́pàá tẹ ọkùnrin mẹ́rin pẹ̀lú orí èèyàn ní ìlú Akure Ìtàn ìgbé ayé Isola Ogunsola 'I-sho Pepper', ògbóǹtagí òṣèré tíátà tó s'eré Yorùbá yíká Nàìjíríà Mọ síi nípa ohun tó ṣẹlẹ ní àwọn ibi tí wọn ti ṣilẹkùn ilé ìwé padà lẹyìn Covid 19 A óò dá ẹnikẹ́ni tó bá gbé ìwé àti àṣírí ìjọba síta lórí ayélujára lọ́nà àìtọ́ dúró - Ìjọba àpapọ̀ Ologbe ọhun ti n ba awọn aisan kan to ni ṣe pẹlu ọjọ ogbo finra ki awẹ Ramada to bẹrẹ, ko pẹ diẹ si asiko yii lo dagbere faye.
Nkan tí a mọ̀ nìyíì Lóòtọ́ ni mo yìnbọn níbi yánpọnyánrin tó wáyé ládúgbò mi-Seun Kuti Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Seun Kuti: Seun, ọmọ Fela, lóòtọ́ lóun yìnbọn níbi yánpọnyánrin pẹ̀láwọn tó wa ọkọ̀ dí ilé òun, àtipé bó jẹ́ ìjọba àpapọ̀ ló ṣ'àìtọ́ nílé òun ìbọn á sọ14 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Murder In Ibarapa: Aborode tó tún jẹ́ olóṣèlú kàgbákò ikú òjijì lọ́nà oko14 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 3:16 Fídíò, Ọgbà ẹ̀wọ̀n ni wọ́n ti já ìbálé Esra lábẹ́ àwáwí àyẹ̀wò wúndíá, Duration 3,1613 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Oyo Coronavirus: Makinde ní kò sí ọwọ́jà Coronavirus ẹlẹ́ẹ̀kejì ní ìpínlẹ̀ Oyo14 Sẹ́rẹ́ 2021 Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí kan sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
Eko Aromisa lẹgbẹlẹgbẹ, Eko Akete, Eko ilu ọgbọn jẹ diẹ lara oriki ilu Eko.
Gbogbo yín, ẹ máa ṣọ́nà, kí ẹ tún máa gbadura, kí ẹ má baà bọ́ sinu ìdánwò.
Àbúrò rẹ ̀ hrh isaac babalola akinyeloni ó padà gorí ìtẹ ́ gẹ ́ gẹ ́ olúbàdàn ti olúbàdàn tí òun náà jẹ ́ olúbàdàn àkọ ́ kọ ́ tí yóò jẹ ́ ọ ̀ mọ ̀ wé .
Àjọ NIMC ti fún MTN, Glo, 9mobile àti Airtel ní àṣẹ láti bẹ̀rẹ̀ ìforúkọsílẹ̀ fún NIN Wo iye àwọn ìpínlẹ̀ tó fòfin de ìsìn àìṣùn ọdún ní ṣọ́ọ̀ṣì Àwọn àjàkálẹ-àrùn tó ti wáyé rí ṣáájú Coronavirus Ọmọ ẹgbẹ́ òkùnkùn mẹ́ẹ̀dógún wọ gàù ọlọ́pàá ségí ní Eko Ikú Adewole Oniluola, tó ní ẹ̀bùn ìlù lílù jùlọ lágbàyéé, yóò nípa lórí Yorùbá - Tunde Kelani EFCC tun ri ọpọ owo ati dukia gba lọwọ àwọn ti aje iwa ibajẹ ṣi mọ lori,"" Abba lo sọ bẹẹ."
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Fìdíhẹẹ́ ní Banji Akintoye nínú YWC, lílọ ni yóò lọ - Tola Adeniyi A kò sí lára àwọn tó ń ṣèwọ́de tako èlé owó epo àti iná ọba - NLC Jàńdùkú olóṣèlú gbàkóso ilé aṣòfin l‘Ondo Temitope Akinnusi: Ọ̀pọ̀ iléeṣẹ́ ló takú láti gbà mí síṣẹ́ torí mo ní ojú kan Eruku ìjà sọ lálá lórí ayelujára láàrin Oyedepo àti Daddy Freeze Ọmọ Nàíjíríà kó N6m jọ lórí ayélujára fún Erica tí wọn lé ní BB Naija Mo fòpin sí àjẹbánu lórí owó ìrànwọ́ epo àti iná ọba, ní èlé ṣe wáyé - Buhari Agba ọjẹ osere tiata naa lo jade laye nile rẹ to wa nilu Abeokuta nipinlẹ Ogun nirọlẹ ọjọ Aiku.
Bakan naa ni wọn ko jẹ ki akọroyin kankan wọle si yara igbẹjọ naa.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Mobile Wash: iṣẹ́ fífọ́ mọ́tò tà ni mó yàn láààyò- Slay Mama Àkíyèsí nípa àìsàn 'Coronavirus' tó ń ṣàkóbá fún bí a ṣe ń mí Arun Coronavirusti, to tun n jẹ 2019-nCoV, to n ja rain ni ilẹ China lo ti di irawọ ọsan to n ba awọn agba lẹru bayii lorilẹede Najiria nitori ọsẹ to n se.
Ẹ wá sọ́dọ̀ Ọlọrun onídàájọ́ gbogbo eniyan ati ọ̀dọ̀ ẹ̀mí àwọn ẹni rere tí a ti sọ di pípé, 
”Ṣugbọn ó sọ fún wọn pé, “Bí n kò bá rí àpá ìṣó ní ọwọ́ rẹ̀, kí n fi ìka mi kan ibi tí àpá ìṣó wọ̀n-ọn-nì wà, kí n fi ọwọ́ mi kan ẹ̀gbẹ́ rẹ̀, n kò ní gbàgbọ́!
2005 ni wọn dajọ iku fun un, ṣugbọn gomina Fayose ni oun ko le bu ọwọ lu iwe iku ẹlomii.
Bi olori ijoba oun se kowe fipo re sile waye latari ifehonu-han iwode awon ara-ilu eyi ti won fi n bere fun idasile awon adari egbe oselu alatako ti won wa latimole.
Yóo ya wọ inú ilẹ̀ rẹ̀ látòkè délẹ̀; yóo sì bo gbogbo rẹ̀ mọ́lẹ̀.
Osogbo Building collapse: Ògiri ilé wó pa Jide ọmọ ọdún mọ́kànlá l'Oṣogbo
Independence Day Nigeria: Lamido Sanusi gbóṣùbà fún ìjọba lórí bó ṣe yọwọ́ ìrànwọ́ epo
Kí ló ṣe ikú pa Adewura Latifat Bello lẹ́yìn ọ̀sẹ̀ méjì tí wọ́n ń wá a?
A kò rrìn tó bẹ́ẹ̀ nígbà tí ó déédéé dúró tí o bá ilẹ̀ sọ̀rọ̀ ó ni, ‘Ìwọ ilẹ̀, la ẹnu fún mi, mo fẹ́ lọ sí ilé ìyá mi.
"Bi alaṣẹwo naa ṣe ni olomi lo maa rẹ, ni arakunrin naa fesi pe ""jẹ ka da a le e""."
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Olusegun Obasanjo: Ọmú ìyá mi ti mo fi ń mùkọ ni kekere ló jẹ ki ń lókun Kini Auxilliary sọ ni tirẹ?
O ni ko si ohun ti Olorun ko lee ṣe lati gba apa kan ileto ti awọn alakatakiti ẹgbẹ Al-Shabab n dari.
"Ìjọba ń ṣapá rẹ̀ lórí ìdènà Covid-19 àmọ́ àwọn awakọ̀ Eko ya aláìgbọràn - Ìjọba ""Ẹ̀yin tẹ̀ ń parọ́ ẹlẹ́yà-mẹ̀yà mọ́ Amotekun Oyo, Seyi Makinde lẹ̀ ń dojú ìjà kọ"" Kí ló ma n fa Àkúfà nílẹ̀ Yorùbá, àti ọ̀nà àbáyọ?"
Kábíyèsì fẹnu ara rẹ̀ tú àṣírí àwọn Fulani Daran daran tó ń ṣọṣẹ́ nílùú rẹ̀ Eleyi ni igbakeji ti ẹgbẹ agbabọọlu Man City yoo fidi rẹmi ninu idije Premier League ni saa yii lẹyin ti Norwich City ti kọkọ na wọn lai ro tẹlẹ bakan naa.
Bí mo fé bí mo kọ̀ mo nílaáti fi irun ori mi sílẹ̀ ní kíkún kí n máa gbé eléyìínì kiri.
O ni ìbẹ̀rù kini àwọn eniyan yoo sọ nipa pé musulumi obinrin ni oun lo kọkọ dena itẹsiwaju oun.
 salzburg ní austria ni wọ ́ n ti bíi .
Wọn ni ijọba n ṣe bi ẹni pe wọn n ṣe wọn loore ni ti wọn ba gbe igbesẹ lati gba wọn ninu igbekun Boko Haram.
Wọ́n kọ ọ́ sí agbègbè kọ̀ọ̀kan ati ẹ̀yà kọ̀ọ̀kan ní èdè wọn, wọ́n sì kọ sí àwọn Juu náà ní èdè wọn.
8 bílíọ̀nù) ni fásitì náà jẹ ìjọba ìpínlẹ̀ Ọ̀ṣun, tí wọn kò sì san-án nígbà tí gbèdéke tí wọ́n fún wọn pé.
O sọ fun akọroyin BBC, Ogechi Obidiebube, pe odiwọn ooru to yẹ ko mu ni iha ibi ti orilẹede Naijiria wa ni agbaye ko yẹ ko kọja a '30 degrees', odiwọn to ba ju eyi lọ kii ṣe nkan to dara.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Osoba: Àwọn tó ń bèèrè fún àtúntò ń jà fún ikùn ara wọn ni 24 Ìgbé 2019 Oríṣun àwòrán, Google Àkọlé àwòrán, Ọ̀jọ̀gbọ́n Olusegun osoba wà ní ara àwọn tó se àpérò lórí ìwé ìlànà àti òfin Naijiria ní ọdún 1976.
leyin naa, ni a o wa kede igbese ti igbimo amusese ti fenuko le lori fun un  yin”.
' Gbenga Adeyinka sọ pe ọpọ awọn adẹrinpoṣonu ni Naijiria lo kawe ju awọn to n dari wa ni Naijriia, ti wọn si ni imọran, erongba ati ọgbọ́n to le gbe Naijiria ga.
Sowore fikun pe awọn nigbagbọ wi pe awọn yoo bori ninu idibo to n bọ ninu awọn ololufẹ rẹ ni APC, PDP ati ZLP yoo dibo fun un.
 Gomina Ambode gbagbọ ninu Ile-iṣẹ ijọba yii lati mu igba ọtun ba awọn ọdọ ti wọn ṣẹṣẹ n jade ile-iwe”.
Dajudaju awọn akẹgbẹ rẹ ninu ere Yoruba ti kan si i tori ọpọlọpọ wọn lo tu sori ayelujara ti wọn n ki i, ti wọn n rọ ọ ko ṣara giri.
"Femi Adebayo, ti gbogbo eeyan mọ si Jẹlili, wa n beere pe ""Bawo la se fẹ sọ fun ọmọ tuntun ẹjẹ ọrun naa pe iya rẹ lo pa baba rẹ, idi si ree ti wọn se yẹgi fun oun naa."
Nítorí mo mọ àníyàn yín, mo sì ti ń fi ọwọ́ sọ̀yà nípa yín fún àwọn ará Masedonia, pé Akaya ti parí ètò tiwọn láti ọdún tí ó kọjá.
Lati ọwọ Gillian Gibs Michelle Roberts Adari iko eleto iroyin ilera ni BBC O kere tan, Ọjọ marun un ni ami coronavirus a bẹrẹ si ni farahan lara eniyan.
NASS: Àbádòfin 2019 yóò fori sánpọ́n ti mínísìtà ò bá bẹ̀bẹ̀
Awọn to fẹ le mi kuro lori oye yoo nilo lati ṣe pẹlẹ daadaa nitori asiko mi niyi.
Mo wá rí ìtẹ́ funfun ńlá kan ati ẹni tí ó jókòó lórí rẹ̀.
Ní ọjọ́ tí OLUWA fi àwọn ará Amori lé àwọn ọmọ Israẹli lọ́wọ́, Joṣua bá OLUWA sọ̀rọ̀ lójú gbogbo Israẹli, ó ní,“Ìwọ oòrùn, dúró jẹ́ẹ́ ní Gibeoni.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Wo ohun àràmàndà tí àwọn olósèlú máa ń ṣe lásìkò ìbò 28 Sẹ́rẹ́ 2019 Oríṣun àwòrán, Facebook Àkọlé àwòrán, Ni idibo ọdun 2015, Fayọse pin adiye fun awọn eniyan.
Èkínní, o níláti gbẹ́kẹ̀lé Ọlọ́run Ọba, kí o fi Olódùmarè ṣe oògùn àjísà rẹ, èkejì, o níláti máa fi òótọ-inú bá àwọn ènìyàn lò, a kò gbọdọ bá ọ ní ìdí kèéta, kí o sọ nǹkan mìíràn fún onítọ̀hún kí o máa gbé igbá rìkíṣí kiri; ẹ̀kẹta, o níláti rẹ ara rẹ sílẹ̀, ẹ̀sẹ̀ ìgbéraga ni ó bí Olódùmarè nínú jùlọ nínú gbogbo ẹ̀ṣẹ̀ tí ọmọ ènìyàn ń dá lórí ilẹ̀ ay’w: nígbà tí ọmọ Olódùmarè wá sí òde ayé ní ijọ́sí, ó wá pẹ̀lú ìrẹ̀lẹ̀: wọ́n lóyún rẹ̀ ní ìlú kékeré, wọ́n bí i sí ibi tí ẹran ti ń jẹun, ó bá àwọn onígbèéraga wí ó sí wẹ àwọn ọmọ-ẹ̀hìn rẹ̀ lẹ́sẹ̀; ẹ̀kẹrin, múra sí iṣẹ́ gidigidi, má ṣe fi í jáfara, ìlọsíwájú jìnnà sí ọ̀lẹ ènìyàn, ẹni tí ó ń fi gbogbo ọjọ́ sùn sí orí ìbùsùn kò ní i lè dúró láàárin àwọn ènìyàn pàtàkì láéláé: ẹ̀karùn-ún, máa mú sùúrù fún àwọn ọmọ aráyé, nítorí bí ìwọ kò bá ṣe èyìínì ìwọ yóó di òmùgọ̀ bíi wọn; ẹ̀kẹfà, má ṣe nírètí títí ọjọ́ ayé rẹ wí pé bí o bá ti ń ṣe oore fún àwọn ọmọ aráyé tó ni ìmọ yóó máa rí ọpẹ́ gbà lọ́wọ́ wọn.
N óo máa dúpẹ́ lọ́wọ́ rẹ títí lae,nítorí ohun tí o ṣe,n óo máa kéde orúkọ rẹ níwájú àwọn olùfọkànsìn rẹ,nítorí pé ó dára bẹ́ẹ̀.
Kọmisana fun isẹ ode, Ọjọgbọn Raphael Afọnja, to sisọ ọrọ yii fawọn akọroyin fikun pe ọjọ aje lawọn yoo kede orukọ awọn alakoso ibudokọ ọhun.
Amọṣa awọn amokunsika ẹda naa ti sa kuro ni ileto naa ki awọn ologun to de siblẹ.
Ṣebí ohun tí a bá ti fojú rí ti kúrò ní ohun tí à ń retí.
Ìyá iyawo Simoni ń ṣàìsàn akọ ibà.
Ẹni to bori: Morocco Ghana vs Tunisia.
 Mo tun lo anfaani yii lati ro awon agbaagba ilu, paapaa julo olori odo lati
"Itakurọsọ wọn fi han pe Ayobami naka abuku sí Sulaimon pe idi to fi n bù ẹnu àtẹ lu ìjọba tó wà lori alefa l'Oyo ni pe ko rí anfaani láti ṣiṣẹ gẹgẹ bí ""ghost worker"" labẹ iṣejọba naa."
Oríṣun àwòrán, Ọba Dikrulahi Ọlaleke Akinrọpo, Ọlabiran Kẹta.
‘UK yóò pèsè isẹ́ 100,000 ní Nàìjíríà’ Minisita fọ́rọ̀ ilẹ̀ òkèèrè kọ̀wẹ́ fipò sílẹ̀ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'O yé kí ìbáṣepọ̀ Nàìjíríà àti UK dán mọ́rán síi lẹ́yìn àbẹ̀wò May' Aarẹ ajọ EU, Jean-Claude Juncker sọ pe ajọ EU ko ni 'pada duna-dura'' lori igbesẹ ti Britain fẹ ẹ gbe ọhun, ṣugbọn anfaani wa fun 'ṣiṣe alaye lẹkunrẹrẹ.
Ọba Adele ati Tinubu tun ko lọ silu Badagry, ti ọba naa si ran Tinubu lọwọ lati gbọrẹgẹ-jigẹ ninu owo ẹru ṣíṣe nilu ọhun, Nibe ni obìnrin takuntakun naa si ti ni awọn ọmọ ogun to maa n ran nisẹ lati lọ jagun, ko ẹrú wa fun lati ta fun awọn oyinbo.
Ara ọbọ ni àwọn èèyàn kan tí kó àrùn náà, tó sì ń jà ranyin-ranyin bíi iso inú ẹku, a sì leè kò láti ara ibalopọ, omi ara ati ẹ̀jẹ̀ ara.
"Èyí ni àwọn nkan tó yẹ kí o mọ̀ nípa ọmọ Italy tó kó Coronavirus wọ Eko ""Inú ìbẹ̀rù bojo làwa ọmọ Nàíjíríà wà ní Italy, a kò leè jáde tàbí ra ọjà"" Coronavirus: Italy sọ àgádágodo sí ilé ẹ̀kọ́ alákọ̀ọ́bẹ̀rẹ̀ àti girama Aṣíwájú ni Nàíjíríà nínú ìdènà Coronavirus, ohun márùn-ún rèé tí àgbáyé ń kọ́ lára wa Ààrẹ Buhari sún eré ìdárayá àpapọ̀ Edo 2020 síwájú Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Àwọn olúlùfẹ́ fí ìbòjú fi ẹnu ko ara wọn ní Philippine Bakan naa lo sọ pe ọkunrin naa gba lati finu-findọ fi odiwọn eroja inu ẹjẹ 'white blood cells' silẹ ko to o kuro nileewosan."
Oríṣun àwòrán, TCNNigeria Amọṣa, ninu atẹjade kan to fi sita, alukoro ileeṣẹ naa, Ọgbẹni Ndidi Mbah ni awọn ti sa ipa lati da ina pada sawọn agbegbe kan lorilẹede Naijiria, ṣugbọn ẹkọ ko tii ṣoju mimu lawọn agbegbe bii Calabar, Ugwuaji, Makurdi, Jos, Gombe, Yola ati Maiduguri.
Awọn ọdọ ti ọjọ ori wọn si wa laarin ọdun mejidinlogun si marundinlogoji, to ni erongba okoowo ti wọn fẹ ẹ ṣe ni eto naa wa fun.
Koda won tun n pe igbakeji aare pe ki o je ki won je  igbakeji re, nigba ti o ba di aare orile ede yii.
World Food Day: Wo àwọn oúnjẹ ìṣẹ̀mbáyé Yorùbá tó ti ń di àpatì Kí ló ń fa ìjàmbá omíyale ní Naijiria?
Ire Oluwa, ọmọkunrin lanti-lanti ti Eleduwa fi jinki idile gbajugbaja osẹre, Toyin Abraham ati ọkọ rẹ, Kolawole Ajeyemi ti pe ọdun kan.
Ṣugbọn ìwọ ní tìrẹ, o ti tẹ̀lé ẹ̀kọ́ mi, ati ọ̀nà ìgbé-ayé mi, ète mi, ati igbagbọ mi, sùúrù mi, ìfẹ́ mi ati ìfaradà mi, 
Nígbà tí ó dídé dé òkè tán, wéré mo mú ọwọ́ kúrò lára ìtàkùn tí ó lọ́ mọ́ igi mìíran yìí mo sì yára dì mọ́ igi tèmi.
“Nítorí náà, mo lòdì sí ọ, ìwọ Tire, n óo sì kó ọpọlọpọ orílẹ̀-èdè wá gbógun tì ọ́, bíi ríru omi òkun.
Ileeṣẹ to n ṣeto ọrọ eeyan ati iṣẹlẹ pajawiri to jẹ agbatẹru eto naa ni iroyin ofege ni iroyin yi.
o tun gbosuba fun ijoba ipinle naa fun ipese ina mona-mana to n lo oorun , ni eyi to je pe iye megawati(330) ti won ni, lo po ju lorile ede Naijiria, ni eyi ti o wa ni ijoba ibile Gwiwa ni ipinle naa.
Ó dé adé pupọ tí a kọ orúkọ sí, orúkọ tí ẹnikẹ́ni kò mọ̀ àfi òun alára.
Ìyìn ni fún Ọlọrun,nítorí pé kò kọ adura mi;kò sì mú kí ìfẹ́ rẹ̀ tí kì í yẹ̀ kúrò lórí mi.
Adeniyi ní àwọn ẹgbẹ́ bi ọgọ́ta to darapọ̀ mọ́ YWC, sùgbọ́n àwọn olùdásílẹ YWC kìí ṣe olórí ti àwọn mọ́.
Kò sí ohun tí mo fẹ́ tí n kò ní.
Láìpẹ́ lẹ́hìn èyí ọmọkùnrin dé, kò rí olùfẹ́ rẹ̀ obìnrin ṣùgbọ́n dípò èyìínì ó bá aṣọ olùfẹ́ rẹ̀ ní ilẹ̀ ó kún fún ẹ̀jẹ̀ bálabála.
ki won si jiya labẹ ofin.
Ewe, eto iranwo ajo UN ohun wa fun
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Coronavirus: Àwọn ọ̀nà tí ẹ le fi dun ara yín nínú lásìkò yìí Wọn fi awọn ara Abuja lọkan balẹ pe ko nii si ewuitankalẹ ajakalẹ arun corona ni Abuja ati agbegbe rẹ.
Eyi tumọ si wipe ni orilẹede Algeria, ti gbogbo ọmọ orilẹede naa ba pa owo oṣu ati ere to n wọle fun wọn papọ, yoo gba wọn ni ọjọ mejila gbako lati san gbese ti orilẹede naa jẹ si ilẹ okeere.
Ní pàtàkì, ìwé yìí wà fún àwọn ọmọ ilé ìwé láti kà gẹ́gẹ́ bí ìwé kíláàsì tí olùkọ́ bá rò pé ó yẹ fún, bẹ́ẹ̀ ni bákan náà ló tún wà fún àwọn ti ń ṣe ìdánwò kémbírìíjì láti fi kọ́ ìjìnlẹ́ Yorùbá.
 Ó tako ìtenpele mó òrò ìbára-eni lòpò ( sex ) .
Nígbà tí àwọn ẹran tí ara wọ́n le dáradára láàrin agbo bá ń gùn, Jakọbu a fi àwọn ọ̀pá náà siwaju wọn, kí wọ́n lè máa gùn láàrin wọn.
Aisha fi ọrọ yi sita lọjọ Eti si oju opo Twitter nibi to ti sọ awọn ọrọ pe ko yẹ ki ẹnikankan kọja ofin ti ijọba gbe kalẹ nipa irina lasiko Covid-19 .
Amọ ajọ naa sọ pe iṣẹlẹ pajawiri tabi iṣẹ pataki nikan lo le mu ki baalu fo tabi ba lawọn papakọ ofurufu naa.
Ohun tí a rí nílé Ajimobi rèé lẹ́yìn ìròyìn òfégè pé ó jáde láyé Kí ló mú ọlọ́pàá wú òkú géńdé nínú sàréè l'Ondo Yẹ̀kínì kan kò lè yẹ ipinnu wa láti ṣí iléèwé pàda lóṣù yí - ìjọba ìpínlẹ̀ Oyo Ìwadìí ti bẹ̀rẹ̀ lórí àrá tó sán pa òṣìṣẹ́ FRSC mẹ́ta nípínlẹ̀ Ogun- Ọ̀gá àjọ FRSC Lósàn òní ni Gómìnà ìpínlẹ̀ Edo Godwin Obaseki tìkara rẹ̀ kéde nílé ẹgbẹ́ òṣèlú People's Democratic Party (PDP) nílùú Benin pé òun ti di ọmọ ẹgbẹ́ náà.
Iroyin ọhun fi kun un wi pe o ṣeeṣe ki panpẹ ti wọn fi mu u nii se pẹlu ifẹhọnu han ti ọgọọrọ ọmọ Naijiria ti yoo waye ni Ọjọ Aje, ifẹhọnu han naa n ke si awọn ọdọ lati dide ja fun ẹtọ wọn.
Yóo sì fi ìka wọ́n díẹ̀ ninu ẹ̀jẹ̀ náà sí ara pẹpẹ nígbà meje, yóo sọ ọ́ di mímọ́, yóo sì yà á sí mímọ́ kúrò ninu àìmọ́ àwọn eniyan Israẹli.
Oríṣun àwòrán, @Akure's PLUG Bakan naa ni 'awọn oṣiṣẹ ile igboku pamọsi naa ko lee si bi oku ọmọ tuntun naa ṣe poora.
Fun apẹẹẹrẹ, onibara ileeṣẹ ina ọba Ikeja to ba ni ina fun wakati mejila o kere tan ti o si n lo feesi kan, naira mejilelogun ni yoo maa san bayii ni wakati t jẹ ilọpo meji ohun ti wọn n san tẹlẹ.
Bí ẹnikẹ́ni bá fi idà pa eniyan, idà ni a óo fi pa òun náà.
Ijoba orile-ede Naijiria so lojo-Isegun pe, ohun ti pinnu lati maa se dara po mo fifowo si adehun ifenuko lori eto kara-kata alai-lowo ori nunu ile-Afrika, won niloo lati tunbo fori-kori lori oro naa.
Èmi a máa sọ ara mi di gbogbo nǹkan fún gbogbo eniyan, kí n lè gba àwọn kan ninu wọn là lọ́nà kan tabi lọ́nà mìíràn.
Olukọ ko tun gbọdọ dínjú si akẹkọọ, ko gbọdọ súfèé tabi ba a ṣere lọna to la erongba ibalopọ lọ.
awọn abuda yii ṣe pataki lati tẹle fun idagbasoke ati igberu orilẹ-ede yii.
9 ninu 1000 eniyan ni telentele .
Lara awon to kopa ninu ayeye naa lati ri, igbakeji aare orile-ede Naijria ojogbon Yemi Osinbajo, aare tele ri lorile-ede Naijiria, ogagun Yakubu Gowon ati Abdulsalam Abubakar.
F Odunjo fi sisẹ olukọ nilu Ibadan, ko to wa lọ di ọga agba fun ileẹkọ alakọbẹrẹ to lọ, eyiun St Augustines Bakan naa lo si tun sisẹ olukọ lawọn ileẹkọ ijọ Aguda lorisirisi laarin ọdun 1940 si 1950, ko to maa kọ iwe taa mọ ọ mọ J.
Ọkunrin kan wà ní agbègbè olókè ti Efuraimu tí orúkọ rẹ̀ ń jẹ́ Mika.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Pottery: Àwọn onímọ̀ nípa amọ̀ wúlò púpọ̀ ju ike àbí irin lọ Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Bí ohun tí fèrè ogun bá ń wí kò bá yé eniyan, ta ni yóo palẹ̀ mọ́ fún ogun?
Bẹẹ ni ijọba pàṣẹ ki wọn ṣẹjọ Yunusa ni ibamu pẹlu ofin niwaju ile ẹjọ to kaju osunwọn.
Omobakunrin Henrik ti Denmark to je amugbalegbe iyawo re, Obabinrin Margrethe ti doloogbe lomo odun metalelogorin odun.
Amọ, o fikun un wi pe awọn to ni iwe irinna ti tẹlẹ naa yoo ni anfaani lati lo o, lai si idiwọ idena kankan.
N óo fìdí wọn múlẹ̀, n kò sì ní pa wọ́n run.
Ẹ mójútó iṣẹ́ náà kí ẹ sì ṣe é kíákíá.
Ìdí ni pé, àwọn kọ́lẹ̀jì ìdìbò ni yóò sọ ẹni tó wọlé gẹ́gẹ́ bi ààrẹ, èyí kìí sì ṣe pé àwọn ni àwọn olùdìbò yàn.
Ṣugbọn iranwọ baba baba rẹ wa sopin nigba to de ipele keji.
OLUWA, gbógun ti àwọn tí ń gbógun tì mí;gbé ìjà ko àwọn tí ń bá mi jà!
Jẹtiro, baba iyawo Mose mú Sipora aya Mose, lẹ́yìn tí Mose ti dá a pada sọ́dọ̀ baba rẹ̀ tẹ́lẹ̀, 
A kò fipá mú ẹnikẹ́ni láti dá Ruga, aàgọ́ Fulani sílẹ̀ -Iléeṣẹ́ aàrẹ Biodun Fatoyinbo fi ipò sílẹ̀ lorí ẹ̀sùn ìfipábánilòpọ̀ Seyi Awolowo, ọmọ-ọmọ Awolowo, kí ló ń wà lórí ètò BB Naija?
Ní òru náà, ó gbéra, ó gbá ìlẹ̀kùn ẹnu ọ̀nà bodè ìlú náà mú ati àwọn òpó rẹ̀ mejeeji, ó sì fà á tu pẹlu irin ìdábùú rẹ̀, ó gbé wọn lé èjìká, ó sì rù wọ́n lọ sí orí òkè kan tí ó wà ní iwájú Heburoni.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Working religious women: Ẹ̀lẹ́hàá kìí ṣe ọ̀lẹ- Aminat Adegoke Wo ìdí tí wọ́n fi dá Alága àjọ EFCC Ibrahim Magu sílẹ̀ Iroyin to n tẹ wa lọwọ sọ pe, wọn ti da alaga ajọ EFCC, Ibrahim Magu silẹ.
Ìgbà tí mo tají ààrin ọ̀gànjọ́ ni, ìyàwó mi ti wọ ìyààrá rẹ̀, ó sí ìlẹ̀kùn sílẹ̀.
Ní gbogbo ibòmíràn ẹ̀wẹ̀, ònkà ọjọ́ ní í ṣíwájú kí ti oṣù tó tẹ̀lé e.
Ajafẹtọ awọn obinrin, Adefunke Adewumi n tiẹ, gba awọn obinrin ati obi ni imọran wi pe, ki wọn maa ṣọra nitori wipe, iwa ifipabanilopọ laarin ile ati nita ti wọpọ bayii.
    Iwin inú fìlà Fìlásayépọ̀ fẹ́ràn mi dáadáa nítorí ẹ̀jẹ̀ níí mu, bí mo bá sì ti ń pa ẹran ni mo ń fún un mu o sì ti gbà pe òun a máa gbé mi lọ sí ọdọ ọmọ náà nígbàkígbà tí o bá wù mi, Èmi náà sì ń lọ síbẹ̀ lemọ́ lemọ́.
Ògo ni fún ẹni tí ó lè ṣe ju gbogbo nǹkan tí à ń bèèrè, ati ohun gbogbo tí a ní lọ́kàn lọ, gẹ́gẹ́ bí agbára rẹ̀ tí ń ṣiṣẹ́ ninu wa.
Ọkunrin ọhun, Emmanuel Ankron, ẹni ọdun mẹtalelogun, wọ yara akẹkọọ obinrin naa pẹlu àdá lọwọ, ati ibọn agbelẹrọ pelebe, to si fi tipa ba lopọ.
3 7050 Orilẹede Niger 77 0.
Biṣọọbu agba ni pẹlu inu mimọ ni ohun ti awọn n ṣe lati fa oju ijọba sinu iṣẹlẹ ọhun kii ṣe lati tako ijọba rara.
Máa gbé kẹ̀kẹ́ rẹ lọ, àwọn akọròyìn kọ̀ ìpàkọ́ sí Femi Fani Kayọde Victoria Rubadir ọmọ Kenya ló gba àmì ẹ̀yẹ Komla Dumor BBC World News Ẹgbẹ́ wa ò dàrú o!
Ati wi pe ohun to jẹ afojusun oun ni lati ri i daju wi pe awọn ọmọ ẹgbẹ ṣe nkan ti awọn eniyan n fẹ lati ọdọ wọn, gẹgẹ bi olukọ ti awọn eniyan n wo; ninu iwọṣọ, ihuwasi ati isọrọ si wọn.
abajade akosile ti igbimo ijoba apapo yan lati se atunse si iko olopaa to n
Jehoṣafati ọba kan àwọn ọkọ̀ ojú omi bíi ti ìlú Taṣiṣi, láti kó wọn lọ sí ilẹ̀ Ofiri láti lọ wá wúrà.
Ó ṣe agbada omi kan tí ó fẹ̀ ní igbọnwọ mẹ́wàá (mita 4½), ó sì ga ní igbọnwọ marun-un (mita 2¼).
Wọ́n gbẹ́ àwòrán igi ọ̀pẹ ati kerubu sí ara ògiri náà láti ilẹ̀ títí dé òkè ìlẹ̀kùn.
Oríṣun àwòrán, Facebook/Nigeria Airforce A fura pé ejò lọ́wọ́ nínú ikú Tolu Arotile, ẹ ṣe ìwádìí ikú rẹ̀ - Afenifere, Gani Adams, Huriwa Yoruba ni bi ọrọ ba ru ni loju, a bi ilẹ leere ni.
Mọrèmi: Ọọ̀ni ní láìsi Mọrèmi, kò leè sí ilẹ̀ Yorùbá
Gomina ipinle naa Simon Lalong so lojo-Bo pe, ijoba ipinle ohun yoo se agbende ilana eto-abo re , latari ati wa ojutu si awon ikolu ti o n waye ni awon agbegbe kan ni ipinle naa.
Elemere ni wọn ma n pe wọn, ko si si ẹni to ma n fẹ ẹ sọ sita pe emere ni ọmọ ti oun bi.
Èyí ni majẹmu tí n óo bá ilé Israẹli dá nígbà tí ó bá yá.
4 Òkùdu 2019 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Oríṣun àwòrán, Getty Images Kinni gbigbe igbe aye to dara tumọ sí?
Eyi le waye nipasẹ oyun tabi ọmọ bibi.
Ninu awọn fọnran fidio kan ti a fidi rẹ mulẹ pe oun lo wa ninu rẹ ni ẹri yii ti waye.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ọ̀gá ọlọ́pàá tó wà ní 'Check Point' kàgbákò ikú òjijì lọ́wọ́ awakọ̀ l'Eko Oxford English Dictionary: Ọ̀rọ̀ 28 túntun ti wọ́n fi kún-un lọ́dun 2020 Mọ̀ síi nípa ǹkan tí o lè ṣe láti dènà ibà Lassa Ara gbígbóná, èébì, ara ríro, àti àwọn àpẹẹrẹ mìrán tí ibà Lassa máá n fihàn Agba amofin naa wa kesi awọn gomina ilẹ Yoruba pe ko tii pẹ ju bayi, yoo si dara lati tete se awọn ofin naa, lati ipasẹ awọn ile asofin ipinlẹ wọn, ki eto Amotekun lee rẹsẹ walẹ digbin.
Ṣé ó rò pé ọ̀rọ̀ lásán lè dípò ọgbọ́n ati agbára ogun ni?
Cardiff fọ́wọ́ òsí júwe Europa fún Manchester United Gbà fọ́gà ẹ!
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Funke Akindele: Ajirebi ní Funke Akindele f'óun lówó t'óun fi gba ilé ni, kò ra ilé f'óun 10 Agẹmo 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 11 Agẹmo 2020 Oríṣun àwòrán, Instagram/kunleafod Odu, ti kii se aimọ fun oloko ni Kayode Olaseinde lagbo tiata lede Yoruba nitori awọn awada adẹrinposonu to maa n se.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù LASTMA: A ṣèlèrí láti fi òṣìṣẹ́ yìí jófin tó bá ṣẹ̀ 22 Òkùdu 2020 Oríṣun àwòrán, @segalink Ajọ to n mojuto igbokegbodo ọkọ loju popo nipinlẹ Eko, LASTMA, ti fesi lori fidio kan to jade sori ayelujara laipẹ yii, ninu eyi ti oṣiṣ rẹ kan ti n ka owo 'to gba lọwọ awakọ kan' to tapa si ofin iriina.
ayo ohun di merin niseju méjídínlọ́gọ́rin lati gbegi dina
Àwọn Mogaji Ibadan kìlọ̀ Oríṣun àwòrán, Ekiti state government O ti to ọjọ mẹta kan bayi ti ọrọ aawọ awọn lọbalọba nipinlẹ Ekiti ti oruyeye ati iṣu ata yan-an yan-an.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Victor Agunbiade ni ojú àlá ni Ọlọrun ti yan iṣẹ́ ọmọ ogun ojú omi fún òun ní America Bi iya ṣe bẹrẹ si ni ya aworan pẹlu Beyonce niyẹn, amọ wọn kilọ fun un pe ko gbọdọ gbe awọn aworan naa sita afi igba ti awọn ba ṣe afilọlẹ awo orin naa.
Báyìí ni gbogbo nǹkan rí, iwin kan báyìí báyìí tí orí rẹ̀ sì ti hu ewú pátápátá tí ó funfun láú ni wọ́n pè kí ó wa ṣe ìgbéyàwó náà fún wa.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Manchester United vs Arsenal: Ta ni yóò borí nínú ìjà arọ méjì yìí?
Mohammed fi ẹyin gomina to wa ni iṣakoso, to tun jẹ oludije fun ẹgbẹ All Progressives Congress, APC, Gomina Muhammed Abubakar janlẹ.
Covid 19 update: Wo ǹkan mẹ́wàá tó yẹ kí o mọ̀ tí o bá fẹ́ lọ fún ìsinmi lẹ́yìn Covid 19
Foonu bii Nokia Lumia 650 jade ni nkan bii dun mẹrin sẹyin ṣugbọn wọn ṣi n ta a lori igba titi di oni.
 O tẹsiwaju pe, Mo lowo, mo lọla, mo si n na owo to to aadọta miliọnu loojọ.
Wọn ni ki a maa gbagbe pe ọpọ alangba lo dakun de ilẹ, a ko mọ ẹni ti inu n run ninu wọn, ti asebi kii si kọ siwaju ori.
ile igbimo asofin,ni iyawo rẹ arabinrin  Toyin Saraki, iya rẹ, arabinrin Florence
to Milioni Meji Naira, ati awon oko ti won fi ko awon eru naa ti owo ori won to
Wo ohun mẹ́wàá tó yẹ kóo mọ̀ nípá ọmọ ọdún mẹ́wàá Emmanuella tó kọ́ ilé ńlá fún ìyá rẹ̀ Bí kìí bá ṣe Buhari ni ààrẹ ni, ológun ì bá ti dìtẹ̀ gba ìjọba - Kukah Ṣé òótọ́ ni àwọn ará Amẹ́ríkà máa ń hán an lọ́wọ́ kan tí wọ́n bá gbọ́ ọ̀rọ̀ ìbálòpọ̀?
ati agbaye lapapo je ohun ti ko se ye sile.
Nítorí náà, ẹ jẹ́ kí á súnmọ́ ọ̀dọ̀ rẹ̀ pẹlu òtítọ́ ọkàn ati igbagbọ tí ó kún, kí á fi ẹ̀jẹ̀ rẹ̀ wẹ ọkàn wa mọ́, kí ó wẹ ẹ̀rí-ọkàn burúkú wa nù, kí á fi omi mímọ́ wẹ ara wa.
” Ọ̀rọ̀ tí Hesekaya ọba Juda sọ sì fi àwọn eniyan rẹ̀ lọ́kàn balẹ̀.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù ENDSARS: Nítorí ìwọ́de #EndSARS, ìjọba gbé iléèwé tì pa ní Oyo, Ekiti, Ondo, Eko, Edo, Plateau àti Osun 20 Ọ̀wàrà 2020 Lọwọ lọwọ yii ipinlé Osun, Ondo, Ekiti, Eko, Plateau, Edo ti gbe ilọkun ile iwe ti pa.
Ọmọbinrin yìí yóo sì di iyawo rẹ̀, nítorí pé ó ti fi ipá bá a lòpọ̀, kò sì gbọdọ̀ kọ̀ ọ́ sílẹ̀ ní gbogbo ọjọ́ ayé rẹ̀.
Ileesẹ Amẹrika wa bu ẹnu atẹ lu iṣẹlẹ ifipajinigbe awọn akẹkọọ to le ni ọọdunrun naa.
to n gbese labe isakoso re lati ri, wiwa atunse si ipenija to n koju eto
O mẹnuba awọn akẹkoo ọmọ Abraka, ọmọ ebonyi, ọmọ Benue ati Plateau to jẹ anafani ẹkọ ọfẹ ni Oke Ila Orangun ni eyi to fihan pe ko yẹ ki a ni ẹlẹyamẹya.
Tabi ẹ fẹ́ jẹ́ agbẹjọ́rò rẹ̀?
Bẹ́ẹ̀ ni Dafidi ṣe gba àwọn ará Keila sílẹ̀.
Niwọn igba to ṣe pe ẹni to ba pa eeyan, pipa naa ni wọn yoo pa, wọn wọ Bayewu lọ sile ẹjọ, ti adajọ si da ẹjọ iku fun oun naa lẹyin ọdun diẹ, ti wọn si yẹ igi fun-un.
Kí ni ìdí tí Àmọ̀tẹ́kùn kò tìí fi bẹ̀rẹ̀ iṣẹ́ rẹ̀?
Wò ó ọ̀nà láti mú ara rẹ dé ibi tó ga jùlọ nínú ìbálòpọ̀ pẹ̀lú ìlànà Tantra Wo àwọn ààrẹ ilẹ̀ Afirika tó kéde òfin kónílé ó gbélé nítorí coronavirus Wo bí àwọn ará Ibadan ṣe ń ṣe lásìkò Corona Virus yìí Eni mẹ́rin míì kó coronavirus ní Nàìjíríà, àfàìmọ̀ kó má dàbi ti China, Italy- Mínísítà kìlọ̀ O ti le ni ẹgbẹrun lọna ọọdunrun awọn eniyan ti wọn ti kagbako Coronavirus yatọ si China nibi to ti kókó bẹ silẹ.
Bí mo ti ń kọ̀wé yìí, mi tuntun náà ń fi ojú pè mí, ó sì d[bí ẹni pé ojjú wọ̀n-nnì ń wí fún mi pé lemọ́lemọ́ báyìí pé, ‘Wò mi pe e, wò mi sùn, ọdọ rẹ ni mò ń bọ̀’
 O ni oko alagbeka naa yoo pese iranwo to ye lasiko ki awon to maa gbemi mi lataari arun yi le dinku jojo.
ẹ̀mí èṣù náà yóo bá lọ mú àwọn ẹ̀mí meje mìíràn wá tí wọ́n burú ju òun alára lọ, wọ́n óo bá wọ ibẹ̀ wọn óo máa gbébẹ̀.
Ìlú kò mọ ohunkóhun nípa iṣẹlẹ màlúù tó kú nilu Ikarẹ - Olukarẹ Ẹ wo ojú owó ìrẹ̀sì báyìí lẹ́yìn tí ìjọba ti ibodè pa Ìgbẹ́jọ́ Naira Marley sún síwájú bí àwọn agbẹjọ́rò ṣe ń jà sí àga ìjókòó Ìdí tí mo ṣe fẹ́ yọ ayédèrú ìdí ńlá tí mo ní- Sophie Adajọ Okon Abang tile ẹjọ giga ni Abuja ni igbẹjọ naa ti n lọ bayii.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ní Ìpínlẹ̀ Ogun, Ọmọ ọgbọ̀n ọdún fi àdá bẹ́ ikùn bàbá rẹ̀ ̀ 18 Èbibi 2019 Oríṣun àwòrán, Punch Ọwọ ọlọpaa Ipinlẹ Ogun ti tẹ arakunrin kan Babatunde Olagesin, ẹni ọgbọn ọdun kan ti wọn fi ẹsun kan wipe of fi adá bẹ́ ikùn baba rẹ ni ilu Ijoko, Ipinlẹ Ogun.
Awọn Mogaji Ibadan ni agba kii wa lọja, ki ọmọ tuntun wọ lọri jẹ fun awọn agbaagba ilẹ Yoruba.
 Lorukọ awọn akẹgbẹ mi ni Ile Igbimọ Aṣofin Ipinlẹ Eko, mo gboriyin fun iṣẹ takuntakun ati ifọkanjin yin lẹnu iṣẹ, eleyii yoo le mu yin figagbaga pẹlu awọn oṣiṣẹ to ku ni agbaye.
Mo wáyé, Mo lapa lára onírúurú ọmọ.
 he was a conscientious pro-japanese thinker and Ìṣèlú .
Ni ikẹyin, o rọ gbogbo awọn akanda ẹda lati gba kadara ki wọn mojukuro lara ihuwasi awọn eeyan kan tí òye ko yé to nipa awọn akanda ẹda lawujọ.
Ayé kí wọ́n tú àṣírí ara wọn!
Wò ó, mo rí àwọn obinrin kan níbẹ̀, tí wọ́n jókòó, tí wọn ń sunkún nítorí Tamusi.
Ìrètí olódodo yóo yọrí sí ayọ̀,ṣugbọn ìrètí ẹni ibi yóo jásí òfo.
Aare tun tesiwaju pe orile ede Mejeeji naa ni opolopo nnkan ti won fi jo ara won nipa eto idagbasoke.
Iroyin ni ki o to lo si ileewosan ni eyi to mu ti ọlọjọ dani yii ni Isa ti sọ fun awọn ẹbi rẹ wi pe oun n lọ ṣe ayẹwo ara oun, ti oun yoo si gba ibẹ lọ gẹ irun ori oun.
iná tún jó ọjà Ògùnpa ní Ibadan lónìí Tọkọtaya lu ọmọ ni gbanjo fun 400k 'Orí ló kó ọmọ mi yọ' Nile iwosan Methodist LeBonheur Hospital ni Germantown, Tennessee ni wọn bi Christina Brown si.
Pẹlu iye owo ti wọn n ta wọn, bi ẹgbẹrun lọna ọgbọn dọla si ẹgbẹrun lọna aadọta dọla, pupọ orile-ede agbaye ti ko ri taje se ni ipa wọn ko ka rira awọn fẹntilatọ yi.
"Ọlọ́pàá kan jáde láyé, èèyàn méjì fara gbọta lásìkò ìdigunjalè ní Falomo l‘Eko ""$2,600 àǹtí mi ni mo jí láti lọ sókè òkun àmọ́ àbámọ̀ ló gbẹ̀yìn ọ̀rọ̀ mi"" ""Olóṣèlú ní Kogi àti Bayelsa ti ń pín Irẹ̀sì, iyọ̀ lásìkò ìpolongo ìbò, INEC, ẹ mú wọn"" Wo díẹ̀ lára àwọn ọ̀rọ̀ ìkẹyìn ti Alexander Akinyele fi léde kó tó papódà Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?"
Trump Impeachment: Ààrẹ Trump n fẹ́ kí ilé aṣòfin gbọ́ ẹjọ́ rẹ̀ ní kíákíá
Awakọ baalu kan, oṣiṣẹ baalu kan, ati ero kan lo wa ninu rẹ.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Lọjọ Iṣẹgun niroyin gbori afẹfẹ kankan lẹyin ti ẹka ẹgbẹ naa ni Benin tii ṣe olu ilu Edo kede pe awọn jawe lọ rọọkun n'le falaga ẹgbẹ naa ni ipinlẹ ohuin, Anselm Ojezua.
Telifiṣọn yii maa n jẹ ki aworan inu rẹ tobi ki o dabi pe wọn n duro ba eeyan sọrọ ninun palọ oluwa rẹ ni!
Aare ni: “mo lo agbara ti mo ni gege bii aare ni ibamu pelu ilana ofin orile-ede Naijiria fun gbogboogbo todun 2007 lati fun awon ile ise orile-ede Naijiria lagbara lati pese awon ohun ti won le se gege bii agbasese ki idagbasoke le de ba Naijiria”.
 gbòngán ni ó ń gbé ṣùgbọ ́ n gẹ ́ gẹ ́ bíi fìlísíà , ó ní ilé sí ibadan .
 nígbà míràn , ó lè ṣe ẹni tí ń dá orin náà ni yíò máa salámọ ̀ láàrin eré , ó sì tún lè jẹ ́ ènìyàn méjì yàtọ ̀ sí àwọn tí ń dárin .
FRSC thunder strike: Lẹ́yìn ìwádìí ìkú àrà tó sán pa òṣìṣẹ́ FRSC mẹ́ta lọ̀rọ̀ ètùtù kò ṣe ètùtù tó lè wáyé
Lásìkò tó ń ba àwọn akọ̀ròyìn sọ̀rọ̀ lóri ìfẹ̀nukò ilé, alága ìgbìmọ tẹ̀ẹ́kótó lóri igbóhùn sáfẹ́fẹ́ àti adarí oko-òwò ijọba Họnọrabu Gbenga Aribisọgan, sàlàyé pé ìgbésẹ̀ ọ̀hún wáyé nílànà ofín ọdún 1999.
Ṣé kí ẹ mu ninu omi tí ó tòrò kò to yín ni ẹ ṣe fẹsẹ̀ da omi yòókù rú?
Lẹ́yìn ikú Saulu, nígbà tí Dafidi pada dé láti ojú ogun, níbi tí ó ti ṣẹgun àwọn ará Amaleki, ó dúró ní ìlú Sikilagi fún ọjọ́ meji.
Ile iṣẹ Uber naa ṣalaye lori ẹrọ ikanni ayelujara wọn pe ọkọ oju omi yii yoo ṣiṣẹ fun ọsẹ meji lati ọjọ kọkanla oṣu yii di ọjọ karundinlọgbọn lati agbegbe Ikorodu si Falọmọ.
Ó sàn kí eniyan ní òye ju kí ó ní wúrà lọ,ó sì sàn kí eniyan yan ìmọ̀ ju kí ó yan fadaka lọ.
Erin wó, gbogbo inú igbó pa kése
Ìwádìí kan ní Ilééṣẹ́ Facebook leè mọ ìgbà tí àwọn tó wà lójú òpó wọn bá ní ìbálòpọ̀
Igbagbọ wọn nipe Adimu oriṣa maa ko iku, arun, aṣeeri ati idaamu lọ kuro nilu Eko.
Wọ́n tẹ́ òkú Jesu sibẹ, nítorí ọjọ́ ìpalẹ̀mọ́ àwọn Juu ni, ati pé ibojì náà súnmọ́ tòsí.
Lara rẹ si ni ibudo isinmi Ọwá ati Dágunró wa fun gbogbo ẹni to ti n gbọ nipa ori oke Idanre tẹlẹ, akoko to lati moju aje ko onisọ bayii gẹgẹ bi BBC Yoruba yoo ṣe mu yin gun oke yii lọ bọ.
Ami ayo meji ọtọtọ sodo ni Everton fi fagba han Chelsea ni papa isere Goodison Park nilẹ Gẹeṣi.
Ti a ko ba gbagbe, laipe yii, ni ipinlẹ Eko gbe owo le owo ori ilẹ, eleyii ti awọn eniyan bu ẹnu atẹ lu, to si mu ki ijọba ipinlẹ naa o din iye owo ori ilẹ ku.
Omi bo àwọn ọ̀tá wọn,ẹyọ ẹnìkan kò sì là.
(kí Ọlọrun gbé mi ka orí ìwọ̀n tòótọ́,yóo sì rí i pé olóòótọ́ ni mí!
Naijiria ati orile ede India lati tubo wa ona ti orile ede mejeeji naa yoo
Ìwádìí nàá fihàn pé àwọn tó dàgbà ló wọ́pọ̀ jùlọ tí yóò dé ilé ìwòsàn nítorí wọn nílò ìtọ́jú tó péye.
"O kọ ọ pe: ""Mo kan fẹ ki o mọ pe mo n ki ọ ku ọjọ ibi."
Ǹjẹ́ ọmọ obìnrin rẹ le múra báyìí
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, ọpọ ero gba pe ko tọ si awọn EKEDC lati sọrọ lori ina bayii O kere tan ijọba ipinlẹ mẹẹdogun ni ko tii fẹnu ko lori ẹkunwo owo oṣu tuntun fawọn oṣiṣẹ, bi o tilẹ jẹ pe ọjọ kọkanlelọgbọn, oṣu kejila, ọdun 2019 ni gbendeke ti ẹgbẹ oṣiṣẹ fawọn gomina.
Ẹwẹ wọn ọlọrọ gan ko tii wa fi ẹjọ ọ̀rọ̀ yii sun awọn lọna to tọ lati le gbe igbesẹ.
BBC Pidgin yoo kan si ẹni to ba gbegba oroke laarin ọjọ kẹwaa si ọjọ kejila, oṣu kẹsan an, ọdun 2018.
Awọn iroyin ti ẹ lee nifẹ si: 'Irọ ni, ko si ologun kankan ni Dapchi' Naijiria k'ọmọogun lati wa'wọn ọmọ Dapchi Buhari dasi ipaniyan Benue Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Ṣùgbọ́n, ìjọ RCCG ní irọ́ pátápáta ni ìròyìn nàá tí ìwé ìròyìn New Telegraph gbé síta.
Awọn wọnyii ni wọn ni ojuṣe lati dibo yan ẹni ti yoo di ipo aarẹ mu.
Ninu àwọn tí wọ́n gbọ́ ọ̀rọ̀ yìí, àwọn kan ń sọ pé, “Òun ni wolii tí à ń retí nítòótọ́.
"Àkọlé àwòrán, Fayẹmi ko sọ ohunkohun to jọ mọ atundi ibo gomina Osun Lọwọ yii, ikede yii ti dabi ẹni pin ìpinnu awọn ọmọlẹyin rẹ àti ọmọ ẹgbẹ oṣelu SDP sí ọtọọtọ nitori bi awọn kan ṣe n kọrin""ibi ọ bá lọ lá n lọ"" fún un l'awọn miran n royin ohun oju ti ri ti ko lee mu ki awọn fara mọ irufẹ ètò bẹẹ."
Bakan naa ni minisita eto iroyin ati aṣa ni ọmọ Naijiria lo pọju ninu awọn oṣiṣẹ ileeṣẹ South Africa to wa ni Naijiria.
Ohun to sokunfa isẹlẹ naa ni bawọn ọdọ kan lagbegbe Olomilagbala ati Bọlọrunduro nijọba ibilẹ ila oorun Ilesa, se fi ẹhonu han lọ si ọọfisi ajọ amunawa to wa nilu Ilesa.
O yanana koko ti awọn eniyan maa n sọ lori lilo awọn aburo rẹ ninu awọn fiimu rẹ.
Òun ni kí ẹ gbọ́ràn sí lẹ́nu ninu ohun gbogbo tí ó bá sọ fun yín.
''A o le lọ gbowo nita tabi ra ohun kankan, a n bẹ ijọba pe ki o wa nkan ṣe si ọrọ yii,'' Akah lo sọ bẹẹ.
UEFA Champions League: Barca yọ Man U dànù bí ẹni yọ jìgá!
Ọgbẹni Raheem Olawuyi ni awọn ọmọ ẹgbẹ gbimọpọ yan gẹgẹ bi oludije ẹgbẹ oselu APC.
Aṣofin Wilfred Onyema lo dada ofin yii latari pipese ọna ati maa ṣe idahun kanmọ kanmọ si atunto ofin to ni ṣe pẹlu owo ori ati imuṣẹ rẹ.
Igbimọ oludajọ naa sọ pe ko si ẹri to daju lati fi idi gbogbo ẹsun ti SDP fi kan igbakeji gomina Kogi mulẹ.
Ohun tí OLUWA bá wí fún mi ni n óo sọ.
 yangí ńlá kan o máa wà ní ẹ ̀ bá ilé àwọn babalawo .
’ Ó pẹ́ ni, ó yá ni, ọba yóo gbọ́ ìròyìn yìí.
Ọ́na lati wa idahun si iwoye awọn eeyan naa lo mu wa pe baba awo, Ifayemi Elebuibon lati mọ ohun to n jẹ akufa, idi to fi le waye ati ọna abayọ si isoro naa.
Ileesẹ ton s'amojuto awọn papa ofurufu ni Naijiria (FAAN) sọ wipe baalu naa ko le ba silẹ fun isẹju diẹ nitori awọn maalu naa.
Àìmọ̀kan ló mú mi hu ìwà tí mo hù kọjá sẹ́yìn, Jonathan dárí jì mí - Dino Melaye Ṣé lóòtọ́ ni pé Aisha Buhari ti kó lọ sí Dubai?
Bakanaa,àjọ elétò ìdìbò Nàìjìria, INEC ti sọ wi pe awọn ko fi igba kankan polongo pe aaye iṣẹ ṣ silẹ fun ẹnikẹni.
Ohun ati awọn agbarijọpọ onimọ iṣegun ti wọn pe ara wọn ni America Frontline Doctors ni wọn ba awọn oniroyin sọrọ ninu fọnran fidio yi ni Washington DC.
9 1062 Erekusu Saint Lucia 6 3.
Lizzy Jay ọmọ Ibadan - BBC News Yorùbá BBC News, YorùbáFò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Omo Ibadan: Ó wù mí láti kàwé di dókítà oníṣègùn òyìnbó tàbí ọ̀mọ̀wé ni Fáṣítì - Lizzy Jay ọmọ Ibadan 5 Bélú 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 16 Èbibi 2020 Oríṣun àwòrán, Lizzy Jay Gbajugbaja adẹrinposonu nì, Adebola Adeyela, ti gbogbo eeyan mọ si Lizzy Jay ọmọ Ibadan tí salaye nipa ọpọ ohun ti oju rẹ n ri ni agbo iṣẹ amuludun.
Bayii, Infinity War ti ta ju ‘The fate of the furious’ lo, eyi to pa okanlelogoji milionu owo dola le ni eedegbeta nigba ti won sii lodun to koja.
To ba ni nkan ti ko tẹ lọrun, ko gbe wa sile ẹjọ.
 gbogbo àwọn orílẹ ̀ -èdè wọ ̀ nyí sì fọwọ ́ sí ìwé tí ilẹ ̀ belgium kọ síwọn .
Bí a fẹ́ yàwòrán ni, òun náà ni.
Oríṣun àwòrán, others Ọkọ oju omi ati awọn ibi ti o maa lọ si lasiko irinajo naa.
Ọjọ́ ìbí bàbá mi ni aàrùn ọkàn ṣekúpa màmá mi lójijì- Davido Ìjọba Kwara kéde ọjọ iwọlé àwọn akẹkọọ lẹyìn ìséde Covid 19!
SERAP: Ìwàdìí ní ẹ̀ka iṣẹ́ ọlọ́pàá àti ìdájọ́ ló kúndùń ìwà àjẹbánu jùlọ
pe won ti wa oko ogun oju omi naa lo si ebute omi ti won ti n wa epo ni Agbami
#EndSARS: Lẹ́yin àṣẹ́ adelé Ààrẹ Osinbajo, ọgá ọlọ́pàá yan orúkọ tuntun fun SARS
Ó ní awon onimoto tí kò leè ṣíṣe nìkan ni ọ̀rọ̀ yìí kan, táwọn sì ń ṣàn owó oṣù fún àwọn òṣìṣẹ́ ọba, bẹ́ẹ̀ ni àwọn tí ń ṣe ìpèsè oúnjẹ fún àwọn tí kò rí oúnjẹ jẹ.
Ile ẹjọ ni ọna ti Wolii Sọtitobirẹ n gba beere fun beeli ko si ni ibami pẹlu ofin.
Lẹ́yìn ìgbeyàwó ọdún mọ́kànlá, Bọsẹ di èrò ọ̀run nílé Saidi 'Òṣòkòmọlẹ̀' ní ẹjọ́ láti jẹ́ lórí owó Káńsù l'Ekiti Ṣe ẹ ti gbọ́ ri?
Eyi nii ṣe pẹlu kindinrin to ba n ṣe aisan.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Coronavirus Ni bayii ti gbogbo agbaye n pariwo lori ọwọ keji ajakalẹ arun COVID-19 to n gbalẹ kan bayii kaakiri gbogbo agbaye, ibẹru bojo lori bi agbara kokoro arun naa tun ṣe n gbilẹ sii ko yee ọpọ paapaa julọ awọn alakoso eto ilera lagbaye, ti wọn si n woye ọna abayọ.
Aarẹ Putin ni oogun 'Sputnik V' lo ti gba gbogbo ontẹ ijọba lẹyin ọpọlọpọ ayẹwọ ti wọn ṣe, ti o si fihan pe, a jẹ bi ewe ni oogun naa.
" orúkọ rẹ ̀ àkọ ́ kọ ́ ni "" fọláṣadé "" , tó túmọ ̀ sí "" "" someone who uses wealth as crown "" "" ."
O ti farada ìyà nítorí orúkọ mi, o kò sì jẹ́ kí àárẹ̀ mú ọ.
Ohun tí ó yẹ wọ́n ni o fún wọn!
Bi o se pe Obaseki woye ohun to sẹlẹ s'ara waju bii Ambọde àti Kwakwanso ninu ẹgbẹ naa ni, ko ni wulẹ daamu ara rẹ.
Ẹja náà ni ǹkan ti wọ́n ń pe ni 'tetrodotoxin' eyí ti oró rẹ̀ ju ti májàlé lọ.
Adajọ Nicholas Oweibo sun igbẹjọ siwaju si Ọjọbọ, nigba naa ni yoo dajọ lori beeli ti wọn beere fun.
National Electoral Commission INEC) ti kede Bell Matawalle , oludije dupo
Itura orí idọ ojú ara (Clitoral Orgasm) Eyi lo wọpọ ju, to si jẹ pe ìdá ààdọ́run ninu awọn obinrin ni yoo ni iriri yii lasiko ti wọn ba fi ọwọ tabi nkan ọkunrin kan idọ̀ oju ara ara wọn, Iṣẹ́ kan ti idọ̀ n ṣe ni pe ko fun obinrin ni adùn ibalopọ.
Ìwọ ni o óo sì fi lé wọn lọ́wọ́.
Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí 'A ti pa Boko Haram run patapata' - Ọmọogun Ikọ̀ ọmọ ogun ilẹ Naijiria sọ nini ifilọlẹ apapọ ọmọ ogun orilẹede Naijiria ati Cameroon pe awọn ti sẹgun Boko Haram ni àsẹ́wọlẹ̀4 Èrèlè 2018 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 3 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 5 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Lẹ́hìn tí àwọn ìfihàn náà ti di gbígbéyẹ̀wò ati títúnṣe, àwọn ọmọ Ìjọ ní Missouri bẹ̀rẹ̀ sí títẹ ìwé kan tí wọ́n pe àkọlé rẹ̀ ní Ìwé Àwọn Òfin fún ìṣèjọba ti Ìjọ Krístì, èyítí ó ní ọ̀pọ̀lọpọ̀ àwọn ìfihàn ìbẹ̀rẹ̀ ti Wòlíì nínú.
Oríṣun àwòrán, Reuters Àkọlé àwòrán, Ọ̀kan lára àwọn Somali to ní sọọbu tó ṣeṣe.
Ogbeni Lai Mohammed so oro naa di mimo lasiko ti ile-ise to n ri si sise ere ori ero amohun-maworan ati bebi ni China sabewo si nilu Abuja.
Joabu bá fọn fèrè ogun, láti fi pe àwọn eniyan rẹ̀ pada.
Ọkùnrin náà jẹ́ Ìbátán Olójú-májèlé ní ìdí ìyá, ṣùgbọ́n ọ̀kan nínú àwọn iwin pátákí ni bàbá rẹ̀ ṣe nítorí baba rẹ̀ ni àbúrò Olókun tíí ṣe alákòóso omi, ó sì tún jẹ́ aburo Èsìdálẹ̀ tí ó jẹ́ ijoye pàtàkì ní òde ọ̀run.
#Zamfarakillings: Ààrẹ Buhari bínú sí àwọn afẹ̀họ́nú hàn Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Ẹnikẹni to ba ti ni apẹrẹ iba, ọfinkin, inu rirun ati ọfun didun gbọdọ sinmi fun ọjọ mẹrinla ko to le fi ẹjẹ silẹ.
Nítorí pé ìrì ìmọ́lẹ̀ ni ìrì yín,ẹ óo sì sẹ ìrì náà sì ilẹ̀ àwọn òkú.
Inú bi Ìjàpá, ó ka iwà Ọ̀bọ yi si à ri fin, ó pinu lati kọ lọ́gbọ́n pé ọgbọ́n wa ninú ki enia mã ṣe “Àmin” si àdúrà àwọn àgbà.
Ọpọlọpọ eniyan lo mọ Shah Rukh Khan gẹgẹ bi gbajugbaja osere to ma n se fiimu ololufẹ ni Bollywood.
Mùjẹ̀-mùjẹ̀ ní Akinyele tún ti mu ẹ̀jẹ̀ obìnrin míràn lónìí Oyè adelé alága APC bọ́ lọ́wọ́ Ajimobi, Buhari fòǹtẹ̀ lu Giadom Ọkùnrin kan bá ọmọ oṣù mẹ́ta lòpọ̀, ìfun ọmọ tú jáde!
Gbogbo àwọn ìlú tí ó jẹ́ tiwọn ní gbogbo ìdílé wọn jẹ́ mẹtala.
Mo rí apẹ̀rẹ̀ èso ọ̀pọ̀tọ́ meji níwájú ilé OLUWA.
Ni ọsẹ to kọja ni ileẹjọ kan nipinlẹ Kaduna, gba fun El-Zakzaky lati lọ gba itọju lorilẹede India, ti o si ṣe bẹẹ gẹgẹ ni ọjọ Aje.
Cindy Gold sọrọ lori bi nkan ṣe ri fun oun ni oṣu mẹfa akọkọ to bẹrẹ ija jija ati awọn idojukọ ti oun ni pẹlu bi o ṣe bori wọn.
Oríṣun àwòrán, Others Àkọlé àwòrán, Aṣa ìkíni ṣe pataki pupọ nilẹ Yoruba.
Àwọn ǹkan tí ó yẹ kí o mọ̀ nípa 'Sharia Law' ní Nàìjíríà À kò gba owó kankan lọ́wọ́ àwọn ẹgbẹ́ agbésùmọ̀mí ISWAP- MURIC Belarus tó ń gbóná lọ́wọ́ torí ààrẹ tó ti lo ọdún 25 lórí oyè, nkan márùn ún tí o kò mọ̀ rèé Ọwọ́ ọlọ́pàá ìpínlẹ̀ Kebbi tẹ bàbá àti ìyàwó rẹ̀ méjì fún pé wọn so ọmọ pọ̀ mọ́ ewúrẹ́ fún ọdún méjì Ẹni akọkọ ni Geraldine Ferraro lati inu ẹgbẹ Democrats lọdun 1984, ti ẹnikeji si jẹ Sarah Palin lati inu ẹgbẹ oṣelu Republican lọdun 2008.
Bakan naa lo ni wi pe ti wọn ba fun awọn ọmọ Naijiria ni anfaani lati gbe ibọn pẹlu ọrọ aje to dẹnukọlẹ ati bi aisi owo to gba igboro kan, ọgọọrọ awọn eniyan ni yoo ma pa ara wọn ni Naijiria.
'Orí ló kó ọmọ mi yọ' Àwọn ẹlẹ́gbẹ́ òkùnkùn dá ìjà sílẹ̀ l'Ékó RRS sọ pe nigba ti ọwọ awọn tẹ Adebayo pẹlu akẹgbẹ rẹ, Tijani, o jẹwọ wi pe ootọ ni wi pe oun lo gbe oruka naa mi.
Ile ẹjọ giga apapọ to wa ni Ikoyi ni ilu Eko ti fun gomina ana nipinlẹ Ekiti, Ayọdele Fayoṣe ni anfani oniduro lori igbẹjọ ẹsun ṣiṣowo ilu baṣubaṣu ati gbigba owo kotọ ti ajọ to n gbogun ti iwa ijẹkujẹ lorilẹede Naijiria, EFCC n fi kan an.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù AD,LP, fìdírẹmii lórí ẹ́jọ́ tí wọn fí takò iyansipo Sanwo Olu 17 Òkùdu 2019 Oríṣun àwòrán, @jidesanwoolu Àkọlé àwòrán, Sanwo Olu bori igbẹjọ iyansipo rẹ Sanwo Olu ti bori ẹjọ ti AD ati LP pè.
Ó wá di àríbẹ̀rù láàrin àwọn orílẹ̀-èdè!
Coronavirus: Soyinka rọ ìjọba láti pe àwọn ilé ìjọsìn tó tàpá sófin kóníléogbélé lẹ́jọ Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Soyinka rọ ìjọba láti pe àwọn ilé ìjọsìn tó tàpá sófin kóníléogbélé lẹ́jọ Ìjọba Naijiria kò ṣe dáadáa tó lórí ìtànkálẹ̀ àrùn Coronavirus- Soyinka Ọjọgbọn Wole Soyinka ti bu ẹnu ẹtẹ lu ijọba apapọ ati awọn olori ẹlẹsin lori iha ti wọn kọ si itankalẹ arun Coronavirus ni Naijiria.
Ileeṣẹ apoogun naa ni awọn yoo bẹrẹ si ni pese abẹrẹ ajẹsara naa fun iṣẹlẹ pajawiri lati opin osu yii.
” “ipinnu wa ni lati mu eto oro aje orile ede yii pada bo sipo , ki o si tun tesiwaju, ni eyi ti yoo se lee maa figa-gbaga pelu awon orile ede agbaye,Ajo to n mojuto isiro  lorile ede yii ti so pe idagbasoke ti de ba eto oro aje lorile ede yii laarin odun 2018.
Inú àwọn ará ilẹ̀ Juda dùn pupọ sí àwọn alufaa ati sí àwọn ọmọ Lefi tí wọn ń ṣe iṣẹ́ ìsìn.
 gẹ ́ gẹ ́ bí ọmọ ilé ẹ ̀ kó gíga , béèyàn bá gbowó fún àwọn orísirísi ìnáwó láti ilé lórí ẹ ̀ kọ ́ ẹni , ó seése kí irú ẹni bẹ ́ ẹ ̀ máa ná ìná-àpà tó bá dé ààrin àwọn ẹlẹgbẹ ́ ẹ rẹ ̀ .
Ko da ayẹwo lati inu omi tun waye lori afara naa ninu oṣu kẹta ọdun lati ni idaniloju awọn ibi to nilo atunṣe lori afara naa.
Nígbà tí wọ́n sọ fún Dafidi pé, Ahitofeli ti darapọ̀ mọ́ ọ̀tẹ̀ tí Absalomu ń dì, Dafidi gbadura sí OLUWA, ó ní, “Jọ̀wọ́, OLUWA, yí gbogbo ìmọ̀ràn tí Ahitofeli bá fún Absalomu pada sí asán.
Fífẹ̀ àgbàlá náà, láti iwájú títí dé ẹ̀gbẹ́ ìlà oòrùn, yóo jẹ́ aadọta igbọnwọ.
ó ní, “Ìwọ náà mọ̀ pé Dafidi, baba mi, kò lè kọ́ ilé ìsìn fún OLUWA Ọlọrun rẹ̀ nítorí gbogbo ọjọ́ ayé rẹ̀ ni ó fi bá àwọn ọ̀tá rẹ̀ tí wọ́n yí i ká jagun, títí tí OLUWA fi fún un ní ìṣẹ́gun lórí wọn.
Ṣugbọn Jeroboamu ti rán ọ̀wọ́ ọmọ ogun kan lọ láti kọlu àwọn ọmọ ogun Juda látẹ̀yìn.
 O fi mulẹ pe laisi aniani Ile naa
Ramadan: Àwọn ọlọ́pàá Sharia tí ń mú aṣéwó àti ọ̀daràn nípínlẹ̀ Kano
sugbọn ni awọn to ku, ko sohun to jọ bẹẹ.
Oríṣun àwòrán, oTHERS Ó jẹ́ ibàlórúkọ jẹ́ fún ìpińlẹ̀ Ondo nítori pe ilu to ni iyi ati ogo ni.
" Ilé aṣòfin kò láṣẹ kankan láti pe ààrẹ Buhari wá rojọ́ lórí ọ̀rọ̀ ètò àbò - Malami Oríṣun àwòrán, Twitter/Presidency Nigeria Saaju la ti sọ fun yin pe, Agbẹjọro agba orilẹede Naijiria, Abubakar Malami ti ni ile igbimọ aṣofin ko lẹtọ labẹ ofin lati pe aarẹ Muhammadu Buhari wa siwaju wọn lati wa ṣalaye ohunkohun.
Gomina Oyetola wa kadi ọ̀rọ̀ rẹ nilẹ pé ọlọkada kan kò gbọ́dọ̀ gbé ju èrò kan ṣoṣo lọ, tí àwọn onikẹkẹ Maruwa kò sì gbọ́dọ̀ gbé ju èrò méjì lọ sí ẹyin ọkọ wọn nígbà tí kò gbọ́dọ̀ sì èrò kankan ní ijoko iwájú.
Thai So atí  Isan ní àríwá-ìwọ̀-oòrùn Thailand;
O ṣe pataki fun mi lati ri i daju pe awọn lọkọlaya yii ti ṣe igbeyawo labẹ ofin naa ki a to le ṣe ti ilana Kristẹni lori ayelujara Zoom""."
Nítorí ìwọ nìkan ni ó pé,nítorí gbogbo àwọn orílẹ̀-èdè yóo wá,wọn yóo júbà níwájú rẹ,nítorí òdodo rẹ farahàn gbangba.
Àkọlé àwòrán, Eeyan to le ni ẹgbẹrun lọna igba lo fọwọ si iwe ẹsun naa pe ki ajọ Commonwealth fiya jẹ awọn adari Naijia Wọn ni fifi iya jẹ orilẹ-ede Naijiria lapapọ yoo pa awọn ọmọ Naijiria lara.
Lara awọn eniyan pataki to ba wọn pejọ pọ sibi ayẹyẹ naa ni alakoso fun iroyin, asa ati irinajo igbafẹ nipinlẹ Ọyọ, Oloye Toye Arulogun, alaga ijọba ibilẹ Ibarapa, Họnọrebu Ibrahim Habib Adegoke ati bẹẹbẹẹ lọ.
Amnoni bá sọ fún un pé, “Gbé e tọ̀ mí wá ninu yàrá mi, kí o sì gbé e kalẹ̀ níwájú mi.
 bakana brasil tun je ikan ninu awon awon orile-ede olohun-orisirisi 17 , ibe je ile fun awon orisi eran igbe , ayika adanida , opo awon alumoni adanida nibi orisi ibi abo .
Nígbà tí inúnibíni tabi ìṣòro bá dé nítorí ọ̀rọ̀ náà, lẹsẹkẹsẹ a kùnà.
Wọn yóo sọ wọ́n sinu iná ìléru.
Aarẹ Trump ni oun ko fẹ iwa ipa ati jagidijagan.
Ẹ wo bi Taiwo ṣe ja fita fita lati borii ainigbagbọ ninu ara ẹni.
0 842 Orilẹede Eritrea 6 0.
Àjọ NCDC kéde èèyàn 260 tuntun míì tó ṣẹṣẹ ni ààrùn Covid-19 ní Naijiria Òṣèré tíátà míì ń ṣàìsàn láti bí ọdún mẹ́ta, ọkan rèé tó ń bẹ̀bẹ̀ f'ówó Onírù tuntun Oba Abdulwasiu Gbolahan Lawal gba ọ̀pá àṣẹ Kayode Fayemi Ojumọ ọjọ kejilelogun oṣu keje ọdun 2020 ni gomina ipinlẹ Ekiti, Kayode Fayemi kede loju opo Twitter rẹ pe oun ti lugbadi arun Covid-19.
Nígbà tí Aṣojú-Olódùmarè dé gbogbo àwọn ọmmọ aráyé tún péjọ, ipò wọn tí wọ́n tí wà kò tún tẹ́ wọn lọ́rùn mọ́, ogunlọ́gọ̀ tún ń fẹ́ẹ́ padà sí ipò rẹ̀ àtẹ̀hìnwá.
Kalu tun so pe  “Ofin ti laa silẹ, pe gbogbo ipinle to wa
gbagede Ile Igbimọ Aṣofin naa ni ilu Ikẹja.
Fasiti Babcock ni ọmọkunrin to ba ọ́kẹkọbinrin naa lopọ wa ni ile iwosan kan to ti n gba itọju nitori ogun oloro mimu, nibi ti akẹkọọ binrin naa ti lọ ba.
Awọn afurasi yii ni wọn sọ pe wọn gbe oogun oloro mii wọ ilẹ naa, eleyi to lodi si ofin orilẹede Saudi Arabia, ati pe iku ni ijiya fun iru ẹsun bẹẹ.
Ọlọ́pàá Èkó gbé ẹni tó pa ìyàwó àti ọmọ rẹ̀ re'lé ẹjọ́
Wọ́n jẹ́ ọ̀kẹ́ meje, ó lé ẹgbaaje ati ẹgbẹta (153,600).
Ó ké rara pé, “Kí ni ó pa tàwa-tìrẹ pọ̀, Jesu ọmọ Ọlọrun tí ó lógo jùlọ?
Jehoṣafati bá ọba Israẹli ṣọ̀rẹ́, alaafia sì wà láàrin wọn.
Ijọba ko pese rẹ fun wọn Àkọlé àwòrán, Awọn obi tẹle awọn ọmọ wọn de ẹnu ọna ileewe lọjọ kini iwọle pada yi BBC News, Yorùbá Ìdí tí ẹ fi le è nígbàagbọ́ nínú ìròyìn BBC Ìlànà Lílò Nípa BBC Òfin Àṣírí Cookies Kàn sí.
Kí ló ń fa awuyewuye nípa ikú ọmọ alága ẹgbẹ́ Afenifere?
Lọganjọ ọjọ abamẹta ni awọn agbebọn doyika abule awọn ẹya Fulani kan, ti wọn ni wọn ni ohun ṣe pẹlu awọn agbesunmọmi jihadi.
Ìyà tí ó fi jẹ wọ́n, ati àwọn tí wọn ń gbé agbègbè wọn ni pé gbogbo ara wọn kún fún kókó ọlọ́yún.
Òun kì í ṣe ẹni tí ó níláti kọ́kọ́ rúbọ lojoojumọ fún ẹ̀ṣẹ̀ ti ara rẹ̀, kí ó tó wá rúbọ fún ẹ̀ṣẹ̀ àwọn eniyan, bí àwọn olórí alufaa ti ìdílé Lefi ti ń ṣe.
n óo mú kí àwọn odò rẹ gbẹ;’
Ǹjẹ́ ó jẹ́ dúpẹ́ lọ́wọ́ ọmọ-ọ̀dọ̀ nítorí pé ó ṣe ohun tí ó níláti ṣe?
Naijiria ati orile ede Cameroon  yoo jo fọwọsowọpọ
Èrò rẹ̀ ti yípadà, nítorí bí ó ti wù kí bàbá fẹ́ràn ọmọ rẹ̀ tó, kò sí ẹni tí o lè fẹ́ kí ọmọ òun pa òun.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Zlatan: Ọ̀rẹ́ ni mo sìn lọ ‘studio’ tí mo fi bẹ̀rẹ̀ orin lẹ́yìn tí mo kùnà ìdánwò WAEC Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Irú iṣẹ́ wo ní Funke Akindele rán sí Bukunmi Oluwasina, tó fa ariwo lórí ayélujára?
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Barister lo bi gbogbo oníṣẹ́ fújì -Oṣupa Bi o tilẹ jẹ pe agbẹjọro fun ajọ EFCC, Rotimi Oyedepo rọ ile ẹjọ lati gbọ ẹjọ ti wọn fi kan an ni wara-n-ṣeṣa, agbẹjọro fun Naira Marley ni akọrin naa lẹtọ si beeli labẹ abala ofin orilẹede Naijiria.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: A kú ewu ọmọ Linda Ikeji ooo Ọ̀rọ̀ LAUTECH gba àpérò f'áwọn Olúdíje Ọṣun Àgbárá òjò bà'lú jẹ́ n'Ípínlẹ̀ Ogun Àṣìlò òògùn burú, ṣùgbọ́n ṣé ẹ̀bi ará ìlú nìkan ni?
    Nígbà tí ọjọ́ lílọ pé mo lọ sí aafin.
30 Àti pé ìwọ ní èyí tí a ti kọ níwájú rẹ; nítori èyí, o gbọ́dọ̀ ṣe e gẹ́gẹ́bí àwọn ọ̀rọ̀ tí a ti kọ.
Ajọ Isọkan Agbaye, United Nations ti fi lede wi pe, jijẹ kokoro bii aayan dara nitori eroja asaraloore protein to wa lara kokoro naa dara fun eniyan.
Àwọn olórí alufaa mú owó fadaka náà, wọ́n ní, “Kò tọ́ fún wa láti fi í sinu àpò ìṣúra Tẹmpili mọ́ nítorí owó ẹ̀jẹ̀ ni.
Mo ti pa ọ́ mọ́,mo sì ti fi ọ́ dá majẹmu pẹlu àwọn aráyé,láti fìdí ilẹ̀ náà múlẹ̀,láti pín ilẹ̀ tí ó ti di ahoro.
Ìkarawun ni obìnrin, ìgbìn sì ni ọkùnrin, ibikíbi tí ìgbín bá ń lọ ti òun ti ìkarawun ní í lọ; ìyàwó bẹẹrẹ ìjàngbọ̀n bẹẹrẹ ni, bí ìyàwó bá ti ń pọ̀ sí i bẹ́ẹ̀ ni ìfẹ́ wọn ń dín sí i, ogunlọ́gọ̀ àwọn ọmọkùnrin ni wọ́n sí ń bá ọ̀tá pàtàkì gbé tí wọn ń pè é ní obìnrin.
"Fún àpẹẹrẹ ""Ààbọ̀ Ọ̀RỌ̀ l'àá sọ fún ọmọlúwàbí, tí ó bá dé inú rẹ̀ á di odindi."
ogun olote Boko Haram lati da alaafia pada ni awon ibi ti ogun ti waye nibẹ.
Kọmísónnà fún eré ìdárayá náà fikún pé ìgbésẹ̀ tuntun yìí wáyé lati fi agbárá kún akitiyan ìjọba ìpínlẹ̀ Ondo lati ri daju wípé ìtẹ̀síwájú dé bá ọ̀rọ̀ eré ìdárayá ìpínlẹ́ náà.
O Fagunwa, Adebayo Faleti, Akinwumi Iṣọla, Lawuyi Ogunniran àti Oladejo Okediji ṣiṣẹ silẹ ki wọn to lọ3 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Ogbontarigi onkọwe yii ni oun ti ya ara oun sọtọ gẹgẹ bi o ṣe yẹ ki oun to mọ lẹyin ọjọ mẹrinla boya oun ni tabi bẹẹkọ Coronavirus- Atọ́nà bí nkàn ṣe ń lọ ní Afirika Coronavirus: Wo ohun tí o ní láti ṣe láti dáàbò bo ara rẹ Báwo ni o ṣe le mọ̀ pé o ní àrùn Coronavirus?
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Coronavirus in Nigeria: Àwọn ìlànà tó tọ̀nà láti tọ̀ tí o bá fura pé o ní àrùn Coronavirus Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Coronavirus in Nigeria: Àwọn ìlànà tó tọ̀nà láti tọ̀ tí o bá fura pé o ní àrùn Coronavirus 20 Ẹrẹ̀nà 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 25 Ẹrẹ̀nà 2020 Arun Coronavirus ti tan de, o kere tan, ọgọrin orilẹ-ede, ilẹ Gẹẹsi ati Naijira si jẹ ọkan lara rẹ.
    Báyìí ni a bẹ̀rẹ̀ síí gbọ́ igbe náà tí o ń túbọ̀ súnmọ́ ọ̀dọ̀ wa.
Ṣugbọn bí opó kan bá ní àwọn ọmọ tabi àwọn ọmọ-ọmọ, wọ́n gbọdọ̀ kọ́ láti ṣe ìtọ́jú ìdílé wọn, kí wọ́n san pada ninu ohun tí àwọn òbí wọn ti ṣe fún wọn.
"O le ya àwọn eǹìyàn lẹ́nu, sùgbọ́n òòtọ́ọ́ ọ̀rọ̀ ni"" ọ̀rọ̀ ti Manager so fun BBC rèé nínú àtẹ̀jáde to fi sọ̀wọ."
Leyii to jẹ wi pe awọn kan ti kọkọ ni afi laa igbesẹ RUGA ti ijọba gbe lati kọ Gaa fun wọn ko le fẹsẹ mulẹ lagbegbe awọn.
Olóòótọ́ ni ẹni tí ó rán mi níṣẹ́; ohun tí mo gbọ́ lọ́dọ̀ rẹ̀ ni mò ń sọ fún aráyé.
Ìjọba ìpínlẹ̀ Oyo kò mọ̀ si Ìyá àti Bàbálọ́jà tí wọ́n yàn- Kọmíṣọ́nnà Okòwò 'O ṣójú mí kóró bí wọ́n ṣé fí àdó olóró pa Dele Giwa lọdún 1986' @tejumania tiẹ́ n pariwo ni pe ki loun se ti Ọ́lọrun fi da oun si orilẹede Naijiria?
ẹ mọ̀ dájú pé, OLUWA Ọlọrun yín kò ní lé àwọn orílẹ̀-èdè wọnyi jáde kúrò fun yín mọ́; ṣugbọn wọn óo di ẹ̀bìtì ati tàkúté fun yín, OLUWA yóo sì fi wọ́n ṣe pàṣán tí yóo máa fi nà yín.
Koda, awọn ọrẹ rẹ ti Mercy pe, ko ri nkankan sọ lori ibi ti o wa.
Nígbà tí ó wí báyìí tán, ó fi ọwọ́ rẹ̀ ati ẹsẹ̀ rẹ̀ hàn wọn.
O kò gbọdọ̀ bá aya baba rẹ lòpọ̀ nítorí pé bí ẹni ń tú baba ẹni síhòòhò ni.
Ẹ má bẹ̀rù, ẹ̀yin ọmọ Jakọbu,bí ẹ tilẹ̀ dàbí kòkòrò lásán,ẹ̀yin ọmọ Israẹli,OLUWA ní òun óo ràn yín lọ́wọ́.
Mo ti sọ fún un pé n óo jẹ ìdílé rẹ̀ níyà títí lae, nítorí pé àwọn ọmọ rẹ̀ ti ṣe nǹkan burúkú sí mi.
O ni lati bere lowo ara re.
Ni mo bá dojúbolẹ̀ níwájú rẹ̀, mo júbà rẹ̀.
Naira Marley ninu gbaga ajọ EFCC fun ẹsun jibiti ori ayelujara.
Ìgbín dá Ọba lóhùn pé kì í ṣe òun ni òun pa abuké Ọba àti pé bí Ọba bá fẹ́ mọ ẹni tí ó pa abuké Ọba òun lè ràn Ọba lọ́wọ́ láti jẹ́ kí ó mọ ẹni tí ó pa á.
APC àti Buhari, ẹ yé irọ́ pa, kẹ sì múra láti kojú ìgbẹ́jọ́ - PDP fèsì Gómínà Bauchi kí olùdíje PDP tó fẹ̀yìn rẹ̀ janlẹ̀ Olùkọ́ aláàánú, tó ń fi owó oṣù tọrẹ́ gba àmì ẹ̀yẹ $1m Mutiu Agboke fi kun wi pe, lasiko ti ọrọ naa gbomi mu fun oun, ni oun pe Alaga apapọ fun Ajọ INEC, Ọjọgbọn Mahmood Yakubu wi pe, ki ni ki oun se, ti o si pasẹ fun un lati ka esi idibo naa, ki oun si se oun lori esi naa Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Èré Ọṣun: Àtáója ní wọn kò jí ère Ọṣun, ó sì wà níbi tó wà Kọmisọnna fun Ajọ eleto idibo INEC ni ipinlẹ Ọyọ naa wa fikun wi pe, Ọjọru ni gomina ti wọn dibo yan ati igbakeji rẹ yoo gba iwe mo yege ibo.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ejo lo gb'owo mi ni Naijiria, anabọ lo kowo lọ ni Burundi 21 Èrèlè 2018 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Isẹlẹ owo pipoora ti n di lemọlemọ ni ilẹ Afirika Njẹ ẹ ranti isẹlẹ ejo to gbe owo mi lorilẹede Naijiria laipẹ yii?
“Yóo pa àwọn olóòótọ́ tí wọ́n jẹ́ tirẹ̀ mọ́,ṣugbọn yóo mú kí àwọn eniyan burúkú parẹ́ ninu òkùnkùn;nítorí pé, kì í ṣe nípa agbára eniyan, ni ẹnikẹ́ni lè fi ṣẹgun.
Danze ti egbe oselu APC , lẹyin to tẹle ilana 
Ikire Tussle: Ìdí tí àwọn ọ̀dọ́ Ikire fí ni dandan ọba gbọdọ̀ kúrò lórí àpèrè
Igbesẹ naa ti wọn kede laipẹ yi ko yọ awọn to kopa tabi ti wọn ṣe agbatẹru dida ibo Naijiria ọdun 2019 to kọja ru.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Buhari: Ọ̀págun ìjìjàgbara fún South Africa ni Winnie 3 Ìgbé 2018 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Winnie Madikizela-Mandela kó ipa takuntakun nínú ìjìjàgbara lórílẹ̀èdè South Africa kúrò nínú ìgbèkùn amúnisìn Ààrẹ Muhammadu Buhari ti ṣe àpèjúwe ikú ògbóǹtagí ajìjàgbara nnì, Winnie Madikizela-Mandela gẹgẹ bíi àdánù ńlá fún ilẹ Áfíríkà nítorí akínkanjú obìnrin ni.
Oríṣun àwòrán, Reuters Àkọlé àwòrán, Lẹ́yìn ọdún meji ti ó ti ku, wọn ṣẹṣẹ gbe posi ọga ẹgbẹ alátako Etienne Tshisekedi Káàkiri ní orilẹ̀-èdè DR Congo laja Jimọ.
Godwin Obaseki wọlé ìbò gómìnà lẹ́ẹ̀kejì ní ìpínlẹ̀ Edo Oríṣun àwòrán, Twitter/Godwin Obaseki Iroyin to n tẹ wa lọwọ bayii lo sọ wi pe Godwin Obaseki lo wọle ibo gomina ipinlẹ Edo.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Africa Eye: Ìjìjàgbara fún àwọn ọmọdébìnrin tó wà lọ́wọ́ ewu 29 Sẹ́rẹ́ 2020 Ikọ ọtẹlẹmuyẹ Africa Eye tun de orilẹede Congo nibi to ti finmu finlẹ nipa igbe aye awọn ọdọbinrin ti wọn dagba soju popo.
Èèyàn 296 ló forí kó Covid -19 ní Nàìjíríà lọ́jọ́bọ Ènìyàn mẹ́rìndínlọ́ọ̀dúnrún ló tún lùgbàdì ààrùn Covid-19 lọ́jọ́bọ gẹ́gẹ́ bi atẹjade àjọ tó n gbogun ti ajakalẹ ààrun lórílẹ̀-èdè Naijiria ṣe sọ.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Hushpuppi di gbajúmọ̀ ẹlẹ́wọ̀n tó ní nọ́ńbà l‘Amẹrika, orúkọ̀ rẹ̀ wà lórí ayélujára Nǹkan tí ojú rí rè é bí pápákọ̀ òfurufú ṣe di ṣíṣí padà ní Nàìjíríà Ṣé lóòtọ́ ni Lateef Adedimeji àti Adebimpe Oyebade ṣe ìgbéyàwó?
Àwọn tí wọ́n jẹ́ olórí láàrin àwọn ọmọ Israẹli rí i pé àwọn wà ninu ewu, nígbà tí wọ́n gbọ́ pé iye bíríkì tí àwọn ń mọ lojumọ kò gbọdọ̀ dín rárá.
A wa n gbadura pe ki Ọba oke tẹ Joseph Folahan Odunjo si afẹfẹ rere.
Àwọn Ọmọ Israẹli Gbógun ti Àwọn Ará Filistia.
Ki lo de ti waa fi ṣe iru nnkan bẹẹ lai sọ fun un?
Ohun tí ó ti wà tẹ́lẹ̀ náà ni yóo máa wà.
Iwe yii ma n se afihan ohun ti ẹgbẹ duro fun ati ọna ti wọn fẹ gba lati mu aye
44 fún lítà kan Ìdí rèé táwọn àkàndá ẹ̀dá fi dí iwájú iléeṣẹ́ ìjọba ìpínlẹ̀ Oyo pa l'Agodi n'Ibadan A kò ní padà sílé ìwé àyàfi t́i ìjọba bá san owó oṣù tó jẹ wá - ASUU Ohun tó yẹ kí o mọ̀ nípa ìgbésẹ̀ tí Amẹ́ríkà fẹ́ gbé lórí Nàìjíríà nítorí ọ̀rọ̀ ẹ̀sìn Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ojú mi ti rí lọ́pọ̀ lọpọ̀, àmọ́ mo dúpẹ́ pé mo ti pé ọdún márùn ún lórí oyé- Ooni Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Akure shooting: Àlááfíà ti padà sí ìlú Akure, ẹnikẹ́ni kò kú - Deji ilu Akure7 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Ondo 2020 Tribunal: Ìgbìmọ̀ olùgbẹ̀jọ́ ìbò gómìnà yóò gbérasọ lọ́jọ́ Iṣẹgun7 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Aisha Buhari: Aya Ààrẹ Buhari ké sí àwọn aya gómìnà pé kí wọ́n lọ paná ìdàrúdàpọ̀ ágbègbè kóówá7 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Fídíò, Soyinka Cancer: Àṣe ara mi ni iso ti n run gbogbo bí mo ṣe n ṣèrànwọ́ lórí jẹjẹrẹ27 Bélú 2019 Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
tucker jẹ ́ ọmọ alákóso ìlú hamilton , bermuda àkọ ́ kọ ́ .
Akeredolu ń fẹ́ kí wọ́n dìbò fún òun ló jẹ́ kó ṣàdínkù owó ilé ìwé AAUA - Akẹ́kọ́ọ̀ AAUA Ta ni Ọmọ ọdún 17 tí wọ́n fẹ̀sùn kàn pé ó pa èèyàn méjì ní Kenosha?
N óo dijú, n óo fi ẹ̀mí ara mi wéwu.
com/yoruba Ẹka akanṣe iroyin ni ede Yoruba yoo wa ni ori opo ayelujara Facebook ati instagram pẹlu idanimọ @bbcnewsyoruba Eto iṣẹ yi yoo maa jade lati ileeṣ BBC nipinlẹ Eko Awọn ọmọ Yoruba ti wa ni pẹsẹ lati ṣe eto ipese iroyin yii lojoojumọ pẹlu ẹrọ igbalode.
   awọn  eniyan naa , ko sai fi idunnu wọn  han si aare orile ede Naijiria Muhammadu Buhari lati ri i pe  awọn  eniyan naa pada wa sile.
'Njẹ ka ni pe awọn olori wọnyi lo mu aseyọri yi wa funra wọn ni tabi ka sọ pe awọn nkan to wa nilẹ yi lo sokunfa aseyọri yi?
Mo ha gbọdọ̀ kọ̀ ọ́ sílẹ̀, Israẹli?
'Òpín yóò débá ìwà jàgídíjàgan ní Ekiti'
Ninu awọn to ti wa ni ikalẹ ni awọn ọmọ ijọ rẹ, awọn mọlẹbi obi ti ọmọ wọn sọnu ati awọn akọroyin.
Ọmọ ju ọmọ lọ, agbára ju agbára lọ ni ọrọ Funmilayọ Kuti tí Ilééṣẹ́ Google ń ṣe ìrántí rẹ̀.
Ohu ti o dara ni pe
ó mú èyí wá sórí rẹ, nítorí o ti bá àwọn orílẹ̀-èdè mìíràn ṣe àgbèrè, o sì ti fi oriṣa wọn ba ara rẹ jẹ́.
OsunElectionUpdates2018: Ọ̀rọ̀ bẹ́yìn yọ fún PDP lórí ìbò ibùdó méje
Mo ti ká àìdára rẹ kúrò bí awọsanma,mo ti gbá ẹ̀ṣẹ̀ rẹ dànù bí ìkùukùu.
Ẹ kọ orin ògo yin orúkọ rẹ̀;ẹ yìn ín, ẹ fògo fún un!
2 1,877 Turks and Caicos Islands 6 15.
Apẹrẹ rẹ ko si ju ẹgbẹrun meji Naijiria lọ lorilẹede Naijiria.
Ẹrọ 4Sale, Haraj ati Instagram faaye silẹ fun awọn to ni ọmọ ọdọ lati tawọn eniyan yii fun ẹlomiran fun ere ti wọn.
Oríṣun àwòrán, Manzo Ezekiel Àkọlé àwòrán, Nísẹ ni àwọn tó n lọ, àti àwọn to n bọ̀ kòrí àáye kọjá nítorí bí ojú ọ̀nà ṣe dí.
Tí a fiṣọwọ́ ní 9:31 16 Sẹ́rẹ́ 20219:31 16 Sẹ́rẹ́ 2021 Irọ́ ni pé ọba tuntun má a ń jẹ ọkàn ọba tó bá wàjà ní ìpèbí - Elebuibon Elebuibon ni lati ilẹ ni baba oun ti sọ foun pe oun ko ni lọ si ile iwe nitori iṣẹ Ifa ni akọsẹjaye oun pe lọna foun.
Àwọn eniyan dúró, wọ́n ń wòran.
Bẹẹ ba gbagbe, alẹ ana la mu iroyin wa fun yin pe abala kan lọwọ ẹyin ibudo itaja aya Ajimobi naa, Grandex, to wa ladugbo Bodija nilu Ibadan gbina.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Majek Fashek: Mọlẹbí nìkan ló péjú síbi ìsìnkú gbajúgbajà olórin reggae náà ní Amẹ́ríkà 2 Òkùdu 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 22 Ògún 2020 Oríṣun àwòrán, others Majek Fashek gbajugbaja olorin reggae ọmọ Naijiria ti wọ kaa ilẹ lọ.
Sùgbọ́n, gẹ́gẹ́ bó se máa ń rí pẹ̀lú àwọn òògùn olóró, èèyàn leè kúndùn rẹ̀, kó sì di bárakú sí onítọ̀ún lára - sùgbọ́n àríyàn-jiyàn sì ń wáyé lórí bí èèyàn se leè kúndùn rẹ̀ sí.
Nigba ti o n menuba awon ohun ti Awolowo ti gbese
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, 'Iṣẹlẹ ifipa bọmọde lopọ yoo tẹsiwaju niwọn igba ti awọn eeyan ko tii ṣetan lati maa sọ nipa rẹ.
Lẹyin ipade naa ni Aṣiwaju Ọmọ ẹgbẹ oṣelu to pọ julọ ninu Ile, Aṣofin
O soro idaniloju pea won agbe yoo lo owo naa daadaa ki o le bi eso rere fun terutomo, ki ebi ma pa ilu mo lasiko yii.
OLUWA ní, òun óo kó kẹ̀kẹ́ ogun kúrò ní Efuraimu,òun óo kó ẹṣin ogun kúrò ní Jerusalẹmu,a óo sì ṣẹ́ ọfà ogun.
Ile Igbimọ Aṣofin Ipinlẹ Eko labẹ ẹgbẹ oṣelu APC ti wọn jẹ ogoji ni
"Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù COZA RAPE: Àjọ pẹntikọsita ní Nàìjíríà (PFN) sọ pé Biodun Fatoyinbo ní kò jẹ́ kí ìwádìí wọn parí 22 Ògún 2019 Oríṣun àwòrán, ""others Àkọlé àwòrán, Iwadii ko le pari laijẹ pe Fatoyinbo yọju si PFN Ajo awọn ẹni ẹmi ni Naijiria, eyi ti wọn n pé ni Pentecostal Fellowship of Nigeria (PFN), ti fi ọrọ lede pe awọn ko tii pari iwadii ti wọn n ṣe lori ẹsun ifipabanilopọ ti Busọla Dakolo fi kan Biọdun Fatoyinbo."
O si ni bi mo ba to bẹẹ, ki n gba temi pada'' Ninu esi rẹ, Ebosereme ni irọ gbaa ni Abunike n pa mọ oun.
 Àwọn ààmì lápapọ ̀ kòpọ ̀ bẹ ́ ẹ ̀ ni wọn kìí ju ọjọ ́ méje lọ .
Báyìí ni ọ̀rọ̀ tí wolii Aisaya sọ ṣẹ, nígbà tí ó sọ pé, “Òun fúnra rẹ̀ ni ó mú àìlera wa lọ, ó sì gba àìsàn wa fún wa.
Ni papakọ ofurufu ni wọn ti gba ipe pe awọn ologun ti da ibo ru o.
Ẹnikeji ti wọn tun foju sun fun ipo kan naa, Ọjọgbọn Ben Ogbojafor ni tirẹ ni ibo mọkanlelọgbọn.
A kò ní gba ẹnikẹ́ni láàyè láti ṣe ìfẹ̀hónúhàn kankan mọ́ ní ìpínlẹ̀ Eko- Iléeṣẹ́ ọlọ́pàá kìlọ̀ Wo ìgbà márùn ún tí Buhari ti rìnrin àjò lọ sókè òkun fún ìtọ́jú ara rẹ̀ Mo ṣetán láti dojú ìjà kọ ẹnikẹ́ni tó bá fẹ́ bá ọ̀rọ̀ ajé Eko jẹ́- Sanwo Olu Sanwo-Olu buwọ́lu ìgbésẹ̀ ìjọba láti tún Eko ṣe lẹ́yìn rògbòdìyàn EndSARS Nigba ti wọn n sọrọ lẹyin ti aya gomina tẹlẹri ọhun jade ile opo, ẹgbẹ awọn obinrin ninu ẹgbẹ oṣelu APC baa ṣajọyọ, wọn si tun kii ku oriire.
Ṣugbọn àwọn ọmọ ogun Kalidea lépa Sedekaya, wọ́n bá a ní pẹ̀tẹ́lẹ̀ Jẹriko, gbogbo àwọn ọmọ ogun rẹ̀ sì túká kúrò lẹ́yìn rẹ̀.
Ó bá lọ gbé e fún ìyá rẹ̀.
Ó yẹ kí àwọn ọlọ́pàá mú Lere Olayinka fún ìwà ọ̀daràn - Oyo PDP Báwo ni mo ṣe fẹ́ fi ìyàwó àfẹ́sọ́nà mi akáta hàn fáwọn òbí mi?
Ifẹsẹwọnsẹ ikẹyin laarin wọn waye ni 2003 nibi ti Man U ti gbewuro soju Juventus pẹlu ami ayo mẹta.
Coffin Ghana: Òkú yóò lọ sílé ìkẹyìn pẹ̀lú afẹ́ tó kẹjẹgbẹ
Bakan naa ni eto igbayegbadun buyaari si nilu naa, to jẹ ilu to dakẹ jẹjẹ tẹlẹ ki Alaafin yii to debẹ.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ààrẹ Buhari pàsẹ kí wọ́n ṣí àwọn ibodè Nàìjíríà padà kíákíá!
Nítorí ẹni tí ó bá ń ṣiyèméjì dàbí ìgbì omi òkun, tí afẹ́fẹ́ ń fẹ́ kiri tí ó sì ń rú sókè.
Ninu oṣù keje ọdún ni ẹ óo máa ṣe àjọ àjọ̀dún náà.
Àkọlé àwòrán, Pupọ awọn obi lo pese awọn ibomu fawọn ọmọ to pada si ileewe.
Ewe, won fi oro naa mule pe, ohun ti o le dena iyanselodi naa ni ki ijoba apapo ati awon toro kan patapata ko tete wa woroko fi sada ki akoko naa o to pe.
Lizzy Anjọnrin fẹ̀si fáwọn agbọ́yì-sọ̀yí lórí ìgbéyàwó rẹ̀, Madam Sajẹ dasójú ilé iṣẹ́, àti àwọn ǹkan míràn tó ṣẹlẹ̀ lágbo tíátà lọ́sẹ̀ yìí Koda, gbogbo mọlẹbi rẹ ni ọmọbinrin naa darukọ lọkọọkan, to fi mọ aja wọn, to si sọ isẹ to fi silẹ fun ikọọkan wọn.
Ó tún tẹ́ pẹpẹ meje, ó sì fi akọ mààlúù kọ̀ọ̀kan ati àgbò kọ̀ọ̀kan rúbọ lórí pẹpẹ kọ̀ọ̀kan.
"kò sí ǹkan ti mo le ṣe.
Ninu idajo naa, adajo John Tsoho ni asise nla gbaa ni fun ajọ EFCC lati maa ro wi pẹ ile asofin agba ko lasẹ lati lodi si iyansipo alaga rẹ.
 Ewe, lataari sise ifilole awon ajo tuntun miiran yii, orile-ede Naijiria wa ni apapo ajo méjídínlọ́gbọ̀n pelu apapo minisita mẹ́rìnlélógójì ti yoo maa tuko won.
Ọpọ lo n foju wo Abba Kyari nigba aye rẹ gẹgẹ bii ẹni to lagbara julọ ni iṣejọba aarẹ Buhari.
Ọ̀lẹ kì í dáko ní àkókò,nítorí náà, nígbà ìkórè, kò ní rí nǹkankan kó jọ.
Lọwọ yi, eeyan mẹjọ ni àrùn Covid-19 n ba fínra ni Osun.
Gbogbo àwọn yòókù patapata ni wọ́n kó lójú ogun.
” Ṣugbọn ẹni tí ń ru ihamọra rẹ̀ kọ̀, nítorí pe ẹ̀rù bà á; nítorí náà, Saulu fa idà ara rẹ̀ yọ, ó sì ṣubú lé e.
Oríṣun àwòrán, Ayodeji Abass Alesinloye O ni ninu aba naa nijọba ti gba lati san awọn nnkan kan fun awọn alaga kansu naa, nitori ala ti ko lee sẹ ni igbiyanju wọn lati pada si ọọfisi bii alaga kansu, to si ni ki wọn tu itọ rẹ danu pe eyi yoo ri bẹẹ.
Nítorí gbogbo àwọn tí wọ́n bá sì ń mu wàrà, kò tíì mọ ẹ̀kọ́ nípa òdodo, nítorí ọmọ-ọwọ́ ni irú wọn.
Oun ni igbakeji alaga obinrin akọkọ fun aarin gbungubn ariwa Naijiria.
Ọ̀yẹ̀ yóò là fún abẹ́rẹ́ ìfètòsọ́mọbíbí fáwọn ọkùnrin láìpẹ́ Adarí Ilé ìgbìmọ̀ Asòfin tako ètò ìjọba tiwantiwa- Agbẹjọ́rọ̀ Ǹjẹ́ o mọ ohun tó ń fa súnkẹrẹ-fàkẹrẹ nílùú Eko?
Láti inú àwọn ẹ̀yà tí wọ́n wà ní ìhà ìlà oòrùn Jọdani, ẹ̀yà Reubẹni, ti Gadi, ati ìdajì ti Manase, ọ̀kẹ́ mẹfa (120,000) ọmọ ogun tí wọ́n ní gbogbo ihamọra ogun ni wọ́n wá.
Ọbinrin ọhun fikun pe asiko kan tiẹ wa, ti inu n run oun, Leah yii lo gbe ọwọ si inu oun, o gbadura fun oun, ti inu riru naa si lọ.
Ó lọ láti apá ìlà oòrùn títí dé apá ìwọ̀ oòrùn: Ìpín ti Dani yóo jẹ́ ìpín kan.
Akinyele tún gbàlejò àwọn mùjẹ̀mùjẹ̀, tìyá-tọmọ̀ fara gbọgbẹ́ Ẹ pèsè ẹlẹ́rìí púpọ̀ bí bẹ́ẹ̀ kọ́, Sotitobire yóò jẹ́rìí fúnrarẹ̀ o!
Ibo 2,772 lo ni ninu idibo abele, eleyi ti o fun lanfaani lati
Ó ti fara hàn nínú eré tó lé ní àádọ́ta.
Grandpa àti Uncle mi, ń fipá bá mi lòpọ̀ láti ọmọ ọdún mẹ́rin"" Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'IBB da Abiola lẹ́yìn tó búra pẹ̀lú Quran' Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!"
- MC Oluomo Láìpẹ́, ará ìlú rẹ ni ọlọ́pàá tí yóò máa ṣọ́ ìlú rẹ Ìdajì owó iṣẹ́ àgbàṣe ló ń padà sápò gómìnà àná àti aya rẹ̀ l‘Ọyọ - Seyi Makinde Ẹ̀tanu ni àwọn ìmáàmù Yoruba fi yan Waziri míì, ojúṣe ọba ni - Oluwo Sanwo-Olu fi ẹ̀gbin dá àrà tuntun l'Eko Àwọn ọ̀rọ̀ apanílẹ̀rín tí Mugabe sọ tó jẹ́ mánigbàgbé O fikun pe ọkọ baalu nla ni awọn gbe kalẹ, o si yẹ ki awọn se gbogbo eto to yẹ ki baalu naa to morile orilẹede South Africa lati ko awọn eeyan naa wale.
A óo wá mú ọ̀rọ̀ ìyìn rere kọjá ọ̀dọ̀ yín, láì ṣe ìgbéraga nípa iṣẹ́ tí ẹlòmíràn ti ṣe ní ààyè tirẹ̀.
Imọ nipa ibaraẹnisọrọ ti a mọ si Mass Communication lo ka ni fasiti Bayero nilu Kano.
awon ọdaran ati lati mọ ibi ti awon odaran ba sapamọ si.
Orile-ede Mali ni orile-ede keta ti o n pese goolu julo nile Afrika, leyin orile-ede South Africa ati Ghana, pelu orisirisi awon olokoowo to n ri si oro goolu lorile-ede naa bi: Randgold Resources limited ati AngloGold Ashanti limited.
Benhadadi ọba tún ranṣẹ pada pé, “Àwọn oriṣa ń gbọ́!
Awọn ololufẹ rẹ ranti iṣẹ takuntakun to ṣe lati gba ami ẹyẹ lasiko idije Afcon 1992 to waye ni orilẹede Senegal.
Drug Trafficking: Obìnrin méjìlá ló wà lára àwn olóògùn olóró náà
fi se mogo-mogo ibo, lona ti awon omo egbe rẹ  yoo fi se aseyọri.
 o máa ń sẹlẹ ̀ ni ọ ̀ pọ ̀ ìgbà pé tí ìlú kan bá parí ọdún tiwọn lónìí , tí àdúgbò míìràn le bẹ ̀ rẹ ̀ ni ọjọ ́ keje ẹ ̀ .
Nítorí bí ìwọ bá béèrè ohun tí o fẹ́, èmi yíò fií fún ọ.
Idẹ ni wọ́n fi ṣe ìtẹ́lẹ̀ wọn, ṣugbọn fadaka ni wọ́n fi ṣe ìkọ́ ati àwọn ọ̀pá tẹ́ẹ́rẹ́tẹ́ẹ́rẹ́ wọn.
Bakanaa lo ko ipa to loorin gẹgẹbii asiwaju ninu ilana iduna-dura eyi to fi opin si isejọba awọn alawọ funfun lorilẹede naa.
Nígbà tí àwọn tí ọ̀gágun rán pada dé ilé, wọ́n rí ẹrú náà tí ara rẹ̀ ti dá.
  Ọdún á yabo fún gbogbo wa o.
Baba mi yóo fẹ́ràn rẹ̀, èmi ati Baba mi yóo wá sọ́dọ̀ rẹ̀, a óo fi ọ̀dọ̀ rẹ̀ ṣe ibùgbé.
Eefin to n jade lati inu ile lasiko ti wọn n dana sun iwe idibo nikan ni àmì pe idibo n lọ lọwọ.
Awon Iko agbaboolu meje ti o wani eka kinni kookan lanfani lati gba owo ti o to ẹ̀gbẹ̀rún lona ẹ̀ẹ́dẹ́gbẹ̀ta (N500,000), beesini iko agbaboolu marundinlogun ti o wani eka keji kookan gba ẹ̀gbẹ̀rún lona irinwó din làádọ́ta (N350,000), tii iko agbaboolu mokandinlogun ti o bo si eka keta si lanfani lati gba ẹ̀gbẹ̀rún lona òjìlénígba lé mewaa(N250, 000).
tun mo si pe, iko agbaboolu Arsenal yoo wa le sipo karun un pelu ami mẹ́rìndínláàdọ́rin(66point) lori tabili,
Nígbà náà Jesu sọ fún wọn pé, “Gbogbo yín ni ẹ óo pada lẹ́yìn mi ní alẹ́ yìí, gẹ́gẹ́ bí ó ti wà ní àkọsílẹ̀ pé,‘Ọwọ́ yóo tẹ olùṣọ́-aguntan,gbogbo agbo aguntan ni a óo fọ́nká!
ng Ẹ mà sọ pátá tí ẹ ò lò mọ́ sọnù - Òsèré Mosun Filani Ọ̀rọ̀ pátá jíjí yìí ti sọ oun tí àwọn obinrin lè ṣe si àwọ̀tẹ́lẹ̀ tí wọn kò bá nílò mọ́ di ọ̀rọ̀ ńlá báyìí.
gbogbo ipinle mẹ́rìndínlógójì(36)  ti mo de lasiko eto ipolongo ibo aare ju awon
Ipele meje ni wọn yoo fi ṣe idibo lorileede India eleyii ti wọn ko si ni ọjọbọ.
Awọn olori ijọ ti ọrọ yii ti ta ba ree: 1.
Lassa fever: ìpínlẹ̀ Èkó kéde èèyàn kan pẹ̀lú ibà Lassa
Ọdun 2017 ni aṣọle Enyeama ṣoju ikọ agbabọọlu kẹyin lẹyin to fi ẹgbẹ agbabọọlu Lille silẹ loṣu kẹjọ ọdun 2018.
com/nimc_ng/status/1340677445435973633 Bayii ni fọọmu naa ṣe ri.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Orisabunmi: Àbúrò èèkàn òṣèré Orisabunmi tó jáde láyé ní ọjọ́ méjì péré ló lò níléèwòsàn kí ikú tó dé 8 Sẹ́rẹ́ 2021 Oríṣun àwòrán, Tundeolayusuf/instagram Awọn iroyin tuntun tun jade nipa iku oloogbe Fọlakẹ Arẹmu ti ọpọ mọ si Oriṣabunmi, eekan oṣere tiata ati sinima lorilẹede Naijiria to jade laye ni ọjs diẹ sẹyin.
Jesu dá a lóhùn pé, “Àwọn kọ̀lọ̀kọ̀lọ̀ ní ihò, àwọn ẹyẹ ojú ọ̀run sì ní ìtẹ́, ṣugbọn Ọmọ-Eniyan kò ní ibi tí yóo gbé orí rẹ̀ lé.
Yatọ si pe awọn naa gbadura, wọn tun ṣe iwọde kaakiri ilu Akure de agbegbe ọja NEPA, Alagbaka, olu ileeṣẹ ọlọpaa ni ọna Igbatoro, ati bẹẹbẹẹ lọ.
Ó wá rí i tí àwọn angẹli Ọlọrun ń gùn ún lọ sókè sódò.
Wo ẹ̀bùn àti owó tí àwọn olùkópa ti jẹ lórí ètò BBNaija season 5 Kíni 'Ẹ̀lẹ̀ daddy' Olorì Abbey Adeyemi ṣe tí ojú òpó ayélujára Instagram rẹ̀ fi ń yeruku lálá?
Awọn miran tun n sọ pe ibatan rẹ ni oye naa tọ si lati joye Emir, wọn ibatan rẹ ọhun ni ni ojulowo ẹni to yẹ ko gori alefa Emir ọhun.
Sugbon asofin , Shehu Sani  to je alaga igbimo to n ri si yiya owo loke okun ati orile ede Naijria ni ko si adehun to fese mule laarin ijoba apapo ati ile ise naa, paapaa julo  lori ise akanse ti oju irin  to lo si Port- Harcourt  ati Maiduguri .
Mo fi ẹnu mi kéde gbogbo àṣẹ tí o pa.
•Instagram, Facebook ati Twitter le e gbegile awọn aworan tabi fidio to ba lodi si aṣẹ to rọ mọ awọn fidio to tọna.
Kò s'ólùrànlọ́wọ́ míì lẹ́yìn Ọlọ́run àtòun yìí nìkan kó tó di pe ojú rẹ lọ.
Tí wọ́n fi ìkorò ṣe adùn,tí wọ́n sì fi adùn ṣe ìkorò.
Wọn óo bọ́ sọ́wọ́ àwọn ọmọ ogun ọba Babiloni tí ó ti ṣígun kúrò lọ́dọ̀ wọn.
"Ẹni ọdun mejidinlaadọrin ni ""Chief Kanran"" a bi ni Keesi,ni ipinlẹ Ogun Jimi Solanke Oríṣun àwòrán, others Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 3 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 5 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!"
Mallam Tunde Kazeem, gba won nimoran lati gbajumo ohun ti won wa ko ni ipago ki won le saseyege ni Algeria.
Trump yọ Tillerson kuro nipo 'Oku ọmọ mi ni wọn gbe wa ba mi lẹnu iṣẹ Ile igbimọ asofin tako Kayọde Fayẹmi Lasiko ti wọn ni ki Jubrin lọ rọọkun n'ile, gẹgẹ bii asofin Nicholas Ossai se daba rẹ, ti gbogbo asofin si kin lẹyin, wọn panupọ fọwọsi pe Jubrin ko lee di ipo asẹ kankan mu lasiko ile asofin to wa lode bayi.
Àpanisáyé ni ẹ̀wà tí wọ́n n fí 'sniper' sí 'Mo kan sara sawọn ayasọlo' 'Èmí ló nilé tí EFCC tì pa kìí ṣe Fayose' Ìrẹsì ọ̀fadà pẹ̀lú ọbẹ̀ ayamáṣe, àjẹpọ́nnulá ni Ṣugbọn Albert pada kọ iwe pinpin ogún silẹ ti ko si owó fun Mileva ninu rẹ.
Lẹ́yìn èyí, o ní, ‘Ẹ padà sí ipò yin’were ni gbogbo àwọn ènìyàn wọ̀nyí tún ti yípadà tí wọ́n di ẹranko àfi àwọn mejìla tí o fi fún Adéforítì ni Adéforítì mú wa sí ilé rẹ̀.
Abdulraheem ti ko lee foju rẹ riran ni funra awọn obi wọn lo mu wọn wa ki wọn ba wọn mojuto ayipada iwa wọn ti wọn si ti yipada lootọ koda atawọn ti wọn mu wa ni were tara wọn ti da bayii.
’ Nítorí náà OLUWA yóo fun yín ní ẹran.
Seyi Makinde fojú hàn n'íta lẹ́yìn tó ṣẹ́gun Coronavirus Màmá Guardiola d'olóògbé lẹ́yìn tó lùgbàdì Coronavirus Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí 3 sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
Adájọ́ pàṣẹ kí wọ́n fi ọlọ́pàá tó lọ́wọ́ nínú ikú Kolade Johnson sí àhámọ́ Ọwọ Ọlọ́pàá tẹ afunrasi méjì tó mọ nípa ikú dókítà LUTH Olórí ilé asòfin l‘Ọ́sun pàdánù N38m sọ́wọ́ gbájúẹ̀ Awọn ọlọpaa miran wa ninu aworan naa to mu wa ro wi pe ibi ti wọn ti n da ọkọ duro fun ayẹwo,''Checkpoint'' ni iṣẹlẹ naa ti waye.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ladoja: Àwọn èèyàn Oyo fì ìbò sọ̀rọ̀ pé ìjọba Ajimobi kò dára Olórí ẹ̀sin ọ̀hun ní, o ṣe pàtàkì ki wọ́n se ìdásílẹ̀ àwọn ọlọ́pàá ìpínlẹ̀ nítori pe, èyí yóò mú ki ààbò to dáju wà láárín àwùjọ.
”Nítorí ẹ̀mí tí ó mú kí eniyan jẹ́rìí igbagbọ ninu Jesu ni ẹ̀mí tí ó wà ninu wolii.
Pẹlu awọn aworan to n fi sita lo ti ye ni pe ara ọtọ leyii bẹẹ si ni Funke Akindele gan an ninu sinima naa yatọ si eyi tẹẹ mọ ninu apa kinni Omo Ghetto.
Amọ ninu gbogbo eyi, ero Olamide Abimbola yatọ ni tiẹ.
 Ẹ ̀ gbọ ́ n ilẹ ́ sanmí ni Àdùnní ìyá dúró orímóògùnjẹ ́ .
Mo fẹ́ kí Ọlọ́run fún wa ní ọmọ olójú búlúù si lẹ́yìn yìgì - Ọkọ olójú búlúù Ọdún Hijri mùsùlùmí tuntun wọlé dé, ẹ wo kókó pàtàkì nípa rẹ̀ Ẹ̀yin gómìnà, Ifá nìkan ló le tọ yín sọ́nà láì kùnà lórí Amotekun - Babaláwo Afurasí lórí ikú Tolulope Arotile ti dé ilé ẹjọ́, èyí ni ẹ̀sùn tí wọ́n fi kàn án Makinde, jọ̀ọ́ kéde Aug 20 ọdọọdún bíi ọjọ́ ìsinmi fún ìṣẹ̀ṣe - Àwọn oníṣẹ̀ṣe Ọyọ Yoruba ni tẹni ba dakẹ, tara rẹ maa n baa dakẹ ni.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Àwọn ìgbà tí ẹ̀ṣọ́ aṣọ́bodè ti pànìyàn lọ́nà àìtọ́ Àjọ aṣọ́bodè gba Codeine N200m Iléeṣẹ́ aṣọ́bodè gba nǹkan ìjagun àìtọ́ Ẹ́ wo iye ààrẹ Nàíjíríà tó sọ̀rọ̀ ìjayà lásìkò ìbò INEC tako àṣẹ Buhari lórí pípa ẹni tó bá jí ìbò gbé Ṣé ọwọ́ ti ká Boko Haram ní Nàìjíríà bí?
“Bí ẹ bá gbọ́, ní ọ̀kan ninu àwọn ìlú tí OLUWA Ọlọrun yín fun yín láti máa gbé, pé, 
Aisha Buhari figbe ta,o ní pé Garba Sheu tí gbàbọde Ìròyìn nípa ìyàwó túntún fún ọkọ mi kò mì mí lọ́kàn rárá-Aisha Buhari DSS gbé olùrànlọ́wọ́ Aisha Buhari tì mọ́lé lórí N2.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fọ́nrán ohùn, Ruga settlement: YCE ní ìjọba àpapọ̀ ko tó bẹ̀ẹ́ láti kọ́ àgọ́ Fulani sílẹ̀ Yoruba Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
 oun ni alaga ana fun awon egbe alagbawi ati onilaja ti eka ofin okoowo ni eka awon amofin ni orile ede naijiria .
Oríṣun àwòrán, AFP Amọ ṣa, awọn janduku ni wọn lo n ṣe ikọlu ni Iwọ oorun Ariwa Naijiria bayii, nitori pe ko si ẹni to mọ ẹgbẹ to wa nidii rẹ.
Ta wá ni òun, tí mò ń gbọ́ gbogbo nǹkan wọnyi nípa rẹ̀?
Oba Akanbi wa ke pe ẹgbe Afẹnifẹre, ẹgbe ọmọ Oodua, Agbẹkọya, ati awọn ẹgbẹ ọmọ Yoruba miran lati fọwọsowọpọ pelu oun lati dide gbogun ti iwa fifi ẹmi eniyan se irubọ lorilẹ-ede Naijiria.
Gbogbo awọn ẹgbẹ oṣiṣẹ ni ijọba ibilẹ naa ni wọn kan sara si igbesẹ naa ni kete ni iro owo bẹrẹ si nii dun lapo awọn oṣiṣẹ naa.
Ṣùgbọ́n bàbá mi múra bí jagunjagun ìlú Òyìnbó, ó di oògùn mọ́ra bi babaláwo, ó ń rìn bi ẹ̀ni ti ń lọ ìjàkadì, ó sì dúró bi ìgbà tí àwọn ọlọ́pàá bá dúró níwájú olórí wọn.
Ṣugbọn ileeṣẹ ologun ti sẹ pe ohun ko mọ ohun nipa iṣẹlẹ to waye ni Lekki, bẹẹ na ni ijọba ipinlẹ Eko naa ni oun ko mọ ohunkohun nipa rẹ, ti Aarẹ Muhammadu Buhari naa ko si sọrọ.
Ní àkókò yìí ni àwọn ọmọ ẹ̀yìn rẹ̀ dé.
" lásìkò yìí ni herbert ogunde ṣe fíìmù tí ó pè ní "" aiye "" ."
O ṣalaye wi pe ni ti oun o, ko si ifarahan awọn agbaagba ẹgbẹ kọkan ni ilu Akurẹ lọjọ ti idibo naa waye.
Adari ile Ghana ninu esi rẹ sọ pe oun ni igbagbọ pe laarin ọjọ kan si meji awọn yoo yanju ọrọ naa.
Odò Gbeferu ni wọ́n ń pe odò ti wọn ń gbà láti kó ẹrú lọ sókè òkun.
 ní àwọn tí a kò tọ ́ jú dáradára ààrùn tún lè jẹyọ ní àwọn oṣù mélòó bóyá .
Ó ti wá tètè tọrọ àforíjì wípé, ìrírí òun kìí se àpẹẹrẹ ohun tó ńsẹlẹ̀ ní ọ̀pọ̀lọpọ̀ idílé.
O jẹ ko di mimọ pe irọ ni awọn ri ọrọ naa si ati gbigbe ọrọ ti ko tọ sori afẹfẹ paapaa bo ṣe bẹrẹ si ni tan ka torinaa awọn ti gbe ọrọ tawọn jade lori rẹ.
"Mo kilọ fun pe maa pariwo, lo ba dahun pe ihoho ni maa kuro ni ile itura naa, ti mo ba fi pariwo.
Justice Folaranmi Oloyede ti ni ijọba apapọ ko bọwọ fun eto idajọ orilẹede Naijiria to ba ilana ati ofin mu.
Ó tún pẹpẹ OLUWA tẹ́ sí ipò rẹ̀, ó rú ẹbọ alaafia ati ẹbọ ọpẹ́ lórí rẹ̀, ó sì pàṣẹ fún àwọn eniyan Juda pé kí wọ́n máa sin OLUWA Ọlọrun Israẹli.
fon ni eya ede topojulo pelu 1.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Odebiyi: ìgbà gbogbo ni Bàbá mi ń polówó iṣẹ́ mi fáráyé Gomina Bayelsa tun sọ pe ko si gomina PDP to lọwọ ninu nina owo ijọba ibilẹ tabi fifi ṣe nnkan miran.
Oríṣun àwòrán, Fatima Muhammad Bi oke si se n ga si, naa lo n lewu si lati sọkalẹ.
36b), owoona lori awọn akanṣe iṣẹ (Capital Expenditure N2.
Wọ́n bá ṣíkọ̀, wọ́n ń pẹ́ ẹ̀bá Kirete lọ.
Mamoudou Gassama eni ti o di ilu mooka, latari iyanju re  bi o se gun ogiri iwaju ile lati gbemi omode-kunrin omo odun merin la.
 O sọ wipe nigba ti Ọsinbajo wa nipo Agbejọrọ agba ati Kọmisọna feto idajọ nipinlẹ Eko, asiko yii ni ilọsiwaju ba eto idajọ nipinlẹ naa."
Ile igbimo asofin kẹ́sán án ti ni awon ko
O ni oun ko ni le maa farahan siwaju sii lori ẹjọ naa tori wipe adajọ kọ lati sun ẹjọ naa siwaju.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Ninu oniruuru idajọ, wọn wẹ mubarak mọ ninu awn ẹsun iwa ibajẹ ṣugbn fi ti ikowojẹ kan an.
Nnkan to ba yẹ ni ṣiṣe lati daabo bo awọn eeyan wa, la o ṣe.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Alaafin: Olori Aanu Adeyemi ṣàlàyé ìdí tó ṣe gẹ́ Oba Lamidi Adeyemi ti ìlú Oyo Imo ẹko ni[pa eto aabo yoo jẹ araalu mọ iru asọ to yẹ ki wọn ma a w ati ọna ti wọn le gba lati lọ asọ ti wọn ba wọ, ẹya ara wọn, lilo tie ọrun, orukun ati ọwọ eniyan to fi mọ igbadi lati fi da abo bo ara wa.
Èyí nì ọ̀kan; lọ́nà kejì, a ó lọ sí òkè Ìrònù ti ń bẹ nínú Igbó.
Agbabọọlu tẹlẹ naa, lasiko to n ba akọroyin Punch sọrọ ni ọpọ awọn ọmọ ilẹ yii ti ko rile gbe, atawọn asẹwo to wa nilu Milan ni oun n se iranlọwọ fun.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Boko Haram yóò dá Leah sílé Garba Shehu ni kaka ki ijọba Mohammadu Buhari sọ ireti nu, ijọba ṣẹṣẹ n gbe awọn igbesẹ tuntun ni lati ri Leah Sharibu gba pada lọwọ awọn oniṣẹ ibi boko haram.
Sibẹ mo sọ fun yín pé Solomoni pàápàá ninu gbogbo ìgúnwà rẹ̀ kò lè wọ aṣọ tí ó lẹ́wà bíi ti ọ̀kan ninu àwọn òdòdó yìí.
O ṣalaye wipe awọn ko ti i gbọ nkankan lati ọdọ ijọba apapọ lati ọdun 2017 nigba ti Boko Haram da awọn mejilelọgọrin lara awọn ọmọbinrin naa silẹ.
Ṣé ẹnìkan lè kọ́ Ọlọrun ní ìmọ̀,nígbà tí ó jẹ́ pé òun ni onídàájọ́ àwọn tí wọ́n wà ní ibi gíga?
2 Nítorí Ọlọ́run kìí rìn ní àwọn ipa ọ̀nà tí ó wọ́, tàbí kí ó yà sí ọwọ́ ọ̀tún tàbí sí òsì, òun kìí yípadà kúrò lórí ohun náà tí ó ti sọ, nítorínáà àwọn ọ̀nà rẹ̀ tọ́, ipa ọ̀nà rẹ̀ sì jẹ́ ọ̀kan yípo ayérayé.
O ṣapejuwe Isaac Promise gẹgẹ bi ẹni ti o ni iwa tutu ti o si mura siṣẹ.
Iye ọdún tí Iṣimaeli gbé láyé jẹ́ ọdún mẹtadinlogoje (137).
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Drowning: Ẹni ọdún mẹ́ẹ̀dọ́gbọ̀n àti ọmọ rẹ̀ oṣù mẹ́tàlélógún kú sómi Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Drowning: Ẹni ọdún mẹ́ẹ̀dọ́gbọ̀n àti ọmọ rẹ̀ oṣù mẹ́tàlélógún kú sómi 13 Agẹmo 2019 Ko si ẹni to rinrinajo to gbadura ko ma bọ̀.
Nollywood: Toyin Abraham ń ta àgbo, Wumi Toriola, Ronke oshodi Oke ń ta ìpara ìbóra
Ṣugbọn ẹ̀ ń jà mí lólè.
Ọdún 2002 ló bẹ̀rẹ̀ eré Tíátà tó sì ti fara hàn nínú ọpọ̀lọpọ̀ eré Nollywood ní ọ̀ àfín èdè Yorùbá àti Gẹ̀ẹ́sì.
Oríṣun àwòrán, @Pear video Àkọlé àwòrán, Iya Onile Lisa Li lo gbe fidio to ṣafihan igbe aye ọbun ti Gbajugbaja Lisa Li n gbe hande ni China Koda, aworan naa ṣafihan igbe ẹran ọsin rẹ ninu iyara rẹ laisọ awọn ohun ẹgbin miran.
Wọ́n bá gba aṣálẹ̀, wọ́n sì yípo lọ sí òdìkejì ilẹ̀ àwọn ará Edomu ati ti àwọn ará Moabu, títí tí wọ́n fi dé apá ìlà oòrùn ilẹ̀ àwọn ará Moabu.
A ti ja aráàlú kulẹ̀, ta bá pè wọ́n fún ìwọ́de, wọn kò ní jẹ́ wa mọ́ - NLC Eko Oríṣun àwòrán, @NLCHQ_ABUJA Saaju la ti mu iroyin wa fun yin pe, ajọ to n se akoso ina ọba ni Naijiria, NERC ti ni, awọn yoo tẹle aṣẹ ijọba apapọ lati da owo ina ọba pada si bo ṣe wa tẹlẹ, ki wọn to fi owo le.
Ṣugbọn Olori Anuoluwapo ati olorin fuji naa ti sọ pe ahesọ lasan ni, nitori ko si ohun to jọ bẹẹ.
"'Mo máa ń ta sí Tolu pé ""ọjọ́ wo ni wàá tó gà'- Musa, Ọ̀rẹ́ àti kékeré Bí ẹgbẹ́ One Million Boys ṣe bẹ̀rẹ̀ rèé àti ọṣẹ́ tó ṣe n'Ibadan Sotitobire: Kò sí èléyìí tó kàn mí nípa ìjínígbé Gold Kolawole!"
Òní ni o mọ̀ pé obìnrin ni ọ́; tí o lè di abiyamọ.
Àjọ NCDC kéde ènìyàn 195 míràn tó ní ààrùn Covid-19 l'órílẹ̀-èdè Nàìjíríà Ìjọba dín owó epo bẹntiró sí N108 Àwọn ọmọ Nàìjíríà 256 tó há sí ìlú Dubai ti gúnlẹ̀ sí Nàìjíríà Ayinla Ọmọwura, orin èébú àti oríyìn lo fi di ọ̀rẹ́ àwọ̀n obìnrin Gẹ́gẹ́ bàa tí ká a ni ojú òpó itakun agbaye Wikipedia, ọba Olateru-Olagbegi keji jẹ́ akanda ẹ̀dá, ẹni tí Ọlọ́run ṣa ní ẹsa, èyí tí kò ṣe fi ara we, bí ìtàn ìgbé ayé rẹ sì ṣe lọ rèé.
akademio de esperanto ni , gege bi ibiitakun re se so , ìdìmúlẹ ̀ elede alominira ti ise re je lati mu duro ati da abo bo awon opo ede esperanto ati akoso idagbasoke re .
Ní ọjọ́ kejì, Miloš Nikolić tí ó jẹ́ adarí ọ́fíìsì tí ó ń ṣe àfikún Novi Sad mọ́ Roma sọ̀rọ̀ tako ìṣẹ̀lẹ̀ náà.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ọlọ́kadà Jigawa: Ìjọba Eko ti wá mọ́lé lọ́nà àìtọ́, a fẹ́ owó ‘gbà má bínú’ 3 Owewe 2019 Oríṣun àwòrán, Twitter/The Lagos State Govt Àkọlé àwòrán, Kini aduru gbogbo ero yii n bọ wa ṣe lEko lati ariwa ni ibeere awọn eniyan Awọn eniyan mẹtalelọgọfa lati ipinlẹ Jigawa to wọ ipinlẹ Eko lẹkan soso pẹlu ọkada wọn, ti n beere fun biliọnu kan naira lọwọ ijọba ipinlẹ Eko pẹlu ẹsun pe wọn fi iya jẹ wọn.
Awọn iyalọja to ba BBC Yoruba sọrọ salaye pe, lati awọn ilu nlanla nilẹ Yoruba ni wọn ti n wa ra ẹran ejo lọdọ awọn.
Ikilọ yi ko sẹyin bi awọn eeyan kan ti se n gbiyanju lati forukọ silẹ loju opo N-Power saaju ki wọn to sii laago mejila ku isẹju mẹẹdogun alẹ ọjọ Eti tii se ọjọ Kẹrindinlọgbọn, osu Kẹfa.
Bangladesh wedding: Khadijah yí àṣà ìgbéyàwó padà ni Bangladesh
Ṣàánú mi, Ọlọrun, nítorí ìfẹ́ rẹ tí kì í yẹ̀;nítorí ọ̀pọ̀ àánú rẹ pa ẹ̀ṣẹ̀ mi rẹ́.
- Amẹ́ríkà fọnmú Èmi àti Kolington kò fẹ́ra padà o, ọba Wákà kò fẹ́ ọba Fuji mọ́ - Salawa Abeni Lọjọ Ẹti ni iwe kan n fẹ kiri loju awọn opo ikansiraẹni lori ayelujara pe ijọba ipinlẹ Ọ́yọ ti fi iwe ransẹ si agbẹjọro awọn alaga kansu naa, Algon, pe oun setan lati san gbogbo owo osu ati ajẹmọnu wọn, ki wọn si maa ba tiwọn lọ.
Oríṣun àwòrán, MPHO LAKAJE Àkọlé àwòrán, Miche Solomon lasiko yii Bawo ni aṣiri ṣe tu pe ibeji ni wọn?
gẹ ́ gẹ ́ bí àwọn òpìtàn ilẹ ̀ yorùbá , àwọ òpìtàn ìlú Ẹ ̀ fọ ̀ n aláayè gbà pé ọ ̀ dọ ̀ odùduwà ni wọ ́ n tí ṣẹ ̀ wá láti ilé-ifẹ ̀ .
Àwọn ìletò wọn ni: Etamu, Aini, Rimoni, Tokeni ati Aṣani, 
Ohun ti igbesẹ yi tumọ si ni pe awọn to ba ke gbajare ẹsun ibanilopo yoo ni aanfaani lati sọrọ sita.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Àwọn ìgbà tí ẹ̀ṣọ́ aṣọ́bodè ti pànìyàn lọ́nà àìtọ́ Àjọ aṣọ́bodè gba Codeine N200m Iléeṣẹ́ aṣọ́bodè gba nǹkan ìjagun àìtọ́ Ẹ́ wo iye ààrẹ Nàíjíríà tó sọ̀rọ̀ ìjayà lásìkò ìbò INEC tako àṣẹ Buhari lórí pípa ẹni tó bá jí ìbò gbé Aṣẹ́wó, olè, gbájúẹ̀ ni 723 ọmọ Naijiria ta lé padà sílé - Ghana APC fẹ́ fa ìṣọwọ́-ṣiṣẹ́ ẹ̀rọ káàdì ìbò sẹ́yìn - Atiku Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Damilọla Ajayi: Ọ̀dá owó ló ṣún mi dé ìdí lílo ìyarun bíi fèrè Dokita Jesuwale ni, afẹfẹ ni aisan yii ma n ba rin, ati pe, ti wọn ba si da adiẹ to ni aisan naa papọ mọ adiẹ ti ko ba ni, ewu nla nbẹ fun wọn.
Ẹni tí ó bá ń sọ̀rọ̀ àbùkù nípa arakunrin rẹ̀ tabi tí ó bá ń dá arakunrin rẹ̀ lẹ́jọ́ ń sọ̀rọ̀ àbùkù sí òfin, ó tún ń dá òfin lẹ́jọ́.
Wọ́n ní kò bá òfin mu bí wọ́n se tì í m'ọ́lẹ́ láti ọdún 2015.
Oríṣun àwòrán, @daar Àkọlé àwòrán, DAAR Communications: AIT kò kọ̀ láti tẹ̀le ìlànà òfin ìgbóhùnsáfẹ́fẹ́ Naijiria Ṣíwájú lórí ọ̀rọ̀ náà: Ẹgbẹ awọn akọroyin ti pàṣẹ ìyípadà laarin ọjọ kan.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Itan Omi Erin Bákan náà, dúkìá àwọn Olorì mẹẹdogun tó ní àti onírúurú dúkìá mẹ́wàá miran tó bajẹ jẹ́ ẹgbẹ̀rún márùn-ún pọn-un, ilé alaja méjì tó wà ládùúgbò Imalefẹalafia n'ilu Ibadan towo rẹ to ẹgbẹ̀rún mẹta àti àbọ̀ pọn-un, ọkọ Land Rovers méjì towo wọn to tó ẹgbẹ̀rún mẹ́rin pọn-un, tó fi mọ ọ̀pọ̀lọpọ̀ dúkìá míì lorisirisi tí a kò leè kọ silẹ.
Naijiria naa dena kikopa Algeria ninu idije 1988 tawọn ọkunrin nigba ti wọn bo idi Algeria pẹlu ami ayo meji sodo ni papa iṣere Enugu.
Ó fi kun pé, gbogbo ìgbà ni ọlọ́paàá ń se ìdánilẹ́kọ̀ọ́ lórí bí wọ́n ṣe ńlo ìbọn àti àwọn ǹkan èlò míràn.
Àti ọ̀gá ibiṣẹ́, àti ìránṣẹ́ kẹ̀kẹ́ ni ọ̀pọ̀ wọn ń gùn káàkiri bíótilẹ̀jẹ́pé wọ́n ní ọkọ̀ ayọ́kẹ́lẹ́ ní'lé.
”Wọn sì sọ fún un pé, “Obinrin kan wà ní Endori tí ó jẹ́ abókùúsọ̀rọ̀.
Àwọn ni ìdílé àwọn tí ń gbé Sora.
 a ti ṣe àkọsílẹ ̀ ìfèsì ara ẹni lọ ́ nà òdì sí ohun tí ènìyàn kòrira lára iye àwọn ènìyàn tó tó ọ ̀ kan nínú ọgọ ́ ọ ̀ rún .
Láti Aroeri tí ó wà ní àfonífojì Arinoni tíí ṣe ilẹ̀ Gileadi ati ilẹ̀ Baṣani.
“O ku ayeye ojo ibi, Gernot Rohr.
aare lori eto aabo,Ogagun feyinti Babagana Monguno (Rtd); oludari ile-ise ọtẹlẹmuyẹ,
N si agbegbe Douma saaju abewo igbimo OPCW, eleyi ti o dina won lati se ise won bi ise.
Ni Osu Kẹsan an, Ile-ẹjo to gaju ni orilẹ-ede India da ẹjọ to niise pẹlu ki wọn iyinbọn pa ẹkun naa nu, eleyii to faaye gba ki wọn bẹrẹ si ni wa ẹkun naa pada.
Iroyin so pe, bi o ti le je pe, Cilic kopa daradara siwaju, sugbon omi poju oka lo, leyin ti Del Potro tara ji lati ami-ayo meji ti o n ti padanu seyin, ti o si bere si ni jawe olubori ninu ifigagbaga ipele keta.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ondo: Dejí sun ọmọ méje àtagbalagba meji mọ́lé nítorí pé ó ń bínú Iye ile iwe meloo ni ẹ ro pe triliọnu mọkanla yii le kọ lagbegbe ti yin?
“Kí ló dé tí ẹ̀ ń pè mí ní, ‘Oluwa, Oluwa,’ tí ẹ kì í ṣe ohun tí mo sọ?
Dokita Vahwere ti ẹ sọ pe, awọn eniyan kan ti n gbagbọ pe lootọ ni arun Ebola wa.
Wo bí ìfigagbágbá lóríi tani yòó di gómìnà lónìí láàrin Obaseki àti Ize-Iyamu yóò ṣe lọ Èèyàn 221 ní àrùn Coronavirus tún ṣẹ̀ṣẹ̀ ràn ní Nàìjíríà Ọkùnrin kan tún pa ọmọ rẹ méjì àti ìyá tó bíi Yatọ̀ sí pé ó ṣe sọ́jà, tó tún jẹ́ ọkọ Oriṣabunmi, wo àwọn nkan tí o kò mọ̀ nípa Jimoh Aliu LASEMA ni awọn ṣiṣẹ pọ pẹlu ileeṣẹ to n risi ijamba ina ni ipinlẹ Eko, LASG ati ileeṣẹ ọlọpaa lati ṣe iwadii kunkun awọn ijamba ọkọ naa ṣe ipalara fun.
Nnkan bii agogo mẹwaa owurọ ọjọ Aiku lo jade laye.
Abrahamu ní obinrin kan tí ń jẹ́ Ketura.
Atẹjade naa ni o ti to ọsẹ kan nayii ti wọn ti fi Tom sahamọ pẹlu asẹ minisita keji feto ohun amusagbara, Godwin Jeddy Agba, lori ẹsun pe o ba oun lorukọ jẹ.
Nigba to maa fi di owurọ ọjọ keji wọn ti pe le mi lori ṣugbọn a dupẹ mo ṣi n mi.
Ẹ rọ́ àlá náà fún mi.
Ni ọtẹ yii, iro ede ti a salaye lori rẹ ni gbolohun ogun eyi to pin si orisirisi, ti a si mu itumọ rẹ fun yin ni ẹyọ kọọkan.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Lebanon: Iṣẹ́ tí kòsí ní Naijiria, la ṣe lọ ṣe ọmọ ọ̀dọ̀ ní Lebanon Iṣẹlẹ Ibugbamu Beirut yii waye lọjọ Iṣẹgun ọsẹ to kogba wọle lọ yii ti o si le leeyan igba to ku ati o le lọgọrun to sọnu to fi mọ ẹgbẹgbẹrun to di alairilegbe.
0 426 St Vincent and the Grenadines 0 0.
"Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Taa gan ló ń jí orin àti ohùn ara wọn lò nínú Adewale Ayuba àti Ajebori Awọn orukọ mii ti wọn n pe wọn to tun lee dun un gbọ leti ni ""inkeeper worm"" eyi ti wn ri mu latara iru igbe aye ti wọn n gbe labẹ ilẹ."
  Ọjọ́ wo náà la bẹ̀rẹ̀ 2013 ná tó ti yáa tún káṣẹ̀ńlẹ̀ báyìí?
Àsíá ibùdó ẹ̀yà Reubẹni yóo máa wà ní ìhà gúsù ní ìsọ̀rí-ìsọ̀rí; Elisuri ọmọ Ṣedeuri ni yóo jẹ́ olórí wọn.
Leyin wakati kan ati iseju mewaa ti aare ti rin ile-ikokanpamo si , ni o lo lati sebowo fun awon ti won padanu emi won lasiko goun agbaye keji .
O ko gbọdọ jade kuro nilu ile ayafi ti o ba fẹ lọ ra ounjẹ tabi o fẹ lọ si ile iwosan tabi ile ifowopamọ loku.
Nítorí náà, sọ àsọtẹ́lẹ̀ burúkú nípa wọn, ìwọ ọmọ eniyan, sọ àsọtẹ́lẹ̀.
mo awon akegbe re ti o je olori ijoba nile Afrika ati lagbaye lati lo ye aare
Lẹ́sẹ̀kan náà, Saulu ṣubú lulẹ̀ gbalaja, nítorí pé ohun ti Samuẹli sọ dẹ́rùbà á gidigidi, àárẹ̀ sì mú un nítorí pé, kò jẹun ní gbogbo ọ̀sán ati òru náà.
“Ẹ kò gbọdọ̀ fún àwọn eniyan wọnyi ní koríko láti fi ṣe bíríkì bí ẹ ti ṣe ń fún wọn tẹ́lẹ̀ mọ; ẹ jẹ́ kí wọn máa lọ kó koríko fúnra wọn.
Laarin ọdun kan aabọ ti wọn da ijọ Satani silẹ, ẹẹmẹta ni ariwo sọ lori rẹ ninu awọn iwe iroyin.
Bí ẹnìkan bá ní òun ò bá ẹnikẹ́ni gbé, tí kò bá gbé nígbó, yóó wábi gbàlọ.
Ìtàn ọ̀rẹ́ tó fi òògùn gba ọkọ ọ̀rẹ́ rẹ̀ ni Akomolede BBC Yorùbá fẹ́ kọ́ wa lònìí Àṣà Oge Ṣíṣe ní Akọ́mọlédè BBC Yorùbá ń gbé yẹ̀wò lónìí, Ó yá, iṣẹ́ ti bẹ̀rẹ̀.
O ni won yoo tesiwaju ninu idanilekoo lodun yii titi osu keta bere lati owo awon dokita eranko atawon akosemose lori eko lori irufe ohun jije to ye fun eran osin ati beebeelo.
Ó wà ní àkọsílẹ̀ ninu ìwé àwọn wolii pé, ‘Gbogbo wọn ni Ọlọrun yóo kọ́ lẹ́kọ̀ọ́.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Police Recruitment: Ìlé ẹjọ ti pasẹ pe ki ilé iṣẹ́ ọ̀lọ́pàá dá ìgbaniwolé Fanfa lori ọrọ yii ko ṣẹṣẹ bẹrẹ nitori loṣu Kẹsan ọdun 2019 ni ajọ to n sakoso ileesẹ ọlọpaa (PSC) ti gba ileẹjọ lọ, lati le fidi agbara wọn mulẹ, nipa gbigba eeyan ṣiṣẹ ọlọpaa.
” Ó bá yipada, ó ń bínú lọ.
Ṣugbọn, eero awọn eeyan kan yatọ.
Oríṣun àwòrán, Instagram/acupofkhafi Àkọlé àwòrán, Ẹsun ibalopọ lori BB Naija Atẹjade ti alukoro Ileeṣẹ ọlọpaa Met, Rebecca Byng fi ṣọwọ si BBC ṣalaye pe, iwadii ti bẹrẹ lori ọrọ Kareem.
Ninu ọrọ rẹ lẹyin idije naa, ile isẹ iroyin ere idaraya Reuters ni ''Ronaldo ti wa gbe afinju ara rẹ kọja ami'' Oju ẹrọ ere idaraya Benchwarmers se apejuwe rẹ gẹgẹ bi ''Isẹlẹ kayefi lati ọwọ Ronaldo to jọni loju julọ'' Bakanna lawọn ololufe ere bọọlu gba ori ẹrọ ayelujara twita lati fi iriwisi wọn sọwọ lori isẹlẹ naa.
Kaini dá OLUWA lóhùn, ó ní, “Ìjìyà yìí ti pọ̀jù fún mi.
Keeyan maa fi suuru ṣe nkan.
Ogudu Bridge Ijọba ibilẹ Kosofe 22.
 , ìyísódì odidi gbólóhùn nìkan ni a lè ṣe fún un .
Alaga awọn ile iṣe to n pese nkan nipinlẹ Kano, Umar Marshall ni oun idunnu ni oye yii nitori ko si awujọ ti o le ni itẹsiwaju lai fi tawọn ajoji ṣe.
Nígbà tí wọ́n ṣí ìdérí òjé tí wọ́n fi bo agbọ̀n náà kúrò lórí rẹ̀, mo rí obinrin kan tí ó jókòó sinu eefa náà.
Ọgagun agba Abdulsalam Abubakar gbe ijọba kalẹ fun Olusegun Obasanjo, to bori ibo aarẹ.
Kogi 2019: Àwọn ará ìlú sọ̀rọ̀ lórí ìrètí wọn lọ́wọ́ Yahaya Bello Lagos Lion: Ó di dandan kí ará India yìí sọ ìdí tó fi ń sìn kìnìhún- Egbeyemi Wo bí àjọyọ̀ ṣe ń lọ lọ́wọ́ ní Kogi 'toríi Yahaya Ẹgbẹ oṣelu PDP kuna lati kẹsẹjari ninu idibo sipo gomina to waye ni ipinlẹ Bayelsa, lẹyin ogun ọdun ti wọn ti n ṣe ijọba ipinlẹ naa.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Oyenusi ló mú mi wọ ẹgbẹ́ adigunjalè kó tó di pé mo b'Ólúwa pàdé' Oṣiṣẹ ile ifowopamọ Asia, Rommel Rabanal lo sọ bẹẹ, o ni ijọba ni lati ṣeto fun ayẹwo awọn eeyan ki o si ṣeto ibudo iyasọtọ aibaamọ aarun covid-19 le bẹ silẹ.
Àwọn olùṣọ́ rẹ ń sùn, ìwọ ọba Asiria, àwọn ọlọ́lá rẹ sì ń tòògbé; Àwọn eniyan rẹ fọ́nká lórí àwọn òkè, láìsí ẹni tí yóo gbá wọn jọ.
Ojú alábaṣiṣẹ́pọ̀ Mompha rèé, EFCC ṣí i síta Arakunrin afurasi to jẹ igbakeji Ismaila Mustapha ti inagijẹ rẹ njẹ Mompha, Kolade Phillip ṣaadede fara han nile ẹjọ lọjọ aje kan naa ti Mompha lọ fara han.
Ṣugbọn láti ìgbà tí a ti dáwọ́ ati máa sun turari sí ọbabinrin ojú ọ̀run dúró, tí a kò sì máa ta ohun mímu sílẹ̀ mọ́, ni a kò ti ní nǹkankan mọ́, tí ogun ati ìyàn sì fẹ́ẹ̀ pa wá tán.
Oríṣun àwòrán, Sajetiologa Wayi o, ọpọ awọn osere tiata lede Yoruba lo ti n sedaro akọni osere to lọ naa, ti ọpọ awọn oju opo ikansira ẹni lori itakun agbaye si ti kun fun idaro iku Dagunro.
Igbesẹ naa si ti mu ki igbimọ ọhun paṣe pe ki awọn agbofinro fi panpẹ ofin mu awọn adari ajọ ọhun, ki wọn lee wa sọ tẹnu wọn bi ọrọ owo naa ṣe jẹ.
O ti mú kí ọ̀rẹ́ kòríkòsùn mi ati àwọn alábàárìn mi kọ̀ mí sílẹ̀;òkùnkùn nìkan ni ó yí mi ká níbi gbogbo.
O ni aare tun ni ipinnu lati tun
nítorí náà, n óo fà yín lé àwọn ará ilẹ̀ ìlà oòrùn lọ́wọ́, ẹ óo sì di tiwọn.
N kò ní yà sí ọ̀tún tabi sí òsì.
Tí ó bá di ọjọ́ kẹjọ, wọn yóo kọ ilà abẹ́ fún ọmọ náà.
Xenophobia: Àdúgbò Lugbe kan gbínrín torí ìkọlù àwọn olùfẹ̀hónú hàn
Sima bí Joa, Joa bí Ido, Ido bí Sera, Sera sì bí, Jeaterai.
Yusuf Buhari f'ara pa ninu ijamba alupupu lọjọ kẹrindinlọgbọn oṣu kejila ọdun to kọja.
Èmi OLUWA Ọlọrun ni mo sọ bẹ́ẹ̀.
Wọ́n níláti máa kọ́ni ní ohun rere.
Wọn ni aṣẹ naa gẹgẹ bii alakoso agba fun eto aabo nipinlẹ Ọyọ pa lati gbẹsẹ le eegun ẹgbẹ awakọ ero pe ko gbọdọ ṣẹyọ bayii nipinlẹ naa ṣi wa nikalẹ, ẹnikẹni to ba si fọwọ pa ida aṣẹ naa yoo jẹ iyan rẹ niṣu.
Oríṣun àwòrán, BBC Sport Àkọlé àwòrán, Idije Premier League n yeruku lala Igba kẹjọ re e ti idije ti ikọ to gba Premier League yoo foju han lọjọ ti idije naa pari.
A gbọ pe baalu kekere naa lo ni isoro ranpẹ laarin isẹju perete to gbera nilẹ.
Chris ni awọn oṣiṣẹ darapọ mọ awọn ọmọ Niajiria to ku kaakiri lati tako igbesẹ ijọba to fi owo kun owo epo ati ina ọba naa.
Wọn yóo gbàgbé ìtìjú wọn ati ìwà ọ̀tẹ̀ tí wọn hù sí mi, nígbà tí wọn bá ń gbé orí ilẹ̀ wọn láìléwu, tí kò sì sí ẹni tí yóo dẹ́rùbà wọ́n.
Bi ọlọpaa ipinlẹ ṣe n ṣiṣẹ l'America L'orilẹẹde Amẹrica, ileesẹ ọlọpa ipinlẹ maa n mojuto awọn ohun to niise pẹlu iwadi iwa ọdaran.
Èmi ń bọ̀ wá sọ́dọ̀ rẹ.
Èèyàn 290 míràn ló ṣẹ̀ṣẹ̀ fara káásá àrùn Covid-19 ní Nàìjíríà, 160 gbàwòsàn Wọ́n ti sún ọjọ́ ìjà Mike Tyson pẹ̀lú Roy Jones Jr síwájú Asojú ìjọba orílẹ̀-èdè Lebanon ti kọ̀wé fipò silẹ̀ nítorí ìbágbàmù tó gbẹ̀mi ènìyàn 200 Olùrànlọ́wọ́ pàtàkì fún ọ̀rọ̀ ibojì òkú, àti àwọn ipò òṣèlú mìíràn tó jẹ́ kàyééfì ní Nàìjíríà Diezani gan an ní Hushmummy tó ń bú àwọn Yahoo boys- Àwọn Ọmọ Naijiria lórí Twitter Àkọlé àwòrán, Awọn ogo ọmọ ti Oba oke yọnda fun Olori ati Alaafin Olori Aanu ṣalaye pe oun pinnu pe oun gbọdọ ni ifọkanbalẹ nile ọkọ lo jẹ ki oun fẹ Alaafin ti ọpọ maa n sọ pe o ti dagba ju oun lọ pupọ ju.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Coronavirus prevention tips: Ọ̀nà àbáyọ fún olóyún lásìkò àjàkálẹ̀ ààrùn Covid-19 11 Ìgbé 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 7 Èbibi 2020 Oríṣun àwòrán, Getty Images Gbogbo ibi nílẹ̀ káràòjíire ni oyún tí jẹ nkan, oyún jẹ́ àdúrà pàtàkì tí ìyàwó osìngín má ń lẹ́yìn ayẹyẹ ìgbéyàwó.
Ẹẹmẹrin ọtọọtọ ni Ruiz fi ẹsẹ kan Joshua mọlẹ lai le dide.
Nigba ti aṣiri maa fẹ tu, mo tọpasẹ iroyin naa titi de ileeṣẹ iroyin akọkọ to gba a, a pe nọmba ẹni to mu u wa lo ba di ti akọroyin Senegal kan ṣugbọn to n gbe ni Amẹrika, Baba Aidara - ọrẹ mi ree e.
  Nítorínáà ni gbogbo olówó ìlu bá ìjọba gbìmọ̀n pọ̀ tí wọ́n nlé ọkùnrin náà ká ṣùgbọ́n ọwọ́ ò tẹ̀ẹ́ láilái.
Okonkwo sàlàyé pé, sáájú àsìkò yìí, àwọn ti kò ṣòwò epo máa ń gbà owó ìrànwọ́ ìjọba lọ́nà àìtọ́, sùgbọ́n nísìnyí kò ni sí gbogbo ìyẹn mọ́.
''Mi ko si le sọ bakan naa lẹyin iṣẹlẹ keji yii pe oye iru ipa tawọn iṣẹlẹ yii yoo ni lori mi.
Ẹ má jẹ́ kí ẹnu yà yín bí ayé bá kórìíra yín.
Iṣẹlẹ yii ti fa ọpọlọpọ gbọnmisi omi o to laarin awọn mejeji ati awọn alatilẹyin wọn.
Ẹwẹ, aarẹ Buhari ti yan adajọ tuntun Ibrahim Tanko Muhammed lati jẹ adele fun un.
Ẹ kò gbọdọ̀ yẹ ẹsẹ̀ kúrò ninu wọn sí ọ̀tún tabi sí òsì, 
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù DNA: Wo àkójọpọ̀ ọ̀nà méje tí ọmọ àlè fi le wọnú ilé láì jẹ́ pé ìyàwó ṣe aṣemáṣe 16 Sẹ́rẹ́ 2021 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 17 Sẹ́rẹ́ 2021 Oríṣun àwòrán, Getty Images Wo bí ìyàwó ṣe le gbé ọmọ Ọbà fún Ọ̀ṣun láì yan àlè O to ọjọ mẹta kan ti ọrọ gbigbe ọmọ ọba fun ọsun ti n ja rain-rain lawujọ wa.
Ẹ lọ kọ́ àwọn ìlú fún àwọn ọmọ yín ati ilé fún àwọn ẹran ọ̀sìn yín, kí ẹ sì ṣe ohun tí ẹ ṣèlérí.
“Bí ó bá jẹ́ alufaa tí a fi àmì òróró yàn ni ó ṣèèṣì dẹ́ṣẹ̀, tí ó sì kó ẹ̀bi bá àwọn eniyan, kí ó fi ọ̀dọ́ akọ mààlúù rú ẹbọ ìmúkúrò ẹ̀ṣẹ̀ níwájú OLUWA, fún ẹ̀ṣẹ̀ tí ó dá.
Ẹwẹ, akọnimọgba Manchester United, Ole Gunnar Solskjaer ti gboṣuba kare fun Odion Ighalo fun iṣe akin to ṣe lati sọ bọọlu sinu awọn Derby County nigba meji ọtọtọ ninu ifẹsẹwọnsẹ FA Cup ọhun.
Ni Russia, ko buruju ti wọn ba fi omi ara ẹja lasiko ti wọn ba n lopọ fi se ọbẹ ẹja, ti wọn yoo jẹ.
O tun so pe “ igbimo egbe  APC to n sakoso lowo bayii yoo tun se daadaa ju ti  awọn igbimo to kogba wole lo, bo tile je pe wọn gbiyanju lati se aseyori ninu eto idibo to waye lọdun 2015.
Gbogbo ayé, ẹ hó ìhó ayọ̀ sí Ọlọrun.
Àwa àti fijilanté pẹ̀lú ọdẹ́ ìbílẹ̀ ló dojú kọ adigunjalè ní First Bank Okeho - Iléeṣẹ́ ọlọ́pàá Ọga ọlọpaa ni ipinlẹ Ọyọ, Joe Nwachukwu Ewonwu ti ṣalaye pe, awon agbebọn kan wa digun ja banki First Bank to wa niluu Okeho lole, ni nnkan bii agogo mẹfa abọ Ọjọru.
Nítorí náà, ó rí ojurere Pọtifari.
'Wọ́n ní a kò lówó tó láti díje dupò ní Nàìjíríà' Kínla!
Amọ, titi di wakati yii ijọba apapọ ko dahun si ibeere wọn, ki wọn to gunlẹ iyanṣẹlodi lati kilo fun ijọba.
Nítorí láti ọ̀dọ̀ rẹ ni ohun gbogbo ti wá, ninu ohun tí o fún wa ni a sì ti mú wá fún ọ.
17 Òkùdu 2018 Àkọlé àwòrán, Wọn kan tilẹ̀ ní àwọn fẹ́ pá'jẹ bi àwọn kan ṣe ní àwọn fẹ́ fi ṣe àsun Ibikíbi tí àwọn olówó ẹlẹ́dẹ̀ arríran tí a mọ̀ sí Marcus the Pig bá wà, wọn ni láti forípamọ́ bayìí nítori àwọn ọmọ Naijiria ń wá ẹlẹ́dẹ̀ nàá lẹ́yin ifẹsẹ̀wọn ti alẹ́ ọjọ́ Àbámẹ́ta.
O tesiwaju, o lo Ile-iwe Girama Bishop Phillips Academy ni
Ọba àkọ́kọ́ tí yóo jẹ níbẹ̀ ni ìwo ńlá tí ó wà láàrin ojú rẹ̀.
Abadofin abo lọwọ iwa aitọ ati irọ lori ayelujara atawọn ọrọ mii to lu mọ ọ - 2019.
ati Gileadi ati agbègbè Geṣuri ti Maakati, ati gbogbo òkè Herimoni ati gbogbo Baṣani títí dé Saleka; 
reasons: Serious security challenges in nigeria demand establishment of state police police is better under state management fg can regulate no justification for abuse of police by state governors, laws should be passed to watch and guide top 3 things to do: 1.
O tako iyansipo alaga ajọ EFCC Daura tun kọ iwe ẹsun si ile aṣofin nipa ọga agba ajọ EFCC, Ibrahim Magu, eyi to mu ki awọn 'koju oro si iyansipo rẹ.
Buhari ni òun ni ìgbàgbọ́ gidigidi nínú ètò ìjọba alágbádá ati pe òun si ṣetan láti mu u dúró ṣiṣin ni ìwọ̀-òòrun ilẹ̀ Afrika.
Ẹlẹ́tàn ni ọkùnrin, tó bá rí nkan tó n wa lára obìnrin, yóò yí ìwà padà - Bimpe Oyebade Ẹ wo nkan tí àwọn akẹẹgbẹ́ Lateef Adedimeji sọ nípa f'ọ́tò ìgbéyàwó òun àti Adebimpe tó jáde Sugbọn, Lateef Adedimeji lasiko to n sọrọ lori eto kan lori tẹlifisan TVC sọ pe, ileeṣẹ kan ni awọn fi awọn aworan naa polowo ọja fun.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ìdílé tí ọkọ da ọmọ síta tóríi ojú Búlùú tí wọ́n ní bá BBC sọ̀rọ̀ Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
yóo mú igi Kedari ati ewé hisopu ati aṣọ pupa tẹ́ẹ́rẹ́ náà, ati ẹyẹ keji, tí ó wà láàyè, yóo tì wọ́n bọ inú ẹ̀jẹ̀ ẹyẹ tí ó pa lórí odò tí ń ṣàn, yóo wọ́n ọn sára ilé náà nígbà meje.
O san láti ma ni ǹkan ṣe pẹlu ẹnikẹni to ba ni ọ̀fìnkìn tàbi to ni ikọ́, eyi ni ọ̀na láti daabo bo ara ẹni lọ́wọ́ COVID19 Ati àwọn onimọ sayensi ni Naijiria ati gbogbo àgbáye ni wan ti jọ n gbimọ pọ lati mọ idi aisan náà ati lati wa ọ̀na abayọ Oríṣun àwòrán, Kevin Frayer Àkọlé àwòrán, Awon alase ni aisan na le ran lati ara eniyan si eniyan miran Kini awon apẹrẹ aisan Coronavirus Awọn apẹrẹ gbòògi ni: Imi to nira tabi ki èèmi ma ja geere Iba Ikọ ati Kata Awon ẹya ara le da iṣẹ silẹ Otutu aya Ati iku Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Coronavirus Symptoms: Full explanation of Covid-19 outbreak, everitin you need to know30 Èbibi 2020 Coronavirus: Nigeria goment promise N36m for scientist wey find cure for di disease and lassa fever14 Èrèlè 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Nígbà tí ó ṣe, atẹ́gùn bẹ̀rẹ̀ sí fẹ́, gbogbo àwọn iggi tí kò ní gbòǹgbò wọn-ọnnì sì ń fi orí balẹ̀ wọ́n tún ń dìde.
” Bẹ́ẹ̀ ni Ọlọrun ṣe sọ ọ́ ní Israẹli.
“Ni bayii, oro ti n lo lowo pelu ajo IHF lati ran wa lowo fun idanileko awon akonimoogba wa gbogbo.
Ìtàn Mánigbàgbé: Adebisi Idikan ni olówó tó kọ́kọ́ ra ọkọ̀ nílẹ̀ Ibadan
Ikede yi jẹ igba ẹlẹkẹẹta laarin ọsẹ yii ti awọn to ko Coronavirus yoo dinku si tatẹyinwa.
Titi di ọjọ́ ikú ọkọ rẹ ni ọdún mejidinlọ́gbọ̀n sẹhin, lẹhin igbéyàwó àádọ́ta ọdún, ó ṣe àti lẹhin fún ọkọ rẹ titi di ọjọ́ alẹ́, eyi jẹ àpẹrẹ rere fún gbogbo obinrin.
Ninu ọrọ ti rẹ, Macron ni adehun tuntun naa yoo seto nipa ado oloro ọlọgọọrọ ti Iran n gbe kalẹ ati ipa rẹ ni agbegbe Middle East.
Bí wọ́n bá bá a lọ́wọ́ èyíkéyìí ninu àwa iranṣẹ rẹ, pípa ni kí wọ́n pa olúwarẹ̀, kí àwa yòókù sì di ẹrú rẹ.
Nibayii awọn ọlọpaa ti bẹrẹ iwadii lori iṣẹlẹ naa.
Kí n máa bá ọ̀rọ̀ lọ bi ilẹ̀ bí ẹní, mo fẹ́ kí gbogbo ènìyàn lórí ilẹ̀ ayé mọ̀ pé bẹ́ẹ̀ ni mo ṣe tí mo ṣìnà sínú igbó náà odidi ọdùn mẹ́ta.
Wọn tun beere lọwọ Malami pe agbara wo ni ọọfiisi rẹ ni lati mọ ọna eto aabo to yẹ fun iran Yoruba lasiko yii?
Àwọn alufaa náà kò tún nǹkankan ṣe ninu ilé OLUWA títí tí ó fi di ọdún kẹtalelogun tí Joaṣi ti jọba.
Àṣírí ilé ìmúni nígbèkùn míràn tú síta ni Katsina Ajínigbé tú ìyá àti ọmọ ọdún mẹ́ta sílẹ̀ lẹ́yìn tí wọ́n gba ₦1.
Bakan naa ọkọ baalu fun iṣẹ ayẹwo inu ofurufu, ọkọ oju omi onibọn, ọkọ ayẹta mẹẹdogun akero atawọn ọkọ oriṣiriṣi mii fun iṣẹ abo.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ibrahim Magu, Alága àjọ EFCC yóò gbé ìwé àwíjàre rẹ̀ tọ ìgbìmọ̀ olùwádìí Aàrẹ wò lónìí 15 Agẹmo 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 24 Agẹmo 2020 Oríṣun àwòrán, others Alaga ajọ EFCC to n rọọkun nile lọwọ bayii, Ibrahim Magu yoo tun farahan niwaju igbimọ oluwadii ti aarẹ gbe kalẹ lati gbe awijare rẹ kalẹ lori awọn ẹsun ti wọn fi kan an.
awon akoroyin leyin ti oun ati iyawo re  dibo tan niluu Daura.
Ẹ padà sílé èyin ọmọ wa tó n ṣiṣẹ́ darandaran - NEF ti Fulani Buhari ti buwọ́lu ẹ̀kúnwó sísan owó oṣù tuntun fáwọn òṣìṣẹ́ àpapọ̀ Ẹgbẹ́ àwọn òṣìṣẹ́ TUC fárígá sí ìjọba Naijiria lórí owó oṣù tuntun Super Eagles gba iṣẹ́ lọ́wọ́ Seedorf olùkọ́ni Indomitable Lions Cameroun Ọjọ kẹẹdọgbọn, oṣu Kinni, ọdun 2019 ni Muhammad bọ si ipo Adele lẹyin ti wọn da Adajọ Agba nigba kan, Walter Onnoghen duro, nitori ẹsun ṣiṣe magomago lasiko to kede dukia rẹ.
ìjàmbá ọkọ lọnà Èkó gba ẹmí Èniyàn márùn ún!
”Àwọn tí ó ṣubú ni àwọn tí kò gba ọ̀rọ̀ náà gbọ́.
Lórí ẹgbẹ̀rún lọ́nà ọgọ́rún Náírà ti Murphy gbà lọ́wọ́ K1, o ní láti le dáàbò bo ẹ̀mi rẹ nítori túlàsì ni wọ́n fi fún un ni owó náà.
Ọjọ 12, Osu Kẹta Aarẹ Muhammadu Buhari kede wipe awọn yoo fọrọwerọ lori bii awọn ajinigbe naa yoo se fi awọn ọmọ naa silẹ lai lo ipa.
Ó dó ti àwọn ìlú olódi wọn, ó lérò pé òun óo jagun gbà wọ́n.
16 Ọ̀wàrà 2020 10:43 Fídíò, Wole Soyinka sọ ìdí tó fi ni òun a fi màálù Fulani ṣe súyà fáwọn èèyàn abúlé, Duration 10,4323 Owewe 2020 Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí 2 sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
Wo àwọn ẹ̀ṣẹ̀ Trump tó mú kí alátakò ilé darapọ̀ mọ́ tìta láti yọ nípò Saaju la ti mu iroyin wa fun yin pe awọn aṣofin kan latinu ẹgbẹ oṣelu Republican, ti Donald Trump ti wa, ti n darapọ mọ ti ẹgbẹ oselu alatako Democrat, lori igbesẹ lati yọ aarẹ orilẹ-ede Amẹrika naa nipo.
Nígbà tí àwọn ará Kenaani tí wọn ń gbé ibẹ̀ rí i bí wọ́n ti ń ṣọ̀fọ̀ ní ibi ìpakà náà, wọ́n wí pé, “Òkú yìí mà kúkú dun àwọn ará Ijipti o!
7 1676 Orilẹede Uruguay 82 2.
ni aare yoo bere ipolongo eto idibo ni ila Gusu ni ipinle Akwa Ibom .
Amọṣa, titi di bi a ṣe n sọ yii, ko tii si ojutu fun un.
Ìtàn fi yẹ wá pé ajakale àrùn alefọ náà gbẹmi èèyàn tó lè ní mílíọ̀nù méjìlá laarin orile-ede China sí India.
Hammed pari ọrọ rẹ pe lati igba ti ajọ naa ti gbe kọkọrọ si ẹnu ibode, ọrọ aabo ti ṣẹnu ire ju ti tẹlẹ lọ.
Lọjọ Abamẹta to kọja ni wọn ji awọn ọmọ Offa yii gbe.
Hẹrọdu bá pe àwọn amòye náà síkọ̀kọ̀, ó fọgbọ́n wádìí àkókò tí ìràwọ̀ náà yọ lọ́dọ̀ wọn.
"Bi awọn kan ṣe n sọ ina sinu ile ijọsin naa ni awọn mii n jo ọkọ̀ ti ọrọ di boolọ koo yago fun mi""Àwọn tó jí ọmọ mi gbé nílé ìjọsìn ní ń kò gbọdọ̀ wa tàbí kí ẹ̀mí mi lọ si""."
Sẹnẹtọ Ajimọbi dagbere faye lẹni aadọrin ọdun nilu Eko l‘Ọjọbọ.
Àwọn eniyan náà sì sinmi ogun jíjà ní ilẹ̀ náà.
Igbesẹ naa si ti fa ọpọ ajọyọ nile Gẹẹsi ati ifẹhonuhan lodi si igbesẹ naa lawọn apa ibikan lorilẹ-ede Ireland.
Àkọlé àwòrán, Akinyele Murder: Iléeṣẹ́ ọlọ́pàá ní aago márùn-ún ìdájí ni wọ́n pa obìnrin náà níwájú ilé rẹ̀ Nibayii, ile iṣe ọlọpaa ni ipinlẹ Ọyọ tun ti jẹjẹ lati ṣawari awọn ọdaran ti o fẹ sọ ijọba ibilẹ Akinyẹle di ibi ẹru fun awọn olugbe ipinlẹ Ọyọ.
Ọ̀nà ẹ̀bùrú ni òfin gbà wọlé, kí ẹ̀ṣẹ̀ lè pọ̀ jantirẹrẹ.
 I reserve the right to defend myself.
Aarẹ Bolsonaro lọpọ igba ti sọ pe ọfinkin kekere ni arun Covid-19 ti ko si bikita fun ilana itakete si ara ẹni lawujọ ti a mọ si social distancing.
sinsisn, yatọ si ahesọ ọrọ ti awọn kan n sọ kiri pe ,won yoo tu igbimo naa ka lọsẹ
 Ni kete ti awọn alasẹ ẹgbẹ ni Abuja ba si ti de si orilẹede yii ni wọn yoo wa kan si gomina Makinde lati yanju ọrọ yii ni itubi n nubi.
Ọkọ mi kò le f'ipá bá ẹnikẹ́ni lò pọ̀ láíláí - Modele Fatoyinbo Ọwọ́ ọlọ́pàá tún tẹ afurasí tó fipá bá odi àti adití lòpọ̀ nílùú Ibadan Lo ba bẹrẹ si ni ki ika ọwọ rẹ bọ oju ara mi (ihoho ni mo ma n sun).
    Bí mo ti fi ìdí balẹ̀ lórí àga ni ariwo ta pé ìyàwó mi ń bọ̀, bí o ti n bọ̀ ni a sì ń gbọ́ tí wọn ń yìnbọn lẹ́ẹ́kọ̀ọ̀kan.
Ìròyìn jẹ́ kó di mímọ̀ pé ọ̀pọ̀lọpọ̀ ènìyàn ni wọ́n pá ní ìlú kọ̀ọ̀kan tí wọ́n sì gbé ọ̀pọ̀ míì tó fara pa lọ sílé ìwòsàn.
Ẹyẹ Spiny Babbler “ti jẹ́ ẹranko tí ó ju ìmọ̀ ènìyàn lọ ní ọjọ́ tí ó ti pẹ́, ọ̀kan nínú ọ̀wọ̀ ẹyẹ márùn-ún ní India, pẹ̀lú Àparò Òkè gíga, kò sí lórílẹ̀ ayé mọ́n.
Iroyin sọ pe odiwọn iye kokoo maaki 3.
Bakan naa wọn a ri i pe wọn mo ju to ago ti awọn ile iwosan mii ma n tilẹkun ki awọn eniyan le maa ba wọn bi wọn ba gbe alaisan lọ.
Àwọn ohun tí a fà yọ nínú ìwé ìtàn Joseph Smith ní ṣíṣe àtúnsọ àwọn ọ̀rọ ángẹ́lì Mórónì sí Wòlíì Joseph Smith, nígbàtí ó wà ní ilé bàbá Wòlíì ní Manchester, New York, ní ìrọ̀lẹ́ 21 Oṣù Kẹsãn 1823.
    Lọ́gànjọ́ oru ọjọ́ kan báyìí ni mo déédéé gbọ́ òjò bẹ̀rẹ̀ síí’kù nígbà tí mo sì dìde ní ibùsùn mi ti mo yọ ojú wo òde, mo rí gbogbo àyíká, ó ṣókùnkùn dudu, bẹ́ẹ̀ ni àkókò òṣùpá ni, àfi bi ẹni pe àwọ̀sánmò ti pinnu lọ́kàn rẹ̀ pé òun kò ní tanná fún ènìyàn mo.
Laipẹ yi ni awọn gomina guusu iwọ oorun ṣepade pẹlu igbakeji aarẹ, Yemi Oṣibajo ati agbẹjọro agba ni Naijiria, Abubakar Malami lati sọ asọyepọ lori eto naa.
okunkundun, wiwa ojutu si eto aabo to mehe, bee si ni mumu igberu ba eto oro
Kò sí ẹni tí ó lè wá sọ́dọ̀ mi àfi bí Baba tí ó rán mi níṣẹ́ bá fà á wá, èmi óo wá jí i dìde ní ọjọ́ ìkẹyìn.
Ni ọdun 2014 ni ọgbẹni Essebsi bori ninu idibo apapọ ti awọn orilẹede naa ṣe lọdun 2014 lẹyin wahala awọn larubawa lagbegbe naa.
Ṣugbọn lasiko tawọn agbofinro n pitu ọwọ wọn niwaju aafin fawọn agbẹ ati ọdẹ yii, to fi de aarin ilu lapapọ, diẹ lara awọn afẹhonu han yii ti yọ kẹlẹ wọnu aafin Soun, ti wọn si ni o di dandan ki ọba faye silẹ lọjọ naa.
Aisan Coronavirus ma n ran lati ara eniyan kan si ẹlomiran.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ọdun 1977 ni Muhammadu Buhari ya aworan yii pẹlu Ọba Sweden, Carl Gustaf ati Sheikh Ahmed Zaki nilu Stockholm, Sweden, lasiko to lọ fun ipade ajumọṣe fun awọn orilẹ-ede to n pese epo rọbi Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Muhammadu Buhari lasiko to fi jẹ aarẹ ologun ni Naijiria lọdun 1983 si 1985 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Buhari lasiko to n gba iṣakoso lẹyin to ṣaṣeyọri ninu iditẹ gbajọba lọwọ Shehu Shagari lọdun 1983 Oríṣun àwòrán, @other Àkọlé àwòrán, Buhari pẹlu iyawo rẹ to ti d'oloogbe, Safinatu, ati awọn ọmọ marun un to bi fun un.
Arabirin Halima Babamale to jẹ olukọ ni fasiti ilu Ilorin to n tẹsiwaju pẹlu ẹkọ rẹ nilu Malaysia naa sọ iriri tirẹ nipa gbigbe ilu okere.
Ẹgbẹ́ òṣèlú PDP ní ìpínlẹ̀ Bayelsa jáwé olúbori nínú ìdìbò ìjọba ìbílẹ̀ Manchester United dáná sun Chelsea bi ẹràn àgbò iléyá El-Zakzaky: Arúfin ni ijọba Muhammadu Buhari gan-an - Ladoja Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Oro Festival: Àwọn olórò ní ọdún Màgbó ló ń gba ibi lọ, kó ire wọlé ní Ikorodu Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Shiite: Ẹ̀mí àti ara wa kọ ohun tí ìjọba ń ṣe sìwa láti 2015 Ó te siwaju pé, àwọn agbebon náà wo aṣọ ológun nígbà tí ṣe akọlù sí ilé ẹ rè ni dédé aago kan òru ọjọ́ ìsimiÓ fi kun pé, akọlù sí ọmọ ẹgbẹ́ òṣèlú PDP ní ìpínlè náà fẹ́ àbójútó látàrí bíi àwọn agbebon tí wón ń wọṣọ ológun láti ṣe irú ìṣe láabi náà ń wọ́pọ̀ sii.
"Ẹní mọ̀ mí ò kò mi, ẹni kò mí ò mọ̀ mí, èmi ati kékeré m'ojú ewé, sanpọna ò gbóògùn""."
Lọdun 2019, ẹgbẹrun lọna aadọrun arinrin-ajo igbafẹ lo ṣabẹwo si Palau, eyi si jẹ ilọpo marun un gbogbo eeyan to wa nilẹ naa.
United Kingdom: Bii ẹgbẹruun mọkandilogun si mẹtalelogun pọun owo ilẹ Gẹẹsi, Wales ati Northern Ireland lawọn Kọnstebu ọlọpaa n gba lodun ni ilẹ Gẹẹsi, Wales ati Northern Ireland.
ó bá rí àwọn angẹli meji tí wọ́n wọ aṣọ funfun, ọ̀kan jókòó níbi orí, ekeji jókòó níbi ẹsẹ̀ ibi tí wọ́n tẹ́ òkú Jesu sí.
1 834 Orilẹede Monaco 7 18.
Àwọn jàǹdùkú pa fadá ní Taraba-Iléeṣẹ́ ọlọ́pàá Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Má kọ̀wé fipò sílẹ̀, àwọn àgbààgbà Yorùbá sọ fún Osinbajo Adigunjalè fọ́ báńkì ní Oye Ekiti, wọ́n tún ṣun ọkọ̀ ọlọ́pàá níná Àráàlú yarí fún fásitì Babcock fún bo ṣe lé akẹ́kọ̀ọ́ tí wọn bá lòpọ̀ nínú fídíò Wọn fikun ọrọ wọn pe mimu ti ajọ DSS mawọn ati iya ti wọn fi jẹ awọn niluu Eko lọjọ keji oṣu kẹjọ ati niluu Oṣogbo lọjọ karun un oṣu kẹjọ tako ẹtọ ọmọniyan awọn.
Nítorí lẹ́ẹ̀kan náà ni ó ti ṣe èyí, nígbà tí ó fi ara rẹ̀ rúbọ.
Àwọn àpẹẹrẹ mẹ́sàn-án tí yóò fihàn pé o ti n darúgbó
Ọ̀rọ̀ ẹnu wọn bá ti gbajúmọ̀ mu, bẹ́ẹ̀ ni ìrìn ẹsẹ̀ wọn dàbí ìrìn ẹsẹ̀ ènìyàn ti afẹ́ ayé ti sọ di réderède.
Bẹnaya, ọmọ Jehoiada ní ń ṣe àkóso àwọn Kereti ati Peleti tí wọn ń ṣọ́ ọba, àwọn ọmọ Dafidi lọkunrin ni wọ́n sì wà ní àwọn ipò tí ó ga ninu ìjọba rẹ̀.
Ẹfunsetan Aniwura, obìnrin tó ju ọkùnrin lọ Ọ̀rọ̀ǹpọ̀tọ̀niyùn, Aláàfin obìnrin àkọ́kọ́ rèé, tó ní nǹkan ọkùnrin Lati mu adinku ba igbokegbodo ọkọ, ijọba apapọ ṣẹṣẹ paṣẹ ki wọn ko gbogbo ohun to n mu ki agbegbe naa ri rudurudu kuro ni.
Ojo tun ṣoju Naijiria ninu idije awọn ọjẹwẹwẹ ti ọjọ ori wọn ko ju ọdun mẹtadinlogun lọdun 2010.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Iléeṣẹ́ ọkọ̀ òfurufú míì ní Nàìjíríà tún gba'ṣẹ́ lọ́wọ́ awakọ̀ 100 tórí Coronavirus Ọlọ́pàá àti àwọn olùfẹ̀hónúhàn gbéná wojú ara wọn níbi ìwọ́de Revolution Now Akpata di aàrẹ àjọ àwọn agbẹjọ́rò ní Nàìjíríà, ọ̀pọ̀ èèyàn kíi kú oríire Ẹ bá mi wá nọ́ńbà ìpè òbí ọmọ Mummy Calm Down jáde - Yinka Ayefele Lakotan ọrọ rẹ, o ni ti awọn eeyan ba farablẹ, wọn yoo ri awọn nkan to ra mọ alaafia orileede Naijiria ati pe abnfaani to kẹyin re lati mu atunṣe ba Naijiria.
 Bẹẹ ni ọpọ awọn akẹkọọ n gbe ike lọ si odo lati lọ pọnmi
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ojú ń kán wa, a fẹ́ gba àfikún owó osù tuntun- NLC 'Ọ̀pọ̀ fẹ́ kí n kú nígbà tí mo ṣàìsàn' OPC ní olórí tuntun, igun New Era OPC yarí Ebi yóò ti lu Nàíjíríà pa, tó bá jẹ́ PDP kò se dáadáa - Jonathan Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Tọkọ-taya Aràrá: Àwọn èèyàn máa ń wò wá, ta bá fa ọwọ́ ara wa ní títì Àwọn kókó mẹ́wàátí Sanwo-Olu sọ: Lórí ìbéère nípa àìní òye tó nípa ìṣèjọba, Sanwo-Olu dáhùn wípé, òun kìí ṣe aláìlóye ènìyàn nítòrí òun ti wà nínú iṣèjọba lati ọdun 2002, àti pé òun ti ṣe kọmíṣọ́nà lẹ́ẹ̀méjì, olùrànlọ́wọ́ fún gómínà àti olórí iléeṣẹ́ ìjọba ri Sanwọ-Olú dáhùn ìbéèrè nípa ayédèrú owó dọ́là tí wọ́n fi ẹ̀sùn kan an pé ó ná nílu Amẹrika.
Kii se iroyin tun tun mọ pe ọdun 2019 to n bọ, ni eto idibo gbogbo-gboo ni orilẹede Naijiria yoo waye sugbọn o yẹ ki awọn araalu mọ iye owo ti ajọ eleto idibo ilẹ wa Inec, ya sọtọ lati se eto isuna naa, ati atupalẹ alaye lori bi eto isuna naa yoo se lọ si.
Àti pé nítorí púpọ̀ nínú awọ̀n ọ̀nà wọ̀nyí gba iwajú ilé àwọn ènìà kọká.
Ṣugbọn ibeere ni pe ṣe wọn yoo gbọ?
Louis Jones Jr, ẹni ọdun mẹtalelaadọta ni ijọba apapọ ilẹ America pa gbẹhin, fun pe o pa sójà kan to jẹ ẹni ọdun mọkandinlogun, Tracie Joy McBride.
Kóníléógbélé kòkan àwọn òṣìṣé tó n ṣiṣẹ́ covid-19 Kò tí sí ìrìnàjò láti ìpínlẹ̀ kan sí òmíràn Kí gbogbo àwọn òṣìṣẹ́ bánkì padà sẹnu iṣẹ́, kí wọ́n sì maa lo àsìkò wọ́n pé, bákan náà ni àwọn ilé iṣẹ́ aládani lé padà sí bí wan ṣe n ṣe tẹ́lẹ̀, níwọ́n ìgbà ti iṣẹ́ wọ́n yóò ba ti maa parí kí àsìkò kóníléógbélé tó bẹ̀rẹ̀.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ondo: Dejí sun ọmọ méje àtagbalagba meji mọ́lé nítorí pé ó ń bínú Awọn kan naa pa oṣiṣẹ ile itaja itakun agbaye Jumia lọdun mẹta sẹyin, ti wọn si ju oku rẹ sinu ile iyagbẹ.
Oluwo tẹsiwaju pe pupọ ninu awọn ọba to n doju ija kọ oun lo ti ta ilẹ awọn baba wọn tan ti wọn wa n wa awọn ilẹ ara ilu ti wọn a ta kun.
Kò jẹ ohunkohun ní gbogbo àkókò náà.
Ni ọkan lara awọn agbegbe ti awọn agbasẹse to nsatunse oju ọna marosẹ naa ti gbe ọna naa gba oju kansoso nitori isẹ atunse to nlọ lọwọ ni ijamba yii ti waye.
Ọba pàṣẹ pé kí àwọn alufaa, àwọn ọmọ Aaroni, fi wọ́n rúbọ lórí pẹpẹ OLUWA.
Àkọlé àwòrán, Alhaji Adeoti Ti a ko ba gbagbe, ni esi idanwo asekagba ile iwe girama WAEC ti wọn fi lede laipe yii, ipinlẹ Osun lo se ipo kọkandinlọgbọn ninu ipinlẹ mẹrindinlogoji.
Ọkunrin naa di ẹni to n kawọ pọn rojọ niwaju adajọ lẹyin ti wọn fẹsun ole jija, ile fifọ ati igbimọpọ hu iwa ọdaran kan.
Aarẹ ASUU - BBC News Yorùbá BBC News, YorùbáFò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù ASUU strike: Mi ò tíì lè sọ ní pàtó ìgbà tí a ó fòpin sí ìyanṣẹ́lódì wa - Aarẹ ASUU 7 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Oríṣun àwòrán, @ASUU A kò ní padà sílé ìwé àyàfi t́i ìjọba bá san owó oṣù tó jẹ wá - ASUU Ẹgbẹ awọn olukọ fasiti ni naijiria, ASUU, ti sọ pe awọn ko ni pada sẹnu iṣẹ ayafi ti ijọba apapọ ba san gbogbo owo to jẹ awọn olukọ naa.
com Ẹrọ isiro fi lede wipe owo apo irẹsi kan jẹ ₦15,000 Pin oju ẹrọ yii Pin oju ẹrọ yii twitter facebook email Njẹ o mọ?
Níbẹ̀ ni ó pàgọ́ rẹ̀ sí, àwọn iranṣẹ rẹ̀ sì gbẹ́ kànga kan sibẹ.
Kí wọ́n pa ìwà ìbọ̀rìṣà wọn tì, kí wọ́n sì gbé òkú àwọn ọba wọn jìnnà sí mi, n óo sì máa gbé ààrin wọn títí lae.
To n tumọ si pe lapapọ, eeyan 13,873 ni ayẹwo ti fihan pe wọn ti ko arun naa ni Naijiria.
N óo fi àwọn ohun tí ó níláti ṣẹlẹ̀ lẹ́yìn èyí hàn ọ́.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Celestine Egbunuche: Òun àti ọmọkùnrin rẹ̀ ti lo ọdún 18 l‘ẹ́wọ̀n, kó tó rí ìdáǹdè 7 Òkùdu 2019 Oríṣun àwòrán, Global Society for anti corruption Yoruba ni bi isẹ ba sẹ ọmọ fun ogun ọdun, ti iya ba jẹ ọmọ fun ọgbọn osu, bi ko ba pa ọmọ, yoo kuku pada lẹyin ọmọ ni.
Ọgbẹ́ inú mú òṣèré lọ Àkójọpọ̀ fọ́tò ìsìnku Aisha Abimbola Tunrayo Adeoye,òsèrè tíátà míì jáde láye Moses Adejumọ, a.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ramadan: Àwọn ọlọ́pàá Sharia tí ń mú aṣéwó àti ọ̀daràn nípínlẹ̀ Kano 29 Ìgbé 2019 Oríṣun àwòrán, PIUS UTOMI EKPEI Àkọlé àwòrán, Ramadan Fast: Àwọn ọlọpàá Sharia tí n mú aṣewo àti ọdaràn nípìnlẹ̀ Kano Àwọn ọlọ́pàá Sharia tí mú àwọn ènìyàn to lé ni ààdọta ti wọn funra si gẹ́gẹ́ bi aṣẹwó àti ọdaran lójúnà àti mú àdínku bá ìwá ẹsẹ̀ lásiko ààwẹ ramadani tó ń bọ̀.
Esther Ajayi: Èmi náà ti borí ìṣòro rí ló ń mu mi ṣojú àánú
Nígbà tí Solomoni gbọ́ pé Ṣimei ti kúrò ní Jerusalẹmu, ó ti lọ sí Gati, ó sì ti pada, 
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Coronavirus Cases in Africa: Adarí àwọn agbóòkú tó ń fi ijọ́ dárà ní ilẹ̀ Ghana sọ bí àwọn ṣe da ìlúmọ̀ọ́ká Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Coronavirus Cases in Africa: Adarí àwọn agbóòkú tó ń fi ijọ́ dárà ní ilẹ̀ Ghana sọ bí àwọn ṣe da ìlúmọ̀ọ́ká 17 Èbibi 2020 Ọdun meji sẹyin ni akọroyin BBC ṣe afihan bi awọn agbokun ni orilẹede Ghana ṣe tayọ pẹlu bi wọn ṣe n gbe oku jọ.
osu kẹ́rin ni deede aago meta ni ijoba ipinle naa gbe ofin konile-gbele jade.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù EFCC: Ààrẹ Buhari ní gbogbo àwọn aṣèbàjẹ́ ni wọn yóò fojú winá òfin 10 Èbibi 2018 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 13 Agẹmo 2020 Oríṣun àwòrán, Reuters Aarẹ orilẹede Naijiria, Muhammadu Buhari ti ni lọọtọ ni iwa ibajẹ ati jẹgudujẹra gbinlẹ ni orilẹede Naijiria.
Bakan naa ni wọn fikun wi pe ijọba naa ti bẹrẹ si ni fin kokoro apakokoro ni gbogbo agbegbe ileewọsan ti iṣẹlẹ naa ti waye.
Nígbà tí Dafidi pè é ní Oluwa, báwo ni ó ti ṣe tún jẹ́ ọmọ rẹ̀?
 Ó jẹ ́ ẹ ̀ ka èdè swahili sùgbọ ́ n ipa púpọ ̀ lọ ́ dọ ̀ èdè lárùbáwá ju swahili lọ .
Wọn ni awọn ti mu awọn eniyan wọnyii si atimọle lataari ile ati ọja awọn ajoji ti wọn n jo nina ni South Africa.
Money ritual: Àwọn àṣà àtọ̀húnrìnwá ló fa títa ẹ̀jẹ̀ sílẹ̀ nítorí òògùn owo
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Tomomewo Favour: olóṣèlú kìí ṣe ọ̀daràn tàbí alágbèrè Gomina ipinlẹ Ondo, ti o tun jẹ aṣoju fun awọn gomina to n bẹ ni ẹkun Iwo-oorun guusu, Arakunrin Rotimi Akeredolu, naa ba awọn eeyan sọrọ nibi apero naa.
DPO ọlọ́pàá ju télọ̀ sátìmọ́lé, gbé e lọ sílé ẹjọ́ n'Ibadan torí ''ó ba aṣọ rẹ̀ jẹ́'' ₦50 bílíọ́nù ni a pín fún gbogbo ìpínlẹ̀ ní Naijiria láti kojú àrùn Covid-19- Ìjọba àpapọ̀ Ọkùnrin kan rí ẹ̀wọ̀n ọdún mẹ́rin he lẹ́yìn tó jí ẹ̀rọ ìléwọ́ iPhone ní ìpínlẹ̀ Ogun Ẹ fún wa lówó oṣù wa tàbí kí a gùnlé ìyanṣẹ́lódì ọlọ́jọ́ gbọọrọ- Àwọn dokita ìpínlẹ̀ Ondo Wo àfipábánilòpọ̀ ẹni ọdún 51 tí ìjọba ìpínlẹ̀ Ekiti tú làṣirí ní gbangba Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 3 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 5 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Ninu ipade apejọ ẹgbẹ oṣelu naa to waye kaakiri orilẹ-ede Naijiria, eyi ti wọn ṣe ni Ipinlẹ Eko ni eto idibo naa ti waye.
Nítorí èyí àwọn Juu dìtẹ̀ sí Jesu, nítorí ó ń ṣe nǹkan wọnyi ní Ọjọ́ Ìsinmi.
Kílódé t'íjọba kò ṣe tíì pe àwọn darandaran ní agbésùmọ̀mí?
"Ẹkún ló kàn ń sun láti ìgbà to ti dé , kò tilẹ̀ le sọ ohunkohun, sùgbọ́n lẹ̀yìn ìgbà díll mo nígbàgbọ́ pé yóò pada bọ sípò.
Ó pẹ́ tí mo ti kọ́ ninu ìlànà rẹ,pé o ti fi ìdí rẹ̀ múlẹ̀ títí lae.
Kọmisọnna fun eto isuna ni ipinlẹ Ondo ninu ọrọ rẹ sọ wi pe aibikita lo mu ki awọn ohun alumọni to wa ni ipinlẹ Ondo ni ifasẹyin.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Wakati kan ni ijọba fún wa lati kúro ni ibi ti a ngbé Ìdá 90% nínú àwọn olówó Naijiria lo n lọ ilé babaláwo- Mr Latin Ọbasanjọ ni ọmọ òrùkàn tó di olóri orílẹ̀èdè lẹ́ẹ̀mẹ́ta ọ̀tọ̀ọ̀tọ̀ Oluwo, lero tiẹ ni bi o tilẹ jẹ pe asa wa nilẹ Kaarọ oojire yaayi pupọ amọ awọn abala kan wa ninu rẹ to yẹ ka parẹ, nitori pe wọn ko ba saa taa wa yi mu mọ.
Wo ohun tí ìrìnàjò ààrẹ Buhari fún ìgbà àkọ́kọ́ lásìkò Coronavirus lọ sí Mali yóò bá bọ̀ Oríṣun àwòrán, Buharisallau1 Niṣe ni aarẹ Buhari de Mali to wọ ibomu fun igba akọkọ nita gbangba ni olu ilu orilẹedeMali lọsan ọjọbọ ni irinajọ ọlọjọ kan to lọ fun ijiroro.
eleyii mu ọpọlọpọ akẹẹkọ miiran ko kuro nile ẹkọ, ti awọn miiran si n san aabọ gẹgẹ bi owo ile iwe.
Ní ọjọ́ keje, nígbà tí ọba mu ọtí waini tí inú rẹ̀ dùn, ó pàṣẹ fún meje ninu àwọn ìwẹ̀fà rẹ̀, tí wọ́n jẹ́ iranṣẹ rẹ̀: Mehumani, Bisita ati Habona, Bigita ati Abagita, Setari ati Kakasi, 
Aago Naijiria ti kún àkúnwọ́sílẹ̀ - Tunde Bakare Fulani nìkan kọ́ ló ń pa ènìyàn ní Naijiria -Tinubu Àjálù ń bọ̀, tí Buhari kò bá ṣàtúnṣe lórí ètò ààbò- Obasanjo Sanwo Olu yan kọ̀míṣọ́nnà 25 àtàwọn olùbádámọ́ràn Mahrez dá Super Eagles dùbúlẹ̀ lórí pápá oko tútù Ooni Ile ife, Ààrẹ Gani Adams fárígá lórí ikú ọmọ Fasoranti Awọn ọdọ bẹrẹ ifẹhonuhan pe iku gbigbona ti to gẹẹ nipinlẹ Ondo ati ijinigbe.
Kò sí obìnrin náà lode ayé tàbí lóde ọ̀run tí o lè ro ẹjọ́ ẹlẹ́jọ́ kiri to bi ìyàwó mi yìí, nítorí ahọ́n abàmì gígùn yìí a máa tìkararẹ̀ ro ẹjọ́ láìjẹ́ pé ìyàwó mi rán an, ahọ́n náà sì máa gbọ́ràn bí ènìyàn, ko sì si ibikíbi tí ẹnikẹ́ni ti lè sọ̀rọ̀ wa lónìí tí ahọ́n yìí kò níí sọ fún wa.
N kò ní já ọ kulẹ̀, bẹ́ẹ̀ ni n kò ní kọ̀ ọ́ sílẹ̀ lae.
Tinubu kò ṣékú, kò ṣé ẹyẹ, o n dibọn ní lórí ọ̀rọ̀ ikọ̀ Amotekun - Fani Kayode Àwọn adigunjalè yabo bánkì méjì nípìnlẹ̀ Ondo, ènìyàn bi i mẹ́ta kú 'Ìbànújẹ́ ló jẹ́ láti rí ìyá àti ọmọ tó ń fẹ̀sẹ̀ rìn ní òru l'Eko nítorí àìsí kẹ̀ẹ̀kẹ́ àti ọ̀kadà' Iléẹjọ́ gíga Akure kọ̀ láti gba onídùróó olórí ìjọ Sotitobire Ọlọ́pàá tó pa èèyàn pokùnso lọ́jọ́ kejì tó dé àhámọ́ àwọn ọ̀tẹlẹ̀múyẹ́ Ẹ fi èmi àti àwọn alága káńṣù APC sílẹ̀, ká yanjú aáwọ̀ wa nítùbí-ǹnùbí - Makinde bẹ iléẹjọ́ ''Awọn ọba alaye atawọn olori awujọ ni yoo ṣe oniduro fawọn eeyan wọn to ba fẹ darapọ mọ ẹṣọ alaabo Amọtẹkun,'' Akeredolu lo ṣalaye bẹẹ.
pé kí ó sọ fún àwọn eniyan Israẹli pé, “Láti ọjọ́ kẹẹdogun oṣù keje lọ, ẹ óo ṣe àjọ̀dún Àgọ́ fún OLUWA; ọjọ́ meje ni ẹ óo fi ṣe é.
Lẹ́hìn tí ọba tí ṣe étò tán, ó fi orí lé inú igbó, òun nìkan àti Ọlọ́run Ọba, ó ń yí inú igbó kiri.
 Àwọn kan sì ti kóra wọn jọ fún ìpolongo láti sọ èdè yìí di àjùmọ ̀ lò ( standardisc ) .
Bíótilẹ̀jẹ́pé àwọn ẹlẹ́sìn Kiristẹ́nì àti Mùsùlùmí kìí bárawọn ṣe dáadáa ní gbogbo ibòmíràn, irẹ́pọ̀ gidi ló wà láàrin àwọn ẹlẹ́sìn méjéèjì ní ilẹ̀ Káàárọ̀-oòjíire.
Naijiria , Voice of Nigeria, ogbeni  Osita Okechukwu naa tun sọ pe bi ajo EFCC se
Ogiri nla kan wa niwaju mi.
Bí ìrì ni n óo máa sẹ̀ sí Israẹli,ẹwà rẹ̀ yóo yọ bí òdòdó lílì,gbòǹgbò rẹ̀ yóo sì múlẹ̀ bíi gbòǹgbò igi kedari Lẹbanoni.
Èmi ni mo mọ ìdí tí ilé ẹjọ́ fi pàṣẹ ẹ̀wọ̀n fún mi - Runsewe Pósí tí wọn ń tà lẹ́nu ọ̀nà ilé ìwòsàn àpàpọ̀ ló ń tètè pa wá - Aláìsàn figbeta Ilé ẹjọ́ pàṣẹ kí wọ́n fi àwọn afurasí tó pa àkẹ́kọ̀ọ́ LASU sí ẹ̀wọ̀n Díẹ̀ lára àwọn ìṣẹ̀lẹ̀ tí yóò mi ìgboro tìtì l'ọ́dún 2020 rèé Ẹtan pe yoo lọ di olukọ ede oyinbo ni wọn fi mu Ọmọlọla Ajayi lọ sorilẹ-ede Lẹbanon, ki ọrọ to di baa mii nigba to de ibẹ tan.
Bí ó bá jẹ́ pé agbára Beelisebulu ni èmi fi ń lé ẹ̀mí èṣù jáde, agbára wo ni àwọn ọmọ yín fi ń lé wọn jáde?
Ọlọrun ní,“N óo gba ìwà aiṣootọ lọ́wọ́ wọn,n óo fẹ́ wọn tọkàntọkàn,nítorí n kò bínú sí wọn mọ́.
N óo run gbogbo igi àjàrà ati igi ọ̀pọ̀tọ́ rẹ̀, àwọn ohun tí ó ń pè ní owó ọ̀yà, tí àwọn olólùfẹ́ rẹ̀ san fún un.
“Ohun tí OLUWA àwọn ọmọ ogun, Ọlọrun Israẹli sọ nípa Ahabu ọmọ Jehoiakini, ati Sedekaya ọmọ Maaseaya, tí wọn ń forúkọ mi sọ àsọtẹ́lẹ̀ èké fun yín ni pé: òun óo fi wọ́n lé Nebukadinesari ọba Babiloni lọ́wọ́, yóo sì pa wọ́n lójú yín.
n lọ ni irọwọ ati irọsẹ.
Ilékílé tí ẹ bá wọ̀, ẹ kọ́kọ́ wí pé, ‘Alaafia fún ilé yìí.
Ọdún méjìlá sẹyìn ni mo rà awọn bàálù ti tẹlẹ.
Wọn ni èyí yóò sì fẹ́ẹ̀ ju iye ènìyàn ti àrùn Covid-19 pa lójoojúmọ́ lọ.
Njẹ iyatọ wa laarin àríwá si gúúsù?
Shekau fa ọpọlọpọ ọmọ ẹgbẹ́ wọle.
Supplementary Election: \Ijọba ìbilẹ Nasarawa nílò àfikun ọlọpàá ló jẹ ká fi kún un\"""
Nígbà tí aba dàgbà aó padà sí bí à ń tí ń sùn tí à ń jí ń gbà tí a wà ní ọ̀dọ́ .
Ẹgbẹfa ni awọn araalu ti wọn ti fun ni ore ọfẹ lati darapọ mọ igbeyawo naa Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ìrọ́-kẹ̀kẹ̀ ìgbeyàwó Ọmọọba ilẹ̀ Gẹ̀ẹ́sì, Harry àti ìyàwó rẹ̀, Meghan Markle ti gbalé kan ní ilẹ̀ Gẹ̀ẹ́sì Ẹgbẹfa awọn araalu ni yoo kopa nibi eto igbeyawo naa.
Promise Akinlade: ọmọ ọdún mọ́kànlá tó ń fi ìlù dárà bíi àgbàlagbà sọ̀rọ̀ nípa tálẹ́ǹtì rẹ̀
"Oluwarotimi Akerdolu ko tọju ẹgbẹ ati awọn ọmọ ẹgbẹ daadaa, o si wu mi pe ki wọn gbe ẹlomiran sita lati rọpo rẹ, ti yoo se daada ju bi Akeredolu ti se lọ.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Baṣọ̀run Gáà, tó yan ọba mẹ́rin, pa ọba mẹ́rin àmọ́ ọba karùn-ún ló pa á Gómìnà Ganduje wọlé fún sáà kejì ní ìpínlẹ̀ Kano Supplementary election: Ọlọpàá gbé ikọ kògbérégbè díde lọ si wọ́ọ̀dù ìdìbò Gama A kẹ̀yìn sí Atiku torí àtúntò Nàíjíríà tó fẹ́ ṣe - Árẹ̀wá Ajimọbi tún gbé iṣẹ́ àgbàṣe ₦30bn jáde lọ́jọ́bọ - Seyi Makinde Iná ṣe ọṣẹ́ ní Mile 12 l‘Eko, ọ̀pọ̀ ilé àti ìsọ̀ jóná PDP ṣe èrú ìbò gómìnà ní Benue àti Sokoto, a kò ní gbà - APC yarí A gbọ pe aisan kan, ti wọn ko darukọ, lo gba ẹmi rẹ.
Wọ́n bá jókòó níbẹ̀, wọ́n ń ṣọ́ ọ.
tí Olodumare wà pẹlu mi,tí gbogbo àwọn ọmọ mi yí mi ká;
Keyamo sọ pe asia naa yatọ patapata, ati pe ila asia ti wọn lo si oke, amọ ti eleyii ti wọn ri naa wa si isalẹ.
Àkọlé àwòrán, Oriṣiriṣi ọrọ aṣiri si ni awọn eniyan maa n lo ilu lati sọ, ẹni to ba si ni eti ilu nikan ni ọrọ naa le ye.
rọrun ti yoo jẹ ki o mọ itumọ awọn ọrọ to ta koko naaAccreditation (Ayẹwo orukọ) : Eyi ni igbese lati se
Siga fifa tabi Mimu: Ọkan gboogi ninu ọna ti a fi n se àkóbá fún ọpọlọ wa leyi jẹ.
Ninu wọn ni oludije fun ipo aarẹ fẹgbẹ oṣelu PDP Atiku Abubakar wa.
 o mọ pé ìhòhò ní àwọn ẹlẹyẹ wa ko to gbà láti ṣe wọn ní àánú .
Ninú oríkì ni a ti lè mọ ìtàn ìṣẹ̀dálẹ̀ ẹbí ẹni àti ohun ti a mọ ìdílé mọ́, bí i irú iṣẹ ti wọn nṣe ni ìdílé, oriṣiriṣi èdè ìbílẹ̀ Yorùbá, oúnjẹ ti wọn njẹ àti èyí ti wọn ki i jẹ, ẹ̀sìn ìdílé, àdúgbò ti wọ́n tẹ̀dó si tàbi ìlú ti a ti ṣẹ̀ wá, àṣeyọrí ti wọn ti ṣe ni ìran ẹni àti bẹ́ ẹ̀ bẹ́ ẹ̀ lọ.
AFCON 2019: Amuneke gbé Tanzania lọ ìdíje ilẹ̀ Afirika fún'gbà àkọ́kọ́ láti ọdun 1980
Ohun ti a gbọ ni pe Grace wa pẹlu ẹgbọn rẹ atawọn ọmọ ijọ miiran ti wọn wa kọ jita ni ṣọọṣi.
Ọlọ́pàá Nàìjíríà àti Ẹgbẹ́ IMN n ṣé fakinfa lórí ikú àwọn olùwọ́de ìdárò Ashura Ajímọ̀bí lè pe Ọlọ́run lẹ́jọ́ bí ìdájó kò bá tẹ́ ẹ lọ́rùn -Kọla Balogun Àwọn ọmọ Nàìjíríà 320 yóò padà wálé láti South Africa lọ́jọ́rú - Adama Ilẹ ẹjọ fagilé ìbò ọmọ ẹgbẹ́ APC nípinlẹ̀ Ogun pè kí àtúndì ìbò wà Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, APC: òfin NYSC ti APC fi mú mi ni wọ́n kò lò fi mú Ajimọbi tí a kò jọ sìnrú ìlú Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Dafidi jọba lórí gbogbo Israẹli, ó ń dá ẹjọ́ òtítọ́, ó sì ń ṣe ẹ̀tọ́ fún gbogbo àwọn eniyan.
Ẹ dúró níhìn-ín kí ẹ máa bá mi ṣọ́nà.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Super Tuesday: ìdìbò láti yan ẹni tí yóò díje tako Trump bẹ̀rẹ̀ O ti sisẹ gẹgẹ bi amofin fún ipinlẹ Minnesota.
Awọn larubawa kii jagun loṣu yi rara ati rara Sha'aban: Oṣu Kẹjọ ni Sha'aban.
31 Agẹmo 2019 Oríṣun àwòrán, @others Àkọlé àwòrán, O ye ki ijoba fun won ni ohun ti won n beere fun to ba wa ni abe ofin Agbẹjọro ati onimọ nipa eto ofin, Jiti Ogunye ti ni kii ṣe gbogbo agbara ti ijọba ni lo yẹ ki o ma a lo lori awọn ara ilu.
 Awon akoroyin Faranse ni agbejoro Colmar, Christian de Rocquigny du Fayel, ni lasiko yii, ko si idi kankan lati ro pe nkan mii lo ṣẹlẹ sii.
Ó bá pada sí ilé, ẹnu yà á sí ohun tí ó ṣẹlẹ̀.
Ǹjẹ́ o mọ̀ pé ètò ìdìbò kan wà tí erin àti òkúta Dáyámọ́ǹdì leè yí èsì rẹ̀ padà Ẹfunsetan Aniwura, ọmọ Ẹ̀gbá tó di akíkanjú obìnrin nílẹ̀ Ibadan Nínú òkuǹkùn birimù birimù ni mo wà báyìí ni ilé Ìjọba - Igbakeji Gomina Kogi àná Oluwagbenga ni ajọ ọlọpa da si awuyewuye ọhun, ṣugbọn ko si họhuhọhu kankan laarin awọn ọlọpaa ati OYTMA.
Kò ní náání oriṣa tí àwọn baba rẹ̀ ń sìn, kò sì ní bìkítà fún èyí tí àwọn obinrin fẹ́ràn; kò ní bìkítà fún oriṣa kankan, nítorí pé yóo gbé ara rẹ̀ ga ju gbogbo wọn lọ.
yii lati je ki gbogbo awon omo orile ede Naijiria to wa nilẹ okeere ati awon omo
Cristiano Ronaldo: Gbajugbaja agbábọ́ọ̀lù Juventus àti Portugal ti lùgbàdì àrùn Coronavirus
Bí ẹgbẹ́ One Million Boys ṣe bẹ̀rẹ̀ rèé àti ọṣẹ́ tó ṣe n'Ibadan Ènìyàn 33,616 ló ti lùgbàdì ààrùn Coronavirus ní àpapọ̀ ní Nàíjíríà Sotitobire: Ẹlẹ́rìí mẹ́rìn ló tẹ̀lé Alfa Babatunde wá síwájú ilé ẹjọ́ Ohun tí ilé ẹ̀jọ́ rí rèé tí kò fi gba Béélì Hushpuppi Oríṣun àwòrán, Facebook/Nigerian Airforce Wọn fikun pe ori ti o fi gba lasiko ti ijamba ọkọ naa waye lo fa iku rẹ.
kí àṣẹ̀ṣẹ̀yọ èso kéékèèké kọ̀ọ̀kan wà lábẹ́ ẹ̀ka meji meji tí ó ya lára ọ̀pá fìtílà náà.
Iṣẹlẹ ogun naa lo da Belarus ru laarin ọdun 1941-1944 to bẹẹ ti wọn padanu ida mẹẹdọgbọn eeyan wọn lasiko ogun agbaye naa ti ilẹ Nazi Germany kogun ja USSR.
Bakan naa lo fi da awọn ọlọpaa loju ko si ọlọpaa ti yoo ku soju ija gbigbogun ti iwa ọdaran mọ lorilẹede Naijiria.
Àpapọ̀ àwọn tó ní ààrùn Coronavirus ní Nàìjíríà ti tayọ 30,000 Àwọn ọmọ onílẹ̀ àti ọlọ́pàá jọ gbìmọ̀ pọ̀ láti gba ilẹ̀ mí- Guru Maharaj Ji Ìpínlẹ̀ Eko kéde ọ̀nà àbáyọ sí súnkẹrẹ-fàkẹrẹ ọkọ̀ lásìkò àtúnṣe afárá Third Mainland Kò ní sí ayẹyẹ ọdún Ojúde Oba lọ́dún yìí- Awujale ilẹ̀ Ijebu Ki lo ti ṣẹlẹ sẹyin?
Olùkọ́ fásitì méjì ń bèèrè ìbálòpọ̀ lọ́wọ́ akẹ́kọ̀ọ́ fún máákì Gbogbo awa obi si lo yẹ ka ranti pe agba to ba ro ẹfọ ika, ọmọ rẹ yoo jẹ ninu rẹ, bẹẹ si lo yẹ ka wa ọna lati fi orukọ rere silẹ de iran wa to n bọ nitori orukọ rere san ju wura ati fadaka lọ.
Mo di ẹni ilẹ̀,sọ mí di alààyè gẹ́gẹ́ bí ọ̀rọ̀ rẹ.
Akẹgbẹ wọn Liverpool n tọ wọn lẹyin pẹlu bi wọn ti ṣe fi goolu kan ju Wolves lọ.
Oríṣun àwòrán, Twitter/Oluwaseunfunmi O fi kun ọrọ rẹ pe, labẹ isejọba ologun ti oloogbe Sani Abacha dari, ni nkan ti ri bayii ni Naijiria kẹhin.
Oríṣun àwòrán, @followlasg O ni ijọba n tun awọn eroja ounjẹ naa di lọwọ ni to si n pin kaakiri, ko to di pe iwọde EndSARS wọle de, to si se idiwọ fun wọn lati tẹsiwaju lori rẹ.
Nítorí pé, ẹ̀ báà ní ẹgbẹrun àwọn olùtọ́ ninu Kristi, ẹ kò ní ju ẹyọ baba kan lọ.
Bo tilẹ jẹ pe o ti n bọ sori fun Knaye West lati dije sipo aarẹ lọdun gẹgẹ bi ofin awọn ipinlẹ kan ṣe gbe kalẹ l'Amẹrika, awọn onwoye ohun to n lọ kan ti sọ pe biba lo ba, ko tii bajẹ.
Major US Twitter accounts hacked: Ẹ wo bí àwọn gbájúẹ̀ ṣe ṣọṣẹ́ ní Amerika
Nítorí náà ni Jakọbu fi sọ ibẹ̀ ní Penieli, ó ní, “Mo ti rí Ọlọrun lojukooju, sibẹ mo ṣì wà láàyè.
” Joabu, ọmọ Seruaya ni ó kọ́kọ́ lọ, ó sì di balogun.
Ẹ̀wẹ̀, ìwádìí kan ti fi ìdí rẹ̀ múlẹ̀ pé iṣe ènìyàn ni ìṣe ẹranko, ẹranko kan náà wà tó máa n ṣe ètò ìyàsọ́tọ̀ lásìkò tí wọ́n ba wà lórí àkéte àìsàn.
Wọn ń lépa mi; wọ́n sì ti yí mi ká báyìí;wọn ń ṣọ́ bí wọn ó ṣe bì mí ṣubú.
Àwọn òwe yín kò wúlò,àwíjàre yín kò lẹ́sẹ̀ nílẹ̀.
Ìkorodu Boiz (NAIJIRIA) Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ikorodu Bois: Ko si ẹni ti a kò lè sín jẹ!
Nigba to n sọrọ lorukọ Ọba Ogunlade Aladetoyinbo Aladelusi, Adeyeye ni mi o gbọ pe ẹnikẹni ku o, wọn gun ọmọ Igbo kan lọbe nigba ti awọn ọdọ kọlu wọn ni Ọdọpetu."
"Ẹ̀ṣọ́ NSCDC ṣèèṣì yìnbọ̀n pa ọlọ́pàá ọ̀tẹlẹ̀múyẹ́ DSS l'Osun Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Wo Adigun ọmọ ọdún mẹ́rin tí òwe Yorùbá àti ìtúmọ̀ gbó lẹ́nu rẹ̀ ju tìrẹ̀ lọ ""Awọn wo lo na a, se Kwam 1 ni."
Ó ní kí ìjọba gbé ìgbésẹ̀ tó yẹ ní kíákíá Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: PDP lè má kópa nínú ìdìbò oṣù keje ní Imo 'Kọ́ ọgbà fún ẹran ọ̀sìn rẹ' Akọ̀ròyìn BBC bá ìkọlù Afghanistan lọ Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Aadun Oríṣun àwòrán, @ojogbon_yoruba Aadun jẹ ounjẹ ipanu nilẹ Yoruba.
Tírélà méjì tẹ ìyá àti ọmọ pẹ̀lú èèyàn méjì míì pa l'Ondo, awakọ̀ sá lọ Wọ́n tún ti pa omidan ẹni ọdún 18 míràn l'Akinyele ní ìlú Ibadan 'Nínúu kí a yọ oyún inú rẹ tórí iṣẹ́ abẹ tàbí kóo wà nínú ìrora' Oyenusi ló mú mi wọ ẹgbẹ́ adigunjalè kó tó di pé mo b'Ólúwa pàdé - Kayode Williams Tunde Idiagbon, ọ̀gágun kògbagbẹ̀rẹ́ tó ní ẹ̀ẹ̀kan lóṣù ló yẹ kí ológun máa rẹ́rìín Amaechi ṣalaye ṣiwaju sii pe ni fasiti naa ni wọn yoo ti maa kọ bi wọn yopo ṣe maa ṣe amojuto ọna reluwe ti ileeṣẹ kan lati China n ṣe lọwọ bayii ni Naijiria.
Nígbà tí ó di ọ̀sán, wọ́n kó ogun jáde, bí Benhadadi ọba ati àwọn ọba mejilelọgbọn tí wọ́n wà pẹlu rẹ̀ ti ń mu ọtí àmupara ninu àgọ́ wọn.
Iroyin naa tun fikun pe iyawo ati awọn ọmọ oloogbe Ajimobi si wa pẹlu oku rẹ nilu Eko, ọjọ Satide si ni wọn yoo dijọ maa bọ wa silu Ibadan.
Won ni ọtọ ní nnkán tí àwọn pé Saraki wá ṣé kí o tó ṣadede fi ayẹyẹ àwọn kéde èrò rẹ láti dije ipò Ààrẹ Nàìjíríà.
Ẹ̀yin ọmọ Israẹli, ẹ wí pé,
Jẹ́ kí jìnnìjìnnì bò wọ́n,kí wọ́n sì gba èrè ìtìjú,àní, àwọn tí ń ṣe jàgínní mi.
Igbimo awon minisita lorile-ede Ethiopia ti kede ilu-o-fara ro olosu mefa.
Ènìyàn méjì tún d'olóògbé lánàá, èyí si ti mú iye ènìyàn ti ààrùn Covid-19 ti ré sí òrun alákeji di ẹgbẹ̀run kan àti mẹ́rin.
A si ni ẹ̀rí to daju lori iroyin yii.
Àwọn tí wọ́n bá ṣẹ́kù láti àwọn orílẹ̀-èdè gbogbo tí ó gbógun ti ilẹ̀ Jerusalẹmu yóo máa wá lọdọọdun láti sin Ọba, OLUWA àwọn ọmọ ogun, ní ìlú Jerusalẹmu ati láti ṣe Àjọ̀dún Àgọ́.
Ibi tí ó ti ń fi ìkánjú gbé ọmọ náà sá lọ, ó já ṣubú, ó sì fi bẹ́ẹ̀ yarọ.
Oun ni alaga igbimọ to n ri si ọrọ owo, ileeṣẹ ati idokowo nile aṣofin agba l'Abuja ki o to fi aye silẹ.
Ọrọ naa da bi ere nigba ti abala kini bẹrẹ amọ bi nnkan ti ṣe n lọ ni Norwhich gbena woju Man City ti wọn si da goolu meji bo wọn.
"Coronavirus: ''Ìjọba kò tíì pàṣẹ ìlànà ìtakété-síra-ẹni padà nínú BRT la ò ṣe máa tẹ̀le'' Wọ́n ní kí ọ̀gá àgbà ""Ede Poly"" lọ rọ́kún nílé lórí ẹ̀sùn pé 'ó kan bẹ́ẹ̀dì sí ọ́fíìsì' Ẹ̀yà kòkòrò Covid-19 míràn jáde ní ọgọ́ta agbègbè nílẹ̀ Gẹẹsi, àjọ eletò ìlera ni k'ára ìlú má fòyà Ìjọba ìpínlẹ̀ Kaduna gbé iléèwé tì pa nítorí ọ̀wọ́ kejì àjàkálẹ̀ COVID-19 5."
Àwọn ọmọ Makiri tíí ṣe ẹ̀yà Manase gbógun ti àwọn ará Amori tí ó wà ní Gileadi, wọ́n lé wọn jáde, wọ́n sì gba ilẹ̀ wọn.
Lára àwọn dúkìá tí Ojerinde pàdánù sọwọ àjọ ICPC ni ileesẹ Rédíò Gravity FM tó wà n'ilu Igboho, ilé ẹ̀kọ́ Sapati tó wà lójú ọ̀nà Ajase Ipo, n'ilu Ilorin, ilé epo Soka tó wà n'ilu Ibadan àti ilé ìtura Òkè Afin tó wà níwájú Fáṣítì imọ ẹ̀rọ Ladoke Akintola n'ilu Ogbomoso.
Nítori náà o ṣe pàtàkì láti maa fi ọṣẹ fọwọ́ lóòrèkóòrè, lati ri dáju pe o dáàbò bo ilé rẹ lọ́wọ́ ààrun Corornavirus Gómìnà Ṣèyí Mákindé ó ní ìdí tí òun kò fi leè ti ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́ pa nítorí COVID-19 Ọlọ́run ló kọọ pé àwọn ọmọ mi yóò ṣiṣẹ tíátà, èmi kọ lo kàn-án nípa fún wọn - Ọga Bello Owó gọbọi wá nídìí oko-owo igbó gbingbin, Ìpínlẹ̀ Ondo kò ní pẹ gba àṣẹ láti gbin - Akeredolu Inú mi dùn pé àṣẹ kónílé-ó-gbélé kò bá mi ní Nàìjíríà-Àwọn ọmọ Nàìjíríà lágbáyé Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí kan sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
Ọpọ eeyan lo si ti n bu ẹnu ẹtẹ lu Aarẹ Muhammadu Buhari, nitori pe ko yọjú si ile ẹ̀kọ́ naa, bo tilẹ jẹ pe o wa lẹnu ìsinmi nipinlẹ Katsina.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Oun tí Kunle Afolayan ṣe sí mi, mi ò lè ṣeé sí i' Ọjọgbọn Richard Iyiola Akindele ni okiki rẹ kan loṣu kẹrin ọdun 2018 pe, o n beere ibalopọ igba marun un ọtọọtọ lọwọ akẹkọbinrin kan, Monica Osagie, ki o to lee yii esi idanwo rẹ kuro ninu awọn to fidirẹmi bọ si awọn to pegede.
Eyi to ba tiẹ wa na obi rẹ, o ti jẹ eewọ.
Seyi Makinde lo sọ eyi lasiko to gbalejo Deji ti ilu Akure, to ṣe abẹwo si lati ba kẹdun lori iku iya rẹ to papoda ni ẹni ọdun mọkanlelọgọrin.
Oju ewe mẹtala tan yaan yaan ni lẹta naa ni leyi ti aarẹ ana bẹrẹ pẹlu pe nitori bi nkan se nlọ lorilẹede yii ni oun se kọ lẹta naa jade.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Oúnjẹ ibìkan jẹ́ èèwọ̀ ibòmíì ni ọ̀rọ̀ ọmú ńlá' Ile iwosan fi idi rẹ mulẹ pe, ọkọ mi ni irufẹ aida kan - o kundun ibalopọ ju bo ṣe yẹ lọ.
Bo tilẹ jẹ pe awọn mejeji ni ko si ninu ọmọ ogun wọn to yi ibọn, ilẹ India sọ pe ̣ ọwọ lasan, okuta, irin ati igi ni awọn awọn ọmọ ogun rẹ fi ja ija naa.
Ọjọgbọn Ṣoyinka ni iwa ki awọn agbofinro ma halẹ mọ awọn eeyan nibi ti wọn ba ti n takurọsọ, ku diẹ kaato.
"Ajọ Fecafoot fi si ori ayelujara pe ọjọ kẹsan an, oṣu Kinni si ọjọ Kẹfa, oṣu Keji, ọdun 2021 ni wsn yoo gba idije AFCON 2021""."
Ọlọ́gbọ́n rí ibi, ó farapamọ́,ṣugbọn òpè ń bá tirẹ̀ lọ láìbìkítà,ó sì kó sinu ìyọnu.
Bi awọn eeyan kan ṣe n tapa si agbekalẹ aagọ Fulani taa mọ si Ruga Settlement naa, lawọn miran n kan sara si ijọba lori igbesẹ naa.
Akinyele Killings: Ilé iṣẹ́ ọlọ́pàá Ibadan fẹ́ fi owó kún móríya ẹni tó bá rí Sunday Shodipe
 Ni kete to gbera kuro ni papako Domodededovo ni Moscow ni won ko ti rii mo.
Nípa ṣíṣe bẹ́ẹ̀, ohun tí ẹníkan bá mọ ẹni kejì kò ní mọ̀ ọ́, bẹ́ẹ̀ bẹ́ẹ̀ ọgbọ́n wọn ń parẹ́.
Èyí kì í ṣe ọgbọ́n tí ó wá láti òkè, ọgbọ́n ayé ni, gẹ́gẹ́ bíi ti ẹran-ara, ati ti ẹ̀mí burúkú.
Oríṣun àwòrán, Others Àkọlé àwòrán, Lateef Adedimeji ati Adebimpe Oyebade ti jọ fi aṣọ igbeyawo ya fọto ri.
Eyi ko ṣẹyin bi abadofin naa ṣe kọja ipele kika kẹta ni ile igbimọ aṣofin ipinlẹ naa.
Ó rọrùn kí ọ̀run ati ayé kọjá ju pé kí kínńkínní ninu òfin kí ó má ṣẹ lọ.
Gbogbo ara yín kún fún ọgbẹ́ ati egbò tí ń ṣẹ̀jẹ̀.
Tèmi ni Gileadi, tèmi sì ni Manase;Efuraimu ni àkẹtẹ̀ àṣíborí mi,Juda sì ni ọ̀pá àṣẹ mi.
Àbọ̀dé Libya: Èeyàn 218 padà dé sí ìlú Èkó
 Ó lọ sí ìletò kan tí a mọ ̀ sí Òdo , láti ibẹ ̀ ní ó sì ti padà wọ ìlú pẹ ̀ lú ìfọn àti orin .
títí òun óo fi wá mú yín lọ sí ilẹ̀ mìíràn tí ó dàbí ilẹ̀ yín, ilẹ̀ tí ó kún fún ọkà ati ọtí, tí oúnjẹ ati ọgbà àjàrà ti pọ̀.
Nígbà tí ó di òru a lọ ri àwọn àdá náà mọ́lẹ̀ sí ojú ọ̀nà Òjòlà-ìbínú a sì kọ ojú àwọn àdá náà sí òkè lọ.
Kgotlele ni akọwe agba fun ajọ to n mojuto ọrọ ere bọọlu ni Botswana (BFA).
Sùgbọ́n ìròyìn ayọ ní pé, ní báyìí ní òun àti ẹbí òun láwọ́n ti bọ́ lọ́wọ́ ààrùn Covid-19 lọẹ́yìn ti àwọn gba ìtójú.
Gómìnà Oyetọla tú àṣírí àwọn tó ń kò àrùn Coronavirus wọ Ọ̀ṣun Mo ti fi ẹjọ́ abanilórúkọjẹ́ tó fẹ́ fi àwòrán ìhòhò mi léde sun ìjọba - Salawa Abeni Wo bí wọ́n ṣe ń fín àyíká láti dènà Coronavirus Lásìkò kónílé-ó-gbélé coronavirus yìí, Òbí gbọ́dọ̀ fi àsìkò sílẹ̀ fi tọ́jú àwọn ọmọ wọn Leyin ojo kini nìkan àwọn kan ti bere si ni ké gbajare pé kí a bá àwọn bẹ aare Muhammadu Buhari kí ó tú àwọn sílè nítorí pé ilé tí sú àwọn, wọn ní gbogbo ojo ni àwọn fi sún àti pé ojú ni òun kò rán àwọn ìṣe mo.
Lẹyi ọjọ meji ti iṣẹlẹ yii ṣe ni awọn ọmọ ẹya Tutsis meji ti wọn ti pa obi wọn yọju de lẹnu ọnà mi pe ki n jẹ ki a ti awọn fara pamọ sọdọ mi.
Lọ́nà kínní, inú rẹ̀ bàjẹ́ láti gbọ́ ìyà burúkú tí ọkùnrin náà ń jẹ lójú kan yìí, lọ́nà kejì, inú rẹ̀ dùn nítorí pé ó rí nǹkan tí ó ń wá, o rí ìdí adágún odò, ó mọ ìtumọ̀ oríṣi ẹja mẹ́ta.
Kolawole, eni ti igbakeji re, ogbeni Bode Ayeku soju fun so pe, ipade ohun yoo pese anfaani lopo yanturu fun awon akowe ile-ise ati awon oga-agba.
Ọ̀pá ni wọ́n fí ń lu ẹ̀gúsí;igi lásán ni wọ́n fí ń lu kumini.
Ṣugbọn wọn kò da owó ìtanràn ati owó ẹbọ ẹ̀ṣẹ̀ pọ̀ mọ́ owó fún àtúnṣe ilé OLUWA, nítorí pé àwọn alufaa ni wọ́n ni owó ìtanràn ati ti ẹbọ ẹ̀ṣẹ̀.
Jẹ́ kí tabili oúnjẹ tí wọ́n tẹ́ fún arawọn di ẹ̀bìtì fún wọn;kí àsè ẹbọ wọn sì di tàkúté.
Olorogun o'tega Emerhor OON - Akọ̀wé 3.
 léhìn èyí , ó gba ònà Ìseri dé Ìbesè , títí ó fi dúró ní Ìjèbú-Òde .
Ẹnìkọ̀ọ̀kan wọn á máa pèsè oúnjẹ fún oṣù kọ̀ọ̀kan ninu ọdún kọ̀ọ̀kan.
"LUTH bed space: ""Ìta gbangba ni àwọn aláìsàn kan ń sùn ní LUTH"""
Ṣé o lè so àjàgà mọ́ ọn lọ́rùn ní poro oko,tabi kí ó máa kọ ebè tẹ̀lé ọ?
Baba mi si na mi gan to bẹẹ ti mo ro pe nina yẹn ti pọ ju tori naa mo kọ lẹta silẹ mo si gbe nkan jẹ.
Hagari jáde nílé, ó bá ń rìn káàkiri ninu aginjù Beeriṣeba.
Makinde soro yii lasiko ti won  n se ibura fun omo ile igbimo asofin kẹ́sán án ni
Ọkunrin kan bá yọ sí mi, ó wọ aṣọ dídán.
- Ẹnu ọna ibudo iṣẹlẹ pajawiri bii ẹnu ọna abawọle ile iwosan, ileeṣẹ awọn ẹṣọ oju popo, ẹnu ọna abawọle agọ ọlọpaa, ileeṣẹ panapana ati bẹẹ bẹẹ lọ.
Aaro ọjọ Jimọ ni wọ sare gbe lọ si ile iwosan kan ni ipinlẹ Ogun ti wọ si daa duro nibẹ, sugbọn ki ilẹ ọjọ naa to su, ọgbẹni Xiavier ti dagbere f'aye.
Tí mo ba ti múra bí ọkùnrin fi kọrin, kò sí ọ̀dọ̀ ààrẹ́ tí mi ò lè wọ̀- Erelu, ọmọ Elemure Ogunyemi Kabiesi ni iṣẹ olukọ ni oun ti n ṣe ni eyi ti oun ko le yipada lẹyin ti o di Ọba ati pe pataki ipo Ọba ni lati mu ayipada rere ba awujọ ti eeyan n dari.
Nisinsinyii, múra gírí bí ọkunrin,mo ní ìbéèrè kan láti bí ọ, o óo sì dá mi lóhùn.
Nigba to n jẹ́ri lori ile naa, Mercy Aigbe ni ọ̀kan lara awọn eeyan oun kan, tyo pe orukọ rẹ ni Luminee, lo fi akara oyinbo ti wọn mọ bii ile alaja kan ta oun lọrẹ lasiko ayẹyẹ ọjọ ibi ogoji ọdun oun ti oun se ni ibẹrẹ̀ ọdun tii.
OLUWA Ọlọrun fi awọ ẹranko rán aṣọ fún Adamu ati iyawo rẹ̀, ó sì fi wọ̀ wọ́n.
Ṣugbọn ní ti ẹ̀yin tí ẹ bẹ̀rù mi, oòrùn òdodo yóo tàn si yín pẹlu ìwòsàn mi, ẹ óo máa yan káàkiri bí ọmọ ẹran tí a ṣẹ̀ṣẹ̀ tú sílẹ̀.
Joe Biden ni ki ologun ati Buhari fopin si ipaniyan Oludije fun ipo aarẹ lorilẹede Amerika latinu ẹgbẹ oselu Democrat, Joe Biden, ti koro oju si iwa ipaniyan sawọn oluwọde naa.
Naijiria (Nigeria Governors Forum NGF)ti ni awon yoo satileyin lati ri i pe ile
O ni eto iṣejọba awarawa lorilẹede Amẹrika la ipenija nla kọja, sibẹ o duro ṣinṣin.
O fi ìyẹ́ apá rẹ ṣíji bò wọ́n;o pa wọ́n mọ́ kúrò ninu rìkíṣí àwọn eniyan;o sì pa wọ́n mọ́ lábẹ́ ààbò rẹ,kúrò lọ́wọ́ ẹnu àwọn ẹlẹ́jọ́ wẹ́wẹ́.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fọ́nrán ohùn, Kọ́ ọmọ rẹ lẹ́kọ̀ọ́ ìbálọ̀pọ̀- Ọ̀jọ̀gbọ́n Fagbohungbe O sọrọ yii ninu ifọrọwerọ pẹlu BBC Yoruba nigba ti o n sọ iwoye rẹ lori akẹkọọ ọmọ ọdun mẹrin ti awakọ kan fipa ba tage nile iwe alakọbẹrẹ nipinlẹ Eko.
Kíni ọ̀nà àbáyọ sí àìsàn Lassa Fever?
O ni ọpọ ninu awọn to n bu ẹnu ẹ̀tẹ́ lu ofin naa ni ko ni imọ kikun nipa rẹ ni.
O ṣe apejuwe bi owo irẹsi, ati ẹja, ẹran nkan abiyẹ, ṣe lọ soke si i, lasiko ti ijọba ti ẹnu ibode, nitori pe abẹle nikan lo ti n wa.
O so pe, igbese ohun pon dandan, toripe, Esan je okan gboogi ti o n pese ounje julo ni ipinle Edo, bakan naa, ni o tun wa ni aarin gbungbun eto oro-aje ti ijoba n gbero re.
Eyi si lo mu wọn bẹrẹ si ni yinbọn mọ ọkọ naa.
 O maa n ṣere itage ko to di gbajugbaja lodun 2005.
Apakun/Apapa-Oshodi Bridge Network, Ijọba ibilẹ Mushin / Oshodi / Isolo Atiku náà kéde àtìlẹ́yìn rẹ̀ fún ẹ̀ṣọ́ alábòò Amọtẹkun Obìnrin tó lówó jùlọ ní Africa 'ja orílẹ̀-èdè rẹ̀, Angola lólè' fi kó ọ̀rọ̀ jọ ni Lalong, Tambuwal, Ganduje ni ilé ẹjọ́ gíga jùlọ kéde bíi gómìnà ìpínlẹ̀ wọn Àǹfààní wo ló wà nínú Brexit fún Nàìjíríà àtàwọn orílẹ́-èdè Afíríkà?
Ọmọ wọn, Sunkanmi, pẹlu ti n goke agba lẹnu iṣẹ tiata pẹlu.
Àwọn nǹkan wọnyi jẹ́ àwòjíìjí ohun tí ó ń bọ̀, ṣugbọn nǹkan ti Kristi ni ó ṣe pataki.
Minisita fun oro ile okere Geoffrey Onyema so pe, “ipinnu Aare lati maa se kopa nibi ipade adehun ifenuko ajo ile Afrika lori eto oro-aje alailowo ori ninu naa, ti a mo si African Continental Free Trade AREA (AfCFTA) tori pe, won ni awon ijirorokan ti won gbodo se, ki orile-ede Naijiria to fowosi iwe adehun naa.
Oríṣun àwòrán, Wasiu Ayinde/instagram Wasiu Ayinde ní àwọn èèyàn méjèèjì náà lo ṣe àwárí òun, tí òun fi di òhun ti oun da lónìí.
Nítorí ìrù wọn dàbí ejò, wọ́n ní orí.
Àkọlé àwòrán, Oriṣii papa iṣere lo wa ni Naijiria Ọpọlọpọ igba lawọn ọmọ Naijiria maa n binu pé awọn maalu ati awọn darandaran ti sọ papa iṣere Abuja yii di ile wọn.
Dyson sọ fún BBC pé àwọn ń sise lori awon eya tí ó wà nílè ṣùgbọ́n awon yóò ṣẹ̀ṣẹ̀ bẹ̀rẹ̀ si ni gbedi rẹ láti ilẹ̀ ni.
Ohun tí mò ń sọ ni pé nígbà tí àrólé bá wà ní ọmọde kò sàn ju ẹrú lọ́, bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé òun ni ó ni gbogbo nǹkan tí Baba rẹ̀ fi sílẹ̀.
Oríṣun àwòrán, Others Àkọlé àwòrán, Ile yii, 'Black House' ni ijọ Satani ti bẹrẹ nilu San Fracisco Awọn iwadii ti LaVey ṣe nipa ẹmi okunkun, lo pilẹ bi wọn ṣe n lo ẹgba ọrun dudu ati pupa, to ni aworan ẹyẹ àdán.
Nípa ṣíṣe ayẹwo fáwọn alárùn Coronavirus àti ẹ̀sùn pé àwọn gómìnà ń fi àrùn náà pá owó ni, Akeredolu ni ìjọba àpapọ̀ kò tii fún ẹnikẹ́ni lowo, bẹ́ẹ̀ sì ni banki agbaye lọ fẹ́ yà àwọn lowo, kii sì ṣe ọ̀fẹ́, àwọn yóò san owó náà padà.
Àdàwólulẹ̀ tí a da ilé yìí ti mú kí àwọn ọ̀pọ̀ ènìyàn ó sọ ẹ̀dùn ọkàn-an wọn síta lórí àìbìkítà fún àwọn ilé tí ó jẹ́ ohun ìṣúra Dhaka.
Amọ alẹ ariwo ni alẹ ọjọ igbeyawo wọn, ti okun ifẹ wọn si rẹ ja patapata nigbati oju Ibrahim koro pe iyawo oun ko ni ibale nigba ti ẹjẹ ko jade lara rẹ lẹyin ajọsepọ wọn akọkọ.
Oríṣun àwòrán, OTHERS Àkọlé àwòrán, Ọ̀pọ̀ ènìyàn lo ti sọ ẹmi nù nítorí àìsàn Iba Lassa Ìbẹ̀rù nípa Amotekun ló ń mú káwọn èèyàn kan máa wí ìwíkùwí - Soyinka Ọọ̀ni obìnrin, Lúwòó Gbàgídà rèé, akọni tó ń gun ọkùnrin ní ẹṣin rìn Àkíyèsí nípa àìsàn ‘Coronavirus’ tó ń ṣàkóbá fún bí a ṣe ń mí Àwọn olùgbé Tarkwa Bay ń fọ́ ọ̀pá epo, jí epo ta, la ṣe lé wọn - Iléeṣẹ́ Ológun Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Nigeria's Under-19:Ẹ wo bí Ikọ̀ Cricket Naijiria ṣe mi àgbáyé titi Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 3 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 5 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Lẹ́yìn náà, ìran tí mo rí bá kúrò lójú mi.
Oríṣun àwòrán, Betty Abah/twitter Àkọlé àwòrán, Ẹ̀bùn Adégborúwà ní àwọn kan nínú ìjọba lo faake kori, láti gba ilé náà pẹ̀lú ipá.
Muka, Murphy àti Lasun Ray Eyiwunmi: Oríṣun àwòrán, Muka ray Àwọn ilumọọka osere tíátà mẹta yìí ni wọn jogún isẹ náà lọ́wọ́ àwọn òbí wọn, olóògbé Ray Eyiwunmi àti aya rẹ, ìyá Ray.
Wọ́n kéde ọjọ́ ààwẹ̀ kan, wọ́n pe àwọn eniyan jọ, wọ́n sì fún Naboti ní ipò ọlá láàrin wọn.
Lori ẹsun pe aarẹ ni ẹgbọrọ maalu to fẹ́rẹ̀ẹ́ tó ọ̀ọ́dúnrún niye, aguntan bọlọjọ mẹẹdọgbọn, ẹsin marun-un, ẹran ọsin abiyẹ ati igi to n pawo wọle to fi mọ ile marun-un ni Kaduna, Daura, Kano, Abuja.
Èyí ni ìpín tiwọn láti ọ̀dọ̀ àwọn eniyan Israẹli.
Sibẹ kí á má baà jẹ́ ohun ìkọsẹ̀ fún wọn, lọ sí etí òkun, ju ìwọ̀ sí omi; ẹja kinni tí o bá fà sókè, mú un, ya ẹnu rẹ̀, o óo rí owó fadaka kan níbẹ̀.
Nǹkankan ni wọ́n sọ fún wa, pé kí á ranti àwọn talaka láàrin àwọn tí ó kọlà.
Ọrọ yii mu ki awọn ọmọ ijọ rẹ sa a ni atẹwọ pe baba, ọrọ lẹ sọ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ile ejo kan ti so ni odun to koja pe ijoba ipinle ati ibile ko le se igbeyawo 6) Iru ẹni bayii a wa gbe igbesẹ akin to ba de ori gongo.
Mr Macaroni, Runtown darapọ̀ mọ́ ìfẹ̀hónúhàn ní Eko, Alausa lórí ìpolongo EndSARS Lẹyin ti awọn ọdọ Naijiria kọwọ rin pẹlu gbajugbaja adẹrinpoṣonu, Debo Adebayo ti gbogbo eeyan mọ si Mr Macaroni sun soju titi mojumọ oni lori iwọde EndSARS, o tun ti fi ọrọ sita pe awọn ṣi wa nibẹ.
Wọ́n kígbe pé, “Ẹ wo ẹ̀jẹ̀!
Àwọn ọmọ Reueli ni Nahati, Sera, Ṣama ati Misa.
EFCC ṣalaye wi pe, ọmọ gomina tẹlẹ nipinlẹ Abia, Theodore Orji Kalu, ati ọrẹ rẹ kan ni awọn mu.
Ilẹ̀ Ijipti yóo di ahoro, yóo sì di aṣálẹ̀.
Ilẹ̀ ṣófo ó sì gbẹ,ìtìjú bá òkè Lẹbanoni,gbogbo ewéko orí rẹ̀ sì rẹ̀ dànù.
Mọkandinlaadọta ninu wọn ni wọn ti ri kan si bayii, gẹgẹ bi kọmiṣọna feto ilera nipinlẹ Eko ṣe sọ.
" Amọṣa, Gomina Ajimọbi ni ko si otits ninu ọrọ naa ati pe ko si idi fun oun lati wa iku oloogbe naa tabi gbiyanju ati da apaadi bo ina eto idajọ lori iṣẹlẹ naa.
Ó bá dáhùn pé, “Ẹ wò ó, mo rí ojú ọ̀run tí ó pínyà.
Iwadi fi han wipe Sẹnetọ Ademola Adeleke forukọ silẹ lati ṣe idanwo NECO ti ọduin 2017.
Ìwọ ni o wó Rahabu mọ́lẹ̀ bí òkú ẹran;o fi ọwọ́ agbára rẹ fọ́n àwọn ọ̀tá rẹ ká.
Ìjọba ní ọmọ Naijiria yóò padà sí ní san owó ‘tollgate' Nipasẹ eyii, ile itaja rẹkọọdu ati iwe naa ti sọ ara rẹ di ọkan pataki lara awọn ibudo ti eeyan ti lee ri orin igba atijọ gbọ seti.
Mo fẹ́ràn rẹ, OLUWA, agbára mi.
 nítorí bẹ ́ ẹ ̀ tí a bá ní òrọ ̀ kan w , ó gbọ ́ dọ ̀ di w max tí a túpalẹ ̀ ní síntáàsì gẹ ́ gẹ ́ bí i wp ( for w-phrase ) tàbí w  ( w- double prime ( = bar ) ) ."
Àjọ tó ń se àkóso ètò ìgbóhùnsáfẹ́fẹ́ nílẹ̀ yì, NBC, ti sọ kọ́kọ́rọ́ sẹ́nu ọ̀nà iléesẹ́ ìgbóhùnsáfẹ́fẹ́ Èkìtì .
Bí kò bá jẹ́ pé Ọlọrun aláàbò wọn ti kọ̀ wọ́n sílẹ̀,tí OLUWA sì ti fi wọ́n lé àwọn ọ̀tá wọn lọ́wọ́.
Ní apá kan wọn ni èròja afúni lẹ́jẹ̀ (protein) àti àwọn fitámìn, ẹ̀wẹ̀, ẹ̀wá ní epo kan ti wọ́n ń pè ni Phytohaemagglutinin ti ẹ̀ya ará ènìyàn ko lágbára lorí rẹ̀.
Ọmọ iya rẹ Hajara to ba BBC sọrọ sọ pe ojojumọ lawọn n ba Zainab sọrọ.
ile-ise aare lojo isegun(Tuesday), niluu Abuja.
Ọ̀rọ̀ Yorùbá sọ wi pé “Ṣe bi o ti mọ ki i tẹ́ ”, nitori eyi gbogbo ọmọ Yorùbá ni ilé, ni oko, ẹ ṣe bi ẹ ti mọ, ẹ ma tori odun na ọwọ́ si nkan ti ọwọ́ yin kò tó, ki ẹ ma ba a tẹ́.
Ojilelẹgbẹta ile iwe girama lo wa yika ipinlẹ Ọyọ, ti wọn si ti n jẹ mula owo iranwọ naa eyi to n pese ẹgbẹrun kan naira ni fun akẹkọ kan ni taamu kan.
Mo níláti mọ̀ pé, aájò tèmi kò bá le, n o fi ọwọ́ bàá lára, láti mọ̀ bí ara rẹ̀ bá ti gbóná sí, n ó béèrè bí ìyàwó mi ti ń gbádùn sí, n ó kìí láti fi hàn pé mo mọ iyì rẹ̀, bí òtútù bá ń pa á, n o mú aṣọ mìíràn, n ó dà á bò ó lára, n o béèrè ohun tí o ń fẹ́ jẹ, bí ó bá sì ti sọ fún mi, n ó yára ránṣẹ́ kí wọ́n máa wá a, n kò ní lọ sí òde.
Venerable Emeka Eze to jẹ alufaa ati archdeacon ni ijọ Angilika nipinlẹ Enugu naa ni iwoye oun nipa oṣelu maa n tẹle ohun ti iwe mimọ ba sọ.
Nítorí èyí, ó di baba fún gbogbo àwọn tí ó ní igbagbọ láì kọlà, kí Ọlọrun lè kà wọ́n sí ẹni rere; 
Kí ló dé tí o kò jẹun?
Aare Muhammadu Buhari n se ipade alatilekun mori pelu awon torokan gbongbon ninu eto aabo lowo bayii nile-ise.
O ni bi kaluku ṣe n gba ọrọ mọra yatọ sira wọn.
Nibayii awọn ololufẹ awọn oṣere tiata mejeeji ti n kan sara si igbesẹ naa eleyi ti wọn ni o tọna lati mu alaafia ati irẹpọ jọba laarin ẹgbẹ naa.
Àwọn àdúgbò Ibadan gborúkọ tuntun látẹnu Ajimobi Rashidi Ladọja ṣe ọjọ́ ìbí alárinrin, Ibadan mì tìtì Sanusi Adebisi Idikan rèé, olówó tó ń san owó orí fún gbogbo ọkunrin ilẹ̀ Ibadan Taiwo Akinkunmi, ọmọ Ibadan tó ya àsìá Nàíjíríà Ọrọ yii fọwọ kan Olubadan ilẹ Ibadan, Ọba Saliu Akanmu Adetunji lẹmi debi pe lọjọ Aje, Olubadan lọgun lori iku ọwọwọ awọn ogo ilẹ Ibadan yii.
Lawọn asiko kan ni igba aye rẹ, irinajo rẹ ṣe bi ẹni wọ diẹ nigba ti iroyin jade pe o n lo ogun oloro.
Toyin Abraham kìí bá èmi náà yọ̀, ni kò jẹ́ kí ń gbé e lárugẹ fún ayọ̀ ọmọ - Lizzy Anjorin Àwọn olólùfẹ̀ Toyin Abraham ati Liz Anjorin ti gbé ọ̀rọ̀ wọn rù sórí, ẹ wo òjò òkò ọ̀rọ̀ Gbẹgẹdẹ gbiná!
Ẹkọ keji ni pe ko yẹ ki awọn òṣìṣẹ́ ti ilu ba gbe ara le ja ilu kulẹ gẹgẹ bi baba Shina Rambo ti ṣe.
Wọ́n wuni ju wúrà lọ,àní ju ojúlówó wúrà lọ;wọ́n sì dùn ju oyin,àní, wọ́n dùn ju oyin tí ń kán láti inú afárá lọ.
Ọ̀lẹ a máa jẹ́ kí ilé ẹni wó,ìmẹ́lẹ́ a máa jẹ́ kí ilé ẹni jò.
“O le mu idagbasoke ba awon ohun amayederun to se koko pelu idolowo igba kukuru, ni bayii, oja idokowo n pe awon eniyan fun anfaani idokowo igba pipe”.
Aarẹ Trump ni Paris Agreement yoo gba iṣẹ lọwọ ọpọlọpọ awọn ọmọ ilẹ Amerika.
Nínú ẹ̀kọ́ nípa àwùjọ-ẹ̀dá, a tún máa ń sọ̀rọ̀ nípa ìsòro tó ń kojú ìbágbépọ̀ ẹ̀dá.
Ikede naa waye lẹyin ipade kan ti wọn ba awọn olukọ naa ṣe lọjọ Aje.
Ọgagun Marcos Perez Jimenez nigba naa lọhun fẹ ki iṣẹ akanṣe yii jẹ apẹrẹ orilẹede bi ẹṣin iwaju ti awọn tẹyin n wo sare.
AMAA 2018 Ami eye fun oserbinrin amugbalegbe to dara ju
Baba rẹ jẹ sọja ti o si ṣiṣẹ pẹlu ile iṣẹ ologun orilẹede Naijiria.
Lẹ́yìn tí Dafidi ati Saulu parí ọ̀rọ̀ wọn, ọkàn Jonatani, ọmọ Saulu fà mọ́ Dafidi lọpọlọpọ ó sì fẹ́ràn rẹ̀ gẹ́gẹ́ bí ẹ̀mí ara rẹ̀.
"Amọṣa ni ọjs aiku lawọn ọkunrin kan tun dide pẹlu apola igi lọwọ ati kums ti wọn si n kaakiri awsn opopona ilu Johanesburg tawọn ti orin 'ajoji gbọdọ fi ilẹ wa silẹ pada si ilẹ wọn"" lẹnu wọn, gẹgẹ biiileeṣẹ iroyin abẹle kan, Sowetan Live ṣe kede."
0 13992 Orilẹede Estonia 316 23.
Kayode Williams ọmọ lẹyin Oyenusi, ògbóǹtarìgì adigunjalè tó ń fi àyípadà rẹ̀ ran àwọn ẹlẹ́wọ̀n lọ́wọ́
 Bi o ti le je pe, a bowo fun iko agbaboolu Naijiria, a ko beru won rara.
Ó dàbí kí ó kúkú fá orí rẹ̀.
Láti ìgbà yìí, ẹni marun-un yóo wà ninu ilé kan, àwọn mẹta yóo lòdì sí àwọn meji; àwọn meji yóo lòdì sí àwọn mẹta.
Nigba ti aare n tewogba awon asoju aare orile ede South Sudan ogbeni Ezekiel Gatkuoth nile -aare nilu Abuja lojo Isegun.
Buratai soro ohun di mimo lasiko abewo re si awon osise ati iko omo ogun ti won si wa labe eto eko (Nigerian Army School of Artillery), nilu Kachia, nipinle Kaduna.
Yára tètè lọ kí o pè é kí o wá rí mi, ọọku o, ọmọ mi.
Ojú òpó Twitter lawọn èèyàn kan ti bi ẹnu àtẹ lu Ayobami Agboola to jẹ ọmọ olori oṣiṣẹ ìjọba ìpínlè naa, Amidat Agboola lẹyìn tí ọgbẹni kan, Sulaimon Adesola ni o ṣèlérí láti fi orúkọ oun sara àwọn òṣìṣẹ́ ìjọba ti yoo máa gba owo oṣù lai yọju si ibiṣẹ.
Bakan naa ni iya onikoko kan to n lo amọ lati fi mọ ikoko sọ fun wa pe ko si bo ti wu ko ri, isẹ amọ ko lee parun nitori iwulo ikoko ti wọn n fi amọ mọ si ọpọ eeyan.
Nígbà tí ó di ìrọ̀lẹ́, àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ wá, wọ́n wí fún un pé, “Aṣálẹ̀ nìhín yìí, ilẹ̀ sì ń ṣú lọ.
 wíwáyé àrùn náà lára ẹnití ó ti níi rí jẹ ́ ohun tí ó wọ ́ pọ ̀ .
kò sí ẹni to ni kí o máà wá síbí.
Lẹyin to kawe jade ni ile iwe Kings college to wa ni ilu Eko, o tẹ siwaju ninu ẹkọ rẹ si fasiti Ahmadu Bello ni Zaria, nibi to ti kẹkọ gboye.
Oríṣun àwòrán, Ajimobi Lives on Àkọlé àwòrán, Iroyin ni pe wọn ti sin oku rẹ ni bonkẹlẹ lai jẹ ki awọn oniroyin wọle.
Ti o bá dá ilé lójú wí pé ẹni náà kún ojú oṣuwọn ti kò sí ní àlébù kánkan yálà nípa ìwé ẹrí rẹ tàbí ìlera rẹ, ilé yóò buwọ́lù iyansipo rẹ tí yóò sì ní anfààní láti ṣíṣe pẹlú Ààrẹ.
Apata ni, àwọn ọdaran náà ji igi gẹdu tó to ẹgbẹ̀rún lónà ọgọrun kan náírà to jẹ ti olufisu, bákan náà ni wọ́n ṣe ìdíwọ fún àwọn ọlọpàá mẹ́rìn kan lásiko ti wọ́n fẹ mu wọ́n.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ọmọ Amẹ́ríkà ń kó ìpara bórabóra N90,000 bọ̀ fún títà ní Naijiria Nàìjíríà gba orúkọ burúkú lórí ìgbẹ́ yiyá síta gbángba Iléẹjọ́ fi Ọ̀jọ̀gbọ́n tó bèérè fún ìbálòpọ̀ ní fásitì OAU pamọ́ sọ́gbà ẹ̀wọ̀n Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Ẹlẹsẹ ayo to jẹ ọmọbibi ilẹ Gẹẹsi Harry Kane lo n siwaju ninu awọn ti wọn gba bọọlu sawọn ju ni Russia pẹlu ami ayo mẹfa.
    Ẹnì kẹta ni ọkùnrin kan bbáyìí ti orúkọ rẹ̀ ń jẹ́ Inúlayéwà tí ó jẹ́ ẹni tí ó gbọ́n púpọ̀ tí ó sì jẹ́ Olókìkí ènìyàn.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Akomolede ati Asa: Mọ̀ si nípa àwọn ọ̀nà tí Yorùbá ń gbà ran ara wọn lọ́wọ́ Mango fikun ọrọ rẹ pe iwadii ti bẹrẹ lati mọ ẹkunrẹrẹ ipa ti ikọlu naa ni.
Àwọn ẹgbẹ́ rẹ̀ sọ fún un pé, “Lọ sọ fún wọn pé, ‘Ìka ọwọ́ mi tí ó kéré jù yóo tóbi ju ẹ̀gbẹ́ baba mi lọ.
tesiwaju pe ipinle ohun yoo bẹrẹ si maa san ẹkunwo
Nítorí náà, sọ àsọtẹ́lẹ̀ kí o wí fún wọn pé OLUWA Ọlọrun ní, ‘N óo ṣí ibojì yín; n óo sì gbe yín dìde, ẹ̀yin eniyan mi, n óo mu yín pada sí ilé, ní ilẹ̀ Israẹli.
Yóo sun ọ̀rá ẹran ẹbọ ìmúkúrò ẹ̀ṣẹ̀ lórí pẹpẹ náà.
Fayose ni ọjọ kan naa l'oun yoo lọ yọju si ajọ to n ri si iwa ajẹbanu ati siṣe owo ilu kumọ-kumọ EFCC l'Abuja.
forukọsilẹ fun idibo jẹ-           2,375,568 iye awon ti won yege lati dibo jẹ –                        911,964 iye ibo ti won fagile jẹ –                              45,039iye ibo to yege jẹ –                                                     851,937Iye ibo ti wọn di jẹ –                                                    896,976.
nítorí ọ̀nà ibi ni ẹsẹ̀ wọn máa ń yá sí,wọ́n a sì máa yára láti paniyan.
14 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Oríṣun àwòrán, Reuters Ọkan lara adilemu fun ẹgbẹ agbabọọlu Arsenal, Kieran Tierney ti sọ pe o yẹ kawọn ololufẹ ikọ agbabọọlu naa yẹyẹ wọn gẹgẹ bi wọn ti ṣe lẹyin ti Burnley lu wọn mọle pẹlu ami ayo kan sodo ninu idije Premier League lọjọ Aiku.
- Mike Bamiloye Wọ́n ti búra wọlé fún Akinwunmi Adesina gẹ́gẹ́ bí ààrẹ Banki ilẹ̀ Afrika, AfDB Àwọn ará ìlú Ikarẹ Akoko ń ṣọ̀fọ̀ Ọba Adegbite, Ọwá Ale Ikarẹ tó wàjà Lẹgbẹ ile iwosan Akala ni Ogbomọṣọ lo pada sọ ikoko ọmọ naa nu si ki awọn alaanu to ba a ri i he ti wọn si gbe e lo fun itọju.
Oríṣun àwòrán, @Ooni Ki wa lode ti Ooni Ogunwusi ko fi le ri ọmọ rẹ tuntun lasiko yii?
Gẹgẹ bo se wi, lara awọn gbedede naa ni iwọnyii: Ibiti wọn ba gbe ọkọ naa si lati ni ibalopọ ko gbọdọ j ibudo ijọsin Awọn akọ ati abo to fẹ ni ibalopọ ninu ọkọ naa ni ọjọ ori ọkọọkan wọn gbọdọ le ni ọdun mejidinlogun Adehun to gunmọ gbọdọ ti wa laarin akọ ati abo to fẹ ni ibalopọ saaju lati se bẹẹ Awọn mejeeji to fẹ ni ibalopọ ninu ọk gbọdọ jẹ akọ ati abo.
OLUWA wí fún Mose pé, “Tètè sọ̀kalẹ̀, nítorí pé àwọn eniyan rẹ tí o kó ti ilẹ̀ Ijipti wá ti ba ara wọn jẹ́.
Makinde sọrọ naa nitori rogbodiyan ti wọn fẹ maa da silẹ nigba naa nitori ati yii ijọba pada pẹlu ayipada to de ba ijọba nigba naa.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù MRKH syndrome: 'Ọjọ́ lọjọ́ tí mo mọ̀ pé wọ́n bí mi láì ní ojú ara obìnrin àti ilé ọmọ' 15 Ẹrẹ̀nà 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 2 Èbibi 2020 Oríṣun àwòrán, julian peter Àkọlé àwòrán, Julian sọ pe to ba jẹ pe oun feti si ọrọ awọn eniyan ni, oun i ba ti maa ro pe otitọ ni nkan ti wọn n sọ.
Sedekaya sì ṣọ̀tẹ̀ sí ọba Babiloni.
Ǹjẹ́ ó bójú mu pé kí obinrin gbadura sí Ọlọrun láì bo orí?
Awako to wa ọkọ naa ba iselẹ ohun lọ.
Emmanuel Macron: Maà á kọ́ ìjọ Àgùdà tó jóná láàárín ọdún máàrún ún
Àwọn kan lọ sọ fún Joabu pé, ọba ń sọkún, ó sì ń ṣọ̀fọ̀ Absalomu.
Òsìsẹ́ Custom tó déédé sọ ara rẹ̀ di Ọ̀gá Àgbà CG ní ìdàmú ọpọlọ - Attah Ẹ yé irọ́ pa, mí o fún Super Eagles ní ẹbùn owó kánkan -Sanwo Olu Ṣé o ti gbọ́ ohun ti Ọọni Ifẹ́ àti Soyinka parí ọ̀rọ̀ Yorùbá sí?
ó ní, “Bí ẹ bá fẹ́ kí n sin òkú aya mi kúrò nílẹ̀ nítòótọ́, ẹ gbọ́ tèmi, kí ẹ sì bá mi sọ fún Efuroni ọmọ Sohari, 
Bẹ́ẹ̀ ni OLUWA ṣe pa gbogbo ẹ̀dá alààyè tí ó wà láyé run: gbogbo eniyan, gbogbo ẹranko, gbogbo ohun tí ń rìn káàkiri lórí ilẹ̀ ati ẹyẹ.
Ọgbọ́n yóo mú ọlọ́gbọ́n lágbára ju ọba mẹ́wàá lọ láàrin ìlú.
Ìpínlẹ̀ Eko ya ọ̀nà tuntun fún ọkọ̀ epo Argentina ti kọrí sílé níbi ìdíje ife ẹ̀yẹ àgbáyé Wọn sọ̀rọ̀ náà nínú àtẹ̀jáde kan ti Augustine Akubeze tó je ààrẹ CBCN fi síta, ti wọn bu ẹnu àtẹ́ lu ìtàjẹ̀ sílẹ̀ tó ń wáye.
Gomina ipinle Osun, Rauf Aregbesola ti pe  ipe lati daabo bo iran Yoruba ati asa won, nitori pe awon eniyan ni won n pe ni iran.
orísìrísì oyè ló wà ní ilé lólọkàn ò jọ kan .
SDP ni 128,049 nigba ti ADP ni 49 744, ti ADC 7 681.
Ṣugbọn ṣa, eniyan 13,792 ti ri iwosan, awọn 754 si ti ku.
1–4, Síṣe iṣẹ́-ìsìn akíkanjú kó àwọn ìránṣẹ́ Olúwa yọ; 5–6, Àwọn ìwà bĩ ti Ọlọ́run mú wọn yẹ fún iṣẹ́ ìránṣẹ́; 7, Àwọn ohun ti Ọlọ́run gbọ́dọ̀ jẹ́ lílépa.
Ọjọ́ ìsinmi tí ó lọ́wọ̀ ni ó jẹ́ fun yín, ẹ sì gbọdọ̀ gbààwẹ̀; ìlànà ni èyí jẹ́ fun yín títí lae.
 nítori ìgbàgbọ ̀ wọn nipa orí , kò fẹ ̣ ́ si nínú isẹ ́ ọnà wọn tí a kì í rì àwòrán ori .
''Awọn ọlọpaa meji wa, ti wọn si ni ki n bọ aṣọ mi.
Ní ọjọ́ kan, ẹ̀mí burúkú láti ọ̀dọ̀ Ọlọrun tún bà lé Saulu, bí ó ti jókòó ninu ilé rẹ̀ tí ó mú ọ̀kọ̀ lọ́wọ́, tí Dafidi sì ń lu dùùrù níwájú rẹ̀, 
Africa lati ojo Ẹti , gege bi ajo eleto orile ede naa se sọ.
Ìjìyà tó fa ọgbẹ́ a máa mú ibi kúrò,pàṣán a máa mú kí inú mọ́.
OLUWA ní, “Kéde rẹ̀ ní ilẹ̀ Jakọbu,sì ṣe ìfilọ̀ rẹ̀ ní ilẹ̀ Juda:
Ó mu dígí onídẹ, tí àwọn obinrin tí ń ṣiṣẹ́ ìsìn lẹ́nu ọ̀nà àgọ́ ń lò, ó fi ṣe agbada idẹ kan, ati ìtẹ́lẹ̀ rẹ̀.
 Ọlọpaa le lo ọnakọna, to fi mọ yinyin ibọn mọ afurasi ti ọwọ ba tẹ pe o n dana sun ile onile, ni ẹsẹ, ti iru afurasi bẹ ẹ ba n saalọ.
To si jẹ pe ere kan ti wọn ti nilo ọmọbinrin ti ko sanra, to si jẹ alawọ dudu lo pilẹ ere ṣiṣe fun oun.
Bẹ́ẹ̀ ni ọba Asiria yóo ṣe kó àwọn ará Ijipti ati àwọn ará Kuṣi lẹ́rú, ati ọmọde ati àgbàlagbà wọn, ní ìhòòhò, láì wọ bàtà.
Aarẹ Buhari paṣẹ fun Ọga Agba ọlọpaa lori ọrọ SARS Ọjọ Ẹti ni Aarẹ Muhammadu Buhari sọ pe oun ti paṣẹ fun Ọga Agba ileeṣẹ ọlọpaa Naijiria ni aṣẹ lori igbesẹ ti yoo gbe lori iwọde #ENDSARS to n lọ kaakiri orilẹ-ede Naijiria, lẹyin ti awsn mejeeji ṣe ipade lọjọ Ẹti.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Farms to You: Irú ajílẹ̀ wo ló yẹ fún lílò lásìkò yìí- Aisha Bakna náà ní ọ̀ps àwọn alaisan ibà lassa lo ti wa ni yàrá ìtọjú pàjáwìrì ní àwọn ilé ìwòsàn òlùkọni.
Ó bẹ̀rẹ̀ sí da gbogbo àwọn ẹran ọ̀sìn rẹ̀ tí ó ti kó jọ ní Padani-aramu siwaju, ó ń pada lọ sọ́dọ̀ Isaaki baba rẹ̀ ní ilẹ̀ Kenaani.
Ọgbọ́n àgbà ń bẹ lọ́dọ̀ tiwọn náà.
Lábẹ́ àròkọ, a wo arokọ wọ̀nyí: alapejuwe, ajemọroyin, alalaye, alariiyan, onisiipaya, ajẹmọ́-ìsonísókí-ìwé ati arokọ onileta.
Nígbà tí ilẹ̀ mọ́ n kò ṣe bí ẹni pé mo mọ nǹkan tí ó ṣẹlẹ̀, ìyàwó mi yìí lò sì kọ́ kí mi, ó kúnlẹ̀ ó fi orí balẹ̀ dáadáa, nígbà tí ó sì ń fẹ́ẹ́ fi ẹnu rẹ̀ kò mi lẹ́nu, ẹnu burúkú tí ó ti fi ń ko baba alágbádá lẹ́nu lóru àná, mo gbé ẹnu mi sí ibòmíràn mo wí fún un pé ẹnu ń dùn mí.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Stealing: Ilé-ẹjọ́ ní kí Danladi, awakọ̀ tó jalè gbálẹ̀ kóòtù f'ọ́jọ́ méjì 11 Owewe 2020 Oríṣun àwòrán, others Ileẹjọ majisireeti ẹkun Wuse niluu Abuja ti pàṣẹ fun awakọ kan, Ahmed Danladi to jale pe ko gba ilẹ kootu fun ọjọ meji.
Ó bá dìde, ó lọ sí ọ̀dọ̀ baba rẹ̀.
Èyí jẹ́ oun pàtàkì lára ànfàní tó wa nínú ìṣọ̀kan nínú àwùjọ-ẹ̀dá.
Fún àwọn tí ó pọ̀ ní ilẹ̀ pupọ ati àwọn tí ó kéré ní ilẹ̀ kéékèèké.
Samuel Olaoluwa, Aduragbemi Olasehinde, tó jẹ́ ọmọ gbajúmọ òṣèré Pa James, ti àwọn ènìyàn tún máa n pè ni Bàbá Ajirebi ló ṣe ọjọ́ ìbí ọdún mẹ́tàdilólogun nínú ọ̀sẹ̀ yìí.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Kwara yóò gbàlejò BBC Yoruba Inu ọgba fasiti Ilọrin ni eto naa yoo ti waye ni Ọjọbọ, ọjọ kẹwaa, osu Kinni, ọdun 2019.
Wọ́n fún àwọn ìdílé Manase yòókù ní ilẹ̀ gẹ́gẹ́ bí iye ìdílé wọn: àwọn bíi Abieseri, Heleki, Asirieli, Ṣekemu, Heferi, ati Ṣemida.
ijoba tiwa-n-tiwa ati eto aabo mulẹ.
,won fenuko  pe ,won kọ ẹgbẹrun mẹ́tàdínlọ́gbọ̀n
Coronavirus cases in Africa- Atọ́nà bí nkàn ṣe ń lọ ní Afirika Ọ̀rọ̀ ìfẹ́ ti wọn fi ń lọ̀ mí lágbo àmúlùúdùn ni ìṣòro kan tí mo ní - Lizzy Jay ọmọ Ibadan Ki ni o fa igbesẹ ka maa fi ọmọ ransẹ silu wọn pada lasiko Coronavirus?
Àwọn ati àwọn baba ńlá wọn ṣì tún ń bá mi ṣọ̀tẹ̀ títí di òní olónìí.
Ìtumọ̀ ọ̀rọ̀ náà sápamọ́ fún wọn.
egbe oselu APM ati awon oludije fun ipo oselu lorisirisi.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Zainab Aliyu: Mo sọkún títí, ojé tán lóju mi ni àhámọ Saudi Bakan naa lo sọ pe kileeṣẹ ọlọpaa ko ni dawọ duro lati ri i daju pe aabo to peye wa ni awọn opopona nlanla ni Naijiria.
Ogagun naa wa ro awon eniyan
Amọ o ni, Wasiu Ayinde ko dahun, ti oun si sọkalẹ loju agbo naa.
Wo awọn orilẹ-ede ti a fẹ darukọ yii fi aaye gba wiwọ ilẹ wọn lai si idaamu tabi dandan iwe aṣẹ.
Ẹẹdẹgbaarin (7,000) eniyan ni ó kú nígbà tí ilẹ̀ náà mì.
Jẹ́ kí àwọn eniyan burúkú ṣubú sinu àwọ̀n ara wọn,kí èmi sì lọ láìfarapa.
Awọn ohun to yẹ ko mọ nipa Ẹfunroye Tinubu: Ọdun 1810 ni wọn bi Ẹfunpọroye Ọsuntinubu, eyi ti wọn ge kuru si Ẹfunroye Tinubu, ni igbo Ojokodo nilẹ Ẹgba.
“Lẹ́yìn èyí, kí alufaa kọ ègún yìí sinu ìwé, kí ó sì fọ̀ ọ́ sinu abọ́ omi kíkorò náà.
Aṣofin Ọbasa sọrọ iṣiti yii ninu ọrọ ikini rẹ fun
Toyin funra rẹ lo wa kede pe oun ti pa orukọ da kuro ni Toyin Aimakhu bayii ohun ti di Toyin Abraham.
Dokita Obinnaadigo sọ pe ko si ẹri tabi alaye ninu iṣegun oyinbo to ṣalaye idi ti awọn obinrin kan fi ma n ni irora lasiko nkan oṣu, tabi idi ti awọn miran kii fi i ni irora.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Nigeria new ministers: Obìnrin méje pèrè nínú ìgbìmọ̀ ìṣèjọba kì í ṣe ìlérí tí Buhari ṣe ní 2015 21 Ògún 2019 Oríṣun àwòrán, @BashirAhmaad Aarẹ Buhari ti bura fun awọn minisita ti yoo baa ṣiṣẹ bayii lẹyin ti o ti bura fun wọn ti o si ti fun ọkọọkan wọn ni ojuṣe rẹ.
Ọdun marun un ni ijọba yoo fi ṣe akanṣe iṣẹ naan Kikọ ile ẹkọ fasiti ati ile iwosan sawọn agbegbe ti ko ni.
Nígbà tì ó ṣe, ọkùnrin olówó kan pinnu láti ran tálákà yìí lọ́wọ́.
Ṣẹ rántí pásítọ̀ South Afrika tó ní òun jí òkú díde?
Eyi sele nigba ti baba isalẹ rẹ, Asiwaju Bola Ahmed Tinubu na ọwọ Babajide Sanwo-Olu sọke gẹgẹ bi oludije sipo gomina ni ipinlẹ Eko lẹyin to ni ki Ambode lo rọọkun nilẹ lẹyin ọdun mẹrin to lo nipo.
Loni ni yoo bẹrẹ si ni ṣe iṣẹ lati ile rẹ, gẹgẹ bi ilana yiya ara ẹni sọtọ ti ileeṣẹ NCDC gbe kalẹ.
Koda, ile ẹjọ giga kan nipinlẹ Rivers fi ofin de Giadom pe ko gbọdọ pe ara rẹ ni ọmọ ẹgbẹ tabi oloye ninu ẹgbẹ APC mọ.
Àwọn obinrin bá tún dáhùn pé, “Nígbà tí à ń sun turari sí ọbabinrin ojú ọ̀run, tí a sì ń rú ẹbọ ohun mímu sí i, ṣé àwọn ọkọ wa ni kò mọ̀ pé à ń ṣe àkàrà dídùn, tí à ń ṣe bí ère rẹ̀ fún un ni, ati pé à ń ta ohun mímu sílẹ̀ fún un?
Oríṣun àwòrán, @PastorEAAdeboye Amọ ọpọ ọmọ Naijiria ko jẹ ki ikede naa balẹ loju opo Twitter, bi wọn ṣe n ka ikede naa, ni wọn n fesi loniruuru le lori.
Awọn ololufẹ rẹ atawọn akẹgbẹ rẹ ti n woye wipe ki lo ṣẹlẹ gangan toripe ọwọ ti wọn n fa diriipu si nile iwosan ni wọn ri wọn ko ri oju rẹ.
Kid boxer: Ọmọọba 'The Buzz' Larbie rèé, ọmọ ọdún méje tó ń fi ẹ̀ṣẹ́ dá bírà tó ju ọjọ́ orí rẹ̀
Àwọn agbébọn fọ́ ọgbà ẹ̀wọ̀n ni Minna Ẹlẹ́wọ̀n 68 kẹ́kọ̀gboyè iṣẹ́ ọwọ́ Ohun tí wọ́n fi ń ṣe báàgì, bàtà ni wọ́n ń tà bíi ‘pọ̀ǹmọ́’— NAFDAC Lọjọ Abamẹta ni wọn ta aṣọ otutu yii ni New York ni $334, 000 ni eyi to jẹ N121.
Ati ẹni tí ó fi ọkà rúbọ,ati ẹni tí ó fi ẹ̀jẹ̀ ẹlẹ́dẹ̀ rúbọ,bákan náà ni wọ́n rí.
Ohun ọ̀gbìn pupọ ni ẹ gbìn, ṣugbọn díẹ̀ ni ẹ kórè; ẹ jẹun, ṣugbọn ẹ kò yó; ẹ mu, ṣugbọn kò tẹ yín lọ́rùn; ẹ wọṣọ, sibẹ òtútù tún ń mu yín.
Nígbà tí ó di ọjọ́ kan, àlejò dé bá ọkunrin olówó ninu ilé rẹ̀.
Iku akẹẹgbẹ wọn naa bu epo bẹtiroolu si iṣẹlẹ yii, odidi ọsẹ kan gbako si lawọn akẹkọọ yii fi n wọ sokoto kan naa pẹlu awọn ọlọpaa ati ologun.
Ifẹhonuhan Lẹkki Salma ọmọ Tanzania lo n fi igba dọla ranṣẹ si ẹbi rẹ ni oṣooṣu ni eyi ti dọla mẹrinla n bọ sọwọ awọn banki ati ile iṣẹ ifiweranṣẹ ati bẹẹ bẹẹ lọ.
Eyi si ti mu ki awọn kan maa sọ pe boya o fẹ fi ẹgbẹ oṣelu rẹ, PDP, silẹ lati darapọ mọ APC.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Obasanjo àti Gani Adams tẹ́ mi pẹ̀lú bí wọn ṣe tahùn síra wọn - Adebanjo Ọ̀pọ̀ nkan tó n ṣẹlẹ̀ kò jẹ́ kí n gbàgbọ́ pé Naijiria wà ní abẹ́ ìdarí ẹnikẹ́ni - Wole Soyinka Ọmọ ẹgbẹ́ òkùnkùn ṣoro ní Ijebu Ode, ọ̀pọ̀ ẹ̀mí sọnù Àlàyé rèé lórí ìdí tí mo fi lọ sílé Tinubu - Rashidi Ladoja ‘Sim Card’ títà àti ìforúkọsílẹ̀ rẹ̀ dèèwọ̀ ní Nàíjíríà - NCC Ààrẹ Akufo-Addo la Mahama mọ́lẹ̀ wọlé ìbò ààrẹ Ghana fún sáà kejì Ẹ̀yin tí ẹ máa ń bú àwon tó sanra ni ẹ ń jẹ́ kí wọ́n ronú pa ara wọn - Eniola Badmus Ṣé lóòtọ́ ni tírélà ti gba ààrín Ronke Odusanya àti bàbá ọmọ rẹ̀, Jago?
Ó fún Ṣafani ní ìwé náà, ó sì kà á.
Mo fẹ́ kí ẹ mọ̀ dájúdájú pé, nígbà tí ó bá rí i, inú rẹ̀ yóo dùn sí i ju àwọn mọkandinlọgọrun-un tí kò sọnù lọ.
Ṣé kò ti lo àwa náà rí?
Iṣẹ iwadii ọhun fidi rẹ mulẹ pe, ọpọ iru igbeyawo bẹẹ ni o ṣeeṣe ki wọn bi ọmọ to ni ipenija ara.
Oríṣun àwòrán, @PoliceNG Bi o tilẹ jẹ wi pe ileeṣẹ ọlọpaa ni ko si ohun to jọ bẹẹ, amọṣa wọn ni arabinrin naa ti wa ni ọdọ ọlọpaa.
 “bayii ti NEHAWU ti ko erongba ijoba ti yoo tun mu ki opolopo padanu ise oojo won ni o je ki a soo sit ape, a ti setan lati gbogun ti ohunkohun ti yoo mu ibanuje aisi ise baa won eniyan.
Mo beere lọwọ rẹ pe ki lo wa ṣe ninu yaara mi, esi to fun mi ni pe ṣe ọmọde ni mi ni.
Loṣu kẹwaa ni ile ẹjọ giga ijọba apapọ paṣẹ pe ko jọwọ ile rẹ meji to wa lagbagbe Ikoyi niluu Eko.
Ọjọ April Fool ni ọdun 1989 ni ile isẹ iroyin BBC gbe e jade loju aworan lasiko ti wọn n ka iroyin ere idaraya, ti awọn osisẹ akọrọyin si bẹrẹ si ni ja ninu aworan naa, amọ irọ lasan pẹlu itanjẹ ni.
Olomidé, ẹni ọmọ ọdun méjìlélọ́gọ́ta ni wọn pàṣẹ fún pé, kó sàn ẹgbẹ̀rún márùn Euro gẹgẹ bii owó ìtanran fún oníjo rẹ̀ nígbà kan.
Ori kó ààrẹ Zimbabwe yọ lọ́wọ́ àdó olóró Zimbabwe yóò dìbò l'ọgbọn ọjọ́ oṣù keje Zimbabwe fẹ́ darapọ̀ mọ́ Àjọ Commonwealth Ni kete ti iṣẹlẹ naa waye ni wọn fi olori ile iṣẹ olopa ti Addis Ababa si atimọle pe ko ṣe iṣẹ rẹ to.
9 2021576 Orilẹede Argentina 45125 101.
Oríṣìíríṣìí ẹ̀yà ni yóo máa gbé Aṣidodu; ìgbéraga Filistia yóo sì dópin.
"Ìdí tí ikọ̀ Àmọ̀tẹ́kùn àti Fulani fi wọ̀yá ìjà nípìnlẹ̀ Oyo Ọkọ̀ bààlú tó gbéro àádọ́ta pòórá lẹyìn tó gbéra láti Jakarta Sójà àti awakọ̀ fìjà pẹ́ẹ́ta nítorí ọgọ́rùn náírà, ọ̀pọ̀ ẹ̀mí sòfò ""Ọjọ́ méjì péré ni Orisabunmi lò níléèwòsàn kó tó jáde láyé"" Ni apapọ awọn to ti ni aarun naa, ajọ naa ni wọn jẹ 99,063."
Oríṣun àwòrán, WATER AID/MACILAU Àkọlé àwòrán, Ile alamọ t'ojo se ijamba fun Oríṣun àwòrán, WATER AID/MACILAU Àkọlé àwòrán, Aworan agba ilu kan ti Macilau ya Oríṣun àwòrán, WATER AID/MACILAU Àkọlé àwòrán, Elisa Piassone ati Zaida nrin lọ loju ọna to wa ni aarin Mmele ati Kimar nibi ti wọn ngbe agbado lilọ lọ Ajọ alaanu to npese iranwọ omi (Water Aid) ati Mario Macilau ni wọn ni awọn aworan wọnyii.
Nígbà tó ṣàlàyé ipò tí irẹsi tí ìjọba àpapọ̀ pín fun ìpínlẹ̀ Ondo wa, gomina ní ọrọ oselu kò sì níbi ọrọ Irẹsi náà rara.
" Oríṣun àwòrán, Others Alaafin tẹsiwaju pe ni gbogbo ọna, ohun amuyangan lawọn Ekiti jẹ fun ilẹ Yoruba, paapa lẹka eto ẹkọ, ko si fẹẹ si agboole kan ti wọn ko ti ni ẹni to kawe de ipo Ọjọgbọn.
Lasiko taa n sọ yi o le ni ida marun le laadọta oludibo ti wọn fi ero han pe awọn n ṣe tiẹ ninu akojọ 'poll' ti ileeṣẹ Ipsos gbe jade.
O ni ikọ ọlọpaa, awọn ọmọ ogun Naijiria ati ajọ eleto aabo NSCDC ti wa ninu igbo lọwọlọwọ bayii ni ibi ti awọn ti n wa awọn meje to ku ninu ọkọ naa.
Adamu ni oun ti fikun awọn ọlọpaa to n sewadii iṣẹlẹ naa lati ri wi pe wọn tete mu awọn to wu iwa ika naa ni kiakia.
Oṣu to kọja ni wọn kọkọ ji awọn oṣiṣẹ naa ko.
Àkọlé àwòrán, Awọn orilẹede kan nilẹ Afrika ti gbe iranlọwọ didie fun obinrin to n ni idojukọ yii Ni Zimbabwe, awọn agbalagba mọkanlelogun ati ọmọde meje lo n gbe ile kan ti ileeṣẹ ti wọn n pe ni Roots One Stop Shelter"" gbe kalẹ."
Gileadi yìí wà ní ilẹ̀ àwọn ará Amoni.
Àmọ̀tẹ́kùn yóo ba dè wọ́n ní àwọn ìlú wọn,tí ẹnikẹ́ni bá jáde ní ìlú,yóo fà á ya pẹ́rẹpẹ̀rẹ.
Jolly Nyame di èrò ẹwọn f'ọdun mẹ́rìnlá Ọwọ́ ìjọba tún tẹ gómìnà míì fún ìgbẹ́jọ́ Só mọ àwọn gómìnà tó ti jẹ́jọ́ lórí àjẹbánu ní Nàìjíríà?
Awọn aarẹ agbaye n ki Johnson ku oriire Ẹwẹ, awọn olori orilẹede kaakiri agbaye naa ti n sọrọ lori wiwọle Johnson ati ẹgbẹ oṣelu Conservatives ninu idibo ọjọ Ẹti.
Jesu dá wọn lóhùn pé, “Ẹ̀kọ́ tèmi kì í ṣe ti ara mi, ti ẹni tí ó rán mi níṣẹ́ ni.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ìdí rèé ti Nàìjíríà fí gbé inú òkùnkùn Ṣé lóòtọ́ ni àdó olóró bú níléeṣẹ́ ìjọba South Africa tó wà nílùú Abuja?
OLUWA yóo ṣíji bò ọ́ ní apá ọ̀tún rẹ.
Lati igba yii wa ni awọn Ẹgba ko ti fi isakọlẹ ransẹ mọ si Ọlọyọ, ti wọn si gba idande lọwọ iwa imunisin Ọlọyọ.
Crystal Chiagbu: Wọ́n sọ fún wa nígbà tó pé ọjọ́ mẹ́fà pé a máa gé ẹsẹ̀ rẹ̀
O ni ọga ọlọpaa DPO gbọdọ san owo gba maa binu fun Adeniyi nitori ẹjọ to pe e ko l'ẹsẹ nlẹ.
Ẹnikẹ́ni kò rí Ọlọrun rí, bí a bá fẹ́ràn ọmọnikeji wa, Ọlọrun ń gbé inú wa, ìfẹ́ rẹ̀ sì ti di pípé ninu wa.
Kí àwa náà lè dàbí àwọn orílẹ̀-èdè yòókù, kí ọba wa lè máa ṣe àkóso wa, kí ó máa ṣiwaju wa lójú ogun, kí ó sì máa jà fún wa.
Àkọlé àwòrán, Oloye Olusọla Saraki kọ fun ra rẹ, eleyi ti wọn maa n fi n ṣe iranwọ fun awọn eeyan ti ko ri ọwọ họri.
Wọ́n ti kọ OLUWA sílẹ̀,wọn kò náání Ẹni Mímọ́ Israẹliwọ́n sì ti kẹ̀yìn sí i.
Àwọn tí wọ́n wà pẹlu rẹ̀ níbẹ̀ ni Eleasari, ọmọ Finehasi, pẹlu àwọn ọmọ Lefi, Josabadi, ọmọ Jeṣua, ati Noadaya, ọmọ Binui.
agbegbe  Gajigana, ti won si se Iko Boko
Egúngún/Eégún ma ńgbé ọ̀pá tàbi ẹgba lati na ẹni ti ó bá hu iwà burúkú ni àwùjọ.
oludari iko omo ogun ofurufu naa ti o padanu emi re lasiko igbaradi fun ayeye
“Bí ó bá jẹ́ pé aguntan tabi ewúrẹ́ ni yóo mú láti inú agbo ẹran rẹ̀ láti fi rú ẹbọ alaafia sí OLUWA, kì báà jẹ́ akọ tabi abo ẹran, ó gbọdọ̀ jẹ́ èyí tí kò ní àbààwọ́n.
Losu keji ọdun yii ni Hailemariam Desalegn s'adede fipo silẹ gẹgẹ bi olotu ijọba.
Gbogbo alaye ti akoroyin wa se pe ki won jọwọ ẹrọ ibanisọrọ to fi ya aworan ibudo naa fun ohun ko wo eti awọn iko naa.
Kò sí àṣà tó faramọ́ fífi èmí ènìyàn ṣe ìrúbọ - Olúwó Ajínigbé ń bèèrè fún epo, iṣu àti ọ̀tí Schinap gẹ́gẹ́ bí owó ìtanràn Ogbeni Attah ni iṣẹ akanṣẹ lori eto aabo ti wọn pe ni Ex-Swift Response ni o n lọ lọwọ ni agbegbe naa.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Onímọ̀: Bí òbí bá ń mú sìgá, ọmọ rẹ̀ leè sàìsàn ọ̀nà ọ̀fun lọ́jọ́ iwájú 19 Ògún 2018 Oríṣun àwòrán, Getty Images Agbalagba ti ki i mu siga n bẹ ninu ewu lati ku iku ojiji nitori aisan ọna ọfun, ti iru ẹni bẹ ba dagba lọdọ obi to n mu siga.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Obasanjọ pàrọọwà sí Makinde: yàgò fún òṣèlú sọ ọ́ sápò 14 Ẹrẹ̀nà 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 15 Ẹrẹ̀nà 2019 Oríṣun àwòrán, Kehinde Akinyemi Àkọlé àwòrán, Makinde ni o jaweolubori idibo Gomina Ipin Oyo to waye laipe yi Aarẹ ana lorileede Naijiria oloye Olusegun Obasanjo ti parọwa si Seyi Makinde pe ki o yago fun oṣelu sọ sapo.
Ṣugbọn nígbà tí àwọn iranṣẹ Isaaki gbẹ́ kànga kan ní àfonífojì náà tí wọ́n sì kan omi, 
Kí wọ́n pàgọ́ tiwọn sí ìhà àríwá Àgọ́ Àjọ.
 Ó ní bodè ilẹ ̀ mọ ́ papua new guinea , east timor , àti malaysia .
Mo rò pé mo ti sọ fún ọ ní ijọ́sí bí ó ti jẹ́ pé mo ti pinnu láti ìgbà èwe mi wá pé n kò ní fẹ́ ẹnikẹ́ni ṣùgban wí pe n o dúró ní tèmi láì ni ọkọ ni, ṣùgbọ́n nígbà tí mo wo aàpọn gbogbo tí o ti ń ṣe lórí mi láti ọjọ́ tí a ti jọ ń bọ̀ yìí, mo rii pé kò ní dára bí mo bá kọ̀ jalẹ̀, nítorí kò yẹ kí nǹkan kan wà tí mo lè fi dù ọ́.
Àwọn oníṣẹ́ lọ jákèjádò Israẹli ati Juda, pẹlu ìwé láti ọ̀dọ̀ ọba ati àwọn ìjòyè rẹ̀, gẹ́gẹ́ bí àṣẹ ọba.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Eid-el Kabir: Buhari rọ àwọn mùsùlùmí láti yàgò fún ìwà ipá nínú ìkíni ọdún 11 Ògún 2019 Oríṣun àwòrán, Twitter/Presidency Nigeria Àkọlé àwòrán, Ọdun Ileya Ẹ yago fun iwa ipa!
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Henry Fajemirokun: Olókoòwò yíká àgbáyé tó bẹ̀rẹ̀ ètò okoòwò lábẹ́ Ecowas 9 Agẹmo 2020 Oríṣun àwòrán, Funeral Programme of Fajemirokun Bi ẹ ko ba mọ erin, se ẹ ko gbọ ohun erin ni, bi ẹ ko ba si mọ ọsa, se ẹ ko jiyọ lọbẹ, bi ẹ ko ba mọ Henry Oloyede Fajemirokun, ẹ sa mọ awo orin kan.
Sex: Aṣà tó wọ́pọ̀ fún ìgbádùn ìbálopọ̀ lágbáyé
Ọkọ mi kò le f'ipá bá ẹnikẹ́ni lò pọ̀ láíláí - Modele Fatoyinbo Ọlọ́pàá ìpínlẹ̀ kọ́ ní ojútùú ìṣòro ìjínigbé ilẹ̀ Yoruba - Onímọ̀ ọ̀rọ̀ ààbò 'A máa ń fí oògùn olóró 'ginger'ká tó ka ẹsẹ bíbélì ni ṣọ́ọ̀ṣì' Orin kíkọ kò dí ìwé mi lọ́wọ́ rárá -Hameen School Boy Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí kan sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
Ọjọ kẹtadinlọgbọn oṣu keje ọdun 2020 yii ni Obesere gbe awo orin ọhun jade.
Arabinrin Oluwatoye tun rọ awọn onile iṣẹ igbohun safẹfẹ lati maa fi aye ilanilọyẹ silẹ lori awọn eto ti wọn n ṣe oye tun bọ le ye awọn ara il sii lori awọn ewu to rọ mọ ifipabanilopọ ati iṣekupani lawujọ wa.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Àwọn ìgba mẹ́rin t'áwọn èèkàn tí dùbúlẹ̀ àìsàn lásìkò tí wọ́n ń jẹ́jọ́ níwájú adájọ́ wákàtí 7 sẹ́yìn Oríṣun àwòrán, other Ọga agba ile isẹ to n risi owo awọn osisẹfẹyinti tẹlẹri, Abdurasheed Maina, ti darapọ mọ awọn eeyan to daku nile ẹjọ lẹyin ti wọn fi ẹsun ikowojẹ kan wọn.
Ẹni to bori: Namibia Namibia Orilẹede Namibia ni wọn lero pe iwa ajẹbanu ti kere julọ lẹka isẹ ọba laarin awọn orilẹede to n dije fun ife ẹyẹ il Afirika, AFCON, to si n lewaju orilẹede Senegal.
Ọga agba ileeṣẹ to n dari ọrọ to ni ṣe pẹlu sisẹ ipolowo ọja nitagbangba, Bolaji Sanusi lo sọ ọrọ yi ninu atejade kan .
Opọlọpọ oṣere Nollywood Naijiria lo kopa ninu Chief Daddy.
”Romelu Lukaku ti o je eni ti o gba boolu sagbon julo fun iko Manchester United ni saa yii, ko lanfaani lati bere ifesewonse naa lataari ifarapa ranpe ti o ni.
Àwọn àjèjì ń wólẹ̀ níwájú mi,ẹsẹ̀kẹsẹ̀ tí wọ́n bá ti gbúròó mi, ni wọ́n ń mú àṣẹ mi ṣẹ.
O le ni ibudo idibo ẹgbẹrun mejidinlogoji ti eto idibo naa ti waye ni ẹkun mẹrindinlogun kaakiri orilẹ-ed ghana.
Ni ọjọ iṣẹgun ni wọn gba aba naa wọle lati ṣe atunṣe abala ofin orilẹede Naijiria ti ọdun 2010, CP F7 to ni ṣe pẹlu ile iṣẹ to n ri si pinpin ibadọgba ẹtọ latọdọ ijọba.
“Ẹ dìde nisinsinyii kí ẹ sì kọjá sí òdìkejì odò Seredi.
Mose bá gòkè tọ Ọlọrun lọ.
Ènìyàn 653 míràn tún kún iye àwọn tó ní COVID-19 ní Nàìjíríà Wo àwọn òṣìṣẹ́ kólẹ̀-kódọ̀tí tó ń fi ẹ̀mí wọn wéwu kí Abuja leè mọ́ tónítóní Wo àwọn nkan tó yẹ́ kí o mọ̀ nípa 'Awawa Boys', ọ̀kan lára ẹgbẹ́ òkùnkùn tó n dá Eko rú Ṣé Akpabio ṣetán láti dárúkọ àwọn Aṣòfin tó gba iṣẹ́ àkànṣe lọ́wọ́ NDDC?
Asoju naa tun so pe ile-ise won to wa lorile ede yii n ba ajo to n ri si eto oro aje ati okoowo fowosowopo lati tun lee mu idagbasoke ba eto oro aje orile ede mejeeji.
méjì ṣe ngba ẹ̀gbẹ́ arawọn kọjá.
nítorí náà, ìwọ ni óo lọ sibẹ ní ọjọ́ ààwẹ̀ láti ka ọ̀rọ̀ tí o gbọ́ ní ẹnu mi; tí o sì kọ sí inú ìwé kíká, sí etí gbogbo àwọn ará Juda tí wọ́n wá láti ìlú wọn.
Ile-ise ologun ohun so pe, ohun se ayewo oro ti ogagun teleri naa so gege bi eyi ti o ku die kaa to lasiko ti orile-ede Naijiria wa nipo elege, ti ile-ise ologun ohun n gbe igbese lati ko awon omo-ogun kuro ni ekun ariwa orile-ede Naijiria.
Ile-igbimo asofin ti bowolu bilionu mẹ́tàlélógójì owo naira fun awon osise ati ajo alaabo ti yoo kopa ninu eto idibo gbo-gbo-gbo o to n bo lọdun 2019 Fifty three billion naira (=N=53b).
Iroyin sọ pe awọn kan n ni ibalopọ tipatipa pẹlu awọn ọmọde to wa nibẹ, bakan naa ni wọn n fiya jẹ wọn lojoojumọ.
EndSARS: Àwọn ayédèrú ìròyìn tó gbà'gboro kan lásìkò ìwọ́de #EndSARS
''Ko ti mò ipò tí akoto owó ijoba ipinle wa, bawo lo ti se fe san owo nigba ti ko ti mo awọn gbese to wa ni ile ati iye owo ti o''n wole fun ijoba ipinle ohun?
ICC ti wa ni abajade iwadii oun yoo di mimọ fun gbogbo agbaye lati mọ ooto ọrọ naa.
O ni awọn n ṣiṣẹ papọ pẹlu awọn aṣọbode ati ọmọ ogun ori omi lati tubọ maa ṣe ayẹwo ni kikun lori awọn to n wọle si Naijiria bayii.
waye ni awon ago idibo ogoji to wa ni ijoba ibile, ipinle naa.
com Àkọlé àwòrán, Ọmọ orilẹede Ethiopia lo se ipo kini labala awọn obirin Obirin akọkọ to gbegba oroke ninu ididje ọun ni Herpha Guta lati orilẹede Ethiopia.
Kwara Kidnap: Ọlọ́pàá láwọn yóò wá àwọn ọmọ ilẹ̀ Turkey mẹ́rin tí wọ́n jígbé rí láàyè
Ṣiṣaki bá gbógun ti Jerusalẹmu, ó kó gbogbo ìṣúra ilé OLUWA lọ, ati ti ààfin ọba patapata, ati apata wúrà tí Solomoni ṣe.
‘Olùkọ́ fipá bá akẹ́ẹ̀kọ́ girama lòpò nítorí máàkì’ Sẹ́nétọ̀ Omo-Agege, tó gbẹ́ ọ̀pá àṣẹ ile lọ́jọ́sí, 'jẹ gbèsè' nítorí àti di Sẹ́nétọ̀ lẹ́ẹ̀kejì Tinubu kìlọ̀ fún Buhari lórí ohun tó leè ṣàkóbá fún sáà kejì rẹ̀ Ajọ naa wa pa se pe Onnoghen gbọdọ wa ro ti ẹnu rẹ lori ẹsun irọ pipa lori ohun ini rẹ.
Lọdun 1993 ni Ibrahim Badamosi Babangida wọgile idibo gbogboogbo ọhun to bi isami ayajọ iṣẹjọba awa ara wa ni Naijiria.
Aare orile ede Naijiria Muhammadu Buhari ti ba awon gomina APC ti won jawe olubori lati dije labe asia egbe All Progressives Congress, APC se ipade po niluu Abuja.
“Ó dára, mo gbọ́, ẹ wá kọ́ mi,ẹ ṣàlàyé ẹ̀ṣẹ̀ tí mo ṣẹ̀ fún mi;n óo sì dákẹ́ n óo tẹ́tí sílẹ̀.
 Ọ ̀ pọ ̀ lọpọ ̀ irú oko ẹ ̀ yìn odi ìlú báyìí lo ti di ìlú fún wọn .
Ọdun yi tọpọ mọ si ọdun Ileya tabi Sallah jẹ ọdun kan pataki fawọn Musulumi Naijiria ati awọn akẹgbẹ wọn jakejado agbaye.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù School resumption in Nigeria: Ibi ọ̀rọ̀ dé dúró rèé lórí ṣíṣí àwọn ilé ìwé padà ní Naijira àti nílẹ̀ Afrika 29 Òkùdu 2020 Oríṣun àwòrán, AFP Àkọlé àwòrán, Ṣaaju ni ipinlẹ Cross Rivers ti pinnu lati ṣi awọn ile iwe rẹ Lẹyin oṣu diẹ ti igbele Coronavirus bẹrẹ kaakiri agbaye, awọn ile iwe alakọbẹrẹ ati girama ni Tanzania ti pada bẹrẹ lọjọ Aje, ọjọ kọkandinlọgbọn, oṣu kẹfa, ọdun 2020.
( what are you doing sneaking around out there ?
 Akobundu tesiwaju pe lati lee ni eto idibo to gbounje fẹgbẹ –gbawo bọ, gbogbo awon ti oro kan ,awon agbofinro, awon eso alaabo, oloselu ati awon oludibo gbodo fowosowopo lati  pese eto idibo to ni alaafia.
Àwọn ọba ayé kò gbàgbọ́,bẹ́ẹ̀ ni gbogbo aráyé kò gbà pé ó lè ṣẹlẹ̀,pé ọ̀tá lè wọ ẹnubodè Jerusalẹmu.
ati fún àwọn ọ̀mọ̀lé, ati àwọn agbẹ́kùúta.
DPO ọlọ́pàá ju télọ̀ sátìmọ́lé, gbé e lọ sílé ẹjọ́ n'Ibadan torí ''ó ba aṣọ rẹ̀ jẹ́'' Ẹ wo ẹyẹ ayékòótọ́ tó kó olówó rẹ̀ yọ lọ́wọ́ ikú gbígbóná Kàyééfì!
àgọ́ daran-daran  (Ruga Settlement Project), sílẹ̀ dúró , pe
Ó ṣeéṣẹ ká pàṣẹ òfin kóníléógbélé pátápátá láìpẹ́ - Ìjọba ìpínlẹ̀ Ondo Omololu Olunloyo Kọmíṣọnnà lẹẹmẹfà tó gbé ọpá àṣẹ fún aláàfin Oyo àti Ṣọun Ogbomọṣọ Gómìnà Makinde, pe Sunday Igboho àti Auxilliary kóo parí ìjà wọn, àwọn ọmọ Nàìjíríà sọ̀rọ̀ jáde Àwọn ọmọ Nàìjíríà yarí lórí àfikún ọjọ ìséde tí Ààrẹ Buhari kéde Gẹ́gẹ́ bi fọ́nrán tó jẹyọ lọ́rí ayélujára, ọkùnrin kan gbé ẹni to ti farapa kọ́ apá to sì gbe gu ọ̀kadà lósí ibi ti ẹnìkan kò mọ.
ọba tún bínú, ó ní, ‘mo ti sọ fún alákọrí yín lẹ́ẹ̀kan pé ó wù mi ni.
awọn iṣẹ akanṣe bii popopona Oṣodi si Papakọ ofurufu Murtala Mohammed
Gbogbo ohun tó bá gbà lá máa fún un láti wa àwọn agbébọn náà- Ọlọ́pàá Ìtọ́jú ara di ìrọ̀rùn!
Rehab Homes: Ọmọdébìnrin kan sọ bí òun ṣe di ẹ̀rọ ìbálòpọ̀ níbùdó aláìgbọràn
Ṣugbọn, njẹ ẹ mọ pe bi ounjẹ jijẹ ninu oyun ṣe ṣe pataki si, naa ni iru ounjẹ ti obinrin ba n jẹ ko to o loyun ṣe pataki, lati le ran an lọwọ fun iloyu, ati fun ọmọ to ba bi.
Gbọnka sọ fun Alaafin pe ko si agbara kankan to le le oun kuro nilu Ọyọ, ti Ọba ba si fẹ mọ bi irọ ni ọrọ naa abi tootọ, ko da ina nla kan silẹ, ko si pasẹ pe ki wọn gbe oun sinu rẹ Inu Ọba dun si imọran naa, to si ṣe bẹẹ gẹẹ.
Oríṣun àwòrán, Instagram/folukedaramolasalako O ti to ọjọ mẹta ti aisan ti n ba Pa Kasunmu finra.
Ọpọlopo iṣẹ rẹ lo ti jẹ itẹwọgba nilẹ yii ati loke okun.
" Wàyí o, ní agbo àwọn Òṣeré tíátà ni ọsẹ yìí, kò fẹẹ sì bẹbẹ tí wọn ṣe nítorí aawẹ Ramadan tó wọlé de.
Àjọ ọlọpàá fẹ̀sun kan ilé iṣẹ́ ọlọpàá pé wọ́n ti tọ́wọ́bọ ètò àwọn ìgbàniwọle náà nipa àyípada àwọn orúkọ ninu iwé orukọ.
Nítorí bí ènìyǹa tilẹ̀ n wọ ẹ̀wù àkísà, tí olúwaarẹ̀ sì ń da aṣọ aláṣọ bora, ṣùgbọ́n tí olúwaarẹ̀ kò bá gbàgbé àwọn ẹni tí ó bí i, Olódùmarè náà kò ni í gbàgbé òun.
Ìwé ìfilọ kan ti nọ́mba rẹ jẹ NCS/ENF/ABJ/180/S.
Ghana Vs Nigeria trade war: Eyín àti ahọ́n a máa bá ara wọn jà, ọ̀kan ṣoṣo ni Nàìjíríà àti Ghana
Ààrẹ Abdulaziz Bouteflika ti kowe fipo silẹ Magu,'estimated billing' àti àwọn ohun míràn tí ilé aṣòfin Nàìjíríà kò rí yanjú Ayédèrú òògùn ààrùn onígbáméjì tó wà ní ta rèé Àjọ INEC ti bẹ̀rẹ̀ ìkéde èsì ìdìbò gómìnà ìpínlẹ̀ Rivers Bakan naa ni adari Ajọ INEC nipinlẹ Rivers, Ọjọgbọn Teddy Adias fikun un wi pe awọn yoo pari ikede esi idibo to ku ni irọlẹ Ọjọru.
Àwọn oriṣa Ijipti yóo máa gbọ̀n níwájú rẹ̀,ọkàn àwọn ará Ijipti yóo sì dàrú.
ní oṣu kejì ọdún 2008 , ó gbé àwo rẹ ̀ kejì jàde tí ó pè ní  no longer at ease "" ."
O wa gba awọn ọmọ orilẹẹde Naijiria nimọran pe ki won,'' sọra daada ki wọn to fi owo wọn sinu ilana ti wọn ko mọ eni to wa ni idi re'' Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 3 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 5 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Kí ló dé tí n kò rí ojurere rẹ, tí o sì di ẹrù gbogbo àwọn eniyan wọnyi rù mí?
Èèyàn 164 ló tún ṣẹ̀ṣẹ̀ ní àrùn Coronavirus ní Nàìjíríà Ipinlẹ Eko ati Abuja lo wa ni ipo kinni, ati ikeji, ninu esi ayẹwo ti ajọ NCDC gbe sita nipa awọn to ni coronavirus.
Ṣugbọn èmi ó máa fi ọkà tí ó dára jùlọ bọ yín,n óo sì fi oyin inú àpáta tẹ yín lọ́rùn.
Wọn óo kó gbogbo àwọn ohun èlò rẹ̀ sórí rẹ̀, àwọn àwo turari, àmúga tí a fi ń mú ẹran, ọkọ́ tí a fi ń kó eérú, àwo kòtò ati gbogbo ohun èlò tí ó jẹ mọ́ pẹpẹ náà, wọn óo fi awọ ewúrẹ́ bò wọ́n, wọn óo sì ti ọ̀pá tí a fi ń gbé e bọ̀ ọ́.
bíi ti ìgbà tí mo yan àwọn onídàájọ́ fún Israẹli, àwọn eniyan mi.
Ìwà rẹ yóò gbé ọ ga, mo dúpẹ́ lọ́wọ́ rẹ o.
Wo ìyá ọlọ́mọ mẹ́ta tó ti pé ọdún 48 tó ń ṣe ìdánwò WAEC, kó le di nọ́ọ́sí Wo fọ́tò àrà MC Oluomo, Pasuma àtàwọn òṣèré tíátà míì níbi ìṣílé Iyabo Ojo Adájọ́ ní kí Ahmed Danladi, tó jẹ́ awakọ̀ tó jalè gbálẹ̀ kóòtù f'ọ́jọ́ méjì ní Abuja Wo àmì márùn-un tí o fi le mọ ẹni tó fẹ́ gbẹ̀mí ara rẹ̀ Àjọ Elétò ìdìbò INEC ti sọ̀rọ̀ lórí iná tó jó àwọn káàdì ìdìbò ní Ondo Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Fídíò, Akomolede: Bolaji Faleke ni Olùkọ́ tó ń kọ́ wa ní àṣà oge ṣiṣe lórí BBC Yorùbá1 Owewe 2020 Fídíò, Akomolede ati Aṣa lori BBC: Mọ̀ si nípa oríṣìí ẹ̀ka ìsọ̀rí ọ̀rọ̀ àti ìwúlò wọn8 Owewe 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Ṣugbọn, o da bi ẹni pe idajọ naa ko ba awọn kan lara mu ni ipinlẹ Ọṣun.
"Madikizela-Mandela, ti o si ni awọn ọrọ ""hamba kahle"", tabi idagbere, tẹ lori wọn."
Loju opo Twitter rẹ loti lede ọrọ naa.
Sheikh Liadi Orunsolu: Ìmáàmù àgbà ilẹ̀ Egba ti jáde láyé lẹ́ni ọdún méjídínlọ́gọ́rùn ún
O ni ohun ti ASUU n fẹ ni ki ijọba to wa lori oye yii mu ileri to ṣe lọdun 2017 ṣẹ lasiko.
"Oríṣun àwòrán, @atiku RCCG: Pásítọ̀ Adeboye ṣáájú ìwọ́de àdúrà CAN lòdí sí ìpànìyàn ní Nàìjíríà 'Èmi tí mo gé lápá àti ẹsẹ̀ náà ló máa ń wá ọ̀rọ̀ sọ fún èèyàn kí wọ́n má baà sá fún mi' Ọ̀rọ̀ di bóò lọ yà á mi l'Abuja lẹ́yìn táwọn kan ní àwọn ti lùgbàdì áárùn Coronavirus Báyìí ni ìgboro Eko ṣe rí lẹ́yìn tí ìjọba fòfin de Keke àti Okada Láé láé, ìjọba Buhari kò tẹ ojú ẹ̀tọ́ ará ìlú mọ́lẹ̀ - Lai Mohammed Ọmọ ìjọ 20 kú bí wọ́n ṣe tẹ̀ wọ́n pa níbi ìsọjí ìtagbangba Mighty Wiglaf ni ""mo sọ fun gbogbo yin pe ọkunrin yii ni ko ṣe daadaa gẹgẹ bi aarẹ wa ṣugbọn ko sẹni to gba mi gbọ ninu yin""."
" Nigba to n sọrọ lori afojusun rẹ lọjọ iwaju, Sanyeri ni o ti wu oun lati kawe si ki ede oyinbo oun lee dan mọran lati maa ṣe ere tiata ni ede miran yatọ si Yoruba.
Saliu Mustapha -Kò yege 2) Abdulfatai Yahaya Seriki -Kò yege 3) AbdulRaham AbdulRasak - Ò yege 4) Ọjọgbọn Ọba AbdulRaheem -Ò yege.
Kọmiṣọnna fun eto iroyin nipinlẹ Kano, Muhammad Garbaṣalaye fun BBC pe ko si ewu kankan fun Sanusi nibi to wa bayii.
Kíyè sí àwọn méjèèjì dáradára, nítorí mo fẹ́ẹ́ sọ̀rọ̀ kan nípa won fún ọ.
Ìdí rẹ̀ sì ni èyí tí ìwọ fí bá mi ní ìhìn níbi tí mo ti ń gbọ́ àkúkọ ọ̀run – èmi náà, Baba-onírùngbọ̀n-yẹ́úkẹ́, ẹni tí ń gbé ibi gegele òkúta.
Akeredolu tun sọ loju opo Twitter rẹ pe  A rọ awọn ara ilu to ti lọ ra aṣọ aloku ni Ọja Ọba, nibi ti a ti mu ẹni kẹtalelogoji to ni arun Covid-19 lati pese ara wọn fun ayẹwo ni kia kia."
Arese Carrington,United Nations Association of Greater Boston,85 Devonshire Street, Suite 1000, Boston, MA, 02109,United States.
Giwa-Osagie n koju ẹsun iwa ibajẹ ati ajẹbanu to lẹ ni miliọnu meji dọla owo ile okeere, eleyii ti Ajọ to n gbogun ti iwa ibajẹ,EFCC fi lede wi pe o fi owo naa ra ibo ni ọdun 2019, ti Atiku dibo gẹgẹ bi aarẹ lorilẹede Naijiria, to si kuna.
Kidnappings in Nigeria: Aráàlú ń bèèrè pé ṣe agbébọn ló ń jí èèyàn gbé àbí Boko Haram?
Ojú ọ̀nà ọba ni a óo máa rìn títí a óo fi la ilẹ̀ rẹ kọjá.
"akọ ibà jẹ aarun àkoràn lati ara ẹ ̀ fọn tí àwọn ènìyàn àti àwọn ẹranko míìràn tí kòkòrò ńfà protozoans ( irúfẹ ́ oní sẹ ́ ẹ ̀ lì kan kòkòrò kékèèké ) ti irúfẹ ́ "" kòkòrò àṣòkunfà "" ."
Oluyole jẹ adarí àwọn ọmọ ogun Ibadan, tí ìwà adarí rẹ si jẹ èyí tí ìlú ń fẹ́.
Ẹ óo jẹ ẹran ara àwọn akikanju, ẹ óo sì mu ẹ̀jẹ̀ àwọn ọba ilẹ̀ ayé, bíi ti àgbò, ati ọ̀dọ́ aguntan, ati ewúrẹ́ ati àwọn mààlúù rọ̀bọ̀tọ̀ Baṣani.
kí ẹgbaaji (4,000) máa ṣọ́nà, kí ẹgbaaji (4,000) sì máa yin OLUWA pẹlu oríṣìíríṣìí ohun èlò orin tí ọba pèsè.
Eburoni, Rehobu, Hamoni, ati Kana, títí dé Sidoni Ńlá; 
Dahun gbogbo ibeere ti oju-ewe naa ba gbe wa fun ọ.
Orile-ede Naijiria n ro lati maa samulo imo-ero kemika epo robi fun pipese ina mona-mona, bakan naa lati tun le mu igberu ba ile-ise to n mojuto ipese kemika lorile-ede yii.
Èrò àwọn ọmọ Naijiria ṣọ̀tọ̀ọ̀tọ̀ lórí Tinubu àti Abbo Dúkìá àti ọkọ̀ jóná, ọlọ́pàá mẹ́sàn-án fara gbọta lásìkò ìwọ́de Shiite Ìjọba ló ń ṣe kóríyá fún àlàfo ńlá láàrin ọlọ́rọ̀ àti mẹ̀kúnnù - Oxfam ''Òsìsẹ́ Custom tó déédé sọ ara rẹ̀ di Ọ̀gá Àgbà CG ní ìdàmú ọpọlọ'' O fikun pe, awọn eeyan to wa ninu ọkọ naa to marun tawọn jọ de ilu Eko, amọ awọn yoku ti sọkalẹ, to si ku oun ati ọkunrin afurasi naa.
Nígbà tí angẹli OLUWA náà fẹ́ bẹ̀rẹ̀ láti máa pa Jerusalẹmu run, OLUWA yí ọkàn pada nípa jíjẹ tí ó ń jẹ àwọn eniyan náà níyà.
Bayelsa Seriake Dickson ati gomina ana fun ipinle naa Timipre Sylva ti n leri
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Nollywood stars: Àwọn èèkàn òṣèré sinimá ní Nàìjíríà jẹ́wọ́ ara wọn lórí fífi àmì ohùn sí ọ̀rọ̀ Yorùbá Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Nollywood stars: Àwọn èèkàn òṣèré sinimá ní Nàìjíríà jẹ́wọ́ ara wọn lórí fífi àmì ohùn sí ọ̀rọ̀ Yorùbá 4 Òkùdu 2020 Wọn ni oogun ti a ko ba fi han ọmọ ẹni kii pẹ parun.
Eyi lo ṣokunfa ibeere nla pe kini ipa ti Aarẹ Buhari n ko ninu alaafia awọn ọmọ ẹgbẹ oṣelu APC?
Ìwọ ni olùrànlọ́wọ́ mi ati olùgbàlà mi,má pẹ́ OLÚWA.
“Juda ń ṣọ̀fọ̀,àwọn ẹnubodè ìlú rẹ̀ wà ninu ìnira.
“Alápà má ṣiṣẹ́” ni àwọn Ìjẹ̀ṣà máa ń pe àwọn ti kò bá lè ṣiṣẹ́ gidi.
Fadeyi ni kete ti isẹlẹ naa waye, ni wọn ti bẹrẹ iwadii, ti wọn si ti ri ọkọ mejeeji ti wọn fi ji ọmọ minisita naa gbe ninu igbo, ti wọn si ti gba a pada.
Lẹyin to pari iwe mẹfa rẹ lo pada si Abeokuta fun eto ẹkọ girama, to si lọ si Abeokuta Grammar School nibi to ti bẹrẹ afihan ifẹ rẹ si ere tiata lasiko ti ọpọ eeyan korira isẹ naa, ti wọn si n rii awọn osere tiata bii alagbe.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Bí Nàìjíríà ṣe gbá eyí tó lọ, mi ò lè sọ àsọtẹ́lẹ̀ti tònìí' Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Wilfred Ndidi: Mi ò fi dáa yín lójú pé a máà bórí o!
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù SW Security: Ìpàdé ààbò wáyé nílẹ̀ Yorùbá, wọ́n fẹnu ọ̀rọ̀ jóná pẹ̀lú ilééṣẹ́ ọlọ́pàá 3 Owewe 2019 Oríṣun àwòrán, Facebook/Seyi Makinde Eto aabo to n fori sanpọn nilẹ Yoruba ti wa di irawọ ọsan to n bawọn agba lẹru bayii.
Kí àwọn ọmọ wọn tí kò tíì mọ̀ ọ́n lè gbọ́ nípa rẹ̀, kí wọ́n sì lè kọ́ láti bẹ̀rù OLUWA Ọlọrun yín, níwọ̀n ìgbà tí ẹ bá wà lórí ilẹ̀ tí ẹ̀ ń rékọjá lọ sí òkè odò Jọdani láti gbà.
Bakan naa ni ipinlẹ Gorgia yoo ma ka idibo naa lati agbegbe kan si omiran nitori ida 0.
"Ènìyàn 653 míràn tún kún iye àwọn tó ní COVID-19 ní Nàìjíríà Lizzy Anjọnrin fẹ̀si fáwọn agbọ́yì-sọ̀yí lórí ìgbéyàwó rẹ̀, Madam Sajẹ dasójú ilé iṣẹ́, àti àwọn ǹkan míràn tó ṣẹlẹ̀ lágbo tíátà lọ́sẹ̀ yìí Bí o ṣe lè forúkọ silẹ̀ fún ètò ""N75BN Nigerian Youth Investment Fund"" rèé."
Ṣugbọn kí ni Ọlọrun wí fún un?
‘Olùkọ́ fipá bá akẹ́ẹ̀kọ́ girama lòpò nítorí máàkì’ Aáwọ̀ ilẹ̀ mú ẹ̀mi márùn-ún lọ ní Makoko Èèwọ̀!
Ko sohun to jọ mọ ede aiyede.
Ofiri, Hafila ati Jobabu; Àwọn ni àwọn ọmọ Jokitani.
Olóòlà òǹkọ̀wé re àjà, òjé ìkọ̀wé gbẹ fírí
kí ẹni tí ó bá gbọ́ má baà dójútì ọ́,kí o má baà sọ ara rẹ lórúkọ.
N óo mú un lọ sí Babiloni ní ilẹ̀ àwọn ará Kalidea.
Ijọ Seventh-Day Adventist lo da fasiti naa silẹ̀ bẹẹ si ni gẹgẹ bi ọkan lara afihan iru igbagbọ wọn pe ki wọn ya ọjọ isinmi si mimọ eyi to maa n bẹrẹ lọsan ọjọ ẹti ti yoo si pari lọsan ọjọ abamẹta.
Adele alaga ijọba ibilẹ Akinyẹle ti o ba ikọ iroyin BBC Yoruba sọrọ, Họnọrebu Taoheed Adedigba Jimoh ṣe alaye wi pe iṣẹlẹ naa jẹ ohun ti o banilọkan jẹ nitori o ti n di igba kẹta bayii ti iru iṣẹlẹ yoo maa waye ni ijọba kan naa.
Ile-ise olopaa to wa lorile ede Naijiria ti so pe gbogbo awọn  to n pese  aabo fun awọn oludije ati fun ipo gomina ni ipinle Ekiti ni awọn  yoo ko kuro leyin wọn  lojo Abamẹta ose yii.
Ọlọrun, tí mò ń fọkàn sìn bí mo ti ń waasu ìyìn rere Ọmọ rẹ̀, ni ẹlẹ́rìí mi pé mò ń ranti yín láì sinmi.
Ṣùgbọ́n ilé ẹjọ́ ti fìdí rẹ̀ múlẹ̀ ní ọdún 2016 pé ebí ìyá Aláàdọ́rin, ló nilẹ̀ tí Guru Maharaj sì ti ràá lọ́wọ́ wọ́n.
Nitori naa, ka wo nkan ti yoo sẹlẹ lọjọ iwaju.
Idà ni yóo pa àwọn ọmọ ogun wọn,kí wọ́n lè parẹ́!
Alága àjọ EFCC Ibrahim Magu yóò tún bẹ ìgbìmọ̀ olùwádìí Aàrẹ wò lónìí Ilé ẹjọ́ wọ́gilé ìgbẹ́jọ́ Olalekan 'Woodberry' Pọnle Òru òní ní ìjọba á ti afárá 'Third Mainland' ní Eko; Wo àwọn ọ̀nà míràn tí o leè gbà lẹ́yìn tí wọ́n bá tìí Wo ohun tí Adájọ́ sọ nípa ìgbẹ́jọ́ Wòlíì Sotitobire l'Ondo Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Working religious women: Ẹ̀lẹ́hàá kìí ṣe ọ̀lẹ- Aminat Adegoke Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù IG Police: Ààrẹ Buhari yan Adamu Mohammed ladelé ọ̀gá ọlọ́pàá Nàìjírìa 15 Sẹ́rẹ́ 2019 Oríṣun àwòrán, @Bashir Ahmad Adele ọga ọlọpaa tuntun lorileede Naijiria,Adamu Mohammed ti pinu lati mu atunto ba eto aabọ ni Naijiria.
“Ìwọ ọmọ eniyan, gbogbo àwọn tí wọn ń gbé Jerusalẹmu, ń sọ̀rọ̀ nípa àwọn arakunrin wọn, tí ẹ jọ wà ní ìgbèkùn, àní gbogbo ilé Israẹli; wọ́n ń sọ pé, ‘Wọ́n ti lọ jìnnà kúrò lọ́dọ̀ OLUWA, OLUWA sì ti fún wa ní ilẹ̀ yìí gẹ́gẹ́ bí ohun ìní.
Ajakalẹ aarun onigbameji niluu Mecca ati Medina lọdun 1858 ko jẹ ki ọpọ musulumi ṣiṣẹ Hajj Ajakalẹ aarun onigbameji ṣekupa ẹgbẹrun un awọn musulumi ti wọn n lọ fun Hajj.
Mo fẹ ki egungun to ba wa, jẹ nnkan iwuri fun awọn ọmọde ati awọn agba, ki gbogbo eeyan lee fi ọwọ kan awọn eegun yii.
Wahala igbesunmọmi to n di baraku ni awọn orilẹ-ede wọnyii Iṣoro eto oṣelu to ṣẹlẹ lorilẹ-ede Mali laipẹ ati bi awọn ologun ṣe da sii ni eyi to fẹ da iṣejọba awa ara wa ru nibẹ.
Orin yii de ori igba awọn orin to peleke julọ ni Apple Music fọdun 2018.
Ibẹ̀ ni àwọn kan ti ròyìn fún ọba Asiria pé, Tirihaka ọba Etiopia ń bọ̀ wá gbógun tì í.
Ohun pato to wọpọ laarin ọkunrin ati obinrin ni ore ọfẹ ti wọn ni lati sọ eso nipa bibi ọmọ ọkunrin ati obinrin.
Ṣugbọn Oluwa dá a lóhùn pé, “Mata!
Lọ́wọ́lọ́wọ́ kò tíì sí àbáyọ Ṣé Coronavirus leè tẹ̀lé ọjà Chinco wọ Nàìjíríà?
Kọmiṣọna feto ilera ni ipinlẹ Ondo, Dokita Wahab Adegbenro lo ṣalaye ọ̀rọ̀ yii lasiko to n ba BBC News Yoruba sọrọ.
Oríṣun àwòrán, oyo insight Gomina Makinde sọ fun Alaafin pe ko ma binu nipa ọrọ naa, oun ko mọ rara pe ọba naa ti gbe igbesẹ saaju nípa kíkọ lẹta lori ọrọ yii.
Ọ̀nà tí ó gbòòrò yóo wà láti Asiria, fún ìyókù àwọn eniyan rẹ̀;bí ó ti ṣe wà fún àwọn ọmọ Israẹli,nígbà tí wọn ń bọ̀ láti Ijipti.
Bàbà ọmọ ọdún 75 kó HIV ran ọmọ ọdún 14 lẹ́yìn tó fi ipá báa lò Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Àwọn ọ̀jọ̀gbọ́n Yorùbá foríkorí gbé ìwé tó lè sọ ẹ̀yà ara yín lédè Yorùbá.
Ko pẹ ko jina ti iroyin gba oju opo ayelujara nipa bi awọn janduku miran ti ṣe n yabo awon adugbo lati le ṣọṣẹ fawọn eeyan mọ inu ile wọn.
Eyi waye nitori atilẹyin ti wọn n ṣe fun awọn oloselu, eyi to mu ko nira fun awọn ọlọpaa ati adari ijọba lati tete ṣẹ eegun ẹyin ẹgbẹ okunkun naa.
Ṣugbọn bí o kò bá fẹ́ rà á pada, sọ fún mi, kí n lè mọ̀, nítorí pé kò sí ẹni tí ó tún lè rà á pada, àfi ìwọ, èmi ni mo sì tẹ̀lé ọ.
Ìjọba Buhari ní kí Ológun pa mí láàrin ọjọ́ kan péré - Omoyele Sowore Bí nǹkan bá ṣe mí àtàwọn ọmọ mi, Aláàfin ni kẹ mú o - Olorì Anu figbe ta Ọ̀pọ̀ òkú fọ́nkálẹ̀ nílé ìwòsàn ìjọba ní Ore, ìpayà àjàkálẹ̀ àrùn gbàlú kan Ìpinu Gómínà láti dẹ́kun owó ìfẹ̀yìntì fáwọ̀n Gọ́mìnà àná dùn mọ́mi- Bola Ahmed Tinubu Ọkùnrin tó ṣe òfegè fọ́nran àwòrán ìgbéyàwó Buhari pẹ̀lú Mínísítà d'èrò ilé ẹjọ́ Ṣé lóòtọ́ ni olorì méjì míì tún ti kúrò láàfin Oyo?
OLUWA, Ọlọrun mi, bí mo bá ṣe nǹkan yìí,bí iṣẹ́ ibi bá ń bẹ lọ́wọ́ mi,
Ìwọ ni àpáta ati ilé ààbò mi;nítorí orúkọ rẹ, máa tọ́ mi kí o sì máa fọ̀nà hàn mí.
Niṣe lo pin owo naa kelekele sinu asunwọn banki kaakiri agbaye.
" Dokita ọhun tẹsiwaju pe ko si awọn irinṣẹ to yẹ ki wọn fi dabo bo ara wọn ti wọn ba ti n ṣetọju awọn to ni arun Covid-19.
Nítorí náà sísá ni ẹ óo sálọ.
Ìdílé tí ó rẹ̀yìn jùlọ yóo di orílẹ̀-èdè,èyí tí ó sì kéré jùlọ yóo di orílẹ̀-èdè ńlá,Èmi ni OLUWA,kíákíá ni n óo ṣe é nígbà tí àkókò rẹ̀ bá tó.
Pe gbogbo àwọn tí wọ́n mọ iṣẹ́ ọnà jọ, àwọn tí mo fi ìmọ̀ ati òye iṣẹ́ ọnà dá lọ́lá, kí wọ́n rán aṣọ alufaa kan fún Aaroni láti yà á sọ́tọ̀ fún mi, gẹ́gẹ́ bí alufaa.
Ki a ma deena pẹnu rara, diẹ re lara awọn iṣẹlẹ to jẹyọ nigbesi aye awọn oṣere tiata Yoruba ni Naijiria rèé.
Laasigbo ti o n waye ohun ti le ogoro omo orile-ede Cameroon kuro ni ekun awon elede geesi naa, iko ti o n ri si oro awon asafogun ninu ajo-isokan UN ti ro awon ti oro kan lati bere ijiroro, latari ati dekun laasigbo naa.
N ò dáwọ́ lé nǹkan ńláńlá,n ò sì dá àrà tí ó jù mí lọ.
United Kingdom kìkì ọmọ Nàìjá, pàápàá ọmọ Yorùbá.
 A gbe igbesẹ yii lati mu ki awọn ileesẹ keekeeke o le dagba, ati fun aabo ẹrù awọn onibaara wọn."
Àbí a lágbára jù ú lọ ni?
Ìwọ Mose nìkan ni kí o súnmọ́ mi, kí àwọn yòókù má ṣe súnmọ́ mi, má sì jẹ́ kí àwọn eniyan ba yín gòkè wá rárá.
Won le awon osise ajo Inec to
Aug 2018 ni ìgbìmọ̀ aláṣẹ APC ti ṣe ìpàdé kẹ́yìn, Oshiomole ti kùnà Lẹnu ọjọ mẹta yii, awuyewuye ti n waye lori iṣakoso Oshiomole gẹgẹ bi alaga ẹgbẹ naa ni Naijiria.
”Jehu dáhùn pé, “Ǹjẹ́ ẹ mọ ọkunrin náà, ati ohun tí ó sọ?
wákàtí 3 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBCwákàtí 5 sẹ́yìn Ìjọba ìpínlẹ̀ Ondo kéde òfin konile-o-gbele ní Ode ati Ishinigbo lẹ̀yìn rògbòdìyàn tó wáyé níbẹ̀wákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Tottenham sọ ọjọ́ ìsinmi olóyin di ''Black Sunday'' mọ́ Arsenal lọ́wọ́ pẹ̀lú ìgbájú-ìgbámú6 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Báyìí ni àgbàọ̀jẹ̀ agbábọ́ọ̀lù Diego Maradona ṣe wọ káà ilẹ̀ lọ lólú ìlú Argentina27 Bélú 2020 Ohun mẹ́wàá pàtàkì nípa Maradona àti ìbáṣepọ̀ rẹ̀ pẹ̀lú ẹlẹ́sẹ̀ ayò Diego Costa rèé26 Bélú 2020 Àwòrán rèé nípa bí 'Hand of God' ṣé dí inagijẹ Diego Maradona25 Bélú 2020 Àrẹ̀mọ Ooni Adeyeye Ogunwusi ti wọ Ààfin Ile Ife fún ìgbà àkọ́kọ́9 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Ṣé ẹ rántí àkọ́lé àwọn ìwé àkàgbádùn yìí?
 Bi o ti le je pe, o le fun mi pupo lati se ipinnu, sugbon mo lero
Ẹ wo Abrahamu baba yín,ati Sara tí ó bi yín.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, G-string tàbí Hip-star, èwo lo fẹ́ràn jù?
 ebi sankara fe ko di alufa ijo katoliki .
Wo àwọn ẹranko tí wọ́n máa figagbaga ni Egypt nínú AFCON 2019 Ọmọ ogun Nàìjíríà bẹ̀rẹ̀ lílo 'Drone' láti gbógun tàwọn ajínigbé ni Ondo àti Ekiti CBN: A ń pariwo tó lórí MMM fáwọn ọmọ Nàíjíríà Ipò ètò ààbò ń já àwa gómìnà láyà, ó ń kọ wá lóminú - Àwọn gómìnà Ni ipari wọn ni ojutu wahala Naijiria ni ki ijọba ri si ọrọ ina mọnamọna ati eto ọgbin fun idagbasoke to yẹ.
yóo mu ninu ògidì ọtí ibinu Ọlọrun, tí ó wà ninu ife ibinu rẹ̀.
0 519 Orilẹede Bhutan 0 0.
Bẹẹ lo ni igbesẹ ijọba to sọ iye owo epo bẹntiroo di Naira mọkanlelaadọjọ lo mu ki awọn naa fi owo kun.
O ni awọn kan n ja fita fita nitori ti ara wọn lati rii wi pe wọn ba ẹgbẹ oṣelu APC jẹ.
Ẹ gbójú sókè kí ẹ wo gbogbo òkè yíká,ibo ni ẹ kò tíì ṣe àgbèrè dé?
Ìròyìn náà sọ wí pé lójúnà ìrìnàjò wọn lọ síbi ìpàdé àdùrà níbi ìpàgọ́ ńlá ti RCCG fún oṣu kẹjọ ni wọn ti bọ́ sí páńpẹ́ ajínigbé.
Ninu ilẹ̀ náà ni àwọn ìlú tí wọ́n wà lórí òkè wà, ati àwọn tí wọ́n wà ní ẹsẹ̀ òkè, ati àwọn tí wọ́n wà ní Araba, ní gẹ̀rẹ́gẹ̀rẹ́ òkè, ní aṣálẹ̀, ati ní Nẹgẹbu.
 lẹ ́ yìn tí egbò àkóràn náà bá ti jinà , ojú ibẹ ̀ a má a ní àpá .
Lẹ́yìn tí Sanwo-Olu fi orúkọ ènìyàn mẹ́jìdínlógójì sọ́wọ́ sí ilé ìgbìmọ̀ aṣòfin, orúkọ márùndínlọ́gbọ̀n ló kógo já Sanwo Olu yan kọ̀míṣọ́nnà 25 àtàwọn olùbádámọ́ràn.
Irin kan ṣoṣo ni afá náà jẹ́, orí irun kékeré yìí ni olúwarẹ̀ sì níláti tẹ̀ kọjá.
O ni Obasanjọ gan an lo bẹrẹ ijọba amunisin lorileede Naijira nigba ti o ṣe ijọba gẹgẹ aarẹ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Albert Einstein: 'Ọ̀rọ̀ lọ́kọláya kọjá ọ̀rọ̀ orí ahọ́n lásán' Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Albert Einstein: 'Ọ̀rọ̀ lọ́kọláya kọjá ọ̀rọ̀ orí ahọ́n lásán' 23 Bélú 2018 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 19 Ìgbé 2020 Awọn ẹbí Albert Einstein gbà pé àjẹ́ ni Mileva to jẹ aya rẹ̀.
Nebukadinesari ọba bá lọ sí ẹnu ọ̀nà adágún iná náà, ó kígbe pé, “Ṣadiraki, Meṣaki ati Abedinego, ẹ̀yin iranṣẹ Ọlọrun alààyè, ẹ jáde wá!
El-Zakzaky fẹ́ jayé ọlọ́ba ní India, kò sígbà tí kò ní padà wálé - Ìjọba àpapọ̀ Àjẹ́ àti Aṣẹ́wó ní ìyá Rainbow - Òjòpagogo Òṣèré tíátà Toyin Abraham daya Kolawole Ajeyemi Ọ̀pọ̀ olólùfẹ́ eré bọ́ọ̀lù bẹnu ẹ̀tẹ̀ lu bí Iwobi àti Lukaku ṣe lọ Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Leyin ti won ti saroye fun ajo eleto idibo nibi ipago eto idibo to wa ni Wilberforce, omo egbe oselu SLPP, Kabineh Kalon bere pe, ki awon omo-ogun fi awon ibi ipago idibo naa sile kiakia.
Adajọ́ Okon Abang nínú ìdájọ rẹ̀ lọ́jọ́rú ni ó ti kọ́ja ọjọ́ mẹ́rìnlá kí olùpẹ̀jọ́ to mu ẹjọ́ wá silé ẹjọ́ gẹ́gẹ́ bi abala iwé òfin 285(9) ṣe làá silẹ̀ lórí ẹjọ to bá níṣe pẹ̀lú ìdìbò.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Sotitobire: Ọkọ mi kò mọ̀ Jegede PDP rí, kódà kò fa ẹnikẹ́ni kalẹ̀ dípò Akeredolu- Bisola ìyàwó Alfa Sotitobire Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Sotitobire: Ọkọ mi kò mọ̀ Jegede PDP rí, kódà kò fa ẹnikẹ́ni kalẹ̀ dípò Akeredolu- Bisola ìyàwó Alfa Sotitobire 14 Ọ̀wàrà 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 16 Ọ̀wàrà 2020 Lati igba ti wọn ti gbe Ọkọ mi ni ọlọpaa ko ti wa ọmọ mọ- Bisola aya Wolii Sotitobirẹ Idajọ buruku ni wọn da fun ọkọ mi ni ariwo ti Arabinrin Bisola Alfa to jẹ iyawo Wolii sotitobire n pa bayii.
LAFIYA DOLE pe“ iko omo ogun naa tun ri abugbamu ado oloro ati awọtẹlẹ ado oloro ti
ijọba apapọ ni lati je ki gbogbo omo orile ede Naijiria ko ipa tirẹ lati mu
com/oSFhnz7enGA third-place finish for the Blues!
Ẹ gbọ alaye Dapọ Sanwo siwaju si lori isẹlẹ yi.
Diezani, Fayose, Uzor Kalu àti awọn míì wa lára àwọn ẹjọ́ tó làmìlaaka ti EFCC ṣe lásìkò Magu Ariṣe ni arika, arika ni baba iregun.
A John Akẹkọgboye ninu im Chemical Engineering lati ile ẹkọ giga Prague Institute of Chemical Technology orilẹede Czech Republic ni.
Nítorí náà kò ní sí ìpín fún ẹnikẹ́ni ninu yín mọ́ nígbà tí a bá dá ilẹ̀ náà pada fún àwọn eniyan Ọlọrun.
Àwọn ìlú yóo rí ẹni máa gbé inú wọn, wọn óo sì tún gbogbo ibi tí ó ti wó kọ́.
Amọ, aarẹ Trump kọ lati buwọlu Paris Agreement to ni ki awọn eniyan ma lo ohun ti yoo ba oju ọjọ jẹ.
Ẹni bá rí ni tán ló ń ṣekú pani
Oríṣun àwòrán, Lasema Ajọ tó ń rí sí ìṣẹ̀lẹ̀ pàjáwìrì ní ìpínlẹ̀ Eko LASEMA ní òun ti bẹ̀rẹ̀ ètò láti pa iná tó ṣẹyọ nilé epo kan ni Baruwa, àgbègbè ìpájà lówùrọ̀ òní.
AareBuhari ki  adari akọkọ fun ajo yii ati pe adari naa tun je okan lara awon eniyan mejo , ti won wa lati ekun marun un,ti o gba ami eye orisirisi naa, ni eyi ti egbe to n ri si gbigbogun ti iwa ibajẹ  (Sheikh Tamin Bin Hamad Al Thani InternationalAnti-Corruption Excellence (ACE) se ni orile ede Malaysia lojo Ẹti ,lasiko ayeye odun keta ti won da egbe yii sile,’’O je anfaani ati imoore fun igbiyanju re nipa gbigbogun ti iwa ibajẹ.
Wọn a máa gbé ẹran tí wọn yóo bá fi rúbọ lé orí àwọn tabili náà.
Ninu atẹjade ti ẹgbẹ agba yii fi sita ti awọn wọnyii fọwọ si ni wọn ti ni ko tọna lati dẹkun ọna eto aabo iran kan tabi omiran.
Bí ọdún tí ó kù tí ọdún jubili yóo fi pé kò bá pọ̀ mọ́, wọn yóo jọ ṣírò iye ọdún tí ó kù fún un láti fi sìn ín, òun ni yóo sì fi ṣírò owó ìràpadà rẹ̀ tí ó kù tí yóo san.
Motara ni oun pada fun ọmọ naa lowo ṣugbọn iyẹn o si ninu fidio tori oun ko ni i lọkan lati fi ṣe aburu.
Iṣẹ́ àṣedànù ni ẹ óo máa ṣe, nítorí pé, ilẹ̀ kò ní mú ìbísí rẹ̀ wá, àwọn igi oko kò ní so.
Ogagun Alex Badeh gbe Mary Iyah niyawo.
FIBA World Cup: D'Tigress tún fakọyọ lẹ́yìn tí wọ́n na Argentina
O ni aarin awọn aṣofin naa ni ki wọn o ti wadi bi wahala naa ṣe waye.
Odunlade fẹ́ j'ọba, Bolanle Ninalowo fun ìyàwó rẹ̀ ni ẹ̀bun kanka, Pá Kasumu rebi àgbà ree Ènìyàn lásán ní ọba ilẹ̀ Yoruba tí kò bá ṣe ètùtù, ẹ má tẹ ìṣẹ̀ṣe mọ́lẹ̀ - Elebuibon Ìdá 90% nínú àwọn olówó Naijiria lo n lọ ilé babaláwo- Mr Latin Ọbasanjọ ni ọmọ òrùkàn tó di olóri orílẹ̀èdè lẹ́ẹ̀mẹ́ta ọ̀tọ̀ọ̀tọ̀ Ọganla Fuji ni nigba to ba ya oun yoo niyawo ṣugbọn suuru lo gba.
Lọnọ miran ẹwẹ, Manchester City nọ Westbrom pẹlu ami ayo mẹta s'odo, eyi ti o gbe wọn soke tente tabili Premier League pẹlu ami méjídínláàdọ́rin.
O lọ si ileewe alakọbẹrẹ Olowogbowo Methodist Primary School, Apọngbọn, nilu Eko ni nkan ni ọdun 1930, ko to di pe o lọ kawe nilu London.
Ààrẹ Akufo-Addo sọ̀rọ̀ yìí nínú àtejáde kan, Ó ní ìjọba òun ń kojú ìfúngunmọ́ láti sọ ìhà tí òun fì sí láti ìgbà tí Theresa May, olórí ilẹ̀ gẹ̀ẹ́sì tí gorí alefa.
Nígbà tí wọ́n dé ilé OLUWA ní Jerusalẹmu, díẹ̀ ninu àwọn olórí ìdílé náà fi ọrẹ àtinúwá sílẹ̀ láti tún ilé Ọlọrun kọ́ sí ààyè rẹ̀.
"Ohun tí o kò mọ̀ nípa Ebila ""One Million Boys"" àti Ekugbemi, olórí ẹgbẹ́ òkùnkùn méjì tó da ìlú Ibadan rú Èèyàn 789 gbèkuru jẹ lọ́wọ́ ẹbọra nítorí COVID-19 ní Nàìjíríà Akanbi mi, má fọ̀ ọ́, mo wà pẹ̀lú ẹ; Ẹni tó ṣe ìgbéyàwó olórùka ló l'ọkọ- Lizzy Anjorin Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Lockdown updates: Naira Marley gbóríyìn fún Jude Chukwuka pẹ̀lú #1 míliọnù Kanye West : Ohun márùn ún tó yẹ kí o mọ̀ nípa Kanye West rèé Ariwo Kanye West gba ori ayelujara kan lọjọ kẹrin oṣu keje ọdun 2020 lẹyin to fi ikede sita pe oun fẹ du ipo aarẹ ilẹ Amẹrika."
Gómìnà mẹ́rin yóò jẹ́jọ́ lẹ́yìn sáà wọn - EFCC Awakọ̀ òfúrufú Ethiopian Airlines pariwo 'lọ sókè!
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Awọn obinrin Sudan forin sẹnu plu bi wọn ṣe tu yaaya si igboro fun ajọyọ Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, KHARTOUM, SUDAN - APRIL 13: Awọn eniyan korajọ lati ṣe ajọyọ niwaju olu ile iṣẹ awọn ologun lẹyin ti Minisita ọ̀rọ̀ abo, Ahmed Awad Ibn Auf kede pe oun fipo silẹ gẹg bi olori ẹgbẹ ọmọ ogun to boju to gbigbe ijọba le ẹlomiiran lọ́wọ́ ni Khatourm, Sudan.
bí ẹni tí wọ́n lù tí ó farapa náà bá dìde, tí ó sì ń fi ọ̀pá rìn kiri, ẹni tí ó lù ú bọ́ lọ́wọ́ ikú, ṣugbọn dandan ni kí ó san owó fún àkókò tí ẹni tí ó lù náà lò ní ìdùbúlẹ̀ àìsàn, kí ó sì ṣe ètò ìtọ́jú rẹ̀ títí yóo fi sàn.
Ó bá fi ọwọ́ ṣe àmì sí wọn kí wọ́n dákẹ́; ó ròyìn fún wọn bí Oluwa ti ṣe mú òun jáde kúrò lẹ́wọ̀n.
 lára ẹbí niger-cong ni èdè yìí wa , ẹka rẹ si ni bantu .
mo rò pé ẹ ṣe iṣẹ pàtàkì níbẹ̀ ni.
Gẹ́gẹ́ bi àwọn ọlọpàá s sọ ninu àwọn ìkìlọ rẹ̀ ni pe, Rẹ́rìrín músẹ́, wùwà tó tọ́, kí ó si dẹ̀yìn nínú bibá ọlapàá jà.
 paul wild ni ose awari planeti yii ni ogun jo , osu kewa odun 1971 .
Bíodun Fatoyinbo ti fojú hàn ní àgọ ọlọpàá Aṣojú Seyí Makinde lásan ní mo jẹ, òṣìṣẹ́ gbọdọ̀ bọ̀wọ̀ fún mi - Ọ̀dọ́mọdé Kọmísánà ‘Pussypedia’ rèé, ojú òpó tó ń mú àdínkù bá ìṣòro ìmọ̀ nípa ẹ̀yà ara obìnrin O ni igi ti arabinrin yii fẹ la mọ oun lori ni oun gba lọwọ rẹ, ti oun si la a mọ leti.
naa pe atundi yoo waye  lori ibo naa.
ÌjÀ ogun ÀgbayÉ kÌÍnÍ láti ọjọ ́ ti aláyé ti dáyé ni àwọn ìwọ ̀ búburú bí i : jàgídígàgan , wàhálà .
Ẹ̀yin náà ẹ wò ó, kí ẹ ṣe akiyesi rẹ̀,bóyá ìbànújẹ́ kan wàtí ó dàbí èyí tí ó dé bá mi yìí;tí OLUWA mú kí ó dé bá mi,ní ọjọ́ ibinu gbígbóná rẹ̀.
Eto oro aje orile-ede America ko ni ni to iko kan ninu ida ogorun 0.
Ọwọ́ ikọ̀ aláàbò STF tẹ afurasí mẹ́jọ tó lọ́wọ́ nínú ìpànìyàn lemọ́-lemọ́ọ Gúúsù Kaduna Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ìdílé tí ọkọ da ọmọ síta tóríi ojú Búlùú tí wọ́n ní bá BBC sọ̀rọ̀ Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Obadiah Mailafia: DSS ti fi igbákejì gómìnà CBN tó ní gómìnà kan ní Àríwá Naijiria ní Ọ̀gá Boko Haram sílẹ̀14 Ògún 2020 5:58 Fídíò, Akomolede ati asa Yoruba: Ẹ wá kọ́ nípa àpòtí ìṣura èdè wa lórí BBC Yorùbá, Duration 5,5820 Ògún 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Kíni ìdí tí àwọn adarí ilẹ̀ Europe fi ń wá sí Nàìjíríà?
Asofin Abu Ibrahim ni o jẹ alaga fun   igbimọ  to se ayewo fun awọn    igbimọ  ti yoo maa se amojuto fun ile –isẹ  ọlọpaa naa.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ọwọ ọlọpaa tẹ eeyan mẹwa lori wahala Kaduna 27 Èrèlè 2018 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 28 Èrèlè 2018 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Lara ipenija ipinlẹ Kaduna ni ikọlu darandaran.
Ninu ọrọ naa to ti parẹ bayii, Ese sọ pe onkọrin naa gba ẹ̀dà kọkọrọ to ṣi ilẹkun yaara ti ọmọbinrin naa sun si nile itura.
ni pataki julo awon ti oko won ba padanu emi re lasiko ti won n ja fun orilede
Orúkọ ẹni tí ó gùn ún ni Ikú.
Àwọn àwòrán kẹ̀kẹ́ tí mo yà láàrìn ìgbòro ni ìwọ̀nyí.
Ẹ máa rìn ninu ìfẹ́ gẹ́gẹ́ bí Kristi ti fẹ́ wa, tí ó fi ara òun tìkararẹ̀ rú ẹbọ olóòórùn dídùn sí Ọlọrun nítorí tiwa.
"Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Jean-Bédel Bokassa ti Central African Republic Bokassa ni aarẹ Central African Republic, CAR, lati ọdun 1966 si 1976, asiko naa lo sọ ara rẹ di ""Emperor"" ilẹ ọhun."
Toò, ọ̀rọ̀ ló kó mokó morò wá.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'A ni òfin púpọ̀ ní Naijiria ṣùgbọ́n a kò bọ́wọ́ fún un ni' Ènìyàn 26,000 ni àìsàn jẹjẹrẹ ń pa lóòjọ́ Àwọn àwòrán ẹ̀yìn ìtàgé níbi ìpàdé ìfọ̀rọ̀wérọ̀ BBC Yorùbá l'Eko Link Day 13: Àwọn ńkan méje tí ẹ lè má mọ̀ nípa Igbákejì Ààrẹ Osinbajo #BBCNigeria2019 Bààlú Sala tó pòórá ti di àwárí nínú òkun Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Falana: Awọn to n dije dupo ìdìbò 2019 fẹ́ fa ogun si Naijiria Ọ̀rọ̀ LAUTECH gba àpérò f'áwọn Olúdíje Ọṣun Àkójọpọ̀ àwòrán láti ìpàdé ìtagbangba pẹ̀lú àwọn olùdije ní Ọyọ Àwọn ohun mánigbàgbé níbi ìfọ̀rọ̀wérọ̀ BBC Yorùbá l'Ọyọ Èwo nínú ìlérí tí Buhari ṣe ní 2015 ló ti mú ṣẹ?
Èèyàn 49 bá ìṣẹlẹ̀ iyìnbọn lọ ní Mọ́sálásí méjì ní New Zealand Àwọn tó gboriyin àti àwọn tó gbàbuku lórí ìṣẹlẹ New Zealand Ọ̀gá àgbá ọlọ́pàá pàṣẹ pé kí wọn ṣàwárí àwọn pásítọ̀ tí wọn jí gbé Arakunrin ọmọ ọdun mọkanlelogun kan la gbọ pe o ti wa ni ahamọ ọlọpaa bayi.
Aarẹ ẹgbẹ TANPAN wa sọ oju abẹ niko pe igbimọ amusẹya ẹgbẹ naa ti paṣẹ pe ki awọn oṣere tiata si jokoo sile wọn titi ti ijọba apapọ yoo fi gbe ẹsẹ kuro lori ofin konile o gbele patapata.
Wọn n fẹ ki Fatoyinbo fi ipo rẹ silẹ gẹgẹ bi Pasitọ Agba ijọ naa.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Yakubu Dogara: Gómìnà Bauchi da ₦4bn owóyàá ìlú sápò iléeṣẹ́ àdáni kan 24 Agẹmo 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 27 Agẹmo 2020 Oríṣun àwòrán, Yakubu Dogara Facebook Olori tẹlẹ fun ile asoju-sofin, Yakubu Dogarati kede fun araye pe, ọna aibofin mu ti ijọba ipinlẹ Bauchi n gba gbe isẹ agbase jade, jẹ ọkan lara ohun to mu oun kuro ninu ẹgbẹ oselu PDP.
Eeyan mẹwa to mu 'Yọllywood' lamilaaka
Ní ọjọ́ keje tí í ṣe ọjọ́ ìwẹ̀nùmọ́ rẹ̀, yóo fá irun orí rẹ̀.
Ajọ The Wellcome Trust to ṣe iwadii naa jẹ ko di mimọ pe, ẹgbẹrun lọna ogoje eeyan kaakiri awọn orilẹede ogoje lagbaye, ni wọn ṣe iwadii naa fun.
Kí o gbé tabili kalẹ̀ ní ọwọ́ òde aṣọ títa náà, kí ọ̀pá fìtílà wà ní apá ìhà gúsù àgọ́ náà, ní òdìkejì tabili náà, kí o sì gbé tabili náà kalẹ̀ ní apá àríwá.
Nisinsinyii adé òdodo náà wà nílẹ̀ fún mi, tí Oluwa onídàájọ́ òdodo yóo fún mi ní ọjọ́ náà.
Wo bí èsì ìdìbò ìpínlẹ̀ Edo ṣe ń jáde Lẹ́yìn olóògbé Barrister àti Kollington, èmi làgbà kàn nínú iṣẹ́ orin Fuji- Obesere yarí Ọkọ̀ méjì jóná ráùráú níbi tí ọkọ̀ tó gbé bẹntiróò ti gbiná Wo bí ìfigagbágbá tani yòó di gómìnà Edo láàrin Obaseki àti Ize-Iyamu yóò ṣe lọ Yatọ̀ sí pé ó ṣe sọ́jà, tó tún jẹ́ ọkọ Oriṣabunmi, wo àwọn nkan tí o kò mọ̀ nípa Jimoh Aliu Lati mọ ohun to n fa aisan yii, ileeṣẹ BBC ba Dokita onimọ iṣegun, Henry King to sọ ohun to n fa ipenija yii ati ọna ti a le gba ran ara wa lọwọ lati bori rẹ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Suicide Prevention: ìwọ́de yìí wáyé láti gbógun ti pípa ara ẹni Ajọ eleto Idibo INEC ko tii sọrọ lori iṣẹlẹ yii paapaa ohun ti owo yii wa fun ni pato.
Mo ṣe lè rí jamba tí ń bọ̀, tabi ìparun tí ń bọ̀ sórí àwọn eniyan mi, kí n sì dákẹ́?
Ọmọ ọdún mẹ́wàá ń fọn fèrè lágbo àríyá Ìtàn ọmọ Afirika tó ló lówó jùlọ lágbàyéé rèé Ohun tí Adeleke sọ rèé nígbà tí ìgbẹ́jọ́ èsì ìdìbò gómínà Oṣun bẹ̀rẹ̀ Èmi ṣì ni Gómìnà ìpínlẹ̀ Ọṣun-Oyetọla Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí kan sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
'Ọdún 2019 pẹ̀lú àwọn àsọtẹ́lẹ̀ tó kó lọ́wọ́ dé' Nibayii, iyawo gomina ipinlẹ Ekiti, Bisi Fayẹmi ti rọ awọn obinrin nipinlẹ Ekiti lati yago fun bibimọ sile tabi si ọdọ awọn agbẹbi agboole ati ibilẹ.
Oríṣun àwòrán, @OnwardNG Igbimọ Aarẹ Ọna Kakanfo ilẹ Yoruba ti sọ pe, awọn ọmọ ẹgbẹ agbesumọmi Islamic State, IS, ti rapala wọ agbegbe Okeogun, ni ipinlẹ Oyo.
Ǹjẹ́ o mọ àwọn olorì àkọ́fẹ́ Aláàfin Adeyẹmi?
 Ó jáde ní ilé ẹ ̀ kọ ́ àgbà ti university of maryland college park .
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Conjoined twins: Ilé ìwòsàn l'Àbuja ti ya àwọn ìbejì tí wọ́n sọpọ̀ láyà 8 Sẹ́rẹ́ 2020 Àkọlé àwòrán, Ọ̀pọ̀ ìbejì tí wọ́n sopọ̀ ní ìsàlẹ̀ ikùn ni wọ́n ti ṣisẹ́ abẹ fún láti tú wọn ká, àmọ́ ìgbà àkọ́kọ́ nì yíì tí àwọn dokìta náà yóò ya ìbejì tí wọ́n sopọ̀ láyà.
Orilẹede Amẹrika ti beere lati ra miliọnu lọna ọgọrun oogun naa bayii.
Oríṣun àwòrán, @TimiBlaze Adeyeye fi kun ope NAFDAC ti fofin de aṣilo oogun naa atawọn oniṣowo to maa n kiri rẹ laarin ọja.
Èémí wọ́n lásán máa n tí ààrùn Coronavirus jáde sí àyíká.
Ó ní ní oṣù tí ó kọjá ni òun náà rí ti òun tí bàbá àti ìyá òun náà ṣe sàráà fún òun.
Ogbeni Clement Oladele to jẹ óga àgbà àjọ náà ni ìpínlè Ogun lo ṣalaye okunfa iṣẹlẹ naa.
aare Muhammadu Buhari ti o je omo odun mẹ́rìndínlọ́gọ́rin(76)  oludije fun egbe APC ati  Atiku Abubakar ti o je omo odun méjíléláàdọ́rin
Ninu ọrọ kan to fi sori oju opo twitter rẹ, Toyin Abraham rọ awọn ololufẹ rẹ lati mojuto ilera wọn fun oun nitori oun nifẹ wọn gidigidi.
Widows Day 2019: Mo máa ń sá kiri wá owó ilé ni -Opó
Ṣugbọn ni China, to jẹ ibudo ọja nla keji fun awọn ọja Apple, ijọba ti ni awọn yoo mu imọ ẹrọ wọn gbooro sii kaakiri orilẹede wọn si kede laipẹ pe itakun ayelujara ti wa daadaa ni Beijing ati Shenzhen.
fa isẹlẹ buruku naa ni awon agbegbe wonyi.
Ibeji ni Eniola jẹ toun ati ikeji rẹ si jẹ abigbẹyin awọn ọmọ mẹfa ti obi wọn bi.
Ooru to n mu ni orilẹede Australia bayii pọ de bi pe o ti ṣeku pa ọpọlọpọ ẹṣin, adan ati ẹja.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Kid boxer: Ọmọọba 'The Buzz' Larbie rèé, ọmọ ọdún méje tó ń fi ẹ̀ṣẹ́ dá bírà Àwọn wo ni yóò pa lára?
Luku nìkan náà ni ó kù lọ́dọ̀ mi.
O se IVF ni ẹẹmẹta ọtọọtọ ni oke okun, amọ igba kẹrin to pinnu lati se IVF ni ilu Eko, lorilẹ-ede Naijiria, lo di iya Ibeji.
Amọ awọn sẹnẹtọ naa gbọdọ buwọlu igbesẹ naa, ki Trump to le lọ.
 O tun sise gege bi oludari agba fun awon osise labe isajoba gomina tele ri fun ipinle ohun, Niyi Adebayo.
Àwọn ẹ̀yà ayé àtijọ́ kan tí wọ́n pe orúkọ wọn ní Maya sọ wipé ayé á parẹ́ ní ọjọ́ kọkànlélógún oṣù kejìlá ọdún 2012.
Titẹle ilana itọju ara ẹni ati imọtoto to peye Oríṣun àwòrán, Getty Images Ni ipari awọn onimọ salaye pe ki a ri pe a moju to ilera ara wa ka si tun gbajumọ imọtọto.
Oríṣun àwòrán, Others Ohun ta gbọ nipa Mamman Daura lati ileesẹ aarẹ: Wọn ni Daura lọ silẹ United Kindom pẹlu iyawo ati ọmọ rẹ meji, ọkan ọkunrin, ti ekeji si jẹ obinrin.
Eyi to yẹ kí ó wáyé láàrin ọjọ Ajé, ọjọ́ kọkàndínlọgbọ̀n sí ọgbọ̀n ọjọ́, ní ìlú Minna Lára ìdí tí wọ́n fi kọ̀ láti kópa ní pé wọ́n pé àwọn ọmọ ẹgbẹ́ Miyetti Allah síbi àpérò náà ati pe àwọn kò si ṣetan láti jọ jòkó pọ̀ fún àpérò pẹlu darandaran.
“Kabiyesi, o rí ère kan níwájú rẹ ní ojúran, ère yìí tóbi gan-an, ó mọ́lẹ̀, ó ń dán, ìrísí rẹ̀ sì bani lẹ́rù.
Nítorí ẹlẹ́san ni Oluwa ninu àwọn ọ̀ràn wọnyi, gẹ́gẹ́ bí a ti sọ fun yín tẹ́lẹ̀, tí a wá tún ń kìlọ̀ fun yín nisinsinyii.
Ṣugbọn igba mii awọn alejo òjijì kan maa n ba ni lalejo ti eniyan maa maa sa kiri inu ile fun.
Agbo ọpọlọpọ ẹlẹ́dẹ̀ kan wà tí wọn ń jẹ lókèèrè.
gbe e lọ si Igbimọ Alakoso Agbeyẹwo Iṣuna Owo Ilu.
Dafidi tún bèèrè lọ́wọ́ rẹ̀ pé, “Báwo ni o ṣe mọ̀ pé Saulu ati Jonatani ọmọ rẹ̀ ti kú?
Ẹni tí ó ń ṣiṣẹ́ déédé, ó yẹ kí ó lásìkò ìgbádùn nítorí isẹ́ lógún ìṣẹ́.
Ki lo sọ eyi si, ni Sẹnetọ Akpabio, to ti fi igba kan jẹ olori ọmọ ẹgbẹ oṣelu to kere julọ nile aṣofin naa, ba na ọwọ lati fesi lori ọrọ ọhun, ṣugbọn Bukọla Saraki ni ko gbọdọ sọrọ, ayafi to ba pada si ibi aaye ijoko rẹ.
Wolii Eliṣa ní ń sọ fún un, títí kan gbogbo ohun tí ẹ bá sọ ní kọ̀rọ̀ yàrá yín.
Eyi ko ṣẹyin iroyin to n tan kaakiri pe ẹgbẹ oṣiṣẹ yoo bẹrẹ ifẹhọnuhan tako bi ijọba apapọ ṣe fi owo kun owo epo bẹntirol.
2 98603 Orilẹede Honduras 2968 31.
Taló ya fídíò ibi tí Aisha Buhari ti ń bínú ní Aso Rock?
Sọ àsọtẹ́lẹ̀ orílẹ̀èdè tí yóò borí ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ t'òní Atiku ni kò tíì dópin fún Adeleke, PDP ni àwọn gba idájọ́ wọlé Bakan naa ni wọn rọ gomina, lati se atunse awọn opopona to wa nilu ọhun ti ọpọ wọn ti dẹnu kọlẹ.
Ó ní nítorí náà, kí wọn má ṣe jẹ́ kí Hesekaya tàn wọ́n jẹ, tabi kí ó ṣì wọ́n lọ́nà báyìí.
Ọlọ́pàá kó àwọn ọmọ ẹgbẹ́ òkùnkùn Ẹiyẹ Confraternity ni Ikorodu Wike kò wó Mọṣáláṣi rárá o -Fayẹmi lórúkọ gbogbo Gómìnà Egbé agbábọọlù Super Eagles gbàgbé ohun eèlò wọn - Ọlajiire Irọ funfun báláwú ni, Boko Haram kò dawa lọnà rárá -Ọmọ ogun Naijiria Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí kan sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
Oríṣun àwòrán, Twitter/ governor kaduna Aṣẹ ti ijọba ipinlẹ naa fi sita rọ gbogbo awọn adari ileewe lati rii daju pe gbogbo idanwo wa sopin lẹyẹ o ṣọka ki wọn si ti ileewe gbogbo l'Ọjọru.
ní ìlú kan tí a ń pè ní Ògirììyàndá , Ọkùnrin kan wà níbẹ ̀ tí wọ ́ n ń pe orúkọ rẹ ̀ ní Òòrẹ ́ .
Kòṣẹlẹ̀rí ni Hajj ọdún 2020, wo ìyàtọ̀ tó wà nínú rẹ̀ sí ti tẹ́lẹ̀ Ẹ̀yin ẹlẹ́gbẹ́ òkùnkùn tẹ fẹ́ ṣe àjọ̀dún lónìí, lákọ la ń dúró dè yín - Iléeṣẹ́ ọlọ́pàá Ìjọba Akeredolu kò ní omi àánú lójú, a kò tọ́jú alárùn Coronavirus mọ́ - Dókítá Ondo Bí àwọn adarí ìjọba ṣe ń kó Coronavirus, ń kọ wá lóminú - Ìjọba àpapọ̀ O ni funra oun ni oun ra tikẹẹti alọ ati abọ lati lọ si Sierra Leone, amọ nigba ti idije naa pari logunjọ osu kẹta, arun Coronavirus ti bẹ silẹ.
 Èdè gẹ ̀ ẹ ́ sì ti ń gbayì ní ilẹ ̀ yìí sí i gẹ ́ gẹ ́ bí èdè òwò àti èdè ìṣe àbẹ ̀ wò sí ìlú ( tourism ) .
Ta ló fi àwọn orílẹ̀-èdè lé e lọ́wọ́tí ó fi lè tẹ àwọn ọba mọ́lẹ̀?
"Ọjọ kẹtala, oṣu Kẹta ni wọn so idije Premier League rọ nitori coronavirus, sugbọn gbogbo awọn ẹgbẹ́ agbabọọlu lo ṣetan lati gba ifẹsẹwọnsẹ mejilelaadọrun to ṣẹku.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Cotonou Museum: Àṣà àti ìṣẹ̀ṣe Yorùbá di àpéwò ní Porto-Novo Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Cotonou Museum: Àṣà àti ìṣẹ̀ṣe Yorùbá di àpéwò ní Porto-Novo 20 Ọ̀pẹ̀̀ 2018 Jakejado orile aye ni aṣa ati iṣẹṣe Yoruba ti jẹ oun amuyangan.
Sugbon won ni awon yoo yoju si ileese olopa to kede orukọ rẹ gẹgẹbi ẹni ti wọn nwa ni kiakia pẹlu ẹsun pe o gbe ayederu iroyin sita.
asoju to gunlẹ si ilu Abuja.
London Bridge: ọlọpàá kí àwọn aráàlú tó kojú agbésùnmọ̀mí náà kú akitiyan
- Oshonaike Bú ààrẹ láwọn orílẹ̀èdè márùn-ún yìí kí o rugi oyin Kí wọ́n tún ìbò Kogi dì nígbà 2,000 Dino ló máa wọle- Dino O fikun un wi pe ofin kan naa lo de Osinbajo lati ma lee fun awọn asewadii lanfaani ṣiṣe iwadii rẹ, ki gbogbo aye le mọ wi pe ko wu iwa ibajẹ.
“mo wa niwaju yin, lati je ki e mope aare Buhari ti se gudu-meje, yaya mefa ni gbogbo ona.
Kí ìwọ náà ṣọ́ra lọ́dọ̀ rẹ̀, nítorí títa ni ó ń tako àwọn ohun tí à ń sọ.
Egbe oselu to n sejoba lorile-ede South Africa ti fenu ko lati pe Aare Jacob Zuma pada leyin ipade pipe, eyi ti o pari lowuro ojo-Isegun.
Garba Shehu - BBC News Yorùbá BBC News, YorùbáFò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ministerial Position: Gbogbo àwọn ilé iṣẹ́ tí ààrẹ yàn mínísítà fún lo ti wà tẹ́lẹ̀ - Garba Shehu 22 Ògún 2019 Àkọlé àwòrán, Ministerial Position: Gbogbo àwọn ilé iṣẹ́ tí ààrẹ yàn mínísítà fún lo ti wà tẹ́lẹ̀ - Garba Shehu Lánà òdé yìí (21-08-2019) ní ààrẹ Muhammadu Buhari kéde àwọn ilé iṣẹ́ márun un tuntun míràn nígbà tó yan àwọn mínísítà.
Mamman Daura ka ile iwe girama ni Okene Provincial School pari lọdun 1956.
McGirt to jẹ atọna rẹ ni oun n ni ko dẹkun ija nigba ti oun rii pe ọrọ fẹ maa bẹyin yọ.
Ọmọbinrin Aarẹ Buhari naa lo gba iṣẹ ati lọ ya fọtọ ni ayẹyẹ naa, lẹyin to gba ipo oni ipele kini (First Class) ninu ẹkọ imọ ayaworan lati Fasiti Ilẹ Gẹẹsi laipẹ yii.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Sanwo-Olu: Àtàrí Àjànàkú ni àkóso Eko, kì í ṣe ẹrù ọmọdé 7 Òkùdu 2019 Oríṣun àwòrán, Babajide Sanwoolu/Twitter Gomina Ipinlẹ Eko, Babajide Sanwo-Olu ti figbe ta pe, oun ti ru laarin ọsẹ kan ṣoṣo ti wọn bura fun oun, gẹgẹ bi gomina.
NLC: Ìgbà kẹta rèé tẹ́gbẹ́ òsìsẹ́ yóò wàákò pẹ̀lú ìjọba lábẹ́ Wabba
Ohun tí ojú opó ń rí láwùjọ kò kéré"" N kò fẹ́ eégún onídọ̀tí ní ààfin mi - Oluwo Mi kò lè ṣe igbẹ́yàwó ìkọ̀kọ̀ - Ọọ̀ni Ọọni pe fun ifọwọsowọpọ Naijiria Ajo ẹlẹyinju aanu ti Ọba Alayeluwa naa da silẹ, Hopes Alive Innitiatives (HAI)"" wa lati ri daju wipe gbogbo ọmọ orukan ati awọn to kudiẹ kaato fun lo bẹrẹ sini gbayegbadun, eyi lo mu ki ajọ naa maa lọ lati ipinlẹ de ipinlẹ ninu igbiyanju ati wa ojutu si iṣoro irufẹ awọn eeyan bẹẹ."
Ṣugbọn Farao dá wọn lóhùn pé, “Ta ni OLUWA yìí tí n óo fi fetí sí ọ̀rọ̀ rẹ̀, kí n sì jẹ́ kí àwọn ọmọ Israẹli lọ?
8 9254 Orilẹede Thailand 60 0.
“Ìwọ ọmọ eniyan, sọ àsọtẹ́lẹ̀ kí o sì wí pé, OLUWA Ọlọrun ní,
Ní àkókò tí Josaya jọba ni Neko, ọba Ijipti kó ogun rẹ̀ wá sí etí odò Yufurate láti ran ọba Asiria lọ́wọ́.
Àti àwọn ìbéèrè míràn Àwọn nǹkan tí obìnrin lè ṣe pẹ̀lú olólùfẹ́ oníwà ipá lásìkò ìgbélé Coronavirus yìí Owó ìtanràn N40,000 ni mo san nítorí pé mí ò wọ ìbòmú- VincentǸjẹ́ òògùn vitamin C lè pa coronavirus?
Okun to lawọ rẹsurẹsu lo maa n da Brian lọrun.
Tesiwaju si, dokita Onu salaye pe, orisirisi ile-ise jankan-jankan ni o fi orile-ede Canada se ibugbe, eyi ti o si n mu igberu ba eto oro aje orile-ede ohun.
Ẹwẹ, adari ile aṣofin agba l'Abuja, Ahmed Lawan sọ pe awọn aṣofin yoo gbiyanju agbara wọn lati ri i pe awọn ṣiṣẹ pọ pẹlu Aarẹ Buhari lori aba eto isuna to gbe wa siwaju ile.
A sọ fún wọn pé kí wọ́n sinmi díẹ̀ sí i títí iye àwọn iranṣẹ ẹlẹgbẹ́ wọn ati àwọn arakunrin wọn yóo fi pé, àwọn tí wọn yóo pa láìpẹ́ gẹ́gẹ́ bí wọ́n ti pa àwọn ti iṣaaju.
Ní àkókò náà, àwọn ẹran ọ̀sìn yín tí yóo máa jẹ ní pápá oko yóo pọ̀.
“Bí OLUWA Ọlọrun yín bá sì mú kí ilẹ̀ yín tóbi síi gẹ́gẹ́ bí ó ti búra fún àwọn baba yín, tí ó bá fun yín ní gbogbo ilẹ̀ tí ó ṣèlérí fún àwọn baba yín, 
" Bayii ni rogbodiyan ṣe n lọ soke si ni Ariwa Naijiria Ila oorun Ariwa Naijiria ti n foju wina wahala lati ọjọ pipọ, awọn eeyan to ku si tun pọ si ni ọdun yii.
Ọga agba ọlọpaa ni orilẹ́-ede Naijiria, Ibrahim Idris ti tun ransẹ pe aarẹ ile asofin agba nilẹ wa, Bukọla Saraki lẹẹkan si, pe ko yọju si ẹka ọtẹlẹmuyẹ to wa nilu Abuja fun ifọrọwanilẹnuwo lori bi wọn se ro mọ isẹlẹ idigunjale to waye nilu Ọffa.
' Èèyàn 78 kú ó lé ní 4000 tó farapa níbi ìbúgbàmù tó wáyé ní Beirut, Lebanon Ariwo ayọ̀ sọ nílé Remi Surutu, ọmọ rẹ̀ mú ọkọ wale Inú odò ni wọ́n ti rí òkú ọmọ ọdún méjì tó sọnù l'ọ́jọ́ ọdún Eid nílùú Ibadan 'Sẹ́nétọ̀ Abiola Ajimobi wà lọ́run rere' O ni ọna ti awọn alaṣẹ ikọ naa ni ipinlẹ Ọyọ fi n gba awọn eeyan si ikọ naa ko bojumu.
bádérìnwá ni ó jẹ ́ akéde ètò ọ ̀ sán tẹ ́ lẹ ̀ kí wọ ́ n tó gbe lọ sí ìdí ètò ago márùún ìrọ ̀ lẹ ́ ( 5 : p.
Akẹ́kọ̀ọ́ wọlé padà, ìjọba Oyo kò pèsè ìbòmú lòdì sí ìlérí rẹ̀ Ni ibamu pẹlu aṣẹ ti ijọba pa fun gbogbo ile ẹkọ to n bẹ n'ipinlẹ Ọyọ, awọn akẹkọọ to n bẹ ni kilaasi ikẹfa nile ẹkọ alakọbẹrẹ, kilaasi ikẹta ati ikẹfa nile ẹkọ girama, ti wọle pada sẹnu ẹkọ lonii.
Exclusive: Buhari ní àìlera lẹ́mìí, lára, àti lọ́kàn- Obasanjo 'Ti mo ba dara pọ mọ ẹgbẹ Obasanjọ, wọn gbọdọ yẹ mi lọpọlọ wo' Ilé iṣẹ ológun tú ọmọdé 223 afurasí agbébọn sílẹ ní àríwá Nàìjíríà Kí nìdí táwọn olùkọ́ ilé ìwé Federal Girls College Akure ṣe fí òkúta fọ́ ẹ̀rọ ìbánisọ̀rọ̀ àwọn akẹ́kọ̀ọ́ Exclusive: Atiku dára ju Buhari ní ìlọ́po méjì - Obasanjo #BBCNigeria2019 Ọmọ atapatadide to la oniruuru ipenija kọja lati de oke tente tabili irinajo rẹ laye.
 Funke Adesiyan, òṣèré Yollywood tó di olùrànlọ́wọ́ aya ààrẹ, Aisha Buhari Rọ́bà ìdáàbòbò gbówó lórí!"
Bi wọn se pa ọga SARS 'Àwọn SARS ló yìnbọn pa ìyá mi' Kíni iyatọ tó wà láàrin FSARS àti SARS?
fun  gbogbo awon ti won yege ninu eto idibo
Awọn afurasi ajinigbe naa, Abubakar Muhammed ati Ayankunle Ayanleye nileesẹ ọlọpa tun fi ẹsun ipaniyan kan pẹlu, ọjọ kewa osu keje ọdun 2020 si ni isẹlẹ naa waye.
Lẹ́yìn náà, gbé tabili náà wọ inú rẹ̀, pẹlu àwọn nǹkan tí wọn yóo máa lò pẹlu rẹ̀, kí o sì tò wọ́n sí ààyè wọn.
aarẹ lori iroyin ati ikede gbe sita, Garba Shehu ,lati kilọ fun awon omo egbe
Amọ sa loju opo ayelujara ati lori ẹrọ redio nise ni awọn ọmọ ilu naa n gbe orisirisi ikini ati eto kalẹ lati fi ba ọba yọ.
Adehun ti Iran se pẹlu awọn orilẹede agbaye naa, faye gba Iran lati dawọ sise ado oloro tuntun duro, ti awọn orilẹede naa ba dẹ okun ofin ọrọ aje ti wọn fi de wọn.
Ètò ọ̀rọ̀ ajé ilẹ́ Gẹ̀ẹ́sì ti dẹnukọlẹ̀ fún ìgbà akọ́kọ́ láti ọdún 2009, wo bí yóò ṣe nípa lórí rẹ̀.
Cholera Vaccine: NAFDAC kìlọ̀ lórí ayédèrú òògùn ààrùn onígbáméjì
A bọ́ siwaju, a wọkọ̀ ojú omi lọ sí Asọsi.
Ọmọde ni àwọn olórí àwọn eniyan mi;àwọn obinrin ní ń pàṣẹ lé wọn lórí.
Bakan naa lo salaye pe, ọdọ iya oun ni oun gbe dagba nigba ti ipinya de laarin baba ati iya oun nitori bi iya oun se lọ si Mecca, lai bun baba oun gbọ.
Fayoṣe: Bẹ́ẹ ṣe yọ fìlà lórí Bola ige tó pa òwe ikú rẹ̀, kò lè ṣiṣẹ́ fún mi
A fi ọ̀yàyà ṣòrọ̀, kí ọ̀ràn má bàa dunni
Ṣaaju ninu ọrọ kan to sọ lọj Aiku nigba ti wọn fi ọrọ wa Tinubu lẹnu wo lo ti s pe oun kọ ni alakoso Lekki Tollgate, oun ko si ni owo nibẹ.
Ṣaaju ninu ọdun 2018, ajọ to n ri si ere bọọlu afẹsẹgba lagbaye, FIFA fun Modric ami ẹyẹ agbabọọlu to pegede julọ.
nipa eto iranwo N-Power fun awon to ti pari ile-iwe giga ati ise owo fun awon
2019 Election: Bí Buhari ba le lọ Kóòtù ní ẹ̀ẹ̀mẹ́ta- Obasanjo A kẹ̀yìn sí Atiku torí àtúntò Nàíjíríà tó fẹ́ ṣe - Árẹ̀wá Bala Mohammed wọlé gómìnà ìpínlẹ̀ Bauchi Leah Sharibu ni wòlíì wa ní àgọ́ Boko Haram - Obìnrin tó jàjàbọ́ Ajọ INEC ṣalaye pe, Ọjọgbọn Tuluen farapa ninu ikọlu naa, bẹẹ lo si n gba itọju nile iwosan lọwọlọwọ.
"Àkọlé àwòrán, Ajà fẹ́tọ ọmọniyan gbàgboro lAbuja lóri mimu obinrin sátimole nitori iwosọ Obinrin míràn to tún jáde fún ìfẹhonu han náà sọpe ""ọ̀rs yìí ti toju ṣú wa"" ǹkan tó ń ṣẹlẹ̀ si obinrin lórill -èdè Naijiria kò dára, a fẹ kí ńkan yí pada, à fẹ ki ọlọpàá máa dáàbò bo obinrin."
Lati kekere ni Dokita Oluyinka Olutoye ti ni ifẹ si iṣẹ dokitaKíni ẹ mọ̀ nípa Ọmọ́táyọ̀ Olútóyè, Ọ̀jọ̀gbọ́n obìnrin àkọ́kọ́ nínú ẹkọ́ èdè Yorùbá lágbàyé Gẹgẹ bii ọrọ rẹ, 'lati kekere ni mo ti maa n ṣe ere dokita kaakiri inu ile wa' nitori ifẹ rẹ si iṣẹ naa.
Wọ́n fẹ́ ré e bọ́ láti ipò ọlá rẹ̀.
Idiagbon ko ko ọrọ̀ aye jọ lori oye, ko kọle alarinrin, bẹẹ ni ko ka ọkọ ayọkẹlẹ jọ bii ẹkọ.
Wo ohun tí yóò ṣẹlẹ̀ ní ìpàdé àwọn èèkàn Yorùbá láti mú kẹ́ẹ dìbò fún Tinubu ní 2023 Jide Kosoko forin sẹ́nu sọ pé òun ni igi lẹ́yìn ọgbà Mr Latin lórí ipò ààrẹ TAMPAN tó wà Gomina Ganduje to sọrọ nibi ifilọlẹ iwe kan nipa aarẹ ana, Goodluck Jonathan ṣalaye kikun nipa iṣẹlẹ naa.
Ó gbàgbọ́ wípé ìgbàkanìgbàkàn “ohun tí yóò jẹ́ àǹfààní gbogbo ará ìlú gbọdọ̀ bo orí àǹfààní ti ara ẹni.
Ọrọ ko ri bi fọnran fidio to lu ayelujara pa ti se sọ pe o n du ipo aarẹ .
 Oríṣun àwòrán, @thesignalng Gbogbo awọn to n mọọmọ rẹ owo naira silẹ, Ọlọrun yoo da si ọrọ wọn ki ilẹ ọla to mọ.
Ó mú mi ranti ọ̀rọ̀ Oluwa nígbà tí ó sọ pé, ‘Omi ni Johanu fi ṣe ìwẹ̀nùmọ́ fun yín, ṣugbọn Ẹ̀mí Mímọ́ ni a óo fi ṣe ìwẹ̀nùmọ́ yín.
a gbọ ́ pé ń ṣe ni Ọ ̀ ràńyàn ń lọ láti ìlú kan sí ibòmíràn tí ó sì ń tẹ ìlú dó bí ó ti ń lọ káàiri .
 kódà kì í ṣe olè tí a kò bá mọ ̀ ọ ́ sí ẹni tó jí nnkan kan nítorí nínú gbólóhùn bí i .
"''Kazeem ṣèlérí pé oun máa mú mi lọ ìlú òyìnbó k'àwọn SARS tó pá á'' Ọmọ oyè wọ gbaga ọlọ́pàá nípìínlẹ̀ Ogun lóríi ayédèrú sabuké WAEC Ilé ẹjọ́ gíga jùlọ dúró gbọingbọin lórí ìdájọ́ ìdìbò gómìnà Bayelsa ""O tun jẹ ọna ti a fẹ gba lati ke si ijọba pe inu wa ko dun pe ijọba ko ṣe to lati da abo bo ẹmi ati dukia awọn araalu pẹlu gbogbo owo ti wọn ti rọ sinu ọrọ naa ati idaniloju ti wọn n fun wa nigbakugba ti ikọlu ba ṣẹlẹ si awọn eeyan wa."
Ó kún fún àwọn nǹkan burúkú ayé yìí.
Lai pẹ yi ni iroyin tan kaakiri pe Yusuf ti ku ṣugbọn ijọba ni ko si ootọ ninu iroyin naa.
Nehemiah n jẹjọ wiwa ọkọ ni iwakuwa lai ṣe akiyesi, aini iwe awakọ gẹgẹ bi dirẹba, ati aigba aṣẹ lọwọ ọlọkọ ko to wa a.
Árẹ̀wá: Bákan náà ni a kò fẹ́ Atiku torí dúkìá àjọni wà tó fẹ́ tà
Je ki a gbadura gege bi eni ti o nife ilu yii lokan, ni paapaa julo, je a pe agbara ajinde ki o ba wa da si oro orile-ede yii.
Ó yẹ kí ó jẹ́ ẹni tí ó fẹ́ràn ati máa ṣe àlejò, tí ó sì fẹ́ ohun rere, ó yẹ kí ó jẹ́ ọlọ́gbọ́n, olódodo, olùfọkànsìn, ẹni tí ó ń kó ara rẹ̀ níjàánu.
aabo ti ijoba aare Buhari ti wa lori aleefa ,aare Buhari ti mu idagbasoke ba
"Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Kayeefi: 'Ọkọ mi ṣẹ̀ṣẹ̀ ní kí n lọ se mọ́í-mọ́í, tó ṣẹ̀ bá mi ṣeré tán ni mo gbọ́ pé ""Mopol"" yìnbọn pa á' Ninu fidio to fi lede loju opo Instagram rẹ lo ti ṣafihan bi awọn ẹbi, ọrẹ, atawọn gbajumọ lawujọ ṣe tii lẹyin lati ṣe ayẹyẹ ikẹyin fun iya naa to di oloogbe."
Minista Akpabio to n risi ẹkun yii lo sọ lasiko to n jabọ bi wọn ṣe na owo pe awọn Aṣojuṣofin lo n gba iṣẹ akanṣe ida ọgọta ninu ọgọrun un ninu iṣẹ ti awọn ba gbe sita.
Nígbà tí mo ri i, mo wí fún ọba mo ni, ‘Ha!
Lóòótọ́ nígbà tí a máa dé ibẹ̀ ni a ti bẹ̀rẹ̀ sí rí àmì wọn-ọnnì.
Ohun to wa jẹ kayeefi pẹlu baba yii ni pe oun ati ọmọkunrin rẹ, Paul, ni wọn dijọ dajọ ẹwọn fun lori ẹsun pe wọn gbindanwo lati seku pa eeyan kan.
Bí ẹnikẹ́ni bá fẹ́ ṣe ìfẹ́ Ọlọrun, olúwarẹ̀ yóo mọ̀ bí ẹ̀kọ́ yìí bá jẹ́ ti Ọlọrun, tabi bí ó bá jẹ́ pé ti ara mi ni mò ń sọ.
Aṣuri, baba Tekoa, ní aya meji: Hela ati Naara.
Ṣùgbọ́n nígbà tí Ọlọ́run Ọba gbọ́ ọ̀rọ̀ yìí, Ó pa á láṣẹ fún àwọn màlékà pé bí mo bá tí gbé ààrin àwọn ọmọ ènìyàn fún àádọ́rin ọdún kí wọ́n mú mi wá sí etí bodè ọ̀run.
"Ìjà d'ópin, fún ìgbà àkọ́kọ́, bàálù gbéra láti Israel lọ sí UAE Wọ́n ti sún ìdájọ́ àwọn sójà tó pa ìyá àti ọmọ ní ọdun 2018 sí oṣù tó m bọ̀ Ṣé Nàìjíríà lẹ́mìí nkan tí Ghana ń ṣe fáwọn akẹ́kọ̀ọ́ ""Secondary"" tí yóò wọlé ní October yìí?"
Ṣugbọn Itai dáhùn pé, “Kabiyesi, mo fi OLUWA búra, bí ẹ̀mí oluwa mi ọba tí ń bẹ láàyè, pé, ibikíbi tí o bá ń lọ ni n óo máa bá ọ lọ, kì báà tilẹ̀ já sí ikú.
Amọṣa, aba naa ko ti i di ofin titi di asiko yii.
Abubakar, to n rinrin ajo lọ si orilẹede Dubai, ti wọn ti fa le ajọ EFCC lọwọ, lo ko awọn ike ATM naa pamọ sinu paali ohun jijẹ Nodu.
Agbẹnusọ fun ileeṣẹ ọlọpaa nipinlẹ Ogun, DSP Abimbola Oyeyemi to fi iṣẹlẹ naa lede ni, awọn mu awọn mẹrin naa lẹyin iroyin ti wọn gbọ pe, awọn mẹrẹẹrin n wu iboji ni agbegbe Odogbolu.
Nígbà tí wọ́n sọ èyí fún Dafidi, ó dá wọn lóhùn pé, “Kì í ṣe nǹkan kékeré ni láti jẹ́ àna ọba, talaka ni mí, èmi kì í sì í ṣe eniyan pataki.
Wọ́n bi í pé, “Kí ló dé tí o fi ń bá àwọn agbowó-odè ati àwọn ẹlẹ́ṣẹ̀ jẹ, tí ò ń bá wọn mu?
" Fidio naa, ti Ibiyeomie se lori pẹpẹ iwaasu lọjọ Aiku ni ọpọ eeyan n pin kiri lori ayelujara, ti wọn si n sọrọ le lori.
O ni Ojẹlu ni gbogbo awọn oloselu ti wọn n fi ẹgbẹ oselu APC silẹ fun ẹgbẹ oselu PDP, ati wipe oju wọ̀n kan wa ni APC ni sugbọn kan wa ni PDP ki wọn to darapọ mọ ẹgbẹ oselu PDP.
Oral Sex: Bóo bá ń gba ẹnu ní ìbálòpọ̀, wo àìsàn tóo lè kó lójú ara rẹ Orilẹ-ede Palau ti ibode rẹ lati oṣu kẹta ọdun 2020.
Ìdí ti mo fi ṣe iṣẹ́ àmúrelé mi lábẹ́ ATM rèé - Dele Ohun tí o kò mọ̀ nípa Hosni Mubarak, Ààrẹ Egypt tó papòdà Ẹ̀wọ̀n ọdún méje gbáko ni Olisa Metuh yóò fi ṣara ridin!
Ohun tí mò ń fẹ́ ni pé kí ẹ lè gbé irú ìgbé-ayé tí ó yẹ, kí ẹ lè fi gbogbo ara ṣe iṣẹ́ Oluwa, láìwo ọ̀tún tabi òsì.
Abiola Ajimobi ti ipinle Oyo ,gomina  Rotimi Akeredolu ti ipinle  Ondo ati igbakeji gomina ipinle Edo, ogbeni
Ìgbà Marún-un ti Aisha Buhari ti tako ìjọba Buhari Ìdí tí ilé fi wó lu ènìyàn méjì ní Oshodi -LASEMA Mo gbàgbé sùnlọ sìnú ọkọ̀ òfurufú, ẹ̀rù ikú bà mí -Tiff Èyí ẹ ṣe tó, England àti VAR júwe ilé fún Cameroon Gẹ́gẹ́ bi akọròyìn NAN sẹ sọ, ẹni ọ̀wọ̀ Simeon Ononogbu sọ sáa'ju idije ife ẹ̀yẹ àgbáyé pé ikọ Super Falcos yóò de ipele tó kangun si aṣekágbá.
Wọn óo fi ọgbọ́n ẹ̀wẹ́ mú ẹ̀kọ́kẹ́kọ̀ọ́ wọ ààrin yín.
“Ṣe aṣọ títa kan, tí ó jẹ́ aláwọ̀ aró, ati elése àlùkò, ati pupa, ati aṣọ ọ̀gbọ̀ funfun, kí wọ́n ya àwòrán Kerubu sí i lára.
OLUWA, o ti ṣeun fún èmi iranṣẹ rẹ,gẹ́gẹ́ bí ìlérí rẹ.
Ó mú Dafidi lọ bá wọn.
Ṣugbọn jíjá ni yóo já ohun tí wọ́n fi dè é, ni yóo bá sálọ sinu aṣálẹ̀.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Epo rọ̀bì ti ṣàkóbá fáwọn olùgbé apá odò l'Ondo Ilé ẹ̀kọ́ ilẹ̀ Amẹ́ríkà kan tó wà ní orílẹ̀ èdè Zambia sì ni ọmọ náà ń lọ.
Lórí ọjà tó gbé owó lórí lásìkò Coronavirus yìí, gomina woye pe, àwa ara ilu ko feran ara wa, ìdí di nìyí tí wón se n gbe owo lè èròjà gbogbo, ìwọ̀nba sì ni ìjọba leè ṣe lórí rẹ."
Ayipada yii ko yọ ilu Kaduna silẹ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Asisat Oshoala: ìbẹ̀rẹ̀ mi kò rọrùn rárá nínú eré bọ́ọ̀lù Wo ohun mẹ́rin tó jẹ́ ki America tún gbá ife ẹ̀yẹ àgbáyé Orilẹ-ede America ati Netherland ni wọn jọ gbena woju ara wọn ninu idije aṣekagba ti awọn obinrin lagbaye lọdun 2019.
Pataki lara awọn to ba Ojaja II wọ ṣọọṣi ni Arẹmọ tuntun ti Eleduwa ṣẹṣẹ fi jinkii oun ati iyawo rẹ, wolii Naomi iyẹn Arẹmọ Tadenikawo Adesoji Aderemi Ogunwusi.
Ninu lẹta naa lo ti kede pe oun ni ọwọ to jinlẹ fun ilẹ Afrika toun yoo si fi awọn asoju ilẹ Amẹrika to dantọ ransẹ lọ sibẹ.
Nigba ti akọroyin wa pe ọkan lara awọn eeyan to n lewaju iwọde naa, Usman Oloyede lori aago, lori idi ti wọn ko fi kofiri wọn lati wa tẹsiwaju ninu iwọde ti wọn n se, Oloyede fesi pe awọn ko lee jade sita mọ wa se iwọde .
O ni lọpọ igba, itiju nkan ti awọn eeyan awujọ yoo sọ nipa ire eeyan bẹ ẹ le mu ki o sọ pe oun ko ṣe ẹjọ mọ.
“Nítorí àwọn ìṣẹ̀lẹ̀ wọnyi ni mo ṣe sọkún;tí omijé ń dà lójú mi;olùtùnú jìnnà sí mi,kò sí ẹni tí ó lè dá mi lọ́kàn le.
O óo ṣe àwọn ìtẹ́lẹ̀ wúrà, 
8 9406 Orilẹede Comoros 38 4.
Amọ nigba ti yoo fi gba awọn eeyan ni amọran ọrọ naa dabi ẹni pe o nṣe afiwe ọrọ to n lọ lode nipa ifipabanilopọ ni.
Èmi a máa fi ìyà ẹ̀ṣẹ̀ baba jẹ ọmọ ati ọmọ ọmọ, títí dé ìran kẹta ati ìran kẹrin ninu àwọn tí wọ́n kórìíra mi.
 Ìdí tí ó fi fẹ ́ ràn rẹ ̀ nip é nígbà tí Ọ ̀ sanyìnnínbí ń ṣe òkú ìyá rẹ ̀ , ó fún un ní ọgọ ́ rùn-ún náírà ( n100.
” Kí ẹ má baà bọ́ sinu ìdájọ́.
Ariwo bá ta pé“Ẹ gbéra nílẹ̀, ẹ̀yin ológun!
"Mummy Calm Down di aṣojú iléeṣẹ́ ńlá kan l'Abuja Wo ojú àwọn tó na ìka máa lọ ilé sí Praise nilé ẹlẹ́gbọ́n àgbà BBNaija Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Ìgbà tí mo máa fi lajú sáyé padà, ọ̀fọ̀ ikú mi ní wọ́n ń kígbe' ""Kọmísọ̀nà mọ ìpò Covid-19 rẹ̀ lẹ́yìn àyẹ̀wò olóòrèkóòrè ti wọ́n máa ń ṣe, ní báyiì, o ti n gba ìtọ́jú, kò si fi àmì hàn"" Lagos Coronavirus :Ìjọba ìpínlẹ̀ Eko ní àwọn ń ná tó N1million lórí aláàrùn Coronavirus kọ̀ọ̀kan Oríṣun àwòrán, Twitter/Sanwo-Olu Ijọba ipinlẹ Eko ti ni o kere tan miliọnu kan naira ni awọn n na lojumọ lori ẹni kọọkan ti arun Coronavirus pa peleke lara wọn."
Won ti ro ijoba orile ede Naijiria lati wa ojutuu si iyanselodi awon osise eleto ilera JOINT Health Sector Unions, JOHESU, lati din emi to n fi  ojoojumo sofo ku.
Eniyan mẹta ni wọn ti kede pe o ni aarun naa ni Kenya.
22 Bélú 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Aare de si ipinle  Katsina lojo Ẹti, ojo kejilelogun osu keji,  pelu iyawo re , Aisha pelu oko ofurufu ti
“Nítorí náà, ohun tí mo sọ fun yín yìí, ẹ pa á mọ́ sinu ọkàn yín.
Samsoni dáhùn pé, “Bí mo bá ṣe àwọn ará Filistia ní ibi ní àkókò yìí, n kò ní jẹ̀bi wọn.
Ẹnikẹ́ni tí ó bá jẹ́ ọkunrin ninu àwọn ọmọ Aaroni lè jẹ ninu rẹ̀, èyí ni ìlànà mi títí ayérayé láàrin arọmọdọmọ yín, ẹnikẹ́ni tí ó bá fi ọwọ́ kan ẹbọ wọnyi yóo di mímọ́.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: SEC: Tinubu kò gbọdọ̀ ṣe olúdarí iléeṣẹ kankan fódùn márùn ún Iléeṣé MTN ti san bíliọnù N55 owó ìtanràn wọn tó kù -MTN Áfíríkà yóò gba ife ẹ̀yẹ UEFA Champions league lónìí Wọ́n ti ni kí àwọn alága ìjọba ìbílẹ̀ Ogun lọ rọọ́kún nílé Nitori eyi, n ṣe ni awọn akẹkọọ ileewe giga naa ya bo ileewosan to wa ni ọgba ileewe naa ti wọn si dana sun oko atawọn ohun elo miran to wa nibẹ.
Bakan naa ni Ogagun Sani sọ fun BBC pe awọn ọmọ ogun ofurufu lo pada gbẹsan lara awọn oniṣẹ ibi naa ninu igbo Sambisa nipinlẹ Borno.
 albert ruskin cook ni ẹni àkọ ́ kọ ́ tó ṣe àpèjúwe ọgbẹ ́ -inú buruli ní ọdún 1897 .
Nígbà tí ó wọ inú ilé oriṣa lọ, àwọn kan ninu àwọn ọmọ rẹ̀ ọkunrin bá fi idà pa á.
Ó ń kọ́ wọn pé, “Kò ha wà ninu àkọsílẹ̀ pé, ‘Ilé adura fún gbogbo orílẹ̀-èdè ni a óo máa pe ilé mi?
Àwọn jẹsí tó gbajúmọ̀ nínú ìtàn ìdíje bọ́ọ́lù Bí àìsàn bàbà mi ṣe ń lọ, ló tún ń padà, kódà kò yé mi mọ- Ọmọ Bàbá Sùwé Coronavirus ti di ara wa, kò le è kúrò mọ láéláé - WHO Kí ló ń mú àwọn adarí obìnrin lágbáyé rọwọ mú nípa kíkojú covid 19?
O ti ran àwọn ọ̀tá rẹ̀ lọ́wọ́;o ti mú kí àwọn ọ̀tá rẹ̀ yọ̀ ọ́.
 boko haram pa àwọn ènìyàn tí ó ju 6,600 lọ ní Ọdún 2014 .
Àwọn eniyan rẹ yóo fi tọkàntọkàn fa ara wọn kalẹ̀,lọ́jọ́ tí o bá ń kó àwọn ọmọ ogun rẹ jọ lórí òkè mímọ́.
Ofin tuntun naa ni ijọba laṣẹ lati sọ igba ti awọn ileeṣẹ iroyin yoo gbe iroyin jade ti rogbodiyan ba bẹ silẹ ni Naijiria.
Saulu Lọ Ṣe Àyẹ̀wò lọ́dọ̀ Abókùúsọ̀rọ̀.
Oríṣun àwòrán, Reuters Agbẹjọrọ fun Jeremy sọ wi pe ko jẹbi ẹsun kankan ti wọn fi kan an, ati wi pe awọn obinrin ni wọn ti ara mọ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Makinde: Ẹgbẹ́ òṣìṣẹ́ faramọ́ wíwọ́gilé ₦3000 táwọn akẹ́kọ̀ọ́ girama ń san Eyi ni igba keji ti akọnimọọgba Jurgen Klopp yoo gbe ẹgbẹ agbabọọlu Liverpool de ipele aṣekagba idije UEFA Champions League lẹyin Real Madrid gba ife naa mọ wọn lọwọ ni saa to lọ.
Nígbà tí o bá ka ẹran ọ̀sìn rẹ,kò ní dín kan.
Awọn to farapa níbí iṣẹ̀lẹ̀ náà ni wọn ti ko lọ si ile iwosan ǹla ti Abuja láti gba itọju.
Mo ti ṣe ohun tí ó tọ́ tí ó sì yẹ,má fi mí sílẹ̀ fún àwọn tí wọn ń ni mí lára.
Ilẹ kọkọ ṣe bi ẹni fẹ pooyi fun Arsenal ninu ifẹsẹwọnsẹ naa nigba ti John mcGinn gba bọọẹu wọle nitori aikiyesara awọn adilemu Arsenal to n woran lẹyin.
Ìgbà tó ṣe díẹ̀ ni òjò bá bẹ̀rẹ̀, tí àrá ń sán fààràrà.
ṣugbọn wọn ń lò ó láti fi san owó fún àwọn òṣìṣẹ́ ati láti ra àwọn ohun èlò fún àtúnṣe ilé OLUWA.
" Ilorin Blue Eyes Family: Ìyá àwọn ọmọ tí bàbá kọ̀ sílẹ̀ torí àwọ̀ ojú wọn bá BBC sọ̀rọ̀ Èèyàn mẹ́tàdínláàdọ́fà ló móríbọ́ lọ́wọ́ Covid-19, 443 míì tún lùgbàdì rẹ̀ lọ́jọ́ Ẹtì Èèyàn 16 kú lẹ́yìn tí bàálù Air India já lulẹ̀ , tó sì kán sí méjì ní Kerala Ilé ẹjọ́ ti dájọ́ Naira Marley, wọ́n ní kó san owó ìtànràn, kó tún tọrọ àforíjì Ilẹeṣẹ orilẹede Amerika wa kesi gbogbo awọn oloṣelu ati awọn ti ọrọ kan lati ma ṣe jẹ ki eto idibo sipo gomina ti yoo waye ni ipinlẹ Ondo ati Edo da rogbodiyan ni ilu.
Eleasari ọmọ rẹ̀ sì ń ṣe iṣẹ́ alufaa dípò rẹ̀.
Àkọlé àwòrán, Damilọla pàdánù ọ̀rẹ́kùnrin rẹ̀ nítorí pé ó kọlà O ni 'awọn ẹlẹgbẹ mi fi aye su mi, nigba ti mo wa ni kekere.
Kí wọn máa gbọ́ràn sí ọkọ wọn lẹ́nu, kí ẹnikẹ́ni má baà lè sọ ìsọkúsọ sí ọ̀rọ̀ Ọlọrun.
Adajọ paṣẹ $25,000 fun oloyun tan fi'ya jẹ Ile-ẹjọ kan ni orilẹede Kenya ti da ẹjọ ki ijọba o san iye ẹgbẹrun mẹẹdọgbọn owo ile Amerika, (milionu naira mẹsan) fun obinrin oloyun ti wọn fi iya jẹ ni ile iwosan ijọba lọdun marun sẹyin.
OLUWA bèèrè lọ́wọ́ rẹ̀ pé, “Kí ló wà ní ọwọ́ rẹ yìí?
Gbogbo àwọn eniyan náà kígbe sókè, wọ́n dáhùn pé, “Òtítọ́ ni o sọ, bí o ti wí ni a gbọdọ̀ ṣe.
Wọ́n ń gbin afẹ́fẹ́, wọn yóo sì ká ìjì líle.
Ó ní adágún omi kan tí àwọn ẹja onírúirú wà, tí àwọn apẹjagbafẹ́ sì máa nwa jòkó sí etí ẹ̀.
orilẹede Kenya yii lo gba ami ẹyẹ ninu gbogbo ere idaraya to ti kopa, to si se aseyọri nla ninu ere sisa onibusọ gbọọrọ.
Areghan sisọ loju ọrọ yii lasiko to se abẹwo sawọn ileẹkọ kan ladugbo Yaba nibi ti idanwo WAEC ti n lọ lọwọ, to si rọ awọn akẹkọ ibẹ lati ta kete si sise makaruru lasiko idanwo.
pẹlu gbogbo akitiyan lati kan si ile iṣẹ to n ri si ibanisọrọ ni Caracas ati aṣoju ijọba Venezuela nilẹ United Kingdom, BBC ko tii ri esi kankan si awọn ibeere yii.
Bẹ́ẹ̀ ni ó sì yẹ kí gbogbo yín kà á sí.
iwadii lati yẹ isẹlẹ naa wo finni –finni laarin wakati mọ́kàndínláàdọ́ta.
O sọ pe NIPOST nikan lo ni aṣẹ lati ta a, tabi gba ileeṣẹ ti yoo maa ba a ta.
Wo dókítà ọmọ Nàìjíríà tí àgbáyé ń wárí fún nítorí abẹ́rẹ́ àjẹsára COVID-19 Ìyàwò lárìnlọọ̀dù mi pè mí ní akálòlò ni mo ṣe paa - Afurasí Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Adeyeye Ile Ife: Kílódé tí Ọọni Ife, Oba Ogunwusi kò fi gbọdọ̀ rí ọmọ rẹ̀ tuntun títí di ẹ̀yìn oṣù mẹ́fà?
Ogoji ìtẹ́lẹ̀ fadaka ni kí o ṣe sí àwọn ogún àkànpọ̀ igi náà, ìtẹ́lẹ̀ meji meji sí àkànpọ̀ igi kọ̀ọ̀kan, kí ìtẹ́lẹ̀ meji wà fún àtẹ̀bọ̀ igi meji ninu olukuluku àkànpọ̀ igi náà.
Ọmọ mi kò tíì mọ̀ pé òun ti di ìlúmọ̀ọ́ká, ó ń wádìí bó ṣe ń rí ara rẹ̀ lórí ayélujára"" Àwa àti fijilanté pẹ̀lú ọdẹ́ ìbílẹ̀ ló dojú kọ adigunjalè ní First Bank Okeho - Iléeṣẹ́ ọlọ́pàá Ẹ káàbọ̀ sọ́jọ́ Arafat, tí Ọlọ́run yóò fi ààwẹ̀ Mùsùlùmí pa ẹ̀ṣẹ̀ wọn rẹ́ Akẹ́kọ̀ọ́ Babcock tí wọn bá lòpọ̀ nínú fídíò rí ẹ̀kọ́ ọ̀fẹ́ ní fásitì òkè òkun Baba ibẹrin naa ṣalaye pe oriṣiriṣi awọn eeyan ni Naijiria, titi de Portugal ati Brazil lo ti n pe lati fowo ṣowọ si oun, lẹyin naa lo dupẹ lọwọ gbogbo wọn."
Lọpọ igba ọkunrin lo maa n sọ ero ọkan lati fẹ obinrin.
Ẹnìkínní ti idà rẹ̀ bọ ẹnìkejì rẹ̀ ní ẹ̀gbẹ́, àwọn mẹrẹẹrinlelogun ṣubú lulẹ̀, wọ́n sì kú.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Fi àmì sórí 'awa gangan lara' Sé orin ń se ìwúrí fún ìwà Yahoo bí?
"Ọjọ kẹta, oṣu Kẹrin ni wọn kọkọ sun idije Premier league siwaju, lẹyin naa ni wọn tun sun un ni ọgbọnjọ, oṣu Kẹrin, nitori ajakalẹ arun coronavirus to n gba ẹbọ lọwọ gbogbo agbaye yiii.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Federal Cabinet: Onímọ̀ ní ewu ń bẹ lórí bí ìsàkóso ìjọba ṣe dúró rigidi 21 Agẹmo 2019 Oríṣun àwòrán, @MBuhari Awọn onimọ nipa ọrọ aje ti mu igbe bọnu pe, ewu n bẹ loko Longẹ fun orilẹede Naijiria, to si seese ki ọrọ aje tun dagun lẹẹkan si ti aarẹ Muhammadu Buhari ko ba tete kede awọn ọmọ igbimọ alasẹ rẹ.
MTN àti BBC World Service bẹ̀rẹ̀ àjọṣepọ̀ lórí ìròyìn ìṣẹ́jú kan BBC Bi o ba jẹ ọkan lara awọn ololufẹ ileesẹ BBC ti o si ti n ronu bi wa a ti se maa gbadun iroyin isẹju kan wa nigbakugba nibi kibi, iroyin ayọ la mu tọ yin wa yi.
Seun Fakorede: Iṣẹ́ tí Seyi Makinde rán mi nipínlẹ̀ Oyo níkan ní màá jẹ́
Ni orile ede Afirika , a maa n bowo fun awon to ba ju wa lo.
Àwọn yìí ń ṣe ìsìn wọn ninu ilé ìsìn tí ó jẹ́ ẹ̀dà ati àfijọ ti ọ̀run.
Lọjọ kẹrinlelogun, oṣu keje ni agbẹjọro awọn mẹta to pe Buhari ọhun, Ukpai Ukairo gbe ọrọ naa lọ siwaju ile ẹjọ to ga julọ.
Ewe, latari ifesun kan ohun, won ti ogbeni Fahngon mo atimole logba ewon ti o wa laringungun iluu Monrovia, nibi ti o ti lo ale akoko re lojoRu(Wednesday).
Aarẹ ASUU ni didun lọsan o so lasiko igabniwọle awọn akẹkọọ ti ohun gbogbo to n run ba tan nilẹ ti awọn ọmọ si wa ni alaafia.
Lati igba naa titi di bi a ti ṣe n sọrọ yii, Zainab to jẹ akẹkọ fasiti Yusuf Maitama Sule ṣi wa ni atimọle.
4 836764 Orilẹede Poland 21630 57.
Ọrọ gbọna mi yọ lọjọ Iṣẹgun, nigba ti iroyin lu sita pe awọn ọlọpa ti mu olorin to kọ orin naa gangan, nibi ti o ti n di ẹru lati sa nilu.
Ilẹ̀ mímọ́ ni gbogbo ilẹ̀ náà yóo jẹ́.
 Àkọtọ ́ lárúbáwá ( arabic ) ni wọ ́ n fi kọ ọ ́ sílẹ ̀ .
Ọba fi eyín erin ṣe ìtẹ́ ńlá kan, ó sì yọ́ ojúlówó wúrà bò ó.
Buhari ni gbogbo àwọn iṣẹ́ ribiribi ti Ọbasanjọ ti gbése lo mu ki ìjọba awa ara wa àti ìsọ̀kàn orílẹ̀-èdè Nàìjíríà ó gbòòrò si.
Coronavirus ti di ara wa, kò le è kúrò mọ láéláé - WHO Kí ló ń mú àwọn adarí obìnrin lágbáyé rọwọ mú nípa kíkojú covid 19?
Oríṣun àwòrán, Reuters Lọdun 2000, oludije ẹgbẹ Democrat, Al Gore fidirẹmi ninu idibo aarẹ lẹyin eyi si ni gbọnmi si omi o to bẹ silẹ to le ni oṣu kan - ile ẹjọ giga julọ lo si pada dajọ ọhun to fi pada gbe lẹyin oludije ti ẹgbẹ Republic, George W Bush.
Afẹ́nifére: Àwọn Ọba kò lè júwe ìdìbò 2019 Oríṣun àwòrán, YOUTUBE Àkọlé àwòrán, Odumakin àti Adebanjo: Àwọn Ọba kàn ń sọ tẹnu wọn ni o Ẹgbẹ Afénifẹ́re ṣe lòdì sí ọ̀rọ̀ àwọn Ọba ilẹ Yoruba kan.
Ajọ to n mojuto bọọlu afẹsẹgba ni Cameroon (Fecafoot) ti kede pe ọjọ kẹsan, oṣu Kinni ni idije Africa Cup of Nations yoo bẹrẹ l'ọdun 2021.
Ìfẹ̀hónúhàn ọ̀dọ̀ tí ó tó bíi 100 wáyé ní ọjọ́ kẹ́rin oṣù Èrèlé, pẹ̀lú àtìlẹ́yìn ẹgbẹ́ àwọn ọmọ ìlú kan tí ó rí ìgbésẹ̀ ìjọba gẹ́gẹ́ bí ọ̀nà láti gbẹ́sẹ̀ lé ẹ̀tọ́ àwọn ènìyàn fún ìrìnàjò ṣíṣe.
Lati igba naa wa, awọn meji to lewaju ninu esi ibo ọhun- Gboyega Oyetọla ti ẹgbẹ oṣelu APC pẹlu Ademọla Adeleke ti ẹgbẹ oṣelu PDP-ti n wọle jade nile ẹjọ kaakiri pẹlu ẹsun emi ni mo bori-iwọ kọ.
Jigawa ati Katsina si je ipin keta ti Ipinle Akwa-Ibom ati Cross River je ipin
Kò sí ẹni tí ó lè mọ ìyàtọ̀ láàrin ariwo ẹkún ati ti ayọ̀ nítorí pé, gbogbo wọn ń kígbe sókè, tóbẹ́ẹ̀ tí àwọn eniyan sì gbọ́ igbe wọn ní ọ̀nà jíjìn réré.
àwọn òrùka yìí ni wọ́n máa ń ti ọ̀pá bọ̀ láti fi gbé tabili náà.
O lewu fun ọ ti o ko ba mọ ẹsun ti wọn fi kan ẹni to n jẹjọ.
 Ó jé òloṣèlú orílè èdè améríkà , ọmọ ilé ìgbìmó aṣòfin láti ìpínlè illinois , ọmọ ẹgbé òṣèlú democrat .
Ó kúrò níbẹ̀, ó lọ gbẹ́ kànga mìíràn, ẹnikẹ́ni kò sì bá a jà sí i, ó bá sọ ọ́ ní Rehoboti, ó wí pé, “Nisinsinyii Ọlọrun ti pèsè ààyè fún wa, a óo sì pọ̀ sí i ní ilẹ̀ yìí.
Àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ sọ pé, “Kedere ni ò ń sọ̀rọ̀ nisinsinyii, o kò sọ̀rọ̀ lówe lówe mọ́.
Ìjà náà sì túbọ̀ ń le sí i, nítorí ọ̀ràn náà ń fẹ́ẹ́ bọ́ sí ìtìjú, nítorí ìyàwó àwọn méjèéjì bi wọ́n dúró tí wọ́n ń wo ọkọ wọn.
Ọlọrun kò sì pa àwọn àgbààgbà Israẹli náà lára rárá, wọ́n rí Ọlọrun, wọ́n jẹ, wọ́n sì mu.
mo fi òṣùmàrè mi sí ojú ọ̀run, òun ni yóo máa jẹ́ àmì majẹmu tí mo bá ayé dá.
Oríṣun àwòrán, Alaafin Oba Adeyemi III Idi ni pe ojo lẹta miran tun ti yọju sita eyi ti wọn kọ si gomina Seyi Makinde, amọ to n fun Alaafin lesi pada nipa ọrọ to ba Fayemi sọ lori ọrọ awọn lọbalọba.
Nítorí náà, mò ń sọ fun yín, mo sì ń bẹ̀ yín ní orúkọ Oluwa pé, kí ẹ má máa hùwà bíi ti àwọn abọ̀rìṣà mọ́, àwọn tí wọn ń hùwà gẹ́gẹ́ bí èrò asán ọkàn wọn.
Idi ree ti ẹgbẹ akẹkọọ lorilẹede yii, NANS ko se fẹ kawọ gbera lori iku to pa meji lara awọn akẹkọọ fasiti Ọyẹ Ekiti lasiko ti wọn n se iwọde pe ko si ina ọba.
Ẹnikan to sunmọ agbabọọlu naa sọ fun akọroyin BBC wipe owo ti wọn ra agbabọọlu naa to aadọruun miliọnu dọla owo orilẹede Amẹrika, iyẹn owo to le ni biliọnu mejilelọgbọn baira.
Lẹ́yìn ìgbeyàwó ọdún mọ́kànlá àti ọ̀pọ̀ ìjà, Bọsẹ di èrò ọ̀run nílé Saidi Wọ́n ti pa ẹni to yìnbọn pa ará Texas márùn ún -ọlọ́pàá Adeboye sọ̀rọ̀ lórí ètò pápá ìjẹko RUGA O ni ipinlẹ Ọṣun kọ ni irufẹ ofin bayii yoo ti kọkọ waye, nitori naa ajọṣepọ yoo wa laarin pẹlu awọn aṣofin ipinlẹ miran lorilẹ-ede Naijiria lati rii pe awọn naa gbe iru ofin bayii kalẹ ni ipinlẹ koowa wọn.
Awọn eeyan mi a ma nilo fẹntilatọ lati le fi mi daada.
Diẹ lara wọn ni: Ṣáájú ìdìbò 2018 Oriṣiiriṣi nkan lọ ṣẹlẹ laarin awọn ẹgbẹ oṣelu to n dije fun ipo gomina Ekiti paapaa àwọn ti PDP ati APC.
A fi aṣọ kan wé e sí ẹ̀yìn efodu.
O fikun wi pe awọn ijọba to ti wa tẹlẹ ti gbiyanju lati ṣe eyi, amọ wọn ko ni igboya lati ri wi pe o wa si imuṣẹ.
Ó tọ Solomoni lọ, ó sì bá a ṣe gbogbo iṣẹ́ rẹ̀.
Ṣé INEC yóò tún ìwé ìdìbò tẹ̀ nítorí Banky W?
Jẹ́ kí n mọ ẹ̀ṣẹ̀ mi, ati ibi tí mo ti kọjá ààyè mi.
Nigba ti BBC kan si banki Naijiria, CBN, wọn ni gbogbo igba lawọn maa n kilọ fawọn ọmọ Naijiria lori owo sogundogoji.
 Obasanjọ sọ pe ara eto ayẹyẹ ọjọ ibi naa ni lati ṣapero pẹlu awọn olori lati Asia, lati mọ aṣiri bi wọn ṣe goke agba lawujọ agbaye ati ẹkọ ti ilẹ adulawọ le kọ lara wọn."
 Òní ọjọ́ Kàrún oṣù Ẹrẹ́nà ni Oluségun Àrèmú Ọbásanjọ́ pé ọdún méjìlèlọgọ́rìn lókè erùpẹ̀.
Alakoso ajo to n mojuto ọrọ owo ifẹyinti lorile ede Naijiria, Sharon
Oṣere tiata lobinrin naa lo ṣe amulo ẹrọ igbalode kan lati sọ ara rẹ di ọmọde pada, ẹni tí ko ba si wo daadaa, ko ni mọ pe oun ni, nitori isọrọ ati oju rẹ to jọ ti ọmọde Lizzy Anjorin ati Kemi Korede ṣe afihan fọto igba ewe wọn : Oríṣun àwòrán, others Ọkan lara igbesẹ idanilaraya to n waye lati ọdọ awọn oṣere tiata ni afihan fọto igba kekere ọpọ wọn.
Ìtàn míràn bí a ṣe tẹ Ijẹ̀bù-Jẹ̀ṣà dò àti bí a ṣe mọ̀ ọ́n tàbí sọ orúkọ rẹ̀ ní Ìjẹ̀bí-Jẹ̀ṣà ni ìtàn àwọn akíkanjú tàbí akọni ọdẹ méje tí wọ́n gbéra láti Ifẹ láti ṣe ọdẹ lọ.
Ní ìgbà ayé Jesu, pẹlu igbe ńlá ati ẹkún, ó fi adura ati ẹ̀bẹ̀ rẹ̀ siwaju ẹni tí ó lè gbà á lọ́wọ́ ikú.
Eto yii jẹ ajóṣẹpọ ẹgbẹ Onimọ Yoruba, YSAN ati ti apapọ ẹgbẹ Akomolede ati Aṣa Yoruba ti Naijiria lapapọ.
Eyi lo mu ki Ṣoworẹ sọ pe oun yoo sọ tita ati lilo igbó di ohun to ba ofin mu.
Kí o gba ṣekeli marun-un-marun-un lórí ẹnìkọ̀ọ̀kan, gẹ́gẹ́ bí ìwọ̀n ṣekeli tí wọn ń lò ní ibi mímọ́.
Oniruuru ero ni yoo maa wako lookan aya awon minisita bayii, latari bi asiko atunto  saa isakoso isajoba aare Buhari  miiran se n sun mo etile.
Ẹfunsetan Aniwura, obìnrin tó ju ọkùnrin lọ Ọ̀rọ̀ǹpọ̀tọ̀niyùn, Aláàfin obìnrin àkọ́kọ́ rèé, tó ní nǹkan ọkùnrin Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí 2 sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 2:23 Fídíò, Water Generator: Ó leè ṣiṣẹ fún wákàtí mẹfà, kó tó sinmi, Duration 2,2310 Òkùdu 2020 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
" Oríṣun àwòrán, realyomifabiyi Fabiyi wa kesi awọn akẹẹgbẹ rẹ to jẹ osere tiata pe ki wọn ti ọwọ ọmọ wọn bọ asọ nidi sise atilẹyin ninu fiimu fun awọn agbofinro lati maa fiya jẹ awọn afurasi.
Baba tí ó ń gbé inú mi ni ó ń ṣe iṣẹ́ rẹ̀.
Baalẹ abule naa ṣalaye pe iru iṣẹlẹ naa ti aye ri lọdun 1998, to si yọri si iku awọn kan ninu abule.
fun ipo yii, nipase pipa ohun pọ lati yan an gege bi aare lasiko ipade apero ajo
Orin ọpẹ ati iyin lo gba ẹnu rẹ pe ohun ati awọn ọmọ rẹ ko padanu ẹmi wọn.
Ile ẹjọ ti paṣẹ pe kii ṣe itapa si ofin mọ ki ọkunrin ati ọkunrin tabi obinrin ati obinrin maa bara wọ lo pọ.
Ọgbẹni Hassan sọ siwaju wipe o jẹ iwa ti ko bojumu fun ijọba ati wipe o n fa irora fun awọn eniyan.
ati òbúkọ kan fún ẹbọ ìmúkúrò ẹ̀ṣẹ̀ láti ṣe ètùtù fun yín.
Ẹ má ṣe oríkunkun, bí àwọn baba yín.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ǹjẹ́ o rí ọlọ́pàá SARS tó ń hùwà àìtọ́ láwùjọ?
 Ephrahim Jackson, to je olori ile iwe naa salaye fawon oniroyin pe Äsiko yii bani ninuje gidi fun gbogbo akekoo ati oluko ile-iwe yii.
leti pe won ni lati san owo die fun agbasese ti yoo maa ko idoti naa.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Obasanjọ: Ọbasanjọ ní òhun yóò fi ìyókù ayé òun san oore Ọlọrun ni Nàíjíríà ti pín yẹ́lẹyẹ̀lẹ láyé Buhari, ìjákulẹ̀ dé!
Awọn ọlọpa yoo pada ranṣẹ pe e ti o ba paa dandan.
Lara awọn oṣiṣẹ kekeeke ti wọn se mọ ẹnu ọna ṣe alaye fun awọn oniroyin labẹ aṣọ wi pe awọn ọga kan lo ni ki wọn maa bọ lẹnu iṣẹ ṣugbọn ọrọ ko ri bi wọn ṣe ro lẹnu ọna abawọle.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Coronavirus in Nigeria: BBC ṣe àbẹ̀wò sí Mọ́ṣáláṣí Alhaja níbití àwọn aládùúgbò ti kọlu àwọn ọlọ́ọpàá ní ìpínlẹ̀ Èkó Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Coronavirus in Nigeria: BBC ṣe àbẹ̀wò sí Mọ́ṣáláṣí Alhaja níbití àwọn aládùúgbò ti kọlu àwọn ọlọ́ọpàá ní ìpínlẹ̀ Èkó 7 Ìgbé 2020 Ọ̀rá ni àwọn dókítà fi ń dáàbò bo ara wọn nílẹ̀ẹ Gẹ̀ẹ́sì Kí lo mọ̀ nípa fẹntilétọ̀, ohun èlò aṣèrànwọ́ èémí Èyí ni ìdí tí coronavirus ṣe n pa àwọn kan, tí kò sì pa àwọn kan Èèyàn mẹ́fà míràn tún ti ní àrùn Coronavirus ní Naijiria Kínni ìtàkùn ayélujára 5G nííṣe gan na pẹ̀lú ààrùn coronavirus?
N óo mú kí á máa ki oríkì rẹ láti ìran dé ìran;nítorí náà àwọn eniyan yóo máa yìn ọ́ lae ati laelae.
Ẹ máa ranti lemọ́lemọ́ láti máa pa gbogbo òfin tí Mose iranṣẹ OLUWA fun yín mọ́, pé kí ẹ fẹ́ràn OLUWA Ọlọrun yín, kí ẹ sì máa rìn ní ọ̀nà rẹ̀, ẹ máa pa gbogbo òfin rẹ̀ mọ́, ẹ súnmọ́ ọn, kí ẹ sì máa sìn ín tọkàntọkàn.
Rapinoe to pada jẹ ọkan ninu goolu to mu ki Amerika na Netherland ko deede ri goolu naa jẹ, awọn kan ni wọn gba bọọlu naa titi to fi de ẹsẹ tirẹ.
Ó ní òun óo fún un ní ibi tí ó dára jùlọ ní ilẹ̀ Ijipti, wọn yóo sì jẹ àjẹyó ninu ilẹ̀ náà.
Iroyin to n jade lati ile iṣẹ iroyin Naijiria ni pe ọpolọpọ ero lo wa kirun Jimọ lana ni mọṣalaṣi ile ijọba apapọ ni Aso Rock nilu Abuja to jẹ olu ilu Naijiria.
 o tun ni bode omi mo japan ( lati egbe okun-omi okhotsk ) ati amerika ( lati egbe bering strait ) .
le so ohunkohun fun yin bayii, nitoripe a sese de ni, sugbon a o maa fi bi oro
Lẹ́yìn náà, ó ra òkè Samaria ní ìwọ̀n talẹnti fadaka meji, lọ́wọ́ ọkunrin kan tí ń jẹ́ Ṣemeri.
Kókó ìròyìn t'òní: 'Ẹ ṣọ́ra ní London', ‘Ìkọlù darandaran pa èèyàn 2000’
Nítorí fìtílà ni òfin,ìmọ́lẹ̀ ni ẹ̀kọ́, ìbáwí sì jẹ́ ọ̀nà ìyè,
ẹ gbọ́ orin kérésì yii; A kú ọdún!
Bí o ti sùn, ò ń ronú ohun tí yóo ṣẹlẹ̀ lẹ́yìn ọ̀la, ẹni tí ń fi ohun ìjìnlẹ̀ han ni sì fi ohun tí yóo ṣẹlẹ̀ hàn ọ́.
Nigba to n fidi isẹlẹ yii mulẹ, Oludamọran agba feto iroyin si gomina ipinlẹ Kwara, Muideen Akorede ni, se ni awọn ọ̀dọ̀ náà ń pariwo Gambari pé kó fi ìlú àwọn sílẹ̀ nítori kò sí ìdí tó fi yẹ kó wà nínú ìlú náà.
Ẹ̀yin gan-an ni ẹ fi idà pa àwọn wolii yín ní àparun,bíi kinniun tí ń pa ẹran kiri.
“Ni bayii, A n wo papa isere ilu Port Harcourt, ti atunse papa isere ilu Abuja ko ba ti pari,”  “Fun igbaradi iko ohun, ipese lorisirisi ti wa nile fun won ati atileyin ijoba, bee si ni o damiloju pe, iko Super Eagles yoo kopa ribiribi.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Olùkọ́ aláàánú: Ìda mẹ́jọ sí mẹ́wàá owó oṣù Peter Tabichi, ló ń fún aláìni 25 Ẹrẹ̀nà 2019 Oríṣun àwòrán, Varkey Foundation Àkọlé àwòrán, Brother Peter Tabichi ni wọn gbe oriyin fun gẹgẹ bii alaanu olukọ Olukọ sayẹnsi kan ni abule kan ni orilẹede Kenya, ti a gbọ pe o maa n fi gbogbo owo oṣu rẹ tọrẹ fun awọn ọmọ ile iwe to jẹ alaini, ti gba ami ẹyẹ agbaye kan ti wọn fi fun un ni miliọnu kan dọla.
Ẹgbẹ Agbẹkọya Peace Movement of Nigeria ti rọ ijọba lati lo ẹgbẹ awọn lati dẹkun eto aabo to mẹhẹ lorilẹede Naijiria paapaa ni ilẹ Yoruba.
BBC ba Peter Goffin sọrọ l'ori ọna to n gba lo igbesi aye rẹ lasiko yii.
Oríṣun àwòrán, ICPC Àkọlé àwòrán, Ilé ẹ̀jọ́ tún pàṣẹ pé ẹnikẹ́ni tó bá nífẹ̀ẹ́ láti ra àwọn dúkìá náà gbọ́dọ̀ yọjú láàárín ọ̀sẹ̀ méjì péré Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Nítorí ọ̀rọ̀ ẹnu wọn ati ìṣe wọn lòdì sí OLUWA,wọ́n ń tàpá sí ògo wíwà rẹ̀.
Ilé Aṣòfin Àgbà fòǹtẹ̀ lu N30,000 owó oṣù òṣìṣẹ́ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Kloe: Èmi kìí mu òògùn olóró, àmọ́ mo fẹ́ràn láti máa wà lẹ́bà omi Ṣugbọn Ugwummadu ni igbesẹ ileeṣẹ to ba dan iru nkan bayii wo lodi si ofin agbaye ati ti Naijiria.
O kò ní lọ láìjìyà, dájúdájú ìyà óo jẹ ọ́.
Amọ, awọn oluworan ni o ṣeeṣe ki Prince jẹ ẹni ti yoo lọ sile, amọ Dorathy ni awọn eniyan wo wi pe ko lee lọ ninu awọn mẹrin naa.
Mo sì rí aadọrin ninu àwọn àgbààgbà àwọn ọmọ Israẹli, wọ́n dúró níwájú àwọn oriṣa wọnyi, Jaasanaya ọmọ Ṣafani dúró láàrin wọn.
Ó tún bẹ̀rẹ̀ láti Jẹriko lọ sí apá àwọn ìlú tí ó wà ní orí òkè, títí dé Bẹtẹli.
Nigba ti yoo si fi di ọjọ Kẹrinla, osu Keji, ọdun 1949, okiki ọrọ naa ti gba ilu kan, tawọn iwe iroyin si ti kede rẹ, bẹẹ ni ijọba eebo tutọ soke, foju gbaa, lori isẹlẹ laabi naa.
O wa nibi aṣekagba ipologo idibo ti ẹgbẹ rẹ PDP ni Osogbo.
3 5524 Erekusu Saint Martin ( Agbegbe ti France) 26 69.
Ayédèrú òògùn ààrùn onígbáméjì tó wà ní ta rèé Àjọ INEC ti bẹ̀rẹ̀ ìkéde èsì ìdìbò gómìnà ìpínlẹ̀ Rivers Ahmed Musa gbàmì ẹ̀yẹ agbábọ́ọ̀lù tó pegede ní ọdún 2018 Ẹ̀ wo bí àwọn ẹ̀ṣọ́ ojú etí òkun ṣe ń ṣiṣẹ́ l'Eko Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fọ́nrán ohùn, Ilé ẹjọ́ kòmítẹlọ́rùn yá lórí ìbò gómìnà Oṣun- PDP Agbẹjọro Adeoye ṣalaye pe ti ile ẹjọ to ga julọ ba sọ pe Sẹnẹtọ Adeleke lo jawe olubori ninu idibo gomina Oṣun, ṣugbọn ti ko ni ẹri to daju pe o pari ile iwe girama, ẹniti o jẹ igbakeji rẹ ni yoo di gomina Ipinlẹ Oṣun.
Umehi ni yoo jẹ alaga fun igbimọ naa ti yoo pari iṣẹ laarin ọgbọn ọjọ Wo nọ́mbà tí o le è pè láti gba owó gbà-má-bínú tí ọlọ́pàá bá fìyà jẹ ọ́ lọ́nà àìtọ́ l'Eko Mo kọ̀ láti kópa nínú ìpàdé orí ayélujára Nàìjíríà yìí- Falz Cardi B ṣàlàyé ohun tó gbé fọ́tò ìhòhò rẹ̀ d'órí ayélujára Instagram Ẹ ṣọ́ra ní òpópónà AIT, ọkọ̀ agbépo kan ti yí dánù lọ́nà agbègbè Alagbado Igbimọ naa yoo ni: Aṣoju kan latodo egbe awon akekoọ.
Nígbà tí Jesu rí ohun gbogbo tí yóo ṣẹlẹ̀ sí òun, ó jáde lọ pàdé wọn, ó bi wọ́n pé, “Ta ni ẹ̀ ń wá?
Ó ń wí pé, ‘Jeroboamu yóo kú sójú ogun, gbogbo ilé Israẹli ni a óo sì kó lẹ́rú lọ.
Won yoo maa ba awon odo orile ede yii soro ati awon oba alade , awon onisowo, awon omo –ologun , awon ayaworan, awon onise-owo ati awon ile-ise ti kii se ti aladaani.
Tunde Braimoh: Itẹ́ òkú ní Vault Garden ní wọ́n sin Aṣòfin náà sí ní ìlànà ẹ̀sìn Musulumi
Kí oore-ọ̀fẹ́ wà pẹlu gbogbo àwọn tí ó fẹ́ràn Oluwa wa, Jesu Kristi pẹlu ìfẹ́ tí kò lópin.
Àkọlé àwòrán, Àgbálùmọ̀ Iwadii fi han pe agbalumọ kan ṣoṣo ni to ohun amuṣagbara mẹtadinlaadọrin to n ṣe ara loore.
Ọpọ eniyan kaakiri agbaye, to fi mọ orilẹ-ede Ghana, Kenya, ati Naijiria, to kopa ninu eto naa lo padanu ọpọlọpọ miliọnu, nigba ti nkan bẹrẹ si ni daru fun eto naa l'ọdun 2016.
Ṣe akojọpọ ọmọ tuntun ti yoo ye nigba ti wọn ba bi, takọ-tabo.
Láti ìgbà náà ni àwọn Musulumi àti ijọba ti ń fa ọ̀rọ̀ náà ti wọ́n si ti wọ́ àra wọ́n ló si ile ẹjọ́.
Ekiti Election: Alailójúti ní Buhari- Fayose
Nígbà tí OLUWA rí i pé Jakọbu kò fẹ́ràn Lea, ó fún Lea ní ọmọ bí, ṣugbọn Rakẹli yàgàn.
Iwadii sọ pe ti o ba sun daada, yoo ra awọ ara rẹ lọwọ lati jọlọ, ati ni ilera pipe.
Ìkẹ́ àti ìgẹ̀ gidi ni wọ́n fi pò ó fún mi.
Sùgbọ̀n ọ̀fọ̀ nla ṣe Nàìjíríà ní ọjọ́ kejìlá, oṣù kẹjọ, ọdún 1989 lásìkò ti Okwaraji pé ọmọ ọdún mẹ́ẹ̀dọ́gbọ̀n.
Alaga awon olusakoso VON, ogbeni Ibrahim Buba gboriyin fun ile-ise naa ati ile-ise iko omo ogun Nigeria Army fun itore gbagede idanileko naa.
''A n bẹ Gomina Kayode Fayemi ati awọn agbofinro lati sa gbogbo agbara wọ́n ki wọn ba le doola rẹ'' Ewẹ alukoro ọlọpaa nipinlẹ Ekoto Sunday Abutu to tẹpẹlẹmọ ipinu ajọ naa lati wa Kọmisana naa jade ni awọn ko mọ si owo ẹmi tawọn ajinigbe naa n beere.
Iná èèsì kìí jóni lẹ́ẹ̀mejì - Ọbásanjọ́ Àwọn ohun tó yẹ kí o mọ̀ nípa igbákejì Jimi Agbaje Gbenga Ọbasanjọ fi ẹsun kan an pe o n ba iyawo oun lopọ Igba akọkọ ni ti ọkan lara awọn ọmọ Ọbasanjọ gbena woju rẹ ni gbangba ni ọdun 2008.
Oludari Ajo LASEMA naa wa parọwa si awọn eniyan lati ri pe wọn tẹle ofin irinna ọkọ oju omi ati lilo aṣọ idaabobo, nigba kugba ti wọn ba wa loju omi.
Tó fi jẹ́ pé mo mọ̀ńmọ̀ ya àwòrán rẹ̀ fún ayé rí ní òwúrọ̀ kùtùkùtù kí ìmọ́lẹ̀ oòrùn tó lágbára jù, kí iyì àwọ̀ rẹ̀ lè hàn dáadáa.
Eyi jẹyọ ninu ikede ti ileeọẹ ọlọpaa fi sita nipa bi iṣẹ ẹka SWAT yoo sẹ ri.
Nígbà tí ẹ bá débẹ̀, ẹ óo fa ara yín kalẹ̀ fún títà gẹ́gẹ́ bí ẹrú, lọkunrin ati lobinrin, ṣugbọn ẹ kò ní rí ẹni rà yín.
N kò lè ka ohun tí ojú mi rí tán ki n tó dé ọ̀hún nítorí n kò ì tíì rin irú ìrìn bẹ́ẹ̀ rí.
”Bẹ́ẹ̀ gan-an ni àwọn ọmọ-ogun sì ṣe.
Ẹrú si ni irú ẹni ti ko ba gba Islam jẹ fún àwọn to ba gbà láti fẹ́ àwọn Boko Haram.
Ọgá olópàá náà ní awọn ajinigbe yii nikan kọ ni ọwọ awọn tẹ.
Bi ọrọ naa ti ṣe ṣẹlẹ lọjọru re e Ile ẹjọ giga kan to fi ilu Abuja ṣe ibujoko ti paṣẹ pe ki alaga ẹgbẹ oṣelu All Progressives Congress, APC,Adams Oshiomole lọ rọọkun nile.
Àwọn Heberu tí wọ́n ti wà lẹ́yìn àwọn ará Filistia tẹ́lẹ̀, tí wọ́n sì bá wọn lọ sí ibùdó ogun wọn, yipada kúrò lẹ́yìn wọn, wọ́n sì dara pọ̀ mọ́ àwọn ọmọ ogun Israẹli tí wọ́n wà pẹlu Saulu ati Jonatani.
7 14065 Orilẹede Sierra Leone 77 1.
Ni Oṣu kẹwaa, wọn da ipinlẹ Gombe silẹ latara Bauchi.
 adéwálé jẹ ́ ọmọṣẹ ́ lẹ ́ yìn akọrin prince adékúnlé òun oẹ ̀ lú ọ ̀ kórin afro-jùjú sínà peters .
 barack obama jé òkan nínú àwọn òṣèlú méjì tí wón figa gbága láti je Àrẹ ilè amerika .
Òun ni ó jókòó lókè àyíká ayé,àwọn eniyan inú rẹ̀ sì dàbí tata lójú rẹ̀.
Wọ́n gbé ògo Ọlọrunfún ère mààlúù tí ń jẹ koríko.
Mo rí ìbẹ́pẹ, ọsàn, ọpẹ òyìnbó, òòro,ọ̀gẹ̀dẹ̀ pupa, òroǹbó, àti ońirúurú èèso igi mìíràn tí ó ti orígun mẹ́rẹ̀ẹrìn ayé wá sí ilẹ̀ náà.
Ijoba ipinle Eko bere igbese lati seto ilana awon abadofin fun idagbasoke irinajo afe ati asa ile Adulawo ninu eyi ti won ti fon rere Pataki agbega ilo aso Ankara ti iran Adulawo ni lorisiirisii.
Agbara ati gbajumọ wa lara nnkan ti wọn fi n tori rẹ ṣẹgbẹ okunkun.
Àdán rò wípé àwọn ẹyẹ fẹ́ bori, nitorina o fo lati lọ darapọ̀ mọ́ ẹyẹ lati dojú ìjà kọ àwọn ẹbi rẹ eku.
 Oríṣun àwòrán, Twitter ""Mo ti mu ileri mi ṣẹ lati pari gbogbo iṣẹ asepati ti ijọba to kọja lọ ti ṣe lati ọdun 2011, ti n ko si fi imọ tara ẹni nikan bẹrẹ iṣẹ tuntun miran, ninu ọdun yii nìkan, iṣẹ ojilenigba o din mẹrin la dawọ le."
Ronaldo ní Tottenham yóò jẹ moyó ìyà lọ́wọ́ Liverpool Àrà kengé!
Inú wọn dùn nítorí ohun rere tí OLUWA ṣe fún Dafidi, ati Solomoni ati gbogbo Israẹli.
"Akọkọ, ninu atẹjade to fi sita laafin rẹ lọjọ Ẹti tii ṣe ọjọ ọdun keresimesi lagbaye, ""lorukọ awọn olori, atawọn ọmọọba laafin"", Kabiyesi Alaafin rọ awọn ọmọ Naijiria, paapaajulọ awọn Kristẹni lati maa tẹlẹ ẹkọ to kalẹ sawọn iwe mimọ gbogbo ninu idawọle wọn lojojumọ."
Mo wí fun yín nisinsinyii kí ó tó ṣẹlẹ̀, kí ẹ lè gbàgbọ́ nígbà tí ó bá ṣẹlẹ̀ tán.
Ẹkẹfa mú Bukaya, òun ati àwọn ọmọ rẹ̀ ọkunrin, ati àwọn arakunrin rẹ̀ jẹ́ mejila.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Shiite: Ẹ̀mí àti ara wa kọ ohun tí ìjọba ń ṣe sìwa láti 2015 Igba Ikẹta lẹyin iku Shekau: Lọdun 2014 ni iroyin tun jade pe awọn ọmọ ogun ilẹ Naijira ti gbẹmi olori awọn oniṣẹ ibi Boko Haram.
 stanley ann dunham pèhìndà ní ọdún 1995 .
Agbẹnusọ ẹgbẹ PDP nílu Èkó Taofiq Gani ló lédè ọrọ yí nígbà tí o n ba BBC sọrọ nínú ìfọ̀rọ̀wánilẹ́nuwò kàn lọ́jọ́ Ajé.
Òun ni ó yàn wá nípasẹ̀ Kristi kí ó tó fi ìpìlẹ̀ ayé sọlẹ̀.
Oríṣun àwòrán, Toyin Abraham/Facebook Àkọlé àwòrán, Òsèré Tíátà Toyin Abraham Toyin Abraham Ọmọ bíbí ìlú Auchi, ìlú kan ní ìpínlẹ̀ Edo ni.
Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Buhari gbọ Faari4 Ẹrẹ̀nà 2018 Àtẹ Àwòrán, Buhari at 76: Àwọn àwòrán tó làmì-laaka nípa Buhari17 Ọ̀pẹ̀̀ 2018 Hanan Buhari wedding: 'Cartoon' tí Bulama yà nípa ìgbéyàwó ọmọ mi kò bójúmu tó - Aisha Buhari8 Owewe 2020 Buhari: Emi ko ni fontẹ lu atunse ofin idibo13 Ẹrẹ̀nà 2018 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Laipẹ́ yi ni awọn akojọpọ agbẹjọro kan ati awọn ajafẹtọ-ọmọniyan kan sọ pe awọn ko fẹ ki wọn gbọ ẹjọ naa ni Abuja bi ko ṣe ni Eko ti wọn ti mẹsun naa wa.
Òjò a pa wọ́n lórí òkè,wọn a máa rọ̀ mọ́ àpáta nítorí àìsí ààbò.
" Oríṣun àwòrán, The nigeria senate Nígbà tó ń sọ bóyá ijoba ati àwọn ọmọ Nàìjíríà tí kẹ́kọ̀ọ́ lórí àrùn Coronavirus, sẹnatọ Ajibola ni a ti kẹ́kọ̀ọ́ tó pọ̀, pàápàá julọ nípa ṣíṣe isẹ ni ile ati ṣíṣe àtúnṣe òfin ajakalẹ àrùn tó wáyé gbẹyin lọ́dún 1926, fifi ìwé ipejọ lè èèyàn lọwọ láti ipasẹ ifiweransẹ Email pẹ̀lú sise ìpàdé àti eto ìdájọ́ lójú òpó ayélujára bíi Skype, Zoom àti bẹẹ bẹẹ lọ.
“Savannah Grass” jẹ́ ìpè sí ìrírí idán ayée àjọ̀dún yìí.
Àjọ ọlọ́pàá, Ìjọba ìpínlẹ̀ Ọyọ jẹ́jẹ̀ẹ́ láti ṣàwárí òòsà tó ń mu ẹ̀jẹ̀ nílùú Ìbàdàn Police brutality during lockdown: Nínú Ọlọ́pàá àti Coronavirus, èwo gan an laráàlú ń bẹ̀rù jùlọ?
Wo àwọn ìjọba ìbílẹ̀ 20 tí àrùn coronavirus pọ̀ sí jùlọ ní Nàìjíríà Mo sunkún nígbà tí mo rí ẹ̀jẹ̀ nílẹ̀ ní sọ́ọ̀ṣì tí wọ́n pa ọ̀mọ mi sí- Bàbá Uwa, akẹ́kọ̀ọ́ fásitì tí wọ́n fipábálòpọ̀ Ẹ wo ọmọ Yorùbá kan tó ru àrùn coronavirus là nílẹ̀ Gẹ̀ẹ́sì Ènìyàn 416 ló ti lùgbàdì àrùn Coronavirus ní Ọjọ́ Ajé ní Naijiria Ni ọjọ aje ni igbimọ amuṣẹya ti ijọba apapọ gbe kalẹ lori arun coronavirus lorilẹede Naijiria, PTF ṣalaye pe awọn ileewe ati ileeṣẹ eto ẹkọ nijọba apapọ gbọdọ joko lati fẹnuko lori ilana ti eto ẹkọ yoo gba bi wọn yoo ba ṣi ileewe pada; paapaa fun awọn akẹkọọ onidanwo aṣejade bii WAEC, NECO ati bẹẹbẹẹ lọ.
Nígbà tí wọ́n rú ẹbọ sísun tán, ọba ati ìjọ eniyan wólẹ̀, wọ́n sin Ọlọrun.
Oloye Ọpẹ Bademọsi tí wọn sọ pe ọmọ ọdọ rẹ ẹ gun pa lagbegbe Ikoyi ni ipinlẹ Eko laipẹ yii ti wọ kaa ilẹ lọ bayii.
Abrahamu dáhùn, ó ní, “Ohun tí ó mú mi sọ bẹ́ẹ̀ ni pé, mo rò pé kò sí ìbẹ̀rù Ọlọrun níhìn-ín rárá ni, ati pé wọn yóo tìtorí aya mi pa mí.
Kemi Afolabi joyè ìmọ́lẹ̀ Adinni Àwọn ọlọ́pàá ti gbé Emia ìlú Kano, Lamido Sanusi kúrò ní ààfin rẹ̀ lẹ́yìn tí ìjọba rọ̀ ọ́ l'óyè Odunlade fẹ́ j'ọba, Bolanle Ninalowo fun ìyàwó rẹ̀ ni ẹ̀bun kanka, Pá Kasumu rebi àgbà ree BBC ṣe atupalẹ awọn idi ti ijọba fi sita, o si ba awọn oloṣelu sọrọ lori awọn idi naa: Emir ilu Kano, kii gbọran si aṣẹ to ba wa lati ọọfisi gomina ati awọn ileeṣẹ ijọba.
Ṣugbọn, bí ìwọ bá tẹ̀lé ìlànà mi gẹ́gẹ́ bí Dafidi baba rẹ ti ṣe, tí o pa gbogbo òfin mi mọ́, tí o tẹ̀lé ìlànà ati àṣẹ mi, 
Inú ọba bàjẹ́ pupọ, ṣugbọn nítorí ó ti ṣe ìlérí pẹlu ìbúra lójú àwọn tí ó wà níbi àsè, kò fẹ́ kọ̀ fún un.
orile-ede Isreal wa si Naijiria, bee si ni ki aare Buhari naa wa sabewo si
Idi si ree ti BBC Yoruba fi fẹ ka mọ nipa itan igbe aye akọni onkọtan naa.
A waye iku o si, orun nikan lare mabọ.
Họnọrebu Oyebanji ṣalaye pe, iṣẹlẹ naa jẹ eyi ti o ba gomina Fayẹmi ninu jẹ pupọ ati pe, kii ṣe idunu rẹ ki awọn obi mejeeji yii padanu ọkan lara awọn ireti ọla wọn.
Ajọ NJC ni ki adajọ agba Onnoghen fesi si ẹsun ti wọn kan an pe o kuna lati kede dukia rẹ gẹgẹ bi ofin Naijiria ti fi lelẹ.
Agbébọn pààyàn méjì ní ṣọ́ọ̀ṣì, olùjọ́sìn yìnbọn p'òun náà Ilé ẹjọ́ tí ṣọ́ọ̀ṣì pa nítorí ariwo tó ń pa sétí aráàlú Pásítọ̀ wọ gàù lórí ìran ikú, ọ̀dọ́ musulumi ya wọ ṣọ́ọ̀ṣì Ẹ wo àwòrán bí ọjà Akẹsan ṣe jóná ràùràù ní ìlú Oyo!
ni yoo tun jẹ fun ẹja inu omi.
naa fi asiko adura naa ke si gbogbo omo bibi ati olugbe Ipinle Oyo lati
” Alaga ,ijoba ibile Kajuru ,
Gbogbo àwọn ará ìlú Ṣekemu ati ti Bẹtimilo bá para pọ̀, wọ́n fi Abimeleki jọba níbi igi Oaku kan tí ó wà níbi ọ̀wọ̀n tí ó wà ní Ṣekemu.
“Gege bi agbaboolu iko yii teleri, ti o si tun je eni to ni iriri to po gege bi akonimoogba, o da wa loju pe oun ni ipo ohun to si lati sun iko yii siwaju ni ibamu pelu awon eto wa gbogbo.
Oríṣun àwòrán, Chinedu Aranotu Ko ni akoko kan ni pato ṣugbọn iwe iroyin Healthline sọ pe ẹẹmẹta loojọ ko póju.
Nígbà tí ó rí Jesu, ó kígbe, ó kúnlẹ̀ níwájú rẹ̀.
Real Madrid: Kí ni ká ti pe ìfarapa gbogbo ìgbàa Eden Hazard lórí pápá?
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ijọba Zimbabwe gbe orukọ awọn to kowo ilu pamọ jade 19 Ẹrẹ̀nà 2018 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Aarẹ Emmerson Mnangagwa fi anfaani osu mẹta sile fun awọn ile isẹ ati ọlọdani to ba fe da owo ti wọn ko pamọ pada.
Ṣugbọn kaka to yẹ ki owo naa jẹ wolii ọhun, ni ṣe lo pe obinrin kan sita, to si ni ki obinrin naa ma ko gbogbo owo ọhun lọ.
Tesiwaju si, ogunlogo awon oluworan ni o fi atewo gbe aare ohun jade niseju mọ́kàndínlọ́gọ́rin ti won ropo re pelu agbaboolu miiran.
Wọ́n ń gbé pọ̀ ní alaafia, kò sí ìjà láàrin wọn, wọ́n ní ohun gbogbo tí ó wà lórí ilẹ̀ ayé, wọ́n sì ní ọrọ̀.
ectropion lára àwọn ajá maa ń ń ṣe pẹ ̀ lú ìdéjú ìsàlẹ ̀ .
Lilowosi idagbasoke orile-ede  Aare Buhari tun tenumo ipa dokita Wogu lawujo, eleyi ti o gbese seyin ati eyi to n se lowo fun idagbasoke orile-ede Naijiria.
 ní ìgbà tí ó maa fi di bíi Ọdún 1911 ó ti di ọmọ ẹgbẹ ́ art institute of chicago .
Ìyàwó mi fi mí sílẹ̀ kó lọ sílé ọkùnrin míì nínú báráàkì kan náà, àmọ́ mò sí tún fẹ́ràn rẹ̀- Sọ́jà Wo àwọn ìṣesí ojoojúmọ́ mẹ́wàá tó le ṣàkóbá fún ọpọlọ rẹ Gomina Sanwo-Olu sún ọjọ́ ṣiṣẹ́ láti ilé"" síwájú fún àwọn òṣìṣẹ́ ìjọba Jubril Martins-Kuye ti jáde láyé Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ado Ekiti Blind Couple: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí School resumption: Ilé aṣojú-ṣòfin l'Abuja dábàá kí ìjọba sún ìwọlé àwọn akẹ́kọ̀ọ́ síwájú pẹ̀lú oṣù mẹ́ta torí covid-19wákàtí 7 sẹ́yìn Fídíò, Oluwo Jogbodo Orunmila: Oluwo sọ ìtàn bí Orunmila ṣe jìyà nílùú Iwo àti ayọ̀ tó gbẹ̀yìn rẹ̀ torí sùúrù13 Sẹ́rẹ́ 2021 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó11 Sẹ́rẹ́ 2021 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!"
wọ ́ n bí adéolókun ní ìlú Ìbàdàn , ní orílẹ ̀ èdè nàìjíría ̀ , Ó lọ sí ilẹ ̀ ireland pẹ ̀ lú àwọn òbí rẹ ̀ ní ọ ̀ dún 2001 nígbà tí ó wà ní ọmọ ọdún mọ ́ kànlá ( age 11 ) .
ọlọtẹ Boko Haram laarin odun merin sẹyin lorile ede yii.
Igbakeji aare orile ede Naijiria ojogbon Yemi Osinbajo lo so eleyii.
A kan da ọwọ duro lori gbigbe awọn fidio to ku jade ni, nitori aabo ẹmi mi ati ti ẹbi mi.
Oríṣun àwòrán, @Iam_MarkPaul Lara awọn to ti ke gbajare yii la ti ri gbajugbaja sọrọ sọrọ nii, Daddy Freeze, ti o ni oun ko ni ra ọja kankan to ba jẹ ti orileede South Afrika mọ.
 pelu awon eya 67 abinibi ti won da duro , brasil ni iye awon eniyan aitibapade to pojulo lagbaye .
O ti sọ wá di ààtànati ohun ẹ̀gbin láàrin àwọn eniyan.
'Awọn aṣofin naa fẹ yọ emi ati gomina ipinlẹ Ondo nipo ni' Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ondo Assembly: Gómìnà Akeredolu ń ti àwọn tó ń da ilé aṣòfin ìpínlẹ̀ Ondo rú- Amọṣa, olori ile naa ti wọn yọ nipo, Bamidele Ọlọyẹloogun ni mimi kan ko mi ohun kuro lori aga olori ile naa.
Eli dáhùn pé, “OLUWA ni, jẹ́ kí ó ṣe bí ó bá ti tọ́ lójú rẹ̀.
Irú oúnjẹ bẹ́ẹ̀ kì í wù mí í jẹ,Ìríra ni jíjẹ rẹ̀ jẹ́ fún mi.
Onimo lori oro omi, imo-toto ayika ati ilera ara ninu ajo UNICEF, George Bekinbo, soro yii di mimo, bakan naa ni o so pe, won ti ko salanga igbonse bi ogoji ni awon ile-iwe alako bere, ni ijoba ibile meji.
“anfaani ti iwo –oorun yoo je lodun 2023 ni lati je aare orile ede Naijiria .
Ọkunrin yìí bá pè mí, ó ní: “ìwọ ọmọ eniyan, ya ojú rẹ, kí o máa wòran, ya etí rẹ sílẹ̀, kí o máa gbọ́; sì fi ọkàn sí gbogbo ohun tí n óo fihàn ọ́; nítorí kí n baà lè fihàn ọ́ ni a ṣe mú ọ wá síbí.
Sibẹ ó tún fi kún ìwà àgbèrè rẹ̀, nígbà tí ó ranti àgbèrè ìgbà èwe rẹ̀ ní ilẹ̀ Ijipti.
Aarẹ Muhammadu Buhari wa fi kun wi pe ohun to pọn dandan fun oun lọwọlọwọ bayii ni lati fi opin si iwa ipaniyan lagbegbe Ariwa orilẹ-ede Naijiria.
Sáájú àsikò yìí ni ìjọba àpapọ tí ṣí pápákọ̀ òfurufú fún awọn to n rin ìrìnàjò abẹ́lé ní ọjọ́ kẹjọ oṣù kèje ọdun yii, to si ti sàlàyé pé, ní òní ọja kàrun, ọsù kẹjọ ni àwọn ilẹ̀ òkèrè yóò bẹ́rẹ̀.
Àwọn ọmọ Efuraimu kó ọrun, wọ́n kó ọfà,ṣugbọn wọ́n pẹ̀yìndà lọ́jọ́ ìjà.
Àwọn eniyan Juda bá dáhùn pé, “Ìdí tí a fi ṣe bẹ́ẹ̀ ni pé, ọ̀kan náà ni àwa ati ọba.
com/czbb3uSkRg— Arsenal FC (@Arsenal) June 5, 2018Ewe, Lichtsteiner je agbaboolu kinni ti akonimoogba tuntun iko agbaboolu Arsenal, Unai Emery yoo ra wa sinu iko ohun lati igba ti o ti gba ise lowo Arsene Wenger losu ti o koja.
O so pe Ogunjọ osu kẹta ni wọn yoo sọ igba ti idibo naa yoo pada waye ati gbogbo ilana ti awọn yoo fi ṣeto naa.
Nigba ti awuyewuye yii bẹrẹ, Adams Oshiomole lo dipo alaga ẹgbẹ APC mu.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Ó máa n fọ àwọn ìdọ̀tí inú ọkàn mọ́ Akano nínú àlàyé tirẹ̀, ni ẹmu máa n ṣe àtúnṣe ọkan nítorí àwọn èròjà kan tó ni, ó ni ó máa ń jẹ́ kí ọkàn ṣiṣẹ́ dáradára tí ó sì máa n fun ni okun.
Jesu ní, “Ta ni fọwọ́ kàn mí?
Iṣẹ́ ribibi lọ́ ṣe fún ànfàní àwa adúláwọ̀ káárí ayé tí kò ṣé fi ẹnu sọ tán.
Awọn ọdọ Ondo fẹ̀họ́nù hàn lórí ìṣekúpani Funke Olakunrin
Ṣugbọn Ọlọrun kan ń bẹ ní ọ̀run, tí ń fi àṣírí nǹkan ìjìnlẹ̀ hàn.
Níhìn-ín ni ìfaradà ati ìdúró ṣinṣin àwọn eniyan Ọlọrun yóo ti hàn.
” Ó bá sọ ọ́ ní Simeoni.
Ìbá ti dára tó kí ẹnìkan ninu yín ti ìlẹ̀kùn tẹmpili pa, kí ẹ má baà máa wá tanná mọ́, kí ẹ máa rú ẹbọ asán lórí pẹpẹ mi!
OLUWA mú wọn jáde láti Ijipti wá,Ó sì ń jà fún wọn bí àgbáǹréré.
Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí US Presidential Election: Ṣé ìrànwọ̀ ni Kamala, ìgbákejì tí Biden yàn yóò jẹ́ fún un tàbí ìpalára?
“Ẹnikẹ́ni tí ó bá rí ọ yóo tẹjú mọ́ ọ,wọ́n óo fi ọ́ ṣe àríkọ́gbọ́n pé,‘Ṣé ọkunrin tí ó ń kó ìpayà bá gbogbo ayé nìyí,tí ó ń mi àwọn orílẹ̀-èdè jìgìjìgì;
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Lagos-Ibadan Rail: Amaechi ní ojú irin Ìjú Àgbàdo gbọdọ̀ se rìn láìpẹ́ 4 Sẹ́rẹ́ 2019 Àkọlé àwòrán, Rotimi Amaechi ti ní òun yóò wá dán ojú irin náà wò láti mọ ibi tí wọ́n bá isẹ́ dé ní Ọjọ́ Kẹrìnlá, Osu Kini, ọdun 2019.
 ní oṣù kẹrin ọdun 2017 , roof gbà pé òhun jẹ ̀ bi ẹ ̀ sùn mẹ ́ sẹ ̀ ẹ ̀ sán tí ìjọba ìpínlẹ ̀ fi kan kó le baà yẹra fún ìdájọ ́ ikú kejì , nítoríẹ ̀ wọ ́ n dá ẹjọ ́ ìjùṣẹ ̀ wọ ́ n ayérayé fún , fún ìkọ ̀ ọ ̀ kan àwọn ẹ ̀ sùn náà , èyí sínà fún ìjọba àpapọ ̀ láti pàṣẹ ikú rẹ ̀ nígbà tọ ́ bá yá .
O ni wọn ti gbe òkú ọrẹ gomina lọ sile igbokupamọsi nigba ti Adeoluwa n gba itọju to peye nile iwosan ijọba ti Federal Medical Center nilu Abẹokuta nipinlẹ Ogun.
Alakoso fun eto ogbin nipinle Benue, James Anbua so pe, laasigbo igba gbogbo laarin awon agbe ati awon daran-daran n safihan ewu ti o dun-koko mo eto ogbin ati ounje.
Ògiri ìta àwọn yàrá ẹ̀gbẹ́ nípọn ní igbọnwọ marun-un (mita 2½), apá kan pèpéle tí kò ní ohunkohun lórí jẹ́ igbọnwọ marun-un.
Ko lee roju se aye, sugbọn Gaa pa ọmọbinrin Alaafin Abiọdun, Agbọrin, nigba to nilo ẹranko Agbọnrin, to si ni orukọ wọn jọra Lisabi Agbongbo Akala rèé, ẹni tó fi ìfẹ́, ìṣọ̀kan àti ìrẹ́pọ̀ gba ilẹ̀ Ẹ̀gbá lọ́wọ́ ìmúnisìn Afọnja, ẹni tó finú wénú ní Ilọrin, àmọ́ tó jẹ iwọ Ọba Lamidi Adeyẹmi, òṣìṣẹ́ adójútòfò àti Abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò kó tó jọba Ọ̀rọ̀ǹpọ̀tọ̀niyùn, Aláàfin obìnrin àkọ́kọ́ rèé, tó ní nǹkan ọkùnrin Ọrọ naa dun Abiọdun to bẹẹ, to si beere fun atilẹyin Onikoyi, ati aarẹ Ọna Kakanfo to jẹ nigba naa, Ọyalabi lati ilu Ajasẹ ipo, ki wọn lee tete rẹyin Basọrun Gaa Alaafin Abọdun kọkọ yọ ibẹru Gaa kuro lọkan awọn araalu, to si jẹ ki ibinu rẹ maa ru jade ni inu wọn, titi ti Basọrun Gaa fi rọ lapa, rọ lẹsẹ Lọdun 1774, ẹgbẹlẹgbẹ awọn eeyan Ọyọ ile ya bo agboole Basọrun Gaa, ti wọn si wọ ọ lọ si ọja Akẹsan, Ki wọn to sun un nina gburugburu, bẹẹ ni wọn pa a tọmọtọmọ, wọn jẹ ile Gaa run patapata Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Helen Paul sọ idi tó fi gba orúkọ ní kékere Sugbọn ori ko akọbi rẹ, Ojo Aburumaku yọ ninu wahala yii, to si sa lọ si ilẹ Ibariba, eyi to fopin si aye fami lete ki n tutọ ti Basọrun Gaa ati idile rẹ n jẹ Idi ree ti awọn eeyan se maa n pa asamọ pe ‘Bo laya ko sika, to ba ri iku Gaa, ko sootọ’ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Lagos King: Mátikú ọba tó lo lo ọdun mẹta lórí oyé latari rogbodiyan Eko Sugbọn iku Basọrun Gaa se akoba nla fun ijọba Ọyọ akọkọ, tori lẹyin iku Gaa ni ẹdinku ba bi awọn ọmọ ogun rẹ ti dangajia si ati agbara ilu naa, tawọn ilu kan si n sa kuro labẹ rẹ, titi ti Ọyọ ile akọkọ fi tu lọdun 1836.
Ó tóbi, ó lọ́lá ẹ̀ka rẹ̀ sì lẹ́wànítorí pé gbòǹgbò rẹ̀ wọ ilẹ̀ lọ,ó sì kan ọpọlọpọ omi nísàlẹ̀ ilẹ̀.
Nígbà tí Abigaili rí Dafidi, ó sọ̀kalẹ̀ kíákíá, ó wólẹ̀, ó sì dojúbolẹ̀ lẹ́bàá 
Koríko ni wọ́n fi bo ilé wọn ìgbà tí òjò bá sì rọ̀, ìgbà púpọ̀ ni ilé ń jò tí gbogbo ilẹ̀ á tùtù nini, ewéko ni wọ́n n tẹ́ sílẹ̀ sùn, wọ́n á fi okúta ṣe ìrọ̀rí, wọn kò ni ẹní kan ṣoṣo.
Agbénusọ fun Aarẹ Zuma naa sọrọ pe ayederu iroyin ni.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Huda Shaarawi: Kò dára kí obìnrin sè’yàwó lọ́mọ ọdún mẹ́tàlá Ọjọ kẹta, oṣu keje, ọdun 2013 ni awọn ologun gba ijọba lọwọ Mohammed Morsi ni Egypt.
Bakan naa, agbẹjọro ati ajafẹtọ ọmọniyan, Femi Falana na sọ pe ṣisẹ iwọde ko ni ohun kankan ṣee pẹlu iditẹ gbajọba.
4 9677203 Orilẹede Mexico 109717 86.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Bobrisky sàlàyé ipò tó wà gẹ́gẹ́ bi ọkunrin tàbí obinrin 3 Bélú 2019 Oríṣun àwòrán, @bobrisky Àkọlé àwòrán, Mó fẹ́ dí obinrin to dára júlọ lágbàyé-Bobrisky Ọ̀pọ̀ àwọn ọmọ Naijíría ló maa n sọ ni ọ̀pọ̀ ìgbà pé àwọn ko mọ ibi ti Idris Olarewaju Okuneye tó si n láàrin àkọ tà bí àbo?
'Idin meloo lo wa ninu irun rẹ?
#BBCGOVDEBATE: Ọgbọ́n ìmọ̀ àti òye ní ń ò fi ṣe ìjọba- GNI ''Buhari, fi kùráànì búra lórí èsì WAEC rẹ'' 'Mo mọ bí Boko Haram ṣe bẹ̀rẹ̀' Ìlú tí ọ̀daràn bá tí dẹ́ṣẹ̀ ló yẹ kí wọn tí gbẹjọ́ rẹ̀ -Agbẹjọ́rò Wọn ṣalaye pe lasiko to n gbiyanju lati tu irun to ṣe tẹlẹ ni imurasilẹ ọjọ ìbí rẹ to m bọ lọna ni o kofiri ina ori ninu irun rẹ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ojú mi ti rí lọ́pọ̀ lọpọ̀, àmọ́ mo dúpẹ́ pé mo ti pé ọdún márùn ún lórí oyé- Ooni 2)Taiwo Oyebola Agbona: Agbona gori itẹ baba rẹ lọdun 2017 lẹyin ti Alaaye ti ilu Aaye, Oba Agbona Orimori dagbere faye lọjọ kẹrin, oṣu Karun un, ọdun 2017.
Nítorí ó sọ fún Mose pé, “Ẹni tí mo bá fẹ́ ṣàánú ni n óo ṣàánú; ẹni tí mo bá sì fẹ́ yọ́nú sí ni n óo yọ́nú sí.
Lootọ ni awọn eeyan ti n pe fun ṣíṣí ọrọ aje pada, yoo sọrọ lati ni ifọkanbalẹ.
Awọn kan ni bi wọn ba ti tẹ ẹ sori ẹrọ aṣewadii google lati mọ ẹni to jẹ ọkọ rẹ, aworan olorin Pasuma lo ma n jade sita pupọ.
Kí àwọn tí ń lo dúkìá ayé máa lò ó láì dara dé e patapata.
Kí ẹni tí ó bá ń rò báyìí mọ̀ pé bí a ti jẹ́ ninu ọ̀rọ̀ tí a kọ sinu ìwé nígbà tí a kò sí lọ́dọ̀ yín, bẹ́ẹ̀ náà ni a jẹ́ ninu iṣẹ́ wa nígbà tí a bá wà lọ́dọ̀ yín.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Access Bank: Ilé ìfowópamọ́ Access ti gbà láti dá owó àwọn oníbàráà wọ́n padà 28 Òkùdu 2020 Oríṣun àwòrán, Access bank Lẹ́yìn awuyewuye to waye lori ayélujára ní àna nipa owó ti ilé ìfowópàmọ Access bank náà yọ lọ́nà àìtọ́ gẹ́gẹ́ bi (Stamp Duty) ń yọ lori àwọn oníbàrá wọn, ilé ìfowopamọ́ náà ti gbà láti dá owó oṣù kejì àti kẹrin padà.
Bí wọ́n ṣe máa n sọ bí Igbo bá n sọ̀fọ̀ gan, wọ́n a sì máa mu ẹmu láti rí ìtùnú.
Ṣé Liverpool ṣì leè tẹ̀síwájú ní ìdíje Champions league?
"Emi naa ni iru àwọ̀ oju yii.
Nigba to n ba awọn akọroyin sọrọ lẹyin ti wọn ṣe awari rẹ, Oludari bareke ologun kẹta, Ọgagun Umar Mohammed sọ pe ọkan lara awọn afurasi to jọwọ ara rẹ fun ileeṣẹ ọlọpaa lẹyin ti wọn kede pe wọn n wa wọn, lo mu awọn ọmọ ogun lọ si ibi kanga alopati naa.
Nigba ti BBC Yoruba pe ago alukoro ọlọpaa ipinlẹ Oyo Fadeyi Olugbenga lati fi mọ nkan to n ṣẹlẹ gaan, o ni ko si ohun to jọ bẹ.
Nitori ajakalẹ arun Covid-19, awọn ọmọ ẹgbẹ Democrat ko ṣe apero elero pupọ ni Milwaukee, Wisconsin, toun ti afẹfẹ yẹyẹ to maa n ba iru apejọ yii wa.
Ọmọ Mikaeli, ọmọ Baaseaya, ọmọ Malikija, 
Àrà mánigbàgbé tí Baba Legba dá lágbo tíátà rèé Àwọn Dókítà Nàìjíríà bẹ̀rẹ̀ ìyànṣẹlódí lónìí Àwọn ọ̀daràn tó jí ìbejì ọmọ Akeugbagold kó ti fojú ba ilé ẹjọ́ lòníì Àjọ ECOWAS yan Aàrẹ Ghana, Nana Akufo-Addo gẹgẹ bíi aàrẹ tuntun Saaju ni wọn ti ni pe ki gbogbo ọmọ ẹgbẹ ma lọ sibi ipade naa ti Femi Fani Kayode pe latari bo ṣe ṣe si akọroyin Daily Trust ni ipinlẹCross River.
Àkọlé àwòrán, idije orisi lo sele to mu inu awon omode dun ni Ife Lẹyin eyi ni awọn ọdọ yii ni oore-ọfẹ lati dije ninu ere idaraya loriṣirisi bii gbigba bọọlu ori tabili, kẹkẹ gigun ati bẹẹ bẹẹ lọ.
“Bí ọkàn mi bá fà sí obinrin olobinrin,tabi kí n máa pẹ́ kọ̀rọ̀ lẹ́nu ọ̀nà aládùúgbò mi;
O fikun un oro re pe, atunse pajawiri ye ko wa laarin osise ijoba.
'Ọgbọn ọdun sẹyin ni mo ṣegbeyawo, mo si ti ni ọmọ-ọmọ meji.
Òwò ẹrú pé irinwó ọdún tó bẹ̀rẹ̀, àwọn Amẹrika tó jẹ́ dúdú wá sí Afirika láti bẹ ilé wò EFCC fẹ́ gbẹ́sẹ̀ lé ilé tí mo fi owó ìfẹ̀yìntì kọ́ nílùú Ilorin- Saraki Eku gba ìjọba ní Estonia, ìjọba pàdánù owó gọbọi Ilé ìwòsàn New Jersey ṣ'àṣìṣe ṣiṣẹ́ abẹ kìndìrín fún aláìṣàn l'Amẹrika Ni ibẹrẹ oṣu yii ni awọn Taliban tu awọn ọjọgbọn meji silẹ ti wọn ti mu lati ọdun 2016 iyẹn: Kevin King ti America ati Timothy Weeks ti Australia.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Abimbọla Kazeem: Hábà!
OLUWA Ọlọrun wa fi lé wa lọ́wọ́, a ṣẹgun rẹ̀, ati òun ati àwọn ọmọ rẹ̀, ati gbogbo àwọn eniyan rẹ̀.
Ọlọrun fi awọn ọmọ si aarin awọn mejeeji, lara awọn ọmọ rẹ ni ilumọọka olokoowo kan to kalẹ silu Eko, Dele Fajemirokun.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ronaldinho: Agbábọ́ọ̀lù Brazil tẹ́lẹ̀, Ronaldinho gba ìtúsílẹ̀ kúrò lẹ́wọ̀n, àmọ́.
Nigba to n dahun ibeere naa lati ọdọ awọn akọroyin, Iku Baba Yeye ni oun ko figba kankan kọ ẹnu si awọn ọdọ olori ọhun pe oun fẹ fi wọn ṣe aya.
Ọpọ awọn ẹlẹgbẹjẹgbẹ, awọn lookọ lookọ lawujọ, awọn oriade, asaaaju ẹsin to fi mọ awọn gomina ipinlẹ kọọkan lo ti sọ ero ọkan wọn lati tako tabi faramọ agbekalẹ abule Ruga naa.
Mane náà tí o ń gba fun Liverpool pẹ̀lú Salah kópa nínú ìfẹsẹwọnsẹ mẹ́rìndílógóji to si gbá bọ́ọ̀lù méjìlélógun tó fi mọ ti aṣekágbá pẹ̀lú Wolves lọ́jọ́ ti Premier League pari.
‘Èmi ni Ọlọrun àwọn baba rẹ, Ọlọrun Abrahamu, Ọlọrun Isaaki, ati ti Jakọbu.
Ẹwẹ, eeyan Ẹgbẹrun kan ati ẹẹdẹgbẹta o le marundinlaadọrin, 1565 lo tun kun awọn to ko aarun naa naa bayii.
Aare tun ni “o maa n komi lominu, bi awon kan se maa n ran awon omo won lọ fun eko loke- okun ,ti won si tun lowo ninu iwa ibaje eto oro aje orile ede yii, iru Naijiria wo ni won fe kọmọ won gbe wa sisẹ,nigba ti won ba pari ẹkọ won loke- okun.
NAFDAC ti parí ìwádìí lórí codeine NAFDAC: Ẹ ṣọ́ra fún ẹja aṣekúpani Puffer Fish Ọmọ Nàíjíríà tako Nafdac lórí ọ̀rọ̀ Codine Àpanisáyé ni ẹ̀wà tí wọ́n n fí 'sniper' sí Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Okùnrin SARS náà sọ pé òun máa pa èèyàn síbi ni- Aladugbo O ṣapejuwe bi paali ti oogun naa ninu rẹ bayii: 1.
Nípa igbagbọ ni Isaaki fi súre fún Jakọbu ati Esau tí ó sì sọ ohun tí yóo ṣẹlẹ̀ sí wọn.
Ohun tí ó kù ni pé kí á máa retí ìdájọ́ pẹlu ìpayà ati iná ńlá tí yóo pa àwọn ọ̀tá Ọlọrun.
Igi funfun eléyìí ní tirẹ̀ mọn’rarẹ̀ lágbà.
Osinbajo: Ẹgbẹ̀rún mẹ́wàá náírà ni ọlọ́jà kọ̀ọ̀kan gbà
Ni ti abileko Nkechi Onyenso, ti o je akowe-agba ile-eko naa pe, ile-eko ohun ti n polongo isakoso isejoba rere nipa sise akosile ifenuko, akosile liana ati itoni-sona ohun elo ile-ise aladani ati ti ijoba.
Awon asoju oga agba fun  osise ijọba lati Eritrea ni won ti de si Ethiopia fun ijiroro pataki , eyi ni yoo je akoko iru re lati ogun odun.
2bn fún Obanikoro Koda o fikun un pe, ọọfisi oludamọran feto aabo fontẹ lu rira ọkọ ijagun mẹtala, ibọn AK 47 ẹgbẹrun kan, ẹwu ayẹta ẹgbẹrun kan, awọn ohun ija lorisirisi to to miliọnu meji, ọta ibọn ẹgbẹrun kan, ate ayẹta bii ẹẹdẹgbẹta, to fi mọ awọn ohun eelo ibaraẹnisọrọ lorisirisi.
Akubuike ni ti ẹ, to jẹ amofin, jẹ oludije to da duro, fun ipo adájọ nile ẹjọ Minnesota 2nd District.
 ní orílè èdè kenya , obama- àgbà bèrè iṣé ní ilé iṣé tí ó nwa epo ròbì , léhìn èyí , ó ṣiṣé fún ìjọba , gégébí olóòtú ètò ọrò ajé .
Anfaani wo lo wa ninu iṣejọba Parliamentary to fi ju Presidential lọ?
 Èyí ló mú kí wọn di kòrí-kòsùn ara wọn láti kékeré wá , wọn kì í sìí yara wọn bí ó ti wù kí ó rí .
mọ pe gbigbogun ti aisan iba  ko rọrun
Ma se wahala jina, a ti ba o te.
” Wọ́n bá lọ, wọ́n sì dé sí ilé aṣẹ́wó kan, tí orúkọ rẹ̀ ń jẹ́ Rahabu.
Kó àwọn ọmọ Lefi wá siwaju OLUWA, kí gbogbo àwọn ọmọ Israẹli sì gbé ọwọ́ lé wọn lórí, 
 lẹ ́ hìn ti èyí wọn ó padà sí àafin láti wá jókòó sí ojú aganjú .
Àkọlé àwòrán, Awọn adigunjalè míràn ti ọwọ́ tún tẹ̀ Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Ta ni yóo bá mi dìde sí àwọn aṣebi?
Iya rẹ lo ya lowo to fi kọkọ bẹrẹ sọṣi nigba to da sọọsi silẹ Odunmejeje ni ọmọ kẹta ninu mẹfa ti iya won bi, oun naa si ti bi ọmọ mẹrin lẹyin igbeyawo Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Nígbà tí àwọn oníṣẹ́ náà dé Gibea, níbi tí Saulu ń gbé, wọ́n ròyìn fún àwọn ará ìlú náà, gbogbo wọn sì pohùnréré ẹkún.
‘Daily Trust fi àsírí ìgbógun tí Boko Haram jáde la se tì í’ Kíni Amosun mú Adekunle lọ ṣé lọdọ Buhari?
Ó tóbi, irin sì ni eyín rẹ̀.
WAEC gbé èsì ìdánwò WASSCE jáde Ooni Ife fohùn ránṣẹ́ sí Boris Johnson, ó ní, bóo bá joun gbé, má johùn gbé"" Bíbéèrè fún ìbálòpọ̀ gbogbo ìgbà sọ ìyàwó ilé dèrò ilé ìwòsàn Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Kayeefi: Facebook ni Wolii Arole Jesu fi tàn an wọ agbo, orí rẹ̀ ni wọ́n fi s'owó Nipa igba ti wọn gburo rẹ gbẹyin, baba rẹ sọ fun BBC pe nkan bii ọdun to kọja ni awọn gburo rẹ gbẹyin ti wọn ko si tii gbọ ohunkohun titi doni."
 bákan náà , a sọ tíọ ́ rì tí a lò fún iṣẹ ́ yìí .
Ó mú kí afẹ́fẹ́ ìlà oòrùn fẹ́ ní ojú ọ̀run,ó sì fi agbára rẹ̀ darí afẹ́fẹ́ ìhà gúsù;
Nítorí náà ni mo ṣe na ọwọ́ ibinu mi si yín,tí mo sì pa yín run.
Èdè igbìrà tàbí ebira tàbí egbira jẹ ́ èdè ní nàìjíríà ( ní àwọn Ìpínlẹ ̀ kwárà àti Ẹdó àti násáráwá ) .
Lori ibeere yii, Fẹmi Joseph sọ pe ''idojukọ kan pataki taa n ni ni pe, nitori pe ipinlẹ Ondo paala pẹlu ipinlẹ to pọ, bi a ṣe n mu ọpọlọpọ wọn ni awọn mi i tun n ṣiṣẹ.
Ó dáhùn pé, “Ọba ni ó rán mi ní iṣẹ́ pataki kan, ó sì ti sọ fún mi pé ẹnikẹ́ni kò gbọdọ̀ mọ̀ nípa iṣẹ́ tí òun rán mi.
Ó wá lọ gbógun ti àwọn ọmọ rẹ̀ yòókù, tí wọn ń pa àṣẹ Ọlọrun mọ́, tí wọn ń jẹ́rìí igbagbọ ninu Jesu.
Nitori naa, wọn n gba awọn olori orilẹede to wa ni Afirika ni imọran wọn yii: Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, afin pupa Igbesẹ to yẹ kawọn olori Afirika gbe lori ọrọ Benin: Ki AU ati ECOWAS gbe igbimọ dide lati lọ rọ Aarẹ Talon ti orilẹede Benin, ko le jẹ ki aarẹ ana lọ gba iwosan ni oke okun ECOWAS ati AU gbọdọ gbe igbesẹ lati ri pe ọrọ naa ko bajẹ kọja ibi to de yii Orilẹede Benin gbọdọ ri wipe ijọba awa-arawa tootọ fidi mulẹ.
Naijiria kọkọ ṣalaye iwulo rẹ, anfani rẹ wọn si gbọ latẹnu awọn tọrọ ọhun kan.
Amọ ile lo kuku ba Adesanya naa, oun naa sọ pe oorun ti ko si Costa loju ohun lo si n ṣakoba fun un.
Àwọn mejeeji lo tun jọ n dije lọjọ Iṣẹgun.
Njẹ́ o mọ̀ pé bíi ọdún 700 sẹ́yìn ni wọ́n ti ń bọ Osun-Osogbo?
Gẹgẹ bi iwe iroyin abẹle, The Punch, ṣe sọ, ọwọ tẹ Salisu, lẹyin ti awọn araalu fi ẹjọ sun ni agọ ọlọpaa to wa ni Ago-Iwoye.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Akomolede àti Aṣa: Ọ̀rọ̀ Ẹ̀yán ni Bunmi Femi Amao ń kọ́ wa lórí ètò Akọ́mọlédè àti Àṣà lórí BBC Yorùbá Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Akomolede àti Aṣa: Ọ̀rọ̀ Ẹ̀yán ni Bunmi Femi Amao ń kọ́ wa lórí ètò Akọ́mọlédè àti Àṣà lórí BBC Yorùbá 22 Owewe 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 24 Owewe 2020 Ẹyan oríṣi meje ló wa ninu girama ede Yoruba.
Àkọlé àwòrán, Toun ti ijakule idibo abẹnu APC,Moshood Adeoti tẹsiwaju ipinu rẹ lati di Gomina ipinlẹ Osun Bákannáà lọmọ ṣori lọdọ awọn alatilẹyin ọgbẹni Akin Ogunbiyi ti wọn ṣe iwode lọ sí ilé ẹgbẹ PDP losogbo.
 alexander babalola akinyele jẹ ́ oè oluódùmarè ní ẹni ọdún méjìlélọ ́ gọ ́ sàán ní ọdún 1968 .
Oloye Oluṣẹgun Arẹmu Ọbasanjọ to tukọ Naijiria lọdun 1999 si 2007 ṣalaye fun BBC Yorùbá pé nitootọ ni Atiku kò dára pupọ ṣugbọn ó sàn ju Buhari lọ nigba igba.
Adekanbi Oluwatuyi to jẹ olori ọdọ ni gbogbo ilu Akure sọ fun BBC Yoruba pe gbogbo agbaye mọ pe iṣẹ agbẹ lo wọpọ ju lagbegbe awọn ṣugbọn gbogbo eniyan lo ti sa kuro l'oko.
nibi ipade apero ọdọọdun lori  eto oro
Èyí ń ṣe àfihàn àdálò tí ẹgbẹ́ òṣèlú tó wà lórí oyè ń dá agbára lò pẹ̀lú Nkurunziza àti àwọn alátìlẹyìn-in rẹ̀ pẹ̀lú bí ẹgbẹ́ òṣèlú náà ṣe ń darí àwọn ìdásílẹ̀ ìjọba.
Ghana ti mu àwọn afurasí ajínigbé ọmọ Naijiria mẹ́ta À ń wo àtubọ̀tán APC níbáyìí tó gba àkóso ilé aṣòfin - PDP #Democracy Day: Pápá ìṣeré Abuja di MKO Abiola Stadium Buhari kò tíì ṣe to lóri June 12- NADECO Ọpọlọpọ lo ni o dabi pe ijọba Naijiria ti moju kuro lara papa iṣere naa tipẹ diẹ bi wọn ṣe ṣiju kuro lara papa iṣere to wa ni ipinlẹ Eko.
Pierre-Emerick Aubameyang lo kọkọ gbayo wọle Liverpool fun Arsenal ki Takumi Minimano to dayo naa pada.
Fi ìfẹ́ rẹ tí kì í yẹ̀ hàn wá, OLUWA;kí o sì fún wa ní ìgbàlà rẹ.
" Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Blind DJ: Etu Omotayo kò ríran àmọ́ ó le to irinṣẹ́ eléré pọ̀ láti kọrin láì sí ìrànwọ́ Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Peers of Heaven: Ààrẹ ẹgbẹ́ Emèrè ní àwọn ti wà tipẹ́, wọn kò pariwo síta ni18 Ògún 2020 Ondo Election: Akeredolu f'ògún ikọ̀ Àmọ̀tẹ́kùn Ondo gbárí fún ìdìbò tó ń bọ̀12 Ògún 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
O ni ileeṣẹ ọlọpaa ti bẹrẹ iṣẹ lati ṣe awari awọn ọdaran naa to ti sa lọ.
Olórí ogun tí ó pọwọ́ lé e ni Jehohanani, ó ní ọ̀kẹ́ mẹrinla (280,000) ọmọ ogun lábẹ́ rẹ̀.
Mo bẹ Yuodia ati Sintike pé kí wọ́n bá ara wọn rẹ́ nítorí ti Oluwa.
Owó tó kàn mí nínú N4 mílíọ̀nù ìbejì Akeugbagold tí a jí gbé, bàtà ni mo fi rà-Afunrasí Wo ipa tí ìlànà tuntun tí ìjọba Eko gbé jáde lórí Covid-19 yóò nìí ní ìgbésí ayé rẹ Àrùn Coronavirus ti mú ẹ̀mí ẹni àkọ́kọ́ lọ nílẹ̀ Madagascar Ta ló da 'ewé' bo N4.
Ǹjẹ́ a lè gba ìkógun lọ́wọ́ alágbára,tabi kí á gba òǹdè lọ́wọ́ òkúrorò eniyan?
Seneto Ovie Ọmọ Agege lo kede esi idibo naa nilu Osogbo.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Students kidnap: Garba Shehu ní iléeṣẹ́ ológun ti yabo ibùdó àwọn jàndùkú tó jí àwọn akẹ́kọ̀ọ́ lọ nílé ìwé katsina 12 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 13 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Oríṣun àwòrán, AFP Oluranlọwọ aarẹ Muhammadu Buhari lori ọrọ iroyin, Garba Shehu ti sọ pe ileeṣẹ ologun ti ṣe awari awọn janduku agbebọn to ji awọn akẹkọọ ileewe girama to wa ni Kankara, nipinlẹ Katsina.
'Penis Fish, ẹ̀ja tuntun tó rí bí ǹkan ọmọkùnrin lùwẹ̀ jáde lórí òkun Kò sí ọkùnrin tí yóò fún obìnrin tó halẹ̀ bíi tèmi lówó - Lizzy Anjorin Ẹ́ wo ojú àwọn òṣèré tíátà tó péjú sí Ibadan fún ìpàdé ọlọ́dọọdún Saheed Balogun sìnkú ìyá rẹ̀, Ogogo ní ẹgbẹ́ agbábọ́ọ̀lù!"
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Iraq, Palestine wà nínú orílẹ̀-èdè mẹ́wàá tí ìwádìí BBC ti wáyé Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Iraq, Palestine wà nínú orílẹ̀-èdè mẹ́wàá tí ìwádìí BBC ti wáyé 30 Òkùdu 2019 O le ni oluwadii ẹgbẹrun mẹedọgbọn ti wọn ṣiṣẹ iwadii naa fun BBC.
Awọn ara ilu Zokutu ni awọn ko tii ko firi ẹni kankan ti wọn gbeṣẹ le lọwọ lati maa polongo nipa Coronavirus pẹlu bo ṣi ṣe jẹ pe ẹgbẹ Abuja lawọn wa.
Atẹjade tuntun kan lo gbe e jade wi pe oun lo n gbowo julọ ninu awọn ilumọọka lagbaye ni ọdun 2019.
gbọ́ adura ati ẹ̀bẹ̀ wọn láti ọ̀run, kí o sì jà fún wọn.
 bàbá rẹ ̀ , abdul baqi , jẹ ́ onímọ ̀ ́ ìjìnlẹ ̀ nípa kùránì tí ó sì ma ń ṣe ìṣítí fún àwọn ènìyàn ní agbègb ̀ e dé agbègbè àti ìlú sí ìlú bíi : Ìbàdàn , abẹ ́ òkúta , Ẹdẹ , osogbo àti wasa tí ó jẹ ́ olú ìlụ ́ orílẹ ̀ èdè benin lónìí , níbi tí wọ ́ n bí adam al-ilory sí ní ọdún 1917 .
Dokita Shuaib soro yii nibi ipade igbimo awon akosemose elekarundinlogoji, ti o waye nilu Abuja.
Won seto ibura fun Ogbeni Maada Bio ni Ojo Ru Wednesday leyin wakati meji ti won kede re gege-bi eni to jawe olubori.
Awọn agbebọn yii tun pa ọkunrin kan to n wa alupupu fi isẹ aje to gbe arabinrin kan ati awọn ọmọ rẹ mẹta ti awọn eeyan si n wa kiri bayii.
 Bee si ni, eti ina mona-mona naa ko gbeyin, pipese ile pelu owo ti o gaju ara lo kaakiri orile-ede yii abbl,”O fikun oro re pe, bi o ti le je pe, awon omo egbe miiran n fi egbe, All Progressives Congress APC sile, ni se lo tun n gboro si.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Lakotan, Adanna rọ awọn eeyan lati maa mu omi to pọ tabi jẹ eso to ni omi ninu daadaa.
Ní òní olónìí, yóo dúró ní Nobu,yóo di ọwọ́ rẹ̀ sí àwọn òkè Sioni,àní òkè Jerusalẹmu.
Mamadou Sy jẹ́ apàṣẹ ẹgbẹ́-ológun nínú ẹgbẹ́ ológun Mauritania, ó ti jẹ́ igbákejì apàṣẹ, kí ó tó wá di apàṣẹ ẹgbẹ́ ológun ẹ̀ka kan kí wọ́n tó mú un ní alẹ́ ọjọ́ yẹn.
"Torinaa, nibi ipade ikọ amuṣẹya aarẹ lorii Covid-19, PTF, oludari ikọ naa, Sani Aliyu fi alakalẹ ati ilana aatẹle sita fun awọn arinrinajo to ba n bọ lati orilẹede South Africa ati United Kingdom tori awọn ti n ni iriri ""new variant"" loju paali."
" Mo si ní ìgbagbọ́ pé àwọn ìjọba gúúsù-ìwọ̀-òòrun Naijiria yoo gba ìmọ̀ tuntun yìi wọ́le ti wọ́n yoo si ma lò ó láwọ́n ilé ẹkọ lakọbẹ̀rẹ̀"" Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?"
Kí olùfẹ́ mi wá sinu ọgbà rẹ̀,kí ó sì jẹ èso tí ó bá dára jùlọ.
Ni bayii, nnkan ti ṣẹnu ire fun awọn obinrin, nitori awọn lo ni aga ida ọgọta ni ile aṣofin kekere, ti wọn si ni aga to jẹ ida mejidinlogoji nile aṣofin agba orilẹ-ede ọhun.
Hesekaya ọba dìde ní òwúrọ̀ kutukutu, ó kó gbogbo àwọn ìjòyè ìlú jọ, wọ́n bá lọ sinu ilé OLUWA.
Lai si atilẹyin yii, pupọ ninu awọn ọmọde ti a dá silẹ̀ yi ni yoo nira fun lati gbe igbe aye to boju mu, nigbati w ọn ko ni ẹkọ kankan tabi imọ iṣẹ ọwọ tẹlẹri.
"Àmì yìí "" ( ) "" dúró fún pé ohun tí ó wà nínú rè kò pon dandan ."
Oríṣun àwòrán, Twitter Lẹyin naa ni awọn aṣofin naa ba awọn akọroyin sọrọ wi pe awọn n se abadofin lọwọ ti yoo mu atunto ba ileeṣẹ ọlọpaa ni orilẹede naa.
Ṣugbọn bí obinrin náà kò bá tí ì ba ara rẹ̀ jẹ́, ègún náà kò ní lágbára lórí rẹ̀, yóo sì lóyún.
Ìyá Barakat fi ẹ̀mí ìmoore hàn sí gbogbo àwọn tó nawọ́ síi lẹ́yìn ikú ọmọ rẹ̀ Òtítọ́ lékè!
"Oluwo kò gbọdọ̀ kọrin òwe tàbí bá àkọ̀ròyìn sọ̀rọ̀, kó má baà ba ẹjọ́ ara rẹ̀ jẹ́ - Ọ̀ràngún ṣàlàyé Lampard àtàwọn agbábọ́ọ̀lù Chelsea dọ́wọ́jọ di ẹrù wíwo lé Mourinho àti Tottenham lórí Ààrẹ Gnassingbe díje fún sáà kẹ́rin, òun àti bàbá rẹ̀ ti ṣèjọba Togo fún àádọ́ta ọdún lé mẹ́ta Makinde fi owó lọ̀ wá àmọ́ a kò fẹ́, sáà wa tó kù ni kẹ jẹ ká parí - ALGON Ọyọ yarí Ayenakin ṣalaye fun BBC Yoruba, ẹsẹ ofin to ni ṣe pẹlu iwa ọdaran, iyẹn ""Criminal code"" to sọ ijiya to wa fun ẹni to ba wọ aṣọ ologun."
Mo mọ iṣẹ́ rẹ, ati làálàá rẹ, ati ìfaradà rẹ.
Baba naa ṣaisan fun igba diẹ ṣaaju ki o to pa'poda lowurọ oni.
Ẹwẹ, iyanlẹnu lo jẹ fun ọpọlọpọ pe Gomina Obaseki lo jawe olubori ni ijọba ibilẹ alako rẹ, Ize-Iyamu.
Yemi Osinbajo tutọ soke foju gba pẹlu bi o ti ṣe ni awọn eeyan kan n ba orukọ oun jẹ.
Awọn onimọ sayẹnsi ni orilẹ-ede Russia ni ayẹwo ti awọn kọkọ ṣe fun oogun naa fihan pe oogun naa yoo ṣiṣẹ fun arun Coronavirus.
Ajọ EFCC ni, wọn gbe igbesẹ naa lowurọ kutu ọjọ Ẹtì, ọjọ́ kọkanla, Osu Karun, ọdun 2018, lẹyin ti awọn eeyan kan gbe si wọn leti pe, awọn afunrasi onijibiti naa n sọsẹ ni agbeegbe naa.
Abẹwo ileeṣẹ iroyin BBC kaakiri ilu Eko fi han pe lootọ ni ijọba Eko ti n ṣatunṣẹ ọna Maryland atawọn opopona miran to sọ.
Idris kede pe agogo mejila oru ọjọ Ẹti, ọjọ kọkanlelogun, oṣu kẹsan an ni ìséde yoo bẹrẹ.
Tóò bá kí ń ṣe ọ̀daràn, kò yẹ kó o sanwóo béélì l‘ágọ̀ọ́ ọlọ́pàá - Agbẹjọ́rò Ilé ẹjọ́ gba onídúró Naira Marley pẹ̀lú mílíọ́nù méjì náírà Ilé ẹjọ sún ìgbéjọ Maina síwájú lati fi okodoro àìlera rẹ hàn Ọwọ́ ọlọ́pàá tẹ afurasí tó ní òun ló jí ọmọ gbé láti parọ́ mọ́ pásítọ̀ ìjọ Sotitobire Ilé ẹjọ́ wọ́gilé ìgbẹ́jọ́ Olalekan 'Woodberry' Pọnle Eyi lo mu BBC News Yoruba ba Amofin Sadiku Ibitayọ sọrọ lori awọn nkan to rọ mọ ṣiṣe oniduro fun ẹni to n j'ẹjọ.
Tiwantiwa ni wọ́n npe ètò náà gẹ́gẹ́ bíi ètò Yorùbá fún àwa Yorùbá.
Abadofin yii ti Sẹnetọ Ibrahim Oloriegbe dabaa rẹ ni lati da abo bo awọn to ni iṣoro ọpọlọ.
Ìjọba ti wọ́gilé, ètò ìgbéyàwó tó le ni 4000 nítori Covid-19 Ó lé ni ètò ìgbéyàwó ẹgbẹ̀rún mẹ́rin tí kóòtù ìgbeyawo ìjọba àpapọ̀ tó wà ni Ikoyi ló ti wọ̀gile forúkọsilẹ̀ àwọn tó fẹ́ ṣe ìgbéyàwó níbẹ̀.
Ọpọ eeyan lori ayelujara lo ti n fi awọn aworan ọkunrin yii ṣe ẹfẹ ati bi awọn alufa ijọ kan nilẹ Afirika, ṣe maa n ṣe iṣẹ iyanu.
 O tun sapejuwe aare Muhammadu Buhari gege bi olooto ati
Gbogbo wọn ni wọ́n jẹ oúnjẹ ẹ̀mí kan náà.
“Mo fẹ́ kí ẹ mọ̀ dájúdájú pé, gbogbo ẹ̀ṣẹ̀ ni a óo dárí ji àwọn ọmọ eniyan, ati gbogbo ìsọkúsọ tí wọ́n lè máa sọ.
O ni ẹgbẹrun mẹfa ti awọn jọ ṣadehun rẹ ni ajọ INEC kọ lati san fawọn oṣiṣẹ ti wọn lo lasiko yii.
Gbogbo igba ni mo maa n ṣafẹri ẹgbẹ agbabọọlu yii,'' Pochettino lo sọ bẹẹ.
7 116365 Orilẹede Dominican Republic 2345 22.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Social Media Bill: Sowore fàáké kọ́rí, ó ní àbádòfin láti ṣàmójútó ayélujára kò lè fẹsẹ̀ múlẹ̀ láéláé 9 Ẹrẹ̀nà 2020 Ajafẹtọ ọmjọniyan, Omoyele Sowore to kuro lahamọ ajọ ọtẹlẹmuyẹ, DSS laipẹ yii, ti faake kọri lori abadofin to yoo maa ṣamojuto ayelujara ni Naijiria to wa niwaju nile aṣofin agba niluu Abuja.
Koda, ipinlẹ́ Ogun ti ni ojoojumọ ni ijọba oun yoo maa satunse ofin alakale, ti yoo mu ki alaafia joba lasiko iwode #End SARS to ti n bi ige ati Adubi kaakiri Naijiria bayii.
N óo fi òfin mi sí inú wọn, n óo kọ ọ́ sí ọkàn wọn, èmi óo jẹ́ Ọlọrun wọn, àwọn náà yóo sì jẹ́ eniyan mi.
Àwọn àlejò jànkàn-jànkàn a sì máa nwá sórí afẹ́fẹ́, tí wọ́n máa nla àwọn olùgbọ́ l’óye, tí wọ́n sì máa ndáhùn ìbéèrè wọ́n.
igbimo amusese ile-ise CRCC wa sile-ise aare, so pe ile-ise CRCC gbajumo
Nígbà tí wọ́n máa padà àṣá álẹ́, wọ́n fi àwọn nǹkan iyebíye wọn-ọnnì ta bàbá mi lọ́rẹ.
Èèyàn mẹ́wàá tó m bọ̀ láti ìpàgọ́ àdúrà kú nínú ìjàmbá ọkọ̀ ojú pópó l'Osun Àrá sán pa aboyún ìnàkí àtàwọn mẹ́ta míì tó jẹ́ àrà ọ̀tọ̀ láyé Àwọn fíìmù Nollywood ń mú kí òògùn owó àti ìjínigbé gbilẹ̀ síi - Fashola Àwọn ológun ṣíná ìbọn pa Sọjà tó pa èèyàn 26 ní Thailand Oyeyemi fi kun un pe kọmisọnna ọlọpaa ipinlẹ Ogun ti paṣẹ ki wọn gbe baba ọmọ naa lọ si ẹka to n risi ifinisowo ẹru ati ilokulo ọmọde fun iwadii to peye ati ijiya to tọ si iru iwa bẹẹ.
Wọ́n yan àgbà ìjọ fún wọn ninu ìjọ kọ̀ọ̀kan.
Ó bá gbé mi ninu ẹ̀mí lọ sí orí òkè ńlá kan tí ó ga, ó fi Jerusalẹmu ìlú mímọ́ náà hàn mí, tí ó ń ti ọ̀run sọ̀kalẹ̀ bọ̀.
Tinubu ni ohun to yẹ ki ijọba o mojuto bayii ni imugbooro iye awọn to n san owo ori.
Șé ewu àti kó ààrùn Coronavirus wà ti mo bá lo ṣe ère ìdárayá níta pẹ̀lú àwọn tí wọn ò lo ìbòmú?
O ni awọn ọmọ orilẹede Naijiria, paapaa julọ, awọn musulumi ni ọpọ ẹkọ lati kọ lara Ramadan eleyi to ni o wa lati 'ro awọn eeyan lagbara nipa ti ẹmi.
Máa yọ̀ nígbà tí ó bá dára fún ọ, ṣugbọn nígbà tí nǹkan kò bá dára, máa ranti pé Ọlọrun ló ṣe mejeeji.
“Bakan naa nijoba FCT ti fe satunse ipese ounje ofe fawon akekoo ni eyi ti yoo gba to okoo din ni bilionu owo naira kan fawon ile iwe to wa labe akoso FCT.
0 1868 Erekusu Channel 48 28.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Working religious women: Ẹ̀lẹ́hàá kìí ṣe ọ̀lẹ- Aminat Adegoke Buruji Kashamu ninu Iṣelu: Buruji Kashamu kopa pupọ ninu oṣelu ipinlẹ Ogun O jẹ agba ẹgbẹ ati Oloye ẹgbẹ ninuẹgbẹ oṣelu PDP ni ipinlẹ Ogun to wa ni Guusu iwọ oorun Naijiria.
Àlaga ajọ Musulumi naa ní agbara láti sọ ọjọ tí àwọn Mùsùlùmí Naijria lèe bẹ̀rẹ̀ ààwẹ̀, ti àwọn ti orilẹ̀ èdè míran ba tilẹ kéde ọjọ́ mìíràn.
Ọkan pataki lara awọn to gbe ẹgbẹ naa kalẹ, Akogun Tola Adeniyi sọ fawọn akọroyin pe, lara idi ti wọn ṣe fi ọwọ osi juwe ile fun Akintoye, ko ṣẹyin awọn iwa kan to n wu, eyi to ni ko bojumu to.
Ó pọ̀ tóbẹ́ẹ̀ tí eniyan kò le kà wọ́n, nítorí pé ọpọlọpọ igi kedari ni àwọn ará Sidoni ati Tire kó wá fún Dafidi.
O ṣá mọ ohun tí Saulu ọba ṣe, tí ó lé gbogbo àwọn abókùúsọ̀rọ̀ ati àwọn oṣó kúrò ní Israẹli.
" Bakan naa ni wọn tun fi ẹsun kan aṣofin Sunday Akinniyi pe o n dun mọhuru mọ awọn aṣofin ile naa, ti gbogbo ile si ti ni ki akọwe agba ile aṣofin ipinlẹ Ekiti o fi ẹjọ rẹ sun lọdọ awọn agbofinro gbogbo nipinlẹ naa.
Ọlọrun nìkan ni mo fi sùúrù gbẹ́kẹ̀lé,nítorí ọ̀dọ̀ rẹ̀ ni ìrètí mi ti wá.
Òtítọ́ ati òdodo ni ìdájọ́ rẹ̀.
Ogun Cholera: Ọdọọdún ni àrùn onígbá-méjì máa n ṣọṣẹ́ ní Nàìjíríà -NCDC
Adamu ṣalaye pe ''ohun ti eyi tumọ si ni pe ileeṣẹ ọlọpaa gbọdọ wa ọna tuntun lati maa ṣe iṣẹ wọn, ati iru anfaani ti araalu n jẹ l'ara wọn ni gbogbo ọna ti awọn ọlọpaa n gba ṣe iṣẹ wọn.
dola lati fi satilẹyin fun atunse si eto ilera, eto ẹkọ , omi  ati ironilagbara fun awon eniyan.
Oríṣun àwòrán, osun state government/ twitter ''O ṣi dara ti awọn ọmọ girama ati fasiti ba pada si ileewe, amọ o buru jai fun awọn ọmọ ileewe alakọbẹrẹ nitori wọn ko le e tọju ara wọn.
Ẹlẹ́wọ̀n Kirikiri tó ń wọ́ke, olùdarí ọgbà ẹ̀wọ̀n ló ṣe onígbọ̀wọ́ fun - EFCC Nigba to n ba ipejọpọ naa sọrọ, gomina Makinde fọwọ gbaya pe oun yoo da si ọrọ̀ naa ki iyansẹlodi naa lee di ohun igbagbe, ti eto ẹkọ kikọ yoo si bẹrẹ lọgan.
Irọ́ ni o, Ebenezer Obey ò kú!
Kí ó tóó parí ọ̀rọ̀ rẹ̀ ọkàn mi ti balẹ̀ díẹ̀ mo sì pinnu àti sọ̀rọ̀ rere fún un kí n baà lè rí ọ̀nà jáde.
Ẹni ti ọrọ ijinigbe yi ba kan lo mọ ni Naijiria ṣugbọn lẹnu ọjọ mẹta yi, iṣẹlẹ ijinigbe loju ọna Kaduna si Abuja jẹ ohun to n ko awọn arinrinajo laya soke.
Awọn mọlẹbi Abdullahi lero pe eleyi yoo mu ki wọn tu silẹ.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ìtàn tó wà nídi òwe ‘Sebótimọ Ẹlẹ́wà Sàpọ́n’ Ọba Adesoji Aderemi, Ọọ̀ni Ifẹ̀ tó gba ipò ọba mọ́ tòṣèlú MKO Abiola, iṣẹ́ aṣẹ́gità ló fi bẹ̀rẹ̀ okoòwò Iṣọla Oyenusi rèé, ẹnití ìfẹ́ obìnrin ṣun dé ìwà ìdigunjalè Taiwo Akinkunmi, ọmọ Ibadan tó ya àsìá Naijiria Ayinla Ọmọwura, orin èébú àti oríyìn lo fi di ọ̀rẹ́ àwọ̀n obìnrin ''Wàhálà Ikẹja ló sọ mí di oníṣẹ́ ọwọ́ àgbọn ní Badagry'' Ìtàn tó rọ̀ mọ́ òwe ‘aṣọ kò bá Ọ́mọ́yẹ mọ́.
Ọmọ ọdọ̀ Ọpẹ Bademosi kò kú
Agba amofin to tun jẹ agbẹnusọ fun ipolongo aarẹ Buhari, Festus Keyamo naa ti pe fun igbesẹ mẹta lati ọdọ awọn ọlọpaa lori ọrọ naa.
Ìdí nìyí tí ọkunrin yóo ṣe fi baba ati ìyá rẹ̀ sílẹ̀, tí yóo sì faramọ́ aya rẹ̀, àwọn mejeeji yóo sì di ara kan ṣoṣo.
Ẹ dakun, tẹkun tẹkun ni mo fi ń bẹ yín pé kẹ bá mi tú àwọn ọmọ mi silẹ, ẹ wo ìrora tí mo jẹ fún ọdún méjìlá tí mo ti ń wá ọmọ, kí n tó rí àwọn ọmọ náà bi."
Saudi Arabia, Kuwait ati Oman naa ti ti ẹnu Ibode wọn nitori ki awọn ara ita ma baa wọ ilu.
"Ni bayii ti Fani-Kayode ti sọ pe oun ko ọrọ ti oun sọ si akọroyin naa jẹ, Eyo sọ pe bo tilẹ jẹ pe ko ti i pe oun gan-an lati tọrọ aforiji, ""nitori pe emi lo sọ ọrọ kọrọ si, ṣugbọn nitori ipo mi gẹgẹ bi biṣọpu, mo ti dariji."
Ẹ kò gbọdọ̀ jẹ́ kí ó ṣẹ́kù di òwúrọ̀ ọjọ́ keji, bí ohunkohun bá ṣẹ́kù, ẹ dáná sun ún.
Àwọn ọlọ́pàá wọn-ọnnì to gbogbo àwa tí a ṣẹ̀sẹ̀ dé lẹ́sẹẹsẹ wọ́n sì wo gbogbo wa lọ, wọ́n fi ọwọ́ tẹ̀ wá ní ìdí wọ́n sì wo igbá-àyà wa láti fi mọ̀ bí a ti ní ọ̀rá sí.
Wọn sọ fun mi pe o wa nibi ti wọn ti n tọju rẹ, amọ nigba ti mi o ri i fun ọjọ meji, ẹru tun n ba mi pe laduru gbogbo nkan ti mo ti la kọja.
Oríṣun àwòrán, @thecableng Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 3 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 5 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Bakan naa ni iyawo aarẹ Buhari, Aisha Buhari fi si oju ikansiraẹni Instagram rẹ pe oun wa ni Mina pẹlu awọn iyawo aarẹ orilẹede miran ni Afirika lati lọ se Hajj.
Ọba bá bi í pé, “Kí ni o fẹ́ gbà?
Àwọn ọkuǹrin tì o ń kí mi nísisì yìí lé ni ẹgbẹ̀rún, àwọn obìnrin tí o ń yẹ́ mi si lé ni ẹgbẹ̀jọ́.
Iya Esther ni ẹni ti o ba n gba idamẹwaa ti ko ṣe ore tabi, ṣaanu, ki a fi silẹ sọwọ Ọlọrun.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ile ẹjọ Myanmar ran akoroyin Reuters méjì lẹwọn labẹ ofin mẹnumọ 3 Owewe 2018 Oríṣun àwòrán, AFP/REUTERS Àkọlé àwòrán, Kyaw Soe Oo ati Wa Lone ni akoba lọlọpa se fun awọn.
Yàtọ̀ si ìgbà Ìjọba Ológun, Èkó gbádùn ìdúróṣinṣin ni àsìkò Ìjọba Alágbádá tàbi Ìjọba Tiwantiwa lati ọdún kẹtàdínlógún sẹhin.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Solar Power Naija: Ṣe lóòtọ́ ní ọmọ Nàíjíríà mílíọ́nù 25 yóò má ló ìná Solar látí Dec 1, 2020?
 ewe, won bi oloogbe Baba Sala lodun 1936 niluu Ilesha.
gbógun ti Bera, ọba Sodomu, Birisa ọba Gomora, Ṣinabu, ọba Adima, Ṣemeberi, ọba Seboimu ati ọba ìlú Bela (tí ó tún ń jẹ́, Soari).
Kolawọle Ajeyẹmi: Ó yẹ ká ro ọjọ́ ìkúnlẹ̀ bímọ mọ́ aya lára lásìkò tó bá ṣẹ̀ wá
Ọpọ awọn eeyan to ba wa sọrọ nilu Ẹdẹ lo rọ gomina Oyetọla, lati mase fi oju alatako ati alaida wo awọn eeyan ilu Ẹdẹ.
Oloyede ni akẹẹkọ to le ni miliọnu (1,792,719) ni wọn yoo ri esi idanwo gba ninu iye awọn to se idanwo naa (1,886,508).
Amọṣa, ṣe awọn agba bọ wọn ni ẹni ku ati ẹni nu yoo pade lọjọ kan, ori ti yoo ba arabinrin ẹlẹha yii ṣe lo ni ki o lọ ra ọja ohun eelo aṣọ riran ni ọja Ogunpa ni ilu Ibadan nibẹ ni o ti ṣe kongẹ awọn mejeeji yii.
Ó rí ọ̀run tí ó pínyà, tí nǹkankan bí aṣọ tí ó fẹ̀, tí ó ní igun mẹrin, ń bọ̀ wálẹ̀, títí ó fi dé ilẹ̀.
 Òpò akékòó ni ó máa n wá sódò rè .
Akonimoogba agba iko agbaboolu Super-Eagles, Gernot Rohr ti kede agbaboolu mokanla ti yoo koju Czech Republic, ninu ifesewonse olorejore keyin ti yoo waye lorile-ede Austria, looRu(Wednesday), eyi ti iko ohun yoo gba saaju idije agbaye naa.
Ileeṣẹ ọlọọpa ni iwa imunilẹru ati iwa ika si ọmọniyan ni iṣẹlẹ naa jẹ.
Eṣinṣin sì ba ilẹ̀ náà jẹ́.
Ó sì dúró lẹ́nu ọ̀nà, ó mú okùn òwú ati ọ̀pá tí wọ́n fi ń wọn nǹkan lọ́wọ́.
OLUWA bèèrè pé, ‘Ta ni yóo lọ tan Ahabu jẹ, kí ó lè lọ sí Ramoti Gileadi kí wọ́n sì pa á níbẹ̀?
Oríṣun àwòrán, Science Photo Library O fikun wi pe, ijọba ipinlẹ Ondo n se itọju awọn ti wọn ko aarun naa ni ile iwosan ijọba ti FMC Ọwọ, ati wi pe, itankalẹ aarun naa ko i tii kọja agbara awọn.
Odunbaku pari ọrọ rẹ pe ilu Eko ni baba wa lasiko ti oun n ba BBC sọrọ, ati pe kokoko lara rẹ le.
Nígbà tí wọ́n bá se àsè náà kárí tán, Jobu yóo ranṣẹ sí wọn láti rú ẹbọ ìwẹ̀nùmọ́ fún wọn.
" Ni ti ile ẹjọ, awọn ti ẹsun ti wọn fi kan wọn ba fi aaye silẹ pe wọn le maa gba ile wọn wa jẹjọ ni adajọ maa n gba oniduro fun.
Yoruba Nollywood: Àgbà òṣèré tíátà, Musiliat Arikeusola 'Osuntoun' jáde láyé
Gẹgẹ bi ajọ FCCPC ṣe sọ ninu atẹjade kan to fi sita lori ayelujara Twitter rẹ, ajọ naa sọ pe awọn awọn eeyan kan to ra ororo ileeṣẹ naa ti ọjọ ti lọ lori wọn nilu Abuja lo fi ọrọ to ajọ naa l'eti.
 Oríṣun àwòrán, Screenshot/gistloverszone/instagram Iroyin naa tẹsiwaju pe wahala bẹrẹ nigba ti Flakky gba Jago ni imọran lati ta ile rẹ, ti owo rẹ to miliọnu lọna aadọrun (90 million) Naira."
Àwọn ilẹ̀ àjogúnbá ẹni ẹlẹ́ni,ilé wa sì ti di ti àwọn àjèjì.
Wahala bẹ silẹ laarin gomina ipinlẹ Ondo, Rotimi Akeredolu ati igbakeji rẹ lẹyin ti Ajayi fi ẹgbẹ oṣelu APC silẹ lọ darapọ mọ ẹgbẹ PDP.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, NLC: Àwọn olósèlú ń la títì láì sanwó osù torí owó tí wọn yóò rí lórí àkànse isẹ́ A gbọ pe awọn eeyan kan ti wọn furasi bii darandaran lo ya bo adugbo naa ni oru mọjumọ ọjọ Ẹti, lasiko tawọn eeyan naa n sun lọwọ.
Wo àwọn bẹbẹ tí Umar Musa Yar'adua ṣe lórí àlééfà Iye ìgbà tí Sani Abacha tí fi owó ransẹ si Nàìjíríà láti ọrun Coronavirus: Kíni àwọn àmì tuntun tó n fihàn?
Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí 7:57 Fídíò, End SARS, End SWAT: Ó pé mi bí SARS kò ṣe sọ mí dolówọ́- Fulani Kwajafa, Duration 7,5717 Ọ̀wàrà 2020 EndSars protests: Fọ́tò àti ìtàn èèyàn tí ikú wọ́n ní ọ́wọ́ ọlọ́pàá Nàìjíría nínú16 Ọ̀wàrà 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Oral Sex: Bóo bá ń gba ẹnu ní ìbálòpọ̀, wo àìsàn tóo lè kó lójú ara rẹ Wo ojú Akeem t'Ọlọ́pàá mú pé ó fipá bá ọ̀dọ́mọbìnrin kan sùn létí odò l'Oṣun Yàtọ̀ sí Eko, wo ohun t'áwọn ìpínlẹ̀ meje míràn ń sọ nípa ìwọlé àwọn akẹ́kọ̀ọ́ Wòlí àti Pásítọ́ ló máa ń rọ̀jọ̀ àdúrà sórí ibọ́n wa kí a tó lọ digunjalè- Kayode Williams Ogun Àgbẹ́kọ̀yà, ìjà òmìnira fáwọn àgbẹ̀ ni tàbí ìfẹ́míṣòfò?
Awon  AseyoriLara awon to wa pade  ogagun agba naa ni, ogagun Oladayo Amao to je adari iko omo oogun ofurufu ni ipinle Benue.
Atẹjade kan ti osisẹ alarina ileesẹ ọlọpaa ilẹ wa, Anjuguri Manzah fisita salaye pe, oun ba imọ awọn ọmọ ẹgbẹ Shiite naa jẹ lati fi tipa gba akoso ile asofin apapọ ilẹ wa lọjọ Isẹgun.
o tun figba kan je ojogbon nile eko giga fafiti ipinle Eko fun opolopo odun.
Awọn ọlọpaa mẹrin ti wọn fi panpẹ ọba mu, nipa iku George Floyd ni wọn ti gba iṣẹ ni ọwọ wọn, ti wọn si ti fi wọn si panpẹ ọlọpaa.
Awọn ọlọpaa ni ipinlẹ New York, California ati New Jersey lowo wọn gbe pẹẹli julọ.
Igbesẹ yi ni ọpọ ti ṣe apejuwẹ rẹ gẹgẹ bi ohun manigbagbe.
Gawat Àkọlé àwòrán, Oshiomole ni akọkọ ojuṣe oun ni lati pari aawọ lẹkajẹka ẹgbẹ oṣelu naa Lori dukuu to n waye lawọn ipinlẹ kan ninu ẹgbẹ oṣelu naa, Oshiomole ni, igbagbọ oun ni pe bi ọpọlọpọ awọn ọmọ ẹgbẹ ṣe gbimọ pọ̀ gbe oun wọle, n fun oun ni idaniloju pe afẹfẹ ifẹ yii ni oun yoo gun lati fi wa ojuutu si awọn aawọ naa.
Ẹ wo bí Isa Funtua, amúgbálẹ́gbẹ̀ẹ́ Aàrẹ Buhari ṣe lo ìgbé ayé rẹ Isa Funtua: Ohun mẹ́jọ tí ẹ kò mọ̀ nípa Isa Funtua, ana Aàrẹ Buhari tó dolóògbé Àwọn ǹkan pataki ti oloogbe Isa Funtai ṣe lókè eèpẹ̀ kó to dagbere faye pe o digboṣe.
Ibi mímọ́ jùlọ, ati ibi mímọ́ ní ìlẹ̀kùn meji meji.
Wí fún wọn pé bí mo bá jẹ́ kí ogun jà ní ilẹ̀ kan, tí àwọn eniyan ibẹ̀ bá yan ọ̀kan ninu wọn, tí wọ́n fi ṣe olùṣọ́; 
Shiite: Ilé ẹjọ́ gíga Kaduna sún ìgbẹ́jọ́ adarí Shiite síwájú
Ìròyìn sọ pé, ìjà tí ó wáyé l'ọ́jọ́ ajé mú ìpalára bá ẹnìkan ti o sì pàdánù ẹ̀mí rẹ̀ lásìkò tí ò ń wọ́n n gbe lọ sí ilé ìwòsàn fún ìtọ́jú.
Èmi kìí se Ọlọ́run, ẹ yé lo fọ́tò mí fún ẹ̀bùn - Adeboye BBC Yoruba ba gbajugbaja onwoye kan toun naa jẹ ojiṣẹ Ọlọrun, Femi Aribisala lori ọrọ yii.
Gẹ́gẹ́ bí a ti sọ tẹ́lẹ̀, mo tún ń wí nisinsinyii pé bí ẹnikẹ́ni bá waasu ìyìn rere mìíràn fun yín, yàtọ̀ sí èyí tí ẹ gbà, kí olúwarẹ̀ di ẹni ègbé.
Agbenusọ fun Ileesẹ ọlọpaa nipinlẹ Ogun, Abimbola Oyeyemi, ẹni to fidi iṣẹlẹ naa mulẹ tun fikun pe wọn ti gbe afurasi naa lọ si Olu Ileesẹ ọlọpaa nipinlẹ naa to wa ni adugbo Eleweran.
Buhari gbe igbimọ kalẹ lori okoowo Afrika Orilẹẹde 44 t'ọwọ bọ'we lori AfCFTA Corovavirus: Àjọ WHO tí bẹ̀rẹ̀ ètò láti ran àwọn orílẹ́-èdè Afrika lọ́wọ́ Bi nkan ti ṣe ri bayi ti banki apapọ orileede Naijiria ti ni kawọn eeyan ma mura kalẹ de igba ti yoo le diẹ, BBC Yoruba fọrọwa awọn onimọ nipa ọrọ aje lẹnu lati ṣalaye ohun ti awọn ọmọ Naijiria yoo ba pade.
Ó tún sọ fún mi pé, “N óo fi nǹkan ìríra ńlá mìíràn tí ó jù báyìí lọ tí wọn ń ṣe hàn ọ́.
Eeyan 9,402 lo ti ri iwosan gba, nigba ti awọn 573 ti dero ọrun nitori arun ọhun.
Bí àwọn òbí ọmọ yìí ti gbée nílè tí wọ́n sì tún nawọ́ láti mú bàntẹ́, ìyàlẹ́nu ni ó jé fún wọn pé orin ni bàntẹ́ fi dá wọn lóhùn bíi ti àkókò.
Ṣé o mọ ibi tí ìmọ́lẹ̀ ti ń tàn wá,tabi ibi tí afẹ́fẹ́ ìlà oòrùn ti ń fẹ́ wá sórí ayé?
Àwọn kànga ìṣẹ̀ǹbáyé rèé ní Badagry tó ń pa ẹrú níyè Bó bá jẹ́ òrìṣà kan ni wọ́n ń fi ẹ̀jẹ̀ bọ l' Akinyele, ẹ wáa jáde- Seyi Makinde Bí Naira Marley ṣe ri ọkọ̀ òfurufú tó gbée lọ si Abuja Abiyamọ ni mi sùgbọ́n mo pa òbí àwọn ọmọ ọlọ́mọ lásìkò ìpìniyàn abéle Rwanda Ninu ọrọ ti wọn, Ijọba ipinlẹ Ọyọ ni awọn akẹkọọ iwe kẹfa nileewe alakọbẹrẹ (Primary Six), iwe kẹta ileewe girama (JSS 3) ati kilasi aṣekagba nileewe girama (SSS 3) nikan ni yoo wọle ikẹkọọ ni ọjọ naa.
Senakeribu ọba Asiria bá pada sílé, ó ń lọ gbé ìlú Ninefe.
"Ọlọ́pàá wú òkú obìrin tó ń múra ìgbéyàwó lọ́wọ́ tí 'gate-man' rẹ̀ ṣekúpa ""A fẹ́ yọ ààrẹ ẹgbẹ́ Yorùbá YCE nípò torí àwọn ìwà tí kò bójúmu"" Wo àànfàní ‘Masturbation’, fífún ara rẹ̀ ní adùn ìbálòpọ̀ Ẹ fura o, Boko Haram ti pàgọ́ sí Abuja, yóò ṣe ìkọlù láìpẹ́ - Iléèṣẹ́ Aṣọ́bodè lọgun Ohun to fa aawọ ni iwaasu kan ti Oyedepo ju soju opo Twitter rẹ lori ọrọ igbeyawo lo sọ nipa pataki ki aya maa bọwọ fun ọkọ rẹ."
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Àwa ọba alayé ń wọ́nà láti ṣẹ́ eegun ẹ̀yin ọ̀daràn Fulani - Ọọ̀ni Àwọn àṣà àti ìse tó yọ obìnrin sílẹ̀ nílẹ̀ Yorùbá Iṣọla Oyenusi rèé, ẹnití ìfẹ́ obìnrin ṣun dé ìwà ìdigunjalè Báwo ni abẹ́rẹ́ àjẹsára ṣe bẹ̀rẹ̀?
Buhari ní òun kò gbàgbé àwọn ọmọ Chibok Àwòrán àjọyọ̀ ìjọba ológun ní Sudan Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Bí o ṣe lè fí òǹkà, ọ̀mọ̀ ìka tàbí ìkúùkù wọn oúnjẹ́ APC ni nitori eleyii, ipẹjọ ti Atiku Abubakar fi sọwọ si ile ẹjọ to n gbọ ẹsun awọn to di ipo nla mu ko lẹ nilẹ ati pe ko tilẹ tọ si Atiku lati du ipo ninu idibo orilẹede Naijiria nitori ọmọ orilẹede Cameroon ni.
Alabọde Amẹrika kan ni ẹni akọkọ ti wọn kede poe o ni arun naa nipinlẹ Ọyọ, wọn si ti daa silẹ pe ki o maa lọ sile bayii lẹyin itọju to peye ni ileewosan ti ayẹwo miran si ti fihan pe arun naa ti kuro ni agọ ara rẹ.
O jẹ ọkan lara awọn ti o lọ si ipade atunṣe iṣelu orilẹ-ede, eyi ti aarẹ orilẹ-ede yi tele ri, Olusegun Obasanjọ gbekale ni ọdun 2005.
Apapọ iye eeyan to ti padanu ẹmi wọn lọwọ Covid-19 jẹ ẹgbẹerun kan le ni mẹrindinlọgọfa,1,116.
OLUWA, Ẹni Mímọ́ Israẹli, ẹlẹ́dàá rẹ ni,“Ṣé ẹ óo máa bi mí ní ìbéèrè nípa àwọn ọmọ mi ni,tabi ẹ óo máa pàṣẹ fún mi nípa iṣẹ́ ọwọ́ mi?
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Fasoranti: Wọn ní kí Buhari kìlọ̀ fáwọn darandaran tó n tẹ Yorùbá lójú mọ́lẹ̀ bí bẹ́ẹ̀ kọ́.
 Mo moomo gbera lati ipinle Eko wa sile wa se fiimu agbelewo yii ni ki awon eniyan le mo pe o seese lati bere idagbasoke lati oode koowa ati lati pese ise fawon odo wa ni ekun yii ni”.
Ọkàn rẹ̀ a máa balẹ̀, ẹ̀rù kì í bà á,níkẹyìn, èrò rẹ̀ a sì máa ṣẹ lórí àwọn ọ̀tá rẹ̀.
 “Egbe oselu APC eka ipinle Benue lo fun mi ni kaadi pupa ki i se egbe oselu APC apapo, eyi si ti to fun mi lati duro digbi ninu egbe yii.
Kí àwọn ọmọ rẹ̀ di aláìníbaba,kí aya rẹ̀ di opó.
Àwọn ohun tí Bẹnaya, ọmọ Jehoiada, ṣe nìyí, tí ó sọ ọ́ di olókìkí, yàtọ̀ sí ti àwọn akọni mẹta tí a sọ nípa wọn.
Abiola Ajimobi papoda lọjọ karundinlogun, oṣu Kẹfa, ọdun 2020 nile iwosan aladani kan nipinlẹ Eko, lẹyin to lugbadi arun Covid-19.
 To ba jẹ pe Ọọni ile Ifẹ lo gbe iru igbesẹ yii, o dara, nitori pe, oun ni olori ade gbogbo ilẹ Yoruba.
Wọ́n ṣe bí OLUWA ti wí; Aaroni na ọ̀pá ọwọ́ rẹ̀, ó fi lu erùpẹ̀ ilẹ̀, iná sì bo àwọn eniyan ati àwọn ẹranko; gbogbo erùpẹ̀ ilẹ̀ sì di iná ní gbogbo ilẹ̀ Ijipti.
"Kaka ki wọn gbe lọ si Abeokuta, wọn gbe e lọ si ọdọ oniṣegun ibilẹ kan pe ki o yọ ọta to wa lara rẹ, lẹyin naa ni wọn gbe e pada lọ si ile iwosan gbogboniṣe Otta sugbọn wọn kọọ nibẹ.
11 Sẹ́rẹ́ 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 28 Agẹmo 2020 Oríṣun àwòrán, tokemakinwa Toke Makinwa to jẹ gbajugbaja sọrọsọrọ lori ẹrọ redio ti sọrọ lori ọrọ ile rẹ ni agbegbe Banana Island ati ileeṣẹ Amcon to ti n ja lori ayelujara yii.
Ó ní túbọ̀mu ó sì máa ń fi ọwọ́ pa á.
Kí ló dé tí àwa fi níláti máa sin Abimeleki?
Láìpẹ́, a óo tú àwọn tí a tẹ̀ lórí ba sílẹ̀.
Nǹkankan náà ni àwọn mẹtẹẹta ń tọ́ka sí.
 Ó wá ń bá wọn ṣiṣẹ ́ aáyan ògbufọ ̀ ni ilé-iṣẹ ́  radio nigeria "" ."
Àwòrán ìwọ́de NLC, TUC, ULC lónìí Ẹgbẹ́ òṣìṣẹ́ so ìyanṣẹ́lódì rọ̀ NLC, TUC, ULC yóò ṣe ìwọ́de l'ónìí NLC, TUC: Àwa ò gba owó lọ́wọ́ Fayose ooo Ẹgbẹ NLC wa kilọ fun ijọba apapọ pe gbogbo awọn osisẹ lorilẹ-ede Naijiria ni yoo da isẹ silẹ, ti ijọba ko ba ṣe ohun totọ lasiko.
Asamoah Gyan: O ṣeéṣe kí èyí jẹ́ ìdíje AFCON ìkẹyìn mi O fẹ́ yọ́ wọ ààyè ibùsùn àwọn obìnrin lọwọ́ ọlọ́pàá bá tẹ̀ ẹ!
Kiki ki ijọba ilẹ ọhun fọwọ si ẹrọ ọhun lo ku ki wọn to gbe jade.
ni ipinle  Sokoto , to jẹ Ila oorun Ariwa
Bakan naa, awọn ọmọ ologun yii ni wọn ti pasẹ fun lati mu awọn eeyan to n sewọde yii si ahamọ.
Bẹẹ ba si gbagbe, Wolii Alfa Babatunde, tii se adari ijọ Sotitobire ni afurasi ati olujẹjọ akọkọ ninu ẹjọ ọhun.
"Wo àwọn ọmọ Naijiria mẹ́ta tó jáwé olúborí nínú ìdìbò sílé aṣòfin ilẹ̀ Amẹrika Biden ni ""Mo jẹjẹ lati jẹ aarẹ ti ko ni wa iyapa orilẹede Amẹrika amọ maa wa ọna ti irẹpọ yoo se wa."
Bakan naa ni ileewe Auchi Polytechnic naa ti bẹrẹ lati ma a ta fọọmu post-UTME.
Lẹyin naa lo ni yoo wu awọn dokita lati pada sẹnu iṣẹ wọn pada lati maa ṣe itọju awọn alaisan, kuku ki ijọba ṣe ohun to tọ nikan lo ku.
Mali, Algeria, Ghana, Zimbabwe, Cote d’ Ivoire, Angola,Tunisia, Cameroon,
Nínú ọ̀rọ̀ rẹ̀ pẹ̀lú BBC lówùrọ̀ òní sàlàyé pé bi ìgbìmọ̀ ààrẹ kò bá ri kò ni sọ.
Ìpànìyàn, ìjínigbé ti gbàkóso ilẹ̀ Yorùbá, Buhari, tètè kéde pé ètò ààbò kò fararọ - Soyinka Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Oro Festival: Àwọn olórò ní ọdún Màgbó ló ń gba ibi lọ, kó ire wọlé ní Ikorodu Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
'Báyìí la ṣe rìn ín láti pápákọ̀ òfurufú Abuja sí Eko bí ìrìnà òfurufú abẹ́lé ṣe bẹ̀rẹ̀' Ẹ́ wo bí sọ̀rọ̀sọ̀rọ̀ yìí ṣe ń fi ara rẹ̀ kọ́ àwọ́n òbinrin ní ìgbádùn ìbálòpọ̀ Nigba to pe ọmọ ọdun mẹwaa, wọn ko si kọ si i lẹnu, wọn jẹ ko bẹrẹ iṣẹ to yan laayo - Ṣebi ori lo mọ iṣ aṣela.
 Arabinrin Abiodun Koya, to je akorin igbalode, akewi, osere ori itage ati sinima so pe, oun fe lo  ajodun orin naa lati  fi gbe ebun ere sise ati idaraya sita fun araye  Koya to n ba awon eniyan dapara, ki ere to bere so pe”iyanu ni yoo je fun awon oluworan, nirori pe pun ati awon akorin lati ile okeere ni awon yoo jo maa fi ebun won da won laraya”.
org lati bere fun ki awọn ẹsọ alaabo o mu ẹkun naa laaye, lai pa.
Oríṣun àwòrán, @ArewaHistory Oju ẹni maa la, a ri to, oju ẹni maa la, yoo ri iyọnu.
Ilu Abuja to jẹ olu ilu Naijiria ni wọn kọkọ fabọ sí lalẹ ọjọ Aiku.
Asiko naa lo ṣawari ìdà to fi pa ejo nla ti ko jẹ ki awọn araalu Daura o raaye pọn omi ninu kanga Kusugu.
Awọn to ba wa lati ẹkun ariwa ati Guusu-Iwọ Oorun yoo ṣe tiwọn ni ile ẹkọ ọlọpaa Mopol to wa ni Ende, Nasarawa ati ni ile ẹkọ awọn ọlọpaa to wa ni ilu Ila Oragun, ipinlẹ Osun.
ati pé ẹ̀bùn Ọlọrun ni pé kí olukuluku jẹ, kí ó mu, kí ó sì gbádùn lẹ́yìn làálàá rẹ̀.
Idije alarinyan-jiyan yoo waye lojo-Bo ni ilu Freetown ti n se olu ilu orile-ede naa laarin awon oludije dupo mefa si ipo Aare lorile-ede Sierra Leone, saaju eto idibo ti yoo waye ni ojo keje osu keta odun 2018.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ekiti Election: Pọpọ sinsin idibo n lọ lori lawọn wọọdi Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, #EkitiDecides: Fayose sùn lórí ibùsùn aláìsàn Eyi lo tun mu PDP sèwọ́de tako ìwà ipá l‘Èkìtì ni eyi to tun bi ero pe Fayoṣe yin Ngige fún bó se polongo ìbò fún PDP Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ekiti Election: Ìjọba ìbílẹ̀ làwọn òsìsẹ́ Inec yóó sùn mọ́jú ọjọ́ ìbò Ọlọ́pàá 30,000 ní yóò mójútó ìdìbo Ekiti Bayii opolopo igbese nijoba atawon agbofinro ti gbe ki eto idibo Ekiti le jẹ aṣeyọri Wo ibi tí ìgbáradì fún ìbò gómìnà l'Ékìtì dé dúró Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ekiti Election: Àwọn ohun èèlò ìdìbò ń dé síjọba ìbílẹ̀ Ajọ eleto idibo INEC naa sọrọ lori iṣẹ ti wọn ti ṣe de idibo Ekiti pe: Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, #EkitiDecides: 'Ìjà ẹgbẹ́ òkùnkùn ló ń ṣẹlẹ̀ kìí ṣe ti òṣèlú' Bi àwọn kan ṣe n yin Fayose ni awọn mii gba pe ọgbọn lo n da pe Fayose kọ́ ni olóṣèlú tí yóò kọ́kọ́ kán l'ọ́rùn' Bayii àwọn eniyan Ekiti n fẹ alaafia, wọn de n fẹ jade dibo fun ẹni to wu wọn loni Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ekiti Election: Ará Èkìtì ń fẹ́ gómìnà tí yòò tù wọ́n lára Ṣe ìwọ mọ Ṣẹgun Adewale, olùdíje Ekiti yìí?
Ṣé ẹ fẹ́ kó gbogbo àwọn eniyan wọnyi kúrò ní ilẹ̀ Juda, ati àwọn ọkunrin ati àwọn obinrin, àtọmọ ọmú, àtọmọ ọwọ́, títí tí kò fi ní ku ẹnikẹ́ni ninu yín lẹ́yìn ni?
Kòjọ àwàdà, kò jọ yẹ̀yẹ́ ni wọ́n ń fi í ṣe.
Ọlọ́pàá ń wa A kò mọmọ pá ọdọ́ kan tó kù ní Portharcourt - Ilé iṣẹ́ ọlọ́pàá Ọga agba ọlọpaa sọ pe igbesẹ naa waye nitori awọn ẹsun pe ọlọpaa ṣeeṣi yinbọn, pa araalu lọna ti ko ba ofin mu, nitori pe o ti rẹ wọn nitori wahala ti wọn ṣe l'ẹni iṣẹ, eyi to n ni ipa lara ihuwasi ati afojusun wọn.
Johanu tún jẹ́rìí pé, “Mo ti rí Ẹ̀mí tí ó sọ̀kalẹ̀ bí àdàbà láti ọ̀run tí ó bà lé e, tí ó sì ń bá a gbé.
Nunieh ni ọmọ kẹrin sẹnatọ ati agbẹjọro akọkọ nilẹ Ogoni, Cyrus Nunieh to wa lati ijọba ibilẹ Beeri Khana, ṣugbọn baba rẹ ọhun ti wọ kaa ilẹ sun.
Ṣugbọn wọ́n túbọ̀ tẹnu mọ́ ẹ̀sùn wọn pé, “Ó ń fi ẹ̀kọ́ rẹ̀ da àwọn eniyan rú; Galili ni ó ti kọ́ bẹ̀rẹ̀, ó ti dé gbogbo Judia níhìn-ín nisinsinyii.
Bakan naa lo se ipade idakonko pelu Omowe Umar Ganduje to je gomina ipinle Kano fun bii aadota iseju.
Lose to koja ni alaga igbimo asofin to n ri si eto eyawo ti abele ati oke-okun asofin Shehu Sani ro awon akegbe re nile igbimo asofin lati gbese kuro lori sise ayewo awon igbimo ile ifowopamo naa.
Oti ní ọmọ náà fi orí àti apá ṣèṣe bí ọkọ Hyundai náà ṣe ré títí fò tí ó sì já sí inú kòtò ńlá kan nítórí pé arábinrin náà kò fa ìjanu ọkọ̀ ti ọlọ́wọ́.
Etí òkun yóo sì di ilẹ̀-ìní fún àwọn ọmọ Juda tí ó kù, níbi tí àwọn ẹran wọn yóo ti máa jẹko, ní alẹ́, wọn yóo sùn sinu àwọn ilé ninu ìlú Aṣikeloni, nítorí OLUWA Ọlọrun wọn yóo wà pẹlu wọn, yóo sì dá ohun ìní wọn pada.
Ori iwe iroyin la ti n ka iroyin yii sugbọn ni kete ti ileesẹ aarẹ ba ti kan si Asiwaju Tinubu, a o sọrọ lori rẹ Kini awọn onwoye ri si igbesẹ yii?
"Eleyi ko yẹ ko fa ija rara""."
Ṣugbọn bii ti olorin Fuji, Ọgbẹni Taiwo Akande Adebisi ti ọpọ mọ si Taye Currency kọ nitori iṣẹ orin kikọ juu ṣe fun un.
Àwọn mẹ́wẹ̀ẹ̀wá jẹ́ ọmọ Hamani, ọmọ Hamedata, ọ̀tá àwọn Juu, ṣugbọn wọn kò fọwọ́ kan àwọn ẹrù wọn.
N óo sọ eniyan di ohun tí ó ṣọ̀wọ́n ju wúrà dáradára lọ,irú eniyan yóo ṣọ̀wọ́n ju wúrà ilẹ̀ Ofiri lọ.
Ajọ NCDC naa fi ikede naa si oju opo ikansiraẹni Twitter wọn, ti apapọ awọn eniyan to ni arun naa ti wa da 10819.
Igbaju igbamu ni kẹri kẹri n ba rode ni ẹgbẹ agbabọọlu Tottenham fi ṣe fun Arsenal ninu ifẹsẹwọnsẹ wọn ọjọ Aiku ninu idije Premier League.
Wọ́n lé e jáde lọ sinu ayé, ati òun ati àwọn angẹli rẹ̀.
•Awọn to n wasẹ yi ni lati fi ẹda iwe ẹri ikẹkọgboye fasiti wọn ati iwe ẹri agunbanirọ NYSC sọwọ loju opo naa .
Benhadadi, ọba Siria kó gbogbo àwọn ọmọ ogun rẹ̀ jọ; àwọn ọba mejilelọgbọn ni wọ́n wá láti ràn án lọ́wọ́, pẹlu gbogbo ẹṣin, ati gbogbo kẹ̀kẹ́ ogun wọn.
Ṣugbọn akọsilẹ lati loju opo itakun agbaye taa ti ko iroyin yii jọ fi ye wa pe, lootọ ni Da Rocha gbe nilu Eko, o lowo lọwọ pupọ nigba aye rẹ, oun si laa lee pe ni Miliọnia akọkọ nil Yoruba.
Ìtàn ayé Ọba James Titus Olateru-Olagbegi keji: Oṣù Kẹjọ ọdún 1910 ni James Titus délé ayé, bàbà rẹ Olateru-Olagbegi Kínní, náà sì jẹ ọba Ọlọwọ tilu Ọwọ, to wá ní ẹba ìlú Àkúré nipinlẹ Ondo A gbọ pé nígbà tí wọn bi Titus, wọn difa láti mọ akọsẹdaye rẹ, gẹgẹ bo se wọ́pọ̀ nígbà náà, tí ifá sì ni yóò jẹ ọba gẹ́gẹ́ bíi bàbá rẹ̀ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Wo àwọn nǹkan mẹ́rin tó yẹ kó wà nínú báàgì rẹ lásìkò Covid-19 yìí Ifa tún ní ọmọ tuntun náà yóò jọba fún ọdún mẹẹdọgbọn, yóò sì ní ipenija lórí ìtẹ́, tí wọn yóò sì lé kúrò bíi ọba fún ọdún mẹẹdọgbọn, àmọ́ yóò sì padà wa jẹ ọba fún ọdún mẹẹdọgbọn mii, kò tó jáde láyé, Ayanmọ ńlá.
O kede pe oun yoo fi ọjọ idajọ ṣọwọ sawọn igun mejeeji laipẹ.
30 Ẹrẹ̀nà 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 31 Ẹrẹ̀nà 2020 Ọrọ coronavirus yi ti di tọrọfọnkale silẹ kaakiri gbogbo agbaye.
Bí o ṣe le fi orúkọ silẹ̀ láti darapọ̀ Nigeria Air Force Ẹni tó ba wù ti o si ni gbogbo ǹkan to nilò lati f'orúkọ silẹ̀ ṣe bẹ́ẹ̀ tabi ki ó ló èyí www.
alaye : eyi yi jẹ oriki awọn ijẹsa .
Iléeṣẹ́ ọlọ́pàá ti dárúkọ àwọn SARS to pa Kolade #EndSARS: Pe nọ́mbà wọ̀nyìí láti fẹjọ́ ọlọ́pàá SARS sùn 'Ejò kankan kò gbé owó mì ní JAMB; àfiwé lásán ni' - Oloyede Ọ̀dọ́kùnrin tó kọ́kọ́ ṣe ẹ̀rọ tó ń tu ìyẹ́ lára adìyẹ Amofin ti ọpọlọpọ mọ si Sega L'évailleur loju òpó twitter ati Segalink ṣalaye fun BBC Yoruba pé adiyẹ awọn ọlọpaa naa n laagun, ṣugbọn ìyẹ́ ni kò jẹ ki a mọỌwọ́ tẹ afurasí méjì tó nííṣe pẹ̀lú ìjínígbe Ọgá panápaná l'Eko.
Ọgbẹni Ayẹni sọ pe ọrọ covid-19 dabi ọmọ tuntun ti kii ṣe akọpa ajẹ fun ileeṣẹ Yemkem.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Ẹgbẹ awọn dokita oniṣegun ni asiko ko ti to Bakan naa, ẹgbẹ awọn dokita ni Naijiria ti ni asiko ko ti i to fun gbigba igbo lilo laaye labẹ ofin .
"Oríṣun àwòrán, Adebayo Adelabu ""Amọ awọn iransẹ okunkun pinnu lati ji asẹ tawọn eeyan ipinlẹ Ọyọ gbe le mi lọwọ lati dari wọn, idi si niyi ti mo se pinnu lati lọ sile ẹjọ ki n lee se ayipada igbesẹ ti ko tọ naa."
Bakan naa, iṣẹ iwadii BBC Swahili tun fi han pe kosi otitọ ninu iroyin ọhun.
Koda, wọn ba awọn ọkọ kan jẹ, wọn si tun fọ kilaasi ọpọlọpọ ọkọ ti wọn ba nibi iwọde naa.
Eyi ni yoo si mu ki ipade miran ko waye lati mọ ọna abayọ.
Nigba ti wọn ri i, awọ ara Nisha wa ni ipo to ba ni lẹru gidi gan.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù OSCOTECH: Òṣìṣẹ́ mẹ́rin ilé ìwé gíga l'Oṣun gb'òmìnira lọ́wọ́ ajínigbé darandaran Fulani 7 Ọ̀pẹ̀̀ 2018 Oríṣun àwòrán, oscotechesaoke Àkọlé àwòrán, Ọrọ lori ijinigbe Awọn oṣiṣẹ mẹrin ile iwe gbogbo nṣe OSCOTECH, Esa Oke nipinlẹ Oṣun ti gba ominira lọwọ awọn ajinigbe Fulani darandaran.
"Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Tí mo bá kú lónìí, Pásítọ̀ Ibiyeomie ló pa mi - Daddy Freeze kébòòsí Àwọn afurasí lórí ẹ̀ṣùn jíjí ìbejì Akeugbagold gbé yọnú sílé ẹjọ́ láì ní agbẹjọ́rò Mo kábàámọ̀ pé ń kò bẹ Baba Legba wò, nígbà tó pè mí - Foluke Daramola Aṣòfin méje yarí mọ́ Akeredolu lọ́wọ́ torí ọkọ̀ ayọ́kẹ́lẹ́ tí kò pín fún wọn Aya gómìnà Kwara gba ilé fún Risikat olójú búlúù àti ọkọ rẹ̀ Risikat, ìyá àwọn ọmọ olójú búlù tí bẹ̀rẹ̀ sí ní kọ́sẹ́ aṣojú lóge Àjọ ECOWAS yan Aàrẹ Ghana, Nana Akufo-Addo gẹgẹ bíi aàrẹ tuntun ""Gbogbo ohun ti a ba fẹ, lo maa n ṣe fun wa nigba to wa laye, a si ṣe ojuṣe wa fun nigba to dubulẹ aisan, ki o to di wi pe o doloogbe."
"Oríṣun àwòrán, Road safety Ó ní, "" Bí a ṣe ń sọ̀rọ̀ yìí ènìyàn mẹ́jọ ló ti bá ìṣẹ̀lẹ̀ náà lọ, bó tilẹ̀ jẹ́ ó ṣeéṣe ki àtún ri àwọn míràn nítórí àwọn kan ti hà sí abẹ́ àjàgbé náà"" Ènìyàn méjì pàdánù ẹ̀mí wọn nínú ìjàmbá ọkọ̀ tó wáyé ní Abúlé Ẹ̀gbá, ní ìpínlẹ̀ Eko Oríṣun àwòrán, LASEMA Ijamba ọkọ laarin ọkọ mẹta ti mu ẹmi eniyan meji lọ ni ipinlẹ Eko."
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Oluwo: Èmi l'ọba lórí òrìṣà, oṣó àti ajẹ́, Olorì tuntun tó ń bọ̀ lẹ́tikẹ 29 Ògún 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 31 Ògún 2020 Oríṣun àwòrán, Instagram/Telu_1 Ọba Abdulrasheed Akanbi, Oluwo mti ilẹ Iwo ti ṣalaye ni kikun fun BBC Yoruba idi ti o fi paṣẹ pe ki wọn ko gbogbo oriṣa kuru laafin Iwo.
Charles the first, ni ìkànnì twitter @9jaBloke ní, kí Codeine to dé ni àwọn ènìyàn kan ti ń fín ṣáláńgá símú bẹ́ẹ̀ iléeṣẹ́ Emzor ni à ń pariwo rẹ̀ NT IPOB AK47 Carrier ni ìkànnì twitter @idmann_mit gbà pé, tí ìjọba kò bá tètè dí àlàfo ti Codeine ti wọn kó nílẹ̀ yìí, ojú awọn tó ń lòó máa ṣí sí lílo ǹkan míràn ni.
Okunrin olorin ọ̀hun tó orukọ rẹ̀ gangan ń jẹ́ Antoine Agbepa Munba tó ń ni ìsòrò pẹ̀lú òfin ní ọ̀pọ̀ ìgbà: Ní ọdun 2018 Zambia pàṣẹ́ ki wọn fi si àtimọlé nítori pé o hùwà àitọ si ayaworan kan Ní ọdun 2016 ọwwọ agbófinro bàá wọn si da pada sile lẹ́yìn to ṣe ọkan nínú àwọn tó ń jó fún báṣubàṣu ní Kenya.
Oluranlọwọ pataki fun Aarẹ Buhari lori ọrọ to jọmọ iroyin, Garba Shehu ti ni irọ patapata ni ọrọ pe ijọba Buhari yoo yi esi idibo gbogboogbo osu to n bọ.
Gbajumọ oṣere tiata naa wa gba awọn ololufẹ rẹ ni imọran pe aye yii fuyẹ, ofo ni, ọna ta ba si gba lati gbe inu rẹ ni yoo jẹ ko ṣe iyebiye fun wa, nitori naa, ẹ gbe igbe aye to ni itumọ.
Ṣugbọn ó mọ gbogbo ọ̀nà mi,ìgbà tí ó bá dán mi wò tán,n óo yege bíi wúrà.
Aare Buhari darapo mo igbimo awon oba, awon oloye ni ipinle Oyo, awon ebi, ọrẹ alaafn to wa ni ipinle Oyo,lati  ki Alaafin ku ori-ire ayeye ojo ibi ti won pe leepẹ ilẹ.
O ni ki òbí wo fun ọmọ to n ṣere tẹlẹ to wa deede n dakẹ ninu ilé, ọmọ tinu rẹ kò dùn mọ.
Wọ́n bá sá pamọ́ sí ààrin àwọn igi ọgbà.
Nígbà tí àwọn eniyan burúkú bá dìde,àwọn eniyan á sá pamọ́,ṣugbọn nígbà tí wọ́n bá parun, olódodo á pọ̀ sí i.
Bákan náà ni àwọn obinrin níláti jẹ́ oníwà pẹ̀lẹ́; kí wọn má jẹ́ abanijẹ́.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Toyin Ibietan: Àlòkù táyà ọkọ̀ ló mú mi rí nǹkan ṣe lásìkò ìgbélé COVID-19 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Inú aṣálẹ̀ ati ilẹ̀ gbígbẹ yóo dùn,aṣálẹ̀ yóo yọ̀ ṣẹ̀ṣẹ̀, yóo rúwé, yóo sì tanná.
Ní ojú tó mọ́ lónìí ènìyàn ojìlélọ́ọ̀dúnrún àti ẹyọkan ló ṣẹ̀ṣẹ̀ lùgbàdi ààrùn Corornavirus ni Naijiria Àpapọ̀ iye ènìyàn to ti ni ààrùn Covid-19 ni Nàìjíríà ti dí ènìyàn ẹgbẹ̀rún lọ́nà lààdọ́ta le méjì àti ẹ̀ẹ́dẹ́gbẹ̀tààbọ̀ dín méjì.
Osise ajo isokan agbaye ti o wa
Àwọn ará Babiloni gbẹ́ ère oriṣa Sukotu Benoti, àwọn ará Kuti gbẹ́ ère oriṣa Negali, àwọn ará Hamati gbẹ́ ère oriṣa Aṣima, 
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù L'Eko awọn eeyan fero wọn han lori ile-isẹ kolekodọti tuntun Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ L'Eko awọn eeyan fero wọn han lori ile-isẹ kolekodọti tuntun 16 Ẹrẹ̀nà 2018 Ọpọlọpọ eniyan sọwipe ile isẹ akodọti tuntun t'ilu Eko ko kun'juwọn nitori idọti si wa lawọn agbeegbe to pọ.
 ní Ọjọ ́ kẹsán oṣù kẹrin , Ọdún 1865 , àwọn ológun àríwá virginia , àwọn ológú ìṣọ ̀ kan gangan , jọ ̀ wọ ́ ara wọn fún Àwọn ológun ti potomac ní appomattox court house .
 A o gbodo kunna lati ri I pe a dena  gbogbo iwa ibajẹ nile -ise ijoba ati lawujo.
0 3575 Orilẹede Singapore 29 0.
Nigba ti Ojelarinaka ati Ojelade fi maa pada si ilu wọn pẹlu ayọ pe wọn foju ri ara wọn ni Iyadunni , to jẹ́ iya Ojelade ba ti ku.
"Bayii ni a ṣe mu gbogbo wọn ti a si ko wọn le Ọlọpaa lọwọ""."
3 ti wọn sì tún ṣe àfíkún rẹ̀ lọ́dún tó tẹ̀le.
Ati ẹni tí ó mọ́ ati ẹni tí kò mọ́ ni ó lè jẹ ninu ẹran náà bí ìgbà tí eniyan ń jẹ ẹran ẹtu tabi ti àgbọ̀nrín.
N óo san ẹ̀san iṣẹ́ wọn fún wọn; n óo sì dá wọn lẹ́jọ́ bí àwọn náà tí ń dá àwọn ẹlòmíràn lẹ́jọ́.
Sibẹsibẹ n óo mú ìpọ́njú bá ìlú tí ń jẹ́ pẹpẹ Ọlọrun.
lgba wo ni iforukọsilẹ yoo dopin?
"Kii ṣe ile mi ni wọn ti ji awọn nkan ti wọn pe ni Palliatives"" ko, awọn nkan ini temi ni wọn ko nile mi, ibajẹ si ni wọn fẹ fi ṣe si mi""."
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ìgò ọtí méje àti sìgá ṣokùnfà ẹjọ́ ikú 'Owó ìbò ni bílíọ̀nù kan tí Buhari bu'wọ́ lù' 'Àwọn Dókítà fẹ́ kẹ́yin s'awọ̀n alárùn lassa' Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 3 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 5 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Awọn ọkọ a wa maa to tẹle ara wọn ni eyi to tun maa fa sunkẹre-fakẹrẹ loju titi Ó gbẹnután!
Orilẹede wo lo gba ami ẹyẹ wura to pọ julọ ninu idije ere idaraya Olympics?
Alaga igbimo amojuto, Asojusofin Victor Ndoma-Egba, lo so eyi lasiko ti ajo naa lo sabewo si odo gomina Seriake Dickson to n tuko ijoba ipinle ohun nile ijoba ni Yenagoa nipinle Bayelsa.
ti gba ami ayo meta meta (3-3) tele pelu iko agbaboolu  odo Freiburg ti won kopa ninu idije German
Arabinrin Damola Funmilola Dorcas ṣalaye lori irir rẹ ṣaaju ko to ni arun yii ati bi o ṣe wa gba oju lọ lọwọ rẹ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Temitope Akinnusi: Ọ̀pọ̀ iléeṣẹ́ ló takú láti gbà mí síṣẹ́ torí mo ní ojú kan Ọjọ kẹrin, oṣu Kẹsan an, ọdun 2020 ni igbeyawo Hanan, to jẹ ọmọ Muhammadu Buhari waye, eyii to jẹ akoko ti ọpọ ọmọ Naijiria n sunkun inira ati ebi nitori bi ounjẹ, ina ijọba ati epo bẹntori ṣe gbowolori.
oloye Adebayo Adelabu naa ti dibo rẹ ni  ibudo idibo kẹ́sán án   to wa ni agbo- ile Adelabu ni agbegbe
Sẹnẹtọ Sani Musa to ṣoju ẹkun ila oorun nipinlẹ Niger lo ṣagbatẹru aba ọhun.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Bayelsa Election: Ẹgbẹ́ òṣèlú APC kọ̀ láti kópa nínú ìdìbò, PDP jáwé olúborí 11 Ògún 2019 Oríṣun àwòrán, Bayelsa State Min of Information and Orientation Àkọlé àwòrán, Ẹgbẹ́ òṣèlú PDP ló jáwé olúbori nínú ìdìbò alága ìjọba ìbílẹ̀ àti kánsẹ́lọ tó wáye lọ́jọ́ sátide ọjọ kẹwàá oṣù kẹ́jọ ọdun 2019 .
Láì ka àwọn nǹkan mìíràn tí n kò mẹ́nubà, lojoojumọ ni àníyàn gbogbo àwọn ìjọ wúwo lọ́kàn mi.
Bakan naa lo fikun pe ọpọlọpọ idanilọyẹ ṣi ku lati ṣe lati gbogun ti idẹyẹsi fun awọn obinrin ni awujọ.
B Joshua púpọ̀ à sì maa n wòó fídíò rẹ lóòrèkóòrè.
”Eliṣa sì dá wọn lóhùn pé, “Ẹ má ṣe rán wọn lọ.
Ó fi kún un wípé ilé isẹ́ náà ti nsisẹ́ takuntakun láti mú kí ọ̀rọ̀ wọ̀ padà pẹ̀lú ilé isẹ́ SSBC láti lè dá àwọn ètò wọn padà sórí afẹ́fẹ́.
Àbí gbogbo yín ni ẹ lè ṣe iṣẹ́ ìyanu?
Nigba to n foju awọn afurasi apaniyan naa han niluu Kafanchan lọjọ Aje, oludari ikọ naa, ọgagun Chukwuemeka Okonkwo ni bi ọwọ ṣe tẹ wọn yii jẹ lara akitiyan ikọ ọhun lati gewọ ipaniyan naa.
 iye ìṣẹ ̀ lẹ ̀ àrùn náà tó tó ẹgbẹ ̀ rún marun sí mẹ ́ fà ló má a nwáyé lọ ́ dọọdún .
To ba ti ọ lẹyin lati de ipo tan, o gbọdọ san owo pupọ lati san an fun un pada.
Igbesẹ wa akọkọ Wọn ni itọwo laa mọ adun ọbẹ, eto ifinimọle awa osisẹ gan ni itọwo akọkọ, eyi to fun wa loye lati mọ ohun ti ileesẹ agbohunsafẹfẹ BBC da le lori.
Owo osu Sẹnatọ kan losu yoo ra apo irẹsi toto 866, nigbati owo osu rẹ yoo ra apo irẹsi kan.
Pe àwọn eniyan rẹ, àwọn ọmọ Lefi, ẹ̀yà ìdílé baba rẹ, pé kí wọn wà pẹlu rẹ, kí wọ́n sì máa jíṣẹ́ fún ọ nígbà tí ìwọ ati àwọn ọmọ rẹ bá ń ṣiṣẹ́ ninu Àgọ́ Ẹ̀rí.
Oríṣun àwòrán, AFP Àkọlé àwòrán, Ọpọlọpọ obinrin maa n ṣiṣẹ olukore ni oko ireke ni India Nitori pe ọpọ obinrin ni agbegbe naa lo n lọ sile ọkọ lọmọde, ọpọ wọn si ti bi ọmọ bi i meji si mẹta ki wọn o to pe ọdun mẹẹdọgbọn, ati nitori pe awọn dokita kii ṣọ iṣoro ti wọn yoo koju ti wọn ba gbe ile ọmọ wọn jade, pupọ wọn gbagbọ pe ko buru ti awọn ba yọ ọ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Láàrín ìdílé ẹlẹ́ni márùn ún yìí, ọmọ kan ṣoṣo ló léè sọ̀rọ̀ Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
#BBCNigeria2019 Àwọn ohùn tó ṣé kókó tó yẹ ká mọ ṣáájú ìdìbò 2019 Njẹ́ ìwọ mọ Àwọn tí ìdìbò kò dí lọ́wọ́ iṣẹ́ wọn?
Oríṣun àwòrán, AFP Àkọlé àwòrán, Ìberu bojo wà gẹ́gẹ́ bí ó ṣe sẹlẹ̀ lọ̀dún 2008, rògbòdìyàn náà le tàn dé àwọn apá ibòmíràn lórilẹ̀-èdè South Africa, gẹ́gk bí akọròyìn wa ṣe sọ Oríṣun àwòrán, AFP Àkọlé àwòrán, Awọn alaṣẹ ìjọba ni àwọn ń bóju wo ẹsùn ti wọn fi kàn pé wọn ń ta ayederu ọja fún ara ìlú BBC News, Yorùbá Ìdí tí ẹ fi le è nígbàagbọ́ nínú ìròyìn BBC Ìlànà Lílò Nípa BBC Òfin Àṣírí Cookies Kàn sí.
Sibẹ ọpọ ọmọ ẹgbẹ lo ṣi n wo o pe iye awọn eekan ẹgbẹ oṣelu APC lọdun 2018 si asiko eto idibo apapọ ọdun 2019 ku diẹ kaa to.
ÌPINLẸ̀ IMO Ní ọdún 2015 Gómìnà Rochas Okorocha ti ìpínlẹ̀ Imo ti ṣe irú ǹkan to jọ báyìí pẹ̀lú Eze Owerri nígbakan ri, olóògbé Eze Emmanuel Emenyonu Njemanze, OzuruIgbo V ti Oweri nígbaà ti Oba ou fẹsun kan pé Rochas ń pin ilú Owerri àti gbogbo ìpínlẹ̀ Imo lápapọ.
Nítorí náà, ẹ fún wa ní ilẹ̀ ìní láàrin àwọn eniyan baba wa.
Mú inú baba ati ìyá rẹ dùn,jẹ́ kí ìyá tí ó bí ọ láyọ̀ lórí rẹ.
Lọdọ ọpọ eeyan, oju awada ni wọn fi n wo awọn to ba hu iru iwa yi niwaju kamẹra tabi lasiko ipolongo.
Awọn to da silẹ ni erongba awọn ni lati tu ẹya alawọdudu silẹ lọwọ igbekun.
Ọmọ márùn-ún sọnù ní Otto l‘Eko, àwọn ìyá wọn kò jẹ́ èèyàn mọ́ lẹ́yìn ọdún kan Ọba Ilorin ló pàṣẹ pé kí ń padà sọ́dọ̀ ọkọ mi - Risikat olójú búlúù Ki lo ti ṣẹlẹ sẹyin?
Lẹ́yìn wọn ni Hananaya, ọ̀kan ninu àwọn onítùràrí ṣe àtúnṣe ọ̀dọ̀ tirẹ̀, wọ́n sì ṣe é dé ibi Odi Gbígbòòrò.
Bi ẹ ko ba gbagbe, opin ọsẹ to kọja yii ni awọn ọmọ ẹgbẹ Boko Haram dumbu eeyan mẹtalelogoji bi ẹni dumbu ẹran ninu oko irẹsi kan ni ipinlẹ naa.
Bí wọ́n ti jóòkó tí wọn ń jẹun, OLUWA bá wolii àgbàlagbà tí ó pè é pada sọ̀rọ̀.
Àwọn ẹgbẹ́ Tijjaniyya ti yọwọ́ kílàńkó Yahaya Sharif kúrò láwo ẹgbẹ́ wọn ní Kano Ẹgbẹ́ Tijjaniyya ní ó tako ìkọ́ni Sheikh Ibrahim Inyas Ẹgbẹ Musulumi Tijjaniyya ti yọ ara wọn kuro ninu ọrọ olorin ni ti wọn dajọ iku fun ni Kano.
"Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Kayeefi: 'Ọkọ mi ṣẹ̀ṣẹ̀ ní kí n lọ se mọ́í-mọ́í, tó ṣẹ̀ bá mi ṣeré tán ni mo gbọ́ pé ""Mopol"" yìnbọn pa á' Mi ò to iṣẹ́ Regina Daniels rárá kí n tó fẹ́ ẹ láàrin ọ̀sẹ̀ mẹ́ta, mo sì tún le fẹ́ ìyàwó míì - Ned Nwoko Ìdí tí mi ò fi lè parí ìjà pẹ̀lú Ààrẹ Ọ̀nà kakanfò, Gani Adams - Obasanjo Ọmọ márùn ún di àwátí ní ilé àwọn ọmọ òrukàn, Stella Obasanjo Motherless Home ní Abeokuta Ọlọ́pàá 200 ni yóò máa ṣọ́ ibojì Diego Maradona torí àwọn olè Obìnrin olówònààbì ta ọmọ rẹ̀ oṣù mẹ́rin ní N300,000 Ṣé lóòtọ́ ni ìjà ti parí láàrin ìdílé Ayinde Barrister àti Kwam 1?"
Oludamọran naa, Arabinrin Temiloluwa Morohunkeji, ti ajọ Temi Love Clinic, sọ pé ọrọ naa dabi ìlù gangan, nitori pe nkan ti Taye le gba mọ́ra, o ṣeé ṣe ki Kehinde o ma le gba a.
Gẹgẹ bi China, Germany fi awọn ilana itakete-sira-ẹni lelẹ lawọn ile ẹkọ to bẹrẹ isẹ pada.
Jesu rán Peteru ati Johanu, ó ní, “Ẹ lọ ṣe ìtọ́jú ohun tí a óo fi jẹ àsè Ìrékọjá.
Kò jẹ́ kí ikú ní agbára lórí rẹ̀.
gbigbogun ti iwa ibaje to ti di aarun  jejere sara omo orile-ede yii.
Àkọlé àwòrán, Àwòrán láti ìpàdé ìtagbangba BBC Yorùba ní ìpínlẹ̀ Ọṣun Lara awọn to kopa ni Alhaji Gboyega Oyetola ti ẹgbẹ oselu APC, Alhaji Fatai Akinbade ADC,Iyiola Omisore SDP ati Alhaji Moshood Adeoti ADP INEC ní kíkùnà ààrẹ láti buwọ́lu òfin ìdìbò kò dí ìbò Ọ̀ṣun, 2019 lọ́wọ́ APC pàdánù aṣòfin míràn ní'pínlẹ̀ Osun Ẹgbẹ́ ọmọ Nàìjíríà ra fọ́ọ̀mù fún Buhari Ọmọ Abiola yan ẹgbẹ́ òsèlú ADP láàyò Àkọlé àwòrán, Alhaji Adeoti Àkọlé àwòrán, Alhaji Gboyega Oyetola ni gbese daa Bí atọ́kùn ṣe ń tọ́kùn ètò náà dáradára ni àwọn ènìyàn ń gbádùn ètò náà nílé àti lórí àwọn ìtàkùn àgbáyé BBC Yorùbá tí wọ́n sì ń fi ọ̀rọ̀ àti ìbéèrè tiwọn náà ránṣẹ́.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Genort Rohr: A ò ní já ẹ̀yin alátìlẹ́yìn wa kulẹ̀ lónìí Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Genort Rohr: A ò ní já ẹ̀yin alátìlẹ́yìn wa kulẹ̀ lónìí 6 Agẹmo 2019 Wakati perete lo ku ki ifẹsẹwọnsẹ laarin ẹgbẹ agbabọọlu Super Eagles ti Naijiria ati ẹgbẹ agbabọọlu orilẹede Cameroon yoo waye.
Èmi ni Ààrẹ tó ṣe rere fún ilẹ̀ adúláwọ̀ jù - Donald Trump Aarẹ Donald Trump ti tun sọ wi pe oun ni aarẹ to ti ṣe rere fun awọn eeyan dudu ju ninu gbogbo aarẹ to ti jẹ, o ni ayafi aarẹ Abraham Lincoln nikan loun yọ silẹ.
Eyi jẹ ki gbogbo àwọn ọbàkan rẹ gbójú le fún ìrànlọ́wọ́.
Ni nnkan bi oṣu meji si asiko yii, ni Braimoh ko ba pe ẹni ọgọta ọdun loke eepẹ.
Page 1 nínú 18 rewind previous Navigate to the next page nextNavigate to the last page forward Padà sí òkè ÀkọléÀkọlé abala Àkọlé abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Rìn káàkiri BBC News Sport Weather Radio Arts Ìlànà Lílò Nípa BBC Òfin Àṣírí Cookies Ìrànlọ́wọ́ Ìwọlé Ìtọ́ni Òbí Kàn sí BBC Get Personalised NewslettersCopyright  2021 BBC.
Lọdun 2011, Ronaldo ni awọn alatilẹhin ẹgbẹ alatako se abuku oun nitori pe oun jẹ agbaboolu to dun un wo loju, to si lowo lọwọ.
 bí ó tilẹ ̀ jẹ ́ pé wọ ́ n ṣé ìrìbọmi onígbàgbọ ́ fún gama , kò fi ẹ ̀ sìn islam àti ìgbàgbọ ́ aláwọ ̀ dúdú ìyá a rẹ ̀ ṣeré rára .
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ijegun Fire: Ẹ̀gbà ọrùn ni wọ́n fi dá òkú ẹnìkan mọ̀ níbi ìṣẹ̀lẹ̀ iná Ijegun Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Ijegun Fire: Ẹ̀gbà ọrùn ni wọ́n fi dá òkú ẹnìkan mọ̀ níbi ìṣẹ̀lẹ̀ iná Ijegun 4 Agẹmo 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 5 Agẹmo 2019 Iròyin tó tẹ̀ wá lọ́wọ́ ni wípé àwọn kan ni wón lọ ji epo ninu ọpa epo rọbi to wa ni Ijegun ni Ipinlẹ Eko.
”O fi awon rogbodiyan to n waye
Olùfẹ́ mi, o dára bíi Tirisa.
O óo jó wọn run bí iná ìléru, nígbà tí o bá yọ sí wọn.
Ìpéníjà owó jẹ́ ọ̀kan pàtàkì nínú ìṣòro àwá òṣèré- Kemi Lala Òrìṣà ni ìyá mi, kìí ṣe ènìyàn, òun sì ni alátìlẹ́yìn mi - Wòlíì Àrólé Coronavirus: Kíni àwọn àmì tuntun tó n fihàn?
Ri wi pe o duro si ibi ti wọn la kalẹ fun awọn eniyan nipa ti tẹle ofin yiyagofunraẹni.
O pe akọle orin naa ni Wonma.
Nígbà tí ó di nǹkan bí agogo mẹta òru, Jesu ń bọ̀ lọ́dọ̀ wọn, ó ń rìn lójú omi òkun.
jẹ́ kí ọmọbinrin tí mo bá sọ fún pé jọ̀wọ́ sọ ìkòkò omi rẹ kalẹ̀ kí o fún mi ní omi mu, tí ó sì dá mi lóhùn pé, ‘Omi nìyí, mu, n óo sì fún àwọn ràkúnmí rẹ mu pẹlu,’ jẹ́ kí olúwarẹ̀ jẹ́ ẹni náà tí o yàn fún Isaaki, iranṣẹ rẹ.
Islamic Development Bank (IDB), lasiko ipade apero ajo isokan ile Afirika.
O di ọranyan bayii lati fi orikori, fikuluku ki a si jumọ pete pero lori ọna abayọ kuro ninu wahala yii.
Àríyá rẹpẹtẹ ló ṣẹlẹ̀ ní àdúgbò ìwọ̀-oòrùn London.
Igbakeji minisita naa sọ pe awọn fẹ ki igbesẹ tuntun yii ko ipa gidi ki ipolongo awọn si kan awọn tọrọ yii kan gan ki rọba idaabobo si wa larọwọto.
Oríṣun àwòrán, @others Àkọlé àwòrán, Nọ́mbà 15: Aju ara wa lọ, ijakadi kọ ni ọrọ telifiṣọn yii, ko si ohun to n ṣẹlẹ lori ayelujara ti eeyan ko le wo ninu rẹ pẹlu ohùn to ja geere.
, ti wọn si sun eto idibo lati fopin si eto isejọba to dẹnukọlẹ ranpẹ to n waye nilẹ Amẹrika siwaju di aago marun irọlẹ oni ọjọ aje.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Church of Satan: ọ̀rọ̀ Femi Fani-kayode fàbínú àwọn ọmọ ìjọ yọ 14 Ògún 2018 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 29 Òkùdu 2019 Oríṣun àwòrán, Church of Satan archive Àkọlé àwòrán, Awọn ọmọ ìjọ sàtánì ń bínú sí Nàìjíríà 'Satani wa kọ́ ló ń yọ Nàìjíríà lẹ́nu o'.
Wọn dibo yan an gẹgẹ bi aarẹ ẹgbẹ awọn obinrin nilẹ Afrika.
Bakan naa ni Biden ni gba gba gba ni orilẹede Amẹrika wa lẹyin awọn oluwọde to n fi ẹhonu han wọọrọwọ.
Ipade naa ni yoo da lori pipese eto iranwọ  owo milionu kan le ni mẹ́rìndínlọ́gọ́ta dola  fun awon ekun  ti ọfọ sẹ si ati pipese eto aabo .
OLUWA Ọlọrun ní, “N óo sọ ìwọ Edomu di ahoro, kí gbogbo ayé lè yọ̀ ọ́; 
Lẹhin Òmìnira, àwọn Òṣèlú pàtàki ni Ìwọ̀-oòrùn lábẹ́ Olóògbé Olóyè Ọbáfẹ́mi Awólọ́wọ fi ipò Òṣèlú ṣe iṣẹ́ ribiribi lati jẹ́ ki àwọn ará ilú jẹ èrè Òmìnira, ṣùgbọ́n lati igbà ti Ìjọba Ológun ti ó fi ibọn gba Ìjọba ti bẹ̀rẹ̀ si ṣe Òṣèlú ni ilú ti bàjẹ́ si, wọn si rò wi pé àwọn lé fi ipá kó orilẹ̀ èdè pọ.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Wo àwọn ẹranko tí wọ́n máa figagbaga ni Egypt Ìdíje ife ẹ̀yẹ láàrin orílẹ̀èdè Áfíríkà 2019 Orúkọ àwọn orílẹ̀èdè tí yóò kópa ní AFCON 2019 rèé Iṣọla Oyenusi rèé, ẹnití ìfẹ́ obìnrin ṣun dé ìwà ìdigunjalè Bakan naa ni Yobo ni inu oun dun lati jẹ agbabọọlu akọkọ ti yoo soju orilẹ́ede Naijiria ninu ere bọọlu fun igba ọgọrun.
Agbegbe Obuasi, ni ẹkun Ashanti lorilẹede Ghana ni iṣẹlẹ naa ti waye ni ọjọ Satide.
Ghana ati Kenya yoo bẹrẹ si ni fun awọn eeyan labẹrẹ naa lẹyin ọsẹ meji.
 wọn a máa jó , wọn a sì máa pa àtẹ ́ wọ ́ tí erá bá ti wọ ̀ wọ ́ n lára .
“Ẹ má ṣe dá eniyan lẹ́jọ́, kí Ọlọrun má baà dá ẹ̀yin náà lẹ́jọ́.
Nítorí náà, kéde fún gbogbo wọn pé, kí ẹnikẹ́ni tí ẹ̀rù bá ń bà pada sí ilé.
nígbà tí ogun bẹ sílẹ ̀ ni mẹ ́ sàn-án lara ìlú gbágùrá sá lọ fi orí balẹ ̀ fún Ọlọ ́ yọ ̀ ọ ́ títí di òní yìí .
Saaju igbẹjọ olori wọn Ibrahim El-zakzaky ti yoo waye l'Ọjọbọ, awọn ọmọ ẹgbẹ Shiite ṣe iwode lati kepe ijọba pe, ki wọn tu olori wọn to wa lahamọ silẹ.
Ahabu ọba bá ranṣẹ pada pé, “Gẹ́gẹ́ bí o ti sọ, oluwa mi, ìwọ ni o ni mí ati gbogbo ohun tí mo ní.
ijamba ina naa jo ile mọ́kàndínlógóje(138
O ṣalaye pe awọn oloṣelu kan lo lo awọn ọmọ ẹgbẹ Boko Haram lati jawe olubori ninu eto idibo, ṣugbọn ti wọn ko ri ti wọn ro mọ lẹyin idibo, ti ko si si iṣẹ fun wọn mọ.
Bí ọlọ́pàá bá mú ọ, kí ló yẹ kí o ṣe?
#7000 sí #10000 ni owó àbẹ̀tẹ́lẹ̀ fún bẹẹdi ní ilé àwọn aláìsàn ọpọlọ Ó kéré tán ọkùnrin 15 ló ń bá mi lòpọ̀ lójúmọ́, mo sì ti ní egbò lójú ara - Adeola tí wọn fi sòwò ẹrú Mo kàn fẹ́ fi ọmọ tó sọnù gba owó lọ́wọ́ Sọtitobire ni - Afurasí Ẹ̀yin obìnrin tẹ́ẹ fẹ́ wá bímọ ní America, ọ̀nà ti tì pa látònì!
Jobu ń fi àpáàdì họ ara, ó sì jókòó sinu eérú.
Imọran atata fun awọn awakọ lasiko yii nitori ohun gbogbo lo n fẹ suuru.
Eyi tumọ si pe orilẹede yii lo se ipo keji nilẹ Afirika lẹyin orilẹede to se ipo kinni lagbaye, Rwanda.
ICC pari iwadi lori pipa Shiites, IPOB Ọ̀pọ̀ èèyàn farapa nínú ìwọ́de Shiite Gbogbo igbesẹ lati ba agbẹnusọ ileesẹ ologun, Ọgagun Kukasheka Usman, sọrọ ni ko so eso rere.
“Bẹ́ẹ̀ ni ẹ óo ṣe pẹlu akọ mààlúù kọ̀ọ̀kan tabi àgbò kọ̀ọ̀kan tabi ọ̀dọ́ àgbò kọ̀ọ̀kan tabi ọmọ aguntan kọ̀ọ̀kan.
Gàárì ẹṣin tí ẹni tí nǹkan bá dà lára rẹ̀ bá fi gun ẹṣin di aláìmọ́.
 O ni, “Niwọn to jẹ pe ilera lọrọ, ijọba ipinlẹ yii ti ṣetan lati mu igberu ba ilera awọn ara ilu.
igbese lori iwa ipaniyan ati odaran, aare tun wa ro awon ara ilu lati ni igbagbọ
Báyìí ni àwọn méjèéjì ṣe ti wọ́n tọ́jú ọkọ wọn, nítorí ìtọ́jú ọkọ ni pàtàkì iṣẹ́ obìnrin tí ó ní ọkọ.
Ṣùgọ́n ìyẹn di ọwọ́ ẹni tó njẹun.
Kò séwu nínú ìdìbò tó ń bọ̀ l'Ondo àfi gìrì àparò- Akeredolu Ọmọ ọkunrin mẹrin ati ọmọbinrin meji lanti-lanti ni Oba Oke fi jinki tọkọtaya Chiaka lẹẹkanṣoṣo nigba ti o ṣamin si IVF ti wọn ṣe to si yọ wọn kuro lagan nigba to wu u.
Gbajugbaja olosere Tunde Kelani sọ wi pe irọ ni ọrọ ti Baba Wande sọ wi pe o yan oun jẹ, lori owo to san fun un lorii fiimu naa.
Àwọn ará Juda yóo wá máa sọ láàrin ara wọn pé, ‘OLUWA, àwọn ọmọ ogun ti sọ àwọn ará Jerusalẹmu di alágbára.
Gbajumọ oloṣelu ati agbẹnusọ ile igbimọ aṣoju-ṣofun tẹlẹ, Yakubu Dogara naa ba gbogbo ẹbi Funtua kẹdun iku rẹ.
14trn), Owoona lori awọn iṣẹ pataki gbogbo (Statutory transfer N492.
Faisal oniduro rẹ ati agbẹjọro rẹ ko yọju sile ẹjọ.
Senẹtọ Godswill Akpabio ni Gomina to wa lori oye nigba ti wọn gbe ofin yii kalẹ ni 2014.
Ojú yóo ti olú-ìlú yín lọpọlọpọ,a óo dójú ti ilẹ̀ ìbí yín.
Ninu ifọrọwerọ pẹlu ileeṣẹ iroyin CNN, Meadows sọ pe, o soro lati mojuto arun naa nitori o rọrun fun lati tan kalẹ bi ọfinkin.
Àrùn coronavirus wọ ìpínlẹ̀ Oyo Ajọ NCDC ti kede tẹlẹ pe eeyan miran to ni aarun coronavirus lorilẹede Naijiria.
Nínú àwọn ọ̀nà abayọ ti awọn ọlọpàá fi sita kò si ibi ti wọn tio gba ẹnikẹni nimọràn láti fún ọlọpàá ni rìbá.
Ní ọjọ́ náà, wọ́n yan àwọn kan láti mójútó àwọn ilé ìṣúra, ati ọrẹ tí àwọn eniyan dájọ, àwọn èso àkọ́so, ati ìdámẹ́wàá, àwọn tí wọ́n yàn ni wọ́n ń mójútó pípín ẹ̀tọ́ àwọn alufaa ati ti àwọn ọmọ Lefi, gẹ́gẹ́ bí ìlú wọn, bí ó ti wà ní àkọsílẹ̀ ninu ìwé òfin.
Awọn iroyin ti ẹ lee nifẹẹ si: Super Eagles bẹ̀rẹ̀ ìgbaradì ní ìlú London Okagbare fakọyọ ninu ere oni'gba mita Awọn agbabọọlu Super Eagles kan n gba'bọde fun Naijiria Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Awon akosemose ni isele yii ko koja aikobiarasi abere ajesara awon eniyan ekun yii.
bi ejo ti won gbe lo sile ile-ejo lori bi ijoba se fun adari ile –ejo lorile
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Akomolede ati Aṣa lori BBC: Mọ̀ si nípa oríṣìí ẹ̀ka ìsọ̀rí ọ̀rọ̀ àti ìwúlò wọn Olori awọn akẹkọọ, Lawrence Kasonde ṣalaye pe o to ọdun mejilelogun ki o to jade laye, ati pe ẹja naa ti gbe inu omi lọgba fasiti Copperbelt fun ogun ọdun o kere tan.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ibikunle Amosun: Owo adani ni'ṣẹ ẹran dida, ko kan ijọba Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
A ba wí fún olójúmájèlé kí ó ba ni fi eyín erin rẹ̀ wo inú igbó náà bóyá ó lè jẹ́ rí i.
Ọ̀pọ̀ èèyàn ló sá fún mi nígbà tí mo dùbúlẹ̀ àìsàn- Ògògó Kí ni ó gbé ọlọ́pàá dé ibi àjọ̀dún ọjọ́ ìbí i Bobrisky?
Eleyii gan lo wa di ọrọ rangbọndọn laarin oun atawọn aṣofin bayii.
OLUWA, pada wá gbà mí,gbà mí là nítorí ìfẹ́ rẹ tí kì í yẹ̀.
Islamic State' ní Nàìjíríà bẹ́ àwọn Kristiẹni lórí ní ìpínlẹ̀ Bornu
"Wo nkan tó yẹ kí o mọ̀ nípa Tolanibaj, Wathoni àti Brighto ni wọ́n lé kúrò ni BBNaija l'ọ́sẹ̀ yìí ""Mi ò ní wọ Uber mọ́ tí wọ́n bá leè fi owó lée nítorí àfikún owó orí tí Sanwo Olu ṣe"" Àwọn nkan tó yẹ kí o mọ̀ nípa ṣíṣe ìṣirò àsìkò tí o bá n yé ẹyin Èèyàn méjì kú, méjìdínlógóje míì ṣẹ̀ṣẹ̀ kó COVID-19 lọ́jọ́ Àìkú Ìjọba ìpínlẹ̀ Eko kéde ọjọ́ tí àwọn iléèwé gígá yóò wọlé Ijọba Naijiria sọ pe ohun ti ni akọsilẹ gbogbo iwa buruku tí awọn alasẹ Ghana n hu si awọn ọmọ Naijiria to n gbe l'orilẹ-ede wọn."
Eji- Idasilẹ ọlọpa agbegbe ati ipinlẹ lati dẹkun ọwọja ohun ija oloro to n wọle si orilẹede yii, lati wa ojuutu si lati mu nkan rọsọmu lẹka eto abo lorilẹede Naijiria.
Aarẹ Buhari se ikilọ yii lasiko abẹwo rẹ si ipinlẹ Nasarrawa to wa lẹkun ila oorun ariwa orilẹede Naijiria.
eto idibo  atundi to waye ni ojo Abameta,
Ojo ni ise ti won fe gunle ni asiko yii ni wiwa ojutu sisoro adanu yii lori ire oko awon agbe Naijiria.
Ó jé amofin nípa eto epo àti gaasi.
Jega salaye pe ọpọ awọn olukọ fasiti yii ni wsn lẹdi apo pọ mọ awọn oloselu lati se mago mago eto idibo to kọja.
Nígbà tí ọba ati àwọn eniyan rẹ̀ yóo fi dé ibi odò Jọdani, ó ti rẹ̀ wọ́n, nítorí náà, wọ́n sinmi níbẹ̀.
Oríṣun àwòrán, Oyo Insight Gẹgẹ bi eeyan kan to wa nijọba ṣe sọ, owurọ Ọjọbọ lo jade laye.
Ìtàn ayé Shina Rambo, adigunjale tó fi oyún 27 gún ọṣẹ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Kìí ṣe ọmọbìnrin nìkan ni Ọlọ́run pàṣẹ fún láti pa ìbálé mọ́ Fila/Atẹ ori awọn obinrin Oríṣun àwòrán, RCCG Kẹti kẹti lawọn obinrin maa n ya lọdọ awọn onifila tori ọpọlọpọ lo mọ pe awọn gbudo bo ori wọn lati gbadura.
Ẹ gbọ́, èwo ló dára jù nínú 'oníjó' àti 'akówó jẹ'?
“Ẹbọ ìmúkúrò ẹ̀bi dàbí ẹbọ ìmúkúrò ẹ̀ṣẹ̀, òfin kan ṣoṣo ni ó de oríṣìí ẹbọ mejeeji: òfin náà sì ni pé alufaa tí ó fi ṣe ètùtù ni ó ni ẹbọ náà.
O ni nígbà ti àwọn ọmọ Niger-Delta ń ji ènìyàn gbé ní ìlú Ikorodu ní ọdún díẹ̀ sẹ́yìn, ìpàdé tó wáye to sì fi òpin sí gbogbo rògbòdìyàn lásìkò náà wáyé láarin àgbàagba Yòrùbá àti ti Niger Delta.
Ni ọjọ́ tí ẹnì kẹta bá ti bọ́ sí ààrin olúfẹ́ méjì ìfẹ́ náà yóò pín sí ọ̀nà ẹgbẹ̀ tàlélógún, ẹnikẹ́ni kò sì ní lè ṣà á jọ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Deji Adeyanju vs Charley boy: Charly Boy l'óun kò gbowó, Deji ní ó já òun kulẹ̀ 21 Ẹrẹ̀nà 2019 Oríṣun àwòrán, Instagram/Deji Adeyanju Àkọlé àwòrán, Ọrọ lori ẹgbẹ ''Our Mumu Don Do'' Gbajugbaja ajijagbara ati olorin Charles Oputa ti ọpọ eeyan mọ si Charly Boy ti ṣalaye ohun to ṣẹlẹ gan an fanran ede-ai-yede laarin rẹ ati Deji Adeyanju.
Ondo election 2020: Kalejaye ní APC kò ní ṣ'èèrú nínú ìbò gómìnà tó ń bọ̀, Wike má gbé jàgídíjàgan wá
Akitiyan lati yan akọnimọọgba mii bẹrẹ lẹyin ti Bayern Munich lu Barca lalu bolẹ ninu idije UEFA Champions League pẹlu ami ayo mẹjọ si meji.
kì í dá ìtumọ̀ ní kó wúlò ìgbà tí a bá kàn án pọ̀ mọ́ fóníìmù mìíràn gan-an ló máa ṣìṣẹ́.
Ẹfun àti osùn ni òun fi ṣe ọ̀sọ́ aláràbarà sí gbogbo ara, àti ojú àti imú ẹbọra náà sì dàbí ẹ̀gbẹ́ ògiri ilé òrìṣà, ó ba ni lẹ́rù gidigidi.
Fọnran fidio ṣe afihan bi Merkel tii ṣe kawọ mọra ti o si bẹrẹ si ni gbọn pẹpẹ nita gbangba.
“Oriṣa Bẹli tẹríba, oriṣa Nebo doríkodò.
Ọjọ kinni oṣù Karun ọdun 1984 ni wọn ṣe ifilọlẹ rẹ.
 kí wọ ́ n máa gbìyànjú lati mú ìtẹ ̀ síwájú bá ìwé-ìmọ ọ ̀ fẹ ́ kí wọ ́ n sì máa hu ìwà tó dára , pẹ ̀ lú ìrẹ ̀ lẹ ̀ , ìwà tútú , pàápàá jùlọ tí ìtàkùrọ ́ sọ ̀ bá ń gbóná jinjin .
Aare soro yii, nigba ti o kan si gomina ti yoo dije fun egbe All Progressives Congress (APC) ni ipinle Kwara ati awon omo egbe naa nile egbe won, to wa ni ipinle Kwara.
Wọ́n bá pada lọ sí Jerusalẹmu.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: BBC Yorùbá sàbẹwo sí ilé iṣẹ́ Suncity FM Ẹlẹ́wọ̀n tó ti pé ẹni ọgọ́rùn ọdún ní Nàìjíríà' n bẹ̀bẹ̀ fún òmìnira Àwọn òṣìṣẹ́ pápákọ̀ òfúrufú MMA2 ṣẹ́welé ìyansẹ́lódì Mo rọ àwọn asòfin Ekiti láti súgbá Fayẹmi - Fayose Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ṣọla Allyson: Obìnrin tí kò bá rẹwà ni yóò máa ṣí ara sílẹ̀ Àkọlé àwòrán, Ilé iṣẹ́ BBC kò ṣe ètò owó ẹ̀kọ́ ọ̀fẹ́ Gẹgẹ bi ileesẹ BBC lagbaye ti wi, yoo dara kawọn araalu yẹra fun awọn iroyin ti ko lẹsẹ nilẹ bii iru eyi.
'' Gbajugbaja oṣere kristẹni naa wa beere pe ''njẹ apayan ni ṣọọṣi kọ niọ bayii.
Ìwọ onídàájọ́ gbogbo ayé kò ha ní ṣe ẹ̀tọ́ bí?
Ni orilẹede to jẹ pe bii ida ogun ninu ọgọrun awọn eeyan rẹ ni ko ni iṣẹ lọwọ ti ọpọ to n ri iṣẹ ṣe gan ko lee fi ẹdọ lori oronro, ileri yii jẹ eyi to fa oju ọpọlọpọ oludibo mọra.
Ogagun Abubakar fikun un oro re pe, ni ibamu pelu ilana ati asa ile-ise NAF, ile-iwosan ohunati awon ohun elo inu re gbogbo yoo wa ni lilo fun awon olugbe ipinle Kano patapatalai yo enikeni sile.
Aṣofin Lanre Ogunyẹmi, Alaga Igbimọ Tẹẹkoto fun Eto Ẹkọ ninu Ile Igbimọ Aṣofin Ipinlẹ Eko yii ni o pe akiyesi ọrọ yii ninu ijoko ijiroro Ile, lỌjọbọ, nibi ti o ti ṣapejuwe Kabiyesi gẹgẹ bi igi lẹyin ọgba idagbasoke ipinlẹ Eko, ẹni ti ọla tọ si lati ṣẹyẹ bẹẹ fun.
EFCC gbé Fayoṣe wà jẹjọ ní Èkó Ileẹjọ pasẹ igbejọ ọtọ fun Nnamdi Kanu O ni ''Mo dupẹ lọwọ Sẹnẹtọ Abaribe, alagba Ayo Adebanjọ to jẹ olotito eeyan ati awọn alatilẹyin mi'' Bakanna lo ni IPOB wa digbi pẹlu Gomina Ipinlẹ Ekiti ana ,Ayo Fayose ti ajọ EFCC n ba se ẹjọ.
nitori naa ni won se gbegile rira aja yii lai gba asẹ ijọba.
Ẹgbẹ OIC ni aṣoju ni ajọ iṣọkan agbaye ati ajọ ilẹ alawọfunfun ti wọn n pe ni European Union.
Ọkọ̀ ẹrù kọ̀ọ̀kan fún olórí meji meji, ati akọ mààlúù kọ̀ọ̀kan fún olórí kọ̀ọ̀kan.
Ẹnikẹ́ni tí ó bá ṣe iṣẹ́kíṣẹ́ kan ní ọjọ́ ìsinmi, pípa ni kí wọ́n pa á.
Ọkan-o-jọkan awọn ọmọ orilẹede Naijiria, paapaajulọ awọn eeyan ipinlẹ Ọyọ ni wọn si ti n kii.
Ọrọ lori eto iṣuna Aarẹ Buahri sọ oko ọrọ si awọn adari ile aṣofin agba l'Abuja, Bukọla Saraki ati Yakubu Dogara, lori ọrọ eto iṣuna ọdun 2019.
ijoba ipinle Ekiti lati ri pe awon to n dana awon ounje naa sise po pelu awoni
"Ọ̀dọ́ orilẹede naijiria ni mi ti mo si gba oye kilasi akọkọ, First class ninu imọ nipa kokoro arun kekeeke, Microbiology mo n se mo si n ta ogi.
Ọlọrun ràn án lọ́wọ́, ó ṣẹgun àwọn ará Filistia ati àwọn ará Arabia tí wọ́n ń gbé Guribaali ati àwọn ará Meuni.
Bakan naa ni ibo yoo tun maa waye lati yan
”Ọba bá bèèrè pé, “Nítorí kí ni yóo ṣe ba yín lọ?
Sotitobire: Ọkọ mi kò mọ̀ Jegede PDP rí, kódà kò fa ẹnikẹ́ni kalẹ̀ dípò Akeredolu- Bisola ìyàwó Alfa Sotitobire
- Mike Bamiloye Ọkùnrin kan da ṣọ́ọ̀ṣì rú lásìkò ìgbéyàwó, Ó ní òun lọkọ àárọ̀ ìyàwó tuntun Mi ò fẹ́ ìrànwọ́ ẹgbẹ́ òṣèré, àwọn kọ́ ló kóbá mi- Chief Kanran Ọkọ oju omi naa n lọ si Ikorodu ni ibi ti wọn ti fẹ lọ ṣeto isinku mọlẹbi wọn, ko to di wi pe iṣẹlẹ naa waye to si mu ẹmi eniyan meji lọ.
 se awari re ni ojo kerin le logun , osun kerin , odun 1985.
Nigba ti Yari n sọrọ lori iye owo ti yoo naa awọn ipinlẹ lorilẹede Naijiria lati gbe ọlọpaa ka'lẹ ni ipinlẹ wọn, o wipe ko pọn dandan fun gbogbo ipinlẹ lati se igbekalẹ yii, sugbọn ki awọn to ba lagbara rẹ o se e""."
Ẹ bá mi dé Ilẹ̀-Ìyanu Ọ̀gìnìntìn tí ń bẹ nínú ọgbà ńlá Hyde Park.
n lọ maa n je ki awon ile –ise to n pese ero ibanisọrọ koju awon isoro kan, ni
Ọmọ Naijiria di asofin agba ni Italy Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
 ní àwọn agbègbè kan , a gbàgbọ ́ pé iye tó tó mẹẹdọgbọn nínú ọgọrun ( 25 % ) àwọn ènìyàn agbègbè náà ni ó ní àkóràn àrùn yìí .
Atẹjade kan ti ajọ INEC fi sita lọjọ Isẹgun, ti alaga ati kọmisọna to wa fun ẹka iroyin ati ilanilọyẹ oludibo, Festus Okoye fọwọsi, lo siṣọ loju iroyin yii.
Iwe Iroyin Associasted Press sọ wipe, Poopu naa sọrọ lori isekupani lorilẹede Naijiria nibi apejọ to waye ni gbagede Saint Peters Square ni ilu Romu.
66 Bẹ́ẹ̀ni, bí wọn yíò bá wá, wọ́n lè wá, kí wọn o sì ṣe àbápín nínú omi ìyè ayérayé lọ́fẹ̀ẹ́.
Luis Cabrera, to je osise eleto aabo awon ara ilu to wa nibi isele naa ni awon alase si n se iwadii ohun to sokunfa ijamba naa.
Kirisipu, ẹni tí ń darí ètò ilé ìpàdé àwọn Juu gba Oluwa gbọ́ pẹlu gbogbo ilé rẹ̀.
 Sam Orthom lo  lọ pade igbakeji aare ni papa oko ofurufu ti awon omo-oloogun ofurufu ti orile ede yii, to wa ni Makurdi.
 O tẹsiwaju pe Mo mọ idi ti wọn ṣe n binu ṣugbọn eeyan mẹrin pere ko lagbara lati yọ adari nipo, o da mi loju pe gbogbo ohun to n run nilẹ maa tan laipẹ jọjọ.
Akọsilẹ fi han pe o sọ ọrọ yi lọdun 2015 ṣaaju ifẹsẹwọnsẹ Chelsea pẹlu Tottenham ninu idije League Cup ni papa iṣere Wembley.
Ori afara gbọọrọ ti wọn n pe ni Long Bridge, nibudokọ Barewa lopopona Ibadan silu Eko ni isẹlẹ naa ti waye eyi to mu ko nira fun awọn ọlọkọ to n bọ lati oju ọna marosẹ Eko si Ibadan lati kọja.
Oríṣun àwòrán, @Aquabi Àkọlé àwòrán, Ina alarabara loriṣiiriṣi ni wọn fi ṣẹẹsọ si mọṣalaṣi nla yii Rajab: Oṣu ọwọ ati eewọ ni oṣu yi jẹ.
ó ń kígbe lórí odi ìlú,ó ń sọ̀rọ̀ ní àwọn ẹnubodè ìlú, ó ní, 
Mò ń rìn níwájú OLUWA, lórí ilẹ̀ alààyè.
Bẹ́ẹ̀ ni ó ṣe parí iṣẹ́ tí ó ṣe sinu ilé Ọlọrun fún Solomoni ọba.
Bakan naa ni wọn ni gbogbo fọnran fidio tawọn fi han jẹ ojulowo sugbọn ti Minisita layederu ni.
Ìsọníṣókí Ko si ẹri pe INEC lo server kankan lati fi ko esi ibo aarẹ jọ Ileẹjọ ni Buhari kaju osunwọn lati dije dupo aarẹ Adajọ ni ko si ẹri pe Buhari parọ iwe ẹri to fi dije dupo aarẹ Ile ẹjọ ti gbọ ẹri awọn mejeeji bayii Wọ́n ti wọ́gilé ẹ̀sùn ìdúnkoòkò mọ́ àwọn èèyàn lọ́jọ́ ìdìbò Atiku kìí ṣe ọmọ ilẹ̀ Cameroon -Ile ẹjọ wọgile ẹjọ pe Atiku kii ṣe ọmọ Naijiria PDP ti tako ìdájọ́ tó dá Buhari láre Ṣé ìwọ mọ àwọn Adajọ to máa da ẹjọ Atiku ati Buhari loni?
Wọn ya mi laṣọ, wọn na gbogbo awọn amugbalẹgbẹ mi.
Gbogbo ẹni tí ó bá ń gbé inú rẹ̀ kò ní máa dẹ́ṣẹ̀.
Ọ̀rọ̀ èmi àti Olorì Chanel Chin kò yé ara wa mọ́ nínú ilé- Oluwo IBB tẹ ń pariwo pé ó kú, kò kú o, Ko ko lara ọta ń le- Agbẹnusọ Kassim Fun ọmọ ọba Ọmọ Ọla, o ni ọgbẹ ọkan ti iku Barrister da si ọkan awọn ololufẹ rẹ si tun wa laya oun.
Ní ọjọ́ tí ẹ bá rú ẹbọ náà gan-an tabi ní ọjọ́ keji rẹ̀ ni ẹ gbọdọ̀ jẹ ohun tí ẹ fi rúbọ tán.
Ajimobi Vs Seyi Makinde: Amòfin ní tí Ajimobi bá jẹ́ mẹ̀kúnnù, ṣé Makinde yóò gbà kí wọ́n sín sí GRA?
O fikun pe awọn adari wọn ni Abuja lo ni ọrọ ikẹyin lori bi idibo abẹlẹ APC yoo ṣe ri.
Ọ̀rọ̀ di ẹni orí yọ, ó dilé.
Ajọ Ọlọpa pe Dino Melaye lẹjọ iwa ọdaran ‘Mí ò lọ́rọ̀ bá ilé aṣòfin sọ’ Naomi Osaka: Obìnrin adúláwọ̀ Japan tó na Serena Okunola tí ó ṣẹ̀ṣẹ̀ kúrò lọ́gbà ẹ́wọ̀n Ikoyin lọ́jọ́ karún oṣù yìí gẹ́gẹ́ bí àtèjáde tí àjọ ọlọ́pàá fí sí ta ṣe sọ, sàlàyé pé Okunola tí lo oṣù mẹ́fà àti ọ̀sẹ̀ méjì lọ́gbà ẹ̀wọ̀n kí wọn tó túu sílẹ̀ sùgbọ̀n ọwọ́ àwọn agbófinró tí tún tẹ̀ẹ́ báyìí nígbà tó fẹ́ ja Gift Omini lólè fóónù láti orí òkadà.
"A ti pese ọpọ àwọn ohun èlò amayedẹrun si ìpínlẹ̀ Ondo, tá si tún ṣe àtúnṣe sì àwọn ilé ẹ̀kọ́ alakọbẹrẹ wá, a ti ṣe ọpọ nkan tó ṣe mú yangàn dáadáa, a sì dúpẹ́ lọ́wọ́ Ọlọ́run.
Bí wọn ṣe ja ogún ìjàyè àti òpin rẹ Ikọ ogún Ibadan tẹ̀dó sì ẹba odò Ọsẹ, èyí tó to maili mẹ́tàlá sì ìlú ìjàyè, nígbà tí ogún ìjàyè, èyí tí Kurunmi àti Ogunbona tilu Abeokuta kò sódì, tẹ̀dó si ilu Olokemeji, tó wá ní ẹba odò Ogun.
Wọn fi kun pe awọn ni igbagbọ pe awọn eniyan yoo bẹrẹ si ni fẹran lati ma a wo ẹrẹ bọọlu Cricket naa bi wọn ti ṣẹ fẹran ẹrẹ bọọlu afẹsẹgba.
Ọba Asiria gbọ́ ẹ̀bẹ̀ rẹ̀, ó sì gbógun ti Damasku, ó ṣẹgun rẹ̀, ó pa Resini ọba, ó sì kó gbogbo àwọn eniyan ìlú náà lẹ́rú lọ sí Kiri.
Bí eniyan bá kẹ́ ẹrú ní àkẹ́jù,yóo ya ìyàkuyà níkẹyìn.
Fún ìgbà díẹ̀ ni àwọn baba wa nípa ti ara fi ń tọ́ wa, bí ó bá ti dára lójú wọn.
Adehun ọdun mẹta ni Chelsea ati Lampard tọwọ bọ.
Gẹ́gẹ́ bí àtẹ̀jáde kan tí ẹgbẹ́ òṣèlú PDP fi síta lórí ìṣẹ̀lẹ̀ náà, o ni irufẹ itaporogan bẹ́ẹ̀ láàárín ọlọ́pàá àti àwọn ọmọlẹyìn Elzakyzaky kì bá tí wáyé, kání íjọba tẹ̀lé àṣẹ ilé ẹjọ́ pé kí wọ́n túu sílẹ Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: ICC pari iwadi lori pipa Shiites, IPOB Koko iroyin: ọmọogun Nàìjìríà àti Shiite, ijinigbe Kano Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
gbosuba  fun   ipa Pataki ti  awọn ẹgbẹ ati ajọ to n pese eto iranwọ n se
6bn padà Air pollution: Nàìjíríà ni orílẹ̀ède kẹrin tí atẹ́gùn búburú ti ń pa ènìyàn jù làgbáyéé Owó wọgbó!
Austin Enabulele – In My Country
Buhari yan Mohammad Sambo, olùdarí NHIS tuntun Ẹ kún fún àdúrà nítorí ìdájọ́ kóòtù àgbà lórí gómìnà l'Ọ́ṣun-APC Ọṣun Ogedengbe Agbógun Gbórò, Akọni tó ń dẹ́rù ba ikú.
N óo kó àwọn apanirun tí yóo pa ọ́ run wá,olukuluku yóo wá pẹlu ohun ìjà rẹ̀.
Ipele kan náà kó ní Yorùbá àti ẹgbẹ́ darandaran Miyetti Allah wà- Afẹnifẹre Ọmọ Yorùbá tó bá ti rú òfin, ẹ gbé e jàntò - Oluwo El-Zakzaky kò fojú hàn nílé ẹ́jọ́ ṣùgbọ́n wọ́n sún ẹjọ́ rẹ̀ síwájú Ilé alájà méjì wó lu ọmọ mẹ́rin ni Bariga 'Nàìjíríà, ṣọ́ra, ogun ń sọ ilé ọlá di ahoro!
Abrahamu bá sọ fún Ọlọrun pé, “Ṣá ti bá mi dá Iṣimaeli yìí sí.
Àwọn ohun tó yẹ kí o mọ̀ nípa NPower àti ọ̀nà ti o fi lè forúkọ sílẹ̀ Awọn alakoso N-Power tii se eto igbanisisẹ fawọn ọdọ lorile-ede Naijiria ti fi ikilọ sita pe ọfẹ ni eto igbanisisẹ naa.
Àti àwọn ìbéèrè míràn Àwọn nǹkan tí obìnrin lè ṣe pẹ̀lú olólùfẹ́ oníwà ipá lásìkò ìgbélé Coronavirus yìí Gbigbe igbesẹ to nira lati gbe Lati le koju arun Covid 19, awọn olori yoo ni lati gbe igbesẹ to le bii ki wọn wọgile eto ọrọ aje ni ibẹrẹpẹpẹ ajakalẹ arun yi ki o to pẹka bi igi iroko.
Esi ifeṣẹwọnsẹ yii ti jẹ ki Manchester United sun mọ Chelsea ni kaṣan ọrun ninu ereje fun ati kopa ninu idije UEFA Champions League ni saa bọọlu to n bọ.
Ogbeni ilo tesiwjau pe, pipese ile-ise ironilagbara ati ohun
Ninu fidio kan ti ajọ ọlọpa fi lede loju opo Twitter rẹ, afura naa ni a ri to n jẹwọ bi o ṣe pa obinrin kan ni ile itura kan ni Port Harcourt.
Amọ, igbiyanju lati kan si ẹgbẹ oselu APC lati fesi si ẹsun naa jasi pabo.
Ọ̀la òde yìí ni ìrìnàjò sí ilẹ̀ òkèèrè yóò padà bẹrẹ ní Nàìjíríà Èèmọ̀!
A óo so àwọn ọmọ wọn mọ́lẹ̀ lójú wọn,a óo kó ilé wọn,a óo sì bá àwọn obinrin wọn lòpọ̀ pẹlu agbára.
 Nibe ni Zulkifli ti ro gomina lati parowa si
 Wo bí àwọn ọmọ Nàìjíríà ṣe n kí fún ìjọba nítorí $1."
Mo bá àwọn eniyan sọ̀rọ̀ láàárọ̀, nígbà tí ó di àṣáálẹ́, iyawo mi kú.
Awọn ọlọpaa ti fi ọkọ wọn gbe awọn afunrasi naa pada si ahamọ.
O ni iyawo gomina Kwara lo mu awọn ọmọdebinrin naa lọ sile ẹkọ aladani Roemichs International School nilu Ilorin to jẹ olowo nla, eyi ti arabinrin Jumoke Harb da silẹ.
Ogbeni Dogara yanana oro ohun lasiko ijiroro oro pataki ti ogbeni Sunday Karimi ti o je asoju eka ila-oorun Yagba ati iwo-oorun ipinle Kogi gbe wa sile awon asoju-sofin ohun lojoBo(Thursday).
Àwọn ẹranko onigbeeraga kò tíì tẹ ojú ọ̀nà náà,kinniun kò sì tíì gba ibẹ̀ kọjá rí.
Wo bí ètò ìsìnkú Tolulope Arotile ṣe lọ nílùú Abuja Bàbá mi Aláàfin, ẹ ṣeun ẹ̀bùn owó tí ẹ fún èmí àti ọkọ mi- Lizzy Anjọrin Eyitayọ Jegede (PDP) ló máa gbéná wojú Rotimi Akeredolu (APC) nínú ètò ìdìbò Ondo tó ń bọ̀!
Obasanjo ti se ojuse rẹ gẹgẹ bi asiwaju  rere, ti o si n se ohun iwuri fun awon to wa lẹyin
"Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Zlatan: Ọ̀rẹ́ ni mo sìn lọ ‘studio’ tí mo fi bẹ̀rẹ̀ orin lẹ́yìn tí mo kùnà ìdánwò WAEC Gẹgẹ bo ṣe sọ loju opo Twitter rẹ, o ni ""mo tọrọ aforiji pe mo sọ pe awọn ọmọ ile iwe mẹwa pere ni wọn ji gbe ni Kankara, ọrọ ti mo sọ ṣaaju kii ṣe ọna lati fi ẹnu tẹnbẹlu iṣẹlẹ naa."
lo ti padanu ẹmi wọn, ti awon eniyan to le ni ọ́ọ̀dúnrún  ti ni aarun yii.
” Mo bá jẹ ẹ́, ó sì dùn bí oyin lẹ́nu mi.
    Orile ede Russia  ti sekilọ pe ki awon orile ede okeere maa se
Nigba ti ere bọọlu naa maa pari, ikọ Super Eagles ti gba ẹjẹ lẹnu Seychelles pẹlu ami ayo mẹta si ọkan.
Atunto ilana oye ọba naa si lo fun Ajimobi lanfaani lati yan ọba mọkalelogun ni ọjọ kansoso labẹ Olubadan tilẹ Ibadan.
'APC kò fẹ́ ire fún mi mọ́ nínú ìṣesí wọn Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ìgbésí ayé àwọn ọmọdébìnrin wọ̀nyìí di ọ̀tun láti 2008 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Kò pẹ́ púpọ̀ lẹ́hìn eléiì’tí ó wo iwájú tí ó si rí àwọn obìnrin mejì ti wọn ń bá ojú ọna bọ̀ ti wọ́n si ń sọ̀rọ̀ti wọ́n ń rẹ́rìn-ín ti wọ́n ń pa atẹ́ẹ́ pó pó gẹ́gẹ́ bí àṣà ogunlọ́gọ̀ obìnrin.
Lẹ́yìn náà Eliasafu, ọmọ Deueli, tún ko akọ mààlúù meji, àgbò marun-un, òbúkọ marun-un, ati ọ̀dọ́ àgbò marun-un ọlọ́dún kọ̀ọ̀kan kalẹ̀ fún ẹbọ alaafia.
Akọroyin BBC to wa nibẹ ṣalaye pe ohun ti iro rẹ jọ iro ibọn ni awọn ṣọja naa kọkọ fi bẹrẹ ki wọn to bẹrẹ si ni yin iṣere ọdun Banga lati tu wọn ka.
Iṣẹ́ lásán ni àwọn eniyan ń ṣe,àwọn orílẹ̀-èdè sì ń yọ ara wọn lẹ́nu lásán ni,nítorí pé iná yóo jó gbogbo làálàá wọn.
Bi ori bá fọ́ Òṣèlú, wọn á lọ si Òkè-Òkun nibiti wọn kó owó ti ó yẹ ki wọn fi tú ilé-ìwòsàn ṣe si.
Ko pẹ si ti Raphaël Guerreiro tun sọ bọọlu sinu awọn Schalke, lẹyin naa lo sọ goolu miran wọle ni abala keji ifẹsẹwọnṣe ọhun.
Gbogbo àwọn aṣọ́nà tẹmpili ni a pín sí ẹgbẹẹgbẹ́ gẹ́gẹ́ bí ìdílé wọn.
Hubert Ogunde rèé, baba àwọn òsèré tíátà O fikun pe oun ko kabamọ pe oun pe akiyesi awọn alasẹ si ihuwasi ọmọ oun ko to di pe asiri rẹ tu, ti oun si n gbadura fun pe ko jade lẹwọn boya loju aye oun ni abi lẹyin rẹ.
" Mó wá ni kí n dúpẹ́ lọ́wọ́ rẹ̀ pé ó ṣeun tó bá mi ti mótò, bi mọ ṣe mu nìyẹn"" Lórí owó ti àjọ ọlọ́pàá fi léde pé àwọn yóò fún ẹni to bá rí ọ̀dọ́mọkùnrin Sunday Shodipe mú Ààrẹ ẹgbẹ́ ọdẹ Soludẹrọ Ajijọlaanabi ní àwọn ọlọ́pàá ti n ṣeto bi owó náà yóò ṣe tẹ àwọn lọ́wọ́ gẹ́gẹ́ bi ìlérí wọ́n."
Koko: The Box TV – Nigeria
Samsoni bá dáhùn pé,“Páárì ẹ̀rẹ̀kẹ́ kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ ni mo fi pa wọ́n jọ bí òkítì,Egungun ẹ̀rẹ̀kẹ́ kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ ni mo fi pa ẹgbẹrun eniyan.
Dípò kí ẹ ṣe bẹ́ẹ̀, onigbagbọ ń pe onigbagbọ lẹ́jọ́ níwájú àwọn alaigbagbọ!
West to jẹ pasitọ sọ ninu fidio naa pe oun sọtẹlẹlẹ ṣaaju pe Godwin Obaseki ni yóò wọlẹ ibo gomina ipinlẹ Edo.
ATUPALE BI NNKAN SE RI PELU CORONAVIRUS NI NAIJIRIA TITI DI ỌJỌ́ KEFA OSU KAARUN 2020 Iye ayẹwo ti wọn ti se - 23,835 Iye awọn to ni arun naa ti wọn fidi rẹ mulẹ- 3,912 Awọn tara wọn ya - 679.
Wọn kò gbọdọ̀ jẹ ẹran tẹ̀jẹ̀tẹ̀jẹ̀, kí wọ́n dẹ́ṣẹ̀ sí OLUWA.
Walter wasn't just a pride to America and Americans, he was also a pride to all the people of African descent.
Bi a ṣe gbọ ọrọ lẹnu Wolii Alfaa ti ọrọ kan gan an, la ba arabinrin Modupẹ to jẹ iya ọmọ ati ọgbẹni Temitọpẹ to jẹ baba ọmọ sọrọ.
Bata olokun buutu naa, ti Ileesẹ Nike ṣe sita, eyi ti Jordan wọ lasiko saa bọọlu alapẹrẹ to fi dojukọ ikọ Chicago Bulls, nireti wa tẹlẹ pe owo tita rẹ yoo wa laarin ẹgbẹrun lọna ọgọrun si ẹgbẹrun lọna aadọjọ dọla nilu Sotheby.
“Nítorí náà, ẹnikẹ́ni tí ó bá jẹ́wọ́ mi níwájú eniyan, èmi náà yóo jẹ́wọ́ rẹ̀ níwájú Baba mi tí ń bẹ lọ́run.
Àwọn oriṣa Hamati ati Aripadi dà?
Ṣé n kò wá ju ọmọ mẹ́wàá lọ fún ọ ni?
A ó ṣèrànwọ́ fáwọn ẹbí ọlọ́pàá tó bá rògbòdìyàn EndSARS lọ láti inú N500m tí a yà sọ́tọ̀- Makinde Eeyan marun un marun un lo lugbadi covid-19 nipinlẹ Oyo, kaduna, ati Taraba l'Ọjọru ni Naijiria.
Nigba naa, o ni aye arabinrin naa ti yipada si rere lati igba ti wọn ti le kuro ni ileewe, to si yege ni ẹkọ rẹ ati ihuwasi rẹ.
gomina to waye ni ọjọ Abamẹta ni awon ipinle yii ko tii pari.
Wọn kò gbọdọ̀ jẹ́ ẹni tí ó ń mutí para.
Chidmma Nwokeji fesi loju opo Instagram Lizzy pe, awọn ololufẹ Lizzy kan n tan an jẹ lasan ni, ati pe Lizzy ti dagba kọja iru ẹni to yẹ ki o maa bu ẹlomiran lori ẹrọ ayelujara.
Oríṣun àwòrán, Crown-art Ọdún mọ́kànlá rèé témi àti ọkọ mi bẹ̀rẹ̀ ìfẹ́ láti ilé ẹ̀kọ́ girama - Bukunmi Oluwasina Ohun méje tí Jimoh Aliu fi yàtọ̀ lágbo tíátà Ikorodu Bois fí àwàdà bọ àwòrán àwọn ọmọ Otedola, ẹ wo ará tí wọ́n dá Adunni Oluwole, akọni obìnrin tó tako òmìnira Nàìjíríà, ó ní òyìnbó kò gbọ́dọ̀ lọ Àṣírí ńlá tó ń bẹ láàrín Alaafin àtàwọn onílù rẹ̀ rèé Àlàyé rèé lórí bo ṣe le è dá Emèrè mọ̀ tàbí dara pọ̀ mọ́ ẹgbẹ́ wọn Oloye Ifayẹmi ni ọpọlọpọ awọn Ọba ni ko karamasiki orò ilu tabi aṣa ati iṣẹṣe mọ.
Aarẹ Buhari sọ eyi ni ibi ipade Ajọ to n risi ipese ounjẹ, National Food Security Council (NFSC) to waye ni Ọjọ Kẹwaa, Oṣu Kẹsan, ọdun 2020.
PTF Covid-19: Ọ̀pọ̀ arìnrìnàjò mú ẹ̀rí àyẹ̀wò moyege lọ́wọ́ láti òkè òkun àmọ́ wọ́n ní Coronavirus
Kollington, Bàbá Suwe, Ogun Majek wà lára àwọn gbajúmọ̀ tí ayé ti parọ́ ikú mọ́ sẹ́yìn Èèyàn 627 ló lùgbàdì àrùn Coronavirus ní Naijiria ní Ọjọ́ Ẹtì Irọ́ ni pé Gómìnà Edo Obaseki ti darapọ̀ mọ́ ẹgbẹ́ PDP Alhaja Kudirat Abiola: Odindi géńdé ọkunrin mẹ́fà ni wọ́n gbé iṣẹ́ ikú rẹ̀ fún Ati pe awọn owo ti wọn ri gba pada naa jẹ awọn owo ti wọn fẹ lo fun awọn nkan miran ni oke okun.
Fasoranti: Àwọn ọ̀dọ́ Ondo fárígá lórí ikú Funke Olakunrin
Awọn tọkọtaya naa, ti oruko wọn n jẹ Ifeanyi ati Emmaculata Elijah, wa lati agbegbe Amakpu nijọba ibile Owerri nipinlẹ Imo, jẹwọ wipẹ awọn ta ọmọ awọn niye owo naa.
 Ó máa ń dínku meningitis àti sepsi láàrín ọ ̀ pọ ̀ ènìyan níbi tí wọ ́ n ti ń lòó káàkìri .
Ǹjẹ́ ẹ̀yin mọ ìtàn bii, tani àwọn tí ó wà nínú àwòrán yìí
Ipa Ankara ninu eto oro ajeOgbeni Wole Oladunjoye to je oludari agba fun awon igbimo amuses fun odun LAAFEST ni aso Ankara ti di orison okowo ni gbogbo ile Adulawo lai yo orile ede Kankan soto bayii.
Mo rò pé n kò ní tún fojú kan OLUWA mọ́ ní ilẹ̀ alààyè,ati pé n kò ní sí láàyè mọ́láti tún fi ojú mi kan ẹnikẹ́ni.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Yemi My Lover: Ìdí rèé tí orin kíkọ fi máa ń pò nínú sinimá mi.
Ilẹ United Arab Emirate (UAE), ti ṣi aṣọ loju ipele akọkọ iwe irinna ọlọdun marun un fun awọn eniyan lati gbogbo orilẹ-ede.
" Sugbọn nínú ifọrọwanilẹnu miran, ọkan lara awọn iyawo baba rẹ sọ pe oun maa n fun un ni oúnjẹ.
Lara awọn eekan ilu to ti ṣedaro rẹ ni igbakeji aarẹ Naijiria nigba kan, Atiku Abubakar.
Nigba to n sọrọ loju opo Twitter rẹ, Dino ni iyawo ni Adeyemi jẹ fun oun lagbo oṣelu.
Wọnyii ni awọn ipo ti adajọ Tanko ti di mu ri
Ṣugbọn eyi to ja ju ni ki eniyan le ba awọn agbabọọlu ti oun funra rẹ ṣa ṣiṣẹ.
Mo fẹ́ràn gbogbo àwọn tí wọ́n fẹ́ràn mi,àwọn tí wọ́n bá fi tọkàntọkàn wá mi yóo sì rí mi.
Ṣugbọn kọmisana ọlọpaa nipinlẹ Ondo, sọ pe kii ṣe ado-oloro.
Ọpọ lo ri igbesẹ yiyan minisita ni oṣu kẹta saa keji iṣejọba rẹ gẹgẹ bii eyi to tun dan mọran ju bi nnkan ṣe ri ni saa akọkọ lọdun 2015.
gbalejo awon adari orile ede ti won jẹ omo egbe ajo naa.
Bákan náà ni gígùn rẹ̀, ati ìbú rẹ̀, ati gíga rẹ̀.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Kidnappings in Nigeria: Aráàlú ń bèèrè pé ṣe agbébọn ló ń jí èèyàn gbé àbí Boko Haram?
 Ṣùgbọ ́ n ilẹ ̀ belgium kọ ̀ jálẹ ̀ pé àwọn ti pínú pé àwọn kò ní dá sí ìjà .
 Ireti mi nipe idanilekoo yii yoo bi eso rere to ye fun idagbasoke oselu Naijiria”.
Yóo sì yí láti Asimoni lọ dé odò Ijipti, òkun ni yóo sì jẹ́ òpin rẹ̀.
Fún ọpọlọpọ ọjọ́, ọkọ̀ kò lè yára rìn.
O ni oun to buru jai ni lati kọju ija si awọn ọmọ Naijiria ti wọn wa ni South Africa bayii, nitori pe Naijiria pẹlu awọn to ja fun ominiran ilẹ naa lọwọ awọn amunisẹru.
kuro lọ si orile ede  miiran ,sugbon ki e
Ogunlogo awon omo orile-ede Mozambique ni won ti padanu ibugbe won, ti awon miiran si n gbe kaakiri bi eye aparo lataari isele iji lile, omiyale agbara ya soobu, ti o waye ni ekun ila oorun orile-ede Mozambique.
”Abiṣai dáhùn pé, “N óo bá ọ lọ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Arsenal fidirẹmi lẹẹkẹta laarin ọjọ mẹjọ 4 Ẹrẹ̀nà 2018 Oríṣun àwòrán, Reuters Àkọlé àwòrán, Nkan o dagun fun Arsenal bayii ri fun ọpọlọpọ ọdun sẹyin Agbabọọlu ọmọorilẹede Naijiria ni, Alex Iwobi ko lee dawọ iya duro fun ikọ agbabọọlu rẹ, iyẹn Arsenal pẹlu bi oun ati awọn akẹgbẹ rẹ tun se bu omi iya mu ninu idije liigi premiership ilẹ Gẹẹsi to waye lọjọ̀ aiku.
Kódà ọ̀pọ̀ ló wá láti ọnà jíjìn àti ìdálẹ̀ láti darapọ̀ mọ́n èrò tó wá bọ̀wọ̀ fú ọba yìí.
Obìrin náà jẹ èrè iṣẹ́ ọwọ́ọ rẹ̀ ní ẹ̀wọ̀n.
Yóo jó gbogbo àwọn tí wọ́n wà ní gúsù títí dé àríwá.
Alága ìgbìmọ̀ amúṣẹ́ṣe lórí ààrùn coronavirus lórílẹ̀-èdè Nàìjíríà tó tún jẹ́ akọwé ìjọba àpapọ̀ Boss Mustapha ló kéde èyí lásìkò tó n jábọ ibi abáṣẹ́dé lorí Covid-19 lọ́sàn òní nílùú Abuja.
Ìwọ ni a gbẹ́kẹ̀lé,nítorí ìwọ ni o ṣe gbogbo nǹkan wọnyi.
Bi igba ti eeyan fẹ ẹ da ẹrẹ si ibi ti a pe ni ibi mimọ ni nkan to ṣe.
Ṣugbọn gbàrà tí ó kú tán, o dìde o sì bẹ̀rẹ̀ sí jẹun!
Òjò bá bẹ̀rẹ̀ sí í rọ̀.
Kò ṣòro fún mi láti kọ àwọn nǹkankan náà si yín, ó tilẹ̀ dára bẹ́ẹ̀ fun yín.
Sugbọn bayi ti o j wi pe Bukola Saraki naa n du ipo Aarẹ orileede Naijiria o le ma rọrun lati mu eeyan kan.
Chukwuemeka ke pe kọmisọna ọlọpaa ni ipinlẹ Rivers Joseph Mukan ati àti awọn ẹsọ alaabo to ku lati wadii nkan to fa iku ojiji ti ẹgbọn oun ku ati lati ri idajọ ododo.
Nigba ti wọn n da si ijiroro yi, asofin meji, Pattegi Ahman ati Muhammed Bago fọwọ sọya pe awọn faramọ pe ki ijọba se afikun owo to ya sọtọ fun atunse marosẹ Ibadan si Eko, wọn ni, tijọba ko ba se bẹẹ, yoo gba ilẹ wa to ọdun mẹjs ko to lee pari opopona marosẹ naa.
Amofin agba Keyamo ṣalaye pe ẹsẹ 318 ninu iwe ofin Naijiria sọ pe oludije gbọdọ ni iwe ẹri girama tabi eleyi to dabi rẹ, bakan naa o gbọdọ mọ ede oyinbo kọ ko si mọ ọ ka.
    Ẹ̀yin ènìyàn wa, tiyín ni àwọn ọdẹ tí ẹ̀ ń wo wọ̀nyí ń fẹ́, wọn kò fẹ́ ti ara wọn nìkan ṣoṣo.
Yatọ si eyi, Kyari tun kẹkọọ lori idagbasoke amojuto ileeṣẹ, ni ileewe eto okoowo, Harvard Business School lọdun 1992 ati 1994.
Pataki lati ran won lowo , ki won si mu won padabo sipo, paapaa julo nipa ise
Mú àwọn olùdámọ̀ràn ibi kúrò lọ́dọ̀ ọba,a óo sì fi ìdí ìjọba rẹ̀ múlẹ̀ pẹlu òdodo.
Èkúté tó sàwárí bọ́mbù ilẹ̀ gbàmi ẹ̀ye wúrà fún iṣẹ́ takuntakun Afurasí Boko Haram pa ológun àti ọlọ́pàá mẹ́rìnlá ní Borno Nǹkan yan, àwọn aṣẹ́wó fẹ́ daṣẹ́ sílẹ̀ nítorí ẹ̀kúnwó epo ní Nàìjíríà Ọwọ́ ọlọ́pàá tẹ arábìnrin tó fẹ́ ta alòkù kọ́ńdọ́ọ̀mù 324,000 padà f'áwọn èèyàn Ìbúgbàmù gbogbo ìgbà nílù ú Èkó, kí ló ń ṣokùnfà rẹ̀?
Mo sì ń wojú Ọlọrun nítorí pé mo ní ìrètí kan náà tí àwọn ará ibí yìí pàápàá tí wọn ń rojọ́ mi ní, pé gbogbo òkú ni yóo jinde, ati ẹni rere ati ẹni burúkú.
Bakan naa ni ijọba ti gbiyanju amọ ko tii si ọna abayo, amọ awọn gba Ọlọrun gbọ nitori yoo gbọ adura awọn ati wi pe awọn ọmọ naa yoo pada wale layọ ati alaafia.
'À ń lọ ilé-ẹjọ́ kòtẹ́milọ́rùn fún ẹ̀kúnwó owó oṣù ẹlẹ́wọ̀n' Ogun ló ń wáyé ní Kogi, kìí ṣe ìbò dídì - Olùdíje gómìnà Lai Mohammed: A kò ní bojú wẹ̀yìn lórí àbádòfin ìṣàkóso ẹ̀rọ ayélujára Olóṣèlú ní Kogi àti Bayelsa ti ń pín Irẹ̀sì, iyọ̀ lásìkò ìpolongo ìbò, INEC, ẹ mú wọn"" Ẹ wo diẹ lara awọn ohun ti Alex Akinyele fi lede lori ẹrọ ayelujara ko to jade laye."
Ó ṣe kọmiṣọna fún eto ìṣẹ ode ni Ipinle Èkó ni ọdun 2009.
Ajayi to kuna ninu idibo abele fun ipo gomina ninu eyi ti Eyitayo Jegede ti jawe olubori mu iwe to fi ẹgbẹ naa silẹ lọ si olu ileeṣẹ ẹgbẹ PDP to wa ni wọọdu Apoi keji niluu Kiribo, ijọba ibilẹ Ese Odo.
”Mo bá bèèrè pé,“Igbe kí ni kí n ké?
Inú bí Mose gidigidi tóbẹ́ẹ̀ tí ó fi ju àwọn wàláà òkúta náà mọ́lẹ̀, ó sì fọ́ wọn ní ẹsẹ̀ òkè náà.
"Oríṣun àwòrán, FACEBOOK/ROCHAS Àkọlé àwòrán, Gomínà Okorocha gbe igab ibo latia di sẹnatọ ni ọdun 2019 lẹ̀yìn to ti lo ọdun mẹ́jọ gẹ́gẹ́ bii gomina Imo Nígba ti gbogbo ẹ gbónà tan láàrin àwọn mejèèji, ní ìjoba Okorocha fún Eze naa ni ìwé lọ gbélé ẹ gẹ́gẹ́ bi ìgbákeji alaga Eze Njemanze fún gbogbo Ndi-Eze to jẹ ẹka to n gbẹ́jọ The state government in a statement denied the allegation saying, ""It has no hand in the suspension of the four traditional rulers and the trial of more than fifty others by the Ezes' Council."
Ènìyàn mẹ́sàn-án ni Abuja, nígbà ti méje wáye ni ìpínlẹ̀ Ogun, Plateau àti Gombe ni márùn-ún, mẹ́rìn ní Imo.
O kọkọ gba itọju ni ile iwosan Cedar Crest ko to di wi pe wọn gbe e lọ si ilẹ okeere fun itọju.
London, Manchester, Belfast àtàwọn ẹkùn míì ni wọ́n ti n fẹ̀hónúhàn lónìí fí kí aàrẹ Trump káàbọ̀ sí UK Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'O yé kí ìbáṣepọ̀ Nàìjíríà àti UK dán mọ́rán síi lẹ́yìn àbẹ̀wò May' Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ìfipábánilòpọ̀: Abiamọ bú sẹ́kún nígbà tí ọkùnrin kan fi tipá bá ọmọ méjì lòpọ̀ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ìjàmbá Ibadan: Abiyamọ tó pọn ọmọ sẹ́yìn kú tọmọ-tọmọ Wọn ni o ṣeeṣe ki o jẹ pe ọkan ninu awọn ibeji naa lo kọkọ jabọ sinu omi ti ikeji rẹ naa si ja sodo nigba ti o n gbiyanju lati doola rẹ.
Ninu ọrọ to ba BBC News Yoruba sọ, Mr.
Ọkùnrin èyí kìí se ọkùnrin lásán óò aṣojú ni ni orílẹ̀ èdè Nàìjíríà
Eto naa yoo si bẹrẹ ni ọjọ kẹwaa, oṣu Kokanla.
 Ó kàwé ní methodist girls high school , ní ìlú Èkó .
Àwọn olóyè rẹ̀ ní ìwọ̀ra bíi kinniun tí ń bú ramúramù; àwọn onídàájọ́ rẹ̀ dàbí ìkookò tí ń jẹ ní aṣálẹ̀ tí kì í jẹ ẹran tí ó bá pa lájẹṣẹ́kù di ọjọ́ keji.
Candido Da Rocha wa saye, o se aye loore, o fi owo rẹ mọ ẹbi ara, ọrẹ ati awọn ojulumọ, taa si lee pe ni olowo to n fi owo saanu laye igba tiẹ.
 bí o wà níbí di ẹgbẹ ̀ rún ọdún , a ò ni fi ìkan pe méjì fún ọ .
Naijiria ko tii gba ife ẹyẹ agbaye FIFA U-20 ri, koda orilẹede Ghana nikan ni orilẹede Afirika to ti gba ife ẹyẹ naa ri.
Nítorí ọ̀kan ni ẹni tí ó ń ya eniyan sí mímọ́ ati àwọn eniyan tí ó ń yà sí mímọ́ jẹ́, nítorí náà ni Jesu kò fi tijú láti pè wọ́n ní arakunrin rẹ̀.
Bí o bá dẹ́ṣẹ̀, kò ṣe Ọlọrun ní àìrójú,bí ẹ̀ṣẹ̀ rẹ bá pọ̀, kò jámọ́ nǹkankan fún un.
Aare Muhammadu Buhari ti kede pe ijoba Naijiria ti bere igbese to maa mu erongba afojusun kebi-ma-palu re se laipe nipa ipese ohun jije to to fun gbogbo ara ilu.
Nisinsinyii gbọ́ ohun tí OLUWA wí.
Nígbà tí Àjọ̀dún Ìrékọjá ati ti Àìwúkàrà ku ọ̀tunla, àwọn olórí alufaa ati àwọn amòfin ń wá ọ̀nà tí wọn yóo fi rí Jesu mú, kí wọ́n pa á.
Kí ló dé tí ìjọba ìpínlẹ̀ Oyo kéde fífagilé Sáà ètò ẹ̀kọ́ kẹta fún àwọn akẹ́kọ̀ọ́?
Abegunde wa gbadura pe ilera pipe yoo jẹ ti gomina ipinlẹ Ondo naa.
Ẹ dẹ̀kun lílo Sniper àti Dichlorvos fún ìtọ́jú oúnjẹ- NAFDAC kìlọ̀ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, EndSars, EndSwat Protest: Òbí agbábọ̀ọ̀lù Gbenga Tiamiyu Kaka àtàwọn míì tí ọlapàá pa sọ̀r Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Fídíò, Akomolede àti Asa lórí BBC Yorùbá: Mọ̀ síi nípa ẹ̀kún ìyàwó níbí3 Bélú 2020 Fídíò, Soyinka Cancer: Àṣe ara mi ni iso ti n run gbogbo bí mo ṣe n ṣèrànwọ́ lórí jẹjẹrẹ27 Bélú 2019 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 3 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 5 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Ọ̀gágun bá ní kí ọdọmọkunrin náà máa lọ.
 ní ọdún 2017 , wọ ́ n yàn án gẹ ́ gẹ ́ bí olùdásílẹ ̀ royal institute of british architects , ní ilẹ ̀ nàìjíríà àti ọkan nínú àwọn ayàwòrán ọgbọ ̀ n ní gbogbo àgbáyé ni naijiria ati ọkan ninu awọn olùyàwòrán ọgbọn ní gbogbo àgbáyé .
”Wabba tun so pe: “ki awon ijọba si tete gbe igbese lona ati maa tun awon agbegbe ti won baje yii se, ki won si tun mojuto awon eniyan ti won padanu dukia won, ki won si wa ona ati dekun isele buruku yii.
Igbe tí wọn ń ké ní oko ẹrú sì gòkè tọ OLUWA lọ.
Ogun gbóná janjan yí Saulu ká, àwọn tafàtafà rí i, wọ́n ta á lọ́fà, ó sì fara gbọgbẹ́, 
Mo rò pé eléyìí náà ló mu kí kúrúnà kúkú pọ̀ tó bẹ́ẹ̀ ní ìlú náà, ṣùgbọ́n èyí tí ó buru ju kúrúnà ni egbò ẹsẹ̀ Olúkúlùkù tí ó dúró gẹ́gẹ́ bí àṣà fún àwọn gbájumọ̀.
Kí wọ́n lè mú wa láàyè, kí wọ́n sì gba ìlú wa.
Ogagun Abdulsalami, lo soro yii , lasiko to n soju fun igbimo eto alaafia(National
Ni ibamu pelu ojuse ile-igbimo naa, awon torokan gbongbon ni o koko se ipade alatilekun mori won, eleyi ti o waye fun wakati kan gbako, ki apapo ile-igbimo ohun o to bere ipade won loni gbayawu.
Àgbo tí mò ń lò láti jò kó bá mi, ìdí mi ti yọ́ tán - Nkechi Blessing figbe ta Ọlọ́pàá tún yìnbọn pa awakọ̀ Márúwá, ìwọ́de gba Portharcourt kan Amotekun yóò gba owó oṣù kẹtàlá ní ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́ - Seyi Makinde Ẹwẹ, gẹgẹ bi agbẹnusọ ile aṣofin naa ṣe sọ fun awọn oniroyin, wọn ti ri ami idanimọ Coat of Arm to wa lori ọpa aṣẹ naa, ṣugbọn ọpa aṣẹ gangan, wọn o tii ri i.
Kí oníkálukú yáa tẹra mọ́n ètò ìmọ́ntótó rẹ̀.
Ẹ yìn ín, oòrùn ati òṣùpá;ẹ yìn ín, gbogbo ẹ̀yin ìràwọ̀ tí ń tàn.
Igba miran, wọn ni wọn ma n fi ẹsun kan wọn pe wọn n ṣe ojo ni oju ogun, abi wọn fẹ tu aṣiri ikọ ọmọogun Naijiria.
Bi awọn kan ṣe n bu ẹnu ẹ̀tẹ́ lu igbeṣẹ naa wi pe arabinrin naa n lo baalu ti awọn ara ilu n san owo ori lẹ lori lati lọ fi sẹ iṣẹ ara rẹ ni ipinlẹ Bauchi ni àwọn miran ni ko buru Ayẹyẹ ọdun Durbar ni Bauchi ni ọmọ aarẹ Buhari lọ ya fọto rẹ gẹgẹ bi iṣẹ aje rẹ nibi to ti ni anfani lati ya aworan nipa ọdun naa ati awọn nkan miran ni Bauchi.
ó sì sọ Josẹfu sinu ọgbà ẹ̀wọ̀n.
17 Agẹmo 2019 Àkọlé àwòrán, O ni ìdí ti a fi wọgile iwọde wa toni Oni ni àwọn ikọ #Church Too ti wọn n ṣe iwọde ṣe lodi si ifipabanilopọ nile ijọsin kede lati ṣe iwọde ni Abuja ati Eko tẹlẹ.
ni egberun lẹ̀ẹ́dẹ́gbẹ̀jọ ( 1,500) ile-iwe ti won ti
O ṣalaye pe ni isọri isọri lawọn to n ṣiṣẹ Haji yoo maa lọ sibi ti wọn yoo ti lẹko mọ Asitani lati le dena titẹ ara ẹni pa.
12 Ìgbé 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Lẹyin ọpọ ifẹhonu han, awọn ologun gbajọba lọwọ aarẹ orilẹede Sudan, Omar al-Bashir.
Ile Igbimọ asofin ipinle Kano ti yọ abẹnugan wọn, Abdullahi Yusuf Atta.
Samuẹli sọ fún Saulu pé, “OLUWA rán mi láti fi òróró yàn ọ́ ní ọba lórí Israẹli, eniyan rẹ̀.
Ahiamu, ọmọ Sakari, ará Harari, ati Elifali, ọmọ Uri; 
Bi awọn eniyan ṣe n mu ẹlẹrindodo si ni agbaye Iwadii naa tu aṣiri pe ibaṣepọ to lagbara lo wa laarin minu ẹlẹrindodo to ni ṣuga ninu ati iku ojiji, lati ipasẹ aarun ọkàn, ati aisan jẹjẹrẹ.
 lẹ ́ yìn ìgbà yìi , òṣèlú aráìlú bẹ ̀ rẹ ̀ ní ilẹ ̀ zimbabwe rhodesia ní ọdún 1979 , lẹ ́ yìn ìparí ìjà láàrín ara wọn ní ọdun tó kọjá , harper kọjá sí orílẹ ̀ èdè gùùsù Áfíríkà .
Oríṣun àwòrán, The Nigerian Senate Àkọlé àwòrán, Ahmad Lawan Ohun naa ko fẹ ki awuyewuye pupọ wa laarin ẹka aṣofin ati ti alaṣẹ ijọba.
 barack obama ní ọbàkàn , obìnrin , ọmọ lolo àti stanley ann .
Ololade, to jẹ adari Prime FC lasiko naa salaye pe, ile igbimọ asofin wa lori ọrọ naa ati pe, wọn ti kilọ fun awọn pe ẹnikẹni ko gbọdọ ba awọn oniroyin sọrọ, titi ti iṣẹ iwadii yoo fi pari.
Igbesẹ Kẹrin: Laarin ọjọ mẹrinla ti awọn aṣofin ba ti fun olori ile ni iwe ẹsun, awọn aṣofin yoo dibo lati mọ boya ki wọn ṣe iwadii ẹsun magomago ti wọn fi kan Igbakeji Gomina naa Ida meji ninu mẹta awọn aṣofin lo gbọdọ fi ọwọ si igbesẹ yii, ki o to le kẹsẹjari.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Dokita onimọ nipa ohun ọsin naa wa parọwa si awọn to n si adiyẹ lati ri daju wi pe wọn fun wọn loogun lasiko ti yoo dena aarun gbogbo.
 Ó kọ ọ ̀ pọ ̀ lọpọ ̀ ewì .
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Nigeria: Kiniun pa olusọ ọgba ẹranko 7 Èrèlè 2018 Àkọlé àwòrán, Igba keji ree ti kiniun yoo sekupa eeyan lorilẹede Naijiria Olusọ ọgba eranko kan ti ku lẹyin igba ti kiniun kan kọlu ni ọgba ẹranko kan to wa nilu Kaduna lẹkun ariwa Naijiria.
oko ati awon ohun ini ijoba je.
Gbogbo nǹkan yòókù tí Jeroboamu ṣe, ìwà akọni rẹ̀ lójú ogun ati bí ó ti gba Damasku ati Hamati, tí wọ́n jẹ́ ti Juda tẹ́lẹ̀ rí, fún Israẹli, gbogbo rẹ̀ ni a kọ sinu Ìwé Ìtàn Àwọn Ọba Israẹli.
Ẹni ọdun marunlelọgọrun ni mama yii nigba to pade ọlọjọ.
Bó tilẹ̀ jẹ́ pé ó lé ni ọgọ́rún un ọjọ́ ti arún náà ti bẹ̀rẹ̀ kí ilẹ̀ Afíríkà to ri ènìyàn ẹgbẹ̀run lọ́nà ọgọ́run un kan to ní ààrùn náà, síbẹ̀ kò jú ọjọ́ méjìdínlógún lọ ti ó fi di ìlópo méjí ẹgbẹ̀run lọ́nà ìgba tó sì tún dí ẹgbẹ̀run lọ́nà irínwó léyin ogúnjọ́ náà.
Bẹ́ẹ̀ náà ni ó fún wọn ní ẹja jẹ.
Wọn mu fun wi pe o pa ọkọ rẹ nigba ti o wa ni ọmọ ọdun mẹtadinlogun Awọn alatilẹyin rẹ to fi mọ Amnesty International so pe awọn ọlọpaa fi iya jẹ ni titi to fi jẹwọ wi pe o pa ọkọ rẹ .
“oni je ojo ma-le-gbagbe lorile ede Russia lati sajoyo ipo wa lagbaaye.
Wọ́n ti pa ẹni to yìnbọn pa ará Texas márùn ún -ọlọ́pàá Alawọ funfun ni Ator jẹ, bẹẹ ni ọmọ odun mẹrindinlogoji si ni.
Ijoba Cuba gba pe siseto idibo lodun marunmarun yii fihan pea won wa nisokan lainaani ohun ti America n se fun won.
Jakọbu tún ń bá ìrìn àjò rẹ̀ lọ, nígbà tí ó ṣe, ó dé ilẹ̀ àwọn ará ìlà oòrùn.
4m fagbábọ́ọ̀lù Super Eagles8 Agẹmo 2019 Sanwo-Olu: Àtàrí Àjànàkú ni àkóso Eko, kì í ṣe ẹrù ọmọdé7 Òkùdu 2019 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Ninu awọn nkan ti wọn ba ninu rẹ la ti ri ibọwọ onirọba ati tawẹli inura kekere kan.
Nebusaradani, olórí àwọn olùṣọ́ ọba bá kó ninu àwọn talaka lẹ́rú pẹlu àwọn eniyan tí wọ́n kù ní ìlú, ati àwọn tí wọ́n ti sálọ sọ́dọ̀ ọba Babiloni, ati àwọn oníṣẹ́-ọwọ́.
Igbimo olupejo lorile-ede naa National Prosecuting Authority (NPA)fun omo Aare naa ni gbegede osu meji eyi ti o wa sopin ni opin osu keta odun lati so idi ti ko fi ye ki o fojuba ile-ejo ,sugbon o kuna lati se eyi,gege-bi agbenuso ile-ise naa Luvuyo Mfaku  se so.
Ṣugbọn nígbà tí wọ́n pada dé, wọ́n mú kí ọkàn àwọn ọmọ Israẹli rẹ̀wẹ̀sì, kí wọn má lè lọ sí ilẹ̀ tí OLUWA ti fi fún wọn.
Oríṣun àwòrán, Others Ere Talo wa Ninu Ọgba naa: Lasiko ti awọn ọmọde ba n ṣe ere idaraya yii, wọn yoo pa agbo ribiti kan, wọn a si ma n kọrin, ẹyi po ka.
Eyi ni lati ba gbedeke ti ajọ naa gbe silẹ fun awọn oṣiṣẹ ọba lati wa kede dukia wọn ki saa iṣejọba ti wọn wa to pari.
EndSWAT: Wo àwọn Májẹ̀kóbàjẹ́ tó wà nídìí ìwọ́de #EndSARS / End SWAT
Ṣọ́ra kí ibinu má baà sọ ọ́ di ẹlẹ́yà,kí títóbi àbẹ̀tẹ́lẹ̀ sì mú ọ ṣìnà.
Ògo OLUWA yóo farahàn, gbogbo eniyan yóo sì jọ fojú rí i.
Asofin Kehinde Ayoola wa ro gomina tuntun naa lati maa gbagbe awon ileri ti o se lasiko ipolongo idibo fun awon ara ilu ipinle Oyo.
Ninu atẹjade ti Minisita fun eto iroyin, Kojo Oppong Nkrumah fi lede ni wọn ti fi lede bẹẹ.
Man City fìbínú gbèsan lára Tottenham
"Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Super Eagles, ẹ máṣe gbá bọ́ọ̀lù fún Nàìjíríà mọ́ nítorí ìhà tí ìjọba kọ sí ìwọ́de EndSARS - John Ogu Ará Eko, ẹ pariwo ó tó gẹ́ẹ́ lórí làásìgbò tó gbòde torí ìwọ́de EndSARS - Sanwo-Olu Ọ̀tá Yorùbá ló lo ìwọ́de láti dojú ogun kọ wá - OPC ""Àwọn ọ̀tá Nàíjíríà tó fẹ́ dojú ìjọba bolẹ̀ ló wà lẹ́yìn ìwọ́de EndSARS"" Ó parí ni ohùn tó gbẹnu ọ̀pọ̀ ọmọ Nàíjíríà lẹ́yìn ọ̀rọ̀ Buhari Koda, isẹlẹ ikọlu bo waye laipẹ yii nibi iwọde EndSARS lẹnu bode Lekki, ti bi oniruuru nnkan miran laarin ilu nitori iroyin eke tawọn eeyan kan n pin kiri nipa isẹlẹ naa."
Ẹnìkejì ní, ‘Mo ra mààlúù fún ẹ̀rọ-ìroko.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ìpínlẹ̀ Oṣun kò nílò Gómìnà oníjó - Oshiomole Èrò Akinbade, Oyetọla, Adeoti àti Omiṣore ṣọ̀tọ̀ọ̀tọ̀ nípinlẹ Ọṣun Aago méjìlá ọjọ́ Ẹti ni ìséde yóò bẹ̀rẹ̀ ṣáájú ìdìbò náà Ọ̀rọ̀ LAUTECH gba àpérò f'áwọn Olúdíje Ọṣun Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí 2 sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
Esi ayẹwo tuntun naa lọ bayii: Ni bayii, apapọ awọn to ti ni aarun naa ni Naijiria ti pe 56,256.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Omah Lay àti Tems yóò tó darí padà sí Nàìjíríà 14 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 15 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Oríṣun àwòrán, Twitter / Bebe Cool / Odas Ijọba orilẹede Naijiria ti fi aridaju han pe awọn olorin ọmọ Naijria meji ti orilede Uganda fẹsun kan, Omah Lay ati Tems yoo to dari wale.
Wo àwọn ọ̀nà to fi leè ní owó lọ́wọ́ láti ipasẹ̀ iṣẹ́ amọ̀ Wòlíì Kasali ní Dolapo Awosika kò lé ìyàwó òun jáde Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Jude fi kun un pe ni kete ti Amcon ba ti gbeṣẹ le ohun ini kan, labẹ ofin, o ti di tita ni ori igba ni yẹn ni eyi ti wọn yoo fi ri owo tiru ẹni bẹẹ ba jẹ gba pada lẹyin tita irufẹ ohun ini bẹẹ.
Akitiyan lati kàn si awọn adari ẹgbẹ NURTW lo ja si pabo Nibi ti ikọ BBC Yoruba ti n ya aworan bi rukerudo yii ti n ṣẹlẹ, awọn ọlọpa kan ti ẹka amuṣẹya ileeṣẹ ọlọpaa nipinlẹ Eko gbiyanju, lati ja ohun eelo iyaworan wa gba, ki awọn lọgalọ́ga wọn kan to da sii.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ọsun Election 2018: Ilé isẹ́ ọlọ́pàá ti bẹ̀rẹ̀ ìmúrasílẹ̀ 17 Owewe 2018 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 21 Owewe 2018 Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ọsun Election 2018: Ilé isẹ́ ọlọ́pàá ti bẹ̀rẹ̀ ìmúrasílẹ̀ Ajọ ọlọpaa ko gbẹyin nibi igbaradi fun idibo si ipo gomina ni ipinlẹ Osun ti yoo waye ni Ọjọ Satide, Ọjọ Kejilelogun, Osu Kẹsan an, ọdun 2018.
Wọn kede pe Saere Mekonnen atawọn olori ikọ ogun mẹrin ti wọn kọkọ faragbọgbẹ ninu iṣẹlẹ naa ti doloogbe.
Àwọn akópa tó ti jáwé olúborí ní BBNaija sẹ́yìn àti ibi tí wọ́n wà báyìí Ọmọ Ọba Dubai yóò san owó ìtọ́jú ọmọ Nàìjíríà tó bí ìbẹrin sí Dubai tí kò sí rówó san Boko Haram da ìbọn bo ọkọ̀ gómìnà Borno, ẹ̀ṣọ́ àláàbò rẹ̀ farapa Ìjọba Oyo fẹ́ mọ ikú tó pa akẹ́kọ̀ọ́ UI níléeṣẹ́ tó ń ṣe ọṣẹ Aàre Donald Trump pàrọwà pé kí wọ́n sún ìdìbò Aàrẹ 2020 síwájú ní America Àwòkọ́ṣe ìwà ìrẹ̀lẹ̀, òtítọ́ àti olùfẹ́ mẹ̀kúnnù ni Ayo Fasanmi - Ìjọba Osun Ìjọba Osun àti ẹgbẹ́ Afenifere dárò ikú akínkanjú olóṣèlú tó kú Awọn eeyan ti n sedaro agba ilu, oloselu ati ọkan lara awọn asaaju ẹgbẹ Afẹnifẹre to papoda, Alagba Ayo Fasanmi.
"Kẹẹ si maa wo o, ni nkan bii ago mejila ọsan kọja iṣẹju mẹwaa ni IBB jade wa lati wa bẹrẹ si ni yọju si awọn alejo rẹ.
O sọ fun BBC Yoruba pé, yatọ si pe ẹgbẹ oṣelu oun ni okikii laarin ọmọ Naijiria, oun ni oludije kan ṣoṣọ to ti fi ẹsẹ ba ipinlẹ marundinlogoji ninu mẹrindinlogoji to wa ni Naijiria.
 Ẹwẹ, agbẹnusọ ileeṣẹ ọlọpaa ipinlẹ naa sọ fun BBC pe iwadii ti bẹrẹ lori iṣẹlẹ na."
Nítorí náà, mo dàbí kòkòrò ajẹnirun sí Efuraimu, ati bí ìdíbàjẹ́ sí Juda.
Ẹ jẹ́ kí á mọ̀ ọ́n, ẹ jẹ́ kí á tẹ̀síwájú kí á mọ OLUWA.
 pẹ ̀ lú òmíràn ìwári n lá irú bí tẹlefisan , ínà gílóbù àti kọmuputa .
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Olólùfẹ́ méjì jábọ́ láti àjà kẹsàn án lásìkò tí wọ́n n ṣe kerewà Ẹ wo ohun tó fàá tí àwọn òbí fi ń pa 340 ọmọ bíbí wọn lọ́dọọdún Ǹjẹ́ ewu wà nínú lílò ẹ̀rọ FaceApp?
Ẹ̀hìnkùnlé ni ọ̀tá wà, ilé ni aṣeni ń gbé, bí ikú ilé kò pa ni ti òde kò lè pa ni, ọmọ-ọ̀dọ̀ ní ń mọ àṣírí olúwa rẹ̀, obìnrin ẹni ní ń mọ àtisùn ẹni.
Olori eto idajọ nilẹ Amẹrika, Nick Hanna lo fidi ọrọ mu lẹ nigba to n ba awọn akọroyin sọrọ l'Ọjọbọ.
Baba Isiaka, Jimoh atanda ṣalaye pe gbogbo awọn lawọn fi ẹjẹ silẹ fun Isiaka ni ile iwosan fasiti Bowen ko to di pe ọlọjọ mu u lọ.
"Wọn ni ko pẹ to gba itọju ""Chemoteraphy"" tan nile iwosan nilẹ Gẹẹsi to fi pada wa sile."
Láyé òde òní gbogbo wa ni ònkọ̀wé níwọ̀n ara tiwa.
Èyí yà wá lẹ́nu ṣùgbọ́n kínni ọmọ ọdún mẹ́sǎn àti mọ́kànlá lè ṣe ju èyí tí a ti ṣe lọ!
Ni ọdun 2000 lo wa si Naijiria nigba to darapọpọ mọ Cool FM ti o si di ẹni ti ọpọ awọn ọmọ Naijiria ti wọn gbo redio gba tiẹ.
Àwọn ọmọ Nàìjíríà kan ń dá ẹ̀bi, òmíràn ń dárò, lórí bí ológun ṣe pa ọlọ́pàá mẹ́ta ‘Ẹyin ará Ondo, Eko, Ogun, Osun, Ọyo, ẹ gbàdúrà ò!
Nibayii ẹgbẹ agbabọọlu Juventus ti jawe olubori ninu gbogbo ifẹsẹwọnsẹ mẹrin ti wọn ti ninu idije liigi Serie A ti wọn ti gba lati igba ti Ronaldo ti darapọ mọ wọn.
nígbà tí orílẹ ̀ èdè nàìjíríà di olóm ̀ inira ní ọjọ ́ kìnní oṣù kẹ ́ wàá ọdún 1960 , awólọ ́ wọ ̀ di olórí ẹgbẹ ́ alátakò ( opposition leader ) sí ìjọba abubakar tafawa balewa àti Ààrẹ nnamdi azikiwe ní Ìlú Èkó .
Bí Ìjànbáforítì ti ṣe báyìí ni a déédéé gbọ́ agogo kan tí ó lù, kí á sì tóó ṣẹ́ ojú pẹ́ẹ́ àwọn ọlọ́pàá ejò wọn-ọnnì ti sá dé wọ́n bẹ̀rẹ̀ sí bu wá jẹ ṣùgbọ́n oró wọn kò ní ipá kan lórí wa nítorí oògùn tí a ti jẹ ní òwúrọ̀ ọjọ́ náà.
Iya Rainbow sọ akoba ti ayelujara n ṣe lasiko yii fawọn oṣere ati awọn alagbata pe ko jẹ ki iṣẹ ọhun fẹ pé mọ.
Gomina pasẹ yii lasiko to yọju sibi isele naa lati ba ẹbi awọn to
Awọn panapana de ibẹ ni bi i wakati mẹta lẹyin ti ọkọ naa ja lulẹ.
"Olorì àgbà mẹ́rin tó jẹ́ igi lẹ́yìn ọgbà fún Aláàfin Adeyemi A fura pé ejò lọ́wọ́ nínú ikú Tolu Arotile, ẹ ṣe ìwádìí ikú rẹ̀ - Afenifere, Gani Adams, Huriwa Ohun tí o kò mọ̀ nípa Ebila ""One Million Boys"" àti Ekugbemi, olórí ẹgbẹ́ òkùnkùn méjì tó da ìlú Ibadan rú Mo ti pinnu láti túṣu dé ìsàlẹ̀ ìkòkò lóríì ìdí tí kò sí ìdàgbàsókè ní Niger Delta - Buhari Ènìyàn 156 ló tún ṣẹ̀ṣẹ̀ lùgbàdì ààrùn Coronavirus ní ìpínlẹ̀ Eko Obinrin naa ti ṣegbeyawo ri, bo tilẹ jẹ pe Akpabio sọ lori ẹrọ tẹlifiṣọn kan pe ọkọ mẹrin lo ti ni sẹyin, ṣugbọn a ko lee fi idi ọrọ naa mulẹ."
Nígbà tí wọ́n dé ilẹ̀ Kenaani, 
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Dangote, jọ̀ọ́ nawọ́ ìrànwọ́ láti dá iléeṣé sílẹ̀ fún wa ní Ọyọ - Aláàfin rawọ́ ẹ̀bẹ̀ Ọ̀ṣun Òṣogbo 2019 bẹ̀rẹ̀, àwọn iléeṣẹ́ àdáni ń bèèrè fún ẹ̀rọ ìgbàlódé láti sàfihàn àjọ̀dún Ó tó gẹ́ẹ́!
Lai Mohammed lo soro yii fun awon akoroyin lẹyin ipade igbimo ijoba apapo ti igbakeji
 Minista wa rọ igbimo naa , ki won maa se ja  igbẹkẹle ti aare  Muhammadu Buhari ni ninu won kulẹ, ki won si je oloootọ ati olufọkansin ninu ojuse wọn.
Iroyin naa ni awọn osisẹ ọlọpaa yoku to wa lẹnu isẹ lo fara gba ọgbẹ ọta ibọn lorisirisi ninu ikọlu naa, eyi to ba wọn lojiji.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Tani Ọ̀jọ̀gbọ̀n Ayodele Awojobi, onímọ̀ ẹrọ tí o ní kí wọ́n wọgi lè ìbò Ààrẹ Nàìjíríà?
Bí àpẹẹrẹ, òfin igbeyawo de abilekọ níwọ̀n ìgbà tí ọkọ rẹ̀ wà láàyè.
A óo sì máa pè é ní àfonífojì Hamoni Gogu.
Ọjọgbọn Wasiu Adeyemo ni iṣẹ awọn Dokita ati Nọọsi ni lati tọju alsisan, nitori naa oun ko ri idi ti awọn ẹbi alaisan yoo fi maa reti lati sun ti ẹni to n gba itọju.
Lẹ́yìn tí Ọjọ́ Ìsinmi ti kọjá, Maria Magidaleni ati Maria ìyá Jakọbu ati Salomi ra òróró ìkunra, wọ́n fẹ́ lọ fi kun òkú Jesu.
Àwọn agbòfinro Ghana gbé Kwesi Nyantakyi
Ayé á pé òun ń bẹ lẹ́yìn rẹ
Ẹ̀jẹ̀ yóò sàn pẹ̀lú bí Amerika se pa Ọ̀gáagún wa - Iran Ọmọ Nàìjíríà ẹ ṣọ́ra fún ìrìn alẹ́ nítorí àwọn tó fẹ́ gbẹ̀san ikú Soleimani Wọ́n tẹ àádọ́ta olùdárò pa níbi ìsìnkú Qasem Soleimani tí kò wáyé mọ́ Soleimani Killing: Ẹgbẹ́ Shiites wọ́de l'Abuja, wọ́n jó Àsìá Amẹ́ríkà Titi di asiko yii ko tii si ẹni to le sọ boya iṣẹlẹ naa ni i ṣe pẹlu ọrọ ilẹ America ati ti Iran to n ja ranyinranyin nilẹ.
Bee si ni, o tun je iyalenu fun mi, nitori pe, mi o ti ri orile-ede ti won ti fesun kan alaisan ti ko le soro tabi ki o gba ara re la.
Èèyàn 179 ló tún ṣẹ̀ṣẹ̀ ní àrùn Coronavirus ní Nàìjíríà Ajọ to n gbogun ti ajakalẹ aarun lorilẹ-ede Naijiria, NCDC ti kede pe eeyan 179 miran ti darapọ mọ awọn to ti ni aarun COVID-19 ni Naijiria.
"Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Olùdíje gbé APC lọ sílé ẹjọ́ nítorí èsì ìbò Ilé aṣòfin kùnà láti ṣe ìpàdé pàjáwìrì tó pè Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Onídájọ́ Fọlahanmi Oloyede léwájú ìwọ́de òṣìṣẹ́fẹ̀yìntì fún ọjọ́ mẹ́ta l'Ọ́ṣun Onidajọ Ọladimeji ni lootọ iwe ti olupẹjọ gbe kalẹ niwaju ile ẹjọ naa ni ""ọpọlọpọ kotọ to lagbara gidigidi"" sibẹ ile ẹjọ ko lee doju rẹ kọ oorun alẹ lori didije fun ipo gomina."
Jakọbu rán Juda ṣáájú lọ sọ́dọ̀ Josẹfu pé kí Josẹfu wá pàdé òun ní Goṣeni, wọ́n sì wá sí ilẹ̀ Goṣeni.
Wọn tun ni ẹsun riran awọn eeyan lọ fun Umrah ni Mecca fun irinajo ẹsin naa tun jẹyọ.
Nígbà tí Solomoni parí adura rẹ̀, iná kan ṣẹ́ láti ọ̀run, ó jó gbogbo ẹbọ sísun ati ọrẹ, ògo OLUWA sì kún inú tẹmpili.
CCC Genesis Global: Ǹkan mẹ́wàá tí ẹ ò gbọ́ rí nípa Israel Oladele, Woli ìjọ Genesis Global Ṣé lóòtọ́ ni ìgbìmọ̀ olùwádìí dábàá kí Ààrẹ Buhari yọ alága EFCC, Ibrahim Magu nípò?
"O wa dupẹ pupọ lọwọ igbimọ alasẹ ile iwosan UCH fun abẹwo wọn, eyi to jọ oun loju lasiko Coronavirus yii.
Nígbà tí ó yá, OLUWA sọ fún Mose pé, “Ó ku ìyọnu kan péré, tí n óo mú bá Farao ati ilẹ̀ Ijipti, lẹ́yìn náà yóo jẹ́ kí ẹ lọ.
Ìwádìí BBC: Àwọn ará Èkìtì ń sáré gba N4,000 sáájú ìbò Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Àwọn èèyàn to n fẹ̀hónú hàn dáná ṣun iléeṣẹ́ MTN n‘Ibadan A ò ní fààyè gba pípa ọmọ Naijirià nípakúpa ní South Africa mọ- Abike Dabiri Irọ́ ni, mi ò sọ pé mọ fẹ di Ààrẹ ní 2023- Tunde Bakare Kíni àwọn ìpèníjà ẹtọ ààbò ṣáájú òmìnira Nàìjíríà?
Amọ, o ṣeni laanu pe, mi o le sọ ọrọ naa fun ẹnikẹni.
Owó ìràpadà wọn jẹ́ ìwọ̀n ṣekeli marun-un.
Iṣẹ́, ìṣe àti ọ̀nà rẹ kò ní di àwátì
- Kemi Afolabi Esi ti aṣoju ajọ naa kan fun pe yoo san ẹgbẹrun mẹta Naira lati fi gba omiran ti ọjọ ba ti pẹ lori ti tẹlẹ ko jẹ nnkan to dun mọ awọn eeyan ninu.
Ọlọ́pàá kọ́ lo pa olórí àwọn ''One Million Boys'' Ebila n'Ibadan- Ọ̀gá ọlọ́pàá Oyo Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
O ko gbọdọ ni arun kogboogun.
“Ẹ ranti òfin ati ìlànà tí mo ti fún Mose, iranṣẹ mi, fún gbogbo àwọn ọmọ Israẹli ní orí òkè Horebu.
Ẹ mọ nnkan to ṣẹlẹ , lori eleyii mi o ni ọrọ kankan lati sọ, ẹni ti ara rẹ ko ya, ẹ pe wọn, oun ti wọn ba ti sọ naa ni mo sọ"" 'Ẹ o lee fi tipatipa mu mi sọrọ abi ṣe ẹ le fi tipatipa mu mi sọrọ ni' Ogun Majek, òṣèré tíátà ní iléèwòsàn UCH lòun ti ń gba ìtọ́jú kí àrùn Coronavirus tó wọ̀lú Oríṣun àwòrán, Other Eekan oṣere tiata ati sinima lorilẹede Naijiria, Gbọlagade Akinpẹlu ti ọpọ mọ si Ogun Majek to wa ni idubulẹ aisan lọwọ bayii ti ṣalaye pe aisan oun ko ṣẹṣẹ bẹrẹ ati pe ọpọlọpọ asiko loun lo ni ileewosan nla UCH nibi ti oun ti n gba itọju."
Oríṣun àwòrán, Getty Images Ibanujẹ ti Biden ni: Lọdun 1972, laipẹ to kọkọ wọle gẹgẹ bi sẹnetọ, ni iyawo rẹ, Neila ati ọmọ rẹ ikoko l'obinrin, kú ninu ijamba ọkọ.
Sotitobire: Alfa Babatunde Sotitobire yóò tún fojú balé ẹjọ́ lọ́jọ́ Ajé tó ń bọ̀ Alfa Babatunde Sotitobire tún fojú balé ẹjọ́ lọ́nìí, ni itẹsiwaju igbẹjọ rẹ niwaju ile ẹjọ giga ni ilu Akurẹ lori sun igbimpọ lati ji mọ gbe.
Lẹyin ọsẹ mẹta ti arakunrin Boboly gba isẹ, a ma a lo pa ẹja laarin aago kan si aago mẹta ki o le ri owo fi ransẹ si ile.
Idije onipele meji ohun ni yoo mu iko agbaboolu Etoile du Sahel wa gba ifigagbaga keji nilu Jos, lati mo iko ti yoo pegede sinu ipele ti o kan ninu idije naa.
Ẹni mẹ́ta wọ gbaga ọlọpàá nítori ajílẹ̀ tí wọ́n kó tà ní ọja Daleko ní Mushin
Ọ̀pọ̀lọpọ̀ dúkìá ṣòfò lásìkò ìfẹ̀họ́nú hàn nítorí ìṣèkúpani George Floyd Awọn ọlọpaa ati awọn afẹhọnu han ti gbena woju ara wọn lorilẹede Amerika lori iṣekupani Geaorge Floyd gba ọwọ ọlọpaa Minnesota.
Ewe, ni kete ti eto ipese iwosan ofe ohun pari, adele gomina ohun, ojogbon Esu ati igbakeji gomina ipinle Ebonyi, ogbeni Eric Igwe pelu apapo awon agbaagba agbegbe ohun ti o fi mo awon oloselu lo jo jiroro bi igbe-aye alafia yoo se joba lagbegbe naa.
Naijiria: Igbakeji aarẹ fẹ s'eyawo ọmọ rẹ Ọmọ tuntun gba ominira lẹyin ti wọn san owo itọju rẹ ni Gabon Agbenusọ fun ajọ naa, Josiah Emerole nigba to n ba BBC sọrọ wipe, iwadi ajọ naa bẹrẹ losu meji sẹhin, lẹyin ti ọwọ sinkun ọlọpa mu obinrin kan ti wọn fẹsun kan wipe o ji ọmọ ọse kan gbe, lati ilu Abuja lọ sipinlẹ Niger, lorilẹede Naijiria.
"Ipinlẹ Ọsun n se aisan, ko si daju pw gomina yoo lee ri owo osu tuntun san.
Ṣugbọn ni eero Bello Taoheed Ọlawale Orukọ tuntun yii naa rẹwa."
ó sì rú ẹbọ sísun ati ẹbọ ohun jíjẹ lórí rẹ̀.
Ohun ìkọsẹ̀ ni o jẹ́ fún mi, nítorí o kò ro nǹkan ti Ọlọrun, ti eniyan ni ò ń rò.
Wo àwárí akọ́ṣẹ́mọṣẹ́ yìí Ẹwẹ, agbẹjọro kan to fi ilu Eko sẹbugbe, Ọgbẹni Malcolm Omirhobo, ti gbe ijọba lọ si ileejọ lori bi o ti tako eto ẹsọ alaabo Amọtẹkun.
Bí bàntẹ́ tí parí orin rè ni àwọn òbí ọmọdé yìí náà fò sánlẹ̀ tí wọ́n kú.
Atẹjade kan lati ileeṣẹ aarẹ ni ọmọ ọdun méjílélọ́gọ́rin naa to ti wa lori oye fun ogun ọdun yoo ri wi pe itẹsiwaju ba eto ijọba ki o to fiṣẹ silẹ.
Iwe iroyin Times ni won wa leni use iwadii ejo re yii lati nkan bii osu melo seyin.
Iye ìgbà tí Sani Abacha tí fi owó ransẹ si Nàìjíríà láti ọrun Pásìtọ̀ ìjọ Sotitobire Alfa Babatunde ti wà nílé ẹjọ báyìí ní ìtẹ̀síwájú ìgbẹ́jọ́ rẹ̀ Ṣé lóòtọ́ ni òjòjò dá Abiola Ajimobi wólẹ̀?
Ṣugbọn lọjọ kẹtalelogun, oṣu Kejila ọdun yii ni ile ẹjọ to wa ni Oke Eda nilu Akure paṣẹ pe ki wọn fi pasitọ ọhun si ọgba ẹwọn Olokuta nilu Akure, ki igbẹjọ rẹ to tẹsiwaju.
Ní ọjọ́ náà, ẹ óo bèèrè nǹkan ní orúkọ mi, n kò ní wí fun yín pé èmi yóo ba yín bẹ Baba.
Ami ayo mẹfa sodo ni Chelsea jẹ lọwọ Man City nigba ti wọn koju ara wọn kẹyin ni papa iṣere Etihad.
Ṣé ojúlówó ni Oogùn apakòkòrò 'Sanitizer' tó ń lò?
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Àwọn aláboyún f'ẹ̀hónú hàn lórí owó ìgbẹ̀bí ní ìpínlẹ̀ Òǹdó Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àwọn aláboyún f'ẹ̀hónú hàn lórí owó ìgbẹ̀bí ní ìpínlẹ̀ Òǹdó 9 Ìgbé 2018 O kere tan, o to ọgọrun aboyun to rọ lọ si Ile-iwosan Alamọja ti ijọba ipinle Ondo nilu Akure ni Ojobo lati fẹhonu han lori awọn idiyele giga fun awọn itọju ati igbẹbi fun alaboyun ni ile iwosan naa.
Ǹjẹ́ fún ìdàgbàsókè àṣà ilẹ̀ China ni gbogbo ọ̀nà yìí tàbí àmì ìpàdánù ìgbẹ́kẹ̀lé àṣà ìbílẹ̀ ẹni?
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Widows Day 2019: Mo máa ń sá kiri wá owó ilé ni -Opó Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Widows Day 2019: Mo máa ń sá kiri wá owó ilé ni -Opó 23 Òkùdu 2019 Bá mi po ògì ní iṣẹ́ t'ọkọ mi rán mi gbẹ̀yìn -Funmi Babayẹmi Opó ni obinrin tabi ọkunrin ti o padanu ọkọ tabi aya rẹ ni awujọ Yorùba.
Àwọn òǹlo Weibo kan ti pín ìkìlọ̀ ilé-ìwé ti a fún akẹ́kọ̀ọ́.
Dìde, tan ìmọ́lẹ̀; nítorí ìmọ́lẹ̀ rẹ ti dé,ògo OLUWA sì ti tàn sára rẹ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Nnamdi Kanu sọrọ lórí àwọn oludije PDP àti APC Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Nnamdi Kanu sọrọ lórí àwọn oludije PDP àti APC 14 Èrèlè 2019 Kanu ṣalaye lori ọna ti oun gba bọ́ mọ́ àwọn ologun lọwọ nitori pe alejo kàn loju lagbari ni, wọn ko lè fi riran to ọmọ onilẹ.
 gbogbo àwọn àjẹsára hib tí à ń lò báyìí jẹ ́ àjẹsára aláàsopọ ̀ .
Wọn ko ni iṣẹ meji ti wọn n ṣe ju iyẹn lọ.
Abenugan ile igbimo asofin Yakubu Dogara ti ba awon ti iji lile kolu lojo Abameta ,ni ipinle Bauchi kedun .
Láti ọmọ ọdún márùn-ún ni Samuel ti ń kopa ninu ere tíátà, tó sì ti jáde nílé ẹ̀kọ́ Fáṣítì Obafemi Awolowo n'ilu Ilé Ìfẹ́ báyìí.
“Àwọn mejeeji yóo di ara kan.
31 Nitori, kíyèsíi, wọn kì yíò ṣe àṣeyọrí awọn ète ibi wọn ní pípa irọ́ lòdì sí àwọn ọ̀rọ wọ̃nnì.
“Èmi ni Alfa ati Omega, ìbẹ̀rẹ̀ ati òpin.
"Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Samuel Ladoke Akintọla jẹ́ Agbẹjọ́rò àti Akọ̀ròyìn tí ọ̀rọ̀ dá lẹ́nu rẹ̀ Hubert Ogunde rèé, baba àwọn òsèré tíátà Ìyàtọ̀ wà nínú ìlépa àwọn òṣèré tíátà ayé àtijọ́ àti ìsisìnyí-Papalolo N kò mọ bí wọ́n ṣe n bá obìnrin sọ̀rọ̀ ìfẹ́ - Aláàfin Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Kékeré ni mo ti mọ̀ pé iṣẹ́ apanilẹ́ẹ̀rín l'ọ̀nà mi' ""Emi kii se Ọlọrun."
Nítorí náà, ìrètí ń bẹ fún talaka,a sì pa eniyan burúkú lẹ́nu mọ́.
Bo tilẹ jẹ pe wọn wa ni idaṣẹṣilẹ, Jimoh sọ pe awọn dokita ọhun ṣi n ṣetọju awọn to ni arun Covid-19.
Ẹni ti o fẹ gbudọ mọ iru iṣẹ ti o n ṣe ati bi o ṣe lee ṣamojuto awọn to jẹ onibara rẹ daadaa.
2 bílíọnù fi tún wáyà iná àti inú ilé Aso Rock ṣe- Buhari Mọ̀ sí i nípa díẹ̀ lára àwọn èèyàn tí ikú wọn 'láti ọwọ́ ọlọ́pàá' milẹ̀ tìtì ní Nàìjíríà Ìbò aráàlú pẹ̀lú ẹ̀yà yókù lá fi yanjú àtúntò Nàíjíríà - YCE Ilé alájà mẹ́ta wó pa èèyan méje, èèyàn 20 farapa ní Obalende, Eko Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ondo election 2020: Àwọn ara ìpínlẹ̀ Ondo ránṣẹ́ sí Akeredolu ohun ti wọ́n ń retí ní báyìí Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Ìwájú ni irúfẹ́ wa fi ń gbọta, àwa kìí ṣojo ní ìran wa rárá.
Ṣugbọn Maria ń ṣe akiyesi gbogbo ọ̀rọ̀ wọnyi, ó ń dà wọ́n rò ní ọkàn rẹ̀.
Lojoojumọ, ni kí ẹ máa fún àwọn alufaa tí wọ́n wà ní Jerusalẹmu ní iye akọ mààlúù, àgbò, aguntan pẹlu ìwọ̀n ọkà, iyọ̀, ọtí waini ati òróró olifi, tí wọn bá bèèrè fún ẹbọ sísun sí Ọlọrun ọ̀run.
Ijọba sapejuwe iwa to hu gẹgẹ bi nkan itiju, idojuti, to si tun tako awọn amuyẹ ti ofin ipinlẹ naa la kalẹ fun awọn ọba ati ijoye.
Wọn jọ fẹnukò pe Mileva naa yoo gba ninu owọ naa tẹle.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Itan Ilu gangan Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Ẹnìkankan ninu yín kò wí pé, ‘Níbo ni ò ń lọ?
Àjọ àwọn oniṣegun fun iṣẹ abẹ atunṣe agọ ara nilẹ Gẹẹsi, British Association of Aesthetic Plastic Surgeons (Baaps) ti fi ikede sita pẹ ki awọn obinrin ṣọra fun iṣẹ abẹ ikebe nla nitori pe o léwu pupọ.
 Aaare fi edun okan re han si awon ebi ati ore oloogbe naa.
Olateru-Olagbegi II: àkàndá ẹ̀dá tó jọba ní ẹ̀ẹ̀méjì láàrín ọdún márùndínlọ́gbọ̀n síra wọn.
Nipasẹ awọn olori ilu la fi ba awọn ara ilu sọrọ, a si pẹtu si awọn ero naa l'ọkan.
Ìṣípayá ọ̀rọ̀ rẹ a máa fúnni ní ìmọ́lẹ̀,a sì máa fi òye fún àwọn onírẹ̀lẹ̀.
O ni lati fi iwe ẹri yi pamọ daada ki o ba le fi han asiko to ba fẹ gba iwe ẹri nọmba NIN rẹ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Africa Eye: Wo ìtàn ìyá kan ìyá kan àtàwọn olè ajọ́mọgbé tó n ta ọmọ ní Kenya Bi o ti ṣe lè mọ ti kaadi Nimc rẹ bá ti ṣetán fún gbígba?
Rògbòdìyàn bẹ́ sílẹ̀ láàrin àwọn ọlọ́kadà àti àwọn òṣìṣẹ́ ọgbà ẹ̀wọ̀n ní Ibadan Wo àwọn oúnjẹ márùn ún tó ń mú kí àtọ̀ ọkùnrin dára síi ‘Sim Card’ títà àti ìforúkọsílẹ̀ rẹ̀ dèèwọ̀ ní Nàíjíríà - NCC Oyedepo ni: ''O sọ fun mi pe bi Oun ṣe maa n ṣi ferese ọrun si awọn eeyan naa ni Oun maa ṣi ferese ọrun sori ileeṣẹ.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ṣé adájọ́ àgbà Onnoghen yóò farahàn nílé ẹjọ́?
”Jehu dá a lóhùn pé, “Kí ni o ní ṣe pẹlu alaafia?
Won bi Temitope si agboole Efungade-Onigbodogi, Alafara Oje niluu Ibadan.
Ìlúkílùú tí ẹ bá wọ̀, tí wọn bá gbà yín, ẹ máa jẹ ohun tí wọn bá gbé kalẹ̀ níwájú yín.
 a maa nfi iru si ọbẹ lati fi jẹ ki oni adun ati orun daadaa .
Lara rẹ ni koo lo tabili giga koo baa le na duro lawọn ọjọ kọọkan, jokoo lawọn ọjọ mii.
Ọkan ninu Algeria tabi Ivory Coast ni wọn yoo ba pade ninu ifẹsẹwọnsẹ ti yoo waye lọjọ kẹrinla oṣu yii.
Ifesewonse Naijiria ati Poland yoo waye ni papa isere Wroclaw lojo ketalelogun osu keta odun ti a wa yii.
Ṣugbọn ko pẹ ti iwọde naa bẹrẹ ni awọn ọlọpaa bẹrẹ si ni wọ iya ija pẹlu àwọn to n ṣe iwọde ọhun, ti wọn si da afẹfẹ tajutaju si agbegbe ti iwọde naa ti n waye.
igbakeji oga agba olopaa, tuko awon olopaa sipinle naa lati lo fowo sikun mu afurasi
Yàtọ̀ sí ẹ̀rọ-ìgbálẹ̀ alátìká, Roomba yìí máa nfúnrarẹ̀ gbálẹ̀ láì sí ìrànlọ́wọ́ enìkankan ni.
Jegede ni agbẹ lo to ida to le ni aadọrin awọn ara Ondo nitorinaa iṣejọba oun yoo ran awọn agbẹ lọwọ lorii eso fun irugbin atawọn nkan to le ṣe moriya fun wọn.
Ìyá Leah Sharibu ké gbàjarè sí ìjọba Buhari ‘Bí ẹ se gba Zainab sílẹ̀, ẹ gba Leah Sharibu lọ́wọ́ Boko Haram’ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Boko Haram yóò dá Leah sílé Gẹgẹ bi ẹni se jẹ ọjọ ibi rẹ, awọn eniyan pejọ si ile ijọsin lati se ẹsin ọjọ ibi fun ọmọ naa to duro sinsin lori igbagbọ rẹ.
Jesu sọ fún wọn pé, “Mo fẹ́ kí ẹ mọ̀ dájúdájú pé, nígbà tí ó bá di àkókò àtúndá ayé, tí Ọmọ-Eniyan bá jókòó lórí ìtẹ́ ìgúnwà rẹ̀, ẹ̀yin náà tí ẹ tẹ̀lé mi yóo jókòó lórí ìtẹ́ mejila, ẹ óo máa ṣe ìdájọ́ lórí ẹ̀yà Israẹli mejila.
Iṣẹ́ rẹ ni ko ṣe àwari àjòjì náà, kí ó si pa.
Awọn araalu naa pejọ pọ, ti wọn si dana sun mẹrin ninu awọn adigunjale naa, ti awọn meji si wa ni panpẹ ọlọpaa.
mi sori aleefa yii je ohun ti o buyi kun mi pupo, bee si ni atileyin ile Afrika
O ni ni kete ti gbogbo eto ba ti to ni ẹbi a fi to Naijiria leti ti Baba yoo si fi ara rẹ lélẹ̀ ni itẹ́ ikẹyin.
Kí á má ṣe gbúròó ìwà àgbèrè, tabi oríṣìíríṣìí ìṣekúṣe, tabi ojúkòkòrò láàrin àwọn eniyan Ọlọrun.
Ẹbọ ohun mímu rẹ̀ yóo máa jẹ́ idamẹrin òṣùnwọ̀n hini fún ọ̀dọ́ aguntan kan.
ileri wa  yooku wa si imusẹ .
Lẹ́yìn tí ó ti gbààwẹ̀ tọ̀sán-tòru fún ogoji ọjọ́, ebi wá ń pa á.
Láti èjìká rẹ̀ sókè ni ó fi ga ju ẹnikẹ́ni ninu àwọn ọmọ Israẹli lọ, ó sì lẹ́wà ju ẹnikẹ́ni ninu wọn lọ.
" Àwọn ìbéèrè tí Tinubu bi gómìnà Sanwo-Olu àtàwọn olùwọ́de tó faragbọta ní Lekki Tollgate rèé Oríṣun àwòrán, Punch newspapers Agba ẹgbẹ oṣelu APC lorilẹede Naijiria, Bola Ahmed Tinubu ni oun ti beere lọwọ gomina ipinlẹ Eko boya oun lo fun awọn ṣọja to yinbọn ni agbegbe Lekki lalẹ ọjọ Iṣẹgun lasẹ lati yin si awọn oluwọde nibẹ.
OLUWA ní, “Ìwọ ọmọ eniyan, fi àsọtẹ́lẹ̀ bá àwọn òkè Israẹli wí.
Koda, wọn yoo tun mu ẹbun eroja ounjẹ lọwọ fun ọba gẹgẹ bii ẹbun ọdun.
Lara rẹ ni pe gbogbo ẹni ba ti n jẹ ọba lo gbọdọ jẹ ẹdọ tabi ọkan eeyan ki o to jọba?
Ọlọrun mi, mo mọ̀ pé ò máa yẹ ọkàn wò, o sì ní inú dídùn sí òtítọ́; tọkàntọkàn mi ni mo fi mú gbogbo nǹkan wọnyi wá fún ọ, mo sì ti rí i bí àwọn eniyan rẹ ti fi tọkàntọkàn ati inú dídùn mú ọrẹ wọn wá fún ọ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Sickle Cell In Nigeria: Makinde ní ìgbàgbọ́ ninú ìdílé òun ṣèdíwọ́ láti ṣàyẹ̀wò ẹ̀jẹ̀ Ajọ to n risi ọrọ awọn ogo wẹẹre lagbaye, UNICEF ninu atẹjade sọ wi pe o kere miliọnu mẹrin o le ni awọn ọmọde ti aisan otutu aya n da ẹmi wọn legbodo ni Naijiria.
Adajọ Akintoye ni ki wọn yẹgi fun Joel.
Wo ọkùnrin ẹni ọdún 55 tí wọ́n ká agbárí èèyàn mẹ́rin, àti àwọn ẹ̀yà ara mìí mọ́ lọ́wọ́ ní Ogun Gbọ́yì-sọ̀yí àti ìròyìn èké láti ọ̀dọ̀ àwọn olólùfẹ́ wa ló ṣáábà ma ń da ìgbéyàwó àwọn òṣèré rú- Ọpẹ Ayeola Ǹkan tí ó yẹ ki o mọ̀ nípa Burna Boy Ilé ẹjọ́ dájọ́ ẹgba mẹ́ẹ̀dóògún fún ọ̀daràn tó jí Iphone ní Kaduna Ọlọ́pàá tó dúró yìí gbá mi létí lẹ́ẹ̀mẹrin-Ajẹ́rìí ìwà ipá níwájú ìgbìmọ̀ SARS Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Kegel: Eré ìdárayá tí àwọn onímọ̀ sọ pé ó n fikún adùn ìbálòpọ̀ fún obìnrin, tó tún n fún ọkùnrin ní agbára24 Bélú 2020 10:17 Fídíò, Oba Adedokun Abolarin ti Oke Ila: Ó ya ọ̀pọ̀ tó súnmọ́ mi lẹ́nu bí mo ṣe ń kọ́ àwọn akẹ́kọ̀ọ́ pẹ̀lú ipò Ọba, Duration 10,1723 Bélú 2020 Ooni of Ife: Àwòrán ọmọ mi kọ́ lẹ ń rí lórí ayélujára o, ọmọ ọ mi ń ṣètùtù lọ́wọ́- Ọba Adeyeye Ogunwusi24 Bélú 2020 Ọwọ́ ọlọ́pàá tẹ àwọn méji tó jẹ ẹran ara ọlọ́pàá tí wọ́n pa n'Ibadan24 Bélú 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Ìkòkò ọtí ti kún àkúnwọ́sílẹ̀,nítorí ìkà wọ́n pọ̀.
Oríṣun àwòrán, Bashir Ahmed Àkọlé àwòrán, Aworan lati ibi ipade igbimọ oludari ẹgbẹ oṣelu APC to waye lọjọ kẹẹdọgbọn, oṣu Kẹfa, ori ayelujara si ni awọn kan ti ko pa Ṣe ilaja laarin awọn ọmọ ẹgbẹ to n binu Ọkan lara ipenija to wa nilẹ fun awọn olori ẹgẹ naa lasiko yii ni lati pari ija to wa laarin awọn ọmọ ẹgbẹ, ki ọrs to de ile ẹjọ.
anfaani naa lati dupe lowo Olorun pe o da ẹmi aare Buhari si, o tun wa ki awon
 Ó yẹ kí a fagi lé àwọn àkóràn tí ó lewu bíi àwọn èyí tí ó n ran egungun tàbí èyí tó ń ran awọ ara fẹ ́ lẹ ́ fẹ ́ lẹ ́ .
Nígbà tí wọ́n gbọ́, wọ́n fi ògo fún Ọlọrun.
Ó dúró lẹ́yìn ògiri ilé wa,ó ń yọjú lójú fèrèsé,ó ń yọjú níbi fèrèsé kékeré tí ó wà lókè.
Àwọn tó bá n lo iphone 4 àti àwọn Android tó ti pẹ́, náà ko ni le lo WhatsApp dáada mọ́, tó bá ti di ọdún 2021.
Ipinlẹ Eko lo ṣiwaju pẹlu mọkanlelaadoje.
 Ó tún gba àmì silver medal níńu 200 metres níbi ìdíje 1993 african championships òun nìkan sì ni ọmọ ilẹ ̀ nàìjírí ̀ a tí ó t ́ iì gba irúfẹ ́ àmì ẹ ̀ yẹ yìí ńińu irú ìfẹsẹ ̀ -wọnsẹ ̀ yí ní ọdún 1993 àti 1994 .
Mo mọ ibi tí ò ń gbé, ibẹ̀ ni Satani tẹ́ ìtẹ́ rẹ̀ sí.
” Joabu bá kọ́ ọ ní ohun tí yóo wí.
Loju opo Twitter rẹ lo ti fi ọrọ yii lede lọjọ Aiku, ọjọ kẹẹdogun oṣu kọkanla ọdun 2020 yii.
Ó jẹ́ kí á gbé àmì agbára rẹ̀ lọ sí ìgbèkùn;ó sì fi ògo rẹ̀ lé ọ̀tá lọ́wọ́.
Awọn mejeeji jọ maa n lọ sode daada, ti wọn yoo dijọ fẹsẹ ra ijo, ti awọn ayaba kekeke to ba si wa nibẹ, yoo lọ wa ibi joko si, wọn a ni ọlọkọ lo n lo ọkọ rẹ.
Inú òkun ni gbogbo odò tí ń ṣàn ń lọ, ṣugbọn òkun kò kún.
Sala omọ orilẹ-ede Argentina ọhun, to jẹ ẹni ọdun mejidinlọgbọn, ati
Mo bá rí àwọn ọkunrin mẹfa kan tí wọn ń bọ̀ láti ẹnu ọ̀nà òkè tí ó kọjú sí ìhà àríwá.
Mallam yii ṣalaye fun BBC pé aigbọraẹniye lo n yọ awọn eniyan lẹnu lori kiko owo ti ko daa mọ nilẹ.
Gomina Abdul Aziz Yari lati ipinlẹ Zamfara lo ju awà silẹ lẹyin to ti tukọ ajọ naa lẹẹmeji laarin ọdun mẹrin Gomina ipinlẹ Sokoto, Aminu Tambuwal ni igbakeji fun Fayemi ninu ajọ awón gomina lorilẹ-ede Naijiria.
Ọ̀lọ́pàá - BBC News Yorùbá BBC News, YorùbáFò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ondo Election 2020:Lóòtọ́ làwọn tọ́ọ̀gì APC kọlu PDP ní Oba Akoko, ìwádìí ti bẹ̀rẹ̀ - Ọ̀lọ́pàá 7 Owewe 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 4 Ọ̀wàrà 2020 Oríṣun àwòrán, Rotimi Akeredolu Facebook Ileeṣẹ ọlọpaa ni ipinlẹ Ondo ti ṣalaye pe lootọ lawọn janduku lẹyin ẹgbẹ oṣelu APC atawọn ti PDP kọlu ara wọn ni Ọjọru ni ilu Ọba Akoko ṣugbọn iwadii ti bẹrẹ lati mọ ohun pato to fa wahala naa.
Osun Elections: Gboyega Oyetola borí Adeleke n'ílé ẹjọ́ kòtẹ́milọ́rùn Àkọlé àwòrán, Gboyega Oyetola Ile ẹjọ kotẹmilọrun to gbọ ẹjọ nipa fa ki fa a to waye lasiko idibo gomina ipinlẹ̀ Ọṣun ninu oṣu kẹsan ọdun 2018 ti kede Gboyega Oyetola gẹgẹ bi ẹni to jawe olubori.
Ọdun mẹrin ti kọja, gbogbo agbaye tun ti n wo bi awọn olootu ijọba se n s'iwadi lori isẹlẹ Daphchi, ti awọn obi si n ke roro lori bii ijọba o se kọbi ara si isẹlẹ naa.
Àgbàrá òjò lé ará ìlú kúrò nílé ní Ìpínlẹ̀ Ogun Bakan náà, ojo to rọ ni Ipinlẹ Ogun ni ọjọ́ Iṣẹgun ti fa agbara ati omiyale to le ọgọrọ awọn ara ilu kuro nile ni Akute.
Ẹwẹ, ni ọpọlọpọ igba, eyi ẹgbọn Kunle a da ara rẹ yọ sọtọ pe ohun kọ o, aburo oun lo sọrọ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù World Malaria Day:Kí gaan láwọn nkán tó n fa àìsàn ibà?
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Bill Clinton ni aarẹ ikẹyin ti wọn buwọlu aba lati yọ nipo Aarẹ meji ni awọn ọmọ ile aṣofin ti buwọlu aba pe ki wọn yọ nipo ninu itan Amẹrika.
Ìdílé Horatio Olunloyo, tíì ṣe ẹlẹsin Kristẹni ati Alhaja Bintu Tejumola Abebi Olunloyo, tíì ṣe musulumi ni wọn bí Omololu sì àmọ́ tó yàn ẹṣin Kristẹni láàyò ni ìlànà baba rẹ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Soyinka: Ohun gbogbo ti dẹnu kọlẹ̀ la ṣe gbọdọ̀ gbé ìgbésẹ̀ pàjáwìrì 9 Ògún 2019 Oríṣun àwòrán, @Opetuyii Yoruba ni agba ti ko ba kẹun sọrọ, yoo kẹ itan sare nitori agba kii wa lọja, ki ori ọmọ tuntun wọ.
Oríṣun àwòrán, dagrin fimilejo/facebook Nigba aye rẹ, orukọ Dagrin lori Twitter ni @Dagrinfimile, o si n lo Dagrin fimilejo lori Facebook.
N óo yan ibìkan fún Israẹli, àwọn eniyan mi, n óo sì fìdí wọn múlẹ̀ níbẹ̀.
 Oríṣun àwòrán, Arewa_ilorin_pple Tá bá fi rí ọ̀sẹ̀ díẹ̀ si, èmi àti aya mi yóò tún yìgì so - Ọkọ Risikat olójú búlúù Arakunrin Abdulwasiu Ọlọmọyọyọ, tii se ọkọ Risikatu Azeez, arabinrin oloju buluu nilu Ilorin, ti fi idunnu ati ayọ rẹ han fun awọn ọmọ naijiria lori aayan ti wọn ko lati jẹ ki ija to wa laarin oun ati iyawo rẹ pari."
 Àjọ Ìlera Àgbáyé gba ni níyànjú pé kí gbogbo ọmọdé má a gba àjẹsára àrùn rọpárọsẹ ̀ .
"Bandile ni, ""Tí a ba yọ wiigi (wig) ti a wọ si ori ni ibi iṣẹ, ẹ o ri wipe, mẹjọ ninu mẹwa lori wa ti pa."
Àwọn àkọ́lé ìròyìn mẹ́ta tó leè tẹ̀lẹ́ ìdìbò Ààrẹ ilẹ̀ Amẹrika US Election 2020: Nígbà wo laó mọ èsì ìdìbò àti pé ṣé ó ṣeé figagbága?
Nítorí náà, ẹni tí ó ń ṣe ìtọ́jú ààfin ati olórí ìlú pẹlu àwọn àgbààgbà ati àwọn olùtọ́jú àwọn ọmọ Ahabu ranṣẹ sí Jehu, wọ́n ní: “Iranṣẹ rẹ ni wá, a sì ti ṣetán láti ṣe ohunkohun tí o bá pa láṣẹ.
Ṣugbọn, ko si iku ti yoo pa agba, tao ni ba poolo ori rẹ nibẹ ni Marichka fi ọrọ 'itiju' naa ṣe.
O wa rọ ijọba lati tete wa wọrọkọ fi ṣada, ki ara ma ba ni ara ilu.
Eyi ko ṣẹyin níwọ̀n ìgbà tó jẹ́ pé ọdún mẹ́ta ni ètò náà yóò fi kọ́kọ́ wà.
Àwọn ènìyàn wa sì wá, mò pé oorun ìfẹ́ ni mo wa ń sùn ní tèmi, wọ́n dá mi ní inú dùn, wọ́n ní, ‘Àlá rẹ dára, Ìrìnkèrindò, àlá rẹ dára, ẹ o fẹ́ ara yín’.
Eyi kò fi ọgbọ́n han nitori ìyà ti ó njẹ ará ilú Nigeria kọjá ki wọn ma sowọ́pọ̀ pẹ̀lú Olóri Òṣèlú Nigeria, Muhammadu Buhari lati ṣe àyipadà kúrò ni iwà ibàjẹ́ ti ó ba ilú jẹ, ki ilú lè tòrò, ki ó si lè pèsè oúnjẹ àti ohun amáyédẹrùn fún ará ilú.
OLUWA ní, “Nítorí náà, n óo sọ Samaria di àlàpà ní ilẹ̀ tí ó tẹ́jú, yóo di ọgbà ìgbin àjàrà sí; gbogbo òkúta tí a fi kọ́ ọ ni n óo fọ́nká, sinu àfonífojì, ìpìlẹ̀ rẹ̀ yóo sì hàn síta.
Eyi ko si sẹyin bi awọn ọkọ ninu idile se n gbe igbesẹ lati se ayẹwo awọn ọmọ wọn boya wọn jẹ ojulowo ọmọ ọkọ abi ọmọ ale.
Hẹrọdu wá tún fi ti Johanu tí ó sọ sẹ́wọ̀n kún gbogbo ìwà burúkú rẹ̀.
Nigba to n sọrọ lori ifilọlẹ ikọ Amọtẹkun o ni ohun taa nilo ni Amotekun jẹ lati fi kun akitiyan awọn ọlọpaa to ti wa latọjọ yii.
Ṣé yóo bẹ̀ ọ́,tabi kí ó fi pẹ̀lẹ́pẹ̀lẹ́ bá ọ sọ̀rọ̀?
Lẹyin iyọnipo rẹ, wọngbe ọpa aṣẹ fun Aminu Ado Bayero gẹgẹ bi Emir tuntun ilu Kano.
"Afurasí Alárun Coronavirus kejì ní Nàíjíríà tún rí ìwòsàn ""N kò kọ̀ kí ń kú, ìfẹ́ tí mo ní sí Buhari ni mo ṣe sáré dì mọ"" Nínú ayéyé tó n lọ lọ́wọ́ orísi ipele àmi ẹyẹ ni yóò wáye níbẹ̀."
Yatọ si pe ọmọge yi n ja wọn kulẹ lai jẹ hoo fun wọn, se ni yoo tun maa sọ ọrọ alufansa, ọrọ kobakungbe si wọn lasiko ti wọn ba dẹnu ifẹ kọọ, eyi to mu ki gbogbo wọn tete maa ba ẹsẹ wọn sọrọ nitori wọn ko lee farada eebu to n bu wọn yii.
Ni ọdun 1995 ti anfani ṣi silẹ fun awọn ọmọ ilẹ agbaye miran lati gbaa ni weah gba ami ẹyẹ yii, nigba ti o n gba bọọlu jẹun ni ẹgbẹ agbabọọlu AC Millan Awọn agbabọọlu wo lo tii gbaa julọ?
Ọkan lara awọn oṣiṣẹ eleto idibo naa ni awọn kan kuna lati ka ibo naa nitori aimọ iṣẹ ṣe wọn.
Awọn alaṣẹ ajọ to n mojuto igbokegbodo ọkọ oju omi nipinlẹ Eko, LASWA atawọn ajọ miran la gbs pe wọn pawọ pọ ṣe bẹbẹ ni kete ti ijamba naa ṣẹlẹ lati doola awọn to wa ninu ọkọ naa.
m , leyin ti awon oluwoko ninu baalu yi bere ija pelu awon afipagboko .
Nítorí náà Hẹrọdiasi ní Johanu sinu, ó fẹ́ pa á, ṣugbọn kò lè pa á, 
Lero tawọn eeyan kan, ohun ti Akpan ba lọ si Aso Rock kọ lo kọju mọ, kaka ko si maa bẹ Buhari pe ko dahun awọn ibeere tawọn olukọ fasiti n beere lọwọ ijọba, ọrọ oselu lo mojuto.
Shoprite leaving Nigeria: Ṣé òótọ́ ni pé Tayo Amusan ni yóò gba ìṣàkóso ilé ìtajà Shoprite?
nítorí àánú rẹ, o kò kọ̀ wọ́n sílẹ̀ sinu aṣálẹ̀.
Ó ti gbẹ̀san ẹ̀jẹ̀ àwọn iranṣẹ rẹ̀ lára rẹ̀.
Olórí ẹ̀yà Sebuluni sì ni Eliabu ọmọ Heloni.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Laduntan Oyekanmi di ìyálóde tuntun fún ilẹ̀ Ibadan Ìtàn tó wà nídi òwe ‘Sebótimọ Ẹlẹ́wà Sàpọ́n’ Taiwo Akinkunmi, ọmọ Ibadan tó ya àsìá Nàíjíríà Ogedengbe Agbógun Gbórò, Akọni tó ń dẹ́rù ba ikú.
Wọ́n dá ọ̀tẹ̀ sílẹ̀ bíi Kora, wọ́n sì parun.
Ó wí fún Jesu pé, “Olùkọ́ni, wo igi ọ̀pọ̀tọ́ tí o fi gégùn-ún, ó ti gbẹ!
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Bolt in Lagos: Àwọn iléeṣẹ́ Uber yóò kógbánílẹ̀ tí ìjọba Eko bá fi lé owó orí wọn- Onimọ̀ nípa ọrọ̀ ajé 13 Ògún 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 14 Ògún 2020 Oríṣun àwòrán, Getty Images Awọn olugbe ipinlẹ Eko kan to maa n wọ ọkọ Uber ati Bolt ti sọ pe kii ṣe asiko yii lo yẹ ki ijọba ipinlẹ naa gbe owo ori gọbọi le awọn ileeṣẹ naa lori.
O ṣalaye pe ọdọmọkunrin ọdun mọkandinlogun kan to ṣẹṣẹ pari ileewe girama wa lara awon mẹfa ọhun ti igba iwa ibajẹ lawọn ibudokọ ti ṣi mọ lori bayii.
Ekeji si ni ibo gomina ni ipinlẹ Ondo.
Ìfẹ́ kì í fi nǹkan burúkú ṣe ayọ̀, ṣugbọn a máa yọ̀ ninu òtítọ́.
O jọ gate ko jọ gate, ibi ti ọrọ naa yoo kangun si ko ti ye wa ṣugbọn BBC beere alaye lọwọ agbẹjọro kan lori iha ti ofin kọ si yiyọ adajọ agba Ìgbìmọ̀ iṣedajọ orílè-èdè Nàìjíríà NJC nikan lo le yọ adajọ Agbẹjọro Solihu Adebayo nilu Ibadan ṣalaye fun ile iṣẹ BBC Yoruba pe lootọ lawọn ẹka aṣofin le daba yiyọ adajọ agba ṣugbọn igbimọ iṣedajọ orile-ede Naijiria NJC nikan lo lagbara lati yọ ọ.
Donald Trump ní àwọn ọmọ ogun IS yi wà lára àwọn tó burù julọ nínú ìkọlù Olùkọ́ àgbà tó fipá bá ọmọ ọdún 13 lò yóò fojú ba ilé ẹjọ́ ni Benue Uganda ti bẹrẹ ìgbésè láti fi ikú ṣefàjẹ fún ẹní bá ṣe ìgbéyàwó akọ si akọ ati abo si abo Ìbéèrè àti ìdáhùn pẹ̀lú Seyi Awolowo ti BBNaija lórí BBC Yorùbá Ọpọ ọmọ Naijiria lo gba pe adura lo ku ki a maa gba fun awọn adari Naijiria lai gba iroyin ofege laaye lati daamu ọkan ẹnikẹni.
Nígbà náà ni OLUWA la Balaamu lójú láti rí angẹli tí ó dúró lójú ọ̀nà pẹlu idà lọ́wọ́ rẹ̀, Balaamu sì dojúbolẹ̀.
 o ku ni 18 / 6 / 2007 .
Ètò tí ó ti ṣe fún wa nìyí, òun tí ó ń mú ohun gbogbo ṣẹ gẹ́gẹ́ bí ìfẹ́ ọkàn rẹ̀.
Ki ṣe eyi nikan, Ìjọba Ológun àti Òṣèlú bẹ̀rẹ̀ iwà ibàjẹ́ nipa ki kó owó ti ó yẹ ki wọn fi tún ilú ṣe jẹ.
Ṣugbọn lónìí, ẹ dìde sí ìdílé baba mi, ẹ sì pa aadọrin àwọn ọmọkunrin rẹ̀ lórí òkúta, ẹ wá fi Abimeleki, ọmọ iranṣẹbinrin rẹ̀ jọba lórí ìlú Ṣekemu, nítorí pé ó jẹ́ ìbátan yín.
Bi orilẹ-ede Naijiria se n jẹ ekuru ọran ko tan lori ọrọ ikọ Boko Haram, tun ni ẹgbẹ ẹlẹsin miran tun dide ni awọn ipinlẹ bii Adamawa, Nasarawa ati Kano.
Àwọn eniyan Israẹli gbéra, wọ́n rìn láti Ramesesi lọ sí Sukotu.
 Ninu irufe ife-eye naa ti eka obinrin, atamatase orile-ede Amerika, ti o tun  je balogun iko naa Megan Rapinoe gba ami-eye agbaboolu obinrin ti o darajulo, leyin ti o tuko orile-ede re gba ife-eye idije boolu agbaye.
Ó dùn mi láti rí i pé ki ń to dé ibẹ̀ agogo ẹkun sísun ti lù, gbogbo ìlú sì ti bẹ̀rẹ̀ síí sọkún, ṣùgbọ́n nígbà tí mo dé ilé Òmògọ́parapọ̀ ni mo rí i pé ẹkùn gan-an ni àwọn ń sun.
 abúlé ni wọn n pe àwọn ìletò wọ ̀ nyí .
14 Lõtọ́, lõtọ́, ni mo wí fún ọ, alábùkúnfún ni ìwọ fún ohun tí ìwọ ti ṣe; nítorí ìwọ ti béèrè lọ́wọ́ mi, àti kíyèsíi, ní gbogbo ìgbà púpọ̀ tí ìwọ ti béèrè ìwọ ti gba ẹ̀kọ́ nípasẹ̀ Ẹ̀mí mi.
Ìtànjẹ lásán ni gbogbo wọn,òfo ni iṣẹ́ ọwọ́ wọn:Ẹ̀fúùfù lásán ni àwọn ère tí wọ́n gbẹ́.
Won gbe asia ajo naa soke lati sami ayeye ipada-bo sinu ajo ohun ni olu ile-ise ajo naa to wa nilu London.
Bakan naa lo n gba iṣẹ lọdọ ileeṣẹ amunawa Naijiria, Electricity Corporation of Nigeria, Nigeria Railway Corporation ati Nigerian Ports Authority.
Láti Tahati wọ́n lọ sí Tẹra.
naa ,eto ilana idibo naa ko waye ni irọwọ irọsẹ.
OLUWA, fa ojú ọ̀run wá sílẹ̀, kí o sì sọ̀kalẹ̀ wá,fọwọ́ kan àwọn òkè ńlá, kí wọ́n máa rú èéfín.
Lẹyin atotonu awọn agbẹjọro mejeji, ile ẹjọ sun igbejo naa si ọjọ kọkandinlogun, oṣu kẹfa ọdun 2020.
Gẹgẹ bii BBC News Yoruba ṣe gbọ, obinrin ẹlẹha yii lọ ra ọja ni ilu Eko ni ọsẹ diẹ sẹyin.
‘Àhesọ lásán ni ọ̀rọ̀ Trump lórí Russia’ Ọwọ́ ba òsìsẹ́ SARS tó pà akẹ́ẹ̀kọ́ ní Iwo Ìbẹ̀rẹ̀ ogun ni à ń rí kò sẹni tó máa ń mọ àdánù rẹ̀ tán Olùdíje fún ipò aàrẹ (Republican) lọdun 2008 jáde láyé Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí kan sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
Ikọ Man U ni tiẹ ti fidi rẹmi nigba meji, bẹẹ ni wọn ta ọmi lẹẹmeji ninu ifẹsẹwọnsẹ mẹfa ti wọn gba ninu idije EPL ti saa yii.
Láti ìgbà èwe mi ni a tí ń jẹ mí níyà,tí mo sì fẹ́rẹ̀ kú,mo ti rí ìjẹníyà rẹ tí ó bani lẹ́rù;agara sì ti dá mi.
Díẹ̀ lára àwọn òṣèré Nollywood ti wọ́n ti ṣe ìgbéyàwó lẹ́ẹ̀kejì Má ṣé tọrọ aforijin lọ́wọ́ Buhari lásìkò àbẹwò rẹ- South Africa Ọnà tí mo fẹ́ gbà láti fòpin sí súnkẹrẹ fàkẹrẹ ọkọ̀ l'Eko rèé - Sanwo-Olu Kíni ẹ mọ̀ nípa àwọn gbajúgbaja Yollywood?
Ṣugbọn Samsoni fa okùn náà já bí ẹni pé fọ́nrán òwú kan ni.
Góòlù méjilélogun Sadio Mane ọmọ bibi orilẹ̀-èdè Senegal, Mohammed Salah ọmọ bibi Egypt àti ọmọ orílẹ̀-èdè Gabon Pierre-Emerick Aubameyang ni wọn fi pegede.
Oríṣun àwòrán, Instagram/currentalhaja Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Nígbà tí ó wà níbẹ̀, òun pẹlu Joramu lọ pàdé Jehu ọmọ Nimṣi, ẹni tí OLUWA ti yàn pé òun ni yóo pa ìdílé Ahabu run.
Atamatase omo orile-ede France, Anthony Martial ti o n kopa fun iko agbaboolu Manchester United   ti bowolu iwe ibasisepo oloodun marun un  lati sun asiko re siwaju ninu iko  Manchester United  di odun 2024.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Pásítọ̀ gún ìyàwó rẹ̀ lọ́bẹ nínú ṣọ́ọ̀ṣì, ló bá tì í bọ ara rẹ̀ náà níkùn 6 Sẹ́rẹ́ 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 3 Òkùdu 2020 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Pásítọ̀ gún ìyàwó rẹ̀ lọ́bẹ nínú ṣọ́ọ̀ṣì, ló bá tì í bọ ara rẹ̀ náà níkùn Pasitọ ijọ kan ni Kenya ti gun iyawo rẹ lọbẹ pa lọjọ Aiku lori aga iwaasu ninu ṣọọṣi ti awọn mejeji jọ da silẹni ilu kan ni Mombasa, ni orilẹ-ede Kenya.
 mú gà ; mú dè .
Ọlọ́pàá Ondo: A ti da ọtẹlẹ̀múyẹ́ síta láti ṣe àwári Fagoriola.
Torinaa kii ṣe awọn ọmọ yii nikan lo koju idẹyẹsi.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Sotitobire church: Àwọn ọ̀dọ́ ilu dáná sun ilé ìjọsìn Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Sotitobire church: Àwọn ọ̀dọ́ ilu dáná sun ilé ìjọsìn 18 Ọ̀pẹ̀̀ 2019 Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí 2 sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
Osuolale ni ìyàwó, èyí tó ti jẹ́ ìpè Ọlọ́run síwájú rẹ, tó sì bí ọpọ ọmọ pẹ̀lú, nínú èyí taa tí rí Amofin Olajumoke Akinjide, tí òun náà jẹ amofin àti minisita tẹ́lẹ̀ fún olú ìlú ilẹ wá, Abuja.
8 1201 Orilẹede New Zealand 25 0.
Ogún mi ti dàbí kinniun inú igbó sí mi,ó ti sọ̀rọ̀ burúkú sí mi;nítorí náà mo kórìíra rẹ̀.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù PDP: APC ń lo EFCC láti halẹ̀ mọ́ ẹbí Adeleke 16 Owewe 2018 Oríṣun àwòrán, @iam_Davido Àkọlé àwòrán, EFCC ko tii sọrọ lori iroyin yii Gbajugbaja olorin nni Davido, ti ké gbàjarè síta pé ajọ to n gbogun ti iwa ijẹkujẹ lorilẹede Naijiria, EFCC ti gbẹsẹ le aṣuwọn owo òun.
Idi niyi  ti won se fa da ile –ise yii sile lati mu eto idagbasoke ba imo ero igbalode lorile ede Naijria, ni eyi ti yoo lee pese ise  fun awon eniyan, ise- owo ati itesiwaju ninu okoowo.
Irun orí lásán ni ó ń gé fún àwọn ẹlòmíràn ní ìṣáájú, ṣùgbọ́n ó tọ́jú iṣẹ́ ó sì tọ́jú òwò rẹ̀.
Wọn gbe oku ọmọ naa lọ sinu igbo kijikiji to wa lẹba ile ijọsin CMS, ti wọn si sin in nibẹ.
Báyìí, ẹnu ìpínlẹ̀ Benue ti gba ọ̀rọ̀ lórí òfin darandaran rẹ̀ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fọ́nrán ohùn, NEC fi òfin de dída ẹran ọ̀sìn kiri nìpínlẹ̀ márùn uń NEC gbà pé ìgbẹ́sẹ̀ yìí yóò fòpin sí ìkọ̀lù àwón darandaran láti ilẹ̀ òkèèrè.
Tinubu, ninu ikede to fi sita loju opo Twitter rẹ lọjọ Aje ni lootọ lawọn oluwode lẹtọ lati fehonu han ṣugbọn nibi ti wọn ba ọrọ de yii,asiko to lati sinmi iwọde.
Ọ̀rọ̀ yìí dára lójú gbogbo àwùjọ, wọ́n bá yan Stefanu.
Lasiko ti aarẹ Zuma fi n koju ipenija ẹsun ifipabanilopọ ti obinrin kan fi kan nigba naa, ọgbẹni Ramaphosa sọ yanyan wipe oun gba obinrin to fi ẹsun ifipabanilopọ kan Zuma gbọ.
Oun ati afẹsọna rẹ ti o jẹ ọmọ orile-ede Sudan sọ pe awọn ko ṣẹyun.
Aarẹ Muhammadu Buhari ti pa asẹ fun olu-ile isẹ ọmọogun lorilẹede Naijiria lati bere iwadii lori isẹlẹ to mu ẹmi ọlọpaa mẹta lọ.
Òfin yi ti orílèèdè India kọ láti yí padà jẹ ọkan lára àwọn òfin tó ti wa tipe to sì lòdì sí ìbálòpọ̀ láàrin ọkùnrin sí ọkùnrin.
 a alvarez ni ó tẹ ́ ìtàn ikú tí ó kú ní rèwerèwe jáde .
Ni ida keji awọn mii ni ayipada lawọn n fẹ latọdọ aarẹ Buhari.
Lai pe yi ni ijọba sika adehun ti wọn se pẹlu awọn onimo isegun sugbọn ti ọrọ ba kan ti awa osise to ku, awawi ni wọn ma n so'' Jack ni awọn ti fun ijoba ni anfaani lopo igba lati yanju oro naa lai se pe awọn dase sile.
Oríṣun àwòrán, Seyi Makinde Nigba to n sọrọ lorukọ awọn ọmọ igbimọ olugbaninimọran naa, alaga igbimọ naa, Sẹnetọ Agboọla seleri pe igbimọ naa yoo maa gbe imọran kalẹ loore koore lati mu ki ipese isejọba rere tẹsiwaju ni ipinlẹ Ọyọ.
mojuto oro abele lo jabo oro ohun fun awon akoroyin.
Akọni obìnrin yii tun ko awọn Iyalọja jọ sinu oniruuru ẹlẹgbẹjẹgbẹ, to si tun da ẹgbẹ Young Women Christian Association, YMCA silẹ.
Awon alufaa ati adari elesin naa
Ẹnikẹ́ni kò gbọdọ̀ ṣe aláìwá nítorí mo fẹ́ ṣe ìrúbọ ńlá sí Baali.
 nítorípé ìyí onírúiyepúpọ ̀ aláìjẹ ́ òdo gbọ ́ dọ ̀ jẹ ́ ìyí ọ ̀ rọ ̀ tó ní ìyí tótóbijùlọ , onírúiyepúpọ ̀ ìgbékalẹ ̀ ọ ̀ rọ ̀ òkè yìí ní ìyí éjì .
Láti ọjọ́ náà ni ó ti sọ ọ́ di òfin ati ìlànà ní Israẹli, títí di òní olónìí.
Nibi ipade karundinlọgọta ti awọn aarẹ ati olori awọn orilẹede to wa ninu ajọ iṣọkan ẹkùn Iwọ oorun ilẹ Afrika, ECOWAs, ni Buhari ti fi ami ẹyẹ naa da a lọla.
Òdodo ni gbogbo ọ̀rọ̀ ẹnu mi, kò sí ìtànjẹ tabi ọ̀rọ̀ àrékérekè ninu wọn.
Mo ṣèlérí láti ṣe ju ohun tí mo ti ṣe lọ fún ẹbí àwọn tó kú torí EndSARS - Seyi Makinde Ìwọ́de 'End SARS' lè tan àjàkálẹ̀ arùn coronavirus lẹ́ẹ̀kejì ní Nàìjíríà- Ọjọ̀gbọ́n Faduyile Ẹ lo ìfẹ̀họ̀núhàn #EndSARS lati fí tún gbogbo ohun tó bàjẹ́ ṣe ní Naijiria- Pásítọ̀ Sam Adeyemi Oríṣun àwòrán, veeQtor Diẹ ree ninu wọn: Awọn oluwọde pin feere fawọn obinrin Feere pinpin fawọn obinrin ni ibi iwọde Lekki jẹ nkan tawọn eeyan kan saara si.
Irú ìmọ̀ yìí jẹ́ ohun ìyanu fún mi,ó ga jù, ojú mi kò tó o.
Ẹ óo rí Ọmọ-Eniyan tí ó jókòó lórí ìtẹ́ pẹlu agbára Ọlọrun, tí ìkùukùu yóo sì máa gbé e bọ̀ wá.
"Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: ""7000 Jàǹdùkú ló fọ́ ọgbà ẹ̀wọ̀n Okitipupa, jó mọ́tò, tí wọn si se òṣìṣẹ́ léṣe"" Buhari kọ́ ni ìṣòro wa, bó ṣe wà láti láéláé rèé - Fr Mbaka Àwọn ọ̀dọ́ fi ọ̀nà àrífín pe Tinubu lórí aago àmọ́ ó ní òun kò mọwọ́-mẹsẹ̀ nípa ìpànìyàn Lekki Wo díẹ̀ lára dúkìá tí jàǹdùkú sun níná l‘Eko torí ìwọ́de EndSARS Á ràgà bo CCTV Lekki bí i ẹ̀rí tó dájú fún ìwádìí ìpànìyàn - Sanwo-Olu SERAP gbé ìjọba àpapọ̀ lọ ilé ẹjọ́ àgbáyé ICC lọrí ẹ̀sùn ìpànìyàn ""Jàǹdùkú gún ẹ̀gbọ́n mi lọ́rùn, jó ilé àti mọ́tò wa méjì, kòròfò la wà"" Olùwọ́de 12 kú ni Lekki, 38 lapapọ kú lọ́jọ́ Isẹ́gun, 56 ni àròpọ̀ àwọn tó bá ìwọ́de lọ - Amnesty International Osinbajo gbarata lórí ìṣẹ̀lẹ̀ Lekki, ó ní ìdájọ́ òdodo yóò wà Ni nkan bi aago mejila ọsan ni iroyin naa jade."
Seyi Makinde tun wa fi  asiko naa dupe lowo gbogbo awon to se atileyin
 Ò lọ sí ilé ẹ ̀ kọ ́ methodist girls college ní yaba , lẹ ́ yìn rẹ ̀ ó tẹrísí fàsítì ìlú Èkó .
Oníbàárà - BBC News Yorùbá BBC News, YorùbáFò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Polaris Bank Nigeria: Ẹ̀rù ń bà wá o - Oníbàárà 13 Èrèlè 2018 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 25 Owewe 2018 Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Èrò àwọn oníbàárà Skye Bank tó porúkọ dà Oríṣun àwòrán, @SkyebankNigeria Gomina banki apapọ ilẹ wa, Godwin Emefiele ti kede pe banki apapọ ilẹ wa ti gbẹsẹ le Skye banki.
Oluranlọwọ Aarẹ Muhammadu Buhari lori ọrọ iroyin, Bashir Ahmad lo fi lede lori ẹrọ ikansiraẹni Twitter rẹ.
Ìwà ti ọmọ ilú lè hù ti yio fa ibinú, bi àlejò bá hu irú ìwà bẹ́ ẹ̀, wọn yio ni àlejò ni, ki wọn fori ji i.
Ogoji ọdún ni ó fi jọba lórí gbogbo Israẹli ní Jerusalẹmu.
28 Ìgbé 2018 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Giroud ati Hazard dawọ idunu pẹluFabregas lẹyin to je goolu keji ninu ifẹ̀sẹ̀wònse wọn.
Arabinrin Odegbami ni o lọ si orilẹ-ede Amerika fun itoju lai mọ wi pe aye rẹ yoo yipada si rere ni oke okun.
Kàkà bẹ́ẹ̀, ojú ayé ni wọ́n ń ṣe.
Ẹgbẹ NLC ni ijọba n fi iya jẹ awọn oṣiṣẹ ni ipinlẹ Rivers, ti wọn ti lẹ n na lara wọn nitori wọn n bere fun ẹtọ wọn.
"O sọ siwaju sii pe ""nigba ti mo si wa labule, lati rii daju pe ina inu asọ ku, ẹ o fi saarin ika meji ni, ẹ o si tẹẹ pa titi yoo fi ku."
Samuẹli ní kí wọ́n kó gbogbo eniyan Israẹli jọ sí Misipa, ó ní òun óo gbadura sí OLUWA fún wọn níbẹ̀.
Messi ò lè dúró mọ́, aṣojú Manchester City ti balẹ̀ sí Barcelona láti dú ìná dúrà Ẹ̀fọn Arsenal já bàálù Liverpool lulẹ̀ ní Wembley ní ìrìn-àjò sí Community Shield Anthony Joshua gba nọ́mbà ìdánimọ̀ NIN, àwọn ọmọ Nàìjíríà kan kérora lórí ètò náà Ìṣẹ́ ló jẹ́ kí n sọ ọmọ nù sórí ààtàn- Dupẹ, Ìyá Muiz Mama Arsenal ṣeé débi èrè, ẹgbẹ́ kan ti fún màmá l'ẹ̀bùn owó Ajagba tiẹ ti bẹrẹ si ni sọ ọna ti o fi le fẹyin AJ gbalẹ ti wọn ba koju ara wọn.
Aláìlera wo ni ẹ ti gbàlà?
Buhari ti sofin aleekun owo ori ileese ọti ati siga
'Ekute jẹ ogun oloro lagọ ọlọpa' Ọdún Ọṣun Oṣogbo wọlé dé wẹ́rẹ́, Òyìnbò gan dáwọ́ọ̀ ìdùnnú 'Fún ìtẹ̀síwájú ìpínlẹ̀ Kwara ni wọ́n ṣe ni Ó tó gẹ́!
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ìṣúná 2021 yóò ṣíjú ọ̀dọ́ kúrò nínú ìwá Yahoo-Yahoo - Sanwo-Olu Ẹ̀yin obìnrin, ẹ jáde du ipò ààrẹ láti gbàjọba lẹ́yìn Buhari - Amina Muhammed Sina Jesu ní orúkọ́ mi báyìí, ń kò jẹ́ Shina Rambo mọ́ - Adigunjalè tẹ́lẹ̀ kìlọ̀ Agbẹjọ́rò wọ́ ìjọba lọ sílé ẹjọ́ pé kó yọ kéú kúrò lára owó Náírà Mọ̀ síi nípa Shina Rambo tó pàdé Jesu lọ́gbà ẹ̀wọn lẹ́yìn tó ti jalè Abẹ́rẹ́ àjẹsára tó dájú fún ìdènà àrùn Coronavirus ti jáde Wàhálà míì dé!
Olusegun Obasanjo lasiko isejoba re lodun 1979.
Ó kọ ohun tí ó wà ninu ìwé àkọ́kọ́ tí Jehoiakimu ọba Juda fi jóná, ó sì fi àwọn nǹkan mìíràn kún un pẹlu.
Tí o ò bá tún wá sí níbẹ̀ lásìkò náà, àwọn kòkòrò àìfojúrí yìí le wà nínú afẹ́fẹ́ fún ìṣẹ́jú péréte ti o sì ṣeéṣe kí o tí fa èyí tó tó sì mú lásìkò péréte náà, tí ààrùn yóò sì wọlé dé.
O fi kún pé, àwọn ilé ẹjọ́ pẹ̀lú kò ṣíṣẹ nítori náà àwọn to yẹ kó kúrò lágọ̀ọ́ ọlọ́pàá lọ silé ẹjọ́ náà ko le kúrò níbẹ̀.
Amọ eyi ko ri bẹẹ fun ọkunrin kan to gbajugbaja ninu isẹ gbogbo elere fun orin taka-sufe, Seun Ọmọgaji, taa mọ si DJ Xgee.
Wo àwọn olorì àgbà mẹ́rin tí Aláàfin ń wárí fún Wo ọ̀nà tí àwọn ‘ẹ̀lẹ̀ Daddy’ gbà dé ààfin Ọyọ Kí ló ń ṣẹlẹ̀ láàfin Oyo táwọn èèyàn fi ń ki Alaafin ní mẹ́sàn án mẹ́wàá?
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Nigeria Population: Báwọn ọmọ Nàíjíríà ṣe ń pọ̀ si jẹ́ ìpèníjà fún Buhari Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Nigeria Population: Báwọn ọmọ Nàíjíríà ṣe ń pọ̀ si jẹ́ ìpèníjà fún Buhari 29 Èbibi 2019 Nibayii ti aarẹ Muhammadu Buhari ti sebura fun saa keji lori aleefa gẹgẹ bii aarẹ orilẹede Naijiria, ọpọ awọn ọmọ orilẹede naa lo ti n fi igbe bọnu pe awọn ko ri isẹ se.
Eto wa lara ayeye ajodun agbaye ti  maa n se ni lati fi tako iwa aito si awon obinrin  ati omode, ojo merindinlogun ni ajo agbaye ya soto lati fi  se ifehonuhan yii .
Rò ó dáradára, kí o sì sọ èyí tí o fẹ́, kí n lọ sọ fún OLUWA.
Ní ti físà L tó wà fún àwọn òṣìṣẹ́ ilé iṣẹ́ ńlá ńlá náà yóò fara káásá, nítori òfin de àwọn náà.
Oríṣun àwòrán, @EKEDP Amọ iwadi fihan pe eyi ko ri bẹẹ nitori ina tawọn ara adugbo Lekki nlo ni wọn n pese funra wọn.
"Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù INEC: Ẹgbẹ̀rún márùn ún náírà ni ìbò Òǹdó,Edo àti Anambra 11 Ìgbé 2018 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, ""Láàárín 2015 sí àsìkò yìí, ìdìbò ọ̀rìnlélúgba ó lé mẹ́fà ni àjọ INEC ti ṣe nínú èyí tí wọ́n ti wọ́gilé méjìdínlọ́gbọ̀n"" Àjọ elétò ìdìbò ní orílẹ̀èdè Nàìjíríà, INEC, ti fẹ̀sùn kan àwọn olóṣèlú àtàwọn olólùfẹ́ wọn pé, wọ́n ń fi ìbò rírà pa ètò ìdìbò sípò Gómìnà lára ní ìpínlẹ̀ Edo, Ondo àti Anambra."
Nígbà tí Dafidi gun òkè náà dé orí, níbi tí wọ́n ti máa ń rúbọ sí Ọlọ́run, Huṣai, ará Ariki, wá pàdé rẹ̀ pẹlu aṣọ rẹ̀ tí ó ti ya, ó sì ti ku eruku sí orí rẹ̀.
” Ṣugbọn ó dá a lóhùn pé, “Èéṣe tí o fi ń bèèrè orúkọ mi?
Ìjọba-àpapọ̀ ti ilú Àmẹ́ríkà gba òfin yi wọlé nitori “Òfin-Òṣèlú ni wọn fi ndari ilú Àmẹ́ríkà”.
Araale: Ta lo fẹran ju lọ ninu gbogbo awọn to kopa ninu ile Ẹlẹgbọn Agba?
"Awọn alaṣẹ ẹgbẹ naa ni ipinlẹ Rivers lo da a duro, ""fun pe o tako ilana ati agbakalẹ ẹgbẹ""."
Ó mà ṣe o, Oyíndayépọ̀ ṣe bẹ́ẹ̀ ó lọ, baba mi ṣe gudugudu méje fún mi, ó ṣe gudugudu méje fún mi, Oyíndayépọ̀ baba mi, baba mi, baba mi.
63 Àti pé èyí ni mo ṣe kí èmi ó lè gbé ìhìnrere mi kalẹ̀, kí á má baà rí ìjà púpọ̀, bẹ́ẹ̀ni, Sátánì máa ńru ọkàn àwọn ènìyàn sókè sí ìjà nípa àwọn kókó ẹ̀kọ́ mi, àti nínú àwọn nkan wọ̀nyí wọn nṣe àṣìṣse, nítorí wọn ńyí ọ̀rọ̀ Ọlọ́run po òye rẹ̀ kò sì yé wọn.
Gẹ̀gẹ̀ bí àkọsílẹ̀ ọlọ́pàá tí Times of India tẹ̀jáde, ìṣọdẹ-àjẹ́ ní Jharkhand ti rán àwọn ènìyàn 123 sọ́run àpàpàǹdodo ní àárín-in oṣù Èbìbí ọdún-un 2016 sí oṣù Èbìbí ọdún-un 2019.
O ni oun mu ibọn agbebọn naa to jabọ, ti oun si gbiyanju lati yin mọ, ṣugbọn ibọn na ko dahun.
Òun náà jẹ́ kí Israẹli dẹ́ṣẹ̀, ó sì mú OLUWA Ọlọrun Israẹli bínú nítorí oriṣa tí wọn ń bọ.
Nígbàkúùgbà tí ó bá ń pa wọ́n, wọn á wá a;wọn á ronupiwada, wọn á sì wá Ọlọrun tọkàntọkàn.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Lesotho vs Nigeria: Nàìjíríà lu Lesotho lu lálùbolẹ̀ mọ́lé wọn 17 Bélú 2019 Oríṣun àwòrán, Twitter/Super Eagles Alubolẹ ni ẹgbẹ agbabọọlu Naijira, Super Eagles lu Lesotho mọle wọn ninu ifẹsẹwọnsẹ ati pegede fun idije ere bọọlu ilẹ Afirika, 2021 AFCON qualifiers.
Koda, wọn tun fi apo asunwọn ile ifowopamọ Ajirebi soju opo Istagram wọn lati beere iranwọ owo fun osere tiata naa, ko le tete bọ lọwọ ajalu ọhun.
Ẹ fi sílẹ̀ fún àwọn àlejò ati àwọn aláìní baba ati àwọn opó, kí OLUWA Ọlọrun yín lè bukun iṣẹ́ ọwọ́ yín.
Saulu bá wọn lọ́wọ́ sí ikú rẹ̀.
Ọpọ ibi ni Germany, paapaa ni Berlin ni wọn ti wọgile awọn ohun to le mu ki awọn eeyan korajọ pọ soju kan naa, bi ile iworan tiata, ati bẹbẹ lọ.
Ẹ̀yà Lefi nìkan ni Mose kò pín ilẹ̀ fún, ẹbọ tí àwọn ọmọ Israẹli bá rú sí OLUWA ni ìpín tiwọn.
Ọ̀gbẹ́ni Diab ti sàlàyé pé ìbígbàmù náà wáye nítori àwọn èròjà tó dín díẹ̀ ni ẹgbẹ̀rún méjì tóònù ti wọ́n kó pamọ si ibùdókọ̀ ojú omi fún ọdún mẹ́fàá ló fàá.
Kàkà bẹ́ẹ̀, ó ní ìfẹ́ sí òfin OLUWA,a sì máa ṣe àṣàrò lórí rẹ̀ tọ̀sán-tòru.
Kí ó mú àwọn nǹkan wọnyi ninu ẹbọ alaafia náà, kí ó fi wọ́n rú ẹbọ sísun sí OLUWA: ọ̀rá tí ó bo nǹkan inú rẹ̀ ati ọ̀rá tí ó wà lára ìfun rẹ̀, 
Ẹni tí ó pa àwọn àkọ́bí ní ilẹ̀ Ijipti,nítorí pé ìfẹ́ rẹ̀ tí kì í yẹ̀ wà títí lae; 
Ninu ọrọ to ba BBC Yoruba sọ, oludari agba fun ajọ SERAP, ọgbẹni Adetokunbo Mumuni titọ ile ẹjọ lọ ni yoo yẹ ọna fun igbẹjọ gan ti yoo waye ni osu kẹta ọdun 2018.
Olori Naomi to ni ko si otitọ kankan ninu iroyin yin sọ loju ẹrọ ikansiraẹni Instagram rẹ pe oun ko ko kuro ni ile Ooni.
    N kò ní lè dárúkọ gbogbo wa bi a ti ṣe tò lọ lẹsẹẹsẹ, ṣùgbọ́n n ó ẹni mẹ́sàn-án nínú wa.
" Ijọba ipnilẹ Eko wa kabamọ lori bi awọn araalu se ya bo ibudo ọhun, to si mọ riri atilẹyin ajọ CACOVID, to pin fun.
Dìde, lọ gbé e, kí o sì rẹ̀ ẹ́ lẹ́kún, nítorí n óo sọ ọ́ di orílẹ̀-èdè ńlá.
Minimum Wage: Apá àwọn gómìnà ò ká ọgbọ̀n ẹgbẹ̀rún Naira owó oṣù-Yari
Ipo Kẹta: Ẹka eto Ilera: Ẹka eto ilera lo ko ipo kẹta ninu eto isuna ọdun 2020 nipinlẹ Ọyọ pẹlu ida marun ati diẹ, 5.
A kò fipá mú ẹnikẹ́ni láti dá Ruga, aàgọ́ Fulani sílẹ̀ -Iléeṣẹ́ aàrẹ Osinbajo ta kété sí ọ̀rọ̀ 'Ruga Settlement' Ẹ̀yin tẹ́ẹ tako àgbékalẹ̀ àgọ́ Fulani, ìkórira ló ń yọ yín lẹ́nu - Ìjọba àpapọ̀ Ileeṣẹ aarẹ sọ pe ''ọna lati fi opin si ija ati wahala to n waye ni gbogbo igba laarin awọn daran-daran ati agbẹ ni.
Amọ, awọn ọdọ langba ti eroja idena aisan ara wọn ji pepe lo ṣeeṣe ki wọn ma tete ri abẹrẹ ajẹsara naa gba.
Ajábọ̀ iṣẹ́ ìjọba ti fúnpá lórí ìpàdé tí Aliyev ní pẹ̀lú Saray, ẹni tí ó ti gba oríyìn gẹ́gẹ́ bí àwòkọ́ṣe rere fún ìfaradà àti ìgbàgbọ́ tí ó ní sí ọjọ́ iwájú orílẹ̀-èdè Azerbaijan lẹ́yìn-in ìṣẹ́lẹ̀ náà.
Ninu ọrs rẹ, oludari agba fun iks Amọtẹkun ni ipinlẹ Ọṣun, Ọgbẹni Amitolu Shittu ni igbesẹ naa wa lara igbesẹ ti ijsba ipinlẹ naa la kalẹ fun pipagidina awọn to fẹ maa gbẹyin ja ipinlẹ naa lole.
#BBCNigeria2019 Fela Durotoye, olùdíje ipò ààrẹ ẹgbẹ́ òṣèlù ANN #BBCNigeria2019 Tani Kingsley Moghalu tó ń duipò ààrẹ?
olukuluku obinrin yóo lọ sí ọ̀dọ̀ aládùúgbò rẹ̀ tí ó jẹ́ ará Ijipti ati àwọn àlejò tí wọ́n wọ̀ sọ́dọ̀ rẹ̀, yóo tọrọ aṣọ ati ohun ọ̀ṣọ́ wúrà ati ti fadaka, ẹ óo sì fi wọ àwọn ọmọkunrin ati àwọn ọmọbinrin yín, bẹ́ẹ̀ ni ẹ óo sì ṣe gba gbogbo ìṣúra àwọn ará Ijipti lọ́wọ́ wọn.
Mo bẹrẹ si ni ba a fa wahala ninu ile titi to fi jẹwọ fun mi ni ọjọ kan lẹyin ọsẹ mẹta pe, lootọ ni oun ati obinrin naa ti n ni ibalopọ lati bi oṣu diẹ.
Lara awon to wa nibi aseye naa ni abenugan
 Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Ìgbésí ayé tí kò pariwo ló dára' A jẹ wipe ko si ibi ti ifẹ kii ti gbilẹ, a ki Michael Adeyemi ati Nkechi Blessing pe wọn ku oju to tun tura ri."
Oríṣun àwòrán, Getty Images Ipa wo ni igbẹjọ yi yoo ko lori erongba ati du ipo aarẹ lọdun 2020 fun Trump?
 ní ìparí ọ ̀ sẹ ̀ ni wọ ́ n ń wálé .
Bi iwadii ti n lọ lọwọ lori ohun fa sababi ile to wo l'Eko, awọn onimọ ẹrọ ti sọ fun wa awọn nnkan ti o maa n fa irufẹ iṣẹlẹ yii gan an.
Ọba ati Jehoiada gbé owó náà fún àwọn tí wọn ń ṣe àkóso iṣẹ́ ilé OLUWA, wọ́n gba àwọn ọ̀mọ̀lé, àwọn gbẹ́nàgbẹ́nà ati àwọn alágbẹ̀dẹ irin ati ti bàbà, láti tún ilé OLUWA ṣe.
igi nadi ati Safironi, Kalamusi ati Sinamoni,pẹlu oríṣìíríṣìí igi turari,igi òjíá, ati ti aloe,ati àwọn ojúlówó turari tí òórùn wọn dára jùlọ.
 ní bíi ọdún 2016 , òṣùwọ ̀ n owó rẹ ̀ lójú pálí kúsí ni amẹ ́ ríkà jẹ ́ $ 70.
Awọn apo olokun tiirin, ti awọn alejo naa fi di ẹru wọn si ni wọn sọ ni Ghana Must Go, sugbọn wọn ti n lo ede ọhun fun awọn oloselu to n gba owo abẹtẹlẹ gọbọi, eyi to n ko ba ọrọ aje Naijiria.
Wọn ti mọ pe ti awọn ba gbaju mọ imọtotọ awọn ko ni ni arun naa bẹ si ni awọn ko ni le ko ran ẹlomiran.
Akinyele local government: Iléeṣẹ́ ọlọ́pàá ìpínlẹ̀ Oyo ti mú àwọn afurasí lórí ìpànìyàn tó wáyé
Paul Sodje: Ọjọ́rùú ló yẹ kó pé ẹni ọdun 55, amọ́ tó kú ikú àìròtẹ́lẹ̀
Ọmọ rẹ, Mide Martins naa jẹ eekan lagbo tiata bayii, Funmi si ṣẹṣẹ bi ọmọ ti ko ju ogoji ọjọ lọ, nigba to jade laye.
21 Ẹrẹ̀nà 2020 Ilumọọka adẹrinpoṣonu ni Yẹmi Ẹlẹṣọ, amọṣa lori eto Se o laya tosẹ yii, o da bẹbẹ pẹlu awọn ibeere wa gbogbo.
Gẹgẹ bi awọn oludari eto naa ṣe sọ, ẹgbẹrun lọna irinwo eeyan ni N-Power n mura lati gba siṣẹ ni ababla kẹta yii.
O si tun ni ẹtọ lati gbe awọn afurasi lọ sile ẹjọ.
2: Alayinde Ma De O Vol.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Sunday Igboho yarí, ó fohùn ránsẹ́ sáwọn èèyàn tó ń pẹ̀gàn rẹ̀ Àwọn iléesẹ́ abáni fi ẹrù ránṣẹ bẹ̀rẹ̀ ìyaṣẹ́lódì tako àfikún owó Nipost Ìkúnlẹ̀ ló bá dé fún Oshiomole, Ize-Iyamu láti bẹ̀bẹ̀ fún ìbò aráàlú ní Edo Sunday Igboho yari, o fohun ransẹ sawọn eeyan to n pẹgan rẹ Ikú Barakat Bello ní Akinyele gbé aláàánú pàdé ẹ́bí rẹ̀ A ṣe ọdún Ọ̀ṣun lásìkò yìí láti kó Coronavirus lọ ni - Ooni ṣàlàyé Wo àwọn nǹkan tí o kò mọ̀ nípa 'Church of Satan' Igbimọ to wadii Magu lo ránṣẹ pe Lawal, lati jẹri lori awọn ẹsun àṣemáṣe to waye ninu isakoso Magu gẹgẹ bi alaga ajọ EFCC.
Ninu atejade kan ti ile  ẹjọ naa gbe jade pe “ Yoo mu idagbasoke ba eto idajọ ati
 Àwọ ̀ funfun àti búúlù rẹ ̀ túmọ ̀ sí àwọn adágún odò ńlá tí o ́ yíí óriĺẹ ̀ - èdè náà kà .
"Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: ""Buhari, ìwọ́de yóò yíwọ́, tó gbá jẹ́ káwọn ológun bá bẹ̀rẹ̀ ‘Operation Crocodile Smile’ "" Bí o bá fẹ́ darapọ̀ mọ́ ikọ̀ ọlọ́pàá SWAT tí yóò rọ́pò SARS, wo àmúyẹ tí o gbọ́dọ̀ ní Aisha Buhari polongo àwo orin tó ní Nàíjíríà ń ṣun ẹ̀jẹ̀ lásìkò ìwọ́de Lizzy Anjorin ń kiri àgọ́ ọlọ́pàá láti gba ọ̀dọ́ afẹ̀hónúhàn, tó wà láhàámọ́ sílẹ̀ 2015 ni mo ti ń kígbe pé gudugbẹ̀ máa já ní Nàíjíríà - Oyedepo Wo ohun tí ìwọ́de ENDSARS ṣé fáwọn akẹ́kọ̀ọ́ tó fẹ́ ṣèdánwò NECO Láàrin wákàtí mẹ́ta, wọ́n dá ₦4m fún àkàndá ẹ̀dá tó kópa nínú ìwọ́de Ọkan lara awọn kọmiṣọna ipinlẹ Eko, ti ko fẹ fi orukọ rẹ lede ni, o kere tan, ijọba n reti miliọnu mẹwaa naira lojumọ lori afara to so Lekki pọ mọ Ikoyi nikan ṣoṣo."
Mose pe gbogbo àwọn ọmọ Israẹli jọ, ó wí fún wọn pé, “Ẹ̀yin ọmọ Israẹli, ẹ gbọ́ àwọn ìlànà ati àwọn òfin tí n óo kà fun yín lónìí; ẹ kọ́ wọn, kí ẹ sì rí i pé ẹ̀ ń tẹ̀lé wọn.
'Pẹlu ọjọ ori mi, iporuru ọkan ba mi.
Bí olúwaarẹ̀ bá sì búra  èké wéré tí olúwaarẹ̀ bá wọ igbó yìí ni kìnnìíun olójúmẹ́rìndínlógójì ti ń bẹ nínú igbó Olódùmarè yóó pa olúwaarẹ̀ jẹ.
Barrister ló sọ mí di èèyàn ńlá - Ayinla Kollington Lẹ́yìn olóògbé Barrister àti Kollington, èmi làgbà kàn nínú iṣẹ́ orin Fuji- Obesere yarí Jide Kosoko forin sẹ́nu sọ pé òun ni igi lẹ́yìn ọgbà Mr Latin lórí ipò ààrẹ TAMPAN tó wà Ibẹrẹ igbe aye Sikiru Ayinde Barrister?
Nítorí èyí ni a fi ń gbadura fun yín nígbà gbogbo, pé kí Ọlọrun wa lè kà yín yẹ fún ìpè tí ó pè yín, kí ó mú èrò gbogbo ṣẹ, kí ó sì fi agbára fun yín láti máa gbé ìgbé-ayé tí ó yẹ onigbagbọ; 
< Kingsley Moghalu Ijọba Naijiria ko ya owo sọtọ bo ti ṣe yẹ fun ẹka eto ilera ti a si ri wi pe ida marun pere 5% ninu ida ọgọrun ni wọn naa si ẹka yi laarin ọdun mẹwa to kọja.
Ṣaroni dàbí aṣálẹ̀,igi igbó Baṣani ati ti òkè Kamẹli sì wọ́wé.
"Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, O ti ọjọ mejidinlogun bayi ti Boko Haram ti ji awọn akẹkọbinrin gbe lọ ni Dapchi Awọn iroyin ti ẹ lee nifẹẹ si: Wo imọran Fọlọrunṣọ Alakija fun awọn ọdọ adulawọ Okei-Odumakin: Awọn obinrin Naijiria nilo ajọ iranwọ fun oṣelu' ""Ọpọ awọn akẹkọ yii ni ọjọ ori wọn wa laarin ọdun mọkanla si mẹẹdogun, ti wọn ko si da ọwọ ọtun yatọ mọ si tosi."
Gbogbo ohun tí mo pa láṣẹ fún un ni kí ó ṣe.
Ogbeni Steve Ayorinde, to je komisona fun irinajo-afe ati asa fun ipinle Eko lo so eyi di mimo lasiko to n gbalejo asoju Trinidad ati Tobago ni oofiisi re ni Alausa, Ikeja.
Ó fún wọn ní ilẹ̀ àwọn orílẹ̀-èdè mìíràn,wọ́n sì jogún èrè iṣẹ́ àwọn eniyan náà.
paapaa julo ninu eto imo ero igbalode , ibanisoro ati iroyin.
Ọna ti Dagrin n gba kọ orin rẹ gbajumọ pupọ laarin igboro nigba naa, nitori pe awọn orin rẹ ma n ba idojukọ ogunlọgọ awọn ọdọ Naijiria mu.
orile ede naa, iyen minisita to n mojuto ọrọ to jẹ mọ ilẹ okeere  lorile ede Naijiria, Geoffrey Onyeama  lati  yanju isoro to n sele ni orile ede Guinea
ede Naijiria ti mu  awon afurasi  onijibiti meji ori ero ayelujara.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Obasanjo, Fayose ṣe'pade pẹlu aare Buhari l'Abuja 22 Èrèlè 2018 Oríṣun àwòrán, @NGRPresident Àkọlé àwòrán, Ọbasanjọ ti kọ lẹta si Buhari eleyi to di gbajugbaja kaakiri agbaye Ipade igbimọ olubadamọran to ga julọ lorilẹede Naijiria ti bẹrẹ nilu Abuja, pẹlu aarẹ tẹlẹri Olusẹgun Obasanjọ ati gomina ipinlẹ Ekiti, Ayodele Fayose.
Tí a bá fi ìjánu sí ẹṣin lẹ́nu, kí wọ́n lè ṣe bí a ti fẹ́, a máa darí gbogbo ara wọn bí a bá ti fẹ́.
Satani dá OLUWA lóhùn pé, “Ohun gbogbo ni eniyan lè fi sílẹ̀ láti gba ẹ̀mí rẹ̀ là.
Wọ́n ti búra wọlé fún Akinwunmi Adesina gẹ́gẹ́ bí ààrẹ Banki ilẹ̀ Afrika, AfDB Ohun tí a mọ̀ nìyí nípa gbọ́nmi síi omi ò tó lórí ọ̀rọ̀ oyè Babaloja-General ní ìpínlẹ̀ Oyo YWC yọ Ààrẹ Banji Akintoye nípò àbi Akintoye tú ìgbìmọ̀ aláṣẹ YWC ká?
Ijọba gbọdọ fopin si ' biili' owo ina ti ko ba iye ina ti araalu n lo mu.
Òfin ṣì gbẹ́sẹ̀lé Ẹgbẹ́ awakọ̀ èrò NURTW ní ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́ Awọn ikọ naa ni ibudo African Centre for Migration and society (ACMS) ti n da si ọrọ ikọlu si ajoji ni South Africa lati ọdun 1994 nitori ko ṣẹṣẹ bẹrẹ.
Ṣùgbọ́n ṣàdédé ni àwọn ọmọ onílẹ̀ tún yọjú ni ọjọ ẹti, ni ifowosowopo pẹ̀lú àwọn ọlọ́pàá àti àwọn òsìsẹ ìgbìmò amuseya fún ìjọba Ìpínlẹ̀ Èkó, tí wọn sì dojú ìjà kọ àwọn ènìyàn.
Bí Buhari wọ́gilé wíwọ bàálù olówó gọbọi fún òṣìṣẹ́ ìjọba kó ṣe aráàlú láǹfàní - SERAP Àwọn ojú oge Yollywood t'ọ́jà wọ́n ṣì ń tà wàràwàrà Aṣoju BBC to wa nibẹ ni awọn ile to ba iṣẹlẹ naa lọ le ni ọgọrun, ti ọpọlọpọ awọn ara ilu naa si n pohunrere ẹkun lori iṣẹlẹ ọhun.
Laarin awọn akẹgbẹ rẹ lo ti gba ile iṣẹ awọn ọlọpaa kogberegbe lọ.
Ní iwájú wọn ni wọ́n ti pa á.
Lati ọdun 1965 ni ofin to lodi si ibalopọ akọs'akọ laye igba ti awọn oyinbo amunisin gbe e wa si orilẹede wọn.
Fayẹmi ni, gbogbo gbese yoowu ti ijọba to n palẹmọ bayii lati kogba wọle nipinlẹ naa ba jẹ, ni oun yoo tẹwọ gba nitori igbagbọ oun ni pe, ijọba n tẹsiwaju ni, ko duro si oju kan.
Bayelsa Lawmakers: Tí o ba buwọlu owo ìfẹyìnti yòó di ọ̀rọ̀ ile ẹjọ
- Ooni Ile Ife Wọn fikun pe awọn gba iwe eri mejilelọgbọn to fi mọ awọn ẹrọ bii hard disc ati flash drive, to fihan pe Maina ati ẹbi rẹ lo ni awọn ile nla naa.
“O óo fi aṣọ aláwọ̀ aró rán ẹ̀wù àwọ̀kanlẹ̀ sí efodu náà.
Ilẹ̀ àwọn akọ kinniun ati abo kinniun,ilẹ̀ paramọ́lẹ̀ ati ejò amúbíiná tí ń fò.
Ó fọ̀rọ̀ ẹnu fà wọ́n títí, sibẹ wọn kò súnmọ́ ọn.
”Ohùn kan bá wá láti ọ̀run, ó ní, “Mo ti ṣe é lógo ná, èmi óo sì tún ṣe é lógo sí i.
Alaye ni kikun wa ninu fidio yii.
O mú híhó òkun dákẹ́ jẹ́ẹ́,ariwo ìgbì wọn rọlẹ̀ wọ̀ọ̀;o sì paná ọ̀tẹ̀ àwọn eniyan.
Ọbasa, ẹni ti Olori Ọmọ Egbẹ-Oṣelu to po ju ninu Ile Igbimọ Aṣofin naa,
Ọrọ̀ ajé Nàíjíríà yóò forí ṣánpọ́n tá a bá san ₦30,000 fún òṣìṣẹ - Ìjọba Kò sí ìfoyà, mò ṣetán láti sàn jù ₦30,000 fáwọn òṣìṣẹ́ l‘Eko - Sanwo-Olu Oríṣun àwòrán, MAMARAINBOWOFFICIAL Àkọlé àwòrán, Mama Rainbow ti kopa ninu ere to le ni ẹẹdẹgbẹta Ere agbelewo ti Mama Rainbow kọkọ ṣe ni Ẹru, lẹyin naa lo kopa ninu Ajẹ Niya mi, ṣugbọn ere tiata to sọ ọ di mọlumọọka ni Aṣiri Nla.
Kí ilẹ̀ wọn kún fún oríṣìíríṣìí àwọn ohun tí ó dára,pẹlu ibukun láti ọ̀dọ̀ ẹni tí ń gbé inú pápá tí ń jó.
Yẹ̀ mí wò, OLUWA, dán mi wò;yẹ inú mi wò, sì ṣe akiyesi ọkàn mi.
“Àwọn eniyan burúkú wà láàrin àwọn eniyan mi,wọ́n ń dọdẹ eniyan bí ẹni dọdẹ ẹyẹ,wọ́n dẹ tàkúté, wọ́n fi ń mú eniyan.
Mí ò rò pe èyí le ṣe akoba kankan fún mi nítori mi o gbagbọ pe o ṣeeṣe ki wọn fofinde eré ifé ni Kannywood Oríṣun àwòrán, Kannywood Àkọlé àwòrán, Ogun ọdún ni Ali Nuhu ti lò gẹ́gẹ́ bi òṣèrè ni Kannywood Nínú ìfọ̀rọ̀wanilẹ́nu wò ti BBC ṣe pẹ̀lú gbájúgbaja oṣèré Kannywood Ali Nuhu lọ́dun to kọja, sọ pe ìdí ti Kannywood ṣe máa ń ṣe ere ifẹ ni pé, òhun lo n ṣe àfihan àwọn ènìyàn, Awọn Hausa dágbà nínú wíwo eré àgbéléwò India, ti gbogbo ènìyàn si mọ pe inú rẹ ni eré ìfẹ́ ti bẹ̀rẹ̀.
Ologun gba 'Camp zero' lọwọ Boko Haram Ileesẹ ologun Naijiria ni awọn ti tu ibuba awọn ikọ adukukulaja mọni nni Boko Haram ka, ninu igbo Sambisa.
Champions League: Chelsea yoo waako pẹlu Barcelona
tun ti gbina leekan si bayii, leyin ti iko agbaboolu mejeeji(Manchester United
8bn ni OAU jẹ lówó orí òsìsẹ́ rẹ̀ 2 Èbibi 2018 Oríṣun àwòrán, Bose Àkọlé àwòrán, Bílíọ̀nù kan àti ẹgbẹ̀rin mílíọ̀nù náírà, (1.
O si tun ni ko kọ iwe ẹbẹ.
V Bello, Adeniyi Babatunde ati Seun Ashamu.
merinla ni o kede pe awon yoo dena eto idibo ti eto ti wa nile pe yoo waye logunjo
Ami eye fadaka (Silver) ni egbe ohun fun  awon ile-ile bi:Total Nigeria Plc, Julius Berger  Nigeria Plc, Berger Paints Plc ati ile-ifowopamo Guaranty Trust .
A ṣe tán láti yọ ìjìyà ikú kúrò nínú àbá ọ̀rọ̀ ìkórìra - Sẹ́nẹ́tọ̀ Sabi Abdullahi EFCC gbé Mompha afurasí ọmọ Yahoo lọ ilé ẹjọ́ lònìí Darandaran Fúlàní kankan kò ṣí kúrò l'Ọ́ṣun - olórí Fulani 'Ẹ̀yin tẹ́ẹ fẹ́ pa ara yín torí olóṣèlú, ẹ wò Fayemi àti Fayose' Inu ọkan lara awọn olugbe agbegbe naa, Bala Sani dun gidigidi lẹyin ti Emir ilu Karaye- ọkan lara awọn Emir tuntun ti Gomina ipinlẹ Kano yan, yi orukọ ilu naa pada si Yalwar Kadana, to tumọ si agbegbe ohun to pọ.
O tun yẹ ko ye wa pe ko si ẹni ti Ọlọrun ko le mu, asegbe kankan ko si si, asepamọ nikan lo wa.
Bí mo ti fi hàn ọ́ ní orí òkè, ni kí o ṣe kọ́ àgọ́ náà.
Eto pataki ni eyi jẹ fun orilẹede Liberia nitori wipe igba akọkọ niyi latọdun 1944 ti agbara o paarọ ọwọ latọwọ oloselu kan si omiran.
Oríṣun àwòrán, LASEMA LASEMA sọ pe ọkunrin ni gbogbo awọn eeyan to ninu ọkọ ofurufu ọhun to jẹ ti ileeṣẹ Quorun Aviation ni ilu Eko.
Buhari yóò rí ara rẹ̀ gẹ́gẹ́ bíi Mèsáyà yóò sì gbìmọ̀ràn sáà kẹta nípò-Dele Momodu
Ọba ni Ọrunmila jẹ onisuuru, alaanu, ati onifarada eniyan, ti oun ati Wuraọla si kuro lọ si ilu Ọrunmila lọjọ keje.
Ooni Ife ké sí olóòtú ìjọba Gẹ̀ẹ́sì tuntun pé kó má gbàgbé ìlérí tó ṣe fún gbogbo àgbáyé
O lé e pẹ títí kí ó tó padà lẹ́yìn rẹ̀.
O óo pa àwọn tí wọ́n gbé ọkàn wọn lé ọ mọ́ ní alaafia pípé,nítorí pé wọ́n gbẹ́kẹ̀lé ọ.
" O ni eto idaṣẹsilẹ, eto ọgbin ati ileeṣẹ kereje fun igbaniisiṣẹ.
O ni orilẹede Naijiria lee wo awokọṣe ajọ ọtẹlẹmuyẹ ilẹ Amẹrika, to kede orukọ awọn afunrasi ẹsun ilunijibiti lorilẹede naa, nipa gbigbe igbesẹ bẹẹ ni kiakia.
Bẹ́ẹ̀ ni àwọn ọmọ Josẹfu, tí à ń pè ní ẹ̀yà Manase ati ẹ̀yà Efuraimu ṣe gba ìpín tiwọn.
Lọ sí ojúewé tó ní orúkọ yìí tí ọ́ bá wà
Enwerem fikun wipe awọn si n wa awọn afurasi meji to ni ise pẹlu isẹlẹ naa.
- Ooni Ile Ife Ìdí tí mi ò fi lè parí ìjà pẹ̀lú Ààrẹ Ọ̀nà kakanfò, Gani Adams - Obasanjo Ìjọba ìpínlẹ̀ Eko fún ẹbí àwọn ọlọ́pàá tó pàdánù ẹ̀mí lásìkò ìwọ́de EndSARS l'ẹ́bún owó 10 mílíọ̀nù Oríṣun àwòrán, Lagos state Government Ìjọba Ìpińlẹ̀ Eko tí fi orúkọ àwọn ọlọ́pàá tó kú lásìkò ìfẹ́hónúhàn #EndSars nípínlẹ̀ Eko.
benito mussolini je oloselu omo orile-ede italia .
Ọmọ onílẹ̀ wọ gàù, ó kó sí gbaga ọlọ́pàá Ipò ètò ààbò ń já àwa gómìnà láyà, ó ń kọ wá lóminú - Àwọn gómìnà Onikaluku ṣalaye bi wọn ṣe bọ nibẹ ati ọna abayọ.
” Jakọbu rọ̀ ọ́ títí tí ó fi gbà á.
Lọsẹ to kọja ni wọn wọgile Umrah fawọn ara ita.
A ò fi físà dun Bísọ̀bù Oyedepo- US Embassy Ninu atẹjade kan ti olori ijọba Gẹẹsi Boris Johnson fi lede ni igba to ku wakati kan ki ipinya naa waye, o ni ipinnya ọhun jẹ akoko ti awọn kan ti n reti, ti wọn ko si lero pe o lee waye.
Ẹ má ṣe jẹ́ kí ẹnikẹ́ni fi ọ̀rọ̀ asán tàn yín jẹ.
Ó ń ṣe iṣẹ́ abàmì ńláńlá.
Jerameeli ọmọ Kiṣi, láti ìdílé Kiṣi.
Ileeṣe Global Sea Investment ati Grand PAct Limited ni wọn jọ fẹsun ọhun kàn.
James Titus jẹ ọba fún ọdún mẹẹdọgbọn, ayé roju, ìlú toro, tí gbogbo ìlú Ọwọ sì tuba tusẹ.
Ibukun ni fún ọ, fún ọgbọ́n tí o lò ati ohun tí o ṣe lónìí, tí o fà mí sẹ́yìn kúrò ninu ìpànìyàn ati ìgbẹ̀san.
Lọjọ Ẹti ni El-Zakzaky pada si orilẹede Naijiria lati India to ti lọ gba itọju pẹlu aya rẹ.
2bn) lati fi san owo osu awọn ọmọogun Naijiria nigbati wọn ko si lo to idaji rẹ lati san owo awọn osisẹ ni ẹka ẹkọ.
Algeria: Ààrẹ Abdelaziz Bouteflika re 'bi àgbà ń rè
Nítorí Kristi ti fi òpin sí Òfin láti mú gbogbo ẹni tí ó bá gbàgbọ́ rí ìdáláre níwájú Ọlọrun.
Duro ki esi naa fi jade Alukoro ajọ WAEC, Demianus Ojijeogu tun ṣalaye pe awọn akẹkọọ le ri esi idanwo wọn ninu atẹjiṣẹ ori foonu.
Ṣaaju ni Ogbeni Agboola ti sọrọ lori bi ZLP ṣe tẹwọ gba oun: Ẹgbẹ́ òṣèlú ZLP gbàmí tọwọ́tẹsẹ̀ láti díbò gómínà ní Ondo- Agboola Ajayi Igbakeji gomina ipinlẹ Ondo, Agboola Ajayi ti ni ẹgbẹ oṣelu Zenith Labour Party gba oun tọwọ-tẹsẹ ni oun fi fi ẹgbẹ oṣelu PDP silẹ lati lọ dije dipo gomina ninu idibo sipo gomina ni ipinlẹ Ondo.
a máa tàn sí wọn bí ìmọ́lẹ̀ òwúrọ̀,bí oòrùn tí ó ń ràn ní òwúrọ̀ kutukutu,ní ọjọ́ tí kò sí ìkùukùu;ó dàbí òjò tí ń mú kí koríko hù jáde láti inú ilẹ̀.
 O wa ro Ile Igbimọ Aṣofin Apapọ lati mu lele aabo ni agbegbe wọn lati le gegi dina iru iṣẹlẹ bayii lọjọ iwaju.
ekunwo owo osu awon osisẹ jẹ eyi ti o tako ofin.
 ""Fun idi eyi, ko si kanjukanju ninu ọrọ gbigbe ofin kalẹ"" Àjọ tó n mójútó ìpèsè òògùn ní America ti fọ́wọ́ sí lílo òògùn Ebola fí tọ̀jú Coronavirus Ìjọba Osun dẹkùn lọrun àṣẹ konile ó gbélé Ká má ri!"
Nítorí èyí ni àwọn eniyan ṣe lọ pàdé rẹ̀ nígbà tí wọ́n gbọ́ pé ó ṣe iṣẹ́ ìyanu yìí.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Man U dero Europa Chelsea ati Tottenham ti wẹ tan kan-in kan-in bayii lati ṣoju ilẹ Gẹẹsi ninu idije Champions League ni saa to n bọ.
Wọn kò ní kú, wọn kò ní wọ inú isà òkú,wọn kò sì ní wá oúnjẹ tì.
lati lee jẹ ki won bẹrẹ isẹ wọn pẹrẹu.
tun tesiwaju pe aheso oro ti awon eniyan n so pe egbe oselu All
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Zainab Aliyu: Mo sọkún títí, ojé tán lóju mi ni àhámọ Saudi Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Ìlànà nípa Ìwà Tí Ó Dára.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Chief Kanran: Mi ò ṣagbe àmọ́ mo nílò ìrànlọ́wọ́ ọmọ Yorùbá 1 Owewe 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 2 Owewe 2020 Oríṣun àwòrán, Others Ẹ́ wo ìrírí tó mú àgbà òṣèré Chief Kanran dí ẹni tí kò rí ilé gbé mọ́, ti irinṣẹ́ jóná Afiniṣẹ̀sín ní ọ̀pọ̀lọpọ̀ ọmọ Yorùbá pàápàá àwọn ọ̀rẹ́ àwa òṣèré tíátà- Olusegun Akinremi Agbaọjẹ oṣere lorilẹede Naijiria, Olusẹgun Akinrẹmi ti gbogbo eniyan mọ si Chief Kanran ti sọ iriri ati ilakọja rẹ fun awọn ọmọ Yoruba.
Ko rọrun lati fi ẹbi ati ara silẹ ni ilu tabi orilẹ-ede kan ki iwọ maa gbe ni orilẹ-ede miran.
Nígbà tí mò ń sọ èyí, nǹkankan wà tí n kò yìn yín fún, nítorí nígbà tí ẹ bá péjọ, ìpéjọpọ̀ yín ń ṣe ibi ju rere lọ.
Ẹ yipada, ẹ̀yin ọmọ Israẹli,ẹ pada sí àwọn ìlú yín wọnyi.
Elihu tún ń bá ọ̀rọ̀ rẹ̀ bọ̀, ó ní,
Lẹ́yìn náà mo lọ sí agbègbè Siria ati ti Silisia.
Ọkọ̀ rélùwéè 16 yóò ná Eko sí Ibadan láti oṣù tó ń bọ̀ lọ - Iléeṣẹ́ Rélùwéè kéde Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Ìgbà tí mo máa fi lajú sáyé padà, ọ̀fọ̀ ikú mi ní wọ́n ń kígbe' Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Ajọ ẹsọ oju popo nipinlẹ Kano ati awọn alakoso ileewe girama naa salaye fun BBC wipe, isẹlẹ buruku yii sẹlẹ nigbati ọkọ bọọsi akero ti wọn wọ ati ọkọ nla kan kọlu ara wọn.
Shiite ati ọlọpa fija pẹẹta nilu Abuja Ẹgbẹ Musulumi Shia ti fẹsun kan awọn ọlọpaa pe, wọn pa eeyan meji to n fẹhọnu han lasiko ti wọn wa se iwọde ni Ile Igbimọ Asofin apapọ ni ilu Abuja.
Garden City,nile idibo to wa ni Lekki, ni ipinle Eko.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Maryam Sanda: Àdájọ́ ní kí wọ́n yẹgi fun títí tí ẹ̀mí yóò fi bọ́ lára rẹ̀ 27 Sẹ́rẹ́ 2020 Oríṣun àwòrán, Others Maryam Sanda, ìyàwó tó pa ọkọ rẹ, ri ìdájọ ikú he Ileẹjọ giga kan to kalẹ si opopona Aguiyi Ironsi ladugbo Maitama nilu Abuja ti gbe idajọ kalẹ lonii pe iku lo tọ si iyawo kan to sekupa ọkọ rẹ, Maryam Sanda.
Adeyeye Ile Ife: Kílódé tí Ọọni Ife, Oba Ogunwusi kò fi gbọdọ̀ rí ọmọ rẹ̀ tuntun títí di ẹ̀yìn oṣù mẹ́fà?
Buhari Foreign Trips: Ìrìnàjò ààrẹ Buhari sílẹ̀ òkèèrè kò nípa kankan lórí ọrọ̀-ajé Nàijíríà
Ṣugbọn Jesu wí fún wọn pé, “Nítorí oríkunkun yín ni Mose fi kọ òfin yìí.
Àwọn ọmọ Bela ni: Adari, Gera, ati Abihudi, 
 Ẹni tí ń lu kon-kon-kolo yóò máa ṣá agogo lọ ní tirẹ ̀ ni .
Ninu adehun iṣẹ naa, Arteta yoo dari ikọ Arsenal fun ọdun mẹta ati aabọ.
Oríṣun àwòrán, Facebook/Funke Adesiyan Àkọlé àwòrán, Ọjọ kẹrinla, oṣu kẹta ni ọjọ ibi oṣere Funke Adesiyan, ọmọ ilu Ibadan nipinlẹ Oyo nii ṣe.
Ayọ̀ọlá: Tí ó bá jẹ́ bẹ̀, ẹ mú ẹ̀pà àti ṣúgà, múrí kàn-àn kàn wá
Nítorí náà, ẹ mọ́kàn gírí kí ẹ sì ṣe akin; nítorí pé Saulu, oluwa yín ti kú, àwọn eniyan Juda sì ti fi òróró yàn mí gẹ́gẹ́ bí ọba wọn.
Irú ìdájọ wò ní Ademola Adeleke gbà nílé ẹjọ ko-te-mi-lorun?
  Ninu ọrọ rẹ, Agbẹnusọ Ile Igbimọ Aṣofin Ipinlẹ
18 Ọ̀wàrà 2019 Oríṣun àwòrán, @Albert Àkọlé àwòrán, Ojo arooroda fa omiyale, agbara ya soobu ni Ghana O kere tan eniyan mejilelogun lo ti doloogbe ni orilẹ-ede Ghana bayii.
"Oríṣun àwòrán, AfricanDrumFestival Àkọlé àwòrán, ""Kani a mọ pataki idagbasoke aṣa si idagbasoke eto ọrọ aje wa, a o tẹpa mọ"" "" Ọpọ àṣà ilẹ kaarọ oojiire ni o ti n lọ, ṣugbọn a dupẹ fun awọn ti Ọlọrun nlo lati gbee soke pada."
Olayemi Oluwabamigbe Samson: Àwọn pàntí ọ̀rá omi yìí ṣì wúlò
Awọn oniṣegun meji, Dokita Yetunde Adeniyi ati dokita Tope Ojo fesi si ọrọ yii, wọn ni, bo ti lẹ jẹ pe nitootọ ni pe oun ti oju ara ilu n ri lati gba iwosan ni awọn ile iwosan ko rọrun, ọpọlọpọ ewu lo wa nidi aṣilo oogun.
O tun so pe“A gbodo lee sa ipa wa lati gbokun ti iwa aito si awon obinrin ni agbaye, paapaa julo  nipa gbigbogun ti  iwa aparo kan, ga ju okan lo lawujo wa.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù BB Naija 2019: Ọlọ́pàá Gẹ̀ẹ́sì bẹ̀rẹ̀ ìwádìí lórí Khafi lórí ẹ̀sùn ṣíṣe ìbálòpọ̀ 13 Ògún 2019 Oríṣun àwòrán, Instagram/acupofkhafi Àkọlé àwòrán, Ẹsun ibalopọ lori BB Naija Ọmọbinrin ọlọpaa ilẹ Gẹẹsi kan, PC Khafi Kareem ti wọ gau lẹyin to kopa ninu ere idije agbelewo ti wọn n pe ni Big Brother Naira.
Ó fi ìwé ranṣẹ sí gbogbo ilẹ̀ ìjọba rẹ̀, ati sí gbogbo agbègbè ati àwọn ẹ̀yà, ní èdè kaluku wọn, pé kí olukuluku ọkunrin máa jẹ́ olórí ninu ilé rẹ̀.
Ahmed ye ko fipo naa sile lojo kokanlelogun, osu keje, odun ti a wayii, sugbon
Àwọn ọmọ Lefi ati gbogbo ọmọ Juda ṣe gẹ́gẹ́ bí Jehoiada alufaa ti pàṣẹ fún wọn.
Ọlọ́pàá, sójà yabo Lekki Toll Plaza láti dènà ìfẹ̀hónúhàn míràn Wo ibi mẹ́rìnlá tí o kò gbọdọ̀ gbé ọkọ̀ rẹ sí lásìkò yìí.
Oríṣun àwòrán, Reuters Àkọlé àwòrán, Ọkunrin kan n wo awọn iwe tita ninu awọn apoti ti wọn lo lati ko ohun ija pamọ tẹlẹ nigba ogun abẹle Libya ni igboro Misrata to wa ni Libya l'ọjọ Iṣẹgun (Tuesday).
Ọmọ márùn-ún sọnù ní Otto l‘Eko, àwọn ìyá wọn kò jẹ́ èèyàn mọ́ lẹ́yìn ọdún kan 'Ẹ̀pa ò bóró mọ́!
Adugbo ti ijọba ya sọtọ, ni Agodi GRA, ni ilẹ to to pulọọ́ti mejidinlaadọta naa wa.
Koda o sọ ifẹ inu rẹ lati ma tii fẹ ni oyun ọmọ ọhun lasiko yii ṣugbọn bi Ọlọrun ṣe fẹ ni.
O ti fi ọpọlọpọ ẹ̀ṣẹ̀ rẹ tí o dá nítorí ìwà aiṣootọ ninu òwò rẹ, ba ibi mímọ́ mi jẹ́.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Promise Akinlade: ọmọ ọdún mọ́kànlá tó ń fi ìlù dárà bíi àgbàlagbà sọ̀rọ̀ nípa tálẹ́ǹtì rẹ El-Rufai, to ṣalaye ninu ọrọ kan to ba awọn eeyan ipinlẹ naa sọ ni yiyẹra oun jẹ ara ọna igi gogoro maa gun mi loju, atokere laa tii woo, ti oun n gbe lati fi dena itankalẹ arun naa, aibaamọ bi oun pẹlu ba ti koo.
Oríṣun àwòrán, Twitter/EFCC Àkọlé àwòrán, Ọrọ dii bo o lọ, oya a mi ni ile igbafẹ Club 57, ni Ikoyi, Lagos Ninu iroyin miran ẹwẹ, ajọ to n gbogun ti iwa ibajẹ lorilẹede Naijiria, EFCC, sọ wi pe, oun ti fi panpẹ ọba mu awọn afurasi ọmọ yahoo yahoo mejila, ni ile igbafẹ Club 57 ni Ikoyi ni ipinlẹ Eko.
Lẹyin naa ni wọn lọ tii m'ọle ni agọ ọlọpaa to wa ni Lugbe.
Ogbontarigi Amofin kan ni Naijiria, Olatunbosun Oyintiloye ti gboriyin fun Ogbeni Toni Iwobi to jawe olubori wole ninu eto idibo omo ile igbimo asofin ti Italy ni eyi to ni o fihan pe oro eleyameya ti n dopin lagbaye.
Ninu ipò titun yìí, kò sí pé ẹnìkan ni Giriki, ẹnìkan ni Juu; tabi pé ẹnìkan kọlà, ẹnìkan kò kọlà, ẹnìkan aláìgbédè, ẹnìkan ẹlẹ́nu òdì, ẹnìkan ẹrú, ẹnìkan òmìnira.
Nollywood Yoruba: Kìí ṣe sinimá ni mò ń ṣe, ìṣẹ̀lẹ̀ ojú ayé gangan ní sùgbọ́n.
O fi eyi gbe ọwọ adura soke si Ọlọrun o si dupẹ lọwọ awọn ololufẹ rẹ.
Ṣé lóòtọ́ ní agbára àti ipá àwọn ọmọ ogun Iran tó ó kojú tí America?
Bí Ọlọrun bá gbà fún ọ láti ṣe bẹ́ẹ̀, tí o sì ṣe é, ẹ̀mí rẹ yóo gùn, gbogbo àwọn eniyan wọnyi náà yóo sì pada sí ilé wọn ní alaafia.
Nítorí náà, lákọ̀ọ́kọ́, mo gbà ọ́ níyànjú pé kí o máa tọrọ ninu adura, kí o máa bẹ̀bẹ̀, kí o sì máa dúpẹ́ fún gbogbo eniyan, 
OLUWA sọ fún Mose pé, “Pípa ni kí ẹ pa ọkunrin náà, kí gbogbo ìjọ eniyan sọ ọ́ lókùúta pa lẹ́yìn ibùdó.
L'ọjọ kẹẹdogun, oṣu Keje ni ajọ to n mojuto isẹ igbohunsafẹfẹ ni Naijiria, National Broadcasting Commission (NBC), ti ileeṣẹ naa pa fun pe o kede esi ibo ti ajọ eleto idibo ko fọwọ si lasiko eto idibo gomina to waye lọjọ kẹrinla, oṣu Keje, ọdun 2018.
Kò gbọdọ̀ jẹ́ ẹni tí ó fẹ́ràn ìjà, tabi ẹni tí ó ní ìwọ̀ra nípa ọ̀rọ̀ owó.
Ojú ń tì mí láti rí àwọn ọmọbìnrin Nàìjíríà tó ń ṣe aṣẹ́wó ní Italy Ààrẹ Buhari padà sí Nàìjíríà lẹ́yìn àbẹ̀wò sílẹ̀ Gẹẹṣi Ọmọ naa ni yoo jẹ ẹẹkẹjọ ọmọ-ọmọ-ọmọ fun Ọbabinrin ilẹ Gẹẹsi.
òun kò le è yọ́ wá - Lekan Balogun Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Orilẹede Afghanistan ni wọn ti n gbin ogun oloro, ti wọn a si gbe gba Mozambique lọ si Europe Onimọ naa fi kun wipe, awọn onibara ma n ra oogun oloro heroin naa ni ọgọọrọ, ti wọn yoo si gbiyanju lati gba a ni orilẹede Mozambique, lẹyin ti wọn ba ti lo Whatsapp lati seto gbogbo nkan ti wọn nilo.
''Mi o le sọ bo kọrin bi ko kọrin, amọ a ti gbe lọ si ile ẹjọ lati wi tẹnu rẹ'' Àkọlé àwòrán, Lẹnu lọọlọ yi ni Gomina Ganduje ati Emir Sanusi pari ija wọn Lati igba ti wọn ti mu Abdullahi, awọn mọlẹbi rẹ ti n ja fitafita lati ri pe wọn tu silẹ.
Amọ aarọ ọjọ Isẹgun ni igbakeji gomina naa lọ sile ẹjọ lati beere pe ki ile ẹjọ da ile asofin ipinlẹ Ondo lọwọ kọ, lati mase yẹ aga mọ oun nidi.
Alaafin Oyo: Kí ló ń ṣẹlẹ̀ láàfin Oyo táwọn èèyàn fi ń ki Alaafin ní mẹ́sàn án mẹ́wàá?
Ni bayii, eka ti ki I se epo-robi, ni ojuse iko 92.
Oluwatimilehin Adeniyi lo fọba lee fun Naijiria nigba ti ere bọọlu ọhun ku iṣẹju mẹjọ ti yoo fi pari.
Amọ, bi igba ba ṣe n lọ, owo epo yoo walẹ si, ti iye ti wọn yoo ma ta a yio si yatọ si ara wọn bi igba ba ṣe n lọ.
Ní ọpọlọpọ ìgbà ni mo wà lórí ìrìn àjò, tí mo wà ninu ewu omi, ewu lọ́wọ́ àwọn ọlọ́ṣà, ewu láàrin àwọn ọmọ-ìbílẹ̀ mi, ewu láàrin àwọn tíí ṣe Juu, ewu ninu ìlú, ewu ninu oko, ewu lójú òkun, ati ewu láàrin àwọn èké onigbagbọ.
Wọn bi Abdelaziz Bouteflika ni Morocco ni ọjọ keji oṣu kẹta ọdun 1937; ara orilẹede Algeria lawọn obi rẹ.
ọdọ ẹgbẹ oselu naa lojo Isegun.
Wo bí o ṣe lè kọ́ ọmọ rẹ lẹ́kọ̀ọ́ ìbálòpọ̀ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ọ̀dọ́kùnrin tó kọ́kọ́ ṣe ẹ̀rọ tó ń tu ìyẹ́ lára adìyẹ Obi àwọn ọmọdebinrin Chibok ṣi ni igbagbọ ninu Olọrun pe lọjọ kan ni awọn yoo foju kan awọn ọmọ awọn ti wọn jẹ mejilelaadọfa (112) laipẹ.
Àìní sí iná mọ̀nàmọ́ná ní Eko ló ń kọ áwọn èèyàn lóminú Ti iroyin naa ba jẹ́ ootọ, o kere tan ekunwo epo bẹntiroo lati naira marundinlaadọjọ si naira mọkanlelaadọjọ,₦151.
" Lẹyin eyi ni Adajọ sọ pe igbeyawo naa ti di titu ka, to si paṣẹ fun ọkọ iyawo, Chike, lati san ẹgbẹrun lọna aadọjọ Naira fun Chioma gẹgẹ bi owo ipinya, eyi ti yoo fi bẹrẹ igbeaye tuntun.
Bí o ti ń rìn bọ̀, o kó ọ̀pọ̀lọpọ̀ kùmọ̀ sí ọwọ́ òsì.
Iroyin sọ pe ṣe lawọn agbebọn da a lọna oko ti wọn si ji i gbe lọ ibi aimọ.
 A mo pe olorun wa pelu wa, a si nigbagbo ninu re; a mop e yoo dari wa lo sibi aseyori.
Nigba ti o n fi kun ọrọ naa, Alaga LASCOTA ti Agboyi-Ketu, Ọgbẹni Adeniyi Akintọla fi mulẹ pe riro awọn ọdọ lagbara lo jẹ ẹgbẹ naa logun, eleyii ti yoo le ṣadinku iwa ipa ti awọn ọdọ n hu ni awujọ bayii.
Àkójọpọ̀ orin àkọ́kọ́ tí Burna Boy gbé jáde ní ilé ìporin pọ̀ ni o pe àkọ́lé rẹ̀ ni L.
Epe mi yii yoo si gbe yin de ori òkun ati ikọja rẹ, awọn ẹru ni yoo maa dari yin, ti awọn adari yin yoo si di ẹrú, bẹẹ ni ilu yin ko ni roju, alaafia ko si ni si nibẹ.
Àwọn àwòrán ọlọkan o jọkan tí ń tọka àyájọ òmìnira Nàìjíría Ìwà pẹ̀lẹ́ àti iṣẹ́ takuntakun ló mú mi ṣàṣeyorí- Pryce Ọnà tí mo fẹ́ gbà láti fòpin sí súnkẹrẹ fàkẹrẹ ọkọ̀ l'Eko rèé - Sanwo-Olu Má ṣé tọrọ aforijin lọ́wọ́ Buhari lásìkò àbẹwò rẹ- South Africa 13: CHAD: Ilu yii wa ni Ila Oorun Adulawọ ti o n fun ọmọ Naijiria ni anfaani iwe aṣẹ igbelu.
Ọpọlọpọ eniyan ati àwọn orílẹ̀-èdè ńlá yóo wá sin OLUWA àwọn ọmọ ogun, wọn óo sì wá wá ojurere rẹ̀ ní Jerusalẹmu.
 Ṣe Eyo Charles ti dariji Fani-Kayode?"
" O wa rọ awọn ọmọ ilẹ Yoruba ki wọn lọ gba kaadi idibo wọn.
  Bí ènìà bá ṣe nsúnmọ́n-ọn lọ ni yó máa pàdé àwọn ènìà míràn tí wọ́n gba ọ̀nà ọ̀tọ̀ọ̀tọ̀ dé ibi ọ̀kúta yìí.
Osinbajo sọ èyí di mímọ̀ níbi àpérò kan ní ìpínlẹ̀ Eko, O ní  mó ro pé ǹkan tí kìí jẹ́ ki n sùn lórun ni bí òsì àti ìṣk ṣe gbilẹ̀ tó ni orílẹ̀-èdè yiìí àti pé ọ̀pọ̀ àwọn yo dìbò fún wa ní àwọ otoṣì pátápátá yìí."
Ohun tí ayé ń fẹ́ lára eniyan ni òtítọ́ inú,talaka sì sàn ju òpùrọ́ lọ.
Bí olúkúlùkù ti ń mu omi Ẹ̀jẹ̀ lo ń kígbe sókè ti o tún ń dárúkọ ọ̀sọ̀ tí òun ti ṣẹ̀ sẹ́yìn.
Bẹẹ ni eeyan kan ṣoṣo ko lee gbe ju $2,800 silẹ lọ.
Nípa iṣẹ́ kọ́ ni Abrahamu baba wa fi gba ìdáláre, nígbà tí ó fa Isaaki ọmọ rẹ̀ lọ sí orí pẹpẹ ìrúbọ?
O ni oun ko nifẹẹ lati dupo
Àwọn òkè Israẹli yóo di ahoro tóbẹ́ẹ̀ tí ẹnikẹ́ni kò ní gba ibẹ̀ kọjá.
"Awọn arinrinajo miran to tun jajabọ lọwọ ajinigbe: ""Nibẹ ni ọkan lara awọn awakọ naa ti n yi nilẹ, to si n dupẹ lọwọ Ọlarun pe o da ẹmi oun si, ti ko si tun bọ si igbekun awọn ajinigbe."
Àwọn náà óo sì dáhùn adura Jesireeli.
Angẹli náà sọ pé “Ìwà ìkà ni obinrin yìí dúró fún.
Bielsa and the Leeds squadIko agbaboolu FIFA ti o dara julo (FIFAPro men’s world XI) – Alisson; Matthijs De Ligt, Marcelo, Sergio Ramos, Virgil Van Dijk; Frenkie De Jong, Eden Hazard, Luka Modric; Cristiano Ronaldo, Kylian Mbappe, Lionel MessiIko ti awon obinrin (FIFPro
Samson Siasia jẹ agbabọọlu to pegede fun Naijiria ni ọpọlọpọ ọdun ko too di akọnimọọgbaÀjọ Fifa fòfin de Samson Siasia títí láíláí .
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Lagos police: Wọ́n ti gba'ṣẹ́ lọ́wọ́ ọlọ́pàá ọ̀mùtí 7 Bélú 2018 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 8 Bélú 2018 Oríṣun àwòrán, Lagos State Police Command Àkọlé àwòrán, Fidio ṣafihan Inspẹkitọ Kadima Useni níbi to ti mu óti yo Ọlọ́paa kan Kadima Useni to di olokiki nigba ti fidio ṣe afihan rẹ nibi to ti mu ọti yo ni agbegbe Akowonjọ, Dopemu ni ilu Eko ni ọga agba ọlọpaa Ibrahim Idris ti paṣẹ pe ki wọn gba iṣẹ lọwọ rẹ.
Oluwa rẹ, àní OLUWA Ọlọrun rẹ, tí ń bẹ̀bẹ̀ fún ẹ̀ṣẹ̀ àwọn eniyan rẹ̀ ní,“Wò ó!
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Coronavirus: Ìjọba àpapọ̀ fi Austria, Sweden kún àwọn orílẹ̀èdè mẹ́tàlá tí kò lè wọ Nàìjíríà 20 Ẹrẹ̀nà 2020 Oríṣun àwòrán, Getty Images Ijọba orilẹede Naijiria ti fi orukọ orilẹede Sweden ati Austria kun awọn orilẹede mẹtala miran ti wọn se ilẹkun ati wọ orilẹede Naijiria mọ.
19 Èrèlè 2020 Oríṣun àwòrán, Getty Images Ìròyìn tó n tàn kan lórí ayélujara ní pe ara adiye Broiler ni àwọn ènìyàn ti n ko àìsàn Coronavirus (COVID19) kalẹ̀, ni NCDC ti sàlàye pé ìròyìn ẹléjé ni .
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Báyìí ni àwọn olùdíje ìpínlẹ̀ Eko ṣe fẹ́ kojú ìṣòro ìlera 27 Sẹ́rẹ́ 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 28 Sẹ́rẹ́ 2019 Oríṣun àwòrán, Babatunde Olalere Gbadamosi/Facebook Àkọlé àwòrán, àwọn olùdíje ìpínlẹ̀ Eko Ọpọlọpọ ni ipenija to maa n koju ilu kan, bẹẹ naa ni ipinlẹ Eko n koju tirẹ.
Ni ipari o ro awon eniyan lati maa da idoti nu bi o ti ye ki alaafia le tubo joba lawujo wa.
Iroyin ni aṣẹ naa ko ṣẹyin ipade ati atilẹyin lati ọdọ awọn gomina ipinlẹ, adari ileewe, awọn adari awọn akẹkọọ ati awọn akẹkọọ.
egbe won, lati maa fi alatako won se ẹlẹya tabi se yẹyẹ bi won se n se ajọyọ
"Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Mercy Aigbe: Èmi ni ìyá onílé tuntun Isẹ́ bọ́ lọ́wọ́ Ọ̀jọ̀gbọ́n tó fẹ́ bá akẹ́kọ̀ọ́ lò pọ̀ Ọwọ́ tẹ ọmọ ẹgbẹ́ ISIS 2 ní Abuja ""Sé wọn rí òsìsẹ́ ilé ìfowó-pamọ́ (Banker) kankan, kó máa se àfihàn mọ́tò àbí ilé wọn lórí afẹ́fẹ́?"
" Amọ Toufah Jallow sọ fun BBC pe, oun fẹ ẹ fi oju kan Jammeh nile ẹjọ ko le doju kọ idajọ.
Oríṣun àwòrán, @ekitistategov BBC Yoruba yoo maa mu ẹkunrẹrẹ ijiroro awọn mejeeji wa fun yin laipẹ.
    Mo kọ̀wé tí ó níláárí sí i, mo sì kọ sí bàbá rẹ̀ pẹ̀lú, bàbá rẹ̀ fèsì o ní bí ọmọ òun bá ti wí pé mo wu òun ó parí, kí a má fẹ́ ara wa.
O ya yin lẹnu pe akukọ ṣe iku pa ọlọpaa abi?
Lẹhin ti àwọn Ìlú-Ọba pin àwọn ọ̀pọ̀lọpọ̀ ilú àwọn Aláwọ̀dúdú, iṣẹ́ Agbẹjọ́rò di ki kọ́ ni ilé-iwé giga.
Agbẹjọrọ fun ijọba to fi ẹsun naa kan wọn, Martins Leo ni ki wọn ti Nehemiah mọ atimọle, ki iwadii fi pari lori ẹsun iṣekupa Tolulope Arotile ti wọn fi kan an.
O o mọ pe oun mu omi bi o ti yẹ ti o ba n lọ ile igbọnsẹ looree koore ti itọ rẹ si mọ, ti ko pọn ti ko si tun ni oorun.
Mo rí àwọn ọmọ Efuraimu bí ẹran àpajẹ; Efuraimu gbọdọ̀ kó àwọn ọmọ rẹ̀ jáde fún pípa.
Ó ní, Ṣebí Hesekaya yìí kan náà ni ó kó gbogbo oriṣa kúrò ní Jerusalẹmu ati ní Juda tí ó sọ fún wọn pé ibi pẹpẹ kan ṣoṣo ni wọ́n ti gbọdọ̀ máa jọ́sìn, kí wọn sì máa rúbọ níbẹ̀?
Nítorí pé mo ti di arúgbó; iyawo mi alára náà sì ti di àgbàlagbà.
Ògiri tó gbé Nàíjíríà ró ń mì tìtì, ó sì le wó - Osinbajo figbe ta Laycon, kú oríire àmọ́ bá ń kó owó orí nínú ẹ̀bùn rẹ nílé BB Naija - Ìjọba Eko Bamiloye sisọ loju rẹ faraye pe, oun kii ṣe pasitọ tabi adari ijọ kankan gẹgẹ bi awọn eeyan ṣe ma n fi oju wo bi igbagbọ rẹ ti gbona to.
Akinwumi Adeṣina ti jẹ minisita eto ọgbin fun orilẹ-ede Naijiria ri.
N óo tẹ́tí sílẹ̀ sí òwe;n óo sì fi hapu túmọ̀ rẹ̀.
Ohun tí a bá pè ní èdè gbọ́dọ̀ jẹ́ ohun tí a fí ìró èdè gbé jáde.
Bákan náà ni ilé ẹjọ tún fi kún-un pé àwọn ẹsùn míràn tó wà nibẹ̀ kìí ṣe ǹkan ti ó kan ilé ẹjọ́ bíkòṣe ǹkan ti wọ́n yóò lọ yanju láàrin ara wọn ninu ẹgbẹ́, nítori náà ó da ẹjọ́ ọhun sígbó.
Ogbeni Mnangagwa, ti o bere isakoso re lati osu kokanla odun ti o koja, so lasiko iwode re pe, aawo pelu ile biritiko ti dopin bayii.
Wá kẹ́kọ̀ọ́ nípa ègé ọ̀rọ̀ ohùn Yorùbá tí a mọ̀ sí Sílébù Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí D.
’ Àwọn ọmọ yín sì lè mú kí àwọn ọmọ wa má sin OLUWA mọ́.
Gbajugbaja iranṣẹ Ọlọrun naa yoo maa fojubale ẹjọ ni itẹsiwaju igbẹjs ẹsun ijọmọgbe ti wọn fi kan an niwaju ile ẹjọ giga kan nilu Akurẹ.
Samuẹli ní, “Bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé o kò jámọ́ nǹkankan lójú ara rẹ, sibẹsibẹ ìwọ ni olórí gbogbo ẹ̀yà Israẹli.
Kini itumọ ‘International passport’ l'ede Yoruba?
Ọ̀rọ̀ náà ni èyí, ẹ̀yin ènìyàn wa.
Oríṣun àwòrán, Road safety Ìròyìn ni ijàmba ọkọ̀ náà kan àjàgbé akẹ́ru to yawọ inú ọjá to si pa ọ̀pọ̀.
N óo gbà yín kúrò ninu gbogbo ìwà èérí yín.
Ṣugbọn nítorí ti Dafidi baba rẹ, n kò ní ṣe ohun tí mo fẹ́ ṣe yìí ní àkókò tìrẹ.
Aare Kagame beere boya awon ile-ijosin yii n se anfaani fun awon eniyan, ni eyi ti o so pe, won n sakoba fun eto aabo orile-ede naa.
5m owó oúnjẹ El-Zakzaky lè bọ́ ẹlẹ́wọ̀n 208 ní oṣù kan Wàhálà bẹ́ sílẹ̀ láàrin àwọn ọlọ́jà ni Ògùnpa, Ìbàdàn Oloyelogun ti wọn yọ nipo wa lori ijoko ni gbogbo asiko ti ariwo ati ys loye fi n waye.
Lára àwọn to bá BBC Yoruba sọ̀rọ̀ lori iṣẹ̀lẹ̀ yìí, wọ́n sàlàyé pé, bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé kò si eyí to sẹlẹ̀ si àwọn gangan síbẹ àwọn fi ojú ri láti ọ̀ọ̀kan bi àwọn ọmọ jàndùkú ṣe n kó , ọbẹ, àdá, òkúta àti igò, ti wọ́n a si maa rin ni ọ̀wọ̀ọ̀wọ́ láti wọ ilé tabi já sọọ̀bù Gẹ́gẹ́ bi ọkùnrin kan to n gbé agbègbè, Agbado Ijaye se sọ pé òpópóna ti o jẹ ikéji si òun ni oun ti ri bi àwọn ọdọ ti ọjọ ori wọ́n ko ti le jú ogun ọdun lọ se pa itú orísiri.
Oríṣun àwòrán, Dino Melaye/Facebook Àkọlé àwòrán, Kò sí ọ̀nà lábẹ́ òfin fún àwọn ará ìlú látí ṣe ìpàdé ìta gbangba tí wọ́n fi lè dìbò yọ Dino Melaye E ó rántí wípe iroyin ti kọ́kọ́ tè wá lọ́wọ́ p, iriri oríṣiríṣi lo wáyé ní awon ẹkùn ìdìbò ti àyẹwò orúkọ tí wáyé.
Wọn kò ní fi ìbọ̀rìṣà kankan, tabi ìwà ìríra kankan tabi ẹ̀ṣẹ̀ wọn, sọ ara wọn di aláìmọ́ mọ́.
Dẹtí sí adura mi;kí o sì tètè dá mi lóhùn nígbà tí mo bá ké pè ọ́.
Idà ni wọn yóo fi pa àwọn ìlú olódi yín tí ẹ gbẹ́kẹ̀lé run.
Ṣugbọn Sebulu dá a lóhùn, pé, “Gbogbo ẹnu tí ò ń fọ́n pin, tabi kò pin?
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ifẹhonuhan Lẹkki lori ẹkun owo irinnọ Nigbati akọroyin wa se abẹwo si ile iṣẹ ti o n se amojuto ati akoso eto irinna, ko si ẹni ti o dahun ibeere akọroyin wa.
Nígbà tí ó yá, tí ibinu ọba rọlẹ̀, ó ranti ohun tí Faṣiti ṣe, ati àwọn àṣẹ tí òun pa nípa rẹ̀.
Onírìkíṣí wí fún àwọn ọ̀rẹ́ rẹ̀ wí pé òun da aṣọ bora, ṣùgbọ́n nígbà tí olóòótọ́ dé ó tọ́ka si ọkùnrin náà wí pé ìhòohò ni ó wà gidigbi.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Àríyá yá!
Eyi wa fun awọn to n ṣeto irinna loju omi, ofurufu ati oju'rin.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, EkitiRapeCastration: ìgbésẹ̀ míì lè dẹ́kun ìwà ìfipábánilòpọ̀ Fatima ni ohun to ṣokunfa fidio naa ni pe ẹbi oun ko tete ri aaye palẹmọ kuro ninu ile naa nitori ibi iṣẹ ni eyi ti oun ati ẹgbọn oun obinrin si wa ṣe ni ọjọ Abamẹta ọsẹ naa.
ede Naijiria ni o lẹtọọ si iru owo bẹẹ.
Lodi si ero ọpọ eeyan, ọti lile kii mu oorun kun eeyan tabi mu ki ara balẹ.
Ṣebí òfin náà sọ nípa nǹkan wọnyi.
‘Ilé ẹjọ́ kò gbé ẹ̀sùn ìfipánílòpọ̀ yẹ̀wò, à ń lọ sí ilé ẹjọ́ - Busola Dakolo Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Bí baba rẹ̀ bá lòdì sí ẹ̀jẹ́ náà ati ìlérí tí ó ṣe, nígbà tí ó gbọ́ ọ, ọdọmọbinrin náà kò ní san ẹ̀jẹ́ náà, OLUWA yóo dáríjì í nítorí pé baba rẹ̀ ni kò gbà á láàyè láti san ẹ̀jẹ́ rẹ̀.
Ìwádìí fi han pé ẹlikọ́pítà náà ni ìwé to pé pérépéré ti o si yẹ láti má a rin lójú òfurufú ti o si múlẹ̀ títí di ọjọ́ kẹfa ọsù kẹjọ ọdún 2020.
Iwe iroyin Daily Mail gbe e pe wọn ri oku obinrin naa to jẹ ẹni ọgbọn ọdun, ni isalẹ ile ọhun to wa ni ilu St Petersburg l'orilẹede Russia, lalẹ ọjọ karun un, oṣu Keje lasiko ti ariya kan ti awọn araadugbo sọ pe o larinrin pupọ.
Nítorí náà àwọn ọmọ Lefi yan Hemani, ọmọ Joẹli ati Asafu, arakunrin rẹ̀, ọmọ Berekaya, ati àwọn arakunrin wọn láti ìdílé Merari, arakunrin wọn, Etani ọmọ Kuṣaaya.
Ó ní ìlẹ̀kùn mejila, àwọn angẹli mejila wà níbi àwọn ìlẹ̀kùn mejila náà.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Mo kàn máa ń lọ́ ayẹyẹ kiri torí ijó láì ṣe pé wọ́n pe mí ló sọ mí di DJ olórin Fuji nìkan' Báyìí ni Àrẹ̀mọ Ooni Adeyeye Ogunwusi ṣe wọ ṣọ́ọ̀ṣì fún ìgbà àkọ́kọ́ láti bá bàbá rẹ̀ ṣe ìdúpẹ́ ìwúyè Ẹ wo nkan tí àwọn akẹẹgbẹ́ Lateef Adedimeji sọ nípa f'ọ́tò ìgbéyàwó òun àti Adebimpe tó jáde Adedimeji ní àdìtú layé, Toyin Abraham sọ pé kò sẹ́ni tó lè táyé lọ́rùn Saheed àti Fathia Balogun dìjọ ń ṣe ọjọ́ ìbí lónìí, ẹ wo àjọṣepọ̀ tó wà láàrin wọn Ìrìnàjò Toyin Abraham, láti orí gbèsè jíjẹ, ó di onílé, onimọto àti aya lọ́ọ̀dẹ̀ ọkọ Adebimpe ni ọrẹ timọtimọ ni oun ati Lateef, ti ko si si ọrọ ifẹ laarin wọn.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù NLC: Àwọn olósèlú ń la títì láì sanwó osù torí owó tí wọn yóò rí lórí àkànse isẹ́ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ NLC: Àwọn olósèlú ń la títì láì sanwó osù torí owó tí wọn yóò rí lórí àkànse isẹ́ 29 Owewe 2018 Iyansẹlodi awọn osisẹ ijọba lẹlẹkajẹka n wáyé ni orilẹ-ede Naijiria nitori owo osu to kere pupọ ti wọn ni ijọba n san fawọn.
igberu ba iṣẹ wa, titi debi lilo ẹro igbalode.
Kò tún nílò pé kí á máa pọ́n ara wa fun yín mọ́.
Igbakeji aarẹ, Oṣinbajo woye ọrọ yii nibi idanilẹkọọ to gbe kalẹ fun ayẹyẹ ikẹkọgboye ẹlẹẹkẹjọ iru rẹ ti fasiti UNIOSUN nilu Oṣogbo.
“Ẹnikẹ́ni ninu àwọn ọmọ Israẹli, tabi àwọn àlejò tí ń ṣe àtìpó láàrin wọn tí ó bá lọ ṣe ọdẹ tí ó sì pa ẹran tabi ẹyẹ tí eniyan lè jẹ, ó níláti ro gbogbo ẹ̀jẹ̀ rẹ̀ sílẹ̀ kí ó sì wa erùpẹ̀ bò ó.
Oloye Adedayọ salaye pe bi o ba jẹ lawọn ilu kan ni; ti wọn ba fẹ ki kabiyesi tete fi oju kan ọmọ rẹ, wọn lee fa irun ọrun rẹ ni ọjọ keji.
O wa tun fikun pe, ile ise oun ti yan awon ti yoo maa
IȘẸ́ OLÙKỌ́ Ẹ bá mi kírà, Fún gbogbo olùkọ́ ayé pátá.
Oríṣun àwòrán, @realDonaldTrump Àkọlé àwòrán, Èmi ni Ààrẹ tó ṣe rere fún ilẹ̀ adúláwọ̀ jù - Donald Trump Ọgbẹni Joe Biden bu ẹnu atẹ lu Trump pe o n fi ọrọ to wa nilẹ yii fa oju awọn alatilẹyn rẹ mọra ni pe o n tẹ ifẹ orirun rẹ lọrun ni""."
O ṣẹṣẹ pe ẹni ọdun mẹtalelaadọta, to si ti de oke tente aye rẹ gẹgẹ bii akọrọyin to ti ṣiṣẹ fun ọgbọn ọdun.
Ilé agbọ́n já lé e lórí; agbọ́n ta á lójú àti nímú.
Loju opo Twitter wọn ati t'awọn mii bíi iyawo aarẹ Amẹrika tẹlẹ, Hillary Clinton niṣe ni wọn n kesi aarẹ Buhari lati dẹkun ipaniyan to n waye.
" Lẹyin naa lo rọ awọn eeyan agbegbe Akinyele lati máa ba iṣẹ oojọ wọn lọ nitori awọn ọlọpaa yoo ṣe ojuṣe wọn lati tun ọdaran ọhun mu ati lati daabo bo awọn eeyan ọhun.
Bii lẹta gbọọrọ tabi episteli gẹgẹ bi awọn to da si ọrọ naa ṣe sọ ọ ni Tacha kọ ranṣẹ si awọn ololufẹ rẹ ati ti BBNaija.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Super Eagles kò rántí kó ohun eèlò ìgbábọọlu wọn dání 9 Owewe 2019 Oríṣun àwòrán, @NFF Àkọlé àwòrán, Super Eagles kò rántí kó ohun eèlò ìgbábọọlu wọn dání.
 Jijawe olubori re je ohun ti
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìwádìí ilé aṣòfin foríṣánpọ́n lórí ẹ̀sùn Gómìnà Ganduje 13 Bélú 2018 Oríṣun àwòrán, DWasiu Alaga igbimọ ẹlẹni meje nile aṣofin ipinlẹ Kano to n ṣewadi Gomina Abdullahi Ganduje sọ pe awọn ti dawọ iṣẹ duro na lori ọrọ rẹ.
Ẹwẹ, minisita abẹle fun eto ẹkọ, Họnọrebu Emeka Nwajiuba sọ pe ijọba apapọ ko tii sọ ọjọ ti awọn ileewe yoo wọle jakejado ṣugbọn ọjọ eyi tawọn ijọba ipinlẹ kede n kọ awọn obi lominu gidi gan.
Eyi ko sẹyin bi awọn ibi kan lara ògiri ati òpó ile naa, ṣe ti sán, nitori ibugbamu to waye.
Lakotan wọn yoo fun ileewe ti ko ba ni ibudo itọju alaisan lanfani lati maa lo awọn mii to wa nilu.
Gege bi Groeneveld  se so“Maria je okan gbogi, akikanju, eni to n sise karakara lara awon ti mo ti ba sise po seyin, bee sini Mo ni owo pupo fun.
Nígbà náà ni n óo tìtorí tirẹ̀ bá àwọn ẹranko, àwọn ẹyẹ, ati àwọn nǹkan tí ń fi àyà fà lórí ilẹ̀ dá majẹmu, n óo sì mú ọfà, idà, ati ogun kúrò ní ilẹ̀ náà.
Nítorí ẹ ti kú, ẹ̀mí yín wà ní ìpamọ́ pẹlu Kristi ninu Ọlọrun.
Iroyin ni ijamba yii fa sunkẹrẹ-fakẹrẹ ọkọ ni eyi to fi kan awọn ọkọ to n rin ni opopona mejeeji awọn to n lọ ati awọn to n bọ pada wọnu Eko.
Gomina ṣe ikéde yìí lósàn oni lásìkò to n ba àwọn oniroyin sọ̀rọ̀, o ní gbogbo àwọn to ba n ta ọjà ti ko niṣe pẹlu Ounjẹ jijẹ àti àwọn to nta òògùn fun ilé ìwòsàn tàbi ọlọdani ki wọ́n jòkó silẹ̀ fun ọṣẹ kan.
Ẹlẹ́wọ̀n Kirikiri tó ń wọ́ke, olùdarí ọgbà ẹ̀wọ̀n ló ṣe onígbọ̀wọ́ fun - EFCC Awọn ẹka to se koko ninu eto isuna 2020 nipinlẹ Ọyọ: Ipo Kinni: Eto isẹ ode ati ipese awọn ohun eelo amayedẹrun Ẹka eto isẹ ode ati ipese awọn ohun eelo amayedẹrun lo ko ipin to pọ julọ ninu eto isuna ọdun 2020 nipinlẹ Ọyọ eyi ti apapọ owo ti wọn bu fun ko ida mẹtalelogun ati diẹ, 23.
Ẹ̀ẹ̀meje ni mo pinnu àti pa Ìrìnkèrindò tí ko ṣe é ṣe.
Shehu ṣalaye pe awujọ ni Amotekun yoo ti maa ṣiṣẹ, nitori awọn awujọ yii gan an lo ni Amotekun.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Buhari lọ sí Plateau sùgbọ́n kò dé àwọn ìlú tó rí ìkọlù Ilé yá!
Ireti baba Olumide Ayẹni ni pe ki Olorun ati ijọba ṣe idajọ ọrọ yii bo ti yẹ.
Àwọn jàndùkú dáná sun Aṣáájú obìnrìn ẹgbẹ́ òṣèlú PDP mọlé ní Kogi Àwọn ọnà ti Olusegun Aroke ń gba wọ́'ke owó nínú ọgbà ẹ̀wọ̀n rèé Ẹ wo fídíò Kìnìhún tí wọ́n mú l'Eko ní ibùgbé rẹ̀ tuntun, Bogije, Lekki Seyi Makinde kò leè gba adé lórí àwa ọba 21, iléẹjọ́ ni yóò là wá níjà - Lekan Balogun 'Iṣẹ́ akólẹ̀ tí mò ń ṣe níbí, mi ò lè ṣe é láí lái ní Nàìjíríà tórí.
Ilé wo pà 'yàn meji l'Èkó
Ẹwẹ, awọn alaṣẹ ileeṣẹ ogun Naijiria ti fagile ipade idanilẹkọ naa eyi to n lọ lọwọ ni ilu Abuja.
Agbẹnusọ ọlọpa, ASP Abimbọla Oyeyẹmi sọ fun BBC pe awọn ọlọpa ti pese awọn ikọ ọlọpa lati ṣe ayẹwo ati ṣawari awọn eniyan ti o to bii ogun ti wọn wọlu wa lati ibilẹ Kaiama ni Ipinlẹ Kwara wa si agbegbe Opeji ni Abeokuta lọjọ ẹti.
Akọwe Ajọ Nigerian Supreme Council for Islamic Affairs, Ọjọgbọn Ishaq Oloyede ti ni ofin ijinasiraẹni lasiko arun Coronavirus ko tako ẹsin Musulumi.
Bí wọ́n ti ń lọ, ìhà ibi tí wọn bá fẹ́ ninu ìhà mẹrẹẹrin ni wọ́n lè máa lọ láì ṣẹ̀ṣẹ̀ yíjú pada, kí wọ́n tó máa lọ.
Ibeere ti gbogbo aye fi lẹnu ni wipe, ta lo pa awọn ọkunrin mẹta yii?
Igbiyanju lati ba ijọba ipinlẹ Kogi sọrọ, ṣugbọn ko tii so eso rere.
Àwọn alufaa ati àwọn ọmọ Lefi wẹ ara wọn mọ́, wọ́n sì ṣe ìwẹ̀mọ́ fún àwọn eniyan ati àwọn bodè ati odi ìlú náà.
Ní ìbẹ̀rẹ̀ ìgbé ayé rẹ̀, ó ṣípòpadà pẹ̀lú ẹbí rẹ̀ lọ sí Manchester ọjọ́ òní, ní ìwọ̀ oòrùn New York.
Chris Daizell: Ọ̀pọ̀ èèyàn ló ń bú mí, wọ́n ní mo dàbí ọ̀daràn
 Ati awọn ibeere miiran ti awọn ara agbegbe idibo Koṣọfẹ keji yii fi ṣọwọ si aṣofin naa lati ba wọn gbe igbesẹ lori wọn.
Chloroquine: Àwọn oníṣègùn òyìnbò ní China sọ pé Coronavirus o le duro wo tan
Ojuṣe ijọba ni lati daabo bo araalu."
Biṣọọbu naa ni, bo tilẹ jẹ pe oun ti fi igba kan dakẹ lori ọrọ Naijiria, ṣugbọn oun ti kilọ ṣaaju ninu ọdun 2015 pe, ewu n bẹ loko longẹ ni Naijiria, ati pe gudugbẹ kan yoo ja laipẹ.
Sugbọn opọ eeyan nigbagbọ wipe igbimọ naa yoo f'ọ̀wọ si gbogbo nkan ti wọn ba ni ko f'ọwọ si.
Bẹ́ẹ̀ sì ni bí olódodo bá dẹ́ṣẹ̀, kò ní yè nítorí òdodo rẹ̀.
Kọ́lá ni ó ràn wọ́n lọ́wọ́ láti mọ ilé yìí.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Premature babies: Ọ̀nà tí orin gbígbọ́ fi ń ṣèrànwọ́ f'ọpọlọ ọmọ ìkókó rèé Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Premature babies: Ọ̀nà tí orin gbígbọ́ fi ń ṣèrànwọ́ f'ọpọlọ ọmọ ìkókó rèé 18 Ògún 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 7 Òkùdu 2020 N jẹ ẹyin mọ pe orin gbigbọ fawọn ọmọ tuntun jojolo maa n ṣe iranwọ nla fun ati dagba ọpọlọ wọn?
”Adari agba ninu ile-ise naa nile Afrika, ogbeni Aruleba Olumide so pe, “Inu ile-ise Cadbury Nigeria Plc, dun pupo lati satileyin fun Super Eagles, besini O kin won leyin lati lo kopa ti o tayo ni Russia.
Ṣugbọn nítorí pé ibi ni o ṣe, ẹ̀ṣẹ̀ ba dè ọ́ lẹ́nu ọ̀nà rẹ, ó fẹ́ jọba lé ọ lórí ṣugbọn tìrẹ ni láti ṣẹgun rẹ̀.
O ti to ọjọ melo kan to ti n kajọ de ere ori itage tuntun to fẹ gbe jade eyi to pe akọle rẹ ni The Prime Minister's Son.
A ti jagun ní Nẹgẹbu ní agbègbè Kereti ati ní agbègbè Juda ati ní agbègbè Nẹgẹbu ti Kalebu, a sì sun Sikilagi níná.
Pẹlu iye awọn eeyan tuntun yii, o ti pe 58,062 eeyan to ti ni arun naa l'orilẹede Naijiria bayii.
Idi ni pe ọpọ ipa ribiribi ni MKO Abiọla ko si ẹka oselu, okoowo, aanu sise, agbega ọrọ aje ati ipese awọn ohun eelo amayedẹrun yika tibu tooro Naijiria.
OLUWA tún bá mi sọ̀rọ̀, ó bi mí pé: 
tí mò ń rí ọpọlọpọ wàrà lára àwọn ẹran ọ̀sìn mi,ati ọpọlọpọ òróró lára igi olifi tí ń dàgbà láàrin òkúta!
Alaga ajọ LSESSOT, Yinka Egbeyemi ṣalaye pe ajọ naa mu awọn eeyan naa pẹlu ọkọ akẹru ti wọn wa ninu rẹ lagbegbe Agege lẹyin tawọn olugbe ilu Eko kan ta wọn lolobo pe ihuwasi awọn ọdọmọkunrin naa le ṣakoba fun eto aabo niluu Eko.
Mo kìlọ̀ fún àwọn baba ńlá yín ní ọjọ́ tí mo kó wọn kúrò ní ilẹ̀ Ijipti, títí tí ó sì fi di òní, n kò yé kìlọ̀ fún wọn pé kí wọ́n fetí sí ohùn èmi OLUWA.
Ile ejo ohun so pe, awon agbejero ohun ko lati pese eri ti o daju ti o le fihan gbangba-gbangba pe Bukola Saraki jebi esun ti won fikan ohun.
Okechukwu soro yii ,nigba to n dahun ibeere lodo awon oniroyin nibi ajodun  ayeye Igwa Nshi, niluu re ni Eke , ni  ijoba ibile Udi,ni ipinle Enugu.
Wọ́n sọ fún un pé, “Kò sí ẹnìkan ninu àwọn mọ̀lẹ́bí rẹ tí ó ń jẹ́ orúkọ yìí.
Kini ijọba Naijiria ni lọkan fun awọn ti wọn n ko bọ pada sile -Abikẹ Dabiri?
Ní oṣù kẹta tí àwọn eniyan Israẹli kúrò ní ilẹ̀ Ijipti ni wọ́n dé aṣálẹ̀ Sinai.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ilé ẹjọ́ fi sinatọ sátìmọ́le Ẹ ṣóra nípa òògùn apakòkòrò yín Ipò àgbà ló yẹ́ kí a ti bá olórí - Fani-Kayode Atiku ati idije àarẹ́ 2019 Ó ní sísọ ìbè di ibi ìgbàfẹ́ yóò fi ìgbàgbé sí àwọn tí tí ṣẹlẹ̀ yóò sì tún mú ìlò igbó Sambisa kojú òṣùwọ̀n Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
    Nígbà tì a lọ jẹun lálẹ́, àwọn ẹranko dá àbá pé ìjàkadì ni kí a fi ṣe ti ọjọ́ kejì àti wí pé àwa ti a jẹ́ olórí ni yóò jà kẹ́yìn lọ́jọ́ ìjàkadì yìí, èyí ni èmi àti Ìnàkí-ìbẹ̀rù.
Pẹ̀lú ìrẹ̀lẹ̀, àwọn akọbúlọ́ọ̀gù Zone9 sọ wípé: “A kò kí ń ṣe ẹni tí ó ní okun tàbí ìgboyà.
Mo ti fi àwọn ọmọ Lefi fún Aaroni ati àwọn ọmọ rẹ̀ gẹ́gẹ́ bí ọrẹ láti inú àwọn ọmọ Israẹli, láti máa ṣe iṣẹ́ ìsìn ninu Àgọ́ Àjọ ati láti máa ṣe ètùtù fún àwọn ọmọ Israẹli, kí àjàkálẹ̀ àrùn má baà bẹ́ sílẹ̀ láàrin wọn nígbà tí wọn bá súnmọ́ ibi mímọ́.
Gbogbo wa ni a óo ṣègbé.
“Gbogbo ọ̀rọ̀ wọnyi ni o óo sọ fún wọn, ṣugbọn wọn kò ní gbọ́.
Labẹ ofin ilẹ Kenya, ẹnikẹni to ba pin iroyin eke yoo san ẹgbẹrun lọna aadọta dọla abi ko fi ẹwọn ọdun meji jura.
Àwọn eniyan náà rékọjá sí òdìkejì ìlú Jẹriko.
Ọkàn ọlọ́gbọ́n a máa fẹ́ ìmọ̀,etí ni ọlọ́gbọ́n fi wá a kiri.
Ọrọ iru orin ti awọn olorin asiko yi n kọ jẹ eleyi ti awọn ara ilu ma n mẹnu baa nigbakigba ti orin to ba ṣe bi ẹni yatọ ninu ẹkọ to kọ tabi bi wọn ti ṣe ṣe fidio rẹ.
Kò dín ní ọ̀dúnrún kìlómítà ló rọ kiriká ìlú yìí tí ẹsẹ̀ bá rìn ín ká.
Samuẹli bá gbéra, ó pada sí Rama.
Ọṣun State: Gboyega Oyetọla di Gómìnà Ọṣun
Japan ṣèrànwọ́ N149m fún Nàìjíríà lórí ètò ààbò!
Ọkan pataki lara ohun ti wón tun mọ ni ilu lilu.
com ''Nkan to ku bayi ni ki a ṣe ipade pẹlu Sanusi lori igbesẹ ti a o gbe.
Ní ọjọ́ kẹẹdogun oṣù kinni, ọdún kejila tí a ti wà ní ìgbèkùn, 
Ẹnikẹ́ni ninu yín kò sì gbọdọ̀ jáde ninu ilé títí di òwúrọ̀ ọjọ́ keji.
Naomi dáhùn, ó ní, “Kí OLUWA tí kì í gbàgbé láti ṣàánú ati òkú ọ̀run, ati alààyè bukun Boasi.
’’Aare  wa ro awon omo orile ede Naijiria lati dibo  gomina ati ile igbimo asofin ti ipinle ni
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Mo fọ́ lójú ṣùgbọ́n mo mọ gbogbo irinṣẹ́ tí mo fi ń ṣe mọkalíìkì' Toke Makinwa ni àwọn ǹkan wọ́nyi sẹlẹ̀ si òun ni, Bi ọkùnrin ba pe mi lori aago tabi kọ lẹta ifẹ́ simi, Mo ti sàgbákò!
O fikun pe, o ti to ọdun meje si mẹjọ ti oun ti bẹrẹ isẹ naa, ti oun si n re owo jọ lati pada sile iwe.
Bi o tilẹ jẹ wi pe awọn mejeji ko fi bẹẹ́ maa gba a lọwọ ara wọn bi ẹni n gba igba ọti gẹgẹ bi wọn ṣe ṣìmẹ̀dọ̀ lẹyin ti aarẹ ẹgbẹ awọn oṣere atawọn agbaagba oṣere kẹnu bọ ọrọ naa.
Ọsẹ to kọja ni awọn ọmọ ile igbimọ aṣoju-ṣofin ranṣẹ si, nitori ọrọ eto aabo aabo to mẹhẹ yika Naijiria.
5 223812 Orilẹede Bosnia ati Herzegovnia 4411 132.
Iroyin lati ọdọ ajọ to n gbogun ti ajakalẹ aarun ni Naijiria NCDC sọ pe eeyan mẹjọ lo ku ti awọn eeyan ẹgbẹjọ din mẹẹdogun si tun ṣẹṣẹ lugbadi aarun naa.
Awọn eleto ilera to ṣe koko nìkan si ni anfaani yoo wa fun lati wọle, wọn si gbọdọ wọ aṣọ idaabo bo.
Nítorí náà OLUWA Ọlọrun rẹ̀ fi í lé ọba Siria lọ́wọ́.
Kí ó sì jẹ ọ́ níyà fún ìwà burúkú tí ò ń hù sí mi, nítorí pé n kò ní ṣe ọ́ ní ibi kan.
Bí ọmọ alaafia bá wà níbẹ̀, alaafia yín yóo máa wà níbẹ̀.
O fi kun ọrọ rẹ pe oun fẹ fi kun ẹgbẹẹfa (1,200) awọn ọmọ Naijiria to n kẹkọ ni orilẹede Germany.
Jesu dá a lóhùn pé, “O kò ní àṣẹ lórí mi àfi èyí tí a ti fi fún ọ láti òkè wá.
"Orilẹede wa ti n kuna"", eyi ni ikilọ oniṣowo kan, Shingi Muyeza, nigba ti wọn ṣe ipade onifọnran ori ayelujara Zoom pẹlu awọn oṣiṣẹ ijọba lori iṣoro ọrọ aje to n doju kọ wọn lọwọlọwọ ati eyi ti Coronavirus naa n da silẹ."
Somorin ṣalaye pe awọn to n lọ ile iwe ẹkọṣẹ ọwọ yoo maa kẹkọọ bi wọn ṣe n ṣe tẹlẹ, lati aago mẹjọ owurọ si meji ọsan.
Àwọn orin tí à n gbọ́ ní ipalórí ìrònú àti ìgbé ayé wa Àjọ tó n mójútó àwọ̀n iléeṣẹ́ ìgbóhùn sáfẹ́fẹ́ ní Nàìjíríà, NBC, tilẹ̀ f'òfin de àwọn iléeṣẹ́ agbóhùn sáfẹ́fẹ́ láti má lo orin nàá.
Ààrin ẹ̀yà tí àjèjì náà bá ń gbé ni kí ẹ ti pín ilẹ̀ ìní tirẹ̀ fún un.
Mo lọ pe ẹ̀gbọ́n mi, mo sì sọ fún un ohun tí bàbá mi sọ fún mi.
Dafidi kó wọn lé àwọn ará Gibeoni lọ́wọ́, àwọn ará Gibeoni sì so wọ́n kọ́ sórí igi, lórí òkè níwájú OLUWA, àwọn mejeeje sì kú papọ̀.
Ó jẹ́ àṣà àwọn alufaa pé nígbà tí ẹnìkan bá wá rúbọ, iranṣẹ alufaa yóo wá, ti òun ti ọ̀pá irin oníga mẹta tí wọ́n fi ń yọ ẹran lọ́wọ́ rẹ̀.
Wo ibi mẹ́rìnlá tí o kò gbọdọ̀ gbé ọkọ̀ rẹ sí lásìkò yìí.
Júpítérì ni plánẹ̀tì karùún láti ọ̀dọ̀ Òrùn àti plánẹ̀tì tótóbijùlọ nínú Sístẹ̀mù Òrùn.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù World Cup 2018: Ijàkàdì kọ́, Ipele àkọ́kọ́ nínú ìdíje pari!
Bakan naa lo gbadura fawọn eniyan ilu Ondo loke okun pe, wọn a ko ire oko dele layọ ati pe Olodumare ko ni jẹ kiru eyi ṣẹlẹ mọ ni Ondo.
Oluranlọwọ pataki si Aarẹ, Garba Shehu lo fi ọrọ naa lede lẹyin abẹwo ti Masari ṣe si Aarẹ Buhari ni ilu Daura.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: 'Níbo lo ti gbé ọmọ aràrá wa ni bàbá mi kò bá bi ìyá mi' - Aràrá adájọ́ Mo fẹ́ ọkọ mi torí bó se ń kọrin, kìí se torí owó - Ìyàwó Aràrá 'Ojú inú mi ni mo fi ń rí àwọn irinṣẹ́ tí mo fi ń ṣe mọkálíìkì' Ìpèníjà ojú kò ní kí ń má ṣiṣẹ́ ‘DJ’ - Etu Sodiq Omotayo Wo ìṣẹ̀lẹ̀ márùn-ún tí kò bá pín Nàíjíríà sí yẹ́lẹ-yẹ̀lẹ Eji Gbadero, ọmọ Ibadan àti jayé-jayé ọmọ ónílẹ̀ ti wọn yẹgi fun l'Eko Lisabi Agbongbo Akala rèé, ẹni tó fi ìfẹ́, ìṣọ̀kan àti ìrẹ́pọ̀ gba ilẹ̀ Ẹ̀gbá lọ́wọ́ ìmúnisìn Ọba Lamidi Adeyẹmi, òṣìṣẹ́ adójútòfò àti Abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò kó tó jọba Ọkọ ni awọn obi oun bi oun ni afọju ni nigba ti aya salaye pe, arun ẹfọju oju Glaucoma lo fọ oun loju.
Super Eagles ti orile ede Niajiria lo
ìjọba Tanzania ko 30 Mílíọ̀nù rẹ̀ wọ̀lú Ìná ẹgbẹ́ òṣìṣẹ́ NLC ati ìjọba kò wọ̀ níbi ìpadé Ọmọ Nàìjíríà, ẹ forijìn mí!
Real SociedadGermany Bundesliga February 10 15:30 Bayer Leverkusen ?
Lẹ́yìn tí ó sọ bẹ́ẹ̀ tán, ó mí sí wọn, ó bá wí fún wọn pé, “Ẹ gba Ẹ̀mí Mímọ́.
Bákan náà ni òòró ati ìbú aṣọ ìgbàyà náà, ìṣẹ́po aṣọ meji ni wọ́n sì rán pọ̀.
#Segun: Kí ló mú akẹ́kọ̀ọ́ mu òògùn apakòkòrò tóríi máàkì 167 nínú JAMB?
Nígbà náà ni àwọn eniyan láti Jerusalẹmu ati gbogbo ilẹ̀ Judia ati ní gbogbo ìgbèríko odò Jọdani ń jáde tọ̀ ọ́ lọ.
Bóyá ẹni tí ó pè ọ́ tún pe ẹlòmíràn tí ó lọ́lá jù ọ́ lọ.
" Abílékọ Bashir tún sọ pé kí ìjọba wá nkan ṣe sí bí àwọn ènìyàn ṣe n gbẹ́ kànga lọ́nà tó wù wọ́n.
Àwọn agbébọn jí ìyàwó bàbá Sẹ́nétọ̀ Abbo tó lu obìnrin nílùú Abuja gbé Ọkùnrin tó pa ìyàwó rẹ̀ tí gba ìdájọ́ ikú Nigba ti o n ba awọn akọroyin orile-ede India sọrọ, obinrin naa, Rita Sarkar ni alubolẹ ni ọkọ oun maa n lu oun fun ọpọlọpọ ọdun nitori owo ori naa.
O rọ wọn wi pe, ki wọn maa kaarẹ ninu akitiyan lati ri wi pe Naijiria toro, nitori oriiṣiriiṣi erongba lawọn ọmọ Naijiria ni eyi to jẹ ko ṣoro fun awọn alaṣẹ lati dari.
seranwo pupo fun ilu Asaba ati awon agbegbe ti o fara ti.
Ademọla Adeleke, lasiko to n bawọn akọroyin sọrọ ni ile rẹ to wa ni Ẹdẹ, tun fikun pe, ẹgbẹ oselu oun, PDP, yoo lo gbogbo agbara ofin to ba wa nikawọ rẹ lati gba ipo rẹ ti wọn ‘ji gbe’ pada.
Ninu fidio kan lo ti han pe awọn mejeeji jọ n fi ara gbo ara lori ibusun, ti wọn si yi aṣọ bori.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Abacha: Al Mustapha ní ète ìdìtẹ̀ gbàjọba méjọ ni Sani Abacha borí 12 Òkùdu 2020 Oríṣun àwòrán, others Loni tii ṣe ayajọ ijọba alagbada ni Naijiria, Al Mustapha to jẹ osisẹ alaabo agba fun aarẹ ologun tẹlẹ, Sani Abacha ti sọrọ nipa aseyọri ọga rẹ lori aleefa.
so eso rere fun orile ede yii.
Èèyàn 162 ló kó àrùn Coronavirus ní Nàìjíríà lọ́jọ́ Ajé Wo ojú àwọn òṣèré yìí láì lo Make-up"" orí ìtàgé bó ṣe rí gẹ́lẹ́ Gbajúgbajà òṣèré tó ṣe fíìmù James Bond tí jáde láyé lẹ́ní ọdún 90 Orúkọ àwọn tó yege láti darapọ̀ mọ́ ikọ̀ Amotekun ní ìpínlẹ̀ Oyo ti jáde Boris Johnson ni isede naa ko ni idije Premier League duro ṣugbọn ko ni si ero iworan nibẹ."
Iya ọlọmọ mẹrin ku sile ale Lai pe yi ni ọga ọlọpa ni Naijiria, Ibrahim Idris, tako ọrọ ti awọn ileese iroyin kan gbe jade pe, oun sọ pe, ijọba yoo gbe akẹko Dapchi kan to ku pada wale laipe.
Nibẹ ni wọn ka mọ ti wọn ti yinbọn pa ki wọn to gbe owo salọ'' Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Ibadan Poly: Àwọn aláṣẹ ní kí àwọn akẹ́kọ̀ọ́ fún ìsìnmi nítorí jàgídíjàgan5 Ìgbé 2019 Fídíò, Kọmisọnà ọlọ́pàá ni àwọn yóò tú iṣu dé ìṣàlẹ̀ ìkòkò lóri ọ̀rọ̀ náà2 Ìgbé 2019 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
"Oríṣun àwòrán, LASEMA Ẹni ti ọrọ naa ṣoju rẹ, Olusunmade Olubunmi Damola sọ pe ""iṣẹlẹ yii ṣẹlẹ ni dede aago mejila kọja iṣẹju mẹrinla, a gbọ ariwo nla kan ninu ọfiisi wa to dun bi iro ibugbamu."
Gbogbo àwọn ìbátan ati ọ̀rẹ́ rẹ̀ lọkunrin ni ó pa láìdá ẹnikẹ́ni sí.
Jehoiada alufaa mú kí Joaṣi ọba ati àwọn eniyan dá majẹmu pẹlu OLUWA pé àwọn yóo jẹ́ tirẹ̀; ó sì tún mú kí àwọn eniyan náà bá ọba dá majẹmu.
    Lẹ́yìn èyí, àwọn ẹlòmíràn tún kọjá tí ètè wọn tún sọ̀rọ̀.
Alagba ni orukọ rẹ, o ni awọn òṣìṣẹ́ lati aafin Kabiyesi to n tọju oun nikan.
Ninu ọrọ tirẹ, oludari eto ilera ni ipinlẹ Ogun, Dokita Olukayọde Soyinka ṣalaye pe ọrọ sisan ẹgbẹrun marundinlọgbọn owo ayẹwo kokoro COVID-19 ṣe ajeji si oun ati pe titi di asiko ti wọn n sọrọ naa, ọfẹ ni ayẹwo kokoro arun COVID-19 ni ipinlẹ Ogun .
Awon adari miiran tun ni Orji
O ṣalaye pe afujusun ijọba Makinde ni lati daabo bo awọn eeyan ipinlẹ Oyo, o si rọ wọn pe ki wọn má ru ofin lori iṣẹlẹ ọhun.
Agbẹ́gilére a ta okùn sára igi, a fi ẹfun fa ìlà sí i, a fi ìwọ̀n wọ̀n ọ́n, a sì gbẹ́ ẹ bí eniyan: ẹwà rẹ̀ a dàbí ti eniyan, wọn a sì kọ́lé fún un.
Gbogbo Ìwé Mímọ́ ni ó ní ìmísí Ọlọrun, ó sì wúlò fún ẹ̀kọ́, fún ìbáwí, fún ìtọ́nisọ́nà, fún ìlànà nípa ìwà òdodo, 
Esi ayẹwo naa waye lẹyin ti ajọ to n ṣamojuto ajakalẹ arun, NCDC, kede esi ayẹwo eeyan 152 to tun ṣẹṣẹ ni i.
Eyi n ṣẹlẹ latari bi iroyin ṣe ni iyawo ati awọn ọmọ aarẹ ṣe gbogun ti akọwe pataki si aarẹ Yusuf Sabiu ọmọ ẹgbọn aarẹ ti wọn fun ni alajẹ Tunde.
Ganduje: Gòmìna Ganduje ni yíyọ Sanusi nípò Emir Kano wà fún àtúnṣe ètò oyè jíjẹ ní ìlú Kano
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Africa Eye: Wo ìtàn ìyá kan ìyá kan àtàwọn olè ajọ́mọgbé tó n ta ọmọ ní Kenya Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Helicopter crash in Lagos: Àbájáde ìwádìí ẹlikọ́pítà to já ni Opebi laipẹ yii ti jáde21 Owewe 2020 Free Pad: Scotland ti di orílẹ̀-èdè àkọ́kọ́ tó bẹ́rẹ̀ pínpín páàdì ǹkan osu fún gbogbo obìnrin lọ́fẹ̀ẹ́25 Bélú 2020 India Wedding: Ìyàwó kan ní India wọ sòkòtò fún ayẹyẹ ìgbéyàwó rẹ̀- Wo ìdí tó fi ṣe bẹ́ẹ̀25 Bélú 2020 Water Resources Bill: Wo ohun tó wà nínú òfin nípà àbádòfin lórí omi tí ìjọba rẹ́ buwọ́lù23 Owewe 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Ní ọdún kejidinlogun ìjọba Josaya ni wọ́n ṣe Àjọ Ìrékọjá yìí.
Aare wa ro ajo kookan ti oro ohun ba bawi, lati maa se ko eti ikun si ase re.
Tọkọtaya lu ọmọ ni gbanjo fun 400k
Adamu ni ohun to buru jai ni nkan to ṣẹlẹ, to si koju ọrọ si awọn aṣebi wọn yii.
Wo àwọn elére ìdárayá míran ti FIFA ti fòfin ayérayé dè: Kwesi Nyantakyi: Àkọlé àwòrán, Kwesi ni wọn mu pe o gba riba Kwesi jẹ ọkan gboogi lara awọn to ni i ṣe pẹlu ọrọ bọọlu alafẹsẹgba ni ilẹ AdulawọÀwọn ọlọ́pàá ọtẹlemuye gbé Nyantakyi .
Children's Day: Àwọn ọmọdé tó ń ṣe bẹbẹ láwùjọ Afíríkà O ṣalaye pe, ko si oṣiṣẹ kankan to yẹ ko padanu ẹmi rẹ nitori wi pe ko fẹ pẹ de ibi iṣẹ ni ọjọ ti ojo ba rọ.
Ondo politics: Àwọn àgbàgbà PDP péjú sí Akure láti gba igbákejì gómìnà Ondo, Agboola Ajayi wọ PDP Igbakeji gomina ipinlẹ Ondo, Agboọla Ajayi ti darapọ mọ gb oṣelu PDP ni san an bayii.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Prostate Cancer: 82% ọkùnrin ní kó mọ̀ pé òun ní àìsàn jẹjẹrẹ asẹtọ ní Naijiria 2 Èrèlè 2018 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 12 Ìgbé 2020 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Aisan jẹjẹrẹ asẹtọ Ọkunrin lo wọpọ julọ ni ilẹ Geesi Iwadii ti fihan pe ida mejilelọgọrin ọkunrin lorilẹede Naijiria ni ko mọ pe awọn ni aisan jẹjẹrẹ asetọ nitori wọn ko se ayẹwo.
Ọgbọ́n tí bàbá kọ́ Dáúdà tí kò gbọ́n ni agbọ́n wá kọ́ ọ yìí.
Adajọ Kocurek ti arakunrin naa gbiyanju lati yinbọn pa ni inu oun dun pe ọrọ naa to ti wa nile ẹjọ fun ọdun meji ati oṣu mọkanla ti wa pari bayi ati wi pe idile oun ko ni lati maa bẹru oun ti Onyeri ati awọn akẹgbẹ rẹ yoo ṣe fun awọn mọ.
Wọn ní Dino lọ́wọ́ sí àwọn tó pa ọlọ́pàá kan.
Ǹjẹ́ ọkunrin kan wà ninu yín tí ó ṣẹ̀ṣẹ̀ fẹ́ iyawo sọ́nà tí kò tíì gbé e wọlé?
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù 2019 Elections: Sowore ní pàṣán ni Buhari yóò fi bá Nàìjíríà ṣe ní sáà kejì 3 Ẹrẹ̀nà 2019 Oríṣun àwòrán, Omoyele sowore Àkọlé àwòrán, Sowore ni omi n bẹ laamu fun idagbasoke eto idibo lorilẹede Naijiria Oludije fun ipo aarẹ to kọja labẹ oṣelu AAC lorilẹ-ede Naijiria, Ọmọyẹle Ṣoworẹ ti sọ pe oun ko lee pe aarẹ Buhari lati kii ku oriire.
Oladele sọ pe iṣẹlẹ naa mu itiju ati ibanujẹ ba oun.
Kò pẹ́ lẹ́yìn rẹ̀ tí àbúrò yìí fi kó gbogbo ohun ìní rẹ̀, ó bá lọ sí ìlú òkèèrè, ó sá fi ìwà wọ̀bìà ná gbogbo ohun ìní rẹ̀ pátá ní ìnákúnàá.
nítorí náà, n óo tú àwọn ìlú Moabu tí wọ́n wà ní apá ọ̀tún ati apá òsì ká: àwọn ìlú tí ó dára jù ní ilẹ̀ Moabu, Beti Jẹṣimoti, Baali Meoni ati Kiriataimu ká.
Wọn kò ní ṣe iṣẹ́ àṣedànù,wọn kò ní bímọ fún jamba;nítorí ọmọ ẹni tí OLUWA bukun ni wọn yóo jẹ́,àwọn ati àwọn ọmọ wọn.
Akowe agba fun ajo UN Antonio Guterres lo soro yii  ninu Atejade kan to n gbe siwaju igbimo Ajo agbaye nipa awon ojuse ile-ise  ajo agbaye to wa nile Afirika ati ti Sahel (UNOWAS).
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ọmọ Risikat olójú búlúù méjèéjì jẹ̀bùn oríire àti ìfà ńlá Àìmọ̀kan ló mú mi hu ìwà tí mo hù kọjá sẹ́yìn, Jonathan dárí jì mí - Dino Melaye Ẹ́ tú èékánná lọ́rùn Sowore, ẹ kò ní ẹ̀rí láti ba ṣẹjọ́ - Ẹgbẹ́ Amòfin Amẹ́ríkà Irú iṣẹ́ wo ní Funke Akindele rán sí Bukunmi Oluwasina, tó fa ariwo lórí ayélujára?
Wo ìdí tó fi tọrọ àforíjì fún ọ̀rọ̀ ẹ̀gbin tó sọ sí Pásítọ̀ David Oyedepo Waya ni ṣe ni Kiddwaya bẹrẹ si ni fi ọrọ ran awọn aburo ati ẹgbọn oun lati ibi to ti ya ara rẹ sọtọ ki wọn to wọ ilee Biggie ki wọn ba a bẹ baba rẹ.
Ko din ni aadọta eeyan ti arun onigbameji yii ti ran lọ sọrun lati ibẹrẹ ajakalẹ aarun ọhun ni opin oṣu kẹta.
"Man U f'aṣọ iyì ya mọ́ Man City lára pẹ̀lú àmì ayò 2-0 Ìdí mẹ́ẹ́rin tí sísùn ní ìhòhò lé gbà ṣe ara a rẹ l'óore Oríṣun àwòrán, Others Àkọlé àwòrán, NFF, LMC Kwara United bá Nasarawa United kẹdun ikú Martins ""A ní ìgbàgbọ́ pé tí a ba mọ irú ikú to pa a, ni yóòjẹ ki a lé mọ irú igbésẹ̀ ti a o gbé láti dẹkun irú ìṣẹ̀lẹ̀ bẹ́ẹ̀."
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ado Ekiti Blind Couple: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú O ni ohun ti Ọlọrun sọ ni pe ki ọkunrin nawo fun obinrin, ki o si fi owo tọju rẹ.
Ikọ ahugbẹ jẹ oriṣi ikọ ti ko mu kẹlẹbẹ jade, to si n ha eniyan ni ọfun, eyi ti eniyan si hu fun ọpọ igba laarin wakati kan, tabi fun bi igba mẹta laarin wakati mẹrinlelogun.
Balogun tí ó wà fún oṣù kejila ni Helidai ará Netofati, láti inú ìran Otinieli; iye àwọn tí wọ́n wà ninu ìpín rẹ̀ jẹ́ ọ̀kẹ́ kan ó lé ẹgbaaji (24,000).
Minisita fun eto iroyin ati asa, Lai Mohammed lo sọ bẹẹ lasiko to n ba awọn akọroyin sọrọ nilu Abuja.
Sowore sọ pe iyansipo naa ti bẹrẹ lati ọjọ Iṣẹgun tii ṣe ọjọ kẹtalelogun oṣu kẹfa ọdun 2020.
"O ko lee gbe ibọn tabi ado oloro, ida tabi ọbẹ lati pa alaiṣẹ, ki o si maa pariwo ""Allahu Akbar""."
Ọpọlọpọ iyannisipo ti Buhari fẹ ẹ ṣe ni awọn aṣofin naa ko buwọlu, ti awọn miran si pẹ pupọ ki wọn to o fọwọ si i.
Ìgbàgbọ́ yìí ni ó ń mú wọn kó ara wọn níjàánu láti hùwà tí kò dára.
Davido ni ayẹwo ọmọ oun ati Chioma fi han pe ọmọ naa ko ni arun naa lara, ati pe Chioma ko ti ma ṣafihan apẹrẹ aarun ọhun.
Progressives Congress ,APC)  se fun un
Lẹ́yìn tí wọ́n rin ìrìn ọjọ́ kan, wọ́n bẹ̀rẹ̀ sí wá a kiri láàrin àwọn mọ̀lẹ́bí ati àwọn ojúlùmọ̀ wọn.
N óo sì fi òkú rẹ̀ kún àwọn àfonífojì.
Ní báyìí, ẹgbẹ́ òṣèlú PDP ti bèèrè fún ìwádìí ìṣẹ̀lẹ̀ náà.
'Ibi àríyá ni àbúrò mi d'ágbére kí ọlọ́pàá tó fi ẹ̀sùn ìbálòpọ̀ akọ-sí-akọ kàn án' Ìgbẹ́ ọmọdé ń dènà ààrun jẹjẹrẹ, àìsàn ìtọ̀ súgà Àwọn olùgbé ilu Ẹdẹ lu akẹ́kọ̀ọ́ pa Ninu ọrọ ti rẹ, Aare Muhammadu Buhari so pe oun yoo sa ipa lati ri pe ijọba tarawa fẹsẹ mulẹ lorile-ede Naijiria.
Nítorí ninu ọpọlọpọ ọrọ̀ ni àwọn yòókù ti mú ohun tí wọ́n dá, ṣugbọn òun, ninu àìní rẹ̀, ó dá gbogbo ohun tí ó ní, àní gbogbo ohun tí ó fi ẹ̀mí tẹ̀.
Èèyàn mẹ́fà míràn tún ti ní àrùn Coronavirus ní Naijiria Ajọ to n risi idẹkun itankalẹ arun lorilẹede Naijiria, NCDC ti kede pe eniyan mẹfa miran tun ti ni arun Coronavirus lorilẹede Naijiria.
Samuel Chukwueze lo kọkọ gba bọọlu ami ayo akọkọ wọnu awọn South
2019 Elections:Yuguda, Mu'azu fi PDP sílẹ̀ lọ APC ní Bauchi
Àní kí ẹ fún ẹni tí ebi ń pa ní oúnjẹ, kí ẹ mú àwọn òtòṣì aláìnílé wá sinu ilé yín,bí ẹ bá rí ẹnikẹ́ni ní ìhòòhò, kí ẹ fi aṣọ bò ó,kí ẹ má sì fojú pamọ́ fún ẹni tí ó jẹ́ ẹbí yín.
O fikun pe ọkọ oun ko mọ awọn ounjẹ alakọwe jẹ ayafi ounjẹ awọn alalẹ.
ni wọn lo si agbegbe naa lati gboju –ija kọ awon agbesunmomi naa,ti awọn ọdaran
Kò dájú pé Drogba gba iyọnda lọdọ ààrẹ ko tó kede ọrọ yí ṣugbọn nitori ifẹ tàwọn èèyàn ni ṣi ìdíje bọọlu, sibẹo ṣi wáyé níbẹ.
Oríṣun àwòrán, @DamienAjayi Wòlíì Sotitobire gúnlẹ̀ sí ilé ẹjọ́ ní ìtẹ̀síwájú ìgbẹ́jọ́ rẹ̀ Kí ló ṣekúpa Ibidunni Ighodalo tí gbogbo ọmọ Nàìjíríà ń selédè lẹ́yìn rẹ̀?
Oluwo ni lẹyin ti mọmọ gbiyanju lo kaadi ATM tuntun to ṣẹṣẹ gba fi gba owo ni o bẹrẹ sii ri awọn atẹjiṣẹ ajeji pe o ti gba owo, eleyi ti ko si rii bẹẹ.
Àwọn ẹlòmíràn sì wà tí wọn ń waasu Kristi pẹlu inú rere.
; Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Àwọn ǹkan ti ọ̀pọ̀ ko mọ nípa Baba Suwe Kollington, Bàbá Suwe, Ogun Majek wà lára àwọn gbajúmọ̀ òṣèré tí ayé ti parọ́ ikú mọ́ sẹ́yìn Loju opo Instagram rẹ, o fi aworan kan sibẹ ni iranti Majek Fashek Bi a ko ba gbagbe ọkan lara awọn ọmọ oloogbe naa Randy Fashek ti ṣaaju kede pe isinku ranpẹ lawọn yoo ṣe nitori Covid-19.
Giwa ile-ifowopamo agba lorile-ede Naijiria, Godwin Emefiele so lojo-Bo pe, Ile-ifowopamo ohun yoo da ipade  atigba-degba ti won maa n se lori owo-ele duro, latari, bi won se se idasile igbimo abadofin ilana lori owo-na.
O dá lóri iye ìgbà ti ẹni náà bá fi n sunkun, bí ẹkun naa ṣe pẹ tó, bọ́ya ẹni kan lo mú u bínú tàbi ó kàn dédé sunkún.
"Nigba to ti wa ṣe aṣeyọri bayii, o ri i bi anfani lati fi itan rẹ gba awọn to ba ni iru iriri ọmọ ti wọn fipa ba iya rẹ lo pọ tabi irufẹ iriri buruku mii bii tirẹ pe ""ti o ba nii lọkan pe waa la, waala""."
Gómìnà Seyi Makinde bá ẹbí Isiaq Jimoh tó kàgbákò ikú òjijì dárò Mọ̀ sí i nípa díẹ̀ lára àwọn èèyàn tí ikú wọn 'láti ọwọ́ ọlọ́pàá' milẹ̀ tìtì ní Nàìjíríà Wo bí ìwọ́de #ENDSARS tí Toyin Abraham ṣe nípínlẹ̀ Oyo ṣe lọ Ẹni méjì kú, ọ̀pọ̀ dèrò ilé ìwòsàn níbi ìjàmbá ọkọ̀ tó ṣẹlẹ̀ ní Okokomaiko nípínlẹ̀ Eko Adamu ni bẹrẹ lati wakati yi, gbogbo awọn oṣiṣẹ ikọ yi ni wọn yoo darapọ mọ ẹka ileeṣẹ ọlọpaa mi.
Ti a ko ba gbagbe, itusilẹ awọn ti wọn jigbe naa ko sẹhin ọpọlọpọ ifọrọwerọ tẹgbẹ Alagbelebu pupa, (International Committee of the Red Cross,) seto rẹ, pẹlu atilẹyin aarẹ Buhari.
Ẹ má jẹ́ kí ìtara yín rẹ̀yìn.
Ija owo yii si ti fa ọpọlọpọ ikayasoke laarin orilẹ-ede mejeeji.
Alaafin: Olori Aanu Adeyemi ṣàlàyé ìdí tó ṣe gẹ́ Oba Lamidi Adeyemi ti ìlú Oyo Ọwọ́ ọlọ́pàá ìpínlẹ̀ Kebbi tẹ bàbá àti ìyàwó rẹ̀ méjì fún pé wọn so ọmọ pọ̀ mọ́ ewúrẹ́ fún ọdún méjì Orílẹ̀-èdè Chad pé ọgọ́ta ọdún, àwọn ara ìlú ń pariwo lábẹ́ Aàrẹ Deby tó gba 'Field Marshal' Diezani gan an ní Hushmummy tó ń bú àwọn Yahoo boys- Àwọn Ọmọ Naijiria lórí Twitter ''Íwa inu awọn oloṣelu ni ko dara, kii se pe eto iṣejọba Naijiria ko i tii dagba to lẹyin ọdun mọkanlelogun.
Àjọṣepọ̀ wo ló wà láàrín Coronavirus àti Chloroquine?
New electricity tariff: Wo ọ̀nà ìsanwó tuntun fún àwọn oníbàárà iná mọ̀nàmọ́ná Eko, EKDC
Àfi tí ènìyàn bá fẹ́ fi’rarẹ̀ wọ́lẹ̀ ní àwùjọ.
nítorí ẹ̀gún ẹ̀wọ̀n ati ẹ̀gún ọ̀gàn ni ó ń hù lórí ilẹ̀ àwọn eniyan mi.
Ènìyàn 170 tún ti ní ààrùn Covid-19 l'órílẹ̀-èdè Nàìjíríà Àjọ tó n mójútó ìpèsè òògùn ní America ti fọ́wọ́ sí lílo òògùn Ebola fí tọ̀jú Coronavirus Ẹ̀rù n ba àwọn agbábọ́ọ̀lù Premier League láti padà sórí pápá nítorí coronavirus Àwọn ọlọ́pàá wú òkú akẹ́kọ̀ọ́ Fásitì Uniport mẹ́ta tí àwọn ajínigbé sin Ki ibomu-bẹnu naa le bo ọ daada, jẹ ki eti rẹ to dabi ẹni pe o le lọwọ diẹ wa ni oke imu rẹ.
Ó bá Ọlọrun pàdé ní Bẹtẹli, níbẹ̀ ni Ọlọrun sì ti bá a sọ̀rọ̀.
Eyi lo mu ki Gomina Amosun leri wi pe ohun yoo gbe lẹyin Adekunle Akinlade to ti gba tikẹti ẹgbẹ oselu miiran ti ṣe Alliied People's Movement, APM.
Iṣẹlẹ yii ṣẹ lẹyin wakati diẹ ti Aarẹ Muhammadu Buhari gunlẹ si ipinlẹ naa fun abẹwo ọlọsẹ kan.
    Bí ó ti wí báyìí tán, ó fò lọ.
 A maa ṣeto to yẹ ki ipinlẹ Eko wa loke nitori pe a ti ri awọn ibudo igbafẹ to dara to pọ.
 fún àpeere , àpólà-orúko ni a fa igi sí ní ìdi ní ( 3a ) àti ( 3b ) .
Àwọn eniyan yóo là ní Jerusalẹmu, àwọn eniyan yóo sì ṣẹ́kù ni Òkè Sioni, nítorí pé ìtara ni OLUWA yóo fi ṣe é.
Ó ṣe ni laanu wi pé, àwọn tó wà ni ilé aṣòfin Nigeria,  àti oriṣiriṣi àwọn Òṣèlú kékeré yókù lo nkọ iwé.
Ogbeni Jammeh lo ti figba kan tele lo se atipo lorile ede Equatorial leyin ti o kuna ninu eto idibo to waye lodun 2016, ni eyi ti Adame Barrow ti di aare orile ede naa.
"Sarumi ni ""maa gba Lautech pada, maa fun ijọba ibilẹ lagbara wọn pada."
 Òfin síńtáásì lè gba àwon gbólóhùn kan láàyè tí ó jé pé èka yìí ni yóò so pé irú gbólóhùn béè kò ni àrògún .
Wọn ṣi aworan Obama ati Michelle
Oríṣun àwòrán, @Kla Àkọlé àwòrán, Ìdána ló ń ṣaaju igbeyawo nilẹ Yoruba.
Buruji Kashamu jẹ́ ènìyàn tó nífẹ̀ aráàlú- Gómínà Dapo Abiodun Èèyàn 334 ló gbàwòsàn lọ́wọ́ Covid-19 l'Ọjọru, 453 míì tún lùgbàdì rẹ̀- NCDC Àwọ̀ ojú pọ̀ bíi àwọ̀ òṣùmàrè, àmọ́ ojú búlúù Risikat kò nílò àtúnṣe- Dókítà Feyi Wo àwọn iléèwé gíga tó ti bẹ̀rẹ̀ sí ní ta fọ́ọ̀mù JAMB post UTME screening ní Naijiria Itan igbesi aye Walter Carrington: Ọjọ kẹrinlelogun, oṣu Keje, ọdun 1930, ni wọn bi Walter Charles Carrington, nilu New York, lorilẹ-ede America.
Bakan naa ni wọn tun beere fun biliọnu kan naira gẹgẹ bii owo gba maa binu lori ẹsun fifi ipa muni lai tẹle ilana ofin, fifini si ahamọ ati ifiya jẹni lọna aitọ.
opolopo awon eniyan lo farapa ni papa isere to wa ni Maiduguri lojo Aje .
Dapọ Abiọdun ree, ẹni tó dépò gómìnà ní àyájọ́ ọjọ́ ìbí rẹ̀ Wo àwọn ìlérí tàwọn Gómìnà tuntun ṣe nínú ìbúra wọn Liverpool ti gba ife ẹyẹ Champions League nigba marun un ọtọtọ, ṣugbọn igba akọkọ ree ti Tottenham yoo de ipele aṣekagba idije Champions League.
Lawọn ipinlẹ to maa n duro de ọjọ idibo ki wọn to ka awọn idibo oni imeeli, o ṣeeṣe ko gbe aarẹ Trump tori ireti wa pe ọpọ ọmọ ẹgbẹ Republican yoo dibo lọlọdani lọjọ idibo.
Nítorí mo ń fẹ́ẹ́ ronú lákòókò náà ni, n kò si fẹ́ ki ènìyàn dí mi lọ́wọ́ rárá, níotrí àkókò iré ni iré yẹ ní ṣíṣe, àkókò ìjà yẹ ní jíjà, àkókò ẹkún ni ẹkún yẹ ní sísun, àkókò ayọ̀ yẹ ní yíyọ̀; ẹni tí o ń lọ sí àwùjọ tí ó dé fìlà ará oko tí ó wọ ẹ̀wù ẹmi tí ń rin ìrìn-àjò, tí ó sì sán ìbàǹtẹ́ ẹni tí ń ṣe ọdẹ, eléyìínì ti gbé kọja oríta, níttorí náà bí èmi ti ń fẹ́ẹ́ ronú lákòókò náà, n kò fẹ kí ẹnikẹ́ni dí mi lọ́wọ́ rárá.
Kí Jesu tó yọjú, Johanu ti ń waasu fún gbogbo àwọn eniyan Israẹli pé kí wọ́n ṣe ìrìbọmi bí àmì pé wọ́n ronupiwada.
Ohun ti eyi tumọ si nipe, ti owo eporọbi ba tun wọn si l'agbaye ki ọdun yii to o pari, ijọba yoo tun fi owo kun owo epo.
’ Ẹ óo le dá wọn lóhùn pé bí ẹ ṣe kọ èmi OLUWA sílẹ̀, tí ẹ sì ń bọ oriṣa àjèjì ní ilẹ̀ yín, bẹ́ẹ̀ ni ẹ óo ṣe sin àwọn àjèjì ní ilẹ̀ tí kì í ṣe tiyín.
95bn sórí reluwé làti Kano sí Niger Republic- PDP Amotekun dé!
Lọdun to kọja bakanna awọn ọlọpaa mu Fresher Siwale ti ohun naa jẹ ogunagbongbo alatako fun pe o ni ko daju pe ọmọ Zambia ni aarẹ.
Ọjọjọ Ọjọjọ jẹ ọkan gboogi lara awọn ounjẹ Yoruba laye atijọ.
Ipade naa to waye lọjọ Iṣẹgun ni olu ile iṣẹ ajọ eleto idibo ẹka ti ipinlẹ Ọyọ tokalẹ silu Ibadan lo da lorii oniruuruu idahun si awọn ọkanojọkan ibeere to ni ṣe pẹlu idibo si ipo aarẹ ati ile igbimọ aṣofin ti yoo waye jakejado orilẹede yii lọjọ Abamẹta.
Tamari dá a lóhùn, ó ní: “Kí ni o óo fún mi tí mo bá gbà fún ọ?
" Iṣẹ lo wa ku bayi, ẹ saanu mi Abdulwasiu ti wa kesi awọn ọmọ Naijiria lati ṣe iranwọ fun ohun ni[pa ọna iṣẹ lati le fi tọju mọlẹbi rẹ.
Agbo ẹlẹ́dẹ̀ náà bá tú pẹ̀ẹ́, wọ́n sáré láti gẹ̀rẹ́gẹ̀rẹ́ òkè lọ sí òkun, wọ́n bá rì sinu òkun.
Oluwo: Yóò nira fún ìjọba láti sanwó oṣù tí kò bá sí àtúntò
Koríko tí a mú lọ́wọ́ tó fún kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ wa, oúnjẹ ati waini tí a sì mú lọ́wọ́ tó fún èmi ati iranṣẹbinrin rẹ ati ọdọmọkunrin tí ó wà pẹlu wa, ìyà ohunkohun kò jẹ wá.
Ọmọ Mínísítà àná, Adewole bọ́ s'ọ́wọ́ ajínigbé Lori boya o ṣeeṣe ki ẹgbẹ OPC ati ẹgbẹ ajijagbara Agbẹkọya jọ ṣiṣẹ pọ lori eto aabo, Aarẹ Adams sọ pe ẹgbẹ agbẹkọya naa ni iwulo fun ilẹ Yoruba lori eto aabo.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Eko Akete yóò gbàlejò BBC Yoruba Aṣedanwo yoo wa gba ọrọ aṣiri (profile code) oni alifabẹẹti tabi/ati nọmba mẹwaa (10 characters) gẹgẹ bi atẹranṣẹ lori ẹrọ alagbeka rẹ.
Ọjọgbọn Bisoye Eleṣin to jẹ olukọ ede ati aṣa Yoruba ni fasiti ijọba apapọ nilu Eko salaye pe oye iyalọja kii ṣe eleyi ti eeyan a maa fi ọwọ yẹpẹrẹ mu nitori ipa ti wọn n ko.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Sunday Igboho gba àwọn èèyàn Soka n‘Ibadan sílẹ̀ lọ́wọ́ àwọn ọmọ onílẹ̀ tó wá ṣọṣẹ́ Lẹ́yìn ọdún 44 tó jáde láyé, igbá tí onírèsé Murtala Muhammed fín sílẹ̀, kò parun Káńsélọ̀ Sajid Javid kọ̀wé fipò sílẹ̀ lẹ́yìn tí Boris Johnson ṣàtúntò ìjọba rẹ̀ Olùdíje gómìnà APC ní Bayelsa ti ń palẹ̀mọ́ fún ìbúra, kílé ẹjọ́ tó ga jùlọ tó yẹgi mọ́ nídìí Ẹ̀yin òṣèrè tíátà, ẹ ní ṣùúrù de àsìkò Ọlọ́run, ẹ máṣe kánjú kọjá kádàrá - Madam Ṣajẹ Fadeyi ni awọn ọlọpa to wa nibi isẹlẹ naa lo tẹle akọwe ileẹjọ to tẹle awọn eeyan ti wọn pe ni awọn ọmọ onilẹ lọ si adugbo naa, lati ri pe asẹ ileẹjọ fidi mulẹ, kii si se pe awọn ọlọpa naa n gbeja awọn ọmọ onilẹ.
National Electoral Commission, INEC ) ti kede gomina  Samuel Ortom ti omo egbe oselu ( Peoples
 eléyìí sì wà títí di 1616 .
Àwọn nǹkan tí ẹ óo máa fi rúbọ ni: ọ̀dọ́ akọ mààlúù meji ati àgbò kan ati ọ̀dọ́ àgbò meje ọlọ́dún kọ̀ọ̀kan, tí kò ní àbààwọ́n.
 Oríṣun àwòrán, Reuters Àkọlé àwòrán, Agbabọọlu ilẹ Afirika, George Weah to ti di aarẹ orilẹede Liberia bayii nikan ni agbabọọlu ti osi gba ami ẹyẹ agbabọọlu to gbayi julo lagbaye, Ballon d'Or Klopp ni oun faramọ bi ajọ ere bọọlu ni Afirika, CAF ye yi akoko idije ife ẹyẹ Afirika pada kuro ni osu kini si osu kẹfa eyi to ni yoo fun awọn agbabọọlu to wa lati ilẹ Afirika lanfani ati lee wọ awọn liigi to lamilaaka lagbaye."
OLUWA wà pẹlu rẹ̀, ó sì ń ṣe àṣeyọrí ninu gbogbo ohun tí ó ń ṣe.
Akowe egbe awon kirisiteni lorile ede Naijiria Reverend Cornelius Fawenu  wa sapejuwe yiyan igbimo yii gege bi “ eyi to ti wo iwe male-gbagbe lailai”.
Awọn ọba alaye nilẹ Yoruba ti wọn ti rọ loye: Ọba Ibikunle Akitoye ati ọba Kosọkọ tilu Eko: Oríṣun àwòrán, Others Ori ọba Ibikunle Akitoye tilu Eko ni itan sọ fun wa pe isẹlẹ iyọnipo ọba ti kọkọ waye nilẹ Yoruba, nigba ti awọn eebo amunisin le kuro lori itẹ, ki isẹlẹ ti ọba Kosọkọ naa to tẹle A si lee ni awọn eebo amunisin lo sefilọlẹ asa rirọ ọba loye nilẹ Yoruba, tori ko si akọsilẹ isẹlẹ kankan to ti waye saaju ki awọn oyinbo to de.
"Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Sunday Igboho: Fulani kò leè dúró, táa bá lo ohun ta jogún lọ́dọ̀ àwọ̀n bàbá wa O ni ""Awọn kan n fẹ atunto Naijiria, awọn si n fẹ iyipada orilẹede wa, ṣugbọn ni ti emi o, idagbasoke ati ominira Yoruba ni mo n fẹ, o si damiloju pe yoo ṣeṣe nitori ọdun yii jẹ tawọn ọmọ Yoruba yoo wa ni ọkan."
O ti sọ àwọn eniyan rẹ, Israẹli, di tìrẹ títí lae, ìwọ OLUWA sì di Ọlọrun wọn.
Laipẹ yii ni ọgọọrọ awọn eekan oselu to wa ninu ẹgbẹ oselu APC nipinlẹ Ondo n fi ẹgbẹ naa silẹ tabi kọwe fi ipo silẹ lẹyin gomina.
Ààrẹ ní kí wọ́n wádìí oun tó fa ìjàmbá bààlú Osinbajo Orí kò òṣìṣẹ́ EFCC méjì yọ lọ́wọ́ ìjàmbá iná‘Olùkọ́ fipá bá akẹ́ẹ̀kọ́ girama lòpò nítorí máàkì’ Ǹjẹ́ o mọ̀ pé mímí afẹ́fẹ́ tí kò dára lè fa àìsàn?
Ìwọ náà mọ ohun tí ó yẹ kí o ṣe gẹ́gẹ́ bí ọlọ́gbọ́n ọmọ, ṣugbọn o kò gbọdọ̀ jẹ́ kí ó fi ọwọ́ rọrí kú.
Ọpọlọpọ ni ko lee gbagbe Fela ati ipa ti o ko loke eepẹ nigba to wa laye ni Naijiria koda ni gbogbo agbaye.
Oríṣun àwòrán, Instagram/Mr Latin O wa n rọ awọn ọmọ ẹgbẹ rẹ lati ro gbogbo nkan wọn yii, ki wọn si fara da akoko yii bo ṣe gba.
Lọdun 1996, Maradona sọ pe ''mo ti loogun oloro, mo si n loogun oloro, mo si maa loogun lọ laelae.
Sweden ti fofin de awon arinrinajo lati ilẹ okere lẹyin to ri ẹya Covid-19 tuntun nibẹ Ẹya tuntun tun yara tan ka laarin awọn eniyan ju ti akọkọ lọ ṣugbọn ko si aridaju pe o yara paniyan ju ti akọkọ lọ.
N óo pàṣẹ fún ìhà àríwá pé,‘Dá wọn sílẹ̀.
22 Sẹ́rẹ́ 2020 Oríṣun àwòrán, Matthieu Aubry Àkọlé àwòrán, Ekute to n fa iba Lassa pọ ni Iwọ-oorun ilẹ Africa.
Nítorí náà, bí ẹ bá gbọ́ tèmi, tí ẹ sì pa majẹmu mi mọ́ ẹ óo jẹ́ tèmi láàrin gbogbo eniyan, nítorí pé tèmi ni gbogbo ayé yìí patapata; 
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fọ́nrán ohùn, Ọti lile ko ni anfaani f‘ara Kinni iwulo awọn ọti lile yi ?
Nkan tó fa wàhálà fún ẹlẹ́sẹ̀ nlá rèé o!
to wa ni orile ede Libya, to jẹ pe won ko ri owo lati fi pada sorile ede mọ, ni
Baba àti ọmọ si ni wọn jọ ń dabira lagbo ere tíátà báyìí bíi gbajumọ osere, ọmọdé kékeré si ni Azeez tí jogún ere tíátà lọ́wọ́ bàbá rẹ̀.
Àwọn aláṣẹ wọn ni wọ́n ń pè ní olóore wọn.
EndSars Protest: Ìjọba àpapọ̀ ní ká ṣọ́ra fún ìpéjọ èrò àti àlejò láti Amẹrika, UK, India, Rusia ati France
“Ẹ gbọ́, ẹ wò mí dáradára,nítorí n kò ní purọ́ níwájú yín.
Jobu, láti ọjọ́ tí o ti dé ayé,ǹjẹ́ o ti pàṣẹ pé kí ilẹ̀ mọ́ rí,tabi pé kí àfẹ̀mọ́jú mọ́ àkókò rẹ̀,
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Nigeria Independence Day: Aráàlú fa ìbínú yọ lórí ọ̀rọ̀ tí Buhari sọ fún àyẹyẹ òmìnira 1 Ọ̀wàrà 2020 Oríṣun àwòrán, @Xahraddeen_ Buhari, ayẹyẹ kí là ń ṣe gan, ṣé ti ìpànìyàn àbí ìjínigbé?
Ṣugbọn ṣa, kii ṣe gbogbo eniyan lo wa ni ilera pipe lasiko yii.
Aṣọ naa jẹ eyi ti ko ni apá.
Ẹ wá lọ sí gbogbo oríta ìlú, ẹ pe gbogbo ẹni tí ẹ bá rí wá sí ibi igbeyawo.
Oríṣun àwòrán, authenticmuy Awọn mii to tun fọrọ ati adura ranṣẹ si Muyiwa ni Aisha Lawal, Kiitan Bukola, Bisola Badmus, Funsho Adeolu, Temitope Solaja ati awọn mii.
Ọpọlọpọ awuyewuye ti tẹle igbesẹ Gomina ipinlẹ Oyo, Seyi Makinde to pe awọn imaamu ni ipinlẹ Ọyọ fun ayẹyẹ Iftar.
” Níwájú Ọlọrun ni Abrahamu wà nígbà tí ó gba ìlérí yìí, níwájú Ọlọrun tí ó gbẹ́kẹ̀lé, Ọlọrun tí ó ń sọ òkú di alààyè, Ọlọrun tí ó ń pe àwọn ohun tí kò ì tíì sí jáde bí ẹni pé wọ́n wá.
Kí wọn lè gbẹ́kẹ̀lé Ọlọrun,kí wọn má gbàgbé iṣẹ́ rẹ̀,kí wọn sì máa pa òfin rẹ̀ mọ́,
Osinbajo wa si Kano fun igbeyawo akowe ew, Alhaji Hafiz Ibrahim Kawu, eyi to waye ni mosalasi Umar Bin Khattab ni Dangi leba opopona Zaria.
O ni oun kabamọ pe oun jẹ ọmọ orilẹ-ede Ghana, nitori ni ṣe ni oun n ṣe ojuṣe oun lati rii pe ọjọ ọla awọn akẹkọọ naa dara, ṣugbọn ẹmi oun ti wa ninu ewu.
Tí a fiṣọwọ́ ní 9:55 11 Òkùdu 20199:55 11 Òkùdu 2019 ìdìbò bẹ̀rẹ̀ ní pẹrẹwu Akọwe ile ti kede pe idibo yoo bẹrẹ bẹẹ si ni ilana idibo bonkẹlẹ ni awọn yoo tẹle lati fi dibo eyi to tumọ si wi pe sẹnẹtọ kọọkan yoo gba iwe to ni orukọ awọn oludije to wa lori rẹ yoo si buwọlu ọkan ninu awn mejeeji ti wọn daba yoo si lọ fi sinu apoti ibo.
Ẹ fi ọ̀rọ̀ náà sọ́kàn, ẹ so ó mọ́ ọwọ́ yín gẹ́gẹ́ bí àmì, kí ẹ fi ṣe ọ̀já ìgbàjú, kí ó wà ní agbede meji ojú yín mejeeji.
pinnu lati bere ibo kika ni ipinle 
Nígbà tí àwọn eniyan gbọ́, ọ̀rọ̀ náà gún wọn lọ́kàn.
Gẹ́gẹ́ bí àṣà, ní àkókò àjọ̀dún, gomina a máa dá ẹlẹ́wọ̀n kan sílẹ̀ fún àwọn eniyan, ẹnikẹ́ni tí wọn bá fẹ́.
Raheem Sterling ti n ti n da bi ẹdun rọ bi owe lati igba ti saa bọọlu tuntun ti bẹrẹ bayii lo kọkọ gba bọọlu sinu awọn, eleyi to sọ iye goolu to ti gba sinu awọn di mẹrin.
Seyi Makinde ni owo naa wa fun iranwọ, to si gba awọn akẹẹkọ imọ ofin naa ni imọran, lati ma se na owo ọhun ni inakuna.
Amọ eyi to fẹran julọ ni oye Basọrun ati Aarẹ Ọna Kakanfo.
Nínú ọ̀rọ̀ àdúrà yìí ni mo fi ọgbọ́n gbe pé àbúrò bàbá wa ti kú.
Awon to wa nibi isele naa so pe ado oloro marun un ọtọtọ lo bu gbamu ni olu-ilu naa ni deede aago meje-abọ ati aago mejọ, ni eyi ti o deru ba awon olugbe ilu naa.
Ọpọ awọn olukọ lo ti n jẹ koriko abẹ wọn, ti wọn n huwa aitọ nipa biba awọn akẹkọọ sun.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Diego Maradona: Báyìí ni àgbàọ̀jẹ̀ agbábọ́ọ̀lù Diego Maradona ṣe wọ káà ilẹ̀ lọ lólú ìlú Argentina 25 Bélú 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 27 Bélú 2020 Oríṣun àwòrán, Casa Rosada Ba a ku laa dere eeyan o sunwọn laaye.
Ile awoṣi fila ti emi ati ọkọ mi ni tobi to lati gba ẹgbẹrun mẹwa ọmọ.
O si n dije fun ipo Adajọ nile ẹjọ Seventh Circuit, ni ijọba ibilẹ Prince George, ni Maryland.
El Rufai, ninu atẹjade kan to fisita ni, ọmọde mejilelogun ati obinrin mejila lo fori sọta isẹlẹ ipaniyan naa.
orile-ede Mozambique se lo n peleke si ju bu won se lero lo.
Solomoni ọba pinnu láti kọ́ tẹmpili níbi tí àwọn eniyan yóo ti máa sin OLUWA ati láti kọ́ ààfin fún ara rẹ̀.
Ki atundi ibo to waye, Ortom ni ibo 410,576 nigba ti Jime si ni ibo 329,022.
Ẹ kò gbọdọ̀ jẹ́ kí ẹnikẹ́ni wọnú ilé OLUWA, àfi àwọn alufaa ati àwọn ọmọ Lefi tí wọ́n wà lẹ́nu iṣẹ́.
Tani ẹni to pasẹ ki awọn ologun kuro ni agbegbe naa ati pw kini idi rẹ?
kí igbagbọ yín má baà dúró lórí ọgbọ́n eniyan bíkòṣe lórí agbára Ọlọrun.
Oríṣun àwòrán, AFP Ṣaaju ni China ti fẹsun kan India pe awọn ọmọ ogun rẹ rekọja ala wọn nigba meji ọtọtọ, ati pe wọn tun ṣakọlu si ẹgbẹgun oun.
Di à- níkàn- dá- jẹ̀ láàrin ìgbẹ́,
Ìgbà tí ó sì súnmọ́ mi dáadáa tí ó ń bá mi ṣiré ó fi ọwọ́ tẹ̀ mí ní ikùn, ó ní, Olówó-ayé o mà tilẹ̀ ń yọ ikùn.
Ninu àgọ́ àkọ́kàn ni àwọn alufaa ti máa ń ṣe wọlé-wọ̀de nígbà tí wọ́n bá ń ṣiṣẹ́ ìsìn wọn.
’ Kí ni kí n wí fún wọn?
O gbọdọ̀ wọ́ Hijab kí ẹmi okunkun ma ba a dé bá ọ Àkọlé àwòrán, Mo ní ìwé àkọsílẹ̀ ìgbé ayé mi ni àgọ́ Boko Haram- Naomi Adamu Wọ́n fún àwọn náà ni Hijab nítori wọ́n kò fẹ́ máá ri àra wọ́n, bákan náà ni wọ́n máa n ka kurani fún wọ́n nigbogbo igba.
gbodo mu eto ogbin lokunkundun nipase mimu alekun ba isuna re’’ .
Bótilẹ̀ jẹ́ pé kò ti si àridáju ààpu òun lórí Aplle Appstore tabi lori Goggle Playstore.
Ohun to yẹ ko mọ nipa Duro Ladipọ: Ọjọ Kejidinlogun, osu Kejila, ọdun 1931 ni Duro Ladipọ de ile aye, ti wọn si bii si ilu Osogbo, se odo kii san, ko ma ni orirun Ọmọlẹyin Kristi gidi, to wa lati idile onigbagbọ ni Duro Ladipọ, ti baba rẹ si jẹ ojisẹ Ọlọrun lati inu ijọ Angilika; amọ, baba baba rẹ to wa lati ilu Ọyọ ijọhun, jẹ Onisango ati Ọlọya Niwọn igba to jẹ pe ẹjẹ ni agbara, bi o tilẹ jẹ pe inu ẹsin igbagbọ ni wọn bi Duro si, sibẹ, o nifẹ si awọn ohun asa isẹnbaye gẹgẹ bi baba rẹ agba ti n se.
Ṣé a ti fi ìlẹ̀kùn ikú hàn ọ́ rí,tabi o ti rí ìlẹ̀kùn òkùnkùn biribiri rí?
Olukuluku yóo sì mọ ẹrù tirẹ̀.
Naṣoni ọmọ Aminadabu ni olórí wọn.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Fake News: Wọ́n padà ká a nílẹ̀ ṣùgbọ́n àbàwọ́n rẹ̀ ṣì wà lára mi By Michelle Madsen Investigative journalist 14 Òkùdu 2020 Oríṣun àwòrán, AFP Gẹlẹ bi mo ṣe n jade ninu kilasi ẹkọ nipa ijo ninu orun lọsan gangan ọjọ kan ni apa ariwa ilu London ni mo dede ba ọpọ ipe lorii foonu mi pẹlu awọn nọmba orilẹede Afirika.
N óo sọ àwọn ìlú Juda di ahoroẹnikẹ́ni kò ní gbé inú wọn mọ́.
3 Ìjọ èyítí a ṣe àkójọ rẹ̀ àti tí a gbé kalẹ̀ nínú ọdún Olúwa rẹ ọgọ́rũn méjìdínlógún ati ọgbọ̀n, ní oṣù kẹrin, àti ní ọjọ́ kẹfà ti oṣù èyítí à npè ní Oṣù Kẹrin.
 Russia ti gbe igbese mokanla lori ona abayo sisoro Syria lati ogun abele ni 2011.
Ni àwọn náà wá ròyìn ìrírí wọn ní ojú ọ̀nà ati bí wọ́n ti ṣe mọ̀ ọ́n nígbà tí ó bu burẹdi.
Gomina Abiodun ni oun kabamọ lori gbogbo idarudapọ to waye lori iṣẹlẹ naa.
Ọpọ awọn atipo naa ngbe lawọn abule to wa lẹnu alaa Naijiria ati Cameroun nipinlẹ Cross Rivers, lẹkun guusu Naijiria, tawọn mii naa si wa nipinlẹ Benue, to wa ni ẹkun aarin gbun-gbun ariwa orilẹede yii.
“OLUWA yóo bukun ìkórè inú àká rẹ, ati gbogbo nǹkan tí o bá dáwọ́ lé.
O fẹ́ yọ wọ́ ààyè ibùsùn àwọn obìnrin lọwọ́ ọlọ́pàá ba tẹ!
Àwọn eniyan mẹfa ni wọ́n ń ṣọ́ ẹnu ọ̀nà apá ìwọ̀ oòrùn ní ojoojumọ, àwọn mẹrin ń ṣọ́ ìhà àríwá, àwọn mẹrin ń ṣọ́ ìhà gúsù, àwọn meji meji sì ń ṣọ́ ilé ìṣúra.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ibrahim Babangida: Buhari ní Nàìjíríà kò lè gbàgbé iṣẹ́ ribiribi tí IBB ṣe láéláé bí ó ti pé ẹni ọdún 79 lónìí 15 Ọ̀pẹ̀̀ 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 17 Ògún 2020 Oríṣun àwòrán, Twitter/Presidency Àkọlé àwòrán, Ọrọ lori orilẹede Naijiria Aarẹ Muhammadu Buhari ti ki olori orilẹede Naijiria nigba kan ri, ajagun fẹyinti Ibrahim Badamosi Babangida ku ọjọ ibi ọdun kọkandinlọgọrin lonii ọjọ kẹtadinlogun oṣu kẹjọ.
N óo fọn yín káàkiri ààrin àwọn àjèjì; n óo tu yín ká sí ààrin àwọn orílẹ̀-èdè, n óo fi òpin sí ìwà èérí tí ẹ̀ ń hù ní Jerusalẹmu.
Ninu ifọrọwanilẹnuwo pẹlu BBC Yoruba, Risikat fidi ọrọ yi mulẹ pe lootọ ni pe oun ti bẹrẹ si ni kọ iṣẹ aṣojuloge yi.
Orúkọ àwọn ọkunrin tí Mose rán láti lọ ṣe amí ilẹ̀ náà nìyí.
Ahitofeli dáhùn pé, “Wọlé lọ bá àwọn obinrin baba rẹ, tí ó fi sílẹ̀ láti máa tọ́jú ààfin, kí o sì bá wọn lòpọ̀.
Ọpọ awọn adari orílẹ̀ ede ati awọn ọmọ oye meji ni Saudi ni wọn ti kọwe gbele ẹ fun ni Saudi.
Miliọnu kan naira ni ileẹjọ fi gba beeli Adene ki o to gba ominira lọ si ile rẹ.
Awọn onimọ isegun oyinbo ni awọn iṣẹlẹ bẹẹ maa n waye, ṣugbọn kii saba n wọpọ.
A fẹ ṣe alabapin itan awọn obinrin naa pẹlu yin ti a o si ṣe iwadi bi awọn oniroyin ti ṣe kọ nipa awọn iṣẹlẹ wọn yi.
Ọba alaye naa sọ pé àwọn igbimọ ti wọn gbé kalẹ ni awọn ipinlẹ kan kò ni Ọba ninu, eyii ti ko yẹ kó rí bẹ́ẹ̀.
O jẹ ọkan lara awọn ọrẹ timọtimọ ti aarẹ ni.
 wọ ́ n wà ní àdúgbò orílẹ ̀ èdè tanzania àti kenya , wọ ́ n sì fẹ ́ ẹ ̀ tó ọ ̀ kẹ ́ mẹ ́ tàdínlógún ààbọ ̀ ní iye .
ng O nì nílò láti san kọ́bọ̀, ọ̀fẹ́ ni Ẹ̀ẹ̀kan péré ni o le fi orúkọ silẹ̀; bi o bá gbìyànjú lati ṣee lẹẹmeji, wọ́n yóò wọ́gile.
“Ìbágbé àwọn eniyan wọnyi tuni lára pupọ, ẹ jẹ́ kí wọ́n máa gbé ilẹ̀ wa, kí wọ́n máa tà, kí wọ́n máa rà, ilẹ̀ yìí tóbi tó, ó gbà wọ́n.
Àjọ ̀ dún ìbílẹ ̀ jẹ ́ mọ ́ bíbọ òrìṣà kan tí àwọn olùsìn rẹ ̀ fi ń wájú mọ ́ ra tàbí láti fi bẹ ̀ bẹ ̀ tàbí san ẹ ̀ jẹ ́ lọ ́ dọ ̀ rẹ ̀ .
Gómìnà Ṣèyí Mákindé ṣàlàyé ìdí tí òun kò fi leè ti ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́ pa nítorí COVID-19 Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Àrìnfẹsẹ̀sí - Ìbéèrè ni a bèrè lọ́wọ́ àwọn èèyàn, ika òṣì ni wọ́n ń ta dànù Akorede ni O yẹ káwọn osere lo àkókò yìí dáadáa, nítorí ọ̀pọ̀ èèyàn ni yóò ṣe oriire lásìkò yìí, kò sì yẹ ká fi ṣòfò.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Overweight and pot belly: Wo oríṣìí oúnjẹ márùn ún tó lè dẹ́kun ikùn yíyọ àti ara àsanjù 8 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Oríṣun àwòrán, Food Ace Njẹ iwọ ominu n kọ ẹ lori bi o ṣe n yọkun tabi bi o ṣe n tobi sii?
Haa, leeyan temi atirẹ ṣẹṣẹ jọ jẹun tan ni ṣọọbu to ni ki n lọ se mọi-mọi wa ni wọn waa n ṣalaye fun mi bi awọn lọpaa meji ṣe yin in nibọn.
Bakan naa lo sọ pe ileeṣẹ FIRS, yoo ri daju pe gbogbo awọn to ba lọwọ ninu inakuna owo ti NIPOST n pa lori Stamp duties to n gba lọna aitọ, fi oju wina ofin.
, Duration 4,2617 Bélú 2020 2:15 Fídíò, The New Pandemic: Kíni àwọn onímọ̀ sáyẹ́ńsì ń sọ nípa rẹ̀?
Diẹ lara aworan igbeyawo to fi oju opo rẹ ree Oríṣun àwòrán, Bunkunmi Oluwasina Oríṣun àwòrán, Bunkunmi Oluwasina Jimoh Aliu Aworo re bi agba ree Ọjọbọ, ọjọ kẹtadinlogun, oṣu Kẹsan-an, ọdun 2020 ni ilumọọka osere tiata, Jimoh Aliu dagbere faye.
Kidney Transplant: Ilé ìwòsàn ṣ'àṣìṣe ṣiṣẹ́ abẹ kìndìrín fún aláìṣàn ní New Jersey
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Omolola Arohunmolase Welder: Mo ti fí iṣẹ́ 'Welder' gbayì láwùjọ, tó mo fi tọ́ ọmọ yanjú Nigba ti BBC Yoruba kan sileesẹ ọlọpa ipinlẹ Ondo, Agbẹnusọ fun ileesẹ ọlọpaa Ondo, Leo Ikoro salaye pe lootọ ni ikọlu mejeeji naa waye ni ọsẹ to kọja ni aafin Ajagunode, ti ikọlu miran si tun waye mọjumọ ọjọ Ẹti ni aafin ọba Isinigbo.
Ẹ kíyèsára, ará, kí ó má ṣe sí ẹnikẹ́ni ninu yín tí yóo ní inú burúkú tóbẹ́ẹ̀ ti kò ní ní igbagbọ, tí yóo wá pada kúrò lẹ́yìn Ọlọrun alààyè.
Man Utd v Juventus: Kíni ipadabọ Ronaldo sí Old Trafford yóò bí?
Ó gbé ẹ̀san wọ̀ bí ẹ̀wù,ó fi bora bí aṣọ.
O papoda nigba ti ko ribi mi mọ.
Ó ń wá ọ̀nà láti yí ọkàn gomina pada kúrò ninu igbagbọ.
"Ọlọ́pàá wú òkú obìrin tó ń múra ìgbéyàwó lọ́wọ́ tí 'gate-man' rẹ̀ ṣekúpa ""A fẹ́ yọ ààrẹ ẹgbẹ́ Yorùbá YCE nípò torí àwọn ìwà tí kò bójúmu"" Wo àànfàní ‘Masturbation’, fífún ara rẹ̀ ní adùn ìbálòpọ̀ Ẹ fura o, Boko Haram ti pàgọ́ sí Abuja, yóò ṣe ìkọlù láìpẹ́ - Iléèṣẹ́ Aṣọ́bodè lọgun Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 3 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 5 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!"
Ọ̀kan pàtàkì lára àwọn èdè orílẹ̀ èdè Nàìjíríà ni èdè Yorùbá.
Ẹ wá wo ata ní onírúirú, ọlọ́kanòjọ̀kan àti oríṣìíríṣìí!
Nígbà tí ó bá tó àkókò láti tẹ̀síwájú, àwọn ìdílé Kohati yóo wá láti kó àwọn ohun èlò ibi mímọ́ lẹ́yìn tí Aaroni ati àwọn ọmọ rẹ̀ bá ti bò wọ́n tán.
Ẹni tí yóo fi mí fún àwọn ọ̀tá ti súnmọ́ tòsí.
 Shuaibu tẹsiwaju pe nigba ti baba rẹ ku lọdun diẹ sẹyin, awọn aburo rẹ ọkunrin meji tun tẹsiwaju lati maa tii mọle sugbọn loni, o ti gba ominira.
Ẹ sọ mí di ọ̀tá gbogbo àwọn tí ń gbé ilẹ̀ yìí, láàrin àwọn ará Kenaani ati àwọn ará Perisi.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fọ́nrán ohùn, Ruga settlement: YCE ní ìjọba àpapọ̀ ko tó bẹ̀ẹ́ láti kọ́ àgọ́ Fulani sílẹ̀ Yoruba Ayédèrú Afenifere ló bá Buhari ṣépàdé - Odumakin gbanájẹ Dapo Abiodun wà lára àwọn tó ta ohun ìjà olóró fún mi - Amoṣun 'A máa ń fí oògùn olóró 'ginger'ká tó ka ẹsẹ bíbélì ni ṣọ́ọ̀ṣì' Orin kíkọ kò dí ìwé mi lọ́wọ́ rárá -Hameen School Boy Idi niyi ti mo fi pinnu lati sọrọ sita lasiko yii, nitori asiko yii gan an lo dara ju fun mi lati sọ iriri mi.
Iroyin ofege ti wọn gbo ni pe awọn ọdọ ti wọn to igba n kaakiri lati ja awọn eniyan lo le.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ sí: Fayoṣe: Mi ò jẹ̀bi ẹ̀sùn kankan Olorì Ìlé-Ifẹ tẹlẹ̀ rí bá Ọọ̀ni Ogunwusi yọ̀ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Ó ṣojú mi kòró, ẹ wọ bí ìgbà ayé Bàbá Fagunwa ṣe rí' Ó ti di ènìyàn márùnléláàdọ́ta tí wọ́n pàdánù ẹ̀mí wọn nínú ìṣẹ̀lẹ̀ náà báyìí.
Ẹ̀kọ́ ìtàn yí ni wípé iyè meji kò dara, ọ̀dalẹ̀ ma mba ilẹ̀ lọ ni, nitorina, ojúkòkòrò kò lérè.
August Agboola Brownie, ọmọ Yorùbá tí wọ́n n wárí fún ní Poland Awọn ọmọ ẹgbẹ oṣelu Democrat ati awọn miran lẹgbẹ oṣelu Republican n na ika alebu si Aarẹ Trump pe, oun lo wa nidi ikọlu naa nipa awọn ọrọ to sọ nibi ipade itagbangba kan to ti n fi ẹsun eru ibo kan, laini ẹri kan pato to daju.
June 12: Àwọn tó ṣojú wọn kòró sọ irírí ọjọ́ náà
Mose rán eniyan lọ ṣe amí Jaseri, wọ́n sì gba àwọn ìlú agbègbè rẹ̀, wọ́n lé àwọn ará Amori tí ń gbé inú rẹ̀ kúrò.
Àwọn akẹ́kọ̀ọ́ tó ń fẹ̀họ́nú hàn ṣe ìkọlù sí Fayemi Òní lòní ń jẹ́.
Nígbà tí o ń bọ̀ ó gba ìwé kan bọ̀ wa fún mi, ohun tí ó wà nínú ìwé náà ni èyí:
Wọn gbe igbesẹ naa lẹyin ti awọn aṣoju lati ipinlẹ Bornu da aba pe o yẹ ki Aarẹ Buhari yọju si ile ọhun.
ati iroyin fun ile-ise Ologun oko ofurufu ,Ibikunle Daramola ni awon fun omo-
À lòdì sí káádì ìdánimọ aráàlú tawọn Ológun fẹ́ máa yẹ̀wò!
Ijọba pasẹ fawọn agbofinro lati tọpinpin ọrọ ikorira lori ikanni ayelujara
Alaga yii menuba awon agbe to le ni egberun metala ti won ti ri owo yiya gba lati ara eto Anchor Borrower tijoba apapo gbe kale lati banki Naijiria ati banki ise agbe.
Ile-ise naa tun tesiwaju pe awon yoo tubo maa pese eto
Yóo gbìyànjú láti yí àkókò ati òfin pada.
Yóo da ìyẹ́ rẹ̀ bò ọ́,lábẹ́ ìyẹ́ apá rẹ̀ ni o óo ti rí ààbò;òtítọ́ rẹ̀ ni yóo jẹ́ asà ati apata rẹ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Àwọn jàndùkú ṣe yabò àwọn olùwọ́de #ENDSARS ní Alausa l'Eko Wo ìlànà ìgbani síṣẹ́ márùn-ún fún àwọn ọlọ́pàá SWAT tó rọ́pò SARS Ọjọ Aje ni Ọga Agba ileeṣẹ ọlọpaa Naijiria, Adamu Muhammad kede ikọ ọlọpaa tuntun Speacial Weapons and Tactics (SWAT) lati rọpo ikọ ọlọpaa Special Anti-Robbery Squad ,SARS, ti wọn tuka.
Aare Buhari kede awon ajo tuntun marun naa
Impeached Kenya Governor: Sonko Mbuvi ní àwọn alájẹbánu tóun dí lọ́wọ́ ló yọ òun nípò
Ṣugbọn kí ẹ mọ̀ dájú pé OLUWA ti ya olódodo sọ́tọ̀ fún ara rẹ̀,OLUWA yóo gbọ́ nígbà tí mo bá pè é.
 bakanna o tun je alabasoju unicef .
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Premier league: Arsenal kọrin 'kọ́stọ́mà daada ni' fún Burnley pẹ̀lú àmì ayò méjì sí ẹyọkan 17 Ògún 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Lacazette, Aubameyang, Ceballos ati Pepe tan yòò bí oòrùn nínú ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ náà Nnkan gbe nnkan hanu loni ni papa iṣire Emirates tii ṣe ibuba ẹgbẹ agbabọọlu Arsenal.
" Akeredolu, Oyetola, àtàwọn míì sọ̀rọ̀ lẹ́yìn tí ìjọba àpapọ ní Amotekun kò bá òfin mu Ilé ẹjọ́ rán ọmọ ìjọ lẹ́wọ̀n ọdún 18 lórí ẹ̀sùn pé ó jí ₦15m owo ìjọ Ó pé ọdún mẹ́rìnlélàádọ̀ta tí Akintola kú, ìdí abájọ ìja rẹ̀ pẹ̀lú Awolowo rè é Ọ̀rọ̀ di kọ̀!
Lara awọn eeyan ti yoo lewaju igbimọ naa la ti ri igbakeji akojanu tẹlẹ fun ile asofin agba nilẹ wa, Senetọ̀ Hosea Ayọọla Agboọla ati oludije tẹlẹ fun ile asofin agba lẹkun idibo Oyo North, Oloye Oyebisi Ilaka.
Jẹ́ kí ó fi pamọ́ di ọjọ́ ìsìnkú mi.
Oríṣun àwòrán, Bose Àkọlé àwòrán, Kùtùkùtù òwúrò ọjọ́ ọ̀rú làwọn òṣìṣẹ́ ikọ̀ amúṣẹ́yá láti àjọ olówó-orí nípínlẹ̀ Ọ̀ṣun, OIRS gúnlẹ̀ sí ọgbà fásitì náà Àmọ́ ṣá, àwọn aláṣẹ fásitì náà ti ṣàlàyé pé, àìgbọ́raẹniyé láàárín fásitì náà àti ìjọba ìpínlẹ̀ Ọ̀ṣun ló fa ìṣẹ̀lẹ̀ náà.
Ó kúkú yàn láti jìyà pẹlu àwọn eniyan Ọlọrun jù pé kí ó jẹ ìgbádùn ẹ̀ṣẹ̀ fún ìgbà díẹ̀ lọ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Baruwa Gas Explosion: Àwọn tó forí sọta ìjàmbá iná ń bẹ ìjọba láti dìde ìrànwọ́ Sáájú ni gómìnà ọhun ti fara kasa ààrùn Coronavirus, sùgbọ́n ó ti n gbádùn.
Kò bá rí bẹ́ẹ̀ lóòótọ́ ni a ò bá yọ̀ pé orí àwọn olórí wa náà ti ń pé bọ̀.
Iye awọn eeyan to ṣẹṣẹ ko arun naa ni ipinlẹ kọọkan ree: Eko-166 Oyo-66 Delta-53 Ebonyi-43 Plateau-34 Ondo-32 FCT-26 Ogun-25 Edo-24 Imo-15 Bayelsa-13 Benue-12 Gombe-11 Kano-11 Kaduna-11 Osun-8 Nasarawa-7 Borno-5 Katsina-2 Anambra-2 Florence Ajimobi tahùn sí igbákeji gómìnà Oyo lórí ikú ọkọ rẹ̀, Gbogbo wa làó kú"" Ilé ìfowópámọ́ Access ti gbà láti dá owó àwọn oníbàráà wọ́n padà Ẹ wo àwòrán bí ìsìnkú Abiola Ajimobi ṣe lọ!"
Neo naa dabi Vee ti ori ko yọ lawọn igba to ti wa lara awọn ti BBNaija fẹ le lọ sile.
Amosa , alaafia joba nigba ti gomina ipinle naa bere si wa n ba awon
Ni ipari gbogbo awon to soro nibi eto naa ro awon agbe lati sise daadaa ki won ma si anfani yii lo ki idagbasoke le ba eto oro aje ipinle Ondo ati ti Naijiria lapapo.
“ ‘Nítorí ẹ̀yin ará Edomu sọ pé, àwọn orílẹ̀-èdè mejeeji wọnyi ati ilẹ̀ wọn yóo di tiyín ati pé ẹ óo jogún rẹ̀, bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé OLUWA wà níbẹ̀.
Ajo isokan mejeeji soro imori ya naa ninu iwe abadofin ti o jade leyin ipade apero oselu kejilelogun(22nd ECOWAS-EU political meeting),ti o waye lojoEti(Friday), niluu Abuja.
Bí wọn tí ń lọ, bẹ́ẹ̀ ni àwọn àgbá náà ń lọ lẹ́gbẹ̀ẹ́ wọn.
Ìjọba ló ń ṣe kóríyá fún àlàfo ńlá láàrin ọlọ́rọ̀ àti mẹ̀kúnnù - Oxfam Iṣu ló wà nínú mọ́tò mi, kìí ṣe èèyàn ni mo sọ di iṣu - Afurasí Ajínigbé figbe ta Ìlú tí ọ̀daràn bá tí dẹ́ṣẹ̀ ló yẹ kí wọn tí gbẹjọ́ rẹ̀ -Agbẹjọ́rò Àgùnbánirọ̀ gbẹ́mìí mì látàrí 'Snipper' tó fi fọ irun rẹ̀ Gbenga ṣalaye bi oun ṣe wa si Badagry fun isinmi lẹnu iṣe pẹlu iyawo oun ko to di pe oun wa di ẹni to n gbe agbegbe yii ni alaafia bayii.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Bí aya bá kọ ọkọ rẹ̀ silẹ̀, kó wà láì lọ́kọ̀' Inu mi bajẹ nitori pe ọpọ lara wọn lo ti n fẹ Philippe ki emi ati ẹ to o pade.
Tí a fiṣọwọ́ ní 4:23 11 Sẹ́rẹ́ 20214:23 11 Sẹ́rẹ́ 2021 Àpapọ̀ àwọn tó ti ní Coronavirus ní Naijiria ti lé ní 100,000 báyìí O ti le ni ọjọ mẹta bayii ti iye eniyan to n lugbadi arun Coronavirus ti n le ni ẹgbẹrun kan ní ojoojumọ.
Nitori eyi ileeṣẹ ọlọpaa pa ikọ SARS rẹ; bẹẹni ijọba apapọ ti ṣalaye fawọn ipinlẹ gbogbo lorilẹede Naijiria lati tete gbe igbimọ oluwadi kalẹ lati boju wo gbogbo ẹsun ati ẹhonu tawọn araalu n gbe sita.
Ajẹ́pé lọ́dọ̀ tiwọn níbẹ̀, àti ọ̀sán gan-gan o, àti gànjọ́ òru, ìkáwọ́ oòrùn ló wà.
Ẹ jẹ́ ká gbafẹ́ pẹ̀lú àwọn àwòdamiẹnu àwòrán nípa ìgbé ayé rẹ
Arakunrin naa ti lọ si ile iwosan bii marun un ki o to di wi pe o ri ile iwosan ti yoo ran lọwọ lati yọ ohun eelo ifoyin naa kuro ninu rẹ, lẹyin ti iwadii fihan pe lootọ ni burọọsi naa wa ninu rẹ.
Nígbà náà ni Hamani lọ bá Ahasu-erusi ọba, ó sọ fún un pé, “Àwọn eniyan kan wà tí wọ́n fọ́n káàkiri ààrin àwọn eniyan ati ní gbogbo agbègbè ìjọba rẹ; òfin wọn kò bá ti gbogbo eniyan mu, wọn kò sì pa àṣẹ ọba mọ́.
Oríṣun àwòrán, Kaduna Govt Nasir El-Rufai Nasir El-Rufai ni Gomina ipinlẹ Kaduna lọwọlọwọ.
Ọmọkùnrin tó ya 'Blue film' nínú igbó Osun Osogbo ti bayé ara rẹ̀ jẹ́ - Yemi Elebuibon Ìbẹ̀rù-bojo dé l'Ado Ekiti!
Ṣe fìtílà meje fún ọ̀pá fìtílà náà, kí o sì gbé wọn ka orí ọ̀pá náà ní ọ̀nà tí gbogbo wọn yóo fi kọjú siwaju.
indonésíà ( tàbí ) , lóníbiṣẹ ́ bíi orílẹ ̀ -èdè olómìnira ilẹ ̀ indonésíà ( ) , jẹ ́ orílẹ ̀ -èdè ní gúúsùìlàorùn Ásíà àti oseania .
Gbọ́, kí o sì mọ̀ pé fún ire ara rẹ ni.
Ọlọrun wá tún yan ọjọ́ mìíràn.
O ni oyun inu oun ti pe oṣu mẹfa nigba ti oun kopa ninu ere yii.
Mercy ló gbadé BBNaija ọdún 2019 Kí ló dé táwọn ọ̀dọ́ dìbò 140m fún BBNaija àmọ́ tí ìbò ààrẹ Nàíjíríà jẹ́ 28m?
Kí alufaa yẹ ojú egbò náà wò, kí ó sì pe abirùn náà ní aláìmọ́, irú egbò yìí jẹ́ aláìmọ́ nítorí pé ẹ̀tẹ̀ ni.
Ayédèrú òṣùnwọ̀n jẹ́ ohun ìríra lójú OLUWA.
Child Engineer: Olamide Odukọya ní òun fẹ́ ṣe ohun kan tí yóò wúlò fún gbogbo àgbáyé
Ọjọ kẹtala, oṣu Kinni si ni ogun naa pari nigba ti awọn ọmọ ogun Biafra jọwọ ara wọn.
Nígbà tí àkókò bá tó, àwọn ará ilé Juda yóo tọ àwọn ará ilé Israẹli lọ, wọn yóo sì jọ pada láti ilẹ̀ ìhà àríwá, wọn yóo wá sí ilẹ̀ tí mo fún àwọn baba ńlá yín tí wọ́n jogún.
Mú díẹ̀ ninu irun náà kí o dì í sí etí ẹ̀wù rẹ.
Òfin ni ó fún ẹ̀ṣẹ̀ lágbára.
tiwa-n-tiwa tun fese mule sii lorile ede yii.
Ó ṣe nǹkan burúkú lójú OLUWA, bíi Manase, baba rẹ̀, ó rúbọ sí gbogbo oriṣa tí baba rẹ̀ ṣe, ó sì ń bọ wọ́n.
Ijọba orilẹẹde Zimbabwe ti kede orukọ ogunlọgo ile isẹ ti wọn kọ lati da owo ti wọn ko pamọ si ile okere pada.
Mose pa àgọ́ mímọ́ náà, ó to àwọn ìtẹ́lẹ̀ rẹ̀ sílẹ̀, ó gbé àwọn àkànpọ̀ igi rẹ̀ lé wọn, ó fi àwọn igi ìdábùú àgọ́ náà dábùú àwọn àkànpọ̀ igi rẹ̀; lẹ́yìn náà, ó gbé àwọn òpó rẹ̀ nàró.
Àkọlé àwòrán, Ìdìbò Kano kò fararọ, bẹ́ẹ̀ láwọn ìpínlẹ̀ to kù náà kò sí ní ìfọ̀kanbalẹ̀ Ajọ eleto ìdìbò ṣì ń réti la'ti ka èsì ìbò nibi tí ìdìbò ba ti waye.
Ẹlẹsẹ ayo fun Naijiria to n gba bọọlu fun ikọ Barcelona, Asisat Oshoala sọ pe bakan naa lọmọ ṣori kaakiri gbogbo ilẹ Afirika.
Ṣugbọn nítorí tìrẹ ni wọ́n fi ń pa wá tọ̀sán-tòru,tí a kà wá sí aguntan lọ́wọ́ alápatà.
Bi kii ba se bẹ, eleyi jẹ nkan to n runi loju ni.
Ni bayii, awon onisowo ati ile oja yoo ma gba
Lọjọ Iṣẹgun ni Maxim wa gbẹmi mi nigba ti ọkan re kọ iṣẹ lẹyin iṣẹ abẹ ti wọn ti ṣe fun un.
won n pe ni Afla-Toxin fun itoju  aarun
Oríṣun àwòrán, George Wafula/BBC Onimọ kan sọ fun mi pe awọn to lee ri anfani lara iru iroyin bayii ni ijọba Senegal tabi awọn ileepo.
Wenger àti Mourinho ti parí ìjà Jose Mourinho gbàwé ìdádúró ní Manchester United Mourinho tún fẹ́ bá Wenger pàdé l'ọ́jọ́ iwájú Bẹẹni,Mourinho ti sọ tẹlẹ pe ifẹ toun ni si Chelsea pọ bẹ debi pe ohun ko le gba iṣẹ akọnimọọgba Tottenham.
Godwin Emefiele  fun ohun ti o pe ni “ o yẹ fun ipo yii, nitori pe o se isẹ
Bi oriade yii si ti n ṣetọju awọn ẹlẹyinju ẹgẹ, naa ni ko gbagbe awọn aya igba ọdọ rẹ, to si n bu ọla ati iyi fun wọn pẹlu, bi o tilẹ jẹ pe ọpọ wọn ti dagba, ti wọn si ti ni ọmọ-ọmọ.
Ọpọ eeyan lo ti fesi si igbesẹ ọba alade naa pẹlu bo se yan oye Emir laayo, ti oju opo ikansira ẹni si kun fun ifapa janu awọn eniyan lori ọrọ yii.
Oríṣun àwòrán, PoliceNG Bi o ba ti fi nọmba yi ṣọwọ si aaye naa, o ma ni lati kọ gbogbo iroyin ti wọn n beere silẹ lati le fi ṣafikun eleyi to ti kọ tẹlẹ.
Ọba Eshinlokun, tii ṣe baba Kosoko, lo wa lori itẹ lasiko ti Oshodi de silu Eko, ti oloye Fagbemi si muu lọ si aafin ọba lati fi ọrọ rẹ to ọba leti.
Wọn yọ oju ọmọ naa mejeeji, pẹlu ahọn rẹ, wọn ko o sinu agolo siga, ti wọn si kun iyoku ara ọmọ naa wẹlẹwẹlẹ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Àmì ohùn ṣe pàtàkì nínú èdè Yorùbá púpọ̀ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àmì ohùn ṣe pàtàkì nínú èdè Yorùbá púpọ̀ 22 Ògún 2019 Ayé kò kúkú lọ bí ọ̀pá ìbọn ni ọ̀rọ̀ ayé jẹ́.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ibadan robbery: Àgbègbè Secretariat ni adigunjalè ti gba ₦446,000 lọ́wọ́ oníbàárà báńki tí wọ́n pa 24 Ògún 2020 Oríṣun àwòrán, others Awọn adigunjale ti yinbọn pa ọkunrin kan, Taoreed Olusola, lagbegbe ọfiisi ijọba to wa ni Agodi, ni ilu Ibadan.
Akiṣi pe Dafidi, ó sọ fún un pé, “Mo fi OLUWA ṣe ẹlẹ́rìí pé o jẹ́ olóòótọ́ sí mi, inú mi sì dùn sí i pé kí o bá mi lọ sójú ogun yìí, nítorí pé n kò tíì rí ẹ̀bi kan lọ́wọ́ rẹ láti ìgbà tí o ti dé ọ̀dọ̀ mi títí di òní.
Wúrà tí wọ́n fi òòlù lù ni kí wọ́n fi ṣe ìtẹ́lẹ̀ ati ọ̀pá fìtílà náà; kí wọ́n ṣe é ní àṣepọ̀ mọ́ òkè ọ̀pá fìtílà náà; kí wọ́n ṣe iṣẹ́ ọnà bí òdòdó tí wọn yóo fi dárà sí ìdí fìtílà kọ̀ọ̀kan.
“Kabiyesi, Ọlọrun tí ó ga jùlọ fún Nebukadinesari, baba rẹ ní ìjọba, ó sọ ọ́ di ẹni ńlá, ó fún un ní ògo ati ọlá.
Awon ologun ohun fi owo sinkun mu awon odaran afunra si kan ni ipinle Taraba lasiko ise-akanse AYEM AKPATUMA,  ti awon omo-ogun naa se ni agbegbe Takum nipinle Taraba, okan lara awon afunra si naa, Rapheal Yakwa ni won fi owo sinkun mu nigba ti o n ya aworan  awon ologun lai gbase.
O ni ko si adehun redio ninu adehun to ba ijọba ṣe.
Wo àwọn gómìnà Naijiria tí àrùn Covid-19 ti bá fínra Gomina ọhun ni igbesẹ yii ṣe pataki fun anfani ara wọn ati fun gbogbo ara ilu lapapọ.
À ń ṣe iṣẹ́ wa pẹlu òtítọ́ inú ati agbára Ọlọrun.
íṣi tó wà - BBC News Yorùbá BBC News, YorùbáFò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Yahoo Yahoo: Dating , Construction, awọn tó ń ṣe credit card - oríṣi tó wà Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Yahoo Yahoo: Dating , Construction, awọn tó ń ṣe credit card - oríṣi tó wà 25 Bélú 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 28 Bélú 2019 A ko lee darukọ rẹ tabi fi oju rẹ gangan han fun idi pataki.
Ẹ gbọ́ ìró àwọn orílẹ̀-èdèwọ́n ń hó bíi ríru omi òkun ńlá.
Kíni ẹ mọ̀ nípa Ọmọ́táyọ̀ Olútóyè, Ọ̀jọ̀gbọ́n obìnrin àkọ́kọ́ nínú ẹkọ́ èdè Yorùbá lágbàyé 'Òṣòkòmọlẹ̀' ní ẹjọ́ láti jẹ́ lórí owó Káńsù l'Ekiti Ṣe ẹ ti gbọ́ ri?
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Awuyewuye lori ọrọ Zuma yoo se ọ̀pọ̀ ijamba fun ẹgbẹ oselu ANC Ẹkẹẹta ninu awọn ọgbun ti minisita fun ọrọ ilẹ okeere nigbakanri lorilẹede Naijiria tun mu ẹnu le ni ti ẹsun iwa kotọ eleyi ti wọn n fi kan Cyril Ramaphosa funrarẹ.
Won fikun oro ohun pe, ikolu naa waye leyin ojo meji ti ibugbami ado-oloro waye, eyi ti o gbemi eniyan ti o leni ogorun-un ti awon miran si farapa yanayana, besini ikolu miran tun waye lose kan seyin nile itura Intercontinental nilu Kabul ohun, leyi ti o gbemi ogun eniyan niye.
Wọ́n bá fà á lọ sọ́dọ̀ Jesu.
Ẹ̀mí sọ fún Filipi pé, “Lọ síbi ọkọ nnì kí o súnmọ́ ọn.
”Jesu dá a lóhùn pé, “Níbi tí mò ń lọ, ìwọ kò lè tẹ̀lé mi nisinsinyii, ṣugbọn nígbà tí ó bá yá, ìwọ óo tẹ̀lé mi.
Oniruuru ni awọn ẹsun ti wọn fi kan olootu ere Yoruba yii to jẹ ẹni mimọ daadaa niluu Eko, ẹsun latorii owo Naira N39,098,100, si owo dollar $90,000 ati Pounds £12,550.
Risipa, ọmọbinrin Aya, fi aṣọ ọ̀fọ̀ pa àtíbàbà fún ara rẹ̀ lórí òkúta, níbi tí òkú àwọn tí wọ́n pa wà.
Arabinrin Nike Davies-Okundaye kii ṣe ọmọde rara ninu iṣẹ to yan laayo ati gẹgẹ bi agbaṣa ga ọmọ orilẹede Naijiria.
Akeredolu, lasiko to n dahun ibeere lori boya afikun yoo wa lori owo ile ẹkọ fasiti ipinlẹ naa to wa nilu Akungba Akoko.
 suku ti je òkan lára kéréjé èyà tó wà lábé yakà rí .
Bí OLUWA ti wà láàyè, bí ó bá jẹ́ pé ẹ dá wọn sí ni, ǹ bá dá ẹ̀yin náà sí.
Wọn a ma jẹ ẹ pẹlu ọti waini.
Oríṣun àwòrán, Rex Features Àkọlé àwòrán, Maradona lagbabọọlu ti o pegede julọ nidije agbaye ọdun 1986 Ọmọ ọdun mẹrindinlogun lo wa nigba naa, orilẹede Hungary ni Argentina koju lọjọ naa.
 Àpapọ ̀ àjẹsára àrùn ìta-àrùn ṣegede-àrùn ìta jámínì ( mmr ) di wíwà fún lílò fún ìgbà àkọ ́ kọ ́ ní ọdún 1971 .
Ṣugbọn lẹ́yìn tí Ahabu kú, ọba Moabu ṣọ̀tẹ̀, kò san ìṣákọ́lẹ̀ náà fún ọba Israẹli mọ́.
Oyo PDP: Olórí ọ̀dọ́ farapa ni, ẹni tó wa ọ̀kọ́ ló kú
Ẹlẹ́rìí gbọdọ̀ tó meji tabi mẹta kí wọ́n tó lè pa ẹnikẹ́ni fún irú ẹ̀sùn bẹ́ẹ̀, wọn kò gbọdọ̀ pa eniyan nítorí ẹ̀rí ẹnìkan ṣoṣo.
Wike kìí ṣe dọ́là tí Ganduje leè kó sápò- Agbẹ́nuso ìjọba ìpínlẹ Rivers APC ní yóò jáwe olúbori ni Bayelsa ati Kogi- Tinubu Dino, Wada àti àwọn olùdíje 11 míràn n dù àsíá PDP fún gómìnà ìpínlẹ̀ Kogi Fábàdà!
Salu ati Amoku, Hilikaya, ati Jedaaya.
Kí o kan ọkọ̀ náà ní ìpele mẹta, kí o sì ṣe ẹnu ọ̀nà sí ẹ̀gbẹ́ rẹ̀.
Ẹ kú ináwó mi àná, ẹ kú aájò, ẹ kú ìtọ́jú wa.
Nígbà tí Jesu sọ̀rọ̀ yìí tán ó tẹ̀síwájú, ó gòkè lọ sí Jerusalẹmu.
O Fagunwa, gẹgẹ bi ọpọ eeyan se mọ si, lo kọ iwe Ogboju ọdẹ ninu igbo Irunmọlẹ̀ lọdun 1938, Igbo Olodumare lọdun 1945, Ireke Onibudo lọdun 1949, Irinkerindo ninu igbo Elegbeje lọdun 1954, Adiitu Olodumare ni 1961, to si n kọ apa keji rẹ, to pe ni Ireọla Olodumare ati Igbo Adimula lọwọ nigba ti Ọlọjọ de.
Nígbà tí jamba bá ń bọ̀,kò ní dé ọ̀dọ̀ wa;nítorí a ti fi irọ́ ṣe ibi ìsádi wa,a sì ti fi èké ṣe ibi ààbò.
com/yoruba/afrika-45851939 Ogundiya: Àṣìṣe Dókítà ló sọ mi di aláàbọ̀ ara lórí kẹ̀kẹ́ Àkọlé àwòrán, Ogundiya: Àṣìṣe Dókítà ló sọ mi di aláàbọ̀ ara lórí kẹ̀kẹ́ Ọtọ ni aisan ti omidan Ṣeun Ogundiya ba lọ si ileewosan, ọtọ ni oogun ti wọn fun, aile gbe ẹsẹ lo ba kuro ni ileewosan.
Nígbà tí ó sọ pé, “Ó lọ sí òkè ọ̀run,” ìtumọ̀ èyí kò lè yéni tóbẹ́ẹ̀ bí kò bá jẹ́ pé ó ti kọ́kọ́ wá sí ìsàlẹ̀ ilẹ̀.
O sapejuwe Alaafin gẹgẹbi asiwaju ọbalaye ni ilẹ Yoruba ati lorilẹede Naijiria lapapọ, to si ni ọrọ ati iṣe rẹ ṣe pataki lasiko ti awujọ awọn lọbalọba n koju ipenija iṣọkan bayii.
Tottenham - Lucas Moura: Tottenham ti gba adehun kan wọle pẹlu ẹgbẹ agbabọọlu Paris St-Germain ni France fun ẹgbẹ agbabọọlu Brazil, Lucas Moura.
Yóo ṣe iṣẹ́ rẹ̀ létòlétò bí ó ti yẹ,nítorí pé Ọlọrun rẹ̀ ní ń kọ́ ọ.
Oloye Azikwe jẹ Ọlọrun nipe ni ọjọ kọkanla, oṣu karun un, ọdun 1996.
Síbẹ̀, bí ìwé ìròyìn ṣe jábọ̀, díẹ̀ lára àwọn ọmọ ìbílẹ̀ ń yọ̀ fún àdàwólulẹ̀ ilé náà.
Ọ̀tẹ̀ tí Kora, Datani ati Abiramu Dì.
"Bi a ṣe n ba Fatoyinbo wi, ẹ jẹ ko a yẹ ara wa naa wo, boya a ko ni ẹṣẹ kankan.
O ko ọpọlọpọ ero sẹyin lọ si agboole ololufẹ rẹ nigba ti o fẹ dabi pe Tariqul ko fẹ tete gbe igbesẹ to yẹ fun igbeyawo.
Ẹgbẹ NLC sọ fun BBC pe wọn so iyanṣẹlodi naa rọ, lẹyin ti ijọba gbe igbimọ ẹlẹni mẹta kalẹ lati jiroro lori owo oṣu tuntun fun awọn oṣiṣẹ.
E wo bi ẹjọ Maina se bẹrẹ 2010 - Wọn fi jẹ alaga ajọ aare to n risi ọrọ ajẹmọnu ati owo osisẹfẹyinti •2012 - Wọn fi ẹsun iwa ibajẹ kan an •2013 - Wọn le ni isẹ ijọba apapọ •2015 - EFCC sọ fun gbogbo eniyan pe awọn n wa Maina Ọwọ ṣìkún òfin ti tẹ Maina, alága àná fún ọrọ owó ìfèyìntì - DSS Khadijah, obìnrin àkọ́kọ́ tó dẹnu ìfẹ́ kọ àyànfẹ́ rẹ̀ O ṣójú mí kóró bí wọ́n ṣé fí àdó olóró pa Dele Giwa lọdún 1986- Soyinka À ń gbé ìjọba ìpínlẹ̀ Ọyọ lọ si ilé ẹjọ- Ẹgbẹ́ Fulani darandaran •2015 - O sa pamọ (awọn eniyan ni Dubai lo salọ) •2017 - Wọn fi je adele fun adari ile isẹ to n risi ọrọ abẹlẹ lorilẹede Naijiria •2017 - Ọjọ Kẹtalelogun, Osu Kẹwa ni aare yo o nise •2017 - Iwadii ti bẹrẹ ni pẹrẹwu lori rẹ - amọ awọn eniyan ni o lo sapamọ.
babi si ni ero pe lọ wo o.
“Ìwọ ilẹ̀, má ṣe bo ẹ̀jẹ̀ mi mọ́lẹ̀,má sì jẹ́ kí igbe mi já sí òfo.
Nitori naa nigbati iroyin jade pe ijọba apapọ ti gbe N15.
Ranti ọ̀rọ̀ tí o bá èmi iranṣẹ rẹ sọ,èyí tí ó fún mi ní ìrètí.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Cancer: Àṣe ara mi ni iso ti n run gbogbo bí mo ṣe n ṣèrànwọ́ lórí jẹjẹrẹ Alagbo nla ni Ogunde, o ni ọpọ iyawo, to si bi ọmọ pupọ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù AFCON 2019: Wo àbájáde èsì àsọtẹ́lẹ̀ rẹ 24 Òkùdu 2019 .
Fonran aworan kan ti fi awon eniyan Paupau New Guinea han nibi ti won ti n sa kaakiri fun igbala emi won ati awon miran ni kete ti ile riri naa wa sopin nibi ti won ti n sayewo si awon ohun to baje nitosi Tabubil.
Mo ti dé odò dúdú tí í ṣe odò aró, mo ti rékọjá odò pupa tí í ṣe odò ẹ̀jẹ̀, mo sì ti sọ fún àwọn ọ̀kẹ́ àìmoye òkú tí wọ́n ń retí ìdájọ́ Ọlọ́run Ọba.
Oludari ile akede Naijria (VON),Osita Okechukwu ti ro awon eya igbo Ohaneze Ndigbo lati maa gbaradi fun ipo aare lodun 2023.
 ( 1958 : 21-25 ) Ṣe àfojúsùn pé ìlú náà tí yẹ kó di ńlá láti ọ ̀ rùndún kọkànlá ( eleventh century ) .
Lara awon Ajo naa ni Ajo ile Europe (European Union)  ati orile-ede  Amerika.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Nollywood: Gbajugbaja òṣèré ''Toromagbe'' nínú fíìmù ''Arelu'' ti jáde láyé 30 Bélú 2020 Oríṣun àwòrán, Facebook Àkọlé àwòrán, Ẹni ọdun mẹtalelọgọta ni Oloye Abdul Tawab Olaitan Ile-Aje Adeniyi ko to jade laye.
A ń fikunlukun pẹ̀lú FBI láti mú àwọn Yahoo Boys"" tó kù- EFCC Amẹ́rika dá akẹ́kọ̀ọ́ padá nítori Facebook Kinni sisio ijokoo ilé rọ̀ tumọ si?"
Atẹjade kan ti wọn fisita nilu Abuja lo sísọ loju ọrọ yii pẹlu afikun pe, iṣẹ atunse afara mejeeji naa ti buse.
"Mo rántí pé lrù máa ń bà mi pé àwọn ọkùnrin máa ń rò pé mi ò nífẹ̀ẹ́ wọ́n tàbí ọkàn mi kò fà sí wọn.
Jesu tún jáde lọ sí ẹ̀bá òkun, gbogbo àwọn eniyan ń lọ sọ́dọ̀ rẹ̀, ó bá ń kọ́ wọn.
Baba kan wà tí ó gbin èso àjàrà sí oko rẹ̀.
Nazir Sarkin Waka: 'Mo ṣetán láti lo gbogbo ayé mi tókù lẹ́wọ̀n'
Agbada náà lè gbà tó ẹgbaa (2,000) galọọnu omi.
Ninu ere-ije ohun ti o waye lagbegbe Greenwich, Farah sepo kinni saaju awon akegbe re, Daniel Wanjiru, omo orile-ede Kenya ti o sepo kinni ninu idije ere-ije nilu London lodun ti o koja ati Scot Callum Hawkins ti oun si se ipo keta.
1 % je katholiki , selestial 5 % , methodisti 3.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Hubert Ogunde rèé, baba àwọn òsèré tíátà Iya Rainbow jẹ́ gbajúmọ̀, àmọ́ kí lo mọ̀ nípa rẹ̀?
Nítorí ìdí èyí ni a fi pè yín, nítorí Kristi jìyà nítorí yín, ó fi àpẹẹrẹ lélẹ̀ fun yín, pé kí ẹ tẹ̀lé àpẹẹrẹ òun.
O ni ẹ jẹ ki n fi ye bayii pe yatọ fun adari ati igbakeji adari, ko tun si ọmọ ile kankan to ni ibi igbalejo tiwọn ka ma wa sọ ọfiisi""."
Lọjọ aiku, ọjọ keji oṣu kẹjọ dun 2020 gẹgẹ bi ajọ NDDC ṣe fi sita, eeyan mẹrinlelọọdunrun pere ni arun naa kora rẹ ran mọ leyi to ṣi kere si iye ti wọn ti n fi sita fun igba pipẹ.
2) Idojuti fun golayati ni orilẹede ati lagbaye.
Nítorí ìwọ OLUWA a máa bukun àwọn olódodo;ò sì máa fi ojurere rẹ tí ó dàbí apata dáàbò bò wọ́n.
ni alaafia ,aseyọri, ati eyi ti ko si ni si iwa si iwa ibajẹ.
Aare Muhhamadu Buhari ati Aare Emmanuel Macron ti orile-ede Faranse ti o se abewo si Orile-ede Naijiria duro gege bi eleri lakoko ijiroro ibasepo laarin orile-ede mejeji  eyi ti o waye ni ile Aare ni ilu Abuja lojo isegun Tuesday.
Wo ọna ti o le gba dẹkun yiyọkun ati titobi sii pẹlu alaye onimọ nipa ounjẹ jijẹ yii.
Weah ge owo osu rẹ fun idagbasoke Liberia O see se ki ọti ati siga gbowoleri Amẹrika kede iranwọ tuntun fun Afirika Àjọ tó ń mójútó àyíká l'Eko mú 123 ọlọ́kadà tó ń bọ̀ láti Jigawa Adari banki GTB ṣalaye fun BBC pe banki CBN ti paṣẹ fun gbogbo banki pe wọn ko gbọdọ fun ẹnikẹni tabi ileeṣẹ kankan ni owo to dọti to jẹ owo atijọ mọ.
O ba mi lojiji ti mi o si mọ oun ti o yẹ ki n ṣe.
< Atiku Abubakar Ijọba n lo iye owo to to 1tn naira ($2.
Napoli vs Arsenal: Ìdùnú subú lu ayọ̀ lórí itẹsiwaju Arsenal nínú ìdíje Europa
 Àwọn àkóràn sábà maa ńlọ pátápátá láìsi àrùn ẹ ̀ dọ ̀ rárá .
Kini Awọn eeyan n sọ nipa idaduro Daura Loju opo Twitter iriwisi otọọtọ ni igbesẹ naa mu wa.
Mọ̀ síi nípa ǹkan tí o lè ṣe láti dènà ibà Lassa Ẹ má mu gaarí mọ́ nítorí ìbà Lassa- Dókítà Boniface Wo iye ibùdó ìtójú ibà Lassa tó wà ní Nàìjíríà Èèyàn mẹ́rin tún di olóògbé lẹ́yìn tí wọ́n lùgbàdì Ibà Lassa WHO yoo kapa aisan Lassa Fever Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Làáhànmí: Ìwádìí ní èèyàn 219 ni ibà Lassa pa lọ́dún tó lọ́, 29 lọ́dún yìí, tètè dènà rẹ̀ Arabinrin Ṣakirat Jaiyesinmi ni gbogbo awọn ohun tawọn n ta yii ni wọn fi ń ṣe asejẹ fun eeyan to n woju Ọlọrun fun ọmọ, alaboyun ati bẹẹ bẹẹ lọ.
3 Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold 4 Ẹ wo ọba kan nílẹ̀ Yorùbá, tí kò ṣe ètùtù tàbí náwó ànájù, kó tó jọba 5 Ọjọ́ orí wo ló yẹ kí ikùn ẹ̀dá bẹ̀rẹ̀ sí tóbi?
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Òṣiṣẹ́ Emzor tó ta Codeine fun BBC ti bọ́ sọ́wọ́ ọlọ́pàá 1 Èbibi 2018 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 18 Ọ̀wàrà 2018 Oríṣun àwòrán, Police Àkọlé àwòrán, Codeine:Ọwọ́ ba òsìṣẹ́ Emzor Ọwọ́ tí ba òsìṣẹ́ Emzor tẹ́lẹ̀ rí Chukwunonye Madubuike tó ta òògún ikọ́ olómí ọmọdẹ́, codeine fún ìkọ̀ BBC tó ṣe ìwádìí bònkẹ́lẹ́.
Àwọn òwe Solomoni nìwọ̀nyí:Ọlọ́gbọ́n ọmọ á máa mú kí inú baba rẹ̀ dùn,ṣugbọn òmùgọ̀ ọmọ a máa kó ìbànújẹ́ bá ìyá rẹ̀.
Ìrètí wà pé leyin ti ìwádìí bá kẹ́sẹ járí àìsàn ibà yoo di oun ìgbàgbé lágbaye.
Adajọ náà tún korò ojú sì bí awọn agbofinro ṣe gbé àwọn oluwode náà lọpọ yanturu, tá àbùkù wọn, fín afẹ́fẹ́ tajú-tajú sì wọn lójú àti fífi wọn sínú túbú.
Ọjọ kẹrindinlọgbọn, oṣu Kẹta, ni ijọba Naijiria ti gbe gbogbo ileewe ti pa, nitori itankalẹ aarun coronavirus.
Ọ̀rọ̀ lórí àwọn ìletò ati àwọn pápá oko wọn, àwọn ará Juda kan ń gbé Kiriati Ariba ati àwọn ìletò àyíká rẹ̀, àwọn mìíràn sì ń gbé Diboni ati àwọn ìletò àyíká rẹ̀, ati ní Jekabuseeli ati àwọn ìletò àyíká rẹ̀, 
Nítorí náà, àwọn òkúta wọnyi yóo jẹ́ ohun ìrántí ayérayé fún àwọn ọmọ Israẹli.
Tọ́ mi sí ọ̀nà nípa òfin rẹ,nítorí pé mo láyọ̀ ninu rẹ̀.
Ó fi ilé oúnjẹ hàn wá, o fi ìkòkò ọbẹ, o ka iye ekìrì ẹran tì o kù nínú gbogbo ìṣaasùn ọbẹ̀ fún ni.
43 million ti o ti N6.
OLUWA Ọlọrun Israẹli, olódodo ni ọ́, nítorí díẹ̀ ninu wa ṣẹ́kù tí a sá àsálà títí di òní yìí.
Nítori àwọn àtúgbẹ́yẹ̀wò, o níra láti ṣe àkójọpọ fún àwọn ọkọ́ naa Orisun: Johns Hopkins University atawọn ajọ eto ilera ilu Iye akọsilẹ to waye gbẹyin 15 Oṣù Ṣẹ́rẹ́ 2021 20:44 WAT+3 Ṣe ó tọ̀nà láti máa lọ fún àyẹ̀wò ìgbàdédéìgbà àwọn aláboyún?
Ṣugbọn amofin naa ṣalaye pe , gẹgẹ bi ofin ṣe gbe kalẹ, ẹni ti kii ba n ṣe ọmọ ologun ko ni aṣẹ lati wọ asọ ologun lorilẹ-ede Naijiria.
Iṣẹlẹ yii fọwọ bani lẹmi tori pe, oun kọ lo kọ orin to n ja rainrain yii'' Iṣẹju mẹsan gbako ni ẹkunrẹrẹ orin naa, to si ni awọn ọrọ eleyi to bẹnu atẹ lu Gomina Ganduje.
Alaga igbimọ agbeyẹwo eto atunto ilẹ Naijiria naa, El-Rufai, lasiko to n gbe aba naa kalẹ fun alaga igbimọ amusẹya fẹgbẹ oselu APC nilẹ yi, John Odigie-Oyegun, nibi ayẹyẹ kan nilu Abuja ni ero igbimọ naa ni pe kawọn ọrọ to nii se pẹlu oogun oloro ati ọpọlọ si duro labẹ ofin ti ko si fun gbogbo-gbo.
"Àwọn ǹkan ti ọ̀pọ̀ ko mọ nípa Baba Suwe Ẹ̀yin òṣèrè tíátà, ẹ ní ṣùúrù de àsìkò Ọlọ́run, ẹ máṣe kánjú kọjá kádàrá - Madam Ṣajẹ Sunday Igboho gba àwọn èèyàn Soka n‘Ibadan sílẹ̀ lọ́wọ́ àwọn ọmọ onílẹ̀ tó wá ṣọṣẹ́ Ìpínlẹ̀ Oyo, Ogun, Ondo buwọ́lu àbádòfin Àmọ̀tẹ́kùn ""Iṣẹ́ ìgbóhùnsáfẹ́fẹ́ lórí rédíò máa ń mú ẹ̀wà àti àpọ́nlé ba ni àmọ́ kò lówó lórí"" Àgbà olórin, Victor Olaiya jáde láyé."
“Sọ fún àwọn ọmọ Israẹli pé nígbà tí ẹnikẹ́ni, bá dẹ́ṣẹ̀, tí ó bá rú òfin Ọlọ́run, tí olúwarẹ̀ sì jẹ̀bi, kí báà ṣe ọkunrin tabi obinrin, 
Maigari,ti o jẹ alaga ẹgbẹ to n pese eto alaafia ni, ti won ba tete fi olori
Idi ree ti BBC Yoruba ṣe bọ sigboro, ta si ni ki awọn ọmọ Oodua fi ami si ori ọrọ Awọlumatẹ.
Koko iroyin: Awuyewuye Dapchi, alaboyun tan’gbaloju nibi irọbi
Nígbà tí wọ́n bá fọn fèrè ogun náà gidigidi, tí ẹ sì gbọ́ ìró rẹ̀, kí gbogbo àwọn eniyan hó yèè!
Lara awon ti yoo wa nibi ayeye naa ni alaga egbe APC
Aarẹ Buhari ni oun ti tubọ fẹ awọn ileeṣẹ ijọba loju sii ki idagbasoke lee tete sun araalu bọ.
Ó hàn sí mi pé kì í ṣe Ọlọrun ló rán an níṣẹ́ sí mi, ó kàn ríran èké sí mi ni, nítorí ti Tobaya ati Sanbalati tí wọ́n bẹ̀ ẹ́ lọ́wẹ̀.
Idibo yii ni oun ati Kola Balogun ti PDP ti dijọ dupo lori ṣiṣoju guusu ipinlẹ Oyo ni Abuja.
ohun tí ẹ óo ṣe sí wọn nìyí kí wọ́n má baà kú: nígbà tí wọ́n bá súnmọ́ àwọn ohun mímọ́ jùlọ, Aaroni ati àwọn ọmọ rẹ̀ yóo wọ inú ibi mímọ́ lọ, wọn yóo sì sọ ohun tí olukuluku wọn yóo ṣe fún wọn, ati ẹrù tí olukuluku wọn yóo gbé.
Èyí ni majẹmu tí n óo bá wọn dá, lẹ́yìn tí mo bá mú ẹ̀ṣẹ̀ wọn kúrò.
Bo tilẹ jẹ wipe Wabaa ko sọ iye ti ijọba gba lati san fun oṣiṣẹ, o sọ pe, ikede owo oṣu tuntun yoo waye lọjọ Iṣẹgun lẹyin ti igbimọ ẹlẹni mẹta naa ba gbe abọ iwadi rẹ fun Aarẹ Muhammadu Buhari.
Atamatase iko agbaboolu Real Madrid, Cristiano Ronaldo lana kopa ribiribi ti ko se yesile, leyin ti atamatase ohun ran iko re lowo lati fagbahan iko agbaboolu juventus mo ile won, ni papa isere Allianz ni Turin.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, ''Ọjà ẹran àgbò kò yá bí ti ọdún tó lọ'' Ayẹyẹ ọdun Ileya a maa waye lati fi kasẹ eto Hajj nilẹ lẹyin tawọn to lọ irinajo mimọ ba ti dari lati Oke Arafat ni Makkah.
Àwọn ibi ààbò rẹ̀ ti wó, àwọn odi rẹ̀ sì ti wó lulẹ̀.
Ọlọrun rán òkùnkùn, ilẹ̀ sì ṣú,ṣugbọn wọ́n ṣe oríkunkun sí ọ̀rọ̀ rẹ̀.
O ti jẹ ana si aarẹ orilẹede Naijiria nigba kan ri, ajagunfẹyinti Ibrahim Babangida.
Ajọ eleto ilera lagbaye, WHO ti sọrọ nipa igbagbọ awọn eeyan kan nipa lilo omi ati iyọ lati dena arun ọhun.
ohun ti o le tabuku ba ẹsin Islam.
omo orile ede Naijiria lati tun fun ijoba yii ni anfaani ti won fun won lọdun 2015
Jesu bá sọ fún un pé, “Mo wí fún ọ, lónìí yìí ni ìwọ yóo wà pẹlu mi ní ọ̀run rere.
Ọlọ́run ló yàn mí ti Arsenal, mi ò lè fi wọ́n sílẹ̀ láéláé- Mama Arsenal yarí Ara meriri , mo ri ori ologbo lori atẹ ni ọrọ mama agba kan, Nosimatu Hazzan, ti ọpọ eeyan mọ si mama Arsenal.
metalelogun lo wa nibi ayeye ijeri naa, ti won si n so nipa anfaani ti won ti
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, EndSars, EndSwat: Ọlọ́pàá ti fi ìbọn lù mí láyà rí torí mó ní 'extra tyre' méjì- afẹ́hònúh Wo bí àwọn jàndùkú ṣe yabò àwọn olùwọ́de #ENDSARS ní Alausa l'Eko àti Abuja Wahala ti waye laarin awọn oluwọde #ENDSARS nilu Abujaati awọn ọdọkunrin kan, ti ko faramọ iwọde to n lọ lọwọ.
O ni yiyọ ọwọ awọn ọmọ ẹgbẹ OPC, Agbẹkọya, ọdẹ ibilẹ ati fijilante kuro ninu awo ikọ Amọtẹkun ni ipinlẹ Ọyọ yoo lẹyin.
Ọkọ̀ ojú omi méjì kọlu ara wọn l‘Eko, èèyàn mẹ́ta fayé sílẹ̀ Ìjọba Ọyọ gbọdọ̀ tanná wádìí ìṣèjọba Abiola Ajimọ̀bi - PDP Ẹ máṣe gba àmúlùmálà ọmọ oyè lọ́wọ́ ìdílé ọba kankan nílẹ̀ Ijebu - Awujale Àwọn ọmọbíbí ìpínlẹ̀ Ọyọ nìkan ni yóò rí iṣẹ́ àgbàṣe gbà lábẹ́ ìjọba mi - Seyi Makinde Khafi wọ gàu lẹ́nu iṣẹ́ lórí ẹ̀sùn ìbálòpọ̀ ní BB Naija El-Zakzaky: Arúfin ni ijọba Muhammadu Buhari gan-an - Ladoja Ajọ DSS naa si tun ti gba asẹ ile ẹjọ lati fi Soworẹ si ahamọ fun ọjọ marundinlaadọta, ki wọn lee raye se iwadi to yẹ nipa idunkooko rẹ eyi ti wọn lo tumọ si pe, o fẹ doju ijọba Buhari bolẹ.
Leyin ti Ivory Coast dari pada nibi idije Ife ẹyẹ agbaye ta n wí yi lọdun 2006 ni Drogba kéde lasiko to n se àbẹwò sí àgbègbè ilu rẹ ni Bouake láwọn yóò tí gba Ifesewonse to n bọ lọnà pẹlu Madagascar.
Oludasilẹ Facebook, Mark Zuckerberg ṣe ipade pẹlu Ọgbẹni Carney loṣu to kọja lati jiroro lori awọn anfani to wa ninu eto naa ati awọn wahala to lee ti inu rẹ jẹyọ.
4bn ni wọn ya sọtọ fawọn inawo pẹpẹ pẹ fun ipalẹmọ feto idibo naa.
ogun oju omi naa ti bẹrẹ isẹ lori omi lati maa fi koju awon odaran ati awon ole
Èmi ni ẹni tí ó wà láàyè.
Ọsẹ to kọja si ni ileeṣẹ ọlọpaa kede pe oun ti mu awọn afurasi ọdaran kan to n pa awọn eniyan naa.
Babcock Sex video: Ohun tó yẹ kóo mọ̀ nípa Fásitì Babcock
Ileeṣẹ BBC lede larubawa, BBC Arabic ba Esra, ọkan lara awọn to tii ṣe ẹwọn ri nitori ọrọ oṣelu lorilẹede Egypt sọrọ; o si ṣalaye iriri rẹ nipa ayẹwo ibale afipa ṣe lasiko to fi wa lọgba ẹwọn.
Oluwa mi, n kò rí àwọn iranṣẹ rẹ nígbà tí wọ́n wá.
Oríṣun àwòrán, AFP Àkọlé àwòrán, ọpọlọpọ ero to wa ninu ọkọ ara wọn lo farapa ninu iṣẹlẹ ọhun wọn ni bi wọn ṣe daa duro lo ṣina bolẹ fun wọn ko to salọ to si n yinbọn si gbogbo ọkọ to n pade lọ.
Àwọn mìíràn a máa pè é ní ìkókó, túnfúlù tàbí aròbó.
Ẹ ma gbagbe pe a ko ni ma ṣalai koju ipenija ninu idokowo'' O mu apere ipenija ti ohun koju pẹlu ile iṣẹ simẹnti rẹ plu bi orileede Benin to wa ni tosi Naijiria ti ṣe yan rira simẹnti lati orileede China dipo tirẹ to wa ni arọwọtoo wọn.
Wo ohun tó yẹ kóo mọ̀ nípa Notre-Dame tó jóná Àwọn ará Ijegun fara ya lórí ọ̀pá epo tó ń gbaná ní gbogbo ìgbà Koda Gomina Sanwo-Olu to n tukọ ipinlẹ Eko naa kẹdun pẹlu Gomina Obiano akẹgbẹ rẹ atawọn eeyan ipinlẹ Anambra pe: Awọn ọmọ Naijiria ni paa lẹẹkini .
Nítorí òdodo ni pé Hẹrọdu ati Pọntiu Pilatu pẹlu àwọn tí kì í ṣe Juu ati àwọn eniyan Israẹli péjọpọ̀ ní ìlú yìí, wọ́n ṣe ohun tí ó lòdì sí ọmọ mímọ́ rẹ, Jesu tí o ti fi òróró yàn ní Mesaya, 
Oríṣun àwòrán, Oyo State Government Amọtẹkun, ninu ọrọ rẹ ni oun ati awọn fijilate Miyetti Allah, awọn ọlọdẹ pẹlu awọn awọn mii, ni wọn dijọ se ikọlu naa eyi to wa lati mu awọn agbegbọn to n dunkooko mọ alaafia ilu.
Ofin ifẹyinti fun awọn gominani ipinlẹ Kwara: Ni osu 2010 ni atunyẹwo de ba ofin yii lasiko isejọba Saraki Iye owo osu ti gomina to ba wa lori oye ba n gba ni wọn yoo maa san gẹgẹbii owo ifẹyinti fun awọn gomina tẹlẹ nibẹ Ọkọ ayọkẹlẹ tuntun marun, ninu eyi ti wọn yoo ti maa gbe tuntun meji rọpo fun-un lọdun mẹta-mẹta Ilẹ oni yara marun ti wọn ra ohun gbogbo to tọ si Owọ ọjẹmọnu fun rira ijoko ati ohun elo ile miran.
àwọn ará Hifi, àwọn ará Ariki, àwọn ará Sini, 
O ni ṣugbọn kii ṣe Ekiti nikan lo fẹ da iru aba bayii, Anambra naa fẹ da papakọ ofurufu silẹ bo ti lẹ jẹ pe papakọ ofurufu Enugu ko jina.
" Aṣofin naa ni pupọ ninu awọn to ti gba ami ẹyẹ naa ṣeyin, bii Aarẹ ana l'Amẹrika, Barack Obama, ko ṣe to ohun ti Trump ti ṣe.
O ni ṣaaju ajakalẹ arun COVID-19 ni iwe ififẹhan si ipo naa ti jade wa lati ọdọ Alhaji YK Abass ti wọn si ti fun wọn ni aaye oṣu mẹrin boya iwe yoo wa lati ọdọ ẹlomiran leyi ti ko wa.
Ẹ̀mí náà dáhùn pé, ‘N óo lọ sọ gbogbo àwọn wolii Ahabu di wolii èké.
Ayọ̀ ọrọ̀ rẹ̀ kò jù báyìí lọ,àwọn mìíràn óo dìde,wọn yóo sì gba ipò rẹ̀.
Àrùn pọ ́ njú-pọ ́ ntọ ̀ ń ṣòkunfà àkoràn 200,000 àti ikú 30,000 lọ ́ dọọdún , pẹ ̀ lú bíi ìdá 90 % ìṣẹlẹ ̀ ní Áfíríkà .
O pe aba yii ni ; ‘Bi
Awọn alagbara yii ni wọn ni wọn n fi ọla jiyọ ti wọn si ti sọ aarẹ Buhari di aarẹ gbẹwudani.
Ti ẹ ba ti po gbogbo ẹ papọ gẹgẹ bi o ṣe wa ninu fidio yi, iṣẹ ti bẹrẹ niyẹn.
Bákan náà ni adarí ètò ilèra gbogboogbo ati dídá àisàn dúro ní ilé iṣẹ́ ilera ìpínlẹ̀ Kano Dokìtà Imam Bello, sàlàyé pé àìsàn náà ti pa Dókìtà mẹrin àti ẹnikan ni ilé ìwòsàn ìkọni Aminu Kano.
Ẹgbẹẹgbẹrun ọ̀nà ẹgbẹẹgbẹrun ni àwọn tí ń ṣe iranṣẹ fún un,ọ̀kẹ́ àìmọye sì ni àwọn tí wọ́n dúró níwájú rẹ̀.
Omotara: Mo kábamọ ìwà tí mo hù sí ọmọ alágbe tó ń tọrọ lọwọ mi nínú ọkọ
Ojisẹ Ọlọrun naa wa n rọ awọn ọmọ ilẹ yii pe, ireti si wa fun wa ni orilẹede Naijiria, to si se agbekalẹ iru orilẹede ti Naijiria yoo jẹ lọjọ iwaju bii eyi: Naijiriaa yoo jẹ eyi ti ẹkun gbogbo to wa lorilẹede yii yoo ti wa ni isọkan Orilẹede yii yoo jẹ orilẹede ti yoo setọju awọn eeyan rẹ, ti awọn eeyan yoo si mọ ipa orilẹede wọn lara si rere Orilẹede ti yoo ni idagbasoke ọrọ aje to pedege, tawọn ohun alumọni bii eto ọgbin ati ipese ohun amayedẹrun yoo si fidi mulẹ Orilẹede ti yoo mu ilera to peye wa fawọn eeyan rẹ, ti idagbasoke yoo si wa fun awọn awọn eeyan, ti awọn ẹka eto ẹkọ yoo si maa se amulo awọn ohun alumọni ilẹ yii lati mu ki eto ẹkọ ati ọmọniyan dangajia Orilẹede ti a maa lo afẹfẹ gaasi ati oorun lati fi pese ohun eelo amusagbara, eyi ta tun maa fi ransẹ sawọn orilẹede alamuleti wa, ti ibi gbogbo yoo si mọlẹ laisi okunkun ni Naijiria Naijira yoo jẹ ibi ti aparo kan ko ti ni ga ju ọkan lọ, tawọn agbofinro wa yoo si mọ pe awọn kan wa ti yoo bi awọn, ti awọn ba siwahu, ti ẹmi eeyan yoo si se iyebiye Naijiria ta fi n la ala yoo bọwọ fun ofin, ti eto idajọ yoo si fiidi mulẹ, ti ọwọ nla yoo si wa fun iwe irinna wa loke okun Naijiria ti yoo ni ẹka ọmọ ologun ti yoo fidi mulẹ, ti yoo si pẹka de ibi gbogboo lati pese eto aabo to peye fun orilẹede wa ati awn aladugbo wa pẹlu Ti gomina yoo ti jẹ alakoso eto aabo ni ipinlẹ rẹ nitootọ, lai sọ lori ahọn lasan.
O ni ajọ naa ti n sa gbogbo ipa rẹ lati le jẹ ki ohun gbogbo lọ ni irọwọrọsẹ saaju, lasiko ati lẹhin ibo.
Ọjọ kẹsan an oṣu keji ọdun 2021 yii ni ijọba fawọn eeyan da lati so kaadi idanimọ NIN wọn pọ mọ nọmba ẹrọ ibanisọrọ wọn.
Orisiiriṣii idi ni awọn eniyan ti wọn ti mu oogun oloro ri ti wọn ti pada fii silẹ ṣalaye fun BBC.
Amọ nigba ti ijọba ko da awọn akẹkọọ naa lohun, ni wọn ba gun le iwọde alagbara eyi to waye nile ẹkọ fasiti kọọkan yika Naijiria.
Akinyemi sọ ọrọ yii nigba ti o n fesi si ọrọ ti Olootu Ilẹ Gẹẹsi, Theresa May sọ lasiko to n se abẹwo si South Africa gẹgẹ bi ara abẹwo rẹ si ilẹ Afrika, pe orilẹ-ede Naijiria lo gba awọn to tosi julọ ni agbaye.
Ninu idajọ rẹ, adajọ Abdul Aboki sọ pe Atiku lẹtọ lati ṣayẹwo ohun elo idibo ti ajọ INEC lo gẹgẹ bi ofin to de eto idibo lorilẹede Naijiria ti sọẹ agbekalẹ rẹ.
Ní bayiì orúkọ rẹ̀ ti wọ ìwé akọsílẹ̀ àwọn olùfipabanilòpọ ní ilé ìṣẹ́ ìdajọ́.
Okocha ni balogun ikọ Super Eagles ni asiko yii.
Mo sì ṣe ìlérí lónìí pé, bí àyípadà bá dé, tí ó di pé báálé kò rí owó jẹun mọ́, ìfẹ́ mi yóò dúró bí tí àtíjọ́ ni, bí àyípadà bá dé, ti ara baálé kò le, ìfẹ́ mi kò ní ṣákì, ń ó máa tọ́jú rẹ̀ náà ni, bí àyípadà ba dé, ti baálé mi túbọ̀ ń dágbà, tí ẹwà eẹ̀ ń dínkù, tí kò le ṣe fáàrí bi ti àtijọ́ mọ́, ìfẹ́ mi kò ní yípadà si i.
Wọ́n ṣẹgun Ogu, ọba Baṣani náà.
O ni oṣiṣẹ ileeṣẹ alaabo ọtẹlẹmuyẹ DSS ni atipe wọn ti faa le awọn ileeṣẹ to yẹ lọwọ fun iwadii ati igbesẹ ibaniwi to rọ mọ iṣẹ rẹ ati ẹṣẹ ti o ṣẹ.
Bótilẹ̀jẹ́pé ọ̀nà kannáà ni wọ́n ngbà lọ́dọọdún, àwọn olùdarí ètò ayẹyẹ a máa gbìmọ̀pọ̀ pẹ̀lú àwọn ọlọ́pàá láti ríi dájúdájú pé kò sí ewu kankan lọ́nà tí gbogbo ètò náà á tọ̀ kọjá.
Wọn da fifi panpẹ ọba mu Ayuk Tabe lori ẹsun pe o nkopa ninu awọn ipade abẹlẹ kọọkan lodi si orilẹede Cameroon.
Nígbà tí inú wọn dùn, wọ́n ní, “Ẹ pe Samsoni náà wá, kí ó wá dá wa lára yá.
OLUWA àwọn ọmọ ogun ní, “Gẹ́gẹ́ bí mo ti pinnu láti ṣe yín ní ibi nígbà tí àwọn baba yín mú mi bínú, tí n kò sì yí ìpinnu mi pada, 
Àwọn ìbéèrè tó yẹ kí o bi ara a rẹ̀ kí ó tó gba ìròyìn kankan nípa coronavirus gbọ́ Ọ̀rọ̀ Coronavirus kì ń ṣe ṣeréṣeré o-K1 de Ultimate, Toyin Abraham Ogun ebi ni Nàìjíríà ń bá fínra lọ́wọ́, ogun coronavirus kò gbọdọ̀ kún un-Oluwo Àwọn ìlànà tó tọ̀nà láti tọ̀ tí o bá funra pé o ní àrun Coronavirus Ninu ọrọ to ba awọn eeyan ipinlẹ naa sọ lori ẹrọ maohunmaworan lori iṣẹlẹ arun naa eyi to ti mu eeyan kan bayii ni ipinlẹ ọhun, gomina Kayọde Fayẹmi fi ọkan awọn eeyan ipinlẹ Ekiti balẹ pe wọn ti kapa arun naa nipinlẹ ọhun ṣugbọn sibẹ oju lalakan fii ṣọri.
Fulani kò leè dúró, táa bá lo ohun ta jogún lọ́dọ̀ àwọn bàbá wa - Sunday Igboho Wo orílẹ́èdè tí wọ́n tí ń dáwó ìsìnkú ara wọn pámọ́ Èmi àti Saheed kìí ṣe ọmọdé, a ti jọ ṣe Sinimá papọ̀, èyí túmọ̀ sí pé ìjà ti parí - Fathia Balogun Kìí ṣe gbájúẹ̀ nìkan lọmọ Nàìjá ń ṣe lókè òkun!
    Bí mo ti ń rìn lọ inú èmi náà ń dùn, yíyẹ́ tí wọ́n sì ń yẹ́ mi sí, àfi bí ẹní pé mo jù báyìí lọ.
Xenophobia: Dabiri ni Naijiria yóò ṣe ohun tó yẹ́ kí irú ìṣẹ̀lẹ̀ yìí má wáyé mọ́ Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Buhari paṣẹ itusilẹ fawọn eniyan Naijiria kuro ni South Africa lẹyẹ o sọka.
Idà ni yóo pa àwọn ẹṣin wọn,ati àwọn kẹ̀kẹ́ ogun wọn,idà ni yóo pa gbogbo àwọn àjèjì ọmọ ogun tí wọ́n wà láàrin wọn,Kí wọ́n lè di obinrin!
O fikun-un pe,“Otunba keju osuwon lati dari igbimo naa latari iriri re gbogbo-o, besini iwuwa si re yaayi, O tun je oniwa tutu bi adaba abbl.
Ninu ọrọ to ba BBC Yoruba sọ, Ayefẹlẹ ni oun gba awọn iwe to yẹ ki oun to kọ ile naa.
Lẹ́yìn tí ó jiyán tán ní ilé olóúnjẹ yìí, ó mu ìgò otí kan àti àbọ̀ nínú ọtí tí Akin Olúṣínà rà.
fun won ni alaafia ni kiakia.
Pẹlu ipenija obitibiti kaadi idibo ti awọn oludibo ko wa gba jakejado orilẹ-ede Naijiria bayii, ajọ INEC ni ipinlẹ Ọyọ ti da ọgbọn kan, eleyii ti wọn yoo maa fi pe gbogbo awọn oludibo ti kaadi idibo wọn wa nilẹ lati wa gba kaadi wọn.
Kí ó yipada sọ́dọ̀ Ọlọrun wa,nítorí Ọlọrun yóo dáríjì í lọpọlọpọ.
Ikilọ yi ti a pẹ sọ nitori bi o ti ṣẹ lagbara to ni Gomina ipinlẹ Kaduna lorileede Naijiria Ahmad El Rufai fi sita eyi to si ti n da awuyewuye silẹ Lori eto kan to waye nileeṣẹ amohunmaworan Naijiria ni Gomina El Rufai ti sọ ọrọ yi lalẹ ọjọ iṣẹgun.
Adesanya na ikeji rẹ pẹlu 3:33 ni iwaju awọn eniyan to to ẹgbẹrun lọna mẹtadinlọgọta ni papakọ ere idaraya naa.
Chad prisoners death: Ẹlẹ́wọ̀n 44 kú lagbà ẹ̀wọ̀n ní Chad látàárí ooru tó mú púpọ̀
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Àlàyé rèé lórí ìdí tí mo fi lọ sílé Tinubu - Rashidi Ladoja ‘Sim Card’ títà àti ìforúkọsílẹ̀ rẹ̀ dèèwọ̀ ní Nàíjíríà - NCC Ààrẹ Akufo-Addo la Mahama mọ́lẹ̀ wọlé ìbò ààrẹ Ghana fún sáà kejì Ẹ̀yin tí ẹ máa ń bú àwon tó sanra ni ẹ ń jẹ́ kí wọ́n ronú pa ara wọn - Eniola Badmus Ilé aṣòfin kò láṣẹ kankan láti pe ààrẹ Buhari wá rojọ́ lórí ọ̀rọ̀ ètò àbò - Malami Ṣé lóòtọ́ ni tírélà ti gba ààrín Ronke Odusanya àti bàbá ọmọ rẹ̀, Jago?
Gbogbo awọn ero to wa loju agbo lo binu, ti wọn si kuro nibẹ.
Ninu iwoye tirẹ, amofin kan to fi ilu Ibadan ṣe ibujoko, Saliu Adebayo, ni APC ti kọgbọn latara ohun to ṣẹlẹ ni saa to kọja.
Gbogbo àwọn eniyan tí wọ́n ṣẹ́kù lára àwọn ará Amori, ati àwọn ará Hiti, ati àwọn ará Perisi, ati àwọn ará Hifi ati àwọn ará Jebusi, àwọn tí kì í ṣe ara àwọn ọmọ Israẹli– 
Ọjọ kẹtala, oṣu Keje, ọdun 2007, si ni igbẹjọ bẹrẹ lori ẹsun naa nile ẹjọ giga ijọba apapọ to wa ni Guru.
Bí ó ti ń gúnlẹ̀, ó rí ọ̀pọ̀ eniyan.
Oríṣun àwòrán, Twitter Àkọlé àwòrán, Oju opo ikansiraẹni Twitter ni awọn eniyan ti n bere wi pe ibugbamu kan dun ni oru ni ipinlẹ Ondo.
E tẹle James loju opo Twitter.
Àwọn ọmọ Lefi ni: Geriṣoni, Kohati ati Merari.
Gbogbo ọmọ ẹgbẹ́ ilẹ̀ káàrọ́ọ̀-òò-jíire jakejado agbaye (Assembly of All Yoruba Groups, Worldwide) lo ṣaaju dibo yan Akintoye gẹgẹ bii asaaju ọmọ ilẹ Yoruba loṣu kẹjọ ọdun yi.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ọlọpaa Naijiria Márosẹ̀ Kaduna di ìbùba fáwọn ajínigbé A ń fikuluku pẹ̀lú FBI láti mú àwọn Yahoo Boys"" tó kù- EFCC 'Ọkọ̀ la rí, a ò tíì rí adárí Ilé iṣẹ́ pána-panà Eko àtàwọn mẹ́fà' - Ọlọ́pàá ""Bi mo tilẹ̀ jẹ́ apárí síbẹ̀ kò tìmí lójú"", Liliya Kukushkina Gẹgẹ bi alaye ti awọn ọlọpaa ṣe, iṣẹlẹ naa waye nigba ti awọn ajinigbe to wọ aṣọ ologun ji awọn ero inu ọkọ gbe lẹba abule Masari loju ọna Kaduna si Abuja ti wọn si ṣina fawọn ọkọ to wa ni ọna naa."
   O je okan lara awon gbaju-gbaja olorin nile Afirika.
Bachchan jẹ́ ọ̀kan gbòógì ti wọ́n kà kún òṣèré tó làmìlaaka jùlọ ni orílẹ̀-èdè India nígbà gbogbo.
Owó bọ̀ọ̀lì ni mo fi rán ọmọ mi mẹ́rin jáde ilé ìwé gíga -Grace Ìdí rèé ti Nàìjíríà fí ń gbé inú òkùnkùn Nítorí ìkọlù àjòjì ní South Africa, èèyàn 5000 ló padánù iṣẹ́ wọn ní Nàìjíríà Àwọn ọ̀dọ́ kan ń ṣèwọ́de láti pè fún lílé àwọn àjòjì kúrò ní South Africa Ajọ OYRTMA nipinlẹ Ọyọ ko ṣai wa tẹnumọ pe titi di bi a ṣe n sọrọ yii, ofin ijọba eleyii ti gomina ipinlẹ naa, Seyi Makinde pa ṣi wa sibẹ.
Ṣugbọn nisinsinyii, ó ti gbẹ, ó sì ti bu.
Ẹran tí ó dára jùlọ ninu agbo ni kí o mú,kó igi jọ sí abẹ́ ìkòkò náà,kí o bọ ẹran náà,bọ̀ ọ́ teegunteegun.
“Bí ẹ bá ń wí pé, ‘Kí ni a óo jẹ ní ọdún keje bí a kò bá gbọdọ̀ gbin ohun ọ̀gbìn, tí a kò sì gbọdọ̀ kórè?
Yobe Desert Stars, laago merin-in eeni, besini okan yooku yoo waye loola laarin iko agbaboolu Niger Tornadoes ?
O jẹ ẹni to lẹkọ ile pẹlu ọrọ pẹlẹ lẹnu ati ẹrin musẹ to maa n di ẹrin keekee.
Awọn tọkunrin tobinrin paapaa a maa ni amojukuro ti wọn ba ti mu ọti lile ni eyi to maa n din asiko ibalopọ ku tabi ki eeyan ma lè ṣe mọ to ba ya.
Wọn kò bìkítà fún ilẹ̀ dáradára náà,wọn kò sì ní igbagbọ ninu ọ̀rọ̀ OLUWA.
Nitori pe o jẹ gbajugbaja oṣere, ọpọ igba lawọn oloṣelu ti pe Toyin Abraham pe ko wa fi epo ati ata si ipejọpọ ipolongo idibo wọn.
Coronavirus cases in Africa- Iye awọ̀n tó ní Coronavirus ní Áfíríkà Ṣugbọn kọmiṣọnna naa ti fesi pe ijọiba yoo yanju aawọn to wa laarin rẹ ati ẹgbẹ oṣiṣẹ awọn adokita ọhun laipẹ.
wa maa gba ọna ẹburu , inu igbo kiji-kiji ,ko dara rara.
(Àwọn arakunrin rẹ̀ kò gbà á gbọ́ ni wọ́n ṣe sọ bẹ́ẹ̀.
Ninu ọrọ tiẹ, ajafẹtọ ọmọniyan, Deji Adeyanju ni, kii ṣe oni ni Omotola bẹrẹ si sọ otitọ.
yoo ri daju pe awon mu gbogbo ileri ti won se lasiko ipolongo ibo sẹ.
Dokita Abraham sọ pe lootọ ni ayipada oju ọjọ jẹ nkan to n banilẹru, ṣugbọn ọna abayọ wa ti awọn araalu ba le gbe igbesẹ lati mojuto o.
Wọ́n ṣe àkíyèsí pé ìbẹ̀ náà dára láti máa gbé ni wọ́n bá kúkú sọbẹ̀ dilé.
Ta ló ni ojú pípọ́n koko?
Ipade na ti o yẹ ki o waye lọjọ kini, osu keji si ọjọ karun osu keji ọdun yi, ni gbọngan ti o wa ni Ile-Ijọba, ni wọn gbekalẹ pẹlu iranwọ ile-isẹ aarẹ.
O ko gbọdọ ti ṣe nkan to lewu ni oṣu mejila sẹyin.
Àwọn ọlọ́lá ní ìlú rán àwọn iranṣẹ wọn lọ pọn omi,àwọn iranṣẹ dé odò, wọn kò rí omi.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Coronavirus in Africa: WHO ní ìwádìí ìmọ̀ ìjìnlẹ̀ yóò ṣèrànwọ́ láti pinwọ́ àrùn náà 24 Èbibi 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 22 Ògún 2020 Adari ajọ to n risi eto ilera lagbaye, WHO, Tedros Adhanom Ghebreyesus ti sọ pe, o ṣeeṣe ki opin de ba kuru-kẹrẹ arun Coronavirus laarin ọdun meji si asiko yii.
Ìrẹ̀wẹ̀sì bá ọkàn mi,nítorí náà mo ranti rẹláti òkè Herimoni,ati láti òkè Misari, wá sí agbègbè odò Jọdani,
Nigba toun naa bẹrẹ si i ba BBC Yoruba sọrọ, Olusola ọmọ baba Suwe ni, aṣeyọri ti baba oun ṣe ninu isẹ tiata lo ṣe iwuri fun oun, lati dara pọ mọ awọn oṣere tiata.
Ọmọ tuntun yii kọ ni akọkọ fun Dupe.
Super Eagles kò ní já àwọn ọmọ Nàìjíríà kulẹ̀- Musa Ẹgbẹ agbabọọlu Naijiria, Super Eagles sọ pe awọn ti ṣetan lati jẹwọ ara awọn fun ikọ agbabọọlu South Africa ninu ifẹsẹwọnsẹ ipele ẹlẹni mẹjọ lalẹ Ọjọru.
Ìdí tí Obìnrin fi lé saǹ ìdajì owó láti ra fọ́ọ̀mù ìfèróngbà hàn
Oríṣun àwòrán, Twitter/ajimobi Àkọlé àwòrán, Ajimobi pẹlu alaga ẹgbẹ oselu APC ti ile ẹjọ ṣẹṣẹ rọ loye, Adams Oshiomole ati igbakeji aarẹ Yẹmi Osinbajo Oríṣun àwòrán, Twitter/abiola ajimobi Àkọlé àwòrán, Ajimobi pẹlu Seyi Makinde to n tukọ ipinlẹ Oyo bayii labẹ akoso ẹgbẹ oṣelu PDP; ọrọ oṣelu ọtọ, ọrọ itẹsiwaju ipinlẹ Oyo ati idagbasoke awọn eeyan ibẹ ọtọ!
Lẹ́sẹ̀kẹsẹ̀ ló bẹ̀rẹ̀ ọṣẹ́, Ẹ̀mí kan ti nù Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Nigeria's Under-19:Ẹ wo bí Ikọ̀ Cricket Naijiria ṣe mi àgbáyé titi Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Keyamo: N kò nígbàgbọ́ nínú àwọn tó ń sisẹ́ pẹ̀lú Buhari
The first of 600 ⚽🔙 Leo's 1st official goal came 14 years ago today 🐐#Messi600 pic.
 Idagbasoke ilana ṣiṣe iṣẹ ijọba gbọdọ jẹ eyi ti wọn le gbe lewọn.
K1 De Ultimate ṣere ninu ijọ naa pẹlu awọn ọmọlẹyin rẹ.
" Ó jẹ ́ ọ ̀ kan lára ọmọ ẹgbẹ ́ "" antidorcas "" , jẹ ́ mánì onímọ ̀ ẹranko eberhard august wilhelm von zimmermann ló kọ ́ kọ ́ ṣe àpèjuwe ọmọ ẹbí bovidae yìí ní ọdún 1780 ."
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Lagos State: Oníṣòwò mẹ̀ta wọ gàù lórí títa pọ̀nmọ́ olóró 29 Ìgbé 2019 Oríṣun àwòrán, FACEBOOK/PONMO-IJEBU NEWYORK Gbogbo ẹyin ti ẹ fẹran lati maa yi pọnmọ lata, ikilọ re e lori awọn pọnmọ oro kan to wa nita.
Ṣé Ìkamọ̀dù l’ó jagun l’ọ́jọ́ kan, ọ́jọ́ kan,
Wọn ṣalaye pe ni kete ti awọn adigunjale ọhun ri ọkọ ọlọpaa, wọn ṣina ibọn bolẹ si awọn lọrọ ba di ogun.
Bakan naa, awọn ti ọrọ naa soju wọn sọ pe ijamba ọkọ ti o waye ni popona marose ọrẹ waye latari bi ọkọ ayọkẹlẹ meji se n sare asapajude lati le wọ iwaju ara wọn.
New York, ki o to maa sepade pelu igbakeji aare orile ede Amerika ni  Washington D.
Ó jẹ́ aṣiwaju ní ilẹ̀ Israẹli fún ọdún mẹjọ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Baba Khadijat Oluboyo jẹ́rìí ọmọ rẹ̀ Ijinigbe ni awọn opopona bi Ileṣa si Akurẹ, Ileṣa si Iwaraja, Orẹ si Ondo ti di ẹru bi awọn arinrinajo ṣe n mu iroyin ikọlu awọn darandaran wa.
Wahala ati ede aiyede bẹ silẹ laarin awọn olukọni ileewe fasiti OAU lasiko ti awuyewuye suyọ lori ẹni ti yoo se giwa ileẹkọ naa ni ọdun 2017.
Wike, má gbé jàgídíjàgan wá sí Ondo, APC kò ní ṣ'èèrú nínú ìdìbò gómìnà tó ń bọ̀- Kalejaye Oríṣun àwòrán, davidoofficial ''Láti òní lọ, FSARS ò gbọdọ̀ káàkiri ìlú mọ́ tàbí tú ẹrù aráàlú wò mọ́''- Ọ̀gá ọlọ́pàá pàṣẹ O to gẹẹ!
Bẹẹ ni ọrọ ri pẹlu oku ọmọ ikoko to sadede di awati nibudo igbokusi to wa nile iwosan awọn ọlọpaa nilu Akurẹ́.
Awon ìbejì to jẹ obinrin, ti wọn jẹ ọmọ oṣù mẹ́sàn àti ẹgbọn wọn, to jẹ ọmọ ọdún méjì, pàdánù ẹmí wọn ní ilé ìwòsan ologun to wa ni ìlú Accra, ni kété ti wọn gbé wọn dé ibè.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Òbí ọmọ Chibok kú nínú ìjàmbá ọkọ̀ 22 Ìgbé 2018 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Awọn ọmọdébìrin yìí ti wà ní àhámọ́ Boko Haram fún ọjọ́ pípẹ́.
O wá rọ gbogbo àwọn tó ti ní ǹkan ṣe pẹ̀lú òun lọ́jọ́ díẹ̀ sẹ́yìn láti lọ ya ara wọ́n sọ́tọ̀ tàbi ki wọ́n lọ fún àyẹwò láti mọ ipò ti wọ́n wà.
Nígbà tí ó pẹ́ ṣá, ó pinnu bí òun ti ṣe máa ṣe é tí òun lè fi fẹ́ ojú àwọn méjì yìí kù.
Abiola Ajimobi, Adebayo Faleti, Alao Akala, Rashidi Ladoja atawọn mii ni wọn ti yi orukọ awn adugbo ọhun padà sí.
Ǹjẹ́ o kò ní bínú sí wa tóbẹ́ẹ̀ tí o óo fi pa wá run, tí a kò fi ní ṣẹ́ku ẹyọ ẹnìkan mọ́ tabi kí ẹyọ ẹnìkan sá àsálà?
Bákan náà ni wọ́n kó àwọn ìkòkò, ọkọ́, ati àwọn ọ̀pá tí wọn fi ń pa iná ẹnu àtùpà; àwọn àwokòtò, àwọn àwo turari, ati gbogbo àwọn ohun-èlò tí wọ́n fi bàbà ṣe, tí wọn ń lò fún ìsìn ninu ilé OLUWA.
Ọmọ ogun Nàìjíríà mẹ́wàá dèrò ọ̀run lẹ́yìn ìkọlù ẹgbẹ́ Boko Haram A ó pe àjọ DSS lẹjọ́ tí wọ́n bá kọ̀ láti tú Sowore sílẹ̀ - Falana Ò bá mi lójijì bí wọ́n ṣe yọ Sẹnetọ Adeyeye bÍi jìgá- Gomina Fayemi Ìdí táwọn ènìyàn South Korea ṣe ń sin èèyàn láàyè!
Àwọn kan ninu àwọn ará Filistia mú ẹ̀bùn ati fadaka wá fún Jehoṣafati gẹ́gẹ́ bíi ìṣákọ́lẹ̀.
O salaye pe, bi oro kata-kara se ri, je ohun ikominu fun awon oludokowo lorile-ede Nigeria.
Oríṣun àwòrán, Adam Gault Ki wọn to gbe abẹreẹ ajẹsara Covid-19 jade, awọn onimọ ṣiṣẹ tọsan-toru lati ri daju pe ko ṣe ijamba si ara gbogbo awọn to ba gba.
Ti apapọ wọn si ti jẹ mejilelogun.
Awon omode-binrin omo ile-iwe Dapchi, ti awon omo-ogun olote Boko Haram tu sile ni ipinle Yobe, darapo mo molebi won lojo-Aiku.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Osun elections: Adeleke gba iléẹjọ́ tó ga jùlọ ní Nàìjíríà lọ pẹ̀lú agbẹjọ́rò àgbà mẹ́fà, òdú amòfin mẹ́tàdínlógún míràn 19 Èbibi 2019 Oríṣun àwòrán, Ademola adeleke Àkọlé àwòrán, Sẹ́nétọ̀ Ademọla Adeleke ń lépa àti yí ìdájọ́ iléẹjọ́ kòtẹ́milọ́rùn tó ní Gboyega Oyetọla ti ẹgbẹ́ òṣèlú APC ló borí ìbò gómìnà l'Ọṣun padà.
Sedekaya ọba ranṣẹ lọ mú un wá sí ààfin rẹ̀, ó sì fi ọ̀rọ̀ wá a lẹ́nu wò níkọ̀kọ̀, ó ní, “Ǹjẹ́ OLUWA ranṣẹ kankan?
Ó gbé tabili náà sí inú àgọ́, ní apá ìhà àríwá àgọ́ mímọ́, níwájú aṣọ ìbòjú, 
Fún bi ọdún mẹ̃dógún ninú ọdún merindinlogun ti Èrò Ẹgbẹ́ Òṣèlú (ti Alágboòrùn) fi ṣe Ìjọba ki ó tó bọ lọ́wọ́ wọn ni ọdún tó kọjá, owó epo rọ̀bì lọ si òkè rẹpẹtẹ, ọrọ̀ ajé yoku pa owó wọlé.
Nítorí náà ni inú ṣe bí OLUWA sí àwọn eniyan rẹ̀,ó sì na ọwọ́ rẹ̀, ó sì pa wọ́n,àwọn òkè sì mì tìtì.
Nibayii, aarẹ Muhammadu Buhari ti paṣẹ fawọn oṣiṣẹ alaabo gbogbo lorilẹede Naijiria lati bẹẹrẹ iṣẹ lori ṣiṣawari awọn to yinbọn pa ọmọ alagba Rueben Faṣọranti obinrin lopopona Ondo si Ọrẹ lọjọ Ẹti.
Vadym Prystaiko ni ọmọ ilẹ Canada mẹtalelọgọta wa ninu awọn to ku ninu ijamba ọkọ ofurufu naa.
Laoye ati awọn ọmọ oye to to mejilelọgbọn ni wọn jọ du oye ọba yii fun osu mọkanla gbako amọ ti ade naa ja mọ lọwọ, to si gori itẹ awọn baba nla rẹ lọjọ Kẹsan osu Kejila ọdun 1946 Amọ eekan kan gbogi ninu awọn ọmọ oye ti wọn jọ lọ apere naa ms ara wọn lọwọ, Memudu Lagunju gbe ọrọ naa lọ sile ẹjọ, to si gba idalare, eyi to mu ki wọn le Ọba Laoye kuro lori itẹ lọjọ kẹjọ osu kinni ọdun 1948, to si n gbe nilu Eko Amọ ileẹjọ ẹkun iwọ oorun Afirika to gbọ ẹjọ kotẹmilọrun nipa oye naa le Memudu Lagunju kuro nipo naa , to si kede pe ki Laoye pada sori itẹ gẹgẹ bii Timi tilu Ẹdẹ lọdun 1952.
Sara lóyún, ó sì bí ọmọkunrin kan fún Abrahamu lẹ́yìn tí ó ti di arúgbó, ní àkókò tí Ọlọrun sọ fún un.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, EndSars, EndSwat Protest: Òbí agbábọ̀ọ̀lù Gbenga Tiamiyu Kaka àtàwọn míì tí ọlapàá pa sọ̀r Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí WAEC 2020 result checker: Wo nkan tí yóò ṣẹlẹ̀ sí àwọn akẹ́kọ̀ọ́ tí àjọ WAEC gbẹ́sẹ̀ lé èsì ìdánwò wọn3 Bélú 2020 Fídíò, Soyinka Cancer: Àṣe ara mi ni iso ti n run gbogbo bí mo ṣe n ṣèrànwọ́ lórí jẹjẹrẹ27 Bélú 2019 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
"O ní "" olukọ ilé ẹkọ alákọbẹ̀rẹ̀ ni mi nígbà tí èmi àti Arinze bẹ̀rẹ̀ eré ìfẹ́ wa ni ọdun 2016."
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Aare Muhammedu Buhari ti setan lati yan ise fun awon minisita tuntun Ìjọba Buhari ń lo agbára láti jà ìjà ẹsìn- Jiti Ogunye Ilé iṣẹ ọlọpàá yóò gba ènìyàn 40,000 sí isẹ Ọkùnrin méjì, obìnrin mẹ́ta jáde láyé ní Mecca lásìkò Hajj 2019 - NAHCON Amọ sa, awọn osisẹ ajọ ẹṣọ oju popo, awọn ọlọpa atawọn ẹsọ to n ri si igbokegbodo ọkọ nipinlẹ Eko ni wọn duro si adugbo naa lati ri daju pe ijamba ko waye.
Ọlọrun rí ìyà mi ati iṣẹ́ ọwọ́ mi ni ó fi kìlọ̀ fún ọ ní alẹ́ àná.
Wọ́n bá gbéra kúrò ní Sinai, òkè OLUWA, wọ́n rìn fún ọjọ́ mẹta.
Uraya sì ṣe bí Ahasi ọba ti pa á láṣẹ fún un.
" Mo n yinmu si ni o nitori ti ko ba san owo ori naa, maa pada sile baba mi Alaafin nilu Oyo ni.
Ìwọ́de bẹ̀rẹ̀ ní Minnesota lórí àwọn ọlọ́pàá mẹrin to pa ọmọ adulawọ ni Amẹ́ríkà Ọdún 38 ni ìyá mí fi ṣiṣẹ́ ní UCH, màá kọ́ ibùdó ìtọ́jú àrùn jẹjẹrẹ ní ìrántí rẹ - Ọọ̀ni Gómìnà Ondo Akeredolu ṣí ilẹ̀kùn ṣọ́ọ̀ṣì àti mọ́ṣáláṣí sílẹ̀ fún ìjọ́sìn Ṣugbọn ko si imọ sayẹnsi ati ẹri to daju lati fi idi igbagbọ yii mulẹ.
Ile-igbimo asofin ipinle Benue ti bowolu yiya owo iranwo bilionu meta abo naira lati ile ifowopamo United Bank for Africa(UBA) fun ipese awon ohun amayederun nipinle naa.
Nígbà tí ó bá rí i, yóo pe àwọn ọ̀rẹ́ rẹ̀ ati àwọn aládùúgbò rẹ̀ jọ, yóo sọ fún wọn pé, ‘Ẹ bá mi yọ̀, nítorí mo ti rí owó tí mo sọnù.
Òkè Ìdànrè: Òkè tó kéré jùlọ jẹ́ ẹsẹ̀ bàtà ẹgbẹ̀rún mẹ́ta
Eyi tun tumo si pe gbogbo agbaye lo mo ipa rere ti a n ko nipa gbigbogun ti iwa ibajẹ lawujo wa.
ọmọ Amaraya, ọmọ Asaraya, ọmọ Meraiotu, 
Wọ́n bá ṣa òkúta, wọ́n fẹ́ sọ ọ́ lù ú, ṣugbọn ó fi ara pamọ́, ó bá kúrò ninu Tẹmpili.
Ṣugbọn àwọn ọmọ ilẹ̀ Juda kò júbà OLUWA, Manase sì mú kí wọ́n dẹ́ṣẹ̀ tí ó burú ju èyí tí àwọn eniyan ilẹ̀ náà tẹ́lẹ̀ dá lọ, àní, àwọn tí OLUWA lé jáde kúrò níwájú àwọn ọmọ Israẹli.
Mimu omi tabi ẹlẹrindodo naa maa n jẹ ki igbẹ rọ.
Bí o ti jábọ́ láti ojú ọ̀run, ìwọ tí o dàbí ìràwọ̀ òwúrọ̀!
He engendered policies that strengthened political and economic ties between these two countries and America.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ìgbátí ìgbámú àná látọwọ́ sọ́jà obìnrin ti bá arákùnrin náà dé iléèwòsàn Mi ò to iṣẹ́ Regina Daniels rárá kí n tó fẹ́ ẹ láàrin ọ̀sẹ̀ mẹ́ta, mo sì tún le fẹ́ ìyàwó míì - Ned Nwoko Àyà mi já nígbà tí Ganduje rọ Sanusi lóyè Emir Kano tó fi Bayero síi, ṣùgbọ́n.
Lootọ ni oogun lilo ati OCD ti mọ mi lara, sugbọn o koba igba èwe mi diẹ, nitori pe ọpọ igba ni mo maa n mu ọrọ imototo kọja bose yẹ.
Àṣẹ ọba ni wọ́n tẹ̀lé nípa ọ̀rọ̀ ọtí mímu.
Iroyin fi mule pe, lara awon ti o be isele ohun lo lati ri, akoroyin meje, ti won sise won lati mo bi isele naa se n lo.
International Women's day 2020: Àwọn obìnrin tọ́kasí pàtàkì ìbáraẹnidọ́gba láárin ọmọnìyàn
O tun ni ki wọn maa gbera irinajo lasiko ki wọn ma baa maa fi oru rin lopopona Bakan naa lo ni ki koowa maa ṣayẹwo ọkọ rẹ bi o ti yẹ ki o to gbera irinajo lasiko yii, ki wọn si maa tẹle ofin irnna loju popo lai sare ju bo ti yẹ lọ tabi lai ya ọkọ miran silẹ lọna aitọ.
Ó dàbí òróró olóòórùn dídùn, bí ẹbọ tí ó jẹ́ ìtẹ́wọ́gbà, tí inú Ọlọrun dùn sí.
Amọṣa ni bayii awọn ọyọkun agbofinro ti di tọrọ-fọnkale, eleyi to si da bi ẹnipe o n kọ awọn adari ẹka ileeṣẹ ọlọpaa lominu.
O tesiwaju pe eto ijoba rere gbodo je ohun akoko to je won logun.
Àwọn jàǹdùkú dojú ìjà kọ ọlọ́pàá, DPO faragbọta, ọlọ́pàá mẹ́rin di àwátì Abiru jáwé olúborí nínú àtúndi ìbò Sẹnatọ ìlàoorùn ìpínlẹ̀ Eko Ọdun 2012, 2016 àti 2020 ni John Mahama àti Nana Akufo-Addo ti jọ ń figagbága dupò aàrẹ Ghana Idi ti Odili fi gba ibi ìbálòpọ̀ lọ sí ọ̀run alákeji nílùú Port Harcourt Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Lagos Senatorial Elections: Abiru ṣ'àbẹ̀wò sí Tinubu lẹ́yìn tó wọlé àtúndi ìbò Sẹnẹtọ ìlà oòrùn ìpínlẹ̀ Eko7 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Kìí ṣéé àwàdà, Ẹ wó arákùnrin Kenya tó 'jíǹde' ní mọ́ṣúárì tó padà wá kú6 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Opeyemi Ayeola: Inú sinimá ni ọkọ mi ti rí mi, ọdún mẹ́ta ló fi wá nọ́mbà mi, kó tó fẹ́ mi6 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 US visa fee for Nigeria: Amẹrika ti yọ àfikún owó Físà kúro fún arìnrìnàjò Nàìjíríà6 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
OLUWA bá a sọ̀rọ̀, ó bi í pé, “Elija, kí ni ò ń ṣe níhìn-ín?
Bẹẹ ba gbagbe, Ibrahim Magu tii adele alaga fun ajọ EFCC fun ọdun marun, ni igbimọ kan ti aarẹ gbe kalẹ n tanna wadi rẹ lọwọ lori ẹsun iwa ajẹbanu ati aigbọran si awọn alasẹ.
Àbí, ta ni í tún máa ń retí ohun tí ó bá ti rí?
Nnkan ko kọkọ ṣẹnu 're fawọn ọjẹwẹwẹ Naijiria lẹyin ti Gyorgy Komaromi gba bọọlu sawọn fun ikọ agbabọọlu Hungary lẹyin iṣẹju mẹta ti ere bọọlu naa bẹrẹ.
Lara awọn iwe aṣẹ inawo to ni ki wọn gbe jade leleyi ti ileeṣẹ to n pese eelo itọju alaisan ni Kenya, Kenya Medical Supplies Agency fi ra nkan.
Adilemu naa sọ pe asiko ti to fun gbogbo agbabọọlu Barcelona lati ati awọn alaṣẹ lati wa nnkan ṣe si ina ẹgbẹ agbbọọlu naa to n jo ajo rẹyin bayii.
 Ṣaaju ni awọn ajinigbe naa sọ pe awọn yoo gba irinwo miliọnu Naira ki wọn o to le tu wọn silẹ."
Nítorí náà ẹ mọ̀ dájú pé ẹ óo kú ikú ogun, ati ti ìyàn pẹlu àjàkálẹ̀ àrùn, ní ibi tí ẹ fẹ́ lọ máa gbé.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Aranṣọ, olórin àti àwọn mì í ti ko fẹ́ kí ìdìbò kásẹ̀ nílẹ̀ ní Nàìjíríà Ìjìyà Amosun n dúró dè é di ẹ̀yìn ìdìbò - APC Inec: Kò sí ìká tí o kò lè fí dìbò, ṣáà tí tẹ̀ ẹ́ sójú ẹ dáadáa Ìjọba àpapọ̀ fẹ́ dènà lílo ayélujára àti ẹ̀rọ ìbáraẹnisọ̀rọ̀ lọ́jọ́ ìbò - Fayose Bí ọkọ mi bá fìdírẹmi, màá gbà f'Ọ́lọ́run - Titi Abubakar Ajọ UN ati INEC gbé ìlanilọ́yẹ̀ lọ Kwara Atẹjade naa wa leri leka pe, gbogbo awọn eeyan to ba lọwọ ninu isẹlẹ isekupani yii ni yoo finmu kata ofin.
Wọ́n yipada, wọ́n sì hu ìwà ọ̀dàlẹ̀bíi ti àwọn baba ńlá wọn;wọn kò ṣe é gbẹ́kẹ̀lé, wọ́n dàbí ọfà tí ó tẹ̀.
Ó tún tẹ́ pẹpẹ mìíràn níbẹ̀, ó sì sin OLUWA.
Lóòótọ́ ọ̀bọ jọ ènìyàn púpọ̀, ó da bi ẹni pé Ẹlẹ́dàá fi wọ́n ṣe ìbátan ara wọn ni.
Iroyin ni ile ifowopamọ kan ni awọn adigunjale ọhun ti n tọpasẹ ọkunrin naa bọ lẹyin to lọ gba owo tan.
Yetunde Ogunsola Arẹwa obìnrin, apọnbeporẹ, ni Yetunde Ogunsola nigba to wa lewe, ti Isola Ogunsola fẹ bii aya.
kí ọwọ́ agbára mi lè máa gbé e ró títí lae,kí ọwọ́ mi sì máa fún un ní okun.
O sin ijọba ilẹ America ni Senegal laarin ọdun 1980 si 1981.
Orile-ede America ti fi ofin de egbe Ansar-ul-Islam lil-Ichad wal Jihad (IRSAD) ti won fi orile-ede Burkina Faso se ibujokoo, ni eyi ti o pe egbe naa ni egbe adunkoko-moni, leyin awon ikolu ti o n waye ni apa ariwa orile-ede naa ti o wa ni eni ibode orile-ede Mali.
Alufaa náà dá wọn lóhùn pé, “Ẹ máa lọ ní alaafia, Ọlọrun fọwọ́ sí ìrìn àjò tí ẹ̀ ń lọ.
South Africa elections: Ǹjẹ́ àlàfo tó wà láàrin àwọn olówó àti tálákà n fẹ̀ si ni?
Irẹwẹsi ọkan ti n mu ki gbogbo ọjọ ri bakan naa loju wọn.
Ṣugbọn ẹ máa dàgbà ninu oore-ọ̀fẹ́ ati ìmọ̀ Oluwa ati olùgbàlà wa, Jesu Kristi.
O si bẹrẹ si ni i gun akasọ oye l'ọdun 1971.
Eko: Ofin ti ipinlẹ Eko ti wọn fi lọlẹ lọdun 2007 laa kalẹ pe, awọn Gomina tabi igbakeji wọn ti wọn ko ba yọ nipo laanfani lati gba deede owo oṣu wọn gẹgẹ bi owo ifẹhinti.
#EndSars Lagos Judicial Panel: Iléeṣẹ́ ológun ní òtítọ́ làwọn sọ́jà gbé ìbọn tó lọ́ta gidi nínú lọ sí Lekki Toll Gate
Nigba ti yoo si fi di aago meji aabọ oru, ajọ INEC ti kede esi ibo nijọba ibilẹ mejila ninu mejidinlogun to wa nipinlẹ Ondo.
Aarẹ Buhari ni bi o ti wu ki awọn ohun to fi jin fun ijijagbara orilẹede South Africa o pọ to, orilẹede Naijiria ko kabamọ lori ipa to ko.
"Ọ̀nà ọ̀tọ̀ ni àjọ EFCC àti NYSC gbé àyájọ́ olólùfẹ́ ọdún 2020 gba Ààrùn coronavirus ti ràn dé ilẹ̀ Afirika, Egypt ló kọ́kọ́ yà Ìjọba Ọ́ṣun, Oluwo kò yẹ lẹ́ni tó leè darí ìlú, ẹ bá wa le kúrò lórí ìtẹ́ - Olú ti Ilé-Ogbó ""Awọn alakoso ibudokọ tuntun yii ni yoo jẹ asoju ijọba, ti wọn yoo si maa gba owo lorukọ ijọba, bẹẹ ni wọn yoo maa san sapo ijọba lati ipasẹ awọn alamojuto, ti yoo san sapo ijọba."
”Ó sì wí fún àwọn òmùgọ̀ pé,
19 Bí ó tilẹ̀ rí bẹ́ẹ̀, ògo ni fún Bàbá, àti pé èmi kópa mo sì ṣe àṣeparí àwọn ìmúrasílẹ̀ mi fún àwọn ọmọ ènìyàn.
Awon agbejoro lorile-ede naa ti pinnu lati gbe Ogbeni Duduzane Jacob Zuma lo si ile –ejo .
Ni Belarus, aarẹ wọn kọ lati tẹle imọran awọn eleto ilera, to si sọ pe ki awọn eniyan o maa mu ọti vodka ati iwẹ sauna lati daabo bo ara wọn.
Ó yọ ojú Sedekaya, ó sì fi ẹ̀wọ̀n bàbà dè é láti mú un lọ sí Babiloni.
Òtítọ́ ni Aisaya ti sọtẹ́lẹ̀ nípa yín nígbà tí ó wí pé,
Ọwọ́jà coronavirus yóò ṣì wà pẹ̀lú àgbáyé fún ìgbà pípẹ́- Ngozi Okonjo-Iweala Laarin ọjọ kẹrin, oṣu Karun si ọjọ kẹjọ, oṣu Karun, awọn to ni aarun naa ti kuro ni 2558 to wa si 3526, nitori pe o ti n tan kalẹ laarin adugbo.
Nínú ètò àti ìlàna tí wọ́n fi yan báálẹ̀ tí ó wà lórí àlééfà ni wọ́n tí ṣé lófin pé ẹni tí kò bá ì tíì tó ọmọ àádọ́ta ọdún kò lè jẹ Báálẹ Abúlé Ọjà, èyí tí ó lè ṣe àkóba ńláǹlà fún ètò ìlú náà.
Ẹ Kú Ọwọ́ Lómi Là Nki Ọlọ́mọ Tuntun – Ìtọ́jú Ọmọ Tuntun ni Àtijọ́
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Arúfin ni Seyi Makinde pẹ̀lú bó ṣe gbà kí wọ́n sin Ajimobi sí GRA - Amòfin Mo ti lùgbàdì àrùn Coronavirus - Akeredolu figbe ta Ṣé ó leè jẹ́ ilẹ̀ tí Makinde kò jẹ́ kí Florence Ajimobi gbà ló ń bi nínú?
Nígbà tí Asa gbọ́ àsọtẹ́lẹ̀ tí Asaraya ọmọ Odedi sọ, ó mọ́kàn le.
Ìyansẹ́lódì MMA2: Alẹ́ Ọjọ́bọ ni ìyansẹ́lódì náà wá sópin
Ó di àrìnàkò, ó dojú àlá Ọ̀jọ̀gbónIGBÓ OLÓDÙMARÈ
Amọ ohun to ya ni lẹnu julọ ni pe Oladimeji, lasiko to n ba BBC Yoruba sọrọ ni oun ko de ile iyawe-kawe ri lati lọ kawe, ki oun to jẹ akẹkọọ to pegede julọ.
Mú òkúta onikisi meji, kí o sì kọ orúkọ àwọn ẹ̀yà Israẹli sí ara wọn.
Sùgbọ́n mo ti pinnu lati rọ okun sápá ìjọba awa-ara wa.
Ajọ to n mojuto ọrọ adojutofo ninu eto ilera awọn eniyan Naijiria ni àwọn ẹsun pupọ jade nibẹ nipa ṣiṣe owo ilu mọkumọku.
Agbẹnusọ rẹ, Gwendolyn Quinn, sọ pe Ọjọbọ lo ku ni ile rẹ ni Detroit, Michigan ni orilẹ-ede Amerika.
Oríṣun àwòrán, Facebook/KamalaHarris Oun ni eeyan alawọdudu akọkọ ti yoo di ipo yi mu.
Wọ́n bá pe Rebeka, wọ́n bi í pé, “Ṣé o óo máa bá ọkunrin yìí lọ?
Àwọn amí yòókù ní, “Rárá o!
Ó níláti jẹ́ pé ọkàn rẹ bàjẹ́ ni.
Wọ́n lọ pàgọ́ sí Kiriati Jearimu ní Juda.
Bi ọrọ ti ṣe ri yi agbẹjọro Solihu Adebayo ni ''Ko ruju ni nnkan ti ofin sọ.
Oríṣun àwòrán, @OfficialOAU Àkọlé àwòrán, Fásitì OAU ní ààbò àṣírí wà fún akẹ́kọ̀ọ́ yóówù tó bá ta àwọn aláṣẹ fásitì náà lólobó ìwà ìbàjẹ́ Bákannáà ló tún ṣàlàyé rẹ̀ pé wọn tí kọ ìwé 'wá wí tẹnu rẹ' sí ọ̀jọ̀gbọ́n Akíndélé lórí ìṣẹ̀lẹ̀ náà.
ti ijoba pese sile fun awon odo ni ona ti o boju mu,.
Koko to wa ninu rẹ ni pe orukọ Kofi Kingston ti wọ iwe itan gẹgẹ bi alawọdudu to gba ami ẹyẹ WWE.
Nítorí èyí, mò ń gbadura pé kí ọkàn yín má ṣe rẹ̀wẹ̀sì nítorí ìpọ́njú tí mò ń rí nítorí yín.
” Wọ́n dá a lóhùn pé, “A mọ̀ ọ́n.
Abrahamu dá a lóhùn pé, “Ọmọ mi, Ọlọrun fúnrarẹ̀ ni yóo pèsè, àgbò tí a óo fi rú ẹbọ sísun náà.
Yóo ti dára tó, bí wọ́n bá ní irú ẹ̀mí yìí nígbà gbogbo, kí wọ́n bẹ̀rù mi, kí wọ́n sì pa gbogbo òfin mi mọ́, kí ó lè dára fún wọn, ati fún àwọn ọmọ wọn títí lae.
Orúkọ ìyá rẹ̀ ni Atalaya, ọmọ ọmọ Omiri.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Omíyalé gbẹ̀mí èèyàn méje, o tún ba dúkìá púpọ̀ jẹ́ O ṣalaye pe awọn eeyan naa sa wọ inu ọkọ ologun lati sa asala fun ẹmi wọn ni, ṣugbọn eyi ko da iku wọn duro.
Ile-igbimo asoju-sofin tun ti sefilole abadofin lati fopin si tita tabi pipa ketekete lawujo.
Umaru Dikko wa lara awọn ti ijọba Buhari / Idiagbon ni o lu owo ilu ni ponpo.
Oyo NURTW: Okùn òfin Makinde ti dí ọ̀nà ìjẹ wa
Ọsẹ to n bọ ni awọn ọmọ ikọ SWAT yii yoo bẹrẹ idanilẹkọ, ni awọn ile ẹkọṣẹ ọlọpaa kaakri Naijiria.
Nibi apejẹ kan fawọn iyawo Gomina ti wọn ṣẹṣẹ yan, ati awọn ti ọkọ wọn pari saa wọn,ni aya aarẹ ti sọ ọrọ to nii ṣe pẹlu yiyi orukọ oye ara rẹ pada lati Wife of the President, iyawo aarẹ si First Lady, obinrin akọkọ.
Ko da, Ugolor ni awọn epo ti wọn n gbe wọ Naijiria buru lọna ọọdurun ju eyi ti wọn n lo ni Yuroopu lọ.
Tinubu lo sọ ọrọ naa loju opo Twitter rẹ, nibi to ti sọ pe iwa ti gomina ọhun wu jẹ idoju ija kọ ofin ati ijọba tiwantiwa.
"Dokita Michael Head, ni Fasiti ilu Southampton, sọ pe idagbasoke ati ipa aarun coronavirus tuntun yii ""yatọ patapata si aisan otutu to wọpọ."
Nítorí ẹni tí kò káwọ́ ilé ara rẹ̀, báwo ni ó ṣe lè mójútó ìjọ Ọlọrun?
Ní gbogbo ìgbà tí àwọn iranṣẹ wọnyi ń dúró pé kí ọba ṣílẹ̀kùn, Ehudu ti sá lọ, ó sì ti kọjá òkúta gbígbẹ́ tí ó wà lẹ́bàá Giligali, ó ti sá dé Seira.
Koda, gomina Abdullaji Ganduje ti ipinlẹ Kano ni gbogbo Fulani Darandaran nibikibi ti wọn ba wa ni Naijiria le maa bọ wa si ipinlẹ Kano tori aaye gba wọn daadaa nibẹ.
Ẹgbẹ Agbabọọlu Enyimba ti ilu Aba yoo maa koju ikọ agbabọọlu Energie FC ti ilu Cotonou ni ifẹsẹwọnsẹ akọkọ ipele naa.
Wahala to de ba agọ ara bayi ti kọja ohun tipa le ka ti a si ma se akoba fun gbogbo ara.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, akeugbagold video Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 3 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 5 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Sotitobire: Ìdájọ́ òdòdò ló fẹsẹ̀ múlẹ̀ lórí ọ̀rọ̀ Pásítọ̀ Sotitobire
Yara mi ti kun fun agbara ojo.
Ṣugbọn Mose dá OLUWA lóhùn pé, “Àwọn eniyan Israẹli gan-an kò gbọ́ tèmi, báwo ni Farao yóo ṣe gbọ́, èmi akólòlò lásánlàsàn.
Nileẹjọ giga apapọ to wa ni Abuja ni wọn kọ iwe ipẹjọ yi sí lootọ ti wọn si sọ sinu rẹ pe ki ileẹjo wọgile awọn igbimọ wọn yi nitori wọn ko lasẹ lati jiroro lori ọrọ aṣemase SARS.
Sani Abacha tún gbé owó míì dé láti Ireland Funke Akindele fún mi lówó tí mo fi gba ilé, kò ra ilé fún mi o - Ajirebi De Bruyne to jẹ ọmọbibi ilẹ Belgium ṣe okunfa bi Man City ṣe gba ogun goolu sawọn.
Lagos Building Collapse: Ilé alájà méjì wó lu ọmọ mẹ́rin ni Bariga
Oríṣun àwòrán, Getty Images Ilana tuntun ti wọn kede yi yoo kan ilu Milan ati awọn ibudo igbafẹ miran ni Venice ti yoo si kan wọn titi di ọjọ kẹta oṣu Kẹrin.
 Àwọ ́ n eléyìí tí ó ṣe pàtàkì jù ni ogun marengo àti hohenlinden ní 1800 ti austerlitz ní 1805 àti ti jena ní 1806 .
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Buhari, ó yá, tètè kọ̀wé fipò sílẹ̀ - Oyedepo Olùdíje ìbò abẹ́nú PDP, APC fárígá l‘Ọ́sun Ìwọ́de, ìkọ̀wéfipò sílẹ̀, ìdìbò abẹ́lé Osun kò fé bí'mọ re Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Wùnmí Toríọlá: Toyin Abraham kìí se ọ̀gá mi nínú tíátà O fi kun pe nigba ti ileesẹ ọlọpaa ransẹ pe Saraki fun igb akọkọ, lẹta kan lo kọ ransẹ, to si sọ ninu rẹ pe oun ko ni anfaani si akọsilẹ ọrọ awọn afurasi ti wọn darukọ oun gẹgẹ bii ẹni to n pese irinsẹ fun awọn.
Bí ó ti bojú wẹ̀yìn, tí ó rí mi, ó pè mí.
Àwọn àdúgbò Ibadan gborúkọ tuntun látẹnu Ajimobi Ayefẹlẹ bá BBC sọ̀rọ̀ lórí ilé orin rẹ̀ tí Ajimọbí ń tún kọ́ Wo àwọn èèyaǹ jàǹkàn mérin tí àrùn Coronavirus ti sọ dèrò ọ̀run ní Naijiria Arisekola ló fún mi ní ilẹ̀ tí ìjọba Ọyọ gbẹ́sẹ̀ lé, ń kò ní gbà - Ajimobi Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
“Manase ọba ti ṣe àwọn ohun ìríra wọnyi, wọ́n burú ju èyí tí àwọn ará Kenaani ṣe lọ.
Ayẹwò kò dáwọ́ dúro botílẹ̀ jẹ́ pé èròjà ayẹwò (Reagents) kò si mọ́ Ìjọba àpapọ̀, ẹ so ifilọlẹ ẹ̀rọ alatagba 5G rọ na - ilé asofin àgbà Mo ti tọrọ aṣọ àti yẹtí etí rí, kí n tó leè ṣe àwo orin - Tope Alabi Ẹ bá mi dúpẹ́ lọ́wọ́ Sunday Igboho, Ajimobi, Seyi Makinde àti àwọn ọlọ́pàá fún iranwọ wọn láti rí ìbejì gbà padà Dokita Osagie ni ọsẹ ti o n bọ yii naa ni ijọba yoo ran awọn si ipinlẹ Cross River ati Kogi lati ṣiṣẹ iwadii naa.
Òdodo ọ̀rọ̀ nìyí, pé,“Bí a bá bá a kú,a óo wà láàyè pẹlu rẹ̀.
Orile-ede méjì Cameroon àti Ivory Coast jó n du aye ẹni tí yóò tẹsiwaju ninu ìsòrí wọn láti kópa níbi ìdíje ife ẹyẹ bọọlu agbaye ni odun 3006.
Bee si ni Hazard fun raa rẹ ti sọ pe o wu oun lati darapọ mọ ikọ
Idanilekoo lori arun jejere, gbigbogun ti arun jejere ati itoju fawon to ti lugbadi arun jejere ni awon akosemose se lorisiirisii fi sami ayajo naa.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ondo election: Rotimi Akeredolu ti yan Lucky Orimisan Aiyedetiwa gẹ́gẹ́ bíi igbákejì tí wọ́n yóò jọ díje ní Ondo 29 Sẹ́rẹ́ 2018 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 28 Agẹmo 2020 Oríṣun àwòrán, others Ni yajoyajo ni iroyin yii jade pe Gomina ipinlẹ Ondo, Rotimi Akeredolu ti kede ẹni ti yoo ba dije gẹgẹ bii igbakeji rẹ ninu eto idibo ti yoo waye ni ọjọ kẹwaa, oṣu kẹwaa, ọdun 2020.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ó dára kí obìnrin níṣẹ́ lọ́wọ́ - Toyin Lawani Bawo ni Opeyemi Ayeola ṣe bẹrẹ ere?
Àwọn Amòye Wá Ọmọ náà Kàn.
” Fi igbagbọ rẹ hàn mí láìsí iṣẹ́, èmi óo fi igbagbọ mi hàn ọ́ nípa iṣẹ́ mi.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Nollywood: Bàbá Sàlá, Ọmọgé Campus, Ajimajasan àtàwọn òṣèré mí ì jáde láyé ní 2018 4 Sẹ́rẹ́ 2019 Bi o ṣe jẹ pe ilakak lati dun ara ilu ninu lawọn oṣere sinima n le, ọdun 2018 mu ọpọ awọn eekan kan lọ ni lagbo naa lọdun 2018.
" Àwọn ọ̀nà láti dẹ́kun ìwọ́de ọ̀dọ́ lọ́jọ́ iwájú nìyí Ó tó gẹ́ẹ́!
Nigba ti o n sọrọ, Akọwe Agba Ile Igbimọ Aṣofin Ipinlẹ Eko, Ogbẹni Azeez Sanni sọ pe pataki ni iru idanilẹkọ yii tun jẹ ninu aṣeyori Ile Igbimọ Aṣofin yii lat fi imọ kun imọ awọn oṣiṣẹ wọn.
Bakan naa ni ọgọọrọ eeyan tako aba naa lori ayelujara, niṣe lori ayelujara n gbona girigiri lati ọjọ Ẹti lori ọrọ naa.
 kò ṣe é ṣe kó máa sì wàhálà láwùjọ ènìyàn .
Kò sí ọkùnrin tí yóò fún obìnrin tó halẹ̀ bíi tèmi lówó - Lizzy Anjorin Kí ló wà ní ìdí igbá tí àwọn olorì Aláàfin máa ń tí lóde Ọ̀yọ̀ O wa n dupẹ lọwọ ọba Alaye naa lori bo ṣe jẹ eegun ẹyin fun oun, to si gbadura pe ade yoo pẹ lori rẹ.
Bẹ́ẹ̀ ni OLUWA ṣe ṣẹgun àwọn ará Etiopia fún Asa ati àwọn ọmọ Juda, àwọn ará Etiopia sì sá.
Gẹ́gẹ́ bàa tí ká a lójú òpó itakun agbaye, ọdún mọkandinlaadọrun ni olóògbé Akinjide lo lókè erupẹ, kò tó tẹrí gbasọ, bí ìtàn ayé rẹ sì ṣe lọ ree: Ìtàn ìgbé ayé Richard Osuolale Akinjide: Ìlú Ibadan, tíì ṣe olú ìlú Ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́ ni Osuolale forí sọ ilẹ̀ sì ni ọdún 1930, ní agboolé Aperin, ládùúgbò Orita Aperin n'ilu Ibadan.
Ki idamu to ba Gomina Obaseki to waye, awọn miran ti ni ipenija iru eyi tẹlẹ bi apẹrẹ Gomina Kano, Sẹnẹtọ Rabiu Kwankwaso ati ẹni to gba ipo lọwọ rẹ, Gomina Abdullahi Umar Ganduje.
30 Ọ̀wàrà 2020 Awọn iṣẹlẹ inu ọdun 2020 yi jẹ eyi to n mu haa hun un wa lọdọ awọn ọmọ Naijiria.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Badagry ní ogún àjogúnbá tó pọ̀ yàtọ̀ sí òwò ẹrú Kehinde Yekini ni orúkọ ọdẹ alẹ naa, to si jẹri pe Eji Gbadero wa si Ileesẹ rẹ ni alẹ ọjọ kejilelogun, oṣu kẹjọ, ọdun 1975 naa.
Dipo ijakulẹ, awọn aṣeyọri ti Oluwo ti ṣe tubọ n mu ki awọn ara ilu Iwo fẹran rẹ si ni."
Ọkan gboogi ninu awọn to dije dupo aarẹ naa, Svetlana Tikhanovskaya kọ lati gba esi idibo naa wọle, to si sọ wi pe oun lo bori idibo naa.
Taraba Killings: IGP ti jọ̀wọ́ Hamisu Wadume fún aádájọ́ àgbà Nàìjíríà
Gomina ipinlẹ Eko, Babajide Sanwo-Olu lo kede bẹẹ loju opo Twitter rẹ laarọ ọjọbọ.
Ki lawọn eeyan n sọ nipa iyansipo Mourinho Gẹgẹ bi ohun gbogbo to ni ṣe pẹlu Mourinho,iriwisi ọtọọtọ lo ti n waye lati igba ti wọn yan si ipo tuntun yi.
Ṣugbọn idamẹfa awọn to laarun naa ni iroyin n gbe jade, nigba ti ida mọkandinlogun ni awọn eeyan mọ lorilẹede Niger.
Ìbà ni n ó f’òní jú, mo r’íbà, k’íbà ṣẹ
Gomina SanwoOlu ni lati ṣe ayẹwo naa nitori iroyin fihan pe ọkan lara awọn amugbalẹgbẹ rẹ kan ti kọkọ ko arun naa laarin ọsẹ ọhun.
Ilẹ̀ di asán níwájú rẹ̀,ayé ati gbogbo ohun tí ó wà ninu rẹ̀ di òfo.
, ni eyi ti yoo pese ise lopo janturu fun awon eniyan.
Inú wọn dùn, wọ́n bá ṣe ètò láti fún un ní owó.
Kí wọ́n jẹ́ kí àwọn aráàlú mọ ohun tó yẹ́ fún wọn láti ṣe.
Ta ni Sadiya Umar Farouq tí ìròyìn ẹlẹ́jẹ̀ ń gbé pé òun ló fẹ́ dí ìyàwó tuntun Buhari?
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù NURTW Oyo: Ìfikùnlukùn yóò wàyé pẹ̀lú Gómìnà Makinde láìpẹ́ 4 Òkùdu 2019 Oríṣun àwòrán, @seyiamakinde Àkọlé àwòrán, NURTW rọ Gómìnà Makinde láti jèbùrẹ́ lórí ọ̀rọ̀ àwọn ọmọ ẹgbẹ́ awakọ̀ èrò ní ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́ Aarẹ ẹgbẹ awakọ ero lorilẹ-ede Naijiria, Alhaji Najeem Yasin ti ke si gomina ipinlẹ Ọyọ, Seyi Makinde lati fi oju miran wo igbesẹ to gbe lati gbẹsẹle ẹgbẹ naa nipinlẹ Ọyọ.
Aare Buhari fi da iyaafin Sharibu loju pe, ijoba apapo yoo sa gbogbo ipa re lati gba omo re kuro lowo awon eniyan ibi yii.
Bí ìtàn ọkùnrin náà ti lọ nì yí.
Opẹbẹ: Oríṣun àwòrán, Miliki express Àkọlé àwòrán, Yọmi King ti ọpọ Ọpẹbẹ Yọmi King ni orukọ abisọ rẹ ṣugbọn Ọpọbẹ ni orukọ ti ọpọ eeyan mọọ si gẹgẹ bii orukọ ti o maa n jẹ ninu awọn sinima.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Akomolede ati Asa: Mọ̀ si nípa àwọn ọ̀nà tí Yorùbá ń gbà ran ara wọn lọ́wọ́ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Akomolede ati Asa: Mọ̀ si nípa àwọn ọ̀nà tí Yorùbá ń gbà ran ara wọn lọ́wọ́ 20 Ọ̀wàrà 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 22 Ọ̀wàrà 2020 Lori eto Akomolede ati Asa lori BBC Yoruba fun tọsẹ yii, ohun ta gbeyẹwo ni asa iran ara ẹni lọwọ.
Wo àwọn gómìnà Nàìjíríà tó tí lùgbàdì Covid-19 àti ipò tí ìlera wọ́n wà Mo ti bẹ̀rẹ̀ sí ń bá àwọn tí a jọ díje nínú ìdìbó abẹ́lé sọ̀rọ̀ kí àláàfíà léè jọba - Akeredolu Bi ẹ ko ba ni gbagbe, laipẹ yii ni Ajayi kogba kuro lẹgbẹ oṣelu APC lọ si PDP laarin wahala ati ede aiyede laarin oun ati gomina ipinlẹ naa, Rotimi Akeredolu.
Amọṣa, igbimọ amuṣẹya lori gbigbogun ti arun coronavirus lorilẹ-ede Najiria, the presidential task force on covid-19 ni ko sohun to jọọ.
Kirusi Ọba Pàṣẹ pé kí Àwọn Juu Pada.
Eyi ko tọna rara, ma si fi ọlọpaa mu ẹnikẹni ti ọwọ ba tẹ pe o n se bẹẹ.
Ninu atẹjade ti agbẹnusọ Ado Isaikọ ọmọ ogun Naijiria gbe jade, ikọ naa wi pe ẹnikẹni ti ko ba ni Iwe idanimọ orilẹ-ede Naijiria ni agbegbe naa yoo wọ gau.
Witches Conference: Àjọ PFN kéde àdúrà ọjọ́ méjì láti tako àpérò àwọn àjẹ́
Àwọn ẹ̀ka rẹ tàn dé òkun, wọ́n tàn títí dé Jaseri,apanirun sì ti kọlu àwọn èso ẹ̀ẹ̀rùn rẹ, ati èso àjàrà rẹ.
Ohùn OLUWA lágbára,ohùn OLUWA kún fún ọlá ńlá.
Jesu wá sọ fún àwọn eniyan pé, “Ẹ ṣọ́ra, ẹ ta kété sí ojúkòkòrò ní oríṣìíríṣìí ọ̀nà, nítorí ọ̀pọ̀ dúkìá nìkan kọ́ níí sọni di eniyan.
Naira Marley: Ẹ wo bí ìgbẹ́jọ́ ṣe lọ lórí ẹ̀sùn tí wọ́n fi kan Marley
Lea ati àwọn ọmọ rẹ̀ náà súnmọ́ wọn, àwọn náà wólẹ̀ fún un, lẹ́yìn náà ni Josẹfu ati Rakẹli súnmọ́ ọn, àwọn náà wólẹ̀ fún un bákan náà.
Obalende Building Collapse: Gbogbo àwọn to há sọ́bẹ́ ilé tó wó la mọ̀
Ọlọrun tún sọ fún Mose pé, “Èmi ni OLUWA.
3 Àti pé bí ìwọ bá mọ̀ pé wọ́n jẹ́ òtítọ́, kíyèsíi, èmi fi òfin kan fún ọ, pé kí ìwọ gbẹ́kẹ̀ lé àwọn ohun tí a ti kọ.
1 12451 Orilẹede Djibouti 61 6.
O ni oun yoo ri daju lati so ise agbe di ohun ti awon eniyan yoo le mu yangan lawujo, bakan naa, won yoo pese awon irinse igbalode fun awon egbe, ti won yoo si maa ta ere oko won soke okun.
Bàbá ọlọ́mọ méjì kú sínú àgbàrà òjò Ọ̀pọ̀ èèyàn bẹnu ẹ̀tẹ́ lu Mercy Aigbe lórí bó ṣe ki Adeniyi Johnson Àjẹ́ àti Aṣẹ́wó ní ìyá Rainbow - Òjòpagogo Akẹ́kọ̀ọ́ mẹ́fa, olúkọ̀ méjì ni wọ́n jígbé ní Kaduna Ẹnikan ninu Seyi tabi Mike Edward, Mercy Eke, Chemeka 'Frodd' Okoye, ati Kola 'Omashola' Oburoh ni yoo jawe olubori lori eto ọhun lọjọ Aiku.
Ẹgbaa mẹẹdogun ó lé ẹẹdẹgbẹta (30,500) kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́.
Ninu kọnga kan ni wọn ti ri oku ọgagun agba naa ki wọn to gbe oku rẹ jade ti wọn si lọ sin in.
Ọ̀gá iléeṣẹ́ gbé £10 mílíọ̀nù ẹ̀bùn owó fún òṣìṣẹ́, èyí lohun tó pawọ́n pọ̀ Ọ̀rọ̀ Soyinka àti Obasanjo papọ̀ lórí pé Buhari n ṣe ìpínyà Nàìjíríà O ṣalaye pe awọn oniṣowo ni ẹka eto ẹkọ nikan ni o le lanfaani lati fi orukọ silẹ fun iranwọ owo naa bayii.
Gege bi atejade kan lati ile ise NNPC pe  awon eniyan die lo n je anfaani iranwo owo ori  epo robi ati ni awon orile ede to je amulegbe pelu orile ede Naijiria latari bi won se n se oja fayawo epo robi ni awon enu ibode orile ede yii.
Minisita feto ilera lorilẹede Ghana, Kwaku Agyemang Manu kede pe eeyan meji ti wọn de sorilẹede naa lati ilẹ Norway ati Turkey ni wọn ni kokoro arun naa lara .
Oriṣiriṣi ni wọn, awọn to dara wa lara wọn, awọn to jẹ idakeji naa si wa.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Oṣiṣẹbirin ọkọ ofurufu jabọ lati inu baalu 15 Ẹrẹ̀nà 2018 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ileese baalu naa to kalẹ si Dubai ti fidi ọrọ naa mulẹ Osisẹbirin ọkọ ofuru kan ti jabọ lati abajade pajawiri baalu Emirates kan ni Uganda.
Ṣaaju lo ti kọ sọ pe ọjọ keji ọsu kẹfa ni oun yoo ṣi awọn ile iwe nilẹ naa.
Nigeria 2019 Elections: Eko, Anambra àti Rivers ló ṣeéṣe kí àtúnbì ìbò ti wáyé
Ìwọ ati àwọn ọmọ rẹ ni mo fún gẹ́gẹ́ bi ìpín yín títí lae.
Dájúdájú bẹ́ẹ̀ ni ibùgbé ẹni ibi yóo rí,àní, ilé ẹni tí kò mọ Ọlọrun.
Kò kàwe ṣùgbọ́n o ní ọ̀yàyà ó sì máa ń ṣe àyẹ́sí ènìyàn.
Gomina Dapọ Abiodun so pe lọdun 1974 ni wọn bẹrẹ opopona marosẹ Eko si Ibadan naa nigba ti wọn si pari rẹ ni ọdun 1978.
Wọn ko fi bẹ ni idojukọ kankan ni awọn agbegbe to yi ilẹ Yoruba ka, nitori naa ni wọn ṣe gba agbegbe naa.
Okhiria sọ pe ibudokọ reluwee to wa ni Yaba ni irinna naa yoo ti gberasọ niluu Eko si Ibadan.
Abineri bá sọ ọ̀kọ̀ ní àsọsẹ́yìn, ọ̀kọ̀ sì lọ bá Asaheli ní ikùn, ọ̀kọ̀ náà sì yọ jáde lẹ́yìn rẹ̀.
Nítorí níwọ̀n ìgbà tí òun alára ti jìyà, ó lè ran àwọn tí wọ́n wà ninu ìdánwò lọ́wọ́.
Yobo gba iko ohun niyanju lati maa se jaya fun iko akegbe won kankan ti won yoo jo maa figagbaga, ti n se Croatia, Argentina ati Iceland.
Ayédèrú Lọ́yà tó ń díbọ̀n gbowó lọ́wọ́ aráàlú bọ́ sí gbaga ọlọ́pàá Wo àwọn gómìnà Nàìjíríà tó tí lùgbàdì Covid-19 àti ipò tí ìlera wọ́n wà Adesoji Aderemi, Ọọ̀ni Ifẹ̀ àti gómìnà Adúláwọ̀ àkọ́kọ́ láyé eèbó amúnisìn Tunji sọ pe igbakeji gomina naa de lẹyin ti adura ti bẹrẹ ati pe, awọn ẹbi oloogbe nikan ni adura ọhun wa fun.
Bí mo ti dúró lẹ́bàá kànga yìí, tí àwọn ọdọmọbinrin ìlú yìí sì ń jáde wá láti pọn omi, 
"Ọgbẹ ́ -inú buruli ( tí a tún mọ ̀ sí Ọgbẹ ́ -inú bairnsdale , Ọgbẹ ́ -inú searls , tàbí Ọgbẹ ́ -inú daintree ) jẹ ́ àrùn àkóràn èyítí ó má a nwáyé nípasẹ ̀ "" mycobacterium ulcerans "" ."
Ti o ba ṣiṣẹ abẹ ẹnu, o gbọdọ duro fun odindin ọjọ kan ki o to le fi ẹjẹ silẹ.
APC primary election in Edo state 2020: Wo bí nǹkan ṣe ń lọ sí níbi ìbò abẹ́nú fún olùdíje gómìnà lẹ́gbẹ́ òṣèlú APC ní Edo Oríṣun àwòrán, Twitter/@idowu553 Awọn aṣoju ti bẹrẹ idibo lati yan awọn Oludije ti yoo gbe aṣia ẹgbẹ oṣelu naa nibi idibo gomina ti yoo waye ni ipinlẹ Edo laipẹ.
Nígbà tí Isaaki di arúgbó, tí ojú rẹ̀ sì di bàìbàì tóbẹ́ẹ̀ tí kò le ríran mọ́, ó pe Esau àkọ́bí rẹ̀, ó ní, “Ọmọ mi.
’’Bakan naa, minisita tun ki ajo NFF, awon osise ti o fi mo awon akonimoogba gbpgbo fun akitiyan won, bee si ni, O ro won lati pa okan won po sojukan fun igbaradi idije naa.
Ẹni tí ó ni ọgbà yìí wá rò ninu ara rẹ̀ pé, ‘Kí ni n óo ṣe o?
Ambode - BBC News Yorùbá BBC News, YorùbáFò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ẹni tí kò jẹ gbì kò lè kú gbì, eré ọmọdé ni EFCC ń ṣe - Ambode 20 Ògún 2019 Oríṣun àwòrán, Ambode Àkọlé àwòrán, Gbogbo ètò ló tí n lọ láti ṣe ìwádìí ẹsún ti wọn fi kan Ambode, lẹ́yìn ti a tí gbsẹ̀ lé owó báǹkì láìpẹ́ yìí Lẹyin ti awọn oṣiṣẹ EFCC atawọn ọdọ ilu Ẹpẹ gbena woju ara wọn lasiko ti wọn fẹ ṣe ayẹwo ile gomina ana ni ipinlẹ Eko, Akinwunmi Ambode, gomina ana naa ti sọrọ sita.
Fayemi ni ''awọn ọdọ Naijiria n binu nitori ajakalẹ arun coronavirus ko jẹ ki wọn ri ileewe lọ, bakan naa ni iyanṣẹlodi ẹgbẹ olukọ fasiti ASUU n mu inu bi wọn.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Genotype: Kí làwọn àǹfàni àti ewu tí ẹ̀yà jínótáìpù rẹ le mú bá ìgbé ayé rẹ̀ Coronavirus ní Nigeria: Makinde kéde àyípadà lórí ọjọ́ táwọn akẹ́kọ̀ọ́ yóò wọlé padà l'Oyo Ijọba ipinlẹ Oyo ti kede ayipada lori ọjọ ti ile iwe yoo di ṣiṣi pada kaakiri ipinlẹ naa.
Kọmisọna f'ọrọ eto ẹkọ ni'pinlẹ Kogi, Rosemary Osikoya ti o fi ọrọ naa lede nigba ti wọn n se ipade awọn oniroyin n'ilu Lokoja lọjọ iṣẹgun, sọ wi pe ajọ WAEC fi lẹta naa ranṣẹ si ile-iṣẹ ijọba ipinlẹ naa.
Ìdí táwọn olùwọ́de EndSARS fi kọ oúnjẹ àti ọtí ẹlẹ́rìndòdò tí MC Oluomo gbé wá rèé Tola Oyediran ọmọ Obafemi Awolowo ti jáde láyé Wo nọ́mbà tí o le è pè láti gba owó gbà-má-bínú tí ọlọ́pàá bá fìyà jẹ ọ́ lọ́nà àìtọ́ l'Eko Ohun tí ojú ìyàwó mi rí lọ́wọ́ SARS kò ṣe é fẹnusọ- Poju Oyemade Awọn akẹkọọ to wa ni iyasọtọ naa ko ni lee lọ si ileewe, paapaa akẹkọọ to ba ṣe aisan ni ileewe ni a n gbe lọ si yara iyasọtọ, ki a le mọ daju wi pe kii ṣe arun Covid-19, ki wọn ma ba koran awọn araale.
Kò sì sọ́nà àti dá a padà mọ́ báyìí.
Nafutali bí ọmọ mẹrin: Jasieli, Guni, Jeseri, ati Ṣalumu.
Gẹgẹ bi ileeṣẹ iroyin Washington Post ṣe sọ, igbesẹ yii lo waye lẹyin ti ọmọ aarẹ ọhun pin fidio awọn dokita kan to n sọrọ ti wọn ni o le e ṣi awọn eeyan lọna nipa ajakalẹ arun Coronavirus.
àkókò bíbí wà, àkókò kíkú sì wà;àkókò gbígbìn wà, àkókò kíkórè ohun tí a gbìn sì wà.
Ẹ̀yin ọlọ́pàá, ẹ di ìhàmọ́ra kẹ́ẹ já àlàfíà ìlú gbà padà - Ọ̀gá àgbà ọlọ́pàá Wo àwọn ayédèrú ìròyìn tó gbà'gboro kan lásìkò ìwọ́de #EndSARS Àwọn ìbéèrè tí Tinubu bi gómìnà Sanwo-Olu àtàwọn olùwọ́de tó faragbọta ní Lekki Tollgate rèé Bí àwọn jàndúkù ṣe yabo ilé Sẹ́nétọ̀ Teslim Folarin, tí wọ́n kó ẹ̀rọ ata, ọ̀kadà, fírìíjì àti àwọn nkan tí owó rẹ̀ tó N200m Ni ọsan ọjọ Satide ni iroyin jade pe awọn janduku kan yabo ile sẹnetọ to n ṣoju ẹkun idibo aarin gbungbun Oyo.
“Ẹ óo ka ọ̀sẹ̀ meje, bẹ̀rẹ̀ láti ọjọ́ tí ẹ kọ́kọ́ ti dòjé bọ inú oko ọkà, tí ẹ sì bẹ̀rẹ̀ sí gé e.
tí Ọlọrun ti sọ fún un pé, “Láti inú Isaaki ni ìdílé rẹ yóo ti gbilẹ̀.
O ni eyi to ku awọn yoo maa se lori ayelujara titi wọ ọjọ ọdun.
“Ṣé o kò mọ̀ péó pẹ́ tí mo ti pinnu àwọn nǹkan tí ó ń ṣẹlẹ̀ wọnyi ni?
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Caracas, Venezuela 'Ifoya de fun gbogbo araalu' Oṣiṣẹ ọgba ẹwọn tẹlẹ ri ti ko fẹ fi oju ara rẹ han sọ fun BBC pe idi ti wọn fi n ṣe eyi ni lati dẹru ba awọn eniyan ni.
Laipẹ́, ọmọ tí kò bá pé ọdún méjìdínlógún kò ní leè jáde girama l’Ọṣun Wọ́n ti pa ẹni to yìnbọn pa ará Texas márùn ún -ọlọ́pàá Adeboye sọ̀rọ̀ lórí ètò pápá ìjẹko RUGA Leah Sharibu ṣì wà láàyè - Iléeṣẹ́ Aarẹ Buhari Dokita Smith ni asiko kan ti igbesẹ yii le yatọ ni ti iru ẹni bẹẹ ko ba ti ṣe iru rẹ ri tẹlẹ.
Ambode ní ó jẹ́ dandan láti yẹ́ Abiola sí nítorí pé ó fi ẹ̀mí rẹ̀ lélẹ̀ fun gbogbo ọmọ Naijiria.
Púpọ̀ nínú àwọn igi ni gbogbo ewé wọn ti rẹ̀ dà sílẹ̀ tán pátápátá.
Èèyàn mẹ́wàá míràn kó àrùn Coronavirus ní Nàìjíríà Aawakọ̀èrò, ọlọ́kadà farakásá àṣẹ ìjọba Ekiti láti dẹ́kun Coronavirus Àwọn ìbéèrè tó yẹ kí o bi ara a rẹ̀ kí ó tó gba ìròyìn kankan nípa coronavirus gbọ́ Kò tíì sí àrùn Coronavirus ní ìpínlẹ̀ Oyo, a ṣi ń retí èsì àyẹ̀wò - Ijọba Oyo Ṣé ẹ̀yin mọ idí ti Abass Akande fi n jẹ Obesere?
a máa n lo ẹ̀rọ ìkàwé se àkọle rẹ̀ si ipele mẹ́fà: Ìròyìn - Àkọsílẹ̀ ìròyìn tó dá lóri òòtọ́, yálà tí wan kan foju ri tàbi èyi ti akoroyin fìdí rẹ múlẹ̀, tàbi jábọ ti a tún wádìí rẹ̀ lọ́wọ́ àwọn onímọ nípa ǹkan náà Àtúpalẹ̀ - Àwọn ìròyìn ti a gbéjáde nípa ǹkan tí onímọ sọ, yálà ti akoroyin BBC tàbi ònímọ miran láti ìta tó ń ràn wá lọ́wọ́ láti fi òyé ọ̀rọ̀ to takókó lásiko kan Bíbèrè lọ́wọ́ àwọn tó n wò/gbọ́ wa: Èyí ni àwọn ìroyìn to fẹ́ fi olùgbọ́ kopa láti gbọ́ èrò tí wọ́n Alálàyé- Èyí ni ìròyìn tó fi òkodoro ọ̀rọ̀ múlẹ̀ lóri ìdí tàbi ààyé ti irú ǹkan bẹ́ẹ̀ fi wáye Èróngbà - Ilé ìròyìn BBC kìí ṣègbè, figbákan bọ̀kan nínú tàbi gbé èrò inú wa jáde, sùgbọ́n nígbà míràn a máá ń ṣe àgbéjáde èròngbà àwọn onímọ̀ láti ìta, a má n sàfihàn èrò pẹ̀lú ṣíṣe àkójọ àwọn onímọ pàápàá jùlọ èyí to ba jẹ́ òòtọ́ọ́ àti òkodoro.
Idi niyi ti mo fi n ro awon gomina lati maa seto idanilekoo fun awon eniyan won , pe kaadi idibo won ni ohun idanimo won gege bi omo orile ede yii.
Bi o ti le je pe, iko agbaboolu Real Madrid fagba han Ajax ninu ifesewonse ikolu kinni pelu ami ayo meji sookan(2-1), esi ohun ko to fun iko Real Madrid lati bosi ipele ti o kan ninu idije UCL ti ifigagbaga ese keji ko ba waye.
fọba le fun Everton pẹlu boolu agbesile gba(Penalty kick).
Banki apapọ fun wọn ni agbara lati ri iru owo bẹ ẹ bi eyi ti ẹni naa ko jọ latara jibiti, nitori o fẹ ṣi oju awọn eeyan kuro lara okowo Bitcoin.
Tí a fiṣọwọ́ ní 9:02 6 Ọ̀pẹ̀ 20209:02 6 Ọ̀pẹ̀ 2020 Gbọ́yì-sọ̀yí àti ìròyìn èké láti ọ̀dọ̀ àwọn olólùfẹ́ wa ló ṣáábà ma ń da ìgbéyàwó àwọn òṣèré rú- Ọpẹ Ayeola Opeyemi Ayeola kílọ pé ká má bu òṣèré tí ìgbéyàwó rẹ̀ dàrú mọ, nitori pe àwọn ará ìta lo n fà á.
 ṣe o mọ pe wọn kọlu awọn eeyan nibi iṣẹlẹ naa?
Gẹgẹ bo ṣe sọ ọ̀, Ajebori ni oun ko kọ orin lọdọ ẹnikẹni tabi ji ohun olohun lo rara.
Nígbà tí Hesekaya kú, wọ́n sin ín sí ara òkè, ninu ibojì àwọn ọmọ Dafidi.
“N kò ní bínú sí Israẹli mọ nítorí ohun tí Finehasi ọmọ Eleasari, ọmọ Aaroni, alufaa, ṣe.
Ohun ta ti jabọ ṣaaju lori ọrọ yii Nkan ko ṣebi ẹni rọgbọ falaga ẹgbẹ oṣelu All Progressives Congress APC, Adams Oshiomole pẹlu bi awọn ọmọ ẹgbẹ naa kan ni ipinlẹ Edo ṣe lawọn jawe lọ rọọkun nile fun un.
Ṣugbọn ilẹ̀ ran obinrin náà lọ́wọ́.
Ṣugbọn ẹ jẹ ki a sọrọ nipa gbangan Mapo to kalẹ si ilu Ibadan nibi ti ole ti n jare olohun.
Mo wo ìtàkùrọsọ àkọ́kọ́ tí Ilham Aliyev ṣe pẹ̀lú oníròyìn ilẹ̀ yìí kan.
Ìlú olódi kò ní sí mọ́ ní Efuraimu,kò sì ní sí ìjọba mọ́ ní Damasku,àwọn tí wọ́n bá ṣẹ́kù ní Siriayóo sì dàbí ògo àwọn ọmọ Israẹli,OLUWA àwọn ọmọ ogun ló sọ bẹ́ẹ̀.
Àwọn ọba Yorùbá kan rèé tí wọ́n rọ̀ lóyè, tí ọba míràn jẹ lójú ayé wọn Ajá kìí rorò kó ṣọ́ ojú'lé méjì, kò tọ́ ọ́ sí Alaafin láti dásí ọ̀rọ̀ ọba l‘Ekiti - Peter Fatomilọla Ilé ẹjọ́ ti sún ìgbẹ́jọ́ pásítọ̀ Sotitobire si Ọjọ́bo̩ Wọ́n gbé òkú ọgá iléẹ̀kọ́ àti òṣìṣẹ́ méjì míì tó kú nínú ìbúgbàmù lọ sílé ìgbókùsí ológun ojú omi l‘Eko Mo kó àrùn Coronavirus lẹ́yìn tí mo ṣalábapàdé ẹni tó ní àrùn náà lára - Idris Elba Oshiomole ṣì ni alága ẹgbẹ́ òṣèlú APC - ilé ẹjọ́ kòtẹ́milọ́rùn Bakan naa ni Ọọni ile ifẹ tun ṣepade pẹlu gomina ipinlẹ Ekiti, Kayọde Fayẹmi lọna ati wojuutu sii iṣẹlẹ ọhun.
Awon naa ni:Ipinle Abia,Anambra,Akwa-Ibom,CrossRiver,Edo,FCT,Kaduna,Katsina,Ekiti,Imo,Enugu,Katsia,Plateau ati ipinle Oyo.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Abiola Ajimobi: Makinde fẹ́ fọwọ́ rọ́ àṣeyọrí ọlọ́dún mẹ́jọ mi sẹ́yìn 27 Ẹrẹ̀nà 2019 Àkọlé àwòrán, Seyi Makinde ti ẹgbẹ́ òsèlú PDP ní àwọn ènìyàn dìbò yàn gẹ́gẹ́ bí gómìnà tuntun ní ìpínlẹ̀ Ọyọ.
Oríṣun àwòrán, @asoo Àkọlé àwòrán, Ṣẹkẹrẹ ati aago wa ninu ohun eelo orin ti Yoruba fi maa n fimoore han si Olorun, Oriṣa, olowo ori wọn ati ẹnikẹni tinu wọn ba dun si.
O ni ''Next Level'' Buhari ko le so eso rere fun Dangote fun idi eyi ki awọn eeyan yaa tete gba Buhari sita Ṣugbọn kii ṣe gbogbo eeyan naa lo sun ti wọn kọri si ibi kan naa.
 olórí lè kọ ́ kọ ́ kọrin kí alámọ ̀ tẹ ̀ lé e tàbí kí ó kọ ́ kọ ́ salámọ ̀ kí ó tó kọrin .
Ó ní wọn ò rí àrísá pé bí wọ́n bá gba onídùró rẹ̀, yíò sá lọ.
Bakan naa, kii ṣe ẹsun owo ti wọn lọ mọ ọ lẹsẹ nikan, wọn tun fi ẹsun kan Magu pe o mọọ mọ ma pese aridaju ti wọn nilo lati ṣe ẹjọ minisita fọr epo rọbi nigba kan ri, Diezani Madueke.
” Wọ́n bá bá a lọ, wọ́n rí ibi tí ó ń gbé.
Àwọn akóniṣiṣẹ́ Farao bẹ̀rẹ̀ sí na àwọn tí wọ́n fi ṣe olórí láàrin àwọn ọmọ Israẹli.
Èéfín rẹ̀ ń gòkè lae ati laelae.
Ajọ NCDC si ti gbe igbesẹ to yẹ lati ya gomina Bala muhammed sọtọ bayii ki o ma baa le tan aarun naa kalẹ.
Ondo 2020 Tribunal: Ìgbìmọ̀ olùgbẹ̀jọ́ ìbò gómìnà yóò gbérasọ lọ́jọ́ Iṣẹgun
O wa rọ ara ilu lati maa ba iṣẹ wọn lọ laisi idiwọ, ki wọn ṣi maṣe jẹ ki ẹnikẹni lo wọn lati da alaafia ipinlẹ naa ru, nipa biba ohun ini ijọba ati araalu jẹ.
Ìwà burúkú ni òun náà ń hù bíi ti Ahabu, nítorí pé ìyá rẹ̀ ní ń darí rẹ̀ sí ọ̀nà ibi.
Ó fi ojúlówó wúrà ṣe ọ̀pá fìtílà.
Àwọn ọmọ ogun Kalidea fọ́ àwọn òpó bàbà tí ó wà ninu ilé OLUWA ati agbada omi tí ó wà níbẹ̀ pẹlu ìtẹ́lẹ̀ rẹ̀.
Nitori naa ko si idi ti awọn eniyan yoo fi ma a wọde lẹyin ti wọn ti tuka.
Baba isalẹ Adedibu ati Ladoja Rashidi Ladoja jẹ gomina ipinlẹ Oyo ni ọdun 2003 si ọdun 2007, ti Adedibu si ṣe agbatẹru fun Ladoja gẹgẹ bi oludije lẹgbẹ oṣelu PDP ni ọdun 2003, ti o si ran an lọwọ lati bori.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Mínísítà 43 ni Ààrẹ Muhammadu Buhari ṣe ìbúra fún to yàn sípò 21 Ògún 2019 Oríṣun àwòrán, @others Àkọlé àwòrán, Buhari bẹrẹ ibura minista tuntun Bakan naa lo tun fun awọn minisita kọọkan ni iṣẹ ati ileeṣẹ ijọba ti wọn yoo mojuto ninu iṣejọba rẹ.
Lara awọn orilẹ-ede ti Duro Ladipọ atawọn ọmọ ẹgbẹ osere rẹ lọ ni Amẹrika, Holland, France, Italy, Yugoslavia¸ Iran, Belgium, Scotland, Swizerland ati bẹẹ bẹẹ lọ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Bisi Alimi: Ìyà mi rò pé n kò leè ṣe ni àmọ́ n kò ní ìfẹ́ abo ni mo ṣe fẹ́ akọ Ọpọ ami ẹyẹ ni Duro Ladipọ gba ninu ere tiata lorilẹ-ede Naijiria ati loke okun.
Diana já kúrò nínú ìdíje BBnaija Titi di asiko yii, awọn agbofinro ko tii sọ nkankan lori awọn #StopRobbingUs ṣugbọn awọn eniyan agbegbe naa ni ajọ to n mojuto ẹsun awọn ara ilu ti bẹrẹ iwadii to yẹ.
Èèwọ̀ méje tí kò fi ìdí múlẹ̀ nípa nǹkan oṣù obìnrin nílẹ̀ Yorùbá
Dabiri-Erewa se adari ajọ ti yoo maa ri si ọrọ to jẹ mọ ilẹ okeere  (Chairman/Chief Executive of
Ìjọba ìpínlẹ̀ Oyo tí bẹ àwọn oníṣẹ̀gùn lọ́wẹ̀ lórí ààrùn Coronavirus Ìjọba yóò ṣe ìwádìí ohun tí kò jẹ́ kí ìpínlẹ̀ Kogi àti Cross River tíì ní coronavirus- Mínísítà Ọgọ́jọ(160) ọmọ Nàìjíríà tí coronavirus ṣé mọ́ Amẹrika ti gúnlẹ̀ s'Abuja O di eeyan mẹjọ ti coronavirus ti pa niluu Abuja bayii.
Àwọn ọmọ ogun náà bá jáde lọ sinu pápá láti bá àwọn ọmọ ogun Israẹli jà, ní aṣálẹ̀ Efuraimu.
Ipele kò-mẹsẹ̀-o-yọ, idije to ṣikeji si aṣekagba lo déé duro bayii ni Russia ti ẹnikẹni to ba ti fidi rẹmi n pada sile.
Jesu bá yipada sí obinrin náà, ó sọ fún Simoni pé, “Ṣé o rí obinrin yìí?
Ko dabi owó beba, tabi owó ẹyọ ti a le ko si àpò tabi apamọwọ, orí ayelujara lo n gbe.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Bí rere ni àbí búburú, wo ohun tí Covid-19 leè ṣe sí àgọ́ ara rẹ Ní Zamfara, Òjò àrọ̀ọ̀dá ló fa ìjàmbá ọkọ̀ kan, tí ọ̀pọ̀ míì si fara gbọgbẹ́ Oríṣun àwòrán, Others Olólùfẹ PDP 18 kú nínú ìjàmbá ọkọ̀ lásìkò tí wọn ń lọ pàdé gómìnà Arinfẹsẹsi ko kan maili, ọba oke ni ko maa sọ wa.
Koko pataki to jẹ yọ re lati inu ọrọ akọkọ ti ọjọgbọn Banji Akintoye fi sita lasiko to n ba awọn akọroyin sọrọ nilu Eko.
A sọ wọ́n di alágbára nígbà tí wọn kò ní ìlera.
Ọjọ Isẹgun ni Daura kede pe, ẹni to ba kunju iwọn lo yẹ ko jẹ aarẹ Naijiria, kii ṣe nipa pinpin ipo aarẹ ni ẹlẹkunjẹkun.
O ni awọn yoo ṣi ta awọn ọlọpaa lolobo nipa awọn ọdaran to ṣe ikọlu eyi to ṣẹṣẹ kọja.
Ipa tí Fathia Balogun kó nínú bí mo ṣe dèèyàn lágbo òṣèré fíìmù Yorùba rèé - Baba Ijesha A ó fún ẹbí akẹ́kọ̀ọ́ Fásitì Ibadan tó dolóògbé ní owóo gbà mábìnú - Ìjọba Oyo Aya gómìnà Kwara fẹ́ ran tìyá- tọmọ olójú búlúù lọ́wọ́ A ti gùnlé ìyanṣẹ́lódì ọlọ́jọ́ gbọọrọ ní ìpílẹ̀ Eko- NUPENG Oríṣun àwòrán, Alabi Rukayat Oyindamola Bayii, awọn ẹgbẹ alaanu meji miran tun ti ṣetan lati dide iranlọwọ fun iya awọn ọmọ oloju buluu yii.
Pẹlu #FreeSowore ni awọn eniyan fi n kesi ijọba lati tarasasa fi arakunrin naa silẹ nitori ẹtọ awọn ọmọ Naijiria ni lati fẹhọnu han, ti ijọba ba n se ohun ti ko tẹ wọn lọrun.
' Alukoro igbimọ iṣedajọ agba orilẹede Naijiria, Sọji Oye ni igbims naa tẹwọ gba iwe ifisun tuntun latọdọ ajọ EFCC lo faa ti wọn fi tun kọwe pada si adajọ agba naa lati fi esi sii laarin ọjọ meje.
wa ni ipẹkun ijoba orile ede Saudi Arabia.
O fi kun un pe oun yoo sa ipa oun gẹgẹ bii aṣiwaju lati mu idagbasoke ba awọn ọdọ to ba fẹ yan orin Fuji laayo Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
    Kò sí ògbojà tí ó dàbí ọdẹ.
Ẹwẹ, ofin yii ti bori gbogbo ẹtọ ti ẹnikẹni ni tẹlẹ lati lo omi.
Majek Fashek: Mọlẹbí nìkan ló péjú síbi ìsìnkú gbajúgbajà olórin reggae náà ní Amẹ́ríkà
O ni bo tilẹ jẹ wi pe awọn ileeṣẹ agbofinro sa ipa wọn, sibẹ, omi pọ ju ọka lọ nitori ọkan lara awọn adari ẹya Yoruba, Reuben Faṣọranti naa padanu ọmọ rẹ sinu laasigbo to n ba ilẹ Yoruba finra ọhun.
Mo sọ ti aarun ti mo ni fun un bakan naa.
Bí ẹsẹ̀ rẹ bá mú ọ kọsẹ̀, gé e sọnù, ó sàn fún ọ kí o jẹ́ ẹlẹ́sẹ̀ kan kí o sì wọ inú ìyè jù pé kí o ní ẹsẹ̀ mejeeji kí á sì sọ ọ́ sinu iná, [ 
Àkọlé àwòrán, Ọdun ibeji agbaye sọkutu wọwọ ni ilu Igbo Ọra Àkọlé àwòrán, Ati agba ibeji, ati ọmọde ibeji ko gbẹ́yin nibi ọdun ibeji ni Igbo Ọra Àkọlé àwòrán, ijo ree lẹsẹ awọn ibeji, ti kọmisọna feto iroyin nipinlẹ Ọyọ, Toye Arulogun si n kọwọ rin pẹlu wọn Àkọlé àwòrán, Ankoo wa laa wọ lawọn ibeji yii se nibi ajọdun wọn ni Igbo Ọra Àkọlé àwòrán, Kọmisọna ree to n bawọn ibeji ya fọto nibi ajọdun ibeji Igbo Ọra Àkọlé àwòrán, Ajọdun ibeji agbaye yii ko yọ ẹlẹsin abi ọdọ silẹ, tọkunrin, tobinrin lo wa nibẹ Àkọlé àwòrán, Eyi wu wa o, awọn ọmọge ibeji ree o, ti wọn fi ilẹkẹ sọrun Àkọlé àwòrán, Ọmọde n bọ wa dagba, bi ẹyin ti n di akukọ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Collapsed Building: Ẹ̀mí kankan kò bọ́ nínú ilé míràn tó wó ládugbó Kakawa l'Eko 25 Ẹrẹ̀nà 2019 Àkọlé àwòrán, Iroyin to tẹwa lọwọ sọ pe ijọbati ti wọgile ile naa fun wiwo Iṣẹlẹ ile wiwo nilu Eko ti wa fẹ di ohun to peleke lẹnu ọjọ mẹta yi pẹlu bi ile miran ṣe tun dawo nisale Eko.
"Sanusi ni, ọkan lara isoro Naijiria ni ọrọ"" Federal Character "" lai fi ti ijafafa ati mimọ iṣẹ doju ami ṣe, ko ni itumọ kankan"" Lasiko to n fi iyatọ han laarin iṣẹ aladani ati iṣẹ ijọba, Sanusi sọ pe, o ṣe pataki lati ṣe agbekalẹ ilana ti yoo yọwọ oṣelu kuro patapata ninu iṣẹ ijọba."
20 Ṣùgbọ́n kí olúkúlùkù ènìyàn lè sọ̀rọ̀ ní orúkọ Ọlọ́run, tí í ṣe Olúwa, àní Olùgbàlà aráyé;
A lè lọ àgbàdo funfun àti pupa pọ̀, ẹlòmiràn lè lọ ẹ̀wà Sóyà pẹ̀lú gẹ́gẹ́ bi àpẹrẹ àwòrán ojú iwé yi
Ireti wà pe igbakeji aarẹ yoo sọrọ lori ọna imubọsipo pada ati awọn anfani itẹsiwaju ti Naijiria ni nile ati loke okun.
Ìbáwí pupọ ń bẹ fún ẹni tí ó yapa kúrò ní ọ̀nà rere,ẹni tí ó bá kórìíra ìbáwí yóo kú.
A ti gbọ́ nípa ìgbéraga Moabu,ó ní ìgbéraga lọpọlọpọ,a ti gbọ́ nípa èrò gíga rẹ̀, ati ìgbéraga rẹ̀,nípa àfojúdi rẹ̀, ati nípa ìwà ìjọra-ẹni-lójú rẹ̀.
Eyi lo mu ki ajọ to n mojuto isẹlẹ pajawiri ni Naijiria, NEMA tete ma fi ikilọ sita fawọn Gomina Naijiria, lori ewu omiyale ti o n bọ lọna.
Oríṣun àwòrán, Reuters Bakan naa ni awọn baba olowo miran maa n pe apejẹ lati fi ko owo jọ fun oludije ti wọn nifẹ si.
” Ó bá fi wọ́n sílẹ̀ ó sì bá tirẹ̀ lọ.
minisita naa, yoo le pupo lati lọ fun isinmi ọhun”.
Ọmọ bibi Ilorin , o ti figba kan jẹ Gomina ni ipinlẹ Kwara o si ni iriri pupọ gẹgẹ bi aṣofin.
Amọ, eyi kan ma n din irora ku ni, kii ṣe itọju fun orisun tabi nkan to fa irora.
Ẹ̀wẹ̀, ìròyìn ayọ̀ ni pé, ìyàwó Amitabh Bachchan tó tun jẹ gbajúmọ̀ òṣèré bákan náà, Jaya Bachchan kò ni ààrun náà.
Lọjọ Kejilelogun, oṣu kọkanla ni ajọ eleto idibo Naijiria, INEC kede esi idibo nini ijọba ibilẹ mọkanlelogun ni Kogi pẹlu ero pe o ṣeeṣe ki iṣẹlẹ ija wa.
Igbimọ oludari naa lo da Adams Oshiomole duro gẹgẹ bi alaga ẹgbẹ.
lelẹ, ninu ofin   Section 26 ti eto idibo  Act, 2010 (atunse ) ati  Clause 47(e)                 Ajo INEC tun ti gbe igbesẹ lati yan igbimọ ti yoo se
Bi o tile je pe, iko agbaboolu AC Milan leto si boolu agbesile gba, leyin asemase asole iko Arsenal, sugbon adari ifesewonse naa ko lati fun won, bee si ni won se gudu meje ohun yaya mefa lati da ami-ayo ohun pada, sugbon omi poju oka lo.
Wọ́n tún kan àwọn ọlọ́ṣà meji mọ́ agbelebu pẹlu rẹ̀, ọ̀kan ní ọwọ́ ọ̀tún, ekeji ní ọwọ́ òsì rẹ̀.
venus and adonis jẹ ́ àwòrán kíkùn tí olóògbé paolo veronese , ayàwòrán ọmọ orílẹ ̀ èdè italy yà ní ọdún 1580 , tí ó wà ní museo del prado ní madrid báỳí .
Ẹnikẹta ni arakunrin miran to wọ orilẹede Naijiria ni ọjọ kẹtala oṣu kẹta lati ilu Frankfurt lorilẹede Germany.
Minisita fun eto ilera ni Naijiria, Osagie Ehanire naa si ti sọ pe awọn ti ran dokita to le ni ọgọta lọ si papakọ ofurufu Murtala Muhammad to wa l'Eko, lati ṣeranwọ ninu ayẹwo awọn arinrinajo to n wọle.
Mo sọ fún ọ̀rẹ́ mi kan pé ìyá àti bàbá mi fẹ́ ṣe sàráà fún mi ní ọjọ́ àbámẹ́ta, tí à ń pè ní Sátidé, mò sì fẹ́ kí o wá.
Àwọn pẹpẹ ìrúbọ yín yóo di ahoro, a óo fọ́ àwọn pẹpẹ turari yín, n óo sì da òkú yín sílẹ̀ níwájú àwọn oriṣa yín.
FIFA U-20 World Cup: Mali pa ẹ̀rùjẹ̀jẹ̀ Argentina lẹ́kún kúrò ni Poland
(Mirror) Ta ni agbábọ́ọ̀lù tó fakọyọ jù lọ ní Afcon 2019?
" Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Damilọla Ajayi: Ọ̀dá owó ló ṣún mi dé ìdí lílo ìyarun bíi fèrè Nollywood: Baba Suwe, Baba Wande àtàwọn òṣèré apanilẹ́rìn ín Yorùbá wọ̀nyí dà?
Bí ó bá sì jẹ́ pé ti ọ̀rọ̀ ẹ̀tọ́,ta ló lè pè é lẹ́jọ́?
Adele alukoro ile iṣẹ ologun Naijiria, Col Sagir Musa, to fi atẹjade ọhun sita ṣalaye pe ileeṣẹ ologun wa lojufo lati rii pe alaafia jọba ni Naijiria ni gbogbo igba.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo Lara awọn orin ti wọn n kọ naa yoo dun to bẹẹ gẹ, eyi ti yoo mu ori Alaafin wu, lati dide fẹsẹ rajo.
Oríṣun àwòrán, facebook/Amotekun Àkọlé àwòrán, Ọjọ kẹsan an Oṣu Kinni ọdun yii ni awọn gomina ipinlẹ mẹfa lati ilẹ Yoruba ṣe ifilọlẹ ikọ Amọtẹkun nilu Ibadan Awọn Gomina ìhà Guusu-Iwọ-òòrun to ku náà ti fi abádòfin wọ́n, siwáju ilé ìgbàmọ àsòfin ìpínlẹ̀ koowa wọ́n.
Ọkọ-ofurufu naa jabọ ni lẹyin igba to leyin igba to gbera kuro ni papa ofurufu Moscow lo si agbegbe Urals.
Ohun to yẹ ko mọ nipa Kofi Annan: Ọmọ Yoruba kan ti orukọ rẹ njẹ Titi Alakija, ni Annan kọkọ fẹ niyawo ni ọdun 1965.
O wa gba awọn ọdọ to n lakaka lati ṣe iṣẹ tiata nimọran pe, ki wọn ni owo ti ara wọn lọwọ ki wọn to dara pọ mọ awọn, ki wọn si mọ eeyan to wa nipo giga nitori irinajo ninu iṣẹ naa ko rọrun rara.
Ìfìdírẹmi Manchester United túmọ si pé wọn United yege nínu ìfẹsẹwọnsẹ kan péré nínú méje to kangun si àṣekágbá ni sáà yìí Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Ìjọ kò ní tilẹ̀kùn ilé ìjọsìn nítorí àrùn Coronavirus - Ondo PFN Ẹyin ilé ìjọsìn, ẹ tilẹ̀kùn ṣọ́ọ̀ṣì àti mọ́ṣáláṣí yín láti dènà àrùn Coronavirus - ìjọba Eko Ẹ wo ohun tí baba Adeboye sọ lórí ọ̀rọ̀ Coronavirus Wo àwọn irọ́ tí wọ́n ń pa fún ọ nípa àrùn Coronavirus Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Coronavirus: Mọ ọ̀nà láti tóju fóònu rẹ kí o ma ba ko àrùn O ṣeeṣe ki adinku to ba owo eporọbi ṣe akoba fun ọrọ aje Naijiria, nitori pe iye ti wọn n ta eporọbi tẹlẹ ni ijọba fi ṣiro owo iṣuna fun ọdun 2020.
Èmi ati baba rẹ dààmú pupọ nígbà tí à ń wá ọ.
Ewe, ile-igbimo naa tun temo igbimo re to n mojuto ile-ise omo ogun leti pe, ki awon oga agba ile-ise omo ogun naa ri daju lati sewadii ohun ti o sokunfa iku awon omo ogun naa.
EndSARS Protest Update: Àwọn olórí orílẹ̀èdè yí nígbàkanrí sọ̀rọ̀ nípa ọ̀nà láti dẹ́kun ìwọ́de ọ̀dọ́ lọ́jọ́ iwájú
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Stray Bullet: Bàbá ọmọ ni ogún náírà péré ni àwọn ọlọ́pàá fi lọ òun àmọ́ òun kò gbàá Amọ lẹyin tile ẹjọ kede idajọ rẹ tan, to si da igbeyawo nilana ẹsin islam naa nu laarin Nasreen ati Mohammed, ni Nasreen ba n lakaka pe ki awọn tun igbeyawo awọn se nilana ofin orilẹede Gẹẹsi.
Ologbe Shuaibu Amọdu ni olukọni fun ikọ Super Eagles nigba naa.
Torí ìdí èyí máa bá wa ronú!
Ṣugbọn ti o ba se pe o n se ẹyin ni kayeefi, ẹkọ nla kan re fun yin lati kọ - oloselu ko ni ọrẹ tabi ọta titi lailai.
Ninu fọnran fidio kan to gboju ayelujara kan la ti ri ti o ti n fi ọti ẹlẹrindodo la ọmọde yi loju ti iwa yi si mu kawọn eeyan faraya si.
Sẹ́nátọ̀ Elisha Abbo kési Naira Marley láti ṣe àríyá fún Leycon tó borí ní BB Naija Ẹ́ yé parọ́ mọ́ mi kiri, n kò múra ìgbéyàwó, ọ̀rẹ́ lásán ni Halima - Femi Fani-Kayode fọnmú Elisha Abbo ṣàlàyé ìdí tó fi lu obìnrin fún BBC Ninu alaye to ṣe ninu iwe to ka sita, Abbo tun sọ pe lati igba ti Naijiria ti pada si ijọba awarawa lọdun 1999, ko ti si aarẹ to mu ọrọ arailu lọkunkundun bi ti Buhari.
 bí ohùn òkè bá wà ní orí ìlà àkọ ́ kọ ́ , fún àpẹrẹ , ohùn tí ọ ̀ rọ ̀ tí ó wá ní ìlà tí a óò fi gbè é gbọ ́ dọ ̀ tako ti àkọ ́ kọ ́ ní ìbẹ ̀ rẹ ̀ , ààrin tàbí ní ìparí .
Igbesẹ sisan owo ori naa ni wọn sọ pe yoo bẹrẹ losu Kinni ọdun 2020, ti yoo si kan awọn ọja ti wọn ba ra lori ayelujara labẹle ati ni oke okun.
Ẹ̀mí ati Iyawo ń wí pé, “Máa bọ̀!
“Ẹ dìde, ẹ bẹ̀rẹ̀ ìrìn àjò yín, kí ẹ sì ré àfonífojì Anoni kọjá.
Nadabu, ọmọ rẹ̀ sì jọba lẹ́yìn rẹ̀.
Oríṣun àwòrán, AFP Àkọlé àwòrán, Losu to koja ni Volodymyr Zelensky jawe olubori ninu idibo aarẹ Bi ere bi ere,ọrọ naa di ododo Voldymyr Zelensky ti ṣe aarẹ ri botilẹ jẹ wipe ninu ere ori amohunmaworan to ti ṣe bi aarẹ Ukrain.
O ni oun lọ kọ iṣẹ iru ṣiṣe ni Ekiti nigba ti ko si iṣẹ lẹyin ti oun jade ile ẹkọ ni.
Bẹ́ẹ̀ ni ìbànújẹ́ da orí mi kọ odò, tí ara mi gbóná bí ìṣaasùn ori iná, tí inú mi dàrú bí ìgbà tí ẹ̀fúùfù ba ń fẹ́ igi oko, tí aye sú mi bi àkísà ẹlẹ́gbin, tí ọ̀run sì dára bi wúrà lójú mi.
iwosan Wayi o, o kere tan egberun
Oríṣun àwòrán, Reuters Gjedde sọ fun ileeṣẹ iroyin Fox pe kii ṣe pe oun gba ti Aarẹ Trump to bẹ lo jẹ ki oun faa kalẹ fun ami ẹyẹ naa, ṣugbọn o n gbiyanju tirẹ to ba jẹ ni ti eto alaafia.
”Akume, ti o je gomina ipinle ana ni ipinle Benue, ni awon ti n la awon eniyan loye ,ti won si n ro won lati lo foruko sile fun kaadi eto idibo won.
”’“o wa ro awon to wa ni agbegbe yii , adari won  ati awon ti oro kan lati fowosowopo pelu iko omo ogun lati je ki eto aabo to peye wa lori oju omi wa.
Lati Ọjọru ni Trump ti sọ pe oun lo jawe olubori ninu eto idibo ọhun nigba ti Biden naa ni o da oun loju pe oun yoo bori ninu ibo aarẹ Amẹrika.
Bakan naa ni Kẹmi Olunlọyọ ti oun pẹlu sun mọ idile naa naa ṣalaye pe ko si ootọ ninu iroyin naa ati pe lẹyin ti oun ba ọmọ agba oye ilẹ ibadan naa sọrọ, o jẹ ko da oun loju pe aaye ni Abiọla Ajimọbi kii ṣe oku ni bi a ṣe n sọrọ yii.
Bakan naa, ni Igbakeji Aarẹ, Yemi Osinbajo naa fikun un wi pe, awọn yoo sepade pẹlu awọn ọba to ku nitori awọn mọ wi pe, awọn lo sun mọ awọn ara ilu julọ.
awon eniyan se n wole –jade lorile ede Naijiria, Muhammad Babandede fọwọsi lọjọBọ
Oríṣun àwòrán, Arewa_ilorin_pple Mo fẹ ki Ọlọrun fun wa ni ọmọ oloju buluu si lẹyin yigi - Ọkọ oloju buluu Saaju la ti mu wa fun yin pe Abdul Wasiu ti sọ fun ileeṣẹ BBC Yoruba pe ni nibayi, ija ti pari laarin oun ati iyawo rẹ.
Oṣù Kínní ọdún 2020 ti pẹ́ jù, ẹ ṣe ìgbẹ́jọ́ mi kíákíaá - Donald Trump Àti lọ s'Amẹrika ti yàtọ̀ báàyí 'Ìdùnnù wa kọ́ ni kí á má fún ọmọ Nàìjíríà ní 'Visa' Ni Ọjọru ọsẹ to kọja ni aarẹ Donald Trump kede pe oun yoo fi kun iye awọn orileede tawọn ko ni gba laaye lati wọ ilu awọn.
Àwọn ọmọ ilé àṣofin náà fẹ maa gba owo ìfẹyinti bii ti ààrẹ orilẹ̀-èdè àti igbákeji wọn, àwọn ggomina àti igbakeji wọn jákejado orilẹ̀ èdè Naàìjíríà.
Eniyan meji lo padanu ẹmi wọn ninu isẹlẹ naa, ti mẹta si farapa.
Ní ti NASU àti ASUU, à ti díbo káre máa bá iṣẹ́ rẹ lọ fún gíwá tó wà níbẹ̀ yìí, nítori náà ẹ̀yìn Ogundipe ni a wà.
awọn agbẹnusọ ile igbimọ aṣofin ni apa Iwọ Oorun Gusu orilede Naijiria to waye ni Ipinlẹ Eko lojuna ati
Lẹ́yìn èyí ni àwọn ọmọ ilẹ̀ Iragbiji tún de pe àwọn gan an ní àwọn nilẹ̀, Bí àrùn Coronavirus ṣe dá gbogbo àgbáyé gúnlẹ̀ sójú kan náà nìyí Ó ṣeéṣe kí àrùn Coronavirus tànkálẹ̀ gba inú afẹ́fẹ́- WHO Ọwọ́ ọlọ́pàá ìpínlẹ̀ Oyo ti tẹ àwọn aṣekúpani tó ń ṣọṣẹ́ ní Akinyele Ìpínlẹ̀ Eko kéde ọ̀nà àbáyọ sí súnkẹrẹ-fàkẹrẹ ọkọ̀ lásìkò àtúnṣe afárá Third Mainland Wọn ni o sì di dandan kí Satguru tún ilẹ̀ náà rà, àti ìgbà yìí ni wọ́n ti maa ń wá láti da omí aláafia abúlé Guru Maharaj rú agbẹnusọ fun Guru, Ojo ni: Sátide, ọjọ́ kẹtàdínlọ́gbọ̀n ní àwọn ọmọ onílẹ̀ kan wa pẹlu awọn ọlọ́pàá láti wá fi katakata hú gbogbo ǹkan ti wọ́n gbìn sórí ilẹ̀ náà ti wọ́n sì tún ṣe àwọn ọmọlẹ́yìn Maharaj tí wọ́n ń ṣiṣẹ́ lọ́wọ́ níbẹ̀ léṣe yánayàna.
Child Trafficking: Ọwọ́ ṣìnkún ọlọ́pàá tẹ èèyàn 5 lórí ìṣẹ̀lẹ̀ náà
Eyi si lo mu kawọn afurasi shun gba ile ẹjọ to ga julọ nilẹ wa lọ Amọ pabo ni ẹjọ wọn ja si lọhun tori ile ẹjọ to ga julọ naa fidi idajọ ile ẹjọ akọkọ mulẹ, to si ni ẹwọn gbere ni ki wọn fi awọn ọdaran naa si, ti ewe nla Ọrẹdẹin ati awọn ọga ọlọpa miran si pada wa ru wẹwẹ.
Ase bo ṣe wa ni liki naa lo wa ni gbanja.
Komiṣọna fun eto igbafẹ ní Ipinlẹ Eko, Steve Ayorinde, ti ni ijọba kò tíì pari iwadii rẹ lori ile ounjẹ China kan ni ipinlẹ Eko to n gbe igbesẹ ẹlẹyàmẹya ti ko jẹ ki awọn ọmọ Naijiria ra ounjẹ.
 Yakubu Dogara: Ẹ maṣe gbagbe ẹkọ nipa ifiraẹnijin, idariji, ijọsin fun Ọlọrun ati ikoraẹni-ni- ijanu pẹlu ifẹ tootọ fun ọmọlakeji Oríṣun àwòrán, @YakubDogara Àkọlé àwòrán, Ẹ maṣe gbagbe ẹkọ nipa ifaraẹnijin, idariji, ijọsin fun Ọlọrun ati ikoraẹni-ni- ijanu pẹlu ifẹ tootọ fun ọmọlakeji Olori ile aṣoju-ṣofin, Yakubu Dogara rọ awọn musulumi lati fi asiko opin awẹ yii ṣe arojinlẹ lori ẹkọ ti wọn ba kọ, ki wọn si ranti awọn to ku diẹ kaa to fun lawujọ."
Ọkan lara awọn ololufẹ AJ ni olorin takasufe, ọmọ Naijiria, DJ Cuppy.
O ni gbogbo ẹka ijọba gbọdọ fi imọsọkan lati gbogun ti eto aabo to dẹnukọlẹ ni Niajiria, ati wi pe eto aabo to dẹnukọlẹ n ba wa finra gidigidi.
Bakan naa lo ni ile aṣofin yoo paṣẹ fun awọn agbẹjọro naa lati pe ẹjọ tako o fun ibanilorukọ jẹ.
Eyi la lee fi se apejuwe ọwọ rogbodiyan to n waye ni aafin Ọyọ nipa ọkan lara awọn ayaba Alaafin Ọyọ, Olori Badrat Olaitan Ajoke Adeyemi, eyi to ti lọ silẹ bayii.
Eyi si ti mu ki apapọ awọn to ti ràn ni Naijiria o pe 21,371 bayii.
Abramu bá Hagari lòpọ̀, Hagari sì lóyún.
aare  Teodoro Obiang Nguema Mbasogo fun
Ile igbimo asofin agba ti rọ ijoba apapọ lati
Ọba yìí ní àwọn ìjòyè tí wọn jọ ń ṣèlú .
Akwaaba jẹ orin to mu ẹsẹ ijo tuntun dani ti gbogbo eeyan n jo si ni iwọ oorun ilẹ Afrika.
Alaga ile igbimo ohun lori oro ifitonileti, AbdulRazak Namdas yanana oro naa lasiko to n ba akoroyin ile igbimo asofin soro nipa iwe isuna odun ti a wa yii.
Gbogbo ọdún tí Lamẹki gbé láyé jẹ́ ẹẹdẹgbẹrin ọdún ó lé mẹtadinlọgọrin (777) kí ó tó kú.
Àwọn kan ninu àwọn ọmọ ìjọ ní Jọpa sì tẹ̀lé wọn.
Èèyàn 20 kú, èèyàn 604 míràn tún kó COVID-19 ní Nàìjíríà l'Ọ́jọ́bọ Eeyan mẹrinlelẹgbẹta ni wọn tun kede pe ayẹwo tun ti fihan pe o laarun COVID-19 lorilẹede Naijiria bayii.
Dafidi sá kúrò ní Naioti, ní Rama, lọ sọ́dọ̀ Jonatani, ó sì bi í pé, “Kí ni mo ṣe?
Òun ni mo yàn láti jọba Israẹli ati Juda.
Pẹlu oṣuwọn ijọba South Africa fun ìṣẹ́ - ile ti owo to n wọle fun wọn ba kere si Dọla marunlelaadọta l'óṣù - akọsilẹ ijọba fihan pe afiwe yii ti dinku lati ìdá mọkanlelaadọta si mẹrindinlogoji laarin ọdun 2006 si 2011.
Inuwa tun mẹnu ba awọn mọṣlaṣi nla ni orilẹ-ede Tunisia, Morroco ati
His was one of the responsible, mature and respected voices to take Nigeria out of the unwholesome situation it had found itself-permanently in crisis, regularly threatened with disintegration, prolongingly devoid of democracy, and economically plundered and mismanaged.
O fi da awon olukopa loju pe egeb naa yoo tesiwaju lati maa wa awon amuye fun idagbasoke ise awon obinrin ninu eto ogbin.
Ọ̀rọ̀ Jeremaya, ọmọ Hilikaya, ọ̀kan ninu àwọn alufaa tí ó wà ní Anatoti, ní ilẹ̀ Bẹnjamini nìyí.
Jakọbu bá gbadura báyìí pé, “Ọlọrun Abrahamu baba mi, ati Ọlọrun Isaaki baba mi, Ọlọrun tí ó wí fún mi pé, ‘Pada sí ilẹ̀ rẹ ati sí ọ̀dọ̀ àwọn ìbátan rẹ, n óo sì ṣe ọ́ níre.
lagbaye, ti o si n sise lorile-ede mẹ́rìnlélọ́gọ́fà, bee
Ajọ to n gbogun ti ajakalẹ arun lorilẹede Naijiria, NCDC lo fidi eyi mulẹ loju opo Twitter rẹ.
" O fi ohun aro ranṣẹ pe: Bi ẹ ko ba gburoo mi mọ ki ẹ mọ pe wọn ti sọ mi sẹwọn, bi ẹ ko ba gburo mi mọ, ki ọ mọ pe wọn ti gba gbogbo nkan lọwọ mi ti wọn si ti ti mi pẹlu gbogbo bi mọ ṣe farapa mọ atimọle""."
Ẹsun ti wọn fi kan awọn eniyan naa ni ede Faranse ti wọn n sọ, ni wi pe awọn ikọ Boko Haram ni obinrin naa ati awọn ọmọ rẹ.
Eto InawoAwon adari orile ede Naijiria tile so pe imo ero igbalode ti ran awon eto ilana ijoba lowo nipa titele ilana ofin , ni eyi ti o ti je ki iwa ibajẹ dinku lorile ede yii, ti o si tun n pa owo sapo ijoba.
Itan sọ pe ni ọpọ ọdun sẹyin ni awọn arinrinajo kan ti ọdẹ kan ti orukọ n jẹ Olutimẹhin ko sodi ni wọn tẹdo si eti odo Ọṣun.
de ba awon odo lati le da duro funra won.
Tí a fiṣọwọ́ ní 11:17 29 Èbibi 201911:17 29 Èbibi 2019 Igbakeji gomina tuntun nipinlẹ Ọyọ, Onimọẹrọ Rauf Ọlaniyan ti bura wọle.
Ó ṣeéṣe kí ènìyàn 12,000 máa kú lójoojúmọ́ lẹ́yìn Covid-19 Wo agbábọ́ọ̀lù Super Eagles Nàìjíríà àkọ́kọ́ tó lùgbàdì coronavirus Bí àrùn Coronavirus ṣe dá gbogbo àgbáyé gúnlẹ̀ sójú kan náà nìyí Ó ṣeéṣe kí àrùn Coronavirus tànkálẹ̀ gba inú afẹ́fẹ́- WHO Àwọn orílẹ̀-èdè Afíríkà wo ni aàrùn náà pọ̀ sí jùlọ?
Ní ọdún keji tí Asa jọba ní Juda, ni Nadabu, ọmọ Jeroboamu, gorí oyè ní ilẹ̀ Israẹli, ó sì jọba fún ọdún meji.
Owo ori epo-robi gbe peeli lojo-Aje, eyi ti o mu ijakule ba akitiyan iwakusa orile-ede America, bi eto oro-aje orile-ede America se n pese ise, eyi ti ireti wa pe, yoo je ki awon eniyan bere fun epo-robi naaOja epo-robi tutu wa ni dollars marundinladorin jala kan 65.
O tun tesiwaju pe “dida ile-isẹ ijọba tuntun meji silẹ waye nibi ipade ti igbimo to n ri si isẹ iwadii ati ọgbọn atinuda se niluun Abuja lati gbokun ti ọrọ omiyale agbara ya sọọbu ni eyi ti o maa n wa lati omi Lake Chad.
" Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Omolola Arohunmolase Welder: Mo ti fí iṣẹ́ 'Welder' gbayì láwùjọ, tó mo fi tọ́ ọmọ yanjú Ojisẹ Ọlọrun naa ni gbogbo ẹka awujọ ni iwa ajẹbanu ti gogo pupọ, tàwọn oloselu atawọn gbajumọ si n ko owo ilu, ti wọn si tun n fi le awọn ọmọ wọn lọwọ.
“Ẹ̀yin ará, mo sọ fun yín láìṣe àní-àní pé Dafidi baba-ńlá wa kú, a sì sin ín; ibojì rẹ̀ wà níhìn-ín títí di òní.
Opo ololufe iko agbaboolu Super Eagles lo ti bu enu ate lu akonimoogba agba iko Super Eagles, Gernot Rohr lataari aise deede iko naa ti won tin baabo lateyin wa.
Akọ̀ròyìn Reuters méjì Wa Lone àti Kyaw Soe Oo rìnrìn òmìnira lẹ́yìn tí a dá wọn sílẹ̀ ní ẹ̀wọ̀n Insein ní  Yangon.
Àwọn ọ̀rọ̀ kan wà tí àwọn ènìyàn sọ ní orú yìí tí ó yẹ kí á ṣe àkíyèsí.
Ìwọ tí ò ń pa àwọn wolii, tí ò ń sọ òkúta lu àwọn tí a ti rán sí ọ, nígbà mélòó ni mo ti fẹ́ kó àwọn ọmọ rẹ jọ, bí adìẹ tií kó àwọn ọmọ rẹ̀ sí abẹ́ ìyẹ́ rẹ̀, ṣugbọn ẹ kò gbà fún mi!
Afurasí Boko Haram pa ológun àti ọlọ́pàá mẹ́rìnlá ní Borno Èèmọ̀!
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Àwọn ọmọ ilẹ́ Afrika tó ń gbábọ́ọ́lù fún orílẹ̀èdè míràn Jẹẹsí àwọn orílẹ́èdè tó ń lọ Russia 2018 ree 'Ààrẹ Buhari, a dúpẹ́ ìdùnnú ńlá ni fún wa' Aisan ọkan lo mu Keshi lọ nigba to pe ọmọ ọdun mẹrinlelaadọta.
Lọjọ Isẹgun ni iroyin sọ pe, gomina ipinlẹ Ondo, Rotimi Akeredolu ṣe ipade pẹlu Aarẹ Muhammadu Buhari lati jiroro lori gbigbin ati lilo igbo fun ṣiṣe oogun oyinbo l'orilẹ-ede Naijiria.
 Afojusun ise fun milionu meedogun eniyan la ni ni erongba wa ti a de mo pe o seese fun wa”.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Adebola Ademilua: Àìrísẹ́ ṣè lẹ́yìn ìwé kíkà ló sọ mi dí ìyá onírú, mo dúpẹ́ tèmi Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Oluwo: Oluwo ṣàlàyé ohun tó ń mú káwọn èèyàn máa gba tirẹ̀ láwùjọ28 Bélú 2020 EndSARS, Daniel Chibuike Ikeaguchi: ọlọ́pàá yìbọn pa Sleek ní Port Harcourt niléẹjọ́ bá bú N50 mílíọ̀nù, owó gbà má bínú28 Bélú 2020 Latest ASUU strike update: Ẹgbẹ́ òṣìṣẹ́ ASUU tí gbà láti fòpin sí ìyanṣẹ́lódí lẹ́yìn tí ìjọba gbà látí sàn N70bn28 Bélú 2020 Ọkùnrin kan lu ìyàwó rẹ̀ pa"" ní ìpínlẹ̀ Ogun nítorí ó lọ síbi ayẹyẹ ìsọmọlórúkọ28 Bélú 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?"
ati eniyan ati ẹranko, ati gbogbo ẹyẹ, ati gbogbo ẹja.
Ni Jesu bá dá wọn lóhùn pé, “Ẹ̀yin aláìmòye wọnyi!
Lasiko to n fi idi isẹlẹ naa mulẹ fun BBC Yoruba, agbẹnusọ fun ẹgbẹ Afẹnifẹre, Yinka Odumakin salaye pe lootọ ni isẹlẹ naa waye, asiko ti Ọlakunrin n bọ lati ilu Akurẹ si lo se alabapade iku ojiji naa.
Mo wò yíká, mo rí i pé gbogbo ilẹ̀ ọlọ́ràá ti di aṣálẹ̀,gbogbo ìlú sì ti di òkítì àlàpà níwájú OLUWA,nítorí ibinu ńlá rẹ̀.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Cute Abiola: Mo ti n bá agbẹjọ́rò mí sọ̀rọ̀ láti gbé ìgbésẹ̀ òfin lórí ẹ̀ṣùn náà 28 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Oríṣun àwòrán, @victoryomogiate Yoruba ni ọrọ ifẹ, bii adanwo ni, oro ọfa ifẹ si mu ju oro abẹ lọ ninu ọkan.
BBC: Ki lo tun ku ki awọ́n eeyan maa reti lọdọ Seyi lẹyin eto agbelewo Ẹlẹgbọn Agba?
JAMB f'ọjọ kun asiko iforukosilẹ Ajọ JAMB fun osisẹ n'iwe lọ gbe'le ẹ Gẹgẹbi ọrọ awọn akẹkọ naa, awọn to kọ idanwo tọdun to kọja, ko tii wọ ile-iwe nitori sunkẹrẹ fakẹrẹ eto ẹkọ lorilẹede Naijiria.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Lionel Messi: Ronaldinho ní Messi kọ́ ni agbábọ́ọ̀lù tó dára jùlọ lágbàáyé 13 Ọ̀pẹ̀̀ 2019 Oríṣun àwòrán, Instagram/Ronaldinho Ọrọ yii dabi ẹni pe ko ni tan nilẹ bọrọ.
Adé ìgbéraga àwọn ọ̀mùtí Efuraimu gbé!
Aṣoju oloogbe Majek Fashek, Omenka Uzoma to ba BBC sọrọ ṣalaye pe ilumọọka olorin fọwọ rọri ku lọjọ kinni oṣu kẹfa niluu New York lorilẹede Amẹrika.
“Èyí ni ohun tí ẹ gbọdọ̀ ṣe nígbà tí obinrin bá ṣe aiṣootọ sí ọkọ rẹ̀, tí ó sì ba ara rẹ̀ jẹ́ nítorí pé ọkunrin mìíràn bá a lòpọ̀; 
Àwọn òṣìṣẹ́ tó ń mójútó ìṣẹ̀lẹ̀ pàjáwìrì ní, àwọ̀n tó kú fara gbọta nígbà tí wọ́n ń gbìyànjú àti sá àsálà fún ẹ̀mí wọn.
O fikun pe ọpọlọpọ gbese ni ijọba to kọja lọ nipinlẹ naa fi silẹ fun òun, gbogbo rẹ̀ si lawọn n gbọ bukata le lori.
Lọdun 2013, nigba ti obinrin naa wa lẹni ọdun mejidinlaadọrun, o n beere fun iranwọ awọn oninure, ko to lee sanwo itọju nile iwosan, ko si tun ri ọwọ mu lọ sẹnu.
Ọwọ ṣìkún òfin ti tẹ Maina, alága àná fún ọrọ owó ìfèyìntì - DSS Aarẹ Buhari ti de si ọdọ Aarẹ Ramaphosa ni Pretoria ni South Africa Ẹ tètè pè fún àjọ tó ní irònú pìwàdà kó tó pẹjù- NLC/TUC Ilééṣẹ́ Aṣọ́bodè Naijiria n pa bílíọ̀nù N5.
Arẹmọ Olusegun Osoba ti ni awọn ọmọ Naijiria nikan lo le gba ara wọn la lọwọ amunisin lorilẹede Naijiria.
idibo to waye ni ọjọ Abamẹta
IS fi ẹsun kan al-Qaeda pe oun satilẹyin fun ijọba orilẹ-ede Yemen lati kọjú ija si oun.
awon asoju ni ẹlẹkunjekun ti yoo maa soju orile ede naa.
Ẹ̀wẹ̀, àtẹjáde ti ìjọba ìpínlẹ̀ Kogi fisíta sàlàyé pé àwọn ẹbi aláìsàn kan níle ìwòsàn náà ti wọ́n kọ̀ láti tójú, dé bi pé o wá bí ọmọ sí ẹnu ọ̀nà ilé ìwòsàn náà.
Ni awọn agbegbe miran, awọn ẹbi yoo joko lalẹ ọjọ igbeyawo lẹba yara ti tọkọtaya wa, aibaamọ, iyawo lee fẹ wa ba wọn lati beere fun itọnisọna lori bi yoo ti se pẹlu ọkọ rẹ lori ibusun.
Olukuluku ìtẹ́lẹ̀ yìí ni ó ní àgbá kẹ̀kẹ́ idẹ mẹrin, igun mẹrẹẹrin rẹ̀ sì ní ìtẹ́lẹ̀, lábẹ́ agbada náà ni àwọn ìtẹ́lẹ̀ tí a rọ wà.
Solomon Dalung to jẹ minista fun ere idaraya lati ipinlẹ Plateau ko wọ inu orukọ tuntun.
Oríṣun àwòrán, NLC WEBSITE Àkọlé àwòrán, Iyansẹ̀lodi wọ̀pọ́ lorilẹ́ede Naijiria Adari egbe osisẹ̀ NUT nipinlẹ̀ naa, Comrade Niyi Akano, nigba ti o ba BBC sọ́rọ́, wipe ki ijọba ipinlẹ̀ Ọ́yọ̀ wa ọ́na abayọ si iyansẹ̀lodi ọlọ̀sẹ́ mẹ̀tala ti awọn osisẹ̀ ile-isẹ́ giga ti ijọba ipinlẹ̀ Ọ́yọ̀ gun le.
Wọn sún igbejo sì ọjọ́ karundinlogbon, ọjọ́ kokandinlogbon àti ọgbọ́n ọjọ́ Oṣù Kẹfà, ọdún yìí.
Ija yii le gan an to bẹẹ to to ọdun mẹsan an ko to dawọ duro.
"Níbití ọ̀pọ̀ àwọn akẹ́kọ̀ọ́ wà, ní kété tí wọn bá ti tọ́ adùn oògùn ikọ́ olómi tó ní èròjà codeine nínú wò, ni wọn yóò máa yọ ọ́ lẹ́nu láti mu síi.
Lati igba naa ni mo ti n lo oogun fun ìrẹ̀wẹ̀sì ọkan, titi di oni.
Níbi tí àwọn ẹ̀yà,àní, àwọn ẹ̀yà eniyan OLUWA máa ń gòkè lọ,láti dúpẹ́ lọ́wọ́ OLUWAgẹ́gẹ́ bí àṣẹ tí a pa fún Israẹli.
Ǹjẹ́ n kò sọ fún ọ kí o má ṣe tàn mí jẹ?
lati jo fọwọsowọpọ, ni eyi ti won yoo fi lee mu ijoba  Omar al-Bashir ti o ti wa lori aleefa lati bi ọgbọ̀n odun ,ti iko
Nígbà tí mo jẹun tí mo yó bámúbámú, mo jókòó, mo fi ẹ̀hìn ti igi kan báyìí, mo sùn lọ.
Ninu igbami-eye ohun, awon eyan jankan-jankan miran ti won tun fi ami-eye da lola ni, aare agba ile igbimo asoju-sofin, Dokita Bukola Saraki, pelu ami-eye oloselu ti ta yo julo(Outstanding Politican of the Year), Gomina ipinle Eko, ogbeni Akinwunmi Ambode gba ami-eye (Man of the Year), Gomina ipinle Rivers, Nyesom Wike (Governor of the Year), Emir ipinle Kano, Alhaji Muhammad Sanusi (Courage in Leadership Award), adari agba  ajo NDDC, Nsima Ekere (Public Service Award), adari agba ile ifowopamo Zenith, Peter Amangbo (Banker of the Year),  Dokita Emeka Okwuosa (Investor of the Year); Dokita Samuel Adedoyin (Lifetime Achievement Award); adari agba ile ifowopamo agba CBN, Godwin Emefiele (Public Service Award), besini asofin Osita Izunaso ati Dokita  gba ami-eye isomoniyan (Humanitarian Service Award).
Lákọ̀kọ́, mo rò pé kò ni fẹ́ ẹ ni ṣùgbọ́n kò bínú sí i àyàfi ti pé mo máa fẹ́ gbádùn ìbálòpọ̀ lọ́nà mìíràn.
Mose pada lọ sí ọ̀dọ̀ Jẹtiro, baba iyawo rẹ̀, ó sọ fún un pé, “Jọ̀wọ́, jẹ́ kí n pada lọ sí ọ̀dọ̀ àwọn eniyan mi ní Ijipti, kí n lọ wò ó bóyá wọ́n wà láàyè.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Adári ilé ìgbìmọ̀ aṣòfin ìpínlẹ̀ Niger àti akọ̀wé náà ti lùgbàdì Covid-19 Iroyin to n tẹ wa lọwọ ni pe adari ile igbim aṣofin ipinlẹ Niger, Abdullahi Bawa ati akọwe ile, Abdullahi Kagara ti ni esi ayẹwo to sọ pe wọn lugbadi arun Covid-19.
    Òmùgọ́diméjì, inú mi kò dùn láti mọ̀ ọ́ rárá.
Ohun tí o ṣe sí mi yìí kò dára rárá!
Ọkunrin ń bá ọkunrin ṣe ohun ìtìjú, wọ́n wá ń jèrè ìṣekúṣe wọn.
Egbe oselu ohun so pe, awon ti padanu omo odun marundinladorin naa lasiko ti o  ku osu kan pere ki eto idibo waye, amo, bi won n kedun naa ni won n ronu eni ti yoo gbapo ologbe naa.
 mo ní kí ẹ gbọ ́ gbólóhun tí mo fẹ ́ bá gbogbo mùtúnmùwà àní ọmo adáríhunrun sọ .
Bí ó wà ninu ara ni o, bí ó rí ìran ni o, èmi kò mọ̀–Ọlọrun ni ó mọ̀.
Àjànàkú lọlẹ̀ wì, ọba ọ̀dàn ṣòjòjò
O ni yatọ si pe awọn ọn abuja miran ti wa lati gba lasiko iṣẹ atunṣe yii.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Samuel Ajayi Crowther: Baba nlá Herbert Macaulay, tó túmọ̀ Bíbélì sí Yorùbá 5 Èrèlè 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 1 Sẹ́rẹ́ 2021 Oríṣun àwòrán, @BAMEAnglican àlùfáà tó túmọ̀ Bíbélì sí Yorùbá , tó tún jẹ́ baba nlá Herbert Macaulay Kii se igba akọkọ ree ti a gbọ orukọ Bisọọbu Samuel Ajayi Crowther nilẹ Yoruba ati ni orilẹ-ede wa Naijiria lapapọ.
Gíga rẹ̀ jẹ́ igbọnwọ mẹta (mita 1½), òòró rẹ̀ jẹ́ igbọnwọ meji (bíi mita kan), ìbú rẹ̀ sì jẹ́ igbọnwọ meji.
Aṣọ Yorùbá, ìró àti bùbá kò pé lai si gèlè.
Wọ́n jí ọmọ yìí gbé láti máa fi tọrọ bárà l'Eko Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Àsìkò Amojúẹ̀rọ Seyi ni ló fi wọlé l'Oyo, kìí ṣe àsìkò èmi Omobolanle' @Sekoni12322 sọ ni tirẹ pe oun n duro de ohun ti ajọ to n gbogun ti iwa ajẹbanu yoo yoo ṣe lori ọrọ yii.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Nigeria 2019 Elections: Èwo nínú ìlérí tí Buhari ṣe ní 2015 ló ti mú ṣẹ?
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ sí: Ìdí tí mo fí kọ̀ èsì ìbò ààrẹ - Atiku ṣàlàyé Èsì ìbò kọ́ àwọn olórí láti sún mọ́ mẹ̀kúnnù - Ogundamisi Ìjọba paṣan ní Nàìjíríà dibo fún, yóò kàn gbogbo wà - Sowore YàjóYàjó- Èsì ìdìbò Ààrẹ Orílẹ̀èdè Naijiria ti 2019 Ṣugbọn awọn iwe iroyin ni arakunrin ti wọn pe ni oloogbe naa ko ku.
O ni Igboho n fa madaru laarin Yoruba atawọn Fulani nibẹ ni nitori ibagbepọ alaafia lo wa laarin awọn ẹya gbogbo lagbegbe naa.
Yóo fì ọ́ nàkànnàkàn, yóo sì sọ ọ́ nù bíi bọ́ọ̀lù, sí ilẹ̀ tí ó tẹ́jú, níbẹ̀ ni óo kú sí.
Ayẹyẹ igbeyawo melo ni Aarẹ Buhari lọ?
ri wi pe, aabo to muna doko wa nile.
Ogbeni Akinola Ojo to jẹ Kọmisọnna fun eto ẹnawo ni ipinlẹ̀ Oyo lo ni ijọba gbe igbesẹ yii ki ara o le tu awọn onile ile isẹ nlanla ati keekeeke ni ipinlẹ Oyo.
Kii si se ajeji mọ lati maa ri awọn eeyan, paapa awọn awakọ ero, ọmọ ẹyin ọkọ taa mọ si Kọndọkitọ ati awọn eeyan miran to n sisẹ agbara, ti wọn yoo maa ra ọti lile wọnyi lori atẹ.
 ‘Awọn to ko ọmọogun kuro ni Dapchi gbọdọ jiya’ ‘ Awọn ọmọ Yobe’ Kini yoo pada jasi?"
Oríṣun àwòrán, The Park Management Oyo State Facebook Àkọlé àwòrán, Ọmọ mi ni Sunday Igboho, kò sì tó dúró de mi, òun gan ló ń dá Ibadan ru - Auxiliary Auxiliary wá parí ọrọ rẹ pé òun kò ní ẹnikẹ́ni tí òun ń bá ja àmọ́ ohun tí gómìnà Seyi Makinde fẹ, ní àwọn n ba fẹ́.
Ìpè orí fóònù tó mú kí America fẹ́ yọ ààrẹ Trump rèé Ariwisi ọtọọtọ si ti n tẹle ọrọ igbakeji aarẹ naa nitori bi awọn kan ti ṣe n bẹnu atẹ lu awọn to ni wọn n gbe iroyin ẹlẹjẹ kaakiri nipa oun ni awọn miran ni ki igbakeji aarẹ ṣe mẹdọ.
Naijiria bẹrẹ iwadi lori owo iranwọ epo Ṣé o rántí itú tí Bright Omokharo fi Algeria pa ní MAROC '88?
Nígbà tí Jesu dé, ó rí i pé ó ti tó ọjọ́ mẹrin tí òkú náà ti wà ninu ibojì.
Pẹ̀gànpẹ̀gàn a máa wá ọgbọ́n, sibẹ kò ní rí i,ṣugbọn ati ní ìmọ̀ kò ṣòro fún ẹni tí ó ní òye.
Ni nkan bi aago mẹwaa owurọ Ọjọbọ ni eto isinku naa bẹrẹ.
Nígbà tí Ọlọrun gbọ́, inú bí i gidigidi;ó sì kọ Israẹli sílẹ̀ patapata.
35 Àti pé bí ìwọ bá jẹ́ olõtọ́ ní pípa àwọn òfin mi mọ́, a ó gbé ọ sókè ní ọjọ́ ìkẹhìn.
Ifẹhonuhan  n waye lori ogbeni Bashir, ti o ti wa lori
“Mú àgbò ìyàsímímọ́ náà, kí o sì bọ ẹran ara rẹ̀ ní ibi mímọ́ kan.
Dokita Akerele to n ṣiṣẹ gẹgẹ bii oluwosan ọpọlọ ni ile iwosan ọpọlọ ti iijọba apapọ to wa ni Yaba ni Ipinlẹ Eko ni ọpọlọpọ awọn dokita bi ti oun ko fọwọ si lilo igbo gẹgẹ bii oogun nitori wipe o le fa awọn aisan ọpọlọ oriṣiriṣi.
Àwọn iranṣẹbinrin mi kà mí kún àlejò,wọ́n ń wò mí bí àjèjì.
Dida fọọmu pada Bi ipele yii ni wa ti da fọọmu ti o ti fọwọ si pada si ọfiisi ajọ FRSC to maa n fawọn awakọ nọmba.
Chelsea fagbahan Manchester United lati gba ife-eye idije FA Cup, ninu ifesewonse ti o waye ni papa isere Wembley lojo Aiku(Saturday).
Ẹwẹ, iroyin nipa idile rẹ nipa ti ọmọ rẹ kan to ku, Hunter yatọ.
ṣùgbọ́n ogun kò pari rárá a sì dúró tó oṣu kan gbóko kí ogun tó pari.
Ni ọjọ kẹrinla, oṣu keje ọdun 2020 ni Arotilẹ ṣalapade iku ojiji ni ibudo awọn ọmọogun ofurufu to wa ni ilu Kaduna.
Ṣaulu bí Ṣalumu, Ṣalumu bí Mibisamu, Mibisamu sì bí Miṣima.
Kódà, àwọn miran nínú wọn kò ní jẹ ará ayé, bẹ́ẹ̀ni wọn kò ní jẹ́ èrò ọrun, tí wọn yóò sì dákú lọ rangbondan fún ọpọ ọjọ́.
Yakubu ti toro aforijin fun bi ajo eleto idibo se sun eto idibo aare ati ile
Irokotọla: Báwo ló ṣe rọrùn láti fi àmì sí ọ̀rọ̀ yìí, ‘Irokotọla’?
O & Associates gẹgẹ bi manija rẹ, ṣeranwọ fun lati sọ orin rẹ di itẹwọgba laarin awọn ọlaju ati awọn miran ni agbo faaji Naijiria.
Ibrahim Sani Shawai to jẹ agbẹnusọ fun ileeṣẹ apinna ọba ni agbegbe Kano, Katsina ati Jigawa ṣalaye fun BBC pe wọn pin ilana naa si ẹlẹkajẹka bii awọn ileeṣẹ, ileeṣẹ ijọba atawọn agbegbe olowonla.
Awọn ọlọpaa ri afunra si naa ni inu ọkọ rẹ gẹgẹ bi atẹjade ọlọpaa ṣe sọ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Akomolede ati Asa lori BBC: Olùkọ́ Kikelomo Ogunboye tan ìmalẹ̀ sí ìwà olè ọ̀gá ọlọ́pàá Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
"Adebayo ni ""Mo le e sọ fun yin ni kedere pe, ootọ ni wọn kọ iwe mọ Oluwo, ṣugbọn ijọba ṣi n yẹ iwe naa wo lọwọ."
Akoko yii si ni awọn Igbo ( kii se awọn eeyan to wa lẹkun ariwa orilede Naijiria o) maa n ko awọn eeyan Ile Ifẹ lẹru, to si nira pupọ fun awọn akọni alagbara ọkunrin ni ilu naa, lati gba Ile Ifẹ silẹ lọwọ awọn ọmọ ogun Igbo, to wa n ko wọn lẹru.
EFCC fẹ́ gbẹ́sẹ̀ lé ilé tí mo fi owó ìfẹ̀yìntì kọ́ nílùú Ilorin- Saraki Rògbòdìyàn tó bẹ́ sílẹ̀ lórí afárá London jọ ìgbésùnmọ̀mí Ilé ẹjọ lé Ọba Èrúwà kúrò lórí Àpèrè lẹ́yìn ọdun 21 Aàrẹ Trump kọ̀ láti jẹ Tòlótòló ìsìn ìdúpẹ́ 2019 nílé, ó gba Afghanista lọ!
Adari ẹka ẹgbẹ Agbẹkọya Peace Movement ni ilu Abuja, Comrade Abioye Akinbola lo sọ eyi lasiko to n ba BBC Yoruba sọrọ lori ọna abayọ si isekupani ati ijinigbe ni ilẹ Yoruba.
Wọ́n tún rán Haṣabaya, òun ati Jeṣaya ọ̀kan ninu àwọn ọmọ Merari; pẹlu àwọn arakunrin rẹ̀, ati àwọn ọmọ wọn.
Bẹẹ si ni diẹ lara awọn ọdọmọde arẹwa olori yii lo ti kẹkọọ jade nile ẹkọ fasiti pẹlu oye imọ ijinlẹ akọkọ.
Jesu bi wọ́n pé, “Kí ni ẹ fẹ́ kí n ṣe fun yín?
Ó lè fi sùúrù bá àwọn tí wọ́n ṣìnà nítorí wọn kò gbọ́ lò, nítorí pé eniyan aláìlera ni òun náà.
eto alaafia , naa so pe ko daju pe eto idibo yoo waye ni irowo-irose.
Gbogbo ọkunrin, lára àwọn alufaa lè jẹ ninu rẹ̀, wọ́n gbọdọ̀ jẹ ẹ́ ní ibi mímọ́ nítorí pé ó jẹ́ mímọ́ jùlọ.
Ni Peteru bá pè wọ́n wọlé, ó gbà wọ́n lálejò.
"Eyi waye gẹgẹ bi esi si gbọyii sọyii to n waye laarin awn ile iṣẹ iroyin lori iwe aṣẹ ""maa ṣiṣẹ"" lati bẹrẹ ile iṣẹ rẹdio Fulani fun anfani ati le maa kọ awọn Fulani lẹkọọ."
Ẹsun ti iroyin sọ pe wọn fi kan nigba naa ni pe, o n ni ifẹ ikọkọ pẹlu gbaju-gbaja olorin Fuji, Wasiu Ayinde, K1.
Bo tilẹ jẹ pe a ko le sọ boya ẹnikẹni farapa nibi rogbodiyan naa, awọn iroyin ati aworan, ati fidio to wa lori ayelujara n sọ pe awọn kan ku.
Loju awọn alatilẹyin rẹ, o jẹ akọṣẹmọṣ ninu aatọ ọrọ ilẹ okere pẹlu iriri ọlọdun gbọrọ ni ilu Washington, ẹnu rẹ dun mọran-mọran pẹlu ọrọ sisọ nita gbangba eyi to n fa oju eeyan mọra to fi mọ koda ẹni ti ko rọwọ họri lawujọ o si tun jẹ eeyan kan toun funrarẹ ti jẹya ri laye.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Àwọn musulumi ma n ya Ọjọ Arafa sọtọ lati fi gba adura kaakiri agbaye pẹlu àwọn ti won rin irinajo lo si ilẹ Mecca.
"Mo mọ iru ipo ibanujẹ ti aya gomina ana naa wa, mi o si binu sii lẹyin iṣẹlẹ ọjọ naa.
 Ó jẹ ́ dandan pé ó mọ ọ ̀ pọ ̀ lọpọ ̀ , lára èyí tí a máa sọ tó bá yá ní ìfìwàwẹ ̀ dá .
safihan Oshoala lori ero alagbata won lojoBo(Thursday).
Tọ Dafidi ọba lọ lẹsẹkẹsẹ, kí o sì bi í pé, ṣebí òun ni ó fi ìbúra ṣe ìlérí fún ọ pé Solomoni ọmọ rẹ ni yóo jọba lẹ́yìn rẹ̀?
atunse tile-igbimo asofin ti fi dawa loju pe, won yoo se si ofin ati ilana to n
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Dagrin: Òní ló pé ọdún mẹ́sán án ti Dagrin dágbére fún ayé 22 Ìgbé 2019 Oríṣun àwòrán, @RayceRollin Akọgun, Omo Ogun, Lyrical werey, Okunrin Ogun.
Ẹ sọkún bí ọmọge tí ó fi aṣọ ọ̀fọ̀ bora,nítorí ikú àfẹ́sọ́nà ìgbà èwe rẹ̀.
Lẹ́yìn tí wọn kó wọn lẹ́rú lọ sí Babiloni, Jekonaya bí Ṣealitieli, Ṣealitieli bí Serubabeli.
Ti Naijiria ba si kọ lati tẹle ofin tuntun yii, o ṣeeṣe ki wọn tun paṣẹ pe ki awọn asare ije wa to jẹ ọmọ Naijiria ma kopa mọ""."
Èèyàn 667 ló lùgbàdì àrùn Coronavirus ní Naijiria ní Ọjọ́ Ẹtì Báwó ni òògùn dexamethasone ṣe ń ṣiṣẹ́ lára Wo orin l'édè Yoruba àti Zulu tí Burna Boy fi fa ayélujára ya Kí ló dé tí Aàrẹ Buhari kìí fí í dá sí aáwò àwọn ọmọ ẹgbé APC?
Bakan naa ni gomina ana nipinlẹ Ekiti naa ni Makinde gbọdọ gba awọn asaaju ẹgbẹ PDP lawujọ kọọkan laaye lati maa sejọba lọ nipinlẹ koowa wọn.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Rape: Oluwaseun Osowobi ní Commonwealth fún lámì ẹ̀yẹ ọ̀dọ́ tó pegedé jùlọ ní 2018 Onimọ kan nipa ihuwasi ẹda, to tun jẹ ajafẹtọ ọmọde, Temiloluwa Morounkeji, lasiko to n ba BBC Yoruba sọrọ, sọ diẹ lara awọn apẹẹrẹ to ṣeeṣe ki iru ọmọ bẹẹ maa fihan, ti iya rẹ si gbọdọ se akiyesi.
    ‘n kò rí ààyè kọ̀wé púpọ̀ nínisì yìí,’
Ìfipábánilòpọ̀ kìí ṣe ìwà ọmọlúwàbí, àwọn òṣèré tíátà pariwo síta Iyabo Ojo, Toyin Abraham, Mercy Aigbe, ta làwọn òṣèrébìnrin yìí gbè lẹ́yìn lórí ọ̀rọ̀ ìfipábánilòpọ̀?
Oun ni egungun ẹja to n ha Trump lọrun ninu eto oṣelu Amẹrika lọwọ lọwọ bayii.
Ẹ so wọ́n mọ́ ọwọ́ yín gẹ́gẹ́ bí àmì, kí ẹ fi ṣe ọ̀já ìgbàjú, kí ó wà ní agbede meji ojú yín.
O ni boun ṣe kọkọ ri fidio naa tawọn si bẹrẹ si ni pe oun lori ẹrọ ibanisọrọ loun ti mọ pe oun ti rugi oyin lọwọ awọn ọmọ Naijiria.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ibadan-Ilesa Road: Àwọn olè Fulani ló ń jí ènìyàn, pànìyàn ní lọ́nà Ibadan sí Ileṣa Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Ibadan-Ilesa Road: Àwọn olè Fulani ló ń jí ènìyàn, pànìyàn ní lọ́nà Ibadan sí Ileṣa 14 Òkùdu 2019 Àìda márosẹ̀ Ibadan sí Iléṣà ló ń fa ìjínigbé àti ìdigunjalè - Àwọn awakọ̀ fárígá Iroyin lori eto abo to mẹhẹ ni opopona Ibadan si Ife fi lede wi pe awọn Fulani darandaran pa arinrinajo kan to n lọ si ilu Ibadan.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Lagos Building collapse: Aisha Buhari ṣàbẹ̀wò ṣàwọn tí ilé wó lù níléèwòsàn 17 Ẹrẹ̀nà 2019 Oríṣun àwòrán, Aishabuhari Àkọlé àwòrán, Ko din ni ogun eeyan to ba ijamba ile to wo ni ilu Eko naa lọ Aya aarẹ orilẹede Naijiria, Aisha Buhari ti sọ pe igbesẹ to tọ ni ijọba ipinlẹ Eko gbe, lati dena atunṣe ijamba ile to da wo ni agbegbe Itafaji ni ipinlẹ Eko.
 bí ẹnìkan bá ní òun ò bá ẹnikẹ ́ ni gbé , tí kò bá gbé nígbó , yóó wábi gbàlọ .
Bab-onírùngbọ̀n àti èmi náà sì ń tọ̀ ọ́ lọ.
Ẹ rant i wi pe South Africa lu Naijiria pẹlu ami ayo kan sodo ninu ifẹsẹwọnsẹ akọkọ awọn mejeeji ninu idije ti ọdun yii lorilẹede Ghana.
Laipẹ yii naa si ni Mompha koju iru ẹsun lilu jibiti ti wọn fi kan Hushpuppi, lasiko ti ajọ to n gbogun ti iwa ibajẹ ni Naijiria, EFCC, mu.
Saaju eyi, ni awon alamojuto eto idibo ti Stuart Mcghie dari won wa si ile akede lati kan si oludari
Ìyè yìí farahàn, a ti rí i, a sì ń jẹ́rìí rẹ̀.
Ìkáwọ́ wa ni gbogbo ilẹ̀ náà wà, nítorí pé à ń ṣe ìfẹ́ OLUWA Ọlọrun wa.
“Subscriber Identifier Module Card” gangan ni orúkọ rẹ̀ lẹ́kùúnrẹ́rẹ́.
"Àrídáju wá, a ri àwọn alùpùpù olówó ńla tó lé ẹ̀ẹ́dẹ́gbẹ̀ta tó wọ inú igbó náà, wọ́n di ẹru ìjà olóró àti òunjẹ wọ́n sórí rẹ̀.
Alukoro fẹgbẹ ọmọ Ilu Offa tẹlẹri, Olayemi Olaboye lo ṣalaye ọrọ yi fun ile iṣẹ BBC Yoruba ninu ifọrọwanilẹnuwo.
Oríṣun àwòrán, @DAWNCommission Ilana Iṣiṣẹ Amọtẹkun Gbogbo ipinlẹ lo da ni ikọ Amọtẹkun tirẹ wọn ko si ni re si ti ipinlẹ mii bii ki ọmọ ẹgbẹ Amọtẹkun kan re wa lati ipinlẹ Ondo lọ ṣiṣẹ ni Ekiti.
Agbebọn pa ọmọ ogun mejila Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ikọlu laarin awọn ọmọ ogun orilẹẹde Naijiria ati awọn agbebọn lariwa Naijiria ki se oun ajoji.
àwọn ọmọ Gasamu, àwọn ọmọ Usa, ati àwọn ọmọ Pasea, 
    Nígbà tí o tó ọjọ́ mẹ́fà lẹ́yìn èyí ti mo tún lọ sí ààfin ǹ jẹ́ kí n lọ bẹ ọba wo, bíbá tí mo bá a bà mi lẹ́rù lọ́pọ̀lọpọ̀, Ilẹ̀ẹ́gbóná ti bò ó, ṣe lo ń gbin ni ẹ̀ẹ̀kọ̀ọ̀kan, ìgbà tí mo kíi, kò lè dá mi lóhùn mọ́ àánú rẹ̀ sì ṣe mi.
 Ó tún jẹ ́ adarí àwọn obìrin ẹ ̀ gbẹ ́ òṣèlú náà tí ó sì maa ń wà ní gbogbo ìpàdé ẹgbẹ ́ náà .
Awa (ti ako mọ ibi awọn ọmọ wa wa) pọ gidigan.
South Africa: Oyún inú nínú ilé ìgbọ̀nsẹ ọkọ̀ bàálú tó fẹ rinrin àjò
Naamani, olórí ogun Siria, jẹ́ eniyan pataki ati ọlọ́lá níwájú ọba Siria, nítorí pé nípasẹ̀ rẹ̀ ni OLUWA ṣe fún ilẹ̀ Siria ní ìṣẹ́gun.
 Awọn iroyin kan sọ pe ni kete ti wahala #ENDSARS gba ọna miran yọ, ni Ahmed Tinubu ti salọ si ilu Paris, l'orilẹ-ede France."
Ni ọdun 2006 lo pada si fasiti ilu Ibadan lati lọ kẹkọ Diploma nipa imọ ẹkọ agba ati idagbasoke agbegbe, (Diploma in Adult Education and Community Development) Ọlanrewaju Omiyinka (Baba Ijeṣa) Oríṣun àwòrán, Olanrewaju Omiyinka/facebook Baba Ijeṣa kii ṣe alejo ni agbo ere sinima, paapaa julọ sinima ede Yoruba.
Lori oro awon akekoo ile-iwe Dapchi, Aare ohun fi idunnu re han pe awon omodebinrin naa ti darapo mo awon obi won.
Gígùn ilé tí Solomoni kọ́ fún OLUWA jẹ́ ọgọta igbọnwọ, ìbú rẹ̀ jẹ́ ogún igbọnwọ, gíga rẹ̀ sì jẹ́ ọgbọ̀n igbọnwọ.
Oríṣun àwòrán, CockFM Radio Ariwo 'ibi ni ile rẹ kii ṣe ilẹ Gẹẹsi' ni ọpọlọpọ awọn eeyan to tu sita wa wo agba ọjẹ akanṣẹ naa n pa, bi gbogbo wọn ṣe n da giiri lati baa ya fọto, ti wọn si tun wọ tọọ lẹyin lati aafin Elepe lọ si aafin Kabiyesi Akarigbo ti ilu Rẹmọ.
Wọ́n gbé orí rẹ̀, wọ́n gba ọ̀nà àfonífojì odò Jọdani lọ, wọ́n sì fi gbogbo òru ọjọ́ náà rìn.
Wọ́n ní etí, ṣugbọn wọn kò fi gbọ́ràn, nítorí pé ọmọ ọlọ̀tẹ̀ ni wọ́n.
Ilu Washington lorilẹ-ede Amẹrika ni wọn bi akikanju ọmọ Yoruba naa si, to si gbe awo orin akọkọ rẹ jade lọdun 2009.
Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Fídíò, Baby abandoned on dunmpsite: Mo ti bímọ mẹ́rin tẹ́lẹ̀ fún bàbá méjì nínú òṣí- Dupe Ogbomọṣọ4 Owewe 2020 Fídíò, Akomolede: Bolaji Faleke ni Olùkọ́ tó ń kọ́ wa ní àṣà oge ṣiṣe lórí BBC Yorùbá1 Owewe 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Siwaju sí i, láti ìgbà tí a ti yàn mí sí ipò gomina ní ilẹ̀ Juda, láti ogun ọdún tí Atasasesi ti jọba sí ọdún kejilelọgbọn, èmi ati arakunrin mi kò jẹ oúnjẹ tí wọ́n yà sọ́tọ̀ fún wa gẹ́gẹ́ bíi gomina.
O ni oun ko mọ idi to fi n na oun, bo tilẹ jẹ pe kii mu siga, kii mu igbo bẹẹ ni ori rẹ ko daru.
Oríṣun àwòrán, Others Bi awọn mọlẹbi ṣe n naka abuku si ijọba Gomina Seyi Makinde, naa ni ijọba n tako wọn pe awọn ko jẹbi ẹsun ti iyawo oloogbe Florence Ajimobi fi n kan ijọba pe, wọn ko fi apọnle to yẹ fun ọkọ ohun lẹyin iku rẹ.
Nígbà náà ni wọ́n tó pada lẹ́yìn àwọn eniyan Israẹli, tí wọ́n sì dáwọ́ ogun dúró.
O fi kun oro pe, “ mo fi asiko yii pea won adari wa lati se amulo awon ohun alumoni orile-ede yii, lati pese awon ohun amayederun fun awon ara-ilu”.
O ni olaju maa n fa omiya sugbon ijoba gbodo mura fun un.
A si le e sọ pe Ọlọrun lo fi ọna iṣẹ ere tiata han Opeyemi Ayeola, to fi di olokiki ati ilumọọka nidi iṣẹ naa.
Kíni ẹ̀yin mọ̀ nípa iṣẹ́ ọnà ti a fi ìṣó ṣe?
dìgbòlugi ń ran ènìyàn láti ara eranko míìràn .
 Erongba yi ni lati je ki gbogbo awon eniyan mo nipa ojuse ile-ise naa  lorile-ede Nigeria ,lojuna lati gbe ise wa denu ona awon eniyan wa labele,’ bi Akobundu se so.
”Oko epo robi kan, oko akero méjìdínlógún marun, oko akeru meji ati oko ayokele márùndínláàdọ́ta lo jona deeru.
Oloye Kamorudeen Okikola to jẹ aarẹ Agbekọya ni ki Malami ko ila kuro lẹkọ nitori pe ẹkọ ko kọ ila rara.
”Nígbà tí wọ́n sọ fún un pé Eliṣa wà ní Dotani, 
 Ẹ wo oju irin , o ti to ogbon odun seyin ti
Ni ọdun 2015 ni wọn fi ẹsun iditẹ mọ ijọba kan Nnamdi Kanu, o si ti lo odun kan ati abọ ni ahamọ.
Jeroboamu tún kọ́ àwọn pẹpẹ ìrúbọ sí orí òkè káàkiri, ó sì yan àwọn eniyan ninu gbogbo ìdílé tí kì í ṣe ìran ẹ̀yà Lefi, láti máa ṣiṣẹ́ alufaa.
Odebiyi: ìgbà gbogbo ni Bàbá mi ń polówó iṣẹ́ mi fáráyé
Ni owurọ kutu ọjọ Aje ni awọn olofẹhonu han naa tu jade sita, lati polongo pe ki ijọba orilẹede Naijiria wa nkan ṣe si eto aabo ati ọrọ aje to mẹhẹ.
Sari Van Veenendaal to jẹ adilemu fun America mọ iṣẹ rẹ bii iṣẹ.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Sunday Igboho yarí, ó fohùn ránsẹ́ sáwọn èèyàn tó ń pẹ̀gàn rẹ̀ Àwọn iléesẹ́ abáni fi ẹrù ránṣẹ bẹ̀rẹ̀ ìyaṣẹ́lódì tako àfikún owó Nipost Ìkúnlẹ̀ ló bá dé fún Oshiomole, Ize-Iyamu láti bẹ̀bẹ̀ fún ìbò aráàlú ní Edo Sunday Igboho yari, o fohun ransẹ sawọn eeyan to n pẹgan rẹ Ikú Barakat Bello ní Akinyele gbé aláàánú pàdé ẹ́bí rẹ̀ A ṣe ọdún Ọ̀ṣun lásìkò yìí láti kó Coronavirus lọ ni - Ooni ṣàlàyé Wo àwọn nǹkan tí o kò mọ̀ nípa 'Church of Satan' Ọrọ naa da bi igba ti wọn ko fẹ ki awọn ọdọ ri isẹ ṣe ni.
Ahọ́n iná ń yọ lẹ́nu rẹ̀ bí iná tí ń ta jáde,bẹ́ẹ̀ ni ahọ́n iná ń yọ lálá.
 nínú oṣù yí kan náà ni àwọn ọlọ ́ pàá méjì kan náà tún tókú lá lọ ́ wọ ́ ìbọn aníní nígbà tí wón ń gbìyànjú láti da ọkọ ́ rẹ ̀ dúró ní ojú pópó.
"Lọ f'ọka, lọ f'ọkọ emi nikan ni mo n foju wina rẹ pẹlu atarodo loju mi bayii o, kaluku yin wa nibi tẹẹwa bayii ẹ n gbadun aye yin Tiyin naa fẹrẹ de, ṣe ẹ gbọ"" Afi suuru."
"Wọn fẹ ki o kuro nibi ni' "" Oríṣun àwòrán, Christian Concern Àkọlé àwòrán, Ninu fọnran fidio to gbode Paitọ Ilesanmi n bẹ awọn ọlọpaa lati ma ṣe gba bibeli rẹ Nigba ti ọgbẹni Ilesanmi fẹ mu bibeli rẹ, ọlọpaa naa sọ fun un pe ''o ba ti ro o daadaa ki o to bẹrẹ si ni sọ ọrọ abuku nipa ẹlẹsin miran'' Ọgbẹni Ilesanmi ni lootọ lohun sapejuwe ẹsin Islam gẹgẹ bi ohun ti ko bojumu amọ ero ọkan tohun ni gẹgẹ bi Kristẹni kii ṣe pe ohun bẹnu atẹ lu awọn musulumi."
Tí a fiṣọwọ́ ní 19:03 15 Sẹ́rẹ́ 202119:03 15 Sẹ́rẹ́ 2021 Ẹ ṣọ́ra o, ayédèrú abẹ́rẹ́ àjẹsára COVID-19 gbòde ní Nàìjíríà, NAFDAC pariwo síta Lati igba ti ọwọ keji ajakalẹ arun naa ti jade ni ilakaka fun abẹrẹ ajẹsara COVID-19 ti gbodeKà Síwájú Síi next Article share tools Facebook Twitter ṢàpínlòView more share options Share this post Copy this linkKà síwájú síi nípa àwọn ìtọ́kasí wọ̀nyí.
Mò kabamọ́ ìṣẹlẹ tó wáyé láàárín èmi àti Agbowu,màá tẹlé àṣẹ lọ rọọ́kún nílé-Oluwo
Segalink ni awọn to n sagbẹtẹru fun Endsars naa, paapaa awọn to wa ni oke okun, kọ lati gbọ ọrọ lẹnu ijọba, eleyii ti oun ri gẹgẹ bi iditẹ mọ ijọba.
Ṣùgbọ́n níwọ̀n bí ó ti jẹ́ pé bàbá mi fẹ́ wí pé dandan ki n lọ sí ibib tí òun rán mi, kò sí ohun tí èmi àti ìyá mi lè ṣe.
Awolowo ni ọpọ gba pe oun ni baba iṣelu ni eyi ti wọn ṣi n ri aritọkasi iṣẹ to ṣe bii NTA, Liberty Stadium ati bẹẹ bẹẹ lọ.
"Oríṣun àwòrán, @Dino Àkọlé àwòrán, Dino Melaye rèé lẹ́yìn ti ó jábọ nínú mọto ọlọpàá Oríṣun àwòrán, @Dino Àkọlé àwòrán, Sẹnatọ Dino Melaye nínú ilé aṣòfin, O kuku mura bii ti àwọn eniyan ilẹ̀ Arewa (Hausa) Oríṣun àwòrán, @Dino Melaye Àkọlé àwòrán, Sẹnatọ Dino Melaye wọ aṣọ ìkẹ́kọọ gboye jáde wa si ipade ile igbimọ aṣofin, lásìkò tí wọ́n ni ko gboye jade fasiti Oríṣun àwòrán, @Dino Melaye Àkọlé àwòrán, Sẹnatọ Melaye ló tun ju ẹ̀gbà ọrun ti awọn kan ṣapejuwe pe ""O make sense"" lori ayelujara lọ si ilé aṣòfin Oríṣun àwòrán, @Dino Àkọlé àwòrán, Ìmúra Dino Melaye tun rèé bi Báàlẹ ìlú tabi alade ti ko fẹ mura tan pẹlu irukẹrẹ lọwọ Oríṣun àwòrán, @Dino Àkọlé àwòrán, Nínú ilé ìgbìmọ asòfin, àwọn ènìyàn máa n ri Dino Melaye àti Ademola Adeleke bii Amuludun, Bi ẹnikan ṣe jẹ olórin, bẹ́ẹ̀ ni ẹni kan jẹ oníjó Oríṣun àwòrán, @Dino Àkọlé àwòrán, Àwọn ǹkan málegbàgbé ti Dino Melaye ti ṣe níle aṣòfin àgbà Dino ní ìyàwó ni Adeyemi jẹ́ f'óun lágbo òṣèlú, Adeyemi l'ọ́mọ ọ̀dọ̀ ni Dino jẹ́ Èso Apple tuntun tí ẹ lè fi pamọ́ fún ọdún kan ti wọ ọjà Kò sí súnkẹrẹ-fàkẹrẹ mọ lópópóna márosẹ̀ Eko si Ibadan Àwọn agbébọn pa ènìyàn mẹ́rinlá lásìkò ìjọsìn Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, FUTA: Àwọn mẹ́jọ ló ṣíná ìyà fún Bolu ní FUTA Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?"
Àwọn orílẹ̀-èdè tí wọn kò mọ̀ ọ́,ni kí o bínú sí kí ó pọ̀,ati àwọn tí wọn kì í jọ́sìn ní orúkọ rẹ;nítorí pé wọ́n ti jẹ Jakọbu run,wọ́n jẹ ẹ́ ní àjẹrun patapata,wọ́n sì sọ ibùgbé rẹ̀ di ahoro.
Ní ọjọ́ keji, Paulu bá lọ sọ́dọ̀ Jakọbu.
Àkọlé àwòrán, Gbajugbaja osere Odunlade Adekola naa peju sibi ayẹyẹ naa Àkọlé àwòrán, Igbakeji Gomina Otunba Bisi Egbeyemi ati Iyawo rẹ n yọ sẹṣẹ Àkọlé àwòrán, Gomina ipinlẹ Eko Akinwumi Ambode naa yọju Àkọlé àwòrán, Babajide Sanwoolu naa wa ba Kayode Fayemi yọ BBC News, Yorùbá Ìdí tí ẹ fi le è nígbàagbọ́ nínú ìròyìn BBC Ìlànà Lílò Nípa BBC Òfin Àṣírí Cookies Kàn sí.
Tottenham tẹ̀yìn gbéru Ajax Aṣọle wọn Neil Etheridge fí han pe bi àwọn tilẹ̀ bá wọn lalejo ó kù nibọ̀n ń ró lọ̀rọ̀ àwọn ló ba n mú gbogbo ìgbìyànju Manchester United láti gba góòlù sáwọn di pàbó.
Eeeyan daada ni wọn'' Adekunle sọ fun ile isẹ BBC Yoruba wi pe, gbogbo eeyan to mọ Bunmi Ojo, to jẹ Komisana to n soju ipinlẹ Ekiti ninu ajo to n risi igbesẹ aparo kan ko gbọdo ga ju ọkan lọ lorileede Naijiria, (Federal Character Commission) ni iroyin iku rẹ dun.
Ṣugbọn ẹ̀yin yóo gba agbára nígbà tí Ẹ̀mí Mímọ́ bá bà lé yin.
ijoba apapo faye gba ipese ina mona-mona ni awon ipinle ati ijoba ibile lorile
Lọdun 2020, isinmi kuro lẹnu iṣẹ maa wa fun awọn eniyan Naijiria lọjọ kinni, oṣu kẹwaa lati fi sami ominira orilẹ-ede wa.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Osun tribunal: Ta ni ilé ẹjọ́ yóò gbẹ́ adé ìdìbò gómìnà ìpínlẹ̀ Ọṣun fún?
Oríṣun àwòrán, Alaafi ObaAdeyemi III Ṣaaju eyi, awọn ọbalaye bii Ọọni, Oluwo ati Olugbo ni wọn ti gbe igbesẹ lori igbayegbadun awọn eeyan wọn lasiko Coronavirus yii.
Oríṣun àwòrán, Ayo Ademokoya/Facebook Eekan Afenifere fikun ọrọ pe, Obasanjo tun ṣe awada pẹlu Gani pe o gbọdọ fún oun lowo oye to jẹ lẹyin ti oun yanju ọrọ naa tan.
ko si ija abi aawọ laarin wa, nse la n gbe bii tmọ-tiya.
Ero nipa iwa Abosi ati ọtẹỌkan lara awọn gbaju-gbaja ninu iwa yii ni TB Joshua, to sọ losu keji, odun pe ẹmi ọrun ru oun soke lati sọ aṣọtẹlẹ pe coronavirus yoo ko ẹru rẹ pada sibi to ti wa nigba ti yoo ba fi di ọjọ kẹtadinlogbọn, osu Kẹta.
Àkọlé àwòrán, Awujalẹ ilẹ Ijẹbu, Ọba Sikiru Adetọna ni nibi ti ọrọ idagbasoke ilẹ Ijẹbu de duro bayii, ọlanrewaju lo yẹ ki ẹni ti wọn yoo fi jẹ Ọba nibẹ o jẹ Ohun ti ọpọ n bi ara wọn leere bayii ni pe, abi baba ti n gbaradi silẹ fun didarapọ mọ awọn alalẹ ilẹ naa ni?
Akojọpọ iroyin tati ọwọ Anthony Zurcher a Tara McKelvey Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 3 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 5 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Ipo minisita fun akanṣe iṣẹ lo wa ti iditẹ gbajọba akọkọ fi waye ninu oṣu Kini, lọdun 1966 Lẹyin ogun abẹle to waye, Ọgagun to wa ni iṣakoso nigba naa, Yakubu Gowon, fi Shagari jẹ Kọmisana ijọba apapọ fun idagbasoke eto ọrọ aje, imupadabọsipo ati atunto laarin ọdun 1970 si 1971.
O ni afojusun oun ni lati di aṣaaju fawọn ọdọ binrin to ṣẹṣẹ n dide ninu ìja jija.
O tun tẹsiwaju pe ibasepọ to wa laarin orilẹ ede Naijiria ati orilẹ ede China jẹ ohun ti o dara, paapaa julọ fun itẹsiwaju orilẹ ede Afirika.
"Moshood ni, ""Ni ọjọ kọkanlelogun oṣu keje, ọdun 2017, ẹka ọtẹlẹmuyẹ ti ọlọpaa ni Ipinle Ọṣun gbọ wipe Sẹnetọ Ademola Adeleke ati Sikiru Adeleke n ṣe magomago idanwo ni ile iwe girama Ojo/Aro ni Osun."
"Ìjọba orílẹ̀-èdè Burundi ti kàn sí wa lórí ìfọ̀rọ̀wánilẹ́nuwò kan tí ilé iṣẹ́ BBC ṣe ni èdè Faranse lórí rédíò.
sekupa awon afehonu han nipinle Zamfara” lori ero  elombah.
 wọ ́ n máa ń kọ ọ ́ tí olórí orílẹ ̀ -èdè mìíràn bá wá bẹ ̀ wọ ́ n wò .
Ranieri ti fi iko Leicester sile.
Mo rí ọ̀pọ̀lọpọ̀ nkan ti ń kó ronú si, mo mọ ọ̀pọ̀ nkan ti mi ò mọ, mo sì bá ara mi ni aaye ti ń kó lérò pé mo lè bá ara mi, mo sì ń rọ àwọn olórí wa lati yí ìwà padà"" Wo àwọn òfin tí ìjọba ìpínlẹ̀ Eko gbé jáde fún àwọn tó n padà sẹ́nú iṣẹ́ lẹ́yìn k'ónílé o gbélé Wo ohun tó yẹ kí o mọ̀ nípa òfin NCDC tó ń dá rògbòdìyàn sílẹ̀ Àjọ tó n mójútó ìpèsè òògùn ní America ti fọ́wọ́ sí lílo òògùn Ebola fí tọ̀jú Coronavirus Àwọn ọlọ́pàá wú òkú akẹ́kọ̀ọ́ Fásitì Uniport mẹ́ta tí àwọn ajínigbé sin Ká má ri!"
"Mo ti ba ọga agba ileeṣẹ ọlọpaa sọrọ lori rẹ, aarẹ pẹlu nreti ẹkunrẹrẹ abọ lori awọn ohun to ti ṣẹlẹ, awọn ohun ti a ti ri nitori fidio ti o ti jade lori wọn ko kere rara.
Ó sì kígbe pé, “Mo rí àwọn ọkunrin kan tí wọ́n ń gun kẹ̀kẹ́ ogun bọ̀.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Premier League: Everton dín'yà fún Chelsea pẹ̀lú àmì ayò 2-0 17 Ẹrẹ̀nà 2019 Oríṣun àwòrán, Twitter/Chelsea FC Àkọlé àwòrán, Premier League Ẹgbẹ agbabọọlu Everton fẹyin Chelsea gbo lẹ ninu idije Premier League eleyi to jẹ ohun iyalẹnu.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, BIAFRA at 50: Ìhàlẹ̀ ológun ni Gowon ni ká kọ́kọ́ fi bẹ̀rẹ̀- Aladejẹbi Bakan naa, gomina ipinlẹ Osun, Gboyega Oyetola sọ pe ipinnu lati da ikọ Amotekun silẹ jẹ ajọsọ laarin awọn gomina mẹfa to wa ni ilẹ Yoruba.
Eliṣa dáhùn pé, “OLUWA ti fi hàn mí pé yóo kú, ṣugbọn lọ sọ fún un pé yóo yè.
Ọba bá pada lọ sí ààfin rẹ̀ ní Samaria, pẹlu ìpayà ati ìrẹ̀wẹ̀sì ọkàn.
Ọgbẹni Eyo sọ pe Minisita ti kọkọ sọ pe oun ti lọ si ipinlẹ bi mẹfa tẹlẹ, lati wo awọn iṣẹ akanṣe ti awọn gomina naa n se.
Aṣedanwo yoo fi ọrọ aṣiri (profile code) naa han nibi to ti fẹ gba fọọmu.
 bí a bá fifúnni , ìwọ ̀ n egbògi náà méjì ni a dámọ ̀ ràn , bẹ ̀ rẹ ̀ láti ìgbà tí ènìyàn bá ti ju ọmọ ọdún kan lọ .
Iwa yii ti sọ ọ di mọlumọka lawọ abule ṣugbọn ko ri bẹẹ nigboro nibi ti ọpọlọpọ awọn alatako rẹ n gbe.
Wọ́n ní, “Dandan ni pé kí á kọ àwọn tí kì í ṣe Juu tí ó bá fẹ́ di onigbagbọ nílà, kí á sì pàṣẹ fún wọn láti máa pa Òfin Mose mọ́.
Mo bá yipada láti wo ẹni tí ń bá mi sọ̀rọ̀.
Ọpọ lo n kọminu lori ede Yoruba ati bi ti yoo de duro nigba ti a o ba fi ri asiko diẹ si.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Kí ló wà nínú Tea tí Abiola mu?
Ọmọ ọkọ ni àwọn ọmọ ìlú Ìjẹ̀bú - Jẹ̀ṣà ní tòótọ̀.
Abidoni ni àkọ́bí rẹ̀, lẹ́yìn náà ni ó bí: Suri, Kiṣi, Baali, Neri, ati Nadabu; 
Ẹ óo pín in fún ara yín ati fún àwọn àlejò tí wọn ń gbé ààrin yín, tí wọ́n sì ti bímọ sí ààrin yín.
Bẹ́ẹ̀ bí òsùpá kò bá tàn kárí ayé láti alède ọ̀run
“Nítòótọ́, a ti di aláìmọ́ nítorí pé a fi ọwọ́ kan òkú, ṣugbọn kí ló dé tí a kò fi lè mú ọrẹ ẹbọ wa wá fún OLUWA gẹ́gẹ́ bí àwọn arakunrin wa?
England kéde ìséde ọ̀sẹ́ mẹ́rin míràn láti dẹ́kun ìtànkálẹ̀ Covid 19 Ènìyàn méjì pàdánù ẹ̀mí wọn nínú ìjàmbá ọkọ̀ tó wáyé ní Abúlé Ẹ̀gbá, ní ìpínlẹ̀ Eko Ta ni Wolii Olapade Agoro tó re ibi àgbà ń rè tí ayé ń pariwo rẹ̀ yìí?
Mufutai, to jokoo lori ibusun pẹlu ọpa lọwọ ni ibi ti wọn ti n tọju mi ni mo wa, n ko ni alaafia rara, awọn ẹgbẹ ti mo n ṣe ati awọn ọrẹ ti gbinyanju, ti mo si ti ta dukia mi tan."
Ìjọba Kano sọ pé Gómìnà kọ́ ló wà nínú fídíò rìbá gbígbà naa.
Ibukun OLUWA ní ń mú ni í là,kì í sì í fi làálàá kún un.
Wo ìdí tí Tẹni, ọ̀dọ́mọdé olórin obìnrin kìí fi ń ṣí ìhòhò rẹ silẹ̀ Ẹ lo ìfẹ̀họ̀núhàn #EndSARS lati fí tún gbogbo ohun tó bàjẹ́ ṣe ní Naijiria- Pásítọ̀ Sam Adeyemi Ẹ wo èrò bìbà níbi ìwọ́de #EndSARS ní ìlú Ibadan Ẹfunsetan Aniwura, ọmọ Ẹ̀gbá tó di akíkanjú obìnrin nílẹ̀ Ibadan Kíni ìyàtọ̀ tí yóò wà láàrin SARS àti SWAT?
Lórí ìmọ̀ràn Sunday Igboho, Ẹlẹbubọn ní yóò dára kí Yorùbá padà sí àmúlò èròjà ìbílẹ̀ fún ààbò Àwọn ọ̀nà ti ẹ lè gbà kojú omí yale àgbára ya sọọbù Ìpínlẹ̀ Ogun, Eko ti gbáradì fún ẹ̀kún omi yalé Aarẹ Buhari ni ibanujẹ lo jẹ fun oun pe ẹmi awọn akọgun to lọ lẹnu isẹ nitori naa lo se pe fun iwadii lẹsẹkẹsẹ lori isẹlẹ naa.
'Street Gospel' tí mò ń kọ, Ọlọ́run ń fi tún ayé àwọn 'Boys' ṣe gan - Testimony Jaga Àlàyé rèé lóríi ìdí tí wọ́n fi ń pe aya ní ìyàwó Àwọn Ọba Yorùbá kan rèé tí wọ́n rọ̀ lóyè, tí ọba míràn jẹ lójú ayé wọn Ìtàn Àrọ̀gìdìgbà jẹ́ kí ń rò pé bàbá mi yan Yemọ̀ja ní àlè - Ọmọ Fagunwa Awọn oye ati ami ẹyẹ ti wọn fi da Oyinkan Abayomi lọla: Oyinkansola Abayomi ni awujọ mọ riri rẹ, ti wọn si fi oniruuru oye ati ami ẹyẹ da lọla.
Oríṣun àwòrán, Satguru Maharaj Kini ile iṣẹ Ọlọpaa ipinlẹ Oyo sọ lori ẹsun Guru yii?
Paulu Ṣe Ìdájọ́ lórí Ìwà Ìbàjẹ́.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Idunu ṣubu layọ fun Andy Ruiz Gbogbo rẹ daru mọ Joshua loju ninu ija ọhun debi wi pe, o n beere lọwọ olukọ rẹ pe ki lo de ti ara oun fi n ṣe bakan, ati pe, nigba wo nija naa yoo pari lẹyin ti Ruiz rọjo ẹṣẹ le lori.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ooni of Ife: Àwòrán ọmọ mi kọ́ lẹ ń rí lórí ayélujára o, ọmọ ọ mi ń ṣètùtù lọ́wọ́- Ọba Adeyeye Ogunwusi 24 Bélú 2020 Oríṣun àwòrán, @ooni Èyí ni ohun tí Ọọ̀ni sọ nípa Àrẹ̀mọ rẹ àti ètùtù tó ń ṣe lọ́wọ́ Laipẹ yii ni awọn eeyan kan n gbe fọto kan kiri lori ayelujara tiwọn kan ni o jẹ ti Arẹmọ tuntun ti Ọọni Ile Ifẹ, Ọba Adeyẹye Ogunwusi ṣẹṣẹ bi Amọṣa, Kabiyesi Ọọni ti pariwo sita pe aworan naa kii ṣe ti Arẹmọ oun.
A wá gbé àwọn mejeeji láàyè, a sọ wọ́n sinu adágún iná tí a fi imí-ọjọ́ dá.
Minisita so pe aare Buhari ti se gudu-gudu meje, yaya mefa, nitori naa , o pegede fun idibo  aare leekeji .
ṣe ni a bẹ àwọn iwin títí kí wọ́n tó dà fún wa, nítorí kò ríran mọ́, ṣe ni à ń fà á lọ́wọ́ kọjá lọ láàrin ìtàkùn àti igi gbogbo tí o kún ojú ọ̀nà wa.
Ẹní mú kóngò dání ló mò èdè àyàn.
Mo bá yọ ọ́ létí kí ng fi lè gbọ́'hun tí arúgbó nwí.
T'ẹrin t'ayọ ni Aarẹ Buhari fi ba t'ọkọ t'aya ya aworan pẹlu awọn obi wọn.
Ambode ní kò sí gìrì, eré ọwọ́ lásán ni EFCC ń ṣe Ìjìyà ń bẹ fún àwọn ti adé ọ̀rọ̀ náà bá ṣí mọ́ lóri -Ọga àgbà FRSC Ni afikun, iya Osumare sọrọ lori ohun toju awọn oṣere n ri ati oju ọlẹ, aṣẹwo ati oniranu ti wọn fi n wo oṣere lati aye atijọ.
Iroyin lawọn iwe iroyin abẹle n sọ pe lasiko iṣejọba oloogbe Oluṣẹgun Agagu ni wọn ti fi owo naa pamọ si aṣuwọn banki igbalode kan.
awon agbofinro , ile-ise ologun ati awon ẹsọ oju ona ko gbeyin nibe .
Ọmọ ilé ẹ̀kọ́ gíga ní ẹ̀wọ̀n fún kíkọ ìkọkúkọ sí orí àwòrán Ààrẹ .
Báyìí ni ìyá mi sọ, nígbà tí ó sì parí ọ̀rọ̀ rẹ̀ tán, ó mú àkàrà ńlá kan fún mi, ó wí pé: wò ó àkàrà òde ọ̀run ni mo fún ọ nì, máa jẹ ẹ́ nínú ìrìnkèrindò rẹ, eléyìí dùn ju àkàrà àwọn ọmọ ènìyàn lọ, kò lè tán bí ó ti wù kí o jẹ̀ ẹ́ tó, ṣùgbọ́n lọ́jọ́ tí o bá padà dé ilé, n ó gba ìyókù lọ́wọ́ rẹ.
Aicha wa lọmọ ọdun marun nigba ti iṣẹlẹ yii ṣẹlẹ ti eeyan lee ni ọmọde o mọ nkankan ṣugbọn lati igba ti oun gan ti wọ ile ọkọ bayii, ti ko gbọ pa tabi gbọ po, ni omije ti bẹrẹ si ni bọ ni oju rẹ́ ti irẹwẹsi si n wọ ọ lọkan.
Ajọ to n gbogun ti iwa ijẹkujẹ lorilẹede Naijiria, EFCC gbe Mahmood Ahmadu ati ileeṣẹ rẹ tẹlẹ, Drexel Tech lọ si ile ẹjọ lori ẹsun gbigbọna ẹburu ko owo lọ soke okun.
Lionel Messi, gbajúgbajà agbábọ́ọ̀lù àgbáyé, ti rí àṣẹ àmì ìdánimọ̀ gbà nílé ẹjọ́ EU General Court.
Ènìyàn 26,000 ni àìsàn jẹjẹrẹ ń pa lóòjọ́ Kí ni àyájọ́ ‘Má wọ kọ́mú’ wà fún?
Òun ni ààlà ilẹ̀ àwọn ọmọ Juda gẹ́gẹ́ bí iye ìdílé wọn.
"Ìmáàmù àgbà ilẹ̀ Egba Sheik Liadi Orunsolu ti jáde láyé lẹ́ni ọdún 98 A óò dá ẹnikẹ́ni tó bá gbé ìwé àti àṣírí ìjọba síta lórí ayélujára lọ́nà àìtọ́ dúró - Ìjọba àpapọ̀ Ènìyàn 229 ló tún ṣẹ̀ṣẹ̀ ní ààrùn Covid-19 ní Nàìjíríà Èrò ọmọ Nàìjíríà sọ̀tọ̀tọ̀ lórí fàákájáa láàrin Abike Dabiri-Erewa àti mínísítà ètò ìbárẹ̀nisọrọ̀, Oríṣun àwòrán, @allafrica Agbẹnusọ ajọ NSCDC ipinlẹ Ondo, Femi Omole ni ""Ọkunrin naa sẹ pe oun ko mọ ohunkohun nipa iṣẹlẹ naa, ṣugbọn ayẹwo awọn dokita ni ile iwosan ijọba apapọ, FMC fi han pe wọn ti ba awọn ọmọ ọhun lopọ."
''Inu mi dun pẹlu ọrọ ti Abẹnugan Ile Igbimọ Aṣofin sọ nipa iṣẹlẹ to waye ni Lekki, amọ o ba oun ninu jẹ pẹlu bi awọn ọmọ Naijiria ṣe n ṣepe, ti wọn tun lo ji ọpa ọba gbe laafin Ọba Ilu Eko.
Ọpọ awọn eeyan lo n ranti ọjọ lori awọn iṣẹlẹ apanilẹrin to ti ṣẹlẹ si wọn sẹyin.
Koda, ọrọ naa kan ọgagun agba Sani Abacha ati gomina Banki apapọ nigba naa, Alhaji Abdulkadir Ahmed.
Agbẹnusọ ileeṣẹ ọlọpaa nipinlẹ Katsina, Gambo Isah ni iṣẹlẹ naa waye ni agbegbe Kofar Kaura Layout, nipinlẹ Katsina.
Awolowo jẹ ẹni to nifẹ orilẹ-ede yii lọkan, to si ṣe aṣeyọri gẹgẹ bi olori ẹkun iwọ oorun orilẹ-ede Naijiria nipa ṣiṣeto ẹkọ ọfẹ ati ilera ọfẹ atawọn nkan miran.
Ojú kan tí gbogbo ènìyàn dúró sí ti kún.
Tí mo bá kú lónìí, Pásítọ̀ Ibiyeomie ló pa mi - Daddy Freeze kébòòsí Oríṣun àwòrán, Others Lẹ́yìn ti orí ayélujara gbóná janjan lọjọ Aje lórí gbómisí-omí-otó láàrin Ifedayo Olarinde tí gbogbo ènìyàn mọ̀ si Daddy Freeze àti Pásítọ̀ Ibiyeomie, Daddy Freeze ti fèsì sí ọ̀rọ̀ pásítọ̀ náà.
Ọdun 1970 ni okiki Iṣọla Oyenusi kan gẹgẹ bii adigunjale, to si n da igboro ru lẹyin ogun abẹle to pari, to si n pa eeyan kukuru ati gungun lọsan ati loru, ti kii si jẹ ki awọn eeyan to ba ja lole gbe ile aye di ọjọ keji Oyenusi ati awọn ikọ adigunjale rẹ to jẹ ẹlẹni mẹfa, ni orukọ wọn n jẹ Joseph Osamedike, Ambrose Nwokobia, Joel Amamieye, Philip Ogbolumain, Ademola Adegbitan ati Stephen Ndubuokwu.
Minisita fọrọ ilẹ okeere ni Ilẹ Gẹẹsi, Boris Johnson ti kọ iwe fi ipo rẹ silẹ.
Ninu oro iyanju naa, atejade ohun tun tesiwaju pe, ki awon omo orile-ede yii jawo ninu iwa tita ibo lasiko idibo.
Wo àwọn oúnjẹ márùn ún tó ń mú kí àtọ̀ ọkùnrin dára síi Wo àwọn Ọba aládé méje tó jẹ́ obìnrin nílẹ̀ Yorùbá Ọmọ ẹgbẹ́ òkùnkùn ṣoro ní Ijebu Ode, ọ̀pọ̀ ẹ̀mí sọnù Ara mi rẹwà ló jẹ́ kí n máa ṣí ara sílẹ̀- Victoria Kolawole Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ojú mi ti rí lọ́pọ̀ lọpọ̀, àmọ́ mo dúpẹ́ pé mo ti pé ọdún márùn ún lórí oyé- Ooni Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Badirat Ajoke sọ pé òun fínnú-fíndọ̀ fi ààfìn Oyo sílẹ̀ ni, wọ́n kò lé òun9 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Murder In Ibarapa: Aborode tó tún jẹ́ olóṣèlú kàgbákò ikú òjijì lọ́nà oko14 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Victoria Kolawole: Òṣèré tíátà Yorùbá ní òun kò tíì ṣe ìgbéyáwó àmọ́ òun kò wá ọkọ''9 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Anthony Joshua vs Pulev highlights: Ẹ̀bùn ọdún Kérésìmesì ni àseyọrí Joshua lẹ́yìn tó na Pulev lálùbolẹ̀ - Dapo Abiodun14 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Ronke Odusanya sọ̀rọ̀ lórí ìròyìn tó ní ó ti jẹ bàbá ọmọ rẹ̀, Jago run9 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Fídíò, Omolola Arohunmolase Welder: Mo ti fí iṣẹ́ 'Welder' gbayì láwùjọ, tó mo fi tọ́ ọmọ yanjú9 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Thiago Alcantara, gba ami-ayo kinni wole niseju mejidinlogun saa akoko ifesewonse naa lati fopin si ireti  Besiktas, bo ya won le pegede siwaju si.
"Àwọn ọ̀dọ́ ń lu pọ̀ mọ́ ohun mímu ẹlẹ́rìndòdò, tàbí kí wọn da ìgò rẹ̀ kọnu tààràtà ní ""agbo ìpéjọpọ̀ oògùn ikọ́ olómi."
OLUWA bá sọ fún mi pé, 
ti awon ọdọ  ilu naa bere ifẹhonuhan.
 ní bíi 2009 , orílẹ ̀ èdè tó fi gbígba àjẹsára yíi lóòrèkóòrè sí ètò wọn jú 130 .
"Tolulope Arotile: Ọ̀rẹ́ Tolu ṣàlàyé bí ìjàmbá ọkọ̀ tó ṣekúpa á ní Kaduna ti ṣẹlẹ̀ Àlàyé rèé lórí bí wọ́n ṣe pa Ebila, olórí àwọn ""One million boys"" n'Ibadan Sotitobire: Ẹlẹ́rìí mẹ́rìn ló tẹ̀lé Alfa Babatunde wá síwájú ilé ẹjọ́ lonìí Oríṣun àwòrán, OTHER Ọmọ bibi ilu Ibadan ni Abiola Ebila, ile ẹkọ girama St Lukes to wa ni Molete nilu Ibadan si lo ti kawe, lati ẹni ọdun mejidinlọgbọn si lo ti n dari ẹgbẹ naa."
Ọlọwọ ti ilu Ọwọ waja ni Ọjọ Kejidinlogun, Osu Kẹrin, ọdun 2019 ni ẹni ọdun 77.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Paul Biya: Kìí ṣèpàdé pẹ̀lú àwọn mínísítà rẹ̀, ilé ìtura ní Switzerland ló ń gbé Leocadia Bongben BBC News Pidgin, Cameroon 6 Bélú 2018 Oríṣun àwòrán, AFP Aarẹ orilẹede Cameroon, Paul Biya, yoo ṣe ibura wọle fun igba keje ni ọjọ Iṣẹgun, ọjọ kẹfa, oṣu Kọkanla.
Dilibe Onyeama, tii se ilumọọka onkọwe lorilẹede yii, tun jẹ ẹgbọn Minisita fọrọ ilẹ okeere nil wa bayii, Geofrey Onyeama.
Orí mi wú, Joke Silva kọ ewì ìfẹ́ lọ́jọ́ ìbí Olu Jacobs Ìgbín ní èmi àti ìyá mi máa ń he kiri, ká tó lee jẹun - Lizzy Anjọrin Adeleke ló ní ọmọ ẹgbẹ́ tó pọ̀jù l‘Ọṣun, nipò gómìnà ṣe tọ́ si ní 2022 - PDP Ọṣun Ìjọba mi ṣetán láti mú àgbéga bá ètò ààbò l‘Ọyọ - Seyi Makinde Ẹwẹ, Pamela Akinboboye jẹ́ onímọ̀ nipa ìṣesí, o tẹnu bọ'rọ lori ohun ti eeyan le ṣe lati gbadun alagbatọ ọmọ rẹ.
Siwaju si, o wipe obinrin jẹ ẹni to le boju to ohun gbogbo.
Oríṣun àwòrán, Ojude Oba Facebook Awọn ohun to yẹ kẹ mọ nipa ọdun Ojude Ọba: Afihan aṣa adayeba ati ajogunba wa lọna to yaayi: Afojusun ọdun Ojude Ọba ni lati se amugbooro awọn aṣa, ajogunba wa ati awọn ise adayeba ọmọ ṣa, ajogunba wa ati awọn ise adayeba ọmọ Yoruba.
ní Sanoa, ati Adulamu, ati àwọn ìletò àyíká wọn, ní Lakiṣi ati àwọn ìgbèríko rẹ̀, ati ní Aseka ati àwọn ìletò àyíká rẹ̀.
Ṣugbọn ọ̀run gan-an ni ó wọ̀ lọ, nisinsinyii ó wà níwájú Ọlọrun nítorí tiwa.
Ìbálòpọ̀ ọ̀lọ́jọ́ méje mú kí ilé ẹjọ́ tú ìgbéyàwó ọdún mẹ́wàá ká ní Ibadan Fatai Rolling Dollar, Ọmọ ìdílé oyè tó gbé igbá orin tí Ebenezer Obey ń ṣiṣẹ́ lábẹ́ rẹ̀!
eleto idibo ,Independent National Electoral Commission (INEC), ojogbon Mahmood Yakubu,
Nítorí Ọlọrun tí ó ní kí ìmọ́lẹ̀ tàn láti inú òkùnkùn, òun ni ó tan ìmọ́lẹ̀ sí ọkàn wa, kí ìmọ́lẹ̀ ìmọ̀ ògo Ọlọrun lè tàn sí wa ní ojú Kristi.
O ṣàìgbọràn sí àṣẹ OLUWA, nítorí pé, o kò pa gbogbo àwọn ará Amaleki ati àwọn nǹkan ìní wọn run.
 “ko yẹ ki ibo jẹ ,bi o-ba-paa, bi –o –ba buu
Heṣiboni, ati Jaseri pẹlu àwọn pápá ìdaran tí ó wà ní àyíká wọn, gbogbo wọn jẹ́ ìlú mẹrin.
Lose to koja ni, Aare Buhari kede pe osu kejila ni yoo maa je” ayajo odun eto ijoba tiwa-n-tiwa” lorile ede Naijiria.
Nibo ni @Mbuhari ti ri onirọ nla bayii?
Odun meji gbáko sì lo fi wáyé, tí ọ̀pọ̀ ẹ̀mí sì báa rìn.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Gbajúgbajà òṣèré tíátà, Baba Suwe ń ṣe àìsàn.
Ọjọgbọn Soyinka fajuro bẹẹ, nigba to n fesi lori lẹta kan ti gomina ologun tẹlẹ nipinlẹ Kaduna, Umar Dangiwa fisita, to si n daba pe ki wọn pin orilẹ-ede Naijiria si ẹlẹkunjẹkun.
Ṣùgbọ́n ọ̀míràn dàbí iṣẹ́ ọnà gidi tí ó sì dùn-ún wò dáadáa.
Awọn akọroyin to lọ ṣe iwadii ni ile ounjẹ naa gbọ wipe, ootọ ni ati wipe, ileeṣẹ naa ni ọmọ Naijiria to ba fẹ ra ounjẹ ninu lọdọ wọn gbọdọ mu ọmọ orilẹede China kan lẹyin.
Atẹjade kan lati ọwọ agbẹnusọ rẹ Garba Shehu rọ awọn ọmọ ẹgbẹ lati ma sa kuro ninu ẹgbẹ nitori pe wọn ko wọle ninu idibo abẹle ẹgbẹ APC.
Saulu bá sọ fún àwọn iranṣẹ rẹ̀ pé, “Ẹ bá mi wá obinrin kan tí ó bá jẹ́ abókùúsọ̀rọ̀, kí n lè lọ ṣe àyẹ̀wò lọ́dọ̀ rẹ̀.
"– Seyi Makinde 2019 Elections: NBC na Channels TV àti ilé iṣẹ́ ìròyìn 44 ní pàsán Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Yinka Ajia: ìbẹ̀rù Ọlọrun ni mo fẹ́ fi tukọ̀ Kwara ti mo ba wọlé ""A fẹ fi da aloju pe ihalẹ rẹ ko lee tu irun kan lara erongba wa lati dide daabo bo awọn oṣiṣẹ ni ipinlẹ Ogun ti wọn n tẹ ẹtọ wọn mọlẹ baṣubaṣu."
inú lè bí i, kí ó sì bèèrè lọ́wọ́ rẹ pé, ‘Kí ló dé tí ẹ fi súnmọ́ ìlú náà tóbẹ́ẹ̀ láti bá wọn jà?
Lara awọn orilẹ-ede ti arun naa ti ra pala wọ ni Naijiria, eyi to ko ibẹru sọkan ọpọ eeyan, ti ọpọ ọmọ orilẹ-ede yii si lero pe ijọba kọ ni le kapa rẹ itankalẹ arun naa.
nítorí pé wọn kò pa òfin mi mọ́, kàkà bẹ́ẹ̀, wọ́n kọ ìlànà mi sílẹ̀, wọ́n ba ọjọ́ ìsinmi mi jẹ́, wọn kò sì mójú kúrò lára àwọn oriṣa tí àwọn baba wọn ń bọ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ìtàn Olaniyi Balogun, ọ̀jọ̀gbọ́n tó fi Nàìjíríà sílẹ̀ lọ gba iṣẹ̀ àgbẹ̀ l'Ámẹ́ríkà Awọn to ku ti wọn fi oju wọn lede ni Alex Ogunshakin, Felix Okpoh, Nnamdi Benson, ati Abiola Kayode ti wọn ni wọn ma n fi ọrọ ifẹ lu jibiti.
 Bakan naa la fi n da awon oludibo nipinle Eko loju pe ijoba ipinle yii ti se ipinnu lati seto iranlowo ati agbekale awon ohun eelo igbalode fun idagbasoke ninu eto ilera wa.
Lẹ́yìn náà, ẹ óo tẹ̀lé e pada wá síhìn-ín kí ó wá jókòó lórí ìtẹ́ mi; nítorí pé òun ni yóo jọba lẹ́yìn mi.
Lẹ́yìn èyí, Saulu kò lépa àwọn ará Filistia mọ́.
Sùgbọ́n ọ̀rọ̀ bẹ́yìn yọ lọ́jọ́ Iṣẹ́gun nígbà ti Igboke lọ si sọọbu Ani láti lọ gba owo ti yóò fi tóju ọmọ rẹ̀, èyi to si mu gbọnmi-si-omi-otó dáni ti Igboke si fi ọbẹ gun láyà.
Wọn kò ní jẹ́ ohun ọdẹ lọ́wọ́ yín mọ́, ẹ óo wá mọ̀ pé èmi ni OLUWA.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ọ̀pọ̀lọ̀pọ̀ ìgbà ni ìjínigbé ti wáyé ní ojú ọ̀nà ìlú Abuja si Kaduna Bala Ciroma, to jẹ ọga agba ọlọpaa nilu naa sọ pe, awọn gba ibọn atọwọda mẹrin, ibọn ẹtu kan ati ibọn atamataṣe kekere kan.
Ogbeni Karimi fi erongba re han latari igbese awon olopaa fun fi fesun kan asofin Melaye pelu ipo ti o wa.
Eyi to tiẹ se ni laanu julọ ni ti ileẹkọ Bethlehem Girls College, to wa ni gbagede ipatẹ ọja to wa ladugbo naa, tawọn akẹkọ ti n gba idanilẹkọ lọwọ, nigba ti ibugbamu naa waye, to si dawo.
  Ogbeni  Thakur  tun so pe orile ede India  yoo tubo maa se ohun iwuri ti yoo je ki  awon onisowo lọwọ si okoowo   eto idagbasoke, eto eko, eto ilera , eto
si bi eto idibo se lee waye ni orile ede bii ti Naijiria, ki awon kudiẹ kudiẹ
Rochas Okorocha, káàbọ̀ sí àwùjọ àwọn gómìnà tí EFCC ń wá - Fayose Sìgá mímu ń di èèwọ̀ oògùn ìlera pípé lagbaye Seyi Makinde kò ní ẹ̀tọ́ láti yọ alága ìjọba ìbílẹ̀ tì kò yàn sípò - Amòfin Sugbọn nigba to n ba BBC Yoruba sọrọ lori igbesẹ gomina tuntun naa,, Amofin Oludare Falana sọ pe, Gomina Makinde ko ni ẹtọ kankan labẹ ofin orilẹede Naijiria lati yọ alaga ijọba ibilẹ ti kii ṣe oun lo yan-an sipo.
Gege bi  Adesina se sọ, “o se dandan lati dahun si iwe iroyin Daily Independent to jade lojo kẹ́rìnlá , ojo Isegun ninu akori pe ‘won n lo ipa fun  aare lati yi ipinnu re pada lati tun dije nibi eto idibo to n bọ,’aheso oro naa ni pe awon  ajo agbaye bi i orile ede America, United Kingdom, ati Saudi Arabia,n lo ipa fun aare lati maa tun dije fun ipo aare fun idi kan tabi ikeji.
Psalm ni orukọ ti wọn sọ ọmọ wọn kẹrin.
Iroyin naa fikun pe, isẹlẹ ọhun lo mu ki Ọba Adeyemi ja okun ifẹ to wa laarin rẹ ati olori Badrat, to si ni ko jade kuro ninu aafin.
"Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Mistura Oseni Akintunde: Ara múmú kìí ṣe oríṣun ìfipábánilòpọ̀, ìran àwòjù ló ń fà á O ni eyi túmọ̀ si pé ""wọ́n ti ṣetò gbogbo rẹ̀, ki wọ́n to gbé ìgbẹ́sẹ̀."
Odumakin sọ pe Naijiria ti di ilu to n ba aye awọn ọmọ onilu jẹ, eyii to mu ki ọpọ eeyan maa funrere pe ki Naijiria tu ka.
[Ẹ tiẹ̀ gbọ́ ná, báwo gan-an ni àwọn ẹlẹ́mu ṣe ń gbé adúrú ẹmu yẹn káàkiri lórí kẹ̀kẹ́, tí akèrègbè ò bọ́ fọ́.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Brexit: Boris Johnson ṣèlérí láti mú UK kúrò ní àjọ̀ ìṣọ̀kan Gẹ̀ẹ́sì tiku-tiye 23 Agẹmo 2019 Oríṣun àwòrán, AFP Àkọlé àwòrán, Boris Johnson ní òun yóò mú UK kúrò ní àjọ̀ ìṣọ̀kan Gẹ̀ẹ́sì tiku-tiye Ni kete ti gbogbo pọpọsinsin ba pari lori iyansipo Olootu ijọba ilẹ Gẹẹsi, ọkan lara awọn ipenija nla nidi oselu ilu ọba ni Boris Johnson yoo kọkọ koju, eyi to nii se pẹlu bi ilẹ Gẹẹsi yoo se kuro ninu ajọ isọkan ilẹ Yuroopu laisi afẹnuko kan gboogi.
Ṣemedi yìí ni ó kọ́ àwọn ìlú Ono, Lodi, ati gbogbo àwọn ìletò tí ó yí wọn ká.
 kaura ti aiyese ja fun aabo ti awon obirin ka otun ati idarasi si ijoba tiwatiwa ilana .
Oríṣun àwòrán, EFCC Bakan naa ni wọn ni awọn kọ orisirisi ọkọ, ẹrọ ilewọ ati awọn nkan miiran lasiko ti wọn n ṣe iwadii naa.
Manase kú, wọ́n sì sin ín sinu ọgba Usa tí ó wà ní ààfin.
Àwọn tí kì í ṣe Juu yóo wó ìlú Jerusalẹmu palẹ̀, títí àkókò tí a fi fún wọn yóo fi pé.
Efuraimu ní ọmọbinrin kan tí ń jẹ́ Ṣeera, òun ló kọ́ ìlú Beti Horoni ti òkè ati ti ìsàlẹ̀, ati Useni Ṣeera.
Àdó olóró míì tún dún ní Báńkì l'Okeho, ènìyàn méjì farapa Oríṣun àwòrán, @SaifRikiji Ọlọpaa kan ati araalu miran lo tun farapa ni Ọjọbọ, lẹyin ti ado oloro dynamite tun bu gbamu ni ile ifowopamọ First Bank to wa ni agbegbe Okeho, nipinlẹ Oyo.
Ṣùgbọ́n ọ̀pọ̀lọpọ̀ èèyàn ló tako èrò rẹ yìí, ní èrò tí Nurudeen Mufc Bamidele, kò sì ibi tí èèyàn kò ti leè gbọ ọrọ Ọlọ́run, tí Dára Dariz Ogunsola náà sì kin lẹ́yìn pé oúnjẹ kii wọnú, kí ọrọ miran wọ ọ, bí àwọn èèyàn kò bá jẹun, ọ̀rọ̀ Ọlọ́run kò leè wọ wọn létí.
Awọn to ti dero ọrun nipasẹ ajakalẹ arun naa Naijiria ti di 956.
Ní òwúrọ̀ kutukutu ọjọ́ keji, àwọn ará ìlú Aṣidodu rí i pé ère Dagoni ti ṣubú lulẹ̀.
èmi tí mo sọ fún Kirusi pé: ‘Ìwọ ni ọba tí n óo yàn tí yóo mú gbogbo ìpinnu mi ṣẹ;’tí mo sọ fún Jerusalẹmu pé:‘A óo tún odi rẹ̀ mọ,’tí mo sì sọ fún Tẹmpili pé,‘A óo tún fi ìpìlẹ̀ rẹ̀ lélẹ̀.
nipa ipe ati gbese owo ti won ya sugbon ti won ko tii san .
Nínú ọ̀rọ̀ rẹ Abass Akande sàlayé ìdí ti oun fi n jẹ Obesere ti gbogbo ènìyàn n pe oun lọ́nìí, o ní èyi kìí ṣe orukọ abísọ ti iyá àti bàbá sọ oun o, sùgbọ́n lásìkò ere ori náà ni oun gba orukọ náà.
Oríṣun àwòrán, Mr Latin Nigba to n dahun ibeere yii, agba ọjẹ kan nidi isẹ tiata, to jẹ odu, ti kii se aimọ fun oloko laarin awọn osere tiata, Ọmọọba Jide Kosọkọ ni ẹgbẹ awọn osere ori itage lede Yoruba, taa mọ si TAMPAN, labẹ akoso ọgbẹni Bọlaji Amusan, ti gbogbo eeyan mọ si Mr Latin, ti n se gudugudu meje, ati yaya mẹfa fun eto adojutodo fawọn ọmọ ẹgbẹ naa.
Awọn gbajugbaja osere miran to tun sọrọ nibi eto iside ọjọ ibi Iya Rainbow naa ni Peju Ogunmọla, Sẹgun Ogungbe, Bọsẹ Akinọla ati Biọla Fowosere, ti gbogbo wọn si gba pe, Iya Rainbow korira kii osere tiata maa si ara silẹ lasiko ti wọn ba n sisẹ, to si maa n rọ wọn lati gbe asa Yoruba larugẹ lọjọkọjọ.
Àjọ tó ń mójútó àyíká l'Eko mú 123 ọlọ́kadà tó ń bọ̀ láti Jigawa Kíni ẹ mọ̀ nípa Ọmọ́táyọ̀ Olútóyè, Ọ̀jọ̀gbọ́n obìnrin àkọ́kọ́ nínú ẹkọ́ èdè Yorùbá lágbàyé Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
wọ́n ń jẹ́ kí àwọn talaka máa kígbe sí Ọlọrun,a sì máa gbọ́ igbe àwọn tí a ni lára.
Paulu lọ sí Masedonia ati Ilẹ̀ Giriki.
Oni lo pe ọjọ kejilelaadọta ti ọwọ ofin ti muu.
Mo gba àṣẹ lọ́wọ́ ọkọ, kí ń tó má ṣeré ìfẹ́ pẹ̀lú ìyàwó rẹ̀ - Àlè kan jẹ́wọ́ Wọ́n fi ikú Tunde Braimoh dá wa lóró ni o - Ẹbí pariwo Ẹ̀yin ọmọ ìta tó ní Funke Akindele ra ilé fún mi, irọ́ ni o - Ajirebi Ìtàn ayé Henry Fajemirokun, olówó tó fi owó mọ Olúwa àti ènìyàn Báwo ni Coronavirus ṣe n tànkálẹ̀ l'Afrika?
O wa lara awọn ti wọn n ja pe ki ajọ FIFA sọ owo idije obinrin di iye kan naa pẹlu ti ọkunrin ni agbaye nitori bi a ṣe bi ẹru ni abi ọmọ.
" Seriki Fulani ni ipinlẹ Ọyọ ni awọn Fulani ko lee kuro lagbegbe naa gẹgẹ bi Igboho ṣe sọ, awọn fa ọrọ naa le ijọba lọwọ nitori pe ijọba lo ni ilu, awọn lo si lẹtọ lati gbe igbesẹ lori ọrọ naa.
 Ìlú tí ẹ ̀ sìn òkèrè bá ti gba ẹ ̀ ṣìn ìbílẹ ̀ lọ ́ wọ ́ wọn , dandan ni kí irú orin bẹ ́ ẹ ̀ kú pẹ ̀ lú ẹ ̀ sìn tí wọ ́ n gbé jù sílẹ ̀ .
Nígbà tí àwa múra tán ní ààfin tí máa jáde ti àwa ti ibọn àti àdá wa, a bá àwọn ènìyàn wa nínú ìjà ńlá.
Ní ọjọ́ náà, o kò gbọdọ̀ ṣe iṣẹ́ kankan, ìwọ ati àwọn ọmọ rẹ ọkunrin, ati àwọn ọmọ rẹ obinrin, ati àwọn iranṣẹkunrin rẹ, ati àwọn iranṣẹbinrin rẹ, ati mààlúù rẹ, ati kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ rẹ, ati àwọn ẹran ọ̀sìn rẹ, ati àlejò tí ń gbé ilẹ̀ rẹ; kí iranṣẹkunrin ati iranṣẹbinrin rẹ lè sinmi bí ìwọ náà ti sinmi.
33 Àti pé èmi, Jésu Krísti, Olúwa rẹ àti Ọlọ́run rẹ, ti sọ̀ ọ́.
O nira fun mi lati tọ."
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Adolf Hitler: Kíni ẹ̀yin rántí tàbí mọ̀ nípa Adolf Hitler yìí?
Ibeere: Ki ni abadofin yii ti ṣe fun araalu?
''Mo mọ pe eniyan iyi lawọn aṣiwaju ẹgbẹ oṣelu APC, adehun kan ti wọn ni lo mu ki Buhari ṣoju ẹgbẹ naa ninu ibo aarẹ ọdun 2015 ati ọdun 2019,'' Ọgbẹni Balogun lo sọ bẹẹ.
Má pa mí run pẹlu àwọn ẹlẹ́ṣẹ̀,má sì gba ẹ̀mí mi pẹlu ti àwọn tí wọ́n nífẹ̀ẹ́ ìpànìyàn,
Ṣọ́ra, nígbà tí o bá lọ sí ilé Ọlọrun, ó sàn kí o lọ máa kẹ́kọ̀ọ́ níbẹ̀ ju pé kí o lọ máa rúbọ bí àwọn aṣiwèrè tí ń ṣe, tí wọn kò sì mọ̀ pé nǹkan burúkú ni àwọn ń ṣe.
Àtàwọn ọ̀dọ́, àtàwọn arúgbówọ́n kú kalẹ̀ lọ lójú pópó,àtàwọn ọdọmọbinrin, àtàwọn ọdọmọkunrin mi,gbogbo wọn ni idà ti pa.
Bí wọ́n ti ń lé Joṣua lọ ni wọ́n ń jìnnà sí ìlú.
tunni  lojo Eti awon eniyan ti iye won le
N óo gbadura bí Ẹ̀mí bá ti darí mi, ṣugbọn n óo kọrin pẹlu òye.
Oluwa sọ pé, “Ta ni olóòótọ́ ati ọlọ́gbọ́n ọmọ-ọ̀dọ̀, ẹni tí oluwa rẹ̀ fi ṣe olórí àwọn iranṣẹ ilé rẹ̀ pé kí ó máa fún wọn ní oúnjẹ lásìkò.
Oríṣun àwòrán, Nbc Àkọlé àwòrán, 2019 Elections: NBC na ilí iṣẹ́ ìròyìn 45 ní pàsán Oríṣun àwòrán, Nbc Àkọlé àwòrán, NBC ní kí àwọn ilésẹ ti tẹ ofin lóju san #500,000 Gẹgẹ bi olorí àjọ náà Mallam Modibo Kawu ni gbogbo àwọn ile iṣẹ́ yìí ni yóò fi ẹgbẹrun lọ́nà ẹ̀ẹ́dẹ́gbẹ̀ta naira jura.
Màlúù, ẹlẹ́dẹ̀, tòlótòló àti adìẹ n'ọ́n pọ̀jù nínú àwọn ẹranko tí àwọn àgbẹ̀ ìgbèríko náà nsìn.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ìyá ọmọ tí ó kú yóò fojú balé ẹjọ́ Iya ọmọ ati aburo ọkọ na ọmọ naa, wọn si tii mọ inu ile.
Coronavirus: Ẹ̀kọ́ márùn ún tí orílẹ̀-èdè àgbáyé lè kọ́ lára Naijiria lórí ìdènà àjàkálẹ̀ àrùn
Èyí ni orin tí orílẹ ̀ -ède kan máa ń kọ nígbà tí wọ ́ n bá ń ṣe ayẹyẹ .
Wedding nights: Kí ni aṣọ ìbálé túmọ̀ si lálẹ́ ọjọ́ ìgbeyàwó ?
lorile ede Naijiria kede aare  Buhari  ,oludije  fun ipo aare labe egbe  All Progressives Congress (APC) gege bi  eni ti o jawe olubori ninu eto idibo  aare to waye lorile ede yii.
“Ta ló gbé ẹnìkan dìde ní ìhà ìlà oòrùn?
Omooba-binrin Gloria Akobundu soro yii nibi eto idanilekoo olojo kan to waye niluu Abuja, lati gbe igbese lori didena wahala to maa n sele lasiko eto idibo, ni eyi ti won pe akori re ni ”Ẹ pale Ibon mo lodun 2020’’.
Wọn a máa sá lọ sọ́dọ̀ àwọn oriṣa káàkiri, wọn a sì máa bọ wọ́n.
    Bí mo ti ń sọ̀rọ̀ báyìí, àfi ìgbà tí ẹnìkan déedée dá mi lóhùn ní ẹ̀gbẹ́ ògiri ilé mi, ó ni, “Bẹ́ẹ̀ ni, máṣejẹ́ kí eléyìí yà ọ lẹ́nu, ìwọ ọ̀rẹ́ mi ojú fèrèsé, bí nǹkan kò bá rí bẹ́ẹ̀ olúkúlùkù ẹ̀dá alààyè ìbà wà ni ìtẹ́lọ́rùn, wọ́n ìbá dúró sí ojú kan bí adágún omi, ni ọ́jọ́ tí ẹnìkan bá ti wí pé ibi ti òun dé ní inu aye yìí tó, ìgbádùn olúwarẹ̀ dé òpin, ẹni tí ó wà ní òde ayé tí kò mùra ìlọsíwájú dàbí òkú láàrin alaàyè, bí ayé bá kún fún ayọ̀, ọmọ ènìyàn kò ní mọ àti kọ ìbànújẹ sílẹ̀ bí ayé bá kún fún owó, ọmọ ènìyàn kò ní mọ ipò tí tálákà wà, bí ayé bá kún fún ìṣẹ́gun, ọmọ ènìyàn kò ní mọ̀ bí a ti ń yọ̀ nígbà tí a bá bórí ìṣòro.
Femi ni bi o ko ba ni aya tabi ọkọ ti ọrọ rẹ ati iru iṣẹ ti o n ṣe ye daadaa, igbeyawo bẹẹ ko ni lee duro fun ọjọ pipẹ.
"Iléẹjọ gíga jùlọ da ẹjọ́ SDP àti PDP nù, wọ́n ní Yahaya Bello ló wọlé ìbò gómìnà Kogi Ìjà d'ópin, fún ìgbà àkọ́kọ́, bàálù gbéra láti Israel lọ sí UAE Ààrẹ Buhari buwọ́lu gbígbé ìṣàkoso nọ́mbà ìdánimọ̀ (NIMC) lọ sí ẹ̀ka ìjọba tó ń rí sí ìbáraẹnisọ̀rọ̀ Ṣé Nàìjíríà lẹ́mìí nkan tí Ghana ń ṣe fáwọn akẹ́kọ̀ọ́ ""Secondary"" tí yóò wọlé ní October yìí?"
’ Mo sọ fún wọn nígbà náà, mo ní, ‘Ẹ máa fetí sí ohùn mi, kí ẹ sì máa ṣe gbogbo nǹkan tí mo pa láṣẹ fun yín.
Broadcasting Service of Ekiti State di ṣíṣí padà lẹ́yìn oṣù máàrùn
Irinajo tuntun bẹrẹ fun Akpabio Saaju ni Akpabio to jẹ Olori ọmọ ẹgbẹ oṣelu to kere ju nile igbimọ aṣofin agba Naijiria, ti kọwe fipo rẹ silẹ, ko to di pe o kuro ninu ẹgbẹ PDP lọ darapọ mọ ẹgbẹ oṣelu APC ni Ọjọru, ọjọ kẹjọ, oṣu Kẹjọ, 2018.
Ṣugbọn o kò gbọdọ̀ fọwọ́ kan òun fúnra rẹ̀.
Gbogbo ọdún tí Metusela gbé láyé jẹ́ ẹẹdẹgbẹrun ọdún ó lé mọkandinlaadọrin (969) kí ó tó kú.
Ẹ̀gbọ́n ọmọbìnrin to ba BBC sọrọ, sọ pe lati bi ọdun meji lo ti maa n lọ ka iwe ninu sọọsi náà.
Agbẹjọro Obiagwu ni, to ba wu ijọba apapọ, o le lọ si ileẹjọ ti o ba ro pe awọn oṣiṣẹ ti tapa si ofin, amọ ọrọ naa ko kan ọlọpaa rara.
Owó tí Kiddwaya bá rí ní BB Naija, ìdá kan fún Erica, ìkejì fọ́mọ aláìníyàá - Baba Kiddwaya Bakan naa ni ileeṣẹ ọlọpaa sọ pe Ofori ti wa latimọle awọn ọlọpaa bayii.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Fásitì OAU ní ohùn ọ̀jọ̀gbọ́n Richard Akindele ni wọ́n ká sílẹ̀ 12 Ìgbé 2018 Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fọ́nrán ohùn, Fásitì OAU ní ohùn ọ̀jọ̀gbọ́n Richard Akindele ni wọ́n ká sílẹ̀ Àwọn aláṣẹ fásitì Ọbafẹ́mi Awólọ́wọ̀ ní Ìlú Ilé ifẹ̀, OAU ti ìdí rẹ̀ múlẹ̀ pé ohùn un ọ̀jọ̀gbọ́n Richard Akindele, ti ẹ̀ka ìmọ̀ nípa ìṣirò owó tí wọ́n ní, o ń bèèrè fún ìbálòpọ̀ ìgbà máàrún ọ̀tọ̀ọ̀tọ̀ lọ́wọ́ ọ̀kan lára àwọn akẹ́kọ́bìnrin tó fìdírẹmi nínú ìmọ̀ ẹ̀kọ́ kan ní ó wà nínú fọ́nrán ohùn àkásílẹ̀ tó ń jà ràìn-ràìn káàkiri báyìí.
"Eyi lo mu ki akaroyin Oloogbe Earnest Okonkwo to n ṣalaye nipa bọọlu naa lọjọ naa lọhun o pariwo o ""Omokharo ti sọ idije toni di mẹwaa-mẹwaa o (Ten-Ten )"" Ọrọ yii lo si gba oju ewe iwe iroyin gbogbo ni ọjọ keji."
bí àwọn ọmọ Esau, tí wọn ń gbé Seiri ati àwọn ará Moabu tí wọn ń gbé Ari, ti ṣe fún mi, títí tí n óo fi kọjá odò Jọdani, lọ sí ilẹ̀ tí OLUWA Ọlọrun wa ti fi fún wa.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Azman Airline: Ọkọ̀ òfúrufú gbiná nítorí obìnrin tó ń fa Shisha!
Wọn pe ẹrọ ibanisọrọ rẹ, sugbọn ko lọ.
Animal accident: Arákùnrin kan dóòlà ẹ̀mí Erin tí alùpùpù gbá lójú pópó
Máa ràn wá lọ́wọ́ lojoojumọ,sì máa jẹ́ olùgbàlà wa nígbà ìṣòro.
Jonatani dáhùn pé, “Máa bọ̀, jẹ́ kí á lọ sinu pápá.
Nigba to n ba BBC Yoruba sọrọ, Lola Omolola salaye pe idi ti oun fi da ẹgbẹ FIN silẹ ni lati fun awọn obinrin lanfaani lati ko ara wọn jọ, ja fun ara wọ, ki wọn si lee jiroro lori awọn isẹlẹ to n sẹlẹ si ọkọọkan wọn.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Ohun marun tawọn akọ ati abo to lẹpọ lee se lati yọ: Ẹ maṣe lo epo.
Omolere ni awọn ẹṣọ ile gomina ana ọhun sọ fun awọn ẹṣọ igbakeji gomina pe, ọwọ iyawo oloogbe naa ni kọkọrọ ẹnu ọna wa, ati pe ki igbakeji gomina ma ṣeyọnu lati jade kuro ninu ọkọ to gbe e wa.
Ninu oṣu Kẹsan an, ọdun 2017 ni Kanu di awati lẹyin ti ijọba orilẹede Naijiria tọka si ẹgbẹ IPOB gẹgẹ bi agbesunmọmi.
Awọn ọdọmọde meji, ọmọ ọdun mẹjọ ati ọmọ ọdun mọkanla ti wọn kopa ni wọn gbiyanju lati rin kilomita mejilelogun.
Bakan naa ni ijọba ipinlẹ Oyo ti paṣẹ lọjọ abamẹta pe ki wọn ti ileeṣẹ ọṣẹ ti Richard, akẹkọọ fasiti Ilu Ibadan ku si lọsẹ to kọja.
Ìdí rẹ̀ nìyí tí wọ́n fi pa ìlú náà run.
Lagos Collapsed Buildings: Ẹ yọ ilé náà kúrò pátápátá
Lẹ́yìn náà, OLUWA fi àwọn alágbẹ̀dẹ mẹrin kan hàn mí.
O ni ọmọ Ogun kii ṣe ọ̀lẹ awon odo ipinle ogun lo mu won ya si yahooyahoo.
'Ipò àpọ́nlé ni mo fi Gómìnà Abdulrahman sí ṣugbọn kò hùwa àpọ́nlé' Èmi ní mo fún Afeez Abiodun ní orúkọ 'Ọwọ' tó ń jẹ́ -Yemi My Lover 'Ohun tóo gbúdọ ṣe lọ́dún yìí bí o bá fẹ́ kí Ọlọ́run bá ọ rìn' Èyí tí a wò jùlọ 5:03 Fídíò, Omolola Arohunmolase Welder: Mo ti fí iṣẹ́ 'Welder' gbayì láwùjọ, tó mo fi tọ́ ọmọ yanjú, Duration 5,039 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 5:39 Fídíò, Akomolede ati Asa lori BBC: Olùkọ́ Kikelomo Ogunboye tan ìmọ́lẹ̀ sí ìwà olè ọ̀gá ọlọ́pàá Audu gẹ́gẹ́ bí àwòkọ́ṣe àsìkò yìí, Duration 5,398 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 4:11 Fídíò, Oba Adeyeye Ogunwusi: Ojú mi ti rí lọ́pọ̀ lọpọ̀, ọ̀pọ̀ èèyàn ni kò tilẹ̀ gbàgbọ́ pé mo lè jọba- Ooni, Duration 4,117 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 4:43 Fídíò, Promise Akinlade: ọmọ ọdún mọ́kànlá tó ń fi ìlù dárà bíi àgbàlagbà sọ̀rọ̀ nípa tálẹ́ǹtì rẹ̀, Duration 4,437 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 0:59 Gbọ́, Ìsẹ̀lẹ̀ jákèjádò orílẹ̀èdè àgbáyé láàárín ìṣẹ́jú kan, Duration 0,59wákàtí 6 sẹ́yìn 4:45 Fídíò, Yoruba Films: Ẹ̀ẹ́ bẹ̀ mi kúrò láyé ni, mi ò lè kú - Fadeyi Oloro, Duration 4,4526 Èrèlè 2020 7:03 Fídíò, Olumuyiwa Bolade Adedeji Military Bruitality: Bí arákùnrin onípèníjà ara tí sọ́jà lù ṣe dé, Duration 7,035 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 2:48 Fídíò, Esther Ajayi: Èmi náà ti borí ìṣòro rí ló ń mu mi ṣojú àánú, Duration 2,481 Ògún 2019 6:08 Fídíò, Adebola Ademilua: Àìrísẹ́ ṣè lẹ́yìn ìwé kíkà ló sọ mi dí ìyá onírú, mo dúpẹ́ tèmi, Duration 6,0827 Bélú 2020 5:55 Fídíò, Soyinka Cancer: Àṣe ara mi ni iso ti n run gbogbo bí mo ṣe n ṣèrànwọ́ lórí jẹjẹrẹ, Duration 5,5527 Bélú 2019 BBC News, Yorùbá Ìdí tí ẹ fi le è nígbàagbọ́ nínú ìròyìn BBC Ìlànà Lílò Nípa BBC Òfin Àṣírí Cookies Kàn sí.
Gbogbo wọn bẹ̀rẹ̀ sí wọ́ lọ sọ́dọ̀ rẹ̀.
O kú àbọ̀, o kú ìrìn náà.
" Ọ̀rọ̀ ìfẹ́ ti wọn fi ń lọ̀ mí lágbo àmúlùúdùn ni ìṣòro kan tí mo ní - Lizzy Jay ọmọ Ibadan Borussia Dortmund ká eyín ọ̀ọ́kań Schalke 04 bí Líìgì ilẹ̀ Germany ṣe padà bẹ̀rẹ̀ 'Èèwọ̀!
Lojo Eti ,ni aare orile ede Naijiria Muhammadu Buhari ni yoo maa dari igbimo ijoba nibi akanse ipade lati jiroro lori iwe isuna odun 2019 ti a wayii.
Gbogbo ilẹ̀ yín yóo kún fún igi olifi, ṣugbọn ẹ kò ní rí òróró fi pa ara, nítorí pé rírẹ̀ ni èso olifi yín yóo máa rẹ̀ dànù.
Àpẹẹrẹ kan ni Bara Katra, àrágbáramúramù ilé tí ó ní ìtàn-ìṣẹ̀lẹ̀-àtẹ̀yìnwá tí Mir Abul Qasim, Diwan (alága ètò ìṣúná) ti ó jẹ́ ọmọba Shah Shuja Mughul kọ́ ní nǹkan bíi 1644 àti 1646.
”‘Iko agbaboolu Croatia lee pegede, bee si ni iko agbaboolu Spain naa sile tesiwaju ti ifigagbaga pelu iko agbaboolu England ati Croatia ba pari si ami dogba-dogba.
Iná sọ níléepo NNPC l'Eko Mo ṣetán láti ta ilé tí mo ń gbé, kí n le rí àwọn ìbejì mi padà - Akeugbagold Àjọ ọlọpàá ìpínlẹ̀ Ondo kò gbọ́ ǹkankan nípa ọ̀daràn tó ní ààrun Corornavirus Ìjọba àpapọ̀ mọ̀ sí bí wàhálà Coronavirus ṣe ń búrẹ́kẹ́ síi ní ìpínlẹ̀ Kano-Ganduje Láti aago mẹsan ọjọ keji osù kaarun, àwọn ọmọ le pada si ilé iwe nígba ti awọn ọlọkọ eero naa le pada si oju popo.
Gudu so ojuse awon ile-ise aladaani, awon ti oro naa kan, ni lati mu idagbasoke ba Niger Delta, won si gbodo wa si ibi ipade naa.
láti fi ẹ̀wọ̀n de àwọn ọba orílẹ̀-èdè mìíràn,ati láti fi ṣẹ́kẹ́ṣẹkẹ̀ de àwọn ọlọ́lá wọn;
10 Owewe 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Gbogbo àwọn aposteli ati àwọn àgbààgbà bá péjọ láti rí sí ọ̀rọ̀ yìí.
Àkọlé àwòrán, PDP sọ wi pẹ idibo naa ko lọ ni irọwọrọsẹ atiwipe wọn ji ibo gbe ni awọn agbeegbe kan.
AMAA 2018 Ami eye fun oserebinrin to saaju to dara ju
Ìdí ẹ̀ ni pé kò lágbára títì nlá rárá.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Naijiria gba àmì ẹ̀yẹ góòlù mẹ̀sán Ere asafogi ọlọgọrun mita fawọn obinrin, Women's 100m Hurdles, ere asadiju ọlọgọrun mita fun awọn akanda, irin gbigbe ati ijakadi ni orilẹede Naijiria ti gba ami ẹyẹ goolu.
Oríṣun àwòrán, Google Àkọlé àwòrán, Ajọ to n risi igbelarugẹ ẹkun Iwọ-Oorun orilẹede Naijiria lo se agbatẹru ipade laaarin awọn gomina mẹfa lati gbogun ti eto aabo to mẹhẹ.
Ṣugbọn Samuẹli kò wá sí Giligali.
O kò gbọdọ̀ yá a ní owó kí o gba èlé, o kò sì gbọdọ̀ fún un ní oúnjẹ kí o gba èrè.
Nítorí ẹni tí ó bá ń fi èdè sọ̀rọ̀ kò bá eniyan sọ̀rọ̀, Ọlọrun ni ó ń bá sọ̀rọ̀.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Adewale Adeyemo: Òun ni wọ́n ṣẹ̀ṣẹ̀ yàn sípò ààrẹ fún àjọ Obama Foundation 7 Ògún 2019 Oríṣun àwòrán, @tvnigerian Adewale Adeyẹmọ tii se ọmọ Yoruba ni wọn ti kede bii aarẹ fun ajọ alaanu kan ti aarẹ ana nilẹ Amẹrika, Barrack Obama da silẹ, ti wọn pe ni Obama Foundation.
Nitori naa, ile ẹjọ da ẹjọ iku fun un pe ki wọn fun okun mọ ọ lọrun ki wọn si yẹgi fun un titi ẹmi yoo fi kuro lara rẹ.
Ọ̀gbẹ́ni Charles Barbier láyé ààrẹ Napoleon Bonaparte ló kọ́kọ́ ṣe irú ẹ̀.
O ní kí n tẹ́tí sílẹ̀,nígbà tí o bá ń sọ̀rọ̀,kí n sì dáhùn nígbà tí o bá bèèrè nǹkan lọ́wọ́ mi.
Ọpọ eeyan si lo gbagbọ pe o fi ẹgbẹ PDP silẹ nitori pe o fẹ di aarẹ ile igbimọ aṣofin Agba l'Abuja ni.
O ni niwọn igba ti oun ṣi wa lori itẹ gẹgẹ bi Oluwo ti ilẹ Iwo, ko si ẹni ti yoo bọ oriṣa laafin Iwo.
Bí ẹ bá yá àlejò ní nǹkan, ẹ lè gba èlé, ṣugbọn ẹ kò gbọdọ̀ yá arakunrin yín ní ohunkohun kí ẹ sì gba èlé, kí OLUWA Ọlọrun yín lè bukun yín ninu ohun gbogbo tí ẹ bá dáwọ́lé ní ilẹ̀ tí ẹ̀ ń wọ̀ lọ láti gbà.
Ọlọrun wo gbogbo ohun tí ó dá, ó sì rí i pé wọ́n dára.
Bí a bá kà á ní ẹníméjì, ó ti tó ènìyàn 500 tí ó ti ṣe ìrìnàjò náà.
nítorí pé, OLUWA ni igbẹkẹle rẹ,kò sì ní jẹ́ kí o ti ẹsẹ̀ bọ tàkúté.
O ni ọkọ to n gbe igbọnsẹ lo gbiyanju lati pa diẹ ninu ina ọhun, ṣugbọn ẹpa ko boro mọ.
Gbogbo àwọn tí wọ́n bá gbójú lé àtilọ sí Ijipti láti máa gbé ibẹ̀ yóo kú ikú ogun, ati ti ìyàn pẹlu àjàkálẹ̀ àrùn, wọn kò ní ṣẹ́kù, bẹ́ẹ̀ ni ẹnikẹ́ni wọn kò ní bọ́ ninu ibi tí n óo mú wá sórí wọn.
Ọkunrin kan tí ń jẹ́ Anania pẹlu Safira, iyawo rẹ̀, ta ilẹ̀ kan.
Obinrin níláti máa fi ìfarabalẹ̀ kẹ́kọ̀ọ́ pẹlu ìtẹríba.
Oríṣun àwòrán, @PastorFOdesola Àkọlé àwòrán, Ìròyìn kan wí pé Olórí Ìjọ Redeem, Enoch Adeboye bá Alaga ẹgbẹ́ òsèlú APC, Ahmed Tinubu sọ̀rọ̀ lóri sáà kejí fún Gomina Ipinlẹ Eko, Akinwunmi Ambode.
Òmìnira ni a pè yín sí, ẹ̀yin ará, ṣugbọn kí ẹ má ṣe lo òmìnira yín fún ìtẹ́lọ́rùn ara yín, ìfẹ́ ni kí ẹ máa fi ran ara yín lọ́wọ́.
Bakan naa lo ri ni @BCCare, idanilẹkọ nipa arun jẹjẹrẹ lo wa nibẹ.
ti ipade yii ba pari  leyin ose kan ti ipade
ede Naijiria ti won jawe olubori ninu eto idibo to sẹsẹ  pari ni iwe moyege.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, BBC Gov Debates: Ètò ẹ̀kọ́ ọ̀fẹ́ ni àwọn olùdíje yóò ṣe Alukoro ileewe giga naa, Alhaji Adewọle Ṣọladoye sọ fun BBC Yoruba pe gbogbo awọn akẹkọọ to farapa nibi iṣẹlẹ naa lo ti n gba itọju nileewosan to jẹ ti ileewe.
 ""A si ti fi asiko yii kigbe iranwọ si aarẹ Buhari ati ọga ọlọpa lorilẹede yii lati wa gba wa silẹ."
ofurufu to wa lorile ede yii.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Xenophobic Attack: Awọn ọmọ Nàìjíria tí yarí pé àwọn náà yóò gbẹ̀san 3 Owewe 2019 Àkọlé àwòrán, Xenophobic Attack: Awọn ọmọ Nàìjíria tí yarí pé àwọn náà yóò gbẹsan Àwọn ọmọ Nàìjíría ní ìpínlẹ̀ Eko ti gba ìgbòrò láti kọju ìkora ẹya miràn ti àwọn South Africa ń ṣe fún àwọn ọmọ Nàìjíríà.
O ni ki Obi ati alagbatọ ma fooya lori eto igbaniwọle sile iwe giga awọn akẹkọọ nitori pe ti asiko ba to, ohun gbogbo a yanju bi o ti yẹ.
8 591756 Orilẹede Chile 15628 83.
Ní ọdún kẹtadinlogoji lẹ́yìn tí wọ́n ti mú Jehoiakini ọba Juda lọ sí ìgbèkùn, ní ọjọ́ kẹtadinlọgbọn oṣù kejila ọdún náà, Efilimerodaki, ọba Babiloni, gbé ọ̀rọ̀ Jehoiakini yẹ̀wò, ní ọdún tí ó gorí oyè, ó sì pàṣẹ pé kí wọ́n tú u sílẹ̀ kúrò ní ẹ̀wọ̀n.
Gomina lede ọrọ yii nigba ti o n dahun ibeere lọdọ awọn akọroyin ni ile ijọba Aso Rock nilu Abuja lọjọ Iṣẹgun.
Ọ̀pọ̀lọpọ̀ ìwé ni Kọ́lá Akínlàdé ti kọ.
Wo ìdí tí ọmọ ọdún mẹ́wàá ṣe ti àbúrò rẹ̀ ọmọ ọdun kan àbọ̀ sínú kàǹga Ọsẹ́ tí ọkọ̀ aképo tó gbiná lẹ́bàá Otedola Estate l'Eko ṣe rèé Òṣèré tíátà Yorùbá yìí la orí mọ́lẹ̀ nígbà tó ń ṣe sinimá lọ́wọ́ Ọmọ Risikat olójú búlúù méjèéjì jẹ̀bùn oríire àti ìfà ńlá Ta ni obìnrin tó fẹ́ bá Dino Melaye ṣe ìgbéyàwó lọ́jọ́ kejì Kérésì?
Dẹjọ Tunfulu: Oríṣun àwòrán, Dejo tunfulu Àkọlé àwòrán, Ohun ọmọde ni o da Dẹjọ yatọ laarin awọn adẹrinpoṣonu yooku ẹgbẹ rẹ Ọkan lara awọn apanilẹrin to gbajugbaja ni ipele sinima agbelewo ede Yoruba ni Kunle Makinde Tokunbọ ti ọpọ mọ si Dẹjọ Tunfulu.
IAAF'S $130,000: Ọ̀gọ̀ọ̀rọ̀ èèyàn lórí ayélujára f'èébú ṣe Sunday fún Dalung
Abegunde ni ikọwe fi ipo silẹ ọhun yoo bẹrẹ ni Ọjọ Kẹfa, Oṣu Keje, ọdun ti a wa yii.
Nàíjíríà tún ń wọnú ọrọ̀ ajé tó dagun lọ lẹ́ẹ̀kejì - Ìjọba àpapọ̀ laago ìkìlọ̀ Afurasí mẹ́rin jí obìnrin oníṣòwò gbé ni Lanlate, wọ́n pa àfẹ́sọ́nà rẹ̀ Bí ìyàwó rẹ bá lóyún tàbí bímọ ní ìpínlẹ̀ Oyo, wo bí o ti ṣe lé gba ìsinmi ìtọ́mọ (Paternity leave) Bakan naa ni ọrọ yoo ṣe ri ni ọjọ kẹsan an, oṣu kẹsan an pẹlu.
pase fun awon komisona ni ekun naa lati mojuto eto aabo ni oju awon popo, ti ọkọ
Àwọn Èdìdàrẹ́ bu  ọlá fún oúnjẹ ju ọba wọn lọ.
Duro Ladipọ, ìlúmọ̀ọ́ká òṣèré tíátà àti ọmọ àlúfà tí kò gbàgbé àṣà ìbílẹ̀ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Wo ohun tí ọkùnrin yìí ń sọ táyà ọkọ̀ dà Ijọba ipinlẹ ti gba pe ojuṣe wọn lori awọn ọmọ wọnyii wọn si ti mu u loju paali nipa sisọ wọn lorukọ Benedict ati Linda Ayade.
Awọn nkan to wa lori ẹrọ ibaraẹnisọrọ alagbeka lo fi n kọ oriṣiriṣi nkan tuntun.
Òòrùn á tètè là nídàájí, á sì pẹ́ wọ̀.
Ati wi pe o jẹ ọna ati ko owo jẹ ati lati se owo ilu basubasu.
Alukoro ile-ise ologun ohun, ogagun Chukwu so pe, “lasiko iforowani lenuwo kan, a gbo pe, arakunrin oun  je okan lara awon odo ti awon kan n lo nipinle naa lati da laasigbo sile ni agbegbe naa.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Mí ò ya wèrè, mí ò burú, ọ̀nà àtijẹ là ń wá' Dokita Bukola Saraki naa ko jẹ ki ọrọ yi balẹ ki o to fi esi sita pe oun ko ṣarifin si baba ẹnikẹni nigba ti ohun wa lori oye nitori naa oun ko ni gba ki ijọba Gomina Abdulrahaman Abdulrazaq ṣarifin si baba oun.
Ẹwẹ, ileẹjọ paṣẹ l'Ọjọru ọsẹ yii pe ki wọn si fi eeyan mẹrin ti wọn fẹsun kan pe wọn ṣekupa ọlọpaa nigba tawọn eeyan yabo ṣọọṣi naa ṣi atimọle.
Àmọ́ gbogbo oun tí mo rí nínú igbó náà kàn ń múnmi yanu ni.
 ) ogbón èwè , ogbón ìsèlú ; ó fí ogbón èwé yanjí ìsoro náà .
Mo fi àwọn kan jẹ balogun lórí ẹgbẹẹgbẹrun eniyan, àwọn mìíràn lórí ọgọọgọrun-un eniyan, àwọn mìíràn lórí araadọta eniyan; bẹ́ẹ̀ ni mo fi àwọn ẹlòmíràn jẹ balogun lórí eniyan mẹ́wàá mẹ́wàá, mo sì fi àwọn kan ṣe olórí ninu gbogbo ẹ̀yà yín.
Oríṣun àwòrán, OTHER Àkọlé àwòrán, Wọn si ti ri owo to to miliọnu mọkanla Naira($30,000) ni aarin ọjọ kan.
Ati pe eyi wu mi, ko wu ọ ni ọrọ naa di bayii laarin ẹbi lori awọn amuyẹ oludije kọọkan.
Bakan naa, ẹni to ku fun un ni iya, oloogbe Henrietta Kosoko naa jẹ oṣere.
Mo tún gbé ojú sókè, mo bá rí ìwé kíká kan tí ń fò ní òfuurufú.
Bẹ́ẹ̀ ni nǹkan yóo rí,títí ẹ̀mí óo fi bà lé wa láti òkè ọ̀run wátítí aṣálẹ̀ yóo fi di ọgbà eléso,tí ọgbà eléso yóo sì fi di igbó.
Ọdun 1963 ni wọn gba Sani sagbo iṣẹ ologun lẹyin to kawe nípa iṣẹ ologun nilu Kaduna lọdun 1969 ati nilẹ Gẹẹsi, to si ja fitafita ninu ogun abẹle Naijiria.
Lẹ́yìn náà, n óo lọ rí ọba, bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé ó lòdì sí òfin, bí n óo bá kú, kí n kú.
O ni ni ilẹ Yoruba, Ọba lo maa n yan iyalọja ati iyalaje ati pe ko si oye to n jẹ Babalọja nitori awọn obinrin ni Yoruba gba pe wọn ṣe akoso ọja.
Wo ohun tó ń fa àfikún epo lóòrèkóòrè ní Nàìjíríà Èyí ni bí ojú ọjà epo lágbáyé ṣe ń fa àfikún epo lóòrèkóòrè ní Nàìjíríà Kaakiri oju ayelujara ni iroyin ti gbode pe ijọba ti fi owo kun iye owo jala epo bẹntiroo ni Naijiria lọjọru.
ninu ere boolu afesegba ni saa meji seyin leyin saa márùndínlọ́gbọ̀n ti o
" Ko tan sibẹ o, o ni oun tun sọtẹlẹ pe 'Trump yoo ja fitafita lati bori, yoo si gbe awọn igbesẹ kan to le mu iyapa ba orilẹ-ede America.
Ọba Israẹli fi ìtọ́jú ẹnubodè ìlú sí abẹ́ àkóso ọ̀gágun tí ó jẹ́ aṣojú rẹ̀.
Iṣẹ́ òdodo tí ó bani lẹ́rù ni o fi dá wa lóhùn,Ọlọrun olùgbàlà wa.
Aare bale si papako ofurufu Nnamdi Azikiwe, niluu Abuja laago merin aabo osan.
Èso wọn yóo wà fún jíjẹ, ewé wọn yóo sì wà fún ìwòsàn.
“Lóòótọ́, o ti sọ̀rọ̀ ní etígbọ̀ọ́ mi,mo sì ti gbọ́ ọ̀rọ̀ rẹ.
Eto wa nibi ti Ojogbon Osinbajo a ti ṣe ipade pẹlu Mike Pence to jẹ igbakeji aarẹ ilẹ̀ Amerika ni Washington DC lọjọru.
Ọjọgbọn Bọlaji Akinyẹmi wa yannana rẹ fun awọn isejọba orilẹede Naijiria wipe ni ẹkọ nla ni orilẹede Naijiria ni lati kọ, paapaajulọ lati rii wipe ẹgbẹ oselu lagbara ju awọn oloselu lọ.
Ní àkókò náà, kò sí ìbàlẹ̀ ọkàn fún àwọn tí wọn ń jáde ati àwọn tí wọ́n ń wọlé, nítorí ìdààmú ńlá dé bá àwọn tí ń gbé ilẹ̀ náà.
Abiola Ajimobi ni gomina ipinlẹ Oyo laarin ọdun 2011 si ọdun 2019, ko to wa du ipo sẹnetọ lati ṣoju ipinlẹ Oyo nile aṣofin agba lọdun 2019 ṣugbọn ko wọle.
Ṣugbọn inú bí olórí ilé ìpàdé nítorí Jesu ṣe ìwòsàn ní Ọjọ́ Ìsinmi.
Ileeṣẹ apoogun,Pfizer ati BioNTech ni awọn yoo pese abẹrẹ ajẹsara naa ni ọlọgọọrọ, ki awọn le gbe lọ si ọdọ ijọba lati fi ontẹ lu.
Ọju opo Twitter EFCC ni iroyin naa ti n ja rain, ti ọpọlọpọ eniyan si n fi ero wọn han nipa iṣẹlẹ naa loju opo ikansiraẹni ọhun.
Mo rán òjíṣẹ́ mi ṣiwaju mi láti tún ọ̀nà ṣe fún mi.
Kò sí ìwúlò ìsọ̀rọ̀ tako ìjìyà abẹ́lé kí ó wá di ẹ̀yìn wá kí a máa ṣe ìgbèlẹ́yìn àwọn òfin tí ó fi àṣẹ fún agbófinró láti yẹ̀yẹ́ obìrin ní títì ní ojúmọ́, kò bá ara mu!
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Kini itumọ ‘International passport’ l'ede Yoruba?
Ofin naijiria se alakalẹ lẹsẹẹsẹ lori ẹni to lasẹ lati dije dupo lorilẹede Naijiria fun ipo asojusofin ni Ile Igbimọ Asofin Naijiria.
Loju opo twitter lawọn ọmọ Naijiria ti tu pẹrẹpẹrẹ ọrọ sita, nibi ti wọn ti n fi ẹhonu wọn han lori ọrọ naa.
 Fatomilola fikun pe, Peter Fatomilola ní 'Ọ̀gbẹ́ni' lásán ni ọba tí kò rí ọ̀pá àṣẹ rẹ̀’ nitori ko ni asẹ lẹnu mọ."
Bí ó bá rí bẹ́ẹ̀, a lè fi ìgboyà sọ pé,“Oluwa ni olùrànlọ́wọ́ mi,ẹ̀rù kò ní bà mí.
Ata gita to pegede ni Tosin, to si wa lara awọn ọgọrun atagita lagbaye to jẹ ilumọọka.
'Kọ ọkọ rẹ sílẹ̀ kí o lọ fẹ́ Buhari' #Elections2019 Bi ogun ṣe bẹrẹ loju ọkọ iyawo -Roshan Ọmọ ọdun mẹrinla ni Roshan nigba ti ogun Sri Lanka bẹrẹ lọdun 2004.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Aisan ibà wa jake-jado awọn agbegbe to n aisko ojo ati ọ̀gbẹlẹ̀, ṣugbọn Afirika lo pọ si ju Gẹgẹ bi ajọ WHO ṣe sọ, ọpọ̀ aisan iba ati iku to waye nipa a rẹ n ṣẹlẹ ni agbgbe ilẹ olooru Afirika, ṣugbọn awọn agbegbe kan ni South-East Asia, Eastern Mediterranean, Western Pacific, ati nilẹ America naa wa ninu ewu.
Fi ibinu rẹ hàn, wo gbogbo àwọn agbéraga,kí o sì rẹ̀ wọ́n sílẹ̀.
Eniyan meje ni ileeọẹ eto ilera Kenya ti kede pe o ni coronavirus l'orilẹ-ede naa.
Tọ́ ọmọ rẹ sí ọ̀nà tí ó yẹ kí ó máa rìn, bí ó bá dàgbà tán, kò ní kúrò ninu rẹ̀.
 Leni ti o ti figba kan je akoroyin ri ati eni ti o ri si eto iwadii lorisirisi labe aburela aja feto omoniyan,” Ogbeni Lourenco, ti o jawe olubori ninu idibo aare ohun, ni ida méjídínlọ́gọ́rùn ún ati mọ́kàndínlọ́gọ́ta ninu apapo ibo ida ọgọ́rùn ún seleri pe, oun yoo ri daju lati se ojuse oun bi o ti to ati bi o ti ye, ti oun ko si ni yowo awon omo egbe tabi awon alatileyin re kuro lawo.
Awon egbe oseu tuntun naa ni :Advanced Alliance Party (AAP) , Advanced Nigeria Democratic Party (ANDP), African Action Congress (AAC), Alliance for a United Nigeria (AUN),Alliance of Social Democrats (ASD), Alliance National Party (ANP) ati Allied People’s Movement (APM).
Ninu ọrọ tirẹ, Nọọsi Similoluwa Olabode ni oun ti ko tọna rara ni ki nọọsi ma a fi iya jẹ alaboyun lasiko ibimọ.
Àwọn angẹli garùn títí láti rí nǹkan wọnyi.
Ọmọọba Alaafin, Bunmi Labiyi lọ sọ bẹẹ fun BBC Yoruba lasiko ti a n fi ọrọ wa a lẹnu wọ nipa iṣẹ ti ipo naa wa fun ni ilẹ Yoruba.
Oríṣun àwòrán, @Sowore2019 Àkọlé àwòrán, Omoyele Sowore lo fi n s#o faw#on #od#o lati gba ipo olori pada l#ow#o arugbo Awọn alatilẹyin rẹ a ma lo akọmọna yi lati fi ipinu wọn rinlẹ nipasẹ gbigba ijọba pada lọdọ awọn agbaagba oloṣelu ti wọn ti wa lori oye ti pẹ.
Wole Soyinka: Buhari kọ́ ló ń darí wa ni ipo òṣèlú ṣe fì sí apá kan
” Wọ́n bá súnmọ́ Joṣua, wọ́n sì tẹ àwọn ọba náà lọ́rùn mọ́lẹ̀.
2007 Bi o tilẹjẹpe wọn pada yan an s'ile igbimọ aṣofin, o jẹ gbajumọ laarin awọn talaka, awọn ọmọ South Africa to jẹ alawọ dudu, ati awọn ọdọ.
Dá mi láre, Ọlọrun, kí o sì gbèjà mi,lọ́dọ̀ àwọn tí kò mọ̀ Ọ́;gbà mí lọ́wọ́ àwọn ẹlẹ́tàn ati alaiṣootọ.
Tí a fiṣọwọ́ ní 8:46 12 Sẹ́rẹ́ 20218:46 12 Sẹ́rẹ́ 2021 N kò jà fún ìṣọ̀kan Yorùbá láti wá ipò tàbí orúkọ - Sunday Igboho Sunday Igboho ni awọn agbagba, lọbalọba atawọn oloṣelu nilẹ Yoruba to yẹ ko ja fun isọkan wa lo n ṣe bi pe ọrọ ọhun ko kan wọn.
Sakaraya, Asieli, Ṣemiramotu, Jehieli, Uni, Eliabu, Maaseaya ati Bẹnaya ń lo hapu, 
html Kete ti ẹ ba ti de ibi yii ni ẹ ki ẹ pese awọn ifitonileti bii ibi ti ẹ ka iwe de, awọn iwe ẹri ti é ni ati bẹẹ bẹẹ lọ bayii: Oríṣun àwòrán, @Nigeria Police force Ṣaaju ni Bashir Ahmed to jẹ olubadamọran si Aarẹ Buhari lori ifitonileti lori ayelujara naa ti kọkọ fi soju opo twitter rẹ nipa eto igbanisiṣẹ naa Lẹ́yìn tí wọ́n fi kakata hú gbogbo iṣú àti ẹ̀gẹ́ mí, wọ́n tún ṣá àwọn ọmọ mi ládàá-Guru Maharaj Ji Báwo ni Coronavirus ṣe n tànkálẹ̀ l'Afrika?
Meji ninu awọn ti wọn n jẹjọ naa ni wọn fi pamọ si ahamọ ọgba ẹwọn nitori aisi nile agbẹjọro wọn lati beere fun gbigba oniduro.
 Turkey Orilẹede Turkey ni awọn fi ọwọ́ mẹ́wẹ̀ẹ̀wá si ikọlu naa, nitori pe, o mu ẹ̀rì ọkàn fun ìwà ọmọnìyàn kuro, lẹ́yìn ìkọlù to wáyé ni Douma.
Kò sí ọgbọ́n, tabi òye, tabi ìmọ̀,tí ó lè dojú kọ OLUWA kí ó mókè.
Tomasi dá a lóhùn pé, “Oluwa mi ati Ọlọrun mi!
Gẹgẹ bi abiyamọ, ironu wo lo maa kọkọ gba ọkan ẹyin naa?
Kò tijú pé ẹlẹ́wọ̀n ni mí.
Awon miran ti won ti gba ami ẹyẹ naa laipẹ ni Margaret Atwood, Sir Salman Rushdie ati onkọ ewi ni, James Fenton.
a sì máa san ẹ̀san lojukooju fún àwọn tí wọ́n kórìíra rẹ̀.
OLUWA kì í tètè bínú;ó lágbára lọpọlọpọ,kì í sìí dá ẹni tí ó bá jẹ̀bi láre.
Ile-isẹ iroyin fun ijọba apaapọ, NAN ranti wipe igbakeji aarẹ, Yemi Osinbajo, nigba se'pade naa lọsẹ ti o kọja, sọrọ lori anfaani to wa ninu ki ipinlẹ kọọkan o sakoso ọlọpaa ti wọn.
Ṣugbọn ìwọ dúró tì mí níhìn-ín, n óo sì sọ gbogbo òfin ati ìlànà ati ìdájọ́ tí o óo kọ́ wọn, kí wọ́n lè máa pa wọ́n mọ́, ní ilẹ̀ tí n óo fún wọn.
O ni lara awọn ipenija ti awọn n koju bayii ni bi awọn kaadi idibo ti iye rẹ jẹ miliọọnu kan aabọ yoo ṣe tẹ awọn to nii lọwọ bayii ni Ipinlẹ Eko.
Kisiria wa dupe lowo awon igbimo egbe yii latii yan an gege bi igi leyin ogba fun eko isiro .
Ẹwà mímọ́ mi yóo sì hàn lára yín lójú gbogbo àwọn orílẹ̀-èdè tí ó kù.
Oyo TUC: A ṣì fa ìjọ̀ba léti ni pẹ̀lú ìyanṣẹ́lódì Èrò ṣe ọ̀tọ̀ọ̀tọ̀ lóri yíyára sàn owó oṣù òṣìṣẹ́ Lẹ́yìn igbe Atiku, Ààrẹ Ilé Ẹjọ́ kòtẹ́milọ́rùn yọra rẹ̀ nínú ìgbẹ́jọ́ èsì ìdìbò ààrẹ Kò sí ààbò, kò síṣẹ́; Àwọn dókítà LUTH bínú tán Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Abdulfatah Ahmed: Àwọn Kwara fẹ́ dán ilé ọkọ kejì wo ni lásìkò yí Lati ọdun 2011 ti ijọba to n kuro ni iṣakoso ti de ipo ni ati jọ n fa awọn ọrọ kan, ti ko si yanju di asiko yii.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ijegun pipeline fire: Ẹ̀mi méjì, ọkọ̀ tó lé ni 30 ṣòfò níbi ọ̀pá epo tó gbaná 4 Agẹmo 2019 Awọn olugbe agbegbe Ijegun ni kii ṣe igba akọkọ niyii ti ọpa epo yoo gbana ni ọdọ awọn.
Awọn eeyan miran ti wọn ni ọkọ ara wọn ni wọn ni lati yago fun awọn opopona ti awọn onikẹkẹ NAPEP naa ti gbajọba.
Keyamo fi ọrọ oludije fun ipo gomina labẹ asia ẹgbẹ oṣelu PDP nipinlẹ Oṣun Ademola Adeleke ṣe apẹrẹ pe wọn gbe e lọ sile ẹjọ lori iwe ẹri WAEC bakan naa.
Sugbọn ninu ifọrọwerọ BBC pẹlu agbẹjọro kan, Onyekachi Umah, o ni lootọ ni ọwọ nla wa fun asia ilẹ wa amọ eyi ko tumọ si pe ologun ko lee gbe igbesẹ lori rẹ.
Àwọn ìbejì yabo Igbó Ọrà fọ́dún ìbejì lágbàáyé Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ọrẹ Falọmọ: Buhari yóò rí ìbò Yorùbá gbà ju Atiku, Ọbasanjọ lọ Nigba to n gbarata lori isẹlẹ ipaniyan to waye ni ipinlẹ Benue laipẹ yii, nibi ti ọpọ ẹmi awọn araalu ti bọ, olori ijọ Winners lagbaye ni, o dabi ẹni pe ẹmi eeyan ko tiẹ wa jọ awọn apaniyan yii loju mọ, ti wọn ko si bikita mọ rara lati da ẹmi awọn eeyan legbodo.
A Mars pẹ́ púpọ̀ ní ilẹ̀ wa, ó dúró gẹ́gẹ́ bí àna fún púpọ̀ nínú ọmọ Yorùbá nítorí ọ̀pọ̀lọpọ̀ àwọn obìnrin tí o ti kọ́ ni wọ́n ń pè é ní ìyá tí wọ́n sì ti di ìyàwó ènìyàn pàtàkì káàkiri.
Ooni Ile ife, Ààrẹ Gani Adams fárígá lórí ikú ọmọ Fasoranti Kí ni Obasanjo sọ lórí ikú ọmọ aṣíwájú Afenifere, Rueben Fasoranti?
Bí àìsàn bàbà mi ṣe ń lọ, ló tún ń padà, kódà kò yé mi mọ- Ọmọ Bàbá Sùwé Àrà méèrírí!
"Àìní leè san àfikún owó ilé ìwé yìí leè mú kí àwọn akẹ́ẹ̀kọ́ ó fi iléẹ̀kọ́ sílẹ̀ tí yóò sì leè ṣílẹ̀kùn ìṣòro ayérayé fún wọn.
Èyí t’ó lọ s’ógun tí kò m’ẹ́rú wálé
Àwọn eniyan yóo kú sára nítorí ìbẹ̀rù, nígbà tí wọ́n bá rí ohun tí ń bọ̀ wá ṣẹlẹ̀ sí ayé.
Gbogbo ohun tí mo pa láṣẹ fún ọ patapata ni wọn yóo ṣe bí mo ti pa á láṣẹ.
O rọ aarẹ Buhari lati tete yan awọn minisita ti yoo baa ṣiṣẹ, idagbasoke ọrọ aje, ipese iṣẹ ati ọrọ ajelẹgbẹ oṣelu Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, #NigeriaDecides: BBC ti wa ni gbogbo ìpínlẹ̀ Naijiria láti firoyin gbogbo tóo yin létí Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Lara awọn ifẹnuko miran ti ile asofin agba orilẹede Naijiria gbe jade lori ọrọ ikọlu ipinlẹ Zamfara naa ni idasilẹ ibudo awọn atipo, IDP ni ipinlẹ Zamfara lati lee fun awọn eeyan ipinlẹ naa ti wọn ti di alarinkiri ati alainilelori ni aaye lati fi ori pamọ si.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Issa Aremu: ṣàlàyé kíkún nípa èròńgbà ẹgbẹ́ Labour to bá jáde Nibayii, ọkan-o-jọkan ọrọ si ni awọn eeyan ti n sọ lori ikanni ayelujara lori rẹ bayii.
 bí ilẹ ̀ ti ń mọ ́ , tó n ṣú , bẹ ́ ẹ ̀ ni ọjọ ́ ń lọ geere bíi kẹ ̀ kẹ ́ ológeere ; bí ọ ̀ sùpá ti ń ràn lálaalẹ ́ bẹ ́ ẹ ̀ ni ọjọ ́ ń yọ ́ gèèrègè bí òrí .
Afurasi naa tẹsiwaju pe ni agbegbe Bodija ni oun ti n ṣiṣẹ alaaru lẹyin to sa kuro ni ahamọ ki o to bọ sọwọ wọn.
”O ni asiko ti to lati pada sipinnu ijoba ninu erongba ti won fi lole pelu duru atifon lodun 2007.
Ó tọ́jú nǹkan jíjẹ fún ọba nígbà tí ó fi wà ní Mahanaimu, nítorí pé ọlọ́rọ̀ ni.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Amosun yóò jìyà ìkọlù sí Ààrẹ Buhari - APC Inec: Kò sí ìká tí o kò lè fí dìbò, ṣáà tí tẹ̀ ẹ́ sójú ẹ dáadáa Ìjọba àpapọ̀ fẹ́ dènà lílo ayélujára àti ẹ̀rọ ìbáraẹnisọ̀rọ̀ lọ́jọ́ ìbò - Fayose Bí ọkọ mi bá fìdírẹmi, màá gbà f'Ọ́lọ́run - Titi Abubakar Ajọ UN ati INEC gbé ìlanilọ́yẹ̀ lọ Kwara Ọ̀rọ̀ bọ́ lórí òjò òkò tó rọ̀ lé àwọn asaájú APC l‘Abeokuta Ni ipalẹmọ fun eto idibo ti yoo waye lọjọ kẹrindinlogun, oṣu Keji, BBC Reality Check ṣe agbayẹwo rẹ boya awọn talaka n talaka si, ati boya alaafo to wa laarin olowo ati talaka n pọ si.
Bakan naa, iroyin ti a ri ko jọ ni pe iṣẹju meji pere lo ku ki ẹlikọpita naa balẹ ni papakọ ofurufu Murtala Muhammed ti Eko lo di wọ̀ọ̀ nilẹ̀.
Ki owó epo rọ̀bì tó dé, a nfi ìrẹsì ṣe ọdún pàtàki fún àwọn ọmọdé, ṣùgbọ́n iresi ti wọn gbin ni ilẹ̀ wa ni a njẹ.
B Joshua 16 Òkùdu 2020 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Mo sàbẹwò sí T.
33 Àti ẹnití kò bá ronúpìwàdà, lọ́wọ́ rẹ̀ ni a ó ti gba àní ìmọ́lẹ̀ tí ó ti ní; nítorí Ẹmí mi kì yíò fi ìgbà gbogbo ja ìjàkadì pẹ̀lú ènìyàn, ni Olúwa àwọn ọmọ ogun wí.
Ibeere yii lo n gba ẹnu ọpọ kan bayii lẹyin ti Ajọ to n risi idagbasoke ọmọ wẹwẹ lagbaye, UNICEF sọ pe awọn ọmọ orilẹ-ede Naijiria to ni ẹrọ ibanisọrọ pọ ju awọn to lanfani ile igbọnsẹ lọ.
 Ṣùgbọ ́ n ní ìgbà tí agbẹjọ ́ rò yìí rí i wí pé ẹrú yìí kò rí ìdáhùn ni ó bá fọ èsì wí pé : ní tòótọ ́ ẹrú yìí yóò gba ìtúsílẹ ̀ nítorí pé kò ní òmìnira láti ba inú jẹ ́ bí ó ṣe wù ú .
Aanu rẹ ṣe mi, bi mo ṣe ri i pe ọmọ marun lo ti bi, lai si iṣẹ tabi ọkọ ti yoo tọju rẹ."
Kwankwaso pada fi APC silẹ lọ sinu PDP nigbẹyin ni Idi ree ti ẹgbẹ APC fẹ fidi rẹmi ninu idibo ọdun 2019 nitori awọn to n se alatilẹyin fun Kwankwaso.
Ẹ̀yin ọmọ, àkókò díẹ̀ ni mo ní sí i pẹlu yín.
Gbedeke iye ọjọ ti eeyan yoo fi lo wa lori kaadi E-Card amọ titi lai ni eeyan o fi ma lo NIN Nibo ni eeyan ti le ri nọmba NIN yii?
Gomina tuntun ti wọn dibo yan lẹgbe oṣelu APC nipinlẹ Ekiti, Omowe Kayọde Fayẹmi ni aṣeyọri oun ni lati tun Ekiti ṣe bi oun ṣe wọle idibo ọjọ Abamẹta to kọja yii.
Canada ń ṣọ́ ẹ o Mohammed ati awọn mẹrin miran ni wọn maa ṣe igbẹjọ wọn papọ ni ileejọ awọn ọmọ ogun ile ni Guatanamo Bay bẹrẹ lati ọjọ kọkanla, oṣu kini, ọdun 2021.
Taoheed se ikilo fawon lokolaya ti won feran ija loorekoore ti won maa n na ara ni igbajuigbamu ti kerikeri n ba rode pe ki won lo dekun iwa ibaje yii nitori pe o n sakoba fun opolo ati oju won niBakan naa lo ro awon oluko atawon osise eleto aabo lati sora fun nina akekoo tabi afurasi pelu igi atawon nkan oloro miran lori.
Àfi ti àwọn tí wọ́n bá súnmọ́ wọn, bíi ìyá tabi baba rẹ̀; tabi ọmọ tabi arakunrin rẹ̀, 
Ilẹ̀ ló ti ṣú yìí, dúró níhìn-ín kí o sì gbádùn ara rẹ, bí ó bá di ọ̀la kí ẹ bọ́ sọ́nà ní òwúrọ̀ kutukutu, kí ẹ sì máa lọ sílé.
Àwámárìídìí ni Olodumare–agbára ati ìdájọ́ òtítọ́ rẹ̀ pọ̀,bẹ́ẹ̀ ni kì í kọ òdodo sílẹ̀.
ti o ti fese mule ni awon eka wonyii.
 Àwọn krómósómù aláìṣẹ ́ po jẹ ́ atínrín onígbọọrọ kansoso , nígbàtí àwọn krómósómù aṣẹ ́ po ní àwòkọ méjì tí wọ ́ n jọ ara wọn ( wọ ́ n únjẹ ́ krómátídì ) jẹ ́ sísopọ ̀ pẹ ̀ lú sentrómẹ ́ rì .
Ó ní awuyewuye àdúgbò náà (orí òkè) bẹ̀rẹ̀ lodun díè sẹ́yìn, tí wọn sì jàre bò nílé ẹjọ́ lábẹ́ Gani Fawehinmi, ṣùgbọ́n síbè àwọn kan nínú ìjọba sì faake kori, láti gba ilé náà pẹ̀lú ipá.
Jakọbu Súre fún Efuraimu ati Manase.
nitori pe, ibo naa ni kọhun-kọhun ninu .
OLUWA, má kọ̀ mí sílẹ̀,Ọlọrun mi, má jìnnà sí mi.
Bi àwọn kan ti gbọ́ ìró iná ajónirun yi, wọn sáré titi ọpọ fi parun si inú irà ni Ejigbo ni ọ̀nà jínjìn si ibi ti ìṣẹ̀lẹ̀ ti ṣẹlẹ̀.
- Sanwo-Olu Eyii lo mu ki awọn ọlọpaa ṣiju lara awọn ọdaran ti wọn le wa gaan ti wọn si bẹrẹ sini dojukọ awọn ero to n lẹ oko mọ wọn nipasẹ ẹni akọkọ ti aṣita ibọn ba.
Ó pín wọn sí ọ̀nà mẹta: ẹgbaarun (10,000) ọkunrin ní ìpín kọ̀ọ̀kan.
Lẹ́yìn náà, mo sọ fún wọn pé, “Ṣé ẹ rí irú ìyọnu tí ó dé bá wa!
Ọgbẹni Joseph sọ pe awọn ọlọpaa ti fi afurasi naa ranṣẹ si ilẹ iṣẹ ọlọpaa Ipinlẹ Eko nibi ti iṣẹlẹ naa ti ṣẹ.
" Ẹ̀tanú pé Olùṣọ́ Genesis kò fẹ́ Laide Williams-Oni ló ṣe rán an lọ́ sí ẹ̀wọ̀n ọdún kan - CCC Genesis Global A kò tíì lè sọ pé ọmọ Ọba tuntun ni yóò jẹ Ooni lọ́jọ́ iwájú - Elebuibọn Ọkùnrin tó pe ìyàwó rẹ̀ lájẹ̀ẹ́ tì í mọ́lé fọ́dún mẹ́rin, fún un lóyún nígbà mẹ́ta!
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Trump: Bí wọn se ń pa Kristiẹ́ni kò jẹ́ ìtẹ́wọ́gbà 1 Èbibi 2018 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Aarẹ mejeeji yoo sọrọ nipa eto aabo, ọrọ ajẹ ati idokowo laarin orilẹede mejeeji Àarẹ ilẹ̀ Amẹrika Donald Trump, ti sọ pé ìṣekúpa àwọn ọmọlẹ́yìn Krístì nílẹ̀ Nàíjírià gbódọ̀ dópin.
ti o je ki owo ori ounje tun lewo sii ju ti ateyinwa lọ.
O ni lẹsẹkẹsẹ ni awọn igbesẹ naa di mimuṣẹ lati ileeṣẹ to n ri si ọrọ owo ori nipinlẹ Ogun, iyẹn Ogun state internal revenue services.
Sabitu ri pe Gbadero wọ sokoto ati ẹwu oloyinbo, to si mu ìbọn dani.
Ẹ̀yin olùfẹ́ tí ẹ jẹ́ àlejò ní ilẹ̀ àjèjì, mo bẹ̀ yín, ẹ jìnnà sí àwọn ìfẹ́kúfẹ̀ẹ́ ara tí ó ń bá ọkàn jagun.
amofin Sharafadeen Alli; Oloye Bolaji Ayorinde ti egbe oselu SDP; Senator
kò jẹ́ kí ẹnikẹ́ni ni wọ́n lára,ó bá àwọn ọba wí nítorí wọn.
Àsìkò tó láti fi ìwọ́de gba ara wa sílẹ̀ lọ́wọ́ ebi àti oko ẹrú - Sowore Èmi kò gbé pọ̀ pẹ̀lú Kollington Ayinla àmọ́ ọjà t'ọ́mọ ti wọ̀ lọ̀rọ̀ àwa méjééjì - Salawa Abẹni Soyinka ni igbesẹ naa lodi sẹtọ ọmọniyan Soworẹ gẹgẹ bi ọmọ orilẹede Naijiria.
Bi o ti le jepe, iko agbaboolu Plateau United FC padanu ifesewonse naa, aye si wa fun iko ohun lati yi esi ohun pada, ti iko naa ba se daradara ninu ifigagbaga keji.
Níbo ni Ọ̀gbẹ́ni 'Emma', tíṣà tí wọ́n ní ó lu ọmọ pa ní Ikorodu wà bayìí?
Àwa gan-an ati Ẹ̀mí Mímọ́ tí Ọlọrun fi fún àwọn tí ó gbọ́ràn sí i lẹ́nu ni ẹlẹ́rìí àwọn ọ̀rọ̀ wọnyi.
Ó ní, “Nítorí pé ẹ kò gbọ́ràn sí mi lẹ́nu, 
Tinubu lo sọ ọrọ naa, nigba to n da si bi awọn ọmọ ileeṣẹ ologun ṣe ṣina ibọn bolẹ fun awọn olufẹhonuhan End SARS ni Lekki Toll Gate, to wa ni ilu Eko lọjọ Iṣẹgun.
Arabic on Naira: CBN ní owó gọbọi ní yóò ná Nàíjíríà láti tẹ owó tuntun jáde
Ohun ta fi n tọju aisan yi ni ki eeyan sinmi daada,ki o mu omi daada ko si lo ogun paracetamọl.
Bi a ko ba gbagbe, irufẹ ilana titi ọja gbogbo yii ko ṣajeji nitori idalu ni iṣelu.
Ìdí rèé tí ilẹ̀ Afirika fi gbọdọ̀ kópa nínú dídán abẹ́rẹ́ coronavirus wò Amọṣa, oloye Adeniyan ni ahess ọrọ lasan leyi ati pe, labẹ ofin Gomina Seyi Makinde ni ojuṣe ti ofin la kalẹ fun un, bẹẹni oun gẹgẹ bii igbakeji pẹlu ni ilakalẹ ojuṣe ti ofin gbe le oun lọwọ paapaa lati maa duro fun gomina gẹgẹ bi o ba ṣe paṣẹ fun oun.
nítorí o kò ní fi ọkàn mi sílẹ̀ ní ibùgbé àwọn òkú;bẹ́ẹ̀ ni o kò ní jẹ́ kí ẹni mímọ́ rẹ rí ìdíbàjẹ́.
'Ọdún 35 ni ọmọbìnrin gbọdọ̀ ti bímọ tán' Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, #Queen Dihya: Obinrin tó gbógun tàwọn agbésùnmọ̀mí ni Algeria Arabinrin Adebiyi Adepeju ni o yẹ ki ọkọ gidi da owo ile iwe pada tori kii ṣe ẹtọ iya, ẹtọ baba ni.
Oríṣun àwòrán, @agbahor_aghogho Ọjọgbọn Odekunle nigba aye rẹ rọ awọn ajọ to n gbogun ti iwa ibajẹ, lati ri wi pe wọn ṣewadii awọn adari to fi mọ awọn ologun lai yọ ẹni kankan silẹ.
Eeyan 44,088 ti ri iwosan, 1078 si ti ku.
Iroyin to gbode kan bayii lorile-ede Angola ni ifeyinti aare Jose Eduardo dos Santos to ti n tuko ijoba orile-ede naa fun ojo pipe, bee si ni ibere isakoso ijoba adele re Joao Lourenco.
OLUWA ní idà kan tí a tì bọ inú ẹ̀jẹ̀,a rì í sinu ọ̀rá,pẹlu ẹ̀jẹ̀ ọ̀dọ́ aguntan ati ti ewúrẹ́,ati ọ̀rá ara kíndìnrín àgbò.
Wọ́n bá fi ẹ̀wù aláràbarà náà ranṣẹ sí baba wọn, wọ́n ní, “Ohun tí a rí nìyí.
Balaki sì sọ fún Balaamu pé, “Níwọ̀n ìgbà tí o ti kọ̀, tí o kò ṣépè lé wọ́n, má súre fún wọn.
Òfin rẹ ni mò ń fi ń ṣe orin kọ,lákòókò ìrìn àjò mi láyé.
Nítorí náà, Saulu fi ṣe ọ̀kan ninu àwọn olórí ogun rẹ̀.
Oluwa mi, máa lọ níwájú, n óo máa bọ̀ pẹ̀lẹ́pẹ̀lẹ́ níwọ̀n bí ìrìn àwọn ẹran ati àwọn ọmọ bá ti lè yá mọ, títí tí n óo fi wá bá oluwa mi ní Seiri.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Okùnrin SARS náà sọ pé òun máa pa èèyàn síbi ni- Aladugbo Ahmed Musa gbàmì ẹ̀yẹ agbábọ́ọ̀lù tó pegede ní ọdún 2018 Ẹ̀ wo bí àwọn ẹ̀ṣọ́ ojú etí òkun ṣe ń ṣiṣẹ́ l'Eko Awakọ̀ òfúrufú Ethiopian Airlines pariwo 'lọ sókè!
Aare tun ni’’Mo tun fe fi idunnu han fun
Ati pé, bí èyí kò bá tó ọ, ǹ bá fún ọ ní ìlọ́po meji rẹ̀.
A bí i ní ọjọ́ karùn-ún osù kẹsan ọdún 1984 sùgbọn ìlú Ibadanní ìpínlẹ̀ Ọyọ ló gbé dàgbà.
Ẹnikẹ́ni tí ó bá súnmọ́ ibi mímọ́, pípa ni kí ẹ pa á.
kí wọn bèèrè lọ́wọ́ gbogbo àwọn ará ìlú Ṣekemu pé, èwo ni wọ́n fẹ́, tí wọ́n sì rò pé ó dára jù fún wọn, kí gbogbo aadọrin ọmọ Gideoni máa jọba lé wọn lórí ni, tabi kí ẹnìkan ṣoṣo jọba lórí wọn?
se wa si ipinle naa lati wa se ifilole awon ise akanse , ni eyi ti yoo fi mu
Gbogbo wọn ti tẹ̀ sí ọ̀nà ara wọn,olukuluku wọn ń wá èrè fún ara rẹ̀.
Igba keji ree tawọn ọlọpaa yon fi ipa ṣi ilẹkun ile ijo laarin ọsẹ kan lorilẹede Belgium.
Yatọ si pe ọpọ wakati ni awọn olugbe ilu Eko lo ninu sunkẹrẹ-fakẹrẹ ọkọ fun ọpọ wakati nitori ojo ọhun ọpọlọpọ ọṣẹ miran ni ojo oniwakati meji naa ṣe lasiko ti o fi da ti inu rẹ kalẹ sori ilu Eko.
Adeoti, kede igbesẹ rẹ naa lẹyin ti ọkan lara awọn ti wọn dijọ dije, tii tun se olori osisẹ lọọfisi gomina nipinlẹ Ọsun, Alhaji Gboyega Oyetọla, jawe olubori ninu ibo naa.
Awọn eniyan lo gbagbọ pe ẹni to ba ni Baba isalẹ ninu ẹgbẹ oṣelu ni Naijiria ni anfaani lati dije dupo ti wọn yoo si bori, bi wọn ko tilẹ ni ọpọlọpọ imọ nipa oṣelu.
Ṣùgbọ́n máṣe dọ̀bálẹ̀ fún-un, bẹ́ẹ̀ ni ìwọ kò gbọdọ ké ‘Kábíyèsí’ nítorí ọjọ́ tí ọmọ ìmọ́lẹ̀ bá tẹríba fún Èṣù ni ayé ọmọ náà pín.
 nigba miran o je gbigba gege bi orile kan soso , eurasia je apapo awon orile europe and Ásíà (  eurasia "" jade ninu oruko won ) , eyi wa latojo pipe ."
Mílíọ̀nù kan ààbọ̀ ìbò ni mo fi borí Buhari- Atiku A gba ìwé ìpẹ̀jọ́ ₦200m lọdọ mọlẹbi Sugar - UCH Owó dé!
" Nínú ọ̀rọ̀ tirẹ̀ bàbá eégún olóòlù fúnra rẹ Ifasuyi Omotosho Kazeem sọ pé àṣẹ ìjọba àti ti Olúbadan ni abẹ́ gé, èyí lòdì sí ọ̀rọ̀ rẹ̀ to ti bá BBC Yoruba sọ tẹ́lẹ̀ pé ti eégún olóólù kò bá jáde, ǹkan le bàjẹ́ nílùú Ibadan.
Agbẹnusọ ilé iṣẹ́ ọlọ́pàá nípìnlẹ̀ Oyo, Olugbenga Fadeyi ṣàlàye fún BBC News Yoruba pé, ni kété ti wọ́n mú ọkùnrin náà ni wọ́n ti gba ọ̀rọ̀ sílẹ̀ lẹ́nu rẹ̀ ti wọ́n sì gba oníruuru ìgbẹ́ ti wọ́n ri lọ́wọ́ rẹ̀ láti gbe lọ fun àyẹwò.
omo egbé quechumaran ni aymara .
Nítorí kí ni ìdí rẹ̀ tí orúkọ mi yóo ṣe díbàjẹ́,n kò ní gbé ògo mi fún ẹlòmíràn.
Dáhún ìbéèrè yìí kí o wo àkókò tí yóò ná ọ̀ Ẹwẹ ni ọjọ aiku ọsẹ ni ẹgbẹ APC, PDP to fi mọ apapọ ẹgbẹ to n jẹ CUPP ni laa, awọn yoo tẹsiwaju pẹlu ipolongo awọn.
 “Oku yii je omo-bibi , okan ninu awon  to wa nile igbimo   asoju-asofin  ilu Abuja   (Lagos Island Constituency 1).
Oríṣun àwòrán, @APCUKingdom Ni ọpọ igba ni ilumọọka afurasi gbajuẹ naa ti ya aworan pẹlu awọn eekan oloselu ninu ẹgbẹ PDP naa nilu Dubai nibi awọn ipade to waye saaju eto idibo 2019, ko si yẹ ka foju fo iru ajọsepọ to wa laarin wọn ati iru isẹ ti Hushpuppi n se fun wọn."
Àlàyé òwe yìí ni pé eja ni èdè.
Ọpọlọpọ iṣẹ́ abàmì ati iṣẹ́ ìyanu ni àwọn aposteli ṣe láàrin àwọn eniyan.
Atẹjade kan ti alaga ẹgbẹ BMO naa, Niyi Akinsiju ati akọwe rẹ, Cassidy Madueke fisita wa bu ẹnu atẹ lu Soyinka, Falana atawọn ẹlẹgbẹjẹgbẹ ajafẹtọ ẹni miran, fun bi wọn se n se koriya fun awọn eeyan ti wọn fẹ da rogbodiyan silẹ lorilẹede Naijiria.
Atẹjade kan ti akọwe ijọba apapọ, Boss Mustapha fisita lo sisọ loju ọrọ yii pẹlu afikun pe Agbefọba agba fun ijọba ilẹ wa, Dayọ Apata ni yoo maa dari igbimọ to n gba dukia ijọba to sọnu pada naa, titi di ọjọ miran, ọjọ rere.
Àṣẹ̀yìnwá, àṣẹ̀yìnbọ̀, wọn yóo jáde kúrò níbẹ̀ pẹlu ọpọlọpọ dúkìá.
" Ogbun kẹrin ti o salaye fun BBC Yoruba ni ọgbun ipa ti awuyewuye to ba ọrọ ati fi iposilẹ Jacob Zuba lọ yoo ni lori eto ọrọ aje orilẹede naa.
 Àmọ ́ tí kò bá bí ' mọ , àwọn ẹbí rẹ ̀ , ní pátàkì jùlọ , àwọn ọmọ ìyá rẹ ̀ tí ó jù ú lọ ní wọ ́ n máa pín ogún náà láàárín ara wọn .
Mercy ló gbadé BBNaija ọdún 2019 Nína afurasí ní àhámọ́ nínú eré tíátà, bí àwọn ọlọ́pàá ti ń ṣe lójú ayé burú jáì"" Ìjọba Borno bẹ àwọn ọgbọ̀n Alfa Saudi lọ́wẹ̀ láti rẹ́yìn Boko Haram Ogundamisi, lasiko to n ba BBC Yoruba sọrọ, salaye siwaju pe, awọn ọmọ Naijiria n mu inu ara wọn dun lori eto naa, ati wi pe, ohun idanilaraya lo jẹ fun wọn."
Àwọn Olúkọ ìpínlẹ̀ Oyo fakọyọ lórí ètò Akọ́mọlédè àti Àṣà púpọ̀ Rògbòdìyàn bẹ́ sílẹ̀ láàrin àwọn ọlọ́kadà àti àwọn òṣìṣẹ́ ọgbà ẹ̀wọ̀n ní Ibadan Wo àwọn oúnjẹ márùn ún tó ń mú kí àtọ̀ ọkùnrin dára síi Ọdun 2012, 2016 àti 2020 ni John Mahama àti Nana Akufo-Addo ti jọ ń figagbága dupò aàrẹ Ghana Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Akure shooting: Àlááfíà ti padà sí ìlú Akure, ẹnikẹ́ni kò kú - Deji ilu Akure7 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Nigeria Bad roads: Àwọn obìnrin abúlé yìí ń pàdánù ọmọ látàrí òpópónà tó mẹ́hẹ7 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Aisha Buhari: Aya Ààrẹ Buhari ké sí àwọn aya gómìnà pé kí wọ́n lọ paná ìdàrúdàpọ̀ ágbègbè kóówá7 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Ondo 2020 Tribunal: Ìgbìmọ̀ olùgbẹ̀jọ́ ìbò gómìnà yóò gbérasọ lọ́jọ́ Iṣẹgun7 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Ghana elections result 2020: Èsì ìdìbò tó gbé aàrẹ tuntun wọlẹ́ ní Ghana rèé.
Ọgbẹni Afọlabi Ayantayọ nikan ni o jẹ ọmọ ẹgbẹ tuntun laarin igbimọ naa, awọn yooku ni wọn ti ba igbimo yii ṣiṣẹ ninu saa to kọja.
Ninu ọrọ to sọ lẹyin ti wọn kaakiri wo nkan to bajẹ, arakunrin Saka ni yoo nira fun ipinlẹ Kogi lati pada bọ sipo latari ijamba ti awọn janduku yi ṣe.
tí o óo fi lè mú un lọ sí ààyè rẹ̀,tí o fi lè mọ ọ̀nà tí ó lọ sí ilé rẹ̀?
” Ìpayà ńlá ti bá gbogbo ìlú nítorí OLUWA ń jẹ wọ́n níyà gidigidi.
2 Kíyèsíi, èmi ni Ọlọ́run; ṣe ìgbọ́ràn sí ọ̀rọ̀ mi, èyí tí ó jẹ́ aláàyè ati alágbára, ó mú ju idà olójú méjì lọ, fún pípín sí ọ̀tọ̀ọ̀tọ̀ àwọn oríkẽ àti mùdùnmúdùn; nítorínáà ṣe ìgbọ́ràn sí àwọn ọ̀rọ̀ mi.
Aare Muhammadu Buhari ti ba iyaafin Rebecca Sharibu soro lori ero ibanisoro lojoRu(Wednesday), leni ti o je iya Leah, akeko nile eko binrin girama Dapchi secondary school girl, ti awon omo ogun olote boko haram ji gbe lo nigba kan seyin.
"O tun darukọ ọpọlọpọ awọn eniyan miran ti o ti yin'bọn pa bii Hamburger, alaga kan ni ẹgbẹ awakọ ni Oshodi, Babajide Dosumu ti wọn n pe ni Mados ni Ebute Meta, Salawe ni Ajah, Ganiyu Asaro ati awọn mẹrin miiran ni agbegbe Badore nibiti o sọ pe oun rọ'jo ọtan ibọn sinu ọkọ wọn ti oun fi pa awọn eniyan maraaarun ti o wa ninu ọkọ naa.
O ti di ilumọọka oṣere Yoruba to si n sọ ijinlẹ ede Yoruba bi awọn to ni ede gan an.
O ni wọn gbe obinrin naa lọ sile iwosan amọ ẹpa ko boro mọ nitori obinrin naa ti jade laye.
Arsenal ṣẹ́ṣó ìyà, búlálà ẹlẹ́nu mẹ́ta ni Leicester City fi lù wọ́n lálù bami Àjọ SERAP ke gbàjarè lóri jíjan àbá owó ìfẹ̀yìti lóntẹ̀ ni Bayelsa Pọ̀nmọ́ olóró ni!
Oríṣun àwòrán, @GovAyoFayose Àkọlé àwòrán, Gomina Fayose gbe ori le iyawo rẹ lejika nibi ajọyọ ayajọ awọn obinrin lagbaye nilu Ado Ekiti Oríṣun àwòrán, @AkinwunmiAmbode Àkọlé àwòrán, Iyawo gomina ipinlẹ Eko se ajọyọ ayajọ awọn obinrin lagbaye pẹlu awọn iyawo oloselu nilu Eko Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Africa Eye: Wo ìtàn ìyá kan ìyá kan àtàwọn olè ajọ́mọgbé tó n ta ọmọ ní Kenya Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Africa Eye: Wo ìtàn ìyá kan ìyá kan àtàwọn olè ajọ́mọgbé tó n ta ọmọ ní Kenya 14 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Opọ lo ro pe ko si ọna abayọ kuro ninu iya ju tita ọmọ wọn lọ Orilẹ-ede Kenya ni BBC ti lọ ṣe iwadii àwọn tó ń jí ọmọ gbé ta fawọn to n woju Oluwa ninu iwadii BBC Africa Eye ti ọtẹ yii.
Ìrìbọmi tí Johanu ń ṣe, láti ọ̀run wá ni, tabi láti ọ̀dọ̀ eniyan?
64 Nítorínáà, èmi yíò sọ ohun ìjìnlẹ̀ nlá yìí di mímọ̀ fún wọn.
Èyí tó wọ́pọ̀ jùlọ ni kiní kan tí wọ́n fi àgbàdo àbí ọkà-bàbà ṣe tí wọ́n npè ni cornflakes.
“laipe yii, a ri pe orisirisi igbese ni awon egbe oselu alatako ti n gbe lori ero ayelujara lojuna lati bu enu ate le isakoso ijoba yii ati gbigbogun tiwa-ibaje ti egbe oselu APC yan laayo.
Nígbà tí àwọn ará Filistia gbọ́ pé àwọn ọmọ Israẹli péjọ sí Misipa, àwọn ọba Filistini kó àwọn eniyan wọn jọ láti gbógun tì wọ́n.
Àwọn ẹ̀yà Lefi kò ní ìpín kankan ninu ilẹ̀ náà, ṣugbọn wọ́n fún wọn ní àwọn ìlú láti máa gbé, ati pápá, ibi tí wọ́n ti lè máa da mààlúù wọn, ati gbogbo ẹran ọ̀sìn tí wọ́n ní.
Bauchi Elections: Gómínà Abubakar ti kí Mohammed oludije PDP to jáwé olú borí
ẹgbẹ́ àwọn dókítà - BBC News Yorùbá BBC News, YorùbáFò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Cure for coronavirus: Ìjọba ti sún wa kan ògiri ló jẹ́ kí a daṣẹ́ sílẹ̀ - ẹgbẹ́ àwọn dókítà 15 Òkùdu 2020 Oríṣun àwòrán, @FcMglobal Awọn dọkita to n ṣiṣẹ nile ẹkọṣẹ iṣegun ni Naijiria ti sọ pe iya n jẹ wọn lo jẹ ki wọn gunle iyanṣẹlodi.
Gẹgẹ bo ṣe sọ, o ni oun ti ya ara oun sọtọ fun ọjọ merinla bayii.
Pẹlu owo pinisin ti wọn n ta igo kan,Codeine le di baraku fun eniyan tabi ko buru to bẹẹ ti yoo ṣe akoba fun agọ ara tabi ya eniyan ni were.
Ohun atẹyinwa leyi yẹ ko jẹ.
Aisha Buhari ké gbàjare pé ètò ìjọba Buhari kò ṣànfàní f'óbìrin Àwọn bàbá ìsàlẹ̀ òṣèlú tó bá ìtìjú bọ̀ nínú ìbò Gómìnà rèé Ọlọ́pàá Adamawa ni #30,000 ni wọ́n fi bọ́ igún látìmọ́lé Ọ̀rọ̀ Aisha Buhari sí Ramaphosa wú ọ̀rọ̀ síta lẹ́nu àwọn ọmọ Nàìjíríà Fun idi eyi, ajọ NBC rọ awọn ile iṣẹ igbohunsafẹfẹ lati jẹ akọṣẹmọṣẹ ki wn si tẹle ilana ajọ naa ni gbogbo igba nitori ojuṣe wọn ni lati mu ilsiwaju ba ibagbepọ alafia lorilẹede Naijiria nipa igbohunsafẹfẹ.
Akintola ṣiṣẹ olukọ nile iwe Baptist Academy lati ọdun 1930 si ọdun 1942, ko too lọ ṣiṣẹ ni ile iṣẹ Reluwe.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Prophet Israel Oladele: Wo díẹ̀ lára àwọn ìwàásù mánigbàgbé tí wòlíì ìjọ CCC Genesis Global ti ṣe 21 Bélú 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 22 Bélú 2020 Oríṣun àwòrán, Facebook/Genesis Global Ọpọ awọn eeyan kaakiri Naijiria lo ti n sọrọ lori iru iranṣẹ Ọlọrun ti wolii Israel Oladele Ogundipe jẹ Lẹyin ti ile ẹjọ kan ni ipinlẹ Eko ran lọ si ẹwọn ọdun meji lori ẹsun gbajuẹ.
  Òun náà ni wọ́n ń pè ní Acarajé ní Brasil.
Ninu ọrọ rẹ si awọn ọmọ ipinlẹ naa ni ọjọ Aje nibi ti o ti salaye wi pe, ayẹyẹ naa pe fun ibara ẹni yọ, sugbọn ni pẹlẹkutu ni ljoba yoo sẹ.
Ó ya ọ̀pọ̀lọpọ̀ ènìyàn lẹ́nu wí pé kò tíì sọ ohunkóhun nípa èsì ìbò náà bí ó tilẹ̀ jẹ́ wí pé igbákejì rẹ̀ tó jẹ́ olùdíje ti jáde láti kọ̀ èsì tí àjọ INEC gbé jáde.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù FA Cup final Arsenal vs Chelsea: Lampard laná!
Ṣugbọn Abiatari, ọ̀kan ninu àwọn ọmọ Ahimeleki sá àsálà, ó sì lọ sọ́dọ̀ Dafidi.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù NURTW Oyo: Ìwà ìdàlùrù ní Ibadan ló mú kí Makinde gbẹ́sẹ̀ lé NURTW 31 Èbibi 2019 Oríṣun àwòrán, @Oyoaffairs Ẹgbẹ awakọ ero NURTW nipinlẹ Ọyọ tijọba fofin de, ti fesi lori bi ijọba ipinlẹ Ọyọ se fi ofin de ẹgbẹ naa lọjọ keji ti gomina Seyi makinde gba ọpa asẹ, to si ni pe eegun rẹ ko gbọdọ sẹ mọ jakejado ipinlẹ naa.
Lai pẹ yii ni Minisita fọrọ ilẹ okere ni ijọba yoo ti awọn ile iṣẹ aṣoju Naijiria kan pa nitori aisi owo to to.
O tenumo pe, aye ti eto ijiroro ohun yoo fi waye ni pe, ipade ijiroro ohun yoo waye pelu awon ti won wa isokan orile-ede Cameroon.
    “Lálẹ́ ni mo tó sọ ohun tí mo bá wá pàtàkì fún un, mo sì bá a wí púpọ̀ pé ohun tí o ṣe kò dará.
Ìdílé Barrister àti K1 Wasiu Ayinde sọ àsọyépọ̀ nílé Obey Commander2 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Borno Zabarmani Rice Farmer Massacre: Àwọn àgbàgbà Òkè Ọya ní ẹ̀mí èèyàn kò níyì mọ́ lábẹ́ ìṣèjọba Buhari5 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Jọ́ náà ni bàbá mi fún mi ní ẹ̀wù ìmọ́lẹ̀, ó wí pé: Ibikíbi tí ìwọ ba ń lọ, ìbáà ṣe ọ̀sán, ìbáà se òru, o  kò ní rìn nínú òkùnkùn láéláé’(gbogbo àwọn màlékà sí dáhùn pé ‘Àmín’) Ìyá mi pẹ̀lú fún mi ni ẹ̀bùn, ó fún mi ni agbáda ńlá tí ìwọ rí lọ́rùn mi yìí, ìsàlẹ̀ àpótí Èṣù ní wọ́n sì ti mú u jáde, gbogbo àwọn ará òde ọ̀run a sì máa pé agbádá náà ni “Ẹ̀wù ìgbéraga” Òótọ́ náà sì ni, nítorí àti ọjọ́ tí ẹ̀wù yìí ti de ọrùn mi ni inú mi ko ti dùn mọ́, bẹ́ẹ̀ ni n kò lè bọ́ ọ, o di ọjọ́ tí mo bá rí ọmọ aráyé tí yóò rán mi lọ́wọ́ nípa rẹ̀.
Fun'ra mi ni mo tọju ara mi nileewosan."
Ẹni to bori: South Africa Ghana vs Mauritania.
Ìyàwó mi ró aṣọ díámọ́ǹdì, ó wé gèlè díámọ́ńdì pẹ̀lú, bẹ́ẹ̀ ni bí ìràwọ̀ ojú ọ̀run ni díámọ́ǹdì, máa n dán yinrinyinrin.
orílẹ ̀ -èdè kan ni ó ń jẹ ́ american samoa .
Leah Sharibu ṣì wà láàyè - Iléeṣẹ́ Aarẹ Buhari Wo àwọn àwòràn tó làmìlaaka nílẹ̀ Adúláwọ̀ lọ́sẹ̀ yìí BBC Yoruba yoo maa mu gbogbo nkan to n ṣẹlẹ nibẹ wa si etigbọ yin: Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Oríṣun àwòrán, The Nation Newspapers Ta ni Kabiesi Adegbitẹ Adedoyin to waja ni Ikarẹ Akoko?
Bi awọn kan ṣe n pariwo pe 'irọ ni o pa'ati pe 'ko yee pa iru iru irọ bẹẹ' ni awọn miran tilẹ n sọ pe 'ko darukọ awọn ipinlẹ naa to ba daa loju.
Lẹ́yìn èyí, ó sọ̀kalẹ̀ lọ sí Kapanaumu, òun, ìyá rẹ̀, àwọn arakunrin rẹ̀, ati àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀.
Lootọ n ko ni ẹri to daju lọwọ nitori mo ti pa ọpọ itakurọsọ wa loriayelujara rẹ, ti mo si ro pe sise bẹẹ yoo jẹ ki n tete gbagbe rẹ ati awọn nnkan to sẹlẹ laarin wa.
Ó kó wọn gba ọ̀nà tààrà jáde,lọ sí ìlú tí wọ́n lè máa gbé.
O dun yin pe ọmọ Yoruba ko gba Oscars abi?
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Obinrin nile iwosan Eyi mu ki awọn mọlẹbi pamọran pọ lati gbe obinrin naa lọ si ile iwosan mi amọ o ku lọju ọna ki o to de ibẹ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Eegunjobi Omotanbaje Ajobiewe- Èébú ní wọ́n kọ́kọ́ ń bù mí nígbà tí mo bẹ̀rẹ̀ ẹ̀ṣà pípé ní Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Fídíò, Obalende Building Collapse: Gbogbo àwọn to há sọ́bẹ́ ilé tó wó la mọ̀14 Ọ̀wàrà 2020 Fídíò, Soyinka Cancer: Àṣe ara mi ni iso ti n run gbogbo bí mo ṣe n ṣèrànwọ́ lórí jẹjẹrẹ27 Bélú 2019 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Ìjàǹbá ọkọ̀ ní Ìlasamàjà: Ẹ̀mí mẹ́ta bọ́, ọ̀pọ̀ farapa
Nígbà tí Jesu rí igbagbọ wọn, ó wí fún arọ náà pé, “Ọmọ, a dárí ẹ̀ṣẹ̀ rẹ jì ọ́.
Nígbà tí wọ́n dé ilé Mika, wọ́n wọ̀ sibẹ.
Ẹurásíà je isupoile nla to je bi 52,990,000 km ( 20,846,000 mi ) tabi bi 10.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ibi ti aye ba ti ba ni laa tii jẹ, Awọn eeyan orilẹede Sudan kan ree ti wọn joko si eti odo ti omi funfun ati alaro odo Nile ti parapọ di ọkan Oríṣun àwòrán, Sia Kambou Àkọlé àwòrán, Ohun ti a ba fi pamọ, lo n niyi.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Akọ́mọlédè àti Àṣà lórí BBC Yorùbá: Kọ̀ síi nípa iṣẹ́ tí oúnjẹ ń ṣe lára níbí Ireti wọn ni pe wọn yoo lee pese aadọta miliọnu abẹrẹ naa titi opin ọdun 2020 ati biliọnu kan o le ọdunrun miliọnu abẹrẹ naa nigba ti ọdun to n bọ yoo ba fi pari.
O wa rọ awọn ololufẹ rẹ lati bu omi suuru mu ki wọn si gba alaafia laaye nitori gẹgẹ bi o ṣe sọ, 'ko si giri!
Kayode Abiara: Ọmọ Nàíjíríà, ẹ má ba ọkàn jẹ́ lórí ààbò tó mẹ́hẹ, ewu ìgbà ìkẹyìn ló jẹ́
" Okina ni iriri pe ki ẹnikẹni maa naani ẹni.
Àkọlé àwòrán, Awọn arugbo to lọwọọwọ lati yan eni ti wọn fẹ ko jẹ gomina wọn ni Ekiti.
 O ni lati nkan bii osu mesan an seyin, ko tii si akosile isele polio tuntun ni Naijiria, lati ojo kokanlelogun, osu kejo, odun 2016.
” (Gbolohun yìí jáde nítorí àwọn Juu kì í ní ohunkohun ṣe pẹlu àwọn ará Samaria.
Ìyà tí mò ń jẹ ninu ara mi yìí ni èyí tí ó kù tí Kristi ìbá jẹ fún ìjọ, tíí ṣe ara rẹ̀.
won wa sile aare to wa niluu Abuja.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù FRSC dá N443,180 padà fún ẹbí ẹni to ní ìjàmbá mọ́tò 22 Ògún 2019 Oríṣun àwòrán, @FRSC Àkọlé àwòrán, Lara iṣẹ ajọ ẹṣọ oju popo ni lati pese aabo fun ẹmi ati dukia awọn ero loju popo Eyi ko jẹ tuntun pé a n da owo pada fun ẹbi awọn to kagbako ijamba ọkọ -FRSC Ajọ ẹṣọ oju popo ni Naijiria, Federal Road Safety Corps (FRSC) ni ipinlẹ Kebbi ni awọn ti da owo to din diẹ ni ẹgbẹrun lọna aadọta o le ni irirnwo naira pada fun ẹbi awọn to ni ijamba ọkọ.
 O ni” “O ti di dandan fun wa gege bi ijoba lati ri aridaju pe a pese iranlowo to ye fawon agbe wa nipa sise edinwo fun awon olohun ogbin gbogbo loko ati ninu oja ki ero le po lenu ise ogbin iresiO menuba koko pe ogbin iresi lorile ede mii n pese ise fawon eniyan ni bii lorile-ede China, India, Thailand, Vietnam ati beebee lo.
Oríṣun àwòrán, others Idile Efunsetan Aniwura: Idile Obìnrin takuntakun miran nidi kata-kara owo ẹru ni idile Oloye Efunsetan Aniwura, tii ṣe Iyalode keji nilẹ Ibadan.
Buhari  ni iye ibo  308,984 ,lati feyin alatako rẹ  Alhaji Atiku Abubakar  to je oludije fun ipo aare ninu egbe  People’s Democratic Party (PDP) janlẹ nigba ti
Awọn ìkọ yí fihàn pé bí a bá gbaruku ti ara wa kò sí bí a kò ṣe ni jo gbe ní àlàáfíà.
 Lori ipo ti iṣẹ tiata wa: Apasẹ ni gbogbo nkan ti bajẹ patapata nítorí ayelujara ti awọn eeyan ti n wo sinima bayii."
Gómìnà Keji – Gómìnà Ori Omi Adékúnlé Lawal – Gómìnà fún ọdún méjilá – ọdún mejilélógójì titi di ogóji ọdún sẹhin
Gẹgẹ bi ohun ti wọn sọ, ibugbamu alakọkọ waye nigba ti wọn n ṣe adura isin niile ijọsin katoliki lagbegbe ibi ti awọn alakatakiti ẹlẹsin musulumi kan wa.
Àwọn ará Rama ń wárìrì,àwọn ará Gibea, ìlú Saulu sá lọ.
Bi o ti le je pe, Joshua gba lati koju Wilder, leyin ti o fenuko pelu re lori ero ayelujara Instagram, papasibe ojo ifigagbaga ohun waye, ti o si tun re koja lo.
Ṣugbọn wọ́n dáhùn pé, “A kò ní mu ọtí kankan nítorí pé Jonadabu, baba ńlá wa tíí ṣe ọmọ Rekabu ti pàṣẹ fún wa pé a kò gbọdọ̀ mu ọtí, ati àwa ati arọmọdọmọ wa títí lae.
Lanre Kuti ni mo fẹ́ - Jaiye Kuti Uganda kó rọ́bà ìdáàbòbò mílíọ̀nù kan kúrò ní ìlú Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ọmọ Yahoo tú àṣírí ara rẹ̀ fún, bí wọ́n ṣe ń ṣe é BBC Yorùbá Alhaji Oluwatoyin Sulaeman ni lootọ ni ara san pa agbo ẹra arakunrin naa ṣugbọn awọn gbaa gẹgẹ bii iṣẹlẹ amuwa Eledumare eyi ti ko nii ṣe pẹlu wahala tabi edeaiyede laarin awọn darandaran ati awọn ara ilu ti wọn tẹdo sii.
Eyi to mu ko lọ ọ sọ fun iya Arinze.
Wo àwọn àdúgbò tí ìpínlẹ̀ Eko ti fòfin de ọ̀kadà àti Marwa
Kí lẹ ò mọ̀ nípa àwọn obinrin Yollywood yìí?
Àwọn ọmọ Hesironi ni Jerameeli, Ramu ati Kelubai.
Ọpọ awọn ounjẹ yii lo n sofo danu ni ayika wa, ti a ko ka wọn si, ọpọ wọn si lo lee wo awọn eeyan san lọwọ oniruuru arun to n ba wọn ja lai se wahala kankan, ti yoo si tun mu ki agọ ara wa ji pepe.
ti je alaga ijoba ibile ri, o tun figba kan je komisona to n mojuto apawole owo
5 2,246 Isle of Man 25 29.
Alaga igbimọ to n ṣe kokaari iṣuna ilu nile aṣofin agba orilẹede Naijiria, Sẹnatọ Matthew Urhoghide ṣ'alaye eyi lasiko to fi n gbe abajade igbimọ naa kalẹ lori ibi ti ọrọ de duro lori bi awọn ileeṣẹ ijọba ṣe tẹlee ofin naa fun ayẹwo iwe inawo wọn.
Awon agbofinro ni Nikolas Cruz to ti figba kan je akekoo ti won le danu nile iwe ohun ni won fura si pe o se ise ibi yii.
Ṣugbọn OLUWA sọ fún baba mi pé nǹkan dáradára ni pé ó wù ú lọ́kàn láti kọ́ ilé kan fún òun Ọlọrun, 
Àǹfàní wà láti fí ìwé ìrìnnà ránṣẹ́ ṣùgbọ́n àwọn èèyàn kò lòó ni -NIS Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, AFCON 2019: Níbo ni ọ̀rọ̀ owó ajẹmọnu ikọ Super Eagles dé dúró?
13 Èbibi 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Segun fi fídíò ara rẹ̀ sórí ẹ̀rọ ayélujára bí o ṣe ní òògùn apakòkòrò náà dùn fi mu tíì.
Sibẹ ẹ kò fẹ́ tọ̀ mí wá kí ẹ lè ní ìyè.
 iye owó ẹ ̀ yà rẹ ̀ kan tó tún ní àwọn àjẹsára àwàlù eyín , ikọ ́ gbẹ ̀ fun gbẹ ̀ fun , àrùn rọpárọsẹ ̀ , àti ti ọ ̀ fìnkì oríṣi b nínú jẹ ́ 15.
Olotu ijọba ilẹ Gẹẹsi naa lọ wo awọn akọrin Soweto Gospel Choir ti wọn n kọrin ni olu ilu orilẹede Scotland gẹgẹ bii ara ajọdun nla naa.
Àwọn ìròyìn tí ẹ lè nífẹ̀ẹ́ sí: Ayédèrú ‘Sim Card’ ló jẹ́ kí ìjínigbé pọ̀si ní Naijiria - NCC Pẹ̀lú abẹ̀rẹ̀ àjẹsára yìí, ẹ̀fọn kankan kò lè mú àìsàn ibà wá Buhari ń bọ̀ l'Eko: Àwọn ọ̀nà láti yàgò fún àyàfi tí ẹ ba gbé ibùsùn dání Iṣẹ́ àkànṣe tí kò parí ni Buhari ń bọ̀ wá ṣí l‘Eko - Aráàlú figbe ta Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí 3 sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 2:23 Fídíò, Water Generator: Ó leè ṣiṣẹ fún wákàtí mẹfà, kó tó sinmi, Duration 2,2310 Òkùdu 2020 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
Nítorí èyí ni wọ́n ṣe wà níwájú ìtẹ́ Ọlọrun, tí wọn ń júbà tọ̀sán-tòru ninu Tẹmpili rẹ̀.
Buhari vs Atiku: Ẹni tó bá kàwé leè di Ààrẹ, dandan kọ́ ni ìwé ẹ̀rí
Àmọ́ o, kii ṣe adugbo Kudeti nikan ni awọn ọmọ ẹgbẹ yii wa.
8 Lõtọ́, lõtọ́, ni mo wí fún ọ, gẹ́gẹ́bí ìwọ ṣe fẹ́ lati ọwọ́ mi bẹ́ẹ̀ ni yíò rí fún ọ; àti bí ìwọ bá fẹ́, ìwọ yíó jẹ́ ohun èlò tí ṣíṣe rere púpọ̀ ní ìran yìí.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Oniru: Oba Oniru wàjà ní Eko tẹbí, tará ń ṣe ìdárò Alayeluwa Alakoso ile itura naa fidiẹ mulẹ pe onibara ile itura yii ni Adio.
O ní ojúṣe ko ṣee fọ́wọ́yẹpẹrẹ nu láwùjọ nítorí ìwà ìbàjẹ́ àwọn kan láàrín ọlọ́pàá, àti pé àìsí ọlọ́pàá láàrín ìlú lẹnú ọjọ́ mẹ́tà jẹ́ ǹkan ti ó kan gbogbo ará ìlú.
Wo àwọn krìstíẹ́nì tó n wẹ̀ nínú odò tó ní yìnyín láti ṣàjọyọ̀ ìrìbọmi Jesu PDP yóò wọ́de nítorí ìdájọ́ ìdìbò gómìnà ìpínlẹ̀ Imo Ìgbéyàwó ọkùnrin s'ọ́kùnrin, obìnrin s'óbìnrin ti di òfin ní Northern Ireland Harry àti Meghan kò ní lo orúkọ oyè wọn mọ́, wọn kò sì lẹ́tọ̀ọ́ sí owó ilú mọ́ ní UK Gẹ́gẹ́ bí ìyá ọmọ náà ṣe sọ, nígba ti ọmọ sọnú, o ni oludásìlẹ̀ ijọ náà Alufa Babatunde rọ àwọn láti lọ sinmi silé ki wọn si ma fi ọ̀rọ̀ náà lọ ọlọpàá.
Tìrẹ ni ìjọba, a gbé ọ ga bí orí fún ohun gbogbo.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, #BBCGovDebate: Olùdíje 5 ni yóò kópa nínú ìpàdé ìtagbangba l‘Ogun Bi o til jẹ pe oṣu mkta lo ku fun gomina Ambode lori alefa, Tunde fi hande pe ijọba kan n lọ ijọba kan n bọ ni.
“Ọkàn wọn dàrú, wọn kò sì lè fèsì mọ́,bẹ́ẹ̀ ni wọn kò ní ohun kan láti sọ.
" Njẹ awọn janduku ti gbe ọ̀pá àṣẹ ọba ri nilẹ Yoruba?
O ni rara sugbọn ninu oșu kẹta, ẹni kan mu iwe wa fun nitori o n se aisan nigba naa oun si fi iwe naa pamọ.
Ọ̀pọ̀lọpọ̀ òṣìṣẹ́ ni wọ́n gbójú lé kẹ̀kẹ́ wọn gẹ́gẹ́ bí ọ̀ná tí wọ́n fi ń dé ibiṣẹ́ wọn lójoojúmọ́.
Fayose: Mí ò ní èsìí fọ̀ f'áwọn tó ní mo dánìkàn ta ilẹ̀ ẹgbẹ́ PDP ní Ekiti
Ibẹ ni wọn yoo ti mu awọn meji to se daradara julọ.
Akowe agba fun ajo naa, Bako Nabasu naa so pe ko si orile
Ajọ to n gbogun ti iwa ibajẹ ati iwa ajẹbanu ni Naijiria, EFCC ti ri N65, 548, 000: 00 ninu ọọfiisi ajọ eleto idibo INEC nipinlẹ Zamfara.
Awọn ọmọ ile-iwe joko sile nitori iyansẹ̀lodi ọlọ̀jọ̀ mẹ̀ta ni ipinlẹ
Wọn gbé wọ ilẹ̀ ní dédé ààgo mẹta àbọ gééregé tí ọjọgbọ́n Shehu Galadachi tó jẹ olóri fasikti Usma-DanFodio ní Sokoto sáájú àdúrà.
Oludari agba PTF, Sani Aliyu lo kede bẹẹ nigba to n ba awọn akọroyin sọrọ niluu Abuja.
Nigba to ba BBC Yoruba sọrọ, Akọwe Ikede fun Gomina Fayẹmi, Yinka Oyebọde, sọ pe awọn gbese ti ijọba Fayẹmi ba nilẹ, paapa ajẹsilẹ owo oṣu awọn oṣiṣẹ, ni ko ti i jẹ ki anfaani ṣi silẹ lati yan kọmisana.
Amọ Ajagba ti kepe Joshua pe ko jẹ ki awọn ṣe ere ọwọ papọ ni Naijiria, o ni ti o ba ti ya eegun Joshua, o ti ya ọlọrẹ t'oun naa.
Sẹnetọ Dino kede eyi ninu fidio to fi sita loju opo instagram rẹ pe oun yoo fidi gomina Yahaya Bello to wa lori alefa bayii janlẹ ninu idibo to n bọ̀.
Ní ààrin àwọn ọ̀pá fìtílà yìí ni ẹnìkan wà tí ó dàbí eniyan.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Iná PHCN tó dé lójijì ṣàkóbá ńlá ní Ibadan Ni igba to n ka idajọ rẹ, Adajọ Raliatu Adebiyi ni iwadii fihan pe otitọ ni pe awọn ọdaran naa lo ṣekupa oloogbe Sikirat, lẹyin naa lo ni ki wọn lọ yẹgi fun wọn.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Kílódé tí ìjọba Nàíjíríà kò fòpin sí lílo ike rọ́bà lẹ́ẹ̀kan?
Oríṣun àwòrán, Yusuf Mohammed Àkọlé àwòrán, Dele Giwa, Yakubu Mohammed ati dokita Doyin Abiola Iṣẹlẹ naa titi di oni jẹ eleyi ti awọn eeyan ṣi fi n ṣakawe ewu to wa nibi iṣẹ akọroyin ni Naijiria.
Iṣe orin takasufe ni ẹni ọdun mẹrindinlọgbọn naa yan laayo, ilu Elko lo si fi n ṣe ibugbe.
Nígbà tí ó gba ọmú lẹ́nu rẹ̀, ó mú un lọ́wọ́ lọ sí Ṣilo.
Mi o ni tan yin, ko si aawọ kan bi alara lẹgbẹ oselu APC, ohun to wa nilẹ nibẹ ni ikunsinu awọn ọmọ ẹgbẹ si iha kokanmi ti aarẹ Buhari kọ ati bo se n ta kete si ẹgbẹ oselu naa.
A dé ọ̀hùn bí ó ti wi lọ́jọ́ kèjì lóòótọ́, ṣùgbọ́n ọba ti lọ sí oko.
Abija ati àwọn ọmọ ogun Juda pa àwọn ọmọ ogun Israẹli ní ìpakúpa, tóbẹ́ẹ̀ tí ọ̀kẹ́ mẹẹdọgbọn (500,000) fi kú ninu àwọn akọni ọmọ ogun Israẹli.
ede Naijiria INEC ,Yakubu Mahmoud lo fun aare Buhari ni iwe ẹri moyege lati pada wa gẹgẹ bi aare orile ede
Ó wí fún wa pé wa pé ẹni tí ó bá pa ejò ní ìlú àwọn ejò kò ní ṣáì rí ìjà ejò àti pàápàá pé èèwọ̀ ìlú náà ni.
Abiṣai, ọmọ Seruaya wí fún ọba pé, “Kí ló dé tí òkú ajá lásánlàsàn yìí fi ń ṣépè lé ọba, oluwa mi?
Aare Buhari salaye pe, ti a ba n tele ilana ti Jesu la kale yii, a ko ni maa huwa ika, jiji omo gbe, iseku-panu, iwa jegudu-jera, anikan-jopon ati iwa laabi miiran ti o n sakoba fun ilosiwaju orile-ede.
Solomoni, ọmọ Dafidi, fìdí ìjọba rẹ̀ múlẹ̀, OLUWA Ọlọrun wà pẹlu rẹ̀, ó sì sọ ọ́ di ẹni ńlá.
Ó ti wá sáre di ǹkan ìṣeré fún àgbàlagbà lọ́jà, ìrètí sì wà wí pé iye owó rẹ̀ yóò ju £22 billion ($29 billion) lọ títí ọdún 2020.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ekiti Election: Pọpọ sinsin idibo n lọ lori lawọn wọọdi Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Bọ̀dé George: Ìpànìyàn ló yẹ ká dẹ́kun, ká tó máa du ààrẹ Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Biden kọkọ dije fun ipo aarẹ lọdun 1988, àmọ́ o yi ero rẹ padà.
Nígbà tí Ahasi ọba kú, wọ́n sin ín sí Jerusalẹmu, wọn kò sì sin ín sinu ibojì àwọn ọba.
7 30613 Orilẹede Estonia 141 10.
Ọwọ́ ọlọ́pàá ìpínlẹ̀ Kebbi tẹ bàbá àti ìyàwó rẹ̀ méjì fún pé wọn so ọmọ pọ̀ mọ́ ewúrẹ́ fún ọdún méjì Orílẹ̀-èdè Chad pé ọgọ́ta ọdún, àwọn ara ìlú ń pariwo lábẹ́ Aàrẹ Deby tó gba 'Field Marshal' Ẹgbẹ́ òṣèlú ZLP gbàmí tọwọ́tẹsẹ̀ láti díbò gómínà ní Ondo- Agboola Ajayi Àwọn akẹ́kọ̀ọ́ da ìdánwò WAEC rú, wọn gún infijilátọ̀ ní 'compass' Bashir Ahmad to jẹ oluranlọwọ fun aarẹ Buhari lori ọrọ ayelujara ti fi soju opo twitter rẹ pe oun faramọ idajọ iku fun Yahaya Sharif.
tun ni awọn  apaniyan daran-daran irinwó(400) lo ti
Ọ̀jọ̀gbọ̀n Pius Adesanmi kú nínú ìjàmbá bàálù Ethiopia!
uk Ninu ọrọ rẹ, Ọga agba fun BBC News Pidgin, Adejuwon Soyinka, sọ pe eto arokọ kikọ ileeṣẹ iroyin BBC News Pidgin ti n di itage fun igbelarugẹ awọn ọdọ to jẹ onkọwe ati alarojinlẹ ni ede Pidgin to jẹ ede to gbajumọ laarin awọn ọdọ ilẹ Afrika."
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Aarẹ Trump fi igunpa gun gbogbo agbaye CHINA: Ni ọdun 2017, aarẹ Donald Trump ṣe apejuwe adari ilẹ China, Xi Jinping gẹgẹ bi ọrẹ oun ti awọn si jọ fẹran ounjẹ aladun bii sokoleeti.
 Àwọn ni àwọn ọmọ tí a sọ di òrìṣà nítorí ìbí tí a bí wọn .
Nígbà tí àkókò Àjọ̀dún Ìrékọjá ku ọjọ́ kan, Jesu mọ̀ pé àkókò tó, tí òun yóo kúrò láyé yìí lọ sọ́dọ̀ Baba.
Ẹni ti isẹlẹ naa soju rẹ, ọgbẹni Muritala Rauf salaye wi pe ọkọ akero naa to n bọ lati agbegbe Ikarẹ ni o padanu ijanu ọkọ rẹ, ti awakọ si duna-dura lati yẹwọ fun ọkọ ayọkẹlẹ ti o wa lẹgbẹ ọja naa.
Tọba-tijoye, olowo ati mẹkunnu lo maa n ra ẹwa sise rẹ fun jijẹ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Asisat Oshoala: ìbẹ̀rẹ̀ mi kò rọrùn rárá nínú eré bọ́ọ̀lù Ki lo ti ṣẹlẹ tẹlẹ?
Gẹ́gẹ́ bi ọ̀rọ̀ Yorùbá ti ó sọ wi pé “Olóri Ẹbi, Baba Bùkátà”, iṣẹ́ nla ni lati jẹ Olóri Ẹbi, ó gba ọgbọ́n, òye àti ìnáwó lati kó ẹbi jọ.
idibo si  ijọba ibilẹ ni ipinle Bayelsa yoo
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Abẹ́rẹ́ àjẹsára nítorí covid-19 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 3 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 5 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Pẹlu iye awọn eeyan tuntun yii, o ti pe 57,145 eeyan to ti ni arun naa l'orilẹede Naijiria bayii.
Lásìkò igbele Covid-19 yìí náà ni Foluke Daramola tún lọ kí bàbá Feyikọgbọn nílé láti fun ní ẹ̀bùn owó èyí tó mú káwọn èèyàn kan rò pé ìyà ló ń jẹ bàbá yìí, tí Foluke ṣe lọ fún ní owó.
O ni:  A gbero igbese tuntun yii ki awon akosemose onisegun oyinbo le wa ni arowoto awon eniyan igberiko ki ero to n wa sile iwosan ijoba nigboro le tubo dinku sii.
Ìtàn ìgbé ayé Isola Ogunsola 'I-sho Pepper', ògbóǹtagí òṣèré tíátà tó s'eré Yorùbá yíká Nàìjíríà Ọwọ́ ọlọ́pàá tẹ ọkùnrin mẹ́rin pẹ̀lú orí èèyàn ní ìlú Akure Mọ síi nípa ohun tó ṣẹlẹ ní àwọn ibi tí wọn ti ṣilẹkùn ilé ìwé padà lẹyìn Covid 19 Awọn ara adugbo lo figbe ta nigba ti wọn n gbo igbe ọkan lara awọn ọmọ ọhun loru ọganjọ nigba to n ba laṣẹpọ.
Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 3 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Mauritania ni orílẹ̀-èdè tí ó gbẹ́yìn láti pa òwò-ẹrú rẹ ní àgbáyé ní ọdún 1981, ṣùgbọ́n wọn kò fi ìdíi rẹ̀ múlẹ̀ títí di ọdún 2007, ìdá 20 àwọn ènìyàn ni wọ́n ṣì ń gbáyé ìṣẹrúsìn tí púpọ̀ nínú wọn sì jẹ́ aláwọ̀ dúdú tàbí elẹ́yà-méjì.
Ṣe ẹ mọ pe ẹkọ ẹlẹkọ lẹgba ẹlẹgba, nibi ti awọn kan ti sọ pe Modric ko yẹ fun ami ẹyẹ FIFA, bẹẹ naa lawọn kan ni agbabọọlu Modric lo pegede julọ lọwọ yii ninu gbogbo awọn agbabọọlu ọkunrin lagbaye.
Ẹ̀yin ará, ẹ wo àpẹẹrẹ àwọn wolii, àwọn tí wọ́n sọ̀rọ̀ ní orúkọ Oluwa pẹlu sùúrù ninu ọpọlọpọ ìpọ́njú.
Ǹjẹ́ mo tílẹ̀ ti ní àrùn Coronavirus?
Ṣaaju ni ijọba Naijiria ti ṣi awọn ile ijọsin, eto irinna ọkọ ofurufu nile tai nilẹ okeere ati awọn igbesẹ miran.
Dangote ni awọn agbekalẹ ilana ati eto iṣejọba ti Aarẹ Buhari gbe kalẹ ti ro awọn agbẹ lagbara ti awọn pẹlu si lee fi ọwọ sọya lawujọ pe iṣẹ ọwọ wọn n to wọn jẹ ti wọn si fi n pa owó sapo.
Risikat olójú búlù dí aya Wasiu ní ìlànà Islam, tẹbí tará péjú síbẹ̀ Oríṣun àwòrán, @Mohammed Jagunma ati Gold Abdulrafiu Loni, ọjọ Satide, ọjọ karun un, oṣu kẹsan an ni Baba Kausara àti Iya Kausara di ara kan naa bii lọkọlaya ninu ẹsin Islam ni Ilorin ni ipinlẹ Kwara.
Ẹnikẹ́ni tí kò bá wá, pípa ni a óo pa á.
Ṣugbọn Jakọbu lọ sí Sukotu o kọ́ ilé kan fún ara rẹ̀ ó sì ṣe àtíbàbà fún àwọn ẹran rẹ̀.
Ìwọ ni o kò jẹ́ kí ọwọ́ ọ̀tá tẹ̀ mí,bẹ́ẹ̀ ni o kò jẹ́ kí ẹsẹ̀ mí kí ó yẹ̀.
8% Gbigba bọọlu si oju ile 4 2 Gba bọọlu 11 5 kọna 6 1 Ṣẹ sofin 22 19 Awọn agbabọọlu ti wọn yan Awọn ti wọn o kọkọ bẹrẹ Nigeria 16 Akpeyi 3 Collins 22 Omeruo 5 Troost-Ekong 20 Awaziem 18 Iwobi 7 Musa 4 Wilfred Ndidi 8 Peter Etebo 13 Chukwueze 9 Ighalo South Africa 22 Williams 14 Hlatshwayo 5 Mkhize 2 Mkhwanazi 18 Hlanti 8 Zungu 12 Mokotjo 15 Furman 19 Tau 9 Mothiba 23 Lorch Awọn iyipada 81 Musa                                                                  down Simon                                                              up 91 Iwobi                                                                  down Balogun                                                              up 58 Lorch                                                                  down Zwane                                                              up 86 Mothiba                                                                  down Veldwijk                                                              up Awọn ti wọn paarọ 17 Kalu 23 Uzoho 21 Osimhen 15 Simon 19 Ogu 11 Onyekuru 10 Mikel 1 Ezenwa 14 Paul Onuachu 2 Ola Aina 12 Shehu 6 Balogun 3 Maela 7 Maboe 20 Kekana 6 Mphahlele 16 Bvuma 11 Zwane 4 Cardoso 17 Vilakazi 10 Serero 13 Mabunda 21 Veldwijk 1 Keet Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Imọran: Ti o ba fura pe o ko gbadun ibalopọ bii ti tẹlẹ, lọ kan si dokita rẹ fun itọju to pe ye.
Wakati mẹ́rìnlélógún ni awon onifayawo fi n sise, bee gege ni awa naa n lo wakati mẹ́rìnlélógún lati fi sise wa.
Àwọn eṣú wọnyi dàbí àwọn ẹṣin tí a dì ní gàárì láti lọ sójú ogun.
Ọ̀kan nínú àwọn tí ó tún ṣe àròyé fún Aṣojú-Olódùmarè lẹ́ẹ̀kejì yìí ni ọkùnrin kan tí ó kọ́ wí pé ìwà ọ̀gá òun le púpọ̀, ó tí bọ́ sí ọ̀dọ̀ọ̀gá mìíràn tí ó tuutù ju omi àmù lọ, ṣùgbọ́n àwọn ẹlòmíràn bẹ̀rẹ̀ sí rẹ́ ọkùnrin yìí jjẹ, ìwọ̀sí tí wọn kò sì fi lọ̀ ọ́ nígbà tí ó wà lábẹ̀ ọ̀gá líle ni wọ́n fi ń lọ̀ ọ́ nígbà tí ó bọ́ sí abẹ́ ọ̀gá rírọ̀ yìí, kò sì ní ìlọsíwájú kan ṣoṣo.
Ọ̀rọ̀ ẹnu òmùgọ̀ dàbí pàṣán ní ẹ̀yìn ara rẹ̀,ṣugbọn ọ̀rọ̀ ọlọ́gbọ́n a máa dáàbò bò ó.
Ile ẹjọ kan ni agbegbe Ikẹja nipinlẹ Eko ti ni ki ayalegbe kan san miliọnu meji owo gba mabinu fun ayale ẹgbẹ rẹ nitori eefin ẹrọ amunawa.
Lẹyin o rẹyin ni wọn kẹsi ọlọpaa ti ayẹwo iṣegun ṣi fihan nipa iku gbigbona ni oloogbe ku lẹyin ti wọn fi ipa baa lopọ tan.
Àwọn ọ̀dọ́ ọmọ ogun ni wọ́n ṣáájú ogun Israẹli, wọ́n bá lọ ṣígun bá Benhadadi.
Ọwọ́ ọlọ́pàá tún tẹ afurasí tó fipá bá odi àti adití lòpọ̀ nílùú Ibadan Ojú Shagbada Erigga rèé lẹ́yìn tó pa ọ̀rẹ́bìnrin rẹ̀ l'Akinyele ní Ibadan Àwọn ọmọ onílẹ̀ lọ ṣe àmúṣẹ àṣẹ iléẹjọ́ ní Soka, làwọn ‘Jàǹdùkú’ fi dá wọn lọ̀nà - Iléeṣẹ́ ọlọ́pàá Ọyọ Auxiliary ń ní wá lára pẹ̀lú gbígba owó aitọ, a ń ko ọkọ̀ wa kúrò lójú pópó - Awakọ èrò Ọgbẹni Enwonwu sọ pe, aṣiri ajọdun ọlọdọọdun ẹgbẹ okunkun Aiye to maa n waye lọjọ keje, oṣu Keje, ti tu si ileeṣẹ ọlọpaa lọwọ.
Pẹlu iye awọn eeyan tuntun yii, o ti pe ẹgbẹrun mẹrindinlọgọrin o le mẹrindinni irinwo, (76, 396) eeyan to ti ni arun naa ni orilẹede Naijiria bayii.
Igbọnwọ kọ̀ọ̀kan ọ̀pá tirẹ̀ jẹ́ igbọnwọ kan ati ìbú àtẹ́lẹwọ́ kan, (ìdajì mita kan).
Wọ́n fọn fèrè, gbogbo wọn sì hó pé, “Kí Solomoni, ọba, kí ó pẹ́.
Wọ́n bá sọ fún Baruku pé, “A gbọdọ̀ sọ gbogbo ọ̀rọ̀ yìí fún ọba.
OLUWA, Ọlọrun mi, ìwọ ni mo sá di;gbà mí là, kí o sì yọ mí lọ́wọ́ àwọn tí ń lépa mi.
"Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: ""Apena fẹ́gbẹ́ Oṣugbo, Opa, Akala àtẹ̀yin awo, ẹ wa ọ̀pá àṣẹ Ọ́ba Akiolu jáde"" Májèlé olóró lẹ jí l‘Ekiti dípò èròjà oúnjẹ Covid-19 - Ariwo sọ lórí ayélujára Ẹ sọ́ra fún ìwà olè àti jàgídíjàgan nílẹ̀ Yorùbá-Sunday Igboho ₦147m la rí kójọ fún ìwọ́de, a kò fẹ́ owó mọ́, ìwọ́de ti parí - Feminist Coalition Sanwo-Olu kéde ìlànà ìséde tuntun l'Eko Ìjọba ìpínlẹ̀ Kwara sọ̀rọ̀ lórí bí àwọn kan se lọ pín ""CaCovid 19 Palliative"" ní Ilorin pé."
O ni oun setan lati pa iṣẹ da ati lati pa ise awon Obayejẹ oloselu da.
gbaruku ti alaafia orilẹ-ede yii siwaju” Agbẹnusọ naa sọ eyi.
Ohun tí a mọ̀ nìyí nípa gbọ́nmi síi omi ò tó lórí ọ̀rọ̀ oyè Babaloja-General ní ìpínlẹ̀ Oyo Mi ò fẹ́ ìrànwọ́ ẹgbẹ́ òṣèré, àwọn kọ́ ló kóbá mi- Chief Kanran Ọkùnrin kan da ṣọ́ọ̀ṣì rú lásìkò ìgbéyàwó, Ó ní òun lọkọ àárọ̀ ìyàwó tuntun Gbajúgbajà òṣèré “Blue film'' wọ gàù ẹ̀sùn fífipá bá obìrin 13 lòpọ̀ Atẹjade naa sọ pe ko si idarudapọ kankan laarin ẹgbẹ YWC 'a o si si ninu fa ki n fa a pẹlu ẹnikẹni tabi ẹgbẹ kankan.
Gbogbo ẹni tí ó bá ń ṣe ti òtítọ́ yóo gbọ́ ohùn mi.
Tí a fiṣọwọ́ ní 12:42 29 Èbibi 201912:42 29 Èbibi 2019 El Rufai búrawọlé fún sáà kejì ní ìpínlẹ̀ Kaduna BBCCopyright: BBC Gomina Nasir El RufaiImage caption: Gomina Nasir El Rufai Article share tools Facebook Twitter ṢàpínlòView more share options Share this post Copy this linkKà síwájú síi nípa àwọn ìtọ́kasí wọ̀nyí.
Ṣugbọn Galio kò pé òun rí wọn.
Bí mo bá sì ti fi ọ̀nà èrú gba ohunkohun lọ́wọ́ ẹnikẹ́ni, mo ṣetán láti dá a pada ní ìlọ́po mẹrin.
Ọba Babiloni ranṣẹ sí gbogbo àwọn eniyan, ati gbogbo orílẹ̀-èdè ati ẹ̀yà ní gbogbo ayé, pé:“Kí alaafia wà pẹlu yín!
Fidio naa to jade sori ayelujara lọjọ Iṣẹgun fi sẹnetọ Elisha Abbo han nigba to ku giiri si obinrin to ni ṣọọbu itaja eroja adun ibalopọ nilu Abuja to si luu bi ẹni lu bara.
Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Doctors on Strike: Coro wà Coro ò sí o, èmi á lọ́ sókè òkún bí mo bá ríṣẹ́ - dókítà17 Agẹmo 2020 Fídíò, Coronavirus Update: Omi mímu wọ́n ju owó ilé lọ nílùú yìí4 Ògún 2020 Fídíò, Zoom Wedding: Àwọn ọkọ àti ìyàwò ló ní àwọn kò leè sún ọjọ́ ayọ̀ wọn síwájú.
“Ní ọdún kinni ìjọba Kirusi ni ó pàṣẹ pé kí wọn tún ilé Ọlọrun tí ó wà ní Jerusalẹmu kọ́ fún ìrúbọ ati fún ọrẹ ẹbọ sísun.
Níbẹ̀ ni ẹ óo ti wá OLUWA Ọlọrun yín tí ẹ óo sì rí i, tí ẹ bá wá a tọkàntọkàn pẹlu gbogbo ẹ̀mí yín.
Á ràgà bo CCTV Lekki bí i ẹ̀rí tó dájú fún ìwádìí ìpànìyàn - Sanwo-Olu Oríṣun àwòrán, @jidesanwoolu Gomina ipinlẹ Eko, Babajide Sanwo-Olu tun ti sọrọ lori isẹlẹ ipaniyan to waye ladugbo Lekki lọjọ isẹgun.
Bakan naa lo ṣalaye pe atunṣe awọn oju popo ati oju odo yoo waye pẹlu ki ipinlẹ Eko lee tẹsiwaju gẹgẹ bii aayo awọn oludokowo gbogbo.
Ṣugbọn ẹ tàbùkù orúkọ mi nígbà tí ẹ sọ pé pẹpẹ OLUWA ti di àìmọ́, tí ẹ sì ń fi oúnjẹ tí ẹ pẹ̀gàn rúbọ lórí rẹ̀.
Oríṣun àwòrán, Twitter/@abdi_adaani Àkọlé àwòrán, Agbesunmọmi to wa nidi ibugbamu naa wa ọkọ to gbe ado oloro wọ inu ọgba oun ni Salah Hassan Omar to jẹ osisẹ ijọba lagbegbe naa sọ pe awọn ọmọ ogun mẹta to ku ko agbako nigba ti wọn dina mọ ki agbesunmọ naa ma gbe ọkọ to fẹ fi se isẹ ibi naa wọnu ọgba ile isẹ ijoba kan.
Iye atẹranṣẹ ti awọn eniyan ti fi ránṣẹ lori ayelujara ni New York, Paris, London ati Berlin ti lọ soke si ni ìlọ́po mẹta laarin ọsẹ diẹ.
Àwọn àdúgbò Ibadan gborúkọ tuntun látẹnu Ajimobi Oní gègé àrà Oladejo Okediji d'ẹni ilẹ!
Bakan naa ni Olukọ Agba fun ile ẹkọ Deeper Life High School, Ndidi Solomon, sọ fun BBC pe, wọn ti fun oun ni iwe idaduro ranpẹ lẹnu iṣẹ, amọ ko sọ ju bayii lọ nitori pe ijọba ti gba akoso ọrọ naa.
Ida okooleleedegbeta ati mẹrin, (524%) ni ipin idokoowo ileeṣẹ Tesla ti fi lọ soke lọdun 2020, Eyi to mu ki alekun ọ̀rọ̀ Musk o le pẹlu nnkan bii ọgọrun un biliọnu dọla ($100 billion) Wo dókítà ọmọ Nàìjíríà tí àgbáyé ń wárí fún nítorí abẹ́rẹ́ àjẹsára COVID-19 Kí lo mọ̀ nípa ìbẹta kan ṣoṣo tí Alaafin Oyo bí?
Ki lo sẹlẹ nilu Efon Alaaye lọdun 1949?
Olakunri sọ eyi lasiko isin ikẹyin fun oloogbe naa, ni ibi ti arakunrin naa ti sun ẹkun kikoro lasiko to n se idaro iyawo rẹ.
Ira, ará Itiri, ati Garebu ará Itiri, 
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: NURTW yóò fikùlukù pẹ̀lú Gómìnà Makinde láìpẹ́ Àwòran bó ṣe ń lọ káàkiri àwọn Yídì rèé Buhari ṣèlérí tuntun fún Nàìjíríà fún ìtúnu àwẹ̀ Atẹjade naa fikun pe, Ọbasanjọ ni oun fara mọ igbe ti Aisha n mu bọnu lasiko yii, ti nkan ko fara rọ lẹka eto aabo wa nitori bi ara ile ba n jẹ kokoro buruku, bi a ko ba tete kigbe sita, huru-hẹrẹ rẹ ko ni jẹ ka sun lori.
Yoruba ni aidun ọsan la a mu mejila, bi ọsan ba dun, eeyan yoo mu igba.
Unagha gẹ́gẹ́ bí ọ̀rọ̀ rẹ̀, 'ẹgbẹ́ òṣèlú APC kò ní jáwé olúbori níwọ̀n ìgbà ti Adams Oshiomole bá ṣì jẹ́ alága àpapọ̀ ẹgbẹ́'.
O ni irufẹ iwa bẹẹ tako abala kini ofin kejidinlogun to de ihuwasi ninu ile eto ẹlẹgbọn agba BBNaija.
Àwọn eniyan mi ti pinnu láti yipada kúrò lọ́dọ̀ mi, nítorí náà n óo ti àjàgà bọ̀ wọ́n lọ́rùn, kò sì ní sí ẹni tí yóo bá wọn bọ́ ọ.
Nike ti safihan awon ohun elo tuntun ti iko agbaboolu Super Eagles’ yoo lo ninu idije boolu agbaye to n bo lona lorile-ede Russia lojo-Ru (Wednesday), nilu London.
Liverpool ni o di ipo keji mu ni saa liigi to kọja yoo si maa lepa ati gba liigi naa lọdun yii lẹyin to ti gba ife ẹyẹ Champions league ni saa bọọlu to kọja.
25 Ìgbé 2020 Ijọba ipinlẹ Oyo ti sọ idi ti awọn fi kọ irẹsi to lẹ ti ẹgbẹsan ti ijọba apapọ fi ransẹ si wọn Awọn alabojuto eto ounjẹ nipinlẹ Oyo ti wọn fi lede fun awọn ara ipinlẹ Oyo.
Dayo Amusa ninu fidio to gbe sita naa sọ pe, o ti di iwa ọdaran ni orilẹ-ede Naijiria lati se irun atọwọda Dàda sórí.
Ọti bia nikan kọ lo n sokunfa bi ikun se n tobi, amọ eroja ọra kan ti wọn pe ni 'Visceral' lo n sokunfa ikun to tobi.
Kìí ṣe ààrùn Covid-19 ló pa adájọ́ àgba ìpínlẹ̀ Kogi-Kọmísọ́nà ìlera Ni bayii, wọn ni ọkan wọn ko balẹ lori idojukọ ti yoo tẹle ṣiṣi daamu Ọyan naa, papa lasiko ajakalẹ arun Covid-19 yii.
Èmi kò ní kí Shiite má ṣe ẹ̀sìn won o -Muhammadu Buhari PDP: Ẹní ṣe nǹkan ètùfù ní kíyèsí ẹ̀hìnkùlé, ọmọ ẹgbẹ́ wà kò hùwà àìtọ́ lásìkò ìdìbò Ṣé irúfẹ́ oúnjẹ tí ò ń jẹ́ lè jẹ́ kí o gbádùn ìbálòpọ̀ rẹ síi?
Ifowosowopo lati gbogun ti awon isoro to n koju eto-abo
Bakan naa, ikọ oniroyin BBC Yoruba naa ti n ko iroyin jọ.
 Abdullahi Zulkifli soro yii lasiko ti ile ise naa n se afihan eru fayawo
Ṣugbọ́n ọkan lára àwọn ọmọ ilé ìgbìmọ̀ aṣòfin Ipinlẹ Ekiti Samuel Omotosho ti ni oun ni oun ni ọkan lara awọn ile naa.
Awọn kan gbagbọ pe iyanjẹ ati mago-mago lo gbe Aarẹ nigba kan, Goodluck Jonathan wọle sipo aarẹ, ti wọn si bẹrẹ si ni fa wahala.
Ìyà ń jẹ Efuraimu, ìdájọ́ ìparun sì ti dé bá a, nítorí pé, ó ti pinnu láti máa tẹ̀lé ohun asán.
“Sibẹsibẹ ẹ̀ ń sọ pé, ‘Kí ló dé tí ọmọ kò fi ní jìyà ẹ̀ṣẹ̀ baba rẹ̀?
Kò tán síbẹ, oníròyìn ni, ó fi eré ìtàgé gbé èdè Yorùbá lárugẹ nipa di dá ẹgbẹ́ ọ̀dọ́ Ọ̀yọ́ fún ìgbéga eré ìtàgé silẹ̀ ni ọdún mejidinlaadọrin sẹhin.
Kọmiṣọnna fun eto ọgbinHeriat Adenike ni kọmiṣọnna fun ile iṣẹ ijọba to n ṣakoso eto iṣẹ agbẹ.
Egbe agbaboolu ,U-17 orile ede Naijiria lo jawe olubori ni ipele B, ninu ere idaraya ti ile orile ede Afirika (WAFU) ni eyi to waye ni ojo Aje.
ki won si dibo fun eni ti won ba fẹ laijẹ pe enikankan dun ikooko mọ wọn .
Oríṣun àwòrán, Facebook/Ike Ekweremadu Ninu ọrọ ti Sẹnẹtọ Ekweremadu fi soju opo Facebook rẹ, o ni oun ko ni gbe iṣẹlẹ naa sọkan nitori oun mọ pe awọn eeyan ko mọ ohun ti wọn n ṣe.
La ọ̀nà fún idà kan láti gbà wọ ìlú Raba ní ilẹ̀ Amoni, kí o sì la ọ̀nà mìíràn fún idà láti gbà wọ ilẹ̀ Juda ati ìlú Jerusalẹmu tí a mọ odi yíká.
Nígbà tí mo lọ sí Jerusalẹmu, àwọn olórí alufaa ati àwọn àgbààgbà àwọn Juu rojọ́ rẹ̀, wọ́n sì bẹ̀ mí pé kí n dá a lẹ́bi.
Ṣé ti ẹni to fi gúrúrú ṣe ọ̀ṣọ́ sí ara aṣọ ni tàbí èyí to lo ẹ̀pà láti ràn aṣọ tírẹ̀ Àkọlé àwòrán, Imúra tó lààmìlaka lọdún 2018 ni aṣọ ẹlẹ́pà yìí.
To da ọ loju pe yoo wa sile ẹjọ lọjọkọjọ ti ile ẹjọ ba sọ pe ko wa, ti ko ni salọ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù JAMB Result 2019: 34,120 akẹ́ẹ̀kọ́ ni kò ní èsì ìdańwò JAMB 11 Èbibi 2019 Oríṣun àwòrán, JAMB Àkọlé àwòrán, Ajọ JAMB ní àwọn akẹ́ẹ̀kọ́ lè wo èsì ìdánwò nípa títẹ àtẹ̀jísẹ́ 'RESULT' si '55019' láti wo iye tí wọn gbà nínú ìdánwò náà.
Nítorí òkúta yóo kígbe lára ògiri, igi ìdábùú òpó ilé yóo sì fọhùn pẹlu.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Fásitì Ibadan: Kò sí àkẹ́kọ̀ọ́ obìnrin tí wọ́n fipá bá lòpọ̀ 12 Agẹmo 2019 Oríṣun àwòrán, University of Ibadan Eemọ nla lo wọ ileekọ fasiti Ibadan mọjumọ ọjọ Ẹti nigba ti awọn adigunjale to to mẹwa niye ba ibugbe awọn obinrin, Obafemi Awolowo, to wa ninu ọgba ileekọ naa lalejo.
Àwọn ilé iṣẹ́ ìtójú ẹranko kan ni ilẹ gẹẹsi ti wọ́n pe ni PDSA lo fún ni àmì ẹyẹ náà nítori iṣk ribiribi tó n ṣe lati dóòlà ẹmi àwọn ènìyàn, pàápàá jùlọ láwọ́n ibùdó to ti ṣiṣẹ́ ni Cambodia.
Oríṣun àwòrán, Facebook/Funke Oshinaike Amọ Funke Oshonaike sọ pe iriri naa ko buru jai ni tootọọ ṣugbọn o ti ran oun lọwọ lati gba ọpọ obinrin ti wọn n la iru rẹ kọja niyanju.
OLUWA ni mò ń wò lójú nígbà gbogbo,nítorí òun ni yóo yọ ẹsẹ̀ mi kúrò ninu àwọ̀n.
Ninu akosile iranse kan, ti o fi sowo si awon akoroyin ile-igbimo asofin, minisita ohun so pe, “ni bayii, iye awon akekoo ti won da sile je mokanlelogorun, o seese ki a ba awon omode-binrin naa pade ni Maiduguri”.
Ọba Siria yóo kó ọpọlọpọ ogun jọ, ṣugbọn Ijipti yóo ṣẹgun rẹ̀.
Ọjọ kinni oṣu erele (February), ọdun 1524 Lọdun 1523, ẹgbẹ awọn kan ti wọn ro pe awọn lee ri ọjọ iwaju ni ilu London sọtẹlẹ pe ọjọ kinni, oṣu keji, ọdun to tẹle e ni ẹkun omi yoo pa aye rẹ.
Bóyá yóo yé wọn bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé ọmọ ọlọ̀tẹ̀ ni wọ́n.
Bakan naa lo ni ọpọ awọn oloselu ni yoo dero ọrun lairotẹlẹ nitori ikọlu oselu lọdun 2021.
Oríṣun àwòrán, @NationalAssembly Nigba to n fesi lori akiyesi yii, Lawan fọwọ sọya fawọn akẹẹgbẹ rẹ atawọn ọmọ Naijiria pe, aarẹ Buhari ko ni pẹ fi orukọ naa sọwọ, eyiun ki ọsẹ yii to pari.
oṣu oṣiṣẹ to kere julọ ohun.
Ẹ gbọ oun ti wọn sọ.
Ajá ni yóo jẹ òkú ẹnikẹ́ni ninu ìdílé rẹ tí ó bá kú láàrin ìlú; ẹni tí ó bá sì kú sinu igbó, ẹyẹ ni yóo jẹ òkú rẹ̀, bẹ́ẹ̀ ni OLUWA wí.
Ní kété tí Mose parí ọ̀rọ̀ rẹ̀, ilẹ̀ tí wọ́n dúró lé lórí là sí meji, 
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ọgbà ẹ̀wọ̀n ni wọ́n ti já àbálé Esra lábẹ́ àwáwí àyẹ̀wò wúndíá Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Ọwọ́ tẹ afurasí 8 tó jí akẹ́kọ̀ọ́ Chibok gbé Ilé ìgbìmọ̀ aṣòfin Ekiti yọ abẹnugan rẹ̀ Ta ni Mohammed Dewji?
Àwọn wọnyi ni ìran Ehudu: (Àwọn baálé baálé ninu ìran Geba, tí wọ́n kó lẹ́rú lọ sí ìlú Manahati): 
Opolopo awon eniyan jankanjankan lo ti wa ni gbagede
28 Bélú 2019 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Pupọ akẹkọọ lo pa ẹkọ rẹ ti nigba ti wahala awọn ọmọ ẹgbẹ okunkun ba fẹ yọ ile aye l'ẹmi wọn.
Koda, awọn ikọ alaabo kan niluu naa n sọ pe awọn lawọn ṣokunfaa bi ọwọ ọlọpaa ṣe tẹ ẹ pada.
Oríṣun àwòrán, AFP/Getty Images Àkọlé àwòrán, Ikọ alakatakiti Al-Shabaab sepade pẹlu awọn alakoso papa isire nilu Mogadishu Bi o tilẹ jẹ wi pe ko si ẹni to fẹ sọ ohunkohun lori ọrọ yii lati iha ijọba tabi awọn alakoso papa isire aladani ni orilẹede Somalia, sugbọn iroyin fi idi rẹ mulẹ wi peko si papa isire kan bayii ti wọn ti n gba bọọlu lorilẹede Somalia, bẹẹni ibẹru bojo ko jẹ ki awọn olugbe ilu Mogadishu.
Àkọlé àwòrán, Arabinrin yii ni oun na ko gbẹyin Àkọlé àwòrán, Ẹrin muṣẹ!
Àwọn ẹnubodè rẹ̀ ti di ahoro,àwọn alufaa rẹ̀ sì ń kẹ́dùn.
Kilo TNT (ti wọn fi n ṣe ado oloro) ti wọn ti fi pamọ si abẹ ọkọ rẹ bu gbamu.
'Bi eeyan ba tapa si ofin, ọlọpa yoo mu iru ẹni bẹẹ, bi ara ilu ba wuwa aitọ nipa ayika, nibo lawọn wolewole wa ti yoo mu iru ẹni bẹẹ?
"O ni ""Nnkan ko rọgbọ bi orillẹ-ede yi ṣe jẹ olu ilu awọn to toṣi julọ lagbaye, bẹẹ naa ni ọpọlọpọ awọn ọmọde to yẹ ko wa ni ileewe n fẹsẹ gbalẹ kiri."
Awọn gomina na N2trn ni ọdun mẹwaa Bakan naa, igbimọ awọn gomina Naijiria ti ni awọn gomina ipinlẹ mẹrindinlogoji orilẹ-ede yii na N2trn ni aarin ọdun mẹwaa lati ṣe iranlọwọ for ileeṣẹ ọlọpaa.
Adajọ ni Taiwo Bamidele Ezekiel ni ile ẹjọ Majisireeti ipinlẹ Ondo.
Nígbà náà ni àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ wá sọ́dọ̀ rẹ̀, wọ́n sọ fún un pé, “Ǹjẹ́ o mọ̀ pé nígbà tí àwọn Farisi gbọ́ ọ̀rọ̀ rẹ, ó bí wọn ninu?
Ẹwẹ, ninu oṣu kẹta, Tara Reade fi ksun kan an pe o fi agiditi oun mọ ara ogiri to si fipa ba a lopọ ni ọgbọn ọdun sẹyin nigba to n ṣiṣẹ gẹgẹ bi oṣiṣẹ oluranlọwọ ni ọfiisi rẹ.
      Ajimobi  bura fun awon akowe ile ise ijoba  mọ̀kànlá ni ipinlẹ Ọyọ   Bakan naa ni o tun mu igbega ba ile eko
N kò ní jẹ́ kí o gbọ́ ẹ̀gàn àwọn orílẹ̀-èdè mìíràn mọ́, bẹ́ẹ̀ ni àwọn eniyan kò ní dójútì ọ́ mọ́, n kò sì ní mú kí orílẹ̀-èdè rẹ kọsẹ̀ mọ́.
oludije fun gomina labe asia egbe APM Adekunle Akinlade yoo jawe olubori ninu
Ó dide, ó dúpẹ́ lọ́wọ́ gbogbo àwọn ti ó joko, ó yan Olóri Ẹrú  gẹgẹ bi àwọn àgbà ti gba a ni ìyànjú.
Nígbà tí mo rí Ìnàkí-ìbẹ̀rù ẹ̀rù bà mi.
Ọgbẹni Abimbọla Oyeyẹmi lo fi ọwọ idaniloju naa sọya nigba to n ba BBC Yoruba fọrọ jomi tooro ọrọ lori agbekalẹ ẹka aabo alajumọse nilẹ Kaarọ Oojire.
Ta ni Ààrẹ tuntun tí wọn yóò búra wọlé fún ní Burundi lónìí?
Ọdọmọkunrin alufaa yìí sì wà ní ẹnu ibodè pẹlu àwọn ẹgbẹta (600) ọkunrin láti inú ẹ̀yà Dani tí wọ́n ti dira ogun.
Ọjọ kẹrinla, oṣu Keji, ọdun 2020, ni iroyin jade sita pe, Oluwo ti Iwo na Agbowu ti Ogbaagba nibi ipade alaafia ti Igbakeji Ọga ọlọpaa pe, lati yanju wahala to n waye laarin awọn ọba mẹjọ kan, ati Oluwo.
Secret Cult in Ogun: Iléeṣẹ́ ọlọ́pàá fojú afurasí ẹlẹ́gbẹ́ òkùnkùn hàn ní Ijebu Ode
“Ẹ wá wo ọkunrin tí ó sọ gbogbo ohun tí mo ti ṣe fún mi.
Nígbà tí ìròyìn ohun tí ó ṣẹlẹ̀ sí Tire bá dé Ijiptiàwọn ará Ijipti yóo kérora.
Ẹni to bori: Namibia South Africa vs Uganda.
Wọn óo kó àwọn ọmọ rẹ ọkunrin ati obinrin lọ, wọn óo sì dáná sun àwọn tí wọ́n kù.
Láti Ayé, Júpítérì le ní ìhàn ìtóbi −2.
Ṣugbọn bíi ìsọkúsọ ni gbogbo ọ̀rọ̀ yìí rí létí wọn.
Oríṣun àwòrán, @ngige Àkọlé àwòrán, Ọrọ n bá ọrọ bọ Chris Ngige to jẹ minista fun ọrọ iṣẹ ni Naijiria ni tootọ ni ijọba ṣe ipade pẹlu ASUU ni eyi ti wọn ti jọ n sọ asọyepọ lori awọn nkan ti ASUU n fẹ.
Ègbè tí àwọn òǹwòran lè kọ tẹ̀lé orin, ní ìdásí àti ìdáhùn tí í ṣe àṣà calinda, tí calypso  àti àdàlù ìgbàlódé, soca  ti wáyé.
Igbimọ yii si lo n mojuto awọn ibudokọ ero dipo ẹgbẹ National Union of Road Transport Workers, NURTW, to ti n mojuto fun ọdun to pọ.
Nígbà tí Ìjàpá gbọ́ ohun tí ó ṣẹlẹ̀ inú rẹ̀ bàjé ó ń ronú pé òun ni ó yẹ kí Ọba dá lọ́lá torí òun ni òun pa abuké Ọba.
Ọlọrun, agbára mi, ojú rẹ ni mò ń wò,nítorí ìwọ, Ọlọrun, ni odi mi.
Nitori naa, a  o gbọdọ da wọn.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Seyi Makinde: Ìyá Akurẹ àti Iya Ibadan kìlọ̀ fún mi lóru ọ̀gànjọ́ làti sọ́ra fún olóṣèlú 26 Ògún 2019 Oríṣun àwòrán, @seyiamakinde Àkọlé àwòrán, Awọn eniyan rere lee darapọ mọ ẹgbẹ oṣelu Ogbẹni Seyi Makinde, gomina ipinlẹ Ọyọ ti sọ pe, bi oun ṣe jawe olubori ninu idibo to kọja jẹ ore-ọfẹ Ọlọrun.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù JAMB, àwọn òbí fún Ààrẹ Buhari lésì lórí àdínkù owó ìdánwò tó kéde 22 Èrèlè 2018 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 29 Bélú 2018 Àkọlé àwòrán, Ààrẹ Muhammadu mú àdínku ba owó ìdánwo fún ìr'srún òbí-JAMB Lọnà ati lee mu ki itẹsiwaju eto ẹkọ rọrun fun tolórí ti tẹlẹ́mù ní orílẹ̀-èdè Naijiria.
Ó kó ọpọlọpọ irin jọ, tí wọn óo fi rọ ìṣó, tí wọn yóo fi kan àwọn ìlẹ̀kùn ati ìdè, ó kó idẹ jọ lọpọlọpọ pẹlu, ju ohun tí ẹnikẹ́ni lè wọ̀n lọ, 
5m péré wá, ko kópa nínú ìbò abẹ́nú fún ipò gómìnà ní Ondo àti Edo - APC kéde Àgbéyẹ̀wò àṣà: Ìdí tí Yorùbá kìí fí tufọ ikú òjìji fún èèyàn Ọkùnrin kan gbé ‘búrọ́ọ̀ṣì ìfọyín’ mì Àwọn dókítà ìpínlẹ̀ Eko tó ń yanṣẹ́lódì ti padà s'ẹ́nu iṣẹ́ Ọrọ yi mu iriwisi wa ti ọpọ ọmọ Naijiria si bẹnu àtẹ lu iwa to wu yi.
Oun ati Donald Trump ree ni ọdun 1987 nigba ti ko ṣi ẹnikankan to ro pe o le di aarẹ.
"Ilé aṣọ̀fin Nàìjíríà ń gbèrò ẹ̀wọ̀n f'áwọn olùkọ̀ tó bá dẹnu ìfẹ́ kọ akẹ́kọ̀bìnrin Ìṣòro Nàíjíríà kọjá kí Bobrisky àtàwọn ẹlẹgbẹ́ rẹ̀ dá ní ilé ìgbọ̀nsẹ̀ lọ́tọ̀"" Ileeṣẹ ologun sọ pe awọn akẹkọọ fẹsẹ fẹ ni kete tawọn ajinigbe de ileewe wọn ti wọn si ji ọga ileewe naa lọ."
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ìfẹ́ Yorùbá ló mú mi fi ẹ̀mí wéwu láti kojú ajínigbé ní Kishi - Sunday Igboho Kò bójúmu kí owó epo ní Nàíjíríà dínwó ju ti Saudi lọ - Buhari Wo ìṣẹ̀lẹ̀ márùn-ún tí kò bá pín Nàíjíríà sí yẹ́lẹ-yẹ̀lẹ Bọ́ síta láti ṣe ìwọ́de mọ́ ìjọba Nàìjíríà lónìí, ko rugi oyin - Iléeṣẹ́ ọlọ́pàá Ẹ̀yin ọlọ́pàá 10,000 tí ọ̀gá ọlọ́pàá gbà ṣíṣẹ́ ní 2019, ẹ padà sílé - Iléẹjọ́ pàṣẹ Ọjọ́ ìbí bàbá mi ni aàrùn ọkàn ṣekúpa màmá mi lójijì- Davido Ìjọba Kwara kéde ọjọ iwọlé àwọn akẹkọọ lẹyìn ìséde Covid 19!
Mo ti rù láàrin ọ̀sẹ̀ kan, iṣẹ́ Eko kò dẹ́rùn - Sanwo-Olu A kò ní ti ọ̀nà pa mọ́ nítorí àbẹ̀wò Buhari -Ìjọba ìpínlẹ̀ Èkó Lọjọ iṣẹgun ni Gomina Sanwoolu pa ilu ẹnu da pe oun ko fi igba kankan ṣeleri lati mu opin ba sunkẹrẹ fakẹrẹ oju ọna Apapa laarin ọgọta ọjọ.
F Kumuyi Ki ni Kumuyi se fun ọmọ Yoruba?
Ṣaaju ni iroyin gbe e pe, awọn elere idaraya lati Kenya, Eritrea, ati Burkina Faso, to gunlẹ si papakọ Murtala Mohammed to wa nilu Eko, ko ti i raye kuro nibẹ lati bi ọjọ melo kan nitori awọn kudiẹ-kudiẹ.
Minisita sọ ọrọ naa niwaju igbimọ tẹẹkoto lori ọrọ isuna nile igbimọ asoju sofin nilu Abuja.
Matiu ati Tomasi, Jakọbu ọmọ Alfeu ati Simoni tí ó tún ń jẹ́ Seloti, 
 Ọ ̀ kan nínú àwọn ọmọ-ọba obinrin ló bii .
òróró fún àwọn fìtílà, ati àwọn èròjà olóòórùn dídùn fún òróró tí wọn ń ta sí eniyan lórí, ati turari, 
 ara àwọn ọmọ ènìyàn ní bíi ẹgbẹgbẹ ̀ rúnkẹta 100 àhámọ ́ ; ìtóbi àhámọ ́ jẹ ́ 10 µm nígbàtí ìkórajọ àhámọ ́ jẹ ́ 1 nanogram .
Sanwo Olu naa ti dibo lẹyin idiwọ diẹ to waye ni agọ idibo naa.
 Àwọn àṣà tó jẹ mọ ́ ètò ìbágbépọ ̀ láwùjọ yorùbá ní ẹ ̀ kọ ́ -ilé , ètò-ìdílé , ẹlẹ ́ gbẹ ́ jẹgbẹ ́ tàbí irọ ̀ sírọ ̀ .
 Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, World TB Day: Funkẹ Dosunmu ni ikọ́ ife kìí pani, ta bá lo òògùn rẹ̀ déédé Bawo ni awakọ mẹrindinlogoji yoo se maa pin ọkọ meji wa?
Kí ni mo lè fi wé ọ,kí n lè tù ọ́ ninu, ìwọ Sioni?
"O dabi ẹnipe isoro kan gboogi to n mi naijiria logbologbo ni eto idibo wa to mẹhẹ, eyi tawọn eeyan ti eto naa wa nikawọ wọn ti se siba-sibo.
Cyril Ramophosa niyi nibi to ti nsọrọ lori 'Ọrọ n lo lorilẹede naa'.
“ ‘Ẹni ìfibú ni ẹnikẹ́ni tí ó bá tàbùkù baba tabi ìyá rẹ̀.
Bótilẹ̀ jẹ́ pé ààrẹ Trump sì lè kó ààrùn náà ran àwọn tó wà ni àyíkà rẹ̀, síbẹ̀ ó yọ ìbòmú rẹ̀ lórí fàrándà tí o dúró sí nilé ìjọba.
Newcastle vs Manchester United: Newcastle da iyọ̀ sójú egbò Manchester United
Botilẹjẹ pe awọn iroyin to kọkọ jade sọ pe tẹlifisan to jabọ lo pa obinrin naa, awọn aworan ti wọn ya nibi ti iṣẹlẹ naa ti waye fihan pe ko si aṣọ kankan ni ara a rẹ lati ibara idi si isalẹ.
Chelsea tún ṣubú dàánù sọ́wọ́ Liverpool Tammy Abraham dáná sun Wolves, ni Twitter bá ń lọgun rẹ̀ tan-tan Jose Mourihno fakọ yọ pẹ̀lú bí Tottenham se na West Ham!
“Alufaa yóo gba agbọ̀n èso náà ní ọwọ́ rẹ, yóo sì gbé e kalẹ̀ níwájú pẹpẹ OLUWA Ọlọrun rẹ.
Àìní ífẹ̀ sí ǹkankan to dára mọ́: Ní kété ti àwọn ènìyàn kò bá ti ni ìfẹ́ sí àwọn ǹkan to dára mọ́, o seese ki wọn pa ara wọn.
Nígbà tí àwọn eniyan gbọ́, ẹnu yà wọ́n sí ẹ̀kọ́ rẹ̀.
Awọn ile iṣẹ iroyin si royin pe akọwe agba ẹgbẹ ọlọsin maalu ni Naijiria, Miyetti Allah Cattle Breeders Association of Nigeria iyẹn Baba Uthman Ngelzarma lo sọ pe igbakeji aarẹ Osinbajo lo n ba awọn Fulani daran daran da Ruga Settlement silẹ kaakiri orilẹede naijiria.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Niger Flood: Omíyalé àgbàrà ti ya ṣọ́ọ̀bù ní Niger 8 Owewe 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Kirkissoye ti kun fun omi ti aya awọn agbegbe naa n ja bayii Bi ojo ṣe n rọ lasiko yii ni orilẹ-ede Naijiria ti ẹru omiyale n ba awọn eniyan bẹẹ naa ni ojo naa n rọ ni orilẹ-ede Niger.
Nígbà tí Ọlọrun yọ ọ́ lóyè, ó gbé Dafidi dìde fún wọn bí ọba.
Fayẹmi sèbúra l‘Ekiti, àwọn èèkàn ìlú péjú Kí ló dé tí ìjọba Èkìtì ń fí àwọn òṣìṣẹ́ ṣé ''helo-helo testing?"
kan ti egbe awon osise gbe jade lojo Aiku niluu Akure lasiko ti won n ki awon
O ṣalaye pe eyi ko ṣẹyin awọn oludibo to jẹ aṣoju kan ti wọn yọ bébà idibo sita lati fi dibo.
ati gbogbo àwọn òkè ńláńlá,ati gbogbo òkè gíga,
me Ẹwẹ, agba Onkọwe, Wole Soyinka ti kesi awọn gomina ipinlẹ ti iwọde #ENDSARS ti mu ki wọn o kede isede, lati ṣọ fun ijọba apapọ pe ko ko awọn sọja kuro laarin igboro.
Nigeria 2019 Elections: Tinubu ní òun yóò sàjọyọ̀ ìsẹ́gun lọ́sẹ̀ tó ń bọ̀
Ifẹhonu àwọn ọmọ ẹgbẹ́ Shi'ite náà kò sẹyìn bi ìjọba orílẹ̀èdè Nàìjíríà ṣe kọ láti tù olórí wọn, Ibrahim Zakzaky silẹ t'ohun ti bi ile ẹjọ tí pàṣẹ pé kí wọn tú silẹ.
ati ilẹ̀ àwọn ará Gebali, gbogbo Lẹbanoni ní apá ìlà oòrùn, láti Baaligadi tí ó wà ní ìsàlẹ̀ òkè Herimoni títí dé ibodè Hamati.
Bẹ́ẹ̀ ni èmi OLUWA àwọn ọmọ ogun wí!
Akọṣẹmọṣẹ ni o jẹ nipa biba eeyan polowo ọja loju ayelujara ti a si tun maa da si ọrọ to ni ṣe pẹlu mimu irọrun ba ara ilu.
Tí wọ́n bá ṣí ìlẹ̀kùn yàrá tí a wà, máà gbe jáde síta kí òòrùn le pá díẹ̀.
Eko, Aṣofin Mudashiru Ọbasa rọ Ajọ Eleto Idibo lati tẹra mọ ṣiṣe
to pọ lorile ede yii, ti a ba lee gbogun ti osi, iwa ibajẹ, eto ẹkọ ati eto
Domestic Violence: Ìjà láàrin lọkọlaya sọ aya dèrò ọ̀run
Wọ́n tún ní kí àwọn òṣìṣẹ́ méjì míràn lọ rọọ́kún níle ná.
Mo sọ fun yín pé ẹni tí ó ju Tẹmpili lọ ló wà níhìn-ín yìí.
À ń ṣọ́ọ yín lórí ayélujára yín bàyìí o!
Èyí ni ìdájọ ikú ẹlẹ́keejì ti ilé ẹjọ́ Sharia yóò dá láàrín ọ̀sẹ̀ kan ní ìpińlẹ̀ Kano.
Osun Election Tribunal: Èyí ni òkodoro ìdájọ tí àwọn eniyan ìpínlẹ̀ Ọsun ti ń reti- Oyetola Dán Yorùbá rẹ wò pẹ̀lú ààmì lórí 'Bobajiroro' 'Kìí ṣe àròsọ, mo ní fọ́nrán fídíò àwọn ẹlẹyẹ ìlú mi' Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí kan sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ami ẹyẹ Nobel Prize lo gba fun iṣẹ alaafia 'Ileesẹ ọlọpa Ghana yoo ri atunto' Àwọn akọ̀rọ̀yìn fárígá l'órílẹ̀-èdè Ghana Òògùn ẹ̀fọn pa ọmọ mẹ́ta ní Ghana Wọn le awọn olutaja kuro niwaju ile Aarẹ Ghana Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Fídíò BBC yọ àwọn èèyàn FIFA níṣẹ́ ṣááju Russia 2018 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
keje odun ti a wa yii.
”Ogbeni Muhammad Musa Soba lati ipinle Kaduna benu ate lu oro ohun pe, ohun ti o buru jai ni oro naa,  ti o si n tapa si isejoba tiwan-tiwan.
Iroyin ti deti igbo ajo eleto idibo lose to koja pe, awon kan n gbiyanju ati deruba awon osise nibi atundi eto-idibo naa.
Nípa ọgbọ́n àrékérekè rẹ̀, yóo máa tan àwọn eniyan jẹ, ìgbéraga yóo kún ọkàn rẹ̀, yóo máa pa ọpọlọpọ eniyan lójijì, yóo sì lòdì sí ọba tí ó ju gbogbo àwọn ọba lọ.
Ọjọ́ náà jẹ́ ọjọ́ ìpalẹ̀mọ́ tíí ṣe ọ̀sẹ̀ ku ọ̀la.
O ni se ni pata rẹ maa n tobi to inuwọ ọmọde, ti oun ko si ri Dayọ ri ko wọ pata G-String lati igba to ti n fi pata nla ya fọto.
 Aṣofin Tunde Braimoh ti on sọju ẹkun idibo Koṣofẹ keji ninu Ile
Bí ó ti nsọ ẹ̀rọ ayárabíàṣà di amóhùnmáwòrán ni ó nsọ ọ́ di ẹ̀rọ asọ̀rọ̀mágbèsì.
Ẹni to bori: Cameroon Tunisia vs Morocco.
Awọn oluwọde ya wọ ile-ẹjọ nitori aṣofin Dino Melaye
Ohun ìní rẹ ni wọ́n, àwọn tí o ti fi agbára rẹ rà pada, tí o fi ipá kó jáde láti ilẹ̀ Ijipti.
Bẹ́ẹ̀ ló ṣe rí fún gbogbo èdè l’áíyé.
Ní ọjọ́ ajinde, ti ta ni obinrin náà yóo jẹ́, nígbà tí ó jẹ́ pé àwọn mejeeje ló ti fi ṣe aya?
Doegi ará Edomu, tí ó dúró láàrin àwọn olórí ogun Saulu dáhùn pé, “Mo rí Dafidi nígbà tí ó lọ sọ́dọ̀ Ahimeleki ọmọ Ahitubu ní Nobu.
kọ eti ikun si abajade ti igbimo ipinle se lori ekunwo owo osu awon osise, nitori
Ninu ifọrọwerọ rẹ pẹlu BBC News Yoruba, agbẹnusọ fun aafin Oodua, Kọmureedi Ọlafare ṣalaye pe ileewosan nla naa ni wọn bi Arẹmọ Ọọni si.
Sùgbọ́n taa ni Omoyele Sowore ga-an?
Ẹ dúpẹ́ lọ́wọ́ rẹ̀,kí ẹ sì máa yin orúkọ rẹ̀.
Nibayii ko din ni ogun papa isire to ti tẹle ikilọ yii Gẹgẹ ohun ti awọn ileesẹ iroyin lorilẹede naa n sọ, awọn asiwaju ẹgbẹ alakatakiti Al-Shabaab se ipade pọ pẹlu awọn alakoso awọn papa isire kan lolu ilu orilẹede Somalia, Mogadishu.
Iléẹjọ gíga jùlọ da ẹjọ́ SDP àti PDP nù, wọ́n ní Yahaya Bello ló wọlé ìbò gómìnà Kogi Ìjà d'ópin, fún ìgbà àkọ́kọ́, bàálù gbéra láti Israel lọ sí UAE Yàtọ̀ sí Eko, wo ohun t'áwọn ìpínlẹ̀ meje míràn ń sọ nípa ìwọlé àwọn akẹ́kọ̀ọ́ Wo ojú Akeem t'Ọlọ́pàá mú pé ó fipá bá ọ̀dọ́mọbìnrin kan sùn létí odò l'Oṣun Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí 6:18 Fídíò, Natalia Mufutau ìyá Yakub, Kamil àti Adam sọ̀rọ̀ lórí bí wọ́n ń sọ èdè mẹ́rin pàpọ, Duration 6,1831 Ògún 2020 Fídíò, Yoruba Language: Akomolede ati Asa Yoruba tọ̀sẹ̀ yí rèé lẹ́nu olùkọ́ wa30 Ògún 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Gẹ́gẹ́ bí àwọn onímọ̀ kan ṣe rò, ipa ìyípadà ojú-ọjọ́, òjò àìdágbá kan, ojú-ọjọ́ tó ń ṣe ségesège, àti àìṣèmọ́tótó ni ọ̀dádá tí ó ń dá àtànkálẹ̀ ibà sílẹ̀.
Ìgbà mìíràn, ẹranko buruku mìíràn a sa sí ẹlòmíìran a gé apá rẹ̀ kan kúrò lójù gbogbo wa, a máa jẹ ẹ́, bẹ́ẹ̀ ni ẹni tí ó ni apá kò ni kú, a o sì máa wò ó ti oun ti kùkùté tí ó kù tí yóò máa kígbe nínú odò náà.
ni bayii aare sun saa re siwaju lati maa base re lo fun odunkan miiran gbako.
 yóò si ṣe ìrànlọ ́ wọ ́ fún àwọnolùkọ ̀ ọ ́ pẹ ̀ lú .
Nígbà náà ni Aisaya sọ fún ọba pé, “OLUWA ní, 
Laarọ ọjọ Ẹti lawọn eeyan peju pesẹ si Nelson Mandela Freedom Park, l'Osogbo, lati fi aidunnu wọn han si igbẹsẹ ijọba lati sọ epo jala di naira mọkanlelọgọta.
 Èyí yọrí sí ikú àwọn ẹ ̀ gbẹ ̀ rún mejila àbọ ̀ ènìyàn ní ọdun 2006 .
    B;ayìí ni ọ̀kàn nínú wa sọ̀rọ̀, Ayédèrú-ẹda tí o ṣe mi ní àlejò ní ìlú rẹ̀ ní ìjọ́sí tí mo sì fi ṣe ìgbá kejì mi ni ìrìnàjò sí Igbó Elégbèje yìí.
Bí à ń sọ itàn, yóò sọ ìtàn òmìrán tí ó dùn ju tiwa lọ.
Kò sí ọkà ninu abà mọ, igi àjàrà ati igi ọ̀pọ̀tọ́ kò sì tíì so; bẹ́ẹ̀ ni igi pomegiranate, ati igi olifi.
Sleeping Lawmakers: Àwọn ọmọ ilé ìgbìmọ̀ aṣòfin l'Abuja ti wọ́n ń sùn lásìkò ìjókòó ilé
“Òkóbò nìkan ni kìí bímọ sí tòsí, a ní ọmọ òun wà ní òkè-òkun” Bákan náà ni pé “arúgbó nìkan ni ó lè parọ́ ti a kò lè já a nítorí pé àwọn ẹgbẹ́ rẹ̀ ti kú tán” Purọ́ n níyì, ẹ̀tẹ́ ní ń mú wá, bi irọ́ ni, bí òótọ́ ni pé àwọn Ìjèṣà jẹ́ akíkanjú, ẹ wo jagunjagun Ògèdèngbé “Agbógungbórò” Ọ̀gbóni Agúnsóyè, “Ologun abèyìngọgọú, ó pẹ̀fọ̀n tán, ó wojú ìdó kọ̀rọ̀, Ọ̀dọ̀fin Arówóbùsóyè, Ọ̀gbọ́kọ̀ọ́ndọ̀ lérí odi kípàyẹ́ bì yẹ̀ẹ̀yẹ̀ẹ̀ séyìn” Ológun Arímọrọ̀ àti àwọn Olórúkọ ńláńlá ni ilẹ̀ Ijẹ̀ṣà láyé ọjọ́un.
Ohun lo difa fun bi gbajugbaja agbabọọlu gọọfu, Tiger Woods ṣe pada wa di ọba ere bọọlu yii lẹyin ọdun mọkanla ti ọpọ eniyan ni agbaye ro pe aye rẹ ti bajẹ patapata.
Rivers United FC 16:00(February 12)Wikki Tourist ?
Ileesẹ ọlọpaa sọ pe iwadii ti n waye lori iṣẹlẹ naa, ti wọn si tun ti n wa Adekunle.
Alaga apapọ fẹgbẹ APC sọrọ pẹlu idaniloju pe, aarẹ Muhammadu Buhari yoo jawe olubori ninu idibo aarẹ ọdun 2019 laisi atilẹyin Obasanjọ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Day 18: Ṣé o fẹ́ mọ òtítọ́ nínu ọ̀rọ̀ ìpolongo àwọn oludije sípò aarẹ Naijiria?
kòkòrò-àrùn tó n fa àìsàn náà lè tan kiri nípa fífi ara kan ojú tàbí imú ẹni tí ó ní àìsàn yìí tààrà tàbí kí ara mà kàn án tààrà .
 Òrò-ìse tí ó gbàbò ni òrò-ìse tí ó bá ní apor gégé bí àfikún .
Ọgbẹni Dickson fikun ọrọ rẹ pe o ṣe pataki lati san ọgbọn ẹgbẹrun un nairia owo oṣu to kere julọ fawọn oṣiṣẹ nitori ọrọ aje Naijiria to dẹnu ko lẹ labẹ ijọba ẹgbẹ oṣelu APC.
Bí ó ti ń bá a sọ̀rọ̀, bẹ́ẹ̀ ni ó bá a wọlé.
Inú àwo orin Fuji Barrister sì ni mo ti mú orúkọ náà síta, ìtumọ̀ rẹ sì ni Okùn sọnù, tíì ṣe orúkọ abiku.
Shogunle mu inu bi ọpọ ọmọ Naijiria nigba to sọ wipe lati yago fun wahala lọdọ awọn ọlọpaa, ki awọn ara ilu maa gbiyanju lati sọ ede oyinbo 'pidgin' dip ede oyinbo to dan mọran.
niluu  Abuja , ni minisita fun iroyin ati
Ìfihàn lóri àkójọ àti àkóso ìjọ, tí a fi fúnni nípasẹ̀ Wòlíì Joseph Smith, ní tàbí nítòsí Fayette, New York.
"Bí Hushpuppi ṣe tiraka rèé l‘Eko, kí ọlà ‘òjijì’ tó dé Akẹ́kọ̀ọ́ wọlé padà, ìjọba Oyo kò pèsè ìbòmú lòdì sí ìlérí rẹ̀ Ẹ wo bí ọ̀rọ̀ òṣèlú, ẹ̀sìn àti ẹ̀yà ṣe fa ogun abẹ́lé Biafra Kàkà k‘éwé àgbọn dẹ̀ lágbo òṣèlú l‘Ondo, akọ̀wé ìjọba tún kọ̀wé fipò sílẹ̀ Popoola sọ pe ""A fẹ bẹrẹ atunse afara Third Mainland laipẹ, o si ṣeeṣe ki a ti afara ọhun lati ọjọ kẹrinlelogun oṣu keje ọdun yii."
Ibeere to ṣe koko ni pe njẹ apẹrẹ diẹdiẹ tabi eleyi to farajọ otutu bi ki eeyan ma sin tabi ko ma yọ ikun nimu a ma farahan lara awọn alaisan kan.
Àṣìṣe ọlọ́pàá àti Adájọ́ sọ mí di ẹni tí wọ́n dájọ́ ikú fún, ọpẹ́lọpẹ́ Fayoṣe tí ko buwọ́lù ú
Ẹwẹ, ẹgbẹ agbabọọlu Man U ti sọ loju opo Twitter pe ohun to jẹ kawọn ṣe adehun tuntun pẹlu Ighalo ni pe o farajin ṣiṣẹ atawọn goolu to ti gba sawọn.
Olorí ilé tuntun ti wọn yan bayìí ní olori ọmọ ilé tó kéré jùlọ tẹ́lẹ̀, Gboyega Aribisogan nígbà ti Sunday Akinniyi tí gbogbo ènìyàn mọ si 'Gbosa' bó tilẹ̀ jẹ́ pe ó ṣẹ̀ṣẹ̀ darapọ̀ mọ́ ẹgbẹ́ APC ló wá jẹ́ olórí ọmọ ilé tó kéré jùlọ báyìí.
Section 131 Bi oo ba tẹle awọn ofin yii, oo le lo omi.
Jehu kúrò ní Jesireeli, ó ń lọ sí Samaria.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Bishop Wale Oke: Ìjọba kò gbọ̀dọ̀ gbè lẹ́yìn ẹ̀sìn kan Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Bishop Wale Oke: Ìjọba kò gbọ̀dọ̀ gbè lẹ́yìn ẹ̀sìn kan 28 Èbibi 2019 Alufa agba ijọ Sword of the Spirit ti iya ijọ rẹ kalẹ si ilu Ibadan, Biṣọọbu Francis Wale Oke gba ẹnu àwọn àlùfáà Nàìjíríà sọ̀rọ̀ nipa ohun ti Oloye Oluṣẹgun Obasanjo sọ pe gbogbo ipaniyan awọn Boko Haram ati ti awọn Fulani daran daran jẹ ọgbọn ati sọ Naijiria di ilu ẹlẹsin musulumi nikan.
Gomina salaye pe, “A ko ni je ki ipenija eto-abo yii sakoba fun erongba wa lati mu igberu ba ipinle Edo, ipinnu wa ni lati je ki idagbasoke ati olaju tan kaakiri, ki a si ri daju pe, awon odo nise lowo, ipinnu ijoba ipinle Edo lori eto ogbin ni lati faye gba awon oludokowo lati tan kiri, ni paapaa awon onile-ise ipese epo-pupa, bakan naa ki o je anfaani fun awon ti o wa ni igberiko gbogbo, agbegbe Esan je okan lara ilana ijoba lati tan eto-ogbin kaakiri ipinle naa”.
án, ninu iwe abadofin to le ni ọ́ọ̀dúnrún lati
Osere omo odun merinlelaadota yii wa si Dubai fun igbeyawo ebi re kan ki o to dagbere faye pe o digbose ninu baafu iwe nile itura to de si.
nítorí ó sọ ninu ara rẹ̀ pé, “Bí ó bá jẹ́ aṣọ rẹ̀ ni mo lè fi ọwọ́ kàn, ara mi yóo dá.
Omowe Badiru Idris to wa ni eka ilaniloye ninu ise agbe ni fafiti Ibadan naa fi ero re han pe iyanselodi naa ko ni bi eso rere lojo iwaju paapaa ninu eto kebi ma palu lojo iwaju.
Bakan naa ni wọn n fa ijọba leti pe ko tun ero rẹ pa lori ikede ologun naa, paapaa lasiko yii ti iwọde n waye yika Naijiria lati tako iwa ika awọn ọlọpaa, ti wọn si n beere fun ifopin si ọlọpaa SARS.
Aarẹ to wa nipo saaju rẹ si ni wọn fi ẹsun kan pe o n dari ijọba to n tẹ ẹtọ ọmọniyan loju pupọ, to si tun n kọju oro sawọn alatako, akọroyin atawọn ajafẹtọ ẹni.
Aarẹ sọrọ yii l'asiko to lọ si ipinlẹ Kaduna l'ọjọ Iṣẹgun ọsẹ yii, lati ba wọn kẹdun ti awọn to kú ninu ija ẹ̀sìn to waye laipẹ yii.
A ti dìbò láàrin àwọn alufaa, àwọn ọmọ Lefi ati àwọn eniyan, bí wọn yóo ṣe máa ru igi wá sí ilé Ọlọrun wa, ní oníléjilé, ní ìdílé ìdílé, ní àwọn àkókò tí a yàn lọdọọdun, tí wọn yóo fi máa rúbọ lórí pẹpẹ OLUWA Ọlọrun wa, gẹ́gẹ́ bí a ti kọ ọ́ sinu ìwé òfin.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù World Cancer Day: Ènìyàn 26,000 ni àìsàn jẹjẹrẹ ń pa lóòjọ́ 4 Èrèlè 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ọjọ́ Kẹẹ̀rin, Osù Kejì ọdọọdún ni Àjọ Ètò Ìlera Lagbaye(WHO), là kalẹ̀ láti pe akíyésí àwọn ènìyàn sí àìsàn jẹjẹrẹ.
Gómìnà márùn ún tó fojú winá ìbínú bàbá ìsàlẹ̀ wọ̀n Wo àwọn Gómìnà Naijiria tí àrùn Covid-19 ti bá fínra Àwọn ohun tuntun tí a mọ̀ nípa ìgbẹ́jọ́ Wòlíì Sotitobire Wo àwòdamiẹnu àwòrán Mọ́ṣáláṣí Ànọ́bì ní Medina!
Oogun ti wọn ṣe latara eso Vitamin C pọ lara rẹ eyi to maa n wọya ija pẹlu awn aisan ọta ara, aisan ọkan, aisan to n ṣaju ibimọ, arun oju koda ati ara hihun jọ.
Eledumare pari ẹwa si ara Fẹmi pẹlu, bẹẹni ko si obinrin ti yoo pade rẹ ti yoo ni oun ko ri eniyan rara.
IS Global: Oúnjẹ alẹ́ lẹ́yìn aago mẹsan leè fa jẹjẹrẹ
Awọn ẹgbẹ́ agbabọọlu to ṣe koko yoo si ṣe ipade lọjọ Ẹti lati jiroro lori ọna ti wọn yoo gbe e gba.
Àṣìta ìbọn àwọn Ọlọ́pàá ló gbẹ̀mí àwọn èèyàn tó kú lọ́jọ́ ọdún Eid n'Ibadan - Ará Àdúgbò Àwọn òbí fárígá lórí sísan N25, 000 owó àyẹ̀wò COVID-19 fáwọn akẹ́kọ̀ọ́ kí wọ́n tó wọ iléèwé Ìjọba ìpínlẹ̀ Eko ti ti ibùdó ìtọ́jú ààrùn Covid-19 tó wà ní Eti-Osa A ó san ẹ̀san ire fún ẹbí Richard, a ó sí san owó gbogbo ètò ìsìnkú - Iléesẹ́ ọṣẹ tí akẹ́kọ̀ọ́ UI kú sí Ileeṣẹ ọṣẹ ti akẹkọọ fasiti Ibadan kan, Richard Gbadebo ku si lọjọ aje ọsẹ to kọja Expanded Global Industries Limited ti nawọ ẹ ma binu si idile Richard.
Jesu rí Nataniẹli bí ó ti ń bọ̀ wá sọ́dọ̀ rẹ̀, ó sọ nípa rẹ̀ pé, “Wo ọmọlúwàbí, ọmọ Israẹli tí kò ní ẹ̀tàn ninu.
Ológun tó ń ṣùn ni Buhari, kò gbogun ti Boko Haram - Fadá Mamza Kò jọọ́!
Olori Memunat, ẹni to gbosuba fun Alaafin lasiko ayajọ ọjọ ibi rẹ, loju opo Instagram rẹ ni oun n dupẹ lọwọ Ọlọrun to ṣe oun ni oloriire julọ lagbaye nitori bo ṣe fi ọkọ to dantọ da oun lọla.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù EndSars Protest: Ìjọba àpapọ̀ ní ká ṣọ́ra fún ìpéjọ èrò àti àlejò láti Amẹrika, UK, India, Rusia ati France 19 Ọ̀wàrà 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 20 Ọ̀wàrà 2020 Oríṣun àwòrán, @kabenny_ Igbimọ amusẹya ti Aarẹ Muhammadu Buhari gbe kalẹ lori ajakalẹ arun Covid-19, PTF, ti kilọ fun awọn oluwọde End SARS, lati ṣọra ṣe nitori itankalẹ arun naa ninu iwọde wọn.
"Awọn iroyin ti ẹ lee nifẹ si: ""Gomina Yobe l'awọn o tii ri awọn ọmọ tan jigbe"" Naijiria ya owo billion sọtọ f'eto ọgbin 'Gba Buhari ni'mọran ifẹyinti' Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!"
Nígbà náà ni ọrùn mi yóo tó mọ́ kúrò ninu ìbúra tí mo bú fún òun.
“Gbọ́, ìwọ Jobu, farabalẹ̀,dákẹ́ kí o lè gbọ́ ohun tí n óo sọ.
5 mílíónù àwọn ìṣẹlẹ ̀ ààmì maa ń wáyé lọdọọdún èyí tí o ṣèéṣe àwọn àkóràn mílíónù ọ ̀ nà mẹ ́ wà ní gbogbo .
ti padanu emi won sinu isele omiyale naa, ti ẹ̀gbẹ̀rún lona márùndínlógójì ile ati ohun ini awon eniyan si ba isele
#BeyondFakeNews: Soyinka ní ọ̀pọ̀ ìgbà ni ìròyìn òfégè ti pa òun
  Ènìà tún lè rí àwọn ère tí wọ́n fi yìnyín yìí gbẹ́ síbẹ̀.
Ẹ mọ ohun tí ó ṣẹlẹ̀ ní gbogbo Judia.
Ni osun kinni, ibugbamu oko ayokele meji waye leba ile-ijosin mosalasi kan nilu Benghazi lasiko ti adura n lo lowo.
Nítorí náà ni mo ṣe pinnu pé n óo máa ran yín létí gbogbo nǹkan wọnyi, bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé ẹ ti mọ̀ wọ́n, ẹ sì ti fi ẹsẹ̀ múlẹ̀ ninu òtítọ́ tí ẹ ti mọ̀.
Nítorí náà, ẹ fi ara yín sábẹ́ àṣẹ Ọlọrun.
Xenophobia: Allen Onyeama ní 300 mílíọ̀nù náírà ní òun fí gbé àwọn ọmọ Nàìjíríà wálé
' Josephine Olawa jẹ́ àgùnbánirọ̀ tó yẹ kó lọ sìnrú ìlú ní ìlú Kaduna.
Ní ti ẹni tí ó dá ìbànújẹ́ yìí sílẹ̀, èmi kọ́ ni ó bà ninu jẹ́ rárá.
Wò ó, àwọn iranṣẹ mi yóo máa rí oúnjẹ jẹ,ṣugbọn ebi yóo máa pa yín;àwọn iranṣẹ mi yóo mu waini,ṣugbọn òùngbẹ yóo máa gbẹ yín.
Mo ti kúrò ní ààfin Oyo, kí ìròyìn tó ò jáde pé èmi àti Wasiu Ayinde n fẹ́ ara wa - Olori Badirat Èyí ni àwọn aṣíwájú ìjọba tí ajé ìwà ìjẹkújẹ ti ṣí mọ́ lórí láàrin ọdún 1960 sí àsìkò yí Ara mi rẹwà ló jẹ́ kí n máa ṣí ara sílẹ̀- Victoria Kolawole Ọ̀rẹ́bìnrin míì dáná sí ọ̀rẹ́kùnrin rẹ̀ lára lẹ́yìn tó kọ̀ láti fẹ́ ẹ gẹ́gẹ́ bí aya Èsì ìdìbò tí yóò gbé aàrẹ tuntun wọlẹ́ ní Ghana rèé.
Iléeṣé tó ní bàálù tí Nara Marley lo lọ Abuja tọrọ àforíjìn lówó Mínístà Wákàtí márùn ún márùn ún ní wọ́n ń fipá bá obìnrin kàn lò pọ̀ ní Nàìjíríà- Ọga Ọlọpaa Ìdí tí mo fi ṣàbẹ̀wò sí ilé ìjọ́sìn T.
Ódá jókòó sínú ibojì ọ̀rẹ́ rẹ.
Ẹ má máa lọ láti ilé dé ilé.
Bakan naa lo bu ẹnu atẹ lu aarẹ Trump pe asiko to ko gba fun Ọlọrun, bi o tilẹ jẹ wi pe Trump ko tii sọ ohunkohun lori rẹ.
 Ó gbá bọ ́ ọ ̀ lù àfẹsẹ ̀ -gbá fún gaelic football àti templeogue synge street tí ó sì tún gbá bọ ́ ọ ̀ lù fún league of ireland àti shelbourne ' s tí ọ ̀ jẹ ̀ -wẹ ́ wẹ ́ tí ọjọ ́ orí wọn kò ju ogún ọdún lọ ( under 20 ) .
Igbọnwọ tí ó péye ni wọ́n fi ṣe ìdíwọ̀n pósí náà.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Onnoghen: Nítorí EFCC, ìgbìmọ̀ ìṣèdájọ́ tó ga jùlọ, NJC kọ̀wé ìfisùn tuntun ránṣẹ́ sí Onnoghen 11 Èrèlè 2019 Oríṣun àwòrán, concisenews Àkọlé àwòrán, Ìgbìmọ̀ ìṣèdájọ́ tó ga jùlọ, NJC ní àwọn yóò pàdé lọ́jọ́rú láti yẹ àbájáde rẹ̀ wò.
Man City yoo gbami ẹyẹ idije Premier League ti wọn ba le jawe olubori ninu gbogbo ifẹṣẹwọnsẹ mẹfa to ku fun wọn lati gba ni saa yii.
US visa fee for Nigeria: Amẹrika ti yọ àfikún owó Físà kúro fún arìnrìnàjò Nàìjíríà
Ewe, fun gbogbo saa odun metadinlogun ti Mancini ti yan ise akonimoogba laayo, O tuko agbaboolu Manchester City gba ife eye idije ile geesi EPL fun igba akoko lodun mẹ́rìnlélógójì  ni odun 2012, bee si ni O tun gba ife eye idije Serie A meta pelu iko agbaboolu Inter Milan, ti o si tun tuko agbaboolu Fiorentina ati  Lazio.
57 Kíyèsíi, èmi ni Jésu Krísti ọmọ Ọlọ́run.
"A kí ajáwé olúborí, Dókítà John Kayode Fayemi kú oríire""."
Ẹ̀wẹ̀, ó jọ bí ẹni pé, àwọn ènìyàn tó péjú síbi ètò ìsìnkú náà ko tẹ̀lé ìlànà ìjìnà síraẹni.
Ninu ọrọ rẹ Ezekwesili ni oun yoo lo anfaani kikopa ninu apero naa lati daba awọn nkan to yẹ ki ijọba South Afrika ṣe lori isẹlẹ ikọlu sawọn ajeji.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Arakunrin Fulani ni aigbede ara eni ni orisun ija pelu agbe Awọn gomina ipinlẹ kọọkan ti fi ye ijọba apapọ pe awọn ko ni ilẹ ti awọn fẹ fun Fulani darandaran kankan ni agbegbe awọn rara.
Igbese naa wa lara adehun ti awon orile ede mejeeji yii jo se lati fowosowopo gbogun ti iko Boko haram ni Ariwa orile ede Naijiria.
Òjòlà-ìbínú jẹ́ ọ̀kan nínú àwọn ẹ̀dá wọn-ọnnì tí kì í tọ́jú ọmọ-ọ̀dọ̀ wọn, ìgbà tí ó sì ti di pé àwa kò jẹ oúnjẹ ti wọ́n ń gbé fún wa mọ́ ni Ènìiyàn-se-pẹ̀lẹ́ ti ń fi oúnjẹ wa náà wá ojú rere ọmọ-ọ̀dọ̀ yìí.
Lẹ́yìn tí Ṣemu bí Apakiṣadi tán, ó tún gbé ẹẹdẹgbẹta (500) ọdún sí i láyé, ó sì bí àwọn ọmọ mìíràn lọkunrin ati lobinrin.
Ojúmọ́ a ti sáré mọ́n ní nkan bí ago mẹ́fà òwúrọ̀.
Jehoiakini bọ́ aṣọ ẹ̀wọ̀n kúrò lọ́rùn, ó sì ń bá ọba jẹun lórí tabili ní gbogbo ọjọ́ ayé rẹ̀.
Bóò bá ní nọ́mbà ìdánimọ̀ NIN, à tí kọ ìdánwò rẹ yóò ṣòro Omiyalé ní Ghana, èèyàn 28 dolóògbé!
Àwọn náà ni ó bá dá majẹmu, tí ó fún ní Òfin rẹ̀, tí ó sì kọ́ lọ́nà ẹ̀sìn rẹ̀.
King Kelvin, to jẹ ololufẹ Toyin ni tirẹ ni, oye ki Toyin gbe ọrọ arabirin Anjorin ti sẹgbẹ kan, nitori iti ọgẹdẹ ni.
Ẹ sì gbọdọ̀ fún àwọn alufaa mi ní àkọ́pò ìyẹ̀fun yín kí ibukun lè wà ninu ilé yín.
ọmọ Ṣalumu, ọmọ Sadoku, ọmọ Ahitubu, 
Nítorí ìdí èyí, oníbodè tuntun yìí yí ìwà rẹ̀ padà, ó bẹ̀rẹ̀ sí hu ìwà tí Ọlọ́run Ọba kò dá mọ́ ọn, àsẹ̀hìnwá-àsẹ̀yìnbọ̀, ìwà náà le ju ti Àǹjànnú-ìbẹ̀rù lọ.
A bá a nínú àwọn kan báyìí tí wọ́n fi irin ṣe, ó dàbí àwọn àwọn apẹja, ó ní igun mẹ́rin, ó dúró ó sì dà bí ilé fun ọkùnrin náà.
Eto eyawo naa ni ijoba yoo pese fun awon egbe onisowo pelu ele kekere.
Jakọbu baba wọn bá sọ fún wọn, ó ní, “Ẹ ti jẹ́ kí n ṣòfò àwọn ọmọ mi: Josẹfu ti kú, Simeoni kò sí mọ́, ẹ tún fẹ́ mú Bẹnjamini lọ.
Ní gbogbo ìgbà tí àwọn ọmọ Israẹli dá oriṣa titun,ogun bo gbogbo ẹnubodè.
Ṣugbọn ẹ̀yin ni orílẹ̀-èdè tí Ọlọrun yàn, alufaa ọlọ́lá, ẹ̀yà mímọ́, eniyan tí Ọlọrun ṣe ní tirẹ̀, kí ẹ lè sọ àwọn iṣẹ́ ńlá tí ẹni tí ó pè yín láti inú òkùnkùn sí ìmọ́lẹ̀ rẹ̀ tí ó yani lẹ́nu.
O wa fikun pe táwọn agbofinro ba gba oun laaye, oun yoo ṣe koriya fáwọn eeyan ti eto aabo gberu labẹle bii awọn ọmọ ẹgbẹ OPC, fijilante, ọdẹ ibilẹ, awọn ọdọ ati Agbekoya.
Nigba ta de ibẹ, a ri ọkọ tirela kan ti wọn gbe Ile ẹru to to iwọn bata ogoji mita naa le lori, lo sọ ijanu rẹ nu.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Dangote vs Arsenal: Dangote lóun ṣì máa ra Arsenal ní 2021 13 Sẹ́rẹ́ 2020 Oríṣun àwòrán, Twitter/Arsenal Ọrọ gbajugbaja oniṣowo, Aliko Dangote ati rira ẹgbẹ agbabọọlu Arsenal ti wa di igbin tẹnu mọ igi bayii.
Idibo ti yoo gbe iṣejọba tiwantiwa wọle fun saa kefa, n waye lasiko ti awọn eniyan n binu lori ẹsun iwa jẹgudugẹra to kaakiri, ọrọ aje to dẹnu kọlẹ ati ọrọ ilẹ ni orilẹede naa.
Èyí àtẹ̀lé rí ìwo àgbáǹréré kan rà, tí ó lu ihò láti apá kan dé apá kejì bí ènìyàn bá gbé ojú bọ ọkan nínú àwọn ihò yìí, ibikíbi tí o bá wí pé òun fẹ́ lati rí ní òde ayé yìí ni yóò rí kedere.
''A ti ba ijọba Naijiria fọrọjomi toro ọrọ ti a ṣi n ṣe bẹẹ nipa ṣise alabapin iroyin to tẹwa lọwọ ati mimọ ohun tawọn alaburu yi n ṣe'' Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Action Against Hunger: Ẹgbẹ́ agbésùmọ̀mí ISWAP ṣekú pa àláànú kan O sọ pe ṣiṣe alabapin iroyin laarin Amẹrika ati Naijiria ṣe pataki lati le fi mọ ohun ti Boko Haram ati ISIS n ṣe lati le fi koju wọn.
''Ni nkan bi ọdun melo kan sẹyin, mo nilati pa asa fifa irungbọn mi ti, nitori pe o ma n yun mi, ti awọn oju irun ti mo fa a si ma di egbo'' Irungbọn naa bẹrẹ si ni hu, ti eleyi si mu ko maa le jade lọsan lati lọ ra nkan, bi kii ṣe lalẹ.
anna sui ( Ìbílẹ ̀ chinese : 蕭志美 , àgékúrú : 萧志美 , pinyin : xiāo zhìměi , japanese : アナスイ ) ( bíi ní Ọjọ ́ kẹrin oṣù kẹjọ Ọdún 1964 ) jẹ ́ aṣaralẹ ́ ṣọ ́ ọmọ orílẹ ̀ èdè amẹ ́ ríkà .
3 Olúwa sì wí fún mi pé: Lõtọ́, lõtọ́, ni mo wí fún ọ, nítorítí ìwọ béèrè èyí, ìwọ yíò dúró títí èmi yíò fi dé nínú ògo mi, ìwọ yíò sì sọ àsọtẹ́lẹ̀ níwájú àwọn orílẹ̀-èdè, ìbátan, èdè àti ènìyàn.
Oríṣun àwòrán, Falz/Youtube Àkọlé àwòrán, nnn Nígbà tí BBC kàn sí Falz, agbénusọ rẹ̀, Fẹ́misọ́rọ̀ Ajayi, ní wọ́n kàn ń pariwo olórin náà fún nkan tí ko kan ni, nítorí ó fi orin náà jíṣẹ́ ni o.
Ariwo ẹkún sọ nílé Abiola Ajimobi ní Ibadan Saaju la ti mu iroyin wa fun yin pe ọjọ Ẹti, ọjọ kẹrinlọgbọn oṣu kẹfa ọdun 2020 ni Gomina ipinlẹ Oyo tẹlẹ, Abiola Ajimobi yoo wọ kaa ilẹ lọ.
Yóo yí àwọn alágídí ọkàn pada sí ọ̀nà rere.
Àwọn tó wà nídìí ìròyìn náà kò fẹ́ ìlọsíwájú mi ni.
Owo rira awon irin ise, ti iye re n lo bi bilionu metalelogoji N42.
com Àkọlé àwòrán, Ẹrù ìyà ni Norway dì lé Super Falcons lórí ní 2019 Women's World Cu Fun igba akọkọ ninu itan idije ife ẹyẹ bọọlu awọn obinrin lagbaye, orilẹede kan yoo maa gbo ewuro soju orilẹede miran pẹlu ami ayo mẹtala.
Awọn ẹgbẹ oselu alatako si ti fi ẹsun kan ijọba orileede Kenya pe o lodi si ẹtọ ati ofin ilu.
Mose bá dá wọn lóhùn pé, “Oúnjẹ tí OLUWA fún yín láti jẹ ni.
OLUWA wí fún Mose pé, “Mú àwọn ohun ìkunra olóòórùn dídùn wọnyi: sitakite, ati onika, ati galibanumi ati ojúlówó turari olóòórùn dídùn, gbogbo wọn gbọdọ̀ jẹ́ ìwọ̀n kan náà.
Bo tilẹ jẹ pe awọn mejeji ti gba ominira bayii, a ko lee fidi rẹ mulẹ boya alaga naa tabi awọn ẹbi rẹ san owo ọhun ki wọn to gba ominira.
ajọdun to n waye ni Durban ni ogunlọgọ ero maa n peju si lati ko ọpọ ẹja sadini Oríṣun àwòrán, Ahmad Gharabli Àkọlé àwòrán, Lọjọ Aje, awọn ọlọpa gba awọn eeyan to n se iwọde mu nilu Tel Aviv nitori iwa ẹlẹyamẹya lẹyin ti ọlọpa kan ti ko si lẹnu isẹ pa ọmọ ilẹ Ethiopia kan.
Kò séwu nínú ìdìbò tó ń bọ̀ l'Ondo àfi gìrì àparò- Akeredolu Yahaya Bello ni alága ìgbìmọ ìdìbò abẹ́lé gómìnà ìpińlẹ̀ Ondo Wo ìyàtọ̀ ńlá tó wà láàrin Oṣó, Àjẹ́ àti Emèrè Akẹ́kọ̀ọ́ ṣe ìdánwò àṣekágbá WAEC ní ibùdó ìtọ́jú aláàrún ní Gombe Starczewski ni igbesẹ naa waye lọna ati fi ẹhonu han lodi si ohun ti wọn sọ ere bọọlu da laye ode oni pẹlu ihoho awọn eeyan naa.
Dokita onimọ nipa ohun ọsin naa wa parọwa si awọn to n sin adiyẹ, lati ri daju wi pe wọn fun wọn loogun lasiko, eyi ti yoo dena aarun gbogbo lara awọn ohun ọsin naa.
Andre Ayew ni Balogun ikọ naa ti Asamoah Gyan yoo ṣi jẹ Balogun kaafata fun ikọ Black Stars.
O si lee gba isinmi koo rin ṣere kiri nigbamii.
” Oga agba ohun wa fi da awon omo ogun naa loju pe, ijoba apapo yoo ri daju lati pese awon ohun elo lolokan-o-jokan ti o wani ibamu pelu tawon akegbe won yooku lagbaye, ti o fimo awon ohun amayederun fun igbaye-gbadun won naa.
Ọ̀pá ìwọnlẹ̀ tí ó wà lọ́wọ́ ọkunrin tí mo kọ́ rí gùn ní igbọnwọ mẹfa.
Ni kete to fi iroyin naa soju opo Instagram rẹ naa lawọn ololufẹ rẹ yii ti bẹrẹ si ni fesi pada fun, ti wọn si n ki pe ohun to sọ dara ati pe Ọlọrun yoo gbọ adura rẹ.
Gẹgẹ bo ṣe sọ pe ọpẹlọpe pe oun jẹ gbajumọ lawujọ lo jẹ ki wọn fi obinrin naa silẹ, anfaani iru eyii ti ọpọ awọn ọdọ Naijiria miran ko ni, eyii to mu ki wọn maa jiya ẹṣẹ ti wọn ko ṣẹ.
Ọdọ ẹgbọn baba rẹ lo n gbe ti onitọun si n tọju rẹ pẹluu awọn ọmọ tirẹ naa.
Ìṣòro kì í hù láti inú erùpẹ̀,bẹ́ẹ̀ ni ìyọnu kì í ti inú ilẹ̀ jáde.
Wọ́n jẹ́ ẹbọ olóòórùn dídùn sí OLUWA.
Ìdí míràn tí àwọn èèyàn ṣe máa ngbé adúrú epo báyìí sílé ni pé wọn kò mọ ìgbà tí epo lè tán ní ilé-epo, tí wọ́n sì máa láti ràá lọ́wọ́ àwọn tí wọ́n ntún un tà lówó iyebíye ìlọ́po méjì tàbí mẹ́ta!
Ẹgbẹ naa ni dokita mẹwaa lo ti ku bayii.
Gege bi aare se sọ pe oun ko ni jaa yin kulẹ.
Ààrẹ Akufo: Òfin kò fààyè gba ìbálòpọ̀ akọ ṣákọ ni Ghana
Ẹ̀yin ọdọmọkunrin, mo kọ ìwé si yín, nítorí pé ẹ lágbára, ọ̀rọ̀ Ọlọrun ń gbé inú yín, ẹ sì ti ṣẹgun Èṣù.
Àwọn ará ìlú Kiriati Jearimu wá, wọ́n gbé àpótí OLUWA náà lọ sí ilé Abinadabu, tí ń gbé orí òkè kan.
Inec já mi kulẹ̀ lẹ́yìn ìgbaradì ọlọ̀jọ́ gbọọrọ - Buhari #NigeriaDecides2019 'Ọrọ Nàìjíríà fẹ itusilẹ' àti àwọn èsì míràn tó tẹlé bí INEC ṣé dajọ sí ìdìbò Bakan naa ni Ọjọgbọn Yakubu kede pe ko si aaye fun ẹgbẹ oṣelu kankan lati polongo ibo nitori sisun ti wọn sun eto idibo siwaju.
àwọn ràkúnmí wọn jẹ́ ojilenirinwo ó dín marun-un (435), àwọn kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ wọn sì jẹ́ ẹgbaata ó lé ọrindinlẹgbẹrin (6,720).
ni o ṣẹlẹ ninu ọdun mẹrin ti Ngige fi ṣe minista yii.
Nínú àtẹjáde ti Garba Shehu tó jẹ́ olùrànlọ́wọ́ pàtàkì fún ààrẹ Buhari lórí ìpolongo fi sita, aarẹ dúpẹ́ lọ́wọ́ àwọn elétò ìdìbò fún bi wọ́n ṣe ṣeto idibo naa nirọwọrọsẹ.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Sàká: Oun tí orí bá yàn fún ẹ̀dá ni kó ṣe Adamu Ciroma jáde láyé Ọlọ́pàá yìnbọn pa Linda, àgùnbánirọ̀ l'Ábujá Oludasilẹ Alibaba, Jack Ma, gbé ìgbésè lórí PVC Russia 2018: Àwọn tó ń lọ sípele kejì ìdíje Fáyòṣe dárà níbi ipolongo ìbò PDP l'Ékìtì ‘Lóòtọ́ọ́ ni òsìsẹ́ Lastma ń gba rìbá’ Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí kan sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
mona-mona n gba lati yan an won jẹ.
O rọ awọn to n bu ẹgbẹ naa loju opo Twitter pe ki wọn ronu si ọrọ naa daadaa ki wọn to maa sọrọ loju opo Twitter.
Àwọn ẹlòmíràn wá si inú ayé ṣùgbọ́n nígbà ti wọ́n fi ayé sílẹ̀ orúkọ wọ́n lọ pẹ̀lú wọn, àwọn wọ̀n-ọnnìrìn kọja nínú ayé bí ìgbà tí ejò kọjá ní orí àapáta a kò si ri ẹsẹ̀ wọn mọ́, ṣùgbọ́n àwọn ẹnlòmíràn wá sí inu ayé nígbà ti wọ́n fi ayé sílẹ orúkọ búburú wọn dúró lẹ́hìn wọn, àwọn wọ̀n-ọnnì da bi ìgbà tí àbàwọ́n dudú ba bọ́ si ara aṣọ funfun tí alágbàfọ̀ fọ aṣọ títí tí aṣọ fẹ́rẹ̀ẹ́ fàya tí àbàwọ́n tubọ̀ń hàn kedere.
Àwọn ọnà ti Olusegun Aroke ń gba wọ́'ke owó nínú ọgbà ẹ̀wọ̀n rèé Adájọ́ fi agbẹjọ́rò si àtìmọ́lé Ẹlẹ́wọ̀n 157 yọò kọ WASSCE, méjì fẹ gba PHD Olùdásílẹ̀, akẹ́kọ̀ọ́ iléẹ̀kọ́ Yahoo-Yahoo wọ gàù EFCC Wilson Uwujaren to jẹ agbẹnusọ Ajọ EFCC sọ pe, awọn mejeeji buwọlu iwe aṣẹ to fun ọgbẹni Hope Aroke lanfaani lati lọ gba itọju nile iwosan nita ọgba ẹwọn.
Theodore Orji lo dabaa yii nile igbinmo asofin.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ilé ìwòsàn UNN: Lóòótọ́ ọjọ́ ti lọ lórí omi náà, ẹ ma bínú 12 Agẹmo 2018 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 13 Agẹmo 2018 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Chidozie ni ọ̀rá omi mẹ́jọ ni wọ́n fún òun láàrin wákàtí méjìdínlógójì nígbà tí èsì àyẹ̀wò kò tí ì jáde Akẹkọọ kan to wa ni ipele kẹta ni fasiti Nsukka (UNN), Chidozie Okonkwo ti fẹsun kan ileewe naa pe wọn fa omi t'ọjọ ti lọ lori rẹ si òun lara.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Ọgbẹ́ inu (Gastric ulcer): Aisan yii ma n bẹrẹ ti eroja to n mu ki oúnjẹ o da ninu ikun, ba n jẹ awọ ikùn, eyi ti yoo fa ọgbẹ́.
Ojude Oba festival: Kò ní sí ayẹyẹ Ojúde Oba lọ́dún yìí nítorí Coronavirus- Ọba Sikiru Adetona Oríṣun àwòrán, @officialpcm Awujale ati alaṣẹ agba ilẹ Ijebu, Ọba Sikiru Adetona ti kede pe ayẹyẹ ọdun Ojude Oba tọdun 2020 ko ni waye nitori arun Covid-19.
Gbogbo lalakokofẹfẹ 5G yi ko sẹyin pe awọn orileede marun un kan ti wọn ko ara wọn jọ lati ma tọ pinpin awọn orileede miran,''Five-Eyes'' latara iroyin gbigba lori ayelujara Lara awọn orileede to ti gba lati lo 5G Huawei yi la ti ri UK,Canada,Australia ati New Zealand .
Diẹ lara nkan ti awọn eniyan sọ: Aisha Buhari gan an ti sọrọ lori koko yii pe: O ni eyi ko sọ pe ki oun ri ootọ nilẹ ki oun ṣali sọọ ti ijọba Buhari ba n ṣe nkan ti ko yẹ.
Láàárìn osu mẹ́ta, adarí mẹ́ta láti ilẹ̀ Europe, Emmanuel Macron tí ilẹ̀ Faranse, Theresa May láti Ilẹ̀ Gẹ̀ẹ́sì àti Angela Merkel láti ilẹ̀ Germany ti wá sí Naijiria.
Neri, baba Abineri jẹ́ ọmọ Abieli.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Obìnrin gbọdọ̀ ṣe ara wọn lọ́kan láti gba ara wọn sílẹ̀ lọ́wọ́ ìfìyàjẹni - Olùdásìlẹ̀ ẹgbẹ́ FIN APC, ẹ bá wa bẹ Buhari kó ṣí bodè ká kó ìrẹsì wọlé - Ìjọba Vietnam ń bẹ̀bẹ̀ Àwọn ológun tó fẹ́ maa yẹ káádì ìdánimọ́ aráàlú wò, ìwà àìríṣẹ́ ṣe ni - Ilé aṣòfin Ọjọ́ mẹ́rin sí ìgbéyàwó wa ní ìyàwó mi b'ómi lọ- Ibrahim Abubakar Bi awọn aṣofin ipinlẹ Eko ṣe n lọgun pe Ambọde ko tẹle ofin lori inawo rira ọkọ naa, ni Ambọde pẹlu n pariwo tan-tan-tan ni tirẹ pe, ṣe awọn aṣofin ipinlẹ Eko lẹ ṣingọọmu moju ni, nigba ti wọn n buwọlu owo fun rira awọn ọkọ bọọsi bọgini akero naa labẹ eto iṣuna ọdun 2018?
2 146956 Orilẹede Azerbaijan 2983 30.
ẹ mú ẹni tí ó ṣe ohun burúkú náà jáde lọ sí ẹnu ibodè yín, kí ẹ sì sọ ọ́ ní òkúta pa.
tóbẹ́ẹ̀ tí ó fi jẹ́ pé kò sí ẹ̀bùn Ẹ̀mí kan tí ó kù tí ẹ kò ní.
Nǹkan meji péré ni mo fẹ́ kí o ṣe fún mi,n kò sì ní farapamọ́ fún ọ:
milionu mefa naira ti ile-ise to n mojuto ogba eranko ni ipinle naa ri lasiko
Ó bá pe àwọn ọmọ rẹ̀, ó wí fún wọn pé, “Ẹ bá mi di kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ mi ní gàárì.
Ooru ati yiyago fun ipanu 'ice cream' Awọn kan ti ẹ n sọ pe ooru maa n pa arun naa, ti wọn si n gba awọn eniyan nimọran lati maa mu omi to gbona, wẹ pẹlu omi to gbona.
Ẹ máa yọ̀, kí inú yín sì máa dùn, ẹ̀yin ará Edomu,tí ń gbé ilẹ̀ Usi.
Amọ o, o ni igbakeji gomina ipinlẹ Ondo ọhun ko ti fẹnuko lori ibi gan an to fẹ lọ nibẹ.
OLUWA sì dáhùn pé, “Bí baba rẹ̀ bá tutọ́ sí i lójú, ṣé ìtìjú rẹ̀ kò ha ní wà lára rẹ̀ fún ọjọ́ meje ni?
Alufaa yóo rú ẹbọ sísun ati ẹbọ ohun jíjẹ lórí pẹpẹ.
Bi ọrọ yi ba di ootọ, Bauchi yoo pẹlu ipinlẹ Kaduna to kede laipẹ yi pe awọn yoo fi ijiya titẹ lọda jẹ awọn afipabanilopọ.
Ìmọ̀ràn tí àwọn èèyàn mìíràn bíi Ojo Omoniyi wá ń gba aráàlú ni pé, bí wọn ṣe gba wọn láàyè láti lọ sí ọjà, ṣe ni kí wọn tẹle òfin títa kété síra ẹni, kí a máa bàa wá jẹbi lẹ́yìn ó rẹyìn.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Christmas 2018: Àkójọpọ̀ àwòrán ọdún Kérésìmesì lágbáyé 25 Ọ̀pẹ̀̀ 2018 Akojopo aworan ọdun keresimesi lagbaye Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ọdọọdun ni gbogbo ẹlẹsin Kristẹni lagbaye ma n parapọ lati se ayẹyẹ Ọjọ ibi Jesu Kristi.
N óo sì fi ìyà jẹ gbogbo àwọn tí wọn ń ni wọ́n lára.
 Ti Daps dariOhun obinrin to dun juButterflies – OmawumiOhun okunrin to dun juFolashade – PraizR n B to je awo to dun juSounds from the Other Side – WizkidRaapu to dun ninu awo juEl Hadj – ReminisceOrin to dun ju lodunIF – DavidoAwon to yato lodunAwo to dara ju lodunSimisola – SimiOnkorin to dara ju lodunDavidoAwon to yato ti a damoKaffyHeadies to dilu mookaChris Ubosi.
Nígbà tí ó sì ń kú lọ, ó ní, “Kí OLUWA wo ohun tí o ṣe yìí, kí ó sì gbẹ̀san.
Wọ́n jọ ní ohun gbogbo ní àpapọ̀.
Ọ̀nà náà tẹ́jú pẹrẹsẹ, ó sì wọnú igbó náà lọ tààrà.
Ayefele fi orin ẹ ṣeun sẹ́nu kí Ajimobi ‘Bi Gomina Ajimobi se yan adarí òsìsẹ́ tuntun ní Oyo kò dí wa lọ́wọ́’ Ajimobi figbe ta, ó ní 'èmi kọ́ ló pa Ṣugar o!
"Lara awọn ohun ti wọn kọ sara iwe alakọle ti wọn gbe sọwọ ni ""Ootọ ni arun COVID-19"" ""Adupẹ fun awọn eleto ilera to n tọju wa"" ati bẹẹbẹẹ lọ Coronavirus in Nigeria: Ènìyàn mẹ́sàn án l'Ọ́ṣun, méjì l'Edo, Ẹ̀yọkan l'Ékìtì kó Coronavirus Oríṣun àwòrán, Getty Images Eeyan mejila miran ni ayẹwo tun ti fihan pe o ni arun Coronavirus bayii lorilẹede Naijiria."
Bakan naa, o tun seleri lati
Oríṣun àwòrán, MO_Adebimpe/instagram Àkọlé àwòrán, Tọkọtaya ori ayelujara Lateef Adedimeji àti Adebimoe Oyebade Lọ́sẹ̀ yìí bákan náà àwọn tọ́kọtiyawó orí ayéluujara tí wọ́n dá awuyewuye silẹ́ lọ́jọsi lórí asọ igbéyawo ti wọ́n wọ̀ papọ tún ti gbe òmíràn yọ.
A se ọmọ mi jojolo n tiraka lati fa ọyan ni pẹlu agbara, titi ti ori ọyan fi n ta mi?
PDP: APC ń lo EFCC láti halẹ̀ mọ́ ẹbí Adeleke
Kí OLUWA má ṣe jẹ́ kí n pa ẹni àmì òróró rẹ̀.
Okonjo-Iweala WTO DG nomination: Kíni ìdí tí orílẹ̀-èdè America ṣe tako ìyànsípò Okonjo-Iweala gẹ́gẹ́ bi olórí ajọ WTO
"Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Wùnmí Toríọlá: Toyin Abraham kìí se ọ̀gá mi nínú tíátà Àwọn ohun to yẹ ko mọ nipa Aisha Abimbọla Njẹ o mọ oju yi ni ""Yollywood"" Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ope Aiyeọla: Nkan pa emi ati Baba Suwe pọ Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!"
Igbimo to n mojuto irinajo awon musulumi lo sile mimo, ni ipinle Kaduna ti fi kun ojo to ye ki gbedeke ba iforukosile  awon eniyan naa, lati ojo kokanlelogbon osu keta  di ogbon ojo, osu kerin.
Oju opo ayelujara Instagram ni awọn ololufẹ mejeeji ti kọkọ pade ni bi ọdun kan sẹyin.
    “Báyìí ní mo sọ tí mo sì lọ sí ọ̀dọ̀ ìyá mi.
 wọ ́ n si máa ń se àpọ ́ nlé àwọn baba ńlá wọn tí wọ ́ n ti kú .
Oríṣun àwòrán, @SpeakerGbaja O ni ninu ifọrọwerọ wọn, ijọba apapọ ṣe adehun fawọn ẹgbẹ oṣiṣẹ ati ọmọ Naijiria lapapọ, eyi ti wọn si gbọdọ tẹle.
Ooni Adeyeye Ogunwusi: Fani-Kayode ní ìwà àbùkù Tinubu yìí ta bá gbogbo ọmọ Oodua
Gbogbo àwọn olórí láàrin àwọn eniyan náà jákèjádò ilẹ̀ Israẹli kó ara wọn jọ pẹlu ìjọ eniyan Ọlọ́run.
Eyi lo mu ki awọn agba ilu ṣa ara wọn jọ gẹgẹ bii ọdẹ ti wọn si n ṣo ara wọn ati ilu.
Àwọn olùdíje dùpò lábẹ́ ẹgbẹ̀ òṣèlú kọ̀ọ̀kan yẹ ki wọ́n ni ìbò tó jọju láti ìjọba ìbílẹ̀ méjìdílógún tó wà ni ìpińlẹ̀ náà ti yóò gbéwọn dé orí àléfà.
                                            Lasiko ti won n jabọ fun aare
Ọ̀gọ̀ọ̀rọ̀ agbébọn lo wà nílúù Kishi, National Park - Gani Adams figbe ta Àgbáríjọpọ ẹgbẹ OPC, fijiláńté VGC, Agbẹkọyà ti bẹrẹ ètò aàbò ní ilẹ Yorùbá A ko ni iroyin to pọ nipa iṣẹlẹ naa ṣugbọn akọroyin BBC, Ishaq Khalid to ba awọn fijilante to n ran awọn ologun lọwọ sọrọ ni awọn ri oku mẹrinla ni abawọle ile iwosan Monguno.
#EndSARS: Àwọn olùwọ́de kọ etí ikún sí àṣẹ ijọba, wọ́n tẹ̀sìwájú ìwọ́de l'Abuja SARS Nigeria: Àwọn olùwọ́de kọ etí ikún sí àṣẹ ijọba, wọ́n tẹ̀sìwájú ìwọ́de l'Abuja Awọn oluwọde #EndSARS kọ eti ikun aṣẹ ijọba ilu Abuja to fofin de iwọde nitori itankalẹ aarun coronavirus.
Da èrò wọn rú, OLUWA,kí o sì dà wọ́n lédè rú;nítorí ìwà ipá ati asọ̀ pọ̀ ninu ìlú.
Oríṣun àwòrán, Kannywood Àkọlé àwòrán, Ibi ere Makanta Biyu to jẹ ere ikfe ti Kannywood ṣe ti BBC si gbe e Lóri bóyá fífòfinde ere ìfẹ yóò sọ àwọn kan di ẹdun arinlẹ gẹ́gk bi olori akoni nijo Ali ni ni ere ìfẹ ni o pọ̀ ti oun maa n ṣe nítori nínú eré ìfẹ́ ni orin àti ijo ti maa n waye.
Ọ̀rẹ́ wa ni Lawrence jẹ́, àmọ́ ó gbẹ̀yìn dẹ́nu ìfẹ́ kọ abúrò wa - Joshua àti Damilola Bamiloye Ẹ jọwọ, ẹ ba mi bẹ ìyàwó mi kí ìgbéyàwó mi ma baà túká - 9ice Oluwo bu èpè lu àwọn tó dá a lẹ̀bi pé ìgbéyàwó rẹ̀ túká Iléẹjọ́ wọ́gilé ìgbeyàwó nílànà ẹ̀sìn Islam pé kò bófin mu Ṣugbọn nigba to n sọrọ nile ẹjọ, Niyi ni lootọ ni oun beere fun ibalopọ ọlọjọ gbọọrọ.
Wọ́n ti ti apá kan afara náà láti owúrọ̀ ọjọ́ sátide, kò si si àniàni súnkẹrẹ fàkẹrẹ ọkọ̀ yóò pọ̀, nítori naa o lé jẹ́ ojú omi ni ọ̀na àbáyọ láti sá fun wàh'\\alà ojú pópó tó n bọ̀ yìí.
Ó ní, “Ẹ gbà, èyí ni ara mi.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ajọ SERAP sọrọ lori owo ifẹhinti awọn oloselu kan Nigba ti wọn n beere ọrọ lọwọ ọmọbinrin ti ọrọ kan yii lo ni ti ebi ba n pa oun ni oun maa n jẹ nkan ki nkan ti oun ba ri.
Ọna meji si ni wọn pin awọn ọmọ ogun si.
O kopa ninu fiimu Orunmoru, Are Agbaye, Mosebolatan, Agbarun, ti Baba Sala ṣe ati Arelu ti Jimoh Aliu gbe jade ni ọdun 1986.
 lílò rẹ ̀ nínú oyún kò léwu rárá.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ado Ekiti Blind Couple: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Association of Stingy Men: Akeugbagold ní àpẹẹrẹ wèrè díẹ̀díẹ̀ ni k'ẹ́ni tó lówó láhun sí obìnrinwákàtí 9 sẹ́yìn Fídíò, Oluwo Jogbodo Orunmila: Oluwo sọ ìtàn bí Orunmila ṣe jìyà nílùú Iwo àti ayọ̀ tó gbẹ̀yìn rẹ̀ torí sùúrù13 Sẹ́rẹ́ 2021 Past week events: Àwọn ìṣẹ̀lẹ̀ ńlà lọ́sẹ̀ tó kọjá tó fi mọ́ bí Covid-19 ṣe gbẹ̀mí èèyàn 23 lọ́jọ́ kan ṣoṣowákàtí 8 sẹ́yìn Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
9 77845 Orilẹede Finland 618 11.
Mo wá wò ó wí pé, ṣé èmi náà ni mò ń gbádùn eré ìbálòpọ̀ báyìí?
Nígbà tí Sisera gbọ́ pé Baraki ti lọ sí orí òkè Tabori, 
Ohun mẹwaa taa mọ nipa oloogbe naa ree: Ọmọ bibi ipinlẹ Kogi ni Tolulope ni agbegbe Iffe ni ijọba ibilẹ Ijumu ni ipinlẹ Kogi.
Awọn ileeṣẹ kan yoo bẹrẹ si ni ṣiṣẹ pada laarin agogo mẹsan owurọ si agogo mẹfa irọlẹ.
 a sì tún le mú un dẹ ̀ .
Ó ní, “Ẹ má wulẹ̀ dààmú ẹ̀mí ara yín, ẹ má sì bínú sí ara yín pé ẹ tà mí síhìn-ín.
“Ọmọ a máa bọ̀wọ̀ fún baba rẹ̀, iranṣẹ a sì máa bẹ̀rù oluwa rẹ̀.
Ṣugbọn bí ó bá ní àbààwọ́n kan, bóyá ó jẹ́ arọ ni, tabi afọ́jú, tabi ó ní àbààwọ́n kankan, ẹ kò gbọdọ̀ fi rúbọ sí OLUWA Ọlọrun yín, 
Àkókò ati fi ayé sílẹ̀ mi fẹ́rẹ̀ tó.
"Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Oral Sex: Àwọn tó kó àìsàn náà máa ń rí oje lójú ara wọn tó ń rùn bí ẹja 26 Ògún 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 29 Ògún 2020 Oríṣun àwòrán, Laurene Boglio Iwadii ti fihan pe gbigba ẹnu ni ibalopọ lee pese ọna fun aisan oju ara obinrin ti oloyinbo n pe ni ""bacterial vaginosis"" tabi ""BV"" gẹgẹ bo ṣe jade ninu iwe iroyin atigbadegba PLos Biology journal."
Oríṣun àwòrán, Other Gẹgẹ bi akọsilẹ ileẹjọ giga niluu Abuja ṣe sọ, ileẹjọ ti fikun asiko ti Giadom yoo lo gẹgẹ bi adele alaga gbogbogbo APC.
 Ó fẹ ́ akéwì ọmọ ilè gẹ ̀ ẹ ́ sì tí orúkọ rẹ ̀ ń jẹ ́ ted hughes .
Ìpànìyàn Benue: Ìsìnkú Fada àtàwọ́n ọmọ ìjọ yóò wáyé l'ọ́jọ́ Ìṣégun
'Oku ọmọ mi ni wọn gbe wa ba mi lẹnu iṣẹ 'Ki lo buru ninu miliọnu mẹtala abọ naira ti a ngba' Oríṣun àwòrán, STATE HOUSE Àkọlé àwòrán, Ọgbẹni Rex Tillerson n pada si America lojo isegun Ọgbẹni Tillerson, ti o figbakan jẹ oludari ati alakoso ileeṣẹ ExxonMobil, wa ni ipo fun ọdun kan pere.
Ọ̀fẹ́ si ni iforukọsilẹ fun eto naa.
Ẹwẹ, dokita ṣalaye pe bi wọn ba gbe eroja inu egungun (Bone Marrow) ẹni to jẹ AA fun apẹrẹ sinu ẹni to jẹ SS lati parọ rẹ, eyi ṣeeṣe o si wa lati wo o san ni ṣugbọn ko yi ẹya SS to ti wa ninu gbogbo ẹya ara to ku pada.
  Koya je omo orile ede Naijiria, bee si ni, O tun kopa ribiribi ninu ere agbelewo sinima ti o gbode kan lasiko odun keresimesi ti o koja, ti akole re je,“The Frankincense Concert’’.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ọmọkùnrin tó pa ọmọ igbákejì Gómìnà Ondo gba ìdàjọ́ ikú 'Fashọla, o ò dẹ̀ bẹ̀rù Ọlọ́run!
Gbogbo ẹ̀yin tí ẹ yí i ká, ẹ hó bò ó, ó ti jọ̀wọ́ ara rẹ̀ sílẹ̀.
Orílẹ̀-èdè bí Kenya, Canada, Australia, India, Colombia, Malayhsia, Nicaragua, Jamaica, Uganda, Lebanon àti Trinidad & Tobego náà ti yọwó orí nínú ìléèdí obìnrin Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Akọ́mọlédè àti Àṣà lórí BBC Yorùbá: Kọ̀ síi nípa iṣẹ́ tí oúnjẹ ń ṣe lára níbí Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Ondo Heardsmen vs Falae: Ilé iṣẹ́ ọlọ́pàá ìpińlẹ̀ Ondo ni Olóyè Falae kò tí ì mú ẹjọ́ wá si àgọ́ ọlọ́pàá kankan24 Bélú 2020 India Wedding: Ìyàwó kan ní India wọ sòkòtò fún ayẹyẹ ìgbéyàwó rẹ̀- Wo ìdí tó fi ṣe bẹ́ẹ̀25 Bélú 2020 Amos Dauda, Iphone: Ilé ẹjọ́ dájọ́ ẹgba mẹ́ẹ̀dóògún fún ọ̀daràn tó jí Iphone ní Kaduna25 Bélú 2020 Senator Ishaku Abbo: ìdí rèé tí mò fi fi kọ̀wé fi PDP sílẹ̀ darapọ̀ mọ́ ẹgbẹ́ òṣèlú APC25 Bélú 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Ṣugbọn bí alufaa bá yẹ̀ ẹ́ wò, tí irun ọ̀gangan ibẹ̀ kò sì di funfun, tí wúwú tí ó wú kò sì jìn ju awọ ara olúwarẹ̀ lọ, ṣugbọn tí ó wòdú, kí alufaa ti ẹni náà mọ́lé fún ọjọ́ meje.
Angẹli náà dá a lóhùn pé, “Ẹ̀mí Mímọ́ yóo tọ̀ ọ́ wá, agbára Ọ̀gá Ògo yóo ṣíji bò ọ́.
Awọn ọmọ ijọ Sotitobire to ba BBC sọrọ sọ pe inuni-bini wolii ijọ Sotitobore tawọn eeyan kan n ṣe lo jẹ ileẹjọ dajọ ẹwọn gbere fun un.
Mahmood sọ pe 'oun tọrọ aforiji fun sisun eto idibo naa siwaju, ati pe oun gba gbogbo ẹbi naa mọra.
Họnọrebu Owoẹyẹ ni ọpọ awọn obi ti n ti awọn ọmọ wọn ni itikuti kọja nileewe girama ju bo ṣe yẹ lọ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ohun tẹ́ẹ gbúdọ mọ nípa kókó orí ọyàn yín lásìkò fífọ́mọlọ́yàn Gẹgẹ bo ṣe sọ, ẹgbẹrun lọna ẹgbẹrin eeyan lo ku ni Rwanda latari ọrọ ikorira.
N50 mílíọ̀nù làwọn ajínigbé tó jí akẹ́kọ̀ọ́ Kaduna gbé ń béèrè Awọn ajinigbepawo to ji awọn akẹkọ mẹfa ati olukọ meji gbe nileewe aladani kan nilu Kaduna ti n beere fun aadọta miliọnu naira gẹgẹ bii owo itusilẹ wọn.
Gẹgẹ ba se ka lori opo Wikipedia lori itakun agbaye, o ni idi ti Oyenusi se gbe igba idigunjale bii isẹ, lẹyin ti ogun abẹle si pari tan lorilẹede Naijiria lo bẹrẹ si fooro awọn ọmọ Yoruba.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Lagos Theft: Ẹrù olè gbé ẹ̀ṣọ́ ilé wọ kóló olọ́pàá 1 Agẹmo 2019 Oríṣun àwòrán, RRS Ikọ kogberegbe ti ileeṣẹ Ipinlẹ Eko (RRS) ti mu awakọ kan ti wọn fẹsun kan wi pe o ra ẹru ole - awọn nkan ikọle ti awọn oṣiṣẹ kan maa n ji ni agbegbe Lekki.
Aya ààrẹ Naijiria Aisha Buhari ni ọmọ oun náà ṣẹṣẹ ti ilẹ̀ Amẹrika de ni àti pé, ìlànà ti ìjọba là silẹ̀ lati ri dáju pé ẹni to ba ti irin ahjò dé láti àwọn iríll-èdè ti ààrun náà n ba fira jùlọ ki wan ma wà ni ìgbélé.
Wọ́n mú Gaiyu ati Arisitakọsi ará Masedonia, àwọn ẹlẹgbẹ́ Paulu ninu ìrìn àjò rẹ̀, gbogbo wọn bá rọ́ lọ sí ilé-ìṣeré.
Irú aṣọ tí wọ́n fi ṣe efodu náà ni wọ́n fi ṣe ìgbàyà rẹ̀, wọ́n fi wúrà, aṣọ aláwọ̀ aró, ti elése àlùkò, aṣọ pupa ati aṣọ funfun onílà tẹ́ẹ́rẹ́tẹ́ẹ́rẹ́ ṣe iṣẹ́ ọnà sí i lára.
O tun le ṣe ere idaraya naa nipa jijoko, ki o si ka ẹsẹ rẹ ko si abẹ ara wọn.
Asafu, arakunrin rẹ̀, ni olórí àwọn ẹgbẹ́ akọrin tí ń dúró ní apá ọ̀tun rẹ̀.
'Ojú mi rí tóó, àwọn ìyàwó kìí ṣiṣẹ́, ọkọ àtàwa ọmọ-ọ̀dọ̀ laláṣekú lórílẹ̀èdè Oman' Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí 2 sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
Kò sì kúkú jìnnà sí ẹnìkan kan ninu wa.
Ní àfẹ̀mọ́júmọ́ ọjọ́ kinni ọ̀sẹ̀, wọ́n dé ibojì bí oòrùn ti ń yọ.
elenu meta fenuko le lori , ni eyi ti o ti yẹ ki aare Muhammadu Buhari gbe lọ
ọmọ Mahili, ọmọ Muṣi, ọmọ Merari, ọmọ Lefi.
- Òǹwòye ìdìbò YIAGA Koko nnkan ti awọn oludije n sọ Nipa Owo oṣu to kere fun osiṣẹ Àkọlé àwòrán, Kunle Olagbegi ati Ahmad Rufai 100,000 ni ẹgbẹ ADC ati ẹgbẹ AAC lawọn yoo san fun ara ilu gẹgẹ bi owo osu to kere julọ fun oṣiṣẹ Kunle Olatẹru Olagbegi ti o jẹ igbakeji oludije Aarẹ ẹgbẹ ADC ati Rabiu Ahmed Rufai ti ẹgbẹ African Action Congress (AAC) nieyi nikan ni na ti awọn eeyan Naijiria yoofi jaanfaani ijọba.
Won pase fun omidan Abdel Wahab ki o san owo itanran owo ile Egypt 10,000 ($728) ati 5000 ($364) fun gbigbe iroyin ti ko lese n le kaakiri.
kí ẹ̀gún hù lórí ilẹ̀ náà dípò ọkà,kí koríko hù dípò ọkà baali.
Ó wá ṣe àlàyé fún mi, ó ní, “Daniẹli, àlàyé ìran tí o rí ni mo wá ṣe fún ọ.
Aṣọ-káṣọ, àpò-kápò kò bá wù ó dára tó, á bu ẹwà iPhone kù ni.
Èyí tó mú mi rẹ́rìn-ín ni àwòrán olóògbé àrẹ́ Líbíà nì tí ń gun kẹ̀kẹ́ ọmọdé tí ẹnìkan fi se araògiri lẹ́ṣọ̀ọ́.
’ Èmi náà wá dáhùn mo ní, ‘Ìgbà tí ẹ mọ̀ pé ìdílé burúkú bẹ́ẹ̀ ni ìdílé wọn ki ní ṣe tí ẹ fi fẹ́ ẹ?
Ó gbé pẹpẹ wúrà náà kalẹ̀ ninu àgọ́ àjọ níwájú aṣọ ìbòjú náà, 
Nigba to n sọrọ lori epo rọbi, ojisẹ Ọlọrun naa sọ asọtẹlẹ pe awọn ileepo ifọpo rọbi to jẹ ti ijọba yoo tubọ dojude, ti wọn yoo si di akurẹtẹ amọ ileepo aladani ti Dangote kọ yoo gbinnaya.
O seese ki sinima “Black Panther” yii ta ju “Titanic” to wa nipo keta pelu  “Star War: The Force Awakens”  to ta julo lagbaye ko to kan “Avatar”.
0 17 Erekusu Falkland Island 0 0.
Ajọ Lasema ti wa kede pe ohun ti bẹrẹ isẹ idoola ẹmi nibi isẹlẹ naa, paapa lawọn inu ile to fori sọta ọrinrin ibugbamu ọhun.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Owó dé!
Ilé ìjọsin yii kuro ni ilé lásan nitori pe nkan bii alejo miliọnu metala lo n wa wo iṣẹ aramọnda rẹ lọdọọdun lati kaakiri agbaye.
komisona adajo lodun 1999 si odun 2007.
Adédèjì Balógun- Eletǔ jẹ Báálẹ̀, Bábá (Olóyè) Tajudeen Agboọlá Elétù Òdìbò ti ilú Èkó ló sì fi wọ́n jẹ.
Ṣugbọn nigba ti awọn kan kora jọ lati gba ijọba lọwọ ẹgbẹ PDP, o darapọ mọ wọn ti o si jẹ olori ọmọ ile to pọ ju lọ labẹ asia APC.
ti awon eniyan ti o le ni àádọ́ta
Koda, o mu mi lọ si idi isẹ Telọ nitori o gba pe n ko lee di eeyan gidi nidi isẹ tiata.
Ní àárín ọdún, mélòó kan tí ó kọjá, pàápàá ní àsìkò ìjì ọdọọdún monsoon, iye àwọn tí àìsàn-an ibàa ẹ̀fọn ti kọlù ní Bangladeshì ti lékún síi.
”Aare tun soro nipa aseyori ijoba yii, paapaa julo nipa gbigbokun ti awon olote ati atunse lori ibugbe awon ti  wahala le kuro ni ibugbe won.
mewaa lasiko odun  Easter nigba ti won n sajoyo odun ibi Jesu, ti
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Obateru Akinruntan: Wíwá ohun tá jẹ títí láé ló gbé wa kúrò nílé Ife Laipẹ yii ni ikọ Boko Haram naa pa ọkan lara awọn ọgagun ati ọmọogun mẹta miran lasiko ti wọn ṣe ikọlu si wọn.
Aare orile-ede France, Emmanuel Macron sabewo sile igbafe Afrika Shrine, eyi ti onkorin oloogbe Fela Kuti da sile, ile igbafe ti o gbajumo nipinle Eko lojo isegun(Tuesday).
 Ṣùgbọ ́ n lincoln padà mọ ̀ wípé ààrẹ kò lọ wo eré ìtàgé .
Omi naa,Ówù Water Falls to ga ni iwọn mita ọgọfa la gbọ pe o jẹ eyi to ga julọ nilẹ Afirika, ibẹ si ni awọn baba nla to sẹ ilu Ọwa Kajọla silẹ tẹdo si lasiko ogun.
Wọn maa n wa ni ipamọ; ko si nkan to jọ tẹlifisan, radio, iwe iroyin tabi ẹrọ ibaraẹnisọrọ.
Nítorí náà, sọ fún un pé mo bá a dá majẹmu alaafia.
lati owo ijoba apapo tun ti ran egbe agbe oniresi lowo lati tun je ki won le
Oríṣun àwòrán, Alaafin of oyo Igba orisi meji ni awọn ayaba maa n lo lati tigba.
"'Ambode ṣì gbọdọ̀ yọjú sí wa - Ilé aṣòfin Eko' Ìpàdé àpérò kọ́ ló kàn, àdánìkànjẹ ẹ̀yà kan ni ká dẹ́kun ní Nàíjíríà - Òǹwòye ""Bi mo tilẹ̀ jẹ́ apárí síbẹ̀ kò tìmí lójú"", ọ̀pọ̀ dẹ́yẹ sí mi nítori mó ni ààrún ori pípa- Liliya Kukushkina A ṣetán láti ran àjọ aláàbò alájùmọ̀ṣe lọwọ fún ààbò tó péye nílẹ Yorùbá - Ọlọ́pàá Ogun O wa fi kun un pe, lara awọn ti àwọn ti ri mu ni Ajayi Gbenga Festus, ẹni ti ọwọ ajọ na tẹ nilu Ado-Ekiti."
nítorí pé Ọlọrun kò fún un ní ọgbọ́n ati òye.
Balaamu sọ fún Balaki pé, “Dúró ti ẹbọ sísun rẹ, n óo lọ pàdé OLUWA lọ́hùn-ún.
Ogun mii ti awọn agba n lo maa n ṣakoba fu igbẹ tabi itọ Ere Idaraya Gbigbe ara pekepeke fun idaraya maa n ran irinkerindo inu lọwọ.
    Àwọn ọ̀rẹ́ mi kí yìn o, àti pàápàá èyí ti ẹ̀ ń gbúròó tí èmi rẹ̀ jọ ń rẹ́rìn-ín ní apá ọ̀nà ilé wa ní ijọ́sí, tàbí ẹ kò rántí mọ́?
Wò ó bí wọ́n ṣe lúgọ dè mí!
Ọmọ Mike Bamiloye tó ṣe fíìmù Ayamatanga fẹ́ ṣègbéyàwó, kà síi nípa ọkọ rẹ̀ Ọlọ́pàá kọlu àwọn ọmọ onílẹ̀, ní ìbọn àṣìyìn pa ènìyàn méjì Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Wo ewu tó rọ̀ mọ́ tí o kò bá bẹ̀rẹ̀ sí ní jẹ oúnjẹ́ aṣaralóòre lẹ́yìn ti oyún ti dúró sí ọ lára26 Owewe 2020 Fídíò, Wole Soyinka sọ ìdí tó fi ni òun a fi màálù Fulani ṣe súyà fáwọn èèyàn abúlé23 Owewe 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
"Ọgbẹni Ndayishimiye gbaruku ti Pierre Nkurunziza o si ba a ṣiṣẹ papọ lasiko akanṣe ijiroro fun alafia ti wọn pe ni ""Arusha peace talks"" laarin ijọba atawọn FDD rebels."
Alábàárìn mi gbógun ti àwọn ọ̀rẹ́ rẹ̀,ó yẹ àdéhùn rẹ̀.
Jẹ́ kí gbogbo àwọn orílẹ̀-èdè dìde,kí wọ́n wá sí àfonífojì Jehoṣafati,nítorí níbẹ̀ ni n óo ti ṣe ìdájọ́ gbogbo orílẹ̀-èdè tí ó wà ní àyíká.
" 'Ẹ sọ́ra fún Christmas Carol"", ẹ̀yin tẹ́ẹ sì wà lókè òkun ẹ má wálé o!"
Ara meriri, mo ri ori ologbo lori atẹ ni ọrọ kan to n gbona lori ayelujara bayii, ti wọn n pe ni igbeyawo ti ko ni kọlọfin kankan ti wọn n fi nnkan pamọ si, Open Marriage.
Herbal Medicine: Gbígboyè fásítì nínú iṣẹ́ ìṣègùn ìbílẹ̀ dára, àrídájú gbọdọ̀ wà lórí rẹ̀
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ọ̀nà ọ̀fun lọ̀nà ọ̀run - omi ò jẹ́ ká ta ọjà Ìjì líle mú ẹ̀mí èèyàn 1000 lọ, odidi ìlú kan bàjẹ́ Ẹgbẹ̀rún kan dín máàrún awakusa bọ lọwọ iku ni South Africa Kò sí èèyàn kánkan tó kù nílé tó wó ní Ibadan- NEMA Botilẹ jẹ wi pe ẹmi ẹnikẹni ko ba iṣẹlẹ naa lọ, ọpọlọpọ dukia lo ṣofo, bẹẹ sini awọn ibusun ati aga ijoko di sisa sinu oorun.
Adamu so pe, sise agbakale ile-iwe giga fafiti naa yoo se anfani pupo lati ni awon omo ogun ti o kaju osuwon.
Ni bayii, iko Manchester City yoo lo koju iko agbaboolu Wolverhampton Wanderers ti o sese darapo mo idije EPL nibere saa yii.
Ẹ jẹ́ kí á máa lọ.
A ti wọ́gilé ìwọ́de lórí COZA tí a fẹ́ ṣe tẹ́lẹ́ nítorí.
Lara awon ere idaraya to waye nibi aseyẹ  naa ni ijo ọlọkan-o-jọ-kan lati awon ẹya  Kanuri, Igbo, Yoruba, Tiv ati Idoma.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 2019 Elections: Èrò àwọn ọmọ Nàíjíríà se ọ̀tọ̀ọ̀tọ̀ lóri ètó àlùfáà tàbí ìmámù lásìkò ìbò Bẹẹ, awọn iṣẹlẹ bayii ni awọn mii gba pe o n waye nitori pe awọn oludije mejeeji to n léwájú wa lati agbegbe kan naa ni ariwa Naijiria.
Báwó ni òògùn dexamethasone ṣe ń ṣiṣẹ́ lára Ohun méje tí o kò gbọ́ rí nípa aláìsàn arunmọ-léegun- Dókítà Igbekele A o gbiyanju lati se atupalẹ diẹ ninu wọn ni meni meji: Ibi a ba ti ki wọn pẹ o daarọ,a tun le sọ pe ekaalẹ níbẹ Awọn agba Yoruba lo maa n pa lowe pe ibi ti a ba ti sọ pe o daarọ, a kii pada sibẹ lati ki wọn pe ẹ kaalẹ sugbọn lagbo oselu Naijiria ọrọ yi ko fẹẹ ri bẹẹ.
"Arákùnrin tó 'jíǹde' ní mọ́ṣúárì tí kú Irọ́ ni pé mò kò ""Palliatives"" pamọ́ sí ilé mí-Abike Dabiri-Erewa Idi ti Odili fi gba ibi ìbálòpọ̀ lọ sí ọ̀run alákeji nílùú Port Harcourt O ni ibo 11,429 lo wa lawọn ibudo idibo marun un eleyi ti yoo ni ipa to lagbara lori ibo ti yoo sọ ẹni to wọle."
Birth tourism: Ẹ̀yin obìnrin tẹ́ẹ fẹ́ wá bímọ ní America, ọ̀nà ti tì pa látònì!
fun un, awon eekan ninu egbe oselu bii asofin Rasidi Ladoja ti egbe oselu ZLP;
O ku iṣẹju aaya ki ifẹsẹwọnsẹ to kangun si aṣekagba laarin Super Eagles ti Naijiria ati Algeria tan ni Riyad Mahraz gbayo keji wọ le Naijiria.
Ni ọrọ ba di boo lọ ko yago fun mi ni eyi ti wọn ni ibọn ti ba ọdọkunrin meji.
Oríṣun àwòrán, AFP Àkọlé àwòrán, Mammaadou ṣe afihan iwe ami eye ti Aare Macron fi da lola L'ọdun to kọ́ja ni Gassama gbà orí omi kọjá dé sí orílè-èdè France.
Ewe, olukopa omo bibi orile-ede Amerika, Jimmy Connors nikan ni apapo ife-eye ti o gba ju ti Federer lo, leyin ti o ti gba ife-eye ti o leni ogorun-un.
Ní àkókò kan náà ni ọba Edomu gba Elati pada, ó sì lé àwọn ará Juda tí wọn ń gbé ibẹ̀, àwọn ará Edomu sì ń gbé ibẹ̀ títí di òní olónìí.
Ìtura ojó oorun (Sleep-Gasm) Nitori pe ọpọlọ eniyan ni agbára, o tumọ si pe awọn obinrin tun le ni itura ibalopọ l'oju oorun wọn.
Aarẹ Donald Trump ti sọ pe alatako rẹ tii ṣe oludije ẹgbẹ oṣelu Democrat, Joe Biden wọle.
" Àkọlé àwòrán, Lagbo faaji awọn ọmọ Naijiria to n ṣe ajọyọ ṣaaju ifẹsẹwọnsẹ Naijiria ati Cameroon.
Iba Gani Adams ni lootọ ipo oun gẹgẹ bii aarẹ ilẹ Yoruba ko faye oṣelu silẹ, sibẹ ohun ti yoo san ilẹ Yoruba ati awọn eeyan rẹ ni oun yoo maa le lẹka ọmọniyan gbogbo.
Awọn oṣiṣẹ pajawiri naa sọ pe, lati igba ti ojo ti bẹrẹ ni India ni oṣu kẹf ọdun 2018, eniyan bii ẹgbẹrun kan lo ti ku.
Abenugan ile igbimo asofin, ni yoo maa ba awon omo ile igbimo asofin ti orile ede Russia  (Senate of Russia) soro.
Lẹ́yìn ìdásílẹ̀ẹ rẹ̀, Alaa yóò máa wá sun oorun alẹ́ ní àgọ́ ọlọ́pàá ìbílẹ̀ẹ rẹ̀ fún àfikún ọdún márùn-ún gbáko.
     A bá àwọn ìjòyè ìlú náà ṣe àdéhùn, wọ́n sì fi ọwọ́ sí ìwé pẹ̀lú wa pé àwọn di tiwa.
Ó yà àwọn àwòrán oríṣíríṣí fún notre dame cathedral ní paris , ní bíi ọdún 1638 sẹ ́ yìn .
Ìwọ́de EndSARS gboró n'Ibadan, kò sẹ́ni tó le wọlé tàbí jáde Awọn afẹhọnu fun opin ifiyajẹni ati iṣekupani awọn ọlọpaa lorilẹede Naijiria, ti ti gbogbo opopona to wọ ilu ibadan ni ipinlẹ Oyo pa.
World Hepatitis Day: A kò leè kó o nípa dídìmọ́ ara ẹni Ṣé lóòótọ́ ni Amcon gba ilé Toke Makinwa ti wọn ní bàbá olówó rà á fun?
Lẹ́yìn náà, Mose sọ fún Aaroni pé, “Súnmọ́ ibi pẹpẹ, kí o sì rú ẹbọ ìmúkúrò ẹ̀ṣẹ̀ rẹ, ati ẹbọ sísun rẹ, kí o sì ṣe ètùtù fún ara rẹ ati fún àwọn eniyan náà.
Eyi ti ko ṣẹyin eto aabo to mẹhẹ, to ti mu ki awọn agbẹ fi oko wọn silẹ.
Kíni ìdí ti wọn fi ń lọ ọmú obinrin Ilé ẹjọ́ dajọ ikú fun ọkunrin tó pa olólùfẹ́ rẹ̀ Olóṣèlú wọ gau torí pé o ní orí ààrẹ dàrú PDP ní gbogbo àwọn sẹnatọ àti ọmọ ile ìgbìmọ̀ aṣojú ṣofin ti wọn dibò yan ló lẹ́tọ̀ọ́, láti dari ile ìgbìmọ̀ aṣofin.
Ni ìgbà àtijọ́, ọkùnrin kan wa ti orúkọ rẹ njẹ́ Ìgbéraga.
Nítorí iná tí ń jó ni run ni OLUWA Ọlọrun yín, Ọlọrun tíí máa ń jowú sì ni.
Nigba ti Ẹgbẹ agbabọọlu Genk pinnu lati ṣe ayẹwo fun gbogbo agbabọọlu wọn ṣaaju ifẹsẹwọnsẹ ọlọrẹsọọrẹẹ kan ni ayẹwo naa ti fihan pe Onuachu ti farakasa.
Wọn tun fidiẹ mulẹ fun BBC pe awọn eeyan meji fara gbọta ibọn ni agbegbe Awutu Senya East.
Ní ọjọ́ kẹta Eliabu ọmọ Heloni, olórí ẹ̀yà Sebuluni mú ọrẹ tirẹ̀ wá.
Nígbà tí àwọn eniyan bá ń wí pé, “Àkókò alaafia ati ìrọ̀ra nìyí,” nígbà náà ni ìparun yóo dé bá wọn lójijì, wọn kò sì ní ríbi sá sí; yóo dàbí ìgbà tí obinrin bá lóyún, tí kò mọ ìgbà tí òun yóo bí.
Àṣìta ìbọn àwọn Ọlọ́pàá ló gbẹ̀mí àwọn èèyàn tó kú lọ́jọ́ ọdún Eid n'Ibadan - Ará Àdúgbò Awọn olugbe agbegbe Oke-Arẹ niluu Ibadan ti ṣe alaye ọrọ wipe aṣita ibọn awọn ọlọpaa to tọ pinpin awọn ọdaran kan wa si gbegbe naa l'Ọjọ Abamẹta lo ṣekupa awọn eeyan meji kan ni bii aago mẹwa owurọ nibi ti wọn ti n ṣe faaji ọdun.
Asamoah Gyan lè má kópa nínú ìdíje AFCON mọ lẹyìn tí Tunisia júwe ilé fún Ghana
Ìmọ́lẹ̀ náà ń tàn ninu òkùnkùn, òkùnkùn kò sì lè borí rẹ̀.
Ọlọ́gbọ́n ní ojú lágbárí, ṣugbọn ninu òkùnkùn ni òmùgọ̀ ń rìn.
Àgùntàn-ìnàkí ni ó máa ń wá oúnjẹ fún ìyàwó rẹ̀ ní ilé wọn ìgbà tí ó bá sì gún iyán tán tí ó ro ọkà tán tí ó se ọbẹ tán a gbée e kalẹ̀ níwájú ìyàwó rẹ̀, onítọ̀hún a sì máa bú u wí pé oúnjẹ tí ó wá kò dára tó, a máa pòṣé a sì máa ro ẹjọ́ lé e lórí.
Inú bí OLUWA sí Solomoni, nítorí pé, ọkàn rẹ̀ ti yipada kúrò lọ́dọ̀ OLUWA Ọlọrun Israẹli tí ó fara hàn án nígbà meji, 
Ọbasa wa tẹnu mọ idi ti o fi ṣe pataki pe ki awọn ọmọ orilẹ-ede
Nkan to si wa ni ọkan mi ni bi maa ṣe pada sileewe.
Ẹnikẹ́ni kò ni fi ọwọ́ kàn yín, wọ́n ni àwọn ó mọ̀ pé ẹ kò fẹ́ láti ṣe ibi.
Ìdílé Dafidi yóo dàbí Ọlọrun, yóo máa darí wọn bí angẹli OLUWA.
Ibi ti a ti ń ronú bí a ti ṣe lè gbà rí àwọn nǹkan wa ni Ènìyàn-ṣe-pẹ̀lẹ́ ti wí fún wa pé òun ti ní ọ̀rẹ́ kan láàrin àwọn ìránńṣẹ́ wọn-ọnnì.
Yóo di ẹni tí ó ṣetán láti ṣe oríṣìíríṣìí iṣẹ́ rere.
Bí èyíkéyìí ninu wọn bá jábọ́ sórí ohun èlò amọ̀, gbogbo ohun tí ó bá wà ninu ohun èlò amọ̀ náà di aláìmọ́, fífọ́ ni kí o fọ́ ohun èlò náà.
Ìtàn Mánigbàgbé: Ṣango gbèrò ibi fún Gbọnka àti Timi, àmọ́ òun gan bá ọ̀tẹ̀ náà lọ
Mo wá bèèrè pé, ‘Ìwọ ta ni, Oluwa?
6 Ẹrẹ̀nà 2018 A kaakiri lati mọ oye awọn eniyan araalu lori ọrọ Yoruba.
Peteru wá ranti ọ̀rọ̀ tí Jesu sọ, pé, “Kí àkùkọ tó kọ, ìwọ yóo sẹ́ mi ní ẹẹmẹta.
Owo osu ọna meji ko lẹtọ Owo ifẹyinti tan fawọn gomina ana ni Kwara Ẹgbẹ oṣelu PDP ni o wa lori alefa ni ipinlẹ naa bayi ti o si jẹ wi pe ijọba APC lo ṣe agbekalẹ ofin yi ki wọn to kuro lori oye.
FCT-305 Lagos-152 Kaduna-103 Bauchi-44 Gombe-35 Plateau-31 Rivers-17 Sokoto-15 Kwara-13 Kano-9 Ebonyi-8 Ogun-5 Osun-5 Oyo-4 Edo-4 Anambra-4 Bayelsa-2 Ekiti-1 Taraba-1 Apapọ awọn to ti ni -74,132 Awọn to ti ri iwosan - 66,494 Awọn to ti ku - 1,200 Ènìyàn mẹ́ta kú, 418 míràn tun ṣubú sínú àrùn COVID-19 ní Nàìjíríà Oríṣun àwòrán, Twitter/ncdc Covid-19 tún ti ran èèyàn 1,145 míràn ní Nàìjíríà Esi ayẹwo coronavirus lati ipinlẹ mọkanla ti ajọ NCDC fi sita ni Ọjọru, ọjọ keji, oṣu Kejila dun 2020, (02-12-2020), fihan pe, eeyan marundlaadọjọ tun ti ni aarun naa ni Naijiria.
Ẹ̀yin tí ẹ lọ ra aṣọ àlòkù ní Ọjà Ọba Akure, ẹ lọ ṣàyẹ̀wò Coronavirus - Akeredolu figbe ta Ọ̀rọ̀ Sotitobire tí a dá sí, àwọn aṣòfin àtàwọn àjọ kan ló fi lọ̀ wá- DSS Èèyà 315 ló lùgbàdì àrùn Coronavirus ní Naijiria ní ọjọ́ Ajé Ìrántí Sani Abacha, apàṣẹ wàá tó tún kó owó Nàìjíríà mì Nancy Pelosi àtàwọn aṣòfin ẹ́gbẹ́ òṣèlú Democrats wọ aṣọ ilẹ̀ Ghana, Kente láti ṣe ìkẹ́dùn George Floyd Abẹnugan Ile Aṣofin Kekere lorilẹ-ede Amerika, Nancy Pelosi ati awọn aṣofin lẹgbẹ oṣelu Democrats ni wọn wọ aṣọ ilẹ Ghana, Kenke lati ṣe ikẹdun George Floyd ti awọn ọlọpaa pa ni Minneapolis.
Nígbà tí àwọn eniyan Israẹli rí i, wọ́n bẹ̀rẹ̀ sí bi ara wọn léèrè pé, “Kí nìyí?
Iṣẹ abẹ ni wọn gba fi bi Christina ti awọn olugbẹbi rẹ si n ṣe eemọ nigba ti wọn kede asiko ati ọjọ ti wọn bi.
Ọjọ keji, to jẹ Ọjọbọ lo yẹ ki ayẹyẹ igbeyawo laarin oun ati ọkọ afẹsọna rẹ o waye.
OLUWA, ṣé o ti kọ Juda sílẹ̀ patapata ni?
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù COZA RAPE Allegation: Ìdí rèé tí mi ò fi yọjú sí ìgbìmọ̀ àjọ PFN- Fatoyinbo 23 Ògún 2019 Oríṣun àwòrán, Instagram/BiodunFatoyinbo & BusolaDakolo Oludasilẹ ijọ Commonwealth Of Zion Assembly ti ọpọ mọ si COZA, Biodun Fatoyinbo ti iyawo gbajugbaja olorin Timi Dakolo, Busola Dakolo fẹsun ifipabanilopọ kan ti ṣaleye pe agbẹjọro oun lo gba oun ni imọran pe k'oun maa yọju si igbimọ ajọ PFN.
Ṣugbọn agbo to fi ẹyin rin lọ, agbara lo lọ mu wa ni ọrọ Eji Gbadero, bẹẹ ni ko si igi kigi ti igbin rẹ tẹnu mọ, ti ko ni mu gun, ko si si ilẹ ti Gbadero ba nifẹ si, ti ko ni gba ni tipatipa.
Awuyewuye lori ẹgbẹ ọmọ Yoruba lagbaaye (Yoruba World Congress), tun ti bẹyin yọ, lẹyin ti aarẹ YWC, Ọjọgbọn Banji Akintoye ti tu igbimọ alaṣẹ ẹgbẹ ọhun ka.
Àwọn tí wọ́n wá láti Silisia ati láti Esia náà sì bẹ̀rẹ̀ sí bá a jiyàn.
6 254148 Orilẹede Saudi Arabia 5965 17.
Ikú Saulu ati Àwọn Ọmọ Rẹ̀.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ibadan Murder: Oyún oṣù méje ló ń bẹ nínú Azeezat, kí wọ́n tó f'òkúta fọ́ ọ lórí O le ni obinrin ogoji ti Muhammad Alfa ti fipa ba lopọ pẹlu wọn laarin ọdun kan; Lẹyin ti ọwọ ọlọpaa ti tẹ ẹ ni awọn obinrin naa si ti n bọ sita wa sọ ohun to ṣe fun wọn.
Ọpọ lo wo o pe bi APC ṣe kuna ni ipinlẹ Imo ko ṣẹyin eyii.
 bí o tilẹ ̀ jẹ ́ pé melarsoprol a má a ṣiṣẹ ́ fún méjèèjì , a má a ńsába lòó fún t.
Lójijì, ó kígbe pe baba rẹ̀, ó ní, “Orí mi!
Àwọn rèé Ẹbí Tolulope Arotilẹ ń bèrè fún iwadii lórí ìkú tó pa á!
Nítorí náà, n óo ko yín lọ sí ìgbèkùn níwájú Damasku.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìgbẹ̀yìn Joe, akínkanjú to dóòlà ẹ̀mí èèyàn 13 ni P/Harcourt 9 Ògún 2018 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 15 Ògún 2018 Oríṣun àwòrán, FACEBOOK/JOE BLANKSON Àkọlé àwòrán, Ọdun maarun sẹyin ni Blankson ati Mercy sẹgbeyawo, ti wọn si bi ọmọ mẹta, Àwọn ti akọni orí omi Blankson dóòlà ẹ̀mí wọn fẹ́ bẹ̀rẹ̀ ètò ìpèsè ààbò lórí omi fáwọn èrò.
Kedeṣi yìí jẹ́ ìlú ààbò fún àwọn tí wọ́n bá ṣèèṣì pa eniyan, wọ́n tún fún wọn ní Hamoti Dori, Katani pẹlu àwọn pápá ìdaran tí ó wà ní àyíká wọn, gbogbo wọn jẹ́ ìlú mẹta.
Noba gbógun ti Kenati ati àwọn ìletò rẹ̀, ó sì gbà wọ́n.
Alaafin bi ibeji l‘ẹẹmeji lọsẹ kansoso Olorì Anu Adeyemi ń ṣe ọjọ ìbí, ẹ gbọ́ ǹkan tò sọ sí Kábíyésì Aláàfin yẹ́ Lizzy Anjọrin sí níbi ayẹyẹ ìwúyè rẹ̀ Bí Gómìnà Makinde bá ṣẹ̀ mí, lẹ́tà lásán ló jẹ mí- Aláàfin Ọ̀yọ́ Ìlú ò rẹ́rìn ín rárá, Alaafin Adeyemi III fárígá fún Buhari nínú lẹ́tà tuntun Bakan naa ni awọn ayaba olo, ẹlẹjẹ tutu yii tun maa n se idije laarin ara wọn pe, ta ni afẹfẹ (Oxygen) ti Alaafin fi n mi laarin awọn?
Òun ni ó gba Daniẹli lọ́wọ́ agbára kinniun.
Ṣugbọn Ẹ̀mí Ọlọrun bà lé Gideoni, Gideoni bá fọn fèrè ogun, àwọn ọmọ Abieseri bá pe ara wọn jáde wọ́n bá tẹ̀lé e.
Omíyalé àgbàrà ti ya ṣọ́ọ̀bù ní Niger Láìpẹ́, ará ìlú rẹ ni ọlọ́pàá tí yóò máa ṣọ́ ìlú rẹ Atẹjade kan ti ẹgbẹ oṣelu PDP fi sita eyi ti alukoro rẹ, Akeem Ọlatunji fi ọwọ si ṣalaye pe ẹgbẹ oṣelu APC nipinlẹ Ọyọ kan Ọ̀Rọ̀ n tun irọ ta faraalu ni.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Àwa kìí jà lásìkò tiwa, ta ló bí ẹ tí wàa máa jà?
Ẹ gbọ́ ohun tí OLUWA Ọlọrun sọ; ẹni tí ó dá ojú ọ̀run tí ó sì ta á bí aṣọ,tí ó tẹ ayé, ati àwọn ohun tí ń hù jáde láti inú rẹ̀;ẹni tí ó fi èémí sinu àwọn eniyan tí ń gbé orí ilẹ̀;tí ó sì fi ẹ̀mí fún àwọn tí ó ń rìn lórí rẹ̀.
Idi niyi ti a fi gunle iyanṣẹlodi yii.
Wọn lo ọna ilanilọyẹ yii lati ba awọn eeyan sọrọ lori ajakalẹ arun Covid 19 tuntun yii.
 ní àwọn orílẹ ̀ -èdè tó ti ní ìtẹ ̀ síwájú dáradára , kò wọ ́ pọ ̀ púpọ ̀ rárá .
OLUWA Ọlọrun ń ràn mí lọ́wọ́, ta ni yóo dá mi lẹ́bi?
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Coronavirus symptoms in Nigeria: Pẹ̀lú èròjà olùgbèjà ara 'Antibodies' Amọ, o pitu meje tawọn ọdẹ n pa ninu igbo nigba to fi n ṣoju ẹgbẹ agbabọọlu Real Madrid ati Barcelona lorilẹ-ede Spain.
Bakan naa, Belgium ti gba apapo kaadi pelebe olomi osan marun un ti orile-ede England si gba a meji pere, eleyi ti o jasi pe, ti ifesewonse ohun ba pari si ami dogba-dogba, England yoo pari sipo kinni saaju iko akegbe won.
Awọn akẹkọọ ile ẹkọ Roemichs yii ni wọn se idanwo fun lati figa gbaga, ki wọn le mọ akẹkọọ to pegede fun ẹbun ẹkọ ọfẹ naa, ti o to miliọnu kan abọ naira niye fun akẹkọọ kọọkan.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, JusticeforBarakat: O lé lọ́mọ ọdún mọ́kànla kí n tó rí abúrò rẹ̀ bí lée Ẹ lọ yànjú rẹ̀ nílé, ọ̀rọ̀ obìnrin ní, Coronavirus wà níta, a kò le mú ẹnikẹni si agọ wá báyìí, ẹ padà wá ti Coronavirus ba pari."
Lẹnu ọjọ mẹta yi, oke tente ni iye awọn to lugbadi arun naa n lọ bi ọdun Keresimesi ti se n kan lẹkun dẹdẹ.
Wo ǹkan tó yẹ kí o mọ̀ nípa Joe Biden, tó ń kojú Trump nínú ìbò America Mọ̀ sí i nípa àwọn ọmọ Nàìjíríà mẹ́sàn-án tó ń díje nínú ìdìbò ilẹ America lọ́jọ́ Ìṣẹ́gun US Election 2020: Ṣé èsì ìdìbò Ààrẹ Amẹrika yóò jáde lálẹ́ ọjọ́ ìdìbò?
Iwadii ọgbọn atinuda ni awọn n lo nigba naa lai lo ibọn fi ṣe ẹnikẹni leṣe.
 Oruko orile-ede yin nikan ko le gbe laruge, e gbe oruko yin naa ga pelu,”Bakan naa, ajo CAF so lori ero ayelujara won pe, iko Super Eagles gbiyanju lopolopo, bee si ni won mu ori awon wu.
Wọ́n lọ sí Mikimaṣi ní ìhà ìlà oòrùn Betafeni, wọ́n pàgọ́ wọn sibẹ.
Títí di ìgbà wo ni àwọn ọ̀tá mi yóo máa yọ̀ mí?
Ọmọ oṣù mẹ́wàá ni Joshua wá nígbà tí bàbá rẹ̀, Knox Daniel sakiyesi pé ọmọ náà kii ṣe ọmọ lásan, nítori ó kàn gbé sori itan lọ́jọ́ kan níwáju Kọmputa ni nigbà ti ọmọ náà ti ha gbogbo àmi ori kọmputa sori.
Ẹ óo jẹ ẹ́ níbẹ̀ níwájú OLUWA Ọlọrun yín, ẹ óo sì máa yọ̀, ẹ̀yin ati ìdílé yín.
Àwọn ẹnìkan ti ṣiṣẹ́, ẹ̀yin wá ń jèrè iṣẹ́ wọn.
Se ni awọn ilumọọka osere naa ko sinu asọ to jẹ oju ni gbese, olowo iyebiye, ti tọkunrin-tobinrin wọn si dun wo loju.
Àfikún ọ̀sẹ̀ méjì la tún fun yín láti kúrò l‘Apapa - Ọsinbajo Àṣà ìbálé lálẹ́ ìgbeyàwó ń dọdẹ àwọn obìnrin òde òní Ọwọ́ ni INEC fi kọ èsì ìbò ààrẹ, kò sí lórí ''server''-Okoye A ò dójúlé Saraki pé kó dá nọ́mbà ọkọ̀ tó lò padà- FRSC Ní ọ̀pọ̀ ìgbà àwọn fóònù máa ní ibi ti a ti le mú àdínku bá iye dáta ti a fẹ lo.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Yoruba Nollywood: Jide Kosoko ní Mr Latin ò lè dá a ṣe gẹ́gẹ́ bí ààrẹ TAMPAN 16 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Oríṣun àwòrán, Odun Adekola Gbajugbaja oṣere fiimu Yoruba Jide Kosoko ti ni oun wa lara awọn to jẹ igi lẹyin ọgba fun aarẹ ẹgbẹ TAMPAN, Bolaji Amusan ti gbogbo eeyan mọ si Mr Latin.
Mo bá ṣí adé orí rẹ̀, mo sì bọ́ ẹ̀gbà ọrùn ọwọ́ rẹ̀.
 Won gba pe igbese yii yoo tete mu idagbasoke ba eto iwosan Naijiria lapapo.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Cameroun: Awọn sọja tu mi sihoho-obinrin to satipo 9 Èrèlè 2018 Àkọlé àwòrán, Oju awọn eeyan un guusu Cameroun nri mabo lọwọ awọn ologun orilẹede naa.
O le ni eeyan miliọnu 900 to n kopa ninu idibo yii eyi ti o mu u jẹ idibo ti awọn eeyan ti kopa julọ lagbaye.
Ẹ má ṣe rò pé alaafia ni mo mú wá sí ayé.
Day 13: Àwọn ńkan méje tí ẹ lè má mọ̀ nípa Igbákejì Ààrẹ Osinbajo #BBCNigeria2019 Ààrẹ Gani Adams sọ ẹni tí Yorùbá yóò dìbò fún ní ọdun 2019 #BBCNigeria2019 Day 18: Ṣé o fẹ́ mọ òtítọ́ nínu ọ̀rọ̀ ìpolongo àwọn oludije sípò aarẹ Naijiria?
Adugbo Kakawa ni a tun gbọ pe ile miran ti dawo lọjọ Aje.
Ìjọba UK ni láìpẹ́, ẹnikẹ́ni láti àwọn orílẹ̀èdè mélòókan, pẹ̀lú Naijiria, tó bá fẹ́ bẹ ilẹ̀ àwọn wò, ó ní láti fí ẹgbẹ̀rún mẹ́ta pọ́ùn (₦750,000) lélẹ̀ gẹ́gẹ́ bí ìdánilójú pé enítọ̀hún yó padà sílé tí ọjọ́ bá pé.
Ẹ̀yin óo yọ̀ ninu OLUWAẹ óo sì ṣògo ninu Ẹni Mímọ́ Israẹli.
Lẹ́yìn náà, wọ́n rú àwọn ẹbọ wọnyi: ẹbọ àtìgbà-dégbà, ẹbọ oṣù titun, gbogbo ẹbọ ọjọ́ àjọ̀dún tí a yà sọ́tọ̀ fún OLUWA, ati ti àwọn tí wọ́n bá fẹ́ rú ẹbọ àtinúwá sí OLUWA.
"Ilé aṣofin Ondo fọwọ́ òsì júwe ilé fún aṣòfin mẹ́ta pé wọ́n tàpá sí òfin ilé Wo ìgbẹ́sẹ̀ méjọ tí ilé aṣòfin ìpínlẹ̀ gbọdọ̀ tẹ̀lé láti yọ igbákejì gómìnà Àlàyé rèé lórí ìdí tí Magu àti awọn alága EFCC míràn ṣe bá ìtìjú kúrò nípò Àwọn ẹlẹ́sìn ìbílẹ̀ ń bèèrè owó lọ́wọ́ àwọn Alfa lórí ìsìnkú ẹni tó pokùnso Owoseni ni ""Gẹgẹ bi a ṣe mọ pe ko si ilu ti ko si ofin tabi ẹṣẹ, mo fẹ fi da a yin loju pe ọwọ ti tẹ awọpn ọdaran to n gbẹmi eeyan ni Akinyele."
Gomina Seyi Makinde seleri bẹẹ lasiko isin alajumọse akọkọ lati ki ọdun tuntun 2020 kaabọ, eyi ti ijọba ipinlẹ Ọyọ seto pẹlu awọn osisẹ, to waye lọgba Secretariat milu Ibadan.
Adetunji, Ajeogungunniso1; Asoju Alaafin ilu Oyo, Agbaakin Yusuf Akinade; Oba
" Àkọlé àwòrán, Ẹṣẹ ko gba eero nibi ayẹyẹ ọdun ibeji niluu Igbo-Ọra Arulogun ni lẹyin ajọdun tọdun yii, ijọba ipinlẹ Ọyọ yoo gbiyanju lati ṣe ọdun ibeji ni ẹkun iwọ-oorun guusu ki o to di wipe yoo kari orilẹede Naijiria ati gbogbo agbaye.
“Ìbájẹ́pé àtìlẹ́yìn tó tó wá láti ọwọ́ àwọn oníṣẹọba àti ìjọba fún iṣẹ́ tí à ń ṣe níbí.
Ìpinu Gómínà láti dẹ́kun owó ìfẹ̀yìntì fáwọ̀n Gọ́mìnà àná dùn mọ́mi- Bola Ahmed Tinubu Oríṣun àwòrán, Tinubu Asíwájú ẹgbẹ̀ òṣèlú All Progressive Congress (APC) tó tún jẹ́ gómìnà ìpińlẹ̀ Eko nígbà kan rí tí gbóríyìn fún gómìnà ìpińll Eko, Babajide Sanwo-Olu lórí ìgbésẹ̀ túntun tó gùnlé.
Ninu aba eto iṣuna tuntun tọdun 2020 ti ijọba apapọ gbe wa siwaju ile laipẹ yii lo ṣafihan pe biliọnu mẹẹdọgbọn le ni ọgọrun un ni awọn aṣoju wọnyii yoo na tan.
Nígbà tí ó rí i pé òun lóyún, ó bẹ̀rẹ̀ sí fi ojú tẹmbẹlu Sarai, oluwa rẹ̀.
Nítorí òpè ni wọ́n, ọkàn wọn ti le.
Nítorí mo ti gbọ́ ìkéde ìparun,tí OLUWA àwọn ọmọ ogun pinnu láti mú wá sórí ilẹ̀ ayé.
Ogun Lara awọn iṣẹ ti igbimọ ti ijọba ipinlẹ Ogun gbe kalẹ ni ṣiṣẹ iwadii iwa titẹ ẹtọ ara ilu loju mọlẹ ati ṣiṣẹ agbeyẹwo ẹri awọn ti ọrọ naa kan.
English Premier league: Liverpool gun Chelsea bí ẹṣin lójúde rẹ̀ ní Stamford bridge
Awọn to si jẹ arugbo ti ko lagbara ati san owo mọda mọda yii ni wọn yoo ṣe e fun lọfẹ.
ó sì dára bákan náà pẹlu kí o máa kọ́ wọn ní òfin ati ìlànà, kí o sì máa fi ọ̀nà tí wọn yóo tọ̀ hàn wọ́n, ati ohun tí wọ́n gbọdọ̀ máa ṣe.
Ẹka to'n dari fifẹsun kan ni labẹ ile iṣẹ eto idajọ lo fi ẹsun mẹta kan awọn afurasi naa ti ọjọ ori wọn wa laarin ọdun mọkandinlogun ati ogoji ọdun.
Oloye Obafemi Awolowo àti Samuel Ladoke Akintola sì ni wọ́n jẹ aṣáájú ẹgbẹ́ òṣèlú náà àmọ́ nígbà tó di ọdún 1962, ìjà de láàrin àwọn aṣáájú méjèèjì yìí, Ija yí tó pín àwọn ọmọ ẹgbẹ́ òṣèlú Ọlọpẹ si méjì, àwọn kan to sẹ́yìn Awolowo nígbà tí àwọn míràn tó sẹ́yìn Akintola.
O n jẹ ki a bori sunkẹrẹ; fàkẹrẹ ọkọ wiwọ ni eyi ti o maa n fi akoko ẹni ṣofo.
Olori Badrat Olaitan Ajoke Adeyemi: Oríṣun àwòrán, queenola2 Instagram Olori Badirat lo kọkọ pe ara rẹ ni afẹfẹ ti Alaafin n mi sinu, ti oloyinbo n pe ni Oxygen, oun naa si lo tun pe ara rẹ ni ẹlẹ Daddy .
Ni ọpọ orilẹede agbaye, ofin ibaradọgba fun awọn obinrin ati ọmọdebinrin pẹlu awọn ọkunrin ni ko si rara, eyi to lee fidi ẹtọ ati anfaani ọgbọọgba ti wọn ni pẹlu awọn ọkunrin mulẹ, nibi to ba si wa, amusẹ ofin naa yoo mu wahala lọwọ.
Wọ́n ti kó ayọ̀ ati ìdùnnú lọ kúrò ninu oko eléso;ẹnikẹ́ni kò kọrin bẹ́ẹ̀ ni kò sí ariwo híhó ninu ọgbà àjàrà wọn.
    Nígbà tí ó di ojú alẹ́, a wá sí ààfin, ìgbà tí a sì máa dé ọ̀hún ìjà náà ti rọlẹ̀, ọkàn ọba pàápàá ti balẹ̀, o sì fetí sí gbogbo ọ̀rọ̀ tí a bá a sọ, ṣùgbọ́n ọba náà jẹ́ ọ̀kan nínú àwọn ẹ̀dá wọ̀n-ọnnì tí wọ́n máa ń jẹ́ ọlọ́gbọ́n lójú ara wọn, tí wọ́n máa ń jiyàn dé gongo lórí nǹkan tí kò yẹ kí ènìyàn jiyàn lé, wọ́n kìí fetí sílẹ̀ kí wọ́n gbọ́ ìmọ̀ràn ẹnìkejì, wọ́n a má le koko lórí ohun ttí kò yẹ.
n gbaradi fun ifesewonse olorejore ti yoo waye laarin iko ohun pelu iko
Diẹ lara awọn aworan bi akanṣe idibo tonii ṣe n lọ ree: Àkọlé àwòrán, Oṣiṣẹ alaabo n dibo Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Coronavirus Update in Nigeria: 'Ẹ sọ́ra fún Christmas Carol"", ẹ̀yin tẹ́ẹ sì wà lókè òkun ẹ má wálé o!"
Nígbà tí iṣẹ́ bá wọ̀ wọ́n lọ́rùn gan-an, bí ẹnikẹ́ni bá tilẹ̀ ń parọ́ fún wọn, wọn kò ní fetí sí i.
'Mímu ọyàn àyà ìyàwó rẹ̀ ní àǹfàní tó pọ̀' Kí lẹ ò mọ̀ nípa àwọn obinrin Yollywood yìí?
Lẹyin awuyewuye tó tẹle ifòròwanilẹnuwo naa, pasitọ ọhun ti ni oun yoo gba ile ẹjọ lọ lori ọrọ naa.
Àwọn tí wọ́n wá láti inú ẹ̀yà Bẹnjamini ni: Salu, ọmọ Meṣulamu, ọmọ Hodafaya, ọmọ Hasenua, 
Ọdọmọkunrin ni OLUWA yóo fi jẹ olórí wọn,àwọn ọmọde ni yóo sì máa darí wọn.
“OLUWA, kí ni mo jámọ́,tí n óo fi dá ọ lóhùn?
’ Ẹ mọ ohun tí àmì ojú ọ̀run jẹ́, ṣugbọn ẹ kò mọ àwọn àmì àkókò yìí.
Kí ó fi ọwọ́ lẹ́rán, kí ó dákẹ́, kí ó sì máa wòye,nítorí Ọlọrun ni ó gbé àjàgà náà kọ́ ọ lọ́rùn.
Kabiyesi Olubadan to gba ẹnu agbẹnusọ rẹ, alagba Deọla Ọlọkọ sọrọ ṣalaye pe lootọ awọn meji to jẹ ṣaaju ko gba ọdọ awọn ọba jẹ, sibẹ wọn pada wa to o lọna to tọ lọdọ awọn Ọbalaye naa.
Odun to koja ni  ijoba mu ogbeni  Rukuki, ti won fi esun kan an pe , o n ba egbe to n tapa si fifi iya alailetoo je awon eniyan se ise papo                   ( Christian Action for the Abolition of Torture),ni eyi to je pe oun ni akapo egbe naa.
Èèyàn bí àparò l’ayé ń fẹ́
Australia Ni ipinlẹ to tobi ju ni Australia iyẹn South Wales, awọn akẹkọọ pada si ileewe bo tile jẹ pe ọjọ kan laarin ọsẹ ni wọn yoo fi kọ ẹkọ.
Géndé ọkùnrin mẹ́ta gba ìdájọ́ ikú fún ẹ̀sùn ìdigunjalè l'Ọṣun Oríṣun àwòrán, Getty Images Gende ọkunrin mẹta ti gba idajọ iku nipa yiyẹ igi fun wọn nile ẹjọ giga kan ni ipinlẹ Ọṣun.
Máa rán wọn létí kí wọn máa tẹríba fún ìjọba ati àwọn aláṣẹ, kí wọn máa gbọ́ràn sí wọn lẹ́nu, kí wọn sì múra láti máa ṣe iṣẹ́ rere gbogbo.
Ondo Governorship Elections 2020: INEC ní ìjọba ìbílẹ̀ Ilaje ní ìṣẹ̀lẹ̀ tó burú jùlọ tí wáyé nínú ìbò 2016 Lára ìgbésẹ̀ ìjọba láti le ri i dájú pé ètò ìdìbò lọ ní ìrọwọ́rọsẹ̀ ní ìpínlẹ̀ Ondo, àjọ elétò ìdìbò (INEC) ní òun ti bèèrè fun iranwọ àwọn ilé iṣẹ́ elétò ààbò to pọ.
Ẹ̀yin alára ni ìwé wa, tí a ti kọ sí ọkàn wa.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù LASTMA: Ẹ̀sùn àgbèrè la gbọ́ pé ó fá ìjà, tó já sí ikú náà 12 Ẹrẹ̀nà 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 6 Agẹmo 2020 Oríṣun àwòrán, Others Oṣiṣẹ ajọ to n mojuto igbokegbodo ọkọ loju popo nipinlẹ Eko, LASTMA, Emmanuel Mekuri, ti gbẹmi ara rẹ, lẹyin to pa ololufẹ rẹ.
lati se ohun ti orile ede  ati ajo agbaye
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: NURTW l‘Abuja yóò kàn sí Makinde láìpẹ́ lórí bó ṣe fòfin dè wá l‘Ọyọ - Ejiogbe Igun ẹgbẹ́ NURTW tó bá da ayẹyẹ ìbúra mi rú, yóo rugi oyin - Seyi Makinde Kíni N11trn owó ìrànwọ́ epo tí ìjọba àpapọ̀ san fún àwọn agbépo lè rà?
Ibadan Refuse: E wo àwòrán bí ìlú Ibadan se di ààtàn nítorí ìdòtí
O tiwa ni aafin Ọba Soun tilu Ogbomọṣọ lati ọọdunrun ole mẹtalelogoji ọdun (343years old) Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Arakunrin kan duro si ẹgbẹ ere kan to sun mọ odo Ọsun.
Ṣé lóòtọ́ ni Shittu kò ní ìwé-ẹ̀rí àgùnbánirọ̀?
Gẹgẹ bi iroyin tun ṣe sọ, ko tii pe ọdun kan ti lẹfutannaati Borgi ṣe iyawo, ti iku mu u lọ yii.
ti fi ero ọkan wọn han lori iroyin nipa pe ijọba Ipinlẹ Eko ko tete gbe
O ni ijọba oun ti kan ni kanpa fun Banki apapọ Naijiria lati fofin de tita owo ilẹ̀ okeere lowo pọ́ọ́ku fun awọn to ba fẹ ra ohun elo ogbin ati ounjẹ lati okeere.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Abiola Ajimobi kò gbọdọ̀ kú, ẹ lọ wọlé àdúrà - APC Oyo pariwo Ọkúnrin kan gún àfẹ́sọ́nà rẹ̀ pa tán ló bá tún pa ara rẹ̀ náà Ohun tí a mọ̀ nìyí nípa àwọn tí yóò láǹfàní àti lọ sí Hajj lọ́dún yìí Àìmọ̀kan ló ń ṣe ìjọba Oyo tó fẹ́ ṣí iléèwé, gbogbo ìpínlẹ̀ ló ní àrùn COVID 19- Ijọba àpapọ̀ Lórí bóyá igbákejì gómìnà Ondo yóò fipò sílẹ̀ tàbí rárá, ohun tó lu sí wa lọ́wọ́ nìyí Ènìyàn 675 ni èsì àyẹ̀wò sọ pé ó tún ṣẹ̀ṣẹ̀ ní Covid-19 ní Nàìjíríà Dilibe Onyeama si lo kọ iwe kan nipa iwa ẹlẹyamẹya ti oju rẹ ri nileewe naa ati bi ti ile ẹkọ naa ko se gba a laaye lati pada wa sibẹ mọ.
Pilatu bá tún bi í pé, “O kò sì fèsì rárá?
Pinnick jẹ igbakeji aarẹ ajọ CAF akọkọ lati oṣu Keje ọdun 2018.
Kò ní ìtumọ̀ kankan pàtó ní èdè Yorùbá.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Favour Oladele: Bó ṣe kàgbákò ikú gbígbóná lọ́wọ́ ọ̀rẹ́kùnrin rẹ̀- Kayeefi 31 Sẹ́rẹ́ 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 10 Èbibi 2020 Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Kò tíì tó oṣù kan tí èmí àti Favour bẹ̀rẹ̀ sí ni fẹ́ ara wa tí mo pa á ṣe ògùn owó Ninu fidio to wa loke yii, ẹ o ri pabanbari bi Owolabi Adeẹkọ ṣe fi ọrẹbinrin rẹ ṣe oogun owo fun oun ati iya rẹ.
 wọ ́ n ri wípé táyà ọkọ ̀ náà kó fi taratara dára ṣùgbọ ́ n ó ń ṣiṣẹ ́.
Niajiria ni yoo je ohun akọkọ ti o wa lọkan oun lati se ninu ijoba rẹ .
Oga agba awọn agbofinro fi da awọn eniyan ipinlẹ Oyo loju pe o di dandan ki agbara ofin mu awọn to ṣiṣẹ ibi naa.
Oríṣun àwòrán, Yemi Elebuibon O fikun ọrọ rẹ pe, lataye baye ni ajinigbe, ole, agbesunmọmi ati awọn ọdaran mii ti wa, ṣugbọn ilu kọọkan nilẹ kuotu ojiire lo ni nnkan iṣọra ti ogun ko fi ni ja ilu.
Aare soro yii nigba to n gba leta lowo asoju orile ede Gambia si orile ede Naijia ogbeni Amadou Taal.
Iru awọn iroyin ti ẹ le nifẹ si: Fọlọrunṣọ Alakija: Imọ ṣe koko 'Ara sisan kii ṣe arun' Abẹwo Aarẹ Buhari si Plateau Buhari ṣ'eleri pipese iṣẹ f'awọn ọdọ Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
mo pàṣẹ pé ní gbogbo ìjọba mi, kí gbogbo eniyan máa wárìrì níwájú Ọlọrun Daniẹli, kí wọ́n sì máa bẹ̀rù rẹ̀.
O tẹsiwaju pe, oun gan paapaa ni ẹbi si Uganda ti ko si omi mimu fun wọn tabi ina mọnamọna.
" Fashola fi orúkọ àwọn ilé isẹ́ tó jẹ́ àjẹbánu síta.
Ejò lé àwọn aṣòfin ìpínlẹ̀ Ondo kúrò nípàdé Amọ ṣa, Egbetokun sọ pe wọn ko san owo kankan fun itusilẹ awọn ọmọ ilẹ okeere naa.
Leyin ti ọwọ tẹ Shodipẹ, fun ẹsun ipaniyan ni ṣisẹntẹle ni agbegbe Akinyẹle ni ilu Ibadan, okiki kan nigba ti awọn agbofinro kede pe o tun ti salọ mọ wọn lọwọ.
Nítòótọ́, ẹ ti fi òkúta tí wọ́n dárà sí kọ́ ilé, ṣugbọn ẹ kò ní gbé inú wọn; ẹ ti ṣe ọgbà àjàrà dáradára, ṣugbọn ẹ kò ní mu ninu ọtí waini ibẹ̀.
Gbà mí lọ́wọ́ àwọn tí ń ṣe inúnibíni mi,nítorí pé wọ́n lágbára jù mí lọ.
Nítorí nígbà tí a wà lọ́dọ̀ yín, a pàṣẹ fun yín pé bí ẹnikẹ́ni bá kọ̀ tí kò ṣiṣẹ́, ẹ má jẹ́ kí ó jẹun.
Ó tún fi kún un pé, “Ìyìn ni fún OLUWA Ọlọrun Israẹli tí ó dá ọ̀run ati ayé, tí ó fún Dafidi ní ọmọ tí ó gbọ́n, tí ó sì ní òye ati ìmọ̀ láti kọ́ tẹmpili fún OLUWA ati láti kọ́ ààfin fún ara rẹ̀.
Chelsea kọ́wọ̀ọ́ rìn pẹ̀lú Arsenal lọ àṣekágbá Europa Àwòrán mánigbàgbé BBC news Yorùbá fún ọ̀sẹ̀ yìí Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ǹjẹ́ o mọ Yoruba daju?
Ṣe ti owo epo to wọn gogo ni?
Won so pe” ko fe si eni ti won fun ni iru ewon ti won  fun a-ji-jagbara omo orile ede Burundi naa ri”.
Ileeṣẹ to n mojuto igbohunsafẹfẹ nilẹ naa, Ofcom ni iwaasu naa ti awọn eeyan orilẹede Gẹẹsi ni anfani lati tẹti si lee ṣe ijamba fun wọn, nitori naa, o lodi si ofin igbohunsafẹfẹ ilẹ wọn.
Ọkunrin tí ó wọ aṣọ funfun, tí ó wà lókè odò na ọwọ́ rẹ̀ mejeeji sókè ọ̀run, mo sì gbọ́ tí ó fi orúkọ ẹni tí ó wà láàyè títí lae búra pé, “Ọdún mẹta ààbọ̀ ni yóo jẹ́.
Ẹ kò gbọdọ̀ tẹ̀lé ìlànà wọn.
 Gẹ́gẹ́ bi alákoso náà ṣe sọ, ní kété ti wọ́n mú wọ́n tan ti wọ́n sì fọ̀rọ̀ wá wọ́n lẹ́nu wò, ni wọn mórílé àgọ́ ọlọpàá Mokọla sùgbọ́n ti àwọn ọlọ́pàá tó wà níbẹ̀ kọ̀ láti gbà wọ́n."
"Wọn kọkọ lọra lati se bẹẹ, amọ bi Tarrant tun se yin ibọn miran to pa olujọsin miran, ni wọn se bẹẹ, nigba to ye wọn pe agbebọn ti de,"" Oríṣun àwòrán, @GbenroAdegbola Alabi sọ siwaju pe, olujọsin kan to n jẹ Aziz, nigba ti ko lee maa wo agbebọn naa niran, lo ba gba ya, to si wọya ija pẹlu rẹ, ti agbara rẹ si kaa, eyi ti ko jẹ ki agbebọn naa wọnu mọsalasi wa ba wa."
Epafirasi, iranṣẹ Kristi Jesu, ọ̀kan ninu yín, ki yín.
Kò sí ẹnìkan ninu wọn tí ó dá àwọn nǹkan tirẹ̀ yà sọ́tọ̀, wọ́n jọ ní gbogbo nǹkan papọ̀ ni.
 kò ní ìbáṣepọ ̀ tí ó dájú pẹ ̀ lú guilain-barre syndrome .
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Tinubu kọ lẹta si Odigie pe o'n gbegi di'na iṣẹ oun 23 Èrèlè 2018 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ọpọ ipinlẹ lo n koju aawọ abẹnu ninu ẹgbẹ APC lorilẹede Naijiria Aawọ abẹnu ti o'n ba ẹgbẹ oṣelu APC finra tun ti gbo'na mi yo pẹlu bi adari agba fun ẹgbẹ oṣelu naa lorilẹẹde Naijiria, Aṣiwaju Bọla Tinubu, ṣe kowe si Alaga ẹgbẹ, John Odigie Oyegun.
"Kii se eto ilera alabọde nikan ni ko gbadun lorilẹede Naijiria, sugbọn ti ilera gbogbo.
Idi ni pe gbogbo aayan igbimọ fidiẹ to n tukọ ẹgbẹ APC lọwọ lọwọ lati yanju aawọ abẹnu to n daamu ẹgbẹ oselu naa, lo ja si pabo.
Ninu ọrọ to fi sita, o sọ pe ẹbun ọjọ ibi to ṣe iyebiye ju ni ọmọ tuntun naa jẹ fun oun.
Lọdun 2014, ọkọ oju omi miran kọlu opo to di afara naa mu eleyi to mu ki apa kan afara naa dawo sinu omi.
Oba Maiwada Galadima jẹ olori ẹya Adara ti wọn si lero wi pe iku rẹ le sokunfa ki ija miran tun bẹ silẹ.
Osaka omo ogun odun ohun fagbahan Williams pelu ami-ayo mefa si meji(6-2) mefa si merin(6-4) lojo abameta(Saturday) lati gba ife-eye idije naa.
Báwó ni òògùn dexamethasone ṣe ń ṣiṣẹ́ lára Coronavirus: Ewu wo làwọn òṣìṣẹ́ elétò ìlèra ń kojú ní Nàìjíríà?
olubori lati gbaa ami eye yii saaju awon akegbe re, Raphael Varane ati Antoine
Èyí ló sì mú kí wọ́n dá ikọ̀ aláàbò nàá sílẹ̀, ṣùgbọ́n, ipá wọn kò ká àwọn géndé agbébọn tó yí abúlé Gwaska ká lọ́sàn ań ọjọ́ Àbámẹ́ta, tí wọ́n sì bẹ̀rẹ̀ sí ní yìnbọn, tó fi mọ́ dídáná sun ilé.
ó ní, “Kí ló dé tí àṣẹ ọba fi le tó báyìí?
Àwọn Ẹ̀gbá ni nkọ mẹ́ta-mẹ́ta tí kò gùn tí kò sì gbọọrọ.
Oríṣun àwòrán, Twitter Igbe to Ẹmiọla fi ta ni ori itakun ayelujara lo mu ki okiki iṣẹlẹ naa kan kaakiri.
Láti January lọ, gbogbo ẹni tó bá ra ọjà lórí ayélujára yóò máa sanwó orí - FIRS BBC lọ beere ero awọn ọmọ Naijiria ti ọrọ naa kan julọ lori koko yii.
Buratai tun salaye pe, “a o pese ibugbe ti o joju ni gbese ati awon ohun amayederun miiran fun awon ologun wa.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Oríṣí ìjìyà ní àwọn bíi Gómìnà El Rufai àti Fayemi ń bèèrè f'àwọn afipábánilòpọ̀ Ìrìnà ọkọ̀ akérò àti ọkọ̀ òfurufú bẹ̀rẹ̀ padà jákèjádò Nàìjíríà!
Bí Saulu bá gbọ́, pípa ni yóo pa mí.
'Bawo la ṣe maa kọju ibọn sirawa?
Òbí ọmọ Chibok kú nínú ìjàmbá ọkọ̀ Buhari ní òun kò gbàgbé àwọn ọmọ Chibok 'Mẹ́ẹ̀dógún lókù láàyè nínú àwọn ọmọ Chibok' Akẹkòó Obìnrin Chibok 57 tí lọkọ ní Cameroon Gbáko!
Èékán ọwọ́ wọn mu bí àdá, Ìgbà tí wọ́n bá sì ń họ ara, a máa dún kùràkùrà bí ìgbà tí àgbẹ̀ ba ń fi ọkọ́ ro oko.
Alaga  igbimo to n ri si epo rọbi nile
OLUWA wí pé: “Mo ti pa àwọn orílẹ̀-èdè run; ilé-ìṣọ́ wọn sì ti di àlàpà; mo ti ba àwọn ìgboro wọn jẹ́ tóbẹ́ẹ̀ tí ẹnikẹ́ni kò lè rìn níbẹ̀; àwọn ìlú wọn ti di ahoro, láìsí olùgbé kankan níbẹ̀.
Wọ́n a sọ pé kí àwọn maa fi pawọ́dà títí tí àwọn yóò fi rí iṣẹ́ gidi ṣe.
Sinima nipa igbe aye Yemi My Lover n bọ Ọmọ bibi ikarẹ ni Ilu Ondo,Yemi Ayebo wa lara awọn to kọkọ tan irawọ ere sinima agbelewo lede Yoruba pèlu awọn sinima bi Yemi My Lover, Joke Onibudo ati Ọdẹ Aperin.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Coronavirus survivor: Àntí Korona ni wọ́n n pè mí l'ádùúgbò láti ìgbà tí mo ti ní Covid-19 Awọn ounjẹ kan wa ti obìnrin ko le ṣe lasiko nnkan oṣu rẹ Igbagbọ kẹfa nipa nnkan oṣu obinrin ti ko tun fi idi mulẹ ni pe awọn oriṣi ounjẹ kan wa ti ko ni jinna laelae, ti obinrin to n ṣe nnkan oṣu lọwọ ba se e.
Ikú Barakat Bello ní Akinyele gbé aláàánú pàdé ẹ́bí rẹ̀ Yoruba ni a tori ọkan se ọkan ni Ọlọrun Ọba, ti ọpọ eeyan si maa n gbadura pe, ko ma fi ọkan gba ọkan lọwọ wa.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Bromage ni ọ̀pọ̀ ló ń lùgbàdì ààrùn Covid-19 nínú ilé wọn nítorí ọ̀kan nínú ẹbí wọn tó ní ló pín fún gbogbo ẹbí lẹ́yìn tó ti rí ààrùn naa he nígboro Ṣùgbọ́n bi ènìyàn ba kúrò nínú ilé ńkọ́?
” Wọ́n dá a lóhùn pé, “Bí o ti rí gan-an ni ẹnìkọ̀ọ̀kan wọn náà rí, gbogbo wọn dàbí ọmọ ọba.
Ní ọjọ́ kẹta tíí ṣe ọjọ́ ìbí Farao, ọba se àsè ńlá fún gbogbo àwọn iranṣẹ rẹ̀, ó sì mú agbọ́tí rẹ̀ ati alásè rẹ̀ jáde sí ààrin àwọn iranṣẹ rẹ̀.
Kuraani ati aṣọ pelebe funfun lati ṣe ayẹwo ibale mi eyi ti Arikẹ Adebayo fun mi""."
Ẹ̀rù jẹ̀jẹ̀ ni Ọlọrun ní ibi mímọ́ rẹ̀,Ọlọrun Israẹli;òun ni ó ń fún àwọn eniyan rẹ̀ ní ọlá ati agbára.
Ṣugbọn ẹni tí ó bá fara dà á títí dé òpin, òun ni a óo gbà là.
Má di ohun ẹ̀rù fún mi,nítorí ìwọ ni ibi ààbò mi ní ọjọ́ ibi.
Baba to bi baba rẹ, Muhammadu Sanusi kinni ni Emir kọkanla ilu Kano lati ọdun 1953 titi di ọdun 1963.
Ó kúnlẹ̀, ó ń bèèrè nǹkankan lọ́dọ̀ rẹ̀.
Ileeṣẹ naa n risi gbigbe sinima jade, o si tun ni ẹka ti wọn ti n kọ nipa iṣẹ sinima ṣiṣe.
 O ni oun n gbero lati de ile Egypt ko to pada sile.
Wọ́n parí kíkọ́ tẹmpili náà bí Ọlọrun Israẹli ti pa á láṣẹ fún wọn ati gẹ́gẹ́ bí àṣẹ Kirusi, ati ti Dariusi ati ti Atasasesi, àwọn ọba Pasia.
Bauchi South ati Aishatu Dahiru, PDP Adamawa Central.
Ọmọ Daura ti tàpá sí òfin ààbò Nàíjíríà, ó sì yẹ kí Buhari le è to ilé rẹ̀ Njẹ́ o mọ pé N3000 ló o sàn láti gbà kaadi ìdánimọ̀ míì bí tí tẹ́lẹ̀ bá sọnù?
Ó tún dáhùn pé “Jọ̀wọ́ dárí àfojúdi mi jì mí nítorí ọ̀rọ̀ mi, bí a bá rí ogún eniyan ńkọ́?
Lásìkò tó n da ẹ́jọ naa, adájọ Adenike Akinpelu ni Adekunle Abraham, to jẹ ọmọ ẹgbẹ òṣèlú People's Democratic Party( PDP) to pe ẹjọ náà, ti kọ̀wé si ilé ẹjọ pe oun ko ṣẹjọ mọ.
A gbọ pe ipele karun-un eto ẹkọ imọ isegun oyinbo ni fasiti Ambrose Ali to wa ni Ekpoma, ni Dara, ọmọkunrin adajọ to ku naa wa.
"Ibẹrẹ ọtun ree"" Runtown ṣe atunpin atẹjade ọkan lara awọn amugbalẹgbẹ aarẹ Buhari to kede ọga agba ọlọpaa ti tu ikọ SARS ka."
Ebi Gnassingbé lo pẹ ju lori aleefa ninu isejoba  nile Afirika.
ede Naijiria lati duro sinsin , ki won si ri i pe awon to ba je omo egbe nikan
O ni ile iṣẹ naa ko lẹtọ lati kọ apa ibi ti ijọba wo, lai ṣe ohun ti ijọba fẹ.
Kò ní já ọ kulẹ̀, bẹ́ẹ̀ ni kò ní fi ọ́ sílẹ̀.
Ni ipinlẹ Ogun, ijọba fòfin de ìsìn aisun ọdun tabi ipejọpọ kankan ni ipinle ọhun.
Èmí sonú púpò nínú ogun abélé Ìbàdàn àti Ìjàyè yìí tí Ààre kúrunmí sì ségun Ìbàdàn fún ìgbà àkókó tí ó sì mú basòrun Ògúnmólá tí ó jé olórí ológun ìlè Ìbàdàn lásìkò náà lérú , ó soó mólè nídìí òkan nínú àwon òrìsà Ògún rè , tí ó sì n fun ní eerú ( ashes ) jé dípò ónjé gidi .
Aṣofin Sikiru Ọṣinọwọ dupe lọwọ Ọlọrun fun aṣeyọri pipari
Àwọn eniyan burúkú ń yan kiri,níwọ̀n ìgbà tí àwọn eniyan ń ṣe àpọ́nlé iṣẹ́ ibi.
” (Efurati yìí ni wọ́n ń pè ní Bẹtilẹhẹmu.
Pèpéle kan wà níbi ẹnu ọ̀nà, tí gígùn rẹ̀ rí bákan náà pẹlu ẹnu ọ̀nà, èyí ni pèpéle tí ó wà ní ìsàlẹ̀.
Ìrìnkèrindò gidi rèé o, ẹ máa bá mi kálọ.
Ṣugbọn tako ẹri naa, ileeṣẹ ologun ni ọmọ ẹgbẹ Shiite meje pere to di opopona ilu, to si tun gbidanwo lati pa ọga awọn, Ọgagun Tukur Buratai lawọn pa.
Oríṣun àwòrán, @ooniadimulaife Bi o tilẹ jẹ pe ọpọ ọdun bii ọdun egungun nilu Ibadan ati ayẹyẹ Ojude Ọba nilu Ijebu Ode ni ko lee waye nitori ọsẹ ti arun Coronavirus n se, sibẹ Ile Ife ko wọgile ọdun Ọsun lọdun yii.
"Biṣọọbu ijọ Aguda ni Washington, Alufa agba Mariann Budde ni ""Aarẹ kan deede lo bibeli eyi tii ṣe ọrọ ijinlẹ julọ ninu aṣa awọn ẹlẹsin Kristẹni lai gba aṣẹ to si fi n ṣe ipilẹ ọrọ to lodi si ẹkọ Jesu Kristi."
Ko pẹ si asiko naa ti kọmiṣọna feto ilera ipinlẹ Eko, Akin Abayomi kede pe, wọn ti ṣawari awọn meji ti wọn n wa, ti wọn wa ninu ọkọ baalu ilẹ Turkey to gbe ọgbẹni naa wa si papakọ ofurufu ilu Eko.
Bakan naa ni awọn onibaara yoo ni anfaani ibi ti wọn ti le fi ẹjọ sun nipa ileeṣẹ amunawa ti ko ba ṣe daadaa.
Ise-akanse ohun je erongba awon eka aladani bi: ile-ise Toleram Group ati China Harbour, awon ni won je agbateru ise-akanse naa.
Nítorí ìwọ OLUWA ti gba ọkàn mi lọ́wọ́ ikú,o gba ojú mi lọ́wọ́ omijé,o sì gba ẹsẹ̀ mi lọ́wọ́ ìṣubú.
 Ìtọjú fún àrùn ẹ ̀ dọ ̀ líle , bí ó bá wáyé , ni pẹ ̀ lú Ìrọ ́ pò ẹ ̀ dọ ̀ .
Àbí àwọn amòye kò ní ìmọ̀ràn lẹ́nu mọ́?
Gbogbo àwọn ọmọ ogun tí wọ́n wà pẹlu rẹ̀ bá a lọ títí wọ́n fi fẹ́rẹ̀ dé ìlú Ai, wọ́n sì pàgọ́ wọn sí apá ìhà àríwá ìlú náà, odò kan ni ó wà láàrin wọn ati ìlú Ai.
Irin ni wọ́n fi ṣe pósí rẹ̀, ó sì wà ní Raba, ní ilẹ̀ àwọn Amoni títí di òní olónìí.
Ṣomolu, Aṣofin Rotimi Olowo ti ẹgbẹ oṣelu APC ni wọn dibo pada yan pẹlu
    “Ìyàlẹ́nu ni ó jẹ́ fún mi nígbà tí mo yọ sí ọba tí ó sì dìde lórí ìtẹ́ lẹ́sẹ̀ kan náà tí ó wọ inú iyààrá rẹ̀ ṣùgbọ́n nígbà tí ó wá pẹ́ díẹ̀ tí ó padà dé ni àwọn ìjòyè rẹ̀ wí fún mi pé yíyọ tí mo yọ ní inú ẹ̀wù ẹtù tí mo wọ̀, mo jọ bàbá mi tó bẹ́ẹ̀ tí orí ọba fi wú, àti wí pé nítorí èyí nì ni ọba ṣe wọlé tí ó lọ sọkún nítorí kò gbọdọ̀ sọkún lójú gbangba.
Nitori eyi, kò yẹ ki enia “Kú silẹ̀ de ikú” nitorina, “Bi ẹ̀mi bá wà, ireti ḿbẹ”.
Ile -isẹ ọlọpaa ni ipinlẹ Eko ti fi panpẹ ọba mu oluko ile-iwe giga Fazir-I-Omar ti wọn fẹsun kan wi pe oun fipa ba awọn akẹẹkọ lọpọ.
Ẹkọ iwe lo tun sọ Abiola silẹ Amẹrika, to si lọ gba oye imọ ijinlẹ nipa akoso okoowo nile ẹkọ fasiti New York to wa ni Buffalo, níbi to ti gba oye imọ ijinlẹ ninu imọ sayẹnsi.
Ṣebí Hesekaya ti gbọ́ ohun tí àwọn ọba Asiria ṣe sí gbogbo àwọn orílẹ̀-èdè, tí wọ́n pa wọ́n run patapata.
Wọ́n sin àwọn ará Filistia fún ogoji ọdún.
Gẹgẹ bi iṣe awọn ọlọpaa, ọlọpaa obinrin yẹ ara afurasi yii wo finifini ki wọn to mu u lọ si ẹwọn.
    “Mo kí gbogbo yin o, mo kí onílé mo sì kí àlejò, mo ki gbogbo ènìyàn pátápátá, mo kí yín lórúkọ àwọn ẹgbẹ́ mi wọ̀nyí, àwọn arákùnrin gbogbo ti ń lọ si oke Ìrònú, ti ń lọ sínú Igbó Elégbèjè.
Èdè Yorùbá jẹ́ èdè kan ti ó gbalẹ̀ tí ó sì buyì kákàkiri àgbáyé.
Nígbà tí kò lè gbé e pamọ́ mọ́, ó fi koríko kan tí ó dàbí èèsún ṣe apẹ̀rẹ̀ kan, ó fi oje igi ati ọ̀dà ilẹ̀ rẹ́ ẹ, ó gbé ọmọ náà sinu rẹ̀, ó sì gbé apẹ̀rẹ̀ náà sí ààrin koríko lẹ́bàá odò.
Jesu dá a lóhùn pé, “N kò sọ fún ọ pé ìgbà meje; ṣugbọn kí ó tó ìgbà meje lọ́nà aadọrin!
Mikel Obi to n dari won ti ni awon ti satunse si gbogbo asise won pelu ileri pe didun losan a so bayii ninu idije ohunOpo ninu won lo je pe ile Geesi ni won ti n mu taje se ninu boolu alafesegba.
Aisaya gbadura sí OLUWA, OLUWA sì mú kí òjìji pada sẹ́yìn ní ẹsẹ̀ mẹ́wàá lára àtẹ̀gùn ilé tí ọba Ahasi ṣe.
Ṣé ọgbọ́n ti rá mọ́ wọn ninu ni?
Kọmiṣọnna ni aarun yii ko le ṣalai maa maa tan kalẹ si nitori awọn eeyan ko tẹ le ilana itakete si ara ẹni.
14 Òkùdu 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 15 Òkùdu 2019 Àkọlé àwòrán, Ọ̀nà tí àṣà ìbálé lálẹ́ ìgbeyàwó ń gbà dọdẹ àwọn obìnrin òde òní Alẹ ọjọ igbeyawo jẹ alẹ ọjọ manigbagbe fun tọkọ taya nitori awọn ohun aramọnda to seese ko waye lalẹ ọjọ naa.
Ogun ebi ni Nàìjíríà ń bá fínra lọ́wọ́, ogun coronavirus kò gbọdọ̀ kún un-Oluwo Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Coronavirus: Àwọn ìlana to tọ̀nà lati tọ ti o ba fún pe o ni ààrun Ẹwẹ o ṣalaye pe, bi iku ti arun Coronavirus ti mu wa yii ṣe pọ to ti o si bani ninu jẹ, sibẹ ko to iye ẹmi ti aisan iba ati ijamba mọto ti mu lọ laarin oṣu mẹta akọkọ ninu ọdun 2020.
Ọkunrin Juu kan, ará Alẹkisandria, dé sí Efesu.
” Mose bá bo ojú rẹ̀ nítorí pé ẹ̀rù ń bà á láti wo Ọlọrun.
Ẹ níláti pa olúwarẹ̀ nítorí pé ó fẹ́ mú kí ẹ kọ ẹ̀yìn sí ọ̀nà tí OLUWA Ọlọrun yín ti là sílẹ̀ fun yín láti máa rìn, nítorí náà ẹ gbọdọ̀ yọ nǹkan burúkú náà kúrò láàrin yín.
 |Eyi je ona lati fi mu idagbasoke ba orisii ere idaraya ti a n se ni Naijiria ati ni agbayeIbi ko gbodo ju ibi ninu ere idaraya
Awọn iroyin ti ẹ le nifẹ̀ si: Charles Okah gba'dajọ ẹwọn gbere 'Naijiria ko laṣeyọri lori gbigbogun t'iwa ijẹkujẹ' Rufai Imam di adajọ agba ile ẹjọ Sharia ‘A ko mọ ibi ti Nnamdi Kanu wa’ Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí kan sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
Shogunle - BBC News Yorùbá BBC News, YorùbáFò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù #ENDSARS: Íjìyà tó tọ́ sí Charles Omotosho ni wọ́n dá fún un - Shogunle 24 Ògún 2018 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 1 Owewe 2018 Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Bí Ọlọ́pàá SARS bá dá ènìyàn dúró kó gbọ́ sùgbọ́n.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù CAMA 2020: Falana, SERAP ní CAMA ni òfin tó tíì burú jùlọ nínú ìtàn Nàíjíríà 5 Ọ̀pẹ̀̀ 2018 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 20 Ògún 2020 Oríṣun àwòrán, Others Ọrọ ko tii tan lori ofin ti yoo maa se akoso awọn ileesẹ atawọn ajọ to rọ mọ ti ijọba sẹsẹ gbe jade.
diẹ lara awọn inagijẹ ti awọn ololufẹ Dagrin mọ ọ si re e .
Iran Yoruba kii ṣe ọlẹ rara, bẹẹ bi Onirese ko ba fingba mọ ni.
" Ìjọba Nàìjíríà gbọdọ̀ ṣàlàyé ìdí tí 13.
Idà yóo pa yín, ààlà ilẹ̀ Israẹli ni n óo ti ṣe ìdájọ́ yín; ẹ óo wá mọ̀ pé èmi ni OLUWA.
Jayathma Wickramanayake to je asoju ajo idagbasoke awon odo ninu ajo Isokan Agbaye lo so eyi di mimo ni orile-ede Gambia lasiko to n soro lori awon igbese akin ti ajo UN fe geb lati fi fopin si oro yii lagbaye.
Seba ati Salimuna bá bẹ̀rẹ̀ sí sá lọ, ṣugbọn Gideoni lé àwọn ọba Midiani mejeeji yìí títí tí ó fi mú wọn.
1 Iṣẹ́ títóbi ati yíyanilẹ́nu kan ti fẹ́ jáde wá ní àárin àwọn ọmọ ènìyàn.
Ẹ jẹ ki n laa ko yee yin daadaa.
Bí wọ́n bá pa ọ̀rọ̀ mi mọ́, wọn yóo pa ti ẹ̀yin náà mọ́.
Lẹ́nu ìgbà tí Nàìjíríà padà sí ìjọba alágbádá, àwọn èèyàn oríṣiríṣi ní àwọn aláṣẹ tí yan láti ṣíṣe pẹlú wọn.
”Awon olopa tun safihan awon ohun ija oloro, ibon, ohun elo ipese ado-oloro ati asia dudu islam ti won gba lowo Lassoued ati Salipada.
Aare soro yii lasiko to n gba
Igba ọtun si lo fẹ bẹrẹ yii.
Ninu ìran náà, mo rí ọkunrin kan lórí ẹṣin pupa, láàrin àwọn igi kan tí wọ́n ń pè ní mitili, láàrin àfonífojì kan.
Sibẹ ó tún rán àwọn ẹrú mìíràn tí wọ́n pọ̀ ju àwọn ti àkọ́kọ́ lọ; ṣugbọn bákan náà ni àwọn alágbàro yìí ṣe sí wọn.
Ẹni to bori: Senegal Madagascar vs Benin.
Sanyeri ẹni to kọ ila, eyi ti ko wọpọ lode oni sọ pe N ko kabamọ pe mo kọla nitori ka ni n ko kọ ila ni, o seese ki n ma de ibi tí mo de loni."
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Kylie Jenner ń gba 1.
Ọgbà ẹ̀wọ̀n ni Naira Marley yóò ti wo ìbúra Buhari ní May 29 Ademola Adeleke lẹ́tọ̀ọ́ láti du ipo gómìnà l‘Ọ̀ṣun - Ileẹjọ́ Kòtẹ́milọ́rùn Ohun tó yẹ kí o mọ̀ nípa OIC rèé Onidajọ Oweibo gbe idajs yii kalẹ lẹyin to gbọ awijare awọn agbẹjọro rẹ ati ti ajọ EFCC to n pe e lẹjọ.
Bakan naa lo ti jẹ ẹbun lati polowo ọja, eroja iṣaraloge, ounjẹ ọfẹ, ohun elo inu ile, aṣoju ileeṣẹ, irinajo si Scotland, ati ẹẹdẹgbẹta Dọla owo Bitcoin.
A óo fi ìdí rẹ̀ múlẹ̀ bí òṣùpá títí lae,yóo dúró ṣinṣin níwọ̀n ìgbà tí ojú ọ̀run bá ń bẹ.
“Bí ẹnìkan bá di wolii láàrin yín, tabi tí ó ń lá àlá, tí ń sọ nípa àmì ati iṣẹ́ ìyanu tí yóo ṣẹlẹ̀, 
” Ó bá kí wọn, ó fi ẹnu kò wọ́n lẹ́nu, ó dágbére fún wọn, wọ́n sì bẹ̀rẹ̀ sí sọkún.
Bakan naa ni aarẹ Buhari rọ awọn obi lati mojuto awọn ọmọ wọn kawọn maa ba ya wọn lo lati fi wọn wuwa ipa lorukọ ẹsin.
Ìlú àwọn ‘òmùgò’ gba orúkọ tuntun lẹ́yìn àádọ́rin ọdún!
2b) kumọkumọ kan Gomina ana ipinlẹ Ekiti.
Iko omo ogun Naijiria so pe, ikolu iko omo ogun olote boko haram si ibudo awon omo ogun ohun lagbegbe Katarko nijoba ibile Gujba LG, nipinle Yobe wa ni abe akoso.
Ẹ fi ìbẹ̀rù sin OLUWA,ẹ yọ̀ pẹlu ìwárìrì.
Pẹpẹ náà yóo jẹ́ ohun èlò tí ó mọ́ jùlọ fún OLUWA.
Nítorí náà, kí ẹnikẹ́ni má ṣe tìtorí eniyan gbéraga, nítorí tiyín ni ohun gbogbo: 
Ijọba orilẹ ede  Naijiria ti safihan baalu  tuntun ti yoo maa lo fun orilẹ ede yii.
Gbọ́ nisinsinyii, ìwọ Joṣua, olórí alufaa, ẹ fetí sílẹ̀, ẹ̀yin alufaa alábàáṣiṣẹ́pọ̀ rẹ̀, ẹ̀yin ni àmì ohun rere tí ń bọ̀, pé n óo mú iranṣẹ mi wá, tí a pè ní Ẹ̀ka.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Mistura Oseni Akintunde: Ara múmú kìí ṣe oríṣun ìfipábánilòpọ̀, ìran àwòjù ló ń fà á Gẹgẹ bi agbabọọlu fun ikọ Naijiria, Yẹkini gba bọọlu wọ inu awọn ni igba mẹtadinlogoji, ti o si ṣoju Niajiria ninu idije gboogi marun pẹlu Idije agbaye meji.
Ni ti pe boya ilẹ Singapore ni awọn aṣofin ti mu abadofin ọhun wa, ọgbẹni Kalu sọ pe irọ patapata ni.
”Wọ́n ní, “Ṣé kí á wá lọ ra oúnjẹ igba owó fadaka ni, kí a lè fún wọn jẹ!
Omi alaafia n fẹ maa daru lẹgbẹ awọn iyalọja ati babalọja ni ipinlẹ Ọyọ lori tani yoo jẹ oye Babalọja agba, iyẹn babalọja general fawọn ọlọja ni ipinlẹ Ọyọ.
"Sowore gba ìtúsílẹ̀ kúrò lọ́wọ́ DSS Òṣìṣẹ́ tó lé ní 600 pàdánù iṣẹ́ ní fásitì Ekiti, EKSU Uzor Kalu tó jẹ́ àṣojú láti ìpínlẹ̀ Abia rí ẹ̀wọ̀n ọdún méjìlá he Ilé aṣòfin àgbà buwọ́lu àbá ìṣúná ọdún 2020 Baba Dayo ni, lẹ́yìn èyí ni oun ṣe akiyesi ǹkan ti o fẹ́ràn láti maa ṣe, eyi ti òun fi mu lọ si ilé awọn to n gẹrun ""Dayo fẹ́ràn láti maa wakọ, ó fẹ́ràn aṣọ lílọ, o si le ṣe gbogbo ǹkan ti gbogbo àwọn ẹgbẹ́ rẹ̀ le ṣe."
Onímọ̀ ẹ̀rọ Makinde ní àjọ elétò ìdìbò INEC kéde pe ó jáwé olúbori nínu ìdìbọ gomins tó wáye lọ́jọ́ kẹsàn oṣù kẹta lkyìn to ní ìbò ẹgbẹ̀run lọ́nà ẹẹdẹgbẹ́ta o lé ti Adelabu si ní ẹgbẹ̀run lana ọ̀ọ̀dúnrún lé díẹ̀ Magu,'estimated billing' àti àwọn ohun míràn tí ilé aṣòfin Nàìjíríà kò rí yanjú Àjọ INEC ti bẹ̀rẹ̀ ìkéde èsì ìdìbò gómìnà ìpínlẹ̀ Rivers Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ojojúmọ ní mọ ń kẹ́kọ̀ọ́ lára ọmọ mi to jẹ akanda Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Okùnrin SARS náà sọ pé òun máa pa èèyàn síbi ni- Aladugbo Awọn to wà nínú ìgbẹ́jọ yìí ni ẹgbẹ́ òṣèlú PDP àti àjọ elétò ìdìbò INECBákan náà ní lóri ìdìbò ilé igbìmọ aṣòfin àgbà àti ilé ìgbìmọ ìpínlẹ̀, ilé ẹjọ tó ń ri si ìgbẹjọ ìdìbò gba ìwé ẹsun mọkanlélọgbọ̀n.
Ní ọ̀la ni iṣẹ́ ìyanu náà yóo ṣẹ.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Kí la tún gbọ́ nípa ìdámẹ́wàá?
O kesi ijọba ati awọn ti o lẹnu lọrọ lẹka iroyin lati pese irinsẹ idaabobo ẹni ati awọn nkan miran to le ko awọn akọroyin yọ́ lọwọ arun Covid 19.
Ẹ pa àwọn ará ìlà oòrùn run!
Awọn iroyin miran ti ẹ le nifẹ si: PDP: Jẹgudu jẹra ni ijọba ẹgbẹ APC Buhari bẹrẹ abẹwo si ipinlẹ Benue Eeyan mẹrin ku ninu ijamba ọkọ l'Eko Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
, a si gbodo ri i pe eleyii jẹ aseyọri.
Ahimeleki dáhùn pé, “Ta ló jẹ́ olóòótọ́ bíi Dafidi láàrin gbogbo àwọn olórí ogun rẹ?
"Oloye Gani Adams ni ""arakunrin mi, ọgbẹni Femi Adeṣina ti sọ awọn ọrọ pataki nipa ipo orilẹede yii, iṣẹ rẹ ló ń ṣe."
pẹpẹ ẹbọ sísun ati gbogbo ohun èlò tí wọn yóo máa lò pẹlu rẹ̀ ati agbada omi ati ìtẹ́lẹ̀ rẹ̀; 
Ìwádìí ìwé ẹ̀rí àwọn olùdíje Ààrẹ lọ́dún 2019 Ẹ̀sùn apànìyàn ni wọ́n fi kan Robert Bowers' Ṣé ìjọba Naijiria lè jọ̀wọ́ ìdajì ipò mínísítà fàwọn obìnrin?
Bi wọn ṣe fi ọmọbinrin naa sẹwọn, ni ijọba bẹẹrẹ iwadii to tu aṣiri pe awọn ikọ oloogun oloro kan lo maa n fi ọgbọn gbe oogun oloro sinu ẹrù awọn eniyan to n lọ si Saudi Arabia.
Gbogbo wa jẹun púpọ̀ ní ààfin Òjòlá-ìbínú a sí mu ọtí pẹ̀lú.
yege lati ni iye ibo to pọju 8,982 , nitori naa ,o jawe olubori , lati jẹ
Ilé Arugbo Saraki: Ramoni padà wólé arúgbó ní Ilọrin!
Ileesẹ rẹ ọhun ni ileeṣẹ olusiro owo agba akọkọ to jẹ ti ọmọ Afrika nilẹ Afrika O si sisẹ fun awọn ileeṣẹ bi ileeṣẹ iwe iroyin Nnamdi Azikiwe (The Pilot), Fawẹhinmi Furniture ati Ojukwu Transport.
ìbá ṣe pé ẹnìkan lè ṣe alágbàwí fún ẹnìkejì lọ́dọ̀ Ọlọrun,bí eniyan ti lè ṣe alágbàwí fún ẹnìkejì rẹ̀ níwájú eniyan.
“Nígbà tí ẹ bá ní ọmọ, ati àwọn ọmọ ọmọ, tí ẹ ti pẹ́ ní ilẹ̀ náà; bí ẹ bá dẹ́ṣẹ̀, nípa yíyá ère ní àwòrán ohunkohun, ati nípa ṣíṣe ohun tí ó burú níwájú OLUWA, tí ó lè mú un bínú, 
Ìyàwó mi sìn mí sí ọ̀nà, nígbà tí ó sì máa padà, ó wí fún mi kí n gbìyànjú tètè dé nítorí kí ojú má baà ro òun.
Ìṣàmúlò ẹ̀rọ-alátagbàa ti Lhamo kún fún àwọn kòbákùngbé ìjábọ̀-ọ̀rọ̀ àti èyí tí ó ń pè fún ìwàa jàgídíjàgan, èyí tí kò ṣẹ̀yìn àwọn akẹ́kọ̀ọ́ òkè-òkun tí ó ń gbé gbùngbùn China.
Ọjà Ọba ní Akure ni ọwọ́ ọloọ́pàá ti tẹ aláàrùn Covid-19 tó sá kúrò ní ilé àyẹ̀wò – Akeredolu #JusticeforTina: Àwọn obi Tina Ezekwe ń bèrè fún ìdájọ́ òdodo pẹ̀lú omijé lójú ₦35,000 ni mò ń gbà bíi Adelé ọba, kò sí ọkọ̀ ayọ́kẹ́lẹ́ - Adelé Olúbọ̀rọ̀pa Kàyééfì BBC News Yorùbá gbé òtítọ́ òògun owó yẹ̀wò Ọmọdé yóò máa sọnù ládùúgbò, arúgbó leè kú láì tọ́jọ́, tí wọn bá jókòó sílé lásìkò ìjọsìn - CAN Ìdájọ́ ikú ni a fẹ́ fún àwọn afipábánilòpọ̀ - Ẹgbẹ́ ajàfẹ́tọmọnìyàn Yorùbá kìí ṣe egúngún oníhòhò, ìwà wèrè ni sinimá oníhòhò táwọn òṣèré kan ń ṣe- Lere Paimo Ẹ̀wọ̀n gbére ni fún ẹnikẹ́ni tó bá fipá bánilòpọ̀ ní ìpínlẹ̀ Ọ̀ṣun A ti bẹ̀rẹ̀ ìwádìí kíkún nípa àwọn tó lọ́wọ́ nínú ikú Barakat Bello - Iléeṣẹ́ ọlapàá Ìyá àádọ́rin ọdún sọ bí ọkùnrin ọdún márùndínlọ́gbọ̀n ṣe fipá bá òun lòpọ̀ Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí 2 sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
Ní gbogbo àkókò yìí, Saulu ń fi ikú dẹ́rùba àwọn ọmọ-ẹ̀yìn Oluwa.
Iwadii yii lo ṣafihan fifi ilọkulọ ibalopọ lọ akẹkọọ ki wọn ba a le fun wọn ni maaki eyi to maa n wa latọdọ awọn olukọ fasiti.
Ṣugbọn tí ọwọ́ bá tẹ olè lojumọmọ, ó níláti san ohun tí ó jí pada.
O bọ siwaju lati fi igboya rẹ han pe igbesẹ awọn ologun tẹ oju ofin ẹtọ awọn ọmọ Naijiria mọlẹ lati dibo yan ijọba ti wọn fẹ.
Adigun ní ọ̀pọ̀ ìgbà ni àwọn ọ̀bọ náà ma ń lé àwọn ènìyàn kúrò ní ilé wọn, nígbàtí àwọn elòmíràn máa ń farapa tí wọ́n bá ń wá ọ̀nà láti kojú àwọn ọ̀bọ tó wọ ilé wọn.
Gbogbo ọgbọ́n àwọn ará Ijipti ni wọ́n fi kọ́ Mose.
Diẹ lara awọn oṣerebinrin tawọn eeyan n kan sara si bi adẹdaa ṣe da wọn ree.
Àkọlé àwòrán, Awọn mejeeji sọrọ lori itako ti wọn jọ ni lati ẹkun onikaluku.
Sultan Abubakar ni bi awọn eeyan ba ri oṣupa ni ọjọ Aje, oun yoo kede ọjọ Iṣẹgun, ọjọ kẹrin, oṣu kẹfa, ọdun 2019 gẹgẹ bii ọjọ akọkọ ninu oṣu Shawwal ti yoo si jẹ ọjọ ọdun 'Eidel fitr' iyẹn, itunu awẹ.
Ó ṣe wàhálà púpọ̀ kí ó tó mọ̀ pé Fọláṣadé tí ó tún ń jẹ́ filísíà nì ó jí owó Orímóògùnjẹ́ kó.
Ko sẹni to fi idi eyi mulẹ nigba naa nitori Abba Kyari funra rẹ gan ke sawọn oṣiṣẹ agbofinro DSS lati wadii oun.
"O ni "" iwọde pẹlẹ kutu ko tako ofin to sì tun jẹ ẹtọ awọn ara ilu ti ofin fún wọn."
Kí o wá tẹ́ pẹpẹ kan fún èmi OLUWA Ọlọrun rẹ lórí òkítì ibi gegele náà.
Angẹli Ọlọrun wọlé tọ̀ ọ́ wá, ó ní, “Kọniliu!
ipinle mẹ́fà ti o ku , ki a si  se ohun to yẹ ka se.
Ma maa sọrọ iya mi lọjọ iwaju sugbọn mo dupẹ lọwọ rẹ pe o n rẹrin si mi, mo si mọ riri ọwọ aanu rẹ.
Àwọn agbébọn pa olóyè ẹgbẹ́ òṣèlú APC ní ìpínlẹ̀ Oyo sínu ilé Ọ̀pọ̀ ẹ̀mí ènìyàn lo ti sọnù nítorí àìsàn Iba Lassa ní Kano àti Ondo Àṣìta ìbọn sọ́já pa ẹgbọn Kamsi tó pé sọ́ja kó wá fìyà jẹ aládùúgbò rẹ̀ Àwọn olùgbé Tarkwa Bay ń fọ́ ọ̀pá epo, jí epo ta, la ṣe lé wọn - Iléeṣẹ́ Ológun Inú ìbànújẹ́ ni mo wà lórí ikú alága CAN tí àwọn Boko Haram pa- Buhari Sef, chop, chop-chop, to eat money, barbing, salon, gist, to gist, put to bed, tokunbo, to rub minds àti àwọn ǹkan míran.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Obateru Akinruntan: Wíwá ohun tá jẹ títí láé ló gbé wa kúrò nílé Ife O ni wọn si n wo iwe ẹhonu ti awọn afọbajẹ ilu Iwo kọ mọ Oluwo, Ọba Abdulrasheed Adewale Akanbi, Telu Kinni, ki awọn to gbe igbesẹ kankan.
Alukoro ẹgbẹ naa, Lanre Isa-onilu ṣalaye pe ajọ eleto idibo ko figba kan fi lede pe oun ṣiye meji lori aridaju to lẹ mọ awọn iwe ẹri to fi ranṣẹ si ajọ naa pe ọwọ awọn ologun ni iwe ẹri idanwo aṣekagba girama wa.
Shehu Abdullahi darapọ mọ Bursaspor ni Turkey
Ajọ NBS sọrọ naa ninu iroyin to fi sita lori ipa ti aarun onigbameji ti ni nipinlẹ Kano, Eko, Rivers ati Abuja.
eleto idibo si n se ojuse won bi isẹ, ti awon oludibo naa ko fi ookan pe eeji
Ṣugbọn o fi kun pe awọn ile iwosan to wa labẹ rẹ n ṣe ojuṣe wọn.
Minisita fun imo sayensi ati ero igbalode omowe Ogbommaya Onu lo soro yii nibi ajodun ile-eko  fun  ile-kiko ati iwadii nipa oju-ona,( Nigerian Building and Road Research Institute (NBRRI)  se ni  International Conference  niluu, Abuja.
Ambọde ninu atẹjade fun awọn oniroyin buwọlu ofin meje ninu rẹ ni ofin to gbe ede Yoruba larugẹ, idaabobo ina mọnamọna, lilo ile-iwe ẹkọ yiya owo, imọ nipa aisan jẹjẹrẹ ati fifi agbara fun ile-ẹjọ to n risi ọrọ lọkọlaya.
Kò sí ohun tó yípadà pẹ̀lú ìwọṣọ akẹ́kọ̀ọ́ ISI Ìtàn tó rọ̀ mọ́ òwe ‘aṣọ kò bá Ọ́mọ́yẹ mọ́.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Obasanjo: Atiku kìí se Áńgẹ́lì, àmọ́ yóò se dáadáa ní ìlọ́po méjì ju Buhari lọ O wa fikun wi pe ijọba o sọ idi ti wọn fi din owo naa ku, ati wi pe ẹgbẹ osisẹ yoo ma se ipade ni Ọjọ Ẹti, ọsẹ yii ni ilu Abuja lati mọ igbesẹ to ku ti wọn yoo gbe.
Ehanire ni akori todun yii to ro mo sise awon oogun ibile ni ekun ile Afrika se Pataki lasiko yii pelu ipa lilo awon egbogi ibile fun itoju lasiko yi.
Oríṣun àwòrán, @HQNigerianArmy Àkọlé àwòrán, Awọn ologun Naijiria ko sinmi lati fẹyin Boko Haram janlẹ.
Ó yíra pada, kí ẹnikẹ́ni má baà mọ̀ ọ́n, ó sì lọ dúró lẹ́gbẹ̀ẹ́ ọ̀nà de ìgbà tí ọba Israẹli yóo kọjá.
Oríṣun àwòrán, Instagram/lizzy Anjorin Lawal Eyi gan an lo mu ki Lizzy Anjọrin aya Lawal figbe bọnu lori ikanni ayelujara rẹ pe, ẹni ba fẹ ọmọ Ibadan, bi ẹni morile igbo Sambisa nibi ti awọn agbebọn Boko Haram fikalẹ si ni.
Èmi wá kí eniyan lè ní ìyè, kí wọn lè ní i lẹ́kùn-únrẹ́rẹ́.
 Bakan naa ni awọn ara Ikosi-Iṣẹri beere fun anfani riro awọn ara agbegbe wọn paapaa awọn ọdọ wọn lagbara lati le ri iṣẹ ṣe.
Oríṣun àwòrán, @Oyinkan Oyinkan dara pọ mọ ẹgbẹ Girls Guildes nigba to wa nilu oyinbo, oun si ni obinrin akọkọ ọmọ Naijiria ti yoo jẹ Alakoso ẹgbẹ naa.
Gege bi eka okan lara gbagede ile-ise awon omo ogun naa, ti o wani Miramar lariwa agbegbe San Diego, O ni, Ijamba oko ofurufu ohun lo sele lojo Isegun(Tuesday), lagogo meji aabo osan(2:35 pm).
3 379657 Orilẹede Hungary 5984 61.
Ọfà wọn dàbí akọni ọmọ ogun, tí kì í pada sílé lọ́wọ́ òfo.
Wọn kò sì bèèrè àkọsílẹ̀ iye tí àwọn tí wọn ń ṣàkóso iṣẹ́ náà ná nítorí pé wọ́n jẹ́ olóòótọ́.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ọdẹ́gbàmí: Púpọ eléré ìdárayá ló ti gba ẹ̀bùn wọn lọ́wọ́ ìjọba 6 Òkùdu 2018 Oríṣun àwòrán, guardian.
"Tí a fiṣọwọ́ ní 10:35 29 Èbibi 201910:35 29 Èbibi 2019 ""Mo ṣèlérí láti fọkàn sin orílẹ̀èdè Nàìjíríà"" Ààrẹ Buhari rèé tó ń búra níwájú adájọ́ àti gbogbo ọmọ Nàìjíríà Video content Video caption: Nigeria Swearing-in 2019: Ààrẹ Buhari búrawọlé fún sáà kejìNigeria Swearing-in 2019: Ààrẹ Buhari búrawọlé fún sáà kejì Article share tools Facebook Twitter ṢàpínlòView more share options Share this post Copy this linkKà síwájú síi nípa àwọn ìtọ́kasí wọ̀nyí."
Akọsilẹ naa ṣe alakalẹ pe lara awọn ijọba ibilẹ ọhun Lagos Mainland ni Eko, Abuja Municipal Area Council l'Abuja, Mushin Eti-Osa ni Eko ati ijọba ibilẹ Tarauni ni Kano.
Bi ẹnikẹni ba si ṣe aṣemaṣe pẹlu iyawo eniyan, igba naa ni yoo ri ibinu ọkọ rẹ.
Agbẹnusọ ilé iṣẹ́ ọlọ́pàá ìpínlẹ̀ Oyo náà kọ̀ láti gbé aago rẹ̀ títí di àsìkò tí à n kọ ìròyìn yìí Oríṣun àwòrán, Lateef Kílo ṣẹlẹ̀ gan?
Eto yii ti fun ọpọ ọmọ Naijiria lanfaani lati beere oniruuru ibeere lori eto iṣuna ile.
Bí àkókò oúnjẹ ba ti ń tó, wọn ó lu agogo, wéré ọlọ́pàá á fọ́n ká inú ilé.
Ohùn OLUWA ń mi aṣálẹ̀;OLUWA ń mi aṣálẹ̀ Kadeṣi.
Ohun mẹ́wàá pàtàkì tí Ṣẹnetọ Osinowo fi ta yọ Seyi Makinde ṣí iléèwé padà ní ìpínlẹ̀ Oyo, Cross River pa ọ̀rọ̀ dà lórí ìwọlé akẹ́kọ̀ọ́ 'Babatunde Fashola' ló ṣe atọ́nà bí Naira Marley ṣe rí bàlùú wọ̀ dé Abuja Àwọn kànga ìṣẹ̀ǹbáyé rèé ní Badagry tó ń pa ẹrú níyè O ti to ọjọ mẹta bayii ti wahala ti bẹ silẹ laarin gomina Obaseki ati alaga apapọ ẹgbẹ oṣelu APC lorilẹede Naijiria, Adams Oshiomhole.
pẹlu àwọn ọrẹ tí ó fẹ́ fún OLUWA: ọ̀dọ́ àgbò, ọlọ́dún kan, tí kò ní àbààwọ́n, fún ẹbọ sísun; abo ọ̀dọ́ aguntan, ọlọ́dún kan, tí kò ní àbààwọ́n, fún ẹbọ ìmúkúrò ẹ̀ṣẹ̀ ati àgbò kan tí kò ní àbààwọ́n fún ẹbọ alaafia, 
Anfaani wa lati pe nọmba yi lati ago mẹfa aarọ di ago mẹfa irọlẹ.
Nípa ìmọ̀ rẹ̀ ni ibú fi ń tú omi jáde,tí ìrì fi ń sẹ̀ láti inú ìkùukùu.
Awọn ohun to yẹ ko mọ nipa Samuel Ajayi Crowther: Ọdun 1809 ni wọn bi Ajayi sile aye silu Oṣoogun to wa lẹba ilu Isẹyin nipinlẹ Ọyọ ni iwọ oorun guusu Naijiria Idile Alaafin Abiọdun ni iya Ajayi, ta si lee pe ni ọmọ ọba Ọmọ ọdun mejila ni Ajayi lasiko ti awọn ọmọ ogun Fulani ko o ni ẹru lọdun 1891, ti wọn si taa fawọn eebo pọtugi to n sowo ẹru Ṣugbọn oriire Ajayi gbe e ko alawoore, nigba ti awọn ọmọ ogun oju omi ilẹ Gẹẹsi, to n gbogun ti owo ẹru ṣiṣe gba ọkọ oju omi rẹ silẹ, Wọn si gbe Ajayi lọ si ilu Freetown, lorilẹ-ede Sierre Leone, nibẹ si lo ti gba idande kuro ni ipo ẹru, to si ni ominira rẹ pada Oríṣun àwòrán, @BAMEAnglican Ọwọ ẹgbẹ CMS ti ijọ Anglican ni Ajayi bọ si ni Sierra Leone, ti wọn si kọọ ni ede oyinbo, bẹẹ lo di ẹlẹsin Kristi pẹlu Ọjọ Kọkanla, osu Kejila, ọdun 1825 ni Ajayi se iribọmi, ti wọn si muu lọ silẹ Gẹẹsi lati lọ jọsin, ko si tun lọ sile iwe O yi orukọ rẹ pada si orukọ adari ijọ Christ Church to wa ni London, to tun jẹ ọkan lara awọn oludasilẹ ẹgbẹ CMS, eyi tii se Samuel Crowther.
 Won ni ọmọkunrin mẹta  (Thiago (6), Mateo (2) ati Ciro (osu meta).
 “A wa rọ aare Muhammadu Buhari lati
Nítorí ogun, ìyàn ati àjàkálẹ̀ àrùn, a óo fi ìlú yìí lé àwọn ará Kalidea tí wọn gbógun tì í lọ́wọ́.
Oríṣun àwòrán, Others Ọba Layode papa parada di eeyan, tawọn afẹhonu han naa si pa a sinu aafin rẹ, wọn la ọfun rẹ, ge e lori, ti wọn si tun yọ nnkan ọmọkunrin rẹ.
Oun ni adari ajọ Ipinlẹ Eko to n ri si akoso ile kikọ (LSDPC).
N óo mú kí wọn rìn ní etí odò tí ń ṣàn,lójú ọ̀nà tààrà, níbi tí wọn kò ti ní fẹsẹ̀ kọ;nítorí pé baba ni mo jẹ́ fún Israẹli, àkọ́bí mi sì ni Efuraimu.
Irú ìyá àgbà àti àwọn ìyá, gẹ́gẹ́ bíi Ìyá àgbà Saray ti ń ṣakitiyan ìpamọ́ àwọn ìṣe orílẹ̀ wa àti ẹ̀mí-àìrí fún àìní ye ọgọ́rùn-ún ọdún.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Èmi sì ní Oluwo tilẹ̀ Iwo, kò sí ìgbìmọ̀ ọba kankan tó lè ní kí ń rọ́ọ́kún nílé - Oluwo Toyin Abraham ọkọ rẹ̀ àti Ire ní London, Odunlade 'kòlábò' pẹ̀lú Mercy Aigbe Èlé owó iná ọba kọ́ ló kàn, ẹ kọ́ ṣàtúnṣe sí ìlànà àdánú tẹ́ ń ṣe fún wa - Iléeṣẹ́ apínná sọ fún ìjọba Àdínkù bá owó ojúmọ́ ọlọ́kadà l‘Ọyọ láti ₦200 si ₦100, owó gbígbà bẹ̀rẹ̀ lónìí A fẹ́ ìtọ́jú fún Boko Haram tó bá ronúpìwàdà, ẹ dá iléeṣẹ́ sílẹ̀ fún ìtọ́jú wọn - Ilé aṣòfin Olùkọ́ tó fi tipá gba ìbálé akẹ́kọ̀ọ́ tó fẹ́ wọ fásitì rí ẹ̀wọ̀n ọdún 21 he Fayose, o kò ní àmúyẹ gidi láti di ọmọ ẹgbẹ́ wa, àyè kò sí fún ọ - APC Ekiti Amọṣa, ninu ifọrọwerọ pẹlu ileeṣẹ iroyin abẹle kan, Alhaja Salawatu Abẹni ṣalaye pe, ko si ohunkohun to jọ fifẹra laarin oun ati Kebe-n-kwara o, ipolowo ọja lasan ni.
Mo tun maa n ri iranwọ latd awọn alabagbe mi atawọn ọrẹ mi ṣugbọn nigba ti ọjọ ikọkgboye mi n sunmọ etile, ẹru bẹrẹ si ni ba mi boya mo maa ri iṣẹ.
 Èyí ló ká ẹlòmíràn lára tó fi ju odidi pọ́ùn kan sínú omi.
Oluranlowo ijoba lori  eto ounje fun ile-iwe ni ipinle Eikiti ,Ademola
''Ọwọ awọn ọlọpaa to wa ni ẹka ileeṣẹ naa ni Alagbado tẹ Adeṣọla lasiko to n ko nkan ija lọ pẹlu ọkọ bọọsi funfun kan ni oju ọna Amikanle, Alagbado.
Igboho, nigba to n fesi si ọrọ asaaju ẹgbẹ Miyetti Allah nipinlẹ Bauchi, Alhaji Sadiq Ahmed, to ni ki ijọba wọgile ikọ naa nitori pe, ko si aabo mọ lati gbe nilẹ Yoruba nitori agbekalẹ ikọ Amotekun.
Àwọn ará Amoni ń san ìṣákọ́lẹ̀ fún Usaya, òkìkí rẹ̀ kàn káàkiri títí dé agbègbè ilẹ̀ Ijipti, nítorí pé ó di alágbára gan-an.
amayedẹrun lorile ede yii lo ti bajẹ pata-pata.
A ri irú igbéyàwó yi, ti ẹbi ọkọ tàbi ti iyàwó kò lè lọ.
Won bi Balogun lojo kéjídínlọ́gbọ̀n osu kefa, odun  1988 silu Berlin, lorile-ede Germany.
“Nígbà tí ẹ bá jẹ́ ẹ̀jẹ́ fún OLUWA Ọlọrun yín, ẹ kò gbọdọ̀ má san ẹ̀jẹ́ náà, nítorí OLUWA Ọlọrun yín yóo bèèrè rẹ̀ lọ́wọ́ yín, yóo sì di ẹ̀ṣẹ̀ sí yín lọ́rùn bí ẹ kò bá san án.
Èmi nìyí, mo ṣetán láti kú.
Aarẹ Buhari to banujẹ si iṣẹlẹ naa fero rẹ nipa oluranlọwọ rẹ lori ọrọ iroyin, Garba Shehu.
Gẹgẹ bi iroyin to jade ṣe sọ ọ, pasitọ naa ra ilẹ to to miliọnu 573 naira ni Dubai lorukọ Magu.
Ṣé nǹkan ìríra tí àwọn ọmọ ilé Juda ń ṣe níhìn-ín kò jọ wọ́n lójú ni wọ́n ṣe mú kí ìwà ìkà kún ilẹ̀ yìí, tí wọn ń mú mi bínú sí i?
Lati ọwọ Louise ni London Iroyin BBC Ikọ eleto ilera Akọṣoilẹ China ati awọn orilẹ-ede mii fihan pe coronavirus ko fi bẹẹ ni ipa lori ọmọde Eyi ṣeeṣe ko jẹ pe awọn ami apẹẹrẹ coronavirus ko han lara wọn tabi nitori pe agọ ara wọn le gbọn ọn danu Awọn ọmọde ti wọn ba ni ailera ẹdọ-fooro tẹlẹ bii ikọ séèmí-séèmí nilo lati tubọ ṣọ ara wọn End of Emi ati ẹbi mi Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Bẹ́ẹ̀ sì ni ìwọ ni o mú mi jáde láti inú ìyá mi;ìwọ ni o sì mú mi wà láìséwu nígbà tí mo wà ní ọmọ ọmú.
n wa kẹkẹ  atapupu lati maa ya ara won ni
 Adeleye tun so pe“Egbe osise nigbagbo pe bi won se tun
Ọlọrun ku isẹ rẹ Àkọlé àwòrán, Ẹni maa bi ibeji ko sẹwa wa, ọdun ibeji ko yọ awọn ibeji ọmọ ọwọ silẹ ni Igbo Ọra Àkọlé àwòrán, O ga ju.
Won fun wọn ni ọpọ ọsẹ alagbara lori ati ni gbogbo ara.
Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí 5:47 Fídíò, Akomolede ati Asa: Mọ̀ si nípa àwọn ọ̀nà tí Yorùbá ń gbà ran ara wọn lọ́wọ́, Duration 5,4722 Ọ̀wàrà 2020 CACOVID Palliatives: Ọwọ́ Ọlọ́pàá tẹ àwọn tó lọ kó ǹkan ìrọ̀rùn Covid-1927 Ọ̀wàrà 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Àwọn ọmọ ogun tí wọn kì í ṣe olórí ogun ti kó ìkógun tiwọn.
Ọpọ eeyan lo n yọ suti ete si Abiola Ajimobi nigba naa pe ki lo tun n wa lagbo oselu, to se tun jade pe oun fẹ lọ sile asofin agba, se ko ni itẹlọrun ni?
Bàbá ẹni ọdún 61 bá ọmọ rẹ̀ lopọ̀, ó fún un lóyún l'Eko Ṣé ó leè jẹ́ ilẹ̀ tí Makinde kò jẹ́ kí Florence Ajimobi gbà ló ń bi nínú?
Iroyin ti awọn alasẹ ọgba ẹwọn naa fisita sọ pe abule Phalaborwa, ti awọn awakusa pọ si julọ, ni wọn ti kofiri awọn kiniun naa, ti wọn n yan kiri.
Wọn si wa ni awọn orilẹede bii Egypt, Sudan, Libya, Amẹrika, Canada, Australia, Italy, United Arab Emirates, Jordan, ati Kenya.
Gẹgẹ bi iroyin kan ti minisita fun eto ilera lorilẹede Naijiria Dokita Osagie Ehanire ṣe fi sita loju opo twitter rẹ lọjọ Abamẹta.
O jẹ ko di mim pe wn ti kọkọ gbe Adoke l si ile ẹjọ lẹyin rẹ gan iyẹn nigba to n kawe lati gboye Masters ni Netherlands.
Gileadi ti di ìlú àwọn ẹni ibi, ó kún fún ìpànìyàn.
‘Pussypedia’ rèé, ojú òpó tó ń mú àdínkù bá ìṣòro ìmọ̀ nípa ẹ̀yà ara obìnrin Ka tun sọ ti gomina ipinlẹ Akwa Ibom, to sọ pe ipinlẹ oun ko ni i gba esi ayẹwo coronavirus ti ajọ NCDC gbe jade fun ipinlẹ oun.
Gẹgẹbi iwadii naa se gbe e jade, Naijiria lo se ipo kẹrindinlogun ninu awọn orilẹede mẹrindinlogun to wa ni ẹkun Iwọ-Oorun Ilẹ Afirika naa, nigba ti Sierra Leone se ipo mẹẹdogun, ti Niger ati Guinea Bissau se ipo kẹrinla ati mẹtala lọwọọwọ.
 Àìlera àti àìríran dáradára lè wáyé .
O tẹsiwaju pe ọkan lara awọn ileeṣe to n ṣe amojuto ọkọ ofurufu nilu Eko ti fi ifẹ han lati maa bọ nilu Ibadan to si ni igbesẹ naa yoo pa kun eto ọrọ aje ipinlẹ Ọyọ.
Àpérò àwọn àjẹ́ kò gbọdọ̀ wáyé - Àjọ PFN Ọpọ lo n sọ pe kawọn alaṣẹ Arsenal gba Massimiliano Allegri tabi Mauricio Pochettino lati rọpo Emery gẹgẹ bi akọnimọọgba Arsenal.
Buhari wa fikun pe, awọn asaaju saa isejọba alagbada akọkọ lo tii pegede julọ ti Naijiria tii ni.
“Tẹ́tí sí ọ̀rọ̀ mi ìwọ Jakọbu, ìwọ Israẹli, ẹni tí mo pè,Èmi ni ẹni ìbẹ̀rẹ̀,èmi sì ni ẹni òpin.
Lẹyin ọpọlọpọ hilahilo eleyi ti o fẹrẹ la ti isiwọluni lọ nigba naa,ni ẹgbẹ ba tuka si meji, ASUU gan an gan ati CONUA.
''Gbàgbe nípa àwọn akọiroyin òfégé, gbàgbé nípa ǹkan to rò nípa mi.
Ni aarin ilu Iwo, gbogbo ọkunrin to wa nibẹ lo n tọ Wuraọla lọ pe o wu awọn lati fi se aya, yoo si dara ko ju ọwọ silẹ fun awọn, ki awọn lee tọju rẹ.
Ọ̀rẹ́ mi yìí ṣe mi ní àlejò púpọ̀ kò sì jẹ́ kì ń fi ẹnu mi kàn àkàrà tí ìyá mi mú wá fún mi láti ìsálú ọ̀run.
Oríṣun àwòrán, @nmanigeria Àkọlé àwòrán, Eto ilera alabde ti di ma-kan fun p m orilede Naijiria Ninu ifọrọwerọ rẹ pẹlu BBC, akọwe agba fun ẹgbẹ awọn dokita isegun oyinbo lorilẹede Naijiria, NMA, Dokita Yusuf Tanko Sununu ṣalaye wi pe lootọ ni ẹka ilera alabọde nilo amojuto gidigidi.
Ọgbẹni Mattis gbe osuba nla fun awọn ọmọogun ilẹ Indonesia paapaa pẹlu bi wọn se nfi ọgbọn mu awọn ejo naa ki to pa wọn ti wọn si mu ẹjẹ wọn.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Akomolede ati Asa lori BBC: Olùkọ́ Kikelomo Ogunboye tan ìmalẹ̀ sí ìwà olè ọ̀gá ọlọ́pàá Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
 síbẹ ̀ síbẹ ̀ , lẹ ́ yìn ọdú méje yìí , gbogbo nkan bẹ ̀ ẹ ̀ rẹ ̀ sí ní dàrú fún wọn .
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Ọ̀lọ́pàá shátà mi láti Mowe dé Magboro dé Shagamu, wọ́n ní ṣé mi ò mọ̀ pé ìjọ́ba ni mo ṣiṣẹ́ fún' Ọ̀pọ̀ àwọn tó ń lo WhatsApp lo ti n káyà sókè pé, ṣe awọn kò ni pàdánù lílo WhatsApp báyìí?
" Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, INEC ní àwọn ràbòràbò r'áyé jẹ lásìkò ìbò ní'pínlẹ̀ Edo, Ondo àti Anambra Bákannáà ni àjọ INEC tún pariwo pé, àìkìí fààyè gba ètò ìṣèlú àwarawa abẹ́nú táwọn ẹgbẹ́ òṣèlú lórílẹ̀èdè Nàìjíríà gùnlé, ń ṣe ọ̀pọ̀ àkóbá fún àṣeyọrí ìdìbò.
Jose Mourinho: Ayélujára ń hó yaya lórí ọ̀rọ̀ Mourinho pẹ̀lú Arsenal
Akitiyan lati ri ileesẹ ọlọpaa ba sọrọ lo ja si pabo lasiko ti a fi n ko iroyin yii jọ.
Àṣepọ̀ ni wọ́n ṣe é pẹlu ìwo rẹ̀ mẹrẹẹrin.
3 183099 Orilẹede Nepal 1663 5.
Nigba ti wọn bi wọn boya wọn gbagbọ pe ajẹsara n ṣiṣẹ: Ida mẹrinlelọgọrin (84%) gba Ida marun (5%) ko gba Ida mejila (12%) ko fi si ibi kan Oríṣun àwòrán, Science Photo Library Àkọlé àwòrán, Arun ẹyi lee mu ẹmi lọ Ki ni eyi tumọ sii?
Ó lè ṣe iṣẹ́ gbẹ́nàgbẹ́nà, ó sì lè ṣe oríṣìíríṣìí iṣẹ́ ọnà tí wọ́n bá ní kí ó ṣe pẹlu àwọn òṣìṣẹ́ tìrẹ, ati àwọn òṣìṣẹ́ oluwa mi, Dafidi, baba rẹ.
Morris gba orukọ rere fun iṣẹ to ṣe pẹlu awọn ọdọ agbabọọlu ọdọ Chelsea.
Aare ni: “Olusoagutan Adeboye je olori rere fun iran yii ti o hande ninu idagbasoke to ti de ba ijo Irapada labe akoso re nipa ti eto eko, ohun amayederun, ilera ati agbekale awon ile ise ti o gba opo eniyan sise paapaa ni Naijiria.
Àkọlé àwòrán, Cosmic Crisp apple: kò le bàjé nínú ẹ̀rọ amúǹkan tutù fún ọdún kan Igi Cosmic Crisp Apple mílíọnu méjilá ni wọ́n ti gbìn ti iwé àṣẹ̀ rẹ̀ si wà fún àwọn níkan, kò si fi ààyè gba ẹlòmíràn láti gbìn ní apá ibi kankan lọ́rílẹ̀-èdè Amerika.
Iléeṣẹ́ ọlọ́pàá ìpínlẹ̀ Ondo - BBC News Yorùbá BBC News, YorùbáFò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ondo: Àwọn afurasí mẹ́rin ti wà ní àhámọ́ lórí ikú ọkùnrin kan ní Igbokoda - Iléeṣẹ́ ọlọ́pàá ìpínlẹ̀ Ondo 19 Òkùdu 2020 Oríṣun àwòrán, Getty Images Ariwo kilode, kilode, kilode lawọn eeyan agbegbe Zion ni ilu Igbọkọda ni ipinlẹ Ondo nigba ti awọn ọlọpaa wa wu oku arakunrin kan nibẹ Awọn eeyan agbegbe naa nfunra pe o ṣeeṣe ko jẹ ọmọ ẹgbẹ okunkun ni arakunrin naa ati pe o ṣeeṣe ko jẹ pe lasiko wahala awọn ẹgbẹ okunkun kan ti wọn gbe ina woju ara wọn lopin ọsẹ to kọja ni ilu naa ni wọn ṣeku pa arakunrin ọhun.
Ẹ̀yin ará Sioni tí ẹ̀ ń gbé Jerusalẹmu, ẹ kò ní sọkún mọ́.
Àwọn ọmọ Ara jẹ́ ọtalelẹgbẹta ó dín mẹjọ (652).
” Saaju eyi ni adari ikọ naa ,ọmọwe
Aṣọ tí wọ́n wọ̀ funfun, ó sì mọ́.
Ó sì sọ fún àwọn ìbátan rẹ̀ kí wọ́n kó òkúta jọ.
Ó ń wá oúnjẹ káàkiri, ó ń bèèrè pé,‘Níbo ló wà?
E wo awọn ọkọ bọgini ti Akin-Olugbade fi se ara rindin nigba aye rẹ: Aarẹ Bolu Akin-Olugbade fẹran ọkọ bọgini nigba aye rẹ, paapaa eleyii ti wọn n pe ni Rolls Royce.
5 335207 Orilẹede China 4748 0.
ojogbon  Tijjani Bade,to n soju fun orile
 Àwòrán wúlò láti bá ènìyàn sọ ọ ̀ rọ ̀ pàtàkì .
11 Èyí jẹ́ ìlànà kan fún ọ, pé ìwọ jẹ́ alàgbà ní abẹ́ ìgbọ́wọ́lé lórí rẹ̀, òun sì jẹ́ àkọ́kọ́ sí ìwọ, pé kí ìwọ baà lè jẹ́ alàgbà sí ìjọ ti Krístì, tí ó ńjẹ́ orúkọ mi—
Oríṣun àwòrán, Alaafin Ọba alaye naa fikun pe, lẹyin ti wọn pari ẹkọ fasiti wọn, oun ni ki wọn kuro amọ wọn ni awọn yoo duro ti oun bii ayaba Kabiyesi Alaafin ko fi ọrọ igbeyawo ṣere rara pẹlu gbogbo ẹru ojuṣe to rọ mọ itẹ Alaafin Oríṣun àwòrán, Alaafin Nigba to n dahun ibeere naa lati ọdọ awọn akọroyin ni ọdun diẹ sẹyin, Iku Baba Yeye ni Emi kii ṣẹ obinrin tabi yan-an lodi, igbeyawo si jẹ ohun to yẹ ka daabo bo, ẹni kọọkan si lo ni ojuṣe lati ṣe ninu igbeyawo, ọkọọkan awọn ayaba si lo ni ile ti wọn n gbe ni ọtọọtọ."
"Itoju ti ẹgbẹ TAMPAN n ṣe fun awọn agbalagba to wa ninu ẹgbẹ oṣere lo mu mi mọ Baba Lẹgba.
PDP Kogi Primary: PDP yóò yan olùdíje tí yóò gbé àsíá ẹgbẹ́ fún ipò gómìnà
Ìtàn sọ pe lasiko ti Ọba yii wa ni ipo, ni wọn da ile ẹ̀kọ́ girama akọkọ nilu Ondo, Ondo Boys High School, silẹ.
 ogun lilo ni o wọpọ julọ ti o nfa anafilasisi .
Nítorí pé lójú rẹ, ẹgbẹrun ọdún dàbí àná,tabi bí ìṣọ́ kan ní òru.
Bala Lukshi(APC) bori ninu Atundi ibo Bauchi Bala Lukshi ti ẹgbẹ oṣelu APC lo jawe olubori ninu atundi ibo ile aṣofin agba l'Abuja to waye lọjọ Abamẹta.
Arsenal náà laná bí Manchester United Lori afara liigi Premiership, ọrọ ipo kini ti di fa-kinfa laarin ẹgbẹ Manchester City ati Liverpool ti esi ifẹsẹwọnsẹ laarin Man United ati Man City lalẹ oni yoo si jẹ atọna ẹni ti yoo gba liigi ọdun yi.
Olódodo a máa kórìíra alaiṣootọ,eniyan burúkú a sì kórìíra eniyan rere.
Kò pẹ́ pupọ lẹ́yìn náà, ni ó pada lọ láti lọ mú iyawo rẹ̀.
Mo si nireti pe mo maa ri iṣẹ ni kete ti mo ba kawe ja."
Ajọ INEC ti ni gbajugbaja olorin, Yinka Ayefele jẹ adari tootọ ni eto iroyin, iṣẹ ṣise ati idagbasoke awujọ lorilẹede Naijiria.
ati idagbasoke yoo se tubọ fẹsẹ mulẹ si lorile ede Naijiria.
Wo àwọn oúnjẹ márùn ún tó ń mú kí àtọ̀ ọkùnrin dára síi Mo ṣèlérí láti rí sí ìrẹ́pọ̀ àti ìwòsàn Amẹ́ríkà - Joe Biden Gbọ́yì-sọ̀yí àti ìròyìn èké láti ọ̀dọ̀ àwọn olólùfẹ́ wa ló ṣáábà ma ń da ìgbéyàwó àwọn òṣèré rú- Ọpẹ Ayeola Amẹrika ti yọ àfikún owó Físà kúrò fún arìnrìnàjò Nàìjíríà Bákan náà Kano-14, Nasarawa-14, Akwa Ibom-10, Katsina-10, ńigbà tí Edo-7.
Nítorí mo mọ iṣẹ́ ọwọ́ wọn ati èrò ọkàn wọn.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ope Bademosi: Ọmọọ̀dọ̀ tó pa Ope Bademosi ti rí ẹ̀wọ̀n gbére he!
Ọwọ ọlọpaa ilu Dubai tẹ Ramoni Olorunwa Abbas, ti inagijẹ rẹ n jẹ Hushpuppi, laipẹ yii, fun ẹsun lilu jibiti lori ayelujara.
Awon baba m sinku laafin ni won yoo gbo si oro re lenu pe ki won salai sin oun siboji ti won gbe si egbe iboji iyawo re eni ti ko kaa kun titi to fi file bora bi aso.
Ó ní awọn òbì-i rẹ̀ gba oko lọ́wọ́ òun ní pọ́ùn kan, wọn kò sì tí-ì sanwό oko tán.
Nígbà tí àwọn tí ó fi ẹ̀sùn kàn án dìde láti sọ̀rọ̀, wọn kò mẹ́nuba irú àwọn ọ̀ràn tí mo rò pé wọn yóo sọ.
Ọmọ bibi ilu Iwere ile, to wa ni ẹba ilu Iganna ni agbegbe Oke Ogun ni ẹkun ariwa ipinlẹ Oyo, ni iya Alaafin Ajagbo ati Abiodun.
Awọn isẹlẹ to dun mi jọjọ - Ọbasanjọ Àmọ́sá, Igbákejì aarẹ tẹ́lẹ̀ náà fi ìdí rẹ̀ múlẹ̀ pé lóòtọ́ọ́ ni orílẹ̀èdè Amẹ́ríkà kọ̀ láti fún òun ní ìwé àsẹ ìwọ̀lú wọn, nígbà tí òun bèèrè fún un.
Bi o tilẹ jẹ pe Ayefele ko salaye idi to fi fẹ kan si awọn obi Oreoluwa, amọ ọpọ eeyan to fesi si ikede naa ni, oriire nla ni ọmọde naa se.
Falale, to wa ni ijoba ibilẹ Danmusa ni ipinlẹ naa.
Awọn ara abule naa ti da a lẹjọ oro, wọn si sin in láàyè pẹlu oku ẹgbọn rẹ naa.
ogunlọlá jẹ ọde , ògbótari , tí ó mọ ̀ n nípa ọdẹ síse ó féràn láti máa lọ sísẹ ́ Ọde nínú igbó ti a máa ni ìlú Ògbómòsọ ́ tí à pè ní igbó ìgbàlè , ṣùgbọ ́ n ọkọ ̀ rin yii ti o jẹ ogunlọlá ṣe baale àdúgbọ ̀ tí ó ogunlọlá gbé nígbà nàá .
 Nigba ti oludije fun ipo aare ninu egbe PDP Alhaji
O si tun jẹ ọrẹ si Aarẹ Muhammadu Buhari, amọ awọn miran bu ẹnu atẹ lu ọna ti o n gba ṣe oṣelu.
2b sọ́wọ́ ìjọba àpapọ̀ orilẹ̀ede Nàìjíríà.
JỌ̀WỌ́ JẸ́WỌ́ Ẹ̀SẸ̀ RẸ KÍ O TÓ KỌJÁ ODÒ Ẹ̀JẸ̀, ẸNI TÍ KÒ JẸ́WỌ́ Ẹ̀SẸ̀ RẸ̀ KÍ Ó TÓ KỌJÁ ODÒ Ẹ̀JẸ̀ A KÀN JÀǸBÁ, JỌ̀WỌ́ JẸ́WỌ́ Ẹ̀SẸ̀ RẸ KÍ O TÓ KỌJÁ ODÒ Ẹ̀JẸ̀.
O ṣalaye pe ọba alaye n ba Eleduwa jẹ orukọ papọ, idi niyii ti ko fi gbọdọ maa fori balẹ fun oriṣa kankan.
Ó sọ ọpọlọpọ ọ̀rọ̀ fún wọn pẹlu òwe.
Ìrètí wa lórí yín sì ti fẹsẹ̀ múlẹ̀, nítorí tí a mọ̀ pé bí a ti jọ ń jẹ irú ìyà kan náà, bẹ́ẹ̀ náà ni a jọ ní irú ìwúrí kan náà.
Eyi ṣẹlẹ nigba ti o n rinrin ajo ni ipinlẹ Ọyọ nigba to wa si Naijiria.
Dafidi sì wà ninu ìbànújẹ́, nítorí pé inú àwọn ọmọlẹ́yìn rẹ̀ bàjẹ́ nítorí àwọn ọmọ wọn, wọ́n sì ń gbèrò láti sọ ọ́ ní òkúta pa.
Ọpọlọpọ abẹrẹ ajẹsara ni o ṣi wa labẹ ayẹwo ipele kẹta lọwọ, amọ eleyii lo si mu aṣeyọri jade.
kí ilẹ̀ náà lè di ìrẹ̀sílẹ̀, kí wọ́n má sì lè gbérí mọ́, ṣugbọn kí ilẹ̀ náà lè máa ní ìtẹ̀síwájú, níwọ̀n ìgbà tí ó bá pa majẹmu ọba Babiloni mọ́.
Ẹni tí kò bá ní iyawo yóo máa páyà nípa nǹkan Oluwa, yóo máa wá ọ̀nà láti ṣe ohun tí ó wu Oluwa.
Wayii o, èrò ọmọ Naijiria kan ree ninu ọpọ eeyan to ti fesi si igbesẹ tuntun Davido naa.
Bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé aṣọ tí ó nípọn ni wọ́n fi ń bò ó, òtútù a tún máa mú un.
 lásìkò tí ó fi wà pẹ ̀ lú ilé-ẹ ̀ kọ ́ àgbà ti ( dublin university ) , Ó gbá rugby sevens fún ikọ ̀ ilé-ẹ ̀ kọ ́ náà .
Olori Mariam Adeyemi: Oríṣun àwòrán, Mariam Jola Adeyemi Facebook Ọpọ eeyan ni ko fi bẹẹ mọ nipa Ayaba yii nitori ko si lara awọn ayaba to saba maa n ta kangbọn lori ayelujara.
* A ko fẹ́ ki ẹnikẹni dan awọn iṣẹlẹ inu fidio yii wo nitori pe o léwu.
Gomina Tambuwal tun wa rọ awon
naa, Abdelaziz Bouteflikakuro lori aleefa losu to kọja.
agbeyẹwo iṣuna owo yoo fi le fẹsẹ mulẹ sii.
"O sọ pe ""Ko yẹ ki o dakẹ nitori pe o ko fẹ ṣẹ ẹlomiran, ti wọn ba ti n sọrọ to ba bi ẹ ninu, iwọ ṣaa maa wo ni tiẹ."
Báyìí ni bàbá ọ̀rẹ́ mi kọ apa’kan nínú ìtàn ìgbésí-ayyé rẹ̀ sílẹ̀, Ọjọ́ méjì ni mo sì gbà kí n tóó kọ apá kan yìí náà tán, mo kọ̀wé títí gbogbo èjìká ń ro mi gooro, Àkàrà-oògùn tí ó jẹ́ ọmọ Olówó-ayé ni ẹni tí ń ka ìtàn náà fún mi.
Inec yoo bẹrẹ iwadi lori oludibo Kano Igbimọ ti ajọ eleto idibo lorilẹede Naijiria, Inec gbe kalẹ fun ayẹwo awọn eeyan bii miliọnu marun to fi orukọ silẹ gẹgẹbi oludibo ni ipinlẹ Kano yoo bẹrẹ isẹ ni ọjọ Aje.
9ice: Ǹjẹ́ olórin tàkasúfèé yìí ń mu igbó bí àwọn òṣèré mìíràn?
Oríṣun àwòrán, Instagram/officialsholakosoko Àkọlé àwòrán, Sola Kosoko ní kò sí ẹ̀sìn tí òun kò le ṣe nítorí Kristẹni ni òun, ọkọ òun sì jẹ́ Mùsùlùmí.
Àmọ́ àkọsílẹ̀ miran ṣàlàyé ọ̀nà míì tó yàtọ̀ tí ikọ ogun Ibadan gba borí ogun Ìjàyè.
Lucas Moura: Ọmọ atàpátadìde tó gbé Tottenham wọ àsekágbá ìdíje Champions League
AfCFTA:Ohun tí Nàìjíríà gbọ́dọ̀ ṣé láti jẹ adùn àdéhùn okòwò kan nàà ní Afrika
Odidi ogoji ọdún ni mo fi ko yín la ààrin aṣálẹ̀ kọjá.
Baba Suwe: Ó lé ní ọdún méjì tó fi sàìsàn láì kópa nínú tíátà
won, ope pataki lowo awon ara ilu fun ibasepo won.
Ibojì wọn yí tirẹ̀ ká, gbogbo wọn ni a fi idà pa láìkọlà abẹ́.
"Ninu ọrọ to ba BBC News Yoruba sọ, Seriki Fulani ni ipinlẹ Ọyọ, Alhaji Yakubu Bello ṣalaye pe Oloye Igboho ""mu madaru"" wa saarin awọn olugbe agbegbe naa."
Ó sọ àwọn tí ń gbé orí òkè kalẹ̀,ó sọ ìlú tí ó wà ní orí òkè téńté di ilẹ̀,ó sọ ọ́ di ilẹ̀ patapata,ó fà á sọ sinu eruku.
Sanwo-Olu náà wá sọ fáwọn ará Eko pé kí wọn 'Calm Down' Oríṣun àwòrán, others Gomina ipinlẹ Eko, Babajide Sanwo-Olu ti sọ pe, oun yoo ṣepade pẹlu ọmọ ọkunrin to ni ki iya oun farabalẹ nigba to fẹ na a lẹgba.
"Coronavirus Cases in Africa: Adarí àwọn agbóòkú tó ń fi ijọ́ dárà ní ilẹ̀ Ghana sọ bí àwọn ṣe da ìlúmọ̀ọ́ká Arsenal rántí ""Invincibles,"" ó pé ọdún mẹ́rìndínlógún tí Arsenal gba ife Premier League Orílẹ̀èdé Naijiria ti gba Àgbo Coronavirus ti ilẹ̀ Madagascar ṣe tọwọ́tẹsẹ̀!"
 Èpè kọ ́ , n ó máa nà án lẹ ́ fọ ̀ ni .
Wọ́n wá OLUWA, wọ́n sì rí i.
Komisona to n ri si oro awon obinrin ati omode, Hajiya Balkisu Bungudu, soro naa di mimo nilu Gusau ti n se olu-ilu ipinle ohun.
 wọ ́ n ní àwọn osteodem tó le ní abẹ ́ awọ ara wọn àti pé ọ ̀ pọ ̀ lọpọ ̀ àwpọn èyà yí ní àwọn ọwọ ́ kúkurú tàbí tí kò sí rárá , léyí tí ó jẹ ́ kí wọ ́ n dàbí ejò bí ó tilẹ ̀ jẹ ́ pé àwọn òmíràn ní ọwọ ́ tó pé .
bí Olodumare bá sì jẹ́ wúrà rẹ,ati fadaka olówó iyebíye rẹ,
9 598933 Orilẹede Belgium 17692 154.
Asiko yii loju ọjọ maa n gbona ju lọdọ awọn agbegbe larubawa.
Wọ́n mọ Ọlọrun, ṣugbọn wọn kò júbà rẹ̀ bí Ọlọrun, bẹ́ẹ̀ ni wọn kò dúpẹ́ lọ́wọ́ rẹ̀.
Ọkunrin to doloogbe naa, Otike Odibi, wa lati ilu Delta.
Ile-ise ile Biritiko to n se iwadii lori aisan aramanda ti o gbemi baba ati omo lorile-ede naa, yoo yan igbimo awon minisita pajawiri lojoBo(Thursday), lati wa ojutu si aisan ohun, lai fi oro naa fale rara ki o to gbale kan.
O ni eyi tọna nitori pe o lodi si ofin ile igbimọ Aṣofin ni abala 24 ti 'Code of Conduct Act' fun awọn aṣofin lati maa gba iru iṣẹ akanṣe bẹẹ.
Ọrọ naa bi awọn obi ti ọrọ kan ninu de ibi pe, wọn ko fẹ ba awọn oniroyin sọrọ mọ.
ti iwa odaran lorile ede yii.
Ko si bi ọ̀bẹ́ ṣe pọ̀ to lọjọ iku erin, awọn ọ̀bẹ kan ṣi maa jẹ ajitanna wo ni ọrọ awọn sinima to jade ni 2018 jẹ.
Adegbenro ni lẹyin ti obinrin naa salọ ni ijọba ipinlẹ Ondo ati Imo parapọ bẹrẹ si ni wa obinrin naa ki wọn to wa ri.
Àkọlé àwòrán, Statue of liberty Awọn ẹgbẹ oselu mejeeji si lo ti n fi ọwọ gun ara wọn nimu lori ẹni to jẹbi isẹlẹ yi biotilẹjẹpe ko sẹni to lee sọ pato ẹni to ni ẹbi isẹlẹ yi.
Iyawo aarẹ orilẹede Amerika, Melania Trump wa lara awọn eniyan ti wọn sunmọ aarẹ Trump to ti lugbadi arun naa, amọ oun gba itọju ni ile ijọba.
Lọwọlọwọ, bi ọgbọn ẹgbẹrun ni awọn ọmọ Naijiria to n gbe ni orilẹede Germany lọna ti ko ba ofin mu.
Wo àwọn tí ò ń ṣe irú èyí sí!
''Komputa Village kii ṣe ọja aarọ, ọja iruwa ogiri wa ni, ti a ba wọ ọpọlọpọ awọn to n ta ọja nibi kii ṣe ẹya Yoruba nikan fun idi eyi, yiyan iyalọja le fẹ mu kọnunkọhọ wa'' Ọpọ lo ti n sọrọ lori igbesẹ ijọba ipinlẹ Oyo lati bẹrẹ iwadii to yẹ lori awọn to n ja si ipo yii ni Ibadan ati igbesẹ to yẹ ka gbe ṣaaju yiyan ni si ipo agba naa.
Olugbaninimọran fun gomina Seyi Makinde lori aato ati eto oselu, Asofin Babatunde Oduyọye lo kede eyi ninu atẹjade kan to fi sita, eyi to fi n fesi lori igbesẹ Lanlẹyin to ni oun yọwọ-yọsẹ kuro ninu adehun agbekalẹ ijọba alajumọse ti wọn fẹnu ko le lori saaju idibo gomina to kọja.
O kú orire ọjọ ibi ọkọ mi, olowo ori mi, baba awọn ọmọ mi, akọni lórí ilẹ̀.
OLUWA ní, nígbà tí ó bá yá, yóo máa pè mí ní ọkọ rẹ̀, kò ní pè mí ní Baali rẹ̀ mọ́.
Ninu ọrọ tirẹ, oludije dupo gomina labẹ asia ẹgbẹ oṣelu People's Democratic Party (PDP) ni ìpínlẹ̀ Ondo Eyitayo Jegede ni, oju oluwa n ri ẹni to dan nkan to ṣẹlẹ naa wò.
Ó bá ń fi òwe kọ́ wọn ní ọpọlọpọ nǹkan.
Alẹ ọjọ Iṣẹgun ni aṣẹ yii jade lati ẹnu kọmisanna fun et ilera, Dokita Aminu Ibrahim Tsanyawa, to gba ẹnu gomina sọrọ.
Mo gbọ́ igbe Jerusalẹmu tí ń pọ̀ọ̀kà ikú,tí ó na ọwọ́ rẹ̀ síta, tí ń ké pé,“Mo gbé!
Ko tan sibẹ o, bi awọn kan ṣe n sọ oko eebu ati epe lu Toyin, ni oun naa n fi ọrọ ranṣẹ si awọn obi wọn nile.
Conjoined twins: Ilé ìwòsàn l'Àbuja ti ya àwọn ìbejì tí wọ́n sọpọ̀ láyà
Lọjọ Abamẹta ni NECO kede pe, idanwo Kọmputa to yẹ kó waye ni ọjọ Aje oni, ni ko le waye mọ, wọn si sun siwaju di ọjọ kẹrindinlogun oṣù Kọkànlá.
 Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, CAN: Samson ni ọrọ awọn ajinigbe ti gba àpérò ní Naijiria Ẹlomii ko farapa, awọn ti a doola si ti n ran wa lọwọ pẹlu iwadii iṣẹlẹ naa.
 louis , missouri , josephine di ara fransi ni 1937 .
Ajọ INEC kede wipe Wike fi ibo to ju ẹgbẹrun mẹjọ ati mẹrindinlaadọrin ju oludije labẹ ẹgbẹ oselu African Action Congress AAC, Biokpomabo Awara lọ ninu idibo naa.
 ni Niamey, ni deede aago mọ̀kànlá
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Baṣọ̀run Gáà, tó yan ọba mẹ́rin, pa ọba mẹ́rin àmọ́ ọba karùn-ún ló pa á Wo àwọn òrílẹ̀èdè 10 tó láyọ̀ jùlọ lágbàyéé Ajàfẹ́tọ̀ọ́ ẹni fẹ́ gbèjà ọmọ Naijiria tí ilé oúnjẹ China kò gba láàyè Àìsàn tó ń ṣe ọ ní ohun ṣe pẹlú oorun rẹ - Onímọ Yorùbá, ọmọ ọdún mẹ́jọ tà ọmọ òyìnbò yọ nínú ayò Chess l‘Amẹrika Òkùnkùn biribiri ni ìjìyà ẹ̀ṣẹ̀ ìjọba ìbílẹ̀ mẹ́fà nílẹ̀ Ìjẹ̀ṣà tó na òṣìṣẹ́ àjọ amúnáwá Kí ló dé tí obinrin tó ní HIV/AIDS fi pọ̀ ju ọkunrin lọ ní Nàìjíríà?
Wọ́n mú Dina jáde kúrò ní ilé Ṣekemu, wọ́n sì bá tiwọn lọ.
Estrosi wa ṣe apejuwe iṣẹlẹ naa bii eyi to farapẹ ikọlu ti wọn ṣe si olukọ kan, Samuel Paty, ti wọn ge lori lẹba ile ẹkọ rẹ lẹyin ilu Paris nibẹrẹ osu yii.
Nítorí náà, OLUWA óo sọ wọ́n di ohun àìmọ́ fún wọn.
Awọn ọdọ lo yari pe ki ijọba apapọ wọgile ikọ naa nitori iwa ika ti wọn n hu sawọn ọdọ ati bi wọn se n pa wọn ni ipakupa.
Ìbẹ̀rù-bojo ni kí ẹ fi máa ṣàánú àwọn mìíràn.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù BB Naija: ọ̀fọ̀ ṣẹ̀ lágboólé Olanrewaju Malcolm, olólùfẹ́ Bisọla rí 25 Ògún 2018 Oríṣun àwòrán, Twitter/Big Brother Naija 2018 Àkọlé àwòrán, Ilẹ n jẹ èèyan, Ikú ti mú Olanrewaju Malcolm ọkọ Bisola lọ Olanrewaju Malcolm, baba ọmọ Bisola Aiyeola to kopa ninu idije Big Brother Naija ni a gbọ pe o ti ku.
Ó tẹ́ pẹpẹ fún Baali, ó sì ri àwọn òpó fún Aṣera.
O ni imo sayensi ati imo ero igbalode nikan lo le mu idagbasoke ba
Saheed-Fathia Balogun: Ọjọ́ Karùn-ún oṣù kejì ni wọ̀n bí wọn, tí wọn sì bí ọmọ méjì fúnra wọn
Bẹ̀rẹ̀ láti ìran kẹta wọn, wọ́n lè bá ìjọ eniyan OLUWA péjọ.
Ebola: ìjọba Gẹ̀ẹ́sì fún DR Congo lówó láti fi gbógunti i
Amotekun: Soyinka fèsì padà fún Balarabe Musa pé ó kùnà lóríí ikọ̀ aláàbò náà
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Oluwatoyin Salau: Òkú Toyin làwọn ọlọ́pàáTallahassee ni àwọn rí lẹ́yìn ìpè rẹ̀ lórí twitter 16 Òkùdu 2020 Oríṣun àwòrán, Virgintoyin/twitter Àkọlé àwòrán, Toyin poora lẹyin to figbe ta nipa ifipabanilopo loju opo Twitter - ka ohun ta mọ nipa iku rẹ Ileesẹ ọlọpaa gẹgẹ bi ohun ti BBC ri fidi rẹ mulẹ ti sọ pe awọn ti ri oku arabinrin Oluwatoyin Salau lẹyin ọjọ meloo kan ti wọn fi se awati.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Olaitan Olamide: mò lè má nílò ìwé ẹ̀rí mi tí mo bá parí ní LASU Awọn eeyan ti ko fẹ ko gbajumọ isẹ to n se lori ipo aarẹ, lo n fura kiri, ti wọn si n fi awọn ẹsun ti ko tọ kan Buhari, sugbọn emi ni mo ti n ja fun ifẹsẹmulẹ ijọba awa ara wa.
Yahaya Bello ni oun ko tu igbimọ iṣejọba ipinlẹ Kogi ka
Ṣugbọn ọba dáhùn pé, “Kò sí ohun tí ó kan ẹ̀yin ọmọ Seruaya ninu ọ̀rọ̀ yìí.
Ifi rẹ̀ si ni ìwọ̀nyí, tí àwọn ọlọ́gbọ́n fi sọ ìjà di májèlé tí wọ́n ń sá fún un lójoojúmọ́, nítorí ìjà kò yẹ ọmọ ènìyàn, òun da bi egungun ẹja pẹ̀lú ọ̀nà ọ̀fun.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Tinubu parí aáwọ̀ Ambode àtàwọn aṣòfin ìpínlẹ̀ Eko #BBCNigeria2019 Ààrẹ Gani Adams sọ ẹni tí Yorùbá yóò dìbò fún ní ọdun 2019 #BBCNigeria2019 Ipẹjọ naa ko ṣẹyin igbesẹ ajọ ọhun lati lo ofin ọfẹ lohun (FOI) labẹ eyi ti wọn ti fun Fashọla ni gbedeke ọjọ mẹrinla lati fi orukọ naa sita bẹrẹ lati ọjọ kẹrin oṣu kini ọdun 2019.
Adari ikọ apapọ ọmọ ogun America, Mark Milley lo kọkọ ki Trump kaabọ.
Gẹgẹ bi o ṣe sọ ọ, ileẹjọ gba lati fi ọkunrin naa si atimọle titi di igba ti ajakalẹ arun Covid-19 yii yoo fi kuro nilẹ.
Gẹ́gẹ́ bí òní ṣe jẹ́ àyájọ ọjọ́ ìdùnnú lágbàyéé, à ń ṣe àgbẹyẹ̀wò àwọn orílẹ̀-èdè mẹ́wàá ti wọn ní ìdùnù jùlọ lágbàyé lọdun 2019.
Okunrin kan kú lójijì lẹ̀yin ọjọ̀ díẹ̀ to jẹ milionu kan dọ́là Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Tọkọ-taya Aràrá: Àwọn èèyàn máa ń wò wá, ta bá fa ọwọ́ ara wa ní títì Agbada ikoko nla kan lo maa fi n se ẹwa fun tita, to si n jẹ ere rẹpẹtẹ nibẹ lojoojumọ.
Bakan naa ni wọn ti gbe awọn ọkọ to ni ijamba kuro ni oju ọna, ki awọn ọkọ to n lọ, to n bọ ba a le ri ọna kọja.
Ìwọ ní tìrẹ, nítorí ẹ̀jẹ̀ tí mo fi bá ọ dá majẹmu,n óo dá àwọn eniyan rẹ tí a kó lẹ́rú sílẹ̀ láti inú kànga tí kò lómi.
Kwakpovwe ni irọ ni wọn pa mọ oun nigba naa, ṣugbọn ọpọ iroyin lo jade lori ọrọ naa.
Igbimo ajo  ile Afirika ECOWAS  ti ni awon yoo gbe abajade won lori bi awon
Yóo fi nǹkan bojú kí ó má ba à rí ilẹ̀.
Ọmọ Yoruba ni wa, a si gbọdọ bu ọla fun ẹni ti ọla yẹ, paapaa awọn ọba alade nilẹ Yoruba, a kọ gbọdọ sọ wi pe nitori ọlaju, ki Tinubu wa joko, nigba ti Ọọni dide lati ki i.
Àmọ́ ọ̀gìnìntìn f'àáké kọ́rí, ó l'óun ò re'bìkan.
Ati Gomina ilu Carlifornia, Gavin Newsom ati Aarẹ Donald Trump lo fi si oju opo ayelujara wọn pe iṣẹlẹ naa buru jai pe ki awn eniyan si ṣe pẹlẹ.
Coronavirus in Nigeria: Ìtànkálẹ̀ coronavirus ṣe ìdíwọ́ fún ìrun Jimọ
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù MC Oluomo: Ẹgbé Awakọ lpińlẹ Èko yan Musiliu Ayìndé Akínsànyà bíi Adarí.
Oloye HID Awolọwọ, Omowe Tai Solarin tó jẹ ogbontarigi olukọni ajafẹtọ ọmọniyan àti Ọjọgbọn Yẹmi Ọṣinbajo to jẹ igbakeji aarẹ Naijiria lati ọdun 2015.
Agbẹnusọ ileeṣẹ ọlọpa nipinlẹ naa, DSP Catherine Anene ni awọn ara adugbo naa ni awọn ri ọkunrin naa to gbe bẹntiroo wọle, ti awọn si rọ pe gẹnẹratọ ni wọn fẹ lo o fun.
" Eyi ni ọrọ to ti ẹnu aarẹ orilẹede yii, Muhammadu Buhari jade lasiko to n gbalejo awọn eekan ọmọbibi ipinlẹ Ogun, to fi mọ gomina wọn, Dapọ Abiọdun ati igbakeji rẹ, Noimot Salakọ, eyi to waye nile ijọba nilu Abuja.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ sí: Ambode àti Sanwoolu, ta lẹ ó gbádé fún?
Oríṣun àwòrán, Twitter/Bashir Ahmad Oríṣun àwòrán, Twitter/Bashir Ahmad Ẹwẹ, ile iṣẹ ọkọ ofurufu Air Peace ti ko awọn Naijiria bi igba meji pada sile lẹyin iṣẹlẹ ikorira alejo to waye ni South Africa.
Nibayii, iye awọn to ti ri iwosan gba ti le ni mejeleẹẹdẹgbẹwa (1907), ti ookanlenigba(211) eniyan si ti ku nitori arun naa.
Sugbọn awọn ọmọ ẹgbẹ Ipob ti wọn wa latimọle lo wa nibi igbẹjọ naa, ti adajọ si fi asẹ si wipe ki wọn gbọ ẹjọ Kanu lọtọ, ki igbẹjọ lee tẹsiwaju Oríṣun àwòrán, AFP Àkọlé àwòrán, Ikọ Ipob n ja fun ominira ilẹ Biafra Lara awọn ọmọ ẹgbẹ Ipob to n jẹjọ ni Ogbeni Chidiebere Onwudiwe, Benjamin Madubugwu ati osise ileesẹ ibaraẹnisọrọ MTN, David Nwawuisi.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Lizzy vs Toyin: Yomi Fabiyi ní òun fa obì yọ lápò láti bá Toyin sọ̀rọ̀ kó parí ìjà pẹ̀lú Lizzy 29 Owewe 2019 Oríṣun àwòrán, @lizzyanjorin, @realyomifabiyi, @toyin_abraham Bii pe yoo tan yoo tan ni ija aarin awọn gbajugbaja oṣere Yoruba meji, Lizzy Anjorin atin Toyin Abraham ṣùgbọ́n awọn ọrọ bi owe bi owe ṣi n ṣere kiri ilẹ.
Àwọn tí wọ́n wà pẹlu Ọ̀dọ́ Aguntan náà ninu ìjà ati ìṣẹ́gun náà ni àwọn tí wọ́n jẹ́ olóòótọ́, tí a pè, tí a sì yàn.
Ọrọ yi waye lati tako ọrọ Buhari wipe oun ti paṣẹ fun awọn agbofinro ki wọn fi ọwọ lile mu ẹnikẹni to ba ko awọn janduku wa si ibi idibo.
Ìpàdé ọmọlẹ́bí tí wọ́n fẹ́ ṣe gan-an ni ó tèlè mú un padà.
Ọkan lara wọn, Shuaibu Haruna sọ pe iṣẹ l'oun wa wa silu Eko nitori oun ni iyawo ati ọmọ nile.
Kini a ń pè ní Fẹntílàtọ̀ àti pé kí ni iṣẹ́ rẹ̀?
 mo ranjú kankan kan mọ ́ dińgi ni.
OLUWA sọ fún Mose pé, “Àwọn eniyan wọnyi yóo ti kọ̀ mí sílẹ̀ pẹ́ tó.
Iroyin fi lede wipe, eto aabọ nile iwe to wa ni Yobe mẹhẹ, bi o tilẹ jẹwipe agbeegbe yii ni wọn ti ji awọn ọmọ Chibok gbe ni ọdun 2014, ti awọn obi si n ran awọn ọmọ wọn lọ sile iwe lagbeegbe naa.
eto ipese ounje yii, tun fi ayesile fun awon to ta eroja ounje miiran bi maluu,
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Mo ké bòòsí tòò bí mo ṣe bí ìbejì, ti ọ̀kan jẹ́ àfín, ìkejì jẹ́ dúdú-Màmá Ọlátẹ́jú Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Mo ké bòòsí tòò bí mo ṣe bí ìbejì, ti ọ̀kan jẹ́ àfín, ìkejì jẹ́ dúdú-Màmá Ọlátẹ́jú 13 Òkùdu 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 31 Ẹrẹ̀nà 2020 Ọ̀pọ́ to mọ wi pe Taiwo ati Kehinde Olateju jẹ ibeji ni o maa n wo wọn ni awoyanu.
Awọn meji to lewaju lati di ipo yii mu ni Sẹnẹtọ Ahmad Ibrahim Lawan to n ṣoju ẹkun ariwa ipinlẹ Yobe.
 leventis professor of greek culture .
Iná sì ń jó lórí òkè náà.
Bee si ni, o waye lataari pipadanu ifesewonse kinni-in ati ikeji sowo iko akegbe won ti won n jo figagbaga ninu ipele ohun.
Wọ́n sin egungun Saulu, ati ti Jonatani, sinu ibojì Kiṣi, baba rẹ̀, ní Sela ninu ilẹ̀ ẹ̀yà Bẹnjamini.
Àfikún ọdún ẹ̀wọ̀n kò tó, arábìnrin igbá-kejì Ààrẹ MPLA [Àjọ Àwọn ènìyàn tó fẹ́ ìdásílẹ̀ Angola], Ó nílò kí orílẹ̀-èdè ṣe ìdásílẹ̀ àwọn ìlànà àtilẹ̀wá tí yóò kojú ìpanilára – Àwọn ohun tí wọ́n fara mọ́ ní 2007 nípa àjọsọ ìlànà Maputo ní láti di ṣíṣe.
Ninu aworan naa ni Chatta ti wa lori ibusun, ti wọn n fa omi ati oogun si lara.
Àwọn odò Nimrimu pàápàá ti gbẹ.
Ṣugbọn kí ẹ dá àwọn ọdọmọbinrin tí wọn kò tíì mọ ọkunrin sí, kí ẹ fi wọ́n ṣe aya fún ara yín.
Títí di òní, àwọn ni wọ́n ń ṣe iṣẹ́ náà ní ibi tí OLUWA yàn pé kí àwọn ọmọ Israẹli ti máa jọ́sìn.
lati lee koju isoro to n sele  ni ila iwo
Ile ẹjọ ni nise ni George Koh gun Uzoka lọbẹ laya.
Taiwan Gbogbo awọn ilana ti China fi lelẹ naa ni Taiwan mulo ti wọn si ti si ile ẹkọ wọn pada lati osu Keji nitori bi wọn ti se jajabọ lọwọ ajakalẹ Covid-19.
Èyí kò ní jẹ́ kí ẹnikẹ́ni fi ojú tẹmbẹlu arakunrin rẹ̀, tabi kí ó ṣẹ arakunrin rẹ̀ nípa ọ̀ràn yìí.
Nítorí náà, OLUWA ti mú kí ìyọnu dé bá wa, ó sì rọ̀jò rẹ̀ lé wa lórí; olódodo ni OLUWA Ọlọrun wa ninu gbogbo iṣẹ́ rẹ̀, sibẹ a kò tẹ̀lé ọ̀rọ̀ rẹ̀.
Sisan owo dogba-dogbaAare Cyril Ramaphosa so ninu oro iranse re fun ayeye isami ayajo ojo awon obinrin lagbaye pe, “South Africa ti n ja fita-fita lagbe tie to ijoba tiwa-n-tiwa ti bere ni odun 1994,lati mu igberu ba awon obinrin, gege bi akitiyan ati maa se si eleya-meya, kosi iyato laarin tako-tabo ilosiju, ife ati isokan orile-ede naa”.
Andrew Johnson ati Bill Clinton ni wọn ti dibo yiyọ nipo ri fun.
ipinle Oyo, ni ekun Gusu orile ede Naijiria.
Ajọ NURTW ṣalaye pe niṣe ni Auxiliary n kaakiri gbogbo ọfiisi ajọ naa ti o si n ko ohun ini ẹgbẹ lọ si ibi tawọn ko mọ.
Àdó ikú tí Boko Haram fi sójú ọ̀nà pa méje lára wọn Davido fi orúkọ bàbá rẹ̀, Adedeji, sọ ọmọ tuntun tó bí O ku isẹju marun un ki ifẹsẹwọnsẹ naa pari ni Adam Lallana ti ikọ Liverpool fi ọba le fun wọn, ti ifẹsẹwọnsẹ naa si pari si ọmi ayo kan(1-1).
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Babcock Sex video: Ohun tó yẹ kóo mọ̀ nípa Fásitì Babcock 24 Bélú 2019 Oríṣun àwòrán, Image copyright@BABCOCK_UNIV TWITTER Ọkan lara awọn ileewe giga amoke ni Naijiria ni Fasiti Babcock eyi to ti wa lati ọdun 1999.
Ile-ise ọlọpaa  to wa ni ipinlẹ naa sọ pe awon agbanipa kan
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Àjọ Ọlọ́pàa Naijiria: A ó fi òsìsẹ́ SARS tó se isẹ́ ibi náà jófin Àwọn ìgbà tí ẹ̀ṣọ́ aṣọ́bodè ti pànìyàn lọ́nà àìtọ́ Iṣẹ́ bọ́ lọ́wọ́ ọlọ́pàá ọ̀mùtí ní ìlú Eko Kíni iyatọ tó wà láàrin FSARS àti SARS?
Bakan naa, Zainab kọju si ọkọ rẹ lati sọ otitọ ninu ile ẹjọ lẹyin to ni awọn ana rẹ mọ idi ti oun fi n bere fun ki ileẹjọ tu igbeyawo awọn ka.
US Embassy ní bí o bá fẹ gbà Visa, àfi kò yọjú funrararẹ
N óo da òkú sí orí àwọn òkè ńláńlá rẹ, yóo kún.
Ẹwẹ, ijọba apapọ ti kọkọ tako ṣiṣi ileewe pada lasiko yii ti aarun coronavirus si n pọ si ni Naijiria, ijọba aika ilera awọn eeyan si ni.
Ẹni to bori: Senegal Aṣekagba Guinea Senegal Guinea vs Senegal.
Baba-onírùngbọ̀n náà sì dá mi lóhùn, ó ní, ‘Bí ó ti wù kí ó sí ṣáá mo rò pé o kò ní ṣàìdé ibẹ̀ lọ́la, nítorí pé ó ti ṣe ìlérí fún un ó sì yẹ kí o mú ìlérí rẹ ṣẹ.
Naijiria ,pe ki won ma gunle ifẹhonuhan nitori bi ajo eleto INEC  se sun eto idibo siwaju.
Ẹ̀yin ẹ̀ṣọ́, ẹ kò gbọdọ̀ fàyè gba jíjí àpótí ìdìbò ní Kogi àti Bayelsa- Buhari Adigunjalẹ̀ fìbọn fọ́ ojú ọmọ tó fẹ́ lọ sìnrú ìlú nílùú Èkó Èèyàn mẹ́tàlá dèrò ọ̀run nínú ìjàmbá ọkọ̀ lópòpónà Ìbàdàn s'ÈKó Ilé ẹjọ́ ni agbábọ́ọ̀lù ọmọ Nàìjíríà, Dickson Etuhu jẹ́bi ẹ̀sùn títa ìdíje Sweden Bakan naa ni wọn maa n ṣe ohun ti wọn maa n kọ nọmba ọkọ si.
“Nítorí náà, n óo da yín lẹ́jọ́, ẹ̀yin ọmọ Israẹli.
Abi eelo ni awọn paapa ń san si apo ijọba l'ọdun?"
Ìwọ ń wá nǹkan ńlá fún ara tìrẹ?
Ẹgbẹ́ IPOB ò tako Ààrẹ Buhari ní Japan- Iléeṣẹ́ Ààrẹ Òfin nìkan ló lè gbadé lórí àwa Ọba ìlú lbadan- Oba Lekan Balogun Pataki ohun toju ri nibi abẹwo wọn naa ni pe awọn agba oye naa ko wa pẹlu ade wọn, ti wọn si dọbalẹ gbalaja lati ki Olubadan.
Ṣugbọn awọn onimọ sọ pe awọn ko gbagbọ pe ẹnikan le ṣe ipawọ apakokoro to le dena aarun naa l'abẹẹle.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Alaafin Ọyọ bí ìbejì lẹ́ẹ̀mẹta láàrin oṣù mẹ́jọ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Alaafin Ọyọ bí ìbejì lẹ́ẹ̀mẹta láàrin oṣù mẹ́jọ 27 Èrèlè 2018 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 23 Ọ̀wàrà 2018 Aláàfin ìlú Ọyọ, Ọba Lamidi Ọlayiwọla Adeyẹmi Kẹta tún ti bí ìbejì mi i.
Ẹgbe oselu ANRP ni awọn n gbe igbesẹ lati ba ile isẹ ọlọpaa sọrọ nitori ẹtọ awon ni lati ba awọn eniyan awọn sọrọ lasiko iwọde itagbangba.
 Bakan naa ni gbogbo ondije dupo gẹgẹ bi ọmọ ẹgbẹ
Bí ọmọlúwàbí bá sọ̀rọ̀ ó yẹ kí ènìyàn bá ọ̀rọ̀ rẹ̀ bẹ́ẹ̀, ìlérí ọmọlúwàbí dà bí ẹ̀wọ̀n tí òun fi de ara rẹ̀, láìjẹ́ pé ó bá sì ṣe bí ìlérí náà ẹ̀wọ̀n náà kò ì tí ì tú; ṣùgbọ́n ènìyàn lásán ka ìlérí sí nǹkan eré, bí òun bá sọ eléyìí lónìí a sọ tọ̀hún lọ́la, gbogbo arayé a sì máa ka ọ̀rọ̀ rẹ̀ sí ọ̀rọ̀ ènìyàn yẹpẹrẹ tó bẹ́ẹ̀ tí kò sí ọ̀rọ̀ tí ó lè sọ tí ọmọ aráyé kò ní í kà sí yẹ̀yẹ́.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Àwọn tó ń sanwó orí ti rúgọ́gọ́ sí lábẹ́ ìjọba Buhari 20 Ògún 2019 Oríṣun àwòrán, Babatundeofficial Àkọlé àwòrán, Àwọn tó ń sanwó orí ti rúgọ́gọ́ sí lábẹ́ ìjọba Buhari Abba Kyari ko fi Fowler si abẹ iwadii kankan - Garba Sheu.
Ọlọ́run yóò ṣe ìdájọ́ nkan tó wà láàrin èmi àti Ireti Ajanaku - Tope Alabi A kò mọ̀ọ́mọ̀ pa ọlọ́pàá mẹ́ta, aráàlú kan, ó ṣèèsì ni, ajínigbé la pè wọ́n - Iléeṣẹ́ ológun Sowore àti àwọn ọmọ ẹgbẹ Revolution Now kò ṣẹ̀ ṣófin lórí ìwọ́de, ẹ tú wọn sílẹ̀ - NLC Òṣùká kékeré kò rẹrùn àgbà, orílẹ́èdè Nàìjíríà ṣòro púpọ̀ láti darí - Ibrahim Babangida Sowore ṣèpàdé pẹ̀lú Nnamdi Kanu láti dojú ìjọba Nàíjíríà bolẹ̀ - Àjọ DSS Ilé-isẹ́ Ológun gbọdọ̀ sèwádìí bí ọmọogun se pa ọlọ́pàá - Buhari Ẹlẹbubọn ni o ṣe pataki ki Yoruba pada si awọn nnkan iṣẹnbaye nitori ẹsin ti gba ọpọlọpọ nnkan danu lọwọ ẹya Yoruba.
Nítorí pé mo gba ẹ̀há kò ní kí ń ṣọlẹ̀ tàbí ṣagbe- Ẹ̀lẹ́hàá Amina Èèyàn 20 ni coronavirus pa l'Ọ́jọ́bọ nìkan Ẹgbẹ́ Boko Haram pa àwọn òṣìṣẹ́ UN márùn ún tó wá ṣiṣẹ́ ìrànwọ́ ní Nàìjíríà Bí o bá ń se N-Power tóo sì ti ríṣẹ́ sí ibòmíràn, olè ni ọ́!
OLUWA àwọn ọmọ ogun ní, ‘N óo jẹ àwọn ará Amaleki níyà nítorí pé wọ́n gbógun ti àwọn ọmọ Israẹli, nígbà tí wọ́n ń bọ̀ láti Ijipti.
Adajọ agba lorile-ede Naijriia, Walter Onnoghen lo jabo oro ohun lasiko ipade apero kerinlelogbon awon adajọ ti o waye niluu Abuja.
Nigba ti Daniel Amartey, Nampalys Mendy,Wes Morgan, Danny Simpson, Rachid Ghezzal, Shinji Okazaki, Harry Maguire, Filip Benković, Matty James, Ricardo Pereira, Adrien Silva ati Çağlar Söyüncü yoo dije fun ami ẹyẹ agbabọọlu to dara julọ ni saa yii.
"Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Honourable SOB Agunbiade: Ọ̀tọ̀ ni ""Palliatives"" ìjọba, ọ̀tọ̀ ni ǹkan ìní tèmi náà tí wọ́n jí kó 29 Ọ̀wàrà 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 30 Ọ̀wàrà 2020 Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Agunbiade: Ọ̀tọ̀ ni ""Palliatives"" ìjọba, ọ̀tọ̀ ni ǹkan ìní tèmi náà tí wọ́n jí kó Ọmọ ile aṣojuṣofin to n ṣoju ẹkun idibo Ikorodu nile igbimọ aṣojuṣofin ipinlẹ Eko kan ti iroyin tan kalẹ pe o fẹ fi awọn nkan iranwọ Covid-19 ṣe ayẹyẹ ọjọ ibi rẹ iyẹn Họnọrebu SOB Agunbiade ti ni irọ patpata ni iroyin naa to tan ka gbogbo agbaye."
Wọ́n fi idà pa Hamori pẹlu, ati Ṣekemu ọmọ rẹ̀.
Gbogbo wọn yóo sì rọ́ wá sí ààrin àwọn àfonífojì, ati gbogbo kọ̀rọ̀ kọ̀rọ̀ ní ààrin àpáta, ati ara gbogbo igi ẹlẹ́gùn-ún ati gbogbo pápá.
Alaga ajọ naa, Alhaji Musiliu Smith lo paṣẹ yii.
Nígbà tí ó sì rí i pé mo pariwo, ó sá jáde, ó fi ẹ̀wù rẹ̀ sílẹ̀ sí mi lọ́wọ́.
Mi o ni ko wa tọrọ aforiji o, nitori pe ko si ẹni to gbadura pe ki oun wa ni iru ipo to wa nigba naa, Ibanujẹ lo ṣokunfa ohun to ṣẹlẹ nigba naa.
Ọna kii gba ẹsẹ tori pe lati kaakiri agbaye lawọn eeyan ti maa n wa fun ipade adura naa.
"Iroyin tun sọ pe aarẹ sọ wi pe ""mo ni gbogbo esi idibo ẹkun jẹkun lọwọ""."
Aare Muhammadu Buhari ti fi da awon ololufe egbe oselu All Progressives Congress APC loju pe, isakoso oun yoo tesiwaju lati tun tepamose si, ni ona lati mu gbogbo ileri eyi ti ijoba oun seleri se patapata fun awon omo orile-ede Naijiria.
Niwọn igba to si jẹ pe bakan meji ni ẹnu ọmọ araye, bi awọn eeyan kan se n foju sọna fun abẹwo naa, ni awọn eeyan kan n yinmu pe awọn isẹ wo gan ni Buhari n bọ wa si ni Eko.
NFF sadehun pẹlu Dennerby fun Falcons Labẹ iṣakoso rẹ ni awọn ẹka ere idaraya ti n ni adari meji bii eyi to n ṣẹlẹ lọwọ lẹka ere bọọlu alajusawọngba.
Ìdámẹ́ta àwọn ọkọ̀ ojú òkun ni wọ́n sì fọ́ túútúú.
2 Èmi sì wí fún un pé: Olúwa, fi agbára fún mi lórí ikú, kí èmi lè wà láàyè kí èmi sì mú awọn ọkàn wá sí ọ̀dọ̀ rẹ.
Ọ̀gágun tó wà ní ìdí ìfipágbajọba ní Ethiopia ti sálọ!
Akeredolu wa rọ gbogbo eeyan lati ri daju pe wọn wa ni alaafia, ki ara wọn si da.
“Ní tèmi, n óo máa wá OLUWA,n óo fọ̀rọ̀ mi lé Ọlọrun lọ́wọ́;
Ẹ óo sì máa gbé orí ilẹ̀ tí mo fún àwọn baba ńlá yín.
Àjèjì tuntun tó wọlé yìí, bí ó ti ngbé ewúrẹ ní í gbé àgùntàn.
Ìwọ ni o ni àkóso ìjọba gbogbo orílẹ̀-èdè.
À kò gba owó kankan lọ́wọ́ àwọn ẹgbẹ́ agbésùmọ̀mí ISWAP- MURIC Ọkọ Risikat ní ojú búlúù tí ìyàwó òun ní gan an lòun ṣe fẹ́ ẹ Ọwọ́ ọlọ́pàá ìpínlẹ̀ Kebbi tẹ bàbá àti ìyàwó rẹ̀ méjì fún pé wọn so ọmọ pọ̀ mọ́ ewúrẹ́ fún ọdún méjì Àwọn ǹkan tí ó yẹ kí o mọ̀ nípa 'Sharia Law' ní Nàìjíríà Gomina tẹnu mọ ọ pe pẹlu ajọṣepọ to dan mọran laarin awọn adari ikọ alaabo to ku pẹlu ti Amotekun, aridaju wa pe ọwọ yoo bẹrẹ si ni tẹ awọn ọdaran koda, ṣaaju ki wọn to pinṣẹ fun awọn ikọ naa.
Ni orilẹede China, wọn ma n jẹ oko akọ maluu.
Ọwọ́ ara mi ni èmi Paulu fi kọ gbolohun ìkíni yìí.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Èyí ni ìtàn bí ẹni tí mó gbọ́njú mọ̀ bíi bàbà ṣe fipá bá mi lájọṣepọ̀ Ileeṣẹ eto ẹkọ nipinlẹ Akwa Ibom, ti kọkọ bẹrẹ iwadii lori ọrọ naa, lẹyin ti ijọba ipinlẹ naa paṣẹ logunjọ, oṣu Kejila, pe ki iwadii waye lori awọn ẹsun ti Arabinrin Deborah fi sita.
“Fi fadaka tí wọ́n fi òòlù lù ṣe fèrè meji fún pípe àwọn ọmọ Israẹli jọ ati títú ibùdó palẹ̀.
laipe yii ni maa pe awon adari iko omo ogun orile ede yii lati jiroro lori igbese ti a o gbe lati dena iru isele yii lojo iwaju.
A óo gé gbogbo igi tí o bá nílò ní Lẹbanoni, a óo sì tù wọ́n lójú omi wá sí Jọpa, láti ibẹ̀ ni ẹ lè wá kó wọn lọ sí Jerusalẹmu.
O ni o yẹ ki ifẹ wa ninu ile ki wọn si tori eyi fi mọ awọn ọmọ.
Africa Drum Festival 2019: Eruku sọ níbi àjọ̀dún ìlù l'Abẹokuta
Koda ẹgbẹ agbabọọlu rẹ Arsenal kan sara si fun ohun to ṣe yi Ki lo mu Aubameyang dawọ idunnu Black Panther Pierre Emerick Aubameyang to jẹ ọmọ orileede Gabon ko ṣẹsẹ ma wọ awọ oju lati fi dawọ idunnu lori papa.
"Malami ṣipaya eyi l'Ọjọru ọsẹ ninu ọrọ to pe akọle rẹ ni ""Pipe Buhari lẹjọ: Ile aṣofin n ṣe lodi alakalẹ ofin""."
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Vaccination: Kí ní ìdí tí àwọn ènìyàn kìí ṣe fọ́kan tan abẹ́rẹ́ àjẹsára ?
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, CAN: Samson ni ọrọ awọn ajinigbe ti gba àpérò ní Naijiria O ni awọn Gomina fọwọ si idasilẹ aagọ ifẹranjẹ lawọn ipinlẹ (Ranching) ṣugbọn nigba ti ikede Ruga jade ọpọ awọn Gomina tapa si.
Nítorí pé ojú rẹ̀ tó gbogbo ọ̀nà tí eniyan ń tọ̀,ó sì rí gbogbo ìrìn ẹsẹ̀ wọn.
Ẹ ṣe àyẹ̀wò bi a ti ńṣe Ọ̀jọ̀jọ̀ lójú iwé yi.
Inú wá bí Ẹranko Ewèlè yìí sí obinrin náà.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ni amẹrika, ipade adura yoo waye fun idapada awọn ọmọ naa Lati naijiria si ilu ọba titi de orilẹede Amẹrika ni iwọde ati eto yoo ti waye lati tubọ tẹnumọ itusilẹ awọn ọmọ yii.
Àtẹ̀jáde náà wá pàsẹ fáwọn adarí ìjọ ní ẹkùn kọ̀ọ̀kan láti fi orúkọ sílẹ̀ tàbí dara pọ̀ mọ́ ilé ìwòsàn ìjọba kan tí wọn ní ìgbàgbọ́ nínú rẹ̀, níbi tí wọn yóò ti máa se àyẹ̀wò ìlera fáwọn àfẹ́sọ́nà sáájú ìgbeyàwó.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Akeugbagold sọ pé pásítọ̀ wà lára àwọn tó n san owó wáàsí òun 26 Ìgbé 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 25 Èbibi 2020 Oríṣun àwòrán, others Ilumọọka onimọ nipa ẹṣin Islam ati oniwaasi agbaye, Sheikh Taofeeq Akeugbagold ti salaye pe musulumi ati Kristẹni lo nifẹ si waasi ti oun maa n ṣe lori redio.
Okan ninu awon agbejoro re so pe, won fesun kan Abdel Moneim Abol Fotouh pe, o di ipo adari awon omo-ogun olote mu, bakan naa ni o n gbe iroyin ti ko lese n-le kaakiri ni orile-ede naa ati ni ile-okere, eyi ti o le sokufa laasigbo lorile-ede naa, amo won koi ti gbe lo si ile-ejo.
Àríyànjiyàn pupọ ni ó bẹ́ sílẹ̀ láàrin wọn.
Lola Omolola FIN: A gbọ́dọ̀ dìde láti ran àwọn obìnrin tó ń la ìwà ipá nínú ìdílé lọ́wọ́
O jẹ eto ti gbogobo ololufẹ rẹ ti nreti, o fa oju ọpọlọpọ ọmọ Naijiria mọra bẹẹ si ni o tayọ orilẹede Naijiria nikan si awọn orilẹede mii nilẹ Afirika nitori oniruuru alakalẹ eto to ndani lara ya ti wọn gbe kalẹ fun awọn akopa lati se.
Iléeṣẹ́ ọlọ́pàá yóò jẹ́jọ́ lórí ìwádìí ayédèrú ìwé ẹ̀rí tí wọ́n fi kan Sẹ́nétọ̀ Adeleke
Agbẹjọ́rò ni n kò bá jẹ́, tí n kò bá bá bàbá mi ṣe tíátà - Sola Kosoko Alága méjì láàrín ọjọ́ kan, sinimá oríta láàrín àwọn adarí APC Ìdílé márùn-ún tó gbajúmọ̀ fún òwò ẹrú nílẹ̀ Yorùbá Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Ẹsita wú Hegai lórí, inú rẹ̀ dùn sí i pupọ.
Gege bi Marie Josée‏ se so lori ero ayelujara re,“Ese pupo fun gbogbo atileyin yin ati adura yii.
Nítorí náà, OLUWA yóo kọ àwọn eniyan rẹ̀ sílẹ̀ títí tí ẹni tí ń rọbí yóo fi bímọ; nígbà náà ni àwọn arakunrin rẹ̀ yòókù yóo pada sọ́dọ̀ àwọn ọmọ Israẹli.
Wàhálà bẹ́ sílẹ̀ láàrín àwọn ọ̀dọ́ ní Oke Odo ní ìpínlẹ̀ Eko Wilfred Ndidi, ọmọ Nàìjíríà pa iná ògo Chelsea ní Stanford bridge Òkú sunkún òkú ní ìpínlẹ̀ BenueMo dáríjì àwọn IPOB tó nà mí ní Germany nítorí wọn o m'ohun tí wọ́n ń ṣe- Ekweremadu Ọlọ́pàá Ogun gb'ọmọ Ìmáàmù lọ́wọ́ ajínigbé, ṣùgbọ́n wọ́n gbé ọkọ̀ ojú omi ọlọ́pàá lọ Ẹsẹ̀ kò gbèrò ní ọdún Ọ̀ṣun Òṣogbo Buhari júwe ọ̀nà ilé fún Obono-Obla lórí ẹ̀ṣùn ayédèrú ìwé ẹ̀rí Gẹgẹ bi o si tun ṣe tẹsiwaju lati sọ,ọjọ aje ni iyanṣẹlodi naa yoo bẹrẹ lẹyẹ-o-ṣọka.
Ẹ kò jẹ oúnjẹ gidi, bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò mu ọtí waini tabi ọtí líle, kí ẹ lè mọ̀ pé OLUWA ni OLUWA Ọlọrun yín.
gege bi oludari ijoba orile-ede Venezuela losu kinni odun ti a wayii, bee si ni
Ko sẹsẹ bẹrẹ , eyi si kọ ni yoo jẹ opin.
Àwọn iranṣẹbinrin ati àwọn ọmọ wọn bá súnmọ́ wọn, wọ́n sì wólẹ̀ fún Esau.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Mo kẹ́kọ̀ọ́ fásitì sùgbọ́n aṣọ òké ló ń jáwó báyìí' Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Aeleye kẹnu bọ ọrọ lorii bi ipo ipinlẹ Ondo ni ilẹ Yoruba gẹgẹ bi aṣaaju gẹgẹ bo ṣe sọ ọ.
Eroja yii jẹ eyi to kun fun oriṣiriṣi nkan aṣaraloore to le kọju ija si arun coronavirus.
Olódùmarè ni o ń kọ́ ọba Igbó Olódùmarè ní ọgbọ́n, kò jẹ́ hùwà bí aláìgbọ́n kí ó máa wá ohun ìkọ̀sẹ̀ sí àlejò lẹ́sẹ̀ nítorí òun ti mọ eléyìí wí pé ìlá tí kò fẹ́ràn àlejò ń ṣe ara rẹ̀ ní ìjàǹbá, ó sì rọrùn fún ọmọ ọlọ́dúnmẹ́ta kí ó ṣe alága ìgbìmọ̀ ìlù ju kí ìlú tí ó kórìíra àlejò ní ìlọsíwájú.
Ó bá tẹnu bọ̀rọ̀, ó ń kọ́ wọn pé:
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, John Ogu bá BBC Yorúbá sọ̀rọ̀ lórí ìgbáradì Nigeria vs Madagascar Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Awon obinrin tun so fun aare
Kí ló dé tí o fi ń bá mi sọ irú ọ̀rọ̀ yìí?
Ori Ade ni lootọ oun ko si ni ilu nigba ti iṣẹlẹ naa ṣẹ ṣugbọn gbogbo rẹ ni wọn ti fi to awọn leti.
PSquare Peter Okoye sàlàyé bí ààrun Coronavirus ṣe mú-un, ìyàwó rẹ̀ àti ọmọ
Kíákíá ni èmi ìbá kọjú ìjà sí àwọn ọ̀tá wọn,tí ǹ bá sì ṣẹgun wọn.
ẹni tí yóo fi ẹsẹ̀ yín múlẹ̀ títí dé òpin, tí ẹ óo fi wà láì lẹ́gàn ní ọjọ́ ìfarahàn Oluwa wa, Jesu Kristi.
“Olorun ti o da oyan gege bi o se wa, O mo daju pe o se pataki fun idagbasoke omo tuntun lopolopo.
Tinubu sọ̀kò òrò sí Obaseki lẹ́yìn tó yọ òrùlé ilé ìgbìmọ̀ aṣòfin ìpínlẹ̀ Edo
Yọ mí ninu irà yìí, má jẹ́ kí n rì,gbà mí kúrò lọ́wọ́ àwọn ọ̀tá mi.
Ọlọrun yóo mú ìfihàn yìí wá ní àkókò tí ó bá wù ú, òun ni aláṣẹ kanṣoṣo, Ọba àwọn ọba ati Oluwa àwọn oluwa; 
Ọlọrun ni ó dá òkè ńlá ati afẹ́fẹ́,tí ń fi èrò ọkàn rẹ̀ han eniyan,Ọlọrun ní ń sọ òwúrọ̀ di òru,tí sì ń rìn níbi gíga-gíga ayé;OLUWA Ọlọrun àwọn ọmọ ogun ni orúkọ rẹ̀!
Coronavirus and OCD: 'Mo fi ogún ọdún gbáradì fún àjàkálẹ̀ ààrùn yìí' Coronavirus: Ǹjẹ́ àwọn dókítà tó ń tọ́jú eyín ń ṣisẹ́ lásìkò pàjáwìrì?
Awọn kan ti n sọ pe awọn ogunna gbongbo ọmọ ẹgbẹ APC kan ti n gbimọ lati gba ipo adari ẹgbẹ naa ati lati bẹrẹ iṣẹ lori idibo gbogbogbo ọdun 2023.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ààwẹ̀ náà kìí ṣe fún jíjẹ àti mímu nìkan Ó ní ààwẹ̀ náà kìí ṣe fún jíjẹ àti mímu nìkan o.
Ó tọ́ mi sí ọ̀nà òdodonítorí orúkọ rẹ̀.
 Òun àti leverrier , astronomer ọmọ ilẹ ̀ faransé kan ni wọ ́ n jọ gba ogo ṣíṣe àwárí neptune ní 1846 .
Kiniun naa fi tipa-tipa jade ninu ile rẹ to wa ni ibudo igbafe Gamji to gbajumọ ni igboro Kaduna, nibi ti kiniun ná ti se Mustapha Adam l'ẹse l'ọrun.
Ìjà ni ó de ní ijọ́sí ni àwọn ara ilé wa purọ́ mọ wa, ti wọ́n wi pe awa ni a pa àwọn lọ́mọ jẹ, bẹ́ẹ̀ ni àkókò tí mo ń sọ̀rọ̀ rẹ̀ yí, emi àti ẹgbọn mi kò ì tí í ní àjẹ́, orúkọ tí kò yẹ wa ni ọmọ aráyé fi fún wa, nígbà tí oṣì mẹta si fi máa pé gbogbo ènìyàn jákèjádò ìlù wa ni wọ́n ti gbàgbọ́ pe àjẹ́ ni èmi àri ẹgbọn mi.
) Kristoffer Nordfeldt88’2 – 3  Sergio Aguero.
Kò pẹ́ lẹ́hìn èyí ni mo rí obìnrin arẹwà kan, o n bọ̀ níwájú mi, mo sì ṣe àkíyèsí wí pé ọ̀pọ̀lọpọ̀ àwọn abàmì ẹ̀dá tẹ̀lé e lẹ́hìn, wọ́n dára púpọ̀, ara wọ́n tutù nini ó ń dán bí ara ọmọ tuntun òòjọ́, bẹ́ẹ̀ ni aṣọ ara wọn ń tan ìmọ́lẹ̀ bí òòrùn ọ̀sán ganagn.
Àwọn Juu wá bi í pé, “Àmì wo ni ìwọ óo fihàn wá gẹ́gẹ́ bíi ìdí tí o fi ń ṣe nǹkan wọnyi?
Oúnjẹ náà sì fún un ní agbára láti rìn fún ogoji ọjọ́ tọ̀sán-tòru títí tí ó fi dé orí òkè Horebu, òkè Ọlọrun.
O ti to ọjọ mẹta ti aarẹ Trump ti n ni itakurọsọ pẹlu awọn ileeṣẹ ọhun, eyi tiko sẹyin iru awọn ọrọ to ma n fi lede loju opo Twitter rẹ.
Ẹ óo mú àwọn nǹkan tí a kà sílẹ̀ wá pẹlu olukuluku ẹran tí ẹ bá fẹ́ fi rúbọ.
" Orilade ní ó pọ̀n dandan lati ṣe àbẹwò sí ilé ẹni ti wọ́n ba ń ṣe ìwádìí, ó jẹ ìtẹsíwájú ìwádìí àwọn ni.
kí wọ́n lè máa rìn ninu ìlànà mi, kí wọ́n sì lè máa pa òfin mi mọ́.
 nítorípé bórọ ̀ nù jẹ ́ dídá pátápátá pẹ ̀ lu ìtúká ìrànká kọ ́ smíkì tí kò sì jẹ ́ pẹ ̀ lù núkléùkíkódájọpọ ̀ oníràwọ ̀ , kò fi bẹ ́ ẹ ̀ pọ ̀ ní inú sístẹ ́ mù òrùn àti nínú ìgbẹ ́ lẹ ̀ ayé .
Ninu idajọ rẹ, Majisreeti Olajumoke Akande yi ẹjọ DPO naa danu, o si ni ki telọ Adeniyi maa lọ lalaafia.
Àkọlé àwòrán, Sarumi ni awọn akanda ẹda ti n dojukọ idẹyẹsi l'awọn bank ati bẹẹbẹ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Twin Festival 2019: Ṣé ọbẹ ìlasa àti àmàlà ló ń ṣokùnfà bíbí ìbejì ní ìlú Igboọrà?
“lorukọ awọn akẹgbẹ mi ni Ile Igbimọ Aṣofin Ipinlẹ Eko, mo ki yin fun
Bí OLUWA kò bá ṣọ́ ìlú,asán ni àìsùn àwọn aṣọ́de.
Ẹwẹ awọn ijọba ipinlẹ kọọkan bi Eko ti kede ọjọ ti gbogbo akẹkọọ ile ẹkọ ijọba ati aladani gbọdọ pari eto ẹkọ saa kini ọdun 2020/2021.
Ahimaasi bí Asaraya, Asaraya sì bí Johanani.
Ki o to di asiko yii, iroyin sọ wi pe adari ikọ awọn ọmọogun Naijiria kii jẹ ki awọn ọmọogun Naijiria fẹyinti lai ti to asiko.
Òun náà gbà bẹ́ẹ̀ fún wa, o ní kí a padà wá ní ojú alẹ́.
Oríṣun àwòrán, The sun newspaper Lara ẹsun ti awọn araalu tun fi kan an ni pe, o n da alaafia ilu naa ru.
Nikodemu, tí ó fòru bojú lọ sọ́dọ̀ Jesu nígbà kan rí, mú àdàlú òróró olóòórùn dídùn olówó iyebíye oríṣìí meji wá, wíwúwo rẹ̀ tó ọgbọ̀n kilogiramu.
Oge sise laye atijọ ati laye ode oni pẹlu awọn apẹrẹ loriṣiriṣi ni wọn fi kọ wa lọsẹ naa.
Mo rí OLUWA, ó jókòó lórí ìtẹ́ rẹ̀, àwọn ogun ọ̀run sì wà ní apá ọ̀tún ati apá òsì rẹ̀.
 Ogoro awon ololufe iko agbaboolu Manchester United jake-jado agbaye lo fi idunnu won han lataari esi ifesewonse ohun, eleyi ti o mu iko naa pegede sipele ti o kan ninu idije UCL.
Ọ burú jáì kí ààrẹ orílẹ̀èdè kọ̀ láti bá aráàlú sọ̀rọ̀ lásìkò ìṣòro - Ibrahim Babangida Iléẹ̀kọ́ Deeper Life, ẹ san N100m owó gbà má bínú fún ọmọ mi, kẹ sì tọrọ àforíjìn - Òbí akẹ́kọ̀ọ́ Àwọn òṣèré Yorùbá t'Élédùwà gbà fún àmọ́ tí wọn kìí ṣe ọmọ ilẹ̀ Yorùbá Dangote já mi kulẹ̀ lóri ọ̀rọ̀ ìfẹ́ àmọ́ ó kọ́ mi bá a ṣé lówó - Ọ̀rẹ́bìnrin Dangote lahùn Ninu ọrọ tirẹ, alaga igbimọ alaṣẹ ẹgbẹ agbabọọlu naa, Nasser Al-Khelaifi sọ pe Pochettino gan an lo to gbangba sun lọyẹ lati tukọ ẹgbẹ agbabọọlu PSG.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Eld Kabir in Nigeria: Mùṣùlùmí àti Kristiẹni sọ̀rọ̀ nípa àdun oúnjẹ́ àti ẹran ọdún Ileya Akintoye ṣalaye fun ipade apapọ igbimọ agbaye naa pe, aisi aabo to peye, ti mu ki awọn iwa ipa bii ijinigbe, ikọlu awọn agbebọn, ikọlu laarin agbẹ ati darandaran ati bẹẹ bẹẹ lọ, di tọrọ fọnkale nilẹ Yoruba.
Nigba to n dahun ibeere lori ohun to fa akude ba igbesẹ yiyanju aawọ naa ni tubiinubi eleyi to kskọ n waye laarin igun mejeeji, Ọmọọba Alẹshinlọyẹ ṣalaye pe gomina ijọba ipinlẹ Ọyọ n fi iwa jẹgujẹra lọ awọn lo faa ti awọn fi yọwọ-yọsẹ ninu igbesẹ naa nigba naa.
Awon gomina naa ni :AbdulAziz Yari ti ipinle  Zamfara, Abubakar Badaru ti ipinle  Jigawa ati Abubakar Bagudu ti ipinle  Kebbi .
Awọn nkan ti wọn ka si ẹṣẹ ni jijẹ omugọ, imọ tara ẹni nikan, ki eeyan o ma a dibọn, titan ara ẹni jẹ, aini Ijọ naa tako lilo, ati katakara oogun oloro.
Ọmọ-ẹgbẹ́ ààrẹ João Lourenço, kì í ṣe nítorí èyí ni àwọn aráa Angola ṣe yàn ọ́ sípò, kò sí ibi tí o ti sọ nínú ìpolongo ìléríi rẹ, o kò sọ pé ìwé ẹ̀rí yóò gbówó lórí, síbẹ̀ kí ni ò ń rò?
Nígbà tí ó wà ní wúndíá tí ó lọ sí oko lọ́dọ̀ bàbá rẹ̀ ni ọjọ́ kan lákòókò ọdún orò, bí ó ti ń rìn lọ ni ó déédéé gbọ́ tí orò ń ké bọ̀ lẹ́yìn, ó bá sá wọ igbó ó ń bá igbó lọ, bí o bá sì ti ń gbúròó orò ni o ń túbọ̀ ń wọ inú igbó si i, nítorí kí ó má ba à rí oró lójú ọ̀nà.
 Aare tun ba awon omo orile ede Naijiria ti won wa ni Poland soro lojo keji ti o de si orile ede Poland.
iwin náà kì í jẹ́ kí ẹnikẹ́ni dé igbó Olódùmarè, a máa fún àwọn ọdẹ ní làálàá ṣe, bẹ́ẹ̀ ni òun kò ga ju ẹsẹ̀ bàtà méjì lọ, inú òkìtì ọ̀gán ni òun sì ń gbé.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù June 12 in Nigeria: Wo àwòrán pápá ìṣeré MKO Abiola National Stadium 13 Òkùdu 2019 Àkọlé àwòrán, Buhari ti fi ori MKO Abiola pe papa iṣere Abuja National Stadium.
Òṣùpá yóo dààmú,ìtìjú yóo sì bá oòrùn.
Sùgbọ̀n ó dàbí ẹni pé àmì ọ̀rọ̀ yìí, nínú èdè Yorùbá, ti ń lọ sí òkun ìgbàgbé.
Awọn to ṣoju wọn koro ni ṣe lawọn oṣiṣẹ alaabo yii tun tunraki lẹẹkeji ti wọn doju kọ wọn ni awọn ba sa lọ si bareke awn ọmọ ogun oju omi lati fara pamọ fun ikọlu wọn to n pẹ.
” Ṣugbọn Samsoni já awọ ọrun náà bí ìgbà tí iná já fọ́nrán òwú lásán.
Afurasí afipábánilópọ̀ kàgbákò, obìnrin tó jà lólè fi eyín gé nǹkan ọkùnrin rẹ̀ jábọ́ lásìkò 'Blow Job' Obinrin ẹni ọdun mẹrinlelogun kan, ti fi eyin ge okó ọkunrin kan, to fi ipa ba a lopọ jabọ, lẹyin ti ọkunrin naa sọ pe ko fi ẹnu fa okó rẹ.
Ki ariwo à-lò-tún-lò tó gbòde ni aiyé òde òni nipa àti dáàbò bo àyíká ni Yorùbá ti ńlo à-lò-tún-lò pàtàki li lo ewé lati pọ́n oúnjẹ.
Awọn ipinlẹ to ku ni Sokoto, Benue, Adamawa ati Plateau.
 kò tíì yé ni bóyá ipa rẹ ̀ a má a dínkù bí ó bá pẹ ́ .
Barakat ni akọbi fun awọn obi rẹ, ọmọ meji si ni awọn obi rẹ bi.
Bakan naa lo fi oju han pe ilu Eko ni Olori Badra n gbe bayii, to si ti si ile itaja nla kan si adugbo Ikeja nilu Eko eyi to si losu kẹwaa ọdun 2020.
OLUWA bá sọ fún mi pé, “Láti ìhà àríwá ni ibi yóo ti dé bá gbogbo àwọn tí wọn ń gbé ilẹ̀ náà.
Man City fi ìkanra na Watford bolẹ̀ Òfò ṣ'ẹ̀dá: Ẹ̀fọn Norwich já bàálùu Man City Awọn meji naa ni wọn ku lairo tẹlẹ ni ilu Uyo, Olu Ilu Akwa Ibom ni ọjọ meji sẹyin, ki ti Issac Promise to tun ṣẹlẹ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, LASTMA Yesufa: Àwọn dókítà gbìyànjú lórí ojú mi ṣùgbọ́n.
5 Kíyèsíi, ìbùkún ni fún ọ nítorí ohun yìí, àti fún sísọ àwọn ọ̀rọ̀ mi èyí tí mo ti fi fún ọ gẹ́gẹ́bí àwọn òfin mi.
O ti gbe apoti ibo lati dije du ipo aarẹ orilẹede Naijiria ri.
Akitiyan láti f’òpin sí ìṣọdẹ-àjẹ́ lè tẹ̀lé ìlànà tí ìjọba fi polongo ètò mímọ̀ọ-kọ-àti-mímọ̀ọ-kà.
“Mo jẹ́ kí ìyàn mú ní gbogbo ìlú yín, kò sì sí oúnjẹ ní gbogbo ilẹ̀ yín; sibẹsibẹ ẹ kò pada sọ́dọ̀ mi.
Jesu bi í pé, “Kí ni o fẹ́ kí n ṣe fún ọ?
Ọgbẹni Chakwera sọ fun awọn ọmọ orilẹ-ede naa lasiko to ba wọn sọrọ pe ko si ifoya fun awọn ti ko dibo fun""."
Lori ọrọ kan ti o n ja rayin-rayin ti wọn ni aarẹ Buhari sọ nilu London pe ọkundun ti ko fẹ iṣẹ ṣe lawọn ọdọ Naijiria.
Aarẹ ẹgbẹ CAN ni Naijiria, Ẹniọwọ Ọlasupọ Ayọkunle sọ wipe, afojusun iwọde naa ni lati kesi ijọba apapọ ati ajọ eleto aabo lorilẹede Naijiria, lati wa ọna abayọ si ọgọọrọ ẹmi ti awọn Fulani darandaran n pa ní aarin gbungun orilẹede Naijiria.
Àwọn tí Silipa, iranṣẹbinrin Lea bí ni: Gadi ati Aṣeri.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Igbó mímu lè ṣe kóríyá, kò lé fi kún orín ẹnu òṣèré - 9ice Ìtàn tó wà nídi òwe ‘Sebótimọ Ẹlẹ́wà Sàpọ́n’ Ọba Adesoji Aderemi, Ọọ̀ni Ifẹ̀ tó gba ipò ọba mọ́ tòṣèlú Kókó ọ̀rọ̀ tí Buhari sọ ní àyájọ́ June 12 Nigba to n ba BBC Yoruba sọrọ, Oga Bello ni oninu ire ni Dagunro, to si ni itẹriba fun awọn asaaju ninu osere tiata nitori o ri oun gẹgẹ bi oga rẹ, to si bọwọ fun oun.
Agbẹnusọ kan nileeṣẹ ọlọpaa sọ pe igbesẹ ti n waye lati doola wọn.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kan Nnkan yìí kò sí mọ́.
“Bẹ́ẹ̀ náà sì ni Ṣimei ọmọ Gera ará Bahurimu láti inú ẹ̀yà Bẹnjamini, èpè burúkú ni ó ń gbé mi ṣẹ́ lemọ́lemọ́ ní ọjọ́ tí mo lọ sí Mahanaimu.
Ki eto idibo ti yoo waye ni ojo kerinla, osu keje yii lee lọ ni irọwọ-irọsẹ.
06% Ẹ̀wẹ̀, àjọ SERAP ti ké si ìjọba Muhammadu Buhari pé ó ṣe pàtàkì ni àsìkò yìí láti mú àdínkù bá àwọn ìlànà ìṣèjọba kan kìí ṣe díndín owó òṣì'sẹ́ ìjọba ku ló ṣe pàtàkì.
Lara awọn isẹ ti DFL n kọ wọn ni isẹ lilo ankara lati fi se bata ati baagi, isẹ kafinta, eyi to jẹ pe awọn obinrin kii saba ya sidi rẹ ati isẹ aso ina taa mọ si Electrician.
Adeleke pegede gẹgẹ bi oludije fun ẹgbẹ oselu PDP ninu idije Gomina nipinlẹ Osun, lẹyin to fẹyin Akin Ogunbiyi janlẹ pẹlu ibo meje.
Nígbà tí àwọn ìjòyè Juda gbọ́ ọ̀rọ̀ yìí, wọ́n lọ sí ilé OLUWA láti ààfin ọba, wọ́n sì jókòó ní Ẹnu Ọ̀nà Titun tí ó wà ní ilé OLUWA.
Bí ọkunrin bá bá obinrin lòpọ̀, tí nǹkan ọkunrin sì jáde lára rẹ̀, kí àwọn mejeeji wẹ̀, kí wọ́n sì jẹ́ aláìmọ́ títí di ìrọ̀lẹ́.
Ìlérí OLUWA fún Àwọn Eniyan Rẹ̀.
Ẹsun ti wọn fi kan Baruwa ni pe o fi tipa tikuuku ba ọmọbinrin kan, ẹni ọdun mejidinlogun lopọ, ẹni to n wọna bi yoo se wọle sinu ọgba ileeẹkọ naa.
Awọn ọmọ ile igbimo a maa lọ fun isinmi atigbadegba ṣugbọn ko gbọdọ jẹ lasiko ti o mu ifura dani bi eyi.
Ihenacho, Mahrez tan bi oorun bi Leicester se na Westbrom Man Utd na Liverpool Watford naa gbiyanju lati gbẹsan, sugbọn wọn ko le gba bọọlu sinu awọn Arsenal titi ti wọn fi lọ fun isimi ilaji asiko.
Orukọ miran fun emere ni Abiku - iyẹn awọn ọmọ ti ori wọn ko gbó, ti ẹmi wọn ko gùn.
Mú ojú rẹ kúrò lára rẹ̀, kí ó lè sinmi,kí ó sì lè gbádùn ọjọ́ ayé rẹ̀ bí alágbàṣe.
Nítorí a bí Olùgbàlà fun yín lónìí, ní ìlú Dafidi, tíí ṣe Oluwa ati Mesaya.
Gẹ́gẹ́ bí ìròyìn tó wà lórí ayélujára ilé iṣk ọmọogun òfurufú, wọ́n ni ẹ̀kọ́ náà jẹ́ ti ọlọ́ja kúkúrú fún àwọn ọkùnrin àti obinrin tọ ṣíṣẹ́ ofurufú, tí kò sì ni ju oṣù mẹ́fà lọ lati fi gba ẹ̀kọ́.
Nigbati Epo-rọ̀bi bẹ̀rẹ̀ si pa owó wọlé, ará ilú kọ iṣẹ́ àgbẹ̀ àti àwọn ohun ti ilú nṣe silẹ̀ fún ifẹ́ ọjà òkèrè.
”Nígbà náà ni Jesu sọ fún wọn pé, “Èmi náà kò ní sọ irú àṣẹ tí mo fi ń ṣe àwọn nǹkan wọnyi fun yín.
 a tún má a nlo clarithromycin tàbí moxifloxacin dípò streptomycin .
Alaafin ni Wasiu gan lo beere fun oye Mayegun ni bi ọdun mọkanla sẹyin nigba to kan si oun laafin pẹlu awọn ọrẹ rẹ.
riri isẹ ribi-ribi ti o gbe se laarin odun merin sẹyin.
Gomina Akeredolu lasiko to ṣe abẹwo si ibi ti ibugbamu naa ti waye sọ fun awọn eniyan ki wọn ranti arun Coronavirus wa nita nitori naa ki wọn sọra lati sun mọ ara wọn.
RUGA: Ààrẹ àná, Goodluck Jonathan ní kí Buhari máà fi ọ̀rọ̀ RUGA kọ́ òun lọ́rùn
 Àbájáde ìwádìí ìgbìmọ ̀ náa wà nínú ìwé ìkéde gómìná ìpinlẹ ̀ Ọ ̀ yọ ́ , olóyè bọ ́ lá Ìge tí ní orí ẹrọ asọ ̀ rọ mágbesí nínú oṣu kẹwàá ọdún 1980 a tún gbọ ́ nínú ìkẹ ́ de yẹn ni pé Òkèwù ló tẹ ìlú Ọ ̀ ra-Ìgbómìnà dó àti pé àwọn ló sọ orúkọ ìlú náà ní Ọ ̀ ra ( a ó ra tán ) ohun tó da àwa lójú ni pẹ ́ ìlú méjì ló papọ ̀ tí wọn so Ọ ̀ ra-Ìgbómìnà ró báyìí .
Síbẹ̀, akọbúlọ́ọ̀gù Zone9 ṣe àtúnlò ìfẹ́-ìlú-ẹni nínú ọ̀rọ̀ àti ìṣe.
Ó tún rán àwọn ẹrú mìíràn, kí wọ́n sọ fún àwọn tí a ti pè pé, ‘Mo ti se àsè tán; mo ti pa mààlúù ati àwọn ẹran ọlọ́ràá; mo ti ṣe ètò gbogbo tán.
fun anfaani awon omo orile-ede Naijiria.
0 2 Orilẹede Vanuatu 0 0.
Awọn alaṣẹ ajọ naa sọ pe James Richard Nolan ati Adam Quinn jẹ oludari ni ile iṣẹ Process and Industrial Developments (P&ID).
“Awon omo-ogun olote ni won wa nidi ikolu wonyii, eyi ti o buru ju ni pe, won ni atileyin awon orile-ede ile okere, pelu atileyin orile-ede Turkey.
(Christian Association of Nigeria),Sheikh Shariff Ibrahim Saleh Al-Hussaini,
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Bolaji Faleke ni Olùkọ́ tó ń kọ́ wa ní àṣà oge ṣiṣe lórí BBC Yorùbá Ijọba apapọ tun fi oye Order of the Federal Republic of Nigeria, OFR da Oyinkan lọla, Nigba ti ijọba Gẹẹsì tun fi oye Member of the order of the British Empire MBE da lọla.
"Obinrin kan, Blessing Ugonna sọ fun akọroyin BBC nilu Eko pe asiko niyi fun awọn to maa n ta omi iyanu, ororo ati awọn nkan miran fun wa lati jẹwọ agbara wọn""."
"Coronavirus in Nigeria: Báyi ni ẹ ṣe leè ṣe \""hand sanitizer\"" nínú ilé yín"
Ẹ óo kọ orin kan bí orin alẹ́ ọjọ́ àjọ̀dún mímọ́,inú yín yóo sì dùn bíi ti ẹni tí ń jó ijó fèrè lọsórí òkè OLUWA, àpáta Israẹli.
Wo òkúta ìsàlẹ̀ òkun, wo ẹja bí ó ṣe kéré
Ṣugbọn mò ń fi ìyà jẹ ara mi, mò ń kó ara mi ní ìjánu.
 ) tabi ( uk ) ; ; iribomi ni 17 december 1770 - 26 march 1827 ) je alakopo orin ati oniduuru ara ile jemani .
Bí ẹ bá dán ọ̀rọ̀ kòbákùngbé wò - Lai Mohammed Èwo nínú àwọn amóhùnmáwòrán yìí lẹ rántí?
minisita  fun eto eko Adamu Adamu ti n
Oríṣun àwòrán, Other Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Ọmọ yìí tó ọmọ ọdún mejila.
Lẹ́yìn náà, wọ́n ṣí kúrò ni Haserotu, wọ́n sì pa àgọ́ wọn sí aṣálẹ̀ Parani.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Budget 2019: Buhari fi ọ̀rọ̀ ẹ̀kúnwó owó tuntun òṣìsẹ́ sínú àbádòfin 2019 19 Ọ̀pẹ̀̀ 2018 Oríṣun àwòrán, Christian C.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Fraud Allegations: Àjọ FBI mú ọ̀pọ̀ ọmọ Nàìjíríà lórí ẹ̀sùn jìbìtì l'Amẹrika 22 Ògún 2019 Oríṣun àwòrán, Twitter/FBI Ileeṣẹ ọtẹlẹmuyẹ orilẹede Amẹrika, FBI sọ pe awọn ti mu ọpọ ọmọ Naijiria ninu iwadii awọn to n lọ lọwọ lori ẹsun jibiti.
Oríṣun àwòrán, Other Nibi tawọn awakọ ti n gbiyanju lati fi jia da awọn tirela naa duro ni ọkọ mejeeji ti lọ fẹnu sọ awọn ṣọọbu to wa lẹba ọna nibi ti eeyan mẹrin ti ṣagbako iku ojiji.
 Èyí fi ìdàgbàsókè ti ń dé bá eré àpìírì hàn .
Wo àwọn ohun tó yẹ kí o mọ̀ nípa àrùn Coronavirus àti ìbálòpọ̀ akọ àt'abo Àwọn olùgbé ìlúu Abidjan ló kò àrùn Coronavirus wọ Ọ̀ṣun-Gómìnà Oyètọ́lá Coronavirus: Àwọn ohun tí a kò tíì mọ̀ nípa àrùn Covid-19 Bi o ba se wí pe ere fiimu ni ọrọ ti a n so yí jé ní, enit to kọọ yóò ti ni eleyii to lati fi pari ere idinnut yi, ṣugbọn kò tan sibe.
Ìdí tí mo fi ń ṣe ayẹyẹ ọjọ́ ìbí 35 lọ́dọọdún rèé- Allwell Ademola Iléẹjọ gíga jùlọ da ẹjọ́ SDP àti PDP nù, wọ́n ní Yahaya Bello ló wọlé ìbò gómìnà Kogi Ìjà d'ópin, fún ìgbà àkọ́kọ́, bàálù gbéra láti Israel lọ sí UAE Wọ́n ti sún ìdájọ́ àwọn sójà tó pa ìyá àti ọmọ ní ọdun 2018 sí oṣù tó m bọ̀ Máa gbé kẹ̀kẹ́ rẹ lọ, àwọn akọròyìn kọ̀ ìpàkọ́ sí Femi Fani Kayọde Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Wo bí Sunday Orimola ṣe gba ikú ẹranko kú ní Ifon ni Ondo lórí ọ̀nà àtijẹ Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí 6:18 Fídíò, Akomolede: Bolaji Faleke ni Olùkọ́ tó ń kọ́ wa ní àṣà oge ṣiṣe lórí BBC Yorùbá, Duration 6,181 Owewe 2020 6:10 Fídíò, Yoruba Language: Akomolede ati Asa Yoruba tọ̀sẹ̀ yí rèé lẹ́nu olùkọ́ wa, Duration 6,1030 Ògún 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Contortionist: Mo lè gbé ìfun mi pamọ́ ki n tún sé èémí pẹ́!
Àyọrísí rẹ̀ ni pé ẹ kì í lè ṣe àwọn ohun tí ó wù yín láti ṣe.
“Inu mi dun pe, mo koju awon ipenija ti mo ba lenu ise yii, mo si se aseyori lori re.
Àkàrà-oògùn ni mí nítòótọ́, oníṣègùn ni bàbá tí ó bí mi í ṣe, babaláwo sì ni pẹlu, oògùn kún inú ilé wa dé ẹnu, bẹ́ẹ̀ ni nǹkan abàmì ń bẹ ní kọ̀rọ̀ iyàrá, egbòogi ńlá ń bẹ lóké àjà, onírúurú ohun alááyyè ní si ń bẹ ní àgbàlá wa.
"Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, ""Kare, ọmọ ni ẹ"", eyi ni ọrọ tawọn agbabọọlu Naijiria n sọ fun Kenneth Omeruo lasiko ti wọn fa mọra, lẹyin to gba ami ayo wọle sile Guinea ninu idije AFCON 2019 to n lọ lọwọ Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ijo ni majẹmu wa, ẹ sa jẹ ka jo."
Àkọlé àwòrán, VIO ni ko si idarudapọ lori ojuṣe ọkọọkan awọn ajọ aggbofinro loju popo nipinlẹ Eko tabi ni ibikibi lorilẹede Naijiria.
Ọjọ́ náà jẹ̀ Ọjọ́ Ìpalẹ̀mọ́, Ọjọ́ Ìsinmi fẹ́rẹ̀ bẹ̀rẹ̀.
Kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ rẹ rí mi, ó sì yà fún mi nígbà mẹta, bí bẹ́ẹ̀ bá kọ́, ǹ bá ti pa ọ́, ǹ bá sì dá òun sí.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Akomolede: Bolaji Faleke ni Olùkọ́ tó ń kọ́ wa ní àṣà oge ṣiṣe lórí BBC Yorùbá Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Akomolede: Bolaji Faleke ni Olùkọ́ tó ń kọ́ wa ní àṣà oge ṣiṣe lórí BBC Yorùbá 1 Owewe 2020 Arabinrin Bolaji Faleke ló kọ wa ni lonii pẹlu iṣẹ Aṣetilewa lori oge ṣiṣe lati Ikeja Central Primary School ni ipinle Eko.
Láti fi dá ṣèríà fún elébi
Ọkan lara wọn ti orukọ rẹ n jẹ, Grace da iborun alawọ buluu bori, bẹẹ lawọn ọkunrin marun un joko lẹgbẹ rẹ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Sotitobire: Ìgbẹ́jọ́ kò le è wáyé mọ́ l‘Ọ́jọ́rùú, wọ́n ṣun síwájú di Ọjọ́bọ̀ 5 Èrèlè 2020 Ileejọ ti sun igbẹjọ to waye yẹ ko waye lọjọru siwaju di Ọjọbọ ọla lori ẹsun ijiọmọgbe ti wọn fi kan oludasilẹ ijọ Sotitobire nilu Akurẹ.
"Ẹ ko ara yin ni ijanu, gbogbo wa la nilo okun lati ṣiṣẹ lasiko idibo, mo fẹ gba yin nimọran lati maa jẹun daadaa, ati pe ki ẹ din nini ibalopọ ku ki ẹ le lagbara fi ṣiṣẹ daadaa ṣaaju, lasiko ati lẹyin idibo ọdun 2020, DCOP Afful sọ fawọn ọọfisa ọlọpaa.
Ọ̀tá fi ìwọ̀ fa gbogbo wọn sókè, ó sì fi àwọ̀n rẹ̀ kó wọn jáde.
Oluwa kan ṣoṣo ni ó wà, ati igbagbọ kan, ati ìrìbọmi kan.
Nítorí ó ti fi ìgbàlà wọ̀ mí bí ẹ̀wù,ó sì ti fi òdodo bòmí lára bí aṣọ;bí ọkọ iyawo tí ó ṣe ara rẹ̀ lọ́ṣọ̀ọ́,ati bí iyawo tí ó ṣe ọ̀ṣọ́ jìngbìnnì.
Èyí ni díẹ̀ lára ìgbà tí Buhari àti àwọn aṣòfin gbéná wojú ara wọn
GOV Bi ọwọ ọlọpaa ṣe tẹ Hushpuppi, ati Lekan Ponle AKA Woodberry, ti wọn si gbe wọn lọ si orilẹ-ede Amẹrika, fa ariyanjiyan lori ayelujara.
Ṣugbọn ẹnikẹ́ni kò gbọdọ̀ ta ilẹ̀ tí ó jẹ́ ti gbogbogbòò, tí ó wà ní àyíká àwọn ìlú wọn, nítorí pé, ogún tiwọn nìyí títí ayérayé.
Nigba to dagbere faye, awọn iwe iroyin Naijiria kan ni lẹyin ọjọ mẹwaa lori akete aisan lo dakẹ ni ile iwosan Marritol Hospital, Surulere, Eko.
Ṣugbọn Ẹ̀mí tí ó sọ yín di ọmọ ni ẹ gbà.
Ko jẹ iyalẹnu pe o ṣe iwaasu gẹgẹ bi iṣe rẹ amọ awọn amọran kan to gba ninu iwaasu to ṣe nibi eto oloṣooṣu ijọ rẹ ti wọn pe akori rẹ ni Swimming In Glory ti n ja rainrain .
Ẹ̀yin tí ẹ̀ ń fi ìwà ìpànìyàn kó ìlú jọ, tí ẹ fi ìwà ọ̀daràn tẹ ìlú dó.
Àwọn àjẹsára kòkòrò ara wíwú ènìyàn ( hpv ) jẹ ́ àjẹsára tí ó maa ń dẹ ́ kun àkóràn ti àwọn irúfẹ ́ kòkòrò ara wíwú ènìyàn .
Ó sì rọ ọpọ́n bàbà meji, ó gbé wọn ka orí àwọn òpó náà.
Dájúdájú, àwọn olódodo yóo máa fi ọpẹ́ fún ọ;àwọn olóòótọ́ yóo sì máa gbé níwájú rẹ.
 Ìríwísí àwọn aráàlú bí EFCC ṣe kó afurasí ọmọ yahoo 49 ní Ibadan Ọọ̀ni obìnrin, Lúwòó Gbàgídà rèé, akọni tó ń gun ọkùnrin ní ẹṣin rìn Ẹ̀yin ẹ máà wò ó, ó ṣeéṣe kí APC túká lẹ́yìn ìṣèjọ́ba Buhari!"
Ọjọgbọn Gambari ni yoo maa gba ipo naa eleyi ti Abba Kyari dimu lati ọdun 2015 ti saa akọkọ iṣejọba aarẹ Buhari bẹrẹ titi di oṣu kẹrin ọdun 2020 ti wọn kede iku rẹ lẹyin to lugbadi arun COVID-19.
Ó bú sẹ́kún, ó sì bẹ̀rẹ̀ sí pohùnréré ẹkún tóbẹ́ẹ̀ tí àwọn ará Ijipti ati gbogbo ilé Farao gbọ́ ẹkún rẹ̀.
Oríṣun àwòrán, AFP/BOKO HARAM Àkọlé àwòrán, Mo ní ìwé àkọsílẹ̀ ìgbé ayé mi ni àgọ́ Boko Haram- Naomi Adamu 9.
Wọn ni o le ni ọgọta eniyan to ku ninu ikọlu ti 2008 ti ọpọ si di aṣatipo ati arinrinajo lataari aini ile lori mọ.
Eyi ni atunbọtan abadofin ti awọn aṣofin ipinlẹ Ọṣun fi ẹnu rẹ jona eyi tiolori ile naa, aṣofin Timothy Owoẹyẹ ṣalaye pe yoo mu adinku ba ọwọja iwa ifipabanilopọ to n fojojumọ gogo sii ni lorilẹede Naijiria bayii.
" O ni oun ti ṣetan lati jẹ ki igbeyawo oun duro daadaa.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Cancer: Àṣe ara mi ni iso ti n run gbogbo bí mo ṣe n ṣèrànwọ́ lórí jẹjẹrẹ Atẹjade naa, ti Kọmisana feto iroyin nipinlẹ Eko, Gbenga Omotoso fọwọsi, wa rọ awọn ara Eko lati maa ba ọrọ aje wọn lọ ni alaafia lai fa ijangbọn rara.
”Jesu wí fún un pé, “Bí n kò bá wẹ̀ ọ́, a jẹ́ pé ìwọ kò ní nǹkankan ṣe pẹlu mi.
Bẹndekeri ni alákòóso fún ìlú Makasi, ati Ṣaalibimu, ìlú Beti Ṣemeṣi, Eloni, ati Beti Hanani.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ọ̀lọ́pàà ìlú ọba ti fi páńpẹ́ ọba mú olùdásílẹ̀ Wikileaks, Julian Assange ní ìlú London.
Ọgbẹni Okoronkwo salaye pe kii ṣe ẹgbẹ oṣelu lo n gbe igbesẹ yi bi kii ṣe ẹgbẹ IPMAN.
Ẹ má bẹ̀rù, ẹ̀yin ọmọ Jakọbu, iranṣẹ mi, nítorí pé mo wà pẹlu yín.
Gege bi Udoh se so,”Gbigba ami-eye meta naa safihan ise rere ti Gomina Udom Emmanuel gbese lati mu ere-idaraya lokunkun- dun nipinle naa,”.
Ìkọlù New Zealand: Jacinda, Alabi ati àwọn mii gboriyin
”Àwọn eniyan náà bá pariwo pé, “A gbà bẹ́ẹ̀.
Ọkùnrin tó yí orúkọ padà sí Muhammadu Buhari ṣ'ayẹyẹ ìsọmọlórúkọ ní Kano Uganda ti bẹrẹ ìgbésè láti fi ikú ṣefàjẹ fún ẹní bá ṣe ìgbéyàwó akọ si akọ ati abo si abo Okunrin kan kú lójijì lẹ̀yin ọjọ̀ díẹ̀ to jẹ milionu kan dọ́là Afurasi onisowo ibọn wọ gau agbofinroAwọn ọna miran:Ni ijọba ibilẹ Agege1.
Ijọba ibilẹ mẹjọ pere ni wọn ni ni Bayelsa.
Bẹ́ẹ̀ ni mo padà tayọ̀tayọ̀ tí mo wá sí ilé ọ̀rẹ́ mi, lọ́dọ̀ Baba-onírúngbọ̀n-yẹ́úkẹ́ ẹni tí ń gbé ibi gegele òkúta.
”Asofin Dino Melaye ni won gbe lo silu Lokoja, nipinle Kogi lati ile iwosan gbogbogbo nilu Abuja pelu sekeseke lowo re.
Onimọ nipa oun to yẹ ki eeyan maa jẹ kole di ogbo to da si ọrọ naa ni “o yẹ ka maa jẹ ounjẹ to maa fun wa ni okun, ki a maa ṣere idaraya, ki a ma si maa wo aago alaago sare.
Ó wá gba àwọn ènìyàn ní ìmọ̀ràn pé, ó ṣe pàtàkì láti yẹ agolo òògùn apakòkòrò wò, kí a sì tèlé ìlànà tó yẹ kí a tó lòó Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fọ́nrán ohùn, Dókítà Yemisi Adeyeye sàlàyá lórí àwọn ìpalára tó wà nínú òògùn apakòkòrò Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
, Duration 1,5831 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 5:58 Fídíò, Yeye Olokun of Lagos Omolara Fasola Fanimokun: Pásítọ̀ ṣọ́ọ̀ṣì ló sọ ìran pé kí n di Olókun, Duration 5,5821 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Nollywood Yoruba: Kìí ṣe sinimá ni mò ń ṣe, ìṣẹ̀lẹ̀ ojú ayé gangan ní sùgbọ́n.
Coronavirus: Ìjọba àpapọ̀ kéde èèyàn márùn ún míràn tó ní àrùn Coronavirus lorilẹ̀ede Naijiria Oríṣun àwòrán, Getty Images Ijọba apapọ ti kede eeyan marun miran pẹlu arun Coronavirus lorilẹede Naijiria.
Ẹfunsetan Aniwura, obìnrin tó ju ọkùnrin lọ Hubert Ogunde rèé, baba àwọn òsèré tíátà Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fọ́nrán ohùn, Oluwo Ìwo ṣ'àlàye lori oyé oba oni lawàni Ọba Akanbi ké si Alaafin Oyo, Oba Lamidi àti Awujale ti Ijebu Oba Sikiru láti sááju ìjàgbara kúrò lọ́wọ́ ẹgbẹ́ okunkun.
”Sebulu dá a lóhùn pé, “Òjìji òkè ni ò ń wò tí o ṣebí eniyan ni.
Wọ́n ro oko gbogbo tí ó wà ní ìgboro, wọ́n ṣe ojú ọ̀nà dáadáa, a mu kí wọ́n ṣe ilé ìgbọ̀nṣẹ̀, gbogbo àwọn igi tí o wà láàrin ilú tí ó mú kí ìlú dàbí inú igbó la mú kí wọ́n ge, wọ́n tún odò gbogbo ṣe.
O ní ó fipa bá ọmọ ọdún méjìlá lòpọ̀ ni abúlé Farsa ni ọdún 2019.
Oríṣun àwòrán, twitter/Arakunrin rotimi akeredolu Awọn ibudo ayẹwo fawọn aṣoju oludibo niwọnyii: Awọn aṣoju lati ẹkun Ariwa Ondo- Gbongan ajọ olomi ẹrọ Water Corporation to wa ni Ijapo Estate, Awọn aṣoju ẹkun Gusu Ondo- Ileewe girama, St Thomas' Aquinas College nilu Akurẹ Awọn aṣoju ẹkun Aringbungbun Ondo- Ileegbimọ aṣofin ipinlẹ Ondo, ODHA Complex ni opopona Igbatoro Akurẹ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Algeria: Ààrẹ Abdelaziz Bouteflika re 'bi àgbà ń rè 5 Ọ̀pẹ̀̀ 2018 Oríṣun àwòrán, AFP Àkọlé àwòrán, Abdelaziz Bouteflika Abdelaziz Bouteflika fẹrẹẹ lo ogun ọdun ninu aginju oṣelu ki wọn to dibo yan an gẹg bi Aarẹ orilẹede Algeria lọdun 1999.
Ọ̀pọ̀ olólùfẹ́ Iya Jogbo banújẹ́ lórí ìròyìn ikú rẹ̀ Àwọn ọmọ ogun ilẹ̀ Nàìjíríà dóòlà ẹ̀mí ẹni méjì ní Owena ní Ondo Wo ǹkan tí ojú àwọn èèyàn rí lẹ́yìn tí wọ́n ti afárá 'Third Mainland' Wo ohun tí Adájọ́ sọ nípa ìgbẹ́jọ́ Wòlíì Sotitobire l'Ondo Wo àwọn tí wòlíì ríran sí pé COVID-19 yóò pa ní ìpínlẹ̀ Edo l'óṣù kẹsàn án Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Bi ọdun kan sẹyin ni ofin naa jade.
Wo àwọn òrílẹ̀èdè 10 tó láyọ̀ jùlọ lágbàyéé Kinni ohun to nmu idunnu ba ọkan re ?
Idije naa rọrun pupọ ju fun ẹgbẹ agbabọọlu Chelsea.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Winter Olympics: Buhari ransẹ oriire sikọ Naijiria 9 Èrèlè 2018 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Naijiria n kopa fun igba akọkọ nibi idije ere idaraya asiko yinyin lagbaye, Winter olympics.
Oríṣun àwòrán, Abiola Ajimobi Ọba Adeyemi wa ba Gomina Seyi Makinde ati ara ilu kẹdun iku Ajimobi, to si sadura pe ki Eledua dẹlẹ fun ẹni rere to lọ.
Eyi to tumọ si bii miliọnu mẹsan abọ si mọkanla abọ naira.
Gbogbo àwọn eniyan jẹ, wọ́n yó.
jawe olubori ninu idibo to waye ni odun 2010 ati 2015, leyin igba ti o ti tọwọbọ
Ko ti i si awon aridaju nipa iduna-dura laarin orile ede Afrika mejeeji yii, amo sa, orile ede Ethiopia ti pese   apeje ale   fun awon asoju ti orile ede Eritrean lojo Isegun ti o koja yii.
Sanwo-Olu kéde ìgbésẹ̀ rẹ̀ lórí ìrìnnà ọkọ̀ àjàgbé l'Eko Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Cancer: Àṣe ara mi ni iso ti n run gbogbo bí mo ṣe n ṣèrànwọ́ lórí jẹjẹrẹ Ẹwẹ, adajọ Muslim S.
Onímọ-tara-ẹni-nìkan ya ara rẹ̀ sọ́tọ̀,láti tako ìdájọ́ òtítọ́.
Wọ́n tún ti fipá bá akẹ́kọ̀ọ́bìnrin míì ọmọ pásítọ̀ lòpọ̀ l'Akinyele n'Ibadan wọ́n sì tún pa á Kollington, Bàbá Suwe, Ogun Majek wà lára àwọn gbajúmọ̀ òṣèré tí ayé ti parọ́ ikú mọ́ sẹ́yìn Wo ohun tí irú ìgbẹ́ tí ò ń yàá sọ nípa ìlera rẹ Amọ, ijọba ipinlẹ Eko ni ọrọ ko ri bẹ ẹ, wọn gbọdọ gba iwe aṣẹ lọwọ ijọba wi pe ohun ti wọn fẹ ṣẹ ko tapa si ofin ijọba.
Ó sì ti ṣe bí ó ti pinnu nítorí pé ẹ dẹ́ṣẹ̀ sí i, ẹ kò sì fetí sí ohùn rẹ̀, nítorí náà ni ibi ṣe dé ba yín.
Amojuto Bitcoin fi ara jọ ti àpò àsùnwọ̀n ni banki, pẹlu ilana pe ti awọn akọsilẹ nipa rẹ ba sọnù, owó Bitcoin rẹ naa wọ igbo nìyẹn.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ruga Settlement: A kò fipá mú ẹnikẹ́ni láti dá Ruga, àgọ́ Fulani sílẹ̀ -Iléeṣẹ́ aàrẹ 1 Agẹmo 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ko si tipatipa ninu ki ẹ fun Fulani ni ilẹ̀ ipagó ni ipinlẹ yin ni ọrọ ijọba Ko si tipa ninu ki o fi ilẹ̀ rẹ fun awọn Fulani darandaran -Ile iṣẹ aarẹ Ileeṣẹ aarẹ ṣalaye ohun ti Ruga, aagọ Fulani jẹ pe o wa fun kiko awọn darandaran jọ soju kan ni.
Ajọ naa tun ke si awọn orilẹ-ede lati fi ofin de lilo taba.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ibà: Ṣé a lè fòpin sí àìsàn yí bí?
Ọ̀rọ̀ ní sókí nípa oúnjẹ àárọ̀ tí wọ́n máa njẹ ní ìlú Gẹ̀ẹ́sì.
Koda, awọn eeyan naa pa ọkan lara awọn ọlọpaa to lọ ọ doola ṣọọṣi naa.
Ta ló lè sọ pé ọkàn òun mọ́,ati pé òun mọ́, òun kò ní ẹ̀ṣẹ̀?
ẹni tí ó ń dárí gbogbo ẹ̀ṣẹ̀ rẹ jì ọ́,tí ó ń wo gbogbo àrùn rẹ sàn;
O ni sugbọn, oun naa ti hu awọn iwa kan to buru ju agbere lọ.
Alabukun fun ni naijiria pẹlu aarẹ ati igbakeji to fi ootọ inu ṣe ọkunkundun.
Ó pẹ́ jù tí mo tí ń bá àwọn tí ó kórìíra alaafia gbé.
Lasiko yii lo sọ nipa ifojusọna ọjọ ibi rẹ lọdun 2013.
Ayẹwo naa yoo waye labẹ amojuto igbimọ oludanilẹkọ - Police Counselling and Support Unit (PCSU.
Ẹ kò gbọdọ̀ jẹ ẹran wọn, bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò gbọdọ̀ fọwọ́ kan òkú wọn, aláìmọ́ ni wọ́n.
Mamman Daura: Ojú òpó ayélujára ń gbóná lórí ìlàkàkà ọmọ Nàíjíríà láti mọ́ ipò tí ìlera rẹ̀ wà
Aarẹ Buhari ṣ'eleri ati pese iṣẹ fun ọpọlọpọ Tever Akase: Ipinlẹ Benue ko fa'gile eto isinku gbogboogbo Agbẹnusọ fun ileeṣe iṣiwa ati iṣilọ Naijiria, Sunday James, sọ fun ileeṣe iroyin Reuters wipe:  a gbọ wipe ọwọ tẹ awọn oṣiṣẹ wa meji kan ni papa ọkọ ofurufu to wa l'Eko nigba ti wọn gbiyanju lati ko awọn ọmọbirin kekeke kan jade lọna aitọ."
O si tun jẹ nkan itiju, ti ko ṣe e sọ fun ẹnikẹni.
Àwọn alufaa náà gba ohun tí ọba sọ, wọ́n sì gbà pé àwọn kò ní máa gba owó lọ́wọ́ àwọn eniyan mọ́, bẹ́ẹ̀ ni wọn kò ní tún ilé OLUWA ṣe fúnra wọn.
Nígbà tó yá, Hẹrọdu, baálẹ̀, gbọ́ nípa gbogbo nǹkan tí ó ṣẹlẹ̀, ó dààmú; nítorí àwọn kan ń sọ pé Johanu ni ó jí dìde kúrò ninu òkú.
Ira, ará ìlú Jairi náà jẹ́ ọ̀kan ninu àwọn alufaa Dafidi.
Ọbasanjọ ni Ajagunfẹhinti Olu Bajọwa lo gba oun la lọwọ awọn aditẹgbajọba naa, lọna ti Bajọwa fun ara rẹ ko mọ.
Dokita Nathalie MacDermott lati fasiti King's College London sọ pe ''kokoro aifoju ri yi lo n mu ki aisedeede ma waye nipa bi awọn ọmọ ogun ara se n doju ija kọ ti a si ma fa titobi agọ ara ju bi o ti se yẹ lọ.
Ohun to kọju sẹnikan, ẹyin lo kọ sẹlomiiran, nibi tawọn ti n sunkun pe Iwobi lọ, lawọn kan ti n yọ pe Iwobi kuro ni Arsenal.
 O ni:“O yẹ ki awọn ọdọ to n huwa buruku yii le mọ
Ṣugbọn bí ìwọ bá kìlọ̀ fún eniyan burúkú pé kí ó yipada kúrò ní ọ̀nà ibi rẹ̀, tí kò sì yipada, yóo kú nítorí ẹ̀ṣẹ̀ rẹ̀, ṣugbọn ìwọ ti gba ẹ̀mí ara tìrẹ là.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Champions League: Tottenham fìyà jẹ Man City 9 Ìgbé 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Ifẹsẹwọnsẹ UEFA Champions League laarin Tottenham ati Manchester City gbona girigiri koda ami ayo kan sodo ni Tottenham fi gbẹyẹ lọwọ manchester City.
Ìyàn náà pọ̀ tóbẹ́ẹ̀ tí Abramu níláti kó lọ sí Ijipti, láti máa gbé ibẹ̀ fún ìgbà díẹ̀.
Ṣugbọn nígbà tí àwọn Farisi gbọ́, wọ́n ní, “Ojú lásán kọ́ ni ọkunrin yìí fi ń lé ẹ̀mí èṣù jáde; agbára Beelisebulu, olórí àwọn ẹ̀mí èṣù ni ó ń lò.
Òun náà ni ó bí Elamu, Aṣuri, Apakiṣadi, Ludi, ati Aramu.
Ni afikun, oludasile ajo Links for Help Foundation to tun je aya minista fun oro ekun Niger-Delta, iyen, Abileko Mfawa Usani naa gba awon eniyan niyanju lati maa lo fun ayewo loorekoore ki alaafia le joba ni awujo wa.
Oríṣun àwòrán, @Rotimi Akeredolu Amọ wahala miran tun ti n rugbo bọ nipinlẹ naa bayii, eyi to lee mu ki ohun gbogbo pakasọ ninu isejọba gomina Akeredolu.
Ihuwasi awọn ọmọ ẹgbẹ alatako yii si fa ede aiyede laarin wọn ati awọn ọmọ ẹgbẹ oṣelu APC.
láti fi òpin sí aáwọ ̀ yìí , àwọn ará ìlú ní kí monigbùwà , ọmọ Ọbańta , jáde rẹ ̀ ti ṣe ní ọjọ ́ kìíní .
Ẹ wo òtítọ́ ọ̀rọ̀ nàá Ó pé ọdún mẹ́wàá tí Barrister kú; wo ǹkan tó yẹ láti mọ̀ nípa rẹ̀ gẹ́gẹ́ bíi olórin, tẹ̀wé-tẹ̀wé, akọ̀wé àti sọ́jà Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsèjẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọ Awọn mii to wa nib nini Damola Olatunji, Sola Kosoko, Odunlade Adekola, Femi Adebayo Salami, Muyiwa Ademola ati awọn to ku.
Ṣugbọn Saulu bẹ̀rẹ̀ sí da ìjọ rú.
O wa pe fun idasilẹ igbimọ apero kan laarin awọn ileegbimọ aṣofin orilẹede mejeeji lati lee ṣe agbedide igba ọtun fun ẹkun naa ati ilẹ Afirika lapapọ.
ti awọn ni ẹgbẹrun lọna igba-le-mẹfa ati mọkanle-ogoje (206,141) esi ibo.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ọ̀gá ọlọ́pàá pàṣẹ kí wọ́n ṣé ìwádìí ọlọ́pàá inú àwòrán 4+4 18 Èrèlè 2019 Oríṣun àwòrán, @kekeTony Àkọlé àwòrán, Ṣadede ni aworan awọn ọlọpaa ti wọn na ika 4+4 yi lu sita loju opo ayelujara Adele ọga ọlọpaa lorileede Naijiria Mohammed Adamu ti pasẹ ki ẹka to n ṣewadi nnkan aworan bẹrẹ iwaadi lori aworan awọn ọlọpaa mta kan ti wọn jọ bi ẹ ni naka soke lati ṣe atilẹyin fun ẹgbẹ oṣelu APC ati Aarẹ Buhari to n du ipo lẹẹkansi.
Ni igba ti idije naa wọ iṣeju mẹtalelọgbọn ni Quincy Promes sọ ayo kan wọle fun ikọ Ajax, ṣugbọn lẹyin isẹju die si ti wọn wo oju ẹrọ ni VAR ni rẹfiri wọgi le goolu ọhun.
A ń kọjá ààyè wa, à ń sẹ́ OLUWA,a sì ń yipada kúrò ní ọ̀nà Ọlọrun wa.
Bí ikú bá torí òfin tí ẹnìkan rú jọba lé wa lórí, àwọn tí ó ti gba ibukun lẹ́kùn-únrẹ́rẹ́, tí wọ́n sì gba ìdáláre lọ́fẹ̀ẹ́, yóo ṣe jù bẹ́ẹ̀ lọ: wọn óo jọba, wọn óo sì yè pẹlu àṣẹ ẹnìkan, Jesu Kristi.
O ni awọn gbọ pe awọn ara ilu rẹ ko sọrọ rẹ daada.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ministerial Screening: Aregbesola, Fashola àti Gbemi Saraki wí tẹnu wọn 29 Agẹmo 2019 Àkọlé àwòrán, Rauf Aregbesola Gomina ana nipinlẹ Osun Ọgbẹni Rauf arẹgbẹsola ni inu oun dun pe ẹni to gba ipo lẹyin oun ṣi n san gbese ti oun jẹ kalẹ.
Irun ori rẹ dabi ti Dada, eyi ti awọn oloyinbo n pe ni rough curls.
si ara ile naa fun wiwo, ni eyi ti awon to kọ ile naa kọ eti ikun si igbesẹ naa.
Ǹjẹ́ Oluwa tí à ń sọ̀rọ̀ rẹ̀ yìí ni Ẹ̀mí Mímọ́.
Mose sọ fún gbogbo ìjọ àwọn ọmọ Israẹli pé, “Ẹ gbọ́ ohun tí OLUWA pa láṣẹ, ó ní, 
ibo ti pari ni awon apa ibikan , ti awon osise eleto idibo si ti n ka awon ibo
Nítorí ìmí ẹ̀dùn di oúnjẹ fún mi,ìráhùn mi sì ń tú jáde bí omi.
Coronavirus in Ondo state: Gómìnà Akeredolu ti gbẹ́sẹ̀ kúrò lórí òfin tó de ìpéjọpọ̀ ìjọ́sìn ní ìpínlẹ̀ Ondo Oríṣun àwòrán, Twitter/Rotimi Akeredolu Iroyin to n tẹ wa lọwọ ni Gomina ipinlẹ Ondo, Rotimi Akeredolu ti gbẹsẹ kuro lori ofin to de ipejọpọ ileejọsin gbogbo ni ipinlẹ naa.
Bi ẹni ti ó mu àmu para àti ẹni lo egbò igi olóró bá wa ọkọ̀, àkóbá ni fún àwọn awakọ̀ yoku àti àwọn arin nà yoku.
Ó fi ìlú náà ṣe ẹ̀bùn igbeyawo fún ọmọ rẹ̀ obinrin, nígbà tí ó fẹ́ Solomoni ọba.
Oríṣun àwòrán, Others Iroyin gbe pe, iyawo Obasanjo ko si nibi eto isinku naa, tori o wa ni Ilẹ Gẹẹsi lasiko isinku iya rẹ, ti Baba Obasanjọ si ṣe oju rẹ ni ibi isinku ohun.
Ẹ tètè pè fún àjọ tó ní irònú pìwàdà kó tó pẹjù-NLC/TUC Ọkùnrin kan ti ṣekú pa Ọlọpàá mẹrin ní Faransé Ni itosi Kakau DajiVillage ni Ijọba Ibilẹ Chikun ni ile iwe naa wa.
Oríṣun àwòrán, @emmyskillful Àkọlé àwòrán, Arabinrin Chidozie sare ya fọto omi naa nigba to ri i pe ọjọ ti lọ lori rẹ Igba ti ikeji rẹ, Chiamaka wa bẹ ẹ wo nileewosan naa lo ṣakiyesi pe ọjọ ti lọ lori omi ti wọn n fa si ara ikeji rẹ lara.
Loju opo ajọ to n gbogun ti ajakalẹ arun ni Naijiria NCDC, ikede yi han lori Twitter Ni bayi awọn eeyan 43,537 ni arun naa ti fara kan lapapọ ni Naijiria Awọn to ti ri iwosan gba ti ara wọn si ti ya ti to 20,087 ti awọn to ti ba arun naa lọ si jẹ 883.
Iroyin tilẹ ti fi idi rẹ mulẹ pe ninu awọn to ti ni arun Ccoronavirus lagbaye bayii, ọmọ kekere jojolo ti wọn ṣẹṣẹ bi wa lara wọn.
Abrahamu gbin igi tamarisiki kan sí Beeriṣeba, ó sì ń sin OLUWA Ọlọrun ayérayé níbẹ̀.
Èmi OLUWA ni mò ń bi yín léèrè.
kí wọn sì máa gbọ́ràn sí àwọn iranṣẹ mi lẹ́nu, ati àwọn wolii mi tí mò ń rán sí wọn léraléra, bí wọn kò tilẹ̀ kà wọ́n sí, 
”Ó dá a lóhùn pé, “Bí o bá di ìdì irun meje tí ó wà lórí mi, mọ́ igi òfì, tí o sì dì í papọ̀, yóo rẹ̀ mi, n óo sì dàbí àwọn ọkunrin yòókù.
Abioye sọ pe bi adari awọn ti le oṣiṣẹ bi aadọrin lọ, ko ba ofin mu.
Nígbà tí ẹnikẹ́ni bá fẹ́ rú ẹbọ alaafia sí OLUWA láti san ẹ̀jẹ́, tabi fún ọrẹ àtinúwá; kì báà jẹ́ láti inú agbo mààlúù tabi láti inú agbo aguntan ni yóo ti mú ẹran ìrúbọ yìí, ó níláti jẹ́ pípé, kò gbọdọ̀ ní àbùkù kan lára, kí ẹbọ náà lè jẹ́ ìtẹ́wọ́gbà.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Kété tí wọ́n bá ti báa yín sùn tàn torí pé ẹ tóbi, ẹ gbà pé ìfẹ́ yẹn ti parí - Auntie Remi Ọlọ́yàn ńlá Erelu ni lai ṣe jagidijagan ni naa ni yoo fẹsẹ ara rẹ rin wa lati da ọpa aṣẹ naa pada.
" Amọ agba oselu kan ninu ẹgbẹ oselu APC, tii tun se oludamọran fun aarẹ lori ọrọ ile asofin, Hon Kawu Sumaila salaye pe igbimọ fidihẹ naa ko tiii tasẹ agẹrẹ rara.
Wọ́n bá ranṣẹ pe àwọn ọba Filistini, wọ́n wí fún wọn pé, “Ẹ gbé àpótí Ọlọrun Israẹli pada sí ibi tí ẹ ti gbé e wá, kí ó má baà pa àwa ati ìdílé wá run.
O ni igba ti wọn ba to da ẹjọ ileẹjọ giga naa nu ki ẹnikẹni to le yọ oun nipo, amọ o dabi ẹni pe ajọ amuṣẹya APC ko ka idajọ ileejọ giga to fi jẹ adele alaga si, ti wọn si kede ẹni ti o jẹ igbakeji alaga ẹgbẹ na ni Gusuu Naijiria.
Ó pàṣẹ pé kí wọ́n dá iná, kí ó gbóná ní ìlọ́po meje ju bíí tií máa ń gbóná tẹ́lẹ̀ lọ.
Mo dàbí agbè ọtí tí ó ti di àlòpatì,sibẹ, n kò gbàgbé ìlànà rẹ.
Osita Chidoka ni tiẹ beere lọwọ awọn to yẹyẹ Ekweremadu lati tọrọ aforiji lọwọ rẹ nitori ko mọwọ mẹsẹ nigba ikọ ''Operation Python Dance.
Obaseki ni ''nigba ti ogun gbona giri giri, emi ati iyawo mi ṣabẹwo si Daddy G.
Mo dá ọ nímọ̀ràn pé kí o ra wúrà tí wọ́n ti dà ninu iná lọ́wọ́ mi, kí o lè ní ọrọ̀, kí o ra aṣọ funfun kí o fi bora, kí ìtìjú ìhòòhò tí o wà má baà hàn, sì tún ra òògùn ojú, kí o fi sí ojú rẹ kí o lè ríran.
Bi o tilẹ jẹ pe ẹsẹ kan aye, ẹsẹ kan ọrun ni ọkunrin naa wa bayii, amọ ajọ LASEMa ti gbe digba-digba lọ sile iwosan fun itọju oju ẹsẹ.
Atẹjade naa ni labẹ ijọba yii, ẹmi eeyan ko niyi mọ, ọpọ igab si ni awọn ọdanran maa n kọlu awọn eeyan bo ṣe wu wọn."
Akure okada attack: Ọlọ́kadà tí àwọn afunrasí darandaran ṣá ní òun mọ ọ̀kan lára àwọn tó ṣa òun ní àdá
Daddys Showkey sí Naira Marley: Mi ò gbè lẹ́yìn Naira Mailey fún ìwà ìbàjẹ́
Nígbà tí wundia kan bá ń lọ siwaju ọba, lẹ́yìn tí ó ba ti ṣe gbogbo nǹkan tí ó yẹ, ó lè gba ohunkohun tí ó bá fẹ́ mú lọ láti ilé àwọn ayaba.
Oríṣun àwòrán, Twitter/@Aroyvinci Oríṣun àwòrán, @Aroyvinci Oríṣun àwòrán, @Aroyvinci Edo State: Ẹ̀kọ́ márùn ún tí a rí kọ́ nípa eré tíátà tó ń wáyé l'ágbo òṣèlú ìpínlẹ̀ Edo Oríṣun àwòrán, Others Àkọlé àwòrán, Edo state news: Godwin Obaseki ti darapọ̀ mọ́ ẹgbẹ́ òṣèlú PDP Bi eeyan ba ti n fi ọkan ba awuyewuye to n waye lagbo oselu nipinlẹ Edo lorilee-de Naijiria lẹnu ọjọ mẹta yi, yoo ri pe ara ọtọ ni oselu Naijiria, Ati pe ọrọ oṣelu yii ti gba ọgbọn ati suuru lasiko yii.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Mali Coup: Ẹgbẹ̀lẹ́gbẹ̀ èèyàn tú jáde ní Bamako láti yọ̀ pé wọ́n rẹ́yìn ààrẹ àná 23 Agẹmo 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 22 Ògún 2020 Oríṣun àwòrán, Getty Images Ẹgbẹlẹgbẹ awọn ọmọ orilẹede Mali lo tu sita lọjọ Ẹti, ni olu ilu ilẹ naa, Bamako, lati se ajọyọ iditẹ gbajọba tawọn ologun se.
Kò sí Ìrètí fún Moabu Mọ́.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Àjẹ́, eégún, kí ni wọn ò pè mí tán tórí Vitiligo lára mi' Aarẹ ajọ EFA ni oun kọwe fipo silẹ nitori iwa akin to yẹ ni lasiko yii ni Egypt.
Ọkunrin yìí mú iranṣẹ kan ati kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ bíi meji lọ́wọ́.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Trump picture: ọjọ́ tí Trump kí mi kú iṣẹ́ lórí 'twitter' ní inú mi dùn jù- Oyedele Ileeṣẹ ọmọ ogun Amẹrika, Pentagon, kede rẹ pe ibudo meji ni Irbil ati Al Asad ni ikọlu naa kan.
Dokita ni eyi tumọ si pé, o ti ń rònú láti gba ẹ̀mí àrà rẹ̀ ni, Ounjẹ kìí wù jẹ, kò fẹ́ ni ọ̀rẹ́ tàbí alábárò, Dókìtà Baka sọ pé, ọ̀rọ̀ náà ti kọjá bẹ́ẹ̀ nìyẹn.
Eliṣa bá rán Gehasi kí ó pe obinrin náà wá.
Makinde wa fi gbogbo ọwọ sọya pe oun yoo ri daju pe wọn se amusẹ eto isuna naa, o kere tan, ida aadọrin ninu ọgọrun, ki ọdun 2020 to buse, lọna ati ba aini awọn araalu pade.
” Ó bá bẹ Filipi pé kí ó gòkè wọ inú ọkọ̀, kí ó jókòó ti òun.
Ẹni tí ó bá fi ọ̀run búra, ó fi ìtẹ́ Ọlọrun ati Ọlọrun tí ó jókòó lórí ìtẹ́ náà búra pẹlu.
ti iwa imuninigbekun, ti o ti jẹ ki eto aabo fẹsẹ mulẹ ni ipinlẹ yii.
Joabu bá wólẹ̀, ó dojúbolẹ̀, ó sì dúpẹ́ lọ́wọ́ ọba, ó ní, “Kabiyesi, nisinsinyii ni èmi iranṣẹ rẹ mọ̀ pé mo ti bá ojurere rẹ pàdé, nítorí pé o ṣe ohun tí mo fẹ́.
A wá mọ̀ wàyí pé o mọ ohun gbogbo, kò ṣẹ̀ṣẹ̀ di ìgbà tí eniyan bá bi ọ́ kí o tó dáhùn ọ̀rọ̀.
Awakọ̀ tó gbé afurasí alárùn Covid-19 ní Kwara kò sí ní ibùdó ìyaraẹni sọ́tọ̀ Fásitì UNIOSUN ṣètò ìgbaniwọlé orí ayélujára fáwọn akẹ́kọ̀ọ́ tuntun fún ìgbà àkọ́kọ́ ní Nàìjíríà, Ohun tí a mọ̀ nípa rẹ̀ nìyí N4,200 la fẹ́ fi pèsè oúnjẹ fún akẹ́kọ̀ọ́ kọ̀ọ̀kan láti ìdílé tó lé ní mílíọ̀nù mẹ́ta yíká Nàìjíríà - ìjọba àpapọ̀.
Kí ló dé tí ò ń fi ẹ̀sùn kàn ánpé kò ní fèsì kankan sí ọ̀rọ̀ rẹ?
A n se koriya fun wọn lati tubọ maa du ipo asiwaju mu lorilẹede yii.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù David Oyedepo pe Biodun Fatoyinbo si ìsìn Shiloh, ọmọ Nìíjíríà fárígá 11 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Oríṣun àwòrán, @biodunfatoyinbo Lẹyin ọdun kan, awọn ọmọ orilẹ-ede Naijiria tun ti hu ọrọ ẹsun ifipabanilopọ ti wọn fikan gbajugbaja pasitọ ijọ COZA, Biodun Fatoyinbo, sita.
 katherine bí ọmọ méjì : henry barca ( 1886-1961 ) àti leo barca ( 1887-1924 ) .
O ni akoko ọdun Keresi jẹ akoko lati fi ifẹ han si awọn elomiran, o si ran awọn tirẹ leti lati fọwọ tọ ọkan awọn elomiran nipa ṣiṣe rere lasiko ọdun ọhun.
Láti ọjọ́ kinni ni kí ẹ ti mú gbogbo ìwúkàrà kúrò ninu ilé yín, nítorí pé bí ẹnikẹ́ni bá jẹ burẹdi tí ó ní ìwúkàrà ninu láti ọjọ́ kinni títí di ọjọ́ keje, a kò ní ka irú ẹni bẹ́ẹ̀ kún àwọn eniyan Israẹli mọ́.
Esther to ru igbeyawo oniwa ipa la ti bẹrẹ si n ṣiṣẹ pẹlu awọn akẹgbẹ rẹ to ti la iru nkan bẹ kọja ri.
Ṣugbọn àwọn ọ̀tá rẹ ni a óo parun.
“Bí ẹ bá rí òkú eniyan tí wọ́n pa sinu igbó, lórí ilẹ̀ tí OLUWA Ọlọrun yín fun yín, tí ẹ kò sì mọ ẹni tí ó pa á, 
🇺🇸🇬🇧 (@realmadriden) 3 April 2018“Mo ni lati so pe, e se pupo fun awon ololufe iko agbaboolu Juventus, ife ati atewo ti won fihan si mi je ohun iwuri ati iyalenu,”Ni bayii, Real madrid ti fi abala idi kan bosi ipele keji si asekagba idije ohun, leyin ami-ayo meta ti o labula ti won fi fagbahan Juventus.
” Agbẹnusọ Ọbasa ninu ọrọ ikini naa so pe,
Ẹsun ti wọn fi kan awọn ọmọ naa gẹgẹ bi ajọ ajafẹtọ ọmọniyan kan, Campaign group Human Rights Watch, ṣe sọ ni pe 'wọn ri olori orilẹede naa fin.
Àṣé bímo ti ń lọ nì, ṣe ni Olóhùn-un-dùùrù ń wo ìpákọ́ mi lọ, àfi ìgbà tí mo déedée gbọ́, tí ẹni náà pòṣé tí ó wí pé: Ẹ kò wo ìpàkọ́ rẹ̀.
Kunle Afolayan ati Aremu Afolayan Oríṣun àwòrán, Kunle Afolayan Àkọlé àwòrán, Kunle Afolayan Ko fibẹẹ kii n ṣe ija a n yọ ẹṣẹ tira ẹni tabi a n tabuku tabi sọko ọ̀rọ̀ sira ẹni loun to waye laarin tẹgbọn taburo ọmọ Afolayan, Kunle atu Aremu.
Ọdun 1974 ni iwe yii jade ni eyi to ṣafihan iwa ati iṣẹ awọn ọdọ Yoruba ni asiko naa ninu itan Naijiria.
O ni tita rira ti n lọ pada ni ẹnubode bayii.
bí Mose iranṣẹ OLUWA ti pàṣẹ fún àwọn ọmọ Israẹli ati gẹ́gẹ́ bí wọ́n ti kọ ọ́ sí inú ìwé òfin Mose pé, “Pẹpẹ tí wọ́n fi òkúta tí wọn kò gbẹ́ kọ́, tí ẹnikẹ́ni kò gbé ohun èlò irin sókè láti gbẹ́ òkúta rẹ̀.
Lẹta ibawi ati ikilọ lori aṣa ati iṣe ilẹ Yoruba ni lẹta naa.
Ajọ to n risi ọrọ ìsẹlẹ pajawiri ni Naijiria, NEMA, ni o ṣeeṣe ki iye awọn to faragba ninu isẹlẹ naa ti peleke sii pẹlu bi wọn ṣe kede ipinlẹ Niger, Kogi, Anambra ati Delta gẹgẹ bi ipinlẹ to faragba julo.
Lizzy Anjọrin: Ilé tuntun tí mo rà yìí jẹ́ oríire ìyá mi tó jáláìsí
Ṣé Ọlọrun ni, òun tí ó dá wọn láre?
”Shehu  tun tẹpẹlẹ mọ pe aare Buhari ko ni se ifẹ ẹnikankan
Omololu Olunloyo: Ọdọmọde Kọmiṣọnnà tí kò pé ẹni ọgbọ̀n ọdún tó tún jé Gómìnà oṣù mẹ́ta
Ti ọrọ fi ba ẹyin yọ ti Deji lọ sun gbogbo ẹbi mọle.
 Bakanaa, lo tun fi da awon akoroyin obinrin naa loju
Ọmọ ile Faranse ọhun ti sọ pe oun ko ni tọwọ bọwe adehun tuntun mii pẹlu ikọ Man United mọ lẹyin ti saa bọọlu yii ba ti pari.
Saulu rí i dájúdájú pé OLUWA wà pẹlu Dafidi ati pé Mikali ọmọ òun fẹ́ràn Dafidi.
8% Gbigba bọọlu si oju ile 4 2 Gba bọọlu 11 5 kọna 6 1 Ṣẹ sofin 22 19 Awọn agbabọọlu ti wọn yan Awọn ti wọn o kọkọ bẹrẹ Nigeria 16 Akpeyi 3 Collins 22 Omeruo 5 Troost-Ekong 20 Awaziem 18 Iwobi 7 Musa 4 Wilfred Ndidi 8 Peter Etebo 13 Chukwueze 9 Ighalo South Africa 22 Williams 14 Hlatshwayo 5 Mkhize 2 Mkhwanazi 18 Hlanti 8 Zungu 12 Mokotjo 15 Furman 19 Tau 9 Mothiba 23 Lorch Awọn iyipada 81 Musa                                                                  down Simon                                                              up 91 Iwobi                                                                  down Balogun                                                              up 58 Lorch                                                                  down Zwane                                                              up 86 Mothiba                                                                  down Veldwijk                                                              up Awọn ti wọn paarọ 17 Kalu 23 Uzoho 21 Osimhen 15 Simon 19 Ogu 11 Onyekuru 10 Mikel 1 Ezenwa 14 Paul Onuachu 2 Ola Aina 12 Shehu 6 Balogun 3 Maela 7 Maboe 20 Kekana 6 Mphahlele 16 Bvuma 11 Zwane 4 Cardoso 17 Vilakazi 10 Serero 13 Mabunda 21 Veldwijk 1 Keet Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Wọn a máa kó àwọn ọmọ wọn jáde bí agbo ẹran,àwọn ọmọ wọn a sì máa ṣe àríyá.
"Àjọ Lasema rí òkú èèyàn nínú èèrù iná àwọn ọkọ̀ agbépo tó jóná ní afárá Kara Ẹ wo òtítọ́ ọ̀rọ̀ nípa bí àwọn agbébọn ṣe wó ile ní iléèṣẹ́ aṣojú Nàìjíríà ní Ghana Wo àwọn oníròyìn méje tó kú láàrin ọjọ́ méje ní Nàìjíríà Lẹ́yìn tí mo gbé ayé mi yẹ̀wò, mo ríi pé asán layé - Toyin Abraham ""A ti ri fidio kan to tan kalẹ lori ayelujara nipa pe awọn oṣiṣẹ wa kan n gba owo ẹyin lọwọ awọn awakọ."
Ẹgbẹ́ awakọ̀ Ekiti fẹ́ pa ìjọba dà lẹ́yìn tí Fayẹmi di gómìnà
yii Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Kini 'Staircase' ni Yoruba?
Ìwọ onigbeeraga ati ọlọ́kàn líle yìí, nítorí kí o lè wo ogun ni o ṣe wá síbí.
Ọ̀rọ̀ ẹnu wọn ba ni lẹ́rù gidigidi; mo sì fẹ́ẹ́ sọ díẹ̀ nínú àyípadà tí ó dé bá wọn.
O ni àwón dokita tó ń tọju agbẹjọrọ naa wa ni agbegbe Ikoyi si Victoria Island ni Eko.
UEFA Champions League: Kí ló ṣẹlẹ̀ nígbà tí ikọ̀ Ilẹ̀ Gẹ̀ẹ́sì méjì wọ àṣekágbá?
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Osun Election 2018: Àwọn ọlọ́pàá fi tajútajú tú àwọn ọmọ ẹgbẹ́ PDP tó fẹ̀hónú hàn nítorí ìbò Ọṣun 5 Ọ̀wàrà 2018 Oríṣun àwòrán, Dele Momodu Àkọlé àwòrán, Sẹnetọ Dino Melaye wọ̀yá ìjà pẹ̀lú àwọn ọlọ́pàá níbi ìfẹ̀hònú hàn tí ẹgbẹ́ PDP ṣe Wahala nla bẹ silẹ l'ọjọ Ẹti lasiko ti ẹgbẹ́ alatako googi ni Naijiria, PDP, ṣe iwọde niluu Abuja.
Nínú ọ̀ṣẹ̀ tókọjá ni òkíkí kan pé ọ̀kan nínú àwọn ẹ̀ṣọ́ tó ń tẹ̀lé abẹnugan ilé ìgbìmọ̀ aṣòfin l'Abuja, Femi Gbajabiamila yìnbọn pa fẹ́dọ̀ kan ni Abuja.
Ẹ máa yọ̀, kí inú yín máa dùn, nítorí èrè yín pọ̀ ní ọ̀run.
Mahila, Tirisa, Hogila, Milika ati Noa fẹ́ ọkọ láàrin àwọn arakunrin baba wọn, gẹ́gẹ́ bí OLUWA ti pa á láṣẹ.
Gẹgẹ bi Lawan se sọ, “Ijoba
Ní ọdún díẹ̀ sẹ́yìn, ọ̀pọ̀lọpọ̀ iṣẹ́ ńláǹlà bíi kòtò ìdarí-omi ṣíṣàn fún Ìpèsè Iná Mànàmáná ti lé àwọn olùgbé jìnà ó sì ń ṣe àkóbá fún nnkan ìṣẹ̀dá odò náà.
Ṣé nítorí náà ni ẹ ṣe gbìmọ̀ burúkú sí mi, tí ẹnikẹ́ni ninu yín kò fi sọ fún mi pé ọmọ mi bá ọmọ Jese dá majẹmu.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Alaafin: Olori Aanu Adeyemi aya Oba Lamidi Adeyemi ti ìlú Oyo ní ohun tó bá kúkú wu ọmọ láti jẹ kìí.
Oríṣun àwòrán, Twitter/NigerianCAA Dokita Aliyu ṣalaye pe, awọn ko ba maa tun ayẹwo ṣe fun awọn arinrinajo yii, ka ni Naijiria ni eto iyasọtọ arinrinajo to munadoko ni.
Nígbà tí ó yá, Jakọbu dé sí Ṣekemu ní ilẹ̀ Kenaani ní alaafia, nígbà tí ó ń pada ti Padani-aramu bọ̀ ó pàgọ́ rẹ̀ siwaju ìlú náà.
Lọ́jọ́ náà gan-an ni mo ń retí ìwé láti ọ̀dọ̀ Ìfẹ́pàtàkì, nígbà tí àbúrò rẹ̀ tí ó rán sí mi sì dé ẹ̀wù búlùú ló wọ̀, ìgbà tí o tún fi ìwé lé mi lọ́wọ́, àpò ìwé ti wọ́n fi i sí nínú búlùú ni àwọ̀ rẹ̀, bẹ́ẹ̀ ni tẹ́lẹ̀tẹ́lẹ̀ àpò ìwé funfun ni ó máa ń lò fi kọ̀wé sí mi, àmì ìfẹ́ sì ni àwọ̀ búlùú jẹ́.
Igbagbọ ni ìdánilójú ohun tí à ń retí, ẹ̀rí tí ó dájú nípa àwọn ohun tí a kò rí.
O ni ko sẹni to ku ninu awn adari ẹgbẹ ẹni to si ku yii kii ṣe ọkan lara awọn adari ẹgbẹ PDP ni ipinlẹ Oyo.
Iroyin so pe, lara awon eyan pataki ti yoo ma kopa ninu ipade ohun ni: Aare ajo CAF, Ahmad Ahmad , akowe agba ajo FIFA, Fatima Samba Samoura, Aare ajo to n ri si boolu afesegba lorile-ede Netherland, Michael Van Praag ati Slavisa Ikokezia, ti o je aare tuntun ajo boolu afesegba lorile-ede Serbia.
Ìtàn tó wà nídi òwe ‘Sebótimọ Ẹlẹ́wà Sàpọ́n’ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Olusegun Obasanjo: Ọmú ìyá mi ti mo fi ń mùkọ ni kekere ló jẹ ki ń lókun Ìdìbò ilé ìgbìmọ̀ aṣojú-sòfin fún sáà 2015-2019 Ẹwẹ̀, lòdì si ìpínu ẹgbẹ́ òṣèlú APC ní sáà tó kọja ni àwọn ọmọ ẹgbẹ́ APC kan pàdí àpò pọ pẹlú ẹgbẹ́ alátako láti gbé Bukola Saraki wolé gẹ́gẹ́ bíi ààrẹ ilé ìgbìmọ̀ aṣofin àti Yakubu Dogara wolé gẹ́gẹ́ bi aggbẹ́nusọ ilé aṣojú-ṣòfin.
Sàká: Oun tí orí bá yàn fún ẹ̀dá ni kó ṣe Kí ló ń fa ikùn yíyọ láàárín àwọn ọlọ́pàá?
Adamu sọ pe dandan ni fun gbogbo awọn oludije, ati alatilẹyin wọn lati pa ofin orilẹ-ede Naijiria mọ, lai si rogbodiyan kankan.
Kí alufaa fi ọ̀kan rú ẹbọ ìmúkúrò ẹ̀ṣẹ̀, kí ó sì fi ekeji rú ẹbọ sísun, kí ó ṣe ètùtù fún un níwájú OLUWA nítorí ohun àìmọ́ tí ó jáde lára rẹ̀.
Lara awọn ẹsun ti wọn fi kan Naira Marley ni pe: 'Iwọ, Azeez Adeshina ti inagijẹ rẹ n jẹ Naira Marley, ati Yad Isril (ti o ti na papa bora), gbimọ pọ ni ọjọ kẹrindinlọgbọn oṣu kọkanla ọdun 2018 lati lo kaadi ti numba rẹ jẹ 5264711020433662 eyi ti kii ṣe tiyin lati fi gba nnkan lọna aitọ.
Eyi ni awọn ohun meje miran ti aarẹ Buhari sọrọ le lori ninu ọrọ rẹ.
Nígbà tí Jesu gbọ́ pé Lasaru ń ṣàìsàn, kò kúrò ní ibi tí ó wà fún ọjọ́ meji.
Eléyìí nì náà bá wa tan díẹ̀, ṣùgbọ́n ìtàn gígùn ni, nítorí bàbá rẹ̀ ni Àìsán-fẹ̀yìntì tí ó jẹ́ ọmọ Àìmọ̀kan tí ó ba ìyá mi, Òkùnkùn tan.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Awọn Fulani a ama da ẹranlati abule kan si imiran Ikọlu laarin awọn ọlọdẹ ẹya Dogon ati awọn Fulani darandaran a ma ṣaba waye lori lilo omi ati ile fun oko dida.
"O ni ""Mo si n kekọọ lati mọ bi mo ṣe le fi ifẹ han si ọ bo ṣe yẹ."
Osupa ni o ni idi ti oun ko fi ni iyawo si ile, amọ o parọwa si awọn ololufẹ rẹ lati fọkan balẹ.
Awọn olori ẹgbẹ oṣiṣẹ sẹ ipade pẹlu ijọba Obasanjo, ṣugbọn ijọba fi aake kọri pe igbesẹ ohun ṣe pataki lati mu atunṣe ba ẹka eto ifọpo ni Naijiria.
: Èyí làwọn ohun tí ọ̀pọ̀ ọmọ Nàìjíríà ń retí ṣùgbọ́n tí ààrẹ Buhari dákẹ́ sí Oríṣun àwòrán, Bashir ahmad Aarẹ Muhammadu Buhari gbe ọrọ rẹ kalẹ lori ibi to fẹ gbe ọrọ gba lori eto gbigbogun ti arun Coronavirus lorilẹede Naijiria.
Ṣé adájọ́ àgbà Onnoghen yóò farahàn nílé ẹjọ́?
Aare ati iyawo re de ibi idibo ni deede aago meje aarọ oni, niluu  Daura,  ti awon osise eleto idibo si se ayewo oruko won, ko ti di pe won dibo pelu kaadi idibo, leyin eyi ni won fun aare ni iwe pelebe ti yoo tẹka si lati dibo fun ẹni ti o fẹ fun ipo gomina ati ile igbimo asofin ti ipinle ti ọdun yii.
 Ọ ̀ pọ ̀ lọpọ ̀ àwọn báyìí ni a kó lásìkò ogun tàbí kí wọn wá fúnra wọn nígbà tí wọn ń sá àsálà fún ẹ ̀ mí wọn , tí wọn sì ǹ wá ibi isádi .
Mo ti fi yín ṣe oúnjẹ fún àwọn ẹranko ati àwọn ẹyẹ.
Wọ́n jókòó ní ilẹ̀ẹ́lẹ̀ pẹlu rẹ̀ fún ọjọ́ meje, tọ̀sán-tòru, láìsọ nǹkankan, nítorí pé wọ́n rí i bí ìrora náà ti pọ̀ tó.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Omonhinmin sọ pé, bótilẹ̀ jẹ́ pe, kò tíi sí ìwádìí ìjìnlẹ̀ lórí bóyá, ọti ń fa jẹjẹrẹ Kàkà bẹ́ẹ̀ ó ni o sàn fún àwọn aláboyun láti jìnà sí ọtí mímu nítori pé, ọti ni súgà tó pọ̀.
Ninu atẹjade ti agbẹnusọ rẹ fi sita, o ni ko si ifarahan awọn ami teeyan le fi mọ pe o ni aarun ọhun bẹẹ si ni o n tẹle gbogbo ofin Covid-19.
org lati beere fun ki awọn ẹsọ alaabo o mu ẹkun naa laaye, lai pa.
Lero tiẹ, @lovedaisy04 naa ni ko yẹ bi fasiti babcock se le akẹkọbinrin naa niwọn igba ti kii se inu ọgba ileewe ọhun ni wọn ti n ba ara wọn lo pọ, obinrin naa si ni ẹts si ibalopọ to ba wu nitori kii se ọmọde rara.
Ò ń bukun iṣẹ́ ọwọ́ rẹ̀, o sì sọ ohun ìní rẹ̀ di pupọ.
Henrikh Mkhitaryan ati Aaron Ramsey ni wọn gba bọọlu si'nu awọn ti wọn si jẹ ki ẹgbẹ agbabọọlu Wenger jẹ ẹgbẹ to nireti ati de ipele to sunmọ eyi to kangun si aṣekagba idije Europa.
Kò pẹ́ púpọ̀ tí a rí Wèrédìran tí o ń jó bọ̀.
2) Abacha ṣe iyipada opopona lati fi gbẹsan ohun ti Amẹrika ṣe Lasiko ijọba ologun bakan naa a ri i ka ninu itan pe olori orile-ede nigba naa Ọgagun Sani Abacha ni ki wọn yi orukọ opopona kan niwaju ileeṣẹ orile-ede Amẹrika ni Naijiria pada.
Etebo Ogenekaro, Victor Osimhen ati Henry Onyekuru.
Iyaafin Ajimọbi tu kẹkẹ ọrọ yii sita lasiko to fi n ba ọmọ rẹ obinrin sọrọ lori fidio kan to n ja ranyinranyin bayii lori ayelujara.
Nkan to ṣe koko ni ipa to ni lara mi.
Esi ree ti agbẹnusọ Gomina ipinlẹ Ondo, Olusegun Ajiboye fọ nigba ti ileesẹ BBC Yoruba beere lọwọ rẹ pe, se lootọ ni arabinrin Betty Anyanwu iyawo Gomina Akeredolu ti lugbadi Covid-19.
” Ìmọ̀ràn yìí dùn mọ́ ọba ninu, ó sì ṣe bẹ́ẹ̀.
Ooloogbe naa se papoda ni lọsan ana, ọjọ satide ogunjọ, oṣu kẹfa ọdun yii.
Bá àwọn ẹlẹ́ṣẹ̀ wí ní gbangba, kí ẹ̀rù lè ba àwọn yòókù.
"31 Ọ̀pẹ̀̀ 2018 Oríṣun àwòrán, @adelovecom Àkọlé àwòrán, Ọba Benin ni atunbọtan oṣo ṣiṣẹ kii dara ""Awọn ọdọ ti wọn n lepa owo gbigbona nipa pipa eeyan tabi jiji awọtẹlẹ awọn obinrin ko ni ṣai foju wina atunbọtan gbigbona."
Ni ọdun meelo kan sẹyin lo sọ iran wipe awọn eekan oloṣelu kan bi Bola Tinubu yoo ku, ṣugbọn wọn ṣi wa laye bayii.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Nikesuliat: Ọ̀dọ́mọdébìnrin akéwì tó n fi ẹ̀ṣà kìlọ̀ ìwá lásìkò yìí Iroyin ifipabanilopọ ti lọ soke si ni Naijiria lẹ́nu ọjọ mẹta yìí.
Lọdun 2003 ni ọwọ tẹ Khalid ni Pakistan ki wọn to wa gbe e lọ si Guantanamo ni Cuba nibi ti wọn ti fẹsun naa kan an.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Igboho Ultimatum to Fulani: Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní gbèdéke ọjọ́ méje láti fi Ibarapa sílẹ̀, àwọn Fulani ní ìwà màdàrú ló ń bá kiri 17 Sẹ́rẹ́ 2021, 15:23 WAT Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn wákàtí 3 sẹ́yìn Oríṣun àwòrán, Snapshot Ni ọjọ Satide, ọjọ Kẹrindinlogun, oṣu kinni, ọdun 2021 ni iroyin jade lori ayelujara pe eekan ajafẹtọ Yoruba kan, Oloye Sunday Adeniyi ti ọpọ mọ si Sunday Igboho fun awọn Fulani ni gbedeke ọjọ meje lati fi ilẹ Yoruba silẹ.
Awọn eniyan 16, 600 ni wọn ni wọn ti di oloogbe bayii.
Ó ní OLUWA ló sọ bẹ́ẹ̀.
Yatọ si eyi, Sanusi ma n sọrọ tako bi awọn eeyan Oke Ọya ṣe n bimọ bẹrẹ, leyi to ni o n fa iṣẹ ati iya lagbegbe ọhun, ti ko si dun mọ awọn eeyan naa ninu.
Òtítọ́ ti ṣubú ní gbangba ìdájọ́,ìdúróṣinṣin kò rọ́nà wọlé.
Nítorí náà bí o bá fẹ́ mú ọrẹ wá sórí pẹpẹ ìrúbọ, tí o wá ranti pé arakunrin rẹ ní ọ sinu, 
"Arabinrin Jewel fi ọrọ sita loju opo instgram rẹ bii ewi pe "" aye wa ṣe ri firi to da bi eyi ti ko pẹ rara koda bi a ba ṣi wa laaye."
World Economic Forum: A ò kópa mọ nínú àpérò ètò ọrọ ajé ní Cape town- Ìjọba Nàìjíríà
Ìríra ni lójú Olódùmarè, wí pé kí igi ńlá gbàgbé gbòǹgbò, kí ọmọbìnrin rí ilé ọkọ kí ó gbàgbé ìbẹ̀rẹ̀ òun.
isà òkú ya ẹnu sílẹ̀ dè mí,ewu ikú sì dojú kọ mí.
Mo kọ̀ láti kópa nínú ìpàdé orí ayélujára Nàìjíríà yìí- Falz Cardi B ṣàlàyé ohun tó gbé fọ́tò ìhòhò rẹ̀ d'órí ayélujára Instagram Ẹ ṣọ́ra ní òpópónà AIT, ọkọ̀ agbépo kan ti yí dánù lọ́nà agbègbè Alagbado Àjẹ́ àti Aṣẹ́wó ní ìyá Rainbow - Òjòpagogo Ìjọba Nàìjíríà ti gbà láti san N30b owó àjẹmọ́nú fún ASUU Ajínigbé tú ìyá àti ọmọ ọdún mẹ́ta sílẹ̀ lẹ́yìn tí wọ́n gba ₦1.
Wo àwọn olórí orílẹ́-èdè tó sọ̀rọ̀ fẹnu kọ pẹ̀lú ẹ̀rọ gbohùngbohùn Ìkọlùkọgbà ńrúgbó bọ̀ pẹ̀lú ènìyàn 200m Àjọ DSS tọrọ àforíjìn lórí ìwà ti wọ́n hù nílé ẹjọ Àjọ ọ̀tẹlẹ̀múyẹ́ ń se ojúṣe wọn lórí ọ̀rọ̀ Soworẹ ní-Ilé iṣẹ́ ààrẹ Dorcas sọrọ lori bi aisan yii ṣe gba oju lọwọ oun ti oun ko fi le ṣiṣẹ olukọ mọ.
O fi idunnu re han lori bi awon oludokowo se jade lopo yanturu lati kopa nibi apapo ipade apero awon olokowo orile-ede Naijiria ati orile-ede Tunisia to waye nilu Abuja lojo-Aje.
Ẹ gbé gbogbo ihamọra Ọlọrun wọ̀, kí ẹ lè dúró láti dojú kọ èṣù pẹlu ọgbọ́n àrékérekè rẹ̀.
pé ní orúkọ Jesu ni gbogbo ẹ̀dá yóo máa wólẹ̀, lọ́run ati láyé, ati nísàlẹ̀ ilẹ̀; 
"$2,600 àǹtí mi ni mo jí láti lọ sókè òkun àmọ́ àbámọ̀ ló gbẹ̀yìn ọ̀rọ̀ mi Yahaya Bello, Gomina ìpínlẹ̀ Kogi kéde Onoja ní ìgbákejì tuntun ""Olóṣèlú ní Kogi àti Bayelsa ti ń pín Irẹ̀sì, iyọ̀ lásìkò ìpolongo ìbò, INEC, ẹ mú wọn"" Dino Melaye tó ń díje dupò gómínà Kogi ni irọ́ ni pé òun ti ju awà sílẹ̀ Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!"
Ewé iran/ẹ̀kọ ló wọ́pọ lati fi pọ́n ẹ̀kọ, ọ̀ọ̀lẹ̀/mọ́in-mọ́in, iyán, àmàlà, irẹsi sisè àti bẹ̃bẹ lọ.
13) Hakeem Lawal -Ò yege Awọn eeyan to yege yii, ti yoo kopa ninu idibo abẹnu ẹgbẹ oselu APC, to n bọ lọjọ Aiku ni yoo maa figa gbaga, ẹni ti odu rẹ ba si kun ju ninu wọn, ni yoo soju ipinlẹ rẹ pẹlu awọn oludije yoku latinu awọn ẹgbẹ oselu alatako lọdun 2019.
Ẹnu ya Adéforítì púpọ̀, ṣùgbọ́n Èṣù wí fún un kí ó maṣe jẹ kí ẹnu ya oun kí o má sì ṣe káàánú rẹ̀, Èṣù ni, o kò mọ̀ bí ọmọ aráyé ti le tó ni, ẹni tí ìwọ́ ń wo yìí ti yọ ojú ẹni mẹ́fà lóde ayé, ó ti pàṣẹ kí wọ́n yọ èékán ọmọ ìka ṣẹ̀ mẹ́wẹ́ẹ̀wá ẹni mẹ́fà láàyè láìjẹ́ pé wọ́n ti kú, kò ha yẹ kí òun náà jìyà díẹ̀ ni?
 a máa ń ri abacavir rà pẹ ̀ lú àwọn oògùn kòkòrò apa sójà ara míràn bíi abacavir / lamivudine / zidovudine , abacavir / dolutegravir / lamivudine , and abacavir / lamivudine .
Huri ni ó bí Uri, Uri sì bí Besaleli.
O ni fidio ibugbamu ado oloro ti awọn eeyan kan n gbe kiri lori itakun ayelujara kii ṣe ti ileeṣẹ aṣoju ilẹ South Africa bi ko ṣe ti ibugbamu to waye ni ibudo Emab Plaza, nitosi Banex, nilu Abuja loṣu kẹfa ọdun 2014.
ile-ise olopaa, ati oga agba ile-ise omo ogun tabi ki o je asoju re.
Òun kò ní fi agbára lo Ṣiṣaki láti rọ̀jò ibinu òun sórí Jerusalẹmu.
Wọn ni o lu awọn to ma n ṣẹ owo ilẹ okeere to le ni ogoji ni jibiti, lẹyin to parọ fun wọn pe oun ni owo lati ṣe laarin ọdun 2015 si 2017.
May 29 Inauguration: Minista mẹ́fà tí kò tẹ́ àwọ ènìyàn lọ́rùn
Ebenezer Obey fi ìkéde síta pé òun n gbèèrò láti gbé ìyàwó tuntun,
Ṣugbọn ẹnikẹ́ni tí ó bá mọ́, tí kò lọ sí ìrìn àjò, ṣugbọn tí kò ṣe Àjọ̀dún Ìrékọjá ni a ó yọ kúrò láàrin àwọn eniyan mi, nítorí kò mú ọrẹ ẹbọ wá fún OLUWA ní àkókò rẹ̀.
Ṣugbọn n óo jẹ yín níyà fún gbogbo ìwà yín níwọ̀n ìgbà tí ohun ìríra ṣì wà láàrin yín.
Má ṣe kọ etí ikun sí ọrọ àwọn aláṣẹ, yala tí eleto Hajj lati orílè-èdè rẹ ni tabi ti ilẹ Sáúdí.
Olori awọn dokita to ṣe iṣẹ abẹ naa, Emmanuel Ameh sọ fun BBC pẹ Oṣu Kọkanla, ọdun to kọja ni wọn ti bẹrẹ iṣẹ abẹ lati pin Goodness ati Mercy Martins ni aya ati ikun oke.
Noa nìkan ni kò kú ati àwọn tí wọ́n jọ wà ninu ọkọ̀ pẹlu rẹ̀.
Ninu Òfin wa Mose pàṣẹ pé kí á sọ irú àwọn bẹ́ẹ̀ ní òkúta pa.
 Fun idi eyi, bi  a ba ri iru ayo bayii, a ri pe rogbodiyan tun ti dinku de bi ti o lapere.
Oríṣun àwòrán, pengassanhq ''Bi wọn ba kesi wa laarin wakati mẹrinlelogun pe awọn ti ṣetan lati gbe wa pada si ori eto ti wọn ti n sanwo wa tẹlẹ, a ko ni kọ lati pada si ẹnu iṣẹ.
Oyo Algon: Àlááfíà Ọyọ yóò dàrú, tí Buhari kò bá yanjú àáwọ̀ yìí
N óo dáná sun igbó yín,yóo sì jó gbogbo ohun tí ó wà ní agbègbè yín ní àjórun.
"Issa ni: ""Otitọ to wa ninu ọrọ yii ni pe awọn obinrin wa ko mọ nkankan nipa ifẹ otitọ rara."
Elisha Abbo: Ilé ẹjọ́ sún ẹjọ́ Sẹ́nétọ̀ tó lu obìnrin síwájú
Oriṣiriṣi nkan bi ki wọn o maa fi ọwọ gba nidi ati ọmu ni oju rẹ ri.
Sibẹsibẹ olódodo kò fi ọ̀nà rẹ̀ sílẹ̀,ẹni tí ọwọ́ rẹ̀ mọ́ sì ń lágbára sí i.
Sẹ́nátọ̀ Elisha Abbo kési Naira Marley láti ṣe àríyá fún Leycon tó borí ní BB Naija Lẹ́yìn ọgọ́ta ọdún tí Nàíjíríà gba òmìnira, wo ipò tí àṣà àti èdè Yorùbá wà Ijoko ile naa, ti abẹnugan ile Femi Gbajabiamila dari, salaye pe, o ṣe pataki ki ijọba apapọ tẹle adehun ti awọn ati ẹgbẹ oṣiṣẹ se ti wọn fi wọgile ipinu wọn lati bẹrẹ iyanṣẹlodi to yẹ ko bẹrẹ lọjọ aje.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Carlo Ancelotti ti fi igba kan jẹ olukọni Chelsea, ko da o gba ife ẹyẹ liigi naa pẹlu wọn Lọrọ Everton ba di ajẹkun iya ni o jẹ.
"O ni ""Ipinlẹ Eko ni pupọ ninu awọn iṣoro ti a doju kọ ti n waye."
Titi di oṣu kẹjọ, gẹgẹ bii Kọmiṣọna fun ajọ INEC nipinlẹ Ọyọ, Mutiu Agboke ṣe sọ laipẹ yii, lo ni o le ni ẹgbẹrun lọna ẹẹdẹgbẹrin awọn kaadi idibo to ṣi wa ni ikawọ ajọ naa ti awọn to nii ko tii wa gba.
Oríṣun àwòrán, Others Ọba Samuel Adedapọ Ademola keji, Alake tilẹ Ẹgba: Ọba Samuel Adedapọ Ademola keji, Alake tilẹ Ẹgba ni ọba keji ta a ka pe wọn le lori itẹ nilẹ Yoruba, bi o tilẹ jẹ pe ọba ọlaju, olokoowo nla ati ọmọwe ni Ọdun 1920 ni ọba Ademola jọba, to si lo ọdun mejilelogoji lori oye amọ wọn le kuro fun ọdun meji laarin ọdun 1948 si 1950 nitori ija igboro ati iwọde kan ti awọn obinrin bẹrẹ rẹ lati tako ọba naa.
Mo rí ogunlọgọ̀ àdó àti àákàrè igba tí ó tó mọ́ra láti ìbàdí títí o fi dé ẹsẹ̀ koko, mo sì rí eyín rẹ̀ tí ó dàbí eyín kìnìhún, bẹ́ẹ̀ ni iwin burúkú yìí ń wo ọ̀tún tí o ń wo òsì tí ó ń wá wa kiri, nítorí ó ti gbóòórùn wa.
Ẹnikẹ́ni tí ó bá fẹ́ jẹ́ aṣaaju yóo ṣe ẹrú fun yín.
N óo dójúlé wọn láti ṣe wọ́n ní ibi, n kò ní ṣe wọ́n ní rere.
Nwa Anam sọ loju opo Twitter rẹ pe owo oju opopna yii yoo mu nnkan le sii fun awọn ọmọ orilẹ-ede yii ni.
“Dán àwa iranṣẹ rẹ wò fún ọjọ́ mẹ́wàá, máa fún wa ní ẹ̀wà jẹ, kí o sì máa fún wa ní omi lásán mu.
láti Ekironi títí dé etí òkun Mẹditarenia, ati gbogbo àwọn ìlú tí wọ́n wà lẹ́bàá Aṣidodu pẹlu àwọn ìletò wọn.
Ẹ ti fi ojú rí gbogbo iṣẹ́ ìyanu tí OLUWA ṣe.
Ope pataki lowo ami-ayo kan soso ti atamatase iko agbaboolu Chelsea, Eden Hazard gba wole niseju méjìlélógún saa akoko ifigagbaga ohun, pelu boolu agbesile gba(Penalty kick).
Eyi fẹrẹ to ilọpo meji awọn to ni iye ami yii ninu idanwo ọdun 2018, eleyi to jẹ ida aadọta o din diẹ, 49.
Bí Jesu pẹlu àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ ati ogunlọ́gọ̀ eniyan ti ń jáde kúrò ní Jẹriko, Batimiu afọ́jú, ọmọ Timiu, jókòó lẹ́bàá ọ̀nà, ó ń ṣagbe.
wọ́n á ní olúwarẹ̀ ní àrùn Kògbóògù, tí wọ́n npè ní AIDS.
Dafidi pe gbogbo àwọn àgbààgbà Israẹli, àwọn alufaa ati àwọn Lefi jọ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Emir Kano: Ganduje fẹ̀sùn ìkọ́wójẹ kan Emir Sanusi 6 Òkùdu 2019 Oríṣun àwòrán, @Lamidoofficial Àkọlé àwòrán, Ajọ tó ń gbógun ti ìwá àjẹbánu àti gbigbọ́ ẹ̀sun ara ìlú ní ìpínlẹ̀ Kano ló fẹ̀sún kan Emir tí wọn si dábàá pé kí Emir lo rọ́kun nílé.
Deede aago mẹfa irọlẹ ni awọn agbegbọn naa da ibọn bo ọkọ ayọkẹlẹ Lexus ti wọn wa ninu rẹ nigba ti wọn de ibi ti oju ọna ko ti dara.
Nǹkan burúkú tí ó kanpá ni, ó kún fún oró tí ó lè paniyan kíákíá.
Iroyin n lọ lawọn ikanni iroyin ori ayelujara kan pe ẹgbẹrun lsna ọgọrun ni aaye iṣẹ to ṣi silẹ ni ajọ naa ti wọn si n polongo eeyan fun.
Oriṣiriṣi ere idaraya lo yẹ ko waye Ounjẹ loriṣiriṣi.
'Ologun ko lee koju Boko Haram' 'A ti pa Boko Haram run patapata' Ile ẹjọ ju ọmọ ẹgbẹ Boko Haram ogun s'ẹwọn Ìjọba Germany mú afurasi ọmọ Boko Haram Ta ni Abubakar Shekau ti Boko Haram?
Idi ni pe igbakeji gomina, Agboola Ajayi ti kede pe ki Akeredolu tete fa akoso ipinlẹ naa le oun lọwọ laarin ọjọ mọkanlelogun nibayii to to wa ni iyasọtọ nitori arun Coronavirus to lugbadi rẹ.
Ìdá mẹwaa ati diẹ ni awọn alawọ funfun to n ṣiṣẹ - ṣugbọn wọn n gba to ilọpo mẹta owo ti awọn ọmọ South Africa to jẹ alawọ dudu, to ko ìdá mẹta ninu mẹẹrin laarin awọn oṣiṣẹ.
Ninu ọrọ to kọ si ori ayelujara Twitter, Buhari bẹ awọn ọmọ Naijiria lati mu suuru, bo tilẹ jẹ pe wọn ni ẹtọ lati ṣe iwọde lori ohun ti ko ba dun mọ wọn ninu.
Ohun tí kò tilẹ̀ jẹ́ kí a lọ sí ilé ọba wọn kò ju èyí pe níwọ̀n ìgbà tí ìlú ti burú tó bí a ti báa yìí a kò ní èrò gíga kan nípa ọba ìbẹ̀ rárá, nítorí kò sí ọba pàtàkì kan tí ó lè fi oju ara rẹ̀ sílẹ̀ títí ìlú fi máa burú tó bí a ti báa nì.
“Kò sí ẹni tíí fi ìrépé asọ titun tí kò ì tíì wọ omi rí lẹ ògbólógbòó ẹ̀wù.
Bẹ́ẹ̀ ni wọ́n ṣe fún baba wọn ní ọtí mu ní alẹ́ ọjọ́ náà, èyí àkọ́bí wọlé lọ, ó sì mú kí baba wọ́n bá òun lòpọ̀, baba wọn kò mọ ìgbà tí ó sùn ti òun, bẹ́ẹ̀ ni kò mọ ìgbà tí ó dìde.
Nítorí náà, ẹ má bẹ̀rù, n óo máa tọ́jú ẹ̀yin ati àwọn ọmọ yín.
Nígbà tí ó gbé ẹnu lé ojú àdá mímú àdá bẹ̀rẹ̀ sí gé e òun náà sì bẹ̀rẹ̀ sí sálọ́ sí iwájú, àdá ń la inú rẹ̀ lọ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Teach your children Yoruba: Wo àwọn òyìnbó tó ń kẹ́kọ̀ọ́ èdè Yorùbá ní Michigan, America Bi wọn si ṣe n ṣe ẹhonu kọrin kiri aba kọọkan, ni wọn tun n ṣe ikilọ fawọn agbẹ akẹẹgbẹ wọn pe, wọn ko gbọdọ san owo ori kankan fun ijọba.
Lodun 2010 ni won gbe iwe lori itan aye Gilbert jade ti won pe ni: All My Flashbacks.
O ni ohun ti ijọba ipinlẹ Ọyọ n gbero lati ṣe nigba naa ni lati san owo fun awọn alaga kansu naa ki wọn si maa lọ eleyi ti wọn ni awọn kọ jalẹ nitori loju awọn bii igba ti awọn gba owo iṣẹ ti awọn ko ṣe ni eyi, iwa jẹgudujẹra si ni.
 Ṣadé rọ ́ pò roz abrams , tí ó kúrò nílé iṣẹ ́ yìí ní ọdún 2003 láti gbaṣẹ ́ ní agogo márùún sí mọ ́ kànĺa alẹ ́ ( 5 and 11 p.
O ni o y ki Naijiria naa ni awọn ọjọ isinmi ti ẹ.
Buhari to rọ awọn ẹlẹsin Musulumi lati gbadura ni ile, ni oun gbe igbeṣẹ yii lati dena itankalẹ arun Coronavirus.
Gbogbo òfin rẹ ló dájú;ràn mí lọ́wọ́, nítorí wọ́n ń fi ìwà èké ṣe inúnibíni mi.
Oríṣun àwòrán, Others Sugbọn ori re, ti i gbe alawore ko ni, lo mu ki awọn eeyan tete fi isẹlẹ naa to awọn ọlọpaa SARS leti, ti awọn onitọun si gba ya wọn, ti ọwọ si tẹ wọn.
Dasuki, olugbani-nimoran lori eto aabo fun aare ana Goodluck Jonathan lo ti koko farahan nile ejo ninu osu kọ̀kànlá lodun 2015.
Bí ó bá sì tún fẹ́, ó lè mú lára amọ̀ kan náà kí ó fi mọ ìkòkò mìíràn fún èèlò lásán.
Lọdun 1980, ijọba rẹ pari kikọ ibudo ifọpo Kaduna refinery, o si bẹrẹ iṣẹ lọdun naa.
’ rèé Ìtàn Àrọ̀gìdìgbà jẹ́ kí ń rò pé bàbá mi yan Yemọ̀ja ní àlè - Ọmọ Fagunwa Irú èpè wo ni Aláàfin Aolẹ ṣẹ́ fún ìran Yorùbá?
Macron pade aare Buhari lojo Aje(Monday), lasiko asekagba ipade apero ajo isokan AU ti o waye nilu Nouakchott,Bakan naa, leyin ipade ohun, aare Macron yoo lo sabewo si ile igbafe Afrika Shrine, ti o wa nipinle Eko, eleyii ti oloogbe Fela Anikulapo Kuti da sile.
"Oríṣun àwòrán, Seyi Makinde Oríṣun àwòrán, Seyi Makinde ""Ni gbogbo Ọjọru ni iya mi fi pe aago mi, ṣugbọn mo ro pe ko ni itumọ ki n gbe ipe naa nitori mo wa ni irinajo ati wi pe l'opin ọsẹ ni ajọ ṣe ileri wi pe a o rira, ṣugbọn l'ọjọbọ ni iya mi jade laye""."
N kò ní jẹ́ kí o ṣe àgbèrè mọ́, bẹ́ẹ̀ ni n kò ní jẹ́ kí o fún àwọn olólùfẹ́ rẹ ní ẹ̀bùn mọ́.
Kinniun, alágbára jùlọ láàrin àwọn ẹranko,kì í sì í sá fún ẹnikẹ́ni.
Orilẹ ede yii ni o ṣe igbalejo iṣafihan aṣa ati ohun iṣẹnbaye, Ouagadougou ti o si gba ami ẹyẹ julọ ni ilẹ adulawọ.
Jesu ati àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ lọ sí ibìkan tí ó ń jẹ́ Gẹtisemani.
Ṣugbọn Peteru sọ fún un pé, “Ìwọ ati owó rẹ yóo ṣègbé!
Awọnamugbalẹgbẹ gomina ṣalaye fun BBC News pe gomina Oyetọla ati igbakeji rẹ ye iṣẹlẹ naa laifarapa ṣugbọn akọroyin kan atawọn amugbalẹgbẹ gomina naa kan fara ṣeṣe.
I ba jẹ pe wọn le ṣe iṣẹ abẹ naa lasiko naa, ọrọ i ba dun.
“O óo ti sọ irú ọ̀rọ̀ wọnyi pẹ́ tó,tí ọ̀rọ̀ ẹnu rẹ yóo sì dàbí afẹ́fẹ́ líle?
Wọ́n sin ín sinu ibojì àwọn baba rẹ̀ ní ìlú Dafidi.
Èémí mi yóo jó yín run bí iná.
Wọn kò bèèrè pé, Níbo ni OLUWA wà,ẹni tí ó kó wa jáde láti ilẹ̀ Ijipti,tí ó sìn wá la aṣálẹ̀ já,ilẹ̀ aṣálẹ̀ tí ó kún fún ọ̀gbun,ilẹ̀ ọ̀dá ati òkùnkùn biribiri,ilẹ̀ tí eniyan kìí là kọjá,tí ẹnikẹ́ni kì í gbé?
Yahaya Bello ni alága ìgbìmọ ìdìbò abẹ́lé gómìnà ìpińlẹ̀ Ondo Nigeria Police recruitment 2020: Bí ó bá fẹ́ dara pọ̀ mọ́ ìṣẹ́ ọlọ́pàá, forúkọ́ sílẹ̀ níbí Ṣe wọn le fi Bitcoin ra nkan?
ti rọ awọn oloṣelu ati awọn olori ilu lati tubọ moju to igbesi aye irọrun
Moshood rọ awọn agbofinro naa lati kilọ fun awọn oloṣelu lati tọwọ ọmọ wọn basọ pẹlu ọrọ to le da wahala silẹ laarin ilu.
Benin: UK ṣetán láti dá Adìyẹ 'Àkùkọ' Nàíjìrìa ti wọ́n gbé padà
Muhammadu Buhari: Amòfin Adebayo wá kábàámọ̀ pé ọ̀pọ̀ nǹkan ni wọ́n ń tọwọ́ òṣèlú bọ
"Mo fura pé ẹ fẹ́ da Nàíjíríà rú, ń kò ṣe ìwọ́de mọ́ - Segalink, agbátẹrù ìwọ́de yọwọ́ ""Buhari, ìwọ́de yóò yíwọ́, tó ba jẹ́ ki ológun bẹ̀rẹ̀ ‘Operation Crocodile Smile’ "" 2015 ni mo ti ń kígbe pé gudugbẹ̀ máa já ní Nàíjíríà - Oyedepo Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí 5:47 Fídíò, Akomolede ati Asa: Mọ̀ si nípa àwọn ọ̀nà tí Yorùbá ń gbà ran ara wọn lọ́wọ́, Duration 5,4722 Ọ̀wàrà 2020 FG Covid Palliatives: Àjọ SERAP ń wá ìdájọ́ tó tọ́ lórí rògbòdìyàn jíjí ǹkan ìrànwọ́ Covid-1925 Ọ̀wàrà 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!"
Ọpọlọpọ lo lé fi ẹjẹ wọn tọrẹ ti ko ba ti si wahala ni agọ ara wọn.
Àwọn ọkunrin náà bá dá a lóhùn pé, “Kí OLUWA gba ẹ̀mí wa bí a bá pa yín.
O kò gbọdọ̀ bá ọmọ tí aya baba rẹ bá bí fún baba rẹ lòpọ̀, nítorí pé, arabinrin rẹ ni.
"Ẹ jẹ ki a wo bi o ṣe sọọ gan ni ẹkunrẹrẹ: ""Ọpọ igba ti mo ba joko ti mo si ronu lọ sori pe iru Adeleke, to jẹ pe ijo jijo nikan lo ti jafafa, ni mo n ba dije du ipo gomina, ara mi a si bu maṣọ, oju ara mi a si gba mi ti."
aṣọle lasiko naa ninu idije Premier League.
Ọlọ́pàá kọlu àwọn ọmọ onílẹ̀, ní ìbọn àṣìyìn pa ènìyàn méjì Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, SS3 ní mo wà báyìí, mo sì ti gba àmì ẹ̀yẹ̀ púpò nílé-lóko gẹ́gẹ́ bí onílù - Ayansike Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí LASEMA: Àwa àti panápaná ń ṣiṣẹ́ kára láti dènà ìjàmbá iná6 Ọ̀wàrà 2020 Police Clash: Ọlọ́pàá kọlu àwọn ọmọ onílẹ̀, ní ìbọn àṣìyìn bá pa ènìyàn méjì26 Owewe 2020 Fídíò, Wole Soyinka sọ ìdí tó fi ni òun a fi màálù Fulani ṣe súyà fáwọn èèyàn abúlé23 Owewe 2020 Ondo Election 2020: Ẹ wo àwọn olùdíje sípò gómìnà nípínlẹ̀ Ondo tó takò bàbá ìsàlẹ̀26 Owewe 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Ahabu ọmọ Omiri ṣe nǹkan burúkú lójú OLUWA ju gbogbo àwọn tí wọ́n ṣáájú rẹ̀ lọ.
Àwòrán apanilẹ́rìn-ín fún ọ̀sẹ̀ yìí, ìtọ́wò rèé Osinbajo ta kété sí ọ̀rọ̀ 'Ruga Settlement' Àwọn orílẹ̀èdè àjọ ECOWAS yóò máa ná owó kan nàá l'ọ́dún 2020 Buhari fi àmì ẹ̀yẹ dá olóògbé Adadevoh tó dènà Ebola l'ọ́lá Sááju ni àwọn Trump ti pe ipade pẹlu Kim láti dáwọ ipinnu rẹ dúro lóri èrongba rẹ lati ṣe ifilọlẹ ohun ija olóro ní orilẹ̀-èdè Singapore ni èyi to fori sọnpọn.
Gbogbo àwọn tí wọ́n fogun kó yín ni ogun yóo kó.
Oríṣun àwòrán, Dino/twitter Ninu iwe ipe sibi ase igbeyawo naa, ni aworan obinrin kan wa, ti orukọ rẹ n jẹ Susu, ẹni to pupa lawọ, to si rẹwa lobinrin.
Kódà ọmọ tí wọ́n bí ju ẹyọ kan ṣoṣo lo.
Wọ́n se ìmọyì fún Wenger kí ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ náà tó bẹ̀rẹ̀.
Mo bèèrè ìdí rẹ̀ tí wọ́n fi jí mi, wọ́n ní ki n fetí sílẹ̀ nítorí àwọn ń gbọ́ ohùn tí kò jọ ti ará ayé tí ó dàbí ẹgbẹẹgbẹ̀rùn àwọn èrò ọjà ti wọn ń ho yànmù létí ẹni.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Awọn ara Sudan fọn si igboro ni olu ilu Sudan, Khatourm.
Diẹ lara awọn ba ilẹ Yoruba tawọn ti ọpa aṣẹ wọn lọjọ iwuye ree.
Oríṣun àwòrán, Per second news 3.
Bi o lo dagba, bi o loo gbo, bo ba pẹ titi, oju a hun jọ, Olaniyi ni agba naa ti de si Otunba.
“Nígbà náà, mo rò pé, n óo gbòó, n óo tọ̀ọ́ láyé,ati pé inú ilé mi ni n óo sì kú sí.
Eléyìí tí wọ́n nfarabalẹ̀ jẹ, tí wọ́n sì fẹ́ràn gidi jùlọ ni wọ́n npè ní Ọúnjẹ Àárọ̀ Gẹ̀ẹ́sì.
Yatọ si awọn wọnyi, awọn mẹsan mii ni ẹgbẹ sọ pe ki wọn lọ sinmi nile nitori pe wọn gbe igbesẹ to tako ẹgbẹ.
Ọkan lara awọn ọkunrin to jẹ aṣoju ẹgbẹ naa, Arakunrin Hamzat Kọlawọle so wi pe iwa ti ko bojumu t ko si yẹ awujọ ni iwa ifipabanilopọ.
ede Naijiria ninu oko oju irin mẹ́rìnlélọ́gọ́ta to yẹ ki orile ede
Olórí Alufaa wá sọ fún un pé, “Mo fi Ọlọrun alààyè bẹ̀ ọ́, sọ fún wa bí ìwọ ni Mesaya, Ọmọ Ọlọrun.
Nítorí pé, OLUWA yóo dá àwọn eniyan rẹ̀ láre, yóo sì ṣàánú fún àwọn iranṣẹ rẹ̀,nígbà tí ó bá rí i pé wọn kò lágbára mọ́,ati pé kò sí olùrànlọ́wọ́ fún wọn,tí kò sì ṣẹ́ku ẹnìkan ninu wọn,kì báà ṣe ẹrú tabi òmìnira.
Olaniyan ko gbeyin nigba ti oun naa darapo mo awon Musulumi ododo lati dupe
Wọn fikun un pe awọn ti wọn n darapọ mọ ọdun Kumbh Mela kii se awọn ti o jinlẹ ninu ẹsin naa.
Dafidi fi àwọn ọ̀rọ̀ wọnyi sọ́kàn ó ṣe bí ẹni pé kò mọ ohun tí wọn ń sọ, ṣugbọn ó bẹ̀rù Akiṣi, ọba Gati gidigidi.
Ní ọjọ́ kan nígbà tí àwọn ọmọ Jobu ń jẹ àsè ninu ilé ẹ̀gbọ́n wọn ọkunrin, tí ó jẹ́ àgbà patapata, 
    Ẹ̀yin ọmọ mi, mo ní ayọ̀ láti sọ fún yín pé, gbogbo yin ni ẹ ẹ dáadáa nínú ìdánwò tí mo gbé kalẹ̀ níwájú yín, kò sí ẹni tí mo lè fi ọwọ́ rọ́ sẹ́yìn pé kò rí ohun ìyanu mú bọ̀, bẹ́ẹ̀ ni bí gbogbo yín kò bá pa ara pọ̀ lo ohun iyanu yín, Ẹwadapọ̀ kò bá tí wà láyé lónìí.
idije Uefa Champions League saa to n boBakan
O jẹ́ kí ara dẹ̀ wá díẹ̀ ní oko ẹrú, o sì ń mú inú wa dùn.
Nítorí náà ẹ óo máa ṣe ìrántí ọjọ́ náà bí ìlànà ati ẹ̀yin ati àwọn arọmọdọmọ yín títí lae.
Ẹ níláti jẹ́ mímọ́ fún mi, nítorí pé, mímọ́ ni èmi OLUWA, mo sì ti yà yín sọ́tọ̀ kúrò lára àwọn eniyan kí ẹ lè máa jẹ́ tèmi.
Nínú ìwé ẹ̀hónú náà tó jáde ní ọjọ́ Kẹ́tàlélógún osù Kọkanla, àwọn òsìṣẹ́ lábẹ́ àsíá Ekiti Workers Rescue Team, sàlaàyé pé, ninu mílíọ̀nú mẹ́fà náírà ti wọn n yọ losoosu, mílíọ̀nù márun ń lọ sọ́dọ̀ ẹgbẹ osisẹ NLC nígbà ti mílíọ̀nù kan ń lọ sọ́dọ̀ ẹgbẹ osisẹ TUC, eyi tí kò fojú hàn nínú ìwé owó ẹgbẹ́.
Ta ló lè dá eniyan pada sáyé, kí ó wá rí ohun tí yóo ṣẹlẹ̀ lẹ́yìn tí ó bá ti kú?
Jẹ́ kí ojú wọn ṣókùnkùn,kí wọn má lè ríran.
Abijamu ọmọ rẹ̀ ni ó sì gun orí oyè lẹ́yìn rẹ̀.
Iko agbaboolu CHAN Super Eagles fagbahan akegbe won lati orile-ede Sudan pelu ami ayo kan sodo(1-0) lojoru Wednesday.
Kò pẹ́, kò jinnà, wọ́n parí gbogbo òpò òkú, wọ́n sì wé e láṣọ, ó di ibojì.
Dájúdájú gbogbo wa la ti gbà pé orúkọ rẹ̀ nìyen.
Wọn si tun n fẹ ki Naijiria o jẹ pipin si ipinlẹ kekeeke.
Ẹ gbọ́ ná, ẹ̀yin tí ẹ̀ ń wí pé, “Lónìí, tabi lọ́la, a óo lọ sí ibi báyìí, a óo ṣe ọdún kan níbẹ̀; a óo ṣòwò, a óo sì jèrè.
O wa fi egun le pe ki iṣẹ oun daru bi oun ba mọ si awọn jaduku to lọ kọlu awọn eeyan naa.
22 Bélú 2020 Ẹ gbé owó silẹ̀ fún àwọn iṣẹ iwadii lori wọn ki wọn to tun maa gbẹbọ lọwọ agbaye- Awon onimọ sayẹnsi Sars, Swine Flu, Spanish Flu, MErs, Ebola ati Coronavirus jẹ diẹ lara awọn ajakalé arun to ti mu ẹmi ọpọ eniyan lọ ni gbogob agbaye sẹyin.
Ọwọ́ tẹ́ àwọn ọkùnrin Fulani mẹ́ta tí wọ́n jí Màálù méjì kó ní Ogbomọṣọ- Àjọ NSCDC Ọmọ́ Yorùbá korò ojú sí Buhari bí kò ṣe fi orúkọ Obasanjo sọ ibùdókọ̀ ojú'rin Lasema ni ibugbamu Kanbaadi ati afẹfẹ gaasi papọ yii si lo se okunfa ijamba ina alagbara kan ninu ile itaja naa.
O ti kọrin débi ti oun ati ẹgbẹ orin to wa nigba naa kọ orin awọn ẹlẹmu orílẹ̀èdè Ghana si ilu highlife ti ilẹ Yoruba eyi si jẹ ẹkọ nla fáwọn ọmọ lẹyin rẹ.
Dafidi dáhùn pé, “Baba rẹ mọ̀ wí pé bí òun bá sọ fún ọ, inú rẹ kò ní dùn, nítorí pé o fẹ́ràn mi.
O ṣalaye nibi ayẹyẹ naa wipe, oun fẹ ki awọn ọmọ ilẹ Afirika to jẹ alaini ni anfani lati di eniyan nla ni ibi iṣẹ wọn.
Awọn oniṣowo to wa nibẹ ṣalaye iwuri to wa ninu iṣẹ ikan hihun ati awọn ipenija to jẹ ko ṣee mani.
Se lawọn dokita ni afi dandan ki wọn maa gbe esi ayẹwo jade laarin wakati mẹrinlelogun.
Lara awon to gba ami eye ni ipele
" Ti mo ba pada dele ma maa gbe igbe aye alafia pẹlu awọn ẹbi mi, n o nifẹ wọn ju ti atẹyinwaa lọ bakan naa ni maa bikita nipa awọn eniyan.
O fẹ́ràn ibi ju ire lọ,o sì fẹ́ràn irọ́ ju òtítọ́ lọ.
N kò wí pé kí eniyan gbadura fún irú rẹ̀.
Buhari, ìjọba rẹ ń jọ bí ègún f'órílẹ̀èdè Nàìjíríà-Oyedepo Ìròyìn Yàjóyàjó - Nàìjíríà kéde èèyàn míràn pẹ̀lúu àrùn Coronavirus Ìdí mẹ́ẹ́rin tí sísùn ní ìhòhò lé gbà ṣe ara a rẹ l'óore Ọmọ Nàìjíríà ni ẹnìkejì tó ní Coronavirus ní Washington Mo lóbìnrin tó bímọ fún mi, ṣùgbọ́n ọ̀rọ̀ ìyàwó kò tíì yọ fún mi báyìí-Pasuma Iroyin ti a kọ gbọ ni pe niṣe lawọn ẹṣọ eleto aabo n yin taju taju ni aafin Emir kano lẹyin ti ijọba rọ Sanusi loye.
Ọmọ-ọ̀dọ̀ tí ó ń kọ́ iṣẹ́ lónìí, tí ó ń múra àti mọ iṣẹ́, tí ó gbẹ́kẹ̀lé Ọlọ́run Ọba tí Ó dá a, kí eléyìínì má ṣe bẹ̀rù, kí eléyìínì máa rọ́jú ǹṣó, bí òun kò tilẹ̀ rí agolo gaàrí wà mu, tí òun kò mu ju ṣíbí ẹ̀kọ kan, tí ọ̀gá ń ṣe  ìgbọ̀nsè tí ó ń da ìgbọ̀nssẹ̀ nù, tí ọ̀gá ń wọ ẹ̀wù àrán tí òun ń wọ àkísà, kí òun náà mọ̀ pé òun ń bọ̀ wáá rí ìgbéga ẹ̀hìn ọ̀la.
“Máa pa àwọn òfin tí mo fún ọ lónìí yìí mọ́.
Awọn mejeeji ti n gbe lọtọtọ fun ọdun mẹrin ki ọkọ rẹ to pa.
pataki  igbaradi naa ni lati lee daabobo
‘Lóòótọ́ ni ọ̀jọ̀gbọ́n fẹ́ bá mi lòpọ̀’ OAU lé ọ̀jọ̀gbọ́n tó bèèrè ìbálòpọ̀ fún máàkì Láti ìgbà náà ni àwọn èèyàn ńlá ní Ghana ti ńtàbùkù bá Boduong tí àwọn ènìyàn sì ńfojú rẹ̀ wò ó.
Ọ̀rọ̀ ńlá, àwọn adigunjalè ja àgọ́ ọ́lọ́pàá lólè Èèyàn 745 ló lùgbàdì àrùn Coronavirus ní Naijiria ní Ọjọ́bọ̀ Wo àwọn Gómìnà Naijiria tí àrùn Covid-19 ti bá fínra Gómìnà márùn ún tó fojú winá ìbínú bàbá ìsàlẹ̀ wọ̀n Pásítọ̀ Adeboye ní òun mọ̀ pé ibi tó dára ni Ibidun Ighodalo wà báyìí Oríṣun àwòrán, Instagram/ibidunnuighodalo Pasitọ agba ijọ Redeem, Enoch Adeboye ti sọ pe ibi to dara ni oloogbe orekelẹwa Ibidunni Ighodalo wa.
Igba akọkọ kọ ni yii ti Aisha Buhari yoo sọrọ tako isejọba ọkọ rẹ, nitori bi ilana isejọba aarẹ naa ko mu idagbasoke ba orilẹede Naijiria.
Awọn afẹhonu han ọhun tí wọn wọ aṣọ dúdú bẹ̀rẹ̀ ìrìn wọn láti Old Parade ground nílu Abuja lọ si ile iṣẹ ọlọpàá FCT.
Iroyin naa ni ti irọloye Emir ti ilu Kano, Sanusi Lamido ti ijọba ipinlẹ Kano kede lẹyin ọpọlọpọ itaporogan pẹlu gomina ipinlẹ naa, Abdullahi Ganduje.
    Ofin méjì tí ó ṣe ni ó bá wa wí, èkejì sì ni èyí: ‘Àlejò kálejè tí ó bá wọ ìlú kò gbọdọ̀ jẹ oúnjẹ ará rẹ̀, oúnjẹ àwọn Èdìdàrẹ́ lo níláti rà jẹ́ kò gbọdọ̀ mu omi ibòmíràn, omi àwọn Èdìdàrẹ́ lo nilati mu, kò gbọdọ̀ gbé ilé ara rẹ̀, ilé àwọn Èdìdàrẹ́ lo nílatí gbe.
 O ni ajo naa yoo fagile awon ise akanse kan to to igba bilionu naira, ki won le se awon ti yoo sawon ara ilu lanfani ni kia.
Gomina ipinlẹ Eko Babajide Sanwo Olu tun kesi awọn ọdọ ati oluwọde ipinlẹ Eko lati faaye gba alaafia laaye.
Iroyin to kun ori ayelujara sọ pe dipo iwosan ti o lọ fun lorilẹede India, awuyewuye lori eto aabo rẹ nibẹ lo tun gba aye kan ni ilu Delhi bayii.
Nígbà tí ó di ìrọ̀lẹ́, mo fi ọwọ́ ara mi dá odi ìlú lu, mo sì gba ibẹ̀ jáde lóru.
Àwọn ará Jafani, Tubali, ati Meṣeki ń bá ọ ṣòwò; wọ́n ń kó ẹrú ati ohun èlò idẹ wá fún ọ, wọn fi ń gba àwọn nǹkan tí ò ń tà.
Leyin ti gomina Seyi Makinde ti ko awọn eeyan to wa ni imuninigbekun kuro lọdọ Aafa Olọrẹ nitosi Ọjọọ nilu Ibadan nipinlẹ Ọyọ Ẹ̀yin òbí, ẹ má kó àwọn ọmọ yín lọ síbùdó atúnwàṣe mọ́ - Seyi Makinde ni BBC ṣabẹwo sibẹ.
Ìtura lati ibi ti ìtọ̀ n gba jade (U-Spot Orgasm) Ibi ti itọ n gba jade ki i ṣe fun ìtọ̀ nikan, nitori pe awọn ẹ̀yà kan lara idọ̀ wa lara rẹ, eyi to maa n fun obinrin ni itura ti wọ́n ba fi nkan rìn ín.
montego european travel , tí ó wà ní wetley rocks , staffordshire , bẹ ̀ rẹ ̀ òwò pẹ ̀ lú ọkọ ̀ akérò méjì ní oṣù kẹrin odún 1990 .
Bí ọkunrin náà ti fi ara kan egungun Eliṣa, ó sọjí, ó sì dúró lórí ẹsẹ̀ rẹ̀.
Ṣugbọn àṣẹ kan náà ni Ọlọrun fi pa àwọn ọ̀run ati ayé ti àkókò yìí mọ́ kí ó lè dáná sun ún, ó ń fi wọ́n pamọ́ títí di ọjọ́ ìdájọ́ nígbà tí a óo pa àwọn eniyan tí kò bẹ̀rù Ọlọrun run.
ọmọ Johana, ọmọ Resa, ọmọ Serubabeli, ọmọ Ṣealitieli, ọmọ Neri, 
Àwọn ọkunrin mejeeji bá jókòó, wọ́n jẹ, wọ́n mu, lẹ́yìn náà ni baba ọmọbinrin yìí tún dáhùn pé, “Jọ̀wọ́ kúkú dúró ní alẹ́ yìí kí o máa gbádùn ara rẹ.
’ rèé 'Kìí ṣe ojúṣe mi láti sọ bóyá òótọ́ ni Buhari fẹ́ gbéyàwó tàbí irọ́' Ti eleyi ba ṣẹlẹ gẹgẹ bi alaye ti NIMC ṣe si oju opo wọn eeyan le ri pada yala ki o lọ si aye iforukọsilẹ tabi ki o si tẹ nọmba *346# lori ẹrọ alagbeka rẹ lati ri pada.
Ìhòòhò ni púpọ̀ nínú àwọn tí a rí wà, tó bẹ́ẹ̀ tí ó jẹ pé bí wọn ba ń kọjá, eeri n gbọ̀n silẹ̀ ni, ọdún mẹ́ta mẹ́ta ni wọn to ń wẹ̀, èérí ara wọ́n pọ̀.
 Nigba ti o n soro leyin to ti se ojuse re, Oloye Adelabu fi ye awon
168trn tí mó ṣe fọ́dún 2020 ni yóò sọ Eko jí padà - Sanwo-Olu Láíláí Apostle Suleiman kò lè gba onídùúró mí!
Iwadii tun fihan pe eroja Amino Acid Tryptophan to wa ninu koko a maa mu inu ẹni dun sii laini idi pataki kankan ni pato.
Ma si ṣe gbagbe lati maa tẹle awọnilana eto ilera tawọn alaṣẹ ijọba lagbegbe rẹ ba fi sita.
Iru awọn iroyin ti ẹ le nifẹ si: Fọlọrunṣọ Alakija: Imọ ṣe koko 'Ara sisan kii ṣe arun' Buhari ṣ'eleri iṣẹ f'awọn ọdọ Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
“Ọkunrin kò gbọdọ̀ fi èyíkéyìí ninu àwọn aya baba rẹ̀ ṣe aya, tabi kí ó bá a lòpọ̀.
Mo tún rí ohun abàmì mìíràn ní ọ̀run, ohun ńlá ati ohun ìyanu: àwọn angẹli meje tí àjàkálẹ̀ àrùn meje ti ìkẹyìn wà ní ìkáwọ́ wọn, nítorí pé àwọn ni wọ́n mú ibinu Ọlọrun wá sí òpin.
Iroyin to n tẹwa lọwọ lati ileesẹ to n gbogun ti idena aisan ni Naijira, NCDC, wọn ni eeyan 3,912 lawọn ti fidi rẹ mulẹ pe wọn ni arun yi,ti ilu Eko si ni iye awọn to pọju tii se 1,667.
O ni bí wọ́n bá ń sọ̀rọ̀ odò wíwẹ̀ lọ́jọ́ 'wájú, mo fẹ́ kí ẹ máà rántí mi""."
Dafidi tún fẹ́ àwọn iyawo mìíràn ní Jerusalẹmu, ó sì bí àwọn ọmọkunrin ati ọmọbinrin sí i.
"Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: PDP àti APC fi ìbọn dárà l'Ondo, ọ̀pọ̀ èèyan farapa, àìmọye dúkìá ṣòfò ""Dípò ìnákúnàá lórí ìgbéyàwó ọmọ mi, mo lò owó fún ìgbéyàwó ọmọ òrukàn mẹ́tàlá"" Àwàdà kẹríkẹrì nígbà táwọn olùdíje ààrẹ́ Amerika méjì kọjú ìjà síra wọn Ìjọba àpàpọ̀, jọ̀ọ́ máṣe yẹ̀ lórí àdéhùn rẹ fẹ́gbẹ́ òṣìṣẹ́ - Ile aṣojú-ṣòfin Ọgọ́rin arìnrìnàjò tó padà wá sí Nàìjíríà ló ní Coronavirus - PTF Wo iye tí ìjọba yóò gbà lọ́wọ́ Laycon gẹ́gẹ́ bí owó orí ẹ̀bùn BBNaija tó jẹ N kò mọ ẹni tó fẹ́ gba ìyàwó mi, àmọ́ wọn máa ń sọ pé ó rẹwà - Mike Bamiloye Ọkan lara awọn to sun mọ kọmisọna to n ri si ọrọ ere idaraya Yemi Lawal, wa lara awọn ti wọn pe si ipade ni ile igbimọ asofin fun iwadii ọrọ naa lọsẹ to kọja."
Ǹjẹ́ mo bẹ̀ yín pé kí ẹ gbà mí lọ́wọ́ ọ̀tá;tabi pé kí ẹ rà mí pada kúrò lọ́wọ́ aninilára?
O ni arabinrin naa ṣalaye fawọn ọlọpaa pe ọmọ aburo ọkọ oun ni ọmọ naa.
ÀWỌN ONÍRÚURÚ IṢẸ́ Ilé iṣẹ́ ìròyìn BBC máá ń fi ìyàtọ̀ sí àwọn ìròyin tí a le fí àwọn ìdí rẹ múlẹ̀ àtí àwọn èyí ti àwọn ènìyàn kan sọ èrò ọkàn wọ́n lásán.
Oríṣun àwòrán, @OfficialPDPNig Àkọlé àwòrán, PDP ni ajọ eleto idibo ilẹ wa ati awọn ileesẹ agbofinro ti yẹsẹ kuro loju opo ofin isẹ wọn, Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, #EkitiDecides: 'Ìjà ẹgbẹ́ òkùnkùn ló ń ṣẹlẹ̀ kìí ṣe ti òṣèlú' Mo lọ́ra púpọ̀ nínú ìwé kíkà - Buhari Fayose kọ́ ni olóṣèlú tí yóò kọ́kọ́ kán l'ọ́rùn' Oríṣun àwòrán, @PDPOfficialNIG Àkọlé àwòrán, Ẹsun bi ajọ eleto idibo Inec se n segbe si ibikan ko tẹ PDP lọrun Awọn koko ẹsun ti ẹgbẹ PDP gbe siwaju ile asofin apapọ ree: 1.
Musibau sọ eyi lasiko to n ba BBC Yoruba sọrọ lori awọn nkan to n fa ijamba ina ninu ile.
Wọ́n bá yà sibẹ, wọ́n sì lọ sí ilé ọdọmọkunrin ọmọ Lefi, tí ó wà ní ilé Mika, wọ́n bèèrè alaafia rẹ̀.
“Bí ọkunrin meji bá ń jà, tí iyawo ọ̀kan ninu wọn bá sáré wá láti gbèjà ọkọ rẹ̀ tí wọn ń lù, tí ó bá fa nǹkan ọkunrin ẹni tí ń lu ọkọ rẹ̀ yìí, 
Ninu ọrọ to sọ lasiko to ba awọn olugbe ni ipinlẹ naa sọrọ lalẹ ọjọ Aje, El-Rufai ba awọn to padanu eniyan wọn tabi dukia sinu iṣẹlẹ naa kẹdun.
Àkọlé àwòrán, Ìbò méje péré ni Adeleke fi fẹ̀yìn Adebiyi janlẹ̀ Alaga eto ìdìbò náà, tó tún jẹ́ Gomina Ipinle Bayelsa Seriake Dickson ló kéde Adeleke gẹ́gẹ́ bí ẹni tó jáwé olú borí, lẹ́yìn tí wọ́n ka ìbò náà ní ẹ̀ẹ̀meji ọ̀tọ̀ọ̀tọ̀.
Ta ló lè ka àwọn ọmọ Jakọbu tí ó pọ̀ bí iyanrìn?
Agbẹnusọ fun Aarẹ Mohammadu Buhari, Garba Shehu lo fi eyi lede lori ikanni twitter ẹ pé: Bakan naa lo fi idi eyi mulẹ pe, ni kete tijọba fi àṣẹ yii sita ni wọn ti ṣi ile iṣẹ Daily Trust pada.
Nibẹ lo si ti kọ bi a ṣe n fun fere ati gita ti o si tun n ko orin jọ pẹlu fun ẹgbẹ akọrin ijọ naa.
Wọ́n bá bẹ̀rẹ̀ sí í se ẹja yìí bí ó sì tún ti tó àkókò àti ro ọbẹ̀ tí ìjòyè kan mú ṣíbí tí ó ń ro ọbẹ̀ ṣe ni ògiri ilé náà tún là sí méjì tí ọkùnrin ńlá méje jáde ti àwọn ti idà olójú méjì lọ́wọ́, ti wọ́n tún da ẹja lu iná – ìjàngbọ̀n dé, ìjòyè ń kọlu ìjòyè, ayaba ń kọlu ayaba, ọba fo ojú fèrèsé jáde, ṣe ni ẹ̀wù agbádá ọba ń fẹ́ lẹlẹ níbi tí ó tí ń sálọ.
Gbogbo ìlú náà po, wákàtí kan náà ni wọn ń lò láti jẹun, ìsẹ́jú kan náàni wọ́n ni láti bu òkèlè.
Ṣugbọn ọkọ̀ wa yóo fàyà sọlẹ̀ ní erékùṣù kan.
Òṣìṣẹ́ ìjọba ẹ̀ni ọdún mọ́kàndínláàdọ́ta pokùn so ní Ekiti
Nigba ti ifẹsẹwọnsẹ naa wọ iṣẹju kẹtalelogun ni Sterling, agbabọọlu Manchester City ṣide goolu ifẹsẹwọnsẹ naa.
Okan pataki lara awọn iwe to kọ ki ọlọjọ to de ni Naija No Dey Carry Last, A 2015 collection of satirical essays.
SWAT ni orúkọ tuntun ti SARS yóò máa jẹ́ 'Mo jíṣẹ́ ẹ rán mi'!
N óo fà wọ́n lọ sí ibi tí wọn tí ń pa ẹran,bí ọ̀dọ́ aguntan, ati àgbò ati òbúkọ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ogbomsho shooting, End Sars, End SWAT: Isiaka fi ọmọbìnrin kan àti ìyàwó tó lóyún sínú síl Toyin Abraham Ilumọọka oṣere, Toyin naa ko gbẹyin nibi ifẹhonuhan #EndSARS.
'Ẹ̀ ń fi ẹ̀wọ̀n run imú o' Ẹ̀yin Olóyè Ibadan mọ́kànlélógún tẹ ń pe ara yin lọ́ba Bàbá akẹ́kọ̀ọ́bìnrin LASU tí ọ̀rẹ́kùnrin rẹ̀ àti pásítọ̀ fi ṣ'òògùn owó ń bèèrè fún ìdájọ́ òdodo Wo àwọn èèkàn tí ikú mú lọ lọ́dún 2019 Eyi kii ṣe igba akọkọ ti ileeṣẹ WhatsApp yoo gbe iru igbesẹ yii.
Ìdí ni pé nígbà tí mo bá ti waasu fún àwọn ẹlòmíràn tán, kí èmi alára má baà di ẹni tí kò ní yege ninu iré-ìje náà.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Ile iwe di titi pa Gbogbo ile iwe lo gbọdọ wa ni titi pa lasiko ti ijọba ba kede ofin konile o gbele nitori ki awọn akẹkọọ maa ba lugbadi arun coronavirus to wa nita.
to n lọ lọwọ  bayii ni orile ede South
Oga agba fun ile-ise omo ogun
Ó ní, “Ọkunrin kan gbin àjàrà sinu ọgbà kan, ó gba àwọn alágbàro sibẹ, ó bá lọ sí ìrìn àjò.
Ọ̀jọ̀gbọ́n onímọ̀ ẹrọ tí o ní kí wọ́n wọgi lè ìbò Ààrẹ Nàìjíríà Awọn ìpínlẹ̀ náà ní Lagos, Ogun, Oyo, Imo, Kwara, Nasarawa, Yobe, Borno, Adamawa, Bauchi, Gombe àti Zamfara, ẹ̀wẹ̀ nínú àwọn ìpínlẹ̀ méjìlá yìí mẹ́rin nínú àwọn gómìnà náà ni wọn ti na ìka àlébù si pé wọn ṣe ol'w ìlú mọ́ku-mọ̀ku, Àwọn gómìnà ọ̀hún ni Rochas Okorocah ti ipínlẹ̀ Imo, Abdulfatah Ahmed ti ìpínlẹ̀ Kwara, alága àwọn ẹgbẹ́ gómìnà tó tún jẹ gómìnà ìpínlẹ̀ Zamfara Abdulaziz Yari àti gómìnà ìpínlẹ̀ Ogun Ibikunle Amosun.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Venezuela: Ọ̀pọ̀ ìdílé tí ebi ń pa, ti ń ta àwọn ọmọ wọn Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Venezuela: Ọ̀pọ̀ ìdílé tí ebi ń pa, ti ń ta àwọn ọmọ wọn 17 Ọ̀wàrà 2018 Arabinrin kan ní ilẹ Venezuela to ta ọmọ rẹ nitori ọwọngogo ounjẹ ti ni, ohun ibanujẹ lo jẹ fun oun, bi oun ko se wa pẹlu ọmọ òun.
Fún ọjọ́ mẹ́wàá ẹ óo ní ìṣòro pupọ.
Kí o ṣe ara rẹ ní àpẹẹrẹ rere ní gbogbo ọ̀nà.
Ṣùgbọ́n nígbà tí a dé ìlú náà tan, ó ṣòro díẹ̀ fún ni kí á tó lè ka èso igi ìrònù.
Ọmọ bibi ilu eko ni ṣugbọn iran Igbo ni awọn obi rẹ ti wa.
O tun so pe “Ijoba ti fun wa ni anfaani lati lowo nibi eto eyawo naa, won si ti seleri pe awon omo egbe wa yoo je anfaani eto eyawo ohun.
”ipinnu naa waye ni ibamu pelu ofin ati ilana ajo CAF, eleyi t o fun awon igbimo toro kan gbongbon ohun ni anfaani lati se ohun ti o to ati ohun ti o ye, ”Iyansipo naa tun kun Amaju niye, leni ti o n tuko igbimo to n sakoso idije boolu afesegba tile Afrika, bee si ni, O tun je omo egbe igbimo to n sakoso idije boolu afesegba lagbaye.
Ìdílé Asafu, ẹ̀yà Lefi, ń lu kimbali wọn, wọ́n fí ń yin OLUWA, gẹ́gẹ́ bí ètò tí Dafidi, ọba Israẹli, ti ṣe.
Ati Lai Mohammed, minista fun eto ifitonileti, aṣa ati iroyin.
Natani bá dá Dafidi lóhùn pé, “Ìwọ gan-an ni ẹni náà.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ajọ SERAP sọrọ lori owo ifẹhinti awọn oloselu kan Ni afikun, Mallam Aaron ni ofin wa fun gbogbo banki Naijiria lati paarọ awọn owo atijọ ti awọn eniyan ba ko wa.
Ṣugbọn mo kọ ọ́ kí ìtara yín lè túbọ̀ hàn níwájú Ọlọrun.
Garba Shehu ni labẹ ofin, eniyan mẹrin lo laṣẹ lati lo ọkọ ofurufu ijọba Naijiria, iyẹn ni Aarẹ, Awọn ẹbi aarẹ, igbakeji Aarẹ ati Aarẹ Ilẹ Igbimọ Asofin agba ati kekere orilẹ-ede Naijiria ati ẹnikẹni ti Aarẹ ba gba laaye pẹlu aṣẹ.
Oríṣun àwòrán, Kwara APC Information Center Àkọlé àwòrán, Aṣọ ti Fatai Seriki wọ ninu awọ́rna yi ti Charles Folayan fi ṣọwọ si BBC yato si eyi to wa ninu aworan ti tẹlẹ ''Ni Ẹkan ni mo ti dibo mi, mi o si gburo nkankan nibẹ.
Bí ọmọbinrin kan bá jẹ́ ẹ̀jẹ́, bóyá ó ti ọkàn rẹ̀ wá tabi kò ti ọkàn rẹ̀ wá, tí ó sì lọ ilé ọkọ lẹ́yìn ẹ̀jẹ́ tí ó jẹ́, 
"Ọjọ́ kan tiẹ̀ wà, tí èmi ati Femi jọ kopa ninu ere, tó si ṣe ọga fún mi, tó ń sọ̀rọ̀ si mi, lẹ́yìn ta parí ère tán, lo padà wá bẹ mi, pé kí n má bínú àmọ́ èyí kò ní ìtumọ̀ kankan sí mi.
mi Fabiyi - BBC News Yorùbá BBC News, YorùbáFò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìtànjẹ ti pọ̀jù nínú iṣẹ́ tíátà, a kò rí kọ́bọ̀ nínú fíìmù tó wà lórí YouTube - Yomi Fabiyi 14 Èbibi 2020 Oríṣun àwòrán, yomi fabiyi Gbajumọ elere tiata, Yomi Fabiyi ti salaye pe, ọpọ eeyan to fi gbogbo ara ṣiṣẹ tiata, ti wọn ni okiki ati ọrọ, ni akude tí de ba lasiko yii.
 wọ ́ n sọ wípé àgbọn ni nam jẹ fún odindin ọdún mẹ ́ ta ; ní àwọn àkókò yìí ó tún maa ń dá sọrọ ̀ ní orí òkúta kékeré .
Ṣugbọn nisinsinyii, n óo kígbe,bí obinrin tí ń rọbí lọ́wọ́.
Gomina Makinde yoo ṣe ibura fun gbogbo wọn laipẹ.
Nibi ipade yii ni onimọ iṣegun ibilẹ naa ti fi ọrọ lede pe, itajẹsilẹ lewu pupọ fun idagbasoke orilẹ-ede yii.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Coptic Christianity bẹ̀rẹ̀ l'órílẹ̀èdè Egypt 8 Sẹ́rẹ́ 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Loni, iwadi sọ pe awọn to jẹ ẹlẹsin Coptic lagbaye wa laarin miliọnu mẹwa si ọgọta miliọnu.
Gomina Samuel Ortom ti  ipinle Benue ni aarin gbungbun orile ede
Dípò igi, bàbà ni n óo mú wá.
Ni bayi, omo-odun merinleladota akonimoogba tuntun ohun lo di akonimoogba keje ti yoo tuko iko agbaboolu orile-ede naa lati odun mejo seyin.
Amọ, awọn ti ọrọ naa ṣoju rẹ ni orẹbinrin Shininenge kọ lati fẹ ọkunrin naa gẹgẹ bi iyawo keji lẹyin ti awọn ọrẹ rẹ ni Nomyange ti dagba julọ, nitori ẹni ogoji ọdun o le ni.
Egbẹ́ agbábọ́ọ̀lù Nàìjíríà sàn N5,000 láti rà agbábọ́ọ̀lù tó n gbowó julọ 9 Owewe 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 10 Owewe 2019 Àkọlé àwòrán, Àrà kengé!
Ó kọ̀ lati lọ jagun, ti kò gbàgbọ́ nitori ó gbàgbọ́ pé alafia dára ju ogun lọ.
Ounjẹ wa maa n ṣaraloore ti o si maa n fun ni lokun ati agbara.
Àwọn ohun kàyéèfì tó le mú kí ọmọbìnrin ní oyún ìju Ẹ dín agbára ìjọba àpapọ̀ kù, kẹ ṣì ṣe àgbékalẹ̀ ọlọ́pàá ìpínlẹ̀ - Tinubu bẹ̀bẹ̀ Jide Kosoko forin sẹ́nu pé òun ni igi lẹ́yìn ọgbà Mr Latin lórí ipò ààrẹ TAMPAN tó wà Ṣé lóòtọ́ ni Bimpe Oyebade lóyún fún Lateef Oladimeji?
Omowe Tedros so pe, ipinnu oun gege bi giwa tuntun naa ni lati je ki ” bogbo omo orile-ede agbaye gbe igbe aye alaafia ati eyi ti o mu idagbasoke wa”.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ìgbátí ìgbámú àná látọwọ́ sọ́jà obìnrin ti bá arákùnrin náà dé iléèwòsàn Wo ọ̀rọ̀ tí Asiwaju Bola Tinubu fi síta lórí ìṣòro ètò àbò Nàìjíríà Ilé ìgbọ̀nsẹ̀ kan ṣoṣo ni aṣòfin mẹ́rin ń pín lò!
Bí n kò bá ṣe iṣẹ́ Baba mi, ẹ má ṣe gbà mí gbọ́.
Oloye Ayo Adebanjo ati agbẹnusọ fun Afénifẹ́re, Yinka Odumakin, sọ fun BBC pe awọn Ọba ode oni ń beru ijọba ni wọn ṣe n sọrọ atileyin fun Buhari lọdun 2019.
A ní láti ṣiṣẹ́ pọ̀ láti yí i padà!
Ilé aṣòfin àgbà: Ìsìnmi olóṣù méjì wa kò le è ṣàkóbá fún àyẹ̀wò mínísítà
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Minister f'eto ilera wipe gbigba awọn abẹrẹ ajẹsara le dẹkun iba pẹlu Minisita fun eto ilera ni lọwọ ti a nsọrọ yii, ko din ni ipinlẹ mẹẹdogun ti aarun yii ti nja bayii, bakannaa lo ni ko di ni eeyan marundinlọgọfa ti iwadi ti fi idi rẹ mulẹ pe wọn ti lugbadi aisan yii.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Kylian Mbappe fakọyọ nínú ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ láàrin France àti Uruguay Diego Costa ti o ti d'ero ile bayi pẹlu ẹgbẹ agbabọọlu Spain naa gb'ayo mẹta sawọn ki wọn to l'ọle lati Russia.
Awọn ohun to ti ṣẹlẹ si Laycon saaju asiko yii: Oríṣun àwòrán, NAirametrics Dapo Abiodun yan Laycon ní aṣojú pẹ̀lú ẹ̀bún ₦5m àti ilé oníyàrá mẹ́ta Saaju la ti sọ fun yin pe, Gomina ipinlẹ Ogun, Dapo Abiodun ti fun yan oludije to bori ninu ile BB Naija lọdun yii, Olamilekan Agbeleshebioba, ti ọpọ eeyan mọ si Laycon gẹgẹ bi asoju fun ipinlẹ naa.
tí àwọn ìràwọ̀ òwúrọ̀ ń jùmọ̀ kọrin,tí gbogbo àwọn ọmọ Ọlọrun sì búsáyọ̀?
Agbẹjọro ati ajafẹtọ, Ben Crump sọ loju opo Twitter rẹ pe loju ọmọdekunrin mẹta Blake lawọn ọlọpaa ti yinbọn fún un.
Ronaldo naa tẹle Messi lọọle lẹyin ti Uruguay fiya jẹorilẹede rẹ Portugal.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ọ̀nà ọ̀fun lọ̀nà ọ̀run - omi ò jẹ́ ká ta ọjà Olórí ìlú Jibia, Alhaji Rabe Rabi'u, ni ohun ko ti i ri iru ojo bẹ ẹ ri laye oun, ati pe o da a loju pe ọtalerugba maalu lo ku nitori iṣẹlẹ naa, ti ọpọlọpọ oko si di bibajẹ.
Lẹ́yìn náà ó lọ sí ẹnu ọ̀nà tí ó kọjú sí ìhà ìlà oòrùn, ó gun àtẹ̀gùn tí ó wà níbẹ̀, ó sì wọn àbáwọlé ẹnu ọ̀nà náà; ó jìn ní ìwọ̀n ọ̀pá kan, (mita 3).
naa ati awon omo orile ede Naijiria ti o padanu ẹmi won ninu isele naa  balẹ pe , ijoba oun yoo ri i pe won fimu awon
Afurasi kẹfa, Fatai Akanji, nikan ni agbejọrọ wa ṣoju rẹ nilẹ ẹjọ naa, ti awọn to ku ko si ni agbẹjọrọ to n soju wọn.
Omíyalé gbẹ̀mí èèyàn méje, o tún ba dúkìá púpọ̀ jẹ́ Wo aláànú tó n wa ọkọ̀ tí wọ́n fi n gbé aláìsàn lọ́fẹ̀ẹ́ Kínni ife ẹ̀yẹ ti Tiger Woods gbà ní Augusta fi yàtọ́?
Eyi to kadi rẹ nilẹ ni ti bi awọn oṣiṣẹ ajọ naa ṣe di ẹnu ọna ile aṣofin lọjọ Aje, ọjọ keje, oṣu Kẹjọ.
Kò sóhun tó kù ninu ọ̀rọ̀ yín,tó ju irọ́ lọ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìbò NFF: Ìbò 34 ni Pinnick fi borí àwọn olùdíje yòkúù 1 Ògún 2018 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 20 Owewe 2018 Oríṣun àwòrán, @thenff Alaga fun ajọ elere bọọlu lorilẹ́-ede Naijiria (NFF), Amaju Pinnick ni wọn tun ti dibo yan pada lọsan ọjọbọ gẹgẹ bii alaga ajọ naa.
yoo maa sakoso eto ni gbogbo ipinle won.
Aya Uraya tẹ́lẹ̀ ni ìyá Solomoni.
Nígbà tí òun náà ń bá BBC Yoruba sọ̀rọ̀ lórí ìṣẹ̀lẹ̀ náà, Ọtunba Lekan Alesinloye, tíì ṣe igbakeji akọ̀wé fún ẹgbẹ́ awakọ èrò nipinlẹ Ọ̀yọ́, NURTW, ti ijọba ti fofin de ṣàlàyé pe, àwọn awakọ tó jẹ́ ọmọ ẹgbẹ́ NURTW ni awakọ, àwọn si ti kúrò ní gareji tí to ọdún kan.
Iru awọn iroyin ti ẹ le nifẹ si: Ìdí rèé tí ilẹ̀ Afirika fi gbọdọ̀ kópa nínú dídán abẹ́rẹ́ coronavirus wò Ta ni Naira Marley jẹ́ gan an?
Àkàndá ẹ̀dá fipá lòpọ̀ pẹ̀lú ọmọ ọdún mẹ́rìnlá, tó sì di óyún Oríṣun àwòrán, Others Afurasi kan, Samuel Eze, to jẹ akanda ẹda, ti wọ panpẹ ọlọpaa lẹyin ti wọn fẹsun kan an pe, o fipa ba ọmọ ọdun mẹrinla kan lopọ, to si fun loyun ladugbo Oshodi nipinlẹ Eko.
Lea lóyún, ó bí ọmọkunrin kan, ó sọ ọ́ ní Reubẹni, ó ní, “Nítorí OLUWA ti ṣíjú wo ìpọ́njú mi; nisinsinyii, ọkọ mi yóo fẹ́ràn mi.
Ile iwe Girama ti Bishop Phillips Academy ni Monatan, Ibadan lo lọ.
Oríṣun àwòrán, BBC Sport Lẹ́yìn oṣù díẹ̀, Onochie tún gbée sórí Twitter ré pé Atiku Abubakar, O fi àwọn ènìyàn si inú òṣì bi o ṣe ń pín Ounjẹ àti owó lásíkò ìpolongo idibò""."
Iwe naa sọ siwaju pe, ti UCH ko ba fesi si ọrọ awọn laarin ọjọ meje, awọn yoo gbe igbesẹ lati pe wọn lẹjọ lori ẹsun aibikita.
Lasiko to n ba awọn akọròyìn, ilé ijọba sọ̀rọ̀, lẹ́yìn ìpàdé pẹlú ààrẹ Buhari, Sirika ni, àwọn yóò dẹkun itankalẹ ajakalẹ ààrun Coronavirus.
Ẹ̀gàn àwọn onírera ti pọ̀ jù fún wa;yẹ̀yẹ́ àwọn onigbeeraga sì ti sú wa.
Òṣùká kékeré kò rẹrùn àgbà, orílẹ́èdè Nàìjíríà ṣòro púpọ̀ láti darí - Ibrahim Babangida Manchester United dáná sun Chelsea bi ẹràn àgbò iléyá Àlàyé rèé lóríi ìdí tí wọ́n fi ń pe aya ní ìyàwó Ofin awọn ọlọpaa Met tun sọ pe, awọn ọlọpaa ko gbọdọ se nnkan ti yoo tabuku tabi mu ẹgbin ba orukọ ileeṣẹ ọlọpaa ilẹ Gẹẹsi.
Agbéraga, o óo fẹsẹ̀ kọ, o óo sì ṣubú,kò ní sí ẹni tí yóo gbé ọ dìde.
Ọwọ́ ọlọ́pàá ti tẹ ọkùnrin kan tó pa ọ̀rẹ́ rẹ̀ nítorí N40 ní Kano Ẹ yé gba owó orí níbi ìdána ìyàwó mọ́, sísọmọbìnrin s'óko ẹrú ni- Daddy Freeze A kò fòfin de owó naira tó ti pẹ́ ní Naijiria -CBN Ọwọ́ EFCC tẹ ọ̀kan lára àwọn ti FBI fi èsún jìbìtì kàn!
Ẹni ọdun mọkàndinlógbọ̀n náà to jẹ́ ọmọ bíbí ìpínlẹ̀ Ebonyi sàlàye fun akọroyin iwé ìròyìn Punch ki àwọn ọlọpàá agbegbe Satellite Town eyi ti Chike Oti saju rẹ̀ to mú u gbogbo ǹkan to fa sábàbi to fi wá ja si ǹkan to ṣẹlẹ̀ yìí.
Awọn fọnran fidio lori ayelujara n ṣafihan bi wọn ṣe n jo ọkọ nile ita ọkọ ati awọn ile itaja miran.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Bring back our girls: Obi àwọn ọmọ Chibok 34 ló kú ní ọdún márùn ún 14 Ìgbé 2019 Oríṣun àwòrán, AFP Àkọlé àwòrán, Bring back our girls: Obi àwọn ọmọ Chibok 34 ló kú ní ọdún márùn ún Awọn obi awọn ọmọ Chibok lẹyin ọdun marun un ti gba ọdọ pasito lọ fun adura itusilẹ fun awọn ọmọ Chibok.
 adeólókun gbá bọ ́ ọ ̀ lù yíi fún ikọ ̀ náà fún ọdún mẹ ́ rin .
 mo wá tẹ ́ ra sílẹ ̀ bí àtẹ ọ ̀ rúnlá tàbí bí obìnrin tí ń sàníyàn ọkọ .
Ọga Agba Ọlọpaa lorilẹede Naijiria, Mohammed Adamu lo fi eleyii lede lasiko to n ba awọn oniroyin sọrọ lasiko to lọ ṣẹ ipade pẹlu aarẹ Buhari lori ọr ifipabanilọpọ to n ṣẹlẹ kaakiri ni Naijiria.
Òun ni Ọlọrun tòótọ́ ati ìyè ainipẹkun.
Ọgbẹni Joseph sọ pe lati igba ti iṣẹlẹ naa ti waye, ni Deji ti sa kuro niluu, ti ileeṣẹ ọlọpaa si ti n wa.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Kloe: Èmi kìí mu òògùn olóró, àmọ́ mo fẹ́ràn láti máa wà lẹ́bà omi Nigba ti wọn bere ohun ti yoo fi owo to ba jẹ lori eto naa ṣe, Seyi ni oun yoo da owo naa sidi owo t'oun n ṣe.
"Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù LUTH bed space: ""Ìta gbangba ni àwọn aláìsàn kan ń sùn ní LUTH"" 27 Bélú 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 28 Bélú 2020 Wo bí ilé ìwòsàn LUTH ṣe ń gba owó ibùsùn lọ́wọ́ àwọn aláìsàn, tí àwọn míràn sì ń sun ìta Awọn eeyan kan ti fẹsun kan ile iwosan ijọba apapọ to wa ni ilu Eko, LUTH, pe o n gba owo lọwọ awọn ẹbi alaisan ko to fun wọn ni aaye lati sun nile iwosan naa tabi ki wọn sun ni ita gbangba."
Loju opo Facebook Ogbeni Bunmi Ojo, isẹ ibanikẹdun orisirisi lawọn eeyan ko sibẹ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Fulani Heardsmen: Afenifere ní àṣẹ tó bá wu àwọn àgbàgbà agbègbè àríwá Nàìjíríà ni Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Boya ẹnikẹni ba iṣẹlẹ yi rin tabi bẹẹ kọ ko tii ye.
Pa Kasumu tó ni ohùn ló lọ,ohùn tó fi sílẹ̀ kò ní parẹ́ Bernie Sander lo n lewaju báyìí nínú idibo to wáye, sùgbọ́n nígbà ti yóò fi di ọjọru, yoo ti ye wa yékeyeke ẹni ti wọ́n yoo yàn láti dije dupo ààrẹ.
Mo sá kúrò nílé tí mo yá mílíọ̀nù 17 kọ́ ní Àkútè- Bayo Okeowo O fikun pe, ọwọ oun di pupọ ni ko jẹ ki oun maa kọ orin fun awọn elere tiata mọ bi o tilẹ jẹ pe, owo ti oun maa n gba fun orin kikọ pọ lọwọ wọn, sibẹ, wọn si maa n fi orin inu ere lọ oun.
Aeroplane House: Látọdún 1999 ni mo ti bẹ̀rẹ̀ kíkọ́ ilé yìí fún ìyàwó mi ọ̀wọ́n Àwọn ẹni òkùnkùn ló já ìṣẹ́gun mi gbà, mò ń lọ sílé ẹjọ́ tó ga jùlọ - Bayo Adelabu Ọmọ ọdún kan póòrá!
Bí ẹ bá wí lọ́kàn yín pé,“Kí ló dé tí irú èyí fi dé bá wa?
naa ni“Ni ibamu pelu ohun ti o n sẹlẹ ni awon orile ede agbaye ati
4 5701 Orilẹede Gabon 60 2.
Agbẹjọ́rò Maina yọ ọwọ́ kúrò nínú ìgbẹ́jọ́, Ó lóun kò ṣé mọ̀ Ni ibamu pẹlu ohun tofin ilẹ yi sọ, o ni Gomina ipinlẹ ko le jẹ alaga ẹgbẹ ti yoo yan ẹlomii lati dije dupo.
Ní ìgbà yẹn  àwọn aṣiṣẹ́ fún Brian Hodgson tí ó jẹ́ aṣèwádìí Nepali tí ṣe àkójọ onírúurú àpẹẹrẹ, ”ó kọ.
Lẹ́yìn náà, Efuraimu bá aya rẹ̀ lòpọ̀, ó lóyún, ó sì bí ọmọkunrin kan.
Won so oro ohun di mimo wi pe, eyi yoo seranwo lati fi ese isejoba tiwan-tiwan mule sinsin lorile-ede Naijiria.
kí á lè fi fadaka ra talaka, kí á lè ta aláìní, kí á sì fi owó rẹ̀ ra bàtà, kí á sì ta alikama tí kò dára?
Gbé ọlọ kí o máa lọ ọkà,ṣí aṣọ ìbòjú rẹ kúrò,ká aṣọ rẹ sókè, kí o ṣí ẹsẹ̀ rẹ sílẹ̀,kí o sì la odò kọjá.
O tun ni ijọba ilu Abuja yoo lo anfaani naa lati pese ilẹ fun awọn  ti ijọba gba ilẹ won.
Ọsẹ diẹ sẹyin ni wọn tu Marley silẹ lẹwọn nibi to wa fun ọjọ diẹ latari ẹsun ole ori ẹrọ ayelujara ti EFCC fi kan an eyi ti wọn n pe ni Yahoo Boy lorilẹede Naijiria.
Gbogbo wọn bá dá àwọn ère oriṣa tí ó wà lọ́wọ́ wọn jọ fún Jakọbu, ati gbogbo yẹtí tí ó wà ní etí wọn, Jakọbu bá bò wọ́n mọ́lẹ̀ lábẹ́ igi oaku tí ó wà ní Ṣekemu.
Igbakeji ajo naa nipinle Kaduna, Alhaji Hassan Tahir-Tanimu, naa fidunnu re han lori ona ti won gab seto owoya naa ko le kari gbogbo agbe to setan lati sise.
Wọn ni Ọba Oke lo fi awọn da ara to wu u, ẹni to ba si le se iranlọwọ fun iru awọn, ko se e, sugbọn awọn si n dupẹ lọwọ Ọlọrun fun isẹda awọn.
Ìdánimọ̀ Onílò”, ká tún gée kúrú sí “Ike NIO”.
Ààrẹ buwọ́lù abadofin mí Ko tan sibẹ.
 Gege bi Kane se so lasiko to n ba awon akoroyin soro,“Mo ni igbagbo pe mo sile se, ti mo ba le pa okan po ninu awon ifesewonse ti o ku.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Pregnancy cravings: Ìgbésẹ̀ wo ní aláboyún lé gbé láti dẹ́kun ìjẹkújẹ nínú oyún?
Emir lọ sile ẹjọ, o si gba aṣẹ to fofin de igbimọ top n wadii rẹ.
Gbajúmọ̀ ọmọ tíí gbàkúnlẹ̀ ìyá, Tíí gbàdọ̀bálẹ̀ lọ́wọ́ baba tó bí í lọmọ.
''Iru awọn to ba ni aisan ''asthma'' ko gbọdọ fin eefin yii simu bi bẹẹ kọ, o le ṣe akoba fun wọn'' Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Kí ni àyájọ́ ‘Má wọ kọ́mú’ wà fún?
6 Bẹ́ẹ̀ni, òun ti dáwọ́lé iṣẹ́ títóbi kan; nítorínáà èmi yíò ṣe òun bíi ọ̀wọ́ inà àti ángẹ́lì tí ó ńjíṣẹ́ ìrànṣẹ́; òun yíò ṣe iṣẹ́ ìránṣẹ́ fún àwọn tí wọn yíò di ajogún ìgbàlà tí wọn ngbé ní ilé ayé.
Sùgbọ́n ni ǹka tó fàrahàn pé ń ṣẹlẹ̀ ni ìgboro báyìí, àwọn ọdọ́ kan ti ń kéde lójú òpó twitter pé ìw'ọ́de míràn ti bẹ̀rl ní ìpínlẹ̀ Eko Kílò ń ṣẹlẹ̀ lójú òpó twitter Ọ̀kan nínú àwọn gbajúgbajà lójú òpó twitter #OurFavonlineDoc sọ pé, ìwọ́de ti bẹ̀rl ni ìlú Eko àti Ibadan, àti pé ọ̀pọ̀ àwọn ojú pópó ni wọ́n tipa Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Promise Akinlade: ọmọ ọdún mọ́kànlá tó ń fi ìlù dárà bíi àgbàlagbà sọ̀rọ̀ nípa tálẹ́ǹtì rẹ Lásìkò ti àwọn alákoso ìfẹ̀hónùhàn Endsars ṣe ìpolongo òmíràn tí yóò wáyé lónìí ni wọ́n ti kéde àwọn ǹkan tí wọ́n ń fẹ́ lọ́dọ̀ ìjọba.
Gomina Ortom so oro ohun di mimo lasiko to n ba awon akoroyin soro leyin ipade alatilekun mori eyi ti o waye nile egbe naa nilu Abuja, laarin gomina ohun ati alaga egbe oselu APC, Adams Oshiomhole.
Nígbà tí àwọn tí ń tọ́jú agbo ẹlẹ́dẹ̀ rí ohun tí ó ṣẹlẹ̀, wọ́n bá sá kúrò níbẹ̀, wọ́n lọ ròyìn ní ìlú ati ní ìgbèríko.
Àwọn Juu yòókù bẹ̀rẹ̀ sí ṣe àgàbàgebè pẹlu Peteru.
Aṣofin Rotimi Olowo to n soju ẹkun Idibo Ṣomolu
Bakan naa ni ọga agba ọlọpa pasẹ kia mọsa fawọn ọlọpa ọtẹlẹmuyẹ, atawọn akọsẹmọsẹ oluwadi iwa ọdaran pe lẹyẹosọka pe ki wọn sugba ileesẹ ọlọpa to wa ni ilu Yenegoa lati mu ki iwadi wọn ya kankan, ki akara awọn olubi ẹda naa lee su sepo kiakia.
 Aare Buhari ni  yoo je aare keta ti yoo lo fun ipade apero ti OIC
Ibẹru IkuIdamu inu ọpọlọ leyi nitori pe ọpọlọpọ wọn lo n bẹru iku ṣugbọn ti wọn ko le sọ ọ jade.
Bi a ko ba gbagbe awọn mejeeji takurọsọ lori pipin nkan iranwọ fawọn arailu lasiko Covid 19.
Awọn eeyan orilẹede Naijiria jẹ ọdọ: mẹrin ninu mẹwa awọn eeyan Naijiria ni ọjọ ori wọn ko to ọdun mẹrinla.
Lati dahun ibeere yii, o ti di igba mọkanla ọtọọtọ bayii to yẹ ki aye parẹ ṣugbọn ti ko ṣẹlẹ.
Armed Robbery: Ọmọ Nàìjíríà mẹ́jọ gba ìdájọ́ ikú ní UAE
Wọ́n bá ara wọn sọ pé, “Ẹ má jẹ́ kí á ya á, gègé ni kí ẹ jẹ́ kí á ṣẹ́ láti mọ ti ẹni tí yóo jẹ́.
Ninu atẹjade ti akowe fun eto iroyin gomina Makinde, Taiwo Adisa sọ wi pe awọn agbẹbọn naa sekọlu si ile itura naa, ti awọn kan si tun gun ọgba naa ni ọsan Ọjọbọ.
Ohun ti a gbọ ni pe, ileewosan ti baba yii ti lọ n gba itọju fun kokoro arun HIV ni ọmọdebinrin yii ti n ṣiṣẹ olubanitaja bẹẹni awọn ọlọpaa ti fi baba agba yii silẹ lẹyin idunadura yii.
e Eyi to ba maa ṣe akoba fun iwọ tabi ọmọ inu rẹ ni ko dara lati jẹ ti o si gbọdọ gbe igbesé lati dẹkun jijẹ wọn.
Ẹlòmíràn kanlẹ̀ ta ilẹ̀ baba rẹ̀ fún un ni l’ówó pọ́ọ́kú.
Sunday Igboho, ẹni to wa ninu ọkọ ayọkẹlẹ rẹ pẹlu ọrẹ rẹ kan lo n sọrọ naa lowe lowe, lai darukọ awọn to n ba wi.
Awọn eniyan ṣalaye kikun lori ohun to ṣokunfa awọn adura ati ikinni fun ọlọmọ tuntun daadaa.
Èèyàn 97 ní àrùn Coronavirus tún ṣẹ̀ṣẹ̀ ràn ní Nàìjíríà ní Ọjọ́ Àìkú Ajọ to n gbogun ti ajakalẹ aarun lorilẹ-ede Naijiria, NCDC ti kede pe eeyan 97 miran ti kun iye awọn to ti ni aarun COVID-19 ni Naijiria.
” (Ìtumọ̀ “Kefa” ni “àpáta”, “Peteru” ni ní èdè Giriki.
Bakan naa, ajọ SERAP tun rọ Bensouda lati ṣewadi ikuna ijọba Naijiria fun ọpọlọpọ ọdun, lati wa nnkan ṣe si ọrọ naa.
"Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: ""Bàbá mi kú, kò sówó ni mo ṣe kúrò ní fásitì Ilorin láti fọ gíláàsì ọkọ̀ lójú pópó"" Adúmáadán ni mí; ọmọ pé síbẹ̀!"
Ọdun 2012 ni Ajọ EFCC ti fi ẹsun iwa ajẹbanu kan Abdulrasheed Maina, ti wọn si ti bẹrẹ si ni wa lati ọdun 2015.
Láti ọwọ́ àwọn angẹli ni alárinà ti gba òfin.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Body Farms: Ṣé ó tọ̀nà láti fi ojú òkú ráre báyìí?
Nítorí Ọlọrun sọ ninu Ìwé Mímọ́ nípa Farao pé, “Ìdí tí mo fi fi ọ́ jọba ni pé, mo fẹ́ fi ọ́ ṣe àpẹẹrẹ bí agbára mi ti tó, ati pé kì ìròyìn orúkọ mi lè tàn ká gbogbo ayé.
Ijọba Naijiria paṣẹ pe ki gbogbo ẹni to n lo ẹrọ ibanisọrọ forukọ silẹ ki wọn le gbogun ti awọn alakatakiti ẹsin Islam, Boko Haram to n dunkooko ni Naijiria.
Akwa United f'agba han ẹgbẹ agbabọọlu Hawks lati orilẹede Gambia pẹlu ami ayo mẹta si meji lati lee kopa ni ipele yii.
Àwọn oníṣẹ́ rẹ̀ wí fún un pé, “A gbọ́ pé àwọn ọba Israẹli a máa ní ojú àánú, jẹ́ kí á sán aṣọ ọ̀fọ̀ mọ́dìí, kí á wé okùn mọ́ ara wa lórí, kí á sì lọ sọ́dọ̀ ọba Israẹli, bóyá yóo dá ẹ̀mí rẹ sí.
Iléeṣẹ́ ìjọba méjì NIPOST àti FIRS, fẹ̀dí ara wọn síta lórí Twitter Mo kábàámọ̀ ìbáṣepọ̀ èmi àti Eric nínú ilé Big Brother - Lilo Ka3na àti Lilo ló kọ́kọ́ dágbére fún ètò Big Brother Naija 2020 Ìdí rèé táa fi fọwọ́ òsì júwe ilé fún òṣìṣẹ́ àádọ́rin ọkọ̀ bààlú - Air Peace O tẹsiwaju wi pe ata ọdun ni ohun lọ ra lasiko ti ọmọ naa ati awọn ọmọ oun jọ n ṣere ni iwaju ita, bẹẹ sini oun sọ fun aburo ọkọ oun kan lati mojuto wọn.
Oríṣun àwòrán, Yusuf_satia/instagram Àkọlé àwòrán, Oloogbe Yusuf Satia ati gbajugbaja olorin Fuji, Wasiu Ayinde Awọn oṣere bi i Toyin Adewale, ati Bose Alao naa ti n ṣe idaro rẹ.
 Èyí nìwé ìròyìn yí fi ń tọ ́ ka sí àìperegedé ètò-ẹ ̀ kọ ́ àwọn ilé-ẹ ̀ kọ ́ girama tí kò múná -dóko , tí àwọn akẹ ́ kọ ̀ ọ ́ jáde ibẹ ̀ yóò fẹ ́ láti wọn ilé-ẹ ̀ kọ ́ olùkọ ́ ti yábàá .
Ni ìyapa bá bẹ́ sáàrin àwọn eniyan nítorí rẹ̀.
Láti inú ẹ̀yà Bẹnjamini, tí wọ́n jẹ́ ẹ̀yà kan náà pẹlu Saulu, àwọn tí wọ́n wá jẹ́ ẹẹdẹgbaaji (3,000).
Mo bá rí ẹṣin funfun kan.
Argentina gbo ewuro soju awọn ikọ Super Eagles pẹlu bi wọn ti ṣe rán Naijiria pada sílé.
Nígbà tí ó di ìrọ̀lẹ́, Josẹfu ará Arimatia, ọlọ́lá kan ninu àwọn ìgbìmọ̀, wá.
Ninu oṣu Kẹta, ọdun 2020, ni iroyin jade pe kọmisana fun awọn alumọni inu omi nipinlẹ Kogi, Abdumumini Danga, fi ipa ba ọmọbinrin kan lopọ, to si tun lu u.
Wọ́n ní kí Aṣíwájú má kò ara rẹ̀ síta nípa sísọ ọ̀rọ̀ kòbákùngbé sí olùdíje ẹgbẹ́ PDP, Atiku Abubakar.
Ṣaaju ni Igahlo ti n kopa ninu igbaradi pẹlu ikọ Shenshua fun saa tuntun, ṣugbọn saa naa ni idaduro nitori arun Corona to bẹ silẹ lorilẹ-ede China.
O ni aisi idagbasoke ti ko jukan lo lo n fa ipe elekunjekun.
O ni rara ka maa ri lọrọ naa.
onisowo nitori pe o ba won lojiji.
fi asiko ohun tenumo pe ki gbogbo eni yoowu to ba n lowo ninu iwa odaran kan
gbọ nipa ipaniyan to waye ni ipinlẹ Kaduna, to jẹ Ila- Iwo oorun orile
Ṣugbọn Kristi ṣe olóòótọ́ gẹ́gẹ́ bí ọmọ ninu ìdílé rẹ̀.
Ko da ayo mẹta ni Ronaldo ko ba sawọn ikọ alatako wọn Sassuolo ṣugbọn ẹsẹ rẹ tase nibi to ti fẹ bọọlu sawọn.
Àkọlé àwòrán, Poposinsin odun Osun Oshogbo Ninu ile iya Osun ni ati fi oju ganni ọpọlọpọ eniyan ti wọn n se adura, lara awọn oloye ilu ti o wa ninu ile naa wi pe ile mimọ ni ile iya Osun jẹ, ati wi pe wọn kii wọ bata wọ ibẹ.
Gomina Ipinlẹ Ọyo, Seyi Makinde ti ni ẹgbẹrun lọna aadọtalelẹgbẹta Naira (N650,000) ni oun n gba gẹgẹ bi owo oṣu lati igba ti oun ti bẹrẹ iṣejọba gẹgẹ bi gomina.
Nibi igbẹjọ to waye ni ọjọbọ, onidajọ Nicholas Oweibo to gbọ ẹjọ ati gba oniduro rẹ gba ki wọn gba oniduro akọrin naa pẹlu milliọnu meji naira ati oniduroi meji.
 bí ó bá ṣe òkùnfà ẹ ̀ jẹ ̀ ṣíṣe lọ ́ pọ ̀ lọpọ ̀ láti inú ẹ ̀ dọ ̀ fóró , a ń pè é ní àkópọ ̀ àmì àrùn ẹ ̀ jẹ ̀ ṣíṣe láti inú ẹ ̀ dọ ̀ fóró tó burú púpọ ̀ .
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù 2019 Election: INEC ya ọ̀sẹ̀ kan sílẹ̀ fún àyẹ̀wò orúkọ oludibo 26 Ọ̀wàrà 2018 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 8 Bélú 2018 Oríṣun àwòrán, @inecnigeria Àkọlé àwòrán, Aworan alaye ayẹwo orukọ awọn oludibo Ajọ eleto idibo lorile-ede Naijiria, INEC ti bẹrẹ afihan iwe orukọ awọn oludibọ jakejado orileede Naijiria.
Bi ọkọọkan wọn, isẹ ti wọn se ati bi wọn se ba itiju kuro lori aleefa se lọ ree: Nuhu Ribadu (2003-2007): awọn 'ọta' aarẹ Obasanjo nikan lo n doju 'ija igbogun ti iwa ibajẹ kọ.
Kò gbọdọ̀ sí ìwúkàrà ninu ilé yín fún ọjọ́ mejeeje, nítorí pé bí ẹnikẹ́ni bá jẹ burẹdi tí ó ní ìwúkàrà ninu, a kò ní ka irú ẹni bẹ́ẹ̀ kún àwọn eniyan Israẹli mọ́, kì báà jẹ́ àlejò tabi onílé ní ilẹ̀ náà.
Kí ni mo lè sọ nípa rẹ,kí sì ni ǹ bá fi ọ́ wé, Jerusalẹmu?
Ní òru ọjọ́ náà, Ọlọrun fara han Solomoni, ó wí fún un pé “Bèèrè ohun tí o bá fẹ́ kí n fún ọ.
Ṣọọṣi naa tun sọ pe lẹyin ọdun diẹ, LaVey bẹrẹ si iṣẹ idán okunkun ati agbara irubọ, o n ṣe nipa igbega lẹni iṣẹ, ẹbun ọfẹ, owo, adun ibalopọ, ati pipa tabi yanju awọn ọta rẹ.
Wizkid dagba ni Ojuelegba nipinle Eko, o bere orin kiko lomo odun mokanla pelu oruko Lil Prince.
Ọ̀pọ̀ eniyan níí máa ń wá ojurere ẹni tó lawọ́,gbogbo eniyan sì ni ọ̀rẹ́ ẹni tí ń fúnni lẹ́bùn.
Mo ti fi pẹ̀lẹ́pẹ̀lẹ́ wádìí ohun gbogbo fínnífínní.
Èmi gan-an ni gbòǹgbò ati ọmọ Dafidi.
A Ayokunle, sọ fun BBC Yoruba pe ẹgbẹ CAN ko le ṣe atilẹyin fun Fatotinbo tabi Busola lai jẹ pe ẹgbẹ PFN ti CAN fun ni aṣẹ lati ṣe iwadii ọrọ naa ba jabọ.
Èyí ni ẹ̀jẹ̀ mi tí a fi dá majẹmu, ẹ̀jẹ̀ tí a ta sílẹ̀ fún ìdáríjì ẹ̀ṣẹ̀ ọpọlọpọ eniyan.
"Emi gan ni mo maa n lọ ra ẹya ara ọkọ fun'ra mi""."
Oríṣun àwòrán, AFP/Getty Images Àkọlé àwòrán, Pyeongchang gbalejo lọjọ kẹsan si ọjọ karundinlogbon osu keji Iroyin fi lede wipe gbajugbaja elere idaraya to le ni ẹgbẹrun mẹta ni yoo kopa ninu Winter Olympics fun ayẹyẹ ami irawọ (Medal) to le lọgọrun ninu orisirisi ere idaraya marundinlogun.
Angẹli, aláṣẹ ìjọba Pasia dè mí lọ́nà fún ọjọ́ mọkanlelogun; ṣugbọn Mikaeli, ọ̀kan ninu àwọn olórí aláṣẹ, ni ó wá ràn mí lọ́wọ́; nítorí wọ́n dá mi dúró sọ́dọ̀ aláṣẹ ìjọba Pasia.
Ní Ọjọ́ Ìsinmi kan, Jesu lọ jẹun ní ilé ọ̀kan ninu àwọn olóyè láàrin àwọn Farisi.
Iko agbaboolu Super Eagles ti setan fun ifesewonse ipegede fun idije boolu afesegba ile adulawo AFCON, eleyi ti won yoo gba pelu orile-ede Seychelles niluu Victoria lojo abameta (Saturday).
Lórí àwọn aposteli ati àwọn wolii ni a ti fi ìpìlẹ̀ ìdílé yìí lélẹ̀, Kristi Jesu fúnrarẹ̀ sì ni òkúta igun ilé.
 yàtọ ̀ sí isẹ ́ àgbẹ ̀ tó jẹ ́ tajá tẹran ló ń seé wọ ́ n fẹràn láti máa da aró , wọ ́ n mọ ̀ nípa àdìrẹ ẹlẹ ́ kọ dáadáa .
, Duration 2,525 Owewe 2020 Fídíò, Akomolede: Bolaji Faleke ni Olùkọ́ tó ń kọ́ wa ní àṣà oge ṣiṣe lórí BBC Yorùbá1 Owewe 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 3 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 5 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Ó ṣeni láànú pé ìwé ẹ̀rí ti èèyàn ní là n wò, kíìṣe irú ìmọ̀ tí wọ́n ní.
O ni arakunrin kan lo ni ki oun ṣe iranlọwọ lati ba oun ti ọkọ lai mọ pe o fẹ mu oun ni.
Dídá aṣọ bo ori ti a ba n sun 7.
Àṣẹ OLUWA ni àwọn ọmọ Israẹli ń tẹ̀lé láti tú àgọ́ wọn palẹ̀ ati láti tún àgọ́ wọn pa.
Ẹ bẹ̀rẹ̀ láti ibi mímọ́ mi.
“Sọ fún Aaroni arakunrin rẹ pé kí ó má ṣe máa wọ ibi mímọ́ jùlọ, tí ó wà lẹ́yìn aṣọ títa, níwájú ìtẹ́ àánú tí ó wà lórí àpótí ẹ̀rí nígbà gbogbo, kí ó má baà kú; nítorí pé n óo fi ara hàn ninu ìkùukùu, lórí ìtẹ́ àánú.
níbi idibo gbogboogbo ti yóò wáyé lósù tó ń bọ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Angela Merkel ti Germany fún ìgbà èkejì, gbọ̀n pẹ̀pẹ̀ lóde 27 Òkùdu 2019 Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Angela Merkel seen shaking during ceremony in Berlin Olootu ijọba orileede Germany Angela Merkel tun ti gbọn pẹpẹ nitagbanga fun igba ẹlẹkeeji.
 ilé ìgbìmọ ̀ méje ọ ̀ tọ ̀ ọ ̀ tọ ̀ ló ti wà , àkọ ́ kọ ́ wáyé ní oṣù kẹwá ọdún 1979 tí èyí tó ń lọ lọ ́ wọ ́ lọ ́ wọ ́ sì bẹ ̀ rẹ ̀ ní ọjọ ́ kẹfà oṣù kẹfà ọdún 2011 .
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ìtàn ayé Ọba Seriki Abass ti Badagry, tó ní aya 128, ọmọ 144 Wo bí o ṣe le fi orúkọ sílẹ̀ fún ìgbani ṣíṣẹ́ ológun Nàìjíríà tó bẹ̀rẹ̀ Ọmọdé 5 àti àgbà 40 bómi òkun lọ, 37 mórí bọ́ lásìkò tí ẹ́ńgínì ọkọ̀ ojú omi gbiná Kò sí ọ̀nà láti jáde tàbí wọlé sí Mali, ikọ̀ ológun ọlọ́tẹ̀ kéde ìṣédeWo ibùdó arẹwà tí ọ̀pọ̀ èrò ń ya lọ ní Abuja Obìnrin kan dèrò ilé ẹjọ́ lórí ẹ̀sùn pé ó fi ọ̀bẹ rẹ́ ọmọ rẹ̀ lọ́rùn Adamu Adamu, Minista ètò ẹ̀kọ́ ti fi òfin àátẹ̀lẹ́ síta kí àwọn ilé ìwé lè wọlé Makinde ti sọ̀rọ̀ lẹ́yìn tí asekúpani Akinyele sálo mọ́ àwọn ọlọ́pàá lọ́wọ́ ní àhámọ́ Olólùfẹ́ mi ṣèèsì fi ọkọ́ gbá mi sí gọ́tà, mo rò pé ọlọ́jọ́ dé ni - Iya Osogbo Nigba ti BBC Yoruba bi Abdulwasiu pe ki ni yoo sẹlẹ lẹyin ti wọn ba tun yigi se, ti aya rẹ si tun bi ọmọ oloju bulu, baba Kaosara dahun pe ọmọ oloju gan ni oun n tọrọ lọwọ Ọlọrun bayii.
Wakati diẹ lẹyin ti Aarẹ Buhari fi atilẹyin rẹ fun Giadom han, ni Giadom kede pe ipade igbimọ amuṣẹya ati igbimọ alaṣẹ ẹgbẹ yoo waye lọjọbọ.
Aláàánú ni ọ́ OLUWA Ọlọrun wa, ò sì máa dáríjì ni, bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé a ti ṣọ̀tẹ̀ sí ọ.
Wọ́n ń fi ẹnu wọn súre,ṣugbọn ní ọkàn wọn, èpè ni wọ́n ń ṣẹ́.
Gẹ́gẹ́ bi àtẹ̀jáde tó fi síta, wọ́n gbé àwọn ilé ìwé tí, yálà ti aládani tàbi ti ìjọba ni láti dènà ààrun coronavirus tó tún n fẹ́ bọ̀, ti àwọn tó ni ààrùn náà sì tún ti n pọ̀ sii ni Nàìjíríà.
Ẹfa, ookan, aarun, 615 ni nọmba tuntun ti ijọba ipinlẹ Ọyọ nipasẹ ajọṣepọ pẹlu ajọ ibaraẹnisọrọ, NCC gbe kalẹ fun araalu lati maa pe lai ni kete ti wọn ba kọlu ipenija abo ninu irinajo wọn.
Ó tẹ orí yín ba, ó jẹ́ kí ebi pa yín, ó fi mana tí ẹ̀yin ati àwọn baba yín kò mọ̀ rí bọ́ yín, kí ẹ lè mọ̀ pé kìí ṣe oúnjẹ nìkan ní o lè mú kí eniyan wà láàyè, àfi gbogbo ọ̀rọ̀ tí ó ti ẹnu OLUWA jáde.
Jesu sọ fún un pé, “Ọ̀rẹ́ kí ló dé o?
Charles Akah to n gbe ni Oyigbo sọ pe inu ile loun wa lati ọjọ kọkanlelogun oṣu kẹwaa ti ijọba ti kede ofin konle-o-gbele nipinlẹ Rivers.
Nigba ti o n soro lati inu iwe-mimo, alufaa oun so pe, imole nikan ni okunkun beru, bi imole ba tan, okunkun a parade laisi anihani.
Ẹgbẹ kan to n jẹ The Osun Civil Societies Coalition (OCSC) lo ṣagbatẹru ifẹhonahan naa.
    Ṣùgbọ́n obìnrin náà ṣe aájò mi púpọ̀ ọ̀ran rẹ̀ ló sì jẹ́ ki n mọ̀ pé ìfẹ́ a máa fa ìfẹ́ yọ, nítorí sáájú àkókò náà, n kìí fẹ́ràn obìnrin rara ó sì dàbí ẹni pé ìṣẹ̀dá mi ni ki n máa kórira wọn ṣùgbọ́n nígbà tí mo máa fi eléyìí sílẹ̀ omi fẹ́rẹ̀ bọ́ lójú mi bẹ́ẹ̀ ni n kò sì tilẹ̀ ní ọkàn àti fẹ́ ẹ.
Awọn ifẹsẹwọnsẹ Champions League ti yoo waye niyii: Ọjọ iṣẹgun, ogunjọ osu keji Chelsea vs Barcelona Bayern Munich vs Besikta Ọjọru, ọjọkọkanlelogun osu keji Sevilla vs Manchester United Shakhtar Donetsk vs Roma.
Oníṣẹ́ àdáni 250,000 ni ìjọba ṣe ìlànà yìí fún Kìí ṣe ebi, ìyà tàbí ìṣẹ́ ló mú kí wọ́n yabo àwọn ilé ìkẹ́rùsí - Femi Adeshina Àkùkọ dojú ìjà kọ ọlọ́pàá, ikú ló já sí fún agbófinró Ẹni tó jí ọ̀pá aṣẹ ń bọ̀ wá túbá fúnrarẹ̀, mo fi dáa yín lójú gẹ́gẹ́ bí ìyá - Erelu Kuti Bakan naa ninu fidio miran to fi lede, o fihan gbangba pe oun ko fọwọsi abadofin to de bi awọn ọmọ eniyan ṣe n sọrọ lori ẹrọ ayelujara, amọ ohun ti oun sọ ni pe, ki wọn ma lo ẹrọ ayelujara lati fi da orilẹede Naijiria ru.
Breastfeeding week 2020: Bí ọyàn ṣe tóbi tàbí kéré sí kò ní ǹkan ṣe pẹ̀lú ìfọ́mọlọ́yàn
 Àrùn sòbìà tì wà láti ìgbà àtijọ ́ .
” Ìtumọ̀ èyí ni, “Ọlọrun mi!
Aare so pe “ojo iwaju orile ede yii dara,idagbasoke ti de ba  eto oro aje orile ede yii.
Ọjọ̀gbọ̀n Dikirullai sàlàyé pé àwọn ètò ti ààrẹ Buhari ti ń gbé kalẹ tẹ́lẹ̀ wà fún àwọn tálákà tó ń dibò jùlọ lórilẹ̀-èdè yìí.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Rotweilers Aja Pitbulls: Pitbulls lo buru ju ninu gbogbo aja ti eniyan ko gbọdọ gbe sile, ti o si ti pa ọpọlọpọ eniyan kaakiri agbaye.
Ìdí rẹ̀ nìyẹn tí ìyá ọkùnrin apànìyàn náà fi ní ìbọn nílé, tí ọwọ́ ọmọ rẹ̀ fi tẹ̀ẹ́.
Ronaldo kọ lati lọ si ibi ayẹyẹ naa to waye lalẹ ọjọ Aje niluu Paris lorilẹ-ede Faranse, koda oun lo gba ipo kẹta nigba ti adẹyinmu ẹgbẹ agbabọọlu Liverpool, Virgil van Dijk ṣe ipo keji mọ Ronaldo lọwọ.
    Bí wọ́n ti wọ ibi tí ọba yìí jókòó sí, wọ́n bá àwọn ìjòyè rẹ̀, ọba sì bẹ̀rẹ̀ síó gbọ̀n bí ẹni tí òtútù ń pa, gbogbo ẹ̀wù rẹ̀ ń fẹ́ lẹ́lẹ́ bí ìgbà tí ẹ̀fúùfù ń fẹ́ igi oko.
lóde òní , yorùbá wà káàkiri ilẹ ̀ àwọn aláwọ ̀ dúdú ( Áfíríkà ) , amẹ ́ ríkà àti káàkiri àwọn erékùsù tí ó yí òkun Àtìlántíìkì ká .
Agbekalẹ ilana yi ni ipalara awọn ara ilu lọna orisirisi paapa awọn ile itaja to n ta ọti ati awọn ile ounjẹ.
Ní ọjọ́ kan, àwọn ọmọ Ọlọrun wá láti fi ara wọn hàn níwájú OLUWA.
Ilé ẹjọ́ pàṣẹ kí Sẹ́nétọ̀ Elisha Abbo san N50m fún obìnrin tó fìyà jẹ Mi o fi ìgbà kankan sọ pé Buhari ni yóò jẹ ààrẹ kẹ́yìn ní Nàìjíríà- Akintoye Ahmed ni ikọ Amotekun jẹ idunkooko nla mọ isọkan orilẹede Naijira, lasiko to ba bẹrẹ isẹ aabo ẹmi ati dukia lẹkun naa.
A o maa fi to yin leti bi isẹlẹ naa se n lọ niluu Abuja.
17 Bélú 2020 Fídíò, #EndSARS : Àwọn ọ̀dọ́ dáná sun tírélà akẹ́rù tẹrùtẹrù ní Ekiti22 Ọ̀wàrà 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Ọ̀pọ̀lọpọ̀ òkú ẹyẹ Igún ré bọ́ lọ́jà Eke-Ihe Mo mọ̀ọ́mọ̀ dá €37,000 ti mo rí he padà ni -Ọmọ ogun Bashir Iléeṣẹ́ ọlọ́pàá Èkó ní àwọn kò mọ ohunkohun nípa ìwadìí ẹjọ́ Dakolo àti pásítọ̀ COZA mọ́ Ìlú ò rẹ́rìn ín rárá, Alaafin Adeyemi III fárígá fún Buhari nínú lẹ́tà tuntun Ṣaaju akoko yii ni awọn ọmọ ẹgbẹ Shiite ti n ja fun ki wọn tu adari ẹgbẹ wọn, Sheikh Ibrahim El-Zakzaky ti wọn ti fi si ahamọ lati ọdun 2015 silẹ.
Wọ́n hán agbọ̀n náà, wọ́n sì ń fò lọ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Yollywood: Saheed Balogun sìnkú ìyá rẹ̀, Ìròyìn ohun tó ṣẹlẹ̀ lágbo òṣèré lọ́sẹ̀ yìí nìwọ̀nyí 6 Ọ̀pẹ̀̀ 2019 Oríṣun àwòrán, ogogo/instagram Nnkan kan lagbo awọn oṣere tiata lọsẹ yii.
Lẹyin eyi ni wọn tun din ku si ọgọrun un miliọnu Naira.
'Ọmọ ọdọ Ọpẹ Bademọsi jẹwọ pe oun l'oun pa ọga oun' Ọmọ ọdọ to n da ina ounjẹ fun Oloye Ọpe Bademosi ti jẹwọ wi pe oun lo pa ọga rẹ lẹyin to jaa lo le.
Ni ti akọwe ikede fun gomina Ondo, sọ fun BBC pe lootọ ni ofin de awọn ọkọ lati ipinlẹ miran si Ondo, aaye gba awọn ọlọkọ eero laarin ipinlẹ Ondo, kiki pe wọn ko gbọdọ gbe ju eero meji lọ.
O ti di asa lorilẹede Naijiria lati maa ri oniruuru ọti lile ti wọn yoo patẹ lẹba oju popo laibikita.
Oyè Ibadan kò sí fún títà - Otun Olubadan, Lekan Balogun Àwọn ògo Ibadan márùn ún tí ikú mú lọ lọ́dún 2020 Bi awọn ara ilu ba ti ṣe n ni ki ijọba yan ọmọ wọn lawọn alakoso yoo ma sọ pe ilana ko yọ ẹnikẹni silẹ.
Ajọ to n koju iwa jẹgudujẹra lorile-ede Naijiria ti figbe bọ ẹnu fawọn eeyan Naijiria lati yago fun eto sogundogoji MMM to wọlu pada.
Wolii arole ni abajade ifẹsẹwọnsẹ naa ba oun ninu jẹ pupọ ṣugbọn ireti ko tii pin.
Nígbà náà ni àwọn ìjòyè kan lára àwọn ará Efuraimu: Asaraya, ọmọ Johanani, Berekaya, ọmọ Meṣilemoti, Jehisikaya, ọmọ Ṣalumu ati Amasa, ọmọ Hadilai dìde, wọ́n tako àwọn tí ń ti ojú ogun bọ̀, wọ́n sọ fún wọn pé, 
O ni sise  akọsilẹ itan abalaye to je mo ti awon ilu ati agbegbe ipinle Osun jẹ ifokansin ti ohun maa n so nipa re.
“Yóo fi gbogbo agbára ati ìgboyà rẹ̀ gbé ogun ńlá ti ọba Ijipti; ọba Ijipti náà yóo gbé ogun ńlá tì í, ṣugbọn kò ní lè dúró níwájú ọba Ijipti nítorí pé wọn yóo dìtẹ̀ mọ́ ọn.
Baba-onírùngbọ̀n-yẹ́úkẹ́ mi ọ̀wọ́n, mo dúpẹ́ lọ́ọ́ yín fún gbogboìtọ́jú wa tí ẹ ti ṣe sẹ́hìn, Ọlọ́run yóó bú sí àpò yín.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Sunday Igboho kàn ń gbé ‘Camera’ lẹ́yìn kiri, kí wọ̀n lè rò pé ó ń jà fún Yorùbá - Gani Adams Donald Trump dèrò ilé ìwòsàn torí àrùn Coronavirus tó mu Ìlànà ‘Referendum’ nìkan la fi le gba orílẹ̀èdè Oduduwa, kìí ṣe ìwọ́de Aṣọ́bodè ṣèèsì pa ‘Panel Beater, aya mẹ́rin àti ọmọ 18 ń bẹ̀bẹ̀ fún ìrànwọ́ ₦750m ni Akeredolu ń gbà lóṣù fún ‘Security Vote’ àti ₦150m owó oṣù - Agboola Ajayi fèsì INEC kéde agbègbè ẹsẹ̀ odò 270 ti èrú ìbò ti le wáyé ní ìpínlẹ̀ Ondo Ẹgbẹ́ tó ń fẹ́ Oduduwa Republic kọ̀wé ẹ̀hónú sí UN, EU, AU àti ìjọba Gẹ̀ẹ́sì Àjọ EFCC ti mú ọ̀dọ́kùnrin mẹ́wàá lórí ẹ̀sùn jìbìtì lílù lórí ayélujára ní Oyo Irọ́ ni o!
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Osun Decides: Adegoke ni òun kò ni lo kọngilá mọ́ nipinlẹ Ọṣun Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Osun Decides: Adegoke ni òun kò ni lo kọngilá mọ́ nipinlẹ Ọṣun 17 Owewe 2018 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 19 Owewe 2018 Alfred Adegoke lo n dije labẹ ẹgbẹ òṣèlú 'Socialist Party of Nigeria' nipinlẹ Ọṣun.
 ohun a ń so nip é òrò-ìse lè ní àfikún nínú gbólóhùn sine kí á pè é ní òrò-àìgbàbò .
Gani Adams: Iléèṣẹ́ ọlọ́pàá ti kàn sí OPC lórí ètò ààbò OPC: Bí a ṣe gbéná wojú awọn ọ̀daràn tó ń d'àlú Ikire rú rèé Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Iba Gani Adams: Bẹ́ẹ gbé màláíkà kan lọ sí Aso Rock, kò lè ṣàṣeyọrí Ọjọ Ẹti to kọja ni awọn kan pa Abilekọ Ọlakunrin loju ọna Ore si Sagamu.
Ilé Arúgbó Saraki: Èyí ni ìdí tí ìjọba ìpínlẹ̀ Kwara fí wó ìlè arúgbó ní ìdàjí
Àníyàn rẹ̀ kanṣoṣo ni láti tẹ́ ọ̀gágun rẹ̀ lọ́rùn.
Ṣé ìwọ láyà ti o mọ òwe Yorùbá dáadáa?
Nigba to wa ni ọmọ ọdun mọkanlelogun lo di olootu iwe iroyin Southern Nigerian Defender, eyi to mu ko jẹ olootu iwe iroyin to kere julọ ninu iwe itan Naijiria.
Ó ní, “Ọtí tí ó bá dùn ni gbogbo eniyan kọ́ ń gbé kalẹ̀.
Ki ọmọ kẹta ma ba ku, lo tun mu ki iya wọn pada si ile Ọrunmila, ṣugbọn iyawo rẹ, Ilẹ lo ba nile.
Àwọn ara ìlú yóò maa san owó gọbọi fún ọjà ti wọ́n ba ra nítori owó ti wọ́n fi n gbe ọjà wọlé.
 a kò lè fi wé ipò ọlá .
 ládípọ ̀ sábà ma ń kópa nínú eré oníṣe rẹ ̀ lọ ́ pọ ̀ ìgbà .
O ni ki ijọba Buhari rọra ṣe pẹlu ootọ inu nitori gbogbo ohun ti a ba ṣe loni yoo di ọrọ itan lọla.
Dafidi bi OLUWA pé, “Ṣé kí n kọlu àwọn ará Filistia, ṣé o óo fún mi ní ìṣẹ́gun lórí wọn?
Alaga ẹgbẹ naa, Tukur Dan Alli, sọ pe asiko yi lawọn akọroyin nilo iranwọ ijọba ati awọn aladani lati le daabo to peye bo wọn.
Bí mo ṣe jàjà bọ́ lọ́wọ́ àrùn Coronavirus rèé- Ayodeji Osowobi Òfìfo ṣọ́ọ̀ṣì pa aṣọ dà fún àwọn Páṣítọ̀ Nàìjíríà Èèyàn 16 míràn tún ti ní àrùn Coronavirus ní Naijiria Màmá Guardiola d'olóògbé lẹ́yìn tó lùgbàdì Coronavirus Mo mọ ẹ̀wà lóúnjẹ àjẹsùn látìgbà tí mo ti ń dá ọmọ mi tọ́-Davido Bí ilumọọka agbabọọlu Drogba ṣe dáwọ ogun dúró ní Ivory Coast Awọn mejeeji gbọdọ wa ni igbele bayii titi di igba ti igbẹjọ wọn yoo fi bẹrẹ.
Toyin Abraham bí ọmọkùnrin jòjòló Àwòrán àwòdamiẹnu rèé lásìkò ọdún Ọ̀ṣun Osogbo Bi o tilẹ jẹ pe Siasia wa nibi ipade akọroyin naa sibẹ ko ba awọn akọroyin sọrọ funrarẹ pẹlu awawi pe awọn amofin oun ti n wo ọrọ naa.
Asaraya ni ó bí Helesi, Helesi ni ó sì bí Eleasa.
Igbokwe  tun tepele mo on pe ti won ko ba  gba awon to wa ni ikawo awon agbesunmomi sile o se e se ki awon eniyan naa padanu emi won.
Titi di igba ti a fi n ṣe akojọ iroyin yii, aafin Oyo ko ti fesi si gbogbo ohun ti olori Aanu n sọ.
"Irọ́ ni pé mò kò ""Palliatives"" pamọ́ sí ilé mí-Abike Dabiri-Erewa Gbọ́yì-sọ̀yí àti ìròyìn èké láti ọ̀dọ̀ àwọn olólùfẹ́ wa ló ṣáábà ma ń da ìgbéyàwó àwọn òṣèré rú- Ọpẹ Ayeola Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Promise Akinlade: ọmọ ọdún mọ́kànlá tó ń fi ìlù dárà bíi àgbàlagbà sọ̀rọ̀ nípa tálẹ́ǹtì rẹ Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?"
Oríṣun àwòrán, Other Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
8 owo dollars ninu osu keji, ti o to gbe soke di bilionu merindinladota 46 billion naaOkoroafor gboriyin bi owo ipamo orile-ede Nigeria se n gberu si naa  fun akitiyan ile-ifowopamo, sise adinku owo ori eru to n wole, epo-robi ati oja ti kii sepo-robi ti won ko lo si ile-okere.
Ó ń ṣiṣẹ́ àánú tí ó yani lẹ́nu ní ọ̀run ati ní ayé.
Fun idi eyi, o ni awọn yoo ya N9.
Mika Bá Àwọn Olórí Israẹli Wí.
Wọn ni ijọba la owo kalẹ lati na fi gba atibaba, gba aga, tabili atawọn ohun eelo abẹle miran lasiko idibo to kọja.
Oríṣun àwòrán, Felix Chukwuneke Bawo ni Chisom ṣe lo igbeaye rẹ?
Oríṣun àwòrán, AFP Àkọlé àwòrán, Owo to to biliọnu mọkanlelogun Naira ni ajọ isọkan ilẹ Yuroopu, EU ti na lori gbigbogun ti iwa kiko awọn eeyan lọ silẹ okeere lọ sowo kotọ lorilẹede Naijiria Nkan bii onibara mẹfa si meje ni a nni lojumọ.
Super Falcons: Thomas Dennerby di olukọni mọọgba
Kíni Gómìnà Sanwo-Olu sọ nípa ìṣẹ̀lẹ̀ ìpànìyàn Lekki tó ń mú awuyewuye wà lórí ayélujára?
Oríṣun àwòrán, Twitter O ni bakan naa lawọn kan si ileeṣẹ Henkel Nigeria Limited, ti Richard ti lọ ṣisẹ ti awọn si paṣẹ pe ki wọn lọ yọju si mọlẹbi Richard ni kiakia.
yálà kí ìyàn mú fún ọdún mẹta, tabi kí àwọn ọ̀tá rẹ máa lé ọ kiri, kí wọ́n sì máa fi idà pa yín fún oṣù mẹta, tabi kí idà OLUWA kọlù ọ́ fún ọjọ́ mẹta, kí àjàkálẹ̀ àrùn sọ̀kalẹ̀ sórí ilẹ̀ náà, kí angẹli Ọlọrun sì máa paniyan jákèjádò ilẹ̀ Israẹli.
Akomolede àti Aṣa: Ọ̀rọ̀ Ẹ̀yán ni Bunmi Femi Amao ń kọ́ wa lórí ètò Akọ́mọlédè àti Àṣà Ọ̀gá iléeṣẹ́ gbé £10 mílíọ̀nù ẹ̀bùn owó fún òṣìṣẹ́, èyí lohun tó pawọ́n pọ̀ Orílẹ̀èdè Amẹrika ti bẹ̀rẹ̀ sí ní wo wọlé-wọ̀de Atiku, àwọn ìyàwo rẹ̀ lórí owó tí wọ́n kó lọ sí òkèèrè Hisbah mú ọkùnrin mẹ́ta tó pín fídíò ìfipábánilòpọ̀ ọmọdébìnrin 16 tó fẹ́ ṣèyàwó lórí ayélujára Dokita Akinbodewa ni ibanujẹ ọkan ni yoo jẹ fun awọn dokita ni ileewosan kaakiri orilẹede Niajiria nitori iṣẹ yoo wọ wọn lọrun.
Ti a ba ti wá sí Saudi, a wa sin Ọlọrun ni.
Ti a ba wo ayipada to ti ba oṣuwọn yii, ti a si ṣagbeyẹwo rẹ lati asiko ti ẹgbẹ ANC ti gba ijọba l'ọdun 1994, aidọgba ga si laarin ọdun 1990 si 2005.
Ó bá pàṣẹ fún Hilikaya alufaa, Ahikamu ọmọ Ṣafani, Akibori ọmọ Mikaya, Ṣafani, akọ̀wé, ati Asaya, iranṣẹ ọba pé, 
Tinubu sọ pe iwa ti Obaseki wu sẹyin to ki awọn aṣofin naa yọ nipo ṣugbọn wọn ko ṣe bẹẹ nitori wọn yan ọna alaafia.
Ile igbimo asofin tun wa ro ijoba apapo lati kede oro airise gege bi igbesẹ pajawiri lorile ede Naijiria , ki won si ya ida ogun ninu ogorun un owo ti won ba n ri gba lati owo awon ti won ji owo orile ede yii , ki won si  maa fi pese  idagbasoke ile ise ati eto oro aje , ti yoo ni ipa Pataki lori awon ọdọ orile ede yii.
Wọn n reti ki awọn Minisita wọn kede lọjọ Aje, bi eto igbanisiṣẹ ọhun yoo ṣe lọ.
gbogbo dídẹnukọlè tàbí ìfàsẹ ́ yìn tí ó ṣẹlè ní ìbẹ ̀ rẹ ̀ pẹ ̀ pẹ ̀ ìjọba smith jẹ ́ kí àwọn oní ìwé ìròyìn ròpé harper ló máa rọ ́ pò ẹ ̀ .
Koda Isiaka di ipo asofin agba to n soju ẹkun idibo iwọ oorun ipinlẹ Osun mu leemeji, ki ọlọjọ to de ni odun 2017.
Wọn kede pe Falana Folarin (Falz), Segalink, ati adari awọn ọlọpaa ni Naijiria, Adamu ati Joe Abbah.
Nígbà tí wọ́n sọ fún Sanbalati ati Tobaya ati Geṣemu ará Arabia ati àwọn ọ̀tá wa yòókù pé a ti tún odi náà mọ, ati pé kò sí àlàfo kankan mọ́ (lóòótọ́ n kò tíì ṣe ìlẹ̀kùn sí àwọn ẹnubodè).
Ojú rẹ̀ ń kọ mànà bíi mànàmáná, ẹyinjú rẹ̀ sì ń tàn bí iná.
Fun apẹẹrẹ, laarin awọn ipinlẹ mẹrindinlogoji tawọn kẹkọ ti kọ idanwo Waec lọdun 2018, ipinlẹ Ọsun ṣe ipo kọkandinlọgbọn .
Sọ asọtẹlẹ ifẹsẹwọnsẹ to n bọ lọna 19/07/2019 Awọn ikọ Mu iko to wa nile Senegal vs Mu ikọkọ to wa koju wọn Algeria Yege Ọ̀mì Fìdírẹmi - Asọtẹlẹ awọn onimọ Asọtẹlẹ awọn onimọ Ifẹsẹwọnsẹ mi Pin asọtẹlẹ rẹ Whatsapp Facebook Twitter oju opo asọtẹlẹ rẹ ṣe ẹda oju opo yii o ti ṣe ẹda rẹ!
Bí ó ti ń sunkún, ó bẹ̀rẹ̀ ó yọjú wo inú ibojì, 
Oríṣun àwòrán, Lasema Àkọlé àwòrán, Ọkọ̀ akẹ́rùn Dangote rọ́lu ọkọ̀ Ikorodu O fí kun pé, gbogbo àwọn osisẹ eleto alabò àti àwọn ẹṣọ́ ojú pópó pátápátá lo ti péju síbi ti isẹlẹ naa ti waye, láti ri dáju pé awọn to farapa ri ìtọ́ju àti láti mú ìgbòkegbodo ọkọ̀ rọrùn lágbègbè náà.
Alamí lo ta àwọn agbóòfiró lólobó nípa ìwà láabi àwọn amòkùnṣìkà yii.
Èèyàn 239 míràn ṣẹ̀ṣẹ̀ kó COVID-19 ní Nàìjíríà Gbajúgbajà òṣèré “Blue film'' wọ gàù ẹ̀sùn fífipá bá obìrin 13 lòpọ̀ Ọ̀kọ̀ ojú omi dànù, ènìyàn méjì kù, ẹnìkan di àwátì Àṣírí tú!
Àwọn ọ̀dọ́ lu 'Ẹja' tó fi mọ́tò pa ọ̀dọ́kùnrin kan pa
Ṣebí o mọ̀ pé ó wá tàn ọ́ jẹ ni?
SERAP ní nínú ìwòyè àwọn ọ̀ps àwọn ọmọ ilé ìgbìmọ àssofin ni yóò jẹ ànfani ọ̀hun ti yóò si máá ná ìpínlẹ̀ náà ni ogún miliọnu náírà lósoosu.
O mẹnuba oniruuru awọn nnkan to n ba orile-ede yii fira to si pe fun ifaraji, ifẹ ọmọlakeji ati igbara ẹni niyanju láti máa ṣe nkan to tọ.
Boasi sọ fún un pe kí ó tẹ́ aṣọ ìlékè rẹ̀, kí ó sì fi ọwọ́ mú un, Rutu náà sì ṣe bẹ́ẹ̀.
Awọn akikanju obinrin bii Obabinrin Idia, Mary Slessor, Efunṣetan Aniwura, Iyalode Ẹfunroye Tinubu, ati bẹẹ bẹẹ lọ lo ti jà fún ominira àwọn eniyan wọn lati ọdun pipẹ sẹyin.
Lorile-ede Malaysia ti wọn ti n lo ofin Sharia pẹlu ọfin ilẹ Malaysia pa pọ, ọpọlọpọ eeyan a ma lo ofin Sharia lati yanju aawọ tabi awọn ejọ to jẹ mọ ọrọ lọkọlaya.
láti inú ẹ̀yà Isakari, ó rán Igali, ọmọ Josẹfu; 
A o gbudọ gba ki awọn agbesinmọmi pin wa niya nipa kikọ ẹyin awọn Kristẹni si ti awọn Musulumi nitori awọn apaniyan yii kii ṣe aṣoju ẹsin Islam rara.
Neymar ti wa ni orilẹede Brazil to n ṣe igbaradi pẹlu ikọ orilẹede naa fun idije Copa América.
Ohun lo tun gbe ọdun naa larugẹ pẹlu ọpọlọpọ igbesẹ lati da ogo ojubọ rẹ pada lẹyin ọpọ ọdun ti awọn eeyan ti paa ti.
Nítorí láti ìgbà èwe àwọn ọmọ Israẹli ati àwọn eniyan Juda ni wọ́n tí ń ṣe kìkì nǹkan tí ó burú lójú mi, kìkì nǹkan tí yóo bí mi ninu ni àwọn ọmọ Israẹli náà sì ń ṣe.
àwa mejeeji lá àlá ní òru ọjọ́ kan náà, olukuluku àlá tí a lá ni ó sì ní ìtumọ̀.
O wa ro ile igbimo asofin orile-ede naa lati fowo-si atunto ati yiyi ipo pada ti o waye.
” Bẹ́ẹ̀ ni wọ́n ń gbá a létí.
Ẹ gbé àsíá sókè sí Sioni,pé kí wọn sá àsálà, kí wọn má ṣe dúró,nítorí mò ń mú ibi ati ìparun ńlá bọ̀ láti ìhà àríwá.
Síbẹ̀ orílẹ̀-èdè yìí ni aarùn náà ti ń peléke si i lójoojúmọ́ lẹyin ti wọn dẹwọ kónílé-ó-gbéle nínú oṣù karun un, ọdún.
“Bí ẹjọ́ kan bá ta kókó tí ó ní àríyànjiyàn ninu, tí ó sì ṣòro láti dá fún àwọn onídàájọ́ yín, kì báà jẹ mọ́ ṣíṣèèṣì paniyan ati mímọ̀ọ́nmọ̀ paniyan, tabi ẹ̀tọ́ lórí ohun ìní ẹni; tabi tí ẹnìkan bá ṣe ohun àbùkù kan sí ẹlòmíràn, ẹ óo lọ sí ibi tí OLUWA Ọlọrun yín yóo yàn, pé kí ẹ ti máa jọ́sìn.
Ohun tí mo fi farahàn ọ́ nìyí: mo ti yàn ọ́ láti jẹ́ iranṣẹ mi, kí o lè jẹ́rìí ohun tí o rí, ati ohun tí n óo fihàn ọ́.
O ni laarin oṣu mẹta, ni kiakia, ijba ati awọn adari ipinlẹ Eko gbudọ ṣeto nkan ti wọn lee ṣe lati pese iṣẹ fun awọn ọdọ toripe wọn o le gbọ nkankan ti awọn n sọ bayii.
Ọjọgbọn Kyari Mohammed to jẹ alamojuto eto idibo naa lo kede ẹni to bori lẹyin ti atundi ibo gomina ọhun waye.
Ẹ kíyèsára, kí ẹ rí i dájú pé ẹ pa àwọn ohun tí mo pa láṣẹ fun yín mọ́, kí ó lè dára fún ẹ̀yin ati àwọn arọmọdọmọ yín títí lae.
Lẹyin ti Babangida da ibo ọjọ Kejila osu kẹfa ọdun 1993 nu, ti gbogbo agbaye gba pe oloogbe Moshood Abiola lo jawe olubori ninu rẹ, ni rogbodiyan gbode, eyi to mu ki Babangida yẹba lori aleefa, ti wọn si fi Ernest Sonekan jẹ aarẹ fidihẹ ni Naijiria.
Lo ba di meji soodo ni abala akọkọ idije naa.
Ti a ko ba gbagbe,laip e yi ni Gomina ti wọn dibo yan ni ipinlẹ Ekiti,Ogbẹni Kayode Fayemi se abẹwo si Iyiola Omisore lai tii pe wakati mẹrinlelogun ti aare ile igbimọ aṣofin agba, Bukọla Saraki ba Omiṣore lalejo lori atundi ibo ti yoo waye lọjọbọ ni awọn ibudo idibo bii meje otọọtọ nipinlẹ Ọsun.
"Àmọ́ o, Akọwe Iroyin fun Oluwo, Alli Ibrahim, sọ ninu atẹjade kan pe ""diẹ lara awọn to fọwọ si iwe ẹsun naa ko finu-findọ ṣe e."
 Ó kú ní ọdún 2006 lẹ ́ yìn tí ó lo àádọrún ọdún láyé.
Ẹsita rí ojurere lọ́dọ̀ àwọn tí wọ́n rí i.
Wọ́n bá yipada, wọ́n sá gba ọ̀nà aṣálẹ̀ tí ó lọ sí ibi àpáta Rimoni, àwọn ọmọ Israẹli sì tún pa ẹẹdẹgbaata (5,000) ninu wọn ní ojú ọ̀nà.
•Biotilẹjẹpe awọn osisẹ eleto idajọ ko ni pa isẹ wọn ti loju ẹsẹ, amọ inu owo to wa nipamọ ni wọn yoo fi maa san owo awọn adajọ atawọn osisẹ lẹka eto idajọ titi di ọjọ kẹẹdogun osu kẹwa ọdun, eyuu ti ọrọ yi ko ba tii lojutu.
"Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Taa gan ló ń jí orin àti ohùn ara wọn lò nínú Adewale Ayuba àti Ajebori Oríṣun àwòrán, lizzyanjorin_original ""Iya mi lo sọ mi di eeyan ti mo da loni, oun si ni igi lẹẹyin ọgba fun ohun ti mo da loni, iya mi le pupọ, nitori emi nikan lo bi, o yẹ ko kẹ mi ra ni, amọ ko ri bẹẹ rara."
Mo sì sọ fún un pé, “O gbọdọ̀ wà fún èmi nìkan fún ọjọ́ gbọọrọ láìṣe àgbèrè, láì sì lọ fẹ́ ọkunrin mìíràn; èmi náà yóo sì jẹ́ tìrẹ nìkan.
Sheu Sani kò lu jibiti, irọ́ ńlá ní wọ́n ń pa mọ́ọ- Agbẹnusọ Shehu Sani
Ọgbẹni Balogun sọ pe ko ni boju mu ti ẹgbẹ APC ba kọ eti ikun si adehun yii.
N kò fẹ́ gba ìlú náà kí ògo gbígbà rẹ̀ má baà jẹ́ tèmi.
N óo mú wọn pada wá sí ilẹ̀ tí mo fún àwọn baba ńlá wọn, yóo sì di ohun ìní wọn.
Huawei ti bẹrẹ si ni jiroro pẹlu awọn orileede kan pe ohun fẹ sagbatẹru lilo ẹrọ alagbeka lori ayelujara ayarabiasa to n lo 5G.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ọkọ̀ rélùwéè 16 yóò ná Eko sí Ibadan láti oṣù tó ń bọ̀ lọ - Iléeṣẹ́ Rélùwéè kéde Ìròyìn ayọ̀!
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Osun Police: Ọlọ́pàá gba òògùn ìbílẹ̀, ìbọn, àáké àti àdá lọ́wọ́ egúngún 30 Òkùdu 2020 Oríṣun àwòrán, Others Ìlúmọ̀ọ́ká egúngún kan ní ìlú Ede, ìpínlẹ̀ Osun ti kó sí panpẹ́ ọlọ́pàá nítorí pé ó ń da ìpayà sílẹ̀ láàrín ìlú.
Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí 2nd wave Coronavirus Update: England kéde ìséde ọ̀sẹ́ mẹ́rin níràn láti dẹ́kun ìtànkálẹ̀ Covid 191 Bélú 2020 AFCON Qualifier: Kò séwu fún gbogbo àwọn tí yóò kópa nínú ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ Naijiria àti Sierra Leone ní Benin - Obaseki1 Bélú 2020 Fídíò, Joke Silva: Olu, ó tó gẹ́ pẹ̀lú obìnrin yìí níkan tó ń ba ẹ ṣeré ìfẹ́ nínú sinimá!
Aare orile-ede Naiiiria, Muhammadu Buhari yo pelu gomina ipinle Plateau ati Katsina teleri, ogagun Lawrence Onoja, leni ti o pe àádọ́rin odun leni ojo kewa osu kejo.
Nítorí náà, kí inú yín kí ó máa dùn, kí ẹ sì máa bá mi yọ̀.
Iwosan Covid-19 A ti ri awọn iroyin kan lori ayelujara to sọ pe eeyan ni anfani ida 99.
Iléeṣẹ́ ọmọogun sáwọn olóṣèlú: Ẹ má t'ọwọ́ òṣèlú b'ọ̀rọ̀ ológun mọ́
Ó ranṣẹ wá pé kí n kó fadaka ati wúrà mi, ati àwọn obinrin mi, ati àwọn ọmọ mi fún òun, n kò sì bá a jiyàn.
Idije ohun ni o maa n waye lodoodun, bee si ni o je ekeeji irure, eleyi ti o waye lojo abameta(Saturday), ni gbagede ile asa China(Chinese cultural centre), nilu Abuja.
Yọ́ wúrà bo àwọn àkànpọ̀ igi náà, kí wọ́n sì ní àwọn òrùka wúrà kí wọ́n lè máa ti àwọn igi ìdábùú náà bọ̀ ọ́, yọ́ wúrà bo àwọn igi ìdábùú náà pẹlu.
Ẹ wò ó bí ìlú olókìkí tí ó kún fún ayọ̀, ṣe di ibi ìkọ̀sílẹ̀!
soju fun alakoso ile akede orile ede Naijiria, Voice of Nigeria ni.
Lara aseyori Dokita Olarinoye ti SWAN to ka si, ni ise takuntakun re ti o se ninu idije boolu agbaye tawon odo naa, todun 2013 ati 2015, eyi ti iko Golden Eaglets gba ife-eye idije ohun wa le.
9 Kíyèsíi, èmi ni Jésu Krísti, Ọmọ Ọlọ́run alààyè, ẹnití ó dá àwọn ọ̀run àti ayé, ìmọ́lẹ̀ tí kò lè fara sin nínú òkùnkùn;
Àwọn ìmúra tó lààmìlaka ní Nàìjíríà lọdún 2018 Àwọn òṣèré tíátà Yorùbá ọkùnrin tí ó rẹwà Gómìnà Oyetọla tìpínlẹ̀ Ọ̀ṣun leè fipò sílẹ̀ nítorí ìbúra Àwọn ohun tó yẹ kí o mọ̀ nípa Shehu Shagari tó d'olóògbé Ọgagun Idris Alkali, adari eto iṣakoso nileeṣẹ ọmọogun oriilẹ lorilẹede Naijiria Oríṣun àwòrán, Nigeria Army Àkọlé àwòrán, Ninu kọnga kan ni wọn ti ri oku ọgagun Idris Alkali Ọgagun Idris Alkali ni adari eto iṣakoso nileeṣẹ ọmọogun oriilẹ lorilẹede Naijiria ki o to fẹyinti ni ọdun 2018.
Ṣe adajọ agba, Walter Onnoghen yoo farahan niwaju ile ẹjọ to n gbọ ẹsun aṣemaṣe awọn to dipo ilu mu lorilẹ-ede Naijiria, CCT ni ibeere ti o n gbẹnu ọpọ onwoye lati igba ti iroyin nipa ẹsun kan ti wọn fi kan adajọ agba naa ni pa kikede dukia rẹ jade sita lopin ọsẹ to kọja.
Ṣáájú ni obìrin náà ti kọ́kọ́ di àwátì ní nǹkan bíi ọ̀sẹ̀ méjì sẹ́yìn kí àṣírí tó tú
“Ǹjẹ́ ó dára kí eniyan sọ ọpọlọpọ ọ̀rọ̀ kalẹ̀ báyìí kí ó má sì ìdáhùn?
Revolution Now: Iléejọ́ ní àjọ DSS kò láṣẹ láti ti Sowore mọ́lé ju ọjọ́ 45 lọ
Ìràwọ̀ ńlá kan bá já bọ́ láti ọ̀run.
Nígbà tí àwọn aposteli mọ̀, wọ́n sálọ sí Listira ati Dabe, ìlú meji ní Likaonia, ati àwọn agbègbè wọn.
Kemi Afolabi joyè ìmọ́lẹ̀ Adinni 1.
Ejike Kanu ni wọn ni ó tan ọmọ kan wọ sọ́ọ̀bù ìyàwó rẹ̀ níbi tí ó ti fipá bá ọmọ náà lòpọ̀.
 Èyí mudájú pé àwòkọ kọ ̀ ọ ̀ kan èlò náà , bótilẹ ̀ jẹ ́ láláàtúnṣe , yíò ní ìwé àṣẹ kannáà .
Onochie gbé àwòràn Ounjé ati owó síta pe eyi wáye ni Sokoto.
kuro ninu aheso oro awon ti ko fe Ilosiwaju Ipinle Ọyọ ko si mura lati mo ipele
Ṣé kí n dúró,nítorí pé wọ́n dúró láìfèsì?
’’O tesiwaju pe bi olori a-ja-fetoo eya Biafra, Nnamdi Kalu se jeyo ti yo ijoba orile ede Naijiria kuro ninu esun ti won fi n kan an pe adari olote naa ko si ni ikawo won.
Nítorí pé ilẹ̀ dáradára ni ilẹ̀ tí OLUWA Ọlọrun yín ń mu yín lọ.
Gbogbo àwọn nǹkan yòókù tí Jeroboamu ọba ṣe: àwọn ogun tí ó jà, ati bí ó ti ṣe ṣe ìjọba rẹ̀, gbogbo rẹ̀ wà ninu ìwé àkọsílẹ̀ Ìtàn Àwọn Ọba Israẹli.
Ẹ gbadura fun un (Trump) tori ti Ọlọrun ba gbe ọkan lara awọn ọmọ rẹ si ipo; Ogun ọrun apaadi maa n fẹ ṣe ohun gbogbo lati ba ti ẹni bẹẹ jẹ.
'Àhesọ lásán ni ọ̀rọ̀ Trump lórí Russia' Ìjọba Ghana kéde ètò ìsìnkú Kofi Annan ‘Ẹ fi páńpẹ́ ọba mú òsìsẹ́ SARS tó pa ènìyàn ní Ìwó’ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Mi o fẹẹkan ni mo fẹ dupo aarẹ' Awọn adari gboriyin fun John McCain to papoda Awọn oloselu ati ọtọkulu ni awujọ ilẹ Amerika ati kaakiri agbaye ti ba ẹbi ati ara Sẹnetọ John McCain kẹdun lori iku akinkanju naa.
Ninu orúkọ rẹ̀ ni àwọn orílẹ̀-èdè tí kì í ṣe Juu yóo ní ìrètí.
Gẹgẹ bi ohun ta ri ka ninu iwe iroyin Naijiria kan,atẹjade kan tawọn alaga Etsako West,Etsako Central fi sita sọ pe ''awa ni alaga ijọba ibilẹ mẹrindinlogun a o si mọ nipa ipade to waye nibi ti wọn ti kọwe akoniigbagbọ ninu rẹ mọ fun alaga ẹgbẹ wa Adams Oshiomole'' Wọn tẹsiwaju pe dipo Oshiomole,Gomina Godwin Obaseki lawọn ko ni igbagbọ ninu rẹ ati alaga ẹgbẹ APC ni ipinlẹ Edo,Anselm Ojezua.
"Tinubu: Kò ṣéèṣe fún aláǹgbá láti bá ẹtu jà Dokita ọmọ Naijiria jàjàbọ́ nílẹ̀ Ọba ""Ohun tí ojú opó ń rí láwùjọ kò kéré"" Ilé aṣòfin Nàìjíríà kò tì í mọ ọjọ́ tí yóò bẹ̀rẹ̀ ìjókò padà Alárùn ọpọlọ lu àwọn nọ́ọ̀sì àti dókítà agba níléèwòsàn ní àlùdákú Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, SMS alert: Wo ọ̀nà láti dẹ́kun jìbìtì lórí àṣùwọ̀n báǹkì rẹ Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!"
Ibi a ba ti ki wọn pẹ o daarọ,a tun le sọ pe ekaalẹ níbẹ Awọn agba Yoruba lo ma n pa lowe pe ibi ta ba ti sọ pe o daarọ, a kii pada sibẹ lati ki wọn pe ẹ kaalẹ sugbọn lagbo oselu Naijiria ọrọ yi ko fẹẹ ri bẹ.
Wọn ni ko si idi fun awọn lati ma lee darapọ mọ iyanṣẹlodi naa ati pe awọn ti paṣẹ fun awọn akẹkọ lati gba ile lọ.
Lójijì, kíá,OLUWA àwọn ọmọ ogun yóo dé ba yín,pẹlu ààrá, ati ìdágìrì, ati ariwo ńlá;ati ààjà, ati ìjì líle,ati ahọ́n iná ajónirun.
A gé wọn kúrò nítorí wọn kò gbàgbọ́, nípa igbagbọ ni ìwọ náà fi wà ní ipò rẹ.
8 Agẹmo 2019 Oríṣun àwòrán, NIGERIAN PORTS AUTHORITY Àkọlé àwòrán, Aarẹ buhari atawọn adari agbaye Àdéhùn okòwò kan nàà ní Afrika tí orílẹ̀èdè Nàìjíríà ṣẹ̀ṣẹ̀ tọwọ́ bọ̀ ti ń mú ìbéèrè jáde lórí bó ṣe kan ọmọ Nàìjíríà kọ̀ọ̀kan.
    Àwọnẹranko ṣe ètò wọn ni ọ̀nà tí ó ya ni lẹnu.
Bakan naa si ni, jijawe olubori re, ni o so di ifigagbaga igba márùndínláàdọ́rùn ún  bayii ti Nadal jawe olubori le ra won, ti o si padanu ifigagbaga meji pere.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Sotitobire church: Ẹgbẹ́ CAN ní kí ìjọba ṣe ohun tó yẹ Lara awọn ẹsun ti awọn obi Gold fi kan Alfa ni pe, ko ja ọrọ ọmọ naa kunra lasiko ti wọn fi to o leti pe o sọnu.
gbogun ti airise to n koju orile ede Naijiria.
Aadọrin ninu àwọn ará ìlú Beti Ṣemeṣi ni OLUWA pa, nítorí pé, wọ́n yọjú wo inú àpótí OLUWA náà.
ifẹ ̀ ni wọ ́ n ń pe yorùbá orílẹ ̀ èdè tógò .
Abrahamu dá a lóhùn pé, “Gba abo ọmọ aguntan meje wọnyi lọ́wọ́ mi, kí o lè jẹ́ ẹlẹ́rìí mi pé èmi ni mo gbẹ́ kànga yìí.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Àwọn onílù tó ń kan ìlù síbàdí àwọn èèyàn níbi àyẹyẹ ìbúra gómìnà tuntun ní Eko, lórílẹ̀ Nàíjíríà Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Awọn asoju ẹgbẹ oselu alatako MDC n dibo lati yan aarẹ tuntun lọjọ Aiku nilu Gweru lorilẹede Zimbabwe Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Toru-toru lawọ̀n alatilẹyin ẹgbẹ oselu MDC fi duro ti ibo wọn, ti wọn si n reti esi ibo ọhun titi wọ idaji ọjọ keji, tii se ọjọ Aje Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Bi esinsin ba ta firi, maa wọn, ni ọ́logun yii n wi lasiko eto ibura fun aarẹ Mutharika ni ilu Blantire, lorilẹede Malawi Oríṣun àwòrán, EPA Àkọlé àwòrán, Ko si ohun tẹ le e fi mi se ni ọkunrin yii n wi, lasiko to ro asia orilẹede Algeria pẹlu ododo pupa lọwọ, to si doju kọ awọn agbofinro lati se iwọde pe ki ijọba orilẹede naa yẹba lori aleefa Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Oju oro lo n leke omi, osibata ni i leke odo.
lasiko to n soju fun ajagunfeyinti Abdulrahman Dambazau, to je minisita fun oro
Boko Haram: igba marun un ti Shekau ku ti ko tun ku mọ
Amerika ni orile ede alaanu to n pese iranwo julo fun ile Amerika nipa ipese owo to to bilionu meta lati ibere odun 2017.
Orílẹ̀-èdè tí ẹ kò mọ̀ rí ni yóo jẹ ohun ọ̀gbìn yín ati gbogbo làálàá yín ní àjẹrun.
Bakan naa iroyin naa tun sọ pe ijọba apapọ ti fofin de Amaju Pinnick lati rinrin ajo lọ si oke okun lasiko yii titi ti igbẹjọ rẹ yoo fi buse.
 Ọjọ ́ yìí ni á gbọ ́ pé ó ṣe pàtàkì nínú ìkà oṣù àwọn yorùbá .
Ẹlẹ́rìí èké kò ní lọ láìjìyà,ẹni tí ó ń pa irọ́ yóo parun.
Àwọn náà ni Àdùkẹ́, Ọmọ́wùmí, Oládípò àti Bándélé.
Ẹ̀yìn ni n óo kọ sí wọn lọ́jọ́ àjálù,wọn kò ní rí ojú mi.
Ọgbọ́n àti kówójẹ n'ìgbèsẹ̀ ìjọba láti ná $1.
Láti ọjọ́ náà, ẹnikẹ́ni kò ní ìgboyà láti tún bi í ní ohunkohun mọ́.
Afenifere sọ pe titẹle awọn aba to jẹyọ nibi apero CONFAB ọdun 2014 nipa ijọba awaarawa lo le mu ilọsiwaju ba Naijiria.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Sé Dino Melaye ti bọ́ sẹ́gbẹ́ PDP ni ?
Gomina Makinde ṣe apejuwe iya rẹ gẹgẹ bi iya rere, iya to ṣọwọn ti ko si ẹni to le dabi rẹ.
Isah ni ileeṣẹ ọlọpaa ri ọbẹ ati aṣọ bẹẹdi ti ẹjẹ wa lara rẹ ninu iṣẹ iwadii wọn.
O ni ohun ti o lee dun mọ ilẹ Yoruba ninu ni ki wọn wọgile eto naa patapata.
Lẹ́yìn tí ó bí Kenani, ó gbé ẹgbẹrin ọdún ó lé mẹẹdogun (815) láyé, ó sì bí àwọn ọmọ mìíràn lọkunrin ati lobinrin.
Kí ni kí n wí nígbà tí ó bá bèèrè lọ́wọ́ mi?
Àbí kì í ṣe bí mo ti mú àwọn ará Filistia jáde láti ìlú Kafitori, tí mo mú àwọn Siria jáde láti ìlú Kiri, ni mo mú ẹ̀yin náà jáde láti Ijipti.
Ìgbésẹ̀ yíyọ Daura níṣẹ́ wáyé lẹ́yìn tí àwọn òṣìṣẹ́ àjọ DSS kan yabo ilé ìgbìmọ̀ asọfin Nàìjíríà, tí wọ́n sì dí ọ̀nà mọ́ àwọn aṣòfin.
Aare de si ipinle  Katsina lojo Ẹti, ojo kejo osu keta,  pelu iyawo re , Aisha pelu oko ofurufu ti aare.
0 8,834 Ivory Coast 140 0.
Ọgbẹni Toyin to jẹ akọwe Kabiyesi ni Kabiyesi fi ọrọ sita lati rọ awọn ọdọ ki wọn ma ṣe jagidijagan tori gẹgẹ bi gomina ṣe s pe ainiṣẹ lo n fa ọpọlọpọ nkan bayii torinaa Kabiyesi rọ gomina lati pese iṣẹ fun awọn ti ko niṣẹ lọwọ.
Aare ro won lati mase da rogbodiyan kankan sile nitori oselu.
Agbára ni ògo ọ̀dọ́,ewú sì ni ẹwà àgbà.
Nítorí nígbà tí ebi ń pa mí, ẹ fún mi ní oúnjẹ.
Asoju ajọ agbaye ni eka eto to n ri si gbigbogun ti aarun kogboogun  Erasmus Murah lo soro yii nibi eto ti ajọ to n gbogun ti aarun kogboogun lorile ede Naijiria NIBUCAA( Nigeria Business of HIV/AIDS) se niluu Abuja, lojoRu ose yii.
Ní ọjọ́ keji, bí wọ́n ti ń jáde kúrò ní Bẹtani, ebi ń pa á.
Nítorí bí o bá mú ìdààmú bá arakunrin rẹ nípa ọ̀ràn oúnjẹ tí ò ń jẹ, a jẹ́ pé, kì í ṣe ìfẹ́ ni ń darí ìgbésí-ayé rẹ mọ́.
Òun ni ó pàṣẹ pé kí àwọn tí wọ́n fi ẹ̀sùn kàn án wá siwaju yín.
Ìdámẹ́wàá gbọ́dọ̀ jẹ́ àtọkànwá ni; kìí ṣe àfitipáṣe Ọpọ pasitọ ati Alfa di oloṣelu - Ladọja Ọmọ Adeboye ni kẹ ma t'ọrọ owó lọwọ RCCG mọ́ Ìgbà mẹ́rin tí ẹ̀sùn àgbèrè ta bá adarí ìjọ olókìkí ní Naijiria Ẹ wo fidio yii, lati gbọ ẹkunrẹrẹ ohun ti Wolii Kayọde Abiara sọ nipa ipo ti orilẹede Naijiria wa ati imọran to ni fun ijọba pẹlu araalu.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: N kò le è dìbò yan Buhari tàbí Atiku ní olórí mi láéláé - Soyinka ‘Nàìjírìà kò nílò àtúntò, ìjìjàgbara la nílò’ Pẹ̀lú abẹ̀rẹ̀ àjẹsára yìí, ẹ̀fọn kankan kò lè mú àìsàn ibà wá Tó bá fi nọ́mbà ìpè rẹ sílẹ̀, ẹ̀wọn ọdún mẹ́ẹ̀dọ́ọ́gbọ̀n lo fi ń ṣeré - NCC Yoruba ni iroyin ko to afojuba lo mu ki BBC fẹsẹ kan de awọn ibudo tawọn akanṣe iṣẹ naa wa, ta si ri pe lootọ iṣẹ ko ti pari lori awọn isẹ naa rara.
Lọ́nà kínnì, inú mi bàjẹ́ láti gbọ́ wíi pé ẹnì kan dá ọjọ́ ikú mi sílẹ̀ fún mi, ṣùgbọ́n lọ́nà kejì mo mọ̀ pé ìparun Òjòlà-ìbínú kò jìnnà mọ́, nítorí ní ọjọ́ tí ẹ̀dá kan bá ti wí pé ti Ọlọ́run kò jámọ́, eléyìíní bẹ̀rẹ̀ ìparun: mo dákẹ́ mo ń wo èyí tí Ọlọ́run máa ṣe.
"O ni ""Kazeem ti sọ fun mi pe ti oun ba ti ri ṣe daadaa nidi iṣẹ bọọlu pe oun maa mu mi lọ si oke okun."
Nítorí bí Baba ti ní ìyè ninu ara rẹ̀, bẹ́ẹ̀ gan-an ni ó ti fún ọmọ ní agbára láti ní ìyè.
Pásítọ̀ gún ìyàwó rẹ̀ lọ́bẹ nínú ṣọ́ọ̀ṣì, ló bá tì í bọ ara rẹ̀ náà níkùn Atẹjade kan ti oludari agba fun Ileesẹ to n ṣe akoso eto irinna ofurufu nilẹ wa, ọgagun Musa Nuhu fọwọsi tun salaye pe awọn papakọ ofurufu yoku labẹle yoo si wa ni titipa nigba ti awọn baalu ilẹ okeere naa ko ni raye ba sawọn papakọ ofurufu wa.
Ìbẹ̀rù OLUWA ni ìbẹ̀rẹ̀ ọgbọ́n,gbogbo àwọn tí ó bá ń tẹ̀lé ìlànà rẹ̀, á máa ní ìmọ̀ pípé.
Garba ṣalaye loju opo twitter rẹ pe: Atejade naa ni ọrọ idaduro yii naa ti kọkọ kan diẹ ninu awọn oluranlọwọ Aarẹ.
Ṣugbọn àwọn arọmọdọmọ Israẹli pọ̀ sí i, wọ́n di alágbára gidigidi, wọ́n sì pọ̀ káàkiri ní ilẹ̀ Ijipti.
Lẹ́yìn èyí, a múra o dí ibi ìjà.
Elizabeth ti lo ọgọ́ta ọdún lórí oyè
Ohun to wa mu ki gbongbo iroyin yii tun fẹ ṣe bi ẹni gbilẹ sii bayii ni ti atẹjade kan ti ẹka ẹgbẹ oṣelu APC ni ilẹ Gẹẹsi gbe jade loju opo twitter rẹ nibi to ti n ki igbakeji alaga ẹgbẹ oṣelu APC lorilẹ-ede Naijiria naa pe ko ṣara giri, aisan ko ni bori rẹ rẹ.
ipa re fi tuko orile-ede Naijiria.
Ní ọjọ́ kan, lẹ́yìn tí wọ́n jẹ, tí wọ́n mu tán, ninu ilé OLUWA, ní Ṣilo, Hana dìde.
Ni alẹ ana (Ojọ Iṣẹgun) ni wọn ku Baba Latin ṣalaye.
A bi ni ọdun 1989 ni ìpínlẹ̀ Eko ni Naijiria, o si ni ẹgbọn ati aburo mẹrin Femi ni orukọ baba rẹ osi jẹ olusiro owo nígba ti iya rẹ Taiwo jẹ Nọoṣi, Isreal lo si ile iwe Chrisland School ni Opebi to si n kọ ẹkọ Takwando to ba kuro ni ile iwe, ọdun 2001 lo lọ si orilẹ̀-èdè Ghana pẹlu ẹbi rẹ ki wọ́n to lọ si Newzealand.
Kò pé sí ìgbà náà ni àwọn fídíò bẹrẹ sí ní gba orí ẹ̀rọ ayélujára, to ṣe àfihàn Dino níbi tí o joko sí ilẹ̀ láàrin ojú títì ní Ábuja.
Àwọn ìlú tó ti fòpin sí ìsekúpani Ajọ Isọkan Agbaye naa ni awọn iroyin lati ọwọ awọn orilẹede naa, awọn ajọ ajafẹtọ ọmọniyan ati awọn to fi ọju gan ni awọn isẹlẹ naa.
org pe ko kan an nipa fun ijọba apapọ lati da ẹsun ọrọ odi ni Naijiria.
N óo yí ojú rẹ pada, n óo fi ìwọ̀ kọ́ ọ lẹ́nu, n óo sì mú ọ jáde, pẹlu gbogbo àwọn ọmọ ogun rẹ, ati àwọn ẹlẹ́ṣin rẹ, ati àwọn ati ẹṣin wọn, gbogbo wọn, tàwọn ti ihamọra wọn, ogunlọ́gọ̀ àwọn ọmọ ogun tí wọ́n ní asà ati apata, tí wọ́n sì ń fi idà wọn.
Sugbọn awọn ọmọ orilẹede yi ko tii sọ ero ọkan wọn nipa asọ ọhun.
"Oríṣun àwòrán, @pulseafricamag ""Ko si ẹni to lee gba ade lori awa ọba mọkanlelogun nilẹ Ibadan nitori ọna to ba ofin mu la fi de ade naa, kii se ọna eru."
B Soule, to jẹ ọkan pataki ninu ẹgbẹ oṣelu NCNC.
Àṣepọ̀ ni kí wọ́n ṣe ọ̀pá fìtílà, ati àwọn ẹ̀ka rẹ̀, ati àṣẹ̀ṣẹ̀yọ èso kékeré abẹ́ ẹ̀ka rẹ̀.
" Oríṣun àwòrán, @pulseafricamag Ọba Lekan Balogun wa n beere pe ki lo de to jẹ ifẹ inu eeyan kansoso ni wọn fẹ tẹ lọrun lai ro idagbasoke ilẹ Ibadan lapapọ, nitori naa, o ni eyi ko lee seese, awọn yoo dijọ pade nile ẹjọ ni, ade yoo wa titi laelae ni, ko si ohun to lee yẹ lori awọn lọna to lodi sofin.
Abbo tọrọ aforojin yii pẹlu ikaanu nla, lasiko ipade akọroyin to se ni olu ile ẹgbẹ PDP to wa nilu Abuja.
Ó sọ fún iranṣẹ rẹ̀ pé, “Jẹ́ kí á lọ sí ọ̀kan ninu àwọn ìlú wọnyi, kí á sì sùn ní Gibea tabi ní Rama.
Sibẹsibẹ mo rán gbogbo àwọn iranṣẹ mi, àwọn wolii, sí wọn, kí wọ́n sọ fún wọn pé kí wọn má ṣe ohun ìríra tí n kò fẹ́.
Tí a fiṣọwọ́ ní 4:57 10 Ọ̀pẹ̀ 20204:57 10 Ọ̀pẹ̀ 2020 Èèyàn márùn-ún kú nínú rògbòdìyàn tó wáyé lásìkò ìdìbò ní Ghana BBCCopyright: BBC Ileeṣẹ ọlọpaa Ghana sọ pe eeyan marun-un lo ku, nitori wahala to ṣẹlẹ lasiko eto idibo aarẹ ati ile aṣofin to waye lọjọ keje, oṣu Kẹjọ.
    Mo dúpẹ́ lọ́pọ̀lọpọ̀ lọ́wọ́ gbogbo ẹ̀yin ọgá ilé ìwé ní ìlẹ̀ Yorùbá fún bí ẹ ti ṣe ń lo gbogbo àwọn ìwé mi tẹ́lẹ̀ rí, mo dúpẹ́ pẹ̀lú lọ́wọ́ ẹ̀yín ti ẹ ń yàn ìwé fún iló àwọn ọmọ náà.
Iṣaya tí ó jẹ́ olórí láti inú ìdílé Rehabaya,
Ènìyàn 653 míràn tún kún iye àwọn tó ní COVID-19 ní Nàìjíríà Wo àwọn olorì àgbà mẹ́rin tí Aláàfin ń wárí fún Wo bí Dorathy Bachor ṣe di gbajúmọ̀ lóríi Instagram lẹ́yìn tí ètò àgbéléwò BBNaija bẹ̀rẹ̀ Àwọn àádọ́ta ọ̀dọ́ wọ gàù nítorí ilé ijó ní Ilorin Gẹgẹ bi ohun to fi sojo opo LinkedIn rẹ, Joy Nunieh jẹ agbaṣẹṣe to da wa laye ara rẹ fun ileeṣẹ to n pan epo rọbi, Shel, fun ọdun mọkanla gbako.
Nítorí pé mo ti fẹ́rẹ̀ ṣubú,mo sì wà ninu ìrora nígbà gbogbo.
Àwọn kọ́kọ́rọ́ ikú ati ti ipò òkú wà lọ́wọ́ mi.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ọmọ Yorùbá ni onímọ̀ ẹ̀rọ ‘Rọ́bọ́tì’ tó ń gbowó jùlọ ní UK Àwọn ohun tó yẹ kó o mọ̀ nípa Adémọ́lá Adélékè Sùúrù àwọn ará Ọṣun ti tó gẹ́ - Saraki Ilé iṣẹ́ ọkọ̀ òfúrufú tuntun 'Nigeria Air' ṣíwọ́ iṣẹ́ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Omiyalé Àkútè: N50 si N100 làwọn èèyàn fi ń kọjá lórí ẹ̀kún omi l‘Ákútè Alukoro ile ise ọlọọpa, Jimoh Moshood fi iwe pe sẹneto Adeleke ati awọn mẹrin miran lori ẹsun yi kan naa.
” Wọ́n dáhùn pé: “Dájúdájú, yóo di aláìmọ́.
O ṣeeṣe ki ẹni to ṣẹṣẹ ra New Kim lo lati bi ọpọlọpọ ọmọ.
Usi ni baálé ní ìdílé Jedaaya,Kalai ni baálé ní ìdílé Salai,
‘Fayose ń lo owó osù òsìsẹ́ fún ara rẹ̀’ Fayoṣe yin Ngige fún bó se polongo ìbò fún PDP Sugbọn iroyin to n tẹ wa lọwọ sọ pe, awọn ọlọpaa duro wamu-wamu ni iwaju Ile Ijọba ipinlẹ naa bayi.
J Omojuwa ni o da ohun loju wi pe awọn ọdaran to tu ẹlẹwọn silẹ kii ṣẹ awọn afẹhọnuhan EndSars, nitori naa ifẹhọnuhan wọn ko si fun iwa ọdaran lawujọ.
15 Sẹ́rẹ́ 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Brexit?
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ọ̀gá Bello: Àìgbọ́n ló ń da àwọn òsèré tíátà tó ń jà lórí ayélujára láàmú Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Ọ̀gá Bello: Àìgbọ́n ló ń da àwọn òsèré tíátà tó ń jà lórí ayélujára láàmú 10 Ògún 2018 Adebayọ Salami, ti gbogbo eeyan mọ si Ọga Bello ti salaye fun BBC Yoruba pe, ko dara bawọn osere tiata se n ko ara wọn sita lori ẹrọ ayelujara pẹlu ija gbogbo igba.
Ìyàwó Ìrìnkèrindò wọ̀ mi lójú púpọ̀, ojoojúmọ ni mo sì ń fẹ́ kí Ìrìnkèrìndò kú kí ìyàwó rẹ̀ di tèmi.
N óo mú wọn kúrò ní ilẹ̀ tí wọ́n ti jẹ́ àlejò, ṣugbọn wọn kò ní dé ilẹ̀ Israẹli.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Jẹẹsí Super Eagles: N5,000, N3000, N2,500.
Awọn ileeṣẹ iroyin l'abẹle jabọ pe l'oni ọjọ kejidinlogun oṣu Kẹrin ni Aarẹ Buhari buwọlu ofin naa lati maa san ọgbọn ẹgbẹrun Naira gẹgẹ bi owo oṣu to kere ju fun oṣiṣẹ.
Abenugan tun tesiwaju pe  ajodun Maulud yii wa lati tun ipinnu se ati lati fi ife han fun gbogbo awon eniyan lawujo.
Ẹni to bori: Egypt Ìpele to kangun si aṣakagba South Africa vs Tunisia.
Oríṣun àwòrán, Kayode Fayemi/Facebook Àkọlé àwòrán, Ààrẹ Buhari kí Fayẹmi kú oríire Ààrẹ Muhammadu Buhari naa ti kí Ọmọwé Kayọde Fayẹmi kú oríire fún àṣeyọrí rẹ̀ gẹ́gẹ́ bíi gómìnà tí ìpínlẹ̀ Ekiti yàn nínú ìdìbò tó ṣẹ̀ṣẹ̀ wáyé.
Ile ẹkọ Eton si ni Dilibe ti gba iwe ẹri girama jade lọdun 1969.
A ṣì ń ṣèwádìí lọ́wọ́ lórí àwọn t'ọ́ta ìbọn pa lọ́jọ́ ọdún Eid n'Ibadan - Ọlọ́pàá A ṣe sùúrù tó, ọmọ wa ló gbọ́dọ̀ jẹ́ ọ̀gá fásitì UI lọ́tẹ̀ yìí - àkóríjọ́ ẹgbẹ́ ọmọ Ibadan Ọkọ lé aya rẹ jáde nílé nítorí ìrísí ojú àwọn ọmọ rẹ méjì ní Ilorin Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ibadan Death: Àwọn ará àdúgbò Akinyele ké sita lórí iṣékúpani tó ń wáyé ní ìlú Ibadan.
Wọn á fẹ́ máa kọ́ni ní òfin, bẹ́ẹ̀ sì ni wọn kò mọ ohun tí wọn ń sọ, ohun tí wọ́n sì ń sọ pẹlu ìdánilójú kò yé wọn.
Agbara ilẹ Adulawọ jẹ ti ajumọṣe gbogbo ẹbi ati ara ni eyi to yẹ ki wọn tun fi ṣe daadaa sii.
O jẹ aarẹ labẹ ijọba ologun lati ọjọ kẹtala oṣu keji ọdun 1976 si ọjọ kinni oṣu kẹwa ọdun 1979.
Ìṣẹ rẹ̀ a sì máà gbà àgbàrá láti ṣe.
Níbẹ̀ ni ààlà rẹ̀ ní apá àríwá ti bẹ̀rẹ̀, 
Alufaa yóo bu díẹ̀ ninu òróró náà sí àtẹ́lẹwọ́ òsì rẹ̀, 
”Samsoni dá wọn lóhùn, ó ní, “Ẹ búra fún mi pé ẹ̀yin tìkara yín kò ní pa mí.
2 14526 Orilẹede Togo 73 0.
Ninu ọrọ ti wọn, ẹgbẹ oṣelu APC daun pe Gomina Obaseki ati awọn ololufẹ rẹ gangan lo n fa wahala ati rogbodiyan ni ipinlẹ naa.
 Shina fikun pe ọjọ yii gan ni oun gba pe oun ti gba iyọnda lẹnu isẹ, ohun to ku ni ki oun gbe ìbọn, bi oun si ṣe bẹrẹ iṣẹ adigunjale ree."
àfi àwọn ọkunrin, láti ẹni ọdún mẹta sókè, tí wọ́n ti kọ orúkọ wọn sílẹ̀ ní ìdílé ìdílé, gbogbo awọn tí wọ́n wọ ilé OLUWA gẹ́gẹ́ bí iṣẹ́ olukuluku ṣe gbà lójoojúmọ́, fun iṣẹ́ ìsìn wọn gẹ́gẹ́ bí ipò wọn, nípa ìpín wọn.
10 (African Songs, 1977) Bisimilai (African Songs, 1977) Omo Nigeria (African Songs, 1977) Olojo Eni Mojuba (Siky Oluyole, 1978) Our Late Artistes (Siky Oluyole, 1978) London Special (Siky Oluyole, 1979) Fuji Reggae Series 2 (Siky Oluyole, 1979) Eyo Nbo Anobi (Siky Oluyole, 1979) Awa O Ja (Siky Oluyole, 1979) Fuji Disco (Siky Oluyole, 1980) Oke Agba (Siky Oluyole, 1980) Aiye (Siky Oluyole, 1980) Family Planning (Siky Oluyole, 1981) Suru Baba Iwa (Siky Oluyole, 1981) Ore Lope (Siky Oluyole, 1981) E Sinmi Rascality (Siky Oluyole, 1982) Iwa (Siky Oluyole, 1982) Ise Logun Ise (No More War) (Siky Oluyole, 1982) Eku Odun (Siky Oluyole, 1982) Ijo Olomo (Siky Oluyole, 1983) Nigeria (Siky Oluyole, 1983) Love (Siky Oluyole, 1983) Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsèjẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọ Barry Special (Siky Oluyole, 1983) Military (Siky Oluyole, 1984) Appreciation (Siky Oluyole, 1984) Fuji Vibration 84/85 (Siky Oluyole, 1984) Destiny (Siky Oluyole, 1985) Superiority (Siky Oluyole, 1985) Fertiliser (Siky Oluyole, 1985) Okiki (Siky Oluyole, 1986) Inferno(Siky Oluyole, 1996) America Special (Siky Oluyole, 1986) Ile Aye Ogun (Siky Oluyole, 1987) Maturity (Siky Oluyole, 1987) Barry Wonder (Siky Oluyole, 1987) Wonders At 40 (Siky Oluyole, 1988) Fuji Garbage (Siky Oluyole, 1988) Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Africa Eye: Wo ìtàn ìyá kan ìyá kan àtàwọn olè ajọ́mọgbé tó n ta ọmọ ní Kenya Fuji Garbage Series II (Siky Oluyole, 1988) Current Affairs (Siky Oluyole, 1989) Fuji Garbage Series III (Siky Oluyole, 1989) Music Extravaganza (Siky Oluyole, 1990) Fuji Waves (Siky Oluyole, 1991) Fantasia Fuji (Siky Oluyole, 1991) Fuji Explosion (Siky Oluyole, 1992) Dimensional Fuji (Siky Oluyole, 1993) New Fuji Garbage (Siky Oluyole, 1993) The Truth (Siky Oluyole, 1994) Precaution (Siky Oluyole, 1995) Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Kollington ṣàlàyé bí orin Fuji ṣe bẹ̀rẹ̀ gan an ní Nàiìjíríà Olympics Atlanta '96 cassette (Siky Oluyole, 1996) Olympics '96 London Version cassette (Zmirage Productions, 1997) with Queen Salawa Abeni Evening Of Sound cassette (Zmirage Productions, 1997) Barry On Stage cassette (Siky Oluyole, 1997) Mr.
Ọmọ bibi ilu Isara-Remo ni Ọjọgbọn Wole Soyinka jẹ to si jẹ ẹlẹkeji ninu ọmọ mẹfa ti iya rẹ bi ni ilu Abeokuta ipinlẹ Ogun.
peter abelard a bí i ní 1079 .
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ina jo ilé ijọsin ti wọn kọ lọdun 1163 Arugbo ṣoge ri, akisa lo igba ri, lọdun 1790 ni wọn pa ile ijọsin yii tì lasiko ijajangbara awọn eniyan Faranse.
 Òun náà sí ni a ṣe n fi orúkọ rẹ ̀ pe àrùn náà .
Trump ni pe oun ko lee gba pe Joe Biden lo bori idibo aarẹ orilẹ-ede Amẹrika to waye lọjọ kẹta, oṣu kọkanla, ọdun 2020.
Peteru sọ fún un pé, “Oluwa, bí ó bá jẹ́ pé ìwọ ni, sọ pé kí n máa rìn bọ̀ wá sọ́dọ̀ rẹ lójú omi.
"Wọn kọkọ gbe e lọ si ti aladani ki wọn to wa gbe e lọ si ileewosan ijọba to wa ni CMS Marina""."
Baba rẹ ati iya rẹ na fara pa.
Rehoboamu fẹ́ Mahalati, ọmọ Jerimotu, ọmọ Dafidi, ìyá rẹ̀ ni Abihaili, ọmọ Eliabu, ọmọ Jese.
Nínú ọ̀rọ̀ rẹ̀ lórí ọ̀rọ̀ náà agbẹnusọ fún àjọ ọlọ́pàá Chike Oti ní ọ̀rọ̀ náà rú oun lójú kí àwọn ènìyàn máa hùwà ọ̀daràn nítori pé ayẹyẹ ńbọ̀ lọ́nà.
Joabu dáhùn pé, “N kò ní máa fi àkókò mi ṣòfò, kí n sọ pé mò ń bá ọ sọ̀rọ̀.
Ṣaaju ni igbimọ to n ri si ọrọ NDDC nile aṣoju-sofin ti kọkọ gbiyanju lati tu iṣu de isalẹ ikoko nipa ẹsun iṣowo baṣubaṣu ti wọn fi kan ajọ ọhun ni ibẹrẹ ọdun 2020.
Iwọnyi ni awọn ohun to yẹ ko waye, ṣugbọn ti awọn ti ọrọ kan gbegile, tabi ṣe atunto rẹ nitori arun ọhun.
Nígbà tí ó wà lọ́dọ̀ wọn, ó pàṣẹ fún wọn pé kí wọn má kúrò ní Jerusalẹmu.
Àwa gan-an ni ẹlẹ́rìí pé bẹ́ẹ̀ ló rí.
O lọ si ile ẹkọ Gbogboniṣe Adamawa ni Yola nibi to ti kọ ẹkọ nipa idena iwa ọdaran lawujọ lọdun 2016.
Makinde fi da awọn eeyan ipinlẹ naa loju ijọba ti bẹrẹ igbesẹ lati daabo bo wọn lọwọ ajakalẹ arun naa, leyi ti oun tikalara rẹ n dari.
Oríṣun àwòrán, ECN Lọwọ orileede Germany ni Namibia ti gba ominira.
Ìwọ òṣùpá, sì dúró jẹ́ẹ́ ní àfonífojì Aijaloni.
Èdè àìyede wà láàrin Equitorial Guinea àti WHO lẹ́yìn ti wọ́n fẹ̀sun kan àṣojú WHO níbẹ̀ pé o ń ṣe àfikún iye àwọn to ni Covid-19.
Oríṣun àwòrán, dss Àkọlé àwòrán, Ọ̀gá àgbà tuntun nàá gba oyè ìmọ̀ ìjìnlẹ̀ nípa ètò òṣèlú nílé ẹ̀kọ́ gíga fásìtì Ahmadu Bello tó wà nílùú Zaria.
Laipẹ yii ni Alaga ajọ eleto idibo, INEC, ọgbẹni Mahmood Yakubu ba awọn akọroyin sọrọ lori awọn alaye to ni se pẹlu idibo to n bọ lọna.
Bello ni ohun to buru jai ni ki Ọba maa fun awọn ijoye ni ẹgbẹrun mẹta si mẹrin losoosu lati maa mu lọ sile, bẹẹ ni oun, Osa, si ni igbakeji rẹ nilana oye ilu Iwo.
 Ó dìlú mọ ̀ ọ ́ ká ní inú iṣẹ ́ sinimá nílẹ ̀ nàìjíríà ní ọdún 2009 , lẹ ́ yìn tí ó gbé ipò kẹ ́ rin nínú ìdíje amstel malta box office .
1 Nísisìyìí, kíyèsíi, nítorí ohun eyítí ìwọ, ìransẹ́ mi Oliver Cowdery, ti ní ìfẹ́ lati mọ̀ nípasẹ̀ mi, mo fi àwọn ọ̀rọ̀ wọ̀nyí fún ọ.
Oríṣun àwòrán, @pauldgoodguy Àkọlé àwòrán, Ilana naa yoo pa iṣẹ wa lara ṣugbọn aye o parẹ Segun tẹsiwaju pe oun atawọn oṣiṣẹ oun yoo rii daji pe gbogbo awọn to wa nibi eto naa ni wọn tẹle ilana ti ajọ NCDC gbe kalẹ lati dena ajakalẹ arun ọhun.
’ Ọ̀kan tún ṣe ìbéèrè ó ni, ‘Adé yín dà?
Ẹwẹ, o ko ipa to jọju ninu idasilẹ Ọja paṣi-paarọ ipin idokowo, Nigerian Stock Exchange, ni 1960.
Orilẹ̀-èdè South Africa ló ti ni ènìyàn tó pọ̀ jùlọ tó ni aàrùn Covid-19, nígbà ti orilẹ̀-èdè tí ó ní àwọn tó ti kú ikú Coronavirus pọ̀ sí.
Wọ́n gbé ẹran ẹbọ sísun tí wọ́n ti gé sí wẹ́wẹ́, ati orí rẹ̀ tọ̀ ọ́ lọ, ó sì sun wọ́n lórí pẹpẹ.
Níbo ni Sẹ́nétọ̀ Abiola Ajimobi, gómìnà àná ní ìpínlẹ̀ Oyo wà?
Wọ́n gbé ohùn wọn sókè, wọ́n ń kọrin ayọ̀,wọ́n ń yin OLUWA lógo láti ìhà ìwọ̀-oòrùn wá.
Eid-el-Kabir: ''A ò rí èèyàn ra ẹran àgbò lọ́dún yìí bíi ọdún Iléyá tó lọ''
Oni lo pe ọdun mẹsan an geerege ti ilumọọka olorin Fuji, Alhaji Sikiru Ololade Ayinde Balogun Barrister jade laye.
Kò sí ẹni tí ó mọ àkókò tirẹ̀.
"O ni ""Ọkọ mi maa n sọ pe alagbere ni mi, ṣugbọn mo maa n sọ pe ọrọ ko ri bẹ, ibi ti wahala ti bẹrẹ niyẹn."
Ó kú, wọ́n sì sin òkú rẹ̀ sí Samaria.
Gbogbo ara ògiri yàrá inú yíká ati ibi mímọ́ ni wọ́n gbẹ́ 
Ẹ̀mí Mímọ́ fihàn nípa èyí pé ọ̀nà ibi mímọ́ kò ì tíì ṣí níwọ̀n ìgbà tí àgọ́ ekinni bá wà.
Ile-igbimo asofin orile-ede Naijiria ti wole pada leyin isinmi ose mejo, eleyi ti ile-igimo ohun gba fun odun 2019.
Wo àwọn òṣèré Yorùbá tí Aisha Buhari yàn fún ìpolongo ìbò Dino: Olúwa, ṣe sí àwọn ọ̀tá mi bí o ṣe ṣe sí Egypti Kí lo fàá ti wọn fi ti i pa tẹ́lẹ̀?
Ohun tí ó lè fà á lè pọ̀ – ọ̀pọ̀ ni ó kó àìsàn ní ọdún tí ó kọjá, tí wọn kò fura.
Awọn ọdaran naa ti wa latimọle fun ọdun meje lati igba ti ọwọ ofin ti ti tẹ wọn ki wọn to da ẹjọ wọn bayii.
O ni o yẹ ki awọn ọlọpaa oju omi wa ti yoo ma tọpinpin bi nkan ṣe n lọ, ati pe ki awọn alaṣẹ maa ko idọti oju omi naa, ko maa ba maa kọ ẹnjinni ọkọ oju omi, eyi to maa n fa ijamba.
 Ìkíní lè ní ìtumọ ̀ kí èkeji maa ní .
Ugwu Blessing Ugochukwu padanu ẹmi rẹ: Lara ẹbu iroyin to gba ori ayelujara nipa isẹlẹ Lekki ni pe obinrin kan Ugwu Blessing Ugochukwu padanu ẹmi rẹ lasiko to jo, to si mu asia Naijiria lọwọ.
#BBCNigeria2019 Link Ẹni ti iṣẹlẹ naa ṣoju rẹ ni ruru omi ati iji lile lo da ọkọ oju omi naa nu.
Àní, kí ni ọmọ eniyan, tí o fi ń ṣìkẹ́ rẹ̀?
 títí di ọdún 2015 , oríṣi àjẹsára náà 15 ni ó wà .
Oluwo: Mo fẹ́ kí gbogbo ọmọ Nàíjíríà gbà mí lórí ìyà tí Oluwo fi jẹ mi, ni mó ṣe pe ẹjọ́
Àwa dúró dè ọ́ ní ọ̀nà ìdájọ́ rẹ, OLUWA,orúkọ rẹ ati ìrántí rẹ ni ọkàn wa ń fẹ́.
Iye àwọn alufaa tí wọ́n pada dé láti, oko ẹrú wọn nìwọ̀nyí:Àwọn ọmọ Jedaaya láti inú ìdílé Jeṣua jẹ́ ẹẹdẹgbẹrun ó lé mẹtalelaadọrin (973)
Ó wí fún Peteru pé, “Simoni, ò ń sùn ni?
 Ìtèsíwájú nípa títa awon ohun ìní náà ní à n réti láì pefurther asset disposols are expected soon .
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìjọba Ìpínlẹ̀ Ogun ti kéde ìbẹ̀rẹ̀ ètò ẹ̀kọ́ ọ̀fẹ́ 21 Owewe 2019 Oríṣun àwòrán, Tweeter Abiodun Àkọlé àwòrán, Gomina Ipinle Ogun Ijọba ipinlẹ Ogun ti sọ eto ẹkọ di ọfẹ fun awọn ọmọ alakọbẹrẹ ati ti girama.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Àrìnfẹsẹ̀sí - Ìbéèrè ni a bèrè lọ́wọ́ àwọn èèyàn, ika òṣì ni wọ́n ń ta dànù Bi isẹlẹ naa ba se n lọ, a maa mu wa fun yin.
Wọ́n bá mú wọn, wọ́n tì wọ́n mọ́lé títí di ọjọ́ keji, nítorí ilẹ̀ ti ṣú.
Everton já Manchester United sí ìhòhò lọ́jọ́ Àjíǹde Ẹni a le mú.
Àgùtàn Arsenal kò tíì paṣọ èṣí dà lábẹ́ Mikel Arteta Awakọ̀ Maruwa tó bá gbé okùnrin àti obìnrin papọ ní Kano yóò jẹ búlálà mẹ́wàá- Hisbah Kí ló ṣẹlẹ̀ tí a fi ń pé ọjọ́ kejì Kérésì ní 'Boxing Day'?
NTACopyright: NTA Ali NdumeImage caption: Ali Ndume Article share tools Facebook Twitter ṢàpínlòView more share options Share this post Copy this linkKà síwájú síi nípa àwọn ìtọ́kasí wọ̀nyí.
"Akinwumi Isola dárà nínú ìwé ""Nítorí Owó"" lórí Akomolede Yoruba Ìtàn ọ̀rẹ́ tó fi òògùn gba ọkọ ọ̀rẹ́ rẹ̀ ni Akomolede BBC Yorùbá fẹ́ kọ́ wa lònìí Ṣé ẹ̀yin ti rí ọkùnrin tó ń sún ẹ̀kún ìyàwó rí?"
Ṣugbọn ní ìdàkejì, òfin titun ni mò ń kọ si yín, èyí tí a rí òtítọ́ rẹ̀ ninu Jesu Kristi ati ninu yín, nítorí pé òkùnkùn ń kọjá lọ, ìmọ́lẹ̀ tòótọ́ sì ti ń tàn.
Sugbọn ileeṣẹ ologun Naijiria ni irọ ni pe ISWAP ṣọṣẹ bi wọn ṣe sọ.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Abi ki ni ka ti pe ti baba agba kan to n ba ọmọ ọmọ rẹ ni ajọsepọ, titi to fi di oyun.
Ṣugbọn lẹyin nnkan bi oṣu kan lẹyin naa ni ileeṣẹ ọlọpaa ipinlẹ Oyo sọ ninu atẹjade kan pe ọdanran ọhun ti salọ ninu ahamọ to wa.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Onisowo kan lọja Komputa Village nilu Eko ''Ki a to le yan iyalọja, a gbọdọ beere pe igba wo lo ti de ibẹ, ipa wo lo ko ninu itẹsiwaju ọja ati pe iru ọja wo lo n ta nibẹ'' Ọjọgbọn Bisoye ni pẹlu bi ohun ti ṣe wo oye nipa ọja Komputa Village nilu Eko, iruwa ogiri wa ni o wa nibẹ, ko si jọ bi igba wi pe awọn obinrin maa n kopa ninu karakata nibẹ ni eyi ti ko ri bẹẹ ni ti ọja ilu Ibadan.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Olootu ijọba Germany bura fun saa kẹrin 14 Ẹrẹ̀nà 2018 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Aarẹ Frank-Walter Steinmeier lo ti kọkọ yan Merkel ko to di pe o sebura nile asofin kekere Olootu ijọba orilẹede Germany , Angela Merkel sebura lọjọru nile asofin orilẹede naa, eyi to fi nsefilọlẹ saa isejọba kẹrin lori aleefa ni orilẹede ti ọrọ aje rẹ gbooro julọ nilẹ Yuroopu.
Ni Dafidi bá pàṣẹ pé kí ọ̀kan ninu àwọn ọkunrin tí wọ́n wà lọ́dọ̀ rẹ̀, lọ pa ọdọmọkunrin ará Amaleki náà.
lojoBo(Thursday) lati wa fi ehonu won han, eleyi ti o si lee sokunfa idasile.
Alasiya Lagos Killing: Oun tójú àwọn ará àdúgbò rí nìyìí
Jesus in Kenya:Ta ni ọkùnrin tí wọ́n ń pè ní ayédèrú Jesu yìí gan an?
Banki Nàìjíríà, CBN ṣàlàyé nípa àwọn tó máa rí gbà nínú owó ìrànwọ́ N75b tíjọba gbé kalẹ̀ Mọ̀ sí i nípa àwọn ọmọ Nàìjíríà mẹ́sàn-án tó ń díje nínú ìdìbò ilẹ America lọ́jọ́ Ìṣẹ́gun Ẹ dẹ̀kun lílo Sniper àti Dichlorvos fún ìtọ́jú oúnjẹ- NAFDAC kìlọ̀ Ajọ WAEC gbé èsì ìdánwò ọdun 2020 jáde ''Àjọ NERC ti fún Disco láṣẹ láti padà sí owó tàríìfù tuntun iná mọ̀nàmọ́ná'' EFCC bẹ̀rẹ̀ ìwádìí lórí ẹ̀sùn ìwà jẹgúdújẹrá tí wọ́n fi kan Fowler tó jẹ́ Alága iléeṣẹ́ FIRS tẹ́lẹ̀ Ṣe emi ti mi o l'agbara lati pasẹ fun ọlọpaa, ni ma a pasẹ fun sọja?
Ìparun ati ìwà ipá wà níwájú mi, ìjà ati aáwọ̀ sì wà níbi gbogbo.
"Kò sí bí mo ṣe leè rí, kódà, kí wọn dín mi nínú rẹ, mo sì nílò iranlọwọ, torí kii se nkan kékeré ni wọn béèrè""."
Àwọn ẹyẹ ni àwọn ti mọ̀ bí ẹ̀yin ọmọ ènìyàn ti n mu ọmọ àwọn, ọ̀kan nínú wọn ti a ń pè ni kàkó gbóyà to bẹ́ẹ̀ tí ó gbá ọba àwọn lórí, orí ọba Aláyélúwà.
Adolf Hitler gbé àpótí ìbò, aráàlú yàn án sípò gẹ́gẹ́ bíi Káńsílọ̀ Àrún ibà pónjú-pọ́ntọ̀ bẹ́ sílẹ̀!
" Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Helgies Bandeira: Ọ̀pọ̀ oúnjẹ Yorùbá ni à ń jẹ ni Brazil Rita ni, lẹyin oṣu diẹ, inira de ba oun, awọn mọlẹbi oun si gbe oun lọ si ọdọ dokita kan.
2 147 Erekusu Virgin Island tilẹ Gẹẹsi 1 3.
”“Lojo keji, Eti ni awon alase igbimo egbe osise (a Joint Central Working Committee CWC), ni yoo maa gba gbogbo esi ọrọ wọle lati ọdọ awon omo egbe osise lorile ede Naijiria, nibi ti won yoo ti maa forikori lati se ipade pelu ijoba apapo.
 Oríṣun àwòrán, GOVERNMENT HOUSE MEDIA Àkọlé àwòrán, Okina ti wa ni yunifasiti bayii Bi ọpọlọpọ ọmọ, Frederick ati ọrẹ rẹ Kelvin n ri ounjẹ oojọ wọn l'atara agbe ṣiṣe lọsan."
A kò lè gbà kí ìjọba àpapọ̀ ṣ'agbátẹrù Amotekun, ìjọba ilẹ̀ Yorùbá yarí Ajọ to n ri idagbasoke awọn ipinlẹ Yoruba (Development Agenda for Western Nigeria Commission), DAWN ti tako ọrọ ti oludamọran Aarẹ Muhammadu Buhari sọ lori ọrọ iroyin, Garba Shehu sọ pe ọga agba ọlọpaa ni yoo sọ bi ìkọ Amotekun yoo ṣe maa ṣiṣẹ.
Nigba ti awon adari orile-ede ti pada si orile-ede won leyin ipade apero ajo isokan AU fun ti odun 2018 ti o wa sopin ni ojo-Aje, Aare kagame darapo mo akegbe re Mohammadou Issoufou ti orile-ede Niger, Aare Yoweri Museveni ti orile-ede Uganda ati  olori ijoba orile-ede Ethiopia,  Hailemarian Desalegn fun ipade naa.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Tinubu: Ọsinbajo ko gberaga pẹlu ipo giga to wa 8 Ẹrẹ̀nà 2018 Oríṣun àwòrán, Google Àkọlé àwòrán, Ọpọ eeyan lo ri Ọsinbajo bii olootọ si Buhari lasiko ti aarẹ lọ gba itọju loke okun Asaaju kan ninu ẹgbẹ oselu APC lorilẹede Naijiria, Bọla Tinubu ti sọ wipe ipo giga ko yi ise Igbakeji Aarẹ, Yẹmi Ọsinbajo pada, bẹẹ lo si tun jẹ oniwa irẹlẹ ati ẹni to jara mọ isẹ ilu.
Ohun tí ó dára lójú OLUWA, tí Asa baba rẹ̀ ṣe ni òun náà ṣe; ṣugbọn kò wó àwọn pẹpẹ ìrúbọ tí wọ́n wà káàkiri.
Ìpín ti Juda yóo wà lẹ́gbẹ̀ẹ́ ìpín ti Reubẹni, láti ìlà oòrùn títí dé ìwọ̀ oòrùn.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Dexamethsone tablets: Báwó ni òògùn yìí ṣe ń ṣiṣẹ́ lára 17 Òkùdu 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 9 Ògún 2020 Oríṣun àwòrán, Others Àkọlé àwòrán, Dexamethsone tablets: Báwó ni òògùn yìí ṣe ń ṣiṣẹ́ lára Kíni à npè ni Dexamethasone, àti pé báwo ni o ṣe ń wo ààrùn covid-19?
Football legends from Nigeria and other African countries converged today at the Agege Stadium to play a testimonial football match in my honour; to mark the end of my tenure as the Governor of Lagos State.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Sotitobire: Mọ̀lẹ́bí ọmọ ọdún kan tó pòórá ní ṣọ́ọ̀ṣì figbe ta Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Sotitobire: Mọ̀lẹ́bí ọmọ ọdún kan tó pòórá ní ṣọ́ọ̀ṣì figbe ta 27 Bélú 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 30 Òkùdu 2020 Ọjọ́ kẹ́wàá oṣù ìkọ́kànlá ló ṣẹlẹ̀.
Àwọn olùwọ́de kọ̀ láti dáwọ́ dúró lẹ́yìn tí IGP tú SARS ká Ọjọ Aiku, ọjọ kọkanla, oṣu Kẹwaa ni Ọga Agba ileesẹ ọlọpaa, Mohammed Adamu kede pe oun ti tu ẹka ileesẹ ọlọpaa SARS ká.
Oriṣiiriṣii fidio ni Laide fi soju opo Instagram rẹ eleyi to ṣayẹyẹ ọjọ ibi rẹ.
Ṣé òótọ ni pé èèyàn leè kó Coronavirus láti ara aṣọ tàbí bàtà?
Wo àwọn ìbejì tó mú ẹ̀dọ̀ àti egungun àyà kan ṣoṣo wá látọ̀run Èèyàn mẹ́tàlélógóje míì ṣẹ̀ṣẹ̀ kó COVID-19 ní Nàìjíríà Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Oyenusi ló mú mi wọ ẹgbẹ́ adigunjalè kó tó di pé mo b'Ólúwa pàdé' Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Fídíò, Akomolede: Bolaji Faleke ni Olùkọ́ tó ń kọ́ wa ní àṣà oge ṣiṣe lórí BBC Yorùbá1 Owewe 2020 Fídíò, Yoruba Language: Akomolede ati Asa Yoruba tọ̀sẹ̀ yí rèé lẹ́nu olùkọ́ wa30 Ògún 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
 Egbe naa gbosuba kare lai fun egbe oselu mọ́kànléláàdọ́rùn ún ti o kopa ninu idibo abele ti o sese pari lai pe yii, fun sise afihan iwa eni ti o balaga lasiko idibo naa.
AWỌN TO NI AARUN COVID-19 NI NAIJIRIA NI 28/05/2020 Ajọ to n mojuto ajakalẹ aarun ni Naijiria, NCDC, ti kede pe awọn to ti ni aarun coronavirus ni Naijiria ti pe 8,733 bayi.
“Nisinsinyii, ìwọ ọmọ mi, OLUWA yóo wà pẹlu rẹ, kí o lè kọ́ ilé OLUWA Ọlọrun rẹ fún un gẹ́gẹ́ bí ó ti sọ nípa rẹ.
Pósí tí wọn ń tà lẹ́nu ọ̀nà ilé ìwòsàn àpàpọ̀ ló ń tètè pa wá - Aláìsàn figbeta Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 3 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 5 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Àwọn ọmọ Tola ni: Usi, Refaaya, Jerieli, Jahimai, Ibisamu ati Ṣemueli, àwọn ni baálé ninu ìdílé Tola, baba wọn, akikanju jagunjagun ni wọ́n ní àkókò wọn.
Nítorí náà pupọ ninu àwọn tí wọ́n wà ninu ọkọ̀ rò pé kí àwọn kúrò níbẹ̀, bóyá wọn yóo lè dé Fonike níbi tí wọn yóo lè dúró ní ìgbà òtútù.
N óo máa dáṣọ fún ọ, n óo sì máa bọ́ ọ.
Ìtàn Mánigbàgbé: Ìnà ẹgba mẹ́sàn-án ni Jesu Oyingbo fi ń kí ọmọ ìjọ ọ́kùnrin tuntun káàbọ̀
BBCCopyright: BBC Ikini lori bbcnewsyorubaImage caption: Ikini lori bbcnewsyoruba BBCCopyright: BBC Ikini lori bbcnewsyorubaImage caption: Ikini lori bbcnewsyoruba Article share tools Facebook Twitter ṢàpínlòView more share options Share this post Copy this linkKà síwájú síi nípa àwọn ìtọ́kasí wọ̀nyí.
Lẹ́yìn náà ni ó mú Joaṣi, ọmọ ọba jáde síta, ó fi adé ọba dé e lórí, ó sì fún un ní ìwé òfin.
" Àwọn tí wọ ́ n ṣẹ ̀ ṣẹ ̀ ń ṣe fíìmù yorùbá ni ìgbà náà ni : jimoh aliu tí ó ṣe "" Ètékéte "" , tunde Àlàbí hundeyin ṣe "" iyawo alhaji "" , professor pellar náà ṣe fíìmù mẹ ́ ta ."
Gbogbo ẹbọ ohun jíjẹ tí a fi òróró pò tabi tí ó jẹ́ ìyẹ̀fun, yóo wà fún àwọn ọmọ Aaroni bákan náà.
Ilẹ̀ tiwọn bẹ̀rẹ̀ láti Mahanaimu, títí dé gbogbo ilẹ̀ Baṣani, gbogbo ilẹ̀ ìjọba Ogu, ọba Baṣani, ati gbogbo àwọn ìlú Jairi tí ó wà ní Baṣani, gbogbo ìlú wọn jẹ́ ọgọta.
O ni koko ipade yii ni lati jo foju sunukun wo ona abayo si sise amojuto si awon ibon to ti bo sowo awon ti ko ye ati ilo oogun oloro to tun ti wopo sii lasiko yii pelu isoro awon to n jinigbe.
Oríṣun àwòrán, Instagram/abiola ajimobi Iṣẹ ti Ajimobi yan laayo: Yoruba ni ajo ko dabi ile nitori ile labọ sinmi oko, idi ree ti Abiola Ajimobi fi pada wa sile, to si ri iṣẹ pẹlu Ileesẹ elepo rọbi kan National Oil eyi to wa labẹ Ileesẹ elepo rọbi Shell, Nibẹ, to si sun kẹrẹ-kẹrẹ de ipo oludari agba fun Ileesẹ naa.
Äbileko yii gba awon eniyan nimoran lati maa je ounje eemeta lojumo lasiko ti ko tii re ara nigba ti ile ko tii su.
Eleyi si ti da ibẹru-bojo silẹ ni agbegbe ti iṣẹlẹ naa ti ṣẹlẹ ni ijọba ibilẹ Ijero.
Bẹ́ẹ̀ ni ẹ gbọdọ̀ máa ṣe kí ẹ má baà jẹ̀bi.
Iye awọn eeyan to ṣẹṣẹ ko arun naa ni ipinlẹ kọọkan ree: Eko-259 Oyo-76 Katsina-69 Delta-66 Rivers-46 Ogun-23 Edo-22 Osun-22 Ebonyi-21 FCT-20 Kaduna-16 Ondo-10 Imo-9 Abia-9 Gombe-5 Plateau-4 Bauchi-4 Ekiti-2 Anambra-1 Ọwọ́ NDLEA tẹ àádọ́jọ èèyàn tó gbé oògùn olóró l‘Ondo Ajimobi kìí bá ọ̀lẹ, olè àti ọlọ́pọlọ kúkú ṣe ọ̀rẹ́ - Alaafin Tinubu, ojú tì ẹ́, o ta Yorùbá fún ọ̀tá torí àdánìkànjẹ - Fani-Kayode Àwọn èèyàn ìpínlẹ́ Ondo kò gbàgbọ́ pé Coronavirus wà lọ jẹ́ kó máa pọ̀ síi - ìjọba Eeyan ẹgbẹtadinmẹfa lo tun ṣẹṣẹ ni Covid-19 ni Naijiria.
Ọba ni Wuraọla mọọmọ n huwa ika yii si awọn to ba dẹnu kọọ ni lọna ati mọ bi wọn se ni suuru, ifarada ati ipamọra si.
Lẹ́yìn náà, kí ẹ dẹ̀yìn lẹ́yìn rẹ̀, kí ogun lè pa á.
Awọn ọmọ ogun mejila la gbo pe awọn agbebọn seku pa nigba ti wọn kọlu wọn ni abule Konmpanin Doka ni ijọba ibile Birnin- Gwari, nilu Kaduna.
Ami ayo mẹjọ sodo ni France fun Super Falcons ninu ere bọọlu ọlọọrẹsọọrẹ ti wọn jọ gba lọdun 2018.
Ninu atẹjade kan ti kọmiṣọnna feto iroyin ati ilanilọyẹ ni ipinlẹ naa, Arabinrin Funkẹ Ẹgbẹmọde fi sita lẹyin ipade igbimọ iṣakoso ijọba ni ipinlẹ naa, ijọba ipinlẹ Ọṣun ṣalaye pe awọn ilana a a tẹle gbogbo yoo ṣi wa nikalẹ fawọn alẹnulọrọ lẹka eto ẹkọ nibẹ ni ibamu pẹlu ilana ti ijọba apapọ ba gbe kalẹ.
awon ise akanse ohun wa si imuse.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Plane crash: Díẹ̀ ló kù kí bàlúù arìnrìnàjò sílẹ̀ mímọ́ Hajj gbaná ní Minna 7 Owewe 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 8 Owewe 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ori ko arinrinajo ẹgbẹta o din aadọta yọ ninu iṣẹlẹ ọhun.
Ọ̀rọ̀ ọ t’òní á fẹ́ jọ yẹ̀yẹ́ létí ẹlòmíì, ṣùgbọ́n kìí ṣ’àwàdà rárá o.
Panuwat Puttakam to jẹ ọlọpaa nileesẹ ọlọpaa Chum Phuang sọ fun iwe iroyin Bangkok Psot pe iya ọmọ naa ti wa ni abẹ amojuto awọn obi rẹ ati onimọ nipa ihuwasi ẹda.
Ilé ẹjọ́ sún ẹjọ́ Sẹ́nétọ̀ Abbo síwájú pẹ̀lú béèlì mílíọ̀nù márùn-ún Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Fulani Kidnapping: Owó púpọ̀ la san kí wọ́n tó fi mi sílẹ̀ Ọgbẹ naa ni awọn yoo yan akọnimọọgba kan na fun 'gba diẹ lẹyin ti awọn ba ṣe ipade pajawiri lọjọbọ ọsẹ oun si ni yoo dari awọn fun idije ife ẹyẹ African Nations Championship (CHAN) eyi ti wọn yoo bẹrẹ loṣu yii.
BBC Sport ri i gbọ wi pe wọn yoo ṣe ayẹwo aarun coronavirus fun awọn agbabọọlu lẹẹmeji lọsẹ, ti igbaradi ba bẹrẹ saaju ki ofin konile o gbele to kasẹ nilẹ.
Oníṣègùn kan tí í ṣe ikọ̀ òṣìṣẹ́ ìlera tí ó ṣe ìrìnàjò náà sọ wípé:
Alukoro ẹgbẹ oṣelu PDP, Kola Ọlọgbọndiyan to ba BBC Yoruba sọrọ, ṣalaye pe ayẹwo ibo lawọn n ṣe lọwọ nigba ti awọn janduku ọhun yabo gbọngan idibo naa ti wọn si bẹrẹ si ni yinbọn pẹrẹpẹ.
Ọpọ awọn orilẹ-ede lo ti ṣagbekalẹ ẹrọ ibaraẹni sọrọ ti awọn eeyan le pe ti ọkọ wọn ba n lu wọn nile, ọpọ awọn obinrin lo si ti bẹrẹ si n pe awọn ẹro ibaraẹni sọrọ naa.
A óo sì yọ̀ǹda gbogbo èso ọdún keje keje, ati gbogbo gbèsè tí eniyan bá jẹ wá.
Tẹ́tí sí adura mi, Ọlọrun,má sì fara pamọ́ nígbà tí mo bá ń bẹ̀bẹ̀.
 Bourdain ni aṣeyọri iwe àsè ti oun kọ nipa jiji dide nidaji ṣaaju iṣẹ oojọ oun ya oun lẹnu gidi.
Dangote, Otedola di olùdámọ̀ràn ìgbìmọ̀ ìpolongo APC Arsenal bọ́ mọ́ Dangote lọ́wọ́ láti rà Dangote: Buhari ti sọ àgbẹ̀ d'ọba Gẹgẹ bi nnkan ti iwe iroyin naa ti sọ, Dangote padanu biliọnu mẹji dọla latari bi nnkan ko ti ṣe lọ deede lẹka Dangote Cement rẹ.
ipinlẹ  ti egbe won gbe n sakoso le lori.
Rogbodiyan ti dinku Oludari agba ohun, ogbeni Osita tesiwaju pe adinku ti ba rogbodiyan lolokan-o-jokan saaju eto idibo gbogbogboo ohun.
Oríṣun àwòrán, Instagram Àkọlé àwòrán, Awẹlẹwa oṣere, Bimbo Osin ni wọn bi ni Ọjọ Kẹrinlelogun, ọdun 1971 ni ilu Ondo, ti o si jẹ ọmọ kẹfa ninu ẹbi marun un.
Gbọ́ àlá mi kí o sì sọ ìtumọ̀ rẹ̀ fún mi.
Ó dá wọn lóhùn pé, “Ẹni tí ó mú mi lára dá ni ó sọ pé kí n ká ẹní mi, kí n máa rìn.
igbagbo ninu ijoba yii pe, won yoo mu wa de ebute ogo, sugbon ẹyin ọdọ  orile ede yii ni irinsẹ fun idagbasoke orile
Bekinbo so pe, ise-akanse ipese ohun elo yii wa ni ipele kinni ati ikeji, nigba ti won yoo bere ipele keta ninu osu karun oddun ti a wa yii.
Àfonífojì Betirehobu ni ìlú Laiṣi yìí wà.
Òkú oúnjẹ ni wọ́n, èmi pàápàá kò gbọ́ ìgbàgbọ́ oúnjẹ rí, ọjọ́ náà ni mo kọ́ gbọ́ ọ, n ó máa kà á nísisì yìí, kí ẹ̀yín náà máa kà á tẹ̀lé mi.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Coronavirus: Àwọn onímọ̀ sáyẹ́ǹsì Nàíjíríà ṣe ẹ̀rọ àyẹ̀wò àrùn jáde 20 Ẹrẹ̀nà 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 10 Agẹmo 2020 Idunnu ti sibu lu ayọ ni orilẹede Naijiria nitori ijọba ti kede pe agbega yoo ba eto ayẹwo awọn eeyan to seese ko ni arun Coronavirus lara.
Ọlọrun dá awọsanma, ó fi ya omi tí ó wà lábẹ́ rẹ̀ kúrò lára èyí tí ó wà lókè rẹ̀, ó sì rí bẹ́ẹ̀.
Beeni aare tun ja Abdur-Raheem Adebayo Shittu silẹ, eni ti o je minisita fun eto ibaraẹnisọrọ.
Bákan náà ni wọn yóo jọ pín oúnjẹ wọn láìka ohun tí àwọn ará ilé rẹ̀ bá fi ranṣẹ sí i gẹ́gẹ́ bí ohun tí ó kàn án ninu ogún baba rẹ̀ tí wọ́n tà.
Ó wá wọn odi rẹ̀, ó ga tó igba ẹsẹ̀ ó lé ogún (220) gẹ́gẹ́ bí ìwọ̀n eniyan tí angẹli náà ń lò.
Èyí ẹ̀kẹfà tí í ṣe àbúrò Àgùntàn-ìnàkí ní ìdí ìyá, orúkọ ẹni tí ń jẹ́ Ilé-ni-ikú-wà, kú lójú ọ̀nà nígbà tí a kúrò ní ìlú náà tán.
Ìbò 3,498 yì ohùn Ifá padà nínú ìdìbò Ọṣun APC yọ orúkọ Shittu kúrò láti kópa nínú ìdìbò abẹ́lé Ọọnirisa pa àwọn aṣàtìpó lẹ́rin ayọ̀ ni Ibùdó Wasa Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Dele Adeleke: Ǹkan tó tọ́sí Ọsun kó ni Ọsun rígbà O ni oju awọn koro-koro si lawọn fi se mẹrin awọn isẹlẹ to nii se pẹlu iwa ọyaju sawọn oludibo ati idunkooko mọ wọn, to fi mọ iroyin nipa titabuku awọn ọmọ ẹgbẹ oselu to n tọpinpin bi ibo naa se n lọ, awọn akọroyin ati awọn olutọpinpin eto idibo labẹle.
Ààrẹ Buhari jámi lórí ètò RUGA ná Ẹ má dá NEF lóhùn, kò síbi t'ọ́mọ Nàìjíríà kò lè gbé nílẹ̀ yìí - Buhari Ìdí rèé táwọn ọmọ Nàíjíríà kan ṣe ń tako ìdásílẹ̀ ‘Ruga Settlement’ Bakan naa ni Minisita naa sọ pe ajọ EU ti fi igba kan gbẹsẹ le, ti wọn si tun fi ofin de awọn ọja to wa lati Uganda.
OLUWA Ọlọrun rẹ yóo bukun ọ ní ilẹ̀ tí ó fún ọ.
To ba si wa sọ iru ọ̀rọ̀ eebu yii niwaju aarẹ Trump tabi OBJ, mo mọ iru esi ti wọn yoo fun un.
Oríṣun àwòrán, Twitter Pẹlu orin naa ni Aisha Buhari kọ atẹjade to fi pe fun ki opin de ba eto aabo to dẹnukọlẹ ni Ariwa orilẹede Niajiria naa.
Bẹẹ ba gbagbe, ileesẹ aṣọbode nilẹ wa gbe Baba Suwe si ahamọ lọjọ kẹrinla, oṣu kẹwaa, ọdun 2011, eyiun ọdun mẹsan an sẹyin lori ẹsun pe o gbe oogun oloro.
Mo tú ẹ̀dùn ọkàn mi palẹ̀ níwájú rẹ̀,mo sọ ìṣòro mi fún un.
Orile ede mejeeji fopin si ija ogun odun to wa laarin wọn  nigba ti wọn  jọ tọwọbọ iwe adehun alaafia ati ibasepọ ni ọjọ kẹ́sán án, osu kéje.
"O ni ""A fi ikede sita pe ki awọn eeyan to ba ni oogun ti wọn gbagbọ pe o le wo Covid-19 ko yọju si ajọ naa."
Ǹkan tí a mọ̀ nípa kọ́lẹ̀jì olùdìbò tó ń fìdì ẹni ti yóò jẹ ààrẹ ilẹ̀ Amérika múlẹ̀ Wo iye owó tí ìjọba Amẹrika ń na sí ìdìbò Ààrẹ àti ibi tí owó náà ti ń wá Mọ̀ sí i nípa àwọn ọmọ Nàìjíríà mẹ́sàn-án tó ń díje nínú ìdìbò ilẹ America lọ́jọ́ Ìṣẹ́gun US Election 2020: Ṣé èsì ìdìbò Ààrẹ Amẹrika yóò jáde lálẹ́ ọjọ́ ìdìbò?
Abayomi ni ipinlẹ Eko lo ti ṣe ayẹwo arun Coronavirus julọ lorilẹede Naijiria pẹlu eniyan 236,212 to ti ṣe ayẹwo ọhun ni ipinlẹ Eko.
Super Falcons fi South Korea ṣ’ẹ̀bùn June 12 fún Nàìjíríà Beckham, àgbábọ́ọ́lù tẹ́lẹ̀ rèé tó ń sọ èdè Yorùbá Dagunro ní ìtẹríba, tó sì ń gbé àṣà lárugẹ - Ọ̀gá Bello Àwọn oun ti a ti sọ tẹlẹ: Akọnimọọgba Super Falcons, Thomas Dennerby sọ pe oun nigbagbọ pe Naijiria si le fakọyọ lalẹ oni bi wọn ti ṣe pẹlu South Korea.
Onimọ nipa eto isuna ti sọ wi pe igbe aye awọn osisẹ yoo dara diẹ ju tẹlẹ lọ lasiko ti ijọba Naijiria buwọlu gbedeke owo osu osisẹ to jẹ ẹgbẹẹrun lọna ọgbọn naira(N30,000).
1284 Poopu mii, Innocent III sọ asọtẹlẹ pe ọdun 1284 eyi to jẹ ọdun 666 lẹyin ti ẹsin Islam bẹrẹ ni aye yoo parẹ.
Atiku n ṣé iranran lórí ìbò 1.
Eyi lo mu ki wọn maa huwa kebe-kebe, ti wọn si da ọkọ awọn duro lati beere fun owo.
Bí Buhari wọ́gilé wíwọ bàálù olówó gọbọi fún òṣìṣẹ́ ìjọba kó ṣe aráàlú láǹfàní - SERAP Obinrin kan àti ọmọ rẹ̀ jóná nínú ìjàmbá iná ọjà Onitsha Àwọn ojú oge Yollywood t'ọ́jà wọ́n ṣì ń tà wàràwàrà O fi we ọmọ ileewe ti ko tii ka ipele ikini yọri na ni fasiti ti wọn ti n sọ fun pe ibi ti yoo ti ṣiṣẹ ree to ba ti pari agunbanirọ rẹ.
"A ó fún ẹbí akẹ́kọ̀ọ́ Fásitì Ibadan tó dolóògbé ní owóo gbà mábìnú - Ìjọba Oyo ""Mo bọ̀wọ̀ fún Fathia Balogun púpọ̀, ẹ̀dá ọ̀tọ̀ táwọn èèyàn ò fura sí ni""."
Ó mú ìgbàyà, ó so ó mọ́ ọn láyà, ó sì fi Urimu ati Tumimu sí ara ìgbàyà náà.
Ninu osu kẹwaa ọdun 2020 yii naa ni iwọde EndSARS waye, ninu eyi ti ọpọ ẹmi ati dukia ti baa rin, ti laasigbo si gbode pẹlu.
Mo mọ ìfẹ́ rẹ ati igbagbọ rẹ, mo mọ iṣẹ́ rere tí ò ń ṣe ati ìfaradà rẹ.
Oríṣun àwòrán, Instagram/queenola2 Ni ọpọ oju opo ibanidọrẹ Olori Badra lori ayelujara, koko ohun to jẹ logun ni ipolowo awọn ọja aje rẹ, eyi to foju han pe kii se ẹyọ kan ni.
 “Isẹlẹ buruku gbaa ni eyi , ijoba yoo ri I pe won fi iya jẹ enikeni to
Olórí Alufaa tún bi í pé, “Ìwọ ni Kristi náà, Ọmọ Olùbùkún?
OLUWA Ọlọrun tún fi ìran mìíràn hàn mí: mo rí i tí OLUWA mú okùn ìwọ̀n àwọn mọlémọlé lọ́wọ́; ó dúró lẹ́bàá ògiri tí a ti fi okùn ìwọ̀n àwọn mọlémọlé wọ̀n.
Live: Ìjọba ìpínlẹ̀ Èkó bẹ̀rẹ̀ ilé wíwó ní Lagos Island Ẹgbẹ agbabọọlu ilẹ Gẹẹsi lawọn ikọ agbabọọlu mejeeji ti wọn si ti koju ara wọn ninu idije Premier League ni saa yii.
lọwọlọwọ , anafilasisi nfa iye iku 500-1,000 l ' ọdun ( 2.
 olùdarí morris tún fi kun wípé kíkọ ́ àwọn ará gúsù ilẹ ̀ nàìjíríà lẹ ́ kọ ̀ ọ ́ gidi nílé-ẹ ̀ kọ ́ yábàá , kí wọ ́ n le dara pọ ̀ mọ ́ àwọn akẹ ́ gbẹ ́ wọ ́ n láti Ìlà-Óòrùn níbi ètò ìgbani síṣẹ ́ ìjọba .
Ó súre fún ẹ̀yà Nafutali pé:“OLUWA ti ṣíjú rere wo Nafutali,ó sì ti bukun un lọpọlọpọ,ilẹ̀ wọn bẹ̀rẹ̀ láti adágún Galili,títí lọ kan gúsù gbọ̀ngbọ̀n.
Ko wa tan sibẹ o, Adebayo Adelabu to jẹ oludije si ipo gomina fẹgbẹ osẹlu APC naa tun fidi rẹmi lẹyin ti Ṣeyin Makinde ti ẹgbẹ PDP wọ le ibo ọhun.
Àwọn nìwọ̀nyí: Sakaraya, ọmọ Jonatani, ọmọ Ṣemaaya, ọmọ Matanaya, ọmọ Mikaaya, ọmọ Sakuri, ọmọ Asafu, 
1 2574319 Orilẹede Argentina 40431 91.
Nínú ìwé ìròyìn ni a ti ṣa àwọn ìròyìn àti àkọsílẹ̀ láti ọwọ́ọ ilé ẹjọ́ Oníwàádìí-ẹni-tí-ó-kú.
Nígbà tí bàbá mi ń rìn tọ obìnrin yìí lọ obìnrin náà dúró, ṣùgbọ́n ẹnìkejì rẹ̀ rìn síwájú díẹ̀ eléyìínì dúró, ó takáté sí i, nítorí nígbàtí ọkùnrin àti oobìnrin bá ń fẹ́ẹ́ sọ̀rọ̀ ìkọ̀kọ̀ ẹnì kẹta kò ní ṣàì jẹ́ ìdíwọ́ fún wọn.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Obasanjo: Ètò ààbò tó mẹ́hẹ lè dá'jà ẹlẹ́yàmẹ̀yà sílẹ̀ 15 Agẹmo 2019 Oríṣun àwòrán, Twitter/Presidency Àkọlé àwòrán, Àjálù ń bọ̀, tí Buhari kò bá ṣàtúnṣe lórí ètò ààbò- Obasanjo Aarẹ ana orilẹ-ede Naijiria, Olusegun Obasanjo ti kọ lẹta miiran si Aarẹ Muhammadu Buhari lori eto aabo to mẹhẹ lorilẹ-ede Naijiria.
Wayi o, Totti omo odun méjílélógójì ohun feyin ti
Alufaa kan tí ó ń bọ̀ ṣe kòńgẹ́ rẹ̀ ní ọ̀nà, ṣugbọn nígbà tí ó rí i, ó gba òdìkejì kọjá lọ.
Mose bá sọ̀kalẹ̀ láti orí òkè, ó tọ àwọn eniyan náà lọ, ó yà wọ́n sí mímọ́, wọ́n sì fọ aṣọ wọn.
” Ó bá fọwọ́ kan etí ẹrú náà, etí náà sì san.
Sista ijọ katoliki, tii se ọga agba ileẹkọ girama Bethlehem Girls college, Henritta Alokha, to wa ladugbo naa, lo jalaisi lasiko to n gbiyanju ati doola ẹmi awọn ọmọ ileẹkọ naa.
 Ọbáńta sì jẹ ́ ọmọ-ọmọ alárẹ ̀ .
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Super Falcons: Wọn nfi ilọkulọ ibalopọ lọ wa 'Ibi àríyá ni àbúrò mi d'ágbére kí ọlọ́pàá tó fi ẹ̀sùn ìbálòpọ̀ akọ-sí-akọ kàn án' Ọ̀rẹ́kùnrin mi fún mi ní àárùn HIV, mo sì gbẹ̀san Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ayàwòrán Obama: Ọ̀pọ̀ ìgbà ni èmi àti ìyá mi pa èbi mọ́nú kí n tó jẹ́ èèyàn Ṣugbọn l'ọjọ kan, mo n wa nkankan to gbe mi de ọọfisi rẹ to wa ninu ile wa.
Wọn beere lọwọ bí i ẹgbẹrun meji eniyan, boya ẹnikẹni ninu ile wọn ni àmì aisan to ni ṣe pẹlu èémí.
"Dokita ba sọ fun un pe ""a ti ṣa gbogbo ipa wa lọna ti a mọ ti a si ro pe a lee lo""."
Bẹẹ, awọn ile iṣẹ Aamin maa n soju abẹ niko lori odiwọn iye awọn ti wọn ba gbe lo ile iwosan fun itọju ni.
"Mo n ṣe agbekalẹ eto iranwọ fun ẹkọ yii lati ṣatilẹyin fun ohun ti ijọba n ṣe.
Àwọn ọmọ ogun sì dúró pẹlu ohun ìjà lọ́wọ́ wọn láti ìhà gúsù ilé náà títí dé ìhà àríwá rẹ̀, wọ́n yí pẹpẹ ati ilé náà ká.
Nítorí ìdí èyí, KFC di gbajúgbajà, wọ́n di ọ̀kan nínú àwọn ilé-oúnjẹ aláràjẹ tó lókìkí jù ní gbogbo àgbáyé.
Nítorí náà, ní wéréwéré yìí ni mò ń rán an bọ̀ kí ẹ lè tún rí i, kí inú yín lè dùn, kí ọkàn tèmi náà sì lè balẹ̀.
Kí àwọn eniyan lè mọ̀ pé, láti ìlà oòrùn títí dé ìwọ̀ rẹ̀,kò sí ẹlòmíràn lẹ́yìn mi.
Ogbeni Okechukwu tun so pe  “ohun to se pataki ni lati lowo ninu awujo to se e gbe ati ona ti igbo yoo se de ipo aare lodun 2023.
Kò tíì sí irú àsè Àjọ Ìrékọjá bẹ́ẹ̀ ní gbogbo ilẹ̀ Israẹli láti ìgbà ayé wolii Samuẹli.
Nitori naa ni wọn ṣe wa kuku kuro ni agbegbe naa patapata, ki ifẹhọnu han ma ba a mu ẹmi ẹnikẹni lọ.
Wọ́n gbógun ti Kedorilaomeri, ọba Elamu, Tidali, ọba Goiimu, Amrafeli, ọba Babiloni ati Arioku, ọba Elasari.
Bakan naa lo ni adugbo tawọn ẹbi ọhun fẹ ni wọn gba ile naa si fun wọn.
ede yii , ti won nifẹẹ si eto aabo ati alaafan lorile ede Naijiria.
8 88389 Orilẹede Ireland 2488 51.
Bí OLUWA ti pàṣẹ fún Mose gan-an ni àwọn ọmọ Israẹli ṣe pín ilẹ̀ náà.
Europa League: Arsenal fi Valencia ṣe àtẹ̀gùn wọ àṣekágbá
Donald Trump Jr to jẹ ẹni ọdun mejilelogoji lọ ṣe ayẹwo lọsẹ yii, nigba to gba esi, o ti wa ni iyasọtọ ninu ile rẹ lati igba naa.
Garba Shehu tun sọ pe gbogbo ariwo awọn ọmọ Naijiria lori iṣẹlẹ naa ni awọn ti gbọ.
Ọgọta ero, ẹsọ meji, osisẹ baalu meji ati awakọ ofurufu meji lo wa ninu baalu naa Agbẹnusọ kan sọ wipe: Wọn ti ta gbogbo awọn osisẹ iranwọ pajawiri ji lati wa ni sẹpẹ."
Àwọn ìwé àkọsílẹ̀ wà ní ṣíṣí.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ọjọ́ Ìsẹ́gun di ọjọ́ ìbànújẹ́ fún ọ̀pọ̀ ìdílé ní Nàíjíríà torí òkú tó ṣùn Ọ̀dọ́ 30 ń gba ìtọ́jú lọ́wọ́ nílé ìwòsàn torí ọ̀gbẹ́ ìbọn ní Lekki - Sanwo-Olu ṣàlàyé Àwọn ṣọ́jà ṣíná ìbọn bolẹ̀ ni Lekki Tollgate Àwọn ọlọ́dẹ darapọ̀ mọ́ ìwọ́de #EndSARS l'Osogbo, wọ́n ní kò sáyè fún jàǹdùkú mọ́ Kíní ìtumọ̀ ''Sọ̀rọ̀ Sókè'' tí àwọn afẹ̀họ́núhàn EndSars ń lò káàkiri Ìpínlẹ̀ Ogun náà ti ilé ìwé títí dí ọjọ́ Ajé tó m bọ̀, kò ní sí lílọ bíbọ̀ ọ̀kádà fún wákàtí 24 O sọ fun ileeṣẹ iroyin abẹle Channels pe, ko bojumu to bi awọn ọmọ ogun naa ṣe lo ọta ibọn to lee gbẹmi eeyan lati tu awọn oluwọde ka.
 Awọn nọọsi funra wọn lo n gbalẹ bayii, eeyan lawọn naa, a ko si lee fi ẹmi wọn wewu.
Oríṣun àwòrán, Adetomi Akin Ogundare fikun pe ẹlẹwọn mejidinlaadọta lo wa ni ọgba ẹwọn naa, gbogbo wọn si ni awọn janduku shun tu silẹ.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ọjọru ni wọn yoo ṣi afara naa fun lilọ-bibọ ọkọ Bakan naa lawọn ẹgbẹ ajafẹtọ ayika naa tun ti n pariwo sita pe wahala ti kikọ afara naa ti ko ba awọn ohun abẹmi ti wọn n gbe ninu okun naa ko kere.
Àwọn ọkunrin mẹrin kan wà lọ́dọ̀ wa tí wọ́n ti jẹ́jẹ̀ẹ́.
“O ní, ‘Ọlọrun ń to àìdára wọn jọ de àwọn ọmọ wọn.
Ọgá ọlọ́pàá, Damian Chukwu, nínú atẹjade kàn sọ pé àwọn afurasi náà jẹwo pe awọn láwọn wa nìdí ikọlù oríṣiríṣi to waye ní ìpínlẹ̀ Borno ati Adamawa.
Ojota Clover Leaf Bridge, Ijọba ibilẹ Kosofe / Ikeja 21.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Fibroid: Ǹjẹ́ o mọ pé o le ní oyún ìju tí o kò bá tètè bímọ?
O kere tan awọn eeyan mẹrinla ti kagbako iku lọwọ afurasi ọmọ ikọ Boko Haram kan to ṣe ikọlu sawọn alaṣẹ ipinlẹ Borno lọjọ Ẹti.
Thabo Makhene, omo odun mejilelogbon ni“ 
Idije naa ni yoo jẹ ti aṣekagba idije ife agbaye awọn obinrin l'orilẹ-ede France.
EFCC: Patience Jonathan gbọdọ foju wina igbẹjọ
Coronavirus: Ìwádìí ń lọ láti fi ẹ̀jẹ̀ àwọn tó ti jajabọ lọ́wọ́ Coronavirus ṣe ìwòsàn fáwọn alárùn míràn
Eji Gbadero, ọmọ Ibadan àti jayé-jayé ọmọ ónílẹ̀ ti wọn yẹgi fun l'Eko Lisabi Agbongbo Akala rèé, ẹni tó fi ìfẹ́, ìṣọ̀kan àti ìrẹ́pọ̀ gba ilẹ̀ Ẹ̀gbá lọ́wọ́ ìmúnisìn A jọ ṣe ìyàwó pọ̀, a jọ bímọ ní ọjọ́ kan náà, a tún jọ máa ń ṣàìsàn pọ̀ ni Ìyàwó mi fẹ́ràn ìrìnàjò òfurufú ni mo ṣe kọ́ ilé Bàálù yìí fún un Omi ìṣẹ̀ńbáyé tó ń dà ní Ówù rèé, èyí tó ga jùlọ ní Afirika Awọn arinrinajo to ba akọroyin BBC Yoruba sọrọ sọ pe, dide si papakọ ọkọ ofurufu ni wakati mẹta ṣaaju irinajo, ko rọrun.
Ọjọ meji lẹyin iṣẹlẹ naa ni ọwọ ọlọpaa tẹ ọdaran naa ni Yaba, to wa ni ilu Ondo.
Kẹrẹkẹrẹ ti ere bọọlu naa n tẹsiwaju ni Sheffield ba tun fọba lee lẹyin ti wọn gbayo ẹlẹẹkeji sawọn.
Ẹ kó gbogbo ìkógun tí ẹ bá rí ninu ìlú náà jọ sí ààrin ìgboro rẹ̀, kí ẹ sì dáná sun gbogbo rẹ̀ bí ẹbọ sísun sí OLUWA Ọlọrun yín.
O kì bá tí dúró sí oríta,kí o máa mú àwọn tí wọn ń gbìyànjú láti sá àsálà;o kì bá tí fà wọ́n lé àwọn ọ̀tá wọn lọ́wọ́ní ọjọ́ ìpọ́njú wọn.
Alasẹ awọn ajafẹtọ-ọmọniyan lagbegbe Asia, Phil Robertson, sọ fun BBC 100 Women wi pe ''awa ko lodi sofin Sharia ni igba ti ko ba ti máa dẹyẹ si awọn obinrin, awọn eeyan lakọ si akọ tabi abo si abo tabi awọn eleya kankan.
Ariwo Shekau ku ti ko tun ku mọ to tun jinde ti waye ni ọpọ igba kaakiri Naijiria.
Ṣugbọn to ba jẹ aisan lo fa yiyi awọ oju pada, o san ki ẹni bẹ́ẹ̀ tete lọ fun itọju bi o ṣe yẹ lasiko.
Ààbò tó péye wà fún àwọn okòwò ará South Africa ni Eko -Sanwo Olu Akeredolu ò ṣe ǹkan àrítọ́kasi ni Ondo- Komísọnà ọ̀rọ̀ to n lọ tẹ́lẹ̀rí Ẹ máṣe gba ààwẹ̀ dójú ikú, ẹ gba iye tí agbára yín gbé - Dókítà Ọ̀nà láti sọ fásitì Lautech di ti Ọyọ nìkan ni Makinde ń sán - Ìjọba Ọṣun O fi kun ọrọ rẹ pe awọn agbabọọlu mẹfa miran ni wọn tun n reti baagi ti ohun eelo wọn wa gẹgẹ bi igbaradi yoo ṣe bẹrẹ ni ọjọ Iṣẹgun ni pẹrẹwu.
Wọ́n gba àwọn olùdámọ̀ràn èké tí wọ́n ń san owó fún láti da ìpinnu àwọn ará Juda rú ní gbogbo àkókò ìjọba Kirusi, ọba Pasia, títí di àkókò Dariusi, ọba Pasia.
4 Èbibi 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 5 Èbibi 2019 Oríṣun àwòrán, @afcbournemouth Àkọlé àwòrán, Son lo kọkọ gba kaadi alawọ pupa nigba ti ifẹsẹwọnsẹ naa wọ iṣẹju kẹtalelogoji ti Foyth si gba tirẹ ni iṣẹju kejidinlaadọta Bi idije premiership ṣe n lọ si ibi ipari bayii ti awọn ẹgbẹ agbabọọlu si n lepa bi saa to n bọ yoo ṣe ri, ẹgbẹ agbabọọẹu Tottenham da ara rẹ lagbo da sina nigba to lọ ba Bournemouth ni ile ni ọsan ọjọ abamẹta.
Lẹ́yìn àjàkálẹ̀ àrùn náà, OLUWA sọ fún Mose ati Eleasari alufaa ọmọ Aaroni pé, 
Ọjọ́ meje láàrin ọdún kan ni ẹ óo máa fi ṣe àjọ̀dún fún OLUWA; Ìlànà títí lae ni èyí jẹ́ fún arọmọdọmọ yín.
Láì-ṣe-àní-àní, kò ní ṣáìyà ọ́ lẹ́nu bí o ti ṣe déédéé bá mi nínú igbó yìí nígbà tí o dé ọ̀dọ̀ mi ní ìjẹta.
Awọn ọpọ ọdun ta maa n ri awọn baba ati arakunrin wa ti wọn maa n gbe bia kiri ti waye sẹyin.
Ó tún jẹ́ ọ̀kan lára àwọn ọmọ ìgbìmọ̀ ayẹ̀wé owó wò fún Caverton Offshore Services Group Plc.
“Nítorí náà, nígbà tí o bá ń ṣe ìtọrẹ àánú, má ṣe gbé agogo síta gẹ́gẹ́ bí àwọn aláṣehàn tí ń ṣe ninu àwọn ilé ìpàdé ati ní ojú títì ní ìgboro, kí wọn lè gba ìyìn eniyan.
Nibayii, aarẹ ẹgbẹ oṣiṣẹ NLC lorilẹ-ede Naijiria, Ayuba Wabba ati igbimọ iṣakoso apapọ ẹgbẹ oṣiṣẹ lorilẹ-ede Naijiria ti ranṣẹ pada si gomina Amosun pe awọn ti gbọ ohun to sọ o, ṣugbọn apo ara rẹ lo sọ ọ si.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ààrẹ Beji Caid Essebsi, torílẹ̀èdè Tunisia jáde fáyé 25 Agẹmo 2019 Oríṣun àwòrán, AFP Ìròyìn tó ń tẹ̀ wa lọ́wọ́lọ́wọ́ ní wí pé Aarẹ akọkọ ti wọn kọkọ finu findọ yan ni orilẹede Tunisia, Beji Caid Essebsi ti jade laye lẹni ọdun mejilelaadọrun.
Ó ń sọ ní ọkàn rẹ̀ pé,‘Ọba orí ìtẹ́ ni mí,èmi kì í ṣe opó,ojú mi kò ní rí ìbànújẹ́.
Orílẹ̀èdè mẹ́wàá tí àjàkálẹ̀ ààrùn náà ti pọ̀ ni : Coronavirus in Nigeria: Èèyàn mẹ́rin míràn ti lùgbàdì àrùn Coronavirus ní Naijiria Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Akojọpọ esi ayẹwo aarun Covid-19 ni orilẹ-ede Naijiria gẹgẹ bi ajọ NCDC ṣe n kede rẹ.
Ọgbẹni Akojede ohun ti awọn n ro tẹlẹ nipe iku awọn mejeeji ko le jina sira wọn nitori bi ṣe fi ifẹ ba ara wọn lo.
Ó wá sọ fún ẹni tí ó pè é fún oúnjẹ pé, “Nígbà tí o bá se àsè, ìbáà jẹ́ lọ́sàn-án tabi lálẹ́, má ṣe pe àwọn ọ̀rẹ́ rẹ tabi àwọn arakunrin rẹ tabi àwọn ẹbí rẹ tabi àwọn aládùúgbò rẹ tí wọ́n jẹ́ ọlọ́rọ̀.
O ti fi igba kan je balogun iko agbaboolu Switzerland lodun 2016, ti o si ti gba apapo ifesewonse mọ́kàndínlọ́gọ́rùn ún fun orile-ede re bayii.
gov Amọ o, agbẹjọro fun Hushpuppi, Gal Pissetzky, sọ fun awọn akọroyin nilẹ America pe ko ti i gba itusilẹ, wọn kan gbe e kuro ni ọgba ẹwọn Chicago, lọ si ti California.
Ọmọwe Oyeyẹmi rọ awọn awakọ pe ki wọn maa sa ere asaju, bẹẹ lo ṣeleri pe ẹṣọ oju ọna lati de ibi kibi ti ijamba ọkọ ba ti ṣẹlẹ tabi ti sunkẹrẹ fakẹrẹ ba wa niṣẹju akan.
"O dun mi lati gbọ pe Dapo Ojoro ti lọ lẹyin ọdun mẹsan ta padanu Gbegi, ẹgbọn rẹ.
Ṣiṣe odiwọn aidọgba Oṣuwọn kan ti awọn onimọ nipa ọrọ aje maa n lo lati mọ bi aidọgba ṣe pọ to ni orilẹede kan ni a mọ si oṣuwọn Gini.
OLUWA mọ èrò ọkàn ọmọ eniyan,ó mọ̀ pé afẹ́fẹ́ lásán ni.
Ipinlẹ Kwara Àkọlé àwòrán, Awọn ara ilorin naa ko gbẹyin ni ibi iburawọle naa Àkọlé àwòrán, Igbakeji Gomina tuntun ati iyawo re ni ipinlẹ Kwara Àkọlé àwòrán, Emir ti ilu Ilorin, Zulu Gambarie naa ko gbẹyin ni ibi iburawọle to waye.
Ni ojumọ toni to mọ yii, ọpọ alagbara aye lo wa, ti wọn n jẹ aye familete ki n tutọ, wọn ni awọn lo ni oni, lai mọ ẹni ti yoo ni ọla, ti wọn si n jẹ aye ọlọba.
Ó fẹ́ rí Jesu kí ó mọ ẹni tí í ṣe.
nítorí pé òun ló fi ìpìlẹ̀ rẹ̀ sọlẹ̀ lórí òkun,ó sì gbé e kalẹ̀ lórí ìṣàn omi.
o kere tan eniyan miliọnu marun le laadọta ni yoo fara gba ninu iṣẹlẹ otutu to le yii.
O ni, E woo, ko si oun ti mo le ṣe."
Oríṣun àwòrán, @___FAREED Bẹẹ ba gbagbe, ọjọbọ ni iroyin gbalẹ kan pe, awọn ọmọ ikọ mujẹmujẹ naa kọlu gomina ipinlẹ Borno, Zullum, ti wọn si se awọn ẹsọ alaabo rẹ lese.
Ọpọ eeyan to si ti n ro pe 'tọkọtaya' naa yoo tun pada da wọn laraya ti ni ijakulẹ bayii, nitori pe Ka3na ti ja kuro ninu eto naa.
Bí wọ́n ṣe ń jẹun lọ́wọ́ ní Misipa, 
Ṣugbọn ní ọdún kan, Hoṣea ranṣẹ sí So, ọba Ijipti pé, kí ó ran òun lọ́wọ́, kò sì san ìṣákọ́lẹ̀ fún ọba Asiria mọ́.
"Agba osere tiata naa ni ""Ti onitiata yoo fi ku, ere lasan ni wọn yoo ro pe o n se."
3) Sadiya Farouq: Arabinrin Sadiya ti figba kan jẹ kọmiṣonna ijọba apapọ fun ajọ to n mojuto ọrọ awọn aṣatipo.
Nítorí náà ẹ̀rù kò ní bà wá bí ayé tilẹ̀ ṣídìí,bí àwọn òkè ńlá tilẹ̀ ṣípò pada, tí wọ́n bọ́ sinu òkun;
 irúfẹ ́ ọ ̀ rọ ̀ ìpìlẹ ̀ bẹ ́ ẹ ̀ ni rárá .
Amọ o ni awọn ọlọpaa mii naa wa ti wọn ṣe daadaa fun oun, nitorinaa, o ni kii ṣe gbogbo wọn ni ko dara.
N óo bukun un, n óo sì fún ọ ní ọmọkunrin kan láti ọ̀dọ̀ rẹ̀, n óo bukun un, yóo sì di ìyá ọpọlọpọ orílẹ̀-èdè, ọpọlọpọ ọba ni yóo wà lára atọmọdọmọ rẹ̀.
Ó ṣì ku ẹẹdégbèta ọmọ Nàíjíríà tó kù sí South Africa - Onyeama Ẹgbé agbabóòlù Arsenal ṣe Frankurt báṣubaṣu pèlu ayò mẹta si odo.
Ibeere nla leyi, ko si ilana fun orukọ awọn ọmọ ọba Ilẹ Gẹẹsi.
B Joshua, Synagouge Church of All Nation.
 O seese ki o je aworan isele miran ti kii se iyara Lassoued.
Ijọba Ekiti ati alatako tahun sira wọn lori aworan ipolongo
Ẹ le ka nipa rẹ si nibi Sabrina Simader Ọjọ ori: Mọkandinlogun Orilẹẹde: Kenya Ere idaraya: Alpine Skiing Simader, ti awọn molebi rẹ ko lo si Austria nigba ti o wa lọmọdun mẹta ni ẹni akoko ti yoo soju ilẹ Kenya nibi idije Winter Olympics.
Oríṣun àwòrán, @Albert Àkọlé àwòrán, Opo ile ti ko duro daadaa tẹlẹ ni wọn ti wo lulẹ bayii ni Ghana Bóò bá ní nọ́mbà ìdánimọ̀ NIN, à tí kọ ìdánwò rẹ yóò ṣòro BBC 100 Women 2019: ọ̀pọ̀ obìnrin ilẹ̀ Afirika ń gbàràdá!
Wọ́n wá Maria kàn ati Josẹfu ati ọmọ-ọwọ́ náà tí a tẹ́ sí ibùjẹ ẹran.
Àwọn onímọ̀ ẹ̀rọ London College tí bá wọn onimo miran tó ń ṣe Mercedes ti wọn n se (CPAP) rí wọn pé ní Continuous Positive Airways pressure Device po tí wọn sì ti lọ làwọn ilé ìwòsàn kan tó sì ń ṣe iṣẹ́tó yẹ.
 laiṣi èmí ko si àrà tí ènìyàn le da láyé .
Ẹ ka ẹkunrẹrẹ rẹ ni bii Awọn nkan miran ti ẹ ni lati mọ loni Ọwọ́ tẹ afurasí 29 lórí ìpànìyàn Ìjẹ̀bú Igbó Ìkéde Buhari: Ta ni yóò kojú u rẹ̀?
Coronavirus ti di ara wa, kò le è kúrò mọ láéláé - WHO Ìdí rèé tí ilẹ̀ Afirika fi gbọdọ̀ kópa nínú dídán abẹ́rẹ́ coronavirus wò Kíni ìdí ti wọn fi ń lọ ọmú obinrin nílẹ Adúlkáwọ?
OLUWA bá bi í pé, ‘Ọgbọ́n wo ni o óo dá?
nítorí ibi tí wọ́n ṣe, ati títàn tí wọ́n tàn yín ní Peori, ati nítorí ọ̀rọ̀ Kosibi, ọmọ baálé kan ní ilẹ̀ Midiani, arabinrin wọn, tí a pa nígbà àjàkálẹ̀ àrùn ti Peori.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Nigeria swearing in 2019: Babajide Sanwoolu gba ọpa àṣẹ láti tukọ̀ Eko 10 Ẹrẹ̀nà 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 29 Èbibi 2019 Ọjọ́ kẹẹdọgbọn, oṣù kẹfà, ọdún 1965 la bí Babajide Olusola Sanwoolu tó ti jawe olubori ninu idibo ipinlẹ Eko.
O ni adura ati iwoye oun ni ọjọ iwaju rere fun Somalia ti ẹnikẹni ko ni ṣọfọ mọ lataari aisi iranlọwọ lasiko.
Ó ní ẹẹdẹgbaarin (7,000) aguntan, ẹgbẹẹdogun (3,000) ràkúnmí, ẹẹdẹgbẹta (500) àjàgà mààlúù, ẹẹdẹgbẹta (500) abo kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ ati ọpọlọpọ iranṣẹ; òun ni ó lọ́lá jùlọ ninu gbogbo àwọn ará ìlà oòrùn.
O ni kii wa ṣe asiko yii lo yẹ ki awọn eeyan kan maa fẹnu tẹnbẹlu rẹ ninu ẹgbẹ.
Awọn koko ohun to si yẹ kẹ mọ nipa bi wọn se na owo naa niyi: Atupalẹ bi ajọ Inec yoo se na owo isuna feto idibo 2019 N31,49bn lo wa fun titẹ awọn iwe idibo ti wọn yoo lo feto idibo 2019, owo yii si lo pọ julọ ninu eto isuna naa N7.
D àti Fellowship20 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Muyiwa Ademola: A ó jọ rọ́ọ̀kì ọdún 2021 papọ̀ ni lágbára Ọlọ́run26 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Lateef Adedimeji and Adebimpe Oyebade: Ohun tí BBC mọ̀ nìyí nípa àjọṣepọ̀ òṣèré tíátà méjéèjì25 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Funke Akindele: Bukunmi Oluwasina ní ọ̀kan lára àlá òun ló wá sí ìmúṣẹ18 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 3 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 5 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Bákannáà ni ààrẹ Mùhámádù Bùhárí ní àwọn ń mójú tó àtipadà wálé e Leah Sharibu, akẹ́kọ̀ Dapchi tó ṣì wà ní àhámọ́ àwọn Boko haram nítórí pé ó kọ̀ láti yípadà sí ẹ̀sìn Islam.
7 364613 Orilẹede Tunisia 5478 47.
Kekere si ni Folasade ti nifẹ lati maa ṣe bii dokita, ti yoo si maa tọju bebi to n ṣe aisan.
Aare so pe “Nigbati mo de ipo aare lọdun 2015,ohun akọkọ ti mo kọkọ se ni lati yọjú  si awọn ti a jọ mu  ala papọ, iyen; orile ede Niger , Chad, Cameroon, ati Benin .
Ijọba ibilẹ Tangaza ni ipinlẹ Sokoto sun mọ orilẹede Niger, nibẹ ni wọn ṣi wa bayii.
Òmíràn nínú àwọn oújẹ àgàdo yìí ni wọ́n á ti fi ṣúgà tàbí oyin àti onírúirú nkan aládùn pa lára.
Má jẹ́ kí pípọ́n tí ọtí pọ́n fà ọ́ mọ́ra,nígbà tí ó bá ń ta wínníwínní ninu ife,tí o dà á mu, tí ó lọ geere lọ́nà ọ̀fun.
A ò gba ìbálòpọ̀ akọ ṣákọ tàbí abo sábo Wo oríṣiríṣi ìgbádun ibálòpọ̀ láwọn orílẹ̀èdè mìíràn Ṣugbọn lẹnu ọdún bi mélòó kan sẹyìn,àwọn ajafeto-omoniyan ti n ṣé ìpolongo nípa òfin yí tó rí ibasepọ láàrin ọkùnrin sí ọkùnrin gẹgẹ bí ẹsẹ.
Aya aarẹ ṣe daada pẹlu bo se n kigbe sita yii, sugbọn o tun ku, nibọn n ro.
Ìtẹ́lẹ̀ rẹ̀ náà ní igun mẹrin, ó ga ní igbọnwọ mẹrinla (mita meje), ìbú rẹ̀ sì jẹ́ igbọnwọ mẹrinla (mita meje).
Máa gbani ní ìmọ̀ràn, pẹlu ọpọlọpọ sùúrù tí ó yẹ kí ẹni tí yóo bá kọ́ eniyan lẹ́kọ̀ọ́ dáradára ní.
Wò ó, a óo sọ Tẹmpili rẹ di ahoro.
Márosẹ̀ Eko sí Ibadan àti Ibadan sí Eko dí pa fún ṣúnkẹrẹ́-fàkẹrẹ ọkọ̀ Àwọn omidan Naijiria ni wọ́n fi ń ṣerú ní Lebanon- Ọmọlọla Bí ìtàn ayé Toyosi Arigbabuwo ṣe lọ rèé láti ẹnu Musiliu Dasofunjo àti Ogun Majek Ki lo ti ṣẹlẹ sẹyin?
Festac Road, Mokola ti di Adebayo Faleti Road.
Coronavirus: Ǹjẹ́ adìyẹ Broiler ni ǹkan tó ń tan àìsàn COVID-19 kálẹ̀?
O gbadura pe ki Eledua fi ẹmi gigun ati alaafia ara jinki baba bi wọn ti pe ẹni ọdun mejilelọgọrin loke eepẹ.
Asọ igbeyawo rẹ kii ṣe nkan ti eniyan le dede ṣe alabapade rẹ ni orilede India.
Títàn tí mo tàn án tán, lóbá dí kùùrùrù, ó di kẹẹrẹrẹ.
Joṣua fa aṣọ rẹ̀ ya láti fi ìbànújẹ́ hàn, òun ati àwọn àgbààgbà Israẹli dojúbolẹ̀ níwájú Àpótí Majẹmu OLUWA títí di ìrọ̀lẹ́, wọ́n sì ku eruku sórí.
"Awọn nkan to ṣẹlẹ yii tu aṣiri pe ẹkun yii wa ninu ewu lọwọ awọn to fẹ sọ ọrọ aje rẹ di akurẹtẹ.
Bo tilẹ jẹ pe BBC Yoruba ko le fidi eyi mulẹ, oriṣiriṣi ni awọn ololufẹ Makinwa ati awọn eeyan ti n sọ lori ọrọ naa.
iko agbaboolu Fulham kopa daradara ninu ifesewonse ti won gba lojoRu(Wednesday),
Ṣugbọn OLUWA Ọlọrun pe ọkunrin náà, ó bi í pé, “Níbo ni o wà?
Biden fi si oju opo rẹ loru mojumọ ọjọ Aje pe oun ti lọ gba a.
Ọ̀gọ̀rọ̀ èèyàn lórí ayélujára bú Dalung lórí owó IAAF Ó ṣe f'ọ́mọ tó ń jeérú!
Wọn ni ilu abinibi rẹ ni Iye Ekiti ni ipinlẹ Ekiti ni Guusu Iwọ́ Oorun Naiiria ni eto isinku naa yoo ti waye.
Ó bẹ́ Jakọbu arakunrin Johanu lórí.
 Ìgbésè yìí máa ń wáyé nínu ìyísódì òǹkà .
Ṣugbọn ní ọjọ́ kẹta, yóo jí dìde.
Àwọn tí wọ́n wá láti ilẹ̀ Juda sì jẹ́ ẹgbaarun (10,000).
Bí ẹnìkan ninu àwọn tí ń wá òkú kiri bá rí egungun eniyan níbìkan, yóo fi àmì sibẹ títí tí àwọn tí ń sin òkú yóo fi wá sin ín ní àfonífojì Hamoni Gogu.
Etuhu: Ilé ẹjọ́ ni agbábọ́ọ̀lù Nàìjíríà, Dickson Etuhu jẹ́bi ẹ̀sùn títa ìdíje
Àwọn ọmọ Iran yarí mọ́ ìjọba lọ́wọ́ lẹ́yìn tó jẹ́wọ́ọ jíjá bàálù Ukrain lulẹ̀ Ilé iṣẹ́ ọmọogun kò sọ fún mi pé ọkọ mi kú fún ọdún kan- Iyawo soja Amotekun kò ní gbé ìbọn o!
Mo ṣe tán láti kú tọmọ taya bí wọn kò bá fi El-Zakzaky sílẹ̀ - ọmọ ẹgbẹ́ Shiite Ọlọ́pàá Kwara ti rí ọmọ orílẹ̀-èdè Turkey mẹ́rin gbà padà lọ́wọ́ ajínigbé!
Lọ sí títì tí à ń pè ní ‘Títì títọ́,’ ní ilé Judasi kí o bèèrè ẹni tí ó ń jẹ́ Saulu, ará Tasu.
Buhari yoo sọrọ lori idi ti awon orile ede ti won je omo egbe ajo naa fi gbodo
Olùdásílẹ̀ ilé iṣẹ́ tó máa ń báni ṣètò ayẹyẹ Elizabeth R ní, àti pé ó ti wà ní ìpínlẹ̀ Bayelsa àti Rivers láti ṣèrànwọ́ kíkọ́ ibudó ti wan yóò ti maa tójú àwọn aláàrùn Covid-19 sí.
Ṣugbọn, mo gbẹ́kẹ̀lé ọ, OLUWA,Mo ní, “Ìwọ ni Ọlọrun mi.
 Ọpọ ọmọ Naijiria to ti n lọgun pe owo naira ko niyi mọ lati nkan bi ọdun diẹ sẹyin, paapaa lẹyin ti owo dollar kan parada di ẹẹdẹgbẹta naira."
Ehudu rọ idà olójú meji kan tí kò gùn ju igbọnwọ kan lọ, ó fi bọ inú àkọ̀, ó so ó mọ́ itan rẹ̀ ọ̀tún lábẹ́ aṣọ.
 Onyeama dari rẹ pẹlu, aare ajo ECOWAS ,
Ajọ to n gbogun ti ilokulo ounjẹ, ohun mimu ati ogun lorilẹede Naijiria, NAFDAC lo ṣe ikilọ yii ni ọjọ ẹti.
"Taa ni Ebila ""One Million Boys"" àti Ekugbemi, olórí ẹgbẹ́ òkùnkùn míì tó da ìlú Ibadan rú?"
’ Nípa ìdámẹ́wàá ati ọrẹ yín ni.
Ẹkú ọjọ́ mẹ́ta o ẹ̀yin ènìà pàtàkì wọ̀nyí.
ipinlẹ Rivers ati ijoba ibilẹ Owerri.
Ilẹ Gẹẹṣi ni awọn obi rẹ to jẹ ọmọ Naijiria bii si, ti wọn si n gbe ni adugbo Dagenham, nibi ti ọpọlọpọ ọmọ Naijiria n gbe.
Ó dá wọn lóhùn pé, “Mika ti bá mi ṣètò, ó ti gbà mí gẹ́gẹ́ bí alufaa rẹ̀.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù EndSARS: Makinde kéde ìrànwọ́ fáwọn ẹbí ọlọ́pàá tó bá rògbòdìyàn EndSARS lọ láti inú N500m tí a yà sọ́tọ̀ 3 Bélú 2020 Oríṣun àwòrán, Twitter/Seyi Makinde Gbogbo awọn ẹbi ọlọpaa to ba rogbodiyan iwọde EndSARS lọ ni ipinlẹ Oyo la o ṣeranwọ owo fun.
Lẹ́yìn rẹ̀, Meremoti, ọmọ Uraya, ọmọ Hakosi, ṣe àtúnṣe apá tiwọn láti ẹnu ọ̀nà ilé Eliaṣibu títí dé òpin ilé Eliaṣibu.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Chinonso Eche: Mo fẹ́ dà bíi Messi, Ronaldo àti Okocha Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Chinonso Eche: Mo fẹ́ dà bíi Messi, Ronaldo àti Okocha 15 Owewe 2019 Ọmọ ti yoo ba jẹ Aṣamu, kekere ni yoo ti maa jẹ ẹnu ṣamuṣamu.
Ṣé ìpèsè iná ọba yóò wà lọ̀dún 2020 torí ₦9bn nìjọba fẹ́ ná fún ẹ̀rọ amúnáwá?
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Mikel Obi: Orílẹ̀èdè Egypt ni mo ti bẹ̀rẹ̀ ayò, ibẹ̀ náà ló parí sí 18 Agẹmo 2019 Oríṣun àwòrán, Instagram/John Obi Mikel Eyi ti mo ṣe to!
lati mo bi won yoo se ri eniketa won mu.
Coronavirus: ''Ìjọba kò tíì pàṣẹ ìlànà ìtakété-síra-ẹni padà nínú BRT la ò ṣe máa tẹ̀le'' Ìjọba gbé ilé ijó oníhòhò tì pa lórí ẹ̀sùn títàpá sí ìlànà àti dẹ́kun coronavirus Ogun abẹ́lé tó ń ja Akeredolu l'Ondo, òní la ó mọ̀ bóyá yó borí rẹ̀ Èyí ni bí èèyàn 538 ṣe ń yan ààrẹ lé èèyàn mílíọ̀nù 331 ní Amẹ́ríkà Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsèjẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọ Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Fídíò, Akomolede ati Aṣa: Mọ̀ síi nípa ìró afárànma àti agbárànmọ́ fáwẹ́ẹ̀lì Yorùbá15 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 New Covid 19 update: Ẹ̀yà kòkòrò Covid-19 míràn jáde ní ọgọ́ta agbègbè nílẹ̀ Gẹẹsi, àjọ elétò ìlera fọkàn ará ìlú balẹ̀15 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Ede Poly Rector suspension: Wọ́n ní kí ọ̀gá àgbà Pólì Ede lọ rọ́kún ńlé lórí ẹ̀sùn pé 'ó kan bẹ́ẹ̀dì sí ọ́fíìsì'15 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Fídíò, Fuji Music: Kollington Ayinla sọ ẹni tó dá orin Fuji sílẹ̀ gan an ní Nàiìjíríà16 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Kankara Abduction: Àwọn ológun ṣàlàyé ìdí tí wọ́n fi yọ̀nda àwọn tó jí àwọn akẹ́kọ̀ọ́ gbé.
Jẹ́ kí gbogbo orílẹ̀-èdè péjọ,kí àwọn eniyan àgbáyé parapọ̀.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Samuel Okwaraji: Ó pé ọdún mọ́kànlélọ́gbọ̀n tí Samuel Okwaraji ṣubú lójú ìjà 19 Èbibi 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 12 Ògún 2020 Oríṣun àwòrán, Twitter/The NFF Awaye ma lọ kan ko si, ọrun nikan lare mọbọ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù John Amanam: Ìfẹ́ tí mo ní sí àbúrò mi ló sọ mi dí ẹni tó ń ṣe 'Prosthetic' báyìí Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ John Amanam: Ìfẹ́ tí mo ní sí àbúrò mi ló sọ mi dí ẹni tó ń ṣe 'Prosthetic' báyìí 1 Bélú 2020 Diedie ni mo kọ lati maa lo ọwọ mi tuntun to jẹ ti alawọ dudu- Sunday Agbegilere ati amọkoko ti tun igbesi aye awọn eeyan ṣe Ubokobong Amanam Sunday ni ina ọdun bu gbamu mọ ọ lọwọ ni ọdun ku ọla lo ba sọọ di alaabọ ara ni eyi to n mu itiju dani.
ṣugbọn wọ́n gbọdọ̀ bẹ̀rù OLUWA tí ó mú wọn jáde kúrò ní Ijipti pẹlu ọwọ́ agbára ńlá ati ipá.
A Wo Arọ Kan Sàn Lẹ́nu Ọ̀nà Tẹmpili.
Wò ó, mo wà pẹlu rẹ, n óo pa ọ́ mọ́ níbikíbi tí o bá lọ, n óo sì mú ọ pada wá sí ilẹ̀ yìí, nítorí pé n kò ní fi ọ́ sílẹ̀ títí tí n óo fi ṣe gbogbo ohun tí mo sọ fún ọ.
Toyin pada wa tuuba fun awọn ololufẹ rẹto si rọ wọn pe ki wọn maa ṣe ta ẹjọ silẹ nitori oloṣelu kankan.
kí ẹ wá fi ife fadaka mi sí ẹnu àpò èyí àbíkẹ́yìn wọn, pẹlu owó tí ó fi ra ọkà.
Wọ́n kúrò níbẹ̀, wọ́n sá lọ sí orí òkè, wọ́n sì farapamọ́ fún ọjọ́ mẹta, títí tí àwọn tí wọn ń lépa wọn fi pada; nítorí pé wọ́n ti wá wọn káàkiri títí ní gbogbo ojú ọ̀nà, wọn kò sì rí wọn.
Ó ń lúgọ káàkiri létí abúlé,níbi tó fara pamọ́ sí ni ó ti ń pa àwọn aláìṣẹ̀;ó ń fojú ṣọ́ àwọn aláìṣẹ̀ tí yóo pa.
Gbé tabili náà kalẹ̀ níwájú àpótí ẹ̀rí, kí burẹdi ìfihàn sì máa wà ní orí rẹ̀ nígbà gbogbo.
Ni ipinlẹ Kwara naa ati ri iru rẹ to sẹlẹ ti Abubakar Olusola Saraki to fa Gomina Muhammed Alabi Lawal silẹ wa pada wa doju ija kọ.
Ó lè pa ara rẹ̀ lára.
Torii oju buluu ti ọmọ mi ni naa lawọn ẹbi rẹ ṣe ń sọ̀rọ̀ pe se iru oju yii naa loo maa bi lọ ni.
Nítorí ọjọ́ ti lọ, ó jáde lọ sí Bẹtani pẹlu àwọn ọmọ-ẹ̀yìn mejila.
Aya aare ana lorile ede Naijiria lasiko ijoba ologun , iyaafin
” Lẹ́yìn náà, ó tún jẹ́ ọba Salẹmu, èyí ni “ọba alaafia.
Iye àwọn eniyan tí Nebukadinesari kó lọ sí ìgbèkùn nìwọ̀nyí ní ọdún keje tí ó jọba, ó kó ẹgbẹẹdogun ó lé mẹtalelogun (3,023) lára àwọn Juu.
nítrójìn tàbí náítrójìn ni ẹ ́ límẹ ̀ ntì kẹ ́ míkà kan tó ní àmì-ìdámọ ̀ n àti nọ ́ mbà átọ ̀ mù 7 .
' Lọjọ kẹẹdogun oṣu kinni ọdun yii ni aarẹ kọkọ yan Ọgbẹni Adamu gẹgẹ bi adele fun ọga ọlọpaa Naijiria tẹlẹ, Ibrahim Idris to fẹhinti.
" Oríṣun àwòrán, Adedoyin O'Chile Adeyemmy Àkọlé àwòrán, Oju ojo mọle kedere ni ọdọ tawọn kan lorileede CYPRUS nitoripe igba oorun ti awon oloyinbo n’pe ni “Summer” ni wọn wa Àkọlé àwòrán, Òjò náà ló ti fa súnkẹrẹ fàkẹrẹ ọkọ̀ lójú pópó ní agbègbè Abiola Garden Oríṣun àwòrán, Oluwatimilehin Faremi Anani Àkọlé àwòrán, Ojo n ro gidigidi ni adugbo tia ni Agric, Ikorodu Oríṣun àwòrán, Olatunde Lawal Àkọlé àwòrán, Ni igboro ilu Eko(Lagos island)aroroda ni ojo na n ro bayi BBC News, Yorùbá Ìdí tí ẹ fi le è nígbàagbọ́ nínú ìròyìn BBC Ìlànà Lílò Nípa BBC Òfin Àṣírí Cookies Kàn sí.
Ṣugbọn ìgbà mẹta lóòjọ́ níí máa gbadura.
Olori ti ko muna doko lo wa nidi gbogbo ipenija aabo.
Kò sì ní yẹ kí n dá iṣẹ́ náà dúró nítorí àtiwá rí wọn.
Nilu Abuja, Sowore fi aworan sita pe ṣe ni wọn ko awọn sọja di gbogbo ọna ki awọn ma baa ṣewọde.
Alhaji Kollington fikun ọrọ rẹ pe ijinlẹ ede Yoruba lawọn maa n fi kọ orin Fuji ṣugbọn laye ode oni ''awọn ọmọ wa ti fi ede oyinbo si orin Fuji lati le jẹ ko jẹ itẹwọgba sii kaakiri agbaaye.
Ìwẹ̀fà náà bá pàṣẹ pé kí ọkọ̀ dúró.
Èyí ni ìmọ́lẹ̀ tòótọ́ tí ó wá sinu ayé, tí ó ń tàn sí gbogbo aráyé.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 2020: Oloye Awurela Ifaleke ti wúré ọdún ìgbéga fún kóówá Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Sugbọn ẹ jẹ ka wo awọn ohun to wa ninu igbo naa to farapẹ awọn ohun ti Fagunwa mẹnuba ninu iwe rẹ.
Bakan naa lo ni orilẹede Niajiria yoo di ohun igbagbe ti awọn ọmọ Naijiria ko ba jawọ ninu bi wọn ṣe n ji awọn nkan gbe tabi fi ina si awọn ile.
owo to kere ju lo yẹ won, nitori ipa pataki ti won n ko lasiko eto ijoba.
Èké ni wọ́n, ní ọjọ́ tí okùn àṣírí bá tú, ojúlówo iyèkan kò ní ṣáìfi ojú hàn gbangba.
Nitori afojusun yii, awọn minisita eto inawo ati awọn gomina banki apapọ lawọn orilẹede naa ṣepade laipẹ yii lati gbaradi fun ṣiṣe idasilẹ owo ti gbogbo awọn orilẹede naa yoo ma na, ati bi paṣipaarọ rẹ yoo ṣe ri.
Wọ́n fẹ́ràn láti jókòó níwájú ninu ilé ìpàdé ati láti jókòó ní ipò ọlá níbi àsè.
Àwọn mejeeji bá kó sinu kànga náà.
Mọ̀ sí i nípa díẹ̀ lára àwọn èèyàn tí ikú wọn 'láti ọwọ́ ọlọ́pàá' milẹ̀ tìtì ní Nàìjíríà Wọ́n kò pa ẹnikẹ́ni sí ààfin Ṣọun Ogbomosọ, òkú tí àwọn ọdọ́ gbé wa ni ọlọ́pàá wọ́ jáde - Agbẹnusọ Ṣọ̀un Inú mi dùn sí iwọ́de EndSARS tàwọn ọdọ́ Nàìjíríà ń ṣè - Ooni Ogunwusi Ilé alájà mẹ́ta wó pa èèyan méje, èèyàn 20 farapa ní Obalende, Eko Àìbìkítà yíì gbọ́dọ̀ dópin, ìjọba gbọdọ̀ mú ẹ̀dùn ọkàn àwọn aráàlú lọ́kùnkúndùn- Agbẹjọ́rò Àgbà Lara ohun ti wọn n pariwo ni pe ki ileesẹ ọlọpaa tu awọn oluwọde #ENDSARS to wa ni ahamọ rẹ silẹ.
 bi kemika , sulfuru le darapo boya bi elimenti olusodioksidi tabi oluresile .
Báwo ni o ṣe lè wí fún arakunrin rẹ pé, ‘Ọ̀rẹ́, jẹ́ kí n bá ọ yọ ẹ̀ẹ́rún igi tí ó wà lójú rẹ,’ nígbà tí o kò rí ìtì igi tí ó wà lójú ara rẹ?
Dandan ni kí wọ́n fọ ọwọ́ ati ẹsẹ̀ wọn, kí wọ́n má baà kú.
Wọn gba iṣẹ lọwọ rẹ nigba ti awọn ẹsun iwa ijẹkujẹ dide si.
“Nígbà tí ẹ bá pín ilẹ̀ náà fún àwọn eniyan, ẹ ya ilẹ̀ kan sọ́tọ̀ fún OLUWA, tí yóo jẹ́ ilẹ̀ mímọ́.
 kò bímọ fún orímóògùnjẹ ́ .
Ó bá wọn sọ̀rọ̀ ninu ọ̀wọ̀n ìkùukùu;wọ́n pa òfin rẹ̀ mọ́;wọ́n sì tẹ̀lé ìlànà tí ó fún wọn.
Kò sí àwọn aláṣẹ mọ́ ní ẹkùn, ìpínlẹ̀ àti làpapọ̀ APC: Ẹgbẹ́ òṣèlú All Progressives Congres tú ilé ká ní ìpele ìpínlẹ̀ àti ti ìjọba àpapọ́ Oríṣun àwòrán, @APC Igbimọ alaṣẹ ẹgbẹ oṣelu All Progressives Congress, APC ni Naijiria ti tu gbogbo awọn adari ẹgbẹ ka ni ipele ipinlẹ, ẹlẹkun-jẹkun ati ijọba apapọ wọn lọjọ Iṣẹgun ọjọ kẹjọ, oṣu kejila ọdun 2020.
 Àlàyé ni o ni pe achamán anfani lati ṣẹgun awọn esu guayota ( nigbati ji oorun ọlọrun magec ) ati tii u inu awọn teide .
Ọjọ Aje ni Minisita fun ọrọ awọn oṣiṣẹ ati igbani sisẹ, Festus Keyamo, ṣe ifilọlẹ igbimọ naa fun ipinlẹ kọọkan lorilẹ-ede Naijiria.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Iroyin ni ọsẹẹsẹ ki otutu yii posi, nitori idinwọn fun bi oju ọjọ yoo se ri fihan wi pe, yoo ma tutu si ni lasiko ti awa yii.
Gómìnà Kọkànlá – Ọ̀gágun Mohammed Buba Marwa – Gómìnà fún ọdún mẹ́ta – ọdún mọ́kànlélógún di ọdún mejidinlógún sẹhin.
Osise oloko ofurufu kan to ji baalu kan gbe ni papako ofurufu Seattle lorile ede America ti lo fori sonpon ni erekusu kan.
A óo kọ orúkọ àwọn tí wọ́n kọ̀ ọ́ sílẹ̀ sórí ilẹ̀,yóo sì parẹ́,nítorí pé wọ́n ti kọ OLUWA, orísun omi ìyè, sílẹ̀.
Ó ṣòro lati lo ayélujára nitori ai ṣe déédé iná mọ̀nàmọ́ná àti ayélujára, pàtàki bi enia ba jade kúrò ni ilú Èkó, ṣùgbọ́n ó sàn ju ti àtẹ̀hin wá lọ.
Ewe, opo eniyan so pe, Djokovic, ko kopa daradara lataari ifarapa ejika ti o ni lojo to ti pe, ti ko si ti lanfaani lati pegede sipele keta idije kankan leyin idije Wimbledon.
Ọpọ oku ti wọn tẹ silẹ ni oko oku yii ni awọn oku funra wọn ti fi ara wọn silẹ, ki wọn to ku tabi tawọn ẹbi wọn fi oku wọn tọrẹ fun oko naa.
Lara awọn gbajugbaja oṣere to tun ti da si ọrọ lati lati gbiyanju pipari ẹ ni Alhaji Yinka Quadri, Idowu Phillips to ni Àwa kìí jà lásìkò tiwa, ta ló bí ẹ tí wàa máa jà?"
“Ẹnikẹ́ni tí ó bá jẹ́ abókùúsọ̀rọ̀ tabi oṣó, pípa ni kí ẹ pa á; ẹ sọ wọ́n ní òkúta pa ni, ẹ̀jẹ̀ wọn yóo sì wà lórí ara wọn.
"Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Wo àwọn àkókò tó yẹ ko sàìsàn, tí ara rẹ yóò fì tètè dá Oníbàárà tó bá fi owó ránṣẹ lórí ẹrọ ibaraẹnisọrọ yóò sanwo orí Ọdún mẹ́rin kò tó láti parí ẹ̀kọ́ ọ̀fẹ́ ní Ọ̀yọ́ - Seyi Makinde Wọ́n ti rí Kìnìún tó sá lọ́gbà ẹrankò lẹ́yìn tó pa gbogbo ewúrẹ́ jẹ tán Ipò aṣaájú ni Yorùbá yóò wà ní Nàíjíríà lásìkò tí mo jẹ Odole - Adebutu Davido ni ""Mo nifẹ aya mi pupọ, koda obinrin alagbara ni"", to si jẹ pe nigba ti awọn olorin to jẹ akẹẹgbẹ Davido n lọ sibi ami ẹyẹ fawọn olorin, Headies Award, yara igbẹbi ni Davido wa, to n rawọ rasẹ si Ọlọrun pe, ko sọ aya oun kalẹ layọ."
4) Boya awọn obinrin ko mu ọti lile to ju kọọbu kan lọ lọjọ kan, ati bo ya awọn ọkunrin ko mu ju igo bia kan lọ?
Ní ọjọ́ náà ni Ọlọrun bá àwọn ọmọ Israẹli ṣẹgun Jabini, ọba àwọn ará Kenaani.
Ibojì kò lè dúpẹ́ lọ́wọ́ rẹ, bẹ́ẹ̀ ni ikú kò lè yìn ọ́;kò sí ìrètí mọ́ fún àwọn tí wọ́n ti lọ sinu isà òkú,wọn kò lè gbẹ́kẹ̀lé òdodo rẹ mọ́.
"Ìjọba Eko kọ orúkọ sí ""Palliatives"" tiwọn lára o, mo ní ẹrù tèmi f'ọjọ́ ìbí mi tí wọ́n jí - Họ́nọ́rébù Agunbiade Lai Mohammed ati ọrọfifi ofin de ọrọ kobakungbe ori ayelujara Ninu awọn Minisista aarẹ Buhari, Lai Mohammed j eleyi ti ọpọ ọmọ Naijiria ko fẹ ri imi rẹ laatan."
Amọ, ileeṣẹ ọlọpaa ipinlẹ Ekiti ti kede pe, oun ti ri ọkọ mẹta tawọn adigunjale naa lo, lati ṣiṣẹ ibi wọn.
---------------------------------------------------------------------------------- Wọn fi ẹ̀ṣẹ́ ja irawọ Anthony Joshua, o tun fi ẹ̀ṣẹ́ gba a pada Erongba abẹṣẹ ku bi ojo ọmọ ile Gẹẹsi ati Naijiria, Anthony Joshua, lati fi irawọ kun irawọ rẹ nilẹ Amẹrika ja si pabo ni ibẹrẹ ọdun 2019.
Orí mi má jẹ́ kí n bá wọn pa ìmọ̀ pọ̀,ẹlẹ́dàá mi má sì jẹ́ kí n bá wọn kẹ́gbẹ́.
Wọ́n sì fi àwọn alufaa ati àwọn ọmọ Lefi sí ipò wọn ninu iṣẹ́ ìsìn inú Tẹmpili, ní Jerusalẹmu, gẹ́gẹ́ bí a ṣe kọ ọ́ sílẹ̀ ninu ìwé Mose.
Ṣugbọn Mose dáhùn pé, “Èyí kì í ṣe ìhó ìṣẹ́gun, bẹ́ẹ̀ ni kì í ṣe igbe ẹni tí wọ́n ṣẹgun rẹ̀, ìró orin ni èyí tí mò ń gbọ́ yìí.
Gẹ́gẹ́ bí omi tútù ti rí fún ẹni tí òùngbẹ ń gbẹ,ni ìròyìn ayọ̀ láti ilẹ̀ òkèèrè rí.
Ninu esi rẹ, o ni ipenija aabo jẹ ohun to j ohun logun lati kọju toun ti bi ijinigbe,ikọlu ati awọn iwa janduku miran ti ṣe gbode .
 Awon naa ni: Edo, Ondo, Bauchi, Nasarawa, Ebonyi, Anambra, Benue, Kogi, Imo, Plateau, Lagos, Taraba, Delta, Osun, Rivers, FCT, Gombe ati Ekiti.
Ijoba orile ede Naijiria ti pari ise akanse to le ni ọgọ́ta ni jake-jado orile ede Naijiria laarin odun meta , ni ipinnu ijoba to wa lori aleefa yii.
Ogbeni Mohammed ni ijoba apapo ti pase fawon osise eleto aabo gbogbo lati ri si aabo ati alaafia awon akekoo ati oluko ile iwe naa nijoba ibile Damaturu.
Mimiko: Mo ti jáwọ́ lórí ìdíje ààrẹ, Sẹ́nétọ̀ ni mo fẹ́ báyìí
O fikun pe, oun kii bikita nipa ohunkohun tẹlẹ, sugbọn ni bayii, oun ti mọ ibiti oun fẹ de nile aye, ti oun si ti n sisẹ tọọ.
Ṣugbọn Abiṣai, ọmọ Seruaya, sáré wá láti ran Dafidi lọ́wọ́, ó kọlu òmìrán náà, ó sì pa á.
OLUWA pàṣẹ láti tún Tẹmpili Kọ́.
Day 23: Àwọn nkan márùn ún tó gbajúmọ̀ nípa Daura #BBCNigeria2019 Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Obìnrin ló ni ilé àti àdúgbò fún ìdí èyí wọ́n lè ṣe ìlú dáadáa' Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 3 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 5 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Eeyan 45,687 ni apapọ ni arun naa ti fara kan labẹ ayẹwo ti awọn 32,637 si ti ri iwosan gba lọwọ ajakalẹ arun ọhun.
 O tesiwaju lati tun ro ijoba apapo ati awon oludari ile-ise omo ogun lati ri pe won pese awon ohun elo, ki won si mu sise itoju awon omo ogun naa lokunkundun.
Oríṣun àwòrán, Others Àkọlé àwòrán, Àtẹjade ilé iṣẹ́ ọlọpàá rèé Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 3 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 5 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Regina Chukwu: Oríṣun àwòrán, Regina chukwu Orukọ Regina Chukwu lasan ti to lati fihan pe kii ṣe ọmọ Yoruba, sugbọn ede Yoruba lo fi n jẹun ninu ere tiata lede Yoruba.
Ọpọ ọdọ kilọ iwa ibajẹ yii larin awọn obi pe ki wọn yee mu itiju ba awọn ọmọ wọn nitori ti aṣiri ba tu tan, tẹbi tara ni itiju yii a kàn.
Igbesẹ yii waye lẹyin ti minisita fun ọrọ ohun amuṣagbara, Sale Mamman ti paṣẹ pe ko lọ rọọkun nile.
"Ẹni ori yọ o di'le Mikhail Savchenko to ni oun jẹ ọkan lara awọn arinrinajo ni oun wa ninu ọkọ baalu naa nigba to gbina oun si tiraka lati ""bẹ sita""."
Ẹ gbọ́ nisinsinyii, ẹ̀yin ọmọ Israẹli, ẹ máa tẹ̀lé àwọn òfin náà, kí ó lè dára fun yín, kí ẹ sì lè pọ̀ sí i, ní ilẹ̀ tí ó dára, tí ó kún fún wàrà ati oyin, gẹ́gẹ́ bí OLUWA Ọlọrun àwọn baba yín ti ṣe ìlérí fun yín.
Ẹ pèsè 'pad' ọ̀fẹ́ fáwọn obìnrin láti ṣe nǹkan oṣù dípò 'condom' ọ̀fẹ́
Mo dupe lowo gomina ipinle Eko.
Sheikh Muhammad Ibn Othman to jẹ Imamu Mọṣalaṣsi Kano ba akọṛoyin ileeṣẹ BBC sọrọ lori bi awọn nkan ti Musulumi le ṣe lasiko Ramadan pẹlu bi arun Coronavirus ṣe wa lode.
– Nítorí náà mo fẹ́ kí o mọ̀ pé kékeré ni èyí tí mo ṣe fún ọ lánàá, kí Olódùmarè dá ẹ̀mí sí, kí Ọlọ̀run jẹ́ kí á lè mọ ara wa pẹ́, nítorí bí ẹ̀mí bá wà, ìyókù kéré, ẹ̀mí làjùlọ.
Àwa fúnra wa ń fọ́nnu nípa yín láàrin àwọn ìjọ Ọlọrun.
"Ousman Rambo Jatta sọ ninu atẹjade kan ti wọn fun BBC pe ""Gbogbo awọn ẹsun ti wọn fi n kan aarẹ wa nigba kanri ti su awa gẹgẹ bi ẹgbẹ oṣelu ati awọn eniyan orilẹede Gambia,'' Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ọdun mejilelogun ni Jammeh fi ṣe aarẹ Gambia."
Ta ni ń bá fi inú hàn bí kò se bàbá mi!
Èyí náà ló si mú kí bàbá mi bojúwo ẹ̀hìn láti wò wọ́n, ṣùgbọ́n àkókò náà gan-anni èyí tí ó kéré jù nínú àwọn obìnrin náà bojúwo ẹ̀hìn pẹ̀lú, nígbà tí àwọn méjéèjì si wo ara wọn lójú, wọn rẹ́rìn-ín sí ara wọn olúkúlùkù tún kọjú si ọ̀nà rẹ̀, ó ń lọ.
Ramadan: Kí ni Buhari, Saraki, àtàwọn gómìnà kan sọ?
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Bolaji Faleke ni Olùkọ́ tó ń kọ́ wa ní àṣà oge ṣiṣe lórí BBC Yorùbá Arabinrin Faleke lo kọ wa nipa oge sise ninu ẹkọ ti Oke yii.
Awọn dokita ni wọn ti bẹrẹ itọju arun ọpọlọ fun ọdọmọbinrin naa.
Ṣé ó tọ́ fún wa láti san owó-orí fún Kesari, àbí kò tọ́?
Aarẹ Donald Trump tako awọn adehun ti wọn ṣe pẹlu awọn orilẹede miran lagbaye, ti o si gbe igbesẹ bi o ṣe wu u lai naani idọrẹpọ laarin orilẹede.
Gbogbo rẹ̀ á wá ṣe rẹ́gí-rẹ́gí l’ọ́nà ikùn.
nígbà tí wọ́n bá dùbúlẹ̀ ninu ihò wọn,tabi tí wọ́n ba ní ibùba wọn?
Ìrìbọmi tí Johanu ń ṣe, báwo ló ti jẹ́: ṣé láti ọ̀dọ̀ Ọlọrun wá ni tabi láti ọ̀dọ̀ eniyan?
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Aishat Lagos flood: Lẹ́yìn wákàtí 24 ní wọ́n rí òkú ọmọbìnrin náà tí àgbàrá òjò gbé lọ ní Suurulere 25 Òkùdu 2020 Àkọlé àwòrán, Aishat dolooogbe ninu odo yii Wón ti rí òkú ọmọbìnrin ti àgbàrá òjò gbé lọ ni Eko.
Bakan naa lo jẹ adari PAF to jẹ awọn to n mojuto ọkọ ofurufu ile iṣe aarẹ lọdun 2002 si 2004.
 solongo , kongo , vili àti yombe jẹ ́ àwọn olùbágbé .
Ní ìgbà mìíràn, ó máa mú wọn pa àwọn ìwàa wọn tì.
Ọ̀dọ́ náà gbọdọ́ mú iṣẹ́ ti ó ṣe kówó le lórí.
Ìròyìn tàn ká gbogbo agbègbè olókè Judia, wọ́n ń sọ ohun gbogbo tí ó ti ṣẹlẹ̀.
Oni yii gan-an, ọjọ kejila, oṣu Kẹsan, si ni Gold, ọmọ kekere to sọnu ninu ijọ Sotitobire Miracle Centre nilu Akure, ko ba pe ọdun meji.
Laipẹ yii ni aworan kan jade kaakiri ninu, eyi ti Kolinghton Ayinla ati Salawa Abẹni ti di mọ ara wọn pẹki-pẹki.
Ṣaaju idibo lo ti kọkọ kede pe oun a gbe igbesẹ yii ti oun ba wọle ni eyi to ti muṣẹ bayii.
 Leyin ipade ti ajo INEC se ni ọjọ kẹ́wàá osu kẹ́ta,
Bákan náà ni àwọn ọlọ́ṣà tí wọ́n kàn mọ́ agbelebu pẹlu rẹ̀ fi ń ṣe ẹlẹ́yà.
Mú un kí o fi fún wọ́n fún owó tèmi ati tìrẹ.
Ìrun àpapọ̀ dèèwọ̀ lọ́jọ́ Jímọ̀, kò sí oúnjẹ alẹ́ Olúwa mọ́ fún Kristiẹni Bakan naa ni wn fikun wi pe awọn n ṣiṣẹ takuntakun lati ri wi pe ayẹwo to peye n waye ni awọn ibudokọ oju omi, ti papakọ ofufuru ati bẹẹ lọ.
Eero Okina ni pe ọmọ naa fẹ tọrọ owo ni.
Oríṣun àwòrán, others Sugbọn awọn ọrọ ti awọn osere kan n sọ lori iku ọkunrin naa ati awọn eeyan to n sọfọ rẹ, n kọ ni lominu.
" Bakanaa ni wọn tun gba ọkọ ayọkẹlẹ Prado, Golf ati Mitsubishi pẹlu ọkọ meje to jẹ ọkọ agbebọn, alupupu.
láti apá etí òkun tí ó kọjú sí ìhà gúsù lọ títí dé àtigun òkè Akirabimu.
ilẹ̀ Firigia ati ilẹ̀ Pamfilia; ilẹ̀ Ijipti ati agbègbè Libia lẹ́bàá Kirene; àwọn àlejò láti ìlú Romu, 
OLUWA, níbo ni ìfẹ́ rẹ ìgbàanì tí kì í yẹ̀ wà,tí o búra fún Dafidi pẹlu òtítọ́ rẹ?
“Ṣugbọn ìwọ ọmọ eniyan, má jẹ́ kí ẹ̀rù wọn bà ọ́, má sì bẹ̀rù ọ̀rọ̀ tí wọn ń sọ.
Erelu ni eyi fihan gbangba pe awọn gẹgẹ bii adari ati obi ti kuna ninu iṣe wọn eyi tawọn si gbudọ dide tara ṣaṣa si.
Atai ni baba Natani, Natani sì ni baba Sabadi.
Anfaani Tí Ó Wà ninu Ọgbọ́n.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Awọn ololufẹ ẹgbẹ oṣelu Sierra Leone kan nibi ipolongo ibo Wọn fi kun pe awọn olori iko alabojuto ibo to wa nilẹ koni gbe lẹyin ẹnikankan bi ki se lati ri wi pe gbogbo nkan lo leto ninu eto idibo to'n bo lọna.
“Ṣebí irú ààwẹ̀ tí mo yàn ni pé:kí á tú ìdè ìwà burúkú,kí á yọ irin tí a fi di igi àjàgà;kí á dá àwọn tí ìyà ń jẹ sílẹ̀ lọ́fẹ̀ẹ́,kí á já gbogbo àjàgà?
Ẹjọ́ kí ni ẹ wá ń bá mi rò?
Kia lawọn ọmọ Naijiria ti han wọn kaun ṣugbọn koko awọn ọrọ ti wọn n sọ ẹka iroyin ileeṣẹ ologun Naijiria fi han pe lootọ bi awọn orilẹede miran l'Afirika tilẹ n lo awọn mọsiini abani ṣiṣẹ yii, kii ṣe ni papakọ ofurufu bii ti Naijiria Ko pẹ lawọn ọmọ Naijiria mii naa tu sita pẹlu lati mẹnu le ọrọ awọn ohun elo iranwọ tuntun yii.
 bákan náà lótún pẹ ̀ ka dé ilé iṣé ìwé ìròyìn tí ó sì tún ní ilé iṣẹ ́ tí ó ń gbé onírúurú àwọn ìtàn eré oníṣe tí ó ti kọ jáde sí sinimá àgbéléwò .
Ẹ o ranti wipe ẹgbẹ oṣelu naa ti pinu pe idibo abẹle ni wọn o fi yan ẹni ti yoo ṣoju ẹgbẹ naa ni idibo gomina ti yoo waye ni 2019.
Sugbọn o, awọn ileewe to jẹ pe esi idanwo JAMB nìkan ni wọn fẹ ẹ fi gba awọn akẹ́kọ̀ọ́ wọle si ile ẹ̀kọ́ ti wọn le bẹrẹ igbani wọle, bo tilẹ jẹ pe igbesẹ naa ko ni i pari di oṣu Kọkanla ti ijọba yoo kede pe ki gbogbo eto igbani wọle wa si opin.
Kèǹgbè lílù ní Ilọrin rèé, orin ìgbéyàwó, àwàdà àti ẹ̀ẹ̀kẹ́ èébú Bo tilẹ jẹ wi pe ẹkunrẹrẹ iroyin ko tii si nipa ijamba yii, ajọ to n ri si iṣẹlẹ pajawiri ni ipinlẹ Eko (LASMA) fi ọpọlọpọ ọrọ sita nipa rẹ, loju opo Twitter wọn.
Òní lóyẹ k'ọ̀gá ọlapàá Ibrahim Idris fẹ̀yìntì Gani Adams ní Ọ̀yọ́mèsì ló fún òun láṣẹ láti yan olóyè Aláàfin Ọyọ pé ọdún 48 lórí àpèrè Orílẹ́-èdè 5 tí takọ-tabo kò gbọdọ̀ fẹnu ko ara wọn lẹ́nu Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Eko Akete yóò gbàlejò BBC Yoruba Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Oduduwa Alphabet: òmìnira èdè ti dé fún Port Novo báyìí Asiko ọdun iwẹ awọ̀n elesin Aghoris nikan ni wọn máa n jade ni Ọjọ Kẹẹdogun, osu kini, odun ni orilẹ-ede India ti wọn n pe ni ọdun Kumbh Mela.
Èkúté tó sàwárí bọ́mbù ilẹ̀ gbàmi ẹ̀ye wúrà fún iṣẹ́ takuntakun Àwọn tó fẹ́ kí ọba máa ta ilẹ̀ ilú ló fẹ́ yọ Oluwo lóyè- Ẹgbẹ̀ Baálẹ̀ Iwo.
Nígbà tí wọ́n dé ilé olórí ilé ìpàdé náà, Jesu rí bí gbogbo ilé ti dàrú, tí ẹkún ati ariwo ń sọ gèè.
'Ò ń f'ẹ̀mí ara rẹ wéwu tó bá fẹ́ kọ́kọ́ yẹ ọlọ́pàá wò' Akeredolu, Ọgá NDLEA lọ kọ nípa gbíngbin igbó ní Thailand Aṣẹ yi ko kan awọn ti wọn ba f gba iwe irina awọn aṣoju(Diplomatic Visa,A,G ati Nato).
Àwọn ǹkan tí ẹ kò mọ̀ nípa Ìjàpá Ogbomoso kó tó kú
 “Ti e ba lo egberun mewaa , egberun meedogun ati ogun egberun daadaa; a le tun fi kun owo yii;gbogbo eniyan ni yoo si je anfaani naa;aare ti so pe ohun fe ki gbogbo awon olokoowo keekeeke ti won n ta oja bi i ata, ireke ati tomato ri owo naa gba.
Ile-ifowopamo agba ni o so eyi di mimo lori ero ayelujara won lojo-Ru, ojo kerindinlogun osu keji odun 2018.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Oríṣun àwòrán, Others Bí ògbójú ọlọ́sà ajínigbépawó, Bobosky ṣe kú sí àhámọ́ àwọn ọlọ́pàá Ileeṣẹ ọlọpaa ipinlẹ Rivers pawọpọ pẹlu awọn fijilante ibilẹ lati fi mu igara ọlọsa agbenipa kan to jẹ olori ẹgbẹ okunkun Greenlanders, Honest Diigbara ti ọpọ mọ si Bobosky.
Esi ayẹwo fihan pe, o ni aarun naa.
Koda awọn oyinbo nla nla lẹ le fi mọ awọn aṣeyọri wọn ati ọpọlọpọ oye ti o ti gba laye - iyẹn ni pe lowe lowe la n lu ilu agidigbo.
Ìyàndá tí a ti sọ̀rọ̀ rẹ̀ ṣubú.
7 Lẹ́ẹ̀kansíi, a kọọ́ pé ìdálẹ́bi ayérayé; nítorínáà ó hàn gbangba ju àwọn ẹsẹ míràn lọ, pé kí èyí lè ṣiṣẹ́ lórí ọkàn àwọn ọmọ ènìyàn, ní àpapọ̀ fún ògo orúkọ mi.
Ègbé ni fún ẹni tí ó wí pé,“N óo kọ́ ilé ńlá fún ara mi,ilé tí ó ní yàrá ńláńlá lókè rẹ̀.
Àgbẹ̀ oníkòkó ni Àkàngbé orímóògùnjẹ́, bàbá Dúró nígbà ayé rẹ̀.
President Muhammadu Buhari takes oath of office pic.
idije naa, leyin ti o fagba han Mayer pelu ami mefa si meje(6-7), mefa si
Kí kabiyesi yan àwọn alabojuto ní ilẹ̀ náà kí wọ́n kó ìdámárùn-ún ìkórè ilẹ̀ Ijipti jọ láàrin ọdún meje tí ọ̀pọ̀ oúnjẹ yóo fi wà.
Nelson Enwerem Prince Oniṣowo ni Prince lati ipinlẹ Abia ilu Eko lo si fi n ṣebugbe.
4 3779 Orilẹede Trinida and Tobago 122 8.
Ki lo le mu ki agbabọọlu sọ fun akọnimọọgba pe ẹnu rẹ n run?
Laipe yii ni awọn ọlọpaa Naijiria kede awọn nọmba ti awọn eeyan le pe wọn sori ẹ bi awọn ọlọpaa SARS ba n dunkoko mọ wọn.
Òkìtì iyanrìn wó pa èèyàn méjí nílùú Ibadan Ọkọ ti wọn da duro naa, Toyota Sienna, to jẹ tile iwosan kan nilu Ibadan si lawọn agbegbọn naa gbe silk lai gbe lọ, tawọn ọlọpa si ti ri nibi ti wọn gbe si, bẹẹ ni wọn ti wa lọ si agọ ọlọpa to wa ni abule Ogunmakin nipinlẹ Ogun.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, '500 level'' ni mo wà nígbà tí mo di adélé Ọba' Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Kété ti ìròyìn jáde ní àwọn èèyàn tí n ki Oladapo Daniel Oyebanjo ku ara feraku ọmọ rẹ.
Amọ gbogbo igbiyanju BBC Yoruba lati ba Sẹneto Iyiola Omisore sọrọ lati fesi si ẹsun naa lo jasi pabo.
6 87097 Orilẹede Belarus 1207 12.
Ninu ẹ̀yà Juda, ó yan ilé baba mi, láàrin àwọn ọmọ baba mi, ó ní inú dídùn sí mi, ó fi mí jọba lórí gbogbo Israẹli.
- Ilé ẹjọ́ ìpínlẹ̀ Ondo Ilé ìwòsàn kan rèé tó ń fi àtùpà gbẹ̀bí aláboyún Lọjọ Iṣẹgun yii kan naa ni fidio kan jade sori ayelujara, to safihan bi awọn ọmọ ile aṣofin Naijiria ṣe le Minisita naa jade lasiko to farahan niwaju wọn fun ibeere nipa eto igbani sisẹ naa.
Baalu aare balẹ si Rotterdam ni papa ofurufu Hague ni deede aago meje koja iseju metalelogun osan, akoko orile ede Naijiria (7: 23 p.
“Àjàgà tí baba rẹ gbé bọ̀ wá lọ́rùn wúwo, ṣugbọn nisinsinyii, dín wahala tí baba rẹ fi wá ṣe kù, kí o sì sọ àjàgà wa di fúfúyẹ́, a óo sì máa sìn ọ́.
Lẹ́hìn èyí ni Elizabeth àti àwọn ẹbí i rẹ̀ padà sínú àfin lọ.
Kalebu tún bí ọmọbinrin kan tí ń jẹ́ Akisa.
Ẹ wá, ẹ jẹ́ kí á sọ̀kalẹ̀ lọ bá wọn, kí á dà wọ́n ní èdè rú, kí wọn má baà gbọ́ èdè ara wọn mọ́.
ti won yoo maa jiroro nibi ipade naa ni ọgbọ̀n egberun  ekunwo owo osu awon osise ati lati fese adele
Àwọn eniyan tí wọ́n wá láti inú ẹ̀yà Juda, Bẹnjamini, Efuraimu, ati Manase tí wọn ń gbé Jerusalẹmu nìwọ̀nyí: 
O pee pe oun ni ọrọ pataki ti awọn dijọ fẹ jiroro ninu ile, asiko yii naa lo si ran ọmọ ẹgbọn rẹ kekere, Farouk, ti wọn jọ n gbe inu ile nisẹ, lati lọ ra asọ pelebe inuju (handkerchief) funfun, wa fun oun.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Obono-Obla: Buhari ti yan Dayọ Apata lati rọ́pò Obono-Obla 15 Ògún 2019 Oríṣun àwòrán, @NGRPresident Aarẹ Muhammadu Buhari ti yẹ aga mọ alaga igbimọ to n sewadi lati se awari awọn dukia ijọba to ti sọnu, to si n gba wọn pada, Okoi Obono-Obla, to si ni ko lọ rọọkun nile na.
kọmisọna fun Ile-isẹ agbofinro ni ipinlẹ Bauchi Ali.
Kí ẹ má baà pa wá run ni a fi ṣe ohun tí a ṣe.
Ajiboye bẹnu atẹ lu ijọba ipinlẹ Ọyọ pẹlu ẹsun wipe igbese naa lọwọ oṣelu ninu.
Ọ̀rọ̀ yii jẹyọ latari ọ̀rọ̀ Oba Ilu Eko, Ọba Rilwan Akiolu, ni ọjọ Ajé pe, ki awọn Naijiria ti Aarẹ Buhari lẹyin fun saa keji.
Bakan naa lo fi idi rẹ mulẹ pe eeyan meji miran tun ti jade laye nipasẹ aarun naa.
Igbẹkẹle ninu alaiṣootọ ní àkókò ìṣòro,dàbí eyín tí ń ro ni, tabi ẹsẹ̀ tí ó rọ́.
 Àrùn tó níí ṣe pẹ ̀ lú ihò nínú ara náà lè fa ikú .
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù SSANU, NASU gbé fásitì Ibadan tì pa nítorí ìyanṣẹ́lódì ọlọ́jọ́ márùn ún 19 Ògún 2019 Ẹgbẹ awọn oṣiṣẹ ti kii ṣe olukọ ni awọn ile ẹkọ giga lorilẹ-ede Naijiria labẹ aburada NASU, NAAT ati SSANU ẹka fasiti ilẹ Ibadan bẹrẹ iyansẹlodi.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ayekofẹnifọrọ: Ó yá, ẹ fi àmì sórí ọ̀rọ̀ náà.
O ní iṣẹ́ Olasope yii jọ mọ abini nítori pe, o mọ bi a tii se àgbékalẹ̀ ìròyìn, èyí ti kò wọ́pọ̀ mọ bayìí láàrin àwọn akọroyin, pàápàá julọ bi awọn sọ̀rọ̀sọ̀rọ̀ kìí ṣe ni ìwé àkọsilẹ mọ, ki wọn to wọ yàrá ìgbóhùn sáfẹ́fẹ́.
Oríṣun àwòrán, Reuters Àkọlé àwòrán, Iwọde ifẹhonuhan ti n waye ni awọn agbegbe kan ni orilẹede Italy lori isele yi Awọn ọkẹ mẹrin eniyan ngbe ilu yii.
Naamani sì rọ̀ ọ́ kí ó gba ìwọ̀n talẹnti meji.
Oríṣun àwòrán, LASEMA Awọn eniyan yii se kongẹ iku nipa bi wọn se ri somi lagbegbe Kirikiri, lẹyin ti ọwọja omi dari ọkọ lọ soju omi to jẹ dagun.
Ọdun 2019 ni ijọba Naijiria kede pe arabinrin naa ti gba ominira, ti o si pada walẹ si Naijiria.
Lẹ́yìn náà, fi ọ̀já efodu tí wọ́n ṣe iṣẹ́ ọnà sí dì í ní àmùrè.
Àwọn tó ní ààrùn Covid-19 ní Nàìjíríà ti pé 8344 Ọkùnrin kan dèrò àtìmọ́lé lórí ẹ̀sùn fífi ipá bá ọmọ bíbí inú rẹ̀ méjì lòpọ̀ Ṣé lóòtọ́ ni Kayode Fayemi, gómìnà ìpínlẹ̀ Ekiti fẹ́ du ipò ààrẹ orílẹ̀èdè Nàìjíríà?
Sẹnetọ Ali Ndume lo sọ eyi, o ni a ni lati maa fiṣẹ yin wọn ki a si maa pese fun wọn."
Gomina fi kún pé igbẹ́sẹ̀ ti n lọ lọ́wọ́ lóri eto la'ti mu ki àwọn ilé iwosan ipinlẹ Kwara lé sàmójú to ààrun náà.
Ni kete ti iroyin ti jade pe ijọba Naijiria fẹ bẹrẹ igbesẹ gbigba owo ori lori ọja ti a ba ra lori ayelujara ni BBC Yoruba ti jade.
‘Jí foonu ọkọ rẹ̀ wò, kóo fi ẹ̀wọ̀n jura’ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ìbejì Àyànbìnrin tó ti ń di gbajúgbajà Bawo ni wọn ṣe mu u?
Awọn ọmọ ipinlẹ Chicago to jẹ alawọ dudu lo ko ida aadọrin ninu ọgọrun awọn eeyan ti ọwọ arun naa ti ba ninu bi o tilẹ jẹ pe ida ọgbọn ninu awọn eeyan to n gbe ilu naa lo jẹ alawọ dudu.
Pọpọsinsin ọdun Ileya bẹrẹ kaakiri orilẹede Naijiria ati lagbayee.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ruga Settlement: Kí ló ń mú ìkùnsínú wá ?
Eyi si lo mu ki awọn alaṣẹ ile aṣofin tun awọn ilana naa yẹwo.
"O ti ba aye ara rẹ jẹ, ori rẹ ti gbalẹ baun, nitori iwa to hu yii.
3 Ọ̀wàrà 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ọmọkùnrin kan sin Baba rẹ̀ láàyè torì pé ó gbàgbọ́ pé oṣó ni!
Wọn ko fẹ ẹ kọṣẹ, wọn a maa bi yin pe ba wo lẹ ṣe maa ba awọn ṣe tawọn maa fi de oke ni kete ti wọn ba ti bẹrẹ iṣẹ ere.
Temitope kawe jade ni fasiti ni orilẹ-ede Naijiria, to si ti n ṣe iṣẹ aje diẹdiẹ ko to o di pe o gbiyanju lati lọ si ilẹ okeere.
bí omi òkun tilẹ̀ ń hó, tí ó sì ń ru,tí àwọn òkè ńlá sì ń mì tìtìnítorí agbára ríru rẹ̀.
Yóo sì yí láti ìhà gúsù lọ sí gẹ̀rẹ́gẹ̀rẹ́ òkè Akirabimu, yóo sì la aṣálẹ̀ Sini kọjá lọ títí dé ìhà gúsù Kadeṣi Banea ati títí dé Hasari Adari ati títí dé Asimoni.
Aare fun iko agba-boolu Barcelona, Joseph  Bartomeu, ti so pe, egbe agba-boolu naa yoo kede akonimoogba tuntun ni ojo kokandinlogbon osu yii, ni kete leyin ifesewonse asekagba idije  Copa del Rey.
“Ní ọjọ́ kẹrinla oṣù kinni, ẹ gbọdọ̀ ṣe ọdún Àjọ Ìrékọjá, burẹdi tí kò ní ìwúkàrà ni ẹ óo máa jẹ fún ọjọ́ meje.
Àbí eniyan a máa fi àjàgà mààlúù pa ilẹ̀ lórí òkun?
Ajọ NAPTIP naa ti wa sọ agadagodo sẹnu ọna ayederu ile -iwosan agbẹbi ti ọmọkunrin naa n lo, bii ile ifọmọsowo l'Abuja.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù EndSARS Protest: Wo bí olùwọ́de EndSARS, Eremosele Adene ṣe gba òmìnira lọ́wọ́ ọlọ́pàá 17 Bélú 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 20 Bélú 2020 Ọkan lara awọn oluwọde EndSARS Eromosele Adene ti gba ominira lọ si ile rẹ lẹyin ti wọn gba beeli rẹ tan.
Ondije dupo fun egbe oselu alatako lorile-ede Sierra –Leone Julius Maada Bio ni won ti bura fun ni ile-itura leyin to jawe olubori ninu atundi eto –idibo to waye lorile-ede naa.
Nítorí ẹni tí ó bá ní, òun ni a óo túbọ̀ fún, kí ó lè ní sí i.
Awọn ọba ati ijoye ni wọn pe ọba Fọlagbade ni ẹni nla, ti o gbe igbe aye akinkanju lasiko rẹ loke eepẹ.
Oríṣun àwòrán, Bashir Ahmad Àkọlé àwòrán, Ààrẹ orílẹ̀-èdè Nàìjíríà buwọ́lu owó ìṣúná 2019 Lara awọn to peju sibi eto naa ni igbakeji aarẹ, Yẹmi Ọṣinbajo, olori ile igbimọ aṣoju-ṣofin, Yakubu Dogara, igbakeji olori ile aṣofin agba, Ike Ekweremadu.
Nígbà ti mo fi sílẹ̀, mo bẹ̀rẹ̀ si ni wá ẹni ti ọkan mi fẹ́ Ọ̀pọ̀ àwọn ọkọ Aguti ti sàlàye bi wọ́n se pade Aguti ni Uganda, Alich fẹ̀yìnti nínu iṣẹ́ ọlọpàá pẹ̀lú ọmọ mẹwàá to ti dàgbà."
Njẹ aarun yii da bi awọn coronavirus yooku ?
O ni ki wọn fọkan balẹ nitori didun ni ọsan ipinlẹ Eko yoo so nitori itẹsiwaju Eko lo jẹ oun logun.
Ó fi òkùnkùn bora bí aṣọ,ìkùukùu tí ó ṣókùnkùn, tí ó sì kún fún omini ó fi ṣe ìbòrí.
"Orukọ oye tuntun, ""Duke of Sussex"" ni o ṣeeṣe ki wọn fun Ọmọọba Harry nigbati iyawo rẹ, Meghan yoo di ""Duchess of Sussex""."
Ṣugbọn ṣa, eniyan 13,671 ti ri iwosan, awọn 744 si ti ku.
Sa gbogbo ipá rẹ láti ran Senasi, lọ́yà, ati Apolo lọ́wọ́ kí wọn lè bẹ̀rẹ̀ ìrìn àjò wọn, kí o sì rí i pé gbogbo ohun tí wọ́n nílò tẹ̀ wọ́n lọ́wọ́.
Yoruba World Congress: Mi o fi gbogbo ẹnu sọ pé ẹ̀yà Yorùbá yóò tún èrò rẹ̀ pa ní October 1- Akintoye
 Won bi omokunrin kan, Thiago (1) ni eyi ti Raheem ti bi Melody Rose (5) pelu ololufẹ rẹ tẹlẹ.
Ẹ yé tako ìjọba lórí iléèjọ́sìn títì pa, ẹ jọ̀wọ́ ṣọ́ọ̀ṣì yín fún ìtọ́jú àwọn tó lárùn coronavirus- Tunde Bakare Oludasilẹ ijọ Latter Rain Assembly, Tunde Bakare ti rọ awọn alufa ijọ bi tiẹ lati jọwọ gbọngan ile ijọsin silẹ fun ijọba lati loo fun ibudo itọju awọn alaisan coronavirus.
Ogagun iko omo ogun omi, Mathew Emuekpere, lo soro yii nibi ayeye idagbere ti won se fun un, ni ile-ise won niluu Calabar ni ipinle Rivers .
Anthony Joshua, ọmọ ọdún méjìdínlógún ti gba ọ̀pọ̀lọpọ̀ àmì ẹ̀yẹ níbi ìjà káàkiri.
Àwọn tí ń fi hapu kọ orin ìrégbè, tí wọ́n sì ń ṣe ohun èlò orin fún ara wọn bíi Dafidi.
Àrùn Ẹ̀yi di ilọ́po mẹ́ta jákèjádò àgbáyé lọ́dún 2019 - UN Abẹ́rẹ́ àjẹsára Covid-19 ti Pfizer ṣe yóò di lílò láti ọ̀sẹ̀ tó ń bọ̀ Wo dókítà ọmọ Nàìjíríà tí àgbáyé ń wárí fún nítorí abẹ́rẹ́ àjẹsára COVID-19 Àwọn àrùn aṣekúpani ti ń yọjú torí àìgba abẹ́rẹ́ àjẹsára Ireti wa pe miliọnu mẹrin eeyan ni yoo ri abẹrẹ yi gba nigba toṣu yoo ba fi pari.
Dino Melaye ọkan pataki lara awọn to n dije dupo gomina naa ti ni ahesọ lasan ni pe oun ti yọwọ ninu idije naa.
 Ìtọ ́ jú a má a ṣòro nígbà púpọ ̀ .
" Ṣùgbọ́n, àwọn ọmọ ẹgbẹ́ Shiite kò dá wọn lóhùn.
Oríṣun àwòrán, tufaceidibia1 Àkọlé àwòrán, Ọ̀pọ̀ àmì ẹ̀yẹ ni 2Baba ti gbà Amọsa, gbogbo awọn olorin Naijiria to gba ami ẹyẹ yii ni ko sí nibi ti eto naa ti waye lorilẹede Ghana, to jẹ ẹlẹkaarun iru rẹ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Leicester best player award: Iheanacho, Ndidi yóò jọ du àmì ẹ̀yẹ Leicester City 20 Ìgbé 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Wọn ti fi orukọ ọmọ orilẹede Naijiria, Wilfred Ndidi ati Kelechi Iheanacho silẹ fun ami ẹyẹ agbabọọlu Leicester City to tayọ ju ni saa yi (Player of the Season).
Nitori èyi, ohun kọ̀ wọ́n lọ́mọ.
O tun tesiwaju lati tun  ni imo eko isejoba ni Fafiti John Kennedy  to wa ni Harvard,lorile ede  United States, ni osu kefa odun 2002.
Akanṣe eto ni ti o si pọn dandan fun gbogbo eniyan lati ṣẹṣẹ lọ tun fi orukọ wọn silẹ."
Our new signing has already been meeting club legends 🤝#WillkommenStephan pic.
Lẹ́yìn ìgbà tí OLUWA ti bá Jobu sọ̀rọ̀ tán, ó sọ fún Elifasi ará Temani pé, “Inú ń bí mi sí ìwọ ati àwọn ọ̀rẹ́ rẹ mejeeji.
ti gbosuba fun ile igbimo asoju-sofin ati ijoba apapo fun ipa rere ti won ko
Òróró ati turari a máa mú inú dùn,ṣugbọn láti inú ìmọ̀ràn òtítọ́ ni adùn ọ̀rẹ́ ti ń wá.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Àwa obìnrin tó ń lépa afòjúsùn máa n ba ọkùnrin lẹ́rù ni -Toyin Lawani Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Bẹẹ si niyi, ilu ti a n wi yii ko jinna si awọn ilu nla ati ibugbe awọn eeyan jankanjankan ni ipinlẹ Eko.
O ti ṣe awọn isẹ ọwọ kan ki o to kuro ni Naijiria ṣugbọn a ko ri aridaju lati fidi ọrọ mulẹ iru iṣẹ to jẹ.
Ẹni tí ó ti wà, tí ó wà nisinsinyii,tí ó sì ń bọ̀ wá.
Nítorí OLUWA Ọlọrun yín ń ba yín lọ láti bá àwọn ọ̀tá yín jà, ati láti fun yín ní ìṣẹ́gun.
Ọrọ náà ko ba ma di awuyewuy,e bi kíì ṣe pé bàálù kẹrin lo n beere fún.
Nígbà tó bá yá, ilé Efuraimu yóo dàbí jagunjagun alágbára,inú wọn yóo sì dùnbí inú ẹni tí ó mu ọtí waini.
Wọ́n kọ́ ilé alágbèékà mẹta mọ́ ara ògiri ilé ìsìn náà yípo lọ́wọ́ òde, ati gbọ̀ngàn ti òde, ati ibi mímọ́ ti inú; wọ́n sì kọ́ yàrá ẹ̀gbẹ̀ẹ̀gbẹ́ sí i yípo.
Àwọn nǹkan ọrẹ tí wọn yóo gbà lọ́wọ́ wọn ni: wúrà, fadaka, idẹ; 
,Okore, Okono ati Bonny ki o to pada si ebute omi to wa ni Onne .
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Police Brutality: Ojú mi rí tó lọ́wọ́ ọlapàá nítorí Múrí màrùn ún- Adebayo Olaide Kunle ni: Ẹnu ẹgbẹ ko le ka ẹnikẹni tabi sọ pe sinima kan ko dara.
N óo ti fara dà á fun yín tó!
Jẹ́ kí ojú rẹ mọ́lẹ̀ sí ara èmi iranṣẹ rẹ;kí o sì kọ́ mi ní ìlànà rẹ.
 lápákan , nítoní ètò òṣèlú nàìjíríà , rotimi lo púpọ ̀ nínu 1990s ẹ ́ ní caribbean àti united states , níbi ti ó ti kọ ́ akẹkọ ní ilé ìwé macalester college ní st.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Fulani Ilorin l'ọkọ mi' Awọn Fulani ti wọn jẹ alakatakiti ẹsin Islam ati awọn ti ko gba ẹsin kankan gbọ ni wọn n fẹsun ikọlu yii kan julọ.
”Ajo eleto idibo INEC  si n foju lamẹẹtọ wo bi eto idibo se n lọ ni
Ọba náà ṣe ènìyàn púpọ̀ nǹkan kan kò si jẹ ní ìyà lọ́dọ̀ rẹ̀ rárá, ó ṣe ìtọ́jú mi dé góńgó, kò sí nínú àwọn ẹlòmíràn tí ó jẹ́ pé nígbà tí Ọlọ́run bá ti jàjà gbé wọn dé ipò ńlá tán wọ́n á máa fi ojú kékeré wo àwọn ẹlòmíràn, wọn a máa rò pé àwọn nìkan ni ayé wà fún láìmọ̀ pé ọmọ kékeré a máa mọ ibi ìṣubú àgbàlagbà, ẹni tí ó tẹ ọká ní ìrù mọ́lẹ̀ yóò rí ìjà ejò, ẹni tí ó dúró ní bi gẹgẹrẹ mọ́tò ń fi ikú ṣiré, ẹni tí ó dàgbà tí kò ní ìwà àgbà nínú, ọmọ kékeré ni.
Ètò ìdìbò gómìnà ìpínlẹ̀ Kogi àti Bayelsa m bọ̀ lọ́nà- INEC Ẹ̀yin olórí ẹgbẹ́ òṣèlú, ẹ kò leè yan aṣáájú fún wa - Dogara Kìnìhún joko jẹ ẹran ara afurásí ọdẹ tí kò gbààyè kó tó ṣọdẹ Wo bí o ṣe lè kọ́ ọmọ rẹ lẹ́kọ̀ọ́ ìbálòpọ̀ Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí kan sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
Ile-ise to n pese ina mona-mona lorile ede Naijiria maa n padanu ogun bilionu naira losoosu lorile ede yii.
"Mo ṣẹṣẹ ba ọmọ iya mi, Oluṣẹgun Abraham sọrọ tan lori foonu ni, o si ti jẹ ko di mimọ fun mi peoun ṣetan lati fọwọ si idije mi nigba keji.
Bẹẹ ba gbagbe, BBC Yoruba mu iroyin kan wa fun yin laipẹ yii pe, aarẹ ile asofin agba, Ahmed Lawan yan Ọmọwe Festus Adedayọ ni amugbalẹgbẹ rẹ feto iroyin, amọ tawọn eeyan kan n fapa janu nipa iyansipo naa.
Gẹgẹ bo ṣe sọ, o ni ara ti ẹ n bu yii na lo n mu oujẹ wọle fun mi, bakan naa ara ti ẹ n bu yii naa lo maa n fun yin ni ayọ ati idunu ti ẹ ba n wo mi lori ẹrọ tẹlifiṣọn yin nile."
àtí ọpọlọpọ ti ẹ ba ranti ti ko lonka Diẹ lara awọn awọn iṣẹ ọwọ Ọjọgbọn Wole Soyinka ree loke.
33 Àti pé àwọn púpọ̀ ni wọn ńdúró láti pa ọ́ run kúrò lórí ilẹ̀ ayé; àti nítorí ìdí èyí, kí ọjọ́ rẹ ó lè gùn, mo ti fún ọ ní àwọn òfin wọ̀nyí.
Ọkùnrin yìí ṣí ìlẹ̀kùn ó wọlé èmi náà sì tẹ̀lé e.
Àwọn ọmọ ogun Israẹli sá fún àwọn ará Filistia, 
Gbogbo eniyan lo mọ pe ka se ere talika kìí ba Chief Kanran lara mu ninu ere ti ọpọ i maa n foju olowo woo.
Alaga ẹgbẹ àwọn Alakoso gareji ọkọ nipinlẹ Ọ̀yọ́, Alhaji Mukaila Lamidi, tí ọpọ èèyàn mọ sì Auxiliary, tí sọ̀rọ̀ lórí rògbòdìyàn tó wáyé ládùúgbò Soka, nílùú Ibadan laipẹ yìí.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, #Queen Dihya: Obinrin tó gbógun tàwọn agbésùnmọ̀mí ni Algeria Gbopgbo ohun to wa ninu rẹ ko si kọja iṣẹju kan ati iṣeju aya mejidinlogun lọ.
Nítorí irú ìre tí baba wọn sú fún Esau yìí ni Esau ṣe kórìíra Jakọbu.
Koeman ẹni ọdun mẹtadinlọgọta fi iṣẹ rẹ gẹgẹ bi akọnimọọgba ẹgbẹ agbabọọlu orilẹede Netherlands silẹ nibi ti adehun to fọwọ si ti ku ọdun meji lati gba iṣẹ Barcelona.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Kid boxer: Ọmọọba 'The Buzz' Larbie rèé, ọmọ ọdún méje tó ń fi ẹ̀ṣẹ́ dá bírà Ivory Coast Orilẹ-ede Ivory Coast wa lara awọn ilẹ ni Afrika to kọkọ ṣi ile iwe rẹ pada.
ati pé kí o kó ọrẹ wúrà ati fadaka lọ́wọ́, tí ọba ati àwọn olùdámọ̀ràn rẹ̀ fi ṣe ọrẹ àtinúwá fún Ọlọrun Israẹli, tí ibùgbé rẹ̀ wà ní Jerusalẹmu.
Eyi ni diẹ lara awọn iroyin naa ti BBC News Yoruba ti ṣe lati fi gbe awọn obinrin larugẹ ati lati mu ipenija wọn jade wa si ita gbangba.
- Atiku bèèrè lọ́wọ́ ọmọ Nàíjíríà Oludije ipo Aarẹ fun ẹgbẹ oselu PDP lorileede Naijiria Atiku Abubakar, ti sefilọlẹ eto ipolongo ibo rẹ ni ọsan ọjọ Aje, to si ni oun ti fa ara oun kalẹ lati ba ireti ati ilakaka awọn ọmọ Naijiria pade.
Orúkọ àṣírí kan wà níwájú rẹ̀, ìtumọ̀ rẹ̀ ni: “Babiloni ìlú ńlá, ìyá àwọn àgbèrè ati oríṣìíríṣìí ohun ẹ̀gbin ayé.
Ó dára, jẹ́ kí èmi pẹlu rẹ dá majẹmu, kí majẹmu náà sì jẹ́ ẹ̀rí láàrin àwa mejeeji.
Kíló fa ìpànìyàn tó tún ń wáyé ní South Africa Àwòkọ́ṣe rere ni Winnie Mandela - Buhari South Africa: Wọ́n jó ọmọ Nàíjììrà nína láàyè 'Ọgbun to wa niwaju aarẹ tuntun ni S/Africa' Milton Nkosi to jẹ akọroyin BBC to wa ni South Africa bayii ṣalaye pe ọpọlọpọ awọn eniyan lo n sa kaakiri Johannesburg.
O ni amọ imọran oun ni pe 'ki awọn eniyan o maa fi owo to pọ dokowo, nitori pe ti o ba ti bẹrẹ, ka ni o fi ọgọrun ẹgbẹrun Naira bẹrẹ, iwọ fun ra a rẹ ni yoo wa eniyan mẹjọ mi i ti yoo da owo rẹ pada fun ọ ti asiko rẹ ba to lati 'ko àjọ'.
24 Èmi ni Jésù Krístì; Èmi wá nípa ìfẹ́ ti Bàbá, Èmi sì nṣe ìfẹ́ rẹ̀.
Adájọ́ pàṣẹ kí wọ́n fi ọlọ́pàá tó lọ́wọ́ nínú ikú Kolade Johnson sí àhámọ́ Ejò lé ààrẹ Liberia kúrò ní ọ́fíìsì Ninu esi ti wọn, Ile iṣẹ ọlọpaa Naijiria ni lori ọrọ ẹni to ku, eyi waye lẹyin ti awọn ẹlẹgbẹ okunkun kolu awọn eniyan awọn to lọ ko wọn.
Biṣọọbu Oyedepo ni lati igba naa ni ijọ Winners ti bẹrẹ si ni san idamẹwaa eyi ti o si n jẹ ki ferese ọrun maa tubọ ṣi sori ijọ naa sii.
Ni ti Bauchi, gomina Bala Mohammed sọ pe awọn janduku naa gbiyanju lati kọlu ile ti awọn ko ounjẹ naa si ṣugbọn ofo ni wọn ba, nitori wọn ti pin gbogbo rẹ tan.
"ibà zika maa ńràn nípa ìbùjẹ ti ẹ ̀ fọn ti irúfẹ ́ "" aedes "" ."
Ẹka ẹkunrẹrẹ rẹ nibi Ọjọ 9, Osu Kẹta Awọn Obinrin wọde ni Abuja lati fi aidunnu wọn han lẹyin osẹ mẹta ti wọn ti ji awọn ọmọ naa gbe.
Safire ń bẹ ninu àwọn òkúta rẹ̀,wúrà sì ni erùpẹ̀ rẹ̀.
Ọjọ Kẹẹdogun, osu Kọkanla ọdun 1889ni wọn bi ọmọkunrin lanti lanti naa.
Aare fi oro re mule lasiko to n se ifilole igbimo eleni metala tuntun naa nile ise re, lojoRu(Wednesday), niluu Abuja.
Ní ilẹ̀ Kipru ni a ti fi eléyìí hàn wọ́n.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù 'Tinubu 2023': 'Èmi kọ́ lò rán ẹgbẹ́ 'Asiwaju Reloaded Ambassadors' níṣẹ́ o' 10 Agẹmo 2019 Oríṣun àwòrán, Twitter/APC Àkọlé àwòrán, Idibo aarẹ ọdun 2023 Asiwaju Bola Tinubu ti fesi si ọrọ to tan kalẹ pe oun dupo aarẹ ọrilẹede Naijiria lọdun 2023.
Lasiko ti Aafa Juhany n pe irun Azahar ni iṣẹlẹ yii ṣẹlẹ ti ọkunrin naa si ja gbohungbohun gba lọwọ Aafa nla naa.
Ohun toju rẹ ri nigba Keresi akọkọ rẹ yi, paapa nipa gbigbin igi keresi ati didana ounjẹ Keresi fjẹ iyalẹnu fun un.
Nítorí náà, OLUWA Ọlọrun Israẹli ní òun óo mú ìparun wá sórí Jerusalẹmu ati Juda, tóbẹ́ẹ̀ tí yóo jẹ́ ìyàlẹ́nu gidigidi fún ẹnikẹ́ni tí ó bá gbọ́.
Gẹgẹ bi ajafẹtọ ilu kan, Shuaibu Sani ti fidi rẹ mulẹ fun BBC, awọn ọlọpaa lo tu ọkunrin naa silẹ, ẹni ti awọn ẹbi rẹ so mọlẹ lori ẹsun pe o ni arun ọpọlọ.
Ẹ sùn mọ́ bí, ẹ wo gbankọgbì!
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Wo àwọn àdúgbò tí ìpínlẹ̀ Eko ti fòfin de ọ̀kadà àti Marwa 21 Sẹ́rẹ́ 2020 Oríṣun àwòrán, @others Àkọlé àwòrán, A ko ni faaye gba gigun ọkada loju ọna marosẹ mọ nipinlẹ Eko Ijọba ipinlẹ Eko ti fofin de awọn ọkada ati marwa pe ki wọn yee rin ni awọn agbegbe kọọkan titi awọn a fi fẹnuko lori igbesẹ to ku.
Wọ́n sáré lọ mú un jáde láti ibẹ̀.
Ó mú kí wọn bọ́ sílẹ̀ láàrin ibùdó;yíká gbogbo àgọ́ wọn,
By The Visual and Data Journalism Team BBC News 24 Ògún 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 25 Owewe 2020 Awọn oludibo Amẹrika yoo kopa ninu idibo aarẹ lọjọ kẹta oṣu Kọkanla lati yan ẹni ti yoo ṣakoso eto ilẹ naa fọdun mẹrin mii.
Nítorí ìdí èyí a kì í ṣe àmúlò èdè Yorùbá fún ìdánilẹ́kọ̀ọ́ ní àwọn ile-ìwé wa, tàbí fún ìjírórò l’áwùjọ òṣèlú, àti bẹ́ẹ̀ bẹ́ẹ̀ lọ.
O ni bi awọn fijilante ba darapọ ṣiṣẹ pẹlawọn ọlọpaa, eto abo to mẹhẹ lorilẹede Naijiria a duro deede.
Yoruba ni aifagbafẹnikan ni ko jẹ ile aye o gun.
Ẹ sọ èdè Yorùbá kíkà di kàńpá níléẹ̀kọ́ alákọ̀bẹ̀rẹ̀ àti girama - Ẹgbẹ́ Akọ́mọlédè A ò ní fààyè gba pípa ọmọ Naijirià nípakúpa ní South Africa mọ- Abike Dabiri Busola Daakolo: Mi ò fọwọ́ sí ìwé kankan tó takò ẹ̀sùn tí mo fi kan Fatoyinbo Sowore takú, kò jẹun ní àgọ́ ọlọ́pàá torí májèlé - Deji Adeyanju Owó dé!
Àwọn angẹli meje tí wọ́n mú kàkàkí meje lọ́wọ́ bá múra láti fun kàkàkí wọn.
Lẹ́yìn ìgbà tí ó fún un ní aṣọ bíboora lẹ́yìn eyí a kí ara wa ó dọ̀la èmi náà wọ iyààrà mi lọ.
Arun yii náà je àrùn masunmọmi àbí mafarakanmi nígbà náà, tó sì wò òfin 180CE ko to dawọ duro.
Nígbà tí ó di ìrọ̀lẹ́, àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ tọ̀ ọ́ wá, wọ́n ní, “Aṣálẹ̀ ni ibí yìí, ọjọ́ sì ti lọ.
O ni ''mo mọ riri ipa ti awọn ọdọ nkọ lorílè-èdè yí, má sì má tẹsiwaju láti má b'awọn ṣíṣe pọ'' Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Nígbà tí ó dá ibẹ̀ ó bá ọkùnrin kan tí ó ti dúró sí ibẹ̀ dè é, ọkùnrin náà wọ ẹ̀wù títóbi ńlá kan, ẹ̀wù agbádá funfun tí àwọn oníṣọ̀nà ti ṣe ẹwà sí lára tí ó rí jìngìnnìjinginni.
Kachikwu ni ọwọngogo epo ati iye ti wọn n ra epo lagbaye to lọ soke, lo fa ọwọngogo epo bẹntirol ni ọdun 2016, ki o to di wi pe wọn tun bẹrẹ si ni san owo iranwọ epo.
Itúmọ èyí ni pé ti ènìyàn bá ni coronavirus láìṣe pé ó ni ǹkan to nii ṣe pọ̀ pẹ̀lú ẹni to wá láti òkè okun pẹ̀lú aàrùn náà, tàbi tó ní ǹkan ṣe pẹlú ẹni tó nii lábẹ́lé, èyí sì máà n jẹ́ kí o nira fun àwọn elétò ìlera láti wá orísun ibi ri ààrùn náà ti jẹyọ lábẹ́lé.
Arẹ́májà kò sí, Olubadan fi tìlù-tìfọn kí àwọn ìjòyè káàbọ̀ lẹ́yìn ọdún méjì Èèkànlú ní ìpínlẹ̀ Ogun lọ kí Buhari l‘Abuja torí ẹ̀yẹ tó fi dá Abiọla lọ́lá Iléẹjọ́ fún Seyi Makinde láṣẹ láti yan adelé alága ìbílẹ̀ ní ìpínlẹ̀ Oyo Jesu orí ayélujára kan rèé tó wa fun isoji ni Afirika Ogunye ni ijọba Naijiria n ba orukọ Naijiria jẹ nitori bẹẹ ni ijọba ṣe sọ ẹgbẹ IPOB to n beere fun orilẹ-ede ara re kuro lara Naijiria ni ẹgbẹ agbẹsunmọni, Ni eyi ti Jiti ni ko pada so eso rere.
Dino ní ìyàwó ni Adeyemi jẹ́ f'óun lágbo òṣèlú, Adeyemi l'ọ́mọ ọ̀dọ̀ ni Dino jẹ́ FUTA pàṣẹ lọ rọọ́kún nílé f'ákẹ́ẹ̀kọ́ méje tó lu akẹgbẹ́ wọ́n Irọ́ lásán ni ìdìbò tó wáyé ní ẹkùn Ìwọ̀-òòrùn Kogi - Dino Melaye Akẹ́kọ̀ọ́ mẹ́fà tó lu akẹẹgbẹ́ wọn ní fásitì FUTA dèrò ilé Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, FUTA: Àwọn mẹ́jọ ló ṣíná ìyà fún Bolu ní FUTA Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Bí obìnrin yìí tí ń se ọbẹ̀ tí ọba dé adé gòǹgò sí ìddí ìṣaasùn ọbẹ̀ tí ọbẹ̀ sì ń hó ni obìnrin náà bá mú ṣíbí ó ń ọbẹ̀ yìí, ṣùgbọ́n bí ṣíbí tí kan ẹja wọn-ọnnì ṣe ni ògiri ilé náà là sí méjì, dípò ọmọbìnrin tí ó yọ jáde ní ìṣáa’jkú ọkùnrin géńdé kan báyìí ló jáde ti òun ti idà lọ́wọ́ tí ó yí ọdẹ̀ lu iná.
naa nireti wa pe won yoo bale sipago iko ohun niluu Asaba, lojo keji osu keja
Ó rọra fi ọwọ́ ọ̀tún mú ìbọn rẹ̀ ó dákẹ́ jẹ́jẹ́ ó ń wo ojú ayé.
Agbẹnusọ fun ile isẹ ọlọpaa ni ipinlẹ Ondo, Femi Joseph to fi idi ọrọ naa mulẹ, ni isẹlẹ naa waye ni agbegbe Awoyaya, ni gareji Ife ni ilu Ondo.
2019 elections: Ìgbésẹ̀ méje fún ìdìbò 2019 tí ó yẹ kí o mọ̀ ‘Yorùbá, ẹ dìbò fún Buhari láti bu ọlá fún M.
Aare so pe oun nigbagbo pe “ opolopo idagbasoke lori eto ẹkọ, asa ati igbaye –gbadun awon eniyan  nile ati loke –okun lo ti waye laarin odun  méjídínláàdọ́ta ti alaafin ti wa ni itẹ awon baba rẹ.
Ni ti Morris Monye, o ni o ṣeni laanu pe awọn eeyan n ku nitori arun Covid-19 ṣugbọn Yahaya Bello ṣe bi pe ko kan oun.
Nǹkan ti NADECO ń bèèrè fún: O pọndandan ki ààrẹ Buhari múra láti jẹ ki àwọn ẹ̀ya ti gẹ̀ẹ̀sí fún ni àgba ti sọ awọn ẹya to ku di olùwòran, nítori náa kí ààrẹ pe ìpàdé pajawiri ki àwọn ẹyà gbogbo pe ìpàde láti le yan aṣoju ti yóò ma sojú wọ́n O pọ́ndandan ki ààrẹ Nàìjíríà lo iwe ofin ọdun 1960 (Independent Constitution) láti fi ṣe àgbákalẹ̀ àwọn òfin tuntun ti yoo mú Nàìjíríà wà ni ìsọkan, ti à ó si fi dá orilẹ̀-èdè tuntun sílẹ̀ Kí ààrẹ ṣe èyí láti dena ki àwọn tó ń fẹ wọ ìjọba ma ni ààfàni láti maa kó ọ̀rọ̀ gbogbo ẹyà tó ku sí ààpò tiwọn nikan, àti àwọn ololufẹ àti àwọn ọmọ wọn bí àpẹrẹ bi Abacha ṣe ko owo Naijiria lo oke okun NADECO tún pè fún ìdápada ètò ìjọba awa ara wá nítori pe ètò ìjọba to ń lọ lọ́wọ́ yìí jẹ ti ìjọba ọlọgún, èyí ti ó gbé àgbára fún ìjọba àpapọ̀ NADECO tún fí kun pé, ó ṣe pàtàkì kí ààrẹ pàsẹ fún àjọ elétò ìdìbò láti kéde pé, Abiola lo jáwe olúbori nínú ìdìbo tó wáyé ní àsìkò náà, nítori pe èyí yóò mú ki àwọn ènìyàn dunnu si igbésẹ̀ ààrẹ, kí fótò Abiọla si wa ninu awọn ti won ti se ìjọba Bákan náà ni pe kí wọ́n fún Kudirat Abiola ni oye to ga julọ lórilẹ̀-èdè Nàìjíríà.
Gbajugbaja olorin ni ilẹ Amerika, Kanye West ti bẹrẹ ipolongo rẹ ni Charleston, ni South Carolina saaju idibo sipo aarẹ lorilẹ-ede naa.
Isa Funtua lọ si ile iwe giga ti Manchester to wa ni Ilẹ Gẹẹsi Funtua di ana Aarẹ Buhari nigba ti ọmọ rẹ, Abubakar fẹ ọmọ Aarẹ Buhari, Safine (lami).
Jakọbu bá dìde, ó gbé àwọn ọmọ ati àwọn aya rẹ̀ gun ràkúnmí.
Àmọ́ wọ́n máa ń kanra nígbà mìíràn.
Èmi kò mọ̀ pe olùbéèrè á bimí, bẹ́ẹ̀ sì ni adẹ́dà á şe ìbéèrè pẹ̀lú.
Ọ̀kan ninu wọn tí orúkọ rẹ̀ ń jẹ́ Agabu bá dìde.
O fidiẹ mulẹ pe ẹgbẹrun okooo le ni ọọdunrun o din meji ati eedẹgbẹta le ni mejilelogun ninu awọn ọmọde to ṣalisi yii jẹ ikoko Naijiria ti wọn ku lati ọwọ awọn aisan ti a le dena.
Àfàìmọ̀ kí Naira Marley má fi ẹ̀wọ̀n bẹ̀rẹ̀ ọdún 2020 Idi ti EFCC ṣe mu Sheu Sani S'ahamọ.
Yatọ si aawọ pẹlu awọn alaga wọn yii, awọn Gomina kan ninu ẹgbẹ APC naa ko yọnu si Oshiomole gẹgẹ bi alaga.
Ààrẹ Gani Adams: Olùdíje tó bá ṣetán lórí àtúntò ìlànà ìṣèjọba ni Yorùbá yóò dìbò fún
n óo jẹ́ kí ẹ máa gbé ibí yìí títí lae, lórí ilẹ̀ tí mo fún àwọn baba ńlá yín láti ìgbà laelae.
Ranti eléyìí fún rere mi, Ọlọrun mi, kí o sì dá mi sí gẹ́gẹ́ bí ìfẹ́ ńlá rẹ tí kì í yẹ̀.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Coronavirus in South Africa: Ẹ̀kọ́ mẹ́jọ tó yẹ kí ilẹ̀ Afirika kọ́ lára àjàkálẹ̀ ààrùn coronavirus 14 Òkùdu 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 2 Agẹmo 2020 Oríṣun àwòrán, Getty Images Se awọn agba bọ wọn ni ẹṣin iwaju ni tẹyin n wo sare.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Pinnick: Àwọn ọ̀tá mi ló fẹ́ b'orúkọ mi jẹ́ 5 Sẹ́rẹ́ 2019 Oríṣun àwòrán, @thenff Aarẹ ajọ elere bọọlu nilẹ wa, NFF, Amaju Pinnick ti ní kò sí òótọ́ kan ninu ìròyìn pé oun n koju ẹsun iwa ajẹbanu bayii, eyi ti owo rẹ to aimọye biliọnu naira.
Nítorí àwọn ọ̀rọ̀ tí o fún mi ni mo ti fún wọn.
“Ẹ kò gbọdọ̀ fi mààlúù tabi aguntan tí ó ní àbààwọ́n rúbọ sí OLUWA Ọlọrun yín nítorí pé ohun ìríra ni ó jẹ́ fún un.
Lẹyin ti wọn ri Samuel, ko wulẹ pada si ilu Kano mọ.
Mo ri awọn agbegbe kan ti wọn kede isede konile o gbele.
Awọn asofin orilẹede Germany lo yan-an pada pẹlu ibo ọtalelọọdunrun ati mẹrin, ti ibo alatako rẹ si jẹ okolelọọdunrun o din marun, nigbati awọn asofin mẹsan ko dibo.
Ikọlu yi mu ki apa kan afara naa dawo sinu odo ti o gba ori rẹ kọja eleyi ti wọn pe orukọ rẹ ni odo Moju.
Ajo to n gbogun ti sise amulo
Ẹ di ara yín ní àmùrè,a óo fọ yín túútúú.
Àṣakẹ́ ni ó bíí Yàtọ̀ sí Àkàngbé Orímóògùnjẹ́, Yéwándé nìkan ni ó tún máa ń mu owó nínú séèfù.
Irin kò yàtọ̀ sí koríko lójú rẹ̀,idẹ sì dàbí igi tí ó ti rà.
    Nígbà tí ó di ọjọ̀ ìgbéyàwó gan-an a wọ asọ tí a o mu lọ sí ibi oúnjẹ tán, agogo lù ní agogo mẹ́jọ àbọ̀ pé kí a lọ̀ jẹun.
Iléeṣẹ́ ológun ti yabo ibùdó àwọn jàndùkú tó jí àwọn akẹ́kọ̀ọ́ gbé níléèwé katsina- Garba Shehu Gẹgẹ bi ohun ti awọn iroyin kan sọ, awọn ọlọdẹ agbegbe naa, ninu eyi ti Yisah wa doju kọ awọn ọlọṣa naa ki o to di pe awọn ọlọṣaa naa pa Yisah lagbegbe Asanmajana ti ileepo naa wa.
Yahaya Bello lẹ́ẹ̀kan síi ni APC ṣe ní ìdìbò abẹ́lé ní Kogi Olugbodi ni ọmọ ti a bi to ni ika ọwọ mẹfa.
Giroud ko si lara awọn ẹlẹsẹ ayo meji akọkọ lẹgbẹ agbabọọlu Chelsea to ti gbabọọlu jẹun, bakan naa ọpọ ni ko nigbagbọ ninu rẹ nigba to fi wa pẹlu ẹgbẹ agbabọọlu Arsenal.
Kí ló dé tí o fi gbàgbé ìpọ́njú ati ìnira wa?
Bakan naa ni minisita feto ẹnawo, Zainab Ahmed kede pe gbese tilẹ Naijiria jẹ ti fo lati triliọnu mọkanlelogun ati biliọnu okoolelẹẹdẹgbẹrin ati marun naira (₦21.
Oríṣun àwòrán, Lizzy Anjorin Kade pẹ lori laa ki ọba, ikunlẹ ati idọbalẹ si ni a ma n ki oriade nilẹ Yoruba, tori awọn arọbafin nikan lo n se lodi si eyi.
Gbolohun yìí jáde kí ọ̀rọ̀ Jesu lè ṣẹ nígbà tí ó ń ṣàpẹẹrẹ irú ikú tí òun yóo kú.
Skin Bleach: Èyí ni ọ̀nà tí àwọn obìnrin n gbà kó ara wọn sí wàhálà nítorí ara bíbó
Ọrun Jonatani kì í pada lásán,bẹ́ẹ̀ ni idà Saulu kì í pada,láì fi ẹnu kan ẹ̀jẹ̀ àwọn tí ó pa,ati ọ̀rá àwọn akikanju.
igbimo asofin yoo se atunse si bi awon aare orile ede Naijiria se n yan awon
Bí ẹ bá mú kí iṣẹ́ wọn jẹ́ ìrora fún wọn, kò ní ṣe yín ní anfaani.
Ni bayii, iko agbaoolu Chelsea wa ni ipo kerin pelu ami méjídínláàdọ́rin(68point) lori tabili, ti iko Man U si dipo kefa mu pelu ami márùndínláàdọ́rin(65point).
O tobi gan to bẹẹ ti wọn lee foju rii ni ibi kibi ninu ilu Caracas.
” Obinrin náà dáhùn, ó ní, “Ejò ni ó tàn mí tí mo fi jẹ ẹ́.
Ìsọníṣókí Iṣẹ́ gbogbo aṣòfin sáà ìjọba tó kọjá d'ópin lónìí Ètò ìdágbére ti wáyé ṣáájú ọjọ́ òní nílé ìgbìmọ̀ aṣòfin Ìfigagbága ti ilé aṣòfin àgbà ń ṣẹlẹ̀ láàrin àwọn sẹ́nétọ̀ méjì tó wà lóké ténté, Ahmed Lawan àti Ali Ndume Ìdíje ti adarí ilé ìgbìmọ̀ aṣojú ṣòfin wà láàrin àwọn aṣojú-ṣòfin méjì tó wà lóké ténté, Femi Gbajabiamila àti Umar Bago Femi Gbajabiamila di olori ile asoju-sofin Jíjábọ̀ ohun tí ń lọ lọ́wọ́ Nípasẹ̀ Yetunde Olugbenga àti Adedayo Owolabi Gbogbo àkókò tí a kọ jẹ́ ti UK Tí a fiṣọwọ́ ní 17:42 11 Òkùdu 201917:42 11 Òkùdu 2019 Kò ní jù báyìí lọ fún tòní A dupẹ pe ẹ n bawa kalọ lati aarọ lori bi eto idibo yan awọn adari ile tuntun nile asofin agba ati ti asoju-sofin nilẹ́ wa ṣe n waye.
Togun ni agbegbe ila orun Saki ati ijọba ibilẹ Atisbo ni wọn n gba wọle si ipinlẹ Ọyọ.
Ọlọpaa ni aṣẹ lati ṣe awọn nnkan wọnyii: tu ile, aṣọ atawọn nnkan ini miran.
George Floyd Funeral: Ìṣẹ̀lẹ̀ mẹ́fà tó mi àgbáyé nípasẹ̀ ikú George Floyd l'Ámẹ́ríkà
Bí Zainab ṣe dèrò ẹ̀wọ̀n Saudi lórí ẹ̀sùn ògùn olóró tí kò mọ̀ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ìbejì Àyànbìnrin tó ti ń di gbajúgbajà O ni ọmọbinrin naa ti wa pẹlu awọn alaṣẹ ọọfisi orilẹede Naijiria to wa ni Saudi Arabia.
Koda igbimọ naa daba pe ki wọn ṣe iwadi Gomina ipinlẹ Rivers tẹlẹ ri,Senatọ Liyel Imoke ati Minisita fọrọ ohun amuṣagbara Alhaji Abdulhamid Ahmed.
O ni asiko ti oju o la ni awọn ayan maa n fi ilu bu eniyan, sugbọn laye ode oni, ko si ẹni to n se bẹẹ mọ.
Ọba Babiloni sì rí i pé òun ń pèsè gbogbo ohun tí ó nílò lojoojumọ fún un títí di ọjọ́ ikú rẹ̀.
Kokumo jẹ ko di mimọ pe esi ayẹwo ti wọn ṣe fi han pe lootọ wọn fipa ba Uwaila lo pọ ni.
Ninu eyi to wa ninu awo to ṣẹṣẹ gbe jade, 'Moral instruction', Falz tẹnu mọ awọn iṣoro to n koju awọn eniyan orilẹede yii.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Kí ló fa ìjà láàrín ìlú mẹ́ta tó ń jà sí odò Nile?
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Orisabunmi: Elebuibon ní àfọwọ́fà wà lára nǹkan tó n fa Àkúfà nílẹ̀ Yorùbá 11 Sẹ́rẹ́ 2021 Laipẹ yii ni gbajugbaja oṣerebinrin, Folake Aremu, ti ọpọ eeyan mọ si 'Oriṣabunmi' kú, ṣugbọn ti ẹgbọn ati aburo rẹ naa tun kú laarin ọjọ mẹta pere.
Òní yìí ló di odidi ọjọ́ méje ti a ti ń ránṣẹ́ sí ọ pé kí jẹ́ kí á wá rí ọ, gbogbo àdéhùn tí o ń bá wa ṣe ni ò ń yẹ̀, síbẹ̀ o kò ronú ara rẹ wò.
Mo ṣẹ́ ẹni ibi lápá,mo gba ẹni tí ó mú sílẹ̀.
parẹ́, àisàn, ọ̀fọ̀, àjálù, à i ri ọmọ bi, ọmọ ti o n hùwà burúkú àti àwọn oriṣiriṣi idi miran.
Ṣugbọn ìwọ OLUWA ti mú kí orílẹ̀-èdè náà pọ̀ sí i,OLUWA, o ti bukun orílẹ̀-èdè náà,gbogbo ààlà ilẹ̀ náà ni o ti bì sẹ́yìn,o sì ti buyì kún ara rẹ.
Asa ní kí wọ́n wí fún Benhadadi, 
Wọn si tun gbọdọ fi ikede sita lọjọ mẹrinla ṣaaju ọjọ ipade, tabi ọjọ meje, to ba jẹ pajawiri ni.
O ni oun a rii pé UK yọ kuro ni Brexit ko to di ọjọ kọkanlelọgbọn, oṣu kẹwaa, ọdun yii ti oun ba de ipo naa.
Lọjọ Aje tii ṣe ọjọ kẹẹdọgbọn oṣu Kọkanla ni ajọ naa ni awọn oṣiṣẹ awọn mu awọn mejeeji.
ICPC: Ìwádìí ti pari lóri iwe ẹ̀ri ayéderú Kemi Adeosun
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Olusegun Obasanjo: Ẹ máṣe bú Ọlọ́run torí ọrọ̀ ajé tí kò dára àti òṣì tó gbalẹ̀ ní Nàíjíríà 28 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 30 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Oríṣun àwòrán, Olusegun Obasanjo Presidential Library Aarẹ ana ni Nigeria, Olusegun Obasanjo ti woye pe orilẹede yii ko se awọn ohun to tọ lati mu mu agbega ba ọrọ aje rẹ to mẹhẹ, ko si mu adinku ba isẹ ati osi.
Nígbà tí mò ń wọ aṣọ ọ̀fọ̀,mo di ẹni àmúpòwe.
Pẹ̀lú àjọṣepọ̀ Mekong Watch, ẹgbẹ́ kan ní Jápáànì ń jà fún ìdàgbàsókè ní agbègbè náà, ọ̀pọ̀lọpọ̀ àwọn àgbà ní Mekong ti bẹ̀rẹ̀ sí ní ṣe àkọsílẹ̀ àlọ́, ìṣẹ̀lẹ̀ àti ìtàn àtọwọ́dọ́wọ́ọ wọn tí ó ní íṣe pẹ̀lú ìṣẹ̀dá.
igbimo ti yoo ri si owo osu to kere ju fun osise ,nitori ipo ti asunwon Ipinle
Asofin Ndoma-Egba ti o gba ipo naa gege bi akowe agba egbe  seleri lati tesiwaju ninu ilana eto rere  ti akegbe re ti  se sile, lati ri I pe ipade naa je aseyori.
Ká kú ní kékeré ṣ'àgbà ká dàgbà di ẹni yẹ̀yẹ́
PDP: Ẹní ṣe nǹkan ètùfù ní kíyèsí ẹ̀hìnkùlé, ọmọ ẹgbẹ́ wà kò hùwà àìtọ́ lásìkò ìdìbò Wo ohun tó yẹ kí o mọ̀ nípa àwọn obìnrin méje ti Buhari forúkọ wọn ránṣẹ Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
    Nígbà tí a máa wọ aṣọ ìgbéyàwó, àwọn iwin ni wọn fún gbogbo wa ní aṣọ, wọ́n fún mi ni ẹ̀wù góòlù, ṣòkòtò góòlù, fìlà góòlù, àti bàtà góòlù gbogbo ohun tí mo fi sí ara jẹ́ góòlù pátápátá, bẹ́ẹ̀ ni ó yà mi lẹ́nu pé agbádá àti dàńṣíkí góòlù yìí kò ba mi lẹ́rù rárá, àti pé aṣọ náà kò wúwo ju ẹ̀wù lásán lọ.
Bẹ́ẹ̀ ni Josẹfu ṣe kó ọkà jọ jantirẹrẹ bíi yanrìn etí òkun.
“Àwọn ẹlòmíràn ni ó rí gbà là, kò lè gba ara rẹ̀ là.
n koju opolopo orile-ede lagbaye  “Gbigbogun ti aarun buruku yii se pataki lojuna
Báyìí ni Baba-onírùngbọ̀n sọ nípa mi, bí ó sì ti ń sọ̀rọ̀ wọn-ọnnì, èmi náà ti gbàgbé pé ilé Ikú ni mo dúró sí, èmi náà dúró bí ènìyàn pàtàkì, mo fi ọwọ́ tẹ ìbàdí, bí ènìyàn pàtàkì tì ń ṣe níwájú ènìyàn pàtàkì, mo dúró bí alágbára tí í dúró níwájú alágbára.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Nínú sọ́ọ̀sì, wọ́n ń sáré lọ síwájú fún ìwòsàn sùgbọ́n lẹ́yìnkùlé,.
Wọ́n kan ọkunrin yìí mọ́ agbelebu.
Oríṣun àwòrán, AProkodoctor/twitter Ni ọjọ Aje ni ipinlẹ Eko ti kede pe ki gbogbo ileewe, yala ti ijọba ni tabi ti aladani o wa ni titi pa titi di igba ti alaafia yoo fi jọba ni ipinlẹ naa pẹlu ọwọ tuntun ti ọrọ iwọde #EndSARS n yọ.
Leyin ipade awon gomina ipinle ti o kogun si eka gusuu ila oorun orile-ede Naijiria, eyi ti o waye nile ipinle Enugu lojo Aiku(Sunday), awon gomina ohun jabo ipade naa pe, ipinle won kookan ko ni ile ti o po ti o le faye gba didaran, eleyi ti o tun mo si pe, won ko le faye gba didaran nipinle won.
Gígùn ibi tí à ń wí yìí jẹ́ irinwo igbọnwọ (200 mita.
3 Kíyèsíi, oko náà ti funfun tán fún ìkórè, nítorínáà ẹnikẹ́ni tí ó bá fẹ́ láti kórè, ẹ jẹ́ kí ó fi dòjé rẹ̀ gún un pẹ̀lú ipá rẹ̀, kí òun sì kórè nígbàtí ọjọ́ sì wà, kí òun baa lè kó o pamọ́ fún ìgbàlà àìlópin ọkàn rẹ̀ nínú ìjọba Ọlọ́run.
Lara awon to wa nibi ipade naa ni , igbakeji aare orile ede Naijiria,Yemi Osinbajo, akowe ijoba apapo, awon gomina ti won jawe olubori labe  asia egbe APC ati awon asoju-sofin egbe APC.
Gẹgẹ bi ohun ti BBC ri ko jọ, wọn ni ki wọn maa wa ni ahamọ nile wọn titi di igba ti iwadii yoo fi bẹrẹ lori ohun to ṣokunfa ibugbamu ọjọ Iṣẹgun.
"Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ẹ san ₦200,000 fún Sowore lórí bí ẹ ṣe ń fi ẹjọ́ falẹ̀ - Iléẹjọ́ pàṣẹ fún ìjọba Buhari, èyí to fí ogún ọdún pilẹ̀ wèrè lórí ètò ààbò Nàìjíríà tó gẹ́ - Bishop Kukah ""Òògùn ni wọ́n fi bò mí lójú tí mo fi bá ara mi láàrin àwọn ẹlẹ́gbẹ́ òkùnkùn"" Na òṣìṣẹ́ Amotekun, ko san ₦250,000 owó ìjìyà, ko sì tún fi ẹ̀wọ̀n oṣù kan jura Wọ́n yìnbọn pa àwọn tó fipá bá ọmọ ọdún 12 lòpọ̀ ní gbangba lẹyin ìdájọ́ Ajínigbé méjì kàgbákò lásìkò tí wọ́n fẹ́ ẹ́ já ọmọ gbà lọ́wọ́ ìyá rẹ̀ l'Ondo A gbọ pe se ni iro ibọn n dun lakọ-lakọ, tawọn eeyan si n sa asala fun ẹmi lasiko ti awọn ọmọ onilẹ ọhun ni ki awọn onile gbe ile wọn kuro lori ilẹ awọn."
Òun ni ó sọ àwọn tí wọ́n kọlà ati àwọn tí kò kọlà di ọ̀kan.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ọlọ́pàá Ondo: Ìyá ọmọ tó kú yóò fojú balé ẹjọ́ 29 Sẹ́rẹ́ 2019 Oríṣun àwòrán, @Sazisokhango Ile isẹ ọlọpaa ni ipinlẹ Ondo ti fi idi rẹ mulẹ wi pe, lootọ ni iya kan lu ọmọ rẹ pa ni Akure, ni ipinlẹ Ondo.
Ori atẹ Twitter rẹ lo ti ṣe ikede naa.
Babiloni yóo sì di òkítì àlàpà, ati ibùgbé ajáko,yóo di ibi àríbẹ̀rù ati àrípòṣé, láìsí ẹnìkan kan ninu rẹ̀.
Bí Dafidi ti dé ọ̀dọ̀ Onani, tí Onani rí i, ó kúrò níbi tí ó ti ń pa ọkà, ó lọ tẹríba fún Dafidi, ó dojúbolẹ̀.
" Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Seyi Makinde: Màá fẹ́ káwọn aráàlú mọ ìpa ìjọba mi lára sí rere Gẹ́gẹ́ bi Buhari ṣe sọ, ọ̀nà ti Nàìjíríà gba láti kúrò nínú ìjọba ológun sí ti alágbáda lọdún 1979, kò ṣẹ̀yìn àwọn iṣẹ́ribiribi ti Obasanjo gbé se fun ìdagbasoke àpapọ orilẹ̀-èdè Nàijiríà""."
Oúnjẹ náà jẹ́ oúnjẹ ìpọ́njú, nítorí pé ìkánjú ni ẹ fi jáde kúrò ní ilẹ̀ Ijipti; ẹ óo sì lè máa ranti ọjọ́ náà tí ẹ kúrò ní ilẹ̀ Ijipti ní gbogbo ọjọ́ ayé yín.
Ẹ̀mí gbé e láti sọ pé ìyàn ńlá yóo mú ní gbogbo ayé.
won ko maa yo owo ori epo robi , nitori pe laisi eyi, iye owo ti awon omo orile
Àṣée, igbà tí Òjòlà-ìbínú ké igbe ńlá, Ewédayépọ̀ gun òkè àjà lọ!
Kí ni yóo jẹ́ ìpín mi lọ́dọ̀ Ọlọrun lókè?
Okorocha Gomina Fayemi ni oun ko ro pe ọrọ Naijiria nilo aduro ero yii lati maa na owo ti wọn n na tan loṣooṣu ki a to lè yanju iṣorọ Naijiria.
Igbimo alasẹ to wa niluu Abuja to je olu-ilu orile ede Naijiria, Federal Capital Territory Administration, FCDA ti bẹrẹ ise lati da ijọba ibilẹ merin silẹ.
Akẹkọọ mẹẹdogun pere lo le wa ni kilaasi.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Oyin sínsìn lérè lórí ṣùgbọ́n ó tún gbé ikú karí' Agbẹnusọ fun ile ifowopamọ to ga ju lọ ni Naijiria, Isaac Okoroafor sọ pe igbesẹ tuntun yii yoo ṣeranwọ lati fopin si awọn owo ilẹ Naijiria to jẹ ayederu yoo si jẹ ki gbogbo eniyan maa na owo tuntun tuntun.
Lẹnu ọjọ mẹta yi, awọn ọmọ Naijiria ti n bẹnu atẹ lu ileeṣẹ ọlọpaa fun bi wọn ti ṣe ni wọn n ṣegbe lẹyin ẹgbẹ oṣelu to wa ni ijọba.
Ọpẹlọpẹ ọdẹ to baa mu ọọni to gun kọja mítà mẹta naa.
Bẹ́ẹ̀ ni Joṣua ṣe gba gbogbo ilẹ̀ náà, gẹ́gẹ́ bí OLUWA ti sọ fún Mose, ó sì pín in fún àwọn ọmọ Israẹli; ní ẹlẹ́yà-mẹ̀yà.
Igba mejidinlogun ni Usman ti ja, mẹtadinlogun lo ti jawe olubori, ti o si fidi rẹmi ninu ọkan ṣoṣo ninu wọn.
 láti nǹkan bíi sẹ ́ ńtúrì kẹrìnlá ( 14th century ) ni èdè yìí ti ní àkọsílẹ ̀ .
Kí ó ranti pé, bí òun OLUWA ti nawọ́ ìyà sí òun ati àwọn eniyan rẹ̀, tí òun sì ti da àjàkálẹ̀ àrùn bò wọ́n; òun ìbá ti pa wọ́n run kúrò lórí ilẹ̀ ayé, 
Aare Buhari salaye pe, oun ti pase fun awon iko eleto abo, lati rii daju pe, abo ti o daju wa ni awon ile-iwe gbogbo, pelu awon ipago awon asafogun.
nítorí pé Abrahamu gbọ́ràn sí mi lẹ́nu, ó sì pa gbogbo òfin ati ìlànà mi mọ́ patapata.
Aawẹ Ramdan ki i ṣe ọrọ ki a ma jẹun tabi ki a ma sun mọ aya wa nikan, o
Nigba to n takurọsọ loju opo Instagram rẹ lori ọrọ awọn ọlọpaa SARS pẹlu alukoro ileeṣẹ ọlọpaa, Frank Uba, Marley ni awọn obinrin to n wọ sikẹẹti penpe ko tumọ si pe alaṣẹwo ni wọn.
Kò gbọdọ̀ pààrọ̀ ẹran tí kò dára sí èyí tí ó dára, tabi kí ó pààrọ̀ èyí tí ó dára sí èyí tí kò dára.
Ọmọ ọdun meje ni Ohene wa nigba ti iṣẹlẹ naa waye, ṣugbọn ko sọ fun ẹnikan nigba naa.
Ṣugbọn bí mo bá bá ọ sọ̀rọ̀ tán, n óo là ọ́ lóhùn, o óo sì sọ ohun tí èmi OLUWA Ọlọrun bá sọ fún wọn.
Mo ṣeleri pe mi o ni ṣe iru rẹ mọ'' Umar ti ile rẹ ko jina si ile ẹkọ naa ni ''aṣọ iya baba oun ni aṣọ ti oun ji ati pe bi oun ti ṣe n wọ aṣọ naa ni ọwọ tẹ oun.
O ti mú ìlérí tí o ṣe fún iranṣẹ rẹ, Dafidi, baba mi, ṣẹ.
Ọmọbinrin naa ti orukọ rẹ n jẹ Grace Oshiagwu jẹ akẹkọọ to wa ni ọdun kinni nile iwe gbogbonṣe Oke Ogun.
Oríṣun àwòrán, others Wo bi wọ́n ṣe sìnkú Kashamu ní Ijebu-Igbo Wọ́n ti pari eto sin òkú sẹnatọ nígbà kan ri Buruji Kashamu tí wọ káà ilẹ̀ sún ni ìlú rẹ̀ ni Ijebu-Igbo.
2 bílíọnù fi tún wáyà iná àti inú ilé Aso Rock ṣe- Buhari Ènìyàn 17 kú nínú ìjàmbá ọkọ̀ mẹ́ta tó ṣẹlẹ̀ ní Osun, òpópónà Ibadan sí Eko àti Delta Owó iṣẹ́ abẹ ìdí kìí ṣe ẹ̀rù ọmọdé- Dr Laser Wo ìdí tí Tẹni, ọ̀dọ́mọdé olórin obìnrin kìí fi ń ṣí ìhòhò rẹ silẹ̀ Ẹfunsetan Aniwura, ọmọ Ẹ̀gbá tó di akíkanjú obìnrin nílẹ̀ Ibadan Kini ẹṣa?
Lara awon eyan jankan-jankan ti o wa ninu ipade ohun ni: Olugbani-nimoran pataki lori oro aabo ilu, Babagana Monguno, Minisita to n mojuto eto aabo, Mansur Dan-Ali, oga agba fun ile-ise olopaa, Ibrahim Idris, adele ajo to n mojuto iwa ibajẹ ati iwadii, Mathew Seiyefa ti o fi mo awon torokan gbongbon ninu eto aabo lorile-ede yii.
Ní ọjọ́ kan, ọmọbinrin náà sọ fún ọ̀gá rẹ̀ pé, “Bí oluwa mi Naamani bá lọ sí ọ̀dọ̀ wolii tí ó wà ní Samaria, yóo rí ìwòsàn gbà.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Gómìnà Amosun f'ohùn sílẹ̀ láti kúrò ní APC Ẹlẹ́wọ̀n, ẹni ọgọ́rùn ọdún n bẹ̀bẹ̀ fún òmìnira Obìnrin míì tún ti kú lórí ìṣẹ́ abẹ ìdí ńlá Kíni ìwọ mọ̀ nípa Funmilayọ Ransome-Kuti?
Mo farabalẹ̀ fun yín,ṣugbọn kò sí ẹnikẹ́ni ninu yín tí ó lè ko Jobu lójú,kí ó sì fi àṣìṣe rẹ̀ hàn án,tabi kí ó fún un lésì àwọn àwíjàre rẹ̀.
Amọṣa, Keita kọ ni akọkọ aarẹ tabi olori ijọba nilẹ Afirika.
Aarẹ sọ pe oun gẹgẹ bi olori ileeṣẹ ologun Naijiria ''gbagbọ pe awọn ọmọogun koju oṣuwọn lati ṣiṣẹ ti ijọba gbe fun wọn,'' bakan naa ni aarẹ paṣẹ fun wọn pe ki ''wọn o wa awọn ọdanran to n da rogbodiyan silẹ lọ sibi kibi ti wọn ba n farapamọ si, ki wọn si mu wọn kuro nilẹ.
Èmi kò forí ṣọta ìjàmbá ọkọ̀ òfúrufú kankan - Obasanjo Wo àwọn ìlérí tàwọn Gómìnà tuntun ṣe nínú ìbúra wọn Ṣé o rántí itú tí Bright Omokharo fi Algeria pa ní MAROC '88?
Kenneth Omeruo finds himself in plenty of space to head Moses Simon's corner into the back of the net and give the #SuperEagles a 1-0 lead over #SyliNationale with 15 minutes to play.
Mò ń wá ìyàwó- Gbajúgbajà òǹkọrin Falz Èyí tí a wò jùlọ 5:03 Fídíò, Omolola Arohunmolase Welder: Mo ti fí iṣẹ́ 'Welder' gbayì láwùjọ, tó mo fi tọ́ ọmọ yanjú, Duration 5,039 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 5:39 Fídíò, Akomolede ati Asa lori BBC: Olùkọ́ Kikelomo Ogunboye tan ìmọ́lẹ̀ sí ìwà olè ọ̀gá ọlọ́pàá Audu gẹ́gẹ́ bí àwòkọ́ṣe àsìkò yìí, Duration 5,398 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 4:11 Fídíò, Oba Adeyeye Ogunwusi: Ojú mi ti rí lọ́pọ̀ lọpọ̀, ọ̀pọ̀ èèyàn ni kò tilẹ̀ gbàgbọ́ pé mo lè jọba- Ooni, Duration 4,117 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 4:43 Fídíò, Promise Akinlade: ọmọ ọdún mọ́kànlá tó ń fi ìlù dárà bíi àgbàlagbà sọ̀rọ̀ nípa tálẹ́ǹtì rẹ̀, Duration 4,437 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 0:59 Gbọ́, Ìsẹ̀lẹ̀ jákèjádò orílẹ̀èdè àgbáyé láàárín ìṣẹ́jú kan, Duration 0,59wákàtí 5 sẹ́yìn 7:03 Fídíò, Olumuyiwa Bolade Adedeji Military Bruitality: Bí arákùnrin onípèníjà ara tí sọ́jà lù ṣe dé, Duration 7,035 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 4:45 Fídíò, Yoruba Films: Ẹ̀ẹ́ bẹ̀ mi kúrò láyé ni, mi ò lè kú - Fadeyi Oloro, Duration 4,4526 Èrèlè 2020 2:48 Fídíò, Esther Ajayi: Èmi náà ti borí ìṣòro rí ló ń mu mi ṣojú àánú, Duration 2,481 Ògún 2019 6:08 Fídíò, Adebola Ademilua: Àìrísẹ́ ṣè lẹ́yìn ìwé kíkà ló sọ mi dí ìyá onírú, mo dúpẹ́ tèmi, Duration 6,0827 Bélú 2020 5:55 Fídíò, Soyinka Cancer: Àṣe ara mi ni iso ti n run gbogbo bí mo ṣe n ṣèrànwọ́ lórí jẹjẹrẹ, Duration 5,5527 Bélú 2019 BBC News, Yorùbá Ìdí tí ẹ fi le è nígbàagbọ́ nínú ìròyìn BBC Ìlànà Lílò Nípa BBC Òfin Àṣírí Cookies Kàn sí.
Alyona: Alyona jẹ onimọ nipa eto ọrọ-aje, o fẹ ọkọ kan ti orukọ rẹ n jẹ Pyotr, wọn si jọ n reti ọmọ.
Ọga ọlọpaa Adamu ṣalaye pe awọn ọlọpaa ti oun yan si ikọ naa 1.
OLUWA ní kí n sọ fún ìdílé ọba Juda pé òun OLUWA ní,
Wọ́n ń dá rìn kiri ninu aṣálẹ̀, níbi tí eniyan kì í gbé, lórí òkè, ninu ihò inú òkúta ati ihò inú ilẹ̀.
Gbogbo òkè Seiri ati gbogbo ilẹ̀ Edomu yóo di ahoro.
Bẹ́ẹ̀ ni a ṣe ń ṣe iṣẹ́ náà tí àwọn apá kan sì gbé idà lọ́wọ́ láti àárọ̀ di alẹ́.
O Abiola’ Nigba ti awọn oṣere gbọ eyi, wọn brẹ si ni fi ọrọ ikini ati adura ranṣẹ si oloye ẹgbẹ NURTW naa.
Arun iba ọrẹrẹ: ipinlẹ Anambra pasẹ ma mu Gaari mọ
Sibẹsibẹ ibinu OLUWA wá sórí Israẹli nítorí rẹ̀; nítorí náà, kò sí àkọsílẹ̀ fún iye àwọn ọmọ Israẹli ninu ìwé ìtàn ọba Dafidi.
DJIBOUTI: Ila Oorun Afrika ni ilu yii wa ti o si bere fun aṣẹ iwe igbelu.
Onidajọ Tsammani ṣalaye pe ori ahesọ ati gbọyisọyi ni awọn alaga kansu ti wọn rọ loye naa gbe ipẹjọ wọn naa le.
Lọjọru ni ikọ Juventus yoo lọ waako pẹlu Atletico Madrid, ti Paris St-Germain yoo si sare kadara pẹlu Real Madrid.
Wo bí o ṣe le fi ẹjọ́ sun àjọ FCCPC tí o bá ra ọjà tó ti 'expire' Ǹkan tí ó yẹ ki o mọ̀ nípa Burna Boy Ìdè jáá!
Ọ̀nà kan ò wọjà fáwọn òṣèré tíátà, bí wọn ṣe ń ta ìpara ìbóra ni wọ́n ń ta aṣọ ẹbí Ṣowore, Bakare gbé ọga DSS lọ sílé ẹjọ́, bèèrè fún bílíọ̀nù kan náírà Mo bọ́ lọ́wọ́ igbó mímu ṣùgbọ́n ìnira ilé Aafa Ọlọrẹ ti pọ̀jù- ọ̀dọ́ kan A jọ ṣe ìyàwó pọ̀, a jọ bímọ ní ọjọ́ kan náà, a tún jọ máa ń ṣàìsàn pọ̀ ni Lisabi Agbongbo Akala rèé, ẹni tó fi ìfẹ́, ìṣọ̀kan àti ìrẹ́pọ̀ gba ilẹ̀ Ẹ̀gbá lọ́wọ́ ìmúnisìn Àgbẹdọ̀!
Eto igbanisiṣẹ ajọ DSS Awuyewuye jẹyọ lori eto igbanisiṣẹ awọn oṣiṣẹ ọrinlenirinwo din ẹyọkan, 479, tuntun fun ajọ DSS.
 Aseyori eto mimu opin de ba ise ati osi je eto ti ko ni afiwe lasiko yii, nitori iranlowo ti imo ero n se lati je ki eto naa je aseyori.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Akomolede ati Asa lori BBC: Olùkọ́ Kikelomo Ogunboye tan ìmalẹ̀ sí ìwà olè ọ̀gá ọlọ́pàá Mama mi tiẹ kunlẹ bẹ mi wi pe ki n maa ṣe ere ori itage nitori ''baba mi ko gbọdọ gbọ.
Se bi ogun ẹni ba da ni loju, aa fi gbari ni.
Ó kó àwọn ọmọ ogun sí gbogbo àwọn ìlú olódi Juda, ó yan olórí ogun fún wọn ní ilẹ̀ Juda ati ní ilẹ̀ Efuraimu tí Asa baba rẹ̀ gbà.
Ẹ̀mí ni ó ń jẹ́rìí, nítorí òtítọ́ ni Ẹ̀mí.
Iṣẹlẹ ọhun waye lasiko to nira fun Zimbabwe.
Orukọ fiimu to si gbe jade naa ni Alubarika, eyi to mu ko gba ami ẹyẹ pe o pegede julọ eyi ti o jáde ni ọdun 2019.
- Yinka TNT Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Oríṣun àwòrán, iSaac Haastrup Bi o tilẹ jẹ pe wọn gba pe ohun ti awọn ọdọ naa se ko bojumu, sibẹ wọn ni ori bibẹ kọ ni oogun ori fifọ, iwa aidaa gbaa si ni ki awọn eeyan maa jiya aisi ina ọba tori ẹsẹ aimọdi.
Meṣobabu, Jamileki, ati Joṣa, jẹ́ ọmọ Amasaya; 
Ìtàn Aláàfin Aole rèé, tó gbé ìran Yòrùbá ṣépè Wèrè tí mò ń ṣe ní Facebook ló pawó fún mi-Esabod Èèyàn 409 míì ti lùgbàdì àrùn Coronavirus ní Naijiria Àwọn ọlọ́pàá kò kọbiara si ọ̀rọ̀ ìwà ipá lásìkò ìgbéle Covid -19 ni ìwà ipá ṣe pọ̀ - Ajàfẹ́tọ obìnrin Olu-Adeleye kilọ fun awọn to ba nifẹ si iṣẹ naa lati sọ otitọ nipa ara wọn ninu fọọmu ọhun.
Ni bi a ṣe n sọrọ yii, aarẹ ti gbe igbimọ kan dide lati lọ ba awọn ẹbi alase rẹ naa kẹdun.
Baba Alaafin lé sááju ìpolongo pẹ̀lú Awujale, wọn mọ ìtàn.
Lásìkò tí Umar Yar'adua sì jẹ Ààrẹ orílẹ̀ èdè yìí, ọ̀pọ̀ igbesẹ tó pegede lo gbé fún idagbasoke ilẹ̀ Nàìjíríà àti igbaye-gbadun ọmọ orílẹ̀ èdè yìí kọ̀ọ̀kan.
Aare egbe naa ,Alhaji Sani Shehu lo so eleyii  niluu Abuja pe ajo to n mojuto wiwa ekusa ati irin  lorile ede Naijiria ni won gbe igbese yii.
– Mo dúpẹ́ lọ́wọ́ Ọlọ́run ọba.
Àkọlé àwòrán, Emir Zulu Gambari ti Ilorin Awọn akọroyin BBC ti wa kaakiri orilẹede Naijiria lati maa mu iroyin lọlọkan o jọkan lori bo ṣe n lọ wa fun araye.
Má fara pamọ́ fún mi,kí n má baà dàbí àwọn tí ó ti lọ sinu isà òkú.
Ó di ọ̀rọ̀ líle ati àríyànjiyàn ńlá láàrin àwọn ati Paulu ati Banaba.
pe eniyan ko ni bimo  mọ sugbon ki
Iroyin to tẹ wa lọwọ sọ pe ọmọkunrin yii n wo ifẹsẹwọnsẹ laarin Liverpool ati Tottenham lori ẹrọ amohunmaworan lọwọ nile ounjẹ igbalode kan nigba ti awọn ọlọpaa SARS ya bo ibẹ ti wọn si dabọn bo lẹ.
Gbogbo eniyan ni wọ́n ń tẹ̀lé ẹranko yìí tí wọ́n fi ń ṣe ìran wò.
tubo tesiwaju nipa gbigbogun ti iwa ibajẹ ,ni eyi ti yoo tun je ki ilọsiwaju ba
nigba  aye rẹ, o pe awon to wa ninu
Agbofinro naa ṣalaye pe ti ijamba ọkọ ba waye, ohun to yẹ ki awọn ara ilu ṣe ni ki wọn fi to ọrọ naa lọ ọlọpaa lati bẹrẹ iwadii.
Lẹ́yìn-ọ̀-rẹyìn, bàbá ọgọ́rùn-ún ọdún gba ìdáǹdè l‘ẹ́wọ̀n Èèmọ̀ wọ̀lú!
26 Owewe 2020 Fídíò, Akomolede: Bolaji Faleke ni Olùkọ́ tó ń kọ́ wa ní àṣà oge ṣiṣe lórí BBC Yorùbá1 Owewe 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Ìwọ́de, ìkọ̀wéfipò sílẹ̀, ìdìbò abẹ́lé Osun kò fé bí'mọ re Ẹ̀mí ológun kan bọ́, ọ̀pọ̀ arìnrìn àjò bọ́ sọ́wọ́ ajínigbé ‘Ìkọlù darandaran pa èèyàn 2000’ O fi kun ọrọ rẹ pe, kin lode ti awọn Fulani darandaran fi n kọlu awujọ awọn ọmọlẹyin Kristi nikan, ti ọwọ sinkin ofin ko si mu wọn.
Ṣugbọn bayii, ijọba ipinlẹ Bauchi ti salaye oun ti ipo naa wa fun.
Igbìmọ̀ májẹ̀-kó-bàjẹ́ Nàìjíríà tẹ́wọ́ gba #27, 000 owó oṣù òṣìṣẹ́ O le ni ọdun mẹwaa ti ẹkunwo owó ọya awọn oṣiṣe Naijiria ti jẹ ẹgbẹrun mejidinlogun.
Amugbalegbe aare pataki lori oro ile
O da gẹgẹ bii Egyptian air.
N kò lóyún, bẹ́ẹ̀ ni ń kò ní ọkọ, ẹ fi mí lọ́rùn sílẹ̀ - Dayo Amusa Idris sàlàyé pé ko si irú ìkorira ti oun lé rí tí yóò mu ki òun dẹ́kun iṣẹ́ rere oun.
N’gbẹ̀hìn idahun rẹ̀, obìnrin yìí béèrè tẹ̀ríntẹ̀rín ó wí pe: Ó da bi ẹni pe mo mọ̀ yín níbìkan rí.
Oríṣun àwòrán, Ooni ife Àkọlé àwòrán, Ọjọ́ kéje oṣù kéjìlá ọdún 2015 ni Adeyeye Enitan Ogunwusi gba ọ̀pá àṣẹ gẹ́gẹ́ bíi Ọ̀ọ̀ni Ilẹ̀ Ifẹ̀ Awọn orilẹede bii Amẹrika, Gẹẹsi, Brazil, Cuba , Ghana ati bẹẹbẹẹ lọ ni Ọọni Ogunwusi ti de lati kan si awọn ọmọ Yoruba ti wọn gbilẹ kaakiri agbaye.
Àkọlé àwòrán, Ni ipinlẹ Eko, awọn eniyan ti n korajọ pọ lati ṣe iwọde lodi si ifipabanilopọ Àwọn agbofinro ti dé sí ṣọ̀ọ̀sì COZA ni Eko.
Iroyin yii ko lee dun lẹnu wa bii ti ẹnu ọlọrọ gangan ninu fidio yii.
Arakunrin ọun, ẹni ọdun mọkanlelaadọta ni a gbọ́ pe o ti n ni awọn ipenija ilera ki o to di àsìkò ti ayẹwo fi han pe o ni aisan jẹjẹrẹ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Gbajugbaja oṣere tiata, Bolaji Amusan fi hann wa bo se láyà to lori ètò ṣé o láyà.
Dokita kan to n gbe Ilẹ Gẹẹsi, Jumoke Koso-Thomas, ni ọṣẹ ti awọn eniyan fi n jo irun wọn lo n fa ori pipa ju, ṣugbọn ẹjẹ awọn eniyan miiran tun lee fa wahala yii.
23 Owewe 2020 Ghana elections result 2020: Èsì ìdìbò tó gbé aàrẹ tuntun wọlẹ́ ní Ghana rèé.
 “Aare ki gbogbo yin kaabo pada, bi o ti le je pe won ko si nile bayii, a ki yin kaabo, e si ku ise takun-takun.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Akomolede ati asa Yoruba: Ẹ wá kọ́ nípa àpòtí ìṣura èdè wa lórí BBC Yorùbá Ọlọ́pàá gbọ́dọ̀ wá àwọn tó gbàbọ̀dè láàrín wọn nítorí ẹ̀mí wa ò dè ní Akinyele Ọbalaye agbegbe Akinyẹle nibi ti iṣẹlẹ iṣekupani lọwọọwọ ti n waye ni ipinlẹ Ọyọ lati nnkan bii oṣu mẹta sẹyin.
Agbaọjẹ nipa eto isegun ati ẹsin ibilẹ ni ilẹ Yoruba, Baba awo Yẹmi Ẹlẹbuibọn, ti se apejuwe awon ayederu babalawo ati awọn ọna ta fi lee da wọn mọ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ẹ̀mí kan náà ló n darí ìrìnàjò wa táa fi jọ kọ́lé papọ̀- Ìbejì Igbagbọ awọn kan ni pe, bi wọn ṣe n gbe awọn olowo ti wọn fura si pe wọn n ji owo ori lọ sile ẹjọ, naa lo ṣe yẹ ki wọn maa fun awọn ọdọ naa ni anfaaani lati sọ awijare wọn lori ẹsun ti wọn ba fikan wọn.
Ọrọ ti Aisha sọ yii ya ọpọlọpọ eniyan lẹnu pe, o le sọ iru nkan bẹ ẹ tabi bu ẹnu ẹtẹ lu iṣakoso ọkọ rẹ ni gbangba.
O tun fi kun ọrẹ rẹ wi pe, gbogbo ferese ile naa ati ilẹkun lo ti di piparọ, bẹẹ si ni iṣẹ n lọ lọwọ lati kọ ile naa pari.
Mo ti ṣetán láti daríi ìfẹ̀họ́nú hàn lòdì sí ìpànìyàn
Iku Fẹ́lẹ́: MC Oluọmọ, àwọn èèkàn ìlú sọ̀rọ̀ lórí ikú alága NURTW, Fẹ́lẹ́
Nítorí pé àwọn ọ̀dàlẹ̀ ń dalẹ̀,wọ́n ń dalẹ̀, wọ́n ń hùwà àgàbàgebè.
''Adura ti mo n gba fawọn to dami lẹbi lori ọrọ naa ni pe ki Eleduwa fun awọn ati ọmọ wọn ni iru iyawo bii ti Chin.
O ti ṣe bẹ laimọye igba, koda awọn ọlọpaa ilẹ Gẹẹsi ti mu u ri ni ọdun 2019, fun pe o dunkooko mọ awọn eeyan ẹya Igbo, ati Fulani lori ayelujara.
Ipade kan ti waye nile ijọba orile-ede Naijiria nilu Abuja laarin Gomina Ipinlẹ Ogun, Ibikunle Amosun ati Aarẹ orile-ede Naijiria Muhammadu.
Toyin Abraham Lẹyin ọjọ diẹ to ṣe ọjọ ibi, Toyin Abraham kede pe oun, ọkọ oun ati awọn eeyan kan yoo ṣi ileeṣẹ fun ọmọ rẹ, Ire, laipẹ.
Wo àwòrán ńkan tó ń ṣẹlẹ̀ ní ìpádé ìran Yorùbá ní Ibadan báyìí Ẹ̀ṣọ́ tó pa Ọ̀gágun Ethiopia tí a sọ pé ó kú, kò kú mọ́!
inu iṣuna-owo ọdun 2018 yii, eyi ni wọn fun Gomina lanfani lati wa ṣalaye.
Ọmọ ọdun mọkanlelọgọta ni Aarẹ Jonathan ko si fi igba kankan kowopamọ si ilẹ okere tabi ko ni ile lẹyin odi'' Ijọba apapọ Naijiria ni aiṣedede waye nipa bi awọn ile iṣẹ ipọnpo Eni ati Shell ṣe gba agbaṣe iṣẹ ni Naijiria ti wn si gbe wọn lọ si ile ẹjọ lati san owo itanran biliọnu dọla 3.
Dokita onimọ nipa obinrin ti sọ wi pe ọmọbinrin gbọdọ bimọ lasiko nitori ko si ẹni to mọ boya nkan osu ohun ma a pin.
Gómìnà ìpínlẹ̀ Kaduna fún Sanusi ní ipò tuntun Gomina ipinlẹ Kaduna ti yan Mahammadu Sanusi keji gẹgẹ bi ọkan lara awọn ajọ to n risi ọrọ karakata ni ipinlẹ Kaduna,(KADIPA).
Nígbà tí ó di ọjọ kan báyìí, bí ó ti jókòó sí àgbàlá rẹ̀ tí ó ṣiré ní ìrọ̀lẹ́ ni ó gbọ́ tí àgbébọ̀ adìẹ̀ kan ń sọ fún àwọn ọmọ rẹ̀ kí wọ́n ṣọ́ra kí wọ́n kúrò ní ibi kan báyìí, nítorí bí wọ́n bá dúró pẹ́ ní ibẹ̀ tí wọ́n ń tan ilẹ̀ ibẹ̀ wọn kò ní í pẹ́ rí àpò owó góòlù ní ìsàlẹ̀, àti pé ẹni tí ó ni ilé náà sì lè ṣe bẹ́ẹ̀ rí i.
“Ọlọrun mi, ojú tì mí tóbẹ́ẹ̀ tí n kò lè gbójú sókè níwájú rẹ.
Ibi tí wọ́n tẹ́ ẹ sí nìyí.
Ẹwẹ, o kere tan eniyan mọkanlelogun ni wọn si n wa lẹyin ijamba ọkọ oju omi ni ipinlẹ Benue.
Ètò fífi akọ ṣe olórí yìí tí ó ti kọ́ wa lọ́rùn tipẹ́ tí ọ̀pọ̀lọpọ̀ sì ń kọ̀ pé kò rí bẹ́ẹ̀ – ìyẹn kò sì ṣe é rí – ohun tí ó ń ṣe rè é: ó ń sọni di aláàbọ̀-ara, ó ń ba ayé àwọn obìnrin jẹ́, bẹ́ẹ̀ ló ń pani.
Kaini bá aya rẹ̀ lòpọ̀, ó lóyún, ó sì bí Enọku.
orile-ede Guinea, Alpha Conde ati awon osise ajo ECOWAS fun akitiyan won to n
Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí 10:17 Fídíò, Oba Adedokun Abolarin ti Oke Ila: Ó ya ọ̀pọ̀ tó súnmọ́ mi lẹ́nu bí mo ṣe ń kọ́ àwọn akẹ́kọ̀ọ́ pẹ̀lú ipò Ọba, Duration 10,1723 Bélú 2020 6:48 Fídíò, Akomolede ati Aṣa lori BBC:Wo ìrúfẹ́ ìgbeyàwó méje tó wà nílẹ̀ Yorùbá àti ojúṣe Alárinà, Duration 6,4810 Bélú 2020 4:26 Fídíò, Akomolede Yoruba: Kí ni ìdí tí aṣọ fi máa ń pọ̀ lára Egúngún ju Orò lọ́?
Bákan náà ni Iléeṣẹ́ Emzor ti dá òsìsẹ́ wọn tó ń pín èròjà náà dúró.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Domestic Chores: Ọ̀pọ̀ àbíkẹ́yìn ń bèèrè pé ṣé ègún ni láti kẹ́yìn nínú mọ̀lẹ́bí?
Kí oore-ọ̀fẹ́ ati alaafia kí ó pọ̀ fun yín.
Ẹni to ba wu lati gba a ni wọn yoo fun.
"Kenya: Ile isẹ amohunmaworan mẹta yoo wa ni titi latari \""iburawọle\"" Odinga"
Ìtàn kíkùn lórí Mọ́ṣáláṣí Anabi ní Medina tó bẹ̀rẹ̀ lọ́dún 1440 sẹyin Coronavirus and OCD: 'Mo fi ogún ọdún gbáradì fún àjàkálẹ̀ ààrùn yìí' Kí ló ń mú àwọn adarí obìnrin lágbáyé rọwọ mú nípa kíkojú covid 19?
Adura naa ma n gba, wọn n jẹri.
Ile iwe girama ni mo wa ni igba naa'' ''Lai si ti Adedibu, oludije fun ẹgbẹ oselu PDP ko ba maa le wọle ibo lati di Gomina lọdun 2003, nigba ti mo jẹ aarẹ Naijiria.
Ọmọ Lefi yìí ní obinrin kan tí ó jẹ́ ará Bẹtilẹhẹmu ni ilẹ̀ Juda.
Tọ́ mi sọ́nà, OLUWA,ṣugbọn lọ́nà ẹ̀tọ́ ni kí o bá mi wí,kì í ṣe pẹlu ibinu rẹ,kí o má baà sọ mí di ẹni ilẹ̀.
Ninu atẹjade ti ileeṣẹ ọlọpaa fi sita lọjọ Ẹti lẹyin ti wọn sọ fun BBC pe ootọ lo ṣẹlẹ, wọn ni awọn ti gba ipe nipa ọrọ na ni ọjọbọ, ni nkan bi agogo mọkanla kọja iṣẹgun mẹẹdogun pe ọkunrin kan to n jẹ Aminu Farawa ti ọmọ rẹ ọkunrin mọle.
Fun idi eyi, a fẹ ki ẹ se agbeyewo ki ẹ si yọ orukọ Fayose kuro ninu awọn ti wọn le sa kuro nilu tori pe awọn agbofinro n se iwadi wọn'' Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, APC Primaries: 'Kò sí 'Faction' ni Kwara APC rárá, NWC ti sọ̀rọ̀' Obafemi pari ọrọ rẹ́ pe wọn gbodo ko iwe lati fi tọrọ aforijin lọdọ Fayose ti wọn si gbọdo san bilionu ogun Naira lowo itanran bi bẹ kọ,ile ẹjọ ni yoo pari ọrọ fun awọn.
O óo ti sùn pẹ́ tó, ìwọ ọ̀lẹ?
Kanya Sesser: láti kekere ni ìyá mí ti kọ̀mí sílẹ̀ ṣùgbọ́n n kò ṣagbe
Atejade ohun waye, leyin ti igbimo awon minisita kede ilu-o-fara ro olosu mefa miiran, eyi ti minisita fun eto abo Siraj Fegessa so pe, fi fofin de eto iwode ifehonu-han ati tite iwe ti yoo sokunfa laasigbo wa lara re.
 tẹ ̀ jáde ní ọdún 1984 , tí Ọ ̀ jọ ̀ gbọ ́ n ayọ ̀ bámgbóṣé sì ṣe olótùú rẹ ̀ .
Àròsọ àti ìgbàgbọ́ àwọn ènìyàn lórí gbígba ẹ̀jẹ̀ 'Òbí mi kú nígbà ti mo wà lọ́mọ́ ọdún kan' Ta ni yóò borí láàrin Aisha Buhari àti ọkọ rẹ̀ lórí ọ̀rọ̀ ‘First Lady’?
Ní àràárọ̀ ni olukuluku máa ń kó ohun tí ó bá lè jẹ tán, nígbà tí oòrùn bá gòkè, gbogbo èyí tí ó bá wà nílẹ̀ yóo sì yọ́ dànù.
Tope, ẹni tó sísọ lójú ọ̀rọ̀ yìí lásìkò tó ń kopa lórí eto BBC Yoruba tún fikùn pé, òun kii ṣe adekodere, òun máa ń lọ ẹsọ etí, àmọ́ nígbà miran ó leè jẹ pe wọn ya òun ni.
"Bi ọdun marun ni mo fi n ṣe atipo, ti eeyan ba si ni iṣoro, Ọlọrun nikan lo le sa ba.
Ẹgbẹ oselu PDP lo gba ile ẹjọ to n gbọ ẹjọ eto idibo lati tako idibo to gbe Kayode Fayemi wọle gẹgẹ bi gomina ipinlẹ Ekiti.
Ẹ̀yin aya, ẹ máa tẹríba fún àwọn ọkọ yín gẹ́gẹ́ bí Oluwa.
Niwọn igba ti a ko ba ti ribi le dahun ibeere yi lẹkunrẹrẹ, BBC Yoruba yoo gbiyanju lati gbe akọsilẹ jade nipa iye igba tawọn ibugbamu waye ni Eko lọdun 2020.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìṣẹ̀lẹ̀ Èkó: Aáwọ̀ Ọbàkan sọ ilé di áláwọ̀ méjì Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Ìṣẹ̀lẹ̀ Èkó: Aáwọ̀ Ọbàkan sọ ilé di áláwọ̀ méjì 12 Ìgbé 2018 Ilé alájà méjì kan wà ládúgbò Bámgbóṣé, lágbègbè Lagos Island nílùú Èkó, tó jẹ́ abala méjì ọ̀tọ̀ọ̀tọ̀.
Igbeaye ni oko ireke ko dara rara; inu ahere ti ko ni ile iyagbẹ ni awọn idile naa maa n gbe nitosi oko ti wọn ba ti n ṣiṣẹ.
Ninu ọrọ ti rẹ Marwan Nawaz gboṣuba kare fun akọnimọọgba Arsenal Unai Emery fun ipa to ko ninu aṣeyọri naa Alebu kan to kan wa ba aṣeyọri yii wa ni bi Aaron Ramsey ti ṣe fi ara pa ninu ifẹsẹwọnsẹ ọhun.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ileya: Àgbò wọ́n torí ọjà ẹran mẹ́ta ni wọ́n tìpa lókè ọya torí Boko Haram Ninu ọrọ rẹ Aregbesola rọ awon musulumi lati fasiko yii gbadura fun alaafia ati idagbasoke orileede Naijiria.
Emi ṣaa ni mo mọ ọrọ ti Ọlọrun fun mi, Ayamatanga kii ṣe ""I am a Tiger"" tabi ""I am at anger"" tawọn eeyan n wi o, baa ṣe pe e ninu ere gẹlẹ, bẹẹ ni Ọlọrun ṣe sọ fun mi, ti mo si kọ ọ silẹ""."
Ajọ ọmọ lẹyin Kristi, CAN ti apa ariwa orilẹede Naijiria ti ba awọn obi Zainab Aliyu yọ lori pe wọn gba itusilẹ rẹ.
" Ẹ̀kọ́ mẹ́jọ tó yẹ kí ilẹ̀ Afirika kọ́ lára àjàkálẹ̀ aàrùn coronavirus Wèrè tí mò ń ṣe ní Facebook ló pawó fún mi-Esabod Ojú pópó ni mo dàgbà sí àmọ́ n kò mu igbó, sìgá tàbí ọtí líle rí - MC Oluomo Kollington, Bàbá Suwe, Ogun Majek wà lára àwọn gbajúmọ̀ òṣèré tí ayé ti parọ́ ikú mọ́ sẹ́yìn Taa ni Jọkẹ Silva, òsèré tíátà tó ń se ọjọ́ ìbí ?
Oríṣun àwòrán, @Hakeem Ọdun 2002 lo gbe awo orin akọkọ jade, to si gba ami ẹyẹ Grammy lọdun 2007.
Flying Eagles yoo koju iko agbaboolu Benin ninu ifesewonse akoko lojo keje osu kejila, ki won o to lo koju Niger Republic lojo kesan an  Tobi Sangotola.
Lẹ́yìn náà tẹ nọ́mbà MTN rẹ sójú rẹ̀.
Lẹ́yìn tí ìyá ọmọbinrin yìí ti kọ́ ọ ní ohun tí yóo bèèrè, ó ní, “Gbé orí Johanu Onítẹ̀bọmi wá fún mi nisinsinyii ninu àwo pẹrẹsẹ kan.
Lẹ́yìn ikú Kudirat Abiola ní wọn yíi orúkọ ilé iṣẹ́ rẹdíò tí wọn pé ni Radio Democracy, ti wọ́n ṣẹṣe dá sílẹ̀ ní Norway, pada sí Radio Kudirat.
Bakan naa, ni awọn ọdọ bii ọgbọn ti n gba itọju lọwọ nile iwosan nitori ọgbẹ ọta ibọn.
Abiola Ajimobi - Ọyọ Abiola Ajimobi to jẹ gomina ana nipinlẹ Ọyọ lo gbe apoti idibo fun ipo sẹnetọ fun ẹkun idibo guusu ipinlẹ Ọyọ.
Yorùbá ń parun lọ kọ́ yìí?
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Osinbajo yẹ́ Woli Arole sí níbi ìṣíde The Call"" Obinrin naa ni ""Lati igba yii ni ọkọ mi ko ti fi owo ounjẹ silẹ fun mi mọ, to si n fa sẹyin lati ba mi sere tabi sọrọ."
Ó sàn láti máa gbé ààrin aṣálẹ̀,ju kí eniyan máa bá oníjà ati oníkanra obinrin gbé lọ.
O tumọ si pe ẹni bẹẹ kii mu omi daadaa.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Russia Boxer: Abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò dágbére fáyé lásìkó ìjà rẹ 24 Agẹmo 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Iku ogun lo pada pa akinkanju abẹṣẹkubiojo Maxim Iroyin ni kete ti wọn pari ija naa ni o ti hande pe Maxim ko le da rin kuro ni gbagede ija.
O ni ko sohun to jọ ọ.
Uwaila Omozuwa: Oríṣun àwòrán, others Ọjọru, ọjọ kẹtadinlọgbọn oṣu Karun-un ọdun 2020 ni wọn pa Uwa Omozowa nilu Benin, lẹyin ti wọn fipa ba lopọ tan Inu ìjọ Redeem kan ni Benin ni wọn pa si lasiko to n kawe lọwọ Ẹni ọdun mejilelogun ni akẹkọọ ọlọdun kinni, lẹka imọ nipa microbiology ni fasiti ilu Benin naa, nigba to ku Afojusun Uwaila ni lati jẹ ilumọọka ojisẹ Ọlọrun ati oniwaasu agbaye, ti yoo yi ọkan awọn eniyan pada sọdọ Ọlọrun Ọwọ ti tẹ afurasi kan lori iku Uwa, ti iwadii ọlọpaa si fihan pe wọn la ẹrọ iyẹfun panapana mọ lori ni Azeezat Somuyiwa: Oríṣun àwòrán, Tribuneonline Ọjọ Eti, ọjọ karun-un oṣu kẹfa ọdun 2020 ni wọn pa Azeezat Somuyiwa, lẹyin ọjọ kẹrin ti wọn pa Barakat Oyun oṣu meje lo wa ninu Azeezat nigba ti wọn pa a lagbegbe Akinyele níbi ti wọn ti pa Barakat naa Ẹni ọdun mọkandinlọgbọn ni Azeezat, ti iwadii si ni wọn gbẹmi rẹ lati fi ṣe oogun owo ni Ọwọ ọlọpaa ti tẹ afurasi kan lori iku obinrin naa, ti kọmisana ọlọpaa si ti gbe ijoko rẹ si agbegbe Akinyele lati sewadii iku awọn obinrin naa Azeezat, ti a ko mọ ile iwe to lọ ni wọn fi okuta ni fọ lori lati gbẹmi rẹ Grace Oshiagwu: Oríṣun àwòrán, others Ọjọ Satide, ọjọ kẹtala oṣu kẹfa ọdun 2020 ni ẹnikan tun sekupa Grace Oshiagwu lẹyin tí wọn fipa ba a lopọ Ọmọ pasitọ ijọ CAC kan to wa ni ori Sasa nii ṣe, inu ile wọn to wa lẹyin ile ijọsin naa si ni iṣẹlẹ yii ti waye.
John Adedayo Adegboyega: Oríṣun àwòrán, EPA Àkọlé àwòrán, Boyega ni inu ohun dun lati pada wale nigba ti o wa si Naijiria lọdun kerẹsi to kọja Abigail ọmọ Aboderin ati Samson Adegboyega lorukọ awọn obi rẹ.
Sí ìjọ eniyan Ọlọrun tí ó wà ní Kolose, sí àwọn arakunrin tí ó jẹ́ olóòótọ́ sí Kristi.
 oba abdullah je omo ebi iran hashemite .
Àwọn ọmọ Nàìjíríà la ohùn Olùdásílẹ̀ Twitter bá wọn jó 'Soapy' ní Nàìjíríà , ó fi òǹtẹ̀ jan Tacha Oludari agba fun ẹgbẹ́ àwọn gomina, Salihu Lukman, lo kede bẹẹ nínú àtẹjáde kan to fọwọsí lọjọru nílùú Abuja.
Nígbà tí àwọn ọmọ Israẹli di alágbára sí i, wọ́n ń fi tipátipá kó àwọn ará Kenaani ṣiṣẹ́, ṣugbọn wọn kò lé wọn kúrò láàrin wọn patapata.
Atejade kan ti o jade nile-ise
Atẹjade naa ni ọjọ kinni, osu Kẹjọ, ọdun yii ni ajọ INEC yoo fi ikede nipa ibo naa to ipinlẹ mejeeji leti, nigba ti eto idibo abẹnu laarin awọn ẹlẹgbẹjẹgbẹ oloselu yoo maa waye laarin ọjọ Keji si ọjọ ikọkandinlọgbọn, osu Kẹjọ, ọdun 2019.
Isẹlẹ naa ti da sunkẹrẹ fakẹrẹ ọkọ silẹ ti awọn ẹsọ ajọ oju popo si n gbiyanju lati dari lilọ bibọ ọkọ.
Ẹmiọla fi kun ọrọ rẹ pe oun tun ba awọn ẹlomii ni akata awọn ikọ ologun yii ti oun si tun ni lati san owo irun wọn naa pẹlu nitori wọn ti lu wọn gẹgẹ bi i ejo aijẹ nitori airi owo san.
Mọ̀ síi nípa ìtàn ojúbọ̀ nàá Ọlọ́run nìkan ló mọ bí ìrìnàjò ìfẹ́ ẹ̀dá á ṣe rí láyé, ọ̀dọ́ Aláàfin ní orí gbémí yà sí, ó sì tẹ́milọ́rùn- Olorì Aanu Wo ọ̀nà tí àwọn ‘ẹ̀lẹ̀ Daddy’ gbà dé ààfin Ọyọ Àṣírí ńlá tó ń bẹ láàrín Alaafin àtàwọn onílù rẹ̀ rèé Wò ó bí Alaafin àti aya àkọ́fẹ́ rẹ̀, Olorì Abibat ṣe pàdé ní èwe Bí Gómìnà Makinde bá ṣẹ̀ mí, lẹ́tà lásán ló jẹ mí- Aláàfin Ọ̀yọ́ Àwọn onílù mí ló ń tú àṣírí ìkà èèyàn tó bá wọ ààfin mi - Aláàfin Ṣe Ọlọrun lo mọ ọkọ iyawo oju ọna, Folashade ni irinajo afẹ fun idanilẹkọ ni oun ati awọn akẹẹgbẹ oun nileewe lọ fun, nigba ti oun kọkọ mọ Alaafin.
 kìí ṣe Ọ ̀ rúnmìlà nikan ní àwọn ẹlẹyẹ bẹ .
“Àwọn amòfin ati àwọn Farisi ni olùtúmọ̀ òfin Mose.
Yatọ si awọn ti o n bẹnu atẹ lu loju opo ayelujara, awọn ara ilu tun safihan pe inu awọn ko ṣe dun loju koroju pẹlu aarẹ Muhammadu Buhari nipinlẹ Borno.
O ran wa leti aye atijọ pe awọn iya wa a maa wa ninu ile fun itọju ile ati ara ile bẹẹ si ni ọkunrin kii fi iṣẹ tirẹ silẹ.
Mo mọ̀ pé OLUWA yóo gba ọ̀ràn olùpọ́njú rò,yóo sì ṣe ìdájọ́ òdodo fún àwọn aláìní.
Ó ní, “Nítorí èyí ni mo ṣe sọ fun yín pé kò sí ẹni tí ó lè wá sọ́dọ̀ mi, àfi bí Baba mi bá ṣí ọ̀nà fún un láti wá.
Wọn tún ti gbẹ̀mí ọmọbìnrin kan lẹ́yìn tí wọn fipá balòpọ̀ n'Ibadan Èèyàn 501 ló lùgbàdì àrùn Coronavirus ní Naijiria ní Ọjọ́ Abámẹ́ta Kollington, Bàbá Suwe, Ogun Majek wà lára àwọn gbajúmọ̀ òṣèré tí ayé ti parọ́ ikú mọ́ sẹ́yìn Coronavirus Updates: Àì gba ìwé àṣẹ ìjọba ṣàkóbá fún sinima orítá ọmọkùnrin yìí Bẹẹ si ni ọrọ ri lagbo awọn oṣere tiata naa, idi si ree ti BBC Yoruba fi ṣa awọn oṣere tiata to bi ibeji sọtọ, lati fi to yin leti.
Awọn sẹẹli ko ni ba ara wọn ṣepọ mọ Awọn sẹẹli maa n ba ara wọn ṣepọ loorekoore, ṣugbọn eyi maa n dinku to ba ya.
Awọn iyipada ta fẹ ninu asa wa ni awọn asa ati ise to n jẹ ka maa huwa bii ẹranko ati ajẹniyan, awọn abala asa wa ti ẹ ko mọ niyi.
O dahun pe oun ko m nipa baba isal ti wọn n sọ.
Dokita Rosemary Onyibe to ti n sisẹ pẹlu eto polio tẹlẹ sọrọ lori lilo ọna pinpin abẹrẹ ajẹsara polio lati fi wa awọn ti o ti lugbadi Covid 19 ati ṣiṣe abẹwo to yẹ.
Oga agba ile-ise Nestle, ogbeni Mauricio Alarcon so ninu oro re pe, idasile ile-ise tuntun ohun ni lati pese ise ati lati maa ra awon ohun elo ti o to iko ogorin ninu ida ogorun awon ohun ipese  ohun mimu Milo naa latodo awon agbe, bakan naa ki a si se idasile awon ile-ise si awon igberiko.
OLUWA bi mí pé, “Jeremaya, kí ni o rí yìí?
Lati igba yii wa ni orilẹede Tunisia ti gba oriyin gẹgẹ bi orilẹede kan ṣoṣo lagbaye to gba eto iṣejọba tiwantiwa labẹ abajade iwọde ẹhonu araalu eyi ti wọn pe ni arab spring.
Kí àyà wọn lè já, kí ọpọlọpọ lè kú ní ẹnubodè wọn.
Àsíá ibùdó ẹ̀yà Dani yóo wà ní ìhà àríwá ní ìsọ̀rí-ìsọ̀rí; Ahieseri, ọmọ Amiṣadai, ni yóo jẹ́ olórí wọn.
Elija bá pàṣẹ pé, “Ẹ mú gbogbo àwọn wolii oriṣa Baali!
Oríṣun àwòrán, Getty Images Orilẹ-ede marundinlaadọrin ti kede pe awọn yoo si ileewe tabi si wọn laabọ, nigba ti awọn mejilelọgbọn si ni loju opo ayelujara lawọn akẹkọọ yoo ti pari saa eto ẹkọ to ku.
Iroyin sọ wipe awọn to wa ninu baalu na jẹ ogota ero, ẹsọ meji, osisẹ baalu meji ati awakọ ofurufu meji.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Iriwisi Lydia,oludokowo lori MMM Iwadii ti BBC ṣe lori ilana tuntun yii fihan pe - bii ti tẹlẹ, awọn eniyan yoo forukọ silẹ loju opo ayelujara wọn, wọn si tun ti da ẹlẹgbẹjẹgbẹ silẹ lori ayelujara Whatsapp fun awọn ọmọ Naijiria lati maa lo.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Crystal Chiagbu: Wọ́n sọ fún wa nígbà tó pé ọjọ́ mẹ́fà pé a máa gé ẹsẹ̀ rẹ̀ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Crystal Chiagbu: Wọ́n sọ fún wa nígbà tó pé ọjọ́ mẹ́fà pé a máa gé ẹsẹ̀ rẹ̀ 17 Bélú 2019 Ọrọ Beulah kọja a n sọ ireti nu, tori ko tilẹ fi aaye silẹ lati maa ronu pe o ni ipenija ara kankan lati kekere.
Yatọ si awọn to gbẹmi mi, ọpọlọpọ ni o padanu dukia ati awọn ọrọ aje wọn.
Yàtọ̀ sí coronavirus, wo ìgbà mẹ́wàá míì táwọn mùsùlùmí kò lè ṣiṣẹ́ Hajj Irinajo sílẹ Mímọ́ Hajj 2018 ti bẹ̀rẹ̀!
Pẹ̀lú ìfilọ́lẹ̀ẹ Panos fún àkòrí orin tuntun fún Caribbean fún Àyájọ́ Ilẹ̀-ayé, ẹgbẹ́ẹ  Jamaica náà ti ṣe tán láti ṣe eré ní iléèwé àti ní àdúgbò, láì yọ Kàwé Jákèjádò Jamaica sílẹ̀ àti iṣẹ́ igi gbíngbìn.
Fashola to je Alaamojuto oro amusagbara Ina, ise ati oro ile gbigbe, pelu, alakoso
4 17096 Orilẹede Guadeloupe 156 39.
Yorùbá ni “Èkó gba olè, ó gba ọlẹ”, ọ̀rọ̀ yi jẹ wi pé kò si irú ẹni ti ko si ni ìpínlẹ̀ Èkó nitori Èkó gba olówó, ó si gba aláini àti wi pé iṣẹ́ pọ̀ ni Èkó ju gbogbo ìpínlẹ̀ yoku lo.
Peteru wá dìde dúró pẹlu àwọn aposteli mọkanla, ó sọ̀rọ̀ sókè, ó ní, “Ẹ̀yin ará, ẹ̀yin Juu, ati gbogbo ẹ̀yin tí ẹ̀ ń gbé Jerusalẹmu, ẹ jẹ́ kí ọ̀rọ̀ yìí ye yín, kí ẹ fetí sí ọ̀rọ̀ mi.
Nítorí kò tọ́ kí ọkunrin bo orí rẹ̀, nítorí àwòrán ati ògo Ọlọrun ni.
Saaju la ti mu iroyin wa pe, oríṣiríṣi ìṣẹlẹ ló n sẹlẹ ni Ekiti, bi ọjọ idibo Gomina ti se n sunmo .
Ààyè wọn ti wà nílẹ̀ fún wọn, ninu òkùnkùn biribiri títí ayé ainipẹkun.
Ati pe ni nkan bi aago mẹta aabọ ọsan ti wọn n mura fun ìrun kiki, ni wọn ri oku ọmọ naa.
Ṣugbọn bí o bá se àsè, pe àwọn aláìní, àwọn aláàbọ̀ ara, àwọn afọ́jú.
Ó dàbí àwọn igi aloe tí OLUWA gbìn,ati bí igi kedari tí ó wà lẹ́bàá odò.
"Ìwọ́de ńlá yóò bẹ́rẹ̀ lọ́jọ́ táwọn gómìnà bá yá ₦17trn nínú owó ìfẹ̀yìntì òṣìṣẹ́ - NLC Ìdí rèé tí mo fi yan ikọ̀ PMS rọ́pò NURTW nípìnlẹ̀ Oyo - Seyi Makinde ""Buhari, Olóṣèlú àtàwọn òjíṣẹ́ Ọlọ́run ló mú àjẹbánu gogò ní Nàíjíríà"" Ooni Adeyeye ti Ile Ife fẹ sèrànwọ́ owó iléèwè fún akẹ́kọ̀ọ́ 5 mílíọ̀nù ní Nàìjíríà Igba to di ọjọ kẹrin, oṣu Kinni, ọdun 2019 ni Melaye fa ara rẹ ileeṣẹ ọlọpaa lọwọ lẹyin ọjọ meje ti wọn ti wa lẹnu ọna ile rẹ."
“Yóo bukun ọ nígbà tí o bá ń wọlé, yóo sì tún bukun ọ nígbà tí o bá ń jáde.
Gbogbo nkan to wa nibẹ lo ju run.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Adebola Ademilua: Àìrísẹ́ ṣè lẹ́yìn ìwé kíkà ló sọ mi dí ìyá onírú, mo dúpẹ́ tèmi Isomọlorukọ ọmọ tuntun ti o jẹ arole Oọni Ifẹ: Kílódé tí Ọọni Ife, Oba Ogunwusi kò fi gbọdọ̀ rí ọmọ rẹ̀ tuntun ti Olorì Naomi bí títí di bíi ẹ̀yìn oṣù mẹ́fà?
Ṣugbọn ohun tí ó ń wí kò yé wọn, ẹ̀rù sì ń bà wọ́n láti bèèrè lọ́wọ́ rẹ̀.
Tolanibaj, TrickTee, Kiddwaya, Prince, Erica, Lucy, Leo, Wathoni, Dorathy, Vee ati Laycon ni awọn ololufẹ eto naa fi orukọ wọn silẹ pe ko kuro nile ẹlẹgbọn agba.
Ìyàwó Ọ̀ọ̀ni Ogunwusi kò bímọ tuntun Ẹ̀yin tẹ́ ń jà fún ẹ̀yà Hausa, Igbo àti Yorùbá, ara yín lẹ̀ ń jà fún - Lamido Sanusi Donald Trump àti ìyàwó rẹ́ ti lùgbàdì àrùn CoronaVirus Fídíò rèé lórí bí Sunday Igboho ṣe korò ojú sí ìwà ọ̀dàlẹ̀ nílẹ̀ Yorùbá Ìfẹ́ Yorùbá ló mú mi fi ẹ̀mí wéwu láti kojú ajínigbé ní Kishi - Sunday Igboho Buhari, ayẹyẹ kí là ń ṣe gan, ṣé ti ìpànìyàn àbí ìjínigbé?
Lara awọn to mọ riri isẹ orin Fatai Rolling Dollar ni ile isẹ ìròyìn BBC nigba ti gbajugbaja olorin míì, Ade Bantu sọ nípa rẹ lori eto kan pe, kii ṣe pe Fatai padanu ẹ̀bùn rẹ kankan.
O jẹ Ọjọgbọn obirin akọkọ ninu ẹkọ ede Yoruba ni orilẹ-ede Naijiria, ati ni gbogbo agbaye.
Amọṣa nigba ti ifẹsẹwọnsẹ naa wọ iṣẹju kẹtalelaadọrun ti orun n rebi atiwọ ni Mohammed Sallah ba tun fi ọba lee fun Liverpool.
Losu kẹwa, eeyan marunlelogoji lo gba idajọ ẹwọn ọdun mẹta si mọkanlelọgbọn nitori wipe wọn jẹ ọmọ ẹgbẹ agbesunmọmi naa.
Aare soro iwuri yii lasiko ti o n safilọlẹ iwe ti akole re n je”wakati isipopada”.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Dangote, Fayemi pari ìjà láàrin Gomina Ganduje àti Emir Kano Sanusi II 8 Òkùdu 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 9 Òkùdu 2019 Àkọlé àwòrán, Emir Kano Sanusi Lamido àti Gómìnà Abdullahi Ganduje Gómìnà ìpínlẹ̀ Kano Abdullahi Ganduje ki Emir ilú Kano Muhammedu Sanusi ní ìlú Abuja ní ọjọ Jimọ lásìkò ti wọn fẹ yanju ààwọ to wà láàrin wọn.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Coronavirus in Nigeria: èyàn 178,000 tó kó ààrùn Coronavirus ti rí ìwòsàn lágbáyé Ìròyìn tó ń jáde láti fásitì Johns Hopkins tó wà l'Amerika, fasiti tó ń ṣe ìwádìí nípa nǹkan tó ń ṣẹlẹ̀ lórií ààrùn Coronavirus, ti fi hàn pé ó kéré jù èèyàn 178,378 tó ní ààrùn Coronavirus tẹ́lẹ̀ ni wọ́n ti rí ìwòsàn .
Nítorí ó sàn kí wọ́n gbeyawo jù pé kí ara wọn máa gbóná nítorí èrò ìbálòpọ̀ ọkunrin ati obinrin.
Adajọ Majisireti agba, Patricia Adetuyibi ko gba ẹbẹ 'o jẹbi tabi o ko jẹbi' lẹnu afurasi naa ki o to ni ki wọn ọs fi si ahamọ ọgba ẹwọn naa titi di igba ti ileeṣẹ eto idajọ ni ijọba ipinlẹ Ọyọ igbẹjọ rẹ yoo fi waye.
Tinubu ni àìsàn tó rọ̀ mọ́ ìdíje òṣèlú ní 2023 ló ń yọ ọ̀tá Oshiomole lẹ́nu Oríṣun àwòrán, Others Eekan ẹgbẹ oṣelu APC, Bola Tinubu ti sọrọ lori awuyewuye lati yọ alaga apapọ ẹgbẹ naa, Adams Oshiomole nipo.
Bí mo ti gbé ojú sókè ni mo rí ìwo mààlúù mẹrin, 
Obasanjo, ẹni tí inu rẹ dun jọjọ lori ọgbin ẹja naa ni, ironu jinlẹ lori iyan to lee sẹlẹ lẹyin ti arun Covid-19 ba kasẹ nilẹ lagbaye, lo mu ki oun gunle ọgbin ẹja naa.
Awọn ilana yii ti tako ki eeyan maa tabuku ọmọlakeji loju opo ayelujara.
 Òní ni àyájọ́ ọjọ́ Èdè abínibí ni gbogbo àgbáyé, ẹ dákún ẹ jẹ́ kí á gbìyànjú láti sọ Èdè Yorùbá sì ara wa lónìí àti lọ́jọ́ gbogbo, láti fi ṣe àjọyọ̀ ọjọ́ yìí nítorí pé Èdè Yorùbá Rewà púpọ̀.
Ojú tí ó gbé sókè, ó rí Bẹnjamini ọmọ ìyá rẹ̀, ó bá bèèrè pé, “Ṣé arakunrin yín tí í ṣe àbíkẹ́yìn tí ẹ wí nìyí?
Ìhàlẹ̀ ọ̀tá bà mí ninu jẹ́,nítorí ìnilára àwọn eniyan burúkú;wọ́n kó ìyọnu bá mi,wọ́n ń bínú mi, inú wọn sì dùn láti máa bá mi ṣọ̀tá.
“Bí ọkunrin kan bá ṣẹ̀ṣẹ̀ gbeyawo, kò gbọdọ̀ jáde lọ sí ojú ogun tabi kí á fún un ní iṣẹ́ ìlú ṣe, ó gbọdọ̀ wà ní òmìnira ninu ilé rẹ̀ fún ọdún kan gbáko, kí ó máa faramọ́ iyawo rẹ̀ tí ó ṣẹ̀ṣẹ̀ fẹ́.
Iroyin ti ileeṣẹ wa gbọ tun fi kun un pe yatọ si eeyan mẹjọ ti awọn oṣiṣẹ adoola ẹmi gbe oku wọn jade yii, oku eeyan meje ni wọn ti kọkọ yọ jade ni alẹ ọjọ Satide ti iṣẹlẹ naa ṣẹlẹ.
Ajibola Otubusin, ti o jẹ ẹni ọdun mẹtadinlaadọrin to tun ṣẹsẹ di ìyá ọmọ tuntun jòjòló ti ni ko si ohun to ṣoro fun Ọlọrun lati ṣe ti eniyan ba ni igbagbọ ati ifọkansin.
Oríṣun àwòrán, APC Nigeria Saaju nii ajọ to n se kokari eto idibo ni Naijiria, Inec, ti kede pe akoko ti to fawọn ẹlẹgbẹjẹgbẹ oselu lati bọ sita wa seto ipolongo ibo wọn fawọn ara ilu,awọn oludije ipo Aarẹ ko fẹ fi asiko ṣofo rara.
PDP fà Buruji Kashamu kalẹ̀ bíi olùdíje Gómìnà l‘Ogun Àwọn Asòfin Naijiria yarí lórí ètò ìsúná 2019 Kachikwu: Mi ò sọ wí pé mo gba ìwé ẹ̀rí tó tayọ jùlọ Linda ní òun àti bàbá ọmọ òun ti túká Oun naa sọrọ oṣelu aini ibadọgba anfani ninu ẹgbe nigab ti ko pada ri tikẹẹti lati dije dupo gomina Oyo'Ó ku Shittu, ó ku Ọlọ́run lórí ohun tó fẹ́ fi san ẹgbẹ́ APC l'ẹ́san' Chris Ngige: Minista fun igbode iṣẹ Oríṣun àwòrán, @NGF Àkọlé àwòrán, Ọkan lara awọn ọna naa ni eyi to sọ laipẹ lori awọn oniṣegun oyinbo ti wọn sa kuro ni Naijiria lasiko yii.
Ori ẹrọ ikansiraẹni Twitter n gbona jainjain ni, lati igba ti orukọ Festus Adedayo ti jade wi pe, yoo ba Lawan sisẹ.
"To ba jẹ wi pe ẹsan to fẹ fi san ẹgbẹ niyẹn, o ku u, o ku Ọlọrun.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Idagbasoke to n de ba ọrọ aje Ghana ko tii han lara awọn ọ̀mọ orilẹede naa Saaju, owo to to ọgọsan miliọnu dọla owo ilẹ Amẹrika ni ijọba ti kọkọ gbe kalẹ lorilẹede naa lati kin awọn ọlọpa lẹyin ninu isẹ gbigbogunti iwa ọdaran eleyi ti aarẹ orilẹede Gahana ni yoo tubọ se miranwọ fun eto abo to munadoko.
Onimọ̀ nipa ounjẹ jijẹ, Oyedeji oluwatobi jẹ ko di mimọ wi pe nigbakuugba ti eeyan ba n gba awẹ, awọn irinṣẹ ara yoo ti paju de to ba maa fi to akoko iṣinu.
Ikọ onimọ ilera mejidinlaadọta lo ṣe iṣẹ abẹ naa lori awọn ibeji ọhun lẹyin oṣu mẹjọ ti wọn bi wọn.
 Ìwúre fún ọba àti ẹbí ọba .
Nígbà tí Apolo dé Akaya, ó wúlò lọpọlọpọ fún àwọn tí wọ́n gbàgbọ́ nípa oore-ọ̀fẹ́ níbẹ̀.
Nítorí náà, fún wa ní meje ninu àwọn ọmọ rẹ̀ ọkunrin, kí á lè so wọ́n kọ́ níwájú OLUWA ní Gibea, ní orí òkè OLUWA.
Ipìnlẹ̀ mẹ́rìnlá ni yóò dìbò láti yan ọmọ ẹgbẹ́ Democrat ti wọ́n ba fẹ́ ko dije nínú oṣù kọkànlá ọdun 2020 lásìkò ìdìbò.
20 Sẹ́rẹ́ 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 21 Sẹ́rẹ́ 2020 Oríṣun àwòrán, @kfayemi Àkọlé àwòrán, Ẹ̀yin ẹ máà wò ó, ó ṣeéṣe kí APC túká lẹ́yìn ìṣèjọ́ba Buhari!
Oríṣun àwòrán, okunu Àkọlé àwòrán, Orúkọ Abiku ni Okunnu tí mo ń jẹ nínú eré, inú orin Barrister ni mo sì ti ri - Wale Akorede Ọlọ́run mọọmọ gbé asiko yi wa fún wa ní."
Wo iye àwọn ìpínlẹ̀ tó fòfin de ìsìn àìṣùn ọdún ní ṣọ́ọ̀ṣì Oríṣun àwòrán, Getty Images Bi itankalẹ arun Covid-19 ṣe peleke si ni Naijiria, awọn gomina ipinlẹ kọọkan to fi mọ apapọ ẹgbẹ Kristẹni ni Naijiria wọgile ìsìn aisun ọdun tuntun, ti wọn maa ṣe lọdọọdun.
Ọlọrun, tí kò dá Ọmọ rẹ̀ sí, ṣugbọn tí ó yọ̀ǹda rẹ̀ nítorí gbogbo wa, báwo ni kò ṣe ní fún wa ní ohun gbogbo pẹlu rẹ̀?
Seyi Makinde: Ibùdó ìlera tó wà ní Idí Iroko-Adewole tí bàjẹ́ pátápátá
O gba awọn akanda ẹda atawọn alaabọ ara miran niyanju pe, ipenija kò yẹ kò sọni di alagbe ati ole.
" A kó ní sanwó oṣú ASUU láìjẹ́ pé wọ́n gba IPPIS- Ìjọba Àpapọ̀ Diego Maradona ṣiṣẹ́ abẹ lórí ẹ̀jẹ̀ tó dì sí i lọ́pọlọ lẹ́yìn ọjọ́ ìbí ọgọ́ta ọdún A ti gbé ìwádìí dìde lórí ìpànìyàn tó wáyé lásìkò ìwọ́de EndSARS- Ilé ẹjọ́ àgbáyé, ICC Oyinkan Abayomi, akọni obìnrin tó fi ìfẹ́ pa orúkọ ọkọ kejì dà sí ti ọkọ àárọ̀ Ikọlu naa ni ìkẹta to waye si awọn ileewe laarin ọsẹ meji pere, lasiko ti awọn ajijagbara n gbe igbesẹ lati fi opin si eto ẹkọ ni agbegbe ti wọn ti n sọ èdè Gẹẹsi lorilẹ-ede Cameroon.
Yóo wá ranti àìdára wọn nisinsinyii, yóo sì jẹ wọ́n níyà nítorí ẹ̀ṣẹ̀ wọn; wọn óo sì pada sí Ijipti.
Dafidi wà ní àlàfo tí ó wà ní ààrin ẹnu ọ̀nà tinú ati ti òde, ní ẹnu ibodè ìlú.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Coronavirus cases in Africa: Ijọba ipinlẹ Oyo ti kọ ẹgbẹsan irẹsi to jẹ iranwọ ti ijọba apapọ fi ransẹ si wọn.
Oríṣun àwòrán, Others Ijọba orilẹede Naijiria ti ni awọn ti jawọ ninu dida Iye le owo ti awọn elepo yoo ma ta epo bẹntirol lorilẹede Niajiria.
Osinbajo ni awon orile-ede ti Naijiria lo n ko iresi lodo won naa n sise lati mu edinwo ba ipese iresi ni.
Aya ọkunrin náà fi nǹkan dé e lórí, ó sì da ọkà bàbà lé e kí ẹnikẹ́ni má baà fura sí i.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Oyo NLC mú ìlérí rẹ̀ ṣẹ, ó bẹ̀rẹ̀ ìyanṣẹ́lódì 24 Èbibi 2019 Àkọlé àwòrán, Oyo NLC mú ìlérí rẹ̀ ṣẹ, ó bẹ̀rẹ̀ ìyanṣẹ́lódì Awọn oṣiṣẹ ijọba ipinlẹ Ọyọ ti bẹrẹ iyanṣẹlodi alainigbedeke lọjọ Ẹti.
Fun alaye, Alawẹ ni alaga igbimọ lọbalọba ni Ekiti, ta gbọ pe awọn ọba yoku kọ lati ba se ipade nitori pe wọn ni o kere si awọn ni ipo, ti ko si lẹtọ lati jẹ alaga le awọn lori.
Oríṣun àwòrán, @Chadwick Iroyin iku Boseman ti domi tutu si agbo ere sinima ti ọpọlọpọ awọn oṣere ati eekan lagbo ere sinima lagbaye si ti n kẹdun iku rẹ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Irokotọla: Báwo ló ṣe rọrùn láti fi àmì sí ọ̀rọ̀ yìí, ‘Irokotọla’?
Oríṣun àwòrán, AFP Joshua sọ pe 'Nigba ti yoo ba fi di ipari osu yii, boya a fẹ tabi a ko fẹ ẹ, koda ko si oogun oyinbo to wu ki wọn o ṣe, bi coronavirus se wá naa ni yoo se lọ'.
 Mo rin erin,  nitori pe aheso oro lasan ni oro naa.
Nígbà gbogbo tí mo bá ranti yín ni mò ń dúpẹ́ lọ́wọ́ Ọlọrun mi.
Nigba to n sọ ero rẹ lori igbesẹ fasiti Babcock naa, @Official_ubeets ni niwọn igba ti a ko ri ihooho eyikeyi ninu awọn akẹkọ naa, ti Jesu funra rẹ si sọ pe ẹni ti ko ba da ẹsẹ ri, ni ko kọkọ sọ okuta lu obinrin oni pansaga kan, ko yẹ ki wọn le akẹkọbinrin naa, ti ọga ileekọ fasiti Babcock ko ba si da ẹsẹ ri, ko jade sita.
Ni bayii, olukọni ikọ Super eagles ti gbe orukọ awọn agbabọọlu ti yoo ṣoju orilẹede Naijiria jade bayii.
 Ó tún ṣiṣẹ ́ ní ilé iṣẹ ́ ìgbóhùn-sáfẹ ́ fẹ ́  rock city 101."
ọkọ̀ ojú omi tuntun bẹ̀rẹ̀ iṣẹ́ Abiy Ahmed gba àmì ẹ̀yẹ̀ ti àláfíà lágbàáyé gẹ́gẹ́ bí ọmọ Africa Bó tilẹ̀ jẹ́ pé ìròyìn òfegè ni pé Buhari fẹ fẹ́ Sadiya, síbẹ̀ àwọn ọmọ Nàìjíríà ń ṣètò ìyàwò náà lórí ayélujára Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Kemi Lala: mo ń gbìyànjú láti mú inú òbí mi dùn Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Àwọn ọkunrin tí wọ́n sọ ara wọn di aṣẹ́wó ní ojúbọ àwọn oriṣa náà sì pọ̀ ní ilẹ̀ náà.
Gomina ipinle Abia, ogbeni Okezie Ikpeazu ati gomina ipinle Kano,  Abdullahi Ganduje, ti panupo ro awon omo orile-ede Naijiria lati lowo si awon iwa ti yoo fayegba ibasepo isokan ti yoo si tun mu idagbasoke ba oro aje orile-ede yii.
Abadofin Ile iwe giga Fasiti ti ijọba ni Wukari - 2019.
Ile ẹkọ girama yii ni akọkọ ladugbo Yaba nigba naa, to si ni ilegbe fun takọtabo akẹkọọ, Oyinkan si ni ọmọ Naijiria akọkọ ti yoo ṣiṣẹ olukọ nibẹ.
Ọjọ kọkanlelogun, oṣu kẹfa, ọdun yii ni Ọgbẹni Ajayi darapọ mọ PDP niluu rẹ, Kiribo nibi to ti dije ninu ibo abẹle fun ipo gomina ipinlẹ Ondo.
Oorun mu, ti oju ọjọ si dara laisi ifarahan ojo wẹli-wẹli kankan to lee ba eto ipolongo ibo naa jẹ.
Jonatani bá dáhùn pé, “Rárá o, kabiyesi ti fi Solomoni jọba!
    “Máṣe gbagbe ohun gbogbo tí mo bá ọ sọ wọ̀nyí ìwọ ọmọ mi.
Ó yẹ kí á máa ran irú wọn lọ́wọ́ kí á lè jẹ́ alábàáṣiṣẹ́pọ̀ pẹlu wọn ninu iṣẹ́ òtítọ́.
Wọ́n bá lọ sí Samaria, wọ́n sì kígbe pe àwọn aṣọ́nà láti ẹnubodè pé, “A ti lọ sí ibùdó ogun àwọn ará Siria, a kò rí ẹnìkan kan níbẹ̀, bẹ́ẹ̀ ni a kò gbúròó ẹnìkan kan.
Gege bi okan lara awon toro kan gbangban ninu igbimo to n sakoso idije Nigeria National League (NNL),  Lawrence Katken, so pe, idije saa 2017/2018 yoo bere lojo Abameta (Saturday).
Macron ṣapejuwe iṣẹlẹ naa ni ohun to ba ni ninu jẹ pupọ.
Nítorí ẹ farada ìbànújẹ́ gẹ́gẹ́ bí Ọlọrun ti fẹ́, kí ẹ má baà pàdánù nítorí ohun tí a ṣe.
Wọn fikun un wi pe, Adari ajọ NDDC naa ti wa ni ile iwosan kan bayii ni Abuja.
'Iṣẹlẹ ifipa bọmọde lopọ yoo tẹsiwaju niwọn igba ti awọn eeyan ko tii ṣetan lati maa sọ nipa rẹ.
Bí ó ṣe ri lójú yín , bẹ́ẹ̀ náà ló ri lójú ọ̀pọ̀ àwọn òṣèré Nollywood bi wan ṣe n ki Ijebu ni mẹ́sàn mẹ́wàá pé ó kú oríre ayẹyẹ ìgbéyàwó.
 kẹ ́ místrì únsọ nípa àwọn átọ ́ mù àti ìbáraṣepọ ̀ wọn pẹ ̀ lú àwọn átómù míràn , àgàgà pẹ ̀ lú àwọn ìní àwọn ìsopọ ̀ kẹ ́ míkà .
Iyawo meji ni o fẹ - Fatima Khalid ati Widada Babikar Omer.
Ugba je ki  awọn  ololufe omo orile ede Naijiria to wa ni Moscow, ni  Russia mo, ipo ti ijọba wa , ki o to lo si orile ede Naijiria.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù EndSars Protest: TB Joshua, Indaboski àtàwọn Wòlíì méjì míràn ti kéde wàhálà ìwọ́de sáájú 20 Ọ̀wàrà 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 24 Ọ̀wàrà 2020 Oríṣun àwòrán, Twitter, Facebook, AFP Ni asiko ti ọdun tuntun ba n kan ilẹkun gbọn-gbọn, tabi to ba wọle de, kii se ajeji mọ lati ri awọn ojisẹ Ọlọrun kan, ti wọn yoo sọ asọtẹlẹ nipa awọn nnkan ti yoo sẹlẹ ninu ọdun naa.
Ọmọ ọdún mẹ́wàá ń fọn fèrè lágbo àríyá Ìtàn ọmọ Afirika tó ló lówó jùlọ lágbàyéé rèé Ohun tí Adeleke sọ rèé nígbà tí ìgbẹ́jọ́ èsì ìdìbò gómínà Oṣun bẹ̀rẹ̀ Èmi ṣì ni Gómìnà ìpínlẹ̀ Ọṣun-Oyetọla Nigba to n sọ iriri rẹ fun akọroyin Punch, obinrin naa ni osu kẹwa ọdun 2018 to kọja, ni oun fi Leah silẹ ni ahamọ, nigba ti oun sa kuro ni agọ Boko Haram.
Nítorí pé àwọn eniyan wọnyi ti kọ̀ mí sílẹ̀, wọ́n ti sọ ibí di aláìmọ́ pẹlu turari tí wọn ń sun sí àwọn oriṣa tí àwọn, ati àwọn baba wọn, ati àwọn ọba Juda kò mọ̀ rí.
Jonatani tún mú kí Dafidi ṣe ìbúra lẹ́ẹ̀kan sí i, pẹlu ìfẹ́ tí ó ní sí i.
Barmasai pari ere to le ni kilomita mejilelogoji laarin wakati meji ati iṣẹju mẹwaa.
Èmi náà ni mo pa ìyá mi ki n ba jogún owo rẹ̀, ìbọn ni mo yin sí bàbá mi ti mo pa á.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Xenophobia: Alùpùpù ni wọ́n fi gbé epo pẹtiró wá dáná ṣun iléeṣẹ́ MTN 4 Owewe 2019 Awọn eeyan kan to n fẹhonu han dana sun ẹka ọọfisi ileeṣẹ ikansiraẹni lati orilẹede South Africa, MTN, to n bẹ ni agbegbe Bodija niluu Ibadan lalẹ Ọjọ Iṣẹgun mọju Ọjọru.
Abimeleki ati Fikoli, olórí ogun rẹ̀, sì pada lọ sí ilẹ̀ àwọn ará Filistia.
Níwọ̀n ìgbà tí ẹ ní ìmọ́lẹ̀, ẹ gba ìmọ́lẹ̀ náà gbọ́, kí ẹ lè jẹ́ ọmọ ìmọ́lẹ̀.
Ni ọdun 2008, wọn ran an lọ ẹwọn ewe fun ọdun mẹrin nitori o kopa ninu ole jija kan, ṣugbọn ọdun meji lo lo nibẹ.
Ajọ Eleto Idibo ni orilẹ-ede Naijiria, INEC, ti kede orukọ awọn oludije si ipo gomina ni ipinlẹ Oṣun, igbakeji wọn ati ẹgbẹ oselu wọn.
"Ilé ẹjọ́ yá lórí òfin CAMA tó fẹ́ gba àkóso ilé ìjọsìn, tẹ ẹ̀tọ́ aráàlú mọ́lẹ̀ - SERAP Ikú Williams Aanuoluwa lágbo òṣèré hú ọ̀pọ̀ ọ̀rọ̀ síta Adamu Adamu, Minista ètò ẹ̀kọ́ ti fi òfin àátẹ̀lẹ́ síta kí àwọn ilé ìwé lè wọlé Fadeyi ni: ""Ọjọ kẹtadinlogun, oṣu Keje, ọdun 2020 ni ọwọ tẹ ẹni ọdun mọkandinlogun ọhun ti ileeṣẹ ọlọpaa si fi oju rẹ lede, ṣugbọn o salọ mo wọn lọwọ ni ọjọ kọkanla, oṣu Kẹjọ, ọdun 2020."
bere eto ipolongo aare  niluu Uyo jẹ eyi
Ninu ifọrọwerọ naa, eyi to da lori ipo ti ijọ ọhun wa lasiko yii ti olori ijọ, Alfa Babatunde wa lọgba ẹwọn, ọmọ ijọ naa, to pe orukọ ara rẹ ni Yetunde salaye pe nkan ko dabi bo se n waye tẹlẹ rara.
Àjọ tó n mójútó ìpèsè òògùn ní America ti fọ́wọ́ sí lílo òògùn Ebola fí tọ̀jú Coronavirus Àyájọ́ òṣíṣẹ́ àti ìpèníjá ọjọ́ ọ̀lá f'óṣìṣẹ́ Nàìjíríà lẹ́yìn COVID-19 Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Megabite: Ilé-ìwé ni mo ti bẹ̀rẹ̀ orin kíkọ Ẹwẹ, àwọn oludari eto ilera yoo sepade lọjọ Ẹti lati jiroro lori ilana ti wọn yoo gbe nkan gba.
Yoruba World Assembly fikun pe Akintoye ti ja ọpọlọpọ ẹgbẹ to gbimọpọ yan an gẹgẹ bi adari, nitori naa kii ṣe adari wọn mọ.
Kete ti o ba ti kẹfin arun yii ni agbegbe rẹ ni ki ẹni naa ti tete gba ile iwosan lọ fun itọju to peye.
OLUWA wa tóbi, ó sì lágbára pupọòye rẹ̀ kò ní ìwọ̀n.
Àkọlé àwòrán, Àjọ ìsọ̀kan àgbáyé ní, àwọn ikọ̀ ọ̀daràn lágbàáyé ló ń kó Tramadol wọ ilẹ̀ Afrika láti ẹkùn gúúsù ilẹ̀ Asia Ní báyìí tí ìlòkulò Tramadol ń wáyé ní Nàíjíríà, ó nira púpọ̀ láti mọ ìdí tí wọ́n se gbé Tramadol sí abẹ́ àwọn òògùn olóró bíi oxycontin, morphineàtàwọn òògùn olóró míì bíi Cocaine ní orílẹ̀èdè Amẹ́ríkà.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Igbimọ oluwadi fẹ ki wọn o da awọn oṣiṣẹ JAMB to ja'le duro 14 Èrèlè 2018 Oríṣun àwòrán, @JAMB/Twitter Àkọlé àwòrán, Iroyin fidirẹmulẹ pe ejo ajoji kan mi miliọnu mẹrindinlogoji naira lọọfisi ajọ JAMB Igbimọ oluwadi ti wọn gbekalẹ lati tọ pinpin obitibiti owo to poora l'ọọfisi ajọ JAMB ti d'aba wipe ki wọn o da awọn ti aje iwa naa ṣi mọ lori duro lẹnu iṣẹ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Apapa Accident: Ọ̀ga RRS ní kò sí ẹ̀mí tó nù lẹ̀yìn ti agolo akẹ́rù wó lu ọkọ̀ 16 Òkùdu 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 17 Òkùdu 2019 Oríṣun àwòrán, @chammyashy Àkọlé àwòrán, Apapa Ọga ẹka ileeṣẹ ọlọpaa to n koju iṣẹlẹ oju popo (RRS) Tunde Disu ti ni agolo akẹru nla to wo lu ọpọlọpọ ọkọ ni agbegbe Tin Can Island, Apapa ni ipinlẹ Eko ni pe ajọ LASEMA ko pa ẹnikankan.
“Obinrin ki ṣe Ẹrú tabi Ẹrù ti wọn njẹ mọ́ Ogún – Àsikò tó lati Dáwọ́ Àṣà ṣì Ṣúpó Dúró” 
Oríṣun àwòrán, others ''Gbogbo awọn onibara wa lo n sọ kaakiri pe ọfẹ ni ijọba n gbe mita ina mọnmọna fawọn eeyan, ṣugbọn niṣe ni wọn dakẹ lori ọrọ tariifu tuntun,'' oṣiṣẹ Disco lo sọ bẹẹ.
Ẹgbẹ agbabọọlu Swansea City na iye owo ti o to milliọnu mejidinlogun pọun lati ra Andre Ayew lọjọ ti katakara awọn agbabọọlu wa s'opin ni osu kini, ọdun 2018.
Kin ni ọjọ iwaju Saraki ni agbo oselu Naijiria Niba yii to ti wa di ‘Ọmọwale’ ni PDP, kin ni yoo jẹ atunbọtan rẹ nibẹ?
Nigbà ti Arabinrin Uzamat Yusuf Akinbile wa lati apa ariwa Naijiria.
Tinubu lasiko to se abẹwo si adari ẹgbẹ afẹnifẹre, Pa Reuben Fasọranti ti wọn ni awọn agbẹbọn pa ọmọ rẹ abileko Funke Ọlakunrin ni opopona Ọrẹ ni ipinlẹ Ondo sọrọ ibanikẹdun.
Ile ẹjọ magisireti ni Igbosere Ileeṣẹ iroyin The Nation.
O Fagunwa Ọdun 1903, eyi to jẹ ọdun marundinlọgọfa sẹyin, ni wọn bi Daniel Ọlọrunfẹmi Fagunwa nilu Oke Igbo to wa nipinlẹ Ondo ni guusu Naijiria.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Police arrest: Kà nípa ohun mẹ́wàá tí o ní láti ṣe bí ọlọ́pàá bá mú ọ 13 Èbibi 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 14 Èbibi 2019 Oríṣun àwòrán, @PoliceNG Ileeṣẹ ọlọpaa ti bọ sita pẹlu awọn igbesẹ to yẹ fun araalu lati gbe lasiko ti awọn ọlọpaa ba fẹ mu wọn.
"Oríṣun àwòrán, Facebook/Seyi Makinde Bakan naa ni Makinde sọ pe "" A ti fẹnu ọrọ jona pe ki awọn ọmọ ẹgbẹ akọya ilẹ Yoruba, OPC, Miyetti Allah, tii se ẹgbẹ awọn darandaran ati awọn osisẹ agbofinro yoku wa ninu igbimọ eleto aabo kan ti yoo wa fun ipinlẹ mẹfẹẹfa nilẹ Yoruba, lati wa ọna ti adinku yoo fi ba eto aabo to mẹhẹ."
Bi o tilẹ jẹ pe Ajọ EFCC ti sọ wi pe awọn ko gbegi le ile rẹ to wa ni Ikoyi, Saraki ni EFCC tun rawọ le ẹsun ti ile ejo fi da oun lare ni.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Akomolede ati Asa: Mọ̀ si nípa àwọn ọ̀nà tí Yorùbá ń gbà ran ara wọn lọ́wọ́ Ologbodiyan ni: 'Ibanujẹ lo jẹ fun wa lati ri orilẹede to wa ni iṣọkan nigba ti Aarẹ Buhari gba ijọba, ti wa da yẹpẹyẹpẹ bayii, ti wọn si bẹrẹ si ni pa awọn eniyan.
Fọ ọwọ rẹ nigba gbogbo pẹlu omi ati ọṣẹ.
Jesu wá, ó mú burẹdi, ó fi fún wọn.
Akanbi mi, má fọ̀ ọ́, mo wà pẹ̀lú ẹ; Ẹni tó ṣe ìgbéyàwó olórùka ló l'ọkọ- Lizzy Anjorin Háà, àṣé Pastor Adeboye kò léè dá èékánná ara rẹ̀ gé, àwọn ọmọ Nàìjíríà kan pariwo Ta ni Ebuka Obi-Uchendu tó ń gbàlejò BBNaija 2020?
    “Báyìí ni mo ṣe tí mo kó ọ̀ràn mi lé Ẹlẹ́dàá mi lọ́wọ́, nítorí nínú ohun gbogbo tí ènìyàn lè fi ẹ̀yìn tì ni òde aye kò sí èyí tí ó lágbára bí Ẹlẹ́dàá ẹni.
Idi ree ti obinrin takuntakun kan, Lola Omolola se da ẹgbẹ agbarijọpọ awọn obinrin kan silẹ lori ayelujara ti wọn n pe ni FIN, to si ni ọmọ ẹgbẹ to fẹẹ to ẹgbẹrun lọna ọgọrun lori ikanni Facebook nikan.
– Seyi Makinde Àwọn oun àjòjì tó ṣẹlẹ̀ nígboro níbi àjọyọ̀ ìṣẹ́gun Buhari Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Issa Aremu: ṣàlàyé kíkún nípa èròńgbà ẹgbẹ́ Labour to bá jáde Amọṣa, gomina Ibikunle Amosun ti fesi ṣaaju pe oun yoo yẹyẹ awọn ẹgbẹ oṣiṣẹ to ba gbiyanju tabi san aṣọ bẹẹ ṣoro ni ipinlẹ naa.
Buhari ni aarẹ orilẹ-ede karun un ti yoo sọrọ nibi to ti sọrọ lori bi oju ọjọ ṣe n yipada.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Marosẹ Ibadan si Eko: Fashola sọ pe asepati rẹ yoo se akoba ọrọ aje 24 Sẹ́rẹ́ 2018 Oríṣun àwòrán, AFP Àkọlé àwòrán, Ijọba gbọdọ pese owo to towo lati s'atunse marosẹ Ibadan silu Eko Igbimọ ile asoju-sofin ilẹ wa to wa f'ọrọ isẹ ode, eyiti Asofin Toby Okechukwu ko sodi, gbalejo minisita fun ohun amusagbara, isẹ ode ati ilegbe, Babatunde Fasọla lana, ẹni to wa sọ okodoro ọrọ nipa ohun to rọ mọ isẹ atunse opopona marosẹ Ibadan silu Eko ati igbesẹ kikọ afara Niger keji.
"m ni ojú mi déédé fọ́ níbi tí mo ti ń darí ọkọ̀ ni Ọrẹgun Ikẹja -LASTMA Yesufa Mo ti kó kúrò nílé Olu Jacobs rí lẹ́ẹ̀mejì- Joke Silva ""Mo fẹ́ pa ara mi torí ojú àbùkù tí wọn ń fi wò mí pé mo fi iṣẹ́ abẹ bímọ"" Bi ogun naa si ṣe jẹ manigbagbe lo mu ka ṣe akojọpọ awọn koko nnkan pataki to yẹ kẹ mọ nipa ogun naa."
Ilẹ̀ ṣú, ilẹ̀ sì tún mọ́, ó di ọjọ́ kẹta.
”OLUWA tún dá a lóhùn pé, “N kò ní pa á run nítorí ti eniyan mẹ́wàá.
Ní ọjọ́ náà,OLUWA yóo kọrin nípa ọgbà àjàrà dáradára kan pé,
Igi Ìrònú ni ó fún ìlú náà lórúkọ, abamì igi ni igi Ìrònú, bàbá mi sì ti ń sọ̀rọ̀ rẹ̀ fún mi kí ó tó di pé títán dé báa, tí èmi wá gun orí oyè.
Wo bí ètò ìdìbò abẹ́lé APC yóò ṣe lọ ní ìpínlẹ̀ Ondo lónìí Afurasí tí Ọlọ́pàá ní ó pa Barakat, Grace àtàwọn míì l'Akinyele ti sọ̀rọ̀ pé.
Oríṣun àwòrán, Instagram/lisahannamp Oríṣun àwòrán, Instagram/lisahannamp Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Ìtàn Mánigbàgbé: Mọrèmi Àjàṣorò fi ọmọkùnrin rẹ̀ kanṣoṣo rúbọ fún odò nítorí ìlú20 Èrèlè 2019 BBC 100 Women: Obìnrin tí o lasẹ lórí kí ọkùnrin fẹ ìyàwó kejì20 Bélú 2018 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Nitori naa ko si ẹni to le e sọ ẹni ti yoo bori eto idibo ipinlẹ Ondo, afi esi idibo ti ko ni magomago ninu ni yoo fi ero awọn eniyan han.
'Orin Olamide, Poverty Die ti di àdúrà àràárọ̀ fún mi' Àwọn olórin Nàìjíríà kẹ́dùn ikú ọmọ DBanj Ọrọ inu orin tuntun kan ti wọn pe akọle rẹ ni Logo Benz lo n dagboro ru o.
" Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Kò sí èèyàn kánkan tó kù nílé tó wó ní Ibadan- NEMA Kínni ó ń fa ilé wíwó?
Lodun 2016, ti aare Bongo tun pada wole gege bi aare orile ede naa ni awon alatako ti n fi esun kan ijoba re pe , o se mago-mago nipa eto idibo re.
Josh Kroenke lasiko to n sọrọ lorukọ igbimọ alaṣẹ ẹgbẹ agbabọọlu Arsenal ati Kroenke Sports and Entertainment so pe: A dupẹ lọwọ Unai ati awọn akẹgbẹ rẹ pupọ nitori pe wọn gbiyanju lati da ogo Arsenal pada de ipele to yẹ ti a beere fun."
Nítorí mo ní ìrètí pé n óo lè dúró lọ́dọ̀ yín fún ìgbà díẹ̀, bí Oluwa bá gbà bẹ́ẹ̀.
Ní ìgbà yìí wá, ó ti fi èrò ọkàn-an rẹ̀ hàn pẹ̀lú àwọn ajàfẹ́tọ̀ọ́ ìlú láti Hong Kong àti Taiwan lórí kókó ọ̀rọ̀ tó jẹ mọ̀, òmìnira ọ̀rọ̀ sísọ, ìdá-gbé nǹkan ṣe, ìjọba àwarawa àti àwọn kókó tó jọ mọ́ ọ ní ìpàdé ìta gbangba.
Àṣeyọrí Anthony Joshua fi hàn pé owó tí à ń ná lórí eré ìdarayá kò lọ lásán - Dapo Abiodun Ajọ NCDC sọ pe igba akọkọ ree tawọn to larun naa yoo pọ to bayii ni nkan bi oṣu mẹrin sẹyin.
Lẹ́yìn ìṣẹ̀lẹ̀ yìí, ọ̀pọ̀ àwọn ọdọ́ àti àwọn ajàfẹ́tọ ọmọniyan ló tú sigboro láti fẹ̀hónú hàn lórí ọ̀rọ̀ náà.
 Àwọn fíìmù kan máa ń gbe ẹ ̀ sìn kìrìsítẹ ́ nì àti mùsùlùmí lẹ ́ sẹ ̀ nígbà tí àwọn kan ń polongo ìhìnrere .
awon eniyan nigbagbọ ninu Olorun pe ko si ohun ti Olorun ko lee se.
Bi awon  janduku ati agbesunmomi naa se foju gan an ni  gomina ati awon ẹmẹwaa rẹ,ni won fẹsẹ fẹẹ , ti
Ipa ti o ko ninu ija fun ominira Ageria fun un ni iyi nla lagbaye bi o tilẹ jẹ wi pe ero tirẹ ati aato maa n tako ohun ti awọn alawọ funfun n fẹ.
Koda, ijọba ti ṣeto ilana aatẹlẹ fun awọn Olukọ lasiko yii ki ọsan le so didun fun awọn akẹkọọ ipinlẹ Oyo Alaafin Oyo kò dàgbà jù fún mi, ohun tó wù mí ní mo ṣe pẹ̀lú ayé mi- Olori Aanu Mo ti bẹ̀rẹ̀ sí ń bá àwọn tí a jọ díje nínú ìdìbó abẹ́lé sọ̀rọ̀ kí àláàfíà léè jọba - Akeredolu Kanye West ti bẹ̀rẹ̀ ìpolongo àti díje dupò aàrẹ ilẹ̀ Amẹrika Wo àwọn nkan tó yẹ́ kí o mọ̀ nípa 'Awawa Boys', ọ̀kan lára ẹgbẹ́ òkùnkùn tó n dá Eko rú Adarí àjọ NDDC, Pondei ṣetán láti sọ ohun tó mọ̀ nípa ìwàdíì tó bá ti gbádùn- NDDC Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Funmi Adewara: Tele Medicine' ní a fi ń ṣàyẹ̀wò èèyàn ìdá ọgọtá láti dènà ìtànkálẹ̀ Covid Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Fídíò, End SARS, End SWAT: Ó pé mi bí SARS kò ṣe sọ mí dolówọ́- Fulani Kwajafa17 Ọ̀wàrà 2020 Fídíò, Soyinka Cancer: Àṣe ara mi ni iso ti n run gbogbo bí mo ṣe n ṣèrànwọ́ lórí jẹjẹrẹ27 Bélú 2019 Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
ni ekun Gusu lorile ede Naijiria nibi ti awon daran-daran ti se n fi ojoojumo
Fọnran fidio yi mu ki awọn akẹkọ fasiti naa faraya ti wọn si ṣigun lọ ba awọn to hu iwa yi.
Juda fi àwọ́nsìn ewúrẹ́ náà rán ọ̀rẹ́ rẹ̀, ará Adulamu, sí Tamari, kí ó le bá a gba àwọn ohun tí ó fi dógò lọ́wọ́ rẹ̀, ṣugbọn kò bá a níbẹ̀ mọ́.
Ní àkókò tí wọ́n kọ́ bẹ̀rẹ̀ sí pa wọ́n, Jonatani ati ọdọmọkunrin yìí pa nǹkan bí ogún eniyan.
Ẹ kò kọ ohun tí ó jẹ́ ìdánwò fun yín ninu ara mi, bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò fi mí ṣẹ̀sín, ṣugbọn ẹ gbà mí bí ẹni pé angẹli Ọlọrun ni mí, àní bí ẹni pé èmi ni Kristi Jesu.
Lẹ́yìn náà, ó mú mi wá sí ibi gbọ̀ngàn inú, lẹ́bàá ẹnu ọ̀nà ìhà gúsù, ó sì wọn ẹnu ọ̀nà náà, bákan náà ni òòró ati ìbú rẹ̀ pẹlu àwọn yòókù.
Ṣoworẹ ṣalaye ọrọ yii lasiko to fi n ba BBC News Yoruba sorọ lori ikanni ayelujara facebook.
Ile ẹjọ to gaju l'orilẹede India sọ pe 'bẹẹni''.
Àkọlé àwòrán, Aarẹ Buhari ni oun ṣetan lati ṣe ijọba lai fi ti ẹ̀yà kankan ṣe Àárọ ọjọ Aiku ni iyawo aarẹ Aisha Buhari fi ẹhonu han nitori pe o ni awọn idibo abẹle ẹgbẹ oṣelu APC ko lọ deede.
" Àpẹẹrẹ ni fíìmù baba latin , òǹṣèrè kan tí ó gbajúmọ ̀ nínú fíìmù yorùbá tí ó pè ní , "" mr president "" tàbí èyí tí òṣèré inú fíìmù òyìnbó ní ilẹ ̀ nàíjáríà kan tí a ń pè ní nkem owoh ṣe ."
Ìdí nìyí tí ó fi sọ pé,‘A kò fi í sílẹ̀ ní ibùgbé àwọn òkú;bẹ́ẹ̀ ni ẹran-ara rẹ̀ kò díbàjẹ́.
Koda, Olu ijọ naa ti kuro ni ile LaVey ni San Francisco, o si ti wa ni ilu New York.
3 Ògún 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 4 Ògún 2020 Oríṣun àwòrán, OTHERS Kii ṣe tuntun mọ pe ile itaja Shoprite ti n gbaradi lati kogba kẹru rẹ kuro ni Naijiria, bo tilẹ jẹ pe ako tii le fi idi rẹ mulẹ, ṣugbon iroyin to n lọ ni igboro sọ pe olowo kan, Tayo Amusan ni yoo gba iṣakoso ileeṣẹ naa.
Gehasi súnmọ́ ọn láti tì í kúrò, ṣugbọn Eliṣa wí fún un pé, “Fi obinrin náà sílẹ̀, ṣé o kò rí i pé inú rẹ̀ bàjẹ́ gidigidi ni?
Aba yii ko wa fun ipese owona fun gbogbo ọdun 2018, amọ yoo se iranwọ fun ijọba ilẹ Amerika lati maa ri owo gbọ bukata rẹ titi wọ idaji osu to n bọ.
" Fayemi ni oun to yẹ ka maa sọrọ rẹ ni bi a ṣe lee ri i daju pe awọn ikọ alaabo n ṣe iṣẹ wọ laarin alakalẹ ijọba awa ara wa.
Ará, à ń rọ̀ yín pé kí ẹ máa gba àwọn tí ń ṣe ìmẹ́lẹ́ níyànjú; bẹ́ẹ̀ náà ni kí ẹ máa ṣe sí àwọn tí ó ní ìrẹ̀wẹ̀sì ọkàn; ẹ máa ran àwọn aláìlera lọ́wọ́; ẹ máa mú sùúrù pẹlu gbogbo eniyan.
Awọn papakọ ofurufu maraarun ti yoo bẹrẹ iṣẹ ni ti Murtala Muhammed nilu Eko, Nnamdi Azikiwe tilu Abuja, Malam Aminu Kano tilu Kano, Omagwa tilu Portharcourt ati Sam Mbakwe tilu Owerri.
Yomi Shogunle di èro Nkalagu lórí ọ̀rọ̀ tó sọ lórí Twitter
 síbẹ ̀ síbẹ ̀ , ó ti ń dínkù .
19 Owewe 2020 US election 2020: Olórí àwọn òṣìṣẹ́ Trump sọ pé ìjọba ilẹ̀ America kò le kápá coronavirus26 Ọ̀wàrà 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Gbọ́ igbe mi, Ọlọrun,fetí sí adura mi.
 Ṣàngó jẹ ́ òrìsà takuntakun kan gbòógì láàárín àwon òrìsà tókù ní ilèe yorùbá .
Nígbà tí Gaali ati àwọn ọkunrin tí wọ́n wà pẹlu rẹ̀ bá sì jáde sí ọ, mú wọn dáradára, kí o sì ṣe ẹ̀tọ́ fún wọn.
Owo orilẹede naa Rand to ti gberu si lẹyin tawọn eeyan gbọ pe Aarẹ Zuma yoo kọwe fipo silẹ lọjọ kejila oṣu keji ja walẹ nigba ti agbẹnusọ ijọba sọ pe irọ ni iroyin SABC.
Johesu n bèèrè fún ìbádọ́gba owo láàrin àwọn oṣiṣẹ ilera to ku ati awon Dókítà.
Mustapha sọ pe bi nkan ṣe wa ni asiko yii naa ni yoo ṣi wa titi di ọjọ kinni, oṣu Kẹfa, ọdun 2020.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù FIFA fòfinde akoọ́nimọ̀ọ́gbá Super Eagles nigbakan ri Samson Siasia 16 Ògún 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Iwadi naa ni ajọ FIFA se pelu ifọwọsọwọpọ awọn ẹka miran ninu ajọ bọọlu alafẹsẹgba.
Ati pe Onnoghen mọ ohun to le ṣẹlẹ si aikede dukia oun gẹgẹ bi adajọ agba ni Naijiria.
Nígbà tí Apakiṣadi di ẹni ọdún marundinlogoji ni ó bí Ṣela.
Ẹgbẹ agbabọọlu Lesotho ti wọn n pe ni Crocodiles ta ọmi 1-1 pẹlu Sierra Leone l'Ọjọru ninu ifẹsẹwọnsẹ lati pegede fun idije 2021 AFCON.
Ní àkókò yìí kan náà, wọ́n tú okùn lára àwọn ajẹ̀ tí wọ́n fi ń tukọ̀.
àwọn ọmọ Kerosi, àwọn ọmọ Siaha ati àwọn ọmọ Padoni;
Oríṣun àwòrán, Others Ìyẹn nìkan kọ́ oo, bí ẹlẹkún ṣe ń sunku bẹ́ẹ̀ ni aláyọ̀ ń yọ, ẹyi lo dífa fún ọmọ binrin kan tó wa ẹkún mu bi omi nítori pe wọ́n le Erica kúrò nile ẹgbọ́n agbà Ẹkún gidi ni ọmọbìnrin yìí ń sun lẹ́yìn ti wọ́n le Erica kúrò nilé ẹlẹgbọ̀n àgbà Nínú fọ́nran náà ni ọmọbinrin kan ti n sùnkun tó sì bẹ̀rẹ̀ sí n'ṣépè fún Laycon.
Nínú wọn ni a ti rí Àjànàkú, Erinmi lókun, Ọmọ́le Àmúùgbàngba bíu ẹkùn, S.
O tun wa ro ijoba apapo lati
Adájọ́ Nasir Ajana tó dárí bíbojú wo ìwe onídùró náà tí wọ́n fi ránsẹ́ níwájú ilé ẹjọ́ gíga ti ìlú Lokoja dá ẹjọ́ rẹ̀ lórí àrídájú tó wà nínù onídùró náà gẹ́gẹ́ bí agbẹjọ́rò rẹ̀, Agbẹjọ́rò àgbà Olóyè Mike Ozekhome se fi sọwọ́ sí ilé ẹjọ́.
Ìran tí Daniẹli Rí Nípa Àgbò ati Ewúrẹ́.
Alukoro fun ile iṣẹ ọlọpaa naa to ba BBC Yoruba sọrọ wipe ṣe gbe oku Khadijat sinu ile fun ọjọ mẹfa pe fun ifurasi.
Ọ̀pọ̀lọpọ̀ ijó àti eré ìdárayá ni àwọn èwe fi dá àwọn akópa lára yá.
Lori owo awọn olukọ to jẹ oṣiṣẹ fẹhinti, Ṣeyi Makinde ṣe ileri lati fi owo oṣu rẹ gẹgẹ bii gomina gbọ bukata wọn.
Ẹyọ ẹnìkan ṣoṣo ni eniyan kan lè dojú ìjà kọ,nítorí pé eniyan meji lè gba ara wọn kalẹ̀.
N ó máa bọ̀wọ̀ fún àwọn ara ilé ìyàwó mi, ẹni tí o ṣe àfojúdi sí àwọn obi aya rẹ̀ ti fi ara rẹ̀ gégùn-ún, ẹni tí o fi àna rẹ̀ bu ti sọ ara rẹ̀ di ẹni èpè.
Pé tí oúnjẹ bá ti láta fẹ́ẹ́rẹ́fẹ́ báyìí, àwọn a yáa yẹra fún un.
lẹ ́ yin àkọ ́ kọ ́ gba àjẹsára yìí lẹ ́ ẹ ̀ mẹta , àyẹ ̀ wò ẹ ̀ jẹ ̀ lè tẹ ̀ le láàárìn oṣù kan sí mẹrin fún àrídájú iṣẹ ́ rẹ ̀ , tí wọ ́ n ń pè ní ìdènàn àìsàn jẹ ̀ dọ ̀ jẹ ̀ dọ ̀ b lójú pẹpẹ áńtíjẹ ́ nì , agbóguntàìsàn tí ó ju 100 miu / ml lọ .
Àwọn ọmọ rẹ̀ gbé e sinu ọkọ̀ tí Farao fi ranṣẹ sí i pé kí wọ́n fi gbé e wá, wọ́n sì kó àwọn iyawo wọn ati àwọn ọmọ wọn lọ́wọ́ pẹlu wọn.
ati lati tun lee ta ounje si oke okun.
Kálukú ló mọ ìbànújẹ́ ọkàn ara rẹ̀,kò sì sí àjèjì tí ń báni pín ninu ayọ̀.
Wọ́n ní àwọn sójà yìí ló pa obìnrin kan àti àwọn ọmọ rẹ̀ méjì ní orílẹ̀-èdè Cameroon.
52301 qumran jẹ ́ plánẹ ́ tì kékeré ní ibi ìgbàjá ástẹ ́ rọ ́ ìdì .
O pari ọrọ rẹ pe eredi gbogbo rogbodiyan naa ko ṣẹyin bi wọn ṣe fi oun jẹ oye Adele, eyii ti Owa ilu Idanre sọ pe o lodi si aṣa ilu naa.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ọ̀kan lára olùwọ́de tó fara gbọgbẹ́ ní Lekki jáde láyé - Sanwo-Olu Kò sí olùwọ́de tó kú ní Lekki - Sanwo-Olu N kò lọ́wọ́ nínú ìpànìyàn, kò dáa bí wọn ṣe lo ọta ìbọn ní Lekki - Tinubu Ọjọ́ Ìsẹ́gun di ọjọ́ ìbànújẹ́ fún ọ̀pọ̀ ìdílé ní Nàíjíríà torí òkú tó ṣùn Ọ̀dọ́ 30 ń gba ìtọ́jú lọ́wọ́ nílé ìwòsàn torí ọ̀gbẹ́ ìbọn ní Lekki - Sanwo-Olu ṣàlàyé Àwọn ṣọ́jà ṣíná ìbọn bolẹ̀ ni Lekki Tollgate Àwọn ọlọ́dẹ darapọ̀ mọ́ ìwọ́de #EndSARS l'Osogbo, wọ́n ní kò sáyè fún jàǹdùkú mọ́ Awọn eeyan kan tisẹlẹ naa soju wọn salaye pe, awọn janduku naa bẹrẹ ikọlu yii pẹlu sisọ okuta sinu ile naa, ko to di pe wọn da epo bẹntiro si lara, ti wsn si jo kanlẹ.
Idahun si eyi atawọn nkan mii ni yoo sọ ibi ti wọn yoo ti tọju ẹni bẹẹ fun aisan Covid19.
Èdè la fi ń kọ tàbí sọ ìtàn orísìrísi, ìbáà jẹ́ ọmọdé tàbí àgbà.
O ni mi o lọ si ibi kankan, ọmọ Eko ni mi, eminaa si ni Asiwaju ilu Eko."
Wọ́n pé ọdún méjìlá báyìí Ohun mẹ́wàá pàtàkì nípa Maradona àti ìbáṣepọ̀ rẹ̀ pẹ̀lú ẹlẹ́sẹ̀ ayò Diego Costa rèé Ọmọbìnrin tó tayọ nínú ìdànwó WAEC ọdún 2019 pẹ̀lú A1 méje ti kú Àwọn olóṣèlú, àti àwọn Ọba n gbàbọ̀dè fún ìpínlẹ̀ Ekiti lórí ọ̀rọ̀ àwọn tó n fi ipá bánilòpọ̀- Kọmísọ́nnà ètò ìdájọ́ Elon Musk, Ọ̀gá àgbà iléeṣẹ́ SpaceX, Tesla CEO ń bá Bill Gates du ipò ẹni tó lówó jùlọ ṣèkejì lágbayé Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Adeyeye Ile Ife: Kílódé tí Ọọni Ife, Oba Ogunwusi kò fi gbọdọ̀ rí ọmọ rẹ̀ tuntun títí di ẹ̀yìn oṣù mẹ́fà?
O fi kun pe awọn eeyan kan ti ara n ni pẹlu idagbasoke ti iṣejọba gomina Makinde n ṣe lo n fina ahesọ iroyin wahala naa ti ko waye.
Ijoba ipinle Yobe lo fun minista naa ni akosile oruko, ojo ori ati kilaasi awon akekoobinrin naa lekunrere ni eyi ti awon igbimo eto eko ipinle Yobe naa gba pe ooto ni.
Ọkunrin náà wí fún mi pé, “Ìwọ ọmọ eniyan, OLUWA Ọlọrun ní, ‘Àwọn òfin pẹpẹ nìwọ̀nyí, ní ọjọ́ tí a bá gbé e kalẹ̀ láti máa rú ẹbọ sísun lórí rẹ̀ ati láti máa ta ẹ̀jẹ̀ sí i lára, 
Busola Dakolo: Ẹ̀sùn tí mo fi kan pásítọ̀ ìjọ COZA ṣì dúró digbí
Ọba Abdulrasheed sọ èyi di mímọ nínú fọ́nran kan to ṣe sita loni ọjọ aje láti sọ idí ti ó fi máa n gbe ìgbésẹ̀ ti òun máà ń gbé àti ìhà ti ó ń kọ si ìṣẹ̀lẹ̀ láwùjọ.
Oríṣun àwòrán, AFP Àkọlé àwòrán, Wọn ti rọ àwọn to ní sọọbu lati tí ibusọ wọn fun ìgba diẹ lkyìn ti \\iṣẹlẹ̀ náà ṣẹlẹ, bákan náà ní ètò ààbò tún gbópọn sí lágbègbè náà.
Ile akede Naijiria (Voice of Nigeria)
àní, àwọn ìlú tí ó wà ní orí ilẹ̀ tí ó tẹ́jú ati gbogbo ìjọba Sihoni ọba àwọn ará Amori, tí ó jọba ní Heṣiboni, tí Mose ṣẹgun, pẹlu gbogbo àwọn olórí ilẹ̀ Midiani.
23 Àti báyìí ni òun ti gbé ète àrékérekè kan kalẹ̀, ní ríro láti pa iṣẹ́ Ọlọ́run run; ṣugbọ́n èmi yíò beerè èyí ní ọwọ́ wọn, yíò sì padà di ìtìjú àti ìdálẹ́bi fún wọn ní ọjọ́ ìdájọ́.
World Autism Day: Ojojúmọ ní mọ ń kẹ́kọ̀ọ́ lára ọmọ mi to jẹ akanda
ati pé, tìrẹ, OLUWA ni ìfẹ́ tí kì í yẹ̀.
Àwọn ọ̀pá náà gùn tóbẹ́ẹ̀ tí wọ́n fi lè rí orí wọn láti ibi mímọ́ jùlọ, ṣugbọn wọn kò lè rí wọn láti ìta.
Ààrẹ Buhari sọ̀rọ̀ ọ̀hún nínú àtẹ̀jáde kan tó ti ọwọ́ olùrànlọ́wọ́ àgbà lórí ìgbóhùn sáfẹ́fẹ́ àti ìpolongo rẹ, Garba Sheu jadé, pẹlu arọwa sàwọn Musulumi lati lo àsìkò àjọyọ̀ ọdun ileya yìí láti wà ni ìrẹ̀lẹ̀ ọkan àti lati yẹ ara wọn wò.
 Ó jẹ ́ olóòtu ìwé-ìróyìn kan tí ó ń jẹ ́ ní avanti ṣùgbọ ́ n ní 1914 , ó dá ìwé-ìroyìn tirẹ ̀ sílẹ ̀ .
Ikú mú Steven tó lọ dẹ́nu ìfẹ́ kọ olólùfẹ́ rẹ̀ lábẹ́ omi lọ Mi ò fẹ́ dá sí ìjà Toyin ati Lizzy!
 Ìtàn ìwáṣẹ ̀ kún fún gbígba ohun kan gbọ ́ láìwádìí , ọ ̀ wọ ̀ wà fún wọn , wọ ́ n ṣáábà máa ń jẹ ́ ìmọ ̀ nípa Ọlọ ́ run àti ọ ̀ nà tí a ń gbà ṣe ẹ ̀ sìn .
Wọn kò bá ẹnikẹ́ni sọ̀rọ̀ ìyìn rere àfi àwọn Juu nìkan.
MTN àti BBC World Service bẹ̀rẹ̀ àjọṣepọ̀ lórí ìròyìn ìṣẹ́jú kan BBC Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ibadan Death: Àwọn ará àdúgbò Akinyele ké sita lórí iṣékúpani tó ń wáyé ní ìlú Ibadan.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Akure Explosion: Bọ́mbù ni, bọ́mbù kọ̀ ọ́!
Ṣùgbọ́n síbẹ̀síbẹ̀, kì í ṣe ìgbà gbogbo ni mo ń rí ààyè láàrin àwọn ọmọ ènìyàn, nítorí bí ọmọ aráyé kò bá ti fi ààyè sílẹ̀, bí ó ti wù tí mo sa ipá tó n kò lè rí ààyè láàrin wọn.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Kayefi BBC Yorùba: Bàbá ọmọ, Mọ́ṣúárì, Ọlọ́pàá kẹ́jọ́ rò nípa òkú ọmọ tó pòórá Asẹyinwa-aṣẹyinbọ, Ọmọyẹ, to ti balaaga to ẹni ọdun ogun ọdun ri oyun apete he, lo ba loyun oge, kẹtẹkẹtẹ ba ku, ni iso ba pin.
Jairi ọmọ Manase gbógun ti àwọn ìlú kan, ó sì gbà wọ́n.
Ọba Adewale lo fi ọrọ naa lede loju opo Instagram rẹ, nibi to ti sọ pe oun ni alaṣẹ lori gbogbo awọn oriṣa.
Ẹ fi ojúlówó turari sí ọ̀nà kọ̀ọ̀kan, kí wọ́n lè fi wọ́n rú ẹbọ sísun sí OLUWA gẹ́gẹ́ bí àmì fún ìrántí.
Bí mo bá jẹ oúnjẹ pẹlu ọpẹ́ sí Ọlọrun, ẹ̀tọ́ wo ni ẹnìkan níláti bá mi wí fún ohun tí mo ti dúpẹ́ fún?
Awọn apari gbàgbọ pé púpọ nínú awọn to ṣe agbejade awọn nkan gidi lagbaye, apari ni wọn.
Won ni ki adari ajo naa kuro lenu ise kiakia.
’ Bẹ́ẹ̀ ni yóo sì rí.
Samsoni bá gbá àwọn òpó mejeeji tí ó wà láàrin, tí ilé náà gbára lé mú, ó gbé ọwọ́ ọ̀tún lé ọ̀kan, ó gbé ọwọ́ òsì lé ekeji, ó sì fi gbogbo agbára rẹ̀ tì wọ́n.
Babalawo Jongodo ni iṣẹṣe ni gbongbo eeniyan ati pe o dara ki a mu imọ nipa ọdun naa kọ awọn ewe yoo mu ki ato ati idurodeede wa lawujọ; yoo si din awọn iwa kotọ gbogbo ku lawujọ.
Nígbà tí Jesu wà ní Bẹtani, bí ó ti jókòó tí ó fẹ́ máa jẹun ní ilé Simoni tí ó dẹ́tẹ̀ nígbà kan rí, obinrin kan wọlé wá tí ó mú ìgò ojúlówó òróró ìpara olóòórùn dídùn kan tí ó ní iye lórí lọ́wọ́.
Lẹ́yin ti o pada lọ si ilé ijọsin láti lọ wo ọmọ rẹ̀ ló ri i pé ọmọ náà ko si nibẹ̀ mọ.
Ohun ti o ṣoju mi koro sọ ni pe ọkan lara awọn oṣiṣẹ ọgba ẹwọn naa lo ṣekupa ọlọkada kan ti ọṣiṣẹ ọgba ẹwọn naa si fi ara pa ni agbegbe ti wahala naa silẹ.
Ikede iku awọn alaaye yii si lo wọpọ laarin awọn amuluudun, gbajumọ ati awọn eekan ilu lorisirisi, to fi mọ awọn oloselu, oloko-owo, akọrin atawọn oṣere tiata.
Dandan ni kí àwọn ohun ìkọsẹ̀ dé, ṣugbọn ẹnikẹ́ni tí ohun ìkọsẹ̀ bá ti ọ̀dọ̀ rẹ̀ wá, ó gbé!
 wọ ́ n dera wọn mọ ́ àgá ni Àwọn tó yin rọ ́ kéẹ ̀ tí yìí sókè , wọ ́ n jìnnà pátápátá sí ibi tí rọ ́ kẹ ̀ tì yìí wà , ẹ ̀ rọ ̀ kọ ̀ mpútà ni wọ ́ n fí yìn ín bi wọ ́ n sẹ gbéná lé rókẹ ́ ẹ ̀ tí yìí tí à ń pè ní apollo 11 ni 1969 dó bá dún gbòà ?
Ibi tí ó dára jùlọ ninu ilẹ̀ náà ni wọ́n mú fún ara wọn,nítorí pé ibẹ̀ ni ìpín olórí ogun wà,ó wá sí ọ̀dọ̀ àwọn olórí àwọn eniyan náà,àtòun, àtàwọn eniyan náà sì ń pa àṣẹ OLUWA mọ́,wọn sì ń ṣe ìdájọ́ òdodo.
ẹ óo di ìran alufaa ati orílẹ̀-èdè mímọ́ fún mi.
Awọn mejeeji lo jẹ ọmọ ijọ, ti wọn si kesi Olori Alufaa wọn, LaVey lati so wọn pọ ni orukọ Satani.
Awon olori orile-ede ile-Europe se ipade ni Brussels nibi ti won ti n reti igbese ti yoo dekun laasigbo eto kara-kata laarin ajo isokan ile Europe ati orile-ede America.
Ọpọ lo ti n foju sii lara pe o ṣeeṣe ki o du ipo aarẹ.
 Àpẹẹrẹ àwọn fíìmù àgbéléwò tí ó wà lábẹ ́ ọ ̀ wọ ́ yìí , tí wọ ́ n sì ti gbé jáde ni ; jógun-ó-mí , odùduwà , efúnsetán aníwúrà àti bẹ ́ ẹ ̀ bẹ ́ ẹ ̀ lọ .
Wọ́n sọ báyìí nítorí pé wọ́n ti kọ́kọ́ rí Tirofimọsi ará Efesu pẹlu Paulu láàrin ìlú, wọ́n wá ṣebí Paulu mú un wọ inú Tẹmpili ni.
'Wọ́n jí bàbá mi gbé ká tó kojú Argentina' ‘Ọlọ́kọ̀ epo to jóná yóò fojú balé ẹjọ́’ Wo bó se ń lọ nínú ìdíje Russia 2018 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Idije ife ẹyẹ agbaye n pari lọ Ipele kò-mẹsẹ̀-o-yọ nidije déé duro bayii ni Russia ti ẹnikẹni to ba ti fidi rẹmi n pada sile.
Serena ni aṣọ ọhun jẹ ki oun dabi ọmọ-ọba-binrin ologun, bẹẹni ki iṣe fun oge rara.
Ṣugbọn bí ẹ̀rù bá ń bà ọ láti lọ, mú Pura iranṣẹ rẹ, kí ẹ jọ lọ sí ibi àgọ́ náà.
7 312728 Orilẹede Bangladesh 6967 4.
Àkọlé àwòrán, Awọn ọmọ Nàìjíríà bá aarẹ Buhari sọ̀rọ̀ lójú òpó BBC lórí ètò ààbò ìlú Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, #Queen Dihya: Obinrin tó gbógun tàwọn agbésùnmọ̀mí ni Algeria Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 3 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 5 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
 pẹ ̀ lú líhàhílo , ìfòyà , aibalẹ ọkàn nípa ogun Ọ ̀ gbÒrỌ ̀ tí ń bẹ ló de Ọ ̀ yọ ́ , kò mú wọn ṣe ohunkóhun lórí ọ ̀ rọ ̀ ogunlọlá , wọ ́ n si fi í pamọ ́ si ilé olósì títí wọn yóò fi ri ìtumọ ̀ sí àrokò náà .
 Eyi ni o mu wa pinnu lati pese awon ohun ti won ba nilo patapata, gege bi ati pese fun awon asaju won naa.
Orile-ede Germany, Brazil ati Belgium wa lori oke tente tabili ohun ni itele n tele, bee si ni Argentina, Croatia ati Iceland wa ni ipo karun un, ipo kéjìdínlógún  ati ipo kéjìlélógún.
“Ọmọ eniyan, ìwọ ni mo yàn ní olùṣọ́ fún ilé Israẹli; nígbàkúùgbà tí o bá gbọ́ ọ̀rọ̀ kan lẹ́nu mi, o níláti bá mi kìlọ̀ fún wọn.
Èéṣe tí o fi tàn mí jẹ, tí o yọ́ lọ láìsọ fún mi?
21 Ìgbé 2019 Ẹ fójú lóúnjẹ lórí àkójọpọ̀ àwọn àwòrán mánigbàgbé ọdún Àjínde l'Afrika Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Aworan ajọdun ajinde l'Afrika Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ajọdun ajinde jẹ ọdun pataki fun awọn ẹlẹsin Kristẹni l'Afrika Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Lati Naijiria titi to fi de South Sudan lawọn Kristeni n ṣe ajọdun ọdun yi Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Awọn olujọsin a ma ṣe ere to ṣe afihan iṣẹlẹ to waye lọjọ ajinde Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Lati ọjọ ẹti rere titi di ọjọ aiku ni ajọdun yi fi n waye Oríṣun àwòrán, SEYLLOU Àkọlé àwòrán, Awọn ọmọ ijọ a ma kopa ninu ajọdun naa lati fi pataki ọdun ajinde han Oríṣun àwòrán, BRIAN OTIENO Àkọlé àwòrán, Lorileede Kenya naa,awọn naa kopa ninu ajọdun ajinde Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Pope kiss feet: Oda times wey Pope Francis don try to settle kontries gbege wey resemble South Sudan12 Ìgbé 2019 Enoch Adeboye: Three facts wey make dis Pastor still dey popular for Nigeria2 Ẹrẹ̀nà 2019 Alpha Lukau: Funeral companies wan drag 'resurrection pastor' for court26 Èrèlè 2019 Prophet wey claim cure for HIV dey face jail or fine option5 Èrèlè 2019 Virginia Gun-in-church bill: State for America wan make am legal to carry gun go church29 Sẹ́rẹ́ 2019 BBC News, Yorùbá Ìdí tí ẹ fi le è nígbàagbọ́ nínú ìròyìn BBC Ìlànà Lílò Nípa BBC Òfin Àṣírí Cookies Kàn sí.
Ọgbẹni Omomuwasan ba sọ fun awọn araa igbimọ ọhun pe ki ẹrọ ayaworan naa ṣi wa lọwọ ile ẹjọ.
Ati irú okun tí awọ inú rẹ̀ ní.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Coronavirus: Kí ní wọ́n ń pè ní “Herd Immunity?
Bawo ni àwọn ayaba ṣe n ti gba?
Àwọn ìṣẹ̀lẹ̀ ńlà lọ́sẹ̀ tó kọjá tó fi mọ́ bí Covid-19 ṣe gbẹ̀mí èèyàn 23 lọ́jọ́ kan ṣoṣo Ọjọ́ orí wo ló yẹ kí ikùn ẹ̀dá bẹ̀rẹ̀ sí tóbi?
"Oríṣun àwòrán, Seyi Makinde ""Mo tun ba awọn ẹlẹgbẹjẹgbẹ osisẹ nile ẹkọ LAUTECH sọrọ lori bi wọn yoo se se amulo owo idoola isoro ti mo gbe kalẹ, ati ọna ti wọn yoo gba fọwọsowọpọ pẹlu ijọba lati wa ọna abayọ titi laelae si awọn ipenija to n koju ileẹkọ naa."
Ó ní Farao sì tún ń gbé ara rẹ̀ ga sí àwọn eniyan òun, kò jẹ́ kí wọ́n lọ.
’ Ni baba bá pín ogún fún àwọn ọmọ mejeeji.
Gege bi oro re, Orile-ede Naijiria ko ipa pataki ninu ijiroro to o sokunfa ipinnu ajo-isokan ile-Afrika nipa sise idasile eto oro-aje kara-kata ti ko lowo ori ninu laarin awon orile-ede nile Afrika.
Ondo Kidnap: Àwọn ajínigbé tú adájọ́ kóòtù àpapọ̀ sílẹ̀ lẹ́yìn ọjọ́ márùn ún lákàtà wọn
"Adeboye O ni ""fun idi eyi, awọn Kristẹni ni lati gbọran, ki wọn si gbadura ipari ọdun yala nile wọn tabi ki wọn ṣe isin ipari ọdun ninu ṣọọṣi wọn ki o si pari si ago mọkanla dipo mejila to maa n pari tẹlẹ."
Oríṣun àwòrán, SOLA ILESANMI Àkọlé àwòrán, Awọn eniyan meje padanu ẹmi ninu ijamba Olori awọn osisẹ FRSC lagbegbe naa, Olusẹgun Ogungbemi sọ pe sisare asapajude loju popo lo s'okunfa ijamba naa, ti o si parọwa fun awọn arinrinajo ati awakọ lati maa se pẹlẹ loju popo.
Koda lati ibẹ lo yẹ ki awọn ara ilu ti maa mọ ipele to kan ninu iṣẹ akanṣe ti aṣoju wọn n gbero atiṣe fun ilu rẹ Bakan naa lo yẹ ki wọn mọ bo ṣe n na owo ilu to n gba ni Abuja fun idagbasoke agbegbe ọhun ti wọn ba ti wọ inu ọọfiisi yii.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú 15 Sẹ́rẹ́ 2021 Ọba alara ni Ọba Oke, ara to ba si wu lo ma n fi ẹda ọwọ rẹ da.
Awọn orilẹede to se idajọ iku ni ọdun 2013 si 2017 Awọn orilẹede mọkandinlogun ni ko se idajọ iku lasiko ti ko ti le jẹ eewọ.
Akomolede àti Aṣa: Ọ̀rọ̀ Ẹ̀yán ni Bunmi Femi Amao ń kọ́ wa lórí ètò Akọ́mọlédè àti Àṣà Ọ̀gá iléeṣẹ́ gbé £10 mílíọ̀nù ẹ̀bùn owó fún òṣìṣẹ́, èyí lohun tó pawọ́n pọ̀ Orílẹ̀èdè Amẹrika ti bẹ̀rẹ̀ sí ní wo wọlé-wọ̀de Atiku, àwọn ìyàwo rẹ̀ lórí owó tí wọ́n kó lọ sí òkèèrè Hisbah mú ọkùnrin mẹ́ta tó pín fídíò ìfipábánilòpọ̀ ọmọdébìnrin 16 tó fẹ́ ṣèyàwó lórí ayélujára Awọn olukọ yii ko ni gba igbẹga lẹnu iṣẹ fun ọdun kan, wọn si gbọdọ duro si ibi ti awọn ọmọ ti n ṣe idanwo fun ọdun mẹta.
Òun fúnrarẹ̀ ni ó ru ẹ̀ṣẹ̀ wa lórí igi, kí á baà lè kú sí ẹ̀ṣẹ̀, kí á wà láàyè sí òdodo.
tí Ọlọrun kò fihan àwọn ọmọ eniyan ní ìgbà àtijọ́, ṣugbọn tí ó fihan àwọn aposteli rẹ̀ mímọ́ ati àwọn wolii rẹ̀ nisinsinyii, ninu ẹ̀mí.
Ninu ọrọ to ba ileeṣẹ BBC News Yoruba sọ ileeṣẹ apinna ọba lẹkun Eko, EKDC ṣalaye pe afikun owo ina to waye lo ṣokunfa ipenija yii.
Alfa Babatunde Sotitobire tún fojú balé ẹjọ́ lọ́nìí, bàbá ọmọ jẹri níwájú adájọ́ Ọwọ́ ọlọpàá tí tẹ ọ̀kan nínú àwọn ọ̀daràn tó ṣekú pa Uwaila WAEC ti ṣetán fún ìdánwò àṣekágbá girama Ọwọ́ bàtá Auxiliary tó ń ró ní àrójù, leè ya láìpẹ́ - Ìjọba Oyo dúnkookò Pataki etutu yi ni ki wọn ba le gbọn gbogbo ojora kuro lara wọn kí wọn si sọ wọn di akin.
Ọlọrun Fi Isikiẹli Ṣe Aṣọ́de ní Israẹli.
Ẹsẹ́ púpọ̀ fún ìfẹ́ àti iranlowo yín fún ìtèsíwájú èdè,àṣà àti ìṣe Yorùbá.
Ikọ̀ ìjọba Ọ̀yọ́ dé lásìkò tí kò yẹ ni wọn kò ṣe wọlé - Ẹ̀bí Ajimobi fèsì Arúfin ni Seyi Makinde pẹ̀lú bó ṣe gbà kí wọ́n sin Ajimobi sí GRA - Amòfin Ohun tí a mọ̀ nìyí nípa ìròyìn Ajimobi kú, kò kú, táyé ń gbé kiri Wo àwọn èèyaǹ jàǹkàn mérin tí àrùn Coronavirus ti sọ dèrò ọ̀run ní Naijiria Ni ibẹrẹ ọsẹ yii ni igbakeji gomina ipinlẹ Ọyọ, Onimọẹrọ Rauf Ọlaniyan ṣalaye pe oun ko fi igba kankan binu si iyawo gomina ana ni ipinlẹ naa, Arabinrin Florence Ajimọbi lori awọn iṣẹlẹ gbogbo to ṣẹlẹ lẹyin iku ọkọ rẹ, Sẹnetọ Abiọla Ajimọbi.
awon ara ilu Abuja ti bere si n lo si oja lati ra awon ounje sile won , ni eyi
Bi o tilẹ jẹ pe ko si irufẹ ounjẹ ilẹ Naijiria ti ẹ o le ri ra nibẹ tabi lọ jẹ, ọpọ wọn ṣi ni ko da bii ki awọn maa jẹ Amala, Iyan, Ẹfọ ati bẹẹ bẹẹ lọ ni ilu ibi awọn lorilẹede Naijiria.
Amọ,alukoro ile Ẹkọ fasiti naa ọgbẹni Tunji Oladejo ninu ifọrọwanilẹnuwo pẹlu BBC salaye pe awọn ko ti le sọ pato nnkan to ṣokunfa iku arakunrin naa.
Moussa Dembele, atamatase ti Lyon gbe wọlẹ ni o da bira pẹlu goolu meji ni abala ikeji idije naa.
Awọn kokoro aifojuri yii maa n wọ ara eniyan lasiko ti abo ẹ̀fọn ti wọn tun maa n pe ni ''olokoowo iba'' ba jẹ eniyan.
Ẹ dá ilẹ̀ oko wọn pada fún wọn lónìí, ati ọgbà àjàrà wọn, ati ọgbà igi olifi wọn, ati ilé wọn, ati ìdá kan ninu ọgọrun-un owó èlé tí ẹ gbà, ati ọkà, waini, ati òróró tí ẹ ti gbà lọ́wọ́ wọn.
E , ó jáde ní ọjọ́ kejìlá, oṣù kẹjọ, ọdún 2013, sùgbọ́n o ti kọ́kọ́ gbé àwo kan jáde to pe àkọle rẹ̀ ni Mixtape Burn Identity.
Winnie Mandela ṣi wà ní ọlọ́mọge nígbà tó di gbajúmọ̀ l'ágbo òṣèlú.
Orukọ afurasi naa ni Feyisola Dosumu, ti ọpọ eeyan mọ si Spartan, deede aago kan ọ̀san si ni ọwọ awọn ọlọpaa tẹ ẹ.
May kede ni owurọ ọjọ Ẹti pe oun yoo fi ipo naa silẹ ni ọjọ keje, oṣu Kẹfa, 2019, eyi ti yoo mu ki idije lati yan ẹlomii sipo naa o waye.
"Nígbà tí wọ́n bí NUPENG bóyá wọn yóò dara pọ̀, èsì tí ààrẹ NUPENG Prince Akporeha fọ̀ ni pé ""ṣé a ò kí ń ṣe ẹ̀ka àpapọ̀ ẹgbẹ́ òṣìṣẹ́ ni?"
Omíyalé àgbàrá ya ṣọ́ọ̀bù, ilé mẹ́ta wó, èèyàn mẹ́rin kú l'Eko Odunlade fijó bẹ́ẹ, Lizzy padà sọ́dún 2012, Toyin Abraham tọ̀ lẹ́ẹ̀mẹwàá Aisha fikun pe, idi naa lo mu ki ilẹ ta si diẹ, ko to di pe oun pada wa si Naijiria.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Àlàyé rèé lóríi àjọṣepọ̀ tó wà láàrin èmi àti MC Oluomo - Ronke Oshodi Oke Ẹ bá mi wá nọ́ńbà ìpè òbí ọmọ Mummy Calm Down jáde - Yinka Ayefele Mò máa ń fọ àwọ̀tẹ́lẹ̀ ìyá mi, ni ìṣe àwọn obìnrin fi wù mí - Bobrisky Ọlọ́pàá sálọ fún aráàlú l‘Okeho, nígbà tí wọn yari láti ṣun olè méjì tó kù Awọn mejeeji wa n beere pe o se jẹ ifun Richard nikan lo jade sita , ti ko sisi ipa ẹjẹ lara rẹ.
Arikeade Daranijo naa bu ẹnu atẹ lu Lizzy lori ọrọ yii, o ni awọn ogun idile Lizzy lo n tẹle lẹyin lo jẹ ko maa bu Toyin, o wa gbadura fun ki ẹnu rẹ ma ko ba a.
A le tọ ipasẹ Baba Keresi lọ si ọdọ Biṣọọpu Greek, Nicholas.
EidAlFitr2019: Bó ṣe ń lọ káàkiri àwọn Yidi rèé
Ileeẹkọ fasiti Queen's lo kede ohun iwuri yii loju opo ikansira ẹni Twitter rẹ, ti Gift funra rẹ naa si ki ara rẹ ku oriire ami ẹyẹ naa loju opo Twitter tiẹ naa.
"Nínú àtẹjade ilé iṣẹ́ náà fi sita la'ti ọdọ Fox News: "" a so fun ọgbẹni Alder àti ẹbi rẹ̀ láti sọkalẹ ninu ọkọ ofurufu náà lẹ́yin ọpọlọpọ àwọn èrò ńkùn nitori wọ́n, ìgbésẹ wa ni ]nkan ti a ro pe o tọna láti ṣe nitori alafia awọn èrò to kù"" "" Ko si eyi to niṣe pẹlu ẹsin ọgbẹ̀ni Adler Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?"
Ajọ SARS naa ri ibọn AK47 ti o ni ọta ibọn marundinlogun ninu.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Dolapo Osinbajo: Dolapo, ìyàwó igbákejì ààrẹ ránṣẹ́ mẹ́ta sáwọn obìnrin 15 Owewe 2019 Oríṣun àwòrán, @ProfOsinbajo Iyawo Igbakeji aarẹ, Dọlapọ Oṣinbajo, ti ke gbajare sita pe, ni ibi ti ọrọ de duro bayii lawujọ, afi ki awọn obi yaa joye fijilante, ki wọn si mojuto awọn ọmọ wọn daradara.
Ọ̀kan lára àwọn Kerubu náà na ọwọ́ sí inú iná tí ó wà láàrin wọn, ó bù ú sí ọwọ́ ọkunrin aláṣọ funfun náà.
’ Ó sọ fún wọn pé, ‘Ẹ̀yin náà ẹ lọ sinu ọgbà àjàrà mi.
Lady Peller: Ọjọ́ ni ọjọ́ tí idán yíwọ́ fún ọkọ mi lẹ́yìn tó gé mi sí méjì, mo kú tán
Wọ́n bẹ̀rẹ̀ sí wí fún ara wọn pé, “Ẹ wò ó, alálàá ni ó ń bọ̀ yìí!
6 million), lara owo jibiti naa.
Yó dára fún gbogbo yín o.
Ọlọ́pàá wú òkú obìrin tó ń múra ìgbéyàwó lọ́wọ́ tí 'gate-man' rẹ̀ ṣekúpa Nibayii, NLC ni awọn ti bẹrẹ ijiroro pẹlu ijọba lati yi igbeṣẹ naa pada.
“Mo tuko yii tokan-toka pelu oye kikun.
Wọn ni lẹyin ti awọn agbofinro yọju sagbegbe naa ni alaafia to pada sibẹ.
O lọ sile iwe alakọbẹrẹ Gar Local Education Primary ni Bauchi lọdun 1964 si ọdun 1970.
Wọ́n jẹ ohun tí wọ́n bá níbẹ̀; wọ́n sì mu.
Nigba ti wọn bẹrẹ ifẹsẹwọnsẹ lẹyin isimi ilaji asiko, Watford ko so ireti nu rara.
Nigba to n fidi iṣẹlẹ naa mulẹ fun ileeṣẹ iroyin abẹle kan, Baalẹ ilu naa, Rafiu Mustapha sọ pe iwadii ti bẹrẹ lati fi panpẹ ofin mu awọn ọdaran naa.
Lara awọn iléeṣẹ́ tó fòfin de ni saa yii ni Air France, KLM, Etihad, RwandAir, Air Namibia, Royal Air Maroc, Lufthansa ati TAAG Angola Airlines.
Gege bi orile-ede, a gbodo sora nipa ounje ti a o maa je, ti a ba gbo iseyo aarun ni awon orile-ede kan, ojuse wa ni lati maa se ko ounje wo orile-ede wa lati iru awon orile-ede bee.
“Lẹ́yìn ogoji ọdún, angẹli kán yọ sí i ninu ìgbẹ́ tí ń jóná ní aṣálẹ̀ lẹ́bàá òkè Sinai.
Ẹni tí ó jókòó lórí ìkùukùu náà bá ti dòjé rẹ̀ bọ ilé ayé, ni ó bá kórè ayé.
Mi ò fẹ́ dá sí ìjà Toyin ati Lizzy!
Nígbà náà ni ìtumọ̀ òdodo ati ẹ̀tọ́ yóo yé ọati àìṣe ojuṣaaju, ati gbogbo ọ̀nà rere.
Ajọ ajafẹtọ naa ni awọn ko igbesẹ naa nitori ọgọrun ọjọ lo ku ki idibo gbogboogbo o waye, ti iINEC ko si tii gba owo eto isuna wọn.
A kò ní ranti gbogbo òdodo rẹ̀ tí ó ti ṣe mọ́, yóo kú nítorí ìwà ọ̀tẹ̀ ati ẹ̀ṣẹ̀ rẹ̀.
Àwọn ati ràkúnmí wọn kò níye, nítorí náà nígbà tí wọ́n bá dé, wọn á jẹ gbogbo ilẹ̀ náà ní àjẹrun.
opolopo awon eniyan to n  sise ninu ile naa ti ha mo ibi kan.
Ọba dìde, ó fa aṣọ rẹ̀ ya láti fi ìbànújẹ́ rẹ̀ hàn, ó sì sùn sórí ilẹ̀ lásán, àwọn iranṣẹ rẹ̀ tí wọ́n wà pẹlu rẹ̀ fa aṣọ tiwọn náà ya.
Nítorí a bí ọmọ kan fún wa,a fún wa ní ọmọkunrin kan.
ni Ṣeyi Makinde, oloṣelu si ni pẹlu.
Nígbà tí OLUWA kó àwọn ìgbèkùn Sioni pada, ó dàbí àlá lójú wa.
Bí angẹli kan bá wà pẹlu rẹ̀,tí ó wà fún un bí onídùúró,àní, ọ̀kan láàrin ẹgbẹrun,tí yóo sọ ohun tí ó tọ́ fún un,
Nítorí Ọlọrun fúnrarẹ̀ ti sọ pé, “N kò ní fi ọ́ sílẹ̀, bẹ́ẹ̀ ni n kò ní kọ̀ ọ́!
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Press freedom: Ohun tó ń fa ojúkòkòrò fún àwọn oníròyìn nìyìí Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Press freedom: Ohun tó ń fa ojúkòkòrò fún àwọn oníròyìn nìyìí 9 Èbibi 2019 Agba ọjẹ oniroyin ni Emmanuel Malagu jẹ, bẹẹ naa si ni, o ti foju wina ọpọlọpọ iriri ti ko ṣee ro tan.
Rwanda Genocide: Ó fẹ́ gba ẹ̀san ṣùgbọ́n ó padà dáríjì í
Amọ o fi ote le pe awọn ọmọ igbimọ amusẹya lori Coronavirus yoo maa lọ yika awọn ile ijọsin naa lati ri pe ero to wa nibẹ ko ju aadọta lọ.
bòtswánà , lóníbiṣẹ ́ bíi orílẹ ̀ -èdè olómìnira ilẹ ̀ bòtswánà ( ) , jẹ ́ orílẹ ̀ -èdè àdèmọ ́ àrinlẹ ̀ tó bùdó sí apágúsù Áfríkà .
tabi àjàkálẹ̀ àrùn tí ń jà kiri ninu òkùnkùn,tabi ìparun tí ń ṣeni lófò ní ọ̀sán gangan.
agbanisisẹ duro lati san ekunwo owo osu fun awon osise won.
Ṣugbọn ariyanjiyan ti n waye lori alaye ijọba pe awọn ko san owo fun igbasilẹ awọn ọmọbinrin yi.
Ẹ̀gún ati òṣùṣú ni ilẹ̀ yóo máa hù jáde fún ọ, ewéko ni o óo sì máa jẹ.
Meji ninu ayo marun ti Liverpool gba wọ inu awọn Roma, lo wa lati ẹsẹ Salah.
 Àìfi ara kàn aláìsàn tààrà lè jẹ ́ nípasẹ ̀ aṣọ tó ti kàn ojú tàbí imú ẹni tí ó ní àìsàn náà tàbí eṣinṣin tó ti bà lé ibẹ ̀ .
idibo ni ipinle naa,Ojogbon Anjela Mary se
Ṣàánú wa OLUWA,ìwọ ni a dúró tí à ń wò.
Nígbà tí ó dé ibẹ̀ ó sọ fún àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ pé, “Ẹ máa gbadura kí ẹ má baà bọ́ sinu ìdánwò.
awon ibugbe ni ibile badagry pin so ona meji .
Àwọn ọmọ Ṣobali ni Alfani, Manahati, Ebali, Ṣefo ati Onamu.
"Àwọn àsọtẹ́lẹ̀ tó já s'ófo lórí ìdìbò 2019 Ẹ wo ọ̀rọ̀ àwọn Wòlíì tó ti sọ àsọtẹ́lẹ̀ saájú nípa làásìgbò EndSARS 'Ọdún 2019 pẹ̀lú àwọn àsọtẹ́lẹ̀ tó kó lọ́wọ́ dé' Ọmọ ọdún mẹ́jọ ni mo ti ń bá Adẹ́rùpọkọ̀ ṣe eré tíátà - Tope Alabi O ni ""lati ọdun 2017 ni mo ti ki Donald Trump nilọ lori erongba rẹ fun saa keji, ṣugbọn ko gbọran."
O óo mu wàrà àwọn orílẹ̀-èdè,o óo mu wàrà àwọn ọba.
Ninu ọrọ rẹ, o ni wọn ti gbegi le sisan owo ile iwe ni ipinlẹ Ogun lasiko yii.
Akowe agba fun ajo CECP, Omowe Abia Nzelu dupe lowo gomina Ambode pe igbese yii dara lasiko ayajo ololufe todun 2018 lagbaye.
Nítorí kí àwọn kan tó ti ọ̀dọ̀ Jakọbu dé, Peteru ti ń bá àwọn onigbagbọ tí kì í ṣe Juu jẹun.
Timi wa rọ yin kẹ mase fi ina sere nitori a kii dagba kọja ohun ti a ko ba mọ, ina si lewu.
OLUWA Ọlọrun yín ni kí ẹ máa tẹ̀lé, òun ni kí ẹ máa bẹ̀rù.
Ààrùn yiì tún ti mú ìpèníjà míràn bá ètò ìlera orílẹ̀-èdè Nàìjíríà tó sì ń tiraka láti bọ́ lọ́wọ́ ààrùn Covid-19 to ti n da gbogbo àgbáyé láàmú láti ìbẹ̀rẹ̀ ọdún 2020.
Àmọ́ ẹ̀hìn ojú ewé ìwé ni wọ́n lu'hò sí; ajẹ́ pé ní iwájú ojú-ewé ìwé, ihò kọ̀ọ̀kan rọra lé sókè.
Ilu Ikorodu, nipinlẹ Eko ni Naijiria ni wọn wa.
Oríṣun àwòrán, Nimc Oríṣun àwòrán, Nimc Wo àwọn nǹkan to tún nílò NIN fún yàtọ̀ fún ìforúkọsílẹ̀ síìmù Oríṣun àwòrán, @NIMC Laipẹ yii ni ajọ to n risi ibaraẹnisọrọ ni Naijiria, NCC fi aṣẹ sita pe, gbogbo ọmọ Naijiria to n lo siimu ẹrọ ibaraẹnisọrọ, gbọdọ fi NIN kun iforukọsilẹ siimu wọn.
" Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Kini Yoru[bá ń pe Necklace?
Ó ní, “Ẹ gbọ́ bí Ẹ̀mí Mímọ́ ti wí: Báyìí ni àwọn Juu yóo di ọkunrin tí ó ni ọ̀já ìgbànú yìí ní Jerusalẹmu; wọn yóo sì fà á lé àwọn tí kì í ṣe Juu lọ́wọ́.
Ileeṣẹ ologun ti kọkọ sọ pe oun ko lọwọ ninu iṣẹlẹ naa, ṣugbọn to tun yi ọrs pada lọjọ Iṣẹgun pe, gomina ipinlẹ Eko lo ranṣẹ pe awọn lati da alaafia pada si aarin ilu.
Ṣugbọn nígbà tí Ẹsita lọ sọ́dọ̀ ọba, ọba kọ̀wé àṣẹ tí ó mú kí ìpinnu burúkú tí Hamani ní sí àwọn Juu pada sí orí òun tìkararẹ̀, a sì so òun ati àwọn ọmọ rẹ̀ rọ̀ sórí igi.
Akọkọ ibudo ajogunba yii ti wọn gbe kalẹ lọdun 1999 ni ibudo Fossil Hominid ti South Afrika - pẹlu sise awari ibudo ti agbari Taung wa - to fi mọ ibudo igbafẹ Wetland ati erekusu Robben Orisun: Ajọ Unesco.
Ọ̀kan ninu wọn bẹ̀ ẹ́ pé kí ó bá àwọn lọ, ó sì gbà bẹ́ẹ̀.
Oríṣun àwòrán, @Oyoaffairs Aṣoju ẹgbẹ orin baba Ebenezer Obey, Tunji Odunbaku ti sọ fun BBC Yoruba pe irọ ni iroyin ti awọn kan n gbe kiri pe gbajugbaja olorin naa ti dagbere faye.
Gomina Seyi Makinde lo sọ eyi lasiko to n gba awọn ọmọ ile-iwe imọ ofin naa lalejo ni ilu Ibadan.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Omidan jáde láyé lẹ́yìn tí ìlú lù ú, jáa sí ìhòhò lórí ẹ̀ṣẹ̀ tí kò ṣẹ̀ Ni Ọjọbọ ni igbakeji olori ọmọ ẹgbẹ to pọ julọ ni ile aṣofin agba orilẹede Naijiria, Sẹnetọ Ajayi Borrofice ti bẹnu atẹ lu eto ti awọn alaṣẹ gbe kalẹ fun didena aarun Coronavirus.
ijọba apapọ gbe igbesẹ gnogbo to ba yẹ lati rii pe igbe aye idẹrun de ba awọn ọdọ ni ipinlẹ Anambra.
#BBCGOVDEBATE: Kò sí ètò ilera ọfk fun àwọn obinrin- Ogunbanjọ Tani otutu ma n mu ju laarin Ọkunrin ati Obinrin?
Amọ, Risikat yari, o ni nitori oju buluu ti awọn ọmọ ti oun bi fun un ni ipinya fi wa laarin awọn.
Díẹ̀ ni ọrọ̀ tí o ní tẹ́lẹ̀ yóo jẹ́lára ohun tí Ọlọrun yóo fún ọ ní ọjọ́ iwájú.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Generator Ban: Àbá ọ̀hún wá yọ àwọn ilé ìwòsàn, pápákọ̀ òfurufú àti àkànṣe iṣẹ́ míì sílẹ̀ 12 Ẹrẹ̀nà 2020 Oríṣun àwòrán, Others Ile asofin agba ilẹ wa ti n se agbeyẹwo aba kan, ti yoo fofin de lilo ẹrọ amunawa jẹnẹratọ lorilẹede Naijiria.
Ìbẹ̀rù-bojo gbalẹ̀ ní Oyigbo lẹ́yìn tí ọlọ́páà mẹ́ta àti sọ́jà kú nínú rògbòdìyàn EndSARS Ẹni mọ́kànléláàdọ́fà 111 ló lùgbàdì àrùn covid-19 ní Nàìjíríà lọ́jọ́ Àìkú Oluwo ti ìlú Iwó kìí ṣe ẹgbẹ́ Àtaọjà Osogbo - Alaafin ìlú Ọ̀yọ́ Wo iye owó tí ìjọba Amẹrika ń na sí ìdìbò Ààrẹ àti ibi tí owó náà ti ń wá Aàbò tó péye yóò wà fún àwọn tí yóò kópa nínú ìfẹsẹwọ̀nsẹ̀ Naijiria àti Sierra Leone ní Benin - Obaseki Remilekun Fatolu bú sẹ́kún fún ohun tó ti pàdánù láyé torí ọyàn ńla rẹ̀.
May ní ilẹ Gẹẹsi kò fẹ́ wawọ́ mọ́ ǹkan ìní ọmọ Nàiìjíríà Olóòtú ìjọba ilé Gẹẹsi,Theresa May,ti seleri lati da owo Nàìjíríà pada sugbọn o le má ya ni kiakia.
O so pe “Inu mi dun lati wa si orile ede Naijiria, paapaa julo si ilu Eko, ibasepo to dan monran wa laarin orile ede Naijiria ati Britain, a si ni opolopo nnkan pataki lati se lojo iwaju.
Baba Suwe bọ́ lọ́wọ́ àìsàn, ó bẹ̀rẹ̀ tíátà padà Ọjọ́bọ̀ la ó mọ̀ bóyá a ní Coronavirus - Aṣòfin Ondo Isakoso gẹgẹ bii oloselu tabi ẹni ẹ̀mí O sọ pe oun ba Ọlọrun pade nigba to jẹ akẹ́kọ̀ọ́, mo si bẹrẹ si ni dari igbeaye si ilana iṣẹ Oluwa."
 nitoripe awon abinibi wa ninu gbogbo awon adirajo alaaye , isiseabinibi se lo lati se akomo gbogbo awon sistemu alaaye , latori awon eran ati bakteria , de ori awon ogbin ( agaga awon eso oko ) ati awon eran osin , de ori awon eniyan ( bi ninu isiseabinibi oniwosan ) .
Wo àwọn tó ń jí owó Covid-19 tí Ìjọba ní wọ́n yóò káwọ́ pọ̀nyìn rojọ́ Ọdun 2003 ni Olatunji sun ti ko ji mọ ni ẹni ọdun mẹrindinlọgọrin.
Lẹyin ipade naa, Atiku Abubakar sọ pe idunnu lojẹ fun oun lati ṣepade pẹlu ọ̀ga oun nigba kan, tawọn si tun jọ jẹ ounjẹ ọsan.
Ó ní ṣé Hesekaya rò pé ọ̀rọ̀ ẹnu ni ọgbọ́n ati agbára tí wọ́n fi ń jagun ni; àbí ta ló gbójú lé tí ó fi ń ṣàìgbọràn sí òun?
Iwọde naa jẹ ọkan lara awọn eleyi to n waye jakejado Naijiria lati fi pe fun iwọgile ikọ ọlọpaa FSARS ti ara ilu ni wọn dẹgun le awọn pupọ.
 Ààrẹ tẹ ́ lẹ ̀ goodluck ebele jonathan buwọ ́ lu òfin tí ó fòpin sí àṣà yí ní oṣù karún ọdún 2015 .
Ó di arúgbó kùjọ́kùjọ́ kí ó tó kú.
Ẹni tó bá fẹ́ ipò ní ìjọba mi, ko lọ yan ẹranko kan láàyò - Gómìnà Lalong Àwọn ohun tó ń fa ariwo nípa Huawei tó yẹ kóo mọ̀?
Eniyan burúkú a máa ṣe ojúkòkòrò ní gbogbo ìgbà,ṣugbọn olódodo ń fúnni láìdáwọ́dúró.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Akomolede ati Asa: Mọ̀ si nípa àwọn ọ̀nà tí Yorùbá ń gbà ran ara wọn lọ́wọ́ O ni awọn n gbe igbesẹ lati da nkan pada sipo lawọn ọgba ẹwọn mejeeji yii.
olowo marun un( five billionaires) ti won sunmọ Bouteflika bii isan ọrun  ni yoo maa kawọ sẹyin rojọ lori ẹsun iwa ibajẹ
wipe, iko agbaboolu ti o ba gba ife-eye idije Europa League yoo lanfaani ati
Nigba to n sọrọ nibi ayẹyẹ naa, kọmiṣọna feto aṣa ati irinajo afẹ, Obawale Adebisi sọ pe, kii ṣe pe bi ijọba ṣe ṣadinku iye ero to pejo sibi ọdun naa wa lati ni awọn ara ilu lara, ṣugbọn lati daabo bo wọn ni.
Oun ni olori agba ẹgbẹ́ Yoruba ti wan pe ni Afenifere titi ti ọlọjọ fi de.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Coronavirus: Ẹ wo ọ̀nà tí ọrọ̀ ajé Náíjíríà tó dẹnu kọlẹ̀ yóó fi ṣàkóbá fún aráàlú 12 Ẹrẹ̀nà 2020 Oríṣun àwòrán, Getty Images Oju ọjọ lẹka ọrọ aje ni Naijiria ṣe bi ẹni ṣokunkun nitori bi ojojo ti n se ogun katakara epo rọbi lagbaye, ti owo agba epo rọbi si ja walẹ.
Dafidi lọ pàdé wọn, ó ní, “Tí ẹ bá wá láti darapọ̀ mọ́ mi gẹ́gẹ́ bí ọ̀rẹ́, ati láti ràn mí lọ́wọ́, inú mi dùn sí yín; ṣugbọn bí ẹ bá wá ṣe amí fún àwọn ọ̀tá mi, nígbà tí ó ti jẹ́ pé n kò ní ẹ̀bi, Ọlọrun àwọn baba wa rí yín, yóo sì jẹ yín níyà.
Aarẹ Buhari sọ nigba naa pe oun ṣi nilo akoko lati fi ikun lu ikun, gba imọran ni orilẹ-ede oun.
Awọn oluwọde ọhun ti wọn ko si inu asọ pupa ati dudu, rin kaakiri awọn opopona to lorukọ nilu Accra, tii se olu ilu oruilẹede Ghana.
Siwaju sí i, mo tún pàṣẹ pé, bí ẹnikẹ́ni bá rú òfin mi yìí, kí wọ́n yọ ọ̀kan ninu igi òrùlé rẹ̀; kí wọ́n gbẹ́ ẹ ṣóńṣó, kí wọ́n tì í bọ̀ ọ́ láti ìdí títí dé orí rẹ̀.
Ó ń ṣẹ́jú sí àwọn ará Asiria: àwọn gomina ati àwọn ọ̀gágun, àwọn ọmọ ogun tí wọ́n di ihamọra, tí wọn ń gun ẹṣin, ọdọmọkunrin ni gbogbo wọn, ojú wọn fanimọ́ra.
Mo ní, “Ẹ̀rín rínrín dàbí ìwà wèrè, ìgbádùn kò sì jámọ́ nǹkankan fún eniyan.
Ṣaaju asiko yi eeyan ẹgbẹrun lọna aadọta ni wọn ti ya sọtọ ti wọn fura si wọn pe wọn le ni aisan naa ni ariwa Italy.
Kí ni pàtàkì nọ́mbà 615 láàrín àwọn èèyàn ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ̀ Àwọn ọmọ ilẹ Indonesia ṣe ìwọ́de lóri fífòfin de ìbalòpọ ṣáájú ìgbéyàwó Inú mí dùn bí ìpínlẹ̀ Ọyọ se setán láti bẹ̀rẹ̀ ilé-ìwé tí àwọn akẹkọ̀ọ́ ń gbé- Òbí Kunle Afolayan, òṣìṣẹ́ báńkì tẹ́lẹ̀ kó tó di gbajúgbajà òṣèré 3.
5 59059 Orilẹede Iceland 29 8.
Nítorí pé mo gba ẹ̀há kò ní kí ń ṣọlẹ̀ tàbí ṣagbe- Ẹ̀lẹ́hàá Amina Èdè Yorùbá dùn lẹ́nu àwọn ọmọ òyìnbó yìí ní Michigan!
Lẹyin iṣẹ ọpọlọ pẹlu oòrùn, ibudo ti awọn oke to han ninu fọnran naa wa, oju ọjọ, aworan ibọn, ati lilo ikanni ayelujara ni aṣiri tu sita.
O fi kun un pe iwadii ṣi n lọ lati doola awọn eeyan to ku ati pe awọn n ṣapa lati mu awọn afurasi naa.
Atejade naa ni awọn asoju lati ipinlẹ kọọkan yoo se ayẹwo kaadi ẹgbẹ wọn ni papa isere Old Parade Ground labuja ki wọn to wa peju si Eagles Square nibi ti ipade naa yoo ti waye.
"Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Winnie wa pẹ̀lu Mandela nigbati o kuro ni ewọn Victor Verster ọdun 1990 in Paarl Wọ́n le kúrò ní ìlú lọ si Brandford ní nkan bí ọdún 1970 fún ipa tó kó nínú ìfẹ̀hónúhaǹ tí wọ́n n pè ní ''Soweto Uprising""."
Oṣu kejila 2017: Awọn agbofinro mu eniyan mẹta.
Johanu bá pe meji ninu wọn, 
A ni lati maa kan sara si wọn fun isẹ takuntakun ti wọn n se ni ileesẹ ati ninu ile.
Ó ní, “Wò ó, n óo ranṣẹ pe ọpọlọpọ apẹja, wọn yóo sì wá kó àwọn eniyan wọnyi.
Lóòótọ́ ọ̀pọ̀lọpọ̀ Alákòóso Ẹ̀kọ́ ló ti wà ni nàìjíríà rí, ṣùgbọ́n púpọ̀ nínú wọn ló jẹ́ pé wọ́n ti ibòmíràn wá ṣe Alákòóso Ẹ̀kọ́ ni nàìjíríà ni láàjẹ́ pé àwọn pàápàá dé nàìjíríà rí.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Àṣìṣe ọlọ́pàá àti Adájọ́ sọ mí di ẹni tí wọ́n dájọ́ ikú fún, ọpẹ́lọpẹ́ Fayoṣe tí ko buwọlu Ẹbun pataki, ẹbun nlanla ni Tunde Kelani jẹ fun orileede Naijiria Lori gbajugbaja oludari ere sinima yi, Yemi Shodimu ni o ṣeni laanu pe awọn to yabara ti wa pọ ninu ere sinima.
Dokita Steven ni ki awọn ara ilu ṣọra fun gaari ati awọn ounjẹ ti ekute ile le ki ẹnu bọ.
Obinrin naa ni wọn gbe lọ si ile igboku-pamọ-si to wa ni Carletonville, ni ẹkùn Gauteng, l'orile-ede South Africa lẹyin ti awọn oṣiṣẹ adoola ẹmi sọ pe o ti ku ninu ijamba ọkọ to waye.
Jesu wí fún wọn pé, “Ìbá jẹ́ pé Ọlọrun ni baba yín, ẹ̀ bá fẹ́ràn mi, nítorí ọ̀dọ̀ Ọlọrun ni mo ti wá.
Lati ọdun bii melo kan sẹyin, lara awọn iṣẹlẹ ipaniyan to lọwọ awọn ẹṣọ aṣọbode ninu ti awọn eniyan n wu sita leyii.
Ó tọ́jú ibìkan fún Àpótí Majẹmu Ọlọrun.
Osu Keji, Ọdun 1999 ni o gori itẹ baba rẹ, amọ ọdun 2003 ni o gba ọpa asẹ ni ọwọ gomina tẹlẹri ni ipinlẹ Ondo, Olusegun Agagu.
Ọgọrọ eeyan lo fẹnu ko pe igbesẹ ẹgbẹ osẹlu PDP lati ṣe ipade naa kudiẹ kaato.
“Àwọn ni àwọn ẹbọ tí ẹ óo máa rú sí OLUWA ní àwọn ọjọ́ àjọ̀dún yín, pẹlu ẹ̀jẹ́ yín, ẹbọ ọrẹ àtinúwá yín, ati ẹbọ sísun yín, ẹbọ ohun jíjẹ yín, ati ẹbọ ohun mímu yín, ati ẹbọ alaafia yín.
ni eyi ti ero rẹ to miliọnu meji.
Ilé ẹjọ́ kòtẹ́mílọ́rùn yọ alága ẹgbẹ́ òṣèlú APC Adams Oshiomhole nípò Agbẹjọ́rò ni n kò bá jẹ́, tí n kò bá bá bàbá mi ṣe tíátà - Sola Kosoko Iléeṣé tó ní bàálù tí Nara Marley lo lọ Abuja tọrọ àforíjìn lówó Mínístà Amọ, nibayii ohun ti awọn eniyan n sọ ni wi pe Sẹnetọ Abiola Ajimọbi wa ni idubulẹ aisan lati bii lóṣu diẹ sẹyin.
Láìsí àní-àní kankan, Ibrahim pe Ishmael kó nìṣó.
Ẹsun lilu jibiti, kiko owo pamọ lọna aitọ, jija banki lole, fifi ara ẹni pe ẹlomiran, ni wọn fi kan wọn.
Olorin Fuji naa gbadura pe ki Eleduwa bukun orilẹede Naijiria, ki o si tun bukun ipinlẹ Oyo.
Á pa àwọn alágbára run láìṣe ìwádìí wọn,á sì fi àwọn ẹlòmíràn dípò wọn.
Ninu ìbànújẹ́ ńlá ati àníyàn ni mò ń gbadura yìí.
Ipinlẹ Ogun lo ṣe ipo kẹta pẹlu eeyan mẹta to ni arun naa, eeyan kọọkan lo ni arun ọhun lati ipinlẹ Ekiti ati Oyo.
Pópóọlá ni orúkọ ọ̀gá ọlọ́pàá yìí.
Tanzania: Àwọn Ìbejì tó so papọ̀ dolóògbẹ́ lọ́mọ ọdún 22
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fọ́nrán ohùn, Imam Fuad tako Oluwo lori wiwe lawani Ija eerin meji: Oluwo ati Ọọni Kíni ìwọ mọ̀ nípa Funmilayọ Ransome-Kuti?
Kọmiṣọna feto ilera ni ipinlẹ naa, Ọjọgbọn Akin Abayọmi lo kede rẹ lẹyin ti wọn ti kọkọ kede lọjọ Ẹti pe yoo lọ yara rẹ sọtọ titi ti igba ti esi ayẹwo kan to ṣe yoo jade.
Àkọlé àwòrán, W#on ko faaye gba awon oludibo to niru kaadi yii lati wo ibudo idibo ki won dibo yan oludije ti won fẹ́ ni Enugu Awọn agbofinro NSCDC ati ọlọpaa ti n de si àwọn ibudo idibo l'Enugu bi ti UNEC ni aarin gbungbun Enugu Àkọlé àwòrán, Eto Idibo abẹlẹ yii n mu ọwọ agbofinro dani fun aabo ni Enugu Ogun: Kò tìí dábì pé ètò ìdìbò abẹ́lé yóò wáyé ní ìpínlẹ̀ Ogun.
Bakan naa lo kawe sii ni fasiti Carlifornia Western University, fasiti ọlọgba ẹranko nibiti sanmọnti gbe dunlẹ ni Ibadan ati ni fasiti California Coast University nibi to ti gba oye ọmọwe ninu interdisciplinary engineering.
Dino kin ọrọ re lẹyin pẹlu abadofin tuntun ti Aare Buhari buwolu.
Heburoni ni wọ́n sin òkú Abineri sí, ọba sọkún létí ibojì rẹ̀, gbogbo àwọn eniyan sì sọkún pẹlu.
Agbenuso igbimo naa tun so pe ,awon eniyan ti iye won ko din ni ẹgboókànlá ni won ti foruko sile lara awon eniyan  to le ni , ẹgbàáta ti igbimo naa ti pese ijokoo fun  .
Bóya àwọn ènìyàn wọ́nyìí yóò wá dúró sẹ́yìn ọmọ wọ́n ni sáá yií, àwọn náà yóò sọ ẹni ti yoo jáwé olúbori.
Mukadam tumọ si ẹni ta to siwaju, ẹni kan lo tii siwaju pe ko maa dari ìjọ eeyan kekere kan, oun naa tun ni ọga.
Mo wá rí i wàyí pé, ó ti di bárakú fún mi, pé nígbà tí mo bá fẹ́ ṣe rere, àwọn nǹkan burúkú ni ó yá sí mi lọ́wọ́.
Èwo ninu wọn ni ó lè kéde irú àsọtẹ́lẹ̀ yìí,tí ó lè fi àwọn ohun àtijọ́ hàn wá;kí wọn pe ẹlẹ́rìí wọn wá, kí á lè mọ̀ pé ẹjọ́ wọn tọ́,kí àwọn ẹlòmíràn lè gbọ́, kì wọn sì jẹ́rìí pé, “Òtítọ́ ni.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Coronavirus in Nigeria: Ẹ wo àǹfààní tó wà nínú àrùn Coronavirus Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Coronavirus in Nigeria: Ẹ wo àǹfààní tó wà nínú àrùn Coronavirus 23 Ẹrẹ̀nà 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 31 Ẹrẹ̀nà 2020 Awọn onimọ ti ṣe iwadii pataki to fi ọna lati kapa Coronavirus lede.
Lẹ́yìn ọdún meji tí nǹkan yìí ṣẹlẹ̀, Absalomu lọ rẹ́ irun aguntan rẹ̀ ní Baali Hasori, lẹ́bàá ìlú Efuraimu, ó sì pe gbogbo àwọn ọmọ ọba patapata lọkunrin sibẹ.
Láti orí 'Our Mumu don do' sí 'Revolution Now' Ọlọ́pàá àti àwọn olùfẹ̀hónúhàn gbéná wojú ara wọn níbi ìwọ́de Revolution Now Ìwọ́de #RevolutionNow forí ṣánpọ́n ní Ibadan, àgbófinró gbàkóso ojú pópó Sowore àti àwọn ọmọ ẹgbẹ Revolution Now kò ṣẹ̀ ṣófin lórí ìwọ́de, ẹ tú wọn sílẹ̀ - NLC Sulaiman Adeniyi tẹsiwaju pe, yoo tun jẹ ọna kan pataki lati ṣe iranti ọdun kẹwa ti oloye Gani Fawehinmi di oloogbe.
"Mo kere diẹ nigba ti mo bẹrẹ ere tiata, bii ẹni ọdun mejidinlogun si mọkandinlogun nigba ti mo wa nile iwe girama, awada ti mo n ṣe lo si mu ki awọn eeyan fi gba mi nimọran pe, ki n lọ ṣe iṣẹ tiata.
2019 Elections: NBC na Channels TV àti ilé iṣẹ́ ìròyìn 44 ní pàsán Ètò tí mo ní fún Kwara yàtọ̀ sí ti ANRP ni mo ṣe fẹgbẹ́ wọ́n sílẹ̀ - Yinka Ajia 2019 Election: Àwọn oloṣelu tó yege àti àwọn to fidirẹmi #Otogelagos: 'Ọlọ́pàá kọ́ ló da ìpàdé àwọn alátakò Tinubu rú' Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Yinka Ajia: ìbẹ̀rù Ọlọrun ni mo fẹ́ fi tukọ̀ Kwara ti mo ba wọlé Gẹgẹ bi o ṣe sọ, o ni iye awọn eeyan to jade fun eto idibo apapọ to kọja lo fẹẹ kere julọ lati igba ti orilẹede Naijiria ti pada sinu eto iṣejọba tiwantiwa lọdun 2019.
gbodo tete dojuko wahala to wa lori eto aabo ni awon ekun naa, ki o to di iru wahala
Ẹ kò ì tíì mọ̀ sibẹ, tabi òye kò ì tíì ye yín?
nipinle Ebonyi lo ti fowo si atundi sipo aare Buhari ati Umahi pe ko maa ba ise
‘Èkó gba olè, ó gba ọ̀lẹ’, bí ọ̀rọ̀ Yorùba.
Ṣé o fẹ́ sọ pé mò ń ṣe àìdára ni?
Má mójú fo àìdára wọn, má sì pa ẹ̀ṣẹ̀ wọn rẹ́ kúrò ninu àkọsílẹ̀ tí ó wà níwájú rẹ, nítorí pé wọ́n ti mú ọ bínú níwájú àwọn tí wọn ń mọ odi.
Kí ni oriṣa ń wá ninu ilé Ọlọrun?
Sọ àsọtẹ́lẹ̀ orílẹ̀èdè tí yóò borí ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ t'òní Ò ti pé ọdún 27 tí Shah Rukh Khan ti ń se fíìmù India Ọlọ́pàá ìpínlẹ̀ kọ́ ní ojútùú ìṣòro ìjínigbé ilẹ̀ Yoruba - Onímọ̀ ọ̀rọ̀ ààbò Buhari ṣàlàyé ìdí tó fi yọ Onnoghen fún Afẹ́nifẹ́re Yoruba Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Ẹ kò fowó yín ra turari olóòórùn dídùn fún mi,tabi kí ẹ fi ọ̀rá ẹbọ yín tẹ́ mi lọ́rùn.
Ipinlẹ Eko ni orilẹ-ede Naijiria ati ni Apa Iwo-oorun ilẹ Afirika ṣe pataki
Dino Melaye kan sárá sí ààrẹ àná, Jonathan, ó ní irú olóṣèlù rẹ̀ ṣọ̀wọ́n láwújọ
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Itaniji: Oluwo sọ ìtàn bí Orunmila ṣe jìyà nílùú Iwo àti ayọ̀ tó gbẹ̀yìn rẹ̀ torí sùúrù Ti emi ko ba si se ijamba fun maalu rẹ, ki lo de to fi yẹ ki iwọ ba awọn ire oko mi jẹ.
Ajọ eleto idibo Naijiria kede isunsiwajuiboAarẹ ati tawnile asofin orileede Naijiria lati ọjọ kẹrindinlogun Oṣu keji si ọjọ kẹtalelogun Oṣu keji ti idibo Gomina to yẹ ki o waye lọjọ keji Oṣu kẹta ti sun si ọjọ kẹsan Oṣu kẹta .
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Coronavirus: Pásítọ̀ Adeboye ní òun faramọ́ ìmọ́tótó, ṣùgbọ́n àwàdà ni ìgbésẹ̀ àwọn ìjọba lágbáyé láti kojú Coronavirus 22 Ẹrẹ̀nà 2020 Oríṣun àwòrán, PAstor enoch adeboye Pasitọ Enoch Adejare, oluṣọagutan agbafun ijọ Redeemed Christian Church of God , RCCG lagbaye ti sọ wi pe awọn igbesẹ ti ijọba n gbe lati wawọ arun Coronavirus bọlẹ lagbaye ati paapaa julọ lorilẹede Naijiria jẹ eyi to n pani lẹrin pupọpupọ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ǹjẹ́ àrùn Coronavirus leè wà lára èèyàn títí láílái?
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Wo àwọn ọ̀nà tí o lè gbà láti di ọjọ́ ogbó pẹ̀lú olólùfẹ́ rẹ ''Paapaa ilu Akure, wọn fihan pe awọn ṣetan lati jẹ ki ọmọ wọn di gomina ipinlẹ naa pẹlu bii wọn ṣe dibo wọn fun ẹgbẹ oṣelu PDP'' ''Amọ, a o tẹsiwaju lati ma a rọ awọn ẹkun to ku nipinlẹ Ondo, lati fi ọwọ sọwọpọ fun gomina to wa lati ilu Akure, nipinlẹ Ondo.
A si lee pe akoko ti bia lee ba ara mu ni igba ewe si ọdun marundinlogoji, lati akoko yii lọ, isọwọ sisẹ eroja to n mu ki ounjẹ tete da ninu ara, ko ni sisẹ bo se yẹ mọ.
Oríṣìíríṣìí igi eléso yóo hù ní ẹ̀gbẹ́ kinni keji odò náà: ewé àwọn igi náà kò ní rọ, bẹ́ẹ̀ ni èso wọn kò ní tán.
Ṣé wọn yóo lè yọ àwọn òkúta kúrò ninu àlàpà tí wọ́n wà, kí wọn sì fi òkúta tí ó ti jóná gbẹ́ òkúta ìkọ́lé?
 gẹ ́ gẹ ́ bí olùkọ ́ , ó dá ẹgbẹ ́ ìṣọ ̀ kan àpapọ ̀ àwọn olùkọ ́ tí ìjọ kátólííkì ( catholic ) láti lè ma bá àwọn aláṣẹ àti olóòtú àgbà sọ ̀ rọ ̀ fún ìgbáyé gbádùn àwọn olùkọ ́ wọn .
Ṣugbọn Joṣua wà pẹlu àwọn eniyan ní gbogbo òru ọjọ́ náà.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù UNICEF: Ẹ̀rọ ìbánisọ̀rọ̀ pọ̀ ju ilé ìgbọ̀nsẹ̀ lọ l'órílẹ̀-èdè Nàìjíríà 18 Owewe 2018 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ida mọkandinlogoji ninu ọgọrun awọn ọmọ orilẹede Naijiria ni wọn lanfani si ile igbọnsẹ to jẹ pe idile kan nikan lo n lo o Ẹ gbọ na, ninu ẹrọ ibanisọrọ ati ile igbọnsẹ ewo gan lo ṣe pataki ju?
nígbà tí agbo mààlúù yín ati agbo aguntan yín bá pọ̀ sí i, tí wúrà ati fadaka yín náà sì pọ̀ sí i, tí ohun gbogbo tí ẹ ní bá pọ̀ sí i, 
Ẹ wo àwọn ilànà tuntun tí ìjọba Nàìjíríà kéde lẹ́yìn tó fi kún ìséde Covid-19 Ni bayii, dipo aago mẹwa alẹ si mẹrin idaji, aago mejila oru si mẹrin idaji ni isede yoo fi ma wa.
Agbaọjẹ oṣere, Joke Silva aya Gbajugbaja oṣere Olu Jacob ba BBC Yoruba lalejo ni olu ile iṣẹ wa.
Kò sí iṣẹ́ ti èèyàn kò lè yàn láàyò ni kete ti o ba ti ṣawari ẹbun ti Ọba òkè fi jinki rẹ.
Gbogbo awọn ti o ba ti fi ọkan si ati lọ ra ọja loni ọjọ Ẹti nilu Akurẹ ko ni le e ṣe bẹẹ nitori Kabiyesi Deji ti ilu Akurẹ ti kede pe titipa ni ki gbogbo ọja ko wa.
Wọ́n fi owó náà ṣe àwọn ohun èlò fún ìsìn ati ẹbọ sísun ní ilé OLUWA, ati àwo fún turari ati ohun èlò wúrà ati fadaka.
Ṣugbọn ṣa, abẹwo ti BBC ṣe si papakọ ofurufu ni owurọ kutukutu ọjọ kẹjọ, oṣu Keje, fihan pe, nkan ko lọ leto-leto.
Onítọ̀un sì wí fún un pé òun fún un ní ọjọ́ mẹ́ta kí o fi máa wá owó náà kiri, àti pé bí kò ba riri, òun ó pèé ni ẹjọ́ ẹ̀wọ̀n.
Lẹ́bàá odò Babiloni ni a jókòó, tí a sọkún,nígbà tí a ranti Sioni.
Wọn á di ẹrù wúwo, wọn á gbé e ka àwọn eniyan lórí, bẹ́ẹ̀ ni àwọn fúnra wọn kò sì jẹ́ fi ọwọ́ wọn kan ẹrù náà.
Bakan naa la tun n boju wo ipese eto adojutofo ati awọn nkan mii to jẹ mọọ, ti ọpọ osisẹ ikọ Amotekun si jẹ osisẹ to n sisẹ idabọ.
Bí o bá pada sí ìlú, tí o sì sọ fún Absalomu, ọba, pé o ti ṣetán láti sìn ín pẹlu ẹ̀mí òtítọ́, gẹ́gẹ́ bí o ti sin èmi baba rẹ̀, nígbà náà ni o óo ní anfaani láti bá mi yí ìmọ̀ràn Ahitofeli po.
Eyi ni pẹtẹẹsi akọkọ (storey building) lorilẹede Naijiria: Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Ó sọ fún un pé, “Kí ló dé tí o fi ń gbọ́ ti àwọn tí wọ́n ń sọ pé mo fẹ́ pa ọ́?
''Ọlọpaa kọlọpaa to ba tapa si awọn ilana ati ofin wọn, yoo foju wina ofin.
Adebayo Ogunlesi: ọmọ ọjọgbọn onimọ iṣegun to ra papakọ ofurufu Gatwick lọwọ èèbó Oríṣun àwòrán, others Àkọlé àwòrán, Ọdun 1988 ni o kẹkọọ gboye ninu imọ iṣegun oyinbo ati iṣẹ abẹ.
Oríṣun àwòrán, Instagram/lisahannamp Àkọlé àwòrán, Arabinrin Hanna ti ṣoju ẹkun idibo rẹ nile aṣofin lẹẹmẹta ọtọọtọ Taa wa ni Lisa Hanna to nb da ori ayelujara ru yi jẹ?
Ile aṣofin Kwara da'ba fif'opin s'owo osu ọna meji
Gomina Dickson fidunnu re han lori ona Ogbia-Nembe naa ni eyi ti o si agbegbe merinla si ojutaye.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Baṣọ̀run Gáà, tó yan ọba mẹ́rin, pa ọba mẹ́rin àmọ́ ọba karùn-ún ló pa á Ọbasanjọ sọ àsírí sàgbàdèwe rẹ̀ Wọ́n ta ère Ọ̀ṣun Osogbo sí Togo - Bàbá Ọṣun figbe ta Amọ o ni bi o tilẹ jẹ pe wọn ni ki oun dakẹ nigba tọrọ yii sẹlẹ ni 2011, sugbọn oun ke sita loju opo Twitter, ti oun si da ẹgbẹ kan silẹ lọdun 2013, ti yoo fun awọn to ba lugbadi ifipabanilopọ ni anfaani lati ke sita.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fọ́nrán ohùn, Nigerians Evacuated from UK: Ko tẹ́wa lọ́rùn bi ijọba ṣe ń ṣe wá Folashade Yemi-Esan, adarí ẹ̀ka òṣìṣẹ́ tuntun tí ààrẹ Buhari yàn Oríṣun àwòrán, Folasade Omolara Yemi-Esan/Facebook Àkọlé àwòrán, Folasade Omolara Yemi-Esan Lọjọru ọsẹ ni aarẹ Muhammadu Buhari yọ adari ẹka awọn oṣiṣẹ ọba Naijiria, arabinrin Winnifred Oyo-Ita to si yan akọwe agba ile iṣẹ to n ri si ọrọ epo rọbi, Ọmọwe Folashade Esan lati rọpo rẹ gẹgẹ bii adele.
Oṣere tiata Yoruba, Damọla Ọlatunji ni o fẹ, Eduwa si ti fi ibeji lanti-lanti ta wọn lọrẹ.
Ó fa àwọn ará Jerusalẹmu sinu aiṣododo, ó sì kó àwọn ọmọ Juda ṣìnà.
Asoju agba kan so pe, “o je ife okan awon omo ajo isokan EU lati je ki alaafia joba ni ekun naa”.
Won kede ipinnu yiyonda awon odo naa fun ile Saudi Arabia ti o je ore timo-timo,  ti  o tun ti seranlowo egbelemukun owo dollars fun orile-ede Egypt  ni odun 2016,Ile-ejo ti o ga ju naa so pe, ko si ile-ejo ti o ni ase lori oro naa, eyi ti o gbegidina awon adajo meji, okan lati ile-ejo agba kan, ti a mo si Supreme Administrative Court eyi ti o tako yiyonda isakoso awon odo meji naa, enikeji lati ile-ejo ti o n ri si oro pajawiri, ti a mo si Court of Urgent Matters, eyi ti o ri ipinnu naa bi adanu.
’Ṣugbọn àwọn akọ̀wé ti fi gègé irọ́ wọn sọ ọ́ di èké.
Eléyìí fa ìdàrúdàpọ̀, nínú èyí tí àwọn òṣìṣẹ́ fi fọ́nká, tí olúkúlùkù sì sá àsálà fún ẹ̀mí rẹ̀.
Mohammed Adoke: Oríṣun àwòrán, Twitter Ajọ EFCC fi ẹsun kan Adoke pe o pin ninu owo katakara epo rọbi Malabu oil Deal, to le ni biliọnu kan owo ile okeere.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Adebayo Faleti: Ọdún mẹ́ta lẹ́yìn Adebayo Faleti, ìran Yorùbá ń ṣe ilédè rẹ!
Ọlọ́pàá Funso ló fi ààyè sílẹ̀ fún mi láti sa kúrò ní àgọ́ ọlọ́pàá tó wà ní Mokola - Sunday Shodipe 'A ní àrídájú, a rí àwọn ẹgbẹ́ ISIS pẹ̀lú àlùpùpù olówó ńlá, ọmọ Yoruba ẹ funra -Gani Adams Báwo ni obìnrin ṣe ń ní ìtura ìbálòpọ̀?
Ninu iwaasu naa ni wolii ọhun ti sọ pe ibalopọ to ba ti ju iṣeju marun lọ kii ṣe ibalopọ mọ, nitori ibalopọ aladun ko gbọdọ ju iṣeju marun un lọ."
Oun gbogbo lori top 4 ni orin to ku ti ẹgbẹ agbabọọlu Chelsea nkọ bayi amọ ki orin naa to le dun lẹnu wọno jọ pe wọn yoo ṣi yi duro diẹ si.
” Ṣugbọn nígbà tí ó jí láti ojú oorun rẹ̀, ó fa èèkàn ati igi òfì náà tu.
"Ààrẹ ní, ""Nígbà tí Lai Mohammed bẹ̀rẹ̀ sí ní tara nípa lẹ́ta tí wọ́n kọ nípa àwọn àiṣedáadáa wa, mo ní rárá, kí ó máa lọ."
Nígbà tí àwọn ẹṣin Farao, ati àwọn kẹ̀kẹ́ ogun rẹ̀, ati àwọn ẹlẹ́ṣin wọ inú òkun, OLUWA mú kí omi òkun pada bò wọ́n mọ́lẹ̀, ṣugbọn àwọn eniyan Israẹli rìn lórí ìyàngbẹ ilẹ̀ láàrin òkun.
Meji ninu wọn lo si ti jade laye.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 67 year old mother: Mo kojú ọ̀pọ̀lọpọ̀ àìsàn fún ọdún 35 lẹ̀yín ìgbéyàwò Igba to de ile lo ran ọmọ rẹ to kere julọ lati lọ ọ pe ẹgbọn oun kan wa, ni adugbo ti ko jinna si wọn.
Nígbà tí o dé, ó jí mi kalẹ̀, o kí mi dáadáa, o ni ko nn ma ṣe jẹ́ ki àyà mi já, n ó ṣẹ́gun àwọn ẹranko.
Oríṣun àwòrán, @GovUmarGanduje Ahesọ ọrọ ni Ṣugbọn ijọba ìpínlẹ̀ Kano ti fi àtẹ̀jáde kan síta lálẹ́ ọjọ aiku pé, àwọn yóò gbe ile iṣẹ́ ìròyìn náà àti akọ̀ròyìn Jafar Jafar lọ sílé ẹjọ́, ní tori pé wọn ń gbìyànjú àti ba gómìnà lórúkọ jẹ́ ni.
Nigeria Ọjọ keje, oṣu kẹwaa, ọdọọdun ni ajọ iṣọkan agbaye, UNO ya sọtọ fun ayajọ ọjọ ibugbe ati lati ranti awọn ti wọn o rile gbe.
O ni nigba ti wọn fi ọrọ wa ọlọpaa naa lẹnu wo, o jẹwọ wipe ootọ ni pe oun lo wa ninu fidio naa, ni wọn ba ṣe idajọ ranpẹ ti awọn ọlọpaa fun un, ti wọn si gba aṣọ lọrun rẹ.
ede Somalia ti kọwe fipo rẹ sile lọjọ kinni osu karun un yii, lori ede ayede to
Iléẹ́jọ́ fún EFCC l’ásẹ láti gbégi lé owó Ayodele Fayose
''Nitori naa ni ijọba, awọn oloṣelu ati awọn adari ijọ gbọdọ fi ọwọ sowọpọ lati rii wi pe awọn eniyan tẹle ofin to rọmọ didẹkun itankalẹ arun Coronavirus ni Naijiria'' ''Ti a ba wo awọn orilẹede miiran lagbaye, ohun ti a ri ni pe ti ijọba ba ti dẹ ofin konile o gbele, ti awọn eniyan si pada si igbeaye wọn tẹlẹ, arun naa ni peleke sii ni, ti o si n mu ọpọlọpọ ẹmi lọ.
7 Owewe 2019 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Ẹni tí ó bá gba ẹ̀rí rẹ̀ gbà dájúdájú pé olóòótọ́ ni Ọlọrun.
Ninu akosile ti  alukoro fun egbe PDP, Kola Ologbondiyan ati oludije fun ipo gomina labe asia egbe PDP Kola Ologbondiyan, naa  gbe sita pe awọn ko ni gba esi idibo naa wọle.
Awọn iyalọmọ ko ni imọ kikun nipa ifọmọlọyan tori ko si iru imọ ti wọn nilo yii larọwọto wọn.
Bakan naa ni wọn fikun pe afiniṣẹsin ni ọpọlọpọ awọn oṣere ni Naijiria, ti wọn si n wa isubu ẹnikeji wọn.
Bàbá Prasek yii lo sadede ri òkú ọmọ rẹ̀ nínú ilé kìnìún, to sí ké sí àwọn akọròyìn abẹ́le lati kede ohun to ṣélẹ̀ àti pé, ilẹkùn ilé kìnìún náà wà ni títì sínú.
Nítorí náà, wọ́n bẹ̀rẹ̀ sí wá ọdọmọbinrin tí ó lẹ́wà gidigidi ní gbogbo ilẹ̀ Israẹli.
Nigeria Elections 2019: Ìjàmbá iná àti àwọn nkan mi i tó mú INEC sún ìdìbò
Isẹ apanilẹrin ni wọn yan laayo, atiwipe Baba Sala lo kọkọ bẹrẹ isẹ amuludun ati orin takasufe lorilẹede Naijiria ni ọdun 1964, to si jẹ olukọ fun ọkan gboogi lara awọn adari orin juju ni orilẹede Naijiria, King Sunny Ade.
Àwọn èkúté ni wọ́n ṣáa’jú, láàrin àwọn èekúuté yìí pẹ̀lú, ẹ̀lírí kkékeré ni aṣáájú pátápátá.
Ẹ́ gba fóónù, ẹ pe ẹbí yín pé a fẹ́ dáná ṣun yín - Aráàlú sọ fún adigunjalè méji Ẹ̀kọ́ ńlá: Ìtàn Gbọnka àti Timi, akọni méjì tó borí Aláàfin Ṣango Lisabi Agbongbo Akala rèé, ẹni tó fi ìfẹ́, ìṣọ̀kan àti ìrẹ́pọ̀ gba ilẹ̀ Ẹ̀gbá lọ́wọ́ ìmúnisìn Ìtàn Manigbagbe: Àwọn àjakalẹ-àrun to ti wáyé rí ṣáájú Coronavirus Afonja gba awọn Fulani naa tọwọ tẹsẹ, to si beere iranwọ Alimi lati jagun sẹgun lori ogun Apomu, nitori onitọHun naa ni ọmọ ogun pupọ ati oogun abẹnu gọngọ to daju.
"Oríṣun àwòrán, Ajirebi1 Instagram ""Mo dupẹ pupọ lọwọ Funke Akindele fun iranwọ owo to fun mi."
Púpọ̀ nínú àwọn Ifẹ̀ kìí kọlà, ṣùgbọ́n àwọn míràn nkọ mẹ́ta-mẹ́ta nígbà míràn.
Nígbà tí wọn sì tún máa ṣe yẹ̀yẹ̀ ń kọ́, wọn ní ó pẹ́ tí àwọn náà ti ń wò mi ti ìfẹ́ náà ń tì mi kà bí ẹni tí ẹmu ń pa kí, orí mi má sa jẹ́ ki ìfẹ́ tì mi sí kòtò ni.
Obinrin tí ó bá jẹ́ opó ati obinrin tí ó ti kọ ọkọ rẹ̀ gbọdọ̀ san ẹ̀jẹ́ wọn.
2 % , awon miran 5.
Eli bi í pé, “Kí ni OLUWA wí fún ọ, má fi nǹkankan pamọ́ fún mi.
Mo mo wi pẹ ko wọpọ ki ọmọ orilẹẹde Eritrea ma kopa ninu idije bayi sugbọn awa ọmọ Eritrea jẹ ẹni to ni ife ilẹ wa lọkan.
' Nigba to tun n sọ nipa ọpọ anfaani to wa nidi ki awọn osisẹ Amotekun fi orukọ silẹ lori ayelujara, Olayanju ni o see ṣe ki igbanisisẹ wọn fi sinu ẹgbẹ kan ju ọkan lọ laarin ẹgbẹ ọlọdẹ, onimọto, agbẹkọya ati OPC.
Ǹjẹ́ ojú rẹ dàbí ti eniyan?
Amọṣa, oludije fun ipo gomina lẹgbẹ oṣelu PDP, Ademọla Adeleke ti gba ile ẹjọ lọ pẹlu awijare pe oun ni o bori atipe ka yọwọ awọn iwa aitọ to sọ pe o waye lasiko idibo naa kuro, oun lo yẹ ki ajọ INEC kede gẹgẹ bii gomina.
Oríṣun àwòrán, Bukola Saraki/Facebook Àkọlé àwòrán, Bukola Saraki rọ́pò abúrò rẹ̀ obìnrin Gbemisola Saraki-Forowa gẹ́gẹ́ bí sẹnẹtọ O jawe olubori ninu ibo naa, o si rọpo aburo rẹ obinrin Gbemisola Saraki-Forowa ti o n ṣoju ẹkun naa tẹlẹ, lai naani atako baba rẹ, to n gbè lẹyin aburo rẹ lati di gomina ipinlẹ Kwara.
Kí ló dé tí ẹ fi wá sọ́dọ̀ mi nígbà tí ìyọnu dé ba yín?
Ṣé ojú Frank Lampard àtàwọn agbábọ́ọ̀lù Chelsea tí wọ́n ń gbá lọ́tùn ún lósì kò ní fọ́ báyìí?
Ó sì mú àwọn ohun ọ̀ṣọ́ olówó iyebíye tí a fi fadaka ati wúrà ṣe jáde, ati àwọn aṣọ àtàtà, ó kó wọn fún Rebeka.
Ryan Coogler lo dari sinima “Black Panther” nibi to ti na igba milionu owo dola fun atunse leyin aworan yiya ti o de jawe olubori laarin awon sinima egbe re lataari pe o pa milionu metadinlogbon o le nirinwo owo dola wole laarin ojo merin ti fiimu naa jade sita.
Ubosi salaye pe, alekun owo naa pon dandan lati le faye gba awon ise-akanse opopona ipinle naa ti o nilo aboju to ni kiakia.
ÒWE: A kó bá ni l’Èkúté ilé, Ejò kìí j’àgbàdo
Bákan nàá ni pé à n fún ìwé ẹ̀rí ní àpọ́nlé ju ìmọ̀ lọ l'órílẹ̀èdè Nàìjíríà.
Lẹyin eyi ni Muyideen Aromirẹ gbe sinima agbelewo akọkọ, to pe akọle rẹ ni 'Ẹkun' jade ni ọdun 1988.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Abiola Ajimobi: Bàbá mi jẹ́ aránsọ, ìyá mi sì jẹ́ ọlọ́jà wóróbo 11 Ìgbé 2019 Oríṣun àwòrán, Tobi James Àkọlé àwòrán, Gọ́mìnà ìpínlẹ̀ Ọyọ tẹ́lẹ̀rí, Abiola Ajimobi ti sọ ìtàn ìgbìyànjú rẹ̀ gẹ́gẹ́ bí ọmọ atàpátadìde títí tó fi gòkè àgbà.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ibrahim Chatta: Ó gba àwọn òṣèré tíátà nímọ̀ràn láti máa ṣaájò ẹgbẹ́ wọn 28 Ògún 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 8 Owewe 2020 Oríṣun àwòrán, ibrahimchatta_lordthespis Ilumọọka osere tiata, Ibrahim Chatta ti dupẹ lọwọ gbogbo awn eeyan to se aajo rẹ lori aworan to gbe soju opo Instagram rẹ lọjọ Abamẹta.
 a rí i pé ẹ ̀ gbọ ́ n àti àbúrò ni wọn .
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Tillerson: Owo yiya lọwọ orilẹede China lewu fun Afirika 8 Ẹrẹ̀nà 2018 Oríṣun àwòrán, AFP/Getty Images Àkọlé àwòrán, Orilẹede China ti di ọkan pataki laarin awọn orilẹede ti o ni ajọsepọ okoowo to pọ julọ ni ilẹ Afirika Minisita fun ọrọ ilẹ okeere lorilẹede Amẹrika, Ọgbẹni Rex Tillerson ti kilọ fun awọn ijọba orilẹede gbogbo ni ilẹ Afirika lati sọra fun yiya owo lọwọ orilẹede China.
 bákan náà ni a pín àwọn pọ ́ n-na tí a rí nínú àwọn ìwé yorùbá díẹ ̀ sí ìsọ ̀ rí .
Oríṣun àwòrán, AFP Ileewe alakọbẹrẹ ati awn ileewe girama lọrọ yi kan ni ariwa Paris nibi ti eeyan meji to padanu mi wọn lọwọ aisan yi n gbe.
How to make cake Who be Aisha Yesufu?
Owó orí tí fásitì OAU jẹ la gbọ́ wí pé, ó jẹ́ owó orí àwọn òṣìṣẹ́ rẹ, èyí tí kò san sínú aṣuwọ̀n ìjọba ìpínlẹ̀ náà lọ́dún 2015 si 2016.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ayefẹlẹ - Ara ìjọba ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́ kọ òtítọ́ ní wọ́n ṣe fẹ́ wó iléèṣẹ́ rédíò mi 'Am in pains' - Ayodele Fayose / Oṣu keje, 2018 Awọn oloṣelu naa a ma sunkun.
Àwọn ọmọ Manase ni wọ́n ni ilẹ̀ Tapua, ṣugbọn ìlú Tapua gan-an, tí ó wà ní ààlà ilẹ̀ àwọn ọmọ Manase, jẹ́ ti àwọn ọmọ Efuraimu.
Nígbà tí mo wà ní ọmọde lọ́dọ̀ baba mi,tí mo jẹ́ ẹni ìkẹ́, ọ̀kan ṣoṣo lọ́wọ́ ìyá mi,
26 Bélú 2020 Elon Musk, Ọ̀gá àgbà iléeṣẹ́ SpaceX, Tesla CEO ń bá Bill Gates du ipò ẹni tó lówó jùlọ ṣèkejì lágbayé26 Bélú 2020 Ilé ẹjọ́ tú ìgbéyàwó ọdún mẹ́wàá ká nítorí ẹ̀sùn ìbálòpọ̀ ọlọ́jọ́ gbọọrọ àti òògùn owó26 Bélú 2020 Fídíò, Akọ́mọlédè àti Àṣà lórí BBC Yorùbá: Kọ́ síi nípa iṣẹ́ tí oúnjẹ ń ṣe lára níbí24 Bélú 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Buhari ṣí olú iléeṣẹ́ tuntun fún EFCC EFCC p'oṣiṣẹ banki l'ẹjọ ‘Àwọn asèbàjẹ́ gbọ́dọ̀ fi ẹ̀wọ̀n ju 'ra’ EFCC tun gbe Akala yọju sile ẹjọ Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Wọ́n wá ń sọ pé, “Ìlú wo ni ó dàbí ìlú ńlá yìí?
Ko da ilu Zealand gan to da wa nibi to wa pada ni lẹyin igba diẹ ti wọn o ni tẹlẹ.
’ Ọba tún dáhùn o ni, ‘Ibi tí o ti ń nà mì ni adé mi ti ṣí bọ́ sínú odó, n kò tilẹ̀ mọ ibi tí ó wà báyìí.
Sipora bá mú akọ òkúta pẹlẹbẹ tí ó mú, ó fi kọ ilà abẹ́ fún ọmọ rẹ̀, ó sì fi awọ tí ó gé kúrò kan ẹsẹ̀ Mose, ó wí fún Mose pé, “Ọkọ tí ọ̀rọ̀ rẹ̀ gba kí á ta ẹ̀jẹ̀ sílẹ̀ ni ọ́.
 to se alaisi lenu ise .
Awọn ọlọpa sọọ nigba naa wipe ajodeeru ni awọn eeyan naa jo.
O si tun le nira lati yawo ni banki.
Ẹ fa àwọn tí igbagbọ wọn kò tíì fẹsẹ̀ múlẹ̀ mọ́ra, kì í ṣe láti máa bá wọn jiyàn lórí ohun tí kò tó iyàn.
Oríṣun àwòrán, @PoliceNG Àkọlé àwòrán, Ibrahim Idris, ọga agba ọlọpa Naijiria Idi rẹ ti o fi da bi wi pe awọn ọmọ Naijiria ko gbagbe rẹ ni bi o ti ṣe n kalolo nibi to ti n sọrọ lode kan nibi ti o ti fẹ ṣe ifilọlẹ kan.
Ọjọ́ ori nlọ sókè ṣùgbọ́n ki wá lẹ̀.
Alaafia ni wọn yóo fi gbin èso wọn, àjàrà wọn yóo so jìnwìnnì, òjò yóo rọ̀, ilẹ̀ yóo sì mú èso jáde.
BIAFRA at 50: Ìhàlẹ̀ ológun ni Gowon ni ká kọ́kọ́ fi bẹ̀rẹ̀- Aladejẹbi
Lara awọn inagijẹ yi la ti ri ''Intercontinental Ballistic Missile Commentator,.
Idije bọọlu afẹsẹgba ilẹ adulawọ AFCON 2019 naa wa lara awọn to lewaju ti Naira Marley tun ja wọ abala yi to fi mọ ibeere nipa Women's World Cup 2019 ati Xenophobia.
Liverpool fi pẹnriti na Chelsea ninu idije UEFA Super Cup to waye niluu Istanbul lorilẹede Turkey.
George Bush: Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Aarẹ Buhari kọ ni aarẹ akọkọ ti yoo foju wina atako awọn eeyan rẹ ti wọn yoo gbe ka ori pepele itiju kaakiri agbaye Lasiko ti o fi n ba awọn oniroyin sọrọ ni aafin olotu ijọba orilẹede Iraq to wa ni ilu Baghdad, aarẹ orilẹede Amẹrika nigba naa pẹlu foju wina irufẹ idẹyẹsi to fa idoju nlanla kaakiri agbaye nigba ti akọroyin kan, Muntadhar al-Zaidi ju bata ẹsẹ rẹ lu aarẹ George Bush.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù NUPENG Strike: Ẹgbẹ́ àwọn awakọ̀ epo rọ̀bì NUPENG so ìyanṣẹ́lódì tí wọ́n gùnlé l'Eko rọ̀ 10 Ògún 2020 Oríṣun àwòrán, @Gidi_Traffic Ẹgbẹ awọn awakọ epo rọbi ni Naijiria, NUPENG ti so iyanṣẹlodi ọlọjọ gbọọrọ to gunle lọjọ Aje ni ipinlẹ Eko rọ.
Wo iye owó tí ìjọba Amẹrika ń na sí ìdìbò Ààrẹ àti ibi tí owó náà ti ń wá Banki Nàìjíríà, CBN ṣàlàyé nípa àwọn tó máa rí gbà nínú owó ìrànwọ́ N75b tíjọba gbé kalẹ̀ Mọ̀ sí i nípa àwọn ọmọ Nàìjíríà mẹ́sàn-án tó ń díje nínú ìdìbò ilẹ America lọ́jọ́ Ìṣẹ́gun US Election 2020: Ṣé èsì ìdìbò Ààrẹ Amẹrika yóò jáde lálẹ́ ọjọ́ ìdìbò?
Nítorí náà Dafidi pàṣẹ pé, “Ibí yìí ni ilé OLUWA Ọlọrun, ati pẹpẹ ẹbọ sísun yóo wà fún Israẹli.
Lyon ni oun fi iwe ẹri naa sọ ori awọn eniyan ipinlẹ Bayelsa lẹyin to dupẹ lọwọ ajo INEC, awọn agbofinro ati awọn oṣiṣẹ elto aabo gbogbo pe wọn ṣiṣẹ daadaa.
25 Owewe 2020 Donald Trump: Àwọn obìnrin ilé ìgbìmọ̀ aṣòfin Amẹrika fọnmú sí ọ̀rọ̀ Trump16 Agẹmo 2019 TrumpBanned: Twitter ní ó tó gẹ́ ,o yọ Ààrẹ́ Donald Trump dànù lórí ẹ̀rọ títí láé9 Sẹ́rẹ́ 2021 Àtẹ Àwòrán, Donald Trump: ṣàbẹ́wò ọlọ́jọ́ mẹ́ta sílẹ̀ gẹ̀ẹ́sì6 Òkùdu 2019 2:18 Fídíò, Robert Mueller ló ni kọ́kọ́rọ́ ìwádìí Donald Trump àti Russia lọ́wọ́, Duration 2,1825 Ògún 2018 Trump yóò gbàlejò Buhari nílé ìjọba16 Ìgbé 2018 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 3 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 5 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
 “O je akinkanju eniyan, ti o fe lati fi gbogbo okan re se ise re.
Bakan naa ni aarẹ ni ijọba ko ṣalai mọ nipa ohun to n ṣẹlẹ nitori naa ki ara ilu ṣe ṣuuru, atunto yoo waye.
Sibẹsibẹ wọ́n kọ̀, wọn kò gbọ́.
’ Lọjọ Iṣẹgun ni ile ẹjọ paṣẹ ki awọn ọtẹlẹmuyẹ tu agbatẹru iwọde Revolution Now ti wọn fi si ahamọ lori ẹsun pe o fẹ fiditẹgbajọba silẹ.
Mo fi òdodo bora bí aṣọ,ìdájọ́ òtítọ́ dàbí ẹ̀wù ati adé mi.
Maihaja tun so pe ajo NEMA ti n se gudu gudu meje, yaya mefa lati pese eto iranwo fun awon to farapa nibi isele omiyale.
N óo fi òpin sí ayọ̀ rẹ̀ ati ọjọ́ àsè rẹ̀, ọjọ́ oṣù tuntun rẹ̀, ọjọ́ ìsinmi rẹ̀, ati gbogbo àjọ̀dún tí ó ti yà sọ́tọ̀.
Ṣugbọn kò sọ fún un pé kò ní kú.
wọ́n kó aadọtaleerugba (250) ọkunrin tí wọ́n jọ jẹ́ olórí ati olókìkí ninu àwọn ọmọ Israẹli sòdí láti dìtẹ̀ mọ́ Mose.
Bobrisky ni ipolowo awọn ọja obinrin ti oun n ta, bii ipara, ohun ẹsọ ara ati atọwọda irun obinrin lo mu ki oun maa se bii obinrin.
Nígbẹ̀hìn, ọ̀ràn yìí bí Ọlọ́run Ọba nínú, nítorí bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé àwọn ọmọ aráyé hùwà òmùgọ̀ ṣaájú rí, àwa náà tún ti hùwà ìlábùrù baba ọ̀bọ.
O ni bakan naa lawọn kan gbe irufẹ iroyin yii ṣaaju eto idibo aarẹ ọdun 2019.
Níbo ni ọ̀rọ̀ de duro bayìí?
Ni tirẹ, Andy Ruiz tọrọ aforiji lọwọ olukọni rẹ, Manny Rabbles fun jija a kulẹ.
Ní ọjọ́ tí àwọn Olófin-íntótó kọ́kọ́ dé ilé rẹ̀ tí wọ́n ń gbàdúrà ó ní kí gbgbo wọn kọ orin wá bá mì gbé olúwa.
Ọkà tí kò bá tú, kò lè lọ́mọ, bí wọ́n bá tilẹ̀ lọ́mọ, tí wọ́n sì gbó, àwọn àjèjì ni yóo jẹ ẹ́ run.
Mo sì gbọ́ tí ó wí fún àwọn yòókù pé: “Ẹ lọ káàkiri ìlú yìí, kí ẹ máa pa àwọn eniyan.
" Oríṣun àwòrán, Lere Olayinka/Facebook Àkọlé àwòrán, Ẹgbẹ́ NURTW n ja l'Ekiti Nígbà tí a kàn sí iléèṣẹ́ ọlọ́pàá, alukoro iléèṣẹ́ ní ìpínlẹ̀ Ekiti, Caleb Ikechukwu, sọ pé lóòtọ́ ni òun gbọ́ pé rògbòdìyàn wáyé láàrin àwọn ọmọ ẹgbẹ́ awakọ̀, ṣùgbọ́n òun kò ní ẹ̀kúnrẹ́rẹ́ ìròyìn nípa rẹ̀.
Igbesẹ naa ko ṣẹyin ẹsun ti wọn fi kan Trump pe, o lo ipo rẹ lati wa iranlọwọ orilẹede miran ki wọn ba le ṣakoba falatako rẹ.
Osisẹ alaanu kan labẹ ajọ isọkan agbaye sọ fun BBC pe gbogbo ile to wa nilu Beira, ti apapọ awn eeyan to to idaji miliọnu n gbe, lo bajẹ patapata.
Nígbà tí ó wọ Jerusalẹmu, ó wọ àgbàlá Tẹmpili, ó wo ohun gbogbo yíká.
Aare Muhammadu Buhari bale sipinle Katsina, ilu ti o kogun si ila oorun orile-ede Naijiria, fun ipade olojo meji.
Foluke, ẹni tó ní inú òun bàjẹ sí ìṣẹ̀lẹ̀ yìí wá ń béèrè pé, òun kò mọ idi ti àwọn èèyàn ṣe máa ń dori ọ̀rọ̀ kodò, táwọn èèyàn sì ń pe oun nípa àwọn àgbàlagbà mẹtẹẹta náà.
Oríṣun àwòrán, Kano State Government Awọn agbofinro ni itaniji ati ariwo ti awọn eeyan n pa kaakiri Naijiria lori ifipabanilopọ yii ti n ṣi oju awọn ọmọde ati obinrin si pipariwo sita lasiko.
Adele aare ,Yemi Osinbajo ti bu enu ate lu bi awọn osisẹ ile-isẹ ọtẹlẹmuyẹ se yawọ ile igbimo asofin lojoRu, lati di awon asofin ati osise ile ise naa lowo isẹ,  lai gba asẹ lati ọdọ enikankan.
A óo sì tún fẹnu kò sí ati máa dá ìdámẹ́ta ṣekeli wá fún iṣẹ́ ilé Ọlọrun wa lọdọọdun.
Ṣàánú mi, Ọlọrun, nítorí pé àwọn eniyan ń lépa mi;ọ̀tá gbógun tì mí tọ̀sán-tòru.
Oríṣun àwòrán, Others Ni kete ti isẹlẹ yii to wa leti, lawọn osisẹ wa lati ẹka ti Ijẹbu Ode ati Ago Iwoye, yara lọ sibi ti isẹlẹ ọhun ti waye, ti wọn si ko awọn oku to fori sọta ijamba naa lọ sile igbokusi, nigba tawọn to farapa wa ni ile iwosan ijọba nilu Ijẹbu Ode."
Àwọn baba ńlá mi ti pa àwọn ìlú Gosani, Harani, Resefu ati àwọn ọmọ Edẹni tí wọ́n wà ní Telasari run, àwọn ọlọrun wọn kò sì lè gbà wọ́n.
FIFA kò ní le f'òfin de Nàìjíríà lẹ́yìn tíjọba gba Amaju Pinnick ní Ààrẹ NFF
“Ṣé o lè fokùn so ìràwọ̀ Pileiadesi,tabi kí o tú okùn ìràwọ̀ Orioni?
Awọn alabaṣiṣẹ aburo mi ni awọn mejeeji to wa ninu ọkọ pẹlu rẹ.
“Bẹ́ẹ̀ ni wọn óo fi orúkọ mi súre fún àwọn ọmọ Israẹli, n óo sì bukun wọn.
Lẹ́yìn náà, OLUWA bá mi sọ̀rọ̀, ó ní, 
Eyi yoo si fa awọn iwa ti ko tọ.
Awọn ohun to niiṣe pẹlu bi eniyan ba tete ri iwosan gba si ni ọjọ ori, ọkunrin tabi obinrin ati boya ẹni naa ni aisan abẹnu tẹlẹ.
Ọ̀nà jamba ati òṣì ni wọ́n ń rìn.
Ko si agbabọọlu to tii gba ami ẹyẹ naa to Messi, ẹni to ti gba a fun igba kẹfa bayii, lati igba ti wọn ti bẹrẹ fifi ami ẹyẹ naa dawọn agbabọọlu to fakọyọ julọ lọla.
Adesina, ninu ọrọ kan to kọ ni ayajọ ọjọ ibi ọdun kejidinlọgọrin aarẹ Muhammadu Buhari salaye pe, aarẹ kii se ẹda rara, oun gan si ni, wọn ko fi ẹlomiran se rara.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù New Minimum wage: Ẹgbẹ́ òṣìṣẹ̀ yóò bẹ̀rẹ̀ ìyanṣẹ́lódì ní Jan.
Rauf Arẹgbẹṣọla Oríṣun àwòrán, @raufaregbesola Ọgbẹni Rauf Arẹgbẹṣọla, ní a bí ni ọjọ́ karundinlọgbọn, oṣù Kàrún un, ọdún 1957.
" Bákan náà lo rọ àwọn ìjọ pé, ki wọ́n fi alafo tó péye silẹ̀ dáada láàrín àwọn ara sọ́ọ̀sì ki wọ́n ma ba fún pọ́.
 a kò gbìdánwò láti parí isé síbí , nítorí náà , ìpàjùbà lásán ni eyí jé fún isé ribiribi tó wa níwájú .
Ojo ni: Nígbà kan ti a lọ fi ẹjọ́ sùn nilé iṣẹ ọlọ́pàá ""Toll gate"" wọ́n padà dá ẹjọ náà nù ni lẹ́yìn tí wọ́n gbà àbẹ̀tẹ́lẹ̀ lọ́wọ́ àwọn ọmọ onílẹ̀."
Dangote ni ìdàgbàsókè ẹ̀ka ọ̀gbìn ti mú àwọn agbẹ gòkè àgbà
    Báyìí ni ọkùnrin náà wí, bí o sì ti dákẹ́ ọ̀rọ̀ rẹ̀, a kò ri i mọ́.
Awon alatako ti n soro lori ero twitter pe baalu orile ede Russia , China ati France naa ni oda pupa, funfun ati buluu, nitori naa ki Trump fi oda naa sile bo se wa.
Mo kan ṣaa fẹ ki wọn di dokita ni ṣugbọn mi o mọ ohun ti wọn maa fẹ funra wọn ti wọn ba dagba tori gbogbo eeyan to dagba lo lẹtọ lati yan ohun to ba wu wọn.
"Ìjọba Ọ́ṣun, Oluwo kò yẹ lẹ́ni tó leè darí ìlú, ẹ bá wa le kúrò lórí ìtẹ́ - Olú ti Ilé-Ogbó Gbogbo ẹ̀yin ọ̀ba abẹ́ mi, tí ẹ̀ ń ta ilẹ̀ ìlú, ẹ kò ní fara re lọ - Oluwo ""Se to ba jẹ ọgọrun ọdun ni igbimọ lọbalọba to tun jiroro lori ọrọ rẹ, se igba yẹ ni maa to sẹsẹ lọ sile ẹjọ, ofin kan si wa, eyi to ni to ba fi lee kọja asiko to yẹ ki n to pe ẹjọ, wọn yoo ni mo ti sun gbagbe ẹtọ mi."
Bakan naa ni O si tun fojusona fun idije 2020 Olympic eleyi ti yoo waye ni Tokyo.
Nibi ipade igbimọ alasẹ ijọba apapọ ti Aarẹ Muhammadu Buhari dari l'Ọjọru ni wọn ti fi ontẹ lu owo naa.
Pochettino ti buwọ luwe adehun lati ṣiṣẹ gẹgẹ akọnimọọgba fun ikọ agbabọọlu PSG fun ọdun meji pẹlu adehun miran lati fi ọdun kan kun un.
” Nítorí náà ó sọ ọ́ ní Galeedi.
Omoyele Sowore: Ẹgbẹ́ aṣòfin Amẹ́ríkà ní ìjọba ń tẹ ẹ̀tọ́ olùdíje ààrẹ́ tẹ́lẹ́ náà lóju
Jobu bá dìde, ó fa aṣọ rẹ̀ ya láti fi ìbànújẹ́ rẹ̀ hàn; ó fá orí rẹ̀, ó dojúbolẹ̀, ó sì sin OLUWA.
Kiní agbórinsétí mà ló gbé ìṣe rẹ̀ dé o.
Nibi ipade ti awọn aṣoju ijọba ati awọn adari ẹgbẹ awọn olukọ fasiti, ASUU, ti aarẹ wọn, Ọjọgbọn Biodun Ogunyemi, ṣe ni alẹ Ọjọbọ ni wọn ti kede eyi.
Ìdí tí mo fi fẹ́ di Gómìnà Kogi - Dino Melaye Ṣaaju, Aarẹ orilẹede Naijiria atawọn eekan mii ti n fi ọrọ ikini ranṣẹ si gomina ti ile ẹj to ga ju lọ fontẹ lu gẹgẹ bi Gomina ipinlẹ Osun, Gboyega Oyetola.
Boko Haram: Ejò lọwọ nínú lórí ikọlù àwọn ọmọ ogun Nàìjíríà
Falz: Èmi kò ní sàtúnse fídíò tó sọ àsìse Nàíjíríà náà
Ta ló tó ṣe irú iṣẹ́ yìí?
Ó ti ṣe àwárí ìjápọ̀ nínú ìlú (láti ìtakò sí ibi ìṣẹ̀ṣe) .
Nigba to n fi idi isẹlẹ yii mulẹ fun BBC Yoruba, agbẹnusọ fun ileesẹ ọlọpa nipinlẹ Ondo, Femi Joseph salaye pe, Chibuzor lo pe ileesẹ ọlọpa naa laarọ ọjọ Ẹti pe ọdọ oun ni Gold wa, ti wọn ba si fẹ gbaa pada, ki wọn san ẹgbẹrun lọna ẹgbẹrin naira (₦800,000) fun oun.
Ketura bí Simirani, Jokiṣani, Medani, Midiani, Iṣibaku ati Ṣua fún un.
Agbẹjọro kan tó kopa ninu ìwọde náà, Olukoya Ogungbeje, ló wọ ìjọba lọ sílè ẹjọ́, lórí ẹ̀sùn pé àwọn òṣìṣẹ́ alaabo yín afẹ́fẹ́ tajú-tajú sì òun àti àwọn èèyàn yókù to ń ṣe ìwọde lójú.
Ohun to mu wọn gun le iyansẹlodi naa ni awọn nnkian koko mẹta ta ti ri owo osu wọn ti wọn ni ko munadoko to,atunto ati atunṣe awọn ile ẹkọ to fi mọ ajẹmunu awọn olukọni naa.
Ewe, iya oloogbe naa se ileri lati gba emi ara  re ti iyawo oloogbe naa Elizabeth Macheka.
Trade Fair Flyover Bridge, Ijọba ibilẹ Ojo 18.
Kii se iroyin mọ wi pe lẹnu lọọlọọ yii, nkan o rọgbọ fun ẹgbẹ oselu APC pẹlu oniruru iroyin nipa edeaiyede, ẹhonu ati ibinu awọn igun kan ati eeyan kan lẹgbẹ oselu naa.
Ilé aṣòfin Ondo bẹ̀rẹ̀ ìgbésẹ̀ láti yọ igbákejì gómìnà nípò Ile asofin nipinlẹ Ondo ti pasẹ pe ki wọn fun igbakeji gomina nipinlẹ naa, Agboola Ajayi ni iwe ifitonileti pe awọn fẹ rọ ọ loye.
Èdè Árámáìkì je ara èdè sèmítíìkì ( semitic ) .
 Ǹ jẹ́ a tún lè rí àwọn ìwé yìí ra
Akisibu, ati Mareṣa; gbogbo ìlú ati ìletò wọ́n jẹ́ mẹsan-an.
Iroyin sọ pe igbakeji ọlọpaa to n ṣiṣẹ ni ipinlẹ Borno n bọ lati ilu Calabar nibi to ti lọ ṣebẹwo si awọn mọlẹbi rẹ nigba ti ọkọ rẹ dede taku lẹgbẹ ọna to si n gbiyanju lati pe awọn mọlẹbi rẹ lori ẹrọ ibanisọrọ pe ki wọn wa gbe e, lasiko yii gan ni awọn kan ṣaadede kọ lu u ti wọn si ṣa a laake pa.
Sùgbọ́n nígbà ti BBC padà pèé ló ní, wọ́n kan yọọ́ kúrò ni ẹ̀ka Covid -19 ní kìíṣe pé wọ́n yọọ́ lẹ́nu iṣẹ́ Atẹ́gùn òjò rán ọ̀pọ̀ lóko àdánù nílùú Ìbàdàn, aráàlú gbarata Ibadan rainstorm: Awọn olugbe ilu Ibadan gbarata lori awọn ile ti atẹgun ojo ṣidanu Awọn olugbe agbegbe Joyce B ni ilu Ibadan ti bẹrẹ sini ke irora lẹyin ti ojo to fi iṣeju marundinlaadọta rọ lopin ọṣẹ ṣe akoba fun awọn ile kan.
Iwe ile ifowopamọ ti wọn ri lara oloogbe naa fi han pe o ṣẹṣẹ gba owo ti iye rẹ to ₦446,000 nile ifowopamọ kan to wa ni Bodija ni, ki wọn to kọlu.
Solomoni ọba bá ranṣẹ lọ mú Adonija wá láti ibi pẹpẹ.
 Àwon òrò yìí ni a gbé kúrò láàyè tí wón wà ní ìhun ìpìlè lo sí ibòíràn kí wón tó dé ìhun òkè .
Atejade kan ti agbẹnusọ fun ajọ to n ṣe iranwọ pajawiri nipinlẹ Eko, Kehinde Adebayọ, gbe jade sọ wipe wọn yọ ẹnikẹta, Mustapher Salaudeen, laaye ninu ile to dawo naa.
 Samson Olasupo Ayokunle,aare egbe awon elesin onigbagbo ,
Ọwọ́ wọn tẹ Saulu ati àwọn ọmọ rẹ̀, wọ́n pa Jonatani, Abinadabu ati Malikiṣua.
 bi a ti n fi kọ ̀ ǹgọ ́ lù ú lápá ọ ̀ tún náà la ó máa fi ọwọ ́ lú ú lápá òsì .
Mourinho ni o dun mọ oun ninu nitori ọpọ igba ni oun ti ma n woye lati je akọnimọọgba fun ẹgbẹ agbabọọlu Tothenham.
ni ohun mo iriri ise Pataki ti awon obinrin ati odo se lasiko eto idibo, ni eyi
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ogun Police: Bàbá fìdí ọmọ ọdún márùn ún jó sítóòfù gbígbònà, ó di aláàbọ̀ara torí ó jí ẹja 10 Èrèlè 2020 Oríṣun àwòrán, Twitter Àkọlé àwòrán, Ajàfẹ́tọ̀ ọmọdé, Oluwatoyin Ojo ti ni obi to ba ti fun ọmọ lẹgba ju meji lọ ni ọwọ ti ṣẹ si ofin Naijiria.
Ẹ ̀ mí náà jẹ ọkan lára obìnrin ọ ̀ rúnmìlà .
Kí oore-ọ̀fẹ́ Oluwa Jesu Kristi kí ó wà pẹlu ẹ̀mí yín.
Àánú kò sí lójú mi mọ́.
Yóo da turari náà sórí iná níwájú OLUWA, kí èéfín turari náà lè bo ìtẹ́ àánú tí ó wà lórí àpótí ẹ̀rí, kí Aaroni má baà kú.
Dagunro ní ìtẹríba, tó sì ń gbé àṣà lárugẹ - Ọ̀gá Bello Mi ò ní ìyàwó nílé, àmọ́ mo ní ọmọ tó pọ̀-Saheed Oṣupa Ilé iṣẹ ọlọpàá yóò gba ènìyàn 40,000 sí isẹ Òṣèré tíátà, Kemi Afolabi dùbúlẹ̀ àìsàn ní ìlú Mecca Aajo aje ni eebu ti emi ati oloogbe Ayinde Barrister fi n bu ara ninu ariyanjiyan wa ninu orin fuji.
wo titi ti iwa odaran yoo fi di ohun igbagbe ni ipinle Oyo.
Lojoojumọ ni àwọn tí wọ́n rí ìgbàlà ń dara pọ̀ mọ́ wọn.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ìlérí àsan ni Atiku ń se lórí àtúntò Nàíjíríà - APC Small Doctor yọ ìbọn sí ọlọ́pàá nílùú Eko Ìtàn tó wà nídi òwe ‘Sebótimọ Ẹlẹ́wà Sàpọ́n’ Samuel Ladoke Akintọla jẹ́ Agbẹjọ́rò àti Akọ̀ròyìn tí ọ̀rọ̀ dá lẹ́nu rẹ̀ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ọdẹrinde Oníjaàálá: Ìjálá mi máa ń mú káwọn onísẹ́ ibi gbàgbé láti sebi Akọwe ipolongo fẹgbẹ APC, Mallam Lanre Issa Onilu ni, Amosun lẹtọ labẹ ofin ẹgbẹ APC, lati ṣọ ero ọkan rẹ laisi idiwọ kankan.
orile-ede Ghana, Titi Camara ati Khalou Fadiga kopa ninu ifigagbaga naa.
Minisista abẹle feto aabo nigbakanri, Musiliu Obanikoro lo n jẹjọ tako Fayoṣe niwaju ile ẹjọ, lori bo ṣe ni oun fun Fayoṣe ni miliọnu marun un dọla owo ilẹ Amẹrika lara owo iyasọtọ fun ofiisi alamojuto eto aabo lorilẹ-ede Naijiria.
Òtítọ́ ni, Joabu ni ó kọ́ mi ní gbogbo ohun tí mo sọ, ati gbogbo bí mo ti ṣe.
Wọn ni anfani ati gba ẹyawo eyi ti ile igbimọ aṣofin ti fọwọ si ti wọn si ti gbe awọn ti yoo maa moju to o kalẹ.
Lẹ́yìn náà, ó wọn ìbú àbáwọlé ẹnu ọ̀nà, ó jẹ́ igbọnwọ mẹ́wàá (mita 5).
Àwọn bísọ̀ọ̀bù sọ̀rọ̀ ọ̀hún lásìkò tí wọn ń sọ̀rọ̀ lórí ìpànìyan tó ń wáyé jákèjádò ilẹ̀ yìí pàápàá jùlọ èyí tó wáyé láìpẹ̀ yìí tí o sì gba ẹmí ènìyan tó tó ọgọ́rùn ní ìpínlẹ̀ Plateau.
Juda fẹ́ aya fún Eri, àkọ́bí rẹ̀.
Fayoṣe lọ, kí la maa fi rántí rẹ̀?
"Ọwọ́ ọlọ́pàá tẹ afurasí ajínigbé 93, àti ìbọn 'AK47' márùndínlógójì Amọṣa ọga ọlọpaa Fẹmi Joseph ni titi di igba ti a fi n ko iroyin yii jọ, ""wọn ko tii fi papnpẹ ofin mu ẹnikẹni lori ọrọ naa."
"Ara ilu naa kan, Mishayi sọ pe ""a kan gbọ pe Coronavirus wa ni Naijiria ṣugbọn a o tilẹ mọ ohun to jọ""."
Latin lórí àìsàn Ogun Majek Iléèwé Christland yóò wọlé padà lọ́jọ́ Ajé, wọ́n ní òfin ìgbélé coronavirus kò mú ìgbẹ̀kọ́ orí ayélujára Wo bí ìgbé ayé Richard Akinjide ṣe lọ gẹ́gẹ́ bí agbẹjọ́rò àti olóṣèlú tó mòye Auxiliary lo ń jà káàkiri ìlú Ibadan lọ́jọ́ Aje, ẹgbẹ́ ọlọkọ èrò NURTW kọ - Ejiogbe Umar-Farouq ni, irọ ni pé èèyàn méjì nínú ẹbí kan gbà ẹgbẹ̀rún lọ́nà ogún náírà ẹni kọ̀ọ̀kan bíi owo ìdẹ̀rùn, ó ní èyí kò leè ṣẹlẹ̀ láéláé.
Hẹrọdu náà kò rí nǹkankan wí sí i, nítorí ńṣe ni ó tún dá a pada sí wa.
Àkọlé àwòrán, Èmí kò ṣetán láti gbọ́ ẹ̀jọ yín lónìí, ó di 2020- Adájọ́ Adeyanju O ni igbẹjọ ni ajọ ọlọpaa n duro de ni kete ti igbejo bá bẹ̀rẹ̀ ni péréwu ni ọjọ́ kẹta, oṣù Kínní ọdún 2020.
Laipẹ yii ni iroyin gbode lori ikanni ayelujara ati iroyin gbogbo pe aarẹ Muhammadu Buhari fẹ gbe ọkan lara awọn minisita rẹ, Sadiya Farouq niyawo.
Kí ọ̀rọ̀ Kristi máa gbé inú yín lẹ́kùn-únrẹ́rẹ́.
Afẹfẹ tajutaju tea gas, ọta ibọn onirọba ni awọn ọlọpaa fi tu awọn oluwọde naa ka.
Orukọ awọn mejeeji, pẹlu Erica ati Praise ni awọn olulufẹ eto naa fi silẹ pe ko pada sile, lẹyin ọsẹ meji ti wọn ti wa ni ile naa.
Iná sọ nínú ilé Big Brother tó ń lọ lọ́wọ́ ní Cameroon Mo ti buwọ́lu àdínkù owó orí nítorí ìrọ̀rùn àwọn èèyàn ìpínlẹ̀ Ogun lásìkò Covid 19- Dapo Abiodun Àwọn adarí lágbàyé ṣèpàdé láti ṣèrànwọ́ fún Lebanon lẹ́yìn ìbúgbàmù tó pa ènìyàn 158 Eric ati Tochi ni wọ́n lé kúrò nílé ẹlẹ́gbọ̀n àgbà BBNaija lọ́sẹ̀ yìí Afárá Third mainland gba ẹ̀gbọ́n Ipinlẹ Kano ni gomina ti fi eeyan kan si ipo yii ni ọdun to kọja.
8 Sẹ́rẹ́ 2020 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Iléèṣẹ́ ojú òpó ayélujára Porn Hub fi àbájáde ìwádìí síta pá àwọ̀n ọmọ Nàìjíríà ló n wo fídíò ìbálòpọ̀ ju síta.
m ni ojú mi déédé fọ́ níbi tí mo ti ń darí ọkọ̀ ni Ọrẹgun Ikẹja -LASTMA Yesufa Mo ti kó kúrò nílé Olu Jacobs rí lẹ́ẹ̀mejì- Joke Silva Ẹ fun oju lounjẹ lati wo ipa ti Fathia ati Saheed Balogun ko ninu sinima Aje Ọja.
Ìyẹn bí ogún ọdún àti díẹ̀ sẹ́yìn báyìí.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ijinigbe: BBC ṣe ìwádìí bí ikọ̀ IRT ṣe ń gbéjà ko awọn ajinigbe lójú Comrade Lana mẹnuba diẹ lara awọn ẹhonu awọn olukọni ileewe giga naa, eyi to ni o kun aisan ajẹẹlẹ abọ owo oṣu wọn fun ọgbọn oṣu, ktitapa si ofin ẹdawo ifẹyinti, ati bi ijọba ko tii ṣe san owo to rọ mọ eto igbega oṣiṣẹ laarin ọdun 2014 si 2018.
Ó sì fi Sedekaya, arakunrin rẹ̀ jọba ní Jerusalẹmu ati Juda.
O bere ere ori itage ati ori ero amohunmaworan pelu awon akegbe re Hubert Ogunde, Kola Ogunmola, Oyin Adejobi ati Duro Ladipo.
Tí ẹ bá rí olè, ẹ̀yin pẹlu rẹ̀ a dọ̀rẹ́;ẹ sì ń bá àwọn panṣaga kẹ́gbẹ́.
Kò sẹ́ni tó jẹ́ fẹ̀sùn kan ẹni ibi lójú rẹ̀,tabi kí ó gbẹ̀san nǹkan burúkú tí ó ṣe.
Ko ti ẹ ro ti ọmọ ẹ ti ko ni ẹṣẹ lọrun rara.
Bo tilẹ jẹ wi pe wọn ni oju ọjọ to dara fun ọgbin irẹsi, sibẹ irẹsi wa lara ounjẹ ti orilẹede naa n ko wọle julọ latilẹ okeere.
Lootọ ni igbogun ti ibà ti lọ soke sii daada lati bi ọdun mẹwaa, ṣugbọn ọ̀rọ̀ naa tun ti kọja agbara lati ọdun 2015: Abọ iwadi ajọ WHO nipa aisan ibà l'agbaye, to fi sita l'ọdun 2018 fihan pe ko fi bẹẹ si adinku ninu iye awọn to ni aisan ibà laarin ọdun 2015 si 2017.
Àfi Kalebu ọmọ Jefune, ọmọ Kenisi ati Joṣua ọmọ Nuni, nítorí pé wọ́n fi tọkàntọkàn ṣe tèmi.
Ẹ̀yin tí ẹ kò gbọ́ Yorùbá, ẹ ṣúnmọ́ bí láti kọ́ lítíréṣọ̀ èdè Yorùbá lórí BBC Ó ṣe mí ní àánú fún ọmọ Yorùbá tí kò le sọ èdè abínibí rẹ́ - Ọmọ Igbo Chukwuka Wo àwọn ọmọdé mẹ́ta tó ń fi èdè Yorùbá dá bírà ní Finland!
Aarẹ Amerika, Donald Trump ati akẹẹgbẹ́ rẹ̀ nilẹ Faranse, Emmanuel Macron, ti ní, awọn yoo se adehun tuntun lori ado oloro asekupani ọlọgọọrọ ti orilẹede Iran n se.
akọ mààlúù kékeré kan, àgbò kan, ọ̀dọ́ àgbò kan, ọlọ́dún kan, fún ẹbọ sísun; 
O ni ajọ eleto aabo Lagos State Security Trust Fund (LSSTF), to n ri si eto aabo ẹmi ati dukia awọn eniyan nipinlẹ Eko yii n ṣiṣẹ bo ti yẹ.
Tí ọ̀kan nínú àwọn méjéèjì bá jẹ́ ọkùnrin tí èkejì sì jẹ́ obìnrin, ọjọ́ kẹjọ ni a ó sọ wọ́n lórúkọ ní ìdílé náà.
O wá rọ àwọn èèyàn tó nífẹ̀ẹ́ láti se ère tíátà, pé kí wọ́n lọ sí orí ayelujara àmọ́ ó ni òun gan ni ileesẹ tó ń kọ àwọn èèyàn ní iṣẹ́ tíátà.
n óo fi irun aguntan lélẹ̀ ní ibi ìpakà, bí ìrì bà sẹ̀ sórí irun yìí nìkan, tí gbogbo ilẹ̀ tí ó yí i ká bá gbẹ, nígbà náà ni n óo gbà pé nítòótọ́, èmi ni o fẹ́ lò láti gba Israẹli kalẹ̀, gẹ́gẹ́ bí o ti wí.
Ṣe ni Olisa Metuh rin wọ inu ile ẹjọ bi ẹni ti ko ni iṣoro kankan, ẹwẹ ko tii mọ iru idajọ ti yoo gba lonii.
Olori ijoba orile-ede Ethiopia Hailemariam Desalegn ti kowe fipo re sile lairo-tele, eyi to so pe, oun fe fopin si pakaleke furo-dan-in ati laasigbo oloselu lorile-ede naa.
Ṣugbọn Jona ti lọ dùbúlẹ̀ sí ìsàlẹ̀ ọkọ̀, ó sì ti sùn lọ fọnfọn.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Trump picture: ọjọ́ tí Trump kí mi kú iṣẹ́ lórí 'twitter' ní inú mi dùn jù- Oyedele Bakan naa ni Ọga Agba Ajọ EFCC, Ibrahim Magu mẹnuba ipenija ti awọn n koju lọdọ ile ẹjọ.
‘Lóòótọ́ ni ọ̀jọ̀gbọ́n fẹ́ bá mi lòpọ̀’ Ilé ẹjọ́ rán ọjọ̀gbọ́n fasiti OAU lọ sẹ́wọ̀n ọdún méjì Kíni ìdí ti wọn fi ń lọ ọmú obinrin Agbẹjọro Ravalo ninu ọrọ rẹ sọ pe iwa naa ko ''bojumu ati pe o lodi si ofin'' Ni bayi,wọn ti paṣẹ ki Pulev farahan niwaju ajọ to n risi ere idaraya nilu California nitori pe wọn ko fi ọwọ yẹpẹrẹ mu ọrọ naa.
ayé rí júujùu, ó sì ṣófo.
Àwọn ọmọ Geriṣomu ni: Ṣebueli, olórí ìdílé Geriṣomu.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Omolola Arohunmolase Welder: Mo ti fí iṣẹ́ 'Welder' gbayì láwùjọ, tó mo fi tọ́ ọmọ yanjú Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Omolola Arohunmolase Welder: Mo ti fí iṣẹ́ 'Welder' gbayì láwùjọ, tó mo fi tọ́ ọmọ yanjú 9 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Lati ile iwe girama ni mo ti n kọ iṣẹ- Iya Wẹda, Omolola Arohunmolaṣe.
 Àpèmọ́nraẹni là á pe tèmídire 🙂
Ilẹ̀ ṣú, ilẹ̀ sì tún mọ́, ó di ọjọ́ kinni.
Òṣìṣẹ́ náà sàlàyé pé àwọn ti ni ìṣòrò pẹ̀lú gómínà ìpínlẹ̀ Kogi s''ajú àsìkò yìí pé, ilé ìwòsàn FMC ti ń gbẹ̀yìn gbẹbọ jẹ́ fúu ìjọba lórí ọpé kò sí ààrùn Covid-19 ni ìpínlẹ̀ Kogi.
277 trillion gbera to billion meta owo naira, tabi iko 0.
(Ó ra ilẹ̀ kan pẹlu owó tí ó gbà fún ìwà burúkú rẹ̀, ni ó bá ṣubú lulẹ̀, ikùn rẹ̀ sì bẹ́, gbogbo ìfun rẹ̀ bá tú jáde.
Wèrédìran ọ̀rẹ́ mi ti sọ fún mi pé ki n ma sàì jáde ní agogo márùn-ún wá wòran nítorí àkókò náà ni àkókò ijó.
Ẹni to bori: South Africa Aṣekagba Namibia South Africa Namibia vs South Africa.
Ṣugbọn ohun to daju ni pe, Daura jẹ ọkan lara awọn ilu meje to jẹ orisun ẹya Hausa.
Iko agbaboolu Falconets gba ami-ayo kookan(1-1) pelu China lojo aje(Monday), eleyi ti o fun won lanfaani lati tesiwaju sinu ipele ti o kan.
Ninu atẹjade naa lo ti ni mimu aṣoju ile Gẹẹsi ni Tehran ṣe lodi si aṣẹ ati ofin ajọṣepọ ni agbaye.
'O fara pamọ nilẹ Yuroopu' Ajọ EFCC ti sọ pe Ọgbẹni Ahmadu, iwe ìpéjọ salaye pe o ti ṣa lọ, ati awọn ti wọn jọ fi ẹsun kan, pa ẹgbẹrun lọna ọrinlelẹgbẹta din mẹta milionu (677m) Naira lara eto igbani sisẹ naa.
Inú ọba dùn pupọ, ó sì pàṣẹ pé kí wọ́n yọ Daniẹli jáde.
Ajọ ọtẹlẹmuyẹ lo gbe Alfa Babatunde lẹyin tawọn obi ọmọ naa fẹsun kan an pe o mọ nipa bi ọmọdekunrin naa ṣe di awati.
Igbakeji agbẹnusọ fun ile iṣẹ ijọba apapọ to n risi eto ẹkọ ni Naijiria, Ben Going ni oun gbagbọ pe, loni ni gbogbo ọrọ naa a yanju.
Obìnrin yìí tún dáhùn pẹ̀lú ó ní, kí ni ìwọ gbẹ́kẹ̀lé?
Onidajọ Haruna Tsammani to gbe idajọ naa kalẹ gbẹsẹle idajọ ti ile ẹjọ giga ipinlẹ Ọyọ gbe kalẹ ni ilu Ibadan leyi to ti ni Gomina Makinde tasẹ agẹrẹ lori igbesẹ naa, pe ko bofin mu.
- Iya Rainbow Ọmọ ọdun mẹrindinlọgbọn ọhun to ti olpaa funrasi pe o jẹ ọkan lara ọmọ ẹgbẹ okunkun Degba ni ọwọ ofin tẹ ni opopona Port Harcourt si Uyo.
"Awọn iroyin ti ẹ le nifẹ si Afẹ́fẹ́ Gáàsì tó rọra ń yọ́ọ́ jò pa Ajibola lẹ́nu iṣẹ́ jórin-jórin 'Irọ́ ni o, àò pinnu láti kógbá Shoprite wọlé ní Nàìjíríà' Wo ìdí tí àwọn ọmọ ilẹ̀ Amẹ́ríkà kan ṣe ń kó bọ̀ wá fi ilẹ̀ Áfríkà sebùgbé Coronavirus já wá sílẹ̀ ju ti àt'ẹ̀yìn wá lọ, kò ju èèyàn 288 tó kó o lọ́jọ́ Ajé Toríi ""Coro"", ẹ wo bí ètò ìsìn ìgbéyàwó orí ayélujára Zoom ṣe lọ Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí kan sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn."
Lẹ́yìn èyí, Jesu ń rìn káàkiri láti ìlú dé ìlú, ati láti abúlé dé abúlé.
"Mo ro pe mo ti ri ọkọ temi ni lai mọ pe o kan n lo mi lati gbadun ara rẹ ni, ti n ko si le gbagbe bo se sọ mi di oniyẹyẹ.
Ọpọ igba ni ika kẹfa yii maa n ré danu bi ọmọ naa ba ṣe n dagba sii tabi ti wọn maa n gee kuro nile iwosan.
Àìsàn ibà Lassa tún pa ènìyàn ní Ondo Olórí òṣìṣẹ́ ìjọba ìpínlẹ̀ Kwara, Adisa Logun ti dágbére fáyé lẹ́yìn tó lùgbàdì àrùn Covid-19 Àwọn alárùn coronavirus ṣe ìwọ́de ní Gombe, wọ́n ní ìjọba n febi pa wọ́n ''O ṣeni laanu pe a tun ti padanu dokita mii sọwọ arun Covid-19, mojumọ oni ni a gbọ pe wọn ṣe alaisi'' Dokita Adeyeri ti fi igba kan jẹ dokita to n tọju alakoso ologun fun ipinlẹ Ondo tẹlẹ ri, oloogbe Ibe Onyearugbulem.
 Ó fẹ ̀ rín sí .
Ètò ìbúrawọlé ní ìpínlẹ̀ Eko Igbakeji gomina ipinlẹ̀ Eko, Obafemi Hamzat, iyawo ati awọn ọmọ rẹ lori pepele iburawọle.
Má yọwọ́ lọ́ràn mi lọ́jọ́ ìṣòro!
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Àmì ẹyẹ ọjọ ìbí 2018:Joshua pẹlú àwọn tí Ọbabìnrin Elizabeth dá lọ́lá 9 Òkùdu 2018 Oríṣun àwòrán, AFP Àkọlé àwòrán, Joshua tí kọ́kọ́ gba àmì ẹ̀yẹ àpọ́nlé MBE ní ààfin Buckingham l'ọ́dún 2013.
“Bí ó bá jẹ́ pé ewúrẹ́ ni yóo fi rú ẹbọ náà, kí ó mú un wá siwaju OLUWA, 
Ki ni o ma n sẹlẹ si agọ ara ti eniyan ba n binu?
Aare ile igbimo asofin agba ni Naijiria, Bukola Saraki, ni yoo ko awon asoju-sofin to ku lo si Ijebu Ode nipinle Ogun fun ayeye odun Ojude Oba todun 2018.
Nibo la ti le yan Iyalọja?
Akukọ gagara ti wọn mọ, ti wọn pe orukọ rẹ ni 'Okukor' ni o da wahala silẹ ni ẹgbẹrun ọdun sẹyin nigba ti wọn ji i gbe lọ kuro lorilẹ-ede Naijiria lọ si Ilẹ Gẹẹsi.
Eyi si mu ki wọn mu ọjọ ija mii, ti awọn afẹṣẹku bi ojo mejeji si ti n leri tantan mọra wọn lọpọ igba ti wọn ba pade.
Obìnrin Kwara tí wọ́n tà sóko ẹrú ní Lebanon figbe ta, ọwọ́ tẹ èèbó kọ̀ráà tó ṣiṣẹ́ náà Ilé ẹjọ́ pàṣẹ kí wọ́n fi àwọn afurasí tó pa àkẹ́kọ̀ọ́ LASU sí ẹ̀wọ̀n Ta ni jide Kosọkọ?
nilo ọkọ oju irin mẹ́wàá  ni osu
Lórí òkè gíga fíofío, ni o lọ tẹ́ ibùsùn rẹ síníbẹ̀ ni o tí ń lọ rú ẹbọ.
fun anfaani miran ti won fun oun lati tun lo soju won nile igbimo asoju-sofin.
O fi kun ọrọ rẹ pe: '' Mi o mọ nipa pe awọn ikọ dokita kankan fẹ ṣe irinajo lọ si ilẹ Gẹẹsi.
Samsoni se àsè ńlá kan níbẹ̀, nítorí pé bẹ́ẹ̀ ni àwọn ọdọmọkunrin máa ń ṣe nígbà náà.
Ọọ kẹrindinlogun oṣu kẹfa ni Dele Momodu ati Oloye Gani Fawehinmi tẹkọ ofurufu leti wa si Naijiria.
Oríṣun àwòrán, AFP Hong Kong Iwọde tako ijọba ni Hong Kong ti n walẹ diẹdiẹ.
Ta ló dàbí rẹ, Ọlọrun, tí ó ń dárí ẹ̀ṣẹ̀ ji eniyan, tí ó sì ń fojú fo ẹ̀ṣẹ̀ àwọn eniyan ìní rẹ̀ yòókù, ibinu rẹ kì í wà títí lae, nítorí pé a máa dùn mọ́ ọ láti fi ìfẹ́ rẹ̀ tí kì í yẹ̀ hàn.
Kí ló sún Seyi dé ilé ẹlẹ́gbọ́n àgbà?
Oba Akanbi ni ikan nla ni Olori to n bọ, o ni o lagbara gan an.
Síbẹ̀, lábẹ́ ìṣàkóso rẹ̀, ààbò ẹ̀mí kò sí pẹ̀lú ìkọlù láàárín darandaran àti àgbẹ̀ bí àwọn darandaran láti àríwá ṣe ń wọ gúúsù láti wá koríko fún ẹran ọ̀sìn-in wọn.
Àwọn agbófinró Nàíjíríà yóò rojọ́ níwájú iléẹjọ́ àgbáyé ICC Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Chelsea vs Tottenham: Lampard àtàwọn agbábọ́ọ̀lù Chelsea dọ́wọ́jọ wó òrùlé Stamford Bridge lu Mourinho àti Tottenham
Wọn tun ni ko le ṣẹyin awọn agbesunmọmi ni ẹkun yii.
Bakan naa ni Olawale tun parọ fun Hayatou pe oun yoo fun lẹbun ẹgbẹrun un lọna ọgbọn owo dọla($30,000) ati ''iPhone'' olowo iyebiye to fi mọ goolu.
Gbogbo aforijin ti olukọ agba to wa nibẹ nisinsin yii n se, ko sẹyin bi awọn ileesẹ nlanla nilẹ Gẹẹsi bii Lloyd's of London ati Greene King, ti se n tọrọ aforijin pe ọwọ awọn ko mọ ninu sise owo ẹru.
Oríṣun àwòrán, PrOMAISODOR GHANA Ilumọọka ni irẹsi jọlọọfu laarin awọn ọmọ orilẹede bii Senegal, Ghana, Naijiria, Gambia, Sierra Leone, Liberia ati cameroon.
Biliha, iranṣẹbinrin Rakẹli tún lóyún, ó bí ọmọkunrin keji fún Jakọbu.
Ìfẹ́ kò jẹ́ ṣe nǹkan burúkú sí ẹnìkejì.
Ẹ óo mú ọ̀dọ́ aguntan meje ọlọ́dún kọ̀ọ̀kan tí kò ní àbùkù lọ́wọ́, pẹlu ọ̀dọ́ akọ mààlúù kan ati àgbò meji, nígbà tí ẹ bá ń kó àwọn ìṣù àkàrà meji náà bọ̀.
Òun ati àwọn ẹlẹgbẹ́ rẹ̀ bá lọ sí orí òkè, wọ́n bẹ̀rẹ̀ sí sọkún, nítorí pé ó níláti kú, láì mọ ọkunrin.
Ọkùnrin kan da ṣọ́ọ̀ṣì rú lásìkò ìgbéyàwó, Ó ní òun lọkọ àárọ̀ ìyàwó tuntun Ẹ́ wo ìrírí tó mú àgbà òṣèré Chief Kanran dí ẹni tí kò rí ilé gbé mọ́, ti irinṣẹ́ jóná Ohun tí a mọ̀ nìyí nípa gbọ́nmi síi omi ò tó lórí ọ̀rọ̀ oyè Babaloja-General ní ìpínlẹ̀ Oyo Oral Sex: Bóo bá ń gba ẹnu ní ìbálòpọ̀, wo àìsàn tóo lè kó lójú ara rẹ Amọ, atẹjade ti ajọ NERC fi sita lọjọ Iṣẹgun, ọjọ kinni, oṣu kẹsan an fihan pe NERC kọ eti ikun si aṣẹ ile igbimọ aṣofin l'Abuja, o ṣi ṣe afikun owo ina bi o ti sọ tẹlẹ.
Ó bá bà lé ṣóńṣó orí igi kedari kan, 
Kì í sì í ṣe Adamu ni a tàn jẹ, obinrin ni a tàn jẹ tí ó fi di ẹlẹ́ṣẹ̀.
Pasitọ naa fi mi lọkan balẹ pe Ọlọrun wa pẹlu mi, ti ko si fi mi silẹ ninu wahala naa, ati pe a ko ri iru eyi ri, ẹru la n da ba ọlọrọ."
Ṣugbọn agbẹnusọ Kabiesi ilu Akure, Oloye Micheal Adeyeye ti sọ pe ẹmi ẹnikẹni ko ba iṣẹlẹ naa lọ.
Àwọn iléesẹ́ abáni fi ẹrù ránṣẹ bẹ̀rẹ̀ ìyaṣẹ́lódì tako àfikún owó Nipost Ìkúnlẹ̀ ló bá dé fún Oshiomole, Ize-Iyamu láti bẹ̀bẹ̀ fún ìbò aráàlú ní Edo Sunday Igboho yari, o fohun ransẹ sawọn eeyan to n pẹgan rẹ Ikú Barakat Bello ní Akinyele gbé aláàánú pàdé ẹ́bí rẹ̀ A ṣe ọdún Ọ̀ṣun lásìkò yìí láti kó Coronavirus lọ ni - Ooni ṣàlàyé Wo àwọn nǹkan tí o kò mọ̀ nípa 'Church of Satan' Ọ̀jọ̀gbọ́n Simon Mallam wa nínú àwọn mẹ́fà tó ti kú nínú ìjàmbá iná gáàsì- Ìjọba Kaduna Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Gas Explosion: Afẹ́fẹ́ gáàsì ṣekúpa ọ̀pọ̀ èèyàn ní Kaduna Awọn agbofinro ipinlẹ Kaduna ti fi ninu orukọ awọn to ba iṣẹlẹ naa rin sita.
Ṣelumieli ọmọ Suriṣadai ni olórí ẹ̀yà Simeoni.
Oríṣun àwòrán, @anaedoonline Ahmed sọ eyi lasiko ti awọn akọroyin n beere lowo rẹ lori igbeṣẹ ijọba lori ibode ti wọn ti pa.
“Fi igi akasia kan tabili kan, kí ó gùn ní ìwọ̀n igbọnwọ meji, kí ó fẹ̀ ní ìwọ̀n igbọnwọ kan, kí ó sì ga ní ìwọ̀n igbọnwọ kan ààbọ̀.
Olori awọn dokita ọun Nuhu Kwajafa lo kede aṣeyọri iṣẹ abẹ naa loju opo Instagram rẹ.
Angẹli náà bèèrè lọ́wọ́ rẹ̀ pé, “Kí ló dé tí o fi lu kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ rẹ nígbà mẹta?
Ọjọ kẹrindinlọgbọn, oṣu kejila, ọdun 1930 ni wọn bi Adebayo ni Agbo-Oye ni Oyo, ni guusu Iwo oorun Naijiria.
Gbajabiamila balẹ̀ sí Ghana láti pẹ̀tù sááwọ̀ láàrin Nàìjíríà àti Ghana Wo ibi fún èsì ìdìbò láti yan aàrẹ tuntun ní orílẹ̀-èdè Ghana Òògùn ẹ̀fọn pa ọmọ mẹ́ta ní Ghana Àwọn akọ̀rọ̀yìn fárígá l'órílẹ̀-èdè Ghana Nọmba naa ti wọn ko ni sanwo lati pe si ni (0800-100-100).
Ni ẹgbaarun (10,000) àṣàyàn àwọn jagunjagun ninu àwọn ọmọ Israẹli bá gbógun ti ìlú Gibea.
Gẹgẹ baa se ka itan Mọremi lori itakun agbaye Wikipedia, taa si tun gbọ lẹnu awọn onpitan, ẹwa ti Ọlọrun fun ọmọbinrin naa, to jẹ ayaba, lo lo lati sẹgun fun ilu rẹ.
Ẹ̀yin ẹ dìde níbi tí ẹ farapamọ́ sí, kí ẹ sì gba ìlú náà, nítorí OLUWA Ọlọrun yóo fi lé yín lọ́wọ́.
Esi ayẹwo naa yatọ si eleyi tawọn ti ijọba bẹ lọwẹ lati ṣee nitori esi naa ko fidi rẹ mulẹ pe wọn fun un lọrun pa ni.
" Ọkan ninu wọn lo maa n tẹle mi lọ gba owo tawọn eeyan ba fẹ sanwo Hajj tabi owo ilẹ tori mo n ta ilẹ ati ile, mo tun ni oko nla ta ti n ṣe nkan ọsin, afurasi yii si lo maa n ba mi gba owo, awọn nkan yii si lo ko si wọn loju.
Gẹgẹ bi ohun ta gbọ, aarẹ Buhari ti tẹwọgba aba lati ma sọ awọn igbo kijikiji to wa nilẹ Yoruba pẹlu awọn irinṣẹ aabo igbalode.
Fowler kò sí lábẹ́ ìwádìí kankan-Garba Sheu Ohun mẹ́fà tí kò yẹ́ kí o gbàgbé nípa Gómìnà Ambode Nǹkan kò ṣẹnuure fáwọn obìnrin nínú ìgbìmọ̀ ìṣèjọba Buhari Èrò àwọn ọmọ Naijiria ṣọ̀tọ̀ọ̀tọ̀ lórí àwọn ti Sanwo Olu yàn sípò Eyi ló mu ki wọ́n ràn ọlọpàá lọ sí ibẹ̀, méjì nínú àwọn afurasi náà sálọ nígbà ti wọ́n mú méjì, agbẹnusọ náà ni wọ́n gba ibọn ìbílẹ̀ méjì àti ọtá ibọn mẹ́fà gbà lọ́wọ́ wọ́n.
Ko si pẹ rẹ, wọn ti bẹ̀rẹ̀ si ni ṣe àwo orí fun ilé isẹ Philips West Africa Record ti wọn si ti fi orúkọ ẹgbẹ́ rẹ silẹ láti ṣeré lọjọ òmìnira orílẹ̀èdè Naijiria lọdun 1960.
Mo ti buwọ́lu àdínkù owó orí nítorí ìrọ̀rùn àwọn èèyàn ìpínlẹ̀ Ogun lásìkò Covid 19- Dapo Abiodun Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, BBC Africa Eye: ìwádìí ìkọ̀ks BBC fihàn pé àwọn kan ń jí ohun èèlò ìdáàbòbò ìjọba tà nígbo Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Toyin Abraham pé 40, wo ohun márùn ún tó mú dá yàtọ̀ láàrín ogójì ọdún Facebook mú àyípadà bá àtẹ̀jíṣẹ́ síra ẹni lórí òpó Instagram, wo àwọn ǹkan tó kàn ọ níbẹ̀ Bí mo bá wọlé padà, mí ò lè yàn Ize Iyamu tàbí Osagiobare sípò olùbádámọ́ràn- Obaseki Ajọ to n risi ọrọ erebọọlu ni Naijiria.
Alukoro ọlọpaa ni wọn ti mu awọn ọlọpaa to yẹ ko mojuto ọdaran to salọ lahamọ, bi o tilẹ jẹ pe oun ko le sọ iye awọn ọlọpaa ti ọrọ naa kan.
Aya ààrẹ wá rọ gbogbo obí láti tọ ipasẹ ti òun tọ nítori pe ìgbọ̀ran sa ju ọ̀rá àgbò lọ.
Iye àwọn ọmọ-ogun ẹlẹ́ṣin jẹ́ ẹgbẹẹgbẹrun lọ́nà ọ̀kẹ́ mẹ́wàá (200,000,000).
Jesu pe àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ sọ́dọ̀ ó ní, “Àánú àwọn eniyan wọnyi ń ṣe mí, nítorí ó di ọjọ́ mẹta tí wọ́n ti wà lọ́dọ̀ mi; wọn kò ní oúnjẹ mọ́.
Ẹ̀mí kan náà ní ń sọ sí wa lọ́kàn pé ọmọ Ọlọrun ni wá.
O ni wọn ta awọn eniyan lolobo lati sa asala fun ẹmi wọn ni eyi to si ni ipa rere."
Eto idibo ipinlẹ Ondo yoo waye ni ọjọ kọkandinlogun, oṣu kẹwaa, ọdun 2020.
Mercy Aigbe kọ loju opo Instagram rẹ pe Adeniyi wu oun lori, bẹẹ lo tun gbadura fun un pe ''Eleduwa yoo maa tọ lọna, yoo si fi ibukun si iṣẹ ọwọ rẹ lorukọ Jesu.
 Ọmọ ìlú kan náà nì òun àti akin olúṣínà .
“Ní àkókò náà, bí ẹnìkan bá sọ fun yín pé, ‘Wò ó!
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Iléeṣẹ́ ọlọ́pàá yóò jẹ́jọ́ lórí ìwádìí ayédèrú ìwé ẹ̀rí tí wọ́n fi kan Sẹ́nétọ̀ Adeleke 29 Ìgbé 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 30 Ìgbé 2019 Oríṣun àwòrán, Ademola Adeleke Àkọlé àwòrán, Awọn ọlọpaa n wadii Sẹnetọ Ademọla Adeleke, lori ẹsun ayederu iwe ẹri girama lọwọlọwọ.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Wo Ọ̀jọ̀gbọ́n Ẹlẹka tó ń díje fún ipò gómìnà Chris Ngige ní kí wọn dá Fayose padà sípò ‘Àláfíà ọmọ Naijiria lo jẹ mí logun' Sé ìwọ mọ Kayọde Fayẹmi tó ń díje ni APC?
Àwọn ọmọ Pahati Moabu, tí wọ́n jẹ́ ọmọ Jeṣua ati Joabu, jẹ́ ẹgbẹrinla ó lé mejidinlogun (2,818).
Ṣé lóòtọ́ ni olorì méjì míì tún ti kúrò láàfin Oyo?
"Ọmọ Yahoo yóò pọ̀ si tẹ bá ní kí ọ̀kadà má rìn lójú pópó Eko - Àwọn ọ̀dọ́ ""Ọlọ́pàá ní kí n bọra sílẹ láti mọ bóyá obìnrin ní mí torí mo ní irùngbọ̀n"" Ojora ń mú mi lọ́wọ́ lórí ìkọlù tó wáyé, ara mi kò tíì balẹ̀ - Toyosi Adesanya Ó gbà mí tó wákàtí kan kí ń tó gbàgbọ́ pé mo bímọ lẹ́yìn ìdádúró ọdún mẹ́jọ - Imoyosola Favour dagbere nile pe oun n lọ si ile iwe lati lọ mura ko to bẹrẹ idanwo aṣekagba ni fasiti rẹ, Fasiti ilu Eko ninu imọ ẹkọ Tiata."
Àwọn òṣìṣẹ́ ààrin ìlú tí wọ́n bá wá láti inú àwọn ẹ̀yà Israẹli ni yóo máa dá oko níbẹ̀.
O ni laipẹ igbimọ agbohungbaroye kan yoo di gbigbekalẹ fun araalu lati maa fi ariwisi wọn nipa iṣẹ ati iṣe Amọtẹkun ṣọwọ si.
Àmì ẹyẹ ọjọ ìbí 2018:Joshua pẹlú àwọn tí Ọbabìnrin Elizabeth dá lọ́lá
Gege bi iwe ofin orile-ede Botswana, nigba ti ile-ejo ba ti fi idajo iku naa mule nipa yiyegi fun odaran naa, won yoo tun gbe ejo naa lo siwaju igbimo ti o n ri iforiji fun awon elewon, ti a mo si Advisory Committee on Prerogative of Mercy, igbimo yii yoo gba Aare nimoran boya, aye wa fun lati lo agbara re labe ofin ipele ketaleladota, lati fi ijiya to mo niwonba je odaran naa.
Lori awọn obi to maa n pa ina ẹbun amutọrunwa mọ awọn ọmọ wọn lara, Fopefoluwa sọ ọrọ iṣiti fun wọ.
Ninu idije CAF Champions League to n lo lowo, Plateau United FC padanu ifesewonse akoko sowo Etoile du Sahel  torile-ede Tunisia pelu ami-ayo merin si meji(4-2), ninu ifesewonse ti o waye lojo isegun(Tuesday) ni papa isere Sousse.
Àmọ́ lọ́jọ́ òní, ìlànà méjéèjì náà tún báramu.
Àsìkò yìí ni ìgbà tí Jésù wà ní ilé-ayé.
Ní òwúrọ̀ kutukutu ọjọ́ keji Joṣua ati gbogbo àwọn ọmọ Israẹli gbéra ní Akasia lọ sí etí odò Jọdani, wọ́n sì pàgọ́ níbẹ̀ kí wọn tó la odò náà kọjá.
Ẹlẹ́sìn Ìgbàgbọ́ ni àwọn ará abúlé náà.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Èkó: Àwọn akínkánjú obìnrín tó ń wa Márúwá Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Èkó: Àwọn akínkánjú obìnrín tó ń wa Márúwá 2 Ìgbé 2018 Àwọn obìnrin ti wọn ń wa kẹ̀kẹ́ lẹ́sẹ̀ mẹ́ta táa mọ̀ sí kẹ̀kẹ́ Márúwá jẹun sọ pé isẹ́ náà kò dí àwọn lọ́wọ́ iṣẹ́ ilé.
2bn fún Obanikoro Wo àwòrán ńkan tó ń ṣẹlẹ̀ ní ìpádé ìran Yorùbá ní Ibadan báyìí Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, International Day Against Drug Abuse and Trafficking: ìdí ti mo fi ń mu oògùn olóró Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
" O jẹ nkan to mu ifura dani pe ọmọbinrin naa kọ iru nkan bẹ ẹ sori ayelujara lasiko ti iwadii ṣi n lọ lọwọ lori ẹsun to fi kan kọmisana.
Kí ni àwọn Juu tí wọ́n wà ní àwọn agbègbè ṣe?
Bakan naa ni igbimọ ọhun awọn ọmọ Naijiria to n bọ lati ilẹ okere wi pe ki wọn ya ara wọn sọtọ fun ọjọ mẹrinla nile wọn kete ti wọn ba ti wọ Naijiria pada.
Maria Magidaleni wà lára wọn, ati Maria ìyá Jakọbu ati ti Josẹfu ati ìyá àwọn ọmọ Sebede.
Yóo fi òdodo ṣe ìdájọ́ ayé,yóo sì fi ẹ̀tọ́ ṣe ìdájọ́ àwọn orílẹ̀-èdè.
Ṣugbọn Mikali iyawo rẹ̀ sọ fún Dafidi pé, “Sá àsálà fún ẹ̀mí rẹ ní alẹ́ yìí, nítorí pé bí o bá di ọ̀la níbí, wọn yóo pa ọ́.
Èèyàn 745 ló lùgbàdì àrùn Coronavirus ní Naijiria ní Ọjọ́bọ̀ Kí ni Hushpuppi ṣe tí àjọ EFCC fi ní ó ní ẹjọ́ láti rò?
Wo àwọn òfin tí ìjọba ìpínlẹ̀ Eko gbé jáde fún àwọn tó n padà sẹ́nú iṣẹ́ lẹ́yìn k'ónílé o gbélé Ẹ bá mi dúpẹ́ lọ́wọ́ Sunday Igboho, Ajimobi, Seyi Makinde àti àwọn ọlọ́pàá fún iranwọ wọn láti rí ìbejì gbà padà Ènìyàn 170 tún ti ní ààrùn Covid-19 l'órílẹ̀-èdè Nàìjíríà Àwọn èèyàn kò fi bẹ́ ẹ̀ ní ìbálòpọ̀ lásìkò ìgbélé yìí - Iléèṣẹ́ kọ́ńdọ́ọ́mù Durex Nibẹ ni arabinrin kan ti orukọ rẹ n jẹ Kẹhinde Afolakẹ ti kọluu to si soo laṣọ mu.
Asoju akowe agba  ajo UN ti o tun je adari ise-akanse ajo UN naa David Shearer,tun bu enu ate lu fifi eto omo eniyan gbole lorile-ede ti ogun abele ti pin yele-yele naa.
Ni ọjọ kẹrindinlogun oṣu karun un ọdun 2019 ni aarẹ Buhari ṣẹṣẹ buwọlu u pe June 12 ti kii ṣe ajoji si gbogbo ọmọ Naijiria ni wọn yoo maa ṣe ayajọ ijọba awa ara wa ni Naijiria.
O ju igba ọdun ti awọn ara ilu Idanre fi gbe ori oke gogoro naa ki wọn to ko lọ si isalẹ nibi ti wọn ngbe bayii.
Fún gbogbo olólùfẹ́ ojú ìwé yìí.
Super Falcons gòkè odò bọ́ sípele ìkẹrìndínlógún ní France Egypt ṣíná fún Zimbabwe, ẹ̀kọ́ mẹ́rin tó yẹ ní kíkọ́ Wo ohun tó yẹ kí o mọ̀ nípa ikọ̀ Burundi Bí eṣinṣin bá kọ́já, wíwọ́n ní, lásìkò ìṣíde AFCON 2019 Orilẹ-ede Germany lo ṣaaju ninu ẹgbẹ B nitori wọn bori ninu idije mẹta wọn nigba ti Naijiria bori ninu idije kan to sọ wọn di alaṣeyọri kẹta ni ẹgbẹ A.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Suicide Prevention Day: Wo àmì márùn-un tí o fi le mọ ẹni tó fẹ́ gbẹ̀mí ara rẹ̀ 11 Owewe 2020 Oríṣun àwòrán, Science Photo Library Gbígba ẹ̀mí àra ẹni jẹ́ àrùn tó ni ṣe pẹ̀lú ọpọlọ, tí ó sì le fa ikú àìtọ́jọ́, sùgbọ́n ó ṣeeṣe kó ní àtúnṣe ti àwọn ènìyaǹ bá tètè mọ̀, tí wọ́n si ran irú ẹni bẹ́ẹ̀ lọ́wọ́.
soro niluu Abuja lori gudu gudu meje, yaya mefa ti iko omo ogun ọwọ kejo ti se
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ejò bu ìdí obìnrin kan jẹ nínú ilé ìgbọ̀nsẹ 28 Sẹ́rẹ́ 2019 Oríṣun àwòrán, JASMINE ZELENY Àkọlé àwòrán, Onimọ nipa ejo ni wọn pe to wa a ba wọn yọ ọ jade.
A ti jọ damọran pe a fẹ fẹra wa, nitori naa la ṣe maa n rira ni ẹẹmẹta tabi ẹẹmẹrin l'ọsẹ.
Aare soro yii nigba ti iko
Ohun ti abẹrẹ ajẹsara naa ṣe ni lati wọ inu isan ara lọ, ti yoo si pese eroja ara 'protein' ti yoo dena arun Coronavirus to fẹ ba sẹẹli ara jẹ.
Ṣugbọn èmi OLUWA yóo sọ ohun tí mo bá fẹ́ sọ, yóo sì ṣẹ.
Níbo ni ìlú tí ó dàbí ihò àwọn kinniun wà?
Ati pé, ‘Kí wọn tẹ́wọ́ gbà ọ́ kí o má baà fi ẹsẹ̀ gbún òkúta.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Kí ló mú PDP lè Kashamu kúrò nínú ẹgbẹ?
Lẹyin ti awọn ọlọpaa ṣe ti ni ina naa ti lọlẹ, wọn ko ti i le fidi ọrọ mulẹ boya awọn eeyan ṣi yi wa ninu ina naa tabi bẹẹkọ.
Kì í ṣe ọ̀pọ̀ ninu yín ni ọlọ́gbọ́n gẹ́gẹ́ bí èrò ẹ̀dá, ọ̀pọ̀ ninu yín kì í ṣe alágbára, ọ̀pọ̀ ninu yín kì í ṣe ọlọ́lá.
Ile ẹjọ Majisireeti agba kan lagbagbe Tinubu nipinlẹ Eko lo paṣẹ pe bi Naira Marley ti orukọ abisọ rẹ n jẹ Azeez Fashọla, ko ba fi ara han niwaju kootu naa ni ọjọ kẹrinla oṣu kini ọdun 2020, ẹwọn lo fi n ṣere.
Ijoba ipinle Kwara ti parowa fun awon olugbe ilu naa lati fokanbale
Loni ayajọ ọjọ awọn ewe kaakiri agbaye gẹgẹ bi UNICEF ṣe laa kalẹ naa ni Oba Ile Ifẹ darapọ mọ gbogbo òbí agbaye lati sami ayẹyẹ yii pẹlu awọn ọmọde.
Ṣugbọn ọkàn ẹ̀yin eniyan wọnyi le, ọlọ̀tẹ̀ sì ni yín.
Ẹni tí ó bá gbà mí gbọ́, láti inú rẹ̀ ni odò omi ìyè yóo ti máa sun jáde, gẹ́gẹ́ bí Ìwé Mímọ́ ti wí.
Nadal ni akonimoogba agba iko Spain Sergi Bruguera ti yan papo pelu Pablo Busta, Bautista Agut, David Ferrer ati Feliciano Lopez lati kopa ninu idije naa.
Ìjọba àpapọ̀, ẹ so ifilọlẹ ẹ̀rọ alatagba 5G rọ na - ilé asofin àgbà Wo àwọn to ti rí ìwòsàn lọ́wọ́ àrùn coronavirus àti ibi tí wọ́n ti wá káàkiri Nàìjíríà Mẹ́rin nínú àwọn mọ́kànlá tó ń bọ̀ láti Sokoto tí wón mú l'Oyo ló ní Coronavirus Iye ìgbà tí Sani Abacha tí fi owó ransẹ si Nàìjíríà láti ọrun Ninu ọrọ rẹ lasiko irinkerindo lati ṣe amojuto awọn dukiya ijọba lasiko ti aarun Corona n ba gbogbo aye finra, alaga ẹka eto ẹkọ kalekako nipinlẹ Ọyọ, SUBEB, Ọmọwe Nureni Adeniran fi aidun inu rẹ han lorii iwa kotọọ to n waye ni ninu ọgba ile ẹkọ naa gẹgẹ bi o ṣe n bura wi pe awọn to huwa ibajẹ naa ko ni lọ lai fi imu k'ata ofin.
O ni Ko din ni ẹgbẹrun lọna ọgọrin ọkọ to maa n gba ẹnu awọn iloro naa lojojumọ, ṣugbọn lati igba ti iwọde End SARS ti bẹrẹ, iloro naa ko pa owo kankan wọle mọ."
 Niṣe ni yoo fi ofin de mi pe mi o gbọdọ maa jade tabi lo ẹrọ ibaraẹnisọrọ.
Àwọn ọmọ Israẹli rán oníṣẹ́ jákèjádò ilẹ̀ Bẹnjamini, wọ́n ní, “Irú ìwà ìkà wo ni ẹ hù yìí?
Ọlọrun wà pẹlu wa, ó dáàbò bò wá lọ́wọ́ àwọn ọ̀tá ati àwọn dánàdánà.
Mo Farah, omo bibi ile biritiko ti sepo kinni ninu idije ere ije maili metala Big Half  lojo Aiku(Sunday), saaju igbaradi fun idije ere-ije ti yoo waye nilu London.
Oríṣun àwòrán, @nassnigeria Wọn tun woye pe, lọwọlọwọ bayii, idaduro to wa nidi yiyan awọn minisita ti n se akoba bayii fun eto ọrọ aje wa, ti Buhari ko ba si gbe igbesẹ lori rẹ ki awọn asofin to gba isinmi, eyi lee paroko ti ko dara ransẹ si awọn eeyan to fk wa dokowo sorilẹede yii lati ilẹ okeere.
“Àwọn ọmọ wa, àwọn aya wa, àwọn mààlúù wa ati aguntan wa yóo wà ní àwọn ìlú Gileadi, 
Ní bayìí ǹkan tó ń ṣẹlẹ̀ ní Nàìjíríà ń kọnilọminú, ibẹ̀ ni iye ènìyàn to n kú tún ti pọ̀ jù ṣikeji gẹ́gẹ́ bi abájade ìròyìn àjọ WHO ni ọjọ́ kínní, oṣù keje, ọdún yìí.
Ọwọ tẹ afurasi mẹta ni Zamfara Wahala Kaduna: Ọwọ ọlọpaa tẹ eeyan mẹwa Oríṣun àwòrán, Lagos State Government Àkọlé àwòrán, Wọn nṣe ipade ni agogo meji oru ladugbo Ẹlemoro ni Ajah Ṣaaju ni awọn agbofinro mu wọn lọjọ kẹtalelogun oṣu keji lẹyin ti awọn araadugbo tawọn lolobo pe awọn afurasi naa n ṣe ipade ni nnkan bi agogo meji oru ladugbo Ẹlemoro ni Ajah.
Iyaafin Agboola ni “ti idọti ba wa loju titi, o le fa
Mo kọ ìwé si yín pé kí ẹ má ṣe darapọ̀ mọ́ àwọn tí ń hùwà ìbàjẹ́.
Awon alase orile-ede America so pe, egbe omo-olote IRSAD ni ajosepo pelu omo-ogun olote ijo al-Qaeda, ti o se ikolu ti o waye lorile-ede Burkina Faso ni odun 2016.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Baby abandoned on dunmpsite: Mo ti bímọ mẹ́rin tẹ́lẹ̀ fún bàbá méjì nínú òṣí- Dupe Ogbomos Magun alakukọ: Bi eeyan ba ti lee lu iru magun yii lara obinrin, yoo maa gun un tabi ṣe e bii ko kọ bi akukọ ni.
Alága SUBEB: A ṣetán lá ti gba owó ìrànwọ́ Almajiri ní ìpínlẹ̀ Oyo
Nigba miran, o le jẹ pe akoko ti iya ikoko naa kọ si baluwẹ lawọn olubi ẹda naa yoo ri aaye paarọ ọmọ sira wọn.
7 Bélú 2020 Fídíò, Fire accident victim: AbdulQudus Bello ṣàlàyé bí òun ṣe dí aláàbọ̀ ara nítorí pọpọ́ọ̀fù àti ìbínú jàǹdùkù àdúgbò7 Bélú 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Àwọn Juu yìí ni wọ́n pa Oluwa Jesu ati àwọn wolii, tí wọ́n sì fi inúnibíni lé wa jáde.
Ni ọdun 2008 wọn fi ẹsun kan pé ó gab ayàworàn kan nípàá lóri amóhùnmáworan DR Congo ti ó si fa ẹ̀rọ ayaworan rẹ̀ níbi ayẹyẹ orin itagbangba, sùgban òun àti ẹni náà fi ṣe ọ̀rọ̀ abẹ́ ilé.
Ọmọ oṣù mẹ́rin ní Coronavirus ní Cambodia, Turkey ya 10,000 sọ́tọ̀ A maa n pe ọrọ arun asekupani yii ni òwè, amọ ni bayii, o ti n ni àáró nínu nitori awọn orilẹede lagbaye lo ti n gbe awọn igbesẹ to lagbara lati kawọ arun naa ko.
Ṣeba la ilẹ̀ gbogbo ẹ̀yà Israẹli já, ó lọ sí ìlú Abeli ti Beti Maaka.
Soladoye fi kun un pe ''Nigba to ti wa di pe kii ṣe ẹni to ba gbe igbaoroke ni wọn yoo mu, a fẹ ki aarẹ o mu ọmọ wa ninu awọn ti orukọ wọn ba de ọdọ rẹ'' Oríṣun àwòrán, Premium Times Àkọlé àwòrán, Aworan ọmọ ẹgbẹ Ibadan lasiko ti wọn n ba awọn akọroyin sọrọ ''Awọn ọmọ wa koju oṣunwọn, o si yẹ ki aarẹ wo nkan mii mọ Ibadan lara lati yan ọmọ wa si ipo ọga fasiti Ibadan.
Alabojuto ọgbà ẹ̀wọ̀n náà kì í fi nǹkan lé Josẹfu lọ́wọ́ kí ó tún bìkítà fún un mọ́, nítorí pé OLUWA wà pẹlu Josẹfu, ohunkohun tí ó bá ṣe, OLUWA ń jẹ́ kí ó yọrí sí rere.
“Ìwọ ọmọ eniyan, ṣé o óo dájọ́, ṣé o óo dájọ́ ìlú tí ó kún fún ìpànìyàn yìí?
Mo ti pinnu láti sọ ọ́ di eniyan pataki tẹ́lẹ̀ ni, ṣugbọn OLUWA ti dí ọ lọ́nà.
ati omo ipinle Borno lori ikolu buruku ohun ,ni eyi ti awon odaran kan fi ado
Itan igbesi aye Ẹfunsetan ko lọ gaara ga bo se yẹ, nitori oniruuru ọna lo pin si.
lẹ́yìn tí wọ́n bá fi ẹ̀ṣẹ̀ rẹ̀ tí ó dá hàn án, yóo mú abo ewúrẹ́ tí kò ní àbààwọ́n wá, yóo fi rúbọ fún ìmúkúrò ẹ̀ṣẹ̀ tí ó ti dá.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Coronavirus Lockdown: Iléèwé Chrisland ṣetán láti fún ìgbẹ̀kọ́ orí ayélujára lọ́jọ́ Ajé tó ń bọ̀ 21 Ìgbé 2020 Oríṣun àwòrán, Other Ko si ṣiṣe, ko si aisẹ, ile iwe Chrisland niluu Eko yoo wọle saa eto ẹkọ tuntun lọjọ Aje, ọjọ kẹtadinlọgbọn oṣu kẹrin ti a wa yii, bo tilẹ jẹ wi pe ofin konile-o-gbele si wa lode.
Ohun tí a rí nílé Ajimobi rèé lẹ́yìn ìròyìn òfégè pé ó jáde láyé Yẹ̀kínì kan kò lè yẹ ipinnu wa láti ṣí iléèwé pàda lóṣù yí - ìjọba ìpínlẹ̀ Oyo Kí ló mú ọlọ́pàá wú òkú géńdé nínú sàréè l'Ondo Ìjọba Amẹrika fi ojú àwọn ọmọ Yahoo mẹ́fà léde, wọ́n gbẹ́sẹ̀ lé dúkìá wọn Gẹgẹ bi awọn onwoye oselu Naijiria ti se sọ, Aarẹ Buhari kii da si ọrọ aawọ to ba n waye laarin awọn ọmọ ẹgbẹ APC.
A o tun ri daju pe, gbogbo awon omo-ogun apetusawo n gba eto won loore-koore fun awon ise-akanse ti won ba se ni odun 2018”.
Makinde ni, ṣe ni Ajimọbi n fa owo yọ lapo ijọba bi nkan miiran nibayii ti ọjọ ti yoo fipo gomina silẹ, May 29, se n sunmọ ile.
1 Kanye West ti bẹ̀rẹ̀ ìpolongo àti díje dupò aàrẹ ilẹ̀ Amẹrika Adelé Ọ̀gá Àgbà àjọ NDDC dákú rangbọndan lásìkò tí ìwádìí n lọ lórí ẹ̀sùn ìnákúnàá Wo bí Dorathy Bachor ṣe di gbajúmọ̀ lóríi Instagram lẹ́yìn tí ètò àgbéléwò BBNaija bẹ̀rẹ̀ Ó yẹ kí ìjọba gbé ilé ìwé tì pa títí di ọdún 2021- ASUU Bawo ni Idibo APC Ondo ṣe lọ?
Òun kan náà tí ó wá sí ìsàlẹ̀ ni ó lọ sí òkè, tí ó tayọ gbogbo nǹkan tí ó wà lọ́run, kí ó lè sọ gbogbo nǹkan di kíkún.
Idagbasoke ti n de ba iye owo ti orile ede Naijria yoo ma ri lori epo robi.
Ó bẹ̀rù OLUWA, ó sì kórìíra ìwà burúkú, ó dúró ṣinṣin ninu ìwà òtítọ́ rẹ̀ bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé o dẹ mí sí i láti pa á run láìnídìí.
Wọn ni awọn ọdọ n sọrọ nipa aini ọjọ ọla to peye ti alaṣẹ ilẹ China si n tẹ ominira ilẹ Hong Kong loju.
“Mú Aaroni ati àwọn ọmọ rẹ̀ ọkunrin ati ẹ̀wù iṣẹ́ alufaa wọn, ati òróró ìyàsímímọ́, ati akọ mààlúù fún ẹbọ ìmúkúrò ẹ̀ṣẹ̀, ati àgbò meji náà, ati agbọ̀n burẹdi tí kò ní ìwúkàrà.
"Kíni ìtumọ̀n ""SIM Card"" l'édè Yorùbá?"
nítorí pé mo fun yín ní ìlànà rere,ẹ má ṣe kọ ẹ̀kọ́ mi.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Coronavirus in Nigeria: Àjọ NBS ní covid-19 ló fa ọ̀wọ́ngógó oúnjẹ ní ìpínlẹ̀ Eko, Kano, Rivers àti Abuja 8 Owewe 2020 Oríṣun àwòrán, others Laisi ani ani, ajakalẹ arun coronavirus ti da ọwọngogo ounjẹ silẹ nipinlẹ Eko, Kano, Rivers ati Abuja.
Wo àwọn ohun márùn ún tó yẹ kí o mọ̀ nípa Sanusi Ẹ́ gbaradì, to bá lo jẹnẹrátọ̀ àbí tà á, ò ń fi ẹ̀wọ̀n ọdún mẹ́wàá ṣeré - Sẹ́nétọ̀ ń dábàá Agbófinró, tó bá wa ọkada àbí kẹkẹ maruwa l'Eko, o rugi oyin - Sanwo-Olu Ará Yúróòpù ẹ fìdí mọ́lé yín, mo ti gbé ìlẹ̀kùn Amẹ́ríkà tìpa torí Coronavirus - Trump Iroyin ni awọn eeyan ilu ọhun gba Sanusi tọwọ tẹsẹ, bo ti tilẹ jẹ pe inu wọn ko dun si bi ijọba Kano ṣe rọ ọ loye.
Boya eyi lo mu ki igbakeji aarẹ nilẹ wa, Yemi Osinbajo fi n lọgun nipa isẹ ati osi to n bawọn ọmọ Naijiria mulẹ, bii ẹgbẹ isu.
Iṣẹ mẹta lo wa fi ransẹ sawọn obinrin lorilẹede Naijiria bayii.
O sọ eyi nigba ti o n ṣabẹwo sibẹ lalẹ ọjọ Aje.
Wọ́n kó ihamọra Saulu sílé Aṣitarotu, oriṣa wọn, wọ́n sì kan òkú rẹ̀ mọ́ ara odi Beti Ṣani.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Kí l'ànfàní àdéhùn okoòwò kan l'Afíríkà, AfCFTA tí Buhari tọ́wọ́ bọ̀?
Oríṣun àwòrán, Empics Àkọlé àwòrán, Àwọn ọlọ́pàá mẹ́ta ṣiṣẹ́ dáràn lórí bí wọ́n ti yabo ilé Edwin Clark Esun tio wwọn fi kan Clark ni pe o ko ohun ija oloro pamọ sile.
Lẹ́yìn náà, Amnoni kórìíra rẹ̀ gidigidi.
Elesho, gẹgẹ bi ọpọ ṣe maa n pe e ninu ere sọ pe, oun pada kọ iṣẹ oogun tita, ti oun si gba iyọnda lọdun 1975, bakan naa loun ṣi ṣọọbu oogun toun ni 1976.
Oríṣun àwòrán, Others Àkọlé àwòrán, Bí a kò bá gbàgbé, ní ǹkán bí ọ̀sẹ̀ méjì ṣẹ́yìn ni ìròyìn gba òde kan pé ó ti kó àrùn Coronavirus.
Bí kò bá ṣe bẹ́ẹ̀,wọn ìbá fi ojú wọn ríran,wọn ìbá fetí gbọ́ràn,òye ìbá yé wọn,wọn ìbá yipada;èmi ìbá sì wò wọ́n sàn.
Odion Ighalo: Ó di 2021 kí Ighalo tó fi Manchester United
Ojú ọ̀nà náà jẹ́ ojú ọ̀nà tí àwọn apànìyàn ti máa ń ṣe ọdẹ ènìyàn kiri, ṣùgbọ́n n kò nìkan rrìn rárá, bí n kò sì ti nìkan rìn yìí náà, a bọ́ sí ọwọ́ àwọn ọlọ́ṣà tó ìgbà mẹ́ta kí á tó dé ọ̀hún.
Àwọn ìjòyè wọn tí wọ́n fọwọ́ sí ìwé náà ni: Paroṣi, Pahati Moabu, Elamu, Satu, ati Bani, 
Asofin ohun so pe, “lara akitiyan awon oluwadii ohun ni sise abewo si ibi isele naa, fifi oro jomi-tooro oro pelu awon ti oro kan, pinnu lori igbese ati aise-dede awon omo-ogun eleto-abo, saaju, lasiko ati leyin isele iji awon akekoo naa gbe”.
Ohun elo aṣeranwọ eemi to n lo ẹrọ 2.
Nígbà tí ìkùukùu yìí bá kúrò ní orí Àgọ́ Àjọ àwọn ọmọ Israẹli yóo tú àgọ́ wọn palẹ̀, wọn yóo sì lọ tún un pa níbi tí ìkùukùu náà bá ti dúró.
"Wọ́n máa n ròó pé wọ́n o maa dẹ́yẹ́ si àwọn ọmọ ọkunrin wọ́n ko si ni bọ̀wọ̀ fún wọ́n láàrin awùjọ"" Gẹ́gẹ́ bi NHS ní ilé Gẹẹsi ṣe sọ kò sí ìtóju kan to pé péré péré fún ìwòsàn àarun náà, bákan náà ni Liliya tako kìí awọn ènìyàn máa ló òògun to n mú irun gùn lái jẹ pé dókìtà dari wọ́n bẹẹ."
Ọ̀gá Ọlọ́pàá: Àwọn ọ̀gá ọlọ́pàá ìpínlẹ̀ ni yóò máa ṣàkósó FSARS báyìí
Akin-Olugbade tun tẹsiwaju si lati kawe gba oye imọ ofin to de awọn ileeṣẹ ni fasiti California, ni orilẹede Amẹrika.
nidii-mọdaru nipa gbigba eto alaafia laaye 
Pẹlu eyi ni dokita tabi nọọsi fi le mọ.
tun ni anfaani lati tun so awon oro miiran pelu aare Buhari.
Gege bi akoroyin ile Birrtiko se
Minisita fun ọrọ ilẹ okere ni Ghana ti sọ pe orilẹ-ede naa ni yoo kọ apa kan ọfisi ileesẹ orileede Naijiria ni Ghana t'awọn kan wo lulẹ ni Accra.
Akọroyin ileeṣẹ BBC to ṣabẹwo si awọn iboji naa jabọ pe pupọ lara awọn ibi isinku ọhun lo fun papọ mọ ara wọn, koda ko si ibi ti eeyan le e gbe ọkọ gba wọle sibẹ.
O sọ eyi nibi ipade nile ijọba ni Abuja lasiko to n jabọ lori iṣoro ifipabanilopọ to n fẹju kaakiri Naijiria bayii.
Akọtun ikọlu miran tun ti bẹ silẹ nipinlẹ Jos ni ipinlẹ Plateau, eyi taa gbọ pe ko sẹyin isẹ ọwọ awọn Fulani darandaran.
Oríṣun àwòrán, Instagram Bakan naa ni iroyin gbe e pe Obinanne Okeke, to jẹ ilumọọka onisọwọ ti wọn mu fun ẹsun lilọ ẹrọ ayelujara lati ṣe magomago ti jẹwọ pe lootọ ni oun jẹbi ẹsun naa.
Iya ọmọ naa sọ pe iyalẹnu lo jẹ fun oun nigba ti awọn eeyan bẹrẹ si ni pe akiyesi oun si iroyin pe gomina ipinlẹ Eko, Babajide Sanwo-Olu fẹ ẹ ri ọmọ oun.
Gbogbo ògo wa ló parun lójú wa,ó sì tú ibinu rẹ̀ jáde bí iná, ninu àgọ́ Sioni.
IRINAJO RẸ NINU ETO IṢELU: Lọdun 1998, ẹrin pa ẹẹkẹ Dapọ, ti wọn si dibo yan-an gẹgẹ bii aṣofin agba sile aṣofin ni Abuja, lati lọ ṣoju ẹkun idibo rẹ, labẹ ẹgbẹ oṣelu UNCP.
Orji wa so pe ojo kẹ́tàdínlógún, osu kejo yii,ni ajo INEC yoo gbe ilana eto idibo odun 2019 jade, ti awon egbe oselu yoo si bere si maa se eto idibo inu egbe won lati yan oludije fun egbe oselu won.
Àjálù ń ṣubú lu àjálù,gbogbo ilẹ̀ ti parun.
PFN: Fatoyinbo kọ̀ láti yọjú ni ìwádìí wa kò ṣe parí Ilé iṣẹ́ márùn ún tí wọ́n dárukọ kìí ṣe túntun- Garba Shehu FRSC dá N443,180 padà fún ẹbí ẹni to ní ìjàmbá mọ́tò Ọlọ́pàá Germany ń wádìí àfurasí mẹ́rin nínú àwọn tó kọlu Ekweremadu ni Germany Diẹ lara awọn aṣoju ẹgbẹ to kopa ninu idibo naa ni Bodija nilu Ibadan ni: Baale Ekotedo, Oloye Taye Ayorinde; Oloye Deji Osibogun; awọn alufaaa ati imaamu aṣaaju ẹsin; ọmọ ẹgbẹ Oodua Peoples Congress (New Era).
Section 125 Awọn to ba laṣẹ nikan lo le maa ṣamojuto bi awọn eeyan ṣe n lo omi wọn si gbudọ ni kaadi idanimọ.
Gbogbo àwọn obinrin tí wọ́n mọ òwú ran ni wọ́n ran òwú tí wọ́n sì kó o wá: àwọn òwú aláwọ̀ aró, elése àlùkò, aláwọ̀ pupa, ati funfun tí wọ́n fi ń hun aṣọ onílà tẹ́ẹ́rẹ́tẹ́ẹ́rẹ́.
Ijoba orile-ede Botswana so pe, “ajo EU gbagbo pe, idajo iku je iwa odaju ati dida emi eniyan loro, ni eyi ti won ti n pe fun didekun re”.
ko ni lọ ni alaafia n tan ara won je ni.
Ẹwẹ, ni lọọlọ yii, ohun ti Alhaji Atiku Abubakar sọ lo n gbe awọn eeyan ninu ju.
 igbowolori ( owon ) ti din sile ni bi odun melo se yin .
Gbogbo àwọn akikanju jagunjagun tí a kọ orúkọ wọn sílẹ̀ ninu ìdílé wọn jẹ́ ẹgbaa mọkanla ati mẹrinlelọgbọn (22,034).
Ó pa ọgbọ́n mọ́ àwọn ọ̀jọ̀gbọ́n ninu,ó sì sọ àwọn onídàájọ́ di òmùgọ̀.
Mo fún wọn lésì pé, “Ọlọrun ọ̀run yóo mú wa ṣe àṣeyọrí, àwa iranṣẹ rẹ̀ yóo múra, a óo sì mọ odi náà, ṣugbọn ní tiyín, ẹ kò ní ìpín, tabi ẹ̀tọ́, tabi ìrántí ní Jerusalẹmu.
Ó kú kí ó lè ṣe ìràpadà fún ẹ̀ṣẹ̀ tí eniyan dá lábẹ́ majẹmu àkọ́kọ́, kí àwọn tí Ọlọrun pè lè gba ìlérí ogún ayérayé.
Pẹlu ibinujẹ ni idile ọba ilẹ Gẹẹsi fi kẹdun iku Ọlọlajulọ Sultan Qaboos bin Said, to jẹ Ọlọrun nipe lọjọ ẹti gẹgẹ bi ọrọ ti ile ẹjọ fi sita.
Bàbá akẹ́kọ̀ọ́ LASU tí ọ̀rẹ́kùnrin rẹ̀ àti pásítọ̀ fi ṣ'oògùn owó ń bèèrè fún ìdájọ́ òdodo Idi ti EFCC ṣe mu Sheu Sani S'ahamọ.
Ni ọdun 2017 ni irufẹ ajalu yii waye eleyi ti o sọ ọpọ di alainile.
yii waye lati lee ran awon oludibo lọwọ lati se ojuse wọn gege bi omo bibi
Loju opo Facebook BBC news Yoruba, Shakirat Oke Ayanbode sọ pe ki aarẹ Buhari o tu awọn silẹ kuro ninu ofin konile o gbele, tabi ki ijọba o fun ẹni kọọkan ni apo irẹsi kọọkan nitori ki ebi o ma ba a pa wọn.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìtàn Mánigbàgbé: Ṣango gbèrò ibi fún Gbọnka àti Timi, àmọ́ òun gan bá ọ̀tẹ̀ náà lọ 8 Bélú 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 9 Bélú 2019 Oríṣun àwòrán, Others Àkọlé àwòrán, Ìtàn Mánigbàgbé: Ṣango gbèrò ibi fún Gbọnka àti Timi, àmọ́ òun gan bá ọ̀tẹ̀ náà lọ Ẹlẹdaa fi ọpọ awọn akọni nla jinki ilẹ Yoruba laye atijọ.
Ayantunde Aluyo Jesu ni ọga to tun kọ Promise ni iṣẹ ilu lilu sii to fi di aluluogo bayii.
Wọ́n ń rú ẹbọ sísun, wọ́n sì ń sun ọ̀rá ẹran níná.
Ọjọ́ ori ti wọn yóò maa wà láàrin ọdún méjìdínlógun sí méjìdílọ́gbọ̀n; (b) Wọ́n gbọdọ̀ ní amí kare nínú ND tabi NCE tabi trade test lati àwọn ilé iṣẹ́ ti ìjọba fọ́wọ́ sí, o kéré tan ninu iṣẹ́ meji ati kírẹ́dítì fun èdè gẹ̀ẹ́sì.
Amọ ti o ba yan lati mase fun ọmọ rẹ ni omi ọyan, ko tumọ si pe o kii se iya rere.
si esun ti won fi kan Walter Onnoghen ninu eyi to wa ninu ofin odaran , ACJA,
Aarẹ ile aṣofin agba lorilẹede Naijiria, Sẹnetọ Bukọla Saraki ti san owo oṣu awọn oṣiṣẹ ijọba ibilẹ irẹpọdun ni ẹkun idibo apapọ gusu ni ipinlẹ Kwara.
Ninu ami-eye iko agbaboolu Arsenal FC fun awon akonimoogba iko agbaboolu odo ti
awọn ti o n dije ni ẹkun kọọkan wa.
7 Nítorí báyìí ni Olúwa Ọlọ́run wí: Òun ni èmi ti mísí láti mú kí ipa ọ̀nà Síónì kí ó tẹ̀ síwájú nínú agbára nlá fún ire, àti aápọn rẹ̀ ni èmi mọ̀, èmi sì ti gbọ́ àwọn àdúrà rẹ̀.
eto aabo awon omo orile ede yii , ki ọkan won lee balẹ.
Kí wundia kankan tó lè lọ rí ọba, ó gbọdọ̀ kọ́ wà ninu ilé fún oṣù mejila, gẹ́gẹ́ bí ìṣe àwọn obinrin wọn.
’’Nigba ti Marafa,to je oludije fun ipo gomina ni ipinle Zamfara naa so pe
" Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Baby abandoned on dunmpsite: Mo ti bímọ mẹ́rin tẹ́lẹ̀ fún bàbá méjì nínú òṣí- Dupe Ogbomos Dupe ko pada si ile awọn obi rẹ ni Odo Ọba.
Èéṣe tí o kò fi sọ fún mi pé iyawo rẹ ni Sarai?
 lóótọ ̣ ́ , àwọn òbí rẹ ̀ lòdì sí kí ó kọrin nítorí wón gbà wípé olè àti ọ ̀ lẹ ni ó ń ṣagbe , ṣùgbọ ́ n ó kọ ̀ jálẹ ̀ tí ó sì ń bá ìfẹ ́ ọkàn rẹ ̀ lọ títí ó fi di ọmọ ọdún mẹ ́ èdógún ( 15 yaers ) .
Wọ́n ń gbọ́ ohùn eniyan, ṣugbọn wọn kò rí ẹnìkankan.
Kì í ṣeiwin inú fìlà Fìlásayépọ̀ ló gbé wa padà, nítorí ọ̀kan nínú àwọn àbúrò ìyàwó mi mọ ọ̀nà àti bá jáq sí ojú ọ̀nà òkè Ìrònú tí kò jìnà púpọ̀ sí odò ìrántí tí a o sì fi lè lọ bá ara àwọn ènìyàn wa yòókù tí kò wá sí ibi ìyàwó.
Adebayo tun fi aidunnu re han
Ẹ óo máa rú àwọn ẹbọ wọnyi yàtọ̀ sí ẹbọ sísun ojoojumọ.
 thi sá kúrò ní ìlú lọ sí cambodia , ṣùgbọ ́ n , ó padàwà lẹ ́ yìn tí wọ ́ n yọ diệm tí wọ ́ n sì paá ní oṣù kọkànlá ọdún 1963 .
Bẹẹ, Yoruba gbà pé, ọmọ ti a kò tọ́ ni yoo gbe ilé ti a kọ́ tà lẹyin ọ̀la.
1 1371103 Orilẹede Peru 36231 113.
Awọn eeyan naa lọ sori papa lai wọ aṣọ kankan, yatọ si ibọsẹ ati bata ti wọn fi n gba bọọlu, bẹẹ ni wọn tun kọ nọmba agbabọọlu si ẹyin wọn.
Ki Ahasi tó dé, Uraya bá mọ irú pẹpẹ ìrúbọ náà, gẹ́gẹ́ bí iṣẹ́ tí Ahasi rán sí i láti Damasku.
Amoni, ọmọ rẹ̀ sì jọba lẹ́yìn rẹ̀.
Oríṣun àwòrán, @Newsweek Wọn ji alaga ọhun ati awakọ rẹ gbe ni opopona Okeho-Ado Awaye, iyẹ ni ipinlẹ Oyo lasiko to n mura lati ṣe ipade pẹlu gomina Seyi Makinde.
Awon miran ti won tun wa nibe ni Emir ti Daura, Alhaji Umar Faruk, Galadima ti Katsina ati Adajo feyinti fun ile ejo kotemilorun Adajo Mamman Nasir atawon miran.
Àwọn ará Anatoti jẹ́ mejidinlaadoje (128).
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìdí tí o kò fi gbọdọ̀ pa oríṣi inú rírun márùn-ún yii mọ́ra 26 Owewe 2020 Oríṣun àwòrán, @others Inu dídùn tabi rírun jẹ ọkan lara awọn ipenija eto ilera to wọpọ, debi i pe awọn eeyan kan kii saba kọbi ara si.
Lẹ́yìn náà, wolii Ṣemaaya lọ bá Rehoboamu ati gbogbo àwọn olóyè Juda, tí wọ́n ti péjọ sí Jerusalẹmu lórí ọ̀rọ̀ Ṣiṣaki ọba Ijipti.
nítorí àánú Ọlọrun wa,nípa èyí tí oòrùn ìgbàlà fi ràn lé wa lórí láti òkè wá,
Lára àwọn tí yòó kọ́wọ̀ọ́rìn pẹ̀lú Ààrẹ Buhari ni gómìnà ìpínlẹ̀ Ebonyi, Dave Umahi, àti akẹgbẹ́ rẹ̀ láti ìpínlẹ̀ Jigawa, Abubakar Badaru.
Itọju ta ma n se fun ẹni to ba ti ni arun yi lasiko yi jẹ eleyi ti yoo ka gbogbo ẹya ara ni.
Lara awọn ohun ti wọn gba lọwọ awọn afunrasi naa ni alupupu marun, ada meji, oogun abẹnu gọngọ ati ẹgbẹrun lọna ọgọfa naira."
Fi òtítọ́ yà wọ́n sí mímọ́ fún ara rẹ; òtítọ́ ni ọ̀rọ̀ rẹ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Coronavirus: Ọmọ Nàìjíríà tó darí láti France wá labẹ àyẹwò lórí Coronavirus 5 Ẹrẹ̀nà 2020 Oríṣun àwòrán, Twitter/LSMOH Kọmisana feto ilera nipinlẹ Eko ti ni tawọn ko ba ri awọn eeyan meji to ku lara awọn mẹẹdogun to ba ọmọ ilẹ Italy to gbe Coronavirus wọ Naijiria titi ọjọ Ẹti, awọn yoo kede orukọ wọn lori afẹfẹ.
Nadabu ati Abihu kú nígbà tí wọ́n fi iná tí a kò yà sí mímọ́ rúbọ sí OLUWA ninu aṣálẹ̀ Sinai.
iroyin ti ko tọ jade lorile ede Naijiria.
Atamatase iko agbaboolu Atletico Madrid, ti o tun n kopa fun Spain, Diego Costa ti ro Argentina lati dupe pe iko naa ni agbaboolu bi lionel Messi ninu iko ohun.
Akọtun awuyewuye to tun waye lori ọrọ naa ni bi agba amofin Femi Falana se se atupalẹ ofin ọhun, to si ni wọn ko kọ ofin naa daada rara.
Ọ̀dọ̀ fásitì jànkàn Oxford ló ti jáde Báwó ni òògùn dexamethasone ṣe ń ṣiṣẹ́ lára Coronavirus cases in Africa- Iye awọ̀n tó ní Coronavirus ní Áfíríkà Ẹwẹ, eeyan 18,203 lo ti ri iwosan gba ti wọn si ti ja ajabọ lọwọ ajakalẹ arun naa.
Ẹgbẹta (600) ìwọ̀n ṣekeli fadaka ni wọ́n máa ń ra kẹ̀kẹ́ ogun kan láti Ijipti, wọn a sì máa ra ẹṣin kan ní aadọjọ (150) ìwọ̀n ṣekeli fadaka.
"Ko seese fun Oluwoo lati di Emir nitori ipo Oluwoo kii se ti Musulumi , oye adayeba ni.
“Àwọn ìlànà ati òfin, tí ẹ óo máa tẹ̀lé lẹ́sẹẹsẹ, ní gbogbo ọjọ́ ayé yín ní ilẹ̀ tí OLUWA Ọlọrun àwọn baba yín ti fi fun yín láti gbà, nìyí: 
Nítorí irú èyí ni ibinu Ọlọrun fi ń bọ̀ wá sórí àwọn ọmọ aláìgbọràn.
- Aráàlú ń bèèrè €10,000, ara owó tí wọn fi ra Ighalo pòórá, Ilé aṣòfin Osun bẹ̀rẹ̀ ìwádìí Eyi tumọ si pe Ronaldo ati Messi yoo tun fojurinju lati ta okoto ayo lori papa.
O salaye nipa awọn akẹkọọ rẹ to jẹ oyinbo ṣugbọn ti n wọn n kọ nipa ede Yoruba ni fasiti ipinlẹ Michigan ni orilẹ-ede America.
N kò ni nkan kan sọ lórí fídíò to gba ayélujára kan pé mo ń we igbó, ẹ mú ẹnu kúrò nibẹ - Oluwo Ani sẹ, Ọọni ran alaabo rẹ simi - Oluwo Ọgbọ̀n ọdún ni mo fi ṣe iṣẹ́ púlọ́mbà kí n tó dí Gomina ìpínlẹ̀ Eko - Babajide Sanwo-Olu Lawuyi Ogunniran, àgbà ọ̀jẹ̀ òǹkọ̀wé Eégún Aláré dágbére fáyé!
Oríṣun àwòrán, Islamic State Propaganda Àkọlé àwòrán, Bayii ni IS ṣe maa n kóra jọ ko to o ṣe ikọlu to ba l'agbara Ẹgbẹ naa yi orúkọ pada si ISIS, ni Iraq lọdun 2006.
Nígbà tí ẹ bá gbúròó ogun ati ìrúkèrúdò, ẹ má jẹ́ kí ó dẹ́rùbà yín.
Won ni ara ile Switzerland kan wa lara awon ero inu oko ofurufu naa.
Ṣugbọn nígbà tí ó bá yá, ojú yóo kojú, a óo sì ríran kedere.
Laipẹ yii ni Ajọ Northern Elders Forum (NEF) ke si awọn darandaran Fulani kí wọ́n padà sókè ọya ní kíákíá pé ẹmi wọn ati dukia lee wa lewu ni iha Guusu ti wọn wa.
Eyi waye lẹyin ọdun mọkanlelọgọta ti tawọn ọkunrin ti bẹrẹ.
Gomina lola, ko se leyin ipa takuntakun ti o ko, lati je ki alaafia joba ni
Àwọn ọmọ Naijiria kóju ija sí àwọn South Africa wọ́n ní Ó tó gẹ́"" Àtúnṣe òpópónà Lagos-Ibadan àwọn ọ̀ná míràn ti e lè gba Dino Melaye tó ń díje dupò gómínà Kogi ni irọ́ ni pé òun ti ju awà sílẹ̀ Iṣẹ́ ṣẹ̀ṣẹ̀ bọ́ lọ́wọ́ Seth Ator tó yìnbọn pa ọ̀pọ̀ èèyàn ní Texas ni- ọlọ́pàá Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!"
tiwa-n-tiwa lori ede yii si Ọjọ kéjìlá,osu kẹ́fà(June
ọmọ Jese, ọmọ Obedi, ọmọ Boasi, ọmọ Salimoni, ọmọ Naṣoni, 
" Baba Adeboye ni koda lasiko ohun, iyawo oun ti gẹ irun fun oun nitori ilu ti iṣẹ iranṣẹ gbe wọn lọ lasiko naa.
Nígbà tí àwọn ará Mẹlita rí ejò náà tí ó ń ṣe dìrọ̀dìrọ̀ ní ọwọ́ Paulu, wọ́n bẹ̀rẹ̀ sí sọ láàrin ara wọn pé, “Dájúdájú apànìyàn ni ọkunrin yìí.
Àwà gómìnà PDP ṣetán láti san #30,000 owó oṣù fáwọn òṣìṣẹ́- Dickson Ilé ẹjọ́ ní kí NBC yí àṣẹ padà lórí DAAR Communications Ọjọ́ tí inú mi bàjẹ́ jùlọ gẹ́gẹ́ bíi ààrẹ ilé aṣòfin àgbà-Saraki Lẹ́yìn-ọ̀-rẹyìn, bàbá ọgọ́rùn-ún ọdún gba ìdáǹdè l‘ẹ́wọ̀n Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Lẹ́yìn náà ó wọn ìloro ẹnu ọ̀nà tí ó wà ninu, ó jẹ́ igbọnwọ mẹjọ (mita 4), 
Ilẹ̀ yóo máa mì ní ọpọlọpọ ìlú.
Lẹyin ọpọlọpọ adura, ọjọgbọn yii ni oun ti yii skan oun pada lori rẹ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Iléeṣẹ́ google gbé àǹfàní internet ọ̀fẹ́ wọ Eko 27 Agẹmo 2018 Oríṣun àwòrán, Punchng Àkọlé àwòrán, Ileeṣẹ ikanni ayelujara, google ti gbe awọn ibudo lilo ayelujara lọfẹ wa si agbegbe marun nipinlẹ Eko Anfani ti wa fun awọn ọmọ orilẹede Naijiria lati maa lo ikanni ayelujara, internet lọfẹ bayii nipinlẹ Eko.
Adamu ni idi ti awọn fi gbe igbeṣẹ yii ni lati koju iṣoro eto aabo to mẹhẹ kaakiri awọn ipinlẹ lorilẹ-ede Naijiria.
Ọjọ Aje, ọjọ Kejidinlọgbọn osu Kejila ọdun 1992, eyi to pe ọdun mejidinlọgbọn bayii ni iku pa oju akọni osere naa de, amọ bi onirese rẹ ko ba fin igba mọ, sibẹ awọn eyi to ti fin ko le parun.
Aare tun gboriyin fun olojo ibi naa pe, ko gun iyan ogbon ori ti Olorun fun kere ninu ise re, bee si ni, O tun re ara re sile nipase mimu igberu ba asa ati ise, dida ayika re si, mimu igberu ba isejoba rere, eleyi ti o mu gba orisirisi ami-eye ati owo jakejado.
Kíni ọ̀nà àbáyọ si ọ̀rọ omíyale ni Naijiria?
Itan sọ fun wa pe ọmọ Alaafin Abiodun ni Aole, o si jọba nilu Oyo laarin ọdun 1789 si 1796, Oríṣun àwòrán, others Alaafin Ajagbo si lo ṣe ifilọlẹ oye Aarẹ Ọna Kakanfo ti Afonja jẹ, bi o tilẹ jẹ pe Alaafin Abiodun lo fi Afonja jẹ oye naa.
Ọpọlọpọ awọn eeyan to sọrọ nibi isin naa lo mu igbesi aye oloogbe wa si iranti nibi akanṣe eto naa.
Bí wọ́n ti ń fa Jesu lọ, wọ́n bá fi ipá mú ọkunrin kan tí ń jẹ́ Simoni, ará Kirene tí ó ń ti ìgbèríko kan bọ̀.
Bakan naa, abala ofin yii sọ wi pe ki awọn ile iṣẹ to kọ ile si igboro, ki wọn kọkọ wo alakalẹ ile naa lati ri i daju pe ko le si idiwọ fun awọn akanda.
Ni Beijing to jẹ olu ilu China ni wọn ti ṣeto ayẹyẹ ayajọ ominira China fun eto bi nkan bii wakati kan pere nibi ti awọn agbofinro ti duro wamuwamu ti wọn n ṣọ awọn eniyan.
OLUWA ní,“Ẹ rọ Moabu lọ́tí yó,nítorí pé ó gbéraga sí OLUWA;kí ó lè máa yíràá ninu èébì rẹ̀,a óo sì fi òun náà ṣẹ̀sín.
Sanusi Adebisi Idikan rèé, olówó tó ń san owó orí fún gbogbo ọkunrin ilẹ̀ Ibadan Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Africa Eye: Olùkọ́ méjì ní fásitì Eko àti Ghana lùgbàdì ọ̀fíntótó BBC lórí ìwà ìbàjẹ́ Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Turkey); Odion Ighalo (Shanghai Shenhua, China)Alexander Iwobi (Arsenal FC,
Wo ohun tí ìrìnàjò ààrẹ Buhari fún ìgbà àkọ́kọ́ lásìkò Coronavirus lọ sí Mali yóò bá bọ̀ O ti lé ní ènìyàn mẹ́wàá tí ina jó gúrúgúrú nínú ìjàmbá tó wáyé ní Delta Èèyàn 20 ni coronavirus pa l'Ọ́jọ́bọ nìkan Ọlọ́lá jù lọ Terry Waya ni Bàbá Terseer Kiddwaya tó ń kópa nínú BBNaija 2020 Àwùjalẹ̀ wọ́gilé Ojude Oba; Ganduje náà wọ́gilé ayẹyẹ lẹ́yìn ìrun ọdún Iléyá nítori Covid 19 Oríṣun àwòrán, Manuel Toledo Àkọlé àwòrán, Ọkan lara awọn ayẹyẹ to ma n waye lasiko ọdun ileya ni Hawan Sallah Oriṣiriṣi eto amuludun, to fi mọ ẹṣin gigun lo ma n waye lasiko ọdun Ileya nilẹ Hausa.
re pe, igbimo AFCON yoo kede orile-ede ti yoo sagbateru idije naa lojo kesan
Eyi ni igba akọkọ ti iru rẹ yoo ṣẹlẹ lati ọdun 2010 ti adari ile tẹlẹ, David Mark ti n ṣe ọrọ eto iṣuna ile ni oku oru.
Nítorí n óo fi àánú fojú fo ìwà burúkú wọn,n kò sì ní ranti ẹ̀ṣẹ̀ wọn mọ́.
Opolopo awọn ero lo ya wa fun Tolulope Arotile ni ẹyẹ ikẹyin lasiko eto isinku rẹ lai yọ awọn Oluṣọagutan silẹ.
Olaleye ni ijọba ti gbe eto kalẹ lati ri pe awọn akẹkọọ wa ni alaafia lasiko arun Coronavirus yii.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Ileeṣẹ ẹrọ ibanisọrọ ṣe ipade lori itakun agbaye: Ni kete ti arun naa tan de Naijiria ni ọkan gboogi lara awọn ileeṣẹ ẹrọ ibanisọrọ, MTN, ṣe adinku si bi awọn eeyan ti kii ṣe oṣiṣẹ, wọn ṣe n wọle sinu ile iṣẹ wọn, eyi ni Yellow Drome to wa nilu Eko.
Ojú alágbe ni wọ́n fi ń wo alága ìdúró- Ayo Oladokun Ìpanu ‘Cheese ball’ ni wọ́n fi jí Ikimot gbé, àmọ́ ó padà sílé lẹ́yìn ọdún márùn-ún Umar wa kadi ọrọ rẹ nilẹ pe A wa ko se ọfọ kankan mọ, a fẹ beere fun idajọ ododo ni lori iku akẹẹgbẹ wa, a ko si ni fara mọ iwa aibọwọ fun ofin."
" gege bi ohun oloselu , oludajoba ni olori orile-ede , won wa nipo yi titi di igba ti wo ba ku tabi sakuro lori ite , be sini "" o je yiyasoto kuro lodo gbogbo awon omo egbe orile-ede miran "" ."
Iwadii fihan pe oogun yii maa n dena aarun rọpa-rọsẹ ati aarun ọkan t'eeyan ba loogun naa ko to sun lalẹ.
Ó sọ omi wọn di ẹ̀jẹ̀,ó sì mú kí ẹja wọn kú.
Bakan naa ni ijọba yoo maa
Ṣugbọn bii ti Ọjọgbọn Sunday Edeko olukọni ni fasiti Ambrose Ali nipinlẹ Edo kọ, lẹyin to kilọ fun ajọ ASUU pe oun ko fọwọ si iyanṣelodi ti wọn gunle.
ọba wí fún Natani wolii pé, “Èmi ń gbé inú ààfin tí wọ́n fi igi kedari kọ́, ṣugbọn inú àgọ́ ni àpótí ẹ̀rí OLUWA wà!
Awọn amuyẹ to gbọdọ ni: Ẹni to ba fẹ ẹ fi orukọ silẹ gbọdọ jẹ ọmọ bibi orilẹ-ede Naijiria.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Kayode Ajulo: Ò dára kí Ilé Ìgbìmọ̀ Asòfin buwọ́lù àwọn àbádòfin tí Buhari kọ̀sílẹ̀ 18 Ìgbé 2019 Oríṣun àwòrán, Wikipedia Àkọlé àwòrán, Ààrẹ Muhammadu Buhari ní ọdún tó kọjá ló kọ̀ láti buwọ́lù àbádòfin lórí àtúnse ẹ̀ka tó ń sàkóso epo bẹntiról.
Henderson’s shot saved and Divock slots home!
Gbogbo ọdún tí ó lò lórí oyè jẹ́ ọdún mẹẹdọgbọn.
Igbákejì kọmíṣánà Ọlọ́pàá, Yọmi Shogunlẹ nigba ti oun fesi si isẹlẹ ni oju opò Twitter rẹ ní, okú ọmọbìnrin akẹ́kọ̀ọ́ ìpele àṣekágbá ní fásitì náà ti ń dí ìbajẹ́ lábẹ́ ìbùsùn ọ̀rẹ́kùnrin rẹ̀, tó ní ó jẹ́ jàgùdà orí ẹ̀rọ ayélujára, tí gbogbo ènìyàn ń pè ní Yahoo Yahoo.
Gbogbo eeyan lo kan sáárá si wọn nigba ti fidio ẹ ṣafihan Chris Brown olorin ilẹ Amẹrika to n jo si orin naa.
EFCC sọ fun ile ẹjọ lati ti apo aṣuwọn naa titi ti wọn yoo fi pari iwadii kan ti wọn n ṣe.
Àwọn nǹkan tí mo fẹ́ ba yín sọ pọ̀, ṣugbọn n kò fẹ́ kọ ọ́ sinu ìwé.
" belafonte gbajumo fun kiko orin "" the banana boat song "" , pelu igbe-orin "" day-o "" ."
 ' ninu awon iwe re ) , je was a -born aṣiṣẹ ́ àbímọ ́ àti aṣeọ ̀ rọ ̀ alàyè onísísodòmíràn ọmọ britani to gba iyin fun ise re ninu idagbasoke ironu oniti-darwin tuntun .
Ẹ wò wọ́n lónìí bí wọ́n ti di ahoro, tí kò sì sí eniyan ninu wọn, 
Ṣalumu ni baba Hilikaya; Hilikaya bí Asaraya, 
Bí ọkọ rẹ̀ bá lòdì sí ẹ̀jẹ́ náà, ọmọbinrin náà kò ní san ẹ̀jẹ́ náà.
Joabu bá gbéra, ó lọ sí Geṣuri, ó sì mú Absalomu pada wá sí Jerusalẹmu.
Àṣà kan wà ní’lẹ̀ yìí tó jọ mí lójú.
Ìwọ ati Aaroni, ẹ ka gbogbo àwọn tí wọ́n lè jáde lọ sí ojú ogun, láti ẹni ogún ọdún lọ sókè.
Ọlọ́pàá Ondo sọ ohun tí wọ́n mọ̀ nípa ẹni tó pa Ọmọ Fasoranti FFK: Ẹ̀jẹ̀ Fulani ti dàpọ̀ mọ́ ti Yorùbá lára mi Ẹ yàgò fún ìwà adìẹ dàmí lóògùn nù, màá fọ lẹ́yin lásìkò ìjà - Buhari Afurasí Fulani ṣekú pa ọmọ olórí ẹgbẹ́ Afẹ́nifẹ́re, Fasoranti Gẹgẹ bi ọrọ rẹ, ni wọn igba ti ko tii si darandaran fulani kan to tii maa di igba ati agbọn rẹ kuro lapa guusu gba ọna ariwa orilẹ-ede Naijiria lọ, eremọde lasan ni ipe naa.
 ní ìlú tí wọn kò b ́ ti láàńfàní púpọ ̀ lati kó àrùn yìí , wón gbani nímọ ̀ ràn wípé àwọn tí láàńfàní púpọ ̀ lati kóo láàrín wọn gbódọ gba àjẹsára .
 Iná sọ lóòtọ́ láàfin mi, ṣùgbọ́n kò sí gìrí- Ooni Ile Ife Wo ibùdó arẹwà tí ọ̀pọ̀ èrò ń ya lọ ní Abuja Olólùfẹ́ mi ṣèèsì fi ọkọ́ gbá mi sí gọ́tà, mo rò pé ọlọ́jọ́ dé ni - Iya Osogbo Ẹgbẹ́ akẹ́kọ̀ọ́ gíga n‘Ibadan ṣèwọ́de lọ iléeṣẹ́ ọlọ́pàá lórí afurasí tó dàwátì Gomina Seyi Makinde ni: A mọ pe awọn eeyan ni ẹtọ labẹ ofin lati ṣe ifẹhonuhan lẹyin iru iṣẹlẹ bayii, ṣugbọn a n rọ ẹyin eeyan wa lati ma dalu ru tabi ba dukia jẹ nitori pe ẹ n ṣefẹhonuhan lori iṣẹlẹ yii.
Akanbi mi, má fọ̀ ọ́, mo wà pẹ̀lú ẹ; ẹni tó ṣe ìgbéyàwó olórùka ló l'ọkọ- Lizzy Anjorin Ó yẹ kí ìjọba gbé ilé ìwé tì pa títí di ọdún 2021- ASUU Èèyàn 789 gbèkuru jẹ lọ́wọ́ ẹbọra nítorí COVID-19 ní Nàìjíríà Lẹ́yìn gbogbo sinimá oríta ní Ondo, Akẹti jáwé olúborí ní APC Òògùn ìtura dé fún Coronavirus!
Wo ǹkan tó yẹ kí o mọ̀ nípa Joe Biden, tó ń kojú Trump nínú ìbò America Kíní ọ̀nà àbáyọ sí ìjàmbá ọkọ̀ tó ń wáyé lemọ́lemọ́ ní Ọjà Akungba,ní Ondo?
Amnesty International ti Naijiria ti ni awọn ṣi n gba iroyin to fidi ẹ mulẹ pe awọn oṣiṣẹ eleto aabo n gbe igbesẹ ti ko yẹ lati wadii ọrọ.
"Wiro pari ọrọ rẹ pe ""idi ree ti a fi n bẹ awọn ọdọ wọnyii ki wọn ye sọ ọmọ nu mọ."
Lasiko ti Aarẹ tẹlẹri, Olusegun Obasanjo wa lori aleefa, Baba Sala gba Ami Ẹyẹ ọlọla lorilẹede Naijiria, Member of di Order of di Niger (MON)ni ọdun 1978.
Láti àkókò tí Johanu Onítẹ̀bọmi ti bẹ̀rẹ̀ sí waasu títí di ìsinsìnyìí ni àwọn alágbára ti gbógun ti ìjọba ọ̀run, wọ́n sì fẹ́ fi ipá gbà á.
idahun si ibeeere yii lo sun ikọ BBC News Yoruba lọ si ibudo iya sinima kan ti akọle rẹ n jẹ Àgbésọrísùn.
Oshiomole nkan ko le fi bẹ ẹ r'ọrun fun APC nitori awọn to fi ẹgbẹ silẹ, o ni sṣugbọn, ẹni kan, ibo kan ni yoo bori lọjọ idibo.
CAMA 2020: Falana, SERAP ní CAMA ni òfin tó tíì burú jùlọ nínú ìtàn Nàíjíríà
Oríṣun àwòrán, Eko Itan aye Oshodi Tapa tun kọ wa lati maṣe raga bo ọmọ tiwa, ka si ran ọmọ ọlọmọ níbi tó le.
Titi di asiko ti a fi n ṣa iroyin yii jọ, ko tii si ẹni lee sọ ohun gan ni pato to fa ijamba ina naa.
Ẹni tí ó fi ìgbádùn òde ọ̀run sílẹ̀ tí ó wáá bá mi níńu àìgbádùn òde ayé!
"O ti n lọ bii ọdun kan abọ ti oju yii ti wa bayii, o si ṣeeṣe ki oju mi maa ri bayii kani agbara mi gbe inawo rẹ ni.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Ọwọja iku awọn oṣiṣẹ ilera lati ọwọ arun Covid- 19 lẹnu ọjọ mẹta yii n peleke si ni Ondo.
Àwọn ará Filistia fi kókó ọlọ́yún marun-un náà tí wọ́n fi wúrà ṣe ranṣẹ gẹ́gẹ́ bí nǹkan ètùtù.
Nígbà tí ó di ọjọ́ kẹjọ, wọ́n wá sí yàrá àbáwọlé ilé OLUWA.
Okoye,to jẹ oludari komisona  fun ajo
Oríṣun àwòrán, APple Àkọlé àwòrán, Foonu iphone 12 to jẹ alawọ buluu, niwaju ati lẹyin Aworan to gidi gan an ni: Uk ni orilẹede keji nilẹ Yuroopu ti yoo bẹrẹ si ni lo itakun ayelujara 5G.
Eyi fihan pe ọpọ ero lo n wa orin yii lori ayelujara.
Olukọ ko gbọdọ ṣẹruba akẹkọọ nitori o n fẹ lati ba a lopọ.
A kò rí ohun tuntun kan gbámu.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Fídíò àkàndá ẹ̀dá tó di amòfin Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Fídíò àkàndá ẹ̀dá tó di amòfin 29 Ìgbé 2018 Patcharamon Sawana jẹ́ ọmọ orílẹ̀èdè Thailand.
 Gbogbo wa la o mọ iku rẹ yii lara ninu igbimọ awa agbẹnusọ Ile Aṣofin orilẹ-ede yii”.
RevolutionNow: Falana àtàwọn míì ṣe àpérò l'Eko lẹ́yìn tí DSS kọ́kọ́ ti gbọ̀ngàn tí wọ́n fẹ́ lò pa
Poly Rufus Giwa, Owo di títì pa di ọjọ́ míì France Vs Nigeria: Super Falcons takú síbẹ̀, àmọ́ ẹ̀pa kò bóró mọ́ Ọlọ́wọ́ idán Houdini kò yè é o, ó bómi lọ!
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ifa Priest: ọdún mọ́kànlá ni mo fi ṣe iṣẹ́ agbejọ́rọ̀ kí n tó gbọ́ràn si Ifá lẹ́nu Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Ajọ FIFA ni igba akọkọ ti awọn maa gbe iru igbesẹ yii.
Mercy Aigbe ṣá ọmọ rẹ̀ sínúu fíìmù tuntun, wo itú tí ọmọ ọdún mẹ́wàá náà pa Àlàyé rèé láti ẹ́nu ẹbí ìyàwó pasitọ Sylvester Ofori ọmọ Ghana tó yìnbon pá aya rẹ̀ l'Amẹrika Ọ̀nà àbáyọ márùn ún rèé tí obìnrin àti ọkùnrin bá lẹ̀pọ̀ lásìkò ìbálòpọ̀ Tí yóò bá fi di 'October,' afẹ́fẹ́ gáàsì lẹ́ máa lò fún ọkọ̀ àti ẹ̀rọ àmúnáwá yín - Mínísítà Ọmọkùnrin tó ya 'Blue film' nínú igbó Osun Osogbo ti bayé ara rẹ̀ jẹ́ - Yemi Elebuibon Yatọ si awọn olori to ti jẹ tẹlẹ, Nengi ko ni ni igbakeji nile.
Awọn ọmọ Yoruba agbegbe yii ko kan ko ara wọn jọ lati maa ṣe ohun to wu wọn nilẹ onilẹ, ijoba Austria naa fi ọwọ si i.
'À ń lọ ilé-ẹjọ́ kòtẹ́milọ́rùn fún ẹ̀kúnwó owó oṣù ẹlẹ́wọ̀n' Itan Igbesi aye Ojogbon Andrew Haruna: A bi Haruna lọdun 1957 ni abule Gar ni ijọba ibilẹ Alkaleri ni ipinlẹ Bauchi.
lẹ́yìn náà, Hoṣaaya ati ìdajì àwọn ìjòyè Juda tẹ̀lé wọn, 
Nkan ti mo gbọ ba mi lọkan jẹ, ma a ṣe iranlọwọ ni ọna ti mo ba l'agbara."
N kò bẹ̀bẹ̀ pé kí o mú wọn kúrò ninu ayé.
Lọdun mẹta sẹyin ni o fi iṣe olukọ dùùrù títẹ̀ sílẹ̀ lọ gba iṣe arinrin oge.
Àjẹ́ àti Aṣẹ́wó ní ìyá Rainbow - Òjòpagogo Ìjọba Ọyọ gbọdọ̀ tanná wádìí ìṣèjọba Abiola Ajimọ̀bi - PDP Àwọn aláṣẹ kéde ìséde lọ́gbà fásitì Ibadan Ìjọba Buhari ń wùwà bíi ìjọba Abacha lórí ọ̀rọ̀ Ṣoworẹ- Ṣoyinka Àṣìta ìbọn ló pa obìnrin nílùú Eko lọ́jọ́ Satide- Ọlọ́pàá Awọn mejeeji lawọn o jẹbi ẹsun ti wọn fi kan awọn.
Shiite Movement: Shiite fèsì lórí àṣẹ ilé ẹjọ́ láti máa pé wọ́n ní ẹgbẹ́ agbésùnmọ̀mí
tí o bá bọ́ sinu tàkútétí o fi ọ̀rọ̀ ẹnu rẹ dẹ fún ara rẹ,tí ọ̀rọ̀ ẹnu rẹ sì ti kó bá ọ,
asif ali zardari ( urdu : آصف علی زرداری ; sindhi : آصف علي زرداري ; ojoibi 26 july 1955 ) ni aare ile pakistan 11k lowolowo ati abase-alaga egbe awon eniyan pakistan ( ppp ) .
Eyi ti fa ọpọlọpọ ariyanjiyan ati ibeere pe ta gan an lo ji awọn ọmọ yii gbe?
A máa gbóhùn sétí, a sì máa gba ohùn lẹ́nù.
“Ṣé ẹrú ni Israẹli ni,àbí ọmọ ẹrú tí ẹrú bí sinu ilé?
Ta ló mọ ohun tí yóo ṣẹlẹ̀ láyé lẹ́yìn òun, lẹ́yìn tí ó bá ti kú tán?
Awọn iroyin miran ti ẹ le nifẹ si: BBC ṣe'filọlẹ Yoruba, Igbo ati Pidgin Akẹkọ Dapchi 101 lo pada de BBC koro oju si ikọlu ijọba ipinlẹ Eko Sugbọn o ni ipenija nla ni eleyi jẹ fun awọn ti yoo mu ala naa se.
Ní ìdakèjì, lẹ́yìn gbogbo ìṣẹ̀lẹ̀ẹ pàjáwìrì wọ̀nyìí, kò sí àní-àní pé àjọ kan ń gbìyànjú láti tìka bọ ìṣẹ̀lẹ̀ wọ̀nwọ̀nyí ní bírípó.
“Nítòótọ́, a ti pa fìtílà ẹni ibi,ahọ́n iná rẹ̀ kò sì mọ́lẹ̀ mọ́.
Níbo sì ni ibi ìsinmi mi wà?
Èyí èkínní di arúgbó kí ó tóó kúrò nínú ayé, kò hùwà ibi, kò ṣèké, kò ba orúkọ ọmọnìkejì jẹ́, kò di rìkíṣí mọ ẹni ẹlẹ́ni, kò tọ babaláwo lọ nítorí àti ba ti ọmọnìkejì jẹ́, kò wí pé kí ni Ọlọ́run máa ṣe, kò búra èké, kò ṣe olè, kò yáájú sí àgbàlagbà, bẹ́ẹ̀ ni kò hùwà ibi kan ṣsoṣo.
Ayajọ ọjọ awọn oṣiṣe: ọjọ kinni, oṣu karun un: Eyi ni ọjọ ti awọn oṣiṣẹ Naijiria ya sọtọ lati fi sami iṣẹ ti wọn n ṣe.
Nípa iṣẹ́ Ọlọrun, ẹ̀yin wà ní ìṣọ̀kan pẹlu Kristi Jesu.
fi aidunnu re han bi won se pa asofin Temitope Olatoye Sugar ti won demi
’ Oríṣun àwòrán, Google Àkọlé àwòrán, Ọpọ igba ni awọn eniyan nla nla lawujọ ma n bere fun iyipada ofin ati ilana orilẹede Naijiria Ọjọgbọn Olusegun Osoba wa fikun wi pe, ọna abayọ si isoro Naijiria ni ki awọn ọmọ Naijiria ma a fi ẹhọnu wọn han lati igba de igba.
Ìyàwò lárìnlọọ̀dù mi pè mí ní akálòlò ni mo ṣe paa - Afurasí Èdè Akurẹ àti Ibadan ni wọ́n fi fà mí léti pé ẹni re kìí 'se òṣèlú - Seyi Makinde Ìpàdé àpérò kọ́ ló kàn, àdánìkànjẹ ẹ̀yà kan ni ká dẹ́kun ní Nàíjíríà - Òǹwòye #Mothersday2019: Àwọn ìpèníjà obìnrin láwùjọ Gẹgẹ bi a ṣe gbọ, ọwọ ṣinkun ọlọpaa tẹ baba agbalagba naa ti wọn pe orukọ rẹ ni Shadrack Ejinwo.
Israel Adesanya to jẹ ọmọ bibi ipinlẹ Ogun lorilẹede Naijiria fi agba han Yoel Romero ninu idajọ gbogbo awọn adajọ to mojuto ija naa.
Orile ede naa lo ti  figba kan koju aarun Ebola lọdun 2014 , ti eleyii si se akoba fun eto oro aje won.
41 Tàbí ìwọ ha le ní ìrẹ̀lẹ̀ ati ìwà pẹ̀lẹ́, àti pé kí ìwọ hùwà bí ọlọ́gbọ́n níwájú mi?
Ninu oro alaga ipade naa, Jacqulina Adebija fi da ijokoo ohun loju erongba wa lati polongo sise adinku iku alaboyun ati omo-wewe, ni eyi ti o ro omo egbe naa lati maa se kaare ninu sise ojuse  won.
'Kò sí ohun tó burú nínú bí Ajimobi ṣe dá Yewande tó pa ọkọ rẹ̀ sílẹ̀' Ìlú ò rẹ́rìn ín rárá, Alaafin Adeyemi III fárígá fún Buhari nínú lẹ́tà tuntun Trump bu ẹnu atẹ lu FBI Mo ni ọwọ nla fun Afrika-Trump Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Olawoye ni aago mẹsan owurọ, lọjọ Isẹgun ni idajọ naa yoo maa waye nile ẹjọ giga ilu Akure.
Bakan naa ni INEC ni àwọn òṣìṣẹ́ aláàbò náà yóò ri i dájú pé, ìdìbò ti kò mú wàhálà dání, pàápàá jùlọ láwọn iha kọ̀ọ̀kan ni ìpínlẹ̀ náà lo waye lọjọ Kẹwaa osu Kẹwaa ọdun yii.
"Akeredolu tun fikun pe oun ti gba ọpọlọpọ awọn dokita si ẹnu isẹ eyi to tun mu kí eto ilera nipinlẹ Ondo túbọ̀ ru gọgọ sì.
Nígbà tí àwọn mọlémọlé bẹ̀rẹ̀ sí fi ìpìlẹ̀ ilé OLUWA lélẹ̀, àwọn alufaa gbé ẹ̀wù wọn wọ̀, wọ́n dúró pẹlu fèrè lọ́wọ́ wọn.
Mú ọkunrin náà wá sọ́dọ̀ mi, kí ó lè mọ̀ pé wolii kan wà ní Israẹli.
L'Ọjọ iṣẹgun kẹlẹ ijọba gbe awọn eeyan mẹjọ naa ni agbegbe Ologunẹru niluu Ibadan nibi ti wọn ri ẹrọ nla to n mọ bulọku si ni ayika ile ẹkọ kan to jẹ ti ijọba ipinlẹ Ọyọ.
Ọlọla Abubakar Tafawa Balewa gba akoso Naijiria ni kete tawọn oyinbo amunisin gbe ijọba silẹ tan, ti wọn si ta asia orilẹede olominira Naijiria soke ni ọjọ Kinni osu Kẹwaa ọdun 1960 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ọdun meje lẹyin ominira Naijiria, ogun abẹ́le bẹrẹ lẹkun ila oorun, ti agbegbe Biafra si yapa.
Àwọn ọmọ Lefi ni wọ́n ní àṣẹ láti gba ìdámẹ́wàá lọ́wọ́ àwọn eniyan gẹ́gẹ́ bí ìlànà òfin.
'Iṣẹlẹ naa n peleke sii' Ni ọsẹ akọkọ ofin konile-o-gbele, ileeṣẹ ọlọpaa South Africa gba ipe to le lẹgbẹrun meji, eyi to jẹ ti iwa ipa akọ si abo to pọ ju bo ṣe ri tẹlẹ lọ pẹlu ida mẹtadinlogoji.
Oríṣun àwòrán, World Health Organisation Cameroon Ọjọ kinni oṣu kẹfa ọdun 2020 ni awọn akẹkọ to wa ni ipele ikẹyin ni ile iwe alakọbẹrẹ ati girama pada sẹnu ẹkọ wọn ni Cameroon.
wọ́n sì yọ́ wúrà bo ilẹ̀ àwọn yàrá náà.
A&B ti odun, 1999 (Ti o ti ni atunse ), Mo 
Ni omi òkun bá bẹ̀rẹ̀ sí ru sókè nítorí afẹ́fẹ́ líle ń fẹ́.
Tí a fiṣọwọ́ ní 9:41 13 Sẹ́rẹ́ 20219:41 13 Sẹ́rẹ́ 2021 Ìdí tí àwọn èèyàn kan kò fí le ni àrùn Coronavirus Ìwádìí fi hàn pé, ìdá ọgójì sí ọgọ́tà àwọn tí kò ni àrun Coronavirus ló ni eroja T Cell""Kà Síwájú Síi next Article share tools Facebook Twitter ṢàpínlòView more share options Share this post Copy this linkKà síwájú síi nípa àwọn ìtọ́kasí wọ̀nyí."
Òsèré tíátà, olóòtú àti olùdarí eré ní Nàìjíríà ni.
Blessing ni mama Laycom ati ọmọ rẹ obinrin ti n pe oun lori aago lati dupẹ fun bi oun ṣe n gbaruki ti i.
" Ẹnití yóò jẹ ààrẹ Amẹ́ríkà gbọdọ̀ tẹ̀lé ìlànà ìdúróṣinṣin Ó ní ẹnití wọ́n bá pè ní ààrẹ gbọdọ̀ máa bọ̀wọ̀ fún àwọn èèyàn, tí yóò sì máa tẹ̀lé àwọn ìlànà tó se iyebíye fún ìdúró sinsin orílẹ̀èdè Amẹ́ríkà.
Ẹ̀mí OLUWA bà lé e, ó sì ń ṣe ìdájọ́ àwọn ọmọ Israẹli.
OLUWA ní,“Ẹ kọ orin sókè pẹlu ìdùnnú fún Jakọbu,kí ẹ sì hó fún olórí àwọn orílẹ̀-èdè,ẹ kéde, ẹ kọ orin ìyìn, kí ẹ sì wí pé,‘OLUWA ti gba àwọn eniyan rẹ̀ lààní, àwọn eniyan Israẹli yòókù.
Nigba ti BBC Yoruba kan si ọgbẹni Tunde Rahman to jẹ agbẹnusọ fun Asiwaju Bọla Tinubu lori ọrọ yii, o ni ileesẹ aarẹ ko tii pe Tinubu gan an lati salaye isẹ tuntun yii fun.
Ni ero Ọjọgbọn Llyod, eniyan takuntakun"" ni Marie Bonaparte."
Ọna lati ṣe aseyọri nidi eyi lo mu ki ijọba ṣe ayipada àwọ̀ owo beba Naijiria, eyi ti yoo ba ọpọ owo ilu tuulu, tawọn oloselu ti di pamọ sinu ile jẹ mọ wọn lọwọ.
Gedoni, ẹni ti o jẹ ẹni kọkanla ti wọn yoo yọ ninu ile naa, ni o lọ lori ekun rẹ, to si n dupẹ lọwọ Ọlọrun lẹyin ti wọn ti yọọ tan.
Trump fi da awọn ọmọ ogun loju pe didun lọsan a so lori ipe alaafia ti wọn fi silẹ ni gbendeke fun Taliban laipẹ.
Ẹ̀ ń fi ara yín wọ́lẹ̀ káàkiri;ẹ̀ ń yà síhìn-ín sọ́hùn-ún!
Ẹwẹ, wọn ti sun ọjọ idibo siwaju ti ijọba si ti ṣadehun pe oun yoo ṣeto apero apapọ nibi ti awọn yoo ti jiroro lori awọn atunto ti yoo mu itẹsiwaju ba ilẹ naa.
''Omiyale le se akoba ti ko lonka, ti o si le fa ki awọn eeyan padanu ẹmi ati dukia, to fi mọ awọn nkan amayedẹrun ti ijọba pese fara ilu'' Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Flood: Ọ̀pọ́ Dúkìá ló sọnù ní 2019 lásìkò tí ìjọba ṣí ’dáàmù Ọyan’ Muhammed ni o ṣeni laanu pe ọdun 2020 jẹ ọdun to lamilaaka pẹlu bi orileede Naijiria ti ṣe n koju ipenija ajakalẹ Covid-19.
Oríṣun àwòrán, @NGRSenate Àkọlé àwòrán, Ọpọ awọn alẹnulọrọ lori owo epo nilẹ Naijria ni wọn ti pe ko wa wi tẹnu wọn lori bi nkan se nlọ pẹlu owo iranwọ lori epo Saaju ninu ọrọ tirẹ, aarẹ ile igbimọ asofin agba nilẹ Naijiria, Sẹnatọ Bukọla Saraki se apejuwe owo iranwọ ori epo rọbi naa gẹgẹbi ọna kan ti awọn kọlọransi ẹda kan n lo lati fun alumọni ilẹ yii gbẹ, ti wọn si ngba ẹgbẹlẹgbẹ owo labẹ eto ti araalu ko lee tan ina wa idi rẹ, eyi ti wọn n pe ni owo iranwọ ori epo rọbi.
Nítorí gbogbo ìlérí Ọlọrun di “bẹ́ẹ̀ ni” ninu rẹ̀.
Gbajabiamila ni iye ibo ọ̀rìnlénígbalékan lati fi jawe olubori lati
Aarẹ Muhammadu Buhari ti kede alakoso tuntun fun ajọ to n gbogun ti iwa ibajẹ nilẹ wa, EFCC.
Nígbà tó ń sọ̀rọ̀ lórí eto ìfọrọwerọ kan, alaga ẹgbẹ́ àwọn ọlọkada nipinlẹ Ọ̀yọ́, ACCOMMORAN, Alhaji Saheed Folaranmi ṣàlàyé pé, àwọn alakoso gareji ọkọ tijọba yàn ni eku ẹda, tó dá rògbòdìyàn àti ìwà itapa sofin silẹ ládùúgbò Soka.
Ìgbésẹ̀ àwọn òṣìṣẹ́fẹ̀yìntì Bakan naa ni Ọgbẹni Ezene ni, awọn ti kọ lẹta si minisita fun igbokegbodo ọkọ ofurufu ni Naijiria, Hadi Sirika, pe ileeṣẹ tuntun Nigeria Air ko ni bẹrẹ iṣẹ, ayafi ti wọn ba san owo awọn to to biliọnu mejidinlọgọrin Naira.
Èyí ni pé, nígbà tí àkókò bá tó, kí ó lè ṣe ohun gbogbo ní àṣeparí ninu Kristi nígbà tí ó bá yá, ìbáà ṣe àwọn ohun tí ó wà ninu àwọn ọ̀run, tabi àwọn ohun tí ó wà lórí ilẹ̀, kí ó lè sọ wọ́n di ọ̀kan ninu Kristi.
Àbí kí àmọ̀tẹ́kùn fọ tóótòòtóó ara rẹ̀ dànù?
Bi a ṣe n ge wọn lọwọ ni wọn n bọruka.
ile ẹjọ orile ede Naijiria nipa eto idibo ni ipinle BauchiO ni atundi ibo yoo waye ni
Coronavirus dòjú ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ PSG àti Strasbourg bolẹ̀ Ni orileede Amẹrika, o le ni ẹgbẹrun kan eeyan to ti ko aisan naa, ti eeyan mejidinlogoji si ti padanu ẹmi wọn.
Ẹ kọ orin ọpẹ́ sí OLUWA,ẹ fi hapu kọ orin dídùn sí Ọlọrun wa.
Oríṣun àwòrán, @Sikiru Adepoju 3) Hakeem Seriki (Chamillionaire): Ojulowo ọmọ Yoruba ni baba ilumọọka olorin takansufe kan, Hakeem Seriki, ti ọpọ eeyan mọ si Chamillionaire, ti iya rẹ si jẹ Akata nilẹ Amẹrika.
Ọkan pataki ninu ijọba Aarẹ Buhari ni Kyari, ti o si tun jẹ ọrẹ timọtimọ si Aarẹ Buhari.
Lẹyin ti Jean Irene Biya ku, ni aarẹ Biya fẹ Chantal, wọn si bi ọmọ meji.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ọdẹrinde Oníjaàálá: Ìjálá mi máa ń mú káwọn onísẹ́ ibi gbàgbé láti sebi Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Ọdẹrinde Oníjaàálá: Ìjálá mi máa ń mú káwọn onísẹ́ ibi gbàgbé láti sebi 4 Ọ̀pẹ̀̀ 2018 Omisore Lateef Oyewale Ọdẹrinde sọ pe ti awọn ẹranko igbo ba ti gbọ ohun oun ni wọn yoo jade sita, ti oun yoo si fi ibọn pa iye to ba wu oun.
"Ijọ Ọlọrun yoo maa kọ awọn eeyan ni ẹka kọọkan lọna to pegede lati se amusẹ awn afojusun wọn, ti yoo si mu esi nla jade.
Wọ́n wo ọkunrin tí wọ́n mú lára dá tí ó dúró lọ́dọ̀ wọn, wọn kò sì mọ ohun tí wọn yóo sọ.
Onidajọ Othman Musa lo fun EFCC ni aṣẹ yii nitori iwe ẹbẹ ajọ naa ti agbẹjọro rẹ, Fatima Mustapha fun ile ẹjọ l'ọjọ Ẹti.
meje yaya mẹfa fun orile ede Naijiria, yẹ fun igbakeji lati lee pari ise rere
Ṣugbọn kò gbọdọ̀ súnmọ́ tòsí ibi aṣọ ìbòjú náà tabi kí ó wá sí ibi pẹpẹ, nítorí pé ó ní àbùkù, kí ó má baà sọ àwọn ibi mímọ́ mi di aláìmọ́; èmi ni OLUWA tí mo sọ wọ́n di mímọ́.
Niṣe ni wọn rọ Ribadu loye kuro ni ipo Igbakeji Ọga agba ọlọpaa, si ipo kọmisana, ni kete ti wọn gba iṣẹ alaga ajọ EFCC lọwọ rẹ.
A ó ṣèrànwọ́ fáwọn ẹbí ọlọ́pàá tó bá rògbòdìyàn EndSARS lọ láti inú N500m tí a yà sọ́tọ̀- Makinde Ilé aṣòfin ìpínlẹ̀ Oyo jáwée lọ sinmi nílé fún alága ìgbìmọ̀ mẹ́tàlá káàkiri ìjọba ìpínlẹ̀ Èèyàn mẹ́tàdínlógóje 137 ló kó covid-19 lọ́jọ́ Ìṣẹ́gun ọgọ́ta wá láti ìpínlẹ̀ Eko Alukoro ileeṣẹ ọlọpaa ipinlẹ Oyo, Olugbenga Fadeyi ṣalaye pe ọga ọlọpaa Gwazarzah ti sọ fun Adeniyi tẹlẹ pe oun lo ma ran aṣọ ti oun gbe fun un funra rẹ.
Ninu itakurọsọ pẹlu ikọ BBC Yoruba, ọkan lara awọn ti o fi ara gba iṣẹlẹ naa, arakunrin Kayọde Popoọla ṣe alaya wi pe iru iṣẹlẹ bẹẹ ko ṣẹlẹ ri lati nnkan bii ogun ọdun sẹyin ti oun ati ayarẹ ti ya ile ti wọn fi da ile ẹkọ silẹ fun awọn akẹkọ to n bẹ ni agbegbe naa.
Ijọba ipinlẹ Oyo lo kede pe biliọnu meji ati miliọnu lsna ẹẹdẹgbẹẹta naira ni oun na fun itọju arun Coronavirus.
Nibayii, igbimọ alaṣẹ tun ti fikun saa ti igbimọ fidihẹ alakanṣe eto ẹgbẹ naa eyi ti Gomina Mai Buni n dari.
Lẹ́yìn náà, kí o lọ sè fún ara rẹ ati fún ọmọ rẹ.
Alaafin of Oyo: Olori Badirat ti fèsì fún ẹ̀yin tó fẹ́ mọ bóyá ó sì jẹ́ olorì Aláàfin àbí bẹ́ẹ̀kọ́ kọ́ Oríṣun àwòrán, Alaafin of oyo Yoruba ni lowe lowe la n lu ilu agidigbo, ọlọgbọn lo n jo, ọmọran si nii mọ.
dari re niluu Abuja, dajo pe igbese ti ajo INEC gbee  lati maa gba oruko iko egbe APC kan to wa ni
Mose sọ ọ̀rọ̀ wọnyi fún àwọn ọmọ Israẹli, wọ́n sì ṣe gẹ́gẹ́ bí OLUWA ti pàṣẹ fún Mose.
Amọṣa, babalawo to n fẹsun kan naa ṣalaye pe irọ patapata lo n pa mọ oun.
Gba ohun tí mò ń sọ rò.
Iran war: Wọ́n ti mu aṣojú ọmọ Britikó ní orílẹ̀-èdè Iran
Bill Gates to je eni to lowo ju lagbaye kesi awọn olori orilẹede Commonwealth lati fi kun iye owo ti won ya soto lati koju aarun iba.
Sugbọn awọn to faramọ ọrọ ti Baba Adeboye sọ ni ko si ohun to buru ninu ọrọ naa, nitori eniyan ni aṣẹ lati yago fun ohunkohun to le e fa ijamba fun ẹmi ati ara rẹ.
Lẹyin to sin Ileesẹ National Oil fun ọdun mẹrindinlọgbọn gbako, Abiola fẹyinti nileesẹ naa, to si dara pọ mọ eto iselu to wa ninu ẹjẹ rẹ nitori ile lo ba a.
Ọsunsanya to jẹ ọmọ ẹgbẹ oṣelu APC ti o si n ṣoju aarin gbungbun ipinlẹ Ogun ti ile Igbimọ Aṣofin kekere.
Ó pe gbogbo àwọn ọmọ ọba lọkunrin, ati Abiatari alufaa, ati Joabu balogun rẹ síbi àsè rẹ̀, ṣugbọn kò pe Solomoni, iranṣẹ rẹ.
Gbogbo wọn jáde pẹlu gbogbo ọmọ ogun wọn, wọ́n pọ̀ yanturu bí eṣú.
Ohun tí OLUWA sọ fún wolii Jeremaya nípa Nebukadinesari, ọba Babiloni nígbà tí ó ń bọ̀ wá ṣẹgun ilẹ̀ Ijipti nìyí: 
” Mose ati Joṣua bá wọ inú àgọ́ àjọ lọ.
Ọba to ba jẹ ni ibikibi nilẹ Yoruba, to si ṣe gbogbo oro ati awọn nkan to yẹ ko ṣe ko to o di ọba, kii ṣe eeyan lasan mọ, o ti di òrìṣà.
Paapaa lori iru aṣọ ti awọn yoo wọ lọjọ igbeyawo awọn.
Ara kìnnìún náà jẹ́ idẹ ó ń dán yinrinyinrin ó sì lẹ́wà púpọ̀.
Ekun Western Cape ni orile-ede South Africa ti ri ogbele to buru julo.
30 Àti bákannáà àwọn ẹnití a fún ní àwọn òfin wọnyìí, lè ní agbára láti fi ìpìlẹ̀ ìjọ mi yìí lélẹ̀, àti láti mú-un jade kúrò nínú ìfarasin àti jáde kúrò nínú òkùnkùn, ìjọ kan ṣoṣo tí ó jẹ́ òtítọ́ àti alààyè lórí gbogbo ilẹ̀ ayé, èyí tí Emi, Olúwa ní inú dídùn sí, ní sísọ̀rọ̀ sí ìjọ ní àpapọ̀ ati kì íṣe ẹni kọ̀ọ̀kan—
Oríṣun àwòrán, @Ayorinde Adedoyin Awọn ẹgbẹ oselu marun un to lewaju ni ẹgbẹ oselu PDP, APC, Accord, Labour ati ANRP.
Ubani lasiko to ba BBC sọrọ ni gomina Wike kuna patapata ninu ọrọ to sọ tako ifẹhọnuhan ti wọn n sọ.
Akanse eto naa lori Facebook BBC Yoruba ree: O ṣalaye pe ainitẹlọrun, awọn ọrẹ ti eniyan n ba arin, ati aini aato fun igbe aye ẹni lo maa n jẹ ki ọpọlọpọ bọ si ọwọ awọn to n muniṣowo ẹru.
Bí wọ́n ti jáde kúrò ninu ọkọ̀, lẹsẹkẹsẹ àwọn eniyan mọ̀ wọ́n.
 Ó tẹ ̀ lé rome àti milan .
Eeyan 1,155 ni covid-19 ti ṣekupa bayii ni Naijiria.
se gudu gudu ,meje yaya mefa lati wa ojutuu si isoro aarun Ebola ni orile ede
Òfin má wàásù láì gbàṣẹ nìpínlẹ̀ Kaduna ti ń gba àpérò Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Iba Gani Adams: Bẹ́ẹ gbé màláíkà kan lọ sí Aso Rock, kò lè ṣàṣeyọrí Kini awọn mejeeji n gbero lati ṣe ti wọn ba de ori aleefa?
(Ìran àwọn òmìrán kan tí à ń pè ní Emimu ní ń gbé ibẹ̀ tẹ́lẹ̀ rí.
Nítorí náà ni wọ́n ṣe ń pe orúkọ kànga náà ní Beeri-lahai-roi, ó wà láàrin Kadeṣi ati Beredi.
Ẹwẹ, aarẹ Trump ti ni o ṣeeṣe ki esi idibo naa pada wọ ile ẹjọ giga julọ nilẹ Amẹrika.
 bí ìyá ṣe ń bí ọmọ , tí bàbá ń wo ọmọ àti bí ọ ̀ rẹ ́ àti ojúlùmọ ̀ ṣe ń báni gbé , bẹ ́ ẹ ̀ ni ìbá gbépọ ̀ ẹ ̀ dá n gbòòrò si .
'' ''Nigba naa ni mo ke Yeeeehhh!
Lẹ́yìn náà wọn yóo jáde kúrò ní ilẹ̀ àjèjì náà, wọn óo sì sìn mí ní ilẹ̀ yìí.
n ri si ọrọ  to jẹ mọ eto aabo, adari
Awọn ọmọ Naijiria ati awọn awọn ọmọ orilẹede adulawọ miran pupọ ti padanu ẹmi ati ominira wọn lori igbiyanju lati gba Libya lọ si Yuroopu lọna aitọ.
Adebayor ranti pe, fun bi ọgbọn iṣẹju lawọn janduku naa fi n dabọn bo ọkọ tawọn wa ninu rẹ, lai le kuro loju kan naa.
Bí Eko ati Abuja ṣe rí rèé lọ́jọ́ àkọ́kọ́ tí wọ́n dẹ ọwọ́ igbele Coronavirus Ìjọba àpapọ̀ ti jẹ Sowore ní ₦1m Àjọ NCDC tún ti kéde ènìyàn 245 míràn tó ní ààrùn Covid-19 l'órílẹ̀-èdè Nàìjíríà Ọwọ́ tẹ báàlẹ̀, Ṣinkó mẹ́tàdínlógún tó ń jí kùsà wà ní ìpínlẹ̀ Ọ̀ṣun Ajibola ni Kii se àwọn aṣáájú nìkan ló ń lọ sókè òkun, àwọn onísẹ adani, oniroyin àti àwọn èèyàn tó lowo lati lọ sókè òkun lo ń lọ gba itọju sugbọn a gbọ́dọ̀ kọ́kọ́ tọju ilé na, ká tó lọ síta ni."
“Ẹ̀yin ará, ọmọ Israẹli, ẹ fetí sí ọ̀rọ̀ mi.
Àwọn mejila tí ó yàn náà nìyí: Simoni, tí ó sọ ní Peteru, 
Ẹlẹka: Ìdá àádọ́rin nínú ọgọ́rùn ni mo ní nínú ìbò Ekiti Níbo ni Fayoṣe wà?
Àwọn èèyàn to n fẹ̀hónú hàn dáná ṣun iléeṣẹ́ MTN n‘Ibadan ShopRite Ibadan gbé ìlẹ̀kùn tìpa torí ìkọlù àwọn tó ń fẹ̀hónú hàn Xenophobic Attack: Àwọn ọmọ Nàìjírìá bínú kọlu Shoprite l'Eko Saaju ni ijọba Naijiria ti kede pe, awọn ko nikopa ninu apero naa ti awọn ilumọọka olorin kan naa si ti ni awọn wọgile lilọ si South Afrika lati lọ ṣere.
Bo tilẹ jẹ wi pe Boko Haram ko lagbara to titẹlẹ mọ, ko ti si aridaju wi pe ijọba ti ribi yọ ọwọ wọn lawo patapata.
ati jijade lorile ede Naijiria,Muhammad Babbandede ti ni ile-ise  won yoo maa bẹrẹ si ni le awon omo orile ede
Àwọn Juu Dìtẹ̀ láti Pa Jesu.
Àwọn yàrá ẹ̀gbẹ̀ẹ̀gbẹ́ náà gùn ní ìwọ̀n ọ̀pá kan, wọ́n sì fẹ̀ ní ìwọ̀n ọ̀pá kan.
Bẹ́ẹ̀ ni a kò jẹ oúnjẹ ẹnikẹ́ni ninu yín lọ́fẹ̀ẹ́.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, ọ̀gá ọlọ́pàá sọ̀rọ̀ lórí SARS Wọn ni nitootọ ni: 'Nitootọ ni Naijiria ti gbe ofin kalẹ lori gbigbogun ti iwa ifiyajẹni lọna aitọ loṣu kejila ọdun 2017.
Gẹ́gẹ́ bí ìlànà òfin, nígbà tí Mose bá ti ka gbogbo àṣẹ Ọlọrun fún àwọn eniyan tán, a mú ẹ̀jẹ̀ ọ̀dọ́ mààlúù ati ti ewúrẹ́ pẹlu omi, ati òwú pupa ati ẹ̀ka igi hisopu, a fi wọ́n Ìwé Òfin náà ati gbogbo àwọn eniyan.
L'ẹgbẹ aworan oloogbe naa ni awọn nkan bi igbalẹ, ike ipọnmi wa.
Ìta ni kí ẹ dúró sí, kí ẹ sì jẹ́ kí ó fi ọwọ́ ara rẹ̀ mú un wá fun yín.
Wọ́n bá wá pàdé wa lọ́nà, wọ́n dé Ọjà Apiusi ati Ilé-èrò Mẹta.
OLUWA ní, “Ìwọ ní tìrẹ, ọmọ eniyan, ní ọjọ́ tí mo bá gba ibi ààbò wọn lọ́wọ́ wọn, àní ayọ̀ ati ògo wọn, ohun tí wọ́n fẹ́ máa rí, tí ọkàn wọn sì fẹ́, pẹlu àwọn ọmọ wọn lọkunrin ati lobinrin, 
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Akomolede Yoruba: Kí ni ìdí tí aṣọ fi máa ń pọ̀ lára Egúngún ju Orò lọ́?
(Iwe ilana ohun ṣiṣe fun aarẹ lẹgbẹ oṣelu YPP) Ayẹwo<br>lati mọ otitọ.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Èrò aráàlú lórí ilé tó ń wó ní ìpínlẹ̀ Eko Ọ̀jọ̀gbọ́n onímọ̀ ẹrọ tí o ní kí wọ́n wọgi lè ìbò Ààrẹ Nàìjíríà Àwọn oúnjẹ tó n gbayì níbi ayẹyẹ báyìí Obìnrin kan bí ibejì lẹ́yìn ọjọ́ 26 tó bí ọmọkùnrin ‘Olùkọ́ fipá bá akẹ́ẹ̀kọ́ girama lòpò nítorí máàkì’ '$800 ni Amẹ́ríkà ń fún ọmọ Yorùbá tó bá gba ìṣẹ́ ológun rẹ̀ lóṣooṣù' Ẹ wo ọmọ ọdún méjì tó mọ orúkọ orílẹ̀èdè 40, àwọn ààrẹ l'ágbàáyé láì lọ síléèwé Wọ́n ta ère Ọ̀ṣun Osogbo sí Togo - Bàbá Ọṣun figbe ta Kí ni àmì ohùn 'Aguntaṣọọlo'?
Obinrin yìí ní, “Nígbà àtijọ́, wọn a máa wí pé, ‘Bí ọ̀rọ̀ kan bá ta kókó, ìlú Abeli ni wọ́n ti í rí ìtumọ̀ rẹ̀.
Ẹ má jẹ́ kí Hesekaya tàn yín, kí ẹ máa rò pé OLUWA yóo gbà yín.
Níwọ̀n ìgbà tí o wà láyé, tí o sì wà láàyè, n kò jẹ́ dán irú rẹ̀ wò.
Oríṣun àwòrán, SCOTT OLSON/GETTY Àkọlé àwòrán, Dokita yii fi ilọkulọ lọ awọn obinrin elere ori papa ni Amerika Awọn eniyan kan sara si idajọ yii dara dara nitori o jẹ ajaye lori ẹjọ yii to ti ko ba nkan bii ọdọmọbinrin mẹrin-din lọgọjọ lorilẹede Amerika.
Koda, eefin n ru jade lati agbegbe ti ibugbamu naa ti waye, ti oju ọrun si dudu fun eefin.
O ni ipa gbogbo ni ijọba yoo sa lati rii pe eto ilera to mu irọrun dani wa larọwọto mutumuwa, paapaa julọ awọn obinrin ati ọmọ wẹwẹ.
ẹni tí ó wá ròyìn ikú Saulu fún mi ní Sikilagi rò pé ìròyìn ayọ̀ ni òun mú wá fún mi, ṣugbọn mo ní kí wọn mú un kí wọ́n pa á.
Onisegun oyinbo yii se ikilo naa nilu Ilorin to je olu ilu ipinle Kwara lasiko to n ba akoroyin fun Ile Akede Naijiria, Voice of Nigeria,  soro lori ewu ki awon eniyan maa  lo sodo awon onisegun opyinbo ti ko kun oju owo fun ayewo.
35 Kí ó má yà ọ lẹ́nu pé mo wí fún ọ: Ọgbọ́n nìyí, má ṣe fi hàn sí ayé—nítorí mo wí, má ṣe fi hàn sí ayé, kí á lè pa ọ́ mọ́.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Kanye West Breakdown: Ìpolongo ìdíje sípò aàrẹ Kanye ti gbéraṣo ní Charleston 5 Agẹmo 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 20 Agẹmo 2020 Oríṣun àwòrán, @10TampaBay Àkọlé àwòrán, Ọjọ́ kẹrin, oṣu Keje, ọdún 2020 ni Kanye West fi èròńgbà rẹ̀ léde láti du ipò aàrẹ Amẹrika.
Alága afúnṣọ́ dé fún APC, níbo ni ìbò abẹ́lé l'Ondo yóò já sí?
Ijọba apapọ Naijiria ti paṣẹ ki wọn tu ikọ ọlọpaa FSARS ka ni kiakia.
IJA LAARIN ILẸ ARAB ATI ISREAL: Joe Biden ti ni oun yoo tẹlẹ ipasẹ aarẹ Donald Trump ninu adehun rẹ pẹlu orilẹede United Arab Emirates, nitori Biden fẹran orilẹede Isreal.
Fr Mbaka, ọmọ ìjọ rẹ̀ kọ̀lu akọ̀ròyìn BBC, wọ́n lù wọ́n ní àlùdojúbolẹ̀ Háà!
Oríṣun àwòrán, Other Sirika jẹ ọkan lara ọmo igbimọ amúṣẹsẹ lori COVID-19 nigba ti Boss Mustapha to jẹ akọwé ijoba apapọ jẹ́ alaga wọ́n.
Nitori naa, igbesẹ yowu ti wọn maa gbe yoo jẹ eyi ti gbogbo wọn jọ fimọ ṣọkan nipa rẹ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Addo: Atunto n bọ ni ileesẹ ọlọpa Ghana laipẹ 8 Èrèlè 2018 Oríṣun àwòrán, Getty images/ISSOUF SANOGO Àkọlé àwòrán, Idagbasoke ọrọ aje orilẹede Ghana ti n mu ireti idagbasoke ọtun ba awọn eeyan ibẹ Aarẹ orilẹede Ghana, Akufo Addo ti pinnu atunto ileesẹ ọlọpa gẹgẹbii ara ipinnu tuntun lati wọ'ya ija pẹlu iwa ọdaran lorilẹede ọhun.
Amọ eyi ko ri bẹẹ ni ọja Agbalata nilu Badagry nitori ẹran ejo ni ojulowo ọja ti wọn n ta nibẹ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Larisa: Má jẹ́ kí ọjọ́ orí rẹ dí ẹ lọ́wọ́ láti bẹ̀rẹ̀ ohunkóhun to wù ọ Àrà ọ̀tọ̀ inú orin tó jáde lọ́dún 2018 ní Nàìjíríà 10) Kuami Eugene -Wish me well Olorin gbajugba ọmọ Ghana, Kuami Eugene lo gbe orin 'wish me well'yii sita lọdun 2018.
Bí wọ́n ti tóbi tó, tí ó jẹ́ pé afẹ́fẹ́ líle ní ń gbé wọn kiri, sibẹ ìtukọ̀ kékeré ni ọ̀gá àwọn atukọ̀ fi ń darí wọn sí ibi tí ó bá fẹ́.
Ṣugbọn Jakọbu dá a lóhùn, ó ní, “Ṣebí oluwa mi mọ̀ pé àwọn ọmọ kò lágbára tóbẹ́ẹ̀ ati pé mo níláti ro ti àwọn ẹran tí wọ́n ní ọmọ wẹ́wẹ́ lẹ́yìn, bí a bá dà wọ́n ní ìdàkudà ní ọjọ́ kan péré, gbogbo agbo ni yóo run.
Olówó márùn-ún péré ní Nàíjíríà leè pá ìṣẹ́ àti òṣì rẹ́ - Àbọ̀ ìwádìí Ọga agba ajọ NNPC naa ni gbogbo igbesẹ to ba yẹ ni ijọba atawọn ajọ alaabo gbogbo yoo gbe lati dẹkun fayawọ epo rọbi lorilẹ-ede Naijiria.
miiran ti aare  Buhari  n se.
Ado oloro lo bọ sinu abule rẹ laisun ọdun Sinhalese ti ẹlẹsin Hindu laarin awọn ọmọ ogun mejeeji.
Idamewa kii se dandan - Pasitọ Tunde Bakare Akẹkọ 76 bọ lọwọ awọn ajinigbe ni Yobe Bakanna ni wọn ni igbesẹ yii nṣe idiwọ fun okoowo, ileewe, ile ijọsin, to fi mọ ileeṣẹ ijọba.
Pẹlu iye awọn eeyan tuntun yii, o ti pe 57,242 eeyan to ti ni arun naa l'orilẹede Naijiria bayii.
Awọn iku to kọkọ t'ati ọwọ arun yi wa Awọn Dokita ti sapejuwe bi awọn alaisan kan se pada gbẹmi mi toun ti akitiyan tawọn se.
Ẹ̀mí Mímọ́ bá gbé Saulu, tí a tún ń pè ní Paulu.
bí wọ́n bá tàpá sí àṣẹ mi,tí wọn kò sì pa òfin mi mọ́;
CP Adeleke Yinka - CP Delta Command xxxvi.
" Oríṣun àwòrán, Sanyeri ati kamilu kompo Ń kó ṣe idanwo WAEC tí mo fi di òní tíátà, àwọn òbí mi yín mi nù, mo bẹ̀rẹ̀ si gbe ni ọdọ ọga mi, tí mo sì ń lọ nù agolo nileesẹ búrẹ́dì láti rí owó jẹun, ebi pa mi, ìyá jẹ mi àmọ́ mo dúpẹ́ lọ́wọ́ Ọlọ́run lonii"" Kamilu wa gbà àwọn èèyàn tó kú díẹ̀ kaato fún ní ìmọ̀ràn pé tí wọn ba ni sùúrù, yóò dára, kí wọn sá ni Ọlọ́run, kí wọn sì mọ ohun tí wọn ń ṣe."
Àwọn ni ọmọ Esau, tí àwọn aya rẹ̀ bí fún un ní ilẹ̀ Kenaani.
Àwọn ẹni òkùnkùn ló já ìṣẹ́gun mi gbà, mò ń lọ sílé ẹjọ́ tó ga jùlọ - Bayo Adelabu Ẹ gbà wá o!
Ó bá dìde dúró láàrin àwùjọ àwọn eniyan.
Ailera yii tumọ si pe ẹni naa ko ni i ni ile ọmọ, tabi oju ara obinrin, o si tun le jẹ kindinrin kan pere ni iru ẹni bẹ yoo ni.
Bí àwọn kan ṣe ń kín ọmọbinrin náà lẹ́yìn pé kìí ṣe òní ni Dino Melaye ti mọ pé ọmọbinrin náà nífẹ̀ẹ́ Dino, tìí kìí sì fi pamọ lórí ayélujára, bẹ́ẹ̀ náà ni àwọn míràń sọ pé, ìgbésẹ̀ obìnrin náà kò bójúmu tó.
"Oríṣun àwòrán, @YeleSowore ""Ọpọ awọn iroyin ti ko fararọ lo ti de etigbọ wa,nipa bi awọn ileesẹ alaabo se n fiya jẹ awọn akọroyin, ti wọn si tun n ti wọn mọle, ti wọn n lo agbara ati iwa ipa lori awọn oluwọde ti ko huwa idaluru ati awọn igbesẹ miran to lee pagi dina ominira sisọ ero ẹni, eyi to n di awọn ọmọ Naijiria lọwọ lati sọ tẹnu wọn gẹgẹ bi ẹtọ ọmọniyan ti gba wọn laaye."
Ṣugbọn Absalomu rán iṣẹ́ àṣírí sí gbogbo ẹ̀yà Israẹli, ó ní, “Tí ẹ bá gbọ́ tí wọ́n fọn fèrè, kí ẹ sọ pé, ‘Absalomu ti di ọba ní Heburoni.
Ọba dáhùn pé, “Ahimeleki, ìwọ ati ìdílé baba rẹ yóo kú.
Ìjọba ìpínlẹ̀ Kogi kéde ọjọ́ ìwọlé àwọn akẹ́kọ̀ọ́ padà sí iléèwé Iléeṣẹ́ ìròyìn Daily Trust gbọdọ̀ san N6 bilion nítorí ìbanilórúkọjẹ́- Femi Fani Kayode Sinimá àwòdamiẹnu, Ẹ̀fáńjẹ́líìsì jìyà àjẹmumi nílé aṣẹ́wó l'Ejigbo ní ìlú Eko Ìjàmbá ọkọ̀ tó ṣẹlẹ̀ sí Adams Oshiomole kìí ṣe ojú lásan, àwọn kan ló fẹ́ pa á- APC Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Fídíò, Akomolede: Bolaji Faleke ni Olùkọ́ tó ń kọ́ wa ní àṣà oge ṣiṣe lórí BBC Yorùbá1 Owewe 2020 Notorious Armed Robbers in Nigeria: Lára àwọn ọ̀daràn méje ni Mufu Oloosa Oko àti Godogodo4 Owewe 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Yoruba ni bi eegun ẹni ba jo re, ori a maa ya atọkun rẹ.
Osun Osogbo: OSUCCIMA ní òun yóò lo ọdún Ọṣun Osogbo pèsè iṣẹ́ àti àgbéga okoòwò aládàáni
Ibikíbi tí ìwọ bá tí rí àwọn ènìyàn mi ni ìwọ ti ń yẹ́ wọn sí, nígbà tí àlejò mi bá dé ìwọ a máa ṣe é tayọ̀tayọ̀, ọjọ́ tí mo bá ríowó ni mo tó ń fi í fún ọ, ìgbà tí agbára mi bá ká ẹ̀bùn ni mo tó ń fún ọ ní ẹ̀bùn, ìwọ kò sì jẹ́ gbé ọ̀rọ̀ mi kalẹ̀ kí ó máa bú mi láàárin àwọn alábàáṣiré rẹ; ibi tí mo bá fi ọ́ sí ni mo máa ń bá ọ.
Fetí sílẹ̀ dáradára sí ọ̀rọ̀ mi,kí o sì gbọ́ mi ní àgbọ́yé.
akanse naa kun fun ero fonran igbalode toju afefe ti o le safihan awon isele
Ṣugbọn nígbà tí Jehoiada kú, àwọn ìjòyè ní Juda wá kí ọba, wọ́n sì júbà rẹ̀, ó sì gba ìmọ̀ràn wọn.
Mbanefo so eyi di mimo nigb ti o wa sayewo iboji naa ni Obu Gad ni Aguleri nijoba ibile ila oorun Anambra.
Ggẹ bi iroyin ti ileeṣẹ to n ri si eto ilera lorilẹede Naijiria fi sita nipa awọn oogun apakokoro, wọn ni beeyan ba bọ sọja lati ra a, o ni lati la oju rẹ daadaa lati wo o boya oogun apakokoro naa ni awọn nkan wọnyii: Wo o boya Sanitaisa ti wọn ta fun ni ọjọ ti wọn ṣe e lara ati ọjọ ti ọjọ ori rẹ yoo tan.
Presidential reward for Super Eagles Abikẹ Dabiri ni: ko si eto ifunni lowo tabi iranlọwọ imu-pada-bọ-sipo lati ọwọ ijọba apapọ fun wọn lataari rogbodiyan to bẹ silẹ ni orilẹ-ede South Africa.
Oríṣun àwòrán, Reuters Àkọlé àwòrán, Eden Hazard ti ji giri si ipo tuntun to dimu ni Chelsea 2) Kò sí ẹni ti itan rẹ kò le yipada.
O ti ṣe olóòótọ́ ninu ohun kékeré.
Yóo mú àwọn alágbára ati àwọn ọmọ ogun kúrò,pẹlu àwọn onídàájọ́ ati àwọn wolii,àwọn aláfọ̀ṣẹ ati àwọn àgbààgbà;
Iwadii tun fihan pe ọpọ ile epo ni ijọba ti ti pa lagbegbe Ipokia nitori ko ju ogun kilomita lọ si orilẹede Benin Republic lẹyin ti ijọba ti ibode Naijiria.
Ìdájọ́ ikú ń dínkù, àmọ́ orílẹ̀-èdè mélòó ló sì ń pa ẹlẹ́sẹ̀?
Dafidi bá dáhùn pé, “Ó dára, n óo bá ọ dá majẹmu.
Igbesẹ yii lo mu ki oun fi opin si wiwo isin naa.
Ọrọ naa lo ti da awuyewuye silẹ ti Toyin si ti fi ọrọ yii lọ agbejẹro rẹ, Legal House Solicitors.
Bí mo tilẹ̀ kéré, tí ayé sì kẹ́gàn mi,sibẹ n kò gbàgbé ìlànà rẹ.
Ṣaaju ni Gomina Wike ti ipinlẹ Rivers ti se abẹwo si Benue ti iroyin si sọ wi pe o kede iranwọ igba miliọnu naira fun ipinlẹ naa.
Yoruba ni bi ẹlẹjọ ba ti mọ ẹjọ rẹ ni ẹbi kii pẹ lori ikunlẹ, idi ree ti gomina Seyi Makinde fi n rawọ ẹbẹ si Alaafin pe ko ma binu, ko fi ọwọ wọnu.
Bẹ́ẹ̀ ni wọ́n ṣe dá majẹmu ní Beeriṣeba.
Bí wọ́n bá dúró àwọn àgbá náà a dúró.
A n gba Oromọdiẹ lọwọ iku, o ni wọn ko jẹ ki oun re akita lọ jẹun ni.
owo keji ni Bareke won to wa ni Odogbo ni agbegbe Moniya niluu Ibadan,ni ekun
Aare Muhammadu Buhari ro awon oludije egbe oselu kookan ati awon ololufe won gbogbo lati ri daju pe ipolongo saaju eto idibo gbogbogbo to n bo lọdun 2019 waye nirowo-rose lai fa wahala kankan bi o se le wu ko mo.
”, “Ǹjẹ́ a lè rí àwọn ẹranko wọ̀nyí ní abúlée yín bí?
Dominic ni o ti hande pe Iran fẹ maa fa jọgọ ti ilẹ UK ko dẹ ni gba fun wọn.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Awọn agbesunmọmi Boko Haram tẹlẹ gba idande Òbí tó n fa sìgá n fi ọmọ rẹ̀ sínú ìdè àìsàn l'ọ́jọ́ iwájú Kónkó jabele lọ̀rọ̀ dà ni Sokoto Boko Haram tu awọn olukọni UNIMAID silẹ Awọn ikọ Boko Haram náà kọlu ìlú Mailari ní agbègbè Guzamala ní ìpínlẹ̀ Borno Ọ̀kan lára àwọn òṣìṣẹ́ ajà fẹ́tọ̀ọ́ ní àgọ́ àwọn ogunlende tó gba àwọn tí orí kó yọ sàlàyé pé àwọn to kú tó mẹ́tàlélọgọ́ta.
O sọ nipa iriri rẹ ni kikun ninu ifọrọwanilẹnuwo pẹlu BBC Yoruba paapaa Ìdí tí obìnrin kò ṣe pọ̀ nínú òṣèlú Nàìjíríà .
Lara awọn to wa ni ipade naa ni awọn alaga NCC, EVC-NCC, DG-NITDA, DG-NIMC, ECTS/ECSM-NCC, Alaga ALTON ati awọn ileeṣẹ MTN, Airtel, Ntel, Glo, Smile, ati 9Mobile.
nítorí pé Olùràpadà wọn lágbára,yóo gba ìjà wọn jà.
A ti tú Israẹli ká, wọ́n ti kọ́ àṣàkaṣà àwọn orílẹ̀-èdè tí wọ́n wà láàrin wọn, wọ́n sì dàbí ohun èlò tí kò wúlò.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fọ́nrán ohùn, Àwọn ènìyàn sọ àwọn ewu tí wọn pàdé nínú lílo òògùn ẹ̀fọn Dókítà Yemisi Adeyeye ní ọ̀pọ̀ ènìyàn ló màa lo òògùn apakòkòrò fún ẹ̀fọn, aáyán àti ìdun, sùgbọn kàkà kó jẹ́ ohun ààbò, ìpalára ni ó jẹ́ fún elòmíràn.
Ọ̀rọ̀ ìtàjẹ̀sílẹ̀ ní Nàìjíríà yìí tí ń kọ àwa Oṣo àti Àjẹ́ lóminú, a fẹ́ wa ǹkan ṣe síi Ìpànìyàn tún wáyé ní Akinyele, àwọn ará àdúgbò ṣe ìwọ́de Mi ò tí ì mọ obìnrin rí; kódà, mí ò ní 'Girlfriend'- Mr Macaroni Mama Arsenal ṣeé débi èrè, ẹgbẹ́ kan ti fún màmá l'ẹ̀bùn owó Ikú dóró!
O ni afurasi naa lo mu awọn agbofinro lọ ibi to sin oku obinran ọhun si lẹyin to gẹ ẹmi rẹ kuru.
Èso ọ̀pọ̀tọ́ tí ó wà ninu apẹ̀rẹ̀ keji ti rà patapata tóbẹ́ẹ̀ tí kò ṣe é jẹ.
"Oníṣẹ́ àdáni 250,000 ni ìjọba ṣe ìlànà yìí fún Ẹ má gbìyànjú láti bo àṣírí ìpànìyàn tó wáyé ní Lekki, á ní ẹ̀rí tó dájú - Amnesty International Mi ò ṣẹ̀ máa pín ǹkan lọ́wọ́ ara mi fún aráàlù, ilé mi gangan kọ́ ni wọ́n ti jí ""Palliative"" kó - Họ́nọ́rébù Agunbiade ""Gẹgẹ bi iya ati ipo mi, mo ti parọwa si awọn to gbe ọpa aṣẹ lọ, o si da mi loju pe ẹni to gbe e lọ yoo pada wa tuba funrarẹ, yoo gbe pa aṣẹ naa wa yoo si tọrọ aforiji""."
Aṣọ àlàárì ati aṣọ pupa ni obinrin náà wọ̀.
Àwọn pidánpidán náà sọ fún Farao pé, “Iṣẹ́ Ọlọrun ni èyí.
Ọmọdé yìí máa ń tẹ́lẹ̀ àwọn òbí rẹ̀ lọ sí oko.
A ti sún ìgbẹ́jọ́ Ganduje, Tambuwal àti Ihedioha sí ọ̀la Ṣo mọ̀ pé J.
Ogun mìíràn tún bẹ́ sílẹ̀ pẹlu àwọn ará Filistia, Elihanani, ọmọ Jairi, pa Lahimi, arakunrin Goliati, ará Gati, tí ọ̀kọ̀ rẹ̀ tóbi tó òpó òfì ìhunṣọ.
 ní united states ó maa ń ṣàkóbá fún bíi ìdá ọgbọ ̀ n nínú ìpín ọgọ ́ rún àwọn obìrin tí ọjọ ́ orí wọ ́ n wà láàrin mẹ ́ rìndínlógún àti ọ ̀ kàndínláàdọ ́ ta .
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Female Driver: Sokunbi ni obìnrin àwakọ̀ Dáńfó l‘Eko, tó ń lọ̀ láti ìpínlẹ̀ kan sí òmíì 20 Èrèlè 2020 Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Female Driver: Sokunbi ni obìnrin àwakọ̀ Dáńfó l‘Eko, tó ń lọ̀ láti ìpínlẹ̀ kan sí òmíì Yoruba ni ohun ti ọkunrin lee se, awọn obinrin gan lee se ju bẹẹ lọ, idi isẹ ẹni si laa ti mọ ni lọlẹ.
Níbi tí mo gbé ń ṣe èyí, wọ́n rí mi ninu Tẹmpili.
Bakan naa lo sọ ijinigbe ati iwa ọdaran gbogbo kiiṣe ọrọ ẹya tabi ẹsin.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Wo bí Sunday Orimola ṣe gba ikú ẹranko kú ní Ifon ni Ondo lórí ọ̀nà àtijẹ Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Fídíò, Akomolede: Bolaji Faleke ni Olùkọ́ tó ń kọ́ wa ní àṣà oge ṣiṣe lórí BBC Yorùbá1 Owewe 2020 Davy dèrò ọ̀run nítorí 'Eré orí ẹní' ní ìlú Eko19 Ọ̀pẹ̀̀ 2018 Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
 “kosi ki asise ma maye nigba miiran, bi asise ohun ko se ni di lemo-lemo ni eyan gbodo sora fun.
Ọmọbinrin kan, Seyitan Babatayo lo fi ẹsun ifipabanilopọ kan Oladapo Daniel Oyebanjo 'D'Banj'.
“Fi ojúlówó wúrà ṣe ìgbátí kan kí o sì kọ àkọlé sí i gẹ́gẹ́ bí a ti kọ ọ́ sí ara òrùka èdìdì, àkọlé náà nìyí: ‘Mímọ́ fún OLUWA.
Ikọ ọmọogun ni kii ṣe ijọba apapọ lo pe awọn lọ si Lekki, amọ gomina ipinlẹ Eko fun ara rẹ lo ni ki awọn lo doju kọ ẹnikẹni to ba rufin igbele rẹ ti ijọba pariwo lati dẹkun rogbodiyan to suyọ ni ifẹhọnuhan EndSars.
Ayé kún fún ìwà ìbàjẹ́ lójú Ọlọrun, ìwà jàgídíjàgan sì gba gbogbo ayé.
Gbèsè Nàìjíríà yóò di $50b tí wọ́n bá tún yáwó- Shehu Sani Missing Child: Òbí àti asọ́nà ṣọ́ọ̀ṣì 14, lọ́ búra nì'dí imọlẹ̀ l'Akure Ibodè tí a tì ló fa ọ̀wọ́ngógó owó ọjà- Ìjọba Naijiria Awọn ọlọpàá MET sàlàyé pé àwọn gba ìpè pé ẹnikan n gú àwọn ènìyàn lágbègbè afárá náà ni ààgo meji ku díẹ̀ lọ́sàn oni Wọ́n fi kun pé àwọn ti mú ọkùnrinkan si ahámọ àwọn nítori pé kìí ṣe ìṣẹ̀lẹ̀ tó kan wáyé lásàn.
    Ọ̀rọ̀ náà kọ́ mi lọ́gbọ́n púpọ̀, lọ́nà kín-ín-ní, o fì hàn mi pé bí ènìyàn bá rí nǹkan dáadáa kò yẹ kí olúwarẹ̀ sọ ọ́, o sì yẹ kí ọkùnrin ronú jinlẹ̀ kí o tó máa sọ irú ẹni tí obìnrin kán jẹ́, nítorí ni ọjọ́ tí mo kọ́ rí ọmọbìnrin náà léti’odò, tí kò pẹ́ púpọ̀ tí ó bèèrè pé ṣe mo ní ìyàwó tàbí n kò ní, mo ṣebí ó fẹ́ ki n fẹ́ òun ni, ṣùgbọ́n ìgbà tí mo tó wá kọ ẹnu nǹkan bẹ́ẹ̀ sí i ni mo tó mọ̀ pé ọ̀ràn kò rí bí èmi ti ń ròó.
Ọrọ ibalopọ ni orilẹede India jẹ nkan to l'agbara.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Minisita ètò ìbáraẹnisọ̀rọ̀ kò ní lé kópa nínú ìdìbò abẹ́lé APC nítorí ìwé ẹ̀rí àgùnbánirọ̀ 20 Owewe 2018 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 27 Owewe 2018 Oríṣun àwòrán, Twitter Àkọlé àwòrán, Adebayo Shittu wà lára awọn to fẹ́ díje fun ipò gómìnà ìpínlẹ̀ Ọyọ Ẹgbẹ́ òsèlú All Progressives Congress, APC, ti kọ̀ láti buwọ́lu Mínísítà fún ètò ìbáraẹnisọ̀rọ̀ , Adebayọ Shittu láti kópa nínú ètò ìdìbò abẹ́le ẹgbẹ́ nàá fún ipò gómínà.
Àjọ Ìlera Àgbáyé ( who ) gbani nímọ ̀ ràn pé kí àjẹsára rotavirus jẹ ́ ara àwọn àjẹsára tí à ń gbà lóòrèkóòrè , pàápàá júlọ ní àwọn agbègbè ibi tí àrùn náà ti wọ ́ pọ ̀ .
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù How to wear face mask properly : Kìí ṣe gbogbo ìbòmù ló ń dá coronavirus dúró Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ How to wear face mask properly : Kìí ṣe gbogbo ìbòmù ló ń dá coronavirus dúró 15 Èbibi 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 19 Èbibi 2020 Coronavirus ti di ara wa, kò le è kúrò mọ láéláé - WHO Kí ló ń mú àwọn adarí obìnrin lágbáyé rọwọ mú nípa kíkojú covid 19?
Leyin re, yoo teko leti lo si
Arsenal ti gba ife ẹyẹ FA Cup ni igba mẹtala sẹyin.
Toogun ni lara awọn akiyesi ajọ Amọtẹkun ni pe, wọn ma n ni oriṣiriṣi nkan oloro bi ibọn, ida, ọbẹ ati bẹẹbẹẹ lọ.
Wọ́n sá títí dé Beti Ṣita, ati títí dé ààlà Abeli Mehola, lẹ́bàá Tabati.
O ti le ni oṣu mẹta bayii ti ijọba ti bẹrẹ si ni yọ ọwọ kuro lori iye ti awọn elepo n ta epo ni Naijiria, ti wọn ko si fi kede iye ti wọn yoo ta epo ni Osu Kẹjọ ati Oṣu Kẹsan an, ọdun 2020.
"Àwọn ọmọ Naijiria kóju ija sí àwọn South Africa wọ́n ní ""Ó tó gẹ́"" Ìjọba South Africa pèpàdé lórí ìkórìíra àlejò Àwọn òṣèré tíátà kan rèé, tí wọn fẹ́ ara wọn, tí ìgbeyàwó wọn sì pẹ́ N kò lóyún, bẹ́ẹ̀ ni ń kò ní ọkọ, ẹ fi mí lọ́rùn sílẹ̀ - Dayo Amusa Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ìyàtọ̀ tó wà láàrin ìṣesí Nàìjíríà àti South Africa Àwọn míràn tíll ń kigbe pé ki wọ́n dáná sun ilé itaja náà lójùnà àti ranṣẹ́ pada sí àwọn ènìyàn South Africa gẹ́gẹ́ bi ẹsàn."
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù NIN Registration:Àjọ NIMC sọ pé ọ̀fẹ́ ni gbígba nọ́mbà NIN 16 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 31 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Oríṣun àwòrán, Google Aimọye igba ni ẹsun ti n jade pe awọn oṣiṣẹ ajọ to n mojuto idanimọ awọn ọmọ Naijiria, National Identity Management Commission, NIMC, ma n gba owo lọwọ awọn to ba fẹ fi orukọ silẹ fun nọmba NIN.
Iwadii fihan pe, ẹgbẹrun lọna ọgọta ọkunrin lo kọwọ rin pẹlu Musa lọ si ilu Mecca.
 Idije naa yoo waye ni deede aago Mẹjọ  asalẹ ọjọRu oni , ni papa isere  Cairo International Stadium.
Òun ati àwọn ọmọ rẹ̀ sì ṣọ̀fọ̀ rẹ̀, ó ní, “Ó ṣe, arakunrin mi!
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Blacksmith: èmí ni ìran keje tó jogún iṣẹ́ àgbẹ̀dẹ yii- Alatiṣe 16 CAPE VERDE: O wa ni Iwọ Oorun Afrika ti o si ni anfaani Oṣu kan lati fun ọmọ Naijiria.
Ijẹwuru ni iyawo kẹrin fun gbajugbaja osere tiata kan to ti di oloogbe, Ishola Ogunsola, to jẹ ọkan gboogi ninu awọn oludasilẹ ẹgbẹ awọn oni tiata lorilẹede Naijiria.
Ṣugbọn àwọn olórí ogun kò gbà pé kí o bá wa lọ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Afcon 2019: Àwọn olólùfẹ́ Super Eagles fẹ́ kí Rohr tún wọn tò Atẹjade naa ni tootọ ni ijọba ti ya awọn ile kan sọtọ ni gbogbo ipinlẹ Naijiria lati fi kọ aagọ Fulani ṣugbọn ko si tipatipa ninu ki ẹnikẹni fi ilẹ rẹ silẹ.
Nígbà tí ọjọ́ ìkúnlẹ̀ rẹ̀ pé, wọ́n rí i pé ìbejì ni ó wà ninu rẹ̀.
Oba Lekan tun so pe “Ti Olubadan ba lero wi pe awa igbimo
Ṣupimu ati Hupimu jẹ́ ọmọ Iri, ọmọ Aheri sì ni Huṣimu.
Ninu ẹ̀yà Isakari, àwọn tí wọ́n tó ẹni ogún ọdún, tí wọ́n tó lọ sójú ogun, gẹ́gẹ́ bí àkọsílẹ̀ wọn ní ìdílé-ìdílé 
Àjọ náà sàlàyé pé ènìyàn mílíọnù mọ́kànlélọ́gọ́fà ní ó ṣeéṣe kí àrùn yìí tì sínú ìṣẹ́ àti òsì, àiníṣẹ́ àti àìsí ounjẹ, tó fi mọ́ aisi ìpèsè àwọn ǹkan tí ènìyàn fí ń gbé ìgbé ayé ojoojúmọ́.
Kí ẹ máa dúpẹ́ lọ́wọ́ Baba wa tí ó kà yín yẹ láti ní ìpín ninu ogún àwọn eniyan Ọlọrun ninu ìmọ́lẹ̀.
“Ọkàn eniyan kún fún ẹ̀tàn ju ohun gbogbo lọ,ìwà ìbàjẹ́ sì kún inú rẹ̀;ta ni ó lè mọ èrò ọkàn eniyan?
Pasitọ Biodun Fatoyinbo ni oludasilẹ ile ijọsin Common wealth of Zion Assembly.
O ni ijọba Buhari gbọdọ ṣiṣẹ takuntakun lati fẹ iye agbara ina to wa fun elo awọn ọmọ orilẹede Naijiria loju sii pẹlu ida aadọta.
“A ti ṣẹ̀, a ti ṣe burúkú; a ti ṣìṣe, a ti ṣọ̀tẹ̀, nítorí pé a ti kọ òfin ati àṣẹ rẹ sílẹ̀.
Oríṣun àwòrán, Twitter/@aishambuhari Àkọlé àwòrán, Aisha Buhari duro pẹlu awọn eekan ilu lasiko ti Aarẹ Buhari n buwọlu iwe nibi ayẹyẹ ọgọta ọdun ti Naijiria gba ominira.
 O ni o jẹ ohun to ku diẹ kaato pe, Seyi Makinde gẹgẹ bi gomina tuntun ti ko ti i yan agbẹjọro ijọba nipinlẹ naa, n yọ alaga nipo.
Labani bá dá a lóhùn pé, “Ó tẹ́ mi lọ́rùn láti fún ọ ju kí n fún ẹni ẹlẹ́ni lọ.
“Lẹ́yìn náà, fi ojúlówó wúrà ṣe ìtẹ́ àánú; kí ó gùn ní ìwọ̀n igbọnwọ meji ààbọ̀, kí ó sì fẹ̀ ní ìwọ̀n igbọnwọ kan ààbọ̀.
Eyi si tunmọ si pe awọn to ba n lo foonu to ni eroja Android ko tii le lanfani ati loo.
Emiliano Sala: Wón ti rí bààlú agbábọ́ọ́lù tó pòórá nínú òkun
FBI List: Ìwa jìbìtì kìí jẹ́ kí àwọn ọmọ Naijiria rí olùrànlọ́wọ́ lókè òkun Iwa gbájúẹ̀ yii ti n bi Ige ati Adubi -Ojọgbọn Oni Fagbohungbe.
Nígbà tí Paulu rí wọn, ó dúpẹ́ lọ́wọ́ Ọlọrun, èyí sì dá a lọ́kàn le.
Egypt ṣíná fún Zimbabwe, ẹ̀kọ́ mẹ́rin tó yẹ ní kíkọ́ Bí eṣinṣin bá kọ́já, wíwọ́n ní, lásìkò ìṣíde AFCON 2019 Wo àwọn ẹranko tí wọ́n máa figagbaga ni Egypt nínú AFCON 2019 BBC ri gbọ pe, ileri ẹnu loriṣiriṣi ni ikọ Super Eagles ri gba pe, wọn yoo san awọn owo ajẹmọnu fun wọn ki idije AFCON to o bẹrẹ ni Egypt.
Ṣugbọn bí ó bá ń gbèrò láti ṣe ọ́ níbi, kí OLUWA ṣe bẹ́ẹ̀ sí mi ati jù bẹ́ẹ̀ lọ, kí OLUWA pa mí bí n kò bá sọ fún ọ, kí n sì ràn ọ́ lọ́wọ́ láti sá àsálà.
Article share tools Facebook Twitter ṢàpínlòView more share options Share this post Copy this linkKà síwájú síi nípa àwọn ìtọ́kasí wọ̀nyí.
Alaga ẹgbẹ́ ọlọkada nipinlẹ Ọ̀yọ́ fikùn pe ọ̀nà láti wádìí òdodo ọ̀rọ̀ yìí ló mú kí ọga ọlọ́pàá pé kọmisana feto irinna, Ọjọgbọn Raphael Afonja lórí ẹ̀rọ ibaraẹnisọrọ, tí ọrọ onitọun kò sì yàtọ̀ sí ohun tí òun sọ.
"O ni ""Mo ki ẹyin ololufẹ, ọrẹ ati ẹbi mi ku ọdun Keresimesi."
Pada wá bí egbin ati akọ àgbọ̀nrín,lórí àwọn òkè págunpàgun.
k dáìíró ní ọdún ( 1970 ) .
Ìrora ara rẹ̀ nìkan ló mọ̀,ọ̀fọ̀ ara rẹ̀ nìkan ni ó ń ṣe.
Àwọn olódodo rí i, inú wọn dùn,àwọn aláìlẹ́bi fi wọ́n rẹ́rìn-ín ẹlẹ́yà,
 Èdè mangbetuti ni wọ ́ n ń sọ , wọ ́ n sì múlé gbe àwọn azande , mbuti àti momvu .
 awon orilẹ ede ti o ni iye akoran kokoro ti o ga ni egypt ( 22 % ) , pakistan ( 4.
Opọlọpọ eto ni awọn eniyan ṣe lati fi sami ayẹyẹ ọdun rẹ ti awọn èrò pupọ si n ki olukọ ati oniwaasu naa lori ayelujara kaakiri agbaye.
'EFCC gbẹ́sẹ̀ lé owó Davido, Adeleke' Wo àwọn orílẹ̀-èdè márùn ún tó fún àwọn obìnrin làńfàní tuntun sí ẹ̀tọ́ wọn Ǹkan mẹ́jọ tó máa kọ́kọ́ ṣẹlẹ̀ kí olólùfẹ́ méjì tó pa ara wọn Dokita àti Nọ́ọ̀sì fìyà jẹ mí lásìkò tí mò ń rọbí- Alaboyún Oríṣun àwòrán, Efcc Àkọlé àwòrán, Ha!
Síbẹ̀síbẹ̀ àwọn mìíràn kò bá ènìyàn mu, àwọn wọ̀nyí sì ṣe fáàrí gẹ́gẹ́ bí ipò wọn.
Àjọ WAEC kan ròó nínú ọgbọ́n inú wọn láti fún ààrẹ ní ìwé ẹrí rẹ̀ ni.
Alaga ẹgbẹ oṣelu All Progressives Congress, APC, nipinlẹ̀ Ọyọ, Oloye Akin Ọkẹ ti fesi si ileri ti minisita Adebayọ Shittu jẹ́ lati ṣiṣẹ tako oludije fun ipo gomina ninu ẹgbẹ́ naa l'Ọyọ.
kí ó sọ fún Aaroni, ati àwọn ọmọkunrin rẹ̀, ati gbogbo àwọn ọmọ Israẹli pé, “Ohun tí OLUWA paláṣẹ nìyí: 
 O tun rawọ ẹbẹ si ijoba ipinlẹ Ogun lati tubọ fi ipa mudunmundun iṣakoso ijoba tiwntiwa han ni ilu Mamu Ijẹbu ki aye le rọrun fun wọn.
Aare Talon naa,wa ni iwa fayawọ ti n se akoba fun orile ede Naijiria ati orile ede  rẹ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Sẹnetọ Lekan Balogun: Taló yẹ kó yan ọba bí kò ṣe Ajimobi?
Balogun iko agbaboolu Super Eagles, Mikel Obi so pe, Super Eagles gbaradi sile fun ifesewonse olorejore ti iko phun yoo gba pelu orile-ede England, eyi ti yoo waye papa isere  Wembley nilu London, lojo keji inu osu kefa odun ti a wa yii.
Labẹ aarẹ ana, Ian Khama, gba oriyin fun eto idaabo bo awọn ẹranko fun orilẹede Botswana.
Lẹyin iṣẹju mẹfa ti ere bọọlu ọhun bẹrẹ ni Marcus Rashford gbayo alakọkọ sawọn fun Manchester United eleyi to mu Man U wa niwaju.
O ṣalaye fun atọkun eto ''Connect the World'' iyẹn Becky Anderson pe awọn yoo fi fọnran fidio CCTV to ya iṣẹlẹ naa ṣọwọ si igbimọ iwadii.
Ṣugbọn Absalomu rọ Dafidi títí tí ó fi gbà pé kí Amnoni ati àwọn ọmọ ọba yòókù lọkunrin bá a lọ.
Oríṣun àwòrán, Joshua Paul for the BBC Àkọlé àwòrán, Awọm musulumi lo po ju lọ lorile-ede Malaysia Ejọ maarun un ni adajọ Nenney Shushaidah maa n da lojumọ kan ti wọn a si maa n gbe ẹjọ to to ọgọ́rin wa si iwaju rẹ lọsẹ.
ninu ifesewonse marun un ti iko ohun ti gba lori ara won ninu idije EPL, bee si
Bákanáà ní wọ́n ti ṣí ìwé ìbánikẹ́dùn kan síwájú ilé ìgbìmọ̀ aṣòfin àti ilé ìjọba ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́ lórúkọ rẹ̀ .
F Kumuyi, gbe Bibeli Yoruba to ṣe jáde.
Ahasaya, ọba Juda, ọmọ Jehoramu, sì lọ bẹ̀ ẹ́ wò ní Jesireeli.
Àkọlé àwòrán, Ilú àdó Ekìtì ní àwọn ará ìlú ti gbòdé láti fi ìdúnú wọn han lóri èsì ìbò.
Agbabọọlu aarin fun Manchester United, Paul Pogba ti gbe eto owo dida kalẹ, to si tun jẹjẹ lati ṣeranwọ owo fun ajọ to n mojuto eto ilera awọn ọmọ de l'agbaye, Unicef, lati fi ran awọn smọde to ni aarun coronavirus.
''Apo suga ti a n ra ni N11,000 tẹlẹ, ti da N18,000 bayii ati 25-lita ororo ti awọn n ra tẹlẹ ni N8,000 ti da N15,000 bayii.
Ó tún rán ẹrú mìíràn lọ sí ọ̀dọ̀ wọn.
Awọn ẹ̀ṣọ́ ààbò ojú pópó ni ijamba naa ṣẹlẹ nitosi ile iwe Day Water Man College ni Kobapẹ.
 Ẹ ̀ dà ìtàn kejì ní pé eré kerekérè ni ó pilẹ ̀ eré sakárà láti ọwọ ́ abúdù , tí ó jẹ ́ ọmọ yorùbá kan tí ó ń ṣe àtìpó ní ìlú bídàá ní ìpínlẹ ̀ náíjà .
Gbogbo àwọn eniyan kún fún ayọ̀, gbogbo ìlú sì ní alaafia lẹ́yìn tí wọ́n ti fi idà pa Atalaya ní ààfin.
" Yoo ṣoro diẹ fun ọpọ awọn obinrin ti wọn n fẹ lati kuro nile ọkọ lasiko yii nitori ofin konile-o-gbele to wa lode lasiko arun Covid-19.
tí o ti pèsè níwájú gbogbo eniyan;
Ó ṣe ohun tí ó dára lójú OLUWA.
Ibeere mẹfa lori ijinigbe Dapchi Ijinigbe Dapchi: Lootọ l'ọmọogun o si nibẹ Saaju ni ijọba apapọ ti fi orukọ aadọfa awọn akẹkọ ti wọn si n wa ni ileewe girama awọn obinrin to wa ni ilu Dapchi ransẹ, ko to di wipe o se ifilọlẹ igbimọ kan lati sọfintoto awọn ohun to rọ mọ bi wọn se ji awọn akẹkọ naa gbe.
Ọpọ awọn to n fi orilẹede Naijiria silẹ ni wọn wa lati agbegbe gusu ipinlẹ Edo.
Yoruba bọ, wọn ni isọrọ nigbesi.
Ṣugbọn mo mọ̀ pé ìwọ ati àwọn ẹmẹ̀wà rẹ kò bẹ̀rù OLUWA Ọlọrun.
Oríṣun àwòrán, Karen Charmaine Chanakira Ko pẹ pupọ lo wa a ba mi, to si bẹrẹ si ni bẹbẹ pe ki n dariji oun.
    Ọjọ́ wo ni ìwọ ń bọ̀ wá kí baálé mi?
Fun ọpọ ti ko mọ, aafin Ile Ifẹ kọ ni wọn bi Arẹmọ tuntun yii si.
26 Ọ̀wàrà 2019 Àkọlé àwòrán, Aworan ile Russia ti ọmọ ogun ilẹ ti da ibọn bo awọn akẹgbẹ rẹ Ọmọ ogun ilẹ Russia kan ti ṣeku pa ojugba rẹ mẹjọ ti o si ṣe meji miran leṣe ninu ipagọ awọn ọmọ ogun ilẹ naa.
Nítorí Dafidi sọ ninu ìwé Orin Dafidi pé,‘Oluwa wí fún oluwa mi pé:Jókòó lọ́wọ́ ọ̀tún mi
Ọmọ ọdún márùn-ún, àgbà mẹ́rin ló bá ìṣẹ̀lẹ̀ ọ̀pá bẹntiróò tó gbiná ní Abule Egba lọ - LASEMA Àwọn ará Ijegun fara ya lórí ọ̀pá epo tó ń gbaná ní gbogbo ìgbà Àwòrán bí ìṣẹ̀lẹ̀ ìjàmbá iná ṣe wáyé ní ọja Balogun l‘Eko rèé Oríṣun àwòrán, Twitter/drobafemihamzat Ẹwẹ, ọga agba ileeṣẹ to n risi ọrọ epo rọbi ni Naijiria, Mele Kyari, naa ti ṣe abẹwo si Abule Egba ti o si ni ileeṣẹ NNPC ti brẹ si nigbe epo gba inu ọpa to gba Abule Egba kọja .
Lẹyin ọjọ diẹ to pada sile ọkunrin naa ni ọkọ rẹ ọhun bẹrẹ si ni na a, to si fi ọbẹ ge imu rẹ sọnu.
O ni nkan bii ago kan oru ku iṣẹju mẹẹdogun lọjọ Aiku lo ṣẹlẹ.
Èèyàn kan bá ìṣẹ̀lẹ̀ ilé tó wó ládúgbò Palmgroove lọ Ìdá 90% nínú àwọn olówó Naijiria lo n lọ ilé babaláwo- Mr Latin Ìjọba àríwá Italy fẹ́ dé èèyàn 16 mílíọ̀nù mọ́lé lórí àrùn Coronavirus Gẹgẹ bi atẹjade kan lori oju opo twitter ajọ to n gbogunti ajakalẹ arun lorilẹede Naijiria, NCDC ṣe sọ, onitọhun wa lara awọn to ni nnkan pọ pẹlu ọmọ orilẹede Italy ti wọn kọkọ kede pẹlu aarun naa ni ọsẹ meji sẹyin.
Petr Cech ti o jẹ asọle iko agbaboolu Chelsea teleri, ki o to lo
Duro Ladipọ, ìlúmọ̀ọ́ká òṣèré tíátà àti ọmọ àlúfà tí kò gbàgbé àṣà ìbílẹ̀ Àwọn ìdí márún ti Atiku kò fi wọlé ààrẹ Amẹrika: Ipa ti idẹnukọlẹ isejọba ni lori araalu Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí kan sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
A ṣì ń ṣe ìwádìí ikú tó pa adájọ́ àgbà náà lọ́wọ́.
 bí wọ ́ n kò tilẹ ̀ ní orírun kan náà .
“A ti ṣẹ̀, a sì ti ṣoríkunkun,ìwọ OLUWA kò sì tíì dáríjì wá.
Jesu dá a lóhùn pé, “Nítorí gbolohun rẹ yìí, máa lọ sí ilé rẹ, ẹ̀mí èṣù náà ti jáde kúrò ninu ọmọ rẹ.
Àwọn aposteli Jesu pé jọ sí ọ̀dọ̀ rẹ̀, wọ́n ròyìn gbogbo nǹkan tí wọ́n ti ṣe ati bí wọ́n ti kọ́ àwọn eniyan.
 1988 ) kí iṣẹ ́ yì lé lè padà sí oníbùú .
Gbaju-gbaja akorin naa gunle ni papako ofurufu Bole ti o wa ni ilu Addis Ababa pelu oko ofurufu  orile-ede Ethiopia, oko ofurufu ohun gbe aworan Akon ati iyawo re Rozina Nigussie bi won n gunle.
Ó sì bẹ̀rẹ̀ sí ní àníkún títí ó fi di ọlọ́rọ̀.
Oyeleye to jẹ oludari agba ajọ DAWN Commission to n ṣamojuto ilọsiwaju idagbasoke ọlọjọ pipẹ ni ẹkun Ila Oorun Naijiria ti wọn tun gbe iṣẹ le lọwọ lori ṣiṣamojuto eto Amotekun ba BBC Yoruba sọ̀rọ̀.
Awọn ọkọ ayọkẹlẹ ti n wa ninu sunkẹrẹ-fa-kẹrẹ latari okunkun ti o a n waye nibẹ.
Awọn a tilẹ ti de sibẹ lati ọsẹ kan tabi ju bẹ lọ tori wọn ti maa n bẹrẹ awọn eto aṣaaju mii ko to di ọjọ aṣekagba.
'Ibi ti awọn obinrin le foripamọ si' Bakan naa ni ilẹ Kenya, oṣiṣẹ awujọ kan, Dianah Kamande ni ileeṣẹ oun ṣi ni aye lati fun awọn obinrin ni abo si lẹyin to ti gba obinrin mẹtadinlogun la ni Nairobi nikan.
airounje je awon omo orile-ede yii ti o si tun mu adinku ba igbaye aye opo eniyan
Eyi lọrọ to jẹyọ ninu apara kan ti gomina ipinlẹ Kaduna, Nasir El-Rufai fi igbakeji aarẹ, Yẹmi Oṣinbajọ da pe oun ni alaga ẹgbẹ awọn eeyan ti ko ga pupọ lorilẹede Naijiria.
Afojusun eyi ni Makinde sọ pe yoo mu ki awọn osisẹ ọlọpa agbegbe naa maa sugba awọn osisẹ agbofinro yoku nipa mimu adinku ba eto aabo.
O ni 'inu mi dun to bẹẹ ti n ko lee duro lati ri ọmọkunrin jojolo naa' Ninu amọran to wa fun iya ọmọ tuntun naa, Michele ni loots ni pe Meghan ko ronu pe irufẹ igbe aye bayii yoo kan an gẹgẹ bi oun pẹlu lori ariwo ọja ti yoo maa wa nitori ipo rẹ lawujọ.
Wo bí ìgbéyàwó ọmọ bàbá olówó, Adama Indimi àti Prince Malik Ado ọmọ Ọba Ohinoyi ilẹ̀ Ebira ṣe lárinrin tó Asojú ìjọba orílẹ̀-èdè Lebanon ti kọ̀wé fipò silẹ̀ nítorí ìbágbàmù tó gbẹ̀mi ènìyàn 200 Ìyàwó Bukola Saraki fún tìyá-tọmọ olójú búlúù ní N250, 000!
Ọrọ owo ayẹwo yi ti n mu iriwisi ọtọọtọ wa paapa ni ipinlẹ Ogun nibi ti awọn obi kan ti n faraya pe owo ayẹwo yi ko rọrun fawọn la ti san.
Wọ́n kúrò níbẹ̀, wọ́n ń lọ.
Bakan naa ni ile ẹjọ naa ni El Zakzaky ati aya rẹ ni anfaani bayii lati rin irin ajo lọ gba itọju ni orilẹede India, amọ awọn asoju ikọ olupẹjọ gbọdọ kọwọrin pẹlu rẹ lọ si ibi ti yoo ti gba itọju naa.
Imaamù: Irọ́ ni pé ọkọ leè kọ ìyàwó rẹ̀ nígbà mẹ́ta 'Bíbélì kò ní kí tọkọ taya lu ara wọn pa' Ìyàwò lárìnlọọ̀dù mi pè mí ní akálòlò ni mo ṣe paa - Afurasí Spaghetti, mílíìkì, Chivita àti Àǹkàrá sọ Rabiu dèrò ẹ̀wọn ni Eko O sọ pataki igbani-niyanju lọdọ Pasitọ, Imaam ati amofin agba fun lọkọ laya ki wọn le jọ wo ọna abayọ si ija ojoojumọ wọn.
Nítorí ẹ̀rù ń bà mí pé nígbà ti mo bá dé, mo lè má ba yín ní irú ipò tí mo fẹ́, ati pé ẹ̀yin náà lè rí i pé n kò rí bí ẹ ti ń rò.
Ọ̀pọ̀lọpọ̀ ní-í gbé ìyàwó níjọ́ tí olόde ńgbòde; wọ́n á gbé ìyàwó nínú ibú ìbìnújẹ́, wọ́n á fi Sàtánì ṣe ìmùlẹ̀, Bìlísì yóò bá wọn kẹ́sọ̀-ọ́ ròde, Wàhálà yóò sì jẹ́ ojúlówó èníyàn níjọ́ àjọyọ̀-ọ wọn.
Ìgbà kẹsàn-án nìyí tí àìsàn Ebola yóò bú jáde ní orílẹ̀-èdè DR Congo.
naira ti igbimo ẹlẹnu meta ti ijoba apapo yan,lati fenuko lori ekunwo owo osu
Ni bayi, ireti Arsenal lati fi ife ẹyẹ yi bẹrẹ saa bọọlu tuntun yi ti ja si asan ti awọn alatilẹyin ẹgbẹ naa kan si ti n faraya loju opo Twitter.
To n tumọ sí pé, awọn ọmọ ẹgbẹ Republican to wa loke tente ni ẹka eto ìdájọ́ ilẹ Amẹrika ni gbongbo ju ti Democrat lọ.
Wo bí èsì ìdìbò ìpínlẹ̀ Edo ṣe ń jáde Ọ̀rọ̀ Soyinka àti Obasanjo papọ̀ lórí pé Buhari n ṣe ìpínyà Nàìjíríà Lẹ́yìn olóògbé Barrister àti Kollington, èmi làgbà kàn nínú iṣẹ́ orin Fuji- Obesere yarí Ọkọ̀ méjì jóná ráùráú níbi tí ọkọ̀ tó gbé bẹntiróò ti gbiná Iléèwé míràn tún dàwó ní ìpínlẹ̀ Eko Ọkùnrin kan tún pa ọmọ rẹ méjì àti ìyá tó bíi Obaseki jawe olubori ni ijọba ibilẹ to pọju ninu ibo naa ti Ize-Iyamu si te le e.
Owo yii si lo pọ julọ sikeji ninu eto isuna naa N6.
Lóòtọ́ ná, bí eré bí àwàdà ni púpọ̀ nínú wa fi nṣe, àmọ́ àwọn kan ní ìgbàgbọ́ nínú àsọtẹ́lẹ̀ yìí tó bẹ́ẹ̀ gẹ́, wọ́n ti lọ́ ba sórí àwọn àpátá nlá-nlá.
Alimi tun rọ awọn eeyan lati mase kaarẹ pẹlu ohun ti wọn fẹ jẹ laye, o ni bo pẹ bo ya, yoo pada wa si imuṣẹ, bi wọn ko ba kaarẹ.
Nígbà tí àwọn ọkunrin náà kúrò lọ́dọ̀ Abrahamu, wọ́n dojú kọ ọ̀nà Sodomu, Abrahamu bá wọn lọ láti sìn wọ́n dé ọ̀nà.
OsunDecides: Saraki ní kò sí ìpínlẹ̀ tó jẹ òsìsẹ́ lówó tó Ọ̀sun
Awon osise eleto ilera ni awon meta miran wa ni ese kan aye, ese kan orun nigba ti ara awon meta to ku ti n bale.
Taiwo ni ọpọ igba ni wọn ti kan si Alagba Ayọ Adebanjọ lati tukọ iran Yoruba ṣugbọn to kọ nitori agba ti de.
Fifi owo si iwe akosile ohun nilu Enugu, Ugwuanyi tenumo erongba isakoso ijoba re lati seto ijoba ti yoo mu irorun baa won ara-ilu.
Muhammadu Buhari: Femi Adesina tọ́ka sáwọn ẹ̀rí pé kìí ṣe ẹ̀dà ààrẹ ló ń darí Nàíjíríà
Wọn kò bìkítà: wọ́n ti fi ara wọn fún ìfẹ́kúfẹ̀ẹ́ ara nípa oríṣìíríṣìí ìwà burúkú nítorí ojúkòkòrò.
Bi kii ba ti ṣe iṣẹ aṣẹwo, o dara""."
4 Àti nítorí ìdí èyí Olúwa sọ fún Pétérù: Bí èmi bá fẹ́ kí ó dúró títí èmi yíò fi dé, kín ni èyí jẹ́ sí ọ?
Ọ̀rọ̀ tí ẹ ń gbọ́ kì í ṣe tèmi, ti Baba tí ó rán mi níṣẹ́ ni.
Ọsinbajo pe fun ọlọpa agbegbe Ile-Igbinmọ naa sọ pe Yẹmi Ọṣinbajo ṣiṣe gẹgẹ bi aare nigba naa ni o fi tẹ ontẹ ki wọn na ọwọ naa in oṣu kẹfa, ọdun 2017.
Eeyan 41,804 ni apapọ ni arun naa ti fara kan labẹ ayẹwo lorilẹede Naijiria.
“Ìwọ ọmọ eniyan, sàmì sí ọjọ́ òní, kọ orúkọ ọjọ́ òní sílẹ̀.
Mo ní ìtara fún Ọlọrun gẹ́gẹ́ bí gbogbo yín ti ní lónìí.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ileeṣẹ BBC gba'lejo ife agbaye FIFA nipinlẹ Eko 9 Ẹrẹ̀nà 2018 Àkọlé àwòrán, BBC gba'lejo ife agbaye FIFA Ileeṣẹ BBC ti gba'lejo ife ẹyẹ agbaye FIFA nilu Eko.
O ni koda, awon ohun eelo lati fi ṣe burẹdi miran yatọ si ṣuga ati iyẹfun gan an kọja bẹẹ.
Ẹgbẹ Conservative ti ni ijoko ejilelọgọtalelọọdunrun, ti awọn ẹgbẹ to ku si n du awọn ijoko to ku mọra wọn lọwọ.
Ambode sara awon ti won yoo maa seranti ni gbogbo igba.
isele buruku ohun, aare seleri lati gbe igbese ti o nipon, eleyi ti yoo foju
Àti pé ó pọ̀ tó bẹ́ẹ̀.
EFCC: Akẹ́kọ̀ọ́ mẹ́rin tó ń kọ́ iṣẹ́ Yahoo l‘Eko lọwọ́ EFCC tẹ̀
''A ko le ma darukọ owo gọboi pe a fẹ fi ṣe isẹ agbaṣe .
OLUWA ti pinnu láti wó odi Sioni lulẹ̀.
Baba isalẹ fasiti to lo saa mẹta: Oríṣun àwòrán, facebook/ alaafin of oyo Lọdun 1980, ijọba apapọ yan Ọba Adeyemi Kẹta gẹgẹ bi Baba isalẹ akọkọ fun Fasiti ilu Sokoto, to ti di Uthman Dan Fodio University bayii, fun ọdun mẹrin.
lasiko ti iko omo ogun orile ede yii ba bere igbaradi  eto aabo Python Dance 111 ni ipinle naa.
Ṣugbọn sibẹ ó túbọ̀ ń kígbe pé, “Ọmọ Dafidi!
Kò sí ohun tí wọn kò lè ṣe láti rí ohun tí wọ́n fẹ́.
Wọn ba ọkọ wa ati tawọn ara ilu ti wọn koja ninu iṣẹle naa.
" Ataoja ilu Osogbo, Ọba Jimoh Oyetunji ba awọn eeyan to peju sibi ọdun naa ati gbogbo awọn ọmọ ipinlẹ Osun ṣajọyọ, lẹyin naa lo gbadura fun alaafia ati itẹsiwaju ipinlẹ ọhun.
eso ati ajilẹ fun awon eniyan 163,117 ni awon  ipinle mẹ́rìnlá .
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìdájọ Ademola Adeleke l'Akure kò túmọ sí pé o kún ojú òṣùwọ̀n-Timothy Owoeye 6 Ìgbé 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 7 Ìgbé 2019 Oríṣun àwòrán, @IsiakaAdeleke1/@Hon_Owoeye Olori ọmọ ẹgbẹ to pojulọ nile asofin ipinlẹ Osun,Timothy Owoeye ti dasi ọrọ idajo ti ile ẹjọ kotẹmilọrun kan nilu Akure fi sita lori kikaju osuwọn Sẹnẹtọ Ademola Adeleke lati du ipo Gomina .
Tí àwọn olórí rẹ̀ ń ṣe àríyá láàárọ̀.
Alaga egbe akoroyin lowolowo, Aare Abdulawaheed Odusile parowa fawon omo egbe lati sora fun asilo agbara ominira ninu iroyin ati ominira oro siso.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Xenophobia: Àwọn ọ̀dọ́ kan ń ṣèwọ́de láti pè fún lílé àwọnjì kúrò ní South Africa 8 Owewe 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Awọn ọmọ orilẹede South Africa ti da ọrọ ru nibi ti odu oloṣelu kan ti n sọrọ lati dẹkun ikọlu awọn ajoji nibẹ.
Oríṣun àwòrán, GHANA EDUCATION SERVICE/FACEBOOK Eyi waye gẹgẹ bi aarẹ Akufo ni ki awọn akẹkọọ ti ileewe jẹleosinmi, alakọbẹrẹ titi de ipele kini ni girama ṣi jokoo sile di inu oṣu kini ọdun 2021.
Àkọlé àwòrán, Samuel ni iya gbe lọwọ yii lọdun diẹ ṣaaju ki wọn o to o jigbe.
 orí keyì sọ ̀ rọ ̀ nípa niger-cong ; ẹ ̀ kẹ ́ ta , afrocasiatic ; ẹ ̀ kẹ ́ rin ; khoisan ; ẹ ̀ kárùn-ún , chari-nile ; ẹ ̀ kẹ ́ fà ; nilo-saharan nígbà tí orí kéje sọ ̀ rọ ̀ nípa niger-kordofania .
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Amọṣa ẹgbẹ agbabọọlu Roma ja fitafita lati da meji pada lati ẹsẹ First Edin Dzeko ati Diego Perotti Sadio Mané gba ayo tirẹ wọle ni iṣẹju kẹrindinlọgọta, ki Firmino to gba meji wọle sii.
Island pe awon asaraloge ile yii le koju ise tawon akegbe won loke okun.
 Ó jẹ ́ ìran armenia .
Bi awọn to ṣaaju ṣe n kọ orin naa ni awọn elegbe n kọ tẹle wọn pe End SARS!"
Aare wa gbadura pe ki Olorun dun orile ede naa, ebi  ati ore oloogbe naa ninu.
“Ayé sú mi,nítorí náà n kò ní dákẹ́ ìráhùn;n óo sọ̀rọ̀ pẹlu ìbànújẹ́ ọkàn.
OLUWA ni ó sọ fún mi pé kí n lọ gbógun ti ilẹ̀ yìí, kí n sì pa á run.
gege bi won ti n se lasiko aawe.
aare Yemi Osinbajo dari rẹ , ni eyi to waye LọjọBọ niluu Abuja.
Iwa-ipa Fulani darandaran: ọlọpa fi panpẹ ọba mu eniyan meji Fayose: Awọn darandaran to pa Tunde ko ni lọ lai jẹjọ Ileesẹ naa se ileri wipe oun yoo di ọna ti awọn maalu naa gba wọ inu papa naa nitori ki iru rẹ ma ba waye mọn.
Ọ̀kọ̀ọ̀kan ni kí wọ́n máa sọ̀rọ̀, kí ẹnìkan sì máa túmọ̀ ohun tí wọn ń sọ.
Àbúrò Orímóògùnjẹ́ ni Ilésanmí tí òun àti Olófìn-íntótó jọ wá ṣe ìwádìí ní ilé-Ifè.
Yatọ si eyi, amofin ni ẹsun ti wọn ba fi kan ẹni naa ni yoo sọ iru oniduro ti adajọ yoo sọ pe ko mu wa.
OLUWA sì rán ìjì ńlá jáde, ó kó àwọn ẹyẹ kéékèèké kan wá láti etí òkun, wọ́n bà sí ẹ̀gbẹ́ ibùdó àwọn ọmọ Israẹli.
Ava Lee to n ba ajọ Global Witness ṣiṣẹ sọ pe, ilẹ iṣẹ Shell ṣe adehun lọna to jẹ pe Naijiria yoo kuna ere to yẹ ko ri latara owo epo naa.
Àwọn bàbá wa bọ̀, wọ́n ní, ṣàṣà èèyàn ló ń fẹ́ni dékùn tá ò bá sí ńlé, àmọ́ tẹrú tọmọ ní ń fẹ́ni lójú ẹni.
Dájúdájú, kò sí ẹni tí ó le ra ara rẹ̀ pada,tabi tí ó lè san owó ìràpadà ẹ̀mí rẹ̀ fún Ọlọrun;
Sọ́ọ́bù irun tí ọmọ àarẹ ṣí sílẹ̀ Amerika fa awuyewuye Kí ló dé tí Igbákejì Gomina Ondo ní kí wọ́n yọ Abẹnugan Ilé Aṣòfin?
OLUWA wí pé,“Nítorí pé ó ti pẹ́ tí ẹ ti bọ́ àjàgà yín,tí ẹ sì ti tú ìdè yín;tí ẹ sọ pé, ẹ kò ní sìn mí.
 leyin ipade naa ni won fohunsokan lati yan
Bayii, wọn ti ko wọn si gbaga ni Olu ileeṣẹ NSCDC ni Agodi ni ilu Ibadan lẹyin ti ọwọ te wọn ni nkan bii aago meji ọsan ni Ogbomọṣọ.
Ajo eleto idibo lorile ede Naijiria , (Independent National Electoral
O ti pe ẹni ọdun mejidinlaadọta bayii, to si jẹ pe iṣẹ́ oko lo n ṣe lati gbọ bukaata awọn ọmọ rẹ.
Ẹ dúpẹ́ lọ́wọ́ Ọlọrun ọ̀run,nítorí pé ìfẹ́ rẹ̀ tí kì í yẹ̀ wà títí lae.
Iru igbẹ yii ni eeyan maa n kan inu lati ya.
 Iroyi lẹkun un rẹrẹ n bọ laipẹ……Ademola Adepoju.
Ìdí tí mo fi gbàdúrà ìyàwó bíi Chanel Chin fáwọn tó d'ẹ̀bi ìkọ̀sílẹ̀ rẹ̀ rù mí rèé - Oluwo Ẹlikọ́pítà Quarom aviation já lulẹ̀ ní Ikeja, gbogbo èrò inú rẹ̀ ló ti tẹ́rí gbaṣọ!
Kí a tó dá ẹjọ́ Pásítọ̀ ìjọ Sọ titobi rẹ, ó di 2020- Adájọ́ ní Akurẹ Wo àwòràn ohun tó ṣẹlẹ̀ nílé ìjọsìn Sotitobire tí wọ́n sun ní àná Missing Child: Òbí àti asọ́nà ṣọ́ọ̀ṣì 14, lọ́ búra nì'dí imọlẹ̀ l'Akure Wọn pa ọlọ́pàá kan níbi tí wọ́n ti dáná sun ìjọ Sotitobire l'Akurẹ - Police PRO Àwọn abiyamọ figbe ta lórí ọmọ ọdún kan ti wọn wá nílé ìjọsìn l'Akure Adajọ Charity Adeyanju lo wa sọ pe ki wọn da awọn ti wọn ko wa siwaju oun pada si ahamọ titi di ọjọ kẹta, oṣu kinni, ọdun 2020.
Mo ní ìgbóyà wípé ẹnikẹ́ni kò ní mú mi níbí.
Bakan naa ni aarun naa yara pa awọn ọkunrin ju obinrin lọ.
Mẹjọ ni ilu Eko, Mẹta ni ipinlẹ Katsina, Meji nilu Abuja, ẹyọkan ni ipinlẹ Niger, Kaduna, Anambra, ati Ondo Iye awọn to ti ri iwosan kuro lọwọ arun yii ti gbera sọ di mejidinlaadọta, ti eeyan meje miran si ti jade laye.
“Bí ọ̀kan ninu ẹ̀yà Lefi bá dìde láti ilé rẹ̀, tabi ibikíbi tí ó wù kí ó ti wá ní Israẹli, tabi ìgbà yòówù tí ó bá fẹ́ láti wá sí ibi tí OLUWA ti yàn fún ìsìn rẹ̀, 
’’Adari orile ede yii tun lo
Bakan naa ni ko ṣeeṣe lati mọ awọn to jawe olubori ninu idije tẹtẹ to gbayii nibẹ lasiko yii.
Ẹkẹtalelogun mú Mahasioti, òun ati àwọn ọmọkunrin rẹ̀, ati àwọn arakunrin rẹ̀ jẹ́ mejila.
Gẹ́gẹ́ bi ìlúmọ̀ọ́ka oloṣèlu Ben Murray-Bruce ṣe sọ, O ni ó kú si ilé ìwòsàn First Cardilogy Consultant ni ilú Eko.
Má ṣe jẹ́ kí ẹnikẹ́ni bọ́ sí ààrin rẹ àti ìyàwó rẹ bíó tí wù tí olúwaarẹ̀ súnmọ́ ọ tó; nítorí lọ́jọ́ tí ìwọ bá ti fún ẹnì kẹta láyè láti bọ́ sí ààrin yín, ìfẹ́ yín yóó dàbí omi tí ẹnì kan lọ fi akèǹgbè pọn láti odò, nígbà tí ó sì dé, ọ̀rẹ́ọkùnrin náà wá, ó gbé kúmọ́, ó lù ú mọ́ akèǹgbè, akèǹgbè náà sì fọ́, bẹ́ẹ̀ ni omi inú rẹ̀ tú jáde, ó ṣán lọ sí ìlà oòrùn, ó ṣan lọ sí ìwọ̀ rẹ̀, ó dé gúsù, ó si dé àríwá, bẹ́ẹ̀ ni ẹnikẹ́ni kò si lè ló omi náà jọ mọ́.
Bákan náà, àwọn onímọ̀ ní láti f’ọwọ́ sí i k’áwọn ènìyàn ó ba f’ohùn sí i.
Ọ̀tọ̀ ni ẹwà àwọn ti orí ilẹ̀.
Awọn alejo fẹnu ko pe niwọn igba ti Naijiria ba le mọ riri ayajọ June 12, ki wọn ṣe oun ti yoo maye araalu dẹrun.
Bí ọdọmọkunrin tií nífẹ̀ẹ́ wundia,bẹ́ẹ̀ ni àwọn ọmọkunrin rẹ yóo nífẹ̀ẹ́ rẹ.
Arsenal tun gbe pẹẹli diẹ ni ti wọn nitori ipo kẹjọ lawọn wa nigba ti Man U wa ni ipo kọkanla lori tabili idije EPL.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Ilu London wa lara awọn ilu ti kẹẹkẹ yi ti kọkọ gbalẹ gẹgẹ bi ohun irinna.
Kànga tí àwọn ọmọ aládé gbẹ́,tí àwọn olórí wàpẹlu ọ̀pá àṣẹ ọba ati ọ̀pá ìtẹ̀lẹ̀ wọn.
Ijọba Naijiria ti fi awọn ilana to le jé ki ajajakalẹ arun Covid 19 naa dinku ni titankalẹ ti awọn akẹkọọ ba pada sile iwe bayii: 1) Ile iwe kọọkan gbọdọ kọ Olukọ nipa eto aabo funra wọn ati akẹkọọ ati awọn oṣiṣẹ nile iwe kọọkan.
Ṣaaju akoko naa, iye eeyan to ni arun naa to pọ ju lọjọ kan ṣoṣo jẹ ẹgbẹrun mẹtadinlọgọrin, ni ọjọ kẹrindinlogun, oṣu Keje ọdun 2020.
Governorship Election Results: Àgbùnbánirọ̀ tó bá INEC ṣiṣẹ́ kú nínú ìjàmbà ọkọ̀ ojú omi l'Ondo 'Ológun kò ṣe àyọjúràn sí ìdìbò 2019' Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, #Governorship Election: Òjò ni wá, a kò bẹ́nì kan ṣọ̀tá -Sanwo Olu Lasiko to fi n sọ ọrọ idupẹ rẹ lẹyin ti ajọ INEC kede rẹ gẹgẹ bii olubori idibo gomina to waye ni ipinlẹ Kwara lo sọ eyi di mimọ.
Amọṣa Ọbalaye naa, iyẹn Kabiyesi Iku baba yeye, Ọba Adeyẹmi Alaafin ti ṣalaye ọrọ pe ko si ija laarin oun ati gomina Makinde lori iṣẹlẹ naa.
Ó ń sìn pẹlu ààwẹ̀ ati ẹ̀bẹ̀ tọ̀sán-tòru.
"China pe fun àtúntò ètò òsèlú lagbaye, ati pe, o ni ó tó ki awọn orilẹede agabye ''maa tẹ̀lé ìlànà to'tọ́""."
Lẹyin ti wọn fin gbogbo ọfiisi aarẹ Buhari tan eleyi to na awọn ọm Naijiria to n san owo ori ni iye to to ẹgbẹrun marun abọ dollar, aarẹ Buhari kọ lati ṣiṣẹ ninu ọfiisi rẹ nitori wn ri awọn ekute nibẹ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Sri Lanka áti India níkan ni irù ològbó yì wá Dokita naa ni awọn ri ẹgba ọrun, goolu imu, yẹti eti, ẹgba ọwọ, goolu ẹsẹ, aago ọwọ ati awọn nkan miran ni wọn ko yọ.
Ìwé ẹ̀sùn tí ọ̀físà jagunjagun kọ nípa àwọn àtẹ̀jáde ‘ìbanilórúkọjẹ́’ tí aya-eré-ìtàgé gbé sí orí Facebook tí ó fà á tí a fi fi òfin mú un.
 Mo ti yẹ awon isoro ti a ni wo lati bi
Nigba ti awọn akẹkọọ ile iwe giga ni anfani lati ṣi ile iwe pada ni ọjọ kọkanlelogun, oṣu Kẹsan an, ọdun 2020, ṣugbọn igbesẹ naa wa lọwọ awọn adari ile iwe bẹẹ.
Wo orúkọ àwọn ẹ̀yà ara rẹ̀ ní èdé Yorùbá Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Buns ni ọmọ mi jẹ tán ní ṣọ́ọ̀ṣì, ló bá di àwátì' Tí a ò bá gbé ìgbésẹ̀ yìí ọ̀pọ̀ ounjẹ lo le di ààrun, májèlé tàbi kó já si ikú, nígbà mira a maa pa ọpọlọ lára.
Mo ṣe àwọn nǹkan wọnyi nípa ọ̀rọ̀ ati ìṣe mi, 
Bi o tilẹ jẹ wi pe wọn ti ri gba pada lara awọn ọmọobinrin wọnyii, sibẹ awọn kan ṣi wa lahamọ awọn ikọ adukukulaja naa.
Ẹnu mi yóo kún fún ìyìn rẹ,pé o ti kọ́ mi ní ìlànà rẹ.
Ìdí tí àwọn ìpińlẹ̀ se ń ti ilé ẹ̀kọ́ ní ìhà ìwọ̀ Oòrun-Àríwá Nàìjíríà rèé Abẹ́rẹ́ àjẹsára Covid-19 yóò dé sí Nàìjíríà nínú oṣù kíní ọdún 2021 Jide Kosoko forin sẹ́nu pé òun ni igi lẹ́yìn ọgbà Mr Latin lórí ipò ààrẹ TAMPAN tó wà Ó pé ọdún mẹ́wàá tí Barrister kú; wo ǹkan tó yẹ láti mọ̀ nípa rẹ̀ gẹ́gẹ́ bíi olórin, tẹ̀wé-tẹ̀wé, akọ̀wé àti sọ́jà Àìmọ̀kan ló mú mi hu ìwà tí mo hù kọjá sẹ́yìn, Jonathan dárí jì mí - Dino Melaye Dokita agba ni ẹka ti wọn ti n mojuto awọn ẹya ara ti obinrin fi n bimọ, Obstetrics and Gynaecology, ni Ile iwosan ẹkọṣẹ iṣegun Fasiti Calabar, Ugwu Brown, sọ fun BBC pe, ìju lo wọpọ ju ninu awọn nnkan to ma n wu ninu ikun obinrin, ni Naijiria.
Bẹ́ẹ̀ ni Solomoni ọba ṣe parí gbogbo iṣẹ́ kíkọ́ ilé OLUWA, ó kó gbogbo fadaka, wúrà, ati àwọn ohun èlò inú ilé ìsìn, tí Dafidi, baba rẹ̀, ti yà sí mímọ́ wá, ó sì fi wọ́n pamọ́ sinu àwọn ilé ìṣúra tí ó wà ninu ilé OLUWA.
Ẹni tí kò fẹ́ ki ti ẹlòmíràn dára jẹ́ kìnìhún láàrin àwọn ẹranko, àsá ìdí láàrin ẹyẹ, paramọ́lẹ̀ láàrin ejò, bẹ́ẹ̀ ni orúkọ àwọn ẹranko wọ̀nyí ti bàjẹ́ láàrin ìgbẹ́ sísá ni gbogbo ẹ̀dá alààyè ń sá fún wọn.
Iko agbaboolu  orile ede yii , Super
Ajafẹtọ ọmọ eniyan lori ọrọ ayika, Rev.
O ni àwọn igbimọ fẹnuko pe ki awon eniyan kirun janmọ jakejado ipinlẹ Kano, sugbọn ki wọn tẹle ilana ijina sira ẹni ati gbogbo ilana lati dẹkun aarun Covid19 ni agbegbe ibi irun janmọ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Olofa ina: ẹ parí òwe yìí pé ìgbà tí ara bá tu ìgbẹ́ láà ri eṣú.
MTN àti BBC World Service bẹ̀rẹ̀ àjọṣepọ̀ lórí ìròyìn ìṣẹ́jú kan BBC Ẹbí Abiola Ajimobi kéde bí ètò ìsìnkú rẹ̀ yóò ṣe rí pé.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ìjàmbá ọkọ̀ ojú'rin tó ṣubú wáyé ní Agége l'Eko A gbọ wi pe ni bii aago meje owurọ ni iṣẹlẹ naa waye, ti wọn si ti gbe awọn to farapa lọ sileewosan bayii.
Ilẹ Gẹẹsẹ, Amẹrika ati Ilẹ Alawọfunfun(EU) naa kuro oju si asiko ti ijọba ni ki adajọ Onnoghen lọ rọkun nle.
Ẹsira, alufaa, gbé ìwé òfin náà jáde siwaju àpéjọ náà, tọkunrin tobinrin, gbogbo àwọn tí wọ́n lè gbọ́ kíkà òfin náà kí ó sì yé wọn ni wọ́n péjọ, ní ọjọ́ kinni oṣù keje.
Èyí yóo mú kí ó jẹ́ ọrẹ àtinúwá, kò ní jẹ́ ti ìlọ́ni-lọ́wọ́-gbà.
Isẹ nla ni aarẹ tuntun yoo se ki wahala to suyọ lasiko ifiposilẹ aarẹ ana lorilẹede naa o maa baa di majẹle fun ọrọ aje rẹ Ẹkọ fun ẹgbẹ oselu lorilẹede Naijiria.
Bí ẹ bá wà ní ipò mi,èmi náà lè sọ̀rọ̀ bí ẹ tí ń sọ̀rọ̀ yìí,kí n da ọ̀rọ̀ bò yín,kí n sì máa mi orí si yín.
O ni awọn fẹ ki awọn ara ilu jẹ adojukọ gboogi awọn to n dari eto ijọba.
Olori Adenikẹ tun sọ nipa ẹkọ asa ati iṣe ati oriki ti oun ti gba ni aafin ati pe oun yoo fi kọwe nipa eto idajọ Alaafin lọjo ọla.
Ṣugbọn Peteru sẹ́ níwájú gbogbo wọn, ó ní, “N kò mọ ohun tí ò ń sọ.
Tí a bá ṣe ìdájọ́ òtítọ́, inú olódodo a dùn,ṣugbọn ìfòyà ni fún àwọn aṣebi.
Bakan naa, lojoRu ose yii ni ajo INEC gbe abajade idajo naa wo , ti won
Ọba Eko ro pe oun n daabo bo awọn ọmọkunrin oun ni lọwọ iparun lai mọ pe anfaani nla ni oun fi n dun wọn, tori a kii ri Ẹfọn ta ni ẹẹmeji.
Ẹgbẹ́ òṣìṣẹ́ ń gbáradì láti gbéná wojú MTN, lórí bó ṣe ń ṣe àwọn òṣiṣẹ́ rẹ̀ ní Naijiria Àwọ̀ ojú pọ̀ bíi àwọ̀ òṣùmàrè, àmọ́ ojú búlúù Risikat kò nílò àtúnṣe- Dókítà Ìdí rèé tí a ṣe fẹ́ sin Majek Fashek sílẹ̀ Amerika- Randy Fashek Àwọn ǹkan tí ó yẹ kí o mọ̀ nípa 'Sharia Law' ní Nàìjíríà ‘Àwọn òlóṣèlú kò ní ìwà ọmọlúwàbí ló jẹ́ kí wọ́n má a lọ láti ẹgbẹ́ òṣèlú kan lọ sí òmìràn’ Owó ti àwọn ẹbi máa ń lò láti ràn ǹka sínú ilé kò tó mọ́, nígbà tí ilé ìtajà àti àwọn ilé iṣẹ́ to ń ṣe ǹkan èlò gbogbo kò fi bẹẹ ṣe ọ̀ps mọ́ nígbà ti ọ̀ps sì n gbé ilé iṣẹ́ wọ́n tà.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Gboyega Oyetola: A ṣetán láti pèsè ọkọ̀ oun ìjà fún ilẹ Yorùbá 27 Ògún 2019 Oríṣun àwòrán, Google Àkọlé àwòrán, Ìjọba ipnlẹ Òsun ní kò sí òṣìṣé tí kò ní gba owó oṣu rẹ pé ní Ipínlè Ọsun .
Iṣẹ ori ran wọn ni wọn jọ n ṣe.
Awọn ilana ati aṣẹ ijọba Onimọ nipa eto oṣelu, Kabiru Safi Sufi, to jẹ olukọni fasiti kan nipinlẹ Kano sọ fun BBC pe idi pataki ti ijọba fi rọ Emir Sanusi l'oye ni bi o ṣe maa n bu ẹnu ẹtẹ lu awọn ilana iṣejọba gomina Abdullah Umar Ganduje.
Inec kede ọjọ idibo titi di 2055 Inec y'orukọ ajeji kuro ninu iwe idibo Mungono sàlàyé pé Ìbrahim Idris tó jẹ́ ọgá àgbà ọlọ́pàá, ní yóò jẹ́ alága ìgbìmọ tí àwọn asojú ẹkùn mẹfẹ̀fà yóò wà níbẹ̀.
Ẹni to bori: Morocco Tunisia vs Egypt.
O ti di ọsẹ kẹtala bayii ti nkan ko tii fararọ ni orilẹ-ede China bayii.
Coronavirus in Nigeria: Èèyàn 318 ló ti ní àrùn Coronavirus ní Naijiria báyìí Àkọlé àwòrán, Coronavirus in Nigeria: Èèyàn 318 ló ti ní àrùn Coronavirus ní Naijiria báyìí Ènìyàn mẹ́tàlá míràn ni àyẹwò NCDC fi han pe o tu ti ni ààrun Coronavirus lórílẹ̀-èdè Naijiria bayii.
Ó mú aṣọ aláwọ̀ aró, wọ́n fi rán ojóbó sára aṣọ títa tí ó kángun síta ninu àránpọ̀ aṣọ kinni, wọ́n sì tún rán ojóbó sára aṣọ títa tó kángun síta ninu àránpọ̀ aṣọ keji bákan náà.
OLUWA bá kọ gbogbo àwọn ìran Israẹli sílẹ̀, ó jẹ wọ́n níyà, ó sì fi wọ́n lé àwọn apanirun lọ́wọ́ títí wọ́n fi pa wọn run níwájú rẹ̀.
Igbakeji aare pelu iyawo re, Dolapo Osinbajo de si ibi idibo ni deede aago   mẹ́wàá  ku ogún isẹjuAdemola Adepoju.
Botilẹjẹ pe ko ti i si ẹni to ni aarun naa nibẹ, ijọba ipinlẹ naa kede ofin konile-o-gbele, fun gbogbo wakati mẹrinlelogun to wa ninu ọjọ kan.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Miss Africa 2018: Àwọn nkan tó ṣẹlẹ̀ ní Miss Africa 2018, Calabar 28 Ọ̀pẹ̀̀ 2018 Oríṣun àwòrán, @JFriks Àkọlé àwòrán, Àwọn nkan tó ṣẹlẹ̀ ní Miss Africa 2018, Calabar Diẹ lo ku ki eto yiyan omidan ilẹ Afrika, ikẹta iru rẹ to waye nilu Calabar lọjọ kẹtadinlọgbọn, oṣu Kejila, 2018, di nkan mi i lẹyin ti wọn kede ẹni to jawe olubori.
Saraki àgbà ló kọ́ ilé yìí fáwa arúgbó kìí ṣe Bùkọ́lá- Arúgbó Ilọrin Bàbá akẹ́kọ̀ọ́ LASU tí ọ̀rẹ́kùnrin rẹ̀ àti pásítọ̀ fi ṣ'oògùn owó ń bèèrè fún ìdájọ́ òdodo Ẹ̀wẹ̀, awọn míran ni ó dàbi ẹni pe ọ̀rọ̀ ìjọba kò yé ààrẹ Buhari mọ.
Police arrest: Kà nípa ohun mẹ́wàá tí o ní láti ṣe bí ọlọ́pàá bá mú ọ
Sugbọn kii se gbogbo eeyan naa lo le kopa.
O ni, “laisi atilẹyin yin pẹlu adura ati ifọwọsowọpọ, eleyii le tete ma foju han.
Awọn osisẹ baalu naa tiraka titi wọn fi pa ina naa lẹyin ti aago ijamba ina ‘alarm’ bẹrẹ si ni pariwo.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Sunday Igboho gba àwọn èèyàn Soka n‘Ibadan sílẹ̀ lọ́wọ́ àwọn ọmọ onílẹ̀ tó wá ṣọṣẹ́ Àgbà olórin, Victor Olaiya jáde láyé.
Àwọn ọmọ Reubẹni ati àwọn ọmọ Gadi ni mo sì fún ní agbègbè Gileadi títí dé àfonífojì Anoni, ààrin gbùngbùn àfonífojì náà ni ààlà ilẹ̀ wọn, títí lọ kan odò Jaboku, tíí ṣe ààlà àwọn ará Amoni; 
ilẹ lati fi ra irinse ti won fi n wa ohun alumọọni ilẹ .
Awọn Sẹnatọ wa n joko le aimọye biliọnu naira, bo si se wa ree lati ọjọ ti alaye ti daye, eyi si kọja ọrọ Buhari.
Bakan naa, ileeṣẹ ipolongo ibo fun Sẹnetọ Adeleke pẹlu ti ke sawọn ẹgbẹ ajafẹtọ atawọn to ni ifọn leekanna lorilẹede Naijiria ati lagbaye lati dide fun Sẹnetọ naa.
Ọpọlọpọ awọn ile iwosan ilera lo ti kogba sile ni Harare, ti ṣe olu ilu Zimbabwe nitori iberubojo ajakalẹ Covid-19.
“Ẹ̀tọ́ wo ni olólùfẹ́ mi níláti wà ninu ilé mi lẹ́yìn tí ó ti ṣe ìfẹ́kúfẹ̀ẹ́ inú rẹ̀?
Àbí kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ ta ni mo gbà rí?
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Barister lo bi gbogbo oníṣẹ́ fújì -Oṣupa Ki wọn to jọ sọ asọyepọ ti wọn fi din owo itanran naa.
Taiwo ati Kẹhinde ti wọn ba BBC Yoruba sọrọ awọn ko tilẹ mọ odo t'awọn fẹ da orunla si bayii, nitori awọn ko tilẹ pe ajọ INEC yoo sun eto idibo ti o yẹ ko waye tẹlẹ lọjọ kẹrindinlogun, oṣu keji siwaju rara.
Oríṣun àwòrán, Reuters Àkọlé àwòrán, Goolu mejilelọgbọn ni Salah ti gba wọle fun Liverpool ni saa yii Nibayii naa, Mohammed Salah ti gba ami ẹyẹ agbabọọlu to yanranti julọ fun igba keji ni sisẹ-n-tẹle bayii nilẹ Gẹẹsi.
Àkọlé àwòrán, Ni ipinlẹ Eko, wọn ni abadofin eyi to lodi si iroyin ayelujara da bi ifipa ba ijọba awa ara wa lo pọ ni wọn si n fẹ ki gbogbo awọn aṣofin ipinlẹ ati aṣofin agba fọwọ wẹwọ lati yọ aba naa kuro ninu aato wọn patapata.
Ẹ tẹ́tí sí ohùn àwọn akọrin lẹ́bàá odò,ibẹ̀ ni wọ́n ti ń sọ̀rọ̀ nípa ìṣẹ́gun OLUWA,ọ̀rọ̀ ìṣẹ́gun àwọn eniyan rẹ̀ ní Israẹli.
Mo mọ̀ pé ibi tó dára ni Ibidun Ighodalo wà báyìí- Adeboye Amọ, bi Ọgbẹni Meade ṣe n sọ eyi naa ni igbimọ awon to n wo inu afẹfẹ to jẹ ẹgbẹ awọn onimọ sayẹnsi, NASA to mọ nipa oju ọrun sọ pe ko si aye kankan to tun n jẹ Planet X, Koda, won ni irọ ni gbogbo ẹ, Wọn ni ko si nkankan ti yoo wo lulẹ sori aye yii.
tun se ipo kerin ninu abajade idibo ami eye agbaboolu ti o darajulo
Bótill jẹ́ pé Davido fí fotò bó ṣe ń ṣe ìforukọsíll ní àgọ agunbanirọ ní Abulé Ẹgbá nínú oṣu tó kọja síbẹ̀ kò dúro lati parí ètò náà bó ṣe tún fi fótò míràn síta pé òun ní òde orin ní ilẹ̀ Amẹríkà.
Àìrόjú lό mú ìyàwó wọlé, Imẹ́lẹ́ ló fà-á lé ọkọ rẹ̀ lọ́wọ́ níbi tí Òfófó àti Owú ti jẹ́ Olόyè láàárín àwọn obìnrin, tí Ìnira sì jẹ́ ẹni iyì láàárín àwọn Ọkùnrin.
" O ni idi ti oun fi se agbekalẹ ikọ Save Nigeria Group (SNG) ree, eyi to kun fun awọn ọlọpọlọ pipe awọn ọmọ ilẹ yii.
O fi n da awon egbe akoroyin naa loju pe,  a gbodo gbe igbese lori sise idasile awon ile-ise sile nipinle naa, eyi ti yoo mu ayipada ba ipinle naa ati orile-ede Naijiria lapapo.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Shagari lasiko to bẹ Ọbabinrin Elisabẹti keji wo nilu London lọjọ kẹtadinlogun, oṣu Kẹta, ọdun 1981.
Yóo ju ẹyẹ náà sílẹ̀ kí ó lè fò jáde kúrò ninu ìlú, lọ sinu pápá, yóo fi ṣe ètùtù fún ìwẹ̀nùmọ́ ilé náà, ilé náà yóo sì di mímọ́.
O tesiwaju wi pe, ile-ise naa gba ase lati ra oko aponmi maarun ati oko tatapupu fun ile-ise to n  mojuto wole- wode lorile-ede Naijiria.
Alágbára ni ata, alùbọ̀sá gbajúmọ̀, bọ̀ọ̀kìní tòmáàtì, ọlọ́rọ̀ ni ègúsí.
Sarah Samuel gbà láti fẹ́ ọ̀kan nínú wan ó sì kọ̀ láti pada wále Àkọlé àwòrán, Iwe àkọsílẹ̀ Naomi ní èyí nibi tí ó kọ gbogbo ìrírí rẹ̀ sí Nígbà ti wọ́n fẹ́ sálọ, ọkan nínú wọ́n ké gbàjare sí àwọn Boko Haram ní wọ́n fí wọ́n mú u pada.
Odi ìlú náà ní ìpìlẹ̀ mejila.
Ajoyo ayeye ose odun ifomo loyan ma n waye lose akoko inu osu kejo lodoodun.
Lara rẹ si ni ibudo isinmi Ọwá ati Dágunró wa.
Awọn alaṣẹ ile ẹkọ giga fasiti Al-Azhar ṣalaye pe, iwa itiju ati abuku ni akẹkọọbinrin naa wu lẹyin to mọ pe, ile iwe ọhun lodi si ki ọdọkunrin ati ọdọbinrin ti wọn ti ṣe igbeyawo maa di mọ ara wọn.
Eto atunto ati atungbeyẹwo ofin ati ilana iṣẹ ọlọpaa n waye kaakiri orilẹede Amẹrika.
Ẹ kọ orin titun sí i,ẹ fi ohun èlò ìkọrin olókùn dárà,kí ẹ sì hó ìhó ayọ̀.
O si ti fín oogun apakokoro si aarin ìlú.
Ìgbà mélòó ni wọ́n dàbí àgékù koríko,tí afẹ́fẹ́ ń fẹ́ kiri,tabi bí ìyàngbò tí ìjì ń gbé lọ?
Wọ́n kọ àkọlé ẹ̀sùn tí wọ́n fi kàn án sí òkè orí rẹ̀ pé, “Èyí ni ọba àwọn Juu.
Nibi ayẹyẹ ami ẹyẹ ọlọdọọdun ajọ eleto bọọlu ni Naijiria eleyi to waye ni ilu Eko lalẹ ọjọ Aje ni wọn ti fi oye yi da lọla.
Iroyin ni ado oloro ni awọn adigunjalẹ naa lo lati sigun bo agọ ọlọpaa naa, ti ado oloro naa si pa awọn ọlọpaa to wa ni bẹ.
Gomina ipinlẹ Eko, Kwara, ati Borno lo kọwọ rin pẹlu aarẹ lọ si orilẹede Japan.
O dabi eyi gan lo mu ki awọn olowo nọbi lorilẹede Naijiria, o gbe ohun soke lorilẹede Naijiria pe awọn igbesẹ ijọba apapọ n ni iṣẹ awọn naa lara gẹgẹ bi 'oṣiṣẹ' Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Toyin Atoyebi mechanic: Ẹ wo Toyin, ọmọbinrin ọdún 16 tó ń tún skadà àti gẹnẹrátọ̀ ṣe ní Awọn olowo nọbi gẹgẹ bi ọpọ ti maa n pe awọn aṣẹwo nilẹ Yoruba naa ti ke gbajare sita pe igbesẹ afikun owo epo ati owo ina ti ijọba apapọ gbe laipẹ yii kii ṣe eyi to ba awọn lara mu rara ati pe ki ijsba apapọ tete daa pada bi owo baba ijẹbu nikan lo lee mu ki awọn pẹlu maa gbe owo ori nọbi awọn soke.
Awọn to ji ọ̀pá àṣẹ ọba fi tabuku ọba naa ni."
Bi awọn kan ṣe n pariwo Magun lawọn oloyinbo naa n sọ pe, ko si babara nibẹ.
Ọjọgbọn Adepoju ṣalaye pe oriṣiiriiṣii awọ ni oju le ni, irufẹ awọ oju dabi awọ oṣumare ni.
Bẹ́ẹ̀ bá gbàgbé, laipẹ yìí ni ìròyìn gbalẹ kan pé àwọn ènìyàn kan fi esun kan Kwam 1 pé ó ń fẹ́ ọkàn lára àwọn olorì Aláàfin, Ayaba Badira.
Ta ní ń wá oúnjẹ fún àwọn ẹyẹ ìwò,nígbà tí àwọn ọmọ wọn bá kígbe sí Ọlọrun,tí wọ́n sì ń káàkiri tí wọn ń wá oúnjẹ?
Àwọn olórí alufaa, àwọn amòfin ati àwọn àgbà ń wá ọ̀nà láti mú un, nítorí wọ́n mọ̀ pé àwọn ni ó pa òwe yìí mọ́, ṣugbọn wọ́n bẹ̀rù àwọn eniyan.
Ìgbà tí ìjà bá lọ tán ìtìjú kò ní í lọ, olúwaarẹ̀ kò ní í gbọdọ̀ ṣe gbólóhùn aṣọ mọ́, ìyàwó á máa pa guurú sí ọkọ: bẹ́ẹ̀ ni ìgbà tí ó bá ń di pé ìyàwó ń gbá ọkọ létí, tí ó ń ta ọkọ ní ìpá, tí ọkọ ń sá wọ iyàrá, tí ọkọ ń gba ọ̀nà ẹ̀hìnkùnlé, tí obìnrin ń lọ aṣọ mọ́ ọkùnrin lọ́rùn, tí ìyàwó ń yí àṣẹ ọkọ padà, tí ìyàwó ń lọ sí òde tí kò sọ fún ni mọ́, tí a béèrè ibi tí ìyàwó ti ń bọ̀ ti ìyàwó ń mọ́ ni lójú, ńjẹ́ o kò rí i pé nǹkan ń dé bẹ́ẹ̀ ńdan?
 Àwọn tí wọ ́ n ń sọ èdè yìí jẹ ́ igba méjì ati àádọ ́ ta ẹgbẹ ̀ rún .
O ni asiko iwadii kikun ni òbí wa bayii lori ohunkohun ti ọmọ ba sọ fun òbí nipa ẹnikẹni.
Taye Currency to fi ilu Ibadan ṣe ibugbe fi fidio ọkọ naa soju opo Instagram rẹ nibi to ti dupẹ lọwọ Gomina Makinde fun ẹbun nla to fun un.
Èwo ninu yín ló fetí sí èyí,tabi tí yóo farabalẹ̀ gbọ́ nítorí ẹ̀yìn ọ̀la?
Àwọn tí ó mọ̀ ọ́ yóo gbẹ́kẹ̀lé ọ;nítorí ìwọ, OLUWA, kìí kọ àwọn tí ń wá ọ sílẹ̀.
Ààfá mẹ́ta réwọ̀n hé nípa ṣíṣe ìrànlọ́wọ́ òjijì fún obìnrin kan pẹ́lù 36 mílíọ̀nù náìrà Ẹ má mu gaarí mọ́ nítorí ìbà Lassa- Dókítà Boniface Ti a ko ba gbagbe, Arabinrin Olawole to jẹ́ iyá Gold Kolawole lo gbe ọmọ rẹ̀ lọ si sọọsi awọn ọmọde nile ijọsin wọn lẹ́yin ọ̀pọ̀lọpọ ọ̀rọ̀ latọdọ àwọn olukọ ọmọde ninu ijọ náà pe ki iya Gold maa gbé ọmọ rẹ̀ wá si ilé ijọsin ọmọ wẹwẹ.
Bi o tilẹ jẹ pe wọn ti ri ọpa aṣẹ naa pada, eleyii ti awọn oṣiṣe alaabo ri labẹ afara kan ni ilu Abuja, awọn aṣofin ni Ile Aṣofin Ipinlẹ Eko yii panupọ bu ẹnu atẹ lu iwa yii gẹgẹ bi idojuti fun orilẹ-ede yii lapapọ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ọlọ́pàá gbé N5m silẹ̀ láti ṣàwárí àwọn adigunjalè Offa 4 Èbibi 2018 Oríṣun àwòrán, NIGERIA POLICE Àkọlé àwòrán, Awọn afurasí náà gbẹ̀mi ogunlọ́gọ̀ ènìyàn pẹ̀lú ọlọ́pàá mẹsan Ile ise lọ́pàá ti Ipinlé Kwara ti gbé miliọnu marun naira silẹ fun ẹnikẹni ti ó bá lé fun wọn ni ifitonileti l'ori awọn adigunjale ti ó kópa nínu ìkọlù si Offa ni Ọjo Kerin Oṣun Kẹrin ọdun yii.
- Ọ̀gá àgbà ọlọ́páà A kò ní padà sílé ìwé àyàfi t́i ìjọba bá san owó oṣù tó jẹ wá - ASUU Bawo ni eto idibo naa se ri?
Lẹyin ti Ajimobi kuro ni ipo gomina, ni ẹgbẹ oselu rẹ, APC tun yan an sipo igbakeji alaga apapọ ẹgbẹ fun ẹkun ìwọ oorun Naijiria, Ninu eyi to si tun di adele alaga fẹgbẹ oselu naa ni ọjọ kẹrindinlogun oṣu kẹfa ọdun 2020.
Awọn orilẹede mẹtala naa ni wọn ṣakiyesi pe ọwọja itankalẹ arun coronavirus pọju si lagbaye.
Wọn ni obitibiti miliọnu Dọla ni wọn sọ pe o ji lara awọn ileeṣẹ nipaṣẹ emeeli, ati awọn ọna miran.
Olori ni ayọ ati idunnu ni oun ati Ooni fi n lo igbeyawo wọn lai si pe wọn ni ariyanjiyan kankan laarin wọn.
Ìdí èyí ni wọ́n fi npèé ní Braille.
Oríṣun àwòrán, Others Ati wi pe ẹṣẹ si awọn afọbajẹ, iyẹn Balogun ati olori ile Olubadan ni ilu Ibadan ko lee sọ wi pe ki wọn yọ ọba bi o tilẹ jẹ pe wọn ni aṣẹ lati yọ Olubadan ni ipo.
N óo jẹ́ kí ọ̀tá fi idà pa àwọn tí wọ́n kù ninu wọn.
Iroyin kan to ti gbale-gboko kaakiri agbaye- ti wọn si sọ pe o wa lata ọwọ ajọ to n mojuto ilera awọn ọmọde l'agbaye.
Mo ti bá ọba Olúwò lórí ọmọbinrin ọdún mẹ́tàlá rìí- Olorì chanel Kò sí ibùdó ayẹwo àrùn Coronavirus ní UCH, ẹ má wá fún ayẹwo lọ́dọ̀ wa - Ọga àgbà UCH Àwọn àràmọ̀ndà ìbomú-bẹnu tó gbòde lásìkò Coronavirus yìí Ẹ wo ẹkunrẹrẹ fidio naa wa: Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí kan sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
Iléejọ́ Cameroon: Wọ́n Jẹ̀bi ẹ̀sùn ìṣelòdì sí ìjọba
Mo parí iṣẹ́ àṣepatì 239, iṣẹ́ 236 míì ń lọ lọ́wọ́- Seyi Makinde Afunrasí ọ̀un nínú ọ̀rọ̀ rẹ̀ fún ọlọ́pàá sàlàyé pé lóòtọ́ òun lòun wà nídìí ìbanilórúkọ jẹ́ náà láti gba owó díẹ̀ ní.
The Polytechnic Ibadan: Ẹ̀rọ abẹ́lé tó ń fọ ọwọ́ àti ‘Ventilator’ ló ṣẹ̀ṣẹ̀ gbé jáde
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ilé Arugbo Saraki: Ramoni padà wólé arúgbó ní Ilọrin!
Wo ọna ti o le gba dena iba lassa Alasẹ ko gbọdọ gba'tọju loke okun mọ Bakanna lo rọ awọn kọmisọna feto ilera kaakiri gbogbo ipinlẹ lorilẹede Naijiria lati rii wipe wọn ko jẹ ki eti awọn gomina wọn di si bi nkan ba se n lọ si lori gbigbogunti arun iba ọrẹrẹ yii.
Sujith Wilson ni orukọ ọmọde to n ṣere ni eti kanga ni bii iwọn ẹsẹ bata ọgbọn si kanga naa ni agbegbe Tamil Nadu ni orilẹ-ede India.
Ó mú kí ẹ ní ìtara.
Ajakalẹ Corona virus to de ju onikaluku mọle lo mu ki oun ati awọn alajijọgbe rẹ gbimọran lori ọna ti wọn yoo fi ṣe ọdun Keresi.
O wa ni ohun ti ri i wi pe ara ohun dara pupọ ju iru wahala ti o bara rẹ yi lọ.
I Language Centre: Yorùbá ló làṣà àti èdè Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
N óo sì sọ ọ́ di àpáta lásán, o óo di ibi tí wọn óo máa sá àwọ̀n sí; ẹnikẹ́ni kò sì ní tún ọ kọ́ mọ́.
Pilatu sọ fún àwọn Juu pé, “Ọba yín nìyí!
Oloye Dele Momodu ati akọbi ọmọ oloogbe ajafẹtọ ọmọniyan, Oloye Gani Fawehinmi, Mohammed kẹnu bọ ọrọ o si da bii ki eto naa ma tan mọ.
#BBCNigeria2019 Muyiwa Fafowora (ADC) Àkọlé àwòrán, àwọn olùdíje ìpínlẹ̀ Eko Fafowora gbagbọ pe ilu Eko lowo gan o si gbagbọ pe ọ̀pọ ninu isuna ipinlẹ lo yẹ ki wọn na sori eto ilera.
Eyi jẹyọ gẹgẹ bi awọn gbajugbaja oṣere ẹgbẹ Aremu Afolayan ṣe bọ soju opo rẹ lati yẹ ọmọ rẹ obinrin si toun naa n ṣe ọjọ ibi ni ọjọ kọkanlelogun oṣu kejila.
 ayẹyẹ naa sélé ni yunifásítì ìlú Ìbàdàn .
"O fí kún-un pé "" ní ìpínlẹ ti èmí ti wá, ìjọba ìbílẹ kan péré ló jẹ ànfàní rẹ̀ nínú ìjọba ìbílẹ̀ méjìlélógun tó wà níbẹ, mí ò bèrè ǹkan to ṣẹlẹ̀ mí ò si fẹ́ mọ."
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Agbègbè Somolu f'ojú winá ìjà ní ìpínlẹ̀ Èkó 18 Ọ̀wàrà 2018 Oríṣun àwòrán, Getty Images Ìjà ìgboro bẹ́ sílẹ̀ ní agbègbè Ṣomolu, ní ìpínlẹ̀ Èkó lásìkò tí ìwọ́de ẹgbẹ́ òṣèlú ń lọ lọ́wọ́.
Lọjọ kẹrinla, osu keji, ọdun 2020 ni iṣẹlẹ akọkọ ṣẹlẹ ni Egypt ni eyi to bi ẹru ati ifoya kaakiri ilẹ Adulawọ.
Jesu wí fún un pé, “Bí ẹ kò bá rí iṣẹ́ àmì ati iṣẹ́ ìyanu ẹ kò ní gbàgbọ́.
Alhaji Aderẹmi Jimoh ṣalaye pe awọn ọlọja lo fa oun kalẹ fun igbimọ majẹobajẹ awọn ọlọja ni ipinlẹ Ọyọ ati pe awọn igbimọ ọlọja naa lo fa oun le ijọba ipinlẹ Ọyọ lọwọ.
Ẹ wo àrà tí ''Ayo the Creator'' ń fi sinimá dá 11 Ògún 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 10 Ògún 2020 Oriṣiiriṣii ara ni Ayodeji Amodu ati ẹgbọn rẹ n fi awọn gbajugbaja sinima da pẹlu ohun eelo ti ko wọn rara.
Ẹ̀yin ọmọ Israẹli, ẹ gbọ́ ohun tí OLUWA sọ nípa yín, gbogbo ẹ̀yin tí a kó jáde láti ilẹ̀ Ijipti: OLUWA ní, 
Ìwọ Àpáta, ni o gbé wọn kalẹ̀ bíi pàṣán, láti jẹ wá níyà.
Ní báyìí eniyan ọgbsn lo ti ni ààrun náà ni orill èdè Naijira Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí 12:41 Fídíò, Baby abandoned on dunmpsite: Mo ti bímọ mẹ́rin tẹ́lẹ̀ fún bàbá méjì nínú òṣí- Dupe Ogbomọṣọ, Duration 12,414 Owewe 2020 Fídíò, Akomolede: Bolaji Faleke ni Olùkọ́ tó ń kọ́ wa ní àṣà oge ṣiṣe lórí BBC Yorùbá1 Owewe 2020 NUJ ìpínlẹ Oyo bà àwọn ọmọ ẹgbẹ́ tó lọ ìpàdé tí Femi Fani Kayode pè ní Ibadan wí7 Owewe 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
O ni paapaa julọ nipasẹ wahala awọn ajinigbe, iwa ọdaran ati ijọgbọn awọn Fulani darandaran.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, CAN: Samson ni ọrọ awọn ajinigbe ti gba àpérò ní Naijiria Ohun to buru ju ni pe, Winnie to kere julọ ninu awọn ọmọ iya rẹ, lo ni aarun naa lati ara iya wọn.
" ní ọdún 1966 , tí smith gba ìwé iṣé padà lọ ́ wọ ́ "" hms tiger "" pèlú alákòóso àgbà gẹ ̀ ẹ ́ sì harold wilson , herper ṣiwájú àtako rẹ ̀ tí ó sì fa ìkọ ̀ sílẹ ̀ ."
Rutu bá wólẹ̀ ó dojúbolẹ̀, ó ní, “Mo dúpẹ́ pé mo rí ojurere lọ́dọ̀ rẹ tó báyìí, o sì ṣe akiyesi mi, bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé àlejò ni mí.
Àbí o ti di ohun èlò àlòpatì?
Laarin ọdun 1966 si ọdun 1969, iyẹn ọdun mẹta pere ni asiko Oba emmanuel Olajide Olayode lori itẹ Ọba gẹgẹ bii Soun.
Ni idaji kutukutu si laa ti maa ri awọn awakọ ero, ọlọkada, atawọn eeyan mii, ti wọn yoo maa ra awọn ọti lile yi, ki wọn to bẹrẹ isẹ oojọ wọn.
Òkè Ìdànrè: Òkè tó kéré jùlọ jẹ́ ẹsẹ̀ bàtà 3000
Nigba to n kẹdun loju opo Twitter rẹ, Saraki ni lasiko yii tawọn eeyan ilu Lafiagi n se ọfọ awọn eeyan wọn yii, oun wa gbadura pe ki Ọlọrun fun wọn ni ẹmi lati gba adanu naa mọra, ki ara awọn eeyan tori ko tọ ninu ijamba naa si tete mokun pada.
Gbogbo àwọn eniyan tí ó wà ninu ilé ìpàdé tẹjú mọ́ ọn; 
Ajọ NHS ti sọ pe o ṣeṣe ki arun yii gbilẹ siwaju si nilẹ Gẹẹsi.
Nígbà tí mo rí i pé ohun tí wọn ń ṣe kò bá òtítọ́ ìyìn rere mu, mo wí fún Peteru níwájú gbogbo wọn pé, “Bí ìwọ tí ó jẹ́ Juu bá ti ń ṣe bí àwọn yòókù, tí o kò ṣe bí àṣà àwọn Juu, kí ló dé tí o fi fẹ́ kí àwọn tí kì í ṣe Juu ṣe ara wọn bíi Juu?
 Àwọn ọmọ ìkọ ́ ṣẹ ́ ifá náà le kó ara wọn jọ lati máa fi orin-ifá dá ara wọn lára yá .
Oríṣun àwòrán, Getty Images Amọ, Kane to wọ le ni ipele keji ere bọọlu ya ọpọ oluworan lẹnu lẹyin to gba bọọlu lati aarin gbungbun ori papa ti bọọlu si wọ inu awọn lọ.
Ọkunrin kan wà tí a rán wá láti ọ̀dọ̀ Ọlọrun, orúkọ rẹ̀ ń jẹ́ Johanu.
 gẹ ́ gẹ ́ bí àwọn asunrárà aláàfin ìlú Ọ ̀ yọ ́ tí wo , ó jẹ ́ ìwá àti ìṣe wọn láti máa lọ ̀ ọ ́ sun rárà fún aláafìn ní àǹfin rẹ ̀ .
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ṣé lóòtọ́ ni Bimpe Oyebade lóyún fún Lateef Oladimeji?
Igba ikeji ni yii ti Megan maa gba ife ẹyẹ agbaye tawọn obinrin lọ sile gẹgẹ bii balogun ikọ USA.
Ni owurọ ọjọ Ẹti ni awọn oṣiṣẹ ijọba ipinlẹ Eko bẹrẹ si ni wo àwọn ile ti ko dara ni adugbo naa.
O ni o ku sowo awon olori orile-ede wonyii paapaa julo South Sudan lati dekun ikolu ati wahala to n koju eto aabo ki won feran awon ara ilu ti won n sakoso le lori.
Ninu ọrọ rẹ, agbẹjọro ọga agba ajọ EFCC, Oluwatoyin Ojaomo, ninu ifọrọwerọ kan salaye pe nipa idi ti ajọ DSS fi n wa onibara rẹ.
Ní bayìí ènìyàn ẹgbẹ̀rún lọ́nà méjì lé lààdọ́ta àti ọ̀tàlénígba ó din mẹ́ta ló ti ni ààrùn náà lápapọ̀ lórílẹ̀-èdè Nàìjíríà, sùgbọ́n ènìyàn tó dín díẹ̀ lẹ́gbẹ̀rún mọ́kàndílógójì ló ti gba ìwòsàn ti wọ́n sì ti wà ni ilé wọ́n.
Mo bá dágbére fún àwọn eniyan níbẹ̀, mo lọ sí Masedonia.
 akoran igbe gbuuru ṣokunfa iku 0.
"By Nesta McGregor Newsbeat reporter 20 Ọ̀wàrà 2018 Oríṣun àwòrán, The Other Richard ""Kìí ṣe ìwọ lò ń ṣàkóso bí ara rẹ ṣe ń se."
Ko da o tun mẹnu ba a pe awọn to n ṣe pasiparọ owo ilẹ okere gan n ba awọn ṣiṣẹ.
“Mo tún fẹ́ mọ̀ nípa ẹranko kẹrin, tí ó yàtọ̀ sí gbogbo àwọn yòókù, tí ó bani lẹ́rù lọpọlọpọ, tí èékánná rẹ̀ jẹ́ idẹ, tí eyín rẹ̀ sì jẹ́ irin; tí ń jẹ àjẹrun, tí ó ń fọ́ nǹkan túútúú, tí ó sì ń fi ẹsẹ̀ tẹ àjẹkù rẹ̀ mọ́lẹ̀.
Ṣugbọn nígbà tí wọn ń bọ̀ láti ilẹ̀ Ijipti, ààrin aṣálẹ̀ ni wọ́n gbà títí wọ́n fi dé Òkun Pupa, tí wọ́n sì fi dé Kadeṣi.
Igbeyawo gbajumọ miran ti ifojusọna tun wa fun ni laarin Khafi Kareem ati Ghedoni Ekpata.
Saaju ninu oro ikini kaabo re, gomina ipinle Oyo, onimo
Ẹ̀rù yóo sì ba gbogbo eniyan;wọn yóo máa sọ ohun tí Ọlọrun ti gbé ṣe,wọn yóo sì máa ronú nípa iṣẹ́ rẹ̀.
Ibasepọ wa dan mọran, a si jọ wa pọ fun ọdun mẹẹrin ataabọ.
Awọn eeyan naa n fẹ́ ki ajọ commonwealth fiya to tọ si ẹni to ba tapa si ẹtọ ọmọniyan, jẹ awọn adari Naijiria.
Nítorí náà ẹni tí ó fún ni ní ìmọ̀ràn dáadáa nǹkan pàtàkì ni olúwaarẹ̀ ṣe.
Oríṣun àwòrán, Ahmed Bashir/twitter Àkọlé àwòrán, Buhar tí gbà fọ́ọ̀mù fún ìdupò ààrẹ ọdún 2019 Lẹyin ti wọn gba fọọmu fun Aarẹ Buhari ni fọọmu gbigba fun awọn to n du ipo ba di asa.
Nígbà náà ni Peteru bẹ̀rẹ̀ sí ṣépè, ó tún ń búra pé, “N kò mọ ọkunrin náà.
Bí a kò bá jẹ, kò bù wá kù, bí a bá sì jẹ, kò mú kí á sàn ju bí a ti rí tẹ́lẹ̀ lọ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Man Utd v Juventus: Kíni ipadabọ Ronaldo sí Old Trafford yóò bí?
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Simon Lalong: Gómìnà ìpínlẹ̀ Plateau ni ẹni tó bá fẹ́ ipò ní ìjọba òun gbọ̀dọ̀ yan ẹranko kan láàyò 21 Èbibi 2019 Oríṣun àwòrán, Nigeriagalleria.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Kayeefi: Facebook ni Wolii Arole Jesu fi tàn an wọ agbo, orí rẹ̀ ni wọ́n fi s'owó Koda, o ri awọn onimọ nipa ihuwasi eniyan ati arun ọpọlọ, ṣugbọn iyatọ ko sii.
Igbese yi jo wipe o se afihan isokan laarin awọn Gomina naa.
DJ Cuppy gbóṣùbà ràbàndẹ̀ fún Anthony Joshua ṣáájú ìjà rẹ̀ pẹ̀lú Andy Ruiz Ajíyìnrere àgbáyé Reinhard Bonnke jẹ́ Ọlọ́run nípè Òkété ti bórù!
May ni ibo okoolelọọdurun ati marun (325) ti awọn to si yọ nipo si ni ibo ọọdurun ati mẹfa (306).
Ọgọta eeyan lati ipinlẹ Eko lo ni aarun naa eyi to pọju ninugbogbo ipinlẹ lọjọ Iṣẹgun.
11 Ẹrẹ̀nà 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 1 Ìgbé 2020 Arun Coronavirus ti tan de, o kere tan, ọgọrin orilẹ-ede, ilẹ Gẹẹsi ati Naijira si jẹ ọkan lara rẹ.
Nítorí náà, àwọn ọmọ wọn tí OLUWA gbé dìde dípò wọn ni Joṣua kọ ilà abẹ́ fún, nítorí pé ẹnikẹ́ni kò kọ wọ́n ní ilà ní ojú ọ̀nà.
àwọn tí ń yọ̀ nítorí orúkọ rẹ tọ̀sán-tòru,tí sì ń gbé òdodo rẹ lárugẹ.
Kò yẹ mí rárá, láti tún bèèrè nǹkankan mọ́ lọ́wọ́ kabiyesi.
Ọlọrun wa ń bọ̀, kò dákẹ́:iná ajónirun ń jó níwájú rẹ̀;ìjì líle sì ń jà yí i ká.
Asiko ipade awọn ajọ amuṣẹya ti wọn ṣe ni ileeṣẹ National Universities Commission ni ilu Abuja ni wọn ti yọ Ọjọgbọn Ogundipe nipo gẹgẹbi ọga agba fasiti ilu Eko.
Ẹ má bẹ̀rù wọnnítorí pé wọn kò lè ṣe ẹnikẹ́ni ní ibi kankan,bẹ́ẹ̀ ni wọn kò sì lè ṣe rere.
Ibọn ti awọn ọlọpaa tun yin ninu laasigbo naa lo ṣe akoba fun eeyan meji mii ni agbegbe naa.
Ìdí rẹ̀ ni pé bí a bá rí ninu àwọn ọkọ tí kò jẹ́ onigbagbọ, wọ́n lè yipada nípa ìwà ẹ̀yin aya wọn láìjẹ́ pé ẹ bá wọn sọ gbolohun kan nípa ẹ̀sìn igbagbọ, 
"Ara mi ti ya bayii mo si ti pada bọ sipo bẹẹni mo ti dari wale si Naijiria"" Ko ye iru aisan pato to ba aya aarẹ kuro ni Naijiria ṣugbọn ko ba a pada wale gẹgẹ bo ṣe sọ."
Mẹ́jọ nínú àwọn ènìyànkéènìà wọ̀nyí ti wà ní akóló ọlọ́pàá.
Ọkàn wa kò pada lẹ́yìn rẹ,bẹ́ẹ̀ ni a kò yẹsẹ̀ kúrò ninu ìlànà rẹ,
Ọyọ: Alaafin bi ibeji l‘ẹẹmeji lọsẹ kansoso
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Mo fẹ́ máa polongo oúnjẹ ilẹ̀ wa ló jẹ́ kí n máa fi oúnjẹ bíi àmàlà ya àwòrán O fi kun ọrọ rẹ pe nitori naa lo ṣe yẹ ki awọn ileewosan ma a ṣe idanilẹkọ ati itọju fun awọn obinrin ki wọn o to loyun, bi wọn ṣe ma n ṣe fun awọn alaboyun.
" ní ọdún 1961 , Òjó dá ẹgbẹ ́ òṣèré akọrin tírẹ ̀ náà kalẹ ̀ tí ó pè ní "" délé Òjó & his star brothers "" lẹ ́ yìn tí Ọláìyá tú ẹgbẹ ́ akọrin tirẹ ̀ ká ."
Ta ni ki wọn wa sa di o?
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ogun iphone theft: Ọkùnrin kan dèrò ẹ̀wọ̀n lẹ́yìn tó jí ẹ̀rọ ìbáraẹnsọ̀rọ̀ tí iye owó rẹ̀ tó ₦950,000 4 Bélú 2020 Oríṣun àwòrán, NAirametrics Ọkunrin ẹni ọdun mejilelogun kan ti ri ẹwọn ọdun mẹrin he lẹyin to jẹbi ẹsun ole jija ni ipinlẹ Ogun.
Faṣọla kun ara awọn minisita ti ọpọ n wo gẹgẹ bii alagbara ni saa iṣejọba akọkọ aarẹ Buhari, paapaa julọ bi o ṣe jẹ pe ohun nikan lo di ileeṣẹ ijọba mẹta to ṣe koko mu.
Ileeṣẹ ọlọpaa ayẹwo naa yoo ni ilbanu pẹlu ilana itaketesiraẹni nitori ajakalẹ arun Covid-19 to wa lode.
Arabirin Hidalgo sapejuwe arakunrin gege bi alantakun okunrin agbegbe 18th , ti o je agbegbe ti isele ohun ti waye nilu Paris, eyi ti o sapejuwe re gege bi apere rere fun awujo.
Ki awọn ọdọ mase fi akoko wọn sofo nipa diduro de ijọba, ki wọn ma si tiju iṣẹ ti wọn ba n ṣe.
Fi ojúlówó wúrà bò ó ninu ati lóde, kí o sì fi wúrà gbá a létí yípo.
 Ó tún lọ sí ilé èkọ ́ frcn láti kẹ ́ kọ ̀ ọ ́ síwájú si .
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Facebook: Naijiria wà lára àwọn orílẹ̀èdè tó ní ojú òpó ayédèrú 17 Èbibi 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ile isẹ Facebook sọ ni oju opo rẹ pe awọn ti yọ oju opo ayederu 265 kuro ni ori ẹrọ ikansiraẹni rẹ.
Ṣe, ni ààfin ìlẹ̀ Yprùbá, inú ààfin pátápátá lọ́hùn-ún ni ilé àwọn ayaba ń wà, kò rí bẹ́ẹ̀ fún Òmùgọ́diméjì, ilé àwọn obìnrin rẹ̀ ló kangùn sí ibi tí ènìyàn ń gbà wọlé, nígbà tí wọ́n sì mú wa wa ilé, ilé àwọn obìnrin ni wọ́n mú wa wọ̀ lọ.
Ó ní, “Àkókò ń bọ̀, tí n óo mú ìlérí tí mo ṣe fún ilé Israẹli ati ilé Juda ṣẹ.
Gbogbo àwọn tí wọ́n fi ọwọ́ kàn án pátá ni ó mú lára dá.
 Àbúrò mẹ ́ rin ni ó ní .
Ní ọjọ́ kejila oṣù kẹwaa ọdún kẹwaa, OLUWA bá mi sọ̀rọ̀; 
Ipinlẹ Kaduna ni wọn ti bi Ibidunni Olajumoke Elizabeth Ituah Ighodalo ni ọdun 1980.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Kí ni àmì ohùn orí ''Aifagbafẹnikan' Iṣi akọkọ awọn ọmọ Naijiria to ha si ilẹ Gẹẹsi naa gunlẹ si papakọ ofurufu muritala mohammed ni ilu Eko lọsan ọjọ Ẹti.
Ṣugbọn nisinsinyii, ojú wọn dúdú ju èédú lọ,kò sí ẹni tí ó dá wọn mọ̀ láàrin ìgboro,awọ ara wọn ti hunjọ lórí egungun wọn,wọ́n wá gbẹ bí igi.
Ẹ wo báwọn òṣèré tíátà kan yóò ṣe rí lọ́jọ́ ogbó Ìgbín ní èmi àti ìyá mi máa ń he kiri, ká tó lee jẹun - Lizzy Anjọrin Ìtàn tó rọ̀ mọ́ òwe ‘aṣọ kò bá Ọ́mọ́yẹ mọ́.
EFCC ní ilé gomina ìpínlẹ̀ Eko tẹ́lẹ̀rí, Akinwumi Ambode ti awọn lọ ni owúrọ òní jẹ́ ìtẹ̀síwájú ìwádìí àwon lóri ẹ̀sùn ìkówó jẹ tí wọ́n fi kàn-àn.
Boxing Day jẹ ọjọ keji, ọdun Keresimesi, o si maa n bọ si ọjọ kẹrindinlọgbọn, ninu oṣu Kejila ọdun.
"Osanyintolu ni "" A gba ipe pajawiri kan ni deede aago mẹwa ku isẹju mẹrindinlogun lalẹ ọjọ Ẹti, wipe ile ẹru kan tun ti ja le awọn eeyan lori."
Kí ipade naa to waye ni ni Omisore sọrọ lori esi idibo to waye ni Osun ni Satide to kọja.
A gbọ́ pé àwọn kan láti ọ̀dọ̀ wa ń fi ọ̀rọ̀ yọ yín lẹ́nu, wọn kò jẹ́ kí ọkàn yín balẹ̀.
Wọ́n á máa sọ fún àwọn aríran pé,“Ẹ má ríran mọ.
Oríṣun àwòrán, Seyi Makinde Atẹjade naa fikun pe, wọn ti gbe ilana bi wọn yoo se pin ipo kalẹ lori adehun ajumọse naa, ti eto si ti de oju ọgbagade lati ri daju pe wọn se amusẹ adehun naa, ti gbogbo ẹgbẹ oselu to kan si ti fọwọsi ilana naa.
"Ki n to wa lọ ra ata yẹn mo mu ọmọ yẹn da ni mo fun ẹni to jẹ aburo ọkọ mi pe ki wọn maa ba mi wo ọmọ yii, kii ṣe oun nikan lo wa nibẹ wọn pọ ati awọn ọmọ temi naa ti gbogbo wọn n jo.
Alamojuto ere bọọlu meji rẹwọn he ni Burundi Ẹnu ń kun ààrẹ Burundi tó jú akẹ́kọ̀ọ́ mẹ́ta sẹ́wọ̀n nítorí wọ́n fi nǹkan kun àwòrán rẹ̀ Ìgbà Marún-un ti Aisha Buhari ti tako ìjọba Buhari Lara ẹsẹ ti ijọba ni Sowore da ni pe o bu aarẹ orileede Naijiria ni ilodi si ofin Naijiria.
Wọ́n mú Fayose wọ inu kòtò ìjẹ́jọ́ gẹ́gẹ́ bí àwọn agbẹjọ́rò ṣe bẹ̀rẹ̀ lórí àwn ẹ̀sùn tí wọ́n fi kàn án.
1 Nísisìyí kíyèsíi, isẹ́ ìyanu kan ti fẹ́ jáde wá láàrin àwọn ọmọ ènìyàn.
Ìjà Toyin àti Lizzy kìí ṣe àkọ́kọ́, àwọn òṣèré t'ọ́rọ̀ ìjà kàn rí rèé Kò sí ìdí láti tọrọ àforíjì lọ́wọ́ Nàìjíríà - Alákòso Johannesburg Folashade Yemi-Esan, ohun tó yẹ kóo mọ̀ nípa adarí ẹ̀ka òṣìṣẹ́ ọba tuntun A ti kọwé sí ìjọba àpapò làti pe agbaṣèṣe odò Asa padà- Gomina Kwara Oògùn olóró cocaine ni Toyin Abraham fi ń sayé - Lizzy Anjorin Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Mo fọ kọ́mú, pátá, ògiri ilé lórí 200,000 láìlèfọhùn lórílẹ̀èdè Oman' Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, South Africa: Àwọn ọmọ Nàìjíríà tó kù ní ìjọba SA ń kó ọ̀pọ̀ tó fẹ́ wále sí ọgbà ẹ̀wọ̀n Sùgbọ́n ọ̀ps lo n náwọ àtako nítori ó n tako òṣèlú awa ara waàti ìwà àjẹbánu.
Nítorí náà, bí mo tilẹ̀ ní ìgboyà pupọ ninu Kristi láti pàṣẹ ohun tí ó yẹ fún ọ, 
Nítorí pé ó bọ̀wọ̀ fún Ọlọrun, adura rẹ̀ gbà.
Gómìnà Obaseki àtàwọn Ọlọ́pàá tó gbàkóso ílé Aṣòfin Edo forígbárí Ohun taa gbọ ni wi pe Gomina ipinlẹ Edo Godwin Obaseki ati igbakeji rẹ ti lọ tu awọn ọlọpaa to duro gbagba si ẹnu ọna ile igbimọ aṣofin ipinlẹ Edo ti wọn si n gbiyanju ati fi tipa tikuuku wọle.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: OAU fẹ́ wádìí olùkọ́ tó fẹ́ bá akẹ́kọ̀ọ́ lò fún máákì Ẹgbẹ olukọni ya si meji ni fasiti Awolọwọ 'Ọ̀jọ̀gbọ́n Akindele kò ṣẹ̀ṣẹ̀ máa bèèrè fún ìbálòpọ̀' Amòfin tó ń ṣojú arábìnrin Monica Osagie, Ọ̀mọ̀wé Abíọ́lá Akínyọdé Afọlábí ní, akẹ́kọ̀ọ́ náà jẹ́ kó di mímọ̀ níwájú ìgbìmọ̀ náà pé, òun kò fìdírẹmi nínú ẹ̀kó náà, ṣùgbọ́n ọ̀jọ̀gbọ́n náà ló mọ̀ọ́mọ̀ fìdí òun rẹmi kó leè rọ́nà bá òun lò pọ̀.
Ẹlomiran to tun ba BBC sọrọ, Lolade Odujoko sọ pe ti wọn ba lee ṣafikun owo ọkọ aladani Uber, o n tumọ si oun ko ba wọn dowopọ niyẹn.
Lasiko ipade apero OIC naa, aare yanana idi pataki ti awon orile ede ti won je omo egbe ajo naa fi gbodo fimo-sokan, bakan naa lati sisẹ papọ lati gbogun ti awon ipenija bi i: Iwa idunkooko -mọni ati laasigbo awon alakata-kiti elesin musulumi, bee si ni aare tun gboriyin fun olokan-o-jokan eto ati ise akanse ti ajo naa sagbakale re eleyi ti o sanfaani lopolopo fun orile-ede Naijiria ati nilee Afrika lapapo.
ni gbagede ti o ni alaafia, ti ko si ni si ijaya kankan bi o se le wu ko mo.
Oríṣun àwòrán, Germany/Twitter Àkọlé àwòrán, Germany fun Naijiria ni ayo mẹta si odo Pẹlú iṣẹju mẹjọ si ipari ifẹsẹwọnsẹ naa, wọn tun ti fi ikẹta lee.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Mò ń fi lẹ̀kẹ̀ ya àwọnran láti jèrè ǹkan méjì - Olaniyi Olaniyan Bakan naa lo tun rọ awọn ontaja, awọn to n kiri ọja, awn onibaara atawọn araalu lapapọ, lati rin jinna kuro lawn opopona oju irin, ki wọn lee dina ijamba.
Òṣìṣẹ́ àjọ FRSC méjì bọ́ sọ́wọ́ àwọn ajínigbé l'Ọsun Ọwọ́ tẹ afurasí méjì tó nííṣe pẹ̀lú ìjínígbe Ọgá panápaná l'Eko Àwọn ajínigbé jí adarí ìlú Daura gbé Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ṣé ẹ̀yin lè ṣe jú àwọn tó f'àmì sí Awọlumatẹ?
Nígbà tí ẹ bá ti ṣe ohun gbogbo tí a pa láṣẹ fun yín tán, kí ẹ sọ pé, ‘Ọmọ-ọ̀dọ̀ ni a jẹ́.
Bi wọn se n dibo wọn ni bonkẹlẹ ree lorilẹede Mauritania lasiko idibo aarẹ to waye lọjọ Satide.
Bi o tilẹ jẹ pe ikọ naa ko ra atamatase kankan ti Harry Kane si ti sese, sugbọn agbo to fẹyin rin, agbara lo lọ muwa.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Koko iroyin: Ìgbésẹ̀ ìjọba l'órí Codeine, ìkọlù NURTW níbi ayẹyẹ ọjọ́ òṣìṣẹ́ 1 Èbibi 2018 Eyi ni awọn akojọpọ iroyin ti toni.
Nibayii ti ijọba ati ọga agba ọlọpaa ti jẹ awọn ọdọ ni hoo, ajọyọ tun bẹrẹ ti awọn kan si tun ni ọrọ lati sọ fun ijọba.
Ṣugbọn ẹ kò gbọdọ̀ jẹ ninu ohun tí o bá jẹ́ ìdámẹ́wàá yín ninu ìlú yín, kì báà ṣe ìdámẹ́wàá ọkà yín, tabi ti ọtí waini, tabi ti òróró, tabi ti àkọ́bí mààlúù, tabi ti ewúrẹ́, tabi ti aguntan, tabi ohunkohun tí ẹ bá fi san ẹ̀jẹ́ fún OLUWA, tabi ọrẹ àtinúwá yín tabi ọrẹ àkànṣe yín.
Gomina ni ijọba tun ti n ba ileeṣẹ aladani kan sọrọ lori ipsese afẹfẹ emi oxygen"" fawọn alarun Covid-19 to ba nilo rẹ."
ijoba apapo se yo adari ile-ejo lorile ede Naiajiria, iyen Walter Onoghen.
Ondo Governorship Elections 2020: Ìjọba ìbílẹ̀ mẹ́ta yìí ní yóò sọ ẹni tí yóò jáwé olúbori ninú ìdìbò Ondo
Hanna fikun ọrọ rẹ pe agbalagbga ti ọjọ ti lọ lori wọn lawọn eeyan yii lu ni jibiti.
Ó jẹ ́ ògbóntagì sọ ̀ rọ ̀ sọ ̀ rọ ̀ orí rédíò ní ipinlẹ ̀ Èkó ní ibẹ ̀ rẹ ̀ ọdún 1980 , ní bi tí ó ti gba ìnagijẹ rẹ ̀ ' fúnwọntán oduọ ́ lọ ́ jì ' .
Owo tawọn orileede kọọkan jẹ ni gbese n ṣakoba fun iye ti wọn n na.
Awọn kan bu mi, awọn kan si gbọ imọran mi pe ki wọn dẹkun nini ibalopọ pẹlu rẹ, ati pe ki wọn lọ fun ayẹwo.
” Esau bá bẹ̀rẹ̀ sí sọkún.
 Igbimọ naa yoo ni agbara lati
Wọ́n fún obìnrin kan lọrùn pa, awuyewuye ti ń wáyé Kí ló ṣẹlẹ̀ tí àwọn ọmọogun Nàìjíríà tó lé ní 350 fẹ́ kọ̀we fi iṣẹ́ sílẹ̀?
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Genevieve Nnaji: Ìbálòpọ̀ pẹlú ọ̀rẹ́kùnrin kọ́ ni ìfẹ́, bẹ́ẹ̀ ni ìfẹ́ kìí ṣe ìbálòpọ̀ 3 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 4 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Oríṣun àwòrán, Genevieve Nnaji/Facebook Gbajugbaja oṣere ori itage Nollywood, Genevieve Nnaji ja gudugbẹ ọrọ lulẹ lori ọrọ ibalopọ ati ifẹ laarin ọkunrin ati obinrin.
Wo nkan tó yẹ́ kí o mọ̀ nípa Adeyinka Godson tó fún ẹ̀yà Igbo ní wákàtí 48 láti kúrò nílẹ̀ Yorùbá Ọ̀nà láti sọ ọ̀rọ̀ ajé ilẹ̀ Yorùbá di akúrẹtẹ̀ ni àwọn ìkọlù tó wáyé ní Eko - Àwọn gómìnà Ìjọba ìpínlẹ̀ Eko tí kéde ìlànà ìséde tuntun fún ará ìlú Ẹni tó jí ọ̀pá aṣẹ ń bọ̀ wá túbá fúnrarẹ̀, mo fi dáa yín lójú gẹ́gẹ́ bí ìyá - Erelu Kuti Lọgan ti Fashọla to lewaju ikọ ti aarẹ Buhari ran si ipinlẹ Eko lori iṣẹlẹ naa ri kamẹra naa lo fi aṣọ ilewọ kan mu u ti o si fun gomina ipinlẹ Eko, Babajide Sanwo-Olu fun ayẹwo iwadii.
Àwọn wolii tí wọ́n ti wà ṣáájú èmi pẹlu rẹ ní ìgbà àtijọ́ sọ àsọtẹ́lẹ̀ ogun, ìyàn, ati àjàkálẹ̀ àrùn nípa ọpọlọpọ orílẹ̀-èdè ati nípa àwọn ìjọba ńláńlá.
yorùbá jẹ ́ ọ ̀ kan lára àwọn ẹ ̀ yà tó fẹ ́ ràn orin púpọ ̀ .
Àwọn eniyan ati àwọn àgbààgbà Gileadi sì bèèrè lọ́wọ́ ara wọn pé, “Ta ni yóo kọ́kọ́ ko àwọn ọmọ ogun Amoni lójú?
Ta ni Sani Musa tó ń ṣe PVC fún INEC, tó tún ń dupò sẹ́nétọ̀?
Ẹ̀ gbọ́ ọ̀rọ̀ lẹ́nu Adelé Ọba Alade Idanre ló rí ohun tó ṣẹlẹ̀ láàárín òun àti Ọba Aroloye Ta ni Wolii Olapade Agoro tó re ibi àgbà ń rè tí ayé ń pariwo rẹ̀ yìí?
Odugbemi soro lori ipo nla yii lori instagram e pe: “Loni ti mo gba leta pe mo di okan lara omo igbimo to n dibo fun Oscar lAmerica yii dun mo mi ninu pupo nitori pe anfani nla ni”.
O ti kọ ìfẹ́ tí o ní nígbà tí o kọ́kọ́ gbàgbọ́ sílẹ̀.
”Ahimaasi dá ọba lóhùn pé, “Kabiyesi, nígbà tí Joabu fi ń rán mi bọ̀, gbogbo nǹkan dàrú, ó sì rí rúdurùdu, nítorí náà n kò lè sọ ohun tí ó ṣẹlẹ̀ gan-an.
Láíyé àtijọ́, ṣèbí ọwọ̀ ìgbálẹ̀ tí wọ́n fi màrìwò  ọ̀pẹ ṣe la fi ngbálẹ̀.
"Sanwo Olu ni : "" idi ti a fi gbe igbesẹ yii ni ki awọn eniyan ipinle Eko le mo pe a mo riri eto ọrọ́ aje to dẹnukole nitori ajakalẹ arun Coronavirus yii ni gbogbo agbaye."
Ikọ Agbẹsunmọmi Boko Haram ti pa ẹgbẹgbẹrun awọn eniyan ni Ariwa orilẹede Naijiria, ti ọpọlọpọ si ti di alairile gbe.
’ Nítorí ìjọba Ọlọrun wà láàrin yín.
Ní ọjọ́ keji, ọjọ́ tí ó tẹ̀lé ọjọ́ ìpalẹ̀mọ́ àjọ̀dún, àwọn olórí alufaa ati àwọn Farisi wá sọ́dọ̀ Pilatu.
Lọpọ igba ni awọn ọmọ Naijiria ti ma n farakasa iṣẹlẹ yii ,ti o si ti ma n mu ki awọn eeyan kesi ijọba awọn orilẹede mejeeji lati mu opin ba iru iwa yii.
Ọ̀dọ̀ fásitì jànkàn Oxford ló ti jáde Kanye West ti bẹ̀rẹ̀ ìpolongo àti díje dupò aàrẹ ilẹ̀ Amẹrika Ètò ìdìbò abẹ́lé sípò gómìnà APC ni ipinlẹ Ondo ti bẹ̀rẹ̀ ní pẹrẹwu Awọn nnkan miran ti Akpabio sọ ree: Akpabio ni oun ko ni erongba kankan lati dije du ipo aarẹ.
Fasiti Ghana ati Fasiti ilu Eko ti ni ki awọn olukọ ti oju wọn han ninu fidio naa ti BBC gbe jade lọ rọkun nile fun igba diẹ, titi ti wọn yoo fi ṣe iwadi ọrọ ọhun.
Aseli bí ọmọkunrin mẹfa: Asirikamu, Bokeru, ati Iṣimaeli, Ṣearaya, Ọbadaya, ati Hanani.
Wọ́n bá kó àwọn ife wúrà ati ti fadaka tí wọ́n kó ninu tẹmpili ní Jerusalẹmu jáde, wọ́n sì bẹ̀rẹ̀ sí fi wọ́n mu ọtí.
Niwaju awọn aṣoju orilẹede Naijiria ni Adamu Adamu ti ṣi aṣọ loju ọrọ naa.
wọ́n wá ń lọ sọ́dọ̀ rẹ̀, wọ́n ń kí i pé, “Kabiyesi!
Fayoṣe: Mi ò jẹ̀bi ẹ̀sùn kankan Àkọlé àwòrán, Fayoṣe ní ilé ẹjọ́ gíga ìpínlẹ̀ Eko Agbẹjọ́rò: Ẹsun pe Fayoṣe gbe owo to jẹ ọọdunrun miliọnu naira, N300 miliọnu, ti ajọ EFCC ni o jẹ ara owo ti ko bofinmu, si aṣuwọn ifowopamọsi rẹ to wa pẹlu banki Zenith ni ọjọ keje oṣu kẹrin ọdun 2015.
"Mo wa fẹ sin awọn pasitọ ni gbẹrẹ ipakọ pe, ẹ n sinmi bayii, amọ ẹ gbaradi fun eto isọmọ lorukọ lọpọlọpọ ni ibẹrẹ ọdun to n bọ, ẹ si maa ti ojule kan lọ si omiran ni nitori igbele Coronavirus.
Dipò ki wọn lo owó ti ó wọlé lati tú ilú ṣe, wọn bẹ̀rẹ̀ si pin owó lati fi ra owó Òkè-Òkun lati kó jade lọ ra ilé nlá si àwọn ilú wọnyi lati sá fún ilú ti wọn bàjẹ́ ni gbogbo ọ̀nà.
Ó yẹ ki a mọ ọ̀rọ̀ sọ, ki á si mọ ọ̀rọ̀ ọ́ kọ sílẹ̀ lẹ́yìn ìgbà ti a bá ka ìwé kékeré yìí.
N óo sì ṣe ìdájọ́ yín.
Lọjọ kẹẹdogun, oṣu Kẹrin, ni awọn alaṣẹ ti ọfiisi Medcontour pa nilu Eko, lori ẹsun pe oun ṣe iṣẹ ti ko ba ofin mu.
ọgbọ̀n àwokòtò wúrà,ẹgbaa ó lé irinwo ati mẹ́wàá (2,410) àwo fadaka kéékèèké,ẹgbẹrun (1,000) oríṣìíríṣìí ohun èlò mìíràn.
Nkirukan kun nile iwosan aladani kan lẹyin iṣẹ abẹ kan to gbodi O ti fi igbakan jẹ akọroyin ẹka ilera ati idajọ.
Ó fi fìlà dé e lórí, ó fi ohun ọ̀ṣọ́ wúrà, adé mímọ́ tíí ṣe àmì ìyàsímímọ́, sí iwájú fìlà náà, gẹ́gẹ́ bí OLUWA ti pa á láṣẹ fún Mose.
Fasiti ibadan ni oun pẹlu ti ṣetan, o si wa lara awọn eekan agbo oṣere tiata nilẹ Yoruba ati lorilẹede Naijiria lapapọ.
Mo mọ̀ pé iṣẹ́ rẹ pọ̀ ṣùgbọ́n ṣíse ni iṣẹ́, n ó tọ́jú ilé rẹ, n ó tọ́jú ọmọ, n ó sì wá oúnjẹ pàtàkì aí ọ ní ọ̀nà ọ̀fun.
Àwọn ni ìjòyè tí wọ́n ṣẹ̀ láti ọ̀dọ̀ Reueli, ní ilẹ̀ Edomu, wọ́n sì jẹ́ ọmọ Basemati, aya Esau.
abewo re ati omo egbe yooku si ogagun Babangida gege bi ona lati gba imoran baba
Bákan náà, àkọsílẹ̀ fihàn wí pé ọ̀pọ̀ owó tó ń wọ àpò ìsúná rẹ̀ jẹ́ owó oṣù àti àwọn àjẹmọ́nú rẹ̀.
 O ni itan fihan pe Nigeria ati India ni awon nkan to pa won po to yato si tawon ile Yuroopu.
ÀFOWÓRÁ; èyí ni kí á beni nísé, kí onítòun wá yo sílè nínú owó ohun tí ó ye kí ó rà.
Sani sọ fún àwọn oníròyin ní Kaduna lọ́jọ́rú ọ̀sẹ̀ pé ọ̀pọ̀lọ́pọ́ àwọn tí wọ́n ṣẹ̀ṣẹ̀ lé dànù náà ni wọ́n kàwé gboyè gíga.
Nítorí náà, sọ fún àwọn ará Juda ati àwọn tí wọn ń gbé Jerusalẹmu pé, èmi OLUWA ní, mò ń pète ibi kan si yín, mo sì ń pinnu rẹ̀ lọ́wọ́ báyìí, kí olukuluku yín yipada kúrò ninu ibi tí ó ń ṣe; kí ẹ sì tún ìwà ati ìṣe yín ṣe.
Yàtọ̀ sí èyí, Italy ti pinnu pe òhún yóò fi òpin sí ìrìnàjò lọ́nà àìtọ́ wọ orílẹ̀-èdè rẹ̀ gẹ́gẹ́ bí wọn ṣe ti sọ ọ̀nà ibẹ̀ di ibi tí wọn ń gbà wọ Yuroopu.
Ẹ kò sì gbọdọ̀ kọ́ àṣà àwọn orílẹ̀-èdè tí n óo lé jáde fun yín, nítorí pé tìtorí gbogbo ohun tí wọn ń ṣe wọnyi ni mo fi kórìíra wọn.
Aare yoo tun maa se ipade po
World War III: Wo ohun tó yẹ kí o mọ̀ nípa awuyewuye tó ń wáyé láàárín India àti China
Tí mi ò bá fẹ́ ìyàwó mi, n ó tí di àgbégbìn- Ayodele Fayose Pásítọ̀ Sam Adeyemi, Taaooma, Falz àti gbogbo àwọn tí ilé ẹjọ́ fẹ́ rí nìyìí Ẹ̀yin akẹ́kọ̀ọ́ fásítì, ẹ múra sílẹ̀ fún ìwọlé lẹ́yìn ìyanṣẹ́lódì oṣù méje - ASUU ''Lẹyin ti ọrẹkunrin naa wọle ti obinrin ọhun ni wọn ti ilẹkun mọ ara wọn'' '' Ohun ti awọn ara adugbọ kọkọ ri ni eefin to n jade lati inu yara naa, ti gbogbo igbiyanju wọn lati pa ina ọhun jasi pabo.
Ọsẹ meji pere ni wọn fun awọn ọlọkọ epo naa nigba naa, lati ko aasa wọn.
Adari awon obinrin ninu egbe oselu APC arabinrin, Salamatu Umar-Eluma naa tun gbosuba fun eto ilana ti  ijọba apapo labe akoso Muhammadu Buhari  gunle.
Hẹrọdu ọba gbọ́ nípa Jesu, nítorí òkìkí rẹ̀ kàn.
” Àwọn àgbààgbà Israẹli bá pàṣẹ pé kí àwọn eniyan náà di aṣẹ́gi ati apọnmi fún gbogbo àwọn ọmọ Israẹli.
Gbajugbaja osere, Verne Troyer, ti awon eniyan mo mo ipa mini me to ko ninu Austin Power ti jalaisi lomo odun mokandinlaadota.
Lara awọn ọmọ Naijiria to fesi si igbesẹ aarẹ naa gboriyin fun aarẹ Buhari nigbati awọn miran bu ẹnu atẹ lu pe ọna miran lati fa ẹkunwo owo osu sisan naa gun ni Aarẹ Buhari dawọ le.
Seyi Makinde: Sunday Igboho ní Auxilliary yóò da ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́ rú mọ́ Seyi Makinde lórí Àkọlé àwòrán, Àwọn Alákòre gárèjì ló kó ìbọn àti àdá tọ ọlọ́kadà wá ní Soka-Alága ẹgbẹ́ ọlọ́kadà Ọyọ Èèkàn àwùjọ kan, Oloye Sunday Adeyemo, tí ọ̀pọ̀ èèyàn mọ sí Sunday Igboho, tí kesi gomina Seyi Makinde pé kò tètè fà alága àwọn Alakoso gareji ọkọ̀ nipinlẹ Ọ̀yọ́, Alhaji Lamidi Mukaila, tí inagijẹ rẹ ń jé Auxiliary létí, nítorí ìwà ìjẹgàba tó ń hù ní àárín ìlú.
Gbogbo ọrọ nipa Kinihun yii Kìnìhún tí wọ́n mú l'Eko kìí ṣe ti orílẹ́èdè Nàíjíríà Wo bí wọ́n ṣe gbé Kinihun tí ará India n sìn ni Eko!
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ilé ẹjọ́ Èkìtì d'ájọ́ ikú f’ọ́kùnrin tó jí ọtí méje áti páálí sìgá 5 Ìgbé 2018 Oríṣun àwòrán, Erik S.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ogun Kidnap: Ìjàmbá ṣàwọn ajínigbé tó fẹ́ fipá gba akẹgbẹ́ wọn lọ́wọ́ ọlọ́pàá 23 Ògún 2019 Oríṣun àwòrán, Facebook/Ogun Police Command Àkọlé àwòrán, Ọga agba ọlọpaa ipinlẹ Ogun Ileeṣẹ ọlọpaa ipinlẹ Ogun ti kepe awọn eeyan ati ile iwosan kaakiri ipinlẹ naa pe ki wọn kan si ile iṣẹ ọlọpaa ti wọn ba ri ẹnikẹni to ba ni apa ibọn lara.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Mo fẹ́ gbé ògo ìdílé ìyá àti bàbá mi ga pẹ̀lú iṣẹ́ Mọkálìíkì' Hate Speech bill: Ilé aṣòfin ṣe tán láti ṣàtúnṣe lórí ìjìyà ikú nínú àbá ọ̀rọ̀ ìkórìra Sẹnẹtọ to ṣagbatẹru aba to maa ṣe amujuto ọrọ ikorira eyi to wa niwaju ile igbimọ aṣofin agba l'Abuja, Sabi Abdullahi, sọ pe ile ṣetan lati yọ aba ijiya iku kuro ninu aba ti wọn gbe kalẹ ọhun.
Oluwa yóo yọ mí kúrò ninu iṣẹ́ burúkú gbogbo, yóo sì gbà mí sinu ìjọba rẹ̀ ní ọ̀run.
Idibo yi n waye fun ipo aṣofin ẹkun idibo Lagos East Senatorial District ati Kosofe 11 Constituency si ile igbimọ aṣofin ipinlẹ.
O fikun ọrọ rẹ pe niwọn igba ti obinrin to ba ti n dagba ko le lanfaani lati di ọdọmọbinrin pada, o ni wiwọ aṣọ to ba igba mu lọna miiran ti obinrin fi le da bi ''ayọngẹ.
Niwọn igba to si jẹ pe ti ọdẹ ba ku, ọdẹ nii soro lẹyin ọdẹ, idi ree ti ẹbi, ara, ojulumọ, atawọn alajọṣepọ rẹ ninu oselu fi korajọpọ sile rẹ l'Ọjọbọ lati sami ogoji ọjọ to dagbere faye.
Ayuba Wabba to jẹ aarẹ ẹgbẹ oṣiṣẹ ni wọn sun ijiroro naa siwaju ki ọrọ awọn ikọ mejeeji le ye ara wọn sii.
Ewọ akojọpọ iroyin bii wọn ṣe ji awọn ọmọ Dapchi naa gbe titi di ọjọ ti mẹrindinlaadofa (106) fi gba itusilẹ.
Botilẹjẹ pe ofin orilẹ-ede Pakistan faaye gba iyawo pupọ, ti ọkunrin si le fẹ to iyawo mẹẹrrin, awsn iyawo ti iru ọkunrin naa ti kọkọ fẹ gbọdọ fi ọwọ si ko to o le gẹ omiran.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Lagos -Ogun Tanker Explosion: Ọkọ̀ agbépo kan tí gbiná lórí afárá Magboro 2 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Oríṣun àwòrán, Twitter Ijamba ina tun ti waye nipinlẹ Ogun lẹyin ti ọkọ agbepo gbina ni opopona Magboro, ọna lati wọ ipinlẹ Eko.
Simoni Peteru dá a lóhùn pé, “Oluwa, ọ̀dọ̀ ta ni à bá lọ?
Ìṣẹ̀lẹ̀ Bakana: àwọn tórí kó yọ fẹ́ bẹ̀rẹ̀ ètò ìrànlọ́wọ́ Ni ọjọ kẹẹdọgbọn, oṣu kejila ni wọn ṣe ayẹyẹ idanilọla fun akinkanju ọdọmọkunrin yii pe o kare!
Eléyìí ló mú kí ẹ̀rí ọkàn Gwynne-Jones lágbára tó bẹ́ẹ̀ nítorí mo ti báa lò rí mo sì rí i pé kì í fẹ́ kí òun ṣe nǹkan sí ẹnikẹ́ni tí ẹ̀rí ọ̀kan òun yóò fi ddá òun lẹ́bi.
Obinrin náà dáhùn pé, “Kí ló dé tí o fi ń dẹ tàkúté fún mi láti pa mí?
Ṣugbọn wolii ará Juda náà dáhùn pé, “N kò gbọdọ̀ bá ọ pada lọ sí ilé rẹ, bẹ́ẹ̀ ni n kò gbọdọ̀ fi ẹnu kan nǹkankan ní ilẹ̀ yìí.
Bakan naa lo tun fi igbe aye rẹ silẹ fun ilọsiwaju awọn ọmọ Yoruba ati ilẹ Kaarọ Oojire lapapọ.
Laipẹ yi ni Sẹnetọ Shehu Sani sọ pe N13.
Ilésanmí rọ́ àlà tí ó lá fún Akin Atọ̀pinpin ọmọ Olúṣínà.
Gbọnmọ-gbọnmọ awọn ikọlu awọn ikọ afẹjẹwẹ wọnyi lo ti wa n legba kan ju ọrin lọ nilẹ Naijiria lẹnu lọọlọ yii, kaka ki ewe agbọn wọn si dẹ, koko lo n le si.
Mo rí gbogbo alààyè tí ń rìn kiri láyé ati ọdọmọde náà tí yóo gba ipò ọba.
Oṣusan Oluwatobi ko jẹ ara aye ko jẹ ara ọrun nigba ti iye rẹ sọ pada nibi ijamba buruku to mu ọkọ kan ati kẹkẹ alupupu to wọ forigbari.
Toyin Abraham fi orin yẹ́ Iyabo Ojo sí níbi ìsìnkú ìyá rẹ̀, Falz di ẹni tí wọ́n fí òpópónà ṣọ orí rẹ̀ Ọkọ mi bẹ̀rẹ̀ sí ní lù mí lẹ́yìn tí mo lòdì sí ibálọ̀pọ̀ láti ihò ìdí lẹ́yìn- Sabira Wo bí ilé ìwòsàn LUTH ṣe ń gba owó ibùsùn lọ́wọ́ àwọn aláìsàn, tí àwọn míràn sì ń sun ìta 'Àwọn ọlọ́pàá ti bẹ́ síta láti ṣàwárí àwọn olè 30 tó jówó kó lọ ní Union Bank l'Ondo' Nibi idanilẹkọ kan ti wọn fi sọri ayẹyẹ ọdun karun Ọọni Ogunwusi lori itẹ, eyi to waye nilu Ibadan ni wọn ti sọrọ yii.
Àkọlé àwòrán, Ni igba ọgun Biafra, Baba Obasanjọ ko ipa ribiribi lati ri wi pe wọn rẹyin iyapa ẹya Igbo kuro lara Naijiria.
Àwọn ọ̀dọ́ ya bo ààfin Akire láti jí oríadé gbé Àwọn ọbá aláye ilẹ̀ Yorùbá márùn-ún pẹ̀lú ọ̀pá àṣẹ wọn Irọ́ ní pé bàbá wa, Soun Ogbomoso paradà di ọmọ tuntun, báyìí ni àwọn ọ̀rẹ́ ṣe dalẹ̀ rẹ̀ tí wọ́n pa á Ẹni tó jí ọ̀pá aṣẹ ń bọ̀ wá túbá fúnrarẹ̀, mo fi dáa yín lójú gẹ́gẹ́ bí ìyá - Erelu Kuti Àṣírí tó ń bẹ láàrín Oluwo àtàwọn ọ̀dọ́ Iwo tí wọ́n fi fi ẹ̀mí wọn lélẹ̀ dáàbò bo ààfin rẹ̀ Adio di ẹni iwọlẹ loju Abẹni, iyawo rẹ ti ko si ọrọ lẹnu rẹ mọ ninu ile.
Reno Omokri fi lede lori ẹrọ ayelujara Twitter rẹ pe igbakeji ọjọgbon kan ti orukọ rẹ n jẹ Kelly Costner lo se ifilọẹ Next Level"" lati jẹ ki awọn ọmọ ile iwe giga Winthrop University kọ ẹkọ Ede Gẹẹsi fun imugbooro ibasepọ laarin idile."
Omiran tilẹ ti maa n waye fun ọpọlọpọ ọdun tabi oṣu ki aṣiri to tu.
Loju opo EFCC lori Facebook ni wọn fi iroyin yi si ninu atẹjade kan.
Ọkunrin elegungun ejo naa ni ko nkan ti oun fẹ ka bii rẹ, ti oun ko lee se.
Ayeye lati bere idije XXI Commonwealth Games  naa yoo waye laago meje ojoru(Wednesday), ni papa isere Carrara ni Gold Coast, Australia.
Ninu oro tire, oga agba okan lara awon agbodegba alamojuto ise-akanse etikun Lekki naa, Navin Nahata so pe, ise-akanse ohun ti safihan pe, orile-ede Naijiria je ibi idokowo.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Oronpoto Animation: Akin Alabi ní kò dára bí eré aláwòrán fáwọn ọmọdé ṣe jẹ́ aláwọ̀ funfun Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 3 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 5 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
"A ko gbọdọ rẹyin ninu adura fun iṣọkan orilẹede Naijiria ati alaafia laarin awọn eeyan rẹ.
Ńṣe ni inú gbogbo àwọn eniyan dùn nítorí gbogbo ohun ìyanu tí ó ń ṣe.
Alaye fi han pe awọn agbofinro n wọ inu awọn adugbo ti wọn ti fẹ ṣe atundi-ibo yii lati gbegidina kaadi idibo tita.
Ijọba ni aifi ọwọ sibi ti ọwọ ngbe aṣaaju ijọ Shitte ọhun lo n faa, ti gbogbo nnkan nipa itọju rẹ nilẹ okeere ṣe lọju pọ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù One Million Boys: Ìforígbárí ẹgbẹ́ òkùnkùn Ebila àti Ekugbemi n'Ibadan 16 Agẹmo 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 20 Agẹmo 2020 Oríṣun àwòrán, Other Ọrọ ti ẹ kan rọra n gbọ nipa Ebila olori ikọ One Million Boys"" lẹnu ọjọ mẹta ti wọn pa Abiola Ebila yii, kii ṣe ibi lo ti bẹrẹ."
Híhunjọ tí ara mi hunjọ, jẹ́ ẹ̀rí láti ta kò mí;rírù tí mo rù ta àbùkù mi,ó sì hàn lójú mi.
OLUWA fẹ́ràn rẹ̀,yóo mú ìfẹ́ inú rẹ̀ ṣẹ lórí Babiloni,yóo sì gbógun ti àwọn ará Kalidea.
 ní ọdún 1979 , àwọn òbí rẹ ̀ pinnu láti mú àkọ ́ bí ọmọ wọn padà sí ìlú Èk ̀ itì kí ó lè kọ ́ àṣà , ìṣẹ ̀ dálẹ ̀ àti iṣẹ ́ ìlú Èkìtì dáadáa ; fún ìdí èyí , ó wọ ilé ẹ ̀ kọ ́ girama ti Ìpótì ní ọdún kan náà .
igbese akin ti yoo mu oniruuru ayipada otun de ba eto  oro aje orile ede yii nipa fifowosowopo pelu
Lẹ́yìn náà ìyá mi wá mú ìbòrùn àrán rẹ̀ tuntun ó sọ ọ́ lé èjìká mi, mo sì tún wá mú sálúbàtà kékeré kan báyìí tí a fi awọ ejò ṣe mo kìí bọ ẹsẹ̀, mo so aago tí mo rà tí ìdálẹ̀ bọ̀ mọ́ ọrùn ọwọ́ mi òsì, mo mú ọ̀pá kan bàyìí tí mo ṣẹ̀ṣẹ̀ rà lọ́wọ́, mo sì wá mú ọmọdé kan lẹ́yìn, mo kọ orí sí ilé ọba, mo ń lọ.
Oríṣun àwòrán, Bashir Ahmad Amọṣa o fi kun un pe, mẹta ninu awọn ti wọn ko wa ni wọn ti da silẹ lẹyin ti wọn gba itọju ti ara wọn si ti da ṣaka.
" Dokita Obinnaadigo sọ pe inu rirun ninu oyun le jẹ ami pe nkan ti fẹ ẹ yiwọ, ninu eyi to le jẹ pe oyun naa n dagba ni ita ile ọmọ obinrin - ectopic pregnancy, ni awọn onimọ nipa ilera n pe e.
nomba je ohun afoyemo to duro fun iye tabi iwon .
Ileeṣẹ MultiChoice Group ṣalaye siwaju si pe bi ọrọ aje to dẹnu kọlẹ ṣe n ṣakoba fawọn ọmọ Naijiria lo n ṣe akoba fun ileeṣẹ ọhun naa.
Apapo awon omo egbe igbimo ohun ni igbakeji Aare tabi minisita ti Aare yan, adajo agba ati eni ti  je akosemose ologun oyinbo lorile-ede Botswana, ti aare si fowo si.
O ni ọpọ awọn oju popo wa ni ko se rin nitori koto ati gegele, ta ba si ni ka maa pariwo nikan ni, ariwo laa pa titi ti ewu yoo fi hu lori wa, sugbọn awọn ọdọ ko gbọdọ dakẹ.
O tesiwaju pe,“Kosi ounje ti e le fun omo ti o le se anfaani lara omo to omi oyan, bi o ba ran omo ohun lowo, ko le gba ipo oyan rara.
Aigbofa ni agbegbe Oja’ba ni ijoba Ibile Iwo oorun Gusu Ibadan, niluu Ibadan
O ni gbogbo wọọdu mejilelaadọwa to wa kaakiri ijọba ibilẹ mejidinlogun ni ipinlẹ Edo ni eto naa yoo ti waye.
Eseri ló bí Bilihani, Saafani ati Jaakani.
Gbogbo ọna lo n tọka si pe awọn ara Demark yoo kọja si Sweden lati lọ ra awọn nkan keresimesi, minisita to n ri si ọrọ idile Mikael Damberg lo sọ be gẹgẹ bi iroyin AFP."
Ti o ba si je owo iranwo fun awon
Sùgbọ́n lẹ́yìn ti ẹlẹ́gbọ̀n àgbà ṣe ìdájọ rẹ̀ tán tó sì fọ́wọ́ òsì júwé ilé fún Erica ní àwọn ọmọ Naijira bá ń sọ èrò tí wọ́n lóri ọ̀rọ̀ náà lórí ayélujára.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Scrabble: Yorúbà Scrabble ni àkọ́kọ́ ní èdè abínibí nílẹ̀ Afrika Wenger àti Mourinho ti parí ìjà Nàìjíríà -orílẹ̀-èdè tí ǹkan márùn ún yì yà sọ́tọ̀!
Ifẹsẹwọnsẹ akọkọ wọn labẹ olukọni tuntun, Mikel Arteta kii ṣe eyi to mu iyatọ pupọ wa si ti atẹyinwa.
" Abajade ifidimulẹ lati ọdọ awọn alaṣẹ fasiti Ibadan ni pe, kii ṣe ileewe naa ni iwe ẹri ti o n lo ti jade.
O ni ẹgbẹ oṣelu PDP bẹrẹ igbesẹ tita ẹka to n pese ina ọba ṣugbọn wọọn ba aye ẹka to n pin ina ọba jẹ"" O ni ẹka yii kii ṣe fun pinpin sapo awọn eeyan kan lorilẹede Naijiria bikoṣe fun idagbasoke gbogbo ilu."
Tí mo bá ń ka àwọn ilẹ̀ tí ó mọ rírì mi,n óo dárúkọ Ijipti ati Babiloni,Filistia ati Tire, ati Etiopia.
Nípasẹ̀ rẹ̀ ni Ọlọrun ti fi Ẹ̀mí Mímọ́ tí ó ṣe ìlérí fun yín bí èdìdì.
Ohun ta si lee sọ nipa awọn bẹbẹ ti olori Badra n dawọle ni pe ayaba naa ti gbajumọ isẹ aje rẹ ju ti tẹlẹ lọ, to si mu okoowo rẹ lọkunkundun.
Àwọn ìbejì Akeugbagold kò le rìn dáadáa mọ́ lẹ́yìn tí wọ́n dáwọn padà Onimọ nipa ẹṣin Islam ti wọn ji ibeji rẹ lọ laipẹ yii, Sheikh Taofeeq Akeugbagold tun ti salaye nipa ohun ti oju awọn ibeji rẹ ri ni ọdọ awọn afurasi to ji ibeji rẹ gbe.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Búrẹ́dì tí wọn ó fi jẹ ẹ̀wà ni wọ́n lọ rà ni wọ́n pàdé ikú gbígbóná' Ọpọ̀ ọkọ̀ bàjẹ́ nígbà tí alátìlẹ́yìn PDP àti APC kọlù àrà wọ́n l'Ondo Awọn alatilẹyin Gomina Rotimi Akeredolu ipinlẹ Ondo ati akẹgbẹ rẹ ninu ẹgbẹ PDP Eyitayo Jegede ti n naka abuku sirawọn lori ẹni to jẹbi ikọlu to waye lọjọru.
Ọkan ninu wọn lo mu tajutaju wa lati ile, amọ ti ẹlomiran si mu u nibi to fi pamọ si to si fi si ara awọn ọmọ kilasii rẹ.
Ondo rape apologist: Olùkọ́ kan di èrò ọgbà ẹ̀wọ̀n fún fífipá bá ọmọ ọdún mẹ́wàá lòpọ̀ ní ìpínlẹ̀ Ondo
Coronavirus: Pé wọ́n bi ọ sínú bàálù orílẹ̀-èdè kan kò túmọ̀ sí pé ó ó di ọmọ ibẹ̀ Oríṣun àwòrán, Getty Images Ọrọ orilẹ-ede ti ọmọ ti wọn ba bi sinu baalu tabi ọkọ oju omi yoo jẹ kii ṣe oni lo bẹrẹ.
Laipe yii ni fọnran ati fọtọ jade lori ẹrọ ayelujare to fihan wipe ọpọ awọn ọmọ Naijiria lo ha si Russia lẹyin ti ikọ Super Eagles ja ninu idije naa.
Ó bá ni, ‘N óo tún pada sí ilé mi, níbi tí mo ti jáde kúrò.
Wọn maa n ṣe awọn iṣẹ aṣọ fifọ, ounjẹ sise, itọju awọn ọmọ, ọkọ wiwa, oko riro, eto aabo, ati bẹẹbẹ lọ.
Amọṣa ẹgbẹ agbabọọlu Roma ja fitafita lati da meji pada lati ẹsẹ First Edin Dzeko ati Diego Perotti.
 Ó wọ ́ pọ ̀ láàrín àwọn ọkùnrin ju obìrin lọ .
Ó mú àwo turari rẹ̀, ó sáré lọ sí ààrin àwọn eniyan náà.
Wọn ti ka abadofin yin fun igab ẹkẹta nile asoju sofin ti irinajo rẹ́ ṣi yi jina diẹ ki o to di ofin ti yoo mu irọrun ba ra ilu.
O ni eto ijọba apapọ ni, ko si si lara nkan ti awọn eniyan ipinlẹ Ọyọ n fẹ.
Wọ́n fẹ́rẹ̀ pa mí run láyé,ṣugbọn n kò kọ ìlànà rẹ sílẹ̀.
Bákan náà lo tún rọ àwọn aráàlú pé kí wọn máa gbàdúrà fún àwọn ọmọ náà, kí Ọlọ́run leè ṣe wọ́n ní rírí kíákíá.
Nígbà tí ó padà dé ilé ó mú owo díẹ̀ tí ó wà ní ọwọ́ rẹ̀ ó fi ra àwọn akèǹgbè mìíràn ó lọ so wọ́n mọ́ orí ọ̀pẹ ṣùgbọ́n nígbà tí ó tún dé ibẹ̀ lọ́jọ́ kejì ó bá àwọn akèǹgbè wọn-ọnnì ní ilẹ̀, wọ́n ti fọ́.
Wọ́n lọ ń gbé Geruti Kimhamu, tí ó wà lẹ́bàá Bẹtilẹhẹmu.
Nígbà tí OLUWA Ọlọrun dá ọ̀run ati ayé, 
Gbajabiamila ni yoo bẹrẹ lilọ rọọkun nile naa titi ti ileesẹ ọlọpaa yoo fi pari iwadii.
Kí ni ó pa tàwa-tìrẹ pọ̀, Jesu ará Nasarẹti?
Awọn ohun to yẹ ki o mọ nipa iṣẹlẹ naa ree.
Gbogbo nǹkan yòókù tí Pekahaya ṣe, ni a kọ sinu Ìwé Ìtàn Àwọn Ọba Israẹli.
Ọpọ wọn sa kuro nilu Eko lọ si agbegbe Ojo ati Badagry, Cotonou nigba ti awọn miran sa wa silu Ibadan, lara awọn to si wa si Ibadan ni Abiola Ebila.
Dípò bẹ́ẹ̀, ó gbé e lọ sí ilé Obedi Edomu, ará ìlú Gati.
Jehu, ọmọ Jehoṣafati, ọmọ Nimṣi, dìtẹ̀ mọ́ Joramu.
Tafawa Balewa: Wọn bi Alhaji Abubakar Tafawa Balewa ni oṣu kejila, ọdun 1912 ni ipinlẹ Bauchi.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Laipẹ́, ọmọ tí kò bá pé ọdún méjìdínlógún kò ní leè jáde girama l’Ọṣun 1 Owewe 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Laipẹ́, ọmọ tí kò bá pé ọdún méjìdínlógún kò ní leè jáde girama l'Ọṣun Ọrọ eto ẹkọ awọn ọmọ jẹ wa logun -Owoẹyẹ Olori ile aṣofin ipinlẹ Ọṣun, Timothy Owoẹyẹ ti fi to awọn eeyan leti pe laipẹ laijinna, ofin kan yoo jade ni ipinlẹ naa eleyi ti yoo kan an nipa fun awọn obi lati rii pe ọmọ wọn pe ọdun mejidinlogun ki wọn to jade ileewe girama.
Ta ni ń dì yín rí?
Hamu ni baba Kuṣi, Ijipti, Puti ati Kenaani, 
Ibrahim Mallaha ati awon osise ijoba ni ipinle naa.
Ninu oro iranse minisita fun eto ilera lorile-ede Naijiria, ojogbon Isaac Adewale so pe, oun fara mo ami eye idalola naa lati fi se kori ya fun awon akoroyin ti won gbe iroyin eka eto-ilera, eyi ti ajo WHO se agbekale re, ni eyi ti o seleri lati se agbateru abala kan ninu ipele ami eye naa.
Ọkan lara awọn eeyan to fori sọta akoko owo ẹru, to si di ẹru nigba naa, amọ ti ori ko yọ, to si pada di ojisẹ Ọlọrun ni oloogbe Samuel Ajayi Crowther.
    “N kò ní jù báyìí lọ.
Igbesẹ yii mu iriwisi ọtọọtọ wa, ti o si tun mi ki awọn eeyan ma sọrọ nipa bi owo obitibiti ṣe rọ mọ didi ipo mu lagbo oṣelu Naijiria.
Jehoiada bá rán àwọn ọ̀gágun ọmọ ogun ọgọrun-un pé, “Ẹ fà á síta láàrin àwọn ọmọ ogun, ẹni tí ó bá tẹ̀lé e, ẹ pa á.
Sọ àsọtẹ́lẹ̀ nípa wọn, kí o wí pé 
Nítorí bí ẹnìkan bá rò pé òun jẹ́ pataki nígbà tí kò jẹ́ nǹkan, ara rẹ̀ ni ó ń tàn jẹ.
Wọn pada yan an sinu awọn ọmọ igbimọ alamojuto ẹgbẹ APC ti aarẹ Buhari ba wọle lati 2015.
Nígbà tí gbolohun yìí dé etí àwọn onigbagbọ, wọ́n bẹ̀rẹ̀ sí sọ pé ọmọ-ẹ̀yìn náà kò ní kú.
Ó làjà láàrin àwọn mejeeji, ó sọ wọ́n di ara kan lọ́dọ̀ Ọlọrun nípa agbelebu.
Ṣugbọn agbẹnusọ ileeṣẹ aarẹ, Garba Shehu ti ni tiwọn ni wọn n wi.
ati Jakọbu ọmọ Sebede ati Johanu àbúrò rẹ̀, ó sọ wọ́n ní Boanage, ìtumọ̀ èyí tíí ṣe “Àwọn ọmọ ààrá”; 
 ogun máa ń fi ọ ̀ pọ ̀ lọpọ ̀ èmí àti dúkìẹ ́ sòfò .
Ile igbimọ Asofin gbe igbesẹ yii pẹlu awijare pe gomina Ambọde n na owo ti ile asofin ko fọwọsi.
Femi Fani Kayode: Ọ yẹ kí wọ́n jó Fairstein ní iná ni
Ó kó àwọn ati ohun gbogbo tí ó ní kọjá sí ìhà keji odò.
"Òrò wá di;"" Omo olórò n sunkún, erú olórò n yò."
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Florida: Ọ̀ọ̀nì àléègbà dé ba Mary lálejò lọ́gànjọ́ òru O ni wọn ti fi da gbogbo agbabọọlu loju pe awọn yoo san ajẹmọnu naa laipẹ ki onikaluku le pada si ibudo rẹ.
A kò gbo̩dò̩ túmò̩ ohunkóhun nínú ìkéde yìí gé̩gé̩ bí ohun tí ó fún orílè̩‐èdè kan tàbí àkójo̩pò̩ àwo̩n ènìyàn kan tàbí e̩nìké̩ni ní è̩tó̩ láti s̩e ohunkóhun tí yóò mú ìparun bá èyíkéyìí nínú àwo̩n è̩tó̩ àti òmìnira tí a kéde yìí.
 O ni: “A ti ra awon apakoriko to dara nipinle yii lati rii pe awon koriko ko yo ire oko wa lenu lasiko odun ogbin tuntun yii.
Bẹ́ẹ̀ ni wọ́n ń sọ oríṣìíríṣìí ìsọkúsọ sí i.
Ó sọ fún ọmọkunrin tí ń ru ihamọra rẹ̀ pé, “Fa idà rẹ yọ, kí o pa mí, kí àwọn aláìkọlà wọnyi má baà pa mí, kí wọ́n sì fi mí ṣe ẹlẹ́yà.
“Ẹranko keji dàbí àmọ̀tẹ́kùn, ó gbé ẹ̀gbẹ́ rẹ̀ kan sókè.
Ni Ilẹ Gẹẹsi, ounjẹ aarọ to peleke ni ki eniyan o fi ẹjẹ ẹlẹdẹ ti wọn ti sè, kun ounjẹ to fẹ jẹ lojumọ.
Wọ́n bá sọ Peteru sẹ́wọ̀n, ṣugbọn gbogbo ìjọ ń fi tọkàntọkàn gbadura sí Ọlọrun nítorí rẹ̀.
Iyaafin  Dabiri-Erewa, to je omo ile igbimo asoju tẹlẹri,
“Ní ọjọ́ kẹẹdogun oṣù keje, tíí ṣe ọjọ́ keje àjọ̀dún náà, yóo pèsè irú ẹbọ kan náà fún ìmúkúrò ẹ̀ṣẹ̀, ati ẹbọ sísun ati ẹbọ ohun jíjẹ ati òróró.
Dafidi a máa lọ sí Bẹtilẹhẹmu nígbà gbogbo láti tọ́jú agbo ẹran baba rẹ̀.
Ṣugbọn Giroud ya agbado ha si awọn to maa n tako o lẹnu lalẹ Ọjọru nigba to gba goolu aramọnda meji ọtọtọ sawọn ninu ifẹsẹwọnsẹ ọlọrẹsọọrẹ to waye laarin ilẹ Faranse ati Ukraine.
Iwadii yii fi aṣemaṣe lasiko idije WAFU 2017 han, o tun fi Jallow, oludari ere bọọlu lati Gambia naa han ninu fiimu ọhun pe o gba riba.
Ààrẹ Muhammadu Buhari ti gbá àwọn èèyàn tó ń pèé ní bàbá go slow pe òun ń lọ́ra láti buwọ́ lu ìwe kankan nítorí èèyàn kìí kánjú lá ọbẹ̀ gbóná.
Ibàjẹ́ ile-iwosan jẹ òfò fún onilé àti àlejò nitori ọ̀pọ̀ àisàn ti kò yẹ kó pani ló ńṣe ikú pani, fún àpẹrẹ, itijú ni pé, Ọba, Ìjòyè àti Òṣèlú ńkú si àjò fún àìsàn ti kò tó nkan.
Bí ọ̀run ti ga, tí ilẹ̀ sì jìn,bẹ́ẹ̀ ni ẹnikẹ́ni kò lè mọ ohun tí ó wà lọ́kàn àwọn ọba.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Fayose: Ojuti nla ni aawọ nipa ibiti Leah Sharibu wa 26 Ẹrẹ̀nà 2018 Oríṣun àwòrán, Facebook/Lere Olayinka Àkọlé àwòrán, Ayo Fayose je alatako to foju han si ijọba orilẹẹde Naijiria Gomina ipinlẹ Ekiti, Ayodele Fayose ni, idojuti nla ni bi ileesẹ ọlọpa Naijiria ko ti se ni iroyin to peye nipa akẹkọ Dapchi kan to sẹku ti wọn ko tii ri.
 lẹ ́ yìn ọ ̀ pọ ̀ lọpọ ̀ oṣù tàbí ọdún àwọn ohun tó wú sí ni lára wọ ̀ nyí lè bẹ ̀ rẹ ̀ síí dun ni , wọ ́ n lè wú síi , kí wọ ́ n tó wá lọ sílẹ ̀ .
Lẹnu ọjọ mẹta yii, ọwọja ikọlu Boko Haram, paapa julọ ni ipinlẹ Borno, fẹ peleke.
Solomoni jọba ní Jerusalẹmu lórí gbogbo Israẹli fún ogoji ọdún.
Àkọlé àwòrán, Witiwiti ni awọn eeyan ra ọja Huawei kaakiri agbaye Awuyewuye robot arm Bi ko ba daju pe Huawei mọ nipa awọn ẹsun miran,eleyi ti ko ruju rara ni ti eleyi ti wọn fi kan awọn onimọ ẹrọ rẹ kan ti wọn ni wọn ji ''robot arm.
Ní ọjọ́ kinni, ẹ óo mú ninu àwọn èso igi tí ó bá dára, ati imọ̀ ọ̀pẹ, ati ẹ̀ka igi tí ó ní ewé dáradára, ati ẹ̀ka igi wilo etí odò, kí ẹ sì bẹ̀rẹ̀ sí yọ̀ níwájú OLUWA Ọlọrun yín fún ọjọ́ meje.
Àwọn olólùfẹ́ Arsenal ní kí Emery kọ̀wé fipò sílẹ̀ Eji Gbadero, ọmọ Ibadan àti jayé-jayé ọmọ ónílẹ̀ ti wọn yẹgi fun l'Eko Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí 6:18 Fídíò, Natalia Mufutau ìyá Yakub, Kamil àti Adam sọ̀rọ̀ lórí bí wọ́n ń sọ èdè mẹ́rin pàpọ, Duration 6,1831 Ògún 2020 Fídíò, Yoruba Language: Akomolede ati Asa Yoruba tọ̀sẹ̀ yí rèé lẹ́nu olùkọ́ wa30 Ògún 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Nigba to n sọrọ nibi ipade ọhun to waye ni gbọngan Mapo, Makinde ni apẹrẹ wi pe ẹgbẹ oṣelu PDP ti bẹrẹ si ni gbori soke ni bi Gomina ipinlẹ Osun tẹlẹ, Olagunsoye Oyinlola ati awọn alatilẹyin rẹ ṣe pada sinu ẹgbẹ naa.
Awon oludije fun igbakeji aare ninu egbe oselu marun un lo
Ọmọ Nàìjíríà kan tó lùgbàdì àrùn coronavirus ti di olóògbé Ẹ wo ǹkan to sẹlẹ̀ sí ọmọ àti ìyàwó ọmọ Atikú tó lùgbàdì ààrun Coronavirus Àrùn Coronavirus ti gba ẹ̀mí ẹni àkọ̀kọ̀ ní Zimbabwe Èyí làwọn ayẹyẹ nlá tí kò ní wáyé nítorí coronavirus Ẹlòmíràn tún ti lùgbàdì àrùn Corona Virus nílùú Abuja àti Eko Ìgbésẹ̀ ìjọba láti kojú àrùn coronavirus ń pani lẹ́rìn ín- Pásítọ̀ Adeboye Ẹ̀mí èṣù ni Coronavirus, kò leè ran ọmọ Ọlọrun - Ààrẹ Tanzania Gẹgẹ bi alaye ajọ NCDC loju opo Twitter rẹ, eeyan meji ninu awọn ogoji eeyan to lugbadi arun Covid-19 ni Naijiria ti kuro nile iwosan.
se idupẹ, mo ki gbogbo omo orile ede Naijiria ku ori-ire, ẹ ku aforiti.
Gbogbo agbaye papaa julọ awọn ogbontarigi agbabọọlu atawọn ololufẹ ere bọọlu lo n ṣe idaro Diego Amando Maradona to jade laye l'Ọjọru lẹni ọgọta ọdun.
N óo súre fún àwọn tí wọ́n bá súre fún ọ, bí ẹnikẹ́ni bá sì fi ọ́ bú, n óo fi òun náà bú.
Lati igba naa wa ni a gbọ wi pe o ti wa nileewosan naa ki o to dagbere faye lọjọbọ.
Kọlawọle ni ko yẹ ki a bi iru awọn ẹda bẹẹ si aye rara de ibi wi pe a o maa pe wọn ni ọkunrin.
Awọn adari ẹgbẹ agbabọọlu Arsenal ko tii kede awọn ti yoo ba Arteta ṣeṣẹ.
 Ye Shuijin so ni ilu Abuja nibi ayeye olodoodun orile-ede China fun ti odun 2018.
O ni ki awọn araalu gaan ma ṣe ti gomina gbọọn gbọọn.
"Amọ ko sai yan pe ""bi Olootu ère kan ba wa le tẹle awọn ofin tijọba la kalẹ lori idena itankalẹ arun Covid-19 ti mo mẹnuba saaju, o le tẹsiwaju lati lọ ya ere amọ ẹgbẹ TANPAN ko lọwọ ninu irufẹ igbesẹ Bẹẹ."
Nítorí náà, ọba pàṣẹ pé kí wọ́n ṣe àpótí kan tí àwọn eniyan yóo máa sọ owó sí, kí wọ́n sì gbé e sí ẹnu ọ̀nà ilé OLUWA.
Wilder so pe,“O di dandan ki ifigagbaga naa waye.
Atẹ́gùn ńlá ti dà ọ́ nù láàrin agbami òkun.
Ẹgbẹ NUJ ti fun awọn alaṣẹ naa ni gbedeke wakati mẹrinlelogun lati yi ofin naa pada Ọjọ kinni, oṣu Kẹfa, ọdun 2019 ni lilo ofin tuntun naa yoo bẹrẹ Amọ ṣa, Ọgbẹni Agada ti sọ pe awọn yoo ṣiṣẹ lori bi ofin tuntun naa ko ṣe ni i ṣe idiwọ fun iṣẹ awọn akọroyin.
Nigeria Air: Ilé iṣẹ́ ọkọ̀ òfúrufú tuntun ṣí'wọ́ iṣẹ́
Amọ, lẹyin wakati mẹfa ni wọn fi silẹ, ti awọn ikọ afẹhọnuhan to jẹ alatilẹyin rẹ ko si kuro nibẹ titi ti wọn fi fi silẹ.
Ọjọ meji ni ijọba Naijiria maa n ya sọtọ fun ayẹyẹ ọdun Ileya.
Nípasẹ̀ mi ẹ̀mí rẹ yóo gùn.
Bí ẹni tí ó ni í kò bá sì rà á pada, kí wọ́n tà á ní iyekíye tí ẹ bá dá lé e.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Jude Chukwuka: Wọ́n yóò fi ojú ọlọgbọ́n wo akúrí tó bá sọ ojúlówó èdè Yorùbá Amọ sa, o ni iwadii si n tẹ siwaju lati mọ ohun to sokunfa isẹlẹ naa, ti BBC Yoruba yoo si mu ẹkunrẹrẹ iroyin wa fun yin.
6 miliọnu ni abi awọn alalufa rẹ lo ta esi ibo yi fun un?
Ohun yòówù tí eniyan lè ṣe sí mi.
O ni, wọ́n tun fi àdá la àwọn igi to tó méjìdínlọ́gbọ̀n ninu oko náà, èyi tó si ti mu àdinku ba iye owo to yẹ ki àwọn igi naa ta lọ́ja, bákan naa ni wọ́n sàkóba fún igi kòkó, igi obì, igi ọ̀gẹ̀dẹ̀, àti ti kókò Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Gbogbo ìgbà tí a ti máa ń wá sẹ́yìn wọ̀n-ọnnì ni ìyà ma ń jẹ wa kí a to lè rí ẹni rán wọle, nítorí èyí inú wa dùn tí a tètè rí ẹnìkan ni ọjọ́ tí a n wí yìí.
Labẹ iṣejọba aarẹ ana, Gooduck Jonathan ni wọn ti yan mi sipo .
Ilẹ̀ ọba yóo wà láàrin ilẹ̀ Juda ati ti Bẹnjamini.
Wọ́n ní awọn kan ni àdúgbò Sango lo ké gbàjare ti wọ́n si fi ọ̀rọ̀ náà tó ilé iṣẹ́ ọlọ́pàá àgbègbè náà léti ki àwọn ará àdúgbò tó ṣe ìdájọ́ fún un láti ọwọ́ ara wọ́n.
Wọ́n ti rí Kìnìún tó sá lọ́gbà ẹrankò lẹ́yìn tó pa gbogbo ewúrẹ́ jẹ tán Ipò aṣaájú ni Yorùbá yóò wà ní Nàíjíríà lásìkò tí mo jẹ Odole - Adebutu Ọgagun Illiyasu fikun pe lasiko ti awọn ologun n paraaro agbegbe Bukarti, nijọba ibilẹ Geidam nipinlẹ Yobe, ni ọwọ wọn tẹ ọkọ mẹsan kan to kun fun ẹja gbigbẹ, ti wọn si mu afurasi mejidinlogun si ahamọ, to fi mọ awakọ awọn Boko haram naa, agbero ọkọ, atọkọse wọn ati awsn asoju wọn lorisirisi ọna.
 fún àpẹẹrẹ , àwọn ààjọ american ornithologists union kó àwọn tetraonidae ( grouse ) , numididae ( ẹyẹ awó ) , àti meleagrididae ( àwọn tòlótòló ) as bíi mọ ̀ lẹ ́ bí ní ẹbí phasianidae .
Aare Emmanuel Macron bale sipinle Eko leyin ipade ipade re pelu aare aare Muhammadu Buhari nilu Abuja, eleyi ti o irin ajo kinni ninu abewo olojo meji re ti ohun.
Alábòyun ṣe iṣẹ́ abẹ pẹ̀lú abẹfẹ́lẹ́, ó gbé ọmọ jádé nínú ara a rẹ̀ Sẹ́nétọ̀ Dino Melaye kéde láti dupò gómìnà Kogi Ẹ dákẹ́ àhesọ ọ̀rọ̀, n kò bí ìbẹta - Yinka Ayefẹlẹ Wo àwọn ìlérí tàwọn Gómìnà tuntun ṣe nínú ìbúra wọn O ni lẹyin o rẹyin iṣẹlẹ naa ja sayọ ni nitori o fun awọn aṣofin lanfani lati fi ẹsẹ wọn tilẹ pe aguda awọn ko jẹ labẹ Gẹẹsi ẹnikẹni tabi ẹka iṣejọba kankan.
Ile-ise ọlọpaa  ni awon agbebọn wa si awon ileto naa ti won si
Wọ́n kúrò ní Mara, wọ́n lọ pàgọ́ sí Elimu níbi tí orísun omi mejila ati aadọrin igi ọ̀pẹ wà.
Ile-ise olopaa orile-ede Senegal, ti gbegi dina igbimo kan to n fi ehonu won han lo si ile igbimo asoju-sofin ti o wa laarin gungun olu-ilu orile-ede ohun Darkar, leyin ti igbimo ohun bu enu ate lu erongba awon asofin ohun lati se atunse si iwe abadofin eto idibo orile-ede naa.
Odò náà sì kún bo gbogbo bèbè rẹ̀, bí ó ti wà tẹ́lẹ̀.
Ẹ́ni ọdún mẹ́tàlélógún ni Patcharamon Sawana bẹ̀rẹ̀ iléẹ̀kọ́ lẹ́yìn tí òfin fààyè gba àwọn àkàndá láti lọ sílé ìwé.
 ( 27b ) náà so pé wá jé òrò-ìse tí ó máa ń gba apat gégé àfikún .
9 billion US dola, eléyìí tó ká owó ìṣúná Naijiria fún ọdún 2017.
Àkọlé àwòrán, Ọpọ ileto ati ilu lo ti wa ninu ibẹrubojo nitori ikọlu awọn ole ajimaluu ni orilẹede Naijiria Eyi kun omilẹngbẹ awọn iṣẹlẹ ikọlu awọn ileto kekeeke to ti waye sẹyin ni ipinlẹ Zamfara ninu eyi ti ọpọlọpọ mi ti sọnu latọwọ awọn ole aji maluu.
Àwọn eniyan yìí ti sọ ọ̀rọ̀ èké nípa OLUWA,wọ́n ní, “OLUWA kọ́!
Ọdún mẹtadinlogoje (137) ni Amramu gbé láyé.
Ó mú lára òróró náà ó wọ́n ọn sí ara pẹpẹ nígbà meje, ó ta á sórí pẹpẹ náà ati gbogbo àwọn ohun èlò tí wọ́n wà níbẹ̀, ati agbada omi ati ìtẹ́lẹ̀ rẹ̀; ó fi yà wọ́n sí mímọ́.
Kì í ṣe lẹ́yìn tí ó ti kọlà, kí ó tó kọlà ni.
Asikò ìgbáradi lóri pápá ni Adun kú lẹ́yin ọjọ mẹta ìṣẹ̀lẹ̀ náà.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìtàn Mánigbàgbé: Ìdílé Mobee, Abass, Aniwura àtàwọn míràn rí owó tabua nínú òwò ẹrú 17 Òkùdu 2020 Owo ẹru jẹ oko-owo to gbajumọ yika agbaye ninu eyi ti wọn ti n ko awọn ọmọ adulawọ lọ ta bíi ẹru soke okun.
 or tàbí arópò-orúko ( ar ) ni ó máa ń jé olórí fún / apor .
Òun óo sì ra Israẹli pada kúrò ninu gbogbo ẹ̀ṣẹ̀ rẹ̀.
OLUWA, àtènìyàn, àtẹranko ni ò ń gbàlà.
"Awọn oṣiṣẹ wa tọju rẹ nileewosan, mo si tun ti ṣeleri pe ma a tọju ọmọ naa titi de ileewe girama.
Wọ́n wá bi Peteru ati àwọn aposteli yòókù pé, “Ẹ̀yin ará, kí ni kí á wá ṣe?
Kòtò tí Iṣimaeli ju òkú àwọn eniyan tí ó pa sí ni kòtò tí ọba Asa gbẹ́ tí ó fi dí ọ̀nà mọ́ Baaṣa ọba Israẹli; ṣugbọn Iṣimaeli, ọmọ Netanaya fi òkú eniyan tí ó pa kún kòtò náà.
Ìkọlù tí ó kọ lu àwọn obìnrin wọ̀nyí (àti àwọn ọkùnrin kan) rorò bí ẹranko ẹhànnà.
25 Má ṣe sẹ́ ẹ̀mí ìfihàn, tàbí ẹ̀mí ìsọtẹ́lẹ̀, nítorí ègbé ni fún ẹnití ó bá sẹ́ àwọn ohun wọ̀nyí.
Àwọn Farisi ati àwọn Sadusi wá sọ́dọ̀ Jesu, wọ́n ń dán an wò, wọ́n ní kí ó fi àmì láti ọ̀run han àwọn.
Mo ṣá wọn lọ́gbẹ́, wọn kò lè dìde,wọ́n ṣubú sí abẹ́ ẹsẹ̀ mi.
Ekiti Election: Àkójọpọ̀ àwòrán bi idibo se n lọ ni Ward ati Unit
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, FFKVS JORNO:Mi o kabamọ ibeere ti mo beere lọwọ FFK Lasiko ipade naa ni Ọgbẹni Eyo Charles ti beere lọwọ minisita tẹlẹ ri ọhun pe ta alo n gbọ bukaata irinkiri rẹ""."
Ìwọ tí ò ń fọ́nnu pé o mọ Òfin, ṣé o kì í mú ẹ̀gàn bá Ọlọrun nípa rírú Òfin?
" Alaga ẹgbẹ ASUU ni fasiti naa, Ọmọwe Adeọla Ẹgbẹdokun ṣalaye pe o di igba ti ijọba apapọ ba mu adehun to ba ẹgbẹ olukọ fasiti ṣe ṣẹ ki awọn to pada si ẹnu iṣẹ gẹgẹ bii igbimọ apapọ ẹgbẹ naa ti ṣe dari.
”Adari orile ede yii, tun gbosuba fun ifowosowopo awon omo-ologun lati orile ede Niger, Benin, Chad, Cameroon, Naijiria ati ajo agbaye lati gbokun ti omo-ogun olote ni ila-oorun.
Leah Sharibu ṣì wà láàyè - Iléeṣẹ́ Aarẹ Buhari Ǹkan mẹ́jọ tó máa kọ́kọ́ ṣẹlẹ̀ kí olólùfẹ́ méjì tó pa ara wọn Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Leyin titowobo iwe adehun yi tan, Aare Muhhamadu  Buhari ati Aare Macron so asodaju wi pe orile-ede mejeji setan lati mu igbeeru deba ibasepo to danmoran laarin orile-ede mejeji .
Ẹ jọ̀wọ́ ẹ jẹ́kí á tún bọ̀ sọwọ́pọ̀ láti gbé ògo ilẹ̀ Yorùbá ga.
Airisese ti n sakoba pupo fun egbe ANC nibi ti won ti padanu awon ilu nla nla bii Johannesburg, Pretoria ati Nelson Mandela Bay lodun 2016.
Dokita Adepoju ṣalaye pe awọn awọ oju to wọpọ ni Naijiria ati ilẹ Afirika ni awọn buluu, awọn ewe(green) ati awọn ''brown.
Ènìyàn méjìdínlọ́gbọ̀n lo tí ṣe pèkí ólọ́jọ́ wọn lónìí níbi Ìkọlù to ṣẹlẹ̀ nínú mọṣalaṣi kan lápá ariwa- ìlà-ọrùn ìpínlẹ̀ Adamawa.
Fásitì UNIOSUN ṣètò ìgbaniwọlé orí ayélujára fáwọn akẹ́kọ̀ọ́ tuntun fún ìgbà àkọ́kọ́ ní Nàìjíríà, Ohun tí a mọ̀ nípa rẹ̀ nìyí N4,200 la fẹ́ fi pèsè oúnjẹ fún akẹ́kọ̀ọ́ kọ̀ọ̀kan láti ìdílé tó lé ní mílíọ̀nù mẹ́ta yíká Nàìjíríà - ìjọba àpapọ̀.
Oríṣun àwòrán, ECOLE SUPÉRIEURE POLYTECHNIQUE DAKAR Diẹ lara awọn ẹrọ ti awọn onimọ ti gbe kalẹ nilẹ Afrika ree:1.
Eniyan meje mii ti wọn ji gbe ni a ri doola lanaa loju ẹsẹ ti a de ibi ti iṣẹlẹ naa ti waye, ti a si n wa ẹnikan to ku lara awọn eero ọkọ keji."
Ilẹkun Baalu Dana fo yọ nilu Abuja Agba Awo kan ni imulẹ fun awọn olowo nabi naa ko muna d'oko Awon alase sọ wipe wọn tan kiniun naa pada si ibugbe rẹ lehin ikọlu naa.
Àwọn ilẹ̀ ìní wọn ati àwọn agbègbè tí wọ́n tẹ̀dó sí nìwọ̀nyí: Bẹtẹli, Naarani ní apá ìlà oòrùn, Geseri ní apá ìwọ̀ oòrùn, Ṣekemu ati Aya; pẹlu àwọn ìletò tí ó wà lẹ́bàá àyíká wọn.
Lori bi awọn eleto ilera paapaa julọ awọn dokita to n tọju awọn alaisan se di ẹni ti o nko arun yii bayii, ọjọgbọn Adewọle ni ohun to bani ninu jẹ pupọ ni pe awọn olutọju alaisan pẹlu ti ẹni to n ko aisan yii sugbọn o ke si awọn dokita ati awọn olutọju alaisan kaakiri orilẹede Naijiria lati tubọ maa da abo bo ara wọn.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Toma Unu: Ọmọbìnrin tó ń fi ẹsẹ̀ rẹ̀ ya àwọran nítori pe ó ni ìpènija ọpọlọ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Toma Unu: Ọmọbìnrin tó ń fi ẹsẹ̀ rẹ̀ ya àwọran nítori pe ó ni ìpènija ọpọlọ 16 Èbibi 2019 Toma, ọmọbinrin tó n fi ẹṣẹ rẹ̀ ya àwọran tó jojú nigbese.
Gẹgẹ bi ohun ti a ri ka, Richard padanu ẹmi rẹ nigba to ko si inu ẹrọ to fi n ṣiṣẹ nileeṣẹ, to n ṣe ọṣẹ abufọṣọ nilu Ibadan.
Orogbo, Obi, Iyọ suga, Ireke, Aadun, Igbin, Ẹja, ỌtiṢinaapu ati awọn nkan miran ni awọn agbaagba lo lati fi sọ ọmọ tuntun ti a bi na ni orukọ.
Nítorí, ta ni ó mọ̀, bóyá ìwọ aya ni yóo gba ọkọ rẹ là?
Duro Ladipọ, ìlúmọ̀ọ́ká òṣèré tíátà àti ọmọ àlúfà tí kò gbàgbé àṣà ìbílẹ̀ Ọ̀dọ́kùnrin tó kọ́kọ́ ṣe ẹ̀rọ tó ń tu ìyẹ́ lára adìyẹ Ta ló gé orí ọkùnrin mẹ́ta ní Lekki?
OLUWA ní, “Àwọn àjèjì ni yóo máa tún odi rẹ mọ,àwọn ọba wọn yóo sì máa ṣe iranṣẹ fún ọ;nítorí pé inú ló bí mi ni mo fi nà ọ́.
Ẹ fi ìyìn fún OLUWA,nítorí pé, àwọn olórí ni wọ́n ṣiwaju ní Israẹli,àwọn eniyan sì fi tọkàntọkàn fa ara wọn kalẹ̀.
Wọn tun ni ta ba gbagbe ọrọ ana, a ko ni rẹni ba sere.
 Ìdá àádọ ́ rùn-ún nínú ọgọ ́ rùn-ún àwọn ènìyàn tí ó ń gbé ibẹ ̀ ni ó ń sọ samoan .
Yemi-Esan tun ni oludari ẹka iroyin ati aṣa ni ile iṣ naijiria to wa ni Paris, France laarin ọdun 2001 si dun 2003.
Orilẹẹde 44 t'ọwọ bọ'we lori AfCFTA Akẹkọ Dapchi 101 lo pada de Awọn olugbe adugbo nlo awọn aṣọ pelebe lati bo imu lati dẹkun fifun eefin naa simu.
Àwọn dókítà méjì kan náà kú látàrí ibà-ẹ̀fọn, èyí sì ti ń mú kí àwọn ènìyàn ó máa bẹ̀rù.
Ayìí tán ọkùnrin náà wò mí títí ó mi orí sókè-sódò, óo ní.
@CaptainGabby100 ni awọn oriroyin ni wọn n gbe ọrọ yii gẹgẹ, o ni kosi nkankan nibẹ.
Sẹnetọ Adeyéye, to jẹ alaga Ile igbimọ asofin lori ọrọ iroyin ati awujọ ni ile ẹjọ to n gbọ ẹjọ ẹsun to ni i ṣe pẹlu idibo ni ko kogba kagbọn rẹ pada sile bayii.
O ni Ọpa aṣẹ eyi ti wọn maa n gbe le ọba tuntun to ba ṣẹṣẹ jẹ lọwọ kii dede si larọwọto araalu.
73 Ẹni náà tí Ọlọ́run pè tí ó sì ní àṣẹ láti ọdọ̀ Jésù Krístì láti rìbọmi, yíò sọkalẹ̀ lọ sínú omi pẹ̀lú ẹni náà tí ó ti fa ara rẹ̀ kalẹ̀ lọ́kùnrin tàbí lóbìnrin fún ìrìbọmi, òun yíò sì sọ pé, ní pípe ẹni náà lọ́kùnrin tàbí lóbìnrin ní orúkọ rẹ̀: Nítorí tí a ti fi àṣẹ fúnmi lati ọ̀dọ̀ Jésù Krístì, mo rì ọ́ bọmi ní orúkọ ti Bàbá, àti ní ti Ọmọ, àti ní ti Ẹ̀mí Mímọ́.
"tori eyi la ṣe n fi ọrọ yii sita loju gbogbogbo pe a ni lati da abo bo ara wa""."
Ó dàbí ẹni pé àwa ni Ọlọrun ń lò láti fi bẹ̀ yín.
OLUWA àwọn ọmọ ogun ti fi ara rẹ̀ búra,pé òun yóo mú kí àwọn eniyan kún inú rẹ bí eṣú,wọn yóo sì kígbe ìṣẹ́gun lé ọ lórí.
Kò sí olùwọ́de tó kú ní Lekki - Sanwo-Olu Oríṣun àwòrán, @jidesanwoolu Gomina ipinlẹ Eko, Babajide Sanwo-Olu ti bawọn eeyan ipinlẹ Eko sọrọ lori ipaniyan to waye ladugbo Lekki nilu Eko.
Àwọn tí wọ́n gún un lọ́kọ̀ náà yóo rí i.
Oríṣun àwòrán, Others Àkọlé àwòrán, Ẹsun ipaniyan ni wọn fi kan Rabi Ismaila ni ọdun 2002 nitori pe o pa ọrẹkunrin rẹ, to si sọ ọ sinu omi.
Macron ni ile ijọsin naa wa lara itan ayanmọ ilẹ Faranse ni eyi ti ẹnikẹni ko le gbagbe.
Awọn ẹsun bi idigunjale, ati ifipabanilopọ ni wọn fi n kan awọn janduku naa.
Obafemi Awolowo University: Àwọn tó jí olùkọ́ wa gbé kò tíì sọ ohun tí wọ́n fẹ́ gbà
Ogbeni Serge Noujim to je oludari ile ise asoromagbesi Wazobia FM to wa nibi igbalejo naa soro lori atileyin tijoba ipinle Eko n se fun igbelaruge irinajo afe ati ase nipa ayeye lorisiirisii.
O ni iwadii n lọ lọwọ lori iṣẹlẹ naa nitori awọn afẹhọnuhan naa ti ti gbogbo opopona to wọ ilu Benini ti wọn ko si jẹ ki awọn eniyan kọja.
Olukọ lori eto Akomolede ati Aṣatoni ni Olalekan Ojelade ti ileewe Orisumibare Community High School, Ondo.
Ọwọ́ tẹ ọkunrìn tó n fi kẹ́míkà ṣe ìtọ́jú àìsàn jẹjẹrẹ àti ibà.
Awọn ajọ naa wá níbẹ̀ láti bójútó súnkẹrẹ fàkẹrẹ ọkọ náà, ati lati ri daju pe epo bẹntiroolu to wa ninu ọkọ naa ko da ijamba ina silẹ.
"''Wọn fẹ dá emi mi lé gbodo"" Ìgbé ti Gómìnà Fayoṣe fi bọ ẹnu rèé níbi tó ti n ba àwọn ọmọ ẹgbẹ òṣèlú PDP sọrọ níbi ìpolongo itagbangba ní ilé ìjọba Ekiti."
Nigeria at 59: Osinbajọ ní Ọlọrun ti ṣèlérí Nàìjíríà tuntun, TUC ní Nàìjíríà ti kùnà Oríṣun àwòrán, Instagram/Osinbajo Àkọlé àwòrán, Nigeria at 59: Osinbajọ ní Ọlọrun ti ṣèlérí Nàìjíríà tuntun, TUC ní Nàìjíríà ti kùnà Naijiria yoo pe ọmọ ọdun mọkandinlọgọta ni ọla!
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù RRS : Ẹwa gbe igbo yin 16 Ẹrẹ̀nà 2018 Oríṣun àwòrán, TWITTER/RRS LAGOS Àkọlé àwòrán, O to ọjọ mẹta ti RRS ti'n dẹgun le awọn to n ta ogun oloro nipinlẹ Eko Ikọ ọlọpa kogberegbe ilu Eko, RRS, ti polongo ki awọn to ni'gbo lọdọ awọn tabi eni to ba mo ẹni to lẹru igbo ko sọ fun wọn ki wọn wa gbẹru wọn.
Kudirat Shorẹmi ni orukọ rẹ ṣugbọn 'No Network' ni ọpọ ololufẹ ere tiata yoruba mọ wọn si.
Hassan ni lasiko ti awọn ṣe ipade pẹlu ijọba ilẹ Saudi ni wọn sọ fun awọn wi pe awọn eleto ilera awọn n ṣe eto ilẹra fun awọn eniyan, amọ awọn fẹ ri aridaju lati orilẹede toku wi pe wọn kapa arun naa ki wọn to gbe igbesẹ le e lori.
Àkọlé àwòrán, Ẹgbẹ́ Atunbi dá dúró gedegbe, ó sì ń ṣe igbe lárugẹ àṣà, kò fi ti òṣèlú àti ẹ̀sìn ṣe.
"Mọ́ngòrò nìkan ni wọ́n fún mi jẹ ní àhámọ́ ajínigbé -Olùdarí eré Kannywood Children's Day: Àwọn ọmọdé tó ń ṣe bẹbẹ láwùjọ Afíríkà ""Àlùfàá méjì wà lára àwọn mẹ́rin tó fi ipá bámilòpọ̀"" Ajimobi figbe ta, ó ní 'èmi kọ́ ló pa Ṣugar o!"
Ọlọ́run nìkan ló mọ bí ìrìnàjò ìfẹ́ ẹ̀dá á ṣe rí láyé, ọ̀dọ́ Aláàfin ní orí gbémí yà sí, ó sì tẹ́milọ́rùn- Olorì Aanu Alaafin bi ibeji l‘ẹẹmeji lọsẹ kansoso Wo ọ̀nà tí àwọn ‘ẹ̀lẹ̀ Daddy’ gbà dé ààfin Ọyọ Irú èpè wo ni Aláàfin Aolẹ ṣẹ́ fún ìran Yorùbá?
Opopona Marosẹ Lagos Abeokuta Expressway Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Super touch: Roller Blader ni mí láti ọdún mẹ́jọ sẹ́yìn 6.
Ọrọ̀ a máa tan eniyan jẹ; onigbeeraga kò sì ní wà láàyè pẹ́.
Ẹ yin OLUWA, Ọlọrun wa,ẹ jọ́sìn níbi àpótí ìtìsẹ̀ rẹ̀;mímọ́ ni OLUWA!
Kí OLUWA mú kí abẹ́ rẹ rà, kí ó sì mú kí ara rẹ wú.
Òṣìṣẹ́ àjọ FRSC méjì bọ́ sọ́wọ́ àwọn ajínigbé l'Ọsun Àgbáríjọ àwọn ajìjàgbara Niger Delta fẹ́ yapa kúrò ní Nàíjíríà Ọgbà ẹ̀wọ̀n ni Naira Marley yóò ti wo ìbúra Buhari ní May 29 Awọn onwoye ni ile iṣẹ orileede China yi ni ikede na doju le.
Àwọn ọmọ Ṣimei ni: Jakimu, Sikiri, ati Sabidi; 
Ọlọrun ti fi Midiani ati gbogbo ọmọ ogun rẹ̀ lé e lọ́wọ́.
Ìgbà tí a tún dé ibi kan a ri àwọn ọkùnrin mẹ́rin, ìgbà tí Èṣù dé ibẹ̀ o ní, ‘ẹ ṣe bi ẹ tíí ṣe,’ bí ó ti wí báyìí àwọn méta mú ẹni kẹrin ti wọ́n kó ọwọ́ rẹ̀ sẹ́yìn tí wọ́n fún un lókùn danin-danin.
Ninu atẹjade kan to fi sita nilu Abuja, ajọ NNPC rọ awọn onimọto lati maṣe tẹti si ahesọ kan to n lọ kaakiri pe ajọ NNPC n gbero ati fi kun owo epo.
Tubali Kaini yìí ni baba ńlá gbogbo àwọn alágbẹ̀dẹ tí ń rọ ohun èlò irin, ati idẹ.
Àti pé àwọn ọmọ ogun Nàìjíríà nàá ṣe bi i akọni pẹ̀lú bí wan ṣe fi bàálù kojú Boko Haram, kí wan tó na pápá bora.
Koda, wọn ni awọn agbofinro wọnyii maa n ni ki awọn obinrin tu aṣọ wọn silẹ lati woo boya wọn gbe oogun oloro tabi bẹẹkọ.
"Ìyà ń jẹ wá ló jẹ́ kí a daṣẹ́ sílẹ̀ - ẹgbẹ́ àwọn dókítà Seyi Makinde ṣí iléèwé padà ní ìpínlẹ̀ Oyo Èèyàn 573 ló lùgbàdì àrùn Coronavirus ní Naijiria ní Ọjọ́ Aje Ààrẹ Buhari kò sí nínú ewu àjàkálẹ̀ àrùn kankan tórí ẹ̀ṣọ́ rẹ̀ tó ṣẹ̀ṣẹ̀ dé sí Aso Rock-Garba Shehu O ni ""Yoruba ni lati ronu, a o ni olori mọ afi awọn akowojẹ""."
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Osun State Elections: Ilé ẹjọ́ sún ìgbẹ́jọ́ Adeleke síwájú 7 Èbibi 2019 Àkọlé àwòrán, Adeleke Ile ẹjọ ti wọn ti gbẹjọ oludije ipo gomina nipinlẹ Oṣun labẹ asia ẹgbẹ oṣelu PDP, Sẹnetọ Ademọla Adeleke ti sun ẹjọ rẹ siwaju di ọjọ kẹrinlelogun oṣu kẹfa ọdun 2019.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Onímọ̀ nípa ìhùwàsí: ibi a gbé dàgbà níi ṣe pẹ̀lú ìhùwàsì 4 Èbibi 2018 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Aisan ọpọlọ ni ki eniyan o maa gbonara nigba ti ọba ni ija pẹlu olubagbe rẹ Afurasi obinrin agbẹjọrọ kan ti gun ọkọ rẹ pẹlu ọbẹ titi tó fi papoda, o tun rẹ́ nkan ọmọkunrin rẹ̀ lée lọwọ ni agbegbe Diamond Estate, Ajah ni ipinlẹ Eko.
4 Ọ̀wàrà 2019 Oríṣun àwòrán, MC Oluomo/Facebook Musiliu Ayinde Akinsanya ti gbogbo eniyan mọ si MC Oluomo ni wọn ti fi jẹ oye ọga awọn awakọ NURTW ni Ipinlẹ Eko.
Ló bá mú 'Ṣeyi' látara Oluwaṣeyi àti 'Law' látara Lawrence.
”O tesiwaju pe“A o tun bere ipade naa laipe lati tesiwaju ninu ijiroro naa.
Èyí yàtọ̀ sí owó ìpolongo, tí ènìkẹ́ni bá fẹ́ fèróńgbà hàn láti dupò ààrẹ, ó di dandan kí ó kọkọ náwó kí ẹgbẹ́ to díbò yan an lati mọ̀ bóyá òun ní yóò sojú ẹgbẹ́ náà tabí bẹ́ẹ̀ kọ́.
” Wọ́n dá wọn lóhùn pé, “Samsoni, ọkọ ọmọ ará Timna ni; nítorí pé àna rẹ̀ fi iyawo rẹ̀ fún ọ̀rẹ́ rẹ̀.
Ramadhan tọdun 2019, pe esin Islam jẹ esin alaafia , ki won si maa ni ifarada
Wo ohun mẹ́wàá tó yẹ kí o mọ̀ tí o bá fẹ́ lọ fún ìsinmi lẹ́yìn Covid 19 Wo bí o ṣe lè ṣe eré ìdárayá tí yóò fún ọ ní adùn àti okun fún ìbálòpọ̀ DSS ti fi ẹ̀sọ́ àbò abẹnugan ilé ìgbìmọ̀ asofin tó pa fẹ́ndọ̀ l'Abuja sátìmọ́lé Wọ́n ti rí òkú Alága ẹgbẹ́ APC ní Nasarawa tí àwọn agbébọn jí gbé lọ́jọ́ Satide Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Fídíò, Oba Adedokun Abolarin ti Oke Ila: Ó ya ọ̀pọ̀ tó súnmọ́ mi lẹ́nu bí mo ṣe ń kọ́ àwọn akẹ́kọ̀ọ́ pẹ̀lú ipò Ọba23 Bélú 2020 Fídíò, Akọ́mọlédè àti Àṣà lórí BBC Yorùbá: Kọ́ síi nípa iṣẹ́ tí oúnjẹ ń ṣe lára níbí24 Bélú 2020 Fídíò, The New Pandemic: Kíni àwọn onímọ̀ sáyẹ́ńsì ń sọ nípa rẹ̀?
” “Won yoo gbe isẹ fun awon agbasẹse màrúndínlógún lati pese eso ọgbin, oogun kemika fun
Ayé ati ọ̀run sálọ fún un, a kò rí ààyè fún wọn mọ́.
Àwọn ikọ̀ Bokoo Haram àti Islamic State ni iwọ òòrun Afrika (ISWAP) tún le lo ìṣẹ̀lẹ̀ náà láti kọlu àwọn ènìyàn Chad, Niger ati Nàijíríà.
Bakan naa lo tun ni isede ti bẹrẹ lati aago mẹsan alẹ si Marun owurọ, to si n rọ awọn ẹlẹgbẹjẹgbẹ ajafẹtọ ilu ati ti oloselu lati fi ọwọ sowọpọ pẹlu ikọ aditẹgbajọba naa, ki wọn lee seto idibo to pegede, ti yoo gbe ijọba silẹ fun alagbada.
Bo tilẹ jẹ pe siimu kan ṣoṣo ni ajafẹtọ ẹni naa n lo, o ni oye owo ti oun n nna lori ẹrọ ibanisọrọ rẹ loṣu le ni ẹgbẹrun un lọna ọgbọn naira.
 Èyí tí kò bá ní apor gégé bí àfikún ni òrò-ìse àìgbàbò .
"Kò sí àyè fún fíìmù eré ìfẹ ṣíṣe ni Kannywood mọ́ ""Àlùfàá méjì wà lára àwọn mẹ́rin tó fi ipá bámilòpọ̀"" Ayẹyẹ ọdún ìbejì dùn, ó lárinrin nílùú Igbó-ọrà Iya awọn naa ni ko rọrun lati kan maa dagba nilẹ Gẹẹsi lai ni iwuri ibi ti o ti ṣẹ wa gan."
Akonimoogba iko agbaboolu Everton teleri, Ronald Koeman ni orile-ede Netherland ti yan bayi gege bi akonimoogba agba tuntun iko ohun.
Femi Fani-Kayode @realFFK daro pé òun ti pàdánù ọrẹ ogójì ọdún táwọn di jọ lọ sílè ẹ̀kọ́ fasiti Cambridge.
Gómìnà ìpínlẹ̀ Eko Babajide Sanwo-Olu kéde ọ̀rọ̀ yìí pé, lẹ́yìn ti àwọn tí ọ̀rọ̀ kan ti fikùnlukùn ni àwọn pínnu láti ṣilèkùn ilé iwé ní ọjọ kẹta, oṣù kẹjọ, ọdun yii.
26 Agẹmo 2020 Kaduna killings: Afurasí mẹ́jọ ti wọ gbaga agbófinró nítorí ìpànìyàn Gúúsù Kaduna11 Ògún 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Ọmọdé ológun bíi 900 ti gba ìtúsílẹ̀ - UNICEF Ọlọ́pàá tó n gba rìbá sọ pé 'Ọlọ́run gan fara mọ́ olè jíjà' Naira Mailey àti ikọ̀ rẹ̀ tí wà látìmọ́lé EFCC Bukola Saraki kò kọjá òfin - EFCC Sàǹgbá fọ́!
World Day for Cultural Diversity: Bí àwọn òṣìṣẹ́ Ìpínlẹ̀ Oyo ṣe f'aṣọ ìbílẹ̀ dárà lati gbé àṣà lárugẹ
Babatunde, lasiko ti wọn gbe de ọgba ileẹjọ, wọ agbada alawọ eweko, ati obinrin kan ninu ijọ rẹ, ti wọn jọ n jẹjọ, wa laarin awọn osisẹ ọgba ẹwọn to gbe wọn wa sile ẹjọ.
Iroyin to n ja rain lori ayelujara ni pe o ṣeeṣe ki awọn ọmọogun ikọ Naijiria to le ni ọọdunrunlelaadọta(350) kọ iwe fi ipo wọn silẹ.
Àkọlé àwòrán, Kika esi idibo ti bẹrẹ ni pẹrẹwu ni Rivers Ajọ INEC ni atundi idibo yoo waye lawọn ẹkun ti awọn ba ti wọgile esi idibo ibẹ lataari iwa ipa to ṣẹlẹ.
O ni ọpọ araalu ni wọn n dibọn pe awọn ko mọ nitori wọn ko faramọ igbesẹ Disco lori ọrọ tariifu ina tuntun.
Iroyin so pe eto idibo ti bere ni pẹrẹu ni  jake jado orile ede  Naijiria bayii.
Bákan náà lo sísọ lójú rẹ pé, ìjọba àpapọ̀ tí ń wá ọ̀nà láti gba nọ́mbà idamọ BVN aráàlú tó tọ́ láti gba owó náà, èyí tí kò ní jẹ ki àṣírí bí wọn ṣe ń pín owó náà bo fún aráyé.
Ẹbẹ ni mo ṣaa n bẹ ki wọn maa binu si mi.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Awọn aworan to ṣafihan aini bayi pọ kaakiri awọn ilẹ Afrika Orileede South Afrika ati Namibia lewaju ninu ilakaka yii, ti Naijiria si ru póò nilẹ Afrika ati lori akasọ agbaye.
Wọn yóo fi idà wọn rọ ọkọ́,wọn yóo sì fi ọ̀kọ̀ wọn rọ dòjé.
O ti fẹrẹ to ọsẹ kan bayii ti iye eniyan to n lugbadi arun Coronavirus ti n le ni 1000 ní ojoojumọ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Lockdown updates: Naira Marley gbóríyìn fún Jude Chukwuka pẹ̀lú #1 míliọnù Awọn igba ti wọn ti bọ sọwọ ọlọpaa Ninu oṣu Kẹsan, ọdun 2019, ni iroyin jade pe ọwọ ọlọpaa titẹ olori ẹgbẹ naa, Tobi Akinbayo a.
Gomina ipinlẹ Katsina, Aminu Masari ati igbakeji rẹ, Alhaji Mannir Yakubu pẹlu awọn to wa ki aarẹ kaabọ si ile ni papakọ ofurufu ipinlẹ naa.
Nígbà náà ni Jobu dá OLUWA lóhùn, ó ní:
Ìdílé kan gbé ilé iṣẹ́ ọkọ̀ òfurufú lọ ilé ẹjọ́ lẹ́yìn tí wọ́n léwọ̀n dànù nínú ọkọ̀ pé ara wọ́n ń rùn
Bakan naa lo rọ awọn ọmọ Naijiria lati dibo fun Mike ko le wọle.
Ọ̀wọ̀n ìkùukùu náà sì wà láàrin àwọn ọmọ ogun Ijipti ati àwọn ọmọ ogun Israẹli, ìkùukùu náà ṣókùnkùn dudu títí tí gbogbo òru ọjọ́ náà fi kọjá, wọn kò sì súnmọ́ ara wọn.
Ọ̀sun Election: Akin Ogunbiyi àti Moshood Adeoti kọ èsì ìbò
Bi o tilẹ jẹ pe ọjọ pẹ ti owo ẹru ti kasẹ nilẹ, sibẹ iyan ogun ọdun tun jo awọn idile to kopa ninu owo ẹru lọwọ, Paapaa lasiko yii ti ibinu araalu si tun dìde si wọn lẹẹkan si nitori adulawọ kan, George Floyd, ti Ọlọpa kan sekupa ni Amẹrika.
”Minisita so pe : “Mo dupe lowo  awọn  AMG ti o dari wa lati se idunna-dura ati  awọn  to n tọ wa sọna lati se aseyege lori  awọn  ipenija ti a dojukọ.
Ominu n kọ ọpọ eeyan ni Naijiria tori ọpọ gbagbọ pe ko si ẹni to mọ ohun to ṣẹlẹ dunjudunju lori ajakalẹ aarun covid-19.
"Dìbò fún un níbí Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Osinbajo yẹ́ Woli Arole sí níbi ìṣíde ""The Call"" Awọn lọbalọba ati awọn oloye nla nla ni ilu Ọwọ, Oloye Jamiu Ekungba ati Ọlanrewaju Famankinwa lo kede iku Ọlọwọ naa."
 kíkọ ́ ni mímọ ̀ ni ọ ̀ rọ ̀ eré yìí .
Ẹ gbọ ohun ti o wi siwaju sii ninu fọran yii: Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ifọrọwanilẹnuwo pẹlu Kayode Esuola Ọpọ aawọ le ṣe okunfa ipinya APC Comrade Kola Ibrahim to jẹ awoye ọrọ oṣelu ni bayi ti ibo 2019 ti'n sunmọ oriṣiriṣi ni yoo ma ṣele ni gbagede oṣelu.
Ọ̀rọ̀ yìí ló díá f’Álákọ̀wé lọ́jọ́ òní.
Ṣugbọn kò fi ipá kó àwọn ọmọ Israẹli ṣiṣẹ́ bí ẹrú, ṣugbọn ó ń lò wọ́n bíi jagunjagun, òṣìṣẹ́ ìjọba, balogun kẹ̀kẹ́ ogun, ati àwọn ẹlẹ́ṣin rẹ̀.
Gẹ́gẹ́ bi òwe Yorùbá “Ọ̀kọ́lé kò lè mu ràjò”, bẹni kò si bi ẹni ti ó kúrò ni ilé ti lè gbé ilé dáni lọ si ilú nlá.
bi orile-ede ti o kun fun asa, eya ati esin, ati fojuri rogbodiyan lorisirisi, ti
OLUWA ní,“Wo iranṣẹ mi, ẹni tí mo gbéró, àyànfẹ́ mi, ẹni tí inú mi dùn sí.
"Èmi kìí se olólùfẹ̀ẹ́ Dino, sùgbọ́n bí wọn se mú Dino dà bíi ìgbà tí wọn mú ìjọba tiwantiwa.
Ìwọ ni mo fi ẹ̀mí mi lé lọ́wọ́,o ti rà mí pada, OLUWA, Ọlọrun, olóòótọ́.
Dokita kan ti ko si panpẹ awọn ọlọpaa nipinlẹ Gujarat lorileede India tori pe o m'ọti yo nigba to ṣe iṣẹ abẹ fun aboyun kan.
Tí wọ́n bá fi ìwọ̀n ọba wọn èyí tí wọ́n bá gé lára irun rẹ̀, a máa tó igba ṣekeli.
Will they look for a director of football?
”Gomina Abubakar wa dupẹ lowo  gbogbo awon omo ipinle  Bauchi  fun isowọpọ ati atileyin ti won se fun ijọba rẹ,
Òun gangan kọ́ ló kọ́kọ́ ṣẹ̀dá irúfẹ́ ọ̀nà àti kàwé báyìí o.
N óo bá wọn dá majẹmu ayérayé, pé n kò ní dẹ́kun ati máa ṣe wọ́n lóore.
Ki gbajumọ afilusọrọ yii to rekọja silẹ Amẹrika lọdun 1985, o ti lu ilu lẹyin gbajugbaja akọrin Juju nni, Ebenezer Obey ri.
oloye razak akanni okoya ni won bi ni ipinle eko ni ojo kejila osu kini , odun 1940 ( 12 january 1940 ) .
Church of Satan: ọ̀rọ̀ Femi Fani-kayode fàbínú àwọn ọmọ ìjọ yọ
Gbà wá, OLUWA, Ọlọrun wa,kí o sì kó wa kúrò láàrin àwọn orílẹ̀-èdè mìíràn,kí á lè máa fi ọpẹ́ fún orúkọ mímọ́ rẹ,kí á sì lè máa ṣògo ninu ìyìn rẹ.
Àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ bi í ní ìtumọ̀ òwe yìí.
Nigba ti a ba ti ni oro lati so, a o je ki eyin akoroyin mo nipa re.
Àwọn fèrèsé aláṣìítì, tí wọ́n gbẹ́ igi ọ̀pẹ sí lára, wà lára ògiri ìloro náà lẹ́gbẹ̀ẹ́ kinni keji.
Amọṣa ni idajọ ti ile ẹjọ kotẹmilọrun gbe kalẹ ni ọjọ ẹti, yatọ si pe ile ẹjọ naa wọgile ẹjọ rẹ, o tun ni ki Sẹnets Omo-Agege ati Waive o san ẹgbẹrun lọna ọọdunrun naira gẹgẹ bii owo gba mabinu.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Ẹlẹ́ẹ̀kẹjọ t'óyún máà bàjẹ́ lára mi ni mo tó rí àànú gbà' Amọ o sọ fun Adajọ Olusegun Odusola to n gbọ ẹjọ naa pe ẹlẹrii mẹta ni olujẹjọ naa yoo ko yọju sile ẹjọ ọhun lana.
Eto idibo tete bere ni agbegbe
Àwọn yìí ni ẹlẹ́tàn ati alátakò Kristi.
Bakan naa ni wọn fikun pe, kii ṣe gbogbo wọn ni ikọ Boko Haram, amọ lara wọn jẹ awọn ti wọn jigbe fun ọpọlọpọ ọdun, ti wọn si kan an nipa fun wọn, lati ma a ba wọn jale.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Èrò àwọn ọmọ Naijiria ṣọ̀tọ̀ọ́tọ̀ lórí ohun tó n wáyé l'ágbo òṣèlú 7 Ògún 2018 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 15 Ògún 2018 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Tinubu ni 'ki awọn to n gbimọ ìkà jawọ, nitori pe 'ko ni ṣeeṣe fun alangba lati ba igala ja; mo ki ara mi kú iṣẹ́ ni Eko' Tinubu: kí ló dé ti Ọbasanjọ kò ṣe fi ìpìlẹ̀ rere lélẹ̀ lásìkò rẹ̀?
Kò sí ẹni tí ó mọ ẹni tí Ọmọ jẹ́, àfi Baba.
 leyin re o tun di ojogbon ninu ida litireso ati ikowe ni fisk university .
Ìwé àwọn wolii ni ó ṣe ìṣípayá ohun tí ó fara pamọ́ gẹ́gẹ́ bí àṣẹ Ọlọrun ayérayé, pé kí gbogbo àwọn orílẹ̀-èdè gbọ́, kí wọ́n mọ̀, kí wọ́n sì gbà.
Ibukun ni fún ẹni tí ó bá súre fún Israẹli,ẹni tí ó bá sì gbé Israẹli ṣépè, olúwarẹ̀ gbé!
awon onise ibi ohun ninu, sugbon ti won ba ko lati siwo ninu ise ibi won, aare
Oshodi yii kii si ṣe orukọ arosọ lasan, tí wọn kan fi sọ adugbo kan; amọ, o jẹ orukọ akinkanju ẹda kan to ṣe gudu-gudu meje ati ya ya mẹfa si idagbasoke ilu Eko, Idi si ree to fi yẹ ka mọ nipa akinkanju ọkunrin naa.
Ọrọ̀ tí a fi ìkánjú kójọ kì í pẹ́ dínkù,ṣugbọn ẹni tí ó bá fi pẹ̀lẹ́pẹ̀lẹ́ kó ọrọ̀ jọ yóo máa ní àníkún.
Ẹlẹ́ṣin kan lọ pàdé rẹ̀, ó ní, “Ọba wí pé, ṣé alaafia ni?
“Má wọ ilé tí wọ́n ti ń ṣọ̀fọ̀, má lọ máa kọrin arò, tabi kí o bá wọn kẹ́dùn, nítorí mo ti mú alaafia mi ati ìfẹ́ mi ati àánú mi kúrò lọ́dọ̀ àwọn eniyan wọnyi.
Gẹ́gẹ́ bí ọ̀pọ̀lọpọ̀ nínú àwọn olówó ti máa ń ṣe, owó a máa ru bo ẹlòmíràn lójú bí omi òkun a sì máa pa ẹlòmíràn bí ẹmu, owó a máa mú kí àwọn ẹlòmíràn gbàgbé ibi tí àwọn tí dìde, dípò kí wọ́n sì máa fi owó wọn yin Ẹlẹ́dàá wọ́n á bẹ̀rẹ̀ sí tàpá sí ẹni tí ó dá wọn.
Nítorí ìwọ̀nyí, nígbà tí o di ẹni àádọ́rin ọdún, Ọlọ́run Ọba pínnu pé ó níláti kúrò nínú ìbànújẹ́, ayé kí ó máa jẹ ìgbàdùn ọ̀run, òní yìí nìkan ṣoṣo ni ó wáá kí mi, gẹ́gẹ́ bí mo ti sọ fún ọ lẹ́ẹ̀kan, kò ní í pẹ́ padà lọ sí òde ọ̀run.
Bí àwọn Amẹrika bá dìbò ààrẹ, ǹkan tí ó maa n ṣẹlẹ̀ gàn an ni pé wọ́n ti yóò dìbò yhan àwọn ti yóò lọ sojú wọn ní kọ́lẹ̀jì ìdìbò.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ọdún 1940 ni wọ́n ti ń sin ọ̀ọ̀nì ilé Delesolu ní Ìbàdàn Kò sáyè ìgbafẹ́ mọ́ fáwọn àgùnbánirọ̀ DBanj gbé àwo tuntun jáde lẹ́yìn ikú ọmọ rẹ̀ Ìṣẹ̀lẹ̀ Bakana: àwọn tórí kó yọ fẹ́ bẹ̀rẹ̀ ètò ìrànlọ́wọ́ Oshiomọlẹ ń se bi adìẹ tí ojò pa, tó ń sunkún kiri- Saraki Fayose: Kàkà kí n darapọ̀ mọ́ APC, màá.
Ṣé yìnyín òkè Lẹbanoni a máa dà ní pàlàpálá Sirioni?
Ṣugbọn Jesu dá a lóhùn pé, “Ó wà ní àkọsílẹ̀ pé, ‘Kì í ṣe oúnjẹ nìkan ni yóo mú kí eniyan wà láàyè, bíkòṣe nípa gbogbo ọ̀rọ̀ tí Ọlọrun bá sọ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù OsunElection 2018: EU, US, Uk ní ominú ń kọ òun lórí àbọ̀ ìròyìn nípa àtúndì ìbò Ọ̀sun 15 Ìgbé 2018 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 28 Owewe 2018 Ajọ isọkan orilẹede nilẹ Yuroopu, EU, awọn asoju orilẹ-ede Amẹrika ati Ilu Ọba, UK, ti sọ pe awọn n kọminu lori atundi ibo to waye nipinlẹ Ọsun.
0 30 Ilu Vatican 0 0.
Odun 1980 ni wọn kọkọ gba alakọkọ nigba ti awọn ati Algeria jọ na an tan bi owo.
Idiagbon dara pọ mọ ile ẹkọṣẹ ologun tilẹ Pakistan lọdun 1962, to si gba oye imọ ijinlẹ akọkọ ninu imọ ọrọ aje, Economics lọdun 1965.
Arole Oodua wa jẹjẹ pe oun atawọn ọba alaye yoku ti setan lati fọwọ sowọpọ pẹlu ijọba, ti wọn si n beere fun afikun eto aabo latọdọ ijsba apapọ, ki wọn lee daabo bo awọn eeyan wọn lọwọ awọn kanda inu irẹsi, o si seese ki wọn ma jẹ ẹya Fulani.
eniyan se jade lati wa dibo yii, paapaa julo nibi ti oun naa ti dibo rẹ.
’ rèé Afọnja, ẹni tó finú wénú ní Ilọrin, àmọ́ tó jẹ iwọ Ẹfunsetan Aniwura, obìnrin tó ju ọkùnrin lọ Ẹ kọ́ nípa ohun tí Yorùbá ń pè ní Àrígiṣẹ́gi Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí kan sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
Samuẹli kúrò ní Giligali, ó lọ sí Gibea ní Bẹnjamini.
Oun pẹlu ti kede adura ati awẹ ọlọjọ meje lati koju arun yii eleyi to ti da gbogbo agbaye wolẹ soju kan naa to si ti ran ọpọ lọ sọrun ọsangangan.
Tinubu ni niwọn igba ti ara awọn ọmọ ẹgbẹ oselu alatako naa ko balẹ mọ, o yẹ kawọn ọdọ ninu ẹgbẹ APC bẹrẹ si ni se koriya lati ri daju pe wọn tẹnpẹlẹ mọ eto koriya ti wọn n se fawọn ọdọ lati dibo.
Ewe, iko agbaboolu orile-ede Germany tun gba iyi won pada pelu bi iko ohun se kopa si ninu ifigagbaga naa, leyin ti iko ohun ja kuro nipele kinni ninu idije boolu agbaye naa ti o waye lorile-ede Russia.
Saaju la ti mu iroyin wa fun yin pe ibẹrẹ ọṣẹ yii ni iroyin kan jade pe ayẹwo ti fihan pe Ajimobi ko ni aarun coronavirus.
26 Òkùdu 2019 Kii ṣe ojulowo ọmọ ẹgbẹ afẹnifẹre lo lọ si Abuja lọdọ Buahri -Odumakin Lẹyin ti iroyin sọ pe Aarẹ Muhammadu Buhari ti ṣe ipade pẹlu awọn ọmọ ẹgbẹ Afẹnifẹre, agbẹnusọ ẹgbẹ naa, Yinka Odumakin ti ni awọn ayederu ọmọ ẹgbẹ Afẹnifẹre lo lọ ibi ipade naa.
Laipẹ yii ni Oloye Adebanjo pẹtu si ija to wa laarin awọn mejeeji nile rẹ ti Obasanjo ati Adams si sọ ohun to n dun wọn nibi ipade ọhun.
Anfaani wà fun yín pé kí irú ẹni bẹ́ẹ̀ ṣe é ní ọjọ́ kẹrinla oṣù keji.
Lara ẹsun ti wọn tun ka si Waziri l'ẹsẹ ni pe, o yọnda awọn gomina tẹlẹ ti ajọ naa fi ẹsun ibajẹ kan.
Ṣugbọn oniruuru iṣoro lo n koju awọn agbabọọlu obinrin lorilẹede Naijiria.
Awakọ mii ni koda, awọn ajinigbe naa yinbọn mọ ọkọ oun, bẹẹ lo ni oun ko awọn ọmọ oun si ẹyin ọkọ, ta si ri oju ibọn lara mọto rẹ.
Abúlé Ọjà wà ní Ìjọba ìdàgbàsókè Yaba (Yaba LCDA) ní Ìpínlẹ̀ Èkó.
Ìgbé ayé Abiola Ajimobi nínú àwòràn pẹ̀lú àwọn ǹkan tó ṣẹlẹ̀ Ìjọba Nàìjíríà ti parí ìwádìí lórí àgbo Covid-Organics ti Madagascar kó ránṣẹ́ sí i 'Kò tọ̀ọ́ kí olórí Nàìjíríà tó bá ní coronavirus gba ìtọ́jú ní ìlú tí kìí ṣe tirẹ̀' Koda, o ti ṣe ku pa awọn kan gomina ipinlẹ Oyo tẹlẹ, Abiola Ajimobi, ati olori awọn oṣiṣẹ fun Aarẹ Muhammadu Buhari, Abba Kyari.
Gege bi atejade kan latodo agbenuso  igbimo ajo awon orile-ede alajo sowopo nile Africa (ECOWAS) Mr Paul Ejime ninu igbimo ajo eleto idibo, loruko awon omo-egbe yoku, won fenuko lati maa sise po pelu awon ti oro kan lorile-ede naa, ati lati sepade ifenuko laarin ara awon ti oro kan, saaju ati leyin idibo.
Oba Samuel Adeniran Asusumasa Atewogboye II: Alaaye ti Efon Alaaye tí wọ́n yẹgi fún lọ́dún 1949
Ati ẹgbẹ agbabọọlu ati akọnimọọgba wọn, Amuneke jọ tọwọ bọwe adehun lati fopin si iṣẹ rẹ gẹgẹ bi TFF ṣe fi si oju opo ayelujara wọn.
“Ta ni ẹ óo fi mí wé?
Aarẹ Buhari ni Jonathan jẹ olori ti ifọkansin rẹ yoo maa jẹ iwuri fun ọpọ irandiran to n bọ lorilẹede Naijiria.
Alaye re e lori ipinlẹ ti awọn ẹni tuntun naa ti wa: Eko-254 Abuja-29 Jigawa-24 Edo-22 Oyo-15 Rivers-14 Kaduna-11 Borno-6 Kano-3 Plateau-2 Yobe-2 Gombe-2 Bauchi-2 Ondo-1 Ènìyàn 182 ni àjọ NCDC kéde pé ó tún ṣẹ̀ṣẹ̀ ní Covid-19 ní Nàìjíríà Oríṣun àwòrán, Ncdc Awọn ti aarun Covid-19 mu l'orilẹ-ede Naijiria ti pọ si, lẹyin ti esi ayẹwo ti ajọ to mojuto ajakalẹ aarun ni Naijiria, NCDC kede fihan pe eeyan 182 lo tun ti ni aarun naa.
 rárá jẹ ́ òdi bẹ ́ ẹ ̀ ni .
Nítorí igbagbọ ni a fi ń gbé ìgbé-ayé wa, kì í ṣe ohun tí à ń fi ojú rí.
Ìwọ ni o pa gbogbo ààlà ilẹ̀ ayé;ìwọ ni o dá ìgbà òjò ati ìgbà ẹ̀ẹ̀rùn.
Bakan naa, ileesẹ eto ilera ni Cape Verde ti kilọ fawọn araalu lati mase se alabapin iroyin to n fọnrere pe ewe kan ti wọn fi n se ọbẹ lee wo Coronavirus san.
Oba Adetunji tun tenumo pe oun ko tile mo ohun ti o faa
Ṣùgbọ́n ní báyìí, àwọn èèyàn ti ń lo ọgbin oyinbo pineapple láti fi ṣe ọtí líle nínú ilé.
Abadofin ọhun ti wọn pe ni Control of Infectious Disease Act"" ni agbẹnusọ ile naa, Femi Gbajabiamila fi lede lọjọ kejidinlọgbọn, oṣu kẹrin ọdun 2020, ṣugbọn ọrọ naa ti di fa ki n fa lori itakun agbaye."
"Victor ni""mo gbagbọ pe lasiko iwadii ti igbimọ ba n ṣe wọn yoo pe ọmọbinrin naa fun ifọrọwanilẹnuwo leyii ti ọpọlọpọ kan mọ gbọyii sọyii lasan nipa iṣẹlẹ naa""."
Mò ń sọ fun yín pé, bí kò tilẹ̀ fẹ́ dìde kí ó fún ọ nítorí o jẹ́ ọ̀rẹ́ rẹ̀, ṣugbọn nítorí tí o kò tijú láti wá kan ìlẹ̀kùn mọ́ ọn lórí lóru, yóo dìde, yóo fún ọ ní ohun tí o nílò.
Nígbà tí wọ́n sọ̀kalẹ̀ wá sinu ìlú láti ibi ìrúbọ náà, wọ́n tẹ́ ibùsùn kan fún Saulu lórí òrùlé, ó sì sùn sibẹ.
Ẹ kí àwọn ará ilé Nakisu tí wọ́n jẹ́ onigbagbọ.
Amọ ṣa, Kunle Olajide ti ni awọn to korajọ yọ oun kii ṣe ọmọ ẹgbẹ tootọ fun idi eyi wọn ko lagbara lati yọ oun.
Ǹjẹ́ òkú pàápàá kò ní jí dìde?
Nibayii, ajọ agbaye UNESCO ti kede Ọdun naa gẹgẹ bii ara awọn ọdun aṣa manigbagbe lagbaye.
“Ní ọjọ́ náà, n óo gbé alágbára kan dìde ní Israẹli, n óo mú kí ìwọ Isikiẹli ó sọ̀rọ̀ láàrin wọn.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Oniru of Iru land: Onírù tuntun Oba Abdulwasiu Gbolahan Lawal gba ọ̀pá àṣẹ 7 Òkùdu 2020 Oríṣun àwòrán, Twitter/Babajide Sanwo-Olu Oniru ti Iru nipinlẹ Eko, Oba Abdulwasiu Omogbolahan Lawal, Abisogun ll ti gba ọpa aṣẹ gẹgẹ bi Oniru ikẹẹdogun.
Awọn dokita ni iru igbẹ yii lo dara ju.
Doris Simon: Oríṣun àwòrán, Doris Simon Ilumọọka oṣere bìnrin alawọ pupa yii lo wa lati agbegbe Okpella ni ẹba ilu Benin.
Ó bá dìde ní ọ̀gànjọ́ òru, ó wá jí ọmọ tèmi gbé ní ẹ̀gbẹ́ mi nígbà tí mo sùn lọ, ó tẹ́ ẹ sí ọ̀dọ̀ ara rẹ̀, ó sì tẹ́ òkú ọmọ tirẹ̀ sọ́dọ̀ mi.
Mo ti rí i gbangba lónìí pé, ìbá dùn mọ́ ọ ninu, bí gbogbo wa tilẹ̀ kú, tí Absalomu sì wà láàyè.
Liverpool fagba han Totenham A da ọjọ, ọjọ pe, a da igba, oni ọjọ kinni, oṣu kẹfa ni a o mọ ẹni ti yoo sunkun ati ẹni ti yoo gba ife UEFA Champions League ti saa yii laarin Liverpool ati Tottenham.
Gẹ́gẹ́ bí ó ti sọ fún wa, nígbà tí ó ń fẹ́ẹ́ lọ bu omi náà, ó yà ẹ̀wù tí àwọn òkú máa ń wọ̀ kí wọ́n tóó lè lo sí òde ọ̀run lọ́wọ́ Ikú eléyìínì náà ló sì wọ̀ kí ó tóó di pé ó lè dé etí odò abàmì yìí tí ó ṣàn la òde ọ̀run kọjá.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìjàmbá iná l'Eko: Ọkọ̀ aképo gbiná ní òpópónà Eko sí Badagry 28 Agẹmo 2018 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 2 Ọ̀wàrà 2018 Oríṣun àwòrán, lagos state police command Àkọlé àwòrán, Aago marun aarọ ni ọkọ naa gbina ni opopona Eko si Badagry Ọkọ̀ aképo kan ti bú gbàmù ní òpópónà Eko sí ìlú Badagry lówurọ̀ ọjọ́ ìṣẹ́gun.
Ṣe adehun wa abi ko si?
kede oruko  awon alamojuto ti yoo maa fun
Ilẹ̀ wọn lọ ní apá ìlà oòrùn títí dé àtiwọ aṣálẹ̀, ati títí dé odò Yufurate, nítorí pé ẹran ọ̀sìn wọn pọ̀ ní ilẹ̀ Gileadi.
Wọ́n wí fún ara wọn pé ọba Israẹli ti lọ bẹ àwọn ọmọ ogun Hiti ati ti Ijipti láti wá bá àwọn jà.
Awon asoju orile ede to je komisona miran ti won fun Aare Buhari niwe itewogba lati orile-ede won ni: Komisona ti Republic of The Philippines, Abileko Shirley Ho-Vicaria ati Komisona Republic of Uganda, iyen Nelson Ocheger.
Nígbà èwe rẹ̀, àwọn ọkunrin bá a lòpọ̀, wọ́n fọwọ́ pa á lọ́mú, wọ́n sì tẹ́ ìfẹ́kúfẹ̀ẹ́ wọn lọ́rùn lára rẹ̀.
Ìtàn tó wà nídi òwe ‘Sebótimọ Ẹlẹ́wà Sàpọ́n’ Taiwo Akinkunmi, ọmọ Ibadan tó ya àsìá Nàíjíríà Ogedengbe Agbógun Gbórò, Akọni tó ń dẹ́rù ba ikú.
O ni awọn yoo si jọ wọde lọ si ọọfisi Ọga agba ileeṣẹ ọlọpaa, lati fun un ni iwe ẹsun lori ọrọ Sẹnetọ Elisha Abbo ti wọn lo lu arabinrin kan nile itaja kan ibalopọ l'Abuja.
Ta ni SS ko gbudọ fẹ laelae?
Ẹ wá sọ́dọ̀ ẹni tíí ṣe òkúta ààyè tí eniyan kọ̀ sílẹ̀ ṣugbọn tí Ọlọrun yàn, tí ó ṣe iyebíye lójú rẹ̀.
Yemi Osinbajo: Ìgbákejì Ààrẹ tó gbọ́ nípa ẹ̀!
Iwe naa lo n ke si awọn orilẹ-ede agbaye to wa ninu ajọ Commonwealth, lati fi 'iya' jẹ awọn olori Naijiria gẹgẹ bi ibawi, fun ẹnikẹni ninu wọn to lọwọ ninu titẹ ẹtọ ọmọniyan loju, gẹgẹ bi ofin ajọ naa ṣe sọ.
Awon eniyan meji padanu-emi won latati bi won se fara pa, bakan naa ni won gbe awon eniyan bi ogoje digba-digba lo sile-iwosan ati awon ile-iwosan ibile.
Yemi Osinbajo: Ìpínlẹ̀ Ondo lè bọ́ Naijiria pẹ̀lú ohun àlùmóọ́nì rẹ̀
Ina lo n jo soke yii, ti oju ọrun dudu lai rọ ojo.
Àwọn ọlọ́ṣà ni wọ́n pa àwọn ológun ikọ́ kò-gbéregbé Akpan Apatuma tó ń gb'ógun tí ìkọ́lú àwọn ọ́lọ́ṣà l'agbegbe náà.
Àkókò tí a ń sọ̀rọ̀ rẹ̀ yìí, Èṣù kò ì tí ì ní gbòǹgbò ní òde ayé, òun wà bí ẹ̀dá pàtàkì ní òde ọ̀ruin.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Oyo Police: Àwọn àkẹ́kọ̀ọ́ náà jẹ́wọ́ pé ọmọ ẹgbẹ́ òkùnkùn Ẹyẹ ni àwọn 13 Òkùdu 2019 Oríṣun àwòrán, @PoliceNG Ọwọ palaba awọn akẹkọ mẹẹdogun nile ẹkọ fasiti imọ ẹrọ Ladoke Akintọla, LAUTECH, nilu Ogbomọsọ ti segi lori ẹsun pe wọn digun jale, sise ẹgbẹ okunkun ati iwa agbodegba fun ọdaran.
Neo Oríṣun àwòrán, BIG BROTHER NAIJA Neo naa ko kawọ gbera lori eto Big Brother Naija Lockdown.
Ọpọlọpọ ni àwọn tí ń sọ kiri pé,Ọlọrun kò ní gbà mí sílẹ̀!
Amọ oludari ẹka itaniji fun araalu labẹ ajọ Naptip wa rọ awọn araalu lati mase maa sa si abẹ ojiji wọn, ki ẹlẹsẹ ma baa lọ laijiya amọ ki wọn kan si ajọ naa, ki wọn si setan lati ba ẹjọ naa de opin, ki idajọ tootọ lee wa.
O dabaa awọn orukọ kan bii Agbekẹ, Kabiyesi, Amuniṣiwi, Amunirẹrinmusẹ ati bẹẹ bẹẹ lọ.
Ìwọ Alákọ̀wé ti mo fi èdè Yoòbá ta lọ́rẹ gẹ́gẹ́ bí ẹ̀bùn, o yíò mọ̀n pé Èmi Olódùmarè ni Ẹlẹ́dàá gbogbo nkan.
Gbogbo àwọn ọmọ ogun Joabu, ati àwọn ẹ̀ṣọ́ ọba, ati gbogbo àwọn ọmọ ogun yòókù, tí wọ́n kù ní Jerusalẹmu bá tẹ̀lé Abiṣai láti lépa Ṣeba.
Bolt in Lagos: Àwọn iléeṣẹ́ Uber yóò kógbánílẹ̀ tí ìjọba Eko bá fi lé owó orí wọn- Onimọ̀ nípa ọrọ̀ ajé
Isamotu ni ijọba gba esi ayẹwo ẹni akọkọ naa ati awọn oṣiṣẹ eto ilera to ri iwosan lalẹ ọjọ Ẹti.
Lara awọn ohun ti igbimọ naa daba ni ominira nla fawọn ijọba ipinlẹ, nipa gbigbe awọn ofin kan kuro labẹ isọri ofin ti ko wa fun gbogbo-gboo, lọ sabẹ awsn ofin to wa fun lilo lati igbadegba.
Ṣugbọn ni iṣẹju meji lẹyin naa lọrọ bẹyin yọ lẹyin ti ọkọ awọn sọja de ibẹ.
Akọroyin Gistloverszone lori Instagram sọ pe Ronke mu ki Jago ta mẹta lara ọkọ ayọkẹlẹ mẹrin to ni.
eka eto iroyin ati igbodegba fun ile ise omo ogun ohun, Air Commodore Ibikunle
3 trillion ni CBN gbé jáde fún ọdun 2020 Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ọmọ Yahoo tú àṣírí ara rẹ̀ fún, bí wọ́n ṣe ń ṣe é BBC Yorùbá Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
India: Ẹ wo bí àwọn ènìyàn ṣe dóòlà èmí erin tó jálulẹ̀
majebi Àkọlé àwòrán, Alupupu naa n gbe alupupu pọn lara ohun ti oju wa ri lasiko tawọn janduku yabo igboro Oríṣun àwòrán, ZurielOlowe Àkọlé àwòrán, Ki la o ti ṣe eyi si o Ekiti kete!
Má bá wọn ṣe onígbọ̀wọ́ ẹni tó fẹ́ yá owó,má bá wọn ṣe onídùúró fún onígbèsè.
    Iyàlẹ́nu ló jẹ́ fún mi pé bí ó tiẹ̀ jẹ́ pé n kò sọ fún púpọ̀ nínú àwọn ọ̀rẹ́ mi nípa ọkùnrin náà tó wọ̀n-ọnnì, síbẹ̀ ogunlọ́gọ̀ àwọn ènìyàn ló ti gbọ́ nípa ọkùnrin náà, kí o sì tó di pé a jẹun àárọ̀ tán lọ́jọ́ náà àwọn ènìyàn ti rọ́ dé ilé wa.
Jin kúkú kọ̀ ó l’óun ò jẹ ìpanu aláta.
Àwọn ọmọ ogun rẹ̀ tí a kà jẹ́ ọ̀kẹ́ meji ó lé ẹẹdẹgbẹjọ (41,500).
Bibalẹ ti àpèrè rẹ balẹ sile aye, bebe odo ti awọn ọmọ eeyan gbe ẹbọ si lo balẹ si i.
Adeboye ni eniyan lasan ni oun, oun kii si se Ọlọrun rara.
Sunday Igboho kàn ń gbé ‘Camera’ lẹ́yìn kiri, kí wọ̀n lè rò pé ó ń jà fún Yorùbá - Gani Adams Ìlànà ‘Referendum’ nìkan la fi le gba orílẹ̀èdè Oduduwa, kìí ṣe ìwọ́de Gbàjarè!
Nígbà tí obinrin yìí ṣe akiyesi pé èso igi náà dára fún jíjẹ ati pé ó dùn ún wò, ó sì wòye bí yóo ti dára tó láti jẹ́ ọlọ́gbọ́n, ó mú ninu èso igi náà, ó jẹ ẹ́.
Ipinle Oyo lati bi odun mejo seyin.
Ijọba apapọ ti kede pe eeyan mẹrin miran ti ni aarun coronavirus ni Naijiria.
O fikun wi pe, ipa ribiribi ti Dagunro ko si ere tiata ni pe awọn eniyan ti ara rẹ dide, ti wọn si di olokiki eniyan.
won ri i daju pe ko si darudapo ni awon ibudo adura jake jado Ipinle Oyo.
Lẹ́hìn èyí ni ọ̀pọ̀lọpọ̀ bẹ̀rẹ̀ sí ṣe àròyé fún aṣojú-Olódùmarè nípa ẹwà ara wọn.
Bakan naa ni ile ẹjọ naa tun ṣalaye pe ẹgbẹ oṣelu PDP kuna lati fi idi rẹ mulẹ pe lootọ ni ibo adile waye lawọn ibudo idibo marundinlaadoje.
Lalẹ oni ni abẹṣẹ ku bi ojo ọmọ bibi orilẹede Naijiria to n ṣoju ilẹ Gẹeṣi yoo maa ta kaungbọn pẹlu alatako rẹ, Andy Ruiz Jr niluu Riyadh lorilẹede Saudi Arabia.
ajo iṣẹlẹ pajawiri, eto isomoniyan ati idagbasoke
Ìyá arúgbó òyìnbó bá dúpẹ́  dúpẹ́.
gomina omo egbe APC ana ati eyi to wa nipo bayii Gbogbo awon
”Atejade yii sapejuwe iwa apaniyan to waye naa gege bi iwa ti ko mogbon wa, iwa ika ti o  si lee pa isokan ati ati eto alaafia orile ede Naijiria lara.
Kì í fi ìgbà gbogbo báni wí,bẹ́ẹ̀ ni ibinu rẹ̀ kì í pẹ́ títí ayé.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Jollof, Iyan, Asaro, Ewa Alagbado kìí wọ́n n'ílé oúnjẹ wá ní Egypt' Gomina Fayemi beere pe njẹ Daniel yoo nifẹ lati di gomina bi o ba dagba, Daniel si gba pe bẹẹ, ni gomina wa gba a niyanju lati tẹra mọ ẹkọ rẹ ki ala rẹ le e di mimuṣẹ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ibadan Murder: Oyún oṣù méje ló ń bẹ nínú Azeezat, kí wọ́n tó f'òkúta fọ́ ọ lórí Ọjà Ọba ní Akure ni ọwọ́ ọloọ́pàá ti tẹ aláàrùn Covid-19 tó sá kúrò ní ilé àyẹ̀wò - Akeredolu Oríṣun àwòrán, @tasty_cubes Àkọlé àwòrán, Wọn ni ibi ti obinrin naa ti n ta aṣọ aloku ni ọwọ ti tẹ ẹ Ọwọ ọlọpaa ti tẹ alaarun Coronavirus to sa kuro nile iwosan to ti n gba iwosan ni Ọja Ọba ni Akure, ni ipinlẹ Ondo Kọmisọnna fun eto ilẹra, Wahab Adegbenro sọ wi pe alaarun naa to jẹ obinrin ni ayẹwo fihna pe o ni arun Coronavirus ni ipinlẹ Imo amọ to salọ si ipinlẹ Ondo.
"Eeyan ko le pe nnkan ti wọn n fun wa lounjẹ rara nitori gbẹmi ro lasan ni.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ọpọ igba lawọn eeyan ti di ẹru ti kii se ti ọlọpa le wọn lori Nkan bii ọsẹ meji sẹyin ni ariwo gbode lori itakun ayelujara kaakiri wi pe ọdọkunrin kan ti di awati lẹyin ti o sọ wi pe oun fẹ sun si agọ ọlọpa to wa lagbegbe Ojodu nilu Eko.
Aarẹ ẹgbẹ́ naa, gẹgẹ bi iwe iroyin Punch ṣe jabọ̀, sọ fun awọn akọroyin pe, awọn yoo fi iyanṣẹlodi ọhun naa tan bi owo pẹlu ijọba, lẹyin ti awọn reti idunadura to nitumọ, ṣugbọn ti ko waye.
Gbogbo àwọn ọba ìlú etí òkun yóo sọ̀kalẹ̀ láti orí ìtẹ́ wọn, wọn óo bọ́ aṣọ ìgúnwà wọn, ati agbádá ọlọ́nà tí wọ́n wọ̀, jìnnìjìnnì óo dà bò wọ́n, wọn óo jókòó sórí ilẹ̀, wọn óo bẹ̀rẹ̀ sí máa gbọ̀n, ẹnu óo sì yà wọ́n nítorí ohun tí yóo ṣẹlẹ̀ sí ọ.
Gẹ́gẹ́ bí ayàwòrán, mo fẹ́ràn àsìkò yìí lọ́pọ̀lọpọ̀ nítorí bí àwọn ewé orí igi ṣe máa npa àwọ̀ dà.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Nigeria Army: àṣírí àwọn ajínigbé kò bò mọ́ ni Ondo àti Ekiti 23 Òkùdu 2019 Oríṣun àwòrán, others Àkọlé àwòrán, Nigeria Army: àṣírí àwọn ajínigbé kò bò mọ́ ni Ondo àti Ekiti Kete ti ijọba apapọ ti paṣẹ pe ki awọn ọmọ ogun lo mojuto ọrọ awọn ajinigbe ni iṣẹ ti bẹrẹ.
Adari ile Ethiopiam Hailemariam Desalegn,  lasiko to n soro lori koko yii ni ki awon orile ede ti won ko tii fi esi akosile ibi ise de duro wo ranse si ajo isokan tete se bee ki won le gbe akosile won yewo ninu ayewo odun 2020.
Ebuka naa lo tun ṣe atọkun eto naa bakan naa fun ọsẹ mejila gbako, ti wọn fi ṣafihan eto naa.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Ẹgbẹ oṣelu APC lo gbe Obaseki wọle fun saa kinni gẹgẹ bi gomina ipinlẹ Edo.
Ọ̀kan yòókù kò ì tíì jẹ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Promise Akinlade: ọmọ ọdún mọ́kànlá tó ń fi ìlù dárà bíi àgbàlagbà sọ̀rọ̀ nípa tálẹ́ǹtì rẹ Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí EndSars in Portharcourt: Ọjọ́ méjì sẹ́yìn ni aya awakọ̀ Márúwá tí ọlọ́pàá pa bímọ tuntun10 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Fídíò, Oba Adeyeye Ogunwusi: Ojú mi ti rí lọ́pọ̀ lọpọ̀, ọ̀pọ̀ èèyàn ni kò tilẹ̀ gbàgbọ́ pé mo lè jọba- Ooni7 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Oyo physically challenged protest: Ìdí rèé táwọn àkàndá ẹ̀dá fi dí iwájú iléeṣẹ́ ìjọba ìpínlẹ̀ Oyo pa l'Agodi n'Ibadan7 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 ASUU strike: Mi ò tíì lè sọ ní pàtó ìgbà tí a ó fòpin sí ìyanṣẹ́lódì wa - Aarẹ ASUU7 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Iyanse-lodi ohun waye lati fungun mo ijoba, leyin ti awon olutoju-aisan ile-iwosan ijoba gbogbo ti bere iyanse-lodi lati bi osun meloo kan seyin, eyi ti o n sakoba fun eto ilera jake-jado orile-ede naa.
Mbam ní ìpínnu ìlànà ti àwọn fẹ́ gúnle yìí ni wọ́n ti dábàá tẹ́lẹ̀ láye Obasanjo, èyí ti ìjọba ìbilẹ̀ yòó ma gba ìdá mẹ́tàlélógun.
Alábòyun ṣe iṣẹ́ abẹ pẹ̀lú abẹfẹ́lẹ́, ó gbé ọmọ jádé nínú ara a rẹ̀ Ọpọ adanu lo de ba MTN lara awọn onibara to le ni miliọnu ọgọta ti wọn ni lọwọ lọdun 2016 tẹlẹ lataari sisan owó itanran yii.
Gbogbo ẹyẹ ojú ọ̀run ni mo mọ̀,tèmi sì ni gbogbo nǹkan tí ń rìn ninu pápá.
com ni   Igbimo naa ti so pe:”awon ti fi okunrin arugbo omo odun mefadinlogorun  ana naa sile leyin ifukun-lukun pelu abenugan ile igbimo asofin.
Joṣua bá pàṣẹ pé kí àwọn eniyan náà máa lọ, kí olukuluku pada sí orí ilẹ̀ rẹ̀.
Kí ẹ mú ẹrú tí kò wúlò yìí kí ẹ tì í sinu òkùnkùn biribiri.
Gẹgẹ bi iwe ẹsun naa ṣe sọ ọ, lara awọn eeyan ti ijọba pe lẹjọ ọhun ti na papa bora.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Aisha Buhari: Ọkọ mi yóò parí gbogbo iṣẹ́ tó ti bẹ̀rẹ̀ 4 Ẹrẹ̀nà 2019 Oríṣun àwòrán, @AISHABUHARI Àkọlé àwòrán, Aare Muhammadu Buhari ló jáwá olúborí fún sáà kejì nínú ètò ìdìbò sìpò ààrẹ lórílẹ̀èdè Nàíjíríà tó wáyé ní Osù Keji, ọdún 2019.
Yara Ward , nile idibo ti 003 ni ijoba ibile 
Ọpọ̀ àwọn ọmọ kárọ̀ọ̀-oò- jíire ló ti ń kí ori ade kú aṣeyẹ ọdun míràn lórí aléfà, tó fi mọ olori tó kéré jùlọ laáàfin Badirat Adeyemi nígba to lọ sójú òpó instagram rẹ̀ láti lọ kí olówó orí rẹ̀.
Ó tọ́ lójú mi láti fi àmì ati iṣẹ́ ìyanu, tí Ọlọrun tí ó ga jùlọ ṣe fún mi, hàn.
Ṣebí ìwà ibi rẹ ló pọ̀;tí ẹ̀ṣẹ̀ rẹ kò sì lópin?
Òtítọ́ ni ọ̀rọ̀ yìí pé, ‘Ọ̀tọ̀ ni ẹni tí ń fúnrúgbìn, ọ̀tọ̀ ni ẹni tí ń kórè.
Tẹ́lẹ̀ rí, ó fẹ́rẹ̀ jẹ́ pé gbogbo àwọn ẹ̀yà Bẹnjamini ni wọ́n jẹ́ olóòótọ́ sí ìdílé Saulu.
Soleimani Killing: Ẹgbẹ́ Shiites wọ́de l'Abuja, wọ́n jó Àsìá Amẹ́ríkà Kano: À ti fa àwọn oníbalòpọ̀ akọsákọ tí a mú le òbi wọ́n lọ́wọ́- Ọlọpàá Hisbah Ẹ wo àwòrán bí ọjà Akẹsan ṣe jóná ràùràù ní ìlú Oyo!
Lẹ́yìn náà, ó fi ọmọ Ahasaya ọba hàn wọ́n.
“N óo mú kí ẹ gba abẹ́ ọ̀pá mi kọjá, n óo sì mu yín wá sí abẹ́ ìdè majẹmu.
Owú jíjẹ Efuraimu yóo kúrò,a óo sì pa àwọn tí ń ni Juda lára run.
O sọ nipa Godwin Obaseki, ti ipinlẹ Edo, ati Rotimi Akeredolu, ti ipinlẹ Ondo.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ọmọ Yahoo tú àṣírí ara rẹ̀ fún, bí wọ́n ṣe ń ṣe é BBC Yorùbá Gomina Sanwo-Olu ni ijọba Eko ti n fi orikori lori awọn ọna lati ṣakoso irinna ọkọ ni ipinlẹ Eko ki wọn si yanju iṣoro bi oju popo ṣe maa n di gadigadi.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Aisha Buhari: Ìpínlẹ̀ Kano kò rí ànfàní ètò ìjọ̀ba Buhari jẹ.
Ìgbéraga Israẹli hàn kedere lójú rẹ̀; Efuraimu yóo kọsẹ̀, yóo sì ṣubú ninu ìwà burúkú rẹ̀, Juda náà yóo ṣubú pẹlu wọn.
Lara awon to kọwọrin pelu Makinde ni a ti ri igbakeji re, ogbeni Rauf Olaniyan; asofin Hosea Agboola; alaga egbe oselu People’s Democratic Party,( PDP ) Ogbeni Kunmi Mustapha; agbenuso fun Makinde, Omooba Dotun Oyelade, ati awon agbaagba egbe Oselu PDP.
O ni Eko loun gba de Ilorin lojo keji koun too gbọ pe won ti n wa oun.
‘Yorùbá, ẹ dìbò fún Buhari láti bu ọlá fún M.
Oniruru ibeere lo ti n waye lori ọna ti Ọgbẹni Nnamdi Kanu gba jade kuro lorilẹede Naijiria pẹlu bi o ti ṣe ti ko awọn iwe irinna ti orilẹede Naijiria ati ilẹ Gẹẹsi to ni silẹ fawọn agbofinro.
Hamzat to ṣoju fun Gomina ipinlẹ Eko,si wa lara awọn eekan ijọba, to ti ṣe abẹwo si abule Egba lẹyin ijamba ina to ṣakoba fun dukia nibẹ.
Yinka Ayefele di Bàbá ìbẹta Oríṣun àwòrán, @Yinkaayefele Gbajugbaja olorin ni to tun jẹ oludaleeṣẹ rẹdio silẹ, Yinka Ayefẹlẹ ti di baba ibẹta bayii.
Awọn ọdọ Naijiria lo ko ara wọn jọ lati tako iwa ika ati ifiyajẹni tawọn ọlọpaa n hu, paapaa awọn ikọ ọlọpaa to n gbogun tiwa idigunjale ni Naijiria, ti wọn n pe ni SARS.
tí o bá jẹ́ ẹni mímọ́ ati olóòótọ́,dájúdájú OLUWA yóo dìde, yóo ràn ọ́ lọ́wọ́,yóo sì fi ibùgbé rere san ẹ̀san fún ọ.
    Nǹkan náà sì wá ṣe é tó bẹ́ẹ̀, ìgbà tí mo dé ilé, ìyàwó mi lọ sí òde.
Idupẹ yii jẹ eyi ti onikaluku fi maa n ṣiro ibukun rẹ lọdun ti wọn yoo si fi imoore han si Ẹ lẹdaa wọn.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Eegunjobi Omotanbaje Ajobiewe- Èébú ní wọ́n kọ́kọ́ ń bù mí nígbà tí mo bẹ̀rẹ̀ ẹ̀ṣà pípé ní Bakan naa ni ijọba fi lede wi pe, awọn ti tu ikọ SARS naa ka, ti wọn si gbe ikọ ọlọpaa SWAT dide lati koju iwa ọdaran lawujọ.
“Bakana naa, ni a tun le ropo dida eran pelu, awon ohun osin bi: sin-sin Ehoro, igbin  ati adie abbl, eleyi ti opo eniyan yoo tun le je anfaani ninu eto naa,”Sise ifilole dida eran 
Mo wí fun yín nisinsinyii kí ó tó ṣẹlẹ̀, kí ẹ lè mọ ẹni tí èmi í ṣe nígbà tí ó bá ti ṣẹlẹ̀ tán.
lo lokan minisita kookan bayii, nipa eni ti yoo si tesiwaju dipo re mu ninu
Kí wọn máa ṣépè, ṣugbọn kí ìwọ máa súre.
Asa ọmọ rẹ̀ jọba lẹ́yìn rẹ̀.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Widows Day 2019: Mo máa ń sá kiri wá owó ilé ni -Opó Shah Rukh Khan to jẹ Musulumi ni awọn ololufẹ kaakiri agbaye, ti ọpọlọpọ miliọnu eniyan si n tẹle e lori awọn ẹrọ ikansiraẹni.
Buhari ti gbe se lati igba ti o ti de ipo aare ni aarin odun merin ti o ti lo .
Gomina ipinle Oyo , Onimo- ero Seyi Makinde  ti ni ohun wa lati sin awon tonile-talejo to n
America yóò tutù ju bó ti yẹ lọ Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí 2 sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 2:23 Fídíò, Water Generator: Ó leè ṣiṣẹ fún wákàtí mẹfà, kó tó sinmi, Duration 2,2310 Òkùdu 2020 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
Awọn igbesẹ naa si lo bi awuyewuye laarin araalu, ti wọn si n pariwo pe ika ni gomina Ajimobi fi igbesẹ naa se.
Koda, ọmọ oṣu mẹrin naa wa lara wọn.
'Logo Benz yóò lẹ́yìn fún àwọn ọ̀dọ́ tó bá ṣògùn owó' Buhari ní ìdìbò 2019 kìí ṣe tikú-tìyè Ṣé ìwọ ní ìpinnu ọdún tuntun?
iranṣẹ mi ti yoo ṣe ifẹ mi ni."
Ọdọmọde to n seranwọ fun awọn ọmọ ita ni Calabar
“O kò gbọdọ̀ jẹ́rìí èké sí ọmọnikeji rẹ.
Oga ile ise Asobode, ekun Oyo/Osun, Comptroller Abdulahi
Alaafia sì wà ní àkókò ìjọba rẹ̀.
Ọlọrun bá la Hagari lójú, ó rí kànga kan, ó rọ omi kún inú ìgò aláwọ rẹ̀, ó sì fún ọmọdekunrin náà mu.
Ẹ̀rọ ayàwòrán ara ọlọ́pàá fihàn pé ìgbà ogún ni George Floyd pariwo, kó tó kú Àwọn 'ẹ̀bùn' tí ikú George Floyd fún àgbáyé Kí ló ṣẹlẹ̀ tí àwọn ọmọogun Nàìjíríà tó lé ní 350 fẹ́ kọ̀we fi iṣẹ́ sílẹ̀?
2018 Ọjọ keji, oṣu Kẹrin Lẹyin aisan ọlọjọ pipẹ, Winnie Masikizela-Mandela fọwọrọri ku.
Adejobi ni otitọ ni pe ọrẹkunrin obinrin naa ni ọlọpaa ọhun.
 Àmọ ́ , ó dá lóri bí onílù bá ṣe lùú .
Ẹ ṣọ́ra gidigidi, kí ẹ sì ṣe pẹ̀lẹ́pẹ̀lẹ́, kí ẹ má baà gbàgbé àwọn ohun tí ẹ ti fi ojú ara yín rí, kí iyè yín má baà fò wọ́n ní gbogbo ọjọ́ ayé yín.
Ni bayi awọn eeyan tuntun to lugbadi aarun naa jẹ marundinlọgbọnlenigba,225.
Ọsẹ to lọ ni ajọ naa ti kọkọ fi atẹjade sita, lati fun awọn ileeṣẹ agbohunsafẹfẹ ni ilana ti wọn yoo tẹlẹ lori iwọde naa.
‘Ikú wo ni ó rí mi nílẹ̀, tí kò pamí, tí ó wá lọ pa ọmọ mi?
Ile ise to n gbe sinima atigbadegba bo sita, iyen, Marvel Studios ti kede pe gbajugbaja fiimu won tuntun ti won pe ni “Black Panther” lo ti di itewogba ni gbogbo agbaye lasiko yii nipa wiwa ni ipo kerin lagbaye.
Wọ́n ń sá fún àwọn tafàtafà,wọ́n sá fún líle ogun.
Ẹ̀sùn apànìyàn ni wọ́n fi kan Robert Bowers' Ọmọ ọdún 46 ni Robert ti wọ́n fẹ̀sùn kàn pé ó yìnbọn tó pa ènìyàn mọ́kànlá ni Sínágọ́ọ̀gù kan ni Amẹrika.
0 18 Erekusu Solomon Islands 0 0.
Nítorí ìpín tìrẹ nìyí láyé ninu làálàá tí ò ń ṣe.
APC Primaries: Oshinowo jáwé olú borí, Ashafa já kulẹ̀ Àwọn PDP méjìlá ló wù láti gba Nàìjíríà kúrò lọ́wọ́ APC INEC: Ètò ìdìbò gómìnà Ọṣun ló dárajù nínú gbogbo èyí tá a ti ṣe Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, È gbọ àlàyé lẹnu àwọn ti ójúẹlẹgba leko irú iṣẹ ti oògùn olóró má n ṣé lara.
CCC Genesis Global: Ǹkan mẹ́wàá tí ẹ ò gbọ́ rí nípa Israel Oladele, Woli ìjọ Genesis Global Genesis Global: Ṣé lóòtọ́ ni pásítò ìjọ Celestial, Israel Oladele Ogundipe rẹ́wọ̀n he?
Ṣebí mo ti sọkún nítorí àwọn tí wọ́n wà ninu ìṣòro rí,tí mo sì káàánú àwọn aláìní.
Ní òwúrọ̀ ọjọ́ keji, Jehu lọ sí ẹnubodè ìlú, ó sì sọ fún àwọn tí wọ́n wà níbẹ̀ pé, “Ẹ kò ní ẹ̀bi, èmi ni mo ṣọ̀tẹ̀ sí Joramu ọba, oluwa mi, tí mo sì pa á.
Nigba to n sọrọ lori bi ajẹbanu naa ṣe n fẹju si, Wolii Ajani ni yoo nira diẹ kiwa ajẹbanu to kasẹ nilẹ ni Naijiria.
Ẹ̀wẹ̀, kí obinrin to lọ gba ìwé àṣẹ ìrìnà ó gbọ̀dọ̀ gbàṣẹ lọ́wọ́ ìyá, Baba tàbí ọmọ ẹgbọ́n tàbí àbúrò ìyá tàbi babarẹ̀ okùnrin kó to rìnrìn àjò lọ sí òkè-òkun.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Diego Maradona gba ife ẹyẹ agbaye ọdun 1986 3.
pade ti ile igbimo asoju fẹnuko lati se pẹlu wọn, ni eyi ti o jẹ ki won fagile
"Laarin ọsẹ meji naa ni ajọ to n risi ọrọ ina oba, DISCOs, yoo fi wọgile owo ina oba ti o ti da owon gogo yii' Bakan naa ni ijọba fikun pe, wọn n gbe igbesẹ lati ma a ṣe iranwọ fun awọn oṣiṣẹ nipa owo ọkọ, owo ina ọba, owo ile gbigbe, eto ọgbin ati awọn owo iranwọ miran.
com/nQravE4C6nKosovo 1-1 BulgariaMontenegro 1-5 England Portugal 1-1 SerbiaLuxembourg 1-2 UkraineTurkey 4-0 MoldovaAndorra 0-3 AlbaniaFrance 4-0 IcelandAwon ifesewonse miiran ti yoo tun waye loni re:EURO2020Ireland ?
Iléeṣẹ́ ọmọogun ní àwọn ọmọ ogun ń ṣe iṣẹ́ wọn bí iṣẹ́, ṣùgbọ́n adìyẹ rẹ̀ tóń làágùn, ìyẹ́ ara rẹ̀ ni kò jẹ́ kí a mọ̀.
Eyi ko si sẹyin awuyewuye ọrọ kan to gba ori ayelujara kan lasiko kan pe, arẹwa ayaba naa n ni ifẹ ikọkọ pẹlu Ọba Fuji, King Wasiu Ayinde Marshall, Kwam 1.
Balogun iko agbaboolu Manchester City, Vincent Kompany so pe, ise takun-takun ohun ati aforiti re ninu iko agbaboolu Man City le ran ohun lowo pupo lati maa kopa fun iko naa fun ojo pipe ju bi oun se lero lo.
Ẹ wá jọ ń rí oúnjẹ ati agbára láti ibìkan náà pẹlu àwọn Juu, tí ó jẹ́ igi olifi inú oko.
Wọ́n lọ káàkiri gbogbo ilẹ̀ Juda pẹlu ìwé òfin lọ́wọ́ wọn, wọ́n ń kọ́ àwọn eniyan.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Fadele: Dán an wò, lóbí ìyá ọ̀kẹ́rẹ́ ni a fi ọ̀rọ̀ ọ̀kadà náà ṣe Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Fadele: Dán an wò, lóbí ìyá ọ̀kẹ́rẹ́ ni a fi ọ̀rọ̀ ọ̀kadà náà ṣe 6 Ògún 2018 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 5 Sẹ́rẹ́ 2020 Àwa kìí ṣe wèrè, ìpinnu wa ni láti ṣe ńkan tuntun ní ọ̀nà tuntun- Fadele Fadele Adu ọkan lara awọn akọni mẹrin naa ṣalaye fun BBC Yoruba pe oun kọ lo kọkọ ṣe eyi ri.
Osise ijoba kan so, ara to san lojo-Abameta ti seku pa awon merindinlogun, ti ogoro eniyan si fara pa yan-na-yan-na ile-ijosin Seventh-Day Adventist lorile-ede Rwanda.
com Àkọlé àwòrán, Gomina tẹlẹ ri nipinlẹ Eko Babatunde Fashola ati iyawo oloogbe Awojobi,Iyabode Mabel Awojobi nibi ifilọlẹ ọgaba igbafẹ Awojobi Park O fi iyawo kan saye lọ,iya afin Iyabode Mabel Awojobi ati awọn ọmọ.
O wa ro awon omo orile ede yii lati maa gbe orile ede yii ga, nibikibi ti won ba ba ara won.
ibasepo to wa laarin orile ede Senegal ati orile ede Naijiria yoo tubo fese mule
Àwon ọ ̀ rọ ̀ , tí a fihàn gẹ ́ gẹ ́ bí i àwon ọ ̀ rò orúkọ , gba àwọn nnkan mìíràn mọ ́ ra dandan ,  det ' , Àwon ipa aṣekókó , ÌsỌdỌ ̀ pỌ ̀ , àwọn kan- npá àti wòfún ( ákámọ ́ ) , àwon Àfikún àti àwon Ìsomọ ́ bákan náà , àti àwon mìíràn tí a kò mẹ ́ nu bà ."
Agbekalẹ naa waye lati bomirin eto aabo nilẹ Yoruba, paapaa julọ lori ikọlu awọn darandaran to n gogo lẹnu lọọlọ yii.
Kopẹ, ko jinna ni wọn ni ọkunrin kan da ibọn bolẹ eyi to ṣe eniyan meje lọṣẹ loju ẹsẹ.
  Naijiria yoo bere ifigagbaga ipegede ninu osu kesan fun idije Cameroun 2019 Nations Cup , won yoo teko lo sorile-ede Seychelles fun ifesewonse keji nipele ifigagbaga ipegede ohun.
” Ṣugbọn Ọlọrun kò dá a lóhùn ní ọjọ́ náà.
"Ẹ wo ìdí tí Oby Ezekwesili ṣe ń pè fún àyẹ̀wò ọpọlọ fún Ààrẹ Buhari Biba ti ọmọlakeji jẹ wa laarin awọn oloṣelu, o wa ninu ile iṣẹ ologun Naijiria koda o wọpọ laarin awọn oṣiṣẹ ijọba"" Gomina ni ọdun mọkanlelaadọta yii fi kun un pe ẹnikẹni ti igba iwa yii ba ṣi mọ lori, o yẹ ki wọn fimu rẹ danrin gidi gan."
Eyi ko ba fun wọn ni akoko, lati duro sipo ti ohun gbogbo wa na, nigba ti igun mejeeji ba n jiroro lori ọna to tọ lati pinya.
Amẹ́rika dá akẹ́kọ̀ọ́ padá nítori Facebook Ìyàwò lárìnlọọ̀dù mi pè mí ní akálòlò ni mo ṣe paa - Afurasí ‘Kò sí ohun tó lè yẹ ìfèhọnú ọjọ karun un Oṣu Kẹsan lórí àtìmọ́lé Omoyele Sowore’ Ọkọ̀ akẹ́rù Dangote rọ́lu BRT lọ́nà Ikorodu, èèyàn kan kú, 59 farapa, ẹsẹ̀ dẹ́rẹ́bà gé Oríṣun àwòrán, @others Àkọlé àwòrán, APC tun ti fa Yahaya Bello aklẹ lẹẹkansii Gẹgẹ bii gomina Abubakar Badaru ti ipinlẹ Jigawa to ṣe alaga eto idibo naa ṣe sọ, Ọgbẹni Babatunde Irukera lo gbe ipo keji pẹlu ibo mọkandinlaadọfa ti Hassan Bewa si ṣe ipo kẹta pẹlu ibo mẹrinlelogoji.
Akosile sọ pe bi gomina ba ti ẹ ṣe bẹẹ, o ṣe e gẹgẹ bi baba to fẹ ki ọmọ rẹ o ṣe daadaa ni.
Ibanujẹ ọkan lo jẹ fun mi bi ẹgbẹ NLC ṣe wogile iyanṣẹlodi - NLC Eko Alaga ẹgbẹ oṣiṣẹ nipinlẹ Eko, Comrade Agnes Funmi-Sessi, ti bu ẹnu atẹ lu bi ẹgbẹ oṣiṣẹ lapapọ, NLC, ṣe paṣẹ pe ki wọn gbegile iyanṣẹlodi ti wọn fẹ gunle ni Ọjọ Aje, tako ọwọn gogo epo bẹntirol ati ina ọba.
Issa ti sọ fun BBC ninu ifọrọwanilẹnuwo kan pe oun ko le fẹran ọmọ Naijiria kankan mọ laye oun lẹyin nkan ti oun ti tọwo Òyìnbó ẹni ọdún 46 wá ṣe mọ̀'mí n mọ̀ ọ́ ní Kano pẹ̀lú Isah olólùfẹ́ rẹ̀.
Leyin opolopo ijiroro lori koko yii Asofin Ibrahim Gobir ni ki ijoba gbajuo mimu idagbsoke ba awon eka ile ise nlanla ni o le mu ilosiwaju to ye sele.
Dokita Kayode Fayemi to jẹ gomina ipinlẹ Ekiti lọwọlọwọ lo fi ipo rẹ silẹ gẹgẹ bi minisita fun ọrọ nkan alumọọni ni Ọgbọnjọ, Osu karun un, ọdun 2018 lati le lo ṣe eto oṣelu to gbe e wọle gẹgẹ bi gomina.
Ewe, lojo Abameta(Saturday), iko agbaboolu Falcons gbo ewuro si iko akegbe won loju, Banyana Banyana ti iko South Africa, ninu asekagba ifesewonse idije boolu afesegba iko obinrin tile Afrika(African women football), pelu ami-ayo merin si meta ninu ifigagbaga boolu agbesile gba(Penalty Kick).
Bákan náà ni òfin yìí tún kan àwọn ìgbákejì gómìnà ìpínlẹ̀ tó bá parí sáà pẹ̀lú ọ̀gá rẹ̀.
Tí o bá ń fọ́nnu, ranti pé kì í ṣe ìwọ ni ò ń gbé gbòǹgbò ró.
O ni ifẹ nla lo wa laarin oun ati Ọba naa, ti oun ko si kabamọ rara pe oun fẹ Alaafin, tii se ẹni ọdun mejilelọgọrin ni ọkọ.
délé Òjó bẹ ̀ rẹ ̀ iṣẹ ́ orin rẹ ̀ ní pẹrẹu nígbà tí ó ṣalábàá-pàdé olórin kan tí ó ń jẹ ́ victor Ọláìyá ẹni tí ó gba délé sí inú ọmọ ẹgbẹ ́ akọrin rẹ ̀ .
Fun ẹni ti ko ni aisan ṣuga, dokita Ikubese sọ pe ki iru ẹni bẹẹ ṣọra fun ara sisan, ko si ṣọra fun ounjẹ jijẹ lẹyin aago meje aṣalẹ.
Bí o bá fi pàṣán nà án,o óo gba ẹ̀mí rẹ̀ lọ́wọ́ ikú.
Ìran nípa Ìwé Kíká Tí Ó Ń Fò.
Ile ejọ́ gíga ìjọba àpapọ̀ tó wà ní ìpínlẹ̀ pàṣẹ ìtúsílẹ̀ rẹ̀ lẹ́yìn tó ti san gbogbo nkan tí ilé ẹjọ́ bèérè fún láti gba onídúró rẹ̀.
Àwọn ọmọ Nàìjíríà 320 yóò padà wálé láti South Africa lọ́jọ́rú - Adama Ara sọrọ lori bi aisan ṣe sọ oun di olominira lọwọ baba oun ti ko kọkọ fẹ faramọ orin kikọ ati ilu lilu fun oun.
Orúkọ ọmọ Israẹli tí ó pa pẹlu ọmọbinrin Midiani ni Simiri, ọmọ Salu, olórí ilé kan ninu ẹ̀yà Simeoni.
Ọkùnrin tí ó béèrè ní ìṣáájú pée kí ọ̀gá òun yéé máa gbé òun láti ìlú kan dé ìlú kan wéréwéré kò í tí ì fi ìlú tí ó ti wà kí Aṣojú-Olódùmarè tóó wá ní ìṣáájjú sílẹ̀.
Mú ẹ̀gàn ati àbùkù wọn kúrò lára mi,nítorí pé mo ti pa òfin rẹ mọ́.
Ewe, awon asofin wa ro aare Buhari lati tete se agbekale iwe atunse abadofin ohun fun ile igbimo asofin lati se afinkun ojo kejila osu kefa naa gege bi ayeye ayajo odun eto ijoba tiwa-n-tiwa sinu iwe abadofin gege bi aare se kede.
A wa n kesi ileesẹ aarẹ, ile asofin apapọ, adajọ agba lorilẹ-ede yii ati gbogbo ọmọ Yoruba pata-pata, pe ki wọn tete yọ suti ete si iwa bayii ko to bọwọ sori.
Ṣugbọn àwọn ẹranko ní yóo máa sùn níbẹ̀ ilé rẹ̀ yóo sì kún fún ẹyẹ òwìwí,ògòǹgò yóo máa gbè ibẹ̀ẹhànnà òbúkọ yóo sì máa ta pọ́núnpọ́nún káàkiri ibẹ̀.
Bó ti wù Ọ ́lo ń ṣ’ọlá Rẹ
Kì í ṣe pé, kí àwọn ẹlòmíràn má ṣe nǹkankan, kí ó jẹ́ pé ẹ̀yin nìkan ni ọrùn yóo wọ̀.
Ẹ má halẹ̀ ju bí ó ti yẹ lọ,ẹ má sì gbéraga.
omo orile ede Democratic Republic of Congo,nigba ti aarun Ebola jẹyọ niluu Goma,
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Oshodi-Oke: Kò dára báwọn òsèré se ń fi dúkìá sakọ 22 Òkùdu 2018 Oríṣun àwòrán, Ronkẹ Oshodi-Oke Ronkẹ́ Oshodi-Oke ní ohun tí kò dara, kò dára ni, bí àwọn akẹẹgbẹ́ rẹ̀ tó jẹ́ òsèré tíátà se máa ń fi dúkìá tí wọn bá sẹ̀sẹ̀ rà, bíi ilé àti mọ́tò, se bùgá lórí òpó ìkànsíra-ẹni.
Ile-igbimo asofin ohun tun se ifilole igbimo tuntun lasiko ipade naa lataari iyansipo agbenusoro tuntun fun ile-igbimo asofin ohun.
Tabi nígbà tí ẹ̀ ń jẹ tí ẹ sì ń mu, kì í ṣe ara yín ni ẹ̀ ń jẹ tí ẹ̀ ń mu fún?
Alaga egbe awon osise eleto ilera fun ipinle Adamawa Naboth Akuna lo ro ijoba , lojo Aje.
Wọ́n sì tún ń dá ẹ̀ṣẹ̀ kan náà, ère oriṣa Aṣera sì wà ní Samaria.
Ileẹjọ ni awọn ọlọpa ko sisẹ wọn bii isẹ lori ẹjọ, nitori naa ko lẹsẹ nlẹ.
    Lóòótọ́, ilẹ̀ ọjọ́ kejì tún mọ́, àwọn ìbátan wọ̀n-ọnnì tún ṣe onírúurú àwáwí, ẹ̀gà tún múra ó bá ibi iṣẹ́ rẹ̀ lọ.
Nigba to n salaye lori gbesẹ to ku ti banki apapọ ilẹ wa gbe lati doola banki naa, Emefiele ni , lati akoko yii lọ, banki tuntun miran, ti wọn pe ni Polaris ni yoo maa se akoso banki Skye bayi.
0 26 Orilẹede Geenlande 0 0.
Ṣugbọn Ronaldinho ati arakunrin rẹ sọ pe awọn ko jẹbi ẹsun ti wọn fi kan awọn.
NLC Protest: Jànduku ya bo àwọn tó ń fẹ̀hónú hàn nílé Míńísítà fún ọ̀rọ̀ òṣìṣẹ́
Wọ́n ń sọ ọ̀rọ̀ ọ̀tẹ̀ nípa rẹ,àwọn ọ̀tá rẹ ń ba orúkọ rẹ jẹ́.
Pásìtọ̀ ìjọ Sotitobire Alfa Babatunde ti wà nílé ẹjọ báyìí ní ìtẹ̀síwájú ìgbẹ́jọ́ rẹ̀ Ṣé lóòtọ́ ni òjòjò dá Abiola Ajimobi wólẹ̀?
Ewe, iroyin ohun tun fi kun pe, ina ti ile-ise naa pese  ti o kere ju lojumo je egberun lona metaleladorin megawasi 73,246MWh.
Oríṣun àwòrán, @nbcgovng Àkọlé àwòrán, Ajọ̀ NBC ni ileesẹ igbohunsafẹf Ekiti yoo si wa ni titi pa fun igba diẹ na.
Àkọlé àwòrán, Sowore salye bi awon egbe okunkun se gun oun Akọroyin Omoyele Sowore mọ awọn ẹgbẹ okunkun yi bi ẹni m'owo nigba to n kẹkọọ ni fasiti ilu Eko, Unilag.
Ahabu dáhùn pé, “Ó ku ọ̀kan tí à ń pè ní Mikaya, ọmọ Imila tí a lè bèèrè lọ́wọ́ rẹ̀.
Nígbà tí Paṣuri alufaa, ọmọ Imeri, tí ó jẹ́ olórí àwọn olùṣọ́ ilé OLUWA, gbọ́ ọ̀rọ̀ tí Jeremaya ń sọ, 
Aṣeyọri ti Ọjọgbọn Dora Akunyili ṣe lasiko naa kuro ni kekere nitori oun lo mu igba ọtun wọ eto gbigbogun ti ayederu oogun oloro lorilẹede Naijiria nigba naa.
Mama Tiamiyu sọ ọrọ yii lasiko ti gomina Dapo Abiọdun ṣe abẹwo si awọn obi Tiamiyu ni ile wọn.
Bakan naa, Minisita fọrọ ilẹ Okeere, Geoffrey Onyeama loju opo Twitter rẹ, ti wa bẹnu atẹ lu iṣẹlẹ yii, to si ni Naijiria yoo gbe igbesẹ to peye lori ọrọ naa.
1 47516 Orilẹede Paraguay 1853 26.
Ọ̀rọ̀ yín ti sú Ọlọrun, sibẹsibẹ ẹ̀ ń bèèrè pé, “Báwo ni a ṣe mú kí ọ̀rọ̀ wa sú u?
Naijiria, Ayuba Wabba lo soro yii lasiko ti o soro lori  iwe abadofin 2019 lori  ekunwo  osu awon osise nile-igbimo asofin, niluu
Ní ìhà àríwá àgbáyé ni o.
Lati ọjọ kọkandinlọgbọn oṣu kọkanla ni awọn ileeṣẹ to n pin ina ọba lorilẹede Naijiria ti fi ọrọ ilanilọyẹ sita lati fi to awọn araalu leti.
Parker so pe, “Mo le fagba-han Anthony Joshua.
O ṣalaye pe kii ṣe gbogbo eniyan ni ẹgbẹrun lọna ọgbọn Naira naa yoo kan.
 Issa-Onilu, ni pe igbimo alase egbe naa ti gba
O ni nitori aṣẹ atunto ti igbakeji aarẹ Naijiria, Ọjọgbọn Yẹmi Ọṣinbajo pa, lasiko to fi jẹ adele Aarẹ, o ti di dandan fun gbogbo ọlọpa FSARS lati maa wọ aṣọ toke-tilẹ aṣọ ileeṣẹ ọlọpa, titi di igba ti ọga agba ileeṣẹ ọlọpa, yoo fi buwọlu aṣọ iṣẹ tuntun fun FSARS.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Lavona Solomon (to bo oju re) nile ẹjọ ni Cape Town lasiko to n wọnu ile ẹjọ lọ fun igbẹjọ Bi o tilẹ jepe Lavona sọ wi pe oun ko jẹbi ẹsun ti wọn fi kan oun, Miche sọ wi pe oun ko gbagbọ pe iya to toju oun ko jẹbi ẹsun ti wọn fi kan an.
Iya Adodo ni ọpọ eeyan n pe, gẹgẹ bo se wọpọ lati maa da awọn olori agba pe laafin, eyi to da lori ojuse wọn.
Lasiko ti wọ̀n n ba akọroyin BBC sọrọ, ọpọ eeyan lo tun ni awọn ni iwe ẹri to yẹ, amọ ti isẹ oojọ di isoro.
Wọ́n yí mi ká, àní, wọ́n dòòyì ká mi,ṣugbọn ni orúkọ OLUWA, mo pa wọ́n run!
Kò yẹ kí ó wà láàyè!
Oríṣun àwòrán, Others Ọba Adetoyese Laoye, Timi tilu Ede: Ọba Adetoyese Laoye lo jẹ Timi tilu Ẹdẹ laarin ọdun 1946 si osu karun ọdun 1975.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Obasanjo àti Gani Adams tẹ́ mi pẹ̀lú bí wọn ṣe tahùn síra wọn - Adebanjo Ẹgbẹ́ òṣèlú alátakò takú láti gba èsì ìbò ààrẹ ní Ghana Ọ̀pọ̀ nkan tó n ṣẹlẹ̀ kò jẹ́ kí n gbàgbọ́ pé Naijiria wà ní abẹ́ ìdarí ẹnikẹ́ni - Wole Soyinka Ọmọ ẹgbẹ́ òkùnkùn ṣoro ní Ijebu Ode, ọ̀pọ̀ ẹ̀mí sọnù Àlàyé rèé lórí ìdí tí mo fi lọ sílé Tinubu - Rashidi Ladoja ‘Sim Card’ títà àti ìforúkọsílẹ̀ rẹ̀ dèèwọ̀ ní Nàíjíríà - NCC Ẹ̀yin tí ẹ máa ń bú àwon tó sanra ni ẹ ń jẹ́ kí wọ́n ronú pa ara wọn - Eniola Badmus Ṣé lóòtọ́ ni tírélà ti gba ààrín Ronke Odusanya àti bàbá ọmọ rẹ̀, Jago?
 Ojo iwaju won lo se pataki si wa, eleyi ti a si gbodo mojuto lati isin yi lo,” O fikun oro re pe, Eaglets yoo lo si Qatar ati Jordan ki won o to teko leti lo sorile-ede Tanzania.
oloogbe naa se kongẹ iku ojiji lowo awon eni ibi loju popo marosẹ lorile ede
Ẹ wo ìdí tí Oby Ezekwesili ṣe ń pè fún àyẹ̀wò ọpọlọ fún Ààrẹ Buhari Wọ́n fẹ́ ba dáadáa ààrẹ Buhari jẹ́ ni wọ́n ṣe ń lọ́ kíkojú ìṣòro àbò mọ́ ikú àwọn àgbẹ̀ Koshebe Ẹ̀yin Oníbàárà wa ọ̀wọ́n, ẹ má mikàn, a ti ń dá gbogbo iná yín padà - TCN Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, ọpọ ero gba pe ko tọ si awọn EKEDC lati sọrọ lori ina bayii Okunkun birimu birimu ṣu bolẹ kaakiri awọn agbegbe kan lorilẹede Naijiria eyi si ti mu ki awọn Naijiria figbe bọ ẹnu pe irọ ni awọn ileeṣẹ apina ọba n pa.
Ile ẹjọ magistrati to wa ni Kubwa ni wọn gbe e lọ lori ẹsun jija ileeṣẹ ọlọpàá lole.
Iyabo Ojo, Toyin Abraham, Mercy Aigbe, ta làwọn òṣèrébìnrin yìí gbè lẹ́yìn lórí ọ̀rọ̀ ìfipábánilòpọ̀?
Nibi ipade idankọkọ ọmọ ẹgbẹ oṣelu APC to n waye nilu Abuja laarẹ Buhari ti tutọ soke foju gba a lọjọ Aje.
Ọpọlọpọ nkan lo n fa airọmọbi lara ọkunrin ati obinrin, amọ awọn ounjẹ asaraloore kan wa lati mu atọ okunrin dara si.
O ni tootọ ni idibo miran maa waye nipinlẹ Kogi nitori oun yoo di gomina ti Kogi n reti.
Wọ́n ti ta èmi ati àwọn eniyan mi fún pípa, wọn ó sì pa wá run.
Ó gba àwọn obìnrin ni ìyànjú láti máa tẹ́lẹ̀ àwọn ìlànà yìí: Yàgò fún ẹnikẹni ti bá ń fi àmì Coronavirus hàn Yàgò fún wíwọ ọkọ̀ èrò lásìkò yìí tí ó bá ṣeé ṣe fún ọ Máa ṣiṣẹ́ láti ilé tí ó bá ṣeé ṣe Jìnà sí ìpéjọpọ̀ elérò púpọ̀ tàbí díẹ̀ Yàgò fún ìpéjọpọ̀ ojúkojú láàrin ebi àti ọ̀rẹ́ Máa lọ fóònù àti àwọn ètò orí ayélujára láti bá àwọn nọ́ọ̀sì agbẹ̀bí, àwọn dókítà àti àwọn òṣìṣẹ́ ìlera miran sọ̀rọ̀.
Orúkọ ọmọbinrin rẹ̀ àgbà ni Merabu, ti èyí àbúrò ni Mikali.
Adamu sọ iyawo rẹ̀ ní Efa, nítorí pé òun ni ìyá gbogbo eniyan.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Alárùn ọpọlọ lu àwọn nọ́ọ̀sì àti dókítà agba níléèwòsàn ní àlùdákú Sé ó yẹ kàwọn pásítọ̀ máa bèèrè èso owó ńlá-ńlá ?
 Àwọn ààmì àrùn yìí tí a maa ń sábà rí ní kí omi maa jáde ní ojú òbò tí ó sì maa ń rùn bí ẹja .
O ni ijọba n gbiyanju gẹgẹ bii ara ọna lati din alaafo to wa laarin ọlọpaa ati araalu ku, lati rii pe araalu gan lo n ṣeto akoso abo agbegbe wọn ti awọn ọlọpaa yoo si fun wọn ni atilẹyin gbogbo to ba yẹ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, afin pupa O wa fọwọ idaniloju sọya pe ileesọ ọlọpa ipinlẹ Ọyọ ti setan lati ri pe adinku nla ba iwa ọdaran nipinlẹ yii.
Lasiko to n sọrọ lori igbesẹ ijọba lori owo ori nibi apero lori owo ori aladani ati onile isẹ lo sọ eyi di mimọ.
Bí o bá rí oyin, lá a níwọ̀nba,má lá a ní àlájù, kí o má baà bì.
Nipa pé tẹ̀gbọ́n tàbúrò ni Ọwá Iléṣà àti Ọba Ijẹ̀bú-Jẹ̀ṣà jẹ́ láti àárọ̀ ojọ́ wà yìí, sọ wọ́n di kòrí – kòsùn ara wọn.
 Ogbeni Obinna Okechukwu ni tirẹ sọ pe ko tọna pe ki awọn ti o ti wa labẹ eto yii kan naa ni ipele ijọba apapọ tun dara pọ mọ ti ipinlẹ bayii.
Fidio naa kii ṣe ẹyọkan, ko da, o to mẹẹdogun tabi ko ju bẹ ẹ lọ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù 2019 election: Àwọn olùdíje fún ipò gómìnà nípínlẹ̀ Kwara sọ̀rọ̀ lórí ohun tí wọ́n fẹ́ ṣe Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ 2019 election: Àwọn olùdíje fún ipò gómìnà nípínlẹ̀ Kwara sọ̀rọ̀ lórí ohun tí wọ́n fẹ́ ṣe 11 Sẹ́rẹ́ 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 12 Sẹ́rẹ́ 2019 Awọn asoju ẹgbẹ oselu ọhun ni Ọmọọba Ayọrinde Adedoyin ti ẹgbẹ oṣelu Accord, Komuredi Issa Arẹmu, ti ẹgbẹ oṣelu Labour, ati Ọmọwe Abdulmunin Yinka Ajia, ti ẹgbé oṣelu ANRP.
Wọ́n ní kí a dán an wò, kí a kọ nǹkan sí orí àwòrán ààrẹ  mo sì ṣe bẹ́ẹ̀.
Ija ti dopin, ogun si ti tan fun aarẹ orileede Amẹrika, Donald Trump, nitori o ti moribọ lọwọ iyọni nipo.
Òjò àrọ̀ọ̀rọ̀dá dá wàhálà sílẹ̀ l'Eko Kí ló ṣekúpa Ibidunni Ighodalo tí gbogbo ọmọ Nàìjíríà ń selédè lẹ́yìn rẹ̀?
Ẹgbẹ́ oníṣòwò ṣèwọ́de lórí ìyànsípò YK Abass gẹ́gẹ́ bí bàbálọ́jà tuntun pe meloo ni awọn wa fẹ ni gẹgẹ bii Babalọja.
Oríṣun àwòrán, Ooni adeyeye Enitan Ogunwusi Bakan naa ni Ọọni tun fi kun pe adanu nla to ti pọ julọ to ba Naijiria ni awari epo rọbi jẹ, nitori bi orilẹede yii se kẹyin si agbega eto irinajo afẹ patapata.
Ekun ti won yapa kuro lorile-ede Cameroon, ti won pe ra won ni Republic of Ambazonia, ti yan Sako Ikome Samuel gege bi adari tuntun won.
Ìjọba àpapọ̀ ti kéde àdínkù owó epo bẹntiróòlù sí N162.
Nígbà tí Farao súnmọ́ àwọn ọmọ Israẹli, tí àwọn ọmọ Israẹli gbé ojú sókè tí wọ́n rí àwọn ará Ijipti tí wọn ń bọ̀ lẹ́yìn wọn; ẹ̀rù bà wọ́n gidigidi.
Oríṣun àwòrán, Facebook/Atawewe Atawẹwẹ fikun ọrọ rẹ pe, o yẹ ki gbogbo olorin Fuji mọ ere Ayinde Barrister ati ti Alhaji Ayinla Kollington, lati fi gboṣuba fun wọn.
Ninu ikede kan to ṣe lori tẹlifisan ijọba kan lorilẹede Naijiria, Sultan Abubakar to jẹ olori ijọ musulumi lorilẹede Naijiria rọ awọn musulumi lati yago fun ipejọpọ ọlọpọ ero ki wọn si duro si ile wọn.
Ẹ dárin, ẹ lu samba, ẹ ta hapu dídùn ati lire.
Ikú Adewole Oniluola, tó ní ẹ̀bùn ìlù lílù jùlọ lágbàyéé, yóò nípa lórí Yorùbá - Tunde Kelani Ayinla Ọmọwura, orin èébú àti oríyìn lo fi di ọ̀rẹ́ àwọ̀n obìnrin Ẹ wo ojú àwọn afurasí tí yóò rojọ́ ẹ̀ṣùn àjẹbánu lọ́dún 2021 Bí Nàíjíríà bá fẹ́ kí ọdún 2021 dára, ohun tí yóò ṣe rèé - Obasanjo Ẹgbẹ́ ọ̀dọ́ méjì fìjà pẹẹ́ta, ẹ̀mí kan bọ́, ọ̀pọ̀ farapa O ni o dara bi ijọba ati awọn ọlọpaa ṣe tete gbe igbesẹ, nitori pe eto naa ko ba fun awọn eeyan mii ni igboya lati tun ṣe bẹ ẹ.
Nǹkan ti òde ara nìkan ni ẹ̀ ń wò!
olubori gege bi aare orile ede Naijiria fun saa keji , aare Paul Biya wa ki
Iroyin so pe ikọwe fi ipo silẹ Boris Johnson to jẹ Minisita fọrọ Ilẹ Okeere ni Ilẹ Gẹẹsi niise pẹlu igbaradi orilẹede Britain lati kuro ninu Ajọ Isọkan Ilẹ Europe ( European Union) , eleyi ti wọn n pe ni 'Brexit'.
Elba sọ siweaju si pe oun ṣalabapade ẹni kan to ti ko arun naa lo jẹ ki oun lọ fun ayẹwo.
Ní orí ìrìn ni mo ti rí ìwé rẹ gbà.
Gege bi ile-ise akoroyin lorile-ede China se so lojo Eti(Friday), o ni, China ti setan lati ko oko oju-omi nla miran, eyi ti yoo lagbara lati gbe oko ofurufu ti o kun fun ohun ija oloro awon omo ogun orile-ede ohun.
70 bn Ajọ eleto idajọ NJC - N110 bn Ajọ iranwọ fun eto ẹkọ alakọbẹrẹ - N70.
Ẹgbẹ́ Ohùn Àgbáyé dúró ṣinṣin pẹ̀lú Luis Carlos, ẹbíi rẹ̀, àti oníròyìn aládàáṣiṣẹ́ gbogbo  àwọn tí ó ń mú ìjọba ṣe bí ó ti yẹ ní Venezuela.
Kọlu olùṣọ́-aguntan, kí àwọn aguntan lè fọ́nká; n óo kọjú ìjà sí àwọn aguntan kéékèèké.
Aarin gbungbun Naijiria ni ipinlẹ Kogi wa, iṣẹ agbẹ ni pataki iṣẹ wọn.
Olugbe agbegbe Kumba ọhun kan sọ fun akọroyin BBc pe alaga ibudo idibo naa ti dibo C naa ti wa lọwọ awọn agbofinro.
Nínú ìrìnàjò BBC Yorùbá sí ilé Ọ̀jọ̀gbọ́n Wole Soyinka nínú igbó kìjikìji tó múlé sí ni ilu Abeokuta tii ṣe ilu ibi rẹ gangan, omi pọ lamu ohun ti BBC Yoruba ba bọ.
Awọn aṣoju ileeṣẹ naa meji Meng Wei Kun ati Xu Kuoi ni wọn fi paali gbe owo naa wa si ileeṣẹ EFCC to wa ni opopona papakọ-ofurufu ni Sokoto.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, CAN: Samson ni ọrọ awọn ajinigbe ti gba àpérò ní Naijiria Bakan naa ni Rapinoe gba ami ẹyẹ bọọlu oni goolu pe oun lo mọ ọ gba julọ ninu idije ọdun 2019.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Mo máa n forin mi kìlọ̀ ìwà ìbàjẹ́ láwùjọ ni -Hameen 'Èèyàn mi mẹ́ta ló wà nínú ọkọ̀ ojú omi tó dà nù l'Eko!
Ẹni iná ọ̀rẹ́ bá jó rí, bó bá ní’hun nínú kò ní lè rò
Ṣugbọn àwọn alágbàro náà mú àwọn ẹrú rẹ̀, wọ́n na àwọn kan, wọ́n pa àwọn kan, wọ́n sọ àwọn mìíràn ní òkúta.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ìtàn ayé Henry Fajemirokun, olówó tó fi owó mọ Olúwa àti ènìyàn Ọwọ́ ọlọ́pàá ìpínlẹ̀ Oyo ti tẹ àwọn aṣekúpani tó ń ṣọṣẹ́ ní Akinyele Ìpínlẹ̀ Eko kéde ọ̀nà àbáyọ sí súnkẹrẹ-fàkẹrẹ ọkọ̀ lásìkò àtúnṣe afárá Third Mainland Wo ìgbẹ́sẹ̀ méjọ tí ilé aṣòfin ìpínlẹ̀ gbọdọ̀ tẹ̀lé láti yọ igbákejì gómìnà Ilé aṣofin Ondo fọwọ́ òsì júwe ilé fún aṣòfin mẹ́ta pé wọ́n tàpá sí òfin ilé Diẹ ree lara awọn ilana ti ajọ to n ṣe amojuto awọn papakọ ni Naijiria, FAAN,gbe kalẹ.
Akẹẹkọ Victor gba ẹbun ẹ̀kọ́ ọ̀fẹ́ fun ọdun kan pẹlu owó iwe ti yoo lo pata lẹyin to jawe olubori ninu idije naa.
Iroyin sọ wipe awọn eeyan mẹjọ ọhun ku nigba ti ọkọ agbepo kan ati ọkọ akẹru kan kọlu ara wọn, ti ọkọ agbepo naa si gbinna.
ọgbọọgba ni ẹ sì gbọdọ̀ pín in.
Ibẹ̀ ni wọ́n ti yin OLUWA.
O ni orilẹ-ede Naijiria lee bọ gbogbo ẹkun iwọ oorun Afirika bi awọn adari rẹ ba gbajumọ idagbasoke eto ọgbin.
OLUWA ní,“Kí ni gbogbo ẹbọ yín jámọ́ fún mi?
Ṣugbọn OLUWA Ọlọrun yín yóo fi wọ́n lé yín lọ́wọ́, yóo sì mú kí ìdàrúdàpọ̀ bẹ́ sílẹ̀ ní ààrin wọn títí tí wọn yóo fi parun.
Ẹ̀ṣẹ̀ wo ni a ṣẹ OLUWA Ọlọrun wa?
Awọn osisẹ eleto ilera ti ni awọn ni abẹrẹ ajẹsara to le tọju awọn ọmọde kaakiri Naijiria, amọ awọn obi miran si n kọ fun ọmọ wọn lati gba ajẹsara.
Nítorí mo gbé òkúta kan tí ó ní ojú meje siwaju Joṣua, n óo sì kọ àkọlé kan sórí rẹ̀.
O gba ami ẹ̀yẹ OFR, to si ti ṣe ọ̀pọ̀lọpọ̀ eré tíátà ní èdè oyinbo àti Yorùbá.
Nítorí ó wà ní àkọsílẹ̀ pé,“Ta ni ó mọ inú Oluwa?
Mo bá tọ àwọn gomina ìgbèríko òdìkejì odò lọ mo fún wọn ní lẹta tí ọba kọ.
Ọrọ ile gbigbe, eto irinna, ati ọrọ awọn asatipo lo jẹ ẹ logun.
Ọdun 2010 ni o kede pe oun ni aarun jẹjẹrẹ inu oronro.
Ṣugbọn nígbà tí ìwọ bá ń gbadura, wọ inú yàrá rẹ lọ, ti ìlẹ̀kùn rẹ, kí o gbadura sí Baba rẹ tí ó wà ní ìkọ̀kọ̀.
Ṣugbọn obinrin náà dáhùn pé, “Bẹ́ẹ̀ ni, alàgbà, ṣugbọn àwọn ajá a máa jẹ ẹ̀rúnrún oúnjẹ àwọn ọmọ tí ó bá bọ́ sílẹ̀ láti orí tabili.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Aarẹ ajọ EU, Jean-Claude Juncker sọ pe ajọ EU ko ni 'pada duna-dura'' lori igbesẹ ti Britain fẹ ẹ gbe ọhun Awọn kan to bẹnu ẹtẹ lu igbesẹ naa woye pe orilẹede United Kingdom ko le yọ ọwọ kuro ninu adehun lilo ofin kan na fun ẹnu'bode ilu pẹlu Northern Ireland laiṣe pe ajọ EU f'ọwọ si.
Gbogbo ẹ̀yin ọ̀ba abẹ́ mi, tí ẹ̀ ń ta ilẹ̀ ìlú, ẹ kò ní fara re lọ - Oluwo Ìgbà mẹ́rin tí ọ̀rọ̀ Oluwo dá awuyewuye sílẹ̀ Ìjọba Ọṣun ti dásí ìjà láàrin Oluwo àti Agbowu Anthony Joshua gba nọ́mbà ìdánimọ̀ NIN, àwọn ọmọ Nàìjíríà kan kérora lórí ètò náà ''Ti awọn eeyan ba wa fẹjọ wọn sun mi, mo maa n sọ fun wọn pe ade mi lo wa lori wọn, ẹ ma ba wọn ja.
Awon asoju ohun ni a ti ri minisita fun oro iroyin ati asa, Alhaji Lai Mohammed, minisita fun oro abele, Abdulrahman Danbazau, minisita fun oro alaafia abele, Khadija Bukhar Abba ni won n lo si Dapchi bayii.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ṣé fífi òrí pa ọwọ́ rẹ leè dáàbò bò ọ́ lọ́wọ́ Coronavirus?
Wolii Ahija bọ́ ẹ̀wù àwọ̀lékè tuntun tí ó wọ̀, ó ya á sí ọ̀nà mejila.
” Adesanya tesiwaju pe, awon oga agba ti won sese yan ni: AVM Charles Otegbade, leni ti o je oga agba to n mojuto eka sise agbakale eto nile ise NAF, ni bayii, oun ni oga agba eka eto ibanisoro ati iforotonileti (CCIS).
Kí a tó bọ sí inú ọkọ̀ ó ti béèrè nípa Fìlásayépọ̀ nítorí ó wí pé ẹgbọ́n òun ni, bàbá rẹ̀ jẹ́ àbúrò bàbá òun àwọn méjéèjì wá jẹ́ àbúrò olókun tíí ṣe alákòóso omi.
"Ibikibi ti a ba rin si, wọn a máa na ika aleebu sí wa pe iyawo Boko haram ni wa Afi bi igba pe ebi wa ni bi wọn ti ṣe mu wa l'ẹru.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù EFCC: Irọ́ ni Fayoṣe ń pa, àwọn ilé rẹ̀ gangan la tì pa 22 Bélú 2018 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 23 Bélú 2018 Oríṣun àwòrán, Olasunkanmi Ogunmuko Ajọ EFCC ti ti awọn ile kan pa ni Ado Ekiti ti wọn funra si pe o jẹ ti Gomina ana ni ipinlẹ Ekiti Ayo Fayose.
 Bakan naa ni o tun rọ ijọba lati din inawo wọn ku paapaa owo ti wọn n na lori awọn alakoso ati oloṣelu gẹgẹ bi owo atigbadegba.
Gomina Ipinlẹ Ondo tun fọwọ sọya pe oun ko ni baba isalẹ kankan, Ọlọrun ni baba isalẹ oun.
Oríṣun àwòrán, Instagram/nairamarley Amọ, oun naa ko faramọ aba awọn eeyan pe ki wọn ko ọlọpaa SARS nlẹ, o ni ijọba ko nilo lati ko ọlọpaa nilẹ wi pe atunṣe ni wọn nilo.
Wọn ni ohun to fa ọwọngogo yii ni wi pe, oke okun ni wọn ti n ra awọn eronja yii tẹlẹ, amọ nitori ijọba ti yọ owo iranwọ lori awọn ounjẹ lati okeere, eleyii ti mu ki ohun gbogbo nira fun awọn eniyan.
Òjò yóo rọ̀ fún Israẹli ní àkókò rẹ̀,omi yóo jáde láti inú agbè rẹ̀;àwọn ohun ọ̀gbìn rẹ̀ yóo sì rí omi mu.
Igbesẹ yi jẹ ọna kan gboogi ti ijọba lawọn fẹ fi ran onileeṣẹ kekeeke lati fidi ileeṣẹ wọn mulẹ lẹyin Covid-19.
 lára àwọn tí ó ní àrùn líle , ikú maa ń wáyé lára àwọn ìdajì ènìyàn tí kògba ìtọjú .
”  “Bakan naa, ki kopa ninu idije La Liga je ohun ti mo ni lokan lojo toti pe.
Kí ni ẹnikẹ́ni tí obinrin bí já mọ́, tí ó fi lè jẹ́ olódodo?
Eleyii ni yoo jẹ igba keji ti
Lọdun 2015,ajọisọkan agbaye UN ṣe afojusun pe iye eeyan to kọja ọgọta ọdun ni Naijiria to 8,108,000 Owo ti wọn yoo na lati tọju ẹni to kọja ọgọta ọdun laarin ọdun kan sunmọ $2,852, gẹgẹ bi ohun ti ajọ to n ri si ifọwọsopọ eto ọrọ aje ati idagbasoke(OECD) Owo ti wọn yoo na lati tọju gbogbo ẹni to kọja ọgọta ọdun laarin ọdun kan ni Naijiria yoo to $1,759,436,000.
agbaboolu ti o ti kopa seyin fun orile-ede Naijiria ati nile Afrika(Nigerian
Ọga ileesẹ panapana Queensland Cameron Thomas ni niṣe ni ayekootọ naa n lọgun Anton"" titi ti olowo rẹ fi taji loju oorun."
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Kí lo mọ̀ nípa Ṣeyi Makinde?
Wo ojú àwọn tó na ìka máa lọ ilé sí Praise nilé ẹlẹ́gbọ́n àgbà BBNaija Iròyìn àyọ, àdínkù tún bá iye ènìyàn tó lùgbàdì Covid -19 ní Nàìjíríà lọ́jọ́ Àìkú Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Ìgbà tí mo máa fi lajú sáyé padà, ọ̀fọ̀ ikú mi ní wọ́n ń kígbe' 'Mo lè fọwọ̀ sọ̀yà fún yín pé Sunday Shodipe ti wà láhàmọ́ wa - Alukoro Ọlọ́pàá Oyo Iroyin to n tẹwa lọwọ sọ pe ọwọ awọn ọlọpaa ipinlẹ Oyo ti tẹ arakunrin kan, Sunday Shodipe to sa mọ wọn lọwọ laipẹ yi.
“Ìwọ ọmọ eniyan, wí fún àwọn eniyan rẹ pé, bí olódodo bá dẹ́ṣẹ̀ ìwà òdodo rẹ̀ kò ní gbà á là, bẹ́ẹ̀ sì ni bí eniyan burúkú bá yí ìwà rẹ̀ pada, kò ní kú nítorí ìwà burúkú rẹ̀.
Gege bi Mahrez se so,“Inu mi dun pupo lati darapo mo iko Man City, iko agbaboolu kan gbogi ti o tun wa labe akoso okan lara akonimoogba ti o darajulo lagbaye, Pep Guardiola,.
Lati le mu ki eyi o ṣeeṣe , ijọba ti paṣẹ fun gbogbo awọn ileeṣẹ to ni ọkọ akẹru ati ọkọ agbepo lati ko ẹru wọn kuro ni awọn oju ọna to wọ ibudokọ oju omi naa laarin wakati mejilelaadọrin.
O ni ki wọn ta kete sawọn owo-o-magọ ati olowo igbo tii n ṣilẹ f'ole, ti wọn lee fẹ fi owo ra apere ọba ilu naa nitori pe, gẹgẹ bi Ọbalaye naa ṣe sọ, ifasẹyin ni iru wọn maa n fa ba ilu.
Ṣe ẹ ranti Favour Daley Oladele ni nkan bii ọsẹ diẹ sẹyin ti ọrẹkunrin rẹ Owolabi ati iya rẹ ati Woli rẹ pa ti wọn si ge ẹran ara rẹ fi ṣe asejẹ ki Owolabi ati iya rẹ le di ọlọla laye.
Nítorí ọpọlọpọ ìwà àgbèrè Ninefe,tí wọ́n fanimọ́ra,ṣugbọn tí wọ́n kún fún òògùn olóró,ni gbogbo ìjìyà yìí ṣe dé bá a;nítorí ó ń fi ìwà àgbèrè rẹ̀ tan àwọn orílẹ̀-èdè jẹ,ó sì ń fi òògùn rẹ̀ mú àwọn eniyan.
N óo mú kí ọjọ́ ọ̀la dára fun yín, n óo sì fun yín ní ìrètí.
'Ohun gbogbo to wa ni bẹ lo danu ati ohun elo wọn, ko si si ohun kankan to ku mọ.
Bawo ni mo ṣe le daabo bo ara mi?
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìjọba Ọ̀sun: N1.
lati maa ṣora fun ọrọ aabo nipa wiwa lojufo ni gbogbo igba fun aabo wa nitori
Ṣekinat Quardir(NAIJIRIA) Àkọlé àwòrán, Sekinat Quadri Ọmọdébìnrin yìí Sekinat Quadri jẹ́ kí àwọn òbí rẹ̀ mọ́ pé abẹ̀sẹ́kùbíòjò ló wu òun, wọ́n sì ń tíì lẹ́yìn.
Lọwọlọwọ, ipo Kẹjọ ti wọn wa lori afara ti ja wọn ni ireti ṣugbọn ti wọn ba fi le na Chelsea ni Wembley, wọn yoo lanfaani lati kopa ninu idije Europa.
Wọn óo pa àwọn ọmọ wọn; tọkunrin tobinrin, wọn óo sì dáná sun ilé wọn.
25 Àti pé, kíyèsíi, mo ti fi ẹ̀bùn kan fún ọ, bí ìwọ bá fẹ́ láti ọ̀dọ̀ mi, láti lè túmọ̀, àní bíi ti ìránṣẹ mi Joseph.
Progressives Congress (APC), Asiwaju Bola Tinubu; gomina ipinle ogun teleri ,
Nígbà tí àwọn olórí alufaa ati àwọn Farisi gbọ́ àwọn òwe wọnyi, wọ́n mọ̀ pé àwọn ni ó ń bá wí.
Amọ, ẹgbẹ oṣiṣẹ NLC ti ni gbogbo ọmọ Naijiria ni yoo kopa ninu iyanṣelodi yii nitori gbogbo ọmọ Niajiria lo n jẹ irọra bi wọn ṣe fikun owo epo ati ina ijọba ni Naijiria.
 ifoloko kerin , eyun ifoloke 93 united airlines jalulole leba shanksville , pennsylvania ni ago 10 : 03 a.
Omotola Jalade-Ekeinde: Olùrànlọ́wọ́ Ààrẹ Buhari fèsì sọ́rọ̀ Omotola
Ile igbimọ aṣofin to ni aṣofin mọkandinlaadọfa to jẹ aṣofin agba ati ọgọta le ọọdunrun to jẹ aṣojuṣofin wa ni olu ilu orilẹede yii, Abuja nibi ti wọn ti n ṣe ofin eyi to yẹ ko ni ṣe pẹlu gbogbo araalu eyi ti wọn n ṣoju.
Ajọ naa ṣalaye siwaju sii wipe ko si idi ati da owo pada fun ẹnikẹni nitori owo naa ni wọn fi se eto ẹkọsẹ wọn ati asọ isẹ wọn.
Ile ẹjọ kotẹmilọrun ti da ẹjọ wi pe Gomina ipinlẹ Ọyo, Abiola Ajimobi ni asẹ lati yan ọba ni ipinlẹ Ọyọ.
isẹ pupọ lo wa fun ile igbimo asofin  lati se, ni paapaa julọ lori eto ẹkọ,eto
Ibẹru yii lo maa n jẹ ki pupọ ninu wa o san owo yii.
Oúnjẹ alẹ́ ni wọ́n ń fi Ọ̀ọ̀nì ṣe níbí Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí 2 sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 2:23 Fídíò, Water Generator: Ó leè ṣiṣẹ fún wákàtí mẹfà, kó tó sinmi, Duration 2,2310 Òkùdu 2020 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
Missing Child: Òbí àti asọ́nà ṣọ́ọ̀ṣì 14, lọ́ búra nì'dí imọlẹ̀ l'Akure Yorùbá tone mark: Fífi àmì ohùn sí orí ọ̀rọ̀ Yorùbá ṣe pàtàkì Àwọtẹ́lẹ̀ ọkùnrin àti Ìdọ̀tí Kilo méje ṣekú pa Ìgalà Ibodè tí a tì ló fa ọ̀wọ́ngógó owó ọjà- Ìjọba Naijiria Pataki 'Speed Limiter' ninu ọkọ rẹ: O fikun un wi pe ti ọkọ ba ni ẹrọ yii ninu ọkọ, igbakiigba ti wọn ba ti kọja ila ni ọkọ naa yoo kọ lati sisẹ afi ti wọn ba da ọkọ naa pada si iye to yẹ ki wọn ma a rin loju popo.
APC, PDP di ẹgbẹ́ aládúrà nítorí ìdájọ́ èsì ìdìbò Ọṣun Ilé ẹjọ́ yọ ìbò 2,029 nínú ìbò APC, 1,246 nínú ibò PDP l'Ọṣun Ninu ọrọ tirẹ, oluranlọwọ fun Olusola Ẹlẹka, Ọgbẹni Felix Olusola sọ pe ẹjọ ti wọn da ni ile ẹjọ akọkọ ati ẹkeji ni bakan ninu.
Tipátipá ni a fi dé Kinidusi.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, World Diabetes Day: Ọdún kọkandinlogun ti mo ti wà lẹ́nu itọ ṣúgà nìyí Bakan naa ni wọn tun fihan ninu iwadii naa pe iwa igbesunmọmi ti n pọ sii lagbaye.
O salaye awọn nnkan maarun to yẹ ki asọra pẹlu bi a ti ṣe n lo wọn ninu ile.
Ṣugbọn bí eniyan bá fi ọrẹ tí ó wà lórí pẹpẹ ìrúbọ búra, olúwarẹ̀ níláti mú ìbúra rẹ̀ ṣẹ.
nítorí pé kò sé inú ìyá minígbà tí ó fẹ́ bí mi,bẹ́ẹ̀ ni kò sì mú ibi kúrò lọ́nà mi.
Ṣugbọn lati igba ti Aarẹ ilẹ America, Donald Trump ti sọ pe Chloroquine le gbogun ti aarun tuntun yii, ni ọpọ eniyan ti n lo oogun naa lọna aitọ.
Ni alágbe náà bá pariwo pé, “Jesu, ọmọ Dafidi, ṣàánú mi!
Jaiye Kuti Lara awọn agba oṣerebinrin ni Jaiye Kuti.
fun awon ipinle Borno,Adamawa ati Yobe ti iko olote Boko Haram so di alainile
Iṣẹlẹ ẹmi akẹkọọ to bọ naa, mu káwọn akẹẹgbẹ rẹ tutọ soke, fi oju gbaa, ti wọn si ransẹ síra wọn yika awọn fasiti ilẹ wa pe rogbodiyan ya.
"Nkan tí a mọ̀ nìyíì Mo ti kúrò ní ààfin Oyo, kí ìròyìn tó ò jáde pé èmi àti Wasiu Ayinde n fẹ́ ara wa - Olori Badirat ""Ṣugbọn inu mi ko dun rara lẹyin ti mo gbọ pe wọn tun ti n tahun si ara wọn, paapaa julọ Obasanjo,"" Adebanjo lo sọ bẹẹ."
Ọlọrun ló ni ọgbọ́n ati agbára,tirẹ̀ ni ìmọ̀ràn ati ìmọ̀.
 ju ìdá 95 % ikú wọ ̀ nyíi ń ṣẹlẹ ̀ ni asia àti africa .
 nígbà tí ìròyìn kàn án nípa ohun tí jìjì ń fẹ ́ kí ó tó lè bá ọkùnrin kan lọ , inú rẹ ̀ dùn púpọ ̀ .
Sugbọn to ba jẹ wi pe nkan to pinnu lati ṣe niyi, a jẹ wi pe yoo ṣe aṣeyọri.
Odunlade fijó bẹ́ẹ, Lizzy padà sọ́dún 2012, Toyin Abraham tọ̀ lẹ́ẹ̀mẹwàá Ajọ Amnesty International ní kò dín ní 119 ọmọ Nàìjíríà ti wọ́n ti gba ìdájọ́ ikú ní Malaysia Taló ya fídíò ibi tí Aisha Buhari ti ń bínú ní Aso Rock?
Ọpọ awọn ololufẹ Manchester United kaakiri agbaye lo ti bẹrẹ si n jẹ ọrọ Ighalo lẹnu bi ẹni jẹ iṣu lẹyin aṣeyọri Manchester United ninu ifẹsẹwọnsẹ naa, papa julọ fun ipa to ko.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ogun Majek: Ọmọ, ẹbí àti àwọn òṣèré tíátà ló péjú sìnkú olóògbé 25 Òkùdu 2020 Gbajumọ osere tiata to doloogbe ni idaji ọjọru, Gbolagade Majekodunmi ti wọ kaa ilẹ sun ni ọsan oni.
N kò lè dá ṣe rere tabi burúkú ní agbára mi, ohun tí OLUWA bá sọ ni n óo sọ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Genotype: Kí làwọn àǹfàni àti ewu tí ẹ̀yà jínótáìpù rẹ le mú bá ìgbé ayé rẹ̀?
Oríṣun àwòrán, Federal ministry of indo&culture Wo bi wa a ṣe fi orukọ silẹ Lọ si oju opo ayelujara nyif.
Nigba to n gbe idajọ kalẹ lori ẹsun sise onigbọwọ lati ji ọmọ gbe, adajọ Odusola ni awọn olujẹjọ kinni de ikẹfa jẹbi ẹsun naa Nigba to n yiiri ẹsun kẹta wo, tii se biba awọn ẹri to se koko nipa ẹjọ naa jẹ, adajọ ni ki olujẹjọ keje, Peter Anjorin maa lọ sile ni alaafia, tori ko jẹbi gbogbo awọn ẹsun ti wọn fi kan rara.
lasiko ti won n pese atileyin fun awon iko ogun 145, ni ami ẹyẹ.
Ọmọ ijọ Christ the King Catholic Church ni agbegbe Ajegunle Apapa ni Immaculate to si ṣi ni baba, laye ati aburo/ẹgbọn ọkunrin l'aye.
Tẹ o ba gbagbe, ọjọ Aje ni ileesẹ ọlọpaa ipinlẹ Oyo ṣe afihan awọn afurasi to ji awọn ibeji ọhun gbe, ki wọn to ri wọn pada, ti obìnrin kan si wa ni aarin wọn.
Lẹ́yìn gbogbo ìgbìyànju ti ọmọ náà kò si jẹ́ rírí, Arabinrin Kolawole ni olùdásilẹ̀ ijọ náà ko gbe igbésẹ̀ kan to ṣe koko, èyí ló fàá ti òun fi ke gbajare sita ti Deji Akure si fi pa a láṣẹ̀ pé ki awọn wa bura.
Alaga ajọ eleto lo ni ojuṣe ati ka gbogbo abajade esi idibo loju gbogbo eniyan.
Nítorí ìjayà bá wọn nígbà tí a pàṣẹ fún wọn pé, “Bí ẹranko bá fi ara kan òkè náà, a níláti sọ ọ́ ní òkúta pa ni!
Sultan Qaboos bin Said ni adari to ṣakoso ijọba orilẹede Oman to pẹ ju lagbaye.
Funkẹ kọ ẹkọ nipa ere itage ni Fasiti Olabisi Onabanjo, bakan naa lo gboye Diploma ninu imọ ofin nile iwe yii kan naa.
Èyí túmọ̀ sí pé iye àsìkò tí a bá lò pẹ̀lú aláàrùn Covid-19 ni yóò sọ bóyá ènìyàn leè kó ààrùn náà, tí a bá lo àsìkò kúkúrú bí ti àwọn to n sáré lójú pópó, o ṣeéṣe ki a máa ni ààrùn náà kódà bi kò sí àlàfo mítà méjì, nítorí náà, àwọn ti ó yẹ kó kàn wá gbọ̀ngbọ̀n ni àwọn tó ti fàmìhàn Oríṣun àwòrán, Getty Images Lóòótọ́ ni ikọ́ àti kàtá máa ṣe ìtànkálẹ̀ ààrùn, ṣùgbọ́n o ní bi èyí ṣe lè wáyé.
Ati pe irọ ni ohun ti wọn n sọ lori ayelujara pe Aisha de pẹlu ibinu si Aso Rock ni ana.
 Ìyen ni pé méjèèjì ni ó wà nínú ìmò wa gégé bí eni tí ó gbó yorùbá .
Àwọn ọmọbinrin yín ni yóo máa ṣe turari fún un, wọn óo sì máa se oúnjẹ fún un.
Síbẹ̀, bí mínísítà fún ètò ìdájọ tó jẹ́ mínísítà kẹ̀ta ṣe tún kọ̀wé fipò sílẹ̀, kò mú àdínkù bá ìbínú àwọn ará ìlú.
Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Ondo politics: Ilé ẹjọ́ da ìpèjọ́ pé Akeredolu kọ ló wọlé ìdìbò ìpińlẹ̀ Ondo nù16 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 US election 2020: Àlàyé rèé lórí bí èèyàn 538 ṣe ń yan ààrẹ lé èèyàn mílíọ̀nù 331 ní Amẹ́ríkà15 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Ede Poly Rector suspension: Wọ́n ní kí ọ̀gá àgbà Pólì Ede lọ rọ́kún ńlé lórí ẹ̀sùn pé 'ó kan bẹ́ẹ̀dì sí ọ́fíìsì'15 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 New Covid 19 update: Ẹ̀yà kòkòrò Covid-19 míràn jáde ní ọgọ́ta agbègbè nílẹ̀ Gẹẹsi, àjọ elétò ìlera fọkàn ará ìlú balẹ̀15 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Kankara Abduction: Àwọn ológun ṣàlàyé ìdí tí wọ́n fi yọ̀nda àwọn tó jí àwọn akẹ́kọ̀ọ́ gbé.
A leè fi Dòdò Ìkirè mu gaarìí, jẹ tàbí mu ẹ̀kọ́.
"Oríṣun àwòrán, @NGRPresident Àkọlé àwòrán, ireti ọpọ ọmọ Naijiria fun igba pipẹ ni lati ri Aarẹ Buhari jade sita gbangba tako ikọlu awọn darandaran fulani to ti n di lemọlemọ ""Ijọba ko ni faaye gba ikọlu awọn darandaran fulani ati janduku mọ."
Urban Study Group, ẹgbẹ́ aṣiṣẹ́ ọ̀fẹ́-tí-kò-ní-èrè tí ó máa ń fi ààbò fún àwọn ohun àjogúnbá Dhaka Àtijọ́ fi ìwé ẹ̀dùn ìdáwọ́dúróo àdàwólulẹ̀ náà ránṣẹ́ sí àwọn tí ọ̀rán kàn, tí ó sì mẹ́nu ba àṣẹ Ilé-ẹjọ́ Gíga.
Ẹ lọ mú apó àti ọfà yín, kí ẹ jẹ́ kí a lọ sínú pápá ti ń bẹ lẹ́yìnkùnlé mi, ìgbà tí a bá dé ọ̀hún, kí olúkúlùkù ta ọ̀fà síwájú, ẹni tí ọfà rẹ̀ bá rìn jìnà jù ni yóò ṣe baálé Ẹwadapọ̀, ìwọ̀ntunwọ̀nsì lobìrin.
7 2211967 Orilẹede Colombia 47491 95.
Bí a bá jẹ́ ojúlówó ọmọ Yorùbá tí ìmọ̀ èdè wa sì dájú, bí i pé à ń fẹran jẹ̀kọ ló yẹ kí títúmọ̀ èdè Yorùbá jẹ́.
Afirika  naa yoo wa nibẹ pẹlu .
Ọwọ́ ọlọ́pàá tẹ afurasí ọkùnrin tó gé akẹ́kọ̀ọ́ ọ̀rẹ́bìnrin rẹ̀ wẹ́lẹ́ wẹ́lẹ́ fún òògùn owó ní Ikorodu Iléeṣẹ́ ọlọ́pàá sọ afurasí ọlọ́pàá tó yìnbọn fún ọ̀dọ́kùnrin tó fún èèyàn lóyún s'átìmọ́lé Wo bí odò Nile tó gùn jù l'Áfíríkà, ṣe ń fójúu ilẹ̀ Egypt, Ethiopia àti Sudan han màbo Ọ̀wọ́ngógó búrẹ́dì gbòde kàn lẹ́yìn tí àwọn oníbúrẹ́dì da iṣẹ́ sílẹ̀ Sudan tí bẹ̀rẹ̀ ìjìròrò lórí bí US yóò ṣe yọ òrúkọ̀ wọn kúrò nínù ikọ̀ agbẹ́sùnmọ̀mí àgbáyé IKILỌ Ijọba ti kilọ pe ki ẹ fara balẹ kọ gbogbo ohun to ba yẹ lasiko iforukọsilẹ.
Àkọsílẹ̀ fihàn pé ọgọ́fà dín méjì ọmọ ilẹ̀ Nàíjììrà ló ti pàdánù ẹ̀mí wọn ní orílẹ̀èdè South Africa láti ọdún 2016 sí àkókó yìí.
Mo ṣe ọ́ lọ́ṣọ̀ọ́, mo fi ẹ̀gbà sí ọ lọ́wọ́; mo sì fi ìlẹ̀kẹ̀ sí ọ lọ́rùn.
Samuel nikan kọ lo n ṣe iru iṣẹ yii ninu ile ti obinrin naa n gbe.
Ida mejilelọgbọn awọn to ri iṣẹ ijọba laarin ọdun mẹta sẹyin ni wọn sanwo riba ki wọn to ri iṣẹ ijọba gba eleyii to pọ ju irufẹ ayẹwo bẹẹ ni ọdun 2016 ni ilọpo meji.
Aare Muhammadu Buhari ti fi idunnu re han lori igberu ti o n ba eto ogbin, igbese kan gboogi lati pese ise fun awon odo langba lorile-ede Naijiria.
Mo wá rí ẹṣin funfun kan.
Mo rántí ìjà emi àti Àǹjànnù-ìbẹ̀rù ní ibodè Igbó Olódùmarè mo sì pinnu àti ṣe gudugudu méje.
àwọn àgbààgbà ìlú náà wí fún Hanuni ọba wọn pé, “Ṣé o rò pé baba rẹ ni Dafidi bu ọlá fún tóbẹ́ẹ̀, tí ó fi rán àwọn oníṣẹ́ láti wá tù ọ́ ninu?
Maricas Road Ọkùnrin kan kú si ìyárá ìtura BBC 100 Women 2019: ọ̀pọ̀ obìnrin ilẹ̀ Afirika ń gbàràdá!
Atunse lori eto aabo yoo dekun
nítorí àwọn ohun-ìjà wa kì í ṣe ti ayé, agbára Ọlọrun ni, tí a lè fi wó ìlú olódi.
Oríṣun àwòrán, @MBuhari Àkọlé àwòrán, Buhari bẹrẹ abẹwo ni Taraba lẹyin awuyewuye Abẹwo rẹ si Taraba je akọkọ ninu eleyi ti o ti la kalẹ si awọn ipinlẹ ti ikọlu ti'n waye lorilẹẹde Naijiria.
Bakan naa, awọn eeyan to ni aisan atọgbẹ tabi itọ suga, aisan ọkan atawọn oniruuru aisan miran to maa n sediwọ fun eroja insulin lati sisẹ ninu ara, naa maa n fa ki ikun tobi.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Botilẹjẹ pe Manchester City ja fita-fita, Manchester United papa tun gba bọọlu miran wọle lati ọwọ Scott McTominay, nigba ti idije naa wọ iṣẹju mẹrindinlọgọrun.
Mike Tyson gangan lo mu mi fẹran jija ẹṣẹ amọ Joshua lo n ti mi soke pe mo lee moke tori ọmọ Naijiria bii emi loun.
Lojoojumọ ni mò ń ké pè ọ́, OLUWA;tí mò ń tẹ́wọ́ adura sí ọ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Wo àwọn àwòràn tó làmìlaaka nílẹ̀ Adúláwọ̀ lọ́sẹ̀ yìí 31 Ògún 2019 Oríṣun àwòrán, Reuters Àkọlé àwòrán, DJ Arafat, gbogbo Abidjan wa riri lati bu ọla fun un.
Alẹ ọjọ Iṣẹgun ni iṣẹlẹ naa waye lẹyin ti àwọn ọdọ naa ti n ṣe iwọde kaakiri Naijiria pe ki ijọba fi opin si aṣilo agbara awọn ọlọpaa.
Olarewaju Bamidele fi 'Screw driver' gún ìyáwo rẹ̀ pa Ọ̀pọ̀ ẹ̀mí ènìyàn lo ti sọnù nítorí àìsàn Iba Lassa ní Kano àti Ondo Ọọ̀ni obìnrin, Lúwòó Gbàgídà rèé, akọni tó ń gun ọkùnrin ní ẹṣin rìn Ìríwísí àwọn aráàlú bí EFCC ṣe kó afurasí ọmọ yahoo 49 ní Ibadan Ki i ṣe awọn oniṣẹ ilera nikan ni aisan naa ti ran, igba eniyan lo ti ni arun yii lara lati Osu Kejila, ọdun to kọja.
“Lọ sọ fún Dafidi pé, ‘OLUWA ní, nǹkan mẹta ni òun fi siwaju rẹ, kí o yan èyí tí o bá fẹ́ kí òun ṣe sí ọ ninu wọn.
”I waited patiently upon the Almighty the King of kings, he eventually did it in the midst of many trials.
Atejade gbogbo oruko ti won yan naa niyi ati ami eye kookan:
Iṣẹlẹ kan to ṣẹlẹ sẹyin ni ile ẹjọ giga ti ijọba apapọ nilu Abuja sọ pe ki awọn to ṣe oniduro fun olori ẹgbẹ́ to n polongo fun idasilẹ orilẹ-ede Biafra, Nnamdi Kanu, san ọgọrun un miliọnu ẹni kọọkan wọn sile ẹjọ.
Ninu ọkan ninu awọn fidio naa, Sẹnetọ Misau sọ pe oun ko faramọ bi Aarẹ Muhammadu Buhari ṣe yan ẹni ti m'ọṣẹ si ipo Oludari Agba fun ajọ Ọtẹlẹmuyẹ Naijiria.
Àwọn ọmọ Jehieli meji: Setamu ati Joẹli ni wọ́n ń bojútó àwọn ibi ìṣúra tí ó wà ninu ilé OLUWA.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, International Day Against Drug Abuse and Trafficking: ìdí ti mo fi ń mu oògùn olóró Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Iyabo Ojo Lasiko isede yii, ọpọ awọn ololufẹ awọn oṣere lo tun n wọ lọ si oju opo ayelujara oṣerebinrin Iyabo Ojo pẹlu ọna to n gba da awọn eeyan lara ya ṣugbọn nigba tọrọ ifipabanilopọ bẹrẹ si ni gbode, ọna mii ni Iyabo gba yọ pẹlu fọnran to fi sita ninu aṣọ dudu ati omije loju pe oun to ba ni lọkan jẹ ni ki awọn to yẹ ko maa da abo awọn ọmọde sọ ara wọn di eṣu to n fipabaniopọ.
Talaka tí ń rìn pẹlu òtítọ́ inúsàn ju ọlọ́rọ̀ tí ń hùwà àgàbàgebè lọ.
" Ó ti di "" architect ' kí ó tó di 1873 ."
Ajọ JAMB sun opin ọjọ iforukosilẹ idanwo s'iwaju
Awọn ipinlẹ ti aarun naa ti de ni Lagos Abuja Osun Edo Oyo Bauchi Akwa Ibom Kaduna Ogun Enugu Ekiti Kwara Rivers Benue Ondo Delta Katsina Anambra Niger Kano Apapọ wọn jẹ: mọkandinlogun ati Abuja to jẹ olu ilu Naijiria.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Alaga apapọ fun ẹgbẹ oselu PDP, Uche Secondus lo ko igbimọ ẹlẹni mọkanlelogun sodi, lati se abẹwo ikinni si ọdọ Ọbasanjọ.
Ogbeni agbaje ni o le ni milionu kan  awon oludibo  ti won gba kaadi idibo won lati fi dibo bayii.
Ní ọjọ́ kan náà, ọba ya ààrin gbùngbùn àgbàlá tí ó wà níwájú ilé ìsìn sí mímọ́.
Ò ti pé ọdún 27 tí Shah Rukh Khan ti ń se fíìmù India Nigba ti wọn pari iṣẹ abẹ naa ni awọn dokita rii pe ọpọlọpọ owó ṣile ni wọn ko sita ninu ọmọbinrin naa ati goolu ti iwọn rẹ tó kilo kan ati abo giraamu.
A ti kọwé sí ìjọba àpapò làti pe agbaṣèṣe odò Asa padà- Gomina Kwara.
Nitori idi eyi, ko tọ bi wọn ti ṣe wo apa kan ileesẹ ijọba Naijiria ni Ghana lọjọ kọkandinlogun oṣu Kẹfa.
Ara rẹ̀ ṣi ń gbọ̀n lẹ́yìn oṣù méjì.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Sogidi Lake: Kòṣẹja-kòṣèèyàn lá bá nínú adágún odò náà -Ojedele Alaafin Sango sọ iwa orikunkun ti Timi Agbale hu si i fun Gbọnka, to si ni ko lọ mu u wa silu Ọyọ; amọ se ni Ọba pe awọn ọmọogun to n tẹle Gbọnka lọ si Ẹdẹ sẹyin, to si pasẹ pé wọn gbọdọ ri i daju pe wọn pa a eyi ti ko han si Gbọnka funra rẹ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, International Womens day: Àwọn obìrintọ́kasí pàtàkì ìbáraẹnidọ́gba láárin ọmọnìyàn 5.
Ọwọ́jà coronavirus yóò ṣì wà pẹ̀lú àgbáyé fún ìgbà pípẹ́- Ngozi Okonjo-Iweala Ìjọba àpapọ̀, ẹ so ifilọlẹ ẹ̀rọ alatagba 5G rọ na - ilé asofin àgbà Wo àwọn to ti rí ìwòsàn lọ́wọ́ àrùn coronavirus àti ibi tí wọ́n ti wá káàkiri Nàìjíríà Mẹ́rin nínú àwọn mọ́kànlá tó ń bọ̀ láti Sokoto tí wón mú l'Oyo ló ní Coronavirus Àwọn ọlọkọ èrò naa, lásìkò ti wọ́n ń báwọn akọroyin ileeṣẹ iroyin kan, 'Oyo insight' sọ̀rọ̀ ṣàlàyé pé, ọọdunrun náírà péré ni ìjọba Ọ̀yọ́ paa ni àṣẹ fún àwọn láti máa san lojumọ, tí Auxiliary gan-an sì wá sọ fún àwọn fúnra rẹ, àmọ́ nígbà tó yá ni àwọn ọmọ ẹ̀yìn rẹ̀ padà wá pé, ibudokọ kọ̀ọ̀kan ni àwọn yóò ti máa san ọgọrun náírà báyìí ni àárọ̀ àti Alẹ́, èyí tí yóò jẹ́ egbèje náírà, #1, 400, yàtọ̀ sí owó tijọba.
Aare so pe : “Ajo ECOWAS yoo tun tesiwaju lati  maa se  ohun iwuri  fun awon to ba da okoowo sile lati ile okeere.
Ọkọ Salami ti lo ọjọ marun-un ninu ọgba TRACE, nitori pe wọn ni ko san ẹgbẹrun lọna okoolerugba o din marun-un Naira, gẹgẹ bi owo itanran.
Wọ́n bá wá, wọ́n bẹ̀ wọ́n.
30 Kíyèsíi, mo wí fún ọ, pé ìwọ kì yíò tún túmọ̀ lẹ́ẹ̀kansíi àwọn ọ̀rọ̀ wọ̃nnì tí o ti jáde lọ kúrò ní ọwọ́ rẹ.
àwọn ìlú marun-un pẹlu àwọn ìgbèríko tí ó yí wọn ká títí dé ìlú Baali.
Bí ẹnikẹ́ni bá wí pé, òun fẹ́ràn Ọlọrun, tí ó bá kórìíra arakunrin rẹ̀, èké ni.
Ṣugbọn Jesu sọ pé, “Kò sí ẹni tí ó bá ti dá ọwọ́ lé lílo ẹ̀rọ-ìroko, tí ó bá tún ń wo ẹ̀yìn tí ó yẹ fún ìjọba Ọlọrun.
3b fún àkanṣe iṣẹ́ Lọjọbọ ni ile ṣe ipinnu yii ti wọn si ni awọn yoo tọ pinpin ijọba to kọja bẹrẹ lati ori aarẹ Olusegun Obasanjo, Umaru Musa Yar Adua, Goodluck Jonathan to fi mọ ti Muhammadu Buhari to wa lori oye bayi.
Nígbà tí Mose wọ inú àgọ́ ìpàdé lọ láti bá OLUWA sọ̀rọ̀, ó gbọ́ ohùn kan tí ń bá a sọ̀rọ̀ láti orí ìtẹ́ àánú tí ó wà lórí àpótí ẹ̀rí, láàrin àwọn kerubu mejeeji.
 Àwọn ni Ẹ ̀ gbá òkè-ọnà .
" Ninu iwe to kọ si awọn igbimọ to n fun eeyan ni ami ẹyẹ ọhun, o sọ pe ijọba Trump gbiyanju lati lati jẹ ki alaafia gbilẹ laarin ijọba ilẹ United Arab Emirates ati Israel.
Lọwọ lọwọ bayii, oun ati ọkọ rẹ ni wọn dijọ fi si igbele, ti Trudeau si wa ni ilera to peye lai jẹ pe ami kokoro Coronavirus foju han lara rẹ.
‘Ẹ jẹ́ kí á lọ gbógun ti Juda, kí á dẹ́rùbà á, ẹ jẹ́ kí á ṣẹgun rẹ̀ kí á sì gbà á, kí á fi ọmọ Tabeeli jọba lórí rẹ̀!
Ibo sì ni ìgò omi tí ó wà ní ìgbèrí rẹ̀ wà pẹlu?
Ṣugbọn bí ẹ kò bá gba ohun tí mo wí, mo ti fi ara mi búra pé ilẹ̀ yìí yóo di ahoro.
Bí wọ́n ti ń jẹun, Èṣù ti fi sí Judasi ọmọ Simoni Iskariotu lọ́kàn láti fi Jesu lé àwọn ọ̀tá lọ́wọ́.
Itumọ eyi ni pe bi owo rẹ ba ṣe mọ loo ṣe lo ina si"" iyẹn gẹgẹ bi Shawai ṣe sọ."
Pẹlu gbgbo ipenija to koju, o ṣi fi aridaju ipinu rẹ han lati jẹ ki gbogbo ọmọ rẹ atawọn to ba pade rẹ nigbagbọ ninu aforiti.
ati pe owo naa ko wa lọna aitọ.
Aba ofin naa n fẹ ki wọn o fi oju ọdaran wo ẹnikẹni to ba kọ ila tabi lọwọ si ila kikọ si oju ọmọde.
Ẹnikẹ́ni tí ó bá sá ti mú akọ mààlúù tabi aguntan meje wá, ẹ̀ ń yà á sí mímọ́ fún iṣẹ́ alufaa àwọn oriṣa tí kì í ṣe Ọlọrun.
Mo ti da ẹ̀jẹ̀ tí ó ta sílẹ̀ sórí àpáta, kí ó má baà ṣe é bò mọ́lẹ̀.
Wọ́n ní, “Oriṣa kan ti dé sí ibùdó wọn!
Wọ́n wá gbọ́ ohùn líle láti ọ̀run wá tí ó sọ fún wọn pé, “Ẹ gòkè wá síhìn-ín.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Èmi ni 'Bàbá àwọn Marlians' - Jude Chukwuka Ǹjẹ́ o ti ẹ̀ mọ ìtumọ̀ òwe tí bàbá Ọ̀lọ́fà iná pa yìí?
Nígbà tí àwọn eniyan gbọ́, wọ́n gba ọ̀nà ẹlẹ́sẹ̀ láti ìlú wọn, wọ́n tẹ̀lé e.
Ilana ṣiṣe oju loge gun o si fẹ plu akori nla ṣugbọn o ṣee pin si ipele ipele tabi iṣọri iṣọri.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù NGA VS GUI: Super Eagles àti Syli National Guinea ṣẹ́ eegun ẹ̀yìn Guinea pẹ̀lú 1-0 26 Òkùdu 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Ikọ agbabọọlu ọkunrin fun orileede Naijiria Super Eagles, wọ iya ija pẹlu akẹgbẹ wọn, syli Nationale lati orileede Guinea.
Ṣe titi ipinlẹ Kano pa yoo jẹ ki a lee mọ ohun gan an to n ṣekupa ọgọọrọ awọn eeyan ni ipinlẹ naa?
OLUWA ní: ṣé ìwọ ni ẹni tí mo sọ̀rọ̀ nípa rẹ̀ ní ìgbà àtijọ́ láti ẹnu àwọn wolii Israẹli, àwọn iranṣẹ mi, tí wọ́n ti sọ àsọtẹ́lẹ̀ fún ọpọlọpọ ọdún pé n óo mú ọ wá láti gbógun tì wọ́n?
Nigba ti laasigbo tako baba re waye, ile-ejo ti o n ri si iwa odaran lagbaye International Criminal Court ICC kowe ifi-owo sinkun mu Saif ninu osu kefa odun 2011, latari iseku-pani ati ifehonu-han to waye, ni odun kan-naa, ni awon omo-ogun olote orile-ede Liibya mu nigbekun titi di osu kefa odun 2017, ki o to gba itusile.
Ẹ gbé ẹjọ́ mi lọ siwaju Kesari ọba.
Ẹni tí ó ti ọrùn bọ ìjà tí kì í ṣe tirẹ̀,dàbí ẹni tí ó gbá ajá alájá létí mú.
Kidnapping: Ọwọ́ ọlọ́pàá ba Pásítọ̀ olórí ikọ̀ ajínigbé tó pa èèyàn márùn ún
Ẹ̀kọ́ keji ni pé, ogún ti ó ṣe pàtàki jù ni ki á kọ ọmọ ni ẹ̀kọ́ lati ilé àti lati bójú tó ẹ̀kọ́ ilé-iwé.
Láìpẹ́, ará ìlú rẹ ni ọlọ́pàá tí yóò máa ṣọ́ ìlú rẹ Ọlabisi Ajala rèé, ó gun ọ̀kadà yíká àgbáyé, tó sì dé orílẹ̀èdè 87 Ṣẹ gbọ́ nípa Alájọ Ṣómólú, tó ta mọ́tò ra kẹ̀kẹ́?
Iṣiboṣẹti ní àwọn ìjòyè meji kan, tí wọ́n jẹ́ aṣaaju fún àwọn tí wọ́n máa ń dánà káàkiri.
Senator Vermont kúna ti ibo rẹ si ja mọ Hillary Clinton lọ́wọ́ ni ọdun 2016.
Bẹẹ ni o si tun kilọ fun awọn ara ilu lati maa ṣọ awọn janduku aṣẹkupani to le wa ni ayika wọn.
Wọ́n lọ, wọ́n rí ọmọ kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ náà tí a so ní ẹnu ìlẹ̀kùn lóde, lẹ́bàá títì, wọ́n bá tú u.
Ki lẹda dẹ il fun ẹni to lọ.
Nigeria Independence Day: Wo ohun tó ṣẹlẹ̀ níbi ayẹyẹ àyájọ́ ọdún òmìnira ní ìpínlẹ̀ Oyo
Akin Olúsínà mu ẹmu ní ilé Ọ̀sanyìnnínbí Ajéwọlé ni ó ra kòkó lówọ́ Ọ̀sanyìnnínbí.
Amọ, awọn miran tun woye pe o ṣeeṣe ko ma ri aye fun ati du ipo naa.
Nígbà yìí ni ọba náà wáá dá a lóhùn, ó ní, M dé o, mo ti ọ̀run dé o, olùfẹ́ mi pàtàkì, máa bọ́ nínú ihò kí ó wáá fà mí lọ́wọ́ dìde.
Ní ọdun 2011, Daniel tii ṣe baba rẹ gbọ́ nípa àkanṣe ètò kan ti fasiti Oxford ń se fun àwọn ọmọ ọdun mẹjọ sí mẹ́tala.
N óo fọ́n wọn ká níwájú ọ̀tá bí ẹ̀fúùfù ìlà oòrùn.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Olootu Ijọba Jacinda Ardern Oríṣun àwòrán, Inpho Àkọlé àwòrán, Omije n jabọ loju awọn olujọsin kan Kini o n ṣẹlẹ lọjọ ẹti yi?
" Awọn iroyin ti ẹ lee nifẹẹ si: Ọmọ Naijiria mọ́kàndínláàdọ́jọ pada sile Akeredolu fidirẹmi lori ibo rẹ nileẹjọ Ọlọpa yoo pada maa sọ awọn eekan ilu Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Àwọn ìròyìn míì tí ẹ tún le nífẹ́ sí: Kò lè ṣééṣe kí Ruga wà lápá gúúsù Nàìjíríà fáwọn Fulani- Ganduje Èmi kò ní kí Shiite má ṣe ẹ̀sìn won o -Muhammadu Buhari Mo ṣe tán láti kú tọmọ taya bí wọn kò bá fi El-Zakzaky sílẹ̀ - ọmọ ẹgbẹ́ Shiite Iheanacho ẹlẹ́sẹ̀ ayò tún ti dábírà Lọsẹ́ to kọja yi ni o pe ọdun mẹwaa ti Naijiria bẹrẹ si ni koju ipenija awọn alakatakiti ẹsin Islam, Boko Haram ti ọpọ ẹmi ati dukia si ti ba a lọ.
Ẹni tí ó bá fẹ́ràn ìjà fẹ́ràn ẹ̀ṣẹ̀,ẹni tí ó bá fẹ́ràn kí á máa fi owó ṣe àṣehàn ń wá ìparun.
Ko sí ohun tó tanilólobó ẹni tó jí i gbé sùgbọ́n ẹgbẹ́ ICRC ní àwọn ńsisẹ́ pọ̀ pẹ̀lú àwọn tọ́rọ̀ kàn láti ríi pé wọ́n tú u sílẹ̀ Ìsẹ̀lẹ̀ ìjínigbé yìí wáyé lẹ́yìn ọjọ́ kan tí àwọn agbébọn pa òsìsẹ́ àjọ elétò ìlera lágbayé, WHO láì mọ̀'dí ìsẹ̀lẹ̀ náà.
O fi da awon oludokowo loju pe, ijoba ipinle Edo n se amulo akotun ilana eto-abo lati pese abo to peye fun awon oludokowo nipinla naa.
Amọ, Agbejọro naa fikun wi pe ari iru awọn obi bẹẹ ti ko bojuto ọmọ wọn, iru awọn yẹn le gba idajọ lọwọ ijọba.
Miriamu bá dá orin fún wọn pé,“Ẹ kọrin sí OLUWA,nítorí tí ó ti ja àjàṣẹ́gun tí ó lógo,ó ti da ati ẹṣin ati àwọn ẹlẹ́ṣin sinu Òkun Pupa.
Ẹni to bori: Ghana Tunisia vs South Africa.
A ba awọn to mo bujebudanu oloore yi sọrọ nipa igbe aye rẹ ati ipa to ko ninu ọrọ ilẹ Yoruba, ẹsin Islam ati idagbasoke orileede Naijiria.
Iwe yii ti Fagunwa kọ lọdun 1949 si ni awọn eeyan kan gbagbọ pe o jẹ iwe arosọ keji ti wọn yoo kọ ni ede Yoruba lẹyin iwe Ogboju Ode Ninu Igbo Irunmole.
Nígbà tí ó jẹ́ pé àwọn ará àtijọ́ tí wọ́n gbọ́ ìyìn rere kò wọ inú ìsinmi náà nítorí àìgbọràn, nítorí náà ó ku àwọn kan tí wọn yóo wọ inú rẹ̀.
OLUWA ní, “N óo wá sí Sioni bí Olùràpadà, n óo wá sọ́dọ̀ àwọn ọmọ Jakọbu,tí wọ́n yipada kúrò ninu ẹ̀ṣẹ̀.
N óo dojú kọ ọ́ pẹlu ibinu, n óo jẹ́ kí wọ́n fi ìrúnú bá ọ jà.
Lẹ́yìn èyí, Jesu ati àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ lọ sí ilẹ̀ Judia, wọ́n ń gbé ibẹ̀, ó bá ń ṣe ìrìbọmi fún àwọn eniyan.
Awọn to ṣoju wọn ṣalaye pe ọrọ lo ṣe bi ọrọ laarin lskọlaya mejeeji yii eleyi to di yanpọnyanrin laarin wọn debi pe baba agbalagba yii ys ẹṣẹ ti iyawo rẹ yii titi ti obinrin naa fi ju ẹmi silẹ Wọn ni ni kiakia ni wọn gbee digbdigba lọ si ile iwosan nibi ti dokita ti sọọ di mimọ pe arabinrin naa ti gba ekuru jẹ lọwọ ẹbọra.
A o tun maa jabọ lẹkunrẹrẹ
World Teachers Day: Ẹ̀kúnrẹ́rẹ́ àlàyé rèé nípa ìlànà àkànṣe owó oṣù tuntun fáwọn òlùkọ́
Nigeria Army Recruitment 2020: Wo bí o ṣe le fi orúkọ sílẹ̀ fún iṣẹ́ ológun Nàìjíríà
Naira Marley funra rẹ polongo pe ọpọlọpọ igba ni wọn ti fi oun jofin ni ilẹ Gẹẹsi.
Awọn ọlọpaa ti ko awọn ẹṣọ si agbegbe naa lati dẹkun rogbodiyan to le waye nitori iṣẹlẹ naa.
com/wSZmwYbmj5— Сборная России (@TeamRussia) July 2, 2018Bee si ni, iko ohun bakan naa, ko lero pe awon yoo fagbahan iko agbaboolu Spain nipele keji idije ohun pelu boolu agbesile gba.
Gbogbo àwọn ọmọ rẹ̀ lọkunrin ati lobinrin lọ láti tù ú ninu, ṣugbọn ó kọ̀, kò gba ìpẹ̀, ó ní, “Ninu ọ̀fọ̀ ni n óo wọ inú ibojì lọ bá ọmọ mi.
Fun apẹrẹ lọdun 2016, Hilary Clinton lo le waju ninu akojọ ero oludibo to si fi ibo to le ni miliọnu mẹta ju Trump lọ ṣugbọn o pada fidirẹmi naa ni.
Lẹ́yìn wọn, àwọn ará Tekoa ṣe àtúnṣe ọ̀dọ̀ tiwọn, ṣugbọn àwọn ọlọ́lá ààrin wọn kò lọ́wọ́ sí iṣẹ́ àtúnṣe náà.
Àwọn ọmọ rí iná wo Cartoon àti pé iṣọwọ jẹun mi, ó lágbára mo sún titi ojú fẹẹ fọ""."
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ìyàwó mi gbà kí n kó ipa ìfẹnukonu tó wọra - Yemi Blaq Ọmọ Ibadan yin iṣẹ́ Woli Arole Níbo làwọn òṣèré apanilẹ́rìn ín wọ̀nyí tó pilẹ̀ sínima àgbéléwò Yorùbá wà?
Liigi naa jẹ ọkan lara awọn idije bọọlu l'agbaye to ṣi n waye, botilẹjẹ pe wọn ko ṣe ni gbangba.
Ẹ̀gbọ́n ọmọbinrin naa sọ pe, wọn ti gbe e lọ sileewosan ki awọn to de sọọsi.
Tí a fiṣọwọ́ ní 17:01 11 Òkùdu 201917:01 11 Òkùdu 2019 Gbajabiamila di olórí ile aṣojú-ṣòfin kẹsàn-án Asofin Fẹmi Gbajabiamila ti bori ninu ibo taa ni yoo jẹ olori ile asoju-sofin, eyi to waye lọjọ Isẹgun.
Kini ọ̀nà àbáyọ sí ooru tó mú lásìkò yìí ní Nàìjíríà?
Awọn ọmọwe to ṣe ayẹwo naa, Ọmọwe Amand Lewis kati fasiti California atawọn akẹgbẹ rẹ mii sọ pe iwadii yii ti ṣawarii bi gbigba ẹnu ni ibalopọ ṣe lee dakun iṣoro aisan BV.
Ìsòkan la fẹ́ ní orílẹ̀ èdè Nàìjíríà.
#Queen Dihya: Obinrin tó gbógun tàwọn agbésùnmọ̀mí ni Algeria
Nigba to n bawọn akọrioyin sọ̀rọ nilu Osogbo, Adeoti, ẹni ti amugbalẹgbẹ rẹ feto iroyin, Kayọde Agbaje soju fun ni awada kẹri-kẹri lasan ni eto idibo abẹnu to waye lọjọ ẹti naa, eyi ti ko se afihan ifẹ ọkan awọn asoju to wa nibẹ.
Alufaa yóo ṣe ètùtù fún wọn, OLUWA yóo sì dáríjì wọ́n.
Gbajúgbajà òṣèré náà ti kópa nínú àwọn orísíríṣí eré bíi Asẹwo to re Mecca, Ohun Ọkọ sọ mi da, Asewo Kano àti bẹ́ẹ̀bẹ́ẹ̀ lọ.
Nibi ayẹye naa to waye ladugbo Ikeja, lo ti ṣe ere ori itage ti oun nikan da ṣe, to si danikan ko ipa eeyan mejila ninu ere naa.
OLUWA ní, “Àwọn tí wọ́n ya ara wọn sọ́tọ̀, tí wọ́n ya ara wọn sí mímọ́, wọ́n ń lọ bọ̀rìṣà ninu àgbàlá, wọ́n ń jó ijó oriṣa, wọ́n ń jẹ ẹran ẹlẹ́dẹ̀, ati àwọn ohun ìríra, ati èkúté!
Lẹ́tà Obasanjo: Àjálù ń bọ̀ bíi ti Rwanda, tí Buhari kò bá ṣàtúnṣe ètò ààbò Èèwọ̀!
Àfi ilẹ̀ àwọn babalóòṣà nìkan ni kò rà, nítorí pé ó ní iye tí Farao máa ń fún wọn nígbàkúùgbà.
Orin tí ó dára lórí ìtàgé fún àwọn ayírapadà láti tú ara sílẹ̀ àti “ṣeré tìkára wọn”, lè fi hàn kedere wípé kò kì í ń ṣe wàsá láti fi ọwọ́ rọ́ sí ẹ̀gbẹ́ nínú ìdíje Ìwọ́de Ojúnà ti ọdún nìí.
O lè mí ìmí ẹ̀dùn, ṣugbọn a kò gbọdọ̀ gbọ́ ohùn rẹ, o kò sì gbọdọ̀ ṣọ̀fọ̀.
Aṣofin Obasa ati lorukọ awọn ọmọ ẹgbẹ Ile igbimọ Aṣofin Ipinlẹ Eko to ku, ki awọn ọmọ orilẹ-ede Naijiria, paapaa awọn musulumi ku aawẹ oṣu Ramadan yii ati pe ẹmi a ṣika oṣu o.
Àwọn arakunrin Josẹfu jókòó níwájú rẹ̀, wọ́n tò wọ́n gẹ́gẹ́ bí ọjọ́ orí wọn, láti orí ẹ̀gbọ́n patapata dé orí àbúrò patapata.
ifowosowopo isejoba to n kogba wole ati isejoba to n bo.
Eniyan rere a máa fi ogún sílẹ̀ fún àwọn ọmọ ọmọ rẹ̀,ṣugbọn àwọn ẹlẹ́ṣẹ̀ ń kó ọrọ̀ jọ fún àwọn olóòótọ́.
Ẹ óo gbéra, ẹ óo máa bọ̀ bí ìjì líle, ẹ óo dàbí ìkùukùu tí ó bo ilẹ̀, ìwọ ati gbogbo ọmọ ogun rẹ, pẹlu ọpọlọpọ eniyan tí ó wà pẹlu rẹ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Somalia: 'Wọ́n pàṣẹ fún mi láti dá Ramla dúró ká tò lè ṣe igbeyàwó' Adan bẹrẹ si ni lọ si oju ọja, gbagede èrò àti ibikibi to ba gbọ pe ijamba ti ṣẹlẹ lati maa ran wọn lọwọ ati lati beere fun iranwọ sii.
Isele yii waye nirole ojo-Abameta ni opopona kan ti o wa ni apa ariwa ilu Paris.
Gbogbo arokọ gbọdọ tẹle ofin ati ilana ede Pidgin, o si gbọdọ pa ofin girama naa mọ.
Mo bojú wo ilé ayé, ilé ayé ṣófo,ó rí júujùu;mo ṣíjú wo ojú ọ̀run,kò sí ìmọ́lẹ̀ níbẹ̀.
OLUWA ní kí n sọ fún wọn pé, “OLUWA àwọn ọmọ ogun, Ọlọrun Israẹli ní kí ẹ mu ọtí kí ẹ yó, kí ẹ sì máa bì, ẹ ṣubú lulẹ̀ kí ẹ má dìde mọ́; nítorí ogun tí n óo jẹ́ kí ó bẹ́ sílẹ̀ ní ààrin yín.
Asoju orile ede Norway ni orile ede Naijiria ,Jen-Peter Kjemprud ti so pe okoowo orile ede Norway ati orile ede Naijiria jẹ ogoji  bilionu dola laarin odun kan, ni eyi to je pe àádọ́ta ile-ise to je ti omo orile ede Norway  lo n lowo ninu eto oro aje orile ede Naijiria.
Ọrọ magomago ti a mẹnu ba ko ṣẹyin bi Ajọ to n risi idanwo aṣewọle si fasiti,JAMB, ṣe sọ wi pe awọn yoo bẹrẹ iwadii lori awọn to ti ṣe JAMB lọna ẹru sẹyin , abi ti ẹlomiran ba wọn ṣe.
IBDEC: Àyàfi tọ́wọ́ wa bá tẹ àwọn ọ̀dọ́ tó na òṣìṣẹ́ wa, ni iná yóò tó tàn nílẹ̀ Ìjẹ̀ṣà
Ṣe ni awn ero to wa woran kawọ mori nigba ti wọn ri i to jade sita lati inu ile ẹjọ tori nigba ti wọn gbe e wọle, awọn oṣiṣẹ DSS yi i ka wọn ko si jẹ ki ẹnikẹni ribi sunmọ ọ.
Sibẹsibẹ wọn kò yipada kúrò ninu ẹ̀ṣẹ̀ tí Jeroboamu ti mú Israẹli dá.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Bí aya bá kọ ọkọ rẹ̀ silẹ̀, kó wà láì lọ́kọ̀' Oloye Agẹṣin adimula ila pẹlu ṣalaye pe, lootọ laye atijọ awọn eeyan kan maa n sọ ọ kiri pe ọba n jẹ ẹdọ eeyan ki o to jsba, amọṣa kii ṣe otitọ.
OLUWA wí pé: “Àwọn olórí ní Juda dàbí àwọn tí wọn ń yí ààlà ilẹ̀ pada, n óo da ibinu mi sórí wọn, bí ẹni da omi.
Ìdẹ́yẹ sí ní Ní báyìí, ó ń ràn àwọn ènìyàn míràn to wà nínú ipò yìí lọ́wọ́ láti bori gbogbo ìsòro wọ́n ní orílẹ̀ èdè Russia.
Kò ní sí eniyan níbẹ̀, ẹnikẹ́ni kò ní gbé inú rẹ̀ mọ́ títí lae.
Nígbà tó ṣe mí bí ẹní fẹ́ bì, mo bá tọ́ pepsi díẹ̀ sẹ́nu.
Ìgbélé náà yóò wáye láti ààgo mẹ́fà òwúrọ̀ sí ààgo mẹ́fà ìrọ̀lẹ́.
Gbajabiamila, ẹni to sọrọ yii ninu akanse ọrọ to bawọn araalu atawọn asoju-sofin sọ nibi ijoko ile asoju-sofin to waye lọjọ Isegun, wa kede awọn igbesẹ to fẹ gbe loti yanju awọn isẹlẹ naa.
29 Agẹmo 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Awọn olokoowo alabọde lo yẹ ki wọn pin owo yi fun ṣugbọn EFCC ni idameji owo naa bọsi owo awọn oloṣelu ati ọba alade kan Omi ti tẹyin wọ igbin lẹnu nipinlẹ Kwara nibi ti ọwọ ajọ to n gbogun ti iwa jẹgudujẹra EFCC ti tẹ oludari ile ise to n risi awọn olowo alabọde nibẹ,Segun Soewu lori ẹsun ajẹbanu.
Lati ọjọ aje ọjọ kẹrin oṣu karun ọdun 2020 ni iye awsn eeyan to n ni arun yii ni ipinlẹ Eko ati lorilẹede Naijiria ti n gbẹnu soke.
Bi a ti ṣe n mu iroyin ijinlẹ pẹlu iwaadi ti ko lẹjanbakan ninu wa, lawọn ọdọ naa n gba ẹtọ tiwọn.
Lasiko idibo gbogboogbo Naijiria eleyi ti o ku abala keji yi, awọn ọrọ akọmọna kan dagboro ru ti wọn si ko ipa ribi ribi ninu oṣelu lawọn ipinlẹ kan.
 bí a se rí ìtokò nì yí .
OLUWA ń gbé talaka dìde láti ipò ìrẹ̀lẹ̀;ó ń gbé aláìní dìde láti inú òṣì rẹ̀,láti mú wọn jókòó pẹlu àwọn ọmọ ọba,kí wọ́n sì wà ní ipò ọlá.
Sheffield faṣọ iyì ya mọ́ Chelsea lára lọ́nà ìrìnàjò sí Champions League
Akọsilẹ ti ileeṣẹ oluwadii Euromonitor International ṣe fihan pe nkan ẹlẹrindodo ti eniyan n mu ni agbaye lọdọọdun jẹ lita 91.
Ṣebí meji kọbọ ni wọ́n ń ta ológoṣẹ́!
“Mo fi da a yin loju pe , erongba okan mi lati mojuto, igbaye-gbadun awon osise .
Ẹ̀wẹ̀ nínú àriyanjiyan náà ni ọ̀pọ̀ ti fi idí rẹ̀ múlẹ̀ pé Baba Suwe lo ti wa láye láti ìgbà ti ẹfẹ ninu eré tíata ti bẹ̀rẹ̀.
"Kò séwu nínú ìdìbò tó ń bọ̀ l'Ondo àfi gìrì àparò- Akeredolu Asojú ìjọba orílẹ̀-èdè Lebanon ti kọ̀wé fipò silẹ̀ nítorí ìbágbàmù tó gbẹ̀mi ènìyàn 200 Wo ìdí tí Risikat Moromoke Azeez n'Ilorin fi ní ""Blue Eyes"" - Dókítà Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí 2 sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn."
Ìyá ìyàwó jókòósílé o ń tọ́jú oúnjẹ.
Ọgbẹni Trump ni oun ba ọgbẹni Zelensky sọrọ nipa ipenija ajẹbanu ati nipa ọgbẹni Biden ati ọmọ rẹ Hunter, to fi mọ awọn nkan miran.
orile-ede Czech Republic ni Cech, ti o si jẹ agbabọọlu ti o kopa julo fun orile-ede
Gómìnà Akeredolu ti ipinlẹ Ondo oun ọga agba ajọ to n ri si igbogun ti ilokulo oogun (NDLEA), Abdallah ti jọ kọwọrin l orilẹede Thailand lati kọ nipa aṣeyọri igbo gbingbin.
Àlàyé rèé lórí ìdí tí ìyá mi fi sọ fáráyé pé mo ti kú 3) Ọpọ igba ni eeyan le goke ọla to ba ni ipinnu lai wo aṣeyọri latẹyinwa.
Pa àgbò náà, kí o sì gbà ninu ẹ̀jẹ̀ rẹ̀ kí o tọ́ ọ sí etí ọ̀tún Aaroni ati ti àwọn ọmọ rẹ̀, ati sí àtàǹpàkò ọwọ́ ọ̀tún wọn, ati sí àtàǹpàkò ẹsẹ̀ ọ̀tún wọn pẹlu.
“Bí o bá fi ọkàn rẹ sí ohun tí ó tọ́,o óo lè nawọ́ sí i.
Kolawole Ajeyemi, to ṣẹṣẹ bi ọmọ tuntun jojolo pẹlu gbajugbaja oṣere tiata, Toyin Abraham, ti ṣapejuuwe awọn obinrin gẹgẹ bi ohun eelo ẹlẹgẹ lawujọ.
“Ṣugbọn ẹ lè pa iye ẹran tí ó bá wù yín, kí ẹ sì jẹ ẹ́ níbikíbi tí ẹ bá ń gbé, gẹ́gẹ́ bí OLUWA Ọlọrun yín bá ti bukun yín tó.
Idi ni pe awọn ẹgbẹ osisẹ mejeeji yii ti n palẹ ogun mọ lati gbena woju ijọba apapọ lori alekun owo eroja epo rọbi to se.
Ajo eleto idibo INEC lorile ede Naijiria ti sun  ikede abajade esi idibo di aago mokanla ni ọla.
Ó fi ìgboyà rìn ní ọ̀nà OLUWA, ó wó gbogbo pẹpẹ oriṣa, ó sì gé àwọn ère Aṣera káàkiri gbogbo ilẹ̀ Juda.
Ajọ UN ni ọ̀pọ̀ ikọlu naa, ti wa di ailasọ lọrun paaka, o si ti di apero fun awọn ọ̀mọ eriwo bayii nitori obiti-biti ofo ati adanu ojojumọ, ni ilẹ Naijiria n ri lawọn agbọn ti ajalu ọhun ti n waye.
OLUWA Ọlọrun wọn wà pẹlu wọn,Òun sì ni ọba wọn.
"Rúfin kóo san N1M táa bá ṣí òtẹ́ẹ́lì, ilé sinimá, gbọ̀ngàn ayẹyẹ padà - Ijọba Eko 'Bí a kò bá fẹ́ ìbínú Ọlọ́run, a gbọ́dọ̀ jẹ́ kí Tinubu du ipò ààrẹ̀ lábẹ́ àsìá ẹgbẹ́ APC ní 2023' Àwa la mọ báa ṣe mú Sunday Shodipe táa fà a lé ọlọ́pàá lọ́wọ́ - Ọlọ́dẹ Soludero Gẹgẹ bi iroyin ti a gbọ ṣugbọn ta o lee fi aworan rẹ sinu iroyin yii tori o buru jai, wọn fẹsun kan pe ""awọn daran daran ge ọwọ ọkan lara wọn ti wọn si tun ba oko wa jẹ, agbẹ kan ni wọn ṣa oun ni ada lori, awọn mii fara pa koda wọn fipa ba awọ́n ọmọde wa meji lo pọ""."
Bí o sì ti dákẹ́ ni a gbọ́ ti àwọn igi pariwo, ti wọ́n ké báyìí pé, ‘o ṣeun, bi a ti ran ọ lo jíṣẹ́’.
 Ẹnití ó ṣe àgbéjáde àjẹsára àrùn rọpárọsẹ ̀ tí à ń gba ẹnu lò ni albert sabin , a sì bẹ ̀ rẹ ̀ sí tàá fún lílò ọ ̀ pọ ̀ lọpọ ̀ ènìyàn ní ọdún 1961 .
"Lara awọn ẹlẹwọn naa tiẹ taku pe awọn ko lọ, wọn ni kawọn janduku naa fi awọn silẹ ninu ọgba ẹwọn yii amọ se ni awọn janduku ọhun fi tipa le wọn jade.
Awọn kan ti wa n bere pe n jẹ o ṣeṣẹ ki eeyan ko arun ọhun lati ara aṣọ tabi bata ti eeyan ba wọ.
Báwo ni Coronavirus ṣe n tànkálẹ̀ l'Afrika?
Ó ní, “Bí ìkún omi tí í ya bèbè rẹ̀, bẹ́ẹ̀ ni OLUWA fọ́n àwọn ọ̀tá mi ká níwájú mi.
Jesu Wo Ọkunrin Tí Ara Rẹ̀ Wú Sàn.
Ijọ Aposteli Kristi, CAC, ni oun ati awọn obi rẹ n lọ.
Awọn ọjẹ wẹwẹ to ni ifọkan sin nilẹ Togo ti sọ ile iṣẹ fíìmù wọn di ilumọọka lagbaye.
Ẹ wo adúrú ẹnu tí mó n bọ́ - Jaiye Kuti Wo orílẹ́èdè tí wọ́n tí ń dáwó ìsìnkú ara wọn pámọ́ Ayédèrú Ọ̀ṣun ni wọ́n ń bọ lónìí, kìí ṣe ojúlówó - Bàbá Ọlọ́ṣun tún figbe ta ''Àwọn ọmọ wa ma ń wọ ọkọ̀ ojú omi láìsí ẹ̀wù ìdàábòbò nítorí àti kàwé'' Tinubu ní kò jẹ́ kí àwọn ọmọ bíbí Eko gbérí nínú òṣèlú Tẹ ba gbọ ọpọ ohun to n jade lori awọn redio ati tẹlifisan wa, ẹ ro pe ogun jija n waye lorilẹede yii ni, abi pe awọn Kristiẹni ati Musulumi ko lee gbe papọ, abi pe iyapa wa laarin ẹkun Guusu ati Ariwa Naijiria."
Ọ̀kàn nínú àwọn akẹgbẹ́ẹ rẹ̀ tí ó wá láti gbùngbùn China fi ìwàǹwara pè é níjà láti fi èrò rẹ s'óde lórí gbígba òmìnira Tibet.
Ọmọ ọdun mejilelogun ni, nigba ti o dagbere faye.
Àyíká etí rẹ̀ jẹ́ ọgbọ̀n igbọnwọ (mita 13½).
Kí o sì kọ́ àwọn tí kò mọ òfin Ọlọrun rẹ kí àwọn náà lè mọ̀ ọ́n.
 Ni bayii, o se pataki fun oludari agba ajo NEMA lati wa woroko fi sada lai fi oro ohun fale, ki o si lo awon osise ati ohun elo isise re lati ran awon ti o fara kaasa ikolu omiyale naa lowo, bee si ni lati tun dena ikolu miiran ti o seese ko tun waye.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Osun Osogbo: Ọdọọdún ni Àtáója ń gbàlejò gbogbo arugbá lásìkò ọdún Ọ̀ṣun Òṣogbo Ni awọn ìyà mi naa ba tun pada si ọdọ Olodurmare lati fi ẹjọ sun.
 ní ọjọ ́ yìí , àwọn ènìyàn máa ń pọ ̀ nínú ìlú jú bí ó ṣe máa ń wà tẹ ́ lẹ ̀ lọ .
Oríṣun àwòrán, Getty Images O le mu ki kidinrin ma le sisẹ fifọ ẹjẹ bo ti se yẹ ti o si tun le mu inira ba awọ eti ifun ẹni naa.
O ti kó ìtìjú bá ilé rẹ nítorí ọpọlọpọ orílẹ̀-èdè tí o parun; ìwọ náà ti wá pàdánù ẹ̀mí rẹ.
Wọn kò gbọdọ̀ jẹ́ oníwọ̀ra eniyan.
Mose ati Aaroni níwájú Ọba Ijipti.
Gomina ipinle Ogun, Ibikunle Amosun so pe, idasile ile-ise ohun je erongba ile-ise Nestle lati mu igberu ba eto oro-aje lorile-ede Nigeria.
N kò fajúro níwájú rẹ̀ rí.
Awọn ọmọ ilẹ Gẹẹsi to n paraaro oju omi lo fi tipa gba ọkọ oju omi to jẹ tawọn eebo Pọtugi naa lori okun Mexico.
Ninu ifọrọwanilẹnuwo lori ẹrọ alagbeka pẹlu BBC, Oluka sọ pe ko si anfaani kankan ti yoo tẹyin didarapọmọ eto naa bi kii ṣe pipadanu owo.
Solomoni ṣe igba (200) apata wúrà ńláńlá, wúrà tí ó lò fún ọ̀kọ̀ọ̀kan jẹ́ ẹgbẹta (600) ìwọ̀n ṣekeli.
com Àkọlé àwòrán, Ikọ Falconets kii ṣe ajeji si idije ife ẹyẹ agbaye, ṣugbọn ikọ yii ko tii fi igba kan pa idije yii jẹ lati igba ti o ti bẹrẹ Olukọni fun ikọ agbabọọlu ọdọbinrin orilẹede Naijiria ti ọjọ ori wọn ko ju ogun ọdun lọ, Christopher Danjuma ti kede orukọ awọn agbabọọlu mọkanlelogun ti yoo ṣoju naijiria nibi idije ife ẹyẹ agbaye awọn ọdọbinrin ti ọjọ ori wọn ko ju ogun ọdun lọ, FIFA U20.
2 legbegberun , aja ( 600,000 ) , bariba ( 460,000 ) , ayizo ( 330,000 ) , the fulbe ( tabi fulani , peul ati fula ) ( 310,000 ) , ati awon gun ( 240,000 ) .
” Ewe, awon agbaboolu ti ko kopa fun MFM FC ninu won lati ri, Sikiru Olatunbosun, Akila Jesse, Shola Brossa ati Waheed Akanni, eyi si waye latari idojuko ti o waye lasiko iforukosile fun idije naa.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Lẹyin ọ rẹyin, Akintola pada gba ipo rẹ gẹgẹ bi alakoso ijọba apa iwọ oorun Naijiria lọdun 1963.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: ‘N5000 ni wọ́n ta ìbò Ondó,Edo àti Anambra’ Ìkọlùkọgbà ńrúgbó bọ̀ pẹ̀lú ènìyàn 200m Winne aya Mandela - Ó dìgbà Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 3 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 5 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
O tesiwaju pe, ile-ise aare yoo kede ababo ipade naa sita fun awon osise.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ọgbà ẹ̀wọ̀n ni wọ́n ti já àbálé Esra lábẹ́ àwáwí àyẹ̀wò wúndíá Awọn ipinlẹ kan wa lorilẹ-ede Amẹrika ti awọn oludije ka si ipinlẹ to n dari ibi ti ibo yoo lọ tọrọ ba ti di tibo aarẹ lorilẹede Amẹrika.
ẹni tí ògo yẹ fún lae ati laelae.
Ó dàbí ìdákọ̀ró fún ọkàn wa.
Ajọ naa sọ pe ''ko si ọna 'otitọ' kankan lo le mu ki gbogbo ara pupa.
“Nítorí náà, ẹ ṣọ́ra kí ẹ sì ṣe gbogbo ohun tí OLUWA Ọlọrun yín pa láṣẹ fun yín; ẹ kò gbọdọ̀ ṣe àìgbọràn ninu ohunkohun.
#BBCNigeria2019 'Obìnrin tórí ẹ̀ pé lè tọ́ ọmọ láì nílò ọkọ rẹ̀' Kí ni àwọn olùdíje ìpínlẹ̀ Eko fẹ́ ṣe nípa ètò ìlera?
oro aje, iyipada oju-ọjọ ati asa .
Lọdun 1968 ti Naijiria kopa ninu idije Olympics, mẹsan an ninu awọn agbabọọlu to ṣoju Naijiria ni Mexico jẹ agbabọọlu lati ẹgbẹ Stationery Stores.
Ṣugbọn ẹ̀yin ará Keni yóo di ẹni ìparun,àwọn ará Aṣuri yóo ko yín lẹ́rú.
Etí wọn ti di, wọn kò lè gbọ́ràn mọ́.
Gbogbo àwọn tí ó kórìíra mijọ ń sọ̀rọ̀ wújẹ́wújẹ́ nípa mi;ohun tó burú jùlọ ni wọ́n ń rò sí mi.
Ile-ise ti kii se ti ijoba,ti
Ọjọgbọn Adeọla Fiwapẹ to jẹ alakoso ètò ìdìbò naa ṣalaye pé, gbogbo ìbò yẹ kó jẹ́ 1, 678, 985.
Bo tilẹ jẹ pe o ti mọ ẹni ọdun mejidinlọgbọn naa lara ki ọkọ rẹ maa na a, ko lero pe yoo de ibi pe imu rẹ yoo di gigie sọnu.
Ara wọn nìkan ni wọn yóo lè gbàlà, ilẹ̀ náà yóo sì di ahoro.
Ọlọpaa mu orin sẹnu lasiko ti awọn oluwọde fẹsẹ fẹ tori afẹfẹ́ alata Se ni awọn ọlọpaa fi orin sẹnu nilu Eko lasiko ti wọn n wo awọn oluwọde ti wọn n sa asala fun ẹmi wọn lasiko iwọde Revolution Now ti wọn n se.
Mo ti yan Oholiabu ọmọ Ahisamaki láti inú ẹ̀yà Dani pẹlu rẹ̀.
Ìdí rèé táwọn ọmọ Nàíjíríà kan ṣe ń tako ìdásílẹ̀ ‘Ruga Settlement’ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, CAN: Samson ni ọrọ awọn ajinigbe ti gba àpérò ní Naijiria Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Kini awọn ọdọ sọ nipa iyansipo yi?
”Oludari ile –eko naa ni ipinle
Akọsilẹ to wa nilẹ salaye pe, ojilenirinwo o din meji ati aabọ dọla ($437,500) ni wọn ta ẹsẹ bata Nike yii lọdun 1972.
" Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Pásítọ̀ àti Ìmàámù yóò gba owó osù lọ́wọ́ ìjọba Àwọn ọmọ Iyabọ Ojo rí bàbá wọn fún ìgbà àkọ́kọ́ ní ọdún mẹ́fà Ṣe 1000 agbofinro tó láti dẹkùn ìpànìyàn Zamfara?
”Here’s our take on tonight’s win… #BURCHEhttps://t.
Nígbà tí èyí bá ṣẹlẹ̀, ẹ óo mọ̀ pé bíbèèrè tí ẹ bèèrè fún ọba, ẹ̀ṣẹ̀ ńlá ni ẹ dá sí OLUWA.
Oríṣun àwòrán, GALI KANKARA Ileeṣẹ ọlọpaa ipinlẹ naa ni awọn n ṣe iwadii lọwọ, ṣugbọn iroyin ni ko din ni irinwo akẹkọọ to poora.
 Àwọn tó fẹ́ kí ọba máa ta ilẹ̀ ilú ló fẹ́ yọ Oluwo lóyè- Ẹgbẹ̀ Baálẹ̀ Iwo."
Emir Kano ti balẹ̀ sí Ilorin, ìlú ìyá rẹ̀ fún àyẹ̀wò ọlọ́jọ́ mẹ́ta Músò Músò!
" orúkọ tí a ń pè ní dracunculiasis jẹyọ láti látínì "" Ìdojúkọ pẹ ̀ lú lámilámi kékeré "" , nígbà tí orúkọ "" sòbìà "" jẹyọ nígbà tí àwọn òyìnbó rí àrùn náà ní guinea etí òkun Ìwọ ̀ oorùn Áfíríkà ní 17th ọgọ ́ rùn ọdún ."
Oludasilẹ ijọ naa, Alufaa Isreal Oladele Ogundipe, ni Oluṣọ ijọ naa.
Afurasí Boko Haram pa ológun àti ọlọ́pàá mẹ́rìnlá ní Borno Ẹ wá ná, kí ló ń ṣẹlẹ̀ pẹ̀lú APC àti Kayode Fayemi ní Ekiti gan an?
Brexit: Bí orílẹ̀-èdè Gẹẹsi ṣe fi àjọ ìṣọ̀kan ilẹ̀ Europe sílẹ̀ rèé
Ooni Ogunwusi àti Wole Soyinka kòrò ojú sí ìṣẹ̀lẹ̀ Lekki Tollgate Oríṣun àwòrán, Premium times Ọọni ile Ifẹ, Ọba Adeyẹye Ogunwusi ati agba onkọwe nni, Wole Soyinka, ti koro oju si ikọlu ati bi awọn ologun ṣe yinbọn lu awọn oluwọde lagbegbe Lekki Toll Gate lọjọ Iṣẹgun.
Orukọ idije naa ko ni yipada kuro ni Tokyo 2020 to n jẹ tẹlẹ.
leyin ipade ti minista to n ri si ọrọ to jẹ mọ ilẹ okeere, Geoffrey Onyeama ati
Awọn miran si n sọ pe ominuu n kọ awọn pe eyi yoo mu ki awọn to ni coronavirus ko pọ si ni Naijiria.
Ṣugbọn kii ṣe goolu mẹta ti wọn jẹ tabi aṣeyọri wọn lawọn eeyan n sọrọ nipa rẹ bi ki ṣe awọ oju ti Aubameyang wọ lati fi dawọọ idunnu.
Akọkọ ni ti Vera Uwaila Omozuwa, ọmọ ọdun mejilelogun ti wọn fi ipa ba lopọ ti wọn si tun ge ẹmi rẹ kuru nile ijọsin kan ni ipinlẹ Edo.
Ibeere: Ọna wo ni aba ofin yii yoo fi ṣeranwọ fun araalu nipa owo ori sisan?
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Hubert Ogunde rèé, baba àwọn òsèré tíátà Ayefẹlẹ bá BBC sọ̀rọ̀ lórí ilé orin rẹ̀ tí Ajimọbí ń tún kọ́ Ǹjẹ́ ó seése kí Buhari se àtúnse ilé-ìwé 10,000 lọ́dọọdún?
Eyi lo mi ki Onidajọ Obiozor gba ẹbẹ EFCC wọle, to si sun igbẹjọ si ọjọ kẹsan, oṣu Kẹsan, ọdun 2019.
N óo fún ọ ní kọ́kọ́rọ́ ìjọba ọ̀run.
 Ohun ti yoo fa ni  iwa aisootọ ati wahala.
Oríṣun àwòrán, Instagram/bintaayomogaji Binta Ayọ Mọgaji, lasiko to n fesi lori bi awọn osere tiata lode iwoyi se n ri owo nidi isẹ naa ju awọn osere tiata aye atijọ lọ ninu eyi ti Binta wa, osere tiata lobinrin naa ni, ohun ti onikaluku fi n jẹkọ, abẹ ewe lo wa.
Iya Rainbow jẹ́ gbajúmọ̀, àmọ́ kí lo mọ̀ nípa rẹ̀?
Mose wí fún àwọn ọmọ Israẹli pé, “OLUWA fúnra rẹ̀ ti yan Besaleli ọmọ Uri, ọmọ ọmọ Huri, láti inú ẹ̀yà Juda.
" Eyi lohun tawọn ileeṣẹ iroyin abẹle kan ka mọ oju opo ayelujara rẹ kan.
Kayode Ajulo, to je agbẹjọrọ fun ọgbẹni Afegbua so fun ileesẹ BBC pe ipade oun lo ni iroworose ati pẹ nsẹ ni awọn asoju oga agba ile isẹ ọlọpa to gba awon lalejo, n toro aforijin fun isele naa.
Owó Ọdún kan Owó Oṣù kan £23, 124 sí £38,382 £1,927 sí £3,198.
‘Ìwà ìdúnkòokòmọ́ni, ọ̀yájú sàwọn olùdìbò ló kún inú àtúndì ìbò Ọ̀sun’ APC yọ orúkọ Shittu kúrò láti kópa nínú ìdìbò abẹ́lé Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ọlọ́jọ́ festival 2018: Láwàní (ọ̀já) ni máa kọ́ka wé kí n tó jẹ Ọọni nítórí Oodua ló nií Idi ni pe ninu awọn ipinlẹ mẹfa to wa lẹkun iwọ oorun guusu Naijiria, ipinlẹ mẹta pere lo ku ti yoo seto idibo gomina lọdun 2019.
Wo àwọn nkan tí o le ṣe gẹ́gẹ́ bi aláboyún lásìkò àjàkálẹ̀ ààrùn Covid-19 Ṣugbọn bawo ni ọrọ abadofin ọhun ṣe jẹ gan?
Ṣugbọn awọn aworan taa ri lori ayelujara fi han pe aṣa kan wa ni pato to wọpọ ti wọn maa n lo lati fi wa ọrọ lẹnu awọn ti wọn ko nigbekun ati lati fiya jẹ wọn koda ko yọ awọn ọmọde silẹ.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ọlọ́pàá mú 115 ẹlẹ́sìn Shiite Ikọ̀ aláàbò Nàìjìríà dojú kọ Shiite Ọlọ́pàá ló ń fa rúkèrúdò lásìkò ìwọ́de wa-ẹgbẹ́ Shi'ite Ìròyìn tó tẹ̀wá lọ́wọ́ láti News Agency of Nigeria sọpé àwọn ọmọ egbẹ́ Shiites ju òkò lu àwọn ọlọ́pàá tí wọ́n sì tún fọ́ gílàsìì àwọn ọkọ̀ tó wà níwájú ilé náà.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Akomolede ati asa Yoruba: Ẹ wá kọ́ nípa àpòtí ìṣura èdè wa lórí BBC Yorùbá Mama Odegbami ni inu awọn dun pupọ lati ṣoju orilẹede Naijiria ati ilẹ Afrika ni apapọ, ti o si dupẹ lọwọ ọmọ rẹ to jẹ ki oun ṣe alabapade Beyonce.
O tó gẹ́; A kò fẹ́ ìwòkuwò mọ́ ní Nàijíríà- Roṣẹwẹ (NCAC) Ọlọ́pàá ti mú ẹni márùn ún lórí ìjà láàrin Hausa àti Yorùbá l'Eko Buhari gbóṣùbà fún D'Tigress lẹ́yìn tí wọ́n lu Senegal gba ife AfroBasketWomen Ọ̀pọ̀ èèyàn bẹnu ẹ̀tẹ́ lu Mercy Aigbe lórí bó ṣe ki Adeniyi Johnson Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Saaju ni oriṣiriṣi iwọde ti bẹrẹ lati ipinlẹ eko ni eyi to si ti ran kaakiri Naijiria lori ọrọ #End SARS to gbode kan.
Kọmísọ́nà ní gbogbo àwọn ọgálọ́gàá ilé iṣẹ́ náà to fi mọ akọwé agba ilé iṣẹ́ iléra to pàṣẹ fun awakọ̀ náà láti lọ gbé ẹni náà ni wọ́n ti gba iwé ìbáwí.
” Ó dáhùn pé, “Mo gbàgbọ́ pé Ọmọ Ọlọrun ni Jesu Kristi.
Ọga ọlọpaa nipinlẹ Ibadan Shina Olukọla na fi to awọn oniroyin leti pe awọn doola ẹmi eeyan mẹta nibẹ.
Brighton & Hove Albion 16:00Swansea City ?
O ni, o ṣe pataki ki awọn ọmọ ipinlẹ Oyo kopa gboogi ninu eto ati sọ aba naa dofin, ki wọn le sọ ohun ti wọn fẹ ko wa ninu ofin naa.
BBC Yoruba lo gbe wọn wa sori akanṣe eto fun ayajọ June 12 eyi ti ijọba apapọ labẹ akoso aarẹ Muhammadu Buhari ti kede ti wọn si sọ ọ di ayajọ eto iṣejọba tiwa n tiwa lorilẹ-ede Naijiria.
 wọ ́ n pèlo Àjẹsára jẹ ̀ dọ ̀ jẹ ̀ dọ ̀ b tí ó wà bayí nípa ọ ̀ nà tàbí ọgbọ ́ n recombinant dna .
Timbuku ti wọn ti kopa pataki ninu ẹkọ fun imọ igbesi aye ẹda.
Mínísítà tó n rí sí ètò ìlera, Osagie Ehanire lo fìdí ìròyìn náà múlẹ̀ l'Ọjọ́rú lẹ́yìn ìpàdé ìgbìmọ̀ aláṣẹ́ ìjọba tó wáye.
Níbẹ̀ ni a tẹ́ ìtẹ́ ìdájọ́ sí,àní, ìtẹ́ ìdájọ́ àwọn ọba ìdílé Dafidi.
Oshiomhole lo lewaju ikọ ipolongo ibo Pasitọ Osagie Ize-Iyamu gẹgẹ bi gomino ipinlẹ naa lọ si Usen nigba ti ọkọ akẹru kan ya lọ kọlu awọn ọkọ to n ba a kọwọrin lọ sibi ipolongo naa lagbegbe Oluku Junction ni ijọba ibilẹ ila oorun Ariwa ipinlẹ naa.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Barrister ló sọ mí di èèyàn ńlá - Ayinla Kollington Afọnja, ẹni tó finú wénú ní Ilọrin, àmọ́ tó jẹ iwọ Ìtàn tó rọ̀ mọ́ òwe ‘aṣọ kò bá Ọ́mọ́yẹ mọ́.
Koda ki iwosan o wa ni ilana ibilẹ, o ṣe koko lati fidirẹ mulẹ pe o n sisẹ ati pe ko le ṣe ijamba fun ara."
Ọ̀pọ̀ eniyan ni ó ń bèèrè pé “Ta ni yóo ṣe wá ní oore?
"O dara lati gbọ pe ṣaka lara iya ati ọmọ ya, mo si n reti abẹwo ẹbi yii si ilu Toronto.
 A o si tun gbiyan lati maa se ohun ti o tọ .
Lọjọbọ yii kan naa ni awọn agbẹnusọ fawọn asofin ti sọ fun BBC Yoruba pe, awọn yoo mọ boya awọn lugbadi Covid-19 laipẹ.
Mose bínú sí àwọn olórí ogun náà ati sí olórí ẹgbẹẹgbẹrun ati olórí ọgọọgọrun-un.
O fi kún pé, àti ilú àti àwọn fulani sa gbogbo ipá wọ́n la'ti dẹ́kun irú ìṣẹ̀lẹ̀ báyìí lọ́ja iwájú.
láti ṣe ìdájọ́ wọn gẹ́gẹ́ bí àkọsílẹ̀.
A ò ní gbà kẹ́ẹ buwọ́lu ofin tí yòó dí wa lẹ́nu lórí ayélujára Àkọlé àwòrán, Fun apẹrẹ, koo kan sọ fun eeyan pe ""mo nifẹẹ rẹ, ki ijọba dẹ gbe ọbe le ọ lọrun, eyi pakasọ."
Lẹ́yìn ò rẹyìn, Wasiu Ayinde sọ̀rọ̀ nípa Ayinde Barrister Èdè àìyedè láàrin Seyi Makinde àtàwọn aṣòfin yanjú, àbá ọdún 2021 dòhun Nigba to n sọrọ lori idi to fi ti aburo rẹ sinu kọnga, ọmọ ile iwe alakọbẹrẹ naa sọ pe ounn ko mọ pe ohun ti oun ṣe yoo yọri si iku ọmọdekunrin naa.
Joabu dá a lóhùn pé, “Nígbà tí o rí i, kí ló dé tí o kò pa á níbẹ̀ lẹsẹkẹsẹ?
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Awọn ọdẹ ti bẹrẹ igbesẹ ati gbogun ti awọn darandaran Fulani nipinlẹ.
Se ni apapọ awọn osisẹ agbofinro, ninu eyi ti a ti ri awọn ọlọpaa ati awọn osisẹ ologun wa, ti wọn si duro wa wa wa si agbegbe naa, pe ti esinsin ba ta firi, awọn yoo wọn ni.
Amọ aya wọn ṣi n ja pe o ṣeesẹ ki Chelsea o ja a gba mọ wọn lọwọ.
Ọba bèèrè pé, “Ta ló wà ninu àgbàlá?
Farao bi àwọn arakunrin rẹ̀ léèrè irú iṣẹ́ tí wọ́n ń ṣe.
Awọn oludije miiran to tun ṣeleri atilẹyin wọn fun Gbajabiamila ni Buba Yakubu, Aliyu Betara, ati Abdulrazak Namdas.
O ni akọni ni wọn, o si fi aidunu rẹ han wipe wọn fun France laaye lati gba wo-mí-ngba-si-ọ lẹẹmeji ọtọtọ.
Oríṣun àwòrán, @istock Àkọlé àwòrán, Ẹni ba láyà Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Ibi yìí ni wọn ti ń fi ìyà jẹ gbogbo ẹni tí o tí ṣe ibi nínú ayé kí wọ́n tó fi àyé sílẹ̀ ṣùgbọ́n èyí tí ó burú jùlọ́ ni pé wọn kò tún lè kú mọ́, kí wọ́n máa jìyà títí ṣá ni, Ẹni tí a kọ́ rí ya ni lẹ́nu púpọ̀, ìránṣẹ́ èṣù kan ló jókòó ti ọkùnrin náà ti o ń gbá ìṣó mọ́ ọ lójú tí onítọ̀hún ńn ké ṣa.
" Nibayii Kọmisọna feto ẹkọ nipinlẹ Ogun ti salaye wi pe ijọba yoo gbe igbesẹ nipasẹ isedajọ rẹ lati rii pe arakunrin naa foju wina ofin.
Òsìsẹ́ Custom tó déédé sọ ara rẹ̀ di Ọ̀gá Àgbà CG ní ìdàmú ọpọlọ - Attah Ṣé o ti gbọ́ ohun ti Ọọni Ifẹ́ àti Soyinka parí ọ̀rọ̀ Yorùbá sí?
amọ kii ṣe gbogbo eeyan ni yoo jẹ anfaani yii.
 Laisi ani ani, o da mi loju pe awọn eniyan to wa nibi n sapa fun eto oṣelu tiwantiwa, ti yoo ni ipilẹ eto idibo ti yoo waye ni irọwọ irọsẹ laisi magomago ninu”.
Ìdí márùn ún tí agbára Covid 19 ní ilẹ̀ Adúláwọ̀ kò fi tó tí àwọn ilẹ̀ àgbáyé míràn Kíni àbájáde ìwádìí nípa báàjì àyà tí àwọn olóṣèlú kan ń wọ̀?
Ohun taa gbọ ni wi pe Sultan Qaboos ko ni ọmọ tirẹ nitori naa o kọ orukọ ibatan rẹ sinu lẹta to kọ silẹ ti wọn ka jade gẹgẹ bi ẹni ti yoo gba eku ida lọwọ rẹ.
Oríṣun àwòrán, @Gbemi Àkọlé àwòrán, Opo gba pe Gbemi ṣiṣẹ lodi si iyansipo ẹgbọn rẹ titi o fi togẹ ni Kwara Gbemi jẹ ọmọ ọdun mẹrinlelaadọta to kẹkọ gboye nipa imọ eto ọrọ aje ni fasiti Sussex nilu Ọba.
 Ìdó ni olórí ìlú wọn .
Ọmọ ogun Nàìjíríà bẹ̀rẹ̀ lílo 'Drone' láti gbógun tàwọn ajínigbé ni Ondo àti Ekiti Jẹ́ kí a jọ sọ àǹfàní US fún Nàìjíríà -Osinbajo Kàyééfì, oyún inú nínú ilé ìgbọ̀nsẹ ọkọ̀ òfurufú Ẹyẹ ju ẹyẹ lọ, Super Eagles fi àmì ayò kan gbé ẹyẹ Swallow ti Burundi mì Lẹyin ti awọn eleri wi tẹnu wọn ti wọn si fi iwe jẹri si ọrọ ti wọn sọ, adajọ Dimgba sun igbejọ naa siwaju titi di ọjọ kẹrin oṣu Kẹwa ọdun 2019.
’“Lẹ́yìn náà, gbé e kalẹ̀ níwájú OLUWA Ọlọrun rẹ, kí o sì sìn ín; 
ó ní: “Ìwọ ọmọ eniyan, kọjú sí Gogu, ní ilẹ̀ Magogu; tí ó jẹ́ olórí Meṣeki ati Tubali, 
Ọdúnjọ/ Ọdún- Ifá/ Ọdúnayọ̀: Ọmọkùnrin tí a bí lásìkò ọdún Ifá tàbí ọdún mìíràn
Ẹwẹ, iroyin ti tẹ wa lọwọ pe awọn oṣiṣẹ panapana ti de bi iṣẹlẹ naa ti wọn si ti pa gbogbo ina to n jo.
 Orí mi wú, ọmọ Nàíjíríà 16 gbàmì ẹ̀yẹ nínu akẹ́kọ̀ọ́ fásitì 27 l‘òkè òkun Àwọn alága ìbílẹ̀ tún wọ́ Seyi Makinde relé ẹjọ́ Ta ni Ààrẹ orílè-èdè Egypt, Morsi tó kú nílé ẹjọ́?"
tí wọn ń káàkiri láti orílẹ̀-èdè dé orílẹ̀-èdè,láti ìjọba kan dé òmíràn,
Dafidi dáhùn pé, “Àwọn ọkunrin tí wọ́n wà pẹlu mi a máa pa ara wọn mọ́ nígbà tí a bá ń lọ fún iṣẹ́ tí kò ṣe pataki, kí á tó wá sọ ti iṣẹ́ yìí, tí ó jẹ́ iṣẹ́ pataki?
Oríṣun àwòrán, @Nairamerley Àkọlé àwòrán, Bí Naira Marley ṣe ri ọkọ̀ òfurufú tó gbée lọ si Abuja Mínísítà fún ìrìnà òfurufú Hadi Sirika ní ọkọ̀ òfurufú tó gbé gbajúgbà olórin to ṣe apẹjọpọ̀ ni ilé ìtajà ìgbàlódé Jabi Lake nílu Abuja gba àṣẹ láti gbé adájọ kan ni.
Báwo ni ìtàn ti ó ti pẹ́ to èyí yóò kan ṣe dojú bolẹ̀ láàrín ọjọ́ mẹ́ta péré, èyi ko bójú mu rárá, ọ̀rọ̀ náà lọ́wọ́ nínú.
"Nigba toun sọrọ lẹyin ti Southampton na wọn m'ọle pẹlu ami ayo meji s'oodo lọjọ abamẹta, akọnimọọgba wọn , Alan Pardew ni ""inu n bi oun si awọn mẹrẹẹrin."
"O fi ẹsun kan wi pe ijọba ipinlẹ Ọyọ n ""Ṣehin-sọhun"" laarin mọlẹbi oloogbe ati awọn apanilẹkun jaye."
Lati kekere ni mo ti maa n ri ara mi ti mo maa n wẹ, ṣere ninu omi Wolii ni Yeye Olokun tẹlẹ fun ogun ọdun ni ṣọọṣi.
Ọmọ ọdún mẹ́tàdínlógún ni Dúró orímóògùnjẹ́.
Ó mú ìbẹ̀rù wá sọ́kàn yín.
Nigba ti yoo fesi si ọrọ naa, Akọwe agba si Gomina Fayẹmi, Yinka Oyebode sọ wi pe, Fayemi ti ṣe gudugudu meje ati yaaya mẹfa.
Nítorí náà ni wọ́n fi sọ ọ́ ní Esau.
Ọdun 2003 ni wọn ṣe ofin to kọ ifiyajẹ ọmọde, ninu eyi to tako fi fi ọmọbinrin ti ko ba ti i pe ọdun mejidinlogun fun ọkọ.
Àwọn wọ́n yìí ni àwọn isan tó máa ń fi iná ránsé sí igun ọpọlọ tó máa ń jẹ́ kí agogo ara ṣe dédé.
Nígbà tí ọmọ náà dé ibi tí ọfà náà balẹ̀ sí, Jonatani pè é, ó ní, “Ọfà náà wà níwájú rẹ,” 
Gẹgẹ bí awọn akọṣẹmọṣẹ atawọn onimọ nipa itọju ẹranko ṣe sọ ọ, aaringbugbun gbekede ti ijapa n lo laye ni aadọjọ ọdun bẹẹ si ni eyi ti eeyan ti ri ri to ju bẹẹ lọ ṣaaju ti Alagba ni o lo Igba ọdun laye.
Má bèèrè ìbéèrè tó pọ̀ jù, sáà má tẹti si wọn, ki o sì maa fi oye gbé ǹkan ti wọ́n n kojú.
Lẹ́yìn tí ogun ti kó Jerusalẹmu, gbogbo àwọn ìjòyè ọba Babiloni péjọ, wọ́n sì jókòó ní bodè ààrin: Negali Sareseri, Samgari Nebo, Sarisekimu Rabusarisi, Negali Sareseri, Rabumagi ati àwọn ìjòyè ọba Babiloni yòókù.
osise bere lati ojo Isegun ọsẹ yii, ojo kọ́kàndínlógún  lati din wahala
Nigba ti  Awad Ibn Ouf n ba awon akoroyin orile ede naa
Bẹ́ẹ̀ ni a kò gbọdọ̀ ṣe àgbèrè bí àwọn mìíràn ninu wọn ti ṣe àgbèrè, tí ọ̀kẹ́ kan ó lé ẹgbẹẹdogun (23,000) eniyan fi kú ní ọjọ́ kan.
Ni ọdun 1969 ni Ọba Olayode fi oye Asipa Ogbomoso da Ajagunfẹyinti Benjamin Adekunle, ti ọpọ eeyan mọ si Black Scorpion lọla, lai mọ pe isẹlẹ manigbagbe kan yoo waye laipẹ sigba naa.
Ayé Aláàfin Abiodun sì ni ọmọ-ọmọ rẹ, Orisabiyi, tí ọmọ Aláàfin Abiodun obìnrin bí, dá ìlú Ìjàyè silẹ, tí Kurunmi sì jáde láti ìlú Ọ̀yọ́ lọ tẹ̀dó si ìjàyè nígbà tó di aarẹ ọna kakanfo àti alágbára jagunjagun, tí kò leè bá Aláàfin wá n'ilu Ọ̀yọ́.
Kí ojú baà lè tì yín ni mo fi ń sọ̀rọ̀ báyìí!
Ìjàmbà ọkọ̀ akẹ́rù ní Ikòròdú fa súnkẹrẹ-fàkẹrẹ ọkọ̀ ní Márosẹ̀ Oríṣun àwòrán, @others Àkọlé àwòrán, Ijamba ọkọ Akẹru naa n fi kun asiko irinajo awọn eniayn Laarọ ni wọn ni awọn ọkọ akẹru meji kọkọ gba ara wọn ni agbegbe Ikorodu ni ipinlẹ Eko ni Guusu Naijiria.
Ní ọdún kẹrin, ẹ ya gbogbo àwọn èso náà sọ́tọ̀ fún rírú ẹbọ ọpẹ́ sí OLUWA.
Bẹ́ẹ̀ ni ìpín ẹni ibi yóo rí.
Wolii tí ó bá fẹ́ sọ àsọtẹ́lẹ̀ pé alaafia yóo wà, nígbà tí ọ̀rọ̀ wolii náà bá ṣẹ ni a óo mọ̀ pé OLUWA ni ó rán an níṣẹ́ nítòótọ́.
4 312851 Orilẹede Israel 3910 46.
Ju ohun gbogbo lọ, ẹ ní ìfẹ́ tí ó jinlẹ̀ sí ara yín, nítorí ìfẹ́ bo ọpọlọpọ ẹ̀ṣẹ̀ mọ́lẹ̀.
Lẹyin ti wọn ba ti gba owo ọrẹ lọwọ awọn ijọ laarin ọdun, wọn maa n ko owo naa sinu apoti, wọn a wa ṣi apoti owo ọrẹ yii lọjọ keji ọdun Keresi, ti wọn a si pin owo inu rẹ fun awọn talaka.
 Mo ṣiṣẹ fun Wole Soyinka ati Bola Ige ri ninu ere ori itage.
Odun kan ni awọn ọmọ ile igbimọ fi maa n jokoo ṣugbọn ti eyi to n lọ lọwọ yii ti bẹrẹ lati oṣu kẹfa, ọdun 2017 to ti fẹẹ pe ọdun meji bayii.
Wọ́n kọ́ ojúbọ oriṣa tí ó wà ní àfonífojì ọmọ Hinomu láti máa fi àwọn ọmọ wọn, lọkunrin ati lobinrin rú ẹbọ sí oriṣa Moleki, bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé n kò pa á láṣẹ fún wọn, tí kò sì wá sí mi lọ́kàn pé wọ́n lè ṣe irú ohun ìríra bẹ́ẹ̀, láti mú Juda dẹ́ṣẹ̀.
Àgbàọ̀jẹ̀ akọ́nimọ̀ọ́gbá Man U tẹ́lẹ́ rí Alex Ferguson l'ógbé ife fàdákà náà fún Wenger láti mọ'yì rẹ̀.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Sowore: Ilé ẹjọ́ pàṣẹ kí ìjọba àpapọ̀ san ₦1m owó ẹ̀bẹ̀ fún ẹgbẹ́ ajijagbara Sowore, torí ìwọde wọn tí wọ́n dà rú 1 Ìgbé 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 5 Èbibi 2020 Oríṣun àwòrán, omoyele sowore Ilé ẹjọ́ gíga tí ìjọba àpapọ̀ tó wà n'ilu Eko ti pàṣẹ fún ìjọba láti san mílíọ̀nù kan náírà fún ẹgbẹ́ ajijagbara Revolution Now, lórí bo se da ìwọde ẹgbẹ́ náà ru ni ọjọ́ Kàrún oṣù Kẹjọ ọdún 2019.
Ọmọ fẹ́ fi ìyá rẹ̀ ṣ'owó l'Eko Òbí tó n fa sìgá n fi ọmọ rẹ̀ sínú ìdè àìsàn l'ọ́jọ́ iwájú Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Obìnrin akunlé ìgbàlódé Lẹ́yin tawọn alarafa yii gbọ waasi tan ni mọsalasi Namira, ni wọn tun wa se adura Dhuhr ati Asr papọ ni ọna kukuru.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Andre Ayew: Baba mi loni ki n pada si Swansea City 9 Èrèlè 2018 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Andre Ayew darapọ mọ agbabọọlu Swansea City ni osu kini, ọdun 2018 Andre Ayew sọ wi pe baba rẹ ti o jẹ agbabọọlu tolamilaaka tẹlẹri fun orilẹede Ghana ati ẹgbẹ agbabọọlu Marseille, Abedi Pele lo parọwa fun ohun lati darapọ mọ ẹgbẹ agbabọọlu Swansea City.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Umrah 2019: Ààrẹ̀ Buhari yóò balẹ̀ bìbà sí Saudi Arabia 16 Èbibi 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Aarẹ Buhari ati Ọba Saudi Aarẹ Buhari ti tẹwọ gba iwe ipeni ti Ọba Saudi Arabia, Ọba Salman Bin Abdulaziz to tun jẹ adari mọ́sálásí mimọ meji to wa fun Umrah iyẹn Hajj kekekere.
N óo sọ àwọn òkè gíga ati àwọn kéékèèké di ilẹ̀,n óo mú kí gbogbo ewéko orí wọn gbẹ;n óo sọ àwọn odò di erékùṣù,n óo sì mú kí àwọn adágún omi gbẹ.
Won tesiwaju pe, awon miiran farapa lopolopo, sugbon won wa labe itoju lowo.
O sọ ọrọ naa lẹyin ipade to ṣe pẹlu awọn eleto aabo ni alẹ ọjọ Aiku.
Eto idibo naa ni Aṣofin Uche Ekwunife to n ṣoju Aarin gbungbun Ipinlẹ Anambra lapa Ila-oorun Gusu ninu Ile Igbimọ Aṣofin-agba, dari rẹ.
Sibẹ, ẹni tí ó kéré jùlọ ninu ìjọba ọ̀run ṣe pataki jù ú lọ.
Kaduna-28 Rivers-9 Ogun-8 Ondo-8 Kano-2 Niger-2 Kwara-1 Plateau-1 Èèyàn 223 míràn ló lùgbàdì coronavirus ní Nàìjíríà lánàá Bi ọrọ Covid 19 se ri ni Naijiria lanaa ree: Ipinlẹ Eko ni 85 FCT-35 Akwa Ibom-24 Enugu-18 Plateau-13 Rivers-10 Abia-7 Ebonyi-6 Anambra-5 Adamawa-4 Bauchi-3 Imo-3 Ogun-3 Oyo-3 Kwara-2 Osun-1 Taraba-1 'Mo ṣetán láti lo gbogbo ayé mi tókù lẹ́wọ̀n' Afẹ́fẹ́ gáàsì tí gbiná ní Ijora ìpínlẹ̀ Eko, bó ṣe n ṣẹlẹ̀ rèé Ẹkún àti ìbànújẹ́ láwọn mọ̀lẹ́bí fi sìnkú ọmọ méje ní Kumba, Cameroon lónìí Ìdájọ́ ikú ló bá dé fáwọn méjì tó fipá bá ọmọ ọdún mẹ́rìnlá lò pọ̀ Afẹ́fẹ́ gáàsì tí gbiná ní Ijora ìpínlẹ̀ Eko, bó ṣe n ṣẹlẹ̀ rèé Wo àwọn ọmọ Naijiria mẹ́ta tó jáwé olúborí nínú ìdìbò sílé aṣòfin ilẹ̀ Amẹrika Coronavirus kò pa ẹnìkankan lánàá Ọjọ́bọ̀ ní Nàìjíríà, àmọ́ èèyàn ọgọ́sàn án 180 míì ló ṣẹ̀ṣẹ̀ kóo Ọgọsan ọmọ Naijiria lo tunko arun coronavirus l'Ọjọbọ gẹgẹ bi akọsilẹ ajọ NCDC to n gbogun ti ajakalẹ arun ni Naijiria loju opo Twitter rẹ.
Ọgbọ̀n yàrá ni ó wà lára àgbàlá náà.
Wọ́n ti fi ọmọ orílẹ̀-èdè Italy tó kó coronavirus sílẹ̀ nílèéwòsàn Eni mẹ́rin míì kó coronavirus ní Nàìjíríà, àfàìmọ̀ kó má dàbi ti China, Italy- Mínísítà kìlọ̀ Ṣe gbogbo nkan to wa ninu iroyin naa jọ otitọ?
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ìtàn ìgbé ayé Bode Thomas rèé, ó kọ́ wa láti máa kó ẹnu wa ní ìjánu Sanusi Adebisi Idikan rèé, olówó tó ń san owó orí fún gbogbo ọkunrin ilẹ̀ Ibadan Ṣo mọ̀ pé J.
Jehoaṣi ọmọ rẹ̀ sì jọba lẹ́yìn rẹ̀.
3 billion, ni eyi ti o se bee gbera, ti o si di bilionu mejilelogoji – le $42.
Kí ẹnikẹ́ni má baà tàn yín jẹ ní àkókò inúnibíni yìí.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Rélùwéè Eko: Alágbe tó kú náà jẹ́ ara àwọn tó ń jókòó lẹ́bàá ojú ìrìn 9 Ìgbé 2019 Oríṣun àwòrán, @Train Ileesẹ reluwe ilẹ wa ti fidi rẹ mulẹ pe lootọ ni ọkọ oju irin kan to ko ero, tẹ alagbe kan pa lagbegbe Muslim, nilu Eko.
" Wọn tẹsiwaju lati sọ pe lẹyin ti gomina ba to o ṣepade ati ijiroro pẹlu igbimọ lọbalaba ipinlẹ Kano nikan lo to le gbe igbesẹ lati rọ Emir kankan l'oye.
Ati pe Yoruba gba pe ẹmi ti ko jẹ ata, ẹmi yẹpẹrẹ ni.
ti won wa ki aare niluu Abuja lasiko ti ikọ awon obinrin to je oloselu, adari ile-ise,
Ẹ ma tii dako nitori ojo akọrọ - Nimet Kí ló ń fa ìjàmbá omíyale ní Naijiria?
Oro yii waye ninu atejade kan, lori ipada bo awon akekoo-binrin ti won jigbe nile-eko  kan ni Dapchi, nipinle Yobe ti o wa ni apa ariwa orile-ede Naijiria.
boolu afesegba lagbaye ti n fojusona fun lati bi osupa meta seyin yoo bere loni
Arabinrin Gileadi kan tí ń jẹ́ Hamoleketu ni ó bí Iṣodu, Abieseri, ati Mahila.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Spanish flu and other pandemic: Ẹ fokan balẹ, àwọn ajakale àrùn kan rèé to burú ju Coronavirus lọ 17 Ìgbé 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 19 Ìgbé 2020 Àkọlé àwòrán, Ìtàn Manigbagbe: Àwọn àjakalẹ-àrun to ti wáyé rí ṣáájú Coronavirus Wọn ní ìgbà kan ń lọ, ìgbà kan ń bọ̀, ayé kò dúró soju kan torí ẹṣin ta ta ta, ó kú, ènìyàn rìn, rìn rìn, ó sọnu.
Akẹ́kọ̀ọ́ ìmọ̀ òfin kọ̀ọ̀kan yóò gba ₦500,000 owó ìrànwọ́ l‘Oyo Bí ọdún Ọ̀ṣun Oṣogbo ṣe bẹ̀rẹ̀ rèé àti pàtàkì rẹ̀ fún Nàíjíríà Awọn obi Adewale Adeyẹmọ la gbọ pe wọn wa jijẹ mimu lọ silẹ Amẹrika lati orilẹede Naijiria.
Lafikun, wọn ni fun ayẹwo gangan, N614.
Idẹ ni ó fi ṣe ìtẹ́lẹ̀ wọn, ṣugbọn fadaka ni ó fi ṣe ìkọ́ ati àwọn ọ̀pá tẹ́ẹ́rẹ́tẹ́ẹ́rẹ́ wọn.
Ibo to le ni ẹgbẹrun mọkanlelọgọrin ni gomina Samuel Ortom ti ẹgbẹ oṣelu PDP fi n la Emmanuel Jime ti ẹgbẹ oṣelu APC.
Amọṣa, Stefan Savic ati Hector Herrera lo ra igba pada fun Athletico Madrid.
O ni irọrun eku lo difa fun irọrun ẹyẹ ni ati pe ti gbogbo nkan ba daru tan, ara ko ni rọ okun ati adiyẹ naa ni.
Ewe, Kano ti o sagbateru idije ohun, yoo maa waako pelu ipinle Eko ninu ifesewonse ti yoo maa waye ni papa isere iko agbaboolu Kano Pillars, Sabon Garri, Kano.
lorile-ede Naijiria(NNPC), so pe oun setan lati mu ibasepo to gboro jeyo laarin
Ìsìnkú Deji Okoya ọmọ-ọmọ ilúmọ̀ọ́ka onísòwò Rasak Okoya ni olùsáàgùntàn náà ṣe, tgí ó sì sọ níbẹ̀ pé gbogbo àyé fẹ́ẹ̀ dojúdé pẹ̀lú ìròyìn ikú ìyàwó òun, sùgbọ́n ènìyàn gbọdọ tẹ̀síwájú ìgbé ayé rẹ̀.
Ọmọ ọdún mẹrindinlaadọrun ni olóògbé Fálétí ki wọn tó jade láyé.
Koda, ẹgbọn mi obinrin lo mu emi ati ọkọ mi mọra.
    Lówùúrọ̀ ọjọ́ keje tí mò ń sọ̀rọ̀ rẹ̀ yìí, nígbà tí a dé aafin, a rí ẹnìkan tí ó jókòó lé orí ogiri tí o yí ààfin po.
Èdè Yorùbá àti ìmọ̀ ẹ̀dà èdè
Para ni baba yii beere pe se Dokita Silva bimọ ni.
Ààrẹ Bouteflika Algeria yoo kọ̀wẹ́ fipò sílẹ̀ ni 28 April Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Lati ọdun 1999 ni Aarẹ Bouteflika ti wa lori oye nilẹ Algeria Ile iṣẹ iroyin orile-ede Algeria sọ pe aarẹ Abdelaziz Bouteflika yoo kọwe fipo silẹ ki saa rẹ to pari ni ọjọ kejidinlọgbọn, Oṣu kẹrin ọdun.
Wọn wa n gbadura pe ki Ọlọrun fi owo ti isẹ igbohunsafẹfẹ nidi, ko ma jẹ pe awsn yoo kan gbe orukọ lori ni.
lero pe eto idibo naa yoo maa lọ bayii laisi wahala rara” .
Ìgbì omi wá ń dààmú ọkọ̀, nítorí afẹ́fẹ́ ṣọwọ́ òdì sí wọn.
ijọba to ku lati le pese ere ijọba tiwantiwa fun awọn ara ilu.
Awọn ọba mẹrindinlogun to wa ni Ekiti jẹ akikanju ati alagbara ti Yoruba lee gboju le.
Ọ̀rọ̀ yìí kì í ṣe ohun tí a lè parí ní ọjọ́ kan tabi ọjọ́ meji, nítorí ohun tí a ṣe yìí, a ti ṣẹ̀ gan-an 
Ijọba orilẹ-ede Naijiria si ti sọ pe awọn ọmọ ogun ti yi agbegbe ti wọn fura si pe ibẹ ni awọn agbebọn naa fi ara pamọ si.
Nípa àwọn eniyan mímọ́ tí ó wà nílẹ̀ yìí,wọ́n jẹ́ ọlọ́lá tí àwọn eniyan fẹ́ràn.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ijọba ko tii sọ ohunkohun lori rẹ O ni awọn ọmọ ẹgbẹ yii a tun maa gbe awọn ọmọde wọ inu igbo lọ lati kọ wọn ni oriṣiriṣi ẹkọ nigba ti wọn pada de.
Yóo dára fún ọ ní Efurata, o óo sì di olókìkí ní Bẹtilẹhẹmu.
Bí mo bá pa ọ́ tán n ó gbádùn ẹran rẹ fún ọjọ́ mẹ́ta.
Ọlọ́run sì wá bá mi ṣe é wí pé ní ọjọ́ tí mo dé oko náà ẹ̀yìn ni ó kọ sí mi, kí ó sì tó yí ojú padà, mo ti sáré sí i, mo dí ì mu.
O ni igbimọ PTF ti ṣe agbeyẹwo gbogbo nkan to n lọ lagbaye ti awọn si ti fi aba to yẹ sọwọ si aarẹ fun ibuwọlu ni kiakia Awọn nkan miran ti ilana tuntun yi mu iyipada ba ni: Didin iye eeyan ti yoo wa nibi ayyẹ eyikeyi tabi apejọ si pe kop ma ju eeyan aadọta lọ Awọn ile ounjẹ gbogbo ni yoo wa ni titi pa ayafi awọn to baa n ta ounj fun ile itura tabi ti awọn eeyan yoo ra ounjẹ lati lọ jẹ nile Awọn ero ti yoo kopa ninu ijọsin ile isin ko ni ju idameji iye eeyan to y ki o wa nibẹ lọ Awọn ọlọkọ ero ko gbọdọ ko ju ida meji dedee iye eeyan to yẹ ki wọn ko lọ Ki awọn eeyan yago fun gbogbo irinajo eyi ti ko ba ti pọn dandan lasiko yi Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Nigerian doctor shoots wife: Dr Benjamin Okigbo pa ìyàwó rẹ̀, pokùnso lẹ́yìn tó gbìyànjú láti pa ọmọ21 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Muyiwa Ademola: A ó jọ rọ́ọ̀kì ọdún 2021 papọ̀ ni lágbára Ọlọ́run26 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Funke Akindele: Bukunmi Oluwasina ní ọ̀kan lára àlá òun ló wá sí ìmúṣẹ18 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Fídíò, Fuji Music: Kollington Ayinla sọ ẹni tó dá orin Fuji sílẹ̀ gan an ní Nàiìjíríà16 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 3 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 5 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Ṣugbọn, Ṣoworẹ sọ pe ọgọrun ẹgbẹrun Naira l'oun yoo san ti oun ba di aarẹ, nitori pe Naijiria ni owo lati san an.
Amọ ṣa, wọn ni awọn kii sọ igbesẹ ti awọn yoo gbe lori awọn iwe ẹsun naa ni gbangba.
Awọn alaṣẹ fi ikede naa sita lẹyin ipade igbimọ alaṣẹ ti orilẹ-ede naa ṣe fun ọdun 2020 l'ọjọ Iṣẹgun.
merin eniyan ni won ti padanu ibugbe won leyin isele buruku yii, ti awon miiran
Ọrọ ko yatọ ni Jigawa ti awọn mọkanlelaadọrun ni arun naa ninu awọn mejidinlaadọsan.
Bí Ẹ̀mí bá ń darí yín, ẹ kò sí lábẹ́ òfin.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Goitre Patients: Àwọn èèyàn tó ní àrùn gẹ̀gẹ̀ ní ọ̀pọ̀ ìkórira àti ìdẹ́yẹsí ní àwọn ń kojú Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 3 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 5 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Ẹkọ apoogun oyinbo ni Baba ka to si gboye to di akọsẹmọsẹ nipa rẹ.
Èyí ni ohun tí ó yẹ gbogbo ẹni tí ó bá ń jẹ́wọ́ orúkọ rẹ̀.
Lẹ́yìn tí Solomoni ọba ti kọ́ ilé OLUWA ati ààfin rẹ̀ tán, ati gbogbo ilé tí ó fẹ́ kọ́.
Oríṣun àwòrán, other O ni, ohun eelo ibulẹ ṣọfẹli ni mo maa fi n pa awọn eeyan ti mo ba fẹ pa, maa si ka ayajọ naa si ori onitọhun ni kete ti mo ba ti rii ti ẹjẹ n jade lara rẹ"" O ni aṣẹ ti baba fun oun ni lati maa rin yi awọn agbegbe ti oku naa ba wa ka ki oun to kọ ẹyin si wọn."
láìrò télè , ògágun murtala dèrò òrun ni ojó ketàlá osù kejì , odún 1976 .
Gẹ́gẹ́ bí ìṣe wọn ní Lọndon lọ́dọọdún tí Kérésìmesì bá ti nsúmọ́, Ọgbà Hyde Park ti paradà di Winter Wanderland.
''Iru rẹ meji pere ni mo ti i ri lati bi ọdun mejila ti mo ti n ṣiṣẹ.
lasiko to n ba awon akoroyin sọrọ lọjọBọ ni olu ilu le -isẹ won to wa niluu
Soleimani ń gbìmọ̀ràn láti kọ lù wá l'Amerika la ṣe kọ́kọ́ yára mú u balẹ̀ - Trump Ìdí rè é tí a fí wó ìlè arúgbó ní ìdàjí -ìjọba ìpínlẹ̀ Kwara Àwọn fóònù wọ̀nyìí kò ní lè ṣe WhatsApp láti ọdún 2020 Idi ti EFCC ṣe mu Sheu Sani S'ahamọ.
Wọn kò rẹ ara wọn sílẹ̀ títí di òní, tabi kí wọn bẹ̀rù, tabi kí wọ́n pa òfin ati ìlànà tí mo fún ẹ̀yin ati àwọn baba yín mọ́.
Mo níláti kìlọ̀ fún ẹnu mi, àṣíírí ilé wa, n kò gbọdọ̀ tú u fún ẹnikẹ́ni, ọ̀rọ̀ tí baálé mi bá fi sí mi lọ́wọ́, n kò gbọdọ̀ gbé e lọ sílé ìyá mi.
Afara naa so awọn ilu nla mẹta to wa letido ni gusu orilẹede China pọ-Hong Kong, Macau ati Zhuhai.
CBN pàṣẹ kí MTN àti àwọn ilé ìfowópamọ́ da $8bn pada
O salaye pe, iwadii ti ajọ EFCC n ṣe jẹ ọkan lara ibaṣepọ ti o wa laarin ajọ EFCC ati FBI, lati foju awọn afurasi naa lede.
EFCC bẹ̀rẹ̀ ìwádìí lórí ẹ̀sùn ìwà jẹgúdújẹrá tí wọ́n fi kan Fowler tó jẹ́ Alága iléeṣẹ́ FIRS tẹ́lẹ̀ Kíní ọ̀nà àbáyọ sí ìjàmbá ọkọ̀ tó ń wáyé lemọ́lemọ́ ní Ọjà Akungba,ní Ondo?
“Ní ìhà gúsù, ilẹ̀ yín yóo lọ láti Tamari dé àwọn odò Meriba Kadeṣi, títí yóo fi kan odò Ijipti títí lọ dé Òkun-ńlá.
Weah to fi igba kan jẹ iluọmọọka agbabọọlu pada si ọfisi rẹ lẹyin ọsẹ meji ti o fi ibẹ silẹ fun awọn ejo naa.
Oríṣun àwòrán, Yemi osinbajo Amọ, Osinbajo fikun wi pe, awọn asebajẹ kan ni awujọ n wa ọna lati fi ọrọ eto abo to mẹhẹ naa lati da Naijiria ru.
Wayi o, Manchester United padanu ifesewonse naa sowo Manchester City pelu ami meji sodo(0-2), ti iko Wolves si di eru iya ru Arsenal lo si le pelu ami ayo meta sookan(3-1).
Ọwọ́ àwọn ọlọ́pàá ti tẹ ọkùnrin kan pẹ̀lú orí ọmọdé nílé aṣòfin àpapọ̀
Economic recession: Ìjọba ní àfàìmọ̀ kí ọrọ̀ ajé má tún dẹnu kọlẹ̀ fún ìgbà kejì láàrin ọdún mẹ́rin
Ṣugbọn sa, ijakulẹ ati ibanujẹ ni ọrọ Aarẹ Buhari ba de fun ọpọlọpọ ọmọ Naijiria, nitori bi aarẹ ṣe fi ọjọ mẹrinla miran kun isede.
Ko si si ẹni ri ariwisi si iwa ati iṣesi rẹ lawujọ lati igba ti o ti gun ori oye.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù 'Daura' di orúkọ tó ń bí awuyewuye lóríṣiríṣi ní ayélujára 7 Ògún 2018 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 9 Ògún 2018 Àkọlé àwòrán, Lati igba ti Lawal Daura ti bẹrẹ iṣẹ ni awuyewuye loriṣiriṣi ti n jẹyọ lori ihuwasi rẹ.
Ṣugbọn ọmọ ogun náà dáhùn pé, “Ò báà tilẹ̀ fún mi ní ẹgbẹrun (1,000) owó fadaka, n kò ní ṣíwọ́ sókè pa ọmọ ọba.
Ẹ wo Bẹnjamini tí ó kéré jù níwájú,ẹ wo ogunlọ́gọ̀ àwọn ìjòyè Juda,ẹ wo àwọn ìjòyè Sebuluni ati ti Nafutali.
Diẹ lara awọn ere to ti ko pa ni Obakeye, Awero, Edun Ara, Jenifa, Opa Kan, Omo Carwash ati bẹẹ bẹẹ lọ.
“Yè-è-é”, Igbe yìí ló ma ń polówo ọjà bàbá fún raa rẹ̀!
Àwọn àdáyanrí ìwà Tibet bíi ìní elẹgbẹ́ ẹni lọ́kàn, ìbọ̀wọ̀ fún àgbà, àìmọ̀kan ní ìpilẹ̀ ìbàjẹ́, ti fún mi ní ìgboyà.
Èyí ni ẹ̀dá tí ó túbọ̀ ń di titun siwaju ati siwaju gẹ́gẹ́ bí àwòrán ẹni tí ó dá a, tí ó ń mú kí eniyan ní ìmọ̀ Ọlọrun.
Kí wọn dìde, tí wọ́n bá lè gbà yín ní àkókò ìṣòro yín!
Ọlọpọlọ pipe ni Sanusi Sanusi ṣeṣẹ lawọn ile ifowopamọ kaakiri ko ti de ipo ọga agba ile ifowpamọ apapọ ni Naijiria.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Eko: Ọja Alaba njona 28 Èrèlè 2018 Oríṣun àwòrán, Getty Images Ọja Alaba to wa nipinlẹ Eko n jona lọwọ bayii.
Mose Súre fún Àwọn Ẹ̀yà Israẹli.
1 10,316 Trinidad and Tobago 130 9.
Láti ìgbà náà kò tún sí ẹni tí ó láyà láti bi í ní nǹkankan mọ́.
 Ramadan kii se fun ayẹyẹ nikan, bẹẹni kii
Nígbà tó yá wọ́n pa á, wọ́n sì tú gbogbo àwọn tí ó ń tẹ̀lé e ká; gbogbo ọ̀tẹ̀ rẹ̀ sì jásí òfo.
Lẹ́yìn náà, wọ́n fi igi akasia ṣe àkànpọ̀ igi tí ó dúró lóòró fún àgọ́ náà.
"Oríṣun àwòrán, Instagram/lizzy Anjorin Lawal Ẹ jẹ ka wo bi o ṣe kọ ọrọ rẹ naa: ""Ẹyin apọn, ẹ gbiyanju ki ẹ fẹ oyinbo ti yoo maa jẹ burẹdi ati tii lowurọ."
Bẹ ẹ si ni kii ṣe gbogbo orilẹ-ede lo ṣi faramọ ofin ọdun 1961 ọhun.
 ní ilẹ ̀ amẹ ́ ríkà iye owó rẹ ̀ jẹ ́ 100 sí 200 usd .
Toyin Abraham bí ọmọkùnrin jòjòló Òṣèré tíátà Toyin Abraham daya Kolawole Ajeyemi Wo àgbáríjọpọ̀ àwọn Arugbá Ọ̀ṣun Òṣogbo látìgbà tó ti bẹ̀rẹ̀ Buhari júwe ọ̀nà ilé fún Obono-Obla lórí ẹ̀ṣùn ayédèrú ìwé ẹ̀rí Àjẹ́ àti Aṣẹ́wó ní ìyá Rainbow - Òjòpagogo Facebook ni oun n reti abọ lati ọdọ awujọ awọn eeyan to n lo oju opo ikanni wọn lori igbesẹ wọn yii, lọna ati se agbeyẹwo awọn iroyin ti kii se ojulowo.
Bi awọn ipinlẹ to ni Coronavirus ṣe lọ ni yii: Plateau-103 Eko-70 FCT-60 Ondo-35 Edo-27 Rivers-27 Kaduna-20 Osun-19 Borno-18 Oyo-18 Kwara-11 Adamawa-9 Nasarawa-7 Gombe-6 Bayelsa-4 Imo-4 Bauchi-2 Ogun-2 Kano-1 Coronavirus kò rẹ́rìín sí ilẹ̀ Afíríkà mọ́ o Aarun naa ti tan kalẹ kọja gbogbo awọn ilu nla nla nilẹ Afirika to fi mọ awọn igberiko mii nibi to jẹ wipe awọn irinṣẹ eto ilera perete lo wa nibẹ ti itju alaisan si lee to jọ pupọ.
Olukuluku yóo pada sọ́dọ̀ àwọn eniyan rẹ̀, yóo sì sá pada sí ilẹ̀ rẹ̀, nítorí idà àwọn aninilára.
“Laarin ọjọ kansoso, eeyan ọrinlenirinwo o din mẹfa, 474 lo ko arun naa, ti eeyan meji si di ero ọrun, to si ti n foju han pe iye eeyan to ni arun Covid-19 lọsẹ yii yoo pọ ju ti ọsẹ to kọja lọ.
Gauri ni nkan pada rọgbọ ninu ile ni eyi ti inu iya Roshan dun si Senuli Chamalka, ọmọ tuntun ti wọn bi ki iya naa to ku.
Àwọn obinrin tí wọn bá Jesu wá láti Galili tẹ̀lé Josẹfu yìí, wọ́n ṣe akiyesi ibojì náà, ati bí a ti ṣe tẹ́ òkú Jesu sinu rẹ̀.
Ọdún ìdásílẹ̀ ilé iṣẹ́ BBC: A dá BBC sílẹ̀ ń ọjọ̀ kejìdílógun oṣù kẹwàá, ọdún 1922.
Ile-ise ologun ti sapejuwe atejade kan ti giwa ile-ise ologun teleri, ajagun feyinti Theophilus Yakubu Danjuma  so gege bi eyi ti ko lese n le, Danjuma soro yii nibi ayeye ikekoo gboye ile-eko giga fafiti ti ipinle Taraba  lojo-Abameta.
O ni, “awọn oṣiṣẹ olutọju ile bii ọmọ-ọdọ, awakọ, aṣọgba, ẹṣọ-ile, ati awọn miiran lo ṣe pataki ninu abadofin yii.
Ninu ifọrọwerọ pẹlu BBC, Dokita okei-Odumakin ni asiko to fun awọn obinrin lati dide ja fun itẹsiwaju ara wọn bayii.
A Goni lati di adari ẹka ologun ni olu ile iṣẹ to n ri si ọrọ to kan ologun kan araalu gẹgẹ bi adari ẹka iroyin.
O wa se ni laanu pe lode oni, asa Kengbe lilu naa ti n lọ sokun igbagbe, ti ọpọ eeyan ko si ya sidi rẹ mọ.
(Advocacy Network of Nigeria), Alhaji (Sheikh) Suleiman Busari ti je ki o di
ìlú Eko kọ́ ló léwu jùlọ láti gbé lágbàáyé- Ìjọba Eko Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
obinrin lo dipo isejoba mu ni saa akọkọ rẹ , bi i ipo akapo, ipo adari eto
Gbogbo ẹ̀ á wá mọ́nlẹ̀ dáadáa.
okan won kuro lori isakoso ijoba yii.
Yara lọ ṣeto tirẹ ki o to bọ sọna fun irinajo.
A ti n foju wo oro iyanselodi naa.
Adadi ati àwọn iranṣẹ baba rẹ̀ wọnyi kúrò ní Midiani, wọ́n sì lọ sí Parani.
Ìdíwọ́ ni eléyìí jẹ́ fún òun, ṣùgbọ́n ìrànlọ́wọ́ ni èyí jẹ́ fún kùkùté, níto’ri ọwọ rẹ̀ kò rí àyè bá kùkùté tí o ń ta gbúrúgbúrú kiri.
Ni ayé òde òni, owó ti dipò iwà.
Oríṣun àwòrán, Kayodebarkre Àkọlé àwòrán, Ebora owu naa ti de ibi ayẹyẹ Nínú ètò ti yóò wáye ni mọsàlási Jimoh nílùú Abuja lásìkò irún Jimoh toni ní wọn ti maa so wọn pọ.
"Kalu sọ pe ""Iwe ofin naa yoo la oniruru ipele kọja gẹgẹ bi awọn ofin to ṣaaju rẹ ko to di ofin nilẹ yii."
“N óo da jìnnìjìnnì bo gbogbo àwọn tí ẹ̀ ń lọ dojú ìjà kọ, rúdurùdu yóo sì bẹ́ sí ààrin wọn, gbogbo àwọn ọ̀tá yín ni yóo máa sálọ, nígbàkúùgbà tí wọ́n bá gbúròó yín.
Amọ ṣa, aarẹ ẹgbẹ naa, Ọjọgbọn Biọdun Ogunyẹmi ti kede pe irọ ni ọrọ naa ti awọn araalu ko gbọdọ ka si.
Igbakeji olori ile aṣojuṣofin, Họnọrabu Lasun Yusuff ni ko daju pe ẹgbẹ oṣelu APC lee kogoja ninu idibo pataki gbogbo to n bọ lọna.
Abeokuta , ti o je olu-ilu ipinle Ogun,nigba ti o n n se ipade pelu  awon ọba alayeluwa , o ni awon oludibo ni yoo
Yusuf ẹni ọdun mẹtalelọgbọn ni iroyin sọ pe o pa Kembi ti o si ge wẹlẹwẹlẹ lati fi ṣe oogun owo.
" Oríṣun àwòrán, Femi Adesina Aarẹ Buhari sọ pe titi lai ni ipa ti Ajimobi ko ninu idagbasoke ipinlẹ Oyo yoo wa ni iranti.
 bákan náà ni ìwé yìío yóò jẹ ́ ìpèníjà fún àwọn akẹ ́ kọ ̀ ọ ́ onímọ ̀ -èdè yorùbá láti túbọ ̀ kọ ibi ara sí àwọn ẹ ̀ ka-èdè yorùbá ju ti àtẹ ̀ yìnwá lọ .
Àwọn oníjàgídíjàgan dìde sí mi ní apá ọ̀tún mi,wọ́n lé mi kúrò,wọ́n sì la ọ̀nà ìparun sílẹ̀ fún mi.
Adamu so pe, ireti wa pe, ise akanse naa yoo wa ojutu si bi damu naa se n baje ni gbogbo igba, eleyi ti o si n ba ere oko awon eniyan je lopolopo.
Olukuluku wọn dúró sí ààyè wọn yípo àgọ́ náà, gbogbo àwọn ọmọ ogun Midiani bá bẹ̀rẹ̀ sí sá káàkiri, wọ́n ń kígbe, wọ́n sì bẹ̀rẹ̀ sí sá lọ.
Bí ọba ti ń kọjá lọ, wolii yìí kígbe pé, “Kabiyesi, nígbà tí mò ń jà lójú ogun, ọmọ ogun ẹlẹgbẹ́ mi kan mú ọ̀tá kan tí ó mú ní ìgbèkùn wá sọ́dọ̀ mi, ó ní kí n máa ṣọ́ ọkunrin yìí, ó ní bí ó bá sá lọ, èmi ni n óo kú dípò rẹ̀.
Boya ọlọkọ ero ni ẹ ni, abi ọmọ onilẹ, baba isalẹ oloselu ni ẹ ni abi agba janduku, ẹ ko ṣe fi igbe aye awọn alagbara aye to ti kọja lọ kọgbọn ati atubọtan wọn.
’ Níwọ̀n ìgbà tí ọmọ bá ti ṣe ohun tí ó bá òfin mu, tí ó sì ti mú gbogbo ìlànà mi ṣẹ; dájúdájú yóo yè ni.
Ní àkókò náà, ọ̀fọ̀ àwọn ará Jerusalẹmu yóo pọ̀ bí ọ̀fọ̀ tí wọ́n ṣe fún Hadadi Rimoni ní pẹ̀tẹ́lẹ̀ Megido.
Ipò àgbà ló yẹ́ kí a ti bá olórí - Fani-Kayode Melaye ni ori lo ko oun yọ lọwọ awọn apaniyan ọhun ati wi pe bi ki baa ṣe wi pe oun sapamọ sori igi, ọta ko ba ti ri oun gbeṣe.
Ninu oṣu kinni ọdun 2019 ni aarẹ Buhari jawe lọ rọọkun nile fun Onnoghen gẹgẹ bi alakalẹ ofin ile ẹjọ to n gbọ ẹsun awọn to du ipo nla mu lawujọ.
agbaye, eto aabo ati  idagbasoke lori eto
Ọdọọdun ni akanṣe isin Shiloh ma n waye ninu ijọ Winners, oriṣiriṣi awọn pasitọ ati akọrin si lo ma n ṣe iṣẹ iranṣẹ nibẹ.
Bíótilẹ̀jẹ́pé òjò nrọ̀, kò dí ayẹyẹ náà lọ́wọ́ rárá.
Dúró ní ilé, títí tí o óo fi gba ọmú lẹ́nu rẹ̀.
Nítorí pé àwọn tí Ọlọrun bá bukun ni yóo jogún ilẹ̀ náà,ṣugbọn àwọn tí ó bá fi gégùn-ún yóo parun.
 Á pá kan nínú ìnáwó yí ni ó kójọ níbi tí ́ ó tí ń ta puff-puff .
O yi ero awọn eniyan pada pé opó kii ṣe arun, bẹẹ wọn kii ṣe gbọkọgbọkọ rara.
Joshua lo fa baba rẹ sẹyin nigba ti o fẹ lọ koju onigbọwọ rẹ, Hearn lẹyin ti ija pari.
FIFA f'ẹsun kan Chelsea pe wọn tapa sofin ti o nii ṣe pẹlu rira awọn ọjẹwẹwẹ agbabọọlu.
Oríṣun àwòrán, AFP Àkọlé àwòrán, Aisan ọkan ni wọn sọ pe, o pa Ọ̀gágun àgbà Sani Abacha 3) Iṣẹlẹ ifofinde baalu lati ilẹ Yuroopu Eyi ni iṣẹlẹ to sunmọ ju to ṣẹṣẹ waye lẹyin ti awọn orile-ede Ajọ Yuroopu ka Naijiria kun awọn orile-ede aadọta ti wọn ko faaye gba ki baalu wa lati ilẹ wọn si Yuroopu.
Ẹni ìyìn ni OLUWA, Ọlọrun Israẹli,lae ati laelae.
O ni yatọ si pe wọn ti da awọn ọlọpaa ati ikọ agboguntiwa ibajẹ si agbagbe naa, awọn alaṣẹ ileeṣẹ ọlọpaa ti n forikori lori ohun ti wọn yoo ṣe si ọrọ naa.
Ijọba ni saaju igba ti awọn janduku naa ṣekọlu si ibẹ, awọn ti gbọ wi pe awọn n bọ lati wa hu iwa ipa si wọn ni agbegbe naa.
Tinubu 2023: Àwọn èèkàn ilẹ̀ Yorùbá ń ṣèpàdé ṣáájú dídìbò fún Tinubu ní 2023
Eyi waye lẹyin awuyewuye to waye ninu ajọ NDDC, ti wọn si fi ọwọ osi juwe ile fun un ti oun naa si fẹsun jẹgudujẹra kan minisita to n ri si ọrọ Niger Delta, Godswill Akpabio.
Lọjọ Satide ọsẹ to kọja ni iroyin ni ajọ to n ṣamojuto ina ọba paṣẹ fawọn ile iṣẹ to pin ina mọnamọna mọkanla to wa ni orilẹ-ede Naijiria pe ki wọn fikun owo ina bẹrẹ lati oṣu kẹrin ọdun 2020.
Ko si akọsilẹ fun Guinea-Bissau ati Guinea.
O ni pe: oníruurú àwọn ìṣẹ̀lẹ̀ tó n bá àsìkò yìí rìn lo pọ.
Wọ́n kìí ṣe àṣìṣe, Kílo fẹ́ jẹ yo láti sọ pé òbí rẹ̀ ṣe àsiṣe, o gbọdọ dá ara rẹ loju jù nitori bi àwọn òbi aye atijọ se maa n ba ọmọ wi O ní ìhà ti àwọn òbi Afrika wa lásìkò ti ọmọ n dàgbà pàápàá julọ lori yíyan ọrẹkunrin tabi ọ̀rẹ́binrin ti jẹ́ ki ẹlọmiran máa ni ìṣòrò nínú igbéyawọ nígba ti wọ́n ba pada lọ ilé ọkọ tàbi fẹ́ ìyàwó."
Dickson Etuhu ni awọn kan ti kọkọ ro pe o ti bọ lọwọ ifiyajẹni tẹlẹ ki igbẹjọ naa to tun jade.
O tẹsiwaju pe Sanwo Olu kan kọwọrin pẹlu igbimọ naa lọ si Egypt ni gẹgẹ bi ''ẹgbẹ alatẹwọ'' Ogedengbe Agbógun Gbórò, Akọni tó ń dẹ́rù ba ikú.
ogun Èkìtì parapọ ̀ yìí ni ó mú orúkọ Ògèdèngbe dúró sinsin nínú ìtàn yorùbá ogn náà si ja fún ọdún mẹsan gbáko ọdún 1910 ní ògèdèngbé kú .
Ìsun omi kíkorò kò lè mú omi dídùn jáde.
Ogbẹni Dewji si tun jẹ alatilẹyin fun ọkan lara awọn ilumọka ẹgbẹ agbabọọlu ni Tanzania ti orukọ rẹ njẹ Simba Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: 'Ọkọ̀ mẹ́ta péré la rí nínú odò adágún' Ìmáàmù yiì dóólà ẹ̀mí 262 Krìstìẹ́nì ni Plateau 'Wọ́n jí bàbá mi gbé ká tó kojú Argentina' Iwe iroyin Forbes so pe ni ọdun 2016, o fi idaji owo rẹ se itọrẹ.
Bakan naa aarẹ Trump ti gbajumọ daadaa lawọn orilẹede to wa ni Afirika bii Naijiria ati Kenya gẹgẹ bi iwadii ṣe fihan ninu oṣu kinni ọdun to si jẹ pe awọn to gba tiẹ ko bikita pe o ṣapejuwe Afirika gẹgẹ bi ibi ẹgbin ti wọn n da ilẹ si lọdun 2018.
Ó wá ku ẹnìkan tíí ṣe àyànfẹ́ ọmọ rẹ̀.
Ileesẹ akoroyinjọ nilẹ Naijiria (NAN) sọ pe, awọn arinrinajo naa de si papakọ ofurufu Murtala Muhammed ti ilu Eko, ni deede agogo Marun abọ nirọle ana, pelu awọn obinrin abilekọ bii marundinlogoji, baale ile mejidinlaadọrin ati awọn ọmọde mẹsan.
inú burúkú, ìmutípara, àríyá àwọn ọ̀mùtí ati irú nǹkan bẹ́ẹ̀.
"Eyi jẹ ibanujẹ fun mi, nitori pe ọpọlọpọ obinrin ti ọjọ ori wọn le ni ogun ọdun, lo ni idalẹbi ati itiju to ma n tẹle ti wọn ba fi le sọ sita.
Yoo faye gba awọn oṣiṣẹ ileeṣẹ to n ri si irina lati kọ iwe irina awọn eeyan to jẹ wi pe idi ti wọn fi n lọ ni lati lọ bimọ.
Bi awọn kan ṣe n gboriyin fun awọn to hu iru iwa yii naa ni awọn kan n bu ẹnu atẹ lu wọn.
Amọ, ọjọ Keji ti awọn agbokusi de lati lọ sin in ni wọn ba a nibi ti o ti n gbọn, ti wọn si tete mọ wi pe o si wa laaye.
ofurufu Nnamdi Azikiwe International Airport ilu Abuja silẹ ni deede aago mẹ́wàá ku isẹju
Àwọn ẹyẹ yóo fi wọ́n ṣe oúnjẹ ní ìgbà ẹ̀ẹ̀rùn,àwọn ẹranko yóo fi wọ́n ṣe oúnjẹ jẹ ní ìgbà òtútù.
Oríṣun àwòrán, LASEMA Àkọlé àwòrán, LASEMA npe fun ohun elo fun isẹlẹ pajawiri lẹnu isẹ ati ni ibudo ipam epo gbogbo Oludari ile isẹ LASEMA, Ọgbẹni Adesina Tiamiyu sọ pe awọn osisẹ rẹ gbiyanju lati pa ina naa ni kiakia ti wọn ti fi to wọn leti, ti wọn si dẹkun ibugbamu ina yi fun awọn agba ikepopamọsi yooku ni ile isẹ naa.
Oríṣun àwòrán, @thecableng Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Wo àwọn ìlúmọ̀ọ́ká tó ṣe ìgbéyàwó ní ọdún 2020 yìí Lawuyi Ogunniran, àgbà ọ̀jẹ̀ òǹkọ̀wé Eégún Aláré dágbére fáyé!
Àwọn ìlẹ̀kùn odò ṣí sílẹ̀,ìdàrúdàpọ̀ wà láàfin.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù 2019 Election: Oniṣẹ́ ibi làwọn to ni kí Atiku ma lọ si ile ẹjọ lóri èsì ìdìbò ààrẹ-Obasanjo 23 Ẹrẹ̀nà 2019 Àkọlé àwòrán, 2019 Election: Bí Buhari ba le lọ Kóòtù ní ẹ̀ẹ̀mẹ́ta- Obasanjo Ààrẹ àná ní orílẹ̀-èdè Naìjíríà Olusegun Obasanjo ti gbéna woju gbogbo àwọn to ń parọwa sí Atiku Abubakar ti ẹgbẹ́ òṣèlú PDP to fidirẹmi ninu ìdìbò ààrẹ to wáyé losu tó kọja pé kí ó màa gbé ọ̀rọ̀ náà lọ si ilé ẹjọ.
Wo bóo ṣe lè mọ̀ ayédèrú Wo bí ètò ìsìnkú Tolulope Arotilẹ yóò ṣe lọ nílùú Abuja lọ́sẹ̀ tó ń bọ̀ Nínú èèyàn 600 tó ní coronavirus lọ́jọ́ Ẹtì, 275 ló wá láti agbègbè ilẹ̀ Yorùbá 'Coro' wà 'Coro' ò sí o, èmi á lọ́ sókè òkún bí mo bá ríṣẹ́ - dókítà Ègún ọ̀dá owó yóò jà yín, tẹ́ ẹ̀ bá san ìdá mẹ́wàá - Oyedepo Oríṣun àwòrán, @ooniadimulaife Ooni pari ọrọ rẹ pe Awọn ọdọ ko gbọdọ gbagbe aṣa ati iṣe ilẹ wọn nitori ohun ni ọrọ ati ọla to gaju ti gbogbo wa gbọdọ ni."
Wo ohun tó yẹ kí o mọ̀ nípa àwọn obìnrin méje ti Buhari fẹ́ yàn sípò minista Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí kan sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
O tun gba awọn onimọ iṣegun ibilẹ nimọran lati mọ daadaa nipa ẹsin wọn, ki wọn ma si faaye gba ọrọ ti ko ba ba ohun ti wọn n ṣe mu.
Nítorí a ti lé Olùfisùn àwọn onigbagbọ ara wa jáde, tí ó ń fi ẹjọ́ wọn sùn níwájú Ọlọrun wa tọ̀sán-tòru.
Oladejọ naa ti ni ipenija nipa yiyi ede kan pada si omiiran bẹ́ẹ̀ si ni oun naa ti ni iriri tirẹ pẹlu awọn ontẹwe.
Isegun(Tuesday), bee si ni balogun iko Super Eagles , Mikel John Obi ati
Iṣẹ́ wọn ni láti tí òjò fún àwọn tó bá ni ìnáwo láti ṣe, yálà òkú àgbà, ìgbéyàwó tàbí láti lọ ta ọjà wọn, nínú ìwádìí BBC wọn tún ni àwọn míràn máa bẹ̀wọ́n lọ́wẹ̀ láti jẹ́ kí òjò rọ̀ níbí ayẹyẹ ọ̀tá wọn.
Bakan naa ni ireti wa pe igbimọ naa yoo ṣe agbekalẹ ilana ti yoo mu ki awọn to n kọle maa ṣe isẹ to pojuowo.
Iṣẹlẹ yii lo waye ni aṣalẹ ọjọ Eti ni ibudo ipagọ ni abule Gorny, ti ko jinna si Chita.
"Ó ṣeéṣe kí ènìyàn 12,000 máa kú lójoojúmọ́ lẹ́yìn Covid-19 Orílẹ̀-èdè mẹ́wàá tí ẹgbẹ́ alákatakítí Islamic State n fínna mọ́ ní àgbáyé N kò gba ₦4bn lọ́wọ́ Magu, ẹ má ró àjẹbánu mọ́ mi láṣọ - Osinbajo pariwo Mi ò tíì gba ìwé ìfitónilétí pé wọ́n fẹ́ yọ mí nípò igbákejì gómìnà ìpínlẹ̀ Ondo- Agboola Ajayi Shehu ni ""Orilẹede Naijiri ti n se ohun eelo ayẹwo arun Coronavirus, ta mọ si Testing Kits funra rẹ, eyi tawọn onimọ isegun oyinbo labẹle se jade."
Healthy lifestyle: Wo irú ìgbé ayé tó lè mú ẹ̀mí rẹ gùn
Isọri C: Awọn to ba wa ni isọri yii yoo lanfani si ipese ina manamana fun wakati mẹjs si mejila lojumọ Isọri D: wakati mẹrin si mẹjọ lojumọ lawọn to wa ni isọri yii yoo maa fi ri ina ọba lo lojumọ.
N óo fà wọ́n lé àwọn ọ̀tá wọn lọ́wọ́ ati àwọn tí wọn ń wá ẹ̀mí wọn; òkú wọn yóo di oúnjẹ fún àwọn ẹyẹ ati àwọn ẹranko.
Balasubramanyam to jẹ ẹni ọdun mẹrinlelaadọrin lo n gbe ni ilu Tamil Nadu, lorilẹede India.
“Oro yii waye lati ni ibasepo ni ona lati samulo awo lorisirisi ti ipinle kano n pese fun pipese orisirisi ohun elo awo niluu Aba.
 ní ọ ̀ pọ ̀ ìṣẹlẹ ̀ , lára aamì ni ibà , òtútù , àìle jẹun , èébì , iṣan dídùn pàápáà ní ẹhìn , àti orí fífọ ́ .
Trump jaweolubori lọna to ya awọn eeyan lẹnu Ohun keji to lee ṣẹlẹ ni ki Donald Trump bori lọna ti yoo ya awọn eeyan kan lẹnu.
Lagos- Ibadan Express: Kò sí ìfòyà lásìkò ọdún iléyá
awon osise pajawiri Red Cross ati awon osise itoju ilera ti n gbe igbesẹ lati tọju
O ni fidio naa kii ṣe ohun to n ṣẹlẹ bayii rara.
Obasani: “Aaye si wa fun awon eniyan lati ba wa da si oro to wa nile yii nitori pe ohun ti a ba jijo wo, gigun ni n gun.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Ní ìjọ wa, ọtí mímú la fi ń pe ẹ̀mí Ọlọ́run sọ̀kalẹ̀' Awọn eeyan ti ọbẹ ofin WAI ge lọwọ Ọpọlọpọ ọmọ Naijiria lo n kerora ifilọlẹ awọn ofin to n gbogun ti iwa ibajẹ ti Idiagbon gbe kalẹ nigba naa, nitori o ṣe ajeji lara wọn, to si tun ṣe akoba fun ọna ounjẹ awọn eeyan miran.
Ọpọ awọn agbalagba ọkunrin lo n fipa bawọn ọmọde lopọ lasiko yii, tawọn eeyan ko si sọ ohun kan nipa rẹ.
Ka ni ọlọpaa ibile wa ni, gbogbo nkan yi o ni maa ṣẹlẹ'' O pẹ fun ikọwefiposilẹ ọga ọlọpa ẹni to ni o ni ipa buruku lori Aarẹ Buhari pẹlu bi o ti sẹ sọ ara rẹ di agbẹnuso ati olugbẹlẹyin fun awọn darandaran'' Fayọṣe ni Gomina ẹlẹkeji ti yoo lọ si ipinlẹ Benue.
Bakan naa kii ṣe gbogbo ọrọ to kan aye rẹ lo yẹ koo maa pin kaakiri lori ayelujara.
Ki Ìjọba tuntun na a mọ̀ pé “Ori bi bẹ́, kọ́ ni oògùn ori fi fọ́”, nitori eyi ki wọn tẹ̀ lé òfin lati ṣe ìdájọ́ fún àwọn ti ó ba ilú jẹ́.
Kí alufaa wọ́n díẹ̀ ninu ẹ̀jẹ̀ ẹbọ ìmúkúrò ẹ̀ṣẹ̀ náà sí ara pẹpẹ, kí ó ro gbogbo ẹ̀jẹ̀ yòókù sí ìdí pẹpẹ, ẹbọ ìmúkúrò ẹ̀ṣẹ̀ ni.
idunkooko -mọni ati laasigbo awon alakata-kiti elesin Islam ohun.
Abrahamu bá pada tọ àwọn ọdọmọkunrin rẹ̀ lọ, wọ́n bá jọ gbéra, wọ́n pada lọ sí Beeriṣeba, Abrahamu sì ń gbé ibẹ̀.
O fikun pe onikaluku ẹda kọọkan lo gbọdọ mọ iwọn aawẹ ti ara rẹ lee gba, ko maa ba fa akoba si ilera rẹ nitori pe ohun ti Taye lee se, Kẹhinde lee ma lee se.
Ọrọ to sọ yii waye gẹgẹ bi esi fun awọn obi kan ni Naijiria, to n beere pe nigba wo ni ijọba yoo ṣi ileewe pada.
Ikú ń dẹ dẹ̀dẹ̀; dẹ̀dẹ̀ na n dẹ ikú ni bi Bukọla Saraki ṣe di aarẹ ile asofin agba laarin atako to lagbara Saraki to wa lati Aarin gbungbun Ariwa ja fun ominira fun awọn sẹnẹtọ lati yan olori fun ra wọn, lai gba asẹ lọwọ baba isalẹ kan-kan, o ja fun ipo aarẹ naa, to si bori, eleyi to muu di Aarẹ ile naa.
Àwọn ọmọ-ọ̀dọ̀ mi méjì ń sọ̀rọ̀ sí ara wọn.
Kí ló mú àwọn obìririn meji yìí pa bàbá wọ́n?
" Àwọn ènìyàn Iba tí ń ba àwọn Fulani gbé láti ọ̀pslọpọ̀ ọdún sẹ́yìn nínú ayọ àti aláfíà, ǹkan tó si sẹlẹ̀ yìí kò ni mú ipinya wáyé láàrin àrá ìlú àti àwọn Fulani.
“Kí baba ati ìyá ọmọbinrin yìí mú aṣọ ìbálé rẹ̀ jáde, kí wọ́n sì mú un tọ àwọn àgbààgbà ìlú náà lọ ní ẹnubodè.
Àwọn aposteli yìí ni ó fi ara rẹ̀ hàn láàyè lẹ́yìn ìjìyà rẹ̀ pẹlu ẹ̀rí tí ó dájú.
Eyi ni esi agbẹnusọ fun ile iṣẹ ọlọpaa Ipinlẹ Ondo, Femi Joseph si atẹjade kan ti OPC, New Era fi sita lọjọbọ.
Awọn ẹlomiran ni, ohun to buru jai ni ki Aarẹ Ile Igbimọ Asofin fi awọn to sisẹ takuntakun fun un lasiko idibo silẹ, lati lọ mu ẹlomiran to tako ẹgbẹ oselu APC.
Lati ọjọ kọkanlelọgbọn oṣu kejilasun 2019, oju opo yii to gbajugbaja eyi tii ṣe ti Facebook ni eeyan biliọnu kan abọ n lo.
    Ilé kan wà ní etí ilé òmùgọ́parpaọ̀ orúkọ ilé náà a máa jẹ́ Wọ̀bìáparapọ̀.
“Mo ti gbaradi pupo fun iru akoko yii, opo olukopa lo n fe lati lowo ninu ami-ayo ti yoo ran iko re lowo gba ife-eye, sugbon gbigbaradi saaju ifigagbaga se pataki.
Ẹni ọdún mejilelogun ni nígbà tí ó jọba ni Jerusalẹmu, ó sì jọba fún ọdún kan.
Mo rí ogun, mo jagun, emi ni mo le sọ nipa bi asiko ogun ṣe maa n ri."
”Naamani rọ̀ ọ́ kí ó gbà wọ́n, ṣugbọn ó kọ̀.
Àjọ elétò ìdìbò kéde ọjọ́ tí ìdìbò aàrẹ Nàìjíríà 2023 yóò wáyé Wo àwọn ojúṣe àti èèwọ̀ fún ikọ̀ ọlọ́pàá SWAT tó gba iṣẹ́ lọ́wọ́ SARS Pásítọ̀ Enoch Adeboye darapọ̀ mọ̀ #ENDSARS, ó fún ìjọba Nàìjíríà ní ìmọ̀ràn ọ̀nà àbáyọ Ijọba ipinlẹ Anambra pasẹ ma mu Gaari mọ 'Èèwọ̀' gààrí fún àwọn èèyàn ipínlẹ̀ Ondo Kíni ọ̀nà àbáyọ sí àìsàn Lassa Fever?
Ojogbon Osinbajo gboriyin fun ijoba ipinle naa fun ise takuntakun ohun to ti fee pari.
Ọmọ ìyá méjì gé orí ọmọ ọdún mẹ́wàá l'Eko 'Orin Olamide, Poverty Die ti di àdúrà àràárọ̀ fún mi' JAMB: Ẹ̀dínwó míràn ṣì leè wáyé lórí owó fọ́ọ̀mù ìdánwò Garba Shehu fikun wi pe ijọba Naijiria n sisẹ papọ pẹlu awọn orilẹede bii Niger, Chad, Cameroon ati Benin Republic lati ri wi pe eto abo to muna doko wa lawọn ibode orilẹede kan si omiran ki awọn ikọ Boko Haram ma baa ri ibi sa pamọ si.
A óo kó ọrọ̀ àwọn orílẹ̀-èdè tí ó yí i ká jọ: ati fadaka, ati wúrà, ati ọpọlọpọ aṣọ.
ogbon lara Ajimobi ki isejoba oun naa le se aseye talakan n sepo.
”Gbogbo eniyan sì tún bú sẹ́kún.
Oríṣun àwòrán, @amnesty Àkọlé àwòrán, Ẹgbẹ ajafẹtọ ẹni, Amnesty International bu ẹnu atẹ lu igbesẹ awọn ọmọ ogun Naijiria Nigbati ikọ Amnesty se ibẹwo si awọn ilu naa lẹyin fifi ina dẹru bolẹ ti awọn ọmọ ogun se lati oju ofurufu, wọn gbọ latẹnu awọn araalu to sapejuwe bi wọn se gbiyanju lati ba ẹsẹ wọn sọrọ nigba idẹru bolẹ ọhun.
Ọjọ Arafa bọ si Ọjọ Kẹsan ti awọn musulumi n pe ni Dhul-Hajjah, to jẹ ọjọ keji Hajj.
Idi ree ti BBC Yoruba fi tọ obinrin kan, Funkẹ Dosumu lọ, ẹni to ti ni arun yi ri, amọ́ ti ori ko yọ.
Awọn bi gomina ipinlẹ Oyo, Delta, Ondo, Bauchi, Kaduna, naa ti ni aarun naa.
 Idi niyi ti mo fi wa sorile ede Naijiria lati wa dije ki n si lo gbogbo imo ati opolopo ohun ti mo ko lorile ede Amerika fun idagbasoke orile ede Naijiria.
Ẹ kò ranti burẹdi marun-un tí mo fi bọ́ ẹgbẹẹdọgbọn (5,000) eniyan ati iye agbọ̀n àjẹkù tí ẹ kó jọ?
 Èkíní ni ohùn alámọ ̀ , tó sábà máa ń jáde lẹ ́ nu nígbà tí eléré àpíìrì bá fẹ ́ salámọ ̀ .
"Toyin Abraham fẹ́ wọ́ Lizzy Anjọrin lọ sílé ẹjọ́ Oògùn olóró cocaine ni Toyin Abraham fi ń sayé - Lizzy Anjorin Ẹ ṣé mo dúpẹ́ fún àdúrótì àti ìfẹ tí ẹ ní sí mi - Toyin Abraham Aya Kolawole jẹ ko di mimọ pe ọpọ obinrin bii toun naa lo n reti ati di iya aburo ti wọn si ti la oniruuru iriri kọja nipa iloyun ""nitori naa ni mo ṣe n fi ohun to ṣiṣẹ fun mi han fun un yin - Itọju pẹlu egboogi""."
Wọn óo wá mọ̀ pé èmi ni OLUWA.
 ni ojo kesan osu kesan odun 1991 ni a se awari planeti kekere yi ni ibudo awari ti o wa ni tautenburg .
" Nígbà miran ti bàbà mi bá dé sílè láti ibi tó ti lọ dá ẹrin posonu, tí a kò si ni oúnjẹ nílé, bí màmá mi bá béèrè pé owó tó mú bọ dà, yóò dáhùn pé òun ti pín owó náà fún àwọn tí ebi ń pá, tí yóò sì ní ká lọ mu gàárì, òun yóò fún wa lowo lọ́la láti fi ṣe irẹsi.
Lagbaye, orilẹede Naijiria lo wa ni ipo karunlelọgọrin, to si gbewọn si ju ipo kọkanlelaadọrun to mu lọdun to kọja lọ.
Asán ni wọ́n, wọ́n ń ṣini lọ́nà,píparun ni wọn yóo parun, ní ọjọ́ ìjìyà wọn.
Lẹ́yìn ọjọ́ mẹjọ, àwọn ọmọ-ẹ̀yìn tún wà ninu ilé, Tomasi náà wà láàrin wọn.
Ijegun Fire: Ẹ̀mí méjì, ọgbọ̀n ọkọ̀ àti ọ̀pọ̀ ṣọ́ọ́bù ló bá ìjàmbá iná rìn
Ijoba orile-ede naa se ileri lati sin oku olori ijoba orile-ede naa bi o tile je alatako.
Musa ku lọdun 1337 ni ẹni ọdun mẹtadinlọgọta, lẹyin naa lawọn ọmọkunrin rẹ bẹrẹ si ni ja si ẹni ti yoo gun ori itẹ baba wọn.
Ààwẹ Ramandan àti irú ouńjẹ tí o lè jẹ Ojú ń tì mí láti rí àwọn ọmọbìnrin Nàìjíríà tó ń ṣe aṣẹ́wó ní Italy Ọjọ̀gbọ́n Fatunde: Báyìí ni bàbá ìsàlẹ̀ nínú òṣèlú ṣe lè dópìn bí El-Rufai ṣe sọ Oluwatobi ni ko boju mu lati maa lo ohun to lee pa ara lati fi ṣinu dipo awọn eroja to lee bẹrẹ si ni ṣi awọn irinṣẹ ara naa pada eyi to ti pa oju de.
 ""Inu wa ko dun rara si bi rogbodiyan ṣe n waye ni ipinlẹ Edo saaju ọjọ idibo"" ""O si ba ninu jẹ pẹlu ẹsun pe awọn eleto aabo n ṣiṣẹ pọ pẹlu awọn oloṣelu lati da awhala silẹ ni ilu."
Oríṣun àwòrán, @NigAirForce Àkọlé àwòrán, Tsaigumi yoo wulo fun gbigbogun ti ikọ̀ adukukulaja Boko Haram Ju gbogbo rẹ lọ, baluu adanikan fo ti ileesẹ ọmọogun ofurufu orilẹede Naijiria sẹsẹ se ti wọn da orukọ rẹ pe ni Tsaigumi yii le e ko ipa pataki ninu eto idaabo bo ẹmi ati dukia gbogbo ti ijọba apapọ n se ni pataki julọ lagbegbe ila oorun ariwa orilẹede Naijiria nibi ti awọn ikọ adukukulaja ni, Boko Haram ti n sọsẹ.
Ó tún gbé igba (200) ọdún sí i láyé lẹ́yìn tí ó bí Nahori, ó sì bí àwọn ọmọ mìíràn lọkunrin ati lobinrin.
Faleti pada kawe ni Fasiti ọlọgba ẹranko nibi ti sanmọnti gbe dunlẹ ni Ibadan to ti gboye imọ nipa Litireṣọ ede oyinbo.
ipolongo fun egbe PDP fun eto idibo odun 2019 ni ipinle Kwara ojogbon Abubakar
Olórí àwọn ẹ̀yà kọ̀ọ̀kan mú ọ̀pá wọn wá fún Mose, gbogbo rẹ̀ jẹ́ mejila, ọ̀pá Aaroni sì wà ninu wọn.
Àwọn ọmọ Nàìjíríà ṣe ìwọ́de l'Osogbo lórí àfikún owó epo bẹntiróò Awọn eeyan niluu Osogbo tii ṣe olu-ilu ipinlẹ Oṣun ṣe ifẹhonuhan lori afikun owo epo bẹntiroo ti ijọba apapọ ṣẹṣẹ kede rẹ.
Oríṣun àwòrán, Adégbóyèga Adébàjò Àkọlé àwòrán, Adebajo ati awọn ọmọ rẹ nibi apeje ajọyọ ife ẹyẹ Challenge Cup lọdun 1968.
Amọ eyi ko ri bẹẹ pẹlu Ọba alaye kan nilẹ Yoruba, ti araalu fẹyin ti, to ja wọn lẹyin kulẹ, ti wọn gboju okun le, amọ ti ko jọ ẹni agba.
Ninu atejade kan ti alukoro fun ẹgbẹ  APC  Mallam Bolaji Abdullahi, gbe jade pe bi awọn ọmọ ẹgbẹ  APC se n yapa kuro ninu ẹgbẹ  wọn ,ki I se ohun ti eti wọn di si.
Kí olukuluku wí fún ọmọ rẹ̀ ní ọjọ́ náà pé, ‘Nítorí ohun tí OLUWA ṣe fún mi, nígbà tí ó mú mi jáde láti ilẹ̀ Ijipti wá, ni mo fi ń ṣe ohun tí mò ń ṣe yìí.
Olumide Apata to jẹ Aarẹ ẹgbẹ naa lapapọ ni Naijiria lo kọkọ fi ikede yii sori ikanni ayelujara twitter rẹ ki ọpọ awọn agbẹjọrọ miran to maa tun ṣe ikede kan naa loju opo ibararẹnisọrọ wọn kaakiri.
Baba Obasanjo: Àwọn ọ̀rẹ̀ sàpèjúwe Baba Obasanjọ ní ọjọ́ ìbí 83 wọn
 Ltd,  ogbeni Plamen Iliev, to n ko papa isere ultra-modern stadium nilu Jos so pe, ise yoo pari lori papa isere ohun ninu osu karun-un odun ti a wa yii.
O tun tesiwaju pe , igbimo naa ti gba awon ibugbe to dun un gbe fun awon arinrinajo naa.
Ọọni ile ifẹ ṣalaye pe nigba ti ijọba ipinlẹ Kano rọ Emir Sanusi Lamido Sanusi loye to yan Emir Ado Bayero sipo, ọkan ọpọ eeyan lo n gbọn riri nitori ko si ẹni to mọ ibi ti afẹfẹ ọrọ naa yoo fẹ si.
Òkìkí rẹ̀ sì kàn káàkiri gbogbo agbègbè tí ó yí i ká.
Bakan naa, iwe ọhun mẹnu ba bi wọn yoo ṣe tọju oku ẹni to jẹ pe Covid 19 lo ṣokunfa rẹ ati pe ohun aa ṣe lasiko irinajo ti wọn ba n gbe oku lọ fun apẹrẹ, Igbesẹ gbigbe oku wọle naa ni: *Titi pa ni posi ti wọn fi gbe oku gbudọ wa wọn ko gbudọ ṣi posi loju popo *Wọn gbudọ ṣe ayẹwo imọ ijinlẹ sayensi fun oku ki wọn si tọju ayika ti wọn yoo lo * Wọn lee gbe oku laarin ipinlẹ si ipinlẹ pẹlu ọkọ agboku awọn onimọ ilera tabi ọkọ mii to wa fun gbigbe oku, to ba jẹ lati oke okun, ki wọn gbe e gẹgẹ bi ẹrù lori ọkọ baalu.
Èyí ni ilẹ̀ ẹ̀yà Juda gẹ́gẹ́ bí iye ìdílé wọn, 
"Orin ọhun eyi ti wọn pe akọle rẹ ni ""Promise"" ni wọn gbe jade sori ikanni twitter ati youtube eyi ti awọn ololufẹ wọn si ti n kan saara si wọn lorii rẹ."
À ń dúró de ìwé ìrìnnà Sowore kí a tó fisílẹ̀ - DSS Aago mẹsan an kọja iṣẹju mẹẹdogun ni Omoyele sowore de sile ẹjọ ni abuja ṣaaju Adajo Ijeoma Ojukwu ti n gbọ ẹjọ ọhun.
A fún un ní turari pupọ kí ó fi rúbọ pẹlu adura gbogbo àwọn eniyan Ọlọrun lórí pẹpẹ ìrúbọ wúrà tí ó wà níwájú ìtẹ́ náà.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Cancer: Àṣe ara mi ni iso ti n run gbogbo bí mo ṣe n ṣèrànwọ́ lórí jẹjẹrẹ O gba iranlowo university fellowship to fi lo kawe laarin odun 1983 si odun 1990 ni School of Oriental and African Studies, ni fasiti London O gba ami ẹyẹ ti Kwame Nkrumah to wa fawọn olori lọdun 2016 si ọdun 2017.
Presidential Debate: Ọ̀rọ̀ bọ́ lórí bí Buhari àti Atiku ṣe kọ̀ láti ṣe ìjírọ̀rọ̀
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ondo: Dejí sun ọmọ méje àtagbalagba meji mọ́lé nítorí pé ó ń bínú Ki ni esi Neymar?
Juda dá a lóhùn, ó ní, “Má wulẹ̀ wá a kiri mọ́, kí àwọn eniyan má baà máa fi wá ṣe yẹ̀yẹ́.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Delta Accident: Orí yọ dírẹ́bà ọkọ̀ tó jóná ráúráú ní Delta 3 Ọ̀wàrà 2020 Oríṣun àwòrán, Google Awakọ kan jajabọ lasiko ti ọkọ rẹ gbina ni opopona PTI Junction, ni ijọba ibilẹ Uvwie, ni ipinlẹ Delta.
”OLUWA ní, “Lọ sí ìlú Heburoni.
 Mo n fi asiko yii dupe lowo awon omo igbimo CECP ti won ro mi lati satileyin lori oro arun jejere to ti n fe gbebo lowo awon eniyan lasiko yii ni eyi to bi eso rira oko alagbaeka yii.
Maryam Sanda: Àdájọ́ ní kí wọ́n yẹgi fun títí tí ẹ̀mí yóò fi bọ́ lára rẹ̀
Ẹyin ilé ìjọsìn, ẹ tilẹ̀kùn ṣọ́ọ̀ṣì àti mọ́ṣáláṣí yín láti dènà àrùn Coronavirus - ìjọba Eko Ẹ wo ohun tí baba Adeboye sọ lórí ọ̀rọ̀ Coronavirus Kí ni ìtumọ̀ Pelúpelú, ìlànà àkàsọ̀ ọba tó fa wàhálà l'ọ́balọ́ba l'Ekiti Nílé ijó Fẹla Anikulapo, àrùn Coronavirus dá fàájì dúró Wo àwọn irọ́ tí wọ́n ń pa fún ọ nípa àrùn Coronavirus Arakunrin naa to jẹ awakọ fun ọmọ ilẹ Amẹrika naa, pẹlu arabinrin kan to jẹ olutọju fun un n lo ọsẹ meji ni ilu Ibadan ki wọn to tẹkọleti lọ si ilu Ado Ekiti nibi ti ọmọ orilẹede Amẹrika naa ti dubulẹ aisan to si ku.
Ó wí fún àwọn arakunrin rẹ̀ pé, “Wọ́n dá owó mi pada, òun nìyí lẹ́nu àpò mi yìí.
Nítorí ọkọ ni olórí aya gẹ́gẹ́ bí Kristi ti jẹ́ olórí ìjọ.
Kunle Afolayan Idile olosere ni awọn Afolayan lati ilu Agbamu nipinlẹ Kwara.
O kadi ọrọ rẹ ni ikẹyin pe ki awọn ara ilu Ondo yi ọna ti wọn n tọ saaju pada ki nkan baa le yatọ ni Ondo.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Coronavirus: Àwọn èèyàn ìpínlẹ̀ Eko ń sunkún ebi lásìkò ìgbélé 4.
Oríṣun àwòrán, unilag Awọn akẹkọ yoo se idanwọ nigba ti a ab ati ri pe a le mojuto wọn daada'' Orileede Naijiria nikan kọ ni awọn ijọba ti gbe igbesẹ ki awọn ileewe wa ni titi pa lasiko arun Coronavirus yi.
Olùkọ́ àgbà tó fipá bá ọmọ ọdún 13 lò yóò fojú ba ilé ẹjọ́ ni Benue Uganda ti bẹrẹ ìgbésè láti fi ikú ṣefàjẹ fún ẹní bá ṣe ìgbéyàwó akọ si akọ ati abo si abo Èmi kò sí nílé, ọkọ́ mi ló leè sọ bóyá lóòtọ́ọ́ ló fẹ́ gbéyàwó àbí bẹ́ẹ̀ kọ́ - Aisha fèsì Àbà ètò ìṣúná 2020 tó kéré yóò mú kí ètò ààbò mẹ́hẹ síi ní Nàìjíríà-Onwoye Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Rape: Ayé obìnrin tí wọ́n fipábálòpọ̀ kò lè rí bákàn náà mọ́ Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Oríṣun àwòrán, Seyi Makinde Oríṣun àwòrán, Seyi Makinde Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Bọọlu kan ṣoṣo ni Manchetser City ri gba soju ile Arsenal lati ibẹẹrẹ titi de opin ifẹsẹwọnsẹ naa, eleyi to kere ju fun wọn lati oṣu kẹrin, ọdun 2018.
Elija bá lọ fi ara han Ahabu.
Nengi sọ pe oun ti n fura pe oun yoo já.
 omi àti ẹran tó jáde láti ara ẹnití ó ní àrùn náà ni a gbọ ́ dọ ̀ gbé tàbí dìmú pẹ ̀ lú ìṣọ ́ ra pàtàkì .
Dájúdájú, àṣà láti bù sí ẹwà ara ni irú àwọn bẹ́ẹ̀ ka ilà kíkọ sí.
Asọ dudu duro fun ibanujẹ, sugbọn fun ti emi, asọ funfun ni kẹ wọ, tori mo nifẹ asọ funfun pupọ̀.
Bẹ́ẹ̀ ni a kò wá ìyìn eniyan, ìbáà ṣe láti ọ̀dọ̀ yín, tabi láti ọ̀dọ̀ àwọn ẹlòmíràn; 
Aṣofin Ipinlẹ Eko, ku aawẹ Ramadan, pe Ọlọrun Allah yoo gba a ni ibada.
Ọ̀tá gidi ni ó jẹ́ fún Israẹli ní ìgbà ayé Solomoni, ó sì ṣe jamba bí Hadadi ti ṣe.
Awọn kan gba ibeere naa nigba ti àwọn miran kò gbáa.
Saulu bá tẹ́ pẹpẹ kan fún OLUWA.
22 Ìgbé 2019 Abolore Adegbola Akande ti awọn ololufẹẹ rẹ mọ si 9ice sọrọ nipa igbesi aye rẹ àti ero rẹ nipa bí àwọn oṣere kan ṣe maa n mu igbo ati ọtin ki wọn to ṣere.
Olórí Alufaa bá fa aṣọ rẹ̀ ya, ó ní, “O sọ̀rọ̀ àfojúdi sí Ọlọrun.
Inú wa ìbá sì dùn kí á kúrò ninu àgọ́ ti ara yìí, kí á bọ́ sinu ilé lọ́dọ̀ Oluwa.
Sáájú ní àkọ̀wé gómìnà Kwara Rafiu Ajakaye ti fi àtẹjáde kan síta pé gómìnà ìpínlẹ̀ Kwara Abdulrazaq Abdulraman ti pàṣẹ pé kí wọ́n fún àwakọ̀ náà ni iwé ìdádúró.
O ni ọdun 2019 ni UNICEF yoo sami ọgbọn ọdun ti wọn gba abadofin ẹtọ awọn ọmọ wẹwẹ wọle lagbaye.
Jean Adukwei Mensa bọ sipo gẹgẹ bi alakoso eto idibo Ghana lọjọ kẹtalelogun oṣu Keje, 2018 lẹyin ti wọn yọ ẹni to wa nibẹ kuro.
Nígbà tí a dágbére fún wọn tán, ọkọ̀ ṣí.
Ninu rẹ, a ko ri oju ẹni to kọrin naa nitori pe iha ati ẹyin lo kọ si oju kamẹra.
Ọmọ aláya ọba, èyí tí ń ṣàǹfàni nínú ilédì, ọmọ àgbàgbà ìmùlẹ̀
Nitori naa ni a ṣe ṣe akọsilẹ awọn nkan mẹwaa ti a nilo lati fi le daabo bo ara wa lasiko arun Covid-19.
 ní ọdún 1979 awólọ ́ wọ ̀ dá ẹgbẹ ́ òṣèlú kan Ẹgbẹ ́ Òṣèlú Ìmọ ́ lẹ ̀ sílẹ ̀ .
Wọn ni eyi ko ṣẹyin itankalẹ aarun coronavirus to n ran kiri agbaye, to si ti de orilẹ-ede to le ni aadọwa.
N óo jẹ́ kí àwọn ẹranko burúkú pa wọ́n jẹ,n óo sì jẹ́ kí àwọn ejò olóró bù wọ́n ṣán.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù BBC: Osisẹ ijọba Eko fi tipa gba irinsẹ akọroyin wa 20 Ẹrẹ̀nà 2018 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Aimọye igba ni awọn akọroyin maa nkoju abuku lẹnu isẹ wọn Ileesẹ ọrọ ayika nipinlẹ Eko ti fi tipa tikuuku gba awọn irinsẹ agbohun ati aworan silẹ to jẹ tileesẹ wa BBC, ti wọn si pa gbogbo awọn fidio ati aworan mii to wa lori ẹrọ wa naa rẹ, ti wọn si tun ko wọn lọ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Lockdown updates: Naira Marley gbóríyìn fún Jude Chukwuka pẹ̀lú #1 míliọnù Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
22 Ṣùgbọ́n nísisìyí pa ẹnu rẹ mọ́; ṣe àṣàrò nínú ọ̀rọ̀ mi èyí tí ó ti jade lọ sí ààrin àwọn ọmọ ènìyàn, àti bákannáà ṣe àṣàrò nínú ọ̀rọ̀ mi èyí tí yíò jade wá ní ààrin àwọn ọmọ ènìyàn, tàbí èyí tí a nṣe ìtumọ̀ rẹ̀ lọ́wọ́, bẹ́ẹ̀ni, títí tí ìwọ yíò fi gba gbogbo ohun tí èmi yíò fi fún àwọn ọmọ ènìyàn ní ìran yìí, àti pé nígbànáà ni a ó fi ohun gbogbo tí ó kù kún un.
O ṣalaye ninu fọnran kan to fi si oju opo Twitter rẹ pe gbogbo ara ni oun ti fi ti iwọde naa lẹyin lati ibẹrẹ pẹpẹ nitori naa oun ko lee si nidi idaru rẹ.
5 owó naira ni ọọfiisi àjọ INEC ni Zamfara Wo àwọn orílẹ̀-èdè márùn ún tó fún àwọn obìnrin làńfàní tuntun sí ẹ̀tọ́ wọn Angelique kidjo pe fun anfani f'awọn obinrin Oríṣun àwòrán, Jessica Nabongo Àkọlé àwòrán, Jessica Nabongo Nibẹ ni o ti bẹrẹ si ni ko owo jọ, ti o si ṣe okoowo aṣọ ṣẹẹti wiwọ.
Síṣe àgbékalẹ̀ aṣọ náà jẹ́ àtòpọ ẹbun ọpọlọ ti ọlọrun fun unàtí ànfààní tó rigbà lọwọ àwọn alábasiṣẹpọ̀ rẹ̀.
 agbára ńlá , ọwọ ́ rẹ ̀ ló wà .
Gbogbo rẹ̀ ni n ó rò fún yín ní apá kèjì ìtàn yìí.
Bẹ́ẹ̀ ni yóo di ohun ìyanu fún ọpọlọpọ orílẹ̀-èdè, kẹ́kẹ́ yóo pamọ́ àwọn ọba wọn lẹ́nu,nígbà tí wọ́n bá rí i,wọn óo rí ohun tí wọn kò gbọ́ rí nípa rẹ̀,òye ohun tí wọn kò mọ̀ rí yóo yé wọn.
Atiku sọ eyi lasiko to n fesi ọrọ ti ẹgbẹ oselu APC sọ wi pe ko tọ ọ si lati dije dupo aarẹ lorilẹede Naijiria nitori ilẹ Cameroon lo ti wa, ti kii si i se ọmọ Naijiria.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Àwọn tó ń wojú ọjọ́ rí ihò dúdú tó tóbi jù láyé àtọ̀run 11 Ìgbé 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 13 Ìgbé 2019 Oríṣun àwòrán, EHT Collaboration Àkọlé àwòrán, Fun ìgbà àkọ̀kọ̀, àwọ̀n tọ́ ń wojú ọjọ́ ti ya àwòrán ihò dúdú tó tóbi jùlọ ní gbogbo aye àti ọ̀run tí ó wà ní ọ̀run galaxy.
Ni nnkan bi ọjọ kan tabi meji lyin ti gbogbo janmọ yoku ba pari awẹ lawọn yoo ṣọdun tiwọn.
Awọn dokita kan bu ẹnu atẹ lu igbesẹ yii pe ibẹru ti koi to lo n ko wọn laya soke nitori naa ilanilọyẹ kikun ṣe pataki nipa ohun to n jẹ sisunmọ alaisan.
Amọ, o da bi ẹni pe ọpọ ọmọ Naijiria ni ko ti i gbọ tabi mọ nipa ilana tuntun yii.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Òǹtàjà aṣọ ni mí tẹ́lẹ̀, ọ̀dá owó ló sọ mi di alábárù Iṣẹ takuntakun ti Oyinkan Abayomi ṣe fun agbega obinrin ati iran ọmọniyan: Oyinkan jẹ agbẹnusọ fun ifẹsẹmulẹ ẹtọ awọn obinrin nigba aye rẹ ati eto ẹkọ wọn, to si tun n ja fun ibaradọgba ati ipo kan naa fun takọtabo.
Ẹni tí yóò gbẹ́ ilẹ̀, àwọn tí yóò wẹ òkú àti bàbá- ń- sìnkú.
O le ni ọdun mẹwa ti wọn fi n wa okuta ni agbegbe yii, ti ẹ́nu si wa n ya awọ̀n olugbe adugbo naa lori bi ọpọ ero si n ya ba wọn ni alejo.
Ọ̀pọ̀ ọ̀rọ̀ nípa ọjọ́ ìbí rẹ̀ yìí ló sì ti gbá síta lóri òpó twitter rẹ pé, òun dúpe lọ́wọ́ Ọlọrun fún ọjọ́ òní, ó fi kún un pé òun ṣetan láti túbọ tẹra mọ́ isẹ́ síì.
Wọn ni awọn ko le sọ ohun kankan lọwọ yii lori fidio CNN titi di igba ti esi igbimọ ti wọn kalẹ lati ṣe iwadii iṣẹlẹ naa yoo fi jade jade.
Nigba ti alakoso naa n soro lori  ile-ise to n samojuto ilu Abuja , Geographics Information System, AGIS ati bi awọn  osise ile ise naa se n gbaradi fun bi awọn  eniyan se n yawọ inu  ilu Abuja.
Gbogbo ènìyàn ni a bí ní òmìnira; iyì àti è̩tó̩ kò̩ò̩kan sì dó̩gba.
’Nítorí pé n óo dá ire wọn pada bíi ti ìgbà àtijọ́.
" Bawo ni ọkọ to n fi ẹyin rin yoo kan ṣe pa ọmọ ologo bayii ninu ọgba ologun?
O ti to ọjọ mẹta ti iroyin Spartan ti gbalẹ kan pe awọn ọlọpaa n wa nitori pe wọn fura si pe oun lo n gba ẹmi pupọ nilu Iperu ati Ogeere.
Ẹ ní mo ní kí n kọ́ ranṣẹ láti sọ fún un ni, kí n lè rí ojurere lọ́dọ̀ rẹ̀.
Igbeyawo ọun, laarin Oluseun Bakare ati Damilọla Osinbajo lo waye nile ijọba nilu Abuja.
Ojú pópó ni mo dàgbà sí àmọ́ n kò mu igbó, sìgá tàbí ọtí líle rí - MC Oluomo Lẹ́yìn tó ṣá Monisola aya rẹ̀ ládá, Oniya ní iṣẹ́ èṣù ni Ọ̀rọ̀ Sotitobire tí a dá sí, àwọn aṣòfin àtàwọn àjọ kan ló fi lọ̀ wá- DSS George Floyd wọ káà ilẹ̀ lọ nílùú Houston l'Amẹrika Iye awọn eeyan to ṣẹṣẹ ko arun naa ni ipinlẹ kọọkan ree: Eko -170 Ogun-108 Bauchi-69 Ebonyi-49 Edo-33 Rivers-30 FCT-26 Jigawa-26 Delta-20 Anambra-17 Gombe-16 Kano-16 Imo-15 Abia-14 Borno-11 Oyo-11 Plateau-8 Kebbi-6 Kaduna-6 Ondo-4 Niger-2 Katsina-2 Osun-1 Ekiti-1 Kwara-1 Nasarawa-1 Èèyà 315 ló lùgbàdì àrùn Coronavirus ní Naijiria ní ọjọ́ Ajé Oríṣun àwòrán, Twitter/todayng Ajọ NCDC ti kede eniyan 315 gẹgẹ bi apapọ awọn to ni arun Coronavirus lorilẹ-ede Naijiria ni ọjọ Aje.
Yatọ si pe ẹni ọdun mejidinlọgọta ni ko to jade laye, ohun to n ṣe ọpọ eeyan ni haa-hin bayii ni iru iku to gbẹmi rẹ.
naa se poora nile ise naa.
oludibo  lo fi aidunnu won han bi awon
awon ti o lo owo won,fun ipolongo eto idibo yii lorile ede Naijiria.
“Nígbà náà ni ìmọ́lẹ̀ yín yóo tàn bí ìgbà tí ilẹ̀ ṣẹ̀ṣẹ̀ mọ́,ara yín yóo sì tètè yá.
O ni awon gomina yoo tun sepade labe ‘ipade apapo awon gomina’lati so nipato nipa ekunwo awon osise.
Agbẹjọro kan, Matteo D'Angelo to da eto iranwọ fun Ọgbẹni Monday silẹ lori ayelujara lati san faani rẹ sọ pe ijiya ti wọn fun un ko boju mu rara.
Access Bank: A kò dá ẹnikẹ́ni dúró lẹ́nu iṣẹ́, Coronavirus ló jẹ́ ká ti àwọn ẹ̀ka wa
Abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Patrick Day dèrò ọ̀run lẹ́yìn tó gba ẹ̀ṣẹ́ s'órí!
Ewe, ogbeni Nkurunziza ti n tuko orile-ede ohun lati odun 2005, won ni, bi won ba fi le gba erongba ohun wole, eyi yoo fun un lanfaani lati tun wa lori aleefa fun saa odun meji miiran.
kí ẹ sì tún máa wá jọ́sìn níwájú mi ninu ilé yìí, ilé tí à ń fi orúkọ mi pè; kí ẹ máa wí pé, “OLUWA ti gbà wá là;” kí ẹ sì tún pada lọ máa ṣe gbogbo àwọn nǹkan ìríra tí ẹ tí ń ṣe?
Ọlọgbọndiyan fesi si ọrọ ti Alaga apapọ fun ẹgbẹ oṣelu All Progressives Congress, APC, iyen,Adams Oshiomole sọ wi pe ki Saraki fi ipo rẹ silẹ gẹgẹ bi Aarẹ ile aṣofin lẹyin to fi ẹgbẹ awọn silẹ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Ìgbà tí mo máa fi lajú sáyé padà, ọ̀fọ̀ ikú mi ní wọ́n ń kígbe' Ìjọba ìpínlẹ̀ Eko ti ti ibùdó ìtọ́jú ààrùn Covid-19 tó wà ní Eti-Osa Ijọba ipinlẹ Eko ti gbe ilẹkun ibudo iyasọtọ awọn alarun Covid-19 to wa ni Eti-Osa ti pa.
 nítorí náà gbáyégbọ ́ run ni ifá ńṣe .
Ann Grace Aguti, Obìnrin kan to fẹ́ ọkọ mẹ́ta lẹ́ẹkàn ṣoṣo A kò tíì rí ọmọ ọdún méjì tó kó sí kànga- Olootu India Fọ́tò ló ṣàfihàn ibi tí ọmọ ti Nọọsi jígbé lódún 1997 wà Ebi ló ń pami ti mo fi já sọọbu láti jí bisikitì- Afurasi Asuquo Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí 3 sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
Ẹni to bori: Congo DR Ìpele to kangun si aṣakagba South Africa vs Mali.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Kókó ọ̀rọ̀ tí El-Zakzaky sọ nínú fidio tó fi ránṣẹ́ sí àgbáyé Wọ́n ta ère Ọ̀ṣun Osogbo sí Togo - Bàbá Ọṣun figbe ta Ayọ̀ abara bíńtín!
Kókó ọ̀rọ̀ tí Buhari sọ ní àyájọ́ June 12 FRSC: Èèyàn mẹ́jọ ló kù nínú ìjàmbá ọkọ̀ nípìnlẹ̀ Ògùn ‘Mo ké bòòsí tòò bí mo ṣe bí ìbejì, ti ọ̀kan jẹ́ àfín, ìkejì jẹ́ dúdú’ Akẹ́kọ̀ọ́ LAUTECH 15 wọ gàù l‘Ọyọ torí ẹ̀ṣùn olè àti ṣíṣe ẹgbẹ́ òkùnkùn Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí kan sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
Àwọn kan ninu àwọn ọmọ ogun wà níwájú wọn, àwọn kan sì tẹ̀lé Àpótí Majẹmu OLUWA.
OLUWA tún fi wọ́n lé gbogbo àwọn ọ̀tá tí ó wà ní àyíká wọn lọ́wọ́, apá wọn kò sì ká àwọn ọ̀tá wọn mọ́.
'Ọdún méjì sẹ́yìn ni òbí àwọn ọmọbinrin Chibok gbọ́ láti ọ̀dọ́ ìjọba kẹ́yìn' Àwọn tó ń wojú ọjọ́ rí ihò dúdú tó tóbi jù láyé àtọ̀run Nàìjíríà wà ní ìsọ̀rí kejì pẹ̀lú Burundi, Madagascar àti Guinea Ẹgbẹ oṣelu All Progressives Congress (APC) lo fi ọrọ lede wi pe oludije fun ẹgbẹ oṣeluPeoples Democratic Party (PDP), Atiku Abubakar kii ṣe ọmọ bibi orilẹede Naijiria.
Èmi Ọba tí wọ́n ń kó jẹ nígboro- Oluwo ti ilú Iwo Donald Trump ti gbà pé Coronavirus yóò burú jáì kí ǹkan tó dára fún Amẹ́ríkà Ìjọba ìpínlẹ̀ Kano tí wọ́gilé ayẹyẹ lẹ́yìn ìrun ọdún Iléyá!
Lẹ́yìn nǹkan bíi ọdún mẹ́wàá tí wọ́n ti jọ ń gbé ilẹ̀ Moabu, 
Àwọn Yorùbá gbàgbọ́ pé o orúkọ á máa ro ènìyàn.
idariji ninu awon iwe iroyin , ki won si tun rii pe won bowo fun ofin nipa titẹle
Ki leyii waye si, a fi bi olori ọmọ ẹgbẹ oṣelu to pọju lọ, Sẹnetọ Ahmad Lawan ati awọn sẹnetọ mi i to jẹ ọmọ ẹgbẹ oṣelu APC, ṣe sọ pe ko si nkan to jọ bẹ, pe ko si ibi ti Akpabio joko si ti ko ti le sọrọ ninu ile aṣofin naa.
 fún ọ ̀ pọ ̀ àwọn aṣeọ ̀ rọ ̀ àwùjọ èrò iṣẹ ́ wọn ni láti ṣe ìwadìí tí yíò ṣe é múlò tààrà sí ètòìlú àwùjọ àti ìtọ ́ jú , nígbàtí àwọn míràn dá ṣẹ ́ wọn lórí ìtúnṣe ìlóye aláròjinlẹ ̀ àwọn àgbéṣe àwùjọ .
Rashidat Fawẹhinmi: Sísọ èdè Yorùbá kò leè ba Gẹ̀ẹ́sì jẹ́ lẹ́yìn odi
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Messi di aláṣẹ lórí ohun eèlò tó gbé orúkọ rẹ̀ UEFA f'ẹ̀sùn kan Bayern Munich Salah 'ti fẹẹ' da bii Messi Agbábọ́ọ̀lù náà t'ójẹ́ ọmọ bíbí orílẹ́-èdè Spain ti ṣojú Barcelona nínú ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ t'ódín díẹ̀ ní ẹ̀ẹ́dẹ́gbẹ̀rin láàrin sáà mẹ́rìndínlógún.
Àkọlé àwòrán, Minisita gba awọn ọmọ Naijiria ni imọran pe ki wọn o ma bẹru, ṣugbọn ki wọn o mu ilera wọn ni pataki.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Àbẹ̀wò Buhari: Mo fẹ́ kí òjò rọ̀ ní Eko, kó sì ba àbẹ̀wò Buhari jẹ́ 24 Ìgbé 2019 Aarẹ Muhammadu Buhari n ṣe abẹwo si ilu Eko loni lati wa si awọn akanṣe iṣẹ kan tijọba ipinlẹ Eko ṣe.
Koda, o ti n jẹ ìgbẹ́ naa.
Iriri Oluwatobi wọ omi loju gbogbo eeyan.
Eleyi fã ki ilú kan fẹ̀ ju òmíràn lọ, pàtàki ni ilú ti ó bá sún mọ́ odò nla bi ti ilù Èkó nitori iṣẹ́ ma npọ̀.
Lonii la o mọ ẹni ti yoo gbade eto agbelewo ile Ẹlẹgbọn Agba, BBNaija 2020.
Ẹ wọ ọna marun un ti wọn ṣi n gba lati dẹyẹ si awọn obinrin ni Naijiria Ẹtọ gẹgẹ bi ọmọ orilẹede Naijiria: Ẹka iwe ofin Naijiria ti ọdun 1999, ti ẹka Section 26 (2) (a) fi agbara fun obinrin ti o ba fẹ ọmọ Naijiria, amọ ko fun okunrin lati orilẹede miran to ba fẹ ọmọbinrin Naijiria ni ẹto lati jẹ ọmọ bibi orilẹede Naijiria.
Ṣugbọn mo ti ṣèlérí fun yín pé, ẹ̀yin ni ẹ ó jogún ilẹ̀ wọn, n óo fi ilẹ̀ tí ó lẹ́tù lójú, tí ó sì ń ṣàn fún wàrà ati oyin fun yín, gẹ́gẹ́ bí ohun ìní.
”Má sì jẹ́ kí n tòṣì, kí n má baà jalè,kí n sì kó ẹ̀gbin bá orúkọ Ọlọrun.
Ẹ níláti kórìíra aṣọ tí ìfẹ́ ara ti da àbààwọ́n sí.
nítorí náà, OLUWA àwọn ọmọ ogun, Ọlọrun Israẹli ní títí lae, kò ní sí ìgbà kan tí Jonadabu, ọmọ Rekabu kò ní ní ẹnìkan tí yóo máa ṣe iṣẹ́ ìsìn níwájú mi.
Àkọlé àwòrán, Nibi asekagba ipolongo ibo to waye ni Ọjọ Isẹgun ni ilu Ado Ekiti, ni Chris Ngige ti sìsọ pe kí wọn dá Fayose padà sípò lọ́jọ́ Satide .
Mo sọ ohun tí OLUWA wí fun yín, ṣugbọn ẹ kọ̀, ẹ kò gbọ́.
 Ko si eni ti o le parowa fun won bayii pe, ko si ile aanu Kankan nibikan.
A n reti Victoria lati mun iwoye rẹ naa wa si oju taye o fi kun.
 Ojúmọ́ kan, ìdàmú kan ni mo fi lo ogún ọdún àkọ́kọ́ lórí oyè - Alaafin Ọlọ́pàááá!"
Wo ohun tó ṣelẹ̀ ní àgbáyé lọ́sẹ̀ tó kọjá Ilẹ̀ Afrika lọ́sẹ̀ yìí nínú àwòrán!
Ìyàwó Ọ̀ọ̀ni Ogunwusi kò bímọ tuntun Fídíò rèé lórí bí Sunday Igboho ṣe korò ojú sí ìwà ọ̀dàlẹ̀ nílẹ̀ Yorùbá Ìfẹ́ Yorùbá ló mú mi fi ẹ̀mí wéwu láti kojú ajínigbé ní Kishi - Sunday Igboho Buhari, ayẹyẹ kí là ń ṣe gan, ṣé ti ìpànìyàn àbí ìjínigbé?
Ó dá Ọlọrun lóhùn, ó ní, “Nígbà tí mo gbúròó rẹ ninu ọgbà, ẹ̀rù bà mí, mo bá farapamọ́ nítorí pé ìhòòhò ni mo wà.
Ṣugbọn Joabu ati Abiṣai ń lé Abineri lọ, bí oòrùn ti ń lọ wọ̀, wọ́n dé ara òkè Ama tí ó wà níwájú Gia ní ọ̀nà aṣálẹ̀ Gibeoni.
Gbogbo àwọn ọmọ Juda mú ìdámẹ́wàá ọkà, ati waini ati òróró wá sí ilé ìṣúra.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Human Rights day: Aṣíwájú ajàfẹ́tọ̀ọ́ ní Àìbọ̀wọ̀ fẹ́tọ̀ọ́ ọmọnìyàn ló ń fa wàhálà ètò àbò Adamu gba awọn eniyan ni imọran lati yẹra fun awọn iroyin ati ikede ti o jinna si ootọ ti o n ko ipaya ba awọn eniyan.
Nítorí àwọn Kristi èké ati àwọn wolii èké yóo dìde, wọn yóo máa ṣe iṣẹ́ àmì ati iṣẹ́ ìyanu láti tan eniyan jẹ.
Iwadii naa jẹ ko di mimọ pe ọmọ ẹgbọn Buhari ni Daura jẹ ti Buhari si ta a lọrẹ ile ti wọn n pe ni Glass House ninu Aso Rock l'Abuja.
Bakan naa, ọpọlọpọ awọn ọmọ Naijiria ati orilẹede agbaye lo n kerora lori wahala to ṣẹlẹ ni agbegbe Lekki Tollgates.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Njẹ Chloroquine nipa kankan lati le koju Coronavirus Ninu oṣu Keje, Iya agba Miller, to jẹ ẹni ọdun mẹtadinlọgọrun, Ruth Glosser, kú nitori ilera rẹ ti Covid-19 bajẹ.
Aṣòfin Tunde Braimoh wọ káà ilẹ̀ sún ní Eko Iṣẹ́ abẹ tí mo ṣe láti fi kún ìkébé mi ṣàkóbá fún mi- Omotola Taiwo Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ìjọba ilẹ̀ Turkey yí ilé Ìṣẹ̀mbáyé tó ti lo ọdún 1,500 padà sí Mọ́ṣáláṣí Lẹyin naa lo di ile iṣẹmbaye lọdun 1934 ti ajọ UNESCO si fọwọ si pe o jẹ ọkan lara awọn ile ti awọn eeyan le maa ṣabẹwo si.
Oríṣun àwòrán, VOH Àkọlé àwòrán, Nadia pade ajọ Voice of Hope, wọn si n ran an lọwọ lati maa sọ itan aye rẹ ni awọn nileewe.
 n kíì sàlejò ní gbogbo ìgbà dá lára yá .
O ni orogun ni awọn oriṣa jẹ si Ọlọrun nitori ko ṣeṣe ki eeyan ki Ọlọrun lara oun ko tun lọ foribalẹ fun awọn oriṣa miran.
Gbogbo àwọn alufaa tí wọ́n wà káàkiri ilẹ̀ Juda ni ó mú wá sí Jerusalẹmu, ó sì ba gbogbo àwọn pẹpẹ ìrúbọ tí wọ́n ti ń rúbọ jẹ́.
Irú iṣẹ́ bẹ́ẹ̀ dára, wọ́n sì ń ṣe eniyan ní anfaani.
Mikali bá sọ Dafidi kalẹ̀ láti ojú fèrèsé kan, ó sì sá lọ láti fi ara pamọ́.
 láti le mú kí á ní àgbéjáde oríṣìíríṣìí kílíìkì .
Àwọn eniyan bá gòkè tọ Pilatu lọ, wọ́n bẹ̀rẹ̀ sí bẹ̀ ẹ́ pé kí ó ṣe bí ó ti máa ń ṣe fún wọn.
Nítorí náà ìwọ Olówó-ayé, múra kí o fún ṣòkòtò le.
Idile Oba Seriki William Abass: Gbajugbaja olowo ẹru ni Oba Seriki Williams Ifaremilekun Abass tilu Badagry laarin saa onka ọdun kọkandinlogun (19th century).
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Keyamo: Cocaine tí ò ń fà ní o da orí rẹ rú 24 Èbibi 2018 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Bi ó tilẹ̀ jé pé Ààrẹ Muhammadu Buhari kò dárúkọ Ààrẹ kankan nínú ọrọ rẹ̀ Lórí awuyewuye tó ń tàn ká lórí ẹ̀sùn tí Ààrẹ Muhammadu Buhari fí kàn ààrẹ àná, Oloye Oluṣẹgun Ọbasanjọ Esun naa kò ṣẹyin owó bilìọ̀nù dọ́là mẹrindinlogun to yẹ fún iṣẹ́ mọ̀namọ́na lórílẹ̀-èdè Nàìjíríà tí kò ní ipa lo tí dì ohun ti à ń gbà bí ẹní gba igbá ọtí láàárín àwọn èèkàn orílẹ̀-èdè yìí.
Ní ọjọ́ àsè ati ìgbà àjọ̀dún, ìwọ̀n eefa ọkà kan ni wọn óo fi rúbọ pẹlu ọ̀dọ́ mààlúù kan, ìwọ̀n eefa ọkà kan pẹlu àgbò kan, ati ìwọ̀n eefa ọkà tí eniyan bá lágbára pẹlu ọ̀dọ́ aguntan, ṣugbọn ó gbọdọ̀ fi ìwọ̀n òróró hini kọ̀ọ̀kan ti ìwọ̀n eefa ọkà kọ̀ọ̀kan.
 gbogbo àwọn nǹkan ló ń parapọ ̀ tí ó sì ń di ogun .
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Cristiano Ronaldo: Gbajugbaja agbábọ́ọ̀lù Juventus àti Portugal ti lùgbàdì àrùn Coronavirus 13 Ọ̀wàrà 2020 Oríṣun àwòrán, Getty Images Coronavirus ti nawọ gan ilumọọka agbabọọlu nii Cristiano Ronaldo.
Bi o tilẹ jẹ pe Seedorf ni inu oun yoo dun lati tẹsiwaju pẹlu iṣẹ naa lẹyin ti wọn ja bọ kuro ninu idije naa, ajọ ere bọọlu ilẹ Cameroun ni ko si ọna mọ fun wọn.
Ò ń nà wọ́n ní pàṣán, ṣugbọn kò dùn wọ́n,o tẹ̀ wọ́n ní àtẹ̀rẹ́,ṣugbọn wọn kò gbọ́ ìbáwí.
 bàyìí ni àwọn méjèèjì pèrè pọ ̀ .
Ọmọ Ilesha ni baba rẹ ti iya rẹ si wa lati Edo.
ọmọ Matati, ọmọ Lefi, ọmọ Meliki, ọmọ Janai, ọmọ Josẹfu, 
Wo àwọn ìlérí tàwọn Gómìnà tuntun ṣe nínú ìbúra wọn Àràmọ̀ǹdà àwòràn láti ilẹ̀ àdúláwọ̀ lọ́sẹ̀ yìí Dapọ Abiọdun ree, ẹni tó dépò gómìnà ní àyájọ́ ọjọ́ ìbí rẹ̀ Dapọ Abiọdun ree, ẹni tó dépò gómìnà ní àyájọ́ ọjọ́ ìbí rẹ̀ Ọgbẹni Abiọla n ṣalaye siwaju sii pe wọn gbe akẹkọọ naa lọ sileewosan miran ni igboro ilu Iree nibẹ ni o si dakẹ si.
Ẹni to bori: South Africa Senegal vs Madagascar.
Ọrọ to mu idagbere rẹ yii wa nigba naa gba gbogbo ori ayelujara kan ni ọsẹ to kọja lẹyin ti oun ati awọn ọmọbirin kan n ta ohun sira lorii pe o fipa ba wọn lo pọ.
Oríṣun àwòrán, Iyabode Omo ladukeade Awọn oṣere jankan jankan ati awọn eeyan miran bii, Alhaji Alabi Pasuma, MC Oluomo atawọn gbajumọ lawujọ lo peju si ibi ayẹyẹ iṣile naa lati ba ṣọjọyọ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Àwọn dọkítà ní bó tilẹ̀ jẹ́ pe àṣìlò òògùn kìí ṣe ẹ̀bi awọn ará ìlú, ó mú ewu púpọ̀ dání Àwọn iroyin miiran ti é le nifẹ si: Èyí ni bí o ṣele dá ayédèrú ìròyìn mọ̀ Àgbárá òjò bà'lú jẹ́ n'Ípínlẹ̀ Ogun 'A fẹ́ dojú kọ ìṣòro Nàìjíríà' Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Ọ̀gá ni mí nínú àwọn ẹlẹ́rìín lágbàáyé' Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Wo ohun tó mú kí Ṣèyí Makinde ó tẹ̀síwájú pẹ̀lú ìpàdé ìtagbangba níbàdàn láàrín ìṣẹ̀lẹ̀ àrùn Coronavirus Ṣé Makinde kò wá rugi oyin báyìí lórí ìpàdé ìtagbangba PDP tó ṣe níbàdàn Láì náání àjàkálẹ̀ àrùn coronavirus?
Nítorí wí pé owó mi kò tó, àwọn ọmọdé kò fi mi lọ́kàn balẹ̀, ojoojúmọ́ ni mo si tún níláti máa kọ̀wèé, tí orí mi ń gbóná janjan.
Ghana elections 2020: NDC ní òun yóò kéde ìgbésẹ̀ tó kàn láìpẹ́
4 6227 Erekusu Reunion Island 42 4.
Lẹnu ọjọ mẹta yi ni ọrọ n ja rainrain boya yoo buwọ lu iwe fẹgbẹ naa tabi yoo lọ amọ bayi, o jọ pe Zlatan tun ti n wa ẹgbẹ mi ti yoo ti darra lori papa.
Wọ́n ti sún ìdájọ́ àwọn sójà tó pa ìyá àti ọmọ ní ọdun 2018 sí oṣù tó m bọ̀ Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí NUJ ìpínlẹ Oyo bà àwọn ọmọ ẹgbẹ́ tó lọ ìpàdé tí Femi Fani Kayode pè ní Ibadan wí7 Owewe 2020 6:18 Fídíò, Akomolede: Bolaji Faleke ni Olùkọ́ tó ń kọ́ wa ní àṣà oge ṣiṣe lórí BBC Yorùbá, Duration 6,181 Owewe 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Sindodotayo Inu ẹni kii dun ki a pa mọ ra.
Akọwe iroyin fun Ọgbẹni Ajayi to ba BBC Yoruba sọrọ, Tope Okeowo lo fidi ọrọ naa mulẹ.
Eyi ni agbekalẹ awọn ipinlẹ ti ayẹwo fihan lọjọ Ẹti ọjọ kẹtadinlogun, oṣu keje pe o laarun naa: Ènìyàn 156 ló tún ṣẹ̀ṣẹ̀ lùgbàdì ààrùn Coronavirus ní ìpínlẹ̀ Eko Oríṣun àwòrán, Others Àpapọ̀ àwọn tuntun to ṣẹṣẹ lugbadi ààrùn Coronavirus ní Nàìjíríà jẹ 595 ní 1/07/2020 Ninu ikede ti Ajọ NCDC fi sita fihan pe , awọn to ti ni aarun naa ti pe 34,854 bayii.
Amọṣa ijọba apapọ Naijiria pẹlu ti fesi pe, awọn ko mọ ohunkohun nipa ẹsun yii, ati pe n ṣe ni El-Zakzaky fẹ maa ṣe bi ọba lorilẹede India.
Control Bill, Good Samaritans Bill, Chattered Institute of Directors of Nigeria
Àjọṣe ti ó wà láàárìn wọ́n pọ̀ gan-an tí ó fi jẹ́ wí pé ní gbogbo ìlẹ̀ Ijẹ̀ṣà, Ọba Ijẹ̀bú -Jẹ̀ṣà àti Ọwá Iléṣà jọ ní àwọn nnkán kan lápapọ̀ bẹ́ẹ̀ náà si ni àwọn ènìyàn wọn.
Àwọn iròyin ẹlẹ́jẹ̀ márùn ún tó fẹ́ẹ̀ tú Nàìjíríà ká Kìnìhún nìkan kọ́ ló burú, àwọn ajá mẹ́wàá yìí náà kò fararọ!
Ajọ to ṣe akoso oogun lilo ni UK, MHRA sọ pe abẹrẹ naa lagbara lati pa arun coronavirus, o si yẹ ní nilo.
wọn si dahun pe ọmọ ẹgbẹ fijilante Miyetti Allah lawọn atipe gbogbo awọn oṣiṣẹ alaabo agbegbe ọhun lo mọ awọn ti wọn si fi kaadi idanimọ wọn han.
O ni oun yoo ṣi maa yẹra fun awọn eeyan titi di igba ti esi ayẹwo lati mọ boya oun ni, eyi ti yoo waye lọjọ Aiku, ba ti waye.
Gbogbo ẹranko tí pátákò ẹsẹ̀ wọn bá là, ṣugbọn tí ẹsẹ̀ wọn kò là, tí wọn kì í sì í jẹ àpọ̀jẹ, aláìmọ́ ni wọ́n; ẹnikẹ́ni tí ó bá fi ọwọ́ kàn wọ́n di aláìmọ́.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Dagrin: Ikú Dagrin pé ọdún mẹ́wàá, wo àwọn nkan mánigbàgbé nípa rẹ̀ 22 Ìgbé 2020 Oríṣun àwòrán, Dagrin Fimilejo/Facebook Oni yii gan-an lo pe ọdun mẹwa ti Oladapo Olaitan Olaonipekun, ti gbogbo awọn eniyan mọ si Dagrin, di oloogbe.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: A kò ní fara mọ́ fífi àkókò ṣòfò lórí ẹjọ́ Sotitobire - Ìjọba Ondo Tinubu, ojú tì ẹ́, o ta Yorùbá fún ọ̀tá torí àdánìkànjẹ - Fani-Kayode Omijé bọ́ níbi ìsìnkú Ogun Majek Ìbánújẹ́ gbọkàn àwọn èèyàn nílé abílékọ ọlọ́mọ mẹ́ta tí wọ́n ṣẹ̀ṣẹ̀ pa ní Ibadan Asiko Ajaalẹ ni Soka: Oríṣun àwòrán, Others Igba keji ti ẹnu tun kun oloogbe Abiola Ajimobi lasiko to wa lori oye gomina ni igba ti isẹlẹ ajaalẹ waye ladugbo Soka nilu Ibadan.
Lẹ́hìn èyìínì mo dáhùn mo wí pé:
"áyé òde òní , àwọn ọ ̀ dọ ́ tilẹ ̀ máa ń dáṣà báyìí pé "" dẹ ̀ ẹ ́ dẹ ̀ ẹ ́ rẹ , ìgbéraga ni ìgbérasán lẹ ̀ "" ."
" Mo ti mọ awọn mọlẹbi Issa to le ni ọgọrun un, inu mi si dun pe gbogbo wọn lo faramọ pe ki a fẹ ara wa.
Alaga ẹgbẹ naa Mohammed Abdullahi Rahi sọ fun awọn akọrọyin ni Kano pe wuruwuru ati iwa janduku lo mu abuku ba eto idibo naa ti ajọ Inec dari.
”Ni ipari, Castro tun kopa fun orile-ede re, Spain ninu idije boolu agbaye lodun 1978 ati 1982, bakan naa lo tun kopa ninu idije European Championship lodun 1980.
 Ijoba ipinle Enugu n sito sise ajile alatowoda ki won le maa pin in lopo lofe fawon agbe”.
Ati ọ̀rọ̀ sísọ, ati iṣẹ́ ṣíṣe kò sí èyí tí kò mọ̀ ọ́n ṣe.
Eyi ni igba kejila ti Man City yoo kopa ninu Community Shield, wọn si ti gba ife naa lẹẹmarun un .
Bí ohun tí ẹ gbọ́ láti ìbẹ̀rẹ̀ bá ń gbé inú yín, ẹ̀yin yóo máa gbé inú Ọmọ ati Baba.
Ọmọ yìí jẹ́ ẹni tí ògo Ọlọrun hàn lára rẹ̀, ó sì jẹ́ àwòrán bí Ọlọrun ti rí gan-an.
”Osinbajo menuba awon ti won wa ninu iko naa lati ile ise ijoab, awon asoju aladani atawon miran pelu ise pe ki won maa samojuto awon abadofin irorun paapaa ni eka eto ogbin, eka irinna ati ipese ohun eelo pelu afefe gaasi atina monamona ni eyi ti won yoo ko jade losu keta pelu erongba imuse titi odun 2020.
Ọwọ́ rẹ yóo tẹ gbogbo àwọn ọ̀tá rẹ;ọwọ́ ọ̀tún rẹ yóo tẹ gbogbo àwọn tí ó kórìíra rẹ.
Àwọn àjèjì darandaran ń wọ ìpínlẹ̀ Oyo àti Ogun lọ́gọ́ọ̀rọ̀ - Amotekun Ikọ alaabo nilẹ Yoruba, Amọtẹkun ti ke gbajare lori awọn darandaran ti wọn n wọle si ipinlẹ Ọyọ ati Ogun ni ọgọọrọ.
Ofin tuntun yii tun fi ofin de ile ise ijoba apapo to n risi oro abele lati fun awon eniyan ile okeere nise tabi iwe irinna lati wa sise ti awon eniyan orile ede Naijiria le se.
Nítorí gbogbo wọn ni wọ́n rí i tí ẹ̀rù sì bà wọ́n.
Dúró Orímóògùnjẹ́ nìkan ni ọmọ tí Àdùnní bé.
Iroyin sọ pe Mourinho n wa iṣẹ si ilẹ Gẹeṣi nitori nibẹ lo ti ṣaṣeyọri nibi to gba ife ẹyẹ idije Premier League nigba mẹta ọtọtọtọ.
Ọjọ́ ibinu ni ọjọ́ náà yóo jẹ́, ọjọ́ ìpọ́njú ati ìrora, ọjọ́ ìyọnu ati ìparun, ọjọ́ òkùnkùn ati ìbànújẹ́, ọjọ́ ìkùukùu ati òkùnkùn biribiri.
Ẹ̀ṣọ́ Amotekun ní láti ṣiṣẹ́ pọ̀ pẹ̀lú ọlọ́pàá agbègbè- Ọ̀gá ọlọ́pàá Naijiria Ó ṣeéṣe kó má sí ẹ̀ṣọ́ aláàbò Amotekun l‘Eko - Ìjọba Eko BBC Yorùbá pé ọdún méjì!
tun maa gba ami eye naa ni Modion Communication, Propertymart, Vitafoam Nigeria
Àwọn ìjòyè tí wọ́n ṣẹ̀ lára Hori nìwọ̀nyí: Lotani, Ṣobali, Sibeoni, 
Pásítọ̀ Sam Adeyemi, Taaooma, Falz àti gbogbo àwọn tí ilé ẹjọ́ fẹ́ rí nìyìí Ṣe lóòtọ́ ni ejò ń pọ owó fún Ginimbi, ọ̀dọ́mọdé olówó kó tó jáde láyé?
'Esi Jamb ko nii jade kiakia' Oga mi lo gba 36m Jamb JAMB 2019: Kí ló yẹ kóo mọ̀?
Awọn obi rẹ pada di ẹlẹsin Kristiẹni, ti wọn si n lọ sinu ijọ kan ni agbegbe Oshodi nipinlẹ Eko.
Mo lérò wípé ẹ gbádùn Àlọ́ yìí.
Wọn sọọ nibi ayajọ isami ọjọ awọn ti a fiya jẹ lọna aitọ lagbaye.
Ní orílẹ̀-èdè Nàìjíríà, NCDC fìdí rẹ̀ múlẹ̀ pé ènìyàn kan kú ni ọjọ́ sátide èyí sì ló jẹ́ kí o pé ènìyàn mẹ́tàdínlẹ́gbẹ̀run kan tó ti bá ààrùn Covid -19 rin ni Nàìjíríà.
Jehu fi gbogbo agbára ta ọfà rẹ̀, ó bá Joramu lẹ́yìn, ó wọ inú ọkàn rẹ̀ lọ, Joramu sì kú sinu kẹ̀kẹ́ ogun rẹ̀.
kí ó ṣe oore kan fún wọn, kí ó fi Paulu ranṣẹ sí Jerusalẹmu.
Ni wọn ba ran Sergio Aguero niṣẹ, loun naa ba tun fi ọkan lee fun totenham lo ba di meji fun Manchester city, ẹyọkan fun Tottenham.
”Aare wa gbosuba fun oloogbe to je omo egbe APC naa fun “iwa akin si egbe APC  ati orile ede Naijiria sugbon oloogbe naa pakoda lasiko ti egbe APC ati orile ede Naijiria nilo ogbon ati imo re fun idagbasoke orile ede Naijiria.
Ẹ̀mí OLUWA sì bẹ̀rẹ̀ sí lò ó ní Mahanedani, tí ó wà láàrin Sora ati Eṣitaolu.
O ro ilẹ̀ fún un;ó ta gbòǹgbò wọlẹ̀, igi rẹ̀ sì gbilẹ̀.
Àwọn orílẹ̀-èdè tí wọ́n súnmọ́ ọ ati àwọn tí wọ́n jìnnà sí ọ yóo máa fi ọ́ ṣe yẹ̀yẹ́, ìwọ tí o kò níyì, tí o kún fún ìdàrúdàpọ̀.
Oun ni wọn yan dipo Ọjọgbọn Usman Yusuf ti aarẹ Mohammadu Buhari yọ kuro nipo naa nitori iwa ajẹbanu.
Minisita Naijiria feto ọrọ abẹle Rauf Aregbesola lo fi ikede ọrọ yi sita lorukọ ijọba.
Iṣẹ́ ju iṣẹ́ lọ: Wọ́n ra Ronaldo ọmọ ọdún 33 ni £99m
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Coronavirus: Seyi Makinde ní ẹgbẹ̀rún mẹ́wàá ọṣẹ apakòkòrò 'hand sanitiser' lòun fi dènà coronavirus nípàdé ẹgbẹ PDP ní'bàdàn 19 Ẹrẹ̀nà 2020 Oríṣun àwòrán, Twitter/seyi makinde Lati ọjọbọ ni ori ayelujara ti n ho ruru, ti ọpọ eniyan si n sọ oko ọrọ̀ si gomina ipinlẹ Ọyọ, Seyi Makinde, ati ẹgbẹ oṣelu PDP, lori ipade itangbangba ẹgbẹ naa to waye.
Baalu ileesẹ Aseman, eleyi to n lọ si igboro Yasuj to wa ni guusu iwọ-orun ilẹ naa lati Tehran, jabọ laarin awọn oke Zagros ti wọn wa laarin-gbun-gbun Iran.
Koo to le darapọ mọ iṣẹ ọlọpaa Naijiria, o gbudọ la ẹkọ igbaradi to gboro kọja.
Orin ti Lizzy Anjorin fi bọnu niyii loju opo Instagram rẹ."
ohun soro naa di mimo ninu iwe abadofin keyin ti o jade ninu ipade apero kẹ́rìnlélógójì, eleyi ti o waye lojo Aiku, niluu Abuja.
O ni awọn yoo ṣe agbeyẹwo abẹwo ti ẹgbẹ oṣelu APC ṣe si Jonathan ati igbesẹ ti awọn yoo gbe lori rẹ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù BBC Africa Eye: ìwádìí ìkọ̀kọ̀ BBC fihàn pé àwọn kan ń jí ohun eèlò ìdáàbòbò ìjọba tà nígboro Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ BBC Africa Eye: ìwádìí ìkọ̀kọ̀ BBC fihàn pé àwọn kan ń jí ohun eèlò ìdáàbòbò ìjọba tà nígboro 10 Ògún 2020 Se o yẹ ki a maa tun fiya jẹ ara wa nilẹ Adulawọ lori ọrọ Coronavirus?
Kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ jẹ́ ẹgbaa mẹẹdogun ó lé ẹẹdẹgbẹta (30,500), ìpín ti OLUWA ninu rẹ̀ jẹ́ mọkanlelọgọta.
Ẹsun ti Oluwo fi kan awọn ọba naa ni pe, wọn n ta ilẹ ilu wọn lọna ti ko ba ofin mu, sugbọn awọn ọba naa sọ pe ọrọ ko ri bẹẹ.
Awọn akọroyin lagbegbe naa sọ wi pe wọn sọ fun awọn mọlẹbi rẹ to n duro nita wi pe ọmọ ti ku ṣugbọn ẹjẹ n da lara iya.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Oyo traders crisis: Ẹgbẹ́ oníṣòwò ṣèwọ́de lórí ìyànsípò YK Abass gẹ́gẹ́ bí bàbálọ́jà tuntun 1 Owewe 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 9 Owewe 2020 Oríṣun àwòrán, others Awọn oniṣowo labẹ asia ẹgbẹ Coalition of Market Groups of Oyo State ṣe iwọde lati tako bi Olubadan ti ilẹ Ibadan, Oba Saliu Adetunji ti yan Ọgbẹni Yekini Abass gẹgẹ bi Babalọja gbogbogbo ipinlẹ Oyo.
kí á máa já ẹ̀tọ́ olódodo gbà lọ́wọ́ rẹ̀ níwájú Ọ̀gá Ògo,
"leptospirosis ( tí a tún mọ ̀ sí ibà orí pápá , àwọ ̀ ìyeyè méku-méku , àti ibà inú egungun ńlá tó lọ láti orúnkún sí kókósẹ ̀ láàárín àwọn ọ ̀ pọ ̀ lọpọ ̀ orúkọ mìíràn ) jẹ ́ àkóràn àrùn tí àwọn kòkòrò kékèké àìlèfojúrí corkscrew-shaped tí à ń pè ní "" leptospira "" ń ṣe òkùnfà rẹ ̀ ."
Ko pẹ to kuro ni agọ ọlọpaa ni Seyitan fi ikede kan sita pe lootọ ni ọlọpaa mẹrin gbe oun lọ si agọ wọn ni Shodipo, Ikeja.
Ikọ iroyin BBC ti Fada Obiekezie lewaju rẹ, wa morile ile Mbaka lẹyin ti isin naa pari ni deede aago marun irọlẹ lati seto ifọrọwanilẹnuwo ọhun.
Igún t’orí ẹbọ, ó f’oríta ṣe ‘lé.
"A ni igbagbọ pe ijọba yoo gbe abajade iwadii jade fun ara ilu ni kete to ba pari.
O sọ eyi latari awọn igbesẹ tuntun eyi ti gomina tuntun Seyi Makinde n gbe ninu iṣejọba rẹ ni idahun si bi gomina ana Ajimoba ṣe se nigba tirẹ naa.
Ni ó bá lọ ń gbé ọ̀dọ̀ ọ̀kan ninu àwọn ọmọ-ìbílẹ̀ ibẹ̀.
Mo ti jèrè àpò marun-un lórí rẹ̀.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Mourinho fẹ́ kojú Wenger nínú ìdíje miràn yàtọ̀ sí EPL 30 Ìgbé 2018 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Mourinho kan sáárá sí Wenger fún isẹ́ tó ṣe nínú eré bọ́ọ̀lù ilẹ̀ Gẹ̀ẹ́sì Akọ́nimọ̀ọ́gbá ikọ̀ Manchester United Jose Mourinho ǹ gbèrò láti bá alátakò rẹ̀ Arsene Wenger pàdé lọ́jọ́ iwájú.
Ta ló dàbí rẹ, ológo mímọ̀ jùlọ?
ninu Ile sọ pe, ko ba ofin mu ki ijọba bẹrẹ si ni na owo isuna-owo laisi pe
Emi o tilẹ ni wo fọnran orin naa rara."
Òun óo fi ẹ̀yà kan sílẹ̀ fún ọmọ rẹ̀, kí ọ̀kan ninu arọmọdọmọ Dafidi, iranṣẹ òun, lè máa jọba nígbà gbogbo ní Jerusalẹmu, ìlú tí òun ti yàn fún ìjọ́sìn ní orúkọ òun.
Kì í ṣe nítorí òdodo wa ni a ṣe ń gbadura sí ọ, ṣugbọn nítorí pé aláàánú ni ọ́.
láti fi wúrà ati fadaka ati idẹ ṣe oríṣìíríṣìí iṣẹ́ ọnà; 
Ogun ẹya si ẹya to n waye lawọn apa kan orilẹede naa ko lee ṣai jẹ ọkan gboogi ninu ọrọ abo to ja igbalejo idije AFCON gba mọ Cameroun lọwọ.
fún BBC Yorùbá fún ayẹyẹ ọdún méjí - Mike Ifabunmi láti Brazil Ìdí tí LASEMA fi dáwọ́ wíwá ọkùnrin tó bẹ́ s'ódò 3rd Mainland Bridge dúró Ọjọ́ orí wo ló yẹ kí ikùn ẹ̀dá bẹ̀rẹ̀ sí tóbi?
Ipade naa waye ni gbagede isepade ile-ise iyawo aare ohun ni agogo meje abo asale.
o wa fi da won loju pe ile-ise agbofinro ko ni kaarẹ lati tepele mo ojuse won,
Àwọn ọbá aláye ilẹ̀ Yorùbá márùn-ún pẹ̀lú ọ̀pá àṣẹ wọn Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Egbò tó ti fẹ́ẹ̀ jiná ni ìtàn bí wọ́n ṣe pa Soun Ogbomoso, Ọba Olayode tẹ ń bèrè' Wákàtí méjì àbọ̀ ní àwọn akẹ́kọ̀ọ́ tó wọlé iléèwè padà yóò fi kẹ́kọ̀ọ́ lójúmọ́ - Ìjọba Oyo Nipinlẹ Oyo, wakati meji aabọ ni akẹkọọ yoo fi wa nileewe lojumọ Bi ojumọ se n mọ, ni ofin ati ara tuntun n jade lẹka eto ẹkọ nilẹ wa, eyi to lee mu agbega abi akude ba ilana eto ẹkọ ilẹ wa.
Lẹ́yìn ọjọ́ mẹta, wọ́n rí i ninu Tẹmpili, ó jókòó láàrin àwọn olùkọ́ni, ó ń gbọ́ ọ̀rọ̀ wọn, òun náà sì ń bi wọ́n ní ìbéèrè.
Oríṣun àwòrán, LASEMA Ninu ifọrọwerọ rẹ pẹlu BBC Yoruba lori isẹlẹ yii, Bode George ṣalaye pe wọn ko gbọdọ gba ọrọ naa sori akitan lai jẹ pe wọn wadii gbogbo bi iṣẹlẹ naa ṣe jẹ, ki wọn si fi awọn to ba ṣẹ jofin.
Mohammed Samuel ni ọsẹ ibanujẹ ni ọsẹ naa jẹ fun Ajọ naa.
SERAP rọ ààrẹ Buhari láti mú àdínkù bá owó ààbò fún àwọn Gómìnà ìpińlẹ̀ (Security Vote) kí àtúnse ilé ìgbìmọ̀ aṣòfin Nàìjíríà sì lọ dúró jẹ́ náà, tó fi mọ́ owó ńla tí àwọn ọmọ ilé ìgbìmọ̀ asòfin ń gbà.
ni ajọ yii lati le sakoso eto ibo.
EFCC- Diezani: Ilé ẹjọ́ ti gbéjilé ẹ̀ṣọ́ ara Diezani tó tó $40m pátápátá
Bashir ni ijọba ko gbe ẹjọ kankan to jọ eyi lọ sile ẹjọ.
Violence against women: Ilé aṣòfin Kano buwọ́ lu òfin gígé ǹkan ọkùnrin afipabánilòpọ̀
Mo tún gbọ́ ohùn kan bí ohùn ọ̀pọ̀ eniyan, ati bí ìró ọpọlọpọ omi, ati bí sísán ààrá líle, ohùn náà sọ pé, “Haleluya!
Jude Chukwuka: Wọ́n yóò fi ojú ọlọgbọ́n wo akúrí tó bá sọ ojúlówó èdè Yorùbá
nítorí pé ohun tí wọ́n ti mú wá ti tó, ó tilẹ̀ ti pọ̀jù fún ohun tí wọ́n nílò láti fi ṣe iṣẹ́ náà.
Ibẹ̀ ni a óo ti gbà yín là, níbẹ̀ ni OLUWA yóo ti rà yín pada kúrò lọ́wọ́ àwọn ọ̀tá yín.
gomina to fe dije labe asia egbe APC  ni
Lọdun 2017 ni iroyin kan jade pe aisan to n ṣe Pa Kasumu tun n le sii lẹyin to pada si Naijiria lati orilẹede India nibi to ti lọ gba itọju.
Labẹ ofin Naijiria, Ajafẹtọ ọmọde, Oluwatoyin Ojo sọ wi pe o ṣeeṣẹ ki obi ri ẹwọn ọdun meji si meje he ti wọn ba fi ija jẹ ọmọ wọn.
Gbogbo awọn iroyin ti a ri kojọ lori eyi wa latawọn iwadii gbankọ gbi tawọn ibudo amojuto ajakalẹ arun lorilẹede China ṣe, Chinese Centers of Disease Control.
Ile Igbimọ Asofin Agba ti kesi ajọ INEC lati pada gbe aba iṣuna oni billiọnu mẹtalelogoje (N143bn ) to wọn nilo fun eto idibo gbogboogbo ni ọdun 2019 wa siwaju oun.
Gbogbo awn aisan bii jẹjẹrẹ, aisan ọkan, ara asanju, atọgbẹ, ironu ati iwa gbigba ẹmi ara ẹni, to maa n tete ran awọn eeyan sọrun ni awọn orilẹede to ti goke agba lagbaye, lo ni nkan se pẹlu oorun sisun.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù WAEC: ANCOPSS ní òun àti ẹgbẹ́ olùkọ́ yóò ṣèpàdé lọ́jọ́ Ẹti lórí ìpínu ìjọba àpapọ̀ 2 Òkùdu 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 10 Agẹmo 2020 Oríṣun àwòrán, dnt Ẹgbẹ agbarijọpọ awọn ọga ileẹkọ girama jakejado Naijiria (ANCOPSS) kede pe, iyalẹnu nla ni ikede ijọba apapọ jẹ pe awọn akẹkọọ ko ni se idanwo asejade WAEC mọ lọdun 2020.
Gẹgẹ bi ajọ WHO ṣe sọ, ti tete ṣe ayẹwo ati itọju fun aisan ibà maa k'apa rẹ, o si tun maa n dena iku ati itankalẹ aisan iba.
"Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Gomina Sanwo-Olu sún ọjọ́ ""ṣiṣẹ́ láti ilé"" síwájú fún àwọn òṣìṣẹ́ ìjọba Opral Benson, ẹni ti oge ṣíṣe sọ di gbajúmọ̀ àti Yeye Oge ìlú Eko Ìyàwó mi fi mí sílẹ̀ kó lọ sílé ọkùnrin míì nínú báráàkì kan náà, àmọ́ mò sí tún fẹ́ràn rẹ̀- Sọ́jà Wo àwọn ìṣesí ojoojúmọ́ mẹ́wàá tó le ṣàkóbá fún ọpọlọ rẹ Dokita Ibrahim Musa ti ile iwosan ẹkọṣẹ ogun ni ilu kano to jẹ akọṣẹ-mọṣẹ nipa ṣisẹ iwadii lori ẹjẹ ati aarun inu ẹjẹ sọ pe, igbeyawo laarin ibatan ni ewu kiko arun lati ara awọn obi ninu."
Nígbà tí Peteru dé ìsàlẹ̀, ó wí fún àwọn ọkunrin náà pé, “Èmi tí ẹ̀ ń wá nìyí, kí ni ẹ̀ ń fẹ́ o?
Nigba to ba BBC News Yoruba sọrọ lori atẹjade kan ti wọn fi sita ninu eyi ti wọn ti yannana rẹ pe ẹya arun COVID-19 kan wa to ti n ja ranyinranyin nilẹ lorilẹede Naijiria fun oṣu diẹ sẹyin bayii eleyii to yatọ si akanṣe kokoro arun naa to kọkọ gbilẹ.
OLUWA bá Jeremaya sọ̀rọ̀ ní Tapanhesi: 
"Ni agbara Ọlọrun, oo ni faisan logba""."
Eyi tumọ si pe ko ni ni itan iru iṣẹlẹ bẹẹ nitori ko ti ko si àwọn ìfẹ́ ri.
Ajọ RBF ni Russia ni o n rẹ Dadashev sii nigba ti awọn oniṣegun oyinbo ni nkan ti ṣe ọpọlọ rẹ.
Igi ìyè wà láàrin ọgbà náà, ati igi ìmọ̀ ibi ati ire.
Joabu wí fún un pé, “Bí o bá rí i pé àwọn ará Siria fẹ́ ṣẹgun mi, wá ràn mí lọ́wọ́.
naa ẹ o si maa roju wa .
Bí wọ́n ko bá wa dibo fun ọmọ wọ́n, ẹnikẹni ti ọ̀pọ̀ wọ́n bá gbà láti dibò fún ni yóò jáwé olúbori fún ìdìbò náà.
"Ọpọ orilẹede lo fẹ kuro ninu oniruuru ilana to gbe kalẹ lati mu adinku ba ọwọja itankalẹ arun naa, ọga agba fun ajọ WHO salaye ""sugbọn aba ti wa ni pe, ifojusọna ati igbaradi irufẹ awọn orilẹ ede bẹẹ gbọdọ gbepọn pupọ."
Agogo mẹrin, ọjọ kejilelogun, oṣu kẹwaa naa ni wọn yoo sin ni ile rẹ.
Anice Badri ọmọ orilẹede Tunisia ree to ya itan de agbari Oríṣun àwòrán, AFP Àkọlé àwòrán, Ara meeriri ree o.
Agbegbe ati ilu kọọkan ni yoo maa paṣẹ tabi sọ iru igbo ti awọn eniyan yoo maa ta tabi ra ni agbegbe kọọkan.
Ohun to ṣẹlẹ gan ni pe mo wa ninu sunkẹrẹfakẹrẹ ọkọ loju popo pẹlu ọrẹ mi, ere lasan ni mo kan n fi ṣe tori mo maa n ṣere gan.
Adamu ni ile-ise to n mojuto oro owo ti n
O tepelemọ bi o ti ṣe ṣe pataki lati yanju aawọ yi ti wọn ba fẹ ki ẹgbẹ naa mu itẹsiwaju ba ara ilu.
Kọ́ńdọ̀mù tó bẹ́ gbé iléèṣẹ́ ìjọba àti aládáni kan dé ilé ẹjọ́ Àwọn ọ̀nà tí obìnrin fi le gbádùn ìbálòpọ̀ Ẹ̀mí aláìsàn là ń gbà là, ẹ yé fojú aṣẹ́wó wò wá - Nọ́ọ̀sì yarí Ṣaaju ni eyi ti kọkọ ṣẹlẹ ni Ondo: Dẹ́rẹ́bà kẹ̀kẹ́ Maruwa rí ẹ̀wọ̀n gbére he lẹ̀yìn tó fi ipá bá ọmọ ọdún mẹ́rìnlá lòpọ̀ Ile ẹjọ giga to wa nilu Akure ti sọ awakọ Kẹkẹ Maruwa kan ṣewọn gbere lẹyin to jẹbi ẹsun fifi ipa ba ọmọ ọdun mẹrinla lopọ, to si tun fun ni arun jẹdọjẹdọ.
Wòlíì Kasali ní Dolapo Awosika kò lé ìyàwó òun jáde Aláàfin Ọyọ pé ọdún 48 lórí àpèrè Ṣugbọn lorilẹ-ede Egypt nikan kọ ni iru nnkan bayii ti n ṣẹlẹ.
O tun wa gbadura alaafia fun awon
Oríṣun àwòrán, others Àkọlé àwòrán, MMM padà dé pẹ̀lú ìlànà tuntun Nigba ti yoo si fi di owurọ ọjọ kẹtalelogun, eniyan bi ọrinlerugba din mẹfa lo ti darapọ mọ ẹgbẹ naa lori Whatsapp.
Wayii o, won yii ni awon ifesewonse idije ile geesi ti yoo waye lopin ose yii lekunrere:.
Obìnrin yìí sì mu ìgò otí kan tán ó sì mu ìkejì dé ìdajì.
Bakan naa lo fi kun pe, ilu ni wọn maa n fi n ji Kabiyesi lori ibusun lowurọ, ati pe oniruuru iṣẹ ni wọn ṣe laafin.
Ṣùgbọ́n gbogbo àwọn ọmọ ọdẹ kò gbà.
 ̣ nípa àkíyèsí wọ ̀ nyìí , a rí i pé ewì ayaba wà fún ọba , ayaba àti ẹbí ọba lápapọ ̀ .
Ọwọ́ òfin ti tẹ ọ̀pọ̀ ọmọ Nàìjíríà lórí ẹ̀sùn jìbìtì l'Amẹrika- FBI Leon van Biljon dí èrò ọrun nípasẹ̀ Kìnìún rẹ̀ Ikú dóró!
N óo máa gbé ààrin àwọn ọmọ Israẹli, n kò sì ní kọ eniyan mi sílẹ̀ laelae.
Bisi Alimi: Èmi tí mò ń tọrọ ilé gbé ní London, wá di onílé méjì
" Eyi ni ọrọ ti Gomina ipinlẹ Ọṣun, Gboyega Oyetọla sọ fawọn ọmọ ẹgbẹ oṣelu APC to wa kii ni ile ijọba ipinlẹ naa to wa ni ilu Oṣogbo, lori ti idajọ ti ile ẹjọ gbe kalẹ lori esi idibo ipinlẹ naa to waye loṣu Kẹsan ọdun 2018.
Ati ẹni gba iṣẹ ati ẹni to padanu iṣẹ, Ekiti lawọn mejeeji yoo pa owo pada wa.
Àwo ati abọ́ náà kún fún ìyẹ̀fun kíkúnná tí a fi òróró pò fún ẹbọ ohun jíjẹ.
Mo ní ọmọbinrin kan tí ó jẹ́ wundia, ọkunrin náà sì ní obinrin kan, ẹ jẹ́ kí n mú wọn jáde sí yín nisinsinyii, kí ẹ sì ṣe wọ́n bí ẹ bá ti fẹ́, kí ẹ tẹ́ ìfẹ́ yín lọ́rùn lára wọn, ṣugbọn ẹ má ṣe hu irú ìwà burúkú yìí sí ọkunrin náà.
Kiki to sọrọ loju opo Instagram rẹ, lo rọ awọn eeyan lati dibo fun Seyi nibayii to kudiẹ ki eto naa pari.
Nígbà tó di ọjọ́ Kẹrìnlá oṣù Kejì ọdún 1968, ọba Olagbegi gbìdánwò láti padà sí ààfin rẹ, tó sì gbéra láti ìlú Ibadan pẹ̀lú àwọn olólùfẹ́ rẹ kan àmọ́ àwọn ọ̀tá rẹ nínú ìlú náà tún dìde ogún sii, ìjà igboro míì tún bẹ silẹ, ni àwọn ọlọ́pàá ba sin-in padà silu Ibadan.
Adajọ Abubakar Malami to jẹ minista eto idajọ tẹlẹ ko ti i sọrọ lori igbesẹ ti yoo gbe lasiko yii.
Ọpọlọpọ eniyan lo ti pe fun iwadii finfini lori iṣẹlẹ naa, lẹyin to da awuyewuye silẹ lori ẹrọ ayelujara.
Ọ̀pá epo NNPC bú gbàmú ní Benin, òṣìṣẹ́ méje kàgbákò ikú òjijì Ọ̀fọ̀ ńlá ṣẹ̀ ní Ivory Coast, Olóòtú ìjọba, Amadou Gon Coulibaly jáde láye Tó o bá fẹ́ wọ bàálù lásìkò yìí, wo òfin tuntun tó tẹ̀lé Àlàyé rèé lórí ìdí tí Magu àti awọn alága EFCC míràn ṣe bá ìtìjú kúrò nípò Oríṣun àwòrán, Getty Images/others Ọdun 2002 ni ijọba da ajọ to n gbogun ti iwa ibajẹ l'orilẹ-ede Naijiria, EFCC, silẹ.
Ṣugbọn olorin naa ti yi orukọ ileeṣẹ ọhun kuro Yeezy si Ye.
 Àwọn ènìyàn zulu gbàgbọ ́ nínú òrìṣà tó ń jẹ ́ nkulunkulu gẹ ̀ gẹ ́ bí asẹ ̀ dá wọn òrishà yìí ko ní àjọsepọ ̀ pẹ ̀ lú ènìyàn bẹ ́ ẹ ̀ ni kò ní ìfẹ ́ sí ìgbé ayé kọ ̀ ọ ̀ kan .
O ni lẹyin ọjọ mọkanla ni akata EFCC, ni awọn oluwadii ajọ naa sọ pe oun gbọdọ san ogoji miliọnu Dọla ti wọn fi kún un.
Ó ní ìgbéyàwó láàárín akọ àti akọ tàbí abo àti abo si lòdì sí òfin lórílẹ̀-èdè Ghana.
Lawal Musa Daura: Ọga agba nigba kan fun ajọ alaabo DSS.
Ayọ̀ ń bẹ fún ẹni tí o bá báwí, OLUWA,tí o sì kọ́ ní òfin rẹ,
Wọn si ni pe fun ileeṣẹ owo kan ṣoṣo, ko ni ju oṣiṣẹ mẹwaa lọ to lee janfani owo naa.
Lẹyin eyi lo jẹ Alaafin ti igba rẹ tuba, tusẹ, to si sẹ oniruuru ogun fun ilu Ọyọ.
Bí ó bá fẹ́ aya mìíràn fún ara rẹ̀, kò gbọdọ̀ dín oúnjẹ ẹrubinrin yìí kù, tabi aṣọ rẹ̀ tabi àwọn ẹ̀tọ́ rẹ̀ gẹ́gẹ́ bí aya.
gbogbo àwọn eniyan pada sọ́dọ̀ Joṣua ní àgọ́ tí ó wà ní Makeda láìsí ewu.
Ẹni tí ó ní ọkàn ẹ̀tàn kò ní ṣe àṣeyege,ẹlẹ́nu meji yóo bọ́ sinu ìyọnu.
Yóo wà ní ẹ̀gbẹ́ ilẹ̀ ti ẹ̀yà kọ̀ọ̀kan; ilẹ̀ mímọ́ ati tẹmpili mímọ́ yóo sì wà láàrin rẹ̀.
Ṣugbọn àwọn ẹ̀yà náà ṣẹ Ọlọrun baba wọn, wọ́n pada lẹ́yìn rẹ̀, wọ́n bẹ̀rẹ̀ sí bọ àwọn oriṣa tí àwọn tí Ọlọrun parun nítorí wọn ń bọ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ẹ̀mí sùn níbi ìkọlù Shiite àti ọlọ́pàá Ọgbẹni Musa ṣalaye pe, pẹlẹ kutu ni iwọde awọn n lọ ko to di pe awọn ọlọpaa da gbogbo rẹ ru.
OLUWA pàápàá dúró lókè rẹ̀, ó wí fún un pé, “Èmi ni OLUWA Ọlọrun Abrahamu baba rẹ ati Ọlọrun Isaaki, ilẹ̀ tí o dùbúlẹ̀ sí yìí, ìwọ ati àwọn ọmọ rẹ ni n óo fi fún.
O wa rọ awọn ọmọ Naijiria lati fiye denu, ki wọn si ṣe suuru fun abajade iwadi lori iṣẹlẹ buruku naa.
Dokita Bukola Saraki tewo gba iyansipo naa lojo kewa, osu kerin-in odun ti a wayii, ti o si tun  lo anfaani naa lati dupe lowo ajo IHRC.
Bakan naa ni eyi yoo mu ki owo to n pa wọle ru gọgọ si.
O ṣalaye pe a ko le ṣe ohunkohun lori ẹsun owo ẹyin gbigba ti 'wọn fi kan gomina Ganduje' mọ ayafi ti ile ẹjọ ba pada gba wa laaye""."
Ẹ dákun fìlà wo ló ba aṣọ yìí mu jùlọ?
Aarẹ ẹgbẹ naa, Aliyu Sokunbo sọ fu awọn akọroyin pe ẹgbẹ ọhun ti gunle idunadura miran pẹlu ijọba apapọ lori awọn ohun ti wọn n bere fun.
Àgbàrá òjò gbé alága àdúgbò àti èèyàn méjì mìí lọ nílùú Ibadan
Gẹgẹ bi ara akitiyan ati ṣatilẹyin fun ijọba ipinlẹ Eko lati polongo ewu to wa ninu dida ohun eelo onike nu lọna aitọ si awujọ, ẹgbẹ kan ti ki i ṣe tijọba (NGO) ti o wa ni ipinlẹ Eko ti pe fun fifi ofin de lilo ohun eelo onike, gẹgẹ bi ọna ti o le fopin si ewu ti awọn idọti onike yii n ko ba ayika.
Nínú àtẹ̀jáde ìwádìí kan ti fásìtì Oxford ṣe lo ti fi ìdí rẹ̀ múlẹ̀ pé, ti àwọn àdán bá wà lórí àkéte àìsan wọ́n máa n sètò ìyàsọ́tọ kí ààrùn náà ma baa tànkálẹ̀.
Ẹbun ọfẹ ni ọmọ jẹ, ìran Yoruba si gbà pé ẹni tó ba wu Aṣẹda ni o le fun ni ọmọ lasiko to wu u.
lilo iwa ipalara lati gba ẹsun  lọwọ eni
Obinrin oníwàrere ni adé orí ọkọ rẹ̀,ṣugbọn obinrin tí ń dójúti ọkọ dàbí ọyún inú egungun.
Farida Ado, onkowe omo Naijiria, to je omo odun mejilelogbon ti wo inu oruko awon to pegede ninu iran olori to m bo fun odun 2018.
Bí Adéforítì bá sì ti mú àdá yìí tí o fi gé ewéko kan, ṣe ni àdá a sá jáde lọ́wọ́ rẹ̀ tí àdá a máa tìkara rẹ̀ ṣiṣẹ́ lọ, bẹ́ẹ̀ náà ni àáké, bẹ́ẹ̀ ni ọkọ, bẹ́ẹ̀ ni akeǹgbè, kí a má sa fa ọ̀rọ̀ náà gùn lọ títí wákàtí kan ni ile náà gba Adéforítì tí ó bá òkè ọ̀run lọ.
ibudokọ igbalode ti agbegbe Oṣodi, afara ọlọkọ agbegbe Agege pẹlu awọn
Ajá ni yóo jẹ òkú Jesebẹli ní agbègbè Jesireeli, kò sí ẹni tí yóo sin òkú rẹ̀.
Coronavirus: Ọmọ ilẹ̀ Amẹrika kú sí Ekiti Bawo ni awọn ifarahan arun coronavirus ṣe maa n ri gan an?
Ija ojoojumọ pẹlu awọn akẹkọọ nile ẹkọ giga ati girama: Oríṣun àwòrán, Others Lasiko ti Abiola Ajimobi wa lori aleefa bii gomina ipinlẹ Ọyọ, ojojoojumọ ni awuyewuye maa n waye ni ẹka eto ẹkọ nitori awọn igbesẹ to n gbe lẹka eto ẹkọ.
1 1482216 Orilẹede Colombia 38484 77.
Oríṣun àwòrán, Others Igba meji ni Femi ti ṣe igbeyawo, iyawo akọkọ rẹ, ti wọn ti kọ ara wọn silẹ Khadijat, si lo bi ibeji naa fun, pẹlu ọmọdebìnrin kan miran, ti wọn fi jẹ ọmọ mẹta ti obìnrin naa bi.
’’Bakan naa aare tun tewogba komisona ile Sierra Leone si Naijiria
Aisha tọrọ aforijin lọwọ awọn ọmọ rẹ, ẹbi atawọn ọmọ Naijiria fun itiju ti fọnran naa mu wa.
Àwọn mẹ́rin t'íjọba Buhari k'etí ikún s'àṣẹ òmìnira iléẹjọ́ lórí wọn rèé Kí ni pàtàkì nọ́mbà 615 láàrín àwọn èèyàn ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ̀ Kíni àwọn ìpèníjà ẹtọ ààbò ṣáájú òmìnira Nàìjíríà?
Mo múra ó di ibi òkúta yìí.
N óo sọ àwọn ìlú Juda di ahoro, kò ní sí eniyan tí yóo máa gbé inú wọn.
Jesu dá wọn lóhùn pé, “Kí ló dé tí ẹ̀yin náà ṣe ń fi àṣà ìbílẹ̀ yín rú òfin Ọlọrun?
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Àwọn ohun kàyéèfì tó le mú kí ọmọbìnrin ní oyún ìju Ìrẹ̀sì kò gbọdọ̀ wọlé níbáyìí ta ṣí ẹnu bodè padà - Ìjọba àpapọ̀ Ìdí tí àwọn ìpińlẹ̀ se ń ti ilé ẹ̀kọ́ ní ìhà ìwọ̀ Oòrun-Àríwá Nàìjíríà rèé Abẹ́rẹ́ àjẹsára Covid-19 yóò dé sí Nàìjíríà nínú oṣù kíní ọdún 2021 Jide Kosoko forin sẹ́nu pé òun ni igi lẹ́yìn ọgbà Mr Latin lórí ipò ààrẹ TAMPAN tó wà Ó pé ọdún mẹ́wàá tí Barrister kú; wo ǹkan tó yẹ láti mọ̀ nípa rẹ̀ gẹ́gẹ́ bíi olórin, tẹ̀wé-tẹ̀wé, akọ̀wé àti sọ́jà Àìmọ̀kan ló mú mi hu ìwà tí mo hù kọjá sẹ́yìn, Jonathan dárí jì mí - Dino Melaye Gẹgẹ bi ileesẹ ọlọpaa ti wi, adugbo Favours, lopopona Awolowo si Bodija nilu Ibadan ni awọn ọkunrin meji to wa lori ọkada ti sẹburu ọkọ Toyota Corolla rẹ, ti wọn si fi tipa gba foonu ati apo kan ti iwe wa ninu rẹ.
Kòrí kòsùn ló pa Jimoh, ọmọ Àgbókí l’ádífá
" Àpẹẹrẹ irú àwọn fíìmù wọ ̀ nyí nii "" agbára ńlá "" tí mike bamiloye ṣe , "" látòrunwá "" àti bẹ ́ ẹ ̀ bẹ ́ ẹ ̀ lo ."
Fidio kan ṣe afihan ibi ti afẹsunkan naa ti n jo lẹyin to pa ọga rẹ lori atẹ Instagram rẹ ninu eyi to ti n jẹ inagijẹ Wil.
 Àṣẹ ̀ yìnwá-àṣẹ ̀ yìnbọ ̀ , ìṣẹbọ-ìṣoògùn , bí a ti lá á rì í láyé .
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Dino vs Adeyemi: Ìyàwó ni Adeyemi lágbo òṣèlú lọ́jọ́kọ́jọ́ 2 Ọ̀pẹ̀̀ 2019 Oríṣun àwòrán, Instagram/Dino Melaye Àkọlé àwòrán, Ìyàwó ni Adeyemi lágbo òṣèlú lọ́jọ́kọ́jọ́ Ọrọ ko tii tan o lori atundi ibo ile igbimọ aṣofin agba l'Abuja ti ẹkun iwọ oorun Kogi ninu eyi ti Smart Adeyemi fi fẹyin Dino Melaye gbalẹ.
Ẹ má jẹ ẹnikẹ́ni ní gbèsè ohunkohun, àfi gbèsè ìfẹ́ tí ẹ jẹ ara yín.
Gbogbo àwọn tí wọ́n fẹ́ sin Ọlọrun Israẹli tọkàntọkàn láti inú olukuluku ẹ̀yà Israẹli, tẹ̀lé àwọn alufaa wá sí Jerusalẹmu láti ṣe ìrúbọ sí OLUWA Ọlọrun àwọn baba wọn.
ng/maintainance tabi ki ẹ kan si : http://policerecruitment.
Àbí ṣe ibẹ̀ làá wà tí ìjọba amúnisìn míràn á tún fi dé bí?
ọ̀dọ́ 47,000 fẹ́ di Amotekun, agbófinró yẹ̀ wọ́n wò yẹ́bẹ́yẹ́bẹ́ Aáwọ̀ oyè PDP gbé Fayose àti Seyi Makinde kọlu ara wọn, ìjà ń bọ̀ Bí nǹkan ọkùnrin bá há sójú ara obìnrin, kìí ṣe Mágùn, ẹ má páyà Bàbálọ́jà márùn ún la ó ò ní l'Oyo tí Makinde bá lè buwọ́lu ìyànsípò YK Abass Ìjọba, e yé dẹ́yẹ sí wa mọ́, àwọn ẹlẹ́sìn ìbílẹ̀ ṣèwọ́de n'Ibadan Auxiliary gbé èèyàn mẹ́fà tó ń jáwèé ayédèrú fáwọn awakọ̀ lọ sí ilèẹjọ́ ní Ibadan Minisita feto ilera, Dokita Osagie Ehanire lo pa aṣẹ yii lọjọru nilu Abuja lasiko to n sọrọ lori iyanṣẹlodi awọn dokita nile iwosan ijọba, NARD.
" O ni kaka ki ijọba maa fi akoko ṣofo lori iye simu ti eeyan nlo, n ṣe lo yẹ ki ijọba wa nnkan ṣe si iwa jibiti ti awọn ileeṣẹ ibanisọrọ n hu si awọn ọmọ Naijiria.
Ṣugbọn ìjọba ipinlẹ Oyo ko peju tabi fi asoju ransẹ sibi adura ọjọ mẹjọ fun Abiola Ajimobi.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Abducted Child: Bàbà Aisha ní iléèwé ló ti ń bọ̀ nígbà tó bọ́ sọ́wọ́ ajínigbé lóṣù Kẹta 25 Ẹrẹ̀nà 2019 Oríṣun àwòrán, @PoliceNG Ileewe ni Aisha ti n bọ nigba to lugbadi awọn eeyan ibi naa lọjọ Kẹrindinlogun osu Kẹta ọdun yii ni adugbo Ibudu nilu Warri, nipinlẹ Delta.
 Èyí ni pé ilẹ ̀ ẹ ́ fẹ ̀ .
Lati bi ọsẹ melo kan ni awọn adari ajọ naa, to fi mọ minisita to wa fun Niger Delta, Godswill Akpabio, ti n koju iwadii lori bi ajọ naa ṣe na owo ti ijọba fun wọn.
(Ọjọ́ Ìsinmi ni ọjọ́ tí Jesu po amọ̀, tí ó fi la ojú ọkunrin náà.
dije labe asia egbe oselu APC, jawe olubori nipinle Kwara, ti o kogun saarin
Oríṣun àwòrán, Nigeria airforce Àkọlé àwòrán, Akẹkọ kan si wa lahamọ awọn Boko Haram fun bo se kọ lati gba ẹsin Islam Ohun ti a gbọ ni wi pe, nitoripe o kọ lati yi ẹsin rẹ pada si Islam gẹgẹbii awọn ikọ naa se n fẹ, ni wọn ko se fi akẹkọ naa silẹ.
Ètò ìdìbò yìí f'ọdun 2018 Ọ̀pọ̀lọpọ̀ àwọn oludije lo ti jade lati dije fun ipò gomina ipinlẹ Ekiti lọdun yii.
Mike Ifabunmi ló kọ́kọ́ kí BBC Yorùbá kú ayẹyẹ lónìí láti orílẹ̀èdè Brazil Ibà Lassa wọ ìpínlẹ̀ Èkó!
Oríṣun àwòrán, EPA Àkọlé àwòrán, Ọkunrin kan ni yii to n rin lọ lẹgbẹ aworan ipolowo ọja kan lẹgbẹ ogiri.
Nígbà tí àwọn ọmọ Israẹli gbọ́, ẹ̀rù bà wọ́n.
Oríṣun àwòrán, Desmond Elliot Àwàdà tàbí óótọ́, kì lò f'ẹkún Kọmíṣọ́nnà ìlera Kogi lórí amóhùnmáwòrán?
Nítorí bí n kò tilẹ̀ jẹ́ nǹkankan, n kò rẹ̀yìn ninu ohunkohun sí àwọn aposteli yín tí ẹ kà kún pataki.
Kí ẹ mọ èyí pé bí ó bá jẹ́ pé baálé ilé mọ àkókò tí olè yóo dé, kò ní fi ilé rẹ̀ sílẹ̀ kí olè kó o.
Láìpẹ yìí ni àjọ to n ri si ìwá jẹgudujẹra tún si iwe ìránti kan àwọn ẹsún tuntun míràn fún Bukola Saraki láti wá wi tẹnu rẹ̀ lásìkò to lò gẹ́gk bii ààrẹ ilé ìgbìmọ aṣòfin àti bí ó ṣe ná owó ìpínll Kwara lásìkò to jẹ gómìnà láàrin ọdún 2003 si 2011.
Lalong ni igbesẹ naa wa lati fa awọn to n rin irinajo igbafẹ wa si ipinlẹ Plateau.
Nítorí kò sí ìyàtọ̀ kan láàrin Juu ati Giriki.
Oloye Elebuibon sọ pe awọn to ba n ṣe iru nkan bayii n ṣe lati fi tabuku ẹsun abalaye ni.
Nigba ti Afonja n bọ lati Apomu, o fi ẹsẹ kan ya nilu Oyo, to si pa aroko si Aole pe ko si igbá wo, eyi to tumọ si pe ko gba ẹmi ara rẹ, to si fi igba ademu ransẹ si i.
O wa gbadura pe ki Olorun jẹ ki Ipinnu aare wa si imusẹ.
Chelsea kọ̀ láti fìyà panu bíi Arsenal àti Man U Jesu Oyingbo rèé, pásítọ̀ tó láṣẹ ìbálòpọ̀ lóri ọmọ ìjọ obìnrin Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Irokotọla: Báwo ló ṣe rọrùn láti fi àmì sí ọ̀rọ̀ yìí, ‘Irokotọla’ Garba Shehu ni ohun gbogbo ti yi pata labẹ isakoso Aarẹ Buhari, ati wi pe awọn ti gbogun ti Boko Haram kọja ami.
O kọ ẹkọ ni ile ẹkọ giga fasiti ti Ibadan, ti akẹkọgboye ninu ede Faranse.
Oun lo si ṣe ikọlu akọkọ to pa ọpọ eeyan ni DRC.
Lẹyin ti ẹgbẹ agbabọọlu Naijiria, Flying Eagles jẹ ajẹtun iya lọwọ Senegal lọjọ Aje, Mali ṣe gudugudu meje ati yahaya mẹfa ninu ifẹsẹwọnsẹ wọn pẹlu Argentina ni ipele komẹsẹoyọ ẹlẹni mẹrindinlogun.
 Sanwo-Olu kéde ìgbésẹ̀ rẹ̀ lórí ìrìnnà ọkọ̀ àjàgbé l'Eko Tí o bá rí àpẹrẹ mẹ́fà yìí, sá àsálà fún ẹ̀mí rẹ̀!"
Oxford English Dictionary: Ọ̀rọ̀ 28 túntun ti wọ́n fi kún-un lọ́dun 2020 Amotekun: Ọ̀rọ̀ Tinubu kò ní ohun àrígbámú kankan- Afẹ́nifẹ́re Tinubu kò ṣékú, kò ṣé ẹyẹ, o n dibọn ní lórí ọ̀rọ̀ ikọ̀ Amotekun - Fani Kayode Mọ̀ síi nípa ǹkan tí o lè ṣe láti dènà ibà Lassa Ẹ̀yin obìnrin tẹ́ẹ fẹ́ wá bímọ ní America, ọ̀nà ti tì pa látònì!
Ni baba rẹ̀ bá jáde lọ láti lọ bẹ̀ ẹ́.
Ẹ wo ìrírí aláboyún tó ń rọbí lọ́wọ́ lásìkò ìbúgbàmù tó wáyé ní Lebanon Kí ló fa iná ńlá tó ṣẹ́yọ lọ́jà Ajman ní Dubai?
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù 'Aláàbọ̀ ara tó ń dari ọkọ̀ ojú pópó ní àìlera kìí ṣàrùn' Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ 'Aláàbọ̀ ara tó ń dari ọkọ̀ ojú pópó ní àìlera kìí ṣàrùn' 6 Agẹmo 2018 Usman gba àwọn awakọ̀ níyànjú ki wọ́n máa rọra sáré lójú pópó.
Fowler kò sí lábẹ́ ìwádìí kankan-Garba Sheu Wo àwọn eléré ìdárayá mẹ́ta tí àjọ FIFA ti fòfin dè títí ayé Ọlọ́pàá ti mú ẹni márùn ún lórí ìjà láàrin Hausa àti Yorùbá l'Eko Buhari gbóṣùbà fún D'Tigress lẹ́yìn tí wọ́n lu Senegal gba ife AfroBasketWomen Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí 7:57 Fídíò, End SARS, End SWAT: Ó pé mi bí SARS kò ṣe sọ mí dolówọ́- Fulani Kwajafa, Duration 7,5717 Ọ̀wàrà 2020 5:55 Fídíò, Soyinka Cancer: Àṣe ara mi ni iso ti n run gbogbo bí mo ṣe n ṣèrànwọ́ lórí jẹjẹrẹ, Duration 5,5527 Bélú 2019 Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí kan sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
Gbọ́yì-sọ̀yí àti ìròyìn èké láti ọ̀dọ̀ àwọn olólùfẹ́ wa ló ṣáábà ma ń da ìgbéyàwó àwọn òṣèré rú- Ọpẹ Ayeola Òṣìṣẹ́ ológun Navy ni mí àmọ́ àwàdà ayélujára ló sọ mí di olókìkí - Cute Abiola Ohun tí a rí nílé Ajimobi rèé lẹ́yìn ìròyìn òfégè pé ó jáde láyé Wo orin l'édè Yoruba àti Zulu tí Burna Boy fi fa ayélujára ya Kíni ẹ mọ̀ nípa àwọn gbajúgbaja Yollywood?
Arẹwà Ibidunni Ighodalo wọ káà ilẹ̀ lọ nílùú Eko Adewale Elesho ni baba oun fun oun lowo bẹẹdi ati foomu nigba ti oun bẹrẹ si ni ta oogun, tori baba oun ni ko yẹ ki ẹni ti o n ta oogun maa sun sori ẹni.
Ọ̀rọ̀ ìninilára ati ọ̀tẹ̀ ni à ń sọ,èrò ẹ̀tàn ní ń bẹ lọ́kàn wa, ọ̀rọ̀ èké sì ní ń jáde lẹ́nu wa.
Àwọn ìsirò ònkà nlá-nlá tí ó sòro púpọ̀ púpọ̀ fún ọmọ ènìà láti ṣe ni ẹ̀rọ yìí nṣe ní kíákíá láì tàsé.
Bo tilẹ je pe ikọ agbabọọlu
Ki oun naa o to kagbako iku lasiko ti ija waye laarin one million boys ati orogún wọn kan lọjọ Aiku, ọjọ kejila, oṣu Keje ni adugbo Olomi.
Wolves bu Arsenal jẹ bí ajá Ìjàmbá ṣe Ole.
Mo sì ń wà pẹlu rẹ̀ ní gbogbo ibi tí ó ń lọ, mo sì ti pa àwọn ọ̀tá rẹ̀ run níwájú rẹ̀, n óo sì gbé orúkọ rẹ̀ ga bí orúkọ àwọn eniyan ńlá ayé.
Ẹ̀ wo bí àwọn ẹ̀ṣọ́ ojú etí òkun ṣe ń ṣiṣẹ́ l'Eko Awakọ̀ òfúrufú Ethiopian Airlines pariwo 'lọ sókè!
” Wọ́n pe Samsoni jáde láti inú ilé ẹ̀wọ̀n, ó sì bẹ̀rẹ̀ sí dá wọn lára yá.
Ninu ifọrọwerọ to n kiri lori ayelujara naa, Olori Chanel Chin ṣalaye pe ọpọ igba ni oun ati Kabiyesi Oluwo ti fa wahala lori ọrọ yii ṣugbọn to jẹ pe lilu ati igbaju igbamu lo maa n kẹyin irufẹ edeaiyede bẹẹ fun oun.
Nígbà tí wọn gbọ́ ọ̀rọ̀ ọba, wọ́n lọ.
 Òun kan náà yí ló ṣagbátẹrù gbígbé ifá ( Ìmọ ̀ elédùmarè ) wá sílé ayé .
Ọkan lara awọn fasiti mejila ti ijọba apapọ da silẹ lọdun naa ni.
Wo ibi tí èsì ìdíje Russia 2018 ti dé báyìí Ọ̀mùtí ọmọ Nàìjíríà kábàmọ̀ ní Russia Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Lórí ìgbéyàwó mi, ẹ̀ ṣáà jẹ́ kó wà báyìí' Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Rehoboamu lọ sí Ṣekemu, nítorí pé gbogbo Israẹli ti péjọ sibẹ láti fi jọba.
Lai, wá wi tẹnu rẹ lóri bílíọnu mẹ́jì àbọ owó DSO
ON THE MOVE AGAIN: TWO PORTFOLIOS IN TWO MONTHS!
Ọgbọ́n àrékérekè ní ìjọba ń dá lórí àfikún owó oṣù òṣìṣẹ́, a o sí ní gbà- NLC Ẹ wo ohun tó yẹ kí ẹ mọ̀ nípa gbajúgbajà òṣèré tíátà Yoruba Tóyìn Afọlayan Ta ni Oba Idowu Abiọdun Oniru tó wàjà nípinlẹ̀ Eko?
"Kíkọ́ ẹ̀kọ́ gboyè nínú iṣẹ́ ìṣègùn ìbílẹ̀ yóò pèsè ìtọ́jú tó péye fọ́mọ Nàìjíríà- Ẹgbẹ́ àwọn dókítà Ǹkan mẹ́jọ tó máa kọ́kọ́ ṣẹlẹ̀ kí olólùfẹ́ méjì tó pa ara wọn Ẹ yé gba owó orí níbi ìdána ìyàwó mọ́, sísọmọbìnrin s'óko ẹrú ni- Daddy Freeze A kò fòfin de owó naira tó ti pẹ́ ní Naijiria -CBN Adeboye ni: ""Eeyan kan o le maa pa arakunrin rẹ ki o si tun maa jẹ maalu rẹ."
Simoni dá Peteru lóhùn pé, “Ẹ gbadura sí Oluwa fún mi kí ohunkohun tí ẹ wí má ṣẹlẹ̀ sí mi.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Super Eagles vs Argentina: Òní lòní ń jẹ́ #Russia2018: Super Eagles ti koju Argentina rí Àwọn olórin Nàìjíríà kẹ́dùn ikú ọmọ DBanj Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí 2 sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 2:23 Fídíò, Water Generator: Ó leè ṣiṣẹ fún wákàtí mẹfà, kó tó sinmi, Duration 2,2310 Òkùdu 2020 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Wọ́n ta ère Ọ̀ṣun Osogbo sí Togo - Bàbá Ọṣun figbe ta Ayọ̀ abara bíńtín!
Oúnjẹ àárọ̀ àti ìpanu àtàtà ní ilẹ Yorùbá.
Àwọn ẹ̀yàYorùba mìíràn ní orúkọ tí wọ́n ń pe ọmọ titun tí kò tíì ní orúkọ ní ẹ̀ka- èdè ti wọn.
OLUWA bá wọn dá majẹmu, ó sì pàṣẹ fún wọn, pé, wọn kò gbọdọ̀ bọ oriṣa, tabi kí wọ́n júbà wọn, bẹ́ẹ̀ ni wọn kò gbọdọ̀ sìn wọ́n tabi kí wọ́n rúbọ sí wọn; 
Gates si asọ loju ọrọ yii pẹlu alaga ajọ alaanu Dangote, Alhaji Aliko Dangote, nibi akanse ipade igbimọ awọn eleto aje lorilẹede yii eyi to waye ni gbọngan apejẹ to wa nile ijọba nilu Abuja.
Àwọn òṣìṣẹ́ tó n bojù tó ìrìn ojú pópó sọ wí pé, wọ́n jí àwọn ènìyàn náà bí wọ́n sé ń rìnrìn àjò ní òpópónà márosẹ̀ kan tó so ìhà àríwá mọ́ Gúúsù.
Òun ni gbogbo àwọn wolii ń jẹ́rìí sí, tí wọ́n sọ pé gbogbo ẹni tí ó bá gbà á gbọ́ yóo ní ìdáríjì ẹ̀ṣẹ̀ ní orúkọ rẹ̀.
 kòsí oogùn ìwosàn kan gbòógì .
Kini awọn ọmọ Naijiria n sọ Oju opo ayelujara gbana jẹ pẹlu ikede yi ti awọn ọmọ Naijiria si n sọ iriwisi ọtọọtọ.
Fi owo osu rẹ we ajẹmọnu Sẹnatọ rẹ
"Lẹyin naa lo gbe awo orin kan jade eyii to pe akori rẹ ni ""So tey,"" ti olorin takasufẹ ilẹ Amẹrika, Busta Rhynes kopa ninu rẹ."
' Jonathan ni o to asiko ki aarẹ Buhari atawọn ẹmẹwaa rẹ yee da ẹbi awọn ijakulẹ wọn ru elomiran ki wọn si mojuto ipenija gbogbo 'ti wọn fi ọwọ ara wọn fa' Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, ẹ mojuto ipenija ijọba yin Ọlọ́pàá gba àna ADC Buhari silẹ̀ lọ́wọ́ ajínigbé Ìdí rèé táwọn ọmọ Nàíjíríà kan ṣe ń tako ìdásílẹ̀ ‘Ruga Settlement’ Agbébọn yabo àgọ́ ọ́lọ́pàá, wọ́n pa DPO àti ọlọ́pàá mẹ́ta míràn Ọ̀nà wo lowó osù tuntun yóò tọ̀, kó tó dé àpò òsìsẹ́?
" Nigba ti akọroyin wa beere idi to fi jẹ wipe awọn aṣofin nikan ni wọn n sọrọ nipa nigba ti awọn oloṣelu to wa labẹ ileeṣẹ aarẹ naa n gba owo yanturu, adari SERAP naa ni lẹyin ti awọn ba pe awọn aṣofin lẹjọ tan, awọn yoo tun gbe igbeṣẹ lori ti ileeṣẹ aarẹ.
Ni ipari, ọ̀kan lara awọn olukopa, Mercy Mercy, n fẹ ki Buhari fi opin si eto isinru ilu, NYSC.
Amọ bi awẹ naa ti ṣe di meji lọjọ iṣẹgun, niṣe ni awọn musulumi kan n sọ pe awẹ ti awọn ṣẹṣẹ di ẹyọkan ni.
Buhari tún ti yan òkú sípò alàyè Bákan náà ni Akeugbagold ni irú nkan kò ṣẹlẹ̀ sí èmi yìí, kò sì ẹni tí kò leè ṣẹlẹ̀ sì."
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Mutallab: Bàbá rẹ̀ ní ọmọ òun ti kábàmọ́ọ̀ ìwà tó wù, kí wọn ṣàánú rẹ̀ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Mutallab: Bàbá rẹ̀ ní ọmọ òun ti kábàmọ́ọ̀ ìwà tó wù, kí wọn ṣàánú rẹ̀ 5 Owewe 2019 Ibanujẹ nla gbaa ni fun obi lati ri ọmọ rẹ ko maa se idajọ ẹwọn gbere nitori ọmọ ẹni kii buru, ka le fun ẹkun pa jẹ.
Ṣugbọn ko pẹ si asiko ti wọn gba a sisẹ ni o pa ọga ọra rẹ laarọ ọjọ kan.
Saaju kikede re,asoju orile-ede naa fun opolopo odun ni awon eniyan ti n ki ku oriire lori ero kalekako.
Igbà meji ló wà fún ojú ọjọ́ – igbà òjò àti ẹ̀rùn.
Oríṣun àwòrán, Screenshot/iyabo ojo Àwọn ọbá aláye ilẹ̀ Yorùbá márùn-ún pẹ̀lú ọ̀pá àṣẹ wọnAgbára wa kò ká àrùn Covid-19 mọ́ - Ìjọba ilẹ̀ Amẹrika Iléèṣẹ́ tẹlifísàn AIT, Arise TV àti Channels wọ gàù àjọ NBC nítorí ìpànìyàn Lekki Àṣírí tó ń bẹ láàrín Oluwo àtàwọn ọ̀dọ́ Iwo tí wọ́n fi fi ẹ̀mí wọn lélẹ̀ dáàbò bo ààfin rẹ̀ Eko, Kwara, Osun àtàwọn ìpínlẹ̀ míì tí àwọn èèyàn ti jí oúnjẹ ìrànwọ́ Covid-19 kó Iyabo, loju opo Twitter ati Instagram rẹ lo n leri leka, to si n tọ ilẹ la pe, oun ko ni polongo ibo fun oloselu kankan ni Naijiria mọ, to ba jẹ ọmọ ẹgbẹ oselu APC tabi PDP.
Bákan náà ni yoo má n ràn wọ́n lọ́wọ́ láti tun le mú ápùù wọ́n wà ní àtúnṣe, ti yóò túbọ̀ wúlò fún àwọn tó n lò ó, pàápàá jùlọ, àwọn tó n lo fóònù tuntun.
Aare muhammadu Buhari ti gunle si orile ede Morocco lojo Aiku, fun akanse irinajo olojo-meji.
Lero tirẹ, Tinubu n gbe lẹyin ijọba apapọ ni: Fani Kayode nikan kọ ni o lero pe Tinubu ko gbe lẹyin awọn eeyan ilẹ Yoruba.
Ọọ̀ni: Gbogbo ẹni tó rí tajé se ló yẹ kó tọ́jú ọmọ òrukàn
Coronavirus ti di ara wa, kò le è kúrò mọ láéláé - WHO Wo aláànú tó n wa ọkọ̀ tí wọ́n fi n gbé aláìsàn lọ́fẹ̀ẹ́ Ìdí rèé tí ilẹ̀ Afirika fi gbọdọ̀ kópa nínú dídán abẹ́rẹ́ coronavirus wò Mo kábàámọ̀ pé n kò kàwé, kí n tó bẹ̀rẹ̀ iṣẹ́ tíátà - Sanyeri Ilumọọka osere tiata, Alhaji Mukaila Olaniyi Afonja, tí gbogbo eeyan mọ sì Sanyeri abi Ambali ti ṣalaye bo ṣe rin irin ajo aye rẹ, ko to di onitiata.
Ọwọ́ ẹni tí kò sì ní, ni a óo ti gba ìba díẹ̀ tí ó ní!
Ṣugbọn Abramu bèèrè pé, “OLUWA Ọlọrun, báwo ni n óo ṣe mọ̀ pé ilẹ̀ náà yóo jẹ́ tèmi?
Ọmọ yii le maa nilo orukọ baba rẹ nitori ọmọba tabi ọmọbabinrin ni yoo maa jẹ nigba ti wọn ba bii.
Okiki iroyin yii kan to bẹẹ gẹẹ, ti awọn akanda ẹda lawujọ pẹlu fi gba pe BBC News Yoruba jẹ ohun wọn, lati fi sọ ẹdun ọkan ti wọn naa faraye.
Oríṣun àwòrán, LASEMA Ko si si ẹni to lee sọ ibi ti ọkunrin naa ti sese, ti eruku ile to wo naa si wa lara rẹ.
Batiṣeba bá bèèrè pé, “Ṣé alaafia ni o?
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ọjọ́ orí tàbí ìrírí; kíni agbanisíṣẹ́ n wá?
olówó rẹ̀ yóo mú un wá siwaju Ọlọrun, ní ibi ìlẹ̀kùn àgọ́ tabi òpó ìlẹ̀kùn, olówó rẹ̀ yóo fi òòlù lu ihò sí etí rẹ̀, ẹrú náà yóo sì di tirẹ̀ títí ayé.
Oríṣun àwòrán, @NGsuper_falcons Àkọlé àwòrán, Ìgbà kẹsàn-án rèé tí wọn yóò gba ife ẹ̀yẹ náà Ikọ Super Falcons ko tii fidi rẹmi ri ninu ifẹsẹwọnsẹ aṣekagba idije ife ẹyẹ ọhun, ṣugbọn South Africa ti kuna lẹẹmẹrin ti wọn ti kopa ninu aṣekagba idije naa Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: AFCON bọ́ mọ́ Cameroun lọ́wọ́ nítorí ìdí méjí-CAF CAF kéde orúkọ àwọn olùdíje àmì ẹ̀yẹ agbábọ́ọ̀lù Áfíríkà Super Falcons pegedé fún àṣekágbá AWCON Igba keji ree ti Naijiria ati South Africa yoo waako ninu ifẹsẹwọnsẹ aṣekagba idije ife ẹyẹ ere bọọlu awọn obinrin nilẹ adulawọ.
 O ni akosile aba naa ko muna doko to nitori pe awon omo igbimo elenu meedogun lori ase alaafia Syria lai ba awon ti oro kan gbogbo soro.
Ọga Agba Ajọ Ọlọpaa lorilẹ-ede Naijiria, Mohammed Adamu to fi ọrọ naa lede lasiko to n ba awọn oniroyin sọrọ ni ilu Abuja sọ wi pe awọn gbe igbesẹ naa lati ri wi pe abo to gbooro wa lori awọn osisẹ lagbegbe naa.
Iwaadi fihan pe igba 76 ni o gun iyawo rẹ lọbẹ ti adajọ si fi wakati mta gbako ka idajọ rẹ.
oju irin mẹ́wàá  naa wa, ko
Ọlọrun mi, ranti mi sí rere nítorí gbogbo rere tí mo ti ṣe fún àwọn eniyan wọnyi.
Bí wọ́n ti ń ṣí ní ibùdó kọ̀ọ̀kan, ìkùukùu OLUWA ń wà lórí wọn ní ọ̀sán.
Oúnjẹ tí ó wà ninu àpò wa ti tán, bẹ́ẹ̀ sì ni kò sí nǹkankan lọ́wọ́ wa tí a lè fún un.
Lónìí ni Ajimobi yóò mọ bó ṣe ń lọ pẹ̀lú ẹjọ́ kòtẹ́milọ́rùn tó pè Irọ funfun báláwú ni, Boko Haram kò dawa lọnà rárá -Ọmọ ogun Naijiria Lẹyin eyi ni BBC kan si ileeṣẹ ọlọpaa ni Kaduna lati fidi ọrọ yii mulẹ.
Bee si ni, isafihan ohun yoo wasi ipari lojo karun si asekagba idije agbaye naa lorile-ede Russia lojo karundinlogun osu keje odun ti a wayii.
Arakunrin naa ti o bẹbẹ pe ki BBC o fi orukọ bo oun laṣiri fi kun un pe awọn ẹgbẹ agbebọn naa tilẹ n rin lati ileto si ileto lati gba owo ori ti wọn si n yọ ẹgba si awọn eeyan ti wọn ba wo pe wọn ṣẹ tako ofin ẹsin Islam.
ọmọ Maati, ọmọ Matatiya, ọmọ Semehin, ọmọ Joseki, ọmọ Joda, 
Ọrọ̀ ajé Nàíjíríà yóò forí ṣánpọ́n tá a bá san ₦30,000 fún òṣìṣẹ - Ìjọba Kò sí ìfoyà, mò ṣetán láti sàn jù ₦30,000 fáwọn òṣìṣẹ́ l‘Eko - Sanwo-Olu 'Kìí ṣe ojúṣe mi láti sọ bóyá òótọ́ ni Buhari fẹ́ gbéyàwó tàbí irọ́' 5.
Amọ ṣa abẹwo awọn igbimọ alakoso ajọ to n ṣe amojuto ileeṣẹ ọlọpaa lorilẹede Naijiria to lọ ki aarẹ lati dupẹ lọwọ rẹ fun igbesẹ naa lo jẹ ki awo ọrọ yii lu sita.
Okunrin kan ati ibeji ọkunrin meji ni awọn ọmọ ti olori badirat bi fun ọba Adeyemi, ọdun 2018 si lo bi awọn ibeji naa.
77 usd fún ìwọ ̀ n egbògi náà kanṣoṣo ní ọdún 2014 .
Àwọn dókítà sọ fún mi pé ọjọ́ orí rẹ̀ lójẹ́ kí ó maa ṣe bi ọmọdé.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Lagos Flood: Wọ́n ṣì ń wa àwọn ọmọ méjì tí àgbàrá òjò wọ́ lọ ní Ketu l'Eko 10 Ìgbé 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 13 Owewe 2020 Oríṣun àwòrán, LASEMA Ibeere to n jẹ jade ni pe ṣe awọn ọmọ naa ṣi wa laaye abi wọn ti gba tibi agbara ojo yii re lọ sọrun?
Ni osu kinni odun 2018 ni won ti ri isele mokanlelaadota ni West Midlands.
Ó mú ìràwọ̀ meje lọ́wọ́ ọ̀tún rẹ̀.
Lasiko to n ba BBC Yoruba sọrọ, Ọlatoyan, to maa n di tai bii oyinbo lasiko to ba n fọ gilaasi ọkọ loju popo salaye pe, iku baba oun lo sọ oun di ẹni to n fọ gilaasi ọkọ, ti oun si pa iwe ti oun n ka ni fasiti Ilọrin ti.
Jesu pe àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ mejila sọ́dọ̀, ó fún wọn ní àṣẹ láti máa lé àwọn ẹ̀mí èṣù jáde, ati láti máa ṣe ìwòsàn oríṣìíríṣìí àrùn ati àìsàn.
lati ki aare Buhari ku ori ire gege bi aare tuntutn lorile ede Naijiria.
Ogun Cholera: Ọdọọdún ni àrùn onígbá-méjì máa n ṣọṣẹ́ ní Nàìjíríà -NCDC Ohùn tó yẹ ní mímọ nípa òfin ojú pópó UK ṣetán láti dá Adìyẹ 'Àkùkọ' Nàíjìrìa ti wọ́n gbé padà Gbogbo ètò ti tò fún àtúndì ìdìbò Kogi lónì - INEC Ilẹ isẹ ọlọpaa naa fikun pe iwadii n tẹsiwaju lori isẹlẹ naa, a ti wi pe awọn ti n tọpinpin bọya oun nikan lo se igbesunmọmi naa tabi pẹlu iranwọ awọn ẹlomiran.
Ṣùgbọ́n èyí tí ó jẹ́ ìyàlẹ́nu jùlọ pátápátá ní èyí pé ọ̀sẹ̀ náà kò ì tí ì parí nígbà tí àwọn ọmọ aráyé tún ti bẹ̀rẹ̀ sí àròyé wọn.
Alaga igbimo amusese tuntun naa, ajagunfeyinti Paul Tarfa (Rtd), fi da aare Buhari loju pe igbimo naa yoo bere ise ni kia-kia lai oro naa fale .
ẹni tíí máa ń dá ẹjọ́ òdodo fún àwọn tí a ni lára;tí ń fún àwọn tí ebi ń pa ní oúnjẹ,OLUWA tíí tú àwọn tí ó wà ninu ìdè sílẹ̀.
Oríṣun àwòrán, @victoryomogiate Bakan naa ni ọmọbinrin ọhun n sepe pe awọn afẹsọna mejeeji naa ko ni ri ayọ ninu igbeyawo wọn tori Cute Abiola lo oun nilokulo ni aimọye igba.
Eyi ko ṣa dede ri bẹ bikoṣe nitoripe ko si eeyan to gbọ iroyin aarẹ kankan nipa eekan oṣere naa ki ọlọjọ to de.
Òmùgọ̀ ń sọ̀rọ̀ láìdákẹ́,kò sí ẹni tí ó mọ ohun tí ń bọ̀ lẹ́yìn ọ̀la,ta ni lè sọ ohun tí yóo ṣẹlẹ̀ lẹ́yìn rẹ̀ fún un.
Wọ́n ti fọ́n wọn káàkiri sí ààrin àwọn orílẹ̀-èdè,wọ́n sì ti pín ilẹ̀ mi.
Ẹ̀ funra, ó lé ní 4,000 ènìyàn tó ń gba ìtọ́jú nílé l'Eko nítórí àrún Coronavirus Ijọba ipinlẹ Eko ti ni o le ni ẹgbrun mẹrin( 4,176 )eniyan to n gba itọju arun Coronavirus ni ile, lẹyin ti wọn ṣẹṣẹ lugbadi arun Coronavirus.
Ọjọgbọn Mohammed Sambo di alaga ajọ NHIS tuntun.
Ohun kan ti a mọ ni pe iwadii yii da le ọrọ Wooli Saint Alfred Akintobi Ajayi to gbe iṣẹ iranṣe lọ si Agelu niwaju Isẹyin nipinlẹ Oyo ti wọn ko ri oku rẹ sin lẹyin to papoda.
Ẹ̀wẹ̀, George Ossom Batsa tó jẹ́ ọ̀jọ̀gbọ́n ẹ̀kọ́ ìmọ̀ ẹ̀sìn ní fásitì Ghana sọ wípé ó yẹ kí wọ́n gbóríyìn fún Boduong fún òtítọ́ rẹ̀ nítorí nípa èyí ni wọ́n fi lè kojú àwọn àìdáa tó wà láwùjọ́.
Gbogbo nǹkan yòókù tí Menahemu ṣe ni a kọ sinu Ìwé Ìtàn Àwọn Ọba Israẹli.
Ọjọ́ OLUWA àwọn ọmọ ogun ni ọjọ́ náà,ọjọ́ ẹ̀san, tí yóo gbẹ̀san ara rẹ̀ lára àwọn ọ̀tá rẹ̀.
Erdogan gba pe America ti ya ara re soto.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Njẹ ọ mọ̀ pé mímí afẹ́fẹ́ tí kò dára lè fa àìsàn?
Bí ìgbà gbogbo, àmì ìpolongo ni FreeAlaa – jọ̀wọ́ darapọ̀ mọ́ wa fún ìpalẹ̀mọ́ ìdásílẹ̀ẹ Alaa.
Awọn ọlọpaati mu Baba baba ọmọ náà Cesar Lopez ti wọn sì ti fi ẹsun kan wí pé o se àkóbá fún ẹmi ọmọdé.
11 Bélú 2020 Alaafin: Wo arẹwà mẹ́jọ̀ tó ń ṣìkẹ́ Ọba Adeyemi13 Ògún 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Nígbà kan, mo gbọ́ tí ba[ɓ ́ mi ń bá a wí pé eré, àwàdà àti yẹ̀yé ni ó máa fi gbogbo ọjọ́-ayé rẹ̀ ṣe, àti pé ní ọjọ wo ni ó máa huwà àgbàlagbà.
Òní tún bọ́ sí ọjọ́ Àbámẹ́ta tí í ṣe ọjọ́ ìgádùn kẹlẹlẹ.
Nebusaradani olórí àwọn tí wọn ń ṣọ́ ọba, kó wọn lọ sọ́dọ̀ ọba Babiloni ní Ribila.
Ohun nikan kọ, abajade iwadii igbimọ ile to n ri si amojuto eto owo ara ilu sọ pe ki adajọ agba naa yẹba lati le dahun si ẹsun ti ayẹwewo agba ipinlẹ naa fi kan an.
O ni iwa ọdaran ni ki eeyan maa lo ajakalẹ arun bii Covid-19 lati sọ ara rẹ di ọlọla, ko si bojumu.
Ijoba ipinle Enugu so pe, ohun yoo na owo ti iye re le ni bilionu mejilelogoji owo Naira, ninu eto isuna owo odun 2018, lati mu igberu ba awon ohun amayederun.
Akeredolu sọ ọrọ yii lasiko to ṣe ipolongo ibo lọ si ilu Igbekebo, nijọba ibilẹ Ese-Odo, tii ṣe ilu Ajayi, ni imurasilẹ fun eto idibo abẹle ẹgbẹ oṣelu APC.
" Iṣẹ́ akin ni ọ̀gá iléẹ̀kọ́ tó kú nínú ìbúgbàmù Eko ṣe, ẹ fàmì ẹ̀yẹ da lọ́lá - PDP késí ìjọba Ẹgbẹ oṣelu Peoples Democratic Party, PDP, ti kesi ijọba apapọ Naijiria, lati fi ami ẹyẹ da Olori ileewe girama Bethlehem, Ẹni ọwọ Henrietta Alokha lọla, to padanu ẹmi rẹ ninu ibugbamu to waye nilu Eko lọjọ Aiku.
US election 2020: Olórí àwọn òṣìṣẹ́ Trump sọ pé ìjọba ilẹ̀ America kò le kápá coronavirus
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ sí: ‘Wọ́n ti sọ Ìbò di kátà-kárà ní Èkìtì’ Wo Ọ̀jọ̀gbọ́n Ẹlẹka tó ń díje fún ipò gómìnà 'Ìjọba tó kúrò lórí àléfà l'Ekiti ti kó wa sínu gbèsè' Àkọlé àwòrán, Awọn oludije gomina l‘Ekiti Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí 2 sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
Ọ̀rọ̀ wọn níyì lọ́dọ̀ àwọn eniyan.
A gbo̩dò̩ pèsè è̩kó̩ is̩é̩‐o̩wó̩, àti ti ìmò̩‐è̩ro̩ fún àwo̩n ènìyàn lápapò̩.
ede Naijiria Supreme Court  ti gbegile ibo
Obìnrin tó bá fẹ́ wọn, igbó Sambisa ló lọ - Lizzy Anjorin Kí ìjọ mi ní Sagamu le gbòòrò ni mo fi ń ṣiṣẹ́ ajínigbé pawó - Pásítọ̀ Àṣẹ àwọn gómìnà là ń retí, àwa ti ṣetán láti dáàbò bo ilè Yorùbá- Gani Adams Awọn ileeṣẹ iroyin Naijiria kan naa sọ pe igbakeji rẹ faragbọta ninu ikọlu pẹlu awọn ọlọpaa.
Awọn oludari ati akọwe ti gbogbo wọn jẹ mẹrindinlogun lo wa ninu igbimọ naa.
Pamela Olubunmi Smith ti tumọ iwe akagbadun yii si ede Oyinbo ni eyi to pe ni: The Freedom Fight lọdun 2010 Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Èmi gan máa ń béèrè lọ́wọ́ ara mi pé ta ni Wole Soyinka gangan' 4) Eegun alare lati ọwọ oloogbe Lawuyi Ogunniran Iwe Eegun Alare lati ọwọ Lawuyi Ogunniran jẹ iwe akagbadun fun gbogbo ọmọ Yoruba sugbọn o tun jẹ iwe to n mu ori ẹni to ba fẹran Ẹsa tabi Iwi Egungun pupọ wu soke.
Àwọn tí wọ́n tó ẹni ogún ọdún ati jù bẹ́ẹ̀ lọ ni gbogbo àwọn tí ó kó jọ.
“Mo mọ̀ pé OLUWA ti fi ilẹ̀ yìí lé e yín lọ́wọ́, jìnnìjìnnì yín ti bò wá, ẹ̀rù yín sì ti ń ba gbogbo àwọn tí wọn ń gbé ilẹ̀ yìí.
nítorí ọmọdebinrin rẹ̀ kan ṣoṣo tí ó ní ń kú lọ.
Ọjọ keji, oṣu Kẹrin Lẹyin aisan ọlọjọ pipẹ, Winnie Masikizela-Mandela fọwọrọri ku.
1–10, Ìran yìí yíò gba ọ̀rọ̀ Olúwa nípasẹ̀ Joseph Smith; 11–18, Àwọn ẹlẹ́ri mẹ́ta yíò jẹ́ri sí Ìwé Ti Mọ́mọ́nì; 19–20, A ó fi ẹsẹ̀ ọ̀rọ̀ Olúwa múlẹ̀ bí ti awọn ìgbà ìṣaájú; 21–35, Martin Harris lè ronúpìwàdà kí ó sì jẹ́ ọ̀kan nínú àwọn Ẹlérìí náà.
Serena Williams to jẹ ẹni to gbe igba oroke julo ninu awọn to n gba bọọlu ẹlẹyin sọ pe, oun kò lè sọ idi ti oun ko fi ni kopa ninu idije naa fun ẹlomii rara.
Ekiti election appeal: Ilé ẹjọ́ kòtẹ́milọ́rùn dá Fayẹmi láàre lórí ẹjọ́ Ẹlẹka
Ẹ óo bí ọpọlọpọ ọmọkunrin ati ọmọbinrin, ṣugbọn wọn kò ní jẹ́ tiyín, nítorí gbogbo wọn ni wọn óo kó lẹ́rú lọ.
Ṣugbọn onigbagbọ nìkan ní ó lè fẹ́.
Wèrè tí mò ń ṣe ní Facebook ló pawó fún mi-Esabod Èèyàn 409 míì ti lùgbàdì àrùn Coronavirus ní Naijiria Àwọn 'ẹ̀bùn' tí ikú George Floyd fún àgbáyé Adari awọn agbẹsan ni Nkurunziza jẹ tẹlẹ, o ni idunu si bi o ṣe ti mu alafia de ba Burundi to si nkọ orilẹede to jẹ ọkan lara awọn ti ko lọrọ lagbaye.
“Fèrè yìí yóo sì jẹ́ ìlànà fún ìrandíran yín.
O fẹ ki wọn lee jẹ oloriire lọjọ ọla, sugbọn gbogbo aayan obinrin yii lo so eso rere lori Ọmọlufa, to si ja si pabo lori Ọmọyẹni.
Wo bí àwọn ará Ibadan ṣe ń ṣe lásìkò Coronavirus yìí Orílẹ̀èdè 11 ni kò tí ì ní àrùn Coronavirus ní ilẹ̀ Afrika Covid-19 ti pa akọni afúnfèèrè Sax ilẹ̀ Africa Ìjọba ìpínlẹ̀ Oyo kéde pé kí àwọn òṣìṣẹ́ ìjọba dáwọ́ iṣẹ́ dúró nítorí coronavirus Coronavirus wọ ìpínlẹ̀ Rivers, èèyàn méjì míì tún ni l'Eko, ó di èèyàn 51 tó níi ní Nàìjíríà Ajọ to n gbogun ti ajakalẹ aarun ni Naijiria, NCDC ti kede pe iye eeyan to ti ni aarun Coronavirus nilẹ yi ti di mọkanlelaadọta bayii.
kí lo ti wí ná nígbà tí ó rí ọ?
Ní àkókò náà, Hasaeli, ọba Siria gbógun ti ìlú Gati, ó sì ṣẹgun rẹ̀.
Saulu bá ju ọ̀kọ̀ rẹ̀ mọ́ ọn, ó fẹ́ pa á.
“Gbogbo àkọ́bí tí ẹran ọ̀sìn bá bí ninu agbo ẹran yín, tí ó bá jẹ́ akọ ni ẹ gbọdọ̀ yà á sọ́tọ̀ fún OLUWA Ọlọrun.
Onnoghen: Ọlọ́pàá ti ọ́fíísì adajọ́ àgbà, wọn tún lé àwọn òṣìṣẹ́ rẹ̀ jáde
Nitori naa, Deji ni ofin lo gbudọ maa bori ninu ohun gbogbo.
láti Idumea ati apá ìlà oòrùn odò Jọdani ati agbègbè Tire ati ti Sidoni.
Nígbà ti BBC pé Kọmísọ́nà ètò ìlera ní ìpínlẹ̀ Ogun dókítà Tomi Coker sàlàye pé, o ti yá ju lásìkò yìí láti sọ ìgbẹ́sẹ̀ tí ìjọba yóò gbé, sùgbọ́n ìjọba ti n ba olóri wọ́n sọ̀rọ̀ láti wa ojúùtú si ìṣòrò to wà nílẹ̀.
Àwọn ọlọkọ náà ni àwọn pe ìpàdé pọ pẹlu awọn ọmọ igbimọ alakoso gareji lori ọrọ yìí ni ọjọ́ Ajé nítorí owó náà pọju fún àwọn láti san, ṣùgbọ́n ní kété tí wọn gunlẹ sì gareji Bẹẹrẹ naa pẹ̀lú àwọn tọọgi wọn, ní wọn ń na àwọn.
Láìpẹ́ yìí gan-an pàápàá, ó dunni láti máa kojú àwọn ìhùwàsí tí ó ń jáde lẹ́yìn ọ̀rọ̀ ti Carolina…
Fake Pastors: Bunmi àti Rukayat ni agbódegbà àwọn afurasi pasitọ náà
Won ni oju ojo ti ko dara to ati arooroda ojo to n ro lasiko ti o fe bale ni o sokunfa isele yii.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Kayeefi: Àkójọpọ̀ ìṣẹ̀lẹ̀ kàyéèfì tó wáyé lásìkò ààrùn coronavirus Ti isunfunraẹni ba le wa nitori alubọsa, o yẹ ko rọrun fun awọn Musulumi ododo lati takete fun ara wọn ninu Ramadan lasiko arun Covid-19 to wa lode.
àkọsílẹ̀ ìwọ̀n wúrà fún gbogbo ohun èlò wúrà fún ìsìn kọ̀ọ̀kan, ti ìwọ̀n fadaka fún gbogbo ohun èlò fadaka fún ìsìn kọ̀ọ̀kan, 
Kíló fa ìpànìyàn tó tún ń wáyé ní South Africa South Africa: Wọ́n jó ọmọ Nàíjììrà nína láàyè Ẹgbẹ̀rún kan dín máàrún awakusa bọ lọwọ iku ni South Africa 'Ọgbun to wa niwaju aarẹ tuntun ni S/Africa' Ìròyìn sọ pé ọkọ ofurufu náà ti balẹ̀ sí Durban láti alẹ ọjọbọ lẹ́yìn to tààjò dé láti Johannesburg.
”lọdun 2015, pupo lara awon omo
ayọ ni 2020 a ja si.
n ṣọfọ ọjọgbọn Bashua lori ayelujara.
)Imọ ijinlẹ akọkọ: Esi idanwo WAEC/WASSCE, iwe ẹri ọjọ ori, ati iwe ẹri ilu abinibi b.
Mo sì tún sọ pẹ̀lú pé àna bàbá mi obìnrin tí ó jẹ́ ẹ̀gbọ́n ìyá mi náà wà pẹ̀lú wọn.
 gírámà yìí yóò lo òfin ti ó níye láti sàlàyé gbólóhùn tí kò niye .
Ẹwẹ, ile aṣofin agba Naijiria paapa fi si ori itakun agbaye rẹ pe awọn ileewe aladani wà lara awọn ti ijọba yoo ran lọwọ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù ICPC rọ ààrẹ Buharí láti dá àwọn ọ̀gá àgbá ilé iṣẹ́ tọ́rọ́ ṣí mọ́ lórí dúró 20 Bélú 2019 Oríṣun àwòrán, ICPC Alága àjọ tó n ri sí ọrọ awọn tó n lu owó ìlú ni pònpó àti àwọn ẹsẹ̀ míràn ICPC, ọjọ̀gbọ́n Bolaji Owasanoye tí naka ìdọ̀tí sí àwọn fásìtì, ilé iwòsàn ijọba apapọ, àwọn ilé iṣẹ́ ijọba tí wọ́n ń tẹ abá ìsúnà.
Nígbà tí wọ́n parí ayẹyẹ wọnyi, gbogbo àwọn ọmọ Israẹli tí wọ́n wá síbi àjọ náà lọ sí àwọn ìlú Juda, wọ́n fọ́ gbogbo òpó oriṣa, ati gbogbo igbó oriṣa Aṣera, wọ́n wó gbogbo àwọn pẹpẹ palẹ̀ ní gbogbo ilẹ̀ Juda, ti Bẹnjamini, ti Efuraimu ati ti Manase.
Ki ni idi ti Ọjọ Arafa fi se pataki si awọn musulumi?
Bí ọ̀kan ninu wọn ti ń gé igi, lójijì, irin àáké tí ó ń lò yọ bọ́ sinu odò.
Bí onílé tilẹ̀ ń wí pé kí olúwaarẹ̀ jókòó ó yẹ́ kí olúwaarẹ̀ má wí pé òun ń lọ.
Báyìí ni gbogbo wa ṣe gúnlẹ̀ ní alaafia.
Iya ọmọ Ajibola Otubusin ti o jẹ ẹni ọdun mẹtadinlaadọrin ko le pa idunnu rẹ mọ ra, o sọ pe oun ko kọkọ gbagbọ pe oun loyun afi igba to de pe ọmọ bẹrẹ sii ru ninu oun ni oun to gbagbọ.
Oluwaseyi Abiodun Makinde je omo odun méjílélógójì(52), won bi l’ojọ kẹẹdọgbọn oṣu kejila
Atunkọ gangan ni orin ọmọ South Africa, Master KG yii jẹ leyi to ti kọkọ kọ, Jerusalema.
nígbà tí ó ṣe iṣẹ́ abàmì ní ilẹ̀ Ijipti,tí ó ṣe iṣẹ́ ìyanu ní oko Soani.
Ipinlẹ Plateau-39, Kaduna-25, Ogun-13, Bauchi-5, Rivers-4 Ekiti-2, Taraba-2 ati kano-2 pẹlu ko gbẹyin.
Ti o ba gbiyanju lati fi ẹrọ iṣiro rẹ tẹ milionu ọ́ọ́dúnrún le méjilelogun dollar ($322.
O ni o ba oun ninu jẹ lati gbọ irọ ti wọn n pa mọ oun pe oun le Risikat nile nitoripe o loju buluu.
Wàhálà bẹ́ sílẹ̀ lọ́jọ́ Jímọ láàrìn àwọn olùgbé Ilesha Baruba níjọba ìbílẹ̀ Baruteen, ìpínlẹ̀ Kwara àti àwọn ọmọọgun tó n sọ ibode lágbègbè náà.
Mo jáde sí kànga Diragoni, mo gba ibẹ̀ lọ sí Ẹnubodè Ààtàn.
Iyanse-lodi awon osise ijoba ti n fi igba gbogbo waye lorile-ede naa ti o wa ni apa ila-orun ile Africa, eyi ti aisan owo maa n sokunfa re.
“Kò sí ẹni tí ó jẹ́ tan fìtílà, tí ó jẹ́ fi pamọ́, tabi kí ó fi igbá bò ó.
 Àwọn èèyàn tí ìdáhun agbóguntàìsàn wọn ò póṣùwọ ̀ n ( tí ìdáhun agbóguntàìsàn wọn bá kéré sí 10 miu / ml ) gbọ ́ dọ ̀ ṣe àyẹ ̀ wò jẹ ̀ dọ ̀ jẹ ̀ dọ ̀ b , wọn á sí gba abẹ ́ rẹ ́ àjẹsára yìí lẹ ́ ẹ ̀ mẹta ọ ̀ tọ ̀ ọ ̀ tọ ̀ .
Buhari: Mo ní ìrètí pé àwọn ọmọ Chibok yóò padà wálé
Bí òfin tí a kọ sí ara òkúta tí ó jẹ́ iranṣẹ ikú bá wá pẹlu ògo, tóbẹ́ẹ̀ tí àwọn ọmọ Israẹli kò lè ṣíjú wo Mose, nítorí ìmọ́lẹ̀ tí ń tàn ní ojú rẹ̀ fún àkókò díẹ̀, 
Nínú àwọn ọmọ ìya rẹ̀ ni sínátọ̀ tó ṣe ojú Abuja nílé asòfin àgbà nígbà kan rí, Khairat Abdulrazaq-Gwadabe.
Chief Kanran sọ awọn ọrọ yii lasiko ifọrọwanilẹnuwo ti BBC News Yoruba ṣe pẹlu wọn ni ile ijọsin ti wọn n gbe.
Awọn mii laye atijọ nil Yoruba a maa fi kẹtẹ jẹ isu tori o ni ọpọlọpọ ororo lara.
Ninu esi ti rẹ, Iyalọja kaafata ni gbogbo Eko,Folashade Tinubu Ojo ni ẹya kan lo n fi ẹhonu han.
Fifọ ọwọ rẹ pẹlu ọṣẹ ati omi mimọ yoo pa awọn kokoro arun to n gbe ni ọwọ rẹ.
 ""Iwọ lo kọ mi bi wọn ṣe n luwẹ ninu odo ifẹ, wo ibi ti a de bayii latẹyin wa""."
Lọdun 1885 ni Aarẹ Latoosa jade laye.
Minisita fun iroyin ati asa ,
Níwọ̀n ìgbà tí mo wà ní ayé, èmi ni ìmọ́lẹ̀ ayé.
Ẹ kọ gbogbo òfin wọnyi sára rẹ̀, nígbà tí ẹ bá ń rékọjá lọ láti wọ ilẹ̀ tí OLUWA Ọlọrun yín yóo fun yín, ilẹ̀ tí ó kún fún wàrà ati oyin, gẹ́gẹ́ bí OLUWA Ọlọrun àwọn baba yín ti ṣèlérí fun yín.
igbakeji adari alukoro ile ise naa, ogagun Onyema Nwachukwu ni iko omo ogun
" Àwọn ọmọ Naijiria dárò Kimono Ìkú rẹ̀ di kókó ọ̀rọ̀ tí àwọn ọmọ òrílẹ̀-èdè Naijiria sọ̀ nípa rẹ̀ jù lórí Twitter bi ọ̀pọ̀ ènìyàn ṣe ń ṣe'rántí olóògbé náà pe: Àwọn Gómìnà Gúúsù-Ìwọ̀ Oòrùn kéde June 12 Buhari: Sáà kan ṣoṣo loó máa lò látìsinyìí lọ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ọ̀rọ̀ fún àwọn tó ń lo ike rọ́bà Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Njẹ́ orí rẹ làá tí tu'pọ́n
Ilana ayẹwo ti ajọ ajọṣepọ ilẹ okeere, CFR, to wa ni ilu Washington lo n gbe awọn iroyin ijinigbe lawọn iroyin abẹle yẹwo eleyi to fihan pe laaarin ọdun 2014 si 2015 ti agbara Boko Haram le kenka julọ ni iṣẹlẹ ijinigbe pọ julọ.
Àwọn ti wọn ránti, ki ṣe nitori ọrọ̀ ti wọn fi silẹ̀ láyé ni èrò ránti ṣùgbọ́n àwọn ọmọ tó gba ẹ̀kọ́ ni ó lè jẹ ki wọn ṣe iránti wọn àti bi wọn ti lo ọrọ̀ na a fún lati ṣe oore fún àwọn aláìní.
Mo bá ra aṣọ funfun náà, bí OLUWA ti wí, mo lọ́ ọ mọ́ ìdí.
Tọkọ taya kú lọ́jọ́ kan náà l'Abeokuta lẹ́yìn ìgbéyàwó ọdún méjìléláàdọ́rin 72 Kayeefi nla ṣẹlẹ niluu Abeokuta tii ṣe olu ilu ipinlẹ Ogun ni ọgbọnjọ oṣu kẹwaa ọdun 2020.
Ìbànújẹ́ yóo sì gún ọ ní ọkàn bí idà.
Lọ́nà kan tabi lọ́nà mìíràn, ìbáà ṣe pẹlu ẹ̀tàn ni, tabi pẹlu òtítọ́ inú, a sá ń waasu Kristi, èyí ni ó mú inú mi dùn.
Amọ lasiko igbẹjọ ni aarọ oni Maina daku, ti wọn si n gbinyanju lati ji pada sile aye.
TY Danjuma ati ologun Naijiria tako 'rawọn 'Iléeṣẹ́ ológun kò mọ̀ nípa ìkọlù Dapchi' Iléesẹ́ ológun Naìjíríà sọ wipe àwọn ológun ọ̀hún ko ní ku lasán.
Ile iṣẹ ologun sọ pe ohun yoo ṣe amojuto bi eto idibo yoo ṣe waye laarin ọdun meji.
Ìdájọ́ tí wọn yóo gbà yóo le pupọ.
Àbí èmi ati Banaba nìkan ni a níláti máa ṣiṣẹ́ bọ́ ara wa?
”O tun ni awon gomina yoo tun maa sepade lonii “lati mo ohun to wa ninu iwe ilana naa,a o si jiroro nipa re , ki a to fenuko lori ipinnu wa, gege bi gomina.
Itira ará Iṣimaeli ni baba Amasa.
A gbadura arinna kore fun wọn bi wọn ti n lọ.
Ni ti pe ipinlẹ Eko n fa sẹyin lati gbe abadofin Amotekun lọ si ile igbimọ aṣofin rẹ, o ṣalaye pe Ati ni ofin to ju ti Amotekun lọ, tile igbimọ aṣofin ipinlẹ Eko ti fọwọsi ṣaaju akoko yii, orukọ nikan lo yatọ."
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ipenija ojú kò di Ademola lọ́wọ́ láti kẹkọọ gboye Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Wòlíì Àrólé sọ àsọtẹ́lẹ̀ s'áyé BBC ní London Wakati mọkanla ni mo lo lori igi - Dino Melaye / Oṣu keje, 2018 Saaju ki o to kuro ninu ẹgbẹ APC lọ si PDP, ilumọọka oloṣelu to jẹ Sẹnatọ to n ṣoju ipinlẹ Kogi, Dino Melaye ti halẹmọ awọn ọlọpaa wi pe oun yoo pa ara oun si wọn lọrun .
Èkúté kọ̀ọ̀kan dúró fún ọ̀kọ̀ọ̀kan ninu ìlú àwọn ọba Filistini maraarun.
O ṣalaye pe bi wọn ṣe f'ofin de irinajo Hajj ọdun 2020 kii ṣe ẹbi orilẹ-ede kankan, ṣugbọn wọn gbọdọ gba a bi akọsilẹ Ọlọrun .
Sùgbọ́n ìwádìí fi yẹni pé èyí kìí ṣe òòtọ rára nítori pé titèlé gbogbo òfin to le dènà ààrun Corornavirus ṣe patakì.
”“iwe mimo so pe”olorun da wa ni aworan ara-wa;o pase fun wa lati lo ogbon atinuda wa lona ti a o fi mu iyipada rere ba orile ede wa.
Ràn wá lọ́wọ́, OLUWA Ọlọrun wa, nítorí pé ìwọ ni a gbẹ́kẹ̀lé.
Sanwo Olu yan kọ̀míṣọ́nnà 25 àtàwọn olùbádámọ́ràn Mahrez dá Super Eagles dùbúlẹ̀ lórí pápá oko tútù Aago Nàìjíríà ti kún àkúnwọ́sílẹ̀ - Tunde Bakare Àwọn olówó Naijiria 5 tí owó wọn ju owó ìsúnná Naijiria lọ!
’’Aare tun so pe eto idagbasoke ti de ba eto agbe lasiko ijoba re, ni eyi ti o ti sọ ọpọlọpo awon eniyan di olowo.
Ọwọ́ rẹ ni ọ̀rọ̀ yí wà; dìde nílẹ̀ kí o ṣe é.
"Lootọ, idile onigbagbọ ni mo ti jade, imọran awọn eeyan lo mu wọn lọ si oriṣiriṣi ibi ti wọn juwe fun wọn.
Amọ bi wọn ba ti paarọ atọ iru ọkọ iyawo bẹẹ, o le loyun pẹlu atọ ọkunrin miran laimọ.
Gbigbọnju ti mo ba baba mi, Rẹmi Afod ni wọn n jẹ.
Nise lo pariwo mọ mi, o si fẹ ẹ ba ọkọ mi jẹ Oríṣun àwòrán, Alyssa Vincent Photography Àkọlé àwòrán, Diane àti Philippe fẹ́ràn ara wọn púpọ̀ Ọjọ ti a fi ara wa silẹ jẹ ọjọ Abamẹta, mo si lọ fun ayẹwo l'ọjọ Aje to tẹle nibi ti wọn ti sọ fun mi pe mo ni aarun to n ba agọ ara jẹ ti wọn n pe ni Human Papiloma Virus, HPV.
Mo ní kí ẹ má bẹ̀rù rárá, kí ẹ má sì fòyà.
Ewe, ninu ipo ate tuntun ohun lagbaye, orile-ede Germany, Brazil ati Belguim si di ipo won mu ni itele n tele, bee si ni, Russia, Poland ati Uruguay lanfaani lati wa laarin ipo kinni in si ogun.
Obasanjo sọ fún àwọn ọmọ ẹgbẹ́ náà ní Ibadan pé iṣẹ́ ńlá ń bẹ níwájúu wọn o, nítorí ojúbọ̀rọ̀ kò ṣeé gbọmọ lọ́wọ́ èkùrọ́.
9 8324294 Orilẹede India 151918 11.
Rán marun-un ninu àwọn aṣọ títa náà pọ̀, lẹ́yìn náà, rán marun-un yòókù pọ̀.
Oríṣun àwòrán, Twitter Gomina ipinlẹ Ogun, Dapo Abiodun nigba to n fesi nibi to ti lọ ba awọn obi naa kẹdun, ṣeleri pe iwadii ti bẹrẹ lẹkunrẹrẹ lori iṣẹlẹ naa.
Ọ̀pọ̀lọpọ̀ àwọn ìwé sì ni wọ́n ti fi Braille tẹ̀ jáde fún ẹ̀kọ́ àti ìgbádùn àwọn afọ́jú.
Omo ile-igbimo asofin ni orile ede Chana , ogbeni Mahama Ayariga ti so pe orile ede  ti o ba wa ni ajo ECOWAS ni eto lati lati da okoowo sile ni orile ede Chana.
Adeoti ro gomina tuntun ohun lati fi apere isajoba rere lele pelu ogbon, Tobi Sangotola.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Èmi àti Bọla Tinubu fẹ́ lo ‘German Mercenaries’ láti gbé MKO Abiọla kúrò lẹ́wọ̀n - Dele Momodu ‘Pussypedia’ rèé, ojú òpó tó ń mú àdínkù bá ìṣòro ìmọ̀ nípa ẹ̀yà ara obìnrin Àlàyé rèé lórí bí wọ́n ṣe mú mi lẹ́rú ní 1837 - Ajayi Crowther Mo nífẹ̀ẹ́ Khafi torí kìí díbọ́n tàbí hùwà oníwà - Gedoni sọ̀rọ̀ ìdágbére Àwọn alálẹ̀ kò ní forí jìn mí tí ń kò bá ṣe ọdún Ṣàngó - Alaafin O ni awọn oludibo ni Ireland kii beere fun owo, asọ, ororo, irẹsi abi tomato, ohun kan soso ti eeyan gbọdọ se ni lati polongo ibo lọ si ojule kọọkan fun awọn oludibo.
Oríṣun àwòrán, Sreenshot Iṣẹlẹ ẹkun sisun tabi wiwu iwa ti yoo mu ki ara ilu kaanu wọn paapa lati ọwọ awọn oloṣelu tabi awọn to dipo mu kii ṣe tuntun ni Naijiria.
Ẹgbẹ agbabọọlu Lyon ti ilu Faranse lo ṣe iya fun Arsenal, ti wọn si gbe ife Emirate Cup naa mọ Arsenal lara niwaju awọn alatilẹyin Gunners.
Ilé aṣòfin àgbà Nàìjíríà láwọn ṣetán láti buwọ́lù owóyàá $29.
Bakan naa lo tun ṣalaye pe afurasi ọhun yoo ran awọn ọtẹlẹmuyẹ lọwọ lati wa idahun si ọpọlọpọ ibeere ti o n yọju lori iṣẹlẹ naa ati ọgba ajara iṣẹ laabi wọn.
Ọrọ rẹ to tun pa awọn eeyan ni ẹrin ni bi o ti sọ pe ikọ Super Eagles ni ami ayo meji, nigba ti ikọ Naijiria ni ami ayo kan.
Gbajugbaja agbẹjọro ni Buhari ko lọ si awọn ile iwosan yii, ilu oyinbo lo n lọ fun itọju ara rẹ, owo ilu lo si n na.
Ni bayii, apapo ami-ayo mejo sookan(8-1), ni iko  Bayern Munich fi pegede sinu ipele keta si asekagba idije naa.
Lati igbà yi ni ilé-iwé kékeré àti giga, ilé-ìwòsàn àti ohun amáyé-dẹrùn ti Òṣèlú pèsè fún agbègbè wọn ti bẹ̀rẹ̀ si bàjẹ́.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Saudi Arabia Hajj 2020: Alaga Hajj ni Naijiria ni inú wọn kò dùn sí bí Hajj kò ṣe ní wáyé.
Oríṣun àwòrán, @npf Àkọlé àwòrán, Awọn agbofinro kò ni fààyè gba 'see and buy' ni ìdìbò Ọṣun O ni ọkọ̀ ofurufu meji yoo ṣiṣẹ pẹlu ọgbọn ọkọ ayẹta ati ọọdunrun ọkọ ọlọpaa ti yoo maa lọ lati ibikan si ikeji ni wọn ti kó ranṣẹ ṣaaju idibo naa.
Oríṣun àwòrán, @PoliceNG O ni nibi ti ọrọ de duro bayii, ijọba gbọdọ bẹrẹ si ni fi awọn to ba n lọwọ ninu iṣẹlẹ didana sun afurasi tabi idajọ ọwọ jofin, lati lee jẹ ifaleti fun awọn eeyan mii lọjọ miran.
“Ẹnikẹ́ni tí ó bá jí eniyan gbé, kì báà jẹ́ pé ó ti tà á, tabi kí wọ́n ká a mọ́ ọn lọ́wọ́, pípa ni kí wọ́n pa á.
” Ọkunrin náà sì ṣe gẹ́gẹ́ bí Josẹfu ti pàṣẹ fún un.
foruko awon minisita ti yoo baa se isẹ papọ ransẹ si ile igbimo asofin.
omowe Akinwumi Adesina gbosuba fun aare Muhammadu Buhari  lasiko ifọrọwanilẹwo to waye nile aare lọjọ    Isẹgun
Bẹ́ẹ̀ gẹ́gẹ́ ló ṣe rí fún àwùjọ-ẹ̀dá.
Ó rán wọn láti wá ṣe amí ilẹ̀ yìí ni, kí ó baà lè ṣẹgun rẹ.
Wọ́n wá ń foríbalẹ̀ fún un, wọ́n ń sìn ín.
ẹ rí i pé ibi tí ògiri ìlú Dafidi ti sán pọ̀, ẹ sì gbá omi inú adágún tí ó wà ní ìsàlẹ̀ jọ.
 hepatitis c kì í sáábà ní ìmọ ̀ lára-àìlera , sùgbọ ́ n èyí tí ó bá ti wọ ara gan an lè dá ọgbẹ ́ sí ara ẹ ̀ dọ ̀ , tí ó sì lè yí sí àìsàn ẹ ̀ dọ ̀ míràn tí a mọ ̀ sí cirrhosis lẹ ́ yìn ọdún díẹ ̀ .
Akọwé ọ̀hún ní kìí ṣe pé àwọn sọ pe kí ààrẹ fi ipò sílẹ̀ súgbọn àwọn fẹ ki ó fi ara rẹ han gẹ́gẹ́ bíì olórukọ rere tí gbogbo eniyan mọ̀ọ́ sí.
Amọ, ọrọ naa tun daru si nigbati awọn ẹka ijọba ati ile isẹ ologun bẹrẹ si ni fon fere ọtọọto, debi wipe wọn kede pe wọn doola ẹmi awọn ọmọbirin kan lasiko igba ti ko si ẹnikẹni to kọkọ gba wipe ijinigbe waye.
Mo rò pé mò ń jà fún Islam ni, ó pẹ́ kó tó yé mi – Boko Haram tẹ́lẹ̀ Èèmọ̀ rèé o, Dókítà yọ eyín 526 lẹ́nu ọmọ ọdún méje Àlùfàá méjì wà lára àwọn mẹ́rin tó fi ipá bámilòpọ̀"" Ìjọ Satani dá MI lóhùn lórí ọ̀rọ̀ Fatoyinbo Àwọn àmì tó fi mọ̀ pé wọn ń fipá bá ọmọdébìnrin rẹ lòpọ̀ Bakan naa ni akọroyin kan ni South Africa fi fidio kan, to ṣafihan awọn alatilẹyin pasitọ naa nibi ti wọn pejọ si niwaju ile ẹjọ ni Port Elizabeth."
Iku tun to wọ agbo awọn oṣere tiata nilẹ yii naa, nigba ti yoo si fi jade, ọkan lara awọn aṣaraloge (Makeup Artist) lẹka ere tiata Yoruba, lo mu lọ.
Mose bá pàṣẹ fún Eleasari alufaa, ati fún Joṣua ọmọ Nuni ati fún àwọn olórí àwọn ẹ̀yà Israẹli nípa wọn, ó ní, 
' 'Iṣẹ́ akólẹ̀ tí mò ń ṣe níbí, mi ò lè ṣe é láí lái ní Nàìjíríà tórí.
Ni awọn asiko kan sẹyin, ni awọn ajafẹtọ-ọmọniyan maa n tabuku ijọba ilẹ naa lori bi wọn ṣe n dari awọn ologun lọna aitọ ṣugbọn ti wọn ti wa ni ologun ni kalẹ bayii.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Dino Melaye kan sárá sí ààrẹ àná, Jonathan, ó ní irú olóṣèlù rẹ̀ ṣọ̀wọ́n láwújọ 16 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Oríṣun àwòrán, Dino Melaye Gbajugbaja oloselu nni to tun fi igba kan jẹ Sẹnetọ to n ṣoju ipinlẹ Kogi ni ile asofin agba Naijiria ti tọrọ aforiji ni gbangba lọwọ Aarẹ Naijiria ana Goodluck Jonathan.
Wọ́n pé ọdún méjìlá báyìí Ìbálòpọ̀ ọ̀lọ́jọ́ méje mú kí ilé ẹjọ́ tú ìgbéyàwó ọdún mẹ́wàá ká ní Ibadan Rògbòdìyàn bẹ́ sílẹ̀ láàrin àwọn ọlọ́kadà àti àwọn òṣìṣẹ́ ọgbà ẹ̀wọ̀n ní Ibadan Dokita Ugo Ezentirioha sọrọ lori awọn ounjẹ bii ẹja, ẹran, ẹyin ati awọn nkan miran Ẹja Jijẹ ẹja loorẹ koore paapaa eleyii to ni eroja ''Omega 3 fatty acids'' n ṣe atọ ọkunrin loore nipa ṣiṣẹ iranwọ fun bi ẹjẹ ṣe n lọ si ibi atọ ọkunrin.
Ajọ to n mojuto idanwo asejade nileewe girama, WAEC gbẹsẹ le awọn esi idanwo àwọn akẹkọọ kan.
" Ijọba n gbiyanju, a ti ṣe iwọn ti a leṣe lati lka awọn eeyan lọyẹ ṣugbọn wọn o gbagbọ.
ede Naijiria kulẹ lati yan awon adari ti yoo mu ipinnu rere awon omo orile ede
Ẹni tí ó sọ àwọn ọba di ẹni ilẹ̀,ó sọ àwọn olóyè ayé di asán.
Gbé ìtẹ́ àánú náà ka orí àpótí náà, kí o sì fi ẹ̀rí majẹmu tí n óo fún ọ sinu rẹ̀.
Eyi ni wọn ni ko wulẹ wu ọpọ ninu awọn ojiṣẹ Ọlọrun lori rara gẹgẹ bi orilẹ-ede America ṣe n gbiyanju lati koju ipenija onibeji to n ba wọn finra iyẹn ti ajakalẹ aarun Coronavirus lẹgbẹ kan ati ifẹhonuhan to n waye tori oṣelu orilẹ-ede naa.
Bí ojú rẹ bá mú ọ kọsẹ̀, yọ ọ́ sọnù, ó sàn fún ọ kí o wọ ìjọba Ọlọrun pẹlu ojú kan jù pé kí o ní ojú mejeeji kí a sì sọ ọ́ sinu iná, 
Chelsea fún Man United lóúnjẹ ẹ̀tẹ́ jẹ, Cuppy bínú yí jọ̀lọ́ọ̀fù dànù Ohun mẹ́fà tí ọ̀pọ̀ kò mọ̀ nípa ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ Arsenal àti Machester City Real Madrid gbadé ògo La Liga, Messi ní Barcelona ò lè ta pútú mọ́ Ọmọ Yorùbá mẹ́wàá tó jẹ́ àmúlùúdùn ní Amẹ́ríkà àti Yúróòpù Henderson tẹwọ gba ife ẹyẹ naa lọwọ ọkan lara awọn eekan agbabọọlu Liverpool, Kenny Daglish to jẹ akọnimọọgba ẹgbẹ agbabọọlu naa nigba ti wọn gba ifẹ ẹyẹ naa kẹyin lọdun 1990.
Ṣàánú mi, kí n lè wà láàyè,nítorí pé òfin rẹ ni ìdùnnú mi.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ajá dóòlà ọmọ tuntun tí ìyá rẹ̀ bò mọ́lẹ̀ láàyè Ọ̀kan lára àwọn akẹ́kọ̀bìnrin Chibok kàwé gboyè l'Amẹrika Akeredolu, Ọgá NDLEA lọ kọ nípa gbíngbin igbó ní Thailand Amọṣa ọrọ di womi-n-wo ọ nigba ti awọn ẹbi arabinrin naa de ile igbokupamọsi ileewosan nla Ondo state specialist Hospital nilu Akurẹ ni ọjọ abamẹta lati gbe oku ounati ẹjẹ ọrun ti wọn jọ jalaisi naa.
Bela, ọmọ Asasi, ọmọ Ṣema, ọmọ Joẹli, tí wọn ń gbé Aroeri títí dé Nebo ati Baali Meoni.
Divorce: Ilé ẹjọ́ tú ìgbéyàwó ọdún mẹ́tàdínlógún ká nítorí ààlè yíyàn
Femi Gbajabiamila to jẹ adari ile igbimọ aṣoju ṣofin gan ko gbẹyin plu ọrọ ikini rẹ si gomina Oyetola.
Irọ́ ni, abẹ́rẹ́ àjẹsára Covid-19 kò lè ṣàyípadà DNA rẹ Àwọn agbègbè tí àtùndi ìbò yóò kàn lọ́jọ́ Àbámẹ́ta nípìnlẹ̀ Eko rèé O si tun wà nínú ofin ti wọn fi da Amotekun silẹ pe ẹnikẹni ninu awọn ẹṣọ Amọtẹkun to ba dunkoko mọ araalu yoo foju wina ofin.
Ìyàwó: Ọkọ mi kúndùn ìbálòpọ̀ kọjá sísọ lẹ́yìn ìgbeyàwó ogun ọdún
Nítorí náà, kò gba ọ̀nà ibi tí ó gbà wá pada, ọ̀nà ibòmíràn ni ó gbà lọ.
Kòṣẹlẹ̀rí ni Hajj ọdún 2020, wo ìyàtọ̀ tó wà nínú rẹ̀ sí ti tẹ́lẹ̀ Awọn ẹlẹsin ibilẹ naa ni wọn gbọdọ ṣe ẹbọ ati etutu fun oku naa, ki iku naa ma ba jẹ akunfa.
Aye ti n kuro ni pe ki a n ro amala lati ile oninawo, nibayii, gbọngan tabi ori papa ti ayẹyẹ naa ti n waye ni wọn ti n ro amala bayii, ti awọn alejo yoo si maa jẹ ni gbigbona fẹli-fẹli pẹlu ọbẹ ti wọn ba fẹ.
Mo bá bèèrè pé, “Olúwa mi, níbo ni nǹkan wọnyi yóo yọrí sí?
Ajọ Amnesty International ní kò dín ní 119 ọmọ Nàìjíríà ti wọ́n ti gba ìdájọ́ ikú ní Malaysia Taló ya fídíò ibi tí Aisha Buhari ti ń bínú ní Aso Rock?
Amotekun: APC ń fẹ́ káwọn ẹkùn yókù wàwòkọ́ṣe Ikọ̀ àbò àmọ̀tẹ́kùn fún àbò ẹkùn wọn
    “Ìnáwó tí Ayédèrú-ẹ̀dá ṣe fún wa ni àkókò yìí pọ̀ tó bẹ́ẹ̀ ó sì jọ mi lójú tí mo fi pinnu pé òun ni yóò jẹ́ ìgbá kejì mi nígbà tí a ba n lọ sí òkè Ìrònú nínú igbó Elégbèje.
Kí àwọn òkè ńláńlá àtijọ́ so ọpọlọpọ èso dáradára,kí ọpọlọpọ èso sì bo àwọn òkè kéékèèké.
kí àwọn ọmọ Israẹli tí wọ́n ti ń sá lọ yipada, kí wọ́n sì bẹ̀rẹ̀ sí jagun.
Adajọ paṣẹ $25,000 fun oloyun ti wọn fiya jẹ Ohun ta gbo ni pe ọrẹbinrin ni wọn n ja si.
Ìwọ̀n wúrà tí ó lò fún ọ̀kọ̀ọ̀kan jẹ́ ọọdunrun (300) ṣekeli.
Sheffield ti wa ni ipo kẹfa lori tabili idije Premier League bayii, nigba ti Chelsea si wa ni ipo kẹta.
Ninu atẹjade naa, FBI sọ pe ẹsun kiko owo pamọ lọna aitọ, ni wọn fi kan an.
Ọkọ̀ àjàgbé agbépo kan tún dànù l'Eko Ìjọba gbé ilé ijó oníhòhò tì pa lórí ẹ̀sùn títàpá sí ìlànà àti dẹ́kun coronavirus Coronavirus: ''Ìjọba kò tíì pàṣẹ ìlànà ìtakété-síra-ẹni padà nínú BRT la ò ṣe máa tẹ̀le'' Àwọn tó jí àwọn akẹ́kọ̀ọ́ GSSS gbé ní Kankara ti kàn sí wa - Masari Igbesẹ yii waye pẹlu bi ajakalẹ arun naa tun ṣe n dabi ẹni to tun fẹ maa gbẹrẹgẹjigẹ sii.
Ọ̀run ati ayé yóo kọjá lọ, ṣugbọn ọ̀rọ̀ mi kò ní kọjá lọ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Komisana ilera ni Ondo: Eku ọlọmu pupọ lo nfa iba Lassa 4 Èrèlè 2018 Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fọ́nrán ohùn, Eku ọlọmu pupọ lo nfa iba Lassa Gomina Oluwarotimi Akeredolu ti ipinlẹ Ondo ti sọ pe lootọ ni aisan iba Lassa ti wọ ipinlẹ naa, o si ti mu ẹmi eniyan mẹsan Bakan naa, Komisana fun eto ilera ni ipinlẹ naa, Dokita Abdulwahab Adegbenro nigba ti o mba ikọ iroyin BBC Yoruba sọrọ wipe aisan iba Lassa yii wọ awujọ wọn ni nkan bi ọsẹ melo kan sẹyin.
Isele naa waye leyin ti orile-ede ohun n reti aare orile-ede Indonesia, Joko Widodo, lati sabewo sorile-ede naa fun ijiroro bi Alafia yoo se joba lAfghanistan.
Ní ọjọ́ kan, Dina, ọmọbinrin tí Lea bí fún Jakọbu jáde lọ kí àwọn obinrin kan ní ìlú Ṣekemu.
Nígbà tí ìwọ bá sì dé náà ń kọ́, máṣe máa bọ̀ nínú ilé mi tààrà, ki àbùkù má ba kàn ọ, ṣùgbọ́n kàkà bẹ́ẹ̀, bí ìwọ dúró lẹ́yìn òde títí èmi yóò fi rí ọ, nígbà tí mo bá rí ọ tán, tí mo bá sì mú ọ wọle, máṣe gbàgbé láti kí baálé mi pẹ̀lú ìrẹ̀lẹ̀, nítorí bí ìwọ kò bá ṣe eléyìí nì, bí ìwọ bá gba ojú ọ̀nà wọlé, ojú fèrèsé ni ìwọ yóò gbà jáde.
Benhadadi bá wí fún un pé, “N óo dá àwọn ìlú tí baba mi gbà lọ́wọ́ baba rẹ pada fún ọ, o óo sì lè kọ́ àwọn ilé ìtajà fún ara rẹ ní ìlú Damasku gẹ́gẹ́ bí baba mi ti ṣe ní ìlú Samaria.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Owo nla ni gilasi oju foonu ti ki fọ jẹ fawọn ile iṣẹ to ba le pese wọn Ile iṣẹ kan ti orukọ rẹ n jẹ Akhan Semiconductor dunadura pẹlu Huawei nipa bi wọn yoo ti ṣe lo gilasi oju foonu wọn to lagabara daada.
Ẹ̀yin tí ẹ fi owó ẹ̀jẹ̀ kọ́ Sioni, tí ẹ sì fi èrè ìwà burúkú kọ́ Jerusalẹmu.
Ṣugbọn ẹni tí kò bá gbé e ní iyawo ni ó ṣe ohun tí ó dára jùlọ.
Serubabeli, ọmọ Ṣealitieli, ati Jeṣua ọmọ Josadaki, ni wọ́n bẹ̀rẹ̀ rẹ̀, pẹlu àwọn arakunrin wọn yòókù, àwọn alufaa, àwọn ọmọ Lefi, ati àwọn tí wọ́n ti ìgbèkùn pada sí Jerusalẹmu.
Ó bá wí fún wọn pé, “Tí ó bá rí bẹ́ẹ̀, ẹ fi ohun tí ó bá jẹ́ ti Kesari fún Kesari, kí ẹ sì fi ohun tí ó bá jẹ́ ti Ọlọrun fún Ọlọrun.
 o bori ni berlin marathon lemerin leralera ati dubai marathon lemeta leralera .
ní Ọjọ ́ kẹtàdínlógún oṣù kẹta Ọdún 1865 , booth sọ fún àwọn ọlọ ̀ tẹ ̀ ẹlẹgbẹ ́ rẹ ̀ pé lincoln máa wá wo eré ìtagé ,  still waters run deep "" , ní Ìlé Ìwòsàn olófun ti campbel ."
Sugbọn ipo naa ko jamọ oun ati Tonye Cole to fẹ ẹ di gomina lọwọ.
Ṣugbọn àwọn ará Edomu dáhùn pé, “A kò ní jẹ́ kí ẹ gba ilẹ̀ wa kọjá, bí ẹ bá sì fẹ́ kọjá pẹlu agídí, a óo ba yín jagun.
Báyìí ni mo ń ṣe tí mo ń lo ìba àǹfáàní díẹ̀ tí mo ní tí mo sì ń bá ìgbésí-ayé mi lọ.
Theresa May: A ó fún Nàìjíríà ní £70-million láti pèsè isẹ́
Yóo kọrin fún mi bí ó tí ń ṣe ní ìgbà èwe rẹ̀, nígbà tí ó ṣẹ̀ṣẹ̀ ti ilẹ̀ Ijipti dé.
Jamilu salaye pe, ''wọn mu Sanusi ni iṣoju iyawo rẹ lọjọ abamẹta.
Awọn onimọ naa sọ pe iho ọhun wa nitosi ibi ti Bibeli sọ pe iyawo Lọọti di ọ̀wọ́n iyọ̀ si.
Ọjọgbọn Adesoji ni, ninu gbogbo ibo ẹgbẹrun lọna ogoji ati ojilelẹẹdẹgbẹrun o din mẹwa (40, 930) ti wọn di, ẹgbẹrun lọna mọkandinlogoji ati ẹgbẹta din ẹyọ kan (39,599) lo jẹ ibo to yanju ninu rẹ, nigbati ibo ojilelẹẹdegbeje o din mẹsan (1,331) si jẹ asadanu.
òṣèré àti ọ̀jọ̀gbọ́n Tiatia, Ayo Akinwale jáde láyé Ayo Fayose, Afẹnifẹre, Ndigbo, Arewa dasi ọrọ Buhari ati Obasanjo Lara awọn to kọkọ fesi ni Gomina ipinlẹ Ekiti tẹleri, Ayo Fayose ni bi o tilẹ jẹ pe oun ko fi igba kan gba ti Obasanjo, otitọ ọrọ gbaa ni Baba Obasanjo sọ.
K Odukoya 'ń gun orí òkè àdúrà nítorí COVID-19'-Wò báwọn èèyàn fi wò wọ́n Ọwọ́ tẹ̀ èèyàn 65 tó tàpá sí òfin gbéléẹ níbi ayaẹyẹ ọjọ́ ìbí Oluwadamilola ni òun kò mọ ibi tí bàbá òun ti rí ẹ̀bùn tó ni àmọ́ ó fikùn pé, àwọn ẹ̀bùn rẹ náà kasiara, tó sì tún ya ní lẹ́nu pupọ.
Islam , ojuse wa ni lati maa fi gbogbo igba wa alaafia agbegbe ati ileto wa lorile
Nigba ti mo n dagba lorilẹ-ede Canada, iṣoro ti mo ni ni bibori ẹ̀rù lati igba ti mo wa ni bi ọmọ ọdún maarun si mẹfa.
OLUWA ní:“Jerusalẹmu, ìwọ ẹni tí a pọ́n lójú, tí hílàhílo bá, tí a kò sì tù ninu,òkúta tí a fi oríṣìíríṣìí ọ̀dà kùn ni n óo fi kọ́ ọ,òkúta safire ni n óo sì fi ṣe ìpìlẹ̀ rẹ.
Yatọ̀ fún orí ìtàgé, wo ohun tí o kò mọ̀ nípà Mr Latin Ọba Lamidi Adeyẹmi, òṣìṣẹ́ adójútòfò àti Abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò kó tó jọba Taló ya fídíò ibi tí Aisha Buhari ti ń bínú ní Aso Rock?
Bí a bá mú òfin kúrò, ẹ̀ṣẹ̀ di òkú.
 Ìwà yìí sì ran mohammed .
Bakan naa ni wọn n se iwọde lati ke si ijọba pe ko fi opin si awọn ọlọpaa to n gbogun ti iwa idigunjale, taa mọ si SARS, ti wọn n yọ wọn lẹnu.
Ṣebí baba kan náà ló bí wa?
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Online Match Making: Ṣé aburú wà lórí yíyan ọkọ àbí aya lórí ayélujára?
Adajọ sun igbẹjọ si ọjọ ẹti, osu keji, ọdun yii fun itẹsiwaju igbẹjọ naa.
Nítorí náà, mo ti dákẹ́ jẹ́ẹ́.
"Iṣẹ́ fẹ́ bọ́ lọ́wọ́ ọlọ́pàá tó gba N100k lọ́wọ́ awakọ̀ tó gba""One way"" l'Eko Ẹ jọwọ, ẹ ba mi bẹ ìyàwó mi kí ìgbéyàwó mi ma baà túká - 9ice Oríṣun àwòrán, Lagos Police Command Ó sàlàyé pé ni kété ti Mohammed gbọ́ nípa ǹkan ti ọ̀rẹ́bìnrin rẹ̀ nígbà kan ri Jemila fẹ́ ṣe ló sáre lọ si ilé rẹ̀, sùgban ẹ̀pa kò bóró mọ́ nígbà ti yóò fi débẹ̀, ilé rẹ̀ ti múná."
Joe: The Rise of Cobra, The Mummy Returns ati Suicide Squad.
“Ọjọ́ ń bọ̀, tí ń óo bá ilé Israẹli ati ilé Juda dá majẹmu titun.
Ọjọ ori awọn ọmọ naa wa laarin ọdun mẹta si mejila.
Ayipada naa le tete ṣẹlẹ, eemi le di iṣoro, ki ọna ọfun sibẹrẹ si ni dun eniyan.
Mo pinu láti dá Iphone tì mo mú padà kí ọlọ́pàá tó mú mi Ẹ gbọ́ Ohun tí Desmond Elliot àti Mojisola Alli-Macaulay sọ lórí ayélujára táwọn ọmọ Nàìjíríà fi ìbínú Àwọn olóṣèlú Nàìjíríà márùn ùn tó sọ̀rọ̀ tí ará ìlú fà ìbínú yọ Gómìnà Sanwo-Olu dẹ okùn ìséde l'Eko, ó gbé ìlànà tuntun jáde Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Fídíò, Akomolede àti Asa lórí BBC Yorùbá: Mọ̀ síi nípa ẹ̀kún ìyàwó níbí3 Bélú 2020 Fídíò, Soyinka Cancer: Àṣe ara mi ni iso ti n run gbogbo bí mo ṣe n ṣèrànwọ́ lórí jẹjẹrẹ27 Bélú 2019 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Ṣé lóòtọ́ ni pé ẹ̀wà jíjẹ máa ń jẹ́ kí èèyàn ga?
''Koda ọkunrin ti mo n fẹ tẹlẹ atawọn obi rẹ naa sọ pe ko le fẹ oṣere,'' Victoria lo ṣalaye bẹẹ.
AMAA 2018 Ami eye fun ere bebi to dara ju
Èmi OLUWA àwọn ọmọ ogun ni mo sọ bẹ́ẹ̀.
"Ologbondiyan ni "" ó ṣe pàtàkì ki ààrẹ Buhari mọ̀ pé kìí ṣe àwọn ará Abuja nìkan ló kọ̀ ọ́, bíkòṣe ogúnlọ́gọ̀ àwọn ọmọ Nàìjíríà ti wọ́n dibo fún ẹgbẹ́ òṣèlú PDP, kí óto di pe àjọ elétò ìdìbò yí ìpinu àwọn ara ilú padà."
Sáájú ni àjọ PPPRA ti sọ pé oṣooṣù ni àwọn yóò maa kéde iyé ti wọ́n yóò ma tepo lábẹ́lé ni Naijiria.
Afi bii ẹni pe eyi ko tun to, se ni awọn osisẹ asọbode naa tun fikun iya naa.
apapo ti fọwọsi owo to le ni bilionu mẹ́sán án naira (N9.
Oko yii ju eeka ilẹ kan lọ, ti awọn oku to to mẹẹdogun si na silẹ gbọọrọ lai si asọ ni ara wọn, koda, wọn gbe awọn miran sinu ago onirin tabi onike, tawọn miran si wa ninu saare ti ko jin rara, amọ gbogbo wọn ni wọn n fi ara gba awọn eroja sayẹnsi kan.
ọmọ Tahati, ọmọ Asiri, ọmọ Ebiasafu, ọmọ Kora, 
Lojoojumọ, wọn á máa gbé e wá sí ẹnu ọ̀nà Tẹmpili tí à ń pè ní “Ẹnu Ọ̀nà Dáradára,” kí ó lè máa ṣagbe lọ́dọ̀ àwọn tí ń wọ inú Tẹmpili lọ.
Orúkọ ọ̀kan ninu wọn yóo máa jẹ́ ìlú Oòrùn.
Oró agbọ́n leè wo àìsàn jẹjẹrẹ ọmú sàn, wo ohun tí wàá lò pọ̀ mọ́ra wọn Ara ló ń ta àwọn ẹgbẹ́ NURTW tó ń pariwo mi kiri, APC ni wọ́n bá lọ nígbà náà l'Oyo- Auxiliary Alaga ijọba ibilẹ idagbasoke Ogbomoso Central, Adeyinka Remi Oluwaseun, sọ fun BBC pe oun ti gba obinrin naa siṣẹ nileeṣẹ ijọba.
Awọn ti ọrọ ṣe oju wọn ni awọn oloogbe naa wa ninu ile kan ti wọn n duro de ojo naa ko da ni ara ba wọ inu ile naa.
Òkú ọmọ ọdún mẹ́ta tó kó sí kàǹga ní Ipaja ni wọ́n yọ' Ó ṣéeṣé ká fí owó kún #500,000 owó móríya ti a fi ń wá Sunday Shodipe- Ilé iṣẹ́ ọlọ́pàá Àwọn ohun tí ẹ nílò fún àyẹ̀wò ìgbanisíṣẹ́ ọlọ́pàá tí yóò bẹ̀rẹ̀ ní ọ̀la rèé Orí àkìtàn ni wọ́n ti rí ọkùnrin tó ń fi ìgbẹ́ jẹ Búrẹ́dì -Iléeṣẹ́ ọlọ́pàá Oyo Bí mo ṣe mórí bọ́ nínú ọkọ̀ bàálù tí kò bá já - Aisha Buhari Nigba to ba BBC sọrọ lọdun 2018, ọgbẹni Blom sọ pe ko si aṣiri kan gboogi si ẹmi gigun oun.
o se ni laaanu pe awon onibara to n sanwo ina deede lo n jiya ina to n se seke-seke nitori pe won ni lati sanwo ina ti awon kan ko san tabi ti won n jale ina ti awon kan  n lò.
O kẹkọ gboye imọ ijinlẹ ninu Ìtàn ati Ọ̀na ibaṣepọ agbaye ni Fasiti Eko ati ti Ifẹ (OAU).
Bakan naa lo fi da awọn eniyan Maiduguri ati awọn aṣatipo loju pe ijọba ti fi kun eto aabo ẹkun yii lati dena iru iṣẹlẹ bayii.
Ṣugbọn, mò ń kìlọ̀ fun yín dáradára lónìí pé, bí ẹ bá gbàgbé OLUWA Ọlọrun yín, tí ẹ̀ ń sá káàkiri tọ àwọn oriṣa lẹ́yìn, tí ẹ sì ń bọ wọ́n, píparun ni ẹ óo parun.
Àwọn Farisi tún bi ọkunrin náà bí ó ti ṣe ríran.
Àyọrísí gbogbo èyí ni pé kí àwa Juu tí a kọ́kọ́ ní ìrètí ninu Kristi lè yìn ín lógo.
Libya Explosion: Èèyàn 44 ló bá ìṣẹ̀lẹ̀ náà rìn lápapọ̀
Igba akọkọ ree ti ẹnikankan labẹ ijọba yoo gba pe ibọn ba Jimoh Isiaq.
Ẹ̀yin tí ẹ bẹ̀rù OLUWA, ẹ máa yìn ín!
Aarọ Ọjọru (oni) ni iroyin kan wi pe awọn ajinigbe da ọkọ elero mejidinlogun kan duro ni ọju ọna Akurẹ si Ado-Ekiti, ti wọn si ji awọn mẹwaa ninu ero inu ọkọ naa gbe.
Ọ̀gá rẹ̀ ṣàkíyèsí pé OLUWA wà pẹlu rẹ̀, ati pé OLUWA ń bukun ohun gbogbo tí ó bá dáwọ́lé.
Oyinkan Abayomi, akọni obìnrin tó fi ìfẹ́ pa orúkọ ọkọ kejì dà sí ti ọkọ àárọ̀ Wo iye àwọn tí wọ́n ti gbà sí ikọ̀ SWAT báyìí àti òfin ti wọ́n fún wọn Ọ̀rọ̀ ìjókòó ìgbìmọ̀ ìwádìí #EndSARS náà dé ìpínlẹ̀ Ogun Àwọn ọ̀dọ́ dáná sun ọkọ̀ akérò tó ṣekúpa ọlọ́kadà ní Ibadan Ẹni ọdun marundinlogoji na fi ẹyin Alan Shilepsky gbolẹ, eyii to jẹ ọmọ ẹgbẹ oṣelu Republican, ati Lisa-Delgado ti Green Party.
Ati pe, o ṣe pataki lati fọ ounjẹ wọn daada ki wọn o to se e nitori pe jijẹ ounjẹ ti 'sniper' wa lara rẹ le fa oju fifọ, gìrì, eebi, ìgbẹ́ gbuuru, to fi mọ jẹjẹrẹ tabi ko tilẹ pa ẹni naa.
O ni aṣọ yii wa lara aṣọ to wọn julọ ti onkọrin takasufe yii wọri.
Wabba ṣalaye siwaju pe igbesẹ yii di dandan nitori pe oriṣiiriṣi ipele ọna sisan owo oṣu oṣiṣẹ ni Naijiria n lo ti afikun owo oṣu yii si gbọdọ kari.
Oríṣun àwòrán, others Ìjọba ìpínlẹ̀ Eko ti kéde orúkọ àwọn ọlọ́pàá tó fi ìyà jẹ àwọn olùwọ́de End Sars Àjọ elétò ìdìbò kéde ọjọ́ tí ìdìbò aàrẹ Nàìjíríà 2023 yóò wáyé Ìyá gómìnà Seyi Makinde dágbére fáyé lẹ́ni ọdún 81 Àbádòfin ìṣúná 2021 ré kọjá ìpele ìkejì nílé aṣòfin àgbà Oríṣun àwòrán, TWITTER/ Àwọn ìṣẹ̀lẹ̀ mánigbàgbé tó wáyé nibi ìwọ́de ENDSARS Nàìjíríà Iwọde ENDSARS to n lọ lọwọ ni Naijiria jẹ eleyi to milẹ titi.
Wọn fi ẹsun kan iṣakoso rẹ fun obitibiti biliọnu Naira ti wọn fi kọ ile ẹkọ DSS ni ipinlẹ Katsina; kikuna lati jẹ ki olubadamọran lori eto aabo Naijiria nigba kan, Sambo Dasuki, wa sile ẹjọ lati jẹri lori awọn ẹsun to ni i ṣe pẹlu iwabajẹ.
Tìmùtìmù ìrọ̀rí-i rẹ̀-ẹ́ jẹ́ ti ẹ̀gbọ̀n òwú olόwó iyebíye; bẹ́ẹ̀ ni itẹ́lẹ̀-ẹ rẹ̀ dàbí àrán ọba pàtàkì.
Ìjọba Èkó figbé ìkìlọ̀ ta Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Lílo òógùn apakòkòrò fún oúnjẹ l'éwu Ẹ wo báwọn òṣèré tíátà kan yóò ṣe rí lọ́jọ́ ogbó Àṣìta ìbọn pa èèyàn kan lásìkò tí SARS ń kojú adigunjalè l'Eko Ọga Aṣọbode ọhun sọ pe ko ṣeeṣe fun ajọ naa lati ṣe iwadii iroyin naa nitori pe wọn ko sọ orukọ ọkọ oju omi to gbe e wọle tabi ọjọ ti wọn gbe e wọle.
Ó sì rán àwọn kan ninu àwọn ọdọmọkunrin Israẹli, pé kí wọ́n lọ fi mààlúù rú ẹbọ sísun ati ẹbọ alaafia sí OLUWA.
Michael Oluronbi Oríṣun àwòrán, West Midlands Police Àkọlé àwòrán, Ilé ẹjọ́ birmingham Crown Court ju Micael Oluronbi àti Juliana Oluronbi sẹwọn ọdún mẹ́rìnlélọ́gbọ̀n Pásítọ̀ ìjọ kan ni Birmingham àti ìyàwọ rẹ̀ ló rí ẹ̀wọ̀n ọdún mẹ́rìnlélọ́gbọ̀n he nínú oṣù kíní ọdún 2020, lẹ́yìn ti ọkan lára àwọn ti ọkọ́ ti fipa bálòpọ̀ ní ọdún 1989 jáde láti fi ẹsùn kan pásìtọ̀ náà.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìtàn mánigbàgbé: J.
Iléẹjọ́ òṣìṣẹ́ tún dáwọ́ ìgbẹ́jọ́ Onnoghen dúró lọ́dọ̀ CCT Àwọn ọmọ Nàìjíríà tahùn sí SERAP lórí ẹjọ́ Onnoghen Èrò àwọn ènìyàn sọ̀tọ̀ọ̀tọ̀ lórí ẹ̀sùn Onnoghen ‘Ayédèrú ìròyìn ni pé EFCC yabo ilé mi’ Iwe Iroyin Cable ni ọkan lara awọn ọmọ igbimọ naa ti wọn tu kẹkẹ ọrọ yi ni awọn ko ni jẹ ki adajọ agba Onnoghen tabi adele rẹ ti ijọba ṣẹṣẹ yan kopa ninu ipade naa.
Awọn onimọ oogun ṣalaye pe to ba ti di pe ẹjẹ ruru n lọ soke lai wa silẹ rara, o le ṣakoba fun ọkan eniyan.
Ti a ba wo eto idibo ti o waye lojo-keje osu keta odun ati eyi ti o waye lojo-Abameta, a o ri iyato pe, awon eniyan ko jade to, ni eyi ti awon oludibo n saroye pe, bi awon ologun ati olopaa se duro sibi ipago idibo naa n deru ba won lati lo dibo, ijoba so pe, ohun ti ko awon omo-ogun eleto-abo kaakiri, latari awon isele laasigbo to n waye lasiko eto idibo akoko ati elekeji.
Ijọba ilẹ naa ti wa ni oun yoo sa gbogbo ipa oun lati ri pe gbogbo awọn to ba lo gbajuẹ fun ọmọ ilẹ wọn ko ni lọ lai fi oju wina ofin.
Oludari agba ajọ NNPC, Ọmọwe Maikanti Baru ninu atẹjade kan ṣalaye pe oun ti paṣẹ fun ọkan lara awọn ẹka ajọ naa to n ṣamojuto ọpa epo ati kiko epo pamọ, NPSC lati tete lọ tu iṣu de isalẹ ikoko ọrọ naa ki wọn lee mọ ohun to ṣokunfa ijamba ina naa.
Ẹ padà sílé èyin ọmọ wa tó n ṣiṣẹ́ darandaran - NEF ti Fulani Buhari ti buwọ́lu ẹ̀kúnwó sísan owó oṣù tuntun fáwọn òṣìṣẹ́ àpapọ̀ Ẹgbẹ́ àwọn òṣìṣẹ́ TUC fárígá sí ìjọba Naijiria lórí owó oṣù tuntun Super Eagles gba iṣẹ́ lọ́wọ́ Seedorf olùkọ́ni Indomitable Lions Cameroun Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí kan sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
Emmanuel Oluwaniyi to jẹ ọga agba awọn ẹlẹwọn ati Hemeson Edson Edwin to jẹ dokita to n mojuto ilera awọn ẹlẹwọn ni EFCC sọ pe, aje iwa ibajẹ ṣi mọ lori.
Osun Cabinet: Kí ló fàá tí gómìna ìpínlẹ̀ osun kò fi yan kọmíṣọ́nà lẹ́yìn oṣù mẹ́sàn án?
20 Òkùdu 2019 Oríṣun àwòrán, @ElgivaStephen Ileeṣẹ to n ṣe ayẹwo ọkọ nipinlẹ Eko, VIO ti sọ pe lẹyin ọlọpaa, oun nikan lofin orilẹede Naijiria ati ti ipinlẹ Eko fun laṣẹ, lati da ọkọ duro fun ayẹwo loju popo laisi pe irufẹ ọkọ bẹẹ ṣẹ ṣaaju.
Tí ó dàbí ìgbà tí kàkàkí bá ń dún, tí ó ń bá mi sọ̀rọ̀.
Àwòràn ọdún egúngún ilu Ìwó jẹ́ àwòpadà-sẹ́yìn
Bawo ni ọrọ naa ṣe ri lara Anthony Joshua?
"Ọdún Kérésì di kọ̀ọ̀ l‘Eko, ìjọba dènà Kánífà òpin ọdún, ayẹyẹ ṣíṣe àti òde fàájì Ẹ́ tú èékánná lọ́rùn Sowore, ẹ kò ní ẹ̀rí láti ba ṣẹjọ́ - Ẹgbẹ́ Amòfin Amẹ́ríkà O ni ""oni yii ni a n ṣiṣọ loju eegun ohun ti Barrister fi gbogbo aye rẹ ṣe, to si tun jiya le lori fun gbogbo agbaye lati mọ pe orin Fuji ti wa orisun rẹ̀ ri."
Ohun tí a ti ṣe tẹ́lẹ̀ náà ni a óo tún máa ṣe, kò sí ohun titun kan ní ilé ayé.
 aare orile ede Naijiria Muhammadu Buhari, igbakeji aare Yemi Osinbajo,akowe fun ijọba apapo, Boss Mustapha; ati awon gomina ana ati awon gomina to wa lori ipo,awon asoju sofin egbe APC ana ati awon to tun wa lori ipo pelu.
Ìtàn Mánigbàgbé: Lúwòó Gbàgídà ló bí Adékọ́lá Telú tó tẹ ìlú Ìwó dó
1999, o tun kopa fun iko agbaboolu Sparta Prague lọdun 2001 ati iko Rennes .
Ṣe ni awon ara ilu Austria gbaruku ti wọn, ko da wọn ba wọn kopa ninu iwọde t'ohun tilu tifọn to n ṣagbega ede ati aṣa Yoruba.
Taye Currency ní ọmọ ibàdàn tí Saheed Oṣupa jẹ́ kò lè já òun gbà lẹ́yìn Pasuma
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ sí: NYSC ní Adeosun kòwé ransẹ́ láti gbààyè Gọngọ a sọ bí Belgium yóò ṣe kojú France Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, CUPP: JJ Ọmọjuwa sọ ohun tí ìdàpọ̀ àwọn ẹgbẹ́ yìí yóò jẹ́ Àyẹwò ihuwasi ẹni tó fẹ gbà iṣẹ Abala kéjìlélógóje òfin orílèèdè Naijirià fún Ààrẹ lágbára láti yan èèyàn sípo yálà gẹgẹ bí Mínísítà tàbí fún ipò míràn.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Afro Brazilians: ìlú Rio ni a máa kọ ilé ìṣẹmbáyé náà sí Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Dan Foster jẹ atọkun redio to dantọ tó si ṣi ọna fun ọpọ sọrọ-sọrọ lori redio ni Naijiria.
Gani Adams: Àwọn agbébọn ń jí ọmọdé, àwọn obìnrin, ti wọn sì ń dúnkookò mọ ọrọ̀ aje Oke Ogun
Abdullahi Mukhtar to jẹ alaga ajọ to n moju to irinajo Hajj sọ pe, o di dandan fun gbogbo ọmọ Naijiria to ba fẹ rinrinajo ọun lati san owo naa, eyi si yato gbedengbe si owo ti arinrinajo kọọkan yoo san gẹgẹ bi owo irinajo eyi ti ijọba apapọ ko tii kede fun ọdun 2018.
A si maa n rọ awọn araalu lati fi to wa leti ti awọn ajinigbe ba kan si wọn, ṣugbọn o ṣeni laanu pe mọlẹbi awọn ti wọn ba ji gbe kii ṣọ fun wa lasiko ti wọn ba kan si wọn tabi san owo itusilẹ.
Àkọlé àwòrán, Mustapha Kolo ní òògùn oníhóró náà máa sèrànwọ́ tóun bá wà nínú igbó láti bá Boko Haram ja Ní ìlú tí kò fararọ yìí, ẹgbẹ̀lẹ́gbẹ̀ èèyàn ni òògùn olóró Tramadol ti di bárakú fún - àwọn ẹ̀sọ́ fijilante, àwọn tí ogun le nílé àti àwọn adúnkookò gan fún ra wọn.
Awọn kan ro pe ọjọ ori Ronaldo le ma gba laye lati fakọyọ fun ikọ Juventus fun igba pipẹ.
Nigba ti awọn agbofinro maa wa alufaa naa ri ni oṣu meji lẹyin rẹ, oku rẹ to ti jẹra ni wọn ri.
A rí àwọn olóyè bí Ọbaálá, Rísàwẹ́, Ọ̀dọlé, Léjòfi Sàlórò Àrápatẹ́ àti Ọbádò ni Ìjẹ̀bú-Jẹ̀ṣà bí wọ́n ti wà ni Iléṣà.
Brinley Pallo to jẹ ẹnikeji Reynold ti wọn jọ huwa buruku yii lo tun jẹri lodi si Reynold nile ẹjọ pe o ṣoju oun.
" Bakan naa lo sọ pe ileeṣẹ ọlọpaa ti pari iwadii lori ọrọ wọn, wọn si ti gbe wọn lọ sile ẹjọ.
tẹsiwaju ni fasiti ilu Ibadan, ki o to tun lo tesiwaju nile iwe giga fasiti British
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Nigerian Police: Àgbègbè odogbolu ní ìpínlẹ̀ Ogun ní ìṣẹ̀lẹ̀ náà ti wáyé 5 Èrèlè 2018 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 29 Owewe 2020 Oríṣun àwòrán, AFP Àkọlé àwòrán, Minisita feto ẹkọ tẹlẹri, Iyabo Anisulowo lo ọsẹ kan ni ihamọ awọn agbenipa naa n'ipinlẹ Ogun Ileeṣẹ ọlọpaa nipinlẹ Ogun ni awọn ti mu ọkọ ati iyawo pẹlu awọn meji kan ti wọn bẹ ori oku nipinlẹ Ogun.
ajo UNESCO, ti o je ikorita ijosin fun awon elesin kristiani, ti o si tun je
Aare Trump ninu oro re daba pe ki won sun ojo ori eni to le lo ibon kuro ni omo odun mejidinlogun si mokanlelogun ki won si maa se iwadii to ye nipa igbesi aye eni to ba fe ra ibon ki won to fun un niwe ase lilo ibon.
APC, PDP, CUPP - BBC News Yorùbá BBC News, YorùbáFò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Nigeria 2019 Election: 'Àwa yóò ṣì polongo ìbò di Ọjọ́bọ̀' - APC, PDP, CUPP 18 Èrèlè 2019 Oríṣun àwòrán, Reuters Àkọlé àwòrán, Awọn oludibo Niwọn igba ti ajọ INEC ti sun ọjọ idibo siwaju, awọn ẹgbẹ to n dije ninu idibo gbogbo gbo ọdun 2019 ni Naijiria ti ni awọn ko ni tẹle aṣẹ ajọ INEC to ni ki ipolongo wa sopin ni ọjọbọ ọsẹ to kọja.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Coronavirus: Àjọ bọ́ọ̀lù ní France sún ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ PSG àti Strasbourg síwájú nítorí Coronavirus 7 Ẹrẹ̀nà 2020 Oríṣun àwòrán, Getty Images Ibanujẹ ba awọn ololufẹ ere bọọlu ni liigi orilẹede France, atawọn ololufẹ Ligue 1 pẹlu bi awọn alaṣẹ Ere bọọlu lorilẹede naa ṣe sun ifẹsẹwọnsẹ laarin ikọ ẹgbẹ agbabọọlu Paris Saint Germain, PSG ati Strasbourg siwaju nitori ọwọja arun Coronavirus nibẹ.
''Ọrọ ti Aarẹ Buhari ba sọ yoo fi ọkan awọn eniyan balẹ, eleyii ti aarẹ fi faye gba ipaniyan ati biba dukia awọn eniyan jẹ.
Ọpọ oju ninu ere oniṣe Naijiria bii Adesuwa, Genevive ati bẹẹ bẹẹ lọ ni wọn ti sin jẹ ti wọn fi sọ ara wọn di adẹrin-poṣonu.
Lẹyin ti Trump ati aya rẹ, Melania, ni aarun naa l'ọsẹ to kọja, oludamọran fun ile ijọba, Stephen Miller, ati ọga ologun kan, ti ni i.
Ronke Ojo àti Toyin Lawani: Ó dára kí obìnrin níṣẹ́ lọ́wọ́
Ẹyọ kan ninu àwọn tí wọ́n kọ̀ mí sílẹ̀ wọnyi kò ní débẹ̀.
Fayemi fojú Alufa to fipa bá ọmọde lòpọ̀ síta l'Ekiti Àjẹ́ àti Aṣẹ́wó ní ìyá Rainbow - Òjòpagogo A padà san owó ìtanràn fáwọn ajínigbé kí wọ́n to fi àwọn mẹ́tẹ̀ẹ̀ta sílẹ̀- Ẹbí Spaghetti, mílíìkì, Chivita àti Àǹkàrá sọ Rabiu dèrò ẹ̀wọn ni Eko Ibrahim ni ilu Badagry l'oun ti n lọ ba ẹgbọn to ti n gbe nibẹ tẹlẹ.
Alufaa náà yóo pa àgbò náà níbi tí wọ́n ti máa ń pa ẹran fún ẹbọ ìmúkúrò ẹ̀ṣẹ̀ ati ti ẹbọ sísun ninu ibi mímọ́, nítorí pé ẹbọ ìmúkúrò ẹ̀bi jẹ́ ti alufaa, gẹ́gẹ́ bí ẹbọ ìmúkúrò ẹ̀ṣẹ̀; ohun mímọ́ patapata ni.
 ""Ma rinrinajo ifẹ pẹlu ẹni to fẹ ẹ fẹ, ẹ o ma nifẹ ara yin ninu igbeyawo."
  Lẹ́ẹ̀kọ̀kan wọ́n á gbójú sókè wòyàn ṣùgbọ́n tí ènìà kò bá ti dẹ́rù bà wọ́n, wọ́n á padà sí koríko jíjẹ.
Èwo ninu àwọn wolii ni àwọn Baba yín kò ṣe inúnibíni sí?
N óo máa yin OLUWA ní gbogbo ìgbà;ìyìn rẹ̀ yóo máa wà ní ẹnu mi nígbà gbogbo.
Tan ìmọ́lẹ̀ sí ojú mi, kí n má baà sun oorun ikú.
Igba o le mọkandinlọgbọn lo dibo fun yiyọ Trump labẹ ẹsun pe o di ile aṣofin lọwọ ti awọn mejidin ni igba si ta ko o.
Elẹhaa Amina Adegoke wa gba awọn obinrin to gba ẹsin bii tirẹ niyanju pe ẹha ko yẹ ko di wọn lọwọ lati ṣe aṣeyọri.
wọ́n sì tẹ̀lé ìwà àwọn eniyan tí OLUWA lé jáde kúrò fún wọn, ati àwọn àṣàkaṣà tí àwọn ọba Israẹli kó wá.
Lẹ́yìn náà, ó mú àwọn ọmọ Israẹli jáde,tàwọn ti fadaka ati wúrà,kò sì sí ẹnikẹ́ni ninu ẹ̀yà kankan tí ó ṣe àìlera.
Wọnyii ni awọn ipo mii ti Aarẹ Buhari ti di mu latẹyin wa Kọmisana fun ọrọ epo bẹntiroolu ati ohun alumọni abẹ omi - Oṣu kẹta, 1976 Alaga ile iṣẹ ipọnpo NNPC - 1977 titi di 1978 Akọwe olu ile iṣẹ ogun - 1978 titi di 1979 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ààrẹ Muhammadu Buhari ati igbakeji rẹ Yemi Oṣinbajo pẹlu awọn iyawo wọn Lẹyin igba mẹta to ti gbiyanju lati dupo Aarẹ lọdun 2003, 2007 ati 2011, Buhari tun gbiyanju lẹlẹẹkẹrin lọdun 2015 labẹ Asia ẹgbẹ oṣelu All Progressives Congress to si fidi Aarẹ to wa lori alefa nigba naa, Goodluck Jonathan ti ẹgbẹ oṣelu Peoples Democratic Party janlẹ - o jẹ igba akọkọ ti Aarẹ to wa lori oye yoo padanu rẹ ninu idibo.
ni ipinle Kano ,ni  Ila- Iwo oorun ,orile
Spartan, to kẹkọ jade nile ẹkọ Gbogbo Nse Poly Moshood Abiola to wa nilu Abeokuta, ni wọn lo jẹ igi wọrọkọ tii da ina ru nilu abinibi rẹ Ogere Remo.
Meṣa, ọba Moabu, a máa sin aguntan; ní ọdọọdún, a máa fún ọba Israẹli ní ọ̀kẹ́ marun-un (100,000) ọ̀dọ́ aguntan ati irun ọ̀kẹ́ marun-un (100,000) àgbò, gẹ́gẹ́ bí ìṣákọ́lẹ̀.
Àwọn ọmọ Israẹli bá bẹ̀rẹ̀ sí í pa wọ́n ní ìpakúpa títí tí kò fi ku ẹyọ ẹnìkan.
Amọ ṣa Inec ti kọkọ da kika ati ikede esi idibo duro nipinlẹ Rivers nitori wahala ti o waye nibẹ.
Ni ipari o ni idi ti awọn ko ṣe yanju ọrọ naa ni pe oun ki onikaluku ri ọjọ diẹ lati wo awọn akọsilẹ naa wò ṣaaju keresimesi.
Ewe, iko Super Eagles yoo teko
O ni nigba ti awọn ọmọ ogun n ṣe tiwọn, bẹẹ naa ni idunadura ọrọ n lọ lẹgbẹ mii fun idoola wọn.
' Oríṣun àwòrán, Ajirebi1 instagram Amọ ọrọ yipada ni ọdun 2020 ta wa yii nigba ti oriiire gbe awọn alawo rere ko Ajirebi lasiko ti ọmọ rẹ, Samuel kigbe sori ayelujara pe ẹkun omi tun ti wọnu ile baba oun.
Ọkunrin yìí fetí sílẹ̀ bí Paulu ti ń sọ̀rọ̀.
À ti fi àwọ̀n ọlọ́kadà 123 láti Jigawa sílẹ̀ -Ọlọpaa Ẹran ara ọlọ́pàá di èkìrí ẹran súyà, wo àwọn tó jẹ́ níbẹ́.
Eyi ti sun iye awọn to ti lugbadi arun naa siwaju di ẹtalelọgọtadinlẹgbẹfa Aworan atọnisọna Iye awọn to ti ni arun naa lagbaye Sunmọ aworan Àgbáyé Orilẹede Afrika Ariwa Amẹrika Apa Latin Amẹrika ati Caribbean Ilẹ Asia Ilẹ Yuroopu Agbegbe Middle East Erekusu Oceania Fihan 69609761 iye iṣẹlẹ arun naa 1583112 Iye awọn to ku Group 4 Jọwọ ṣe atunṣe ilana ikansi ayelujara rẹ lati ri ẹkunrẹrẹ rẹ Aworan n ṣafihan awọn ti ayẹwo ti fi han lorilẹede kọọkan Orisun: Johns Hopkins University atawọn ajọ eto ilera ilu Igba ti wọn kede iṣiro awọn to nii kẹyin 11 Oṣù Ọ̀pẹ̀ 2020 13:00 WAT+3 Eniyan marundindinlọgọtalenigba ninu awọn to ni arun ọhun ni Naijiria ti ri iwosan gba, ṣugbọn ogoji eniyan ti filẹ ṣaṣọ bora.
’ rèé Ṣe ni wọn n tẹnu mọ ọ pe awọn Fulani darandaran ti gba gbogbo ilu awọn tan wọn si ti n ke si ijọba titi titi ti ko si oun ti ijọba ṣe.
Agbẹ́nusọ fún àjọ ọlọ́pàá ìpínlẹ̀ Ekó, Chike Otu tó bá BBC sọ̀rọ̀ sàlàyé pé wọn gbá a mú lásìkò tó ń ta òògùn tí ìjọba ti fòntẹ̀ dè tó sì ti lòdì sófin.
Má gbẹ́kẹ̀lé ìlọ́ni-lọ́wọ́-gbà,má sì fi olè jíjà yangàn;bí ọrọ̀ bá ń pọ̀ sí i, má gbé ọkàn rẹ lé e.
"Kí ìjọ mi ní Sagamu le gbòòrò ni mo fi ń ṣiṣẹ́ ajínigbé pawó - Pásítọ̀ Àwa àti fijilanté pẹ̀lú ọdẹ́ ìbílẹ̀ ló dojú kọ adigunjalè ní First Bank Okeho - Iléeṣẹ́ ọlọ́pàá Ìtàn ọba Yorùbá tí wọn yẹgi fún torí ó jí ọmọ gbé ṣe ètùtù Ẹ káàbọ̀ sọ́jọ́ Arafat, tí Ọlọ́run yóò fi ààwẹ̀ Mùsùlùmí pa ẹ̀ṣẹ̀ wọn rẹ́ ""Ọmọ mi kò tíì mọ̀ pé òun ti di ìlúmọ̀ọ́ká, ó ń wádìí bó ṣe ń rí ara rẹ̀ lórí ayélujára"" Boko Haram da ìbọn bo ọkọ̀ gómìnà Borno, ẹ̀ṣọ́ àláàbò rẹ̀ farapa Bẹẹ ba gbagbe, igbimọ ile asoju-sofin to wa fọrọ adehun lo ke gbajare sita lori adehun to wa nidi gbigba owoya lọwọ ilẹ China naa, eyi tijọba apapọ buwọlu."
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Daura Kidnap: Àna ààrẹ Buhari, Musa dàwátì ní ìlú Daura 2 Èbibi 2019 Oríṣun àwòrán, AFP Àkọlé àwòrán, Wọ́n jí àwọn arìnrìnàjò gbe ní òpópónà márosẹ̀ Alhaji Musa Umar to jẹ adari ilu Daura ni ipinlẹ Katsina ti di awati ni ilu rẹ.
Dafidi túbọ̀ di olókìkí sí i nígbà tí ó pada dé, láti ibi tí ó ti lọ pa ẹgbaasan-an (18,000) ninu àwọn ará Edomu, ní Àfonífojì Iyọ̀.
Ondo 2020: Afẹnifẹrẹ ní kí Tinubu sọ fún ẹgbẹ́ APC láti ṣe àmúṣẹ́ ilérí rẹ̀ fọ́mọ Nàíjíríà
Ǹjẹ́ ò ń gbọ́ ohùn mi bí!
A máa tẹ̀síwajú láti béèrè fún àwùjọ tí a óò ti ní òmìnira ti ara, òmìnira ìmọ̀lára, òmìnira ìrìn àti òmìnira ríronú bí a ṣe fẹ́.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ondo election 2020: Gómìnà Akeredolu la Jegede mọ́lẹ̀ wọlé ìbò gómìnà Ondo fún sáà kejì 11 Ọ̀wàrà 2020 Oríṣun àwòrán, Twitter Aarẹ orilẹede Naijiria, Muhammed Buhari ti ki gomina ipinlẹ Ondo, Oluwarotimi Akeredolu ku oriirẹ pẹlu bi o ṣe jajabọ ninu idibo sipo gomina to waye ni ipinlẹ Ondo.
Lẹ́yìn náà, láti Ṣekemu ó lọ mọ odi yí ìlú Penueli ká.
“Lotitọ, eto iṣemọtoto tuntun Ipinlẹ Eko, ti wọn pe ni “Claener Lagos Initiative” ti ijọba gbe kalẹ dara, sugbon o dabii pe agbara wọn ko ka awọn idọti yii to.
Jakọbu bá súnmọ́ baba rẹ̀, ó fi ẹnu kò ó lẹ́nu.
Mo mọ̀ pé ọba yóo fetí sílẹ̀ láti gbọ́ tèmi, yóo sì gbà mí kalẹ̀ lọ́wọ́ ẹni tí ó fẹ́ pa èmi ati ọmọ mi, tí ó sì fẹ́ pa wá run kúrò lórí ilẹ̀ tí Ọlọrun fún àwọn eniyan rẹ̀.
Bo imu rẹ ati ẹnu rẹ ti o ba n wukọ lati sin Ṣe ayẹwo finni-finni lati ṣere pẹlu ẹni to n wukọ tabi sin Fọ ọwọ rẹ pẹlu ọṣẹ ati omi lati igba de igba Ri daju pe o ṣe ẹfọ tabi ẹran daradara ki o to jẹ ẹ.
Awuyewuye to wa laarin Olubadan ti ile Ibadan, Oba Saliu
Kí o sì ṣe àkànpọ̀ igi meji meji fún igun mejeeji ẹ̀yìn àgọ́ náà.
Oríṣun àwòrán, Nimc National Identification Number di dandan fún ìforúkọsílẹ̀ Siimu Ajọ to n mojuto ibaraẹnisọrọ ni Naijiria, Nigerian Communication Commission (NCC), ti bẹrẹ si ni lo aṣẹ mii lori awọn to fi orukọ siimu foonu alagbeka wọn silẹ.
Ajọ to n mojuto igbayegbadun awọn atipo lorilẹede Norway lo sọ bẹẹ.
Bakan naa ni ajo UNICEF tun ba awon molebi awon omode-binrin ti won koi ti pada sile kedun pupo.
mọ ilẹ okeere lorile ede Naijiria ogbeni Musa Nuhu ti fi idaniloju han pe
Lassa fever: Ìjọba Eko ní akẹ́kọ̀ọ́ fásitì Ebonyi tó wá kẹ́kọ́ ìmọ̀ òfin, ní wọ́n bá Lassa lára rẹ̀
Àwọn olórin ń yòǹbó bó se leè mú kí èèyàn wà pa.
Ẹ maa gbagbe pe eyi ko tumọ si pe gbogbo awọn eeyan to wa nibi eto wọnyii lo ti koo, ṣugbọn iwadi ati ayẹwo to gbọngbọn nikan lo lee fi idi eyi mulẹ.
Yatọ si Ọjọgbọn Ṣoyinka ati agbẹjọro Falana, awọn eekan mi to tun wa lara ẹgbẹ naa ni Ọjọgbọn Omotoye Olorode, Ọgbẹni Femi Aboriṣade, Ọjọgbọn Anthony Kila, agbẹjọro Affiong L.
Ile iṣẹ ọlọpaa ko sọ bo ya awọn yoo mu ẹnikẹni to ba kopa ninu iwọde ọhun lọjọ Aje.
Ìwé yìí wà fún gbogbo ènìyàn ní ilẹ́ Yorùbá, ó wà fún ọmọdé, ó wà fún àgbàlagbà, ó sí wà fún ẹnikẹ́ni lóde ayé ṣá tí ó mọ èdè Yorùbá á kà dáadáa.
" Ni oṣu kejila 2017, Street Priests ṣeayẹyẹ kan lati fi imoore han si awọn oloore wọn.
O wa sọ pe oun ko le gbagbe ipa ribiribi ti iya naa ko ninu aye oun atawọn ẹko ti oun kọ lara rẹ ko to fi aye silẹ.
julo lati odo awon omo egbe to n sakoso lọwọ ,All Progressives Congress , won
Orile-ede Japan fi idunnu won han pupoc si Naomi Osaka fun jijawe olubori ninu asekagba idije boolu afowogba “U.
Ohun tí ó ṣe burú lójú OLUWA.
OLUWA Ọlọrun wa, ṣebí ìwọ ni?
Mo wí ninu ọkàn mi pé, n óo dán ìgbádùn wò; n óo gbádùn ara mi, ṣugbọn, èyí pàápàá, asán ni.
Awọn eeyan mẹrin farapa ninu iṣẹlẹ yi.
 Amosa ,  iṣẹ idoola ẹmi yoo tẹsiwaju titi di igba ti wọn
Ninu idajọ ti wọn gbe kalẹ ni ile ẹjọ giga to wa ni Ekiti, adajọ to pe orukọ ẹni ti wọn f'ẹsun kan naa gẹgẹ bii Babatunde jẹbi ẹsun ole jija ati nini ada ati okọ nigba ti wọn mu u wipe o jale.
O fi kun ọrọ rẹ pe ọpọ iru garri bayi ni o se e se ki aleebu ti baa.
Kí ló ń ṣẹlẹ̀ láàfin Ọ̀yọ́?
Igbọwọle wà ní ẹ̀gbẹ́ kọ̀ọ̀kan ìtẹ́ náà, tí ère kinniun meji wà ní ẹ̀gbẹ̀ẹ̀gbẹ́ wọn.
Ṣugbọn awọn iroyin kan tun sọ pe, ẹrọ gbohungbohun ti Akpabio n lo lati sọrọ ko ṣiṣẹ daada lo mu ki Saraki sọ fun un pe ko lo omiran - ti Sẹnetọ Alli Ndume.
O gba awọn ọdọ nimọran pé ki wọn ṣawari ẹbun ti Ọlọrun fun wọn nitori kii ṣe gbogbo eeyan lo maa fi iwe kika jẹun bi igboro ṣe ri lasiko yii.
Ní báyìí eniyan ọgbsn lo ti ni ààrun náà ni orill èdè Naijira Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí 12:41 Fídíò, Baby abandoned on dunmpsite: Mo ti bímọ mẹ́rin tẹ́lẹ̀ fún bàbá méjì nínú òṣí- Dupe Ogbomọṣọ, Duration 12,414 Owewe 2020 Fídíò, Akomolede: Bolaji Faleke ni Olùkọ́ tó ń kọ́ wa ní àṣà oge ṣiṣe lórí BBC Yorùbá1 Owewe 2020 NUJ ìpínlẹ Oyo bà àwọn ọmọ ẹgbẹ́ tó lọ ìpàdé tí Femi Fani Kayode pè ní Ibadan wí7 Owewe 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, China virus advice: 'Wash your hands, be honest with your doctors', says Hong Kong expert O ti le ni ọọdunrun eeyan to ti jẹ Ọlọrun nipe latipasẹ arun naa, eyi ti ibẹrubojo wa pe ọwọja rẹ lee tan de orilẹede yii.
Gomina Ganduje wa ro iko agbaboolu kookan nipinle naa lati tun bo tepamose won si, beesini O fin dawon loju pe, isakoso oun yoo sa ipa re lati satileyin ti o to fun won nigba kuugba ati loore-koore.
Adari ẹka to n risi ọrọ to jẹ mọ ara ilu ni ile iṣẹ NNPC, Ndu Ughamadu lo sọ pe irọ lasan ni awọn eniyan n pa ati wi pe ko si owongogo epo.
Mike Zhang ọmọ China di 'Wakilin Yan China' ní ìpínlẹ̀ Kano
Musa gbayp kan wọle, o ṣi sẹ iranwọ fun ẹlẹẹkeji bi ẹgbẹ agbabọọlu Al Nassr FC ti fagba han AlJazira UAE ninu idije Arab Clubs Champions Cup.
$2,600 àǹtí mi ni mo jí láti lọ sókè òkun àmọ́ àbámọ̀ ló gbẹ̀yìn ọ̀rọ̀ mi"" World Diabetes Day: Ọdún kọkandinlogun ti mo ti wà lẹ́nu itọ ṣúgà nìyí Ìbò gómìná Bayelsa ku ọjọ́ méjì, Iléejọ́ yẹ àga mọ́ olùdíje APC ńídìí, Góòlù pọ̀ ní ìlú Madaka ṣùgbọ́n wọn kò ní ọ̀nà fún ọgọ́rùn ún ọdún Fatoyinbo ni lati ibẹrẹ ni Busola ti n ba oun lorukọ jẹ, ti o si ba awọn oniroyin sọrọ lasiko ile isẹ ọlọpaa ti bẹrẹ iwadii lori ẹsun naa."
Ileeṣẹ The Ring sọ ninu iroyin kan to gbe jade pe awọn onigbọwọ sun ija naa siwaju lati le fi ija naa pa owo daadaa.
Nígbà tí a ti ṣe ìpinnu báyìí ti Baba-onírùngbọ̀n rí i pé ó dájú pe à ń lọ ó pinnu láti ràn wá lọ́wọ́ dé ibi tí ipá rẹ̀ tó, ó wọlé ó mú fèèrè kan jáde ó sì fi í hàn wá, ó béèrè lọ́wọ́ wa bí a bá rí ẹni tí ó mọ fèèrè í fun nínú wa.
Etí àwọn yòókù di sí ìpè Ọlọrun, 
O tun ni awon ile-ifowopamo ati ile –itaja naa le maa da awon onibara won lohun bayii.
Inu ọpọlọ awọn ololufẹ idije Premier lo dun pe idije naa yoo pada laipẹ ọjọ.
Bẹẹ lo kilọ fun awọn obinrin pe ki wọn ranti pe, ko si oun ti eniyan ṣe silẹ, ti ko ni ba.
Àwọn akọni Nàìjíríà padà sílé pẹ̀lú àmì ẹ̀yẹ 121 láti Morocco Ìfẹ̀hónúhàn l'Abuja lórí ìdájọ́ ilẹ̀ Gẹ̀ẹ́sì tó gbẹ́sẹ̀ lé $9.
Human Trafficking: Wọ́n fun mi ni omí ìmùlẹ̀ kí wọ́n to sọ fun mi pé iṣẹ́ aṣẹwo ni mo wá ṣe- Adeola
Nítorí náà bí ó bá wu ọba, kí ọba pàṣẹ, kí á sì kọ ọ́ sinu ìwé òfin Pasia ati ti Media, tí ẹnikẹ́ni kò lè yipada, pé Faṣiti kò gbọdọ̀ dé iwájú ọba mọ́, kí ọba sì fi ipò rẹ̀ fún ẹlòmíràn tí ó sàn jù ú lọ.
Jeremaya bá ń gbé gbọ̀ngàn àwọn tí wọn ń ṣọ́ ààfin.
Ọrọ yii lọpọ eeyan n gba bi ẹni n gba igba ọti lori ayelujara opo Twitter papaajulọ lati igba ti Arsenal ti ri iya he lọwọ Liverpool ninu idije Carabao Cup ni papa iṣere Anfield lalẹ Ọjọru.
Ìtàn tó wà nídi òwe ‘Sebótimọ Ẹlẹ́wà Sàpọ́n’ Taiwo Akinkunmi, ọmọ Ibadan tó ya àsìá Nàíjíríà Taiwo Akinkunmi, ọmọ Ibadan tó ya àsìá Nàíjíríà Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Kayefi BBC Yorùba: Bàbá ọmọ, Mọ́ṣúárì, Ọlọ́pàá kẹ́jọ́ rò nípa òkú ọmọ tó pòórá Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Balogun iko agbaboolu Super Eagles teleri, Joseph Yobo, so pe, oun ni igbagbo pe iko Super Eagles yoo fakoyo ninu idije boolu agbaye to n bo lona lorile-ede Russia.
Ọ̀pọ̀ aráàlú Owo wà nílé ìwòsàn, síbẹ̀ APC àti PDP kò gba ẹ̀bi Makinde gba àwọn òṣìṣẹ́ LAUTECH 41 tí ìjọba Ajimobi dá dúró lẹ́nu iṣẹ́ padà Obabinrin Elizabeth kejì kí Nàìjíríà kú oríire òmìnira ọgọ́ta ọdún Ọba oke si lo mu ki ẹsẹ Naijiria duro re pada, bibẹẹkọ, wahala ibo June 12 ko ba ti ree isọkan ati irẹpọ Naijiria ni ẹfasẹ.
Fásitì ìpínlẹ̀ Ekiti dá òṣìṣẹ́ 355 padà sẹ́nu iṣẹ́ Ilé ìwòsàn l'Àbuja ti ya àwọn ìbejì tí wọ́n sọpọ̀ láyà lọ́fẹ̀ẹ́ Kò sí wàhálà lórí ìkọlù Iran, lákọ ni America wà- Trump Adebayor ni iṣẹlẹ naa jẹ ọkan lara awọn manigbagbe iṣẹlẹ to buru ju to ṣẹlẹ s'oun laye.
Idi ni pe inira ti n ba awọn sẹẹli ara ti kokoro aifojuri yi ti nawọ gan.
Bí ó bá ní ẹ̀bùn láti fúnni ní ọ̀rọ̀ ìwúrí, kí ó lò ó láti lé ìrẹ̀wẹ̀sì jìnnà.
Nǹkan burúkú wo ni ó ṣe?
Wo ohun tí ilé ẹjọ́ ní kí wọ́n ṣe fún Sunday Shodipe, afurasí ìṣekúpani l'Akinyele Ile ẹjọ Majisireeti agba kan nilu Ibadan ti ran Sunday Shodipẹ, afurasi tọwọ ọlọpaa tẹ lori iku ọwọọwọ lagbegbe Akinyẹle nilu Ibadan lọ si rimandi ọgba ẹwọn.
Ẹ wo àbájáde ìwádìí wa Amina ṣalaye bi awọn onibara rẹ ọkunrin ṣe maa n fi Whatsapp baa sọrọ nitori wọn ti mọ pe Elẹhaa ni oun tabi ki awọn iyawo wọn ba oun sọrọ tabi ki wọn ba ọkọ oun sọrọ lori ẹrọ foonu oun.
Igi ẹ̀gún bá dá àwọn igi lóhùn pé, ‘Tí ó bá jẹ́ pé tinútinú yín ni ẹ fi fẹ́ kí n jọba yín, ẹ wá sábẹ́ ìbòòji mi, n óo sì dáàbò bò yín.
Biliha lóyún, ó bí ọmọkunrin kan fún Jakọbu.
Iṣẹlẹ to waye lọjọbọ ni agbegbe Mile 2, Diobu, ni Port Harcourt, ipinlẹ Rivers to wa ni Guusu-guusu Naijiriani wọn sọ pé ọkunrin kan ku lẹyin to lọ gbadun ara rẹ ni otẹẹli kan.
apero apapo awon elesin musulumi lagbaaye.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Bàbá Wande ní gbajúmọ̀ agbábọ́ọ̀lù lòun ì bá jẹ́ ká ní òun kò ṣeré tíátà 14 Èbibi 2018 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 8 Èbibi 2020 Oríṣun àwòrán, Baba wande Gbajumọ àgbà ọjẹ osere tíátà, Alhaji Kareem Adepoju, tí gbogbo ènìyàn mọ sí bàbá Wande, tí ṣàlàyé nípa iru èèyàn tó jẹ́ àti bó ṣe bẹ̀rẹ̀ ère tíátà.
O tesiwaju pe, fifun arawon ati asa won ni owo, ti o fi mo esin onikaluku se koko lojuna lati mu idagbasoke ba orile-ede yii.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Lagos- Ibadan Express: Kò sí ìfòyà lásìkò ọdún iléyá 30 Agẹmo 2019 Àkọlé àwòrán, Kò sí ìfòyà lásìkò ọdún iléyá ní òpópónà Marosẹ Eko si Ibadan Ìjọba àpapọ̀ ti fi ọkàn àwọn ará ìlú balẹ̀ pàápàá jùlọ àwọn to ń lo ọ̀pópónà márosẹ Lagos -Ibadan wi pé àwọn yóò fi ààyè silẹ̀ fún ìrìnnà ọkọ̀ ju ti tẹ́lẹ̀ lọ.
“Ṣugbọn wọ́n yẹ àdéhùn tí mo bá wọn ṣe, bí Adamu, wọ́n hùwà aiṣododo sí èmi Ọlọrun.
Ìyàwò lárìnlọọ̀dù mi pè mí ní akálòlò ni mo ṣe paa - Afurasí Ẹ wá ná, kí ló ń ṣẹlẹ̀ pẹ̀lú Brexit?
Èmi ní mo fún Afeez Abiodun ní orúkọ 'Ọwọ' tó ń jẹ́ -Yemi my Lover Iṣẹlẹ ọhun ni kọmisọnna sọ loju opo Twitter rẹ pe o ṣẹlẹ lopopona Kachia ni ijọba ibilẹ Chikun.
Ẹ́tà dín l'ọ́jọ èèyàn ló ṣòfò ẹ̀mí l'ọ́jọ́ ẹlẹ́kọ ọ̀run ń polówó
- Ìjọba Oyo Ọkọ mi kò fẹ́ràn oúnjẹ òyìnbó àfi ti ìbílẹ̀ - Lizzy Anjorin Ó mà ṣe o!
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Àìmọye ìgbà ni darandaran ti rán ọ̀gọ̀ọ̀rọ̀ èèyàn ìpínlẹ̀ Benue sí ọ̀run ọ̀sán gangan Ẹ̀wẹ̀, ẹgbẹ́ àpapọ̀ àwọn ọmọlẹ́yìn Kristi CAN àti PFN ní ìpínlẹ̀ Benue ti ń gbarata pé ìgbàwo ni ìkọlù àwọn darandaran yóò d'ohun ìtàn ní ìpínlẹ̀ náà nítori ọ̀pọ̀ àwọn ọmọ Nàíjíríà yókù ni kò leè fi ẹ̀dọ̀ lórí òróǹro mọ́.
Ẹ padà sẹ́nu iṣẹ́ kíá bí bẹ́ẹ̀ kọ́.
Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí NÍ YÀJÓYÀJÓ Covid 19: Ìjọba ìpínlẹ̀ Ogun pàṣẹ kí wọ́n ṣí gbogbo ilé ìjọsìn, ilé ìgbafẹ́ padà lẹ́kúnrẹ́rẹ́ Fídíò, Akomolede: Bolaji Faleke ni Olùkọ́ tó ń kọ́ wa ní àṣà oge ṣiṣe lórí BBC Yorùbá1 Owewe 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Wọ́n wó gbogbo pẹpẹ oriṣa ati àwọn pẹpẹ turari tí ó wà ní Jerusalẹmu, wọ́n dà wọ́n sí àfonífojì Kidironi.
Bakan naa lo dari oniruuru awọn fọnran orin fun ile isẹ Chocolate City, Styplus, Gabriel Afolayan.
Ẹgbẹrun mẹrindinlaadọrin o le aadọrun (66, 090) lawọn ti ara wọn ti ya nigbati aarun naa si ti gbẹmi awọn ẹgbẹrun kan ati igba o din mẹta (1197) eeyan.
Ajọ EFCC ti fi aridaju eyi han nipa fifi si oju opo Twitter wọn.
Ajọ EFSC sọ wi pe awọn meje ni awọn doola ẹmi wọn ninu ijamba ọkọ naa, amọ ti ẹmi mẹrindinlogun ba iṣẹlẹ naa lọ.
Ami ayo meji sodo ni wọn fi fẹyin Arsenal gbi lẹ ni Anfield.
Nínú ọ̀rọ̀ rẹ̀ Akintola tún parọwa sí ìjọba láti rii dáju pé ìjọba àti gbogbo àwọn eléto ìjọba gbọdọ máà rán àwọn ọmọ wọn náà lọ si ilé ẹkọ ti ìjọba dá sílẹ̀ nítori ọnà yìí níkàn ní ọnà àbáyọ ti tolórí tẹ́lẹmù yòó fi gbárùkù ti ètò ẹkọ lórílẹ̀-èdè Nàìjíríà 2018 Jamb: Awọn akẹkọ fọnmu lori iforukọsilẹ Oríṣun àwòrán, @JAMB Àkọlé àwòrán, Ajọ JAMB sun ọjọ iforukosilẹ idanwo UTME siwaju lati ọsẹ meji sẹhin Ọgọọrọ awọn akẹkọ to n gbaradi fun idanwo asewọle sile ẹkọ giga, UTME tọdun yii ti fẹhọnu han lori bii ajọ Jamb se ti oju opo ti wọn ti n forukọ silẹ fun idanwo UTME tọdun yii.
Salimoni bí Boasi, Boasi bí Obedi; 
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Suicide Prevention: ìwọ́de yìí wáyé láti gbógun ti pípa ara ẹni Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù APC: Kí ni àwọn ẹ̀ṣẹ̀ tó ń da Oshiomole láàmú?
Buhari ti buwọ́lu ẹ̀kúnwó sísan owó oṣù tuntun fáwọn òṣìṣẹ́ àpapọ̀ CAN kò rán ẹnikẹ́ni lọ ṣọ́ọ̀ṣì COZA, iṣẹ́ ara wọn ní wọ́n lọ jẹ́ -Samson Ayokunle Yinka Ayefele di bàbá ìbẹta Super Eagles gba iṣẹ́ lọ́wọ́ Seedorf olùkọ́ni Indomitable Lions Cameroun Oloye Egbule ni wọn yoo bẹrẹ si ni san owo oṣu tuntun yii lati ọjọ kejidinlogun, oṣu kẹrin, ọdun 2018 ni awọn ileeṣẹ ijọba apapọ bi o ṣe yẹ.
Ẹ kò gbọdọ̀ bá àwọn tabi àwọn oriṣa wọn dá majẹmu.
Àkọlé àwòrán, Ija ominira fun ẹkun guusu Cameroun lo sọ awọn eeyan yi di alainilelori Sugbọn ọkunrin naa fi ẹsẹ re rin fun asiko to ju ọse kan lọ.
Amọṣa o ni 'ṣaka lara emi ati idile mi le' Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
5 ṣibiOdiwọn ti ajọ WHO fọwọ si fun agbalagbaOrisun: Coca-Cola/WHO Orilẹede bi ọgbọ̀n lo ti fi owo ori le awọn nkan mimu to ni ṣuga ninu.
Awọn olubẹwo - Awọn eeyan yi lo ma n ṣe amojuto awọn to ba ṣẹṣẹ darapọ mọ ijọ CCC Genesis Global.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Seyi Makinde: Gbogbo ẹ̀yin tí ipò kò tíì kàn, ẹ fọkàn balẹ̀, yóò kàn yín láìpẹ́ 14 Ògún 2019 Oríṣun àwòrán, Facebook/Seyi Makinde Gómìnà ìpínlẹ̀ Oyo Seyi Makinde ní àwọn agbáṣésẹ abẹ́lé ní ìjọba òun yóò maa gbé kọ́ngila ìpínlẹ̀ Oyo fún, lójunà àti kó ipa tiwọn nínú ìdàgbàsókè ìpínlẹ̀ náà.
Ninu ija alagbara naa, Joshua lo kọkọ fi ẹyin Ruiz lelẹ ni ipele kẹta ija wọn, amọ ko pẹ ni Ruiz gba ani ẹṣẹ kan ni iwaju ori, eyi to mu ki oju Joshua pooyi ran-in.
 A maa lo anfani ero pupọ ti ani nipinlẹ Eko to le ni milọnu merinlelogun bayii”.
 ibi ònà ti pín sí mèjì gba èyí ti ó lo sí apá òtún níbi tí ònà ti pin sí méjì náà .
Wo ohun mẹ́wàá tó yẹ kí o mọ̀ tí o bá fẹ́ lọ fún ìsinmi lẹ́yìn Covid 19 Lẹyin naa lo bẹrẹ si n lọgun, to si n kilọ fun awọn eeyan pe ki wọn ṣọra fun titapa si ofin irinna oju popo.
Gẹgẹ bi Sanwo-Olu ṣe sọ, àwọn ilé ijó kò ti di ṣíṣí títí di àsìkò yìí, ṣugbọn ki wọn ti eyikeyi to ba ti di ṣiṣi pada titi di gbedeke aláìlọ́jọ́.
Ọlọrun wò ó, ó rí i pé ìmọ́lẹ̀ náà dára, ó sì yà á kúrò lára òkùnkùn.
Nígbà tí ó di ọdún kẹta, Jehoṣafati, ọba Juda, lọ bẹ Ahabu, ọba Israẹli wò.
Building Collapse: Àlàyé rèé lórí bí ilé kẹ̀ta ti wó l'Eko
Bakannaa ni CBN ni ki wọn da owo to to biliọnu mẹjọ dọla pada si akoto ijọba fun pe MTN n fi ọna eru da owo pada si orileede South Africa.
Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Alaafin Oyo: Olorì Anuoluwapo Adeyemi gba àmì ẹ̀yẹ lórí oge ṣíṣe1 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Alaafin Oyo: Níbo ni Olorí Anu àti Dami wà?
Ki isẹju kẹrindinlọgbọn ifẹsẹwọnsẹ naa to ko ni Arsenal ti mu bọọlu ninu awọn wọn lẹẹmeji ọtọọtọ lẹyin ti agbabọọlu Brighton, Lewsi Dunk ati Glenn Murray ti gba bọọlu wọ inu awọn Arsenal ni isẹju keje ati ikẹrindinlọgbọn ifẹsẹwọnsẹ naa.
Bẹ́ẹ̀ sì tún ni, bí eniyan meji bá sùn pọ̀,wọn yóo fi ooru mú ara wọnṣugbọn báwo ni ẹnìkan ṣe lè fi ooru mú ara rẹ̀?
Lara awọn àgbà olorin to tun jẹ gbajugbaja to darapo mọ ẹgbẹ́ orin Fatai Rolling Dollar lọdun 1958 ni Ebenezer Obey, to di ọkan gbòógì lára àwọn Irawọ olorin Juju ni Naijiria.
Ka rí ọkọ̀ ayọ́kẹ́lẹ́ to já èrò sílẹ̀, kí lágbájá kọrí sí ṣọ́ọ̀ṣì lọ ké alelúyà, ki tẹ̀mẹ̀dù náà sì gba mọ́ṣáláṣí lọ rèé ké láìláà.
“Aṣọ títa mẹ́wàá ni kí o fi ṣe inú àgọ́ mi, kí aṣọ náà jẹ́ aṣọ ọ̀gbọ̀ funfun, kí wọ́n dárà sí aṣọ náà pẹlu àwọ̀ aró, ati àwọ̀ elése àlùkò ati àwọ̀ pupa, kí àwọn tí wọ́n bá mọ iṣẹ́ ọnà ya àwòrán Kerubu sí ara gbogbo aṣọ títa náà.
Rafael Nadal jawe olubori ninu asekagba idije French Open, leyn ti o fagbahan akegbe re ti o wa lati orile-ede Austria,  Dominic Thiem pelu ami-ayo mefa si merin(6-4), mefa si meta(6-3), mefa si meji(6-2) lati gba ife eye idije naa.
kí ó tún rí fún mi bí ìgbà tí ara dẹ̀ mí,nígbà tí ìrẹ́pọ̀ wà láàrin Ọlọrun ati ìdílé mi;
Má wò mí tìka-tẹ̀gbin, nítorí pé mo dúdú,oòrùn tó pa mí ló ṣe àwọ̀ mi bẹ́ẹ̀.
''Nibayii, iṣejọba to ba gbọ ti araalu nikan lo le ni aṣeyọri ni Naijiria, nitori awọn ọdọ ti gbọn bayii.
A bọ́ lọ́wọ́ ẹkùn bọ́ sọ́wọ́ ònì ni.
Máa fi idà gé ìdámẹ́ta, kí o sì fọ́n ọn káàkiri lẹ́yìn ìlú, fọ́n ìdámẹ́ta yòókù káàkiri sinu afẹ́fẹ́, n óo sì fa idà yọ tẹ̀lé e.
Wọ́n sì ṣe àkànpọ̀ igi meji fún igun àgọ́ náà tí ó wà ní apá ẹ̀yìn.
Ọ̀jọ̀gbọ́n Simon Mallam wa nínú àwọn mẹ́fà tó ti kú nínú ìjàmbá iná gáàsì- Ìjọba Kaduna Eeyan mẹjọ jona ninu ijamba ọkọ agbepo Koko iroyin: Ijamba ina l’Eko, DJ Naijiria to n ṣowo nọbi ni Spain Bakanna ni o tun ṣe abẹwo si Oba ilu Eko, Akiolu Rilwan nibi to ti beere iranwọ lọdọ awọn lọbalọba nipa mimu aabo to peye ba awọn adugbo to wa labẹ wọn.
Ami ayo meji sodo ni ikọ Amẹrika fi fagba han Naijiria, ọdọmọde ẹleṣẹ ayo ti orukọ n jẹ Sebastian Soto lo gbayo mejeeji wọ le fun ilẹ Amẹrika.
Aarẹ orilẹ-ede Faranse, Emmanuel Macron lo kọkọ ṣe ipolongo rẹ pe ipade yoo waye lati da owo iranwọ fun orilẹ-ede Lebanon.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Damọla Ọlatunji ati Bukọla Awoyẹmi: Àwọn òṣèré tíátà Yorùbá tó fẹ́ òṣèré ẹgbẹ́ wọn 10 Èrèlè 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 2 Sẹ́rẹ́ 2020 Oríṣun àwòrán, Rasaq olayiwola/damola olatunji Àkọlé àwòrán, Ariwo ìgbéyàwó ò'sèré tó bá tú ká ni aráyé máa ń gbọ́ Ọpọ igba lo jẹ pe igbeyawo to foriṣọnpọn laarin awọn oṣere tiata ni araye maa n ri tabi ni iroyin maa n fọnrere rẹ.
Coronavirus ti di ara wa, kò le è kúrò mọ láéláé - WHO Ohun tó yẹ kí o mọ̀ nípa ìbòmú tí ń lò yẹ́n Ǹjẹ́ ènìyàn tó ní àrùn coronavirus rí lè níi lẹ́ẹ̀kejì?
Pípa ni kí o pa á, ìwọ gan-an ni kí o kọ́ sọ òkúta lù ú, kí àwọn eniyan yòókù tó kó òkúta bò ó.
O ni ninu ibẹru-bojo lawọn olukọ ati akẹkọ n gbe bayii ni ọgba fasiti naa lẹyin ti awọn ajinigbe ji ọjọgbọn naa gbe ni opopona Ibadan si ifẹ to jẹ ọkan lara awọn ọna pataki to wọ ileewe naa.
Lẹyin ogun iṣeju, ikọ Germany fun Naijiria ni ami ayo kan.
O ni ko si ẹnikọkan ti agbofinro yinbọn fun bi awọn Shiite ṣe n pa irọ kiri lori ayelujara.
Bẹ́ẹ̀ ni ó wà ní àkọsílẹ̀ pé, “Nítorí èyí, n óo yìn ọ́ láàrin àwọn orílẹ̀-èdè,n óo kọrin sí orúkọ rẹ.
Mílíọ́nù mẹ́sàn àti ààbọ tọ́ọ́nù ìrẹsì (9.
Nítorí mo mọ̀ pé láìpẹ́ n óo bọ́ àgọ́ ara mi sílẹ̀, gẹ́gẹ́ bí Oluwa wa Jesu Kristi ti fihàn mí.
Orile-ede Islamic republic of Iran so pe, erongba ohun ni lati ni ajosepo to dan moran pelu awon orile-ede nile Africa.
 Àkò mọ ̀ dájú bóyá lílo kòkòrò tí a gbà pé ó ń ṣe ìwòsàn tàbí oògun apa àkòran kòkòrò àtùnwáyé rẹ ̀ wáyé ní ìpalára fún olóyún .
Jẹ́ kí iṣẹ́ rẹ hàn sí àwọn iranṣẹ rẹ,kí agbára rẹ tí ó lógo sì hàn sí àwọn ọmọ wọn.
Obinrin náà mọ ohun tí ó ṣẹlẹ̀ lára òun, ó bá yọ jáde.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ sí: A dájọ́ ọjọ́ pé, Ìpàdé ìtagbangba Ọṣun kò Àwọn ohun tó yẹ́ kí o mọ̀ nípa Ọ̀gá DSS tuntun Àwọn àwòrán bí ètò ìsìnkú Kofi Annan ṣe lọ Àwọn olùdíje Ọṣun jẹ́wọ́ ara wọ́n Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí 2 sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 2:23 Fídíò, Water Generator: Ó leè ṣiṣẹ fún wákàtí mẹfà, kó tó sinmi, Duration 2,2310 Òkùdu 2020 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
Lopopona Agbor ni ipinlẹ Edo ni ijamba ọkọ ọhun ti ṣẹlẹ nigba ti George ati awọn akẹgbẹ rẹ n rinrin ajo ni opopona ilu Onitsha si Eko.
Naijiria ,INEC ti fi kun wakati to yẹ ki eto idibo pari lonii yii.
Nibayii, a ti n fi inu han ara a wa, a si n ba ara wa jiroro.
Irú àwọn ẹni bẹ́ẹ̀ yẹ fún ìdálẹ́bi.
Ó fi irin hun àwọ̀n meji fún àwọn ọpọ́n orí mejeeji tí wọ́n wà lórí àwọn òpó náà, àwọ̀n kọ̀ọ̀kan fún ọpọ́n orí òpó kọ̀ọ̀kan.
- Ẹgbẹ́ àgbẹ̀ kìlọ̀ Ikú Dagrin pé ọdún mẹ́wàá, wo àwọn nǹkan mánigbàgbé nípa rẹ̀ O ni ijọba ilẹ naa yoo gbe e lọ si ileẹjọ nitori ijọba tako fifi ọmọ eeyan ṣe kata-kara.
Ṣugbọn ọba pàṣẹ pé kí Absalomu máa gbé ilé rẹ̀, nítorí pé òun kò fẹ́ rí i sójú.
Láti ẹnu alufaa ni ó ti yẹ kí ìmọ̀ ti máa jáde, kí àwọn eniyan sì máa gba ẹ̀kọ́ lọ́dọ̀ rẹ̀, nítorí pé, iranṣẹ OLUWA àwọn ọmọ ogun ni.
Awọn miran ni igbesẹ to fi yọ kuro ninu awọn nkan to ti gbe sori ayelujara tẹlẹ naa ku diẹ kaato.
" Ààrẹ ilé ìgbimọ aṣòfin àgbà Ahmed Lawan gba abá ọhun wọle, o si fi kun pe o ṣe pataki ki àwọn ènìyàn tèlé òfin igbéle ọlọjọ mẹrinla ki wọ́n si lọ fun àyẹwo.
Bo ba jade, awọn ọmọde a pe tẹle e lẹyin wọn a maa kigbe le e lori bi oromadiyẹ."
Gẹ́gẹ́ bí mo ti sọ fún àwọn tí wọ́n ti ṣẹ̀ tẹ́lẹ̀ ati àwọn yòókù, tí mo tún sọ nígbà tí mo wá sọ́dọ̀ yín lẹẹkeji, bẹ́ẹ̀ ni mo tún ń sọ nisinsinyii tí n kò sí lọ́dọ̀ yín, pé nígbà tí mo bá tún dé, n kò ní ṣojú àánú; 
Bakan naa ni a gbiyanju lati kan si Alhaji YK Abass ti Olubadan fi jẹ, ṣugbọn awọn naa ni awọn ko lee raye sọrs bayii.
agbofinro naa tun so pe  “ko si iroyin kankan lonii yii,” bi
O ni ibudo yii yo mu idagbasoke ba eto ilera awon eniyan ipinle Bayelsa ni eyi ti o gba pe o fi san ju bi Bayelsa se ri ni ogun odun seyin ti oun wa sibe wa polongo idibo.
Kí ni ìdí tí ilé ẹjọ́ tún ti sún ìgbẹ́jọ́ Alfa Babatunde Sotitobire síwájú Auxiliary korò ojú sí àwọn ọmọ ẹ̀yìn rẹ̀ tó ń dàlú rú Ẹ̀wọ̀n gbére ni fún ẹnikẹ́ni tó bá fipá bánilòpọ̀ ní ìpínlẹ̀ Ọ̀ṣun Irú kí lèyì?
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Òsìsẹ́ SARS mẹ́rin d'èrò ẹ̀wọ̀n lóri N7m Jàǹdùkú yìnbọ́n pa alága PDP kan l‘Èkó To ba n pẹ jẹun alẹ́, o le ni jẹjẹrẹ ọyan àti asétọ̀ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Bọlanle Aliyu: N kò nílò bàbá ìsàlẹ̀ láti di gómìnà Arinrinajo miran jẹri wipe, ọlọpa kan naa wa lara awọn ti wọn padanu ẹmi wọn ninu iṣẹlẹ ọhun.
Oríṣun àwòrán, Instagram/profosinbajo Àkọlé àwòrán, Àyẹ̀wò ti fihàn pé igbákejì ààrẹ Yemi Osinbajo ò ní covid-19 Ọjọgbọn Osinbajo ti ya ara rẹ sọtọ fun ayẹwo nitori ajakalẹ arun Coronavirus tẹlẹ.
Egbe AFCO ti o ni awon omo egbe jake-jado orile-ede Naijiria, n gbero lati lo ilana eto agbe lati pese ise fun awon ti ko nise lowo, ati lati lo ilana ipinnu ijoba lati mu igberu ba eto oro-aje orile-ede Naijiria.
Yóo kọ Israẹli sílẹ̀ nítorí ẹ̀ṣẹ̀ tí Jeroboamu dá ati èyí tí ó mú kí Israẹli dá pẹlu.
Nítorí náà, àwọn ọmọ yín ni yóo ṣe onídàájọ́ yín.
Aarẹ ẹgbẹ naa ọjọgbọn Biodun Ogunyemi ninu ifọrọwanilẹnuwo pẹlu BBC sọ pe arumọjẹ lasan ni owo yi jẹ ati pe kii ṣe owo tawọn beere ninu adehun pẹlu ijọba.
Olori Ramat Adedayo Adeyemi (Iya Koto): Oríṣun àwòrán, Olori Ramat Adedayo Adeyemi Olori Ramat Adedayo Adeyemi ni ayaba keji to dagba julọ ninu aafin Ọyọ, oun si ni Ọba Adeyemi fẹ sikeji ninu awọn olori rẹ.
Nítorí tí ẹ bá ní àwọn nǹkan wọnyi; tí wọn ń dàgbà ninu yín, ìgbé-ayé yín kò ní jẹ́ lásán tabi kí ó jẹ́ aláìléso ninu mímọ Jesu Kristi.
Bi orile ede yin se n se idaro awon akinkanju wonyi, a gbadura pe
Osun elections: APC pè fún àdúrà lórí ìdájọ́ kóòtù àgbà tó ń bọ̀ lórí gómìnà l'Ọ́ṣun
Mose a máa pa àgọ́ àjọ sí òkèèrè, lẹ́yìn ibùdó àwọn ọmọ Israẹli, ó sì sọ ọ́ ní àgọ́ àjọ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Akomolede ati Asa: Mọ̀ si nípa àwọn ọ̀nà tí Yorùbá ń gbà ran ara wọn lọ́wọ́ Kíní ìtumọ̀ Sọ̀rọ̀ Sókè tí àwọn afẹ̀họ́núhàn EndSars ń lò káàkiri: Bisoye Ẹlẹsin to ba BBC Yoruba sọrọ ni ede lagbara lawujọ nitori naa ni ede asa ṣe n jade ninu ọrọ ti awọn eniyan ma n lo.
” Wọ́n dáhùn pé, “Kò sí!
Ipinlẹ mẹrinlelogoji pẹlu olu ilu Naijiria, Abuja ni coronavirus ti wọ pẹlu ohun ti a ri gbọ lọdọ wọn lọwọ yi.
O tun han ninu atẹjade naa pe, ayẹwo awọn akẹkọọ lati mọ boya wọn ni arun Coronavirus kii ṣe dandan mọ fawọn akẹkọọjade to fẹ wọle pada sile ẹkọ.
Gbogbo wa la o gbẹyin arugbo wa o.
Minisita fun iroyin ati asa lorile ede Naijiria, Lai
Orúkọ “SIM Card” yìí kìí ṣe ọ̀rọ̀ ẹyọọ̀kan ṣoṣo o, ọ̀rọ̀ mẹ́rin ni wọ́n mú pọ̀, tí wọ́n tún wá gée kúrú.
Oríṣun àwòrán, Alaafin Oba Adeyemi III Iyatọ to wa laarin arugba Ọṣun ati arugba Ṣango ni pe nigba ti arugba Ọṣun jẹ obinrin, ọmọ ọkunrin ni arugba Ṣango jẹ.
Kò sí ohunkohun ninu Àpótí Ẹ̀rí náà, àfi tabili òkúta meji tí Mose kó sinu rẹ̀ ní òkè Sinai, níbi tí OLUWA ti bá àwọn ọmọ Israẹli dá majẹmu, nígbà tí wọn ń ti Ijipti bọ̀.
''Ẹnu Ayinde Barrister ni mo ti gbọ orukọ Okunnu, ṣugbọn okun nu ni itumọ orukọ naa lẹyin ti mo ṣe iwadii lori rẹ,'' Okunnu lo woye bẹẹ.
Mo fẹ́ kí ẹ mọ̀ dájúdájú pé a kò ní fún wọn ní àmì kan.
to dari ayeye naa ni alaga egbe APC Adams Oshiomhole ati Godswill
Ìrudi kọ̀ọ̀kan wà lábẹ́ ẹ̀ka meji meji tí ó so mọ́ ara ọ̀pá fìtílà náà lọ́nà mẹtẹẹta.
Abẹrẹ Ajẹsara Wọn ti n fun awọn eniyan ni abẹrẹ ajẹsara kan ti wọn ṣẹṣẹ ṣe jade lati dena itankalẹ aarun Ebola.
Baba wá kí á siré awo!
 Sound Sultan & KokerOsere ile Adulawo fun odun 2018Nasty CEyi ti awon onworan Headies dibo funCome Closer – WizkidFidio orin to dun ju Come Closer – Wizkid.
Nígbà tí Akisa dé ọ̀dọ̀ ọkọ rẹ̀, ọkọ rẹ̀ bẹ̀ ẹ́ pé kí ó tọrọ pápá ìdaran lọ́wọ́ baba rẹ̀.
"àwọn ẹ̀sùn tí wọ́n fi kàn án ti lóòrìn tó sùgbọ́n bí ó ṣe kan àwọn aṣòfin lórí ẹ̀sùn tí wọ́n ń fi kàn án, o tí wá sọ ọ di ọ̀rọ̀ tó le tí ǹkan gbúdọ̀ tibẹ̀ jáde"" Kini ijọba n sọ?"
Mọsalasi kan ni asaadoku mọ́ra kan kọlu l'oṣu Kẹta, ọdun 2015.
Àwọn yìí ni wọ́n ń tẹ̀lé Ọ̀dọ́ Aguntan náà káàkiri ibi gbogbo tí ó bá ń lọ.
Maria dúró lọ́dọ̀ Elisabẹti tó bíi oṣù mẹta, ó bá pada lọ sí ilé rẹ̀.
Hanani, ọmọ Maaka, ati Joṣafati, ará Mitini; 
O fi kun un pe gba-gba-gba lawọn ọmọ igbimọ majẹobajẹ ẹgbẹ oṣelu naa wa lẹyin oun lori igbesẹ naa.
Àwọn oníṣẹ́ Benhadadi ọba wí fún un pé, “Oriṣa orí òkè ni oriṣa àwọn ọmọ Israẹli.
EFCC fẹ́ gbẹ́sẹ̀ lé ilé tí mo fi owó ìfẹ̀yìntì kọ́ nílùú Ilorin- Saraki Òṣìṣẹ́ LASTMA kan àgbákò ikú lọ́wọ́ àwọn jàǹdùkú méjì nílùú Èkó 'A kò ní w'ojú olóṣèlú kankan lóríi ìwádìí àpapín owó N5bn ní Kwara' Òṣìṣẹ́ LASTMA kan àgbákò ikú lọ́wọ́ àwọn jàǹdùkú méjì nílùú Èkó Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Kó sí ìtọ́jú kan pàtó fún ààrún ibà pójú, ẹfọn sì ló máa n gbée láti ara ẹnikan si ara ẹlòmíràn.
Adájọ gbà ìdájọ ikú lọ́wọ́ ejò O jẹ ọkan lara awọn akọṣẹmọṣẹ akọrin olohun gooro perete to orisun wọn jẹ ilẹ Afirika.
Wọ́n ní àwọn wá bẹ Farao ni, pé kí ó jẹ́ kí àwọn máa gbé ilẹ̀ Goṣeni.
O kò gbọdọ̀ fa èyíkéyìí ninu àwọn ọmọ rẹ kalẹ̀ fún lílò níbi ìbọ̀rìṣà Moleki, kí o sì ti ipa bẹ́ẹ̀ ba orúkọ Ọlọrun rẹ jẹ́.
awon eniyan lasiko ati leyin eto idibo.
''Agogo mẹjọ aarọ ni iṣẹlẹ naa ti bẹrẹ, nigba ti awọn janduku naa si ko ohun ti wọn nilo tan, wọn pe awọn ara adugbo lati wa bẹrẹ si ni ko awọn ohun elo naa.
Nítorí náà OLUWA ń dúró dè yín,ó ti ṣetán láti ṣàánú yín.
Igbakeji Aarẹ oilẹ-ede Naijiria, Ọjọgbọn Yẹmi Ọṣinbajo ti pe fun pipese agbara kikun fun awọn ipinlẹ gẹgẹ bi ọna kan lati fopin si oṣi ati iṣẹ ni orilẹ-ede Naijiria.
 òun ló ń pàrí ìjà láàrin ẹbi .
Ọba ń yọ̀ nítorí agbára rẹ, OLUWA;inú rẹ̀ ń dùn lọpọlọpọ nítorí ríràn tí o ràn án lọ́wọ́!
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Swearing in 2019: Seyi Makinde ní òun kò yan igun ẹgbẹ NURTW kankan nípọ̀sìn 28 Èbibi 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 29 Èbibi 2019 Oríṣun àwòrán, Seyi Makinde Yoruba ni o n bọ, o n bọ, awọn laa dẹ de, amọ ni ti gomina ti ilu dibo yan nipinlẹ Ọyọ, Onimọ ẹrọ Seyi Makinde, oju lo fẹ mu to.
Ṣugbọn wọn kò sọ ọ̀rọ̀ rẹ̀ ní gbangba nítorí wọ́n bẹ̀rù àwọn Juu.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ogun: Ọlọ́pàá ní iwádìí ṣì ń lórí bóyá ìyàwó ló sokùnfà bí ọkọ rẹ̀ ṣe pokùnso Ọjọru, ọjọ kẹtadinlọgbọn, oṣu Karùn-ún, ọdun 2020 ni iṣẹlẹ naa waye, sugbọn ọmọbìnrin Uwa pada ku si ile iwosan to ti n gba itọju lẹyin ọjọ mẹta.
Naijiria fi ilu Abuja silẹ ni ojo Abameta , ireti wa pe yoo pada si orile ede
 Ìwòye àwọn méjéèjì fì ìmọ ̀ ṣòkan pé ilé-ifẹ ̀ jẹ ́ ilẹ ̀ kan gbòógì láààrin òrùndún kéje sí ìkejìlá ( seventh to twenth centuries ) àti pé ilé-ifẹ ̀ ti wà ní ìletò kékèèkéé tẹ ́ lẹ ̀ rí kó tó di pé ó wá para pọ ̀ dí odidi tí ó wà lónìí yìí .
(Bursaspor FC, Turkey); Chidozie Awaziem (Caykur Rizespor, Turkey); William
ko si ẹka ọrọ aje kankan lorilẹede yii ti awọn ọmọ orilẹede Botswana ti n moke.
Ṣugbọn ti obinrin ba wa fi agidi mu ọkunrin lati ba a lo pọ nkọ?
Abileko Lami Joseph, ti o je olugbe Keffi so pe, ise agbe  ni awon obinrin igberiko mu lokunkundun,Arabinrin Joseph so pe, “pupo awon omo orile-ede Naijiria ni won n gbe ni igberiko”.
Ọkan ninu awọn ifẹsẹwọnsẹ ti ko lẹgbẹ yoo waye nigba ti ẹgbẹ agbabọọlu Chelsea yoo maa gba'lejo ẹgbẹ agbabọọlu Barcelona lẹyin ọdun kẹfa ti iru rẹ waye kẹyin.
He enjoined fasting Muslims to increase their love for humanity, acts of charity, kindness, generosity and gratitude.
Àgùnbánirọ̀ mẹ́san pàdánù ẹ̀mí wọn Tọkọtaya lu ọmọ ni gbanjo fun 400k Bayii wọn ti ko ọpọlọpọ àwọn èrò lọ kuro ni Gili nibi ti wọn ṣi ti n ko àwọn arinrinajo kuro pẹlu ọkọ oju omi.
Ajọ kan to n jẹ The Campaign Global Witness ṣalaye pe, owo epo yii ti wọn ṣe ni ọdun 2011, ti jẹ ki Naijiria kuna ni ilọpo meji owo isuna ọdun kan fun eto ẹkọ ati ilera.
O ní ọ̀pọ̀ àwọn oṣere kéèké aye ode oni ni oun ti ba kọ́wọ́ pọ la'ti ṣe àwo orin jáde àti pe àànu ọlọrun ni oun ri gba ti o si fi jẹ ẹni ti aye n fẹ titi di àsìkò yìí láti igbà ti oun ti bẹrẹ orin.
"Ọlọ́pàá fi pańpẹ́ ọba mú Ọmọyele Sowore Mo rò pé mò ń jà fún Islam ni, ó pẹ́ kó tó yé mi – Boko Haram tẹ́lẹ̀ Èèmọ̀ rèé o, Dókítà yọ eyín 526 lẹ́nu ọmọ ọdún méje ""Àlùfàá méjì wà lára àwọn mẹ́rin tó fi ipá bámilòpọ̀"" Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Imperial Majesty ni Olubadadan, Royal Majesty làwa, òfin sì tẹ̀lé e - Ọtun Olubadan Bẹẹ ba gbagbe, laipẹ yii ni BBC Yoruba mu iroyin wa fun yin pe ara osere tiata naa ko ya lasiko to fi lọ fun eto Hajj nilu Mecca, ti ọpọ ọmọ Naijiria si n gbadura fun ajinde ara rẹ."
Pẹ̀lú ìbínú ni ọmọ yìí fi jáde níwájú bàbá rẹ̀.
”“Inu mi dun, o si buyii kun mi lopolopo lati je okan lara iko agbaboolu yii!
Sùgbọ́n ṣe ẹ mọ̀ pé kìí ṣe òun ni ẹni àkọ́kọ́ tí yóò dèrò ẹwọn nítori ẹsùn ìwà ọdaran tó wáyé nínú ọgbà ilé ìjọsin wọn Onírúurú ẹ̀sùn si ni ó ti gbé ọ̀pọ̀ dé ọgbà ẹwọn lẹ́yìn ti wọ́n ṣe ẹjọ wọ́n tán, láti orí ìpànìyàn dóri ìfipá bánilòpọ̀ àti olè jíjà Ọjọ́ ìdájọ́ déé!
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Oyo state: Rauf Adeniyan, igbákejì gómìnà ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́ ní àwọn ọ̀tá ìdàgbàsókè ló ń gbé ìròyìn ààwọ̀ láàrín òun àti gómìnà Makinde 14 Èbibi 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 27 Èbibi 2020 Oríṣun àwòrán, Rauf adeniyan Igbakeji gomina ipinlẹ Ọyọ, Oloye Rẹmi Ọlaniyan ti sọ pe ko si idi ija kankan laarin oun ati gomina Seyi Makinde gẹgẹ bi awọn eeyan kan ṣe n sọ kiri.
Ẹ ti mú kí ọ̀nà yín wọ́,ẹni tó bá ba yín rìn kò ní ní alaafia.
Orukọ wọn ni Kazeem Iyanda Olabankẹwin ati Jamiu Olabankẹwin.
“Ègún ni fún ọjọ́ tí wọ́n bí mi,ati alẹ́ tí wọ́n lóyún mi.
Ẹ̀wẹ̀, ó jẹ́ ọ́kan lára àwọn díẹ̀ tó bu ẹnu àtẹ́ lu kìkọlù àwọn àjèjì ní South Africa lásìkò ìṣèjọba ààrẹ Thabo Mbeki.
Ile ẹjọ naa ni ẹjọ kotẹmilọrun ti oludije ẹgbẹ oṣelu PDP, Ọjọgbọn Oluṣọla Ẹlẹka gbe wa si iwaju rẹ ko munadoko to.
Kaini bá kúrò níwájú OLUWA, ó lọ ń gbé ìlú tí ń jẹ́ Nodu.
Nigba to n sọ asiri ẹrọ naa fun ileesẹ BBC, ọkunrin ọhun salaye pe, ọna lati yọ awọn ọmọ Naijiria kuro ninu okunkun, ki wọn si maa ri ina ọba lo ni owo ti ko gunpa lo ti oun lati se ẹrọ amunawa naa.
Bí mo bá ṣe nǹkan kékeré fún ọ a máa jọ ọ́ lójú, ìwọ a sì máa sọ̀rọ̀ mi ní rere fún àwọn ènìyàn gbogbo.
Ẹgbẹ alagbelebu pupa lagbaye si ti se apejuwe isẹlẹ ajalu yii gẹgẹ bii eyi to lagbara julọ, to si ba ni lẹru.
"Àkóràn àrùn náà a má a wáyé nípasẹ ̀ jíjẹ oúnjẹ tàbí mímu omi tí ẹyin aràn tí à npè ní "" ascaris "" náà , èyítí ó ti inú ìgbọ ̀ nsẹ ̀ jáde wá , bá ti kó sí , tí ó sì ti sọ di àìmọ ́ ."
Pàápàá ní ọdúnnìí tó tún bọ́ sí àrin ìdíje nlá méjì tí ìlú London gbà lálejò.
Nítorí èyí, mo fẹ́ kí ẹ mọ̀ pé, ohun gbogbo tí ẹ bá bèèrè ninu adura, ẹ gbàgbọ́ pé ẹ ti rí i gbà, bẹ́ẹ̀ ni yóo rí fun yín.
Ọkan lara awọn aṣofin ni orilẹ-ede South Africa, Julius Malema lo sọju abẹ niko ninu imọran to fun Aarẹ Ramaphosa ti wọn ṣẹṣẹ tun yan ni South Africa.
Góòlù pọ̀ ní ìlú Madaka ṣùgbọ́n wọn kò ní ọ̀nà fún ọgọ́rùn ún ọdún Kò sí ẹnikẹ́ni tó kú níbi rògbòdìyàn tó wáyé lánàá - Deji ilu Akure Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Cancer: Àṣe ara mi ni iso ti n run gbogbo bí mo ṣe n ṣèrànwọ́ lórí jẹjẹrẹ Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 3 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 5 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Ohun tó wù kí ileẹjọ́ kòtẹ́milọ́rùn sọ, Adeleke kò lè di gómínà Ọ́ṣun - APC Ará ìlú dájọ́ oró fún ọkùnrin to bẹ́ orí ẹ̀gbọ́n rẹ̀ ní Cross River Èrè ńlá ńbẹ fáwọn obìnrin nínú okoòwò ọ̀fẹ́ ní Áfíríkà Ilé ẹjọ́ gba onídúró Naira Marley pẹ̀lú mílíọ́nù méjì náírà Liverpool fiya jẹ Tottenham lẹẹmeji ti wọn ti koju Tottenham ni saa bọọlu yii.
Ẹ kò gbọdọ̀ jẹ ajá mọ́' Ọjọ kẹrindinlogun oṣu karun un ọdun 2020 ni agbo naa balẹ si orilẹede Naijiria.
lawọn wọọdu miran, eeyan marundinlogun lo n wa lori ila lẹẹkanṣoṣo ti awọn ọmọ ẹgbẹ si n ṣe afihan kaadi ọmọ ẹgbẹ wọn lasiko ti wọn fi n reti ati dibo.
Toshiyuki Doi, olùdámọ̀ràn àgbà fún Mekong Watch, ní èyí láti sọ:
’Nítorí pé gbogbo wọn ni wọn óo mọ̀ mí,ohun tí ó ṣẹ̀ láti orí àwọn mẹ̀kúnnù inú wọn títí dé orí àwọn eniyan pataki pataki.
Àfojúsùn jẹ ́ ohun pàtàkì tàbí information abẹ ́ nú nínú gbólóhùn .
Awọn obi ati alagbatọ ṣi n mu awọn ọmọ wọn wọle lọkọọkan-ejeeji, bẹẹ si ni ko si ẹni to wọ Hijab wọle ninu awọn akẹkọ naa.
BBC gba'lejo ife agbaye FIFA Falconets bú sẹ́kún bí Spain ṣe nà wọ́n wálé #U20WC: Flying Eagles fìyà ṣínu ààwẹ̀ lórílẹ́èdè Poland Wo àwọn agbábọ̀ọ́lù obìnrin ti wọ́n jọ máa figagbága ni France 2019 Ẹkọ mẹ́rin ti a lè kọ́ lára America: 1) Ko si ìgbà ti a ko le da aṣọ ki a tun fi wọ́lẹ̀ pẹlu iyì: Kii ṣe dandan ko jẹ pe ninu abala idije akọkọ ni ẹgbẹ agbabọọlu ti le yege ninu idije.
 ni aarin ti awọn erekusu ni awọn teide oke onina , awọn ga oke ni spain .
lataari rogbodiyan oro oselu kan tabi keji to n sele lorile-ede Togo, igbimo
Oríṣun àwòrán, EPA Àkọlé àwòrán, Tidunnu ati ayọ l'awọn akẹkọ fi pade awọn obi wọn lẹyin isẹlẹ naa O s'afikun wipe ọgbẹni Cruz wa ninu awọn ti tọju ati wipe wọn ti nawọ rẹ si awọn ọlọpa.
Má máa bèèrè pé, “Kí ló dé tí ìgbà àtijọ́ fi dára ju ti ìsinsìnyìí lọ?
Idibo naa ni yoo ṣe atọna oludije ẹgbẹ ti yoo kopa ninu idibo gomina ti yoo waye lọjọ kọkanlelogun, oṣu Kọkanla, ọdun 2019.
Iwadii miran tun fihan pe ida mọkanla ninu ọgọrun un oyun ti awọn eniyan Uganda n ni lo jẹ eyi to wu wọn lati ni funra wọn lasiko naa.
Mo ti sa ipá tèmi láti pèsè oríṣìíríṣìí nǹkan sílẹ̀ fún ilé OLUWA: wúrà fún àwọn ohun tí a nílò wúrà fún, fadaka fún àwọn ohun tí a nílò fadaka fún, idẹ fún àwọn ohun tí a nílò idẹ fún, irin fún àwọn ohun tí a nílò irin fún, pákó fún àwọn ohun tí a nílò pákó fún, lẹ́yìn náà, òkúta ìkọ́lé, òkúta olówó iyebíye, àwọn òkúta tí ó ní oríṣìíríṣìí àwọ̀, ati mabu.
Igba ti o di ilumọọka fun awọn ọmọ orrilẹede yii ni asiko ti aarẹ orilẹede nigba naa, Oluṣẹgun Ọbasanjọ yan an gẹgẹ bii oludari agba fun ajọ to n gbogun ti ilokulo ounjẹ, ohun mimu ati ogun lorilẹede Naijiria, NAFDAC laarin ọdun 2001 si 2008.
Aṣiwaju Tinubu ni asiko ti to bayii lati gbe ọlọpaa agbegbe kalẹ gẹgẹ bi ọna ati mu ki eto abo wa fun tẹru-tọmọ laisi pe araalu n kọ iha kokanmi si abo layika ati orilẹede wọn.
"Shonibarẹ ni, ""Wọn fi awakọ mi si ahamọ, lẹyin naa ni awọn ọlọpaa lọ ile re lati lọ wo boya wọn maa ri ẹri kankan, tabi awọn oun ti asẹwo naa ni o gba lọwọ oun."
“Bí ẹnikẹ́ni bá dẹ́ṣẹ̀ sí OLUWA nípa ṣíṣe èyíkéyìí ninu nǹkan wọnyi: kì báà jẹ́ pé ó kọ̀ láti dá ohun tí aládùúgbò rẹ̀ fi dógò pada ni, tabi pé ó ja aládùúgbò rẹ̀ lólè ni, tabi pé ó rẹ́ ẹ jẹ ni, 
”Ṣugbọn Eliṣa dáhùn pé, “Bí OLUWA ti wà láàyè tí ìwọ náà sì wà láàyè, n kò ní fi ọ́ sílẹ̀.
Nítorí náà, níwọ̀n ìgbà tí àwọn ọmọ jẹ́ ẹlẹ́ran-ara ati ẹlẹ́jẹ̀, Jesu pàápàá di ẹlẹ́ran-ara ati ẹlẹ́jẹ̀ gẹ́gẹ́ bíi wọn, kí ó lè ti ipasẹ̀ ikú rẹ̀ sọ agbára Satani tí ó ní ikú ní ìkáwọ́ di asán.
Ọba Siria ti pàṣẹ fún àwọn olórí kẹ̀kẹ́ ogun rẹ̀ mejeejilelọgbọn, pé kí wọ́n má lépa ẹnikẹ́ni lójú ogun, àfi ọba Israẹli nìkan.
Minisita feto ẹkọ ni saa iṣejọba akọkọ aarẹ Muhammadu Buhari, Adamu Adamu lo kede iroyin yii.
Ọlọ́pàá 200 ni yóò máa ṣọ́ ibojì Diego Maradona torí àwọn olè Obìnrin olówònààbì ta ọmọ rẹ̀ oṣù mẹ́rin ní N300,000 Ìdí tí a fi pa àwọn àgbẹ̀ onírẹ̀sì ní Borno, Boko Haram ṣàlàyé nínú fídíò tuntun Iná sọ ní abáwọlé Eko, ọkọ̀ agbépo tún tí gbiná lórí afárá Magboro Iru awọn abẹrẹ bẹẹ le to ọdun mẹwaa lati poo pọ nigba mii.
Ẹ̀ṣẹ̀ bí ẹni wí pé kí ọmọdé jẹ ẹ̀kọ mẹta nígbà tí a wí fún un pé kí ó jẹ méjì, kí á rán ọmọdé lọ sí òde kí ó máa ṣiré lójú ọ̀nà, kí ọmọdé lọ sí odò ki ó fọ́ akèǹgbè mọ́lẹ̀, ki ọmọdé wọ aṣọ tuntun lánàá kí aṣọ bàjẹ́ lónìi, kí á ṣe ìbéèrè kékeré kí ọmọdé purọ́ fún ni, kí á mu ọmọ lórí irọ́ kìínní kí ọmọ purọ́ kejì, kí á mu ọmọ lorí irọ́ kejì kí ó purọ́ kẹta, kí ó sì wáá dà bí ẹni pé ọmọdé ń gbé àpótí irọ́ kiri – gbogbo nkan wọnyi nì ó wà nínú ìwé àǹjànnú-ìbẹ̀rù tí í ṣe on;ibodè igbó Olódùmarè.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Risikat Moromoke Azeez: Inú èmí àti Òbí mi dùn nígbà ti Risi bí ọmọ olójú búlù- Wasiu Iroyin ni Ilorin Emirate Dev.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Agbekoya War: Ọta ìbọn kan ṣoṣo ló fa ogun tó fi ọ̀pọ̀ ẹ̀mí ṣòfò nínú ìtàn mánigbàgbé lẹ̀ Yorùbá 13 Ògún 2020 Oríṣun àwòrán, others Àkọlé àwòrán, Ogun Agbekoya Yoruba ni ogun ko dabi iyan, ogun ko ri bii ẹkọ, ẹni ti yoo si royin ogun, ko ni ku.
Pa Kasuma tun fi kun ọrọ rẹ pe irọ ni iroyin tawọn eeyan kan n gbe kiri pe oun ti ni ipenija pẹlu oju oun.
Cameroon (2002) Ko ṣẹlẹ ri ni Cameroon fi ọrọ jẹsi rẹ to gbe sita lọdun 2002.
Lagos State: Ẹbí èèyàn márùn ún àti àlejò kú sínú ilé l'Eko
Ẹ̀rọ ìgbàlódé tó gbajú-gbajà tí à mọ̀ sí ‘Aiyélujára’ ti s’aiyédẹ̀rọ̀ báyìí o!
Awọn sẹẹli ara yoo sọ agbara wọn nu Adinku to maa n deba awọn eroja to n sọ ẹya ara di titun jẹ ọ̀kan lara apẹrẹ pe o ti n darugbo.
"Aarẹ ni ""nibayii ti awọn orilẹede agbegbe wa ti ri ẹkọ kọ, ijọba ti ṣetan lati ṣi awọn ibode pada""."
Oríṣun àwòrán, Getty Images Owo epo ilẹ Amẹrika ti dẹnukọlẹ fun igba akọkọ ninu itan.
Ajọ NSE sọ pe oun ko ni akọsilẹ tabi iforukọsilẹ kankan nipa eto naa, ati pe o lewu fun ẹnikẹni to ba n fi owo rẹ ṣe e.
Linda ni Jayce lorukọ ọmọ naa ti o ṣapejuwe gẹgẹ bi ẹbun to dara julọ t'oun ri gba lati ọdọ Ọlọrun.
Àwọn oriṣa ni wọn óo máa bọ, èmi OLUWA yóo bínú si yín nígbà náà, n óo sì pa yín run kíákíá.
Ibadan Accident: Èèyàn méjì kú, ẹnìkan wà nílé ìwòsàn
Kílódé tí Ọọni Ife, Oba Ogunwusi kò fi gbọdọ̀ rí ọmọ rẹ̀ tuntun ti Olorì Naomi bí títí di bíi ẹ̀yìn oṣù mẹ́fà?
27 Bélú 2020 Ilé ẹjọ́ tú ìgbéyàwó ọdún mẹ́wàá ká nítorí ẹ̀sùn ìbálòpọ̀ ọlọ́jọ́ gbọọrọ àti òògùn owó26 Bélú 2020 Covid 19 vacine updates: America kan sárá si Dókítà Ogbuagbu, ọmọ Nàìjíríà tó ṣàwárí abẹ́rẹ́ àjẹsára COVID-19 àkọ́kọ́25 Bélú 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Buhari sọrọ lori idasilẹ papa ijẹko Ọwọ ologun tẹ darandaran mẹwa ni Benue O ní ìjọba òun n s'apa lati kojú ipenija aawọ darandaran àti àwọn àgbẹ eleyii ti àjọ ajafeto ọmoniyan kan lo ti gb'emi to ju ẹgbẹrun meji ló laipe yii.
Ọdún marun un lẹyìn ogun tun waye nitori ija to tẹlẹ esi ìdìbò.
Oríṣun àwòrán, Presidency of Ghana Àkọlé àwòrán, LOati igba to ti dori oye lọdun 2018, awn kan ti n naka abuku si pe ti ijọbọ ori aleefa lo n ṣe O di amofin ni ọdun 1996.
Èmi ṣì ni Jagaban, aṣíwájú Eko gangan, èmi ò lè sá kúrò l'Eko- Ahmed Tinubu Òkú ọ̀dọ́ 15 ni mo kà ní Lekki amọ́ mo kábàámọ̀ pé a gbà kí ológun gbé okù wọn lọ - DJ Switch Awọn jàndúkù yabo ilé Sẹ́nétọ̀ Teslim Folarin, wọ́n kó ẹ̀rọ ata, ọ̀kadà, fírìíjì àti àwọn nkan tí owó rẹ̀ tó N200m Amọ sibẹ sibẹ Erelu ni oun ri bi awọn ọdọ naa ṣe n sọrọ pẹlu ibinu oun si ni imọlara rẹ gẹgẹ bi iya tori bi eeyan ba n ba ọmọ sọrọ, o ni iru esi to yẹ keeyan ri.
Awọn janduku naa si lo gbe ọpa asẹ, bata, owo ati eroja ounjẹ lọ ninu aafin ọba naa, koda, wọn ba aafin ọhun jẹ kanlẹ, to fi mọ adagun omi iwẹ ọba, taamọ si swimming pool.
Ọmọ tuntun tí ìyá tó bá ní àrùn jẹ ̀ dọ ̀ jẹ ̀ dọ ̀ b bá bí a máa gba abẹ ́ rẹ ́ àjẹsára jẹ ̀ dọ ̀ jẹ ̀ dọ ̀ b pẹ ̀ lú imunogulobulínì .
Orúkọ ìyá rẹ̀ ni Nehuṣita, ọmọ Elinatani ará Jerusalẹmu.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ijamba baalu Ethiopia Ọgbẹni Paul Njoroge ati baba iyawo rẹ John Quindos Karanja fi ibanujẹ kuro nibi eto isinku ọhun lẹyin ti wọn ko ri oku iyawo wọn ati awọn ọmọ to ku.
Iko agbaboolu Tanzania gbo igi ewuro soju iko akegbe won lati orile-ede Uganda pelu ami-ayo meta(3-0), ni papa isere National Stadium niluu Dar es Salaam, lojo Aiku(Sunday).
Interpol ko darukọ wn lẹkunrẹrẹ ninu atjade naa ṣugbọn wn ni awọn tọwọ tẹ wa lara ikọ onigbajuẹ to pin si ẹka lorisirisi.
 ní1900 osborne ti ń ṣiṣẹ ́ gẹ ́ gẹ ́ bíi aṣenilẹ ́ ṣọ ́ .
Máa ṣọ́ ara rẹ ati ẹ̀kọ́ rẹ.
6m ni mo fi borí Buhari, ojú òpó INEC gan leè jẹ́rì si - Atiku Atiku n ṣé iranran lórí ìbò 1.
Eyan ti arun naa ti nawọ gan labẹ ayẹwo lapapọ ni Naijiria jẹ 43,151.
O ni : “igbimọ ijọba apapọ si duro ni digbi .
Ikọ̀ ọmọogun Naijiria ti kéde ‘Operation positive identification’!
Ó ní òun óo fi mí ṣe ìmọ́lẹ̀ fún àwọn orílẹ̀-èdèkí ìgbàlà òun lè dé òpin ayé.
Ile ișẹ ọlọpaa, ninu atẹjade ti kọmisọna ọlọpaa nipinlẹ Oyo, Joe Nwanchukwu fọwọsi, wa rọ ara ilu lati se atilẹyin fun wọn ki wọn le e ri afurasi naa mu nitori iranlọwọ ara ilu ṣe pataki pẹlu.
Leah Sharibu ṣì wà láàyè - Iléeṣẹ́ Aarẹ Buhari Adeboye sọ̀rọ̀ lórí ètò pápá ìjẹko RUGA Ọwọ́ EFCC tẹ ọ̀kan lára àwọn ti FBI fi èsún jìbìtì kàn!
8bn) ti oun san si àsùnwọ̀n ti EFCC n ko owo pamọ si ni Banki Apapọ, laarin ọjọ, oṣu Karùn-ún, si ọjọ, oṣu Kẹfa, ọdun 2016.
Àkọlé àwòrán, Ẹnu ọ̀nà yìí ló yẹ́ kí ìwọ́se Revolution Now ó ti bẹ̀rẹ̀ l'ékòó, ṣùgbọ́n kò sí olùwọ́de kankan ni ààrọ̀ kùtù Àkọlé àwòrán, Kìíṣe ẹnu ọ̀nà pápá ìṣeré nìkan ni àwọn òṣìṣẹ́ aláàbò dúró sí.
1800 fun dola kan , 0.
Ajimobi: Obaseki, Ambode àtàwọn gómìnà míràn tí tírélà gba ààrín àwọn àtàwọn bàbá ìsàlẹ̀ wọn kọjá
Ere apanilẹrin lo ma nse lọpọ igba, paapaa ninu ere ''Muniru ati Ambali''.
Wọ́n fi ẹ̀mí wọn wéwu láti gbà mí lọ́wọ́ ikú.
Bẹẹ ba gbagbe Olori Badrat ni ariwo sọ nigba kan pe wọn lo ni ifẹ ikọkọ pẹlu Ọba Fuji,Wasiu Aynde Marshal.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Victor Osimhen Salary: $96m ni wọ́n ra atamátàsé náà láti Lille 31 Agẹmo 2020 Oríṣun àwòrán, @ZachLowy Ẹgbẹ agbabọọlu Napoli ti tọwọ bọ iwe adehun lati ra ọmọ Naijiria to n gba bọọlu fun ikọ Lille, Victor Osimhen.
Oríṣun àwòrán, AFP Ko da ọjọ Aje ni yoo ba minisiat naa yoo bawọn aṣoju orilẹede ṣepade.
Ìkọlù Shiite àti ọlọ́pàá Ikọ̀ aláàbò Nàìjìríà dojú kọ Shiite Àgùnbánirọ̀ akọ̀ròyìn Channels náà ti dágbére fáyé látààrí ìkọlù Shiite l'Abuja Dúkìá àti ọkọ̀ jóná, ọlọ́pàá mẹ́sàn-án fara gbọta lásìkò ìwọ́de Shiite Opọlọpọ ẹmi ati dukia awọn eeyan lo ti ba iṣẹlẹ iwọde awọn Shiite rin ni Naijiria.
Rebeka bá ranṣẹ pe Jakọbu, ó wí fún un pé, “O jẹ́ mọ̀, Esau ẹ̀gbọ́n rẹ ń dá ara rẹ̀ lọ́kàn le pẹlu ìpinnu láti pa ọ́.
Àkọlé àwòrán, Oja bẹrẹ nibi ti wọn ti n ta elubọ - ojulowo ọmọ ilẹ Ibadan kii fi ọka ati gbẹgiri pẹlu eweedu ṣere Àkọlé àwòrán, Ọja alẹ wọpọ nilẹ Yoruba gẹgẹ bi o ṣe wa laye atijọ - ero witiwiti lo maa n yọju sibi ọja alẹ lati ra nkan ọbẹ Àkọlé àwòrán, Ijapa yi ni wọn n pe ni Alagba.
Ẹkẹrindinlogun mu Hananaya, òun ati àwọn ọmọ rẹ̀ ọkunrin, ati àwọn arakunrin rẹ̀ jẹ́ mejila.
Aara ti san, atẹgun nla ati iji lile ti fẹ pẹlu, koda, iji ti ja lorilẹede Naijiria, eyi to ti dunkooko mọ eto irẹpọ ati isọkan orilẹede yii, diẹ si lo ku ki orilẹede yii tuka.
Nítorí yóo pàṣẹ fún àwọn angẹli rẹ̀, nítorí rẹ,pé kí wọ́n máa pa ọ́ mọ́ ní gbogbo ọ̀nà rẹ.
Iroyin sọ pe niṣe ni awọn ọdọ naa le e kuro laarin wọn bi ẹni le ajá, nibudo iwọde kan, ti wọn ko si gba a laaye lati ba wọn sọrọ.
Oun gan ni imaamu agba msṣalaṣi Murtal a ni ilu Kano.
Iyọnipo Sanusi ko bofin mu, a le gba ile ẹjọ lọ Ẹwẹ, agbẹjọro Sanusi Abubakar Mahmoud ti sọ pe iyọnipo ati aṣẹ ki Sanusi fi ilu silẹ tako ofin.
Àṣẹ́ bí èmi ti jókòó  wọ̀n-ọnnì, ẹnìkan ń bẹ ní igbó ṣúúrú kan lẹ́bàá ọ̀dọ́ mi, bẹ́ẹ̀ ni èmi kò mọ̀ tẹ́lẹ̀ ní tèmi, jíjókòó ni mo jókòó tí mo ń wo iwájú, n kò sì eo ibi kọ́lọ́fín tí ó yí mi ká gbogbo.
Ẹ yé irọ́ pa, mí o fún Super Eagles ní ẹbùn owó kánkan -Sanwo Olu Èyí ni ọ̀nà tí àwọn obìnrin n gbà kó ara wọn sí wàhálà nítorí ara bíbó Awọn miran n fi oju sunnukun wo ọrọ Remi Tinubu pe, ṣe o ṣeeṣe fun awọn aṣojuṣofin lati daabo bo ara wọn gẹgẹ bii ibeere Remi Tinubu Ni ipari awọn kan gba pe onile ni lọwọ, alejo naa di mẹru ni ọrọ awọn mejeeji Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
A o maa mu ẹkunrẹrẹ iroyin naa wa fun yin ni kopẹ kopẹ.
' O saleye pe ki wọn to pada si Naijiria, Busari wa pẹlu ikọ to n bojuto awọn ọmọ Naijiria to wa ni Beirut, Lebanon, lẹyin ti wọn gba pada lọwọ olowo rẹ.
Ṣugbọn mò ń bọ̀ láìpẹ́, bí Oluwa bá fẹ́.
Ni ibudo idibo ti wọ́n ti kọ Àkọlé àwòrán, Ẹ̀yin ti Ondo, èsì ẹgbẹ́ òṣèlú rèé Kí ló ń ṣẹlẹ̀ nípa olùwọ́de EndSARS tí wọ̀n yìnbọ̀n lù ní Ogbomosho?
Nibayii, eeyan 1,054 lo ti ba ajakalẹ arun naa lọ ni Naijiria.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù World Environment Day: Atẹ́gùn burúkú ń pa mílíọ̀nù 8.
Ọlọrun ti ṣe ètò àwọn ẹ̀yà ara ní ọ̀nà tí ó fi fi ọlá fún àwọn ẹ̀yà tí kò dùn ún wò, 
lẹ ́ hìn alárẹ ̀ ni lúwà ( olÙ-ÌwÀ ) náà dé láti aṣálẹ ̀ núbíà .
Wọ́n kó kúrò ní Efurata ti Bẹtilẹhẹmu, ní ilẹ̀ Juda, wọ́n kó lọ sí ilẹ̀ àwọn ará Moabu, wọ́n sì ń gbé ibẹ̀.
Ọjọ́bọ̀, ọjọ́ kẹrìnlá, oṣù Kẹsàn án ni Àárẹ Muhammmadu Buhari buwọ́lu ìyànsípò Yusuf Magaji Bichi, gẹ́gẹ́ bi Olùdarí Àgbà fún àjọ Ọ̀tẹlẹ̀múyẹ́ DSS.
ÌYÀTỌ̀ TÍ Ó WÀ LÁÀRÍN ÍN ELÉTÙ ÒDÌBÒ ÀTI BÁÁLẸ̀
Ni kete ti wọn ri wa, awọn ọmọ ẹgbẹ okunkun one million boys ba bẹrẹ si ni yinbọn, nibi ti awa pẹlu naa ti ṣina ibọn bolẹ fun wọn ni a ti pa Abiọla Ebila, ti a si wọ inu akọku ile naa lọ nibi ti a ti ri ẹni ti wọn ji gbe naa ti orukọ n jẹ Olufẹmi Awogboro ti a si doola ẹmi rẹ.
Bí ó bá rí bẹ́ẹ̀, fi ọlá ati ìyìn ṣe ara rẹ lọ́ṣọ̀ọ́,kí o sì fi ògo ati ẹwà bo ara rẹ bí aṣọ.
Angelique kidjo pe fun anfani f'awọn obinrin Wo ìdí tí Tẹni, ọ̀dọ́mọdé olórin obìnrin kìí fi ń ṣí ìhòhò rẹ silẹ̀ Àwọn obinrin wa lè máa rìrìnàjò lọ orilẹ̀èdè míì báyìí - Ìjọba Saudi Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Fídíò, Akomolede àti Aṣa: Ọ̀rọ̀ Ẹ̀yán ni Bunmi Femi Amao ń kọ́ wa lórí ètò Akọ́mọlédè àti Àṣà lórí BBC Yorùbá24 Owewe 2020 Fídíò, Akomolede ati Aṣa lori BBC:Wo ìrúfẹ́ ìgbeyàwó méje tó wà nílẹ̀ Yorùbá àti ojúṣe Alárinà10 Bélú 2020 Fídíò, Akomolede ati Aṣa lori BBC: Kí ní ìtúmọ̀ Sílébù àti àmi ohun tó ń fún ni?
Ìkébé mi tóbí ju ohun tí mo lè dọwọ́ bò lọ, n kìí fí ṣakọ- Nkechi Blessing Bí èsì ìdìbò gómìnà ìpínlẹ̀ Ondo se ń jáde rèé.
Bẹ́ẹ̀ ni ó sì máa ń rí nígbà gbogbo.
O ni oun n pe ipe naa nitori iha ti ijọba apapọ kọ si iwọde End SARS.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ondo Kidnap: Àwọn ajínigbé tú adájọ́ kóòtù àpapọ̀ sílẹ̀ lẹ́yìn ọjọ́ márùn ún lákàtà wọn 26 Ọ̀wàrà 2019 Oríṣun àwòrán, The Nigeria Lawyers Onidajọ Abdu Dogo ti awọn ajinigbe kan ji gbe lọjọ Iṣẹgun ọsẹ yii ti gba itusilẹ oGéńdé agbébọn jí adájọ́ gbé lọ ní ìpínlẹ̀ Ondo.
Cow rustlers caught: Ọwọ́ tẹ́ àwọn ọkùnrin mẹ́ta tí wọ́n jí Màálù kó ní Ogbomọṣọ- Àjọ NSCDC
Ọ̀pọ̀ òpópónà la fi sọrí Obasanjo ní Kano, ni a kò ṣe fi ibùdókọ̀ rélùwéè sọrí rẹ̀ - Buhari Oríṣun àwòrán, others Oriṣiriṣi awuyewuye lo ti n waye lati igba ti ikede jade pe Aarẹ Muhammadu Buhari ti fi orukọ àwọn ọmọ Naijiria kan sọ ibudokọ oju'rin.
Ikorodu Road / Anthony Clover leaf Bridge Ijọba ibilẹ Somolu / Ikeja 17.
Ọ̀tẹ̀ náà sì ti gba ẹ̀yẹ ìdílé
Sọ àsọtẹ́lẹ̀ orílẹ̀èdè tí yóò borí ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ t'òní Ola Aina, àwọn akẹgbẹ́ rẹ̀ bá BBC sọ̀rọ̀ lórí owó àjẹmọ́nú wọn Ààrẹ fi nǹkan ọkùnrin rẹ̀ pa mí lójú, kó tó fipá bámi lòpọ̀ - Ọmọge Arẹwà Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fọ́nrán ohùn, Ruga settlement: YCE ní ìjọba àpapọ̀ ko tó bẹ̀ẹ́ láti kọ́ àgọ́ Fulani sílẹ̀ Yoruba Aladesewa ni awọn gba tẹle wọn ti oun si ba ọkan ninu wọn.
Lati oṣu keji, ọdun 2018, eyi ni igba akọkọ ti wọn yoo maa yọ ọwọ Manchester City kuro ni ifẹsẹwọnsẹ idije bọọlu abẹle (League cup ati FA cup) Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ọmọ Yahoo tú àṣírí ara rẹ̀ fún, bí wọ́n ṣe ń ṣe é BBC Yorùbá Igba mẹfa ọtọọtọ sẹyin ni Arsenal ti di igbaju olooyi ru awọn ikọ to gbe ife ẹyẹ naa dani ni ọdun to ba tẹle aṣeyọri wọn.
O sọ pe ọlọpaa kan arakunrin Emmanuel Gene lo ṣi yi wa lọdọ awọn ajinigbe yi ati pe awọn ti da ọlọpaa sita lati ṣawari rẹ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Badagry Historical Wells: Omi inú kànga Wawú ló ń kó ọpọlọ àwọn ẹrú lọ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Badagry Historical Wells: Omi inú kànga Wawú ló ń kó ọpọlọ àwọn ẹrú lọ 28 Ògún 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 14 Òkùdu 2020 Ilu Badagry kun fun ọpọ itan to nii se pẹlu owo ẹru, a ko si lee sọ itan owo ẹru ni Naijiria lai ma darukọ Badagry.
Mo jí ní òwúrọ̀ kutukutu, mo sì kígbe fún ìrànlọ́wọ́;mò ń retí ìmúṣẹ ọ̀rọ̀ rẹ.
Yinka Ayefele, lo kede pe o ti rọrun fun oun bayii lati rin pẹlu kẹkẹ tuntun naa loju opo Instagram rẹ lọjọ Ẹti.
Muhammadu Buhari je eyi ti ko lafiwe , ti o si je eyi ti awon eniyan lee foju
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, World Aids Day: Wo bí kòkòrò ààrùn HIV se bẹ̀rẹ̀ lágbàyé!
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Èyí ni àwọn arẹwà ‘ẹ̀lẹ̀ Daddy’, àfẹ́fẹ́ tí Aláàfin fi ń mí Oyè adelé alága APC bọ́ lọ́wọ́ Ajimobi, Buhari fòǹtẹ̀ lu Giadom Ọkùnrin kan bá ọmọ oṣù mẹ́ta lòpọ̀, ìfun ọmọ tú jáde!
Èmi pàápàá ní ìmọ̀ràn tí mo níláti fún ọ nítorí nǹkan tíó bá kàn ọ́ kan mí.
Ọpọlọpọ awọn eniyan to ba ni arun Coronavirus ko ni awọn apẹẹrẹ to koja agbara ju.
Lẹ́yìn odi ìlú kọ̀ọ̀kan, kí ẹ wọn ẹgbaa igbọnwọ ní ìhà kọ̀ọ̀kan ní ìhà ìlà oòrùn, ati ìhà gúsù, ati ìhà ìwọ̀ oòrùn, ati ìhà àríwá; kí ìlú wà ní ààrin.
Wàhálà bẹ́ sílẹ̀ láàrín àwọn ọ̀dọ́ ní Oke Odo ní ìpínlẹ̀ Eko Òkú sunkún òkú ní ìpínlẹ̀ Benue Àwọn òṣìṣẹ́ fásitì yóò fi ìyanṣẹ́lódì ṣẹ Nàìjíríà lọ́wọ́ lọ́jọ́ Ajé Mo dáríjì àwọn IPOB tó nà mí ní Germany nítorí wọn o m'ohun tí wọ́n ń ṣe- Ekweremadu Ṣe laipe yìí ni ọwọ ṣìkún àwọn agbófinró tẹ pupọ lára àwọn ọmọ àjọ náà ni ìpínlè Ogun, Kogi àti àwọn Ìpínlẹ̀ Abia, Ebonyi àti Imo ni ila oorun guusu Naijiria.
Ilé ẹ̀kọ́ gírámà Odùduwà College nílùú Ilé-Ifẹ̀ ni Osuolale lọ lẹ́yìn tó parí ẹ̀kọ́ alakọbẹrẹ ni Ibadan, tó sì ṣe àṣeyọrí ńlá nibẹ.
 A maa ko titi de eyi to wo inu ibudo to wo papako ti Aare ti n fo lo ni eyi to je ona lati tubo maa pese ohun amayederun  fawon ara ilu.
Gege bi aare Buhari se so,“Mo pa edun okan mi po mo tijoba apapo ati awon omo orile-ede Naijiria lapapo lati fi han si ebi ati awon obi Leah, bi ijoba se n sa gbogbo ipa wa lati mu Leah wale pelu ipo alafia ara,”Aare wa fi edun okan re han si ebi ati awon obi Leah, bee si ni O fi n da ebi naa loju pe ijoba yori daju lati gba omo naa kuro nipo ihamo.
Omọ Naijiria to jẹ gbajugbaja onkọwe itan arosọ ni, Chimamanda Ngozi Adichie tigba ami ẹyẹ o pegede ti PEN Pinter f’ọdun 2018.
Adetuberu tun sọ pe niṣe ni igbimọ ajọ PFN tun kọ lati fi iwe pe Fatoyinbo.
Ẹ wo fidio yii fun ẹkunrẹrẹ bii ọmọ Igbo, Jude Chukwuka ṣe ṣe atupalẹ owe naa.
Ẹnìkan kò sì ní kó òkú yín jọ, bẹ́ẹ̀ ni wọn kò ní sin yín.
Ẹ ma si gbagbe pe Faṣola naa ni orukọ abisọ Naira Marley gan an ṣan an.
Gbogbo ilu to wa ni agbegbe naa lo jade lati wa bawọn dunnu lori bi wọn se gba orukọ tuntun lẹyin ọpọlọpọ ọdun.
Ijamba Italy: Awọn arinrinajo fori sọta ni Macerata
Beebẹ lorisirisi awọn aworan ati fọnran fidio ti awọn eeyan se alabapin wọn lasiko ti isẹlẹ ikọlu awọn ọmọogun Naijiria yi waye.
"Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Yollywood: ""Ben Murray Bruce, jọ̀ọ́ ṣàánú ajé, kó sàfihàn sinimá mí táyé ń fẹ́"" 13 Ọ̀wàrà 2019 Oríṣun àwòrán, toyin_abraham Idi isẹ ẹni la ti n mọ ni lọlẹ, ẹni ti wọn ba si n wo, kii woran, bẹẹ ni ẹni to ba n sun, kii sun siwaju."
Ó ń kọ mi lóminú pé mi ò lè ṣe láì lo ǹkan ìṣeré ìbálòpọ̀ mi.
11 Bíkòṣepé ìwọ bá ṣe èyí, a o jọ̀wọ́ rẹ lọ́wọ́ ìwọ yíò sì dàbí àwọn ènìyàn míràn, ìwọ̀ kì yíò sì ní ẹ̀bùn mọ́.
Ó bá ń kiri gbogbo ìgbèríko odò Jọdani, ó ń waasu pé kí àwọn eniyan ronupiwada, kí wọ́n ṣe ìrìbọmi, kí Ọlọrun lè dárí ẹ̀ṣẹ̀ jì wọ́n.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Senate: Ṣé kí Nàìjíríà dín iye àwọn Sẹ́nétọ̀ tó ń ṣojú wọn kù ni tàbi ka kuku pa ipò náà rẹ́?
Mo yàra gbé ibọn mi mo bẹ̀rẹ̀ sí sálọ.
Ó bá sọ fún wọn pé, “Ẹ̀yin ni a fi fún láti mọ ohun ìjìnlẹ̀ ìjọba Ọlọrun, ṣugbọn bí òwe bí òwe ni fún àwọn ẹlòmíràn tí ó wà lóde.
Salah dá iná yá Anfield lára Messi di aláṣẹ lórí ohun eèlò tó gbé orúkọ rẹ̀ Klopp yọnu si Mo Salah Eléyìí ṣẹlẹ̀ lẹ́yìn tí Bayern Munich fìdí rẹmi pẹ̀lú ayò kan sí méjì nínú ìfẹsẹwọnsẹ̀ wọn pẹ̀lú ikọ̀ Real Madrid nínú eré bọ́ọ̀lù tó kángun sí àṣekágbá Champions League.
Koda, awọn miran sọrọ nipa Innoson Motors to n ṣe moto bii ti panapana ni Anambra ti iṣẹlẹ yii ti ṣẹlẹ Awọn eniyan Naijiria n beere ohun to ṣẹlẹ si ileeṣẹ panapana to wa ni ipinlẹ anambra tẹlẹ to fi jẹ panapana ipinlẹ Delta ni wọn duro de wa pa ina naa.
Àwọn ọba kó ara wọn jọ;wọ́n jùmọ̀ gbógun tì í.
O rọ awọn ọmọ Naijiria lati kọ eti ikun si iroyin naa.
"Alága àjọ INEC, Ọ̀jọ̀gbọ́n Mahmood Yakubu, wá fi dá àwọn èèyàn ìpínlẹ̀ Èkìtì lójú pé, àjọ náà kò ní ṣègbè lásìkò ìdìbò náà.
Ibikíbi tí wọn kò bá ti gbà yín, tí wọn kò gbọ́ ọ̀rọ̀ yín, ẹ jáde kúrò níbẹ̀, kí ẹ gbọn eruku ẹsẹ̀ yín sílẹ̀ gẹ́gẹ́ bí ẹ̀rí láti kìlọ̀ fún wọn.
oṣelu Social Democratic Party, SDP nibi tó ti dije gẹgẹ bii gomina ipinle Oyo
Ó yá gbọ́ ìtumọ̀ tí àwọn èèyàn fún 'Àródan' nínú fọ́rán yìí Ṣé ọ̀rọ̀ yìí ò wa tóbi jù láti túmọ̀ sí Yorùbá?
Ọpọ iran to n bọ lẹyin, ni yoo si maa ka itan nipa ohun ribiribi ti akinkanju ọmọ Yoruba yii gbe ile aye se.
A kò fòfin de owó naira tó ti pẹ́ ní Naijiria -CBN Ẹ yé gba owó orí níbi ìdána ìyàwó mọ́, sísọmọbìnrin s'óko ẹrú ni- Daddy Freeze Ọwọ́ ọlọ́pàá ti tẹ ọkùnrin kan tó pa ọ̀rẹ́ rẹ̀ nítorí N40 ní Kano Wọ́n mú ọjọ́ ìgbẹ́jọ́ agbésúnmọ́mí 9/11 tó ṣẹlẹ̀ l'Amẹrika Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Má jẹ́ kí ẹnikẹ́ni kẹ́gàn rẹ, nítorí pé o jẹ́ ọ̀dọ́.
Ẹru ba mi pupọ, mo si ro o pe boya ki n sọ fun awọn obinrin mi i to n ba ni ibalopọ.
Kí ó tó dá wọn, ó ti ṣe ìpinnu tẹ́lẹ̀ nípa ìgbà tí wọn yóo gbé ní ayé ati ààlà ibi tí wọn yóo máa gbé.
Lara ẹsun ti wọn fi kan Batubara ni pe o gba owo to le ni miliọnu kan dollar lọwọ awọn agbaṣẹṣe meji ti ijọba gbeṣẹ fun lati pese ounjẹ fun awọn ti arun Covid-19 ṣakoba fun eto ọrọ aje wọn.
A o ni orile ede miiran yato si orile ede Naijiria.
Luis Enrique bowolu iwe adehun odun meji pelu orile-ede naa.
Ìṣẹlẹ yìí sí ti mu kí ọpọ bẹnu àtẹ lú ètò ààbò lorílẹ̀-èdè eleyii ti wọn ní ko gbámúsé.
 Nipase yii, a o pese ise fun ara ilu, besini sisowo karakata ero igbalode ohun fun awon orile-ede ile Afrika yooku naa, ko ni gbeyin.
Àwọn ọkunrin tí wọ́n wá láti inú ẹ̀yà Gadi láti darapọ̀ mọ́ Dafidi, ní ibi ààbò tí ó wà ninu aṣálẹ̀ nìwọ̀nyí; akọni ati ògbólógbòó jagunjagun ni wọ́n, wọ́n já fáfá ninu lílo apata ati ọ̀kọ̀, ojú wọn dàbí ti kinniun, ẹsẹ̀ wọn sì yá nílẹ̀ bíi ti ẹsẹ̀ àgbọ̀nrín lórí òkè.
Wọ́n pa Jonatani ati Abinadabu ati Malikiṣua, àwọn ọmọ Saulu.
Àkọlé àwòrán, Gbogbo oludibo n woju ajo INEC nipinle Rivers Awọn agbofinro, ọtẹlẹmuyẹ, ọmọ ogun ilẹ̀ ati awọn ẹṣọ alaabo ilu ti awa ara wa ni wọn n ṣayẹwo kikun fun gbogbo awọn to ba fẹ wọnu ọgba naa.
14 Dúró ṣinṣin nínú iṣẹ́ náà èyí tí mo ti pè ọ́ sí, àti pé irun orí rẹ kan kì yíò sọnù, a ó sì gbé ọ sókè ní ọjọ́ ìkẹhìn.
Odu ni Biden kii ṣe aimọ foloko lagbo oṣelu Amẹrika to si wa ninu ẹgbẹ Democrat.
OLUWA ju gbogbo orílẹ̀-èdè lọ,ògo rẹ̀ sì ga ju ọ̀run lọ.
Obìnrin kò nílò láti gbé tí ó pọ̀ ju bó ṣe yẹ lọ, ìwọ̀nba èyí tí àwọn òṣìṣẹ́ ìlera bá ní kí ó mú wá náà ni, ó sì gbọdọ sọra gidi.
ní òwúrọ̀ á máa gbilẹ̀, á sì máa jí pérépéré;ní ìrọ̀lẹ́ á sá, á sì rọ.
Ìgbà tí ilẹ̀ ọjọ́ kẹta mọ hàì ni a já sí igbó àwọn ẹran kan báyìí tí wọn kò sì sá fún ni títí a fi kànj wọ́n lára.
A máa fi ìyà ẹ̀ṣẹ̀ baba jẹ ọmọ títí dé ìran kẹta ati ikẹrin.
Dokita Ratcliff ni aiṣe ere idaraya daadaa lee fa ijamba si ara.
Seyi: Ile iwe Girama ti ijọ̀ba Odogbolu, Fasiti Olabisi Onabanjo, Fasiti Caleb(mi o pari ti mo fi bẹrẹ iṣẹ), Udegbe North American Univeristy.
Èyí yóo mú kí ó rọ̀ ọ́ lọ́rùn, wọn yóo sì máa bá ọ gbé ninu ẹrù náà.
anfaani ayajọ odun Ramadan yii lati fi kẹdun pelu awon eniyan ti iko olote,
Ẹ má ṣe iṣẹ́ ibi mọ́.
“Kí ló dé tí ẹ kò fi jẹ ẹran ẹbọ ìmúkúrò ẹ̀ṣẹ̀ ní ibi mímọ́ nígbà tí ó jẹ́ pé, ohun tí ó mọ́ jùlọ ni, tí ó sì jẹ́ pé ẹ̀yin ni OLUWA ti fún, kí ẹ lè máa ru ẹ̀ṣẹ̀ ìjọ eniyan yìí, kí ẹ sì máa ṣe ètùtù fún wọn níwájú OLUWA.
Opo awon ololufe boolu afesegba, ti won n ta tete lo gbowo lori orile-ede Colombia pe won yoo bori, sugbon omi poju oka lo.
Gbogbo wọ́n jọ ń lọ sí ọ̀nà apá ijù.
Won ti kinlo fun awon omo orile-ede Libya latojo pipe, lori akoba awon omo-ogun olote ti won ni ajosepo pelu awon omo-ogun olote ijo al-Qaeda ti won n fi apa gusu orile-ede Libya se ibujokoo.
Agbẹnusọ fun ajọ NAFDAC, Dokita Abubakar Jimoh ṣalaye pe oṣu mẹta lajọ naa maa fi n ṣe iru ayẹwo bẹẹ, ṣugbọn o ni ayẹwo agbo Madagascar ko ni pẹ rara.
Tí o bá jẹ́ wọ̀bìà eniyan, ṣọ́ra,kí o má fi ọ̀bẹ lé ara rẹ lọ́fun.
Oríṣun àwòrán, Babcock University Atẹjade naa fikun pe kii se inu ọgba fasiti naa ni awọn mejeeji ti n se asemase naa to waye losu kẹrin ọdun 2019, bikose ile iwosan St Bridget to wa nilu Abeokuta nibiti ọmọkunrin naa ti n gba itọju lọwọ.
Eyí a máa fúnni ní ìmísí ayọ̀, a sì máa lé ìrẹ̀wẹ̀sì sí kọ̀ọ̀rọ̀.
nipa ibasepo to wa laarin orile ede Naijiria ati orile ede Naijiria.
william bliss baker ( Ọjọ ́ kẹtàdínlọ ́ gbọ ̀ n oṣù kọkànlá ọdún 1859 - ogúnjọ ́ oṣù kọkànlá ọdún 1886 ) jẹ ́ ọmọ bíbí Ìlú amẹ ́ ríkà , tí ó jẹ ́ oníṣẹ ́ ọnà tí ó bẹ ̀ rẹ ̀ iṣẹ ́ ọnà ṣíṣe ní àkóko tí ilé Ìwé hudson river ń kó ' gbà wọ ' lé .
Ẹ̀jẹ̀ ẹbọ ìmúkúrò ẹ̀ṣẹ̀ ni yóo máa fi ṣe ètùtù náà lórí rẹ̀ lẹ́ẹ̀kan lọ́dún ní ìrandíran yín.
Iṣẹlẹ ijinigbe, paapaa jiji awọn oloṣelu ati ọbalaye gbe ti n di gbọnmọgbọnmọ bayi nipinlẹ Ondo.
Olamide wa beere fun iranlọwọ latọdọ ijọba lati lọ kọ ẹkọ ni ile ẹkọ nipa imọ ẹrọ, ki oun lee se ohun nla-nla ti yoo jẹ itẹwọgba fun gbogbo eeyan agbaye ati awọn ijọba ni orilẹede agbaye.
O ni lilo ọtẹlẹmuyẹ to peye jẹ ọna lati koju ipenija Boko Haram.
 dìgbòlugi lèràn nígbà tí eranko tí ó ní lára fèkanná ha tàbí bu ẹranko tàbí ènìyàn míìràn jẹ .
kejila odun ti a wayii, nile ipinle Eko, ti o bale si Alausa, niluu Ikeja.
Lati igba naa wa lo ti di alekun-alekun fun un lagbo awọn oṣere sinima titi kan eyi to gbe jade gbẹyin, Elevator Bab.
Institute of Construction Technology and Management (Establishment)
Bernarndo Silva fi orí gbá góòlù kẹẹ̀rin sí àwọ̀n nígbà tí Nicolas Otamendi gbá ìkaàrún un sínú àwọ̀n.
Àwọn tí ó bá a wá bá ṣùrù mọ́ Jesu, wọ́n mú un.
– Seyi Makinde Ifidirẹmi Saraki-Kì ló túmọ̀ sí nínú òṣèlú Kwara?
Naamani bá lọ ti òun ti àwọn ẹṣin ati kẹ̀kẹ́-ogun rẹ̀, ó sì dúró lẹ́nu ọ̀nà ilé Eliṣa.
Agbarijọpọ ẹgbẹ awọn ajafẹtọ ni awọn pinnu lati tubọ pariwo si eti ijọba pẹlu iwọde lowurọ ọjọọru kani ijọba o tu akọroyin naa silẹ ni.
Wọn yoo fi pamọ si ibi kan ninu apo iwe ti wọn lẹ pa, eyi ti wọn ko le ṣi ti poopu ko ba paṣẹ rẹ.
Nigeria Election 2019:Awọn wò ní Gómìnà El Rufai n ba wi pẹlu ihalẹ 'body bag'
Àkọlé àwòrán, Bakan naa si ni o pọn dandan fun ajọ kolẹkodọti ni ipinlẹ Ọyọ lati ṣe iṣẹ wọn gẹgẹ bi iṣẹ.
Mo kábámò pé mo fipá bá Ìyá ẹni ọgọrin ọdún sún ní Kano- Muhammad Zulfara'u 'Ǹkan ìṣeré ìbálòpọ̀ mi ńpaná iṣẹ́ mọ́ mi lára' 'Larisa ọmọ ọdún 66 bẹ̀rẹ̀ iṣẹ́ arìnrìn oge' Àwọn akínkanjú obìnrín tó ń ṣe iṣẹ́ ọkùnrin O sọrọ lori bi oun ṣe pade ololufẹ oun, Yesufa Adenikẹ lẹnu ikọni nipa igbe aye afọju ati awọn ipenija rẹ gbogbo.
Elija ati Eliṣa sì dúró létí odò Jọdani.
Daily Trust: A kò mọ̀ ohùn tó mú Iléeṣẹ́ ológun tí ọọfisi wà ní Maiduguri àti Abuja
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Wo imọran Fọlọrunṣọ Alakija fun awọn ọdọ adulawọ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Wo imọran Fọlọrunṣọ Alakija fun awọn ọdọ adulawọ 8 Ẹrẹ̀nà 2018 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 9 Ẹrẹ̀nà 2018 Ọkan lara awọn obirin adulawọ to lowo ju lagbaye, Fọlọrunṣọ Alakija, gba awọn ọdọ l'amọran lori bi wọn ti le ṣe aṣeyọri laye wọn.
Hanani, ọ̀kan ninu àwọn arakunrin mi, pẹlu àwọn kan tọ̀ mí wá láti ilẹ̀ Juda, mo bá bèèrè àwọn Juu tí wọ́n ṣẹ́kù, tí wọn kò kó lọ sóko ẹrú, mo sì tún bèèrè nípa Jerusalẹmu.
Ìlú Eko: Ààrẹ Buhari yóò sàbẹ̀wò , àwọn òsìsẹ́ gba ìsinmi l’Ọ́jọ́bọ̀
”Oludari ijoba orile-ede Japan, Shinzo Abe ti sun irin ajo re lo sile okere siwaju lataari isele omiyale ohun.
 Ó gboyè enjiníà ní ilẹ ̀ gẹ ̀ ẹ ́ sì .
Aago mẹrin aabọ ni ifẹsẹwọnsẹ yoo bẹrẹ ni papa iṣere Liverpool tii ṣe Anfield.
BBC Yoruba ṣe alaye lẹkunrẹrẹ lori ọna lati le dena aarun covid-19 lai lo oogun vitamin C.
Aare oun fun won ni gbedeke osu meta ohun ninu osu kokanla odun to koja, nigba ti o funra awon omo-ogun olote IS seku-pa awon olusin ti won le ni odunrun, nile-ijosin mosalasi to wa ni Sinai.
Ọba yóò kú, ẹrú rẹ̀ yóò r’ọ̀run
 Ṣugbọn nigba ti ọkan lara awọn obinrin naa ni ko si owo lọwọ awọn, ọkan ninu awọn afẹsun kan naa fa eti ọkan lara awọn obinrin naa lojiji lati bọ yẹti eti rẹ."
Fetí sílẹ̀ ìwọ Laiṣa,kí Anatoti sì dá a lóhùn.
Àwọn orílẹ̀-èdè sá nígbà tí wọ́n gbọ́ ariwo tí ó dàbí ti ààrá,wọ́n fọ́n ká nígbà tí o gbéra nílẹ̀.
Eyi si le yọri si eemi ti ko ṣe deede.
o darapo mo iko Super Eagles was impressed with how Ozornwafor performed in all
US Election 2020: Ta ni Kamala Harris obìnrin àkọ́kọ́ tí yóò jẹ igbá-kejì ààrẹ orílẹ̀èdè Amẹrika?
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, SS3 ní mo wà báyìí, mo sì ti gba àmì ẹ̀yẹ̀ púpò nílé-lóko gẹ́gẹ́ bí onílù - Ayansike Boya ibi ti wọn ti n woran ija laarin awọn ọlọpaa ati awọn to n ṣe iwọde ni ibọn ti ba wọn.
O tun so pe“ ohun ti a so nibi ipade ni pe , ti a ba wo eto ilana ajo eleto idibo pe ki gbogbo egbe dibo yan oludije won lati ipo aare titi de ile igbimo asofin, ko to di ojo keje ,osu kewaa odun yii.
Mo ranti ifọrọwanilẹnuwo @Tejubabyfacetv yii lọdun 2010.
Níbi tí ẹ̀ṣẹ̀ bá sì ti pọ̀, oore-ọ̀fẹ́ Ọlọrun a máa pọ̀ ju bí ẹ̀ṣẹ̀ ti pọ̀ tó lọ.
O salaye pe, ekun gusu ila-orun ni asiko fun ise ogbin , eyi to yato si ti awon agbegbe miiran lorile-ede Naijiria, o fi kun oro re pe, ni agbegbe won, eto ogbin maa n bere laarin osu keta si pari osu karun-un lodoodun.
Ekwo fikun pe, awọn oludije mejeeji ko lee fi ẹri mulẹ pe lootọ ni awọn wa ni olu ileeṣẹ ajọ INEC lọjọ naa ati pe oṣiṣẹ ajọ naa lo kọ lati gba iwe iforukọsilẹ wọn, gẹgẹ bi wọn ṣe sọ.
Ó pada wá ní ẹẹkẹta, ó sọ fún wọn pé, “Ẹ ṣì wà níbi tí ẹ̀ ń sùn, tí ẹ̀ ń gbádùn ìsinmi yín?
Àwọn ìpànìyàn mánigbàgbé tó wáyé lọ́dún 2018 Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ṣọla Allyson: Obìnrin tí kò bá rẹwà ni yóò máa ṣí ara sílẹ̀ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Alapinni Oosa ṣàdúrà fún gogbo ọmọ kúoótù, oò jíire bí?
Kí ẹsẹ̀ kẹrin jẹ́ òkúta bẹrili, ati òkúta onikisi, ati òkúta jasiperi, wúrà ni kí wọ́n fi ṣe ìtẹ́lẹ̀ àwọn òkúta wọnyi.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Iyan South Sudan: Eeyan miliọnu mẹfa ni ebi nba finra 22 Ẹrẹ̀nà 2018 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Miliọnu marun lawọn ti ohun elo iranwọ n de ọdọ wọn lorilẹede South Sudan Nkan bii ilaji awọn eeyan orilẹede South Sudan lo seese ko fara kaasa iyan eyiun bi iranwọ to tọ ko ba tete de ọdọ wọn.
Ó tẹ́ pẹpẹ kan fún oriṣa Baali ninu ilé tí ó kọ́ fún oriṣa náà, ní Samaria.
Igbesẹ rẹ yìí ló mú kí àlàáfíà jọba lágbègbè Niger-Delta lásìkò tíẹ, tí ọ̀rọ̀ ajé Nàìjíríà si dúró rẹ.
 Ó fi kun pé àwọn òṣìṣẹ́, tó n pèsè ọrọ̀, gbọdọ̀ rí ìtọ́jú tó péye gbà, pàápà bí owó ọjà ṣe gbẹ́nu s'ókè.
Buhari ní ìdìbò 2019 kìí ṣe tikú-tìyè US Shut down: Embassy Nàìjíríà kógbá nílé Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, New year message: Buhari, Jonathan, Atiku, kí àwọn ọmọ orílẹ̀èdè Nàìjíríà Ironside Pernille, to jẹ adele aṣoju UNICEF ni Naijiria ṣalaye pẹ odiwọn ẹmi gigun awọn ọmọ ti wọn maa bi ni Naijiria loni ko ju ọdun marundinlọgọta.
Oluwo ni eleyi ṣẹlẹ nitori ko si awọn ooṣa kankan mọ laafin.
Oluwo ni gbogbo ọmọ Naijiria lo ni ojuṣe lati rii pe arun naa ko gbilẹ lorilẹede Naijiria gẹgẹ bi o ti ṣẹ lawọn orilẹede kan lagbaye.
Awọn to ba ti n fi apẹrẹ arun naa han lee ko ran elomiran ṣugbọn awọn ami kan ti fi han pe, awọn to ni arun ọhun le ko ran elomiran lai ṣe pe wọn ti bẹrẹ si n fi apẹrẹ rẹ han.
Ìtàn ayé Henry Fajemirokun, olówó tó fi owó mọ Olúwa àti ènìyàn Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ọmọ ọdún méjìlá yìí sọ bó ṣe di téélọ̀ táwọn àgbà ń bẹ́rí fún Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Adeleke: Àwọn ará Ẹdẹ bẹ síta pẹ̀lú ìdùnnú lórí ìdájọ́ èsì ìdìbò gómínà Ọṣun Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Adeleke: Àwọn ará Ẹdẹ bẹ síta pẹ̀lú ìdùnnú lórí ìdájọ́ èsì ìdìbò gómínà Ọṣun 22 Ẹrẹ̀nà 2019 Oun tí a gbọ́ tí ojú wa sì rí rèé ní ìlú Ẹdẹ bí ilé ẹjọ́ ṣe kéde pé Ademola Adeleke ni olúdíje ipò gọ́mínà to jawé olúborí nínu idibo gomina Ipinlẹ Osun to kója.
Lọdun to kọja, nigba to bori ibo naa gẹgẹ bii oludije to n tako ẹgbẹ awo, lo wa si oju rẹ sita fun araye lati ri.
Johesu ń dí wa lọ́wọ́ isẹ́ nílé ìwòsàn Ifẹ̀ - Dókítà Kín ló kan ṣọ́ọ́sì pẹ̀lú ọkọ tí kò leè ta pútú?
Ní ọdún kẹrin tí Jehoiakimu, ọmọ Josaya jọba ní Juda, tí ó jẹ́ ọdún kinni tí Nebukadinesari jọba Babiloni, Jeremaya wolii gbọ́ ọ̀rọ̀ OLUWA nípa gbogbo àwọn ará Juda.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù 2018 FIFA U-20: Falconets Nàìjíríà kúrò ni France padà wálé 6 Ògún 2018 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 17 Ògún 2018 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Nàìjírìa ti ń bọ̀ wálé láti ìdíje FIFA Under 20 World Cup nílẹ̀ Faranse lẹ́yìn tí wọ́n kùnà láti tẹ̀síwájú Awọn agbabọọlu Niajiria bu sẹkun lẹyin ti ikọ agbabọọlu Spain le wọn lọ le ninu idije FIFA Under 20 World Cup lorilẹ-ede France.
Amofin omo orile-ede Tanzania ni won ti fun ni ewon osu marun-un latari pe, o so kobakugbe oro si Aare John Ponbe Magufuli ninu “oro alufansa”, nigba ti o n ba awon eniyan soro lasiko iwode kan ninu osu kejila odun to koja.
Oríṣun àwòrán, Insatagram/lizzyanjorin Gómìnà ìpínlẹ Kwara yan Kọmíṣónnà tí ó kéré julọ!
Lizzy Anjorin vs Toyin Abraham: Madam Saje, Antar Laniyan, àtàwọn míì wí tẹnu wọn
Amọ, o ni loun ti gba ẹbẹ awọn ọmọ mii tawọn naa ti ṣe aṣiṣe kan tabi omiiran.
eniyan,ti a si gbo oro lati enu gbogbo  awon ti no ni fesun kan tabi meji ati awon ti won
Lẹyin naa ni wọn rawọ ẹbẹ si awọn lati dẹkun iwa ifipa bani lopọ nitori obinrin naa waye tiwọn ni.
m ni ojú mi déédé fọ́ níbi tí mo ti ń darí ọkọ̀ ni Ọrẹgun Ikẹja -LASTMA Yesufa Mamora, Lai Mohammed, Gbemi Saraki wà lára minista Buhari tuntun Òkìtì iyanrìn wó pa èèyàn méjí nílùú Ibadan Àgùnbánirọ̀ akọ̀ròyìn Channels náà ti dágbére fáyé látààrí ìkọlù Shiite l'Abuja Osinbajo ni pẹlu oju inu ati ọgbọn atinuda Jakande lo fi mu ayipada rere ba ilana eto ẹkọ nipinlẹ Eko lasiko to wa ni ipo gomina, eyi to mu ki ayipada rere ba eto ẹkọ Naijria patapata, paapa bi wọn se pa eto ẹkọ ọlọsan rẹ patapata.
Leyin ise takun-takun, eleyi ti orile-ede Russia ti n gbese lataari sise agbateru ifesewonse idije boolu agbaye to n bo lona, won ti n reti bayii lati se ikinni kaabo awon orile-ede ti yoo kopa ninu idije ohun, ti o fi mo awon ololufe iko agbaboolu kookan jakejado agbaye.
Mo níláti sọ̀rọ̀ kí ara lè rọ̀ mí,mo gbọdọ̀ la ẹnu mi kí n sì dáhùn.
Ó sàn kí ojú ẹni rí nǹkan, ju kí á máa fi ọkàn lépa rẹ̀ lọ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ẹ̀mí sùn níbi ìkọlù Shiite àti ọlọ́pàá Lẹyin ọpọlọpọ nkan to ti ṣẹlẹ lori Ibrahin el Zakzakky ti wọn fi si atimọle ni igbẹjọ ile ẹjọ ni ki wọn kede awọn IMN gẹgẹ bii agbesunmọmi ni NaijiriaMo ṣe tán láti kú tọmọ taya bí wọn kò bá fi El-Zakzaky sílẹ̀ - ọmọ ẹgbẹ́ Shiite .
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: SERAP fẹ́ pe UI, AAUA lẹ́jọ́ lórí àfikún owó iléẹ̀kọ́ Bùhárí sọ ìdí tó fi ń díje lẹ́ẹ̀kejì Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ìṣẹ̀lẹ̀ Èkó: Aáwọ̀ Ọbàkan sọ ilé di áláwọ̀ méjì Ìdí rèé tí BBC Yorùbá se ń bèèrè pé ǹjẹ́ àwọn aráàlú mọ ipa àdínkù owó ọjà náà lára bí?
Igba wo ni o nilo lati lọ sileewosan?
Nínú ọ̀rọ̀ rẹ̀ lásìkò ìfọ̀rọ̀ wánilẹ́nuwó ni BBC, ló ni ìyá òun gan ló fá òun le àwọn eléré tíátà lọ́wọ́.
Ekeji sì wà ní apá gúsù, ó dojú kọ Geba.
Owo agba epo to wa ni ogoji dọla si ni wọn gbe isuna naa le, ti ireti si wa pe wọn yoo ri owo to din diẹ ni miliọnu meji dọla ($1.
Gbogbo awọn ọti inu ọra ati inu igo wọnyii ni ijọba apapọ ti n gbe igbesẹ lati fi ofin de e laipẹ, iyẹn bi ọrọ oludari agba ajọ to n gbogun ti ilokulo ohun jijẹ ati ogun, lorilẹede Naijiria, NAFDAC, Ọjọgbọn Mojisọla Adeyẹye ṣe sọ.
lati mọ boya iranlọwọ kankan le ti ibẹ jade.
Tóò bá mọ̀ọ́, ayé ti dáa dé báyìí láti mọ gbogbo ẹ̀tọ́ tóo ní ní èdè abínibí wa ní Nàíjíríà.
Gbọ́ irú iṣẹ́ tí Senakeribu rán tí ó ń fi ìwọ Ọlọrun alààyè ṣe ẹlẹ́yà.
Ìtàn fi yé wa pé àwọn igi náà ti wà níbẹ̀ láti ayé-báyé ni.
” Dafidi á sì dáhùn pé, “Ìhà gúsù Juda ni, tabi kí ó sọ wí pé ìhà gúsù Jerameeli tabi ìhà gúsù Keni.
" sùgbón èyí kéyií tó bá ṣẹlè , àpólà gbọ ́ dọ ̀ ní orí , títèlé àwon ohun tí òfin níní orí gbà , tí a pè ní "" endocentricity requiremrnt ' ."
Laipẹ yii ni awọn alaga ijọba ibilẹ n gbosuba kare fun ilana tuntun ti ileeṣẹ ijọba to n mojuto eto isuna National Financial Intelligence Unit, NFIU gbe kalẹ lati fun ijọba ibilẹ lagbara.
Ohun ìní àwọn ará Kalidea yóo di ìkógun; gbogbo àwọn tí wọn yóo kó wọn lẹ́rù ni yóo kó ẹrù ní àkótẹ́rùn, Èmi OLUWA ni mo sọ bẹ́ẹ̀.
" Àmọ́ ṣa, awọn ololufẹ Omah Lay ti n faraya lori ayelujara, ti wọn si n fi #freeOmahLay beere fun itusilẹ rẹ.
Ohun tí ojú ìyàwó mi rí lọ́wọ́ SARS kò ṣe é fẹnusọ- Poju Oyemade Ìjọba ìpínlẹ̀ Eko ti kéde orúkọ àwọn ọlọ́pàá tó fi ìyà jẹ àwọn olùwọ́de #EndSARS Ajínigbé tú ìyá àti ọmọ ọdún mẹ́ta sílẹ̀ lẹ́yìn tí wọ́n gba ₦1.
Iko ọmọ oogun orile ede Naijiria ti so pe  ọmọ oogun ọlọtẹ Boko Haram , Maje Lawan ti won ti n wa tele , ti wa ni ikawọ won bayii,won mu afurasi naa niluu Banki, ni ipinle Borno.
’Èṣù bá rẹ́rìn-ín díẹ̀ báyìí, èyí sì ni ìgbà kín-ín-ín tí a rí ẹ̀rín ní ẹnu rẹ̀.
Won tun pase fun adari omo ogun to n pese aabo ati iko omo ogun ori ile lati se atunse si iko omo ogun DELTA SAFE to wa ni  Niger Delta, LAFIYA DOLE ni Ila oorun Ariwa, SHARAN DAJI to wa ni  Zamfara ati ipinle  Katsina ati AWATSE  to wa ni ila Gusu.
” Alakoso eka  ile-ise to n mojuto eto ilaniloye lorile ede Naijiria, omowe Davidson Aminu naa so pe awon odo ni awon oloselu sa ba maa n lo lati da wahala ati rogbodiyan sile lasiko eto idibo.
Bakan naa, ni iko Super Eagles yoo tun koju England lojo keji osu kefa odun ti a wa yii, ni papa isere Wembley saaju ifigagbaga olorejore keyin pelu Czech Republic lojo kefa si ifesewonse ohun.
Àwọn àgbà ọkunrin níláti jẹ́ ẹni tí ó ń ṣe pẹ̀lẹ́, ẹni ọ̀wọ̀, ọlọ́gbọ́n, tí ó jinná ninu igbagbọ, ninu ìfẹ́ ati ninu ìfaradà.
Sanwo-Olu kéde ìlànà ìséde tuntun l'Eko Oríṣun àwòrán, Babajide sanwo-olu Gomina Babajide Sanwo-Olu ti dẹ okun konile o gbele ọlọjọyipo to fi sita silẹ bayii.
Dokita gbajugbaja agbabọọlu naa, Leopoldo Luque lo ṣi aṣọ loju eegun ọrọ yii fawọn akọroyin.
’Òun gan-an sì nìyí, oúnjẹ àwọn igún!
Mo fẹ́ bẹ̀rẹ̀ sí sọ̀rọ̀,ọ̀rọ̀ sì pọ̀ tí mo fẹ́ sọ.
Nígbà tí ó bá pada dé ninu ògo rẹ̀, ayọ̀ ńlá ni ẹ óo yọ̀.
Ṣugbọn àwọn Juu ń kígbe pé, “Bí o bá dá ọkunrin yìí sílẹ̀, ìwọ kì í ṣe ọ̀rẹ́ Kesari, gbogbo ẹni tí ó bá fi ara rẹ̀ jọba lòdì sí Kesari.
Ìgbádùn kò yẹ òmùgọ̀,bẹ́ẹ̀ ni kò yẹ kí ẹrú jọba lórí àwọn ìjòyè.
O ṣalaye pe ninu igbo Zango/Paula ni Kankara lawọn sọja pẹlu itanlọwọ awọn ọmogun ofurufu ti ri awọn janduku ajinigbe naa.
Amọṣa awọn alaṣẹ awọn Fulani ni ipinlẹ Ọyọ ti ṣalaye pe ko sohun to jọọ rara ati pe awọn eeyan wọn ko ni ibi kankan ti wọn n ṣi lọ gẹgẹ bi Igboho ti ṣe paa laṣẹ.
Iya mi tilẹ tuin fi oludije naa.
À kò gba owó kankan lọ́wọ́ àwọn ẹgbẹ́ agbésùmọ̀mí ISWAP- MURIC ‘Àwọn òlóṣèlú kò ní ìwà ọmọlúwàbí ló jẹ́ kí wọ́n má a lọ láti ẹgbẹ́ òṣèlú kan lọ sí òmìràn’ Àmọ̀tẹ́kùn gbéra!
Tí a fiṣọwọ́ ní 4:514:51 Buhari, Olóṣèlú àtàwọn òjíṣẹ́ Ọlọ́run ló mú àjẹbánu gogò ní Nàíjíríà"" Wolii Adegboyega Ajani wa rọ awọn ojisẹ Ọlọrun lati maa waasu tako iwa ibajẹ naa, ko le di ohun itan ni Naijiria."
O tun wa ro gbogbo omo orile ede Naijiria lati ri I pe won ko se oju saaju nipa ise akanse oju irin ti won gunle lorile ede Naijiria.
Kano lack of burial ground: Àìtó ibójì ti ń fa awuyewuye ní ìpínlẹ̀ Kano- Àwọn òṣìṣẹ́ ibojí
Gege bi ile-ise ohun se so lori ero ayelujara(Twitter):“Lasiko iwode awon omo ogun, a kofiri awon omo ogun olote boko haram yii ni agbegbe Arboko, eleyi ti o sokunfa idi ti a se sekolu si ipago won”.
" Oríṣun àwòrán, iSaac Haastrup Sugbọn ọpọ awọn olugbe adugbo naa lo ti n fapa janu lori ipinnu ajọ amunawa yii, ti wọn si ni ipa nla ni aisi ina ọba lagbegbe awọn ti n ko ba ọrọ aje ati igbaye gbadun awọn.
Amofin agba, Oloye Afẹ Babalọla (SAN) ni iwa idẹyẹsi iwe ofin orilẹ-ede Naijiria ni igbesẹ lati fa adajọ agba orilẹ-ede Naijiria lọ si ile ẹjọ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ekiti: Àyọjúràn ni Fayoṣe tó yọjú sí Ilé Igbìmọ̀ Aṣòfin l'Ekiti 30 Ògún 2019 Oríṣun àwòrán, @GovAyoFayose Àkọlé àwòrán, Fayoṣe yọjú sílé ìgbìmọ̀ aṣòfin l'Ekiti lórí ọ̀rọ̀ owó Káńsù, óní kòséwu lòko Ile Igbimọ Aṣofin ipinlẹ Ekiti ti sọ wi pe, alejo apapandodo"" ni Fayoṣe wa se lasiko ti o yọju sile igbimọ aṣofin ipinlẹ naa."
Eliṣa lọ sí Damasku ní àkókò kan tí Benhadadi ọba Siria wà lórí àìsàn.
Muazu sọ pe gẹgẹ bi oludari ere, oun yoo lo iriri naa lati ṣe sinima ti yoo gba ami ẹyẹ fun oun.
Ṣugbọn àwa ní igbagbọ, a sì ti rí ìgbàlà.
Wọn kò sì lè dá a lóhùn.
Àwọn olórí alufaa ati gbogbo ìgbìmọ̀ ń wá ẹ̀rí èké tí ó lè kóbá Jesu kí wọn baà lè pa á.
 ( Ọ ̀ la ni ó tẹ ̀ lẹ ́ òní ) .
Ẹni tí ó jẹ́ ti ayé, ti ayé ni, ọ̀rọ̀ ti ayé ni ó sì ń sọ.
 olù-wò-wèrè tàbí olù-tójú-alárùn-opolo ( psychiatrist ) ni .
N kò ní ṣe ojuṣaaju ẹnikẹ́ni,bẹ́ẹ̀ ni n kò sì ní gbèjà eniyan.
BBC lọ ṣe iwadii nipa Sima Sarkar ati ọmọ rẹ Hridoy ti àwòrán wọn jade lori bi iya rẹ ṣe pọn ọmọ ọdun mejidinlogun naa sẹyin lọ ṣe idanwo aṣewọle si fasiti Dhaka.
Mo ṣe ìrìbọmi fún ìdílé Stefana.
Klopp seleri lati mu Salah ati Mane gba ami ẹyẹ Ballon d’Or
Ìsẹ̀lẹ̀ náà wáyé ní ǹkan bí ago mẹ́jọ alẹ́ ọjọ́rú ọ̀sẹ̀ èyí tó jẹ́ àfikún ọ̀pọ̀lọpọ̀ gbọ́nmi síi omi ò tó tó ti sọ orílẹ̀èdè Somalia di ọ̀kan lára àwọn orílẹ̀èdè tó léwu fún àwọn olùtọ́tú aláìsàn láti sisẹ́.
“Mo ro awon ololufe wa lati tun bo duro sin-sin pelu iko yii lati pari si ibi ti o lapere lori tabili ni saa yii.
Gowon naa so ninu oro re pe orile ede Naijiria nilo adura, ki won si tun tesiwaju lati maa gbadura fun orile ede Naijiria.
Nítorí olukuluku gbọdọ̀ ru ẹrù tirẹ̀.
Gege bi awon ara ilu ti isele ohun soju won, o kere tan omo ogun ijoba India meta ati awon omo ogun olote metala lo ba isele ibi ohun lo lesekese.
Ẹ se ẹran náà dáradára, ẹ da omi rẹ̀ nù, kí ẹ jẹ́ kí egungun rẹ̀ jóná.
Èyí túmọ̀ sí pé, bí yóò ṣe kan olúkúlùkù kìí ṣe bákan náà, ó ṣe é ṣe kí ẹlòmíràn má tilẹ̀ mọ̀ ọ́ lára rárá.
“Alufaa yóo sì mú kí obinrin náà dúró níwájú pẹpẹ OLUWA, 
A gbọ pe ni agbegbe Elegbeka, ni awọn agbebọn naa ti jade lati inu igbo, ti wọn si yinbọn mọ ọkọ rẹ laimọye igba.
Bí ó bá jẹ́ ọ̀dọ́ aguntan ni yóo fi rúbọ, kí ó mú un wá siwaju OLUWA, 
Lẹ́yìn náà, ẹ̀yin ẹ ké pe oriṣa Baali, Ọlọrun yín, èmi náà yóo sì ké pe OLUWA.
Nibayii, ti ọdun mẹrin miran ti de, ọpọlọpọ nkan ti yi pada, Adams Oshiomọle ti le Obaseki kuro lẹgbẹ Oṣelu APC Eyi waye lẹyin ti o fi lede wi pe oun naa fẹ dije dupo gomina fun saa keji lẹgbẹ oṣelu APC.
Hajj 2018: Àwòrán bí àwọn Alálàájì àkọ́kọ́ ṣe ń gbéra l’Abuja
Ọpọlọpọ àwọn eniyan tún lọ sí ọ̀dọ̀ rẹ̀.
Arsenal fa Chelsea ya pẹ́rẹpẹ̀rẹ gba ife FA Cup Mama Arsenal ṣeé débi èrè, ẹgbẹ́ kan ti fún màmá l'ẹ̀bùn owó Olùrànlọ́wọ́ pàtàkì fún ọ̀rọ̀ ibojì òkú, àti àwọn ipò òṣèlú mìíràn tó jẹ́ kàyééfì ní Nàìjíríà Buruji Kashamu jẹ́ ènìyàn tó nífẹ̀ aráàlú- Gómínà Dapo Abiodun Baba Obasanjọ kò ní àrùn Coronavirus- NCDC Igba akọkọ ree ti gbajugbaja abẹṣẹ ku bi ojo, Tyson yoo maa lewọ ninu ẹṣẹ kikan lẹyin to ti fẹyinti ni bii ọdun mẹẹdogun sẹyin.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Kí ló dé t'awọn Gómìnà Nàìjíríà fẹ̀ yá N17trillion nínú owó ìfẹ̀yìntì òṣìṣẹ́?
Kì í ṣe àwọn tí wọ́n gbọ́ ohun tí Òfin sọ ni Ọlọrun ń dá láre, àwọn tí wọn ń ṣe ohun tí Òfin sọ ni.
Ìgbádùn wa ti pọ̀ ju nǹkan tí ènìyàn lè fi ẹnu sọ ní ìlú Ìsimi – Àlááfìà yìí.
O yẹ ki ọga mi pe aadọrin dun ninu oṣu kẹrin ọdun to m bọ.
Alukoro fun ileeṣẹ ọlọpaa nipinlẹ Ekiti, Caleb Ikechukwu sọ pe lootọ ni awọn ajinigbe tun ji awọn oṣiṣẹ ijọba ibilẹ mi i gbe nipinlẹ naa.
BBC Yorùbá ṣabẹwo si ijọba ibilẹ Ikẹnnẹ lati mọ boya àwọn eniyan ijọba ibilẹ yii n janfaani igbakeji aarẹ gẹgẹ bi ọkan lara awọn ogidi ọmọ Ikẹnnẹ.
Tabi ta ni ó mọ̀, ìwọ ọkọ, bóyá ìwọ ni o óo gba aya rẹ là?
Ọ̀rọ̀ǹpọ̀tọ̀niyùn, Aláàfin obìnrin àkọ́kọ́ rèé, tó ní nǹkan ọkùnrin Iléẹjọ́ kòtẹ́milọ́rùn ti ní Ajimobi létọ̀ọ́ láti yan ọba l’Ọyọ Oladejo Okediji àti ìgbé ayé ìtàn kíkọ rẹ̀ Eyi lo mu ki Akanbi gbe igba owo pipa adiyẹ ta.
Àwọn ìtẹ́ mẹrinlelogun ni wọ́n yí ìtẹ́ náà ká.
 bi ọlọ ́ ọ ́ dẹ tàbí olórí ọdẹ kan bá ku ni a n lù agẹrẹ .
Ẹ̀yin ará, mo bẹ̀ yín ni, ẹ dàbí mo ti dà nítorí èmi náà ti dàbí yín.
Ṣugbọn ẹ dúró ninu ìlú yìí títí agbára láti òkè wá yóo fi sọ̀kalẹ̀ sórí yín.
Won fagile  iru iyanse-lodi yii ninu osu kejila odun to koja, leyin ti awon osise ati ijoba ti fenuko lori ekunwo naa.
Egbe oselu to wa lori alefa lorile-ede Ivory Coast jawe olubori ninu eto idibo si ile-igbimo asofin ti o waye lojo-Abameta  lorile-ede naa, eyi ti awon egbe-oselu alatako ko lati kopa ninu re, latari esun pe, ajo eleto-idibo n se ojusaaju.
Arabinrin naa ni ojoojumọ lọpọ eeyan n lugbadi arun coronavirus, debi wi pe coronavirus lẹ maa ri lori foonu tabi lori ẹrọ ayelujara ati ẹrọ agbọrọkaye.
Lionel Messi: Ronaldinho ní Messi kọ́ ni agbábọ́ọ̀lù tó dára jùlọ lágbàáyé
Bẹẹ ba gbagbe , o ti to ọdun meji ti Olubadan ati awọn agba ijoye nilẹ Ibadan ti dijọ jade sita gbangba papọ bayii, eyi ko si sẹyin wahala to waye nitori bi ijọba ana nipinlẹ Ọyọ se de ade fun awọn agba ijoye mọkanlelogun nilẹ Ibadan.
Kí wọn máa ṣe nǹkan tí yóo tẹ́ wọn lọ́rùn, kí wọn má máa fún wọn lésì.
Ọkan Funmilayọ poruru nigba ti o gbọ ohun to n ṣelẹ sawọn obinrin Egba lọwọ awọn oṣiṣẹ Alake ati Ajẹlẹ ati pe, wọn n tún irẹsi ti wọn fagídí gbà lọwọ awọn obinrin tà, ti wọn n kowo rẹ sapo ara wọn.
BBC Yoruba ba akọroyin naa, Charles Eyo sọrọ Akọroyin ileeṣẹ iroyin Daily Trust Eyo Charles ti ba BBC Yoruba sọrọ lori ohun to waye laarin rẹ pẹlu Minisita Naijiria tẹlẹ, Femi Fani Kayode.
Síbẹ̀, Nàìjíríà tí tẹ àwọn òfin kan tí ó tẹ orí àwọn ẹ̀tọ́ òkè yìí bọlẹ̀.
  Oriyin Aare Muhammadu Buhari ti o gboriyin lopolopo fun awon omo orile-ede
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Aarẹ Rwanda, Paul Kagame gba eku ida adari ajọ AU 28 Sẹ́rẹ́ 2018 Oríṣun àwòrán, @channelstv Àkọlé àwòrán, Aarẹ orilẹede Congo, Alpha Conde ti gbe eku ida isejọba ni ajọ AU fun aarẹ Rwanda, Paul Kagame Ni bayii, omi tuntun ti ru, ẹja tuntun si ti wọ 'nu ẹ ninu ajọ isọkan awọn orilẹede Afrika gẹgẹ bi wọn se yan aarẹ Paul Kagame ti orilẹede Rwanda si ipo alaga ajọ naa.
Ileejọ gbe asofin agba lẹyin lati tako iyansipo.
Eyi ni awọn aworan igba ti o gunlẹ si ileẹjọ giga nilu Akurẹ lowurọ ọjọ Aje.
Adekunle ni isọri isọri lawọ n se eto pinpin owoya naa, ti ipinlẹ mejila si wa labẹ isọri kan, eyi ti yoo jẹ ko rọrun lati tọpinpin eto naa.
Bí wọ́n ti ń gbé Àpótí Majẹmu OLUWA wọ ìlú Dafidi, Mikali ọmọbinrin Saulu yọjú láti ojú fèrèsé, ó rí Dafidi tí ń jó, tí ń fò sókè tayọ̀tayọ̀, ó sì pẹ̀gàn rẹ̀ ninu ara rẹ̀.
Farao bá pàṣẹ fún gbogbo àwọn eniyan rẹ̀ pé, “Gbogbo ọmọkunrin tí àwọn Heberu bá bí, ẹ máa gbé wọn sọ sinu odò Naili, ṣugbọn kí ẹ dá àwọn ọmọbinrin wọn sí.
Oríṣun àwòrán, Global Society for anti corruption Nigba to n ba ikọ iroyin BBC sọrọ, Chisom Celestine salaye pe inu oun dun pupọ pe baba oun pada ri itusilẹ lọgba ẹwọn sugbọn o se oun laanu pe oun ko ni agbara lati lee setọju baba naa bo se yẹ.
" Ọ ̀ rọ ̀ àkọ ́ kọ ́ ní olùsọdipúpọ ̀ 3 ( ẹ ́ ta ) , ayípadà "" x "" , àti agbénọ ́ mbàga 2 ( éjì ) ."
Mo bọ̀wọ̀ fún àṣẹ rẹ tí mo fẹ́ràn,n óo sì máa ṣe àṣàrò lórí ìlànà rẹ.
Nígbà tí Dafidi fúnrarẹ̀ pè é ní ‘Oluwa,’ báwo ni ó ti ṣe jẹ́ ọmọ rẹ̀?
5 58305 Orilẹede Iceland 28 8.
Wo ọ̀nà míràn tó rọrùn láti fi se ọbẹ̀ Ẹ̀gúsí aládùn lásìkò yìí Nàìjíríà bí ìkókó 26, 039 lónìí ọjọ́ kíní, oṣù kínií, ọdún 2020- UNICEF Ó ti tán fún mí lọ́dún 2023- Ààrẹ Muhammadu Buhari Bolanle Ninalowo: Mo ṣiṣẹ́ agbèrò rí láti ṣe àṣeyege Bakan naa ni Aafa nla yii rọ awọn eniyan lati tẹpa mọ iṣẹ ki ilepa ati erongba wọn lọdun tuntun le wa si imuṣẹ.
Gẹ́gẹ́ bi àṣà ibilẹ̀ Yorùbá, àwọn ọkùnrin gbà ki iyàwó  wọn ṣe iṣẹ́ lati ran ẹbí lọ́wọ́, eyi lè jẹ́ nitori àwọn ọkùnrin ni iyàwó púpọ̀, nitori èyi, kò nira bi iyàwó kan tàbi méji bá lọ ṣòwò ni òkèèrè, àwọn iyàwó yókù yio bójú tó ilé.
”“Ilana ti a n tele yii dara , pelu gbogbo ohun ti won foju ri yii , won ri I pe ijoba ko kaare lati mu idagbasoke ba to oro aje.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Melaye tako èsì ìbò tó gbé Smart Adeyemi wọlé sẹ́nẹ́tọ̀ Ìwọ̀-òòrùn Kogi 30 Bélú 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 1 Ọ̀pẹ̀̀ 2019 Oríṣun àwòrán, Others Àkọlé àwòrán, Smart Adeyemi ti ẹgbẹ́ òṣélú APC ló borí ní àtúndì ìdìbò sípò ṣẹ́nẹ́tọ̀ ẹkùn Ìwọ̀- Òòrùn Kogi.
 ibí yìí gan-an ni òógùn ti ń bọ ́ kíkan-kíkan lára ọmọ awo tó bá le jó ju òkòtó lọ .
Nígbà náà ni mo sọ pé,‘A ti ta mí nù kúrò níwájú rẹ;báwo ni n óo ṣe tún rí tẹmpili mímọ́ rẹ?
Awọn Senatọ ni Amẹrika pe adari Facecook, Mark Zuckerberg lati wa salaye nile igbimọ asofin lori ọna to maa gba lati daabo bo akọsilẹ iroyin awọn eniyan to wa lori Facebook.
Ijba ṣe ọna bii melo kan amọ ni ilu ti eniyan to le ni miliọnu mọkanlelogun n gbe nibẹ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Arsenal: Cazorla jẹ́ agbábọ́ọ̀lù tí irú rẹ̀ ṣ'ọ̀wọ́n 21 Èbibi 2018 Oríṣun àwòrán, Arsenal Àkọlé àwòrán, Lẹ́yìn ọdún mẹ́fà, Santi Cazorla dágbére fún Arsenal Gbajugbaja agbabọọlu Arsenal, Santi Carzola, ti fi ẹgbẹ agbabọọlu Arsenal silẹ.
Ṣebí ẹ̀ka igi tí a yọ jáde láti inú iná ni ọkunrin yìí?
Ọ̀nà rẹ wà lójú omi òkun,ipa ọ̀nà rẹ la omi òkun ńlá já;sibẹ ẹnìkan kò rí ipa ẹsẹ̀ rẹ.
Ara ọtọ ni ti ẹyẹle New Kim to wa lati orilẹ-ede Belgium nitori o maa n dije ninu ere sisa.
Àwọn alufaa, àwọn wolii ati gbogbo àwọn eniyan gbọ́ tí Jeremaya ń sọ ọ̀rọ̀ yìí ní ilé OLUWA.
ṣugbọn ayé, ati ìtànjẹ ọrọ̀, ati ìfẹ́kúfẹ̀ẹ́ mìíràn gba ọkàn wọn, ó sì fún ọ̀rọ̀ náà pa, kò sì so èso.
Abraham Olusegun Michael, Gomina Rotimi Akeredolu ati Dokita Nathaniel Adojutelegan.
Saaju ami ẹyẹ yii, Asisat Oshoala ti gba ami ẹyẹ odu agbabọọlu laarin awọn agbabọọlu obinrin ni ilẹ Afirika fun ọdun 2017 losu kini ọdun 2018.
Ọba bi í pé, “Níbo ni ó wà?
àìsàn burúkú ni yóo pa wọ́n.
Odu ni, kii se aimọ fun oloko paapaa ninu itan ẹsin awọn ọmọlẹyin Kristi ni orilẹ-ede Naijiria ati iwa imunilẹru jake-jado agbaye.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Irun gígẹ̀ kọjá orí fífá lásán Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 3 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 5 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Atẹjade rẹ sọ pe irọ gbaa ni igbesẹ naa tori pe ọfiisi ẹgbẹ ko tii gba ọrọ kankan latọdọ ẹka ti ipinlẹ Ekiti lori yiyọ Fayemi kuro lẹgbẹ.
 Ajo eleto idibo lorile ede Naijiria (Independent National Electoral Commission,INEC) ati ile-se agbofinro  ti wa nikale lati mojuto bi eto idibo  gomina se n lo si ni ipinle Osun.
Wo ìpọ́njú mi, kí o gbà mí,nítorí n kò gbàgbé òfin rẹ.
Aarẹ Trump ati Kim Jong-un ti gba lati jọ ṣe'pade
Ni asikọ ti ọdọmọkunrin naa yibọn l'ọwọ, wọn fi tipa mu awọn akẹko f'ori pamọ ti awọn ọlọpa si ya bo ile-iwe naa.
Bakan naa lo daro pe afẹsọna oun ku nigba ti ayẹyẹ igbeyawo wọn ku diẹ ko waye.
Ọmọ náà sọ fún un pé, ‘Baba, mo ti ṣẹ Ọlọrun, mo sì ti ṣẹ ìwọ náà.
Kọmisọnna Ọlọpaa ni ipinlẹ Kogi, Hakeem Busari ti ni irọ ni pe wọn se ikọlu si Gomina ipinlẹ oyo, Seyi Makinde ni ilu Lokoja.
Amọ nigba to jẹ pe, bu fun mi, kin bu fun ọ, ni ọpọlọ nke lalẹ odo, eyi naa lo mu ki awọn asofin latinu ẹgbẹ oselu Democrat se n beere pe ki aarẹ Trump naa bawọn dunadura pẹlu aba to nii se pẹlu ofin eto irinna silẹ Amẹrika gẹgẹbi ara ofin to wa ninu aba eto ẹnawo naa, amọ tawọn ọmọ ẹgbẹ oselu Republican kọ jalẹ lati tẹwọgba ibeere wọn naa, eyi to mu ki ohun gbogbo dojude.
somo lati mo awon ona kan tabi keji bi won yoo se tuko ile-igbimo asoju-sofin
Cristiano Ronaldo se gudugudu meje ohun yaya mefa ninu ifesewonse naa, leyin ti o gba boolu meji otooto wole ninu ami-ayo meta ti won fi fagbahan iko akegbe won, eyi ti o so apapo boolu ti o ti gba sinu agbon ninu idije UEFA Champions League bayii dii merinla.
Ṣé lóòtọ́ ni pé Hushpuppi ti kúrò ní ọgbà ẹ̀wọ̀n l'America?
Nítorí èyí, mo lọ sí ọdọ Oníbodè ni agogo mẹ́jọ mo sì sọ fún un pé a ò níí kó ìbọn ọwọ wa sílẹ̀ kí o sọ fún Ìnàkí-ìbẹ̀rù kí wọ́n múra fun ogun.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Gba àsẹ kóo tó lọ Russia fún FIFA NFF bẹ̀rẹ̀ ìwáàdí olùkọ́ni Super Eagles lórí ẹ̀sun rìbá Olórí ilé asòfin l‘Ọ́sun pàdánù N38m sọ́wọ́ gbájúẹ̀ Ọmọ Yorùbá ni onímọ̀ ẹ̀rọ ‘Rọ́bọ́tì’ tó ń gbowó jùlọ ní UK Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Onigbinde àti Owolabi: Ààrẹ NFF tuntun gbọdọ̀ sàwárí ọ̀jẹ̀ wẹ́wẹ́ agbábọ́ọ́lù Awọn asoju mẹrinlelogoji la gbọ pe wọn wa lati awọn ipinlẹ gbogbo to wa lorilẹ-ede yii, pẹlu awọn ajọ miran, bii ajọ awọn adari ere bọọlu, ẹgbẹ awọn to n se akoso ere bọọlu lori papa ati ẹgbẹ awọn agbabọọlu gbogbo wọn ni wọn si kopa ninu eto idibo naa, to waye ni ipinlẹ Katsina.
Aare orile-ede Naijiria, aare Buhari so pe oun yoo bere ipolongo eto idibo re ni gbayawu lai pe, saaju eto idibo gbogbogbo-o odun 2019 to n bo lona.
Kì í ṣe nípa omi nìkan, ṣugbọn nípa omi ati ẹ̀jẹ̀.
Ninu atẹjade kan ti ajọ amojuto lilọ-bibọ ọkọ nipinlẹ Ọyọ, OYRTMA fi sita ni ọrọ yii ti jẹyọ.
O ti kọ gbogbo àwọn tí ó yapa kúrò ninu ìlànà rẹ sílẹ̀,nítorí pé asán ni gbogbo ẹ̀tàn wọn.
Bẹ́ẹ̀ ni wọ́n ṣe tẹ̀síwájú, olukuluku wà ninu ìdílé tirẹ̀, gẹ́gẹ́ bí ilé baba wọn.
Àwọn ìjọba ìbílẹ̀ méjìdínlógún yìí kò tíì lè bọ́ lọ́wọ́ ìséde - Ìjọba àpapọ̀ Òfin ìjọba de ọdún eégún ìlú Ibadan,eégún Olóòlù kò ni kọ́ja agboolé rẹ̀!
Amosa, iroyin so pe ipade naa
Lásán ni mò ń ṣe wahala, gbogbo ìpẹtà náà kò ní jóná.
Gẹgẹ bi Sophia ọmọ iya Barbara Tommey ṣe sọ, Pasitọ Ofori ri wi pe bi iyawo oun ba file kọ silẹ, gbogbo dukia r ni yoo bọ si lọwọ.
Ninu ọrọ rẹ to sọ lẹyin ti wọn yọọ jade, Kaisha ni ko ya oun lẹnu pe awọn ẹgbẹ ohun dibo yọ oun jade nitoripe oun mọ ninu iwa ati iṣe wọn si oun pe wọn ko nifẹ oun rara.
Àwọn sẹnatọ ọmọ ẹgbẹ́ òṣèlú PDP, nínú àtẹjade kan tí olori ọmọ ilé tó kéré jùlọ, Abiodun Olujimi àti Sẹnatọ Dino Melaye fọwọ́si sọ pé, ki wọn yọ ṣenatọ Bukola Saraki kúrò nínú awuyewuye àti eto ti wọn fẹ́ lò, láti yan ààrẹ ilé ìgbìmọ̀ asòfin kẹsán.
Òfin lè má mọ oògùn ṣùgbọ́n èmí gbàgbọ́ pé ǹkan wà nídìí bí wọ́n ṣe pa ọmọ mi- Baba Favour Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ondo: Dejí sun ọmọ méje àtagbalagba meji mọ́lé nítorí pé ó ń bínú Wọn ko ẹgbẹ yi kuro lawọn fasiti lọdun 1984 ki awọn obilẹjẹ ma ba bawọn l'orukọ jẹ.
Ileesẹ ọlọpaa Ipinlẹ Eko sọ wipe, ipade awọn alaga ijọba ibilẹ ẹgbẹ PDP nilu Eko waye ni adugbo Igbosuku lopopona marosẹ Lekki si Ẹpẹ to wa ni ijọba ibilẹ Eti Osa, nibi ti ija ti bẹ silẹ laarin igun (faction) meji ẹgbẹ naa.
N óo dárí ẹ̀ṣẹ̀ wọn jì wọ́n, n kò sì ní ranti àìdára wọn mọ́.
Ṣugbọn pẹlu òtítọ́ ni ò ń kọ́ eniyan ní ọ̀nà Ọlọrun.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Victor Agunbiade ni ojú àlá ni Ọlọrun ti yan iṣẹ́ ọmọ ogun ojú omi fún òun ní America Bakan naa lo tun sọ pe aarun ìpá n ba oun finra, eyi to tumọ si pe oun ko le ba ẹnikẹni ni ibalopọ.
Tí a fiṣọwọ́ ní 11:46 11 Sẹ́rẹ́ 202111:46 11 Sẹ́rẹ́ 2021 Ìlú tuntun tó kún fún ohun àdáyébá láìsí ọkọ̀ tàbí òpópónà ń bọ̀ ní Saudi Arabia Iṣẹ akanṣẹ Neom jẹ ọkan lara afojusun Mohammed, lati wa ọna miran ti orilẹ-ede Saudi Arabia fi le pa owo wọle, yatọ si owo epo rọbi.
Awọn yoku ni Adam Idris Abubakar, Saka Zakaria, Biola Lawal, Isa Abubakar Adam, Ibrahim Chiroma, Hafis Amosu, Aliu Muhammad, Funmilayo Omoyemi Bishi, Mistura Yekini, Amina Ajoke Alabi, Kuburat Ibrahim, Alhaja Olufunke Alọlade Abdulqadir, Fawsat Balogun Alabi, Aisha Muhammad Amira ati Adebayo Zakariya.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù UTAS, ASUU, IPPIS, FGA kó ní sanwó oṣú ASUU láìjẹ́ pé wọ́n gba IPPIS- Ìjọba Àpapọ̀ 4 Bélú 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 5 Bélú 2020 Oríṣun àwòrán, @Unilag Ijọba Apapọ ti ni, ibi ti oun wa lori ọrọ sisanwo owo oṣiṣẹ ijọba ninu asunwọn kan naa (IPPIS) loun duro si paapaa julọ lori sisan owo oṣu awọn olukọ fasiti Minisita isuna, Zinab Ahmed salaye pe IPPIS ni awọn yoo maa lo titi eto UTAS ti awọn fasiti n se yoo fi yanju.
Ayọ̀ ń bẹ fún ẹni tí ó bá sá di í!
Wò ó wò, bóyá ẹ̀wù ọmọ rẹ ni, tabi òun kọ́.
”Akonimoogba omo ile bririko ohun tuko South Africa ti o fagbahan iko agbaboolu  Naijiria lọdun 2004 ninu ifesewonse olorejore, eyi ti o waye lati fi buyi fun Mandela, leyin re ni iko Super Eagles tun padanu ami ayo meji sodo ninu ese kinni ifesewonse ipegede fun idije AFCON.
ibo aarẹ lati inu ẹrọ ayelujara ti ajọ INEC.
Yari ní àwọn gómìnà ṣetán láti ṣe àtìlẹyìn fún fífi owó kún owó osìsẹ́, àmọ́ kò sí owó tàbí ohun àlùmọ́nì tí wọ́n yóò fi san àfikún owó oṣù náà.
Eyi yoo jẹ owo to po ju ti ise ona igbalode lati owo omo orilẹẹde yi yoo pa .
Ki o ma dabi ẹni wi pe a n ṣe oju saaju, a kaakiri oju opo ayelujara lati wa ẹni to fara mọ pe Beyonce ju Micheal Jackson lọ.
Fidio naa re e: Ninu lẹta ibanikẹdun naa to wa lori ayelujara, Makinde ṣapejuwe oloogbe Ajimobi, gẹgẹ bi ẹni to fi igbe aye rẹ sin ọmọniyan.
  Díẹ̀ nínú àwọn tó jọmí lójú nìwọnyí.
@PatrickOkouzi, iwa nini ibalopọ ninu ọkọ ni ita gbangba lee sokunfa ijamba ọkọ tabi iwa ajẹbanu, ko si yẹ ka gbaa laaye.
Bakan naa ni o jẹ igbakeji ọga agba fasiti Eko lọdun 2017, ẹka iṣẹ idagbasoke, ipo yii si lo wa ti wọn fi kede rẹ bii ọga agba fasiti naa.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Naira Marley: Adájọ́ ṣún ìgbẹ́jọ́ síwájú di oṣù kejì ọdún 2020 Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Naira Marley: Adájọ́ ṣún ìgbẹ́jọ́ síwájú di oṣù kejì ọdún 2020 12 Ọ̀pẹ̀̀ 2019 Gbajugbaja olorin takasufe, Azeez Fasola, ti gbogbo eeyan mọ si Naira Marley tun yọju sile ẹjọ giga to wa ladugbo Ikoyi nilu Eko lọjọbọ, nitẹsiwaju ẹjọlilu jibiti ti wọn fi kan-an.
“Ẹ ṣọ́ra kí ẹ má ṣe fi ojú tẹmbẹlu ọ̀kan ninu àwọn kékeré wọnyi; nítorí mo fẹ́ kí ẹ mọ̀ pé, àwọn angẹli wọn ní ọ̀run ń wo ojú Baba mi tí ń bẹ lọ́run nígbà gbogbo.
Awọn eeyan to fori sọta ijamba naa la gbọ pe wọn nrinrin ajo lọ silu Eko ninu ọkọ bọọsi akero kan ti nọmba rẹ jẹ KJA278DS nigbati wọn lọ fori sọ ọkọ ayọkẹlẹ jiipu Ford Explorer kan ti nọmba rẹ jẹ GGE 873XU eyi to nbọ lọna keji.
Ile-ise ohun tun so pe, awon ipinle ti won n san owon gogo owo irina oko oju omi ni ipinle Bayelsa (N1,962.
Amotekun kò le ṣe èso rere nílẹ̀ Yorùbá àyàfi ni Èkó nìkan - Alao Akala ṣaaju ni amofin agba ipinlẹ Ondo ti agbẹjọro ijọba meji, Oluṣẹgun Akeredolu ati Arabinrin Ọmọtọla Ologun ṣoju fun ṣalaye fun ile ẹjọ pe ni sjọ kẹta oṣu kẹta ọdun 2016 ni pasits Kọlawọle ṣa oloogbe Ayọ Ọlaniyi lọgbẹ lori nigba to lọ ṣọdẹ kọnkọ pẹlu awsn ọrẹ rẹ mẹta miran ni odo ẹja kan ti wọn ni o jẹ ti ọdaran pasitọ naa.
Ààlà ilẹ̀ wọn tún lọ sí apá ìsàlẹ̀ títí dé odò Kana, àwọn ìlú wọnyi tí wọ́n wà ní apá gúsù odò náà, láàrin ìlú àwọn ọmọ Manase, jẹ́ ti àwọn ọmọ Efuraimu.
Ọlọ́pàá Sharia Kano mú èèyàn tó lé ní 80 tori oúnjẹ nínú ààwẹ̀ Àwọn àdúgbò Ibadan gborúkọ tuntun látẹnu Ajimobi Iwe igbẹjọ naa fẹsun kan gomina Ganduje pe ikunsinu lo mu ki o gbe igbesẹ naa lati din agbara Emir Lamido Sanusi ku gẹgẹ bi Emir ilu Kano.
Ni ipari, idije British Open naa yoo bere lojo kọ́kàndínlógún osu keje titi di ojo kéjìlélógún osu kannaa odun ti a wa yii(July 19 to July 22).
Àkọlé àwòrán, Agbẹjọro rẹ ni irẹwẹsi ọkan de ba Onyeri fun oun to ṣẹlẹ si adajọ Kocurek Iroyin ni aaye wa fun Onyeri lati lọ ile ẹjọ kotẹmilọrun.
Ajọ to n ri si iṣẹlẹ pajawiri, NEMA sọ nigba naa wi pe o le ni miliọnu meji ọmọ Naijiria ti agbara ojo sọ di alainile lori nigba naa.
Ti wọn si ṣa ba maa n ran an pada lati le mu ki iho oju ara o kere si.
" A tí sọ níbi ìpàdé PTF tí a ṣe lónìí, tó bá di ọ̀la, ilé iṣk ètò ẹ̀kọ́ yóò mọ ìgbésẹ̀ tó kù.
Alágbára ni àwọn ọba ilẹ̀ Yorùbá nṣe nígbàkan rí.
Ni ipari, labe akoso igbimo to n ri si eka awon to n so ede geesi lorile-ede naa Ambazonia Governing Council (AGC), orisirisi igbese ti ko bofin mu ni won ti gbe ni ona lati sagbakale ise akanse won ni tipatipa.
Sadede lo ni awọn gbọ iro ibọn.
Awọn afẹhonuhan si n sẹ iwọde ni gbogbo igba pe ki ijọba alagbada pada sori aga iṣakoso.
Ayika ile-igbimo asofin bale woorowo pelu bi awon osise alabo se kun sita ile-igbimo ohun.
Ayọ̀ ń bẹ fún ọ nítorí o gba ohun tí Oluwa ti sọ gbọ́, pé yóo ṣẹ.
ti o gba iyansipo tuntun gege bi akowe agba ni: dokita Goncalves Titilayo
Federal Government scholarship 2021/2022: Wo bi o ṣe le fi orúkọ̀ sílẹ̀ fún ètò ẹ̀kọ́ ọ̀fẹ́ ìjọba Nàìjíríà
iko agbaboolu Liverpool ati Arsenal, eleyi ti o mumu lookan aya awon ololufe ere
ìyàn tí ẹ̀ ń bẹ̀rù yóo tẹ̀lé yín lọ sí Ijipti; ebi tí ẹ páyà rẹ̀ yóo gbá tẹ̀lé yín, ibẹ̀ ni ẹ óo sì kú sí.
Oba yii fidunnu rẹ han lori awọn ọmọde nipa bi bawọn kọrin ati jijo ijo ayọ laarin wọn.
Jakejado agbaye,idanwo ni wọn ma fi n ṣe ayẹwo bi eeyan ṣe kun oju oṣuwọn si ti a si maa fa ijakulẹ fun ẹni ti ko ba ṣe daada ninu rẹ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Cancer: Àṣe ara mi ni iso ti n run gbogbo bí mo ṣe n ṣèrànwọ́ lórí jẹjẹrẹ Iyalẹnu ni iku gbajugbaja naa jẹ fun ọpọlọpọ eniyan kaakiri agbaye, nitori pe ko fẹẹ si ẹni to mọ pe iru aisan bẹẹ n ṣe e ko to ku.
Mo tún rí i bí àwọn eniyan tí ń ni ẹlòmíràn lára láyé.
Agbegbe wo lo wọpọ si julọ?
 nnkan to je mó ìmabo olùkó kó àwon akékòó náà ní àwon ohun to jé mo ìmabo yàtò .
Ṣimei bí Usali, Usali bí Ṣimea, Ṣimea bí Hagaya, Hagaya sì bí Asaya.
Alaga ile lori eto ẹkọ, Ọjọgbọn Julius Ihonvbere lo ṣi aṣọ loju eegun ọrọ yii ninu atẹjade kan to fi sita lorukọ igbimọ rẹ.
Igi èso àjàrà ń joró,gbogbo àwọn tí ń ṣe àríyá ti ń kẹ́dùn.
Ẹwà ògo rẹ̀ tí ń ṣá bí ìtànná náà gbé!
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Kò dùn mí pé mo sọ̀rọ̀ tako Buhari -Adedayo Festus 21 Òkùdu 2019 Oríṣun àwòrán, @SP Àkọlé àwòrán, Adedayo ni maa tun si maa so ooto oro lo ni Aarẹ ile igbimọ aṣofin agba ni Abuja ni oun ko le yan Festus mọ.
Gomina Sanwo-Olu náà dín owọ́ orí lórí ilé àti ilẹ̀ kù nítorí Covid 19 Oríṣun àwòrán, @jidesanwoolu/others Gomina ipinlẹ Eko, Babajide Sanwo-Olu ti bu ọwọ lu yiyọ owo ori ọdun mẹta kuro fun awọn onile ti won ko san owo ori lori ilẹ̀ ati ile wọ́n ni ipinlẹ́ Eko.
Bio ti le je pe, Belgium kopa ribiribi ni saa kinni ifesewonse naa, sugbon ipa naa ko to fun won lati koju idojuko awon agbaboolu iwaju iko France, eleyi ti Kylian Mbappe dari re.
Kíní àwọn ewu to wà nibẹ̀?
Àwọn ọmọ ilẹ̀ Juda bá fi Joahasi, ọmọ Josaya, jọba ní Jerusalẹmu lẹ́yìn baba rẹ̀.
Mose bá pe gbogbo ìjọ eniyan náà jọ sí ẹnu ọ̀nà Àgọ́ Àjọ, gẹ́gẹ́ bí OLUWA ti pàṣẹ fún un.
Dokita Adegbenro ni awọn ti ni ki awọn alaṣẹ ọgba ẹwọn lorilẹede Naijiria o mojuto ẹlẹwọn naa funrawọn.
Kò sí ẹnìkan tí ń gbadura ní orúkọ rẹ,kò sí ẹni tí ń ta ṣàṣà láti dìmọ́ ọ;nítorí pé o ti fojú pamọ́ fún wa,o sì ti pa wá tì nítorí ẹ̀ṣẹ̀ wa.
Àtàwọn àgùnbánirọ̀ àtàwọn òbí wọn ni ìbẹ̀rù bojo ti gba ọkàn wọn.
Òdodo ẹni pípé a máa mú ọ̀nà rẹ̀ tọ́,ṣugbọn ẹni ibi ṣubú nípa ìwà ìkà rẹ̀.
Nítorí Ọlọrun kan ni ó wà, alárinà kan ni ó sì wà láàrin Ọlọrun ati eniyan; olúwarẹ̀ ni Kristi Jesu, tí òun náà jẹ́ eniyan, 
 Èyí tí a wò jùlọ 5:03 Fídíò, Omolola Arohunmolase Welder: Mo ti fí iṣẹ́ 'Welder' gbayì láwùjọ, tó mo fi tọ́ ọmọ yanjú, Duration 5,039 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 5:39 Fídíò, Akomolede ati Asa lori BBC: Olùkọ́ Kikelomo Ogunboye tan ìmọ́lẹ̀ sí ìwà olè ọ̀gá ọlọ́pàá Audu gẹ́gẹ́ bí àwòkọ́ṣe àsìkò yìí, Duration 5,398 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 4:11 Fídíò, Oba Adeyeye Ogunwusi: Ojú mi ti rí lọ́pọ̀ lọpọ̀, ọ̀pọ̀ èèyàn ni kò tilẹ̀ gbàgbọ́ pé mo lè jọba- Ooni, Duration 4,117 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 4:43 Fídíò, Promise Akinlade: ọmọ ọdún mọ́kànlá tó ń fi ìlù dárà bíi àgbàlagbà sọ̀rọ̀ nípa tálẹ́ǹtì rẹ̀, Duration 4,437 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 0:59 Gbọ́, Ìsẹ̀lẹ̀ jákèjádò orílẹ̀èdè àgbáyé láàárín ìṣẹ́jú kan, Duration 0,59wákàtí 6 sẹ́yìn 4:45 Fídíò, Yoruba Films: Ẹ̀ẹ́ bẹ̀ mi kúrò láyé ni, mi ò lè kú - Fadeyi Oloro, Duration 4,4526 Èrèlè 2020 7:03 Fídíò, Olumuyiwa Bolade Adedeji Military Bruitality: Bí arákùnrin onípèníjà ara tí sọ́jà lù ṣe dé, Duration 7,035 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 2:48 Fídíò, Esther Ajayi: Èmi náà ti borí ìṣòro rí ló ń mu mi ṣojú àánú, Duration 2,481 Ògún 2019 6:08 Fídíò, Adebola Ademilua: Àìrísẹ́ ṣè lẹ́yìn ìwé kíkà ló sọ mi dí ìyá onírú, mo dúpẹ́ tèmi, Duration 6,0827 Bélú 2020 5:55 Fídíò, Soyinka Cancer: Àṣe ara mi ni iso ti n run gbogbo bí mo ṣe n ṣèrànwọ́ lórí jẹjẹrẹ, Duration 5,5527 Bélú 2019 BBC News, Yorùbá Ìdí tí ẹ fi le è nígbàagbọ́ nínú ìròyìn BBC Ìlànà Lílò Nípa BBC Òfin Àṣírí Cookies Kàn sí."
 Oloye Olusegun Obasanjo to je Aare Naijiria tele naa ki won pe: “ Inu mi baje gidi ni, mo gbadura fun idle Dapo pe won ko ni ri iru eyi mo”Bakan naa ni olotu ile ise to n gbe orin jade, Don Jazzy naa fi soju opo twitter re pe: “Inu mi baje fun iroyin buruku yii to pe ti mo ti gbo iru re seyin”.
 ( to avoid meeting her he made a swift exit .
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Africa Eye: Olùkọ́ méjì ní fásitì Eko àti Ghana lùgbàdì ọ̀fíntótó BBC lórí ìwà ìbàjẹ́ Àkọlé àwòrán, Owo to kere julọ ni Naijiria Efunjoke Coker: Abiyamọ́ tó ṣé atọna àwọn akẹ́kọ̀ọ́bìnrin Queens College Gbèsè niye èèyàn tó pọ̀ ní Nàìjíríà kìí ṣe dúkìá- Emir Sanusi Kí ló mú kí Adájọ yin ìbọn lu ará rẹ láyà nílé ẹjọ́?
Ọgbẹni Omotosho ni oun ko ro pe Gomina Sanwo-Olu yoo lọ fun ayẹwo coronavirus miiran nitori Ọjọgbọn Abayomi ṣẹṣẹ lugbadi aarun ọhun.
"Ajọ WAEC gbé èsì ìdánwò ọdun 2020 jáde Kàyééfì tuntun rèé lórí #EndSARS, ọ̀rọ̀ pọ̀ nínú ìwádìí BBC Akinwumi Isola dárà nínú ìwé ""Nítorí Owó"" lórí Akomolede Yoruba Ìbẹ̀rù-bojo gbalẹ̀ ní Oyigbo lẹ́yìn tí ọlọ́páà mẹ́ta àti sọ́jà kú nínú rògbòdìyàn EndSARS Ènìyàn méjì pàdánù ẹ̀mí wọn nínú ìjàmbá ọkọ̀ tó wáyé ní Abúlé Ẹ̀gbá, ní ìpínlẹ̀ Eko Ṣugbọn ohun to jẹ iyalẹnu ni pe ọpọ awọn onibara lo ti n kọminu pe lati inu oṣu kẹwaa ni ileeṣẹ Disco ti bẹrẹ si fawọn onibara wọn ni ni biili tuntun."
Ni ọdun 2018, 7% ni wọn ya sọtọ lara owo isuna ọdun to jẹ bii 650bn naira ($1.
Nígbà tí yóo bá fi mọ bí a ti í kọ nǹkan burúkú, tí a sì í yan nǹkan rere, wàrà ati oyin ni àwọn eniyan yóo máa jẹ.
Wọ́n ṣe àjọ̀dún àsè náà fún ọjọ́ meje, ní ọjọ́ kẹjọ, wọ́n pe àpéjọ tí ó lọ́wọ̀, gẹ́gẹ́ bí ìlànà tí ó wà ninu àkọsílẹ̀.
O ni nibayii ti wọn ti fi aye rẹ silẹ bayii, eyi to ba ṣe obinrin lanfani ju lo maa mu lai si idiwọ kankan mọ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Omotara: Mo kábamọ ìwà tí mo hù sí ọmọ alágbe tó ń tọrọ lọwọ mi nínú ọkọ 29 Bélú 2020 Gbajugbaja ori ayelujara nni ti iroyin tan ka pe o huwa aidaa nipa fifi ọti ẹlẹrindodo la ọmọ alagbe kan loju, Omotara ti ba BBC sọrọ pe oun ko ro o bi awọn eeyan ṣe ri ohun to ṣẹlẹ.
Ọmọọba ilẹ̀ Gẹ̀ẹ́sì bí ọmọ ọkùnrin Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Aafin Ọba ilẹ Gẹẹsi kede pe ni owurọ ọjọ aje ni o wọ ile igbẹbi lọ Iyawo ọmọọba ilẹ gẹẹsi, Meghan Merkel ti bí ọmọ ọkùnrin.
Lẹyin eyi ni awọn agba ọjẹ ninu iṣẹ oṣere nilẹ Yoruba bii Mr Latin, Jide Kosọkọ àti Mama Rainbow sọrọ lori ija naa, wọn si gbiyanju lati dasi i.
Buhari, Makinde, Sanwo-Olu kẹ́dùn pẹ̀lú ẹbí Tola Oyediran, àkọ́bí lóbìnrin tí Obafemi Awolowo bí tó papòdà Báwo ni Donald Trump ṣè ń rí ọwọ́ mú sí nínú àkójọ èrò àwọn olùdìbò?
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ayé mà le o!
 O gbe ni Chateau ni guusu iwo oorun Faranse laiko iyawo re sile nile ofin rara.
Otinieli ọmọ Kenasi, arakunrin Kalebu, ni ó ṣẹgun ìlú náà.
Atiku ni kò tíì dópin fún Adeleke, PDP ni àwọn gba idájọ́ wọlé Àlàyé rèé lórí ìdí tí ìyá mi fi sọ fáráyé pé mo ti kú Niṣe lo fi gbogbo asiko to yẹ ko fi maa gbaradi fun igbeyawo, ṣe itọju ara rẹ eyi to n gba asiko rẹ ati owo rẹ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Joseph Hanlon: Ogójì tọ́ọ́nù heroin ló ń gba Mozambique kọjá 11 Agẹmo 2018 Oríṣun àwòrán, iStock Àkọlé àwòrán, Pupọ lara ogun oloro to n wọ ilẹ Europe n wa lati Mozambique.
"‘Adájọ́ Àgbà Nàíjíríà, Walter Onnoghen ní ẹjọ́ láti rò’ ‘Olùkọ́ fipá bá akẹ́ẹ̀kọ́ girama lòpò nítorí máàkì’ Kíni ìdí ti wọn fi ń lọ ọmú obinrin Mìmì kan kò mì wá, Ẹlẹka yóò jíǹde bí i Lasaru inú Bíbélì -PDP Ekiti ìfipábánilòpọ̀: Má dákẹ́ - Oluwaseun World TB Day: ""Ó dùn mí jù pé ń kò rí ọmọ mi fún ọdún kan"" Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí 2 sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn."
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Obateru Akinruntan: Wíwá ohun tá jẹ títí láé ló gbé wa kúrò nílé Ife Ko tan sibẹ o, Minisita fun ọrọ iroyin, Lai Mohammed ati akọwe ijọba apapọ, Boss Mustapha naa bawọn peju sibẹ pẹlu.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Domestic Violence: Ìjà láàrin lọkọlaya sọ aya dèrò ọ̀run Igbagbọ rẹ ni pe awọn ololufẹ a tubọ ṣọ ihuwasi ara wọn ki ọrọ ifẹ ma la okun ẹmi ololufẹ lọ.
eto isejoba aare  Muhammadu Buhari  fun orile ede Naijiria ati ilẹ Afirika.
Àwọn ọmọ Lefi tí wọ́n bẹ̀rẹ̀ iṣẹ́ ṣíṣe ní tẹmpili nìwọ̀nyí: láti inú ìdílé Kohati: Mahati, ọmọ Amasai, ati Joẹli, ọmọ Asaraya; láti inú ìdílé Merari: Kiṣi, ọmọ Abidi ati Asaraya, ọmọ Jahaleleli; láti inú ìdílé Geriṣoni: Joa, ọmọ Sima ati Edẹni, ọmọ Joa.
Eyi fihan pe wolii Alfa Babatunde yoo lee na owo inu aṣuwọn ifowopamọ si rẹ bayii, amọṣa yoo ṣi wa ninu ahamọ ọgba ẹwọn to wa titi di igba ti idajọ yoo fi waye lori ẹsun ti wọn fi kna an.
Latari ẹkun omi yii lawọn ẹlẹwọn fi fẹsẹ fẹ ẹ nigba ti wọn rii pe ogiri ibi ti wọn ko wọn pamọ si ti ya.
@shittuisiakao tiẹ binu tan, o ni ọpọlọpọ eeyan ko mọ pe ko boju mu rara fun oludije fun ipo aarẹ lati ni ofisi rẹ si ilu okere.
Láyé àtijọ́ ni ìṣẹ̀lẹ̀ náà ṣẹlẹ̀.
Ipenija ti o wa ni iwaju Adamu Adamu yoo ni awọn ipenija lati koju paapa julọ lori idibo ọdun 2019 to de tan.
16 lori awọn Gomina tẹlẹri, ti wọn a si ma na miliọnu lọna mẹtalelaadọrun o le diẹ naira, N93.
Tottenham ya aṣọ iyì mọ́ Manchester United lára nírọ̀lẹ́ ọ̀jọ́ ìsinmi Àwọn ọmọ FIBAN kò gbọdọ̀ lo orin Wasiu Ayinde mọ́ lẹ́yìn ìfìyàjẹní Murphy- FIBAN Yoruba wo ló fẹ́ gbé Oduduwa Republic tẹ́ n pariwo?
Bakan naa lo fikun pe ki osu kẹta taa wa yii to buse, iks alaabo naa yoo gberasọ, ti yoo si bẹrẹ isẹ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Bollywood padanu Sridevi 25 Èrèlè 2018 Oríṣun àwòrán, Mr Jayakumar Àkọlé àwòrán, Sridevi ya awọran yii to jẹ ọkan lara awọn aworan to ya kain nibi ayẹyẹ kan to lọ ni Dubai Gbajugbaja osere fiimu Bollywood Sridevi Kapoor ti ba arun ọkan lọ, gẹgẹ bi awọn ẹbi rẹ ti sọ.
"Ati pe iṣọri awọn kan pere lo lee forukọ silẹ, awọn yii si bọ sabẹ iṣọri ti wọn n pe ni ""Payroll support""."
Kini ki ni to ti n bọ iyawo ati ọmọ pẹlu iru iṣẹ bẹ wa ṣe nigba ti wọn ba le lnu iṣẹ?
Àwọn agbébọn tó ń gba ojúgbó wọlé máa ń tó 1000 lẹ́ẹ̀kan náà - Amotekun Oríṣun àwòrán, @Worldstagegroup Adari ikọ Amọtẹkun nipinlẹ Ọyọ, Ajagunfẹyinti Olayanju ti salaye lẹkunrẹrẹ nipa awọn ajeji agbebọn to ma n gba inu igbo ya wọ ilẹ Yoruba lati agbegbe Oke Ogun nipinlẹ Oyo.
Jẹ́ kí ọba ó dàbí òjò tí ó rọ̀ sórí koríko tí a ti géàní, bí ọ̀wààrà òjò tí ń rin ilẹ̀.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ondo Election 2020: Ẹgbẹ́ òṣèlú PDP ní ó dá àwọn lójú pé àwọn yóò jáwé olúborí 10 Owewe 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 21 Owewe 2020 Oríṣun àwòrán, Google Ẹgbẹ oṣelu PDP ti ni bi awọn ṣe jawe olubori ni idibo sipo gomina nipinlẹ Edo, bẹẹ ni yoo ṣe ri fun awọn ni ipinlẹ Ondo.
Ó ní kí wọ́n má ronú àwọn dúkìá wọn nítorí àwọn ni wọn yóo ni ilẹ̀ tí ó dára jù ní Ijipti.
Ọ̀kan ninu àwọn ọ̀gágun tí wọ́n wà níbẹ̀, tí ó jẹ́ aṣojú ọba dá Eliṣa lóhùn, ó ní, “Bí OLUWA bá tilẹ̀ da àwọn nǹkan wọnyi sílẹ̀ láti ojú ọ̀run wá, ǹjẹ́ ohun tí o sọ yìí lè rí bẹ́ẹ̀?
”Bakan naa, Mi o ti setan lati feyinti bayii,”Serena Williams , omo odun merindinlogoji ohun, bi omo obinrin Alexis Olympia ninu osu kejila lodun ti o koja.
Jesu dá wọn lóhùn pé, “Ìmọ́lẹ̀ wà láàrin yín fún àkókò díẹ̀ sí i.
kuro ni orile ede kan si omiran , jẹ ohun to dara , ko si eni to ni ki ẹ maa
Ghana Election 2020: Ẹ dín iye ìgbà tẹ n gorí obìnrin kù kẹ́ẹ lè lágbára.
Nígbà tí àwọn iranṣẹbinrin Ẹsita ati àwọn ìwẹ̀fà rẹ̀ sọ fún un nípa Modekai, ọkàn rẹ̀ dàrú.
''Emi nikan ko le maa da ara mi wo ni jare, ẹ maa binu si mi,'' osẹre Victoria lo sọ bẹẹ.
Ati pe awọn ọlọpaa ko fun awọn ni anfaani lati sọ ọrọ gbe ara wọn lẹsẹ.
Kò pẹ́ lẹ́yìn náà, àwọn oníṣòwò ará Midiani ń rékọjá lọ, wọ́n bá fa Josẹfu jáde láti inú kànga gbígbẹ náà, wọ́n sì tà á fún àwọn ará Iṣimaeli ní ogún owó fadaka.
Ko si ẹni ti o ku ninu wọn, gbogbo wọn ye.
Lagos APC Rally: MC Oluọmọ fara gb'ọ̀bẹ níbi ìpolongo ìbò
7m kó sí páńpẹ́ EFCC Kii ṣe ajoji mọ bi iroyin ṣe maa n jade lọtun losi lori ọṣẹ ti ikọ SARS n ṣe si awọn araalu yala ọkunrin tabi obinrin.
ibasepo to wa laarin orile ede mejeeji naa ,aare Biya tun ni, ‘‘Mo
Bí olódodo bá yipada kúrò ninu ìwà òdodo rẹ̀, tí ó bá ń dẹ́ṣẹ̀, yóo kú nítorí ẹ̀ṣẹ̀ rẹ̀.
Ìwọ̀n tí wọn ń lò ní Àgọ́ Àjọ ni wọ́n fi wọ̀n ọ́n.
Ko si àní-àní, awọn igbesẹ to lagbara gbọdọ jẹ gbigbe, paapa nipa itankalẹ aarun coronavirus, ati ọna lati gbogun ti iwa ibajẹ, ati mimu idagbasoke ba ọrọ aje.
Àwọn akẹ́ẹ̀kọ́ kan tó ti kọjá ní fásitì náà ní ọ̀jọ̀gbọ́n Akíndélé kò ṣẹ̀ṣẹ̀ máa ṣe e.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ebola ti di ohun ti gbogbo àgbáyé ń mójútó báyìí Iranlọwọ ilẹ United Kingdom yii yoo jẹ ki iṣẹ tubọ rọrun fún àjọ WHO to n mojuto ìlera agbaye lati ri si ìtànkálẹ̀ Ebola.
Iko agbaboolu Naijiria tawon odo tojo ori won koju metadinlogun lo fagbahan orile-ede Niger pelu ami-ayo meji sookan(2-1) ninu ifigagbaga ipele keji si asekagba idije WAFU U-17 ti o waye niluu Niamey, ti n se olu-ilu orile-ede Niger.
" Bakan naa ni minisita fọrọ abẹle tun rọ awọn ọmọ Naijiria lati maa tẹriba fun ara wọn ni, ki wọn si di ikuuku ọwọ mọ aya lati fi ki ara wọn.
Nitootọ ọmọ ọdun mẹ́fà ni ọmọ tirẹ̀ nigba naa sùgbọn o fi si ilé ẹko náà láti pe ọpọlọ rẹ̀ níjà.
Ṣugbọn ní ọjọ́ náà, n óo mú kí ilẹ̀ Jerusalẹmu le kankan bí òkúta tí ó wúwo, orílẹ̀-èdè tí ó bá dábàá pé òun óo ṣí i nídìí, yóo farapa yánnayànna.
Gbogbo orílẹ̀-èdè dòòyì ká mi,ṣugbọn ní orúkọ OLUWA, mo pa wọ́n run!
Nígbà tí ó bá fẹ́ sùn, ṣe akiyesi ibi tí ó sùn sí dáradára, lẹ́yìn náà, lọ ṣí aṣọ kúrò ní ẹsẹ̀ rẹ̀, kí o sì sùn tì í, lẹ́yìn náà, yóo sọ ohun tí o óo ṣe fún ọ.
Lẹ́yìn igbe Atiku, Ààrẹ Ilé Ẹjọ́ kòtẹ́milọ́rùn yọra rẹ̀ nínú ìgbẹ́jọ́ èsì ìdìbò ààrẹ Ìgbìmọ̀ ìgbẹ́jọ́ fún Atiku láǹfàní láti wo ohun èlò ìdìbò ààrẹ Adeleke yóò borí nílé ẹjọ́ tó gajù lọ- Dele Adeleke Kò sí àjòjì darandaran kankan ní Nàìjíríà -NIS Igbimọ ẹlẹni mẹta naa ni titete kọ iwe yi jẹ opa kutẹlẹ pataki ninu pipe ẹjọ ati pe bi eeyan ko ba file kọ iwe yi lasiko, ẹjọ naa ko le tẹsiwaju.
Gomina to wa lori aleefa lọwọ
Ọlọrun wá bá a dá majẹmu, ó fi ilà kíkọ ṣe àmì majẹmu náà.
Ẹni to bori: South Africa Guinea vs Uganda.
A Majekodunmi, to jẹ minisita eto ilera nigba naa gẹgẹ bi alakoso ijọba.
Kò pẹ́ díẹ̀ táa rìn nínú igbó náà dé'bìkan ni mo pe àkíyèsí àwọn ẹlẹgbẹ́ mi sí nkankan tí mo rí lókèrè.
Oríṣun àwòrán, Twitter/arsenal Àkọlé àwòrán, Ohun mẹ́fà tí ọ̀pọ̀ kò mọ̀ nípa ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ Arsenal àti Machester Real Madrid gbadé ògo La Liga, Messi ní Barcelona ò lè ta pútú mọ́ Àlùbami ní Kamuru na Jorge Masvidal láti dí Àmí Ẹ̀yẹ UFC Welterweight Champion rẹ mú!
Ó dá àwọn ẹranko ńláńlá inú omi ati oríṣìíríṣìí ẹ̀dá alààyè tí ń gbé inú omi, ati oríṣìíríṣìí ẹyẹ.
Irun bo iwin náà lára bí aṣọ, gbogbo ara rẹ̀ sì dàbí ara ajá ìlú Òyìnbó, bẹ́ẹ̀ ni òṣú bàràkàtà kan ń bẹ ní àtàrí rẹ̀.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Police Killing: Ọlọpàá mẹ́rìn to pa afurasí dèrò ẹ̀wọ̀n lẹ́yìn tíṣẹ́ bọ́ lọ́wọ́ wọn 22 Ògún 2019 Oríṣun àwòrán, Twitter/Nigeria Police Force Àkọlé àwòrán, Ileeṣẹ ọlọpaa ipinlẹ Eko gbaṣẹ lọwọ ọlọpaa mẹrin Awọn agbofinro tó yinbọn pa awọn afurasi meji ti dero ẹwọn bayii.
Odidi ọdún mejidinlogun ni wọ́n fi ni àwọn ọmọ Israẹli tí wọ́n wà ní òdìkejì odò Jọdani, ní Gileadi lára.
Fadaka ati wúrà yìí ni mo fi ta ọ́ lọ́rẹ; pa majẹmu tí ó wà láàrin ìwọ ati Baaṣa ọba Israẹli tì, kí ó baà lè kó ogun rẹ̀ kúrò lọ́dọ̀ mi.
Liverpool jẹ Chelsea máye ni Stamford bridge Ilẹ̀ Afrika lọ́sẹ̀ yìí nínú àwòrán!
Arsenal fagbahan iko agbaboolu AC Milan mole pelu ami-ayo meji sodo(2-0), ninu idije Europa  ti o waye lana ode yii.
N óo sì jẹ́ kí àwọn ẹranko ilẹ̀ ayé jẹ ẹran ara rẹ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Eegunjobi Omotanbaje Ajobiewe- Èébú ní wọ́n kọ́kọ́ ń bù mí nígbà tí mo bẹ̀rẹ̀ ẹ̀ṣà pípé ní Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Eegunjobi Omotanbaje Ajobiewe- Èébú ní wọ́n kọ́kọ́ ń bù mí nígbà tí mo bẹ̀rẹ̀ ẹ̀ṣà pípé ní 13 Ọ̀wàrà 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 14 Ọ̀wàrà 2020 Ìyàwó mẹ́tàlá ni bàbá mi fẹ́ ṣùgbọ́n èmí níkàn ní wọ́n bí- Ajobiewe Apẹ̀ṣà Iṣẹ Oniburẹdi ni mo kọ ki ifẹ aṣa Yoruba to mu mi ya si idi iṣẹ ẹṣa pipe to sọ mi di eeyan loni- Ajobiewe Gbajugba apẹṣa ni, Eegunjọbi Ajobiewe ni BBc ba lalejo lori aṣa Yoruba.
Kogi PDP Primaries: Wada fẹ̀yìn Dino gbálẹ̀ nínú ìbò abẹ́lé PDP fún ìpò gómìnà ní Kogi
1 billion) lasiko to jẹ gomina ipinlẹ Abia laarin ọdun 1999 si 2007.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Dele Momodu : Lẹ́yìn Buhari àti Atiku, èrò ọjà làwọn olùdíje yóòkù ní ìdìbò 2019 Bello Abdullahi Bodejo tun ko aroye balẹ o ni, gbogbo ọran ijinigbe pawo tabi pa, idigun jale atawsn iwa ọdaran miran ti wọn n so akengbe ọran rẹ mọ awọn Fulani lọrun lori oju opo ayelujara gbogbo lawọn kan gbe kalẹ o lati ba orukọ awọn ọmọ ẹya Fulani jẹ.
 Ko si ohun ti o ko lee fi wo, kii tan bẹẹni anfani yii yoo kan awọn agbegbe miran laipẹ."
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Farting offense: Ọkùnrin yasó nínú ọkọ̀ Uber rí ẹ̀wọn he ní ilẹ̀ Gẹ̀ẹ́sí 15 Ọ̀wàrà 2020 Oríṣun àwòrán, Twitter/Uber Uk Eleduwa ko daa akitan iso ni wọn maa n wi nilẹ ku otu o jiire.
10 Agẹmo 2019 Oríṣun àwòrán, @others Àkọlé àwòrán, Lamidi Adeosun di ọga agba ninu iṣẹ ologun A bi Ọgagun Lamidi Adeọṣun ni ọjọ Kejilelogun, oṣu Kẹjọ, ọdun 1963 nijọba ibilẹ Olaoluwa nipinlẹ Osun, lẹkun iwọ oorun guusu Naijiria.
Awọn ọmọ ile aṣofin naa tun koro oju si iṣejọba Aarẹ Muhammadu Buhari, fun bo ṣe n kọlu awọn to kopa ninu iwọde ENDSARS, to tun n dẹruba wọn.
Nítorí náà ẹ fi òye ati ìwà pẹ̀lẹ́ gbé ìgbé-ayé yín ninu adura.
Ọjọ́ kẹrinlélógùn ọsù kèje ni ilé iṣẹ́ náà si ojú òpó rẹ̀ fún gbogbo ẹni to ba fẹ́ gba iṣẹ́, ọjọ́ kan lẹ́yìn tí wọ́n sin Tolulope Arotile.
N óo fọ́n àwọn ará Ijipti káàkiri gbogbo ayé, n óo sì tú wọn ká sí ààrin àwọn orílẹ̀-èdè mìíràn.
Wo ìdí tó fi tọrọ àforíjì fún ọ̀rọ̀ ẹ̀gbin tó sọ sí Pásítọ̀ David Oyedepo Ọkọ mi kò fẹ́ràn oúnjẹ òyìnbó àfi ti ìbílẹ̀ - Lizzy Anjorin Àwọn dókítà Nàìjíríà ti fòpin sí ìyanṣẹ́lódì wọn Ẹgbẹ awọn dokita ni Naijiria ti da iyanṣẹlodi ti wọn gunle duro fun saa diẹ.
Obesere ko ṣai sọ nipa oba orin oloogbe Ayinde Barrister, o ni Sikiru Ayinde ti papoda ni tootọọ ṣugbọn orukọ rẹ ko le parun laelae.
ododo ninu re jade pe, awon omo ogun yinbon pa awon afehonu han.
Uniport: Àwọn ọlọ́pàá wú òkú akẹ́kọ̀ọ́ Fásitì Uniport mẹ́ta tí àwọn ajínigbé sin Oríṣun àwòrán, RIVERS STATE POLICE COMMAND Ileeṣẹ ọlọpaa nipinlẹ Rivers ti wu oku akẹkọọ Fasiti ilu Port Harcourt mẹta jade lọjọ Ẹti: meji jẹ ọkunrin, ẹnikan si jẹ obinrin.
 Ọmọ ọdún mẹ ́ tàdínlógún ni dúró orímóògùnjẹ ́ .
“Lẹ́yìn gbogbo èyí, bí ẹ ba kọ̀, ti ẹ kò yipada, ṣugbọn tí ẹ kẹ̀yìn sí mi, 
O ṣalaye fun BBC pe lati kekere olun ti ni ipinu lati kawe rẹpẹtẹ lẹyin ti baba rẹ ku.
Ó kó gbogbo Jerusalẹmu ní ìgbèkùn; gbogbo àwọn ìjòyè, àwọn akọni, àwọn oníṣẹ́ ọwọ́, ati àwọn alágbẹ̀dẹ, gbogbo wọn jẹ́ ẹgbaarun (10,000), kò ṣẹ́ku ẹyọ ẹnìkan ní ìlú náà, àfi àwọn talaka.
lọpọ ̀ wọn ló joko sí iwájú ọkọ ̀ .
Nigba to n bu ẹnu atẹ lu iroyin ileeṣẹ CNN, Lai sọ pe ko si oku kankan ti wọn ri he ni iloro Lekki, ati pe ko si ẹbi kankan to wa sọ fun ijọba pe eeyan wọn di awati lẹyin iṣẹlẹ naa.
Ṣugbọn ninu àpò awọ titun ni wọ́n ń fi ọtí titun sí.
Ọga ileeṣẹ Reckitt Benckiser ni ọpọ eeyan papaa julọ nilẹ Gẹẹsi ati Italy ni ibaṣepọ wọn ko dọn mọran mọ lati igba ti ofin konle-o-gbele ti bẹrẹ.
omo orile-ede yii pata-pata lati maa Salai fi ejo enikeni ti o ba n lo ile-ise
Ojọ kẹwaa, oṣu kẹta, ọdun 2019 lo wa ninu awọn ẹmi to sọnu nigba ti ijamba ọkọ ofurufu yii ṣẹlẹ.
Àti àwọn ìbéèrè míràn Lóòtọ́ lò n lo ìbomú-bẹnu, ṣùgbọ́n ṣe bóṣeyẹ kí o wọ̀ ọ́ ló ṣe n ṣe?
nitorina eto ayewo ara, paapaa ifunpa to ga, ṣe koko Oyun nini: Asiko iloyun jẹ asiko ẹlẹgẹ fun awọn obinrin, nitori naa o se koko ki oloyun se ayẹwọ ara ati ọmọ ni igba de igba Omi mimu: Ti eniyan ko ba mu omi deede ati lasiko, o ṣeeṣe ki iru eniyan bẹẹ sagbako iku ojiji.
Fiwapẹ ni àwọn ojulowo ibo ti wọn dì jẹ́ 721, 621.
Lẹ́yìn náà alufaa yóo yán ẹ̀jẹ̀ ẹbọ ìmúkúrò ẹ̀ṣẹ̀ náà sí ara ìwo pẹpẹ ẹbọ sísun, yóo wá da ẹ̀jẹ̀ yòókù sídìí pẹpẹ.
ọpọlọpọ awọn oṣiṣẹ ni iroyin jẹ ko di mimọ pe awọn alaṣẹ ileeṣẹ wọn ti sọ sinu isinmi ọlọdọọdun ni tipa.
" oùn ni ó jẹ ́ ẹni àkókó ti ó jẹ oyè awùjalẹ ̀ - "" a-mu-ìjà-ilẹ ̀ ' -èyí ni ẹni tí ó parí ìjá tí ó bá nílẹ ̀ ."
Bẹẹ si ni Olori Memunat Omowunmi Adeyemi ti oun ati Olori Badrat Olaitan dijọ jẹ korikosun ninu aafin gan, ni wọ̀n ko dijọ se bii ti atijọ mọ.
Wọn fikun pe Ajọ̀ to n gbogun ti ajakalẹ arun lorilẹede Naijiria,NCDC ti bẹrẹ si ni wa awọn ti wọn ti ni ibaṣepọ pẹlu oloogbe naa fun ayẹwo arun Coronavirus.
" Awọn igbesẹ ti ileeṣẹ ọlọpaa la silẹ niyi o: Ma ṣe lo agidi lati lasiko ti ọlọpaa ba fẹ mu ọ: Oríṣun àwòrán, @PoliceNG Àkọlé àwòrán, Ileeṣẹ ọlọpaa ti wa fi si oju opo twitter rẹ, igbesẹ ti o yẹ fun araalu ni gbigbe lasiko ti awọn ọlọpaa ba fẹ mu wọn.
Aarun naa ti n ran bi ina inu ọyẹ lati ilu Wuhan lọ si awọn ẹkun miiran ni China, ko da o ti ran de ilẹ Amẹrika, orilẹede Thailand ati South Korea.
O ṣalaye pe olorin kan to ṣẹṣẹ n bọ, M2 lọ kọwe ẹsun ti wọn fi gbe e.
Gege bi oro re, bi ile-ifowopamo se da si tita oja owo ile-okere tun ti seranlowo fun owo ipamo ohun nipa fifese oja owo ori ipin idokowo mule, ni eyi ti o ti mu igberu ba ipese nnkan ati eto kara-kata.
iwa ti o lodi si ilana ti egbe APC ba silẹ.
A máa pèsè oúnjẹ fún àwọn tí wọn bẹ̀rù rẹ̀,a sì máa ranti majẹmu rẹ̀ títí lae.
Orúkọ odo ti wọn ti ṣe àwárí rẹ ni wọn fi perí ààrùn náà.
Aworan ati fidio lo kọkọ jade lori ẹrọ ayelujara nibi ti wọn ti fi lede pẹlu #OgunUnrest ati #LagosUnrest lori ẹrọ ikansiraẹni Twitter, amọ ko si agbegbe kankan ti iru rẹ ti ṣẹlẹ.
Nítorí ṣókí ati wéré wéré ni ìdájọ́ Ọlọrun yóo jẹ́ lórí ilẹ̀ ayé.
Ó ní ọkùnrin àgbàlagbà kan pariwo pé kí wọ́n “kó pàǹtí yẹn jáde”, ìyẹn túmọ̀ sí wípé kí àwọn òṣìṣẹ́ ó ju òun jáde síta nínú ilé ìtajà náà nítorí pé òun jẹ́ ọmọ ìbílẹ̀ Rome.
Oríṣun àwòrán, INEC Àkọlé àwòrán, Àjọ ọ̀hún tún jẹ́ kó di mímọ̀ pé àwọn kò kéde ìgbanisíṣẹ́ kankan.
Agbẹnusọ fun aarẹ orilẹede Naijria, Garba Shehu ṣalaye, lasiko to n se ifọrọwanilẹnuwo pẹlu BBC Yoruba, pe ohun kan ti oun mọ ni pe idaji owo naa ni awọn ti fi ra ohun ija lati orilẹede Amẹrika, sugbọn oun yoo bere bi wọn se na iyoku.
14 Ọ̀wàrà 2019 Igboọra jẹ ilu kan to kalẹ si agbegbe Ibarapa nipinlẹ Ọyọ, ti igbagbọ si wa pe ko si ile kan ninu ilu naa ti wọn ko ti bi ibeji, ibẹta tabi ibẹrin nibẹ.
Ohunkohun tí wọ́n bá sọ fun yín ní ibi tí OLUWA bá yàn ni ẹ gbọdọ̀ ṣe.
Baba Enjiníà, baba lọ́yà, bàbá adájọ́
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìkọlu Ifọ: Ọlọ́pàá pòórá lẹ́yìn tí àwọn jàndùkú yọ àdá sí wọn, 22 Ìgbé 2019 Oríṣun àwòrán, Ogun State/Facebook Àkọlé àwòrán, Àwọn janduku naa lọ fi ibinu sọ ina si ọgba Kunle Oluọmó Awuyewuye ti bẹ silẹ ni Ifọ ni Ipinlẹ Ogun bi awọn ọlọpaa ṣe yinbọn pa ọkunrin kan ti wọn funra si pe ọmọ ẹgbẹ okunkun ni.
O sọ pé àwẹ̀ gbígbà fún wákàtí méjìlelogun kìí ṣe òun tó rọrùn ṣùgbọ́n tó bá jẹ pé àgbègbè náà ní Ọlọrun dá èèyàn sí, ''o di dandan láti gbà àwẹ̀ náà'' Lọdọ ti rẹ, Lateefat aya Ahmad ni t'oba se agbègbè bi Greenland loun ba wa,òun yóò gba àwẹ̀ náà lai bikita.
Ó sì yọ́ wúrà dáradára bò ó lórí, ó ya igi ọ̀pẹ ati ẹ̀wọ̀n, ó fi dárà sórí rẹ̀.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Oluwo tí sọ̀rọ̀ nípa awuyewuye láàrin rẹ̀ àti Agbowu tìlùu Ogbaagbaa 18 Èrèlè 2020 Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Oluwo ilu Iwo ba BBC Yoruba sọrọ lori awuyewuye pẹlu awọn Ọba Oluwo ilu Iwo Ọba Abdulrasheed Adewale Akanbi ti ba BBC Yoruba nipa ohun to ṣẹlẹ laarin rẹ ati Agbowu ilu Ogbaagba.
INEC ní òṣìṣẹ́ rẹ̀ tó sá lọ kò ní gbowó iṣẹ́ rẹ̀ Àwọn wo gan an ló wà nínú bàálù Ethiopia tó já ni Nairobi?
Cannabis: Akeredolu, Ọgá NDLEA lọ kọ nípa gbíngbin igbo ní Thailand
ewu naa pọju lọ ni aarin awọn ọdọ ati awọn obinrin .
Ileeṣẹ TCN ṣalaye ọrọ yii lasiko to n fesi si ihalẹ awọn ẹgbẹ oṣiṣẹ TUC ti wọn ni awọn yoo da họwuhọwu silẹ laggo ipese ina ọba nitori ẹsun ti wọn fi kan ileeṣẹ TCN pe o n fi iya jẹ awọn oṣiṣẹ rẹ.
Ọpọlọpọ nǹkan mìíràn ni ó ti di àṣà wọn, gẹ́gẹ́ bíi fífọ àwo ìmumi, ìkòkò ìpọnmi ati àwọn àwo kòtò onídẹ.
Obasanjo: Eré ìtàn nípa ìbí, àti jéèyàn pẹ̀lú ìpèníjà Olusegun Aremu Obasanjo
Gẹgẹ bi wọn ṣe sọ ọ, sọ́jà kan to ba wọn sọ̀rọ lati bareke ologun to wa ni Maimalari sọ fun wọn pe wọn sin ọpọlọpọ ologun sinu saree ikọkọ naa ni alẹ nibi ti o to ẹgbẹrun kan ologun to n gbe nibẹ, bi wọn ṣe n ku ni wọn n pa orukọ wọn rẹ ninu itan""."
Ẹfunsetan Aniwura, obìnrin tó ju ọkùnrin lọ Ọ̀rọ̀ǹpọ̀tọ̀niyùn, Aláàfin obìnrin àkọ́kọ́ rèé, tó ní nǹkan ọkùnrin Orin oni ẹ̀dà Afro ti wọn lu iya ilu si jẹ ọkan lara orin ti Kakaki gbe jade eyi to n ṣafihan aṣa ibilẹ Afirika.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Buhari: Àìsí ìtọ́jú tó péye ló mú ṣọ́jà gba iṣẹ́ ọlọ́pàá ṣe láwùjọ 14 Owewe 2018 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 26 Bélú 2018 Oríṣun àwòrán, Bashir Ahmad Àkọlé àwòrán, Ọga ọlọpaa lorilẹede Naijiria ni awọn ọlọpaa yoo tubọ tẹpa mọ iṣẹ wọn Idunnu ti ṣubu lu ayọ fun awọn ọlọpaa lorilẹede Naijiria lẹyin ti iroyin kan sita ni ọjọ aje pe Aarẹ Buhari ti buwọlu owo oṣu tuntun fun awọn ọlọpaa.
Ìpín mẹ ́ rin ni a pín iṣẹ ́ yìí sí .
Ní bayìí, orilẹ̀-èdè mẹẹdogun ni wọ́n ti fi ofin de láti ma wọ Naijira mọ Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí 6:30 Fídíò, Akomolede ati Aṣa lori BBC: Mọ̀ si nípa oríṣìí ẹ̀ka ìsọ̀rí ọ̀rọ̀ àti ìwúlò wọn, Duration 6,308 Owewe 2020 Fuel hike protest: Àwọn akẹ́kọ̀ọ́ ìpínlẹ̀ Oyo, Osun àti Ondo ṣe ìfẹ̀hónúhàn lórí èlé owó iná àti owó epo8 Owewe 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Àkọlé àwòrán, 'Mama mama mi ko tilẹ beere ohun kan lọwọ mi, o kan ṣaa tọju mi ni.
Ẹni to bori: Benin Nigeria vs Uganda.
Amọ agbẹnusọ ileeṣẹ ọlọpaa awọn ko tii ri ọdọbinrin naa mu.
Fọnran CCTV naa fihan pe ohun gbogbo si n lọ nirọwọ rọsẹ ni bii aago meje ku iṣẹju mẹtadinlogun lọjọ naa.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Kínni ààrùn coronavirus nííṣe pẹ̀lú ìmọ̀ ẹ̀rọ 5G?
Awọn ti wọn gbiyanju de abala to kangun si asekagba naa gba $925,000 owo dolla ni gba mabinu.
Bíótiwùkíórí, ìpolongo rẹ̀ jẹ́ ìgbàwọlé nítorí ìparí ìjà tí ó wà ní àárín òun àti ọ̀gáa rẹ̀, Ààrẹ ìgbà kan rí Olusegun Obasanjo  tí ó sọ wípé ìṣàkóso ìjọba Buhari kùnà.
Chelsea wọ Arsenal lẹ́wù ìyà ní Europa pẹ̀lú 4-1!
Ṣugbọn Amasaya kọ̀ kò gbọ́, nítorí náà, Jehoaṣi ọba Israẹli kó ogun lọ pàdé Amasaya ọba Juda ní Beti Ṣemeṣi tí ó wà ní Juda.
Òun ni yóo jẹ́ ààlà ilẹ̀ Juda ní apá ìhà gúsù.
Àwọn ọkunrin náà bẹ̀rẹ̀ ìrìn àjò wọn, Joṣua sì kìlọ̀ fún wọn, pé, “Ẹ rin ilẹ̀ náà jákèjádò, kí ẹ sì kọ àpèjúwe rẹ̀ sílẹ̀ wá fún mi.
Aaroni bá na ọwọ́ rẹ̀ sí orí gbogbo omi ilẹ̀ Ijipti, ọ̀pọ̀lọ́ bá wọ́ jáde, wọ́n sì bo gbogbo ilẹ̀ Ijipti.
 tí a bá fẹ ́ ṣẹ ̀ dá àwọn ọ ̀ rọ ̀ yìí , a máa ń lo mọ ́ fíìmù ìsẹ ̀ dá mọ ́ ọ ̀ rọ ̀ ìpìlè , èyí tó jẹ ́ pé ọ ̀ rọ ̀ -ìṣe ló máa ń jẹ ; àkànpọ ̀ àwọn méjéèjì máa ń yọrí sí ọ ̀ rọ ̀ -orúkọ .
Nítorí pé èrò ọkàn olukuluku ni ẹrù OLUWA lójú ara rẹ̀; ẹ sì ń yí ọ̀rọ̀ Ọlọrun alààyè po, ọ̀rọ̀ OLUWA àwọn ọmọ ogun, Ọlọrun wa.
Ọpọ to dibo fun Trump lọdun mẹrin sẹyin lo yi ọkan wọn pada nitori ihuwasi rẹ.
“Bakan naa, ipa re ninu iko Super Eagles ko se yesile, fun idi eyi, tani koni nife si iru agbaboolu yii,”.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Àwọn ènìyàn ìràn ń jó fótò Trump níná lásìkò ti wọ́n wọde lòdì si Trump ni Tehran ni inú oṣù karun, ojo kẹsan ọdun 2018 Osakwe ni wàhálà ti yóò bẹẹ́ silẹ̀ ni Nàìjíríà le jẹ́ láàrin Shiite àti Sunni nígbà ti àwọn mírànn yoò ma ri ìjà náà bi èyi to n ṣẹ̀lẹ̀ si Islam.
MTN àti BBC World Service bẹ̀rẹ̀ àjọṣepọ̀ lórí ìròyìn ìṣẹ́jú kan BBC Wo bí o ṣe lè fí orúkọ rẹ sílẹ̀ fún iṣẹ́ N Power tuntun ti ọdún 2020 Yàtọ̀ sí coronavirus, wo ìgbà mẹ́wàá míì táwọn mùsùlùmí kò lè ṣiṣẹ́ Hajj A wà nínú igbó tí a ti ń wá àwọn arinrìnàjò mẹ́jọ láti Abuja sí Eko tí wọ́n jígbé lọ- Ọlọ́pàá Ondo Oríṣun àwòrán, Twitter/Godwin Obaseki Godwin Obaseki: Ṣé Godwin Obaseki yóò darapọ̀ mọ́ PDP ni tàbí yóò gba kádàrá?
Àwọn dókítà Eko bẹ̀rẹ̀ ìyanṣẹ́lódì lórí owó oṣù àti ètò adójútòfò fún ìtọ́jú coronavirus Kò sí ìfòyà, ọkọ̀ bààlù wà tí ìjọba ba ti afárá 3rd Mainland lósù yìí Taló pa olórí àwọn ''One Million Boys'' Ebila n'Ibadan?
Ọgbẹni Mubarak to n ṣoju ẹkun Kumbungu nile aṣofin agba ni Ghana lo ṣide eto ipade naa pẹlu ibeere nla yii.
Lóru, wọn á máa lọ fọ́ ilé kiri,ṣugbọn bí ilẹ̀ bá ti mọ́,wọn á ti ìlẹ̀kùn mọ́rí,wọn kì í rí ìmọ́lẹ̀.
Ẹ̀mí fẹ́ ṣe é, ṣugbọn ara kò lágbára.
A fi orúkọ Kristi bẹ̀ yín, ẹ bá Ọlọrun rẹ́.
Gbogbo ohun tí mo bá pa láṣẹ fún ọ ni o gbọdọ̀ sọ.
Oga agba fún awọn ọlọpaa, Idris Ibrahim lo kede pe àwọn kọmiṣọna mẹjọ ati igbakeji kan ni wọn yoo ṣiṣẹ amojuto ìdìbò náà ti yoo fun àwọn ènìyàn ìpínlẹ̀ Ọṣun laaye lati dìbò yan ẹni tó wù wọn.
Irisi BBC Yoruba ni ṣoki Iroyin ni ede Yoruba, fun awọn ọmọ kaarọ o jiire BBC Yoruba yoo maa jade lori ikanni agbaye bbc.
Wo ohun tí ọkùnrin yìí ń sọ táyà ọkọ̀ dà 'Ilé iṣẹ́ DSS kò mú òṣìṣẹ́ INEC kankan lórí ọ̀rọ̀ Atiku' Tó o bá ṣàdéhùn ìfẹ́ tó ò mú u ṣẹ, ẹ̀wọ̀n lo fi ń ṣeré Yoruba rẹ ko fi taratata dan daada ṣugbọn ni ibamu pẹlu ifẹ ati ibaṣepọ ti ọdun yi kọwa, o da wa loju wi pe ẹ o nifẹ́ si ikini rẹ yi.
Ọmọbìnrin ọdún 25 gún ọ̀rẹ́kùnrin rẹ̀ pa nítorí ó ní ko lọ ṣẹ́ oyún Ó tó gẹ́ẹ́!
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ìdílé tí ọkọ da ọmọ síta tóríi ojú Búlùú tí wọ́n ní bá BBC sọ̀rọ̀ Eto atundi idibo si aga aṣofin ipinlẹ lẹkun aringbungbun Nasarawa ti yoo waye ni ipinlẹ Nasarawa ni wọn yoo ti kọkọ lo oju opo yii.
Ẹ dín ohun tí ẹ bá fẹ́ dín, kí ẹ sì se ohun tí ẹ bá fẹ́ sè, ohun tí ó bá ṣẹ́kù, ẹ fi pamọ́ títí di òwúrọ̀ ọ̀la.
Kò sí àkọsílẹ̀ pé ó ní baba tabi ìyá; kò ní ìtàn ìdílé.
Tí a fiṣọwọ́ ní 13:46 11 Òkùdu 201913:46 11 Òkùdu 2019 Ogbeni Rauf Aregbesola kí Omo-Agege kú oríire View more on twitterView more on twitter Article share tools Facebook Twitter ṢàpínlòView more share options Share this post Copy this linkKà síwájú síi nípa àwọn ìtọ́kasí wọ̀nyí.
Coronavirus Update: Iná jó àwọn ènìyàn 10 tó ń gbà ìwòsàn àrùn Coronavirus ní Isolation Center
com/iamcertified_eyinjueledu Bakan naa ni Mustipha Sholagbade gbe ọrọ yii soju opo rẹ, to fi mọ awọn osere tiata miran.
Mo sì rí angẹli alágbára kan tí ń ké pẹlu ohùn rara pé, “Ta ni ó yẹ láti ṣí ìwé náà, ati láti tú èdìdì rẹ̀?
"Ariwo ""Allahu Akbar"" kò tọ́ sawọn Agbébọn àti Boko Haram - Buhari Buhari júwe ọ̀nà ilé fún Obono-Obla lórí ẹ̀ṣùn ayédèrú ìwé ẹ̀rí Òṣèré tíátà Toyin Abraham daya Kolawole Ajeyemi Bí Khafi ṣe ní ìbálòpọ̀ ojútáyé tako àṣà Yorùbá - Ìjọba Ekiti Wo àwọn oúnjẹ tí àṣẹ Buhari leè mú kó gbówó lórí Amọ beere to wa gba ọkan awọn eeyan ni pe se gbogbo awọn ileeṣẹ ọlọpaa ni ipinlẹ mẹfẹẹfa to wa lẹkun yii ni eto agbajọ ọwọ naa kan tabi boya ileeṣẹ ọlọpaa nipinlẹ Ekiti nikan lo n da ọwọ wu lori rẹ."
Oríṣun àwòrán, Others Àkọlé àwòrán, Abdurasheed Maina àti ọmọ rẹ̀ Faisal ni wọ́n gbé ní ìlú Abuja lẹ́yìn tí wọ́n ti ń wá láti ọdún 2017 fún ẹ̀sùn lilu owo ilú ní póńpò.
 gbogbo awọn fiimu fiimu 31 yoo han , pẹlu argentinian , kannada , india , kenyan , pakistani , portuguese , ati awọn fiimu tunisian .
“Fetí sílẹ̀, n óo sọ fún ọ,n óo sọ ohun tí ojú mi rí,
wahala to maa n waye  laarin awon agbẹ
Ati wi pe ki ẹnikẹni ti ko ba fẹ jẹ ki ijọba gbẹsẹle awọn dukia naa jade pẹlu ẹri wi pe awọn ni wọn ni.
Gẹgẹ baa se gbọ, ohun to fa idasilẹ ayajọ ọjọ 'Ma wọ kọmu' ni Naijiria ni lati pe akiyesi awọn obinrin si aisan jẹjẹrẹ ọyan ati awọn ọna ti wọn lee gba dena rẹ.
Tí a bá pe ìrìnàjò náà ní ìrìnkèrindò, a kò parọ́ rárá!
ó bèèrè lọ́wọ́ OLUWA pé, “Ṣé kí n gbógun ti àwọn ará Filistia?
O ni ijọba ti jẹ ko di mimọ fun wọn pe ẹsẹ ni lati bẹbẹ fun ẹni ti wọn ba fi ẹsun ifipabanilopọ kan.
Ẹ fún orúnkún tí kò lágbára ní okun.
Guru Maharaji : Aṣòfin Adéyẹmọ kì bá tí kú kání ó mọ mi
Lẹ́yìn ìwé yìí ni wọ́n lọ kọ́ṣẹ́ ìwé títẹ̀, èyí ni wọ́n ń ṣe títí tí wọ́n fi joye Báálẹ̀ ní ọdún 2013.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Laipẹ yii ni awọn ọlọpa tu awọn inu igbo kan ti igbagbọ wa pe awọn ajinigbe naa fi ṣe ibuba wọn ni oju ọna ti ọrọ kan Awọn meji to ku ni wọn ji gbe ni ilu Ọsẹ loju ọna to lọ Ọwọ si Ikarẹ-Akoko, nipinlẹ Ondo bakan naa lasiko ti wọn n rinrinajo.
"Mercy Aigbe ṣá ọmọ rẹ̀ sínúu fíìmù tuntun, wo itú tí ọmọ ọdún mẹ́wàá náà pa Iléeṣẹ́ ọlọ́pàá ti bẹ̀rẹ̀ ìwádìí lórí fídíò ọkùnrin kan tó ń fi ""shisha"" ṣagbeji ara Wo nǹkan tí ìjọba àpapọ̀ yóò ṣe fáwọn tó ń ta 'pẹlẹbẹ', 'pàrágà' àti 'fònàgáú' Awọn to ti ṣaaju rẹ lọ ile ni Lilo, Ka3na, Eric, Tochi, Kaisha, Prince, Wathoni, Tolanibaj, Bight O ati Lucy."
"'A kẹ̀yìn sí Ivory Coast, owó yín ò lè máa jẹ́ ""eco"" táa ti mú fún àjọná owó ECOWAS' Ẹgbẹ́ kan fún Tinubu ní wákàtí mẹ́rìnlélógún láti sọ èrò rẹ lórí Amọtẹkun 'Ẹ yé pè wá ní NEPA mọ́ tí ẹ bá fẹ́ ká fún yín ní iná, DisCos ni wá' Ọwọ́ ọlọ́pàá tẹ afurasí tó ní òun ló jí ọmọ gbé láti parọ́ mọ́ pásítọ̀ ìjọ Sotitobire Ohun ti iroyin loju opo ayelujara atawọn ileeṣẹ iroyin abẹle n sọ ni pe, igbesẹ naa waye lẹyin ti Ọga ileeṣẹ agborinjade Golden Boys Record, King Patrick ke gbajare sita pe ibi a foju si ọna o gba bẹ ati pe arakunrin Peruzzi ti ọpọ n wo gẹgẹ bii ẹgbọn Chioma, iyawo Davido kii ṣe ẹgbọn rẹ, ọrẹ ikọkọ rẹ ni."
Exclusive: Atiku dára ju Buhari ní ìlọ́po méjì - Obasanjo #BBCNigeria2019 Tani Ọjọgbọn Mahmood Yakubu ti yóò ṣètò ìdìbò 2019?
Owó oṣù tuntun ọ̀hún nìrètí wà pé yóò gbérasọ l'óṣù Kẹjọ ọdún 2018.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ọjọ Satide ní àwọn mọ̀lẹ́bí rẹ̀ ní sẹ́nétọ̀ náà pinnu láti máse gba ìtójú àìsàn jẹjẹrẹ mọ́ nítorí ọjọ́ orí rẹ̀.
Toyin Abraham tun fi nọmba ti awọn obinrin le pe lati fẹjọ ifipabanilopọ sun.
Ọ̀pọ̀ èèyàn farapa nínú ìwọ́de Shiite Dúkìá àti ọkọ̀ jóná, ọlọ́pàá mẹ́sàn-án fara gbọta lásìkò ìwọ́de Shiite Ìbọn ọlọ́pàá ló pa èèyàn, ẹgbẹ́ wa kìí lo ìbọn - Shiite fárígá Zakzaky yọjú sílé ẹjọ́ lórí ẹ̀sùn ìpànìyàn Garba Shehu to jẹ olubadamọran fun Aarẹ Muhammadu Buhari lori eto iroyin ṣalaye fun BBC pe aṣẹ ile ẹjọ ko sọ pe ki awọn ẹlẹsin Shiite ma sin ẹsin wọn bikoṣe pe fun awọn IMN.
Alaga gbogbogbo apapo egbe awon osise meteete naa Samson  Ugwoke  kede ida iyanselodi naa duro lojo-Ru lasiko ti o n ba awon oniroyin soroO salaye pe, won ti so fun apapo awon osise egbe meteeta lati bere ise pada lojo-Bo, ti o je ojo keedogun osu keta odun 2018.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Akomolede ati Aṣa lori BBC:Wo ìrúfẹ́ ìgbeyàwó méje tó wà nílẹ̀ Yorùbá àti ojúṣe Alárinà Ajọ UNICEF fikun pe arun Coronavirus to tun wa lode ko jẹ ki ijọba o ibi ara si aisan otutu aya naa mọ, eleyii ti yoo mu ki ọpọlọpọ ṣe kongẹ aisan naa ni Naijiria.
Àwọn wọ̀nyí ní ẹbi àti ọ̀rẹ́ tí wọ́n a máa wá bẹ̀ wọ́n wò.
Ṣugbọn bí bẹ́ẹ̀ kọ́, iná yóo jáde láti ara Abimeleki, yóo sì run gbogbo àwọn ará ìlú Ṣekemu ati Bẹtimilo.
Ikú Dagrin pé ọdún mẹ́wàá, wo àwọn nǹkan mánigbàgbé nípa rẹ̀ Auxiliary lo ń jà káàkiri ìlú Ibadan lọ́jọ́ Aje, ẹgbẹ́ ọlọkọ èrò NURTW kọ - Ejiogbe Ẹnìkan ṣoṣo nínú ìdílé kan ni yóò gbà N20, 000 owó ìdẹ̀rùn igbele Covid-19 - ìjọba àpapọ̀ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Òǹtàjà aṣọ ni mí tẹ́lẹ̀, ọ̀dá owó ló sọ mi di alábárù Eniyan igba din mẹta ti ri iwosan, mejidinlọgbọn si ti ku.
Ijọba Obasanjo ṣalaye pe afikun owo epo waye nitori ijọba ṣe adinku owo iranwọ to wa lori ero.
Ó sì ti tún pe èmi ati ọba sí àsè mìíràn ní ọ̀la.
Dafidi Dá Ẹ̀mí Saulu sí lẹẹkeji.
Àjọ NCDC kéde ènìyàn 594 tó tún ṣẹ̀ṣẹ̀ ní Coronavirus ní Nàìjíríà Èyí ni àwọn arẹwà ‘ẹ̀lẹ̀ Daddy’, àfẹ́fẹ́ tí Aláàfin fi ń mí Ejò wo ló mi ₦118m láàrin UCH àti ìjọba Oyo?
Araale: Ọmọ ọdun melo gan ni Seyi Awolowo, ati pe ṣe Dokita ni?
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù NAPTIP: Babalawo to n fọmọ sowo lugbadi ofin 15 Èrèlè 2018 Oríṣun àwòrán, AFP Àkọlé àwòrán, ọgọọrọ awọn ọmọ ati iya, lọti bo sowo awon ọdaran ti wọn n fi ọmọ kekeeke sòwò Ajọ to n gbogun tiwa ifinisowoeru lorilẹede Naijiria, NAPTIP ti fi panpẹ ofin mu onisegun ibilẹ kan to n ta awọn ọmọ kekeeke.
Aarẹ Uhuru Kenyatta gbe igbesẹ yi lẹyin ti ọrọ jẹyọ pe awọn alaṣẹ kan ji ọpọ miliọnu dọla to yẹ ki wọn fi ra nkan eelo itọju arun Covid-19.
Siwaju sii ninu alaye re, Comptroller Zulkiflu tun so pe
Joṣua ṣẹgun gbogbo ilẹ̀ náà, ati àwọn ìlú tí ó wà ní orí òkè, ati àwọn tí wọ́n wà ní ilẹ̀ Nẹgẹbu ní apá gúsù, ati àwọn tí wọ́n wà ní pẹ̀tẹ́lẹ̀, ati àwọn tí wọ́n wà ní gẹ̀rẹ́gẹ̀rẹ́ òkè, ati gbogbo àwọn ọba wọn.
Ìyá Alájé: Bẹ́ẹ̀ni, ó yé, ẹ ṣeun gan- an fún àlàyé yín
Agígírì yí ni Ọba Ìjẹ̀bú-Jẹ̀ṣà kiíní, àwọn ìran ọlọ́dẹ méje ìjọ́sí ló di ìdílé méje tí ń jọ́ba Ìjẹ̀bú-Jẹ̀ṣà títí di òní.
Àwọn ẹbi sọrọ nipa iwa ikonimọra ti Orlando ni.
Wo oríṣiríṣi ìgbádun ibálòpọ̀ láwọn orílẹ̀èdè mìíràn A yoo ṣe àyẹ̀wò ọpọlọ fàwọn òṣìṣẹ́ SARS - Iléesẹ́ ọlọ́pàá Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Femi Adebayo: Ẹyin ọ̀dọ́, ẹ káàbọ̀ ságbo ilé Tíátà Nigba to n ba akọroyin Punch sọrọ, Fẹmi Adebayọ ni, oun ko ri baba oun bii baba oun rara to ba di ẹnu isẹ tiata, o ti di akẹẹgbẹ oun ti awọn dijọ n sisẹ, tawọn si gbọdọ se ojuse awọn daadaa.
Nígbà tí ẹ bá wà ní ilẹ̀ àwọn ọ̀tá yín, ilẹ̀ ti ẹ̀yin pàápàá yóo wá ní ìsinmi, níwọ̀n ìgbà tí ó bá wà ní ahoro, ilẹ̀ yín yóo gbádùn ìsinmi rẹ̀.
Ó pé ọdún mẹ́rìnlélàádọ̀ta tí Akintola kú, ìdí abájọ ìja rẹ̀ pẹ̀lú Awolowo rè é Àgbẹ́kọ̀yá yarí; Afẹnífẹ́re ní ilé ẹjọ́ ló kàn lórí ọ̀rọ̀ Àmọ̀tẹ́kùn Ile ẹjọ ri ẹri daju pe wọn fun akapo ijọ naa ni owo lati fi pamọ fun ijọ naa, ti akapo naa ati igbakeji rẹ si ṣe wuruwuru pẹlu owo naa lai fi si ile ifowopamọsi.
Fidio ọhun ṣafihan bi ọrẹkunrin rẹ ti dẹnu ifẹ kọ ọ lori ikunlẹ pe, ṣe yoo fẹ oun ni ọkọ, lẹyin to fesi pe bẹẹni, ni ọrẹkunrin rẹ dimọ gbagi.
idibo a da ibo naa nu nitori itẹka naa ko si loju ibi to yẹ ko wa.
Kò yẹ mi ìdí tí Wasiu Ayinde fi hu ìwà àbùkù tó hù sí mí- MC Murphy Àdigunjalè báńkì ní Iyin-Ekiti fẹsẹ̀ fẹ, bí wọ́n ṣe rí wa - Iléeṣẹ́ ọlọ́pàá Ìlànà ‘Referendum’ nìkan la fi le gba orílẹ̀èdè Oduduwa, kìí ṣe ìwọ́de Ẹ̀yin tẹ́ ń jà fún ẹ̀yà Hausa, Igbo àti Yorùbá, ara yín lẹ̀ ń jà fún - Lamido Sanusi Wo àkọsílẹ̀ lórí bí ìpínlẹ̀ kọ̀ọ́kan ní Nàìjíríà ṣe gba ilẹ̀ tí wọ́n wà báyìí Buhari, ayẹyẹ kí là ń ṣe gan, ṣé ti ìpànìyàn àbí ìjínigbé?
Ẹni ọdun mẹrinlelogoji ọhun, ni iwe ẹri lati Ileewe ikọsẹ ologun ilẹ America, ni West Point.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù #WhereIsEspiritDCorp: Ohun tó kọjú sẹ́nìkan, ẹ̀yìn ló kọ sí ẹ́lòmíì lọ̀rọ̀ yìí lórí ayélejára 9 Ògún 2019 Oríṣun àwòrán, Twitter/Nigeria Police Force Àkọlé àwòrán, Ikọlu ọlọpaa ati ologun Oju opo Twitter ti kun pitimu nipa ero awọn ọmọ Naijiria lori ibeere ti ileesẹ ọlọpa ilẹ wa n bi ileesẹ ologun pe, ki wọn salaye bi ọlọpa mẹta se di ero ọrun lati ipasẹ ibọn tawọn ologun yin mọ wọn niluu Takum, ni ipinlẹ Taraba.
Ọkùnrin olόwό kan-án wà ní ayé àtijọ́ tí orúkọ rẹ̀ ńjẹ́ Olόwό-Ìbínú.
A fẹ́ lo ẹ̀jẹ̀ àwọn èèyàn tó ye àrùn Coronavirus láti fi ṣe ìwòsàn fún àwọn tó wà lórí àárẹ- UK Kí làwọn ìdàmú tí Coronavirus n mú bá àgọ́ ara?
Nkan to ṣe pataki ni pe olùkopa kọọkan gbọdọ ni iye ipo to pọ ju ti gbogbo àwọn to ku lọ, awọn àsoju naa si din mẹ́wàá ni ẹgbẹ̀run meji.
wọ́n wọ sálúbàtà tí ó ti gbó ati aṣọ àkísà, gbogbo oúnjẹ tí wọn mú lọ́wọ́ ni ó ti gbẹ, tí ó sì ti bu.
Eniyan bii ẹẹdẹgbẹta lo fara pa, ti awọn ajoji to wa lara awọn to ku si to marundinlogoji.
Iroyin ohun fi mule wipe, ohun
"Ko tan sibẹ o, lasiko ti ọrọ bi ọmọ naa ṣe sọnu ṣi n gbona janjan, ni awọn eeyan kan dana sun ṣọọṣi Sotitobire, ""nitori wọn fura pe ori pẹpẹ inu ṣọọṣi naa ni wọn ri Gold Kolawole mọlẹ si""."
Ẹ̀yin eniyan mi, bí ẹ ti jìyà ní òkè mímọ́ mi,bẹ́ẹ̀ ni gbogbo àwọn orílẹ̀-èdè náà yóo jìyà;wọn óo jìyà yóo tẹ́ wọn lọ́rùn,wọn yóo sì wà gẹ́gẹ́ bí ẹni pé wọn kò sí rí.
Ewe, gbogbo awon agbaboolu ohun patapata ni ireti wa pe, won yoo de sile itura iko naa ti n se (Le Meridien Hotel and Golf Resort), ti o wa nilu Uyo, lojo aje(Monday) ti n se ojo kokanlelogun osu karun un odun ti a wa yii .
Nibayii, ipinlẹ mejidinlogun ni ọwọja aarun lassa ti ja de lorilẹede Naijiria bayii; bẹẹni aadọfa eeyan lo ti ran lọ sọrun.
Nígbà tí àwọn Farisi gbọ́ pé ó ti pa àwọn Sadusi lẹ́nu mọ́, wọ́n kó ara wọn jọ.
Ọba wọn yóo lókìkí ju Agagi lọ,ìjọba rẹ̀ ni a óo sì gbéga.
Ṣugbọn ní tèmi, èmi ń rìn ninu ìwà pípé;rà mí pada, kí o sì ṣàánú mi.
"Taya moto to fọ lojiji lo sokunfa ijamba ọkọ naa, ti wọn si ti gbe oku awọn eeyan to lugbadi ijamba naa lọ si ibudo igbokusi aladani kan to wa ni ilu Isara Rẹmọ.
Nítorí pé, òfé lásán ni olùbéèrè Mirshahin Aghayev àti ìbéèrè rẹ̀.
Ka ni Okwaraji ko ku ni, oni yii, ni ko ba pe ọmọ ọdun marundinlọgọta lori oke erupẹ.
Ìyàwó mi ṣẹ̀ṣẹ̀ bímọ tuntun, kò si oúnjẹ fún wa torí ìgbélé Coronavirus- Yakubu Ìtàn Manigbagbe: Àwọn àjakalẹ-àrun to ti wáyé rí ṣáájú Coronavirus Ìjọba yóò lo BVN àtàwọn ọ̀nà méjì míràn láti pín owó ìrànwọ̀ fún aráàlú Orin 'if I die', to tu mọ si 'Ti mo ba ku', lo gbe jade kẹhin.
Awọn miran gba pe igbesẹ to dara ni ki a bẹrẹ sini san owo ori lori ọja ti a ra lori ayelujara.
Wò ó, ẹni tí ń pa Israẹli mọ́kò ní tòògbé, bẹ́ẹ̀ ni kò ní sùn.
Ni kete ti iya ọmọbinrin yii ṣe kẹfin pe ọdọbinrin naa n figba gbogbo bì ni o ba gbe e lọ sile iwosan fun ayẹwo.
Bakan naa lo tun fi ẹsun pe wọn n gba ju owo ti ijọba ipinlẹ Oyo ni ki wọn maa gba lọwọ awọn awakọ lọ.
Bo tilẹ jẹ pe wọn ti gbe oku Ngorgi lọ ile igbokusi, ileeṣẹ ologun ni wọn ti fi panpẹ ofin mu ọdanran naa, iwadii si ti bẹrẹ.
Awọn oniṣowo oogun oloro naa ti kọ ẹyẹ ọhun lati pariwo ''mama, ọlọpaa'' ni ede Pọtugi lati jẹ ki awọn ọdaran naa mọ pe awọn ọlọpaa n bọ.
Lẹ́yìn rẹ̀ ni wọ́n bí Kesedi, Haso, Pilidaṣi, Jidilafi ati Betueli.
Tí a fiṣọwọ́ ní 5:185:18 Wo oríṣìí àrùn márùn ún tí ìgbéyàwó láàrin ìbátan si ìbátan máa ń fà Dokita Ibrahim Musa to jẹ akọṣẹ-mọṣẹ nipa arun inu ẹjẹ sọ pe, igbeyawo laarin ibatan ni ewu ninu nitori awọ̀n arun ajẹ́bi ti wọn le jogun.
“Niwon igba ti a o ba mojuto awon aala ti o pa orile ede kan po si ekeji, o di dandan ki isoro ati ipenjia ti a n koju tubo maa po si, bo tile je pe, a n sa ipa wa, lati pese eto aabo to peye fun emi ati dukia awon eniyan.
Mẹ́ta nínú àwọn ajínigbé Fulani náà bá ìṣẹ̀lẹ̀ náà lọ ti wọ́n sì gba ìbọn wọn Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Oyo Insecurity: Kí lo dé tí ìpànìyàn, ìjínigbé, ìdigunjalè ń peléke síi lábẹ́ Gómìnà Makinde?
ẹmi won pe ki Olorun tẹ wọn si afẹfẹ rere.
Ǹjẹ́ kò béèrè bí ara mi ti le sí?
O fikun pe igbesẹ naa jẹ gbogbo eleyi ti wọn ti gbe kalẹ bẹrẹ lati ọdun 1959, pupọ awọn dukia ajumọni ti wọn gbẹsẹ le naa ni wọn ko mojuto daradara, ti ọpọ si tun ti parun.
orilẹ-ede South Africa lati san owo gba-mabinu fun awọn ọmọ orilẹ-ede
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ọ̀tá Yorùbá ló lo ìwọ́de láti dojú ogun kọ wá - OPC Àwọn ọ̀tá Nàíjíríà tó fẹ́ dojú ìjọba bolẹ̀ ló wà lẹ́yìn ìwọ́de EndSARS"" Ó parí ni ohùn tó gbẹnu ọ̀pọ̀ ọmọ Nàíjíríà lẹ́yìn ọ̀rọ̀ Buhari Ìwọ́de EndSARS kìí ṣe ọ̀rọ̀ ẹlẹ́yàmẹ̀yà, ara ti kan àwọn èèyàn ni - Afenifere Buhari kọ́ ni ìṣòro wa, bó ṣe wà láti láéláé rèé - Fr Mbaka Àwọn ọ̀dọ́ fi ọ̀nà àrífín pe Tinubu lórí aago àmọ́ ó ní òun kò mọwọ́-mẹsẹ̀ nípa ìpànìyàn Lekki Á ràgà bo CCTV Lekki bí i ẹ̀rí tó dájú fún ìwádìí ìpànìyàn - Sanwo-Olu SERAP gbé ìjọba àpapọ̀ lọ ilé ẹjọ́ àgbáyé ICC lọrí ẹ̀sùn ìpànìyàn ""Iṣẹlẹ to waye ni Lekki lọjọ Iṣẹgun ba ni lọkan jẹ, gbogbo wa si ti fẹnu kò pe iru iṣẹlẹ naa ko tun ni waye mọ."
lati ipinle lorile ede yii fun ipade apero yii.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: MKO Abiọla gba oyè GCFR tó ga jùlọ ní Nàìjíríà 'Boko haram kọ́ ló fa ìbúgbàmù Mubi' Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ẹtàn ni àwọn ọ̀rẹ́ fi ń tan èèyàn lọ si Libya pé iṣẹ́ gidi wà níbẹ̀ Ènìyàn mọkàndinlọgbọnlélẹgbẹta ní àwọn àjọ náà dóòlà nínú odò Meditereanian lágbàgbè tó súnmọ́ Libya.
 Ati pe awọn ohun ti wọn tori rẹ kọ ọ yii lo
Lara awọn koko ọrọ mii ti wọn mẹnu ba lọlọkan ojọkan niyii.
A kan bere sini gburo ibọn ni laarin iseju die, eyi lo mu ka bere sini sa asala lai mọ ibi ta nlọ.
"Lẹ́yìn àyẹ̀wò, kò sí alárùn Coronavirus ní Nàíjíríà, sáká lara wa dá - Mínísítà ""Àbámọ̀ ló gbẹ̀yìn bí mo ṣe yípadà láti obìnrin sí ọkùnrin, ń kò bá tí ṣe bẹ́ẹ̀"" Kaduna tún gbàlejò ìkọlù àwọn agbébọn, àádọ́ta èèyàn míì rọ̀run ọ̀sán gangan Eto naa gba wa nimọran lati yẹra fun ọpọ ero, ka mu imọtoto ni pataki, ka maa se ounjẹ wa jinna daadaa, ka si joko sile, ti ara wa ko ba da."
Oríṣun àwòrán, Ronkẹ Oshodi-Oke Àkọlé àwòrán, Ronkẹ Oshodi-Oke wá ń bèèrè pé kín ni àwọ́n òsèré tíátà ń se èyí fún?
Àbí o kò gbọ́ ohun tí wọ́n sọ pé o wí?
Ẹ ̀ ka ìlù yìí máa ń le díẹ ̀ .
 Gege bi oga agba Okechukwu se so,“Awon oludije mejeeji aare Muhammadu Buhari ati akegbe re Alhaji Atiku Abubakar je eya Fulani, bee si ni won tun jo je musulumi bakan naa, eleyi ti o mu ikunsinu eleyameya  ati esin kuro  .
Sugbọn oun ti awọn ọmọ Naijiria n bere ni anfaani to mu wa.
“Nítorí náà, ẹ gbọdọ̀ kíyèsí gbogbo àwọn ìlànà mi ati àwọn òfin mi, kí ẹ sì máa pa wọ́n mọ́, kí ilẹ̀ tí mò ń ko yín lọ má baà tì yín jáde.
Arabinrin ọhun ni adajọ agba ipinlẹ California tẹlẹ, nibi to ti n lọgun atunṣẹ ileeṣẹ ọlọpaa lataari oriṣiriṣi iwọde to waye lodi si iwa ẹlẹyamẹya.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Epo rọ̀bì ti ṣàkóbá fáwọn olùgbé apá odò l'Ondo O ni pẹlu bi arun naa ti ṣe tan kalẹ de awọn ipinlẹ marundinlọgbọn bayii, awọn gomina ti fọwọ si pinpin eto idojukọ arun COVID-19 kakiri awọn ipinlẹ lorilẹede yii.
Ọmọ ogun Nàìjíríà bẹ̀rẹ̀ lílo 'Drone' láti gbógun tàwọn ajínigbé ni Ondo àti Ekiti Báwo ni ọkùnrin tí ọlọ́pàá bá òkú rẹ̀ nínú àgbá ní Oyingbo ṣe kú?
Nítorí pé mò ń ran àwọn aláìní tí ń ké lọ́wọ́,ati àwọn aláìníbaba tí wọn kò ní olùrànlọ́wọ́.
Ó sọ ọmọ keji ní Efuraimu, ó ní, “Ọlọrun ti mú mi bí sí i ní ilẹ̀ tí mo ti rí ìpọ́njú.
Dá mi lóhùn nígbà tí mo bá pè ọ́,Ọlọrun mi olùdániláre.
13 Ògún 2020 Alaafin Oyo: Kíni 'Ẹ̀lẹ̀ daddy' Olorì Abbey Adeyemi ṣe tí ojú òpó ayélujára rẹ̀ fi ń yeruku lálá?
Pàṣán ni baba mi fi nà yín, ṣugbọn àkeekèé ni èmi óo fi máa ta yín.
Gómìnà Ganduje wọlé fún sáà kejì ní ìpínlẹ̀ Kano Ìdìbò Kano kò fararọ, Atiku fẹ̀sun kan pe ìdúkoko mọ́ni pọ O ṣalaye pe awọn eeyan pupọ si tun padanu ẹmi wọn ti ibo rira si peleke.
Àgbàrá òdì ọ̀rọ̀ sí Kérésìmesì ti ṣàn gba orí ẹ̀rọ-alátagbà ó sì ti mú kí àwọn òǹlò kan ó kó ara wọn ní ìjánu.
Bí inú ti bí mi tó, ati bí inú mi ṣe ń ru tó, ni wọn yóo ṣe fi ìyà jẹ Edomu.
Gomina naa wa pa laṣẹ pe, ko si ile iwe kan ti o gbọdọ gba owo lọwọ akẹkọọ kan mọ lati asiko yii ni ipinlẹ naa.
Ẹ̀yin olólùfẹ́ mi àti ẹbí ni mo bẹ̀ Kò sí ìdí tí ó yẹ kí a fi tọrọ àforíjì lọwọ Nàìjíríà - Alákòso Johannesburg Baba Wande ati Tunde Kelani Oríṣun àwòrán, KAREEM ADEPOJU Àkọlé àwòrán, Kareem Adepoju Nigba diẹ sẹyin, ariyanjiyan bẹ́ẹ́ 'lẹ̀ lori ẹni to ni fiimu ‘Ti Olúwa nilẹ̀’ ti ‘Mainframe’ gbe jade lọdun 1993, Tunde Kelani pẹlu Kareem Adepoju ti gbogbo eniyan mo si ‘Baba Wande’, ti Tunde Kelani si se olootu rẹ.
Nígbà náà ni Ahabu ọba pàṣẹ pé kí wọ́n mú Mikaya lọ sọ́dọ̀ Amoni, gomina ìlú ati sọ́dọ̀ Joaṣi, ọmọ ọba, kí wọ́n sì sọ fún wọn pé: 
Mo ní kí ẹ yan àwọn ọlọ́gbọ́n, tí wọ́n ní ìmọ̀ ati ìrírí láàrin ẹ̀yà kọ̀ọ̀kan, n óo sì fi wọ́n ṣe olórí yín.
Ọjọ kẹẹdọgbọn, oṣu kẹwaa, ọdun 1900 ni a bi Frances Abigail Olufunmilayọ Thomas sinu idile ti wọn fẹran ẹ̀kọ́ iwe.
"Òní ló yẹ kí Ibidunni Ighodalo pé ogójì ọdún, Tope Alabi, Kenolly àtàwọn míì tí yóò kọrin níbẹ̀ rèé Coro wà Coro ò sí o, èmi á lọ́ sókè òkún bí mo bá ríṣẹ́ - dókítà A fura pé ejò lọ́wọ́ nínú ikú Tolu Arotile, ẹ ṣe ìwádìí ikú rẹ̀ - Afenifere, Gani Adams, Huriwa Ohun tí o kò mọ̀ nípa Ebila ""One Million Boys"" àti Ekugbemi, olórí ẹgbẹ́ òkùnkùn méjì tó da ìlú Ibadan rú Kò tán síbẹ̀ o, àwọn òṣèré kan tún ṣe ayẹyẹ ọjọ́ ìbí wọn l'ọ́sẹ̀ yìí."
Russia 2018: Àwòrán nọ́mbà jẹẹsí Super Eagles fún Russia rèé
Alufaa yóo fún Nasiri náà ní apá àgbò tí a ti bọ̀ pẹlu burẹdi dídùn kan tí kò ní ìwúkàrà ninu, ati burẹdi fẹ́lẹ́fẹ́lẹ́ kan tí kò ní ìwúkàrà ninu, lẹ́yìn ìgbà tí ó bá ti fá irun orí rẹ̀.
Ojo kefa osu keji lodoodun ni ayajo igbogun ti abe dida fomobinrin patapata lagbaye ki igbese naa le je itewogba kariaye.
Kì í ṣe pé ọwọ́ mi ti bà á ná, tabi pé mo ti di pípé.
Orúkọ àwọn ọmọ Merari ni Mahili ati Muṣi.
Awọn alaga naa ti kọkọ fi atẹjade kan sita pe awọn yoo lọ si ilu Dubai loṣu kẹfa yii.
(Èyí ṣẹlẹ̀ ní ayé ọba Kilaudiu.
Ó ṣe, ikú o ṣèyí tán!
Se ti eegun eni ba jore , ori a ya atọkun rẹ  , Gbẹgẹdẹ gbina,nigba ti ikọ omo–ogun orile ede Naijiria ti won n pe ni “Operation HARD STRIKE”  pade ikọ olote Boko Haram ni agbegbe Surdewalla, Ranwa, Baladayo, Sabon Gari ati Shetimeri ni ipinle  Borno , ekun ila oorun orile ede Naijiria, ti iko omo ogun orile ede Naijiria si fi oju won han eemọ.
Ileeṣẹ ọlọpaa sọ pe ni nkan bi aago meji oru ni ijamba naa waye ni agbegbe Kintampo South.
Orísìírísìí là ń gbọ́ nípa kí la lè ṣe láti dáàbò bo’ra ẹni.
Ọgbẹ́ni Adewale sọ pe, kii ṣe pe awọn ni ki ijọba mase gba owó, sugbọn o yẹ ki wọn o ṣe diẹ diẹ ni.
Ipese owoO ni ko si ijọba to le da nikan maa na owo lori eto ẹkọ, o wa ro awon ti oro kan lati fowosowopo pelu ijọba orile ede Naijiria lati le se adinku si iye awon omo ti ko lọ si ile iwe ni jake jado orile ede Naijiria.
Ko si ẹni n sọ pe mohunmaworan ESAT TV dọgbọn si fidio yii tabi pe wọn mọọmọ gbe e sori afẹfẹ pẹlupẹlu pe wn mọ pe ayederu ni.
Alhaja Kudirat Abiola, akọni obìnrin, tó gba ọkùnrin mẹ́fà kí wọ́n tó leè pa á Bí Gómìnà Makinde bá ṣẹ̀ mí, lẹ́tà lásán ló jẹ mí- Aláàfin Ọ̀yọ́ Buhari yóò báwọn ọmọ Nàìjíríà sọ̀rọ̀ lọ́la 'June 12' tí ṣe àyájọ́ ìjọba àwarawa Èèyàn 104 kó covid-19 ní iléeṣẹ́ kan ṣoṣo ní Sagamu- Ìjọba Ogun Wèrè tí mò ń ṣe ní Facebook ló pawó fún mi-Esabod Ki ni igbẹ tabi imí tumọ si?
Kódà, orílẹ̀-èdè Nàìjíríà ti darapọ̀ mọ́ àwọn kan lágbàyé, bi wọn ṣe yọ owó orí kúrò nínú àwọn èròjà ǹkan osu.
Ninu aabọ iwadi naa ni wọn ti gbero pe ki owo oṣu oṣiṣẹ to kere ju jẹ ọgbọn ẹgbẹrun Naira.
Àwọn to wa ninu ọkọ naa ko fara pa.
Oríṣun àwòrán, others Ki lo ti ṣẹlẹ sẹyin?
gary leon ridgway ( Ọjọ ́ ìbí - ọjọ kejìdínlógún , oṣù kejì , ọdún , 1949 ) , ẹnì tì á tún mọ sì green river killer , jẹ apànìyàn tí òun pá ọ ̀ pọ ̀ lọpọ ̀ ènìyàn pẹ ̀ lú bartani kàn .
Ọmọ ijọ rẹ kan, Cheryl Zondi, to ti pe ẹni ọdun mejilelogun bayii lo fi ẹsun kan an l'ọdun 2018 pe o fi ipa ba oun ni ibalopọ lati igba ti oun ti pe ọmọ ọdun mẹrinla.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Sekinat Quadri ọmọ ọdún méje ajẹ̀sẹ́ to fẹ dabi Anthony Joshua Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Sekinat Quadri ọmọ ọdún méje ajẹ̀sẹ́ to fẹ dabi Anthony Joshua 27 Ọ̀pẹ̀̀ 2018 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 27 Èbibi 2020 ''O wun mi ki n di Naijiria 'Champion' bi Anthony Joshua '' Erongba Sekinat Quadri abẹṣẹkubiojo ọmọbirin ọmọ ọdun mẹjẹ re e nilu Eko.
Bakan naa lo jẹ oloye to n mojuto agbegbe Ajah ati awọn agbegbe miran to sunmọ.
Tinubu fi eyi lede ninu atẹjade ti ikọ iroyin adari naa buwọlu.
Lẹyin naa ni wọn lọ si ilegbe awọn akẹkọọ nibi ti wọn gbe awọn akẹkọọ ti ẹnikan ko tii mọ iye rẹ lọ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Toyin Abraham: Ọ̀pọ̀ èèyàn ní èké ni Mercy Aigbe ń ṣe lórí bó ṣe ki Adeniyi Johnson 17 Ògún 2019 Oríṣun àwòrán, Instagram/realmercyaigbe Ọpọ eeyan lori ayelujara lo ti bẹnu ẹtẹ lu bi oṣere tiata Mercy Aigbe ṣe ki Adeniyi Johnson to jẹ ọkọ akọkọ Toyin Abraham to ṣẹṣẹ bimọ.
Awon miran ti won wa nibe ni Sen.
 O salaye pe, lati bi odun kan seyin, ajo NACA ti ni aseyori to po, lara eyi ti a ti ri kikopa ninu igbimo  lori eto oro-ajo orile-ede Naijiria nigba meji otooto, nibi ti won ti gba awon ijoba ipinle niyanju  lati yo iko marun-un ninu ida ogorun ninu eto isuna won fun igbogun ti aarun HIV/AIDSO temumo pe, erongba ipade igbimo ohun ni lati mu igberu ba eto ilera awon alarun HIV, ni eyi ajo ohun n ja fita-fita lati ri pe, aarun HIV/AIDS di ohun igbagbe lorile-ede Naijiria.
Kaakiri oju iwe iroyin ati loju ayelujara ni iroyin ati fọnran fidio orisirisi ti n ṣe afihan bi wọn ti ṣe n doju ija kọ awọn ọmọ Naijiria ati ọmọ ilẹ Afrika miran.
Ọdun Ekimogun jẹ ayẹyẹ asa ati igbelaruge ilu Ondo, ti tọmọde ati agba lati ilu okeere si ma n pejọ lati se ayẹyẹ yii.
Kò sì ní sí igi tí ń fa omi, tí yóo ga tó ọ; nítorí gbogbo wọn ni wọn óo kú, tí wọn óo sì lọ sí ìsàlẹ̀ ọ̀gbun ilẹ̀ bí àwọn alààyè eniyan tí wọ́n ti lọ sí ipò òkú.
Ní àárọ̀ ọjọ́ kejì, kòì tíì tó aago márǔn ni ẹkún ìyá wa kan jí mi.
 ifá ní kí ó rúbọ kí ó sì gbe ère ọmọ lángidi rù sórí jó , pẹ ̀ lú ẹ ́ gba irin lẹẹ ́ sẹ ̀ , ìgbà náà ni ó tó lè dọlọ ́ mọ láyé .
Mò ń kìlọ̀ fún ọ níwájú Ọlọrun ati Kristi Jesu, tí ó ń bọ̀ wá ṣe ìdájọ́ àwọn alààyè ati àwọn òkú; mò ń kì ọ́ nílọ̀ nítorí ìfarahàn rẹ̀ ati ìjọba rẹ̀.
A padà san owó ìtanràn fáwọn ajínigbé kí wọ́n to fi àwọn mẹ́tẹ̀ẹ̀ta sílẹ̀- Ẹbí Spaghetti, mílíìkì, Chivita àti Àǹkàrá sọ Rabiu dèrò ẹ̀wọn ni Eko Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Domestic Violence: Ìjà láàrin lọkọlaya sọ aya dèrò ọ̀run Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Lẹ́yìn ọdún mejidinlogoji gbáko tí a ti kúrò ní Kadeṣi Banea, ni a tó kọjá odò Seredi, títí tí gbogbo àwọn ọkunrin tí wọ́n tó ogun ún jà ninu ìran náà fi run tán patapata, gẹ́gẹ́ bí OLUWA ti búra pé yóo rí.
Àgbáríjọ àwọn nọ́ọ̀sì fẹ́ gbé Olamide Baddo lọ sílé ẹjọ́ fún ìbanilórúkọjẹ́ Ariwo ayọ̀ sọ nílé Remi Surutu, ọmọ rẹ̀ mú ọkọ wale 'Wọ́n fi ọmọ orogún mi tí wọ́n rí òkú rẹ̀ nínú odò lọ́jọ́ Ileya ṣọ́ mi ni' Àwọn òbí fárígá lórí sísan N25, 000 owó àyẹ̀wò COVID-19 fáwọn akẹ́kọ̀ọ́ kí wọ́n tó wọ iléèwé Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Oyo Schools: Akẹ́kọ̀ọ́ Fásitì, Poly wà nílé, kí ló mú ti alákọ̀ọ́bẹ̀rẹ̀, girama wà níta?
Ọrẹ mi ni bi o ba gba wọn laaye lati maa da oko ni ẹyinkule rẹ bi o ba ya wọn o le ẹ kuro ninu ile rẹ pẹlu.
 dí ọdún 2013 oríṣi àjẹsára náà méjì ni ó wà káàkiri àgbáyé , rotarix àti rotateq , pẹ ̀ lú àwọn oríṣi díẹ ̀ mìíràn tó tún wà ní àwọn orílẹ ̀ -èdè kọ ̀ ọ ̀ kan .
Oríṣun àwòrán, Hamisu Mallamawa Àkọlé àwòrán, Iwaju ile Musa Ede fulani lawọn agbebọn naa n sọ Adamu sọ pe awọn agbebọn naa ti wọn wọ aṣọ Fulani, ti wọn si tun n sọ ede wọn, sọ pe awọn fẹ gba miliọnu kan naira lọwọ ẹni kọọkan.
Ninu esi ayẹwo ti ajọ naa fi sita lori Twitter, ipinlẹ Eko ni eeyan mẹtalelọgbọn.
A n fẹ agbofinro ati Amotekun lagbegbe wa ni gbogbo igba - Elerinmo BBC Yoruba tun ba ọba alaye lagbegbe naa, Ẹlẹrinmọ tilu Ẹrinmọ, Oba Dokita Michael Adebowale Odunayo Ajayi, Arowotawaya Keji sọrọ nipa isẹlẹ ijinigbe to n waye lemọ-lemọ ni agbegbe naa.
lo maa n kede fun awon eniyan lori eto ilana ijọba orile ede naa ati eto
Ìjà bẹ́ sílẹ̀ làsikò àyẹ̀wò àwọn olùdìbò láti yan ẹni tí yóò díjé fún PDP nií Akurẹ Ikú ti yọ́wọ́ òṣèré Nollywood Yorùbá, Yusuf Satia l'áwo Gómìnà ìpínlẹ̀ Ekiti, Kayode Fayemi nàá ti ni aàrùn Coronavirus Lẹyin ti ẹlẹri ikarundinlogun ti olujẹjọ pe sọ tẹnu rẹ tan, adajọ to n gbọ ẹjọ ọhun, Olusola Odusola mu Sotitobire si ọjọ kẹrinla, oṣu Kẹsan an ọdun 2020 gẹgẹ binọjọ to kan ki ọjọ idajọ to de.
3 Àti pé àwọn ọlọ̀tẹ̀ yíò gbọgbẹ́ ìbànújẹ́ púpọ̀, nítorí àwọn àìṣedẽdé wọn yíó di sísọ ní àwọn orí-ilé, àti àwọn ìṣe ìkọ̀kọ̀ wọn ni yíò di fífihàn.
Orilẹede Namibia wa lara awọn orilẹede ti iwa ifipabanilopọ pọ ju si ni Africa Oríṣun àwòrán, Reuters Chile Ni oṣu kẹwaa, ọdun to kọja lawọn ara Chile ni tiwọn ti n wọde nitori owo ọkọ to gbowo leri.
Onimọ nipa ajakalẹ arun Tolbert Nyenswah to jẹ ọjọgbọn ni fasiti John Hopkins sọ pe'' o ni awọn orileede kan ti wọn gbe igbesẹ lati koju arun yi,mo si lero pe o yẹ ki a kẹkọ lọdọ wọn'' Alamuleti China ti se Taiwan fapẹrẹ ti iye eeyan to wa nilu wọn jẹ miliọnu mẹtalelogun le diẹ ko ni ju iye eeyan marundinlọgọrun to ko aisan naa ti eeyan meji si ku.
Akori ọrọ gangan ti atupalẹ iwe yii wa labẹ rẹ ni Litiresọ Apilẹkọ.
Abineri ọmọ Neri, arakunrin baba Saulu, sì ni balogun rẹ̀.
Ó fún un ní nǹkan ìpara ati oúnjẹ kíákíá.
Ṣugbọn Jesu dá wọn lóhùn pé, “Baba mi ń ṣiṣẹ́ títí di ìsinsìnyìí, èmi náà sì ń ṣiṣẹ́.
Oríṣun àwòrán, Presidency Àkọlé àwòrán, Awọn eekan lo ti jade lati ilu Daura sẹyin Akanṣe Ayẹyẹ Àkọlé àwòrán, Ilu Daura ti di orukọ ilumọọka kaakiri lẹyin ti Buhari di aarẹ lẹẹkeji Ayẹyẹ pataki nilẹ Hausa, Durbar, maa n waye lasiko ọdun ileya.
Ijoba apapo ti se ifilole omi Daamu niluu Maska nijoba ibilẹ Funtua Local Government, nipinle KatsinaMinisita to n mojuto ohun ipese omi, Suleiman Adamu, se agbekale ise akanse naa eleyi ti igbimo Ecological Funds Office (EFO) gbe se ohun fun awon eniyan agbegbe naa lojoBo(Thursday).
Ẹgbẹ awọn olukini -Awọn eeyan to ma n ki awọn alajo kaabọ sinu ijọ naa.
“Kì í ṣe gbogbo àwọn tí ń pè mí ní, ‘Oluwa, Oluwa’ ni yóo wọ ìjọba ọ̀run, bíkòṣe àwọn tí ó bá ń ṣe ìfẹ́ Baba mi tí ó ń bẹ ní ọ̀run.
Àwọn ọmọ Israẹli sin ín, wọ́n sì ṣọ̀fọ̀ rẹ̀ bí ọ̀rọ̀ tí OLUWA gba ẹnu wolii Ahija, iranṣẹ rẹ̀ sọ.
Ọkan gboogi ninu ọmọ ẹgbẹ oṣelu PDP ni Kashamu, to si ṣe sẹnetọ laarin ọdun 2015 si 2019.
Fayose ni asiko to fun Aarẹ Buhari lati bẹrẹ si nii hu iwa bii aarẹ gbogbo-gboo ilẹ Naijria dipo bii aarẹ ẹya kan soso.
Bí ọmọdé bá ti gbé nǹkan tí ó wúwo díẹ̀ lọ́wọ́, àwọn àgbà nílatí sáré gbà á lọ́wọ́ rẹ̀.
O ni: Aare  Buhari yoo sebewo sawon ipinle yii bi eyi ti won ti ji awon akekoobinrin aadofa ko lo lati oni, ojo karun un, osu keta, Aare yoo lo si Taraba ko to gba Benue lo si Yobe ko to lo si Zamfara ko to pari irinajo naa si Rivers.
29 Bélú 2019 Ara mee riri lọrọ Wooli A-gbọ-ti-Jesu-ma-gbọyinbo!
Ó ní kí n máa kéde ọdún ojurere OLUWA, ati ọjọ́ ẹ̀san Ọlọrun wa;kí n sì máa tu àwọn tí ń ṣọ̀fọ̀ ninu.
Bí Géḿbérí bá wọlé ẹ, á jẹun
Oyeyemi ni Baba ọmọ yii fi tipatipa fi idi ọmọ rẹ jo ina ẹlẹtiriki lẹyin ti o ni ọmọ naa mu ẹja ti wọn ti se, eleyii ti o jẹ ki idi ọmọ naa o bo falafala.
"Obinrin to ṣe iyebiye si mi julọ ti fi mi silẹ.
Ni olúkálukú wá sá bọ́ sábẹ́ àwọn ìsọ̀ olónjẹ.
Bí ọkunrin kan bá bá aya ẹ̀gbọ́n rẹ̀ lòpọ̀, tabi aya àbúrò rẹ̀, ohun àìmọ́ ni, ohun ìtìjú ni ó sì ṣe sí ẹ̀gbọ́n tabi àbúrò rẹ̀, àwọn mejeeji yóo kú láì bímọ.
Ibrahim Chatta: Tí olólùfẹ́ méjì bá ti ń na ara wọn, ọ̀kan má a pa èkejì!
Lara ohun to ṣeeṣe ko jẹ titun ti ẹ ko tii mọ nipa adele adari ẹka oṣiṣẹ tuntun ree.
Ẹgbẹrun mọkanlelogun agbara ina (Megawatts) laarin ọdun kan - Oludije naa ko ba lo anfaani lati ṣariyan-jiyan lori ohun to fa a ti orilẹede Naijiria ṣi fi n lo ẹgbẹrun mẹta agbara ina mọna-mọna, nigba to yẹ ko ti tayọ ọ rẹ.
Lẹ́yìn náà yóo jáde, wọn óo sì ti ìlẹ̀kùn ẹnu ọ̀nà náà.
Ìbú rẹ̀ yóo jẹ́ ọ̀kẹ́ kan ati ẹẹdẹgbaata (25,000) igbọnwọ (kilomita 12.
Ọ̀kan nínú ohun tí ó gbajúgbajà tí ó sọ àwọn ikọ̀ náà di ìlúmọ̀ọ́ká ni mímú Chukwudidumeme Onuamadike tí púpọ̀ èèyàn mọ̀ sí Evans ajínigbé.
Irú òfin tí ẹ bá fi ń ṣe ìdájọ́ fún eniyan ni a óo fi ṣe ìdájọ́ fún ẹ̀yin náà pẹlu èlé.
Yatọ si pe wọn n ra awo orin, wọn mọ iyi orin nitori pe wọn ti wo oniruuru olorin.
Jehoiada wí fún wọn pé, “Ẹ wò ó!
Awọn mi,titi laye ni wọn yoo fi ṣẹgbẹ naa.
Awọn ọmọ ileeṣẹ ologun naa gbe iru igbesẹ yii ninu oṣu Karun un, ṣugbọn ko pẹ ti wọn dawọ duro ni iroyin sọ pe awọn ajinigbe naa tun bẹrẹ iṣẹ ibi wọn.
Kì báà sì jẹ́ ọjọ́ meji ni, tabi oṣù kan, tabi ọdún kan tabi jù bẹ́ẹ̀ lọ, níwọ̀n ìgbà tí ìkùukùu náà bá sì wà ní orí Àgọ́ Àjọ, wọn yóo dúró ni.
Kí wọn má sọ ìsọkúsọ sí ẹnikẹ́ni.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Zoom Wedding: Àwọn ọkọ àti ìyàwò ló ní àwọn kò leè sún ọjọ́ ayọ̀ wọn síwájú.
Kikida awọn akẹkọọ to wa ni kilaasi kinni si ikẹta lawọn ile ẹkọ alakọọbẹrẹ ijọba nìkan, ni yoo jẹ anfaani ipese ounjẹ naa, eyi ti yoo kan ojule biliọnu mẹta o le diẹ, 3,131,971."
Iwin tún wo àwọn ìjòyè, ó dá sèríà fún gbogbo wọn, ó pa wọ̀n, ó pe gbogbo ìlú jọ, bí wọ́n fẹ́ bí wọ́n kọ̀, wọ́n dé, o tún múra ó fi ọkùnrin tí ó jẹ́ ọkọ àbúrò rẹ̀ jọba, o lọ sí ìsàlẹ̀ ilẹ̀ ó pe àbúrò rẹ̀, wéré eléyìí nì di ayaba.
Tàbí tí o bá wà ní ipò àtàtà, ayé a yẹ́ ọ sí tẹ̀rín-tẹ̀rín
Eeyan mọkandinlọgọrin lo ko covid-19 l'Oyo lọjọ Ẹti, mẹtadinlogoji l'Ogun ati Osun.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ekiti Decides: Abiọdun Aluko ní báwọn se kàwé tó l‘Ekiti, ìyà sì ń jẹ àwọn Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Ekiti Decides: Abiọdun Aluko ní báwọn se kàwé tó l‘Ekiti, ìyà sì ń jẹ àwọn 10 Agẹmo 2018 Olùdíje fún ipò gómìnà nínú ẹgbẹ́ òsèlú Accord, Ọ̀mọ̀wé Abiọdun Aluko, lásìkò tó ń bá BBC Yorùá sọ̀rọ̀ ní àwọn isẹ́ tó nira láti se, tí gómìnà Ayọdele Fayose ń gbé fún òun, èyí tó leè pa òun lára, ló mú kí òun kúrò nínú ẹgbẹ́ òsèlú PDP ni sáà àkọ́kọ́ Fayose.
"Nixon tun sọ pe ""O seé se ko jẹ pe orilẹede Naijiria ni ẹya ológbò alawọ̀ wúrà ilẹ̀ Afrika ọhun to pọ̀ jùlọ kù sí, ati pe, o jẹ ohun tawọn oniwadii ko mọ pupọ̀ nipa rẹ̀."
Idile kan ree ti tọkọ-taya, Will Smitt ati iyawo rẹ Jada Pinkett Smith jẹ gbajumọ osere tiata nilẹ Amẹrika, ti wọn si se igbeyawo lọdun 1997, Ọlọrun si fi ọmọ meji si aarin wọn.
“Ní gbogbo àkókò yìí, èyí ẹ̀gbọ́n wà ní oko.
Àwọn ọmọ Lefi fi ilẹ̀ wọn sílẹ̀ ati ẹran ọ̀sìn wọn ati gbogbo ohun ìní wọn, wọ́n kó wá sí Juda, ati Jerusalẹmu; nítorí pé Jeroboamu ati àwọn ọmọ rẹ̀ lé wọn jáde, wọn kò jẹ́ kí wọ́n ṣe iṣẹ́ wọn gẹ́gẹ́ bí alufaa Ọlọrun.
Awon olopaa ni won ti le ogbeni Cruz kuro nile iwe naa tele pe o huwa ibaje ti won si faa le olopaa lowo ni Coral Springs ni wakati kan leyin to kuro nile iwe ohun.
Ẹ óo ṣe àkọsílẹ̀ ìpín mejeeje, ẹ óo sì mú un tọ̀ mí wá.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Torí ₦300, awakọ̀ ojú omi ṣokùnfà ikú èèyàn méjìlá l‘Eko - Ọlọ́pàá Ààrẹ orílẹ̀èdè Mali, Boubacar Keita kọ̀wé fipò sílẹ̀ Inú mí dùn láti kọrin pẹlú Beyonce nílẹ̀ Amerika- Ìyá àgbà láti Nàíjíríà Àwọn òṣèré tíátà Yorùbá kọjú ìjà síra wọn lórí ìdárò akẹẹgbẹ́ wọn tó kú Ìpàkọ́ kò gbọ́ sùtì ní ọ̀rọ̀ ẹ̀yin tí ẹ̀ ń bú mi- Oyedepo Mo kọ̀ láti pín ọkọ mi pẹ̀lú ẹnikẹ́ni, nítorí náà ẹ tú wa ká- Abílékọ Idowu faraya ní kóòtù kọkọ-kọkọ Kíákíá lọ daṣọ bo igbá àyà rẹ to ṣí kalẹ̀!
Solomoni mú iyawo rẹ̀, ọmọ Farao kúrò ní ìlú Dafidi, lọ sí ibi tí ó kọ́ fún un.
 inú bí agígírì ó sì gbé e bú .
Alákọ̀wé kan tọ aṣojú-Olódùmarè wá, ọkùnrin tí a ń wí yìí jẹ́ olùkọ́ ilé-ìwé, nígbà tí ó dá ọ̀dọ̀ Aṣojú-Olódùmarè tí ó bẹ̀rẹ̀ sí ọ̀rọ̀ í sọ, ó ní, ìwọ ìránṣẹ́ Ẹlẹ́dàá ayé, ìwọ iranṣẹ́ Ẹlẹ́dàá ọ̀run, bá mi wí fún Ọlọ́run Ọba wí pé iṣẹ́ tí mo ń ṣe yìí kò tẹ́ mi lọ́rùn rárá.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Akomolede ati Aṣa lori BBC: Mọ̀ si nípa oríṣìí ẹ̀ka ìsọ̀rí ọ̀rọ̀ àti ìwúlò wọn Afihan pe Olori Abibat Nihinlola Adeyemi koni mọra lo farahan pẹlu bo se se koriya fun ọkọ rẹ lati ni ayaba pupọ, ti ko si si ija laarin wọn.
Mi o kabamọ pe mọ lọ si ọdọ wọn'' Goolu ọgọrin(80) ni Sanchez jẹ ninu ifẹsẹwọnsẹ mẹ́rìndínláàdọ́sàn án (166) ni Arsenal lẹyin to buwọlu iwe adehun miliọnu ọgbọn poun lati Barcelona lọdun 2014.
"'Ọ̀rọ̀ Amotekun ti dàrú bíi ẹsẹ̀ télọ̀ ní ìpínlẹ̀ Oyo' Miyetti Allah ní kí wọn wọ́gilé Amotekun, Sunday Igboho yarí Orúkọ àwọn tó yege láti darapọ̀ mọ́ ikọ̀ Amotekun ní ìpínlẹ̀ Oyo ti jáde Ọwọ́ wa ti tẹ àwọn afurasí tó lọ́wọ́ nínú ikú Olufon ti Ifon, Oba Israel Adeusi - Amotekun Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Kayeefi: 'Ọkọ mi ṣẹ̀ṣẹ̀ ní kí n lọ se mọ́í-mọ́í, tó ṣẹ̀ bá mi ṣeré tán ni mo gbọ́ pé ""Mopol"" yìnbọn pa á' Ikede ti ẹṣọ Amọtẹkun ipinlẹ Ọsun fi sita yii wa ni ibamu pẹlu bi awọn ọlọpaa Shariah, Hisbah lapa Ariwa Naijiria ṣe n ṣiṣẹ."
Ẹni to bori: Egypt Ìpele to kangun si aṣakagba Morocco vs Mauritania.
OLUWA, ìwọ ni mo gbé ojú ẹ̀bẹ̀ sókè sí.
Mama Rainbow ti kopa ninu ere to le ni ẹẹdẹgbẹta, ọpọlọpọ lara awọn ere naa jẹ ni ẹde Yoruba, ṣugbọn o tun ma n kopa ninu ere ti wọn ti n sọ ede Gẹẹsi.
Ṣùgbọ́n Irina kò ní le è wúlò gẹ́gẹ́ bí alámọ̀dájú, ó nírú ẹni tí àwọn olùgbọ́ọ wa máa ń nífẹ̀ẹ́ sí.
O wa pase fun minisita fun eto abele ati akowe agba fun
Oríṣun àwòrán, @KSG Ọdun 2019 ni ijọba ipinlẹ Kano,tun fi ofin de eto adura, eyi to ba awọn ọdọ ati awọn ọmọbinrin lọkan jẹ pupọ.
Ni ọdun 1976 ni wọn bi Kelvin Ikeduba lagbegbe Ebute Metta ni ilu Eko.
wọ́n wá sọ fún Jesu pé, “Olùkọ́ni, a ká obinrin yìí mọ́ ibi tí ó ti ń ṣe àgbèrè, a ká a mọ́ ọn gan-an ni!
Òṣìṣẹ́ àjọ FRSC méjì bọ́ sọ́wọ́ àwọn ajínigbé l'Ọsun Ọwọ ọlọpa tẹ adigunjale ajọkọgbe nipinlẹ Ọsun Àwọn adigunjalè pa èèyàn mẹ́fà ní báńkì kan nìpínlẹ̀ Ondo Ilé ẹjọ́ pàṣẹ ki wọ́n sọ́ afurasí 5 sì àhámọ́ lórí ìdigunjalè Ido-Ani Odoro sọ pe, Kọmiṣọna ọlọpaa ipinlẹ naa Abiodun Ige ti mu da awọn ara ilu loju wi pe, aabo wa fun ẹmi ati dukia wọn.
11 Àti pé ní àfikún sí ẹ̀rí rẹ, ẹ̀rí láti ẹnu mẹ́ta nínú àwọn ìránṣẹ́ mi, àwọn tí èmi yíò pè tí n ó sì yàn, sí àwọn ẹnití èmi yíò fi àwọn ohun wọ̀nyí hàn, wọn yíò sì jade lọ pẹ̀lú ọ̀rọ̀ mi èyí tí a ó fi fúnni nípasẹ̀ rẹ.
"Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Kid boxer: Ọmọọba 'The Buzz' Larbie rèé, ọmọ ọdún méje tó ń fi ẹ̀ṣẹ́ dá bírà Dokita Aliyu ni ""o lee ko Coronavirus bi o ba jade lai tẹle awọn ofin ti a ṣe""."
Tí wọ́n bá parí ilé náà, wọn yóo gbé e kalẹ̀ sibẹ.
Mo lero wi pe awọn onimọ sayẹnsi to n bẹ laarin wa le ṣiṣẹ pọ pẹlu awọn oniṣegun ibilẹ lati wa ọna abayọ.
Ó ní Saulu yóo dẹ́kun láti máa wá òun kiri ní ilẹ̀ Israẹli, òun óo sì fi bẹ́ẹ̀ bọ́ lọ́wọ́ rẹ̀.
CP Olukolu Sina - CP Oyo Command liv.
Akeredolu ni oun yoo tun dabira siwaju si nidi atunse ọna, agbega ile ẹkọ ati ipese awọn ohun eelo amayederun lorisirisi.
Olusegun Obasanjo sọ̀rọ̀ síta pé ọpẹ́lọpẹ́ Walter Carrington láyé òun nígbà tí Sani Abacha ń lé òun kíri
“Àwọn ni mò ń gbadura fún, n kò gbadura fún aráyé; ṣugbọn mò ń gbadura fún àwọn tí o ti fún mi, nítorí tìrẹ ni wọ́n.
Ṣugbọn Emir sọ pe ọrọ ko ri bẹ ẹ.
Ibidun Ighodalo: Ǹkan ti amọ̀ nípa ilúmọ̀ọ́ká arẹwà obìnrin nígbà kan rí tó d'olóògbé
Nigba ti wọn ba BBC Yoruba sọrọ, awọn araalu naa ni o wu awọn kijọba jẹ ki awọn maa rin opopona ọhun lọfẹ ni ojoojumọ.
O ti wa se iwọn to lee se, o si ti dagbere fun aye pe o digbo se, a wa n gbadura pe Ọba oke yoo dẹ ilẹ fun akikanju ọmọ Ibadan to rele.
Erica lo n binu lori bi ọpọ eeyan se gba pe oun fi ẹnu ko Leycon lẹnu, to si lọ ba ọmọkunrin naa pe ko mu ẹri to ba ni wa lati fi idi rẹ mulẹ pe awọn fi ẹnu konu.
NAF Aircraft neutralize several Terrorists at their hid out near Baga https://t.
Mo ti fihàn yín pé bẹ́ẹ̀ ni a níláti ṣiṣẹ́ láti ran àwọn aláìlera lọ́wọ́.
Nigba ti o n ba BBC Yoruba sọrọ lori ọrọ naa, alukoro ileesẹ ọlọpa nipinlẹ Ekiti DSP Adeyẹmi Albert Ademọla ni ileesẹ ọlọpa ko tii lee fi idi rẹ mulẹ boya daranadaran fulani lo se isẹ ibi naa.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Cancer: Àṣe ara mi ni iso ti n run gbogbo bí mo ṣe n ṣèrànwọ́ lórí jẹjẹrẹ Ilana wa naa yoo tun ṣe alakalẹ ọna lati maa ko idọti lọna to yẹ ati kikọ awọn eeyan lẹkọ nipa dida idọti sayika.
Awọn mejeeji jijọ n ṣe irinajo inaju ni.
won baa lee lo iro owo bẹẹ fun igbaye- gbadun awon osise.
Kí o ṣe é bí o ti ṣe Sihoni ọba àwọn ará Amori tí ń gbé Heṣiboni.
Ìran kan ń kọjá lọ, òmíràn ń dé, ṣugbọn ayé wà títí laelae.
Wòlíì Kasali ní Dolapo Awosika kò lé ìyàwó òun jáde Bakan naa, O ni oun ko ni igbagbọ ninu Ajọ INEC lati se eto idibo ti yoo muna doko ni idibo gbogboogbo ti yoo waye ni 2019.
Ìgbà mẹ́rin tí ẹ̀sùn àgbèrè ta bá adarí ìjọ olókìkí ní Naijiria COZA: Mi ò fípá bá obìrin lò pọ̀ rí láyé mi - Pásítọ̀ Fatoyinbo Ọmọọ̀dọ̀ tó pa Ope Bademosi ti rí ẹ̀wọ̀n gbére he!
Fún àwọn ẹ̀yà aláwọ̀ dúdú tó ni ẹbi ni ilẹ̀ òkèèrè, èyí le jẹ́ ìpalára fún wọ́n nítorí, bi iná bá ń jóni, tó ń jó ọmọ ẹni.
"Oogun naa, bi o tilẹ jẹ pe mi o kii ṣe dokita iṣegun oyinbo, oogun yii kan naa yoo wulo fun iṣẹ kan naa, arun kan naa ati fun eeyan kan naa.
wọ́n to jasiniti, agate ati ametisti sí ẹsẹ̀ kẹta; 
”Natani dá a lóhùn pé, “OLUWA ti dáríjì ọ́, o kò sì ní kú.
 Ẹ wo àwòrán bí ìsìnkú Abiola Ajimobi ṣe lọ!"
Kí alaafia máa wà ní Israẹli.
Máa rán àwọn eniyan létí nípa nǹkan wọnyi.
Bẹẹ ba gbagbe, Omoyele Soworẹ ni awọn osisẹ ọtẹlẹmuyẹ gbe si ahamọ lasiko to n leri pe ẹgbẹ Revolution Now yoo se iwọde.
Lẹ́yìn náà, ó mú mi lọ sí ìhà ìlà oòrùn gbọ̀ngàn inú, ó sì wọn ẹnu ọ̀nà rẹ̀, bákan náà ni ó rí pẹlu àwọn yòókù.
igbesẹ lati pese ounjẹ lọpọ janturu ni awọn ipinle ti ijamba ogun awon
Lẹ́yìn ọ̀ rẹyìn, Seyi Makinde ránṣẹ́ ìbánikẹ́dùn sí ẹbí Ajimobi Oríṣun àwòrán, Vanguard newspaper Ikini naa waye lẹyin ti iyawo oloogbe naa, Florence Ajimobi, fi ẹsun kan ijọba ipinlẹ Oyo ti Makinde n dari rẹ pe, wọn ko ki oun ku ara fẹraku ọkọ oun.
Bo tilẹ jẹ pe o ja kulẹ, ko fi ibinu sa kuro ninu ẹgbẹ.
Odidi ọdún mẹ́ta gbáko nni wọn ffi dá a dúró, tí wọ́n ń rán an níṣẹ́ sí òde ọ̀run.
 o jẹ ede orilẹ-ede pakistan .
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Oba Lamidi Adeyemi: Aláàfin àkọ́kọ́ tí yóò lo àádọ́ta ọdún lórí ìtẹ́ 14 Sẹ́rẹ́ 2021 Oríṣun àwòrán, @AlaafinofOyo Yoruba ni ori ti yoo dade, ko ni ṣe alai dade, ọrun ti yoo si lo ejigbara ilẹkẹ, ko ni ṣalai lo ó, ibadi ti yoo lo mọsaji, aṣọ ọba to jinna koro koro, ko kuku ni ṣe alai lo.
Àmọ́ nígbà tí aawọ de láàrin Awolowo àti Akintola, Ọba Olagbegi pọn sẹ́yìn Akintola, tí Ajasin sì pọn lẹ́yìn Awolowo, èyí tó mú kí ọrẹ méjì kọ ẹyin síra wọn, tí wọn si di ọ̀tá gidigidi.
Àwọn òpó àyíká àgbàlá ati ìtẹ́lẹ̀ wọn, àwọn èèkàn àgọ́, okùn wọn, ati gbogbo ohun tí wọn ń lò pẹlu wọn.
Oyebamiji wa rọ awọn to ṣẹṣẹ de lati Amẹrika, ilẹ Gẹẹsi atawọn orilẹede mii ti arun ọhunn ti ṣọṣẹ julọ si ipinlẹ Osun lati pe nọmba 293 fun alaye kikun lori bi wọn ṣe le dabo bo ara wọn ati awọn to sun mọ wọn.
₦750m ni Akeredolu ń gbà lóṣù fún ‘Security Vote’ àti ₦150m owó oṣù - Agboola Ajayi fèsì INEC kéde agbègbè ẹsẹ̀ odò 270 ti èrú ìbò ti le wáyé ní ìpínlẹ̀ Ondo Ọ̀pọ̀ aráàlú Owo wà nílé ìwòsàn, síbẹ̀ APC àti PDP kò gba ẹ̀bi Ọgọ́rin arìnrìnàjò tó padà wá sí Nàìjíríà ló ní Coronavirus - PTF Arakunrin Palmer naa ni oun ko mọ bi ori ṣe ko oun yọ ti oun ko ba ijamba ina naa lọ.
Nítorí ẹ̀yin fúnra yín ti mọ̀ dájú pé bí ìgbà tí olè bá dé lóru ni ọjọ́ tí Oluwa yóo dé yóo rí.
Ọjọ Abamẹta, ọjọ kọkandinlọgbọn, oṣu kẹsan an ni ẹgbẹ APC dìbò yan Mohammadu Buhari gẹgẹ bi oludije kan ṣoṣo fun ipo aarẹ lọdun 2019.
Ṣugbọn tí egbò yìí bá jiná, tí ojú rẹ̀ pada di funfun, kí ẹni náà pada tọ alufaa lọ.
Awọn ọmọlẹhin Kristi yii padanu ẹmi wọn lat'ọwọ awọn darandaran ni Ipinlẹ Benue l'ọjọ iṣẹgun.
Iwadi ti wa fidi rẹ mulẹ pe, aisun maa n ni ipa to buru julọ lori ọpọlọ ati ẹya ara wa.
Lasiko to n ba iwe iroyin abẹle The Punch sọrọ, Lawal sọ pe lootọ ni aṣiwaju ẹgbẹ oṣelu naa, Bola Tinubu, ko ipa pataki ninu bi aarẹ Muhammadu Buhari ṣe wọle ibo si ipo aarẹ l'ọdun 2015.
Wo ìdí tí ààrẹ Buhari kìí fi ṣe ẹ̀dà Jubril láti Sudan Àwọn ohun kàyéèfì tó le mú kí ọmọbìnrin ní oyún ìju Ilé ẹjọ́ da ìpèjọ́ pé Akeredolu kọ ló yẹ kó wọlé ìdìbò ìpińlẹ̀ Ondo nù Mínísítà dèrò àgọ́ ọlọ́pàá nítorí ẹ̀sùn kíkó owó ìrànwọ́ Covid-19 sápò Oríṣun àwòrán, Dabiri Sáájú àsìkò yìí, ní fọ́nran kan jẹyọ níbi ti àwọn àkẹ́kọ̀ọ́ ti wọ́n jí gbé náà ti n bẹ ìjọba pé, ko dá isẹ idoola ẹmi to n se duro, ko si ko gbogbo àwọn sójà pàda si bareke.
Bakan naa o ni awọn yoo pin iṣi kaarun nkan iranwọ Covid-19 lopin ọsẹ yii.
Fayose yóò lọ ilé ẹjọ́ Supreme 'torí owó rẹ̀ EFCC tun gbe Akala yọju sile ẹjọ Ogunbanjo jáwé olúborí nínú ìdìbò abẹ́lé ANN Ọjọbọ ni atejade naa jade nibi ti agbẹjọro Fayose, Obafemi Adewale ti bẹnu atẹ lu igbese ajọ EFCC ninu iwe kan ti wọn fi sita lọjọ kejila, Osu kẹsan pe ki ''awọn ile isẹ alaabo ma sọ Fayose tọwọ tẹsẹ ni awọn ibode Naijiria ki o ba ma sa mọ wọn lọwọ.
Naijiria to wa ni ilẹ ajoji.
Oríṣun àwòrán, @PoliceNG Amọṣa ninu ọrọ tirẹ, ọga ọlọpaa ni ipinlẹ Ọṣun, Abiọdun Ige pẹlu Akẹgbẹrẹ nipinlẹ Ọyọ, Sina Olukolu ni, awọn ko ni ajọṣepọ kankan pẹlu awọn ẹgbẹ alaabo kankan, eyi to kọja irufẹ ajọṣepọ to wa laarin ọlọpaa atawọn araalu lọ.
Baba ati ìyá rẹ̀ dá a lóhùn pé, “Ṣé kò sí obinrin mọ́ ninu gbogbo àwọn ìbátan rẹ tabi láàrin gbogbo àwọn eniyan wa ni o fi níláti lọ fẹ́ aya láàrin àwọn ará Filistia aláìkọlà ni?
Ninu fidio yii, oo ṣalaye fun BBC oun toju oun ri ni ahamọ.
“OLUWA, jẹ́ kí n mọ òpin ayé mi,ati ìwọ̀nba ọjọ́ ayé mi,kí n lè mọ̀ pé ayé mi ń sáré kọjá lọ.
Ọgbẹni Akinola Ojo ni kọmiṣọna tuntun fun eto inanwo nipinlẹ Oyo.
Lara awọn obinrin takuntakun to gbe ounjẹ fẹgbẹ, to si tun gba awo bọ nilẹ Yoruba ni obinrin bi ọkunrin kan nilẹ Ibadan, Ẹfunsetan Aniwura, tii se Iyalode ilẹ Ibadan.
NLC, TUC, ULC yóò ṣe ìwọ́de l'ónìí Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Orangun: Èdè àti àṣà Yorùba ní láti jọ wá lójú Ọdún 2018 ni wọ́n bẹ̀rẹ̀ àtúnṣe ilé náà èyí tí wọ́n ti párí báyìí gẹ́gẹ́ bí àwọn oníròyìn ṣe jábọ̀.
Ọgbẹni Dojumo ni ọrọ ti Shehu sọ fihan pe kọ mọ nipa ofin to da ikọ Amotekun silẹ.
Ninu ìdílé Bani: Maadai, Amramu, ati Ueli;
Jesu dá wọn lóhùn pé, “Ẹ kò ì tíì ka ohun tí Dafidi ṣe, nígbà tí kò ní oúnjẹ, tí ebi ń pa òun ati àwọn tí ó wà pẹlu rẹ̀?
Nitori pe adajọ ti ni ki wọn fi Dansuki Sambo ati El Zakzakky silẹ tẹlẹ.
Ọkunrin kan tí ó ń jẹ́ Jairu, tí ó jẹ́ alákòóso ilé ìpàdé, wá sọ́dọ̀ rẹ̀.
“Láìsí àní àní,ẹ̀yin ni agbẹnusọ gbogbo eniyan,bí ẹ bá jáde láyé,ọgbọ́n kan kò tún ní sí láyé mọ́.
“Ẹ fi owó fadaka kan hàn mí.
Kò fi tọkàntọkàn ṣe olóòótọ́ sí OLUWA Ọlọrun rẹ̀ bí Dafidi, baba ńlá rẹ̀ ti ṣe.
OLUWA àwọn ọmọ ogun, Ọlọrun Israẹli ní, “Ẹ rí gbogbo ibi tí mo jẹ́ kí ó bá Jerusalẹmu ati gbogbo ìlú Juda.
Mi ò ní ìyàwó nílé, àmọ́ mo ní ọmọ tó pọ̀-Saheed Oṣupa Ọmọ ọgbọ́n ọdún pa bàbá rẹ̀ ní ìpínlẹ̀ Ogun Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Sagbokoji, ìlú tó sún mọ́ ọ̀làjú pẹ́kípẹ́kí ṣùgbọ́n tí iná ẹ̀lẹ́ńtíríkì kò sí Ẹ gbọ naa, imọran wo ni Ọjọgbọn Yẹmi Oṣinbajo fun Gomina Okorocha ti ko gba naa?
Agiripa wá yíjú sí Paulu, ó ní, “Ọ̀rọ̀ kàn ọ́.
US Open 2019: Bianca júwe ilé fún Serena Williams nínú ìdíje l'America
Ṣugbọn kii ṣe awọn ajijagbara yii nikan lo n ṣe ikọlu, awọn araalu naa n kọlu awọn oṣiṣẹ eto ilera.
Wọ́n bá fún àwọn ọkunrin Bẹnjamini láṣẹ pé, “Ẹ lọ ba ní ibùba ninu ọgbà àjàrà, 
Igbesẹ kẹwa: Ẹ ma gbagbe lati ti oju opo naa bi ẹ ba ti ṣetan.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, afin pupa Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí UN Human Rights Council urges Sri Lanka war crimes court16 Owewe 2015 The broken survivors of Sri Lanka's civil war11 Ọ̀wàrà 2012 Sri Lanka country profile18 Bélú 2019 Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Serena Williams yọwọ́ ní Italian Open Serena fẹ ṣe idije tennis ni Afirika 'Mo kọ̀ láti kópa nínú Ife Ẹ̀yẹ Rogers Cup' Orí ló mọ iṣẹ́ àṣelà Ikú mú Olanrewaju tó jẹ́ bàbá ọmọ Bisola lọ Si iyalẹnu gbogbo ero iworan to wa lori papa ni Bianca fidi Serena janle ti o si jẹ ki Serena padanu ife ẹyẹ yii lẹẹkẹrin bayii.
Àwọn ohun ọ̀ṣọ́ tí mo ní nígbà tíi mo ṣẹ̀ṣẹ̀ bẹ̀rẹ̀ iṣẹ́ ti bàjẹ́ tán, wọ́n ń bàjẹ́ ní ojú ọ̀nà nibi tí mo gbé ń di ẹrù kiri; ìkòkò ìyàwó mi méjìlá ti fọ́, àádọ́jọ ṣíbí ti sọnù, àwọn ọmọdé kò rí ẹni sùn mọ́, ohun ọ̀ṣọ̀ ilé ń din lójoojúmọ́, a kò lè ka àwọn nǹkan kéékèèkéé tí a kò mọ ọ̀nà tí wọ́n gbà lọ, nígbà tí a bá sì ń fẹ́ẹ́ gbádùn àwọn ọ̀rẹ́ wa ní ibi kan ni wọ́n máa ń yà wá ni ipa kúrò lọ́dọ̀ wọn.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù PTF Covid-19: Ọ̀pọ̀ arìnrìnàjò mú ẹ̀rí àyẹ̀wò moyege lọ́wọ́ láti òkè òkun àmọ́ wọ́n ní Coronavirus 21 Ògún 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 30 Owewe 2020 Awọn arinrinajo ọgọrin to n de sorileede Naijira lati ilẹ́ okeere, ni ayẹwo fi han pe wọn ti lugbadi arun Coronavirus.
Minimum Wage: Saraki dúpẹ́ lọ́wọ́ àwọn òṣìṣẹ́ fún sùúrù wọn lórí owó oṣù tuntun
naa ba se n lo si.
Bẹ́ẹ̀ ni gbogbo iṣẹ́ àgọ́ àjọ náà ṣe parí, àwọn ọmọ Israẹli ṣe ohun gbogbo gẹ́gẹ́ bí OLUWA ti pàṣẹ fún Mose.
BBC Yoruba gbiyanju lati ba alukoro ọlọpaa ipinlẹ Ondo arakunrin Tee-Leo Ikoro sọrọ lori iṣẹlẹ yi ṣugbọn ko gbe ago rẹ.
 fún àpeere , àwon kan lè so pé ( 2a ) kò jé ìtéwógbà fún àwon wi pé ( 2b ) ni àwon gbà wolé .
sibẹ o óo tì mí sinu kòtò ìdọ̀tí.
Olubadan  ti ile Ibadan, Oba Saliu
Lẹyin naa lo ṣalaye pe ko din ni ọmọ ogun mẹfa ati ọlọpaa mẹtadinlogoji ti ẹmi wọn ba atunbọtan ifẹhonuhan EndSARS ọhun lọ, yatọ si awọn ọkọ ati agọ ọlọpaa to jona.
Afẹsẹkubiojo Deontay Wilder ti fi ayo kun inu awọn ololufẹ rẹ, lẹyin to di igbaju igbamu bo Dominic Breazeale lati di Ife Ẹyẹ WBC World Heavyweight mu digba digba ni ilu New York lorilẹede Amerika.
“Ninu ìran, lóru, mo rí ẹnìkan tí ó rí bí Ọmọ Eniyan ninu awọsanma, ó lọ sí ọ̀dọ̀ Ẹni Ayérayé náà, ó sì fi ara rẹ̀ hàn níwájú rẹ̀.
Bakambu l'agbabọọlu to wọn ju l'Afirika Amẹrika kilọ fun Afirika lori owoya China Latin nkan bi ogun ọdun sẹyin ni China ti sofin to ni ki aarẹ ma lo ju saa meji lọ lori oye.
Wọ́n ṣe bẹ́ẹ̀, wọ́n kó nǹkan rán Banaba ati Saulu sí wọn.
Ọlopaa Kenya kolu awọn oluwọde Ọwọ tẹ afurasi mẹta ni Zamfara Ìwádìí bẹ̀rẹ̀ l'órí ikú agbẹjọ́rò Ajah Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Àjọ Ọlọ́pàa Naijiria: A ó fi òsìsẹ́ SARS tó se isẹ́ ibi náà jófin Ẹsun mọkandinlọgbọn ni wọn fi kan ọkunrin ọmọ ọdun mẹrindinlaadọta yii bii didena ijọsin ati igbagbọ ẹlomii àti ipaniyan.
Iṣẹlẹ ọhun waye ni ni nnkan bi aago mọkanla owurọ lọjọ Ẹti loju ọna marosẹ Gbogan si Ife, ni ijọba ibilẹ Ayedaade, ni ipinlẹ ọhun.
Àwọn ọkunrin mẹẹdọgbọn kan wà lẹ́nu ọ̀nà náà, mo rí i pé àwọn meji láàrin wọn jẹ́ ìjòyè: Jaasanaya, ọmọ Aṣuri, ati Pelataya, ọmọ Bẹnaya.
Sugbon ko waasu rara ninu isin toni.
Bí ẹ bá bẹ̀rù OLUWA, tí ẹ̀ ń sìn ín, tí ẹ̀ ń gbọ́ tirẹ̀, tí ẹ sì ń pa àwọn òfin rẹ̀ mọ́, tí ẹ̀yin ati ọba tí ń ṣe àkóso yín bá ń tẹ̀lé àwọn ìlànà OLUWA Ọlọrun yín, ohun gbogbo ni yóo máa lọ déédé fun yín.
Ó bi wọ́n léèrè, ó ní, “Kí ni ìmọ̀ràn tí ẹ lè gbà mí, lórí irú ìdáhùn tí a le fún àwọn eniyan tí wọ́n ní kí n dín ẹrù wúwo tí baba mi dì lé àwọn lórí kù?
Amọ, Agbẹjọrọ to tun jẹ ajafẹtọ fun awọn ọmọde naa, Arabinrin Elizabeth Udeh fikun un pe idi ti awọn obi fi le jẹbi ni ti wọn ba kọ lati bojuto ọmọ wọn, Abi ti wọn ba fi ẹjọ ọmọ wọn sun pe wọn hu iwa buruku, amọ ti iya gbe lẹyin ọmọ rẹ lai ṣe iwadii to tọ lori ẹsun naa.
Ẹwẹ, ijọba n gbero lati ṣe afihan ipo ti apo aṣuwọn ijọba ipinlẹ Ekiti wa l'ọjọ to ba ṣe ajọyọ ọgọrun ọjọ lori oye.
Alufaa yóo fi àyà ẹran náà gẹ́gẹ́ bí ẹbọ fífì níwájú OLUWA.
Ẹnu ya gbogbo àwọn eniyan, wọ́n ń sọ pé, “A kò rí irú èyí rí ní Israẹli.
Ẹ wá gbọ́, ẹ̀yin òmùgọ̀, aláìlọ́gbọ́n, ẹ̀yin tí ẹ lójú, ṣugbọn tí ẹ kò ríran;ẹ létí, ṣugbọn tí ẹ kò gbọ́ràn.
Ní ọjọ́ kẹtalelogun oṣù keje, Solomoni ní kí àwọn eniyan máa pada lọ sílé wọn.
Ẹnìkan tí ó dàbí eniyan wá, ó fi ọwọ́ kàn mí ní ètè; ẹnu mi bá yà, mo sì sọ̀rọ̀.
ipinle Ogun labe asia egbe APC, Dapo Abiodun.
Oko ofurufu Azman to n lọ lati Eko si Abuja ni o deede yọ eefin lana.
Olori oṣiṣẹ ọba lọfiisi gomina, Oloye Oyebisi Ilaka sọ fawọn akọroyin lọjọ Ẹti pe, idibo ijọba ibilẹ to waye lasiko ijọba Gomina ana, Abiola Ajimọbi ko wa ni ibanu pẹlu ofin, ati pe eto idibo to gbe awọn alaga ibilẹ naa wọle lodi si aṣẹ ileẹjọ.
Àṣìlò òògùn: Ará ìlú sọ oun tó ń sún wọn dé'dí ìwà yí
Gbogbo eyi naa ni BBC News Yoruba gbe yẹwo ninu iroyin ijiroro itagbangba yii to pe akori rẹ ni 'Ìwà ipá nínú ìdílé máa ń bí ìgè àti àdùbí ni tó lè já sí ikú' Ẹ wo ẹkunrẹrẹ rẹ nibi: https://www.
èmi OLUWA Ọlọrun sọ pé, ‘Ègbé ni fún àwọn obinrin tí wọn ń so ẹ̀gbà òògùn mọ́ gbogbo eniyan lọ́wọ́, tí wọ́n sì ń ṣe ìbòjú fún gbogbo eniyan, kí ọwọ́ wọn lè ká eniyan.
Ṣaaju ni ajọ to n gbogun ti iwa jẹgudujẹra, EFCC ti fẹsun kan pe o ko owo ilu sapo nigba iṣejọba rẹ gẹgẹ bi gomina laarin ọdun 199 si 2007.
Ìjọba àpapọ̀ ti ń wádìí #EndSARS Òsìsẹ́ SARS mẹ́rin d'èrò ẹ̀wọ̀n lóri N7m Ẹgbẹ́ ajàfẹ́tọ̀ọ́ ẹni yóò bẹ túbú ọlọ́pàá wò Eyi nikan kọ, Kọmiṣọna ọlọpàá kan ni yoo maa dari ajọ naa bayii, yoo si maa jẹ abọ fun ẹka ileeṣẹ olopaa ni Abuja to n ri si iwa ọdaran.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Fẹla: Àwọn olólùfẹ́ Abàmì Ẹdá s'ayẹyẹ ọjọ́ ìbí ọgọ́rin ọdún rẹ̀ 3 Agẹmo 2018 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 15 Ọ̀wàrà 2018 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Àwọn olólùfẹ́ Fẹla Anikulapo-Kuti s'ayẹyẹ ọjọ́ ìbí ọgọ́rin ọdún rẹ̀ Iku n pani, ilẹ n jẹniyan, oni Ọjọ Kẹẹdogun, Oṣu Kẹwa ọdun 2018 ni ajafẹtọ ọmọniyan ati olorin Afro ni, Fẹla Anikulapo Kuti ko ba pe ẹni ọgọrin ọdun loke eepẹ.
Sán idà rẹ mọ́ ìdí, ìwọ alágbára,ninu ògo ati ọlá ńlá rẹ.
"Bill Gates ni, ""Orilẹede Naijiria jẹ ara awọn orilẹede to lewu julọ lati bimọ lagbaye, nitori ilẹ wa lo nse ipo kẹrin lọwọlọwọ lagbaye, taa ba nsọrọ iku awọn iyalọmọ, to si n lewaju orilẹede Sierra Leone, Central African Republic ati Chad."
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: ‘Fayose ń lo owó osù òsìsẹ́ fún ara rẹ̀’ Wo Ọ̀jọ̀gbọ́n Ẹlẹka tó ń díje fún ipò gómìnà Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, ‘Ki lo buru ninu keeyan wẹwu agbọta?
19 Àti pé Ó fún wọn ní àwọn òfin pé kí wọ́n ó ní ìfẹ́ kí wọ́n ó sì sìn òun, Ọlọ́run kan ṣoṣo tí ó wà láàyè tí ó sì jẹ́ òtítọ́, àti pé òun nìkan ni ó níláti jẹ́ ẹnití wọ́n ó máa foríbalẹ̀ fún.
Nígbà tí ó rí i pé ọmọ náà jẹ́ arẹwà, ó gbé e pamọ́ fún oṣù mẹta.
Koda, oṣiṣẹ ẹṣọ oju popo aadọta ati igba FRSC ni yoo ṣiṣẹ ko ma baa si sunkẹrẹ-fakẹre ọkọ lasiko naa.
"Ìhà Arewa ní àwọn ìtàn to làmìlaka pẹ̀lú àwọn ènìyàn to tí ṣe orire, gbogbo àwọn ǹkan wọnyii ló yẹ ki a kọ ibi ara sí"" ""Nítori náà ni aṣe sọ pé láìpẹ́ yìí ti a ba ti pari ìdìbò ẹgbẹ́, a ti pinu lati máa wo ìwé ere ti àwọn ènìyàn ba kọ, èyí to ba ti jẹ mọ èrè ìfẹ́ ni a ó kó ni gbàá láye lati di ṣíṣe titi ti à ó fi ríì dáju pe àwọn ìhà toku náà ri amoju to"" Oríṣun àwòrán, KAnnywood Àkọlé àwòrán, Onijo ni Ali Ali Ìgbẹ́sẹ̀ yìí kìí ṣe ǹkan to dùn mo awọn kan nínú, Ali Ali tó jẹ ọ̀kan lára àwọn to máa n kọ àwọn ènìyàn ní ijo ni kannywood sọ pé àbá ti wọn ń da ọhun ko le múlẹ̀ rára àyà fi ti wọn ó ba pa Kannywood run pátápáta."
Jeremaya wolii bá sọ fún Hananaya pé, “Tẹ́tí sílẹ̀, Hananaya, OLUWA kò rán ọ níṣẹ́, o sì ń jẹ́ kí àwọn eniyan wọnyi gbẹ́kẹ̀lé irọ́.
A ó fi idà pa wọ́n lójú ogun,ẹranko ni yóo sì jẹ òkú wọn.
’bẹ́ẹ̀ ni mo sọ̀rọ̀ fún èkúté yìí òun náà sì fún mi ní èsì tí ó yẹ, ó dáhùn ó wí pé:
 Ẹmọ ́ ọ ̀ rọ ̀ náà ti lójú òpó , kí aré bẹ ̀ rẹ ̀ ló kù .
Gawuna salaye pe, Gomina Ganduje fe lati kopa ninu asekagba idije naa latari ife ti o ni fun idagbasoke awon odo ati fun ere-iadaraya.
Samuẹli bá yipada, ó fẹ́ máa lọ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Mane dá iná yá Kepa lábẹ́ lẹ́ẹ̀mejì bí Liverpool ṣe lu Chelsea lálùmọ́lẹ́ bíi bẹ̀m̀bẹ́.
”Wọ́n dá a lóhùn pé, “Rárá o!
papa ofurufu tuntun ni Port Harcourt ati Abuja ni ogunjọ osu kejila odun yii.
Bi awọn ti Ronaldo ko ṣe fẹ wọn ọn kun, lawọn ti Messi naa ko fẹ gba a laabọ.
Oyo drivers'crisis: Auxiliary ń ní wá lára pẹ̀lú gbígba owó aitọ, a ń ko ọkọ̀ wa kúrò lójú pópó
“Mo ti pinnu lati se awon ayipada kan ninu igbimo amusese, atunto ohun ni lati ri daju pe, won mu igberu ba eto isakoso ijoba orile-ede South Africa”.
Ta ló jẹ́ ṣe iṣẹ́ ọmọ-ogun tí yóo tún máa bọ́ ara rẹ̀?
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Trump picture: ọjọ́ tí Trump kí mi kú iṣẹ́ lórí 'twitter' ní inú mi dùn jù- Oyedele Oloogbe Oloye Joseph Folahan Odunjo jẹ eeyan nla, ẹni takuntakun to ko ipa tiẹ, ti kii se keremi si ilọsiwaju ede Yoruba ati isẹ olukọ nilẹ Yoruba.
Onidajọ to n gbọ ẹjọ naa ni ọgba ẹwọn ikoyi ni Fayoṣe yoo wa titi ti yoo fi mu awọn ilana beeli rẹ ọhun ṣẹ.
Dájúdájú ọ̀rọ̀ arò ni ọ̀rọ̀ yìí, ó sì ti di orin arò.
Wọn ni ọrọ yii kii se ti ija bi ko ṣe pe ijọba ṣe ohun to yẹ.
Tí a fiṣọwọ́ ní 11:46 29 Èbibi 201911:46 29 Èbibi 2019 Awọn àlejò jànkàn-jànkàn l'Abuja Lara awọn eekan oṣelu Naijiria ree gẹgẹ bi alejo pataki nilu Abuja nibi eto ibura wọle.
Atiku to msọrọ lojun opo Twitter ni aarẹ tẹlẹ ri, Yar'adua jẹ alaanu eeyan, bẹẹ lo si fẹran orilẹede rẹ nigba to wa loke eepẹ.
Orúkọ ìnagijẹ mẹ́jọ tí wọ́n fi ń pe Abiola Ajimọbi nígbà ayé rẹ̀ Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Awọn ti wọn ti wa ni ahamọ ọlọpaa bayii ni awọn alaga PDP fun ijọba ibile Eti Osa, Surulere, Amuwo Odofin, Mushin ati Lagos Island.
O tenumo pe,  Lassoued lo ti n rinrin ajo lo sorile-ede Malaysia, Philippines ati Turkey lati bi odun meji seyin, ti o si koko de si Manila ninu osu kefa odun 2016 pelu iwe-irinna orile-ede Tunisia, ti ko si kin se ojulowo iwe-irinna.
Eyi ko ṣẹyin bi ileewe giga fasiti kan ni oke okun, ṣe fun arabinrin naa ni anfaani lati kawe lai san owo ileewe.
Wọ́n fẹ̀sun kan an wipe o ti pa ọ̀pọ̀lọpọ̀ eniyan lakoko ikọlu meji ni awọn ile iwe, ikọlu kan si ilu kan ati omiran si ilu mii ninu eyi ti awọn ọmọ ẹgbẹ́ Boko Haram ti ko awọn ọmọbinrin nigbekun ti wọn si fi ina si ile ijọsin kan.
'Ọmọ SS 1 mu èso olómi, ṣùgbọ́n ilé ìwé wa kọ́ ló kú sí' Sultan pàṣẹ fún àwọn mùsùlùmí láti ṣ'ọdẹ òṣùpá lónìí Àwọn òṣìṣẹ́ aláàbò kọlu àwọn tó n ṣe ìwọ́de ní Sudan Ibanuje d'orí agbà k'odò, Ruiz fi ẹ̀ṣẹ́ sọ Anthony Joshua di ọmọ ológo àná Ìfẹ̀hònúhàn ni àwọn ará UK fi ki Donald Trump káàbọ̀ Odindin ọjọ́ mẹ̀ta ni Trump a lo ni ilẹ̀ Gẹẹsi.
Ajá kì í gbàgbé olóore rẹ̀: n kò jẹ́ gbàgbé rẹ láéláé, ènìyàn ni ọ́.
Eyi waye lẹyin ti Ghana ti awọn ile itaja keekeeke to jẹ ti awọn ọmọ Naijiria pa.
Ijọba lo sọ ọ di òfin lọdun 1988 pe ki ijọba apapọ naa o bẹrẹ rẹ pada.
Àwọn bàhámà ( ) tabi lonibise bi orílẹ ̀ -èdè Àjọni ilẹ ̀ awọn bàhámà , je orile-ede elede geesi to ni awon erekusu 29 , 661 cays , ati 2,387 erekusu kekere 2,387 ( apata ) .
Awọn iroyin miran ti ẹ le nifẹ si: Eeyan mẹrin ku ninu ijamba ọkọ l'Eko Wọn ri oku ọmọ to sọnu ninu ọkọ orogun iya rẹ O see se ki ọti ati siga gbowoleri Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
"'1 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Alaafin Oyo: Olorì Anuoluwapo Adeyemi gba àmì ẹ̀yẹ lórí oge ṣíṣe1 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Fídíò, Akomolede ati Asa Yoruba: Kí ni ""Future tense"" lédè Yorùbá?"
Ki ṣe dandan ni ki a se ìrẹsì fún ọdún, a lè fi oúnjẹ ẹ̀yà miràn ṣe ọdún fún àwọn ọmọ.
Ìpínlẹ̀ Oyo àti Eko kò nífẹ̀ẹ́ láti gba 'Ruga Settlement' láyè Biodun Fatoyinbo fi ipò sílẹ̀ lorí ẹ̀sùn ìfipábánilòpọ̀ Seyi Awolowo, ọmọ-ọmọ Awolowo, kí ló ń wà lórí ètò BB Naija?
Nítòótọ́ ó ṣubú, ṣugbọn ojú rẹ̀ kò wà ní dídì.
FIFA fẹsun kan Ahmad Ahmad lẹyin ọpọlọpọ iwadii lori ṣiṣe magomago owo ati titẹ oju awọn ofin ajọ naa molẹ nilẹ Afrika.
Abẹwo Aarẹ Buhari si Plateau Àwọn àwòrán ọlọkan o jọkan tí ń tọka àyájọ òmìnira Nàìjíría Ilẹ China ń sàmì àádọrin ọdun tí wọn gbòmìnira pẹ̀lú ìfẹ̀hònúhàn Ọwọ́ tẹ babaláwo àti adigunjalè márùń ni Imo - Olọpàá 1.
Ọpọ igba ti gomina tẹlẹ ni ipinlẹ Ọyọ naa ko ba si nile ni Ibadan naa ṣi ni lawọn ololufẹ rẹ kan tabi meji ṣi maa n wa bẹ ile naa wo lati ṣe baba kẹẹ pẹ si 'Akanji' gẹgẹ bi ọpọ tun ṣe maa n pe e.
Ó ni ikú Khaleel, tó jẹ́ ọmọ ipele kẹta nínú ẹ̀kọ́ ìmọ̀ ẹ̀rọ lo jẹ́ èyí tó burú jùlọ to ti wáyé lórílẹ̀-èdè náà.
O ni o daju pe Fẹla n ṣe ayẹyẹ ọjọ ibi rẹ lajule ọrun bayii.
" Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ìdílé tí ọkọ da ọmọ síta tóríi ojú Búlùú tí wọ́n ní bá BBC sọ̀rọ̀ Ọkọ kọ àwọn ọmọ méjì lé ìyàwó lọ́wọ́ nítorí ìrísí ojú wọn ní Ilorin Ọkọ'yàwó jẹ àjẹranjú ìyà lẹ́yìn tí ìyàwò rẹ̀ yọjú síbi ìgbéyàwó òun àti obìnrin mìràn Iwa nabi tu igbeyawo ọgbọn ọdun ka Èmi náà kọ́, àṣìṣe ló mú kí ń gún ọkọ mi pa láàrin ọjọ́ 51 taa fẹ́ ara wa"" Oríṣun àwòrán, Dr Zalmai Khan Ahamadzai Zarka fẹ ọkọ rẹ ni nnkan bi ọdun mẹwaa sẹyin, o si ni ọmọkunrin to jẹ ọmọ ọdun mẹfa."
Ewe, awon ti o pada sinu egbe oselu APC ohun ni: ojogbon Hafiz, awon alabasisepo asofin Rabiu Kwankwaso, ti o kowe fise sile gege bi igbakeji gomina  Abdullahi Ganduje, ogbeni Aminu Dabo; ogbeni Bala Mohammed Gwagwarwa; ogagun Danjuma Dambazau, ogbeni Mu’azu Magaji.
Bẹẹ lawọn mii ni ọrọ Naijiria jẹ atari ajanaku ti kii ṣe ẹru ọmọde ti ẹnikẹni le dagbe pẹlu irun dudu.
Ẹ má jẹ́ kí á fi ọ̀rọ̀ náà falẹ̀.
Àlàyé rèé lóríi ìdí tí wọ́n fi ń pe aya ní ìyàwó Lisabi Agbongbo Akala rèé, ẹni tó fi ìfẹ́, ìṣọ̀kan àti ìrẹ́pọ̀ gba ilẹ̀ Ẹ̀gbá lọ́wọ́ ìmúnisìn Afọnja, ẹni tó finú wénú ní Ilọrin, àmọ́ tó jẹ iwọ Ẹ̀kọ́ tí ìgbé ayé ọba Olateru-Olagbegi kejì kọ́ wa: Ẹ̀kọ́ àkọ́kọ́ tí a rí kọ́ láti ara ìtàn ìgbé ayé ọba alaye náà ni pé, àkọsílẹ̀ tí kò lórí ayé onikaluku.
foliage : n ; ( foliage is very good for the livestocks .
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ohun tí ó yé kóò kọ́ nípa ìròyìn òfégè ṣáájú ìdìbò 2019 17 Owewe 2018 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 12 Bélú 2018 Àkọlé àwòrán, Iroyin òfegè máa n ṣakoba fawọn ara ìlú ni Ọ̀pọ̀lọ́pọ̀ ènìyàn ni kìí ronú jinlẹ̀ kí wọ́n tó máà pín ìròyìn lórí ayélujára.
Èèyàn mẹ́tàlélógóje míì ṣẹ̀ṣẹ̀ kó COVID-19 ní Nàìjíríà Koda iroyin sọ pe awọn ọmọ ẹgbẹ awakọ National ni ọkọ iyawo tuntun ti wọn pe orukọ rẹ ni Henry jẹ, ti wọn si pe wọn bakan naa lati wa pẹtu si aawọ ọhun.
Tí a bá wo àwọn ìtàn àtijọ gbogbo, a ó ri pé gbogbo àwọn nnkan wònyí kò jẹ́ tuntun.
Minisita Chilufaya sọ pe idojuti nla ni isẹlẹ yi jẹ si ijọba nitori naa gbogbo awọn ti igba ibajẹ fidio yi ṣi mọ lori ko ni lọ lai jiya.
Gbogbo ìjọ eniyan sì gbà bẹ́ẹ̀ nítorí pé ó dára lójú wọn.
2 lára wọn sì ti fọ ́ jú patapata .
Ilẹ South Amẹrika lo tun tẹ le Afirika, igba marun un le laadọrun ni ifipagbajọba ṣẹlẹ, igba ogoji si lo kẹsẹjari.
 ni odun 1991 ni ijoba babangida da sile lati apa ipinle imo .
” Sẹ́ láyà lètò, ètò ni sẹ́ láyà.
Ẹnikẹ́ni kò mọ ohun tí yóo ṣẹlẹ̀ lẹ́yìn ọ̀la; ta ló lè sọ fún eniyan bí yóo ṣe ṣẹlẹ̀?
"Àwọn ọba Yorùbá kan rèé tí wọ́n rọ̀ lóyè, tí ọba míràn jẹ lójú ayé wọn Bí Fayemi bá tasẹ̀ àgẹ̀rẹ̀, àwọn oníbáwí rẹ̀ wà l'Ekiti-Peter Fatomilọla Coronavirus: Wo ohun tí o ní láti ṣe láti dáàbò bo ara rẹ Wọ́n gbé òkú ọgá iléẹ̀kọ́ àti òṣìṣẹ́ méjì míì tó kú nínú ìbúgbàmù lọ sílé ìgbókùsí ológun ojú omi l‘Eko Oríṣun àwòrán, @PastorEAAdeboye Ninu amọran to tẹlẹ fidio naa ni baba Adeboye ti sọ pe ""Ẹ maṣe gbagbe pe ara gbigbe labẹ ojiji Ọlọrun ni pe ki ẹ maa gbe igbe aye imọtoto."
Wolii obinrin kan wà tí ń jẹ́ Ana, ọmọ Fanuẹli, ẹ̀yà Aṣeri.
Ebi àti ìṣẹ́ kò sí ní Nàíjíríà, kódà a fẹ́ eré ìdárayá láti yọ́ ọ̀rá ara wa - Ìjọba àpapọ̀ Ọlọ́pàá ti bẹ̀rẹ̀ ìwádìí láti mọ òkodoro bí wọ́n ṣe gbé ọmọ tuntun náà sin láàyè ní India Ajọ Amnesty International ní kò dín ní 119 ọmọ Nàìjíríà ti wọ́n ti gba ìdájọ́ ikú ní Malaysia Ko si si idi meji bikose bi fidio kan, ninu eyi ti aya aarẹ ti n lọgun tantan se bọ sori ayelujara lọjọ Ẹti.
Ṣé lóòótọ́ ni pé Ambode ni APC fún ní tíkẹ́étì sẹ́nétọ́ fi dípò Osinọwo?
Ọjọ keje oṣu kẹta ọdun 2020 ni ọjọ buruku eṣu gbomi mu naa ti Oluwatobi de ọrun bọ̀.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù NCC: Á gbógun ti àwọn èèyàn tí kò bá fi orúkọ nọ́mbà ìpè wọn sílẹ̀ 24 Ìgbé 2019 Oríṣun àwòrán, @NgComCommission Ajọ to n bojuto awọn ileesẹ ẹrọ ibanisọrọ lorilẹede Naijiria, NCC, ti ni iwe ofin Naijiria to nii se pẹlu idabobo orilẹede,ni awọn yoo lo fi gbogun ti awọn ti ko ba se iforukọsilẹ 'Sim Card' wọn kaakiri orilẹede Naijiria.
12 Ògún 2019 Ìdásílẹ̀ Shi'ite bẹ̀rẹ̀ ní ọgbọ̀n ọdun lé díẹ̀ sẹ́yìn ní orílẹ̀-èdè Nàìjíríà pẹ̀lú ìrànlọ́wọ́ orílẹ̀-èdè Iran àti Iraq níbi ti wọ́n pọ̀ si jùlọ.
 Ko si iyan pe a si ni idojuko to n koju isokan orile-ede yii, sugbon pelu ifowosowopo awon omo orile-ede Naijiria, a duro sinsin.
- Ooni Ile Ife Ìdí tí mi ò fi lè parí ìjà pẹ̀lú Ààrẹ Ọ̀nà kakanfò, Gani Adams - Obasanjo Ilé ìgbọ̀nsẹ̀ kan ṣoṣo ni aṣòfin mẹ́rin ń pín lò!
Oríṣun àwòrán, DNA Ero ọpọ eeyan ni pe ti iru ifẹ ikọkọ bẹẹ ba ja si oyun fun abilekọ, lo maa n ti iru ọmọ bẹẹ mọ ọkọ rẹ lọrun ninu ile.
Gègé ni wọ́n ṣẹ́ tí wọ́n fi mọ iṣẹ́ olukuluku; ati kékeré ati àgbà, ati olùkọ́ ati akẹ́kọ̀ọ́.
Wo iye ìgbà tí ẹgbẹ́ òṣìṣẹ́ àtàwọn ọmọ Nàìjíríà ti ṣèwọ́de lórí àfikún owó epo bẹntírò Èkúté tó sàwárí bọ́mbù ilẹ̀ gbàmi ẹ̀ye wúrà fún iṣẹ́ takuntakun Ẹ gbó òhun tí àwọn olùdíjé sípò gómìnà nípínlẹ̀ Ondo sọ nípa bàbá ìsàlẹ̀.
Koi tii lee san beeli owo miliọnu marun un ti ile ẹjọ giga wọ̀n fun un niluu Eko.
Adewale Adeyemo: Òun ni wọ́n ṣẹ̀ṣẹ̀ yàn sípò ààrẹ fún àjọ Obama Foundation
James Okina ko fi nkan kan pamọ ninu gbogbo awọn iwa kebe-kebe to wu nigb to wa ni ọdọ langba: Afọwọra, mimu dukia awọn akkkọ akẹgbẹ rẹ to fi mọ sisa kuro n'ile.
Gbogbo àwọn tí a kà ninu ẹ̀yà Aṣeri jẹ́ ẹgbaa mẹrindinlọgbọn ó lé egbeje (53,400).
Ijọba sọ pe iwa aigbọran ni.
 ni Ọsirelia , iku anafilasisi ti ounjẹ nfa maa nsaba waye laarin awọn obinrin nigbati iku ti o nwaye nitori kokoro ti o jẹ ni maa nsaba waye laarin awọn ọkunrin .
Ìdí tí mo fi gbàdúrà ìyàwó bíi Chanel Chin fáwọn tó d'ẹ̀bi ìkọ̀sílẹ̀ rẹ̀ rù mí rèé - Oluwo Gbajúgbajà òṣèré Black Panther jáde láyé!
Ajọ eleto idibo ni gbogbo oṣiṣẹ oun ni oun ṣeto adotofo fun nitori iru iṣẹlẹ bayii.
Àtẹ̀jáde tí wọ́n fi síta fihàn wí pé, ìdá kan nínú mẹ́ta àwọn eléré ìdárayá mẹ́rìnlélógún tí wọ́n kó lọ sí ìdíje ọ̀hún, làwọn èèyàn yìí jẹ́.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Emir of Kano: Oríṣiríṣi ẹ̀sùn ni ìjọba ìpínlẹ̀ Kano kà sí Sanusi l'ẹ́sẹ̀ 9 Ẹrẹ̀nà 2020 Oríṣun àwòrán, Majeeda Studio Ọsan ọjọ Aje ni ijeba ipinlẹ Kano kede lati ẹnu akọwe ijọba, Alhaji Usman Alhaji pe awọn ti rọ Emir ilu Kano, Sanusi Lamido Sanusi loye.
Àbí, ta ló lè yìn ọ́ ninu isà òkú?
Bi esi ayẹwo naa ṣe lọ niyii.
Lẹ́yìn náà, ó wọn Tẹmpili, ó gùn ní ọgọrun-un (100) igbọnwọ (mita 45).
Nígbà tí ó yọ siwaju Farao, ọba Ijipti, Ọlọrun fún un lọ́gbọ́n, ó sì jẹ́ kí ó rí ojú àánú ọba Ijipti.
Orúkọ àwọn olórí ninu àwọn òṣìṣẹ́ rẹ̀ nìwọ̀nyí: Asaraya, ọmọ Sadoku ni alufaa.
"O ni: Won fipa ba mi lopọ, wọn si fi mi fun awọn ọmọ ikọ boko haram gẹgẹ bi iyawo Bi Boko Haram ti ṣe wọ ilu wa, wọn pa gbogbo awọn ọkunrin ilu wa sọna si awọn ile wọn si ko gbogbo awa obinrin lọ"" ""Ni ọjọ yi ni ibatan mi to jẹ Boko Haram wa sọ fún mi pe lati oni lọ, mo ti di iyawo ohun,dukia ohun ."
Onímọ̀ nípa ọ̀rọ̀ oúnjẹ, Cadre Harmonise, sọ èyí di mímọ̀ nínú àtejáde kan pé yóò ṣélẹ̀ bíi ọdún mẹ́rin sì àsìkò yìí.
"Ìbọ̀wọ́ tàbí ìfẹnukora d‘èèwọ̀ torí Coronavirus ""Ẹ gbà wá o!"
Ohun tí mo bẹ̀rù jù ti dé bá mi,ohun tí ń fò mí láyà ti ṣẹlẹ̀ sí mi.
Ọsinbajo kó Ambọde, Sanwo-Olu lẹ́yìn láti pín owóyàá l‘Eko Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Grandma Maruwa: Ó yẹ kí obìnrin sisẹ́ láì wojú ọkọ kó tó jẹun John Agbaja sọ wi pe oun ni gbagbọ ninu Aarẹ Buhari lati sa ipa rẹ ki irọrun o le de ba awọn osisẹ lorilẹede Naijiria.
O ni awọn Fulani meji ni wọn ri oun ti wọn si bẹrẹ si sọ gbogbo ohun to n ṣẹlẹ ninu ikọ Boko Haram fun oun nitori oun gbọ ede ti wọn n sọ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Nigeria at 59: Ẹ wo àwọn olóṣèlú méje pàtàkì tó jà fún òmìnira Nàìjíríà 1 Ọ̀wàrà 2019 Oríṣun àwòrán, others Àkọlé àwòrán, Awọn akọni okunrin to ja fitafita fun ominira Naijiria E wo awọn oloṣelu meje to ja fitafita fun ominira Naijiria.
OLUWA sọ fún àwọn eniyan rẹ̀ ní Babiloni pé,“Ẹ̀yin tí ẹ bọ́ lọ́wọ́ idà,ẹ má dúró, ẹ máa sálọ!
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Njẹ ọ mọ̀ pé mímí afẹ́fẹ́ tí kò dára lè fa àìsàn?
Wọn ni ẹni ti yoo ba ba esu jẹun, sibi rẹ yoo gun, Shina ro ara rẹ lagbara ninu oogun debi pe o fi ọmọ odo gun ọlẹ̀ inu alaboyun mẹtadinlọgbọn lati fi ṣe oogun ìṣọ́ra.
O jẹ adari ẹka ile iṣe ologun fun iṣe akanṣe pẹlu ọpọlọ pipe NDC ni ọdun 2006.
Ṣebí Ọlọrun ti sọ ọgbọ́n ayé yìí di agọ̀!
Akọsilẹ fihan pe awọn aṣikiri to le ni ọdunrun un lo ti ku sinu okun Mediterranean lọna irin ajo wọn lati Libya si ilẹ Yuropu.
Idanre Hills, Ondo: Ogun gan kò láyà láti dédé gun òkè Idanre
Oru ọjọ Satide ni ẹbi gbajugbaja oṣere sinima ni orilẹede Amẹrika, Chadwick Boseman ti ọpọ mọ fun ipa Black Panther to ko ninu ere sinima Black Panther, kede pe o ti jade laye.
Bí Zainab ṣe dèrò ẹ̀wọ̀n Saudi lórí ẹ̀sùn ògùn olóró tí kò mọ̀ Champions League: Ajax f'imú Tottenham fọn fèrè Àwọn ọmọge wọ gàù l'Abuja nítorí asọ péńpé Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Oyin sínsìn lérè lórí ṣùgbọ́n ó tún gbé ikú karí' Ajọ CAN naa wa ke si aarẹ orilẹede Naijiria, Muhammadu Buhari lati dari awọn eleto aabo ati ile-isẹ ologun Naijiria lati rii wi pe wọn se ohun to yẹ lati gba Leah Sharibu to jẹ ọmọ lẹyin Kristi naa silẹ.
Sanwo Olu dá Bello padà; ó yan kọ̀míṣọ́nnà 25 àtàwọn olùbádámọ́ràn
Ẹ óo máa ronú ìnira tí ẹ ti ní pé:“Níbo ni akọ̀wé wà?
Àjọ tó n mójútó ìpèsè oúnjẹ àti òògùn lílò ní Nàìjíríà, NAFDAC, ti gbẹ́sẹ̀ kúrò lórí òfin tó fi de àwọn ilé iṣẹ́ apòògùn kan látàrí ìwádìí BBC lórí codeine.
Aaroni yóo fi ọ̀dọ́ mààlúù kan rú ẹbọ ìmúkúrò ẹ̀ṣẹ̀ fún ara rẹ̀, yóo sì ṣe ètùtù fún ara rẹ̀ ati ilé rẹ̀.
Wọ́n bá ranṣẹ lọ sí inú ẹ̀wọ̀n kí wọn lọ mú àwọn aposteli náà wá.
Sugbọn nkan to ya ọpọ eeyan to gbọ si ọrọ naa nigba naa lẹnu, ni bi wọn ṣe ri ti ọmọbinrin naa fi aworan kọmisana naa sori ayelujara Facebook rẹ, lọjọ kẹtadinlọgbọn, oṣu Karun, ọdun 2020.
Ẹ ranti ohun tí ó ṣe sí àwọn ọmọ ogun ilẹ̀ Ijipti ati sí àwọn ẹṣin wọn ati kẹ̀kẹ́ ogun wọn; bí ó ti jẹ́ kí omi Òkun Pupa bò wọ́n mọ́lẹ̀ nígbà tí wọ́n ń le yín bọ̀, ati bí OLUWA ti pa wọ́n run títí di òní olónìí.
Ó ní àfikún owó náà kò sí nínú ǹkan tí òun búwọlù fún wọ́n ní ọjọ́ Jímọ̀, ọjọ́ kẹrìnlélógún oṣù kéje ọdún yìí.
Àwọn ẹgbẹ́ bíi Southeast Asian Press Alliance kí Wa Lone àti Kyaw Soe Oo káàbọ̀ lẹ́yìn-in tí a dá wọn sílẹ̀ àmọ́ wọ́n sọ ìyànjẹ tí ó kojú àwọn akọ̀ròyìn méjèèjì:
Awọn agunbanirọ naa ba ajọ INEC ṣiṣẹ ninu eto idibo naa.
eniyan mẹta ti won ji gbe naa ni won yoo gba kalẹ lọwọ awọn ọdaran naa lai
Nítorí náà, wò ó, àkókò ń bọ̀ tí n óo jẹ́ kí ariwo ogun sọ, ní Raba ìlú àwọn ọmọ Amoni;Raba yóo di òkítì àlàpà,a óo sì dáná sun àwọn ìgbèríko rẹ̀;Israẹli yóo wá pada fi ogun kó àwọn tí wọ́n kó o lẹ́rú.
Ó yọ́ wúrà bo gbogbo igi àjà ilé náà patapata, ati àwọn òpó rẹ̀, ati àwọn ẹnu ọ̀nà rẹ̀, ògiri rẹ̀ ati àwọn ìlẹ̀kùn rẹ̀; ó sì fi àwòrán àwọn kerubu dárà sí ara àwọn ògiri.
O ni oun fẹ ki Lisa kọ ẹkọ imọtoto ki awọn ololufẹ rẹ to le ni miliọnu kan lori Instagram naa le mọ pe iyatọ wa ninu igbe aye ori Instagram ati igbe aye ẹni loju aye.
Ṣugbọn nígbà tí Hiramu ọba wá láti Tire tí ó rí àwọn ìlú tí Solomoni fún un, wọn kò tẹ́ ẹ lọ́rùn rárá.
Ilẹ̀ ti mọ́ ní àkókò yìí.
Ile Igbimọ Asofin ti kọ iwe ranṣẹ si Adajọ Agba ni ipinlẹ Ondo, Oluwatoyin Akeredolu pe ki o gbe igbimọ kalẹ ti yoo se iwadii ẹsun ti wọn fi kan Agboola Ajayi.
Kábíyèsì fẹnu ara rẹ̀ tú àṣírí àwọn Fulani Daran daran tó ń ṣọṣẹ́ nílùú rẹ̀ Oríṣun àwòrán, Funkejennifaakindele Funke Akindele ni oludasilẹ ati alakoso Scene One Film Production ti wọn ti n kọ nipa ere tiata.
Owanbẹ: Gari Ijẹbu, bọ̀ọ̀lì àtàwọn oúnjẹ lágbo ayẹyẹ 'owanbẹ' báyìí
Oludamọran lori ọrọ ilu ati ilẹ okeere naa ni, ko si ohun to ti ni loju ninu eto adanilaraya, ati wi pe awọn eniyan fẹran idaraya ju ogun tabi ija lọ.
Ahieseri ọmọ Amiṣadai, kó akọ mààlúù meji, àgbò marun-un, òbúkọ marun-un ati akọ ọ̀dọ́ aguntan marun-un, ọlọ́dún kọ̀ọ̀kan wá fún ẹbọ alaafia.
O si ṣeeṣe ko jẹ wi pe nigba ti owo oloṣelu ko wọle fun wọn mọ, ni wọn gba oko olè lọ nitori atijẹ, ati atimu.
Bí Josẹfu ti dé ọ̀dọ̀ àwọn arakunrin rẹ̀, wọ́n fi ipá bọ́ ẹ̀wù aláràbarà rẹ̀ lọ́rùn rẹ̀, 
Loju opo ayelujara ni kete ti aworan Google yii lu jade ni awọn ọmọ Naijiria ti n fi ọrọ iranti ati adura ranse loju opo Twitter lori ọjọ ibi Dokita Adadevoh.
"Àwọn ọmọ yìí nìkan sì la bí ní ìlànà ọmọ bibi tí ìgbàlódé IVF, ohun tí mo ń bẹbẹ fún ní ààbò àwọn ọmọ mi, mo sì ń gbàdúrà pé kí wọn pé mi lórí foonu""Wàyí o, òṣìṣẹ́ alarena fún ileesẹ ọlọ́pàá nipinlẹ Ọ̀yọ́, Olugbenga Fadeyi tí ṣàlàyé pé, ọwọ àwọn tí bá èèyàn mẹrin lórí ìṣẹ̀lẹ̀ yìí."
Ó ṣeéṣe kí a pàṣẹ òfin Kónílé-ó-gbélé tuntun láìpẹ́ - Ìjọba ìpínlẹ́ Ekiti Iṣẹ́ ọpọlọ ló yẹ ká ṣe nínú tíátà, kìí ṣe àfihàn ara bíbó àbí ìhòòhò wa - Binta Mọgaji Ojú pópó ni mo dàgbà sí àmọ́ n kò mu igbó, sìgá tàbí ọtí líle rí - MC Oluomo Ọ̀rọ̀ Sotitobire tí a dá sí, àwọn aṣòfin àtàwọn àjọ kan ló fi lọ̀ wá- DSS O tun ṣe akọnimọọgba ẹgbẹ agbabọọlu awọn ologun Muzinga ati ti Union Sporting nibẹrẹ 1990s.
Afurasi tó fa ìpayà nílé ìwé Port Harcourt ti wọ gàù Ọlọ́pàá Adamawa ni #30,000 ni wọ́n fi bọ́ igún látìmọ́lé Aisha Buhari ké gbàjare pé ètò ìjọba Buhari kò ṣànfàní f'óbìrin Ààrẹ Muhammadu Buhari buwọ́lu owó ìṣúná ọdún 2019 Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ẹgbọ́n olóògbé Suga: Wọ́n yìnbọn fún Suga lójú mi, n kò sì lè dá wọn dúró Ní kété ti wọ́n rii ni wọn fa ọlọ́kadà náà lọ sí àgọ́ ọlọ́pàá ti agbegbe Mọṣálásí ti wọ́n si rọ ẹbí ọmọ náà láti ṣe àbẹwò si àgọ ọlọ́pàá láti jẹ́ kí ọlọ́kadà ọhun ṣàlàyé ìrú ẹni tó gbé.
Isaaki fẹ́ràn Esau nítorí ẹran ìgbẹ́ tí ó máa ń fún un jẹ nígbà gbogbo, ṣugbọn Jakọbu ni Rebeka fẹ́ràn.
"Ọlọ́pàá wú òkú obìrin tó ń múra ìgbéyàwó lọ́wọ́ tí 'gate-man' rẹ̀ ṣekúpa ""A fẹ́ yọ ààrẹ ẹgbẹ́ Yorùbá YCE nípò torí àwọn ìwà tí kò bójúmu"" Wo àànfàní ‘Masturbation’, fífún ara rẹ̀ ní adùn ìbálòpọ̀ Ẹ fura o, Boko Haram ti pàgọ́ sí Abuja, yóò ṣe ìkọlù láìpẹ́ - Iléèṣẹ́ Aṣọ́bodè lọgun Atẹjade naa ni yiyọ ti aarẹ yọ owo iranwọ naa yoo fopin si iwa ibajẹ ati iwa jẹgudujẹra, ti awọn kan n ṣe lori owo iranwọ to wa lori epo bẹntirol, ina mọnamọna ati awọn ohun elo to n mu nkan ọgbin gbooro si."
Ọlọ́pàá ní àwọn ṣì ń ṣèwádìí ẹni tó bẹ́rí ní Alasiya l'Eko Lọ́wọ́lọ́wọ́: Ìjọ àgùdà tó ti wà lát'ayédáyé ǹ jóná Àwọn ìkìlọ̀ tí ọ̀gá àgbà ọlọ́pàá là kalẹ̀ lórí ìpànìyàn Eko Atâyi Babs fi kun un wi pe ijọba apapọ Naijiria ni isẹ pupọ lati se, lati ri i wi pe opin de ba lilo ike rọba ni awọn igberiko, ẹsẹ kuku ati awọn ilu nla nla.
Oríṣun àwòrán, Twitter/Pius Adeasanmi Àkọlé àwòrán, Iku mu Pius Adesanmi lọ Adesanmi jẹ Ọjọgbọn ninu ede oyinbo ni fasiti Carleton nibi to ti n ṣiṣẹ ki ọlọjọ to de gẹgẹ bi oludari ẹkọ nipa ilẹ Afirika.
Wọn tun ṣe idaro pẹlu idakẹrọrọ iṣeju meji jakejado orileede naa bi o ti ṣe pe ọsẹ kan ti iṣẹlẹ naa waye.
Ṣugbọn ìyá rẹ̀ dáhùn pé, “Rárá o!
Àkọlé àwòrán, Awọn jagunjagun to to gbangba sun lọyẹ nii jẹ aarẹ Amọsa, ija bẹẹlẹ laarin awọn agba oselu mejeeji yii to si mu ki Akintọla o di ero ẹgbẹ oselu NNDP Lasiko iditẹgbajọba awọn ologun to kọkọ waye lorilẹede Naijiria lọdun 1966 ni wọn ti pa Akintọla.
Asofin Gbọlahan Yishawu naa ni o yẹ ki ijiya wa fun iwa itanu si awọn eniyan bayii, tabi iwa ibalopọ pẹlu wọn ati awọn iwa buruku miiran si awọn alarun ọpọlọ bayii.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Nigeria-Ghana trade war: Ààrẹ Ghana pàṣẹ kò sáàyè òwò fọ́mọ China tàbí Nàìjíríà mọ́ ní Ghana 15 Ọ̀pẹ̀̀ 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 16 Ọ̀pẹ̀̀ 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ààrẹ Ghana pàṣẹ kò sáàyè òwò fọ́mọ China tàbí Nàìjíríà mọ́ ní Ghana Aarẹ orilẹ-ede Ghana ti kede pe ko si aṣiwi tabi aṣitumọ ninu itumọ ti ẹgbẹ awọn ọlọja Ghana fun ofin kan eleyi to gbẹsẹ le ifarahan awọn ọlọja lawọn ọja abẹle gbogbo.
Ohun tó sì fa àríyànjiyan náà ni pé, ibeere ru soke pe taa ni o lé panilẹ́rin jù nínú Babatunde Omidina ti gbogbo ènìyàn mọ si Baba Suwe àti Bolaji Amusan ti gbogbo ènìyàn mọ si Baba Latin.
Ṣugbọn o ṣeni laanu pe, ko ri bo sẹ sọ.
Ipade ohun ni o waye laarin aare orile-ede Naijiria, Muhammadu Buhari ati awon akegbe re lati orile-ede Chad, Niger Republic, ati Republic of Cameroon lati wa ojutu si gbogbo ikolu awon omo ogun olote papaa julo iko boko haram.
Hotspur AFC Bournemouth 0-1 Fulham Huddersfield Town 1-2 Watford West Ham United 2-2 Leicester City Wolverhampton Wanderers 0-0 Brighton
Akintola ni, kii se ẹbi adajọ pe ijiya lọpọ igba lori ẹsun kikowo je, ki farajọ bi ẹse ti se wuwo si.
Gege bi adajo Musa se sọ, “Ile
Aláàfin Oyo: Kìí ṣe pé ìgbéyàwó èmi àti Aláàfin fi bẹ́ẹ̀ dán mọ́rán àmọ́ a tiraka láti jẹ kó láyọ̀-Olori Memunat Adeyẹmi Oríṣun àwòrán, olori memunat adeyemi Lẹnu ọjọ mẹta yii oniruuru iroyin lo ti jade lati aafin Kabiyesi Alaafin ti ilu Ọyọ eyi to ti mu ọpọ eti gbọn belebele, ṣugbọn lọtẹ yii iroyin tuntun lo tun ṣẹyọ nibẹ.
Ìbùkún ni òjò jẹ́ o jàre.
N óo gbẹ̀san àìdára wọn, ati ẹ̀ṣẹ̀ wọn ní ìlọ́po meji, nítorí wọ́n ti fi ohun ìríra wọn sọ ilẹ̀ mi di eléèérí.
Ọ̀kan ninu wọn tí ń jẹ́ Kilopasi dá a lóhùn pé, “Ṣé àlejò ni ọ́ ní Jerusalẹmu ni, tí o kò fi mọ ohun tí ó ṣẹlẹ̀ níbẹ̀ ní ààrin bí ọjọ́ mélòó kan yìí?
Àwọn Juu dìtẹ̀ láti pa Jesu.
- Aráàlú ń bèèrè Lẹ́yìn ọgọ́ta ọdún, ṣé Nàíjíríà le wà ní ìṣọ̀kan bí?
Bukola Saraki ati Shaba Lafiaji wa lara awọn to jẹ Gomina tẹlẹ ri taa n sọ, ti wọn si tun jẹ Sẹnẹtọ to n soju agbegbe wọn.
Ọrọ iyanu nla ni igbeyawo arakunrin Olawale Yesufa to jẹ oṣiṣẹ ajọ ẹṣọ oju popo nipinlẹ Eko, LASTMA.
Kò pẹ́ púpọ̀ tí mo ń simi yìí mo bẹ̀rẹ̀ sí gbọ́ ìró bọ̀ lẹ́hìn mi nígbà tí mo sì wo ibẹ̀ mo rí onírúurú ẹranko, wọ́n ń ti ìpàdé bọ̀ wọ́n sì kọjú sí apá ọ̀dọ̀ mi, ẹ̀rù bà mí gidigidi n kò sì tó ẹni tí ń yìnbọn si èyíkéyì nínú wọn, ọ̀pọ̀lọpọ̀ ẹranko alágbára ní ń bẹ nínú wọn.
Ṣé ó ti pa wọ́n bí ó ti pa àwọn tí ó pa wọ́n?
ti Oshiomhole,ti je adari egbe awon osise lorile ede Naijiria, fun opolopo odun,o
Òní ni àyàjọ́ ọjọ́ tí àwọn akẹ́kọ̀bìnrin Chibok sọnù
Ṣugbọn nígbà tí a bá ń retí ohun tí a kò ì tíì fojú rí, dídúró ni à á dúró dè é pẹlu ìfaradà títí yóo fi tẹ̀ wá lọ́wọ́.
Johnson wọgile apero rẹ pẹlu awọn akọroyin nitori pe ọpọ gba pe ẹru baa, ki wọn ma lọ pariwo lee lori.
Oríṣun àwòrán, @realyomifabiyi O wa lahun pe ko si aawọ laarin oun ati Toyin o bi o tilẹ jẹ wi pe awọn mejeeji ṣẹṣẹ n sọrọ fun igba akọkọ ni lati nkan bii ọdun meji.
Wọ́n ṣẹ́ gègé lórí aṣọ rẹ̀ láti mọ èyí tí yóo kan ẹnìkọ̀ọ̀kan wọn, bẹ́ẹ̀ ni wọ́n ṣe pín àwọn aṣọ náà mọ́ ara wọn lọ́wọ́.
Bakan naa, adigunjale yii ni ọpọ igba ni baba oun yoo tu ìbọn Sọja rẹ kalẹ loju oun, ti yoo si tun to o pada, bẹẹ ni oun n fi oju si oun to n ṣe.
Jonatani, ọmọ Ṣimei, arakunrin Dafidi pa á, nígbà tí ó ń fi àwọn ọmọ Israẹli ṣe yẹ̀yẹ́.
si ibi ti ọpọ eniyan n gbe.
Ó sọ fún mi pé, “Iranṣẹ mi ni ọ́, ìwọ Israẹli,àwọn eniyan óo máa yìn mí lógo nítorí rẹ.
O ti pe ọjọ mejila ti iwọde ENDSARS naa ti bẹrẹ yika Naijiria.
ajagun buka suka dimka ( ẹniti ó ṣe aláìsí ní ọj ́ ọ karùńdínlógún , osù karùń , ọdún 1976 ) j ́ ẹ ọmọ ogun oríléèdè nàìjíríà .
OLUWA ni ààbò fún àwọn tí a ni lára,òun ni ibi ìsádi ní ìgbà ìpọ́njú.
Èmi OLUWA ni mo ti kọ́kọ́ sọ fún Sioni,tí mo sì ròyìn ayọ̀ náà fún Jerusalẹmu.
Yorùbá ni “Bi a bà jẹ̀kọ à dári ji Ewé”.
Nígbà tí mo wò, mo rí ọwọ́ tí ẹnìkan nà sí mi, ìwé kan tí a ká sì wà ninu rẹ̀.
Ninu ifọrọwerọ rẹ pẹlu BBC News Yoruba, aṣofin George ni idi ti awọn aṣofin mejidinlogun fi gbe igbesẹ ati yi adari ile naa pada ko ju wi pe awọn aṣofin ipinlẹ naa ko lanfani lati ṣe ojuṣe wọn gẹgẹ bii iṣẹ ti awọn araalu fi ran wọn.
Saulu gbé ihamọra ogun rẹ̀ wọ Dafidi, ó fi àṣíborí idẹ kan dé e lórí, ó sì gbé ẹ̀wù tí a fi irin pẹlẹbẹ-pẹlẹbẹ ṣe wọ̀ ọ́.
Taa ba wa beere boya o kabamọ pe o tilẹ ka iwe, o ni inu ko ba ma bi oun to bayii bi ko ba ka iwe.
Tani olórí 'Ẹgbẹ́ Onímọ̀ Èdè Yorùbá?
Wo àwọn èèkàn, ìlúmọ̀ọ́ka olórin tó ṣàbẹ̀wò sí ijọ Celestial Church ti Genesis Global CCC Genesis Global: Ǹkan mẹ́wàá tí ẹ ò gbọ́ rí nípa Israel Oladele, Woli ìjọ Genesis Global Ẹ̀tanú pé Olùṣọ́ Genesis kò fẹ́ Laide Williams-Oni ló ṣe rán an lọ́ sí ẹ̀wọ̀n ọdún kan - CCC Genesis Global Saka ń wá ọ̀rẹ́ rẹ̀ kan nítorí aṣọ kóòtù ọdún 34 sẹ́yìn Kà nípa ibi tí wọ́n bí Àrẹ̀mọ tuntun Ọọ̀ni Ife sí, àti orúkọ tó ń jẹ́ A kò tíì lè sọ pé ọmọ Ọba tuntun ni yóò jẹ Ooni lọ́jọ́ iwájú - Elebuibọn Gẹgẹ bo ṣe ṣalaye fun BBC Yoruba, ara ọtọ to n gba mura lo n fun un ni ọgbọn atinuda fun iṣẹ rẹẹ bẹẹ si ni o ni oun n ri iyi ati ọwọ gba latara eyi.
Alfa Babatunde Sotitobire tún fojú balé ẹjọ́ lọ́nìí, bàbá ọmọ jẹri níwájú adájọ́ Àkọlé àwòrán, Alfa Babatunde Sotitobire tún fojú balé ẹjọ́ lọ́nìí, bàbá ọmọ jẹri níwájú adájọ́ Bàbá ọmọ ọdún kan tí wọ́n jígbé ni ilé ìjọsìn Praising Chapel Akure ní inú oṣù kọkánlá ọdun tókọja, Temitope Kolawole ti jẹri níbi ìgbẹ́jọ tó n lọ lọ́wọ́ láàrín òun àti olórí ìjọ náà wòlí Alfa Babatunde àti àwọn mẹ́fà míràn.
Gbogbo ibi ìpakà ni yóo kún fún ọkà,ìkòkò waini ati ti òróró yín yóo kún àkúnwọ́sílẹ̀.
Nígbà náà ni olukuluku yín yóo to pada sórí ilẹ̀ tí mo ti fun yín.
Ṣugbọn Adadi ati díẹ̀ lára àwọn iranṣẹ baba rẹ̀, tí wọ́n jẹ́ ará Edomu sá lọ sí ilẹ̀ Ijipti, Adadi kéré pupọ nígbà náà.
Kọlawọle wa rọ awọn oṣere sinima lati jẹ apẹrẹ rere fun awọn ololufẹ wọn, ati awọn elomiran to n wo wọn loke bi aṣaaju.
Lẹ́yìn náà mo ya àwọn àgbààgbà alufaa mejila sọ́tọ̀: Ṣerebaya, Haṣabaya ati mẹ́wàá ninu àwọn arakunrin wọn.
Àwọn ohun tí ó ń ṣe sì ń yọrí sí rere.
Eto iforukọsilẹ yii wọn n ṣe ni ijọba ibilẹ kọokan.
Oríṣun àwòrán, Instagram/officialafeezowo Yatọ si arọwa to pa yii, o tun mẹnu ba awọn koko ọrọ miran to ni ṣe pẹlu irinajo rẹ lagbo oṣere tiata ati ibaṣepo laarin oun ati iyawo rẹ, Mide Martins.
Nígbẹ̀hìn ọ̀rọ̀ yìí ọ̀kan nínú àwọn ọkùnrin wọn-ọnnì ṣe é ní ibi, ó lo òògùn burúkú fún un ẹ̀jẹ̀ ara obìnrin náà kò sì ṣàn mọ́, nígbà tí ọkàn rẹ̀ kò lù kìkì mọ́, mo lọ ṣe iṣẹ́ tí Olódùmarè rán mi, mo mú ẹ̀mí rẹ̀ jáde, ìbànújẹ́ sì pọ̀ ní agbo-ilé náà gidigidi.
awon oko n lo lai si idaduro rara.
Ọpọlọpọ orílẹ̀-èdè dojú ìjà kọ yín nisinsinyii, wọ́n sì ń wí pé, “Ẹ jẹ́ kí á sọ Sioni di aláìmọ́, kí á sì dójúlé e.
leyin ti won se ifilole oorun ti yoo maa mu ina 
Ibadan Refuse: Kọmísánà fọ́rọ̀ àyíká ní ìṣẹ̀lẹ̀ náà ní bó ṣe jẹ́, kò ṣàdédé wáyé
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Mayowa Omoniyi: Kò sí orin Obey, Sunny Ade abí tàkasúfèé tí ń kò le ta gìtá sí Magun ma mu omi: Iru Magun yii ni yoo ma mu ki ọkunrin to ba lu maa pongbẹ fun omi, ni kete ti o ba ti ba obinrin ti wọn ba le ni magun ni aṣepọ.
Ajọ elepo rọbi Naijiria ti fidi ọrọ naa mulẹ nigba ti wọn gbee si oju opo ikansiraẹni Twitter wọn.
Gẹgẹ bi Iyalode, o jẹ aṣoju awọn obinrin ninu igbimọ Olubadan.
Ṣugbọn ibi ẹrọ̀fọ̀ ati àbàtà rẹ̀ kò ní di mímọ́ gaara, iyọ̀ ni yóo wà níbẹ̀.
Ọwọ́ àwọn alásẹ ọgbà ẹ̀wọn ní ọ̀daràn to ni Corornavirus wà báyìí-Kọmísọ́nà ìlera Ondo Sunday Igboho dá sí ọ̀rọ̀ ìbejì Akeugbagold tí wọ́n jí gbé Ìjọba àpapọ̀ mọ̀ sí bí wàhálà àjàkálẹ̀ àrùn Coronavirus ṣe ń búrẹ́kẹ́ síi ní ìpínlẹ̀ Kano-Ganduje Kí ló fà ogun Ìjàyè àti ìṣubú Kurunmi, ìfẹ́ ìlú ni àbí orí kunkun?
8 Bélú 2018 Oríṣun àwòrán, @FMICNigeria Àkọlé àwòrán, Lai ni aye ọba ni adari ijọ ẹsin Shiite lorilẹede Naijiria, Ibrahim El-Zakzaky n jẹ lahamọ Ni ọjọru ni iroyin kan jade pé minisita fun eto iroyin ati aṣa lorilẹ-ede Naijiria, Lai Mohammed ṣalaye fun awọn oniroyin pe miliọnu mẹta abọ naira ni ijọba apapọ fi n yanju ọrọ ounjẹ fun adari ijọ ẹsin Shiite lorilẹ-ede Naijiria, Ibrahim El-Zakzaky loṣu.
Lati bi ọdun melo kan sẹyin ni a ti n gbọ awuyewuye lori iku Baba Sala sugbọn Baba ni anfaani ẹmi gigun titi di ana.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Marylove, ọ̀jẹ̀wẹ́wẹ́ agbábọ́ọ̀lù orí pákó gbógo Nàìjíríà yọ 5 Èbibi 2018 Oríṣun àwòrán, @marylovedwardtwitter Àkọlé àwòrán, Marylove ń digi àràbà lágbàyé Ọmọ ọdún mẹ́tàlá di àjítannáwò lágbàyé Marylove Edwards jẹ́ ọmọ Nàìjíríà tó ń gbèrò láti ṣe ju Serena Williams lọ́jọ́ ọ̀la lágbàyé.
" no longer at ease "" jẹ ́ èyí tó so òṣèlú pọ ̀ mọ ́ ara ẹni nípa pé ó jẹ ́ àwònú bọ ̀ nú orin soul , hip-hop a [ ti reggae."
Ṣugbọn nisinsinyii, a kò lókun ninu mọ́, kò sí ohun tí a rí jẹ bíkòṣe mana yìí nìkan lojoojumọ.
Ìjọba Buhari kò mọ̀ pé ìyà ń jẹ́ aráàlú ló ṣe ní ebi kò pa wá - Ọmọ Nàíjíríà Ewé súnko!
Àwọn ìdájọ́ ti ilé ẹjọ́ Sharia máa n ṣe ni Fífún ènìyàn lẹ́gba, Gígé apá tabi ẹsẹ̀ ènìyàn, idájọ́ ikú tàbí kí wọ́n sọ ènìyàn lókuta pa.
Yato so oro Isegbe, ile-ise ijoba ti o n ri oro ohun ogbin ati idagbasoke ilu, ti se agbekale igbimo kan lori kiko oja wole lona aibofin mu ati fayawo, eyi ti minisita abele je alaga re, o fi kun oro re pe, igbimo ohun se olokan-o-jokan ipade lori ona ati dekun iwa aibodin mu ti awon eniyan n hu naa.
 nínú ẹ ̀ sìn ìbílẹ ̀ ni a ti rí oríṣìíríṣìí àwọn òrìṣà tí wọn ń sìn , èyí tí òrìṣà òkè Ọ ̀ gbàgì jẹ ́ ọ ̀ kan pàtàkì tó wà fún gbogbo ìlú Ọ ̀ gbàgì .
Sanwo-Olu, El-Rufai fara pamọ́ torí COVID-19 lẹ́ẹ̀kejì Wo ìgbéyàwó olówó iyebíye tí awakọ̀ Kabúkabú ti jẹ̀bùn ọkọ N3.
Bẹ́ẹ̀ náà ni gbogbo ibi tí ó kọ́ pẹpẹ ìrúbọ rẹ̀ sí, àwọn ère tí ó gbẹ́ fún Aṣera, ati àwọn ère tí ó ń sìn kí ó tó ronupiwada.
Ọjọ akọkọ ninu ọdun 2020 Lọdun 2020, ọjọ kinni, oṣu kinni, ọdun ni ọjọ isinmi akọkọ ni eyi ti onikaluku fi sami ayajọ pe oju koowa ri ọdun tuntun.
 Àwọn ohun-èlò ìbílẹ ́ tí wọ ́ n tún mú wọ inú eré jùjú ni gágan , sákárà tàbí orùn ìṣà , gudugudu , agogo , àgídigbo tàbí móló .
Ìwọ tí o kórìíra oriṣa, ṣé o kì í ja ilé ìbọ̀rìṣà lólè?
Àwọn ọ̀rẹ́ Paulu kan tí wọ́n jẹ́ ìjòyè ní agbègbè Esia ranṣẹ lọ bẹ̀ ẹ́ pé kí ó má yọjú sí ilé-ìṣeré nítorí gbogbo àwùjọ ti dàrú.
Ninu ọrọ rẹ, o gbaruku ti Dokita yi to si sọ pe awọn onimọ iṣegun n tako lilo oogun yi nitori pe ohun ni oun kọkọ sọ pe ki awọn eeyan ma lo.
Halimatu Saadiyya ni o kede pe wọn sọ ọmọ naa.
Dájúdájú asán ati ìmúlẹ̀mófo ni èyí.
Ọpọ ninu wọn lo n ju igo sawọn ọlọpaa nigba ti wọn kọlu ara wọn.
9 278912 Orilẹede Bangladesh 6838 4.
Bufunmi ki n bu fun ọ ni ajọṣepọ to wa laarin igi igbo ati awọn kokoro inu igbo gẹgẹ bi iwadii ti onimọ ijinlẹ Thomas Crowther fidiẹ mulẹ.
Gbogbo akitiyan BBC Yoruba lati kan si arabinrin Kẹmi Adeọṣun lati wi ti ẹnu rẹ lo jasi pabo nitori pe ipe si ori number ibanisọrọ rẹ gbogbo ti akọrọyin BBC ṣe ni o dun ṣugbọn ti ẹnikẹni ko gbe.
O ni ki ẹnikẹni ma ṣe gba imọran dokita Stella Emmanuel wọle titi di igba ti imọ ijinlẹ yoo fidi rẹ mulẹ pe lootọ ni awọn oogun naa le wo alarun Coronavirus san Ẹwẹ, ileeṣẹ atẹsjiṣẹ Twitter ti pa a laṣẹ fun ọmọ aarẹ ilẹ Amẹrika, Donald Trump kekere pe ko yọ ohun to sọ nipa oogun Hydroxychloroquine kuro loju opo rẹ nitrori o le e ṣi awọn eeyan lọna.
Nígbà tí ọdún náà parí, wọ́n tún wá sọ́dọ̀ Josẹfu ní ọdún keji, wọ́n ní, “A kò jẹ́ purọ́ fún oluwa wa, pé kò sí owó lọ́wọ́ wa mọ́ rárá, gbogbo agbo ẹran wa sì ti di tìrẹ, a kò ní ohunkohun mọ́ àfi ara wa ati ilẹ̀ wa.
O Fagunwa: Ó kó ipa sí àgbéga Yorùbá àmọ́ dúkìá rẹ̀ kò tó nkàn
N ó sọ ìba díẹ̀ ṣókí nínú ohun tí ojú mi rí nínú ọdún mẹ́ta yìí kí ó tóó di pè mo rí òye ọ̀ràn mi.
Josẹfu bá ra aṣọ funfun kan, ó sọ òkú Jesu kalẹ̀, ó fi aṣọ náà wé e, ó tẹ́ ẹ sí ibojì tí wọ́n gbẹ́ sí inú àpáta, lẹ́yìn náà ó yí òkúta dí ẹnu ibojì náà.
Gift Sotonye-Frank: Bó ṣe gba oyè ọ̀mọ̀wé nípa òfin, náà ló gba àmì ẹ̀yẹ
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Chef Adefunkẹ: Òórùn ewé tí wọ́n n pọ́n ìrẹsì ọ̀fadà si jẹ́ adùn lọ́tọ̀ Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Njẹ o mọ pe ileeṣẹ ọlọpaa, awọn oṣiṣẹ ẹka ipẹjọ fun ijọba, awọn adajọ atawọn oṣiṣẹ aṣọbode lo gba riba julọ lorilẹ-ede Naijiria?
Gbogbo ẹgbẹ oṣiṣẹ ijọba, awọn oniṣẹ ọwọ, awọn ọdọ, awọn adari ẹgbẹ akẹkọọ lo parapọ sọ wi pe ki iyanṣẹlodi yii tẹsiwaju.
Bi awọn darandaran, ti iwadi ni ọpọ wọn kii se ọmọ Naijiria si se n gba ẹmi ni Plateau, ni wọn n se ọsẹ ni Benue, ti ipinlẹ Oyo, Ekiti, Akwa Ibom, Rivers ati bẹẹ bẹẹ lọ si n pariwo wọn pẹlu.
Nítorí nípa ẹbọ kan ó sọ àwọn tí a yà sọ́tọ̀ di pípé títí lae.
Nígbà tí Finehasi alufaa, ati àwọn olórí ìjọ eniyan, ati àwọn olórí ìdílé Israẹli tí wọ́n wà pẹlu wọn, gbọ́ ohun tí àwọn ẹ̀yà Reubẹni, ẹ̀yà Gadi ati ìdajì ẹ̀yà Manase wí, ọ̀rọ̀ náà dùn mọ́ wọn ninu.
Atiku fìdí ọ̀rọ̀ yìí múlẹ̀lóri ẹrọ̀ ay;elujara twitter rẹ̀ pé níwọ̀n ìgbà ti kìí ṣe gbogbo ìpínlẹ̀ ló ń ṣe ètò ìdìbò lónìí, ó yẹ ki gbogbo ǹkan lọ ni ìrọwọ́rọsẹ.
Nígbà tí ó wí báyìí tán ó kọjú sí ọ̀nà ó ń lọ, èmi náà yára dìde mo fa àdá mi yọ mo rọra ń tẹ̀lé e lọ.
" Tinubu fẹsun kan Obaseki pe o na owo ilu lati fi ba ilu jẹ kaka ko fi tun ilu naa ṣe.
Ìjọba Burundi fi akẹ́kọ̀ọ́bìnrin sí àtìmọ́lé látàrí ẹ̀sùn ìkọkúkọ sí orí àwòrán ààrẹ.
lorile ede Naijiria, eyi wa lara ilana lati mu eto idagbasoke ba ẹrọ igbalode nilẹ
 Mo ro pe ohun to se Pataki ni pe ka rii pe igbese inu leta aare di mimuse ki a ma se soro lori eleyameya mo.
O ni nitootọ ni oun ni ki awọn SARS naa ni igbooya lati koju ẹnikẹni ṣugbọn awọn kii rin kaakiri igboro rara.
Wayi o, ifesewonse ese keji yoo waye lojo isegun(Tuesday) to n bo, lorile-ede England.
Ṣugbọn ẹ gbé Oluwa Jesu Kristi wọ̀ bí ihamọra.
A kú ewu ọmọ Linda Ikeji ooo Ọ̀rọ̀ LAUTECH gba àpérò f'áwọn Olúdíje Ọṣun Aago méjìlá ọjọ́ Ẹti ni ìséde yóò bẹ̀rẹ̀ ṣáájú ìdìbò náà Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Osun Decides: Adegoke ni òun kò ni lo kọngilá n Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Ọlọ́pàá dóòlà ẹ̀mí èèyàn 10 nínú àwọn 16 tí ajínigbépawó jí gbé l'Óǹdó Ìpínlẹ̀ Oyo, Ogun, Ondo buwọ́lu àbádòfin Àmọ̀tẹ́kùn Ṣé Fulani daran-daran ni àwọn tó n jí ènìyàn gbé ní ìpínlẹ̀ Ondo?
 Aarẹ ẹgbẹ TANPAN naa tun n beere pe, ṣe awọn yoo bo imu ati ẹnu ni lasiko ti awọn ba n ya sinima, ṣe o si ṣee ṣe ki awọn ma dimọ ara awọn tabi fi ara kanra to ba jẹ pe ere ti awọn n ya gba kawọn ṣe bẹẹ?"
Gbígbé papọ̀ yìí máa ń mú ìdádúró láì sí ìbẹ̀rù dání nítorí bí òṣùṣù ọwọ̀ ṣe le láti ṣẹ́, bẹ́ẹ̀ ni àwùjọ tó fohùn ṣọ̀kan.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Ṣé òótọ ni pé èèyàn leè kó Coronavirus láti ara aṣọ tàbí bàtà?
Lori esun yii ni awon olopaa se fe mu Joyce Banda  lodun 2017 Ademola Adepoju.
Ojoojumọ ni ó ń ṣí mi létí láràárọ̀,kí n lè máa gbọ́rọ̀ bí àwọn akẹ́kọ̀ọ́.
Nibi ipade kan eyi ti gomina ipinlẹ Eko tẹlẹ naa ṣe pẹlawọn aṣofin naa ati gomina Ambọde pẹlawọn eekan ẹgbẹ oṣẹlu APC nipinlẹ Eko, GAC ni iroyin sọ pe wọn ti yanju aawọ naa.
Ní àsìkò ti BBC Yoruba ba akowe ikéde fun Gomina ipinlẹ Oyo sọ̀rọ̀ ọgbẹ́ni Taiwo Adisa sàlàye pé ẹjọ too wà nilẹ kìí ṣe ọ̀rọ̀ òni, biko ṣe pé ẹjọ ti wà lori àwọn alága ijọba ibilẹ Oyo lati àsìkò ijọba Senator Ajimobi.
Pilatu wá bi í pé, “Èyí ni pé ọba ni ọ́?
Oríṣun àwòrán, Twitter/Bashir Ahmad Ni ọdun 2015 ni aarẹ Buhari yan Abba Kyari gẹgẹ bii olori awọn oṣiṣẹ ni ọfiisi aarẹ; ipo yii lo si wa di ọdun ọjọ kẹtadinlogun oṣu kẹrin, ọdun 2020.
Wo oríṣi inú rírun márùn-ún tí o kò gbọdọ̀ pa mọ́ra Mo ṣetán láti ṣe Paulo Costa bí ọṣẹ sẹ ń ṣojú lọ́la- Israel Adesanya Ọwọ́ ọlọ́pàá tẹ arábìnrin tó fẹ́ ta alòkù kọ́ńdọ́ọ̀mù 324,000 padà f'áwọn èèyàn Kọ́ sí i nípa àwọn oúnjẹ aṣaralóore tó yẹ kí Aláboyún máa jẹ Wike, má gbé jàgídíjàgan wá sí Ondo, APC kò ní ṣ'èèrú nínú ìdìbò gómìnà tó ń bọ̀- Kalejaye Oludari ileeṣẹ reluwee lorilẹede Naijiria, Fidet Okhiria lo sọrọ naa niluu Ibadan nigba ti minisita eto irinna, Rotimi Amaechi n ṣe abẹwo ibi ti iṣẹ de lori ojuurin reluwee lati Eko si Ibadan ninu oṣu kẹjọ.
Bi iye awọn eeyan to ṣẹṣẹ ko arun naa ni ipinlẹ kọọkan ṣe lọ ree: Lagos- 128 FCT-34 Rivers- 32 Edo- 28 Oyo- 22 Kaduna- 20 Gombe- 13 Ogun- 8 Plateau- 5 Delta- 7 Kwara- 7 Kano- 5 Bauchi- 4 Katsina- 2 Àjọ NCDC kéde èèyàn 260 tuntun míì tó ṣẹṣẹ ni ààrùn Covid-19 ní Naijiria Oríṣun àwòrán, Twitter Àkọlé àwòrán, Akojọpọ esi ayẹwo aarun Covid-19 ni orilẹ-ede Naijiria gẹgẹ bi ajọ NCDC ṣe n kede rẹ.
kí ó ṣírò iye ọdún tí ó ti tà á, kí ó sì san iye owó tí ó bá kù pada fún ẹni tí ó ta ilẹ̀ náà fún, lẹ́yìn náà kí ó pada sórí ilẹ̀ rẹ̀.
ede yii se isẹ wọn lọna to ba ofin mu ati lati 
Pupọ ninu awọn nkan to ba sọ lawọn eeyan ma n ran mọ ẹnu, to si maa n da awuyewuye silẹ nigba mi.
Ìyàlẹnu ló jẹ bí oníruuru àwọn ènìyàn ṣe ya sí ilé iṣẹ́ NIKE láti lọ ràá, tó si tan laáàrin iṣẹ́ju mẹ́tà ti wọn bẹ̀rẹ̀ si ni tà.
Lori eyi, alaga ẹgbẹ APC nipinlẹ Ọyọ, , Oloye Akin Ọkẹ sọ pe ohun to ba wu Shittu ni ko ṣe.
"Lara ohun ti a kojọ, ibi iṣẹlẹ naa jẹ ibi ti wọn n ko gaasi pamọ si ti wọn si n pe ni ""gas farm"" ni agbegbe ibi ti ileeṣẹ ati katakara pọ si ni Eko."
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Oro Festival: Àwọn olórò ní ọdún Màgbó ló ń gba ibi lọ, kó ire wọlé ní Ikorodu Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
nipa bibọwọ fun ẹmi ara ẹni.
"O ni ""A ko le ṣẹgun ainiṣẹ ati ebi ti a ko ba jẹ ohun ti a gbe jade lati inu oko wa,"" ""Lọpọ ipinle ti mo lo tofimọ Kano, Nasarawa ati Taraba, mo ri ọplọpọ ọdọ ti wọn ko ni iṣẹ lọwọ."
Wọ́n mú àwọn ọmọ Aaroni náà jáde, Mose tọ́ ninu ẹ̀jẹ̀ náà, ó fi kan etí ọ̀tún wọn, ati àtàǹpàkò ọwọ́ ọ̀tún wọn, ati àtàǹpàkò ẹsẹ̀ ọ̀tún wọn, ó sì da ẹ̀jẹ̀ yòókù sórí pẹpẹ yípo.
Bí mo bá sì fún ọ ní ìmọ̀ràn, o kò ní gbà.
Ọdọọdun ni òjò arọọda maa n waye ni orilẹ-ede Naijiria, ti ọpọlọpọ ile to wa leti omi si ma n faragba ninu isẹlẹ omiyale.
awon osise alaabo yoo ri daju lati daabo bo awon ayika idibo patapata.
kejila ọdun to kọja ti wọn ko gbe e wa.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ẹ̀kùn omi Katsina: Omi gbé òpó àti ọmọ mẹ́ta lọ 17 Agẹmo 2018 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 18 Agẹmo 2018 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ìṣẹ̀lẹ̀ omíyalé wọ́pọ̀ l'órílẹ̀èdè Nàìjíríà lásìkò òjò.
"Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Awọn alẹnulọrọ sọ wi pe asiko ti Naijiria gbe igbesẹ lati jawọ kuro ninu adehun idokoowo ilẹ Afirika ku diẹ kaato "" Lati ibẹrẹ ni ọrọ naa ti wọ wa."
Shehu s'alaye pẹ ni ile awọn ibẹta ni ina ti sẹyo.
Ọdun 2017 ni ọwọ ọlọpaa ba Onweniwe lẹyin to pa oloogbe naa, to jẹ ọmọ ile iwe Rufus Giwa Polytechnic to wa ni Owo.
" SSANU, NASU gbé fásitì Ibadan tì pa Ọlọ́pàá ti mú afurasí ajínigbé Hamisu Wadume Fowler kò sí lábẹ́ ìwádìí kankan-Garba Sheu Wo àwọn eléré ìdárayá mẹ́ta tí àjọ FIFA ti fòfin dè títí ayé Bakan naa, ninu ero tirẹ, ọmọwe Ademọla Adetokun to jẹ aarẹ tẹlẹ fun ẹgbẹ Akọmọlede Yoruba ni aṣiwi o to aṣisọ lori ọrọ naa ati pe kii ṣe gbogbo eeyan ni ọrọ naa kan 'bikoṣe awọn ọmọ Ekiti nikan lati lee ran ede ati aṣa Yoruba lọwọ.
Nítorí Hamani, ọmọ Hamedata, láti ìran Agagi, ọ̀tá àwọn Juu ti pète láti pa àwọn Juu run.
Orílẹ̀-èdè Nàìjíríà fẹnukò lórí ọ̀rọ̀ yìí lásìkò ìpàdé láàrin Ààrẹ Muhammadu Buhari, ìgbákeji rẹ̀ Yemi Osinbajo àti mínísita fún ọ̀rọ̀ ilẹ̀ òkèrè Geoffrey Onyeama tó wáyé ilé ìjọba ní ìlú Abuja.
Ọlọ́fa dúpẹ lọ́wọ́ Ọ̀ọ̀ni Ifẹ̀ lori iṣẹ́ ribiribi tó ń ṣe láti ìgbà tó ti dé orí àpèrè àwọn baba rẹ̀.
Jẹ́ kí á ṣe yàrá kékeré kan sí òkè ilé wa, kí á gbé ibùsùn, tabili, àga ati fìtílà sibẹ, kí ó lè máa dé sibẹ nígbàkúùgbà tí ó bá wá síbí.
Ṣugbọn ti ọba ni ó ṣẹ, Joabu bá lọ kà wọ́n jákèjádò gbogbo ilẹ̀ Israẹli, ó sì pada wá sí Jerusalẹmu.
Jakande pé 90 láì gba àmì ẹ̀yẹ kankan ní Nàíjíríà -Osoba Eeyan kan to jẹ olotitọ si oloye Ọbafẹmi Awolọwọ ni Alhaji Lateef Jakande jẹ, ti ko si yapa ninu ala ati iran onitẹsiwaju ti Awolọwọ fi lelẹ."
Gomina ipinlẹ Edo, olori ile aṣofin nibẹ, igbakeji olori ile aṣofin ipinlẹ naa wa ni ileegbimọ aṣofin naa lati ba igbesẹ naa jẹ.
Ayọ̀ ń bẹ fún ẹ̀yin tí ẹ̀ ń sunkún nisinsinyii,nítorí ẹ óo rẹ́rìn-ín.
Loṣu kẹta nijoba bere igbesẹ lati yi ero awọn eniyan pada lori kikoni mọra lai maa dẹyẹsi alejo.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Àdó olóró Iran: Trump ati Macron fẹ́ s’àdéhùn tuntun 25 Ìgbé 2018 Oríṣun àwòrán, Reuters Àkọlé àwòrán, Awọn adari naa wipe adehun tuntun naa yoo koju aibale okan to n sẹlẹ ni Middile East.
Mo ti fẹ́ wọn bí ẹni fẹ́ ọkà ní ibi ìpakà,ní ẹnubodè ilẹ̀ náà.
Adari ile iwosan naa, Jaff Momoh ni iṣẹ abẹ awọn ibeji naa yatọ ninu eleyii ti awọn ti n ṣe nitori o nii ṣe pẹ̀lu isale igba aya wọn ati ẹdọfooro.
Ajọ NERC fi idi ọrọ naa mulẹ lasiko ti wọn fesi si ikede ijọba to mu ki ẹgbẹ oṣiṣẹ fagile iyanṣẹlodi ti wọn fẹ bẹrẹ ni Ọjọ Aje.
 idojukọ naa wa lori awọn idinudọpọ dede , paapaa ni awọn eniyan lati agbaye gusu .
O ni afihan awọn sinima to n waye lori ayelujara, ti awọn alagbata n gbe sinima silẹ ni gbẹfẹ lai jẹ kò ṣe iyebiye loju araye, n din ifẹ ati ojulowo isẹ tiata ku.
Nigba ti aare Buhari n ba awon
“Tí ẹ bá ṣọ́ra, tí ẹ sì pa gbogbo òfin tí mo fun yín mọ́, tí ẹ fẹ́ràn OLUWA Ọlọrun yín, tí ẹ̀ ń rìn ní ọ̀nà rẹ̀, tí ẹ sì súnmọ́ ọn pẹ́kípẹ́kí, 
Wọn tun gbọdọ ri daju pe owo to tọ si ijọba n de apo rẹ, ojuṣe ikọ PMS si tun ni lati ri pe kosi sunkẹrẹ-fakẹrẹ ọkọ, nipa ṣiṣe amojuto awọn ibudokọ.
Ṣé ẹ mọ̀ pé olóògbé Ìjàpá tó kú lẹ́ni ọdún 344 yìí kò gba abẹ́rẹ́ rí?
Saulu ati àwọn ọmọ ogun rẹ̀ kó ara wọn jọ, wọ́n lọ sójú ogun náà.
Nigeria models: Ẹ má bóra mọ́, ọmọ dúdú dùn lọ́mọbìnrin
"A ti ṣe ohun gbogbo tí òfin ní ká ṣe, kí wọ́n dá Fayoṣe sílẹ̀ ló kù.
Ewe, agbenusoro nile iwosan ti won gbe awon ti o fara kaasa ikolu ohun lo so pe, eniyan mejilelogun ni won ti gbe wo ile iwasan naa lati ibi ti isele ohun ti waye.
Èyin ènìyàn yìí ìto le kò ( kò túmò sí kí á pa igi ) .
- Primate Ayodele sọ àsọtẹ́lẹ̀ Saaju la ti sọ fun yin pe, oludasilẹ ijọ INRI Evangelial, Wolii Elijah Ayodele ti kede pe, ẹkun ariwa orilẹede Naijiria si ni ipo aarẹ yoo duro si lọdun 2023.
Loṣu Kẹwa ọdun 2019 lo fi ọrọ yii sita, eyi to jẹ ki a lero pe oṣu Kẹwa ni wọn bi.
Ninu atẹjade ti wọn naa, awọn ẹgbe oniroyin naa pe fun ibọwọ fun ofin orilẹede naa ati opin si idukoko mọ awọn oniroyin ni Kenya.
Amọ, o dabi ẹni pe gbogbo nkan lo ti yipada bayii bo ya nitori pe aye ti di aye ọlaju ni.
Opo ẹmi ati dukkia lo sọnu ninu ikọlu naa.
Gbogbo àwọn aṣẹ́wó ọkunrin tí wọ́n wà ní ojúbọ àwọn oriṣa káàkiri ní ilẹ̀ Juda, ni Asa lé jáde kúrò ni ilẹ̀ náà; ó sì kó gbogbo àwọn oriṣa tí àwọn baba ńlá rẹ̀ ti ṣe dànù.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Rivers Governorship Election: INEC ní Nyesom Wike ti PDP ló jáwé olúborí 3 Ìgbé 2019 Àkọlé àwòrán, Osú tó kojá ní wọ́n sún ìdìbò tí wọ́n sẹ̀sẹ̀ ń kà síwájú níbiti PDP àti AAC pẹ̀lú àtìlẹyìn APC ló ń figagbaga.
Bí àwọn eniyan tí wọn ń gbé ilẹ̀ náà bá mójú fo ẹni tí ó bá fi ọmọ rẹ̀ fún oriṣa Moleki, tí wọn kò pa á, 
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Bolaji Faleke ni Olùkọ́ tó ń kọ́ wa ní àṣà oge ṣiṣe lórí BBC Yorùbá Abala kẹta eto ẹkọ naa yoo bẹrẹ lọjọ Kẹta osu karun, ti yoo si pari ni ọgbọnjọ osu keje ọdun 2021.
Awọn alẹnulọrọ sọ fun ileeṣẹ BBC wipe iṣẹlẹ ina yii ṣadeede bẹrẹ ni agogo kan abọ oru ti o si jo awọn ile itaja (ṣọọbu) ti o to aadọta patapata.
Ilaji awọn ọmọ orilẹede Cameroon tilẹ sọ pe Biya lo ti wa ni ipo lati igba ti wọn ti bi wọn.
lati dibo nile idibo kan naa.
Gomina Tambuwal kede yii, ni ile ijọba ipinle Sokoto to wa ni Ila- Iwo oorun orile ede Naijiria.
 Èyí ni ó ń ṣe tí ó fi ń ṣiṣẹ ́ nílé iṣẹ ́  tribune "" àti nílé iṣẹ ́ "" radio nigeria "" ."
Ẹ ranti wi pe Asofin Melaye ti figba kan kọrin 'Ajẹkun Iya' si awọn alatako rẹ ni ọdun 2017.
Nítorí náà, èmi OLUWA Ọlọrun óo fi ilẹ̀ Ijipti lé Nebukadinesari, ọba Babiloni lọ́wọ́.
Wọ́n wá rí Mose ati Elija tí wọn ń bá Jesu sọ̀rọ̀.
Àkọlé àwòrán, Gómínà ìpínlẹ̀ Eko, Babajide Sanwo-Olu sàbẹ̀wò sílé olóògbé Àkọlé àwòrán, Gomina ipinlẹ Kano ti o tun jẹ ana oloogbe Abiọla Ajimọbi, Abdullahi Umar Ganduje ati gomina ipinlẹ Jigawa, Mohammed Badaru Abubakar ti de si Mọsalaṣi Abiọla Ajimọbi to n bẹ ni Oke Ado niluu Ibadan, nibi ti eto adura ti n lọ lọwọ fun oloogbe Oríṣun àwòrán, Ajimobi Lives On Àkọlé àwòrán, Wọn gbe Sẹnetọ Abiola Ajimobi bọ ilẹ ni inu ọgba ile rẹ ni Oluyole, Ibadan.
 Dokita Francis ni lọpọ  igba ni awon n se  ipolong olati jẹ ki awon gomina mọ ojuse wọn ,
Orí òké Ìyámàpó ni wọ́n ti sọ Ìlú Ìgbẹ́tì kalẹ̀.
S Ikorodu - Addax/Falomo Liverpool - Igbo Elejo Liverpool - Olodi Apapa Marina/C.
Lẹ́yìn ìgbeyàwó ọdún mọ́kànlá àti ọ̀pọ̀ ìjà, Bọsẹ di èrò ọ̀run nílé Saidi Ọkọ̀ òfúrufú ọlọ́pàá yóò bẹ̀rẹ̀ sí ní káàkiri Naijiria - Ọgá Ọlọ́pàá N650,000 péré ni mò ń gbà gẹ́gẹ́ bíi owó oṣù -Gomina Ọyọ Ọwọ́ EFCC tẹ ọ̀kan lára àwọn ti FBI fi èsún jìbìtì kàn!
Ẹgbẹ́ APC dá ọmọ Alao Akala padà sípò alága Ogbomọṣọ North Ọjọ́ Àbámẹ́ta la ó mọ ẹni tí yóò lékè láàrín bàbá ìsàlẹ̀ àti àwọn mẹ̀kúnnù nipinlẹ̀ Ọyọ.
Idi si ree to fi n jẹ Ifaremilẹkun Fagbemi Abass.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Omolola Arohunmolase Welder: Mo ti fí iṣẹ́ 'Welder' gbayì láwùjọ, tó mo fi tọ́ ọmọ yanjú 5) Adekemi Omorinbola: Omorinbola ni Asin ti ilu Oka Akoko ni ipinlẹ Ondo.
Ninu atẹjade naa o sọ pe: Garba Sheu n lẹdi apo pọ pẹlu awọn kan lati maa toju bọ ohun to n ṣẹlẹ ninu mọlẹbi aarẹ Naijiria Garba Sheu kan naa n lodi si idasilẹ ọọfisi iyawo aarẹ (Office of the First Lady) ti o si sọ pe ijọba Buhari ni o lodi si idasilẹ ọọfisi yi Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Akure Kidnap: Àwọn abiyamọ fẹ̀hónúhàn lórí ọmọ tí wan jígbé nílé ìjọsìn Akurẹ O ni Garba Sheu wa lara awọn to gbimọran ọtẹ lati tan ara ilu pe awọn ti oun mọ ita nigba ti oun dari irinajo pada si Naijiria Bẹẹ ni Aisha Buhari sọ pe Garba Sheu kanra mọ awọn oṣiṣẹ ileeṣẹ amohunmaworan Naijiria ti wọn n ṣiṣẹ pẹlu ọọfisi iyawo aarẹ ti o si mura pe dandan ni ki wọn gbaṣẹ lọwọ wọn.
O wa gbosuba fun awon osise ile
Àwọn òkè ńláńlá mì tìtì níwájú rẹ̀,àwọn òkè kéékèèké sì yọ́.
Àkọlé àwòrán, Lara awọn eeyan pataki ti o tun darapọ mọ ipejọpọ naa ni Ọọni Ile Ifẹ, Ọba Enitan Ogunwusi.
Awọn akẹkọọ naa jẹ alaisi lasiko rogbodiyan to waye laarin awọn ọlọpaa ati akẹkọ fasiti FUOYE, pẹlu awọn olugbe ilu Ọyẹ Ekiti.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Curruption Scandal: Ọ̀gá NIMASA tẹ́lẹ̀ r'ẹ́wọ̀n ọdún méjìlélógójì he 3 Òkùdu 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 4 Òkùdu 2019 Oríṣun àwòrán, EFCC Àkọlé àwòrán, Ọ̀gá NIMASA tẹ́lẹ̀ r'ẹ́wọ̀n ọdún méjìlélógójì he Ile ẹjọ giga kan niluu Eko ti dajọ ẹwọn ọdun mejilelogoji fun adele ọga ajọ NIMASA (Nigerian Maritime Administration and Safety Agency), Ọgbẹni Calistus Obi.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ẹgbẹ́ agbábọ́ọ́lù AS Roma dá sí awuyewuye jọ̀lọ́fù 19 Òkùdu 2018 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 1 Ọ̀wàrà 2018 Oríṣun àwòrán, NDUDU BY FAFA Awuyewuye to wa lori orilẹ-ede to ni irẹsi jọlọfu to dara ju ti de ibi ti eniyan ko tilẹ lero bayi - ọdọ ẹgbẹ agbabọọlu Italy ti orukọ wọn n jẹ AS Roma.
Ìjọba àpapọ̀ kéde ọjọ́ tí ìdánwò NECO, NABTEB àti BECE yóò bẹ̀rẹ̀ Ìdí tí ìjóba ìpínlẹ̀ Eko fí ṣí àwọn ilé ìwé kan padà Ìjọba ìpínlẹ̀ Eko ti ti ibùdó ìtọ́jú ààrùn Covid-19 tó wà ní Eti-Osa Yatọ si lilo ibomu ati fifọ ọwọ wọn ki wọn to wọ kilasi, awọn ipinlẹ bi Ogun ti paṣẹ ki gbogbo awọn akẹkọọ mu iwe ẹri ayẹwo wa to ṣafihan pe wọn ko ni arun Covid-19 lara.
O tesiwaju pe egbe JOHESU ti se aseyori nipa iyanselodi, lori pipese awon ajemonu fun awon omo egbe won ati idagbasoke lori  eto ilera.
Bakan naa lo ṣe ọpọ ere ninu iwe Atọka, oun naa si tun ni oṣere tiata kẹrin to ya ere sinima lẹyin Hubert Ogunde, eyi to gbe lọ si orilẹ-ede United Kingdom (UK).
” Wọ́n bá tẹ́ aṣọ kan sílẹ̀, olukuluku sì bẹ̀rẹ̀ sí ju yẹtí tí ó wà ninu ìkógun rẹ̀ sibẹ.
" Èyí ni fídíò bí wọ́n ṣe fi bàálù gbé Emir Sanusi kúrò ní ìpínlẹ̀ Nasarawa Iroyin kan to tẹwa lọwọ sọ pe wọn ti gbe Emir ilu Kano tẹlẹ, Sanusi Lamido Sanusi kuro ni ipinlẹ Nasarawa lọ si ibi ti ẹnikẹni ko mọ.
Igbakeji aare orile-ede Naijiria, ojogbon Yemi Osinbajo ti ro ajo to n ri si oro ile-okere Ministry of Foreign Affairs lati wani ibamu pelu aseyori ti eto idanilaraya ati ere-idaraya ti mu ba orile-ede Naijiria.
ó ní kí wọn lu Jeremaya, kí wọn kàn ààbà mọ́ ọn lẹ́sẹ̀ ní ẹnu ọ̀nà Bẹnjamini ti òkè, ní ilé OLUWA.
Ó wá wádìí ẹni tí ó jẹ́ ati ohun tí ó ṣe.
Bo tilẹ je pe ijọba kede konile-o-gbele nipinlẹ Eko, Ogun ati olu ilu Naijiria, Abuja nitori ajakalẹ aarun coronavirus, ọpọ nnkan lo ṣi ṣẹlẹ lagbo oṣere lọsẹ yii.
Dákú-dáji iná mọ̀nà-mọ́ná ti ó sọ ilú si òkùnkùn jẹ́ òfò fún olówó àti aláini nitori, yàtọ̀ si ariwo àti òórùn, ai mọye enia ni ikú ẹ̀rọ mọ̀nà-mọ́ná ti pa.
ọrọ Agbẹnusọ naa, “ninu gbogbo igbesi aye rẹ, Jesu Kristi ni ifarada,
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù SSANU, NASU yóò bẹ̀rẹ̀ ìyanṣẹ́lódì lọ́jọ́ Ajé láti fa ìjọba létí 18 Ògún 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images O da bi ẹni pe iṣẹkuṣẹ ni awọn oṣiṣẹ fasiti yoo fi ṣẹ orilẹede Naijiria lọwọ ni ọjọ aje ọjọ kọkandinlogun oṣu kẹjọ ọdun 2019 pẹlu bi wọn ni kede pe awọn yoo bẹrẹ iyanṣẹlodi jakejado orilẹede Naijiria.
Odiwọn ọja eroja ibora l'agbaye to biliọnu marun un Dọla ($4.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, È gbọ àlàyé lẹnu àwọn ti ójúẹlẹgba leko irú iṣẹ ti oògùn olóró má n ṣé lara.
”Saulu dáhùn pé, “Mo wà ninu ìpọ́njú ńlá nítorí pé àwọn ará Filistia ń bá mi jagun, Ọlọrun sì ti kọ̀ mí sílẹ̀, nítorí pé kò fún mi ní ìtọ́sọ́nà, yálà láti ẹnu wolii kan ni, tabi lójú àlá.
Catherine wa isẹ se ni ile itọju ọmọ wẹwẹ, to si pinnu lati wa owo fun isẹ abẹ ọmọ naa, ni awọn isoro miran ba tun yọju lẹyin ọdun kan.
N jẹ ọmọ yii le di ọba ile Gẹẹsi lọjọ iwaju?
”Ogbéni Asiimwe sọrọ lori awọn aṣa Uganda ti wọn n gbe igbese lati mu pada bọ sipo.
Olatunde, lasiko to n ba BBC Yoruba sọrọ salaye pe ọdun 2016 ni oun bẹrẹ si jo irin mọ irin lati se mọto naa, to si gba oun ni odidi ọdun mẹta ko to pari.
 irú àwọn ọjà báyìí ni Ìtọ ̀ kú , Ìta Ẹlẹ ́ gà , ọjà ọba àti Ìbẹ ̀ rẹ ̀ kòdó .
Nítorí pé ó wà ní ìkáwọ́ wọn láti ṣe é.
Gbogbo wọn dúró lórí òrùlé ilé wọn,ati ní gbogbo gbàgede, wọ́n ń pohùnréré ẹkún,omijé sì ń dà lójú wọn.
Osinbajo rọ awọn eniyan lati fọwọ sowọpọ pẹlu ara wọn lasiko ti wọn fi wa ni ibudo ogunlende naa, ki wọn le wa ni alaafia.
 ohun kan ni wọ ́ n mọ ̀ nípa jìjì , òun náà ni pé kò jẹ ́ tàpá sí ìpè ẹbí rẹ ̀ .
Ẹ̀yin ọmọ Israẹli, OLUWA Ọlọrun ní, “Kí olukuluku yín lọ máa bọ oriṣa rẹ̀ láti ìsinsìnyìí lọ, bí ẹ kò bá fẹ́ gbọ́ tèmi, ṣugbọn ẹ kò ní fi ẹbọ ati oriṣa yín ba orúkọ mímọ́ mi jẹ́ mọ́.
Bẹẹ ni ọrọ Ọba Lamidi Olayiwola Adeyemi kẹta rí,ẹni ti ori gbe de ipo awọn baba rẹ leyin ọpọ ifigagbaga laarin awọn ọmọ oye to le ni mẹwa, ti wọn dìjọ du ipo.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ladoja: Àwọn èèyàn Oyo fì ìbò sọ̀rọ̀ pé ìjọba Ajimobi kò dára Sugbọn Agbẹnusọ Ajimọbi kò sọ nipato lati dahun ibeere boya Ajimọbi ni arun Coronavirus tabi bẹẹkọ rara.
Lẹyìn náà kọ orukọ rẹ ti baba rẹ ki o si wo boya kaadi rẹ ti wa nilẹ fun gbigba.
Wọn kò fura títí ìkún-omi fi dé, tí ó gba gbogbo wọn lọ.
O ni ọkan ninu awọn agbabọọlu ti ko fẹ ki wọn darukọ oun sọ pe awọn ṣẹṣẹ pari ipade pẹlu alakoso ere bọọlu Naijiria NFF ni.
Loṣu Keje ni ikọ agbesunmọmi yi mu oṣiṣẹ ajọ ẹlẹyinju aanu naa kan,awakọ meji ati oṣiṣẹ ile iṣẹ ilera meji ni Borno.
Fifi ifẹ han laarin ọkunrin kan si omiran lodi sofin orilẹede Naijiria, koda ẹwọn ọdun mẹrinla ni ẹni ti ọwọ ba tẹ yoo fi gbara, bẹẹni igbeyawo ọkunrin s'ọkunrin naa lodi si ofin.
11 Àti kíyèsíi, ìwọ ni Dáfídì, ìwọ̀ ni a sì pè láti ṣe ìrànlọ́wọ́; èyítí bí ìwọ bá ṣe ohun náà, bí o bá sì jẹ́ olõtọ́, a ó bùkún fún ọ ní ti ẹ̀mí àti ní ti ara, púpọ̀ ni èrè rẹ yíò sì jẹ́.
ipade miiran yoo tun tesiwaju lojo Aje(Monday), ti n se ojo ketadinlogun osu
Laipẹ yii lo ke si aarẹ Buhari lati ṣe kanmọ nipa atunto orilẹede Naijiria, ki o ma ba pin yẹlẹyẹlẹ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Toyosi Adesanya: Iléeṣẹ́ ọlọ́pàá ní Kwara ní àwọn àti Fijilanté wà nínú igbó láti ṣàwárí ọ̀daràn tó ṣèkọlù náà 28 Sẹ́rẹ́ 2020 Gbajugbaja osere ori itage lobinrin, Toyosi Adesanya Ileyemi ti iroyin gbalẹ kan pe awọn gende agbebọn kọlu ti ba BBC Yoruba sọrọ.
- MC Oluomo Ẹ máṣe gba ààwẹ̀ dójú ikú, ẹ gba iye tí agbára yín gbé - Dókítà Ọ̀gá ọlọpàá gbẹ̀mí ara rẹ̀ l'Ógun Ìdí tí mo fi bẹ̀rù Mugabe, tí mo sì tún fi bu ọlá fún un Ọkọ̀ akẹ́rù Dangote rọ́lu BRT lọ́nà Ikorodu, èèyàn kan kú, 59 farapa, ẹsẹ̀ dẹ́rẹ́bà gé O kéré tán ènìyàn mẹ́ta kú lójú ẹsẹ̀ nígbà tí ó tún kọlu ènìyàn mẹ́ta míràn nígbà tó n gbé òkìtì.
5bn eyi ti awọn jogun lati ọdọ ijọba Fayemi ati awọn eyawo miran to ti ati ọwọ ijọba apapọ wa latari bi wọn ti ṣe ṣe atunto awọn eyawo ohun.
Ẹ kó àwọn aláṣẹ ibùdó ìkẹ́rùsí Beirut tó búgbàmù sáhàámọ́ - Ìjọba Lebanon pàṣẹ Awọn alaṣẹ ibudo ikẹru si ti ibugbamu ti waye ni Beirut ti wa ni ahamọ.
Aba Iwo lo bi ọmọbinrin orekelẹwa kan, to dun wo, to si jẹ oju ni gbese eyi ti wọn n pe ni Wuraọla.
Eyi tumọ si pe Akeredolu ti wọle ibo gomina ipinlẹ Ondo bayii fun igbakeji.
Jemila dáná sún ilé ọ̀rẹ́kùnrin rẹ̀ àti ọ̀rẹ́bìnrin tó bá nílé
Ọọdunrun ọdún ó lé aadọta (350) ni Noa tún gbé sí i lẹ́yìn ìkún omi.
Aniamaka kọ lati sọ boya wọn san owo lati fi doola ẹmi wọn.
Yoo sọ ọrọ diẹ, yoo si gba adura ibukun Urbi et Orbi - si ilu yii ati si aye""."
Ọkùnrin ti o ni ìyàwó kan, ni àlè sita ma fara pamọ́ lati lọ sí ọ̀dọ̀ obìnrin keji ti wọ́n rò wípé́ á fún wọn ní ìgbádùn.
Àwọn Ọmọ Israẹli Bá Àwọn Ará Amaleki Jagun.
Gbogbo òwúrọ̀ ọjọ́ keji ni wọ́n sì fi rìn kí wọ́n tó pada dé Mahanaimu.
Kaduna: Àwọn agbébọn pa ènìyàn 14 níbi ìgbéyàwó ní Ungwan Pa-Gwandara
Awọn ti wọn yan naa ni: Pernille Harder - Vfl Wolfsburg forward Ada Hegerberg - Olympique Lyonnais striker Lindsey Horan - Portland Thorns midfielder Sam Kerr - Chicago Red Stars and Perth Glory striker Saki Kumagai - Olympique Lyonnais defender Ọjọ keji ọjọbọ oṣu karun ni gbedeke ọjọ ti idibo yoo wa sopin (09:00 BST, 08:00 GMT) ti wn yoo si kede ẹni to ba jawe olubori lọjọ kejilelogun oṣu karun loju opo agbaye BBC World Service ati lori itakun ere idaraya ti BBC, BBC Sport.
Dìde, ké pe ọlọrun rẹ, bóyá a jẹ́ ṣàánú wa, kí á má baà ṣègbé.
o si fe ko din, a fe ki o kaakiri  lati ipele
Àwọn tó wà nínú ìjàmbá ọkọ̀ órí afára Otedola ń lọ ìpínlẹ̀ míì láti Eko ni - LASTMA 'Ìbọn dún láàfin Ọ̀ọ̀ni ilé ifẹ̀ lóòtọ́, ṣùgbọ́n kò séwù' Arákùnrin tó jí Ese Oruru gbé ti rí ẹ̀wọ̀n ọdún 26 he Ọmọ Nàìjíríà 292 láti Saudi Arabia gúnlẹ̀ sí Abuja Mumuni tẹsiwaju pe ajọ SERAP ko faramọ igbesẹ APC lati sọ fun awọn oludije sipo gomina lati lọ wa owo gọbi fun fọọmu, nitori iru awọn igbeṣẹ bẹẹ lo n fa iwa ajẹbanu ti awọn oloṣelu n wu.
Ìgbà tí iwin tí mo fi ran sì dé o ní kò rí ààyè kọ̀wé padà ṣùgbọ́n ó fi ẹnu ran òun kí òun sọ fún mi pé òun ó fèsì ní ọjọ́ kejì.
Olateru-Olagbegi II: àkàndá ẹ̀dá tó jọba ní ẹ̀ẹ̀méjì láàrín ọdún márùndínlọ́gbọ̀n síra wọn Èmi àti Sanyeri ti tọrọ oúnjẹ jẹ rí nílé oninawo torí ebi, ká tó di gbajumọ oṣere Èrò ọmọ Nàìjíríà ṣ'ọ̀tọ̀ọ̀tọ̀ lórí ọ̀rọ̀ Bíṣọ́ọ́bù Oyedepo pé kò sí ìdí tí iléèjọ́sìn láti wà ní títì pa Ẹ̀dínwó epo bẹntíró tí NNPC kéde kò kan ará ìlú Lọ́wọ́ lọ́wọ́ báyìí, ìjọba Nàìjíríà tí gbé ilẹ UK lọ sile ẹjọ́ láti gba àwọn owó náà, kò tó ko ìdá àádọ́rin fún Atiku Bagudu, tíì ṣe alájọsisẹpọ Sani Abacha, tí àdéhùn jọ wà láàrin òun àti ìjọba Nàìjíríà nípa owó náà.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Adeleke: Àwọn ará Ẹdẹ bẹ síta pẹ̀lú ìdùnnú lórí ìdájọ́ èsì ìdìbò gómínà Ọṣun Ni bayi ti ile ẹjọ Akure ti ni Adeleke koju ọsuwọn,igbimọ ipolongo rẹ ni ko si nnkan mi ju ki ile ẹjọ ti yoo gbọ ẹjọ kotẹmilọrun awọn L'Abuja naa dajọ to jọ iru ti Akure.
Lọwọlọwọ bayii, wahala naa tun ti peleke si lati Ọjọ Aje, ọjọ Kẹfa osu Kinni ọdun 2020 nigba ti wọn tun ti abala titi naa pa, ti ọpọ awọn eeyan to n gba opopona ọhun si n lo wakati mẹta, o kere tan, ki wọn to ri ọna kọja.
Àkójọ gbogbo ojúewé wiki tó jápọ̀ s'íbí
Gbogbo wa lati si gbọdọ tẹsiwaju lati ṣiṣẹ pọ pẹlu ijọba ipinlẹ Eko ati ijọba apapọ nipa diuro nile, fifọwọ loorekoore ati sise iyagosiraẹni.
Iroyin naa ni deede aago marun kọja isẹju meje ni irọlẹ ọjọ Aiku, ni Auxillary ati ikọ rẹ gunlẹ si ile Tokyo, ti wọn si ki wọn kaabọ tilu tifọn, ki awọn mejeeji to wọle lọ se ipade bonkẹlẹ alatilẹkun mọri se.
Ileẹjọ giga apapọ kan nilu Ado Ekiti lo ti kọkọ gbe ẹsẹ ajọ EFCC kuro lori aṣuwọn Gomina Fayoṣe pẹlu awijare pe gẹgẹ bii anfani, koṣeebawii ti ofin ilẹ Naijiria fifun un gẹgẹ bii gomina, aṣiṣe nla ni fun ajọ EFCC lati pàalè aṣuwọn ifowopamọsi rẹ.
Amọ Alaafin ninu lẹta ti wọn lo kọ si Fayẹmi sọ wi pe, agbarijọpọ awọn ọba ni ilẹ Yoruba lo fọwọsowọpọ fi ikilọ naa ranṣẹ si gomina naa, lati maṣe fi ori ade tẹlẹ ni ipinlẹ rẹ.
" O tẹsiwaju lati sọ pe ohun to ṣe pataki ni pe ajọṣepọ to dan mọran ti wa laarin ẹgbẹ mejeeji lati igba ti oun ti de ipo.
Irinwó lé méje èèyàn ló gbàwòsàn lọ́wọ́ Covid-19 lọ́jọ́ Àbámẹ́ta, 453 míì tún lùgbàdì rẹ̀ Wọn fikun wi pe dokita kan ti orukọ rẹ n jẹ Olukunle Oluwasemowo ti ileewosan Molecular Genetics Laboratory 54gene, nipinlẹ Eko lo ṣe ayẹwo naa.
Fún wa ní oúnjẹ òòjọ́ wa lónìí.
OLUWA ti ṣe bí ó ti pinnu,ó ti mú ìlérí rẹ̀ ṣẹ,bí ó ti sọ ní ìgbà àtijọ́.
 Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Mo ní àṣírí ìyá tó fẹ́ ọmọ rẹ̀ láya fún Boko Haram torí ẹbí rẹ̀' Ọjọ tí ǹkan fẹ́ yíwọ́ lórí ìtàgé "" Sùgbọ́n ní ọjọ́ kan, ǹkan ṣẹlẹ̀ ní Cultural Centre, mo nígbàgbọ́ pé àwọn ènìyàn yóò ṣì rántí."
Wọ́n kó fadaka pẹlẹbẹ wá láti ìlú Taṣiṣi,ati wúrà láti ìlú Ufasi.
Ìwọ́de EndSARS ti yíwọ́ pátápátá ní Ondo - Ọlọ́pàá Oríṣun àwòrán, @aproko_doctor Iroyin to n tẹ wa lọwọ ni yajoyajo ni igboro ilu Akure ti daru nitori iwọde EndSARS to gbode.
Abimeleki bá bi Abrahamu, ó ní, “Kí ni ìtumọ̀ abo ọmọ aguntan meje tí o yà sọ́tọ̀ wọnyi?
Iyaselodi ti  won gunle ohun ni ko je ki ise lo de e de ni  gbogbo awon ile-iwosan to wa jake-jado orile ede yii.
” Aṣofin Ọbasa fi eyi kun ọrọ rẹ.
Nítorí ó wá láti òpin ilẹ̀ ayé láti gbọ́ ọ̀rọ̀ ọgbọ́n Solomoni, Ẹ wò ó!
Goolu meji pere lo jẹ ninu ifẹsẹwọnsẹ mẹtadinlọgbọn ni saa to kọja botile j wi pe o ṣe daada forileede Chile ninu idije Copa Amerika to ti jẹ goolu meji.
Nítorí pé, ọdún jubili ni yóo máa jẹ́ fun yín, yóo jẹ́ ọdún mímọ́ fun yín, ninu oko ni ẹ óo ti máa jẹ ohun tí ó bá so.
Ẹ̀yin baálé ilé, ẹ yé sá tẹ̀lé mi kiri mọ́!
Ewe, iroyin fi mule pe oloogbe naa jade laye nile iwosan ti o ti n gba itoju niluu London, lojo Aiku(Sunday), ti n se ojo kokanlelogun, osu kewa odun ti a wayii, ki won to gbe wa siluu Abuja, ti n se olu ilu orile-ede Naijiria, lojoRU(Wednesday).
 Ìtọjú fún ẹ ̀ tẹ ̀ multibacillary ni rifampicin , dapsone , àti clofazimine fún osù méjìlá .
Iyawo aarẹ lorileede Naijiria, Aisha Buhari ki i ṣe ẹni to n bẹru lati sọ ohun to wa lọkan rẹ.
O ṣeṣe ki wọn dajọ ẹwọn ọgbọn ọdun fun ti wọn ba gbẹjọ rẹ l'Amẹrika.
Igba ti a kọkọ pade, a pade nile ounjẹ igbalode kan.
O sọ pe awọn alakoso nigba naa ki ṣe alayaba.
Aigbọ ede ti wọn n sọ ni abule yii ko tẹ Roshan lọrun lẹnu iṣẹ rẹ ko to pade Gauri to n tumọ ede wọn fun un lẹnu iṣẹ.
Mose ati Aaroni bá lọ sọ́dọ̀ Farao, wọ́n sì ṣe gẹ́gẹ́ bí àṣẹ tí OLUWA pa fún wọn.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Sex for grade: Òkìkí olùkọ́ fásitì OAU míràn tún ti kàn lóríi pé ó fẹ́ bá akẹ́kọ̀ọ́ rẹ̀ lò pọ̀ fún máàkì 18 Sẹ́rẹ́ 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 19 Sẹ́rẹ́ 2020 Oríṣun àwòrán, @OAUniversity Àkọlé àwòrán, Òkìkí olùkọ́ fásitì OAU míràn tún ti kàn lóríi pé ó fẹ́ bá akẹ́kọ̀ọ́ rẹ̀ lò pọ̀ fún máàkì Ariwo kinla!
Aawọ naa ko jẹ kawọn musulumi lati Mecca ati Medina le ṣiṣẹ Hajj fun ọdun mẹjọ to fi di 991, A.
OLUWA sọ fun Joṣua pé, “Na ọ̀kọ̀ tí ó wà ní ọwọ́ rẹ sí ọ̀kánkán Ai, nítorí n óo fi lé ọ lọ́wọ́.
Ilu naa ni a mọ si orilẹ ede ti o mọ nipa iṣẹ ọwọ bii apẹrẹ hihun,ṣiṣe ere ati amọ mimọ.
Tun wẹ, ọpọ awọn gomina oloselu ati ti ologun to ti jẹ nipinlẹ Ọyọ lo mọ ipa ribi ribi ti Alaafin ko lati jẹ ki isejọba wọn se aseyọri.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fọ́nrán ohùn, Oluwo ti Iwo Ọba AbdulRasheed Akanbi kí Aláàfin Ọyọ kú ọjọ́ ìbí Ẹ̀wẹ̀, Iba àṣà wá fi kun un pé àwọn ǹkan to n ṣẹlẹ̀ láye òde òni ń ṣẹlẹ̀ nitori pé àwọn ènìyàn kò tèlé ìṣẹ̀ṣe Yoruba mọ, gbogbo ètùtu ti o yẹ ko wáye saaju ìgbéyawo ko wáye mọ, èyio sì ló mu kí olúkúlukù máa ṣ ǹkan to wù wọ́n.
Ó sì mú mi la odò kan tí ó mù mí dé kókósẹ̀ kọjá.
”Mikaya dáhùn pé, “Ẹ lọ gbógun tì í, OLUWA yóo fi wọ́n lé yín lọ́wọ́, ẹ óo sì ṣẹgun.
Ẹ lọ sinu iná àjóòkú tí a ti pèsè sílẹ̀ fún èṣù ati àwọn angẹli rẹ̀.
Nígbà tí ilẹ̀ yóo fi mọ́, gbogbo wọn ti kọjá tán.
gbogbo àwọn tí à ń fi orúkọ mi pè,àwọn tí mo dá fún ògo mi,àwọn tí mo fi ọwọ́ mi ṣẹ̀dá wọn.
Osun poly: Ọ̀pọ̀ òògùn, àti ohun eèlò ni àwọn akẹ́kọ̀ọ́ tó ṣèwọ́de náà dá iná sun
Oríṣun àwòrán, sunday_igboho Àkọlé àwòrán, Ọrọ lori awọn ajinigbe nilẹ Yoruba Agba awo naa ṣalaye pe, ijọba le maa faramọ kawọn ipinlẹ lo ọna ibilẹ lati jagun awọn ajinigbe nitori ko si ninu iwe ofin orilẹede Naijiria, ṣugbọn alatiṣe ni yoo mọ atunṣe ara rẹ.
iwaju fun iko DR Congo, to n sojoyo ayeye odun marundinlogbon lo gba ami ayo
Bi Iyalufa ti ri ohun ti Ọmọyẹ se yii, lo ranti eewọ ijọsi ti oun ka fun Ọmọyẹ, ipa to lee ni ati ọna abayọ, ni oun naa ba sare mu iro ti Ọmọyẹ bọ silẹ, to si n sare lee lọ si aarin ọja, toun tọmọ lọwọ.
Mi ò fẹ́ tẹ́tí sí àhesọ kankan.
Agbébọ́n tún ṣoro ní márosẹ̀ Ibadan sí Eko, wọ́n jí èèyàn mẹ́ta gbé Wo ohun tó yẹ kí o mọ̀ nípa àwọn obìnrin méje ti Buhari forúkọ wọn ránṣẹ Kò sí ìwé ìrìnnà 'VISA' fáwọn ọmọ Naijiria tó hùwà àìtọ́ nígbà ìdìbò Àlàyé rèé nípa bí èrùpẹ̀ ṣe wó pa òṣìṣẹ́ akóyọyọ méjì n‘Ibadan Ṣugbọn bawo ni wọn ṣe ń ra iru, ewedu, ẹfọ Gure, Tẹtẹ ṣe ń rọrùn fun wọn bi wọn ṣe sọ?
Àkọsílẹ̀ yìí sọ bí ó ti ṣe ìjọba rẹ̀, bí agbára rẹ̀ ti tó; ati gbogbo nǹkan tí ó ṣẹlẹ̀ sí i, ati èyí tí ó ṣẹlẹ̀ sí àwọn ọmọ Israẹli ati sí gbogbo àwọn orílẹ̀-èdè tí wọ́n wà ní àyíká wọn.
Manoa tún bèèrè pé, “Nígbà tí ọ̀rọ̀ rẹ bá ṣẹ, báwo ni ìgbé ayé ọmọ náà yóo rí?
Bakanna ni ile tun ke si ijọba apapọ orilẹede Naijiria lati tubọ ba orilẹede Niger ati Chad sọrọ lọna ati di gbogbo aaye ti awọn janduku agbebọn naa n sa pamọ si.
Shilekunola Naomi bọ̀wọ̀ fún àṣà ilẹ̀ Yorùbá kó tó wọlé tọ Ọọni Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Olorí tuntun bọ̀wọ̀ fún àṣà ilẹ̀ Yorùbá Ọọni ti Ile -Ife, Ọba Adeyẹye Ogunwusi, Ọjaja Keji ti kede arẹwa ọmọbinrin kan, Shilekunola Moronke Naomi gẹgẹbi olori laafin ni ọjọ kejidinlogun, oṣu Kẹwaa, ọdun 2018.
Ṣugbọn Tomasi, ọ̀kan ninu àwọn ọmọ-ẹ̀yìn mejila tí wọn ń pè ní Didimu (èyí ni “Ìbejì”) kò sí láàrin àwọn ẹlẹgbẹ́ rẹ̀ nígbà tí Jesu farahàn wọ́n.
Osisẹ ọlọpaa yii si lo wa lara awọn ọlọpaa to wa lẹnu isẹ lasiko naa tawọn agbebọn ọhun ba wọn ni alejo.
Àṣà òkè-òkun fi fẹ́ iyàwó  kan àti ẹ̀sìn òkèère ti Yorùbá gbà ló sọ àdìrò di ipò fún obinrin àti “Alá-bọ́dó, Ìyàwóilé tàbi Oníṣẹ́-ilé” ti ó di iṣẹ́ obinrin.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Xenophobia: Àwọn agbófinró dúró sẹ́nu ọ̀nà àbáwọlé Palm Mall Ibadan láti dẹ́kun ìkọlù 4 Owewe 2019 Ọrọ ikọlu ti awọn ọmọ Naijiria n se sawọn ileesẹ to jẹ tilẹ South Africa lati fi gbẹsan bi wọn se n kọlu awọn ọmọ Naijiria lorilẹede tiwọn naa, ti wa di ọrọ egbinrin ọtẹ, ba ti n pakan ni omiran n ru.
Bí ẹlẹ́ṣẹ̀ tilẹ̀ ṣe ibi ní ọpọlọpọ ìgbà tí ọjọ́ rẹ̀ sì gùn, sibẹsibẹ mo mọ̀ pé yóo dára fún àwọn tí ó bẹ̀rù Ọlọrun.
Ẹ ma ṣe yan awọn ti yoo fa ọwọ Ijẹbu sẹyin.
Ó di owó náà sinu àpò meji pẹlu aṣọ meji.
Orile ede GuineaAare orile ede Guinea ,Alpha
Asiko yii ni ìrántí ọdún márùn-dínlọ́gbọ́n ti ìpànìyàn ẹlẹ́yàmẹ̀yà wáyé lórílẹ̀-èdè náà.
Alaga igbimọ ile lori eto iroyin, aṣofin Fatai olotu ṣalaye fun awọn oniroyin lẹyin ijoko ile pe ẹsun ṣise owo baṣubaṣu, aikun oju iwsn lẹnu iṣẹ ati ẹsun miran ni wọn tun fi kan Bamidele Oloyelogun ati igbakeji rẹ, Iroju Ogundeji ki wọn to yọọ.
Àwọn ọmọ-ogun bá mú un lọ sí inú agbo-ilé tí ààfin gomina wà.
Lẹ́yìn náà yóo mú àwọn ewúrẹ́ mejeeji, yóo fà wọ́n kalẹ̀ níwájú OLUWA, ní ẹnu ọ̀nà Àgọ́ Àjọ.
A ṣe agbeyẹwo diẹ lara awọn iwasan ti awọn eniyan ti n polongo kiri, ati nkan ti imọ sayẹnsi sọ nipa wọn.
N óo máa mójú tó o, n óo sì máa dáàbò bò ó nígbà gbogbo.
Kíni iyatọ tó wà láàrin FSARS àti SARS?
Angẹli Ọlọrun bá sọ fún mi ní ojú àlá náà, ó ní, ‘Jakọbu.
Àjọ tó n ṣe ìdánwò àṣewọlé sí àwọn iléèwé gíga ní Nàìjíríà nàá kò ṣe tó.
Akọ̀ròyìn méjì, ọkùnrin àti obìnrin kan ń gbèrò láti ṣàfihàn ìyàtọ̀ tí ó wà nínúu bí ọkùnrin àti obìnrin ṣe ń hùwà sí ìfowópamọ́.
Ẹ óo jẹ́ eniyan mi, n óo sì máa jẹ́ Ọlọrun yín.
 Ajo INEC ti wa ri i pe ko si aabo to peye fun  ẹmi awon osise ajo INEC ati ajo naa, nitori
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, FUTA: Àwọn mẹ́jọ ló ṣíná ìyà fún Bolu ní FUTA O ni ka ni alẹ ni iṣẹlẹ naa ṣẹlẹ ni, ko ba buru ju bo ti jẹ naa lọ.
Aarẹ Buhari lasiko to bu ọwọ lu owo oṣu tuntun naa l'Ọjọbọ ṣalaye nipasẹ oluranlọwọ rẹ lori ọrọ ile aṣofin apapọ, Ita Enang, pe l'oju ẹsẹ ni sisan owo oṣu tuntun naa bẹrẹ.
ologun orile ede naa ti  gba ijoba lọwọ rẹ bayii , ni eyi ti won si ti tun mu un pẹlu.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Sola Kosoko: Ẹ tẹ ọkùnrin tó bá fipá bá obìnrin lòpọ̀ ní ọ̀dá, ìwà ìkà ni 16 Òkùdu 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 17 Òkùdu 2020 Oríṣun àwòrán, Instagram/officialsholakosoko Àkọlé àwòrán, Sola Kosoko ní kò sí ẹ̀sìn tí òun kò le ṣe nítorí Kristẹni ni òun, ọkọ òun sì jẹ́ Mùsùlùmí.
Ọwọ́ ọlọ́pàá ti tẹ ọkùnrin kan tó pa ọ̀rẹ́ rẹ̀ nítorí N40 ní Kano Lẹ́yìn ìgbeyàwó ọdún mọ́kànlá àti ọ̀pọ̀ ìjà, Bọsẹ di èrò ọ̀run nílé Saidi Àwọn jàǹdùkú pa fadá ní Taraba-Iléeṣẹ́ ọlọ́pàá Dadi G.
Ileejọ Kenya wọgile ofin to ti ileesẹ tẹlifisan pa
Alaga tuntun fun ajo isokan ile Africa, Paul Kagame ti bere isakoso re pelu sise ipade lori eto oro aje ati eto idokowo, ninu eyi ti o ro awon ile-ise aladani gbogbo lati fowosowopo pelu mu igberu ba ile-Africa.
Femi Falana lori eto kan ni ile isẹ iroyin Channels Television ijọba to wa lode yii ti fihan gbangba pe wọn ko le e da abo bo awọn ọmọ Naijiria nitori ijinigbe ati ipaniyan n peleke si ni.
Akẹkọ naa ni a gbọ wi pe o jẹ akẹkọ ileewe girama GSSS Gombe.
Nígbà tí mo ro ohun tí ó dé bá mi,ẹ̀rù bà mí, mo sì wárìrì.
Àjẹsára àrùn rọpárọsẹ ̀ àkọ ́ kọ ́ ni àjẹsára àrùn rọpárọsẹ ̀ tí a fi kòkòrò tí a ti pa ṣe .
Najiria ti di orile ede to je pe ohun nikan lo n ta iresi si oke okun ati awon
Ìwọ, ọ̀rẹ́ mi, ó rántí lánàá pé ibi tí a bá ọ̀rọ̀ yìí dé ni ibi tí bàbá mi ti kọ ojú sí Igbó Olódùmarè tí ó ń lọ, òun àti ìyàwó rẹ̀ àfẹ́sọ́nà ti wọ́n bá ara wọn pàdé nínú igbó ti wọ́n si ń lo àyè kékeré ti wọ́n rí tí wọn ń gbàdún ìgbési-ayé wọn láàárin igi àti ọ̀pẹ.
Ada bí Elifasi fún Esau, Basemati bí Reueli.
Ti ikilọ si wa pe wọn yoo yọ ẹnikẹni to ba sọrọ jade l'ẹgbẹ.
Ireti wa fun Sisi pe, yoo jawe olubori fun saa keji ninu eto aare ti yoo waye  ni ojo kerindinlogbon si ojo kejidinlogbon osu keta odun ti a wa yii, amo, ibo ohun ni awon egbe kan ti bu enu ate lu, leyin ti awon ti won jo n figa-gbaga fagile ipolongo eto idibo naa, ninu eyi ti won safihan ideye sini ati bi won se fi owo sinkun mu enikan gboogi ti o le ba a figa-gbagaAbol Fotouh wa lara awon eniyan jankan-jankan lorile-ede Egypt ti won pe fun, aikopa ninu idibo naa ninu osu to koja.
Báyìí ni ọkùnrin náà sọ, ọ̀rọ̀ wọ̀nyí sì wọ inú ọkàn mi lọ, nígbà ti èmi náà máa fún un ní èwsì, mo mí kanlẹ̀, mo húkọ́ ‘kẹ̀hẹ̀’, kí ó ma baà sí ohun ìdíwọ́ ni ọ̀nà ọ̀fun mi.
N óo da ibi tí wọ́n ṣe lé wọn lórí.
Ẹ ṣèwádìí ikú Ọ̀jọ̀gbọ́n Gideon Okedayọ - ASUU, Ọmọdé 27 jóna ráuráu mọ́'le níléèwè Liberia.
"Ṣé Amotekun ti di ""HisbahTekun"" ní ìpínlẹ̀ Osun ní?"
Okah ati Nwabueze gba idajọ ẹwọn gbere Lush beauties: Ara sisan kii n ṣe arun Pupọ ninu awọn aṣofin agba to da si ọrọ naa ni gbagede ile ni wọn yanana rẹ wi pe iwa awọn ileeṣẹ ati lajọlajọ ti ọrọ kan ko lorukọ meji ju iwa ọdaran eleyi ti iwe ofin si la ijiya to tọ kalẹ fun.
Awon iko olote marun un lo padanu  ẹmi won, nibi ikolu to  fe waye lati gbemi awon eniyan ni  ipinle Maiduguri.
Ọmọ ẹgbẹ APC faramọ iwoye Obasanjo
Mo dupe lọwọ  ọkẹ aimọye ọmọ orilẹ ede Naijiria fun ifẹ ti won fihan lati tun yan mi  gege bi aare ti yoo maa tukọ orile ede yii fun igba mẹrin miiran.
Itumọ orukọ ile ijọsin naa ni ede oyinbo ni: Our Lady.
Ohun to mu ki eto idibo naa o ṣe e tọka si ni pe, igba akọkọ niyii lati aadọta ọdun sẹyin ti awọn ọmọ orilẹede naa yoo l'anfaani lati dibo yan ẹni to wu wọn, dipo bi awọn aṣoju ṣe maa n ba wọn dibo tẹlẹ.
“Ẹ tẹ́tí sí mi, ẹ̀yin ará ilé Jakọbu,ati gbogbo ará ilé Israẹli tí ó ṣẹ́kù;ẹ̀yin tí mo pọ̀n láti ọjọ́ tí wọ́n ti bi yín,tí mo sì gbé láti inú oyún.
Ati pé, mo pàṣẹ ohun tí ẹ gbọdọ̀ ṣe láti ran àwọn àgbààgbà Juu lọ́wọ́ láti kọ́ ilé Ọlọrun náà pé: Ninu àpò ìṣúra ọba ati lára owó bodè ni kí ẹ ti mú, kí ẹ fi san gbogbo owó àwọn òṣìṣẹ́ ní àsanpé, kí iṣẹ́ lè máa lọ láìsí ìdádúró.
Onílara kì í fẹ́ kí ẹlòmíràn lọ síwájú àfi òun; onílara kì í fẹ́ kí ẹlòmíràn mọ ìwé àfi òun; onílara kì í fẹ́ kí ẹlòmíràn dé ipò ńlá àfi òun; onílara kì í fẹ́ kí ẹlòmíràn kọ́ ilé àfi òun; onílara kì í fẹ́ kí ẹlòmíràn ní ọmọ tí ó níláárí àfi òun – bẹ́ẹ̀ ni ayé kún fún ọ̀pọ̀lọpọ̀ ènìyàn a kò si lè ṣe aláìrì àwọn tí yóó maa lọ síwájú lọ́nà wọ̀nyí bẹ́ẹ̀ ni bíi wọ́n bá ti ń lọ síwájú ni inú onílara yóó máa bàjẹ́, nítorí náà inú onílara kò lè dùn láé, bí ayé yípadà tí ó di ọ̀run.
Lootọ awọn eeyan kan daaro pe boya ki iya rẹ o gba ipo yii, ṣugbọn lẹyin ọpọlọpọ ijiroro ni wọn ni ki Ọbalọla, iyẹn ọmọọba Charles to jẹ baba ọkọ iyawo o mu iyawo wọ ileejọsin lati faa le awọn alufaa lọwọ.
Yẹ̀yẹ́ tí wọ́n ń fi Dáúdà ṣe yìí dùn ún púpọ̀.
Àwọn eniyan ń gbé àwọn ọmọ-ọwọ́ wá, pé kí ó lè fi ọwọ́ kàn wọ́n.
N óo mú Nebukadinesari, ọba ńlá Babiloni wá, láti ìhà àríwá, yóo wá gbógun ti Tire.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: 'Buns ni ọmọ mi jẹ tán ní ṣọ́ọ̀ṣì, ló bá di àwátì' Ẹ wo ìpínlẹ̀ táwọn gómìnà tẹ́lẹ̀ àti igbákejì wọn ń gba dúkìá ìfẹ̀yìntì tabua Mẹ̀kúnnù 80,000 l'Ọṣun ti j'ànfàaní ètò ìlera láìsan kọ́bọ̀ - Oyetola Iná mọ̀nàmọ́ná lọ fún wákàtí 24 ní Ghana, lariwo bá sọ!
Àt’orógbó àt’obì o, wọn ò ṣé rà lọ́jà mọ́n, ńṣe ni wọ́n gbówó lérí tete.
Bio ti le je pe, won ti yo oruko re kuro ninu awon ti yoo dari ifesewonse tele-tele lataari aise daradara re ninu idije agbaye ti o waye lọdun 2014 lorile-ede Brazil.
Lẹ́yìn tí ẹ bá ti kórè tán, ẹ kò gbọdọ̀ pada lọ tún kórè àwọn èso tí ẹ bá gbàgbé.
Nigeria 2019 Elections: Àwọn aráàlú kan ní ìṣúnsíwájú ìbò ṣàkóbá fún ọrọ̀ ajé
"Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ni ipade AU Buhari ati Obasanjo d'ọrẹ apapandodo Ileesẹ aarẹ Naijiria fesi lori lẹta Ọbasanjọ Obasanjọ sabẹ̀wò sí Akurẹ́ lórí ìbo 2019 ‘Buhari kò bú àwọn ọdọ’ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, ""Ẹ jẹ́ kí Buhari lọ jókòó"" Ààrẹ Muhammadu Buhari kò dárúkọ Ààrẹ kankan, sùgbọn ní báyìí àwọn olólùfẹ́ Ààrẹ Buhari àti Ààrẹ Ọbasanjọ tí bẹ̀rẹ̀ sí ní tahùn sí ara wọn bayii."
Mohamed Loukal , ti o tun je adari 
Bakan naa ni wọn lo ni ibasepọ to dan mọran pẹlu awọn to n huwa ibajẹ lawujọ, paapaa julọ awon ti wọn si n kowo ilu pamọ lọna aitọ.
Bakan naa lo tun fa akoso fun ijọba alagbada lẹyin to seto idibo apapọ lorilẹede Mali lọdun 1992.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Oluwo: Mo lè jẹ Ọba ní Ile Ife Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Oyin sínsìn lérè lórí ṣùgbọ́n ó tún gbé ikú karí' Atiku gbadura pe ki Ọba oke ko dẹlẹ fun ẹni 're to lọ.
Awọn eniyan Egypt ni ko mu awọn ileri rẹ ṣe lọdun kan to fi ṣe ijọba ki awọn ologun to gba ijọba lọwọ rẹ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Blind DJ: Etu Omotayo kò ríran àmọ́ ó le to irinṣẹ́ eléré pọ̀ láti kọrin láì sí ìrànwọ́ 'Àwa ọmọ Nàìjíríà tó farapa fẹ́ wálé láti Lebanon, ìjọba kó wa pamọ́' Ọlọ́pàá gbọ́dọ̀ wá àwọn tó gbàbọ̀dè láàrín wọn nítorí ẹ̀mí wa ò dè ní Akinyele Àwọn nkan tó yẹ kí o mọ̀ nípa ṣíṣe ìṣirò àsìkò tí o bá n yé ẹyin Èèkàn ẹgbẹ́ òṣèlú APC mií Lanre Razak jáde láyé lẹ́yìn àìsàn ráńpẹ́ Ilé ẹjọ́ ní kí ''Yahoo boy'' lọ darí ọkọ̀ f'óṣù mẹ́ta pẹ̀lú N50,000 owó ìtanràn Oríṣun àwòrán, EPA Ẹ wo ìkìlọ̀ tí ìjọba America fi léde lórí ìdìbò gómínà Ondo, Edo Ẹ wo ìkìlọ̀ tí ìjọba America fi léde lórí ìdìbò gómínà ní Ondo àti Edo Ijọba orilẹede Amerika ti fi aidunnu rẹ han lori bi awọn oṣiṣẹ eleto aabo ṣe n dasi eto oṣelu ni Naijiria, saaju idibo sipo gomina ti yoo waye ni ipinlẹ Ondo ati Edo.
‘A lù fun yín, ẹ kò jó, a pe òkú, ẹ kò ṣọ̀fọ̀.
Imira wa fun awon eniyan lati riran ti eefin naa si gbalẹ ka to mu oju ọjọ ṣu biribiri.
Ilu gangan: O jẹ́ atọ́nà fún Alaafin àti àwọn ara ilu- Rahman Wahab
Lẹ́yìn èyí, nígbà tí Jesu mọ̀ pé ohun gbogbo ti parí, kí Ìwé Mímọ́ lè ṣẹ, ó ní, “Òùngbẹ ń gbẹ mí.
Nígbà tí ó dúró láàrin wọn, kò sí ẹni tí ó ga ju èjìká rẹ̀ lọ ninu wọn.
Bí ó bá so èso ní ọdún tí ń bọ̀, ó dára.
Nisinsinyii, ó ń gbéààrin àwọn orílẹ̀-èdè mìíràn,kò sì ní ibi ìsinmi.
Ọ̀gbẹ́ni ààrẹ, àkósoò rẹ ti ṣe àmúlò òfin ìyàsọ́tọ̀ àti ìyọkúrò ẹ̀yà.
Oríṣun àwòrán, Other Bi a ko ba gbagbe, laipẹ yi ni MMM, ti apeja rẹ n jẹ Mavrodi Mundial Moneybox tun wọlu pada ni Naijiria.
N óo máa jẹ́ Ọlọrun wọn, wọn yóo sì máa jẹ́ eniyan mi.
O ni lootọ ni pe ohun ti ijọba Fayose naa ṣe nigba ti o de ori alefa ni pe o yọ awọn ti Fayemi gba siṣẹ ṣugbọn ki wọn jijọ ma taka ẹni to le yọ oṣiṣẹ ko dara to.
Ipa ẹlẹyamẹya ninu idibo Kogi Oṣelu ipinlẹ Kogi lati igba iwasẹ jẹ eleyi ti ẹya ma n ko ipa ribiribi ninu rẹ.
Yoruba ni Bọmọ ko ba ba itan, o maa n ba arọba to jẹ baba itan, Bode George ni asiko ti to ki a ma kọ awọn nipa ohun to ti ṣẹlẹ sẹyin ni June 12 ati May 29.
Nigba to n ṣuju Makinde nibi ipade ita gbangba kan pẹlu awọn olugbe Akinyele, olubadamọran Pataki lori eto abo, Fatai Owoseni sọ pe, ki awọn ọlọpaa sa gbogbo ipa wọn lati tun ọdanran naa mu.
Ẹbí Tolulope Arotilẹ ń bèrè fún iwadii lórí ìkú tó pa á!
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Tunde Kelani k'ẹdun iku Akinwunmi Ishola Oun ni aarẹ alagbada akọkọ ati aarẹ kan ṣoṣo to jẹ lasiko eto oṣelu awaarawa keji (1979-1983).
Àsìlò oògùn Codeine: Ọwọ́ ba òsìṣẹ́ Emzor 'Ọdún 35 ni ọmọbìnrin gbọdọ̀ ti bímọ tán' Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Shomolu gbajúmọ̀ fún ìwé títẹ̀ Ẹka ileeṣẹ ọlọpa ipinlẹ Eko to n gbogun ti iwa ọdaran, Rapid Response Squad, RRS, sọ loju opo Twitter rẹ pe ọwọ tẹ eniyan mọkanlelogun lori iṣẹlẹ naa, ti iṣẹ iwadii si n tẹsiwaju.
Èmi àti Kolington kò fẹ́ra padà o, ọba Wákà kò fẹ́ ọba Fuji mọ́ - Salawa Abeni Èmi sì ní Oluwo tilẹ̀ Iwo, kò sí ìgbìmọ̀ ọba kankan tó lè ní kí ń rọ́ọ́kún nílé - Oluwo Toyin Abraham ọkọ rẹ̀ àti Ire ní London, Odunlade 'kòlábò' pẹ̀lú Mercy Aigbe Èlé owó iná ọba kọ́ ló kàn, ẹ kọ́ ṣàtúnṣe sí ìlànà àdánú tẹ́ ń ṣe fún wa - Iléeṣẹ́ apínná sọ fún ìjọba O ni lẹyin ti wọn n gbe lọ ni ọkọ wọn taku loju ọna, ṣugbọn nigba ti ologbe naa gbiyanju ati sọda loju popo, ni ọkọ miran kọlu.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Operation Amotekun: Àwọn ajínigbé ṣá mi láàkéé nínú igbó, ìdásílẹ̀ Amotekun dára 15 Sẹ́rẹ́ 2020 Oríṣun àwòrán, Other Oludije fun ipo aarẹ labẹ asia ẹgbẹ oṣelu AD tẹlẹ ri, Oloye Olu Falae naa ti da si ọrọ ẹṣọ ilẹ Yoruba, ''Amọtẹkun tawọn gomina apa iwọ oorun Naijiria ṣẹṣẹ ṣe ifilọlẹ rẹ.
Yóo sọ pé, “Dájúdájú Ọlọrun wà láàrin yín.
Nítorí náà, wá kí á jọ jíròrò nípa ọ̀rọ̀ náà.
"O ni ""A o jẹ ki gbogbo ara ilu mọ ohun ti a ba babọ lẹyin iwaddi wa."
Ará, mo fi ìgbéraga tí mo ní ninu yín búra, àní èyí tí mo ní ninu Kristi Jesu Oluwa wa.
Awọn apẹẹrẹ ẹpa ni ''Tiger Nuts'' ti awọn kan n pe ni ofio tabi imumu, agbọn, asala ati bẹẹ bẹẹ lọ.
naa ni:“IGBIMO TI YOO MAA FUN AARE
Ẹ wo ojú àwọn afurasí tí yóò rojọ́ ẹ̀ṣùn àjẹbánu lọ́dún 2021 Oríṣun àwòrán, Twitter Ileẹjọ giga julọ lorilẹede Naijiria da awọn ẹjọ to niiṣe pẹlu iwa ibajẹ awọn oloṣelu kan nu ni ọdun 2020.
Ẹwẹ o ni bi wọ́n ba kọ ti wọn o ba gbọ, wọn yoo mu awọn lọranyan lati fi ọna ofin kọ aṣẹ wọn o.
Hushpuppi: APC ní kìí ṣe ojú lásán ni afurasí gbájúẹ̀ náà fi sún mọ́ olóṣèlú Yoruba ni fi ọrẹ rẹ han mi, ki n le sọ iru eeyan to jẹ nitori agutan to ba n ba aja rin, yoo jẹ igbẹ.
Oríṣun àwòrán, @Issa Aremu BBC Yoruba wa n kesi awọn eeyan ipinlẹ Kwara to ba nifẹ lati peju sibi ipade ita gbangba naa pe, ki wọn lọ fi orukọ wọn silẹ lori ikanni isalẹ yii.
Buhari yoo tun sejọba lẹẹkan síi.
nítorí pé àsọtẹ́lẹ̀ èké ni wọ́n ń sọ fun yín ní orúkọ mi, n kò rán wọn níṣẹ́.
Igbesẹ yii ti jẹ ki ọpọlọpọ maa ro pe Serena tun lee ma kopa ninu idije French Open ti yoo bẹrẹ lọjọ kẹtadinlọgbọn osu yii.
“Ìwọ ọmọ eniyan, dojú kọ òkè Seiri, kí o sì fi àsọtẹ́lẹ̀ bá a wí.
    Ẹ ó rí àkàṣù ẹ̀kọ mẹ́fà tí mo fi ránṣẹ́ sí yìn, mo sì fi mọ́ìnmọ́ín mẹ́fà tí ẹ o fi jẹ wọn sii.
14 Àti pé apá Olúwa yíò di fífihàn, ọjọ́ náà sì dé tán tí àwọn ẹnití kì yíò gbọ́ ohùn Olúwa, bẹ́ẹ̀ni ohùn àwọn ìránṣẹ́ rẹ̀, bẹ́ẹ̀ni ní ṣíṣe àkíyèsí sí àwọn ọ̀rọ̀ àwọn wòlíì àti àwọn àpóstélì, yíò di kíké kúrò láàrin àwọn ènìyàn;
ó ṣètò yàrá ńlá kan fún Tobaya níbi tí wọ́n ń tọ́jú ọrẹ ẹbọ ohun jíjẹ sí, ati turari, àwọn ohun èlò ìrúbọ, pẹlu ìdámẹ́wàá ọkà, ati waini ati òróró tí wọ́n fún àwọn ọmọ Lefi, ati àwọn akọrin, ati àwọn olùṣọ́ ẹnu ọ̀nà, pẹlu àwọn ohun tí wọ́n dá jọ fún àwọn alufaa gẹ́gẹ́ bí òfin.
Oríṣun àwòrán, Rufus Giwa Polytechnic Àkọlé àwòrán, Lẹta Iwe naa ti Sule Atiku to jẹ adele Giwa ile iwe naa fọwọ si ṣalaye pe igbesẹ naa ṣe pataki lati yanju ọrọ to ni ṣe pẹlu riru ofin.
Ǹjẹ́ kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ igbó a máa kétí ó bá rí koríko jẹ?
Bẹ́l ni àwọn orin náà ti bàbá mi ń kọ tàánútàánú ni ọjọ́ tí òun àti ẹbọra kékeré inú ọ̀gán fi ojú rí ara wọn.
Ọpọ awọn ọmọ orilẹede Naijiria ni wọn ti n fi ẹhonu han lori ohun to n ṣẹlẹ yii paapaa ọgọrọ awọn eeyan to n ku iku ọwọọwọ nipinlẹ Kano.
Nibayii, awọn ọlọpaa ti wa ninu ọgba ileewe naa lati ṣewadii lori iṣẹlẹ shun ati lati dena wahala to ba tun le fẹ ẹ bẹrẹ.
Ninu iwe naa ẹyi to fi ṣọwọ si Aare Buhari, igbakeji Aarẹ Yemi Osinbajo, Aarẹ ile asofin agba, Bukola Saraki ati abẹnugan ile aṣofin, Yakubu Dogara, Tinubu ni o kan oun lomi nu bi alaga Odigie Oyegun ti ṣe'n ṣe adina gbooku iṣẹ ti Aarẹ Buhari gbe fun oun.
(Àwọn ni ọmọ tí Silipa bí fún Jakọbu.
Ìgbà tí ọ̀gà dé lálẹ́ ọjọ́ náà, àwọn ọmọ rẹ̀ wí fún un pé àggbẹ̀ ti rán ọmọ rẹ̀ lọ sí ilé kí ó wí fún àwọn ọ̀rẹ́ rẹ̀ kí wọ́n bà wá ba a ya àgbàdo nítorí ọwọ́ òun dí púpọ̀ òun kò rí ààyè ṣiṣẹ́ náà fún ara òun.
"Oríṣun àwòrán, nkechiblessingsunday O ni ""lẹyin ti mo wo inu digi daadaa lonii, mo ṣakiyesi pe ibadi mi ti n lọ silẹ."
Arsenal gbẹ̀yìn gbé ru Aston villa Ilẹ̀ Afrika lọ́sẹ̀ yìí nínú àwòrán!
asofin ipinlẹ naa , ohun ti o ku bayii ni ki a maa pin awon ohun elo ati irinsẹ
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Wo àwọn ìbejì tó lẹ́ pọ̀ lẹ́yìn àṣeyọrí ìṣẹ́ abẹ dókìtà 70 Fídíò bí ìgbẹ́jọ́ Pásítọ̀ ìjọ Sotitobire ṣe lọ níléẹjọ́ Májísíréètì lónìí rèé Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Fídíò bí ìgbẹ́jọ́ Pásítọ̀ ìjọ Sotitobire ṣe lọ níléẹjọ́ Májísíréètì lónìí rèé Ile ẹjọ majisireeti to wa ni Oke Eda ni ilu akure, ipinlẹ Ondo ti sun igbẹjọ Pasitọ Alfa Babatunde ti ijọ Sotitobire ilu Akure siwaju di ọjọ karun un oṣu keji ọdun 2020.
Ẹ̀yin ẹrú, ẹ máa gbọ́ràn sí àwọn olówó yín lẹ́nu ninu ohun gbogbo.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Àwọn òṣèré tíátà Yorùbá ọkùnrin táyé ni wọ́n rẹwà 'Òkú bí àádọ́ta ni iná jó gúrú-gúrú ní mọ́ṣúárì l'Anambra' Olamide ati Lil Kesh dá wàhálà sílẹ pẹ̀lú 'Logo Benz' Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Alapinni Oosa ṣàdúrà fún gogbo ọmọ kúoótù, oò jíire bí?
Dafidi ṣẹgun àwọn ará Moabu, wọ́n di iranṣẹ rẹ̀, wọ́n sì ń san ìṣákọ́lẹ̀ fún un.
Èyí ló mú kí wọ́n wojú ara wọn.
A óo sì máa mú ìdámẹ́wàá èso ilẹ̀ wa lọ fún àwọn ọmọ Lefi, nítorí pé àwọn ọmọ Lefi ni wọ́n máa ń gba ìdámẹ́wàá káàkiri gbogbo ilẹ̀ wa.
Al Shabab ṣe ìkọlù sí ibùdó ogun America ní Kenya, ẹ̀mí mẹ́ta lọ síi Ọlọ́pàá hú òkú akẹ́kọ̀ọ́ fásítì LASU tí ọ̀rẹ́kùnrin rẹ̀ àti pásítọ̀ ṣekúpa Èèyàn méjì gbẹ́mìí mì nínú ìjàmbá ọ̀kọ̀ tó ṣẹlẹ̀ lórí afárá Otedola Ọ̀sẹ̀ àkọ́kọ́ ọdún 2020: Àwọn ìròyìn tó mí ìgboro tìtì Loju opo ikansiraẹni Twitter lọga ọlọpaa ti fi ọrọ naa lede.
Erongba BBC Yoruba ni ki ede, aṣa ati igbagbọ iran Yoruba ma parun ni a ṣe jade lọ beere nipa awọn Aina ki a tun fi rán ara wa leti iru ọmọ to n jẹ Aina.
Atẹjade to waye loju opo twitter rẹ leyi ti wọn fi tufọ rẹ ti di ọrọ ori twitter ti awọn eeyan fi ifẹ han si julọ lagbaye ninu itan idasilẹ oju opo ayelujara Twitter.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Muhammadu Buhari: APC ẹ ṣọ́ra, ẹgbẹ́ kò gbọdọ̀ túká lẹ́yìn ìsàkóso mi 22 Bélú 2019 Oríṣun àwòrán, Instagram/Prof Yemi Osinbajo Ko si ohun to jọọ rara!
Kanga miran ta tun foju ri ni kanga to maa n ko ọpọlọ ẹru lọ, ki wọn to tẹkọ leti lọ soke okun.
Gbogbo àwọn ọmọ Dafidi yòókù bá gun kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ wọn, wọ́n sì sá lọ.
Kí ẹ ka àwọn ọkunrin wọn, láti ẹni ọgbọ̀n ọdún títí dé aadọta, àwọn tí wọ́n lè ṣiṣẹ́ ninu Àgọ́ Àjọ.
Èyí ni iṣẹ́ abàmì keji tí Jesu ṣe nígbà tí ó kúrò ní Judia, tí ó wá sí Galili.
ti figba kan je olugbani-nimoran pataki si ijoba ipinle Eko, bee si ni o tun jẹ
com Àkọlé àwòrán, Àwọn ọlọpàá sọ wípé ọmọ̀ ọ̀dọ̀ Sunday Adefonou Anani ti jẹ́wọ́ pé òun ló pa ọ̀ga rẹ̀, Ọpẹ Bademọsi, tó wà nínú àwọran yìí Ọmọkùnrin tó pa ọmọ igbákejì Gómìnà Ondo gba ìdàjọ́ ikú 'Óṣeéṣe kí ọ̀rẹ́kùnrin Khadijat fẹ́ fi ṣowó' Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ọlọ́pàá Ondo: A bá òkú ọmọ igbákeji gómínà tẹ́lẹ̀rí nílé ọ̀rẹ́kùnrin rẹ̀ Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
O ti to aadọta ọdun ti wọn ti da ileeṣẹ ọlọpa ipinlẹ.
ó rán ọpọlọpọ àwọn ọmọ ogun ati ẹṣin ati kẹ̀kẹ́-ogun lọ sibẹ.
Ninu ikede to fi sita lori ayelujara Twitter, Brenda sọ pe sọọbu naa tobi pupọ, ati pe o wa fun awọn obinrin to ba fẹ ẹ ṣe irun wọn ni ọsọ tàbí ra wiigi ti wọn fi 'irun eniyan' ṣe.
Emir Kano: Ganduje fẹ̀sùn ìkọ́wójẹ kan Emir Sanusi
"Ọkùnrin tó pa ìyàwó rẹ̀ tí gba ìdájọ́ ikú Ṣáájú ìdìbò Sátidé nípínlẹ̀ Ọyọ, ọwọ́ ọlọ́pàá tẹ àwọn afurasí pẹ̀lú ìbọn ""Àwa Mọ́gàjí ilẹ̀ Ibadan kò dásí ọ̀rọ̀ òṣèlú"" Adelabu yóò sọ ìpínlẹ̀ Oyo jí tó bá di gómìnà - Akala Àwọn olóṣèlú kan fẹ́ da ìbò gómìnà rú - Burutai Ile iwosan nla UCH ni ilu Ibadan lo ku si ni ọjọ kẹsan oṣu kẹta ọdun 2019, lẹyin ti o fara gba ọta ibọn ni agbegbe Lalupọn lasiko idibo sipo gomina to waye nibẹ."
Mu pàrágá wakọ̀ l'Oyo, kóo kó sí gbaga ìjọba Oríṣun àwòrán, EPA Lọdọọdun ẹgbẹgbẹrun awọn eeyan ni o maa n padanu ẹmi wọn nitori pe wọn n mu awọn ayederu ọti wọnyii.
Oríṣun àwòrán, Others Àkọlé àwòrán, Akojọpọ esi ayẹwo aarun Covid-19 ni orilẹ-ede Naijiria gẹgẹ bi ajọ NCDC ṣe n kede rẹ.
Kí ló dé tí o káwọ́ gbera?
"Tí ẹ ba ni ìgbáyawo ni òpin ọ̀sẹ̀ yìí, ẹ wá gbé àkàrà oyinbo yìí"" Tí ẹ ò bá gbàgbé àwọn ọlọpàá yabo ibi ayẹyẹ ọjọ́ ìbí Bobrisky lọ́jọ́ Satide tí ayẹyẹ ọjọ ìbí náà ko fi wáye mọ Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?"
Àwọn ọmọ Naijiria fèsì sí Osinbajo tó ṣetán láti wàákò pẹ̀lú Timi Frank Bú ààrẹ láwọn orílẹ̀èdè márùn-ún yìí kí o rugi oyin ISWAP ti ṣekú pa òṣìṣẹ́ ẹgbẹ́ aláànù Action Against Hunger Yoruba Language: Ṣé ẹ mọ ìdí tí ọmọ fi ń jẹ́ orúkọ yìí?
Ijọba orilẹede Naijiria ti bu ẹnu atẹ lu isekupani pẹlu ado oloro to waye ni mọsalasi ati ọja to wa ni Adamawa ni ila-oorun ariwa orilẹede Naijiria.
Ruben Loftus-Cheek, David Luiz ati Gonzalo Higuain lo gba goolu sawọn fun Chelsea ti wọn si jawe olubori pẹlu ami ayo mẹta sodo.
Látàrí ìbálòpọ̀ tí kò ní ààbò, ọ̀pọ̀ l'ó ti kó àrùn kògbéwékògbègbó HIV àti AIDS.
Wọ́n fòru bojú, wọ́n bá jáde ní ìlú; wọ́n gba ọ̀nà ọgbà ọba, ní ọ̀nà ibodè tí ó wà láàrin odi meji, wọ́n sì dojú kọ ọ̀nà Araba.
srīnivāsa aiyangār rāmānujam frs , daada bi srinivasa iyengar ramanujan ( ) ( 22 december 1887 - 26 april 1920 ) je ara india olusemathimatiki ati akekofunraeni to , lai gba eko alagbese kankan ninu mathimatiki ogidi , ko ipa pataki si ituwo onimathimatiki , iro nomba , awon eseese alailopin ati awon ida aromoniso .
Iléeṣẹ́ náà ti yege nínúu ìtànká àwọn ìkéde tí ó ṣe kókó nípasẹ̀ẹ iṣẹ́ Ohùn fún Àyípadà Ojú-ọjọ́.
Mo sì ṣe ìlérí pé, n o máa yẹ́ ọkọ mi sí, n ó máa gbé e gẹ̀gẹ̀, n o máa pọ́n ọn, n o máa bu ọ̀wọ̀ fún un, n o máa ṣe fáàrí hàn án, n o máa ró aṣọ mi dáadáa, n o máa wé gèlè mi dáadáa, n o sì máa tọ́jú irun orí mi dáadáa, n o máa wọ bàtà mi dáadáa, n o máa wẹ̀ dáadáa, n o maa run orín mi dáadáa, n ó máa tọ́jú èékán mi dáadáa, bẹ́ẹ̀ ni n ó máa ṣe títí ikú yóò fi yà wá.
tí ọkàn mi fà sí wọn;tí mo sì tẹ́wọ́ adura sí wọn.
Ọgagun Ibrahim Babangida lo wa lori alefa lasiko ti wọn n sọ ọ yii.
Gbogbo ohun èlò tí wọ́n kó fún ọ fún lílò ninu Tẹmpili Ọlọrun ni kí o kó lọ sí Jerusalẹmu, níwájú Ọlọrun.
Enikeni ti o ba n sọ pe Buhari n bọ leekeji, ó n tan ara re jẹ pata ni.
Ọpọ awọ oniṣẹ ọwọ ati awọn oniṣowo ibilẹ bii awọn to n ṣe epo pupa, awọn to n se ounjẹ ta ati awọn agbẹ ni wọn n bẹ ijọba lati ri si ọrọ owọngogo omi ati idagbasoke ilu naa ki igbeaye le rọrun fun wọn.
Kì í ṣe nítorí pé ó bà yín lọ́kàn jẹ́, ṣugbọn nítorí pé bíbà tí ó bà yín lọ́kàn jẹ́ ni ó jẹ́ kí ẹ ronupiwada.
"Pásítọ̀ Enoch Adeboye darapọ̀ mọ̀ #ENDSARS, ó fún ìjọba Nàìjíríà ní ìmọ̀ràn ọ̀nà àbáyọ Mọ̀ nípa iPhone 12, fóònù ológo 5G tí kìí lo ""Charger” tó ṣẹ̀ṣẹ̀ jáde Àjọ FCTA fòfin de ìwọ́de nílùú Abuja Wo àwọn ojúṣe àti èèwọ̀ fún ikọ̀ ọlọ́pàá SWAT tó gba iṣẹ́ lọ́wọ́ SARS Lara awọn gbajumọ to ti sọrọ lori iwọde naa ni: Kanye West Oríṣun àwòrán, PA Onkọrin ọmọ ilẹ America, to tun n dije fun ipo aarẹ ilẹ America, Kanye West."
Kemebradikumo Pondei Oríṣun àwòrán, NDDC Àkọlé àwòrán, Ọjọgbọ́n Kemebradikumo Pondei Oṣu Keje ọdun 2020 ni adele Ọga Agba ajọ to n mojuto idagbasoke agbegbe Niger Delta, Ọjọgbọn Kemebradikumo Pondei, daku rangbọndan lasiko ti iwadii ẹsun bi wọn ṣe na owo ajọ NDDC labẹ rẹ n waye.
Awọn ọdọ naa n sọ pe o di igba ti Aarẹ Muhammadu Buhari fun'ra rẹ ba kede pẹlu aṣẹ, to si fi ontẹ lu u ju ikede ori ahọn lasan lọ.
83 million km ) ati iye to ju 309 egbegberun eniyan lo , awon ipinle aparapo je orile-ede totobijulo keta tabi kerin bii apapo iye aala , ati iketa totobijulo bii aala ile ati bi awon olugbe .
Bẹẹ ni ọrọ ri ni aafin Oyo nigba ti ọkan lara awọn olori Alaafin tilu Oyo, ayaba Badirat Olaitan Adeyemi da awọn eeyan to n sọrọ nipa rẹ lohun lori ayelujara.
Yóo wá rán àwọn angẹli láti lọ kó àwọn àyànfẹ́ jọ láti igun mẹrẹẹrin ayé, láti òpin ayé títí dé òpin ọ̀run.
"Ṣugbọn o ni oun maa sọ fun wọn pe ki wọn naa le ran awọn mii to lẹpọ bii tiwọn lọwọ lọjọ iwaju""."
gbogbo agbara rẹ lati ri i pe eto ọgbin, eto ẹkọ, ina mọna-mọna ati imọ ẹrọ ni
Laipẹ ni aṣọle fọwọ ṣeeṣe debi pe wọn ni lati gbe lọ sile iwosan lati ori papa.
nise ni Breazeale sun gbalaja silẹ ti ko si le e dide si pipe ago, eleyii to mu Wilder bori ninu ija naa.
Ṣugbọn ẹni tí ó bá gba ẹnu ọ̀nà wọlé ni olùṣọ́-aguntan.
Àwọn dókítà LUTH daṣẹ́ lẹ̀ ṣè ìwọ́de lórí àìsí ààbò
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Olusegun Obasanjo: Ọmú ìyá mi ti mo fi ń mùkọ ni kekere ló jẹ ki ń lókun Oríṣun àwòrán, @General_Ibbro Alatako fun ipo aarẹ latinu ẹgbẹ oṣelu NRC ni Bashir Tofa, ẹni to jẹ ọdọmọde, to si wa lati ẹkun ariwa orilẹede yii, nigbati igbakeji rẹ jẹ Sylvester Ugoh.
OLUWA bá ti ìlẹ̀kùn ọkọ̀ náà.
Iṣẹ́ẹ gbogbo wa ni láti dóòlà ẹ̀míi wọn ní yàráa pàjàwìrì.
Nígbà tí ó rí oníbodè, o rẹ́rìn-ín si i, ṣùgbọ́n ìgbà tí ó rí mi, o fa ojú ro, ó bẹ̀rẹ̀ síí sọ̀rọ̀ ó ni:
Oyo: Abass Bello rọ́pò ọmọ Akala bíi alága káńsù Ogbomọṣọ North
Ó ní, “Kí ni ẹ jáde lọ wò ní aṣálẹ̀?
Alábòyun ṣe iṣẹ́ abẹ pẹ̀lú abẹfẹ́lẹ́, ó gbé ọmọ jádé nínú ara a rẹ̀ NURTW l‘Abuja yóò kàn sí Makinde láìpẹ́ lórí bó ṣe fòfin dè wá l‘Ọyọ - Ejiogbe Amọṣa, eyi o wu ko gbe'gba oroke laarin awọn ẹgbẹ agbabọọlu mejeeji yii, o daju ṣaka pe ọwọ ilẹ Afirika ko ni gbẹyin lara ife ẹyẹ naa lọdun yii.
Ṣugbọn awọn iṣẹlẹ kan to jẹ manigbagbe waye lori eto naa.
Jẹ́ kí àwọn nkan-ọ̀gbìn ráàyè yọrí jáde l'éèpẹ̀.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù EidAlFitr2019: Bó ṣe ń lọ káàkiri àwọn Yidi rèé 4 Òkùdu 2019 Ẹ kú ọdún ìtúnu àaàwẹ̀ gbogbo ẹ̀yin olólùfẹ́ BBC Yoruba, a muú àwọn àwòrán bi àdúà ṣe ń lọ ni àwọn Yidi ni agbègbè wa.
Lalẹ Ọjọbọ ni ajọ NCDC kede rẹ loju opo ayelujara Twitter rẹ @NCDCgov.
Ayé kún fún ibùgbé ìyanu, Ọba bí Ọlọ́run kò sí, Olódùmarè ní n ṣe alákòóso ohun gbogbo ti ń bẹ ní òde ayé àti òde ọ̀run.
Ǹ bá wí pé kí n fọ́n wọn káàkiri,kí ẹnikẹ́ni má tilẹ̀ ranti wọn mọ́,
Ọlọ́pàá Ogun gb'ọmọ Ìmáàmù lọ́wọ́ ajínigbé, ṣùgbọ́n wọ́n gbé ọkọ̀ ojú omi ọlọ́pàá lọ Wo àwọn eléré ìdárayá mẹ́ta tí àjọ FIFA ti fòfin dè títí ayé Yàtọ̀ sí Ọ̀ṣun Òṣogbo, Ṣàǹgó pẹ̀lú a máa ní arugbá lóde Ọ̀yọ̀ Ìpínlẹ̀ Ọ̀ṣun kéde ìsinmi lẹ́nú iṣẹ́ nítorí ọdún Ìṣẹ̀ṣe Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Kí ó tó dákẹ́ adura rẹ̀ ni Rebeka ọmọ Betueli yọ sí i pẹlu ìkòkò omi ní èjìká rẹ̀.
Ẹ máa yá eniyan lówó láì ní ìrètí láti gbà á pada.
 Ìyen tí òrò yìí kò bá ní èyán .
Awọn mẹfa ni awọn ẹgbọn ati aburo rẹ, mẹta jẹ obinrin, meji ninu wọn si jẹ ọkunrin.
- arìnrìn oge Lẹ́yìn ìgbeyàwó ọdún mọ́kànlá àti ọ̀pọ̀ ìjà, Bọsẹ di èrò ọ̀run nílé Saidi Abẹnugan Ile Asofin Ipinlẹ Ọyọ, Adebo Ogundoyin ni ijọba ana ko se dara to lori eto isuna ọdun 2019, ati wi pe kii se abadofin to le wa si imusẹ ni ipinlẹ naa.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Nigeria Bad roads: Àwọn obìnrin abúlé yìí ń pàdánù ọmọ látàrí òpópónà tó mẹ́hẹ 14 Bélú 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 7 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Oríṣun àwòrán, @others Àkọlé àwòrán, Awọnn eeyan naa ma n koju iṣoro pupọ ki wọn la oriṣiriṣi odo kọja Ti ọjọ ikunlẹ alaboyun ba de, idunnu ati ayọ lo maa n jẹ, ṣugbọn ko ri bẹẹ fun awọn olugbe abule Madaka ni ipinlẹ Niger ni aarin gbungbun Naijiria.
Tite fun ra rẹ ṣalaye pe lootọọ loun ti n ṣaroye fun rẹfiiri pe nipa bi ifẹsẹwọnsẹ ṣe n lọ, ati pe oun ati Messi jọ ni gbolohun asọ nigba ti ipele akọkọ ere bọọlu pari.
 Bush so ninu oro re pe, “Si gbogbo ebi, O je iya ti a ko le e gbagbe rara, O fi wa si ojuna ti o to, bee si ni O maa mu inu wa dun ni gbogbo igba ki o to jade laye.
 Ọ ̀ pọ ̀ ìgbà ni àìsàn yìí máa n farahàn fẹ ́ ẹ ́ rẹ ́ fẹ ́ tàbí kí ó má tilẹ ̀ farahàn rárá pàápàá júlọ ̀ lára àwọn ọ ̀ dọ ̀ .
Kurt sweater: Wo aṣọ òjò tó wọ́n jùlọ ní àgbáyé!
Lọ́wọ́lọ́wọ́ báyìí, owó oṣù tí ó kéré jù lọ nínú tó HK$16,800 (US$2,200) dollars.
OLUWA bá rán ọpọlọpọ ejò amúbíiná sí àwọn eniyan náà, wọ́n bẹ̀rẹ̀ sí bù wọ́n jẹ, ọpọlọpọ ninu wọn sì kú.
Aya Falẹyẹ rawọ ẹbẹ yii ninu ọrọ ikinni kaabọ rẹ nibi ayẹyẹ iside ipade apero ọlọdọọdun ẹgbẹ Akọmọlede ati Aṣa Yoruba, eyi ti wọn tun fi n sami aadọta ọdun ti wọn da ẹgbẹ naa silẹ, to waye nilu Kabba, nipinlẹ Kogi.
Nípa agbára rẹ ni a fi bi àwọn ọ̀tá wa sẹ́yìn,orúkọ rẹ ni a fi tẹ àwọn tí ó gbógun tì wá mọ́lẹ̀.
26 Àti báyìí ni ó pọ́n wọn lé, ó sì sìn wọn títí ó fi wọ́ ọkàn wọn lọ sí ọ̀run àpáàdì; àti báyìí ni ó jẹ́ kí wọn ó mú ara wọn bọ́ sínú ìkẹ́kùn tí àwọn tìkara wọn dẹ.
 Ó maa ń fi okùn kọ ́ rùn tí ó sì maa ń múra bí àwọn ẹlẹ ́ sìn búdà .
O ti n ba iṣẹ imọ iwadii to si n dari ipolongo bọ o to ogun ọdun.
Yatọ si pe a n kede awọn iroyin nipa eto idibo to n bọ naa loore-koore, BBC Yoruba ti ṣeto lati ṣe ariyanjiyan fawọn eeyan to n dije lati du ipo gomina ninu eto idibo naa, paapa awọn to wa lẹkun ilẹ Oodua.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù CACOVID Palliatives: Ọwọ́ Ọlọ́pàá tẹ àwọn tó lọ kó ǹkan ìrọ̀rùn Covid-19 22 Ọ̀wàrà 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 27 Ọ̀wàrà 2020 Oríṣun àwòrán, Yabgi Mohammed Awọn agbofinro ti n fi ṣikun ọba mu awọn to kọlu awọn ile itaja ati ileeṣẹ aladani lati ji ọja ati dukia awọn eeyan ko lẹyin iwọde EndSARS.
Àwọn tí wọ́n jọ ń gbé ni Peteru, Johanu, Jakọbu, Anderu, Filipi, Tomasi, Batolomiu, Matiu, Jakọbu ọmọ Alfeu, Simoni ti ẹgbẹ́ Seloti ati Judasi ọmọ Jakọbu.
Ìdí nìyí tí àwọn baba wa fi ṣubú lójú ogun tí wọ́n sì kó àwọn ọmọ ati àwọn aya wa lẹ́rú.
Dáàbò bò wọ́n lọ́wọ́ àwọn apanirun.
Amọ iwe ofin naa ko faye gba ẹni ti wọn ko ba bi si Naijiria, ti iya ati baba rẹ ko si jẹ ọmọ orilẹede Naijiria lati dije dupo lorilẹede Naijiria.
9 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Oríṣun àwòrán, Joshua Adetunji O ṣeeṣe ki ẹ ti ẹ ti maa gbọ bi awọn eeyan kan maa ṣe maa n sọ pe, ara sisan kii ṣe arun.
Ọba pàṣẹ fún un pé kí ó wádìí ọmọ ẹni tí ọmọ náà í ṣe.
 túndé atòpinpin máa ń lọ gbé ojà ní Èkó .
“Tí ẹ bá fẹ́ ṣe ìwẹ̀nùmọ́ wọn, ẹnìkan tí ó jẹ́ mímọ́ yóo mú lára eérú mààlúù pupa tí a sun fún ìmúkúrò ẹ̀ṣẹ̀, yóo bu omi odò tí ń ṣàn sí i.
Tàbí kí ẹ tẹ̀lé mí ní 
Bótilẹ̀jẹ́pé àwọn màndààrú àti jàgùdà kọ̀ọ̀kan ò lè sàì wà níbẹ̀, àti pé ọ̀pọ̀lọpọ̀ a máa mu igbó níbẹ̀, gbogbo ẹ̀ a máa sábàá lọ ní ìrọwọ́-rọsẹ̀ ni.
Ìtàn rèé nípa bí Ogbomoso ṣe pa ọba, yọ nǹkan ọkùnrin rẹ jó kiri ìlú Alámì ẹ̀yẹ Scrabble Paul Sodje àti ọ̀rẹ́ rẹ́ kú lásìkò tó fẹ́ lọ́ sanwó ìdóòlà ẹ̀mí àbúrò rẹ̀, tí afurasí darandaran jí gbé Ìjàmbá iná míràn tún wáyé ní pápákọ̀ ojú omi Beirut Femi Fani-Kayode sọ̀kò ọ̀rọ̀ sí Tinubu tori kò dìde kí Ooni ''Eyi yoo fun awọn eniyan laaye lati bẹrẹ si ni ran nkan ounjẹ labẹlẹ, eleyii ti yoo mu ki a bẹrẹ si ni pese awọn oun ti a n jẹ ati eyi ti a n wọ'' Bakan naa ni o kesi ijọba lati lọ owo ti ijọba ba ri lori igbeṣẹ yii lati pese owo iranwọ fun awọn onisowo ati agbẹ kekeeke labẹle.
Ó bá rán Gehasi iranṣẹ rẹ̀ kí ó pe obinrin náà wá.
Mose bá dìde pẹlu àwọn àgbààgbà Israẹli, wọ́n lọ sọ́dọ̀ Datani ati Abiramu.
Ọpọ Ọba oke ti ko jẹ ki ọrọ naa ju bo se wa lọ, ko to ba wa bomi pa ina rẹ, amọ rabaraba isẹlẹ naa ko ti tan nilẹ ni Naijiria.
pese iranwọ fun awọn to farapa nibi isẹlẹ naa.
igbiyanju  ijoba rẹ lori eto alaafia ni
Àwọn náà yóo lọ sí ipò òkú pẹlu rẹ̀, sọ́dọ̀ àwọn tí wọ́n fi idà pa; àwọn orílẹ̀-èdè tí wọ́n ti ń gbé abẹ́ òjìji rẹ̀ yóo sì parun.
Lara orukọ awọn awẹlẹwa ayaba naa ni Olori Memunat Ọmọwumi àti olori Badirat Olaitan Ajoke, Eyi ni awọn ohun mẹta ti a mọ nipa Iku Baba yeye atawọn olori rẹ laafin Iku Baba Yeye kii kọnu ifẹ sawọn obinrin Ni ọdun diẹ sẹyin ti Kabiyesi alaafin Ọys n dahun ibeere kan lori ọgbọn agba ti baba n lo lati kọnu ifẹ sawọn obinrin, esi ti Baba fọ lọjọ naa lọhun ni pe awọn ko fi igba kọọkan kọ ẹnu si obinrin kankan rii.
Surajo ni won yoo sagbekale ile ikoni nise agbe fun idagbasoke eto ogbin ni ariwa Naijiria.
BBNaija 2020: Terry Waya ní torí ìfẹ́ tí Erica ní sọ́mọ òun ló fi ní ọ̀pọ̀ ìṣòro
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Divorcee: Ó sàn kí wọ́n yàgò fúnra wọn ju ki wọ́n ṣe ara wọn léṣe- Fisayo Lẹyin naa, Akinyele tun ṣiṣe goke agba ni ileeṣẹ ijọba to n risi wọlewọde, to si di agbẹnusọ fun ẹka ileeṣẹ ọhun.
 ní ọjọ ́ 10 oṣù kínní , ọdún 2017 , wọ ́ n dá ẹjọ ́ iku fun .
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, FUTA: Àwọn mẹ́jọ ló ṣíná ìyà fún Bolu ní FUTA Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Aare ni igbese yii ti je ki orile-ede Naijiria ni opo ounje janturu, ni eyi ti
Àlàyé rèé lẹ́nu awakọ̀ tó mọ̀ nípa ìbúgbàmù tó la ọ̀nà sí méjì l'Akurẹ̀
Nítorí pé Chen kò gbà wípé òun dá ẹ̀ṣẹ̀, ó sì wà lábẹ́ẹ ṣìgún òfin.
Àkọlé àwòrán, Owuro yii ni wọn se ayẹwo orukọ, ki idibo to bẹrẹ ni pẹrẹwu lati yan gomina mii dipo Ayọdele Fayọse Àkọlé àwòrán, Oni loni n jẹ, ẹni a bẹ lọwe lori eto idibo ni ipinlẹ Ekiti Àkọlé àwòrán, Ètó gbogbo ti n lọ ní ìmúra sílẹ̀ fún ìdìbò gómìnà to n sẹlẹ lọwọlọwọ ní ìpínlẹ̀ Ekiti Àkọlé àwòrán, Ayẹwo orukọ n lọ lọwọ ni awọn Ward ati Unit to wa kaakiri ipinlẹ Ekiti Àkọlé àwòrán, Akanda kan niyi ti Ko mo ibi ti yoo teka si BBC News, Yorùbá Ìdí tí ẹ fi le è nígbàagbọ́ nínú ìròyìn BBC Ìlànà Lílò Nípa BBC Òfin Àṣírí Cookies Kàn sí.
Bẹẹ naa ni kí gbogbo àwọn òṣìṣẹ̀ ìjọba lati ipele ikẹrinla si isalẹ maa ṣiṣẹ lati ile wọn fun ọjọ mẹrinla gbako, bẹrẹ lati ọjọ Aje to n bọ, àyàfi to bá jẹ́ pàjàwìrì tàbi tí wọn bá jẹ àwọn oṣíṣẹ kòṣeemáni.
Ijọba ni iboju ti ko din ni miliọnu kan ni oun ti pin si awọn ile iwosan ni ọjọ kinni oṣu kẹrin ọdun 2020, ṣugbọn dokita Robert sọ pe ọrọ ko ri bẹ nitori ile iwosan ohun ko ri ohunkohun gba.
Nítorí ó ń sọ pé, ‘Kò sí èrè kankan,ninu ṣíṣe ìfẹ́ Ọlọrun.
Nígbà tí ẹ̀gún dàgbà, ó fún wọn pa, nítorí náà wọn kò so èso.
Ajọ naa wa n rọ awọn eeyan ati ajọ ti ipese eto aabo to peye kan ni Naijiria, lati tete pakiti mọlẹ wa wọrọkọ fi sada, lori awọn isẹlẹ naa, ko to bọwọ sori Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Àwọn òṣìṣẹ́ iranwo fun àjò United Nation lorile-ede South Sudan ni wọn ti sọnù Àwọn òṣìṣẹ́ iranwo fun àjò United Nation lorile-ede South Sudan ni wọn ti sọnù Èka UN tó ń mójú tó àlàáfíà Ọmọniyan sọ pé àwọn ikọ náà jé onírúurú àwọn ènìyàn yọ wá láti oríṣiríṣi àjọ mìíràn, tí wọn sì ń lọ fún àmójútó ohun tí àwọn èèyàn kan nílò.
Aworan atọnisọna Iye awọn to ti ni arun naa lagbaye Sunmọ aworan Àgbáyé Orilẹede Afrika Ariwa Amẹrika Apa Latin Amẹrika ati Caribbean Ilẹ Asia Ilẹ Yuroopu Agbegbe Middle East Erekusu Oceania Fihan 69609761 iye iṣẹlẹ arun naa 1583112 Iye awọn to ku Group 4 Jọwọ ṣe atunṣe ilana ikansi ayelujara rẹ lati ri ẹkunrẹrẹ rẹ Aworan n ṣafihan awọn ti ayẹwo ti fi han lorilẹede kọọkan Orisun: Johns Hopkins University atawọn ajọ eto ilera ilu Igba ti wọn kede iṣiro awọn to nii kẹyin 11 Oṣù Ọ̀pẹ̀ 2020 13:00 WAT+3 Ẹkunrẹrẹ data Sun atẹ wa silẹ tabi oke lati ri ẹkunrẹrẹ akọsilẹ *Iye awọn to tọwọ aisan ku ni isọri eeyan ẹgbẹrun lọna ọgọrun Gbe e yẹwo: Àgbáyé Orilẹede Afrika Ariwa Amẹrika Apa Latin Amẹrika ati Caribbean Ilẹ Asia Ilẹ Yuroopu Agbegbe Middle East Erekusu Oceania Iye to ti ku Iye awọn to ku %* Apapọ awọn iṣẹlẹ arun Akọtun arun yii 0 10 100 1000 10000 ** Orilẹede Amẹrika 280985 85.
Cameroon: Àṣírí èèyàn kan tó dìbò ní ìgbà 89 tú, Ọlọ́pàá gbé e jàǹtò!
Ní ọjọ́ tí ẹ bá ń fi ìtí ọkà yín rú ẹbọ fífì, kí ẹ fi ọ̀dọ́ akọ aguntan ọlọ́dún kan, tí kò ní àbààwọ́n rú ẹbọ sísun sí OLUWA.
Ẹ̀ wo àwọn ìgbéṣẹ̀ tí ó ṣeeṣe kí ìjọba àpapọ̀ gbé lórí òfín kónílé ó gbélé ní Eko, Abuja, Ogun Kí ló yẹ ká se sí ẹkùn tó pa ènìyàn márùn ún?
Olatunbosun ni ijọba fẹ lo iye owo to to N9.
A dúró títí ní iwájú a kò rí Ìbanújẹ́-ìsàlẹ̀ bẹ́ẹ̀ ni a kò sì mọ̀ bí ó ti rìn ní àfonífojì náà.
3 181405 Orilẹede South Korea 572 1.
 orin ifá ni orin tí Ọ ̀ rúmìlà máa ń kọ nígbà ayé rẹ ̀ .
33 Báyìí ni Sátánì ronú láti fi agbára tẹ ẹ̀rí rẹ mọ́lẹ̀ ní ìran yìí, pé kí iṣẹ́ náà má baà lè jade wá ní ìran yìí.
Tí oníṣẹ́ ọwọ́ ṣe; tí alágbẹ̀dẹ wúrà yọ́ wúrà bòtí ó sì fi fadaka ṣe ẹ̀wọ̀n fún?
”Inyamkume  soro lori pataki ki awon eniyan maa tun nkan lo leekan sii bi won se n se nile okeere.
Àfikún ọ̀sẹ̀ méjì la tún fun yín láti kúrò l‘Apapa - Ọsinbajo kéde fáwọn ọlọkọ̀ epo Ṣé ìnàkí tún gbé owó tó lé ní mílíọ̀nu mẹ̀fà Náírà mì ni?
Ṣé èmi ni wọ́n ń mú bínú?
Aarun coronavirus tuntun yii, ti wọn n pe ni Sars-Cov-2, to n fa Covid-19, jọ pe o n tan kaakiri bi awọn aarun coronavirus yooku.
Kedere ni isà òkú rí níwájú Ọlọrun,bẹ́ẹ̀ ni ìparun kò farasin.
Ko si eyi ti iwadii tii ṣafihan odiwọn iṣe won ni ara eeyan ninu imọ sayẹnsi.
Eyi tubọ mu ki ọpọ akẹkọọ lawọn iipinlẹ yokuu o maa beere pe igba wo ni yoo kan awọn naa pẹlu.
Ẹgbẹ agbabọọlu Sevilla ti orilẹ-ede Spain sọ lori Twitter pe ibanujẹ lo jẹ fun wọn lati kede iroyin laabi naa.
6%) Amọṣa ni ti ipinlẹ si ipinlẹ, ipinlẹ Kogi ni iwa riba gbigba ti pọju lọ lorilẹ-ede Naijiria, lẹyin naa ni ipinlẹ Gombe tẹlee.
Nígbà tí mo bá rán Atemasi tabi Tukikọsi sí ọ, sa ipá rẹ láti wá sọ́dọ̀ mi ní ìlú Nikopoli, nítorí níbẹ̀ ni mo pinnu láti wà ní àkókò òtútù.
Awọn eekan ninu oṣelu ni wọn ti nii ṣe pẹlu Ikẹnnẹ bẹrẹ lati Oloye Obafemi Awolowo ti gbogbo eyan kà sí baba nla iran Yoruba ninu iṣelu Naijiria.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Coronavirus: Agbábọ́ọ̀lù Manchester United, Paul Pogba ṣètò owó dídá fún coronavirus, ó tún jẹ́jẹ́ àtìlẹ́yìn 15 Ẹrẹ̀nà 2020 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Igba akọkọ kọ niyii ti Pogba fi ayẹyẹ ọjọ ibi rẹ sọ ori iranlọwọ ṣiṣe.
Àwọn ileeṣẹ ijọba apapọ mẹfa ni wọn ti ri awọn to n lo iwe ẹri ayederu yii.
Beseri, Hodi, ati Ṣama, Ṣiliṣa, Itirani, ati Beera.
Bakan naa lo tun fikun ọrọ rẹ pe, ero ọkan awọn akọroyin lasan, ni awọn ileeṣẹ iroyin to gbe iru iroyin bayii sita, oun ko ba ẹnikẹni ja tabi ni ẹnikẹni sinu.
O ni ọmọ ogun mẹwaa ni wọn pa lọjọ naa, to fi mọ Lẹfutannaati Borgi.
Bo tilẹ jẹ pe o tun sọ awọn ọrọkọrọ, lasiko yii, igbimọ ipolongo rẹ ri i daju pe ko kọja bo ṣe yẹ.
Wọ́n fi akọ mààlúù meje, àgbò meje, ọ̀dọ́ aguntan meje ati òbúkọ meje rú ẹbọ ìmúkúrò ẹ̀ṣẹ̀ fún ìjọba Hesekaya, ati ilé OLUWA ati ilé Juda.
" Ẹ̀yin gómìnà, Ifá nìkan ló le tọ yín sọ́nà láì kùnà lórí Amotekun - Babaláwo Kí ló ń ṣẹlẹ̀ lọ́wọ́ sí Mamman Daura àti ìlera rẹ̀?
A fi ogun náà ati ẹbọ sísun ojoojumọ lé e lọ́wọ́ nítorí ẹ̀ṣẹ̀, a sì já òtítọ́ lulẹ̀.
David Oyedepo kede bẹẹ ninu iwaasu rẹ to se laarọ ọjọ isinmi oni ni olu ijọ rẹ to wa nilu Ota.
Abadofin naa yoo fun awọn afurasi iwa ọdaran lanfani ati gbe ni orilẹede China bẹrẹ lati ọjọ kini, oṣu kẹrin nitori ninu ero wọn, abadofin naa yoo fi idajọ ododo dun awọn ọmọ HongKong.
Ọpọlọpọ wọn ko ti i ri obinrin oyinbo ri, niṣe ni wọn n fi irun ori mi ṣere, ti wọn a tun maa fi ọwọ kan ọwọ mi.
Nígbà tí ó tó àkókò oúnjẹ, ó jókòó láti jẹun pẹlu àwọn aposteli rẹ̀.
Pẹlu ìnira ni o óo máa mú oúnjẹ jáde láti inú ilẹ̀ ní gbogbo ọjọ́ ayé rẹ.
Sanyeri ni ọjọ ti oun ko leè gbagbe laelae ni ọjọ ti oun gba iwe irinna lọ si ilẹ Amẹrika lẹyin osu mẹta ti oun se fiimu 'Ọ̀pá kan' to sọ oun di olokiki.
Daromosu ni asiko ti to ki a je ki awon eniyan nimo kikun sii lori ohun to sokunfa arun yii.
Dino ti ni irọ nla ni eyi nitori pe aja kii jẹ obi, oun ko le yọ kuro bii ọmọ ọwọ̀ ninu idije naa.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Coronavirus in Nigeria: Èèyàn 1,598 míì tún ti lùgbàdì covid-19 ní Nàijíríà, 85,367 ló ti rí ìwòsàn 12 Sẹ́rẹ́ 2021 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 17 Sẹ́rẹ́ 2021 Oríṣun àwòrán, Twitter/Chikwe Ihekweazu Ajọ to n gbogun ti ajakalẹ arun ni Naijiria, NCDC ti kede loju opo Twitter rẹ pe eeyan 1,598 lo tun ko coronavirus lọjọ Abamẹta kaakiri orilẹede Naijiria.
Mi ò m'àwọn ẹgbẹ́ tó ń gbé ''Tinubu 2023'' kiri- Bola Tinubu Kíló burú nínú kí Sanwo-Olu fún Super Eagles lówó?
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Mike Ifabunmi: Òrìṣà ló gbè wà jù ni Brazil Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
” Ó dáhùn, ó ní, “N kò mọ̀.
Ọ̀rọ́ náà ṣe ọtọọtọ láàrin àwọn Gomina Guusu- ìwọ-òòrùn Nàìjíríà àti ẹgbẹ to n soju ọmọ yoruba, Afẹnifẹre lórí àríwísí àsáju ẹgbẹ́ APC, Bola Ahme Tinubu, lẹyin to fi èrò tirẹ̀ han lórí ìdásilẹ̀ ètò àabo Amotẹkun to ti n dá gbọn-mi-si i-omi-o-to silẹ̀ láàrin ìjọba apapọ àti ìjọba ìpinlẹ̀.
Ènìyàn 653 míràn tún kún iye àwọn tó ní COVID-19 ní Nàìjíríà Wo bí Dorathy Bachor ṣe di gbajúmọ̀ lóríi Instagram lẹ́yìn tí ètò àgbéléwò BBNaija bẹ̀rẹ̀ Àwọn àádọ́ta ọ̀dọ́ wọ gàù nítorí ilé ijó ní Ilorin Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Black women live matters: Ọdún 2015 ní àwọn ọlọ́pàá pa India Kager láìní ìdí- Gina Best Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí US election 2020: Ibú-owó Bloomberg fẹ́ wàákò pẹ̀lú Trump nínú ìbò ààrẹ Amẹrika9 Bélú 2019 Trump impeachment: Àṣírí tùú, àkọsílẹ fihàn bí Trump ṣé béèrè iranwọ lọ́wọ́ ààrẹ Ukraine25 Owewe 2019 Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Eyi lo si mu ki wọn o wọ inu ọgba ile naa, ṣugbọn oorun buruku lo ki wọn kaabọ.
 Oríṣun àwòrán, Instagram/iyaboojofespris Iyabọ Ojo ni lọpọ igba ni oun maa n rẹwẹsi ninu ọkan, ti ọkan oun si maa n yapa, bẹẹ si pẹlu gbogbo wahala oun yii, oun ko ko ere jọ fun ara oun tabi ni akoko lati sinmi rara."
Kìnìún Ìdímù tíí ṣẹ́mọ à á ṣẹ́ mọ kọ́lá ó dígbọ́n
O tun jẹ ẹbun ohun elo inu ile, ounjẹ ọfẹ, aṣoju ileeṣẹ, irinajo si orilẹ-ede Scotland, ati ẹẹdẹgbẹta Dọla owo Bitcoin.
Eko dabaa ati gbe igbesẹ ati yọ Gomina Akinwunmi Ambode nipo bi ko ba wa da Ile
Ǹjẹ́ ìkòkò lè wí fún ẹni tí ó ń mọ ọ́n pé, “Kí ló dé tí o fi ṣe mí báyìí?
Òṣèrébìnrin tí wọ́n bá fi ìbálòpọ̀ lọ̀ 'torí ìṣẹ́, kó bọ́ síta láti sọ̀rọ̀ - Kunle Afod Saraki àgbà ló kọ́ ilé yìí fáwa arúgbó kìí ṣe Bùkọ́lá- Arúgbó Ilọrin Wo àwọn èèyàn jáńkán tí yóò ṣe ọdún tuntun ní ọgbà ẹ̀wọ̀n Àwọn fóònù wọ̀nyìí kò ní lè ṣe WhatsApp láti ọdún 2020 Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ọbẹ Ẹgusi sise ati jijẹ Bakan naa ni Baba Adeboye ni adura nikan lo le e ṣẹgun ilẹ riri ati awọn ijamba miran ti yoo waye ni ọdun 2020.
 ohun àsọmórọ ̀ ni àwọn ẹ ̀ ka-èdè yorùbá jẹ ́ nínú àwọn ìwé gírámà yorùbá tí ó wà lórí àtẹ .
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Coding Kids: Ẹ wo àrà t'àwọn ọmọ kékeré ń fi ẹ̀kọ́ kọ̀mpútà dá Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Coding Kids: Ẹ wo àrà t'àwọn ọmọ kékeré ń fi ẹ̀kọ́ kọ̀mpútà dá 11 Èbibi 2019 Ọmọ ti yoo ba jẹ Aṣamu, ati kekere lo ti n ṣẹnu ṣamuṣamu.
Agbẹjọro to kọkọ fẹ ẹ ṣ'oju Hafeez, Rashid Rehman, ni awọn kan yinbọn pa ni ọdun 2014 lẹyin to gba lati gba ẹjọ rẹ wi nile ẹjọ.
Ẹ wa kòtò sí ààrin ògiri mejeeji, Kí ẹ lè rí ààyè fa omi inú odò àtijọ́ sí.
Adanna ni iru awọn ewe yii lo maa n kọju ija arun to le ṣuyọ ninu agọ ara.
Ọjọ ti yoo bajẹ- 2020-04 4.
Ó bá lọ sí ilé baba rẹ̀ ní Ofira, ó pa gbogbo aadọrin àwọn arakunrin rẹ̀ lórí òkúta kan, àfi Jotamu àbíkẹ́yìn Gideoni nìkan ni ó ṣẹ́kù, nítorí pé òun sá pamọ́.
Sugbọn nibo ni Baba Wande wa lasiko yii ninu ere tiata, gẹgẹ bii awọn yoku ti a ti mẹnuba saaju?
Wọ́n yí mi ká tọ̀sán-tòru bí ìṣàn omi ńlá;wọ́n ká mi mọ́ patapata.
Lẹ́yìn náà, n óo ranṣẹ sí ọpọlọpọ ọdẹ, wọn yóo sì wá dọdẹ wọn ní orí gbogbo òkè gíga ati àwọn òkè kéékèèké, ati ninu pàlàpálá àpáta.
Ti iru obinrin bẹẹ ba dede jade kuro nile lọwọ alẹ, awọn agbofinro le da duro lọna lati ṣalayae ibi to n lọ, tabi ko ma ri ọkọ loju popo.
Àwọn ìlà fún àyẹ̀wò BBC Charter and Framework Agreement BBC World Service Operating Licence Onírúurú ìlànà ìṣe: Ní ìmọ̀ nípa bi ilé iṣe BBC ṣe farajì fún ṣiṣe àmojúto oríṣiriṣi ẹ̀yà BBC Charter.
BBNaija: Terry Waya sọ oun tó fojú Kiddwaya rí nílé nígbà tó ń bẹ̀bẹ̀ láti lọ BBNaija
Ẹsun ipaniyan, idaluru ati ijinigbe ni wọn fi kan wọn.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Election Tribunal: INEC ní òfin kò ní kí èsì ìbò ààrẹ wà lórí ''server'' 14 Òkùdu 2019 Oríṣun àwòrán, Twitter/INEC Àkọlé àwòrán, Ọwọ́ ni INEC fi kọ èsì ìbò ààrẹ, kò sí lórí ''server''-Okoye Ala ti ko lee ṣẹ ni ''server'' ti oludije ipo aarẹ fẹgbẹ oṣelu PDP, Atiku Abubakar n beere fun.
Bákan náà ni ẹ ṣe ní Kadeṣi Banea, nígbà tí OLUWA ran yín lọ, tí ó ní kí ẹ lọ gba ilẹ̀ tí òun ti fi fun yín.
Bí o ti ń wò ó, òkúta kan là, ó sì ré bọ́ láti òkè, ó bá ère náà ní ẹsẹ̀ mejeeji tí ó jẹ́ àdàlú irin ati amọ̀, mejeeji sì fọ́ túútúú.
"O san lati duro sile tun orilẹede yii ṣe ju ki a maa sa kuro nilu lọ""."
Ẹ máa wádìí ohun gbogbo dájú, kí ẹ sì di èyí tí ó bá dára mú ṣinṣin.
Walter Onnoghen kọ̀wé ìfẹ́yìntì ara rẹ̀ gẹ́gẹ́ bí adájọ́ àgbà Nàìjíríà
” Ó bá dáhùn pé, “Mò ń lọ wọn Jerusalẹmu, kí n lè mọ òòró ati ìbú rẹ̀ ni.
Bakan naa ni ẹka isejọba to n risi ọrọ ofurufu, FAAN fikun un wi pe iwadii n lọ lọwọ lori isẹlẹ naa, amọ ko seese ki eniyan gbe Shisha kọja ni awọn ibi ayẹwo igbalode to wa ni papa ofurufu.
Àwọn eniyan náà sì ṣọ̀fọ̀ nítorí pé OLUWA pa ọpọlọpọ ninu wọn.
"Oríṣun àwòrán, Presidency ""Alatako ni mo jẹ tẹlẹ fun Buhari ko to di pe erongba sise saa kẹta de, eyi ti asaaju kan tẹlẹ nilẹ yii kuna lati gbe kalẹ."
Oríṣun àwòrán, NAF/Twitter Ọrẹ Tolu ni kii gbohun soke ti o ba ẹnikẹni n sọrọ, jẹjẹ rẹ ni o maa n lọ.
Leyin eto igbeyawo yii ni ọkọ iyawo ko lọ baa ninu ile rẹ.
Pasito Biodun Fatoyinbo to da ijọ COZA silẹ fi atẹjadee sita pe irọ ni ẹsun naa nitori oun ko fipa ba ẹnikẹni lo pọ ri laye ounCOZA: Mi ò fípá bá obìrin lò pọ̀ rí láyé mi - Pásítọ̀ Fatoyinbo.
Botilejẹpe awọn orileede kan ti wọn ti n jajabọ lọwọ arun naa ti ni ki awọn ipele eto ẹkọ kan bẹrẹ isẹ pada diẹdiẹ.
agbabọọlu to pegede wọ abala ti o kan naa ati awọn ti iko kookan yoo ba
Wọn óo dúró ní òkèèrè nítorí ẹ̀rù tí yóo máa bà wọ́n nítorí ìrora rẹ̀.
láti lè gba ọkàn rẹ̀ là lọ́wọ́ ikú,kí ó lè wà láàyè.
Ọgbẹni Tillerson ko sai kan sara si eto karakata orilẹede Amẹrika pẹlu ilẹ Afirika eleyi to ni o ti tubọ mu ki awọn karakata ti kii se ti oowo epo o burẹkẹ sii.
Ṣé obìnrin leè ní àǹfààní ọ̀gbọọgba pẹ̀lú ọkùnrin lágbo òṣèlú Nàíjíríà?
Ọkọ̀ ojú irin pa ènìyàn mẹ́rin ní Eko Ǹjẹ ẹ ṣì rántí Fúnwọntán, Alhaji pásítọ̀, Olúwo,Gbenga Adeboye?
Senate: Ṣé kí Nàìjíríà dín iye àwọn Sẹ́nétọ̀ tó ń ṣojú wọn kù ni tàbi ka kuku pa ipò náà rẹ́?
Ilé aṣòfin Ekiti ní kí àwọn alága ìjọba ìbílẹ̀ dá N3.
 Isakoso yi gori aleefa ni akoko ti awon omo orile-ede Naijiria ni lo ayipada otun, ayipada otun eyi ti a seleri re yoo lati tesiwaju lati ma fifun awon omo orile-ede yi.
Wọn tẹsiwaju wi pe ọkọ akero naa dede ya lọ si oju opopona ibi ti ọlọkada naa n gba bọ ti o ko si ẹnu rẹ.
Gbogbo wọn jẹ́ baálé ninu ìdílé wọn, tí ń gbé Jerusalẹmu.
LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé
encourage : v ; ( her parents always encourage her in her studies .
Ẹni ogoji ọdún ni mí nígbà tí Mose iranṣẹ OLUWA rán mi láti Kadeṣi Banea láti ṣe amí ilẹ̀ náà.
Kaduna sex party: Mọ̀ si nípa àríyá oníhòhò àti ìbálòpọ̀ tó yẹ́ kó wáyé ní Kaduna
Tolani jẹ oludari iṣẹ ẹgbẹ awọn ọmọ ilẹ Adulawọ ni fasiti Michigan.
"Oríṣun àwòrán, yomi fabiyi O ni ""ko si bi awọn ti yoo ṣe onigbọwọ sinima ṣe le e gbe owo kalẹ, nitori ko si ilana to tọ lati ọdọ awọn oni sinima Yoruba."
Mr Kampondeni tun sọ pe aarẹ mọ pe iyatọ nla lo wa laarin jijẹ olori ẹ̀sìn àti oloṣelu.
Raji ní òun leè fọwọ́ gbáyà pé ètò ìdìbò náà bẹ̀rẹ̀ lásìkò láwọn àgọ́ ìdìbò, àmọ́ omi gínńgín tó ba ojú epo jk nínú ìdìbò náà ni tàwọn jàǹdùkú tó já àpótí ìbò gbà ní àgọ̀ ìdìbò márùn-ún sí mẹ́fà, àmọ́ ó ní èyí kò dá àseyọrí ìdìbò náà dúró.
Bàbá mi náà dáhùn ó wí pé, mo gbẹ́kẹ̀lé {ibọn, mo gbẹ́kẹ̀lé àdá, mo gbẹ́kẹ̀lé oògùn, mo si gbẹ́kẹ̀lé  Ọlọ́run Ọba.
Ohun ti Ferdinand n sọ ni pe bi a ba pẹ lori imi, eṣin keṣinṣin lo n ba ni nibẹ.
Jonatani, ọmọ Usaya, ni ó wà fún àwọn ilé ìṣúra tí ó wà ninu àwọn ìlú kéékèèké, àwọn ìlú ńláńlá, àwọn ìletò ati àwọn ilé ìṣọ́.
Wọ́n tú àṣírí ìfiyàjẹni àwọn Ológun àti SARS káàkiri Nàìjíríà Buhari ń fowó aráàlú gbàtọ́jú nílùú òyìnbó nígbà táwọn ilé ìwòsàn wa ti di mọ́ṣúárì - Falana Ìgbìmọ̀ ọ̀tẹ̀ ní ọ̀rọ̀ àwọn àgbààgbà ẹkùn àríwá pé ìjọba Buhari ti kùnà- Femi Adesina Àṣírí èèyàn kan tó dìbò ní ìgbà 89 tú, Ọlọ́pàá gbé e jàǹtò!
Ẹnìkọ̀ọ̀kan yín níláti fẹ́ràn aya rẹ̀ bí òun tìkararẹ̀.
Ohun tí eniyan burúkú ń bẹ̀rù ni yóo dé bá a,ohun tí olódodo ń fẹ́ ni yóo sì rí gbà.
Ipo ate ohun ni ajo FIFA gbe jade lori ero ayelujara won lojoBo(Thursday), eleyi ti orile-ede mẹ́tàdínláàdọ́ta di ipo won mu gege bi won se wa tele.
Lilo ede: Kini ‘technology’ ni ede Yoruba?
Ago mẹwaa alẹ ọjọ Aje ni ijọba fi ikede sita pe oju opo yoo ṣi silẹ fun awọn eeyan ti yoola janfani owo iranwọ ijọba apapọ Bẹẹ si ni wọ́n ti fi ilana atẹle lati ri owo naa gba sita fun gbogbo ọmọ Naijiria to ba forukọ silẹ.
Nibayii ọjọ karun un, oṣu kẹjọ ni igbẹjọ naa yoo waye nitori El-Zakzakky funrarẹ ati iyawo rẹ ko fara han nile ẹjọ bi o tilẹ jẹ wi pe agbẹjọro wọn, Femi Falana sọ eredi pe tori ailera ni.
ile-igbimo ajo isokan agbaye, eleyi to waye niluu New York, lojo Isegun(Tuesday).
Ondo judgment: Pásítọ̀ Kolawole ṣá Olaniyi pa lóko kọ̀ǹkọ̀, adájọ́ bá ní kí wọ́n yẹgi fún un
Ibrahim Babangida: Buhari ní Nàìjíríà kò lè gbàgbé iṣẹ́ ribiribi tí IBB ṣe láéláé bí ó ti pé ẹni ọdún 79 lónìí
" ní ọdún 2014 , Ó dá ile- iṣẹ ́ orin "" don ' t sleep "" kalẹ ̀ pẹ ̀ lú àjọṣepọ ̀ phoniks ."
Ìpọ́njú ni bí, tabi ìṣòro, tabi inúnibíni, tabi ìyàn, tabi òṣì, tabi ewu, tabi idà?
Pauline Tallen - Minisita fun ọrọ awọn obinrin.
Wo bí o ṣe leè lo èròjà agbohùnsílẹ̀ tuntun tí Twitter gbé dé Òjò àrọ̀ọ̀rọ̀dá dá wàhálà sílẹ̀ l'Eko Kí ló ṣekúpa Ibidunni Ighodalo tí gbogbo ọmọ Nàìjíríà ń selédè lẹ́yìn rẹ̀?
Eyi lo mu ki Parveena se agbekalẹ ẹgbẹ awọn obi ọmọ to poora , to si ni oun ko tii sọ ireti nu pe oun ko ni ri ọmọ oun mọ, nibayii ti yoo pe ọgbọn ọdun ti ọmọ rẹ naa poora.
Ikọ̀ ẹlẹ́sìn Hàkíkà rèé, níbití wọn ti ń pààrọ̀ ìyàwó láàrín ara wọn Alárùn ọpọlọ lu àwọn nọ́ọ̀sì àti dókítà agba níléèwòsàn ní àlùdákú Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Sunday Adelaja: Tẹ́tẹ́ làwọn pásítọ̀ tó ń gba owó ‘ìserere’ ń ta Adajọ Ayeomọni la gbọ pe o lọ wo awọn ọmọ rẹ to wa ni fasiti naa, nigba to si n pada bọ ni isẹlẹ naa waye.
Lataari esi ifesewonse ti o waye laarin iko agbaboolu Man U ati Chelsea lana ode yii, o seese ki iko agbaboolu Chelsea pegede fun idije UEFA Champions League saa to n bo.
Wolii Chukuemeka Odumeje ( Indaboski): Wolii Chukwuemeka Odumeje, ti ọpọ eeyan mọ si Indaboski naa jẹ wolii keji to kede pe Ọlọrun ti fi isẹlẹ EndSARS han oun saaju.
Nígbà tí Jabini ọba Hasori, gbọ́ ohun tí ó ṣẹlẹ̀, ó ranṣẹ sí Jobabu, ọba Madoni, ati sí ọba Ṣimironi, ati sí ọba Akiṣafu, 
Babachir salaye ara rẹ lori ẹsun pe o se owo ti o to igba miliọnu naira to yẹ fun nina fun gige koriko lọgba awọn ti wahala le kuro nile lẹkun ila oorun ariwa orilẹede Naijiria, basubasu.
Wole Soyinka rèé láti kékeré Kí ló mú àwọn adarí Nàìjíríà tako ra wọn lórí ikú ọmọ alága ẹgbẹ́ Afenifere?
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Parental Guidance: Ọdún méjì ni kí ẹ ti bẹ̀rẹ̀ kíkọ́ ọmọ nípa ìbálòpọ̀ Awọn olè náà ni: Kunle Ogunlẹyẹ ti àpèjà rẹ ń jẹ Arrow.
Ṣugbọn kí ẹ kọ́kọ́ mọ èyí pé, kò sí àsọtẹ́lẹ̀ kan ninu Ìwé Mímọ́ tí ẹnìkan lè dá túmọ̀.
 “lara awon ise akanse ti  a se ni ina mona-mona ati fifi owo idokoowo si
Amọ ohun iyalẹnu ni bi wọn se ni igbin tobi ju ijapa lọ ninu igbo naa.
O ni wọn ba nkan to pọ jẹ ni aafin.
Oríṣun àwòrán, Omogoriola Hassan Oge sise lasan ni Tattoo ara mi, ko di ọba jijẹ lọwọ: Kabiyesi tun sọ fawọn akọroyin pe, ko si ohun tuntun labẹ ọrun mọ lori laali tawọn oloyinbo n pe ni ''tattoos'' to wa lara oun.
Wọn ni ijọba lo laṣẹ ati ẹtọ lati gbe irufẹ gbedeke bẹẹ kalẹ, bẹẹ nigba ti ijọba tabi awọn agbofinro ko sọ ohun to jọ bẹẹ, ko si idi fun awọn lati gbe igbesẹ lori rẹ.
Adetunji n wu nitori ojo iwaju ile Ibadan.
Kini ohun to yẹ ki eeyan ṣe to ba n ni idojukọ ninu igbeyawo rẹ lasiko yii?
Ṣugbọn obinrin yìí kò dá a lóhùn.
Ìgbà míràn bí a ti ń lọ, ejò a déédéé já sílẹ̀ ní ìwàjú wa, ìgbà míràn ejò á já kọ́ wa ní èjìká, ìgbà míràn ejò á máa lọ mọ́ wa lẹ́sẹ̀ wọ́n á máa bá wa ṣiré.
Ìbejì ní wá ṣùgbọ́n àyẹwò fí hàn pé baba ọtọ́ọ̀tọ̀ ló bí wà Ẹ̀kúnrẹ́rẹ́ àlàyé rèé lórí àyẹ̀wò DNA Wo ọ̀nà tí Yoruba ń gbà dá ọmọ àlè mọ̀ nínú ìdílé- Elebuibon Àwọn àpẹẹrẹ pé o ti ń darúgbó Pupọ isẹlẹ gbigbe ọmọ ale wọnu ile si ni awọn eeyan saba maa n di ẹbi rẹ ru awọn iyawo ile pe wọn se asemase nita pẹlu ọkunrin mii.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Diaspora: Ẹyin nikan kọ́ ni ọ̀rọ̀ idibo Naijiria kàn nílé Igba akọkọ ni yii ti Manchester United yoo maa fidirẹmi ninu idije liigi ilẹ Gẹẹsi lati oṣu kejila ọdun 2018.
Bakan naa, awon mejeeji si jo wa papo fun osu marundinlogun ti ajo to n ri si ere-idaraya ohun ni Russia fofin de, latari lilo ogun eyinbo afunilokun ti a mo si meldonium lodun 2016.
Robin Hood jẹ́ alágbára ọkùnrin ó sì mọ ọ̀fàa ta ju enikẹ́ni lọ ní gbogbo àgbáiyé!
Olakunrin murder: Ọlọ́pàá ní OPC kò láṣẹ láti fipa lé ẹ̀yà kan nílẹ̀ Yorùbá
ti a wayii, lo yẹ ki idibo naa kọkọ waye ṣugbọn fun awọn idi kan tabi keji ajọ
Ọkunrin kan tún wà tí orúkọ rẹ̀ ń jẹ́ Uraya, ọmọ Ṣemaaya, láti ìlú Kiriati Jearimu.
Ó fi ọ̀pá ìwọnlẹ̀ náà wọn ìlú náà.
Ẹ óo mọ̀ pé mo wà láàrin Israẹli;ati pé èmi OLUWA ni Ọlọrun yín,kò sí ẹlòmíràn lẹ́yìn mi mọ́.
” Jotamu ọmọ rẹ̀ sì jọba lẹ́yìn rẹ̀.
''Jẹki wọn ma bere wi pe nibo ni iru ijọba yi wa lati ọjọ yi.
Ọ̀dọ̀ fásitì jànkàn Oxford ló ti jáde
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Àwọn Ajẹ́lẹ̀ miran huwa kòtọ́ nilẹ alawọ dúdú.
Ẹni tó bá ń bínú kàn ń bínú lásán ni14 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Ede Poly Rector suspension: Wọ́n ní kí ọ̀gá àgbà Pólì Ede lọ rọ́kún ńlé lórí ẹ̀sùn pé 'ó kan bẹ́ẹ̀dì sí ọ́fíìsì'15 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 5:21 Fídíò, Akomolede ati Aṣa: Mọ̀ síi nípa ìró afárànma àti agbárànmọ́ fáwẹ́ẹ̀lì Yorùbá, Duration 5,2115 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 US election 2020: Àlàyé rèé lórí bí èèyàn 538 ṣe ń yan ààrẹ lé èèyàn mílíọ̀nù 331 ní Amẹ́ríkà15 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 11:24 Fídíò, Africa Eye: Wo ìtàn ìyá kan ìyá kan àtàwọn olè ajọ́mọgbé tó n ta ọmọ ní Kenya, Duration 11,2414 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Kankara Abduction: Àwọn ológun ṣàlàyé ìdí tí wọ́n fi yọ̀nda àwọn tó jí àwọn akẹ́kọ̀ọ́ gbé.
Gẹ́gẹ́ bí ètò tí Dafidi ti ṣe, iye àwọn ọmọ Lefi láti ogún ọdún sókè nìyí: 
Oríṣun àwòrán, AFP Bii ti pasitọ Chogo, oun naa gbagbọ pe ki wọn ma fi aṣiṣe kinkin ti Trump ba ṣe bo daadaa rẹ mọlẹ.
O óo pè mí, n ó sì dá ọ lóhùn,o óo máa ṣe àfẹ́rí iṣẹ́ ọwọ́ rẹ.
A ti sún ìgbẹ́jọ́ Ganduje, Tambuwal àti Ihedioha sí ọ̀la Ọbabìnrin Elizabeth ti fara mọ́ ìpinnu ọmọ ọba Harry àti Meghan láti lọ ṣiṣẹ́ ajé Mo fi iṣẹ́ agbẹjọ́rọ̀ sílẹ̀ lọ bẹ̀rẹ̀ Ifá dídá ní ìlú òyìnbó- Ella Popoola Dangote ni kete ti oun ba ti kọ ile iṣẹ ifọ epo rọbi to tobi julọ lagbaaye ti oun n kọ lọwọ tan loun yoo ra Arsenal lọdun 2021.
Kò ní ṣe nǹkankan;ibi kankan kò ní dé bá wa,bẹ́ẹ̀ ni a kò ní rí ogun tabi ìyàn.
Liverpool fí ogun ẹ̀yìn ja Barcelona Kíni ìtumọ̀ oyè Balógun káàfàtà tí wọ́n fí Asamoah Gyan jẹ?
O ni wọn ni oun digunjale pẹlu awọn awọn eeyan kan lati ja Omolade Yemi lole, eyi to sọọ di ero SARS Sinimá àwòdamiẹnu, Ẹ̀fáńjẹ́líìsì jìyà àjẹmumi nílé aṣẹ́wó l'Ejigbo ní ìlú Eko Ọba Saudi Arabia yọ ọmọ rẹ̀ àti àbúrò rẹ̀ kúrò nípò nítorí ìwà àjẹbánu lórí owó tó yẹ fún ààbò ìlú Bàbá ẹni ọgọ́ta ọdún dèrò ilé ẹjọ́ nítorí ó wọ inú oko Obasanjo láì gba àṣẹ Mi ò fẹ́ ìrànwọ́ ẹgbẹ́ òṣèré, àwọn kọ́ ló kóbá mi- Chief Kanran Àṣà Oge Ṣíṣe ní Akọ́mọlédè BBC Yorùbá ń gbé yẹ̀wò lónìí, Ó yá, iṣẹ́ ti bẹ̀rẹ̀.
Wọn tun n fẹ ki gomina san owo ti wọn n yọ ninu owo osu wọn lati osu keji titi de osu kẹfa ọdun 2020.
Wọ́n ń lé wa lórí òkè,wọ́n sì ba dè wá ninu aṣálẹ̀.
Ni Serubabeli, ọmọ Ṣealitieli ati Joṣua ọmọ Jehosadaki, olórí alufaa, ati gbogbo àwọn eniyan tí wọ́n ṣẹ́kù bá gbọ́ràn sí OLUWA Ọlọrun wọn lẹ́nu, wọ́n fetí sí ọ̀rọ̀ wolii Hagai, gẹ́gẹ́ bí OLUWA Ọlọrun wọn ti rán an; wọ́n sì bẹ̀rù OLUWA.
Nígbà tí ó wọlé, Eliṣa bèèrè lọ́wọ́ rẹ̀ pé, “Níbo ni o lọ?
Bí wọ́n ti ń dákú láàrin ìlú,bí ẹni tí a ṣá lọ́gbẹ́,tí wọ́n sì ń kú lọ lẹ́yìn ìyá wọn,wọ́n ń sọkún sí àwọn ìyá wọn pé:“Ebi ń pa wá, òùngbẹ sì ń gbẹ wá.
O ti di ọjọ kẹta bayii ti ẹgbẹ NAAPE naa gunle iyanṣelodi ọhun.
 Àwọn àbọ ̀ ilẹ ̀ sàró ni ó jẹ ́ kí ọ ̀ rọ ̀ òwò síse yìí túbọ ̀ gbilẹ ̀ tó bẹ ́ ẹ ̀ .
Aare wa gbadura pe, Olorun yoo fun Kelani lokun ati agbara pelu ilera ti o peye lati tesiwaju ninu ise rere ti o yan laayo.
O wa ro awon omo ogun ohun lati mase ni ijakule ni igba kookan, ki won si se ara won bi osusu owo loju ogun.
Gómìnà Kẹwa – Ọ̀gágun Ọlágúnsóyè Oyinlọlá – Gómìnà fún ọdún meta – ọdún mẹ́rinlélógún di ọdún mọ́kànlélógún sẹhin
Fidio ree lori bi Maryam Sanda se foju ba ileẹjọ: Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Maryam Sanda: Ṣe ló ń wa ẹkún mu nílé ẹjọ́ lórí ìdájọ́ ikú tí wọn fun Bi o tilẹ jẹ pe Maryam sọ pe oun ko mọwọ mẹsẹ lori ẹsun ipaniyan ti wọn fi kan oun naa, sibẹ o papa foju ba ileẹjọ.
Oríṣun àwòrán, Facebook/Nana Akufo-Addo Bakan naa ni Akufo-Addo jẹ minisita ọrọ ilẹ okeere laarin ọdun 2003 si 2007 labẹ aṣẹ Aarẹ John Kuffour.
Ileeṣẹ eto ilera nijọba ipinlẹ Kano lo kede eyi ni ọsan ọjọ Aje.
Iroyin so pe, Joshua koi ti padanu ifigagbaga Kankan lateyin wa, beesini igbagbo wa pe o seese ki O jawe olubori ninu ifigagbaga ohun latari iriri re ti o ni ni gbagede Principality.
Akori ipade apero naa ni: ‘Wiwa ọjọ iwaju to dara fun eto okoowo: Mimu
Naijiria, Muhammadu Buhari pẹlu Olusegun Ọbasanjo fi ki ara wọn sibi ipade awọn
Mose dáhùn pé, “Ọ̀dọ̀ mi ni àwọn eniyan náà ti máa ń bèèrè ohun tí Ọlọrun fẹ́ kí wọ́n ṣe.
O kò gbọdọ̀ fi aṣọ bo ẹnu, o kò sì gbọdọ̀ jẹ oúnjẹ ọlọ́fọ̀.
Igbesẹ naa si lo mu ki ileesẹ aarẹ orilẹede Sierra Leone gbe igbesẹ lati se amusẹ ati atunse ofin to n gbogun ti iwa ifipabanilopọ.
Bí ó ti kù díẹ̀ kí bàbá mi dé ọ̀dọ̀ rẹ̀, bàbá mi ké tagbáratagbára ó sì wí fún iwin náà pé: Njẹ́ ìwọ ni Àǹjànnú-ìbẹ̀rù tí i ṣe oníbodè Igbó Olódùmarè bẹ́ẹ̀?
Bí a kò bá jí Kristi dìde ninu òkú, a jẹ́ pé asán ni iwaasu wa, asán sì ni igbagbọ yín.
Ẹni tí ó bá gbà mí, ó gba ẹni tí ó rán mi níṣẹ́.
O fikun pe ikọ SARs to wa labẹ́ ijọba apapọ̀ ni igbakeji ọga agba ọlọpaa ati ẹka to wa fun isẹ iwadi ati ọtẹlẹmuyẹ yoo maa dari.
 Ìdá ààdọ ́ ta sí ọgọ ́ rin ninu ọgọ ́ rùn ún ènìyàn tí a fún ní òògù yìí ni wọn gba ìmúláradá .
Yar'adua ti figba kan ri jẹ gomina ipinlẹ Katsina ni iha ariwa orilẹede Naijiria laarin oṣu karun ọdun 1999 si oṣu karun ọdun 2007.
N óo wí fún un pé, “Baba, mo ti ṣẹ Ọlọrun, mo sì ti ṣẹ ìwọ náà.
18 Nítorínáà jẹ́ alãpọn; dúró ti ìránṣẹ́ mi Joseph, pẹ̀lú òtítọ́, nínú èyíkéyí ipò ìsòro tí òun lè wà nítorí ọ̀rọ̀ náà.
O ni ere tete ni gbogbo wọn sa wọle nigba ti ara naa san, iyalẹnu nla lo si jẹ lati rii pe ara naa ti pa awọn maluu ati aguntan naa.
Bí Jesu ti ń sọ̀rọ̀ lọ́wọ́, Judasi, ọ̀kan ninu àwọn ọmọ-ẹ̀yìn mejila dé, pẹlu àwọn eniyan tí ó mú idà ati kùmọ̀ lọ́wọ́.
’’kọmisọna fun Ile-isẹ agbofinro naa,Ali Janga  , wa  kilọ fun awon janduku to ba fẹ da wahala silẹ lasiko eto idibo pe , ti ọwọ awon agbofinro ba tẹ wọn, won yoo foju wina ijọba.
Ko to o di pe oloogbe ku, o sọ fun ọkọ rẹ lori ẹrọ ibaraẹnisọrọ pe oun ko gbọran mọ, bẹẹni oun ko riran mọ, eyi ti ko ribẹ ki ejo to o bu jẹ.
Oríṣun àwòrán, Reuters Bakan naa ni Ile Aṣofin Agba ni ilẹ Amẹrika ṣewadii wipe Atiku fi iye owo to to ogoji miliọnu dọla ilẹ okeere, nigba ti iyawo Atiku kẹrin, Jennifer Douglas fi iye owo to to miliọnu marundinlọgbọn ranṣẹ si ile ifowopamọsi to le ni ọgbọn ni ilẹ okeere.
Maria Street ni agbegbe Baruwa kan naa ni Ipaja ti iṣẹlẹ ti ṣẹlẹ ni wọn rii pe o ti dakẹ.
 awon elesin kristi gbagbo pe o loyun jesu nipa emin mimo .
atunyansipo gege bi aare orile-ede Naijiria, ti o n si n ki ijoba apapo fun
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìbejì Oníbẹ̀mbẹ́ Òru: Owó, ọmọ àbí aya kò leè yà wá Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Ìbejì Oníbẹ̀mbẹ́ Òru: Owó, ọmọ àbí aya kò leè yà wá 5 Ọ̀pẹ̀̀ 2018 Alhaji Taiwo ati Kehinde Onibẹmbẹ Oru ti pe ẹni ọdun mẹtalelọgọta, amọ ti wọn pa isẹ ọwọ ti wọn kọ ni aarọ ọjọ ti.
 Made at @FCBarcelona⚽ #Messi600🙌 YannDalon pic.
 orúkọ tí wọ ́ n mọ ̀ ọ ́ pẹ ̀ lú rẹ ̀ ni ' awon ' .
 a fi oruko re sori henri debehogne ( 1928 -2007 ) .
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Àwọn olórí orílẹ̀èdè lágbàáyé sọ èrò wọn lori ìkọlù Syria 14 Ìgbé 2018 Oríṣun àwòrán, Getty Images Lẹ́yín ti orilẹede Amerika, France ati ilẹ̀ Gẹ̀ẹ́sí pawọ́pọ̀ se ìkọlu si orilẹede Syria, awọn orilẹede àgbàye ti n fi èrò wọn hàn lorisirisi.
Òun ni ìpín ti ẹ̀yà Simeoni, gẹ́gẹ́ bí iye ìdílé wọn.
 Ose meji saaju iku re ni won ni o ni arun jejere lopolo re ko to wa doloogbe.
Iṣọla Oyenusi rèé, ẹnití ìfẹ́ obìnrin ṣun dé ìwà ìdigunjalè Ẹfunroye Tinubu - Ògbóǹtagí oníṣòwò, olówò ẹrú àti afọbajẹ Samuel Ajayi Crowther, òjíṣẹ́ Ọlọ́run tó gbé èdè Yoruba lárugẹ Mọrèmi Àjàṣorò, akọni obìnrin tó gba Ilé Ifẹ̀ sílẹ̀ lóko ẹrú Ọ̀rọ̀ǹpọ̀tọ̀niyùn, Aláàfin obìnrin àkọ́kọ́ rèé, tó ní nǹkan ọkùnrin Ṣé ìwọ mọ odò adágún Adó Àwáyè tí kò ní òpin ní ìsàlẹ̀?
Àwọn orílẹ̀-èdè yòókù yóo wá mọ̀ pé èmi OLUWA ni mo ya Israẹli sọ́tọ̀, nígbà tí ibi mímọ́ mi bá wà láàrin wọn títí lae.
Ìmọ̀ràn wọn ni ó tẹ̀lé tí ó fi pa ogun tirẹ̀ pọ̀ mọ́ ti Joramu, ọba Israẹli, láti bá Hasaeli ọba Siria jagun ní Ramoti Gileadi.
Abacha Loot: Amẹ́ríkà ní gómìnà Kebbi ló bá Abacha kó ọ̀pọ̀ bílíọnù dọ́là wá, tó sì lo oṣù mẹ́fà ní àhámọ́ òun
ti o si ṣe afihan rẹ nigba ti o ṣe abẹwo si llu kọọkan lati mọ oun ti wọn fẹ.
Adina, ọmọ Ṣisa, láti inú ẹ̀yà Reubẹni, olórí kan láàrin ẹ̀yà Reubẹni, pẹlu ọgbọ̀n àwọn ọmọ ogun rẹ̀; 
O wa ro awon oba alayeluwa naa
31 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Adajọ to n gbọ ẹjọ ọhun, Ibrahim Karaye, ti ni ki wọn gbe e lọ si ile iwosan awọn alaarun ọpọlọ fun ayẹwo.
je minisita fun eto eko lorile ede Naijiria , o ni ko si akọsilẹ fun iye awon
Loni ni Naijiria n reti awọn ọmọ Naijiria ti wọn n pada bọ wale fun irinajo abala akọkọ.
ijoba ti nawọ iranwọ si lati da wọn pada sorilẹ ede yii.
Mohammed Umar jẹ ọga ti o gaju lọ ni ipo to tẹle Ibrahim Magu, ti ijọba ni ko lọ rọọkun nile, lori ẹsun pe o ṣe owo kumọkumọ ati awọn ẹsun miran ti wọn fi kan.
Àwọn oníṣẹ́ náà tún pada wá sí ọ̀dọ̀ Ahabu, wọ́n ní Benhadadi ọba tún ranṣẹ, ó ní, òun ti ranṣẹ sí Ahabu pé kí ó kó fadaka rẹ̀ ati wúrà rẹ̀, ati àwọn obinrin rẹ̀, ati àwọn ọmọ rẹ̀ fún òun, 
Kí ló dé tí ẹ fi mú ọkàn àwọn ọmọ Israẹli rẹ̀wẹ̀sì kí wọ́n má baà rékọjá lọ sinu ilẹ̀ tí OLUWA fi fún wọn?
lati “Mu Ayipada rere ’ ti
Gẹgẹ bi akọsilẹ ti fasiti John Hopkins fi sita, o le ni ẹgbẹrun mẹtalelọgọrin eeyan to lo fara kasa arun ọhun lọjọ Abamẹta nikan ṣoṣo.
Oríṣun àwòrán, facebook Àkọlé àwòrán, Oja Ochanja ni Anambra jona; ajé wọgbo Ṣaaju lonii ni Aarẹ Muhammadu Buhari ti banujẹ lori iṣẹlẹ ijamba ina to ṣọṣẹ ni Ipinlẹ Anambra lọjọru ọsẹ yii titi di ọjọbọ ọjọ keji.
Ìjọba Ọyọ: Olówó nìkan kọ́ ni ìdájọ́ iléẹjọ́ yóò máa gbè ní Ọyọ
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Coronavirus in Osun: Ìlànà tuntun fún òkú sínsin wọlé dé sí ìpínlẹ̀ Ọ̀ṣun 28 Sẹ́rẹ́ 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 28 Èbibi 2020 Oríṣun àwòrán, osun state government Gẹgẹ bi ara ọna lati dena ajakalẹ arun coronavirus ni ipinlẹ Ọṣun, ijọba ipinlẹ naa ti gbe awọn ilana tuntun jade fun oku sinsin, eleyi ti gbogbo awsn mọlẹbi oku gbọdọ tẹle.
Láàrin ọpọlọpọ inúnibíni ẹ gba ọ̀rọ̀ ìyìn rere tayọ̀tayọ̀ láti ọ̀dọ̀ Ẹ̀mí Mímọ́.
Kini wáàsí Yusuf maa n dá lé lórí: Erongba Yusuf ni pe ki awọn eeyan maa tẹle ofin Sharia ninu igbesi aye wọn.
‘ASSU kò gba owó tó tó N15.
Ọkunrin naa ko laya jẹ debi pe oun lo n ṣakoṣo owo rẹ ati ohun gbogbo to ni, bẹẹ si ni ko le yi ẹnu pada.
Ọsinbajo kó Ambọde, Sanwo-Olu lẹ́yìn láti pín owóyàá l‘Eko Ọsinbajo sàbẹ̀wò sílé tó dàwó ní Abuja TraderMoni: Ṣé owó ìbò rírá ni lóòótọ́?
Ogboju adigunjale laarin ọdun 1990 si 2000 nii ṣe, ki ọwọ agbofinro to ba a, o lọ ṣe ẹwọn, nibẹ lo si ti ba Ọlọrun pade, o di ajihinrere fun Oluwa.
Amotekun kò tọ́ lábẹ́ ìjọba, ẹ búra fún wá, ká bọ́ sígbó láti ṣeré ọwọ́ pẹ̀lú ọ̀daràn - Sunday Igboho Mọ̀ síi nípa Shina Rambo tó pàdé Jesu lọ́gbà ẹ̀wọn lẹ́yìn tó ti jalè Ogun Àgbẹ́kọ̀yà, ìjà òmìnira fáwọn àgbẹ̀ ni àbí ìfẹ̀míṣòfò?
Saaju eyi ni won ti koko  bura fun
Wọ́n pàgọ́ sí Giligali ní ìhà ìlà oòrùn Jẹriko.
Ẹrọ to maa n fọ ọwọ Ọmọ ọdun mẹsan an kan, Stephen Wamukota, lo fi igi ṣe ẹrọ ọhun ni Kenya lati ṣadinku itankalẹ arun naa nilẹ ọhun.
 bí igi kan ò ṣe lè dágbó ṣe , bẹ ́ ẹ ̀ náà ni ẹnìkan ò lè dálùúgbé .
Bristow Helicopters: Awakọ̀ òfurufú tó lé ní ọgọ́rùn ún pàdánù iṣẹ́ toríi Covid-19
Tinubu: Buhari kò leè du ipò fún sáà kẹta láéláé
Nigba ti akowe agba fun ile ise iroyin, asa ati igbafe
Maaka ọmọ Absalomu ni ìyá baba rẹ̀.
Àyà pá àwọn àlejò,wọ́n sì fi ìbẹ̀rùbojo sá jáde kúrò ní ibi tí wọ́n sápamọ́ sí.
O ni o yẹ ki wọn ṣe ju bẹẹ lọ fun awọn oniṣẹ ibi oloju komu-ko-lọ wọnyii.
obinrin agbabọọlu meji ree ti wọn lẹ ori pọ yii lọjọ Sunday.
Múra, pa ilẹ̀ mọ́, máa dúró de ìdájọ́ ní ìgbẹ̀yìn ayé, àwọn ẹ̀dá alaàyè yóò mú ọ wá sí ìdájọ́ níwájú Olódùmarè ní ọjọ́ náà, eṣinṣin lásán yóò ro ẹjọ́ mọ́ ọ, èèrà yóò jẹ́rìí gbè ọ́ lẹ́sẹ̀, o kò sì níí rí ọ̀rẹ́ láàrin ènìyàn àti ẹranko: nítorí ìwọ ti ba onírúurú iṣẹ́ ọwọ́ Olódùmarè jẹ́, ìwọ ti gé ayé àwọn ẹja kúrú, o ti ba ìgbádùn àwọn kòkòrò jẹ́, ekòlò aláìmọ̀kan kiò sì kúrò lọ́wọ́ pàsán rẹ.
A lérò wi pé ni àsìkò ọ̀wọ́n owó pàtàki owó òkèrè ni ilú lati ṣe nkan gidi, ifẹ́ iná àpà fún ayẹyẹ á din kù.
Ọmi ayo meji ni awọn ati CSKA jijọ gba ni Moscow.
Kí ojú lè tì ọ́ fún gbogbo ohun tí o ṣe tí o fi dá wọn lọ́kàn le.
Adajọ ni ki wọn ko awọn afurasi mejeeje naa lọ si ọgba ikọ ọlọpaa to n tako iwa idigunjale, SARS nilu Ibadan.
"Pípa Orílẹ̀-Èdè k'Órílẹ̀-Èdè run kò gba lílo àdó olóró tàbí àwọn ohun-èlò ìjà olóró alárìnjìnà.
Àwọn iṣẹ́ tí Baba ti fún mi pé kí n parí, àní àwọn iṣẹ́ tí mò ń ṣe, àwọn ni ẹlẹ́rìí mi pé Baba ni ó rán mi níṣẹ́.
8 638 Orilẹede Brunei 3 0.
Ọkùnrin tí kò ríran kan rèé tó ń lọ ẹ̀rọ ata Ìpanu ‘Cheese ball’ ni wọ́n fi jí Ikimot gbé, àmọ́ ó padà sílé lẹ́yìn ọdún márùn-ún Mo fẹ́ pa ara mi torí ojú àbùkù tí wọn ń fi wò mí pé mo fi iṣẹ́ abẹ bímọ"" 5:30 p."
  Mo kí gbogbo yín kú àlàjá 2013.
Awon akekoo Zimbabwe ko itan tuntun lagbaye nipa gbigba ami eye ti Guiness World Record fun tito Marimba to poju lagbaye.
"Sotitobire àti àwọn wòlíì ọmọ Nàìjíríà míràn tó ti lọ sẹ́wọ̀n nítorí ẹ̀sùn ìwà ọ̀daràn Ìdájọ́ ẹ̀wòn gbére kò ní kí Wòlíì Sotitobire má lọ sí ilèẹjọ́ kòtẹ́milọ́rùn - Agbẹjọ́rò Pásítọ̀ Alfa Babatunde Àwọn kan ṣónú bí wọ́n bá di gómìnà, ẹ fún wa láyè láti wá parí iṣẹ́ táa bẹ̀rẹ̀ - Akeredolu Bo tilẹ jẹ pe agbẹjọro fun ijọba ipinlẹ Ondo lori ẹjọ naa, Adekola Olawoye, sọ pe idajọ ododo lo waye lori ọrọ naa, nitori pe ""bi irọ ba lọ logun ọdun, ọjọ kan ni otitọ yoo ba""."
Eri ati Onani kú ní ilẹ̀ Kenaani.
Owό ni èrò ọkàn Olόwό-Ìbínú ní ìgbà gbogbo, owó sì ni ό fẹ́ràn júlọ ní òde ayé.
Irawọ rẹ bẹrẹ si ni tan nigba to wa ni ile iwe rẹ ni Washington DC nibi to ti kọkọ kọ nipa ẹkọ katakara ko to lọ kọ nipa ẹkọ orin kikọ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Seyi Makinde; Ilé iwosan kan ṣoṣo tó wà ní Idí-Iroko /Adewole tí bàjẹ́ pátápátá.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ikọ̀ Super Falcons kijó mọ́lẹ̀ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Asisat Oshoala: ìbẹ̀rẹ̀ mi kò rọrùn rárá nínú eré bọ́ọ̀lù Senegal ati South Africa naa wa lara awọn orileede ti yoo ṣoju ilẹ Afrika ti ireti si wa wi pe ọkan lara Ghana tabi Mali yoo jẹ́ orileede kẹrin lẹyin ti wọn ba gba ifẹsẹwọnsẹ wọn ti yoo waye lọjọ abamẹta.
O ni ẹẹkan ṣoṣo to laju, 'Iṣẹ́ Olúwa' nikan ni ọrọ to sọ lẹyin ti wọn mu.
Odusile fikun wi pe awọn ọmọ to wa nibi ile ibugbe awọn ọmọ orukan naa wa ni abẹ aabo to daju nitori gbogbo wiwọle-jade wọn ni awọn n tọpasẹ rẹ.
"Ibo là ń lọ ní orílè èdè Nàìjíríà, Ibo là ń lọ náà, Mo nífẹ̀ẹ́ orílẹ̀ èdè mi ti ṣe Nàìjíríà, Mo fé mọ ibi tí a ń lọ ní orílè èdè Nàìjíríà.
Idi ree ti wọn se gbe Sara kuro ni South Afrika lọmọ osu meje, ti wọn si gbe fun alagbatọ nilu ọba, ẹni to ti orukọ Karoline pada si Sara, ngba ti awọn obi Sara si pada de si South Afrika, ni wọn kede pe Karoline, ọmọ wọn ti ku.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Yoruba Language: Akomolede ati Asa Yoruba tọ̀sẹ̀ yí rèé lẹ́nu olùkọ́ wa Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Yoruba Language: Akomolede ati Asa Yoruba tọ̀sẹ̀ yí rèé lẹ́nu olùkọ́ wa 25 Ògún 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 30 Ògún 2020 Imọ ede Yoruba ko yọ ẹnikẹni silẹ.
Ó bá sọ fún ọmọ-ẹ̀yìn náà pé, “Wo ìyá rẹ.
Pa mí mọ́ Ọlọrun, nítorí ìwọ ni mo sá di.
Yóo pa àwọn ìlú yín run,kò sì ní sí eniyan ninu wọn mọ́.
Àkọlé àwòrán, ṣugbọn ohun ti mo le ranti ni pe o fi ọwọ rẹ to dọti bọ oju ara mi.
Samson Siasia: Ẹ rànmí ìrànwọ́ pẹ̀lú N100m láti ṣejọ́ jìbìtì tí FIFA fi kàn mi
” Ṣugbọn ẹ̀ ń bèèrè pé, “Kí ló fihàn pé o fẹ́ràn wa?
 sugbon , ikisi re kereju ti awon planeti onile mererin lo .
Wọn tún ń kọ Àbàjà mẹ́ta-mẹ́ta , tàbí Gọ̀mbó, Kẹ́kẹ́ àti Gọ̀mbó papò.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Idije FA Cup Agbabọọlu Manchester City lo gbe ọkan ninu awọn agbabọọlu Swansea ṣubu, ti rẹfiri si fun wọn ni pẹnariti.
O so pe : “Mo wa niluu London nigba ti iroyin nipa Nnamdi Kalu to wa lorile ede Isreal, te mi leti, sugbon mi o tete fesi laarin wakati die , ni mo ri aworan mi  ati iroyin naa lori ero ayelujara pe mo ti fun orile ede Isreal ni gbedeke lati da Nnamdi Kalu pada tabi ki a fi ado oloro ranse si won.
“Lẹ́yìn náà, fi awọ àgbò tí a ṣe ní pupa, ati awọ ewúrẹ́ tí a ṣe dáradára, ṣe ìbòrí keji fún àgọ́ náà.
Oríṣun àwòrán, Stelladimokorkus Àkọlé àwòrán, Eyi ni yo lè jẹ ki ọ mọ ibi ti oju gọ́tà tabi ihò wà láti yago fun.
O tẹ siwaju pe: iru iwa jibiti yi kii jẹ ki awọn ọmọ wa ri oluranlọwọ, ati pe o lee jẹ ki awọn oludokoowo fa sẹyin lorilẹ-ede wa."
Ẹgbẹgbẹrun eniyan lo ti ku latari itankalẹ aarun coronavirus naa, to bẹ silẹ ni ilu Wuhan, lorilẹede China, to si ti tan kalẹ de awọn orilẹede miran lagbayẹ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó Iwadii ajọ NHS tun fihan pe, igbeyawo laarin ẹbi wọpọ laarin awọn ọmọ orilẹede Pakistan to n gbe ni UK.
Ìkọ ́ ni ni orílẹ ̀ -èdè yi ti dojú kọ ́ ọ ̀ pọ ̀ lọpọ ̀ ìsòro tí ósì ti ń se àkóbá fún ètò ọrọ ̀ ajé àti ìdàgbà sókè ilẹ ̀ yí .
Wọ́n dó ti Juda, wọ́n gbógun tì wọ́n, wọ́n kó gbogbo ìṣúra tí ó wà ní ààfin lọ, pẹlu àwọn ọmọ Jehoramu ati àwọn iyawo rẹ̀.
Oríṣun àwòrán, TAJUDEEN Adesola Àkọlé àwòrán, Wọn ti gbe awọn to farapa lo si ile iwosan Agbẹnusọ fun ileeṣẹ to n risi iṣẹlẹ pajawiri ni ipinlẹ Eko, Adebayo Kehinde (Lasema) to si fi idi isẹle naa mulẹ so wi pe iṣẹlẹ ijanba yi da ẹmi awọn ọkunrin mẹta legbodo lẹsẹkẹsẹ.
O ni orukọ tawọn obinrin ilu naa sọ Muhammad tẹlẹ ki ọwọ too tẹ ni '''Mai Sikẹti'' Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Joke Silva: Olu, ó tó gẹ́ pẹ̀lú obìnrin yìí níkan tó ń ba ẹ ṣeré ìfẹ́ nínú sinimá Muhammad Jamil tó jẹ Kansẹlọ wọọdu Yalwa ni ilu Dangora sọ fun akọroyin BBC pe idunnu ti ṣubu lu ayọ gbogbo awọn olugbe ẹkun yii nitori pe arakunrin Mai Sikẹẹti yii ti da ọpọlọpọ igbeyawo awọn eniyan ru.
Igba akọkọ si ree ti awọn alasẹ yoo fidi isẹlẹ naa mulẹ fun awọn akọroyin pẹlu atẹjade.
Awọn eeyan kan ni ọna lati gba owo lọwọ awọn ara ilu ni igbesẹ yii, kii se ootọ rara.
" Kò sáyè iwọ́de mọ́ l'Eko ẹ lọ tọwọ́ yín bọṣọ - Ọlọ́pàá N kò ní buwọ́ lu ìṣúná tí kò pèsè owó fún ẹ̀bí àwọn tó kú nínú ìwọ́de EndSARS - Gbajabiamila Buhari, jáde bá ọmọ Nàíjíríà sọ̀rọ̀, orí àgbá ẹ̀tù la dúró lé - NUJ pariwo O salaye pe awọn ko ni fẹ gbe igbimọ kalẹ ti ko wa ni ṣi awọn eeyan ti yoo gbẹjọ wa ba wọn.
''Ṣugbọn awọn ọta lo kan n polongo ohun ti ko ṣẹlẹ kaakiri,'' Pasitọ Oba lo sọ bẹẹ ninu iwaasu rẹ.
Ọgbẹni Bashir ti wa lori alefa gẹg bi aarẹ fun o ti fẹrẹẹ to ọgbọn ọdun bayii, lati igba naa lo si ti n kọjalẹ lati faye gba gbigbe agbara le ijọba mii lọwọ.
Okan lara awon olukopa ninu idanilekoo naa nipinle Eko, Adekumbi Odusoga fidunnu re han si ise ti won ti n ko nibi eto idanilekoo naa pelu ifimoorehan fawon agbateru eto ohun nipa rirogun sawon odo Naijiria lapa.
Wákàtí mẹ́rìnlá làwẹ̀ gbígbà ni Nàìjíríà,Kenya wákàtí mẹ́tàlá, Egypt si jẹ́ wákàtí mẹẹdogun.
22 Bélú 2020 Fídíò, Erelu Elemure: Ìyá mi rò pé mi ò lè tibi kíkọrin bíi bàbá mi là21 Bélú 2020 Covid 19 update: Wo ǹkan mẹ́wàá tó yẹ kí o mọ̀ tí o bá fẹ́ lọ fún ìsinmi lẹ́yìn Covid 1923 Bélú 2020 Fídíò, Akomolede Yoruba: Kí ni ìdí tí aṣọ fi máa ń pọ̀ lára Egúngún ju Orò lọ́?
18 Agẹmo 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ọ̀pọ̀ ènìyàn ló ti ń fi ẹni tó se móríyá fún wọn jùlọ ní ìdíje erébọ́ọ̀lù ilẹ̀ Afirika, Afcon 2019.
O mu apẹrẹ ọrọ bi Ifa lede Yoruba ati Afa ni ede Igbo, Atọ ati ẹta, owu ti awọn ẹya mejeeji jijọ n lo lati sapèjuwe owu iranṣọ ati ori jijẹ ti awọn mejeeji jọ n lo ọrọ kanna fun.
Paulu wá tẹjú mọ́ ọn lára, ó rí i pé ó ní igbagbọ pé wọ́n lè mú òun lára dá.
Nígbà tí igbe yìí pọ̀ jú àwọn ọlọ́pàá ejò jí wọ́n mú un, wéré wọ́n sì bù ú jẹ.
Toyin Abraham fi ikede yi sojuopo Instagram rẹ to si ni ki awọn ololufẹ ohun ma foya nitori pe ọjọ naa de tan loju ẹlẹmi.
Bí ẹnikẹ́ni bá ba Tẹmpili Ọlọrun jẹ́.
“Bí ẹ bá kọ̀, tí ẹ kò tẹ̀lé gbogbo òfin tí a kọ sinu ìwé yìí, pé kí ẹ máa bẹ̀rù orúkọ OLUWA Ọlọrun yín, tí ó lẹ́rù, tí ó sì lógo, 
 Inu mi dun pe ipinle yii ti bere igbese kebi ma pelu ninu eto ogbin ati ki onikaluku gbin igi kaakiri.
Ọpọ awọn eniyan ni kii tete fura pe o ti n ba awọn ja ni eyi to maa n gba oju lọ to ba ti pẹ lara.
Gege bi atejade ipo ate tuntun ohun, Quadri wa nipo kejilelogun losu ti o koja, pelu akojo ami ẹ̀gbẹ̀rún mewa le ni òjìlénígba dín mẹfa(10,234), saaju akegbe re, Assar ti oun ni akojo ami ẹ̀gbẹ̀rún mewa le ni òjìlénígba dín meje(10,233), bee si ni Assar tun jawa le lati ipo kẹ́tàdínlógún sipo kọ́kànlélógún ninu ipo ate naa.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Rape cases in Nigeria: Ọmọ ọdun 5 àti 14 ni Kalu wà nígbà tí obìnrin fipá ba lòpọ̀ Wọn ni ai lọ si ileewe tun ti jẹ ki ọpọ awọn akẹkọọ maa ṣe kongẹ iwa ipa lawujọ.
O ní àwọn míràn rò pé ìdásílẹ̀ DISCO ní ọ̀nà abáyọ sí ibi ti wọ́n maa dájọ ìná mọ̀nàmọ́na sí gẹ́gẹ́ bi wọ́n se ti n ṣe láti ọdún díẹ̀ sẹ́yìn.
“Ohun tí yóo jẹ́ àmì fún ọ nìyí Hesekaya: Ní ọdún yìí, ohun tí ó bá lalẹ̀ hù ni ẹ óo máa jẹ.
Ìbejì tó so papọ̀ dolóògbẹ́ ní Tanzania IVF ni obìnrin yìí se lẹ́ẹ̀mẹrin tó fi bí ìbejì Dokita ni ọpọlọ awọn mejeeji n ṣiṣẹ funrawọn sugbọn lati ya wọn, wọ́n á kọ́kọ́ pín àwọn ẹ̀jẹ̀ tó so mọ́ ọpọlọ.
Pọtifera yìí jẹ́ babalóòṣà oriṣa Oni, ní ìlú Heliopolisi.
Lẹyin eyi ni igbakeji aarẹ Trump, Mike Pence ni: ijọba Trump ṣetan lati ṣiṣẹ papọ pẹlu awọn agbaagba ẹgbé mejeeji nile igbimọ aṣofin lati gbe igbesẹ to yẹ lati wa ojutuu si iṣoro aṣiyin ibọn to n koju orilẹ-ede wa.
Ile ẹjọ ọhun tun ni, oludije labẹ asai ẹgbẹ PDP ko fi idi rẹ mule pe, itakun ayelujara to ti ri esi idibo naa jẹ ti ajọ eleto idibo tabi kii ṣe ti ajọ INEC Ati pe Atiku kuna lati fidiẹ mulẹ pe aiṣe deede wa lasiko idibo naa ati pe wọn dibo kọja iye.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Da Rocha: Ìlú Iléṣà ni bàbá miliọníà àkọ́kọ́ ti wá, àmọ́ ó ṣe ẹrú ní Brazil 18 Sẹ́rẹ́ 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 23 Owewe 2020 Oríṣun àwòrán, NigerianMuseum Ni ọpọ igba, lawọn eeyan maa n ṣe apejuwe eeyan kan to ba ri jajẹ ni awujọ pe ẹni naa lowo bii Da Rocha tabi pe o lowo ju Da Rocha lọ.
 Oríṣun àwòrán, @aishambuhari Nigba to n dahun si bawọn eeyan kan se woye pe o binu fi ile ọkọ rẹ silẹ, to si gba ilẹ okeere lọ, Aisha ni ahesọ lasan ni ọrọ ọhun nitori ko si ohun to jọ bẹẹ."
 oluile-ise re wa ni washington , d.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ibo Sierra Leone: Awọn alabojuto ibo pinu ibo to yanranti 5 Ẹrẹ̀nà 2018 Oríṣun àwòrán, ECONEC/Paul Ejime Àkọlé àwòrán, Iṣẹ nla wa ni iwaju awọn aarẹ naa lati ri ki eto idibo lo ni rọwọ n rọ sẹ Awọn olori ikọ alabojuto ibo ti ṣe'pade ni olu ilu Sierra Leone, Freetown lati ṣe agbekalẹ eto to yaranti fun eto idibo ni orilẹede naa.
 ní bíi ọdún 2014 , òṣùwọ ̀ n owó rẹ ̀ lójú pálí ní àwọn ìlú tí ó ń dàgbàsókè kúsí us $ 0.
Lójú kan náà ó bá mú àwọn ọmọ-ogun pẹlu àwọn balogun ọ̀rún tí ó wà lábẹ́ rẹ̀, ó sáré lọ bá wọn.
O ni Ọlọrun sọ fun oun pe ki oun ko gbogbo naa fun oninrin ọhun.
Agbábọ́ọ̀lù Super Falcons tẹ́lẹ̀, Chiejine jáde láyé lẹ́ni ọdún 36 Wo àwọn eléré ìdárayá mẹ́ta tí àjọ FIFA ti fòfin dè títí ayé Amọṣa, ṣe awọn agba bọ wọn ni bi ẹṣin ba da ni aa tuu gun ni.
O ṣalaye pe awọn yoo ṣeto tuntun eleyi ti awọn ipinlẹ tọrọ kan naa yoo da si eto wọn.
Ìjọba Èkó figbé ìkìlọ̀ ta Arsenal ṣẹ́ṣó ìyà, búlálà ẹlẹ́nu mẹ́ta ni Leicester City fi lù wọ́n lálù bami O ti le lọjọ marun bayii ti Baalẹ Razak ti di awati.
Beteṣasari, olórí gbogbo àwọn pidánpidán, mo mọ̀ pé ẹ̀mí Ọlọrun mímọ́ wà ninu rẹ, ati pé o mọ gbogbo àṣírí.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ayinla Kollington: ọ̀rẹ́ ni èmí àti Barrister kó tó jáde láyé Salawa ni ''ọjọ ti inu mi dun ju laye lọjọ ti mo gbe awo akọkọ mi jade, bẹẹ ni ọjọ ti inu mi bajẹ ju ni ọjọ ti mo padanu ọmọkunrin mi.
Israẹli yóo sì máa pọ̀ sí i ní agbára.
N ṣe ni awọn eniyan to bẹẹrẹ bẹ fun ọpọlọpọ wakati lati sẹ ayẹwo ara wọn, ki wọn o to kọja lọdọ awọn ẹsọ aṣọbode.
 ní awọn ibikan , ìtànkálẹ ̀ lè wà láàrin awọn ọgọta sí aadọrun un ninu ọgọrun un awọn ọmọde , tí ó sì maa n wọ ́ pọ ̀ laarin awọn obinrin ju ọkunrin lọ nitori awọn ni wọn n fara kan awọn ọmọde jù .
Ọmú rẹ mejeeji dàbí ọmọ àgbọ̀nrín meji,tí wọn jẹ́ ìbejì.
Naijiria balẹ lati pese eto aabo fun ẹmi ati dukia fun gbogbo omo orile ede
 O ni, “inu mi dun lati ṣe iranlọwọ bayii fun awọn eniyan ẹkun oṣelu mi, lat fẹmi imoore han si atilẹyin wọn fun mi.
 o k ' eko gboye imo nipa ere ori itage lati ile eko giga yunifasiti ti ibadan .
Ki o to kuro lorilẹ-ede Naijiria lọ ba iyawo rẹ ni Amẹrika lo ti sọ fun un pe, ko si iṣẹ miran ti oun nifẹ si lati ṣe lorilẹ-ede Amẹrika to fẹ ki oun wa ju iṣẹ agbẹ lọ.
O ni lootọ ni owo ori sisan wa ninu Bibeli, amọ, ko wa ni ibamu pẹlu ilana ẹsin awọn ọmọlẹyin Kristẹni.
eto ọgbin ati ohun alumọọni n se agbatẹru rẹ , nitori pe eto yii ko wa ni ibamu
Nigba ti awon akoroyin kan si
Nigba ti wahala naa yoo fi dẹkun, ọpọ ẹmi lo ti lọ si i ti awọn ọlọpaa si kede iku Mohammed Yusuf to wa ni ahamọ lọdọ wọn.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Rashidi Ladoja: Èmi kìí ṣe olóṣèlú mọ́, n kò sí nínú ẹgbẹ́ òṣèlú kankan 10 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Oríṣun àwòrán, Akanbi Abiola/Facebook Gomina ana nipinlẹ Oyo, Sẹnetọ Rashidi Ladoja ti asalaye idi to fi ls se abẹwo si gomina tẹlẹ nipinlẹ Eko, Asiwaju Bola Ahmed Tinubu.
Kí ẹ má sì di abọ̀rìṣà bí àwọn mìíràn ninu wọn.
Wọ́n lọ títí tí wọ́n fi dé Tapanhesi.
Sophie ti wa ri ẹni ti yoo le ba ṣe iṣẹ abẹ daada lẹyin ti o ti o ti ṣe iwadii lori ẹrọ ayelujara.
Nkrumah ni awọn dokita ti gba Aarẹ ilẹ Ghana, Nana Akufo ni imọran lati wa ni iyasọtọ fun ọjọ mẹrinla bẹrẹ lati Ọjọ Kẹrin, Oṣu Keje, ọdun 2020.
”Wayii o, Oshiomhole so pe egbe oselu APC ti yan asofin Ahmed Lawan ati eni owo Femi Gbajabiamila lati dije dupo Abenugan ile igbimo asofin ati agbenusoro nilee igbimo asoju-sofin(Senate President and Speaker House of Rep).
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ìbànújẹ́ ló pọ̀ nínú òṣèlú Nàìjíríà tórí a ti lo Pásítọ̀, Wòlìí, Ọ̀jọ̀gbọ́n Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Òkété bórù mọ àwọn ọjọgbọ́n méji lọ́wọ́, UNIABUJA jù wọ́n síta Kínla!
Ní bayìí, orilẹ̀-èdè mẹẹdogun ni wọ́n ti fi ofin de láti ma wọ Naijira mọ Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí 6:30 Fídíò, Akomolede ati Aṣa lori BBC: Mọ̀ si nípa oríṣìí ẹ̀ka ìsọ̀rí ọ̀rọ̀ àti ìwúlò wọn, Duration 6,308 Owewe 2020 Fuel hike protest: Àwọn akẹ́kọ̀ọ́ ìpínlẹ̀ Oyo, Osun àti Ondo ṣe ìfẹ̀hónúhàn lórí èlé owó iná àti owó epo8 Owewe 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Ni Bangladesh, olootu ijọba Sheikh Hasina n tiraka ni lati mu adinku ba iye eeyan to gba tọwọ arun yi ku nilẹ to ni ọkan lara awọn eeyan to pọju lọ lagbaye.
Ilé-ẹjọ́ ìlú Èkó fi Nwaoboshi sátìmọ́le fún ìkówójẹ
Igbakeji aare ni ti won ba dibo fun aare Muhammadu Buhari yoo tun
 oluilu re ni hamilton sugbon ibile titobijulo ni ilu saint george ' s .
Nígbà tí mo bá ta ọfà burúkú mi si yín: ọfà ìyàn ati ọfà ìparun, tí n óo ta lù yín láti pa yín run, ìyàn óo mú lọpọlọpọ nígbà tí mo bá mú kí oúnjẹ yín tán pátá.
"Bo ba wa dari ere kan lonii to di oṣu to m bọ to mu omii, ọtun ọtun lẹ o maa ri ninu iṣẹ rẹ""."
Ìpànìyàn Akinyele: Àwọn ìgbésẹ̀ tí ọlọ́pàá ń gbé lórí ikú Mujeeb tí wọ́n pa nílùú Ibadan
Ọ̀tá ti tọwọ́ bọ ilé ìṣúra rẹ̀,wọ́n sì ti kó gbogbo nǹkan iyebíye inú rẹ̀ lọ;ó ń wo àwọn orílẹ̀-èdè mìíràn,tí wọn ń wọ ibi mímọ́ rẹ̀.
Irọ́ ni pé Gómìnà Edo Obaseki ti darapọ̀ mọ́ ẹgbẹ́ PDP Kí ló mú Aisha Buhari figbe bẹnu pé kí Ọ̀gá Ọlọ́pàá tú àwọn ẹ̀sọ́ rẹ̀ siíẹ̀?
Ní àkókò náà, èmi Daniẹli ń ṣọ̀fọ̀ fún ọ̀sẹ̀ mẹta.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Àwọn ìgbà tí ẹ̀ṣọ́ aṣọ́bodè ti pànìyàn lọ́nà àìtọ́ Àjọ aṣọ́bodè gba Codeine N200m Iléeṣẹ́ aṣọ́bodè gba nǹkan ìjagun àìtọ́ Ẹ́ wo iye ààrẹ Nàíjíríà tó sọ̀rọ̀ ìjayà lásìkò ìbò INEC tako àṣẹ Buhari lórí pípa ẹni tó bá jí ìbò gbé Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Damilọla Ajayi: Ọ̀dá owó ló ṣún mi dé ìdí lílo ìyarun bíi fèrè Awọn ohun meje to jẹyọ ninu ọrọ ti oludije fun ipo aarẹ ninu ẹgbẹ oselu PDP, Alhaji Atiku Abubakar naa ree: APC fẹ lo ẹrọ igbalode lati fa isọwọ-sisẹ ẹrọ kaadi idibo sẹyin Ninu ọrọ rẹ, Alhaji Atiku Abubakar ni ẹgbẹ oṣelu APC ti ran awọn kan lọ sorilẹede China lati lọ kọ iṣẹ, ti wọn si ti ko ẹrọ igbalode le wọn lọwọ.
Ibidun Ighodalo: Oríṣun àwòrán, Others Iroyin iku Abilekọ Igbhodalo lo ba ọpọlọpọ ọmọ Naijiria lojiji, lẹyin to ki aye pe o digboṣe ni Ọjọ Kẹrinla, Oṣu Kẹfa, ọdun 2020 lẹni ọdun mọkandinlogoji.
Ninu oúnjẹ tí òun pàápàá ń jẹ ni ó ti ń fún un jẹ, igbá tí ọkunrin yìí fi ń mu omi ni ó fi ń bu omi fún ọmọ aguntan rẹ̀ mu.
O ni ọrọ náà nise pẹlú ààbò ẹmi Seneto Dino.
O ni wọn fẹ fi tipa ba iya oun lopọ, ti oun si tako wọn, ni wọn ba fi idi ibọn fọ oun loju.
Àwọn ìbéèrè tó ṣàlàyé ohùn tó fẹ mọ nípa bi wọ́n ṣe ń yọ ààrẹ nípò l'Amẹrika Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Awọn oluwọde ni New York n lọgun ki wọn yọ Trump nipo loru ọjọ idibo lati yọ Trump Awọn to n fọkan ba iyọni nipo aarẹ Trump ti n beere ọrọ nipa ohun to le tẹyin iṣẹlẹ yi wa.
Charles Okah gba'dajọ ẹwọn gbere Lush beauties: Ara sisan kii n ṣe arun Ọgbẹni Peter Njonjo to jẹ aarẹ ileeṣẹ Coca cola lẹkun iwọ oorun ilẹ Afirika, lo ko ikọ FIFA sodi lọ si ọdọ aarẹ orilẹede Naijiria.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ọ̀pá epo bẹntiróò gbina nílu Èko Bùhárí padà dé sí Nàíjíríà Àwọn mọ̀lẹ́bí tó ti kópa nínú ife ẹ̀yẹ àgbáyé Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí 2 sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 2:23 Fídíò, Water Generator: Ó leè ṣiṣẹ fún wákàtí mẹfà, kó tó sinmi, Duration 2,2310 Òkùdu 2020 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
Nítorí náà, máa bá ọ̀rọ̀ rẹ lọ.
Aye lati ri omi to mo gaara mu je ipenija fun ogoro awon omo orile-ede Naijiria, ni paapaa julo awon ti won n gbe ni igberiko, gege bi osuwon iwadii ti ijoba orile-ede Naijiria se laarin odun 2016 si odun 2017, safihan pe io ogoji ninu ida ogorun 40%, eyi ti o je milionu mokandinladorin 69 awon eniyan ni won ko ni anfaani si omi to mo gaara muNi awon igberiko, awon eniyan ti iye won to milionu mokandinlogun ni won n rin ona to ji, ki won to ri omi ti ko dara to pon ni awon odo to n san.
Ààwẹ Ramandan: Àwọn ouńjẹ tí a fi ń sínu àwẹ̀
Láti ìgbà náà lọ, àwọn orílẹ̀-èdè káàkiri bẹ̀rẹ̀ sí kókìkí rẹ̀.
20 Owewe 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 21 Owewe 2020 Oríṣun àwòrán, Getty Images Aisan tabi ipenija lori ki agbalagba ma a tọ sile jẹ ọkan lara awọn aisan ọpọlọ ti o maa n ṣẹlẹ si awọn eniyan lawujọ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Sotitobire: Ọkọ mi kò mọ̀ Jegede PDP rí, kódà kò fa ẹnikẹ́ni kalẹ̀ dípò Akeredolu- Bisola Itakun Ayelujara 5G: Oṣu keji Ọdun 2019 ni ileeṣẹ Samsung ṣe ifilọọlẹ 5G fu foonu Galaxy S10 lẹyin naa ni Huawei, OnePlus ati Google ṣe tiwọn naa pẹlu foonu oni 5G.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Trump-Mo ni ọwọ nla fun ilẹ Afrika 28 Sẹ́rẹ́ 2018 Àkọlé àwòrán, Donald trump yoo fi awọn asoju to dantọ ransẹ silẹ Afrika Aarẹ ilẹ Amẹrika, Donald Trump ti fi iwe sọwọ sibi ipade awọn orilẹede nilẹ adulawọ to nlọ lọwọ nilu Addis-Ababa, lorilẹede Ethiopia.
Àrá sán pa ènìyàn mẹ́ta Ìtàn ọmọ Afirika tó ló lówó jùlọ lágbàyéé rèé Bí wọ́n ṣe ń ta káádì ìdìbò ní Kano nìyì Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Sẹ́gílọlá: Arúgbó awẹ́lẹ́wà tó ń ṣiṣẹ́ omidan Wọn fi kún pé àwọn yóò ma woye lóri bi ètò ìdìbò ṣe ń lọ nítori kò sí ẹgbẹ́ tàbí ẹni kankan ti àwọn ń gbè sí lẹ́yìn.
Ọlọ́pàá méjì dèrò ọ̀run nínú ìjàmbá ọkọ̀ l'Akure lẹ́yìn tí wọ́n kúrò níbi tí Akeredolu ti gba ìwé-ẹ̀ri moyege Mo fẹ́ ìdájọ́ òdodo lórí ikú tó pa ọmọ mi- Baba ọmọ ti SARS pa Kíni ìyàtọ̀ tí yóò wà láàrin SARS àti SWAT?
Oríṣun àwòrán, @ojude oba Àkọlé àwòrán, Lara awọn ọdun ilẹ Yoruba ni ọdun ojude Oba to maa n waye ni ọjọ keji Ileya nilu Ijẹbu Ode nipinlẹ Ogun.
James Manager náà wà lára àwọn ti Akpabio naawọ́ sí pé ó gba kọngilá mẹ́fà, sùgbọ́n Manager náà ni òun ko gba kọgila kankan.
Ọkùnrin kan, Kabiru dèrò ẹ̀wọ̀n lẹ́yìn tó jí súùtì àti àwọ̀tẹ́lẹ̀ ọkùnrin nílé ìtàjà ní Abuja Nigeria police brutality probe: Ohun tí akọròyìn BBC rí rèé lásìkò ikọlù níbi ìwọ́de Lekki Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Wọ́n kúrò ní Aluṣi, wọ́n lọ pàgọ́ sí Refidimu níbi tí wọn kò ti rí omi mu.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Coronavirus in Nigeria: Ẹ wo àǹfààní tó wà nínú àrùn Coronavirus Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Bakan naa ni aare wat un pase fun  awon agbofinro lati mojuto eto aabo awon awako
Yinka Odumakin (fun guusu iwọ oorun Naijiria); Ogagun CRU Iherike (fun Guusu Ila oorun Naijiria); Senetọ Bassey Henshaw (fun Guusu-Guusu) àti Omowe Isuwa Dogo (fun Aarin Gbungbun) lo fọwọ sii.
Mo kọ̀ láti yí ọ̀rọ̀ mi padà lórí ètò ẹ̀kọ́ ọ̀fẹ́ - Gómìnà Dapo Abiọdun Ẹ ṣèwádìí ikú Ọ̀jọ̀gbọ́n Gideon Okedayọ - ASUU Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí kan sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
O ní láì jẹ́ pé enikẹni bèèrè lọ́wọ́ òun, ohun to bójúmu láti ṣe ni, tori ohun ti ìgbàgbọ òun rọ mọ láti ṣe ni.
O ni o ti di itẹwọgba bayii nitori ko wọpọ laarin awọn eeyan dudu tẹlẹ, to si wa n beere iranwọ ijọba fun ipese ibudo ti awọn yoo ti maa se idanilẹkọ nitori ibi ti awọn wa bayii ko ni aabo to.
Àkọlé àwòrán, Jafar Jafar niwaju igbimo ile asofin ipinle Kano Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: 'Pọ́ńbélé Yorùbá ni mí, n ò sì ní tijú rẹ níbikíbi' Wo òtítọ́ nípa oúnjẹ Nódùùlù táwọn ọmọde ma ń jẹ 'Irọ́ ni, mi ò ṣàdéhùn ìfẹ́ pẹ̀lú ẹnikẹ́ni' Igbimọ ile naa ti saaju fi iwe pe Ja'afar Ja'afar lati wa wi tẹnu rẹ nipa fidio naa ti o n ja rain-rain.
Lasiko to fi n gba itọju fun aisan jẹjẹrẹ lo jade laye ni orilẹede Canada.
Akàrà tú sépo fún àwọn kọ̀lọ̀rànsí náà nígbà tí wọ́n ní kí ọ̀kan lára àwọn oníìbárà wọn, Abdulrahman Mumini ó lọ wá ẹgbẹ̀rún lọ́nà ọ̀rìnlélúgba náírà wá láti fi ṣètùtù, tí onítọ̀ún sí fi ìsẹ̀lẹ̀ náà tó àwọn ọlọ́ọ̀pá létí.
Ẹ máa bu ọlá fún wọn gẹ́gẹ́ bí ẹni tí kò lágbára to yín.
Akonimoogba agba iko agbaboolu Croatia, Zlatko Dalic so pe: “A gba ere fun akitiyan ati bi a se kopa ninu ifesewonse yii.
Joabu ní, “Bí àwọn ọmọ ogun Siria bá lágbára jù fún mi, wá ràn mí lọ́wọ́, bí ó bá sì jẹ́ pé àwọn ọmọ ogun Amoni ni wọ́n bá lágbára jù fún ọ, n óo wá ràn ọ́ lọ́wọ́.
Ẹ óo sì mọ̀ pé òun ni OLUWA Ọlọrun.
 ní ọ ̀ pọ ̀ europe àti australia , ara àdán nìkan ni dìgbòlugi wà .
Ẹni tí ó gùn ún mú ìwọ̀n kan lọ́wọ́.
Ọmọ ọdún mẹ́rìnlá kàwé gboyè jáde ni Oxford Àwọn ọ̀gá rẹ ní ìjọba ni mò ń bá ṣe -Bobrisky fún ọ̀gá Arts & Culture lésì!
OLUWA Ọlọrun wa fi gbogbo wọn lé wa lọ́wọ́, 
Awuyewuye náà tọ́ka sí ìṣẹ̀lẹ̀-àtẹ̀yìnwá Eight-Nation Alliance, ẹgbẹ́ ìṣọ̀kan tí a dá ní ìdáhùnsí Tẹ̀mbẹ̀lẹ̀kun Akànṣẹ́ ní China láàárín-in ọdún 1899 àti 1901 nígbàtí àwọn àgbẹ̀ rokoroko fi ẹ̀hónú hàn sí ìjọba amúnisìn, ètò ìṣèlú ní ìlànà Krìstẹ́nì àti àṣà.
Oríṣun àwòrán, @Oyo matters Àkọlé àwòrán, Awọn olórò lasiko ọdun oro ni ilu Isẹyin nipinlẹ Oyo.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Afeez Agoro: O ṣòro fún mi láti wọ Danfo jáde Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Afeez Agoro: O ṣòro fún mi láti wọ Danfo jáde 27 Èbibi 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 16 Ìgbé 2020 Gígùn ti mo gùn ti gbé mi dé America rí -Afeez.
Nitori eyi, Atiku ti ni ki o san owo itanran miliọnu lọna ẹẹdẹgbẹta tabi ko fi oju ba ile ẹjọ nibi ti oun yoo ti wa beere biliọnu meji fun ẹsun pe o n du kooko mọ oun lori ayelujara.
 A ti gbe awon igbese to ye ki won fi ni ohun gbogbo ti awon olukopa nilo ni arowoto won.
Ọ̀fẹ́ ní à ń kò àwọn ọmọ Nàìjíríà tó há sí Lebanon bọ̀ wá sílé- Abike Dabiri Àgbo Covid-19 Madagascar kò ṣiṣẹ́, àwọn ènìyàn tí bẹ̀rẹ̀ sí ní kú níbẹ̀ Mo fi Àlìkùrání búra pé mò ń tọ́jú Risikat àti àwọn ọmọ mi- Bàbá àwọn ọmọ olójú búlúù Ilé ẹjọ́ ju olè orí omi mẹ́ta sí ẹ̀wọ̀n, ó tún ní kí wọ́n san 60 miliọ̀nù Abọ́ fífọ̀ àti ilẹ̀ ọkọ̀ ojú omi ní gbígbá ní mó fi kọ́kọ́ bẹ̀rẹ̀ iṣẹ́- Victor Agunbiade Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Peers of Heaven: Ààrẹ ẹgbẹ́ Emèrè ní àwọn ti wà tipẹ́, wọn kò pariwo síta ni18 Ògún 2020 Kano Torture: Inúu gáréèjì ni àwọn ẹlẹ́yinjú àánú ti rí Ahmed tú sílẹ̀14 Ògún 2020 Burna Boy Twice as Tall: Ǹkan tí ó yẹ ki o mọ̀ nípa Damini Ebunoluwa Ogulu Rex (Burna Boy) ti orin rẹ̀ lu ìgboro pa báyìí25 Bélú 2020 Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí 3 sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 2:23 Fídíò, Water Generator: Ó leè ṣiṣẹ fún wákàtí mẹfà, kó tó sinmi, Duration 2,2310 Òkùdu 2020 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
" Nipa ti owo ti wọn ri kojọ, tii se miliọnu lọna mẹtadinlaadọjọ naira fun iwọde naa, o ni awọn ti na miliọnu lsna ọgọta ninu rẹ laarin ssẹ meji, gẹgẹ bi alaye to wa lori ayelujara wọn.
Iku ni yoo gbẹyin awọn maraarun ti wọn ba ni wọn jẹbi awọn ẹsun wọnyii.
Bí mo bá sọ fún òmíràn pé, ‘Wá!
Bẹẹ ni wọn tun sọ nipa irufẹ ounjẹ ti wọn n jẹ, eyii to maa n fun wọn ni okun.
  Aare so pe, awon ise akanse ti
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 2020: Ọdun 2020 yii ko nìí nira fún àwọn tó bá bẹ̀rù Olorun Ẹwẹ, ẹgbẹ OPC atawọn ẹgbẹ ajijagbara mii nilẹ Yoruba ti kepe awọn gomina yii tẹlẹ pe ki wọn fawọn laṣẹ lati ṣiṣẹ pọ pẹlu awọn agbofinro lati gbogun ti awọn janduku to n da rogbodiyan silẹ nilẹ Yoruba.
Awọn mẹta gba ominira 'lẹyin ti awọn mọlẹbi wọn san owo itusilẹ, nigba ti eniyan kan si padanu ẹmi rẹ si akata awọn ajinigbe.
Ni ìdáhùn si ibeere pé awọn igbesẹ wo lo ti waye to ba nkan ti awọn eeyan ja fun nigba naa: Ogbeni Kehinde Oyè Tunji ni lati ọdun 1979 si 1993, ijọba ologun lo wa ṣugbọn nigba ti Abiola fẹ dije, awọn agbekalẹ rẹ fara pẹ jẹ fun imayerọrun gbogbo eeyan bíi eto ẹkọ ọfẹ, ìlera ọ̀fẹ́ ati bẹẹ bẹẹ lọ.
Ileeṣẹ ọlọpaa bu ẹnu atẹ lu ahesọ iroyin gbogbo to n lọ nipa bi iku oloogbe naa ṣe waye.
O yẹ ki wọn maa padanu ipò wọn ti wọn ba ti kuro lati inu ẹgbẹ òṣelu kan si omiran ni.
'Àwọn SARS ló yìnbọn pa ìyá mi' Kolade Johnson; Iléeṣẹ́ ọlọ́pàá ní ọwọ́ ti tẹ àwọn afurasí ọlọ́pàá tó ṣekúpaá Omotola Jalade ní Nàìjíríà dàbí ọ̀run àpáàdì lábẹ́ ìjọba Buhari Gẹgẹ bi ohun ti aṣoju oṣiṣẹ ajọ ajafẹtọ ọmọniyan kan, Wilfred Olal, ti ajọ Dandora Community Justice Centre sọ nibi ipade naa.
Èyí tí ẹranko burúkú bá pajẹ tí n kò bá gbé òkú rẹ̀ wá fún ọ, èmi ni mò ń fara mọ́ ọn.
rẹ ki o to di amulo fun ọdun.
NCDC: Àlàyé bí a ó ṣe gbé òkú àwọn tó bá Covid 19 lọ látòkè òkun wálé rèé Ajọ NCDC ti kede pe fun awọn idile to ni eeyan loke okun tabi ipinlẹ mii ti wọn ti padanu ẹmi wọn lasiko aarun Coronavirus yii, awọn ti ṣe ilana lati gbe wọn wale.
Ni ọjọru si ni Gaidom gun ori aga naa gẹgẹ bi adele alaga apapọ ẹgbẹ oṣelu APC.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Cancer Marriage: Oṣù kan péré ni Tash fi ṣe ìgbéyàwó pẹ̀lú Simon kó tó kú Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Cancer Marriage: Oṣù kan péré ni Tash fi ṣe ìgbéyàwó pẹ̀lú Simon kó tó kú 26 Agẹmo 2020 Yoruba ni airin jinna ni airi abuke ọkẹrẹ, bii eeyan ba rin jinna, yoo ri ibi ti wọn ti n fi odo ibulẹ jẹun.
Wọn yóo dàbí aṣọ yìí tí kò wúlò fún ohunkohun.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Nigeria international flight resumption: Àwọn ìlànà tuntun ti o gbọdọ tẹlèé rèé ki ó to le wọkọ̀ òfurufú lọ sókè òkun 17 Ògún 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 5 Owewe 2020 Oríṣun àwòrán, Others Bàálù àkọ́kọ́ balẹ̀ si pápákọ̀ òfurufú ìlú Eko lẹ́yìn oṣù márùn gbáko tí ijọba orilẹ̀-èdè Nàìjíríà ti fòfinde ìgbòkègbodo ọkọ̀ òfurufuú ilẹ̀ òkèrè.
Ajọ Amnesty International ti da si ọrọ naa, wọn ni ileeṣẹ ọlọpaa gbọdọ wadi Abbo ni kiakia.
owo to le ni tirilionu kan naira (N1 trillion) ni ijoba ya sato fun ise akanse lodun 2016 ,1.
Ọ̀gá ọlọ́pàá náà sàlàyé pé, àti eégún àti àwọn tókù rẹ̀ kò ni lọ láì jìyà ẹ̀ṣẹ̀ wọ́n.
Oríṣun àwòrán, Nigeria Immigration Service Fisà Kò sí ẹni tó yé, iye ti owó ìwé ìrìnnà yóò jẹ́ yálà kí o wọ́n síi tàbi kó tún wálẹ̀.
Aini, Juta, ati Beti Ṣemeṣi, gbogbo wọn jẹ́ ìlú mẹsan-an ní ààrin ilẹ̀ àwọn ẹ̀yà mejeeji.
Naira Marley dáa padà fún ile iṣẹ Executive Jet tó pè é ni alaiwulo pé elebi ni awọn naa: Ọrọ irinajo Naira Marley lọ kọrin nilu Abuja ti di iṣu ata yan an yan an bayii pẹlu bi ọrọ naa ti wa di eyi ti wọn n gba bi ẹni n gba igba ọti laarin ijọba apapọ orilẹ-ede Naijiria, ileeṣẹ to ni baluu to gbe Naira Marley pẹlu Naira Marley funra rẹ.
 O menuba awọn idojukọ bii ti ọda owó ati aisi ẹkọ to jilẹ to fawọn oṣiṣẹ fiimu ni Togo.
Ṣé kí n fi àkọ́bí mi ṣe ètùtù fún ẹ̀ṣẹ̀ mi, àní kí n fi ọmọ tí mo bí rúbọ fún ẹ̀ṣẹ̀ mi?
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Kìí ṣe gbájúẹ̀ nìkan lọmọ Nàìjá ń ṣe lókè òkun, Yoruba ń mókè, wọ́n ń gbéṣẹ́ ńlá ṣe 30 Ògún 2019 Oríṣun àwòrán, other Àkọlé àwòrán, Kìí ṣe gbájúẹ̀ nìkan lọmọ Nàìjá ń ṣe lókè òkun!
tí àwọn agbófinró sì ń gbẹ́sẹ̀ lé ìwọ́n kílò tó tó ọ̀ọ̀dúnrún ní ọdọọdún.
“A fojú wa rí ilé-ẹ̀wọ̀n ní títì, a bá àwọn tí wọn ń ṣọ́ ọ tí wọ́n dúró lẹ́nu ọ̀nà.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Coronavirus in Nigeria: Ọmọ Italy tó kọ́kọ́ kó Coronavirus wọ Eko tún lọ́ sí ìpínlẹ̀ Ogun nàá 28 Èrèlè 2020 Oríṣun àwòrán, Getty Images Ileewosan Mainland Hospital ti wọn ti n tọju ajakalẹ aarun ni adugbo Yaba nilu Eko ni ọmọ orilẹ-ede Italy to ko aarun Coronavirus wọ ipinlẹ Eko ti n gba itọju lọwọlọwọ.
Ìdí márùn ún tí agbára Covid 19 ní ilẹ̀ Adúláwọ̀ kò fi tó tí àwọn ilẹ̀ àgbáyé míràn Awọn alakalẹ bi wọn ṣe fẹ na owo naa ni wọn gbe si abẹ ERGP 7102245"" to jẹ atunṣe awọn waya ina ni eyi ti wọn maa na N4,854,381,299."
Ó wá bú ramúramù bíi kinniun.
”Atiku seleri yii nigba ti o n ba awon ogunlogo omo egbe oselu PDP soro  ni Ila- Iwo oorun orile ede Naijiria ,nibi to n ti n se ifilole ipolongo ipo aare fun Atiku /Obi ni ipinle Sokoto.
ki won si yago fun wahala.
Koye Sowemimo, ti o je olori eka ere-idaraya nile ise Temple Management Company (TMC), fi idunnu re han pupo lati ri Ebi pada lori papa.
Yìnyín náà pọ̀ tóbẹ́ẹ̀ gẹ́ẹ́; kò tíì sí irú rẹ̀ rí ní gbogbo ilẹ̀ Ijipti láti ìgbà tí ó ti di orílẹ̀-èdè.
Igba keji taa maa rira waye ni agọ ọlọpaa nibi ti wọn ti n sọ fun awa gan fun igba akọkọ pe wọn n ṣe ayẹwo lọwọ lori oku rẹ lati mọ ohun to pa a.
Mo pe idì láti ìlà oòrùn,mo sì ti pe ẹni tí yóo mú àbá mi ṣẹ láti ilẹ̀ òkèèrè wá.
Ni didun ati nigba ikoro, nigba ilọrọ ati nigba ipọnju.
Lawal Rukayat (Iyabadan) Oríṣun àwòrán, Iyabadansneh Toyin Abraham Oríṣun àwòrán, Toyin Abraham Jaiye Kuti Oríṣun àwòrán, Jaiye Kuti Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Egbò tó ti fẹ́ẹ̀ jiná ni ìtàn bí wọ́n ṣe pa Soun Ogbomoso, Ọba Olayode tẹ ń bèrè' Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Onkọwe ere, onkọwe arosọ ati arokọ, iwe kika fun akẹkọọ to gbaju gbaja kọja afẹnusọ ni Wole Soyinka pẹlu ọpọlọpọ ami ẹyẹ ati ami idanimọ to ti gba ko lonka.
Èmi ò rí i rí o.
O sọ pe ofin orilẹ-ede Naijiria faaye gba ipinlẹ kọọkan pẹlu aṣẹ lati da aabo bo awọn ara agbegbe rẹ labẹ iṣejọba alagbada.
“Gbogbo wọn gbóná bí ààrò, wọ́n pa àwọn olórí wọn, gbogbo ọba wọn ni wọ́n ti pa léraléra, kò sì sí ẹnìkan ninu wọn tí ó ké pè mí.
Àtúnyẹ̀wò - Ìròyin tó ba dálé àgbéyẹ̀wò tó ṣe kókó pàápàá jùlọ lórí ìṣẹ̀lẹ̀ kan, ìṣẹ́ onímọ̀ kàn tó ní èròngba tó ṣe kókó ÀWỌN ÀPẸRẸ ÀTI ÌTỌ́KASÍ Àgbéjáde iṣẹ́ wa bótiwù kórí máà n kún ojú oṣùwọ̀n, a máá n ṣe ìwádìí láti orísun to múná dóko pẹ̀lú ẹ̀ri to dáju, àyẹwò fínifíní, ati àgbekalẹ ni ede ti o daju, àti òtitọ.
Ni Joramu, ati ọba Juda ati ọba Edomu bá gbéra láti lọ sójú ogun.
Oríṣun àwòrán, @AsiwajuTinubu Ohun ti awọn ọmọ Naijiria kan to n fọwọsi Tinubu fun ipo aarẹ lọdun 2023 n sọ, loju opo Twitter ni pe, ati ranmu gangan idagbasoke to de ba ipinlẹ Eko lẹnu ọdun melo kan sẹyin, ko ṣẹyin eekan Tinubu.
Buhari gbe awọn ọmọ ogun ilẹ̀ mẹta ga: Aarẹ Muhammadu Buhari ti sọ Ogagun Lamidi Adeosun to jẹ oludari ẹka ikọni ati iṣẹ ṣiṣe di ọgagun agba pata lẹnu iṣẹ ogun.
" Àlàyé rèé lóríi ìdí tí wọ́n fi ń pe aya ní ìyàwó Khafi wọ gàu lẹ́nu iṣẹ́ lórí ẹ̀sùn ìbálòpọ̀ ní BB Naija Àlàyé rèé lóríi ìdí tí wọ́n fi ń pe aya ní ìyàwó Asọ́ ń pe aṣọ ránsẹ́ níbi ayẹyẹ ojúde Ọba ní'lùú Ijẹbu Ẹgbẹ oselu PDP wa n kesi Ajimsbi pe ko maa ranti atubọtan, ati itan ti ọjọ ọla yoo sọ nipa rẹ ati isejọba rẹ, ti wọn si n rọọ lati kesi awọn eeyan to yan sipo pe ki wọn tete da awọn ọkọ ayọkẹlẹ naa pada.
A tun ni lati gbiyanju lati maa ṣọ awujọ, ki a si tete fi to awọn agbofinro
Ṣugbọn bí ọ̀gangan ibẹ̀ bá funfun tí kò sì jìn ju awọ ara rẹ̀ lọ, tí irun ọ̀gangan ibẹ̀ kò sì di funfun, kí alufaa ti abirùn náà mọ́lé fún ọjọ́ meje.
OLUWA gbé Solomoni ga lójú gbogbo àwọn ọmọ Israẹli, ó sì fún un ní ọlá ju gbogbo àwọn ọba tí wọ́n ti jẹ ṣáájú rẹ̀ ní Israẹli.
Ìwọ ni Ọba mi ati Ọlọrun mi;ìwọ ni o fi àṣẹ sí i pé kí Jakọbu ó ṣẹgun.
Osinabjo ni o ṣeni laanu pe ọpọ awọn ọdọ lorilẹ-ede Naijiria ni ko mọ nipa asiko idẹra ti awọn aṣiwaju bii Awolọwọ, Nnamdi Azikiwe ati Ahmadu Bello gbe kalẹ fun orilẹ-ede Naijiria.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ekiti Election: Fayẹmi bá BBC sọ̀rọ̀ gẹ́gẹ́ bíi gómìnà tí Ekiti yàn 15 Agẹmo 2018 Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Fayẹmi bá BBC sọ̀rọ̀ ní kété tó di gómìnà Ekiti Ní kété ti àjọ elétò ìdìbò ìpínlẹ̀ Ekiti kéde Kayọde Fayẹmi gẹ́gẹ́ bíi gómìnà ìpínlẹ̀ Ekiti, Fayẹmi ti fi ọrọ ìdúpẹ̀ ránṣẹ́ síta sí gbogbo àwọn tó jẹ́ kí ìdìbò náà lọní ìrọwọ́rọsẹ̀.
Alamojuto idije naa ti kọkọ fun agbabọọlu Naijiria, Ademọla Adeshina ni kaadi pupa to si lee jade eleyi to sọ ikọ Naijiria di agbabọọlu mẹwaa.
Bi o ti le je pe, jijawe olubori ninu asekagba idije naa koi to lati fese akonimoogba iko ohun, Antonio Conte mule, leni ti ireti wa pe won yoo gba ise lowo re ti saa idije yii ba pari, lataari aise deede iko naa, ti won ko si tun pegede fun idije UEFA champions league ti saa to n bo, leyin ti won pari sipo karun un lori tabili idije EPL.
Coronavirus: Wo ohun tí o ní láti ṣe láti dáàbò bo ara rẹ Lẹyin eyi ni o ṣalaye pe gbogbo awọn to ti ni nnkan n ba oun ṣe laarin asiko ti oun fi lọ sibi ipade igbimọ ọrọ aje orilẹede Naijiria si ọjọ ti oun bẹrẹ igbele ni wọn ti n wa; koda iroyin kan tilẹ ss pe gbogbo awọn to baa da nnkan pọ laarin asiko naa, paapaa awọn kọmiṣọna atawọn amugbalẹgbẹ rẹ gbogbo ni wọn ti wa ni igbele bayii lati lee mọ boya awọn naa ko abi rara.
Ó ní, “Olùkọ́ni, kí ni kí n ṣe kí n lè jogún ìyè ainipẹkun?
ẹ mọ̀ dájú pé ẹni tí ó bá mú ẹlẹ́ṣẹ̀ pada kúrò ninu ìṣìnà rẹ̀ gba ọkàn ẹni náà lọ́wọ́ ikú, ó sì mú kí ìgbàgbé bá ọpọlọpọ ẹ̀ṣẹ̀.
5% ninu ida ogorun yoo ba eto oro-aje agbaye, bi o ba fi maa di odun 2020, lai tile ni owo ori oja ninu rara.
Eto igbani sisẹ naa ya mi l'ẹnu, nitori mi o mọ nipa rẹ"", ni ohun ti Ọga Agba ajọ Immigration nigba naa, David Paradang, pada sọ fun ile ẹjọ giga ti jọba àpapọ̀ nilu Abuja."
” Peteru bá ṣe bí angẹli náà ti wí.
Afárá 3rd Mainland: Ìjọba ṣí afárá lẹ́yìn àtúnṣe
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ọmọ ọdún márùn-ún àti àgbà mẹ́rin ló bá ìṣẹ̀lẹ̀ ọ̀pá epo bẹntiróò tó gbiná ní Abule Egba lọ láìpẹ́ yìí.
Èso Apple tuntun tí ẹ lè fi pamọ́ fún ọdún kan ti wọ ọjà Kò sí súnkẹrẹ-fàkẹrẹ mọ lópópóna márosẹ̀ Eko si Ibadan Àwọn agbébọn pa ènìyàn mẹ́rinlá lásìkò ìjọsìn Erin mẹ́fa wó níbi tí wọ́n ti fẹ́ dóòlà ẹ̀mí ara wọn Oríṣun àwòrán, Google Àkọlé àwòrán, Ààrẹ Ilé Ìgbìmọ̀ Àsòfin.
Mose ati Aaroni bá lọ sí Ijipti, wọ́n kó gbogbo àgbààgbà àwọn eniyan Israẹli jọ.
"Toyin Abraham bí ọmọkùnrin jòjòló Ariwo ""Allahu Akbar"" kò tọ́ sawọn Agbébọn àti Boko Haram - Buhari Facebook fi kọ́kọ́rọ́ ti àwọn ojú òpó ayédèrú ìròyìn léde Yorùbá àti Igbo Gẹgẹ bi awọn iroyin abẹle ṣe sọ, pẹlu fidio kan ti El-Zakzaky funra rẹ gan ti sọrọ, anfani meji ni wọn fun olori ẹsin naa."
Ni ipinlẹ Ondo ọrọ dojuru si nibi ti igbimọ amuṣẹya ti fi ountẹ lu idibo alabẹle to yan Rotimi Akeredolu gẹgẹ bi ẹni ti yoo gbe apoti idibo labẹ asia ẹgbẹ fun ipo Gomina nipinlẹ naa.
OLUWA bá sọ fún Mose pé, “Na ọwọ́ rẹ sórí ilẹ̀ Ijipti, kí eṣú lè tú jáde, kí wọ́n sì bo gbogbo ilẹ̀ náà, kí wọ́n jẹ gbogbo ohun ọ̀gbìn tí ó ṣẹ́kù ní ilẹ̀ náà tí yìnyín kò pa.
Ẹ̀yìn rẹ̀ tẹ̀, kò lè nàró dáradára.
Ṣugbọn, lọ, fi ara rẹ han alufaa, kí o ṣe ìrúbọ gẹ́gẹ́ bí Mose ti pa á láṣẹ, bí ẹ̀rí fún wọn pé ara rẹ ti dá.
 Mo si fẹ sọ fun Ọlọla julọ pe o ni alabasisẹpọ ninu me nitori mo n foju sọna fun eto ajọsepọ lọna kọna laarin orilẹede Naijiria ati Ghana nidi wiwa egbo dẹkun fun arun ijẹkujẹ to ntan kalẹ kaakiri.
Lẹ́yìn náà, wọn yóo gbé òkú akọ mààlúù ati ti òbúkọ tí wọ́n fi rú ẹbọ ìmúkúrò ẹ̀ṣẹ̀, ati ẹ̀jẹ̀ wọn tí wọ́n gbé wọ ibi mímọ́ lọ láti fi ṣe ètùtù, wọn yóo rù wọ́n jáde kúrò ní ibùdó, wọn yóo sì dáná sun ati awọ, ati ara ẹran ati nǹkan inú wọn.
Ihonvbere sọ pe ibeere to yẹ ki a bi ara wa ni pe ''ṣe a ti gbaradi fun wiwọle pada awọn akẹkọọ?
Àwọn ẹ̀ka igi náà yóo dánígbà tí wọ́n bá gbẹ,àwọn obinrin yóo sì fi wọ́n dáná.
Wọ́n ní kí wọ́n kó àwọn igi náà wá sí Jọpa ní etí òkun fún wọn gẹ́gẹ́ bí àṣẹ tí Kirusi, ọba Pasia pa.
Ẹ̀yin ará, ẹ má ṣe sọ̀rọ̀ àbùkù nípa ara yín.
ti o je olu-ilu eto oro aje orile ede Naijiria lati lo se ifilole awon ise
Arabinrin Georgina Ndukwe ni oun nigbagbọ ninu awọn ọmọbinrin pe wọn lagbara lati yi aye pada si rere ti wọn ba fun wọn laaye.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Black women live matters: Ọdún 2015 ní àwọn ọlọ́pàá pa India Kager láìní ìdí- Gina Best Ohun ti a mọ nipa Isa Funtua, ọrẹ Buhari to dagbere fun aye re: Ismaila Isa Funtua ni wọn bi ni ilu Funtua ni Oṣu Kini, ọdun 1942, ti o si ti kekere gba ẹkọ imọ Quran.
Lẹyin ti ọrọ naa ba ti n wọ ọ lara, a o wa bẹrẹ si ni paṣamọ fun un bi ka maa sọ pe ''eyi ma ga o!
Owó oúnjẹ ni mo lọ ọ gbà, oyún ọmọ tí mo jù sí àkìtàn ni mó gbé wálé- Dupe, ìyá Muiz
Abike Dabiri Erewa to jẹ alaga ajọ to n mojuto ọrọ awọn ọmọ Naijiria nilẹ okeere ṣalaye ohun ti ijọba ni fun won ti wọn ba kọkọ de sile.
Ní ọjọ́ kan, lẹ́yìn tí Isaaki ti ń gbé ìlú náà fún ìgbà pípẹ́, Abimeleki, ọba àwọn ará ìlú Filistia yọjú lójú fèrèsé ààfin rẹ̀, ó rí i tí Isaaki ati Rebeka ń tage.
ọdaran mẹfa , ni eyi ti won tun gba ibọn AK 47 ati  kẹkẹ atapupu  meji lasiko ikọlu to waye ni awon ileto to wa
Kí ògo yìí wà fún un ninu ìjọ ati ninu Kristi Jesu láti ìrandíran títí laelae.
1–16, Ìwé ti Mọ́mọ́nì fi ìdí jíjẹ́ ti ọ̀run iṣẹ́ ọjọ́-ìkẹhìn múlẹ̀; 17–28, Àwọn ẹ̀kọ́ nípa ìṣẹ̀dá, ìṣubú, ètùtù, àti ìrìbọmi ni a fi ìdí wọn múlẹ̀; 29–37, Àwọn òfin tí wọn nṣe àkóso ironúpìwàdà, ìdáláre, ìyàsímímọ́, àti ìrìbọmi ni a fi kalẹ̀; 38–67, Ojúṣe àwọn alàgbà, àlùfáà, olùkọ́, àti àwọn díakonì ni a ṣàlàyé ni ìkékúrú; 68–74, Ojúṣe àwọn omo ìjọ, bíbùkún fún àwọn ọmọdé, àti ọ̀nà ṣíṣe ìrìbọmi ni a fihàn; 75–84, Àwọn àdúrà oúnjẹ alẹ́ Olúwa àti àwọn ìlànà síṣe àkóso jíjẹ́ ọmọ ìjọ ni a fi fúnni.
Austin to jẹ kọnsitebulu ọlọpaa jẹ ọmọ ọdun mẹrinlelogun nigba ti o pa ọmọ Naijiria to fi orilẹ-ede South Africa ṣe ibujoko.
Fi si ọkan pe ọfẹ ni iforukọ silẹ ati idanilẹkọ Ori ayelujara ni idanilẹkọ naa yoo ti waye fun ọjọ marun-un gbako.
Wọ́n dákẹ́ rọ́rọ́, wọ́n ní, “Ẹ jẹ́ kí á dúró títí di ìdájí kí á tó pa á.
Oríṣun àwòrán, Instagram/currentalhaja Olori Abbey ni ọpẹ oloore, adaadatan ni, o ni lailai l'oun yoo maa dupẹ lọwọ Ọba Lamidi Adeyemi.
Ó bá kígbe pé, “Oluwa, gbà mí!
Níwájú OLUWA Ọlọrun yín, níbikíbi tí ó bá yàn, ni kí ẹ ti jẹ ẹ́; ẹ̀yin ati àwọn ọmọ yín, lọkunrin ati lobinrin, ati àwọn iranṣẹkunrin ati àwọn iranṣẹbinrin yín, ati àwọn ọmọ Lefi tí wọ́n bá wà ninu ìlú yín.
Bí àjálù ìbúgbàmù tó gb'ẹ̀mí ọ̀pọ̀ nìlùú Eko ṣe wáyé nìyí 'Àìjáfáfá àwọn panápaná ló mú kí ọṣẹ́ iná Akure pọ̀' 'Iná tó n jó àwọn ọjà l'Eko kìí ṣe ojú lásán' Wo ọ̀nà tí o fi lè dáàbò bo ọmọ rẹ lọ́wọ́ COVID-19 níléèwé Oríṣun àwòrán, TWITTER/LASEMA Isẹlẹ Ibugbamu gaasi ni Abule Ado Ọjọ kẹẹdọgun ọsu kẹta ọdun yii jẹ ọjọ manigbagbe fun awọ́n olugbe adugbo Abule Ado nibi ti iṣẹlẹ ibugbamu ọpa gaasi ti ṣẹlẹ niluu Eko.
NCDC kéde èèyàn 601 tó ṣẹ̀ṣẹ̀ lùgbàdì Covid-19 ní Nàìjíríà 1.
Àjẹ́ àti Aṣẹ́wó ní ìyá Rainbow - Òjòpagogo Ọdẹ ìbílẹ̀, OPC àti agbófinró ń pèèlò tí yóò se ọbẹ̀ ààbò jinná nílẹ̀ Yorùbá El-Zakzaky: Arúfin ni ijọba Muhammadu Buhari gan-an - Ladoja Buhari o, pèsè ohun tó yẹ sí ọgbà ẹ̀wọ̀n, kí àyípadà orúkọ wọn léè pegedé Ṣe ile rẹ ni yoo gba lọ ni, ṣe ileewosan kan ni Naijiria ni yoo lọ ni tabi yoo pada sinu ahamọ awọn agbofinro DSS, eyi to ti wa fun bii ọdun mẹrin gbako?
Tolulope Arotile lo ti wọ iyara ikẹyin ni itẹ́ awọn ologun ni Abuja laarọ yii.
Afara yii gun fun iwon kilomita 11 ati mẹjọ.
A tún fojú inú ròó pé ẹni bá jókòó sórí okùn náà, àfi kí ilé wó lu olúwarẹ̀ pa.
Awọn ọmọ gbẹ Boko Haram ti n ngbogun ti orilẹede Naijiria fun bi ọdun mẹjọ bayii wọn n beere wọn fun idaduro orilẹede wọn ni agbegbe naa.
Kollington, ẹni to kede eyi lasiko to n dahun ibeere lori eto BBC Yoruba, tun salaye pe obinrin to bi ọmọ fun ni, ti kuro ni ale ẹni, ọmọ mẹta si ni Salawa Abẹni bi fun oun, nitori naa, iyawo oun nii se.
Ijọba Salami yii lo seto idibo mii, ti Oloye Olusegun Obasanjọ fi jawe olubori ninu ibo aarẹ to waye lọdun 1999, eyi to fopin si laasigbo oselu ati ti ẹlẹya mẹya naa.
"Oṣu mẹta ni mo fi n wa iṣẹ ni Addis Ababa.
Ṣé òkun ni mí ni, tabi erinmi,tí ẹ fi yan olùṣọ́ tì mí?
Wọ́n pé ọdún méjìlá báyìí Elon Musk, Ọ̀gá àgbà iléeṣẹ́ SpaceX, Tesla CEO ń bá Bill Gates du ipò ẹni tó lówó jùlọ ṣèkejì lágbayé Ganiyat tó fi irin gbígbóná àti àdá ya ara ọmọ àbúrò ọkọ rẹ ti dèrò àgọ́ ọlọ́pàá l' Ogun Ohun mẹ́wàá pàtàkì nípa Maradona àti ìbáṣepọ̀ rẹ̀ pẹ̀lú ẹlẹ́sẹ̀ ayò Diego Costa rèé Orúkọ Aisha Yesufu náà wọ inú BBC 100 Women tí a fi ń sọri àwọn obìnrin tó pegedé ní 2020 Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ọmọ Yahoo tú àṣírí ara rẹ̀ fún, bí wọ́n ṣe ń ṣe é BBC Yorùbá Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Adeyeye Ile Ife: Kílódé tí Ọọni Ife, Oba Ogunwusi kò fi gbọdọ̀ rí ọmọ rẹ̀ tuntun títí di ẹ̀yìn oṣù mẹ́fà?
Oluranlọwọ pataki fun naa ni awọn eniyan yoo ranti aarẹ Buhari si rere ni ọjọ iwaju.
Ibi ki bi ti nnkan meje yii ba ti ṣẹlẹ, ki ẹ mọ pe ofin konile o gbele n ṣẹlẹ nibẹ.
Eliṣa fi àjàgà mààlúù rẹ̀ sílẹ̀, ó sáré tẹ̀lé Elija, o wí fún un pé, “Jẹ́ kí n lọ dágbére fún baba ati ìyá mi, kí n fi ẹnu kò wọ́n lẹ́nu, kí n tó máa tẹ̀lé ọ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ẹ wá gbọ òwe lẹnu ọmọ Igbo bíi àgbà ilẹ Yoruba Oru ọjọ Ẹti to kọja ni awọn janduku agbebọn kan ṣadede kọlu ileewe naa to wa fun awọn akẹkọọ ọkunrin nikan, ti wọn si ji awọn akẹkọọ kan gbe, nigba ti awọn miran sa asala fun ẹmi wọn.
pe awon kan lara omo egbe yin tun seranwọ lati la awon eniyan lọyẹ  ni awon igberiko ati ati  ni ibugbe, ni eyi ti o je ki eto idibo naa lọ  ni irọwọ ati irọsẹ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Election Update 2019: Sowore dẹ́bi aijáde dibo àwọn èèyàn rú ìhàlẹ̀ Buhari 27 Èrèlè 2019 Oríṣun àwòrán, Omoyele Sowore Àkọlé àwòrán, Ẹgbẹ Sowore ti wọn daalẹ laipẹ yi lo ṣe ipo kẹta ninu ibo aarẹ Naijiria Oludije ipo aarẹ labẹ ẹgbẹ oṣelu African Action Congress, AAC, Omoyele Sowore ti fesi si ijawe olubori Aarẹ Muhammadu Buhari ninu idibo aarẹ Naijiria.
Ẹnikẹ́ni tí ó bá paniyan, pípa ni a óo pa òun náà, nítorí pé ní àwòrán Ọlọrun fúnrarẹ̀ ni ó dá eniyan.
Lanka lojo ajọdun  iranti iku Jesu krisiti
Ile-ise omo-ogun oju ofurufu Naijiria, NAF  ti se atunto si ipo awon oga agba méjílélógójì  jake-jado orile-ede Naijiria.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ sí: Ọmọ Yorùbá ni onímọ̀ ẹ̀rọ ‘Rọ́bọ́tì’ tó ń gbowó jùlọ ní UK Game of thrones gbayì níbi àmì ẹ̀yẹ EMMY Awards 2018 ‘A ti rí $470.
Ọpọlọpọ iwadii ni awọn onimọ ijinlẹ ti ṣe lori ohun to n ṣokunfa arun jéjéré.
O kuro ni Uzbekistan lo si orile ede  Sweden lodun 2014 sugbon ni osu kejila odun 2016 , ni won fun un ni ose merin lati fi orile ede naa sile.
Lai Muhammed yóò fojú ba'lé ẹjọ́ - ICPC Àwa náà dántọ to lati ta ẹru Diezani ní gbànjo-Nigerian Auctioneers Bukola Saraki kò kọjá òfin - EFCC ‘Patience Jonathan yoo yọju sileẹjọ’ Yusuf Olaniyọnu to jẹ agbẹnusọ fun Saraki ṣalaye ninu rẹ pe: ''Irọ pọnbele ni ọrọ ti EFCC sọ pe ọna aitọ ni Saraki fi kọ ile naa.
Pelu erongba ohun etikun yii yoo je okan ti o tobi julo ni ekun yii ati ni ile Afrika.
Sagay: olùdámọ̀ràn Buhari wọ gàu lórí ọ̀rọ̀ Adeosun
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìtàn Mánigbàgbé: Ọ̀rẹ́ àjèjì ló kóbá Afọnja, tí Ilọrin fi bọ́ lọ́wọ́ Yorùbá 18 Agẹmo 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 24 Ìgbé 2020 Oríṣun àwòrán, Goodbooksafrica Àkọlé àwòrán, Afọnja gba ilu Ilọrin labẹ akoso ilu Ọyọ, to si kede pe ilu naa ti di ilu olominira Laarin ọdun 1700, paapa ọdun 1750, ọkunrin akọni kan lalẹ hu ni ilu Ọyọ ti orukọ rẹ n jẹ Afọnja, to si kẹrẹkẹrẹ di Aarẹ Ọna Kakanfo fun ilẹ Yoruba eyi to safihan bo ti jẹ akikanju to.
Ìtàn ayé Abiola Peller, ọlọ́wọ́ idán tó fi ọ̀bẹ gé ìyàwó rẹ̀ sí méjì Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Bí o bá bá ààrùn ìpẹ́pẹ́ gbígbẹ lára arẹwà obìnrin rẹ̀, kí loó ṣe?
Salawa Abeni:Ọwọ́ ọlọ́pàá ti tẹ ẹni tó fẹ́ ba Queen Waka lórúkọjẹ́ lọ́jọ́sí
Bi o ti le je pe, iko agbaboolu Juventus kopa ribiribi ninu ifesewonse naa, leyin ti iko ohun padanu ifigagbaga ese kinni sowo Madrid pelu ami-ayo meta sodo, sugbon iko naa taraji ni ifesewonse ese keji lati gba ami-ayo meta wole, sugbon omi po ju oka lo, leyin ti Madrid gba ami-ayo kan wole niseju perete ki ifesewonse ohun wa si ipari, leyi ti o fun won lanfani lati so apapo ami-ayo ohun di ami-ayo merin si meta(4-3).
olódùmarè fún ọbàtálá ní adìyẹ ẹlẹ ́ sẹ ̀ márùn-ún àti erùpẹ ̀ pé kí ó lọ fi tẹ ilé ayé dó .
“Bí ẹ bá wí pé ẹ kò ní dúró ní ilẹ̀ yìí, tí ẹ kò sì gbọ́ràn sí OLUWA Ọlọrun yín lẹ́nu; 
Wọ́n ti mú ninu àwọn ohun tí a yà sọ́tọ̀, wọ́n ti jalè, wọ́n ti purọ́, wọn sì ti fi ohun tí wọ́n jí pamọ́ sábẹ́ àwọn ohun ìní wọn.
nipa bi o se yẹ ki a maa se itoju oju ati lati yera fun ohun to le fa ailera
Ó sọ wípé òun ti ní ìdojúkọ ìjọba, pẹ̀lú àtìmọ́lé ní ọdún-un 2015 láti dénà dè é kí ó máà lọ sí ìdánilẹ́kọ̀ọ́ ẹ̀tọ́ ọmọnìyàn ní Geneva.
Awọn ikọ akọroyin fun aarẹ kọ lati ba mi sọrọ.
Ó ní, ‘Ẹ máa lọ fi ṣòwò kí n tó dé.
Lọdun 2015 ni wọn dajo fun un lẹyin igbẹjo pe o jẹbi fifa iku ọmọ ọdun mẹfa kan, Jack Adcock, to ku si ile iwosan Leicester Royal Infirmary nibi to ti n ṣiṣẹ ni 2011.
Awọn ti iṣẹ wọn ba ṣe pataki nikan bi awọn oṣiṣẹ eto ilera lo le lanfaani ati maa rinrin ajo lasiko ofin konile o gbele.
O da bi baba fun mi.
Ti a bá fí eleyii ṣe oṣuwọn ipò Mínísítà, a jẹ wí pé ìwé erí yunifásítì tàbí ìwé ẹrí kikopa nínú ètò àgùnbánirọ̀ kò ṣe dandan.
Mo sa gbogbo ipá mi láti pa á run.
Coronavirus: Ilé ijó Fẹla Anikulapo, New Africa Shrine gbé ìlẹ̀kùn rẹ̀ tì pa nítorí àrùn Coronavirus
Awọn to n du ipo naa Odu lawọn mejeeji ti wọn du ipo aarẹ lẹyin ti Bukola Saraki pari saa rẹ.
5bn ti ijọba pinnu lati na ninu eto isuna ọdun 2020 ti pọ ju fun itọju baalu ọkọ ijọba.
Ẹni ọdun mejilelaadọrin ni iyaafin pasitọ Folu Adeboye da lọdun yii ọrọ ikini ti baba Adeboye si fi ranṣẹ sii lori ayelujara ti n fa wahala.
ohun igbafẹ lorile ede Naijiria , lati le mu idagbasoke ba ohun adayeba ti o wa
Wọ́n ń jẹbọ kiri lórí àwọn òkè ńláńlá, wọ́n sì ń ṣe ohun ìtìjú.
Ṣe Bobrisky kii ṣe eeyan ni?"
Ni ti awọn oluwọde, o ni ki wọn kọkọ pada sinu ile wọn na, ki wọn si ṣe ijiroro lori igbesẹ to kan.
Ni a bá ju nǹkankan tí ó dàbí òkè gíga tí ó ń jóná sinu òkun.
Apapọ awọn to ti ni arun naa kaaakiri orilẹ-ede Naijiria ti wa di 25,133 bayii.
sọrọ ni Mokola niluu  Ibadan ni ipinle
"Kí ló dé tí ìjọba Èkìtì ń fí àwọn òṣìṣẹ́ ṣé ''helo-helo testing""?"
8biliọnu ti wọn kọ fun owo awọn oṣiṣẹ, ileeṣẹ eto iṣuna buwọlu lu iwọnba biliọnu mẹrin abọ, N4.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Palmwine Tapping: Ọ̀dọ́mọdé àdẹ́mu ní ìṣẹ́ náà kò wú òun lórí Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Ambode ní kò sí gìrì, eré ọwọ́ lásán ni EFCC ń ṣe Ambode ní kò sí gìrì, eré ọwọ́ lásán ni EFCC ń ṣe Ìjìyà ń bẹ fún àwọn ti adé ọ̀rọ̀ náà bá ṣí mọ́ lóri -Ọga àgbà FRSC Ike Ekweremadu, igbákejì ààrẹ ilé aṣòfin àgbà tẹ́lẹ́ rí èèmọ̀ he nilùú Germany!
“Ọkan  wa balẹ pe , a o se aseyọri.
Wilayat Khorasan lo pe orúkọ rẹ.
Nibayii naa, ipinlẹ meji lo ti gbe igbimọ isakoso kalẹ fun ikọ naa ni ipinlẹ koowa wọn.
Allen Onyema: Iro ni ile Amerika pa mo mi lori esun jibiti
Ṣugbọn àwọn tí wọn ń pè ní aṣaaju ninu wọn kò kọ́ mi ní ohun titun kan.
5 owó naira ni ọọfiisi àjọ INEC ni Zamfara Opọ eyan Naijiria lo ti gboriyin fawọn ọmọ ogun to doola awọn akẹkọọ naa pe iṣẹ takuntakun ni wọn ṣe.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Africa Eye: Coronavirus di adákẹ́jà ní Somalia, ikú ọ̀wọ́ọ̀wọ́ ń peléke si Ọpọ awakọ to si fẹ gba ori afara naa kọja lo tete bẹ sita lai naani pe ilẹ si dudu, koda, oju ọna to lọ si Ikoyi gan ti kun fun ọpọ ọkọ lati aago mẹrin abọ owurọ.
Ọba dá mi pada sí ààyè mi, ó sì pàṣẹ kí wọ́n so alásè kọ́.
Amọ a ko mọ boya abẹrẹ ajẹsara naa yoo dẹna itankalẹ arun naa lati ara eniyan kan si omiran, boya yoo pa kokoro naa ni kiakia, ti ẹni to nii ko si ni lee ko ran ẹlomiran.
Ó sàn fún un kí á so ọlọ mọ́ ọn lọ́rùn, kí á jù ú sinu òkun jù pé kí ó mú ohun ìkọsẹ̀ bá ọ̀kan ninu àwọn kékeré wọnyi.
Ọkọ mi kò le f'ipá bá ẹnikẹ́ni lò pọ̀ láíláí - Modele Fatoyinbo COZA: Mi ò fípá bá obìrin lò pọ̀ rí láyé mi - Pásítọ̀ Fatoyinbo Agbejọ́rò Dakolo:Mílíọ́nù mẹ́wàá náírà tí a béèrè kì í ṣe owó gbà má-bínú Ìgbà mẹ́rin tí ẹ̀sùn àgbèrè ta bá adarí ìjọ olókìkí ní Naijiria Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, COZA: Ọpọ èrò ló jáde ṣe lòdì sí ẹ̀sùn ìfipábánilòpọ̀ Fatoyinbo Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
BENIN REPUBLIC: Osu Mẹta pere ni wọn fun awọn ọmọ Naijiria lati gbe ni ilu naa lai si iwe aṣẹ igbelu .
Ó sọ àgàn di ọlọ́mọ,ó sọ ọ́ di abiyamọ onínúdídùn.
Ẹ jẹ́ kí á jọ máa fẹ́ ọmọ lọ́wọ́ ara wa, ẹ máa fi àwọn ọmọbinrin yín fún wa, kí àwa náà máa fi àwọn ọmọbinrin wa fún yín.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, The Polytechnic Ibadan: Ẹ̀rọ abẹ́lé tó ń fọ ọwọ́ àti ‘Ventilator’ ló ṣẹ̀ṣẹ̀ gbé jáde Shehu ni ni kete tawọn eeyan naa jẹun tan, ni wọn n lọ inu mọlẹ, eyi to papa ran wọn sọrun ọsan gangan.
Ọpọlọpọ ariwo ni o ti n wọ tọ iye ajẹẹlẹ owo oṣu ti ijọba jẹ awọn oṣiṣẹ ni pinlẹ Ọṣun papaa bi eto idibo sipo gomina ni ipinlẹ naa.
Titi di oni, ami idanimọ to wa niwaju ile Ogedengbe ni ida lati ran ni leti asiko jijẹ akọni ti wọn bẹẹ lori to si tun ye e.
A kò fi ọba mìíràn jẹ, ṣùgbọ́n ohun tí a ṣe ni pé a fi ẹnikàn ṣe Gómìnà fún wọn láàrin w, orúkọ ọkùnrin náà ni Àpáta-ìgbẹ̀yìn tí ó jẹ́ aládùúgbò Kùmọ̀dìran ní ìlé.
$2,600 àǹtí mi ni mo jí láti lọ sókè òkun àmọ́ àbámọ̀ ló gbẹ̀yìn ọ̀rọ̀ mi A ti gba aṣẹ ilé ẹjọ míì to tako àṣẹ́ ilé ẹjọ to wọ́gile olùdije APC ni Bayelsa Góòlù pọ̀ ní ìlú Madaka ṣùgbọ́n wọn kò ní ọ̀nà fún ọgọ́rùn ún ọdún Èèyàn méjì farapa nínú ilé tó jóná ní Tejuoso l‘Eko Akinyele jẹ ọkan pataki lara awọn to gbe owo kalẹ ti wọn fi da ileeṣẹ iroyin Newswatch silẹ, o si ko ipa pataki fun idagbasoke ileeṣẹ ọhun ki ijóba to tii pa lọdun 1986.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù World Aids Day: Wo bí kòkòrò ààrùn HIV se bẹ̀rẹ̀ lágbàyé!
9 Òkùdu 2018 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ọbasanjọ ti ṣe nnkan ìtùfù sẹyin lo ṣe n kíyèsí ẹninkule rẹ̀ Ẹní jẹ fufu lára n fu lọrọ Ọbasanjọ Èsì ọrọ ree láti ọdọ ìjọba Buhari sí Obasanjo to so pe Buhari n pète láti ka ẹsùn sí òun lọrùn lasiko yii.
Gbogbo àwọn ọmọ Hosa ati àwọn arakunrin rẹ̀ jẹ́ mẹtala.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Divorce: Ilé ẹjọ́ tú ìgbéyàwó ọdún mẹ́tàdínlógún ká nítorí ààlè yíyàn 17 Ọ̀pẹ̀̀ 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 18 Ọ̀pẹ̀̀ 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ilé ẹjọ́ tú ìgbéyàwó ọdún mẹ́tàdínlógún ká nítorí ààlè yíyàn Ile ẹjọ ibilẹ kan ni agbegbe Igando nilu Eko ti tu igbeyawo ọdun mẹtadinlogun ka.
Wọn ni wọn yoo fi N274m fi san owo ina ọba PHCN ti wọn yoo si fi N67.
 a le şe àfiwé ẹ ̀ sìn ìgbàgbọ ́ pẹ ̀ lú àwọn ẹ ̀ sìn míràn làtàrí pe ọ ̀ pọ ̀ lọpọ ̀ èsìn ló ní àwon àbùdá tí èsìn ìgbàgbọ ́ ní .
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ẹgbẹ́ alátakò fẹ́ lo Boko Haram láti da ìbò 2019 rú - Lai Muhammed Ọlọ́pàá kò tíì fi Dino Melaye sílẹ̀ Irú àtúntò wo ni àwọn ọmọ Nàìjíríà fẹ́ kó bá FSARS?
Dokita Syvester Akande lati ajọ USAID n sọ ọrọ kan naa lori atunṣe si abala keji ati ikẹfa ofin yii.
A ti gba aaye lati ṣe ipolongo.
‘Ní ti gbígbọ́, ẹ óo gbọ́,ṣugbọn kò ní ye yín;ní ti pé kí ẹ ríran, ẹ óo wò títí,ṣugbọn ẹ kò ní rí nǹkankan.
O rọ Kumuyi ki o jẹ ki ọmọ Naijiria fi ero wọn han lori awọn adari wọn.
Wọn pada ni ki wọn maa gbe e lọ si ile iwosan gbogboniṣe ti Otta nipinlẹ Ogun nibi ti wọn ti toju rẹ diẹ ti wọn si ni ki wọn maa gbe e lọ si ile iwosan gbogbonise ni Abeokuta.
Kí ló mú kí àwọn èèyàn máa jẹ ọ̀rọ̀ Adeboye lẹ́nu lórí Twitter 'Ọdún 2019 pẹ̀lú àwọn àsọtẹ́lẹ̀ tó kó lọ́wọ́ dé' Boko Haram àti àwọn Fulani daran daran jẹ́ ọgbọ́n áti sọ Nàíjíríà di ìlú mùsùlùmí - Wale Oke O ni ọrọ iṣoro ti Ọlọ̀run jẹ ki emi naa bori lo jẹ kaa bẹrẹ Esther Ajayi Foundation.
Ọkùnrin kan gbé ‘búrọ́ọ̀ṣì ìfọyín’ mì Coronavirus ti di ara wa, kò le è kúrò mọ láéláé - WHO Àfi ìgbà tí mo bọ́ sọ́wọ́ ọ̀tá mí nínú ìrìnàjò ìfẹ́- Roshan Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Coronavirus tips: Kìí ṣe gbogbo ìbòmù ló ń dá coronavirus dúró Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 3 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 5 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
"Bakan naa ni Ooni tun sọ ninu fọran kan ti gbajugbaja oṣere ati apanilẹrin ti gbogbo eniyan mọ si Mr Macaroni, Debo Adebayo gbe jade lẹyin abẹwo naa pe ""Aye ṣi n ma n kunlẹ fun agbalagba."
"O ní "" Àwọn ẹgbẹ́ òkùnkùn ti gbá gbogbo ẹtọ Ọba."
Ogunjọbi papoda lowurọ ọjọ Aje, ọjọ kọkanla oṣu keji odun 2019 niluu Ibadan lapa iwọ oorun gusu Naijiria.
“Nítorí náà, nisinsinyii Ọlọrun wa, Ọlọrun tí ó tóbi, tí ó sì lágbára, Ọlọrun tí ó bani lẹ́rù, Ọlọrun tí máa ń mú ìlérí ìfẹ́ rẹ̀ tí kì í yẹ̀ ṣẹ, má fi ojú kékeré wo gbogbo ìnira tí ó dé bá wa yìí, ati èyí tí ó dé bá àwọn ọba wa, ati àwọn olórí wa, àwọn alufaa wa, ati àwọn wolii wa, àwọn baba wa, ati gbogbo àwọn eniyan rẹ, láti ìgbà àwọn ọba Asiria títí di ìsinsìnyìí.
Ẹ ma ṣe ti oṣelu bọ eto yiyan ẹni ti yoo gba ade lẹyin mi.
Bi o ba fi le jawe olubori yoo jẹ obinrin akọkọ lati Afrika ti yoo di ipo yi mu.
Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Fídíò, Efunsetan Aniwura: Àwọn fíìmù òde òní ń kọ́mọ lólè àti ọ̀pọ̀ ìwà burúkú23 Ẹrẹ̀nà 2020 Ọjọgbọn Akinwunmi Ishola pa'poda lẹyin ọdun mọkandinlọgọrin17 Èrèlè 2018 Nollywood: Wo àwọn òṣèré tíátà Yorùbá tó ti kú àmọ́ tí iṣẹ́ wọn ń fọhùn síbẹ̀22 Èbibi 2020 Ìtàn Mánigbàgbé: Ìdílé Mobee, Abass, Aniwura àtàwọn míràn rí owó tabua nínú òwò ẹrú17 Òkùdu 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Lizzy Anjorin vs Toyin Abraham: Àwọn àgbààgbà ẹgbẹ́ òṣèré tíátà fa ìbínú yọ
Awọn eniyan ko le gbagbe Fela laelae Yẹni Anikulapo-Kuti to jẹ akọbi Fẹla gboṣuba fun Fẹla loju opo Twitter rẹ.
Awọn ti iṣẹlẹ naa ṣe oju wọn ni ọsan ọjọ aiku nitosi ibudo ikẹgbin dasi kan lopopona Kabang ni ijọba ibilẹ Mubi.
Ẹni ti o jẹ abẹnugan fun gomina ana ni Ipinlẹ naa, Lere Olayinka ṣalaye pe ko si idagbasoke kan ti Fayemi gun le lati bii ọdun kan sẹyin.
Nígbà náà ni Anasi fi Jesu ranṣẹ ní dídè sí Kayafa, Olórí Alufaa.
Gbogbo ìjọ tí ó wà ní Esia kí yín.
Rochas Okorocha Gẹgẹ bi Gomina Ibikunle Amosun ṣe ṣatilẹyin fun oludije ẹgbẹ oṣelu miran fun ipo gomina nipinlẹ Ogun, bẹẹ naa ni Gomina Rochas Okorocha naa ṣe nipinlẹ Imo.
Ṣùgbọ́n akọ̀wé láti ẹ̀ka ètò-òṣìṣẹ́ ti fi òró Kérésìmesì (ẹ̀bùn Kérésìmesì tí ó wọ́pọ̀) fún àwọn òṣìṣẹ́ ní ìkọ̀kọ̀.
“O kò gbọdọ̀ ní oríṣìí ìwọ̀n meji ninu àpò rẹ, kí ọ̀kan kéré, kí ekeji sì tóbi.
Kò sí ẹnikẹ́ni tó kú níbi rògbòdìyàn tó wáyé lánàá - Deji ilu Akure Wo ibi fún èsì ìdìbò láti yan aàrẹ tuntun ní orílẹ̀-èdè Ghana *Atẹjade naa tun sọrọ lori bi ileeṣẹ ọtẹlẹmuyẹ DSS ṣe mu awọn Musulumi kan ni ipinlẹ Kano nitoripe wọn n jẹun ni ita gbangba lasiko Ramadan nigba ti awon musulumi n gbawẹ ati abadofin ti wọn fọwọsi lati tako iwaasu itagbangba nibẹ.
Àwọ̀n náà kún fún ẹja ńláńlá, mẹtalelaadọjọ.
lole ni agbegbe Kishi to wa ni ijoba ibile Irepo ni ipinle Oyo, ni ogbonjo osu
Ọpọ iwa kokanmi, tani yoo mumi ati aibikita awọn awakọ, yala awakọ ero ni tabi aladani, lo n fa sunkẹrẹ fakẹrẹ ọkọ.
Ṣugbọn inú OLUWA dùn sí àwọn tí ó bẹ̀rù rẹ̀,àwọn tí ó ní ìrètí ninu ìfẹ́ rẹ̀ tí kì í yẹ̀.
Bẹẹ lọrọ ṣe ri pẹlu ajakalẹ coronavirus ẹlẹẹkeji to n kan ilẹkun bayii lorilẹede Naijiria papaa julọ nipinlẹ Eko.
”Lẹyin gbogbo ọrọ yii, Agbẹnusọ naa, Aṣofin
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Yetunde Bakare dárà lórí ètò Ṣé o láyà, ẹ ràn án lọ́wọ́ nínú ìbéèrè tó ṣì 8) Alase ìlú Rẹmọ - Ọba Oyebajo: Ọdọ ni ọba yii nigba to jẹ.
Ẹ gbé àsíá kan sókè, ẹ gbé e ti odi Babiloni;ẹ ṣe ìsénà tí ó lágbára.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ìdìbò Èkìtì lọ̀ nírọwọ́-rọsẹ̀ - Rec EFCC fẹ́ bẹ̀rẹ̀ ìwádìí Fayoṣe Ekiti!
Ìwọ ọdẹ tíń bẹ lórí igi, mo dúpẹ́ púpọ̀ fún ọ̀rọ̀ rere tí o sọ nípa mi.
 Àpẹẹrẹ àwọn fíìmù tí ó ti wà lórí igbá tí ó sì wa lábẹ ́ ọ ̀ wọ ́ yìí ni ; tombolo , isakaba àti bẹ ́ ẹ ̀ bẹ ́ ẹ ̀ lọ .
Arabinrin to lo wọn fi ṣowo ọmọ bibi lo ko wọn lọ si ibomiran ti ẹnikankan ko mọ.
Lẹ́yìn náà ó dágbére fún àwọn onigbagbọ, ó bá wọ ọkọ̀ ojú omi lọ sí Siria; Pirisila ati Akuila bá a lọ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Arsene Wenger: Arsenal ja bi ẹlẹṣẹ nidije Europa pẹlu AC Milan 9 Ẹrẹ̀nà 2018 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Arsenal ko ba fidirẹmi lelekarun ni telentele nigba akọkọ lati ọdun 1977 ki wọn o to fọkọyọ ni San Siro Olukọni ẹgbẹ agbabọọlu Arsenal, Arsene Wenger, ṣ'apejuwe ẹgbẹ agbabọọlu rẹ bi ẹlẹṣẹ to n gbiyanju lati dide lẹyin igba ti wọn gba subu lori bi wọn ṣe sọ aiṣedada wọn di afiẹyin ti eegun fisọ.
Ọlọ́pàá mú afẹ̀sùnkàn Boko Haram tó ti pa ju ènìyàn 200 Osinbajo: Ẹ dìbò fún Buhari, kí ẹ̀yà Yorùbá lé gbàjọba ní 2023 Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ipenija ojú kò di Ademola lọ́wọ́ láti kẹkọọ gboye 5) Falz - This is Nigeria Ọmọ Naijiria to n kọrin taka sufe Falz lo fi orin to pé akọle rẹ ni 'This is Nigeria' da igboro ru lọdun yii.
Láti ibẹ̀, wọ́n ṣí lọ sí Beeri, níbi kànga tí ó wà níbẹ̀ ni OLUWA ti sọ fún Mose pé, “Pe àwọn eniyan náà jọ, n óo sì fún wọn ní omi.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Thomas Crowther ṣe àtúpalẹ̀ ìwádìí yìí ni orilẹ-ede àádọrin ní àgbáyé Ọkan lara awọn oṣiṣẹ ileeṣẹ rẹ to ba BBC News Yoruba sọrọ ṣalaye pe ori oju opo ikansiraẹni Whatsapp to jẹ tawọn oṣiṣẹ ileeṣẹ Redio rẹ lo ti tu iroyin ayọ naa fun awọn oṣiṣẹ rẹ loni.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Láàrín ìdílé ẹlẹ́ni márùn ún yìí, ọmọ kan ṣoṣo ló léè sọ̀rọ̀ Libya: Oṣu Kọkanla, ọdun 2014, ni IS kede pe oun ti wọ orilẹ-ede Libya.
3 Ẹrẹ̀nà 2020 Oríṣun àwòrán, EPA Àkọlé àwòrán, Iwòye fi han pé Joe Biden ni àǹ fani la'ti di asoju ẹgbk òṣèlú Democratic.
2m) lo n tẹ le Laycon loju opo Instagram rẹ.
Bẹ́ẹ̀náàni èyí tí ènìà bá kórira, kò fa dandan.
Wọ́n bá lọ sọ fún Dafidi pé, “OLUWA ti bukun Obedi Edomu, ati gbogbo ohun tí ó ní, nítorí pé àpótí ẹ̀rí OLUWA wà ní ilé rẹ̀.
Aarẹ ile asofin agba salaye pe, ijọba apapọ n sisẹ kara lori akọsilẹ orukọ awọn eeyan to fẹ gba ipo minisita naa lọna ati ri daju pe awọn eeyan ti musemuse wọn da musemuse ni wọn yan lati sisẹ sin orilẹede yii.
Iroyin sọ pe awakọ to jẹ ọmọ ọdun mẹrinlelọgbọn, jẹ ọkan gboogi lara awọn ẹgbẹ awakọ, NURTW nipinlẹ naa.
" Wá gbọ́ ìmọ̀ràn tí Jonathan fún Buhari lórí ọmọ Fasoranti tó kú!
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Èmi kò mọ obìrin tí DSS mú rí —Aisha Buhari 5 Ọ̀pẹ̀̀ 2018 Oríṣun àwòrán, Twitter/@AishaBuhari Ìyàwó ààrẹ Nàìjíríà, Aisha Buhari ti sọ wí pé òun kò mọ ọbìrin tí ilé iṣẹ́ ọ̀telẹ̀múyé orílẹ̀èdè Nàìjíríà, DSS, fi ẹ̀sùn jìbìti kan rí.
2 bílíọnù fi tún wáyà iná àti inú ilé Aso Rock ṣe- Buhari Ba wo ni ọrọ naa ṣe bẹrẹ?
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Adeleke: Àwọn ará Ẹdẹ bẹ síta pẹ̀lú ìdùnnú lórí ìdájọ́ èsì ìdìbò gómínà Ọṣun Oríṣun àwòrán, Adejare Taofeek Àkọlé àwòrán, 'Oyetọla ni Ọṣun dibo fun.
Minisita to n mojuto oro awon osise, dokita Chris Ngige soro naa di mimo lasiko ipade peluegbe awon osise ohun(ASUU), ti o waye niluu Abuja.
Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Fídíò, Nigeria movie industry: Àgbà òṣèré, Lere Paimo ní àìgbọràn ló ń da ọ̀pọ̀lọpọ̀ àwọn òṣèrè sinimá láàmú11 Ọ̀wàrà 2020 Fídíò, Wole Soyinka sọ ìdí tó fi ni òun a fi màálù Fulani ṣe súyà fáwọn èèyàn abúlé23 Owewe 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
O ni koda Gomina Oyetola mẹnu ba ọrọ yi lọjọ ti awọn janduku ṣe ikọlu si ni Osogbo ati lọjọ keji ọjọ naa lasiko to n ba ara ilu sọrọ lori ẹrọ amóunmáwòrán.
Wọn gbe oriyin fun Olatunji pe orin rẹ ṣe igbalarugẹ asa ati orin ilẹ Afrika, eleyii to gbe awo orin naa wa si gbagede lagbaye.
Ileeṣẹ naa sọ fun ile ẹjọ wipe ọdun 2007 ni Moi ta ilẹ naa fun awọn.
Ẹ̀rù kò ba odò Joshua, ojora kò mu, kó tó ríyà he lọ́wọ́ Ruiz Kini Pásítọ̀ Kumuyi fi ṣẹ ọmọ Naijiria?
Eyi jẹ ohun ti aarẹ Trump ta pada si Joe Biden, igbakeji aarẹ ana ni Amẹrika to sọ wi pe oun ti ṣe daadaa fun awọn alawọdudu ju ohun ti alatako rẹ ti ṣe lọ laarin ọdun mẹtalelogoji.
Bàbá mi ti pín ogún sílẹ̀ kí ó tó kú, ńitorí náà kò sí àríyànjiyàn nípa èyí nì.
Ọ̀kan lara awọn minisita to wa ni iṣakoso aarẹ South Africa, Nkosazana Dlamini -Zuma sọ pe ''aidọgba kọ̀ lati dinku.
Irinajo Libya: Ọmọ Naijiria mọ́kàndínláàdọ́jọ pada sile
Inu iwe ‘A song of Ice and Fire’ ti George Martins kọ ni wọn ti se fiimu yii bẹẹ naa si ni wọn da iwe Ireke Onibudo ṣe si sinima agbelewo eyi ti Tunde Alabi dari ẹ.
Oluwa wá sọ pé, “Ẹ kò gbọ́ ohun tí adájọ́ alaiṣootọ yìí wí!
    “Ní ayé àtijọ́, àwọn ẹranko a máa sọ ara wọn di ènìyàn, wọn a sì máa wá sí ọjà láti ra oúnjẹ won á bọ àwọ̀ ara tìwọn sílẹ̀, wọn a bẹ̀rẹ̀ sí í tọr\p ẹ̀yà ara ènìyàn kiri lọ́wọ́ àwọn iwin inú igbó ti ẹ̀yà ara wọn dàbí ti ènìyàn wọn a máa tọrọ lóríṣìíríṣìí ni, wọn á gba apá lọ́wọ́ ẹnìkan, wọ́n á gba ẹsẹ̀ lọ́wọ́ ẹni kejì wọ́n á gba orí lọ́wọ́ ẹnì kẹta, ìgbà tí wọ́n bá to ìwọ̀nyí jọ wọ́n á dàbí ènìyàn gidi gan-an.
Lára àwọn ọmọ Reueli, ọmọ Esau, àwọn tí wọ́n jẹ́ ìjòyè ni: Nahati, Sera, Ṣama, ati Misa.
Ayanyẹmi nikan lo mọ ohun to n fi omele sọ Oríṣun àwòrán, @ProfOsinbajo Àkọlé àwòrán, Àwọn eléré ìdárayá jẹri síi pé Osinbajo mo bí nnkan ṣé n ló ní ìgboro Oríṣun àwòrán, @ProfOsinbajo Àkọlé àwòrán, N gbó Olamide.
Oríṣun àwòrán, @nimc Àwọn ìgbà tí ìmọ̀ràn Pásítọ̀ Adeboye lóri igbéyàwó ti fa àríyànjiyàn Àwọn ọba tó wà lábẹ́ mi ń talẹ̀ nítàkutà- Oluwo Oyè Ibadan kò sí fún títà - Otun Olubadan, Lekan Balogun Yàtọ̀ sí eku gọ́tà tàbí èku inú ilé, kò sí eku téèyàn ò lè jẹ - Òǹtajà Eléwé ọmọ Pa-pa-pa ti eto naa lọ fun Anthony Joshua lo wu ariwo awọn ọmọ orilẹ€de Naijiria sita ti olukuluku si bẹrẹ si nii sọ ohun oju wọn ri lori ilana ati gba.
“Yóo ti pẹ́ tó tí ẹ̀yin óo máa fi aiṣododo ṣe ìdájọ́,tí ẹ óo sì máa ṣe ojuṣaaju fún àwọn eniyan burúkú?
“ lonii yii, ti e ba wo iye awon agbejoro ti a ni bayii, , ti opolopo, e o ri I pe itesiwaju ti de ba eto ofin yato si bi o se wa ni awon odun kan seyin, nitori pe a ti ni awon agba ọjẹ agbejoro ati adajọ to dangajia lorile ede yii.
àwọn ọmọ Hagabu, àwọn ọmọ Ṣamlai ati àwọn ọmọ Hanani;
Awọn Akọroyin ṣalaye pe, ni kete ti iṣẹlẹ naa waye ni iya rẹ ti bẹrẹ si n pe e ṣugbọn ti ko si dahun.
Egbe to n sakoso lọwọ, lorile ede Naijiria, APC ti satunse si ojo ti eto idibo inu egbe won yoo waye.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, SS3 ní mo wà báyìí, mo sì ti gba àmì ẹ̀yẹ̀ púpò nílé-lóko gẹ́gẹ́ bí onílù - Ayansike Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí EndSARS Ogbomosho: Gómìnà Makinde f'òkò kan pẹyẹ méjì nílé àwọn tó kàgbákò ìwọ́de EndSARS àti ààfin Soun13 Ọ̀wàrà 2020 Fídíò, Wole Soyinka sọ ìdí tó fi ni òun a fi màálù Fulani ṣe súyà fáwọn èèyàn abúlé23 Owewe 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 3 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 5 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Jẹ́ kí wọ́n mọ àwọn nǹkan ìríra tí àwọn baba wọn ṣe.
Nitori naa, lati akoko yii lọ, maa se eso carrot rẹ, ko rọ diẹ lori ina, ki o to maa jẹ.
Ni bayii, Gomina Obaseki ti wọle gẹgẹ bi Gomina ipinlẹ Edo fun saa keji.
Ṣé lóòtọ́ ni àjọ ọlọ́pàá dá Abayomi Shogunle àti Dolapo Badmus dúró?
Laycon, kú oríire àmọ́ bá ń kó owó orí nínú ẹ̀bùn rẹ nílé BB Naija - Ìjọba Eko Oríṣun àwòrán, Twitter/jidesanwoolu/BBNaija Ijọba ipinlẹ Eko ti ranṣẹ ikini ku orire si 'ọmọ ologo' Laycon, to jẹ owo ati ẹbun BBNaijia to kasẹ nilẹ lọjọ Aiku.
Ọjọ kẹẹdọgbọn, oṣu Kẹwa ọdun 1984 ni wọn bi , ṣugbọn o ku lẹni ọdun mẹẹdọgbọn, ni ọjọ kejilelogun, oṣu Kẹrin, ọdun 2010 lẹyin to ni ijamba ọkọ nilu Eko.
Nígbà tí Arauna wo ìsàlẹ̀, ó rí ọba ati àwọn iranṣẹ rẹ̀ tí wọn ń bọ̀ wá sọ́dọ̀ rẹ̀.
Richard Gbadebo: Àwọn ajafetoo ẹni dìde láti ṣe ẹjọ́ lórí ikú akẹ́kọ̀ọ́ UI nílé isẹ ọṣẹ Oríṣun àwòrán, others Ẹgbẹ ajafẹtọ ọmọniyan ti dasi ọrọ iku akẹkọọ fasiti Ibadan, Richard Gbadebo, to ku l'ẹnu iṣẹ ni ileeṣẹ kan ti wọn ti n ṣe ọṣẹ ni ilu Ibadan.
Oṣu mẹfa gbako si ni wọn kede pe wọn a fi ṣiṣẹ lori afara naa.
Kódà, ètò ìrìnsẹ̀ tí ìjọba pèsè fún ará ìlú – kẹ̀kẹ́ ń bẹ níbẹ̀.
Oluwa rẹ ni Mohammed Umar, tii se oludari tẹlẹ fun eto akoso isẹ ajọ EFCC, amọ nibayii, oun ni olori patapata fun ajọ ọhun.
Mo gbọ́ ìkérora àwọn ọmọ Israẹli tí àwọn ará Ijipti dì ní ìgbèkùn, mo sì ranti majẹmu mi.
Sẹ ilẹkẹ ma ja sile, ma ja sita ni ọrọ ọhun, Lẹyin ọ rẹyin, ile igbimọ aṣofin ipinlẹ Oyo buwọlu iyansipo rẹ l'Ọjọbọ.
Ní ọdún 2016, Sanaa lo oṣù mẹ́fà ní ẹ̀wọ̀n nítorí wípé ó sọ̀rọ̀ àfojúdi sí alaṣẹ ìjọba.
Òun ni yóo sọ ọ̀rọ̀ fún ọ nípa bí ìwọ ati ìdílé rẹ yóo ṣe ní ìgbàlà.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'A ò tíì rí omi mu, ẹ ní ká máa fọwọ́ tóríi Coronavirus' Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Sowore takú, kò jẹun ní àgọ́ ọlọ́pàá torí májèlé - Deji Adeyanju Ìròyìn ayọ̀!
Wọ́n bá kọsẹ̀ lórí òkúta ìkọsẹ̀, 
Nígbà tí Jesu dìde kúrò níbẹ̀, ó lọ sí agbègbè Judia, ó rékọjá sí òdìkejì odò Jọdani.
Eyí ni àwọn arẹwà 'ẹ̀lẹ̀ Daddy', àfẹ́fẹ́ tí Aláàfin fi ń mí Wo àwọn olorì àgbà mẹ́rin tí Aláàfin ń wárí fún Wo ọ̀nà tí àwọn ‘ẹ̀lẹ̀ Daddy’ gbà dé ààfin Ọyọ Èsì ìdìbò tí yóò gbé aàrẹ tuntun wọlẹ́ ní Ghana rèé.
Ninu ikede to fi sita, ajọ naa sọ pe gbogbo wọn ni ayẹwo fihan pe ko ni coronavirus lara, ṣugbọn wọn yoo ko wọn si ibi kan fun iyasọtọ tipatipa fun ọjọ mẹrinla.
May yoo jiroro pẹlu Olootu ijọba orilẹede Netherlands, Mark Rutte ati ti Germany, Angela Merkel, lẹyin to ti sun ọjọ toyẹ ki ile aṣofin kekere ni orilẹede UK o dibo lori bi Britain ṣe fẹ ẹ kuro ninu ajọ EU siwaju.
Lẹ́yìn náà, gbogbo ilẹ̀ àwọn ará Kenaani ati Meara, tíí ṣe ilẹ̀ àwọn ará Sidoni, títí dé Afeki ní ààlà ilẹ̀ àwọn ará Amori, 
Missing Child: Òbí àti asọ́nà ṣọ́ọ̀ṣì 14, lọ́ búra nì'dí imọlẹ̀ l'Akure Ẹ̀wọ̀n oṣù mẹ́ta àti #3000 ni awakọ̀ tí kò bá ní ‘speed limiter’ yóò fi gbára - FRSC Àwọtẹ́lẹ̀ ọkùnrin àti Ìdọ̀tí Kilo méje ṣekú pa Ìgalà Owó ìfẹ̀yìntì àwọn Gómìnà ní ìpínlẹ̀ Zamfara dì àlọrámirámi Ọpọlọpọ ọdun ni o ti wa lowo wọn ko to di wi pe awọn akẹkọọ kan an ni ipa fun wọn lati da a pada si ibi ti wọn ti gbe e wa.
Ṣọla Kosọkọ: ọlá bàbá mi ni mò n jẹ́ nínú iṣẹ́ tíátà
John ni awọn ko ni kẹrẹ rara ninu igbaradi fun ifẹsẹwọnsẹ eyi ti yoo waye lọjọ aiku pẹlu Madagascar.
Nígbà tí Abramu ń pada bọ̀, lẹ́yìn tí ó ti ṣẹgun Kedorilaomeri ati àwọn ọba tí wọ́n jọ pa ìmọ̀ pọ̀, ọba Sodomu jáde lọ pàdé rẹ̀ ní àfonífojì Ṣafe (tí ó tún ń jẹ́, àfonífojì ọba).
Àwọn alufaa kọ orúkọ wọn sílẹ̀ pẹlu àwọn ọmọ wẹ́wẹ́ wọn, àwọn aya wọn, àwọn ọmọ wọn lọkunrin ati lobinrin gbogbo wọn patapata, nítorí pé wọ́n jẹ́ olóòótọ́ nípa pípa ara wọn mọ́.
Manchester City ṣina iya fun Liverpool lati gba ife ẹyẹ community Shield ni papa iṣere Wembley.
Ara ko rọ okun, bẹẹ ni ko rọ adiẹ ni ibasepọ Saraki ati ijọba Muhammadu Buhari, ti ọpọ eeyan si mọ pe ilẹkẹ ma ja sile ma ja sita ni, ibi kan naa lo ma ja si ni awọn mejeeji jọ n se.
Ó ń waasu ìyìn rere ìjọba Ọlọrun.
Lẹyin-ọrẹyin wọn fi abẹ ṣekele ṣe irun rẹ baṣabaṣa wọn si tun fi ipa gba ẹẹdẹgbẹta naira lọwọ rẹ gẹgẹ bi i owo irun ti wọn baa fa.
Mo ti gbọ́ ìròyìn láti ọ̀dọ̀ OLUWA,wọ́n ti rán ikọ̀ kan sí àwọn orílẹ̀-èdè,wọ́n ní kí wọn kéde pé,“OLUWA ní, ‘Ẹ kó ara yín jọ, kí ẹ kọlu Edomu,ẹ dìde, kí ẹ gbógun tì í!
waye nipa ikede eesi idibo ijoba Ibile Iwo-oorun Gusu Ibadan, Ogbeni Mutiu
Ẹfunsetan Aniwura, obìnrin tó ju ọkùnrin lọ Ọ̀rọ̀ǹpọ̀tọ̀niyùn, Aláàfin obìnrin àkọ́kọ́ rèé, tó ní nǹkan ọkùnrin Bawo lo ṣe kan araalu lasan ni Naijiria?
Garba tun mẹnu ba bi aarẹ Buhari ṣe mu ọkan akin lati yọ owo afikun epo rọbi taa mọ si ''subsidy'' eleyi ti ijọba Obasanjo da laba ṣugbọn ti wọn ko ṣọkan akin lati sọ di mimuṣẹ.
Tesiwaju si, iko agbaboolu Tunisia wa ni ipo méjìlélógún lagbaye, Senegal wa ni ipo márùndínlọ́gbọ̀n(25th).
Ẹ̀kọ́ sì tún n sọni dọ̀gá, mú́ra kí o kọ dáradára
Ṣugbọn kò pa àwọn ọmọ wọn nítorí pé òfin Mose pa á láṣẹ pé, “A kò gbọdọ̀ pa baba nítorí ẹ̀ṣẹ̀ ọmọ, bẹ́ẹ̀ ni a kò gbọdọ̀ pa ọmọ nítorí ẹ̀ṣẹ̀ baba.
Ninu ọrọ kan ti Aarẹ Muhammadu Buhari sọ laipẹ yii pe ni ti oun, abo lagbara ju ibọwọ fun ẹtọ araalu lọ, amofin Adela Oyinlade ti o ṣẹṣẹ gba ami ẹyẹ amofin ti o dantọ julọ lagbaye lori ọrọ ija fun ẹtọ araalu lati ọwọ ẹgbẹ awọn amofin lagbaye, IBA, ṣalaye pe ko lee si abo bi ko ba si ibọwọ fun ẹtọ ọmọniyan.
Oríṣun àwòrán, Instagram/Lateef Adedimeji Awuyewuye ti waye lori awọn mejeeji ri pe, wọn n fẹ ara wọn.
Ṣùgbọ́n níggbà tí àwọn ẹranko tún ṣe àlàyé pé àwọn iwin ni yóò bá àwọn ọẹ jà àti pé ìjà èmi àti Ìnàkí-ìbẹ̀rù ni yóò jẹ́ ìjà láàrin ènìyàn àti asoju Ẹranko, a pinnu láti sa ipá wa.
Oríṣun àwòrán, @sosintayo Ipinlẹ Eko: Lara awọn ibi ti wọn gbe iwọde ọhun de ni ilu Eko ni, opopona marosẹ Lekki si Ajah, Alausa ni Ikeja, Oba Akran, Allen Avenue, ati bẹbẹ lọ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ijọba Ondo wa ọdẹ to p'erin ni Idanre 9 Ẹrẹ̀nà 2018 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Pipa erin wopo ni ilu India naa Ijọba ipinlẹ Ondo ti pariwo faraye wipe awọn n wa ọdẹ ti o yinbọn pa erin kan ninu igbo, ni ilu Idanre, loṣu to kọja.
“Ìtumọ̀ òwe yìí nìyí: irúgbìn ni ọ̀rọ̀ Ọlọrun.
Níbẹ̀ ni ó wà títí Hẹrọdu fi kú.
Kevin Gameiro ti Valencia tun gbiyanju lẹẹkan sii to si fun ikọ rẹ ni ami ayo miiran.
Angẹli OLUWA farahàn án ninu ahọ́n iná láàrin ìgbẹ́; bí ó ti wò ó, ó rí i pé iná ń jó nítòótọ́, ṣugbọn igbó náà kò jóná.
À ń retí rẹ̀ kí ó wá báwa ṣeré ọjọ́ Sátidé tí ìṣẹ̀lẹ̀ ńlá ṣẹlẹ̀ yìí títí di alẹ́.
ede Cameroon, ninu eyi ti o ran won lowo lati se aseyọri ninu ere bọọlu alafẹsẹgba
O ku lojo ketalelogun osu keji odun yii, won yoo sin in ni Monaco nibi to n gbe ko too dologbe.
Wọ́n kọ OLUWA sílẹ̀, wọ́n ń bọ oriṣa Baali ati Aṣitarotu.
Ìwé àkàgbádùn láti ọwọ́ Fagunwa, Faleti, Iṣọla, Ogunniran àti Okediji tó yẹ kí o kà lásìkò yìí.
Oríṣun àwòrán, Twitter/Sanwo-Olu Kọmiṣọnna eto ifitonileti fun Sanwo Olu tun ṣalaye pe: '' Awọn ti wọn ba ni arun Coronavirus, amọ ti ko gboro lara wọn, ijọba n na o kere tan N100,000 lori wọn lojumọ, Amọ fun awọn ti arun Coronavirus ti peleke ni ara wọn, o kere tan ijọba n na miliọnu kan naira lori wọn ni ojumọ.
Ni ọdún mọ́kànlélọ́gbọ̀n sẹhin, Olóri Òsèlu tuntun Muhammadu Buhari àti àtẹ̀lé rẹ Túndé Ìdíàgbọn ṣe Ìjọba fún ogún oṣù gẹgẹ bi Ìjọba Ológun.
OLUWA dá mi lóhùn, ó ní, ‘Ó tó gẹ́ẹ́, má ṣe bá mi sọ̀rọ̀ nípa rẹ̀ mọ́.
Nígbà tí ó dé ibìkan tí wọ́n ń pè ní Bẹtekedi, níbi tí àwọn olùṣọ́ aguntan ti máa ń rẹ́ irun aguntan, 
O tẹsiwaju pe oun ati Deji lo mọ ohun to n bii ninu, amọ ṣa oun si fẹran rẹ.
Idi si niyi to fi jẹ pe ọjọ keje oṣu kinni ọdun ni awọn kristẹni ẹya wọnyii ni agbegbe ilẹ larubawa atawọn to wa ni orilẹede Russia ti o n tẹle iwe onka ọjọ yii maa n ṣe ajọyọ ọdun keresimesi tiwọn.
    Nígbà tí ọjọ́ pé, èmi àri ìránṣẹ́ ọba múra a yí agbègbè lọ.
''Nígbà míràn, ó maa n bi mí pé kíni àwọn ènìyàn yìí (àwọn ẹlẹ́wọ̀n) n ṣe níbí?
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Plastic for School fees: Àwọn èèyàn rò pé wọ́n fẹ́ máa lò wá ni Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Plastic for School fees: Àwọn èèyàn rò pé wọ́n fẹ́ máa lò wá ni 3 Òkùdu 2019 Àwọn ike rọba yii n ran wa lọwọ lati ṣe ọpọlọpọ nkan to wulo bii irọrí, aṣọ itẹ ibusun.
Wọn gba àṣẹ̀ ìgbóhùnsáfẹ́fẹ́ lọ́wọ́ iléeṣẹ́ AIT àti Ray Power.
Seun Kuti: Gbogbo mọ̀lẹ́bí mi ló wọ bàtà ti Fẹla bọ́ sìlẹ̀
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Kàkà k‘éwé àgbọn dẹ̀ lágbo òṣèlú l‘Ondo, akọ̀wé ìjọba tún kọ̀wé fipò sílẹ̀ Ẹ wo bí ọ̀rọ̀ òṣèlú, ẹ̀sìn àti ẹ̀yà ṣe fa ogun abẹ́lé Biafra Mà á gbẹ̀san bàálù àjọ UN tó já ní Borno - Buhari yarí Ẹ̀kún omi ṣọṣẹ́ ní Ogun, ìjọba yarí láti wó ilé ojú odò Ẹ sá àwọn akẹ́kọ̀ọ́ sínú òòrùn fún ọgbọ̀n ìṣẹ́jú lójojúmọ́ - Ìjọba Oyo pàṣẹ Òṣìṣẹ́ LASTMA gún olólùfẹ́ rẹ̀ l'ọ́bẹ, ó tún gba ẹ̀mí ara rẹ̀ l'Eko Lara awọn adari ile ẹkọ to ba wa sọrọ ṣe alaye wi pe, gbogbo ipa ni awọn n sa lati daabo bo awọn akẹkọọ ati awọn olukọ wọn gẹgẹ bi wọn ṣe wọle pada sẹnu ẹkọ.
o soro yii, bi o se n wọnu ọkọ
Ninu aworan naa, ti awọn ayaba ọhun fi soju opo ayelujara wọn, ni apapọ awọn ẹlẹ Daddy naa ti jẹ meje, dipo mẹjọ taa mọ wọn mọ tẹlẹ.
Aarẹ Buhari nikan ni a gbọ pe o jẹ olori ilẹ okeere ti wọn pe sibi ayẹyẹ ọun gẹgẹ bi alejo pataki.
O si jẹ awakọ ọkọ oju omi.
Ni àrìn-kẹ́yìn rẹ, àpérò Ilẹ̀ Áfíríkà lò ń lọ
Ẹ le ka gbogbo idahun naa ni Ọpọlọpọ lo gbagbọ pe ti ọkọ tabi iyawo wọn ba yan aale nikan lo le mu wọn binu tabi tu igbeyawo wọn ka, àmọ́ onimọ sọ pe awọn nkan miran tun buru ju u lọ.
Kini awọn ohun to yẹ ki o mọ nipa Ohun ti o ko mọ nipa baluu adanikan fo ti ileesẹ ọmọogun ofurufu orilẹede Naijiria sẹsẹ se yii.
Ọ̀pọ̀ èèyàn tí kò yin Ajimobi lojú ayé, tó ń yìn-ín lẹ́yìn ikú, yóò jẹ ìyà - Oníwáàsí Ọ̀pọ̀ ìgbà ní Hushpuppi àtàwọn èèkàn PDP ti ya fọ́tò ní Dubai, EFCC ẹ wádìí wọn - APC ń lọgun Àwòrán rèé nípa àwọn gbajúmọ̀ tó ti bá Hushpuppi ṣe Mo ti bá ọmọ ọwọ́ mẹ́ta lòpọ̀ sẹ́yìn, ọmọ oṣù mẹ́ta ló ṣìkẹrin - Afurasí jẹ́wọ́ Oluwọde tako ele owo epo ni Ghana Àkọlé àwòrán, Awọn eeyan ti n fẹhonu han fun irora to ba wọn lori ele owo ori epo bẹntiroolu lorilẹede Ghana Ẹkunwo epo bẹntiroolu to waye ni orilẹede Ghana laipẹ yii ti nfa ẹhonu bayii, tawọn oluwọde si ti fun ijọba orilẹede Ghana ni gbedeke ọsẹ meji lati fi mu ayipada ba ọwọngogo owo epo bẹntiroolu to waye lorilẹede naa.
“Ninu ipade gbogboogbo naa a tun sọrọ lori awọn ọrọ to jẹ awọn ara ilu logun bayii, bẹẹ naa ni a tun yan igbimọ alakoso tuntun fun Igbimọ awọn Agbẹnusọ Ile Igbimọ Asofin Ipinlẹ Lorilẹ-ede Naijiria nibi ti wọn ti dibo yan agbẹnusọ ile igbimọ Aṣofin Ipinlẹ Eko, Aṣofin Ọbasa gẹgẹ bi alaga tuntun.
Ilẹ̀ tí ó yí àwọn ìlú náà ká yóo wà fún àwọn ẹran ọ̀sìn wọn ati mààlúù wọn.
Bakan naa ni Olori Badra tun ti sẹsẹ si sọọbu asọ tita bayii eyi to pe ni Queen Ajoke Closet, bẹẹ lo tun n ba awọn ileesẹ asaraloge miran se ipolowo ọja wọn.
Kò sí rògbòdìyàn tó lè sẹlẹ̀ ju wákàtí 24 lọ láì ní ọwọ́ ìjọba níbẹ̀- Ogagun Ibrahim Babangida Wo awọn ipinlẹ̀ naa: Ipinlẹ Plateau: Ni ipinlẹ Plateau, ijọba ipinlẹ naa ti ni ki ofin konile o-gbele o rọlẹ si nipinlẹ naa, paapaa ni agbegbe ijọba ibilẹ Ariwa ati Guusu Jos nipinlẹ naa.
Ṣugbọn awọn olugbe ilu yii ni awọn ko gbọ iroyin daadaa nipa bi arun naa ṣe n ran ati bo ṣe le ṣakoba fun awọn.
Àwọn eniyan sì ń wá láti oniruuru orílẹ̀ èdè, ati láti ọ̀dọ̀ àwọn ọba ní gbogbo ayé, tí wọ́n ti gbúròó nípa ọgbọ́n rẹ̀, wọn á wá tẹ́tí sí ọgbọ́n rẹ̀.
Ní tèmi o, mo máa nlọ sínú ọgbà kan nítòsí láti gba ìsinmi.
Orukọ naa si ni Ajayi n jẹ titi ti ọlọjọ fi de si O pada si ilu Freetown lọdun 1827, oun si ni akẹkọọ akọkọ ti yoo lọ sile ẹkọ Fourah Bay College, to si n sisẹ olukọ lẹyin to pari ẹkọ rẹ tan Ajayi nifẹ lati gbọ oniruuru ede, idi niyi to fi kọ ẹkọ ede Latin, Greek ati Temme Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Cancer: Àṣe ara mi ni iso ti n run gbogbo bí mo ṣe n ṣèrànwọ́ lórí jẹjẹrẹ Musulumi ati olukọ ni iyawo Ajayi, tii orukọ rẹ n jẹ Asano abi Hassana, wọn ko oun naa lẹru ni, ki wọn to gba silẹ wa si Freetown.
Ni bayii, a ko ti ri Sarkozy tabi agbejoro re lati ba awon akoroyin soro lati mo bi oro ohun se n lo, leyin ti ifesunkan ohun bere lati odun marun-un seyin.
ati ìjọ àwọn àkọ́bí tí a kọ orúkọ wọn sọ́run.
Harry Obi ni tiẹ sọ pe, ta lo lo ro pe oogun Chloroquine le ṣe itọju coronavirus, o ni o daju pe, awọn dokita oniṣegun oyinbo yoo tun ni oogun naa nitori wọn ti lo ọpọ rẹ fun itọju aarun iba tẹlẹ.
 O si ni ami-ayo ọgọ́rin ninu ifesewonse òjìlénígba o lé meje ti o gba fun iko agbaboolu Bayern lapapo.
Ẹ wo OLUWA tí ń bọ̀ láti ilẹ̀ òkèèrè,ó ń bọ̀ tìbínú-tìbínú;ninu èéfín ńlá tí ń lọ sókè.
Ti eeyan ba si de oju opo Instagram rẹ, Wumi ko fi bo rara nipa okoowo to yan laayo, to si n ke si iruwa, ogiri wa lati wa ra ohun to n ta.
” Wọ́n kọ́ àwọn ìlú náà, wọ́n sì ń ní ìtẹ̀síwájú.
 ara àwọn opera tí ó kọ ni  the marrcege of figaro ' "" dio giovanni ' àti the magic flute ' ."
Oríṣun àwòrán, @NGRSenate Àkọlé àwòrán, Lẹ́yìn wàhálà tó wáyé nílé aṣòfin ni Bukọla Saraki ṣe ìpàdé pẹ̀lú àwọn oníròyìn àgbáye Eyi ri bẹẹ nitori wahala to waye nile aṣofin naa ni owurọ kutu-kutu ọjọ ipade, pẹlu bi awọn aṣofin kan ti ko ṣe ti Aarẹ Muhammadu Buhari ṣe fẹsun kan pe awọn oṣiṣẹ eleto aabo DSS di ọna mọ wọn lati wọn ile aṣofin.
Kí tafàtafà má kẹ́ ọrun rẹ̀,kí ó má sì gbé ẹ̀wù irin rẹ̀ wọ̀.
Paali bata tapasẹgun awọn ọmọogun marundinlogun ninu eyi ti ọkọọkan rẹ ni ogun bata yii.
O fi kun ọrọ rẹ wi pe, ipo ti eto aabo orilẹede yii wa ti di ohun ijaya fun awọn eeyan ilu, ọrọ yii ṣi jẹ ohun to n kọ awọn gomina lominu.
Olukemi Olufunto Badenosh, tii se ẹni ọdun mọkandinlogoji ni Boris Johnson yan gẹgẹ bii minisita fun awọn ọmọde ati mọlẹbi.
fun ire ati idagbasoke orile ede yii bi eto awẹ Ramadhan odun yii se bẹrẹ ni pẹrẹu.
" Lẹyin naa lo rọ awọn ara ilu lati fa ọdaran ọhun le awọn agbofinro lọwọ ni kete ti wọn ba gba a mu.
Àwọn eniyan náà bá sinmi ní ọjọ́ keje.
fẹ waye ki o to di ọjọ idibo Gomina wa gbadura pe ki
Oríṣun àwòrán, Getty Images Ko si iyọnu, ọmọ wa naa ṣi ni, aṣoju wa si ni,"" ọkan lara wọn, Okunore lo sọ bẹẹ."
Nígbà tí ó kúrò lọ́dọ̀ àwọn eniyan, tí ó wọ inú ilé lọ, àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ ń bi í ní ìtumọ̀ òwe yìí.
Ẹgbẹ́ ALGON, tí Ọgbẹ́ni Kunle Sobaloju jẹ́ agbẹjọ́rò wọn, dárukọ agbẹnusọ ilé ìgbìmọ̀ asofin , kọmisọna fọrọ ijọba ibilẹ̀, kọmisọna fun ètò ìdájọ àtí agbẹjọrò àgbà ìpínlẹ̀ Oyo nínú ìwé ẹsùn náà.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Premier League: Tottenham yọ ṣọ́ọ̀kì lẹ́sẹ̀ , ọ̀mì ni wọ́n ta lọ ní pápá ìṣiré Etihad 17 Ògún 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Ṣe wọn ni ẹṣin ta-ta-ta, o ku, eeyan rin-rin-rin o sọnu, gbogbo agbara emi ni mo to yii ti Manchester city fi gba ife ẹyẹ Premier league ni saa bọọlu to kọja lo sa pẹlu eyi to fi na Westham mọ ile lọsẹ to kọja ṣugbọn pabo lọrọ jasi fun iks naa nigba to gbalejo Tottenham ni gbagede papa iṣire Etihad lọjọ Abamẹta.
ní ìlú Ọ ̀ yọ ́ àti Ìbàdàn , ó dà bí ẹni pé a ya ọjọ ́ kan sọ ́ tọ ̀ fún rárà sísun yìí .
Igba akọkọ ni yii ti wọn yoo dajọ ẹwọn fun ẹnikẹni lori iwa ijinigbe naa to mi gbogbo agbaye titi.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Arẹgbẹsọla fowó lé isẹ́ àgbàse ní ìlọ́po márùn-ún - Omisore Ìpínlẹ̀ Oṣun kò nílò Gómìnà oníjó - Oshiomole Ọ̀rọ̀ LAUTECH gba àpérò f'áwọn Olúdíje Ọṣun Àwọn ohun tó yẹ kó o mọ̀ nípa Adémọ́lá Adélékè Àlòkù fíríjì di ọkọ̀ ojú omi lórí àgbàrá omiyalé Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí kan sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
’ rèé Àwọn olówó Naijiria 5 tí owó wọn ju owó ìsúnná Naijiria lọ!
Baba kii binu nitori eniyan ṣe aṣiṣe, amọ o fẹran ki eniyan mọ ẹbi rẹ ni ẹbi,ki o si ṣe atunsẹ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù 2019 Elections: Oshiomole ní Buhari yóò wọlé láìsí àtìlẹ́yìn Ọbasanjọ 11 Ògún 2018 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 26 Bélú 2018 Àkọlé àwòrán, Oshiomole gbá kuru ti àwọn olóyè ẹgbẹ́ APC Alága àpapọ̀ fẹgbẹ́ òṣèlú All Progressives Congress APC, Adams Oshiomole sọ pe, igbesẹ aarẹ ana Oluṣẹgun Obasanjọ lati fi ẹnikẹni jẹ aarẹ orilẹede orilẹede Naijiria ninu idibo ọdun 2019 ko le ṣeeṣe.
gbogbo wọn, nitori pe, o ti pase fun ajo agbofinro lati se ise won lona to ba
Oyedele Adedokun Isaac ni orukọ ọdọmọkunrin ayaworan yii Oun funra rẹ lo kọ ara rẹ ni iṣẹ ayaworan, ko kọọ nibi kankan rara.
Church of Satan: Báwo ni ìjọ́sìn ṣe n rí nínú ìjọ Sátánì?
Nígbà tí èmi àti Ènìyàn-ṣe-pẹ̀lẹ́ rí ara wa a dì mọ́ ara wa ni; òun náà sì sọ  ọ̀pọ̀lọpọ̀ nǹkan fún mi.
Kòkòrò oyin lé ọ̀pọ̀ èèyàn kúrò nílé l'órílẹ̀-èdè Cameroon
Yatọ si ile Ilorin, ajọ EFCC ti n tọ pinpin awọn dukia Saraki ti Iroyin si kan nigba kan pe wọn gbẹsẹ le ile rẹ kan ni adugbo Ikoyi nilu Eko.
Abẹwo ti ikọ iroyin BBC Yoruba ṣe si awọn ile epo kan to n bẹ nilu Ibadan lowuro Ọjọbọ lo fi idi ọrọ mulẹ.
 Àwọn ìwé tí ó kọ tí ó tẹ ̀ jáde náà ló jẹ ́ àkàsọ ̀ fún àwọn òǹkọ ̀ wé èdè yorùbá òde òní ní ìwúrí láti gbé àpilẹ ̀ kọ yorùbá lárugẹ síwájú si .
7 tabi ko kere si i.
Bi iye awọn to ni ni awọn ipinlẹ to ku ṣe lọ ni yii; Eko-192 Edo-41 Rivers-33 Kaduna-30 Kwara-23 Nasarawa-18 Borno-17 FCT-14 Oyo-10 Katsina-7 Abia-5 Delta-5 Adamawa-4 Kano-4 Imo-3 Ondo-3 Benue-2 Bauchi-2 Ogun-2 Niger-1 Ènìyàn 307 ló lùgbàdì àrùn Coronavirus ní Ọjọ́ Aiku Ajọ NCDC ti kede eniyan 307 gẹgẹ bi apapọ eniyan to ni arun Coronavirus lorilẹede Naijiria ni Ọjọ Aiku lorilẹede Naijiria.
Awọn iroyin ti ẹ lee nifẹẹ si: Buhari n dunkoko mọ alatako - PDP 'Iléeṣẹ́ ológun kò mọ̀ nípa ìkọlù Dapchi' Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Pẹtẹsi akọkọ ni Naijiria Ọ̀pọ̀ oríllèdè lágbàáyé ni wọ́n ti tẹ́wọ́gba ìlànà sogúndogójì MMM yìí, tó fi mọ́ oríllèdè wa Nàìjíríà sùgbọ́n ìjọ̀ba ilẹ̀ wa ti gbẹ́sẹ̀lé ìlànà sogúndogójì MMM yìí, tí owó ọ̀pọ̀ ènìyàn sì wọ igbó.
Ẹwẹ, ni idahun si eyi, oluranlọwọ pataki si aarẹ lori ọrọ ori ayelujara, Lauretta Onochie kede lọjọ Aje wipe Aarẹ yoo ba apapọ ile igbimọ aṣofin sọrọ.
A ti sún ìgbẹ́jọ́ Ganduje, Tambuwal àti Ihedioha sí ọ̀la Àwọn sẹ́nétọ̀ Nàìjíríà fa ìbínú yọ 'torí N2Miliọ̀nù owó àjẹmọ́nú Kérésì tí wọ́n fún wọn Ṣugbọn iyalẹnu lo jẹ fun ọlọpaa naa lati ri i pe o di aṣọ sinu kọmu rẹ lati fi ṣe bii pe ọmu rẹ ni.
 Ọ ̀ pọ ̀ orin inú àwo náà ni ó ní í ṣe pẹ ̀ lú ọ ̀ rọ ̀ -òṣèlú , tí ó ń sọ nípa ìṣòro àwọn èyà gúsù - úsù ilẹ ̀ yìí àti àwọn ìwá ọbaàyéjẹ ́ mìíràn tí ń wáyé l ' ágbègbè abínibí nneka .
gbọ́ adura wọn lọ́run lọ́hùn-ún, dárí ẹ̀ṣẹ̀ ji Israẹli, iranṣẹ rẹ, àní, àwọn eniyan rẹ, kí o sì kọ́ wọn ní ọ̀nà rere tí wọn yóo máa tọ̀; lẹ́yìn náà, rọ òjò sórí ilẹ̀ rẹ tí o fi fún àwọn eniyan rẹ bí ohun ìní.
án lori iwe isuna odun 2019 , bi
O ni awọn  agbofinro duro si oju ona Fajuri ti o lọ si ile-ijoba lati dena wahala ati titapa si ofin.
Lẹ́yìn náà, wọ́n tọ Hesekaya ọba lọ, wọ́n sọ fún un pé, “A ti tọ́jú ilé OLUWA: ati pẹpẹ ẹbọ sísun, ati gbogbo ohun èlò rẹ̀, ati tabili àkàrà ìfihàn ati gbogbo ohun èlò rẹ̀.
Dìde nílẹ̀ kí o jẹun, kí o sì jẹ́ kí inú rẹ dùn, n óo gba ọgbà àjàrà Naboti fún ọ.
 http://Ewe, arabinrin ohun ni won yinbon mo nigbati oyun-un inu re pe ose merindinlogoji, eyi ti o sokunfa ise-abe ti o la koja ki o to bimo ohun pelu apa ibon lara.
DSS ti fi ẹ̀sọ́ àbò abẹnugan ilé ìgbìmọ̀ asofin tó pa fẹ́ndọ̀ l'Abuja sátìmọ́lé Wàhálà mìíràn déba Trump bí Biden ṣe tún gbégbá orókè nínú atunka ibo Georgia Èyí ni bí wọ́n ṣe pín fásitì LAUTECH láàrín ìpínlẹ̀ Oyo àti Osun A dúro bí iké lẹ́yìn ìròyìn táa gbé jáde nípa Lekki Tollgate; CNN tako Lai Mohammed Sùgbọ́n ìdájọ́ Adájọ́ Charles Ikpe to dá ẹja náà nù nítorí pé kò ní ẹ̀rí arígbámú tó dájú, èyí sì ló mú kí wọ́n mórí lé ilé ẹjọ́ kòtẹ́milọ́rùn.
Manchester United ni Ronaldo ti fakọyọ ti o si ti di ilumọka agbabọọlu.
O ni, bi wọn ṣe n yan ọba nilẹ Yoruba tẹlẹ ko to di pe ijọba ati ọlaju de, ti ijọba si n lọwọ ninu ọba yiyan.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Gbèsè àti Kérésì elébi ni ìyansẹ́lódì ASUU bádé fún wa - Òǹtàjà ní fásitì Èéfín gẹnẹratọ gbé ayálégbé délé ẹjọ́ Lekan kingkong lọmọ Yorùbá tó ń fi òwe dárà lẹ́yìn odi Ìfipábánilòpọ̀ kìí se àwàdà - Ireti Yusuf Ninalowo: Mo ṣiṣẹ́ agbèrò rí lati ṣe aṣeyege O wa gba awọn obinrin nimọran lati mase maa woju ọkọ wọn, ki wọn to jẹun tori iwuri nla ni ti ọwọ meji ba n sisẹ.
Alọ rẹ ni wọn ri, wọn ko ri abọ rẹ fun ọdun mẹfa.
Èèyàn mẹ́tàdínláàdọ́fà ló móríbọ́ lọ́wọ́ Covid-19, 443 míì tún lùgbàdì rẹ̀ lọ́jọ́ Ẹtì Inú ibojì kan náà pẹ̀lú aya rẹ̀ ní wọ́n a sin Bàbá Fasanmi sí lọ́jọ́ kẹrin, osù kẹjọ!
6 125550 Orilẹede Austria 3897 43.
Bi a ko ba ni gbagbe, laipẹ yii pẹlu ni ileẹjọ giga kan nilu Oṣogbo gbe idajọ kalẹ pe lati faaye gba ile aṣofin apapọ pe ko bẹrẹ igbesẹ irọloye fun aarẹ lori awọn ẹsun kan ninu eyi ti a ti ri ẹsun to nii ṣe pẹlu iwe ẹri pẹlu.
Ṣé kò yẹ kí èmi foríji Ninefe, ìlú ńlá nì, tí àwọn ọmọde inú rẹ̀ ju ọ̀kẹ́ mẹfa (120,000) lọ, tí wọn kò mọ ọwọ́ ọ̀tún yàtọ̀ sí tòsì, pẹlu ọpọlọpọ ẹran ọ̀sìn tí ó wà ninu ìlú náà?
Òùngbẹ kò gbẹ wọ́n,nígbà tí ó mú wọn la inú aṣálẹ̀ kọjá,ó tú omi jáde fún wọn láti inú àpáta,ó la àpáta, omi sì tú jáde.
Rán ìmọ́lẹ̀ rẹ ati òtítọ́ rẹ jáde,jẹ́ kí wọ́n máa tọ́ mi sọ́nà;jẹ́ kí wọ́n mú mi wá sí orí òkè mímọ́ rẹ,ati ibùgbé rẹ.
 oríìsírísìí ni ọ ̀ nà tí yorùbá máa ń gbá láti ran wọn lọ ́ wọ ́ , èyí sì ni à ń pè àṣà ìràn-ara-ẹni-lọ ́ wọ ́ .
títí tí OLUWA fi run wọ́n kúrò níwájú rẹ̀, bí ó ti kìlọ̀ fún wọn láti ẹnu àwọn wolii, iranṣẹ rẹ̀.
Frank Lampard di olùkọ́ni tuntun fún Chelsea Ààrẹ Buhari jámi lórí ètò RUGA ná Gbẹgẹdẹ fẹ́ gbiná l‘Ọṣun, àwọn olùkọ́ iléẹ̀kọ́ gíga fẹ́ gba àjẹẹ́lẹ̀ owó oṣù ìdajì Àwọn àṣà àti ìse tó yọ obìnrin sílẹ̀ nílẹ̀ Yorùbá Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Kunle Afolayan: èmi kò fẹ́ fi ogún sílẹ̀ fún ọmọ mi Ninu ọrọ to ba BBC News Yoruba sọ lọjọbọ, agbẹnusọ fun ẹgbẹ Afẹnifẹre, Yinka Odumakin wi pe ẹtan ni ikede ijọba apapọ naa nitori kii ṣe ijọba apapọ wọgile igbesẹ naa patapata, wọn kan n jawọ lori rẹ fun igba diẹ lasan ni.
NFF: Olóògbé Taiwo Ogunjobi gbá bọ́ọ̀lù fún Nàìjírìa nígbà ayé rẹ̀
Àwọn bàbá ìsàlẹ̀ òṣèlú tó bá ìtìjú bọ̀ nínú ìbò Gómìnà rèé NBC fọwọ́ sí ìdásílẹ̀ ilé iṣẹ́ Fulani Radio Aisha Buhari ké gbàjare pé ètò ìjọba Buhari kò ṣànfàní f'óbìrin Awọn wọn yii lo bẹ jade gba oju ferese ti wọn si bẹrẹ si ni sa asala fun ẹmi wọn, eleyii to da ipaya si lẹ, ti gbogbo ile iwe fi daru lọjọ naa.
Àwọn òyìnbó aláwọ̀ funfun kówa lọ sí oko ẹrú lẹ́hìn-ọ̀rẹhìn, wọ́n sì pín àwa ìyókù ní Afirika wẹ́lẹwẹ̀lẹ mọ́nrawa.
Aseyọri yii lo mu ko ri oniruuru atilẹyin gba lati ọdọ awọn ileesẹ nla-nla, to fi mọ ileesẹ London Ventures Patners, ti wọn fun ni miliọnu mẹwa dọla ($10m) lọdun naa.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Niṣe lawọn olugbe awọn ilu to wa leti bọda n ke lẹyin ti jala epo kan di ẹgbẹta naira dipo naira marundinlaadọjọ, eleyi waye nitori bi ijọpa apapọ ṣe fi ofin de gbigbe epo lọ si awọn agbegbe ti ko ju ogun kilomita lọ si ibode Naijiria sawọn orilẹede mii.
A ni lati yẹra fun awọn ọrọ tabi iṣe ti o le gegi dina alaafia laarin ilu.
Àwọn ojú oge Yollywood t'ọ́jà wọ́n ṣì ń tà wàràwàrà Ànọ́bì ni màá tẹ́lè.
Akeugbagold, nigba to n ba BBC Yoruba sọrọ lọjọ Isegun lori iṣẹlẹ naa salaye pe, ọmọkunrin to ni laakaye ni afurasi naa, o ni ọpọlọ, to si maa n ronu kọja ọjọ ori rẹ.
 O ni, “eyi yoo tun faaye silẹ fun awọn onimọ lati ṣe iwadii ijinlẹ siwaju lori itọju awọn alarun ọpọlọ bayii”.
Awon miiran ti won yoo tun maa reti loni ni: John Ogu, Kenneth Omeruo, Leon Balogun, William Troost-Ekong, Shehu Abdullahi, Oghenekaro Etebo, Ahmed Musa, Moses Simon, Henry Onyekuru, Semi Ajayi, Ikechukwu Ezenwa ati Ola Aina.
olubori ninu eto idibo naa  ni iwe ẹri mo
‘Òní ni ọjọ́ tí ẹ óo ré ààlà àwọn ará Moabu kọjá ní Ari.
Ìjàmbá ọkọ̀ ọ̀ún ni a gbọ́ pé ó wáyé nígbà ti awọn obi náà fẹ́ lọ yọjú sí awọn ọmọ wọn tí wọ́n dá sílẹ̀ ní àhámọ́ Boko Haram tí wọ́n wà ní ile ẹ̀kọ́ gíga ti ilẹ̀ Amerika to wà ní Yola.
Ọba bá dá a lóhùn pé kí ó máa lọ ní alaafia, Absalomu bá dìde ó lọ sí Heburoni.
Ṣugbọn OLUWA fi àrùn burúkú bá Farao ati gbogbo ìdílé rẹ̀ jà nítorí Sarai, aya Abramu.
Níbẹ̀ ni ẹ óo ti máa sin oriṣa, tí ẹ óo máa bọ wọ́n tọ̀sán-tòru, nítorí pé n kò ní ṣàánú yín.
“Mo tun ri pe, ohun kan ti awon eniyan won ko tun mo nipa mi ni pe, yatosi awon ifarapa ti mo n ni lateyin wa, mo tun ni ore ofe lati je elere idaraya ti ago ara re pe yege-yege.
Nígbà tí Abigaili pada dé ilé ó bá Nabali ninu àsè bí ọba.
Ijoba orile-ede Kenya se ikilo fun awon omo orile-ede re lori irin-ajo lo si orile-ede South Sudan.
Lẹ́yìn náà, ó tún àwọn ìlú tí Huramu ọba, fún un kọ́, ó sì fi àwọn ọmọ Israẹli sibẹ.
ó di kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ rẹ̀ kan ní gàárì, ó sì tọ Akiṣi ọba lọ sí ìlú Gati láti lọ wá àwọn ẹrú rẹ̀.
Oríṣun àwòrán, Twitter/@afobaje1000 Loju opo Twitter Sunday Dare to jẹ ọmọ bibi Ogbomoṣo, ni awọn janduku ya bo aafin Soun ti wọn si da ipade igbimọ ilu tawọn n ṣe lọwọ, ru.
Ṣugbọn ati oúnjẹ ati ikùn ni Ọlọrun yóo parun.
 wọ ́ n mọ ̀ ọ ́ sí àwọn ipa tí ó kó nínu fifipá gba ìjọba ní bí 1960 tí ó sì wà lára àwọn ológun tí o ṣe ìjọba gúúsù vietnam láti ọdún 1964 sí 1966 , tí ó sì jẹ ́ wípé nígbà tí ọ ̀ gá ológún òfúrufú ti ilẹ ̀ vietnam àti alákóso tí orúkọ rẹ ̀ ń jẹ ́ nguyễn cao kỳ borí rẹ ̀ , ó kọjá sí Àmẹ ́ ríkà .
Yóo jẹ́ ọjọ́ ìsinmi tí ó lọ́wọ̀, ẹ sì gbọdọ̀ gbààwẹ̀.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: ‘Olùkọ́ fipá bá akẹ́ẹ̀kọ́ girama lòpò nítorí máàkì’ Obìnrin kan bí ibejì lẹ́yìn ọjọ́ 26 tó bí ọmọkùnrin Pizza: Èló ni yóò ná ọ láti ra ìpápánu Pizza wá láti London?
BBC yoruba ko ri àrídáju pé lóòtọ ni Alfa Babatunde dáku ni àgọ àwọn àjọ DSS.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Ni ọdun 1988 ni o gba ami ẹyẹ Oscar gẹgẹ bi oṣere to jẹ oluranlọwọ pataki ninu fiimu '' The Untouchables'', to si se bi ọlọpaa ile Ireland nibẹ.
Oríṣun àwòrán, Sunshine Apata Adimula: Ẹsẹ bata to to mẹtalelaadọrin ni eeyan yoo ka ko to de ori Apata Adimula, nibi ti awọn agbaagba meje ti lọ sepade pẹlu Ojola ibinu, tii se olori ejo aye gbogbo, gẹgẹ bo se wa ninu iwe Fagunwa.
Alaafin: Ó wu àwọn ìyàwó mi ni wọ́n fẹ́ mi, èmi kọ́ ni mo dẹnu ìfẹ́ kọ wọ́n
Ni osu kẹta ọdun ti arun Covid-19 burẹkẹ ni Naijiria, agbarijọpọ ẹgbẹ awọn oṣere tiata ni ede Yoruba, taa mọ si TANPAN, labẹ akoso aarẹ ẹgbẹ Bolaji Amusan, ti ọpọ eeyan mọ si Mr Latin, pasẹ pe ọmọ ẹgbẹ naa kankan ko gbọdọ ya sinima.
Bẹ́ẹ̀ ni Solomoni ọba ṣe kọ́ ilé ìsìn náà parí, ó sì fi ọ̀pá àjà ati pákó igi kedari ṣe àjà rẹ̀.
Mummy calm down: Oreoluwa di 'Ambassador' ilésṣẹ́ tó ń ṣòwò ilẹ̀ àti ilé
Adari ijoba orile ede Britain, Theresa May ti so pe orile ede oun ti towobo iwe adehun lori eto aabo pelu orile ede Kenya.
Nígbà tí Mose bá pada sí ibùdó, Joṣua, iranṣẹ rẹ̀, ọmọ Nuni, tí òun jẹ́ ọdọmọkunrin, kìí kúrò ninu àgọ́ àjọ.
’ Gbogbo ẹni tí ó bá gba ọ̀rọ̀ Baba, tí ó kọ́ ẹ̀kọ́ rẹ̀, á wá sọ́dọ̀ mi.
Paystack Shola Akinlade: Ìgbésẹ̀ 5 yìí ni mo gbé tíléeṣẹ́ Stripe fi dókòwò $200m pẹ̀lú mi
Nibi igbẹjọ naa, awọn afurasi ẹgbẹ Boko Haram meji ni wọn da silẹ nitori pe ko si ẹri to tako wọn.
Sibẹ kò ṣàì fi àmì ara rẹ̀ hàn: ó ń ṣe iṣẹ́ rere, ó ń rọ òjò fun yín láti ọ̀run, ó ń mú èso jáde lásìkò, ó ń fun yín ní oúnjẹ, ó tún ń mú inú yín dùn.
Nínú agbo olórín lórílẹ̀ -èdè Nàìjíríà lọ́nìí àkjọ́jọpọ orin náà ni ó wà ní ipò kẹwàá tí o si pe àwọn olórin bi 2face Idibia, M.
Saaju asiko yii ni Malam Tanko Tete, to je olori Tum Ninkyob ti Kaninkon ni aafin re ni  Bakin Kogi, ni yiyan tijoba yan awon to beru Olorun sigbimo idapada yii fihan pe isele naa koi job alominu pupo.
Solomoni bá gbogbo àwọn ọmọ Israẹli sọ̀rọ̀: àwọn balogun ẹgbẹẹgbẹrun ọmọ ogun ati ti ọgọọgọrun-un ọmọ ogun, àwọn adájọ́, àwọn olórí ní Israẹli ati àwọn baálé baálé.
Ki lo n faiyatọ to n waye ni ilu Chicago?
Àwọn eniyan ilẹ̀ náà ń fi ipá gba nǹkan-oní-nǹkan; wọ́n ń ni talaka ati aláìní lára, wọ́n sì ń fi ipá gba nǹkan lọ́wọ́ àwọn àlejò láì ṣe àtúnṣe.
Saaju ki ipinlẹ Edo si to gbe igbesẹ yi, ni ipinlẹ Ekiti ati ipinlẹ Benue ti fofin de asa ẹran dida ninu igbo ati laarin igboro ilu.
Premier league: Ìjà orogún London, Arsenal ati Tottenham ranjú mọ ara wọn, ṣùgbọn iná ojú wọn kò ran tábà
WAEC: A ò ní fún-un ní ìwé ẹ̀rí ti ààrẹ kò bá bèrè fún ìwé ẹ̀rí rẹ̀.
N kò sì dúró pẹ́ títí tí mo ri i tí ahọ́n yìí sá wọlé tan tí ahọ́n mìíràn yọ dípò rẹ̀ tí ó ṣe ìwọ̀n ẹnu.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù 2019 Nigeria Election: Àgbùnbánirọ̀ pàdánù ẹ̀mí rẹ̀ nínú ìjàmbà ọkọ̀ ojú omi l'Ondo 10 Ẹrẹ̀nà 2019 Oríṣun àwòrán, NYSC Àkọlé àwòrán, Iku agunbanirọ Iroyin to tẹ wa lọwọ sọ pe agunbanirọ kan, Ibrahim Okanlawon to ṣiṣẹ pẹlu ajọ eleto idibo INEC ninu ibo gomina ati ile igbimọ aṣofin ipinlẹ lagbegbe Ewerebubou, wọọdu Arogbo ni ipinlẹ Ondo padanu ẹmi rẹ.
Game of Thrones tàbí Ìrèké Oníbùdó, èwo lẹ dìbò fún?
”, àti”bóyá àwọn ẹranko wọ̀nyí ti dínkù sí ti ìgbà kan, kí ni ìwọ rò wípé ó ti ṣẹlẹ̀?
Wọ́n gbé àpótí ẹ̀rí náà wọnú ìlú, wọ́n sì gbé e sí ààyè rẹ̀, ninu àgọ́ tí Dafidi ti kọ́ sílẹ̀ fún un.
O so pe: “Idi ti mo fi wa sibi loni ni
Falz ni oun sọ ohun gbogbo to yẹ ki ẹ mọ nipa iṣejọba Aarẹ Buhari ninu fidio oni iṣẹju mẹta o le iṣẹju aaya mejidinlọgbọn.
Lẹyin naa lo ni kii ṣe ohun toju ko ri ri nitori aye n ṣe iru ẹ, o sit un tọrọ aforiji lọwọ awọn ololufẹ rẹ.
Homepage Accessibility links Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Ìrànlọ́wọ́ Ìwọlé News Sport Weather Radio Arts Ààtò BBC News Yorùbá BBC Yoruba ÀkọléÀkọlé abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Àkọlé bọ̀tìnnì síwájú síi Olùmúdọ́gba bọ́tìnnì síwájú síi Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Media player Close player Close player Close player Ìròyìn ìbúrawọlé jákèjádò orílẹ̀èdè Nàìjíríà ní ẹ̀kúnrẹ́rẹ́.
Nibo wa lo ti tan iṣoro idagbasoke ta fẹ ki wọn ṣe ni fasiti?
"Ohun mẹ́wàá pàtàkì nípa Maradona àti ìbáṣepọ̀ rẹ̀ pẹ̀lú ẹlẹ́sẹ̀ ayò Diego Costa rèé Àwòrán rèé nípa bí 'Hand of God' ṣé dí inagijẹ Diego Maradona Atẹjade naa ni ""gbogbo wa ni ipinlẹ yii ni a gbadura fun aṣeyọri rẹ lai wo ti ẹsin."
Eyi ni igba kẹta ti iṣẹlẹ ajalu ara sisan pa awọn maluu yoo maa waye laarin oṣu mẹta.
Ó sọ̀rọ̀, àwọn eṣú sì rọ́ dé,ati àwọn tata tí kò lóǹkà;
Albert Einstein gba ami ẹyẹ nobel; prize lọdun 1921 lori imọ sayẹnsi ti wọn n pe ni Physics.
Wọn ti darukọ orilẹ-ede Naijiria gẹgẹ bi orilẹ-ede to n wọ ori ayelujara lati wo fidio ibalopọ julọ lọdun 2019.
Oríṣun àwòrán, Others Nigba to n ba BBC Yoruba sọrọ, Alhaji Ayanyemi Atokowagbowonle, tii se gbajumọ onilu Juju ati Sẹkẹrẹ nilu Ibadan, salaye pe kii se gbogbo eniyan lo mọ ede ayan, ẹni to ba mọ nikan lo le ye.
Nítorí náà, ni mo ṣe ń sọkún tẹ̀dùntẹ̀dùn, tí mò ń kígbe sókè nítorí Moabutí mo sì ń ṣọ̀fọ̀ nítorí àwọn ará Kiri Heresi.
Sugbọn lẹhin ọkanojọkan ifẹhonu han lati ọdọ awọn alẹnulọrọ ati awọn ipade to waye laarin awọn obi ati alakoso ile ẹkọ naa, eto ẹkọ ti bẹrẹ pada lowurọ Ọjọ Aje.
A ṣe títí a kọ́lé gíga roro bí ẹni pé kí àwa ọmọ ènìyàn gan-an lọ máa fi ojú-ọ̀run ṣe ibùgbé.
Ohun ìṣògo ni èyí jẹ́ fun yín.
Ko tii si aridaju ohun to n fa a gan ṣugbọn bi o ko ba ṣọra, o lee ko arun BV bi o ba: Bi o ba jẹ ẹni to fẹram ibalopọ gidi da ṣugbọn ko yọ awọn obinrin ti ko tii ni ibalopọ ri naa silẹ.
Jàǹdùkú jó agboolé Sanwo-Olu, Iléeṣẹ́ Channels ń kógbá wọlé Oríṣun àwòrán, @ChinasaNworu Nitẹsiwaju rogbodiyan to n lọ lọwọ nilu Eko, awọn janduku tun ti dana sun agboole gomina ipinlẹ Eko, Babajide Sanwo-Olu.
“Ẹ kò gbọdọ̀ kó àwọn ìgbèkùn wọnyi wọ ibí wá, kí ẹ tún wá dákún ẹ̀ṣẹ̀ ati ẹ̀bi tí ó wà lọ́rùn wa tẹ́lẹ̀.
O jẹ ọkan lara awọn gbajugbaja ọgagun lati ọdun 2005 nigba ti awọn ọrẹ timọ timọ ati akẹgbẹ rẹ ditẹ mọ ọ, Pierre Nkurunziza gbajọba.
Lara awọn ere to ṣe, ko to silẹ bora ni Ọba Koso, Ọba Waja, Ṣango ati bẹẹ bẹẹ lọ.
BBC Pidgin Essay Competition 2019: Njẹ́ ìwọ le kọ àròkọ̀ ní èdè Pidgin?
"Ẹ̀wẹ̀ "" Mohammed ti jẹ́ri sí i nínú àtẹjáde kan pé wọ́n ṣi òun lọ́na ni, gẹ́gẹ́ bi ilé ẹjọ ṣe mọ láti ẹnu ẹni to jẹri fún ICPC, Osanato Olugbemi."
Adamu ni ọda owo awo olokun lo n fa wahala yii o.
O ni gbogbo ọmọ Naijiria lo n reti ki wọn gbe ife ẹyẹ AFCON wa si ile.
Awọn ọdaran to fọ ile ifowopamọ First Bank nilu Okeho naa ko gbẹyin ninu awọn ọdaran ti wọn fi oju wọn han, to fi mọ awọn ara ilu kan ti wọn tun ji owo ti wọn ri gba lọwọ awọn ọdaran ọhun.
Ṣe latẹwọ n ro nibi ti wọn ti tun Infantino yan lẹyin ti ayipada ofin wa pe ko ma tun si eto idibo mọ niwọn igba to ba ti jẹ pe oludije kan ṣoṣo lo wa.
Ọọni Ilẹ Ifẹ: Isọkan ni a nilo lorilẹede Naijiria
Oríṣun àwòrán, Others Risikat Azeez: Ẹgbẹ́ ọ̀dọ́ ní Ilorin ti fi iṣẹ́ Emir jẹ́ fun Risikat àti ọkọ rẹ̀ Yoruba ni agba kii wa lọja, ki ori ọmọ tuntun wọ, bẹẹ si ni aye ko gbọdọ toju awọn agba bajẹ.
Bí ó bá sín, ìmọ́lẹ̀ á tàn jáde ní imú rẹ̀,ojú rẹ̀ ń tàn bíi ìmọ́lẹ̀ òwúrọ̀ kutukutu.
Eji Gbadero, ọmọ Ibadan àti jayé-jayé ọmọ ónílẹ̀ ti wọn yẹgi fun l'Eko Omijé bọ́ níbi ìsìnkú Ogun Majek Ẹ wo ìṣẹ̀lẹ̀ nípa ẹ̀sùn ìfipábánilòpọ̀ tí wọ́n fi kan D'banj ní sísẹ̀-n-tẹ̀lé Ayẹwo ti wọn ṣe si ara rẹ nigba ti wọn fẹ sin in, lo fihan pe wọn ba a lopọ, paapa bi oju ara rẹ ṣe wa ni ṣíṣí silẹ.
Àwọn Ọba alayé ní Naijiria ṣàbẹ̀wò sí Ọba Eko, Gómìnà Eko àti Bola Tinubu lẹyin ìwọ́de EndSARS Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Ẹ̀ẹ̀kan n l’ọ́kan ni n ó kú Ikú kan, ọkùnrin kan
Awọn awọran igbe aye rẹ ree: Má ṣe ri talẹnti rẹ̀ mọ́lẹ̀, Ọdọmọde olorin olokiki ni o jẹ nigba to wa l'ewe.
 Ìwádìí fi hàn pé ọ ̀ rọ ̀ oyè ló dá ìjà sílẹ ̀ ní ààrin tẹ ̀ gbọ ́ ntàbúrò .
Agbabọọlu Diaby kan naa lo fun Argentina lanfaani lati tun siwaju lẹyin to ṣaṣiṣe gba bọọlu sawọn ile rẹ, eleyi to mu Argentina siwaju pẹlu ami ayo meji sẹyọkan.
Ẹ̀yin ará mi, ṣé igi ọ̀pọ̀tọ́ lè so èso olifi, tabi kí àjàrà kó so ọ̀pọ̀tọ́?
"Nitori naa, imọran wa fun ẹ ni pe, lọ yẹ fóònù rẹ̀ wò ni ""Settings"" láti mọ̀ bóyá iOS 9 tàbi Android 4."
Bi awọn esi naa ṣe lọ niyii: Eko-61 Oyo-39 FCT-13 Yobe-10 Bauchi-6 Kaduna-5 Kano-4 Kwara-4 Plateau-4 Edo-2 Ogun-2 Rivers-2 Èèyàn 157 míràn ló tún lùgbàdì Coronavirus ní Nàìjíríà Apapọ awọn to ni arun Coronavirus ni Naijiria ti pe 65,148 bayii.
N óo fi ojú mi rí i; òun náà yóo wá di àtẹ̀mọ́lẹ̀ bí ẹrẹ̀ ní ìta gbangba.
Lẹ́yìn tí àwọn eniyan ti jẹ ẹja ní àjẹtẹ́rùn, Jesu wí fún àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ pé, “Ẹ kó oúnjẹ tí ó kù jọ, kí ohunkohun má baà ṣòfò.
Lọjọ Aje nilu Abuja la ti gbọ wi pe awọn ọmọ ẹgbẹ ASUU binu jade kuro ninu ipade ti o yẹ ki wọn ṣe pẹlu awọn aṣoju ijọba ti Minisita fun ọrọ iṣẹ ni Naijiria Chris Ngige le waju wọn.
Ọ̀rọ̀ kẹ́lẹ́kẹ́lẹ́ olófòófó dàbí òkèlè oúnjẹ dídùna máa wọni lára ṣinṣin.
Boko Haram pa olùkọ̀ 2,295 ni àríwá Nàíjíríà Ọlọ́pàá Sharia Kano mú èèyàn tó lé ní 80 tori oúnjẹ nínú ààwẹ̀ Èèwọ̀!
Kii ṣe igba akọkọ niyẹn ti ẹgbẹ naa ati awọn orogún wọn fa wahala ni agbegbe naa.
 sáájú àsìkò yìí , àwọn ìsẹ ̀ lẹ ̀ kan sẹ ̀ lẹ ̀ tí ó bẹ ̀ rẹ ̀ sí mú kí àwọn orílẹ ̀ -èdè àgbáyé máa ṣe gbún-ùn gbùn-ùn gbún-ùn sí ara wọn .
 Ó tó gẹ ́ ẹ ̀ , aludùndún kì í dárin .
Theresa May bú sẹ́kún, ó ní òun kò ṣe olóòtú ìjọba UK mọ́ Ọgbà ẹ̀wọ̀n ni Naira Marley yóò ti wo ìbúra Buhari ní May 29 Láti 1999 títí di 2019, wo àwọn ààrẹ tó jẹ ní Nàìjíríà Wo àwọn míniístà mẹ́fà tí ẹnu ń kùn jùlọ Awọn aṣoju mọkanla lati ẹgbẹ oṣelu Conservative nilẹ Gẹẹsi ni wọn jọ n gbero lati dupo yii.
Ọpọ lo bu ẹnu ẹtẹ lu iṣẹlẹ naa loju opo Twitter ti gbogbo wọn si fohun sọkan pe ki wọn ọlọpaa SARS nilẹ lo dara.
Amọsa, ijoba orile ede naa, ko
Ní ọjọ́ keji ó jókòó ninu kóòtù, ó pàṣẹ pé kí wọ́n mú Paulu wá.
Ọmọ Aisaya jẹ́ Àmì fún Àwọn Eniyan.
Nínú ọ̀rọ̀ tó tẹ̀ jáde lórí òpó Twitter rẹ̀, El-Rufaí sọ wípé òhun gbé ìgbésẹ̀ náà ni nítorí ìlọsíwájú ìpílẹ̀ náà.
Ọdún 1976 ni wọ́n kọ́kọ́ ṣe àwárí kòkòrò afàìsàn náà nígbà tí orúkọ orílèèdè náà shì n jẹ Zaire.
Mose gbọ́ bí àwọn eniyan náà ti ń sọkún lẹ́nu ọ̀nà àgọ́ wọn, olukuluku pẹlu àwọn ará ilé rẹ̀.
Nítorí kò sí òtítọ́ kan lẹ́nu wọn;ìparun ni ó wà ninu ọkàn wọn.
Gẹgẹbii ajọ Amnesty International se sọ, iroyin eke ni ileesẹ ipọnpo Shell ati Eni n gbe kaakiri lori ohun to n sokunfa ifọnka epo rọbi lẹkun Niger Delta.
Sanwo-Olu kò lè tori ìjà Ọjọta fòfin de NURTW ní Eko - Agbẹnusọ gómínà Lẹ́yìn ọlọ́pàá, VIO nìkan ló láṣẹ láti dá ọkọ dúró láìṣẹ̀ - Ọ̀gá VIO Eko Àròsọ àti ìgbàgbọ́ àwọn ènìyàn lórí gbígba ẹ̀jẹ̀ Ìṣẹ́ tó mu ọmọ Nàíjíríà lómi ti gba oorun lójú mi - Osinbajo A tun ni ejo, Amọtẹkun ti DR Congo, Kọlọkọlọ ti Algeria ati awọn ẹranko mii ti yoo gori papa ni Egypt lọdun 2019 lati dije ninu ifẹ ẹyẹ AFCON to n bẹrẹ yii.
Dafidi ati àwọn eniyan rẹ̀ sọkún títí tí ó fi rẹ̀ wọ́n.
Adájọ́ sọ wòlíì Sotitobire àtàwọn márùn-ún míì sẹ́wọ̀n gbére!
Oríṣun àwòrán, @OOFoundation Ọbasanjọ fikun pe orilẹede Naijiria nilo olori ti ọpọlọ rẹ ji pepe, ti ilera ara rẹ si dangajia pipọ.
Nígbà tí ó di alẹ́ tí ó mú wa padà wá sí ilé wa, a bá àwọn àlejò mélǒ kan tí wọ́n doríkodò.
25 Ògún 2020 Oríṣun àwòrán, Funke Akindele JJCSkills to jẹ ọkọ gbajugbaja oṣere fiimu Yoruba to tun jẹ adẹrinpoṣonu, funke Akindele ti gbogbo eniyan mọ si Jenifa ṣe oun iwuri nla fun ololufẹ rẹ.
Eyi ni diẹ lara awọn aṣeyọri ile igbimọ aṣofin agba kẹjọ l'Abuja.
Ṣùgbọ́n mo bẹ̀ ọ́ lọ́pọ̀lọpọ̀, máṣe dà bí àwọn aláìmóye ènìyàn, tí wọ́n jẹ́ ọlọ́gbọ́n lójú ara wọn tí wọn kì í fi ọ̀rọ̀ wọn lọ ènìyàn, àwọn wọn-ọnnì a fi aṣọ bo ìwèrèpè mọ́ra, ọ̀rọ̀ burúkú a fi ara mọ́ wọn tímọ́-tímọ́, nígbà ti wọn bá sì ń rẹ́rìn-ín lójú àwọn ọmọ aráyé báyìí, ìbànújẹ́ a fẹ̀hìn tí lórí àga ní ibi kọ́lọ́fín inú wọn.
Onamu bí ọmọ meji: Ṣamai ati Jada.
Wọ́n kó wọn lọ sí ilẹ̀ Ijipti, nítorí wọn kò fetí sí ọ̀rọ̀ OLUWA Ọlọrun wọn.
Saulu mú ẹgbẹẹdogun (3,000) akọni ọmọ ogun lára àwọn ọmọ ogun Israẹli, wọ́n lọ láti wá Dafidi ati àwọn eniyan rẹ̀ ní orí àwọn àpáta ewúrẹ́ ìgbẹ́.
Awọn eelo Ọjọjọ ni iṣu ewura, ororo, ata rodo, alubọsa, ede, iyọ diẹ, ati bẹẹ bẹẹ lọ.
Láíyé àtijọ́ tó jẹ́ pé ọ̀pọ̀lọpọ̀ ẹbí ni wọ́n ngbé pọ̀ nínu agbolé kannáà, àjọ́gbá ni ilẹ̀, àjọṣe ni iṣẹ́.
Ilé wó pa Jide, ọmọ ọdún mọ́kànlá, l'Oṣogbo Ilé alájà mẹ́ta wó pa onímọ̀ ẹ̀rọ́ tó ń kọ́ ọ lọ́wọ́ Awọn mejeeji to fara kaasa iṣẹlẹ naa wa nile iwosan bayii nibi ti wọn ti n gba itọju.
Adari ileeṣẹ ọlọpaa naa, Superintendent Samuel Odame ni awọn yinbọn fun Precious nitori o n dunkooko mọ awọn eniyan ni agbegbe naa ni.
Àwọn iranṣẹ Isaaki tún gbẹ́ kànga mìíràn, òun náà tún dìjà, nítorí náà Isaaki sọ ọ́ ní Sitina.
3 Ògún 2019 BBC News Pidgin ṣe ifilọlẹ eto kikọ arokọ ni ede Pidgin to maa n ṣe lọdọọdun fun igba keji.
Eyi si lo mu ki awọn eeyan kan maa pe fun iwadi lori iku to pa obinrin ologun akọkọ ti yoo wa baalu ni Naijiria, Tolulope Arotile.
Ijọba yoo si bẹrẹ eto naa pẹlu awọn kẹkẹ ẹlẹsẹ mẹta nilu Portharcourt.
Bí ìjọba bá pè wá ní ẹgbẹ́ Sùnmọ̀mí lóòtọ́, ìjà ṣẹ̀ṣẹ̀ bẹ̀rẹ̀ ni - Shiite Mo ṣe tán láti padà sórí pápá - Enyeama Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, N100,000 Nairà mà ni Dino gbé dání lójú agbo, kò náwó yàlà-yòlò - Ayefele Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, LASTMA Yesufa: Àwọn dókítà gbìyànjú lórí ojú mi ṣùgbọ́n.
Lẹ́yìn tí àwọn oníṣẹ́ Johanu lọ tán, Jesu bẹ̀rẹ̀ sí sọ ọ̀rọ̀ nípa Johanu fún àwọn eniyan.
Ọ̀pọ̀ aráàlú Owo wà nílé ìwòsàn, síbẹ̀ APC àti PDP kò gba ẹ̀bi Makinde gba àwọn òṣìṣẹ́ LAUTECH 41 tí ìjọba Ajimobi dá dúró lẹ́nu iṣẹ́ padà Obabinrin Elizabeth kejì kí Nàìjíríà kú oríire òmìnira ọgọ́ta ọdún Lasiko ipade kan pẹlu awọn ọga ọlọpaa ni ipinlẹ Eko, ni Kọmisana ọlọpaa Eko, Hakeem Odumosu fi ikilọ yi sita.
Adamu: Olùkọ̀ 2,295 ni Boko Haram pa láàárín ọdún mẹ́sán
Ko sọ ni pato boya ọmọ Naijiria lohun n ṣe ṣugbọn ninu apejuwe to ṣe si oju opo Facebook rẹ, o kọ sibẹ pe fasiti ilu Calabar, ni Naijiria ni ohun ti kẹkọ nipa imọ ilera.
Wọn n garun, ti wọn si n kopa ribiribi, ti wọn ko si kawọ gbera rara lati mọ ohun to n sẹlẹ lawujọ wọn, paapa ni ede abinibi wọn.
Aisha Buhari tọrọ ìdáríjì lórí fídìo tó jáde Ọkọ̀ agbépo tó gba iná ṣe àkóbá ní ọjà Onitsha Rọ́bà ìdáàbòbò gbówó lórí!
Alumuntu ti kii jẹ ki araye dagbere fun ara pe asiko ti to!
Gẹ́gẹ́ bí ìwọ náà ti mọ̀, àwọn iranṣẹ mi kò mọ̀ bí a tií gé igi ìkọ́lé bí àwọn ará Sidoni.
Wo ohun tó ṣẹlẹ̀ nilẹ̀ Adulawọ lọṣẹ tó lọ
Eniyan óo máa kéde iṣẹ́ agbára rẹ tí ó yani lẹ́nu,èmi óo sì máa polongo títóbi rẹ.
Ṣugbọn Ọlọrun wí fún Abrahamu pé, “Má ṣe jẹ́ kí inú rẹ bàjẹ́ nítorí ọ̀rọ̀ ọmọ yìí ati ti ẹrubinrin rẹ, ohunkohun tí Sara bá wí fún ọ ni kí o ṣe, nítorí pé orúkọ Isaaki ni wọn yóo fi máa pe atọmọdọmọ rẹ.
Eyi ko sẹyin bi Apapọ ẹgbẹ osisẹ lorilẹede Naijiria, NLC ti ni awọn yoo gbe ijọba ipinlẹ to ba kọ lati san gbedeke owo osu tuntun lọ sile ẹjọ.
Arakunrin Ariyo Dare Atoye tilẹ sọ apẹrẹ ni aworan ti Fayose ati Fayemi ya pọ jẹ to si n fi han pe awọn mejeeji yoo yi pada ba ara wọn ṣiṣẹ Bi a ko ba tilẹ le sọ ohun to wa ninu ọkan wọn eyi to han ni pe agbo oṣelu ni Naijiria jẹ ibi ti a ti ma n da ọrẹ.
Kọmisọnna feto iroyin nipinlẹ Ondo, Yẹmi Owolabi sọ pe eniyan mejidinlogun lo wa labẹ itọju iba ọrẹẹrẹ lati agbegbe ijọba ibile Ọwọ, ti meji miran si tun wa lati ijọba ibilẹ Guusu-Akure, ti ọkan tun wa lati Ariwa-Akurẹ ati mẹji miran lati Iwọ-Oorun ijọba ibilẹ Akoko.
Òṣèré tíátà míì ń ṣàìsàn láti bí ọdún mẹ́ta, ọkan rèé tó ń bẹ̀bẹ̀ f'ówó Idi ree ti BBC Yoruba fi ṣe akojọpọ igbe aye akọni ologun naa ati ọpọ iṣẹlẹ manigbagbe to gbe ile aye ṣe, lati la awọn ọdọ lọyẹ.
baba mi kọ́ mi, ó ní,“Fi ọ̀rọ̀ mi sọ́kàn,pa òfin mi mọ́, kí o lè wà láàyè.
Solomoni ni orúkọ rẹ̀ yóo máa jẹ́.
Opolopo awon omo ogun ile ni won ti ko ranse si Makurdi to je olu ilu ipinle Benue nigba ti awon agbofinro ati awon aja olopaa ti kun igboro.
Nàìjíríà fohùn ránṣẹ́ padà sílé aṣofin UK pé ọ̀rọ̀ EndSars kò sí lẹ́nú wọn láìgbọ́ ìwádìí tán!
Ọba Lamidi Adeyẹmi, òṣìṣẹ́ adójútòfò àti Abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò kó tó jọba MC Oluọmọ gbé ara rẹ̀ ṣépè nítorí ìwọ́de #ENDSARS Toyin Abraham tú àṣírí ohun tí ọlọ́pàá Náìjíríà sọ mọ́lẹ́bí rẹ̀ kan dà #EndSARS: Àwọn olùwọ́de kọ etí ikún sí àṣẹ ijọba, wọ́n tẹ̀sìwájú ìwọ́de l'Abuja Oríṣun àwòrán, Twitter/Nigerian Army Ẹ̀yin olùwọ́de, ẹ lọ kọwọ́ ọmọ yín bọṣọ, bí bẹ́ẹ̀ kọ́.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Nǹkan kò ṣẹnuure fáwọn obìnrin nínú ìgbìmọ̀ ìṣèjọba Buhari Àwọn ọmọ Yorùbá wo ni mínísítà ní ìjọba Buhari?
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Coronavirus: Gbogbo igbá ti ṣófo láwọn ilé ìtajà káàkiri London Ni bayii, ijọba ilẹ naa ti gbe agadagodo sẹnu ọna awọn ile ijọsin ati ile ọti, ṣugbọn ko tii gbeṣẹle ile iwe gẹgẹ binawọn orilẹ-ede miran.
Ọjọ Ẹti to kọja ni Minisita fun eto ilera ni Naijiria, Ọjọgbọn Osagie Ehanire kede pe ọsẹ yii ni wọn yoo yọnda ọmọ orilẹ-ede Italy to ko aarun naa wọn Naijiria kuro nileewosan.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Igbákejì ààre Osinbajọ yan Tolani Alli gẹ́gẹ́ bíi ayàwòrán rẹ́ tuntun 23 Ògún 2019 Oríṣun àwòrán, @tolanialli Àkọlé àwòrán, Iṣẹ tokunrin n ṣe, obirin naa le ṣe e Igbakeji aare, Yemi Osinbajo ti yan Tolani Alli, gẹgẹ bi ayaworan rẹ tuntun.
Adeyeye ṣalaye pe oogun apakokoro ti awọn ile nla ti wọn n ko ounjẹ pamọ sati awọn ohu ọsin si ni DDVP jẹ.
Gbolagade Majekodunmi (Ogun Majek) : Oríṣun àwòrán, Others Laipẹ yii ni ariwo ta pe gbajugbaja oṣere tiata kan lede Yoruba, Ogun Majek, ti ọpọ eeyan gbọ tẹlẹ pe o n ṣe aisan, ti jade laye.
Oko oku naa, ti wọn da silẹ lọdun 2017, jẹ ti awọn onimọ sayẹnsi lati ileẹkọ fasiti South Florida, to n se iwadi lori ohun ti yoo sẹlẹ si oku lẹyin to ba jade laye, ti ọgba ileẹkọ naa si sunmọ ọgba ẹwọn kan.
'Báyìí la ṣe rìn ín láti pápákọ̀ òfurufú Abuja sí Eko bí ìrìnà òfurufú abẹ́lé ṣe bẹ̀rẹ̀' Ikede Ọgbẹni Sileshi yii si lo fidi ootọ nipa awọn aworan to jade mulẹ, eyi to ṣe afihan pe odiwọn omi inu ibudo ìṣe omi lọjọ si naa n lọ soke, eyi to n pa lati inu adagun odo.
"Buhari ní, ""Torí awuyewuye tó ń jà láàárín àwọn ọmọ Nàìjíríà lórí bóyá màá díje tàbí n kò ní díje ló jẹ́ kí n kéde kí n tó kúrò ní Nàìjíríà."
Bakan naa lo sọ pe ofin konile-o-gbele ko mu igbẹkọ lori ayelujara lasiko yii.
kí ẹ lè jẹ́ Ọmọ Ọlọrun, tí kò lẹ́bi tí kò sì ní àléébù, ọmọ Ọlọrun tí ó pé, láàrin àwọn ìran tí ọ̀nà wọn wọ́, tí ìwà wọn sì ti bàjẹ́.
"Yetunde tẹnu mọ ọ pe ""ko si iyatọ ninu ọkunrin olootọ ati eyi ti ko sootọ mọ"" Àkọlé àwòrán, Níbo láyé kọjú Awọn mejeeji fẹnu ko wi pe o da lori adehun ti awọn mejeeji ba ṣe ki wọn to bẹrẹ si ni gbe gẹgẹ bii lọkọ laya."
Lati igba ti Martial si ti gba bọọlu sinu awọn ni nkan ti n gbona janjan.
Àjàkálẹ̀ àrùn tí OLUWA yóo fi bá àwọn tí wọ́n bá gbógun ti ilẹ̀ Jerusalẹmu jà nìyí: Ẹran ara wọn yóo rà nígbà tí wọ́n ṣì wà láàyè, ojú wọn yóo rà ninu ihò rẹ̀, ahọ́n wọn yóo sì rà lẹ́nu wọn.
Eegunjobi Omotanbaje Ajobiewe- Èébú ní wọ́n kọ́kọ́ ń bù mí nígbà tí mo bẹ̀rẹ̀ ẹ̀ṣà pípé ní
Linda ní òun àti bàbá ọmọ òun ti túká Salah gba àmì ẹ̀yẹ̀ agbábọ́ọ̀lù Afirika BBC NAFDAC: Ẹ ṣọ́ra fún ẹja aṣekúpani Puffer Fish Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, È gbọ àlàyé lẹnu àwọn ti ójúẹlẹgba leko irú iṣẹ ti oògùn olóró má n ṣé lara.
Alufaa Bakare nisẹ lo yẹ kawọn ojiṣẹ Ọlọrun ṣiṣẹ pọ pẹlu ijọba lati gbogun ti ajakalẹ aarun coronavirus to n ba gbogbo aye finra lọwọ yii.
A ṣe àkọsílẹ̀ àlọ́ Orí Erinmi ní ọjọ́ 16, oṣù Belu, ọdún 2014, ní etídò  Songkran ní àríwá-ìwọ̀-oòrùn Thailand.
Ọpọlọpọ ọmọ Naijiria lo fi oju aitọ wo o, nitori pe ipinlẹ Katsina l'oun ati Aarẹ Muhammadu Buhari ti jọ wa, ati lori 'aikoju oṣuwọn rẹ fun iṣẹ naa'.
Gomina ipinlẹ naa, Aminu Masari to fi idi iṣẹlẹ naa mulẹ f'awọn oniroyin ni ko din ni eniyan mẹrinlelogoji to padanu ẹmi wọn sinu i'sẹlẹ yii, ti ogun eniyan o si tii jẹ rírí ni ìlú Jibia, ti iṣẹlẹ naa ti waye.
Ileeṣẹ ọmọgun naa ni ikọ Forward Operating Base(FOB) ni Igbokoda lo mu awọn ole naa ni agbegbe ijọba ibilẹ Ilajẹ ni ipinlẹ Ondo.
Aare orile ede Naijiria ,Muhammadu Buhari ti ba ijoba
Ṣe é ní ẹlẹ́mìí kúkúrú,kí ohun ìní rẹ̀ di ti àwọn alọ́nilọ́wọ́gbà.
agbaye ( United Nations UN), ile-ise ologun ati ẹsọ alaabo miiran.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ifilọlẹ ẹgbẹ alajumọse n waye n'ipinlẹ Ogun 1 Èrèlè 2018 Oríṣun àwòrán, Kazeem Olowe Àkọlé àwòrán, Ifilọlẹ agbarijọpọ ẹgbẹ awọn ọmọ Naijiria ti waye nilu Abẹokuta Ifilọlẹ agbarijọpọ ẹgbẹ awọn ọmọ Naijiria n waye loni nilu Abẹokuta nipinlẹ Ogun.
sòbìà , tí a tún mọ ̀ sí ààrùn sòbìà ( gwd ) , jẹ ́ àkóràn ti àràn sòbìà .
Ọdun 2015 ni aarẹ Buhari fidi Jonathan janlẹ ninu idibo sipo aarẹ to waye, eyii to ṣilẹkun akọsilẹ tuntun oludije sipo aarẹ akọkọ ti yoo gbo ewuro soju aarẹ to wa lori alefa ni Naijiria.
"A ko ni àpá lati fi idunnu han, ẹkọ diẹ lasi ri kọ lara alaafia.
Wọ́n ní pánsá ò fura ó já, àjà ò fura ó jìn.
“Lẹ́yìn tí mo ti fi ìwé ilẹ̀ náà lé Baruku ọmọ Neraya lọ́wọ́, mo gbadura sí OLUWA, mo ní: 
Gbogbo wọn ń fi ọkàn kan gbadura nígbà gbogbo pẹlu àwọn obinrin ati Maria ìyá Jesu ati àwọn arakunrin Jesu.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ogbomsho shooting, End Sars, End SWAT: Isiaka fi ọmọbìnrin kan àti ìyàwó tó lóyún sínú síl Ajọ LASEMA, ẹṣọ oju popo, FRSC, ati LNSC naa ti tete de ibẹ lati mojuto iṣẹlẹ naa ko ma pọ ju bẹẹ lọ.
O ti ta àsíá ogun fún àwọn tí ó bẹ̀rù rẹ,kí wọ́n baà lè rí ààbò lọ́wọ́ ọfà ọ̀tá.
Ẹ̀ ń lọ káàkiri lórí gbogbo òkè,ati lábẹ́ gbogbo igi tútù;ẹ̀ ń foríbalẹ̀, ẹ̀ ń ṣe bíi panṣaga.
Ọ̀gá àgbà ọlọ́pàá ní ọjọ kẹta oṣù keji ọdun yìí fi ẹ̀sùn onípele mẹ́rìnlá, ìgbésùnmsmí, ìpànìyàn, ìjínígbé àti kíkó ǹkan olóró síkàwọ́ lọ́nà àìtọ́ pẹ̀lú àwọn ogun míràn.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ní Kaduna, wọ́n ti sin ọmọógun11 tí àwọn ọ́lọ́ṣà pa 29 Ẹrẹ̀nà 2018 Wọ́n tí sin àwọn ologun mọ́kànla tí wọ̀n pa ní ìpínlẹ Kaduna l'ogúnjọ oṣu yíi.
Bí ẹnìkan ninu àwọn alaigbagbọ bá pè yín wá jẹun, tí ẹ bá gbà láti lọ, ẹ jẹ ohunkohun tí ó bá gbé kalẹ̀ níwájú yín láì wádìí ohunkohun, kí ẹ̀rí-ọkàn yín lè mọ́.
A Yan Banaba ati Saulu fún Iṣẹ́ Pataki.
Àwọn ẹgbẹ́ ajàfẹ́tọ musulumi náà sàpèjúwe ẹ̀sùn náà bi ìwà ìkà àti irọ́ pọ́nbélé láti inú ọ̀gbùn àìlópin.
“Bí ẹnìkan bá ṣẹ ọmọnikeji rẹ̀ tí wọ́n sì ní kí ó wá búra, tí ó bá wá tí ó sì búra níwájú pẹpẹ rẹ ninu ilé ìsìn yìí, 
Àwọn àlejò náà pe Lọti, wọ́n sọ fún un pé, “Bí o bá ní ẹnikẹ́ni ninu ìlú yìí, ìbáà ṣe ọmọkunrin tabi ọmọbinrin tabi ọkọ àwọn ọmọ rẹ, tabi ẹnikẹ́ni tí ó jẹ́ tìrẹ ninu ìlú yìí, kó wọn jáde kúrò níhìn-ín, 
Ààrẹ Buhari buwọ́lu gbígbé ìṣàkoso nọ́mbà ìdánimọ̀ (NIMC) lọ sí ẹ̀ka ìjọba tó ń rí sí ìbáraẹnisọ̀rọ̀ Wọ́n ti sún ìdájọ́ àwọn sójà tó pa ìyá àti ọmọ ní ọdun 2018 sí oṣù tó m bọ̀ Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí 6:18 Fídíò, Natalia Mufutau ìyá Yakub, Kamil àti Adam sọ̀rọ̀ lórí bí wọ́n ń sọ èdè mẹ́rin pàpọ, Duration 6,1831 Ògún 2020 6:10 Fídíò, Yoruba Language: Akomolede ati Asa Yoruba tọ̀sẹ̀ yí rèé lẹ́nu olùkọ́ wa, Duration 6,1030 Ògún 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
3) O ṣeeṣe fun ẹ lati paṣẹ fun foonu rẹ pe ko má lo batiiri pupọ nipa titan ibi ti wọn pe ni 'Low battery mode' ninu foonu rẹ.
Gbẹ́kẹ̀lé OLUWA títí lae,nítorí àpáta ayérayé ni OLUWA Ọlọrun.
Ohùn Yoruba lo yẹ ki a fi maa kọ ede Yoruba silẹ ni imọran to ni fun iran to mbọ.
Ko tan sibẹ, Gbajabiamila tun ni oun yoo ri daju pe oun kan sawọn mọlẹbi awọn eeyan to padanu ẹbi wsn lasiko iwọde EndSARS yii, lati tu wọn ninu.
Olóògùn ni gbogbo àwọn ara ilé Wọ̀bìáparapọ̀ jẹ, wọn kò sì ní èrò búburú kan lọ́kàn rárá nígbà tí wọ́n wí bẹ́ẹ̀.
Nígbà mìíràn, ẹ̀ẹ̀méje ni wọn yóò fi ara ọmọ náà gbe ẹ̀kán omi náà bí wọn ti ń gbé e wọlé, tí wọ́n ń gbé e jáde, bí ó bá jẹ́ obìnrin.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, UEFA Champions League Adile mu fun ikọ Man U, Chris Smalling ti kọkọ fi igboya sọrọ pe ko si ohun ti ẹlẹsẹ ayo ati ageni bi ẹni layin, Lionel Messi yoo ṣe bi o tilẹ jẹ wi pe akọnimọọgba Man U, Ole Gunnar Solskjaer ni yoo ṣoro diẹ lati mu Messi.
Ngige ni iṣẹ́ n lọ lọ́wọ́ lórí ǹkan ti ASUU n bèèrè Ìpàdé ìjọba ati ASUU forí sánpọ́n ASUU: A kò ṣetán láti fòpin sí ìyanṣẹ́lódì Aarẹ ẹgbẹ awọn olukọ ni fasiti Naijiria, Biọdun Ogunyẹmi ti oun naa wa nibi ipade naa sọ wi pe igbimọ alaṣẹ́ ẹgbẹ naa yoo ṣe ipade lati ṣe agbeyẹwo nnkan ti ijọba sọ.
Amọ, ijọba ko fun wọn ni esi lori gbogbo lẹta ati iwe ti awọn fi ranṣẹ si ijọba ko to di wi pe awọn gbe igbesẹ lati ṣe ifẹhọnuhan ati iyanṣẹlodi tako igbesẹ ijọba.
Awọn ara adugbo to ba BBC Yoruba sọrọ tọka wa si awọn ikorita ti iṣẹlẹ naa ti waye.
Bakan naa, awon nkan miiran ti mo tun nife si lara re ni, O je oniwa irele, O ga, bee si ni O ma n jade lasiko ti o ba ye.
Alexandre Lacazette naa gba ayo meji wọle ti Pierre-Emerick Aubameyang na gba bọọlu wọ awọn fun igba meji ọtọtọ.
 ""Ilẹ Afirika duro daadaa lati ko ipa to jọju ninu irapada eto ọrọ aje gbogbo agbaye."
"Oríṣun àwòrán, Getty Images ""Owo ori ọja jẹ ọna kan gboogi to n mu owo wa fun awọn orilẹede nilẹ adulawọ, to si maa n ko ida mọkanlelọgbọn ninu ọgọrun owo to n wọle nigba miran, eyi gan pọ ju iye ti ajọ to wa fun idagbasoke ọrọ aje n ri lọ tii se ida ogun ninu ọgọrun."
N óo pa àwọn tí ń rú ẹbọ níbi pẹpẹ ìrúbọ run, ati àwọn tí ń sun turari sí oriṣa ní ilẹ̀ Moabu.
OLUWA Ọlọrun yín yóo dá ibukun yín pada, yóo ṣàánú yín, yóo sì tún ko yín pada láti ààrin àwọn orílẹ̀-èdè gbogbo tí ó fọn yín ká sí.
Ọrọ ifẹ bi adanwo ni awọn agba maa n sọ nilẹ Yoruba.
Bí ìfẹ́ láti mú ọrẹ wá bá wà, Ọlọrun gba ohun tí eniyan bá mú wá.
Ni ilu Abẹokuta ni Ọga ọlọpaa Adamu ti gbe ọrọ yii kalẹ.
“Mo gbọ́ bí Efuraimu tí ń kẹ́dùn,ó ní: ‘O ti bá mi wí, ìbáwí sì dùn mí,bí ọmọ mààlúù tí a kò kọ́.
Ojo ti n pa igun bọ, ọjọ ti pẹ ni ọrọ Ọba Adeyẹmi, tori pe oju rẹ ti ri ọpọ iriri sẹyin ko to jọba ati lẹyin to jẹ ọba tan.
Ileeṣẹ ologun ni ṣọja mẹta lo fara gbọgbẹ ninu ikọlu naa.
"Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Làásìgbò ọ̀tun súyọ nínú ẹgbẹ́ òṣèlú APC Afurasí afipábánilópọ̀ kàgbákò, obìnrin tó jà lólè fi eyín gé nǹkan ọkùnrin rẹ̀ jábọ́ lásìkò ‘Blow Job’ Àwọn ọba alayé, Mínísítà àti gómìnà nílẹ̀ Yorùbá ṣèpàdé pẹ̀lú ìjọba àpapọ̀, àbọ̀ rèé ""Ìyá mi sì wà ní páńpẹ́ ajínigbé, ọlọ́pàá, irọ́ lẹ̀ ń pa pé ó ti gba ìdáǹdè"" Iná ṣẹ́yọ nílé ìtajà aya Ajimobi lẹ́yìn ọjọ́ mẹ́ta tó jáde opó ""Ìfẹ́ akọ sákọ àti abo sábo tó wọ́pọ̀ ní Àríwá Nàíjíríà ló fa ìbínú Ọlọ́run"" Ọ̀pá àṣẹ Ọba Akiolu tẹ gbé, a kò ní fọwọ́ yẹpẹrẹ mu - Ìgbìmọ̀ Ọba l‘Eko yarí Olori Badra sọ̀rọ̀ nípa ayé rẹ̀, ó ní ẹ́ bá òun sọkún Lara awọn ohun ti Joe Biden yoo ṣe ni lati ṣe atunṣe pẹlu Ajọ NATO lagbaye."
 Idi ti Buhari fi da abadofin Peace Corps nu Peace Corps: Ileesẹ ọlọpaa lo wa nidi ọrọ wa Ohun ti ọdọ kọọkan la kọja ki o to wọ ajọ Peace Corps Nigba ti awa naa dẹ wo eyi gẹgẹbi ọna kan ati ri isẹ a gba fọọmu ẹgbẹrun kan abọ naira ni ileesẹ wọn.
 Ẹnití ó ṣe àgbéjáde rẹ ̀ ni jonas salk , a sì bẹ ̀ rẹ ̀ síí lòó ní ọdún 1955 .
"Coronavirus: Bóo ṣe lè sọ iṣẹ́ láti ilé lásìkò ""Coro” di ìgbádùn fún ara rẹ"
Awon miran ti won wa nipade naa ni oga agba asobode fun Naijiria, oga agba ile ise ijoba apapo to n ri si irinkerindo awon eniyan to n wole to n jade ni Naijiria, alaga igbimo ijoba apapo to n ri si ilo ibon, asoju lati ile ise ijoba to n risi gbigbogunti asilo oogun oloro, ile ise ijoba eleto aabo awa ara wa tawon ara ilu, awon agbofinro, awon otelemuye, ile ise alaabo onidakonko atawon asoju eleto aabo miran.
Ẹni tí kò bá fẹ́ràn mi kò ní tẹ̀lé ọ̀rọ̀ mi.
Opo aworan rẹ lo ṣafihan Lisa lasiko to n rirnrin ajo kaakiri agbaye, nibi to ti n jẹun ni awọn ile olounjẹ to lorukọ lagbaye ati ni awọn ibi inawo eeyan jankan jankan ni awujọ.
Gbogbo ènìyàn ló dó̩gba lábé̩ òfin.
Aare orile ede Naijiria Muhammadu Buhari ti pase pe lati odun to n bo lo , ni ki  eto ijoba tiwa-n-tiwa ti won ti maa n sajodun re lati bi odun mejidinlogun seyin , ni won yoo maa  sayeye re ni, ojo kejila ,osu kefa bayii .
Àwọn oúnjẹ tó n gbayì níbi ayẹyẹ báyìí Ninu atẹjade kan ti Kọmisọna eto ilera nipinlẹ naa Dokita Jide Idris fi sita, ijọba ipinlẹ Eko lawọn ti ''ko awọn eeyan mẹta ti ọwọ tẹ lori pọnmọ oloro yii lọ si iwaju ile ẹjọ ti awọn si ti fi awọn pọnmọ naa ranṣẹ si ile ayẹwọ ile iṣẹ NAFDAC ti yoo sọ boya wọn ṣee jẹ'' Idris salaye ninu atẹjade naa pe ijọba bẹrẹ si ni tojubọ ọrọ pọnmọ oloro yi lẹyin igba ti awọn kẹfin pe awọn kan n ta pọnmọ ni ago mẹrin si ago mẹfa aarọ lawọn aaye kan ni Ọjọ ati Iba.
Ayọ̀ ń bẹ fún àwọn tí ń gbé inú ilé rẹ,wọn óo máa kọ orin ìyìn sí ọ títí lae!
Anisa Maye Maalim, to jẹ iya Ramla ni ibẹru pé oun ko ri obinrin musulumi to n ṣere idaraya ri ni oun ko ṣe kọkọ fọwọ si i ṣẹ́ Ramla.
O tun jẹ orilẹ ede ti ko ni idojukọ eto abo ti iwa ọdaran ko si ṣe bẹẹ wọpọ.
Oríṣun àwòrán, @Bego Àkọlé àwòrán, Ijọba mi maa ṣeto ilana ti eto ẹkọ ipinlẹ Yobe a gunle lati isisinyi lọ Maa tún àwọn Kọmiṣọnna tó ba ṣiṣẹ daadaa lò lẹẹkansii- Gomina Ebonyi Gomina Dave Umahi ti ipinlẹ Ebonyi ṣeleri láti ṣe itọju awọn arugbo ni saa iṣejọba rẹ ikeji yii Àkọlé àwòrán, Maa gbiyanju lati san owo ọya oṣiṣẹ bi o ti yẹ Gomina Dave lo gboriyin fawọn to baa ṣiṣẹ sẹyin pe wọn gbiyanju.
Olufẹmi Lanlẹhin - ADC Àkọlé àwòrán, ìpàdé ìfọ̀rọ̀wérọ̀ àwọn olùdíje gómìnà ìpínlẹ̀ Ọyọ Lanlẹhin ni tirẹ salaye pe nitori bi ipinlẹ Ọyọ ṣe tobi kun ara ohun to n fa ipenija eto ilera.
Ahitubu ni baba Sadoku, Sadoku bí Ahimaasi, 
 mẹ ́ tàdínlọ ́ gọ ́ rin nínú ọgọ ́ rún obìrin ní wọ ́ n ti dábẹ ́ fún ní gúúsù , márùndínláàádọ ́ rin nínú ọgọ ́ rún obìrin ní wọ ́ n ti dábẹ ́ fún ní ìwọ ̀ oòrùn gúúsù tí wọ ́ n sì ti dábẹ ́ fún méjìdínláàádọ ́ rin obìrín ní gúúsù ìlà oòrùn nàìjíríà .
O tẹsiwaju pe erongba ilu Ogbomọṣọ ni lati gbe iyoku ara ijapa ọhun si gbagede, ti gbogbo eeyan yoo si le ma wo nilẹ yi ati loke okun.
to jẹ ibuba Westham united nibi ti wọn ti lu wọn ni goolu meji sodo.
Bí o tì wù kí ó jẹun to kò níí yó bí ó sì mu omi odò gbẹ kò ní ní ìtẹ́lọ́rùn, abàmì ẹ̀dá pátápátá gbáà ni.
Yínká tilẹ̀ sọ fún mi wí pé ọjọ́ tí mo bá ti mú ìlérí-ì mi ṣẹ òun yóò ra ògidì ẹmu fún mi.
Láti òní lọ, àwọn obinrin, pàápàá àwọn obinrin Pasia ati ti Media, tí wọ́n ti gbọ́ ohun tí Ayaba ṣe yóo máa fi ṣe ọ̀rọ̀ sọ sí àwọn ìjòyè.
0 3316019 Orilẹede Italy 81325 134.
Wo àwọn nkan tí o le ṣe gẹ́gẹ́ bi aláboyún lásìkò àjàkálẹ̀ ààrùn Covid-19 Ìgbẹ́jọ́ ti bẹ̀rẹ̀ lórí àwọn afurasí tó pa ọmọ Fasoranti, Funke Olakunrin Afọnja, ẹni tó finú wénú ní Ilọrin, àmọ́ tó jẹ iwọ Nàìjíríà tún ní àkọsílẹ̀ ènìyàn 108 tó ní ààrùn coronavirus Awọn mẹtẹẹta, Sẹnetọ Enyinnaya Abaribe; alufa ijọ Juu kan, Immanuel Shalom, ati oluṣiro owo, Tochukwu Uchendu, ni onidajọ Binta Nyako paṣẹ fun lati san owo gọbọi naa si apo asunwọn ile ẹjọ.
Oríṣun àwòrán, others Àkọlé àwòrán, ọrọ airiṣẹ ṣe awọn ọdọ ati aisi ina mọnamọna ni a fẹ ki o gbajumọ bayii Nigba ti akọroyin wa ran Odumakin leti wi pe, Baba Ayo Fasanmi wa ninu ipade naa, o ni Baba Fasanmi kii ṣe ọmọ ẹgbẹ Afẹnifẹre nitori pe ko wa si ipade ẹgbẹ naa mọ.
Bode George s'ọrọ lori abadofin tuntun ipinlẹ Eko
“Bẹ́ẹ̀ gan-an ni n óo ṣe sọ ògo Juda ati ti Jerusalẹmu di ìbàjẹ́.
Awọn orilẹede ti yoo kopa ninu idije naa ni Egypt, Madagascar, Tunisia, Senegal, Morocco, Nigeria, Uganda, Mali, Guinea, Algeria, Mauritania, Ivory Coast, Kenya, Ghana, Angola, Burundi, Cameroon, Guinea-Bissau, Namibia, Zimbabwe, DR Congo, Benin, Tanzania, ati South Africa.
Nítorí ọ̀rọ̀ yìí, Solomoni ń wá ọ̀nà láti pa Jeroboamu, ṣugbọn Jeroboamu sá lọ sọ́dọ̀ Ṣiṣaki, ọba Ijipti, níbẹ̀ ni ó sì wà títí tí Solomoni fi kú.
Olori awọn oṣiṣẹ fun aarẹ naa sọ fun BBC pe lẹyin ti wọn dan agbo naa wo lara bi ogún eniyan, ni wọn to ṣe e sinu igo ti wọn si n ta a gẹgẹ bi agbo mimu.
ile – ẹjọ  naa so pe  wiwa si orile ede Naijiria wa lara igbesẹ lati
Ajọ to n ri si iṣẹlẹ pajawiri nipinlẹ Eko, LASEMA lo fi atẹjade sita pe awọn ti gbe ọkọ naa to gun to iwọn ẹsẹ bata ogun le awọn ọlọpaa lọwọ ki wọn maa ba iṣẹ lorii rẹ.
Ìjọba ní yato sí pe wọn tu awọn ẹlẹwọn silẹ, awọn to kọlu ogba ẹwọn wọnyi tun ji nkan nibẹ to fi mọ ibon nibi ti wọn kọ wọn si.
Nínú ọ̀rọ̀ ìkádìí wọn, Ogunbanjọ ní òun ni ọmọde to wa laaarin won.
Awọn meje naa niyi ati itan diẹ nipa wọn.
Ninu ọrọ tirẹ, Oyetunji ni pe aisi ifẹ, aini igbẹkẹle ati iwa kotọ iyawo oun lo fa ipẹjọ kọkọ-kọkọ naa.
Àwọn ẹṣin pupa ni wọ́n ń fa kẹ̀kẹ́ ogun àkọ́kọ́, àwọn ẹṣin dúdú ń fa kẹ̀kẹ́ ogun keji, 
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Premiership: Arsenal ta ọ̀mì 1-1 pẹ̀lú Bournemouth ní ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ àkọ́kọ́ Arteta 26 Ọ̀pẹ̀̀ 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 27 Ọ̀pẹ̀̀ 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Arsenal ta ọ̀mì 1-1 pẹ̀lú Bournemouth ní ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ àkọ́kọ́ Arteta Ọmi goolu kọọkan ni Bournemouth ati Arsenal gba ni idije premiership to waye lale Ọjọbọ yii.
Wọ́n bá pinnu pé, “Ọdọọdún ni a máa ń ṣe àjọ̀dún OLUWA ní Ṣilo, tí ó wà ní apá àríwá Bẹtẹli, ní apá ìlà oòrùn òpópó ọ̀nà tí ó lọ láti Bẹtẹli sí Ṣekemu, ní apá gúsù Lebona.
Oríṣun àwòrán, CHESTER ZOO Àkọlé àwòrán, Awọn Àmọ̀tẹ́kùn kii saaba fara wọn hàn Oríṣun àwòrán, CHESTER ZOO Àkọlé àwòrán, Awọn ológbò alawọ̀ wúrà nilẹ̀ Afrika n gbe ninu agunju equatorial nilẹ̀ Afrika Wọn tun sawari ológbò alawọ̀ wúrà nilẹ̀ Afrika ninu awọn àwòrán ọun.
29 Àti pé ìwọ yíò kéde àwọn ìrohìn ayọ̀, bẹ́ẹ̀ni, kéde rẹ̀ ní orí àwọn òkè, àti ní gbogbo ibi gíga, àti lààrin àwọn ènìyàn gbogbo tí a ó gbà ọ́ láàyè láti rí.
7, ti wọn ji lati ori ayelujara pamọ.
Adájọ - BBC News Yorùbá BBC News, YorùbáFò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ajimobi: A gùnlé ìdájó ilé Ẹjọ́ àkọkọ lórí ẹjọ Ajimobi - Adájọ 1 Bélú 2019 Oríṣun àwòrán, FACEBOOK Àkọlé àwòrán, Abiola Ajimobi Gomina ana ni Ipinlẹ ọyọ Abiola Ajimọbi ti fidi rẹmi ninu ipẹjọ rẹ lati tako ibo ti o gbe ojugba rẹ Kola Balogun wọle gẹgẹ bii Sẹnatọ.
Ẹrọ ayaworan 3D to n ṣe ibomu: Onimọ ẹrọ Natalie Raphil lo ṣe ẹrọ naa ni South Africa, ẹrọ ọhun si lagbara lati pese ọgọrun un ibomu lojumọ.
Nítorí kò sí ìpìlẹ̀ kan tí ẹnikẹ́ni tún lè fi lélẹ̀ mọ́, yàtọ̀ sí èyí tí Ọlọrun ti fi lélẹ̀, tíí ṣe Jesu Kristi.
Awọn ọlọpaa ati ologun ni wọn kun oju popo ti wọn si n ṣe afihan ohun ija tuntun ti ijọba ilẹ naa ṣẹṣẹ ra.
Wọn óo máa jíṣẹ́ fún ọ, wọn óo sì máa ṣe iṣẹ́ wọn ninu Àgọ́ Ẹ̀rí, ṣugbọn wọn kò gbọdọ̀ fọwọ́ kan ọ̀kan ninu àwọn ohun mímọ́ tí ó wà ninu ibi mímọ́ tabi pẹpẹ ìrúbọ, kí gbogbo wọn má baà kú.
Lẹ́yìn oṣù meje wọn yóo yan àwọn kan tí wọn óo la ilẹ̀ náà já, tí wọn óo máa wá òkú tí ó bá kù nílẹ̀, tí wọn óo sì máa sin wọ́n kí wọ́n lè sọ ilẹ̀ náà di mímọ́.
Àbí n kò ní ẹ̀tọ́ láti ṣe ohun ìní mi bí mo ti fẹ́?
Ajọ to n ri si ere bọọlu l'orilẹ-ede Naijiria NFF ati awọn ololufẹ ere bọọlu n ṣe ranti agbaọjẹ akọnimọọgba ni Naijiria ati kakiri agbaye naa.
‘Ẹ máa kọ́ ilé kí ẹ sì máa gbé inú wọn, ẹ máa dá oko kí ẹ sì máa jẹ èso wọn.
"Ninu atẹjade tirẹ, Iba Gani Adams ni gbọnmọgbọnmọ awọn ""Fulani to n ya wọ ilẹ Yoruba lati ṣe iṣẹ ibi bayii"" n fẹ amojuto gidgidi."
Eto iwadii ilana fun itọpinpin arun coronavirus tuntun ọhun ni akọkọ nilẹ Afririka, eleyi si fi ẹri si ohun ti ajọ ilera agbaye, WHO sọ pe igbaradi orilẹede Naijiria yanranti ju bo ṣe n lọ lọpọ awọn orilẹede lagbaye.
Iroyin kan ti kọkọ jade pe igbakeji gomina ipinlẹ Oyo sọ pe ija to wa laarin oun ati Makinde ko le pari laelae.
O ni ko si ẹni to ni idi pataki lati wọle tabi jade ti ko ni le wọle laisi wahala.
Àjọ aṣọ́bodè gba Codeine N200m Àsìlò oògùn Codeine: Ọwọ́ ba òsìṣẹ́ Emzor NAFDAC ti parí ìwádìí lórí codeine Sọ́ra, òògùn ikọ́ codeine lee yi ọ lórí Bi oogun naa ṣe n ba aye awọn awọn eniyan j kọja afẹnusọ kaakiri orilẹede Naijiria leyii ti ko mọ olowo tabi talaka, ọmọde tabi agba, ọkunrin tabi obinrin to fi mọ awọn ẹlẹsin gan.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Àṣìṣe ọlọ́pàá àti Adájọ́ sọ mí di ẹni tí wọ́n dájọ́ ikú fún, ọpẹ́lọpẹ́ Fayoṣe tí ko buwọlu Aisan jejere Bakan naa ni ẹni to ba ni aisan jẹjẹrẹ to ti tan ka gbogbo ara rẹ lee maa tọ si ara.
Ẹ ta kété sí àjọṣepọ̀ tí kò bá fún yín láyọ̀ torí ẹ̀mí kò ní ààrọ̀ - Àwọn òṣèré tíátà gbarata lórí ìdájọ́ ikú Rárá o, ẹ kò gbọdọ̀ sìnkú akẹ́kọ̀ọ́ LASU tí wọn fi ṣe òògun owó - Ìjọba Eko yarí Ojú Shagbada Erigga rèé lẹ́yìn tó pa ọ̀rẹ́bìnrin rẹ̀ l'Akinyele ní Ibadan Iwadii ọlọpaa lẹyinwa ṣafihan pe arumọjẹ ijingbe lo waye ti wọn si gba Ujunwa ati Precious to ṣalatilẹyin fun Ifesinachi.
Iṣẹ aṣọ riran lo yan laayo.
Awọn ẹlomiran ni o yẹ ki ijọba apapọ ko fesi si si awọn ẹsun ti Baba Obasanjo fi kan an, kii se ki wọn ma a bu ẹnu atẹ lu ọrọ rẹ.
N óo fi ẹni tí ẹ̀ bá bẹ̀rù hàn yín.
African Parents: Òbí ayé àtijọ́ ló tọ́ ọ dàgbà tí o bá ṣe àwọn ǹkan wọ̀nyii Oríṣun àwòrán, @TokeMakinwa/Instagram Àkọlé àwòrán, African Parents: Obí ayé atijọ ló tọ́ ọ ti o ba ṣe àwọn ǹkan wọ̀nyii Gbájugbaja sọ̀rọ̀ sọ̀rọ̀ orí radio kan Toke Makinwa lo fa ibínuyọ laipẹ yìí lori ayelujara tirẹ̀ to n dari pé obí aye atijọ l'Afrika lo baye ọ̀pọ̀ ọmọ míràn jẹ́.
lẹ ́ yìn àwọn ojú odù mẹ ́ ríndinlógún yìí , àwọn òjìlérúgba odù míràn tún wà tí à ń pè ni ọmọ odù tàbí àmúlù odù wọ ́ n jẹ ́ ọmọ odù nitorí pé a gbà pé wọn se ọmọdé si àwọn ojú odù , à ń pè wọ ́ n ni Àmúlù odù nítorí pé orúkọ odù méjì ni ọ ̀ kọ ̀ ọ ̀ kan wọ ́ n jẹ ́ .
Ṣe ogún àkànpọ̀ igi sí ẹ̀gbẹ́ àríwá àgọ́ náà, 
Bí ó tí ń wọ abúlé kan lọ, àwọn ọkunrin adẹ́tẹ̀ mẹ́wàá kan pàdé rẹ̀.
Ọdẹ atamátàsé ni ọkùnrin ogun yìí jẹ́ ó sì tún kó àwọn ọ̀rẹ́ tímọ́ timọ́ mọ́ra tí àwọn náà mọ ìjàa jà gidigidi.
olúbákin ni orúkọ ẹni àkọ ́ kọ ́ tí ó jẹ olúbo ní òde ugbo .
Nítorí náà, Oholiba, OLUWA Ọlọrun ní, “Mo ṣetán tí n óo gbé àwọn olùfẹ́ rẹ dìde, àwọn tí o kọ̀ sílẹ̀ nítorí ìríra.
Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Anthony Joshua ti na Joseph Parker nibi ìdijé ẹ̀ṣẹ1 Ìgbé 2018 Anthony Joshua vs Andy Ruiz: Págà!
Oríṣun àwòrán, @abolarinwa Àkọlé àwòrán, Ifura ṣe pataki, tete sa kuro nibi ti ẹru ba ti fẹ maa ba ẹ.
 Atupalẹ iṣuna owo naa fi han pe Ile
- Kemi Afolabi Njẹ́ o mọ pé N3000 ló o sàn láti gbà kaadi ìdánimọ̀ míì bí tí tẹ́lẹ̀ bá sọnù?
Fun bi wakati meloo kan lori ayelujara lawọn mejeeji n tahun si ara wọn lori ọrọ idi nla.
Ki Ambode to kuro lori oye ni oun ati ile aṣofin ipinlẹ Eko ko ti gbọ ara wọn ye daadaa, ti iroyin si kan nigba naa pe wọn fẹ yẹ aga ni idi rẹ.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Bakan naa ni ajọ Un tun fi ipaya rẹ han, lori eto aabo to mẹhẹ ni Naijiria ati iya to n jẹ awọn eeyan, paapa awọn ti ko nile lori lati-pasẹ ikọlu ikọ Boko Haram.
Nígbà tí Juda rí i pé ogun wà níwájú ati lẹ́yìn wọn, wọ́n ké pe OLUWA, àwọn alufaa sì fọn fèrè ogun.
Salah gbá góòlù ọgọ́rùn ún wọlé, àyẹ̀wò ìgbàlódé VAR d'òkúta sí gààrí Liverpool Cristiano Ronaldo ti fara kásá àrùn Coronavirus Mo sì ń gba ìtọ́jú lọ́wọ́ lẹ́yìn tí Fury fẹ̀ṣẹ́ já iṣan ọwọ́ mi loṣù mẹ́jọ sẹ́yìn- Deontay Wilder Eyi mu ki ọpọ maa fi oju ifigagbaga laarin ọga ati ọmọṣẹ wo ifẹsẹwọnsẹ to ba waye laarin wọn.
Omotara pàdánù isẹ́ olówó ńlá nítorí ó fi ọtí ẹlẹ́rìndòdò sódà lá ọmọ alágbe lójú Ilé aṣòfin orílẹ̀-èdè UK ti faramọ́ fífí ìyà jẹ àwọn adarí Naijiria tọ lọ́wọ́ nínú rògbòdìyàn ENDSARS Jemila dáná sún ilé ọ̀rẹ́kùnrin rẹ̀ àti ọ̀rẹ́bìnrin tó bá nílé Èyí ni ohun tí Ọọ̀ni sọ nípa Àrẹ̀mọ rẹ àti ètùtù tó ń ṣe lọ́wọ́ Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Fídíò, Akọ́mọlédè àti Àṣà lórí BBC Yorùbá: Kọ́ síi nípa iṣẹ́ tí oúnjẹ ń ṣe lára níbí24 Bélú 2020 Lagos State Task Force: Lóòótọ́, a tí mú Ọlọ́páà to f'ọ̀nà ẹ̀bùrú gba owó ẹ̀yìn N100k lọ́wọ́ awakọ̀24 Bélú 2020 Omotara: Mo kábámọ̀ ìwà tí mo hù sí ọmọ alágbe, mo wá a títí ṣùgbọ́n mi ò mọ ibi tó wà26 Bélú 2020 Nigeria government - Lekki Toll Gate - Kí ló wà ninú lẹ́tà tí ìjọba Naijiria kọ sí CNN24 Bélú 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Awọn oṣiṣẹ eleto ilera si ti sọ pe ami leyi jẹ pe ajakalẹ arun covid-19 ẹlẹẹkeji n kan ilẹkun gbọngbọn papaa nipinlẹ Eko.
Delta, ni ifesewonse olorejore iko agbaboolu Super Eagles ati
Yóo jẹ́ àmì ati ẹ̀rí fún OLUWA àwọn ọmọ ogun ní ilẹ̀ Ijipti.
Kí ló mú Sanusi kọrin bù Gómìnà ìpínlẹ̀ Kano, Abdullahi Ganduje?
Nítorí OLUWA yóo ra ilé Jakọbu pada,yóo rà wọ́n pada lọ́wọ́ ẹni tí ó lágbára jù wọ́n lọ.
wa ni ipinle naa, ni eyi ti o je pe awon janduku ji awon ohun elo ibo gbee,
Ọjọgbọn Wole Soyinka kilọ ni tirẹ pe bi wọn ba file buwọlu u, yoo fun aarẹ ni gbogbo agbara lori gbogbo ọna omi lori ilẹ ati labẹ ilẹ.
Àwa kìí jà lásìkò tiwa, ta ló bí ẹ tí wàa máa jà?
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Kò sí ẹni tó lè yọ mi nípò Sẹnetọ -Dino Melaye 23 Ògún 2019 Oríṣun àwòrán, @Dino Àkọlé àwòrán, Irọ lẹ pa lori ọrọ igbẹjọ mi - Dino Igbẹjọ to n gbọ ẹjọ ẹsun idibo lo ṣẹṣẹ gbe idajọ rẹ sita bayii.
Ààrẹ Buhari ti fawọ kónile -ogbéle wálẹ díẹ̀ ní Eko, Ogun ati Abuja Gbogbo ìgbésẹ́ to yẹ ni a gbé nígbà ti àwọn ọ̀daràn dé ọgbà wa- Agbẹnusọ ọgbà ẹ̀wọ̀n Ilé epo NNPC gbiná ní ìpínlẹ̀ EkoÀjọ NCDC kéde èèyàn 239 míràn tó ni ààrùn Covid-19 lórílẹ̀-èdè Naijíríà Covid-19 60seconds: Ṣé ìjìnà síra-ẹni ṣe paàtàkì lẹ́yìn lílo ìbòmú?
Tafa jẹ amugbalegbe ẹda itan ti onkọwe sapejuwe drẹ ninu iwe itan arosọ naa.
 Àwọn alábàgbéé wọn ni luballunder .
Wọ́n di ẹrù wọn ru àwọn kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ wọn, wọ́n sì gbọ̀nà ilé.
Nígbà tí wọ́n bá nà án tán, wọn óo sì pa á.
Ọpọlọpọ eniyan ni yóo bá ọ yọ̀ nígbà tí ẹ bá bí ọmọ náà.
Kò sí ẹni tí ó lè kò wọ́n lójú nítorí pé gbogbo àwọn eniyan ni wọ́n ń bẹ̀rù wọn.
Lẹ́yìn náà, Esau sọ fún Jakọbu pé, “Jẹ́ kí á múra kí á máa lọ n óo sì ṣáájú.
“Lẹ́yìn náà, pe Aaroni arakunrin rẹ sọ́dọ̀, ati àwọn ọmọ rẹ̀ wọnyi: Nadabu, Abihu, Eleasari, ati Itamari.
Bí àwọn ẹ̀dá alààyè náà bá ti ń lọ ni àwọn àgbá kẹ̀kẹ́ náà a máa yí tẹ̀lé wọn, bí àwọn ẹ̀dá alààyè náà bá gbéra nílẹ̀ àwọn àgbá kẹ̀kẹ́ náà a sì gbéra nílẹ̀ pẹlu.
Ọfà wọn mú wọ́n kẹ́ ọrun wọn.
Igba akọkọ ree ti maa ri iru iṣẹlẹ bayi lati nkan bi ọdun marundinlọgbọn ti mo ti wa lẹnu iṣẹ yi'' O sọ bakan naa pe oun ti fi ikini ibanikẹdun ranṣẹ si mọlẹbi ọlọpaa to padanu ẹmi rẹ yi.
Bakan naa ni wọn tun duro idakẹjẹ iṣẹju kan ni iranti Ọbaalaye naa, kabiyesi Olufọn ti ilu Ifọn-Ọwọ, Oríṣun àwòrán, flashinfoNg12/twitter Àràbà nlá tó wó nípìnlẹ̀ Ondo jẹ́ ká mọ̀ pé inú ìpèníjà ètò ààbò tó kọjá ojú lásán la wà - Ìjọba ìpínlẹ̀ Ondo Ijọba ipinlẹ Ondo ti kẹdun iṣẹlẹ to waye ni agbegbe Elegbeka, ni oju ọna Ifon si Owo.
Oríṣun àwòrán, Lugard Fredo Àkọlé àwòrán, Minisita fun ere idaraya tẹlẹ ni odẹ aperin ti yóò pese gbogbẹlan ti wan nilo Awọn ọmọ Naijiria ba fi fidio bi igbeyawo naa ṣe lọ sita pe: Oríṣun àwòrán, BadMAnLade Àkọlé àwòrán, Awon mogbọ moya rèé ti wan mu iwe iwole dani E seun ti ẹ wa, ẹbun àmurele rèé fun gbogbo awọn ti wan wa fun ayẹyẹ igbéyawo yìí: Oríṣun àwòrán, #sirtunji Àkọlé àwòrán, Awọn ẹbun ti wọ́n pin fun alejo Kini o ti ṣẹlẹ sẹyin?
Wọ́n dáhùn pé, “Ìwọ ni o gbà wá lọ́wọ́ ikú, bí ó bá ti wù ọ́ bẹ́ẹ̀, a óo di ẹrú Farao.
O ni ihuwasi awọn awakọ agbepo ati ọkọ akeru lopopona yii ko kọja pe aitete pari atunṣe si ọna marosẹ naa.
Oríṣun àwòrán, MURIC Ọwọ́ ọlọ́pàá ìpínlẹ̀ Kebbi tẹ bàbá àti ìyàwó rẹ̀ méjì fún pé wọn so ọmọ pọ̀ mọ́ ewúrẹ́ fún ọdún méjì Ẹgbẹ́ òṣèlú ZLP gbàmí tọwọ́tẹsẹ̀ láti díbò gómínà ní Ondo- Agboola Ajayi Coronavirus: Ewu wo làwọn òṣìṣẹ́ elétò ìlèra ń kojú ní Nàìjíríà?
Mo fẹ gbe ile aye lati se iya awọn ọmọ mi.
MKO Abiola, iṣẹ́ aṣẹ́gità ló fi bẹ̀rẹ̀ okoòwò Ìdààmú ńlá ńbọ̀ fún Nàíjíríà lábẹ́ ìjọba Buhari - Ọbasanjọ À ń wo àtubọ̀tán APC níbáyìí tó gba àkóso ilé aṣòfin - PDP Lori papa iṣere yii naa ni ogunlọgọ ọdọ Naijiria ti lọ pade fun idanwo ati gba iṣẹ aṣọbode lọdun 2015.
Mo si fi aṣiri oyun naa pamọ, debi pe ti awọn eeyan ba beere pe ṣe mo loyun, ma a sọ pe rara.
Bẹ́ẹ̀ ni ọkọ náà kò gbọdọ̀ kọ aya rẹ̀.
Aṣọ àwọ̀kanlẹ̀ alápá gígùn, irú èyí tí àwọn ọmọ ọba, obinrin, tí kò tíì wọlé ọkọ máa ń wọ̀, ni Tamari wọ̀.
Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo
Gbogbo eniyan yóo sì mọ̀ pé ọwọ́ OLUWA wà lára àwọn iranṣẹ rẹ̀,ati pé inú bí i sí àwọn ọ̀tá rẹ̀.
Igi ìyè ni fún àwọn tí wọ́n rọ̀ mọ́ ọn,ayọ̀ sì ń bẹ fún àwọn tí wọ́n dì í mú ṣinṣin.
Mo sì rò pé o óo máa pè mí ní baba rẹ,ati pé o kò ní pada kúrò lẹ́yìn mi.
Ìwọ ọ̀rẹ́ mi, o kò rí i pé nǹkan tí ó gbé aya lulẹ̀ tí ó tún gbé ọkọ lulẹ̀ kúrò ní nǹkan yẹpẹrẹ?
AWỌN IROYIN TẸẸ LE NIFẸ SI NIPA RẸ Àwọn olólùfẹ̀ Toyin Abraham ati Liz Anjorin ti gbé ọ̀rọ̀ wọn rù sórí, ẹ wo òjò òkò ọ̀rọ̀ Lizzy Anjorin: Mi ò bẹ Toyin o!
Saraki: Ilana gbigbogun ti iwa ijẹkujẹ ṣi n mẹhẹ lorilẹede Naijiria
kò kí ń ṣe wí pé àbíkú nìkan ni ẹ ̀ mí ọmọ tí ó kú ní kékeré , ìgbàgbọ ́ wa ni pé ẹ ̀ mí náà á padà sí ara Ìyá rẹ ̀ kan náà ní àìmọye ìgbà láti tún n bí ní ọ ̀ pọ ̀ lọpọ ̀ ìgbà .
"Aarẹ Trump ni awọn ọmọ ogun ilẹ Amẹrika ṣe iṣẹ iṣekupani ọhun lai labawọn kankan eyi to si fa iku adunkoko mọni to lagbara ju lagbaye, Qassem Seleimani""."
" die ninu awari rẹ ́ lórí herbal slimming ni slimming ring , slimming aroma and slimming water , slimming "" gari "" , natural skincare products gbogbo èyí ní ó ṣe apèjúwe rẹ ́ ní "" egbògi Ìbílè pánbélé "" tí wọn fi ímọ ́ -íjínlẹ ́ gbé kalẹ ̀ ."
Wọ́n ṣe aadọta ìkọ́ wúrà, wọ́n fi àwọn ìkọ́ náà kọ́ àránpọ̀ aṣọ títa náà mọ́ ara wọn, bẹ́ẹ̀ ni àgọ́ náà ṣe di odidi kan.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ọwọ́ ọlọ́pàá tẹ ọlọ́kọ̀ epo tó fa ìjàmbá nílú Eko Dino ní irọ́ l'ọlọ́pàá pa mọ́ àbúrò òun Igbakeji aarẹ Oṣinbajo ni iwa awọn oṣiṣẹ ikọ naa tabi ẹnikẹni to ba n hu iwa aitọ si araalu kii ṣe ohun ti ijọba to wa lode bayii yoo fi ọwọ awẹwa mu.
Iroyin ni nibi ti won ti n ju oku Nwafor sinu odo, ni Ugbala si raaye sá lọ, gbogbo igbiyanju lati ri oku oloogbe naa, lo ja si òfo.
'Ọọ̀nì ńlá méjì ní wọ́n jọ ń gbé nínú iyàrá' #BBCGOVDEBATE: Ọgbọ́n ìmọ̀ àti òye ní ń ò fi ṣe ìjọba- GNI Anthony Joshua ni ìwúrí ọmọ ọdún méje yìí Children's Day: Àwọn ọmọdé tó ń ṣe bẹbẹ láwùjọ Afíríkà Small Mummy sọ bo ṣe n kawe papọ mọ iṣẹ alawada ti ọkan ko di ikeji lọwọ.
Ó yan àwọn mẹta láti máa ṣe àbojútó gbogbo wọn, Daniẹli sì jẹ́ ọ̀kan ninu wọn.
Àti pé kò maa ṣe àmójútó àwọn alágbàtà tó ní òntẹ̀ Àjọ NAFDAC nínú àtẹ̀jáde kan tí olùdarí rẹ̀, Ọ̀jọ̀gbọ́n Mojisọla Christianah Adeyẹye, fi ọ̀wọ́ sí, ti ní kí àwọn iléeṣẹ́ apòògùn mẹ́tẹ̀ẹ́ta dáwọ́ ṣíṣe òògùn ikọ́ olómi tó ní èròjà codeine dúró lọ́gán, kí wọ́n ó sì gba gbogbo èyí tí wan ti tà síta padà fún àyẹ̀wò lọ́dọ̀ NAFDAC.
Pipin aṣẹ Emir ilu Kano Oríṣun àwòrán, others Àkọlé àwòrán, Ijọba ipinlẹ Kano fi awọn Emir mẹẹrin miran jẹ lati din agbara ti Emir Sanusi ni ku.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Ti a ba woye pe awọn ọmọ ile aṣojuṣofin yi naa ni wọn fẹ ya Trump ni po,ko daju pe wọn yoo buwọlu iyansipo rẹ gẹgẹ bi igbakeji aarẹ lẹyin ti wọn ba yọ tan.
Oṣu Kẹwa ọdun 2006 ni agba oṣere naa dagbere faye lasiko aisan oṣu mẹta to ṣe.
Ni awọn orilẹede ni Ilẹ Yuroopu, iwadii fihan pe awọn eniyan ko ri ilẹ Amerika bi ti tẹlẹ mọ, fun igba akọkọ ni ogun ọdun.
Lọ́gán tí wọ́n kéde èsì ìbò náà ni ajọ̀ EFCC ti sọ wí pé wọn yóò bẹ̀rẹ̀ títọpinpin Ayo Fayoṣe lórí bó ṣe na owó iṣẹ́ àkànṣe Integrated Poultry Project / Biological Concepts Limited to yé ko lo fun iṣe akanṣe l'Ekiti.
" O sọ pe ẹlomiran ma n ti itori pe oun fẹ ẹ gba ẹsan, ko lọ ọ gba ajẹ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Oyo Corornavirus: Gbogbo ìgbìmọ́ aláṣẹ ìjọba ìpínlẹ̀ Oyo ló ṣe àyẹwò àrùn Covid-19 Sùgbọ́n.
Ekiti election appeal: Ìpèníjà ráńpẹ́ ni èsì ilé ẹjọ́ kòtẹ́milọ́rùn jẹ́ fún wa -PDP
Osun Osogbo: Àtáója ní káwọn èèyàn wá bọ Ọ̀ṣun lónìí, torí kò ṣe é jígbé,
Olùdaríi wa ni, kò sí eni tí a lè fi wé e nínú ẹgbẹ́ẹ wa.
Nísisìyí, nǹkan tí mo sì fẹ́ẹ́ tọrọ lọ́wọ́ yín báyìí ni pé kí ẹ fún mi láyè nínú àa[fin yìí kí n ṣe ibojì ẹ̀gbọ́n mi yìí sí ibẹ̀, kí n sì máa fi ojú wo ibojì náà báyìí, nítorí ọ̀rọ̀ náà ká mi lára púpọ̀.
Iyawo Naamani ní iranṣẹbinrin kékeré kan tí àwọn ará Siria mú lẹ́rú wá láti ilẹ̀ Israẹli, nígbà tí wọ́n lọ bá wọn jagun.
 Sunday Igboho gba àwọn èèyàn Soka n'Ibadan sílẹ̀ lọ́wọ́ àwọn ọmọ onílẹ̀ tó wá ṣọṣẹ́ Oríṣun àwòrán, Sunday Igboho Ọrọ di boo lọ, ko yago fun mi ladugbo Soka nilu Ibadan lasiko ti gende meji to gbe ohun ija oloro lọwọ, ti wọn pe ara wọn ni ọmọ onilẹ ya bo agbegbe naa."
Nígbà tí wọ́n gbọ́ àwọn ọ̀rọ̀ yìí, ó gún wọn lọ́kàn.
Ó ṣẹgun àwọn ará Moabu bákan náà, ó sì mú kí àwọn tí ó kó lẹ́rú ninu wọn dọ̀bálẹ̀ lórí ilẹ̀ ní ìlà mẹta, ó pa gbogbo àwọn tí wọ́n wà lórí ìlà meji, ó sì dá àwọn tí wọ́n dọ̀bálẹ̀ lórí ìlà kan sí, bẹ́ẹ̀ ni àwọn ará Moabu ṣe di ẹrú rẹ̀, tí wọ́n sì ń san owó ìṣákọ́lẹ̀ fún un.
Ṣugbọn Jesu kò tún dá a lóhùn rárá mọ́, èyí mú kí ẹnu ya Pilatu.
Ọjọ kẹrinla, oṣu Keje, ọdun 2020 ni Tolulope kú, lẹyin ti ẹnikan fi ọkọ gba a ninu ọgba ileeṣẹ ologun naa nilu Kaduna.
Ní tèmi, bí a bá gbé mi sókè kúrò láyé, n óo fa gbogbo eniyan sọ́dọ̀ mi.
”O tesiwaju pe, gege bi omo egbe ajo UNRSTF, ogbeni Amaechi yoo ri daju lati mu ibasepo ti o donmonran jeyo laarin orile-ede Naijiria, ile Afrika ati igbimo naa lati mu adinku de ba isele ijamba oju opopona, bee si ni lati tun mu igberu ba eto irnna lapapo.
Bi Funke Adesiyan ti wọ agbo oṣelu ree Lẹyin ti Funkẹ bẹrẹ oloṣelu, lo sọ erongba rẹ lati ṣoju Ẹkun Ila Oorun Guusu Ibadan nile igbimọ aṣofin Ipinlẹ Oyo ninu eto idibo ọdun 2015.
Nǹkankan wà tí a lè fi ṣe ìgbéraga, ẹ̀rí-ọkàn wa sì jẹ́rìí sí i pé pẹlu ọkàn kan ati inú kan níwájú Ọlọrun ni a fi ń bá gbogbo eniyan lò, pàápàá jùlọ ẹ̀yin gan-an.
Òṣùpá yóo mọ́lẹ̀ bí oòrùn; oòrùn yóo mọ́lẹ̀ ní ìlọ́po meje, ní ọjọ́ tí OLUWA yóo bá di ọgbẹ́ àwọn eniyan rẹ̀, tí yóo sì wo ọgbẹ́ tí ó dá sí wọn lára sàn.
Síbẹ̀ Baba-onírùngbọ̀n-yẹ́úkẹ́ rí omi náà bù ṣùgbọ́n kí ó tóó lè bù ú ojú rẹ̀ rí nǹkan, nítorí ó sọ fún wa pé bí kò bà sí ọ̀rẹ́ òun, Ikú, ẹni tí ilé rẹ̀ ń bẹ lágbede méjì ayé òun ọ̀run òun kò bá tí lè rí omi náà bù rárá.
lati orile ede Naijiria ati ni oke-okun, Osinbanjo ni ko si ọpẹ to kere pupo
Àkọlé àwòrán, Ibadan Awọn ara ipinlẹ Kwara ti wa nikalẹ ni gbngan igbalejo ijọba ipinlẹ to wa ni ilu Ilorin.
Baba Ẹlẹbuibọn la awọn eeyan lọyẹ nitori bi ajọ to n gbogun ti iwa ibajẹ lorilẹede Naijiria, EFCC, se fi panpẹ ọba mu ayederu babalawo kan ni ilu Ibadan.
Àkọlé àwòrán, COZA: Iléejọ́ Abuja ké si Fatoyinbo ati Busola Dakolo pé kí wọ́n yọjú.
Bí ó ti ń lọ, ó yà wo òkú kinniun tí ó pa, ó bá ọ̀wọ́ oyin ati afárá oyin lára rẹ̀.
Oríṣun àwòrán, @IsiakaAdeleke1 Àkọlé àwòrán, Adeleke lọ si ile ẹjọ lati pẹjọ ẹhonu lori esi idibo naa Ni bayii, ajọ INEC ti kede Gboyega Oyetọla gẹgẹ bii gomina ipinlẹ Ọṣun, wọn si ti bura fun un wọle gẹgẹ bii gomina lati oṣu kọkanla ọdun 2018.
Oríṣun àwòrán, EPA Awọn wo ni yoo kọkọ gba abẹrẹ ajẹsara yii?
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Coronavirus in Nigeria: Nítorí COVID-19, ìjọba ìpínlẹ̀ Kwara kó ọ̀dọ́ 50 tó lọ sí ilé ijó sí gbaga 19 Agẹmo 2020 Oríṣun àwòrán, Bhenji Àkọlé àwòrán, Nítorí COVID-19, ìjọba ìpínlẹ̀ Kwara kó ọ̀dọ́ 50 tó lọ sí ilé ijó sí gbaga Aadọta awọn ọdọ ti ọjọ ori wọn ko ju ogun ọdun si ọgbọn ọdun lọ lọwọ ofin tẹ lowurọ ọjọ Abamẹta nile ijo kan nilu Ilọrin Igbimọ amusẹya lori ajakalẹ arun COVID-19 ni ipinlẹ Kwara lo ko wọn si gbaga.
to n mojuto isele pajawiri lorile-ede Indonesia ti n wa awon eniyan ti o fara
Iroyin yii ko fẹrẹ ṣe ọpọlọpọ eeyan ni kayeefi nitori awọn iroyin ati iriri awọn irufẹ edeaiyede bẹẹ to ti waye laarin awsn gomina tabi aarẹ atawọn igbakeji wọn lorilẹede Naijiria.
Olusegun Obasanjo bọ́hùn nípa ìṣẹ̀lẹ̀ ìpànìyàn Oríṣun àwòrán, Thisdaylive Aarẹ ana lorilẹede Naijiria, Oloye Oluṣẹgun Ọbasanjọ ti ke gbajare sita pe, asiko to fun aarẹ Muhammadu Buhari bayii lati sọrọ soke, ki ọrọ to kọja atunṣe bayii lorilẹede Naijiria.
O ni SARS ati SWAT gbọdọ wa si opin lorilẹede Naijiria lai beṣu bẹgba.
Asoju ajo INEC ninu idibo naa, ojogbon Joseph Fowape, salaye lojo Aiku(Sunday) pe, awon ibo lati ibudo idibo kookan nipinle naa bi, ijoba ibile Ife North, Orolu ati Ife South ko si ni ibamu pelu ofin ati ilana ajo INEC, eleyi ti o sokunfa idi ti ajo INEC se fagile egbejidilogun-din-ọgọrun ibo ti o wa lati awon ibudo idibo ohun.
Ninu ẹ̀yà Sebuluni, àwọn tí wọ́n tó ẹni ogún ọdún, tí wọ́n tó lọ sójú ogun, gẹ́gẹ́ bí àkọsílẹ̀ wọn ní ìdílé-ìdílé 
Ṣugbọn ó ṣàánú mi nítorí n kò mọ̀ọ́nmọ̀ ṣe é; ninu aigbagbọ ni mo ṣe é.
Àyìnlá banújé, ó sì toro ààyè láti kó àwon dúkìá Oba pamó kí ó tó wá máa sin Adéláyò, àmó Basòrun sàlàyé pé kò sí dúkìá kankan tí ó lè fowó kàn mó àyàfi èyí tí olúwa rè tuntun (Omo Oba Adéláyò) bá fún un, Nítorí pé eni tí ó lerú ló ni erù.
Oríṣun àwòrán, Femi Adesina Àkọlé àwòrán, Ààrẹ Muhammadu Buhari nínú ìwé ìpolongo rẹ̀ ní òhun yóò se àtúnsẹ ilé ìwé ẹgbẹ̀wá lọ́dọọdún.
Araba ilu Osogbo ṣalaye siwaju pe, oun tun fi ọfọ ji saye ẹnikan to daku pada.
"O pari ọrọ rẹ pe ""kii ṣe igba akọkọ ree ti banki naa yoo ṣe ohun to lodi si ofin, ti wọn ba si n tẹsiwaju lati maa tẹ ẹtọ awọn onibara wọn loju mọle, o tumọ si pe ko si abo fun owo mi to wa lọwọ wọn."
Oríṣun àwòrán, PAstorEAAdeboye Baba Adeboye ni Alaga igbimọ naa eleyi ti awọn gomina tẹlẹ ni ipinlẹ naa atawọn to di di ipo Oṣelu mu pẹlu awọn oludaleeṣẹsilẹ pẹlu wa.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Barcelona fàgbà han Deportivo láti gba ife ẹ̀yẹ 30 Ìgbé 2018 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Andres Iniesta gba ife ẹ̀yẹ La liga pẹ̀lú Barcelona fún ìgbà ìkẹyìn kó tó kúrò níbẹ̀ Ikò Barcelona gba ife ẹ̀yẹ La liga lẹ́yìn tí wọ́n f'àgbà han ẹgbẹ́ agbábọ́ọ̀lu Deportivo La Coruna pẹ̀lú àmìn ayò mẹ́rin sí méjì .
Àwọn ìròyìn míì tí ẹ lè nífẹ sí Duro Ladipọ, ìlúmọ̀ọ́ká òṣèré tíátà àti ọmọ àlúfà tí kò gbàgbé àṣà ìbílẹ̀ Hubert Ogunde rèé, baba àwọn òsèré tíátà Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Gẹgẹ bi iroyin ti o tẹwa lọwọ ti wi, ko si ẹmi kankan to padanu ninu iṣẹlẹ tuntun yi.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ọgọ́ta ẹ̀mí tún bá àdó olóró Adamawa lọ ‘Ó dáa ká jẹ òsìsẹ́ lówó ju ká lé wọn lọ’ Ìjọba Ọ̀sun ti OAU pa nítorí owó orí òsìsẹ́ Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
O ni gẹgẹ bii gomina, oun mọ iru ẹru to wa lori oun, nitori naa ni oun yoo ṣe ṣiṣẹ pẹlu ijọba apapọ lati ṣe iwadii bi ọrọ naa ṣe ṣẹ.
E jẹ ka ran ara wa leti nipa diẹ ninu wọn: Ọmọ Ọba Eko Adewale Oyekan: Ẹni aadọta ọdun ni ọmọọba Eko ana, Adewale Oyekan, ti o si gba idajọ iku lọdọ adajọ ile ẹjọ giga kan nilu Eko lori ẹsun pe o pa oniṣowo kan, Alhaja Sikirat Edun.
Ko ṣai mẹnu ba atunto ti Ijọba n muba gbogbo ohun ti Ijọba ana ti bajẹ ni Ipinlẹ naa bii gbigba owo ori lọwọ awọn ọmọ ile ẹkọ.
Ìsọ ̀ ngbè ọbalórìṣà nínú bíbọ Àgàdá ni àwọn olórí ọmọ ìlú .
lorile ede Naijiria, igbakeji aare orile ede Niajiria , ojogbon yemi osibanjo
"Ǹjẹ́ ẹ mọ ohun tí igbákejì ààrẹ Yemi Osinbajo sọ nílé bàbá Fasoranti Kògbérèégbè mẹ́ta nínú òṣèré Yorùbá Olórí Ọ̀dọ́ l'Ondo ní oníkálùkù yóò bẹ̀rẹ̀ sí ní jà fúnra wọn Àṣìta ìbọn pa èèyàn kan lásìkò tí SARS ń kojú adigunjalè l'Eko Ẹ wo bí ẹ ṣe lè ṣe ""hand sanitizer"" nínú ilé yín láàrín ìṣẹ́jú díẹ̀ Adaku ni awọn eeyan maa n sọ pe awọn ọmọ obinrin ti ko si nile ọkọ ko le yanju ṣugbọn Olorun ju ẹda lọ."
Ati pe ofin Sharia wa fun musulumi nikan ti o si gbọdọ tẹ́le e.
Jẹtiro bá rú ẹbọ sísun sí Ọlọrun.
 , tí ọ ̀ pọ ̀ sì sọ wípé àjọ náà ti kùnà níbi èrò tí wòn fi gbe kalẹ ̀ , tí wọ ́ n sì ri gẹ ́ gẹ ́ bí ọ ̀ bà ìfàkókò , ìfọ ̀ mọ nìyàn àti ohun àlùmọ ́ nì ìlú ṣòfò lásán àti bẹ ́ ẹ ̀ bẹ ́ ẹ ̀ lọ .
Jeroboamu ọba bẹ wolii náà pé, “Jọ̀wọ́, bẹ OLUWA Ọlọrun rẹ, kí o sì gbadura sí i pé kí ó wo apá mi sàn.
Bayi ti isunsiwaju yi ti waye, o ṣeeṣe ki ẹgbẹ naa ma palẹmọ gbogbo eto lori gbigbe asia ẹgbẹ fun Obaseki lati dupo Gomina naa labẹ orukọ ẹgbẹ wọn.
Èyí ni àyè fi sílẹ̀ láti lè rí wọn bá sùn bí wọn bá ń ṣiṣẹ́ fún wákàtí púpọ̀, láì jẹun tí ó ṣe ara ní oore, àti bẹ́ẹ̀ bẹ́ẹ̀ lọ.
Onyeari lati olu ile iṣẹ awọn ologun lati lọ se adele adari ẹka ounjẹ.
Ẹ̀yin ọmọbinrin Jerusalẹmu,mo dúdú lóòótọ́, ṣugbọn mo lẹ́wà,mo dàbí àgọ́ Kedari,mo rí bí aṣọ títa tí ó wà ní ààfin Solomoni.
Lojo Aiku nile ise ijoba embasi ile Amerika fi ikede sita pe won ko ni sise lojo Aje lataari idunkookomoni ti won ri gba.
International Day Against Drug Abuse and Trafficking: ìdí ti mo fi ń mu oògùn olóró
Kọmisọna ọlọpa fun ipinlẹ Ọyọ, Sina Olukọlu lo sisọ loju ọrọ yii lasiko to n bawọn akọroyin sepade ni olu ileesẹ ọlọpa to wa ni Ẹlẹyẹle nilu Ibadan.
Wo àdúgbò tó ń jẹ́ orúkọ èèbó amúnisìn tí yóò pa orúkọ dà l’Eko Biliọnia ni kanye West O ti to nnkan bi ọdun diẹ sẹyin ti West ti darapọ mọ awọn abulẹṣowo biliọnia nilẹ Amẹrika.
Ohun tó yẹ kẹ́ẹ mọ nípà olùdíje mèjì tó lágbára nínú ìdìbò Ghana rèé Omiyalé ní Ghana, èèyàn 28 dolóògbé!
Wo ìròyìn tuntun tó tún jáde laááàfin Oòduà nípa Àrẹ̀mọ tuntun Ọọ̀ni Ile Ifẹ̀ Oríṣun àwòrán, Olori Moronke Shilekunola Ogunwusi Iroyin lati aafin oodu ni ile Ifẹ ni yewa pe rẹpẹtẹ ni wẹjẹwẹmu n lọ laafin Kabiyesi Ọọni niluu ile Ifẹ lẹyin ibi Arẹmọ ile Oodua lowurọ Ọjọru.
Ninu atẹjade kan ti ileeṣẹ Ofcom fi lede, wọn ni ileeṣẹ amohunmaworan Loveworld ti gba pe wọn ko ni ṣe bẹ mọ.
Èṣù bá mú un lọ sí orí òkè kan, ó fi gbogbo ìjọba ayé hàn án ní ìṣẹ́jú kan.
Lizzy sọ èyí di mímọ lójú òpó Twiiter rẹ̀ pé ìdí ti òun fi jáde fẹ̀sì sí ọ̀rọ̀ náà nitóri ìrú ipò ti òun dìmú láwùjọ.
fi kun ọrọ rẹ pe, “ a ni ilana pe, ki a kọkọ fori kori pẹlu Gomina lati le mu
Oríṣun àwòrán, IRT Àkọlé àwòrán, Musa Umar lẹyin ti awọn ọlọpaa gba silẹ Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Ẹ rọ̀ mọ́ ara yín, kí ẹ sì kí ara yín pẹlu alaafia.
to  ba n ji owo ijọba , lati tu won ni
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Adúmáadán ni mí; ọmọ pé síbẹ̀!
Ohun tí ó bá fẹ́ gan-an ni yóo ṣe.
Àwọn náà pàápàá ń fẹ́ simi díẹ̀.
Láti ìgbà tí mo ti rí ìnáwó ọ̀rẹ́ mi yìí ni mo ti pinnu àtilọ.
Wo aṣọ òtútù tó wọ́n jùlọ ní àgbáyé!
Ẹ óo wá mọ̀ nígbà náà pé èmi ni OLUWA.
Emi ko ni pe se ayeye  ojo ibi mẹ́rìndínlọ́gọ́rin mi .
“Ṣugbọn òtítọ́ inú ni kí o máa fi bá àwọn ọmọ Basilai ará Gileadi lò.
Nítorí náà àwọn eniyan burúkú kò ní rí ìdáláre,bẹ́ẹ̀ ni àwọn ẹlẹ́ṣẹ̀ kò ní le wà ní àwùjọ àwọn olódodo.
Lẹyin to fẹhinti l'ọdun 1983, Akintọla Williams fi ara ji fun idasilẹ gbọngan fun iṣẹ orin kikọ ati ajọdun orin, MUSON Centre, to wa ni Onikan, nilu Eko Ijọba Naijiria fi ami ẹyẹ Officer of the Order of the Federal Republic, O.
Ilé jóná ní Òkè Àdó Ibadan, ọ̀pọ̀ dúkìá ṣòfò Ganduje Video - Ìwádìí ilé aṣòfin foríṣánpọ́n Ilé ẹjọ́ Kano: Ganduje kò lẹ́tọ̀ọ́ láti yan Emir Ninu awọn to kọwọrin ni ibi ipade yi la ti gbọ pe Oloye Mike Omoleye,Jibade Oyekan,Adegboye Onigbinde,Ọjọgbọn Adetoun Ogunsheye ati Sam Agbetuyi wa.
oun polongo lodun 2015 si se Pataki; oun yoo si mu gbigbogun ti iwa ibaje ni
Awọn eeyan naa ni awọn ọmọ igbimọ amusẹ ọhun ti tasẹ agẹrẹ pẹlu gbigbe awọn igbesẹ ti ko si ninu ojuse wọn, ti wọn ko si yẹ lati maa tukọ ẹgbẹ oselu naa mọ.
Oun lo si gba wọn ni imọran lati mu adiyẹ meji to jẹ kan naa wa a.
Ni ipari, ni ale oni, ifigabaga idije UEFA Champions League yoo tesiwaju leyin ti iko agbaboolu Liverpool yoo maa waako pelu Manchester City, beesini Barcelona FC yoo maa gbalejo AS Roma.
Botilẹ jẹ wi pe ko sọ boya ile ẹkọ naa ti fi aye gba lilo Hijab tabi bẹẹkọ, ọrọ rẹ kun fun arọwa si awọn obi lati mase fi aye gba ohunkohun ti o le da omi alafia ile ẹkọ naa ru, pẹlu alaye pek, ohun ti o tọ ni ifọwọsọwọpọ ti o le mu itẹsiwaju ba ile ẹkọ naa.
Orí àtẹ̀jíṣẹ́ ẹ̀rọ ayélujára rẹ̀ ló ti kéde pé, òun yọ ọwọ́ àti ẹsẹ̀ òun lẹ́yìn tó sọ pé, àwọn aláwọ dúdú kò lèe ronú láti ṣẹ̀dá ohunkohun.
 Àwọn ìdá mẹ ́ fà nínú ọgọ ́ rùn-ún àwọn ènìyàn tí ó ń gbé rọ ́ sía ni ó ń sọ èdè yìí .
Ọ̀gọ́rún sọ́ọ̀bù, àìmọye dúkìá ni iná tún jó lọ́jà Sabo nílùú Sagamu Ojora ń mú mi lọ́wọ́ lórí ìkọlù tó wáyé, ara mi kò tíì balẹ̀ - Toyosi Adesanya Bí Amẹrika bá dínà mọ́ Nàíjíríà láti wá sílẹ̀ wọn, ewu ń bẹ fún wa - Lai Muhammed Máṣe jẹ́ kí ibà Lassa pa ọ́, wo ọ̀nà láti dènà rẹ̀ Idajọ náà ti ile ẹjọ gíga ìpińlẹ Oyo gbe ìdájọ kalẹ pe awọn àlága àti minisita fun idájọ àti agbejoro àgbà fun ijọba apapọ Abubakar Malami, Isipẹtọ ọlọpàá Mohammed Abubaka, to fi mọ kọmisọna ọlọpàá ìpínlẹ Oyo Shina Olukolu àti alaga ẹgbẹ òṣèlú APC ọgbẹni Akin Oke lọ ki ọwọ́ ọmọ wọ́n bọ aṣọ.
Iye awọn ti o ṣẹṣẹ lugbadi arun Coronavirus lorileede Naijiria ti dikun sii pẹlu bi ajọ to n mojuto ajakalẹ arun NCDC ṣe kede pe eeyan 288 pere lo ko arun naa lọjọ Aje.
Akojọpọ awọn aworan ‘jẹẹsi’ Super Eagles naa ree: Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Super Eagles: Akojọpọ aworan asọ fun ife ẹyẹ agbaye Oríṣun àwòrán, Nike/Twitter Àkọlé àwòrán, Asọ tẹgbẹ Super Eagles wọ nibi idije ife yẹ agbaye lọdun 1994 jọ tdun 2018 Oríṣun àwòrán, Nike/Twitter Àkọlé àwòrán, Orilẹede Croatia, Argentina ati Iceland ni Super Eagles yoo koju ni igun kẹrin idije ife ẹyẹ agbaye Oríṣun àwòrán, Nike/Twitter Àkọlé àwòrán, Nike ni wọn se asọ ọhun lọna ti yoo fi mu ki ara awọn ọmọ Naijiria ya gaga ni Oríṣun àwòrán, Nike/Twitter Àkọlé àwòrán, Ilu London ni wọn ti safihan asọ tuntun naa faraye Oríṣun àwòrán, Nike/Twitter Àkọlé àwòrán, Nike ni awọn jẹẹsi tuntun yi ko ni si lori atẹ titi osu kẹfa ọdun 2018 Oríṣun àwòrán, Nike/Twitter Àkọlé àwòrán, Gbajugbaja akọrin takasufe, Wizkid gan tẹle wọn lọ sibi ayẹyẹ afihan jẹẹsi naa Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Ó ní: “OLUWA Ọlọrun Israẹli sọ fún ìwọ Baruku pé, 
tí ò ń bẹ̀ ẹ́ wò láràárọ̀,tí o sì ń dán an wò nígbà gbogbo?
Ajọ EFCC fi soju opó twitter wọn pe inawo ti pari bayii l'Ekiti ki Fayoṣe wa sọ bo ṣe na owo to le ni biliọnu kan Naira, 1.
"Obasanjo da a pada sipo lẹyin saa rẹ akọkọ, 'fun pe o ṣe daada""."
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù EFCC: Ilé ẹjọ́ rán ọmọ ìjọ lẹ́wọ̀n lórí ẹ̀sùn pé ó jí ₦15m owo ìjọ 15 Sẹ́rẹ́ 2020 Oríṣun àwòrán, EFCC/TWITTER Àkọlé àwòrán, Ilé ẹjọ́ rán ọmọ ìjọ lẹ́wọ̀n lórí ẹ̀sùn pé ó jí ₦ 15m owo ìjọ Akapo ijọ kan ti ri ẹwọn ọdun mejidinlogun he lẹyin ti wọn fi ẹsun kan an pe oji miliọnu mẹẹdọgbọn dọla ti o wa fun igbelarugẹ ijọ naa.
Àmì ohùn yìí yi bóbó lẹ́nu wọn OGÚN: Ogún yii naa tun tumọ si dukia tabi imọ ti a ri gba lati ọwọ ẹnikan.
Ẹ gbọdọ̀ pa àwọn òfin OLUWA Ọlọrun yín mọ́ dáradára, kí ẹ sì máa tẹ̀lé àwọn òfin ati àwọn ìlànà rẹ̀, tí ó fi lélẹ̀ fun yín.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Obinrin lo mu mi fẹran orin kikọ - Patoranking Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
" Á máa ṣíjú àánú wo ẹlẹ́wọ̀n láti mú àdínkù bá ọgbà ẹ̀wọ̀n - Ìjọba Ọyọ Toyin Abraham kìí bá èmi náà yọ̀, ni kò jẹ́ kí ń gbé e lárugẹ fún ayọ̀ ọmọ - Lizzy Anjorin Ọ̀pọ̀ èèyàn bẹnu ẹ̀tẹ́ lu Mercy Aigbe lórí bó ṣe ki Adeniyi Johnson Àjẹ́ àti Aṣẹ́wó ní ìyá Rainbow - Òjòpagogo N30,000 ni mo gbà fún orí, ọwọ́ àti ẹran ara wòlíì Bosede - Kayeefi Onilu ni, taa ba gbọ ohun ti Wadume sọ yii daada, a jẹ pe ọmọ ẹgbẹ APC ni yoo jẹ pẹlu awọn alaye to se.
Ọdun 2015 ni wọn kopa kẹyin ti wọn si ti de aṣekagba idije naa ti wọn ti gba ipo keji lẹẹmeji ọtọọtọ lọdun 1989 ati 2005.
Idi ree to fi sọ wi pe ẹrọ rẹdio lo yẹ ki ijọba fi maa polongo imọran nipa bi awọn eniyan ṣe le ṣọra lasiko ojo.
Ẹ hó ìhó ayọ̀, ẹ̀yin ọ̀run, nítorí OLUWA ti ṣe é.
ajayi kọ ifiyajẹni ni eyi to sọọ si oko ẹru.
Ṣadé dara pọ ̀ mọ ́ ilé iṣẹ ́ wabc ní ọdún 2003 lẹ ́ yìn tí ó ṣe díẹ ̀ ní ìlú abínibí rẹ ̀ baltimore , maryland , ní bi tí ó ti darí ètò ìròyìn lórí wbal-tv fún bí ọdún mẹ ́ ta .
kì í ṣe gbogbo ìgbà ni ìlà kan inú orin-ifá máa ń gbé èrò kan jáde .
Ki ṣe igba akọkọ niyii ti ọlọpaa Naijiria yoo pa ọmọ Naijiria laipẹ yii.
Komisona fun ilaniloye ati ise akanse ,Ogbeni Adelani Baderinwa lo soro yii nigba ti o n soju fun gomina ipinle Osun ogbeni Rauf Aregbesola , nibi ayeye ti eka to n mojuto igbaye –gbadun, idagbasoke  ati  ilaniloye ti ofiisi gomina se onigbonwo rẹ.
Àwọn tí Wọ́n Pada ti Oko Ẹrú Dé.
Ọjọ Ẹti ati Satide, ọjọ kẹsan-an ati ọjọ kẹwaa, oṣu Kẹwaa, ni ayẹyẹ igbeyawo naa waye nilu Ibadan.
Coronavirus: Agbábọ́ọ̀lù Manchester United, Paul Pogba ṣètò owó dídá fún coronavirus, ó tún jẹ́jẹ́ àtìlẹ́yìn
1 1789 Erekusu Channel 48 28.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Adebola Ademilua: Àìrísẹ́ ṣè lẹ́yìn ìwé kíkà ló sọ mi dí ìyá onírú, mo dúpẹ́ tèmi Awọn wo ni Hisbah?
Gẹ́gẹ́ bí ó ti wà ní àkọsílẹ̀ pé,“Ohun tí ojú kò ì tíì rí, tí etí kò ì tíì gbọ́,Ohun tí kò wá sí ọkàn ẹ̀dá kan rí,ni ohun tí Ọlọrun ti pèsè sílẹ̀ fún àwọn àyànfẹ́ rẹ̀.
Tọkọ taya kú lọ́jọ́ kan náà l'Abeokuta lẹ́yìn ìgbéyàwó ọdún méjìléláàdọ́rin 72 Remilekun Fatolu bú sẹ́kún fún ohun tó ti pàdánù láyé torí ọyàn ńla rẹ̀.
Kò sí ẹni tí òye yé,kò sí ẹni tí ó ń wá Ọlọrun.
Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Algeria country profile23 Ọ̀pẹ̀̀ 2019 President Hollande accepts French injustice in Algeria20 Ọ̀pẹ̀̀ 2012 Ruling FLN party wins Algeria parliamentary polls11 Èbibi 2012 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Ajọ to n gbogun ti ajakalẹ arun lorilẹ-ede Naijiria, NCDC lo fidi eyi mulẹ loju opo Twitter rẹ.
Koda, wọn ni niṣe ni awọn Boko Haram se awọn eniyan Kukawa mọ ile.
 Èdè ìṣèjọba Àkọtọ ́ rómáànù ni wọ ́ n lò láti kọ ọ ́ sílè .
 Ó kọ ́ kọ ́ gbá fún rugby union gẹ ́ gẹ ́ bí akẹ ́ kọ ̀ ní de la salle college ní churchtown .
Igbeyawo nilẹ Oodua jẹ laarin ẹbi ọkọ ati aya ni eyi ti ikọsilẹ ko fi ki n wọpọ nitori gbogbo ẹbi a fẹ ki igbeyawo naa ni ayọ.
Awọn ẹgbẹ agbabọọlu mẹrinlelogun to n ṣoju orilẹ-ede mẹrinlelogun ni yoo kopa ninu tọdun 2019.
    Lóòótọ́ náà, bí mo ti rò ó si ló bọ́ sí.
” Dokita Kyobutungi to jẹ adari ajọ African Population and Research Center (APHCR) sọ fun BBC pe o di dandan ki ẹnikẹni to ba fẹ dan abẹrẹ tabi oogun kankan wo wa ọna ilepa ilera to peye fun irufẹ ẹni to ba fẹ lo Ati pe igbesẹ loriṣirisi lo ti wa ti wọn gbọdọ tẹle ki wọn to le dan abẹrẹ tabi oogun naa wo lara enikeni nilẹ Adulawọ Ọpọ ọdun nilẹ Afrika ti ko si owo iranwọ to tó lati ṣe iṣẹ iwadii Airi owo to too na lati fi ṣe awọn iṣẹ iwadii ninu eto ilera jẹ ọkan lara awọn nkan to n mu iṣoro ba eto ilera Afirka.
JAMB: Ìgbésẹ̀ ti ń lọ lórí èsì ṣùgbọ́n kò tíì sí gbèdéke ọjọ́ tí yóò jáde
Wọn a máa sọ̀rọ̀ ẹ̀gàn sí ohun tí kò yé wọn.
Bí àpẹẹrẹ, bí ẹnìkan bá wọ àwùjọ yín, tí ó fi òrùka wúrà sọ́wọ́, tí ó wọ aṣọ tí ń dán, tí talaka kan náà bá wọlé tí ó wọ aṣọ tí ó dọ̀tí; 
Tẹ o ba gbagbe, ẹ o ranti pe igba akọkọ kọ niyii ti eto sogun-dogoji yoo gbajumọ ni Naijiria, ti ọpọlọpọ rẹ kii si pẹ to fi n kogba wọle lẹyin ti awọn eniyan ba ti ko obitibiti owo le e lori.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Cerebral Palsy: Ìyá Najeebah ní oyún oṣù mẹ́rin ààbọ ni wọn gbe jáde kúrò nínú òun O ni Mo fẹ gboriyin fun Deontay Wilder fun iṣe takuntakun to ṣe, o ja fitafita titi di abala keje ija ọhun, ṣugbọn ọba ti pada sori itẹ rẹ."
Wọn yóo sì wí pé, “Ẹ múra kí á bá a jagun;ẹ dìde kí á lè kọlù ú lọ́sàn-án gangan!
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù NDLEA: A kò tíì mọ àwọn tó ni Tramadol náà 18 Èbibi 2018 Oríṣun àwòrán, NDLEA/Twitter Àkọlé àwòrán, Àjọ NDLEA ti gbésèlé tọ́ọ̀nù mẹ́rin Tramadol Àjọ NDLEA ti gbésèlé tọ́ọ̀nù mẹ́rin Tramadol ní pápákọ̀ òfurufú Muritala Mohammed ìlú Èkó, bẹẹ ni ìjọba ṣẹ̀ṣẹ̀ pàṣẹ pé kò gbọdọ̀ sí lórí àtẹ mọ́, Ọ̀gá àgbà àjọ NDLEA, Ahmadu Garba ló sàlàyé ọ̀rọ̀ ọ̀hún, fún àwọn akọròyìn pé ọ̀nà méjì ni wọ́n gbé tramadol òhún gbà wọ inú ìlú láti orílẹ̀-èdè India, tí àwọn sì ríi gbà ní ibùdó ìkẹ̀rùsí ilé iṣẹ́ náà tó wà ní pápákọ̀ òfurufú ìlú Èkó.
Ọ̀fọ̀ ṣẹ̀ nílé agbábọọlu Ahmed Musa!
20 Ọ̀wàrà 2019 Oríṣun àwòrán, Inpho Àkọlé àwòrán, Marcus Rashford ló kọ́kọ́ gbá bọ́ọ́lù wọ inú àwọn fún Manchester United, kí Adam Lallana tó gbá bọ́ọ̀lù wọnú àwọ̀n fún Liverpool.
Johesu: Òsìsẹ́ ìlera ti bẹrẹ iyanselodi
Ní ilẹ̀ rẹ ní ibi tí a ti dá ọ, ni n óo ti dá ọ lẹ́jọ́.
ni won si tun n korin pe Bahir ti subu : “O ti subu”.
Ganiyat tó fi irin gbígbóná àti àdá ya ara ọmọ àbúrò ọkọ rẹ ti dèrò àgọ́ ọlọ́pàá l' Ogun
Marta Moreiras salaye pe oun ya aworan awọn baba to gbe ọmọ pọn sẹyin, ti oun si n gbe si oju popo ki awọn ero to n lọ, ati eyi to n bọ lee maa peju wo.
ninu ifesewonse kookan yala fun orile-ede tabi iko agbaboolu re PSG ko se ye
9 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Àwọn ọmọ Israẹli yóo ṣẹgun àwọn tí wọ́n kù ní Edomu, ati gbogbo orílẹ̀-èdè tí à ń fi orúkọ mi pè.
Gbogbo iroyin wa ni a maa n wadii daada ki a to gbe jade.
A óo yọ olúwarẹ̀ kúrò láàrin ọmọ Israẹli, nítorí kò fi omi ìwẹ̀nùmọ́ wẹ̀; ó sì jẹ́ aláìmọ́ sibẹ.
Tí ó bá béjì, ọ̀kan á dìso
Itamari ọmọ Aaroni alufaa ni yóo jẹ́ alabojuto wọn.
To fi mọ awọn mọlẹbi rẹ, ọrẹ ati awọn akẹgbẹ rẹ ninu fiimu Yoruba lo ni wọn ṣeun fun gbobo ẹbun, owo, ọrọ ti wọ́n fi ranṣẹ si oun ni ipo ti o wa.
To ba ti wa ninu idile kan, to jẹ wipe tẹẹ́ ba ṣa ọkunrin mẹwaa ninu idile, eeyan marun a pari ninu wọn, ẹ o ti mọ pe ajogunba ni.
Ènìyàn 653 míràn tún kún iye àwọn tó ní COVID-19 ní Nàìjíríà Àwọn àádọ́ta ọ̀dọ́ wọ gàù nítorí ilé ijó ní Ilorin Báwó ni òògùn dexamethasone ṣe ń ṣiṣẹ́ lára Èèyàn 789 gbèkuru jẹ lọ́wọ́ ẹbọra nítorí COVID-19 ní Nàìjíríà Ki lo ti ṣẹlẹ sẹyin?
Oríṣun àwòrán, OTHERS Àkọlé àwòrán, EFCC ń gbé ọ̀gá Pension tẹ́lẹ̀ lọ sÍ ilÉ ẹjọ́ fún ìwà ìbàjẹ́!
    Bẹ́ẹ̀ ni iwin náà bẹ̀rẹ̀ sí í wí tí ó ń wọ igbó kiri tí o ń kígbe pe orí ara rẹ̀, o n wo ìhìn, o ń wo ọ̀hún o ń wo òkè o ń wo odò, o ń wá wa kiri, olúkúlùkù pa lọ́lọ́, ẹnìkan kò gbọdọ gbin, ẹni wúkọ́ dáràn, ẹni yísẹ̀ padà gbé, ẹnikẹ́ni kò gbọdọ̀ sọ̀rọ̀ pínkín, ta ni baba tí ó bí olúwarẹ̀!
Tollgate Fee: Àwọn ọmọ Naijiria ní àsìkò sísan owó 'tollgate' kò tíì tó báyìí
Oríṣun àwòrán, EDO STATE POLICE COMMAND Fọto ọmọdekunrin naa nibi to joko si nilẹ ileeṣẹ ọlọpaa pẹlu aṣọ iṣẹ sajenti naa lọrun rẹ ti lu ori ayelujara pa ṣugbọn alukoro ileeṣẹ olopaa nipinlẹ Edo ni awọn ko ṣe afihan ọmọ ọdun mọkanla naa pẹlu awọn janduku ti wọn fihan lọjọbọ nitori ọjọ ori rẹ.
Super Eagles: Akojọpọ aworan asọ fun ife ẹyẹ agbaye Ikọ agbabọọlu Ọsun United kede awọn agbabọọlu tuntun Awọn agbabọọlu Super Falcons yoo waako ninu ifesewonse akọkọ ninu idije ife ẹyẹ WAFU, ikẹjo iru rẹ, pẹlu akẹgbẹ wọn lati orilẹẹde Benin lojọbo.
Ameh ni iṣẹ abẹ naa yẹ ko na awọn obi awọn ibeji naa ni ẹgbẹrun lọna marundinlogoji owo ilẹ okeere dọla $55,000 (£42,000).
Oyedele ni awokọṣe awujọ lo maa n jẹ iwuri lori nkan ti ohun ba fẹ ya pẹlu kalamu oun.
Aláìgbọ́n ènìyàn pátápátá gbáà ni, ìwà rẹ̀ sì dà bí ìwà ẹranko, bẹ́ẹ̀ ni ìrìn ẹsẹ̀ rẹ̀ dà bí ti àgùntàn ìdí rẹ̀ náà sì ni èyí tí gbogbo àwọn ará ìlú wa fi máa ń pè é ní Àgùntàn-ìnàkí, dọ̀ǹgíṣọlá ọkùnrin.
3bn Wòlíì èké 'John of God' tó bá obìnrin 300 lò pọ́ gba ìdájọ́ ẹ̀wọ̀n ọ́dún 19 Kìí ṣe olórí ọ̀dọ́ ẹgbẹ́ wa ló kú o, ọkọ̀ gb'ókìtì, ọ̀dọ́ kan gba 'bẹ̀ lọ - PDP Oyo Gbajue ń lọ orúkọ mi láti gba owó- Mama Rainbow Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Sotitobire church: Ẹgbẹ́ CAN ní kí ìjọba ṣe ohun tó yẹ Bayii ni wahala ṣe bẹ̀rẹ̀, nitori pé o hàn gbangba pé ẹnikan ti ji ọmọ gbé.
"Àlàbí ti fi ìgbà kan jẹ ́ ọ ̀ kan lára ọmọ ẹgbẹ ́ "" jesters international comedy group "" ."
Olólùfẹ́ méjì jábọ́ láti àjà kẹsàn án lásìkò tí wọ́n n ṣe kerewà Ẹ padà sílé èyin ọmọ wa tó n ṣiṣẹ́ darandaran - NEF ti Fulani Ǹjẹ́ ewu wà nínú lílò ẹ̀rọ FaceApp?
Aare  Muhammadu Buhari ti ni ipenija to n dojukọ
Ilá ọ̀hún sì yọ̀ bọ̀lọ̀-bọ̀lọ̀ gidi.
Gẹgẹ bi o ṣe sọ, nnkan ko fi bẹẹ rọgbọ latigba ti ọmọ rẹ ọkunrin ti ku.
Ki Olorun tu ẹbi Isiaka Jimoh ninu lo ku bayii.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Premiership league: Liverpool fẹ́rẹ̀ ẹ́ forígbá níwájú Southampton ṣùgbọ́n orí kó o yọ 17 Ògún 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Ẹgbẹ agbabọọlu Liverpool ṣi n tẹsiwaju ninu fifi agbara wọn han awọn ikọ agbabọọlu yooku pẹlu bi wọn ṣe na ikọ Southampton pẹlu ami ayo meji si ẹyọkan mọle.
Dafidi ṣí adé wúrà orí ọba wọn, ó sì rí i pé adé náà wọ̀n tó ìwọ̀n talẹnti wúrà kan, òkúta olówó iyebíye kan sì wà lára rẹ̀; wọ́n bá fi dé Dafidi lórí.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, George Floyd: Àwọn ọlọ́pàá darapọ̀ mọ́ àwọn olùwọ́de lórílẹ̀èdè Amẹ́ríkà Ọkan lara awọn agbẹjọrọ to fi fidio iwadii tuntun naa lede, lo n pe fun ki ijọba da ẹjọ ti wọn pe mọ Thomas Lane nu, nitori ko kopa ninu iṣekupani naa.
BBC Yoruba gbiyanju lati ba Minista feto ilera lorileede Naijiria sọrọ sugbọn ẹni to gbe ipe rẹ ni o wa ninu ipade kan.
Baálé baálé ni àwọn tí a ti dárúkọ wọnyi ninu ìdílé wọn, olórí ni wọ́n ninu ẹ̀yà Lefi, wọ́n ń gbé Jerusalẹmu.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Sogidi Lake: Kòṣẹja-kòṣèèyàn lá bá nínú adágún odò náà -Ojedele Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Agbẹnusọ ile isẹ ọlọpa ni ipinlẹ Ondo, Femi Joseph to fi idi isẹlẹ naa mulẹ fun BBC Yoruba sọ wi pe, isẹlẹ naa jẹ oun ibanujẹ fun awọn obi arabinrin to jẹ akẹẹkọ ipele asekagba (400 level) ni fasiti, ko to di wi pe o papoda.
Nigba to sọrọ lori igba to bẹrẹ ere Fuji, o ni lọdun 1983 iyẹn bi ọdun mẹtadinlogoji sẹyin loun bẹrẹ si ni maa ri owo nibi iṣẹ orin Fuji.
O so pe “Afurasi naa si wa ni ahamo iko omo ogun orile ede Naijiria nibi ti won ti n fi oro wa lenu wo, ki won to fi ranse si awon agbofinro.
Ẹwẹ, Aarẹ Muhammadu Buhari ti ṣalaye wi pe oun ati oloogbe Shehu Musa Yaradua ni awọn jọ joko ṣe idanwo aṣekagba girama ni ọdun 1961 nitori ni asiko kan naa ni awọn darapọ mọ iṣẹ ologun.
Èrò ọmọ Nàìjíríà ṣ'ọ̀tọ̀ọ̀tọ̀ lórí ọ̀rọ̀ Bíṣọ́ọ́bù Oyedepo pé kò sí ìdí tí iléèjọ́sìn láti wà ní títì pa Bisọọbu David Oyedepo, nínú ìsìn irọlẹ Ọjọru faraya lórí bí ìjọba àpapọ̀ ṣe ti ilẹkun mọ àwọn sọọsi àmọ́ tó ń sì àwọn ọjà oúnjẹ gbogbo fún wákàtí mẹ́fà gbáko, nibiti àwọn aráàlú kò ti bọ̀wọ̀ fún òfin títa kété síra ẹni.
Ọdun 1994 lo ku diẹ ki ikọ agbabọọlu Burundi yege lati kopa ninu idije ife ẹyẹ Adulawọ.
Bakan naa ni ijọba kede lọjọ Iṣẹgun pe oúnjẹ sísè yoo jẹ́ pinpin lojoojumọ fun awọn ọdọ bi ẹgbẹrun lọna ọgọrun.
Ko le ma a jo skelewu.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Òkú sùn nínú ìṣẹ̀lẹ̀ ìdigunjalè ní Ọ̀ffà Saraki bẹ Ọlọ́ffá wò lori ìkọ̀lú ọlọ́ṣà Ìkọlù Ọ̀ffà pa èèyàn mẹ́tàdínlógún — Ọlọ́pàá Kí ní ńǹkan tó ṣẹlẹ̀ ní Ọ́ffà Ìlú Ọ̀ffà ní ìpínlẹ̀ Kwara wárìrì lọ́jọ́bọ, tí kowéè ké láì ha, nítorí ìṣẹ̀lẹ̀ ìdigunjalè kan tó wáyé nílé ìfowópamọ́ márùn ún ọ̀tọ̀ọ̀tọ̀ ní ìlú náà.
Kí gan an ni ẹgbẹ́ NURTW ní ṣe pẹ̀lú òṣèlú Nàìjíríà?
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Iko BBC Yoruba tuntun Bi o tilẹ jẹ pe o se ni laanu pe, akoko amulo oju opo ayelujara taa wa yi, n faaye silẹ fun itankalẹ iroyin eke ti ko fẹsẹ mulẹ, eyi to ti mu ki alafo nla wa laarin awọn iroyin to jẹ otitọ ati awọn araalu.
Gẹgẹ bi adehun ti wọn ṣe, ẹgbẹ OIC pinnu lati maa gbe ohun to jẹ mọ ẹsin musulumi larugẹ lawọn orilẹede to jẹ ọmọ ẹgbẹ naa.
" Nigba to n salaye bi wọn ṣe na miliọnu lọna ọgọrin naira, Obasa ni ogun iyawo awọn asofin lo na owo ọhun lọ si ilu Dubai fun idanilekọọ kan.
Gẹgẹ bo ṣe sọ, ọjọ Iṣẹgun ni Akufo-Addo ba Aarẹ Muhammadu Buhari sọrọ lori ẹrọ ibanisọrọ, to si sọ pe tinu-tinu ni oun fi rawọ ẹbẹ fun bi awọn ọmọ orilẹ-ede oun kan ṣe wo ileeṣẹ aṣoju Naijiria ni Ghana.
Àwọn ọ̀dọ́ ẹ̀yà Hausa kan àtàwọn ọmọ ẹgbẹ́ òkùnkùn 'Awawa boys' da ìgboro Eko rú
'Mo ro pe o yẹ ko sọ fun mi, amọ mi o tun le da a l'ẹbi nitori pe o n gbiyanju lati daabo bo mi gẹgẹ bi ọmọde.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fọ́nrán ohùn, 'Igbe àwọn ọ̀dọ́ kọ́ ló mú wa pèsè iná l'Ondo' Ṣé Fulani daran-daran ni àwọn tó n jí ènìyàn gbé ní ìpínlẹ̀ Ondo?
 láàárín ọdún 1993 sí ọdún 1996 , àwọn tí wọ ́ n ń ṣe fíìmù yorùbá ti pọ ̀ sí .
Oríṣun àwòrán, Ogun State Governor's office Àkọlé àwòrán, Ọdọọdun la n rorogbo, ọdun ilu ti ilẹ Afirika ti ọdun yii tun soju ẹmi wa.
a ) ní ọdún 2010 , àti oyè ọ ̀ mọ ̀ wé ( phd ) ní ọdún 2016 nínú ìmọ ̀ eré orí ìtàgé  theatre arts "" ."
Ni ọsan ọjọ abamẹta ni wọn ji i gbe lasiko to wa ninu oko rẹ lopopona akurẹ si Ikẹrẹ Ekiti lati mojuto awọn alagbaro ti wọn n baa ṣiṣe.
Ní ọjọ́ kan ṣoṣo, yóo gé Israẹli lórí ati nírù.
Ninu atẹjade kan ti ileeṣẹ ọlọpaa fi sita latọdọ alukoro ileeṣẹ ọlọpaa ni ipinlẹ naa, ni eyi ti jẹyọ.
Ko si si ẹni meji to doju ọla Real Madrid bolẹ bikoṣe Angel di Maria, agbabọọlu rẹ nigbakan ri ṣugbọn to ti darapọ mọ PSG bayii.
Ọ̀mì ni ikọ memeji gba ni ipari abala akọkọ ifẹsẹwọnsẹ ọhun.
 Ó lo ipò rẹ ̀ bí olórí ìlú àti ọmọ odùduwà ní ìlú Àkúrẹ ́ .
Mo wá di ẹlẹ́yà lójú àwọn ọ̀rẹ́ mi,èmi tí mò ń ké pe Ọlọrun,tí ó sì ń dá mi lóhùn;èmi tí mo jẹ́ olódodo ati aláìlẹ́bi,mo wá di ẹlẹ́yà.
Wọn gbe okuta naa lọ si Bahrain, wọn si foote le iṣẹ Hajj fun ogun ọdun, to fi di igba ti ọkunrin alagbara kan, Abbadis san owo itanran ki wọn le da okuta naa pada 2) Ọrọ oṣelu fopin de Hajj fun ọdun mẹjọ Lọdun 983, A.
Awọn olukọ labẹ aṣia ẹgbẹ olukọni ileẹkọ giga gbogbonise lorilẹede Naijiria, ASUP lawọn ileẹkọ giga gbogboniṣe nipinlẹ Ọṣun gunle iyanṣẹlodi naa lati fi ẹhonu han lori aisan owo oṣu mejidinlogun ti ijọba jẹ wọn.
" Oke, to kẹkọọ nipa imọ nipa ẹrọ ayarabiasa, ni iroyin kan sọ pe ibọn ba nile rẹ to wa lopopona Paul, Mafoluku-Oshodi nilu Eko.
Ta ni Ọgágun àgbà Lamidi Adeosun tó ṣẹṣẹ gba ìgbága?
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Rex Tillerson: Amẹrika yoo ṣe'ranwọ owo tuntun fun Afirika 7 Ẹrẹ̀nà 2018 Oríṣun àwòrán, AFP Àkọlé àwòrán, Ọpọ n kọminu lori iroyin yii pẹlu bi Aarẹ Donald Trump kii se yee tẹnu mọọ wi pe ohun yoo din gbogbo owo ti orilẹede naa n na silẹ okeere ku Ẹẹdẹgbẹta o le ọgbọn ati mẹta miliọnu dollar owo ilẹ Amẹrika ni orilẹede Amẹrika ti la kalẹ lati gbogun ti iyan lorilẹede South Sudan, Somalia, Ethiopia ati awọn agbegbe adagun omi Chad.
Kí ni n óo mú wá fún OLUWA, tí n óo fi rẹ ara mi sílẹ̀ níwájú Ọlọrun, ẹni gíga?
Oríṣun àwòrán, Twitter/@WWE Àkọlé àwòrán, Ijankadi Ọpọ awọn ololufẹ ere idaraya ijakadi ni wọn sọ pe The Rock ti ọpọ ka kun alawọdudu akọkọ ti yoo gba ami ẹyẹ WWE kii ṣe alawọdudu.
Iléèṣẹ́ ológun kò tíì sọ nkankan lórí ọ̀rọ̀ yìí, bẹ́ẹ̀ni a kò sí tí ì rí wọn bá sọ̀rọ̀ títí di àsìkò tí a kó ìròyìn yíì jọ.
Dagunro dagbere faye pe o digbose Iku ti pa agbe, bii ẹni ti ko lee daro; iku ti pa aluko, bii ẹni ti ko lee kun osun; iku ti pa lekenleke, bii ẹni ti ko lee kun ẹfun.
Mo sọ fun yín pé yóo sàn fún Sodomu ní ọjọ́ ńlá náà jù fún ìlú náà lọ.
Ile-ise iroyin orile-ede Egypt ti o fi otito aworan naa mule so pe, bibi omo sinu omi ko je babara mo, ni paapaa laarin awon omo orile-ede Russia, ti won lo n bimo won sinu odo Dahab ti o wa ni apa ariwa ila-orun ilu Sharm el-Sheikh Ronke Osundiya.
Ipinlẹ Zamfara ti wọn tun ti fa eeyan silẹ, lọsẹ to kọja ni ile ẹjọ to ga ju lorilẹ-ede Naijiria ti wọgile gbogbo awọn oludije to jẹ ti APC nipinlẹ naa.
A ti fi epo pa á kí ó lè máa dán, kí ó sì máa kọ mànà bíi mànàmáná.
Ninu ipo ate tuntun ajo FIFA ti o se se jade, orile-ede Naijiria ti ja wale lati ipo mẹ́tàdínláàdọ́ta  si ipo méjídínláàdọ́ta lagbaye, bee si ni lati ipo kefa si ipo keje nile Afrika.
ti dana sun ile-ise ajọ naato wa ni ijoba ibilẹ 
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù #Revolution Now: Ara ló ń ta ìjọba àpapọ lórí ìfèhọnú hàn ní Naijiria 27 Ògún 2019 Àkọlé àwòrán, Comrade Sulaiman Adeniyi ti ni o lodi si ofin bi ijọba se n tako itusilẹ Ọmọyele Sowore to ti wa ni ahamọ DSS.
Àmì ìkìlọ̀ kan ń bẹ níbẹ̀ tó wípe “Ìwọ máṣẹ yà kúrò lójú ọ̀ná yìí títí tí ìwọ yó ṣe tọ igbó yìí já o!
Islam kọ́ ló ni kí ọmọ ọdún méjìlá lọ sílé ọkọ- Ààrẹ ilẹ̀ Niger Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Nigeria Independence Day: Wo ìlérí tí àwọn ènìyàn ṣe Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Ninu orin rẹ kan to n kaakiri lori ayelujara bayii, K1 ṣalaye pe ọrọ coronavirus yii ki ṣe ṣereṣere rara, gbogbo ọmọ Naijiria lo si gbọdọ gbaruku ti awọn alaṣẹ lati gbe awọn igbesẹ gbogbo to yẹ ni didẹkun arun naa.
Ni opin ọsẹ to kọja ni ajọ ilera agbaye, WHO ṣekilọ pe ọpọ awọn ilana eto ilera lawọn orilẹede Afirika ni ko duro deede lati koju ajakalẹ arun Coronavirus yii.
lasiko to n jiroro lori akori iwe to pe ni:’Iwa asiwaju nile Afirika ni awon Fafiti ilẹ
Akọsilẹ si fi ye ni pe, Efunsetan maa n ni to ẹgbẹrun meji ẹru to maa n ko lọ ta nilu Badagry loore koore, To si tun ni awọn ẹru to n ṣíṣẹ fun ninu ile, ti ẹru-binrin rẹ kankan ko si lori laya lati loyun, kiku ni onitọun yoo ku, lati ipasẹ ida.
OLUWA sọ fún un ní òru ọjọ́ kan náà pé, “Gbéra, lọ gbógun ti àgọ́ náà, nítorí pé mo ti fi lé ọ lọ́wọ́.
Má jẹ́ kí àwọn tí ń bá mi ṣọ̀tá láìnídìí yọ̀ mí,má sì jẹ́ kí àwọn tí ó kórìíra mi wò mí ní ìwò ẹ̀sín.
Mo nigbagbọ ninu atunto ilana iṣejọba lorilẹede Naijiria, mo ni igbagbọ ninu iṣọkan orilẹede Naijiria, mo si tun ni igbagbọ ninu eto iṣejọba tiwantiwa."
Akeugbagold sọ pé pásítọ̀ wà lára àwọn tó n san owó wáàsí òun
ni eto idibo, bi ki i se ihuwasi leyin idibo.
Àwọn àṣẹwádìí ọmọ orílẹ̀èdè Kenya pẹ̀lú àwọn kan láti ilé ẹ̀kọ́ fún ìsègùn ní ìlú Liverpool lórí àìsàn ibà tí ṣàwárí oògùn tí ó jẹ́ májèlé fáwọn ẹ̀fon tí wọ́n bá ti fẹnu kan ẹ̀jẹ̀ ènìyàn.
Amọ awọn oludibo to wa ni agbegbe Sulu nibi ti erekusu Jolo wa lodi si esi yi.
ti Ike Ekweremadu ti o je omo egbe oselu People’s Democratic Party, PDP  ni iye ibo mẹ́tàdínlógójì ( 37 ).
Atẹjade kan ti ileesẹ ọlọpaa naa fisita lowurọ ọjọ Satide ni awọn osisẹ awọn to wa lẹba titi nidojukọ agọ ọlọpaa Ikolaba ni awọn agbegbọn naa kọlu.
WAEC gbé èsì ìdánwò WASSCE jáde Orílẹ́-èdè 5 tí takọ-tabo kò gbọdọ̀ fẹnu ko ara wọn lẹ́nu Segun, Máàkì tóo ní kọ́ ni yóò ṣé atọ́nà oríire rẹ láyé Facebook gbégilé àwọn ojú òpó ayédèrú Iṣẹ iwadii yii gbero pe to ba maa fi di ọdun 2019, gbogbo ẹrọ ibanisọrọ ti awọn eeyan yoo maa lo ni UK a ti to biiliọnu meji le ni ọọdunrun pọun.
"Wọn sọ fun mi pe iṣẹ abẹ ni ọrọ ẹsẹ mi gba a.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Sunday Igboho: Ẹ fi Ògún búra fún wa láti jà fún ilẹ̀ Yorùbá láì gbé Amotekun sábẹ́ ìjọba Lẹyin eyi ni wọn wa fi biriki, iso ati paanu kọ ile naa eyi ti wọn ko wa lati oke okun, nibiti wọn n ko ọpọ ẹru pamọ si, eyi to wa nilu Badagry di oni olonii.
Nígbà tí Jesu gbọ́ pé wọ́n ti ju Johanu sẹ́wọ̀n, ó yẹra lọ sí Galili.
Abala keji saa eto ẹkọ naa yoo bẹrẹ lọjọ kọkanla osu kinni si ọjọ kẹsan-an osu kẹrin ọdun 2021.
 O ni asiko ti to ki egbe akoroyin bere igbese lori ati fi ofin maa de iru awon iroyin ti ko fesemule wonyii to n di ariyanjiyan ni ile igbimo asofin.
Ẹ kún fún àdúrà nítorí ìdájọ́ kóòtù àgbà lórí gómìnà l'Ọ́ṣun-APC Ọṣun Ogedengbe Agbógun Gbórò, Akọni tó ń dẹ́rù ba ikú.
 ni 2008 , egbe oloselu alawoewe orile-ede amerika pe mckinney fun ipo aare orile-ede amerika ninu idiboyan igba na .
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ọmọ tuntun káàbọ̀ Bakan naa ni wọn gba awọn baale ati ẹbi alaboyun nimọran lati maa ṣe iranlọwọ fun wọn lai daamu ọkan alaboyun.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Obinrin Akansẹ: Ẹsẹ kiku bi ojo kọ mi lati di alagbara Wọn ti tumọ ninu awọn iwe wọnyii si ede oyinbo ki awọn ti ko gbọ ede Yoruba naa le maa ka wọn ni akagbadun.
 Àkóràn yíì ni kokoro rna ti gẹ ́ nùsì  flavivirus "" ."
O ni bi i ẹgbẹrun meji eeyan pere lo ṣeeṣe ki wọn gba lẹyin gbogbo ayẹwo naa, bo tilẹ jẹ pe ọgọọrọ awọn eeyan lo forukọ silẹ nitori aisi iṣẹ lorilẹede yii.
"Adari ẹka iroyin ni fasiti AAUA, Victor Akinpelu tẹnu mọ pe ile iwe ti gbe igbesẹ lori iṣẹlẹ na bi o tilẹ jẹ pe ""ọmọbinrin naa ko tii wa fi ẹjọ sun awọn alaṣẹ ile iwe lọna to tọ""."
Oríṣun àwòrán, Instagram/adedimejilateef Àkọlé àwòrán, Ìgbà akọkọ kọ niyii ti aworan igbeyawo ti jade nipa awọn mejeeji O ni tako nkan ti awọn eeyan ma n sọ pe oun ma n ṣere bi Odunlade Adekola, Adedimeji sọ pe eyi gan-an lo jẹ wahala fun oun nigba ti oun ṣẹṣẹ bẹrẹ ere ṣiṣe.
Ègún ni fún arẹ́nijẹ; tí ó jẹ́jẹ̀ẹ́ akọ ẹran láti inú agbo rẹ̀, ṣugbọn tí ó fi ẹran tí ó ní àbùkù rúbọ sí OLUWA.
Oríṣun àwòrán, @justempower Lọwọlọwọ bayii, o seese ki erekusu Tarkwa Bay, ti ọpọ eeyan maa n lọ lati gbafẹ lee ma si mọ nitori isẹlẹ to waye yii.
39 bn Ileeṣẹ ijọba to n risi eto ẹkọ (owo iranwọ fun awọn akẹkọọ labẹlẹ ati loke okun) - N545.
Bakan naa ni ijọba apapọ fi iroyin lede loju opo Twitter rẹ́ nipa abọ ipade wọn ọhun nibiti wọn ti fẹnuko pe ki awọn gomina to wa lẹkun iwọ oorun Naijiria, lọ gbe ofin kalẹ nipinlẹ koowa wọn lati se atilẹyin fun eto Amotekun labẹ ofin.
Ìwà Jẹgúdújẹrá ní Naijiria kò gba òjú bọ̀ọ̀rọ̀ - Aarẹ Buhari Taló pa olórí àwọn ''One Million Boys'' Ebila n'Ibadan?
mọlẹ ati awon iwa ibaje miiran.
Igba ti ọkunrin naa wọle sinu sọọsi lo ba aburo mi ninu agbara ẹjẹ, ki wọn o to sare gbe lọ sileewosan aladani, sugbọn ileewosan ikọsẹ isegun Fasiti ilu Benin lo pada ku si.
Lati igba ti iwọde End SARS ti bẹrẹ, gbogbo awọn ilu nla nla ni Naijiria lo ti ni imọlara iwọde naa, lara awọn ilu nla nla ti iwọde naa ti milẹ titi ni Eko, Abuja, Osogbo, Ibadan, Ilorin, Ado Ekiti, Abeokuta ati bẹebẹẹ lọ.
egbe APC nile igbimo asofin ati fun ipo gomina lojo kerindinlogun osu keji yii
ogun olote Islam, ti won n pe ara won ni Islamic State of West Africa Province
“Ẹ lọ wádìí wò bí ó bá ṣẹlẹ̀ rí kí wọ́n tó bí yín, láti ọjọ́ tí Ọlọrun ti dá eniyan, ẹ wádìí káàkiri jákèjádò gbogbo àgbáyé bóyá irú nǹkan ńlá báyìí ṣẹlẹ̀ rí, tabi wọ́n pa á nítàn rí.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Wo bí o ṣe leè ṣe ìjìnàsíraẹni ní ibiṣẹ́ lásìkò Coronavirus yìí Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Awọn agbalagba at'awọn olutọju wọn ni yoo kọkọ lanfaani lati gbabẹrẹ yii, lẹyin naa lawọn to ti le lọgọrin ọdun at'awọn oṣiṣẹ eleto ilera yoo gbabẹrẹ ọhún.
“Nítorí náà, gbogbo ẹni tí ó bá gbọ́ ọ̀rọ̀ mi yìí, tí ó bá fi ṣe ìwà hù dàbí ọlọ́gbọ́n eniyan kan, tí ó kọ́ ilé rẹ̀ sórí àpáta.
ayelujara ajọ eleto idibo INEC , asiko ti bọ mọ wọn lọwọ.
O ni mejeeji yoo ran ara wọn lọwọ lati kapa aarun naa.
Ìṣe Rẹ, Ìwọ ló yé o; Ògo Rẹ, é dibàjẹ́
Abẹwo akọroyin BBC si mọṣalaaṣi apapọ Naijiria nilu Abuja fihan pe, paro-paro lo da a.
Nibi ti ọrọ de duro bayii, bo tilẹ jẹ pe ilẹ Gẹẹsi ti yapa kuro ni ajọ EU, ọpọ ohun bii eto ọrọ aje, ifọwọsowọpọ lori eto abo, atawọn ọrọ mii lo ṣi wa nilẹ ti wọn ko tii yanju.
ninu igbo kan ni agbagbe ekun ila Gusu Mbeya .
Wọ́n ń la ilẹ̀ ìṣòro ati wahala kọjá.
Lẹ́yìn náà ẹ lè wọlé tọ̀ ọ́, kí ẹ sì di tọkọtaya.
Sùgban ọ̀pọ̀ ni ko gbà pé Laycon ló jẹ̀bi nínú ọ̀rọ̀ yìí, wọ́n ni gbogbo ìkìlọ̀ ti Erica ti gba jẹ́ èyi ti kò bá má wáye, tó ba jẹ́ pé kò ni ìbáṣepọ̀ pẹ̀lú Kiddwaya ni.
Ṣugbọn n kò ní káwọ́ ìfẹ́ ńlá mi kúrò lára rẹ̀, bí mo ti ká a kúrò lára Saulu, tí mo sì yọ ọ́ lóyè, kí n tó fi í jọba.
Irufẹ isẹlẹ bayii si le waye ni orisi ọna meji eyi to nii se pẹlu iwa amọọmọ se latọdọ awọn osisẹ eleto ilera, olugbẹbi alaboyu tabi dokita.
Ẹsita bá ranṣẹ sí Modekai, ó ní, 
Ọ̀kan ninu àwọn ọmọ ogun Joabu dúró ti òkú Amasa, ó sì ń kígbe pé, “Kí ẹnikẹ́ni tí ó bá ń ṣe ti Joabu ati ti Dafidi tẹ̀lé Joabu.
O salaye pe, “a niloo ifowosowopo latodo eka aladani, laisi ajosepo to dan monran nnkan ko le lo deedee”.
Ṣugbọn Jesu yipada, ó sọ fún Peteru pé, “Kó ara rẹ̀ kúrò níwájú mi, Satani.
Kí ló wá dé tí n óo ṣe fi ìyókù gbẹ́ ère kí n máa bọ ọ́?
”’Aare Buhari tun gbosuba fun awon ijo naa nipa ipinnu won lati da ile-ise , ile-iwe  ati ile-iwosan sile lorile ede Naijiria.
Bio tile je pe, iko agbaboolu Chelsea gbiyanju lati da ami-ayo naa pada ni saa keji ifigagbaga naa, sugbon omi poju oka lo.
Awọn ologun naa wa lara awọn to n dola ẹmi awọn ara ilu.
Codeine: Ijọba àpapọ̀, ilé ìgbìmọ̀ aṣofin gbé ìgbésẹ̀ akin Oríṣun àwòrán, Frankieleon Àkọlé àwòrán, òpin dé bá lílo oògùn ikọ́ olómi Codeine àti Tramadol Ijọba àpapọ̀ fòfin de títà àti rírà tramadol àti oògùn ikọ́ olómi to ni codeine Lẹ́yìn ti BBC gbe fidio jade ti o fi ṣàfihàn ewu ńlá to wa ninu mímu àpọ̀jù iru oògùn ikọ́ báyìí ni òfin jáde lórí rẹ̀.
 Ọba Adeyemi ni Gẹgẹ bi olori gbogbo awọn Ọba ilẹ Yoruba, mo maa sa ipa mi lati gbe ede, aṣa ati iṣe Yoruba leke, nitori o dabi pe o ti n di ohun igbagbe.
Àwọn ọmọ ogun tí wọn ń fi ẹsẹ̀ rìn, tí wọ́n sì ń lo idà, tí wọ́n kó ara wọn jọ níbẹ̀ tàwọn ti idà lọ́wọ́ wọn jẹ́ ogún ọ̀kẹ́ (400,000).
Olukuluku àwọn ìlú yìí ní pápá ìdaran tí ó yí i ká, bẹ́ẹ̀ náà ni gbogbo àwọn ìlú yòókù.
Ara àwọn ọrẹ rẹ̀ tún ni: àwo kòtò kan tí wọ́n fi wúrà ṣe, tí ìwọ̀n rẹ̀ jẹ́ ṣekeli mẹ́wàá, tí ó sì kún fún turari.
N óo run àwọn ère oriṣa Aṣera láàrin yín, n óo sì run àwọn ìlú yín.
Iroyin sọ pe eniyan kan ti padanu ẹmi rẹ, ti ọpọ eniyan si tun farapa.
itoju oju ati eya ara yooku, awon obi ati alagbato ati awon oluko naa yoo nimo
Àìkún ojú ìwọ̀n INEC ló ń fa ìdìbò tí kò yanjú láwọn ìpínlẹ̀ kan-Fawẹhinmi Háà!
lára awọn akitiyan lati dènà àìsàn naa ni kí àǹfààní sí omi mímọ ́ gaara gbèrù sí i , kí wọn sì dín iye awọn tó ní àìsàn naa kú nípa títọ ́ jú wọn pẹlu àwọn òògùn-apakòkòrò .
Orúkọ ìyá rẹ̀ ni Meṣulemeti ọmọ Harusi ará Jotiba.
" Bakan naa lo fi kun un pe bi ọrọ ṣe ri yii, ẹsẹ ofin ni awọn yoo tọ lori ọrọ naa.
December 12 - 13, 2014 Ẹ̀sùn kàn pé ilé iṣẹ́ ológun Nàìjíríà pa ǹkan bíi ọ̀ọ́dúnrún ẹlẹ́sìn Shia wọ́n sì bo òkú wọn mọ́lẹ̀.
Ẹnu eniyan yoo maa run: omi dara pupọ lati pese itọ, bakan naa ni o maa n ṣan awọn kokoro aigojuri inu ẹnu si isalẹ, eyi si maa n jẹ ki eniyan ni eyin ati erigi to ji pepe.
Mo wí fún OLUWA pé, “Ìwọ ni Ọlọrun mi.
Ọọni ti Ile-Ifẹ, Oba Adeyeye Enitan Ogunwusi, ti kesi Ajọ to n gbogun ti iwa ibajẹ lorilẹede Naijiria, EFCC pe ki wọn se atunse lori awọn ọna ti wọn n gba gbogun ti iwa ọdaran lawujọ.
Maradona gba ami ẹyẹ pẹlu oriṣiiriṣii ẹgbẹ agbabọọlu lorilẹede Argentina, Italy ati Spain.
Balogun tẹlẹ fun ikọ agbabọọlu Super Eagles , Joseph Yobo ti fọwọ sọya pe didun lọ̀san yoo so fun ikọ agbabọọlu ilẹ wa naa.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Làá hàn mí: Ètò yìí ló ń kìlọ̀ fún wa láti mú ìmọ́tótó ní pàtàkì láti dènà Coronavirus Fun apẹrẹ wọn ni ki a maa jinna si ara wa nitori kokoro arun yii, ṣugbọn nibi ti wọn ti n sọ ọ gan ni mo ti n ri awọn minisita ti wọn n joko sun mọ ara wọn pẹkipẹki."
 E fi ise naa sile fun awon ti o n se e.
Kola Shittu ní ìdájọ ilé ẹjọ kàn sí wà n'ilẹ eléyìí tó fòfin dè èyíkéyìí Gómìnà tó bá fẹ yọ àwọn alága ìjọba ìbílẹ̀ tàbí jáwé lọ rọọkun nílé fún wọ́n.
Ohùn kan bi í pé, “Elija, kí ni ò ń ṣe níhìn-ín?
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù AFCON: Amuneke lọmọ Nàìjíríà kejì tó gbé orílẹ́èdè míì lọ sí ìdíje ilẹ̀ Afirika 25 Ẹrẹ̀nà 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Awọn agbabọọlu Naijiria Akọnimọọgba Emmanuel Amuneke ti di ọmọ orilẹede Naijiria keji to ṣagbatẹru bi ẹgbẹ agbabọọlu ilẹ okere ti pegede fun idije AFCON.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Kakaki 1: Àwọn òbí mi rí iṣẹ́ orin bí iṣẹ́ alágbe Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Kakaki 1: Àwọn òbí mi rí iṣẹ́ orin bí iṣẹ́ alágbe 18 Òkùdu 2019 Peter Olatunde Adeshile ti inagijẹ rẹ lori itage orin jẹ Kakaki 1 afunfere to n da awọn ọmọ Naijiria lara ya loke okun.
Iroyin naa ni ibi ti aarẹ naa ti n dahun ibeere lo ti kọkọ daku gbọnrangandan ki o to di pe o gba ibẹ re ọrun alakeji.
Nítorí ẹnu yà á ati gbogbo àwọn tí ó wà lọ́dọ̀ rẹ̀ fún ọpọlọpọ ẹja tí wọ́n rí pa.
àwọn alatilẹyin Liverpool yóò gbè lẹyìn Man Utd 24 Ìgbé 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 25 Ìgbé 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Lalẹ oni, nkan ti ko fẹ ṣẹlẹri lagbo ere boolu Premiership yoo ṣẹlẹ.
"Ajọ naa sọ lọjọ Aje to kọja pe ""awọn ọmọ ilẹ Afrika lẹtọọ lati lo oogun ti iwadii nipa rẹ wa ni ibamu pẹlu awọn eeyan to ku ni agbaye""."
Debora ati Baraki ọmọ Abinoamu bá kọrin ní ọjọ́ náà pé:
Irọlẹ oni ọjọ Aje si ni wọn yoo fi iyoku ara Baba Legba fun ilẹ nile rẹ nilu Abeokuta nilana ẹsin Musulumi.
Ọ̀nà titun kan ti balẹ̀ wàyí o!
Ó ṣeésẹ kí ọkùnrin tó n mu àmujù ọtí ó maa lo ìwà ipá pẹ̀lú ìyàwó rẹ̀ Irú kí lèyì!
Bashir Ahmad, ẹni ti o jẹ oludamọran fun aare Muhammadu Buhari lori ọrọ ẹrọ ayelujara, lo fi ọrọ naa lede lori opo Twitter rẹ.
Àwọn ọmọ Juda bá àwọn ọmọ Simeoni, arakunrin wọn, lọ sí ilẹ̀ àwọn ará Kenaani tí wọ́n ń gbé Sefati.
“A gba ilẹ̀ náà lọ́wọ́ àwọn ọba Amori mejeeji tí wọ́n wà ní òkè odò Jọdani nígbà náà.
“Tí ẹ bá yá ẹnìkejì yín ní nǹkankan, ẹ kò gbọdọ̀ wọ ilé rẹ̀ lọ láti wá ohun tí yóo fi dógò.
Lónìí, mò ń sọ̀rọ̀ ní ohùn ìrara nípa àwọn ará Tibet ní kíkankíkan àti ìwúrí ọlọ́pẹ́ tí ìdánimọ̀ọ mi gẹ́gẹ́ bí ọmọ Tibet fún mi.
Bakan naa ni itan yii tun kọ wa pe, ohun aye yoo ba aye lọ, ka mase ko ọrọ aye le aya tabi ji owo ilu nitori ko si ohun ta mu wa saye, ko si ohun ta mu lọ.
Akowe agba lorile-ede Naijiria, Boss Mustapha so eyi di mimo, nibi ipade apero igbimo lori oro aarun kogbogun AIDS elekerin iru re, ti o waye nilu Abuja.
Awọn akọroyin lorilede Naijira n koju oniruuru ipenija gẹgẹ ọkan lara awọn to n lewaju lati koju aarun coronavirus ti wọn si n ṣiṣẹ ni yara ikoroyin jọ lojoojumọ.
Ẹwẹ, DCP Tunji Disu sọ loju opo Twitter rẹ pe ko si eniyan kankan labẹ ẹru tabi awọn ọkọ naa.
Awọn iroyin ti ẹ lee nifẹẹ si: Kini 'pen' lede Yoruba?
"Àwọn ọlọ́pàá mú ẹnìkan níṣojú mi, mí ò si le sọ bóyá ẹnikẹ́ni fi ara pa.
Ọjà ti wọn ti n ta igbó di ṣiṣi ni oru Ọjọru, bo tilẹ jẹ wi pe awọn araalu ko ti i mọ ipa ti yoo ni lori ilera, ofin ati aabo ilu.
 O ni ki won rora maa lo ipo won ati agbara oro ati kalamu ti won fi n kowe nitori idagbasoke ati isokan Naijiria lo ye ko je gbogbo akoroyin logun.
    ẹni tí àwọn ọmọ ọba ń fẹ́ láti fẹ́ ni èyí.
Ẹ ṣọ́ra fún ìròyìn ẹlẹ́jẹ̀ lórí ètò ààbò - Ọlọ́pàá N3.
Ìwọ́de Shiite: Ọwọ́ ọlọ́pàá tẹ ogójì ọmọ ẹgbẹ́ Shiite lẹ́yìn ìwọ́de
Àwọn Ilé Meji Tí Wọ́n Wà ní Ẹ̀gbẹ́ Tẹmpili náà.
Ninu atẹjade kan ti Frank Mba fi sita lorukọ ọga agba ọlọpaa, o ni Sunday Shodipe jẹ afurasi ninu ipaniyan to waye nijọba ibilẹ Akinyele.
Wọ́n fi àwọn òmùgọ̀ sí ipò gíga, nígbà tí àwọn ọlọ́rọ̀ wà ní ipò tí ó rẹlẹ̀.
Ṣé èmi a máa jẹ ẹran akọ mààlúù?
Onírúurú ewéko ni ó wà lójú ọ̀nà, àti èyí tí ó dára àti èyí ti kò dára, ọ̀kẹ́ àìmọye àwọn igi ẹlẹ́gùn-ún ni wọ́n sì ń dí ènìyàn lọ́nà bí ènìyàn bá ti ń kọjá lọ bẹ́ẹ̀ ni àwọn alákọrí ìpàǹtí gbogbo ni wọ́n ń dìmọ̀mlù pẹ̀lú àwọn oníjàngbọ̀n itàkùn ti wọ́n ń lọ́ mọ́ onírúurú igi, àwọn ẹranko pàápàá kò tilẹ̀ jẹ́ kí ènìyàn simi, àwọn ìjímèrè àti ìnàkí àti àwọn ọ̀bọ tí ìrù wọn gùn gbọ̀ọ̀rọ̀ ni wọ́n ń ti orí igi dé orí igi, ojú wọn sì fi ara wé ti ènìyàn bẹ́ẹ̀ náà sì ni ọmọ ìka ọwọ́ wọn.
Ẹ kò mọ̀ pé ìwúkàrà díẹ̀ ni ó ń mú burẹdi wú sókè?
Ọjọ́ ti pẹ́ nísisì yìí tí mo ti ń gbúròó rẹ, mo sì ti ń ṣe àníyàn ki n lè mọ̀ ọ́ ṣùgbọ́n a kò bá ara wa pàdé.
Àwọn olórí ogun náà gbọ́ àṣẹ tí Jehoiada, alufaa, pa fún wọn, wọ́n sì kó àwọn ọmọ ogun wọn, tí wọ́n ṣíwọ́ iṣẹ́ ní ọjọ́ ìsinmi ati àwọn tí wọn yóo wọ iṣẹ́ wá sí ọ̀dọ̀ rẹ̀.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Risikat Moromoke Azeez: Inú èmí àti Òbí mi dùn nígbà ti Risi bí ọmọ olójú búlù- Wasiu Ko tan sibẹ o, ele tun ba owo tijọba n ra koko lọwọ awọn agbẹ, to si tun ṣe atunṣe awọn oju popo to wọ abule kọọkan.
Pupo awon olugbe agbegbe ohun dupe pupo lowo Aare fun akitiyan re lati ri awon omode-binrin naa gba pada, ni eyi ti won ro Aare oun lati mase kaare nipa gbigba awon yoku ti won si wa nigbeku awon omo-ogun olote naa.
O wa ro awon omo ipinle naa, ti won lee dibo lati jade wa dibo won fun
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Obasanjo: Àwọn èèyàn ìpínlẹ̀ Ogun ní iṣẹ́ ṣì pọ̀ fún Ọbasanjọ láti ṣe fún mẹ̀kúnù Nàìjírìà Háà, Coronavirus ba ọjọ́ ìbí mi jẹ́ tán, díẹ̀ ló kù, mo yára ṣàtúnṣe sí i - Obasanjo Ààrẹ Naijiria àná, Olusegun Obasanjo ti ní àrun Coronavirus ló jẹ́ kí àtúnṣe débá ètò ayẹyẹ ọjọ́ ìbí rẹ̀ tó wáyé ní Abeokuta.
Nigba ti Yari n ba awon akoroyin ile aare soro leyin ipade ti o se pelu adele aare Yemi Osinbajo tan, tun so pe igbese ti ajo EFCC gbe yii “ko ba ofin mu nitori pe bi igba ti eniyan da oju ijoba bolẹ ni.
 tí a ṣàkọsílẹ ̀ lọ ́ wọ Àjọ Ìlera Àgbayé gẹ ́ gẹ ́ bí àrùn tí a gbàgbé ti ipa ọ ̀ nà oorùn .
 Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí 2 sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 2:23 Fídíò, Water Generator: Ó leè ṣiṣẹ fún wákàtí mẹfà, kó tó sinmi, Duration 2,2310 Òkùdu 2020 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn."
Ninu àpótí yìí ni apẹ wúrà kékeré kan wà tí wọ́n fi mana sí ninu, ati ọ̀pá Aaroni tí ó rúwé nígbà kan rí, ati àwọn wàláà òkúta tí a kọ òfin mẹ́wàá sí.
Ajo eleto idibo lorile ede Naijiria ,(INEC) ti kede Kayode Fayemi, oludije labe egbe oselu (APC),  gege bi gomina to jawe olubori ninu eto idibo to waye lojo Abameta.
Ao si fi atẹjade sita laipẹ.
Sugbọn, lati bi ọdun melo kan si asiko yii, awuyewuye n wa lori àwọ eefin naa.
Àwọn kan ń fi ìfẹ́ waasu Kristi nítorí wọ́n mọ̀ pé nítorí ti ọ̀rọ̀ ìyìn rere ni wọ́n ṣe sọ mí sẹ́wọ̀n.
Kò sí alaafia fún àwọn eniyan burúkú.
N óo rán ọ lọ sí Ijipti.
Aarẹ Obasanjo ni asiko to n se ayẹyẹ ọdun kejilelogun ni ilu abeokuta sọ wi pe ko si ija laaarin oun ati Aarẹ Muhammadu Buhari.
"A ń fikunlukun pẹ̀lú FBI láti mú àwọn ""Yahoo Boys"" tó kù- EFCC Amẹ́rika dá akẹ́kọ̀ọ́ padá nítori Facebook Ṣé àwọn ọmọ rẹ lè sọ Yorùbá tó àwọn ọmọ Amẹrika yìí?"
Àwọtẹ́lẹ̀ ọkùnrin àti Ìdọ̀tí Kilo méje ṣekú pa Ìgalà Ẹ wo iye t'óúnjẹ dà báyìí lọ́jà lẹ́yìn tí ìjọba ti ibodè Ẹ̀wọ̀n oṣù mẹ́ta àti #3,000 ni awakọ̀ tí kò bá ní ‘speed limiter’ yóò fi jura- FRSC Missing Child: Òbí àti asọ́nà ṣọ́ọ̀ṣì 14, lọ́ búra nì'dí imọlẹ̀ l'Akure Èyí tí a wò jùlọ 5:03 Fídíò, Omolola Arohunmolase Welder: Mo ti fí iṣẹ́ 'Welder' gbayì láwùjọ, tó mo fi tọ́ ọmọ yanjú, Duration 5,039 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 5:39 Fídíò, Akomolede ati Asa lori BBC: Olùkọ́ Kikelomo Ogunboye tan ìmọ́lẹ̀ sí ìwà olè ọ̀gá ọlọ́pàá Audu gẹ́gẹ́ bí àwòkọ́ṣe àsìkò yìí, Duration 5,398 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 4:11 Fídíò, Oba Adeyeye Ogunwusi: Ojú mi ti rí lọ́pọ̀ lọpọ̀, ọ̀pọ̀ èèyàn ni kò tilẹ̀ gbàgbọ́ pé mo lè jọba- Ooni, Duration 4,117 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 4:43 Fídíò, Promise Akinlade: ọmọ ọdún mọ́kànlá tó ń fi ìlù dárà bíi àgbàlagbà sọ̀rọ̀ nípa tálẹ́ǹtì rẹ̀, Duration 4,437 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 0:59 Gbọ́, Ìsẹ̀lẹ̀ jákèjádò orílẹ̀èdè àgbáyé láàárín ìṣẹ́jú kan, Duration 0,59wákàtí 6 sẹ́yìn 7:03 Fídíò, Olumuyiwa Bolade Adedeji Military Bruitality: Bí arákùnrin onípèníjà ara tí sọ́jà lù ṣe dé, Duration 7,035 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 4:45 Fídíò, Yoruba Films: Ẹ̀ẹ́ bẹ̀ mi kúrò láyé ni, mi ò lè kú - Fadeyi Oloro, Duration 4,4526 Èrèlè 2020 2:48 Fídíò, Esther Ajayi: Èmi náà ti borí ìṣòro rí ló ń mu mi ṣojú àánú, Duration 2,481 Ògún 2019 6:08 Fídíò, Adebola Ademilua: Àìrísẹ́ ṣè lẹ́yìn ìwé kíkà ló sọ mi dí ìyá onírú, mo dúpẹ́ tèmi, Duration 6,0827 Bélú 2020 5:55 Fídíò, Soyinka Cancer: Àṣe ara mi ni iso ti n run gbogbo bí mo ṣe n ṣèrànwọ́ lórí jẹjẹrẹ, Duration 5,5527 Bélú 2019 BBC News, Yorùbá Ìdí tí ẹ fi le è nígbàagbọ́ nínú ìròyìn BBC Ìlànà Lílò Nípa BBC Òfin Àṣírí Cookies Kàn sí.
”Ṣugbọn Adadi dá a lóhùn pé, “Ṣá jẹ́ kí n máa lọ.
owo ti o le die ni Bilionu marundinlogoji naira ti won fojusun lati fi da ibudo
Amọ bi wọn ṣe dakẹ, ti Sabitu wọle lọ, ni Gbadero yọ si Raji, to si da ìbọn bo o ni orí, bi iyawo Raji si ṣe sare bọ sita, lo ri akọyinsi Eji Gbadero ati awọn ọmọ ẹyin rẹ ti wọn n sa wọnu igbo lọ.
US Shut down: Embassy Nàìjíríà kógbá nílé Buhari ní ìdìbò 2019 kìí ṣe tikú-tìyè 'Logo Benz yóò lẹ́yìn fún àwọn ọ̀dọ́ tó bá ṣògùn owó' Alapinni Oosa wúre ọdún 2019 fún gbogbo ìran Yorùbá Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí kan sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
Sibẹsibẹ, bí ọwọ́ bá tẹ̀ ẹ́, yóo fi san ìlọ́po meje,ó lè jẹ́ pé gbogbo ohun ìní rẹ̀ ni yóo fi san án.
Oríṣun àwòrán, @FemiAdesina Àkọlé àwòrán, ọmọbinrin Yoruba to gbẹkọ ilé maa n kunle ki agbalagba ni.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Winnie Mandela di olóògbé lẹ́ni ọdún mọ́kànlélọ́gọ́rin 2 Ìgbé 2018 Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ìtàn ìgbésí ayé Winnie Madikizela-Mandela Winnie Mandela, aya nígbà kan rí fún ààrẹ alawọ̀ dúdú àkọ́kọ́ ní orílẹ̀èdè South Africa ti papòdà lẹ́ni ọdún mọ́kànlélọ́gọ́rin.
A óo yọ olúwarẹ̀ kúrò láàrin àwọn ọmọ Israẹli.
 yorùbá bọ ̀ wọ ́ n ní àjòjì ọwọ ́ kan ò gbẹ ́ rù dórí .
Ó ní, “Ẹni tí mo bá kí, tí mo fi ẹnu kàn ní ẹ̀rẹ̀kẹ́ ni ọkunrin náà.
Yóo sì jẹ àwọn ọ̀tá rẹ̀ níyà,yóo sì ṣe ètùtù fún ilẹ̀ àwọn eniyan rẹ̀.
Àwọn ọba Yorùbá kan rèé tí wọ́n rọ̀ lóyè, tí ọba míràn jẹ lójú ayé wọn Ìtàn Gbọnka àti Timi, akọni méjì tó borí Aláàfin Ṣango Alaye si ree lori bi Ọba Seriki Abass se lo igbe aye rẹ gẹgẹ baa se ka a loju opo Wikipedia ati awọn oju opo itakun agbaye miran.
Mo ti fi ọ́ ṣe orí fún àwọn orílẹ̀-èdè ati ìjọba lónìí,láti fà wọ́n tu ati láti bì wọ́n lulẹ̀,láti pa wọ́n run ati láti bì wọ́n ṣubú,láti tún wọn kọ́ ati láti gbé wọn ró.
Oun si ni Emir ọgọta to jẹ ni Daura.
Awọn iroyin ti ẹ lee nifẹẹ si: Dòdò Ìkirè dúdú sùgbọ́n oyin ni Fídíò bí Salisu Yusuff se gba àbẹ̀tẹ́lẹ̀ Ǹ jẹ́ o leè fi àmì sórí ‘Àgbàlagbà-akàn’ ?
Ṣugbọn àwọn eniyan tí ń gbé inú rẹ̀ lágbára, ìlú ńláńlá tí wọ́n sì mọ odi yíká ni ìlú wọn.
1–26, Sátánì rú àwọn ènìyàn búburú sókè láti ṣe àtakò iṣẹ́ Olúwa; 27–33, Òun nwá láti pa ọkàn àwọn ènìyàn run; 34–52, Ìhìnrere yíò lọ sí ọ̀dọ̀ àwọn ará Lámánì àti sí gbogbo àwọn orílẹ̀ èdè nípa Ìwé Ti Mọ́mọ́nì; 53–63, Olúwa yíò gbé Ìjọ Rẹ̀ àti ìhìnrere Rẹ̀ kalẹ̀ ní ààrin àwọn ènìyàn; 64–70, Òun yíò kó gbogbo àwọn ẹni ironúpìwàdà jọ sí inú Ìjọ Rẹ̀ yíò sì gba àwọn olùgbọ́ràn là.
Bẹrẹ lati ipinlẹ Ọṣun nibi ti awọn ero ile ẹjọ ti deero ẹwọn nitori pe wọn lọ sile ẹjọ lasiko konile-o-gbele to wa lode.
Kí oore-ọ̀fẹ́ ati alaafia láti ọ̀dọ̀ Ọlọrun Baba wa ati Oluwa Jesu Kristi kí ó wà pẹlu yín.
Ẹ fihàn ninu ìwà yín pé ẹ ti ronupiwada.
Ṣugbọn bí èyíkéyìí ninu wọn bá fà sẹ́yìninú mi kò ní dùn sí i.
Igba akọkọ niyii ti ẹnikẹni lara awọn to ni arun naa ni Naijiria gbadun, to si bọ lọwọ rẹ.
Bí Elisabẹti ti gbọ́ ohùn Maria, bẹ́ẹ̀ ni ọlẹ̀ sọ ninu rẹ̀; Elisabẹti sì kún fún Ẹ̀mí Mímọ́.
Nigba ti ọrẹ rẹ timọ timọ ọhun, to tun jẹ ẹni to n ba a ṣeto igbeyawo rẹ, n ba BBC sọrọ, o ni oun l'ero pe ileewosan naa ni wọn de ti wọn duro toripe bi wọn ṣe debẹ, o ṣi n gba omi ti wọn so mọ ọ lara ninu buutu ọkọ, ti awọn ileewosan ko si ya si i.
Ẹ óo tún odi yín tí ó ti wó lulẹ̀ mọ,ẹ óo sì gbé àwọn ìpilẹ̀ṣẹ̀ àtijọ́ dìde.
Ninu ọrọ to fi soju opo Twitter rẹ, aarẹ orilẹ-ede Amẹrika, Donald Trump ni, iṣẹlẹ naa jẹ eyi to buru jọjọ.
ọkọ̀ ojú omi tuntun bẹ̀rẹ̀ iṣẹ́ Abiy Ahmed gba àmì ẹ̀yẹ̀ ti àláfíà lágbàáyé gẹ́gẹ́ bí ọmọ Africa Bó tilẹ̀ jẹ́ pé ìròyìn òfegè ni pé Buhari fẹ fẹ́ Sadiya, síbẹ̀ àwọn ọmọ Nàìjíríà ń ṣètò ìyàwò náà lórí ayélujára Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Kemi Lala: mo ń gbìyànjú láti mú inú òbí mi dùn Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 3 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 5 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Aare SHEGOFAN, Wahabi Salami lo parowa yii lasiko ti awon agbe olosin eranko n kopa ninu eto ise akanse ti Banki Agbaye gbe kale lati fi ko won lori ona igbalode lati pese ohun osin ati wara re sii fun lilo nile yii ati loke okun.
Nígbà tí ó jẹ́ pé Ọlọrun kanṣoṣo ni ó wà, òun ni ó sì ń dá àwọn tí ó kọlà láre nípa igbagbọ, tí ó tún ń dá àwọn tí kò kọlà láre nípa igbagbọ bákan náà.
Àwọn ọmọ ẹgbẹ́ PDP tó sápamọ́ kọlù mí lásìkò tí mò ń lọ sí ibi iṣẹ́, ló fa rògbòdìyàn - Olamiju Akala Ìtàn ìgbé ayé Arap Moi, ààrẹ kejì ní Kenya tí ọ̀pọ̀ ń rántí ìjọba rẹ̀ fún ìwà àjẹbánu 'Ẹ bá wa sọ fún Sanwoolu kó dárí jì wá o, ìpinú tí wọ́n ṣe l'Eko kò m'ọ́gbọ́n wá rárá' Kò sí ìfòyà tí ẹ bá ti ní nọ́mbà ìdánimọ̀, kékeré ni káàdì ìdánimọ̀ - NIMC Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Ninu ifẹsẹwọnsẹ mẹta ni Arsenal ti fakọyọ ninu meje ti wọn ti gba ni saa bọọlu yii.
Ọmọ àwọn iranṣẹ rẹ yóo ní ibùgbé;bẹ́ẹ̀ ni arọmọdọmọ wọn yóo fẹsẹ̀ múlẹ̀ níwájú rẹ.
Bukola Saraki ti sọ fún Àjọ EFCC pé kí wọ́n fi òun sílẹ̀, kí wọ́n yé é dìtẹ̀ mọ́ òun.
Ọtí waini ń ti àwọn wọnyi,ọtí líle ń mú wọn ta gbọ̀n-ọ́n-gbọ̀n-ọ́n.
Ibode yoo di titi pa: Oríṣun àwòrán, EMMANUEL OYELEKE Igbesẹ akọkọ tawọn ijọba orilẹede ti ofin konile o gbele wa yoo ṣe ni titi ibode ori ilẹ, ori omi ati ti ofurufu pa.
Níbikíbi tí mo bá pa láṣẹ pé kí ẹ ti sìn mí, n óo tọ̀ yín wá, n óo sì súre fún yín níbẹ̀.
Bí iwin àti ènìyàn yìí ti ń bọ̀ ni gbogbo ẹni ti o rí wọn ń bẹ́ lu igbó, ìgbà tí wọ́n sì dé ààrin ìlú, wọ́n kọ orí sí ààfin.
Odumosu ni awọn ero ọkọ mejila ri somi, nigba ti wọn ri awọn marun yọ, awọn ti ori ko yọ yii lo salaye nnkan to ṣẹlẹ si wọn, ati nnkan ti Bimbo se.
Ipò yìí ni ọ̀rẹ́ ọ̀dàlẹ̀ yí wà títí tí ilẹ̀ fi mọ́ bá a tí àwọn èèyàn sì bẹ̀rẹ̀ sí í ṣe háà, háà, háà, à ṣé bí ayé ṣe rí rè é!
Ninu iwadii wọn ni RIA ti rii pe awọn ekute lo ṣọṣẹ fun awọn waya ti wọn ri mọlẹ kaakiri ni eyi to jẹ ki awọn irin iṣẹ Estie digital services portal da iṣẹ silẹ ni orilẹ-ede Estonia.
Ondo state money: Ìjọba Ondo ṣàwárí N4.
Ifesewonse ìkẹta lera rèé ti wọn yóò pokọ iya fún Arsenal
Mo yìn ọ́, nítorí pé ẹ̀rù jẹ̀jẹ̀ ati ẹni ìyanu ni ọ́;ìyanu ni iṣẹ́ ọwọ́ rẹ!
Botilẹ jẹ pe orile-ede Amerika ko ti tọ ilana yii, sibẹ ọkọ ofuru British Airways ati Delta yoo maa di aaye gba awọn ti ayẹwo fi han pe ko ni aarun Covid-19 nikan ki wọn to le fo lọ si papakọ ofurufu John Kenedy ni New York.
Àwọn eniyan náà sì mú ìlérí wọn ṣẹ.
 látàrí gbogbo èyí , ìwádìí fi yé mi pé ikú pàpà mulo .
OLUWA wí fún mi pé, ‘Gbéra, kí o máa lọ láti ṣáájú àwọn eniyan náà, kí wọ́n lè lọ gba ilẹ̀ tí mo búra fún wọn pé n óo fún wọn.
Eeyan 54,743 ni apapọ ni arun naa ti fara kan labẹ ayẹwo, ti awọn 42,816 si ti ri iwosan gba lọwọ ajakalẹ arun ọhun.
Ìjọba ìpínlẹ̀ Kogi kéde ọjọ́ ìwọlé àwọn akẹ́kọ̀ọ́ padà sí iléèwé Iléeṣẹ́ ìròyìn Daily Trust gbọdọ̀ san N6 bilion nítorí ìbanilórúkọjẹ́- Femi Fani Kayode Sinimá àwòdamiẹnu, Ẹ̀fáńjẹ́líìsì jìyà àjẹmumi nílé aṣẹ́wó l'Ejigbo ní ìlú Eko Ìjàmbá ọkọ̀ tó ṣẹlẹ̀ sí Adams Oshiomole kìí ṣe ojú lásan, àwọn kan ló fẹ́ pa á- APC Ọba Saudi Arabia yọ ọmọ rẹ̀ àti àbúrò rẹ̀ kúrò nípò nítorí ìwà àjẹbánu lórí owó tó yẹ fún ààbò ìlú Kini iroyin naa sọ ati pe bawo lo ṣe bẹrẹ?
Irọlẹ ọjọ Aje ni iṣẹlẹ naa ṣẹlẹ eleyi to ti sọ ilu iṣẹmbaye naa sinu ọfọ nla.
Stadium ,pe ki won dibo fun oludije to ba wu won sugbon aare Muhammadu Buhari
Seal jẹ onkọwe orin, ọdun 1991 si lo gbe awo orin akọkọ, 'Crazy' sita, eyi to mi agbaye titi, amọ awo orin rẹ ti aye tẹwọgba julọ, 'Kiss from a Rose' lo gbe jade lọdun 1994.
Nígbà tí wọ́n dé ibi òkúta ńlá kan, tí ó wà ní Gibeoni, Amasa lọ pàdé wọn.
awon yọ kuro gẹgẹ  bi ile-ẹjọ se paa lasẹ
OLUWA ti fún ẹ̀yin ati àwọn ọmọ Lefi yòókù ní anfaani yìí, ṣugbọn nisinsinyii, ẹ̀ ń ṣe ojú kòkòrò sí iṣẹ́ alufaa.
''Orin gidi ni orin Fuji, o ti kan kaakiri gbogbo agbaaye bayii, gbogbo eeyan ni Naijiria lo fẹ kọ orin Fuji bayii,'' Kollington lo sọ bẹẹ.
Ó gbógun ti àwọn ará Filistia, ó sì wó odi Gati, ati ti Jabine ati ti Aṣidodu lulẹ̀.
Abalọ ababọ abẹwo yi ni pe o ni ki wọn gbe igbesẹ ijiya to tọ lori oludari ile iwosan ọhun.
Wo àwọn ìgbésẹ̀ tí ó lè gbé láti bọ lọ́wọ́ ẹ̀sọ́ ọlọpàá lóju pópó Àkọ́dá oró.
Alaafin Oyo, iku Baba Yeye, Ọba Lamidi Adeyẹmi III bẹ Oluwo ti ilu Iwo, Ọba Abdulrasheed Akanbi wo ni aafin rẹ nilu Iwo.
Kìí ṣe pé ó fi ẹnu rẹ̀ sọ, èmi rò bẹ́ẹ̀ ni.
Àgbẹ̀ tí kò bu ọlá fún ọ kò lèrí iṣu jẹ, olóko tí ó bá wí pé kí ni ìwọ jámọ́ yóó maa ṣiṣẹ́ dànù ni, nítorí náà mo bẹ̀ ọ́ nítorí Ọlọ́run Ọba má ṣàì gbìyànjú àti yọ nínú ọ̀ràn mi yìí kí n kúrò níbi tí mo bọ́ há sí lórí igi.
sa lati fopin si ruke-rudo naa.
Ninu eyi ti o ti fun ẹgbẹ agbaboolu ti orilẹ ede yii ni anfaani lati fi ẹyin ojugba wọn gbolẹ Bàbà ọmọ ọdún 75 kó HIV ran ọmọ ọdún 14 lẹ́yìn tó fi ipá báa lò Gbogbo ọjà di títì pa nílùú Akure, ṣugbọ́n nítorí kí ni?
Oyetola ni ajọ INEC kede gẹgẹ bi ẹni to jawe olubori ninu atundi ibo gomina to waye losu to lọ.
“Ayọ̀ ń bẹ fun yín nígbà tí àwọn eniyan bá kórìíra yín, tí wọ́n bá le yín ní ìlú bí arúfin, tí wọ́n bá kẹ́gàn yín, tí wọ́n bá fi orúkọ yín pe ibi, nítorí Ọmọ-Eniyan.
Alamojuto  eto idibo ni ipinle naa, ọjọgbọn Azubuike Sony
Nítorí náà bí Ọlọrun bá fún wọn ní ẹ̀bùn ọ̀fẹ́ kan náà bí ó ti fún àwa tí a gba Oluwa Jesu Kristi gbọ́, tèmi ti jẹ́, tí n óo wá dí Ọlọrun lọ́nà?
Bí wọn bá ti dúró, wọn a ká ìyẹ́ wọn wálẹ̀.
Pupọ ninu wọn gbàgbọ́, ati pupọ ninu àwọn Giriki tí wọ́n jẹ́ eniyan pataki-pataki, lọkunrin ati lobinrin.
Àwọn Ìjẹ̀bú náà tẹle Kurunmi lẹ́yìn láti tako Ibadan, lọ́nà àti dáa lọwọkọ, nìdí ìgbésẹ tó ń gbé láti dá èdè aiyede silẹ laarin Ìjẹ̀bú àti Remo, Eyí tí yóò fun Ibadan láǹfààní láti rí ọna kọjá si etí òkun feto okoowo.
odun mẹ́rìndínlógún ti won fi tuko
Àkíyèsí pàtàkì - Ti ẹ bá ní ohun láti sọ nípa àròkọ yìí, ẹ̀yin náà lè bọ́sí gbàgede.
 “Ni ọjọ kẹ́tàlélógún  osu keta,a ni
"Ko si ẹni ti wọn ko fẹ ẹ, yatọ si Trump Oríṣun àwòrán, Getty Images Koko ọrọ to gbajumọ ninu ipolongo Biden ni pe idibo naa wa fun ""ijakadi fun ọkàn ilẹ America"", ati anfaani lati mu opin ba rogbodiyan ati ipinya, to ti wa lati ọdun mẹrin."
Ọ̀pọ̀ awuyewuye tó rọ mọ aba akoso ajakalẹ-arun yìí ló mú kí BBC Yoruba máa béèrè pé, kí ló wà nínú àbá náà, tó fi ní àtakò tó èyí, tá sì ṣàgbéyẹ̀wò abá náà láti mú àwọn kókó tó wà nínú rẹ jáde.
Sọ àsọtẹ́lẹ̀ orílẹ̀èdè tí yóò borí ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ t'òní Ò ti pé ọdún 27 tí Shah Rukh Khan ti ń se fíìmù India Thomas John: Kí ló yẹ kóo mọ̀ nípa adelé alága NNPC tuntun?
Nígbà tí Sebulu, olórí ìlú náà gbọ́ ohun tí Gaali, ọmọ Ebedi wí, inú bí i gidigidi.
O ni lasiko ipade wọn, ohun ti wọn jiroro le lori ni pe akoso owo ori epo lorilẹede Naijiria buru pupọ, ta ba gbe yẹwo si tawọn orilẹede yoku lẹkun iwọ oorun Afirika.
Bi o tilẹ jẹ wi pe o ti ṣe diẹ ti iroyin lori pipe Ambọde ti n waye nile asofin ipinlẹ Eko, ṣugbọn ọrọ naa ṣẹṣẹ ja gbangba ni pẹlu bi ile ṣe fi iwe ipe rẹ soju ewe iwe iroyin lọjọ abamẹta.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Cardless Withdrawal: Èyí ni àwọn ìlànà tí o le fi gbowó ní ATM láì lo káàdì 16 Ìgbé 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Yatọ si 'Cardless Withdrawal, awọn ọrọ ti awọn ileefowopamọ tun maa n lo ni Cash-on-The-Go, Dial4Cash, Magic Cash, ati bẹẹbẹ lọ.
Ẹ óo wá mọ̀ pé èmi ni OLUWA.
Wọ́n bi OLUWA pé, “Àbí ọkunrin náà kò wá ni?
Gbogbo ọjọ́ ayé Saulu ni ó fi bá àwọn ará Filistia jagun kíkankíkan.
Ọdun 1961 ni wọn da ileeṣẹ ọhun silẹ, ṣugbọn lara awọn ohun to mu ko kogba wọle ni ina ọba ti ko ṣe dede ati awọn igbesẹ ijọba apapọ miran.
Òjò ló lè mú kí ìtànkálẹ̀ àrun ìgbẹ́ ọ̀rìn má tètè dópin ni Eko- Iléeṣẹ́ ìlera Makinde vs Adelabu: Ilé ẹjọ́ tó ga jùlọ ní Nàìjíríà ní yóò yanjú ọ́rọ́ ìdìbò Gómìnà Oyo Ipo to to gbedeke maaki ida ọgọrun ni akọnimọọwẹ rẹ, Joe Jacobs fun Aidan gẹgẹ bi ọmọde omuwẹ.
Mo ń bá ọ́kùnrin 15 sùn lọ́ọ̀jọ́ láti sàn owó ọ̀gá mi- Ngozi Ẹyin ni wọ́n fi n gba ìbále ẹlòmiran lára wa ki a to lọ pàde àwọn oníbara Ìpínlẹ̀ Oyo gba ipò ìkíní mọ́ Edo lọ́wọ́ nínú fífí ọmọdé ṣ'ẹrú Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Human trafficking: Iṣẹ́ irun ṣíṣe ló di iṣẹ́ aṣẹ́wó Ẹyin o rẹyin ni wọn tun sọ fun pe ilu miran, Omar, ni awọn yoo mu u lọ.
ati fi ese idagbasoke mule sinsin si lawujo,” Aare
Ogbeni Peter Dada, ọkan lara awọn ọdẹ ti iṣẹlẹ naa ṣoju ẹ ni pe nigba ti ibọn ko ran wọn ni awọn afurasi yii ba gun wọn ni eyi to jasi iku fun oloogbe.
Ní ti ọ̀rọ̀ wolii, wọn yóo di ohun tí kò wúlò mọ́.
Oríṣun àwòrán, ccc genesis global/instagram Wọn tun ma n ṣeto fifun awọn alaini awujọ ni iranlọwọ loṣooṣu.
" Oríṣun àwòrán, Other Saaju ni Ajọ NCC ti fun araalu ni gbedeke titi di ọgbọnjọ Oṣu Kejila ọdun 2020 lati lọ gba NIN wọn tabi ki wọn padanu siimu wọn.
Oríṣun àwòrán, Abiola Ajimobi Gẹgẹ bi mọlẹbi oloogbe Ajimobi kan to kọ lati darukọ rẹ ti fi to wa leti, wọn sun eto isinku naa siwaju nitori ki aaye lee wa fun ipalẹmọ isinku naa.
Bẹẹ gẹgẹ lọrọ ikọ Barcelona ri lẹyin ti na Manchester United mọ le.
Ìdigunjale Offa: Ọlọ́pàá gbé N5m sílẹ̀ Saraki lọ́rọ̀ láti dáhùn lórí ìdigunjalè Offa Ṣugbọn ohun kan to han sita faye ri ni pe janduku oloṣelu ni awọn afurasi ole ọhun.
Lẹyin iṣẹju marun ni erin naa dide.
Koda, o tun fi ẹsun kan awọn ẹgbọn rẹ pe wọn roju debi pe wọn ko lee fa ina tọọṣi kuro lẹnu ina funra wọn, oun ni oun n se e.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Falling Containers: Ilé ẹrù náà ló já bọ́ lé ọkọ̀ akérù lórí 15 Ọ̀pẹ̀̀ 2018 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 22 Ògún 2020 Oríṣun àwòrán, Others Ile ẹru, taa mọ si container to to iwọn bata ogoji mita, tun ti ja bọ lori ọkọ tirela, to si ti mu ẹmi eeyan meji lọ.
Gbogbo wọn si ni wọn n mi imi ẹdun nipasẹ aisi eto ẹyawo lati le ṣe iṣẹ wọn botiyẹ.
0 10 Erekusu Marshall islands 0 0.
' amọ se ni Malivehood sọ pe ',,,Nigba ilọrọ ati nigba Ilọrọ.
O ni ariwo obinrin oloyun yii ti lọ ti awọn eeyan n pariwo lo ta oun ji, ti ọpọlọpọ eeyan si n gbiyanju lati fa ẹsẹ rẹ yọ kuro ni abẹ 'Maruwa' to ha si.
Doris Okuwobi ni alaga igbimọ naa.
Ìdí abájọ ni pé ilé-iṣẹ́ ìfowópamọ́ ti mo ń lò máa ń yọ eélòó kan nínú owó mi lóṣooṣù.
Eniyan burúkú a máa lo ògbójú,ṣugbọn olóòótọ́ máa ń yẹ ọ̀nà ara rẹ̀ wò.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Omolola Arohunmolase Welder: Mo ti fí iṣẹ́ 'Welder' gbayì láwùjọ, tó mo fi tọ́ ọmọ yanjú Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Nkechi Blessing: Blessing ní ìkébé òun tóbí ju ohun tí òun lè dọwọ́ bò lọ, gbogbo èèyàn ló mọ̀26 Owewe 2020 Yoruba film: Irú ẹ̀ṣẹ̀ wo ni gbajugbaja òṣèré, Nkechi Blessing ṣẹ Toyin Abraham tó fi ní kó jèbùrẹ́?
Pakistan new rape law: Ìjọba yóò fààye gba fífi kẹ́míkà tẹ ọkùnrin lọ́dàá
Nígbà tí ó ṣí i, ó rí ọmọ kan ninu rẹ̀, ọmọ náà ń sọkún.
Anastasia Balandina lati London ni balikoni oun loun ti maa n sisẹ ti oorun ba ti jade.
Mo fojú sọ́nà títí, agara dá mi,níbi tí mo tí ń retí ìmúṣẹ ìlérí rẹ.
Ẹ̀yin ti ẹ lójú tí ẹ kò lè fi ríran- bí ẹ kò bá sọ́ra yín n oo báa yín jà kí ẹ tó kúrò ní ìlú mi.
Bayii lọrọ ri pẹlu ẹgbẹ agbabọọlu Real Madrid ati Barcelona.
A gbọ pe ọdun Ọṣun Oṣogbo ti le ni ẹẹdẹgbẹrin ọdun to ti bẹrẹ, a ko si lee sọ nipa isẹdalẹ ọdun Ọṣun Oṣogbo, ka ma mẹnuba itan idasilẹ ilu Osogbo funra rẹ.
O ni bo tilẹ jẹ pe Malami lẹtọ lati gba ijọba apapọ lamọran nipa ọrọ ofin, o han kedere pe inu ofiisi rẹ kọ ni wọn ti n ṣe ofin Naijiria.
Ṣugbọn nígbà tí wọ́n súnmọ́ ọn tí wọ́n mọ̀ pé òun ni, wọ́n bú sẹ́kún, wọ́n fa aṣọ wọn ya, wọ́n sì ku eruku sórí.
Jesu dáhùn pé, “Ẹni tí mo bá fún ní òkèlè lẹ́yìn tí mo bá ti fi run ọbẹ̀ tán ni ẹni náà.
“Mo ro Aare Buhari, lati maa se kaare lori pipolongo iwa ibaje yii, awon eniyan ko ni gbagbe akitiyan isakoso re lori atunbi orile-ede Naijiria tuntun”.
Ṣé kí á máa dá ẹ̀ṣẹ̀ nítorí pé a kò sí lábẹ́ òfin, abẹ́ oore-ọ̀fẹ́ ni a wà.
Asọ igbeyawo ti iyawo wọ: Oríṣun àwòrán, Instagram/thebridalmoments Kaba iyawo ti arabinrin iyawo asẹsẹgbe naa wọ lọ sile ijọsin lo kun fun kiki okuta olowo iyebiye diamond.
Kaka ko san fun ẹgbẹ agbabọọlu Tottenham, niṣe lo buru si o.
Seyi Makinde ṣe ètò ìdágbére ìkẹyìn fún ìyá rẹ̀, àwọn èèkàn sọ nípa ìyá náà Oríṣun àwòrán, Seyi Makinde Gomina ipinlẹ Ọyọ, Onimọẹrọ Ṣeyi Makinde ti ṣe alaye ọrọ lorii bi o ṣe padanu anfani to yẹ ki o fi ba iya rẹ sọ ọrọ ikẹyin ki ọlọjọ to de.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ondo politics: Ilé ẹjọ́ da ìpèjọ́ pé Akeredolu kọ ló wọlé ìdìbò ìpińlẹ̀ Ondo nù 14 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 16 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Oríṣun àwòrán, Akeredolu Ilé ẹjọ́ gíga kan ní ìlú Abuja ti da ẹjọ́ to ní Gómìnà Oluwarotimi Akeredolu kọ́ ló wọlé gẹ́gẹ́ bii gomina lábẹ́ àsíá ẹgbẹ́ òṣèlú All Progressive Congress (APC) nínú ìdìbò gómìnà tó wáyé nípìnlẹ̀ Ondo.
Ọba Lamidi sọ ọrọ yi lasiko to n fi oye da Wasiu Ayinde Marshal lọla gẹgẹ bii Mayegun ilẹ Yoruba nilu Oyo.
Nígbà tí wọ́n sọ ọ́ nù, ni ọmọ Farao, obinrin, bá tọ́ ọ gẹ́gẹ́ bí ọmọ ti ara rẹ̀.
Àwọn àjèjì ti gba agbára rẹ̀, sibẹsibẹ kò mọ̀; orí rẹ̀ kún fún ewú, sibẹsibẹ kò mọ̀.
orile ede Naijiria bi won se gba alaafia laaye ni jake-jado orile ede Naijria.
Aare fikun un oro re pe, ami eye NNMA jeami eye ti o tobi pupo, ti o si gbayi lorile-ede yii lati igba ti won tisefilole re lọdun mọ́kàndínlógójì seyin(39 years ago).
Koda, iroyin kan ti ko tii fidi mulẹ ni awọn ọlọpaa lo yinbọn mọ awọn janduku naa, eyi to mu ki wọn dana sun agọ ọlọpaa ibẹ.
 fún ìdí èyí , àwọn olùkọ ̀ wé kan maa ń pe henry carr ní  atukọ ̀ king ' s college "" ."
Mo lè ṣe ohun gbogbo ninu Kristi ẹni tí ó ń fún mi ní agbára.
Ìdí rèé tí Aisha Buhari kò tíì padà sí Nàìjíríà- Iléeṣẹ́ ààrẹ Ìgbà Marún-un ti Aisha Buhari ti tako ìjọba Buhari Taló ya fídíò ibi tí Aisha Buhari ti ń bínú ní Aso Rock?
" yorùbá bọ ̀ , wọ ́ n ní , "" ohun gbogbo lọ ́ wọ ́ orí , orí la fi ń mú ẹran láwo "" Òródùdùjoyè tí ó jẹ ́ àbúrò ni àwọn afọbajẹ yàn dípò olúbákin tí ó jẹ ́ ẹ ̀ gbọ ́ n gẹ ́ gẹ ́ bí i Àwùjalè tuntun ti ilẹ ̀ Ìjẹ ̀ bú ."
Ojúde Ọba: Ayẹyẹ tó ń ṣàfihàn àṣà àjogúnbá Yorùbá
Ìtàn Àrọ̀gìdìgbà jẹ́ kí ń rò pé bàbá mi yan Yemọ̀ja ní àlè - Ọmọ Fagunwa Ó pé ọdún mẹ́rìnlélàádọ̀ta tí Akintola kú, ìdí abájọ ìja rẹ̀ pẹ̀lú Awolowo rè é Bakan naa ni Akinlade salaye awọn ọna to tọ, ti gbajugbaja ileesẹ Stripe fi dokowo igba milọnu Dọla pẹlu ileesẹ rẹ lori ayelujara.
Èyí kọ́ èmi ní ọgbọ́n, nítorí náà n kò gun màlúù ní tèmi, ìgbà tí ọba sì rá pálá dide tan ó tún tọ lé màlúù lẹ́yìn ó ń lọ pẹ̀lú hílàhílo.
”Eto idibo to je itewogbaAdari ajo eleto idibo lorile ede Naijiria,ojogbon Yakubu, dupe lowo awon adari ile igbimo asoju-sofin fun atileyin won, ojogbon Yakubu ,fi idunnu re han lori atileyin ti INEC n ri gba lati ile igbimo asofin, ni eyi ti yoo tun je ki ajo INEC se aseyori ninu eto idibo odun to n bo.
Mo rò ó pé kí ni ẹnìkan lè ṣe lẹ́yìn èyí tí ọba ti ṣe ṣáájú rẹ̀?
Lori ọrọ Ọga ọlọpaa, wọn fẹnu ko wi pe, Aarẹ Muhammadu Buhari ni yoo dahun fun gbogbo awọn to yan sipo.
Oríṣun àwòrán, @iyalojageneral Àkọlé àwòrán, Aworan Iyalaje kafata nilu Eko nibi ajọdun kan ni Ile Ifẹ Elesin tẹsiwaju pe Oba nikan lo lagbara lati yan Iyalọja tabi ko si jẹ wi pe awọn obinrin ọja naa yan ẹnikan lara wọn ti wọn yoo si fi orukọ rẹ ranṣẹ si ọba tabi ẹka ijọba ti o n mojuto ọrọ yi.
Kenaani yìí náà ni baba ńlá àwọn ará Jebusi, àwọn ará Amori, ati àwọn ará Girigaṣi; 
N kò ní jẹ òṣìṣẹ́ ni owó oṣù, tí mo bá wọlé gómìnà ní èkejì Gomina Akeredolu ti kede pe oun ti mu ileri oun ṣẹ lati mase jẹ awọn osisẹ ni owo oṣù.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Shoprite leaving Nigeria: Ṣé òótọ́ ni pé Tayo Amusan ni yóò gba ìṣàkóso ilé ìtajà Shoprite?
Alaga PFN sọ pe ''ọwọ Ọlọrun ni ipinlẹ Enugu wa, nitorinaa a ko ni gba ko di ipinlẹ tawọn ajẹ yoo jẹ gaba le lori.
Ẹni tí ó tẹ̀lé e ni, Eleasari, ọmọ Dodo, ti ìdílé Ahohi, ó wà pẹlu Dafidi nígbà tí wọ́n pe àwọn ará Filistia níjà, tí wọ́n kó ara wọn jọ fún ogun, tí àwọn ọmọ ogun Israẹli sì sá sẹ́yìn.
Judasi ọmọ Jakọbu ati Judasi Iskariotu, ẹni tí ó di ọ̀dàlẹ̀.
Ile ẹjọ si ti sun igbẹjọ naa siwaju di ọjọ kẹtadinlogun oṣu kẹsan ọdun 2020.
Ni pataki julọ ife ẹyẹ agbaye yoo farahan ni ileeṣẹ BBC to wa ni ilu Eko ni ọjọ ẹti gẹgẹbii ara ilakalẹ ajọ FIFA.
 Àjẹsára ẹlẹ ́ ẹ ̀ kún sẹ ́ ẹ ̀ lì náà ní ìwọ ̀ n agbára àti ṣiṣẹ ́ tó tó 78 % nígbàti àjẹsára aláìní sẹ ́ ẹ ̀ lì ní ìwọ ̀ n agbára àti ṣiṣẹ ́ tó tó 71-85 % .
Ó pe àwọn ọ̀gágun rẹ̀ jọ,wọ́n sì ń fẹsẹ̀ kọ bí wọ́n ti ń lọ,wọ́n yára lọ sí ibi odi,wọ́n sì fi asà dira ogun.
Oṣù méjìlá sẹ́yìn, ní oṣù Ọ̀pẹ ọdún 2017, Ilé-iṣẹ́ Ọkọ̀ òfuurufú Ethiopia fún ìgbà àkókọ́ gbé ikọ̀ òṣìṣẹ́bìrin fò.
Ọjọgbọn Ọṣinbajo tun mẹnu ba pataki idasilẹ ọlọpaa ipinlẹ, eleyii ti yoo le koju awọn ipenija aabo orilẹ-ede yii bayii.
Inú odò ni wọ́n ti rí òkú ọmọ ọdún méjì tó sọnù l'ọ́jọ́ ọdún Eid nílùú Ibadan Àwọn adarí lágbàyé ṣèpàdé láti ṣèrànwọ́ fún Lebanon lẹ́yìn ìbúgbàmù tó pa ènìyàn 158 Obasanjọ dúró lórí ọ̀rọ̀ tó sọ lẹ́yìn ikú Kashamu- Kehinde Akinyemi Mo ti buwọ́lu àdínkù owó orí nítorí ìrọ̀rùn àwọn èèyàn ìpínlẹ̀ Ogun lásìkò Covid 19- Dapo Abiodun Awọn ọmọ inu ile mẹrindinlogun ni orukọ wọn wa ni bebe lati ko kuro ninu ile: Ozoemena Chukwu AKA Ozo Victoria Adeyele AKA Vee Boluwatife Aderogba AKA Lilo Timmy Sinclair AKA Trikytee Terseer Kiddwaya Dorathy Bachor Praise Nelson Florence Wathoni Anyansi Tochukwu Okechukwu AKA Tochi Kate Jones AKA Ka3na Eric Akhigbe Ngozi Nlewedim AKA Erica Ezekiel Bright Osemudiame AKA Brighto Aisha Umaru AKA Kaisha Emuobonuvie Akpofure AKA Neo Tolani Shobajo AKA Tolanibaj Olamilekan Agbeleshe AKA Laycon Rebecca Hampson AKA Nengi Lucy Oríṣun àwòrán, @bbnaija/twitter Àkọlé àwòrán, Esi ibo ti awọn ololufẹ eto Big Brother Naija Laockdown di lati mọ ẹni ti yoo kọkọ kuro nibi eto naa.
Oluranlọwọ si Gomina ipinlẹ Kogi lori ọrọ aabo, Jerry Omadara naa sọ pe, o le ni ọgbọn awọn ẹlẹwọn to salọ ti awọn ti ri mu pada.
Eyi ni ọrọ mánéjà Toke Makinwa nigba ti BBC kan sii lati mọ okodoro ọrọ to n ṣẹlẹ.
Wọn ni lasiko ti ẹ̀kun omi naa n pọ si, ni awọn ara adugbo to ti raaye gun ibi to ga n gbọ igbe ẹ gbami lẹnu obinrin naa atawọn ọmọ rẹ.
O bẹrẹ ọti mimu, to si n mu oogun oloro Codeine.
'Ẹ̀ maa ṣe gbagbe pe ẹkun yii ni adajọ agba orilẹ-ede Naijiria, Onnoghen ti wa, ni pato, ọmọ ipinlẹ Cross river ni.
30 Ati pé bí èyí bá rí bẹ́ẹ̀, kíyèsíi, mo wí fún ọ Joseph nígbàtí ìwọ bá ti túmọ̀ àwọn ojú ewé ìwé díẹ̀ síi ìwọ yíò dúró fún ìgbà kan, àní títí tí èmi yíò fi tún pàṣẹ fún ọ; nígbàyìí ni ìwọ ó tún le túmọ̀.
ohun idagbasoke ilu, eyi ti Ile Igbịmọ Aṣofin yii ti n ṣatileyin fun
Olùfẹ́, kì í ṣe òfin titun ni mò ń kọ si yín.
N kò sì ní ni yín lára.
Obìnrin kò gbọdọ̀ jáde alẹ́ mọ́ ní Kano Sọ́ra fún gbájúẹ̀, BBC kò ṣètò owó ẹ̀kọ́ ọ̀fẹ́ ‘Alẹ́ làwọn ọkùnrin fẹ́ bá mi jáde, torí mo kọ ilà’ Kíni ìwọ mọ̀ nípa Funmilayọ Ransome-Kuti?
ohun ti won yoo maa jiroro nibi ipade naa ni ọgbọ̀n egberun  ekunwo owo osu awon osise ati lati fese adele
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Wo Adigun ọmọ ọdún mẹ́rin tí òwe Yorùbá àti ìtúmọ̀ gbó lẹ́nu rẹ̀ ju tìrẹ̀ lọ Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí EndSARS Protest Update: Aisha Yesufu ní Buhari jẹ́wọ́ pé òun kò láànú aráàlú nínú ọ̀rọ̀ rẹ̀23 Ọ̀wàrà 2020 Fídíò, Wole Soyinka sọ ìdí tó fi ni òun a fi màálù Fulani ṣe súyà fáwọn èèyàn abúlé23 Owewe 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Idrissa Deby kọ ni aarẹ akọkọ ni Afirika ti yoo gbiyanju lati wa lori oye titi pẹ to fi di ọjọ iku rẹ.
Lílọ́ ni kí alufaa lọ́ ọ lọ́rùn, ṣugbọn kí ó má fà á lọ́rùn tu.
Lara awon to wa nibi ayeye ohun ni awon aare ana, Abdulsalam Abubakar, Yakubu Gowon,Olusegun Obasanjo ati oludije fun ipo aare labe  egbe oselu  PDP Atiku Abubakar, alaga egbe oselu APC Adams Oshiomhole, igbakeji aare ana ,Namadi Sambo, abenugan ile igbimo asoju -sofin Bukola Saraki, awon gomina  ana  fun egbe PDP ati awon asoju fun ile okeere.
Ṣùgbọ́n níwọ̀n ìgbà tí ìfẹ́ bá ṣì wà níbẹ̀, ó ti bẹ̀rẹ̀ sí ni rò ó bóyá ó ń ṣèrànwọ́ fún ìgbádùn ìbálòpọ̀ rẹ̀ ní ọ̀nà mìíràn.
Jazz àtàwọn orin àtijọ́ tẹ́ ò mọ̀ pé ẹ ṣì lè rí gbọ́ Ẹ̀gbà ọrùn ni Yoruba n pe Necklace!
Oríṣun àwòrán, Festus Ojo Àkọlé àwòrán, Inu awọn ọmọ Iyabọ Ojo dun lati fi oju kan baba wọ̀n lẹyin ọdun mẹfa ti wọn ti foju-rinju kẹyin.
Nítorí èmi ni mo ṣe ètò láti fà yín fún Kristi bí ẹni fa wundia tí ó pé fún ọkọ rẹ̀.
O wa ro awon oludibo nipinle Osun lati tu yaya sita wa dibo fun egbe oselu APc ninu eto idibo ohun to n bo lona.
Ajọ NCDC naa fi lede loju opo ikansiraẹni Twitter wọn ni Ọjọ Satide.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Buhari: Iṣẹ́kíṣẹ́ ni awọn akọ́lé ń ṣe pẹ̀lú ilé tó ń dàwó ní Eko lemọ́lemọ́ 27 Ẹrẹ̀nà 2019 Aarẹ Muhammadu Buhari ti kilọ wi pe ẹnikẹni to ba ko ile lọna ẹburu yoo foju wina ofin lorilẹede Naijiria.
Ajọ PPPRA to n ṣamojuto owo epo rọbi lo ṣe ikede naa ninu atẹjade kan to fi sita.
Awọn onimọ naa ni diẹ ni ti Alaba lọrọ ibeji taa ba n sọrọ eto isakoso ati awọn osisẹ ọba nitori iwọnba ni wọn lee si, ọpọ asẹ si lo wa lọwọ awọn minisita ti yoo ba aarẹ sisẹ.
Wọ́n sì ń júbà ẹranko náà, wọ́n ń sọ pé, “Ta ni ó dàbí ẹranko yìí?
Eto idibo ti bere ni pereu ni ipinle Osun bayii.
Dokita Ugonna ni lootọ omi lee ṣebi ẹni pọ ju ọka lọ fun ijọba lori eto iwosan ati ilera oju, ṣugbọn ohun to tọna bayii ni ki awọn ti Ọlọrun ṣẹgi ọla fun lawujọ o dide fun ipese owo lati seto itọju fun awọn ti oju n dun lawujọ.
6 8403 Orilẹede Cameroon 443 1.
Aare Muhammadu Buhari ti ro awon oloselu ati awon ti oro kan, lati yera fun awon ohun ti yoo tabuku ba igbese eto idibo orile-ede Naijiria, amo, ki won fowosowopo lati le je ki alaafia joba lorile-ede Naijiria.
“Ko si eni to le so fun awon omo
Ẹ sọkún tẹ̀dùntẹ̀dùn, ẹ̀yin igi oaku ní Baṣani,nítorí pé, a ti gé àwọn igi igbó dídí Baṣani lulẹ̀!
Barrow lo wọle sipo aarẹ ninu eto idibo to waye l'oṣu Kejila, ọdun 2016.
Darandaran Fulani kìí lo ìbọn, 'pọ̀pá' la máa ń lò Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Ṣugbọn àwọn ẹlẹ́ṣẹ̀ yóo parun patapata,a óo sì run ọmọ àwọn eniyan burúkú.
 < / ref > Ó ṣíṣẹ ́ gẹ ́ gẹ ́ bí Ọmọ ogun ní Ẹ ̀ ka kẹwàá ' 10th brigade ' ti ìpín kejì ' 2nd division ' ti ilé-iṣẹ ́ ológun nàìjíríà lábẹ ́ Ọ ̀ gágun ' adéníran ' ó sì jà fitafita ní awka , abagana àti onitsha .
5 5159 Orilẹede Liberia 83 1.
Iléeṣẹ́ ọlọ́pàá tún ti ṣèlérí àtúntò ikọ̀ ọlọ́pàá kògbérégbè FSARS
ko waye lataari orisirisi ise to n waye lotun-losi  Ninu oro re, dokita Baru so pe bi o ti le
 Ilana eto naa ni pe awọn agbẹ yoo fi oruk ara wọn silẹ, gbogbo ere oko tabi ẹran ọsin to wa lati ọdọ wọn yoo maa ni ami idanimọ pataki.
Gege bi Bankole se so, “Won gunle sipago yii losu kan seyin lati gbaradi sile fun idije agbaye naa.
Lẹ́yìn tí ó ti sọ báyìí tán, ó tú àwọn eniyan náà ká.
Akintoye ti kọ iwe apilẹkọ loriṣiiriṣii yatọ si orí kan ninu iwe ka to sọ awọn jọọna ati awọn beba iwe iṣẹ akanṣe ti wọn ti gbe sita kaakiri agbaye.
Olùrànlọwọ pataki fun Aarẹ Muhammadu Buhari, Femi Adeshina, lo lede ọrọ yi ninu atẹjade kan to fi sita lori abẹwo May si Aarẹ Muhammadu Buhari ni ile ijọba l'Abuja.
Ni àwọn eniyan náà bá ń kígbe pé, “Ohùn Ọlọrun nìyí, kì í ṣe ti eniyan!
Mò ń lọ láti ilé ìpàdé kan dé ekeji, mo sì ń jẹ wọ́n níyà, bóyá wọn a jẹ́ fẹnu wọn gbẹ̀ṣẹ̀.
Akọnimọọgba ẹgbẹ agbabọọlu Man U, Ole Gunnar Solskjaer sọ pe oun fẹ ki Ighalo gba ife ẹyẹ pẹlu Man U ko to fi ẹgbẹ agbabọọlu naa silẹ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Widows Day 2019: Mo máa ń sá kiri wá owó ilé ni -Opó Akọroyin BBC to wa pẹlu ikọ agbabọọlu naa nile itura ti wọn wa ni France sọ pe lẹyin ọpọlọpọ ipade ọrọ ti n yanju lọ.
Awọn musulumi kan ni Turkey fi idunnu wọn han lori igbese yii pe o dara.
Oúnjẹ wọ́n bí ojú iṣu kan jẹ́ pọ́nùn kan, garawa epo jẹ́ pọ́nùn mẹ́fà, páànù èlùbọ́ jẹ pọ́nùn méjì, àkùkọ adíẹ̀ si jẹ́ pọ́nùn méje.
Kò sí ọ̀nà ti èèyàn kò lè fi pèsè ìrànlọ́wọ́ fún ará ìlú ẹ
Amọ a ni lati gbọ lati ile ẹjọ lori ọrọ wọn ki a to le da wọn pada saarin ilu lati di oniṣẹ ara wọn.
 kòlà-kò-ṣagbe sì ni pẹ ̀ lú .
Gbogbo awọn orilẹede yii lo fẹ ṣe ohun ti wọn lagbara o ṣugbọn ohun to tilẹ kere ju lọ ti Amẹrika ka silẹ, wn ko ri i gbeṣe.
Àwọn ọmọ Naijiria to ti kú lóri pápá lásìkò ìfẹsẹwọ́nsẹ Kòsi àniàni, eré ìdáraya bọọlù jẹ́ èyi tó gbàjúmọ jùlọ ni orílẹ-èdè Naijiria àti ní gbogbo àgbàyé, ọ̀pọ́ àwọn ènìyàn lo si máa n lọ wòràn.
Nítorí Ọlọrun ti sọ mí di aláìlera,ó sì ti rẹ̀ mí sílẹ̀,wọn dojú ìjà kọ mí ninu ibinu wọn.
Oríṣun àwòrán, Twitter/FRSC Nigeria Baba Ṣango kii ṣadeedee payan bayẹn ti ko ba jẹ wi pe awọn eeyan naa ti jale tabi ṣe nnkan aitọ kan.
Oríṣun àwòrán, others Ikú Williams Aanuoluwa lágbo òṣèré hú ọ̀pọ̀ ọ̀rọ̀ síta Kí ló ń ṣẹlẹ̀ lọ́wọ́ sí Mamman Daura àti ìlera rẹ̀?
Seriki Abass jẹ Oba nilu Badagry, lẹyin ti owo ẹrú dopin amọ o ti lowo, o lọla, to si laami laaka saaju nidi owo ẹrú ṣíṣe, Bẹẹ ni ibudo kan wa nilu Badagry bayii, ti wọn ya sọtọ bii ìṣe nnkan isẹnbaye lọjọ si, fun iranti ọba Seriki Williams Ifaremilekun Abass.
A kò ṣẹgun ohunkohun láyébẹ́ẹ̀ ni àwọn tí ń gbé ayé kò tíì ṣubú.
Kọmiṣọna ọlọpaa nipinlẹ Ekiti, Asuquo Amba wa ṣe apẹrẹ iṣẹlẹ iwadii kan eleyii ti o waye ni inu igbo to wa laala ipinlẹ Ekiti ati Kogi.
”Samsoni bá dá a lóhùn pé, “Ohun tí n kò sọ fún baba tabi ìyá mi, n óo ti ṣe wá sọ fún ọ?
Ni bayii,ipinle merin ni isele buruku yii n dojuko, ti a si n foju wo awon ipinle mejo miiran, nitori awon ajalu omiyale ti o lee waye lati omi adagun  Benue ati Niger ti o n ti n ru soke bayii.
Àkọlé àwòrán, Odun yii dun o lárinrin, awon alawo funfun péju láti bọ Osun Osogbo Àkọlé àwòrán, Àtàọjá àti àwọn olori níbi ayẹyẹ Osun Osogbo, ètò si ti gbera sọ Àkọlé àwòrán, Awọn lẹgbẹlẹgbẹ-loyeloye ati ọkanọjọkan ẹgbẹ lawujọ ti n ṣe ikini sí Kabiyesi Ataọja ti ilu Ọṣogbo Ọba Jimoh Oyetunji, Kabiyesi naa si n wure fun wọn.
Èyí ni ìpín yín,ìpín tí mo ti yàn fun yín,nítorí pé ẹ ti gbàgbé èmi OLUWA, ẹ sì gbẹ́kẹ̀lé ọlọrun èké.
O salaye pe iyalẹnu lo jẹ fun oun pe iwe ẹri ayederu ni oun gbe ka ati wi pe oun ko mọ wi pe ọna eru ni wọn fi ba oun gba.
Awọn aworan yii wa lat'ọdọ AFP, Reuters, EPA ati Getty Images Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Oríṣun àwòrán, @NNPC Àkọlé àwòrán, Ọpọ igba ni awọn ile epo maa nda paro-paro ni ilẹ̀ Naijiria nitori ọwọngogo epo Alaga Igbimọ tẹẹkoto fun ile asofin agba ilẹ yi to wa fun ọrọ epo rọbi, Sẹnatọ Kabir Marafa ni pẹlu ibi ti nkan de duro bayii, orilẹede yii fẹ mọ iye owo ti jala epo kan ba de lati ilẹ okeere tawọn alagbata epo ti nko epo wọle pẹlu iye owo iranwọ ti wọn ngba lori jala epo kan ti wọn ba ko wọ ilẹ yii.
Ole Gunnar Solskjaer ti ti jawe olubori ifẹsẹwọnsẹ ere bọọlu mẹrinla ninu mọkandinlogun lati igba ti o ti jẹ adele fun osu mẹrin.
Ará, ẹ má ṣe jẹ́ kí rere su yín í ṣe.
Mose sì wí fún wọn pé, “ẹ gbọ́, ẹ̀yin ọlọ̀tẹ̀, ṣé kí á mú omi jáde fun yín láti inú àpáta yìí?
Odun 2019 yii ni igba akọkọ ti Burundi a yege lati kopa ninu idije ifẹ ẹyẹ Adulawọ AFCON.
Ọkunrin naa, lawọn ọkọ ọlọpa kan sadede da duro lẹba titi, ti wọn si wọ bọ silẹ ninu ọkọ rẹ.
Christchurch shootings: New Zealand pá lọlọ ni ìrántí awọ́n ti agbebọ́n pa ní Mọ́ṣáláṣí Christchurch
O ni ko si ohun ẹni to lee fi atọna miran to yatọ si ifa jẹ ọba nilẹ Yoruba ti ko ni ta ko awọn eewọ gbogbo ti ipo naa da le lori ti yoo si ni ipa lori ilu.
Bẹ́ẹ̀ ni ara yín yóo ṣe yá, ẹ óo sì mọ ìdí tí Ọlọrun fi ń jẹ yín níyà.
Mí ò tíí ní ìpinnu lóri ìdíje ààrẹ ọdún 2023 Oríṣun àwòrán, Getty Images Uganda Ni ti Aarẹ Yoweri Museveni, o sọ pe oun ko tii ṣetan lati ṣi ile iwe bayii.
 Òun ni ó jẹ president ilẹ ̀ Àméríkà lẹ ́ yìn washington .
Àwọn nkan tó yẹ kí o mọ̀ nípa ṣíṣe ìṣirò àsìkò tí o bá n yé ẹyin Èèyàn méjì kú, méjìdínlógóje míì ṣẹ̀ṣẹ̀ kó COVID-19 lọ́jọ́ Àìkú Ìjọba ìpínlẹ̀ Eko kéde ọjọ́ tí àwọn iléèwé gígá yóò wọlé Ọba ni mí, mi ò le b'ọ̀rìṣà, Olorì tuntun tó ń bọ̀ já gbogbo ''scale''- Oluwo ti Iwo Wọ́n tún ti pa omidan ẹni ọdún 18 míràn l'Akinyele ní ìlú Ibadan Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Natalia Mufuta ìyá Yakub, Kamil àti Adam sọ̀rọ̀ lórí bí wọ́n ń sọ èdè mẹ́rin pàpọ Ileẹjọ to ga julọ tun da ẹjọ onikoko meje ti oludije ẹgbẹ oṣelu SPD, Natasha Akpoti naa pe wi pe igbakeji gomina Kogi, Edward Onoja parọ ọjọ ori rẹ ati pe o tun fi ayederu iwe ẹri ranṣẹ si ajọ INEC nu.
Ǹ báà hu ìyẹ́, kí n fò lọ sí ibi ojúmọ́ ti ń mọ́ wá,kí n lọ pàgọ́ sí ibi tí òkun pin sí,
Wo àwọn ìlérí tàwọn Gómìnà tuntun ṣe nínú ìbúra wọn Ọba Adesoji Aderemi, Ọọ̀ni Ifẹ̀ tó gba ipò ọba mọ́ tòṣèlú Ìtàn tó wà nídi òwe ‘Sebótimọ Ẹlẹ́wà Sàpọ́n’ 'Ọmọ Naijiria 25,794 ló kú sí rògbòdìyàn láàrin ọdún mẹ́rin' Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ajayi: ṣé ìwọ mọ irúfẹ́ ọmọ tí Yorùbá ń pè bẹ́ẹ̀?
Ó ní, “Ẹ dúró títí ìlérí tí Baba mí ṣe yóo fi ṣẹ, gẹ́gẹ́ bí ẹ ti gbọ́ tí mo sọ fun yín.
Akọwe agba ẹgbẹ NUT lorilẹede Naijiria, Ọmọwe Mike Ike-Ene ṣalaye fawọn oniroyin pe ọpọ igba lo jẹ pe awọn olukọ nii fi ara ko ina wahala igbesunmọmi tabi rogbodiyan lasiko to ba ṣẹlẹ lawọn agbegbe oke ọya orilẹede Naijiria.
Jin bá bọ̀ bí ẹní pòwe.
O ni kii ṣe nkan to pamọ pe igun Tinubu wa ninu ẹgbẹ oṣelu naa.
19 Àwọn ohun aláìlágbára ti ayé yíò jade wá, wọn yíó sì wó àwọn alágbára àti àwọn tí wọn ní ipá lulẹ̀, pé kí ènìyàn máṣe gba ọmọnìkejì rẹ̀ ní ìmọ̀ràn, bẹ́ẹ̀ni kí ó má gbẹ́kẹ̀lé apá ẹran ara—
ni itagbangba nibi ti Ajọ INEC fi ọwọ si wi pe idibo yoo ti waye.
Ẹwẹ, o ni awọn ṣọọṣi kan o ti sọ iwe aṣẹ wọn d'ọtun, ati wipe awọn alaṣẹ o ni faaye gba wọn lati maa ba iṣẹ lọ.
leti bi a ba fura si iwa kan tabi awọn eniyan kan ti iṣesi wọn le ṣakoba
Iyawo rẹ nìyí, gba nǹkan rẹ, kí o sì máa lọ.
Ekiti Election: Ẹgbẹ́ awakọ̀ Ekiti pa ìjọba dà lẹ́yìn tí wọ́n kéde Fayẹmi
Ajo to n ri si boolu afesegba lorile-ede Naijiria, NFF sajoyo ayeye ojo ibi pelu akonimoogba agba iko Super Eagles, Gernot Rohr leni ti o se ayeye ojo ibi odun márùndínláàdọ́rin nilu Essentuki, lorile-ede Russia lojobo (Thursday).
Nibayii lẹyin ti o ti han gbangba pe agba orin yii ko jade laye gẹgẹ bi awọn kan ṣe sọ, baba funrarẹ ti jade sita pe o ṣeeṣe ki iyawo tuntun o wọle laipẹ o.
Gẹ́gẹ́ bí mo ṣe rántí, nígbà tí ó bẹ̀rẹ̀ sí í yé mi, mo ti máa ń ṣàkíyèsí pé àwọn aláwọ̀ dúdú kì í ní ẹ̀tọ́ kankan, ṣùgbọ́n àwọn aláwọ̀ funfun ará Mauritania máa ń ní àǹfààní tí ó pọ̀.
Makinde ti sọ̀rọ̀ lẹ́yìn tí asekúpani Akinyele sálo mọ́ àwọn ọlọ́pàá lọ́wọ́ ní àhámọ́ Iná sọ lóòtọ́ láàfin mi, ṣùgbọ́n kò sí gìrí- Ooni Ile Ife Risikat, ìyá àwọn ọmọ olójú búlù tí bẹ̀rẹ̀ sí ní kọ́sẹ́ aṣojú lóge Ìjọ́ mí ní Italy ni mo fi ń ṣèrànwọ́ fáwọn aṣẹ́wó ọmọ Nàíjíríà tó há - Taribo West 3) Ile iwe kọọkan gbọdọ ṣeto ọkọ to n gbe alaisan nipa iṣẹlẹ apajawiri ki wọn si ni oore ọfẹ lati tete ṣe ayéwo lasiko pẹlu itọju pẹlu ajọ NCDC to n risi itankalẹ ajakalẹ arun ni NAijiria.
Àwọn ọmọ Lefi yóo máa ṣe ìtọ́jú gbogbo ohun èlò Àgọ́ Àjọ, wọn óo sì máa ṣe iṣẹ́ iranṣẹ fún gbogbo ọmọ Israẹli bí wọ́n ti ń ṣe iṣẹ́ níbi mímọ́.
OLUWA, dáríjì Israẹli, àwọn eniyan rẹ, tí o ti rà pada, má sì ṣe jẹ àwọn eniyan Israẹli níyà nítorí ikú aláìṣẹ̀ yìí.
Kìí ṣe gbogbo ohun tí dókìtà ni kí n má jẹ torí àìsàn jẹjẹrẹ ni mo tẹ̀lé- Soyinka Ìjọba Ọ̀yọ́ bẹ̀rẹ̀ fínfín àwọn ìgboro pẹ̀lúu apakòkòrò nítorí COVID-19 Ìrìnàjò Toyin Abraham, láti orí gbèsè jíjẹ, ó di onílé, onimọto àti aya lọ́ọ̀dẹ̀ ọkọ Kí làwọn ìdàmú tí Coronavirus n mú bá àgọ́ ara?
O ni awọn mẹta lo ku loju ẹsẹ ti awọn yooku si ti n gba iwosan nileewosan ọgba ẹwọn naa.
"Oríṣun àwòrán, Getty Images Pasitọ Chogo tilẹ tun sọ pe ""koda koo jẹ Saddam Hussein tabi Muammmar Gaddafi, ohun kan tabi meji ṣi wa ti o ti ṣe fawọn eeyan rẹ ni daradara""."
Mo dúpẹ́ o, mo dúpẹ́ o, mo dúpẹ̀ o, o ṣe é o, o ṣe é púpọ̀, mò ń lọ, o dìgbà, o dìgbà, o dìgbà abbl.
Wọ́n ni ìjà náà bẹ́ sílẹ̀ nítori owó tí àwọn ọlọ́kọ̀ máa n san ti wọ́n bá fẹ́ gbe ìrẹsì wọ inú ọja Sinawa tó wà ni ìlú Ilésha Baruba.
Jehu bá gbé ojú rẹ̀ sókè, ó ní, “Ta ló wà lẹ́yìn mi ninu yín?
Olóògbé Adébáyọ̀ Fálétí padà si ilé-ìwé  lati lọ pari ìwé mẹfa ti ó dá dúró nigbati kó si agbára fún bàbá rẹ.
Ọkunrin kan wà níbẹ̀ tí ó ti ń ṣàìsàn fún ọdún mejidinlogoji.
Gbogbo ènìyàn ń wá kí wa ní ilé wa, àwọn ẹbí bàbá mi ń pòòyì, wọ́n á sọ ọ̀rọ̀ kẹ́lẹ́kẹ́lẹ́, ṣùgbọ́n kò sí ayọ̀ ní ojú wọn, ojú wọn kan gógó, kò sì sí ẹni tí ó pariwo sọ̀rọ̀ tàbí tí ó bèèrè óńjẹ lọ́wọ́ ìyá mi gẹ́gẹ́ bí àṣà ènìyàn kan tí ó fi ara mọ́ wa púpọ̀.
yálà àwọn àlùjọ̀nnú ojú-ọ̀run tabi àwọn ẹbọra inú ilẹ̀; lọ́rọ̀ kan, kò sí ẹ̀dá náà tí ó lè yà wá kúrò ninu ìfẹ́ tí Ọlọrun ní sí wa nípasẹ̀ Kristi Jesu Oluwa wa.
Toyin Abraham: Òṣèré Nollywood ti daya Kolawole Ajeyemi.
Nítorí náà, n óo fún wọn ní igi tí ó korò jẹ, n óo sì fún wọn ní omi tí ó ní májèlé mu.
"Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: N kò fẹ́ ṣiṣẹ́ aṣẹ́wó ló mú mi máa wa ọkọ̀ taxi - Obìnrin tó ń wa Uber Boko Haram ń kó ẹja gbígbẹ wọlé láti rí owó ra oúnjẹ - Iléeṣẹ́ ológun Èrò márùn-ún kú, méjì farapa, tí awakọ̀ sì fẹsẹ̀ fẹ nínú ìjàǹbá ọkọ̀ l‘Ondo Wo àwọn àkókò tó yẹ ko sàìsàn, tí ara rẹ yóò fì tètè dá Gẹ́gẹ́ bi ọ̀rọ̀ rẹ̀ "" wọ́n ti pe àkíyèsí ilé iṣẹ́ to n se akoso eto ìbáraẹnisọ̀rọ̀ Nàìjíríà, sí ìpínu ilé iṣẹ́ MTN láti máa yọ nàira mẹ́rin láàrin ogún ìṣẹ́jú ààyá bí owo àtẹjisẹ́ si bánkì."
Bakan naa, laipẹ yii ni won si awon
Dokita onimọ nipa bi egungun inu ara ṣe n ṣiṣẹ, Abubakar Ahmad Tsafe, ti ileewosan Gbogboogbo Farida, nilu Gusau nipinlẹ Zamfara, sọ nipa awọn iwulo ati anfaani ere idaraya fun ibalopọ to dara fun ọkunrin ati obinrin.
Yóo ti pẹ́ tó tí èrò burúkú yóo fi máa wà lọ́kàn rẹ?
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, #Oshimole: Àwọn aṣáájú APC kò mọ ohun ti wọ́n n ṣe lásìkò yí Ọga agba ileewe girama naa, Hajiya Adama Abdulkarim ṣalaye fun awọn oniroyin pe ida ọgọrin ninu ọgọrun awọn akẹkọ ati olukọ ileewe naa ni wọn ti pada si ẹnu ẹkọ ati iṣẹ wọn.
Wọn óo máa sọ pé, “Kí ni ó ṣẹlẹ̀ sí ìlérí pé Jesu tún ń pada bọ̀?
“Ẹ dìde, ẹ jẹ́ kí á kúrò níhìn-ín.
Children's Day: Àwọn ọmọdé tó ń ṣe bẹbẹ láwùjọ Afíríkà
Sugbọn iroyin to tun tẹ wa lọw nirọlẹ Ọjọru lo fi lede pe ìjọba Oyo naa tun ti pahunda, to si faaye gba awọn ile ijọsin lati se aisun ọdun.
Lẹ́yìn tí wọ́n kúrò ní Obotu wọ́n pa àgọ́ sí Òkè-Abarimu ní aṣálẹ̀ tí ó wà níwájú Moabu, ní ìhà ìlà oòrùn.
Nítorí bí ẹ̀jẹ̀ ewúrẹ́ ati ti mààlúù ati eérú abo mààlúù tí a bù wọ́n àwọn tí wọ́n bá ṣe ohun èérí nípa ẹ̀sìn bá sọ wọ́n di mímọ́ lóde ara, 
Oríṣun àwòrán, @aishambuhari Florence Ajimobi jáde ilé opó lẹ́yìn ọjọ́ 140 tí ọkọ rẹ̀ jáde láyé Aya gomina ipinlẹ Oyo tẹlẹ, Abiola Ajimobi to ti di oloogbe bayii, Florence Ajimobi ti jade ile opo lẹyin ogoje ọjọ.
Ẹ kò mọ ibi tí ó ti yọ wá, sibẹ ó là mí lójú.
Nigba to n sọrọ nibi ipade naa, Ajimobi ni gbogbo ọmọ ẹgbẹ lo kopa ribiribi ninu aṣeyọri ẹgbẹ APC nipinlẹ Oyo lọdun 2011 ati 2015.
lori bi won yoo se yọ arabinrin  Zainab
Gomina Ifeanyi Ugwuanyi fowo si eto isuna owo ti yoo mu igberu ba eto oro-aje, ti iye re le logorun bilionu fun odun 2018 laipe yii,O salaye pe, owo rira awon irin-ise fun ti odun 2018 yii, gbe peeli ju ti odun 2017 lo, eyi ti iye re le ni adota bilonu owo Naira.
Iléẹjọ́ Ekiti: Bàbá àti ọmọ jí igi gẹdú tó tó ₦100,000
Nígbà náà ni Jonatani mọ̀ dájú pé, baba òun pinnu láti pa Dafidi.
Òfin ṣe ìlànà nípa irú ẹbọ kan náà tí àwọn eniyan yóo máa rú lọdọọdun.
Lọpọ igba, awọn ara Amẹrika ti ni ẹni to ba ni oun kii ṣe ara inu ile nla funfun White House eyi si jẹ ohun to nira fun Biden lati sọ ni ti ara rẹ lẹyin to ti fẹẹ lo aadọtun nipo giga ninu oṣelu wọn si le lo iriri ọlọdun gbọọrọ yi lodi si i.
alaafia ni awon ẹkun ila oorun Ariwa paapaa jul,ọ ni ipinle Borno .
Number Plate: Ìlànà FRSC rèé láti gba nọ́mbà àdáni fún ọkọ̀ rẹ
Oríṣun àwòrán, lizzy anjorin/instagram screenshot Lizzy tẹsiwaju ninu ọrọ rẹ pe, ọdun mẹrinla ni oun fi ba ọkọ oun rin, eyi to fun oun ni anfaani lati mọ irinsi rẹ, ati awọn to ti fẹ ri, ṣugbọn ti ko si fẹsẹmulẹ ninu ofin igbeyawo.
Ní ọjọ́ ìpọ́njú mi, mo wá OLUWA;ní òru, mo tẹ́wọ́ adura láìkáàárẹ̀,ṣugbọn n kò rí ìtùnú.
Faye Mooney: Ìlú Eko ló ti lọ sóde àríyá ní Kaduna ni wọ́n yìnbọn fun
Awọn alaṣẹ sọ pe igbesẹ naa jẹ ọna lati pa ofin tita kete siraẹni mọ.
Wọn ti yọ olori ile aṣofin ipinlẹ Ondo, Bamidele Oloyelogun ati igbakeji rẹ, Iroju Ogundeji kuro nipo.
ti aare Muhammadu Buhari bo sori aleefa ni oun ri owo ifeyinti ati awon owo
Dotun Ajon ni iru nkan bayi ni awọn ọmọ ẹgbẹ oselu YPP ti n pariwo lọjọ to ti pẹ.
889 legbegberun ati agbegbe 18,098 km ² .
Koda a ma fun wọn láánfàní iṣẹ tó da ati ibaṣepọ pẹlu awọn to lẹnu lọrọ láwùjọ.
Ìrìnkèrindò, o tún di ẹni ti ń fẹ́ pa mi!
Nigba ti Minisita fun ajọ to n ri si ọrọ to je mo awon osise ati ise  lorile ede Naijiria ,Chris Ngige n ba awon
Aare ni igbagbo pe, ”Ipa ati ise akinkanju, bee si ni aforiti re ninu ise naa mu iyipada ati igberu ba ise ohun lawujo.
Nígbà tí Jehoahasi gbadura sí OLUWA, tí OLUWA sì rí ìyà tí Hasaeli fi ń jẹ àwọn eniyan Israẹli, ó gbọ́ adura rẹ̀.
Àyẹ̀wò ti fi hàn pé ewé igi mimosa yóò ṣí sílẹ̀ tàbí kó padé nínú òkùnkùn, nípasẹ̀ agogo ara rẹ̀, yàtọ̀ sí oòrun.
Wọn ni ko wa lọ ṣere ni ọgba ẹwọn titi di Ọjọ Kọkanlelogun, Osu Keji, ọdun 2020.
Merkel sọ igbesẹ naa di mimọ nibi ipade ajumọṣe kan ti oun ati Aarẹ Naijiria, Muhammadu Buhari sẹ pẹlu awọn oniroyin nilu Abuja.
Ṣugbọn Ọlọrun yóo ra ẹ̀mí mi pada lọ́wọ́ ikúnítorí pé yóo gbà mí.
Kia ni wọn ti bẹrẹ 'hash-tag' lori ayelujara lati fẹhonu han.
 ní àwọn ìpò líle ó lè fa ara pípọ ́ n , ìmú lójìjì , dákú tàbí ikú .
Wọn ni bi abẹrẹ naa yoo ṣe ṣiṣẹ ni pe, yoo pese eroja aṣara loore, eyii ti yoo le gbena woju kokoro arun Coronavirus ninu agọ ara.
Ewe, bi a ko ba gbagbe wi pe, ikọ agbaboolu Real Madrid ti n fẹ
“Bí ọ̀rọ̀ ti rí yìí, ó yẹ kí kabiyesi yan ọkunrin kan tí ó gbọ́n, tí ó sì lóye, kí ó fi ṣe olórí ní ilẹ̀ Ijipti.
Bakan naa lo fikun pe ilana ẹkọ ọfẹ ti Jakande se lo fun ọpọ ọmọ nipinlẹ Eko lanfaani lati lọ sile ẹkọ, to si tun kọ ilegbe olowo pọọku to pọ julọ ti ijọba kankan yoo kọ ri, boya ni ipinlẹ ni abi labẹ ijọba apapọ.
"Emi ko ri iru isẹlẹ ipaniyan bi eyi ri, ti awọn eeyan n sare kiri, ti ọpọ wọn si n subu lulẹ, ti wọn n ku.
Ẹni tí ó bá ń dẹ́ṣẹ̀ kò ì tíì rí i, kò sì tíì mọ̀ ọ́n.
Tinubu kìlọ̀ fún Buhari, Osinbajọ lórí àfikún owó orí ọjà VAT 'Fashọla, o ò dẹ̀ bẹ̀rù Ọlọ́run!
Ẹ wo bí Hushpuppi ṣe farahàn nílé ẹjọ́ l'Amẹrika fún ìgbà àkọ́kọ́ láti jẹ́jọ́ Bàbá Aláàfin ìlú Ọ̀yọ́, Elérúwà àti àwọn Ọba Ilẹ̀ Yorùbá míràn tí wọ́n rọ̀ lóyè Ìjọba Nàìjíríà ti mú Dókítà Anu tí àwọn kan f'ẹ̀sùn kàn pé ayédèrú iṣẹ́ abẹ ìdí ló n ṣe Erépá ní bàbá àti ìyá mi ṣe tí wọ́n fi bí mi, wọn kò fẹ́ra wọn- Funsho Adeolu Eyi lo si fi opin si ìjẹ gàba rẹ ni agbegbe naa.
awon to jawe olubori ninu eto idibo naa ni iwe ẹri mo yege ki o to di  ọjọRu ọsẹ 
Ẹwẹ, ogun antibiotics ti wa to lee wo aisan naa.
Nebusaradani kó gbogbo wọn lọ sí ọ̀dọ̀ ọba Babiloni ní Ribila.
Ajẹ́pé kò sí nínú àṣà wa láti ìbẹ̀rẹ̀ pẹ̀pẹ̀.
Ìfilọ́ọ́lẹ̀ rẹ̀ lọ́dún 1980s ló sọ ǹkan ìṣeré ìbálòpọ̀ di gbajúgbajà - ìrísí rẹ̀ jọ ti èkúte.
Àwọn ọmọ Aaroni ni Nadabu, Abihu, Eleasari ati Itamari.
gbungbun Oyo (Oyo Central Senatorial District) ninu idibo to waye ni ose meji
Wọ́n bá gba owó ìdúró lọ́wọ́ Jasoni ati àwọn yòókù, wọ́n bá dá wọn sílẹ̀.
Fun apẹrẹ, wọn a maa lo Aapu kan to n jẹ Fliters"" lati fi yọ ohun bii kurukuru to ba wa loju wọn ṣaaju ki onifọto to ya wọn."
Ni ọjọ iṣẹgun ni Tottenham ti kọkọ ṣide ijiya naa nigba ti ẹgbẹ agbabọọẹu Ajax ti ilu Amsterdam lorilẹede Netherlands naa mọle pẹlu ami ayo kan.
Police Recruitment: Ìlé ẹjọ́ ti pàsẹ pe ki ilé iṣẹ́ ọ̀lọ́pàá dá ìgbaniwolé dúró
Taribo ni ijọ oun, The Storm Miracle Ministry of All Nations, ni oun n lo lati tọ awọn eeyan naa sọna nipa igbe aye rere to yẹ ki wọn gbe.
Ti erongba Boris Johnson ba ṣẹ, o di ọjọ kẹrinla, oṣu kẹwaa ki wọn to tun jokoo pada.
Ojogbon Osinbajo so eyi di mimo lasiko ipade apero ajo naa, ti o waye ni gbagede Rotunda, nilu Abuja.
Ẹgbẹ agbabọọlu Manchester City ti wa loke tente idije Premier League lẹyin ti wọn na ẹgbẹ agbabọọlu Fulham pẹlu ami ayo meji sodo.
Ẹni ti kò ni ẹbi àti ará tàbi gbé ilú miran pàtàki Òkè-Òkun/Ilú Òyìnbó, yio lọ ṣe igbéyàwó ọmọ ni òkèrè.
Inú balùwẹ̀ ni kí ẹ máà sá pátá yín sí, ẹ má sa sí ẹ̀gbẹ́ fèrèsé.
ti ìwọ̀n àwọn ọ̀pá fìtílà wúrà ati àwọn fìtílà wọn, ti ìwọ̀n fadaka fún ọ̀pá fìtílà kan ati àwọn fìtílà wọn, gẹ́gẹ́ bí ìlò olukuluku wọn ninu ìsìn.
Ṣugbọn bí ẹni tí kì í ṣe onigbagbọ bá yàn láti fi ẹnìkejì tí ó jẹ́ onigbagbọ sílẹ̀, kí ó fi í sílẹ̀.
Ọba Israẹli wí fún Jehoṣafati pé, “Ṣé o ranti pé mo ti sọ pé kò sọ àsọtẹ́lẹ̀ rere fún mi rí?
Adebisi ní ìjọba gbé ìgbésẹ̀ yìí nítorí bi àrùn Covid-19 ṣe n peléke sii lójoojúmọ́ ní ìpińlẹ̀ Osun.
Swansea lo kọkọ gbayo meji wọ le ami ninu ifẹsẹwọnsẹ ọhun.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Coronavirus lockdown: Bí àrùn Coronavirus ṣe dá gbogbo àgbáyé gúnlẹ̀ sójú kan náà nìyí 9 Ìgbé 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 8 Agẹmo 2020 Aarun coronavirus ti kọlu eniyan to le ni miliọnu kan ni agbaye báyìí, sugbọn ipa to ni to ni kọja ọdọ awọn to ni i.
Ami-ayo kan soso ti agbaboolu eyin orile-ede France, Samuel Umtiti gba wole niseju mọ́kànléláàdọ́ta saa keji ifesewonse ohun lo ran iko re lowo lati fagbahan orile-ede Belgium, pegede fun asekagba idije agbaye ohun.
Serena Williams gba ife ẹ̀yẹ àkọ́kọ́ láàrin ọdún mẹ́ta sẹ́yìn Naira Marley, Burna Boy àti Rema ló kó àmì ẹ̀yẹ tó pọ̀jù ló ni MVP Ọbabinrin Ilẹ̀ Gẹ̀ẹ́sì àti Ọmọọba Harry yóò sèpàdé ní Ọjọ́ Ajé Ṣé àsọtẹ́lẹ̀ ìjàmbá iná kò tíì máa ṣe báyìí?
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Trump picture: ọjọ́ tí Trump kí mi kú iṣẹ́ lórí 'twitter' ní inú mi dùn jù- Oyedele Siasia to wa lara awọn agbabọọlu Naijiria to gba ife ẹyẹ ilẹ Afirika lọdun 1994 lorilẹ-ede Tunisia, sọ pe lori ayelujara loun naa ti gbọ ẹsun ti ajọ FIFA fi kan oun gẹgẹ bi ọpọ ọmọ Naijiria naa ṣe rii.
Eeyan 46,140 ni apapọ ni arun naa ti fara kan labẹ ayẹwo, ti awọn 33,044 si ti ri iwosan gba lọwọ ajakalẹ arun ọhun.
Iroyin n bo lori rẹ lẹkununrẹrẹAdemola Adepoju.
Nígbà tí ó dé ìlú baba rẹ̀, ó ń kọ́ àwọn eniyan ninu ilé ìpàdé wọn lọ́nà tí ó yà wọ́n lẹ́nu.
Bi awada bi ere ni awọn mejeeji fi bẹrẹ ṣiṣe ẹda sinima, koda wọn ko ka a si nigba naa.
Jẹ́ kí ẹ̀mí rere rẹ máa tọ́ mi ní ọ̀nà tí ó tọ́.
” Eli tún dá a lóhùn pé, “N kò pè ọ́, ọmọ mi, pada lọ sùn.
Ni nkan bi ọdun 1850 ni wọn kọkọ gbe Bibeli jade ni èdè Yoruba, lati ọwọ Oloogbe Ajayi Crowther, to jẹ ọmọ bibi ìlú Osoogun nipinlẹ Oyo.
Vice Presidential Debate: Àwọn olùdíje n fọ̀rọ̀jomitoro
Eyi lo ṣebi ẹni difa fun awọn eeyan agbegbe Kosobo ni ilu Ọyọ alaafin ti wọn ni wọn ke gbajare tọ iku baba yeye, Alaafin Lamidi Ọlayiwọla Adeyẹmi kẹta lori ilẹ kan ti wọn ti pati eleyi ti wọn ni o ti di igbo nla saarin ilu ti wọn si ni o ti di ibuba fawọn oniṣẹ ibi gbogbo.
Akitiyan lati kàn si awọn adari ẹgbẹ ọlọkọ ero NURTW nipinlẹ Eko, lo ja si pabo lasiko ti a fi nko iroyin yii jọ.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: APC ni kìí ṣe àsíà Kelly Costner làwọ́n lò Ẹ fójú lóúnjẹ níbi ìbúra wọlé Oyetọla l'Ọṣun Ninu ijọba Buhari lawọn ole wa — Fayose Hubert Ogunde rèé, baba àwọn òsèré tíátà Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Onigbajamọ: Báwo lẹ se gbọ́ èdè Yorùbá sí?
Bákan náà ni Gani rọ Fayose láti dẹkun àwọn ọrọ to le dá wàhálà sílẹ̀ láàrin àwọn àgbà ẹgbẹ́, tàbí èyíkéyìí tó lo dènà ìlọsíwájú ẹgbẹ́ òṣèlú PDP ni ìhà Iwọ̀oorù-Gúúsù Naìjíríà.
N kò tẹ́wọ́ gba ọrẹ ẹbọ sísun tí ẹ mú wá siwaju mi,bẹ́ẹ̀ ni ẹbọ yín kò dùn mọ́ mi.
O ti gé ìgbà èwe rẹ̀ kúrú;o sì ti da ìtìjú bò ó.
Ki ẹ gba aaye to ba sofoO wa ro awon obinrin lati gba aaye to ba sofo ninu egbe oselu, ki won si lowo ninu idagbasoke.
Iroyin sọ pe awọn janduku naa bẹrẹ si nii lọ kaakiri ijoko ni papa iṣire naa ti wọn si n le awọn ti wọn ba funra si pe wọn jẹ ololufẹ Dapọ Abiọdun kuro ni aye wọn.
Agbẹnusọ rẹ Lere Olayinka lo buwọlu atejade yi to si ni Fayose ko ni yẹ ko ni gbo lati maa sọ ododo nigbakugba.
 wọ ́ n wá sí ilẹ ̀ Ìjẹ ̀ ṣà láti dó sí kí wọn lè ni àyè ìjọba tiwọn .
Ohun ti mo mọ ni pe pupọ awọn ti ọrọ kan ni wọn ti gba ẹbun ile tiwọn lọwọ ijọba.
Ekene ni awọn ọrọ ẹlẹya yii dun oun de ibi pe, oun mu ọbẹ lati lọ gba ẹmi ara oun lọjọ kan.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Mo máa n forin mi kìlọ̀ ìwà ìbàjẹ́ láwùjọ ni -Hameen Ni ọjọ Ẹti, ohun ti ileeṣẹ ọlọpaa kọkọ kede ni pe ọwọ ti tẹ ẹsọ naa, lẹyin igba naa ni wọn ni o yinbọn pa ara rẹ lẹyin to ṣeku pa awọn ọgagun mejeeji.
Aṣiri to tun ọhun lo mu ki wọn o yọju si ọọfisi orilẹede Saudi to wa ni ilu Abuja lati bẹrẹ igbesẹ lori bi Zainab yoo ṣe gba ominria.
 olá tí pò títí , olá tí ò lábùkù .
Ajẹ́pé àwọn ewé ti bẹ̀rẹ̀ sí í wọ́ lórí àwọn igi.
Ó fi Adoniramu ṣe alabojuto wọn.
 ọ ̀ rọ ̀ geere , ìwé tí a kọ ní ọ ̀ nà ọ ̀ rọ ̀ sísọ tààra tí kì í ṣe lọ ́ nà ti orin .
Isco ti oun naa jẹ ọkan lara awọn akẹgbẹ Modric ni ikọ Real Madrid ni oun naa ni akọni agbabọọlu to fakọyọ julọ lasiko yii.
Nígbà tí Ahasi lọ pàdé Tigilati Pileseri ọba, ní Damasku, ó rí pẹpẹ ìrúbọ kan níbẹ̀, ó sì ranṣẹ sí Uraya alufaa pé kí ó mọ irú rẹ̀ gan-an láìsí ìyàtọ̀ kankan.
tí fèrè ń dún kíkankíkan, tí ohùn kan wá ń sọ̀rọ̀ ní ọ̀nà tí ó jẹ́ pé àwọn tí ń gbọ́ ọ bẹ̀bẹ̀, pé kí àwọn má tún gbọ́ irú rẹ̀ mọ́.
Àní ọ̀rẹ́ kòríkòsùn mi tí mo gbẹ́kẹ̀lé,tí ó ń jẹun nílé mi,ó ti kẹ̀yìn sí mí.
Nítorí ẹ̀ ń kọ́ ibojì àwọn wolii, bẹ́ẹ̀ sì ni àwọn baba yín ni wọ́n pa wọ́n.
Gbadebo to jẹ akẹkọọ ọlọdun kẹta ni fasiti Ibadan lo lọ ṣiṣẹ fun igba diẹ ni ileeṣẹ Henkel Nigeria Limited, amọ to kò si inu ẹrọ to n ṣe ọṣẹ, to si gba ibẹ ku.
 Genevieve sọ pe ọkunrin to ba ni ki o fi ìfẹ hàn s'oun nipa Ibalopọ n lo ẹ ni, yóò ja ẹ ju silẹ to ba ti ri ẹlomiran to gbadun Ibalopọ pẹlu rẹ ju ẹ lọ.
Mo sá kúrò nílé tí mo yá mílíọ̀nù 17 kọ́ ní Àkútè- Bayo Okeowo À ń gbé ìjọba ìpínlẹ̀ Ọyọ lọ si ilé ẹjọ- Ẹgbẹ́ Fulani darandaran A kò mọ̀ bóyá a le è san owó osù tuntun fún òsìsẹ́ - Ìjọba Ondo, Oyo, Kwara jẹ́wọ́ Géńdé agbébọn jí adájọ́ gbé lọ ní ìpínlẹ̀ Ondo 'Àwọn ti Micra ló jẹ̀bi rògbòdìyàn awakọ̀ tó wáyé lánàá n'Ìbàdàn' Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí kan sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
Nítorí ohun tí a rí ni pé nípa igbagbọ ni Ọlọrun ń dá eniyan láre, kì í ṣe nípa pípa Òfin mọ́.
"O ni "" Mo si dupẹ lọwọ awọn obi mi; mo lọ sileewe, mo ni iwe ẹri to dara, mo niṣẹ gidi lọwọ, mo ti rinrinajo kaakiri agbaye, mo tun n fun awọn eeyan ni nkan ni awujọ."
ọjọRu ọsẹ yii sọtọ fun isinmi lati fi sami ayajo odun awon osise ti odun 2019.
OLUWA yóo fi wọ́n lé ọba lọ́wọ́.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Tsunami: Lẹ́yìn ọ̀sẹ̀ kan ti Jumasil ti sọnù ni wọ́n rii padà Oṣu kẹta ọdun 2018 ni wọn jii gbe lasiko to fi n ba ajọ idagbasoke awọn ọmọde labẹajọ iṣọkan agbaye, UNICEF, ṣiṣẹ ni ilu Rann, lẹkun ila oorun ariwa orilẹ-ede Naijiria.
Eni kan to ba wa sọrọ to jẹ ogbontarigi nile ijọba ti ko fẹ ki wọn darukọ oun fidiẹ mulẹ fun BBC pe otitọ ni iroyin naa.
O ba awọn oniroyin sọrọ ninu ifọrọwanilẹnuwo kan nibi to ti sọ wipe, oun n ki Atiku ku ori ire, nitori wipe, yoo bori ninu idibo 2019.
Ẹ má gbàbọ̀de kankan láti tú Wolii ìjọ Sotitobire sílẹ̀ o!
Nígbà tí ẹ bá sì dúró, àwọn ọmọ Lefi ni kí wọn pa Àgọ́ náà.
N óo sọkún tẹ̀dùntẹ̀dùn,omi yóo sì máa dà lójú mi,nítorí a ti kó agbo OLUWA ní ìgbèkùn.
Ọdún Kérésì jẹ́ ọdún Onigbàgbọ́ lati ṣe iránti ọjọ́ ibi Jésù Olùgbàlà.
Alukoro ẹgbẹ agbabọọlu Rangers ṣalaye pe awọn agbabọọlu naa rinrin ajo lọ si ilu Eko lẹyin ti idije liigi Naijiria(NPFL) ti di siso rọ ki ijamba naa to ṣẹlẹ.
Ọgbọ́n níye lórí ju wúrà ati dígí lọ,a kò lè fi ohun ọ̀ṣọ́ tí a fi wúrà dáradára ṣe dípò rẹ̀.
Aseyori yii jẹ ko jẹ igba mejidinlogun (18-0) ti afẹsẹkubiojo Adesanya ti jawe olubori to si fi gba Ami Ẹyẹ UFC Middleweight Champion.
Ó gba àmì ìkọlà bí ẹ̀rí iṣẹ́ rere nípa igbagbọ tí ó ní nígbà tí kò ì tíì kọlà.
" Tinubu ni ilakaka oun lo wa lati ran awọ̀n eeyan ipinlẹ́ Ọsun lọwọ.
Apapọ awọn to ti ni arun naa kaaakiri orilẹ-ede Naijiria ti wa di 14,554 bayii.
“Ṣugbọn kò ní sí ẹnikẹ́ni ninu yín tí yóo jẹ́ talaka, nítorí pé, OLUWA Ọlọrun yín yóo bukun yín, ní ilẹ̀ tí ó fun yín láti gbà, 
Àwọn ọmọ ogun Juda hó ìhó ogun, bí wọ́n sì ti kígbe ni Ọlọrun ṣẹgun Jeroboamu ati àwọn ọmọ ogun Israẹli fún Abija ati àwọn ọmọ ogun Juda.
Kaduna, Zamfara àti àwọn ìpínlẹ̀ tó ti ilé ìwé nítorií wahala Boko Haram àti ìdí míràn.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ọwọ́ ọlọ́pàá ti tẹ ọkùnrin kan tó pa ọ̀rẹ́ rẹ̀ nítorí N40 ní Kano 31 Ògún 2019 Oríṣun àwòrán, @others Àkọlé àwòrán, Ṣe o yẹ ki ẹmi eeyan sọnu nitori ogoji naira pere?
Gawat Àkọlé àwòrán, Ọpọ onwoye gbagbọ pe omi n bẹ lamu fun Oshiomole lori iṣọkan ẹgbẹ oṣelu naa Ẹgbẹ oṣelu APC ti bẹnu atẹ lu igbesẹ awọn ọmọ ẹgbẹ naa kan ni ipinlẹ Edo, ti wọn lawọn paṣẹ lo fidimọle fun alaga ẹgbẹ naa lapapọ, Adams Oshiomole.
Ó sọ fún un pé, “Dìde, gbé ọmọ náà ati ìyá rẹ́, kí o pada lọ sí ilẹ̀ Israẹli, nítorí àwọn tí wọ́n fẹ́ pa ọmọ náà ti kú.
Nítorí náà, ó dá ọba lóhùn pé, “Báyìí ni ó ṣe yẹ kí á dá ẹni tí inú ọba dùn sí lọ́lá: 
Messi ṣekú pa Man United ní Nou Camp Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí kan sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
 Àwọn ìmọ ̀ lára-àìsàn kì í sáàbà le ni ara , wọn kì í sì fi ojú hàn dáradára , lára wọn ni kí oúnjẹ má wù ènìyàn jẹ , kí ó máa rẹ ̀ ènìyàn , kí èébì máa gbé ni , ìrora inu-ẹran ara tàbí ìrora oríkèé-ríkèé ara , kí ènìyàn máa rù .
Ẹ má máa fi ojú tẹmbẹlu ẹ̀bùn wolii.
 whitehead ati david hilbert n sefilole lilo ogbon ati ironusi akojopo lati ṣèyé àwon ifilole mathematiki .
Aibọwọ fun ofin ti to gẹẹ Onochie fi kun un pe, Oyedepo n ti iwa aitẹle ofin lẹyin ni Naijiria, o ni ati ilu Ọba ni wọn ti n fi owo iranwọ ranṣẹ si Oyedepo, sugbọn o n dunkoko mọ ijọba ni Naijiria."
Nollywood stars: Àwọn èèkàn òṣèré sinimá ní Nàìjíríà jẹ́wọ́ ara wọn lórí fífi àmì ohùn sí ọ̀rọ̀ Yorùbá
Ọdun marun un ni Adesina yoo lo lori oye gẹgẹ bi aarẹ Banki ilẹ Afrika, AFDB lẹyin iburawọle fun saa keji naa.
Ijoba orile-ede ohun yan ogunjo inu osu karun un lati sajoyo pelu aare teleri, Ahmadou Ahidjo fun igbese re lati fopin ofin ati ilana ijoba ohun ti o sanfaani fun awon ara-ilu.
O le ni ida meji awọn obinrin ẹgbẹrun lọna mẹ́tàdínláàdọ́rùn ún ti iwadi naa ni lọdun 2017, wọn lugbadi iku lọwọ awọn to sunmọ wọn julọ.
tí ó ń wá ikú,ṣugbọn tí kò rí;tí ó ń wá ikú lójú mejeejiju ẹni tí ń wá ìṣúra tí a fi pamọ́ lọ?
Ẹ má ṣe jẹ́ kí á máa dá ara wa lẹ́jọ́ mọ́.
Onírúirú àwọn òṣèré  ni wọ́n máa ń ṣeré l’óde ibẹ̀.
Olukuluku ń purọ́ fún ẹnìkejì rẹ̀;ọ̀rọ̀ ìpọ́nni èké ati ẹ̀tàn ni wọ́n ń bá ara wọn sọ.
BBC Yoruba fi ọrọ wa takọtabo lẹnu wo lori pataki ibadọgba fun idagbasoke eyi to jẹ akori eto ti ọdun yii.
Ekong (Udinese FC, Italy); Leon Balogun (Brighton & Hove Albion, England);
Ninu ipo ate ajo FIFA lagbaye, iko agbaboolu Belgium dipo kinni mu pelu ami mẹ́tàlélọ́gbọ̀n le ẹ̀ẹ́dẹ́gbẹ̀sán(1733 points) lori tabili, ti France si di ipo keji mu pelu ami méjílélọ́gbọ̀n le ẹ̀ẹ́dẹ́gbẹ̀sán (1732 points).
Amọ Adamu lo kilọ fun pe ko sọra nipa awọn gbolohun to n jade lẹnu rẹ si ọrẹbinrin oun, bibẹẹkọ, oun yoo fi imu rẹ darin.
Mo dáríjì àwọn IPOB tó nà mí ní Germany nítorí wọn o m'ohun tí wọ́n ń ṣe- Ekweremadu Ọlọ́pàá Ogun gb'ọmọ Ìmáàmù lọ́wọ́ ajínigbé, ṣùgbọ́n wọ́n gbé ọkọ̀ ojú omi ọlọ́pàá lọ Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Awọn wo ni ọ̀rọ̀ yii kan ju?
'Ọdún 35 ni ọmọbìnrin gbọdọ̀ ti bímọ tán' Ogedengbe Agbógun Gbórò, Akọni tó ń dẹ́rù ba ikú.
Ó ní, “Bí ó bá jẹ́ pé Ọmọ Ọlọrun ni ọ́ nítòótọ́, bẹ́ sílẹ̀ láti ìhín.
Mo rí OLUWA, ó dúró lẹ́gbẹ̀ẹ́ pẹpẹ, ó pàṣẹ pé, “Lu àwọn òpó tẹmpili títí tí gbogbo àtẹ́rígbà rẹ̀ yóo fi mì tìtì, tí yóo sì wó lé gbogbo àwọn eniyan lórí.
Ibà jẹ aisan to maa n dunkoko mọ ẹ̀mí, eyi ti kokoro aifojuri mẹrin n fa: P.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Mike Zhang ọmọ China di 'Wakilin Yan China' ní ìpínlẹ̀ Kano Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Mike Zhang ọmọ China di 'Wakilin Yan China' ní ìpínlẹ̀ Kano 26 Ìgbé 2019 Onisowo Mike Zhang ti lo ọdun mẹtadinlogun ni ipinlẹ Kano gẹgẹ bíi oníṣòwò, o ní niṣe ni inu oun dun pẹlu ọla ti wọn da oun yii.
Ó ní àwọn ohun tí a fọwọ́ ṣe kì í ṣe oriṣa!
" Oríṣun àwòrán, @victoryomogiate Bakan naa lo fikun pe gbajumọ ti aye mọ ni mọ ni onibara oun, nitori naa, eeyan kan ko kan le wa lati fẹ fi onibara oun gun oke nitori iru iwa bayii pọ nilu ta wa yii, obinrin naa si kan fẹ jẹun ni lati bẹyin bẹbọjẹ fun onibara oun.
Ifipagbajọba lagbaaye Lagbaaye, ifipagbajọba ti ṣẹlẹ nigba 476 lati ọdun 1952.
Ọmọbinrin náà bá lọ sí ọ̀dọ̀ ìyá rẹ̀, ó ní, “Kí ni kí n bèèrè?
Obìnrin àti ọmọdé tó há sábẹ́ ilé tó wó ní Ebute Meta ti ń gba ìtọ́jú, LASEMA ń ṣàyẹ̀wò ilé náà lọ́wọ́ Yakubu Dogara padà sí APC, Buhari kí i kúàbọ̀ ní Aso Rock Wo àwọn tí wòlíì ríran sí pé COVID-19 yóò pa ní ìpínlẹ̀ Edo l'óṣù kẹsàn án Obìnrin àti ọmọdé tó há sábẹ́ ilé tó wó ní Ebute Meta ti ń gba ìtọ́jú, LASEMA ń ṣàyẹ̀wò ilé náà lọ́wọ́ Kọmisọnna fun eto ilera nipinlẹ Eko naa fikun un pe awọn n ṣiṣẹ pọ lati ri pe awọn mọ iye oju owo ti awọn n na lori awọn alaisan Coronavirus, ti awọn a si fi n ṣọwọ si awọn akọroyin.
Ǹjẹ́ ẹ tún ní arakunrin mìíràn?
 Àwọn ènìyàn kan láàrín ọjọ ́ kan tí ara wọṅ ti ń dá , ìbà náà padà wá , inú dídùn maa ń wáyé , àti ẹ ̀ dọ ̀ bíbàjẹ ́ bẹ ̀ rẹ ̀ èyí to ń fa àwọ ̀ ara pípọ ́ n .
Sunday Igboho: Mo fẹ́ jẹ́ ọ̀kan lára àwọn tó jà fún ilẹ̀ Yoruba
Ìfipábánilòpọ̀ kìí ṣe ìwà ọmọlúwàbí, àwọn òṣèré tíátà pariwo síta Ìdájọ́ ikú ni a fẹ́ fún àwọn afipábánilòpọ̀ - Ẹgbẹ́ ajàfẹ́tọmọnìyàn Kalu ni nigba ti oun wa ni ọmọ ọdun marun ati mẹrinla ni isẹlẹ naa waye.
“Ojú iná kọ́ ni ewùrà ń hurun”.
Ó bá wọ inú ilé lọ, ó ní, “Kí ló dé tí ẹ fi ń kígbe, tí ẹ̀ ń sunkún bẹ́ẹ̀?
Ìwọ́de afẹ́ àwọn abódiakọ-akọ́diabo àkọ́kọ́ lè tú èrò nípa wọn ní Pakístánì ká
Fun wa lorilẹede Naijiria, iyatọ nla ni ajọyọ ayajọ yii ba de.
jọ maa jiroro lori pipese eto alaafia ni ile afririka ati ni agbegbe to sunmọ ọn.
Ó tún gbé agbada omi ńlá tí a fi idẹ ṣe, tí wọ́n gbé ka ẹ̀yìn àwọn akọ mààlúù idẹ mejila, ó sì gbé e lé orí ìpìlẹ̀ tí a fi òkúta ṣe.
Wọ́n dá àwọn ọmọ rẹ̀ lọ́lá, ṣugbọn kò mọ̀,a rẹ̀ wọ́n sílẹ̀, sibẹ kò rí i.
papa isere naa, komisona to n mojuto ere idaraya ati oro awon odo nipinle Akwa
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Coronavirus: Ìjọba ní kò sí ìrìn-àjò sílẹ̀ òkèrè mọ́ fáwọn òṣìṣẹ́ ìjọba lásìkò yìí 18 Ẹrẹ̀nà 2020 Oríṣun àwòrán, Twitter/Muhammadu Buhari Lati akoko yii lọ, oṣiṣẹ ijọba kankan ko gbọdọ riinrin ajo lọ si ile okere mọ, ijọba apapọ lo kede ọrọ nitori ajakalẹ arun coronavirus to tan kalẹ kaakiri agbaye.
Mo wòye, mo sì rí i pé àgbá mẹrin ni ó wà lẹ́gbẹ̀ẹ́ àwọn Kerubu náà: àgbá kọ̀ọ̀kan wà lẹ́gbẹ̀ẹ́ Kerubu kọ̀ọ̀kan.
Igbese tipinle Ogun ti gbeGomina Ibikunle Amosun to n tuko ipinle Ogun ni guusu Naijiria ni ipinle Ogun ti setan lati gbalejo eleeketa iru re nibi ti onikaluku yoo ti ni anfani lati safihan ilu ile koowa lorisiirisii.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Mother's day: Ka àwọn ìròyìn tí BBC News Yorùbá tí ṣe fún ìdàgbàsókè àwọn obìnrin 31 Ẹrẹ̀nà 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Àyájọ́ àwọn ìyá lórílẹ̀èdè Nàìjíríà ń wáyé lónìí Ọpọ nnkan ni oju obinrin n ri lawujọ.
‘Jẹgúdújẹrá làwọn olórí tó ń lọ sókè òkun láti sèpàdé’ Ẹ fójú lóúnjẹ níbi African Drum Festival 2019 Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Africa Drum Festival 2019: Eruku sọ níbi àjọ̀dún ìlù l'Abẹokuta Musa sọ wi pe Ọgagun S.
O ni igbesẹ naa yoo ran ẹgbẹ Republican lọwọ lati yọ Trump kuro ninu ẹgbẹ naa.
gbólóhùn ni àwon wònyí sùgbón wón jo apis lásán .
Ẹ̀yin ọmọ Chelsea kí ló ǹ ṣẹlẹ̀ gan an?
Aarẹ mejeeji yoo sọrọ nipa eto aabo, gbigbogun ti awọn agbesunmomi, Ọrọ ajẹ ati idokowo laarin orilẹede mejeeji.
O ni ọbẹ̀ kìí mì nikun àgbà ni ati pé ọlọgbọn nikan lo le jó ilu agidigbo ti asọtẹlẹ ọdun 2019 jẹ fun Naijiria.
Bí o bá fẹ́, o lè fi ọwọ́ mú ohun tí ó jẹ́ ẹ̀tọ́ mi yìí, nítorí pé n kò lè rà á pada.
Koko nipa ajakalẹ arun iba Lassa lorilẹede Naijiria Awọn ọjọ ori ti aarun naa n damu julọ ni ni ọdun mọkandinlogun si ogoji ọdun.
Ọpẹ́lọpẹ́ rẹ̀ ni a fi rí ọ̀nà gbà dé ipò oore-ọ̀fẹ́ tí a wà ninu rẹ̀ yìí.
Ekiti Election: NBC ní EKBC ń gbé ayédèrú èsì ìbò síta
Ẹ dẹ́kun àbùkù tẹ fi ń kan Nàíjíríà, ẹ fi Sowore sílẹ̀ láhàmọ́ọ́ - Wole Soyinka Ọ̀pọ̀ àwòrán rèé tó ń sàfihàn bí Ibadan se kún fún ẹ̀gbin àti òórùn Àbádòfin ìdájọ́ yíyẹ igi fún 'ni tórí ọ̀rọ̀ ìkóríra!
Adele oludari agba fun ajọ to n ri si eto okoowo, ileesẹ nlanla, eto iwakusa ati ọgbin nipinlẹ Ọsun, OSUCCIMA, Oloye Jide Falọdun lo rawọ ẹbẹ bẹẹ, to si tun woye pe ko si orilẹede to lee goke agba laisi agbega asa rẹ.
ọjọ kọ̀kandinlọgbọn, oṣu Kọkanla, fihan pe, eeyan mejilelọgọrin tun ti ni aarun naa ni Naijiria.
Ràn mí lọ́wọ́, OLUWA, Ọlọrun mi,gbà mí, nítorí ìfẹ́ rẹ tí kì í yẹ̀.
O ni Ajimobi ni ko gba fun awọn ti wọn darapọ mọ APC lati ẹgbẹ CPC to jẹ pe awọn ti wọn tẹlẹ Ajimọbi wa lati ANC nikan lo n gbe sipo.
Nígbà tí Jesu dé ọ̀dọ̀ àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀, ó rí ọpọlọpọ eniyan pẹlu àwọn amòfin, wọ́n ti ń bá ara wọn jiyàn.
Nítorí náà kọ́ wa láti máa ka iye ọjọ́ orí wa,kí á lè kọ́gbọ́n.
Nítorí náà, wò ó, ọjọ́ ń bọ̀tí n óo fìyà jẹ àwọn ère ilẹ̀ Babiloni.
Ìbá wù mí kí àwọn tí ó ń yọ yín lẹ́nu kúkú gé ara wọn sọnù patapata!
lẹ ́ yìn èyí nínú ọdún 1960 , bámijí Òjó ṣe iṣẹ ́ díẹ ̀ láti fi kówó jọ .
Nibi ti wọn tin gbiyanju ati gbẹsan ni Pierre-Emerick Aubameyang ti gba bọọlu sinu awọn Watford lẹyin ti Henrikh Mkhitaryan gba bọọlu si ọdọ rẹ.
Ọsẹ kẹfa ree ti wọn ti gbọ ẹjọ wọn gbẹyin nigba ti wọn pa oju ẹjọ eyi ti agbẹjọrọ afurasi gangan n wi de ni ọjọ kejilelogun oṣu keje, ọdun 2020.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, East Africa: Àwọn kokoro ti ba èrè oko jẹ nílẹ̀ Afirika Ile Ẹjọ naa tun ni awọn eeyan gbọdọ mọ awọn eeyan to ni oju ara meji bii ara isẹda, ti ko si gbọdọ si idẹyẹsi.
 Eleyii wa ninu aba ti asofin Sanni , to je asoju ni ijoba ibile  ariwa ni ipinle Jigawa pe akiyesi ile igbimo asofin si, pe ti awon osise ijoba yii ba tun gunle iyanselodi ti won n gbero, o le pa eto oro aje ati iselu orile ede yii lara.
O ni: ọpọ n ṣe igbeyawo wọn ninu kọọtu, awọn miran ni mọṣalaṣi ṣugbọn igbeyawo alaṣa ni awa ṣe.
Ní ọjọ́ kinni, oṣù kẹfa, ọdún keji ìjọba Dariusi, OLUWA rán wolii Hagai sí Serubabeli, ọmọ Ṣealitieli, gomina ilẹ̀ Juda, ati sí Joṣua ọmọ Jehosadaki, olórí alufaa.
Wọn gba Segun Abraham ti Tinubu kin lẹyin sẹgbẹ kan.
Wọn ni iwọde yi se pataki lati fi pe akiyesi ọga agba ọlọpaa si isẹlẹ yi.
Ni bayii, apapo awon afurasi ti o wa ninu atimole je merin pelu awon meji ti o sese darapo mo won.
31 Àti pé àwa mọ̀ bákannáà, pé ìyàsímímọ́ nípasẹ̀ ore ọ̀fẹ́ ti Olúwa àti Olùgbàlà wa Jésù Krístì jẹ́ títọ́ àti òtitọ́, sí gbogbo àwọn wọ̃nnì tí wọ́n fẹ́ràn tí wọ́n sì ńsìn Ọlọ́run pẹ̀lú gbogbo agbára, iyè àti okun wọn.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fọ́nrán ohùn, Lẹ́yìn ọ̀pọ̀lọ́pọ̀ oṣù tí òjò kò rọ̀ ní orílẹ̀èdè Cuba, Ọba ilẹ̀ Yorùbá ló Ẹ jẹ ki a kọ wọn, ki a tun tun wọn kọ, eyi gan ni yoo mu idẹrun ba wa."
Ìdí nìyí tí inú fi bí OLUWA sí ilẹ̀ yìí, tí ó sì mú gbogbo ègún tí a kọ sinu ìwé yìí ṣẹ lé wọn lórí.
Ó ń bọ̀ sórí àwọn oníṣẹ́ ibi.
Aṣofin Tunde Braimoh, Alaga Igbimọ fun Ọrọ Iroyin ati Ọgbọn Iṣakoso Ilu ninu Ile naa dupẹ lọwọ Kabiyesi fun imọriri akitiyan Ile Igbimọ Aṣofin yii, pe awọn ọrọ iwuri yii yoo jẹ ki awọn ọmọ Ile naa o tun le sapa siwaju ninu akitiyan wọn, pe “bi a ba ki ni kuuṣẹ, o n mori iṣẹ wu ni”.
Awọn agba awo ni ilẹ Yoruba ti sọ ọ di mimọ pe ọdun to yẹ ki gbogbo ọmọ Yoruba o mu ni koko.
O ni lara igbesẹ to lamilaaka ti wọn gbe ni ti irinwo ati ọgbọn awọn ẹlẹwọn ti wọn kẹkọgboye imọ ijinlẹ nileẹkọ giga fasiti agbele-gboye National Open University.
Ofin yi tun fi aye silẹ fun awọn ajẹmọnu orisirisi eyi to kọ ọpọ ẹniyan lominu, paapajulo bo ti se jẹ wi pe awọn gomina kan to fipo silẹ tun lọ gba ipo oselu miran nile asofin agba tabi minista orileede Naijiria.
Wayii o, Super Eagles yoo tun
Gbogbo ilẹ̀ tí ò ń wò yìí, ìwọ ati àwọn ọmọ rẹ ni n óo fún títí lae.
Ìdí míràn tún ni pé ìdìbò Eko, Nassarawa, jíjí àpóti gbé àti ìpaniyàn pọ̀ nínú ìdìbò ti ó kọ́ja O fíkun pé àṣẹ tí ààrẹ Muhammadu Buhari pa pé ki wọn pa ẹni ti ó ba ji apoti ìdìbo kún oun to jẹ ìbẹ̀ru fun àwọn ara ilú ti wọn o fi jáde lọ dibo.
Iye awọn eeyan to ṣẹṣẹ ko arun naa ni ipinlẹ kọọkan ree: Eko-229 FCT-65 Abia-54 Borno-42 Oyo-35 Rivers-28 Edo-28 Gombe-27 Ogun-21 Plateau-18 Delta-18 Bauchi-10 Kaduna-10 Benue-9 Ondo-8 Kwara-6 Nasarawa-4 Enugu-4 Sokoto-3 Niger-3 Kebbi-3 Yobe-1 Kano-1 Èèyàn 681 ló lùgbàdì àrùn Coronavirus ní Naijiria ní Ọjọ́bọ̀ Eeyan 681 tuntun mii lo ṣẹṣẹ lugbadi aarun Coronavirus ni Naijiria.
Gege bi akonimoogba iko agbaboolu France, Didier Deschamps “ ifesewonse yii se deede, nigba miiran a o se daradara, igba miiran a o tu se idakeji,”“O farahan gbangba pe, awon agbaboolu mi ko si ni ipo ti o ye ki won wa, sugbon won sa gbogbo ipa won.
Kò sí olúwarẹ̀ ní gbogbo ayé.
 ajíbógun ló lọ bomi òkun wá fún bàbá wọn - ọlọ ́ fin tí ó fọ ́ jú láti fi ṣe egbogi fún un kí ó lé ríran padà .
Ọkunrin tí ẹ̀ ń wò yìí ni gbogbo àwọn Juu ní Jerusalẹmu ati níbí ń yan eniyan wá rí mi nípa rẹ̀, tí wọn ń kígbe pé kò yẹ kí ó tún wà láàyè mọ́.
“Ẹ kò gbọdọ̀ rẹ́ alágbàṣe yín tí ó jẹ́ talaka ati aláìní jẹ, kì báà jẹ́ ọmọ Israẹli ẹlẹgbẹ́ yín, tabi àlejò tí ó ń gbé ọ̀kan ninu àwọn ìlú yín.
Bakan naa ni Adewale Akorede taa mọ si Okunnu ba wọ asọ ọlọpaa naa, ti Mr Latin si duro si aarin wọn.
‘Jibiti ni isẹlẹ Dapchi, kii se ootọ’ PDP: Buhari n dunkoko mọ alatako Ọmọbinrin kan ṣi wa nigbekun nitoripe o kọ lati tako ẹsin Kristiẹni.
Lati kekere ni Adebayo ti ṣẹnu ṣamuṣamu ti a si le sọ wi pe ile lo ti baa.
Ẹgan ni ẹ, awọn panapana se isẹ.
Ìfọ̀rọ̀wérọ̀ nípa ohun inú ojúewé yìí
Ní gbogbo ọdún rẹ̀ kò sí ogun, nítorí OLUWA fún wọn ní alaafia.
6m lórí ètò BBNaija torí pó sọ̀rọ̀ ìwúrí nípa Nàíjíríà Bí mo ṣe dúró ti Toyin nílé ìgbẹ̀bí jẹ́ kí ń mọ̀ pé ó yẹ kí ọkùnrin máa bọ aya wọn - ọkọ Toyin Abraham Ìjíròrò forí ṣánpọ́n lóri sísan owó oṣù tuntunÌdí rèé tí mi ò fi yọjú sí ìgbìmọ̀ àjọ PFN- Fatoyinbo Oriade naa wa daba pe kawọn eeyan maa kọ awọn ogo wẹkrẹ wa ni ede abinibi ninu ile ati nile iwe.
44 Àti pé láti ọwọ́ yín èmi yíò ṣe iṣẹ́ yíyanilẹ́nu kan láàrin àwọn ọmọ ènìyàn, sí fífi dá ọ̀pọ̀lọpọ̀ lójú ní ti awọn ẹ̀ṣẹ̀ wọn, kí wọ́n ó lè wá sí ironúpìwàdà, àti pé kí wọn ó lè wá sí ìjọba Bàbá mi.
Oríṣun àwòrán, others Ko si ẹni to lee sọ ni pato ododo ọr yii gan an.
Bakan naa, awọn alaabo fun ara ilu,Civil defense naa o gbẹyin ninu igbaradi fun idibo ti yoo waye lọla ode yii.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ìtàn ayé Ọba Seriki Abass ti Badagry, tó ní aya 128, ọmọ 144 Ọmọdé 5 àti àgbà 40 bómi òkun lọ, 37 mórí bọ́ lásìkò tí ẹ́ńgínì ọkọ̀ ojú omi gbiná Kò sí ọ̀nà láti jáde tàbí wọlé sí Mali, ikọ̀ ológun ọlọ́tẹ̀ kéde ìṣéde Wo ibùdó arẹwà tí ọ̀pọ̀ èrò ń ya lọ ní Abuja Obìnrin kan dèrò ilé ẹjọ́ lórí ẹ̀sùn pé ó fi ọ̀bẹ rẹ́ ọmọ rẹ̀ lọ́rùn Adamu Adamu, Minista ètò ẹ̀kọ́ ti fi òfin àátẹ̀lẹ́ síta kí àwọn ilé ìwé lè wọlé Makinde ti sọ̀rọ̀ lẹ́yìn tí asekúpani Akinyele sálo mọ́ àwọn ọlọ́pàá lọ́wọ́ ní àhámọ́ Olólùfẹ́ mi ṣèèsì fi ọkọ́ gbá mi sí gọ́tà, mo rò pé ọlọ́jọ́ dé ni - Iya Osogbo Wọn fi kun ikede naa pe gbogbo ọmọ bibi orilẹ-ede Naijiria ni eto igbani wọle fun SSC wa fun, to fi mọ awọn to n sisẹ ologun lọwọ.
O ni ode ariya gbogbo ti oun lọ fun oṣu mẹta laisimi dipo ki oun tete maa gbaradi lo ṣakoba fun oun nitori oun ti wa sanra asanju ṣaaju ija naa.
Donald Trump ti pàdé Ọbabìnrin Elisabeth tilẹ̀ Gẹ̀ẹ̀sì Eto ikini-kaabọ n lọ lọwọ ni aafin Obabinrin ilẹ̀ Gẹẹsi fun aarẹ Amerika, Donald Trump.
samojuto eto idibo naa , leyi naa ni won yoo tun maa fun awon to ba jawe
Chelsea lu West Brom lalubomi Ọlọ́pàá tó mú àwọn obinrin wọ gau -Ọ̀gá ọlọ́pàá Wo àwọn ìgbésẹ̀ tí ó lè gbé láti bọ lọ́wọ́ ẹ̀sọ́ ọlọpàá lóju pópó Watford lu Chelsea la'lubolẹ Bóti lẹ jẹ́ pe ọmọ agbabọọlu mẹ́rin ni Chelsea ti pààrọ lẹ́yìn ìdíje wọn to wáye lopin oṣẹ́ lẹ́yìn ti wọn waàákò pẹ̀lú Watford.
Awọn Iroyin mii ti ẹ le nifẹ sii Barrister ló sọ mí di èèyàn ńlá - Ayinla Kollington Ìtàn tó wà nídi òwe ‘Sebótimọ Ẹlẹ́wà Sàpọ́n’ Ìtàn tó rọ̀ mọ́ òwe ‘aṣọ kò bá Ọ́mọ́yẹ mọ́.
Eyi ni igba ẹkẹẹta ti ileewosan ijọba ti Yola yoo ṣe iṣẹ abẹ fun awọn ọmọ to lẹpọ lẹyin eyi ti wọn ṣe lati ọdun 2018.
Bí o bá pa gbogbo òfin tí Ọlọrun fún Israẹli láti ọwọ́ Mose mọ́, o óo ṣe rere.
Oríṣun àwòrán, Jessica Nabongo Àkọlé àwòrán, Jessica Nabongo ọmọ ilẹ Uganda Ko ṣai mẹnu baa wi pe, ki awọn obinrin o dẹkun wipe boya wọn ko le da rin irin ajo nitori ẹru tabi ifoya, o wi pe, irọ funfun balau ni iru ọrọ bẹẹ.
Ó dáa, dájúdájú onígbọràn ọmọ ẹgbẹ́ òṣèlú àti àwọn ará ìlú ni ọ́.
Ọgbẹni Egbeyemi fikun ọrọ rẹ pe awọn mejidinlaadọta ninu wọn ṣalaye pe awọn gbe okada wa lati fi ṣiṣẹ l'Eko nigba tawọn to ku ni awọn wa ṣiṣẹ niluu Eko lati rowo ni.
Ó sì dá mi lójú pé ó lè pa ìṣúra tí mo fi pamọ́ sí i lọ́wọ́ mọ́ títí di ọjọ́ ńlá náà.
Ìná ẹgbẹ́ òṣìṣẹ́ NLC ati ìjọba kò wọ̀ níbi ìpadé Ṣaaju naa ni ọrọ fifi iyalọja jẹ ni ọja ti wọn ti n ta nnkan elo kọmputa nipinlẹ Eko, Computer Village naa tri fa awuyewuye tẹlẹ.
ÌFORÍTÌ NI OLÓWÓ-AYÉ FI ṣẹgun ÀǸJÀNNÚ-Ìbẹ̀rù TÍ Í ṣe ONÍBODÈ IGBÓ OLÓDÙMARÈ.
Nibẹ ni awọn obinrin meji kan si ti lu u ni jibiti ti wọn si gba owo rẹ.
Bakan naa lo tun ke si awọn eeyan lati fi owo ran ipolongo naa lọwọ.
Egbe oselu to n sejoba lorile-ede South Africa, Africa National Congress (ANC) ti fun Aare Jacob Zuma ni gbedeke ojo lati kowe fipo sile, bi bee ko, ile-igbimo asofin yoo dibo aini-igbekele ninu re.
Ahmed Rufai Abubakar lo jabọ ohun ti oju wọn ri ni South Africa fun Aarẹ Buhari ti aarẹ si ni: Wo àbọ̀ tí wọn jẹ fun Aarẹ Buhari lori ọrọ ikọlu South Africa: Lọwọlọwọ yii, awọn ọmọ Naijiria ti wọn ṣetan lati pada wa sile ti di oji le ni ẹgbẹta bayii.
Ijoba orile ede Naijiria ti fi aidunnu re han lori bi won se n pa awon omo orile ede yii bi eran –ije  ni UK, paapaa julo lasiko yii.
Kò sí ẹ̀dá alààyè tó dá wà láì ní Olùbátan tàbí alájogbé.
 Okoye tun ni ,ajo NEC yoo rii pe  ”Gbogbo awon alamojuto ni yoo lọ si ibi ti
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Arákùnrin Ethiopia yìí ń fi ọwọ rin Ki lo ṣẹlẹ sẹyin: Olootu ijọba Ethiopia, Abiy ahmed sọ pe lootọ ni olori ogun orilẹ-ede naa fi ara gba ibọn.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Adeleke: APC ní ìdájọ́ ileẹjọ́ kòtẹ́milọ́rùn kò fún Adeleke ní ìrètí kankan 30 Èbibi 2019 Oríṣun àwòrán, Ademola Adeleke Lẹyin ti ileẹjọ kotẹmilọrun wọgile idajọ to ni Adeleke ko yẹ lati du ipo gomina, eyi tí Wahab Raheem and Adam Habeeb gbe wa siwaju rẹ, ẹgbẹ oṣelu APC ti fesi wipe, idajọ naa ko tumọ si wipe, Adeleke yoo di gomina.
Nípasẹ̀ rẹ̀ ni a dá ayé, sibẹ ayé kò mọ̀ ọ́n.
Àwọn ọ̀gá rẹ ní ìjọba ni mò ń bá ṣe -Bobrisky fún ọ̀gá Arts & Culture lésì!
Arabinrin Pauline Tallen to je minista fun ọrọ obinrin ni Naijiria ti ni Isede konile-o-gbele lati dekun itankalẹ ajakalẹ arun Covid 19 lo faa.
Àwọn ọmọ Israẹli ni wọ́n ranṣẹ sí i, òun ati gbogbo àwọn ọmọ Israẹli lọ sọ́dọ̀ Rehoboamu, wọ́n wí fún un pé, 
Esi ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ yi tun mo sí pé ipenija àti ma fidiremi nínú Premiership tunbo peleke sí ní fún Swansea.
Nínú ìkéde ti àjọ tó ń gbógun ti àjàkálẹ̀ ààrùn lórílẹ̀-èdè Nàìjíríà (NCDC) fi síta lónìí, lójú òpó twitter rẹ̀ lo ti ṣe àtúpalẹ̀ àbájade àyèwò àwọn ìpínlẹ̀ kọ̀ọ̀kan ní Naijiria.
 Òun ni ó jẹ ́ aṣojú ẹkùn Èrúwà ní ìlà oòrùn ìjọba ìbílẹ ̀ Ìbàràpá àti agbọ ̀ rọ ̀ sọ tàbí agbẹnusọ fún ilé-ìgbìmọ ̀ aṣòfin ẹlẹ ́ kẹẹ ̀ sán irú rẹ ̀ ní ìpínlẹ ̀ Ọ ̀ yọ ́ làbẹ ́ ẹgbẹ ́ òṣèlú peoples democratic party ( pdp ) .
Chief Commander sọ pe, ilu gangan ni Ọlọrun ran oun wa si aye lati wa kọ, lati kekere si ni oun ti yan ilu naa laayo.
"A rọ yin lati jẹ akọṣẹmọṣẹ ṣugbọn bi ẹnikẹni ba wa fi ilọkulọ lọ yin, ẹ lee da abo bo ara yin""."
Àwọn ajìjàǹgbara yìí kan náà ṣẹ̀ṣẹ̀ fi ẹ̀hónú hàn ní gbàgede ìlú láti tako ìfìyàjẹ àwọn aṣe-ìbálòpọ̀-akọ-àti-akọ ní Russia, pàápàá jùlọ ní orílẹ̀ Chechnya.
Wo àwọn ọ̀nà míràn tí o leè gbà lẹ́yìn tí wọ́n bá ti afára Third Mainland Aarẹ o lo ibomu lasiko ijabọ rẹ yii, nitori o woye pe ko pọndandan.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ọ̀fọ̀ ńlá ṣẹ̀ sí Amosun: Akọ̀wé Adeoluwa àti Adesanya ṣàgbákò ìjàmbá Ìtàn nípa bí ètò ìdìbò ṣe bẹ̀rẹ̀ ní Nàìjíríà INEC kìlọ̀ fáwọn ọmọdé tó fẹ́ dìbò Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Damilọla Ajayi: Ọ̀dá owó ló ṣún mi dé ìdí lílo ìyarun bíi fèrè Koda, a tiẹ ri ibi ti wọn ti dana sun ọkada kan ati awọn iwe idibo, ti wọn si tun sọ ọkunrin kan ti wọn fẹsun kan pe oun lo wa nidi idaluru naa, ni oko pa.
Lasiko to n gba fọọmu naa, Dino Melaye ni o da oun loju pe oun yoo jẹ Gomina Kogi ni oṣu Kọkanla ọdun yii lẹyin ti idibo ba waye.
Nollywood :Àwọn òṣèré Yorùbá márùn ún tí kò sí lójú ìwòran mọ́ ṣùgbọ́n tí wọ́n wà láyé.
Gbogbo ìdíje ló ni ẹ̀kọ́ àti àwòkọ́ṣe to yẹ ni mímọ̀ fún ọjọ́ iwájú
-Ọlọ́pàá ‘Ìpè pàjáwìrì fún mítìnì lóru kìí jẹ ki òṣèlú rọrùn fún obìnrin’ Presidential Election Tribunal: Láyé, a ò lè gba ẹ̀bẹ̀ PDP láti yẹ ojú òpó ayélujára INEC wò Awọn gomina ti ireti wa wi pe wọn o darapọ mọ eto naa.
Ajọ UNICEF sọ pataki omi tó mọ́ ni mimu fun alaboyun ati irufẹ ounjẹ to dara fun un bii èso bii ọsan, ọgẹdẹ, ibẹpẹ; ewébẹ̀ bii ẹfọ ugwu, ẹfọ tẹtẹ, ewedu, karọọti, ẹfọ gbure; ẹ̀wà, ẹja àti bẹẹ bẹẹ lọ Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Adura gbigba ni awọn alaboyun mii gbagbọ ninu ẹ Bakan naa ni awọn alaboyun mii gbagbọ pupọ ninu awọn iya alagbo ti awọn mii n pe ni iya elewe ọmọ ati iya Ijaw.
Wọ́n pàṣẹ fún àwọn eniyan náà pé, “Nígbà tí ẹ bá rí i pé, àwọn alufaa, ọmọ Lefi gbé Àpótí Majẹmu OLUWA Ọlọrun yín, tí wọ́n sì bẹ̀rẹ̀ sí lọ, kí ẹ̀yin náà gbéra, kí ẹ sì tẹ̀lé wọn.
Ìwé Mímọ́ sọ báyìí pé: “Ta ni mọ inú Ọlọrun?
Amọ, Aarẹ Buhari ni awọn obinrin to ni iwa ọmọluwabi to si fẹran orilẹede Naijiria ni oun yoo yan sipo.
Wọ́n sọ fún un pé, “Josẹfu kò kú, ó wà láàyè, ati pé òun ni alákòóso gbogbo ilẹ̀ Ijipti.
Wọn ni ibọn ọhun ba a nigba ti awọn agbofinro ati awọn oluwọde Shiite gbena woju ara wọn ni.
Ìwọ, àwọn ọmọ rẹ, ati àwọn iranṣẹ rẹ, ni ẹ óo máa ro gbogbo oko Saulu; ẹ ó máa kórè àwọn ohun ọ̀gbìn tí ẹ bá gbìn, kí ọmọ oluwa yín lè ní oúnjẹ tó, ṣugbọn Mẹfiboṣẹti alára, yóo máa wá jẹun lórí tabili mi nígbà gbogbo.
"to ba jẹ́ pe ẹni ti kìí peju dédé lásiko ipade ẹgbẹ́ ni, o ṣeeṣe ki ẹgbẹ́ náà ma kọ ibi ara sii Ní ti Kayode Odumosu ti gbogbo ènìyàn mọ si ""Pa Kasumu"" Alaga Tanpan ni ẹgbẹ́ ṣe gudugudu méje àti yàyà mẹfa lati ìgbà to ti bẹ̀rẹ̀ si n ṣe àisan, eyi si de ọ̀dọ̀ gómìnà àná ní ìpinlẹ̀ Ogun Ibikunle Amosun, owo to to mílíọnu meji ni gomina fún láti fi wo ara rẹ."
Nitorinaa, awọn eeyan labẹle ninu awọn ilu naa lo jẹ awọn ti wọn ko jọ lati di ikọ Amọtẹkun niwọn igba ti wọn ba ti ni ikoju osuwọn to yẹ fun didara pọ mọ Amọtẹkun.
Àmọ́, ìjọba ti dási i, tí àwọn aláṣẹ sì ti n bá igun méjèéjì ṣèpàdé láti yanjú àáwọ̀ nàá.
Kódà, a rí gbo pé nínú ọdún kan, lásìkò tí ajakale àrùn náà dojú rẹ, èèyàn mílíọ̀nù mẹẹdogbon lo dagbere fàyè, tí èèyàn ẹgbẹ̀rún mẹ́wàá sì ń kú lojumọ.
Ta ló láyà láti lọ jí i níbi tí ó bá sùn sí?
 Àlèébù to wà nínú ilé ọba .
Wọ́n pa ọ̀dọ́ aguntan Àjọ Ìrékọjá ní ọjọ́ kẹrinla oṣù keji.
” Wá wò ó, ó ti dahoro, ó ti di ibùgbé fún àwọn ẹranko burúkú!
Àjọ elétò ìdìbò kéde ọjọ́ tí ìdìbò aàrẹ Nàìjíríà 2023 yóò wáyé Ìyá gómìnà Seyi Makinde dágbére fáyé lẹ́ni ọdún 81 Tani Akeredolu tó wọlé láti tukọ̀ ìṣàkóso ípìnlẹ̀ Ondo lẹ́ẹ̀kejì yìí?
Eyi to fihan pe iṣẹlẹ nla kan ṣẹṣẹ waye nibẹ ni.
Òkú ọmọ ọdún mẹ́ta tó kó sí kàǹga ní Ipaja ni wọ́n yọ' Ta ni arẹwà obìnrin yí tí àwọn ọmọ Nàìjíríà fẹ́ kó di àárẹ wọn?
Fidio kan to jade sita ṣe afihan George Floyd, to n pariwo fitafita fun iya rẹ to ṣẹṣẹ doloogbe, ati awọn ọmọ rẹ pe awọn ọlọpaa naa yoo pa oun.
31 Èbibi 2019 Oríṣun àwòrán, Pulse Àkọlé àwòrán, Kíni N11trn owó ìrànwọ́ epo tí ìjọba àpapọ̀ san fún àwọn agbépo lè rà?
Lati opin ọsẹ to kọja to jẹ ayajọ isami ọdun ajinde Kristi ni iroyin kan gba oju opo ayelujara kan pe awọn adugunjale ti ya si igboro.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ìtàn ayé Taiwo Oredein rèé, àgbà òṣèlú tó parí ayé rẹ̀ sọ́gbà ẹ̀wọ̀n Pa Kasumu,gbajúgbajà òṣèré tíátà Yorùbá jáde láyé Ó dá mi lójú pé ọmọ ìjọ mi kò lé è kó àrùn Coronavirus - Adeboye Èdè àìyedè bẹ̀rẹ̀ lórí bí àgbélẹ̀rọ òyìnbó Nàíjíríà ṣe wọ ìwé atúmọ̀ èdè Gẹ̀ẹ́sì Oxford Ògbólógbòó ìjàpá rèé, tó bí ọmọ 800 kí ìran rẹ̀ má ba à parun Bakan naa ni wọn fẹsun kan ọpọ awọn osisẹ asọbode to wa ni papakọ ofurufu Naijiria pe, wọn n lẹdi apo pọ mọ awọn to n ko awọn obinrin lọ sowo ẹrun lawọn orilẹede Larubawa.
Àwọn arọmọdọmọ rẹ yóo pọ̀,bí ewéko ninu pápá oko.
Ẹnìkan sọ fún un pé, “Ìyá rẹ ati àwọn arakunrin rẹ dúró lóde, wọ́n fẹ́ bá ọ sọ̀rọ̀.
1 11456 Orilẹede Namibia 275 11.
N óo yan alufaa mìíràn fún ara mi, tí yóo ṣe olóòótọ́ sí mi, tí yóo sì ṣe gbogbo ohun tí mo bá fẹ́ kí ó ṣe.
Nítorí pé ọ̀rọ̀ Ọlọrun wà láàyè, ó sì lágbára.
Ninu Kristi kan náà ni ẹ̀yin tí kì í ṣe Juu ti gbọ́ ọ̀rọ̀ òtítọ́, tíí ṣe ìyìn rere ìgbàlà yín tí ẹ gbàgbọ́.
Wo àwọn Gómìnà Naijiria tí àrùn Covid-19 ti bá fínra Lizzy Anjorin sun ẹkún ìyàwó, èèyàn kan fún un lẹ́bùn aṣọ funfun láti mọ ìbálé rẹ̀ Wo bí ètò ìdìbò abẹ́lé ẹgbẹ́ òṣẹ́lú PDP ṣe ń lọ ní ìlú Akure Pásítọ̀ ìjọ Sotitobire padà yọjú sílé ẹjọ́ lónìí, àbọ̀o rèé.
Má ṣe yà sí ọ̀tún tabi sí òsì,yipada kúrò ninu ibi.
Nítorí ìpọ́njú yóo pọ̀ ní àkókò náà, irú èyí tí kò sí rí láti ìbẹ̀rẹ̀ ayé títí di ìsinsìnyìí; irú rẹ̀ kò sì tún ní sí mọ́.
Lọpọ igba ti ile ba ti wo ni ilu Eko, ipenija nla ni o ma n jẹ fawọn to n ṣeto idoola ẹmi lati ṣiṣẹ wọn nitori ero ti ma n pọju to wa woran nibẹ.
O so pe  “O da mi loju ninu ipade yii pe eyin odo yii ni yoo gbe ogo orile ede yii ga, a seleri lasiko eto idibo 2015, sugbon  ninu eto idibo ọdun 2019, a o lo salaye awon aseyori wa.
Arabinrin yii to gba bọọlu fun ẹgbẹ agbabọọlu obinrin agba ti orilẹede Naijiria - Super Falcons ri sọ wipe bi o tilẹ jẹ pe awọn obinrin njiya, awọn onisẹ iroyin Naijiria ko se agbejade to tọ nipa fifi ilọkulọ ibalopọ lọ awọn agbabọọlu obinrin.
Bi a ko ba mọ telẹ, Gomina ipinlẹ Ekiti ana Ayodele Fayose lo jẹ ki a mọ.
Ileeṣẹ ọlọpaa ti kesi awọn to ti gba omi iyanu naa lati yọju sita fun ẹrí.
Olukọ kankan ko gbọdọ ba akẹkọọ ni ibalopọ tabi ko beere fun ibalopọ lọwọ ọmọ to n kọ nile iwe.
Àwọn ará Sioni gbọ́, inú wọn dùn.
Ni nkan bii agogo meje ku diẹ lalẹ ọjọ ẹti, ni baalu to gbe aarẹ gunlẹ si papakọ ofurufu Nnamdi Azikwe nilu Abuja.
Atipo Naijiria 50 rigbala kuro ninu odo Libya
"He came to Nigeria with love, ate and drank Nigerian delicacies and drinks, showed a significant demonstration of oneness by walking the aisle to tie the nuptial knot outside nationality bounds with one of our illustrious daughters and that is you, and he was loved and appreciated by the people through giving him a Yoruba name ""Omowale"" and naming a street after him in Victoria Island, Lagos."
Bakan naa lo fikun pe ọwọ ti ba awsn eeyan kan ti wọn ka mọ idi iwa ika yii lagbegbe Gauteng, ti eeyan mẹrinlelaadọrin si ti wa lahamọ ọlọpa lẹkun Katlehong.
Rẹfiri Nestor Pitana lo dari idije aṣekagba naa.
nibi ti awon odaran kan ti seku pa awon eniyan, ni eyi  to waye ni ijoba ibile Tsafe, ni ipinle
Ṣugbọn àwa kò mọ̀ bí ó ti ṣe wá ń ríran nisinsinyii.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Sudan removed from terrorist list: America yọ Sudan kúrò nínú ìwé orílẹ̀-èdè tó ń ṣagbátẹrù ẹgbẹ́ agbésùnmọ̀mí lágbàyé 14 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Oríṣun àwòrán, @Suribelle1 Ọọfisi ijọba ilẹ Amẹrika to wa ni Khartoum ti kede pe wọn ti yọ orukọ orilẹ-ede Sudan kuro lara awọn orilẹ-ede to n ṣatilẹyin fun ẹgbẹ agbesumọmi lagbaye.
Shitte:El-Zakzaky tún kùnà láti rí ojúrere níle-ẹjọ́ Oríṣun àwòrán, @i_batoula Ile-ẹjọ giga to n joko si ipinlẹ Kaduna ti kọ lati gba oniduro adari ẹgbẹ musulumi Shitte, El-Zakzaky ati iyawo rẹ.
Iku oloogbe yi ti mu ki awọn o n woye ohun to n sẹlẹ lawujọ wi pe, kiniun kii se ọkan lara ẹranko ti o yẹ ki awọn eniyan maa sin ninu ile.
Lónìí ọjọ́ kẹrinlelogun oṣù kẹsan-an, ni ẹ fi ìpìlẹ̀ tẹmpili lélẹ̀; láti òní lọ, ẹ kíyèsí ohun tí yóo máa ṣẹlẹ̀.
Oral Sex: Bóo bá ń gba ẹnu ní ìbálòpọ̀, wo àìsàn tóo lè kó lójú ara rẹ Wo oríṣiríṣi ìgbádun ibálòpọ̀ láwọn orílẹ̀èdè mìíràn Ẹ̀mi arákùnrin yìí kò gbé e, ó bá aláṣẹ́wò lò dórí ìgbà ìkéje ló bá ré sálákeji Wo bí o ṣe lè mọ orúkọ àwọn afípabánilòpọ̀ ní Nàìjíríà Nigba miran, wọn yoo gbe iru awọn eeyan bẹẹ lọ sile iwosan tabi agọ ọlọpaa, ti wọn yoo si pe ero le wọn lori, eyi to tabuku ẹtọ ọmọniyan pupọ Oríṣun àwòrán, Youtube viral Laipẹ yii si ni fidio kan n ja ranin-ranin lori ayelujara nipa ọkunrin kan to n sere ifẹ pẹlu iyawo ile ẹlomiran, ti nnkan ọkunrin rẹ si ha soju ara obinrin naa.
Láti ọdún 2006 ni 'Headies' tí ń fáwọn to bá pegede nínú ìṣe orin takasufe lami ẹyẹ lorile-ede Naijiria.
Onírúurú oúnjẹ ni ó pé sí ààfin ọba, iyán pẹ̀lú ọbẹ̀ ìlá àti ẹran, ìrẹsì àti òróró ẹ̀gúsí tí wọ́n ti sè pẹ̀lú àlùbọ́sà àti ata.
nígbà tí wọ́n bá fi ẹ̀ṣẹ̀ tí ó dá yìí hàn án, yóo mú òbúkọ kan tí kò ní àbààwọ́n wá, yóo fi rúbọ.
Àìsàn sànpọ̀ná jẹ́ àjàkalẹ̀ àrun ní ayé ìgbà náa ti ó si pa ìdá ọgbọ̀n ninú ọgọ́rùn àwọn ènìyàn to lùgbàdì rẹ̀.
''O jẹ iyalẹnu pe iru iwe iroyin nla bi Punch yoo gbe ahesọ iroyin bayi.
Ohunkohun tí o bá ti dáwọ́ lé, fi gbogbo agbára rẹ ṣe é nítorí, kò sí iṣẹ́, tabi èrò, tabi ìmọ̀, tabi ọgbọ́n, ní isà òkú tí ò ń lọ.
Ṣaaju ni mẹta lara awọn to n ba gomina Rotimi Akeredolu dije ti kọkọ sọ pe wọn ko ṣe mọ.
Nígbà tí mo fi omijé gbààwẹ̀,ó di ẹ̀gàn fún mi.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ LASTMA Yesufa: Àwọn dókítà gbìyànjú lórí ojú mi ṣùgbọ́n.
Ọdọmọkunrin kan wà ní Juda, ará Bẹtilẹhẹmu, tí ó jẹ́ ọmọ Lefi láti inú ìdílé Juda, ó ń gbé ibẹ̀.
Nígbà tí ó di alẹ́ ọjọ́ kinni ọ̀sẹ̀, níbi tí àwọn ọmọ-ẹ̀yìn wà, tí wọ́n ti ìlẹ̀kùn mọ́rí nítorí wọ́n bẹ̀rù àwọn Juu, Jesu dé, ó dúró láàrin wọn.
,(June 6) odun yii, ni eyi ti yoo fun awon eniyan miiran lati tun dije dupo
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Coronavirus lockdown updates in Nigeria: Adeboye ni ọpọ nǹkan ńlá ńlá ni yóò ṣẹlẹ̀ lẹ́yìn ìgbélé Coronavirus 2 Ìgbé 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 1 Òkùdu 2020 Oríṣun àwòrán, PAstor adeboye Olusọ agutan agba fun ijọ Redeemed, Pasitọ Enoch Adejare Adeboye ti sọ aṣọtẹlẹ pe ọpọlọpọ nnkan nla nla ni yoo maa ṣẹlẹ tori igbele Coronavirus.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Yorùbá dùn Egypt: Bàálù méjì yóò kún tí ìjọba bá ṣèrànwọ́ láti kó wa kúrò ní Egypt Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Yorùbá dùn Egypt: Bàálù méjì yóò kún tí ìjọba bá ṣèrànwọ́ láti kó wa kúrò ní Egypt 24 Ògún 2019 BBC Yoruba fẹsẹ kan de orilẹede Egypt lati lọ bẹ awọn ọmọ Oduduwa to wa nibẹ wo, a si ri pe ohun ti wọn n la kọja nibẹ ya ni lẹnu pupọ.
Ijọba Naijiria ni bi wọn ṣe ṣe akanṣe iṣẹ ọhun gan ti jẹ eyi ti yoo kuna ati pe ami ẹyẹ ti wọn gba gan kii ṣe ẹtọ to dara.
    Ìgbà tí a kọrin dídún tán tí gbogbo ẹni ti ó wá jókòó tán, iwin náà ní kí èmi àti ìyàwó mi bọ́ síwájú a sì lọ, lẹ́yìn tí o sì ti béèrè lọ́wọ́ mi lójù gbogbo aye bí mo bá pinnu láti fẹ́ obìnrin náà, ti mo ti jẹ́wọ́ tán ó ni, ki n máa wí àwọn ọ̀rọ̀ wọ̀nyí tẹ̀lé oun: 
Ninú ọ̀rọ̀ rẹ, ó ni nitori ohun polongo ki wọn dúró ninú ẹgbẹ́ Ilú-Oyinbo ṣùgbọ́n àwọn aráilú ti sọ̀rọ̀ wi pé ki wọn kúrò, nitori eyi ohun yio gbé Ijọba silẹ̀.
Ẹ wá OLUWA, kí ẹ sì yè; bí bẹ́ẹ̀ kọ́, yóo rọ̀jò iná sórí ilé Josẹfu, ati sí ìlú Bẹtẹli; kò sì ní sí ẹni tí yóo lè pa á.
Kì í ṣe irú èyí tí wọ́n fi yíǹkì kọ, Ẹ̀mí Ọlọrun alààyè ni wọ́n fi kọ ọ́.
Bi ọmọ ò jọ ṣòkòtò á jọ kíjìpá: Ibáṣe pọ Idilé Yorùbá
Koda ẹni to ba fẹ ra Tọki gbọdọ mu apo mẹjọ naira lọwọ ko to le ri kilo Tọki kan ra bayii.
Oríṣun àwòrán, Abia state Government Awọn to ṣayẹwo ṣugbọn ti ko ni Covid-19 Gomina ipinlẹ Ondo, Arakunrin Oluwarotimi Akeredolu ṣe ayẹwo arun Coronavirus ṣugbọn ori koo yọ Akeredolu sọ loju opoTwitter rẹ pe Kọmisọnna eto ilẹra nipinlẹ Ondo lo fi esi ayẹwo naa sita pe oun ko ni arun Coronavirus.
Ninu ìdílé Satu: Elioenai, Eliaṣibu, ati Matanaya, Jeremotu, Sabadi, ati Asisa.
oniruuru eru ti won ri gba lowo won, oga agba ile ise olopa ni ipinle Oyo,
BBNaija 2019: Gedoni kúrò ní BBNaija.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Kemi Afolabi: Dókítà ní ìrìnàjò wákàtí mẹ́jọ láti Mecca sí Medinah ló fa ibà 30 Agẹmo 2019 Oríṣun àwòrán, kemiafolabiadesipe Ara kii se okuta, igbakuugba si lo lee beere itọju lọwọ ẹni.
Ilé tí ẹ bá wọ̀ sí, níbẹ̀ ni kí ẹ máa gbé títí ẹ óo fi kúrò ní ìlú náà.
- Ìwádìí BBC Ẹ má dá NEF lóhùn, kò síbi t'ọ́mọ Nàìjíríà kò lè gbé nílẹ̀ yìí - Buhari Ṣugbọn lorilẹede Russia, gẹgẹ bi o ti rii lọpọlọpọ orilẹede naa, o nira lati gbaye gbadun nitori ọrọ aje to dẹnu kọ lẹ.
Gbogbo òkúta olówó iyebíye ni wọ́n fi ṣe ọ́ lọ́ṣọ̀ọ́, àwọn òkúta bíi: kaneliani, topasi, ati jasiperi; kirisolite, bẹrili, ati onikisi; safire, kabọnku ati emeradi.
”Ó dá wọn lóhùn pé, “Wọ́n ti gbé Oluwa mi lọ, n kò mọ ibi tí wọ́n tẹ́ ẹ sí.
Amosa, ti ile igbimo asofin ba
Ohun ni oludasile àti aarẹ Genesis Leadership Academy, nibi to tin kọ awọn ọdọ bi a ṣe n dipo adari mu.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ẹ̀sùn àìmọ̀dí gbé Theophilous dọ́gbà ẹ̀wọ̀n, ìwé ẹ̀rí ìmọ̀ ìjìnlẹ̀ méjì ló gbé jáde 26 Ọ̀wàrà 2019 Oríṣun àwòrán, The Nigeria Lawyers Àkọlé àwòrán, Ẹ̀sùn àìmọ̀dí gbé Theophilous dọ́gbà ẹ̀wọ̀n, ìwé ẹ̀rí ìmọ̀ ìjìnlẹ̀ méjì ló gbé jáde Ṣe wọn ni ba o ku iṣe o tan.
Nígbà tí ọba Moabu rí i pé ogun náà le pupọ, ó mú ẹẹdẹgbẹrin (700) ọkunrin tí wọ́n ń lo idà, ó gbìyànjú láti la ààrin ogun kọjá níwájú ọba Edomu, ṣugbọn kò ṣeéṣe.
Ẹ̀ṣọ Gbajabiamila yìnbọn pa fẹ́ńdọ̀ kan l'Abuja, àwọn akẹgbẹ́ rẹ̀ fẹ ṣe iwọde Oríṣun àwòrán, Twitter Olori ile asojusofin Naijiria Femi Gbajabiamila ti ni ki ọlọpaa kan lara awọn ẹsọ rẹ lọ rọọkun nile nitori pe o yinbọn pa arakunrin kan to n ta iwe iroyin Ifeanyichukwu Elechi nilu Abuja.
Ajo CAF ati NFF sekinni ohun lori ero ayelujara won lati kii atamatase teleri naa.
Nítorí a ti kọ òfin rẹ sílẹ̀, 
Ìgbéyàwó ọkùnrin s'ọ́kùnrin, obìnrin s'óbìnrin ti di òfin ní Northern Ireland Ilé ẹjọ́ pàṣẹ kí Netflix dáwọ́ fíímù Jesu tó n ní ìbálòpọ̀ akọ s'ákọ dúró Ṣugbọn, imọran lasan ni wọn fun oun nitori bi iroyin ṣe n gbe ọrọ rẹ lọtun, ati l'osi.
Awọn da Emerald lohun pe ko si ohun ti ko le ṣẹlẹ, Olukayode Bakre ni tiẹ sọ pe ko si ibi ti ọrọ ifẹ ko ti le ṣẹlẹ.
Àkójọ́pọ̀ àwòrán rèé lórí bí ìwọlé akẹ́kọ̀ọ́ ṣe lọ sí ní Oyo Ilé aṣofin Ondo fọwọ́ òsì júwe ilé fún aṣòfin mẹ́ta pé wọ́n tàpá sí òfin ilé Olórí òṣìṣẹ́ ìjọba ìpínlẹ̀ Kwara, Adisa Logun ti dágbére fáyé lẹ́yìn tó lùgbàdì àrùn Covid-19 Fọwọ́ kan obìnrin lọ́nà àìtọ́, kí o rẹ́wọ̀n ọdún mẹ́rìnlá he- Àwọn aṣòfin yarí Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Kemi Dairo: Iṣẹ́ abẹ nínú ọpọlọ àti ẹ̀rọ ni mo fi ń gbọ́ ọ̀rọ̀ báyìí Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 3 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 5 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
com/jumokeodetola/ Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Ooni ile Ife: Iná sọ láàfín Ọọ̀ni Ilé Ifẹ̀, Ọọ̀ni ilé ifẹ̀ ní kò sí ẹ̀mí tó báa lọ19 Ògún 2020 5:58 Fídíò, Akomolede ati asa Yoruba: Ẹ wá kọ́ nípa àpòtí ìṣura èdè wa lórí BBC Yorùbá, Duration 5,5820 Ògún 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Oríṣun àwòrán, LASG Àkọlé àwòrán, Gov Sanwo-Olu fi kun pé àwọn ọkọ èrò ńlanla ẹgbẹ̀ta yóò wo ìlú Eko ni inú oṣù kẹjọ Ojú ọna naa ni wọn o tọ titi de Iyana Adekunle, nibi ti awọn to n bọ lati ọna Ebute Mẹta n gba jade, ki wọn o tun to ya nibi ti wọn ti la silẹ laarin meji afara, pada si ọna Iyana Oworo.
Ki Abiọla to ku lo ti n kọ ile Aarẹ si Abẹokuta eyi to ti di àkọ́tì bayii.
Iroyin naa sọ wipe agbegbe tikọlu naa ti sẹlẹ ko jinna si aarin gbungbun ilu Kaduna to lọ si ipinlẹ Plateau, Nasarawa ati Benue.
Loni to jẹ ayajọ ọjọ ounjẹ lagbaye, a fẹ wo diẹ lara awọn ounjẹ ilẹ Yoruba to ti da bii pe o ti n kasẹ nilẹ laye ode oni.
Mo sì ti fi ẹ̀mí Ọlọrun kún inú rẹ̀, mo ti fún un ní òye ati ọgbọ́n ati ìmọ̀ iṣẹ́ ọnà, 
Dafidi farapamọ́ ninu pápá, ní ọjọ́ àjọ̀dún oṣù tuntun, Saulu ọba jókòó láti jẹun.
”Rutu bá sọ inú oko ẹni tí ó ti ṣiṣẹ́ fún ìyá ọkọ rẹ̀, ó ní, “Inú oko ọkunrin kan tí wọ́n ń pè ní Boasi ni mo ti ṣa ọkà lónìí.
Aare Muhammadu Buhari yoo se ifilole ibi ti oko ofurufu ilu Port Harcourt, lojoBo(Thursday).
Jọ̀wọ́, má kúrò níhìn-ín títí tí n óo fi mú ẹ̀bùn mi dé, tí n óo sì gbé e kalẹ̀ níwájú rẹ.
Tí ọkàn rẹ yipada kúrò lọ́dọ̀ Ọlọrun,tí ò ń jẹ́ kí irú ọ̀rọ̀ bẹ́ẹ̀ ti ẹnu rẹ jáde?
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Awọn akópa jẹ́ kó di mímọ̀ pé awọn iroyin ayederu ti n gbayi gaan laarin awujọ yala ọ̀rọ̀ ti wọn kọ, fọto tabi fidio Eto naa waye gẹgẹ bi idibo orilẹede Naijiria yoo ṣe waye ninu oṣu keji ọdun 2019, ọkan lara akitiyan ile iṣẹ igbohunsafẹfẹ BBC ni lati jẹ ki awọn eniyan m ohun ti iroyin ofege jẹ.
Agbẹnusọ fun ẹgbẹ Shiites, ti o ba BBC Yoruba sọrọ salaye wipe awọn ko tii gba ọrọ yi lati ile ẹjọ naa, ati wipe ti awọn ba riigba, awọn yoo se apero lori rẹ lati fi atẹjade sita lori rẹ pẹlu.
Amọ, Oluyemi Fasipe loju opo Twitter rẹ s wi pe ibugbamu naa ba awọn ile ati dukia jẹ, to fi mọ ile epo to wa ni agbeegbe Ogbẹsẹ.
 Lojo Ru ni akowe agba fun ajo UN, Antonio Guterres bebe pe ki won fopin si ogun yii.
Lara awọn ọba alaye to wa nibi ipade Ọọni ti Ile Ife, Alaafin ti Oyo, Eleko ti Eko, Ọ́lọwọ ti Ọwọ, Ọrangun ti Oke-Ila, Ayangburen ti Ikorodu ati Alawẹ tilu Aawẹ pẹlu Olu ti Ilaro ati Ọwa-Ooye ti Okemesi.
Mo tilẹ̀ rò pé n o já sínú odò Ẹ̀jẹ̀ náà ni, àfi ìgbà tí mo sì gbé ẹṣẹ̀ lé irin tí ẹṣẹ̀ mi fe méjéèjì ń gbé ara wọn láìjẹ́ pé mo gbé wọn, bẹ́ẹ̀ bẹ́ẹ̀, mo kọjá sí òdì kejì.
Bí a bá ṣe àkíyèsí ìtàn ilẹ̀ Yorùbá lẹ́nu lọ́ọ́lọ́ọ́ yìí, a ó rí i pé àwọn kan ti ba orúkọ wọn jẹ́ nípa ìwà búburú tí wọ́n ti hù.
Onímọ̀ àwùjọ Mbangula Kemba sọ̀rọ̀ tako ojú tí wọ́n fi wo ọ̀rọ̀ yìí, ó tẹnumọ́ọ pé wọn ò gbọdọ̀ fi ìfìyàjẹni yanjú ìṣòro nínú ìgbéyàwó.
Lori nkan ti awọn eeyan to kù ninu ẹbi naa le ṣe lati dena tabi fi opin si akufa, Baba Ẹlẹbuibọn sọ pe wọn yoo difa, lati mọ nkan ti wọn yoo fi ṣe etutu.
Akọwe ijọba apapọ Boss Mustapha lo kede orukọ Ọjọgbọn Gambari lasiko ti ipade igbimọ iṣejọba apapọ lorilẹede Naijiria fẹ bẹrẹ lọjọru niluu Abuja.
" Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Winnie Mandela di olóògbé lẹ́ni ọdún mọ́kànlélọ́gọ́rin Winnie Mandela di olóògbé lẹ́ni ọdún mọ́kànlélọ́gọ́rin Fani Kayode: Bùhárí ló lẹ̀bi Emir tí Olúwòó ń pe ara rẹ̀ Ó ní yàtọ̀ sí wí pé ó jẹ́ ààyò àti àwòkọṣe fún gbogbo obìnrin ilẹ Áfíríkà, Winnie Madikizela-Mandela jẹ́ àwòkọṣe fún gbogbo ọmọ ilẹ̀ Áfíríkà.
Ninu isọrọ tirẹ, alaga ẹgbẹ oṣelu PDP ni ipinlẹ naa, Adegboyega Oguntuasẹ sọ wi pe lootọ ko si oun ti a le tọka si ṣugbọn idajọ n bẹ lọwọ ara ilu.
Ohun ìní ọlọ́rọ̀ ni ìlú olódi wọn,lójú wọn, ó dàbí odi ńlá tí ń dáàbò bò wọ́n.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Yoruba: Mi ò fẹ́ kí àwọn ọmọ má gbọ́ èdè Yorùbá níbi tí a wà yìí Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Yoruba: Mi ò fẹ́ kí àwọn ọmọ má gbọ́ èdè Yorùbá níbi tí a wà yìí 26 Èbibi 2019 Torin tijo tilu ni wọn fi n kọ ede Yoruba.
 Hâte de démarrer le prochain chapitre en espérant que Dieu me bénisse une fois de plus comme il l’a fait pendant toute ma carrière 🙏🏾🙏🏾🙏🏾 DD11 #Dunkerque #Abbeville #Tourcoing #Vannes #LevalloisPerret #Lemans #Guingamp #Marseille #Chelsea #Shanghai #istanbul #Montreal #phoenix @usldunkerqueofficiel @levalloisfootball @lemansfc.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Jazz music: Ayọ̀ tó ń bẹ nínú orin Jazz 3 Ọ̀wàrà 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 8 Ọ̀wàrà 2019 Oríṣun àwòrán, AP Àkọlé àwòrán, Olakunle Tejuoso at his record and book store in Lagos Ni aarin ile itaja rẹkọọdu orin rẹ, The Jazzhole, lo duro si.
Ati pe, awọn onimọ nipa rogbodiyan ninu ajọ naa ti ṣe iwadii, wọn si ri i daju pe ileeṣẹ ologun lọwọ ninu ipaniyan to waye ni Lekki.
 Aliyu – Yobe, Minisita Abẹle fun iṣẹ ode ati ile gbigbe(Works and Housing), State mẹ́tàlélógójì ) Sadiya Umar Faruk – Zamfara,  Minisita fun iṣẹlẹ pajawiri, eto isomoniyan ati idagbasoke eto igbafe (.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ìtàn rèé nípa bí Ogbomoso ṣe pa ọba, yọ nǹkan ọkùnrin rẹ jó kiri ìlú Afenifere fara ya lórí bí Tinubu ṣe jókòó kí Ooni Háà ilẹ̀ wẹ!
Ní ọjọ́ keji, mo sọ fún un pé kí ó mú ọmọ tirẹ̀ wá kí á pa á jẹ, ṣugbọn ó fi ọmọ tirẹ̀ pamọ́.
Wo awọn iwe to gbọdọ ni ko to le forukọ silẹ: •Nọmba idanimọ ile ifowopamọ BVN •Aworan pelebe •Oju opo ikansiraẹni e-mail ati nọmba ẹrọ ibanisọrọ ti wọn le fi pe ọ si •Iwe ẹri ikẹkọ gboye fasiti ati sabuke agunbanirọ NYSC Kete ti o ba ti de oju opo N-Power, awọn ohun to yẹ ko se ree: •Fi e-mail rẹ tabi nọmba foonu rẹ si oju aye ti wọn pese.
Bakan naa ni ijapa yii maa n ba Sọun sọ̀rọ̀ nigba to ba wu ninu ọdun kan.
Inù mi dùn púpọ̀ sí àwọn ọ̀jọ̀gbọ́n ẹ̀ẹ̀tí kẹ́kọ̀ọ́ tí wọ́n sì jẹ́ ọmọ ilẹ̀ Yorùbá yálà nílẹ̀ Yorùbá tàbí ní òkè òkun bá lè bẹ̀rẹ̀ láti máa kọ́ ọ̀pọlọ̀pọ̀ nínú àwọn àròkọ wọn ní èdè abínibí wà nítorí òní kọ́ àmọ́ nítorí ọjọ́ ọ̀la kí àwọn ọmọ tí wọn kò ì tíì bí lè rí nnkan kà nípa gbogbo ohun mère mère tí ó n sẹlẹ̀ jákè jádò àgbáyé.
Ọ̀tá mi pa àwọn ọmọ mi run,àwọn tí mo tọ́, tí mo sì fẹ́ràn.
Ọgbẹni Adamu tun ni awọn agbofinro to farapa ninu iṣẹlẹ naa yoo gba igbega lẹnu iṣẹ.
Àkọlé àwòrán, Kinaya ni nigba ti oun wa ni omo odun mewaa ni won ti lọ omu òun mọlẹ Igbàgbọ wà wí pé ó lé ni ọmọ ẹgbẹ́run kan ni wọn ti lọ ọmu fún ni ilẹ Gẹẹsi.
0 27 Erekusu Solomon Islands 0 0.
Lọjọ ẹti ni ileeṣẹ ologun ofurufu kede ọrọ naa loju opo Facebook rẹ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Chichi Igbo: Ọ̀pọ̀ máa ń rò pé mo ní nǹkan ọkùnrin lábẹ́ torí ìrísí mi jọ ti ọkùnrin Sugbọn gbajumọ osere lobinrin naa ti fesi sọrọ ọhun, to si ni oun ati ọkọ oun mu akọrin naa, August Alsina ni ọrẹ ni ọdun mẹrin sẹyin lati ipasẹ ọmọ awọn, Jaden, tii se ẹni ọdun mejilelogun.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Olubadan of Ibadan: Olóye Ọ̀tún ní ìjà ti parí ṣùgbọ́n àwa ò gbé adé sílẹ̀ o!
OLUWA àwọn ọmọ ogun ní, “Nítorí pé èmi OLUWA kì í yipada, ni a kò fi tíì run ẹ̀yin ọmọ Jakọbu patapata.
Yóo fi èyí tí apá rẹ̀ bá ká rúbọ: yálà àdàbà tabi ẹyẹlé; 
Akọsẹmọsẹ olutọju alaisan ni Iyalode tuntun yii to si kẹkọ gboye nilẹ Gẹẹsi lọdun 1960, o si se igbeyawo pẹlu Amofin Diti Oyekanmi to wa lati agboole Matanmi nilu Osogbo lọdun 1961.
O ni asiko yii ni oun n kopa ninu ajọdun ọlọdọọdun 'Ṣiṣe atunṣe si iboji mọlẹbi'ti wọn n pe ni: Qing Ming Tomb-Sweeping Festival lọwọ.
Kí òdòdó aláràbarà mẹrin wà lórí ọ̀pá fìtílà náà gan-an, kí àwọn òdòdó náà dàbí alimọndi tí ó ṣẹ̀ṣẹ̀ so, 
Jesu dá a lóhùn pé, “Bí burúkú ni mo bá sọ, wí ohun tí ó burú níbẹ̀ kí ayé gbọ́.
Nígbà tí Mẹfiboṣẹti ti Jerusalẹmu dé láti pàdé ọba, ọba bi í pé, “Mẹfiboṣẹti, kí ló dé tí o kò fi bá mi lọ?
Ọkọ̀ ojú omi méjì kọlu ara wọn l‘Eko, èèyàn mẹ́ta fayé sílẹ̀ Ìjọba Ọyọ gbọdọ̀ tanná wádìí ìṣèjọba Abiola Ajimọ̀bi - PDP Ẹ máṣe gba àmúlùmálà ọmọ oyè lọ́wọ́ ìdílé ọba kankan nílẹ̀ Ijebu - Awujale Àwọn ọmọbíbí ìpínlẹ̀ Ọyọ nìkan ni yóò rí iṣẹ́ àgbàṣe gbà lábẹ́ ìjọba mi - Seyi Makinde Khafi wọ gàu lẹ́nu iṣẹ́ lórí ẹ̀sùn ìbálòpọ̀ ní BB Naija El-Zakzaky: Arúfin ni ijọba Muhammadu Buhari gan-an - Ladoja Ṣe ẹ si mọ wi pe ko si bi a ba ṣe fa gburu, ti gburu ko ni fa igbo, eyi lo mu ka ṣe ayẹwo awọn ounjẹ ti a n ko wọ orilẹede Naijiria lati oke okun atawọn to ṣeeṣe ko gbowo lori nitori igbesẹ yii.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ẹ̀yin òṣìṣẹ́, ẹ kọ ìyà tí wọ́n fi ń jẹ yín lórí owó oṣù tuntun - Oshiomole gbarata Àwọn Pásítọ́ ijọ Redeem márùn ún bọ́ sọ́wọ́ ajínigbé ní Ijebu Ode Ó tó gẹ́ẹ́!
E̩nì kò̩ò̩kan ló ní ànfàní sí gbogbo è̩tó̩ àti òmìnira tí a ti gbé kalè̩ nínú ìkéde yìí láìfi ti ò̩rò̩ ìyàtò̩ è̩yà kankan s̩e; ìyàtò̩ bí i ti è̩yà ènìyàn, àwò̩, ako̩‐n̄‐bábo, èdè, è̩sìn, ètò ìs̩èlú tàbí ìyàtò̩ nípa èrò e̩ni, orílè̩‐èdè e̩ni, orírun e̩ni, ohun ìní e̩ni, ìbí e̩ni tàbí ìyàtò̩ mìíràn yòówù kó jé̩.
Ṣugbọn, ajọ WHO ṣi n ṣe iwadii boya lilo rẹ le ran awọn araalu lọwọ Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Amosun ṣọ̀fọ̀ Adesanya ọ̀rẹ́ tímọ́tímọ́ rẹ̀ l'Abẹokuta
Oyo NLC: A kò bẹ̀rẹ̀ ìyanṣẹ́lódì láti d'ẹ́rù ba ìjọba tuntun
Buhari sọ otitiọ nipa pe orilẹede Naijiria lawọn eeyan to n ṣe igbọnsẹ si ita gbangba pọ si julọ ṣekeji lagbaye, eyi to tums si pe wọn ko lanfani si ile igbọnsẹ to dara.
 Alukoro ọlọpaa sọ pe oun ti pàṣẹ fún lati ṣe iwadii oun to ṣẹlẹ ni pato, ko si fun oun ni abọ."
Roomba náà a ti dákẹ́ rọ́rọ́ sí ẹ̀bá ibi tí wọ́n gbé e sí.
Lopin ọsẹ ti o kọja ni gomina Ṣeyi Makinde kede wi pe ki gbogbo awọn oṣiṣẹ ijọba ipinlẹ Ọyọ to n bẹ ni ipele ikẹtala soke wọle pada sẹnu iṣẹ wọn lonii ọjọ aje lẹyin ti onikaluku wọn ti deju mọle fun osẹ melo kan nitori aarun Corona to n ba gbogbo aye finra lọwọlọwọ.
 Awọn ekun meta ọtọtọ ti o to ilu Lebanon  ni Ikọ Boko Haram ti gba lorile ede Naijiria , ti wọn si n gba owo ori , ti wọn tun ti ri asia wọn sibe, koda wọn tun ni emir tiwọn.
Ekiti: Ọwọ́ ọlọ́pàá tẹ afurasí tó pa ìyàwò lárìnlọọ̀dù lẹ́yìn tó fipá bá a lòpọ̀
Ninu alaye re, ogagun Omozoje tenumo pe ile ise ologun orile ede
ọna ti wọn gba ni pe, wọn yoo pe ẹrọ ilewọ rẹ lori Whatsapp, boo gbe e, boo gbe e, ‘spy software’ yoo wo ori ẹrọ ilewọ rẹ, eleyii ti yoo fun wọn ni anfaani lati wo gbogbo ohun to ba wa lori ẹrọ ilewọ rẹ.
Àkọlé àwòrán, Àwọn òṣìṣẹ́ MMA2 Ẹ o ranti pe awọn ẹgbẹ́ òṣìṣẹ́ naa da ẹ̀rù bolẹ̀ wí pé àwọn yóò ti pápákọ̀ òfurufú Murtala Muhammed international Airport 2 (MMA) tó wà ní ìlú Eko pa.
Oríṣun àwòrán, Instagram/sanyeri12 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Ẹṣẹ ni aṣọ to n fi ara han ati sikẹẹti lọntínrín Wọn ko faaye gba akẹkọ lati wọn awọn sikẹẹti to lẹ mọ ni lara pẹki pẹki tabi aṣọ to ba n ṣi ara silẹ.
ẹ̀yin ọmọ mi gbogbo, mo fẹ́ kí ẹ fi í sí ọkàn láti òní lọ pé, kò sí nǹkan tí ń bẹ ní orí ilẹ̀ ayé tí ẹnikẹ́ni kò lè ṣe, ẹni tí ó bá ń fẹ́ẹ́ di olówó lè di olówó, ẹni tí ó bá ń fẹ́ẹ́ di ènìyàn pàtàkì lè di ènìyàn pàtàkì, ṣùgbọ́n ọ̀lẹ tí kò fẹ́ẹ́ jìyà tí ó sì ń fẹ́ẹ́ di ènìyàn pàtàkì yóò máa wà láàrin àwọn èrò ẹ̀hìn láéláé.
Àwọn tí ń ṣe wọ́n yóo dàbí wọn,ati gbogbo àwọn tí ó bá gbẹ́kẹ̀lé wọn.
Yinka Ayefele di asojú Àjọ INEC Ayefele fi orin ẹ ṣeun sẹ́nu kí Ajimobi Ayefẹlẹ bá BBC sọ̀rọ̀ lórí ilé orin rẹ̀ tí Ajimọbí ń tún kọ́ Awọn Iroyin ti ẹ le nifẹ si Ìtàn tó wà nídi òwe ‘Sebótimọ Ẹlẹ́wà Sàpọ́n’ Ìtàn tó rọ̀ mọ́ òwe ‘aṣọ kò bá Ọ́mọ́yẹ mọ́.
Gbèsè Nàìjíríà ti lé ní 18 tírílíọ́ọ́nù lábẹ́ ìṣèjọba Ààrẹ Buhari- DMO Wo bí iṣẹ́ abẹ wákàtí mẹ́fà, tí wọ́n fi dóòlà ẹ̀mí ìjàpá tí ọkọ̀ tẹ̀, ṣe lọ Kò sóhun tó ń jẹ́ ‘Captivus’ nílẹ̀ Oodua, mágùn ni mágùn ńjẹ́ - Babaláwo Wo àwọn obìnrin abúlé kan tó dáwó ra ọkọ̀ láti máa gbé aláboyún lọ ilé ìwòsàn Ìtàn rèé nípa bí Ogbomoso ṣe pa ọba, yọ nǹkan ọkùnrin rẹ jó kiri ìlú Koda, ẹnikan ni kii ṣe gbogbo obinrin lo le duro lati lo ifẹ pẹlu ọmọ ọlọsan lasan lasan, dipo bẹẹ, wọn yoo maa le awọn eeyan to n lo ọkọ ofurufu kiri ni.
Òṣìṣẹ́ reluwé tó bá gbé owó gun tíkẹ́ẹ́tì, yóò gé ìka jẹ - Amaechi Rélùwéè tẹ alágbe kan pa ní Eko Beckham, àgbábọ́ọ́lù tẹ́lẹ̀ rèé tó ń sọ èdè Yorùbá Dogara sọ pe oun gan ko le sọ fun awọn ọmọ ile lati yan ẹnikan, bi ko ṣe ki wọn dibo yan ẹni to ba wu wọn.
    “Nísisì yìí, ẹ ti gbọ́ orúkọ àwọn mẹ́sàn-án pàtàkì nínú wa, n kò ní lè dárúkọ àwọn mọ́kànlélógójì yòókù, nítorí àkókò ń lọ, ṣùgbọ́n gẹ́gẹ́ bí ètò wa Olúkúlúkú ló gbé ìbọn lọ́wọ́, àfi Ìrèkè nìkan ni kò gbé ìbọn, o ń fọn fèrè rẹ̀ kí ìrìnàjò wa bà dàbí ìrèkè kí ó gbadùn bí oyin.
Ṣugbọn àwọn eniyan náà kọ̀, wọn kò gba ohun tí Samuẹli wí gbọ́.
Àwọn ọmọ ìjọ ẹ̀sìn Shi'ite naa ni wọ́n ń pè fún ìtúsílẹ̀ aṣíwájú ìjọ náà, Sheikh Ibrahim Elzakyzaky tí ìjọ ba fi sí àtìmọ́lé láti bíi ọdún mẹ́ta sẹ́yìn Ikọ̀ aláàbò Nàìjìríà dojú kọ Shiite Ọlọ́pàá mú 115 ẹlẹ́sìn Shiite Nínú ìfọ̀rọ̀wérọ̀ rẹ̀ pẹ̀lú BBC Yoruba, agbẹnusọ fún ìjọ ẹ̀sìn Islam naa, Ibrahim Musa ní ìwọ́de alá àláfíà lawọn máa ń ṣe ṣùgbọ́n àwọn ọlọ́pàá ló máa ń fi ipá àti ìbọn kò wọ́n lójú.
Eyi gaan lo pe ni ayẹyẹ ọjọ ibi rẹ lẹyin eyi to gba foonu lọwọ ẹni to n ṣafihan rẹ to si ṣe adura pupọ fun awọn ololufẹ rẹ pẹlu ede to maa n fi ṣe ere awada rẹ bii ẹni ti ede gẹẹsi ko dan mọnran rara lẹnu rẹ.
Bakan naa ni egbe ohun yoo sabewo si awon ile-ise, awon eka ati ajo ile-ise nipinle Kaduna, nipa sise agbateru ipolongo sisatileyin owo fun ifesto somo-bibi naa.
'Àgbàrọ́ òjò wọ́ ọmọ méjì lọ ní Ketu l'Eko lálẹ́, a ṣì ń wá wọn di òní' Daddy Freeze túbá!
Ẹ lọ pè é wọlé, kí ó wá jẹun.
" Bakan naa lo fikun pe ile ti ijamba naa bajẹ to aadọta niye, nigba ti ọpọ eeyan ti wọn ko tii mọ iye wọn, ti jalaisi ninu ijamba ina naa.
Nítorí pé, jákèjádò gbogbo ayé, láti ìlà oòrùn títí dé ìwọ̀ rẹ̀ ni orúkọ mi ti tóbi láàrin àwọn orílẹ̀-èdè, ibi gbogbo ni wọ́n sì ti ń sun turari sí mi, tí wọ́n sì ń rú ẹbọ mímọ́ sí mi láàrin àwọn orílẹ̀-èdè.
Àwọn ọbá aláye ilẹ̀ Yorùbá márùn-ún pẹ̀lú ọ̀pá àṣẹ wọn Àṣírí tó ń bẹ láàrín Oluwo àtàwọn ọ̀dọ́ Iwo tí wọ́n fi fi ẹ̀mí wọn lélẹ̀ dáàbò bo ààfin rẹ̀ Àwọn ọ̀dọ́ ya bo ààfin Akire láti jí oríadé gbé Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Láàrín ìṣẹ́jú díẹ̀, ẹ ka ìwé Akinwumi Ishola, Nítorí Owó"" lórí Akomolede Yoruba Oríṣun àwòrán, Seyi Makinde Ipade rẹ pẹ́lú awọn eekan yii waye lati jiroro lorii ọna itẹsiwaju fun ipinlẹ naa lẹyin ọpọpọlọ ọsẹ titi iwọde ifẹhonuhan EndSARS ti fa."
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù UFC 243: Isreal Adesanya sán bàǹtẹ́ ìyà fún Robert Whittaker pẹlu 18-0 6 Ọ̀wàrà 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Isreal Adesanya tó jẹ́ ẹni ọgbọ́n ọdún ló lu Robert Whittaker ní Melborne, Australia.
Èrò àwọn oníbàárà Skye Bank tó porúkọ dà A yoo ṣe àyẹ̀wò ọpọlọ fàwọn òṣìṣẹ́ FSARS - Iléesẹ́ ọlọ́pàá Lẹyin orẹyin, ala d'ohun Awọn onimọ fidi ẹ mulẹ ni Taiwan pé igba akọkọ ni yii ti wọn yoo ri iru iṣẹlẹ yii lẹnu iṣẹ wọn.
Akinwumi Adesina jáwé olúborí gẹ́gẹ́ bí adarí Báńkì AFDB Wo àṣẹ tuntun tí Buhari gbé síta nípa owó iná ọba Awọn afurasí Babaláwo pa ìyáwó Ìmáàmù àgbà ìlú Ayere ní Kogi, Alayere dá sọ́rọ̀ Oríṣun àwòrán, LASEMA Kọmiṣọna ileeṣẹ ọlọpaa ipinlẹ Eko, Hakeem Odumosu sọ fun BBC lojuko iṣẹlẹ ọhun pe ni kete ti iroyin naa tẹ awón ọlọpaa leti ni awọn oṣiṣẹ rẹ tẹkọ leti lọ sojuko ọhun.
Ninu oṣu keji ọdun yii ni ile iwe naa kọkọ le ọkunrin to wa ninu fọnran lọ ile, lẹyin ti wọn fẹsun kan an pe o wu iwa to tapa sofin fasiti naa.
'Ọmọ tó bá lanu gbàgà sọ̀rọ̀ sí àgbà, bàbá àti ìyá rẹ̀ ló ń bá wí' Buhari mórí lé Saudi lẹ́yìn ìbúrawọlé fún sáà kejì Barrymade ọmọ Barrister to jẹ oloogbe ti ọpọ n bu ọla fun ni olorin fuji lo tahun si King Wasiu Ayinde Marshal.
Dokita Hassan ni ''arun yii maa n bẹrẹ nigba ti ọmọ ba wa ni ikoko, yoo si maa gbilẹ sii bi ọmọ ṣe n dagba, nigba to ba ya ọmọ naa le ma riran mọ.
Awon ile ise yii kedun iku awon to doloogbe ninu ijamba naa.
Awọn ọlọpa kan ree ni Tunisia, ti wọn n gbe oku akẹẹgbẹ wọn ti ado oloro pa lasiko ti wọn n paraaro yika ilu lọ̀ọjọ Ẹti lọ si iboji.
Liverpool fiya jẹ ẹgbẹ agbabọọlu Barcelona lati pegede fun aṣekagba idije Champions League, nigba ti Tottenham fagba han Ajax lati wọ ipele aṣekagba.
Ọkunrin Italy kan ti o jẹ ọmọ ọdun mejidinlọgbọn, Luca Traini, lọ si ọdọ rẹ ni Alfa Romeo o si yin in nibọn.
Fetí sí mi, ọmọ mi, kí o sì gbọ́n,darí ọkàn rẹ sí ọ̀nà títọ́.
Ó ní ọ̀nà ọ̀tọ̀ ní àwọn yóò gbé owó ìrànwa eléyìí gba lójuna àti mase kó sínú wàhálà tí wọn kojú, lásìkò owó ìrànwọ́ epo bẹtiro, nítori náà ìgbìmọ tẹ̀ẹ́kótó yóò dìdé, tí mínísítà fún ìsúna yóò wà nínú rẹ̀ pẹ̀lú, láti sètò tó bá yẹ.
Gba ẹjọ́ mi rò, kí o sì gbà mí,sọ mí di alààyè gẹ́gẹ́ bí ìlérí rẹ.
Chief Kanran: Mi ò ṣagbe àmọ́ mo nílò ìrànlọ́wọ́ ọmọ Yorùbá
Àwọn òṣìṣẹ́ pápákọ̀ òfúrufú MMA2 ṣẹ́welé ìyansẹ́lódì Ilé iṣẹ́ ọkọ̀ òfúrufú tuntun 'Nigeria Air' ṣíwọ́ iṣẹ́ Ngige ni iṣẹ́ n lọ lọ́wọ́ lórí ǹkan ti ASUU n bèèrè Lucky Izebhokun ti o jẹ alaga ATSSSAN ati Ayodele Sofolayan ti NUATE ni o to gẹ pẹlu bi wọn ti ṣe n ko iyan awọn ọmọ ẹgbẹ awọn kere.
Ramil, omọ ogun ilẹ̀ ní Russia yìnbọn pa akẹgbẹ́ rẹ̀ mẹ́jọ!
Ṣé ìfẹ́ rẹ̀ tí kì í yẹ̀ ti pin títí lae ni;àbí ìlérí rẹ̀ ti dópin patapata?
Lizzy ṣalaye loju opo instagram rẹ pe ayelujara ti mu ayipada ba igbe aye eleyi to si n mu ọpọ eeyan parọ tawọn mii si n wuwa buruku kiri.
Amole festival in Akure: Deji pàṣẹ kí gbogbo ọjà àti ṣọ́ọ̀bù wà ní títì pa
"O ni ""Oju ti a fi wo bi awọn oṣiṣẹ alaabo ṣe kọlu awọn oluwọde alaafia ọhun, ni titẹ ẹtọ ọmọniyan loju."
, ni sise-n-teleMinisita fun eto isuna ati ilana eto lorile-ede Nigeria, Udoma Udo Udoma, eni ti o so fun awon akoroyin ile-igbimo asofin leyin ipade apero awon igbimo amuses lojo-Ru pe, igberu ti o ba eto oro-aje  safihan wipe, oro-aje orile-ede Nigeria ti kuro ni bi o se denu-kole tele.
Abramu bá sọ fún Lọti pé, “Má jẹ́ kí ìjà bẹ́ sílẹ̀ láàrin èmi pẹlu rẹ, tabi láàrin àwọn darandaran mi ati àwọn tìrẹ.
Nítorí àṣà ilà abẹ́ kíkọ náà ni Sipora ṣe wí pé, ọkọ tí ọ̀rọ̀ rẹ̀ gba kí á ta ẹ̀jẹ̀ sílẹ̀ ni Mose.
Lẹ́yìn náà tí o bá ti wò ó tán, ìwọ náà yóo kú gẹ́gẹ́ bíi Aaroni arakunrin rẹ, 
"A wa n rọ awọn araalu lati kẹyin si ayederu esi ibo to gba oju opo ayelujara kan.
( 4 ) apor : Èyí ni eni ti ó kópa nínú ohun ti òrò-ìse ń so .
Ọmọ Ibadan, to ni oun ti ni iwe ẹri diploma kekere taa mọ si OND lọwọ tun salaye pe, ni kete ti oun padanu eto igbaniwọle si fasiti Obafemi Awolowo naa, ni oun ba kuku pada lọ sile ẹkọ Poly, lati gba iwe ẹri diploma agba, tii ṣe HND.
Iyawo rẹ Catherine n bọ lọna lati wa si Zambia.
Wọn ni ọṣe ti awọn oniṣẹ laabi yii n ṣe lagbegbe wọn ti n kọja afara da to si nilo iwadi gidi.
Awon miiran ti yoo tun maa
ajo eleto idibo, o tun dupe lowo awon igbimo ati awon ti oro naa kan pelu
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Rain: Ìgbà òjò léwu, ohun tó o ní láti mọ̀ rèé 27 Èbibi 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 18 Ọ̀wàrà 2019 Oríṣun àwòrán, Pulse Ni ọdọọdun ni agbara ojo maa n gbẹmi ara ilu ni orilẹ-ede Naijiria.
Arabinrin May, so pe awon ti seto eyawo ti iye.
To ba n pẹ jẹun alẹ́, o le ni jẹjẹrẹ ọyan àti asétọ̀ Ìgbẹ́ ọmọdé ń dènà ààrun jẹjẹrẹ, àìsàn ìtọ̀ súgà Àwọn àpẹẹrẹ pé o ti ń darúgbó Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Ogbẹni Sanni sọ pe idanilẹkọọ yii jẹ ohun ti awọn alaṣẹ Ile ri pe o ṣe pataki lati fi mu igberu ba iṣẹ awọn oṣiṣẹ yii.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Coronavirus: Àrùn Coronavirus fa'lẹ̀ya láwọn ìletò aláwọ̀dúdú ní Amẹ́ríkà 7 Ìgbé 2020 Oríṣun àwòrán, Getty Images Akojọpọ iroyin nipa awọn ti arun Coronavirus n ṣe lati ọdọ awọn oṣiṣẹ eto ilera ni Chicago n jẹ ko di mimọ bayii pe ọpọ awọn eeyan to jẹ ọmọ Amẹrika alawọ dudu lọwọ arun naa ti tẹ.
Ẹ wá fún ìwòsàn láàrin àwọn ọjọ́ mẹfa yìí.
Ẹ óo ṣá ti gbọ́ nípa iṣẹ́ tí Ọlọrun fi fún mi nípa oore-ọ̀fẹ́ rẹ̀ láti ṣe fun yín.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ikú ọmọ Dbanj: Ohun ti awọn òṣeré n sọ 25 Òkùdu 2018 Oríṣun àwòrán, @iambangalee Àkọlé àwòrán, Oṣù tó kọjá ní Daniel pé ọmọ ọdún kàn Ọ̀fọ̀ ti ṣẹ̀ ní ìdílé gbajúgbajà akọrin tàkasúfèé ọmọ orílèèdè Nàìjíríà, Daniel Oyebanjo tí gbogbo ènìyàn mọ̀ sí Dbanj.
Ọjọ kẹẹdogun, oṣu Kẹwa, ni ile aṣofin ipinlẹ naa gbe igbimọ ẹlẹni meje kalẹ lati ṣewadii awọn fidio kan to fihan pe Gomina Ganduje n gba owo ẹyin lọwọ awọn kọngila.
O ni oun gbo nipa eto adojutofi ilera sugbọn oun ko tii ri nitorinaa oun yoo se ise lori re.
Ki ni o faa ti ẹ fi du ipo ni igba mẹrin ọtọọtọ lai ni iwe ẹri kan ṣoṣo?
Ẹ̀yin ará Galatia, ẹ mà kúkú gọ̀ o!
Joṣua, ọmọ Nuni, tí ń ṣe iranṣẹ òun, ni yóo dé ilẹ̀ náà.
Tiwa ti di olorin to gbayii gan loke okun.
Nígbà tí a sò máa dé ọ̀hún, àwọn ewéko wọ̀n-ọnnì ti hù, iná tí a dá ti kú, ohun gbogbo tún ti pada di bí ti àtẹ̀yìnwá.
A n ṣetọju wọn ati pe a gba wọn ni ọwọ ati iyi ti o b'ojumu.
nígbà tí Ọba Ìlú àjìdò gbọ ́ pé ajénifújà kò rí jìjì mú lọ sílé fi ṣe aya , ó pinnu lọ ́ kàn rẹ ̀ pé dájúdájú ipò ọlá , ipò ẹ ̀ yẹ ni jìjì fẹ ́ rẹ ̀ jù , tó fẹ ́ kí a fi fun òun .
Ọkunrin kan jáde lọ láti fúnrúgbìn.
Ẹ níláti faradà á bí ìtọ́sọ́nà.
Lẹ́yìn náà, yóo ṣẹ́ gègé lórí àwọn ewúrẹ́ mejeeji, gègé kan fún OLUWA, ekeji fún Asaseli.
O wa sọ ọ di mimọ nibi ipade naa pe awọn amofin oun ti n gbe igbesẹ lori ohun ti yoo kan lori ọrs naa.
Níbẹ̀ ni balogun ọ̀rún tí ó ń mú wa lọ ti rí ọkọ̀ Alẹkisandria kan tí ó ń lọ sí Itali.
Awọn agbabọọlu miran to ti gba ami ẹyẹ naa lera Yaya Toure ọmọ orileede Ivory Coast ti o fi igba kan jẹ agbaaarin fun ẹgbẹ agbabọọlu Manchester City lo ṣi yi gba ami ẹyẹ naa lerawọn lẹẹmẹrin laarin ọdun 2011-2014.
ṣe fẹ gbe igbesẹ ati yọ ọ nipo, Aṣofin Agunbiade sọ pe eleyii ki i ṣe
awọn ohun ti ẹgbẹ oselu kan nireti lati se ti wọn ba jawe olubori lasiko idibo.
Ṣemida bí ọmọkunrin mẹrin: Ahiani, Ṣekemu, Liki, ati Aniamu.
Ilé wá di ohun à mu ṣowó.
Abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò dágbére fáyé lẹ́yìn ìjà rẹ Transfer Window: Pogba, Maguire, Bale, Neyman, báwo ni nkan ṣe ń lọ?
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù UFC248: Israel Adesanya ti fi ẹ̀ṣẹ́ yanjú Romero ní ìjà ẹ̀ṣẹ́ kíkàn 8 Ẹrẹ̀nà 2020 Oríṣun àwòrán, Getty Images Abẹṣẹkubiojo ọmọ Naijiria ni, Iṣrael Adesanya ṣi ni ẹṣin iwaju ti gbogbo tẹyin n wo sare ni ere idaraya ẹṣẹ ati ipa kikan, iyẹn UFC248 ni ipele middlewight.
O ni aruwo lasan ni awọn ara ilu n pa lori ọrọ awọn ti ọlọpaa mu naa.
Omotola sọ pe oun ya aworan kan lasiko kan ti oun ko si fẹran bi ikun oun ṣe yọ sita ninu aworan naa, ṣugbọn ọkọ oun ni bo tilẹ jẹ pe ikun oun yọ tandi sita, oun ṣi rẹwa sibẹ.
Ikú, kí ni ìwọ ha ṣe ni ọjọ́ ìgbẹ̀yìn rẹ!
Ninu oro ibanikedun re, Aare Muhhamadu Buhari so wipe Arabirin yi je akikanju ati onisuuru eniyan ti ko wopo .
Kete ti eyi to wa nita ri wa lo ke si awọn to ku rẹ ti wọn si fẹsẹ fẹ ẹ."
durmmy : n ; ( my mother has a talor ' s dummy .
Aarẹ ọna kakanfo Yoruba Diẹ lara awọn akẹkọọ Yoruba oloṣu meji ti BBC ba sọrọ ni Fasiti ti sanmọnti gbe dunlẹ ni Hannah Sawyer, Aminat Sanusi, Fredrick Clement, Damilola Abigeal atawọn mii.
eniyan ti o lee fowo ra lọ.
Tí aago méjìlá bá tún wá kọjá ìṣẹ́jú méjìlá àti aaya-ìṣẹ́jú méjìá, gbogbo rẹ̀ a wá báramu rẹ́gí-rẹ́gí tán pátá-pátá poo.
 paríparí rẹ ̀ àwọn Ẹ ̀ gbá fẹ ́ ràn láti máa kọrin lásán.
Igbesẹ Gomina ana Abdulaziz Yari to kọwe si ijọba ki wọn san owo ifẹyinti ti wọn jẹ ohun lo mu gbogbo awuyewuye to pada wa bi iyipada ofin yi waye.
Òùngbẹ ń gbẹ mí, ẹ kò fún mi ní omi mu.
Ọkùnrin tí wọ́n fẹ̀sùn kàn pé ó jí ǹkan nílé ìjọsìn rí ẹ̀wọ̀n he!
Ìjàǹbáforítì dúró sí iwájú àwa náà sì ń tẹ̀lé lọ.
Oludari ere ni Mercy o si tun jẹ oniṣowo.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, '500 level'' ni mo wà nígbà tí mo di adélé Ọba' Flaming Flamingos Awọn to ba n fi ọkan tẹle ere boolu nilu Eko ati kaakiri orile-ede Naijiria lasiko igba ti ọlaju Premiership ko ti gbode, kete ti a ba darukọ Stationery Stores ni wọn yoo ranti ẹgbẹ agbabọọlu ti o milẹ titi yii.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Awọn Dokita ati awọn osise ilera miran ko gba dede iye owo kannáà.
Fayose: Dídarapọ̀ mọ́ APC dàbí bíbá adigunjàlè ṣ'ọ̀rẹ́ ni
Alhaji Remi Lukman to bi oloogbe naa ṣalaye pé ọfọ nla lo ṣẹ oun ati pe ki ijọba gbe igbesẹ to yẹ kiru eyi maa ṣẹlẹ mọ sawọn alaiṣẹ.
Ẹ má fi owó wúrà tabi fadaka tabi idẹ sinu àpò yín.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Violence against women: Ìjọba pàṣẹ lọ rọọ́kún nílé fún òṣìṣẹ́ káńsù tó lú obìnrin kan ní ìpínlẹ̀ Ogun nítorí ìséde 22 Òkùdu 2020 Oríṣun àwòrán, @TeeBaibie Wọn ti paṣẹ rọọkun nile fun awọn oṣiṣẹ ijọba ibilẹ Ifọ ni ipinlẹ Ogun ti wọn fihan ninu fidio kan to n ja rayinranyin lori ayelujara nibi to ti n lu arabinrin kan lolu ileeṣẹ ijọba ibilẹ naa labẹ awawi pe oun n fi ofin konile o gbele mulẹ nibẹ.
Òun ni a bá máa pè ní, Olówó-ayé ẹgbẹ̀rún-ojú-mọ̀-ọkùnrin.
Nínú lẹ́tà ti wọn kọ ránsẹ si gómìnà, ìgbákeji olùdarí SERAP Kolawole Oluwadare sàlàyé pé àbádofin ọ̀hún jẹ àṣìlò ẹ̀tọ́ àwọn ọmọ ilé ìgbìmọ àṣofin.
Ọgbọn eeyan lajọ NCDC ti kede pe wọn ti ni arun coronavirus ni Naijiria, ninu eyi ti awọn meji ti ri iwosan.
Oríṣun àwòrán, @AlaafinofOyo Oba Adeyemi bii Alaafin akọkọ ti yoo lo aadọta ọdun lori itẹ: Ko si yẹ ko ya ẹnikẹni lẹnu pe ọba to lọla, niyi ati ẹyẹ yii lo aadọta ọdun lori oye eyi to mu agbega nla ba agbegbe rẹ.
Ọdun meji ati ija meje pere ni Afẹsẹkubiojo Isreal Adesanya to jẹ ọmọ orilẹede Naijiria ati Australia lo lati gba Ami Ẹyẹ UFC.
 akokoso ilana-ibagbepo yi setumo india gege bi orile-ede olominira toseluaralu sovereign , sosialisti , ti araaye .
Oun naa ni o dari awọn ikọ to pa ogunlọgọ eniyan ni agbegbe Okene ni Ipinlẹ Kogi O dari ikọ rẹ lati ṣe ikọlu si ọgba ẹwọn Kuje nibi ti awọn ọgọrun awọn ẹlẹwọn ti sa lọ.
Bi ileewe kan ba ti se ofin pe awọn nkankan wa ti awọn ko fọwọ si, akẹkọọ to ba n kawe nibẹ ko gbudọ jẹ arufin.
Alaafin: Kabiyesi ẹ má bínú, àìmọ̀ lo fa ìgbésẹ̀ mi, n kò takò yín
Rehoboamu bá múra kíá, ó bọ́ sinu kẹ̀kẹ́ ogun rẹ̀, ó sá lọ sí Jerusalẹmu.
Lẹ́yìn náà, mo rí àwọn ìtẹ́ kan tí eniyan jókòó lórí wọn.
 wọ ́ n bíi pẹ ̀ lú ara pípé , ìṣẹ ̀ lẹ ̀ ìjàmbá ọkọ ̀ tí ó ṣẹlẹ ̀ ní ọdún 1998 ni ó sọ ọ ́ di alábọ ̀ ara tí wọ ́ n fi gé ẹsẹ ̀ rẹ ̀ .
Ko i tii ran gbangba boya ijọba yoo ṣewadii ileewosan aladani naa, bakan naa ni awọn mọlẹbi ati dokita naa ko gbe ipe BBC lati ṣewadii naa.
"Bi o tilẹ jẹ pe emi naa ri i ka lori ayelujara, mo gbagbọ pe o wa laaye""."
OLUWA ti fi òpin sí àwọn àjọ̀dún tí a yà sọ́tọ̀, ati ọjọ́ ìsinmi ní Sioni.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Kidnapped Turkish Nationals: Iléèṣẹ́ ọlọ́pàá Kwara dóòlà ọmọ Turkey mẹ́rin tí wọ́n jígbé 26 Agẹmo 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 27 Agẹmo 2019 Oríṣun àwòrán, others Àkọlé àwòrán, Alẹ ọjọ Abamẹta to kọja ni wọn ji awọn ọmọ ilẹ okeere naa gbe nile ọti kan.
Kò sí ẹyọ ẹnìkan ní gbogbo Israẹli tí òkìkí ẹwà rẹ̀ kàn bí ti Absalomu.
15 Ìgbé 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Àjọ tó ń rísí ọ̀rọ̀ ojú ọ́jọ́ ti ní Naijiria sí ń lo ike nígbàkúgbà lẹ́ẹ̀kan sọsọ lẹ́yìn tí àwọn orílẹ̀èdè míràn ti fí òpin si.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Victor Agunbiade ni ojú àlá ni Ọlọrun ti yan iṣẹ́ ọmọ ogun ojú omi fún òun ní America Ileeṣẹ Madagascar Institute of Applied Research ni wọn lo egbogi artemisia, to n koju aisan iba ati awọn egbogi miran lati fi ṣe akojọpọ agbo naa.
Dafidi bá sọ fún Ọlọrun pé, “Mo ti dá ẹ̀ṣẹ̀ ńlá, níti ohun tí mo ṣe yìí.
"O ni, ""Mo ri iyatọ gidi gan ni ayika yii nitori nigba ti iṣẹlẹ yẹn ṣẹlẹ, gbogbo ibi kun fun igbo ni."
Iko agbaboolu obinrin Super Falconets orile-ede Naijiria, ti bo si ikoko keji ninu iyikoto ifigagbaga idije boolu agbaye tawon obinrin to n bo lona lorile-ede France, FIFA U-20 Women’s World Cup France 2018.
” ”Ni kukuru , a n sọ
isoro ti awon eniyan lee koju lasiko idibo yii ku.
Pẹlu akọsilẹ, igbagbọ ni wi pe Saybie ni ọmọ ti wọn bi ti iwọn rẹ kere ju lọ to si ye e.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, A nilo agọ ọlọpa ni Orin Ekiti fún aabo wa -Falua Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Ti eniyan ba tete lọ si ile iwosan, ki o bẹrẹ iwosan naa niiṣe pẹlu bi eniyan yoo ṣe gba iwosan si.
”Aare wa ro awon adari orile ede South Sudan lati tubo maa farada fun orile ede won, titi ti eto ijoba rere yoo se fese mule lorile ede naa.
Ní ọjọ́ keji ẹ óo fi òbúkọ tí kò ní àbààwọ́n rú ẹbọ ìmúkúrò ẹ̀ṣẹ̀, ẹ ya pẹpẹ náà sí mímọ́ bí ẹ ti fi ẹbọ akọ mààlúù yà á sí mímọ́.
O ni iru igbesẹ bẹẹ ko le deede waye laisi pe ijọba pe ijoko ijiroro pẹlu gbogbo awọn ara ilu ti ọrọ kan ṣaaju fifi owo kun owo ina mọnamọna.
Lọwọ lọwọ bayii, Lekan Babalola ti gba ami ẹyẹ Grammy ni ẹẹmeji, akọkọ lọdun 2006, ẹẹkeji lọdun 2009.
Itse Sagay wọ gàu lórí ọ̀rọ̀ Adeosun Adeosun ninu iwe ifiposilẹ rẹ loun dupe lọwọ Aarẹ Buhari fun anfaani ti o fun oun l;ati di ipo mu ninu ijọba rẹ.
Nitori ipa ti o ko ninu ẹka amuludun lorilẹede Naijiria, ni ijọba apapọ se fi ami ẹyẹ orilẹede Naijiria, MON daa lọla.
"Lěyin naa lo tun pada gbe Oloruntoba lọ si ile ẹgbọn rẹ ni Ipaja nibi ti o ti pada wa ku.
Nígbà tí ó dé Galili, àwọn ará Galili gbà á tọwọ́-tẹsẹ̀, nítorí wọ́n ti rí ohun gbogbo tí ó ti ṣe ní Jerusalẹmu ní àkókò Àjọ̀dún Ìrékọjá, nítorí pé àwọn náà lọ sí ibi àjọ̀dún náà.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Mo leè di ààrẹ láì lọ sí Amẹ́ríkà - Àtíkù Ẹ múra fún ogun ijọba àpapọ̀ - Ọbásanjọ́ Agbẹjọ́rò tí kò ní apa méjì Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí kan sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
Ta ni ìwọ odidi ọba Israẹli ń gbìyànjú láti pa?
Source: Abọ iwadi idunnu lagbaye tọdun 2019.
O ni Nitori pe lọpọ igba ti wọn ba fẹ ẹ pe oun, Adekola ni wọn kọkọ ma n pe."
Adele gomina ipinle ohun, ojogbon Ivara Esu ati Dokita Edu, ni won jo pawo po lati pin ounje, awon ohun elo ipese ounje, aso, ohun elo igbonse abbl fun awon alabarapa ati awon alaisan ni agbegbe naa.
Sugbọn Shonibarẹ ni nigba ti wọn gbe Darlington de agọ ọlọpaa, wọn bọ aṣọ rẹ, wọn ko ri àpá eyin kankan.
Wòlíì Kasali ní Dolapo Awosika kò lé ìyàwó òun jáde Sanusi Adebisi Idikan rèé, olówó tó ń san owó orí fún gbogbo ọkunrin ilẹ̀ Ibadan Lara oriki Alaafin ni, Iku baba yeye, Adeyẹmi Alowolodu, ojo pa sẹkẹrẹ ma dẹ, ọmọ Atiba, ọmọ iku ti iku ko gbọdọ pa, ọmọ arun ti arun ko gbọdọ se.
n kò sì ní dáríjì wọ́n mọ́, ṣugbọn n óo fẹ́ràn ilé Juda, n óo sì ṣàánú wọn, èmi OLUWA Ọlọrun wọn yóo gbà wọ́n là, láìlo ọfà ati ọrun, idà tabi ogun, tabi ẹṣin ati àwọn ẹlẹ́ṣin.
Elija dáhùn pé, “Èmi kọ́ ni mò ń yọ Israẹli lẹ́nu, ìwọ gan-an ni.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Oluwatoyin Bayegun: Nígbà tí mo di gbájúgbajà tán ni mo bẹ̀rẹ̀ sinimá Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Oluwatoyin Bayegun: Nígbà tí mo di gbájúgbajà tán ni mo bẹ̀rẹ̀ sinimá 18 Ìgbé 2019 Irin ajo ọjọ pipẹ ni ṣiṣe ere agbelewo eyi to ti wa lọkan mọlumọọka apanilẹrin Oluwatoyin Bayegun ti gbogbo eniyan mọ si Woli Arole.
Èyí náà sì ni ìtàn tí àwọn Juu ń sọ káàkiri títí di òní olónìí.
Bi ogun Agbekoya ṣe lọ: Awọn agbẹ ko ara wọn jọ lati tako ijọba ọgagun Adeyinka Adebayo to n dari ẹkùn Iwọ oorun guusu Naijiria nigba naa nitori ele gọbọi to gun owo ori naa.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: 'Gbèsè dáa fún ìpínlẹ̀ Ọṣun' Kẹmi Adeosun ti fi ipò mínísítà ìṣúná sílẹ̀ APC àti PDP takora wọn lórí Olùsirò owó àgba Ọsun tó fisẹ́ sílẹ̀ PDP ni ọrun aarẹ Buhari ni ẹbi ẹsun gbogbo ti wọn fi kan Adeọṣun wa nitori, gẹgẹ bii ẹgbẹ oṣelu naa ṣe sọ, Buhari ni anfani si gbogbo awọn iwadi lori iwe ẹri rẹ lai ṣe ohun to tọ sii.
“Asoju naa tun sọ pe ‘‘idaniloju wa pe irinajo aare yoo tun fihan pe orile ede Naijiria  je alatileyin fun ipinnu Rome .
oOgbeni Osita Okechukwu soro yii di mimo lasiko abewo awon akeko to n polongo fun saa keji ijoba aare Buhari(Buhari Student Campaign Group, BSCG), sile-ise re niluu Abuja, to je olu- ilu orile-ede Naijiria.
Ilẹ̀ tí a pín fún ìran Aaroni nìyí, pẹlu ààlà wọn: ìdílé Kohati ni a kọ́kọ́ pín ilẹ̀ fún ninu àwọn ọmọ Lefi.
Eyi ni wọn fi n se adura fun pe ki irinajo rẹ lẹyin aye yii yọri si rere Oríṣun àwòrán, Fellipe Abreu Àkọlé àwòrán, Posi ile alarabara ni wọn fi n sin oku baba tabi iya onile to ba kọle, to si ya awọn eeyan lati gbe lai ni wọn lara.
Awọn ọmọ ile igbimọ aṣofin ti wọn tẹle Dino lọ gbẹjọ ni awọn bii Philip Aduda, Shehu Sani, Tayo Alasoadura, Ben-Murray Bruce ati awọn miiran.
Kọmísọ́nà ọlọ́pàá ní ìpínlẹ̀ Imo Rabiu Ladodo tó fi ìdí ọ̀rọ̀ náà múlẹ̀ ṣàlàyé pé àwọ́n ti bẹ̀rẹ̀ ìwádìí ní pẹrẹwu lóri ọ̀rọ̀ náà.
Kọmiṣọna feto ilera ni ipinlẹ Eko, Ọjọgbọn Akin Abayọmi salaye pe igba mẹta ọtọọtọ ni wọn ti ṣe ayẹwo fun gomina Sanwo-Olu ṣugbọn piri bayii lolongo rẹ n ta.
Alhaja Kudirat ni iyawo keji ti Abiola fẹ ṣugbọn oun ni iyale ninu awọn iyawo rẹ lasiko ti wọn pa a.
“Nítorí bí ẹ bá dárí ẹ̀ṣẹ̀ àwọn eniyan jì wọ́n, Baba yín tí ń bẹ ní ọ̀run yóo dáríjì yín.
Ẹni to bori: Madagascar Morocco vs Senegal.
'Coronavirus ló mú mi fẹ́ ọkọ mi tí a sì ṣèyàwó lóríi ‘Zoom’ A yìnbọn lu Precious láti dáa dúró ni, akò mọ̀ pé o máa kú- Ọlọ́pàá Èèyàn 576 míràn tún kún àwọn tó ní àrùn COVID-19 ní Nàìjíríà Mo ti bẹ̀rẹ̀ sí ń bá àwọn tí a jọ díje nínú ìdìbó abẹ́lé sọ̀rọ̀ kí àláàfíà léè jọba - Akeredolu Ọpọlọpọ ẹbun lo kọ kalẹ ṣugbọn pabanbari rẹ to si n mu ibere wa latọdọ awọn ololufẹ rẹ ni aṣọ funfun ti ọmọ ẹkọṣẹ rẹ ti ọpọ eniyan mọ si Arikẹ fi fun un lẹbun.
Awọn eeyan ti iṣẹ wọn ba ṣe pataki bi awọn oṣiṣẹ eleto ilera, atawọn eeyan to n ṣiṣẹ nile ifowopamọ.
eto oro aje ati idagbasoke si awon ohun amayederun.
How to get your National Identification Number: Àwọn ọ̀nà tí o le gbà rí fọ́ọ̀mù ìforúkọsílẹ̀ fún NIN rẹ gbà àti àwọn ibùdó ìforúkọsílẹ̀ lágbáyé nìyí
Bí ọwọ́ kò bá wá tẹ olè, ẹni tí ó gba ìṣúra pamọ́ yìí gbọdọ̀ wá sí ilé Ọlọrun kí ó fi Ọlọrun ṣẹ̀rí pé òun kò fi ọwọ́ kan ìṣúra tí aládùúgbò òun fi pamọ́ sí òun lọ́wọ́.
Aare soro ohun di mimo lasiko abewo igbimo egbe oselu APC kan ti ojogbon Hafiz Abubakar wa pelu won, leni ti o ti figban kan je igbakeji gomina ipinle Kano,  sile ise re, niluu Abuja.
John McCain fikun pe Aarẹ Barack Obama gbọdọ wa lara awọn ti yoo sọ ọrọ ikẹyin nipa oun ni ibi ayẹyẹ isinku oun.
fun ijoba apapo nipa ekunwo owo osu awon osise, 
Ẹ óo fẹ́ wọn bí ọkà, atẹ́gùn yóo gbé wọn lọ,ìjì yóo sì fọ́n wọn ká.
Kemoṣi yóo di ohun ìtìjú fún Moabu,gẹ́gẹ́ bí Bẹtẹli, tí Israẹli gbójú lé, ṣe di ohun ìtìjú fún Israẹli.
Ó bá jáde kúrò ní ilẹ̀ Kalidea láti máa gbé Kenaani.
Ọlọrun tún jí wa dìde pẹlu Kristi Jesu, ó wá fi wá jókòó pẹlu rẹ̀ lọ́run, 
Bí wọ́n ti ń la àfonífojì Baka lọ,wọ́n ń sọ ọ́ di orísun omi;àkọ́rọ̀ òjò sì mú kí adágún omi kún ibẹ̀.
yii yoo rii pe won jiya ẹsẹ wọn, ti wọn yoo tun foju bale ẹjọ.
Amotekun : Gómìnà ìpínlẹ̀ Ondo, Akeredolu buwọ́lu àbádòfin nípa Àmọ̀tẹ́kùn
Igbagbọ rẹ ni ó mú ọ lára dá.
Ilé iṣẹ́ BBC ni Fayẹmi kọ́kọ́ bá sọ̀rọ̀ gẹ́gẹ́ bíi gómìnà tí Ekiti yàn Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ekiti Election: Kọmísánà fétò ìdìbò ní jàǹdùkú já àpótí gbà ní wọ́ọ́dù mẹ́fà Kola Ologbodiyan to jẹ akọwe apapọ ẹgbẹ oṣelu Peoples Democratic People to fọwọ si atẹjade naa ni akọ okuta ni PDP ti ibo Ekiti ko lee fọ rara.
Nígbà tí ó ṣe èyí tán, obbìnrin náà padà wá sí ibojì olùfẹ́ rẹ̀ yìí, ó ké sí i, ó ní, Ẹni tí m,o fẹ́ràn ju gbogbo ènìyàn lọ, mo tí parí iṣẹ́ tí o rán mi o.
Bẹ́ẹ̀ náà ni Arisitakọsi ati Sekundu; ará Tẹsalonika ni wọ́n.
Ọlọ́pàá Ogun gb'ọmọ Ìmáàmù lọ́wọ́ ajínigbé, ṣùgbọ́n wọ́n gbé ọkọ̀ ojú omi ọlọ́pàá lọ Ọ̀pọ̀ èèyàn bẹnu ẹ̀tẹ́ lu Mercy Aigbe lórí bó ṣe ki Adeniyi Johnson Mo dáríjì àwọn IPOB tó nà mí ní Germany nítorí wọn o m'ohun tí wọ́n ń ṣe- Ekweremadu Àwọn òṣìṣẹ́ fásitì yóò fi ìyanṣẹ́lódì ṣẹ Nàìjíríà lọ́wọ́ lọ́jọ́ Ajé Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí kan sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
Àkọlé àwòrán, Wọ́n kọlu báríkè ológun ní Damascus àtàwọn agbègbè méjì míì ní Syria Ẹ̀wẹ̀, asojú orílẹ̀èdè Russia ní àwọn kò ní lajú 'lẹ̀ kí tàlùbọ̀ ó kó wọ̀ ọ́ pẹ̀lú ìgbésẹ̀ tí orílẹ̀èdè Amẹ́ríkà àtàwọn tó kù se.
Temidayo Adeleke: Ilé ẹjọ́ ní kí wọ́n yẹgi fún ọmọ Cameroon tó pa ọ̀gá rẹ̀ ni Ikoyi
Àkọlé àwòrán, Olori Aanu tu kẹké ijo laafin olowo ori ẹ Olori Aanu ṣalaye fun BBC gbogbo nkan to wu oun ti ọkan oun n fẹ ni Alaafin n pese fun oun ati pe gbogbo olori ni Oba fẹ ki wọn kawe lo ṣe n ran gbogbo wọn nile iwe.
O ni eyi ti o bani ninu jẹ julọ naa ni bi iṣẹlẹ ijinigbe ati igbesunmọmi naa ti ṣe sun de ipinlẹ Ọṣun nibi ti ọpọ n fi ọkan si gẹgẹ bii ọkan lara awọn ipinlẹ ti alaafia sodo si julọ lorilẹede Naijiria.
Bi a se n ko iroyin yii jọ, omi alaafia ko tii toro ni adugbo Lugbe ọhun nitori awọn eeyan to n sewọde ko tii kuro nibẹ.
Àwọn ni wọ́n ń gbé Reka.
Jet lag Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, It can take time to catch up on your sleep after crossing time zones You feel jet lagged when your body's master clock is at one time and other parts of your body such as your liver, gut, brain and muscles are at slightly different times.
''Abdulrasheed Maina yóò wà ní ọ̀gbà ẹ̀wọ̀n Kuje kó má ba tún sálọ'' Oríṣun àwòrán, Twitter Ileẹjọ giga nilu Abuja ti ni ki Ọga agba ẹka owo ifẹhinti lorilẹede Naijiria tẹlẹ, Abdulrasheed Maina wa ni ẹwọn Kuje titi igbẹjọ rẹ yoo fi pari.
asobode ti ẹkun Oyo/Osun ti pa owo to le ni bilioni Metala Naira ni osu meta
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Akomolede ati Asa lori BBC: Olùkọ́ Kikelomo Ogunboye tan ìmalẹ̀ sí ìwà olè ọ̀gá ọlọ́pàá Anene ṣalaye pe lootọọ nile iṣẹ ọlọpaa gba ipe pe ọdọbinrin kan tu epo si ile ọrẹkunrin rẹ ti o si tun fi ina sii.
Gombe Adamawa Plateau Borno Ebonyi Cross River Sokoto Kebbi Imo Bayelsa Taraba Kogi Nasarawa Zamfara Yobe Jigawa Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Èmi gan máa ń béèrè lọ́wọ́ ara mi pé ta ni Wole Soyinka gangan' Igbesẹ wo ni wọn n gbe lati ri pe ajakalẹ aarun yii ko de ipinlẹ wọn?
Àwọn ọkọ̀ Taṣiṣi ní ń bá ọ ru ọjà rẹ lọ ta.
APC Oyo: Àkọsílẹ̀ rere wà pé Ajimobi ni gómìnà tó dáńtọ́ jùlọ ní Ọyọ
Ni asiko ti a n sọ yii, Holyfield ti gba igbanu WBA rẹpada nigba to lu Mike Tyson ni igba meji ọtọọtọ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Data Usage: Ọ̀nà márún-ún láti mú àdínkù bá dátà fóònù lílò 15 Òkùdu 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 13 Èbibi 2020 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Data Usage: Ọ̀nà márún-ún láti mú àdín kù bá dátà (Data) rẹ̀ lílò Njẹ eyi ti ṣẹlẹ̀ sí ọ ri, tí wà á sùn lálẹ pẹ̀lú dátà ti ilẹ̀ si mọ ti gbogbo ǹkan to kù kò tó mẹgábáítì mẹ́wàá lọ mọ?
Àwọn ọba Filistia wá sọ́dọ̀ obinrin yìí, wọ́n ní, “Tan ọkọ rẹ, kí o sì mọ àṣírí agbára rẹ̀, ati ọ̀nà tí a fi lè kápá rẹ̀; kí á lè dì í lókùn kí á sì ṣẹgun rẹ̀.
Adajọ Nicholas Oweibo sọ wi pe Madueke ati Agbẹjoro Aku Kalu kuna lati fi ẹri to daju lede idi ti ijọba ko ṣe gbọdọ gbe ẹṣẹ le ẹṣọ ara (tirinkọwọ, tirinkẹsẹ, ẹsọ ọwọ ati tọrun, ẹrọ ilewọ iphone) ti o to ogoji miliọnu owo ilẹ okeere dọla.
Bo ṣe pari nibi lo ni anfani lati lọ si Pitman College ni London ni ibi to ti kọ nipa amojuto oko owo ṣiṣe.
 Ìtàn ọ ̀ rùn pé kí ó wá ṣẹ ̀ dá ayé àti àwọn ènìyàn inú rẹ ̀ .
Èèyàn 225 ló tún ṣẹ̀ṣẹ̀ ní àrùn Coronavirus ní Nàìjíríà l'Ọjọ́rú Eeyan kan lo padanu ẹmi rẹ lọwọ aarun Covid-19 lorileede Naijira lọjọ Isegun to kọja yi ninu ikede ti ajọ to n gbogun ti ajakalẹ arun NCDC kede.
Osu mẹfa gbako si ni atunse abala mejeeji afara naa yoo fi waye.
" Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Gómìnà Akinwunmi Ambọ́de gan wà níkàlẹ̀ nígbàtí wàhálà yìí ń wáyé Awọn oṣisẹ naa ni, gbogbo awọn ti wọn ṣe leṣe ni wọn ti gbe lọ sileewosan.
 Ó sàlàyé pé òun fé kí àwon orin tí óun ti ko di kíká sórí fóńrán fídíò .
Kì í ṣe pé kí ọkùnrin kan máa fẹ́ràn obìnrin kan, kí ó máa fẹ́ràn obìnrin yìí, kí òun nìkan máa fẹ́ràn rẹ̀ láì jẹ́ pé onítọ̀hún náà fi ìfẹ́ hàn sí òun ni ìfẹ́ fi lè dàgbà, bẹ́ẹ̀ ni kì í ṣe pé kí obìnrin maa fẹ́ràn ọkùnrin kí òun nìkan máa fẹ́ràn ọkùnrin sá láì jẹ́ pé ọkùnrin náà fi ìfẹ́ tirẹ̀ hàn sii ni ìfẹ́ fi lè gòkè rárá.
Ìbàlòpọ̀ pẹ̀lú ọ̀rẹ́kùnrin kìí ṣe ìfẹ́, bẹ́ẹ̀ ni ìfẹ́ kọ́ ni ìbálòpọ̀ - Genevieve Nnaji Àwọn Ọba alayé ní Naijiria ṣàbẹ̀wò sí Ọba Eko, Gómìnà Eko àti Bola Tinubu lẹyin ìwọ́de EndSARS Ṣé ẹ rántí àkọ́lé àwọn ìwé àkàgbádùn yìí?
Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
Bakan naa ni akọroyin wa sọ pe awọn ọlọpaa mu diẹ lara awọn to n fi ẹhonu ha, wọn ko wọn sinu ọkọ́, wọn si gbe wọn lọ.
  Apapo ibo ti won di ohun ni; ẹgbẹ̀ta le méjílélọ́gọ́rin o le die lẹ̀ẹ́dẹ̀gbẹ̀rin(Total vote cast 714,682).
láti fi Ọmọ rẹ̀ hàn ninu mi, kí n lè máa waasu ìyìn rere rẹ̀ láàrin àwọn tí kì í ṣe Juu.
“mo fe ki gbogbo wa dupe lowo Olorun nitori pe o ti ran wa lowo, Olorun si tun ti setan lati ran wa lowo si i.
’ rèé Ìgbín ní èmi àti ìyá mi máa ń he kiri, ká tó lee jẹun - Lizzy Anjọrin Ẹ wo báwọn òṣèré tíátà kan yóò ṣe rí lọ́jọ́ ogbó Ijọba ipinlẹ Niger naa, lati ipasẹ akọwe ijọba ipinlẹ ọhun, Ahmed Matane ti kede pe ko iyatọ laarin ibudo ifẹranjẹ ati abule Ruga, awọn alanikanjọpọn kan lo kan fẹ lo lati da wahala silẹ ni Naijiria.
Amugbalegbe aare Pataki lori oro ile-igbimo asofin, ogbeni Ita Enang lo jabo oro naa fun awon akoroyin ile-ise aare lojoBo(Thursday), niluu Abuja.
Bi aye ṣe n yi ti aṣa naa n ba a yi pẹlu, Ọba Adedokun Abolarin sọ pe bi a ba gbe aṣa larugẹ, yoo wu ajoji ati ara ilẹ okeere lori yoo si ya wọn lara lati fẹ mọ nipa aṣa wa sii.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Army Vs Police: Ẹ gbọdọ wẹ́ orúkọ ilé iṣẹ́ ọmọ ogun mọ́ kúrò nínú ọ̀rọ̀ yìí- Buratai 13 Ògún 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Army Vs Police: Ẹ gbọdọ wẹ́ orúkọ ilé iṣẹ́ ọmọ ogun mọ́ kúrò nínú ọ̀rọ̀ yìí- Buratai Olú ilé iṣẹ́ àwọn ọmọ ogun ti pàṣẹ fún 93 Battalion tó wà ní Takum, ìpínlẹ̀ Taraba láti sàwári ọ̀daràn Hamisu Wadume tó sá mọ́wọn lọ́wọ́ láti yọ ilé-iṣẹ́ ọmọogun kurò nínú ẹrẹ̀ tí wan wà yìí àti láti dúró bí ẹlẹ́ri pe kò si ọwọ́ àwọn ọmọ ogun ninu ìwà ìbàjẹ́.
Wọ́n dàbí idẹ àdàlú mọ́ irin,àmúlùmálà ni gbogbo wọn.
Ni ipari, o sọrọ lori ipinnu rẹ lati tẹsiwaju ninu oṣelu nitori pe o wa ninu súrà oun lati tukọ̀ ipinlẹ Oyo lọjọ iwaju.
Lara awọn gomina ti aje ọrọ yii ṣi mọ lori ni gomina ipinlẹ Ọṣun, Gboyega Oyetọla.
Ìpàkọ́ kò gbọ́ sùtì ní ọ̀rọ̀ ẹ̀yin tí ẹ̀ ń bú mi- Oyedepo Adari ijọ Living Faith Church Worldwide ti ọ̀pọ̀ n pe ni Winners' Chapel, Bisọ̀ọ̀bù agba David Oyedepo ti fun awọn to n bu u lesi pe ko kan oun.
Oniruuru ariwo ati ọrọ lawọn ọmọ orilẹede Naijiria ti n sọ lori iṣẹlẹ yii.
Olùyà pọ̀ láàárín àwọn ọ̀rẹ́, Ẹni-Ìyà sì pọ̀ láàárín ìbátan.
Sugbọn iyalẹnu gbaa lo jẹ lati ri pe ode ijo kan lee wa, ti yoo wa fun kikida awọn obinrin nikan, ti wọn yoo si le awọn akọ sẹyin.
Bi awọn to ṣẹṣẹ ni arun naa ṣe lọ ree: Eko-90 Rivers-13 FCT-8 Kaduna-8 Oyo-6 Ondo-3 Katsina-2 Nasarawa-2 Plateau-1 Èèyàn 4,161 bọ́ lọ́wọ́ àrùn Coronavirus ní ìpínlẹ̀ Eko Ajọ to n gbogun ti itankalẹ ajakalẹ arun aijiria,NCDC ti kede pe eeyan 4,161 t bọ lọwọ arun Coronavirus ni ipinlẹ Eko, wọn si ti pada sile wọn layọ ati alaafia, ṣugbọn awọn 113 tuntunmiran tun ni arun ọhun.
Dafidi sì dáhùn pé, “Kí ni mo ṣe nisinsinyii?
idibo kii se bi o ba, ki o paa, bi o baa ,buu lẹsẹ.
BBC Yoruba ṣeleri lati ṣagbekalẹ ifọrọwerọ gomina ni ipinlẹ Ogun o si ti de bayii.
Mchy Batshuayi dayo naa pada lai fọta pe.
Bakan na ni adajọ ọhun tun ni ki ijọba gbẹsẹle ẹrọ ibanisọrọ iPhone rẹ pẹlu ẹrọ kọmputa alagbeka to fi n ṣiṣẹ ibi ọhun.
1 2110 Orilẹede Malaysia 586 1.
Òfin kí wọ́n máa pa ajínigbé ló yẹ kí ìjọba ṣe""."
Okan ninu awọn ẹbi Roshan ni: ọpọlọpọ awọn ọmọge lo wa ni Sinhalese.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, AFCON 2019: Níbo ni ọ̀rọ̀ owó ajẹmọnu ikọ Super Eagles dé dúró?
Àwọn òpè ati àwọn tí wọn kò fẹsẹ̀ múlẹ̀ a máa yí ìtumọ̀ àwọn ọ̀rọ̀ bẹ́ẹ̀ pada sí ìparun ara wọn, bí wọ́n ti ń yí àwọn ọ̀rọ̀ Ìwé Mímọ́ yòókù.
O fi ṣe igi kan ko le da igbo ṣe ni nitori oun ati Terri ati Spotless pẹlu Ceeza Milli ni wọn jọ sọ àwo naa di odindin.
Ọpẹ nla ni, nitori emi ni mo mọ nkan ti oju mi ri, ti eeyan ko le gbadura iru rẹ fun ẹnikẹni.
Ẹgbẹ́ naa n fẹ ki ijọba maa san ọgbọ̀n ẹgbẹrun Naira gẹgẹ bi owo oṣu fun oṣiṣẹ to kere ju.
Diẹ lasan ni apẹrẹ eleyii ninu ọpọlọpọ ajọṣepọ ti wọn ṣe.
Afẹ́fẹ́ojúọ̀run òde rẹ̀ jẹ́ yíyàsọ́tọ̀ sí orísirísi ẹ̀gbẹ́ ní ojúibigbọọrọ ọ̀tọ̀ọ̀tọ̀, tó ún fa ìjì àti ìṣe rudurudu lẹ́ẹ̀gbẹ́ àwọn bodè tó únkanra wọn.
Àyàfi ọmọ tuntun tí a ṣẹ̀ṣẹ̀ bí sáyé, àti àwọn tí Olódùmarè bá fún ní ẹ̀mí gígùn gbọ̀rọ̀-gbọrọ, ṣàṣà ni ẹni tí ò ní tíì jẹ́ ìpè Ẹlẹ́dàá rẹ̀ kí ìgbà náà tó dé o.
 Ortom ni iye ibo  434, 473 lati gbomi ewuro si  awon alatako rẹ loju lati inu egbe  oselu miiran.
Eyi ni ọrọ Amofin Akeem Fadun, eekan agbẹjọro kan nilu Eko lasiko to n ba BBC Yoruba sọrọ lori ohun to mu ki idajọ ọwọ lawujọ di lemọ-lemọ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ibadan Sallah Killing: Àwọn tó ṣojú wọn kòró bá BBC Yorùbá sọ̀rọ̀, Ọlọ́pàá fèsì 2 Ògún 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 3 Ògún 2020 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Àwọn ọlọ́pàá kìí jáfara láti dá àlàáfíà padà sáwọn ágbègbè tí wàhálà bá ti ń wáyé Nigba ti ikọ iroyin BBC Yoruba kan si ileeṣ Ọlọpaa ilu Ibadan lori iku awọn ti a gbọ pe aṣita ibọn ọlọpaa lo pa wọn, awọn ọlọpaa naa ko alaye wọn ṣe.
Tunmise salaye pe, iyawo larinlọọdu pe oun ni akalolo, alailẹkọ ati awọn orukọ miran ti ko ṣee gbọ seti ni oun ṣe paa.
 nínú ètò ìkànìyàn tó wáyé ní ọdún 2006 nílẹ ̀ nàìjíríà , ìjọba ìbílẹ ̀ náà ( lga ) ni ìwọ ̀ n èrò tó pọ ̀ tó 209,437 ní agbègbè tí kò ju ìwọ ̀ n ibùsọ ̀ 8.
Awọn eekan ilu n lọ wo ileesẹ redio Ayefẹlẹ tijọba wo Awọn eeyan ya kẹti-kẹti lọ si ileesẹ redio Fresh FM lẹyin ti ijọba wo ile naa.
Olùkọ́ fásitì méjì ń bèèrè ìbálòpọ̀ lọ́wọ́ akẹ́kọ̀ọ́ fún máákì Músò!
Olùfẹ́ mi ni ó ni mí, èmi ni mo sì ni olùfẹ́ mi,ó ń da àwọn ẹran rẹ̀, wọn ń jẹko láàrin òdòdó lílì.
Ṣugbọn nígbà tí Sanbalati ará Horoni ati Tobaya iranṣẹ ọba, ará Amoni gbọ́, inú bí wọn pé ẹnìkan lè máa wá alaafia àwọn ọmọ Israẹli.
Sọ fún mi bí eniyan ṣe lè gbé ọ dè.
Nibayii awọn ọdọ ti wa ya wọ ile, bẹẹni ijọba kaakiri awọn ipinlẹ lorilẹede Naijiria si ti wa kede konile o gbele lati lee da alaafia pada silu ṣugbọn awọn eeyan ṣi n sọrọ lori ayelujara nipa rẹ.
Okechukwu  tun so pe :“Ni temi, oju meji ni aye ni.
“Kò sí àgbègbè Nàìjíríà kánkan tó wà lábẹ́ àkóso Boko haram” Adájọ́ pàṣẹ kí wọ́n fi ọlọ́pàá tó lọ́wọ́ nínú ikú Kolade Johnson sí àhámọ́ Ọkọ̀ ojú omi ''fẹri'' kọlu afárá, ọkọ̀ méjì já sódò Wike ti PDP ló borí ìdìbò sípò gómìnà Rivers Adamu wa kesi awon ajeji to wa lati ilu okeere lati wa sisẹ ni bẹ lati kuro ni bẹ ni wara n ṣesa, ki ijọba ma ba a gba iwe asẹ ati ṣe iwakusa lagbegbe naa.
"Èmi àti Sanyeri tí tọrọ oúnjẹ jẹ nílé oninawo rí, wọn tí fi ada lè wá lójú agbo ìnáwó rí, tí oro si ti lè wá ni abule kan lẹba Oyo rí, ṣùgbọ́n loni, a dúpẹ́ pé Ọlọ́run gba àdúrà wa.
 látàrí ìṣirò yìí , dídábẹ ́ fún ọmọbìrin ní orílẹ ̀ èdè nàìjíríà láàrín obìrin tí ó ti bàlágà kúsí mẹ ́ tàlá nínú ọgọ ́ rún ní àríwá ìlà òòrùn , mẹ ́ sán lé díẹ ̀ ní ọgọ ́ rún ní àárín àríwá , kòpé ìdákan tán nínú ọgọ ́ rún ní àríwá ìwọ ̀ oòrùn , bíi mọ ́ kànlélógójì nínú ọgọ ́ rún ní gúúsù ìwọ ̀ oòrùn , bíi márùnlélọ ́ gbọ ̀ n ní gúúsù , bíi mẹ ́ rìnléláàdọ ́ ta olé díẹ ̀ ní gúúsù ìwọ ̀ oòrùn .
Ileeṣẹ ọmọogun ti ṣalaye pe awọn ko tii ni ọrọ kankan lati sọ bayii, lori iṣẹlẹ to waye lagbegbe Lekki TollGate nilu Eko ni alẹ ọjọ Iṣẹgun.
Orin ‘Living Things’ tí 9ice kọ Oríṣun àwòrán, 9ice/Instagram Àkọlé àwòrán, Àjọ NBC f'òfin de orin 9ice tó fọnrere iṣẹ́ 'Yahoo' Gbajú-gbajà olórin tàka-súfèé, Abọlọrẹ Akande, tí gbogbo ènìyàn tún mọ̀ sí 9ice, nàá gbé orin ọ̀hún tó polongo iṣẹ́ yahoo bí ọ̀nà ìwá n kan jẹ.
Mo mọ èrò ọkàn yín,mo sì mọ ète tí ẹ ní sí mi láti ṣe mí níbi.
Bákan náà ni àwọn miran ń kesi àwọn aláṣẹ Nàìjíríà pé, kí wọn kọ ẹ̀kọ́ ńlá nípa ohun tí àwọn ọmọ Nàìjíríà ń sọ lẹ́yìn ikú Abba Kyari Wọn ni ki wọn sì máa rò ohun tí aráyé yóò sọ nípa tiwọn náà, tí wọn ba papoda.
Mo fẹ́ kí o mọ̀ pé ìmọ̀ràn ní iye lórí púpọ̀, òmíràn dà bí fàdákà, òmíràn dà bí wúrà, òmíràn sì dà bí dáyámọ́ndì tíí ṣe òkúta olówó iyebíye.
Ìròyìn sọ pé, arẹwa náà kú ní ìdájí òní Ọjọ́ àìkú ní ìlú Port Harcourt, nípìnlẹ̀ Rivers.
Ilé ìgbìmọ̀ Aṣòfin Nàìjíríà kó igbá wọlé l'Abuja nítorí coronavirus Nǹkan méje tí yóò ṣẹlẹ̀ nìyíí tí ìjọba bá kéde òfin kónílé ó gbélé nítorí coronavirus Orílẹ̀èdè 11 ni kò tí ì ní àrùn Coronavirus ní ilẹ̀ Afrika Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Nikesuliat: Ọ̀dọ́mọdébìnrin akéwì tó n fi ẹ̀ṣà kìlọ̀ ìwá lásìkò yìí Awọn méjèèjì náà ni wọ́n ri ọkan ni Abuja nígba ti okán wà ni Bauchi Ní dede ààgo mẹfa kọjá iṣẹju mẹẹdọgbọ̀n ni NCDC kédé ènìyàn méji túntun náà Oríṣun àwòrán, NCDC 102,000 ènìyàn jàjàbọ́ lọ́wọ́ COVID-19 lágbàáyé coronvirus world: 102,000 ènìyàn jàjàbọ́ lọ́wọ́ COVID-19 lágbàáyé Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Awọn kan ti n ri iwosan gba lori coronavirus Fasiti iwadii ti John Hopkins to ni Baltimore ni Maryland lorilẹ-ede America ti fi abajade akọsilẹ iṣẹlẹ corona virus lagbaye ti wọn ṣe sita.
Recall (Yiyọ oloselu) : Yiyọ oloselu jẹ eto ti
Wọ́n ń wá sọ́dọ̀ rẹ bí àwọn eniyan tií wá, wọ́n sì ń jókòó níwájú rẹ bí eniyan mi.
Wọn ni awọn n fẹ ki ìjọba atawon asofin lati pasẹ fun Ileesẹ Multichoice pe iye akoko ti onibara ba fi wo oju opo wọn, ni ko maa sanwo rẹ, eyi ti wọn pe ni Pay As You Go.
fun ekun Gusu – Adejoke Orelope AdefulireOludari eto
Bí àwọn ará ilé kan náà bá ń bá ara wọn jà, ilé náà kò lè fi ìdí múlẹ̀.
    Lẹ́yìn èyí ó kọjú sí mi ó ni, Háà!
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Buhari yan Kyari ní olùdarí tuntun fún àjọ NNPC Erin fara gbọgbẹ̀, ó ṣekú pa ènìyàn méjì Agbébọn kọlu àwọn ènìyàn níbi ìdíje eré sísá ẹṣin Iṣọla Oyenusi rèé, ẹnití ìfẹ́ obìnrin ṣun dé ìwà ìdigunjalè Ọgbẹni Toriọla ni, ko si idarudapọ laarin iṣẹ ọlọpaa, VIO, ẹṣọ oju popo FRSC, LASTMA atawọn ajọ agbofinro oju popo miran kaakiri orilẹede Naijiria, paapaa julọ ni ipinlẹ Eko.
O ni koko pataki ni pe ti adajọ ba dajọ, aaye wa lati pe idajọ naa ninu ẹjọ kotẹmilọrun bi o ti yẹ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Independence Day Nigeria: Lamido Sanusi gbóṣùbà fún ìjọba lórí bó ṣe yọwọ́ ìrànwọ́ epo 1 Ọ̀wàrà 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 2 Ọ̀wàrà 2020 Oríṣun àwòrán, @Realshisha Emir ilu Kano nigba kan ri, Sanusi Lamido ni ọpọ awọn to n kigbe kiri pe awọn n ja fun ẹtọ ẹkun awọn, ifẹ apo wọn nikan ni wọn fẹ.
Wọ́n ń júbà Ẹranko Ewèlè náà nítorí pé ó fi àṣẹ fún ẹranko yìí.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Akomolede àti Asa lórí BBC Yorùbá: Mọ̀ síi nípa ẹ̀kún ìyàwó níbí Kini o tun wa ṣẹlẹ si Fatai Rolling Doller lẹyin igba naa?
ALGON Oyo: Ìjọba ní àlá lásán tí kò le è dòhun ni ìlàkàkà àwọn alága APC láti padà sí káńṣù
Juda kò sì ní ọba mìíràn tí ó dà bíi rẹ̀, yálà ṣáájú rẹ̀ ni, tabi lẹ́yìn rẹ̀.
Idajọ naa f'ọwọ rọ ẹjọ ti ọgbẹni Olusọla Eleka ti ẹgbẹ PDP gbe wa si iwaju rẹ pe ko fẹsẹ rinlẹ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Zlatan: Ọ̀rẹ́ ni mo sìn lọ ‘studio’ tí mo fi bẹ̀rẹ̀ orin lẹ́yìn tí mo kùnà ìdánwò WAEC Ẹgbẹ naa wa n rọ awọn agbofinro lorilẹede naijiria ati ijọba apapọ lati fi Sowore lọrun silẹ nitori awọn ẹri ti wọn ko jọ ko lẹsẹ nilẹ lati ba se ẹjọ.
Àwọn ọmọ Bẹnjamini ni: Salu ọmọ Meṣulamu, ọmọ Joẹdi, ọmọ Pedaaya, ọmọ Kolaya, ọmọ Maaseaya, ọmọ Itieli, ọmọ Jeṣaya.
Bi o tilẹ jẹ pe asa gbigba ibale iyawo lalẹ ọjọ igbeyawo ti n wọọkun lọ laarin ẹya Yoruba, amọ asa si rinlẹ digbin laarina ẹya Larubawa, eyi to n se akoba fun ọpọ igbeyawo bayii laarin ẹya naa.
Naijiria nifẹẹ ara wọn, pẹlu igbe aye alaafia ati nini ẹmi ifarada funra wọn
Bakan naa, Opolopo awon akoroyin ati ayaworan ni Somaliland ti mu fun iru esun yii.
Ohun ti wọn kọkọ ṣe ni pe wọn gbọ omi to le ni mita mẹrindinlogun kuro ninu ihọ̀ naa, ki wọn to bẹrẹ si ni wa ọna lati yọ.
Ẹ̀rù ba gbogbo wọn; wọ́n sì gbé orúkọ Jesu Oluwa ga.
Lọjọ karun un oṣu kẹwaa ọdun 2020 ti ọja kata-kara kasẹ nlẹ ni Arsenal ra Partey ni miliọnu marundinlaadọta owo pọun.
” Minista tun tesiwaju pe bi awon iko olote se n da
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Saraki: Àwọn aṣòfin àpapọ̀ ṣ'àfihàn ìṣọ̀kan lásìkò tí jàǹdùkù jí ọ̀pá àṣẹ ilé gbé 7 Òkùdu 2019 Oríṣun àwòrán, @NGRSenate Àkọlé àwòrán, Sáà kẹjọ ilé aṣòfin àpapọ̀ parí ní Ọjọ́bọ̀, ọjọ́ kẹfà oṣù kẹfà ọdún 2019 Aarẹ ile aṣofin agba, Bukọla Saraki ti ṣalaye ọjọ ti inu rẹ bajẹ julọ lasiko to fi jẹ aarẹ fun ile aṣofin apapọ lorilẹ-ede Naijiria.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Kunle Afolayan: èmi kò fẹ́ fi ogún sílẹ̀ fún ọmọ mi Ọrọ pọ ninu iwe kọbọ nipa Ogedengbe Agbogungboro, ko si ṣe sọ tan nitori akọni ti ko ṣee gbagbe ni nilẹ kaarọ o jiire ni.
Sọ gbogbo ìwà ìríra rẹ̀ fún un.
Ọrọ yii ti di ajumọṣe gbogbo ilu, funra wa ni a n mojuto nkan wa.
Asofin Abiodun Awoleye  to n soju fun Ariwa Ilu Ibadan ni ipinle Oyo , ti ro ile igbimo asoju-sofin lati satunse si iwe-abadofin odun 1999,  nipa didasile awon olopaa ipinle lati le je ki eto aabo to wa jake jade gbogbo ipinle  lorile ede Naijiria gbounje-fegbe gbawobo, ki gbogbo omo orile ede yii tun  le fedo le ori oronro.
Ẹ bẹ̀rẹ̀ pẹlu nǹkan ti ẹ̀mí, ẹ wá fẹ́ fi nǹkan ti ara parí!
Wọ́n sọ fún wọn pé, “Oluwa nílò rẹ̀ ni.
A ko le e sọ ọmọ ẹgbẹ ti Ekugbemi jẹ́ ninu one million boys, Indomie, ati Abe igi Boys.
Gbogbo awọn aladugbo ati alagbatọ lo fọn sita lati ṣe awari ọmọ naa titi di oru ọdun Ileya ti igbiyanju wọn si ja si pabo.
Ẹgbẹ oselu National Democratic Congress NDC naa ni laipẹ ni oun yoo kede igbesẹ to kan lori ọrọ yii.
 inu mi dun gidi gan-n .
Ṣugbọn Simoni Peteru ń tẹ̀lé Jesu pẹlu ọ̀kan ninu àwọn ọmọ-ẹ̀yìn.
Lẹyin naa lo tu igbeyawo naa ka, ki alaafia le jọba.
Torí ǹkan oṣù, Iléèwé pàṣẹ kí àwọn akẹ́kọ̀ọ́bìnrin tú síhòhò Bí orí ṣe yọ akẹ́kọ̀ọ́ Cameroon kan tó bọ́ lọ́wọ́ Coronavirus rèé Bi Olabode Thomas ko tilẹ dagba tabi darugbo ko to jade laye, nitori ko lo ju ọdun mẹrinlelọgbọn lọ, to fi tẹri gbasọ, sibẹ a ko gbọdọ gbagbe akanda ọmọ Yoruba yii, tori ipa to ko si idagbasoke iran Yoruba ati Naijiria lapapọ.
Aja lo lẹru ni iwe Akagbadun ti a n ka loni lori eto Akomolede ati Asa lori BBC Yoruba.
ati agbogunti iwa ọdaran ( Special Anti-Robbery Squad ,SARS) , hu ,ni eyi ti
idibo Somolu keji ẹwẹ, Aṣofin Rotimi Abiru ti ẹgbẹ oṣelu APC ni ẹgbẹrun
Iroyin waye pe ki Daura jọwọ gbogbo awon ise to wa lowo re fun oga agba ajo naa.
“Bí ó bá jẹ́ pé àwọn tí ó fẹ́ràn yín nìkan ni ẹ fẹ́ràn kí ni fáàrí yín?
Bakan naa ni ọjọgbọn Osinbajo yoo sọrọ lori koko to jẹ mọ idagbasoke eto ọrọ aje Naijiria nibi apero kan ni Amerika.
Bẹẹ ba gbagbe, asoju-sofin to n soju ẹkun idibo naa tẹlẹ, Funkẹ Adedoyin lo dagbere faye lọjọ kejidinlọgbọn osu kẹsan ọdun 2018, lasiko aisan kan to mu, eyi to mu ki aga ẹkun idibo naa sofo nile asofin apapọ ilẹ wa.
Àwọn ìlú tí eniyan ń gbé yóo di òkítì àlàpà, gbogbo ilẹ̀ náà yóo di ahoro.
Oríṣun àwòrán, @AAAjimobi Olaniyan naa han ninu fidio naa, ti wọn ká silẹ ninu yara igbalejo kan nile Ajimobi lẹyin eto isinku rẹ.
Yóo ti pẹ́ tó tí n óo máa wo àsíá ogun,tí n óo sì máa gbọ́ fèrè ogun?
 O ni oun ba Naijiria kẹdun, to si gbadura ki ""Ọlọrun gba Naijiria là""."
Nitori pe ẹgbẹ wọle lo ṣe di minisita.
Ìtara àti ìtaníjí nínú ẹ ̀ sìn mùsùlùmí ni a gbọ ́ pé ìpilẹ ̀ ṣẹ ̀ eré ajíwéré , nígbà tí àwọn olúfọkànsìn kan máa ń lọ káàkiri àdúgbò ní ìdájí láti jí àwọn mùsúlùmí lati kírun àárọ ̀ .
Lẹ́yìn náà, Hamani ati ọba jókòó láti mu ọtí, ṣugbọn gbogbo ìlú Susa wà ninu ìdààmú.
Ó fi ìṣákọ́lẹ̀ náà jíṣẹ́ fún Egiloni, ọba ilẹ̀ Moabu.
Ẹwẹ, adari agba NCDC, Chikwe Ihekweazu ti fesi pe awọn meji kan ti ayẹwo ṣẹṣẹ fihan pe wọn ni arun ọhun sọ pe ipinlẹ Kogi ni wọn ti wa.
June 12 in Nigeria: Wo àwòrán pápá ìṣeré MKO Abiola National Stadium
"Oriṣa kan to si farajọ iru nkan to fẹ ni Satani - ""ẹda to n fun ni ni èrè to yẹ."
Ọrẹ mi ṣalaye pe bi a ba dẹkun ati maa jẹ ẹran maalu, arakunrin ti o n ta maalu naa a tun ero rẹ pa.
Ewe, iseju perete die toku ki ifigagbaga ohun wa si ipari ni Ogunbowale ju boolu wole sinu agbon Mississippi State lati ran Notre Dame lowo gba ife-eye idije NCAA tawon obinrin akoko lati odun 2001, eyi ti o si di eekeji iru re ti iko ohun ti gba bayii.
Wọ́n ń mú àwọn onigbagbọ lọ́kàn le pé kí wọ́n dúró ṣinṣin ninu igbagbọ.
Dani, Josẹfu, ati Bẹnjamini; Nafutali, Gadi ati Aṣeri.
Lori ọrọ yii ni Seyi fi gba awọn to jẹ pe idojukọ to tun ju ti oun lọ lo n mu wọn fẹ pa ara wọn ara wọn.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ifọrọwanilẹnuwo pẹlu Ọmọ Baba Sala Orin Highlife ni Baba Sala kọkọ n kọ ti o si da ẹgbẹ akọrin kan silẹ ti wọn pe orukọ rẹ ni ''Federal Rythym Dandies'' ki o to wa ya si ere tiata.
gba kan tuko agbaboolu lorisirisi bi: FC Talanta lorile-ede Kenya, Heegan FC ni
Eyi si mu ki ọpọlọpọ o ma a sọ pe ko si idi ti awọn ko fi gbọdọ salọ kuro ni Naijiria, ti iyawo aarẹ ba le ṣe bẹ ẹ.
EFCC kó akẹ́kọ̀ọ́ fásitì UNIOSUN Wo itan igbesi aye Bashir Umar: A bi Bashir Umar ni ọjọ kinni, oṣu kẹfa, ọdun 1995 sinu ẹbi Mallam Bashir Abdulmumuni ati Salamotu Aliyu.
Dafidi ni ó bí gbogbo wọn, yàtọ̀ sí àwọn ọmọ tí àwọn obinrin mìíràn tún bí fún un.
ẹgbẹ oṣelu APC ṣalaye ọrọ yii ninu atẹjade kan ti alukoro ẹgbẹ oṣelu naa ni ipinlẹ Ọṣun, Amofin Kunle Ọyatomi fi sita ni ọjọ ẹti.
WHO: Naijiria n koju itankalẹ Lassa to ti i l'agbara ju
Òmíràn kò mọ itumọ̀ ọ̀rọ̀ Èkó/Yorùbá pé “Bi ó ti ẹ lówó bi Da Rocha” lai bèrè pé tani Da Rocha?
ti won ba wa lati ilu okeere”.
Abramu jẹ́ ẹni ọdún marundinlọgọrin nígbà tí ó jáde kúrò ní Harani.
Ó tún lọ gbadura, ó sọ àwọn ọ̀rọ̀ kan náà bíi ti àkọ́kọ́.
 Ó kékò ológun ní british academy , sandhurst .
Wọn á máa wá ojú rere àwọn tí wọ́n bá lè rí nǹkan gbà lọ́wọ́ wọn.
Orúkọ ọ̀hún sì fẹ́ dá’yà já’ni.
Nibi ipade apero naa ẹwẹ, aarẹ orilẹede Naijiria, Muhammadu Buhari ti se ifilọọlẹ akanse koko ọrọ lori didoju ija kọ iwa jẹgudujẹra.
Bawo ni a ṣe le mọ iroyin ayederu?
Eléyìí hàn gbangba lára àwọn ìránṣẹ́ rẹ̀ pẹ̀lú, tó bẹ́ẹ̀ tí Adéforítì fi bi Èṣù wò ìdì rẹ̀ tí ọkàn gbogbo wọn ko fi balẹ̀ bẹ́ẹ̀.
Minisita fun ọrọ ilẹ okeere naa ni awọn ọmọ ilẹ Naijiria kii sọ otitọ nipa iye owo ti wọn n pa nibi isẹ wọn, nitori naa akọsilẹ ti awọn ilu okeere ni nipa Naijiria ko jẹ otitọ lọpọlọpọ igba.
Lẹyin eyi ni kọmisọna ọlọpaa ipinlẹ Oyo, Nwachukwu Enwonu atawọn lọga lọga ọlọpaa ni ipinlẹ naa kọwọ rin pẹlu awọn aṣoju gomina lọ ba idile oloogbe kẹdun ti wọn si ṣeleri pe gbogbo awọn to lọwọ ninu iṣẹlẹ yii ni yoo bọ sọwọ ofin.
Bí olukuluku wa ti lá àlá tirẹ̀, bẹ́ẹ̀ náà ni ó túmọ̀ wọn.
N10m suit: ‌Agbẹjọ́rọ̀ ọmọ Nàìjíríà, Ogedi Ogu gbé Fásitì Oxford lọ sílé ẹjọ́ lórí ìtumọ̀ ọ̀rọ̀
“ ‘Ẹni ìfibú ni ẹni tí ó bá yí ìdájọ́ òdodo tí ó tọ́ sí àlejò po, tabi ti aláìní baba, tabi ti opó.
Ṣùgbọ́n nítorí tí ọfà àbíkẹ́yìn kò rìn ní irin ìkọsẹ̀ rárá, dandan ni kí òun ṣe baálé Ẹwadapọ́, ìwọ̀ntunwọ̀nsì lobìnrin.
Awon miiran tun ni  Sadiq Umar, APC Kwara North; Gershom Bassey,
Ọjọ keji, oṣu kẹjọ ni ile ọwọ sinkun ajọ DSS tẹ Sowore nile rẹ l'Eko ṣaaju ki eto iwọde ifẹhonuhan to n pete to waye ti wọn si ti gbe e si atimọle.
O fikun pe, oun yoo se atunse ofin naa lati ri daju pe ẹnikẹni to ba beere lati jẹ ọmọ ilẹ Liberia atawọn ọmọ ilẹ okeere di baba onile lorilẹede Liberia.
Ẹwẹ, aarẹ Buhari tun mẹnu ba isunsiwaju ibo aarẹ fun ọsẹ kan eleyi ti ajọ eleto idibo Naijiria kede.
omi ni mo fi bọ́jú, òun ni mo fi fọnu.
O ni ko dẹrun fun awọn ọdọ lati ma a lo ọkọ ati ada lati lọ wa ebe, amọ ti wọn ba ri iranwọ to peye, wọn le ṣe iṣẹ oko ni ọna igbalode ti wọn yoo si ri ere nibẹ.
Adajọ Saminu fidi rẹ mulẹ niu idajọ rẹ pe ki o digba ti igbẹjọ ba pari ki gomina Ganduje to lo gbe igbesẹ kan tabi omiran lori ọrọ Emir ilu Kano.
@Zolonye, oun ni ọmọbinrin naa nilo ifẹ ati atilẹyin awọn eeyan lasiko yii ju ki wọn maa bu lọ tabi ki ileewe rẹ le kuro.
"Mínísítà àti iléèṣẹ́ Nipost ń jiyàn lórí àfikún owó ìfìwéránṣẹ́ tuntun Ikú Barakat Bello ní Akinyele gbé aláàánú pàdé ẹ́bí rẹ̀ Bí o ṣe lè forúkọ silẹ̀ fún ètò ""N75BN Nigerian Youth Investment Fund"" rèé."
Ọ̀pọ̀lọpọ̀ òkú ẹyẹ igún ré bọ́ lọ́jà Eke-Ihe Àwọn kan fẹ́ da Naijiria rú torí ààbò tó mẹ́hẹ - Osinbajo gbarata Ọ̀rọ̀ ti ń gba ibòmíràn yọ lórí ẹ̀ṣùn ìfipábánilòpọ̀ - Timi Dakolo Pariwo Amọṣa, ijọba ipinlẹ Ondo ni awọn ko mọ eegun to n jẹ fijilante Miyetti Allah ni igboro ipinlẹ Ondo nitori naa, ki awọn agbofinro bẹrẹ si nii mu ẹnikẹni to ba n pe ara rẹ ni ọmọ ẹgbẹ naa ni wara-n-ṣeṣa.
" Ninu awọn ti wọn pe lẹjọ yii la ti ri igbakeji aarẹ, Yemi Osinbajo, aarẹ ile aṣofin agba Ahmad Lawan, Olori ile aṣoju-ṣofin, Femi Gbajabiamila ati awọn mii.
Olori Anuoluwapo lo kede bẹẹ loju opo Instagram rẹ lọsan ọjọ Aje.
Ìjọba Eko yóò bẹ̀rẹ̀ sísan N35,000 owó oṣù tuntun lóṣu yìí Owó ìfẹ̀yìntì àwọn Gómìnà ní ìpínlẹ̀ Zamfara dì àlọrámirámi Makinde sàbẹ̀wò sí LAUTECH, ó gbé owó ₦500m kalẹ̀ láti tán ìyanṣẹ́lódì àwọn olùkọ́ Amọ, Mateo Kovacic dayo naa pada lẹyin iṣẹju kan pere, eyi to mu ere bọọlu naa di ọmi alayo kọọkan.
Oríṣun àwòrán, @Mohammed Jagunma ati Gold Abdulrafiu Ki lo ti ṣẹlẹ sẹyin?
Ẹ kí Ampiliatu àyànfẹ́ mi ninu Oluwa.
Tó o bá ṣàdéhùn ìfẹ́ tó ò mú u ṣẹ, ẹ̀wọ̀n lo fi ń ṣeré #67yearoldmother: Mo kojú ọ̀pọ̀lọpọ̀ àìsàn fún ọdún 35 lẹ̀yín ìgbéyàwò Ìgbéyàwó àjùmọ̀ṣe 'Shao' ní Kwara, ìyàwó 25 lọ sílé ọkọ lọ́jọ kan Ìyàwó gbà sí ọkọ lẹ́nu láti ṣègbéyàwó abẹ́ odò Àwòrán ìgbeyàwó ọmọ Fayose dùn, ó lárinrin Ọkọ iyawo to jẹ onimọ nipa ayarabiaṣa ni kii ṣe owo ti awọn maa na nibi ase apejẹ lẹyin igbeyawo ni ko si, ṣugbọn o wu oun pe ki ero wa sibi ileri ifẹ oun ni ṣọọṣi ju ki wọn wa si apejẹ lasan lọ ni.
Awọn ọmọ Naijiria ko mo o wẹ, amọ ti o ba sọ fun wọn, wọn ko ni gbo, won a ma a ba ẹ jiyan "" O salaye."
Togo Elections: Ààrẹ Gnassingbe díje fún sáà kẹ́rin, òun àti bàbá rẹ̀ ti ṣèjọba Togo fún àádọ́ta ọdún lé
Ibẹ̀ ni ẹ̀yin ati gbogbo ìdílé yín yóo ti jẹun níwájú OLUWA Ọlọrun yín, inú yín yóo sì dùn nítorí gbogbo iṣẹ́ ọwọ́ yín tí OLUWA ti fi ibukun sí.
Àwọn ọmọ Senaa jẹ́ ẹgbaaji ó dín aadọrin (3,930).
Àwọn ọmọ ati ọmọ ọmọ rẹ̀ pọ̀.
”Ni bayii, ipinnu ile ejo naa yoo fopin si ikunsinu awon ara ilu pe ijoba ile kenya koi gbe igbese ti o to lori awon olopaa lataari iwa ibi won ti won wu si awon ara ilu.
Ọmọ Emir Kazaure ni ipinlẹ Jigawa ni Amina Bala Kazaure, ṣugbọn ọmọ ipinlẹ Katsina ni Buhari.
Ìjọba Buhari ń wùwà bíi ìjọba Abacha lórí ọ̀rọ̀ Ṣoworẹ- Ṣoyinka O ni kii ṣe nitori ajakalẹ aarun Covid-19 nikan, ṣugbọn ọpọlọpọ awọn iṣẹlẹ to waye, ati iha ti ijọba kọ si wọn.
Oro ohun waye leyin ti akonimoogba agba iko naa, Maurizo Sarri yoo oruko re kurp lara awon agbaboolu ti o kopa fun ifesewonse idije Europa League ti won gba pelu iko agbaboolu Bate Borisv.
Ní àkókò kan náà ni Libina ṣọ̀tẹ̀ sí Juda, ó sì gba òmìnira nítorí pé Jehoramu ti fi ọ̀nà OLUWA àwọn baba rẹ̀ sílẹ̀.
Dafidi dá ẹsẹ̀ àwọn ẹṣin tí ń fa kẹ̀kẹ́ ogun rẹ̀, ṣugbọn ó dá ọgọrun-un (100) sí ninu wọn.
Buhari yẹ awọn ọmọde yii si, o sọ pe ọkan lara wọn, Nicole Benson fi ẹgbẹrun marun un ati ẹẹdẹgbẹrin Naira kun owo ipolongo ibo oun l'ọdun 2015 Oríṣun àwòrán, Muhammadu Buhari Àkọlé àwòrán, Agbẹ l'ọba, aarẹ Buhari ko fi iṣẹ agbẹ silẹ nitori pe o di aarẹ.
Ninu papakọ ofurufu naa, ri wi pe o yago fun awọn eniyan ni gbogbo igba ti o ba n mura lati wọ ọkọ baalu.
ifa jẹ ẹwi tí ó máà ń lọ láti ilú kan ṣì èkejì láti dífá .
Wọn maa n da koriko tutu mọ aro ti wọn fi n dana sun wọn, lati le mu eefin naa dudu.
    Nígbà tí a dé ààrin ọjà, a lọ sí ibi tí wọn ti pèsè sílẹ̀ fún wa.
" Ọ̀ọ̀ni Ilẹ̀ Ifẹ̀ ní oun kò ṣ'àdéhùn ìfẹ́ pẹ̀lú Elizabeth Odunlami, tó ń gbé l'Amẹ́ríkà Iroyin kan lọ kaakiri pe Ọọni ti ile ifẹ, Ọba Adeyẹye Ogunwusi ati omidan kan ti wọn pe orukọ rẹ ni Elizabeth Odunlami ẹni to ni ọrọ adehun ifẹ n bẹ laarin oun ati arole Oodua, Ọba Adeyẹye Ogunwusi ki kabiyesi tó to igba ifẹ rẹ pẹlu Yeyeluwa tuntun, Olori Naomi Shilẹkunọla laipẹ yii.
Ṣugbọn Peteru dáhùn pé, “Ọkunrin yìí, n kò mọ ohun tí ò ń sọ!
Arugba: Lara awọn eto to se pataki lasiko ọdun Ọṣun Oṣogbo ni igba riru lọ si ojubọ Ọṣun Oṣogbo.
Buhari ṣ'eto igbimọ fun abẹwo awọn ipinlẹ Ile Asofin pasẹ fun NNPC lati dẹkun ọwọngogo epo Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Aisi epo fa irora fun ọpọlọpọ mẹkunnu Iye owo epo bentiroolu jẹ ọrọ kan ti o maa n da awuye-wuye silẹ ni orilẹ-ede Naijiria.
Ijọba Ondo n wa ọdẹ aperin Òkè Ìdànrè rèé níbi tí ilé ayé ti tẹ́jú pẹrẹsẹ Òkè Ìdànrè rèé níbi tí ilé ayé ti tẹ́jú pẹrẹsẹ 'Fashọla, o ò dẹ̀ bẹ̀rù Ọlọ́run!
Ṣugbọn ẹ̀yin, ará, ọmọ ìlérí bíi Isaaki ni yín.
Bórípẹ́ nílẹ̀, á dire; ẹlẹ́wọ̀n méjì yóò di dókítà ọ̀mọ̀wé
Oríṣun àwòrán, Getty Images Idile ọlọla Ashanti ati Fante ni wọn bii si ni orilẹede Gold Coast to di Ghana bayii.
gbogbo ẹnu ibode to wọ orile-ede yii, ki awon odaran maa  fi orilede Naijiria se ibugbe.
Wọ́n ń kígbe sókè nígbà tí wọ́n rí èéfín iná tí ń jó ìlú náà.
Gege bi oro re, o je okan lara awon eto ti a ti la kale fun isami ayeye odun merindinladorin 66 year ojo ibi adari egbe-oselu All Progressives Congress (APC) asofin.
Ninu atejade kan ti alukoro  ajo naa ,omowe Fabian Benjamin gbe jade pe, “O
Eeyan le sọ wipe ka fọwọ rọ akojọ ero ara ilu yi nitori bi o ti ṣe gbe gbagi pẹlu Hilary Clinton lọdun 2016.
Orílẹ̀-èdè Japan ní Musiọmu mẹ́ta tí wọn fi sílẹ̀ fún Núdùlù Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Shirataki, Soba, Ramen, Sōmen, Udon, Hiyamugi, Tokoroten.
O ni atubọtan ṣiṣe idajọ lati ọwọ ara ẹni kii so eso rere nitori kii jẹ ki awọn agbofinro mọ ẹni to jẹbi."
Ajẹ́pé ara ẹni kò lè bá nkankan jà mọ́.
Ìkini fún ọdún tuntun“A ki i jẹ Igún, a ki i fi Ìyẹ́ Igún rinti: Ẹnu Ayé Lẹbọ
Mo yára tẹ̀lé e mo sì ń lé háhá náà lọ títí ó fi dé ibi ìtàkùn kan tí ó wà lójú omi tí ó dúró; níbẹ̀ náà ni mo sì bá a tí mo mú un.
Isẹlẹ ọkọ ofurufu to ja yi ti mu ki awọn orilẹede kaakiri agbaye dawọ lilo ọkọ ofurufu Boeing 737 duro nitori pe baalu iru rẹ meji lo ja laarin oṣu maarun sirawọn.
Bidemi kawe gboye ninu imọ tiatia lati fasiti ilu Eko.
Nigba ti BBC Yoruba se abẹwo sile oloogbe naa nirọlẹ Ọjọbọ, awọn abanikẹdun ti kora jọpọ sibẹ lati daro ẹni rere to lọ.
Ile ẹjọ ti gba oniduro Gomina tẹlẹ, Ayọdele Fayoṣe.
Bakan naa ni aare tun n pese owo iranwo fun awon olokoowo keekeeke ati
Ọ̀nà tí a óo fi mọ Ẹ̀mí Ọlọrun nìyí: gbogbo ẹni tí ó bá jẹ́wọ́ pé Jesu Kristi wá sáyé gẹ́gẹ́ bí ẹlẹ́ran-ara jẹ́ ẹni tí ó wá láti ọ̀dọ̀ Ọlọrun.
12 Máṣe sọ ẹ̀bùn rẹ di mímọ̀ fún ẹnikẹ́ni bíkòṣe àwọn tí wọ́n ní ìgbàgbọ́ kan náà pẹ̀lúù rẹ.
Wizkid gori itage nipa pipon Fela Anikulapo Kuti to je baba agba orin Afro nile Adulawo le.
O tẹsiwaju pe oun ti fẹ gun ọkada ki ọkan ninu awọn ikọ naa to ke si oun wi pe oun ni ẹjọ lati jẹ.
Ìtàn sọ fún wa wipe ọmọ mẹ ́ jo ni ọ ̀ rúnmìlà bí nígbà tí ó wà láyé , nígbà tí ó di ọjọ kan ti ọ ̀ rùnmìlà ńṣe ọdún ni ọ ̀ kan nínú àwọn ọmọ yìí tíí ṣe àbíkèhìn pátápátá báse àfójúdi sí ọ ̀ rúnmìlà , ni ọ ̀ rùnmìlà bá binú fi ayé sílẹ ̀ lọ sí òde ọrun .
Ologun Nigeria gbakoso ibuba Boko Haram Boko Haram kọlu abule Kofa ni Maiduguri Nigba ti igbẹjọ naa bere losu kẹwa ọdun to kọja, awọn eniyan marundinlaadọta ni wọn s'ẹwọn ọdun mẹta si mọkanlelọgbọn, ti wọn si da awọn igba meji eniyan silẹ nitori ẹsun ti ko lẹsẹ n lẹ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Alaafin: Olori Aanu Adeyemi ṣàlàyé ìdí tó ṣe gẹ́ Oba Lamidi Adeyemi ti ìlú Oyo Ọdaran naa lo ṣe ẹlẹrii ara rẹ nile ẹjọ, nigba ti awọn olupẹjọ gbe ẹlẹrii mẹrin kalẹ.
33 Nítorínáà ẹ jẹ́ kí ìjọ kíyèsára kí ẹ sì máa gbàdúrà nígbà gbogbo, kí wọ́n má baà bọ́ sínú ìdánwò;
pẹlu ogoji ìtẹ́lẹ̀ fadaka; ìtẹ́lẹ̀ meji meji lábẹ́ àkànpọ̀ igi kọ̀ọ̀kan.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Libya shipwreck: Aṣàtìpó lọ sí Yuropu 45 kú sínú òkun ní Libya, 37 m'órí bọ́ 20 Ògún 2020 Oríṣun àwòrán, Getty Images O kere tan aṣatipo marundinlaadọta lo dero ọrun, lẹyin ti engini ọkọ oju omi to n gbe wọn lọ si ilẹ Yuropu lati Libya gbina ti wọn si ja sinu okun.
Oludije dupo  gomina ni  ipinle Bauchi, Bala Mohammed, lo jawe olubori
Akọroyin BBC Yoruba to ti balẹ silu Abẹokuta fi awọn aworan ransẹ nipa ibi ti igbaradi naa de duro.
Ma ṣe wa ọkọ̀ ti ko dara mọ loju pópó Oríṣun àwòrán, Getty Images Ọkan lara awọn nkan to tun n fa oju ọjọ ti ko dara ni eefin ara ọkọ̀.
" Ipinlẹ Plateau lo tun lewaju iye awọn to laarun naa lojumọ lọjọ Aje pẹlu eeyan marundinlogoji (35), ipinlẹ Kaduna eeyan mọkanlelogun (21), ipinlẹ Eko eeyan mọkandinlogun (19) olu ilu ilẹẹwa Abuja eeyan mẹtala (13), Ebonyi eeyan mẹsan (9), ọkọọkan ipinlẹ Adamawa, Enugu ati Katsina ni meje (7), ipinlẹ Edo mẹfa (6), ipinlẹ Kwara marun un (5), ipinlẹ Osun mẹta (3), ọkọọkan ipinlẹ Anambra, Kano, Benue ni eeyan neji, ipinlẹ Benue, Borno ati Sokoto ni eeyan kọọkan (1).
 “A o lo milionu òjìlénígba lé mewaa owo dollar($250 million) lati fi se atunse si gbagede ikoja ori omi niluu Ibadan, nipinle Oyo, eleyi ti yoo tun mu adinku ba ero to n lo koja nipinle Eko,”Ogbeni Chen wa gbosuba kare
Parry wá sọ àsọtẹ́lẹ̀ pé  tá bá fi òpin si ofin tó dena kata-kara ọtí líle yìí, a rí tó aláìsàn ẹgbẹ̀rún márùn-ún tó ní nkan ṣe pẹlu ọtí líle, tí yóò máa yọjú ni ọṣẹ kọ̀ọ̀kan""."
Adama Traore lo gba goolu mejeeji sawọn fun Wolves Lampard ń dábírà!
Isiaka ni ona meji ni oro naa.
Inú wọn ru sókè, wọ́n wá ń bá ara wọn jíròrò nípa ohun tí wọn ìbá ṣe sí Jesu.
Atiku ni kò tíì dópin fún Adeleke, PDP ni àwọn gba idájọ́ wọlé Àlàyé rèé lórí ìdí tí ìyá mi fi sọ fáráyé pé mo ti kú Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Àjẹ́, eégún, kí ni wọn ò pè mí tán tórí Vitiligo lára mi' Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí 4:32 Fídíò, Fulani Kidnapping: Owó púpọ̀ la san kí wọ́n tó fi mi sílẹ̀ lẹ́yìn ọjọ́ mẹ́fà, Duration 4,328 Agẹmo 2019 Èyí ni ìdí tí àwọn obìnrin kan to n ṣe nkan oṣù fi n yọ ilé ọmọ wọn kúrò ní India7 Agẹmo 2019 Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Koda, ẹni tawọn agbofinro mu pe o pa iyawo oniwaasu kan ni ijọ Deeper Life, lo ti gba idande kuro lahamọ, ti wọn si tun dana sun ọpọ sọọsi lorilẹ-ede yii.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Senator Elisha Abbo: Ọga àgbà ọlọ́pàá Nàìjíríà ti pàṣẹ ìwádìí sí ọ̀rọ̀ Sẹ́nétọ̀ Abbo tó lu obìnrin l'Abuja 3 Agẹmo 2019 Oríṣun àwòrán, @adeyanjudeji Àkọlé àwòrán, Ọjọ Iṣẹgun ni fidio kan jade to ṣafihan bi Sẹnetọ naa ṣe n lu obinrin kan nile itaja eroja ibalopọ Ileeṣẹ ọlọpaa lorilẹ-ede Naijiria ti ni ko si igba kankan ti àwọn paṣẹ mimu Seneto Abbo.
Oríṣun àwòrán, Olamide Lawal/Facebook Ọmọ 28 lapapọ lo di awati Kọmisọna fun ọrọ awọn obinrin ni ipinlẹ Ogun, arabinrin Funmi Efuwape ni lati ijẹta ni awọn ọlọpaa ti ri awọn ọmọ marun eyi ti awọn oniroyin n gbe kiri pe wọn di awati nile ọmọ orukan Stella Obasanjo Motherless Homes niluu Abeokuta.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ghana elections 2020 winner: Nana Akufo-Àddo àti John Dramani ló jọ ń díje lọ́là 6 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 7 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Oríṣun àwòrán, Getty Images Lọjọ keje, oṣu kejila, ọdun 2020 ni awọn eeyan orilẹ-ede Ghana maa ni anfani lati yan ẹni to wu wọn sipo aarẹ.
Ẹ gba ilẹ̀ wọn, mo sì pa wọ́n run lójú yín.
Serena Williams: Mo fẹ́ àkókò si láti díje lorí amọ̀
Àwọn abiyamọ figbe ta lórí ọmọ ọdún kan ti wọn wá nílé ìjọsìn l'Akure Kayeefi BBC Yoruba fun ipari ọdun 2019 yanana ootọ ati irọ to wa ninu gbogbo awọn ohun to ti ṣẹlẹ ni Akurẹ lati ọjọ ti ọmọ yii ti sọnu.
Yóo jẹ́ ti àwọn alufaa tí a yà sọ́tọ̀, àwọn ọmọ Sadoku tí wọ́n pa òfin mi mọ́, tí wọn kò sì ṣáko lọ bí àwọn ọmọ Lefi, nígbà tí àwọn ọmọ Israẹli ṣáko lọ.
Gómìnà Karun – Alhaji Lateef Jakande – Gómìnà Ìjọba Alágbádá fún ọdún mẹrin – lati ọdú́n mejidinlogoji titi di ọdún merinlelogbon sẹhin
Ní ọjọ́ náà, wọn yóo máa fi yín kọrin ẹlẹ́yà, wọn yóo sì sọkún le yín lórí tẹ̀dùntẹ̀dùn.
Nígbà tó yá ni ìlú ọ̀hún gbòòrò dé bó ti rí.
Àwọn olùpolongo ìdìbò Aketi àti Jegede ń forígbárí l'Ondo, bí wọ́n ṣe n yìnbọn ni wọn n sun táyà Ṣé lóòtọ́ ni ẹgbẹ́ òṣèlù mọ́kànlá darapọ̀ mọ́ PDP l'Ondo láti gbárùkù ti Jegede?
 Ti idije ohun yoo si waye ni ipinle Akwa ibom, Uyo, lojo kewaa, osu kefa odun yii.
Ọjọ Iṣẹgun ni iwe iroyin ori ayelujara, Premium Times fi fidio kan sita, to ṣafihan bi Sẹnetọ naa, to jẹ pe oun lọjọ ori rẹ kere ju nile aṣofin agba Naijiria, ṣe n lu obinrin kan nile itaja eroja ibalopọ.
O ṣalaye pe ijọba ti n ṣe ipade pẹlu awọn tọrọ kan lati ojutu si ohun tawọn ọdọ to n ṣe iwọde n beere fun.
Oríṣun àwòrán, Instagram Àkọlé àwòrán, Mustapha Solagbade jẹ ilumọọka oṣere, ti wọn bi si agbeegbe Ebute Mẹta ni ipinlẹ Eko, ni ọjọ Kini, Osu Kini, ọdun.
Lati bi ọjọ mẹta kan ni iroyin ti gbori ayelujara kan pe Aarẹ Muhammadu Buhari fẹ gbe iyawo miran.
olorejore ti yoo waye ninu osu to n bo.
Mo sì ṣe ìlérí, níwájú ènìyàn, àti níwájú iwin, níwájú ẹ̀mí ti à ń rí, àti níwájú èyí tí a kò rí, níwájú ejò àti níwájú ẹranko, níwájú ẹyẹ àti níwájú kòkòrò, níwájú ọ̀pọ̀lọ́ àti níwájú akàn, wí pe: bí mo ti fẹ́ ọmọ náà yìí, nn kò níi jẹ́ kí ìyà jẹ ẹ́, n kò ní jẹ́ kí ebí pa a, n ó sì máa ṣe aájò rẹ̀ bí ó ti yẹ.
5 15107 Orilẹede Andorra 78 101.
Àwọn adigunjalè ṣọṣẹ́ l'Èkìtì 'Iṣẹ́ orí rán mi ní mò fi ń jẹun' Atẹjade ti awon ọlọpaa fi sita ni pe Adikwu di ọlọ́ṣà ni kete to jade kuro ni ẹwọn.
O ki wọn fun ẹmi ifọkansin wọn ati ifaraẹnijin ti wọn fi ri afurasi naa mu.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, N100,000 Nairà mà ni Dino gbé dání lójú agbo, kò náwó yàlà-yòlò - Ayefele Bakan naa ni Ọba Akanbi wa rọ Aarẹ Buhari lati ba awọn adari ni gbogbo ẹkun lati sọra fun ọrọ ẹnu wọn, ki alaafia ba le jọba lorilẹede Naijiria.
Lagos-316 FCT-210 Kaduna-83 Plateau-70 Gombe-56 Oyo-56 Katsina-47 Nasarawa-35 Kano-33 Ogun-21 Rivers-17 Niger-14 Imo-14 Delta-12 Kwara-12 Edo-12 Benue-9 Anambra-8 Taraba-4 Ekiti-4 Ebonyi-6 Bayelsa-1 Sokoto-1 Èèyàn márùn ún kú, 1,133 tuntun míràn tún ní Coronavirus ní Nàìjíríà Oríṣun àwòrán, Twitter/NCDC Ènìyàn 1,133 lo tun ṣẹṣẹ lugbadi aarun Covid-19 ni Naijiria.
Àpẹrẹ pé àwọn igi wọ̀nyí àti àwọn ewéko gbogbo ti ń gbáradì fún  ọ̀gìnìntìn tó ń bọ̀ lọ́nà.
Alaafin Oyo: Kíni 'Ẹ̀lẹ̀ daddy' Olorì Abbey Adeyemi ṣe tí ojú òpó ayélujára rẹ̀ fi ń yeruku lálá?
Awọn obinrin naa fi aake kọri pe, a fi ti Alake ba kọwe fipo rẹ silẹ ni awọn yoo to dẹkun iwọde.
Wúrà, fadaka, òkúta iyebíye, oríṣìíríṣìí ìlẹ̀kẹ̀, aṣọ funfun ati àlàárì, ati sányán ati aṣọ pupa; oríṣìíríṣìí pákó, ati àwọn ohun èèlò tí a fi eyín erin, igi iyebíye, idẹ, irin, ati òkúta ṣe; 
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ibadan Jungle Justice: Àwọn èèyàn kan ní alárùn ọpọlọ ni Saheed, tawọn mii ni ajínigbé ni 26 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 29 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Oríṣun àwòrán, @essienudom Fun igba ti ko fẹrẹ ṣee ka mọ bayi lẹnu ọjọ mẹta yii ni ilu Ibadan, iṣẹlẹ idajọ ọwọ miran tun waye.
Gẹ̀ẹ́sì gbẹ́sẹ̀ lé ₦82bn owó Abacha NURTW yóò fikùlukù pẹ̀lú Gómìnà Makinde láìpẹ́ Iṣẹ́ Kudirat Abiọla ṣì ń fọhùn síbẹ̀, lẹ́yìn ọdún 23 tó papòdà Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Dambe fight: ìdíje ìjà láàrin àwọn akóni tó n ja ẹ̀ṣẹ̀ O ni inu oun bajẹ nigba ti oun bi awọn ibeji naa, amọ ayọ oun ti kun bayii ti oun ti ri wọn ni alaafia.
Awọn igbimọ alakoso ileeṣẹ naa ni wọn pe birikoto paṣẹ lọ rọọkun nile naa fun ẹni to jẹ ọga agba ileeṣẹ naa, Ọjọgbọn Usman Yusuf lori ẹsun iwa ko-tọ ti wọn fi kan an.
Shehu/Sheikh :Shehu tumọ si agbalagba, Sheikh si ni kurani n lo fun wọn, oye Shehu abi Sheikh yii si maa n lọ sọdọ ẹni to ba ku ni olori ile tabi ẹni ti imọ, oye abi ẹṣin rẹ pọ.
 ( bí 6 okudu 1984 ) .
Ó ní, “Ẹ̀yin ni a fi fún láti mọ àṣírí ìjọba Ọlọrun, ṣugbọn fún àwọn yòókù, bí òwe bí òwe ni, pé wọn yóo máa wo nǹkan ṣugbọn wọn kò ní mọ ohun tí wọn rí, wọn yóo máa gbọ́ràn ṣugbọn òye ohun tí wọn gbọ́ kò ní yé wọn.
Solskjaer fárígá lẹ́yìn tí Van Persie ló ń rẹ́rìn-ín Gómìnà mẹ́ta àtí ènìyàn 1,242 ló kó sí panpẹ EFCC ni ọdún 2019 Ṣo mọ̀ pé J.
Gomina ìpínlẹ̀ Eko Babajide Sanwo-olu ti kede pe ki gbogbo ọja ní ìpínlẹ̀ Eko wa ni títìpa láti ọjọbọ lọ nítori pe ìbẹru bojo ti wà láàrin ilú.
" Oríṣun àwòrán, @RadioToday Lai Muhammed wa fọwọ idaniloju sọya pe igbesẹ naa ko wa lati ga awọn ileesẹ iroyin lọrun, to si rọ ajọ BON lati sugba ijọba nidi aayan rẹ lati mu agbega ba eto igbohunsafẹfẹ ni Naijiria.
Ati ẹni to n fẹsẹ rin atawọn to n gun ọkọ, awọn ofin wa to de bi eeyan ti ṣe maa n lọ loju ọna.
Ṣugbọn ninu làálàá ati ìṣòro ni à ń ṣiṣẹ́ tọ̀sán-tòru, kí á má baà ni ẹnikẹ́ni ninu yín lára.
Nípasẹ̀ wolii kan ni OLUWA ti mú Israẹli jáde kúrò ní Ijipti, nípasẹ̀ wolii kan ni a sì ti pa á mọ́.
Bush, ààrẹ Amerika tẹ́lẹ̀ jáde láyé
Lalong, Tambuwal, Ganduje ni ilé ẹjọ́ gíga jùlọ kéde bíi gómìnà ìpínlẹ̀ wọn Ìríwísí àwọn aráàlú bí EFCC ṣe kó afurasí ọmọ yahoo 49 ní Ibadan Ọmọ ọdún mẹ́wàá ń jẹ ìrora lẹ́yìn tí ọ̀gá tì í sínú iná àrò búrẹ́dì Ọkan lara awọn obinrin naa ni wi pe awọn ti bere boya awọn lee lo gbọngan naa lati Osu Kẹrin, ọdun to kọja, ti wọn ṣẹṣẹ wa da wọn lohun ni ọṣẹ ọjọ igbeyawo wọn.
ba fọ ọpa epo rọbi , yoo ba omi jẹ, awon apẹja ati agbe ni yoo jiya rẹ, koda akoba
Ebi pa wọ́n, òùngbẹ gbẹ wọ́n,ó sì rẹ̀ wọ́n wá láti inú.
”Jesu dá wọn lóhùn pé, “Ẹ kò mọ̀ mí, bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò mọ Baba mi.
Nigba ti Minisita fun oro awon osise ati ise lorile ede Naijiria, Chris Ngige  n ba awon akoroyin soro leyin ipade igbimo ijoba apapo so pe  awon igbimo si n jiroro lori ekunwo awon osise ati pe awon  ko i ti fenuko lori  iye ti awon osise yoo maa gba.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Emir Sanusi: Kò dára báwọn gómìnà, mínísítà kò se yọjú sípàdé ìdókòwò 22 Ìgbé 2018 Oríṣun àwòrán, Reuters Àkọlé àwòrán, Emir Sanusi korò ojú sí ìwà àílákàsí àwọn alásẹ tí ọ̀rọ̀ ìdókówò náà kàn ní Nàíjíríà Emir tìlú Kano, Mohammadu Sanusi kejì, ti bu ẹnu àtẹ́ lu àwọn gómìnà àtàwọn mínísítà tó yẹ kí wọn sọ̀rọ̀ níbi àkànse ètò kan láti fa ojú àwọn olùdókòwò mọ́ra sí orílẹ̀èdè Nàíjíríà, èyí tò wáyé ní ilé Nàíjíríà, ní ìlú Washinton, lórílẹ̀èdè Améríkà.
Ẹ ti fi ìṣekúṣe yín ba ilẹ̀ náà jẹ́.
 ""A n bọ ara wa, ẹbi wa ati awọn eeyan miran lawujọ, ta si tun n se iranwọ fawọn eeyan miran bii awọn ọlspa ta n gbe lọfẹ sinu kẹkẹ Maruwa wa."
Ṣaaju ni ijọba ilẹ Gẹẹsi ti sọ pe oun n ni idojukọ pẹlu pinpin awọn ohun elo idabobo ara ẹni ọhun, ṣugbọn iṣẹ n lọ pẹlu ifọwosoẉọpọ awọn ọwọn ọmọ ogun lati ri pe ohun elo naa kari.
Nígbà tí Mata ti sọ báyìí tán, ó lọ pe Maria arabinrin rẹ̀ sí ìkọ̀kọ̀.
Iroyin sọ pe ọjọ Aje ni Adeniyi kuro latimọle ọjọ Iṣẹgun ni ọga ọlọpa DPO gbe lọ si ileẹjọ.
Bakan naa ni Grandma Maruwa tun rọ wọn lati wa isẹ se, ki wọn lee gbiyanju ipa tiwọn naa nidi eto ẹkọ awọn ọmọ wọn.
Nígba ti BBC Yoruba ba ọ̀kan lára àwọn ti ọ̀rọ̀ náà ṣẹlẹ̀ sí sọ̀rọ̀ sàlàyé pé, ìlé ìṣe àrìrinajó sí ilẹ̀ òkèrè kan to se ìforúkọsílẹ̀ fún àwọn ní kò ṣe ètò tó péye, tí pápákọ̀ òfurufú sì sọ pé kò sí ǹkan tí àwọn le ṣe síi.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ifẹhonu han lorilẹede Venezuela Ni bi ogun ọdun sẹyin, iṣẹlẹ ifipagbajọba ti dinku nilẹ South America.
Ọlọrun mi, àpáta mi,ọ̀dọ̀ ẹni tí mo sá pamọ́ sí.
Ọ̀nà àti là yìí náà ni wọ́n ń lépa.
Baba ati iya Ọṣun ni, awọn to ji ere Ọṣun naa fẹṣun kan Ataoja atawọn eeyan miran pe, wọn ti gba owo to le ni miliọnu mẹẹdogun naira lọwọ awọn, awọn yoo si gba owo naa pada, kawọn to gbe ere naa silẹ.
Idi ti o fi fagile irinajo re si orile-ede Rwanda ni lati tunbo faye gba ijiroro pelu awon ti oro kan.
Awọn òṣèré Yoruba tí wọ́n bí ní ọjọ kan náà Ki ni Toyin Abraham sọ ni tirẹ?
Ó dárúkọ gbogbo ìyàwó ọba hàn wá, ó sọ bí ilé ìyá àti bàbá oníkálùkù  ti rí àti bí ọba ti fẹ́ràn olúkúlùkù tó, nígbà tì ó sì tún n tú àṣíírí ọkọ rẹ̀ báwọ́n-ọnnì mo wí fún un kí ó yé sọ gbogbo nǹkan wọ̀n-ọnnì fún wa ṣùgbọ́n ó wí fún mi pé bẹ́ẹ̀ ni baálé òun ní kí òun máa ṣe.
Ọkùnrin kan ń bẹ nígbà náà tí orúkọ rẹ̀ ń jẹ́ Ibrahim.
Ijoba apapọ tun ti pe ipade miran ni ọla lori awọn igbesẹ ti ile iwe kọọkan a gbe ki ọsan eto ẹkọ le so didun.
Ileeṣẹ to n ri si eto idajọ ni Wsconsin ti ni iwadii ti bẹrẹ lori bi ọrọ naa ṣe ṣẹ, wọn si ti ni ki awọn ọlọpaa to lọwọ ninu iṣẹ ọhun lọ rọkun nile fun igba diẹ na.
O ni ida ọgọrin ninu ọgọrun un awọn ti ololufẹ wọn n pa ti maa n fura tẹlẹ ṣaaju ki wọn to pa wọn.
Ìyẹn ni pé ọjà dọ̀la ni ó kú Orímóògùnjẹ́ máa ń fún àwọn ìyàwó rẹ̀ ní owó-ìná tí ó bá ti mówó.
Ṣugbọn nigba to de, ile ti aarẹ n gbe ni wọn mu u lọ.
Fún ọdún meji gbáko ni Paulu fi gbé ninu ilé tí ó gbà fúnra rẹ̀.
Fáàrí tí ẹ̀ ń ṣe kò dára!
Amọ, Facebook ni awọn ti wa wọrọkọ fi sada, ati wi pe ọna abayọ ti de si isoro naa.
Sugbọn mo se alabapade awọn obinrin mẹta ati ọkunrin kan, wọn n bọ lati ijọsin ti wọn lọ ọ ṣe nile ẹnikan.
Sotitobire church news: Ilé ẹjọ́ sún ìgbẹ́jọ́ pásítọ̀ ìjọ Sotitobire sí ọjọ kẹrinla, oṣu Kẹsàn án
95bn sórí reluwé làti Kano sí Niger Republic- PDP Oluwo kọ̀ láti sọ̀rọ̀ lórí àwọn afọbajẹ tó fẹ́ yọ ọ́ nípò, aráàlú fọ́n síta láti fẹ̀hónú hàn Wo bí ìwọ náà ṣe lè rí gbà nínú owó ìrànwọ́ tí ìjọba Nàìjíríà fẹ́ pín Ẹ yé parọ́ kiri!
Ní ọjọ̀ kan Ìrèke nìkan ni o fi fèrè rẹ̀ ṣe nǹkan àràmọ̀dà lójú ogun.
Wọ́n ka ẹsùn mẹ́ẹ̀dógún sí i lọ́rùn, eyi ti ìfipábánilòpọ̀ àti ìfìyàjẹni wà lára rẹ̀, iwé ẹsùn náà fi kún un pé, ó ti tó ènìyàn méjìdíláàdọ́rùn tó ti hùwà àìtọ́ yìí sí láàrín ogún ọdún, èyí ti àwọn ọmọ kéékèèké àti àgbà wà nínú wọ́n.
Nígbà tí mo bá rí ẹ̀jẹ̀ náà, n óo re yín kọjá; n kò ní fi àjàkálẹ̀ àrùn ba yín jà láti pa yín run nígbà tí mo bá ń jẹ àwọn eniyan ilẹ̀ Ijipti níyà.
"Ẹ́ ràgà bo ìṣọ̀kan Nàíjíríà, ìyàpà le mú ìṣẹ́ àwọn akọni wa já sásán - Osinbajo August Agboola Brownie, ọmọ Yorùbá tí wọ́n n wárí fún ní Poland Mínísítà ní "" Lórí ìwalé ọjọ́ kejìdílógún, a ó ṣe àtúngbéyẹ̀wò rẹ̀."
Ọjọ karun un ti awọn ọlọja ti wa nile ni Aarẹ Muhammadu Buhari kede ofin konile o gbele fun ọsẹ meji, eyi to bẹ̀rẹ̀ ni ọgbọnjọ, oṣu Kẹta.
Nigba ti awọn mẹta tó kù si wa lati ipinlẹ Sokoto, Nassarawa ati Kano.
Má máa fi ohùn líle bá àwọn àgbàlagbà wí, ṣugbọn máa gbà wọ́n níyànjú bíi baba rẹ.
Bi ó bá jẹ́ ijà nitori ilẹ̀ oko, Baálẹ̀ Abúlé naa ni wọn yio kó ẹjọ́ lọ bá fún idájọ́, ti ó bá jẹ àdúgbò kan si ekeji ló njà, wọn á kó ẹjọ́ lọ bá Ọba ilú àti bẹ́ ẹ̀ bẹ́ ẹ̀ lọ.
Ibi ti o dara lati da okoowo sileAmbode fi kun oro re pe, ilu Eko fi aaye gba awon onisowo lati da ile-ise won sile, paapaa julo ,won ni eto  isejoba ti o fẹsẹ mulẹ, bi eto oro aje ilu Eko se tobi pupo si, iye awon eniyan to n gbe inu ilu naa, ibowo fun ofin ati eto idajo to fẹsẹ mulẹ .
Kì í yáni lówó kí ó gba èlé,kìí sìí gba àbẹ̀tẹ́lẹ̀ lọ́wọ́ aláìṣẹ̀.
Orile-ede Netherland se ipo keji ninu irufe idije boolu agbaye ohun ti o waye lodun 2010, besini won tun se ipo keta lodun 2014, idije boolu agbaye ti o waye lorile-ede Brazil, sugbon ti won kuna lati pegede fun idije todun yii, ti yoo waye lorile-ede Russia.
"Oríṣun àwòrán, @yelesowore Nigba to n salaye idi ti iwọde naa yoo fi waye, Sowore ni ""ede kan ṣoṣo tijọba gbọ ni ifẹhonu han, bẹẹ si ni ọpọ ohun ti araalu n pohungbẹ rẹ, nijọba kọ eti ikun si""."
Nígbà tí ọba Ai ati gbogbo àwọn eniyan rẹ̀ rí i, gbogbo àwọn ọkunrin tí wọ́n wà ní ìlú náà bá yára, wọ́n jáde lọ sí gẹ̀rẹ́gẹ̀rẹ́ apá ọ̀nà Araba láti kó ogun pàdé àwọn ọmọ Israẹli, ṣugbọn wọn kò mọ̀ pé àwọn kan ti farapamọ́ sẹ́yìn ìlú.
Ìtàn sọ fún wa pé , aga , ẹni tí a tún wá mọ orúkọ rọ ̀ bí alákùnrẹ ́ ni ó kọ ́ kọ ́ tẹ ìlú Àkúrẹ ́ dó .
Àwọn alufaa ati àwọn ọmọ Lefi gbé àpótí náà wá pẹlu àgọ́ àjọ, ati gbogbo ohun èlò mímọ́ tí ó wà ninu àgọ́ àjọ náà.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Chelsea wọ gau lori ọrọ agbabọọlu rira Ọrọ yii jẹyọ lẹyin iwadii ti FIFA ṣe lori bi Chelsea ṣe ra ọdọmọde ẹlẹsẹ ayo, Bertrand Traore ati awọn agbabọọlu miran ti ọjọ ori wọn ko ju ọdun mẹẹdogun lọ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Suicide Prevention: ìwọ́de yìí wáyé láti gbógun ti pípa ara ẹni Lara awọn to wa ninu igbimọ ti aarẹ Buhari gbe dide yii ni amugbalẹgbẹ fun aarẹ lori ọrọ itọju ile, Sarki Abba, Garba Shehu to jẹ amugbalẹgbẹ fun aarẹ lori ọrọ iroyin ati ipolongo, oludari eto ati ilana gbogbo ni ile ijọba l'Abuja, Ambasadọ Lawal Kazaure.
Oyedepo: Ẹni tó bá ń sàánú àwọn apànìyàn, kò ní mú 2018 jẹ
Ninu oṣu kẹta ọdun 2019 ni Helen Paul gba oye PhD lati ile iwe giga fasiti ti ipinlẹ Eko.
'Ọmọ Naijiria 25,794 ló kú sí rògbòdìyàn láàrin ọdún mẹ́rin' Iṣẹ́ Kudirat Abiọla ṣì ń fọhùn síbẹ̀, lẹ́yìn ọdún 23 tó papòdà Ilé aṣòfin Ekiti ní kí àwọn alága ìjọba ìbílẹ̀ dá N3.
 Ise akanse ipese omi yii yoo ran ijoba ipinle Ogun lowo ni agbegbe wonyii”.
Mo fẹ́rẹ̀ lè gbadura pé kí á sọ èmi fúnra mi di ẹni ègún, kí á yà mí nípa kúrò lọ́dọ̀ Kristi nítorí ti àwọn ará mi, àwọn tí a jọ jẹ́ ẹ̀yà kan náà.
Ìyá gómìnà Seyi Makinde dágbére fáyé lẹ́ni ọdún 81 Oríṣun àwòrán, @Makinde Iya to ṣe ọlọkọ to wa gomina ipinlẹ Oyo wa saye, Arabinrin Abigail Omojolagbe Makinde ti faye silẹ.
Ọmọ ọdun mọkandinlogun to wa lati Soweto ni agbegbe Johannesburg ni orilẹ-ede South Africa yii ta awọn ọdọ jí nilẹ Adulawọ pe, ko si nkan ti eeyan ko le ṣe ti o ba ti ni ifọkansin.
Ọgbẹni Abiy sọ pe lasiko ti awọn ọmọ ogun naa n ṣepade lọwọ ni 'awọn akẹgbẹ wọn kan'' kọlu wọn, ti wọn si yinbọn pa wọn.
Balaamu lu kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ náà láti darí rẹ̀ sójú ọ̀nà.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ìfàsẹ́yìn díẹ̀ tí yóò ní àtúnse ni àdánù ìbò gómìnà mi - Adeleke Wo àwọn tó ń du ipò gómìnà lábẹ́ APC nílẹ̀ Oòduà Kíni ìwọ mọ̀ nípa Funmilayọ Ransome-Kuti?
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Champions league draw: Kà bí Juventus àti Barcelona, PSG àti Man United, pẹ̀lú Bayern ati Athletico Madrid yoo ṣe dáná sun ara wọn ní Champions League tọdun yii 1 Ọ̀wàrà 2020 Oríṣun àwòrán, Giveme sport Iyikoto idije champions league fun ti saa idije bọọlu ọdun yii ati ọdun 2020/21 waye lọjọbọ.
Lasiko to fi n kọ awọn akẹkọọ mi, a maa n ṣere jade lẹyin iṣẹ, ao si jọ sun mọju.
Lẹ́yìn náà, ọbabinrin Ṣeba fún Solomoni ọba ní ọgọfa (120) ìwọ̀n talẹnti wúrà, ati ọpọlọpọ turari olóòórùn dídùn, ati àwọn òkúta olówó iyebíye.
Wọn pa ọpọ eeyan, ti wọn si tun ba ọkẹ aimọye dukia jẹ, to fi mọ ile ajagunfẹyinti Paul Tarfa.
Zainab Habib Arábìnrin wà ní àhámọ́ ní Saudi lórí ẹsùn tí kò mọ
Ijọba Ondo n wa ọdẹ aperin Ìpínlẹ̀ Ondo tú ìgbìmọ̀ eré ìdárayá ká Rotimi Akeredolu tọ ileẹjọ to ga julọ lorilẹede Naijiria lọ, lati lodi si idajọ ti ileẹjọ giga ilu Abuja gbe kalẹ, ti ileẹjọ kotẹmilọrun nilu Abuja kannaa si faramọ, ninu idajọ to gbe kalẹ losu keje ọdun 2017 lati gba Olusẹgun Abraham laaye, lati fun Akeredolu ni iwe ipẹjọ lori ẹjọ to pe gomina ipinlẹ Ondo naa.
Wo bí Gómìnà Obaseki ṣe yọ òrùlé ilé aṣòfin Edo lẹ́yìn tó fìjà pẹẹ́ta pẹ̀lú ọlọ́pàá Al-Qaeda ń gbèrò láti kógun wọ Ìwọ̀ Oòrùn àríwá Nàìjíríà - Amẹ́ríkà ké gbàjarè Ẹ wo ìrírí aláboyún tó ń rọbí lọ́wọ́ lásìkò ìbúgbàmù tó wáyé ní Lebanon Ìtàn ayé Shina Rambo, adigunjale tó fi oyún 27 gún ọṣẹ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ìdílé tí ọkọ da ọmọ síta tóríi ojú Búlùú tí wọ́n ní bá BBC sọ̀rọ̀ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Kìí ṣe ọmọbìnrin nìkan ni Ọlọ́run pàṣẹ fún láti pa ìbálé mọ́ Kini itumọ sisọrọ kubakugbe?
’ rèé Ìgbín ní èmi àti ìyá mi máa ń he kiri, ká tó lee jẹun - Lizzy Anjọrin 'Ẹnikẹ́ni ò lè tì mí gbọ̀ngbọ̀n láti gbé orúkọ mínísítà jáde' Kí ló mú àwọn adarí Nàìjíríà tako ra wọn lórí ikú ọmọ alága ẹgbẹ́ Afenifere?
Fi igi akasia ṣe ọ̀pá, kí o sì yọ́ wúrà bò wọ́n; àwọn ọ̀pá wọnyi ni wọn yóo máa fi gbé tabili náà.
Àfi ìgbà tí mo wọ ibi mímọ́ Ọlọrun lọ,ni mo tó wá rí òye ìgbẹ̀yìn wọn.
Wọ́n sọ fún ìjọ eniyan Israẹli pé, “Ilẹ̀ tí a lọ wò náà jẹ́ ilẹ̀ tí ó dára lọpọlọpọ.
lowo lati sagba iko akegbe won.
Eyi ni yo lè jẹ ki ọ mọ ibi ti oju gọ́tà tabi ihò wà láti yago fun.
O sọ ninu fidio kan pe oun o mọ pe gbajuẹ ni Hush n ṣe.
Beckham, àgbábọ́ọ́lù tẹ́lẹ̀ rèé tó ń sọ èdè Yorùbá Àdúrà mi ni kò jẹ́ kí ìyà Manchester United ó pọ̀ jù lọ́wọ́ Barcelona- Wòlíì Àrólé 'Ọdún méjì sẹ́yìn ni òbí àwọn ọmọbinrin Chibok gbọ́ láti ọ̀dọ́ ìjọba kẹ́yìn' Ṣé ìfipágbàjọba àwọn ológun kò maa pọ̀ si l'Afirika?
"Mumuni sọ pe, ""A ko ni da ẹnu duro lẹyin ti a ba gbe awọn aṣofin lọ ile ẹjọ."
Airwo gee lo gba ẹnu awọn alatilẹyin Modi kaakiri orilẹ-ede India bi wọn ṣe kede esi idibo naa ti wọn ti n ka lati ọsan ọjọ Aiku.
Wọ́n ń jẹ, wọ́n ń mu, wọ́n ń rà, wọ́n ń tà, wọ́n ń fúnrúgbìn, wọ́n ń kọ́lé, 
 wọ ́ n máa ń kọ ọ ́ níbi tí àwọn ènìyàn bá pé jọ sí tàbí ibi òṣèlú tó bá ṣe pàtàkì .
Ijọba ipinlẹ Ọyọ ti kede pe awọn ti fagile isinmi aarin taamu ti wọn ma n fun awọn akẹkọọ nipinlẹ naa.
Wo odò tí wọ́n ti rí Aishat tí àgbárá òjò gbé lọ ní Eko Ẹbí Abiola Ajimobi kéde bí ètò ìsìnkú rẹ̀ yóò ṣe rí pé.
Ìtànjẹ ti pọ̀jù nínú iṣẹ́ tíátà, a kò rí kọ́bọ̀ nínú fíìmù tó wà lórí YouTube
” Esau bá búra fún Jakọbu, ó sì ṣe bẹ́ẹ̀ gbé ipò àgbà fún un.
Wọn ni ori Toke ni baba awọn n run owo le.
Wo nkan tó yẹ́ kí o mọ̀ nípa Adeyinka Godson tó fún ẹ̀yà Igbo ní wákàtí 48 láti kúrò nílẹ̀ Yorùbá Wo àwọn ayédèrú ìròyìn tó gbà'gboro kan lásìkò ìwọ́de #EndSARS Ojú àwọn tọ́wọ́ ti tẹ̀ lára àwọn tó jí 'tíá rọ̀bà ọ̀kadà', fíriìjì, ẹ̀rọ ata kó nílée Sẹ́nétọ̀ Teslim Folarin rèé Kaduna Ọjọ Abamẹta ni awọn eeyan yabo Gwari, ti wọn si ko gbogbo ounjẹ Covid-19 to wa nibẹ lọ.
-Olugbo Obateru Akinruntan Ọjọ Iṣẹgun, ọjọ keji oṣu kẹfa ọdun 2020, 02/06/2020 Ni ọjọ keji oṣu kẹfa ọdun 2020, itakun ina pinpin lorilẹede Naijiria lati ilu Oṣogbo tun daku patapata to si sọ orilẹede Naijiria sinu okunkun.
A ti mọ òbí 40 nínú 108 t'ọ́mọ wọn bọ́ ní ayédèrú ibùdó atúnwàṣe Ilorin - Ọlọ́pàá Kwara Wọ́n ti ṣí ilé oúńjẹ oní ọgbọ̀n náírà (N30) ní Kano Capital Funeral Home and Cemetary ni wọn ti maa sin ọjọgbọn ọmọ ipinlẹ Kogi ni aarin gbungbun Naijiria yii si lọsan oni.
"- Sanwoolu Àṣé àṣírí wà nínú Hijabu tí Aisha Yesufu ń wọ̀ lọ ìwọ́de Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: 'Ko sẹni to ba mi lopọ lati fun mi nisẹ' Njẹ o mọ oju yi ni ""Yollywood"" Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí EndSARS School Resumption: Àwọn akẹ́kọ̀ọ́ lè padà sílé ìwé láti ọjọ́ Ajé - Ìjọba ìpińlẹ̀ Eko29 Ọ̀wàrà 2020 5:55 Fídíò, Soyinka Cancer: Àṣe ara mi ni iso ti n run gbogbo bí mo ṣe n ṣèrànwọ́ lórí jẹjẹrẹ, Duration 5,5527 Bélú 2019 Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí kan sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn."
Nígbàtí a dé òkè tán, yàrá ńlá mìíràn la tún bọ́ sí.
wu ko mo lagbegbe naa, bee si ni ki awon ara ilu mase teti si awon iroyin eleje
Adajo agba Onnoghen salaye pe, ”E gbodo fi otitp siwaju ejo ti won ba gbe fun yin.
Òun ni mo fi ń ṣe àṣàrò tọ̀sán-tòru.
Nígbà tí ọjọ́ tí a óo gbé níbẹ̀ pé, a gbéra láti máa bá ìrìn àjò wa lọ.
Nikodemu wá bi í pé, “Báwo ni nǹkan wọnyi ti ṣe lè rí bẹ́ẹ̀?
" Akinsilu salaye pe Ajagunode lo kọkọ gbe awọn lọ sile ẹjọ lori ilẹ ti awọn ti kọle le lori, to si ni kawọn wa san ẹẹdẹgbẹta miliọnu naira lori ilẹ naa.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Amad Diallo: Manchester United ra Ahmad Diallo lọ́wọ́ Atalanta fun ọ̀dun mẹ̀rin abọ̀ 8 Sẹ́rẹ́ 2021 Oríṣun àwòrán, Twitter/Ahmad Diallo Ẹgbẹ agbabọọlu Manchester United ti fi ẹnu adehun jona lori rira Amad Diallo, agbabọọlu Atalanta bayii.
Oluwo ti ìlú Iwó kìí ṣe ẹgbẹ́ Àtaọjà Osogbo - Alaafin ìlú Ọ̀yọ́ Wo iye owó tí ìjọba Amẹrika ń na sí ìdìbò Ààrẹ àti ibi tí owó náà ti ń wá Aàbò tó péye yóò wà fún àwọn tí yóò kópa nínú ìfẹsẹwọ̀nsẹ̀ Naijiria àti Sierra Leone ní Benin - Obaseki Ǹkan tí a mọ̀ nípa kọ́lẹ̀jì olùdìbò tó ń fìdì ẹni ti yóò jẹ ààrẹ ilẹ̀ Amérika múlẹ̀ Owatapa ti Itapa Ijesha, Wolii Olapade Agoro jáde láyé Ẹnikọọkan wọn sile kọwe beere fun owo to to ẹgbẹrun lọna ọtalerugba din mẹwaa (250,000) si miliọnu marun-un Naira.
O kò fún mi lọ́mọ, ẹrú tí wọ́n bí ninu ilé mi ni yóo di àrólé mi!
Ișẹ́ tÁdániwáyé yọ́nú sí nișẹ́ olùkọ́, Ẹ jẹ́ ká ṣe é bó bá ṣe yẹ.
Eyi tumọ̀ si pe bi ifẹ ba wa, yara kekere gba ọpọ eeyan, inu ko gba, ni aaye ko gba Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ọdọọdun ni awọn adan maa n rababa yika oju ọdun nilu London, lati fo pada wa si ilẹ Afrika.
Adesanmi, to wa lara awọn to padanu ẹmi wọn ninu ijamba oko ofurufu Ethiopia to
Àwọn ọmọ Efuraimu kò lé àwọn ará Kenaani tí wọ́n ń gbé Geseri jáde, wọ́n jẹ́ kí wọ́n máa gbé ààrin wọn.
Ileẹjọ giga ran an lọ si ẹwọn ọdun meje, amọ Metuh gbe ẹjọ naa lọ si ileẹjọ kotẹmilọrun pe adajọ naa ko ṣe otitọ pẹlu idajọ rẹ.
Sanwo-Olu ni pẹlu Ọlọlajulọ Ọba Abdulwasiu Ọmọgbọlahan ati Olori rẹ ni ko si ani ani, ọjọ iwaju ilu Iru yoo dara o si nireti at pe gigun ori itẹ Oniru tuntun yii yoo jẹ ibẹrẹ irinajo lọ sinu ọjọ iwaju naa.
O kọ̀ mí sílẹ̀, o bọ́ sórí ibùsùn, o tẹ́ ibùsùn tí ó fẹ̀.
Ẹ má fetí sí ọ̀rọ̀ àwọn wolii tí wọn ń wí fun yín pé ẹ kò ní ṣe ẹrú ọba Babiloni, nítorí pé àsọtẹ́lẹ̀ èké ni wọ́n ń sọ fun yín.
 Karma ati awọn  komisona meta ni yoo jọ se ise papo lati mojuto awọn  ekun metẹẹta to wa ni ipinle Ekiti.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Cosmic Crisp apple: kò le bàjé nínú ẹ̀rọ amóhun tutù fún ọdún kan 2 Ọ̀pẹ̀̀ 2019 Oríṣun àwòrán, PVM Àkọlé àwòrán, Cosmic Crisp apple: kò le bàjé nínú ẹ̀rọ amóhun tutù fún ọdún kan Èso Apple tuntun tí wọ́n ṣẹ̀ṣẹ̀ ṣe yìí gba àwọn ónímọ ìjìnlẹ̀ sáyẹnsì ní ogún ọdún láti ṣèwádìí náà yanjú.
Nítorí mò ń ṣe nǹkan ìyanu kan ní àkókò rẹ, tí o kò ní gbàgbọ́ bí wọ́n bá sọ fún ọ.
O ni ṣebi o ṣaa ni ki minisita mẹta wa si ile mi lati tu wa ninu ati fi aridaju han wa pe wọn yoo wa ọmọ wa ri ṣugbn lẹyin naa, lati oṣu kẹwa, ko sẹni to wa tabi kan si mi""."
Ọmọwe Sabo Kurawa Ọmọwe Sabo Kurawa naa jade laye ni ọjọ Satide, ọjọ kẹrindinlọgbọn lẹyin aisan ọjọ pipẹ gẹgẹ bi awọn mọlẹbi rẹ ṣe sọ.
Wọ́n ní owọ ti ọmọ ilẹ̀ Amẹrika yóò fi gba físà wá si Nàìjíríà ti pọ̀ jú iyé ti Nàìjíríà fí n gbà físà lọ si ilẹ̀ Amẹrika lọ Ilẹ̀ Amẹrika kọ̀wé ránṣẹ́ nínú oṣù kẹjọ pé gbogbo ẹni tó bá gba físà (irú èyí tí kì báà jẹ́) yóò san àádọ́fà dọ́là fún físà.
O ni awọn ko kede fun ẹnikankan pe iyawo Ọọni bimọ nitori naa, iroyin ayederu gba a ni ọrọ naa jẹ.
Igbimọ naa ti wọn pe ni National Salaries Income and Wages Commission ni wọn ti ṣe iṣẹ wọn tan.
Ọwọ́ ni wọ́n fi ti ọba Ahabu ninu kẹ̀kẹ́ ogun tí ó wà, tí ó sì kọjú sí àwọn ará Siria.
Ko daju iye owo ti oloogbe naa lọ gba nile ifowopamọ .
Atẹjade kan to wa loju opo Twitter ijọba Eko, ti adele Kọmisana feto ọgbin, Abisola Olusanya fọwọsi, lo sisọ loju ọrọ yii.
- Lizzy Anjorin Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ìdájọ́ òdòdò ló fẹsẹ̀ múlẹ̀ lórí ọ̀rọ̀ Pásítọ̀ Sotitobire - Agbẹjọ́rò fún ìjọba Kanu ni iṣẹ́ esù ló mu òun gbé ìgbésẹ̀ náà lásìkò tí àwọn ọlọ́pàá ń bèrè ìdí tó fi hu irú ìwà bẹ́ẹ̀.
Nitori naa ọkọ mi nikan lo le ṣalaye bi ọrọ ṣe jẹ.
Àwọn ọkunrin marun-un náà bá kúrò níbẹ̀, wọ́n wá sí Laiṣi, wọ́n sì rí àwọn eniyan tí wọ́n wà níbẹ̀ bí wọ́n ti ń gbé ní àìléwu gẹ́gẹ́ bí àwọn ará Sidoni tií máa ṣe.
"Wo bi awọn mejeeji ṣe fakọyọ lọdun to kója si: Oríṣun àwòrán, ""others Àkọlé àwòrán, ọmọ ju ọmọ lọ ninu idije bọọlu gbigba Laarin ọjọ kọkanlelọgbọn, oṣu keje, ọdun 2018 si ọjọ kọkanlelọgbọn, oṣu keje, ọdun 2019 ni esi abajade ifakọyọ awọn mejeeji ti fihan."
Lara awọn to fun lesi ni oju opo Twitter naa ni, Segun fẹran lati jẹ gaba lori awọn eniyan, nitori naa ni wọn ko ṣe gbọran si i lẹnu.
àwọn ará Arifadi, àwọn ará Semari, ati àwọn ará Hamati.
Nollywood: Ìdá 90% nínú àwọn olówó Naijiria lo n lọ ilé babaláwo
Ẹni to ba gbiyanju lati tete jẹ ki awo koto tirẹ kun fun ayo ni yoo gbegba oroke ninu idije naa.
Ẹni to bori: Guinea Guinea Ni ọdun 2018, awọn eeyan orilẹede Guinea jẹ odiwọn aadọwa kilogiramu irẹsi.
Ṣùgbọ́n kíni àwọn ìjọba ìpínlẹ̀ ń sọ?
 Ó lè ran àwọn ẹranko mìíràn bíi ẹlẹ ́ dẹ ̀ , mààlúù àti ẹṣin .
OLUWA ní, “Inú mi ru sí àwọn olùṣọ́-aguntan, n óo sì fìyà jẹ àwọn alákòóso.
Bí iṣẹ́ tí à ń torí rẹ̀ dá wa lẹ́bi bá lógo, báwo ni iṣẹ́ tí à ń torí rẹ̀ dá wa láre yóo ti lógo tó?
Ní àkókò tirẹ̀, ó mú kí fadaka pọ̀ bí òkúta ní Jerusalẹmu, igi kedari sì pọ̀ bíi igi sikamore tí ó wà ní ẹsẹ̀ òkè Juda.
Ṣebí ohun tí a bá gbọ́ ni à ń gbàgbọ́, ohun tí a sì gbọ́ yìí ni ọ̀rọ̀ Kristi?
0 Ile ijọba orilẹẹde Amerika fidi ọrọ mulẹ pe ipade naa yoo waye laye ati akoko ti awọn ko tii le sọ.
Bí ọ̀kan bá ṣubú,ekeji yóo gbé e dìde.
Wọ́n fẹ́ ṣe màgòmágó ìbò tó ń bọ̀ - Danjuma figbe bọnu Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, ìpàdé ìtagbangba ìfọ̀rọ̀wánilẹ́nuwò pẹ̀lú àwọn olùdíje sípò gomina ní ìpínlẹ̀ Eko.
NIN Registration:Àjọ NIMC sọ pé ọ̀fẹ́ ni gbígba nọ́mbà NIN
Alakoso igun ọdọ kan ti wọn n pe ni OFI, Ọgbẹni Ayọ Adekanmbi lo gbe imọran yii kalẹ ninu atẹjade kan to fisita nilu Ibadan eyi to da lori bijọba Seyi Makinde se fẹ gba owoya biliọnu meje ati aabọ naira.
Ọkọ̀ ojú omi dànù ní Kwara, ọmọ́dé 9 ba rìn Kwara ò jẹ̀gbádùn Saraki- Aráàlú Àsírí ajọ́mọgbé méjì tú ní Kwara Saraki gbé N16.
Gba nọ́mbà ìbánisọ̀rọ̀ ẹni tí ó fẹ́ láti bá sọ̀rọ̀ nígbà tí ọmọ bá ti ń mú ọ, mọ ẹni tí fẹ́ kí ó ràn ọ lọ́wọ́ lásìkò ìrọbí, máa ṣe àwọn ǹkan bí eré ìdárayá nínú ilé, èyí yóò máa mú kí ara rẹ balẹ̀ tí yóò sì mú ọkàn rẹ kúrò níbi ẹ̀rù.
Sáájú, ló si ilé iṣẹ́ tirẹ̀, Mag Divas Boutique tó ti ń ṣe aṣọ tó sì ń ta ọjà láti ọdún 2014.
Ìfẹ́ ati òtítọ́ níí mú kí ọba pẹ́,òdodo níí sì ń gbé ìjọba rẹ̀ ró.
Eeyan mọkanla lo kaarun naa lati ipinlẹ Plateau, mẹfa lati Katsina, marun un ni Kaduna nigba ti mọkanlelogun wa lati Abuja.
Wo àwọn ìlérí tàwọn Gómìnà tuntun ṣe nínú ìbúra wọn Ìtàn tó wà nídi òwe ‘Sebótimọ Ẹlẹ́wà Sàpọ́n’ Àbẹ́wò ọlọ́jọ́ mẹ́ta Trump sí UK nínú àwòrán Ganduje ń bèèrè bí Emir Sanusi ṣe se owó ìlú mọ́kumọ̀ku Atẹjade kan lati ọwọ adari awọn gomina apa ila oorun Naijiria naa, Rotimi Akeredolu sọ pe o ti di oun to pan dandan bayii lati dẹkun iwa janduku to n gbilẹ.
Àwọn òńkọ̀wé ń dárò Okediji tí kò bá pé ẹni ọdún 90 lókè eèpẹ̀ lónìí Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
  Kò dùn tó èyí tí ìyá mi máa ń dín, àmọ́ kò burú jù náà.
gbogbo eniyan lo mo pe, eye okin ki segbe eye keye nigbo, eleyi ti o mu ki iko agbaboolu Super Eagles fiko Guinea paroko sile ninu idije 2019 AFCON to n lo lowo lorile-ede Egypt.
Oun ni obinrin akọkọ ti yoo wọ iwe ẹyẹ Rock and Roll.
Ẹbọ ìmúkúrò ẹ̀bi ẹ̀ṣẹ̀ tí ó dá sí OLUWA ni.
Ǹjẹ́ o mọ̀ pé ọdọ 43m ló wà lára olùdìbò?
Kọmisọnna fun Ajọ eleto idibo INEC ni ipinlẹ Ọyo, Mutiu Agboke ti ni ọpẹlọpẹ isẹ akin ti awọn osisẹ INEC se, ko ba ma si esi idibo fun eto idibo gomina fun ipinlẹ Ọyọ, nitori ko ba ti lọ ni irọwọrọsẹ.
Ẹni tí kò bá sì ní, a óo gba ìwọ̀nba díẹ̀ tí ó ní lọ́wọ́ rẹ̀.
iwosan UCH losan oni  sugbon ti o padanu ẹmi
" Wasiu sọ pe Barrister lo ṣe olulana fun awọn olorin Fuji bi oun, ati pe Barrister ko ku, nitori ohun to ti ṣe silẹ ṣi n fọhun sibẹ.
O gboriyin fun awon olugbe agbegbe Kachia fun ifowosowopo won lolokan-o-jokan si eto awon omo ogun ohun ti won tin se ninu ilu naa lateyin wa.
Ṣugbọn awọn eleto ilera ti n ṣeṣẹ lati ri ogun to le koju arun naa.
Duro Ladipọ, ìlúmọ̀ọ́ká òṣèré tíátà àti ọmọ àlúfà tí kò gbàgbé àṣà ìbílẹ̀ Ìtàn ìgbésí ayé Oshodi, ọmọ Tápà léǹpe tó di akọni ní ìlú Eko Ìtàn Manigbagbe: Àwọn àjakalẹ-àrun to ti wáyé rí ṣáájú Coronavirus Wo àwọn gbajúmọ̀ òṣèré Yorùbá tí kìí ṣe ọmọ káàárọ̀ oòjíire Ǹjẹ́ o mọ àwọn òṣèré bí Oyin Adejọbi, Funmi Martins àtàwọn míì tó ti dágbére fáyé?
Ebuka Obi-Uchendu to kopa ninu apa kinni eto naa lo se atọkun eto, nigba ti Efe Ejeba si jawe olubori lasiko naa.
Oun ni aarẹ ẹgbẹ Young Yoruba for Freedom, YYF, ẹgbẹ kan to ni afojusun oun ni lati tun ìtàn kọ, nipa fifa ẹya Yoruba jade kuro ni Naijiria, lati da orilẹ-ede tuntun Oduduwa Republic silẹ.
Iroyin sọ pe, saaju ni Malami ti fi ẹjọ Magu sun Aarẹ Buhari pe, kii jẹ ki ile iṣẹ oun to jẹ ile iṣẹ to n bojuto ajọ EFCC mọ nkankan nipa ohun to n lọ nibẹ.
Keyamo to fọrọ naa lede loju opo Twitter ṣalaye pe awọn nnkan miiran wa to jẹ amuyẹ fun awọn oludije fun ipo gomina tabi aarẹ gẹgẹ bi akọsilẹ iwe ofin orilẹede Naijiria.
tesiwaju pe ipade ti awon osise ijoba apapo ko da ti ijoba ipinle tabi awon
Ayiloge to jẹ́ kọmisọna fún ọ̀rọ̀ tó n lọ ní ìpínlẹ̀ náà kédé pé òun yóò gbégba ipò gómina dije pẹ̀lú Akeredolu ní ọdun tọ ń bọ.
Aisaya tún bi í pé, “Kí ni wọ́n rí láàfin rẹ?
Ọmọ Nàíjíríà tó jẹ́ Ìmáàmù mọ́ṣálásí tí wọn kọlù ní New Zealand ṣàlàyé ìṣẹ̀lẹ̀ Bàbá ọmọ tí Mammadou Gassama dóòlà ẹ̀mí rẹ̀ lọ ẹ́wọ̀n France kéde àfikún owó oṣù lẹ́yìn ìwọ́de alágbára Ọwọ́ pálábá ségi fún gbajúgbajà olè méjì tó ń ṣọṣẹ́ lọ́wọ́ l‘Eko APC, n kò ní yí èsì àtúndì ìbò fún yín, ẹ ṣiṣẹ́ kára -Buhari Amọ bi ẹni to sisẹ ibi yii ti ṣe n gba eebu ati abuku, ni awọn kan n gba oriyin fun iwa akin ti wọn wu lasiko ati lẹyin iṣẹlẹ naa.
Ọ̀jọ̀gbọ́n àgbà, Moses Mabayọjẹ ló ṣe àgbékalẹ̀ gbólóhùn yìí sí orí ìwé-ìmọ̀ ọ̀fẹ́ tí nbẹ lórí Ayélukára tí wọ́n npè ní Wikipedia.
Àwọn àgbá mẹrẹẹrin ní ojú yíká wọn.
Orí mi wú, ọmọ Nàíjíríà 16 gbàmì ẹ̀yẹ nínu akẹ́kọ̀ọ́ fásitì 27 l‘òkè òkun Poly Rufus Giwa, Owo di títì pa di ọjọ́ míì Sobaloju ni, sááju ni ilé ẹjọ ti pàṣẹ fun Makinde lati máṣe tú àwọn alága ijọba ìbílẹ̀ náà ka, sùgban gómìnà kọti ọgbọnin si aṣẹ náà, ní kéte ti wọ́n bura fún-un wọle tan.
N óo rán àjàkálẹ̀ àrùn láti pa gbogbo wọn run, n óo sì kọ̀ wọ́n sílẹ̀, ṣugbọn n óo sọ ọ́ di baba orílẹ̀-èdè tí yóo pọ̀ ju àwọn wọnyi lọ, tí yóo sì lágbára jù wọ́n lọ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Iriwisi Tunde,oludokowo lori MMM MMM sọ pe awọn ti pa ilana da ninu eto tuntun yii, ati wi pe dipo eniyan, rọbọọti ni yoo ma ṣakoso bi nkan ṣe n lọ.
Ó ní, “Òní ni mo di ẹni ọgọfa ọdún (120), kò ní ṣeéṣe fún mi mọ́, láti máa fò síhìn-ín sọ́hùn-ún.
Ninu atẹjade kan to fi sita lọjọ Aiku, Tinubu ni arun a ti dije fun ipo oṣelu lọdun 2023, lo n ṣe awọn ọmọ ẹgbẹ APC to fẹ yọ Oshiomole nipo alaga.
Bello ní ó ṣe pàtàkì ki àwọn ọmọ ọ̀dọ́ ayé òde òní gbé ìgbésẹ̀ tó yẹ láti mú àyípadà rere bá orílẹ̀-èdè yìí.
Sobaloju sàlàyé fún ile ẹjọ́ pe, iwé ìpẹ̀jọ láti da gomina duro lóri aṣẹ̀ náà ní wọ́n gbé wá silé ẹjọ ni ọjọ kẹwàá oṣù kẹfa.
Ọdọmọkunrin to fọ ẹyin mọ aṣofin lori ni Ausralia Will Connoly ni orukọ ọmọkunrin to fọ ẹyin mọ asọfin orileede Australia kan, Sẹnatọ Fraser Anning lori, nibi ti o ti n sọrọ.
Ṣé o bá a láàrin àwọn ọlọ́ṣà ni,tí ó fi jẹ́ pé nígbàkúùgbà tí o bá ń sọ̀rọ̀ rẹ̀, ń ṣe ni o máa ń mi orí rẹ?
Ọwọ́ ọlọ́pàá tún tẹ afurasí tó fipá bá odi àti adití lòpọ̀ nílùú Ibadan Èèmọ̀!
Wọn ni iru anfani bẹẹ wa lati fi gba iwe irinna ati pe o ti wa tipẹ ṣugbọn awọn eeyan ko lo anfani ọhun ni.
Bí o bá rí owó nínú àpótí a ka gbogbo rẹ̀ fún ni, ìgbà tí o mú wa dé ibi tí wọ́n ti ń ṣe igbọ̀nẹ̀ o tun ń fẹ lọ fi Ìgbọ̀nsẹ̀ gan-an han ni, a bá kọ̀ fún un.
Ikú Arẹwa: Ìdíje omidan to rẹwà jùlọ ló fẹ́ kopa nínú rẹ̀
Àwọn ọ̀rọ̀ apanílẹ̀rín tí Mugabe sọ tó jẹ́ mánigbàgbé Ọ̀pọ̀ ń gbé nínú ìbẹ̀rù ní South Africa ́lọ́wọ́lọ́wọ́ báyìí"" Ìdájọ́ ọmọ mi tó gbé àdó ìkú wọ bàálù le púpọ̀, ẹ bá mi wòó ṣe - Bàbá Mutallab O ni awọn ọrọ rẹ naa lee jẹ ki wọn maa gboju agan sijọba ipinlẹ Ọsun abi gomina Adegboyega Oyetọla, ẹni to maa n tete kọbi ara sawọn ọrọ to ba jẹ mọ ti osisẹ."
Arakunrin kan ti orukọ rẹ lori Twitter n jẹ @RaySensualCalls ni ko si ofin l'orileede Naijiria ati pe ọrọ to wa nilẹ yi dabi ọrọ Yoruba to sọ pe amúkùn ún, ẹru rẹ wọ, to ni oke lẹ n wo, ẹ ko wo isalẹ.
Ike pẹlẹbẹ tí kò tóbi ju bí èkana ọwọ́ lọ ni.
Iṣẹlẹ naa la gbọ wi pe o waye ni ilu Gajaja, ijọba ibilẹ Danbatta, nipinlẹ Kano.
Adura lori oke Arafa lo lọla julọ: Gbígba àdúrá nígbà tí èèyàn bá wà l'Árafat ni àdúrà tó lọlá jù lágbáyé.
Ó bá sọ fún àwọn ẹrú rẹ̀ pé, ‘A ti parí gbogbo ètò igbeyawo, ṣugbọn àwọn tí a ti pè kò yẹ.
" Awọn kan ni ki ijọba apapọ ṣe iru akitiyan to ṣe si ipaniyan to n waye l'awọn ibomi i ni Zamfara naa.
BBC Yoruba n parọwa pé ki a jẹ ki awọn ewe iwoyi mọ sii nipa itan ati awọn ohun ajogunba ilẹ Yoruba.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Kengbe Ilorin: Àṣà ẹ̀yà Fulani, Bariba àti Gambari tó dàpọ̀ mọ́ ti Yoruba Lara awọn okoowo to dawọle ni ibudo ounjẹ Jolly makers ati Happy day food canteen, sise burẹdi Deluxe ati Goodluck, ibudo agẹrun ati ile igbalejo, Guest house.
Super Falcons fi South Korea ṣ’ẹ̀bùn June 12 fún Nàìjíríà Victor Moses, Oshoala gba ami ẹyẹ CAF kéde orúkọ àwọn olùdíje àmì ẹ̀yẹ agbábọ́ọ̀lù Áfíríkà France Vs Nigeria: Super Falcons takú síbẹ̀, àmọ́ ẹ̀pa kò bóró mọ́ O ti gba bọọlu fun ẹgbẹ oriṣii meje ni ọpọlọpọ orilẹ-ede agbaye.
Ní ti àwà ọmọdé- ilé, ènìyàn pàtàkì ni ó jẹ́ fún wa, a sì ní ìfẹ́ rẹ̀ lọ́pọ̀lọpọ̀.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Abiọla ti jẹ́ olùdárí iwe ìròyìn Trumpeter rí ti Obasanjọ sì jẹ́ igbákejì rẹ̀ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Abiọla ti jẹ́ olùdárí iwe ìròyìn Trumpeter rí ti Obasanjọ sì jẹ́ igbákejì rẹ̀ 15 Òkùdu 2018 Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí 2 sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 2:23 Fídíò, Water Generator: Ó leè ṣiṣẹ fún wákàtí mẹfà, kó tó sinmi, Duration 2,2310 Òkùdu 2020 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
Kwara ni ipinlẹ akọkọ to lawọn yoo tẹle ipaṣẹ Eko.
Ṣugbọn Saulu fa ẹ̀wù àwọ̀lékè rẹ̀, ó sì ya.
Ko gbọdọ si lilọ bibọ ọkọ ati ero kankan ni gbogbo awọn agbegbe to wa nipinlẹ Eko yatọ si awọn onisẹ kose maase nikan.
O ma n fi owe sọrọ ni lati igba ti iroyin naa ti jade ni bi oṣu diẹ sẹyin.
Dide nlẹ, ma fọwọ ọla tẹlẹ Oríṣun àwòrán, @ekitistategov Lẹyin naa ni awọn aworan miran tun fi wọn han nibi ti wọn ti jọ joko, n ka iwe kan to jọ lẹta ti Alaafin ti kọkọ kọ si Fayemi, lori ọrọ kan to sọ pe oun yoo rọ awọn ọba Ekiti l'oye."
ỌJỌ́ KẸTA LỌ̀DỌ̀ BABA-ONÍRÙNGBỌ̀N-YẸ́ÚKẸ́ Ẹ́NI TÍ Ń GBÉ IBI GEGELE ÒKÚTA
Link Coronavirus: Kíni àwọn àmì tuntun tó n fihàn?
Bí ó ti lẹ̀ jẹ́ pé Spiny Babbler náà ti fa àwọn onímọ̀-nípa-ẹyẹ àgbáyé mọ́ra fún ọdún pípẹ́, ìbàjẹ́ àyíká ti ń ṣe ìdẹ́rùbà àkàndá, ẹyẹ tí àwọn ènìyàn fẹ́ràn yìí.
Ìgbéraga rẹ ti tàn ọ́ jẹ,ìwọ tí ò ń gbé inú pàlàpálá òkúta,tí ibùgbé rẹ wà lórí òkè gíga,tí o sì ń wí ninu ọkàn rẹ pé, ‘Ta ni ó lè fà mí lulẹ̀?
 Ó sọ wípé oun kò ní ìpinu láti ta àwòrán yìí , nítorí oun ni ìyàwó rẹ ̀ fẹ ́ ràn jùlọ .
Ikolu ohun ni awon toro naa soju won wi pe, o waye lataari erongba awon omo ogun olote al-Shabab lati mu ki awon ara ilu Halfoley, abule ti o fara pe agbegbe Jalalaqsi, ni ekun Hiran sanwo ori ni tipatipa.
Lati igba ti o ti bẹrẹ iṣẹ rẹ, yoo ti le ni ọgọrun un fidio agbelewo ti o ti ṣe.
Nígbà náà ni Eliakimu, ọmọ Hilikaya ati Ṣebina ati Joa sọ fún Rabuṣake pé, “Jọ̀wọ́, bá àwa iranṣẹ rẹ sọ̀rọ̀ ní èdè Aramaiki nítorí pé a gbọ́.
Funmilayọ ni akẹkọbinrin akọkọ to lọ sile iwe Abẹokuta Grammar School.
Ninu ọrọ ti alukoro ọlọpaa ipinlẹ Eko, Muyiwa Adejobi fi sita, o ni wọn ri ọpa aṣẹ naa ni agbegbe Abule Ado, nipinlẹ Eko.
Cardiff fọ́wọ́ òsí júwe Europa fún Manchester United 12 Èbibi 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Europa League ní Manchester United o pada fàbọ̀ sí oo Kíní káti gbọ́ pé Cadiff ló fẹ̀yìn Manchester United gbolẹ̀ nínú ìdíje Premier League, ẹni ti a rò pé kò le pàgọ́ tó ń kóle alárinrin lọ̀rọ̀ náà jẹ.
O sọ pe fun ẹlomiran, yiyan ale le ma dùn ún.
Yóo sọ̀rọ̀ òdì sí Ẹni Gíga Jùlọ, yóo sì dá àwọn eniyan mímọ́, ti Ẹni Gíga Jùlọ lágara.
Ni ọdun mejeeji yi, osu kinni ọdun ni ikọlu Boko Haram peleke julọ, ti ọwọja wọn si rinlẹ pupọ eyiun lẹyin ti aarẹ Muhammadu Buhari ti ni oun ti ri opin ikọ naa.
Victor Giadom: Iléẹjọ́ gíga pàṣẹ pé kí Giadom jẹ adelé alága APC Victor Giadom gbàṣẹ iléẹjọ́ gíga láti jẹ adelé alága APC Igbakeji akọwe apapọ agba ẹgbẹ oṣelu APC, Victor Giadom ti gbaṣẹ lati ileẹjọ eyi to fun un lanfaani lati maa tukọ ẹgbẹ naa gẹgẹ bi adele alaga gbogbogbo APC.
"Sheikh Isola tun salaye siwaju lori awọn apemọ orúkọ tabi oye ẹṣin ti ọpọ musulumi n jẹ bii Malam, Alfa, Sheikh, Uztas, Imaam, Amir, Amirah ati bẹẹ bẹẹ lọ.
Bí ó bá ṣe pé ẹni tí ó kórìíra mi ní ń gbéraga sí mi,ǹ bá fara pamọ́ fún un.
Eyi ṣe pataki nitori bi o ba nilo itọju.
A máa ba níbùba bí olè,a sì máa sọ ọpọlọpọ ọkunrin di alágbèrè.
Nítorí bí ọ̀rọ̀ tí ó ti ẹnu àwọn angẹli sọ bá fẹsẹ̀ múlẹ̀, tí gbogbo ìwà àìṣedéédé ati ìwà àìgbọràn bá gba ìbáwí tí ó tọ́ sí wọn, 
Ṣaaju ni wọn ti kọkọ fi ṣikun ofin mu Sunday lori iku Barakat Bello, Azeezat Shomuyiwa ati ọmọdekunrin ẹni ọdun marun un kan lọjọ kẹtadinlogun, oṣu Keje, ọdun 2020.
Èmi fúnra mi ni n óo jẹ́ odi iná tí n óo yí i ká, tí n óo máa dáàbò bò ó, n óo sì fi ògo mi kún inú rẹ̀.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Abayomi Shogunle: Íjìyà tó tọ́ sí Charles Omotosho ni wọ́n dá fún un Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Abayomi Shogunle: Íjìyà tó tọ́ sí Charles Omotosho ni wọ́n dá fún un 1 Owewe 2018 Charles Omotosho jìyà tó tọ́ fún ẹ̀ṣẹ̀ tó ṣẹ̀.
Ẹni tí ó bá kí i di alábàápín ninu àwọn iṣẹ́ burúkú rẹ̀.
Àwọn tí ebi ń pa níí jẹ ìkórè oko rẹ̀,bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé ààrin ẹ̀gúnni ó ti mú un jáde,àwọn olójúkòkòrò a sì máa wá ohun ìní rẹ̀ kiri.
Mo yára bẹ àwọn ìwin ti ń bẹ lágbègbè ibẹ̀ kí wọ́n bá mi tú Ìbínú-ẹkùn sílẹ̀, kí wọ́n sì tó ṣe è’yi tán, mo ki iré malẹ̀ mo sáré tagbáratagbára.
Ọ̀pọ̀lọ̀pọ̀ wọn ló péjú síbẹ̀, bí wọn ṣe wá péjú yìí bẹẹni àwọn aṣọ aláranbara náà ṣe ń jẹyọ.
Láìkò tí mó wà ni Iseyin District Grammar School, Wọ́n wá ṣere nílé ìwé wa, ibẹ̀ ni a ti di ọ̀rẹ́, nígbà tí ó yá, ni a jọ ṣe ìgbéyàwó ti mo sì bẹ̀rẹ̀ sí ní ràn lọ́wọ́ bi ìgbákejì pídánpidán."
"Oríṣun àwòrán, Getty Images ""Covid-19 yóò nípa burúkú lórí àwọn ọmuti alamupara, bẹ́ẹ̀ si ni nilẹ South Africa, àwọn èèyàn ń gbé ní àgbègbè tó kún fún èrò"" Nítorí náà, kata-kara ọtí líle leè mú kí itankalẹ àrùn Covid-19 ni agboolé pọ si, nítorí àwọn èèyàn máa ń ṣe awọmu ni, ó si ṣeé ṣe kí ọwọja ìwà ipá sì abo àti ọmọdé pọ sì"" Ọjọgbọn Parry tún ṣe ikilọ."
Eliṣa sọ fún un pé, “Lọ yá ọpọlọpọ ìkòkò lọ́wọ́ àwọn aládùúgbò rẹ.
Ọpọ̀ èèyàn ní kó mọ pẹ pápákọ̀ ofurufú ń bẹ nílùú Ibadan- Òṣìṣẹ́ Òwò ẹrú pé irinwó ọdún tó bẹ̀rẹ̀, àwọn Amẹrika tó jẹ́ dúdú wá sí Afirika láti bẹ ilé wò Lọjọru ni iroyin gbode pe, aarẹ igbimọ to wa feto iroyin fẹgbẹ Shiite, Ibrahim Musa fi atẹjade ṣọwọ pe awọn so iwọde naa rọ, ti awọn si ṣetan lati gbe ijọba Naijiria lọ si ile ẹjọ lori bo ti ṣe pe wọn ni agbesunmọmi.
Bótilẹ̀jẹ́pé àwọn ẹ̀yà Maya ti parẹ́ kúrò lórí ilẹ̀ ayé ní nkan bíi ẹgbẹ̀rún ọdún sẹ́hìn, òkìkí wọn ti kàn gidi gidi lọ́dúnnìí nítorí ọ̀rọ̀ àsọtẹ́lẹ̀ wọn yìí.
Ẹgbẹ oṣelu APC ni ipinlẹ Ondo ti ni lootọ ni pe, ajọ INEC da lẹta ifitonileti nipa eto idibo abẹle ẹgbẹ naa nipinlẹ Ondo nu.
Awọn onimọ nipa ilera ọpọlọ, eleto ilera, pasitọ ati imaamu, ara ilu, ati awọn ajafẹtọ ọmọniyan, ni yoo wa ninu igbimọ naa.
Asán ni ìgbẹ̀yìn gbogbo ohun tí ń bọ̀ wá ṣẹlẹ̀.
 Leyin re ni mo ni anfani lati teko leti lo sile okere lati tesiwaju ninu ebun ere-idaraya naa.
A ti mọ òbí 40 nínú 108 t'ọ́mọ wọn bọ́ ní ayédèrú ibùdó atúnwàṣe Ilorin - Ọlọ́pàá Kwara Adajọ ileẹjọ giga apapọ orilẹ-ede Naijiria ni ilu Akurẹ ni Onidajọ Dogo.
Nígbà tí yóo fi di ọjọ́ kinni oṣù kinni, wọ́n ti parí ìwádìí lórí gbogbo àwọn tí wọ́n fẹ́ obinrin àjèjì.
Awọn onwoye ni igbesẹ yi ko ṣẹyin bi awọn ọlọpaa ilẹ Gẹẹsi ti ṣe doola ẹmi Umaru Dikko ti ijọba Naijiria fẹ fipa gbe lati pada wale wa jẹjọ ajẹbanu.
Olukayode Abimbola Thomas to ti jẹ ọmọ igbimọ AFN tẹlẹ ri ṣalaye fun BBC pe ki saa igbimọ awọn to pari, bi ọrọ a sanwo, a ṣi owo fi ranṣẹ ti a sọ loke yii, bẹẹ gẹlẹ lo ri.
Ademọla Nurudeen Adeleke tó ń ṣojú ẹkùn ìdìbò Ìwọ̀ Oòrùn ìpínlẹ̀ Ọṣun ni wọ́n fi ẹ̀sùn kàn wí pé kò kẹ́kọ̀ọ́ jáde ní Fásitì Jacksonville State University(JSU).
Abimbọla oyeyẹmi to jẹ agbẹnusọ ajọ ọlọpaa ni ipinlẹ Ogun ni awọn agbofinro ko mọ nipa owo itanran ati ohun jijẹ yii rara.
Orúkọ ọmọge yìí ni fìlísíà Olówólàgbà.
Ó tún wí fún un pé, “Mo fẹ́ kí ẹ mọ̀ dájúdájú pé, ẹ óo rí ọ̀run tí yóo pínyà, ẹ óo wá rí àwọn angẹli Ọlọrun tí wọn óo máa gòkè, tí wọn óo tún máa sọ̀kalẹ̀ sórí Ọmọ-Eniyan.
Awọn to ni aarun coronavirus ni Naijiria ti pọ si bayii, lẹyin ti ajọ NCDC tun kede okoolelọọdunrun din meje eeyan ti esi ayẹwo wọn ṣẹṣẹ jade.
''O ni ki n fi dáàbò èmí mi, kín sí lò wọn fún ìpolongo ìdìbò mi lodun 2014 ni '' 'Ìyapa láàrin àwa araalu àti awọn oloselu ti pọju'' Adetokunbo Mumuni, to je Olùdarí àjọ ajàfètọ́ ọmọnìyàn kàn lorílè-èdè Nàìjíríà, SERAP ní, òun ko ro wí pé lóòótọ́ ni Senato náà fe fi àwọn ọkọ naa doola ẹmi re.
Nítorí náà, kí gbogbo olódodo máa gbadura sí ọ;ní àkókò tí ìpọ́njú bá ń yí lura wọn bí ìṣàn omi ńlá,kò ní dé ọ̀dọ̀ wọn.
Kò y'é ni ìhà tó kọ́kọ́ bẹ̀rẹ̀ ìwà ipá náà bẹ́ẹ̀ sì ni àwọn ọlọ́pàá kò tíì fèsì.
Iléeṣẹ́ ológun ti yabo ibùdó àwọn jàndùkú tó jí àwọn akẹ́kọ̀ọ́ gbé níléèwé katsina- Garba Shehu Gomina naa sọ pe adura awọn eeyan lo n gba lori abẹṣekubiojo naa ti ade IBF, WBA ati WBO ko tii fi bọ mọ lọwọ.
Eeyan 9,007 lo ti ri iwosan gba, nigba ti awọn 565 ti dero ọrun nitori arun ọhun.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Gomina Ambode buwọlu aba isuna ti o le ni trillionu kan naira 27 Èrèlè 2018 Oríṣun àwòrán, @AkinwumiAmbode Àkọlé àwòrán, Gomina se ileri lati se awọn akanse isẹ tuntun Owo to le diẹ ni triliọnu kan naira ni ipinlẹ Eko yoo na fun isuna rẹ lọdun 2018.
Àwọn orílẹ̀-èdè kò ní yọ idà sí ara wọn mọ́,wọn kò sì ní kọ́ ogun jíjà mọ́.
"Ìyá gómìnà Seyi Makinde dágbére fáyé lẹ́ni ọdún 81 Gbọ́ ìtàn bí ikọ̀ SARS ṣe dà bó ṣe dà láti ẹnu Ọ̀gá ọlọ́pàá tó dá SARS sílẹ̀ Ìjọba kéde ọjọ́ ìwọlé àwọn àgùnbánirọ̀ sí ìpàgọ́ lẹ́yìn Covid 19- Sunday Dare #EndSARS: Àwọn olùwọ́de kọ etí ikún sí àṣẹ ijọba, wọ́n tẹ̀sìwájú ìwọ́de l'Abuja Kanye West, Ozil, Boyega, àti àwọn gbajúmọ̀ ilẹ̀ okèèrè tó ṣàtìlẹyìn fún ìpolongo #ENDSARS ""Owó tà ń ná láti ṣe Garri tà kìí ṣe kékeré""."
Oríṣìíríṣìí ẹja ni yóo wà níbẹ̀ bí ẹja inú Òkun Ńlá.
Ninu oro oludari agba ile-ise LADOL, dokita Amy Jadesimi, so fun aare pe afojusun ile-ise naa ni lati fa oju awon olokoowo labele ati loke okun mora  lati din owo ti n won na lori epo robi ku.
O ni: Laisi atileyin ipinlẹ Eko ni, ipade naa ko ni yọri si rere nitori gomin ayii maa n pese iranlọwọ fun wa loorekoore ni”.
Ti apẹẹrẹ arun Coronavirus ko ba buru ju nkọ?
" Aworan atọnisọna Iye awọn to ti ni arun naa lagbaye Sunmọ aworan Àgbáyé Orilẹede Afrika Ariwa Amẹrika Apa Latin Amẹrika ati Caribbean Ilẹ Asia Ilẹ Yuroopu Agbegbe Middle East Erekusu Oceania Fihan 93418283 iye iṣẹlẹ arun naa 2000905 Iye awọn to ku Group 4 Jọwọ ṣe atunṣe ilana ikansi ayelujara rẹ lati ri ẹkunrẹrẹ rẹ Aworan n ṣafihan awọn ti ayẹwo ti fi han lorilẹede kọọkan Orisun: Johns Hopkins University atawọn ajọ eto ilera ilu Igba ti wọn kede iṣiro awọn to nii kẹyin 15 Oṣù Ṣẹ́rẹ́ 2021 20:44 WAT+3 Ẹkunrẹrẹ data Sun atẹ wa silẹ tabi oke lati ri ẹkunrẹrẹ akọsilẹ *Iye awọn to tọwọ aisan ku ni isọri eeyan ẹgbẹrun lọna ọgọrun Gbe e yẹwo: Àgbáyé Orilẹede Afrika Ariwa Amẹrika Apa Latin Amẹrika ati Caribbean Ilẹ Asia Ilẹ Yuroopu Agbegbe Middle East Erekusu Oceania Iye to ti ku Iye awọn to ku %* Apapọ awọn iṣẹlẹ arun Akọtun arun yii 0 10 100 1000 10000 ** Orilẹede Amẹrika 387741 118.
foju si ona o gbabe rara.
Awọn nkan meji yii ni ibaṣepọ pẹlu jẹjẹrẹ.
Bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé OLUWA rán àwọn wolii sí wọn láti darí wọn pada sọ́dọ̀ rẹ̀, tí wọ́n sì ń kìlọ̀ fún wọn, wọ́n kọ etí dídi sí àwọn wolii.
Gomina Oyetọla darapọ mọ awọn oluwọde naa lẹnu irin ti wọn n rin lati agbegbe Alekuwọdo si Ọlaiya to si n ba wọn kọrin pẹlu ileri pe gbogbo ẹdun wọn ni oun yoo gbe yẹwo.
 Mo n ro omode, odo ati agba lati sise papo fun ayipada rere fun ekun yii”Dickson gba ajo NDDC nimoran lati pese owo sile fawon ise aknse bi o ti ye.
Àkọlé àwòrán, Iwe yii lo ti jade fun lilo bayii, ki gbogbo omo Oodua lo ra ki a le tun ni imo kun imo nipa eya ara eniyan ati ti eranko ni ede abinibi wa gege bi awon ojogbon onimo kikun ninu ilera eda ati ede Yoruba ni fasiti Ibadan se gbee jade loni Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Ìdí akitiyan mi ni pé kí Ọlọrun lè mu yín ní ọkàn le, kí ó so yín pọ̀ ninu ìfẹ́ ati ọrọ̀ òye tí ó dájú, kí ẹ sì ní ìmọ̀ ìjìnlẹ̀ àṣírí Ọlọrun, tíí ṣe Kristi fúnrarẹ̀.
Ọgbẹ́ni Prasek, ẹni ọdún mẹ́tàlélọ́gbọ̀n, ra kìnìún lọ́dún 2016, o tún wa ra abo ni ọdun to kọja, to si kó àwọn méjèèjì pọ̀ sinu àgò kannáà lẹ́yìnkùlé rẹ ni abúle Zdechov.
o sunmọ ọdun mẹrin si mẹfa ki eyan to le jẹ akosemose nidi ere idaraya yi nito ri pe ere ayara bi asa ni.
 Àwọn tí ó ń sọ ọ ́ tó mílíọ ̀ nù lọ ́ nà igba gẹ ́ gẹ ́ bí èdè abíníbí ní àríwá aáfíríkà àti ìlà-oòrùn-gúsù eésíà ( asia ) .
Lẹ́hìn ìgbà tí ó bá sì tóó nà mi tán a lọ sí ibi tí òkú olùfẹ́ rẹ̀ wà nínú ihò, nígbà tí ó bá dé ibẹ̀, a sọ ọ̀rọ̀ wọ̀nyí, a wí pé: Ọ̀rẹ́ mi ayé, ọ̀rẹ́ mi ọ̀run, ọjọ́ wo ni ìwọ ń bọ̀ wáá rí mi?
“Nígbà tí àwọn ọmọ yín bá bèèrè lọ́jọ́ iwájú pé, kí ni ìtumọ̀ àwọn ẹ̀rí ati ìlànà ati òfin tí OLUWA pa láṣẹ fun yín.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Oniruuru awọn aarẹ orilẹede Afirika ni o ti ṣiṣẹ fun gẹgẹ bii olubadamọran ptataki Lasiko to fi jẹ minisita feto ẹkọ ni Oby, gẹgẹbi ọpọ ṣe maa n pe e, ṣe eto atunto ẹka eto ẹkọ lorilẹede Naijiria ninu eyi ti spọ awọn orilẹede Afirika mira ti ya lo bayii.
Ọlọrun ní, “Má ṣe súnmọ́ tòsí ibí, bọ́ bàtà ẹsẹ̀ rẹ, nítorí pé, ilẹ̀ tí o dúró sí yìí, ilẹ̀ mímọ́ ni.
Àjò ní ààrẹ Tunísia nígbà kan rí kú sí.
Ko si aniani pe awọn wolii wọnyii ni ipa pupọ ninu ironu awọn eeyan lorilẹ-ede Naijiria ọpọ lo si maa n gba gbogbo ohun ti wọn ba n sọ gbọ lorilẹ-ede Naijiria.
Njẹ awọn olori ẹlẹsin wọnyi jana nipa asọtẹlẹ wọn abi ofutufẹtẹ lasan ni iriran wọn jẹ?
Lẹ́yìn náà, ó dìde, ó rìn síwá sẹ́yìn ninu ilé náà, ó tún pada lọ nà lé ọmọ náà.
Gadi bá lọ sọ́dọ̀ Dafidi ó lọ sọ fún un pé, “OLUWA ní kí o yan èyí tí o bá fẹ́ ninu àwọn nǹkan mẹta wọnyi: 
Ni adánniwò bá yọ sí i, ó sọ fún un pé, “Bí Ọmọ Ọlọrun bá ni ọ́ nítòótọ́, sọ fún àwọn òkúta wọnyi kí wọ́n di àkàrà.
Nítorí mo jẹ́rìí yín pé bí ó bá ṣeéṣe nígbà náà ẹ̀ bá yọ ojú yín fún mi!
Wọn ti gbe wọn pada si ilu wọn a si n pe wọn lori ago lai si iyọnu kankan."
Èyí ni bí àwọn ọmọ̀dé 20 ṣe kú sínú kànga ní Kano
Ó dì í mú,ṣugbọn kò lè mú un dúró.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Osinbajo: Ikẹnnẹ yẹ kó jẹ́ Mẹ́kà òṣèlú ni Day 25: Àwọn àkànlò èdè lásìkò ìdìbò #BBCNigeria2019 Ohun márùn ún tí o kò mọ̀ nípa òfin tó dáàbò bo àwọn àkàndá Tani Ọjọgbọn Mahmood Yakubu ti yóò ṣètò ìdìbò 2019?
Oríṣìíríṣìí nkan olókìkí ló ti ṣẹlẹ̀ ní Naijiria àti ni gbogbo àgbáyé.
Ṣugbọn ọkunrin talaka yìí kò ní nǹkankan, àfi ọmọ aguntan kékeré kan tí ó rà, tí ó sì ń tọ́jú títí tí ó fi dàgbà ninu ilé rẹ̀, pẹlu àwọn ọmọ rẹ̀.
Lasiko ti arun naa fi n gberu yi,iyen asiko ti eeyan fi n ko si igba ti apẹrẹ yoo fi han a ma yatọ lara eeyan kan si ẹlọmiran sugbọn o kere tan yoo yọju laarin ọjọ marun.
Àwọn olè ń fọ́lé, àwọn jàgùdà sì ń jalè ní ìgboro.
Ọjọgbọn Akintoye ni igbimọ Yoruba lagbaye, Yoruba World Congress gba alaafia laaye ninu iṣe rẹ gbogbo, ti ko si fa ijangbọn kẹsẹ rara.
Bí ebi bá ń pamí oo
Oríṣun àwòrán, Garba Shehu Eyii tun n tumọ si pe iye gbese ti Naijiria jẹ ga soke sii ni ida aadọjọ.
    Ìgbà tí Èṣù parí ọ̀rọ̀ rẹ̀ yìí, Adéforítì rí i pé àkókò ti lọ, ó wí fún Èṣù kí ó mu òun lọ sí ọ̀dọ̀ àwọn lébìrà tí òun ń fẹ́ nítorí òun fẹ́ tètè padà.
Lẹyin ti wọn ki ara wọn tan ni aare Buhari, Ọbasanjọ ati Goodluck Jonathan wa se ipade idakọnkọ, ki wọn to lọ si yara ipade igbimọ majẹkobajẹ ilu.
apero ajo agbaye to n lọ lọwọ ni ilu New York lojo Isegun.
Eleyi jẹ́ ikan ninú idi pàtàki ti ọ̀pọ̀lọpọ̀  Agbejoro ti fẹ́ fi ọ̀nàkọnà dé ipò “Ọ̀gá Àgbà Agbẹjọ́rò”.
Lẹ́hìn èyí, ó kọ ọkọ rẹ̀ sílẹ̀, fún odidi ọdúnmẹ́rìnlélógójì ni Àrùn sì fi ń ṣe ìyàwó Èṣù tí ó jẹ́ ọba ìlú Ọ̀run Àpáàdì ṣùgbọ́n nígbà tí ó di oṣù karùn-ún, ní ọjọ́ kọkàanlá, ní ọdún kẹrìnlélógójì, ó sá kúrò ní Ọ̀run Àpáàdì nítorí ó wí pé èéfín iná Ọ̀run àpáàdì pọ̀ jù ní ti òun.
Ninu oṣu kọkanla ni Rahama gbayi lori google tori awọn fọto rẹ to fọnka sorii ayelujara.
Eyi lawọn ibeere to jẹ yọ lẹyin ti ileeṣẹ ajọ to n pin ina ọba nipinlẹ Eko, Eko Electricity Distribution Company, buwọlu iwe adehun kan pẹlu awọn olugbe kan lagbegbe Magodo Estate.
- Amẹ́ríkà fọnmú Nnkan bi ọdun kan o le diẹ sẹyin ni wọn kọkọ pade, ṣugbọn awọn to n ri si ija naa ni ọmi ni wọn ta lọjọ naa lọhun.
”Wọ́n wá wí fún afọ́jú náà pé, “Ṣe ara gírí, dìde, ó ń pè ọ́.
Ẹ wo àwòrán tó làmìlaaka níbi ọjọ́ ìbí Gomina ìpínlẹ̀ Ọyọ Yinka Ayefele di asojú Àjọ INEC Goodluck Jonathan kí Ààrẹ Buhari kú ọjọ́ ìbí Àjọ Òsìsẹ SSANU bẹ̀rẹ̀ ìyansẹ́lódí ní ọjọ́ Ajé Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Gbogbo ènìyàn ló wọ agbádá ikú, ẹni tó kàn lẹnìkan kò mọ̀ Ẹ̀kọ́ inú ìdíje náà Kò sí ìgbà ti ikọ agbabọọlu meji to gbona bii Liverpool ati Manchester United a pade ti gbogbo eniyan kò ni mọ pe irin lo ko irin.
Sisọ itan, alọ apagbe ati Ijala jẹ ohun amuyẹ orilẹ ede naa.
 níwọ ̀ nba , àwọn olóòtú gbọ ́ dọ ̀ ḿa bọ ̀ wọ ̀ fún ara wọn .
O gbọdọ mu iwe to jẹ ẹri idaniloju pe o ti sanwo ni tootọọ pẹlu fọọmu ti o fọwọ si lọ si ọfiisi FRSC.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Masturbation: Ire ni àbí ibi fún ìlera ẹ̀dá?
OLUWA ní,“Ègún ni fún ẹni tí ó bá gbẹ́kẹ̀lé eniyan,tí ó fi ẹlẹ́ran ara ṣe agbára rẹ̀;tí ọkàn rẹ̀ yipada kúrò lọ́dọ̀ èmi OLUWA.
Ibẹ̀ ni olódodo yóo ti lè sọ ti ẹnu rẹ̀,yóo sì dá mi sílẹ̀ títí lae.
"Ijọba ìbílẹ̀ Takai ni mo wà ti gbogbo ǹkan sì ń lọ létòletò, ẹ gbagbé gbogbo àwọn ọ̀rọ̀ ti ẹgbẹ́ alátako ń sọ Ní Kano, wàhálà àwọ̀n jàǹdùkù, àìtètèdé òṣìṣẹ́ ìdìbò ń dá àtúndì ìbò dúró Eto idibo ko tete bẹrẹ ni nnkan bii ida ọgọrin ninu ọgọrun awọn ibudo idibo ti atundi idibo ti yẹ ko waye lọjọ abamẹta.
Ó bẹ̀rẹ̀ láti òwúrọ̀ títí di àkókò tí ó yàn jákèjádò ilẹ̀ Israẹli.
Tilu tifọn ni awọn eeyan ilu Ọwọ fi jade lẹyin ti wọn gbọ ikede orukọ ọba wọn tuntun naa.
Ṣé olorì ṣì ni Badirat Ọla láàfin ikú bàbá yèyé?
Lẹyin to bimọ tan lo wa sọ asiri ọna to gba bi ọmọ eyi to ni ko sẹyin egboogi ibilẹ kan to pe ni agbo Lati igba naa si lo ti n polowo egboogi yii fun awọ̀n eeyan to n woju Ọlọrun fun ọmọ tiwọn pe ki wọn wa ra agbo naa, ki lọ ayọ lee sọ ninu wọn.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ọwọ́ ba ọlọ́pàá mẹ́rin tó pa ọmọ Nàíjììrà ní S.
 Ọ ̀ pọ ̀ àwọn agbègbè náà sì ni àrù yìí tún ti gbilẹ ̀ sí i títí dé ọdún 2014 .
A bi Lewis lodun 1920 nilu London, o bere ise gege bi osere lewe ko to bere si ni dari awon ere to nii se pelu ogun jija bii Carve Her Name with Pride, ko to dari awon ere akoni James Bond bii You Only Live Twice, The Spy Who Loved Me ati Moonraker.
Àwọn ọbá aláye ilẹ̀ Yorùbá márùn-ún pẹ̀lú ọ̀pá àṣẹ wọn Ìwọ́de EndSARS kìí ṣe ọ̀rọ̀ ẹlẹ́yàmẹ̀yà, ara ti kan àwọn èèyàn ni - Afenifere Buhari kọ́ ni ìṣòro wa, bó ṣe wà láti láéláé rèé - Fr Mbaka Àwọn ọ̀dọ́ fi ọ̀nà àrífín pe Tinubu lórí aago àmọ́ ó ní òun kò mọwọ́-mẹsẹ̀ nípa ìpànìyàn Lekki Á ràgà bo CCTV Lekki bí i ẹ̀rí tó dájú fún ìwádìí ìpànìyàn - Sanwo-Olu SERAP gbé ìjọba àpapọ̀ lọ ilé ẹjọ́ àgbáyé ICC lọrí ẹ̀sùn ìpànìyàn Ajọ NBC sọ pe awọn ileeṣẹ amohunmaworan mẹtẹẹta yii fi awọn fidio nipa ibọn yinyin to waye ni Lekki sita, lai wadii boya otitọ ni wọn tabi ayederu.
Fólúkẹ́ sọ pé aṣọ sáfẹ́ẹ̀tì ni ó wọ̀.
Ṣe ẹ si mọ pe ọrọ ti akuwarapa ba sọ latode ọrun ni, eyi lo si n mu ki ọpọ maa kaya soke lori ọrọ yii.
Dafidi gba àwọn apata wúrà tí wọ́n wà lọ́wọ́ àwọn iranṣẹ Hadadeseri, ó kó wọn lọ sí Jerusalẹmu.
ni eyi ti o ya lọ si Gusu Afirika.
wọ́n rí ìṣe OLUWA,àní iṣẹ́ ìyanu rẹ̀ ninu ibú.
‘Ìfagilé ìwóde ìtagbangba ní Kwara kò bá òfin mu’ Day 15: Ka ìtàn Abdulrahman Abdulrazak tí APC ìpínlẹ̀ Kwara?
Ọpọ eeyan lagbo akada ati lagbo oṣere lo n ṣe ilede lẹyin Baba Adebayo ọmọ Faleti to re iwalẹ asa lọdun mẹta sẹyin.
 Sugbọn, o fi ẹsun kan awọn ọlọpaa pe 'wọn ko bẹrẹ iwadii ni kiakia nitori pe wọn ni baba oun ko fun wọn ni owo lati wu wọn lori'."
 Ìmọ ̀ àisàn nílò àyẹ ̀ wò ẹ ̀ jẹ ̀ bíi àwọn ààmì rẹ ̀ ṣe farajọ àwọn ti ààrùn míìrán .
Mose dáhùn pé, “O níláti jẹ́ kí á kó ẹran tí a óo fi rúbọ lọ́wọ́, ati èyí tí a óo fi rúbọ sísun sí OLUWA Ọlọrun wa.
“siwaju gbogbo ife-eye ti a gba lakoko odun mesan ti o lo pelu wa, Cristiano Ronaldo je agbaboolu kan gbogi ti a ko le gbagbe, O fi apere rere sile, fifarasin, O sise takun-takun abbl.
Obasanjo se'leri lati gbaruku ti ijọba tuntun naa ati wi pe nigbakigba ti wọn ba nilo amọran ohun,oun yoo duro gẹgẹ bi baba fun wọn.
Àwọn tó ní ààrùn Coronavirus ní Nàìjíríà ti pé 29,789 Olórí òṣìṣẹ́ ìjọba ìpínlẹ̀ Kwara, Adisa Logun ti dágbére fáyé lẹ́yìn tó lùgbàdì àrùn Covid-19 Ko din ni eeyan marun un ti wọn ti da ẹmi wọn legbodo lagbegbe Akinyele laarin oṣu Karun un si oṣu Kẹje ọdun 2020.
Ṣugbọn ni bayii, kilo ẹran adiẹ tutu kan ti di apo mẹjọ naira.
Kí wọn má baà mu ún tán, kí wọn gbàgbé òfin,kí wọn sì yí ìdájọ́ ẹni tí ojú ń pọ́n po.
Ọlọrun Olódodo ati Olùgbàlàkò tún sí ẹnìkan mọ́, àfi èmi.
Bí ọkunrin kan tí ń jẹ́ Simoni, ará Kirene, baba Alẹkisanderu ati Rufọsi, ti ń ti ọ̀nà ìgbèríko bọ̀, bí ó ti ń kọjá lọ, wọ́n fi tipátipá mú un láti gbé agbelebu Jesu.
Agbẹnusọ fún gómìnà Zailani Bappah to bá BBC sọ̀rọ̀ sàlàyé pé gómìnà gbé ìgbésẹ̀ yìí nítorí ọ̀rọ̀ ààbò tó dẹnukọla ni pàápàá jùlọ ni ìpínll tọ múlé tì wọ́n.
Pasitọ Ofori to jẹ ẹni ọdun marundinlogoji ni oludasilẹ ile ijọsin Floodgates of Heaven to wa ni adugbo Coburn Avenue, Orlando.
 Àkíyèsí pé láti sọ pé oba bìnrin náà , láà jẹ ́ pé ènìyàn n gbé nílẹ ̀ gẹ ̀ ẹ ́ sì tàbí tí iyè rẹ ̀ sọ pèlú oríle - èdè náà , máà ṣàì nítumọ ̀ .
ni àwọn Juu fi sọ ọ́ di òfin fún ara wọn, ati fún arọmọdọmọ wọn, ati fún àwọn tí wọ́n bá di Juu, pé ní àkókò rẹ̀, ní ọdọọdún, ọjọ́ mejeeji yìí gbọdọ̀ jẹ́ ọjọ́ àsè, gẹ́gẹ́ bí àṣẹ Modekai, 
Alufaa náà yóo wá gbà ninu ẹ̀jẹ̀ akọ mààlúù náà, yóo gbé e wá sinu Àgọ́ Àjọ.
ṣugbọn Matitaya, Elifelehu, Mikineiya, Obedi Edomu, Jeieli ati Asasaya ni wọ́n ń tẹ dùùrù.
Ibrahim Gambari: Olórí àwọn òṣìṣẹ́ lọ́fíìsì Ààrẹ ní oun tí ààrẹ Buhari nílò ni ìjólóòtọ́, ìfọkànsìn pẹ̀lú àtìlẹ́yìn òun
Minisita eto ẹkọ, Adamu Adamu lo kede bẹẹ nibi ipade kan to waye lori ayelujara.
Bákan náà ló fi kún un pé ìjọba yóò ṣe àfilọlẹ̀ ojú raluwe Lagos-Ibadan àti Itakpe-Warri.
Ìfẹnukonu rẹ dàbí ọtí waini tí ó dára jùlọ,tí ń yọ́ lọ lọ́nà ọ̀fun,tí ń yọ́ lọ láàrin ètè ati eyín.
Lórí gbogbo rẹ̀ tálákà ni ìrandiran rẹ̀, wọn kò ní nǹkan kan.
O ṣalaye pe ohun to ṣe koko ni pe ki onibara la oju rẹ silẹ daadaa, ki o si fi iye si nkan ti o ba n ra nipa ọjọ ti iwulo rẹ yoo d'opin.
Mo ran yín lọ bí aguntan sí ààrin ìkookò.
Ṣugbọn ìwọ ní tìrẹ, wọ aṣọ ìgúnwà rẹ.
Orukọ pasitọ naa ni Kolade Arowolo, ti ile ẹjọ si fidi ẹsun iwa ọdaran naa mulẹ pe oun funra rẹ lo pa iyawo rẹ sinu ile wọn.
" Atẹjade kan ti ileesẹ to wa fọrọ ibaraẹnisọ̀rọ lorilẹede yii lo kede bẹẹ nilu Abuja .
N30,000 ni mo gbà fún orí, ọwọ́ àti ẹran ara wòlíì Bosede - Kayeefi Ẹ kọ́ nípa ohun tí Yorùbá ń pè ní Àrígiṣẹ́gi Wọ́n ta ère Ọ̀ṣun Osogbo sí Togo - Bàbá Ọṣun figbe ta Baṣọ̀run Gáà, tó yan ọba mẹ́rin, pa ọba mẹ́rin àmọ́ ọba karùn-ún ló pa á Wọn ni nitori ailera awọn mejeeji ni wọn ko fi le lọ si ileẹjọ fun igbẹjọ lati gba beeli fun wọn lẹẹmeji ọtọtọ bayii.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Omolola Arohunmolase Welder: Mo ti fí iṣẹ́ 'Welder' gbayì láwùjọ, tó mo fi tọ́ ọmọ yanjú Eekan Afenifere naa sọ pe ti ina ko ba tan laṣọ, ẹjẹ kii tan leekanna, o ni oun ṣetan lati pe awọn mejeeji pada lati yanju ọrọ naa.
Àwọn ọmọ Nàìjíríà ṣe ìwọ́de l'Osogbo lórí àfikún owó epo bẹntiróò Èèmọ̀!
gbogbo igbaradi fun isipo-rọpo ti yoo waye ni ojo kokandinlogbon osu karunun   lọ ni irọwọ ati irọsẹ.
Ilééṣẹ́ Facebook leè mọ ìgbà tí àwọn tó wà lójú òpó wọn ń ní ìbálòpọ̀ Ìpínlẹ̀ Ogun fẹ́ fi òfin wọ́gilé ìsìnkú ọba lọ́nà ìṣẹ̀mbáyé Awakọ̀-èrò, ọlọ́kadà farakásá àṣẹ ìjọba Ekiti láti dẹ́kun Coronavirus Ẹ wo ǹkan to sẹlẹ̀ sí ọmọ àti ìyàwó ọmọ Atikú tó lùgbàdì ààrun Coronavirus Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Ó wí fún wọn pé, “Èyí ni ẹ̀jẹ̀ mi tí a fi dá majẹmu, ẹ̀jẹ̀ tí a ta sílẹ̀ fún ọpọlọpọ eniyan.
7 1882 Orilẹede Guinea 81 0.
Ninu àtẹ̀jáde ọ̀ún ni Abdullahi tun ti sọ pe ẹgbẹ́ APC ti sí awọn ìkanni tuntun ti yoo fun awọn olólùfẹ́ wọn, awọn oníròyìn ati gbogbo eniyan lapapọ̀ ní ooreọ̀fẹ́ lati mọ oun to n lọ ninu ẹgbẹ́ òsèlú ọ̀ún.
Lati kekere ni mo ti maa n ran aṣọ fun bebi mii."
lọwọ -lọwọ bayii (All Progressives Congress, APC) ti yan igbimo ti yoo se
Bí o bá lọ ní oyún ní àkókò tí o wà ní ilé- ìwé, ìwọ ni yóò pòfo.
Ǹǹkan márùn ún nínú ilé tó lè ṣe ikú pa ni
Ṣugbọn ko si baba nla rẹ kankan to jẹ awa eedu - o kan ji ọrọ yẹn ati ọpọlọpọ mii lo ni latinu ọrọ oloṣelu ilẹ Britain kan, Neil Kinnock, eyi ti awọn mọlẹbi rẹ jẹ awa eedu.
Joṣua bá súre fún wọn, lẹ́yìn náà, ó ní kí wọ́n pada lọ sí ilẹ̀ wọn, wọ́n sì pada lọ.
Baba rẹ, Aroke Ooduduwa, Olofin Adimula, Ooni Adeyeye Enitan Ogunwusi, Ojaja II, Ooni Ife to ni gbogbo aṣẹ lati fi oju ọmọ naa han fun araye ko tii ṣe bẹẹ nitori pe awọn etutu gbogbo to yẹ lati fi ki Arẹmọ kaabọ ṣin lọ lọwọ.
Ìjọba àpapọ̀, ẹ so ifilọlẹ ẹ̀rọ alatagba 5G rọ na - ilé asofin àgbà Wo àwọn to ti rí ìwòsàn lọ́wọ́ àrùn coronavirus àti ibi tí wọ́n ti wá káàkiri Nàìjíríà Mẹ́rin nínú àwọn mọ́kànlá tó ń bọ̀ láti Sokoto tí wón mú l'Oyo ló ní Coronavirus Kí ló wà nínú àbá àkóso ajakalẹ àrùn tó fi ní àtakò?
Àwọn obinrin ò gbọdọ máà bèrè fun ètò ilera ọfẹ́ kí wọn tun maa bèrè fún ìdọgbágba nítori naa ilera ọfẹ yóò wà fun àwọn ọmọde àti àgbalagba nìkan.
  “Ti a ba fi isakoso ijoba yii ati tateyin wa we ra won, a ri pe iyato ti o fara han gbangba-gbangba lo wa ni be, lataari  gbigbogun ti iwa ibajẹ tisakoso yii yan laayo.
A kò ní ǹkan ṣe pẹ̀lú ẹgbẹ́ òsèlú -Adeboye Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Osun Decides: Adegoke ni òun kò ni lo kọngilá n Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ọṣun Decides: ADC, ADP, APC àti SDP soju abẹ níkòó lórí ìwà ìbàjẹ́ Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
O ni iṣẹ oludari paapaa kii ṣe kekere nitori ero oṣere ati oludari maa n yatọ ni ọpọ igba ni.
Baba Suwe bọ́ lọ́wọ́ àìsàn, ó bẹ̀rẹ̀ tíátà padà Ọjọ́bọ̀ la ó mọ̀ bóyá a ní Coronavirus - Aṣòfin Ondo Ijọba ilẹ Canada ti ni ọrọyan ni fun ẹnikẹni to ba ṣẹṣẹ wọ ilẹ naa lati wa ni igbele fun ọjọ mẹrinla gbako.
Asoju ijọba ilẹ Gẹẹsi Boris Johnson ṣalaye pe oun ati aarẹ France Emmanuel Macron n siṣẹ pọ lati bẹrẹ owo pada, ati pe igbagbọ wa pe ọrọ naa yoo yanju laipẹ yii.
Ọmọ ọdún márùn-ún, àgbà mẹ́rin ló bá ìṣẹ̀lẹ̀ ọ̀pá bẹntiróò tó gbiná ní Abule Egba lọ - LASEMA Hepatitis: A kò leè kóo nípa dídìmọ́ ara ẹni Àwọn ọmọ ẹgbẹ́ PDP fẹ̀hónúhàn l'Abuja lórí ìdájọ́ ílé ẹjọ́ gíga jùlọ Atiku náà kéde àtìlẹ́yìn rẹ̀ fún ẹ̀ṣọ́ alábòò Amọtẹkun Agbẹjọrọ afurasii naa, Isaac Adubazi sọ pe ọkunrin naa kan n wa atije ni ati ọna lati gba ọwọ lọwọ iyawo Sọtitobire ki ọwọ palaba rẹ to segi.
"Ko lọwọ ninu iṣẹlẹ naa o""."
 Aare ranti pe Lugga lo irir re to koja egbe abewu yii lati so banki ariwa ji pada leyin to fe ku tan tele.
ògòǹgò, ati ẹyẹ kan bí ẹ̀lulùú tí ń gbé aṣálẹ̀, 
Wọ́n kọ OLUWA Ọlọrun àwọn baba wọn tí ó kó wọn jáde láti ilẹ̀ Ijipti sílẹ̀, wọ́n ń bọ lára àwọn oriṣa àwọn tí wọ́n yí wọn ká, wọ́n ń foríbalẹ̀ fún wọn, wọ́n sì mú inú bí OLUWA.
Àwọn ọlọ́gbọ́n yóo máa tàn bí ìmọ́lẹ̀ ojú ọ̀run, àwọn tí wọn ń yí eniyan pada sí ọ̀nà òdodo yóo máa tàn bí ìràwọ̀ lae ati títí lae.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù #DaysOfRage: Sowore ní ìwọ́de náà kò ni gbèdéke ọjọ́ tí yóò parí 2 Ògún 2019 Oríṣun àwòrán, @YeleSowore O ti to asiko lati sọ fun ijọba orilẹede Naijiria pe o to gẹẹ, bawọn ọmọ ipinlẹ Kwara ti sọ ninu idibo gbogbogbo to lọ.
Ẹnu ya àwọn tí ó gbọ́ ẹ̀kọ́ rẹ̀, nítorí ó ń kọ́ wọn bí ẹni tí ó ní àṣẹ, yàtọ̀ sí bí àwọn amòfin ṣe ń kọ́ wọn.
lọwọ  rẹ lati gbiyanju, pe iye awon omo
Losu kọkanla, ọdun 2018, awọn ọmọ ileeṣẹ ologun Naijiria kan fifidio sita nibi ti wọn ti ni o kere tan ọgọrun ọmọogun lo padanu ẹmi wn ninu ikọlu pẹlu Boko Haram .
Agbẹjọ́rọ̀ fún Elzakzaky, Femi Falana ní ọdún 2015 tí wọn ti wà látìmọ́lé ni wọ́n kò tíì ní ìtọ́jú tó péye.
Egbẹ́ agbábọ́ọ̀lù Nàìjíríà sàn N5,000 láti rà agbábọ́ọ̀lù tó n gbowó julọ Ẹ wo oju agbabọọlu yi daadaa, nitori igba ti yoo ba bẹrẹ si ni jẹ goolu.
Alakoso fidihẹ fun ajọ naa, Kemebrandikumo Pondei, to ko awọn alabaṣiṣẹpọ rẹ lọ sibi iwadii ọhun sọ pe, alaga igbimọ oluwadi naa, Olubunmi Tunji-Ojo ko yẹ lẹni ti yoo dari iwadii naa nitori wọn ti fi ẹsun aṣemaṣe nipa ajọ ọhun kan oun naa ri.
Nítorí ọ̀pọ̀ yóo wá ní orúkọ mi, tí wọn yóo wí pé, ‘Èmi ni Mesaya’ ati pé, ‘Àkókò náà súnmọ́ tòsí.
Wo fidio yii lati mọ bo se lee mu irọrun ba ara rẹ ti nkan osu rẹ ba dawọ duro.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Kegel: Eré ìdárayá tí àwọn onímọ̀ sọ pé ó n fikún adùn ìbálòpọ̀ fún obìnrin, tó tún n fún ọkùnrin ní agbára 24 Bélú 2020 Awọn onimọ ilera maa n sọ pe pataki ni ere idaraya jẹ, ninu ilera ẹda.
Amọṣa, o ni awọn olukọ naa fẹ jiroro pẹlu ijọba, iyẹn bi ijọba ba ṣetan fun ifikunlukun to dan mọran.
Èmi a máa rí àwọn nkan ìyanu káàkiri gbogbo ilẹ̀ tí mò ń tẹ̀, èmi a sì máa gbé orúkọ́ Ọlọ́run ga.
Buhari yan Mohammad Sambo, olùdarí NHIS tuntun Ẹ kún fún àdúrà nítorí ìdájọ́ kóòtù àgbà lórí gómìnà l'Ọ́ṣun-APC Ọṣun Ọga agba ajọ LASEMA naa ṣalaye pe eto wiwa awọn to ku ninu agbami ṣi n tẹ siwaju.
Arọmọdọmọ rẹ̀ ni yóo máa jọba títí lae,ìtẹ́ rẹ̀ yóo sì máa wà níwájú mi, níwọ̀n ìgbà tí oòrùn bá ń yọ.
Wahala orile ede yii ni iwa esin ati eleya-meya, sugbon ti awon eniyan ba ni imo eko, won yoo lee yago fun iru iwa bayii.
Yan Aaroni ati àwọn ọmọ rẹ̀ láti máa ṣe iṣẹ́ alufaa.
Òní ni ẹ̀bí akọni Pius Adesanmi n ṣètò ìkẹyìn fún ogbontarigi náà Adájọ́ Dogo tí wọ́n jí gbé ti gba ìtúsílẹ̀ Ẹlẹ́wọ̀n tẹ́lẹ̀ gboyè ìmọ̀ ìjìnlẹ̀ méjì lọ́gbà ẹ̀wọ̀n Kini o ṣẹlẹ gangan nibudo ipagọ awọn ọmọ ogun?
O ni awọn alatako lo n se agbatẹru iroyin pe awọn ọmọde n dibo ni ipinlẹ naa.
À ti Ìlú Biní ni baba ńlá bàbá àwọn ọmọ àti Oònilẹ̀ Abúlé Ọjà ti ṣẹ̀wá bí ó ti ṣe rí fún púpọ̀ àwọn ìlú tí ó wà ní Èkó.
Gomina Yari ni owo nla ni ipinlẹ Zamfara n na si ọrọ abo eleyi to ni o nmu ifasẹyin ba idagbasoke ba ipinlẹ naa pẹlu bi ko se si owo pupọ mọ lẹyin ti wọn ba ti yọ owo fun aabo, lati na fun awọn isẹ idagbasoke miran ni ipinlẹ ọhun.
Ẹ̀ni ọgọ́ta ọdún gbẹ̀mí ara rẹ̀ ní UCH Ibadan Mọ̀lẹ́bí Adéyẹmọ fẹ wadi ikú rẹ̀ ''A ti gba iwe ti awọn ẹbi Olatoye kọ si wa lori iku ọmọ wọn sugbọn awọn agbẹjọro wa yoo fesi si pada fun wọn bo ti ṣe tọ ati bi o ti ṣe yẹ'' Akinrinọla ni oun ko le fesi si awọn ọrọ ti molẹbi oloogbe kọ, bi kii ṣe pe ki awọn agbẹjọro UCH wo awọn ẹsun naa wo yekeyeke, ki wọn si dahun si.
Báwo ni ìbá ti dára tó lónìí, bí ó bá jẹ́ pé àwọn eniyan jẹ lára ìkógun àwọn ọ̀tá wọn tí wọ́n rí.
Joṣua ati àwọn ọmọ Israẹli bá pada sí àgọ́ wọn ní Giligali.
Orilẹ-ede Naijiria naa n sami ayẹyẹ ominira ọdun mọkandinlọgọta.
Ṣugbọn àwọn oríṣìíríṣìí orílẹ̀-èdè tí ń gbé Samaria ṣì ń gbẹ́ ère oriṣa wọn, wọ́n fi wọ́n sinu àwọn ilé oriṣa tí àwọn ọmọ Israẹli ti kọ́.
Dokita Pratipha Ramani, tii se olori ẹka to wa itọju eyin nile iwosan naa salaye pe, lati igba ti ọmọde naa ti wa lọmọ ọdun mẹta, ni wọn ti se akiyesi pe agbọn rẹ naa wu amọ wọn fi silẹ nitori pe ko fọwọsowọpọ pẹlu wọn.
Ìtàn mìíràn ṣe ìrántí bí pípa àgbànrere kan ṣe fa iyọ̀ títà ní apá orílẹ̀-èdè yìí.
” Tabi nípa bíbèèrè pé, “Níbo ni Ọlọrun onídàájọ́ òdodo wà?
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Jide Kosọkọ: Isẹ́ tíátà yóò gòkè tíjọba bá gbówó kalẹ̀ láti seré Ọlọpaa ti kan si awọn obi ọmọ naa ti wọn ni orukọ rẹ n jẹ Joseph Makinde.
Omi bá bẹ̀rẹ̀ sí fà lórí ilẹ̀.
    Bẹ́ẹ̀ náà ni mo ṣe, ìgbà tí emi àti àwọn ọdẹ díẹ̀ tó kù padà dé ìlú wa, ọba wa tí ó ti darúgbó yọ̀ lọ́pọ̀lọpọ̀, ó fún wa ni ẹ̀bùn pùpọ̀, a sì tún fun un ni eso igi méjéèjì, èso igi ìrònú àti èso igi Ìfẹ̀yìntì-Olódùmarè, lẹ́yìn èyí, mo padà lọ sí ọdọ ìyàwó mi.
Ẹ̀mí wá darí rẹ̀ sí Tẹmpili ní àkókò tí àwọn òbí ọmọ náà gbé e wá, láti ṣe gbogbo ètò tí ó yẹ gẹ́gẹ́ bí òfin.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù IVF: Ìyá ìbejì se IVF mẹ́ta lókè òkun, ìkẹrin tó se ní Nàíjíríà, ló fi bímọ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ IVF: Ìyá ìbejì se IVF mẹ́ta lókè òkun, ìkẹrin tó se ní Nàíjíríà, ló fi bímọ 16 Ọ̀wàrà 2018 Ọdun meje ni Okiki Marinho fi n wa ọmọ, to si gbiyanju ilana fifi atọ ọkunrin si ara ẹyin obinrin ni ilana isegun igbalode, taa mọ si IVF.
Awọn iwe ti o ma ni lati fi ṣọwọ: •Iwe ẹri sabuke akẹkọjade ileewe girama •Iwe ẹri ọjọ ori tabi iwe miran to tọka ọjọ ibi rẹ •Iwe ẹri ọmọ ilu to ti wa eleyi ti oloyinbo n pe ni Certificate of Origin Lẹyin to ba ti fi awọn nkan wọn yi ranṣẹ, tẹ aaye atẹjisẹ, buwọlu laaye ti wọn la kalẹ ki o si fi ṣọwọ.
Ile ijọsin kan ti wọn n pe orukọ rẹ ni Ghabola Church to wa ni guusu olu ilu Johannesburg ni awọn ọmọ ijọ bẹẹ ti ni ki ijọba wa nkan ṣe si ofin ma ta ọti yi.
Ọjọ iṣẹgun, ti awọn ẹgbẹ oṣiṣẹ gunle iyanṣẹlodi jakejado orilẹede Naijiria ni ifẹnuko naa to kẹsẹjari lẹyin ifikunlukun ọjọ mẹta.
Nítorí a wòó pé o yẹ kí ilé ọ̀hún wó lulẹ̀ sí ẹ̀gbẹ́ tó léfò.
Eleyi wọ́pọ̀, pàtàki ni idilé Ọba, Ìjòyè nla, Ọlọ́rọ̀ ni àwùjọ àti àgbàlagbà ti ó fẹ́ iyàwó púpọ̀.
Eku ba oko ìrẹ́sì jẹ́ ni Kebbi Eku jẹ $17,600 nínú ẹ̀ro apọwó ATM Eku ọlọmu pupọ lo n fa iba Lassa Ìpínlẹ̀ Ọ̀ṣun kéde ìsinmi lẹ́nú iṣẹ́ nítorí ọdún Ìṣẹ̀ṣe Ọpọlọpọ igba lawọn oniṣẹ ibi lori ayelujara ti n fẹ doju eto ọrọ aje Estonia ru tẹlẹ ṣugbọn ti ko ṣeeṣe fun wọn nitori pe ijọba Estonia ni igbesẹ idaabobo to dara.
APC kò ni ṣe ìdìbò nípínlẹ̀ Ondo ti ìgbìmọ̀ bá yọ mi kúrò nínú ìdíje- Segun Abraham Wo iye owó tó wọlé fún ìjọba lórí COVID-19 àti bí wọ́n ṣe ná an Ìjọba fí ìlànà tuntun lédé lórí àti ṣí iléèwé káàkiri Nàíjíríà láì fí ọjọ́ tí wọn yóò ṣí iléèwé sí bẹ̀ Kí ló fa ìjà láàrin Wunmi Toriola àti Seyi Edun?
Bàbá mi gbé ìwé sílẹ̀ ó pa òṣé ó wí fún Àǹjànnú-ìbẹ̀rù wí pé òun kì í búra fún ẹnikẹ́ni – gọ́ngọ sọ, ọ̀gọ lẹ́hìn aṣiwèrè, àǹjànnú àti ènìyàn bẹ̀rẹ̀ ìjà, sẹ̀lẹ̀ ṣẹ̀ ní Igbó Olódùmarè, eruku sọ làù lójú ọ̀run, bàbá mi àti ẹbọra oníbodè bẹ̀rẹ̀ ìjàkadì, ìwọ ọ̀rẹ́ mi, nǹkan ṣe!
Ọmọ bíbí ìlú Auchi, ìlú kan ní ìpínlẹ̀ Edo ni.
Ipolongo egbe naa, Alhaji Sarafa Tunji Ishola, naa tun so pe bi awon oludibo ati
Aarẹ tun rọ awọn olori ẹsin ati awọn ọba alade lati rii wi pe ọrọ ti yoo mu alaafia jọba, ni wọn n sọ jade lẹnu.
11 Bélú 2019 Oríṣun àwòrán, TIM LAMBONI/GREENPEACE Àkọlé àwòrán, Ken Saro-Wiwa àtí àwọn mẹ́jọ míràn tó jẹ́ adarí àwọn Ogoni ní ìjọba ológun yẹgi fún ní ọdún 1995.
Ninu ọrọ akọsilẹ ti fasiti naa fi ṣọwọ ileeṣẹ BBC, agbẹnusọ wọn, Joshua Suleiman ni iṣẹlẹ naa ti ṣ latinu oṣu kẹrin ti kii sii ṣe inu ọgba ileewe lo ti ṣẹlẹ.
 o ropo alakoso agba o ' tkir sultonov to je lilekuro .
Àdúrà ni mo nílò kìí ṣowó - Pa Kasumu 'Penis Fish,' ẹ̀ja tuntun tó rí bí nǹkan ọmọkùnrin lúwẹ̀ẹ́ jáde nínú òkun Kò sí ǹkankan tó ń jẹ́ Ọba Fuji - Ajebori Onifuji Ni kete ti Covington could barely stand to listen to Usman's victory speech, charging out of the Octagon to the back as soon as the Nigerian's hand was raised.
Ẹ dẹkun ere sísá lójú pópó láti dẹkun ìjàmbá- FRSC Ààrẹ Buhari wọ́gilé kí àwọn òṣìṣẹ́ ìjọba máa wọ ọkọ̀ bàálù olówó gọbọi A ti gbé kọ́kọ́rọ́ sẹ́nu ibodè Nàìjíríà kí ọrọ̀ ajé wa leè gbé pẹ́lí- ìjọba àpapọ̀ Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Ẹnikẹ́ni tí ó bá sì ṣe iṣẹ́ kankan ní ọjọ́ náà, n óo pa á run láàrin àwọn eniyan rẹ̀.
Aṣoju ajọ to n mojuto igbokegbodo ọkọ ni ipinlẹ Ọyọ, Ọgbeni Adeoye Ayọade ṣe alaye fun awọn akọroyin pe, alẹ Ọjọ Iṣẹgun ni isẹlẹ naa waye.
) Jehu sọ fún àwọn ẹlẹgbẹ́ rẹ̀ pé, “Bí ẹ bá wà lẹ́yìn mi, ẹ má ṣe jẹ́ kí ẹnikẹ́ni jáde kúrò ní ìlú láti lọ ròyìn fún wọn ní Jesireeli.
Ọjọgbọn Soyinka ni bakan naa ni ọpọ oniroyin ofege ti kọ awọn ọrọ kan ni orukọ oun ti wọn si ni oun ni oun sọ awọn ọrọ naa.
Sibẹ ẹ̀rí wọn kò bá ara wọn mu.
igbese ti won yoo gbe lati ri i pe won mu ifẹ egbe won sẹ lori ekunwo owo osu
Iwadii ajọ EFCC lo fihan pe owo to din diẹ ni miliọnu mẹtala naira(N12.
Nítorí àwọn tí wọ́n kọlà pàápàá kì í pa gbogbo òfin mọ́.
Nígbà tí ìsáǹsá ará Efuraimu kan bá ń sá bọ̀, tí ó bá sọ fún àwọn ará Gileadi pé, “Ẹ jẹ́ kí n rékọjá.
Jesu bá wọ inú Tẹmpili lọ, ó lé gbogbo àwọn tí wọn ń tà, tí wọn ń rà kúrò níbẹ̀.
Àwọn oníṣòwò Solomoni níí máa ń tà wọ́n fún àwọn ọba ilẹ̀ Hiti ati àwọn ọba ilẹ̀ Siria.
Wọ́n ní bí àwọn babánlá àwọn tó tẹ ilẹ̀ Amẹrika dó ṣe fẹ́ ẹ nìyẹn.
Ewéko tútù ni yóo jẹ́ ibùsùn wa.
patapata fun gbogbo akoko ti won yoo lo fi se ise won.
Ṣugbọn bí ó ti rí yìí náà, mo gbà yín níyànjú pé kí ẹ ṣara gírí.
Ó dé sílé ẹnìkan tí ń jẹ́ Simoni, tí ń ṣe òwò awọ, tí ilé rẹ̀ wà létí òkun.
Aarẹ tuntun yii n gbajọba orilẹede ti wọn fi ẹsun kan ẹni to gbaṣẹ lọwọ ẹ pe ijọba to dari tapa si ofin ẹtọ ọmọniyan ati ainaani ẹgbẹ alatako, awọn oniroyin atawọn ajafẹtọ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Coronavirus Cases in Africa: Gomina Makinde gbàlejò àwọn Imam lásìkò àrùn Coronavirus 11 Èbibi 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 14 Èbibi 2020 Oríṣun àwòrán, OTHERS Àkọlé àwòrán, Ẹgbẹ́ àwọn Imam, the Joint Action Committee for the Preservation of the Rights and Honours of Imams tako àyẹyẹ naa.
INEC: Àìmọ̀kan-mọ̀kàn ló ń ṣe àwọn tó ń sọ̀rọ̀ tako ìyànsípò Amina Zakari Àwọn òṣèré tíátà Yorùbá tó bá 2018 lọ BBC Yorùbá yóò se ìpàdé ìtagbangba ní Kwara Àkọlé àwòrán, Dino Melaye Lonii, ọjọ ẹti, ọjọ kẹrin oṣu kinni ni èyí wáyé gẹgẹ bi iroyin ṣe sọ ọ wi pe awọn akẹgbẹ Melaye kan lo ba a sọrọ.
" Ṣaaju ni iroyin kan gbode kan lowurọ yii pe wọn ri oku ọmọdekunrin Gold to dawati nile ijọsin Sotitobire nilu Akure, ni awọn ọlọpaa lọ si ile ijọsin ọhun.
Nígbà tí oòrùn yọ, Ọlọrun mú kí afẹ́fẹ́ ìhà ìlà oòrùn fẹ́, oòrùn sì pa Jona tóbẹ́ẹ̀ tí ó fi fẹ́rẹ̀ dákú.
Ajo to n ri si boolu afesegba nile Afrika CAF, lo so oro ohun di mimo pe, won yoo lo ero igbalode naa ninu idije 2018 Caf Super Cup, eyi ti yoo waye larin iko agbaboolu Wydad Athletic Club ati TP Mazembe lojo Aiku(Saturday).
Tí a fiṣọwọ́ ní 4:28 5 Ọ̀pẹ̀ 20204:28 5 Ọ̀pẹ̀ 2020 Adolf Hitler gbé àpótí ìbò, aráàlú yàn án sípò gẹ́gẹ́ bíi Káńsílọ̀ Adolf Hitler Uunona jawe olubori labẹ asia ẹgbẹ Swapo to jẹ ẹgbẹ to wa lori oye níbẹ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Jude Chukwuka: Wò ó bí òwé Yorùbá ṣe yọ̀ lẹ́nu ọmọ Igbo Ikọlu nla yoo waye lati ọdọ awọn Darandaran si awọn agbẹ ni ẹkun ariwa ati ila oorun Naijiria, ti Ọlọrun si fi han mi pe ọpọ awọn darandaran naa ni wsn n lo fun awọn idi kan, ti asiri rẹ ko ni pẹ tu."
Muhammadu Buhari  ti ni, o da oun loju pe
Ìtan fihan pe Daurama ni Ọbabinrin to wa lori itẹ lasiko ti akọni igbanni, Bayajidda lọ si Daura, to si pa ejo nla to n ba awọn araalu l'ẹru.
O jẹ ẹni to ni ọpọlọpọ oye nipa eto oṣelu abẹle Naijiria.
"lẹ ́ yìn tí ó parí Àgùnbánirọ ̀ ( nysc ) , ó tè síwájú láti ṣe agbátẹrù "" bísí Ọlátilọ show "" ( bos ) ."
Ọpọ awọn ọmọ orilẹede Naijiria ni wọn ti gbiyanju ati rin irinajo to lewu ninu gidigidi gba aṣalẹ ilẹ Sahara Desert ati ori okun Meditaranean lati lee de ilẹ Yuroopu.
Idi ni pe ti gomina ba n sọrọ nipa ẹnikẹni, yoo bẹrẹ si sọrọ nipa ọjọ ori onitọun, ti yoo si ni aburo oun ni tabi pe oun ju wọn lọ.
Bí mo ti ṣe yìí gan-an ni ẹ̀yin náà gbọdọ̀ ṣe, ẹ kò gbọdọ̀ fi aṣọ bo ẹnu yín tabi kí ẹ máa jẹ oúnjẹ ọlọ́fọ̀.
Ọmọkùnrin tó ya 'Blue film' nínú igbó Osun Osogbo ti bayé ara rẹ̀ jẹ́ - Yemi Elebuibon Mercy Aigbe ṣá ọmọ rẹ̀ sínúu fíìmù tuntun, wo itú tí ọmọ ọdún mẹ́wàá náà pa Ọmọ ọdún 23 jẹ́wọ́ bó ṣe pa ẹ̀gbọ́n ìyá rẹ́, ẹni ọdún 60 nípinlẹ̀ Ogun Irọ́ ńlá ní pé mo fẹ́ fi ògùn ba tì akẹ́gbẹ́ mi tó ń bá ọmọ mi du ọkọ jẹ́ - Rita, ìyá Regina Daniels “Ninu idile mi, a fẹrẹẹ pe ogun ti baba mi bi ṣugbọn emi nikan ni arara”.
Gbogbo wọn ni yóo gbọ̀n dànù bí aṣọ,kòkòrò yóo sì jẹ wọ́n.
Gbogbo ọba ládéládé Ilẹ̀ Odùduwà ní wọn ránmi sí ọ
 Saraki kọọ wi pe:”lẹyin ọrọ ti mo sọ lori ẹrọ twitter pe, mo ti gba lẹta lati ọdọ  awọn  ọlọpaa @PoliceNG.
Laycon: Oríṣun àwòrán, Instagram/Laycon Olamilekan ''Laycon'' Agbeleshe lo ṣeeṣe ko gbade eto BBNaija ti ọdun yii, nitori ogunlọgọ eeyan to n fifẹ han si, ti wọn si n dibo fun ni gbogbo igba.
Lara bi oju wọn ṣe ri eyi taa ka mọ ree nigba ti wọn o kun ọda ologe soju tabi ara wọn ati lai lo Filters Fausat Balogun (Madam Saje) Oríṣun àwòrán, Madam Saje Aisha Lawal Oríṣun àwòrán, Aisha Lawal Wumi Toriọla ti sọ̀rọ̀ sóke láti fi idí rẹ̀ múlẹ̀ pé òun àti ọ̀rẹ́ òun níjà Àlàyé rèé lóríi àjọṣepọ̀ tó wà láàrin èmi àti MC Oluomo - Ronke Oshodi Oke Mercy Aigbe ṣá ọmọ rẹ̀ sínúu fíìmù tuntun, wo itú tí ọmọ ọdún mẹ́wàá náà pa Ẹ wo báwọn òṣèré tíátà kan yóò ṣe rí lọ́jọ́ ogbó Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Tóo bá pá lórí, Mílíìkì sóyà àtàwọn ǹkan mẹ́ta yìí leè mú irun rẹ hù padà!
Kí ẹnìkọ̀ọ̀kan yín mọ ọ̀nà láti máa bá aya rẹ̀ gbé pọ̀ pẹlu ìwà mímọ́ ati iyì, 
 Ewe, ninu awon ise akanse naa
Fun apẹẹrẹ,iyẹ ọmọ to ti gba abẹrẹ ajẹsara to le dena arun ko to idaji lorileede Naijiria.
Àwọn mìíràn dàbí irúgbìn tí a fún sórí ilẹ̀ rere.
n óo mú kí òjò rọ̀ ní àkókò rẹ̀, ilẹ̀ yóo mú ìbísí rẹ̀ wá, àwọn igi inú oko yóo sì máa so èso.
Awọn ẹya ọ̀bọ n kojú orisirisi isoro, bii pipaje, fifi wọn se oogun abẹnu gọngọ ati sisọ̀ ilégbèé wọn nù.
Ọjọ́ tí o bá jáde kọjá odò Kidironi, pípa ni n óo pa ọ́, ẹ̀jẹ̀ rẹ yóo sì wà lórí ara rẹ.
Bẹrẹ lati ọgbọnjọ, oṣu Kejila, ọdun 2020, ẹni to ba fẹ gba nọmba NIN gbọdọ kọkọ lọ si ọfiisi ajọ NIMC to ba sun mọ laarin aago mẹsan owurọ si aago kan ọsan.
"Wo àpẹẹrẹ, àti ǹkan tó ń fa 'colon cancer' tó pa Chadwick Boseman 'Black Panther' Akori ọ̀rọ̀ fun agbeyẹwo loni ni ""Apola Ọrọ Orukọ"" eyi ti ẹ mọ loyinbo si ""Noun Phrase"" ati awọn isọri rẹ."
Ẹ jẹ́ kí á gbé ojú wa sókè,kí á ra ọwọ́ ẹ̀bẹ̀ sí Ọlọrun ọ̀run:
Ifenuko alaafia odun 2015 lati fopin si aawo naa forisopon ni osu keje odun 2017 leyin ti ajakuakata bere lakotun eyi ti o sokunfa eredi ti  igbakeji naa Riek Machar se sa lo farapamo ni awon orile-ede to mu le ti won .
Akomolede Eko round up: Àwọn Olùkọ́ ìpínlẹ̀ Eko dárà lórí Akọ́mọlédè àti Àṣà lórí BBC
Babalola lo sọ ọrọ naa ninu ifọrọwerọ kan pẹlu akọroyin ileeṣẹ BBC Yoruba.
 níb ́ i ni wọn tì le ṣàkóràn fún eṣinṣin dúdú míìràn tí yóò gé ènìyàn jẹ .
O ni: ''Nitorinaa, iwa ọdaran gbaa ni pe ki eeyan mọọmọ tapa si ofin yi'' Coronavirus: Ǹjẹ́ àwọn dókítà tó ń tọ́jú eyín ń ṣisẹ́ lásìkò pàjáwìrì?
Ni ọjọru ni iṣi akọkọ awọn ọmọ orilẹede Naijiria to ha si orilẹede UAE pada de lati ilu Dubai ti wọn si ti fi wọn si ahamọ.
Àwọn tí ojú ń pọ́n yóo jẹ àjẹyó;àwọn tí ń wá OLUWA yóo yìn ín!
O fikun ọrọ rẹ pe oun gbagbọ ninu pinpin ipo aarẹ lati apa kan si omiran kaakiri Naijiria.
Ọdun mẹtala lo fi ṣe eyi lẹyin naa ni wọn yan an si ara awọn adajọ agba ile ẹjọ kotẹmilọrun lọdun 1993.
Oró agbọ́n leè wo àìsàn jẹjẹrẹ ọmú sàn, wo ohun tí wàá lò pọ̀ mọ́ra wọn Isiaka Busari, Mighty Joe tó jẹ́ adigunjalè tó rọ́pò Ọyenusi lẹ́yìn tí wọ́n pa á Oríṣun àwòrán, Twitter/British_Airways Kini ikede ti minista kọkọ ṣe tẹlẹ?
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: 'Adájọ́ ẹ tú wa ká, ìyàwó mi n gbé ààlè wá sórí ibùsùn wa' A jọ ṣe ìyàwó pọ̀, a jọ bímọ ní ọjọ́ kan náà, a tún jọ máa ń ṣàìsàn pọ̀ ni Pope Francis wọ́gilé òfin tó n dáàbò bo àlùfáà tó bá bá ọmọdé l'òpọ̀ Ọmọ Downsydrome ti mo bí ló fún mí láǹfàní láti de ilú Oyinbo Oluwo: Chanel Chin rẹwà gidigidi lóbìnrin, ṣùgbọ́n.
1 2081 Orilẹede United Arab Emirates 602 6.
Ọga ajọ NAFDAC, Ọjọgbọn Moji Adeyẹye ṣalaye pe ede oyinbo ati Faranse lo wa lara oogun ọhun ti orukọ n jẹ Dukoral.
Lawọn ipinlẹ mọkandinlogun to wa ni ariwa Naijiria, bi awọn ọmọ kan ba ti se n lọ lawọn miran n bọ ti wọn n kiri lati ipinlẹ kan si ikeji lorukọ Almajiri.
Iyabo Ojo, lo sẹsẹ gunlẹ si papakọ ofurufu Muritala Muhammed nilu Eko lati Ilẹ Turkey ni aarọ ọjọ Aje.
Awọn oṣere tiata Yoruba naa ko gbẹyin ni bi wọn ṣe ṣe ọdun naa loriṣiriṣi ọna.
Josẹfu dáhùn, ó ní, “Ìtumọ̀ rẹ̀ nìyí: àwọn agbọ̀n mẹta náà dúró fún ọjọ́ mẹta.
OLUWA ní, “Ìwọ Jeremaya ní tìrẹ, má bẹ̀bẹ̀ fún àwọn eniyan wọnyi, má sọkún nítorí wọn, tabi kí o gbadura fún wọn.
Buhari  gege bi aare tuntun ati igbakeji
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fọ́nrán ohùn, Oluwo fe fi oye Waziri lọle nilẹ Yoruba Imaamu mii naa ni ẹkọ gbigbona nfẹ suuru Imam Abdulsalam Olayiwola to je Imam masalasi Radio Kwara ni ilu Ilorin so pe iru ọrọ bayi gba suru.
" Inu mi dun gidi lori ọrọ yii laarin kan, sugbọn to ya ọrọ naa damu mi diẹ.
Elégbodo kan ò lè dún kowéè lé ọ lérí mọ́
O ni oun gbiyanju lati fi ina sori ẹrọ ibanisọrọ oun ṣugbọn ko ṣeeṣẹ.
Wọ́n mú ohun èlò ìpakà onírin ṣómúṣómú, wọ́n fi pa àwọn ará Gileadi ní ìpa ìkà.
Ọpọlọpọ lo reti ki alaga ẹgbẹ oṣelu APC naa o gbe igbesẹ lati tete yanju ọrọ naa ki o to burẹkẹ.
Orile ede Amerika ta agba  epo robi tire ni 68.
Ileesẹ eto ilera ni fọnran naa jẹ ohun ti wsn jiroro nibi idanilẹks kan amọ ti ko ye wọn bi fọnran naa se lu sita.
apapo ti fenuko lori adehun ti won se , nipa sise atunse si ofin ti o da ile
Ní ọjọ́ náà, ẹni tí wọn sọ pé kí ó jẹ olórí yóo kígbe pé,“Èmi kò ní jẹ oyè alátùn-únṣe.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Arúfin ni Seyi Makinde pẹ̀lú bó ṣe gbà kí wọ́n sin Ajimobi sí GRA - Amòfin Àwọn ògo Ibadan márùn ún tí ikú mú lọ lọ́dún 2020 Mo ti lùgbàdì àrùn Coronavirus - Akeredolu figbe ta Ṣé ó leè jẹ́ ilẹ̀ tí Makinde kò jẹ́ kí Florence Ajimobi gbà ló ń bi nínú?
Rògbòdìyàn bẹ́ sílẹ̀ láàrin àwọn ọlọ́kadà àti àwọn òṣìṣẹ́ ọgbà ẹ̀wọ̀n ní Ibadan Tí a bá yọwọ́ àwọn ọba alayé kúrò, kò ní sí Nàìjíríà mọ́- Alaafin Oyo Makinde, Dele Momodu ń ṣèdárò Àgbà Oyè Ilẹ̀ Ibadan, Harry Akande tó jáde láyé Wo àwọn oúnjẹ márùn ún tó ń mú kí àtọ̀ ọkùnrin dára síi Ni ti aarẹ Akufo-Addo, ipolongo to n ṣe da lori eto ọrọ aje, eto ọgbin, ati ipese iṣẹ yatọ si ikoju ajakalẹ arun Covid 19.
Jẹ́ kí ikú jí àwọn ọ̀tá mi pa;kí wọ́n lọ sinu isà òkú láàyè;kí wọ́n wọ ibojì lọ pẹlu ìpayà.
Ní ọdún 2013, a mú u a sì fi sínú àhámọ́ fún ọjọ́ 115 láì ṣe ìgbẹ́jọ́.
Orí rẹ̀ ni mo ti ń wò oun tí ago wí, òun sì ló ń jí mi láràárọ̀.
Ohun tí Solomoni ṣe burú lójú OLUWA, kò sì jẹ́ olóòótọ́ sí i gẹ́gẹ́ bí Dafidi, baba rẹ̀.
Islamic New Year: Ọdún mùsùlùmí Hijiri tuntun bẹ̀rẹ̀ ní Nàìjíríà
Ọmọwe Okonjo-Iwealla to ba BBC News Sọrs ṣalaye pe ko si nnkan meji ti awọn orilẹede lorilẹ Afirika lee fi gba ara wọn la ju awọn ẹka bii eto ogbin atawọn ohun alumsni miran ti Eleduwa fi jinkin wọn ati pe ki banki apapọ na ọwọ iranwọ si awọn ileeṣẹ kerejekereje nitori pe ẹka wọnyii lo gba ọpọlọpọ awọn eeyan lawsn orilẹede wọnyii si iṣẹ julọ.
Èwo ni tèmi láti dá alaigbagbọ lẹ́jọ́?
A ti ṣẹ̀, àtàwa, àtàwọn baba wa,a ti ṣe àìdára, a sì ti hùwà burúkú.
jẹ isoro to  faa ki awon omo kuro
Wí fún wọn pé àwọn ọlọrun tí kì í ṣe àwọn ni wọ́n dá ọ̀run ati ayé yóo parun láyé ati lábẹ́ ọ̀run.
Kò sí ẹni tí ń bẹ àfi Ọlọ́run Ọba.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Yinka Ayefele di bàbá ìbẹta 16 Agẹmo 2019 Oríṣun àwòrán, Yinka ayefele Àkọlé àwòrán, Iroyin ti a ri gbọ sọ pe gbajugbaja olorin naa ṣalaye fawọn oṣiṣẹ rẹ loni Gbajugbaja olorin ni to tun jẹ oludaleeṣẹ redio silẹ, Yinka Ayefẹlẹ ti di baba ibẹta bayii.
Debora wí fún Baraki pé, “Dìde nítorí pé òní ni ọjọ́ tí OLUWA yóo fi Sisera lé ọ lọ́wọ́.
Bí ẹ kò bá gbàgbọ́ ẹ kò ní fẹsẹ̀ múlẹ̀.
Nibo ni Ronaldo wa nigba ti ayẹyẹ Ballon D'or n lọ lọwọ niluu Paris?
kì báà jẹ́ pé láti ọgbà ẹ̀wọ̀n ni òmùgọ̀ ọba náà ti bọ́ sórí ìtẹ́, tabi pé láti inú ìran talaka ni a ti bí i.
Wọ́n bá fọ́n káàkiri gbogbo ilẹ̀ Ijipti láti wá àgékù koríko.
Eid celebrations in Africa: Báyìí láwọn mùsùlùmí ti ṣe ọdun ìtúnu ààwẹ̀ káàkiri ilẹ̀ Afirika lásìkò covid-19 yìí
Buhari kẹdun pẹlu awọn obi awọn akẹkọọ ti wọn jigbe lọ atawọn alaṣẹ ileewe naa.
Àìsàn ìtọ̀ súgà kò túmọ̀ sí pé èèyàn ti gba ọjọ́ ikú- Dókítà Wilson Kí láwọn ohùn àmúyẹ tí kọmẹńtátọ̀ tó dáńtọ́ gbọ́dọ̀ ní?
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Network of Niger Delta Republic Fighters: Àwọn ajìjàgbara Niger Delta fẹ́ yapa kúrò ní Nàíjíríà 21 Èbibi 2019 Ẹgbẹ ajijagbara kan ti wọn pe ara wọn ni 'Network of Niger Delta Republic Fighters' ti dun'koko pe wọn yoo yapa kuro lara orilẹede Naijiria, ti wọn yoo si daduro ni ọjọ kini, oṣu kẹfa ọdun yii.
N óo kọ ohun tí mo kọ sí ara àwọn tabili ti àkọ́kọ́ tí o fọ́ sí ara wọn, o óo sì kó wọn sinu àpótí náà.
Ẹmi adari tabi aṣiwaju: Ohun miran ti awọn aṣofin tun maa n wo ni boya ẹmi adari wa lara ẹni ti wọn fẹ yan sipo naa.
Ká fi Èkó wé àwọn olú ilú yoku ni àgbáyé àti àwọn ilú nla ti omi yi ká, inira Èkó pọ̀ ju àwọn ilú wọnyi lọ.
Okeowo ni Mi o le sọ ni pato ohun to fa họwuhọwu larin wọn, ṣugbọn ohun to ṣe pataki ni pe ko lodi si ofin ki eeyan fi ẹgbẹ oṣelu kan silẹ lọ omiran."
Kò tún sí àpáta kan mọ́, n kò mọ ọ̀kan kan.
Òǹlo Weibo mìíràn fi èròńgbàa rẹ̀ hàn pẹ̀lú ohun tí ó fẹ́ fún Kérésìmesì:
Ìfipábánilòpọ̀: ọlọ́pàá ní àáfà aríran yóò jìyà ẹ̀sẹ̀ rẹ̀
 Ó lọ , ó si bọ ̀ .
Koda, wọn n kesi awọn ijọba ipinlẹ ẹkun Iwọ oorun guusu Naijiria lati gba wọn silẹ lọwọ wahala ti wọn wa lorilẹ-ede naa ki wọn si ko awọn wale.
Ẹ fi ìfẹnukonu mímọ́ kí gbogbo àwọn onigbagbọ.
Attah ni awọn eniyan ni oore-ọfẹ lati wọle tabi jade lati Naijiria si Benin Republic.
Àwọn nkan márùn ún tó gbajúmọ̀ nípa ìlú abínibí Buhari #BBCNigeria2019
Ẹ wa nkan fidi le ki ẹ fidi le nkan ma bawa fi ọkan ba awọn ofin wọn yi lọ ni ṣiṣẹntẹle.
Bakan naa, Gomina Ortom ati asofin ipinle re, leni ti o je gomina ipinle naa tele ri asofin George Akume, ni ikunsinu ti n waye laarin won latari eni ti o dari egbe oselu ohun nipinle naa.
Awọn nkan ti ọpọlọpọ lee ma mọ nipa akọni ọkunrin Ghana yi pọ pupọ, ẹni to dele aye ni ọdun 1938, amọ diẹ ninu wọn ree.
A óo gbà ọ́ lọ́wọ́ obinrin oníṣekúṣe,àní lọ́wọ́ obinrin onírìnkurìn pẹlu ọ̀rọ̀ ẹ̀tàn rẹ̀.
Wọ́n wá láti gbogbo ìletò Galili ati ti Judia ati láti Jerusalẹmu.
Àwọn mejeeji bá jọ wọ inú yàrá lọ, ọdọmọkunrin wolii náà da òróró sí orí Jehu, ó sì wí pé, “Báyìí ni OLUWA Ọlọrun Israẹli wí, ‘Mo fi òróró yàn ọ́ ní ọba lórí Israẹli, àwọn eniyan OLUWA.
Ogbontarigi olorin yii ni kò wu oun ki ọmọ oun yan iṣe orin kikọ laaye rara nitori pe inira oriṣiiriṣii lo rọ mọọ.
Nígbà tí ìyá mi ti rí àwọn àlúfáà wọ̀nyí, ń ṣe ni ó bú sẹ́kún, tí ó ń pariwo, tí ó ń jára mọ́lẹ̀.
olúmuyiwa ( 1994 : 2 ) wòye pé ọ ̀ kọ ̀ ọ ̀ kan ẹ ̀ ka-èdè ilẹ ̀ yorùbá ni wọ ́ n ní ẹ ̀ yà .
Àti àwọn ìbéèrè míràn NFF fi #30,000 kún #10,000 owó ìrànwọ́ oṣooṣù fún ìyá Rashidi Yekini àti Samuel Okwaraji Bẹẹ ni ọrọ ri fun obinrin yii, Catherine (kii se orukọ rẹ gangan niyi), ẹni ti dokita ko fi ẹnu sọ boya ọkunrin lo bi abi obinrin lẹyin ọjọ marun un to ti bimọ, amọ to fi ami ibeere si ori iwe to fi yẹ ko sọ iru ẹda ti ọmọ obinrin naa n se.
3 Ránti, rántí pé kìí ṣe iṣẹ́ ti Ọlọ́run ni a mú díbàjẹ́, ṣùgbọ́n iṣẹ́ ti ènìyàn.
 Mo fi tokan-tokan ki akegbe mi ogbeni Babajide Sanwo-Olu ku oriire yii.
Ninu isẹ ti EFCC n tọ pinpin yii la ti ri isẹ agbaṣẹ oju ọna laarin ilu bi ti Gummi, Bukkuyun, Anka ati Nassarawa to fi mọ isẹ agbaṣe gbigbẹ ẹrọ kanga igbalode(borehole) mejidinlaadọsan ni ijọba ibilẹ mẹrinla ni ipinlẹ naa.
Tàbí onímàle di Àlàaájì, kí ó di Lèmọ́mù kékeré, kí ó tún kúrò nínú èyínìi kí ó di olórí fún àwọn Lémọ́mù, síbẹ̀síbẹ̀ kí ó tún máa nàgà, eléyìínì ń fẹ́ẹ́ di ànábì ni?
Lẹyin ti wọn kede Atiku Abubakar gẹgẹ bi oludije fun ipo aarẹ ninu idibo ọdun 2019, ayederu opo Twitter kan lorukọ olori ẹgbẹ alatako fi ọrọ kan lede ti o fi ki ẹgbẹ awọn ololufẹ ọkunrin s'ọkunrin fun atilẹyin wọn.
yii sẹ ati lati pese igbe aye to dara fun awon omo orile ede yii.
Lẹsẹkẹsẹ nǹkankan bọ́ sílẹ̀ lójú rẹ̀ bí ìpẹ́pẹ́, ó sì tún ríran.
Paapaa ni ilẹ Afirika atawọn orilẹ-ede to ku diẹ kaa to fun lagbaye, awọn ọna miran yatọ si ileewosan ni awọn eeyan n lo fun igbẹbi nitori ọpọlọpọ ipenija ninu eyi ti ọda owo wa.
O bẹrẹ iṣẹ ni at Brasserie Les Halles, New York City lodun 1998.
Níbẹ̀ ni kí o ti bọ́ aṣọ alufaa tí ó wà lọ́rùn Aaroni, kí o gbé e wọ Eleasari.
Àwọn náà jáde sójú ogun, wọ́n pàgọ́ tiwọn siwaju àwọn ọmọ ogun Siria, wọ́n wá dàbí agbo ewúrẹ́ meji kéékèèké níwájú àwọn ọmọ ogun Siria tí wọ́n tò lọ rẹrẹẹrẹ ninu pápá.
Nígbà tí ó bá di ọjọ́ kẹjọ, kí ó mú àdàbà meji, tabi ọmọ ẹyẹlé meji, kí ó wá siwaju OLUWA lẹ́nu ọ̀nà Àgọ́ Àjọ, kí ó sì kó wọn fún alufaa.
Mú ọkàn gírí kí o sì ṣe bí ọkunrin.
Ààmì ara ìgò náà ní àwòrán “Ọkùnrin ọkọ̀-ogun” tí a kọ “Máà ṣe gbàgbé, máà ṣe sọ̀rètí nù”.
Ahabu bá pada lọ sílé pẹlu ìrẹ̀wẹ̀sì ọkàn ati ibinu, nítorí ohun tí Naboti ará Jesireeli wí fún un.
Bakan naa ni atẹjade ọhun tun kede pe, aarẹ orilẹede yii, Muhammadu Buhari ti fọwọ si pe ki adele alaga tẹlẹ fun ajọ EFCC, Ibrahim Magu lọ rọọkun nile na.
Ǹjẹ́ o nímọ̀ nípa agogo inú ara rẹ?
Ogidi ọmọ Yoruba ti ede Yoruba dáńtọ́ lẹnu rẹ nigba ti o n ba BBC sọrọ ti kò tun tijú lati sọ èdè abinibi rẹ mẹnuba ipa rere ti ipò baba rẹ kó ninu idagbasoke iṣẹ tiata ti oun n ṣe.
Darandaran gun awakọ pa l'Ondo Ogagun Zakari ni Ogagaun agba Tukur Buratai ti paṣẹ lati Abuja pe ijinigbe gbọdọ dopin ni ẹkun yi lẹyẹ-o-soka.
Bí o bá jáde sí wọn ní ọ̀nà kan, OLUWA yóo tú ọ ká níwájú wọn.
Nibẹ naa si lo yi orukọ rẹ pada si Karoline Kings ti wọn sọ lọjọ to dele aye, eyi si lo sọ pada di ọmọ orilẹede South Afrika tootọ lẹyin ọpọlọpọ ọdun.
Nítorí pé wàrà ati oyin ni àwọn tí ó kù ní ilẹ̀ náà yóo máa jẹ.
1–3, A pe Joseph Smith lati jẹ́ aríran, olùtúmọ̀, wòlíì, àpóstélì, àti alàgbà; 4–8, Ọ̀rọ̀ rẹ̀ yíò ṣe ìtọ́ni sí ipa ọ̀nà Síónì; 9–12, Àwọn ènìyàn mímọ́ yíò gba àwọn ọ̀rọ̀ rẹ̀ gbọ́ bí òun ṣe ńsọ̀rọ̀ pẹ̀lú ìmísí Olùtùnú.
   Egbe osise  fi idunnu won han bi ile igbimo asoju-sofin
Rochas Okorocha, káàbọ̀ sí àwùjọ àwọn gómìnà tí EFCC ń wá - Fayose Èrè ńlá ńbẹ fáwọn obìnrin nínú okoòwò ọ̀fẹ́ ní Áfíríkà Ilé ẹjọ́ gba onídúró Naira Marley pẹ̀lú mílíọ́nù méjì náírà Dapọ Abiọdun ree, ẹni tó dépò gómìnà ní àyájọ́ ọjọ́ ìbí rẹ̀ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Makinde: Ẹgbẹ́ òṣìṣẹ́ faramọ́ wíwọ́gilé ₦3000 táwọn akẹ́kọ̀ọ́ girama ń san Ṣugbọn ki lo faa ti Ojemba fi bẹ ori ẹgbọn rẹ?
Aarẹ yan awon minisita tuntun si ipo loni ni ilu AbujaWo ohun tó yẹ kí o mọ̀ nípa àwọn obìnrin méje ti Buhari fẹ́ yàn sípò minista.
 lẹ ́ yìn tí ó parí ẹ ̀ kọ ́ rẹ ̀ ní ilé-ẹ ̀ kọ ́ yìí ni ó kọjá sí Ìlaròó tí ó sì dá iṣẹ ́ tẹ ̀ wétẹ ̀ wé sílẹ ̀ ńbẹ ̀ fúnrarẹ ̀ ni ó ka ìwé gba ìwé-èrí g.
Ṣugbọn Hamani pa á mọ́ra, ó lọ sí ilé rẹ̀.
 iṣu ló parade tó diyán , àgbàdo parade ó di ẹ ̀ kọ .
Ṣaaju ni aarẹ Trump ti kọdi iyansipo awọn adajọ si igbimọ ipẹtusaawọ ajọ naa.
Oluwa pè é ní ojú ìran, ó ní, “Anania!
Koda, ni ipinlẹ Jigawa, ọmọ ọdun mejila kan sọ fun awọn ọlọpaa pe ọkunrin mejila lo ti n fipa ba oun lo pọ fun oṣu meji sẹyin.
Wọ́n tún ní àwọn ẹja kéékèèké díẹ̀.
" Saraki tẹsiwaju wipe jakejado orilẹede Naijiria ni awọn gomina ti n wa ojutu si ọrọ owo oṣu awọn oṣiṣẹ, titi to fi de awọn apa ibi ti Boko Haram ti n ṣoro bi agbọn, sugbọn bakan naa kọ lọmọ ṣori nipinlẹ Ọṣun.
Lásìkò àbẹwò Obasanjo si ẹbi Abiola Ajimobi, gómìnà àná ní ìpínlẹ̀ Oyo tó d'ológbèé lọ́jọ́sí, ni gómìnà Seyi Makinde ti gbaa ààrẹ àná lálejò.
Nítorí èyí ni iṣẹ́ tí ẹ ti gbọ́ láti ìbẹ̀rẹ̀, pé kí á fẹ́ràn ara wa.
Ìyìn ni fún ọ, OLUWA,kọ́ mi ní ìlànà rẹ!
Oríṣun àwòrán, Reuters Àkọlé àwòrán, Iku ọgagun Soleimani mu ki Amẹrika ati Iran gbena woju ara wọn Aarẹ Trump lo paṣẹ pé ki wọn ṣeku pa, nítori pe o ni pe ọgagun Soleimani lọwọ ninu iku awọn ọmọ ilẹ Amẹrika ati pe o n gbimọọtẹ lati se ikọlu si Amẹrika.
dupe lowo gbogbo eyin ti e fara se ise fun mi.
Ó ní àwọn ìlú Juda ati àwọn tí wọn ń gbé Jerusalẹmu yóo ké pe àwọn oriṣa tí wọn ń sun turari sí, ṣugbọn àwọn oriṣa kò ní lè gbà wọ́n lọ́jọ́ ìṣòro.
Lin Gaoyuan bo sipo keta lati ipo karun un ti o wa tele, ti Xu Xin si jawa le lati ipo karun un sikefa.
Iroyin ayo lo je fun iko agbaboolu Brazil lana lasiko igbaradi fun ifesewonse ipele ti o kan ninu idije boolu agbaye to n lo lowo lorile-ede Russia, leyin ti Marcelo ati Douglas Costa darapo mo iko ohun leyin ifesewonse otooto meji ti won ko le kopa lataari ifarapa ti won ni.
Ninu atẹjade ti wọn fi si ori itakun ibanisọrọ Facebook wọn, ile iṣẹ ọmọogun naa ni aṣiri ti ile iṣẹ iroyin naa fi lede mu ki awọn ikọ agbesunmọmi Boko Haram mọ gbogbo irinsi wọn, eleyi ti o le fa ikọlu si orilẹ-ede naa.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Kano lack of burial ground: Àìtó ibójì ti ń fa awuyewuye ní ìpínlẹ̀ Kano- Àwọn òṣìṣẹ́ ibojí 13 Ògún 2020 Awọn oṣiṣẹ iboji ni ipinlẹ Kano ti bẹrẹ si n ke sita nitori aito iboju ni ipinlẹ ọhun.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Sogidi Lake: Kòṣẹja-kòṣèèyàn lá bá nínú adágún odò náà -Ojedele Yoruba ni ma fi oko mi sọna, ọjọ kan ṣoso laa kọ, nigba to di ọjọ kan, aaro kan Lisabi lẹyin ti gbogbo awọn ọrẹ rẹ ti gba tan.
Òṣèré tíátà, Ọmọba Femi Oyewunmi tí ọ̀pọ̀ mọ̀ sí Laditi ti jáde láyé Femi Adebayo di àgbà àáfà òníláwàní, Iyabo Ojo fi sìgá dárà, Allwell Ademola di ọmọdé padà, tí Wazo si bímọ tuntun Awọn òṣèré Yoruba tí wọ́n bí ní ọjọ kan náà Ẹ wo àwọn gbajúmọ̀ òṣèré tíátà tó jogún eré ṣíṣe lọ́dọ̀ òbí wọn Agba Inaki wa n rọ awon eeyan to ni iru ipenija bayii, tabi ti wọn wa ni ikorita 'ko ye mi mọ', pe ki wọn ṣe suuru, ki wọn si gba pe ti ẹmi ba wa, ireti n bẹ.
Awọn adigunjale naa gbe apoti owo nla kan ninu ọkọ banki yii, eyi to kun fun ẹgbẹrun mẹtala pọun, owo nla si ni laye igba naa, Awolọwọ si ni minisita feto isuna laye igba naa Ọga agba fawọn ọlọpaa nigba ta n wi yii, Kam Salem Kiamssa paṣẹ pe ki wọn se awari awọn adigunjale to huwa laabi yii, ko si pẹ, ko jinna, lọwọ tẹ asaaju ikọ apamọlẹkunjaye ọhun, Felix Dumeh, ti gbogbo eeyan ilẹ Naijiria si n yọ pe akara tu sepo Nigba ti Felix de ahamọ awọn ọlọpaa, se lo n ka boroboro pe ki wọn se oun jẹjẹ nitori pe oun nikan kọ lo gbimọpọ ja ole naa, O ni awọn ni baba nigbẹjọ, ti wọn jẹ baba isalẹ fun oun, iromi oun to si n jo loke odo, onilu rẹ wa nisalẹ odo.
Ọ̀gbìn ìrẹsì dìrọ̀rùn, ìjọba àpapọ̀ yóò yá àgbẹ lówó Naijiria bẹrẹ iwadi lori owo iranwọ epo Niger-Delta: Ẹ maa reti ikọlu Èlò la fí leè dáàbò bo aṣòfin Nàìjíríà?
Aarẹ George HW Bush ni aarẹ kọkanlelogoji lorilẹede Amẹrika lẹyin ti o ti jẹ igbakeji fun aarẹ Ronald Reagan fun saa meji.
Àwọn ìpín díẹ̀ lẹ́hìnnáà ṣe àfihàn iṣẹ́ Wòlíì Joseph Smith ní síṣe ìyírọ̀padà Bíbélì pẹ̀lú ìmísí, láàrin ìgbà tí ọ̀pọ̀lọpọ̀ àwọn ìpín pàtàkì ti ìpìlẹ̀ ẹ̀kọ́ jẹ́ gbígbà (wò, fún àpẹrẹ, àwọn ìpín 37, 45, 73, 76, 77, 86, 91, àti 132, ọ̀kọ̀ọ̀kan èyítí ó ní ìbáṣepọ̀ tààrà pẹ̀lú ìyírọ̀padà Bíbélì).
Ẹni to bori: South Africa South Africa Ọrọ aje South Africa fi diẹ ju ti Amẹrika lọ pẹlu ẹgbẹrun mẹfa Dọla lọdun kan, gẹgẹ bi Banki agbaye ṣe sọ.
    Ọba ńlá kan wà ní ayé àtijọ́, tí ó ní owó dé góńgó, tí ó bí gbajúmọ̀ lọ̀mọ, tí ìgbèríko rẹ̀ pọ́ bí ọ̀kẹ́ àìmọye àwọn alápàńdẹ̀dẹ̀ tí wọ́n ń fò kaakiri ojú ọ̀run.
Gbogbo igbiyanju lati sawari ọmọdekunrin naa si lo ja si pabo, ti awọn agbofinro si mu wolii naa, atawọn ọmọ ijọ rẹ mẹfa lori ẹsun ijọmọgbe Bi igbẹjọ ba se n waye lọjọ Isẹgun, ni BBC Yoruba yoo maa mu wa fun yin.
220,000 ni osisẹ ajọ to n bojuto eto idibo gbogboogbo yii Amọ, ọdọ to to miliọnu mẹfa ni ko ni kopa ninu idibo naa.
Gbogbo eniyan ni wọ́n ń ròyìn Demeteriu ní rere.
Nígbà tí ìwọ wà ní ayé, o ṣe ìtọ́jú mi bí ó ti yẹ, ó bá mi ṣiré nígbà tí ó yẹ kí a bá ọmọ ẹni ṣiré, o jẹ mi ní ìyà nígbà tí ó yẹ kí á jẹ ọmọ ẹni ní ìyà, o kò ro ẹjọ́ bàbá mi ní búburú fún mi bí àṣà àwọn obìnrin mìíràn, o kò ròyìn mi ní búburú káà kiri òde.
Ko tii si aridaju nipa ayanmọ ati ipo awọn ọmọbinrin marun ti o ku ninu awọn ti wọn jigbe pẹlu awọn iroyin wipe wọn ti ku si igbekun.
Bakan naa lo fikun pe, lara awọn eniyan naa ko wọ aṣọ idaabobo loju omi (life jacket) eleyii to ni o ṣe akoba fun wọn.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ẹ gbà mí, Nàíjíríà gbá mi lórí àyẹ̀wò Covid-19 - Iyabo Ojo figbe ta A ti ja aráàlú kulẹ̀, ta bá pè wọ́n fún ìwọ́de, wọn kò ní jẹ́ wa mọ́ - NLC Eko Àlàyé rèé lórí ìdí tí ẹgbẹ́ òṣìṣẹ́ kò fi ní bẹ̀rẹ̀ ìyanṣẹ́lódì mọ́ lónìí Ẹgbẹ́ òkùnkùn yìnbọn lu ọmọ kan ní ikùn lásìkò ìdárò akẹẹgbẹ́ wọn Laycon ni ọmọ ológo tó jáwé olúborí ní ètò BBNaija season 5 'Lockdown' Kí ló wà láàrin Olorì Badra àti Bobrisky, tí ọ̀rọ̀ wọn fi wọ̀?
“Ní tèmi, èrò mi ni pé kí á má tún yọ àwọn tí kì í ṣe Juu tí wọ́n yipada sí Ọlọrun lẹ́nu mọ́.
Ajo to n ja fun eto omoniyan nile okere, International Human
 Èyí ni kò jẹ ́ kí ilẹ ̀ faranse rí ilẹ ̀ gẹ ̀ ẹ ́ sì gbà .
O ni pe oun ṣetan lati gba awọn ọmọ naa tọwọtẹsẹ, niwọn igba ti ayẹwo ba fi idi rẹ mulẹ pe ọkọ oun lo bi wọn.
Agbẹnusọ fun ile iṣẹ ọlọpaa Ipinlé Ondo Femi Joseph sọ pe o ṣeeṣe ki Adeyemi Alao to jẹ ọrẹkunrun khadijat ọmọ Igbakeji Gomina Ipinle Ondo tẹlẹri, Alhaji Lasisi Olubọyọ fẹ lo fun oogun owo.
Wọn bi Kudirat Olayinka Adeyemi ni ilu Zaria lọdun 1951.
Makinde sọ pe ipinnu Oloye Akande lati wọ agbo oṣelu Naijiria lo fun ọpọ oniṣowo ni igboya lati dije fun ipo osẹlu ni Naijiria bayii.
Mo ran yín láti kórè níbi tí ẹ kò ti ṣiṣẹ́ ọ̀gbìn.
Ó gbààwẹ̀, orí aṣọ ọ̀fọ̀ ni ó sì ń sùn; ó sì ń káàkiri pẹlu ìdoríkodò ati ìrẹ̀wẹ̀sì ọkàn.
yoo pawopo lati se gbogbo ohun to wa nikawọ won lati ri i pe aabo to moyan lori
  Bẹ́ẹ̀náàni òkúta ọ̀hún á máa ṣe bí ẹ̀nipé ó nparadà.
Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Covid 19 update: Wo ǹkan mẹ́wàá tó yẹ kí o mọ̀ tí o bá fẹ́ lọ fún ìsinmi lẹ́yìn Covid 1923 Bélú 2020 6:48 Fídíò, Akomolede ati Aṣa lori BBC:Wo ìrúfẹ́ ìgbeyàwó méje tó wà nílẹ̀ Yorùbá àti ojúṣe Alárinà, Duration 6,4810 Bélú 2020 4:26 Fídíò, Akomolede Yoruba: Kí ni ìdí tí aṣọ fi máa ń pọ̀ lára Egúngún ju Orò lọ́?
Ẹni tí ó bá ń sọ̀rọ̀ ti ara rẹ̀ ń wá ògo ti ara rẹ̀.
Òun ni ìpín Mose ninu àgbò ìyàsímímọ́ yìí, gẹ́gẹ́ bí OLUWA ti pa á láṣẹ fún un.
Ọlọ́pàá ni yóò ma mú ẹnikẹni tó bá tàpa sófin ìjọba Eko Àwọn ìbéèrè tó yẹ kí o bi ara a rẹ̀ kí ó tó gba ìròyìn kankan nípa coronavirus gbọ́ Ọ̀rọ̀ Coronavirus kì ń ṣe ṣeréṣeré o-K1 de Ultimate, Toyin Abraham Ọjọ Satide ni arakunrin naa de papkọ ilẹ wọ ni Asmara International Airport, ti wọn si ya a sọtọ fun ayẹwo to fihan pe arakunrin naa ti ni arun Coronavirus.
Iroyin so pe, Zuma gba pe, oun yoo kowe fi ise sile, amo ki won fun oun ni osu meta pere lati kopa nibi ipade ajo isokan ile Africa ti o n bo, ni eyi ti igbimo ohun faake kori.
Iya to bi jẹ ọmọ Emir ti aburo rẹ naa si jẹ Emir.
” Ṣugbọn àwọn ọmọ Bẹnjamini kò gba ohun tí àwọn arakunrin wọn, àwọn ọmọ Israẹli ń wí.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Akpabio list: James Manager, Peter Nwaboachi, Samuel Anyanwu fèsì sí ẹ̀sùn ti Godswill Akpabio NDDC fi kàn wọ́n 17 Agẹmo 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 27 Agẹmo 2020 Oríṣun àwòrán, OTHER Àkọlé àwòrán, Sen.
Adé ayọ̀ ni wọn óo dé sórí,wọn óo láyọ̀, inú wọn yóo dùn;ìbànújẹ́ ati ẹ̀dùn wọn yóo sì fò lọ.
Ati pe ki énikẹni ma ṣe da ina kankan lasiko yii nibẹ.
Akonimoogba agba iko agbaboolu Croatia, Zlatko Dalic so pe, oun yoo gbe awon ojulowo agbaboolu oun mejo joko ninu ifigagbaga keyin ipele akoko idije agbaye to n lo lowo ni Russia ti won yoo gba pelu orile-ede  Iceland.
17 Bélú 2020 9ice Marriage: Ẹ ba mi bẹ ìyàwó mi, òun ni igi lẹ́yìn ọgbà mi22 Bélú 2020 Akomolede Eko round up: Àwọn Olùkọ́ ìpínlẹ̀ Eko dárà lórí Akọ́mọlédè àti Àṣà lórí BBC7 Bélú 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Ida ẹẹdẹgbẹta mili-lita ni jala ẹjẹ ti wọn maa n saba fa ni ara.
’ rèé Ẹ̀yin èèyàn Oyo, ẹ sọ tẹnu yín lórí àbá àjẹbánu tí Makinde dá - SERAP Orí mi wú, Joke Silva kọ ewì ìfẹ́ lọ́jọ́ ìbí Olu Jacobs Ọkùnrin mẹrin wọ gàù torí ìgbéyàwó orí Facebook Ìgbín ní èmi àti ìyá mi máa ń he kiri, ká tó lee jẹun - Lizzy Anjọrin Ọladẹjọ salaye pe, irọ to jinna sootọ ni ahesọ ti awọn eeyan kan n gbe kiri pe awọn adigunjale naa fi tipa awọn awọn akẹkọbinrin ọhun lo pọ.
2021 yoo je bilonu márùndínláàdọ́rùn ún le die owo dola(85.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Alaafin: Olori Aanu Adeyemi ṣàlàyé ìdí tó ṣe gẹ́ Oba Lamidi Adeyemi ti ìlú Oyo Ọjọ kejilelogun, oṣu Kẹjọ, ọdun 2020 ni ajọ JAMB ti kọkọ dari awọn ile ẹ̀kọ́ giga lati bẹrẹ eto igbani wọle.
Lẹ́sẹ̀kan náà òkúta yìí bá fọ́ gbogbo ère náà, ati irin, ati amọ̀, ati idẹ, ati fadaka ati wúrà, ó rún gbogbo wọn wómúwómú, títí wọ́n fi dàbí ìyàngbò ní ibi ìpakà.
Bi o tilẹ jẹ pe a ko jẹbi bọ lati ile ẹjọ, se ni Boboye tun tun ẹjọ pe nile ẹjọ naa dipo ko pe ẹjọ kotẹmilọrun, a si n rọ ijọba ki wọn gba wa lọwọ rẹ."
n aka x7 , tóyìn abraham ti fara hàn nínú ọ ̀ pọ ̀ lọpọ ̀ eré , tí ó sì tún ṣẹ ̀ ṣẹ ̀ kópa nínú sinimá àgbéléwò aré tí orúkọ ̀ rẹ ̀ ń jẹ ́ black val .
Igbesẹ Appiah yii ko sẹyin ipade ti ajọ to n mojuto ọrọ bọọlu ni Ghana ṣe lati mu ki ohun gbogbo pada sipo.
Wọ́n fi igi akasia ṣe òpó mẹrin, wọ́n sì yọ́ wúrà bò ó.
Gẹgẹ bi wọn ṣe maa n ṣe, ẹgbẹ ni igbimọ eleto ilera tiwọn to ti sare ṣe asúgbàá awọn to farapa lọ si ile iwosan.
Kọmisọnna fun ọrọ ilera, Wahab Adegbẹnro lo ke gbajare naa lasiko ti iroyin jade wi pe Lassa Fever tun ti pa eniyan kan ni ipinlẹ Ondo.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Oyenusi ló mú mi wọ ẹgbẹ́ adigunjalè kó tó di pé mo b'Ólúwa pàdé' Bẹẹ ni ọwọ ọlọpaa ba lara awọn eeyan ko n gbe ori ọba jo kiri ilu naa, ti wọn si ko wọn wa silu Ibadan fun ẹsun ipaniyan ati idaluru.
O wa gbadura pe Ọlọrun yoo dẹ ilẹ fun ẹni re to lọ naa.
Òdú ni bàbá yìí, kìí ṣe ẹni tí olóko kò mọ̀n.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Fanny gbà kádàrá lórí àwọn orin rẹ̀ kí wọn to ṣe alakọkọ lọdun 2012 Arun igbẹ ọrin yii maa n pa eniyan ti ko ba tete ri itọju to peye lẹyin ti inu rẹ ba ti n daru.
"Ijọba Obama ti n pete awọn akanṣe aato kan nilẹ Afrika eyi to si n kọ awa adari Kristẹni kan lominu.
Oríṣun àwòrán, CHISOM CHUKWUNEKE Àkọlé àwòrán, Bayii ni Chisom Chukwuneke ṣe ri lasiko to n gba itọju aisan jẹjẹrẹ inu ẹjẹ Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí World Cancer Day: Ènìyàn 26,000 ni àìsàn jẹjẹrẹ ń pa lóòjọ́4 Èrèlè 2019 Fídíò, Cancer: àpọ̀jù ṣúgà nínú ẹ̀jẹ̀ ń ṣàkóbá fún àgọ́ ara èèyàn1 Owewe 2019 Iléèṣẹ́ ọlọ́pàá mú ọkùnrin ẹni ọdún 55 tó gé ẹ̀yà ara èèyàn nílẹ̀ ìsìnkú ṣọ́ọ̀ṣì l'Ogun25 Bélú 2020 Ìbẹta, Oba Lamidi Adeyemi, Alaafin Oyo pé ọdún méjìlá; nkan tó yẹ kí o mọ̀ nípa wọn nìyíì26 Bélú 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
    “Bí ẹni tí ó ń polóeó ọjà èèmọ̀ yìí ti ń pa á ni à ń gbọ tí àwọn kan ń pè é tí wọ́n ń rà á lọ́wọ́ rẹ̀.
Diẹ lara awọn ere to ti kopa ni Magun Thunderbolt (2001); Afọnja (2002); Baṣorun Gaa (2004); Sawo-Sọgbẹri (2005) Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Itan Ilu gangan Adebayo Faleti gba oye ati ami ẹyẹ to pọ loriṣiriṣi bii OON, Justice of Peace, Afro-Hollywood Award for outstanding Performance in Arts ni America lọdun 2002, Breeze Award (Baṣọrun Gaa) ni London lọdun (2004) ati awọn miran.
O ni ileesẹ nigba kan nilẹ Gẹẹsi, ti ko si si ibi to le sapamọ si nitori awọn akọsilẹ nipa rẹ lori ayarabiasa.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Akinyele murder: Àwọn aṣekúpani tún ti pa ọmọ ọdún 16 ní Akinyele nípìnlẹ̀ Oyo 22 Agẹmo 2020 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Àwọn aṣekúpani tún ti pa ọmọ ọdún 16 ní Akinyele nípìnlẹ̀ Oyo Ọmọdebinrin ọmọ ọdun mẹrindinlogun kan, Toke, ti di ero ọrun lẹyin ti awọn kan pa a nijọba ibilẹ Akinyele, nipinlẹ Oyo.
ilu ati agogo lai yọ ohun gooro pipe iṣẹ ni ilana ti ologun ni wọn fi sin Tolulope Arotilẹ de itẹ ikẹyin rẹ.
Bisọọbu Oyedepo, lo sọ loju opo Twitter rẹ pe egun ọda owo yoo ja ẹnikẹni ti ko ba da ida mẹwaa fun ijọ Ọlọrun.
Ọjọ 'April Fool' kii se ọjọ isinmi amọ ẹgbẹgbẹrun eniyan lagbaye lo máa n sayajọ ọjọ yii lati sọ nkankan tabi ominiran nipa bi April Fool se bẹrẹ ni agbaye.
Àwọn ọmọ Israẹli ṣí kúrò, wọ́n lọ pa àgọ́ wọn sí pẹ̀tẹ́lẹ̀ Moabu ní òdìkejì Jọdani tí ó kọjú sí Jẹriko.
odaran yii si n ran won lowo lati ri awon odaran miiran ti won dijo n lowo ninu
Wọ́n mú awọ ìpọnmi tí ó ti gbó, tí wọ́n sì ti lẹ̀, 
Orí mi má mà jẹ́ n pàdánù omi
ACF ni awọn gbagbọ pe laipẹ Naijiria yoo bori gbogbo iṣoro to n la kọja, ni ọna ati mu irọrun ba awọn ọmọ Naijiria.
Dòkítà tó ṣe iṣẹ́ abẹ fún oyún inú l‘Amẹrika ló ń sọ Yorùbá yìí, bíi ẹní la oyin Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí kan sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, John Amanam: Ìfẹ́ tí mo ní sí àbúrò mi ló sọ mi dí ẹni tó ń ṣe 'Prosthetic' báyìí Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Coronavirus in Nigeria: Èèyàn mẹ́jọ kú , 1585 míràn tún ṣẹ̀ṣẹ̀ lùgbàdì ààrùn náà ní Nàìjíria10 Sẹ́rẹ́ 2021 11:51 Fídíò, EndSARS, EndSWAT Protests: Òbí agbábọ́ọ̀lù Kazim Tiamiyu Kaka àtàwọn míì tí ọlọ́pàá pa sọ̀rọ̀, omijé bọ́ lójú, Duration 11,513 Bélú 2020 Fídíò, Akinwumi Isola: Wo ohun tí Abeni fi ojú ọkọ rẹ rí tórí iṣẹ́ bọ́ lọ́wọ́ rẹ̀ nínú ìwé Nitori Owo""27 Ọ̀wàrà 2020 Fídíò, Soyinka Cancer: Àṣe ara mi ni iso ti n run gbogbo bí mo ṣe n ṣèrànwọ́ lórí jẹjẹrẹ27 Bélú 2019 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!"
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Police Brutality: Ọlọ́pàá kan sọ pé òun ní láti ṣàyẹ̀wò ìlédìí ǹkan oṣù Arabìnrin kan kó tó lè kọjá 22 Agẹmo 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 25 Agẹmo 2020 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ọlọpaa kan to fẹ ṣe ayẹwo ìdígò ńkan oṣu obinrin kan láyé ń bẹnu atẹ lu bayii.
to n sise lorile ede yii ko lee too.
Gẹgẹ bi a ti ka ni oniruuru awọn oju opo ikansiraẹni lori itakun agbaye, kii kuku se pe Basọrun Gaa ko ni ipa rere to ko si idagbasoke ilu rẹ, Ọyọ ile.
yii je abala keji eleyii ti awon fi so ori ogo weere  ti ojo ori won ko ju merinla lo, nigba ti o si
Mo ní ìgbàgbọ́ pé ìjìyà gbogbo ń bọ̀ wá dópin…Mo ní ìrètí pé ọjọ́ kan ń bọ̀ tí mo máa wọ aṣọ Chuba mi lọ sí Tibet.
"Lọdun 2016, ""awọn mẹrindinlogoje la gba silẹ ti a si mu awọn afini ṣ'owo ẹrun mejidinlogoji, awọn to n lo wọn meje le ọgọrun pẹlu eniyan mọkanla ti wọn ti gba."
Eyi lo sun ajọ kan to nja fẹtọ araalu, SERAP lati gbe amofin agba orilẹede Naijiria lọ si iwaju ileẹjọ nibi ti o ti rọ ileẹjọ lati kan-an ni ipa fun-un pe ko gbe awọn ipinlẹ ti ọrọ kan naa lọ si ileẹjọ lati wọ igi le ofin naa lẹyẹ-o-sọka.
iwe adehun  naa, ni eyi ti aare
Awọn ọmọ Naijiria ọhun fesi si ibeere kan ti BBC News Yoruba fi sita loju opo Facebook rẹ pe 'Ti ẹ ba ni anfaani iṣẹju meje pẹlu Aarẹ Buhari, ki lẹ o ba a sọ?
Aisan ni yoo ko ba ẹni bẹẹ eleyii ti o si lee ja si iku fun un.
Jesu bá ń bá wọn lọ.
Nítorí àwọn ọmọ àgàn pọ̀ ju ti obinrin tí ó ní ọkọ lọ.
ohun mere-mere ijosin sinu isele ijamba ina naa.
1 Èbibi 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, A se àgbéyẹ̀wò ipa tí N30,000 gbèǹdeke owó osù tí ìjọba sẹ̀sẹ̀ fọwọ́ sí gẹ́gẹ́ bí òní se jẹ́ Àyájọ́ Ọjọ́ àwọn òsìsẹ́ ní Naijiria.
"Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Christmas: Ẹni ti ọdun ba ti bá láyé yẹ kó dúpẹ́ Bí ètò ìdìbò ṣe n wáyé Gbọngan ile isin Sistine Chapel ni eto idibo naa ti maa n waye, ""nibi ti ohun gbogbo ti faaye gba iwa laaye Ọlọrun, niwaju ẹni ti gbogbo eniyan yoo ti gba idajọ ni ọjọ kan""."
Ewe, die gbagbo pe, eto idibo le waye laisi agbekale ilana ofin, bakan naa ni egbe awon omo-ogun ti won pin ti fi dani loju pe, awon yoo fara mo abajade esi idibo naa bi o ba se ri.
atundi fun ipo gomina si n lọ lọwọ ni ipinlẹ Adamawa ati pe awon oludibo si n
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Báwo lo se gbọ́ èdè Yorùbá sí ?
Onnoghne ni ohun ko jẹbi ẹsun ti wọn fi kan.
Awọn ile iṣẹ iroyin tí igbá ọ̀rọ̀ náà kan náà ṣí mọ lóri ni Channels, TVC, NTA, AIT, Vision Fm, Arewa radio, Radio Lagos àti àwọn míràn.
Nitori èyi ni Yorùbá fi npa lowe pé “Kàkà ki Kìnìún ṣe akápò Ẹkùn, onikálùkù yio má ba ọdẹ rẹ̀ lọ”.
Yóo ṣẹlẹ̀ bẹ́ẹ̀ níṣojú yín, ní ìgbà ayé yín.
) Pẹlu apá ìsàlẹ̀ Beti Horoni, 
Aarẹ ni ijọba ko ni jẹ ki awọn kan fi imọtara ẹni ba ọrọ aje Naijiria jẹ nitori wipe, Apapa jẹ agbegbe gboogi ninu ọrọ aje Naijiria nitori ebute to wa nibẹ Ẹ̀mí mẹ́ta ṣòfò nínú ìjàǹbá ọkọ̀ nípìnlẹ̀ Èkó Buhari ń bọ̀ l'Eko: Àwọn ọ̀nà láti yàgò fún àyàfi tí ẹ ba gbé ibùsùn dání Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Àwọn èèyàn àti awakọ̀ ké igbe ìrora bí àwọn ọkọ̀ ńlá ṣe dí ọ̀nà mọ́rosẹ̀ Apapa-Oshodi pa Kayode Opeifa to jẹ igbakeji igbimọ amuṣẹṣe lori ọrọ naa ni, ijọba ti n gbe igbesẹ lati kọ awọn ibudokọ fun awọn ọkọ ajagbe to ba fẹ ko ẹru ni Apapa.
Fredie Blom: Ọkùnrin tó dàgbà jù lágbàyé jáde láyé lẹ́ni ọdún 116 ní South Africa
Ilé ẹjọ́ sún ẹjọ́ Sẹ́nétọ̀ Abbo síwájú pẹ̀lú béèlì mílíọ̀nù márùn-ún Agbẹnusọ fun ile isẹ Custom, Joseph Attah lo fidi eyi mulẹ lasiko to n ba BBC sọrọ.
Nigba to ya, oju aanu n pa obinrin ẹlẹwa yii ku lọ, tori ọpọ gbese tawọn eeyan jẹ ẹ, ko jẹ ko ri owo ta ọja mọ, ti odiwọn ikoko ẹwa to n se si n din ku lojoojumọ.
15 Ọ̀wàrà 2018 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 17 Èbibi 2020 Oríṣun àwòrán, Forest department Àkọlé àwòrán, Orílẹ̀-èdè India tó ní ẹranko igbó tó pọ̀jù lágbàáyé ń kojú ìsòrò òhún tó yẹ kí wọ́n se láti kojú àwọn ẹranko igbó to n pa àwọn ènìyàn.
Carter Bridge Lagos, Ijọba ibilẹ Ikeja Lagos Mainland 30.
Lateef Adedimeji: Adebimpe Oyebade kọ́ ni àfẹ́sọ́nà mi, ọ̀rẹ́ lásán la jẹ́
Lara wọn ni onikẹkẹ alupupu to gbe e, Ismaila Lukman ati iya oloogbe, arabinrin Mojisọla Martins.
Akọroyin BBC Yoruba to wa nibi isẹlẹ naa ni, deede aago mẹrin aarọ ọjọ Aiku ni awọn ẹrọ kata-kata ijọba ipinlẹ Ọyọ de si adugbo Challenge, nilu Ibadan ti ileesẹ naa wa, ti wọn si wo lulẹ.
N jẹ Arsenal ò ti dà òkùtà sí Newcastle nígbá báyìí?
Kò sí ọjọ́ kan tí mo ń rántí Revd.
Nígbà tí Samila kú, Ṣaulu ará Rehoboti létí odò Yufurate, jọba tẹ̀lé e.
Ìjìyà ti wà nílẹ̀ fún ẹlẹ́yà,a sì ti tọ́jú pàṣán sílẹ̀ fún ẹ̀yìn òmùgọ̀.
Ni ilẹ Yoruba ọpọlọpọ eewọ lo de Ọba alaye.
Ó máa ń gbàdúrà ni alaalé kí ó tó sùn.
lasiko ajodun keresimesi ni jake jado orile ede Naijiria.
Wo ìdí tí Osun fi kede ìsinmi fún ọdún ìṣẹ̀ṣe, tàwọn ìpínlẹ̀ yókù kò dáhùn, Ọ̀fẹ́ ni iforukọsilẹ: Lẹyin naa ni ki o ti ọwọ bọ fọọmu to wa nibẹ.
Ẹwẹ, agbẹjọro Hushpuppi, GalPisseyzky sọ fun awọn akọroyin abẹlẹ pe wọn kan gbe onibara oun kuro ni ọgba ẹwọn Chicago lọ si ti Califonia ni, kii ṣe pe o ti kuro lẹwọn.
Ida owo ti ijọba apapọ na to poju lẹka ilera Naijiria jẹ ida mẹfa 6% lọdun 2012 sugbọn ninu owo isuna 2018 ati aba isuna 2019 owo ida mẹrin 4% pere ninu ida ọgọrun ni wọn ya sọtọ.
Àkọlé àwòrán, Ẹgbẹ Canal naa ni wọn sin oku ọmọ naa si ni ilana Islam Iroyin fikun un wi pe ounjẹ ni iya Aishat n ta ni agbegbe Omololu ni Suurulure, ti baba rẹ si n ṣe oṣelu ni abẹle.
Ọkunrin kan ti ko fẹ ka darukọ rẹ sọ fun BBC pe, ọọ idajọ iku yii fun awọn afipabanilopọ yo ṣeranwọ lati mu adinku ba bi iwa ọdarsn ṣe n pọ sii.
Àwọn ọmọlẹ́yìn Dafidi rí ọmọkunrin ará Ijipti kan ninu oko, wọ́n sì mú un wá sọ́dọ̀ Dafidi, wọ́n fún un ní oúnjẹ ati omi, 
Bí mo bá ṣe àìdára, mo gbé,ṣugbọn bí mo ṣe dáradára, n kò lè yangàn,nítorí ìbànújẹ́ ati ìtìjú bò mí mọ́lẹ̀.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Rochas Okorochas ní ìlàkàkà àti gbé ìpínlẹ̀ Imo sókè ti sọ mí di ọlọ́dẹ orí 18 Èbibi 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ọpọ awuyewuye lo n wọ tọ gomina Rochas lẹyin bayii ni ipinlẹ rẹ ati laarin ẹgbẹ oṣelu rẹ.
Gẹgẹ bi akọsilẹ iroyin loju opo itakun agbaye taa ti ko iroyin yii jọ ti wi, Taiwo Sonaike gbajumọ bii baba alajọ nigba aye rẹ ladugbo Owotutu, Bariga, Awolọwọ, Oyingbo ati bẹẹ bẹẹ lọ.
N kò ní yẹ ìfẹ́ ńlá mi tí mo ní sí i, bí mo ti yẹ ti Saulu, tí ó ṣáájú rẹ̀.
Ọjọ Aje ni ile ẹjọ gbe idajọ kalẹ pe, ki ayalegbe naa san owo ọhun fun ayalegbe ẹgbẹ rẹ, Bunmi Ọdẹniyi, nitori pe eefin ẹrọ amunawa rẹ n wọ ile Ọdẹniyi, nile ti awọn mejeeji n gbe ni Gbagada, nilu Eko.
O ni awọn mejeeji ti n ṣwi tẹnu wọn fajọ EFCC.
oṣu pẹlu awọn ẹtọ miiran gẹgẹ bo ṣe wa ninu ofin to nii ṣe pẹlu iṣẹ
Ariwo ti ibugbamu naa mu lọwọ lo gbalẹ kan, ti awọn eeyan si n sa asala fun ẹmi wọn, a ko si ti lee sọ iye ẹmi to ti ba isẹlẹ naa rin.
Fun Ogbe Enhakkore @MyNameIsOgbe, o ni oun mọ pe bi wọn ṣe yẹ Fatoyinbo si, ni shiloh, bi ọpọ eeyan ninu.
34 Bẹ́ẹ̀ni, fún ìdí èyí mo ti sọ pé: Dúró, kí o sì dúró jẹ́ẹ́ títí tí èmi ó fi pàṣẹ fún ọ, èmi yíò sì pèsè ọ̀nà àbáyọ nípa èyítí ìwọ yíò le ṣe àṣeyọrí ohun èyití mo ti paláṣẹ fún ọ.
O si ti setan lati se  atileyin fun wa lati seranwọ eto eyawo ati idagbasoke lori eto inawo.
Yàrá bàbá mi ni wọ́n gbé e lọ.
Kọmiṣọna fun eto ilera ni ilu Chicago, Dokita Allison Arwady ṣalaye fun awọn akọroyin pe igbelewọn ẹmi awọn alawọ dudu ni ipinlẹ naa ti ja wa silẹ pẹlu ọdun mẹsan din diẹ ju tawọn to jẹ alawọ funfun lọ.
Oríṣun àwòrán, Twitter/Eddie Heran Àkọlé àwòrán, Ija Anthony Joshua ati Eddie Heaen Ọpọ lo n sọ lori ayelujara pe, o dabi ẹni pe ooyi n kọ Joshua nigba ti ija naa n lọ lọwọ, eyi to ṣokunfa bi o ti fidi rẹmi ninu ọja ọhun.
Gowon so pe “Ki Olorun gbo gbogbo awon adura rere wa ati gbogbo erongba rere orile ede yii.
Mo pa òfin rẹ mọ́, OLUWA,má jẹ́ kí ojú ó tì mí.
Wo nkan tí ìjọba UK sọ lórí ìwé ẹ̀sùn tí àwọn ọmọ Nàìjíríà kọ si lórí ENDSARS Oríṣun àwòrán, EPA Àkọlé àwòrán, Awọn oluwọde ENDSARS to gbe asia orilẹ-ede Naijiria dani ni agbegbe Ikeja nilu Eko, lọjọ kẹẹdogun, oṣu Kẹwaa, sun 2020 Ijọba orilẹ-ede United Kingdom, ti fesi lori iwe ẹsun ti awọn ọmọ Naijiria fọwọ si, ti wọn si fi ransẹ si.
Eyi jẹyo lẹyin ti awọn eekan ẹgbẹ APC nipinlẹ Ogun se ipade nile akọwe ijọba ipinlẹ Ogun nigba kan ri Oloogbe Poju Adeyemi lori ọna ti wọn yoo fi yan oludije ẹgbẹ fun ipo Gomina.
Ninu ọrọ tirẹ, Igbakeji ọga agba ọlọpaa to wa ni ẹka iwadii iwa ọdaran, Peter Ogunyonwo to ṣoju ọga agba ọlọpaa, Mohammed Adamu naa ba ẹbi ati ara kẹdun.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Blind DJ: Etu Omotayo kò ríran àmọ́ ó le to irinṣẹ́ eléré pọ̀ láti kọrin láì sí ìrànwọ́ Ọrọ yi bi ọgagun Idiagbon ninu ti o si paṣẹ ki baalu ilẹ Gẹẹsi kan to ti gbera kuro ni Naijiria pada si papakọ ofurufu Murtala Muhammed nilu Eko.
Ibẹ maa n yọ awọn ẹranko ti wọn ba n kọja lati igba de igba ni.
Ọṣẹ yòówù tí mo lè fi wẹ̀,kódà kí n fi omi yìnyín fọ ọwọ́,
Gbogbo ohun ìní rẹ̀ ni ó ti run sórí àìsàn náà.
Ṣùgbọ́n èyí tí ó tilẹ̀ wáá dùn mí ni pé ṣe ni mo rí ọkùnrin náà ti ó fi ìdí lé àpáta tí ó tun fi ara mọ́ mi tímọ́tímọ́ bí ìgbà tí ọmọdé fi ara mọ́ abiyamọ, mo ní ǹkan parí náa wwàyí, ìjàngbọ̀n lé mi kúrò ninu ilé mo bá ìjàngbọ̀n lórí àpáta, mo bu òkèlè kọjá ibi ti ẹnu mi gbà, mo fi omi tútù ro èlùbọ́, mo fi àkàrà jẹ ìrẹsì, mo gbé gaàrí fún òyìnbó wà mu.
Awọn kan yan iṣẹ orin kikọ laayo, amọ wọn o ri ṣe nibẹ nitori iṣẹ orin kọ lori ran wọn.
Man United vs Chelsea: Ajá to bá wọlé tí ẹkùn yóò fẹjẹ̀ wẹ̀
Nítorí pé wúrà ati fadaka ló mú wọn dẹ́ṣẹ̀.
Bí ìyàwó mi bá sọ̀rọ̀ ẹ̀dùn ọkàn rẹ̀ hàn mi, n ó fún un ní èsí tí ó yẹ.
Ṣugbọn, o jẹ ọgbẹ ọkan fun mi.
Dafidi iranṣẹ mi ni yóo sì jẹ́ ọba wọn títí lae.
Ǹjẹ o yẹ kí èèyàn máa sùn lẹ́nu iṣẹ́?
Ẹ̀yin ọmọ, ẹ máa gbọ́ ti àwọn òbí yín nítorí pé bẹ́ẹ̀ ni ó dára.
Ẹgbẹ́ òṣìṣẹ́ fi ẹsun kan mínisita pé ó n yan àwọn jánduku láti máa koju ija si awọn osisẹ.
Ọjọ kẹfa, oṣu Keje, ọdun 1967, si ni ogun naa bẹrẹ ni pẹrẹwu, nigba ti awọn ọmọ ogun Naijiria gba ọna meji wọ ilẹ Biafra.
Ọba Israẹli bá dáhùn pé, “Ẹ mú Mikaaya pada lọ fún Amoni, gomina ìlú yìí, ati Joaṣi ọmọ ọba.
11 Ògún 2020 Oríṣun àwòrán, EPA Ọjọ aiku ni aarẹ Alexander Lukashenko jawe olubori fun saa ikẹfa lori ye lẹyin idibo tawọn eeyan n kun yunmu yunmu le lori eyi to si ru ibinu awọn afẹhonuhan soke ti wọn tu si gbogbo igboro jakejado orilẹede naa.
Nigeria Independence Day: Ẹ wo kókó àwọn ọrọ́ tí Aàrẹ Buhari sọ ní October 1
O tun ni ki Geoffery Onyeama tete mojuto awọn adehun ti wọn ṣe pẹlu ijọba South Africa lati rii pe iru ikọlu yii ko waye mọ sawọn ọmọ Naijiria to fi South Africa ṣe ibujoko.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Láì rọ lápa rọ lẹ́sẹ̀, ẹ wo ọmọ ọdún mọ́kànlá tó ń lọ́ ara lóríṣi ọ̀nà O fikun pe ikọ Amotekun ko ni gbe ibọn rara, isẹ gboogi ti wọn yoo maa se ni ifimufinlẹ, isẹ ọtẹlẹmuyẹ ati kiko iroyin iwa ọdaran jọ ati fifi iwa ọdaran to awọn agbofinro leti, to si wa fọwọ gbaya pe awọn ikọ Amotekun yii ko ni maa jẹ abẹsinkawọ fun awọn gomina ipinlẹ rara.
yii, o si je agbaboolu ti akonimoogba yoowu ti o n ba n dari iko yoo nife lati
Lọdun 1982, ija nla waye laarin Kollington Ayinla, to jẹ ọrẹ rẹ, ati olorin Fuji mii.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Lizzy Anjorin vs Toyin Abraham: Wo àwọn òṣèré Tíátà t'ọ̀rọ̀ ìjà ta mọ́ etí aṣọ wọn tẹ́lẹ̀ rí 19 Owewe 2019 Oríṣun àwòrán, Other Àkọlé àwòrán, Awọn Oṣere Bi ti n ri, laipẹ ni gbọnmi si i omi o to o tun bẹ silẹ lagbo ere tiata Yoruba laarin molumọka oṣere to ṣẹṣẹ di iya aburo, Toyin Abraham ati akẹgbẹ rẹ Lizzy Anjorin.
Ẹ̀wẹ̀, o jọ bi ẹni pé ipińlẹ̀ Plateau ń burẹkẹ si ni nítori ojojúmọ́ ni àwọn ènìyàn to n lùgbàdì ààrùn náà ń pọ̀ si níbẹ̀ bi wọ́n ṣe ti ni ènìyàn marun lélọ́gọ́rín lọ́jọ́bọ.
Emirate Cup: Lyon figbájú olóòyì méjì gba Emirate Cup lọ́wọ́ Arsenal
Eyi ti sun iye awọn to ti lugbadi arun naa siwaju di mẹrinlelọgọsan an.
Ni bayii, Arsenal yoo koju Valencia lọjọ keji oṣu Kaarun labala to kangun si aṣekagba idije Europa.
OLUWA àwọn ọmọ ogun tí ó gbìn ọ́, ti ṣe ìdájọ́ ibi fún ọ, nítorí iṣẹ́ ibi tí ẹ ṣe, ẹ̀yin ilé Israẹli ati ilé Juda; ẹ mú mi bínú nítorí pé ẹ sun turari sí oriṣa Baali.
Ibinu rẹ̀ ń bọ̀ bí ìjì líle.
Yóo mú kí ìdúróṣinṣin wà ní gbogbo àkókò rẹ̀.
darajulo – Jill Ellis (United States)Asole okunrin ti o darajulo  – Alisson Becker (Liverpool ati Brazil)Asole Obinrin ti o darajulo  – Sari Van Veenendaal (Atletico Madrid ati
Abeli jẹ́ ọ̀kan ninu àwọn ìlú tí ó fẹ́ alaafia, tí ó sì jẹ́ olóòótọ́ jùlọ ní Israẹli.
Pinnick fikun-un pe“Alaga igbimo ohun, Alhaji Abba Yola ko nilo sise afihan re rara.
O salaye wipe ọrọ naa tapasi gbogbo iye owo ribiribi ti wọn n naa lori ohun ija ti wọn n ko wọle si orilẹede Naijiria, ati wipe ikọ naa n sọọsẹ ni agbeegbe Lake Chad.
Ìwárìrì á bò ó mọ́lẹ̀ bí ìkún omi,ní alẹ́, ìjì líle á gbé e lọ.
Ogbontarigi akorin omo orile-ede Tanzania Diamond Platnumz ti toro aforoji fun fonran ti o gbe sori ero kalekako Instagram, eyi ti o se afihan re nibi ti o fenuko obirin lenu.
Kí ló ha tún kù fún mi lẹ́hìn irú èyí!
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ìlú Eko ló jẹ gbèsè jù ní Nàìjíríà lẹ́yìn ìjọba àpapọ̀ Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Lakanu ṣiṣẹ ọlọpa fun ọpọ ọdun ko to fẹyinti lọdun 2019.
Àmọ́ ọ̀pọ̀ èèyàn tó dá sí ọ̀rọ̀ yìí lójú òpó Twitter lo ń kan saara si bàbá náà lórí bo se n bá ọmọ rẹ wí.
Akoroyin Musvanhiri ni o le ni igba awon osere Marimba ti won korajopo lati opolopo ile iwe ni Zimbabwe ni won papo sile iwe girama Prince Edward ni Harare to je olu ilu Zimbabwe fun odun Zimariba fest.
Gbogbo ìwà burúkú tí ẹ̀ ń hù sí àwọn eniyan ni mò ń gbọ́.
Ní ọdún yìí àjọ tó ń ri sí bí ojú ọjọ ṣe ri ti kìlọ pé àwọn ìpínlẹ̀ marun un ní gúúsù ìwọ̀-oorù Nàìjíríà Lagos, Ogun, Ondo, Oyo àti Osun yóò kojú ẹkún omi yale àgbàrá sọọbù.
Mo pe iranṣẹ mi, ṣugbọn kò dáhùn,bíbẹ̀ ni mo níláti máa bẹ̀ ẹ́.
Ọpọlọpọ kilaasi gan an ni awọn akẹkọọ to n bẹ ninu rẹ ko to ogun, pẹlu bi o ṣe jẹ wi pe, aye akẹkọọ bii ọgbọn ni ijọba ipinlẹ Ọyọ sọ wi pe ki wọn pese silẹ.
Apapọ awọn to ti ni arun naa kaaakiri orilẹ-ede Naijiria ti wa di 24,077 bayii.
"Iya kan to ni ọmọ tuntun lọwọ sọ fun akọroyin BBC pe: ""wọn ko gba mi laaye lati sun pẹlu ọmọ mi, idi niyẹn ti mo fi san owo fun wọn ki wọn le faaye gba mi lati sun si yara ti wọn pese pẹlu ọmọ mi."
Oju awọn alufa ijọ aguda ri to lọwọ ajinigbe ni 2018 Ko ti ju ọsẹ mẹta lọ ti wọn ji awọn obinrin ijọ aguda ti wọn yàn lati má lọkọ marun un gbe ni Ipinlẹ Delta nigba ti wọn n ti ibi isinku kan bọ.
Jọ̀wọ́ má ṣe ka aláìmòye yìí sí, nítorí Nabali ni orúkọ rẹ̀, bí orúkọ rẹ̀ tí ń jẹ́, bẹ́ẹ̀ náà sì ni ìwà rẹ̀ rí.
Ẹ̀fúùfù ló fẹ́ tí igi ṣubú lulẹ̀ tí mo jókòó, àfi ìgbà tí ẹ̀fúùfù kò fẹ́ mọ́ tí igi dìde mọ́ mi ní ìdí tí mo sì bá igi lọ sí òkè tí àti padà di ìṣòro fún mi.
Ọjọ Ẹti, ọjọ kejidinlogun, oṣu Kẹrin ni Aarẹ Buhari buwọlu ofin tuntun naa.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Africa Eye: Olùkọ́ méjì ní fásitì Eko àti Ghana lùgbàdì ọ̀fíntótó BBC lórí ìwà ìbàjẹ́ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Africa Eye: Olùkọ́ méjì ní fásitì Eko àti Ghana lùgbàdì ọ̀fíntótó BBC lórí ìwà ìbàjẹ́ 7 Ọ̀wàrà 2019 Yoruba ni ẹsin kii jẹ koriko abẹ rẹ amọ eyi ko ri bẹẹ fun awọn olukọ fasiti meji kan to n beere fun ibalopọ lọwọ akẹkọ.
O ní àwọn kọ̀ ní káàrẹ̀ láti rí i dájú pé Ìpínlẹ̀ Eko kìí ṣe ibi ti gbogbo àwọn ọ̀daran le dúró sí Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Kàkà kó ká'gbá ń'lẹ̀ kó máa re'lé, ńṣẹ ló tún rọ funfun sílẹ̀ bí èlùbọ́.
Ṣugbọn ní àkọ́kọ́, ọgbọ́n tí ó ti òkè wá jẹ́ pípé, lẹ́yìn náà a máa mú alaafia wá, a máa ṣe ẹ̀tọ́, a máa ro ọ̀rọ̀ dáradára, a máa ṣàánú; a máa so èso rere, kì í ṣe ẹnu meji, kì í ṣe àgàbàgebè.
Abigaili kò sì sọ nǹkankan fún un títí di òwúrọ̀ ọjọ́ keji.
Ni bayii, ọmọ ẹgbẹ mẹtadinlogun ni yoo maa ba a ṣiṣẹ titi di igba ti wọn yoo fi ṣe eto ifinisipo to peye.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìpàdé ìtagbangba BBC Yorùbá: Gbọ̀ngàn Mapo ṣeé mú yangàn ní Ibadan 31 Sẹ́rẹ́ 2019 Ọjọ kan ṣosọ lo ku ti ipade ita gbangba ti BBC Yoruba ṣe agbekalẹ rẹ fun awọn oludije fun ipo gomina nipinlẹ Oyo.
Ṣé lọ́dọ̀ òkú ni ó ti yẹ kí alààyè ti máa wádìí ọ̀rọ̀?
Ẹ máa fò fún ayọ̀, ẹ̀yin ọmọ Israẹli,ta ló tún dàbí yín,ẹ̀yin orílẹ̀-èdè tí OLUWA tìkalárarẹ̀ gbàlà?
Jatiri, Soko, Dana, Kiriati Seferi (tí à ń pè ní Debiri), 
Àwọn aworan yii ṣe alaye bi owo yii ṣe to: 1.
Ti PDP ba mu oke ninu idibo yii, a jẹ wi pe gbogbo awọn asofin Kwara yoo jẹ ti wọn ni sugbọn tio APC ba fi le ri aaye rẹ gba,ohun iwuri ni yoo jẹ fun wọn.
Bakan naa ni wọn tun na Algeria pẹlu ami ayo ẹyọ kan si odo nigba ti wọn pade ni idije AFCON 2002 ti Mali gbalejo ẹ.
Nígbà tí àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rí i, ẹnu yà wọ́n.
Ẹ gáfárà fún àwọn ọkunrin yìí; ẹ fi wọ́n sílẹ̀ o!
Lara awọn to da si ọrọ naa ni Gomina ipinlẹ Ekiti tẹlẹ, Ayodele Fayose to sọ pe, iba ti dara ki Obasanjo sọ ọrọ to sọ lẹyin iku Kshamu lọju rẹ nigba to ṣi wa lori oke eepẹ.
Ṣugbọn ohun tí yóo ṣe, nígbà tí yóo bá wọ ibi mímọ́ náà nìyí: kí ó mú ọ̀dọ́ akọ mààlúù kan lọ́wọ́ fún ẹbọ ìmúkúrò ẹ̀ṣẹ̀ ati àgbò kan fún ẹbọ sísun.
kopa ninu eto naa, awon naa ni Allied Congress Party of Nigeria ,ACPN)Ganiyu
Olumuyiwa Bolade Adedeji Military Bruitality: Bí arákùnrin onípèníjà ara tí sọ́jà lù ṣe dé
OLUWA pe Samuẹli nígbà kẹta, ó bá tún dìde, ó tọ Eli lọ, ó ní “Ìwọ ni o pè mí; mo dé.
Etani arakunrin wọn láti inú ìdílé Merari ni olórí àwọn ẹgbẹ́ akọrin tí ń dúró ní apá òsì rẹ̀.
fi iroyin ohun mule pe,” iro pata-pata ni
Mo lọ, mo bọ́jú, mo sì ríran.
Nítorí nípasẹ̀ rẹ̀ ni àwa mejeeji ṣe rí ààyè láti dé ọ̀dọ̀ Baba nípa Ẹ̀mí kan náà.
julo oro to ba kan omo orile ede Naijiria nilẹ 
Lẹ́yìn náà ó pada sí Jerusalẹmu.
Àjọ NCDC kéde èèyàn 239 míràn tó ni ààrùn Covid-19 lórílẹ̀-èdè Naijíríà Ìjọba yóò ṣe ìwádìí ohun tí kò jẹ́ kí ìpínlẹ̀ Kogi àti Cross River tíì ní coronavirus- Mínísítà Ọmọ ìjọ 20 kú bí wọ́n ṣe tẹ̀ wọ́n pa níbi ìsọjí ìtagbangba Ọọni, Aláàfin, Ojisẹ Ọlọ́run àti oniṣẹ ìwádìí fi Ògún gbari pé òògùn ìbílẹ̀ le wo Covid-19 Ilé ẹjọ́ tó ga jùlọ ní Nàìjíríà wọ́gilé ẹ̀wọ̀n Orji Uzor Kalu, pàṣẹ ìgbẹ́jọ́ tuntun Eko ni ile iwe Favour wa, Fasiti ti ipinlẹ Eko (LASU) nibi to ti n kọ nipa imọ ẹkọ Tiata.
‘Itusilẹ yoo wa fawọn onde Boko Haram’ Awọn agbesunmọmi Boko Haram tẹlẹ gba idande Boko Haram tu awọn olukọni UNIMAID silẹ 'Ologun ko lee koju Boko Haram' Bunu ni ''oku eeyan mẹtalelogun lawọn eeyan wa gbe kuro nibi iṣẹlẹ naa lowurọ oni'' Awọn alaṣẹ ko ti i fi idi ọrọ yi mulẹ fun BBC titi di igba ti a fi ṣe akojọpọ iroyin yi.
Gbogbo àwọn ọmọ Israẹli yòókù, ati àwọn alufaa ati àwọn ọmọ Lefi wà ní àwọn ìlú Juda, kaluku sì ń gbé orí ilẹ̀ ìní rẹ̀.
OLUWA ní ẹnìkan,tí ó lágbára bí ẹ̀fúùfù líle, ati bí ìjì apanirun,bí afẹ́fẹ́ òjò tí ó lágbáratí àgbàrá rẹ̀ ṣàn kọjá bèbè;ẹni náà yóo bì wọ́n lulẹ̀.
wọn ìbá gbé wa mì láàyè,nígbà tí inú bí wọn sí wa;
Ó dùn lati wé, ó si yẹ ni.
Ọ̀rọ̀ OLUWA ń ba yín wí, Kenaani, ilẹ̀ àwọn ará Filistia; n óo pa yín run patapata láìku ẹnìkan.
'Àwọn olósèlú rán aṣọ ọlọ́pàá f'àwọn ayédèrú ọlọ́pàá ní Kogi ati Bayelsa' Ṣé o rántí kan sára sí ọkọ rẹ, bàbá tàbí ẹ̀gbọ́n láyàjọ́ ọkùnrin lágbayé Ẹni tó bá kàwé dé ipele girama leè di Ààrẹ, dandan kọ́ ni ìwé ẹ̀r - í Ilé ẹjọ́ Lorilẹ-ede Afghanistan to wa ni ipo kinni, ojilelegbeje ati mẹta, 1443 ikọlu igbesunmọmi lo waye nibẹ ninu eyi ti ẹgbẹrun meje ati ọọdunrun o le mọkandinlọgọrin, 7379 ẹmi si dero ọrun ọsan gangan.
Ní tèmi, mo wà lọ́wọ́ yín, ohun tí ó bá dára lójú yín ni kí ẹ fi mí ṣe.
Ẹ má ṣe gbọ́ ti Hesekaya; nítorí pé ọba Asiria ní kí ẹ jáde wá kí ẹ bá òun ṣe àdéhùn alaafia; òun yóo gbà yín láàyè láti máa jẹ èso àjàrà ninu ọgbà àjàrà yín.
Osun Election Tribunal: Èyí ni òkodoro ìdájọ tí àwọn eniyan ìpínlẹ̀ Ọsun ti ń reti- Oyetola Bukola Saraki kò kọjá òfin - EFCC Naira Mailey àti ikọ̀ rẹ̀ tí wà látìmọ́lé EFCC 'Àwọn kọ́ńsítébù t'ílé iṣẹ́ ọlọ́pàá fẹ́ gbà kò ní gbébọn' Ìyá 73 rọ ọmọ ní oúnjẹ dèrò ẹ̀wọ̀n l'Ámẹ́ríkà Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, '500 level'' ni mo wà nígbà tí mo di adélé Ọba' Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ẹ wo àrà àwọn ọmọ kékeré ń fi ẹ̀kọ́ kọ̀mpútà dá Awọn aṣofin naa ni igbesẹ lati yan awọn Emir miiran nipinlẹ Kano lodi si ofin ipinlẹ naa.
Teni entertainer: Idi ti mí kìí fi ṣí ìhòhò mi bi àwọn olórin obinrin míran
Alamojuto ile epo kan ni agbegbe New Garrage ṣe alaye fun ikọ BBC News Yoruba wi pe ara ko rọ okun - ara ko rọ adiye ni ọrọ aleekun to de ba owo epo.
"Ọkọ rẹ, oloogbe MKO Abiola sọ lọjọ kan nigba aye rẹ pe : ""mo n lọ sile lọjọ kan lati lọ bẹ iyawo mi ati ọmọ wa ọkunrin wo, nigba ti mo ri ọkọ ayọkẹlẹ iyawo mi loju ọna, o ni oun ti n gbadura ki n pade oun lọna ile tori pe awọn ọkunrin kan ti wa ta oun lolobo pe ọlọpaa n bọ wa mu mi lati fẹsun kan mi."
    Nígbà tí ohun gbogbo parí tán, ìṣẹ̀lẹ̀ ńlá sẹ̀, ilẹ̀ bẹ̀rẹ̀ sí í mì, àrá ń sán, igbó n pariwo, àwọn igi àti ọ̀pẹ̀ sì bẹ̀rẹ̀ sí í ké wí pé: Ẹ ṣeun, a dúpẹ́, a dúpẹ́, a dúpẹ́, ọ̀nà yín yóò dára, ilé yín yóò sunwọ̀n, ẹ ṣeun, A!
Ijọba Naijiria lo ti n pe fun ẹbun gba ma-binu fun awọn ọmọ Naijiria latari dukia ti wọn bajẹ ni ilẹ naa.
Bẹ́ẹ̀ ni n óo ṣe fun yín.
Ilé ẹjọ́ ju ọmọ ìjọ tó fi ìpá bá ọmọ pásítọ̀ rẹ̀ sùn ní ìpínlẹ̀ Ondo sí ẹ̀wọ̀n gbére Omotara pàdánù isẹ́ olówó ńlá nítorí ó fi ọtí ẹlẹ́rìndòdò sódà lá ọmọ alágbe lójú Ogun Àgbẹ́kọ̀yà, ẹ̀kọ́ wo ló yẹ́ kí àwá ọ̀dọ́ kọ́ níbẹ̀?
O gbọdọ ṣe àyẹwò dáadáa kí ọ sí mó irú owó tí ìjọba ti tẹlẹ fi sinu akoto ìjọba bi bee kọ, oun ati awọn osise yoo pada gbena wo oju ara wọn''.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Yoruba Culture: ọjọ́ méje ni wọ́n fí n rẹ ẹ̀kú Danafojura kó tó jáde Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Ṣé ìwọ sàn ju Balaki, ọmọ Sipori, ọba Moabu lọ ni?
komisona ipinle Oyo , Shina Olukolu dupe lowo adari ile-ise olopaa orile ede yii  fun abewo re si ile- ise olopaa ipinle Oyo.
Agara tun gboriyin fun awon ile-ise alaabo to n mojuto isele pajawiri fun itara sasa won lati koju ibugbamu naa, papaa julo fun itpju awon ti o farapa ninu isele naa.
Stephen Mamza ló fẹ̀sùn kan Ààrẹ Buhari gẹ́gẹ́ bí ológun tó ń sùn lójú ogun.
 Ti ọwọ palaba osisẹ agbofinro Kan tabi osise ijoba
O fikun pe oun ko fi igba kankan kabamọ pe oun ya sinu iṣẹ sinima ṣiṣe.
Dayọ Amusa tún jẹ́ olùdarí ilé ìwé tírẹ̀.
Wahala Kaduna: Ọwọ ọlọpaa tẹ eeyan mẹwa Ọwọ ologun tẹ darandaran mẹwa ni Benue Awọn kan ti ọrọ naa soju wọn ni awọn agbebọn naa doju ija kọ ibudo awọn ọmọ ogun to wa ni Doka, lagbegbe kan to wa laarin Funtua ati Birnin Gwari, ti wọn si pa awọn ọmo ogun to wa nibe.
Ọ̀gọ̀rọ̀ ìpànìyàn ní Yau Ma Tei jẹ́ ẹsẹ̀ tí ó ti ọwọ́ àwọn ènìyàn fún ra wọn wá, tí ó jẹ́ ẹsẹ̀ tí wọn kò gbèrò tàbí pa ète rẹ̀ tẹ́lẹ̀, tí àwọn tí ó dá ẹ̀ṣẹ̀ sì ṣe àṣìṣe.
Wọn yoo lee kuro pada wa si Naijiria to ba jiya ẹṣẹ rẹ tan lẹwọn.
N óo mú ọkà pọ̀ ní ilé yín, n kò sì ní jẹ́ kí ìyàn mu yín mọ́.
Mo mú un wá sọ́dọ̀ àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ, ṣugbọn wọn kò lè wò ó sàn.
Ṣé lóòtọ́ọ́ làwọn ọlọ́ṣà tún gbẹ̀mí èèyàn kan ní Moniya, Ibadan?
bẹ́ẹ̀ ni mo tún pinnu nisinsinyii láti ṣe ẹ̀yin ará Jerusalẹmu ati àwọn ará ilé Juda ní rere.
Alli so pe“Oko oju irin to bere ise naa fi  ilu Eko sile lo si ipinle Kano bere lojo Eti, ti yoo pada si ilu Eko ni ojo Aje.
June 21 ni pápákọ̀ òfurufú márùn-ún yóò di ṣíṣí padà - Ìjọba àpapọ̀ Ijoba apapọ ti kede pe, papakọ ofurufu marun-un pere ni oun yoo si lati bẹrẹ iṣẹ pada ni ọjọ kọkanlelogun oṣu kẹfa ọdun 2020.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Fídíò mánigbàgbé nípa ìgbà ayé Bàbá Sala Bawo ni Oyin ṣe di onile ninu ẹyinju Obinrin yii: Arabinrin Ms He ni oun n tu koriko ni bebe iboji mọlẹbi oun nigba ti oyin ko sinu ojú oun.
Ewe, Ahmad ti wa lo anfaani ohun lati fi kede eto idibo ti yoo waye lorile-ede Egypt logbon ojo, osu kesan an odun ti a wayii fun àádọ́ta awon ajo to n ri si boolu afesegba nile Afrika, fun ipo re ti o sofo naa.
Ajọ NEMA to n ri si iṣẹlẹ pajawiri ni Naijiria naa ni gbogbo iṣẹ lawón n ṣe lati wa gbogbo awọn to ri sinu ile to wo naa.
Orúkọ àwọn ọmọ Kohati ni Amramu, Iṣari, Heburoni ati Usieli.
Ṣugbọn nítòótọ́, níwọ̀n ìgbà tí mo wà láàyè, tí ògo mi sì kún ayé, 
A wọ̀nà títí fún ìrànlọ́wọ́lọ́dọ̀ orílẹ̀-èdè tí kò lè gbani là.
Ikọlu awọn ole aji maluu ti n di tọrọ fọnkale ni ipinlẹ Zamfara.
Oríṣun àwòrán, US embassy Khartoum Olori ijọba orilẹ-ede Sudan, Abdalla Hamdok si ti fesi pe wọn ti fi owo naa ranṣẹ.
Èéṣe tí o fi sọ pé tẹ̀gbọ́n-tàbúrò ni yín, tí o jẹ́ kí n fi ṣe aya?
Oríṣun àwòrán, Toyosi Adesanya Amusan ni isẹlẹ naa ko mu inu oun dun debi pe oun yoo maa sọrọ rẹpẹtẹ lori rẹ amọ lẹyin ti ẹgbẹ awọn ba se ipade tan lori isẹlẹ yii, awọn yoo fi iroyin sita nipa oloogbe to salaisi ninu isẹlẹ naa, ati ohun ti ẹgbẹ fẹ se fun.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù IBDEC: Àyàfi tọ́wọ́ wa bá tẹ àwọn ọ̀dọ́ tó na òṣìṣẹ́ wa, ni iná yóò tó tàn nílẹ̀ Ìjẹ̀ṣà 17 Ẹrẹ̀nà 2019 Oríṣun àwòrán, Jude Ugwu Ko din ni ijọba ibilẹ mẹfa nilẹ Ijẹṣa to wa ninu okunkun biribiri bayii lati Ọjọbọ to kọja.
Ó ṣeéṣe kí ènìyàn 12,000 máa kú lójoojúmọ́ lẹ́yìn Covid-19 Orílẹ̀-èdè mẹ́wàá tí ẹgbẹ́ alákatakítí Islamic State n fínna mọ́ ní àgbáyé N kò gba ₦4bn lọ́wọ́ Magu, ẹ má ró àjẹbánu mọ́ mi láṣọ - Osinbajo pariwo Mi ò tíì gba ìwé ìfitónilétí pé wọ́n fẹ́ yọ mí nípò igbákejì gómìnà ìpínlẹ̀ Ondo- Agboola Ajayi Ohun lo buwọlu iwe aṣẹ ti wọn fi beere iwe ẹri to fi mọ awọn iwe adehun iṣẹ kọngila gbogbo ti Bukola Saraki fọwọ si nigba ti o wa ni Gomina.
 orí ọpọ ́ n ni àwòrán ère Èṣù máa ń wà , òjíṣẹ ́ ifá àti àwọn irúnmọlẹ ̀ tókù .
Ó la àpáta ni aṣálẹ̀,ó sì fún wọn ní omi mu lọpọlọpọ bí ẹni pé láti inú ibú.
Ọwọ́ tẹ èèyàn kan pẹ̀lú orí ọmọdé nílé aṣòfin àpapọ̀ Ọmọkùnrin tó ya 'Blue film' nínú igbó Osun Osogbo ti bayé ara rẹ̀ jẹ́ - Yemi Elebuibon Ajínigbé kọlu òṣìṣẹ́ FRSC, èèyàn méjì kú, mẹ́rin farapa, mẹ́wàá di àwátì Iléeṣẹ́ ọlọ́pàá ní Kano tí ṣe àyẹ̀wò àwọn 13, 048 tó fẹ́ darapọ̀ mọ́ wọn Agbẹnusọ ileeṣẹ ọlọpaa ilu Orlando Frank Chisari sọ fawọn akọroyin pe Pasitọ yi a maa jẹ orukọ wolii lori ayelujara tawọn eeyan si mọ ọ daada.
Ṣaaju asiko yii gomina Makinde ti ṣapejuwe iya rẹ ri gẹgẹ bii ẹni ti wi bẹ ki wọn ba a bẹẹ to si ni oun fi iru eyi jọ iya to bi oun lọmọ.
Nígbà tí kẹ̀kẹ́ ẹrù náà dé ibi oko Joṣua, ará Beti Ṣemeṣi, ó dúró níbẹ̀.
"82% ọkùnrin ní kó mọ̀ pé òun ní àìsàn jẹjẹrẹ asẹtọ ní Naijiria Pogba ṣalaye pe: ""Mo fi ẹsẹ mi ṣẹṣẹ lasiko ti a n gba bọọlu pẹlu Southampton ni ọjọ kọkanlelọgbọn, oṣu Kẹjọ."
Wọ́n rú ẹbọ alaafia, Saulu ati àwọn ọmọ Israẹli sì jọ ṣe àjọyọ̀ ńlá.
Loṣu kan abọ sẹyin ni irufẹ iṣẹlẹ naa ṣẹlẹ ni Ijarẹ, ni Ijọba Ibilẹ Ifẹdọrẹ, ti maalu ti ko din ni mẹrindinlọgbọn si ku.
Osun state: PDP ní nítorí ẹjọ́ lórí ìbò gómìnà Ọ̀ṣun ni Ọlọ́pàá fi mú Sẹ́nétọ̀ Ademọla Adeleke sí àhámọ́
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Yoruba: Báwo lo ṣe gbọ́ èdè rẹ sí?
Ọlọrun á pàtẹ́wọ́ lé e lórí,á sì pòṣé sí i láti ibi tí ó wà.
I Language Centre: Yorùbá ló làṣà àti èdè 29 Ògún 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 14 Èbibi 2020 Ede Yoruba dùn lẹnu awa ọmọ ilẹ̀ Amẹrika.
yaya mefa lati daabobo orile ede yii losan ati ni oru.
New Minimum wage: Ìjọba Eko bẹ̀rẹ̀ sísan N35,000 gẹ́gẹ́ bí owó oṣù tó kéré jùlọ fáwọn òṣìṣẹ́
Àwòrán ìrántí ní ìdíje Madrid, Juventus Ronaldo tàn bí oòrùn níwájú Juventus Sugbọn àwọn ìkọ Arsene Wenger da ayo méjì padà.
“Ìwọ ọmọ eniyan, mú igi kan kí o kọ sí ara rẹ̀ pé, ‘Igi Juda ati àwọn ọmọ Israẹli tí wọ́n wà pẹlu rẹ̀.
Ife Ẹyẹ Agbaye ti Russia 2018 balẹ bagẹ si BBC
A fẹ́ bẹ̀rẹ̀ òfin má lo fóònù mọ́ fàwọn ọmọ wa -Òbí Dino, Wada àti àwọn olùdíje 11 míràn n dù àsíá PDP fún gómìnà ìpínlẹ̀ Kogi Àwọn akọni Nàìjíríà padà sílé pẹ̀lú àmì ẹ̀yẹ 121 láti Morocco Ǹkan mẹ́jọ tó máa kọ́kọ́ ṣẹlẹ̀ kí olólùfẹ́ méjì tó pa ara wọn Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Ile aṣofin: Jubrin maa pada bọ wale
Idi niyi ti Ọba ko fi gbọdọ si nibẹ nigba ti wọn ba fe gbẹbi ọmọ bẹẹ.
Awọn ti ọrọ naa ṣoju wọn ni bii agogo mẹji aabọ ni ọkọ ofurufu naa balẹ ni papa iṣere kan ni Kabba ti fáànù ori rẹ si fo yọ.
Buhari ti rọ awọn adari oirle ede agbaye lati wa wọrọkọ fi sada lori bi imọ ẹrọ igbalode yoo se wa larọwọto awon eniyan ati
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù FIBAN: Ìpàdé àláàfíà wáyé láàrin KWAM 1 àti FIBAN, ìjà pari 3 Ọ̀wàrà 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 9 Ọ̀wàrà 2020 Gbonmi si omi o to to waye laarin ẹgbẹ awọn sọrọsọrọ Naijiria ta mọ si FIBAN ati akọrin Fuji KWAM 1 ti pari.
O tun fakọyọ ninu idije Champions League bi Liverpool ti kopa ninu aṣekagba idije ọhun.
jẹ́ ẹgbaa mejidinlaadọsan-an ó lé ẹẹdẹgbẹjọ (337,500) aguntan.
Lẹsẹkẹsẹ ni àwọn onigbagbọ bá ṣe ètò fún Paulu láti lọ sí èbúté.
Ni kete ti esi ba si jade, laa fun ni itọju to yẹ.
Eto pipa owo wọle fun Naijiria: Aarẹ Buhari ti ni awọn ti bẹrẹ si ni gbogun ti awọn ti kii san owo ori wọn, eleyii ti o n dena bi owo se n wọle si apo ijọba.
Bakan naa lo tun foju laifi wo ọrọ kan to ni igbesẹ Ladoja naa tako ofin ẹgbẹ oselu rẹ, pẹlu afikun pe oloye Ladoja kii se oloselu mọ, ti ko si kede inu ẹgbẹ oselu to wa fun ẹnikẹni.
Kris Ero to jẹ onimọ nipa ilera pipe sọ fun BBC Pidgin ninu ifọrọwerọ kan, awọn idi to fi dara ki awọn eniyan o maa sun lai wọ aṣọ.
Ìfẹ́kúfẹ̀ẹ́ baba yín ni ẹ ń fẹ́ ṣe.
Ó mú kí ọkàn mi kún fún ìbànújẹ́,ó fún mi ní iwọ mu ní àmuyó.
Lẹ́yìn náà, wọ́n sinmi ogun jíjà.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Tìlù tìfọn ní Ọṣun fi kí Buhari káàbọ̀ l'Óṣogbo 18 Owewe 2018 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 19 Owewe 2018 Àkọlé àwòrán, Eyi ni yoo jẹ aṣekagba ipolongo idibo gomina fun ẹgbẹ oṣelu APC Alaga apapọ ẹgbẹ oṣelu APC, Adams Oshiomole ti fọrọ lede wipe mimu itesiwaju ba awọn iṣẹ rere ti ẹgbẹ naa ti fi lọlẹ nipinlẹ Ọṣun da lori ẹni ti yoo gba iṣakoso lọwọ gomina Rauf Arẹgbẹṣọla.
Ṣé o kò tíì mọ̀,o kò sì tíì gbọ́pé Ọlọrun ayérayé ni OLUWA,Ẹlẹ́dàá gbogbo ayé.
Adájọ́ ẹ tú wa ká, ìyàwó mi n gbé ààlè wá sórí ibùsùn wa- Ọkọ ìyàwó Pope Francis wọ́gilé òfin tó n dáàbò bo àlùfáà tó bá bá ọmọdé l'òpọ̀ Ààrẹ Muhammadu Buhari ti buwọ́lu owó ìṣúná ọdún 2020 Ẹ̀wọ̀n tí mo lọ ni ẹ̀san ìwà tí mo hù gẹ́gẹ́ bíi olórí ológun- Buhari Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Oluwo Divorce: ko si ẹni ti kò mọ pé ọmọ ilẹ̀ òkèrè ni mó fi ṣe aya Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Fídíò, Ondo election 2020: Àwọn ara ìpínlẹ̀ Ondo ránṣẹ́ sí Akeredolu ohun ti wọ́n ń retí ní báyìí12 Ọ̀wàrà 2020 Fídíò, Wole Soyinka sọ ìdí tó fi ni òun a fi màálù Fulani ṣe súyà fáwọn èèyàn abúlé23 Owewe 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
O so pe, “Naijiria wa lara orile-ede ti o le gba ife-eye yii.
Ikọ Manchester city ni Arsenal koju, goolu mẹta ti ko ṣee bomi la ni wọn si fi bori Arsenal.
kí OLUWA sọ ọ́ di ẹni ègún ati ẹni ìfibú láàrin àwọn eniyan rẹ̀.
A o tii mọ igba ti wọn yoo ni ko maa lọ ile ṣugbọn a o fẹ ko wa nibẹ fun igba diẹ.
Bẹẹ ba gbagbe, lọjọ Aje ọsẹ to lọ ni Ikeja niluu Eko lawọn ologun, ọlọpaa ati ọtẹlẹmuyẹ ti gbọngan kan pa, eyi tawọn ajafẹtọ ọmọniyan bii Ṣoyinka, agbẹjọro Femi Falana atawọn eeyan miran, ti fẹ ṣe apero.
 O ro awon odo to si wa laye lati se rere ki won le fi iwa irele, ife orile ede atiwa omoluwabi ranti won leyin ola bii ti oloogbe Ajetunmobi.
Ọpọ ninu wọn lo jẹ iyawo ile, ti awọn miiran si jẹ gbajugbaja oniṣowo.
Asọtẹlẹ yii waye lẹyin Osun meji ti adari ijọ Divine Seed of God ti ilu Ibadan Wooli Wale Olagunju sọ asọtẹlẹ wipe, ki Buhari ma ṣe wahala pupọ o, nitori wipe Atiku ni yoo gbe igba oroke.
Àwọn náà ni wọ́n sì ń bá a tà wọ́n fún àwọn ọba ilẹ̀ Hiti ati ti ilẹ̀ Siria.
O ti to ọdun marundinlaadọta sẹyin ti ikọ agbabọọlu mejeeji ti jọ n kọlu ara wọn ninu idije ere bọọlu alafẹsẹgba, Ṣe ti ọmọ ko ba ba itan, o yẹ ko ba arọba to jẹ baba itan koda ninu idije ere bọọlu.
Oríṣun àwòrán, Abiola Ajimobi Ikede yii lo si jẹ igba akọkọ ti ijọba yoo fi idi rẹ mulẹ pe oloogbe naa ni arun Covid-19, bi o tilẹ jẹ pe ẹnu ti n kun tẹlẹ.
Síbẹ̀-síbẹ̀ afọ́jú náà wọ ọkọ̀ akérò láìsí ìṣòro kankan.
Akọwe iroyin fun gomina ipinlẹ ọhun, Segun Ajiboye lo sọ bẹẹ ninu ifọrọwerọ kan pẹlu BBC Yoruba.
àwọn alágbẹ̀dẹ wúrà, ati ti fadaka, ti idẹ, ati ti irin.
Nígbà tí oorun wọ̀ ọ́ lára, ó ré bọ́ sílẹ̀ láti orí pẹ̀tẹ́ẹ̀sì kẹta.
“Obinrin kò gbọdọ̀ wọ aṣọkáṣọ tí ó bá jẹ́ ti ọkunrin, bẹ́ẹ̀ sì ni ọkunrin kò gbọdọ̀ wọ aṣọkáṣọ tí ó bá jẹ́ ti obinrin nítorí pé ẹnikẹ́ni tí ó bá ṣe bẹ́ẹ̀, ìríra ni ó jẹ́ lójú OLUWA Ọlọrun yín.
Ehi ni ọpọlọpọ awọn iho ti oloyinbo n pe ni 'manhole' pọ̀ ni oju popo Ipinlẹ Eko to jẹ ewu fun awọn eniyan ni ọsan lai tii sọ iru ewu ti wọn jẹ fun ara ilu ni alẹ tabi nigba ti ojo ba rọ.
 ní ilẹ ̀ amẹ ́ ríkà ètò ìtọ ́ jú lẹ ́ ẹ ̀ kanṣoṣo ti àjẹsára dìgbòlugi jú 750 usd lọ .
A ṣe sùúrù tó, ọmọ wa ló gbọ́dọ̀ jẹ́ ọ̀gá fásitì Ibadan lọ́tẹ̀ yìí - akóríjọ́ ẹgbẹ́ ọmọ Ibadan Kí ló dé tí Shoprite fẹ́ kógbá kúrò ní Nàìjíríà?
Minisita keji fun eto iṣuna ni Naijiria, Ọgbẹni Clem Agba lo sọrọ yii niwaju igbimọ ile aṣofin agba to n ri si ọrọ eto inawo ati ọrọ aje l'Abuja.
Nítorí OLUWA Ọlọrun ni oòrùn ati ààbò wa,òun níí ṣeni lóore, tíí dáni lọ́lá,nítorí OLUWA kò ní rowọ́ láti fún ẹni tí ọkàn rẹ̀ mọ́ní ohun tí ó dára.
Báwó ni òògùn dexamethasone ṣe ń ṣiṣẹ́ lára Èèyàn 667 ló lùgbàdì àrùn Coronavirus ní Naijiria ní Ọjọ́ Ẹtì Godwin Obaseki ti darapọ̀ mọ́ ẹgbẹ́ òṣèlú People's Democratic Party Ninu ọpọlọpọ awọn ọmọ Naijiria to ti jọ kọrin pẹlu ọmọ South Africa ti a gbe yẹwo nisalẹ yii ati akọle orin wọn, a fi awo tuntun Burna Boy ati Master KG ṣe akọkọ ti wọn fi ede Yoruba ati Zulu kọrin ninu rẹ.
Pasitọ Sotitobirẹ wọ aṣọ olomi ewe ti wọn si ti ge irun rẹ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ìwà olè, jìbìtì àti ìjẹkújẹ ló n jé káwọn mii yí ọjọ́ orí wọn padà Ogbẹni Doku ṣalaye pe ẹrọ ibanisọrọ wulo fawọn akẹkọọ ọdọmọde wọnyii nitori pe ọpọ obi lo maa fẹ mọ irin ẹsẹ wọn.
Ó ní, “Olùkọ́ni ti dé, ó ń pè ọ́.
Nígbà tí gbogbo àwọn eniyan bá sì rí ìkùukùu tí ó dàbí òpó yìí, lẹ́nu ọ̀nà àgọ́, gbogbo àwọn eniyan á dìde, olukuluku wọn á sì sin OLUWA ní ẹnu ọ̀nà àgọ́ rẹ̀.
Sylva ni wọn yoo ṣe eyi lọfẹẹ fawọn ọmọ Naijiria lọna ati mu adinku ba owo epo petirolu to gbowo lori.
Ọdún nìín, ọjọ́ díẹ̀ sí Kérésìmesì, ìjọba ní àwọn ìlú ńlá bíi Langfang, ní agbègbèe Hebei, ti pa á ní àṣẹ fún ìsọ̀ gbogbo láti yọ ẹ̀ṣọ́ ọdún Kérésìmesì kúrò lójú títí àti fèrèsé.
Ilé ẹjọ́ dá pásítọ̀ ìjọ Sotitobire padà sọ́gbà ẹ̀wọ̀n, ó sún ẹjọ́ síwájú Ṣé òògùn Chloroquine lè dènà ààrùn Coronavirus bí?
Ọpọ awọn ololufẹ Lisa lori ayelujara ni wọn kọkọ fi ṣe yẹyẹ nigba ti fidio kan jade to ṣafihan Lisa to n ko igbẹ aja rẹ ninu iyara rẹ.
 Òun ló fí awọn bushoong se asíwájú àti olórí -Ẹ ̀ sin baba ńlá wọn ni wọn ń sìn .
Ìgbà tí o sí ìlẹ̀kùn yìí wò, ó rí àkàsọ̀ kan tí ó lọ sí gbọn-ọnran sí ìsàlẹ̀ ó bá ń tọ àkàsọ́ yìí lọ.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Igbakeji Aarẹ Ere Mubarak wa lẹyin ọdun meji, nigba aarẹ Anwar Sadat fi i ṣe igbakeji rẹ.
Yatọ si awọn marun un to ku ninu ile naa, awọn ti wọn ti yọ kuro gan an ti di eeyan ti ọpọlọpọ n tẹle loju opo ayelujara wọn.
Electricity Regulatory Council (NERC), lati fagile igbese ti ile-isẹ aminunawa  ( disco) fe gbe nipa gbigbe awon  ero- amunawa (transformers) kuro lataripe awon
Ki ọdún titun lè bá wa láyọ̀, ikilọ ni àsikò yi ni wi pé “Ki ẹni bá mú ọti tàbi ẹni tó lo egbò igi olóró ma ṣe wa ọkọ̀”.
OLUWA sọ fún un pé, “Èmi ni OLUWA, sọ gbogbo ohun tí mo rán ọ fún Farao, ọba Ijipti.
Gẹgẹ bi adajọ Amina Augie to ka idajọ naa lọjọru ọsẹ ṣe sọ ọ, o ni ipẹjọ ẹgbẹ APC kuna lati tọka si aṣiṣe kankan o si jẹ ko di mimọ pe idajọ awọn duro titi laelae.
Ọmọ ile igbimọ asofin, Dino Melaye, ti fi fidio miran sita ninu eyi ti o ti sọrọ, kọrin eebu si Gomina ipinlẹ Kogi, Yahaya Bello.
Láti àtẹ́lẹsẹ̀ dé orí yín,kò síbìkan tí ó gbádùn.
 Bakan naa bi a ko bat un gbagbe
"Kò si irú èébu ti ko bu Laycon tan, o tún pe e ni ""Skinny drum Stick"" èyi to tumọ si ki wọ́n pe ènìyàn ni kọ̀ngọ́ ìlù."
 naples dara pọ ̀ mọ ́ italy ní 1861 .
Ọ̀pọ̀ àwọn eniyan péjọ pọ̀ sọ́dọ̀ rẹ̀.
Ọmọbinrin Farao dá a lóhùn pé, “Lọ pè é wá.
”Alhaji Mohammed gba awon ile-ise naa niyanju lati samulo awon oniruuru ilana ti ijoba pese sile.
Ẹka ilera Kikọ ile iwosan 101 pẹlu ọgọrun un bẹẹdi/kikọ 100 ile iwosan igbalode.
osise  ajo INEC se n se isẹ wọn.
Ibo mẹwaa pere ni Yahaya Audu ni ti Sanni Abdullahi ni tirẹ si ni meje.
Eyi si to ilọpo meji ohun ti wọn fun awọn apapọ awọn orilẹede marun un to ku.
Dokita onimọ nipa ọsin ẹranko ọhun se alakalẹ awọn ami to ma n jẹyọ lara adiẹ to ba ni aisan lukuluku, eyi taa to sisalẹ yii: Awọn ami ti ẹ o fi mọ adiẹ to ni aisan lukuluku (bird flu) Oju adiyẹ ati ipin ẹsẹ ori adiyẹ a maa wu.
Ṣugbọn wọn kò ì tíì joyè.
Obinrin kan báyìí wà ninu ìlú tí ó gbọ́ pé Jesu ń jẹun ní ilé Farisi, ó mú ìgò òróró olóòórùn dídùn lọ́wọ́, 
Kini awọn ipinlẹ sọ ṣaaju ikede minisita eto ẹkọ?
O wọpọ ni awọn orilẹ-ede bi Naijiria, Saudi Arabia, ati awọn miran nilẹ Asia ati kaakiri agbaye.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Kwara governorship: Gómìnà tí wọ́n yàn ní Kwara, Abdulrazaq ní òun yóò tún ìdigunjalè Offa yẹ̀wò 11 Ẹrẹ̀nà 2019 Oríṣun àwòrán, Rasaq Abdulrahaman Àkọlé àwòrán, Ó ní òun yóò foríkorí pẹ̀lú agbófinró láti ṣàwárí àwọn tó wà ní ìdí ìdigunjalè náà Gomina tuntun ti wọn ṣẹṣẹ dibo yan ni Kwara, Abdulrahaman Abdulrazaq ti ṣeleri ati fikunlukun pẹlu awọn ọlọpaa lati rii pe gbogbo awọn ti wọn lẹbọ lẹru lori idigunjale to waye ni ilu Ọffa jẹjọ bi o ti tọ ati bi o ti yẹ.
Ọjọ kẹrinla, oṣu Kẹrin ni ijamba alagbara naa waye, lasiko ti ọkọ ayọkẹlẹ rẹ forigbari pẹlu ọkọ akẹru kan ni adugbo Mushin.
ni: “A fẹ ki ipinlẹ wa ṣiṣẹ daradara ju tawọn ipinlẹ to ku lọ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Jẹ́ kí a jọ sọ àǹfàní US fún Nàìjíríà -Osinbajo 23 Òkùdu 2019 Oríṣun àwòrán, others Àkọlé àwòrán, Ọrọ wa maa wọ̀ ti a ba jọ ran ara wa lọwọ Igbakeji aarẹ Naijiria de si Amerika fún idagbasoke eto ọrọ aje Naijiria.
Nítorí àwa ni òórùn dídùn tí Kristi fi rúbọ sí Ọlọrun lọ́dọ̀ àwọn tí à ń gbàlà ati àwọn tí ń ṣègbé.
Ati pe wọn sakiyesi pe oogun oloro Tramadol ni o lo nigba ti wọn mu nitori wọn ba saṣẹẹti oogun naa ni apo rẹ.
Ọbasanjọ ni ọmọ òrùkàn tó di olóri orílẹ̀èdè lẹ́ẹ̀mẹ́ta ọ̀tọ̀ọ̀tọ̀ Oshiomole: irọ́ ni wọ́n ń pa,èmi ṣí ní Alága APC!
" Akọwe YCE ọhun ni o yẹ ki Aarẹ Buhari rawọ ẹbẹ si awọn ọdọ, ko si rọ awọn obi wọn pe ki wọn bawọn sọrọ, ki wọn le dawọ iwọde naa duro dipo bawọn ologun ṣe ṣina ibọn fun wọn.
Laipẹ yii ni ariwo Naira Marley gbode kan lori ikanni ayelujara gbogbo lori awọn ọrọ to n sọ lati fi kan sara sawọn to n fi ẹrọ ayelujara lu jibiti.
N óo bínú sí wọn gan-an, n óo sì mú kí ibi dé bá wọn.
Mo ní, “OLUWA Ọlọrun, tí ó tóbi, tí ó bani lẹ́rù, tíí máa ń pa majẹmu ìfẹ́ rẹ̀ mọ́ pẹlu gbogbo àwọn tí ó bá fẹ́ ẹ, tí wọ́n sì ń pa òfin rẹ̀ mọ́.
Láti ọjọ́ náà ni Saulu ti ń ṣe ìlara Dafidi.
Bí mo bá dé ipò gómìnà ìpínlẹ̀ Kwara."
Mo kórìíra èké ṣíṣe, ara mi kọ̀ ọ́,ṣugbọn mo fẹ́ràn òfin rẹ.
Ni tirẹ, Enenche ni nkan to lewu gidi ni igbesẹ ti wọn gbe lati doola awọn akẹkọọ ọhun tori bi wọn ko ba fi ikọṣẹmọṣẹ ṣe iru iṣẹ yii, o lee yiwọ.
“Bí ẹ bá ń tẹ̀lé ìlànà mi, tí ẹ sì ń pa àwọn òfin mi mọ́, 
Oriṣiriṣi iṣẹlẹ manigbagbe lo ti n waye lati igba ti aṣẹlẹ igbele lati dena itankalẹ arun COVID-19 yii ti bẹrẹ.
Jesu bá bi í pé, “Bíi kí ni?
Isele mokandinlogun sele nipinle Edo, isele marun un sele ni Ondo, okan nipinle Bauchi, mesan an nipinle Ebonyin, eyo kan nipinle Plateau.
“Lọ́kàn mi, mo fẹ́ fèsì sí ọ̀rọ̀ rẹ,ara sì ń wá mi, bí ẹni pé kí n dá ọ lóhùn.
Nígbà wo ni n óo lọ, tí n óo tún bá Ọlọrun pàdé?
Ninu ifẹsẹwọnṣe ohun to waye ni papa iṣere NSC Olimpiyskiy
Ẹ o ranti wipe nigba ti wọn ṣe ikede idasile ileeṣẹ naa, ẹgbẹ awọn oṣiṣẹ fẹhinti, ẹka ti Nigeria Airways sọ fun BBC pee awọn ko ni jẹ ko ṣiṣẹ ti wọn ko ba san owo ajẹsilẹ awọn Alaga ẹgbẹ naa, Sam Ezene ni iyalẹnu lo jẹ fun oun ati awọn ọmọ ẹgbẹ nigba ti wọn gbọ pe ijọba kede ileeṣẹ ọkọ ofurufu tuntun, pe ko yẹ ki ijọba Naijiria da ileeṣẹ mi i silẹ nigba ti wọn ṣi n jẹ awọn oṣiṣẹ fẹhinti ni owo ọdun mẹrinla O ni 'O yẹ ki wọn yanju owo ajẹmọnu awọn oṣiṣẹ to n ba ileeṣẹ ọkọ ofurufu akọkọ, Nigeria Airways, to kogba wọle naa ṣiṣẹ.
O salaye pe gbese Naijiria lọ soke lọna ati mu ki ọrọ aje lowura, ko si tun lagbara si bi o tilẹ jẹ pe awọn araalu ko tii le foju rii.
O tun ṣalaye wipe kaka ki Oshiomhole sọrọ gidi, ṣe ni oun lo eebu ati epe.
pm news ) kan pẹ ̀ lú bill ritter .
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Àṣìṣe ọlọ́pàá àti Adájọ́ sọ mí di ẹni tí wọ́n dájọ́ ikú fún, ọpẹ́lọpẹ́ Fayoṣe tí ko buwọlu Ariwo obinrin yii ni oludari ile itura naa gbọ ki awọn agbofinro to mu un.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ami ẹyẹ BBC Salah gba goolu mẹrinlelogoji sawọn fun Liverpool ni saa ere bọọlu afẹsẹ̀gba to lọ, lẹyin to kopa ninu ifẹsẹwọnsẹ mejilelaadọta.
Wọn ni ijọba paṣẹ pe ki onikaluku oṣiṣẹ ile ijọba gbe ile rẹ lasiko yii nitori wahala.
Solomoni ní ọgbà àjàrà kan,ní Baali Hamoni.
E̩nì kò̩ò̩kan ló ní è̩tó̩ sí ààbò lábé̩ òfin kúrò ló̩wó̩ irú àyo̩júràn tàbí ìbanijé̩ bé̩è̩.
Bi ififunni lasiko Keresi ṣe bẹrẹ niyi.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Bakan naa, wọn kede pe idanwo WASSCE yoo bẹrẹ lọjọ kẹtadinlogun oṣu kẹjọ titi di ọjọ kejila oṣu kẹsan ọdun 2020.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, AbdulQudus Bello ṣàlàyé bí òun ṣe dí aláàbọ̀ ara nítorí pọpọ́ọ̀fù àti ìbínú jàǹdùkù àdúgbò Gba imọran lọwọ awọn onimọ nipa arinrinajo Bi o tile jẹ pe ọpọlọpọ awọn arinrinajo lo fẹran lati ma a ṣe ohun gbogbo ti wọn nilo fun ara wọn.
Sọkún tẹ̀dùntẹ̀dùn, ìwọ Heṣiboni,nítorí pé ìlú Ai ti parun!
Ẹ n bi mi pe ki lo ṣẹlẹ?
Ṣugbọn Jesu wí fún wọn pé, “Ẹ̀yin ni kí ẹ fún wọn ní ohun tí wọn óo jẹ.
" O sọ pe ko tọ ọ lati jẹ tabi lo ohunkohun ti ọjọ ba ti lọ lori rẹ nitori pe awọn kokoro aifojuri to lewu fun ara ni yoo ti farahan ninu iru nkan bẹ.
Ó tún Milo tí ó wà ní ìlú Dafidi ṣe kí ó fi lágbára síi, ó sì pèsè ọpọlọpọ nǹkan ìjà ati apata.
isoro naa, ki o to di pe o dibo.
igbesẹ ifiyajẹni lori iru kudiẹkudiẹ ti wọn ṣakiyesi naa.
Ìjọba kò tú Dasuki àti Sowore sílẹ̀ látàri akitiyan ilẹ̀ Amẹrika- Dasuki Èyí ni ìdí tí Bàbá Kérésì fi máa n wọ aṣọ pupa àti funfun nígbà gbogbo Olè yabo báńkì,fọ́n owó ká fáwọn èrò lẹ́yìn tó pariwo 'Merry Christmas' Ẹ ronúpìwàdà lásíkò ọdún, àti àwọn ìkíni mìrán tó jẹ yọ fún Kérésì 2.
Awọn gende agbebọn ti wọn to mẹẹdogun, lo da ọkọ kan duro ti wọn si ji eeyan mẹta gbe loju ibọn.
Idile Adio ni afojusun iwe yii.
wọ́n rin ilẹ̀ náà jákèjádò, wọ́n sì ṣe àkọsílẹ̀ àpèjúwe àwọn ìlú tí wọ́n wà ninu rẹ̀ ní ìsọ̀rí meje sinu ìwé kan, wọ́n pada wá sí ọ̀dọ̀ Joṣua ninu àgọ́ ní Ṣilo.
Nigba ti BBC beere lọwọ rẹ nipa iroyin to gbode pe awọn dokita ko tọju awọn alarun Covid-19 ni IDH mọ, o sọ pe ''ohun ko le dahun ibeere yi nitori ohun ko mọ nkan to n ṣẹlẹ nibẹ bayi'' Ìjọba Akeredolu kò ní omi àánú lójú, a kò tọ́jú alárùn Coronavirus mọ́ - Dókítá Ondo Awọn dokita onisegun oyinbo to n sisẹ nile iwosan ti wọn ti n tọju ajakalẹ arun, IDH nilu Akure, nipinlẹ Ondo to n wo isẹ wọn niran.
Nígbà náà ni angẹli OLUWA sọ fún Elija pé kí ó bá wọn lọ, kí ó má sì bẹ̀rù.
Onnoghen: Àjọ NJC fún Onnoghen lọ́jọ́ méje láti wá sọ tẹnu rẹ̀
Ọkùnrin ọmọ ogún ọdún kan ló gbé ìbọn ìyá rẹ̀, tó sì yin ìyá rẹ̀ pa nínú ilé wọn.
Fọfọ ni oju opo ayelujara rẹ kun fun oriṣiriṣi ikini latọdọ awọn oṣere ẹgbẹ rẹ, awọn olorin to jẹ ọrẹ rẹ, awọn oṣiṣẹ rẹ koda to fi mọ awọn aladugbo rẹ nibi to n gbe.
Ìyá dú ọmọ rẹ̀, o yíi láta, ó sì tún jòkó jẹ ẹ́ Àráàlú yarí fún fásitì Babcock fún bo ṣe lé akẹ́kọ̀ọ́ tí wọn bá lòpọ̀ nínú fídíò Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Agbábọ́ọ̀lù Barcelona àti Argentina náà ti wà lẹ́nu ẹjọ́ lílo orúkọ rẹ̀ sí ara àwọn ohun eèlò bíi aṣọ, bàtà, ọjà lóríṣíriṣii àti àwọn ohun eèlò eré ìdárayá tipẹ́tipẹ́.
Awon atamatase iko agbaboolu Leicester City mejeeji, Kelechi Iheanacho ati Wilfred Ndidi, ti o fi mo agbaboolu owo eyin iko Udinese, William Troost-Ekong nireti w ape won yoo bale sipago naa loni.
Ibrahim Kalin to jẹ agbẹnusọ fun Aarẹ Turkey ni sisọ ibudo iṣẹmbaye yii di mọṣalaṣi ko di awọn arinrin ajo afẹ lọwo lati ṣi wa maa ṣe abẹwo sibẹ.
Aare Muhammadu Buhari ti ro egbe to n sejoba lọwọ ( All Progressive Congress, APC ) lati seto idibo ẹgbẹ  won ni irọwọ irọsẹ,saaju eto idibo odun 2019 to n bọ.
se awon eniyan lọsẹ ni ekun naa.
Ǹ bá rà wọ́n pada, ṣugbọn wọ́n ń parọ́ mọ́ mi.
Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Ìtàn Mánigbàgbé: Bode Thomas ní ọpọlọ pípé, ó jẹ́ aṣaájú àmọ́ ó ní inú fùfù19 Sẹ́rẹ́ 2020 Ìtàn Mánigbàgbé: Mọrèmi Àjàṣorò fi ọmọkùnrin rẹ̀ kanṣoṣo rúbọ fún odò nítorí ìlú20 Èrèlè 2019 Ìtàn Mánigbàgbé: Ọ̀rẹ́ àjèjì ló kóbá Afọnja, tí Ilọrin fi bọ́ lọ́wọ́ Yorùbá24 Ìgbé 2020 Ìtàn Mánigbàgbé: Adebisi Idikan ni olówó tó kọ́kọ́ ra ọkọ̀ nílẹ̀ Ibadan20 Èbibi 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Wo imọran Fọlọrunṣọ Alakija fun awọn ọdọ adulawọ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Obinrin jẹ amuludun' Igbákeji ààrẹ, Ọjọgbọ́n Yemi Osinbajo gbadura kí Ọlọrun túbọ̀ lọ́ra ẹ̀mí wọn Oríṣun àwòrán, Osibajo/twitter Àkọlé àwòrán, O ni àwọn iṣẹ́ ìrànwọ́ ti ó ń se fawọn ọ̀dọ́ àti àwọn alaini kò lẹ́gbẹ́.
ati ìdámẹ́wàá òṣùnwọ̀n efa fún ọ̀dọ́ aguntan kọ̀ọ̀kan; 
9 2292497 Orilẹede Iran 50310 61.
Ọmọge Campus Oríṣun àwòrán, AISHAT ABIMBOLA/FACEBOOK Àkọlé àwòrán, Aishat Abimbola jáde láyé lẹ́yin tí ó ní ààrùn jẹjẹrẹ ọyàn Ọmọge campus ni ọpọ mọ Aishat Abimbọla si nigba aye rẹ.
State Joint Local Government Accounts: Ìjìyà ti wà fún báńkì tó bá ṣí àṣùwọ̀n ìjọba ìbílẹ̀ sílẹ̀ fún gómìnà jẹgúdújẹrá
Ọkùnrin kan tó yasó nínú ọkọ̀ Uber rí ẹ̀wọn he Àṣé àṣírí wà nínú Hijabu tí Aisha Yesufu ń wọ̀ lọ ìwọ́de 'Kìí ṣe àròsọ, mo ní fọ́nrán fídíò àwọn ẹlẹyẹ ìlú mi' Ìyá 73 rọ ọmọ ní oúnjẹ dèrò ẹ̀wọ̀n l'Ámẹ́ríkà Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí End SARS protest: Lára àwọn ìlú tí ìwọ́de ti wáyé ní Ibadan, Ado Ekiti, Osogbo, Ado Ekiti ati Eko19 Ọ̀wàrà 2020 NYSC Camp, After coronavirus: Ìjọba kéde ọjọ́ ìwọlé àwọn àgùnbánirọ̀ sí ìpàgọ́ lẹ́yìn Covid 19- Minista ọ̀rọ̀ ọ̀dọ́ Nàìjíríà15 Ọ̀wàrà 2020 Farting offense: Ọkùnrin yasó nínú ọkọ̀ Uber rí ẹ̀wọn he ní ilẹ̀ Gẹ̀ẹ́sí15 Ọ̀wàrà 2020 5:55 Fídíò, Soyinka Cancer: Àṣe ara mi ni iso ti n run gbogbo bí mo ṣe n ṣèrànwọ́ lórí jẹjẹrẹ, Duration 5,5527 Bélú 2019 Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí kan sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
Lẹ́yìn nǹkan wọnyi, OLUWA bá Abramu sọ̀rọ̀ lójú ìran, ó ní, “Má bẹ̀rù Abramu, n óo dáàbò bò ọ́, èrè rẹ yóo sì pọ̀ pupọ.
76 miliọnu eniyan lo forukọsilẹ lati dibo Ida 55% ninu wọn jẹ obinrin Ẹgbẹ oṣelu mejidinlaadọta lo n dije dupo.
Aaye ọtọ lo wa ninu iṣẹnbaye.
wọ́n fà á jáde lọ sí ẹ̀yìn ìlú, wọ́n bá ń sọ ọ́ ní òkúta.
Ọba bá ranṣẹ pé kí wọ́n bẹ́ Johanu lórí ninu ẹ̀wọ̀n tí ó wá.
Ṣugbọn idà wọn ni o óo fi pa wọ́n,ọrun wọn yóo sì dá.
Ninu ọrọ ti Aisha Buhari sọ ninu atẹjade kan loju opo Twitter rẹ, o ni Garba Sheu ti gba abọde ti o si tọ ki o kọwe fiposilẹ.
silẹ lasiko eto idibo tabi lati ji apoti ibo gbe.
Minisita fun ayika ati igbafe Pohamba Shifeta ti so pe:“Awon ko ni san owo  gba-ma-binu ohun fun awon ti ooni ati erinmilokun pa nibi ti won ti n luwe  tabi we ninu omi nitori pe, won mo ohun ti won le e se lati gba ara won sile nibi isele burku ohun.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Kemi Remi Dairo: Iṣẹ́ abẹ nínú ọpọlọ àti ẹ̀rọ ni mo fi ń gbọ́ ọ̀rọ̀ báyìí Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Kemi Remi Dairo: Iṣẹ́ abẹ nínú ọpọlọ àti ẹ̀rọ ni mo fi ń gbọ́ ọ̀rọ̀ báyìí 7 Agẹmo 2020 Igba laye, to ba lo siwaju, a tun lo sẹyin, ko si si ẹni to wa laye, to kọja adanwo.
 A o si tun maa se ipade pelu awon egbe lorisirisi.
lati fi tako gomina ipinle Osun Adegboyega Oyetola, to je omo egbe All
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ẹgbẹ CAN gbe iroyin sita wipe ijọ Katoliiki ti pada si aarin rẹ lẹyin ọpọ ifinukonu Lọjọ aiku ni ẹgbẹ CAN gbe iroyin sita wipe ijọ Katoliiki ti pada si aarin rẹ lẹyin ọpọ ifinukonu.
isele naa gege bi ipenija lati fowosowopo pelu ijoba apapo ati ipinle, lona ti
“Ile-ise NITDA, pelu ajosepo ile-ise to n mojuto igbe aye- gbadun awon eniyan, (the National Social Investment Office (NSIO)lo n sagbateru ile-ise  imo ero igbalode mejo ti yoo wa ni elekun-jekun , lara won ni ilu -Eko ati Abuja yoo wa nibe .
@burina_NG ni tiẹ sọ wi pe o yẹ ki ijọba tọrọ aforiji lọwọ gbajugbaja oṣere, Funke Akindele ti ijọba ipinlẹ Eko fi ọwọ ofin mu lẹyin to ṣe apejẹ ọjọ ibi ọkọ rẹ.
Ó ní Ọlọ́run fi ẹ̀bùn awada sise pamọ sì ara ìyá òun, àmọ́ kò fi ṣe iṣẹ́ ṣe, kí Ọlọ́run tó wà gbé ẹ̀bùn náà jáde lára òun.
Alaga ile igbimo asoju lori  oro to je mo  ile gbigbe ni ipinle eko to je ekun Gusu orile
Ni alẹ ọjọ aje ni ajọ yii kede ogun eeyan miran to ti ko arun naa.
Idi niyi ti awon se mu Oby
Àkọlé àwòrán, Aarẹ Donald Trump to n dari ilẹ Amerika ati iyawo rẹ, Melania Trump ni wọn jọ de si UK lọjọ Aje nínú baalu Air Force One.
ùgbọ́n ki ní kan kò ní ṣàì yà yín lẹ́nu nípa èmi pàápàá, ẹ kò bi mi nǹkan náà dan?
Ara mi kò gba ẹ̀ṣẹ̀ tí ẹ̀ ń dàpọ̀ mọ́ ẹ̀sìn mọ́.
“Ìwọ ọmọ eniyan, sọ àsọtẹ́lẹ̀ pé ohun tí èmi OLUWA Ọlọrun sọ nípa àwọn ará Amoni ati ẹ̀gàn wọn nìyí:‘A ti fa idà yọ, láti paniyan.
Wọn ni awọn ẹya kan ti lọ darapọ mọ Islamic State of West Africa Province.
Fayemi soro yii ,nigba to n ba awọn akoroyin soro leyin igba ti o se ipade bonkẹlẹ pelu alaga ẹgbẹ  APC ,Adams Oshiomhole nile ipade ẹgbẹ  to wa niluu Abuja.
 O ni, o di dandan ki a toju won bi o ti ye fun idagbasoke Naijiria.
tí àwọn ìlẹ̀kùn yóo tì ní ìgboro, tí ariwo òòlọ̀ yóo rọlẹ̀, tí ohùn ẹyẹ lásán yóo máa jí eniyan kalẹ̀, tí àwọn ọdọmọbinrin tí wọn ń kọrin yóo dákẹ́; 
CACOVID Palliatives: Ọwọ́ Ọlọ́pàá tẹ àwọn tó lọ kó ǹkan ìrọ̀rùn Covid-19
Kaakiri agbaye si ni Ọọni ti lọ lati lọ igi ifẹ, iṣọkan ati idagbasoke Yoruba ati gbogbo ọmọniyan ni alọye.
Ṣugbọn awọn eeyan mẹta yii ti gbe Buhari lọ si ileẹjọ giga l'Abuja lati ọdun 2018 ninu eyi ti wọn ti sọ pe aarẹ Buhari ko ni awọn sabuke to sọ fun ajọ INEC pe oun ni.
Èmi Paulu, ikọ̀ Kristi, tí mo di ẹlẹ́wọ̀n nisinsinyii nítorí ti Kristi Jesu, 
”O wa ro ijoba orile ede Naijiria lati tesiwaju lori eto ilana naa,ni eyi ti idagbasoke yoo fi ba to oro aje.
Tirẹ̀ ni ògo nisinsinyii ati títí laelae.
Mama Arsenal: Ẹgbẹ́ kan ti fún màmá ní ẹ̀bùn owó
Gbogbo ohun tí mo pa láṣẹ fún ọ ni kí o sọ; Aaroni, arakunrin rẹ yóo sì sọ fún Farao pé kí ó jẹ́ kí àwọn eniyan Israẹli jáde kúrò ní ilẹ̀ rẹ̀.
Ọpọlọpọ awọn ti mo sọ fun fimi silẹ.
Àwọn ẹranko àti ẹyẹ tí ó wá, wọ́n wá láti woran ni, àwọn iwin tí o ń lu ìlú fún ìnàkí-ìbẹ̀rù, bí ènìyàn gan-an ni wọ́n rí, bàtá tí wọ́n sì ń lù, bàtá gan-an ni.
O ni kìí ṣe pé òun ń fi idí ọ̀rọ̀ náà múlẹ̀.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, afin pupa Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí UN Human Rights Council urges Sri Lanka war crimes court16 Owewe 2015 The broken survivors of Sri Lanka's civil war11 Ọ̀wàrà 2012 Sri Lanka country profile18 Bélú 2019 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Kegel Dokita Abubakar Ahmad Tsafe sọ pe ere idaraya Kegel, jẹ eyi ti ko nira rara, to si ma n fun awọn iṣan to wa lara egungun to so ara ati ẹsẹ pọ 'pelvis', ni okun.
Òsìsẹ́ Custom tó déédé sọ ara rẹ̀ di Ọ̀gá Àgbà CG ní ìdàmú ọpọlọ - Attah Ẹ yé irọ́ pa, mí o fún Super Eagles ní ẹbùn owó kánkan -Sanwo Olu Amuneke fipò sílẹ̀ gẹ́gẹ́ bí akọ́nimọ̀ọ́gbá Tanzania Aṣafa Salamọt gba awọn ewe bii tirẹ nimọran pe ki wọn gbọran si obi wọn lẹnu laiyọ iwe kika silẹ.
Paulu wá sọ fún un pé, “Ọlọrun yóo lù ọ́.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Saudi Arabia Hajj 2020: Alaga Hajj ni Naijiria ni inú wọn kò dùn sí bí Hajj kò ṣe ní wáyé.
Ilumọọka arẹwa oṣerẹ ọkunrin nii Odunlade Adekola jẹ ọmọ bibi ilu Ọtun Ekiti ti a si gbọ pe ile ọba lo ti wa, ọmọ oye si ni pẹ̀lú.
Ọlọ́gbọ́n a máa pa òfin mọ́,ṣugbọn òmùgọ̀ onísọkúsọ yóo di ẹni ìparun.
Kenule Beeson 'Ken' Saro-Wiwa jẹ onkowe, adari ere ori amohunmaworan, ajijangbara fun agbegbe lati ilẹ Ogoni, lorilẹ-ede Naijiria.
O ni O ni ootọ ni pe igboro ti daru ni ilu Akure lẹyin ti awọn janduku to darapọ mọ awọn oluwọde End SARS, di gbogbo oju ọna to yẹ ki awọn eeyan gba pa."
Sagamu: Ògo ọjọ́ iwájú ìdílé wa ni Kazeem tí àwọn SARS ṣekúpa
Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Sowore: Èmi ṣì ni alága ẹgbẹ́, kò sẹ́ni tó yọ mí lóyè13 Èbibi 2019 Free Sowore: Ilé ẹjọ́ ti gba béèlì Omoyele Sowore24 Owewe 2019 Omoyele Sowore ní Apostle Suleiman o le gba onidúro òun5 Bélú 2019 Omoyele Sowore: Femi Falana ní òfin ilé-ẹjọ́ ilẹ̀ òkèrè nìkan ni ìjọba lè pamọ́11 Bélú 2019 Revolution Now: Ilé ẹjọ́ dá Omoyele Sowore padà sí àhámọ́ DSS30 Owewe 2019 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 3 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 5 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Oríṣun àwòrán, @GovWike Ọba Ewuare ke si awọn oloye rẹ lati bẹrẹ adura ni kankan lati jẹ ki alaafia jọba lasiko idibo to n bọ lọna naa.
Kanye West pa orúkọ dà sí 'Ye' Aisan jẹjẹrẹ asẹtọ ọkunrin paniyan ju jẹjẹrẹ ọyan lọ O ni iṣẹju mẹwaa ṣaaju iṣẹ abẹ naa loun to foju kan dokita to fẹ ṣee fun oun ati pe, oun ṣaisan lẹyin ti oun ṣee tan ki oun to pada lọ si UK fun itọju to peye.
Bí ẹnikẹ́ni bá rò pé òun mọ nǹkankan, irú ẹni bẹ́ẹ̀ kò tíì mọ̀ tó bí ó ti yẹ.
Ẹ máa yọ̀, bí ẹ ti ń gbádùn àjọ̀dún yín, ẹ̀yin, ati àwọn ọmọ yín lọkunrin ati lobinrin ati àwọn iranṣẹkunrin ati iranṣẹbinrin yín, àwọn ọmọ Lefi, àwọn àjèjì, àwọn aláìní baba, ati àwọn opó, tí wọ́n wà ní àwọn ìlú yín.
Kọmiksọna ọlọpàá ìpínlẹ̀ Ogun Kenneth Ebrinson ti paṣẹ pe ti ìwádìí ba ti pari ki wan gbe ọkùnrin náà lọ si ilé ẹjọ.
ikede  gbe jade niluu Abuja , pe  awẹ Ramadhan jẹ iwẹmọ ati gbigba ẹmi tuntun,
OLUWA, nǹkan wọnyi ni ó mú eniyan wà láàyè,ninu gbogbo rẹ̀ èmi náà yóo wà láàyè.
Ta ni yóo lọ fún wa?
‘Arákùnrin tó fipá bá ọmọdekunrin méjì lò pọ̀ ni Eko rè é’ 'Ààrùn arunmọléegun ti lóògùn báyìí' Ọwọ́ ṣìnkú ọlọ́pàá tẹ àwọn adigunjalè apanìyàn Ọffa mìíràn Oríṣun àwòrán, PRNigeria Àkọlé àwòrán, Ojú olè rèé!
"Ọlọ́pàá tó n gba rìbá sọ pé 'Ọlọ́run gan fara mọ́ olè jíjà' A ti rí akẹ́kọ̀ọ́ ABU tí wọ́n jígbé lọnà Kaduna-Abuja gbà -Ọlọ́pàá ""Bi mo tilẹ̀ jẹ́ apárí síbẹ̀ kò tìmí lójú"", Liliya Kukushkina A kó dúnkoòkò mọ́ Ambode, isẹ́ wa là ń ṣe - Ilé Aṣòfin Eko Lẹyin igbẹjọ naa lọjọru ni Adajọ Osunsanmi ni ki Rabiu lọ lo ọdun meji nile ikọni niwa ọmọluwabi ti ijọba to wa ni agbegeb Adigbẹ nilu Abẹokuta to jẹ olu ilu ipinlẹ Ogun."
Wò ó, wí fún wọn pé tẹ̀gbọ́n-tàbúrò ni wá, kí wọ́n lè ṣe mí dáradára, kí wọ́n má baà tìtorí rẹ pa mí.
kí ó lọ sọ fún Hesekaya pé, òun, OLUWA Ọlọrun Dafidi baba ńlá rẹ̀ ti gbọ́ adura rẹ̀.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ sí: Ẹgbẹ́ ọmọ Nàìjíríà ra fọ́ọ̀mù fún Buhari 'ìjọba àpapọ̀ fẹ fi N10,000 rà ìbò ni' Ààwẹ̀ gbẹ̀mí ọmọ Naijiria ní orílẹ̀èdè Amẹ́ríkà Kí lẹ ò mọ̀ nípa àwọn obinrin Yollywood yìí?
    Báyìí ni mo gbọ́, ṣùgbọ́n àyà mi kò já ju bẹ́ẹ̀ lọ, nítorí láti ìgbà tí mo ti di olórí ni mo ti pinnu pé n kò ní bẹ̀rù mọ́, nítorí bí olórí ba ń bẹ̀rù jù, kò ni lè ṣe alákòóso àwọn ọmọ ẹ̀yìn, bí aṣáájú bá bá ẹsẹ̀ rẹ̀ sọ̀rọ̀, àwọn èrò ẹ̀yìn yóò sáré tágbára tagbára.
''Wàhálà Ikẹja ló sọ mí di oníṣẹ́ ọwọ́ àgbọn ní Badagry'' Ọkọ̀ aképo gbiná ní òpópónà Eko sí Badagry Olorunwa Ariwayo, Jumoke Hassan, Isaiah Abass atawọn miran ṣalaye fun BBC Yoruba bi awọn ọmọ erekuṣu yii ṣe maa n gba ori omi nla Badagry yii lọ sile iwe lojoojumọ.
Ọrọ naa si ti fẹ da aawọ silẹ lawọn ileewe to jẹ ti ijọba nipinlẹ Osun.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù PSquare Peter Okoye sàlàyé bí ààrun Coronavirus ṣe mú-un, ìyàwó rẹ̀ àti ọmọ 27 Òkùdu 2020 Oríṣun àwòrán, Screenshot/ Peter Okoye, ìyàwó rẹ̀, àti ọmọ ló lùgbàdì ààrùn coronavirus fún odidi ọ̀sẹ̀ mẹ́ta, gbájugba olórin náà sàlàyé ọ̀rọ̀ náà lórí fọ́nran Instagram lọ́sàn òní sátíde' O ní ìdí nìyìí ti ètò orí zoom tó máa n ṣe fi ni ìdíwọ́ díẹ̀ lásìkò tí òun ya ara òun sọ́tọ̀ ''O ní kí ènìyàn ni ìgboyà lo fi le borí ààrùn yìí, èyí ni ǹkan tó sọ nínú fọ́nran náà lórí Instagram rẹ.
Ní ọjọ́ keji, àwọn olórí ìdílé kọ̀ọ̀kan àwọn eniyan náà, pẹlu àwọn alufaa, ati àwọn ọmọ Lefi, péjọ sọ́dọ̀ Ẹsira, akọ̀wé, kí ó lè la ọ̀rọ̀ òfin náà yé wọn.
Ọjọ Karun un, Osu Keji, ọdun ni wọn bi Saheed Balogun ati Faithia Williams ti wọn ti figbakan jẹ lọkọlaya , ki wọn to tuka.
Ọ̀kan nínú àwọn tó lọ́wọ́ nínú ikú ọmọ Fasoranti ni Corornavirus Lánàá òde yìí ni ìròyìn tàn pé àwọn afurasí ti ọlọpàá mú nítori wọ́n ni ọwọ́ nínú ikú tó pa ọmọbìnrin Fasoranti ni wọn ti ṣe àyẹwò ààrun Corornavirus fún nígbà tí wọ́n sí n réti àsìkò tí ìgbẹ́jọ́ wọ́n yóò jẹ́ Èsì àyẹwò tó jáde fi yéni pé àwọn ènìyàn mẹ́ta to tún ṣẹ̀ṣẹ̀ ni ààrùn Coronavirus ni ìpínlẹ̀ Ondo jẹ ọ̀kan nínú àwọn afurasíu yìí.
Olè ni eni tí ó mú/gbé/yo nnkan tí kìí se tirè láìgbàse lówó Olóhun(eni tí ó ni nnkan).
Ṣùgbọ́n bí ojú ọjọ ti ṣe rí a má ṣe òkùnfà ìyè wákàtí ti awọn èèyàn fi n gba àwẹ ní àwọn orílẹ̀èdè àgbáyé.
Mo mọ àwọn tí mo yàn.
Iroyin naa tẹsiwaju pe Flakky fẹ ki ile ẹjọ fi ofin de Jago, lati ma ni anfaani si ọmọ naa mọ.
o ku ki won ra awon ohun elo ti won yoo maa lo nibẹ, ati eyi ti won yoo
" O wa daba pe ipese awọn ohun eelo amayedẹrun gbọdọ maa lọ nifẹgbẹ-kẹgbẹ pẹlu eto idokowo ninu awọn araalu eyiti yoo mu ki ọrọ aje tọjọ.
Ifayemi Elebuibon: Mo jẹ páànù ìyà nítori mo fẹ́ mọ̀ọ́kọ, mọ̀ọ́kà
Gbogbo eniyan ni yóo rí i pé èmi OLUWA ni mo dá iná náà, kò sì ní ṣe é pa.
Ẹ yin OLUWA, ẹ̀yin angẹli rẹ̀,ẹ̀yin alágbára tí ẹ̀ ń ṣe ìfẹ́ rẹ̀,tí ẹ sì ń fetí sí ọ̀rọ̀ rẹ̀.
O ti kopa ninu awọn ere bii: The Bourne Identity, G.
Kete ti wọn ba ti mu aṣẹ yii ṣẹ lo ti tumọ si pe IMN ni ikeji ti wọn maa kede ni agbesunmọmi yato si ti IPOB nile Igbo.
Ki Olorun dẹlẹ fun ẹni to lọ ni adura aarẹ.
Ó bá bẹ̀rẹ̀ sí kọ́ wọn ní ọpọlọpọ nǹkan.
Wọ́n kọ ilé OLUWA Ọlọrun àwọn baba wọn sílẹ̀, wọ́n sì ń sin oriṣa Aṣera ati àwọn ère mìíràn.
Koko iroyin: Ìgbésẹ̀ ìjọba l'órí Codeine, ìkọlù NURTW níbi ayẹyẹ ọjọ́ òṣìṣẹ́
Àwọn tí ó gbógun tì ọ́yóo di òfo patapata.
Tí a fiṣọwọ́ ní 4:164:16 Covid-19 pa èèyàn mẹ́fà ní Naijiria lọ́jọ́ kan ṣoṣo, ó tún ran èèyàn 675 Akojọpọ esi ayẹwo Covid-19 ni Naijiria gẹgẹ bi ajọ NCDC ṣe n kede rẹ.
Iṣẹ́ nlá ni fún àwọn ọlọ́pàá nítorí ojúṣe wọn ni láti pèsè àbò àti ìdarí èrò nlá yìí.
 Weah soro naa di mimo lojo isegun(Tuesday).
Ṣugbọn nítorí ó jẹ́ aríran, ó sì mọ̀ pé Ọlọrun ti búra fún òun pé ọ̀kan ninu ọmọ tí òun óo bí ni yóo jókòó lórí ìtẹ́ òun, 
 ọdún mẹ ́ ta péré ni ó lò ní ẹ ̀ wọ ̀ n ní ìlú calabar tí ìjọba ológun yakubu gowon fi da sílẹ ̀ ní ọjọ ́ kẹ ́ ta oṣù kẹ ́ jọ ọdún 1966 .
Ẹ wo fidio naa fun ẹkunrẹrẹ alaye nipa igbadun ibalopọ nilana Tantra.
Mànàmáná rẹ̀ tan ìmọ́lẹ̀ sí ayé,ilẹ̀ ayé rí i, ó sì wárìrì.
ẹ́yìn èyí, a kọjú sí ọ̀nà Igbó Elégbèje à ń lọ.
Èmi náà bá dá lóhùn pé njẹ́ ó mọ̀n pé ṣàkì kìí ṣẹgbẹ́ ọ̀rá bí?
Mo fa Fayoṣe lé Ọlọrun lọ́wọ́"" Fayẹmi sèbúra l‘Ekiti, àwọn èèkàn ìlú péjú O ni wi pe o ti to ọjọ mẹta si isinyii ti ẹgbẹ oselu APC ti n yọ, ti wọn si n dunnu silẹ wi pe awọn ni yoo jawe olubori, ati wi pe ohun iyalẹnu ni yoo jẹ fun oun, ka ni wi pe PDP lo jawe olubori."
5 Àti pé ẹ̀yin yíò jẹ́rìí pé ẹ̀yin ti rí àwọn ohun wọ̀nyí, àní bí ìránṣẹ́ mi Joseph Smith, Kekere, náà ṣe rí wọn; nítorí nípa agbára mi ni òun fi rí wọn, àti nítorípé ó ní ìgbàgbọ́.
Bakan naa ni iwadii oun fihan wi pe, awọn eniyan to n binu laye atijọ ma n ni ẹmi gigun ju awọn ti o tutu niwa ati ise, ti wọn si ma n gba ki awọn onibinu rẹ wọn jẹ.
Fulani Kidnapping: Owó púpọ̀ la san kí wọ́n tó fi mi sílẹ̀ lẹ́yìn ọjọ́ mẹ́fà
Awọn eniyan ni igbesẹ isejọba naa ko sẹyin bi Sanusi se n tako ọpọlọpọ igbesẹ gomina Ganduje, eleyii ti wọn ni o fa igbesẹ naa.
 Shilekunola, Moronke, Naomi; the greatest Arsenal you can apply on this highly revered throne with many rules and regulations in the midst of undiluted tradition, heritage and culture is the “Fear Of God In You”, which is the beginning of your wisdom on this throne of Oduduwa.
Adelé ọba kan ní ń ṣàkóso ilẹ̀ náà.
Iko agbaboolu Super Falcons yoo bere igbaradi n kikun fun ifesewonse ipegede idije boolu ile Afrika tawon obinrin to n bo lona, eleyi ti won yoo gba pelu iko agbaboolu orile-ede Gambia.
Kini idi ti aye igbalode n jẹ ki awọn eniyan binu fufu?
Akowe Ilẹ Gẹẹsi wa parọwa si ijọba orilẹede Naijria lati ri wi pe wọn pese awọn ohun igbaye-gbadun si awọn agbeegbe ti awọn ọmọogun ilẹ Naijiria ti le awọn Ikọ Boko Haram kuro ki wọn ma ba a raye pada si agbeegbe naa mọ.
lorile ede yii to lo ni irowo-irose julọ.
2019 Guber election: Mi ò fara mọ èsi ìdìbò Ọyọ́ ‘Kò tọ́sí Adeleke láti díje dupò gomina Ọṣun’ Ààrẹ Abdulaziz Bouteflika ti kowe fipo silẹ Ilé ìgbìmọ aṣofin ti dájọ tí wọn ó fọwọsi àbádofin ìsúna 2019 Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Okùnrin SARS náà sọ pé òun máa pa èèyàn síbi ni- Aladugbo O ni lakọkọ, akoko lati pẹjọ lori bo ya Sẹnẹtọ Adeleke koju oṣuwọn lati dije fun ipo oṣelu ti kọ ja nitori o ti ju ọgọsan ọjọ ti ofin la kalẹ lọ.
EFCC ni bo tilẹ jẹ wipe lootọ ni ẹsun iwa ọdaran n bẹ l'ọ́rùn Fayose, o ni ile ẹjọ giga ijọba apapọ̀ to wa nilu ado-Ekiti nikan lo le sọ boya igbẹjọ yoo wa lori ẹ̀sùn naa, ti Fayose ba pari saa rẹ gẹgẹ bi gomina Ekiti.
Ẹ sì ti rí àwọn ohun ìríra wọn: àwọn oriṣa wọn tí wọ́n fi igi gbẹ́, èyí tí wọ́n fi òkúta gbẹ́, èyí tí wọ́n fi fadaka ṣe, ati èyí tí wọ́n fi wúrà ṣe.
Wọ́n mú àwọn ẹbọ wọnyi wá sí ẹnu ọ̀nà ibi mímọ́.
Bẹ́ẹ̀ ni OLUWA ṣe di ọba ní Jeṣuruni,nígbà tí gbogbo àwọn olórí péjọ,àní, gbogbo àwọn olórí ninu ẹ̀yà Israẹli.
Ẹnikẹ́ni tí ó bá ń ṣe burúkú a máa kórìíra ìmọ́lẹ̀; kò jẹ́ wá sí ibi tí ìmọ́lẹ̀ bá wà, kí eniyan má baà bá a wí nítorí iṣẹ́ rẹ̀.
Osise ajo to n ri si eto idibo ni Naijiria, INEC iyen ogbeni Anya Uche ti o wa ni bi eto idibo ohun, gboriyin fun igbimo naa fun eto idibo ohun ti o waye ni irowo-irose.
Nítorí náà, ìyàwó mi, Ìfẹ́pàtàkì, mú ọwọ́ rẹ wá, èmi, Ìrìnkèrindò fi òrùka díámọ́ǹdì yìí, bá ọ dá májẹ̀mú wí pé láti òní lọ, mo di tìrẹ; wí pé, láti òní lọ, o di tèmi; wí pé láti òní lọ, ayọ̀ rẹ ni yóò jẹ́ ayọ̀ mi; ìbànújẹ́ rẹ ni yóò jẹ́ ìbànújẹ́ mi; àwọn ara ilé rẹ yóò sì jẹ́ ará ilé mi.
osu kẹ́sán án, odun, 2019 ni bi tuntun ti
aare nipinle KwaraAare Muhammadu Buhari ti o n
Ṣebí mo ti kọ ọgbọ̀n àkọsílẹ̀ fún ọ lórí ìmọ̀ràn ati ọgbọ́n,
25 billion dollars), lodoodun won yoo si
“Ní ìhà àríwá, ààlà yín yóo gba ẹ̀gbẹ́ òkun ńlá lọ títí dé Òkè Hori.
Mo bá ranṣẹ pe àwọn olórí wọn wọnyi: Elieseri, Arieli ati Ṣemaaya, Elinatani, Jaribu, Elinatani Natani, Sakaraya, ati Meṣulamu.
Ṣùgbọ́n ní ìkẹhìn ṣáá mo dé ibi tí Ọba Igbó Olódùmarè wà.
Bẹ́ẹ̀ ni ẹ̀ka igi firi kò sì tó ẹ̀ka rẹ̀.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Oluwo Divorce: ko si ẹni ti kò mọ pé ọmọ ilẹ̀ òkèrè ni mó fi ṣe aya Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Oluwo Divorce: ko si ẹni ti kò mọ pé ọmọ ilẹ̀ òkèrè ni mó fi ṣe aya 17 Ọ̀pẹ̀̀ 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 19 Ọ̀pẹ̀̀ 2019 Nínú oṣù keje, ọdún yìí ni Oluwòó sọ̀rọ̀ nínú ìfọ̀rọ̀wérọ̀ kan pẹ̀lú BBC.
Ṣugbọn bí ẹ bá ń bá ara yín jà, tí ẹ̀ ń bu ara yín ṣán, ẹ ṣọ́ra kí ẹ má baà pa ara yín run.
a ṣe n gbaradi fun eto idibo gbogbo ọdun 2019, a gbọdọ wa ni iṣokan, ki a
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Say no to rape: Àwọn òṣèré tíátà Yorùbá pariwo síta lórí wàhálà ìfipábánilòpọ̀ Ijọba orilẹede naa ti wa kede eto idaro ọlọjọ meje, bẹrẹ lati ọjọ Iṣẹgun jakejado orilẹ€de naa ni iranti rẹ.
Jeremaya bá fún Baruku akọ̀wé, ọmọ Neraya, ní ìwé mìíràn, Baruku sì kọ gbogbo ọ̀rọ̀ tí Jeremaya sọ fún un sinu rẹ̀.
Ohene sọ pe oun ko le gbagbe oorun ara ọkunrin naa ati eekanna rẹ to fi bọ oju ara ohun titi di ọjọ oni ti iṣẹlẹ naa ti pe ọdun mẹtadinlaadọrin.
Àwọn ọmọ Lefi sì ṣe gẹ́gẹ́ bí Mose ti wí, àwọn tí wọ́n kú láàrin àwọn eniyan náà tó ẹgbẹẹdogun (3,000) ọkunrin.
Sugbọn ọrọ aro ti ọpọ wọn n kọ soju opo Instagram wọn lo safihan pe, wọn n paroko ọrọ ransẹ saarin ara wọn, to si ni itumọ to jinlẹ.
Èyí ni ìdí tí coronavirus ṣe n pa àwọn kan, tí kò sì pa àwọn kan Coronavirus- Atọ́nà bí nkàn ṣe ń lọ ní Afirika Èyí tí a wò jùlọ 5:03 Fídíò, Omolola Arohunmolase Welder: Mo ti fí iṣẹ́ 'Welder' gbayì láwùjọ, tó mo fi tọ́ ọmọ yanjú, Duration 5,039 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 5:39 Fídíò, Akomolede ati Asa lori BBC: Olùkọ́ Kikelomo Ogunboye tan ìmọ́lẹ̀ sí ìwà olè ọ̀gá ọlọ́pàá Audu gẹ́gẹ́ bí àwòkọ́ṣe àsìkò yìí, Duration 5,398 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 4:11 Fídíò, Oba Adeyeye Ogunwusi: Ojú mi ti rí lọ́pọ̀ lọpọ̀, ọ̀pọ̀ èèyàn ni kò tilẹ̀ gbàgbọ́ pé mo lè jọba- Ooni, Duration 4,117 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 4:43 Fídíò, Promise Akinlade: ọmọ ọdún mọ́kànlá tó ń fi ìlù dárà bíi àgbàlagbà sọ̀rọ̀ nípa tálẹ́ǹtì rẹ̀, Duration 4,437 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 0:59 Gbọ́, Ìsẹ̀lẹ̀ jákèjádò orílẹ̀èdè àgbáyé láàárín ìṣẹ́jú kan, Duration 0,59wákàtí 6 sẹ́yìn 7:03 Fídíò, Olumuyiwa Bolade Adedeji Military Bruitality: Bí arákùnrin onípèníjà ara tí sọ́jà lù ṣe dé, Duration 7,035 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 4:45 Fídíò, Yoruba Films: Ẹ̀ẹ́ bẹ̀ mi kúrò láyé ni, mi ò lè kú - Fadeyi Oloro, Duration 4,4526 Èrèlè 2020 2:48 Fídíò, Esther Ajayi: Èmi náà ti borí ìṣòro rí ló ń mu mi ṣojú àánú, Duration 2,481 Ògún 2019 6:08 Fídíò, Adebola Ademilua: Àìrísẹ́ ṣè lẹ́yìn ìwé kíkà ló sọ mi dí ìyá onírú, mo dúpẹ́ tèmi, Duration 6,0827 Bélú 2020 5:55 Fídíò, Soyinka Cancer: Àṣe ara mi ni iso ti n run gbogbo bí mo ṣe n ṣèrànwọ́ lórí jẹjẹrẹ, Duration 5,5527 Bélú 2019 BBC News, Yorùbá Ìdí tí ẹ fi le è nígbàagbọ́ nínú ìròyìn BBC Ìlànà Lílò Nípa BBC Òfin Àṣírí Cookies Kàn sí.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Man City: Gìrìgìrì kọ́ o!
Iléeṣẹ́ ọlọ́pàá ṣàfihàn ojú àwọn afurasí tó se ẹran ara ọlọ́pàá jẹ ní Ibadan Wo ọ̀nà tí ọrọ̀ ajé Naijiria tó dẹnu kọlẹ̀ gba kàn ọ Mílíọ́nù mẹ́wàá Náírà ni ilé ẹjọ́ ni kí Kábíyèsí san gẹ́gẹ́ bí owó ìtaran ilẹ̀ tí ó gbà lọ́nà àìtọ́ Kíni àjọ ọlọ́pàá ń ṣe lórí bí agbófinró ṣe ń ṣèèṣì pànìyan lójoojúmọ́?
Ìgbà tí òògùn ẹ̀jẹ̀ ríru lè ṣiṣẹ́ jù rèé- Onímọ̀ Ó rẹ ẹni ọdún 49 tó ri ẹ̀wọ̀n ọgọ́ta ọdún he lẹ̀yìn tó bá ọmọ ọdún méjì lòpọ̀ Mo pàṣẹ pé kí ọ̀gá owó ìfẹ̀yìntì tẹ́lẹ̀, Maina sì wà látìmọ́lé- Adájọ́ Ṣé irúfẹ́ oúnjẹ tí ò ń jẹ́ lè jẹ́ kí o gbádùn ìbálòpọ̀ rẹ síi?
“Gbà wá ní ìmọ̀ràn,máa ṣe ẹ̀tọ́ fún wa.
ẹ óo dá wọn lóhùn pé, ‘Ẹbọ ìrékọjá OLUWA ni, nítorí pé ó ré ilé àwọn eniyan Israẹli kọjá ní Ijipti, nígbà tí ó ń pa àwọn ará Ijipti, ṣugbọn ó dá àwọn ilé wa sí.
Ẹni tí ó bá ń pọ́n aládùúgbò rẹ̀,ń dẹ àwọ̀n sílẹ̀ fún ẹsẹ̀ rẹ̀.
2 Bélú 2020 Fídíò, Soyinka Cancer: Àṣe ara mi ni iso ti n run gbogbo bí mo ṣe n ṣèrànwọ́ lórí jẹjẹrẹ27 Bélú 2019 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 3 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 5 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Ni Carson ni California ni ija naa yoo ti ṣẹlẹ.
won yoo gbe maa rọ irin niluu Abuja FCT, ni eyi  o si gbodo pari rẹ laarin osu marunun.
Gbogbo eniyan ni ko si f'oju ire wo o.
Kristi sì ni Olùgbàlà ara rẹ̀ tíí ṣe ìjọ.
‘Jẹ́ kí n kọjá láàrin ilẹ̀ rẹ.
Bí a kò bá rẹ́ni fẹ̀hìn tì, bí ọ̀lẹ là á rí
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fọ́nrán ohùn, Onimọ nipa ile kikọ sọwipe ijọba nilo awọn onimọ nipa owo ori ile Akoroyin BBC ni ajọ alagbelebu pupa to n ṣiṣẹ nibẹ ti fidiẹ mulẹ pe Baba onile naa ati awọn ọmọ rẹ meji wa lara awọn ti wọn ti ri oku wọn yọ nibẹ.
Lizzy Anjorin vs Toyin Abraham: Ẹ wá ọ̀nà láti parí ááwọ̀ ààrin yín
Gege bi ogbeni Nuhu se sọ, “Lọjọ
Ọba Mohammed bin-Salman ti Saudi yọ ọmọ rẹ̀, Fahad, Abdulaaziz àti àbúrò rẹ̀, Ahmed kúrò nípò nítorí ìwà àjẹbánu
Mò ń dókòòwò láti pín ọrọ̀ mi yíká Nàíjíríà kí àdínkù leè bá ìṣẹ́ - Dangote Kí ló dé tí Ilé ẹjọ́ sún ìgbẹ́jọ́ Naira Marley sí ọ̀la?
Nígbà tí a ti gúnlẹ̀ ní alaafia tán ni a tó mọ̀ pé Mẹlita ni wọ́n ń pe erékùṣù náà.
Nígbà tí ó rí i pé ó dùn mọ́ àwọn Juu, ó bá tún mú Peteru náà.
Ọwọ palaba rẹ segi ni bi ọsẹ meji sẹyin nigba ti awọn ọlọpaa ikọ ọtẹlẹmuyẹ marindọti ti a mọ si IG intelligence Squad mu ni ipinlẹ Taraba.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Omolola Arohunmolase Welder: Mo ti fí iṣẹ́ 'Welder' gbayì láwùjọ, tó mo fi tọ́ ọmọ yanjú Nnamdi Azikiwe: Ni ọdun 1956, igbimọ oluwadii kan ti a da pe ni Foster-Sutton Tribunal of Inquiry se iwadii olootu ijọba ẹkun ila oorun ọjọhun, Ọmọwe Nnamdi Azikiwe, lori ẹsun pe o n lo ipo rẹ lati fi ṣe akoso banki African Continental Bank (ACB) nigba naa.
Wọn á máa wí pé, “Báwo ni Ọlọrun ṣe lè mọ̀?
Ilu Ilaro, tii ṣe ilu abinibi rẹ ni wọn ti ko Seriki Abass ni ẹru lasiko ogun Ẹ̀gbá ati Dahomey, ti wọn si ta a fun Williams, tii ṣe oyinbo olowo ẹru lati Brazil.
Oríṣun àwòrán, Nigeria Presidency Àkọlé àwòrán, Gbajugbaja agbabọọlu orilẹede France ni, Chritian Karembeu lo gbe ife ẹyẹ yii le aarẹ Buhari lọwọ Gbajugbaja agbabọọlu orilẹede France ni, Chritian Karembeu lo gbe ife ẹyẹ yii le aarẹ Buhari lọwọ lorukọ ajọ to n se amojuto ere bọọlu afẹsẹgba lagbaye, FIFA.
Ẹnu ọ̀nà àgbàlá náà yóo ní aṣọ títa kan tí yóo gùn ní ogún igbọnwọ, aṣọ aláwọ̀ aró, èyí tí ó ní àwọ̀ elése àlùkò ati àwọ̀ pupa fòò ati aṣọ ọ̀gbọ̀ ni kí o fi ṣe aṣọ títa náà, kí wọ́n ṣe iṣẹ́ ọnà sí etí rẹ̀, kí ó ní òpó mẹrin ati ìtẹ́lẹ̀ mẹrin.
Jakọbu bá ranṣẹ pe Rakẹli ati Lea sinu pápá níbi tí agbo ẹran rẹ̀ wà.
Dokita Olarinoye je omo bibi adari eka awon agbaboolu ile-okere ninu ajo NFF teleri, Dokita Steve Olarinoye.
Omowe yii ṣalaye ni kikun bi awọn Fulani naa ṣe dira ogun pẹlu ihamọra loriṣiiriṣii.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù US election 2020: Bi kò tilẹ̀ wọlé, ẹ wo ayípadà tí Ààrẹ Trump mú bá awọn orilẹede ní àgbáyé 1 Bélú 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 4 Bélú 2020 Aarẹ orilẹede Amerika kii ṣe aarẹ ilẹ rẹ nikan, amọ awọn orilẹede lagbaye ma n rii gẹgẹ bi adari ni agbaye.
Kò sí ọ̀kan ninu àwọn wọnyi tí kò ní sí níbẹ̀,kò sí èyí tí kò ní ní ẹnìkejì.
Owo ti wọn ni o lu ni ponpo ko ni din ni irinwo miliọnu naira.
"Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Adebisi Idikan: Òun ló gba Ìbàdàn sílẹ̀ lọ́wọ́ ìyà owó orí sísan Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Adebisi Idikan: Òun ló gba Ìbàdàn sílẹ̀ lọ́wọ́ ìyà owó orí sísan 15 Ẹrẹ̀nà 2018 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 9 Owewe 2018 Asamọ to wọpọ nilu Ibadan ni pe ""N o kọle mi bii ile Adebisi, esu aini kọ ile kankan niyẹ."
1585 new cases of #COVID19Nigeria; Lagos-573 FCT-182 Plateau-162 Gombe-81 Oyo-75 Rivers-68 Sokoto-58 Ondo-55 Ogun-42 Nasarawa-40 Akwa Ibom-36 Edo-31 Kaduna-27 Anambra-22 Delta-19 Kano-17 Osun-17 Ebonyi-16 Katsina-14 Niger-14 Bayelsa-9 EKiti-8 Borno-7 Jigawa-5 Abia-4 Bauchi-3 COVID-19 pa èèyàn mọ́kànlá láàrín ọjọ́ méjì, ènìyàn 1565 míràn tún ko lọ́jọ́ kan ṣoṣo ní Nàìjíria Eeyan mọkanla ni ajakalẹ aarun COVID-19 ti ran lọ sọrun lorilede Naijiria laarin ọjọ meji pere ni Naijiria bayii.
Ọrọ̀ kò jámọ́ nǹkankan ní ọjọ́ ibinu,ṣugbọn òdodo a máa gbani sílẹ̀ lọ́wọ́ ikú,
Akọwe ijọba pari atẹjade naa pe awọn ẹbi oloogbe naa atri ijọba yoo kede bi eto isinku rẹ yoo ṣe lọ laipẹ.
Ní ti obìnrin àǹfání wà láti san ìdajì owó nínú ẹgbẹ́ òṣèlú APC nígbà ti ó jẹ́ ọ̀fẹ́ pátápátá nínú ẹgbẹ òṣèlú PDP fún obìnrin tó ba dá ara rẹ̀ lójú tó sì ṣetan láti díje, sùgbọn ohun tó yani lẹ́nu ní pe kò sí ẹgbẹ́ kankan tó ti fa obinrin sílẹ̀ gẹ́gẹ́ bíi aṣojú ẹgbẹ́ òṣèlú wọn láti ìgbà ti ìjọba awa ara wa ti bẹ̀rẹ̀ lọ́dún 1999 àti pé obìnrin kan ṣoṣo Sarah Jibril nìkan ló kópa nínú ìbò kòmẹ́sẹ̀ yọ.
Wayii o, aawo ti wa laarin ijoba apapo ati ijoba ipinle Eko nile ejo, lori eni ti yoo maa sakoso irinna oko oju-omi ohun lataari ohun alumoni oro aje to ro mo on.
Ohun mẹrin ti igbimọ naa yoo bẹrẹ sise lati ọjọ Aje lọ ni: Iwadi boya iwe idibo ti ajọ eleto idibo ipinlẹ Kano beere fun lọwọ ajọ Inec lo fi se idibo sijọba ibilẹ to kọja.
Jakọbu ti gbọ́ pé ó ti ba Dina, ọmọ rẹ̀ jẹ́, ṣugbọn àwọn ọmọ rẹ̀ wà pẹlu àwọn ẹran ninu pápá, Jakọbu kò sọ nǹkankan títí tí wọ́n fi dé.
Dafidi bá sọ fún àwọn eniyan rẹ̀ ní ọjọ́ náà pé, “Jẹ́ kí ẹnikẹ́ni tí ó bá fẹ́ pa àwọn ará Jebusi gba ojú àgbàrá lọ pa àwọn afọ́jú ati àwọn arọ tí ọkàn Dafidi kórìíra.
Àwọn ọmọ ti Beraya ni Heberi, ati Malikieli.
10) Ṣọra fun fifi foonu rẹ si ibi to gbona bii inu oorun tabi ibi to tutu pupọ nitori bi oju ọjọ agbegbe too fi foonu si ṣe ri maa n jẹ ki o tun bajẹ Buhari já ọ̀ra lára ọkọ̀ ìjagun ológun tiwantiwa ní Kaduna Bàbá mi fún mi ní kíndìnrín rẹ̀ láti dóòlà ẹ̀mí mi- Sam Òṣìṣẹ́fẹ̀yìntì, ọmọ ọdún 71 wọ gbaga ọlọ́pàá fún pípe iléeṣẹ́ kan fún ìgbà 24, 000 A ó kàn sí mọ̀lẹ́bí àwọn ẹlẹ́wọ̀n tó kú létí ná kí a tó kéde orúkọ wọn-Iléeṣẹ́ Ọgbà ẹ̀wọ̀n 11) Sọra fun fifi foonu rẹ sinu ina nigba gbogbo, rii pe batiiri rẹ ti fẹ tan ki o to kii bọ inu ina.
Jẹ́ kí ó ṣe àwọn nǹkan ọwọ́ rẹ̀ bí ó bá ti fẹ́, mo ṣá fi àwọ́nsìn ewúrẹ́ tí mo ṣèlérí ranṣẹ, o kò rí i ni.
awa ti ṣe tan tẹwọ gba aba iṣuna owo yii, paapaa ti Gomina ba ti ṣe ohun
Ile-ise iroyin  kan lorile-ede Egypt so lojo-Isegun pe, ile-ejo orile-ede Egypt ti fi oruko oludije-dupo Aare teleri, Abdel Moneim Abol Fotouh kun  iwe oruko awon adunkoko-moni, eyi waye leyin ifi owo sinkun ofin mu arakunrin naa latari esun pe, o ni ajosepo pelu egbe Muslim Brotherhood ti ijoba fofin de lorile-ede naa.
wa lori won sile, oun ko lodi si pipada wa won si aafin .
Mo kí i òun náà sì kí mi, lẹ́hìn tí ó kí mi tán ó ṣe ìbéèrè lọ́wọ́ mi báyìí, ó wí pé, ‘Kí lo ń wá láàárin ọgbà wa?
” Bẹ́ẹ̀ ni Labani ṣe wá àwọn ère oriṣa rẹ̀ títí, ṣugbọn kò rí wọn.
Sugbọn sa, ọrọ naa ko le dun baba, nitori pe ọpọlọpọ ibi, oju ọna, ati agbegbe ni wọn ti fi sọ orúkọ rẹ.
Ibe Kachikwu sọ eyi lasiko to n sọrọ lori eto ‘Good Morning Nigeria’ ni ile isẹ Iroyin NTA lori ero ijọba lati yọ owo iranwọ ti ijọba n san lori epo bẹntirol.
(Farao, ọba Ijipti ti gbógun ti ìlú Geseri ó sì dáná sun ún, ó pa gbogbo àwọn ará Kenaani tí wọn ń gbé inú rẹ̀.
Ọjọ́ ńlá ati ọjọ́ ẹ̀rù ni ọjọ́ OLUWA!
Five Fingers for Marseilles- Michael Mathews- South Africa
    Ó pe ọmọ rẹ̀, ó wí fún un kí o lọ̀ bá òun wá nǹkan tí ó ṣòro.
Amọ fun iyalẹnu oun, se ni wọn tun n beere owo mii, tii se gbẹrun mejilelaadọta naira o din diẹ, N51, 950.
Ajọ NNPC fikun pe, iwadii ni kikun ti bẹrẹ lori bi ibugbamu naa ṣe ṣẹlẹ.
won yoo bẹrẹ si ni gbe igbesẹ yii.
Gege bi aare se so: “Mo ro awon oludije egbe oselu kookan ati awon ololufe won gbogbo lati ri daju pe ipolongo saaju eto idibo gbogbogbo to n bo lọdun 2019 waye nirowo-rose lai fa wahala kankan bi o se le wu ko mo.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù EFCC vs Naira Marley: Nítorí ẹ̀sùn 'yahoo-yahoo' Adájọ́ ní kí Naira Marley ó máa gbatẹ́gùn láhámọ́ ọgbà ẹ̀wọ̀n 20 Èbibi 2019 Oríṣun àwòrán, EFCC Adajọ to n gbẹjọ olorin takasufe kan lorileede Naijiria, Naira Marley lori ẹsun ''Yahoo Yahoo'' ti paṣẹ pe ki wọn lọ fi si ahamọ titi di igba ti wọn yoo fi gbẹjọ rẹ.
Ìwọ tí ò ń dá àwọn ẹlòmíràn tí ó ń ṣe nǹkan wọnyi lẹ́jọ́, tí ìwọ alára sì ń ṣe nǹkankan náà, ṣé o wá rò pé ìwọ óo bọ́ ninu ìdájọ́ Ọlọrun ni?
Òw;urọ̀ ọjọ́ tí mo sì dé ibẹ̀ yìí ni àwọn ìyàwó ránṣẹ́ sí wọn pé àwọn kò wá mọ́ nítorí pé àwọn ti ní ọkọ mìíràn sí ilé Wọ̀bìáparapọ̀.
Ọmọkunrin kan sáré wá sọ fún Mose pé Elidadi ati Medadi ń sọ àsọtẹ́lẹ̀.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Coronavirus Vaccine: Ṣé abẹrẹ àjẹsára ti wà fún àrùn COVID-19?
Solomoni ọba bá pàṣẹ fún Bẹnaya, pé kí ó lọ pa Adonija, ó bá jáde, ó sì lọ pa á.
Bẹẹ naa ni awọn agbarijọpọ ẹgbẹ ọmọ Yoruba mii naa ni awọn fẹ ṣe iwọde lati beere fun Oduduwa Republic.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Lekki Toll Gate: Ìjọba ìpínlẹ̀ Èkó fajúro lórí ìpolówó tó ṣe àfihàn obìnrin ní ìhòòhò 4 Ògún 2019 Oríṣun àwòrán, @LASAAONLINE Ijọba ipinlẹ Eko ti bẹnu atẹ lu bi ọlọkọ kan ti ṣe afihan awọn obinrin to n jo ni ihoho nitagbangba.
 káàkiri ilẹ ̀ adúláwọ ̀ ni ẹ ̀ mí orin àti ijó ti jẹ ́ ẹ ̀ mí ìgbésí ayé .
Eniyan mejilelaadọrinlenirinwo( 1742) lo ti ri iwosan gba, nigba ti eniyan mẹrindinlọgọsan to ti papoda nitori arun Coronavirus.
Ohun tí Ọlọrun bá wó lulẹ̀,ta ló lè tún un kọ́?
 ní oṣù kọkànlá ọdún yí , Ìjọba Àpap ̀ ọ ilẹ ̀ nàìjíríà fi ẹ ̀ sùn kan awólọ ́ wọ ̀ wípé ó dìtẹ ̀ láti dojú ìjọba bolẹ ̀ .
Bo tilẹ jẹ pe ileesẹ BBC Yoruba ko gbe lẹyin ẹnikẹni, a lero pe o yẹ ki a ṣe alaye lori ohun ti Ruga tumọ si ati bi awọn eeyan ti ṣe n tumọ rẹ.
Egbe Olokowo nla nile South Africa ti a mo si African National Congress (ANC) ti ni awon lee fopin si atileyin ti awon n se fun eto idibo gbogboogbo todun 2019 ti egbe ko ba dekun bi awon eniyan se n padanu ise oojo won pupo lasiko yii.
A ko ti i rin jina ti awọn ọlọpaa to wa ninu ọkọ lẹyin ọkọ akẹru mi fi sọ pe ki n duro.
Sanwo Olu ni ijọba oun setan lati yanju ọrọ ifiyajẹni to n fa iwọde kaakiri Naijiria lasiko yii.
"Ara idi ti baba ọmọ mi fi kọ mi silẹ ni pe ko fẹ maa fi mi han loju taye.
Ogbeni Rashid Kassim to n soju fun ekun iwo oorun Kenyan , ni Nairobi to je olu –ilu orile ede Kenya ni won ti fi esun kan pe,o gba  arabinrin akegbe re nile igbimo asoju sofin, Fatuma Gedi leti nitori pe, o kọ lati fi owo isuna ti o je ti ekun naa fun won.
Agbábọ́ọ̀lù Super Falcons tẹ́lẹ̀, Chiejine jáde láyé lẹ́ni ọdún 36 PFN: Fatoyinbo kọ̀ láti yọjú ni ìwádìí wa kò ṣe parí Ṣe o ti gbọ nipa Akintoye Alakada?
 Ọmọ ́ tọ ́ ṣọ ̀ ọ ́ ní sítọ ́ ọ ̀ .
Oríṣun àwòrán, @gidabless Gloria pe ọrẹ rẹ , Gida lori foonu, afi to di pe Kemi lo gbe foonu to si bẹrẹ si ni s fun Gloria pe ko fi ọkunrin rẹ lọrun silẹ to si fesi pe ki o dẹkun gbogbo radarada yẹn ki o ye ṣe bi ọmọde.
Awọn oluwọde naa wa n ke si ijọba lati din iye akanse owo ori to n fi si ori epo bẹntiroolu ku ni ida mẹẹdogun ninu ọgọrun.
  Mo jẹ́ kó yé wọn pé “òkò tí a bá sọ lu ọ̀pẹ ní í sọ padà sí ẹni”.
Mo ha gbọdọ̀ pa ọ́ run bí mo ti pa Adimai run;kí n ṣe sí ọ bí mo ti ṣe sí Seboimu?
Bakan naa ni nkan ri ni Mọṣalaaṣi An-nur to jẹ gbaju-gbaja nilu Abuja bakan naa.
Pẹlu omije loju ni Bakare fi sọ wi pe aago Naijiria ti kun akunwọsilẹ pẹlu bi ẹmi awọn eniyan ko ṣe jọ ijọba loju mọ, ti ipaniyan n waye lọtun losi.
'Ọdún méjì sẹ́yìn ni òbí àwọn ọmọbinrin Chibok gbọ́ láti ọ̀dọ́ ìjọba kẹ́yìn' Bi wọn se pa ọga SARS Ọkan pataki lara awọn amofin to n pariwo lori ẹrọ ayelujara pe ki ijọba wa nkan ṣe si ọrọ awọn agbofinroArá ìlú túbọ̀ ń polongo ìfòpin sí SARS paapaa awọn SARS ni Amofin Segun Awosanya to jẹ alakoso #END SARS.
Emma Andy - Ọmọ ẹgbẹ́ 7.
Loni ni ile ẹjọ to ga ju lọ lorileede Naiijiria yoo kede idajọ lori esi idibo Gomina ipinlẹ Osun.
Lọsan Ọjọru ni iroyin tan ka ori ayelujara pe sọrọsọrọ naa ti papoda.
Bi mo tilẹ̀ jẹ́ apárí síbẹ̀ kò tìmí lójú"", Liliya Kukushkina Nínú gbèsè Nàíjíríà, ₦121,000 ló kàn ẹnìkọ̀ọ̀kan, ṣó o ṣetán láti san tìẹ?"
 Ìgbàgbọ ́ yorùbá ni pé bí àwọn áńgẹ ́ lì tí jẹ ́ olùrànláwọ ́ fún olódùmarè lóde ọ ̀ run ni àwọn òrìṣà náà jẹ ́ aṣojú rẹ ̀ lóde ìṣálayé , àwọn òrìṣà wọ ̀ nyí jẹ ́ alágbàwí àwọn ènìyàn níwájú olódùmarè .
Àkọlé àwòrán, Igbimọ alakoso NHIS ni ki ọga agba ileeṣẹ naa, Ọjọgbọn Usman Yusuf lọ rọọkun nile naa Amọṣa, eyi kọ ni igba akọkọ ti ọga agba ajọ adojutofo ilera lorilẹede Naijiria yoo maa ko sinu ọgbun wahala bayii.
5 3893 Erekusu Cape Verde 115 21.
Kìí ṣe nítorí pé wọn kìí gbàdúrà ni wọ́n ṣe nísòro, pé wọ́n tilẹ̀ ń sọ̀rọ̀ fún ọ, ǹkan tó dára ni gẹ́gẹ bi Dókítà Kadiri ṣe sọ.
aje ko lọ de e de.
Iroyin to to wa leti sọ pe, ko to yọju si ile ejo ni Ọjọru, ile isẹ ọlọpa nipinlẹ Kaduna ti fofin de eto irinna awọn eniyan lagbeegbe ilu Kaduna.
O ṣalaye siwaju sii pe ko ba tiẹ wu Tinubu gan an ki Buhari wọle ibo aarẹ ọdun 2003 nitori oun ti Obasanjo ṣe fun ipinlẹ Eko nigba to gbẹsẹ le owo to n wolẹ lati apo ijọba apapọ.
Aaroni yóo sì máa ṣe ìtọ́jú àwọn àtùpà tí wọ́n wà lórí ọ̀pá fìtílà wúrà, kí wọ́n lè máa wà ní títàn níwájú OLUWA nígbà gbogbo.
Iya olooṣa yii fi ẹsun kan iya arugbo ọhun, ti orukọ rẹ n jẹ Akua Denteh pe ajẹ mujẹmujẹ ni.
Ọ̀rá ni àwọn dókítà fi ń dáàbò bo ara wọn nílẹ̀ẹ Gẹ̀ẹ́sì Kí lo mọ̀ nípa fẹntilétọ̀, ohun èlò aṣèrànwọ́ èémí Èyí ni ìdí tí coronavirus ṣe n pa àwọn kan, tí kò sì pa àwọn kan Kínni ìtàkùn ayélujára 5G nííṣe gan na pẹ̀lú ààrùn coronavirus?
Ológun mú àwọn sọ́jà tó kọ́wọ̀ọ́ fipá bá akẹ́kọ̀ọ́ fásitì AAUA lò pọ̀ Kí ni Oluwo lọ ṣe ní Aso Rock lẹ́yìn lẹ́tà rẹ̀ sí ààrẹ Buhari?
2m tí kò sí nílé ìwé Àwọn kan fẹ́ da Naijiria rú torí ààbò tó mẹ́hẹ - Osinbajo gbarata Lẹ́tà Obasanjo: Àjálù ń bọ̀ bíi ti Rwanda, tí Buhari kò bá ṣàtúnṣe ètò ààbò Ọ̀rọ̀ ti ń gba ibòmíràn yọ lórí ẹ̀ṣùn ìfipábánilòpọ̀ - Timi Dakolo Pariwo Harry Kane fọ́ Ronaldo àti Juventus lẹ́nu pẹ̀lú góòlù àràmọ̀ndà Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Yinka Ayefele: Oṣù àwọn ìbẹ́ta mi kò pé ní kò jẹ́ kí n kọ́kọ́ kéde ìbí wọn Okasanmi ṣalaye pe kete ti iṣẹlẹ ọhun ṣẹlẹ ni ọga ọlọpaa ipinlẹ Kwara, Kayode Egbetokun paṣẹ fawọn ọlọpaa kogberegbe, Operation Puff Adder pe ki wọn bẹrẹ si wa awọn ọmọ ilu okere naa.
Àrùn Coronavirus ti mú ẹ̀mí ẹni àkọ́kọ́ lọ nílẹ̀ Madagascar Awọn ilana isede tuntun fun ipinlẹ Eko niyii 1.
Ọmọ ki dédé rù lai ni idi.
Bu ẹ̀yinná tí ó wà láàrin wọn kún ọwọ́ rẹ, kí o sì fọ́n ọn sórí ìlú yìí káàkiri.
Gbẹnga Ogunbọtẹ gba ẹyẹ akọnimọgba to fakọyọ ti awọn alatilẹyin Kano Pillars, Kano naa gba alatilẹyin to pegede.
Joabu ati Abiṣai arakunrin rẹ̀ bá ń lépa Ṣeba lọ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Grace Oshiagwu: Afurasí ní abọ́ oúnjẹ kan, ẹ̀ẹ́dẹ́gbẹ̀ta náíra lòun ń gbà lóri àwọn tó pa l'Akinyele 18 Agẹmo 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 20 Agẹmo 2020 Oríṣun àwòrán, oyo nsight.
gẹ́gẹ́ bí igbẹkẹle ati ìrètí mi pé n kò ní rí ohun ìtìjú kan.
Ni Ilú-Ọba, ẹ̀tọ́ ará ilú ni ki Ìjọba pèsè ohun amáyédẹrùn, pàtàki ibùgbé fún ọmọ ilú, ilé-ìwòsàn ọ̀fẹ́ fún ọmọ àti ará ilú.
"Opeyemi salaye pe: ""Wale Adenuga lo n ya ere kan lọwọ, emi kan ṣe gbeborun lọ woran nibẹ ni."
Àwọn aposteli nìkan ni kò kúrò ní ìlú.
Ọpọlọpọ ohun ẹlẹ́mìí yóo wà ní ibikíbi tí omi náà bá ti ṣàn kọjá.
”Akiṣi bá ní, òun óo fi Dafidi ṣe olùṣọ́ òun títí lae.
Ogbontarigi olootu sinima agbelewo nile Amerika, Harvey Weinstein, ti fi ara re sile fawon agbofinro New York lojo Eti lori esun ifipabanilopo ti awon osere-binrin fi kan an.
Ija MMA mọkandinlogun ni Adesanya ti kopa ninu rẹ ti o si jawe olubori ninu gbogbo wọn, nigba ti alako rẹ, Costa ko tii fidi rẹmi ninu ija MMA mẹtala to ti ja.
Ni bayii, ti a ba ka leni meji Lionel Messi ti gba apapo ẹgbẹ̀ta(600-goal mark) ami-ayo sagbon fun iko agbaboolu Barcelona.
Miliọnu mẹẹrin Naira ni wọn gba.
Igbese ise-akanse yii bere ni odun 2017, ni eyi ti a n se akitiyan lori re lati le je sise, ijoba ipinle Eko ni iko ogun ninu ida ogorun ninu ise-akanse etikun Lekki naa”.
Oríṣun àwòrán, @AISHABUHARI Aarẹ naa fikun ọrọ rẹ wi pe oun yoo pese ohun ọgbin fun awọn agbẹ aroko ni iye owo ti ko kan ni leegun ẹyin, ki o ba le mu iwuri ba awọn ọdọ lati mu iṣẹ agbẹ lokunkundun.
Ọjọ ori ọba Adeyemi ati olori akọkọ rẹ sunmọ ara wọn pupọ, osu lasan si ni wọn gba lọwọ ara wọn.
Ṣugbọn ninu ìjọ, ó yá mi lára kí n sọ ọ̀rọ̀ marun-un pẹlu òye kí n lè kọ́ àwọn ẹlòmíràn, jù kí n sọ ọ̀rọ̀ kí ilẹ̀ kún ní èdè àjèjì lọ.
Oríṣun àwòrán, Instagram/somolu ''Ko digba ti wọn ba to lo odidi eeyan ṣe irubọ, ki eeyan to le jọba, a o ni lati faye ni ẹnikeji lara,'' Oba ilẹ Uba lo sọ bẹẹ.
Oríṣun àwòrán, @Aminu Bello Masari Iye àwọn ti Shehu sọ yii kere si nkan ti awọn oṣiṣẹ ile ẹ̀kọ́ naa ti kọkọ sọ.
Wọn kò bá àṣìṣe kankan lọ́wọ́ rẹ̀.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Coronavirus in Nigeria: Àwọn ọmọ Nàìjíríà bu ẹnu àtẹ́ lu ètò ìsìnkú Abba Kyari, wọ́n ní ó tako ìlànà ìjìnàsíraẹni Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Coronavirus in Nigeria: Àwọn ọmọ Nàìjíríà bu ẹnu àtẹ́ lu ètò ìsìnkú Abba Kyari, wọ́n ní ó tako ìlànà ìjìnàsíraẹni 18 Ìgbé 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 19 Ìgbé 2020 Iku n pa ni, ilẹ n jẹ eeyan.
Oríṣun àwòrán, @iam_Davido Àkọlé àwòrán, Ọmọ Adeleke T red jẹ olorin takasufe Oríṣun àwòrán, @SINARAMBO Àkọlé àwòrán, Orin kikọ jẹ atewọgba laarin awọn ọmọ okunrin mọlẹbi Adeleke Ki a to gbagbe, onisowo ni Adeleke, ti o si ti fi igba kan jẹ oga ni ile ise Pacific Hoildings to jẹ́ ti ẹgbọn rẹ, laarin odun 2001 si 2016.
Nibayii, Magu n koju ijẹjọ niwaju igbimọ kan ti Amofin Ayo Salami to jẹ adajọ ileẹjọ nigba kan ri kotẹmilọrun n dari.
Awọn eeyan kan ti ẹ wa, to ma n gbe awọn ọmọde yii lọ si ile itura, lati ba wọn ni ibalopọ.
Jesu wá sọ fún wọn pé, “Ẹ má bẹ̀rù.
Amọṣa diẹ niyi lara awọn ọmọ Yoruba to n da bi ẹdun, rọ bi owe ni Olutoye Olayinka.
FA CUP FINAL 2020: Lacazette ṣàlàyé ìdí tí Arsenal ṣé gbọ́dọ̀ fìdí Chelsea rẹmi ní àṣekágbá
Wọn óo sọ wọ́n di ohun eléèérí.
Ẹgbẹ awọn ọkunrin to lahun koro oju si igbesẹ rẹ.
Ẹ wá wo orí ológbò látẹ o ẹ̀yin èèyàn mi!
Coronavirus in Osun: Ìlànà tuntun fún òkú sínsin wọlé dé sí ìpínlẹ̀ Ọ̀ṣun
láti ẹni ọgbọ̀n ọdún títí dé aadọta, àwọn tí wọ́n lè ṣiṣẹ́ ninu Àgọ́ Àjọ 
Mílíọ̀nù Márùn-ún ènìyàn n bẹ nínú ewu ìyàn
Codine: Ọ̀pọ̀ èèyàn tako iléesẹ́ mẹ́ta tíjọba tì pa
Ni bayii, Falconets yoo maa waako pelu USA, Mexico ati Zealand.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Idije Premier League Laipẹ lai jina, Salah tun gbayo sawọn eleyi to jẹ ki Liverpool siwaju pẹlu ami ayo mẹta sodo ti Arsenal ko si ri ọkankan da pada.
Nípa bẹ́ẹ̀ ni ìfẹ́ ṣe di pípé ninu wa, kí á lè ní ìgboyà ní ọjọ́ ìdájọ́ pé bí ó ti rí ni àwa náà rí ninu ayé yìí.
 fun ile-ise olopaa ni gbogbo ona, ni eyi
Ìròyìn tó tẹ̀wá lọ́wọ́ sọ pé àwọn ọmọ ẹgbẹ́ awakọ̀, NURTW, ní ìpínlẹ̀ Ekiti, n da ìgboro ru.
Ninu oro tire, asofin Aliyu Sabi Abdullahi pe fun idasile ohun elo iwosan ijoba kookan ni awon ekun mefeefa, ni iyanju ati wa ojutu si isoro awon ile-iwosan ijoba lorile-ede Naijiria, eyi le seese nipa akitian ile-igbimo asofin, latari ati se adinku orisirisi aisan ti o n seyo lorile-ede Naijiria.
Ẹ óo wá máa sọ pé, ‘A jẹ, a mu níwájú rẹ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Jude Chukwuka: Wò ó bí òwé Yorùbá ṣe yọ̀ lẹ́nu ọmọ Igbo Eeyan ti ori ko yọ naa ni wọn ṣalaye pe, o ṣi n gba itọju lọwọ nile iwosan awọn ọlọpaa to wa lagbegbe Ẹlẹyẹle ni ilu Ibadan.
Ọgbẹni Adamu lo paṣẹ fawọn ọlọpaa lati ko gbogbo irinṣẹ ti wọn nilo ati ikọ alaabo jọ lati lee dẹkun gbogbo rogbodiyan to n ṣẹlẹ jakejado orilẹede Naijiria.
Awọn ohun to yan laayo Eto ẹkọ ati ọrọ awọn oṣisẹ wa lara awọn ohun ti Gbajabiamila gbajumọ, to si ma n sọrọ nipa mimu idẹrun ba ara ilu.
Bẹ́ẹ̀ ni n óo ṣe ṣe ìdájọ́ Ijipti, wọn óo wá mọ̀ pé èmi ni OLUWA.
"Kò sí ọmọ ti kò yẹ láì lọ sí ilé ìwé"" Aládùgbò mí ni wọ́n Ilorin kò jìn à sí Ogbomosho, ọ̀rọ̀ ìwé mímọ́ náà sì sọ pé kí a fẹ́rà ọmọlàkejì wa gẹ́gẹ́ bi ara wa."
Buhari wa n bi awọn minisita naa pe to ba jẹ pe awọn ni Trump kọju ibeere naa si, ki ni wọn yoo se nitori ibeere naa ba oun labo.
Ṣugbọn ó kọ ìmọ̀ràn tí àwọn àgbààgbà fún un.
Ẹlòmíràn ń tọrọ ojú mìíràn nítorí ojú tí ó ńi kò tẹ́ ọ lọ́rùn, òmíràn ní ojú òun dàbí ojú ajá, òmíràn fi ojú ara rẹ̀ wé ojú mààlúù, bẹ́ẹ̀ ni wọ́n ń ṣe àròyé nípa ojú ara wọn.
Ìgbésẹ̀ àìwọ́pọ̀ yìí wáyé ní kété tí ìròyìn ìkọ̀lù òjijì sẹlẹ̀ sí ìjọ Kátólíkì ní ìpínlẹ̀ Benue èyí tó mú ẹ̀mí ènìyàn mẹ́rìndínlógún lọ tó fi mọ́ fadá méjì.
Lati ọwọ Louise ni London Iroyin BBC Ikọ eleto ilera Akọṣoilẹ China ati awọn orilẹ-ede mii fihan pe coronavirus ko fi bẹẹ ni ipa lori ọmọde Eyi ṣeeṣe ko jẹ pe awọn ami apẹẹrẹ coronavirus ko han lara wọn tabi nitori pe agọ ara wọn le gbọn ọn danu Awọn ọmọde ti wọn ba ni ailera ẹdọ-fooro tẹlẹ bii ikọ séèmí-séèmí nilo lati tubọ ṣọ ara wọn End of Emi ati ẹbi mi Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
 Oríṣun àwòrán, @adedimejilateef Lateeef tun kan sara si baba rẹ loju opo Instagram ọhun kan naa, nigba to ni Baba mi, baba ti ko gba gbẹrẹ, mo ni ifẹ rẹ gan ni baba mi.
Dafidi bá sọ fún Solomoni, ọmọ rẹ̀ pé, “Múra gírí, mú ọkàn le, kí o sì ṣe bí mo ti wí.
Bẹẹ, iyọ rẹ ko tẹ lawujọ awọn erupẹ nigba aye rẹ, idi si ree ti a se gbe itan aye rẹ wa fun un yin gẹgẹ bi a se ka a lori itakun agbaye Wikipedia ati awọn oju opo ayelujara miran.
Paulu gbé ààrin wọn fún ọdún kan ati oṣù mẹfa, ó ń kọ́ wọn ní ọ̀rọ̀ Ọlọrun.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Idije Premier League Tamọtiye!
O tún tesiwaju sì ilé ìgbìmò asofin àgbà lé èkejì ni odun 2007.
Tomale Akinbanji, to jẹ ọrẹ Ojo sọrọ ilẹ kun fun BBC lori iṣẹlẹ arinfẹsẹsi yii.
Afínjú ońmùlẹ̀ tí ń so kùtúkùtú mọ́wọ́
2 mílíọ́nù owó ìtanràn Ìjọba Nàìjíríà ti gbà láti san N30b owó àjẹmọ́nú fún ASUU Mercy Aigbe Aworan ibi to ti gbe ibọn dani to si duro niwaju ọkọ awọn ọlọpaa ni gbajugbaja oṣere Mercy Aigbe fi si oju opo Instagram tiẹ.
Lọjọ kọkanlelogun, oṣu Kẹta, ipinlẹ Kebbi kede pe ki gbogbo ileewe o wa ni titi pa.
Ileesẹ naa sọ pe iwadii to mundadoko lawọn se ki awọn to gbe iroyin naa jade nitori gbọin gbọin lawọn duro lori iroyin tawọn gbe jade ṣaaju lori iṣẹlẹ naa.
Ajo to n koju arun Coronavirus ni Naijiria, NCDC to fi lede ni Ọjọ Aje ni iye awọn to ti ni arun naa ti le ni ẹgbẹẹta(6175).
“Ọmọ àlè ní í rínú tí kì í bí, ọmọ àlè la ń bẹ̀ tí kì í gbọ́” báyìí ló gba ìpẹ́ (ẹ̀bẹ̀) bàbá rẹ̀.
Gbogbo nkan ti mo ni, ni ma a fi dena rẹ pe ko ta ẹyọkan ṣoṣo to ku.
Eredi ni bi Lizzy ṣe sọ oko ọrọ miiran si Toyin Abraham ninu fidio kan to fi soju opo Instagram rẹ.
Eṣeki, arakunrin Aseli, bí ọmọ mẹta: Ulamu ni àkọ́bí rẹ̀, lẹ́yìn náà Jeuṣi, lẹ́yìn náà Elifeleti.
Champions League: Àwọn ohun tóyẹ kí ẹ mọ̀ nípa ti sáà yíí
Coza Rape: Ọlọ́pàá ránṣẹ́ pe Timi Dakolo àti ìyàwó rẹ̀ lórí ẹ̀ṣùn ìfipábánilòpọ̀
''Omi tuntun, igba ọtun, ipinlẹ Oyo, iṣẹ ya.
” Nítorí náà ni wọ́n ṣe sọ ìlú náà ní Soari.
Ẹni to bori: Senegal Nigeria vs Cameroon.
Àwọn ìròyìn tí ẹ lè nífẹ̀ẹ́ sí: Àwà gómìnà PDP ṣetán láti san #30,000 owó oṣù fáwọn òṣìṣẹ́- Dickson Àìle è ka kéú ló sọ mí di Krìstíẹ̀nì - Adewale Ayuba Èèmọ̀ wọ̀lú!
Aare  Muhammadu Buhari  ti ro gbogbo awon musulumi lati maa hu iwa
Chantel ti kọkọ bi ibeji fun ọkunrin kan.
OLUWA ní, “N óo sọ wọ́n di ìjẹ fún àwọn àjèjì, n óo sì fi wọ́n ṣe ìkógun fún àwọn eniyan burúkú ilé ayé.
Mo gbéra lóru, mo gba Ẹnubodè Àfonífojì.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Aisha Buhari: Àwọn alágbára ti já ìjọba gbà mọ́ ọkọ mi lọ́wọ́ 10 Ọ̀pẹ̀̀ 2018 Oríṣun àwòrán, @aishambuhari Àkọlé àwòrán, Aisha Buhari ní ìfẹ́ ìdájọ́ òdodo ti òun ní ló fàá tí òun fi n sọ̀rọ̀ tako ọkọ òun Aya Aarẹ orilẹede Naijiria, Aisha Buhari, ti gbaju-gbaja ni ọpọ igba, paapa fun sisọ ọrọ to tako ọkọ rẹ, Muhammadu Buhari, iṣakoso rẹ, ati ẹgbẹ oṣelu to gbe e wọle, All Progressives Congress, APC.
Nítorí mo wòye pé ẹ̀tanú ti gbà ọ́ lọ́kàn, àtipé aiṣododo ti dè ọ́ lẹ́wọ̀n.
Emeka Abugu ni oun di afoju lọmọde tori aisan igbona.
Lojoru(Wednesday), ojo kokanlelogun, osu kejo odun ti a wayii.
OLUWA ni orúkọ rẹ̀;ẹ máa yọ̀ níwájú rẹ̀.
Heavy rains in #Mozambique northern province of #CaboDelgado are raising floodwater levels and rendering communities affected by #CycloneKenneth harder to reach.
Òfin tuntun yìí yóò bẹ̀rẹ̀ sí ní múlẹ̀ láti inú oṣù kẹ́fa gẹ́gẹ́ bi àlága ẹgbẹ́ àwọn óní fíìmù ní ìpínlẹ̀ Kano ti a mọ si Motion Pictures Practitioners Association of Nigeria (MOPPAN) ọgbẹni Kabiru Maikaba tó bá BBC sọ̀rọ̀ ṣe sọ.
Gege bi ile-ise akoroyin ori ero amohun-maworan lati ile igbimo asofin ohun, won fi mule pe, eto n lo lowo lai si wahala Kankan bi o ti le wu ko mo.
Nítorí ní ọpọlọpọ ìgbà ní í máa ń dé sí i.
Egbeyemi lasiko to n ba BBC sọrọ ni pe iwadii awọn fihan wi pe irọ patapata ni iroyin to sọ pe awọn agbesunmọmi ti wọ ipinlẹ Eko.
Ọwọ́ ọ̀tún rẹ̀ fi agbára rẹ̀ hàn,ó tú àwọn tí ó gbéraga ninu ọkàn wọn ká.
Ní ti bíbu ọlá fún ara yín, ẹ máa fi ti ẹnìkejì yín ṣiwaju.
Ile-ise iko omo-ogun Naijiria ti setan lati bere idanileko ose kan fun ikunwo iko omo ogun ti won pe ni: Combat Support Arms Training, COSAT  eyi ti yoo waye lojo ketala Aje(Monday) si ojo ketadinlogun Eti(Friday) osu ti a wayii, niluu Maiduguri, nipinle Borno.
Wọn óo dàbí koríko tí ó hù lórí òrùlé,tí kì í dàgbà kí ó tó gbẹ.
sekọlu si awon ijoba ibile ti won n lo lati ka ibo .
Dafidi dáhùn pé, “Kí ni mo ṣe?
Nigba to n tesiwaju ninu oro re,lati je ki Orile ede Naijiria se ojuse re.
Ni ibamu si adehun ti o wa larin wọn ati ẹgbẹ agbabọọlu Leicester City.
Aare soro yii lojoBo lasiko ti minisita to
"Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: ""Ọkọ kọ̀ mí, mo fẹ́ jẹ májèlé torí mo bímọ tó ní ojú ara takọtabo"" Omotola Jalade ní Nàìjíríà dàbí ọ̀run àpáàdì lábẹ́ ìjọba Buhari Duro Ladipọ, ìlúmọ̀ọ́ká òṣèré tíátà àti ọmọ àlúfà tí kò gbàgbé àṣà ìbílẹ̀ Oṣojumi-koro kan fi to awọn BBC Yoruba leti wi pe jala epo bii ẹgbẹrun marundinlaadọta ni ọkọ epo naa gbe, ki o to dede ṣubu laarin ọna."
Ọbadaya bá lọ sọ fún ọba, ọba sì lọ pàdé Elija.
Maria bá bi angẹli náà pé, “Báwo ni yóo ti ṣe lè rí bẹ́ẹ̀, nígbà tí n kò tíì mọ ọkunrin?
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Kenyan Dance Party: Òde ijó yìí kò sí fáwọn abo tó ń fẹ́ ara wọn pẹ̀lú 13 Ògún 2019 Oríṣun àwòrán, The nest collective Ti a ba n se ayẹyẹ, tọkunrin tobinrin lo maa n peju pesẹ lati fi ara kinra, eyi ti yoo mu ki ayẹyẹ naa dun, ko si larinrin.
Nígbà tí ó ṣe, ó rántí àpò rẹ̀ tí ó bọ́, o fi àwa méjéèjì sílẹ̀ ó wá àpò rẹ̀ lọ.
Joṣua bá lọ láti Giligali, òun ati àwọn ọmọ ogun rẹ̀, pẹlu gbogbo àwọn tí wọ́n jẹ́ akikanju ati akọni.
Ó yẹ kí ẹ dàbí ọmọde tí kò mọ ibi, ṣugbọn kí ẹ jẹ́ àgbàlagbà ninu èrò yín.
com/w7A9ZY1TeCGege bi iroyin ti o jade lori
    Nigbà tí ó di ọjọ́ kan, erin wá gẹ́gẹ́ bí ọkùnrin ẹkùn sì wá gẹ́gẹ́ bí obìnrin, wọ́n rí ara wọn, wọ́n fẹ́ ara wọn.
Akure-Owo Accident: Ẹ̀mí 18 ṣòfò ní òpópónà ti ọ̀pọ̀ ti ń kú ní ìpínlẹ̀ Ondo
Ti wọn si fi ẹsun kan Trump pe, o ṣi ipo rẹ lo.
” Nítorí kò sí ẹni tí ó lè fi nǹkan burúkú dán Ọlọrun wò.
Ǹjẹ́ o mọ ìdí tí mílíọ̀nù 16 ọmọdé kò fi rí iléèwé lọ ní Nàìjíríà?
Lati igbà ti ìròyìn ìdájọ́ yi ti jade, ọ̀pọ̀lọpọ̀ ni àgbáyé, pàtàki àwọn Ẹlẹ́sin Igbàgbọ́ ti nda ẹ̀bi fún Ìjọba Àmẹ́ríkà pé wọn rú òfin Ọlọrun nipa Igbéyàwó.
“Ẹ jẹ́ kí àwọn ọ̀rọ̀ wọnyi wọ̀ yín létí.
Alẹ́ ọjọ́ Aiku ní a o mọ ẹni ti yóò fi ilé ẹlẹ́gbọ́n ọn àgbà sílẹ̀ Oríṣun àwòrán, Bigbrother Kiddwaya, Lilo, Wathoni, Eric, Tolanibaj ṣe bẹbẹ lásìkò àríyá Sátide àkọ́kọ́ ní Big Brother Naija 2020 Kiddwaya, Lilo, Wathoni, Eric, Tolanibaj jètè àrà awọn lásìkò àríyá àkọ́kọ́ Àwọn akópa nínú Ilé Ẹlẹ́gbọ́n Agbà ti ọdún 2020 ti ṣe ìfẹnukónu fún ìgbà àkọ́kọ́ lásìkò àríyá ti o má n wáye ni alẹ́ ọjọ sátide.
6, 787); Indonesia (13, 020); America (10, 452); Democratic Republic of Congo DRC (10, 247); ati Ethiopia (8, 493).
Àṣà ọ̀hún ni bí wọ́n ṣe máa ń dárà sí oúnjẹ àti oúnmu wọn.
Lóòtọ́ ni mo yìnbọn níbi yánpọnyánrin tó wáyé ládúgbò mi-Seun Kuti Àwọn tó jí àwọn akẹ́kọ̀ọ́ GSSS gbé ní Kankara ti kàn sí wa - Masari Ìjọba Amẹrika yọ orúkọ Sudan kúrò nínú ìwé orílẹ̀-èdè tó ń ṣagbátẹrù ẹgbẹ́ agbésùnmọ̀mí Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Africa Eye: Wo ìtàn ìyá kan ìyá kan àtàwọn olè ajọ́mọgbé tó n ta ọmọ ní Kenya Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Oríṣun àwòrán, Twitter/@AyindeBarrister Àkọlé àwòrán, Ọrẹ ni Ayinde Barrister ati Ayinla Kollington nigba aye rẹ.
"Ó ní "" ìjọba yóo pèsè bílíọ̀nù mẹ́tàdílógójì ó lé díẹ̀ fún ètò ìlú àti ààbò nínú ètò ìṣúná ọdún 2021"" kọmíssọnà ọlapàá lásìkò ìpàdé náà sàlàyé pé àjọ ọlọpàaá kò jẹ́ ki ìwà ọ̀daran tó dín díẹ̀ ni ọ̀ọ̀dúnrún wáyé, nígbà ti wọ́n mú ọ̀daran tó le ni ẹgbẹ̀rún kan tí wọ́n sì pa mẹ́tàdílọ́gbọ̀n láàrín oṣù kẹwàá ọdún 2019 sí oṣù kẹsàán ọdún 2020."
Sunday Igboho: Sé èmi nìkan ló wà ní Nàíjíríà ni, ó lé ní 1m ọlọ́pàá tó yí ilé mi po
Oríṣun àwòrán, @OfficialSeyiMakinde Bakan naa lo ni o yẹ ko ye wọn pe ijọba yoo beere nipa bi wọn se naa owo naa, ti yoo si fiya to jogbin jẹ ẹnikẹni to ba gbidanwo lati ya kuro loju opo ilana ipese ojulowo ẹkọ ọfẹ tabi to n dọgbọn gba owo kotọ lọwọ awọn akẹkọ.
Fun Ọjọgbọn Ọlaniyi Balogun, irinajo yii yatọ.
Ṣugbọn tí ẹ bá kọ̀, tí ẹ sì ṣoríkunkun;idà ni yóo run yín.
Ọmọ mi, bí o bá kọ etí dídi sí ẹ̀kọ́,o óo ṣìnà kúrò ninu ìmọ̀.
Lara awon ti o tele ojogbon Osinbajo, ni oludije fun ipo gomina ni
Aare wa lo anfaani ohun lati fi yanana awon aseyori ti isakoso ijoba re ti se lati ibere saa re di akoko yii, O seleri pe bi won ba tun oun yan sipo pada oun yoo se ju bi awon eniyan se lero lo.
Ìlú náà fẹ̀, ó sì tóbi, ṣugbọn àwọn tí wọn ń gbé inú rẹ̀ kéré níye, kò sì tíì sí ilé níbẹ̀.
Omotola ni oun ko ṣai gbọ iroyin bi ọkọ tirela ati apoti ikẹru ti wọn n pe ni ''container'', ti n ṣeku pa awọn ọdọ niluu Eko.
Ìsọdọ ̀ tun nollywood tàbí nollywood reinvented , tí a tún mọ ̀ sí nr , jẹ ́ pèpéle ẹ ̀ rọ ayélujára t ́ i wọ ́ n dá sílè ní ọdún 2011 , pèpéle yí wà fụ ́ n ìṣàgbéyẹ ̀ wò àwọn fiímù àti sinimá ọlọ ́ kan ò jọ ̀ kan.
O ni kii se gbogbo igba ni oun maa nra eroja, nitoripe oun mọ pe o lewu fun agọ ara.
”Ṣugbọn wọ́n túbọ̀ kígbe pé, “Kàn án mọ́ agbelebu.
Ẹ̀yin ọmọde, ti Ọlọrun nìyí, ẹ ti ṣẹgun ẹ̀mí alátakò Kristi nítorí pé ẹni tí ó wà ninu yín tóbi ju ẹni tí ó wà ninu ayé lọ.
Fun ẹkunrẹrẹ alaye lori bi o ṣe le kopa, to fi mọ ofin ati ilana, lọ si oju opo BBC Pidgin everi year essay Competition Terms and Conditions Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Àwọn òṣìṣẹ́ BBC News Yorùbá sọ̀rọ̀ ìdùnnú lórí ayẹyẹ ọdún kan iléeṣẹ́ náà Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Nitori naa e je ki a satileyin fun aare, ki a si dekun igbe pe won ti ya Igbo soto nibi ijoba”.
Bẹ́ẹ̀ ni o gbọdọ̀ ṣe ọgbà àjàrà rẹ, ati ọgbà olifi rẹ pẹlu.
Máa gbe ilẹ̀ náà; ewu kò sì ní wu ọ́.
Abrahamu ati Sara ti di àgbàlagbà ní àkókò yìí, ogbó ti dé sí wọn, ọjọ́ ti pẹ́ tí Sara ti rí nǹkan oṣù rẹ̀ kẹ́yìn.
Dipo eyi, o pinu lati sapa fawọn eeyan orileede Ukraine.
O ṣalaye wi pe iwadii si n lọ lọwọ lati mu awọn afurasi to ku ti wọn ṣiṣẹ laabi ọhun.
Joshua, ti awọn oniṣegun gba nimọran pe ko sinmi nile di Ọjọru, ti fagile isinmi ọlọjọ mẹwaa to fẹ ṣe tẹlẹ l'Amẹrika, ko le tete pada silu London.
Ìdí ẹ̀ rèé tó fi jẹ́ pé àwọn mùsùlùmí a máa pa ẹran àgbò ní àjọ̀dún yìí tí orúkọ rẹ̀ ń ṣe Eid al-Adha ní èdè Lárúbáwá.
E be awon eniyan yin , ki won ni suuru fun mi.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìjọba Máli: Ìbọn àti àdá ni wọn fi pa àwọn Fulani náà ni lagbegbe Mopti.
Oníṣòwò tí ó dáńgájá ni Olόwό-Ìbínú, ohun tí ó sì ń fi inú–un rẹ̀ rò ní ọ̀sán àti òru kò ju owό lọ.
Ọlọrun ko ni pa yin fun wa Àkọlé àwòrán, Se ibeji ọmọ-ọba lawọn ibeji yii ni?
Ẹ̀yin olùfẹ́, mo ti gbìyànjú títí láti kọ ìwé si yín nípa ìgbàlà tí a jọ ní, nígbà tí mo rí i pé ó di dandan pé kí n kọ ìwé si yín, kí n rọ̀ yín pé kí ẹ máa jà fún igbagbọ tí Ọlọrun fi fún àwọn eniyan rẹ̀ mímọ́ lẹ́ẹ̀kan gbọ̀n-ọ́n.
Àwọn ọba Yorùbá kan rèé tí wọ́n rọ̀ lóyè, tí ọba míràn jẹ lójú ayé wọn Ìtàn Gbọnka àti Timi, akọni méjì tó borí Aláàfin Ṣango Sugbọn nilu Efon Alaaye, eyi ko ri bẹẹ o, gẹgẹ bi a se ri ka loju opo itakun agbaye nigba ti Ọba alaye ibẹ ja awọn eeyan rẹ kulẹ, to si ja igbẹkẹle ti wọn ni ninu rẹ si asan.
Lori eto aabo, oga agba ile-ise olopaa, Ibrahim Idris so pe, ẹ̀gbẹ̀rún lona ọgbọ̀n olopaa ati apapo awon osise alaabo ẹ̀gbẹ̀rún lona merin ni ohun yoo ko lo sipinle naa lati mojuto eto aabo lakoko idibo ohun.
Ó ní, “Ṣugbọn ìwọ Daniẹli, pa ìwé náà dé, kí o sì fi èdìdì dì í títí di àkókò ìkẹyìn.
Àwọn ìlú ààbò tí wọ́n fún wọn, pẹlu àwọn pápá oko tí ó yí wọn ká, ní agbègbè olókè Efuraimu nìwọ̀nyí; Ṣekemu, ati Geseri; 
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù West Brom: Awọn agbabọọlu sa fun igbẹjọ ẹsun ole 19 Èrèlè 2018 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Gareth Barry, Jonny Evans, Jake Livermore ati Boaz Myhill ti kopa ninu ifẹsẹwọnsẹ ere bọlu n'igba 1,236 Awọn ọmọ ẹgbẹ agbabọọlu West Brom mẹrẹẹrin ti wọn fi ẹsun kan wipe wọn ji ọkọ takisi kan gbe n'ilu Barcelona, ti ngbaradi lati sa nile ẹjọ nitori pe ko si ẹri ni wọn se bẹẹ.
Katsina Child sale: Obìnrin olówònààbì ta ọmọ rẹ̀ tuntun jòjòlò ní N300,000
Yóo ti pẹ́ tó, tí gbogbo yín yóo dojú kọ ẹnìkan ṣoṣo, láti pa,ẹni tí kò lágbára ju ògiri tí ó ti fẹ́ wó lọ, tabi ọgbà tí ó fẹ́ ya?
4 539107 Orilẹede Iran 12526 32.
Oyo: Ọkùnrin mẹ́tàlá, obìnrin kan ni Makinde fi orúkọ wọn sílẹ̀
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Sowore: Èmi ṣì ni alága ẹgbẹ́, kò sẹ́ni tó yọ mí lóyè 13 Èbibi 2019 Oríṣun àwòrán, omoyele Àkọlé àwòrán, Aworan Sowore Ẹgbẹ oṣelu AAC ti le akọwe apapọ ẹgbẹ oṣelu naa, Leonard Ezenwa kuro lẹyin ti wọn ni o ṣiwaju igbesẹ yiyọ alaga apapọ ẹgbẹ oṣelu naa, Ọmọyẹle Ṣoworẹ ninu ẹgbẹ naa.
Yatọ si awọn eeyan to ku, ọpọlọpọ awọn oṣiṣẹ miran ni wọn tun ti di alabọ ara tabi fi ara ṣeṣe lasiko kikọ afara naa.
Pa gbogbo nǹkan wọnyi pọ̀, kí o fi ṣe òróró mímọ́ fún ìyàsímímọ́.
" Ibo ni ileeṣẹ ọlọpa ba iṣẹ de?
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Mama Arsenal: Màmá àgbà yìí máa ń lọ sí ìbùdó tí wọ́n ti ń wo bọ́ọ́lù láti wòran Lọwọ lọwọ ta n sọrọ yii, awọn dokita ti daṣẹ silẹ lawọn ile iwosan ijọba nitori pe, aini asọ aabo to peye (PPE) lati fi koju arun Covid -19.
Wọn tun fi ẹsun kiko owo ilu lọ si ilẹ okeere kan naa kan Kalu.
Ọmọ Yorùbá tó bá ti rú òfin, ẹ gbé e jàntò - Oluwo Ooni Ife fohùn ránṣẹ́ sí Boris Johnson, ó ní, bóo bá joun gbé, má johùn gbé"" Israel Adebajo: Ìlúmọ̀ọ́ká oníṣòwò tó fi òkò Stationery Stores pa ẹyẹ púpọ̀ Ìjọba ti bẹ̀rẹ̀ sí báwọn tó gbé òṣìṣẹ́ aláàánú mẹ́fà sọ̀rọ̀- Garba Shehu Oluwo ti ilu Iwo ni ija ati asọ kọ ni ọna abayọ si eto aabo to mẹhẹ, amọ ki ijọba fi agbara fun ẹkọ ati iwe kika, eleyii ti o le mu ki awọn eniyan ni ọgbọn ati imọ wi pe ogun kọni ọna abayọ si ipenija to n koju araalu ni Naijiria."
Igbimo alabe-sekele egbe oselu APC, eyi ti alaga igbimo naa, oloye John Odigie Oyegun dari  re n se ipade pelu awon omo egbe oselu to wa lori alefa naa nile-igbimo asofin orile-ede Naijiria.
Oloye Abdul Tawab Olaitan Ile-Aje Adeniyi pe ara rẹ ni araye-rọrun nitori iji gbe e lọ fun ọjọ mẹrinla lasiko ti wọn n ṣe fiimu ''Arelu'', ti o ni oun si le sọ nipa igbeaye eniyan nipa wiwo ọwọ rẹ.
Ogunbanjo ni aisi ato ilu nko ba oro omiyale.
Awọn oṣiṣẹ eto ilera naa fẹsun kan ijọba ipinlẹ naa pe wọn ko kọbi ara si ẹdun ọkan wọn.
Ṣugbọn a rí Jesu, tí Ọlọrun fi sí ipò tí ó rẹlẹ̀ díẹ̀ ju ti àwọn angẹli fún àkókò díẹ̀.
Ewe, orisirisi atunse lo ba eto isuna naa, leyin ti ile igbimo ohun yo kuro ninu isuna ile-ise otelemuye DSS, ile-ise olopaa ati abbl.
Wá gbàkàrà, gba dùǹdù ni Tottenham fi gba ọ̀mì lọ́wọ́ Manchester city Lati ibẹrẹ idije naa ni Arsenal ko ti ba Chelsea rẹrin rara ti wọn si n dẹgun soju ile Chelsea titi ti wọn fi jẹ goolu akọkọ lati ọwọ Lacazette ni iṣju marundinlogoji ifẹsẹwọns naa.
" Awọn ti ọwọ wa tẹ ni alamojuto ibudo naa, Ivan Ddungu, Omay Lay, ati alamojuto eto naa to pe Omay Lay sibi ariya naa, Prim Kasana.
Èyí yóo jẹ́ àmì fún ilé Israẹli.
O soro lati se atunlo nylon tabi rọba kuro ni ohun elo kan si omiran A ti ra nylon ati rọba jẹ owongogo, bẹ ẹ naa ni ati ko wọn kuro nilẹ lẹyin ti awọn eniyan ba lo wọn.
Wọn kede pe Biafra ni awọn yoo maa pe orilẹ-ede tuntun naa; orilẹ-ede olominira, ni ọgbọnjọ, oṣu Karun un, ọdun 1967.
Ẹ̀gún kún bo ọ̀nà ọ̀lẹ,ṣugbọn ọ̀nà olódodo dàbí òpópó tí ń dán.
West Brom: Awọn agbabọọlu sa fun igbẹjọ ẹsun ole
Ìwọ tí ò ń waasu pé kí eniyan má jalè, ṣé ìwọ náà kì í jalè?
Isẹlẹ naa kii se ohun ti a lee pe ni ipenija abo lawọn ileewe wa."
Orúkọ ọmọ Aṣeri obinrin sì ni Sera.
Ọgbà tí a tì ni iyawo mi;àní orísun omi tí a tì ni ọ́.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ṣọla Allyson: Obìnrin tí kò bá rẹwà ni yóò máa ṣí ara sílẹ̀ Okunronmu sọ pe, Atiku lo to gbangba sun lọyẹ lati gba awọn ọmọ orilẹede Naijiria lọwọ iṣẹ ti o n ba wọn finra, ati pe Atiku lo le ṣe eto aabo to peye lorilẹede Naijiria.
Ìṣe èèyàn ni ìṣe ẹranko, ẹ wo àwọn ìnàkí tí wọn fẹ́ràn fọ́tò yíyà bíi èèyàn Irọ́ ni ò, òjò kìí fa àìsàn ibà - Dokita Ìlù n pe ìlù rán níṣẹ́ níbi àjọ̀dún ìlù l'Abẹokuta Eniyan to le ni ẹgbẹrun kan ni wọn sọ pe o n bẹ ibudo naa wo lojumọ.
Mo bá bi í pé: “OLUWA mi, títí di ìgbà wo?
Nigba ti awọn awakọ yoo maa gba ọna to wa lati Lagos Island si Oworonsoki ni abala to lọ si Lagos Island lati aago kan ọsan si mejila oru.
Bí ilẹ̀ bá ṣú, apànìyàn á dìde,kí ó lè pa talaka ati aláìní,a sì dàbí olè ní òru.
com/dtmcsVFqQhWalk it like I talk it 🎶 #WilderBreazeale pic.
igba ọtun, mo ni ireti pe ọjọ iwaju orile ede yoo dara.
SIM jẹ́ lẹ́tà kíní tó bẹ̀rẹ̀ ọ̀rọ̀ mẹ́tẹ̀ta àkọ́kọ́.
Ọmọ ilu Idoani ni Dokita Olayinka Olutoye.
Nigba to ṣi wa labẹ obi, ko le fi gbogbo ara tẹle ifẹ rẹ lati maa tẹle awọn elere ni gbogbo igba tori iwe ni awọn rẹ fẹ ko ka.
26 Owewe 2020 Fídíò, Akomolede: Bolaji Faleke ni Olùkọ́ tó ń kọ́ wa ní àṣà oge ṣiṣe lórí BBC Yorùbá1 Owewe 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Osinbajo: Ikẹnnẹ yẹ kó jẹ́ Mẹ́kà òṣèlú ni Kíni ìdí tí NLC fi kọ N27,000 owó osù òsìsẹ́?
Amòfin kan wá, ó fi ìbéèrè yìí wá Jesu lẹ́nu wò.
siwaju Ile Igbimọ Aṣofin Ipinlẹ Eko lọjọ Iṣẹgun.
Ó wà lára àwọn tí ó ń pa majẹmu rẹ̀ mọ́,tí wọn sì ń ranti láti pa òfin rẹ̀ mọ́.
Nibayii, Aarẹ Muhammadu Buhari ti ranṣẹ ibanikẹdun si awọn ọmọlẹyin Kristi lori iku iranṣẹ Ọlọrun naa.
Igbagbọ rẹ̀ ni ẹ̀rí pé a dá a láre, nígbà tí Ọlọrun gba ọrẹ rẹ̀.
Awọn dokita labẹ asia ẹgbẹ awọn dokita onisẹgun nipinlẹ Eko, Medical Guild Association sọ pe ijọba n jẹ awọn ni owo oṣu meji.
Àwọn gómìnà ilẹ̀ Yorùbá parapọ̀ láti gbógun ti ààbò tó mẹ́hẹ!
"Ó ní "" bi òun kò bá mu oògùn lọ̀jọ kan, oúnjẹ kò kí ń hu ú jẹ kò ní fi se ẹni tó fi oúnjẹ náà ọ̀ ọ́."
pin oṣiṣẹ kaakiri, lati le wọn kuro lẹnu iṣẹ bo ba yẹ ati lati ko awọn
"Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: ""Àhámọ́ ajínigbé ni ń bá wà lónìí, ọ̀pẹ́ awakọ̀ mi"" Ẹ wo nkan tí Deeper Life High School tún sọ lórí Don Davis, akọ́kọ̀ọ́ JS1 tí wọ́n fi ipá bálòpọ̀ Àjọ NIMC ti gbé ìlànà tuntun jáde fún gbígba NIN lọ́nà ìrọ̀rùn Wo ọ̀pọ̀ mílíọ̀nù fóónù tí Whatsapp kò ní bá ṣiṣẹ́ mọ́ lọ́dún 2021 Ibodè àgbáyé ní Saki, ìbẹ̀ ni agbébọn ń gbà wọ ilẹ̀ Káàrọ̀ Oòjíire - Makinde gbarata Ohun taa gbọ ni pe, wọn yìnbon pa Abeeb bí ọwọ agọ meje kú iṣẹju mẹẹdogun aṣalẹ ọjọ Aje nigba ti ìjà yi bẹ sílẹ."
Orile-ede China ti yan Guus Hiddink gege bi akonimoogba agba iko agbaboolu orile-ede ohun tawon odo tojo ori won koju mokanlelogun lo.
Ameenah Gurib-Fakim je Aare obinrin akoko  ti won bura fun lorile-ede Mautinius ni odun 2015.
O le jẹ okete, akika, awọn nnkan inu ẹran bi ifun, ati ẹdọ, o si le jẹ ẹyin adiyẹ.
Agbẹ̀nusọ fún Ajọ ọlọpàá ní ìpínlẹ̀ Osun (SP) Folashade Odoro, náà fìdí ọ̀rọ̀ náà múlẹ̀ àtí pé iṣẹ́ sì ń lọ lọ́wọ́ láti mú àwọn afunrasí adigùnjalè náà.
Ó fi jẹ aláṣẹ ilé rẹ̀,ati alákòóso gbogbo nǹkan ìní rẹ̀; 
Aarẹ lo si maa n yan ẹni ti yoo ba jẹ olori oṣiṣẹ fun, eyi ti ko nilo ontẹ ilẹ aṣofin.
Lẹ́yìn náà, Abrahamu lọ sin òkú Sara sinu ihò ilẹ̀ Makipela, tí ó wà ní ìhà ìlà oòrùn Mamure, ní agbègbè Heburoni ní ilẹ̀ Kenaani.
Ṣe o mọ nọmba jẹẹsí agbabọọlu ti o fẹ́ràn julọ?
Àwọn ọmọ Israẹli ní, “Ojú ọ̀nà ni a óo máa tọ̀, bí àwa tabi ẹran wa bá tilẹ̀ mu omi yín, a óo sanwó rẹ̀.
Àwọn agbénipa tún ti pa ọmọ ọdún márùn ún kan ní Ibadan Ohun tí a mọ̀ nìyí nípa àwọn tí yóò láǹfàní àti lọ sí Hajj lọ́dún yìí Ize-Iyamu borí ìbò abẹ́nú fún idíje gómìnà l'Edo Ìjọba Nàìjíríà ránṣẹ́ pe aṣojú Ghana lórí ilé Nàìjíríà tí wọ́n wó lulẹ̀ ní Ghana Ohun tí a rí nílé Ajimobi rèé lẹ́yìn ìròyìn òfégè pé ó jáde láyé Àwọn ohun tuntun tí a mọ̀ nípa ìgbẹ́jọ́ Wòlíì Sotitobire Bakan naa ni ẹlomiiran, Allen Sowore fi si oju opo Facebook rẹ pe Ọgbẹni Ajayi ti yan oun gẹgẹ bi oludamọran paraki lori ọrọ iroyin.
Titi di asiko yii ko tii si ẹ\\ro ibanisọrọ to ṣiṣẹ ni agbegbe naa lati fi ba awọn eeyan naa sọrọ ni kikun nitori pe lati ọdun mẹwaa sẹyin ni ogun yii ti n ba wọn finra.
Ẹgbẹ́ agbábọ́ọ̀lù Manchester City àti Liverpool ṣíde sáà bọ́ọ̀lù tuntun Saa bọọlu tuntun bẹrẹ lọjọ Aiku, ọjọ kẹrin, oṣu kẹjọ, Manchester City ti wọn gba ife ẹyẹ Premier League ni saa to lọ yoo ṣide saa tuntun pẹlu Liverpool tawọn gba ife ẹyẹ UEFA Champions League.
Ṣugbọn Paulu kò rò pé ó yẹ láti mú un lọ, nítorí ó pada lẹ́yìn wọn ní Pamfilia, kò bá wọn lọ títí dé òpin iṣẹ́ náà.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Libya: Aadọrun atipo ri somi 2 Èrèlè 2018 Oríṣun àwòrán, AFP Àkọlé àwòrán, Ogunlogo awọn eniyan lo n gba ori okun Libya k'oja si ile Yuroopu Awọn atipo to n lọ bi aadọrun ni wọn ti ri s'omi lẹyin ti ọkọ oju omi ti o n gbe wọn kuro ni bebe orilẹede Libya.
Wọn yí láwọn ìbéèrè ti ọ gba ẹnu ará àdúgbò ati awọn ọlọpa ni ìlú California lorílè-èdè Amerika níbi tí ọmọ ọkùnrin ọdún mẹrin kan ti yin ìbon pá ìbátan rẹ tó jẹ ọmọ ọdún méjì.
won ri, ni eyi ti o ti mu idagbasoke ba awon omo orile ede Naijiria.
Baba Ẹlẹbuibọn ni Ọba to ba rọ mọ Bibeli tabi Kurani lori oye gbọdọ ranti pe ilẹ Yoruba ni oun ti jẹ ọba kii ṣe ilẹ Larubawa tabi Isrẹli.
Gbajugbaja ni Aremu Afolayan laarin awọn oṣere Yoruba toun gan si tun jẹ ọmọ agba oṣere kan funrarẹ, Adeyemi Afolayan bẹẹ o fẹrẹ jẹ gbogbo ọbakan rẹ ni oṣere.
Adajọ Gideon Kurada pasẹ naa lasiko ti wọn gbo ẹsun onigun mẹjọ ti ijọba ipinlẹ Kaduna fi kan awọn mejeeji pe wọn n daabo bo awọn ọdaran ati awọn apaniyan to n gbogun ti ipinlẹ naa.
O ni kíkó ipa ṣiṣe aṣẹwo, ọmọ ọlọja irọle lo jẹ ipenija to le julọ fun oun ninu iṣẹ tiata.
Aarẹ Muhammadu Buhari ti rọ awọn musulumi Lati yago fun iwa jagijagan bi wọn ti n ṣayẹyẹ ọdun Ileya.
Dokita Siobhan Weare ti fasiti Lancaster University Law School kọkọ ṣe iwadii ifipabanilopọ l'orilẹede UK ni ọdun 2016 si 2017 laarin awọn ọrẹkunrin to le ni igba.
Oloye Balogun tun ni Olubadan ti gbe asẹ to wa ninu aafin rẹ le Olori lọwọ, ohun to ba si wu olori lo n pa lasẹ.
Aláàfin ìlú Oyo, Ikú Bàbá Yèyé tún bímọ tuntun làǹtì lanti Ìpínlẹ̀ Oyo, Ogun, Ondo buwọ́lu àbádòfin Àmọ̀tẹ́kùn Akẹ́kọ̀ọ́ wọlé padà, ìjọba Oyo kò pèsè ìbòmú lòdì sí ìlérí rẹ̀ Ilé aṣòfin Oyo àti Ogun buwọ́lu àbádòfin ikọ̀ aláàbò Amotekun Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
N kò pè yín ní ọmọ-ọ̀dọ̀ mọ́, nítorí ọmọ-ọ̀dọ̀ kì í mọ ohun tí ọ̀gá rẹ̀ ń ṣe.
Ẹ sọkún tẹ̀dùntẹ̀dùn, ẹ̀yin igi Sipirẹsi,nítorí igi kedari ti ṣubú,àwọn igi ológo ti parun.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Nollywood stars: Àwọn èèkàn òṣèré sinimá ní Nàìjíríà jẹ́wọ́ ara wọn lórí fífi ohùn àmì Ni ọdun 2012 tun ni wọn yan Olumilua gẹgẹ bii baba isalẹ fasiti ipinlẹ Ekiti, EKSU.
com/jumokeodetola/ Àwọn òṣèré tíátà Yorùbá kọjú ìjà síra wọn lórí ìdárò akẹẹgbẹ́ wọn tó kú Awaye ku ko si, Ọba oke mase jẹ ka fi ọjọ ọlọjọ lọ ni.
Iewadi iroyin to lọ kaakiri wi pe awọn ọmọ ti ọjọ ori wọn ko to ọdun mejidinlogun dibo pẹlu iwe idibo naa.
 Marcus Rashford is the coolest man on the planet, pass it on…🙌🙌🙌 pic.
Ifẹsẹwọnsẹ naa ni alakọkọ iru rẹ ti Musa yoo ti kopa lẹyin to darapọ mọ ẹgbẹ agbabọọlu.
Ní àkókò yìí n kò wá òògùn tí mo fi ń rii, wọn ń múu wwá bá mi ni: mo ni òrùka idẹ àti ti irin, mo ní òrùka òjé àti ti bàbà, bẹ́ẹ̀ ni onírúurú ońdè ní ń bẹ ní ìbàdí mi: nítorí mo fi awọ erin ṣe ońdèe, mo fi ti ẹkùn ṣe mo sì fi ti ìjímèrè ṣe pẹ̀lú.
Huṣai bá lọ sọ fún Sadoku ati Abiatari, àwọn alufaa mejeeji, irú ìmọ̀ràn tí Ahitofeli fún Absalomu ati àwọn ọmọ Israẹli, ati èyí tí òun fún wọn.
Àwọn tó jí kọmíṣọ́nnà gbé l'Ekiti ń bèèrè fún N30 mílìọnù kí wọ́n tó le è tú u sílẹ̀ Ogbeni Sani Adamu to jẹ alaisan kan ṣalaye fun akọroyin BBC pe nigba ti oun joko di aago kan lataarọ ti ko si dokita kankan to yọju si oun ni oun kuro nibẹ Awọn ẹṣo Federal ministry of health naa tun fidiẹ mulẹ pe ko si oṣiṣẹ kankan nile iṣẹ naa.
Ààrẹ Muhammadu Buhari sàlàyé pé, ẹ̀sìn níkàn lọ̀nà àbáyọ láti jẹ kí ènìyàn hùwà tó tọ́ sí Ọlọ́run àti ọmọ ẹ̀dá.
Aare soro naa di mimo nile egbe oselu All Progressives Congress, APC, niluu Abuja,  lasiko isiso loju eegun lati bere ipolongo fun ipo aare ati ile igbimo asofin saaju idibo odun 2019.
A fẹ́ kí ọba mọ̀ pé àwọn Juu tí wọ́n wá láti ọ̀dọ̀ rẹ̀ sí ọ̀dọ̀ wa ti lọ sí Jerusalẹmu, wọ́n sì ti bẹ̀rẹ̀ sí tún ìlú burúkú náà, tí ó kún fún ọ̀tẹ̀ kọ́.
Nítorí pé orúkọ Jesu ni ó mú wọn máa rin ìrìn àjò láì gba ohunkohun lọ́wọ́ àwọn alaigbagbọ.
Rògbòdìyàn bẹ́ sílẹ̀ láàrin àwọn ọlọ́kadà àti àwọn òṣìṣẹ́ ọgbà ẹ̀wọ̀n ní Ibadan Wo àwọn oúnjẹ márùn ún tó ń mú kí àtọ̀ ọkùnrin dára síi Wo ìgbà tí Ààrẹ Buhari yóò ṣí 'bọ́dà' padà ‘Sim Card’ títà àti ìforúkọsílẹ̀ rẹ̀ dèèwọ̀ ní Nàíjíríà - NCC SP Fadeyi ṣalaye ninu atẹjade to fi sita laarọ ọjọ Abamẹta pe awọn agbebọn lo ṣekupa oloṣelu naa lẹyin ti wọn ja a lole tan.
Lọsẹ to kọja ni oludari ajọ HRW ni Central Africa, Lewis Mudge sọ pe ''pẹlu gbogbo iwa ọdaran to n waye ni Burundi, o jẹ ibanujẹ pe awọn awọn ọmọde ni wọ̀n n fi ofin gbe nitori wọn fi nkan kun aworan aarẹ.
Diẹ lara awọn ilana to wọpọ ni ofin ijọba l'ori ijina sira ẹni láwùjọ ni awọn agbegbe kan tabi jakejado orilẹ-ede.
Tí mi ò bá fẹ́ ìyàwó mi, n ó tí di àgbégbìn- Ayodele Fayose Gbogbo ìgbésẹ̀ Aláàfin láti jí mi gbé ló já sí pàbó, n kò le panumọ́ - Olori Anu ''Ọrọ iwa ifijẹni awọn ọlọpaa kan onile bẹẹ naa ni o kan alejo.
Ta ló dà bí Ọlọ́run Fayoṣe?
Ẹ darijin mi, ẹ̀mí ẹ̀tàn ló lò mí -Pasitọ.
Dangote to jẹ ọkan lara awọn ololufẹ ẹgbẹ agbabọọlu Arsenal lorilẹ-ede Naijiria ti fi erongba rẹ lati ra ẹgbẹ agbabọọlu naa han lọpọ igba, ṣugbọn ko ni anfani lati ṣe bẹẹ.
Nígbà tí wọ́n ké pe OLUWA, nítorí ìyọnu àwọn ará Midiani, 
Ile Igbimọ Asofin naa wa parọwa si ẹnikẹni ti ko ba tẹ lọrun lati fi ẹri han wi pe, awọn san owo fun ilẹ naa.
Nígbà tí wọ́n gbọ́ pé òkú jinde, àwọn kan ń ṣe yẹ̀yẹ́, àwọn mìíràn ní, “A tún fẹ́ gbọ́ nípa ọ̀rọ̀ yìí nígbà mìíràn.
Yakubu Dogara padà sí APC, Buhari kí i kúàbọ̀ ní Aso Rock Wo àwọn tí wòlíì ríran sí pé COVID-19 yóò pa ní ìpínlẹ̀ Edo l'óṣù kẹsàn án Nǹkan mẹ́sàn án tí Mùsùlùmí gbọdọ̀ ṣe nínú oṣù Dhual- Hijjah Alága àjọ EFCC Ibrahim Magu yóò tún bẹ ìgbìmọ̀ olùwádìí Aàrẹ wò lónìí Atẹjade naa fi kun un pe wọn ti mu afurasi meji bayii.
" Oríṣun àwòrán, InSTAGRAM/MCOLUOMO Oluomo wa leri leka pe bi Ọlọrun ba bo oun ni asiri, awọn ọmọ ita ni oun yoo ran lọwọ julọ nitori ọmọ ita ni oun naa, idile ti ko si toro lo mu ki ọpọ awọn ọmọ yii di ọmọ ita.
Lara awon gomina ti o kopa ninu ipade naa ni: gomina ipinlẹ Osun, Kebbi, Zamfara, Plateau, Ebonyi, Adamawa, Edo, Lagos, Niger, Borno, Ogun, Ekiti bee si ni gomina ipinle Kogi ko gbẹyin ni bi ipade igbimọ majẹkobajẹ yii.
Nítorí pé gbogbo iṣẹ́ rẹ̀ pé, ọ̀nà rẹ̀ tọ́, ó sì lè rẹ àwọn agbéraga sílẹ̀.
láti fi ìyàtọ̀ sí ààrin ohun tí ó mọ́, ati ohun tí kò mọ́, ati sí ààrin ẹ̀dá alààyè tí eniyan lè jẹ, ati ẹ̀dá alààyè tí eniyan kò gbọdọ̀ jẹ.
O ṣe eyi nipa titu awọn ẹlẹwọn oṣelu silẹ, o si tun pa ofin ti ko faaye gba ṣiṣe ẹgbẹ oṣelu rẹ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Coronavirus: Ọṣẹ́ wo ni Coronavirus ń ṣe ní àgọ́ ara?
Lara awọn olujẹjọ ninu ẹjọ naa, to wa nile ẹjọ giga ipinlẹ naa to kalẹ silu Ibadan ni, agbẹjọro agba ati kọmisana feto idajọ nipinlẹ Oyo.
Bi awon omo orile ede Naijiria
America yóò tutù ju bó ti yẹ lọ Àgbálùmọ̀, ohun mẹ́fà tó ń ṣe lára tí o kò mọ̀ BBC Gov Debates: Ètò ìlera alábọ́dé la ó ṣe fún àwọn ènìyàn Ọyọ Oríṣun àwòrán, Getty Images Bakan naa, ni Ilẹ Gẹẹsi, ni se ni yinyin bo gbogbo ọkọ ayọkẹlẹ, ti ko si ẹni ti o le jade sita ju igba diẹ lọ.
Nguma so wipe botilẹ jẹ wipe awọn sọja yi ko fi tipa ba oun lo pọ.
Kini awa ọmọ Naijiria fun ara wa le ṣe?
Ìwọ OLUWA Ọlọrun ni o ṣèlérí yìí, ibukun rẹ yóo sì máa wà lórí arọmọdọmọ mi títí laelae.
Nípa bẹ́ẹ̀, ó mú OLUWA Ọlọrun àwọn baba rẹ̀ bínú.
Ìwọ ni Ọlọrun tí ń ṣe ohun ìyanu;o ti fi agbára rẹ hàn láàrin àwọn eniyan.
World theatre Day: Kosọkọ ní ètò adójútòfò wà fọ́jọ́ alẹ́ àwọm onítíátà
'Ileesẹ ọlọpa Ghana yoo ri atunto' Buhari dasi ipaniyan Benue Adesina sọ pe, 'Aarẹ Buhari yoo lo anfaani ọun lati fidi ibasepọ to dan mọọran to wa laarin awọn eniyan ati ijọba orilẹede mejeeji ọun tẹlẹ mulẹ.
Èyí yóo wá burú ju gbogbo ibi tí ó ti bá ọ láti ìgbà èwe rẹ títí di òní lọ.
O sàpèjúwe ìdásílẹ̀ ìjọba túntún yìí gẹ́gk bi dída ìtàn ẹ̀yà kan rú ti kò si yẹ kí ẹnikẹni gbàá láàyhe láti wá si ìmúṣẹ Oríṣun àwòrán, ISSOUF SANOGO Àkọlé àwòrán, Ado Bayero to waja jẹ ara ilé baba Emir Muhammed Sanui II Ǹkan tó ṣẹ̀lẹ̀ ni ìpínlẹ̀ Kano ni ọ̀sẹ̀ to kọja ṣe àfihan gbangba ọ̀nà láti tún ìtàn àwọn ènìyàn ìpínlẹ̀ Kano kọ, ìtàn to ti pé ẹgbẹ̀rún kan ọdún, kódà nígbà ti àwọn ìjọba òyìnbó amúnisin wá wọn ó fọ́wọ́ kan ìtàn wa, kílo wá de ní àsìkò yìí?"
Ṣé ìwọ wá fẹ́ gbà á ni?
Igbimọ idajọ orilẹede Naijiria, NJC ti kọ iwe tuntun ranṣẹ si adajọ agba orilẹede Naijiria, ti wọn ni ko lọ rọọkun nile fun igba diẹ, Walter Onnoghen lati wa wi tẹnu rẹ lori iwe ẹsun tuntun ti ajọ to n risi iwa ijẹkujẹ lorilẹede Naijiria, EFCC kọ ranṣẹ si igbimọ naa n itori Onnoghen.
Ogbeni so pe“Yiyapa kuroninu egbe yii ti je ka mo awon olufokansin, ati ati awon ti ko si wa pelu wa.
Awon agbaagba ti won n jiroro kikan ninu ipade naa ni Ojogbon Yemi Osinbajo, to je igbakeji Aare, olori eto aabo Naijiria, Ogagaun agba Gabriel Olonisakin atawon olori eka eto aabo kookan.
Láti Aroeri tí ó wà ní etí àfonífojì Anoni lọ, ati ìlú ńlá tí ó wà ní àfonífojì, títí dé Gileadi, kò sí ìlú tí ó ju agbára wa lọ.
Kano Governorship: Ilé ẹjọ sún ìgbẹ́jọ Ganduje sí ogunjọ oṣù kíní Abdularahaman, Ọmọ ọdún 17 kó sí páńpẹ́ EFCC lórí ẹ̀sùn yahoo-yahoo ní Ibadan Naira Marley ti tèṣù mọ́lẹ̀ nílé ẹjọ́ májísíréètì lórí ẹ̀sùn ìjọ́kọ̀gbé Aláàfin Ọyọ: Ọba tó bá n mú ọtí ní ìta kò yẹ ní ẹni tàá bọ̀wọ̀ fún Oríṣun àwòrán, @others Àkọlé àwòrán, Ijamba oko akeru ni Obanikoro ti fa sunkere fakere oko Idásilẹ̀ Amotekun ko ba òfin ọdún 1999 mu- Malami Ọ̀gá mi fẹ́ fi tipá bámi lòpọ̀ ní Lebanon àmọ́ ìjọba yọ mí l'óko ẹrú - Ọmọ Nàíjíríà míì Bí ìtàn ayé Toyosi Arigbabuwo ṣe lọ rèé láti ẹnu Musiliu Dasofunjo àti Ogun Majek Àsọtẹ́lẹ̀ Fada Mbaka, tó yẹ àga mọ́ gómìnà Imo nídìí rèè Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, BIAFRA at 50: Ìhàlẹ̀ ológun ni Gowon ni ká kọ́kọ́ fi bẹ̀rẹ̀- Aladejẹbi Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
n óo ranti majẹmu tí mo bá ẹ̀yin ati gbogbo ẹ̀dá alààyè dá pé, omi kò ní kún débi pé yóo pa ayé rẹ́ mọ́.
 O wa fi asiko ohun ro gomina
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Sheu Sani kò lu jibiti, irọ́ ńlá ní wọ́n ń pa mọ́ọ- Agbẹnusọ Shehu Sani 1 Sẹ́rẹ́ 2020 Oríṣun àwòrán, Sani Àkọlé àwòrán, Idi ti EFCC ṣe mu Sheu Sani S'ahamọ Àjọ tó n gbógun ti lílu owó ìlú ni pònpó (EFCC) ti fi ọwọ́ òfin mu sẹnatọ to n soju ẹkun aarin gbùngbùn Kaduna tẹ́lẹ̀ri Sehu Sani.
O ki gbogbo awọn eeyan to dibo fun un loju opo instagram rẹ, bẹẹ naa lo fi ami ẹyẹ ọhun sọri wọn.
 Lóde òní, Bath jẹ́ ọ̀kan nínú àwọn ìlú pàtàkì ní orílẹ̀ UK.
com/2kHxRabbAyDeontay Wilder jawe olubori niseju mẹ́tàlélógójì ti
 A o ri daju lati fowosowopo pelu won lati ri pe gbogbo kudie-kudie tabi awon ohun to nilo atunse di titun se patapata lai foju fo okan sile.
Nígbà tí Balaamu jí ní òwúrọ̀, ó sọ fún àwọn oníṣẹ́ Balaki pé, “Ẹ máa lọ sí ilẹ̀ yín nítorí OLUWA ti sọ pé n kò gbọdọ̀ ba yín lọ.
 Òun ni ó bí dúró fún orímóògùnjẹ ́ .
Ní oṣù kẹsan-an, ọdún karun-un tí Jehoiakimu ọmọ Josaya jọba ní Juda, gbogbo àwọn tí wọn ń gbé Jerusalẹmu ati àwọn eniyan tí wọ́n ti àwọn ìlú Juda wá sí Jerusalẹmu, kéde ọjọ́ ààwẹ̀ níwájú OLUWA.
Ṣeyi Makinde tun mẹnuba pataki eto ẹkọ ati igbiyanju rẹ lati mu ko di irọrun f'awọn akẹkọọ.
Ọpọ awọn ilumọọka lawujọ, awọn osere ori itage ati awọn olorin si lo ti n dawọ idunnu loju opo ibadọrẹpọ lori itakun agbaye pẹlu ọlọjọ ibi naa, fun bi ọba oke se mu ki oju rẹ tun ri ọdun tuntun.
Bẹ́ẹ̀ ni ó ń gba gbogbo àwọn tí ó ń wá rí i.
Bakan naa lo ni mẹta lara awọn iwe ẹri ti wọn gba naa ni wọn gba lati ọwọ oludije APC ati oludije PDP fun awọn oludije ẹgbẹ oṣelu miran.
Ṣé Yorùbá bọ̀ wọ́n ní ‘bí kò bá ní ìdí, obìnrin ò kí ń jẹ́ Kúmólú’.
iwa janduku, agbesunmomi, iwa ipanle, ole, egbe buburu ti o fi mo awon omo ogun
OLUWA yóo fọ́n yín káàkiri àwọn orílẹ̀-èdè ayé, ẹ óo sì máa bọ oríṣìíríṣìí oriṣa káàkiri, ati èyí tí wọ́n fi igi gbẹ́, ati èyí tí wọn fi òkúta ṣe, tí ẹ̀yin ati àwọn baba yín kò mọ̀ rí.
Ninu atẹjade kan ti ijọba Amẹrika fi lede loju opo Facebook rẹ lo ti kede ipinu naa.
"O ni ""Mo ti paṣẹ fun awọn aṣoju-sofin ati agbofinro lati fọwọ-sowọpọ ki wọn lee mọ ibi ti owo ti ijọba n la kalẹ fun agbegbe naa n wọlẹ si."
0 13 Orilẹede Cambodia 0 0.
Miliọnu mẹta ati aabọ ti Lai Mohammed ni El-Zakzaki fi n jẹun ja si N117,000 lojoojumọ.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Obey padà fi ẹgbẹ́ Fatai silẹ pẹlu awọn ọmọ ẹgbẹ́ mẹfa míì lọdun 1963.
"A ti bẹrẹ iwadii ti wa ni kikun bayii""."
Bakan naa lo fi kun pe, nigba ti Bimbo ri pe atẹgun ti gba ọkọ lọwọ oun, lo ba bẹ sinu omi, to si fi gbogbo awọn ero kalẹ, ti wọn si ri somi.
Eyi lo mu ki awọn dokita to n ṣiṣẹ lawọn ile iwosan ipinlẹ Eko gunle iyanṣẹlodi ọlọjọ mẹta lati ṣe ikilọ fun ijọba.
 Ìyísòdì ẹ ̀ yán asòǹkà nínu gbólóhùn ( 86 a-d ) yóò fún wa ni ( 87 a-d ).
Bí a bá wí pé a ní ìrẹ́pọ̀ pẹlu rẹ̀, tí a bá ń gbé inú òkùnkùn, òpùrọ́ ni wá, a kò sì ṣe olóòótọ́.
Gbogbo wọn ní àpapọ̀ jẹ́ ọgbọ̀n ọ̀kẹ́ ó lé ẹgbẹsan ó dín aadọrin (601,730).
Awon ajo mejeeji yii salaye , nigba ti won n fara han niwaju ile igbimo  asoju-asofin to n sako lori ajo NEMA, nipa iwadii lori awon ise ti ajo naa n se.
Ẹ wo bi eto aabo ṣe dẹnukọlẹ ni ilẹ Yoruba, ti ijinigbe n waye loore-koore lai ka awọn ẹmi ti awọn ajinigbe n pa ni ilẹ Yoruba'' ''Lẹyin ti wo gbogbo iṣẹlẹ yii ni a ṣe apero awọn agbagba ilẹ Yoruba, ki a to da ẹgbẹ Yoruba World Assembly silẹ'' ''Otitọ si ni pe imọ awọn ọmọ Yoruba ko ṣe ọkan ni gbogbo igba, nitori aigbọraẹniye to wọpọ laarin awọn agbaagba'' ''A ko nifẹ si iru ẹgbẹ ti ina wọn n jo ajorẹyin mọ, nitori naa ni ẹgbẹ ti yoo mu ifimọsọkan ni okunkundun ṣe koko, o ṣe pataki.
Kí ni ó wá dé nisinsinyii!
Bí ẹ bá ti ń bá ìṣòro pàde nínú ayé mo fẹ́ kí ẹ máa bú sí ẹ̀rín kí ẹ sì mọ̀ pé ọjọ́ ń bọ̀ tí ìgbádùn yóó wọlé tọ̀ yín wá.
Awọn ọdọ naa ni owo ina ti awọn osisẹ IBDEC n mu wa fun awọn ti pọ ju, ti ina ọba si n se segesege lati osu mẹfa sẹyin.
Utai ọmọ Amihudu, ọmọ Omiri, ọmọ Imiri, ọmọ Bani, ọ̀kan lára àwọn ọmọ Pẹrẹsi, ọmọ Juda.
& Hove Albion Newcastle United 3-1 Southampton 😍 | Four beautiful goals that you'll want to watch back again and again and again and again… #EFC 🔵Everton 4-0 Manchester United ⭐️ You voted @chrisbenteke as our #ARSCRY Man of the Match.
Ọmọ atàpátadìde ni mí, télọ̀ ni bàbá mi- Abiola Ajimobi EFCC ya bo ìlé Akinwumi Ambode Mahassin Quadri ló gbà ìrànwọ $5,000 Tony Elumelu YIAGA: Gbájú-ẹ̀ ni Saraki lò fún wa Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ogundamisi: Ọbasanjọ ni ko jẹ k'awọn ọdọ de'po Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
00 bn Ile igbimọ Aṣofin apapọ - N128.
Ebuka ko duro ka iwe alakọbẹrẹ de ipele iwe kẹfa rara ko to bọ si ti girama nitori pe o jafafa pupọ.
Lẹ́yìn tí Nebukadinesari, ọba Babiloni ti kó Jehoiakini ọba Juda, ọmọ Jehoiakimu kúrò ní ìlú Jerusalẹmu lọ sí Babiloni, pẹlu àwọn ìjòyè Juda, ati àwọn oníṣẹ́ ọnà, ati àwọn alágbẹ̀dẹ, OLUWA fi ìran yìí hàn mí.
Bí ẹrubinrin yìí kò bá wù olówó rẹ̀ láti fi ṣe aya, ó níláti dá a pada fún baba rẹ̀, baba rẹ̀ yóo sì rà á pada.
Isọri kẹta ni Tanzania ti agbbọọlu Naijiria tẹlẹ Emmanuel Amuneke n dari wa pẹlu Kenya, Algeria ati Senegal.
Mo wà pẹlu rẹ̀ ní gbogbo ibi tí ó lọ, mo sì ń ṣẹgun gbogbo àwọn ọ̀tá rẹ̀ fún un, bí ó ti ń tẹ̀síwájú.
Ijoba orile ede yii yoo tun gba awon omo orile ede yii sinu ajo eleto aabo, won yoo  tun pese idanilekoo,awon irinse igbalode , ki eto aabo tun le  tubo fese mule si i.
Ara wọn ni àwọn tíí máa tọ ojúlé kiri, tí wọn máa ń ki àwọn aṣiwèrè obinrin mọ́lẹ̀, àwọn obinrin tí ìwà ẹ̀ṣẹ̀ ti wọ̀ lẹ́wù, tí wọn ń ṣe oríṣìíríṣìí ìfẹ́kúfẹ̀ẹ́.
Nibẹ ni wọn ti fi si ori ikanni naa nipa Ramoni Igbalode ati Olalekan Jacb Ponle ti wọn n pe ni 'Woodberry'ati awọn ọmọ ilẹ Adulawọ miran.
Nítorí rẹ̀ ni mo fi sọ fún ẹ̀yin ọmọ Israẹli pé, ẹnikẹ́ni ninu yín kò gbọdọ̀ jẹ ẹ̀jẹ̀, bẹ́ẹ̀ sì ni àlejò tí ń ṣe àtìpó láàrin yín kò gbọdọ̀ jẹ ẹ̀jẹ̀.
Lara awon eniyan jankan-jankan ti o kopa ninu adura ikeyin ohun ni, adajọ agba nile-ejo giga, adari igbimo ijoba tele ri, Abdulsalami Abubakar, ogoro awon gomina, awon asofin, oludari agba ile-ise olopaa  Idris Ibraahim abbl.
Orilẹede France kọ ni akọkọ orilẹede tawọn alaṣẹ ere bọọlu yoo ti wọgile ifẹsẹwọnsẹ bọọlu nitori arun Coronavirus.
aare orile ede Naijiria Muhammadu Buhari lasẹ lati yọ adari ile –ejo lorile ede
Lori kiko ọja wọle lọna aitọ, Enelamah ni ko tọ naa ni bi apejuwe rẹ ṣugbọn kii ṣe pe tori rẹ kii ṣe pe ki a dawọ pipese ounjẹ fun apẹrẹ irẹsi duro.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Nollywood: Femi Adebayo, Damola Olatunji àti Muyiwa Ademola wà lára àwọn òṣèré tíátà Yorùbá tó bí ìbejì 14 Òkùdu 2020 Oríṣun àwòrán, Others Àkọlé àwòrán, BBC Yorùbá ṣe àkójọpọ̀ àwọn òṣèré tíátà Yorùbá márùn-ún tó bí ìbejì Ipo pataki ni Yoruba to ibeji si ninu awọn ọmọ nitori orisa ni wọn ka wọn si, ti wọn si maa n gbe wọn larugẹ.
A máa ṣe ìdájọ́ òtítọ́ fún àwọn aláìníbaba ati àwọn opó.
A tẹ eniyan lórí ba,a sì rẹ̀ wọ́n sílẹ̀ojú àwọn onigbeeraga yóo sì wálẹ̀.
Nítorí pé n óo polongo orúkọ OLUWA,àwọn eniyan rẹ yóo sì sọ nípa títóbi rẹ̀.
Egbe  oselu  African National Congress (ANC) lo si n jawe
Nítorí pé talaka ati aláìní ni mí,ọkàn mí bàjẹ́ lọpọlọpọ.
Freixa ni ko si iru adehun ti Barcelona le fẹ fun Messi to le mu duro si Barcelona, o ni aṣọ ko ba ọmọyẹ Messi mọ.
Theresa May ti tẹsiwaju pẹlu irinajo rẹ lo si orile-ede Kenya.
O bá sọ fún àwa iranṣẹ rẹ pé bí àbíkẹ́yìn wa patapata kò bá bá wa wá, a kò ní rí ojú rẹ nílẹ̀ mọ́.
Àwọn ààrùn náà ni ààrùn Fòníkú-fọ̀la dide Etí dídi.
Ju gbogbo ẹ lọ, ẹ fi si ọkàn, yala gẹgẹ bi awakọ tabi eero ọkọ, pe o ṣe e ṣe ki ẹ há sinu sunkẹrẹ-fakẹrẹ ọkọ lasiko ti atunse afara Third Mainland Bridge.
"Hursh Jaswal ti o jẹ agbẹnusọ fun minisita to wa fun iwọle-wọde ni Canada, Ahmed Hussen ni, ""Iru awọn wọnyi, bi wọn ba ṣe de orilẹ ede Amerika, ti wọn duro diẹ bayi ni wọn ma maa sabọ si Canada."
láti tan ìmọ́lẹ̀ sí àwọn tí ó wà ní òkùnkùnati àwọn tí ó jókòó níbi òjìji ikú,láti fi ẹsẹ̀ wa lé ọ̀nà alaafia.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Abiodun Koya: Láti ọmọ ọdún mẹ́ta ni mo ti ń kọrin bi ẹyẹ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Abiodun Koya: Láti ọmọ ọdún mẹ́ta ni mo ti ń kọrin bi ẹyẹ 21 Èbibi 2019 Abiodun Koya jẹ akọrin ọmọ Naijiria to ni ohun gooro fun awọn orin bii ti igbaani tabi paapaa julọ awọn orin ti wọn ki lu ilu si.
Wọ́n gba ilẹ̀ rẹ̀ ati ilẹ̀ Ogu, ọba Baṣani, Sihoni ati Ogu ni ọba àwọn ará Amori tí wọn ń gbé òdìkejì odò Jọdani ní apá ìlà oòrùn 
O ni nitori pe ko si idaniloju fun oun pe lootọ ni aarẹ Buhari bori lọna to tọ lasiko idibo naa.
Ẹni tí ó wo ilẹ̀, tí ilẹ̀ mì tìtì,tí ó fọwọ́ kan òkè, tí wọ́n bẹ̀rẹ̀ sí yọ èéfín.
13 Àti pé ìbínú Olúwa ti ru sókè, àti idà rẹ̀ ti di wíwẹ̀ ní ọ̀run, àti pé yíò ṣubú lórí àwọn olùgbé ilẹ̀ ayé.
Ìwọ̀n ṣekeli tí wọn ń lò ní ibi mímọ́ ni wọ́n fi wọ̀n wọ́n.
“Kúrò níhìn-ín, kí o doríkọ apá ìhà ìlà oòrùn, kí o sì fi ara pamọ́ lẹ́bàá odò Keriti, tí ó wà ní apá ìhà ìlà oòrùn odò Jọdani.
 ní gbogbo orílẹ ̀ -èdè tí a dárúkọ , yàtọ ̀ sí orílẹ ̀ -èdè nàìjíríà , òwò ẹrú ni ó gbé àwọn ẹ ̀ yà yorùbá dé ibẹ ̀ .
Nígbà tí èyí ṣẹlẹ̀, àwọn yòókù tí ó ń ṣàìsàn ní erékùṣù náà bá ń wá sọ́dọ̀ Paulu, ó sì ń wò wọ́n sàn.
Ẹ wò ó bí Jerusalẹmu ṣe parun tí àwọn ẹnu ọ̀nà rẹ̀ sì jóná.
Àwọn eniyan Israẹli jẹ mana náà fún ogoji ọdún, títí wọ́n fi dé ilẹ̀ tí wọ́n lè máa gbé, òun ni wọ́n jẹ títí tí wọ́n fi dé etí ilẹ̀ Kenaani.
Èyí tó burú jùlọ níbẹ̀ ni pé, ní ọ̀pọ̀ ìgbá tí àwọn oníṣẹ́ nla ibi yìí bá bá àwọn ènìyàn yìí lòpọ̀ tipatipa tán, wọ́n a tún dá ẹ̀mí wọ́n légbodò.
Ọkùnrin yìí bí ọmọbìnrin kan tí orúkọ rẹ̀ ń jẹ́ Ẹwàdàpọ̀, àti ìgbà tí ó sì ti kú ni ọba ti fi ọmọbìnrin yìí ṣe ọmọ rẹ̀ tí ọmọ náà ń gbé ààfin.
" Ó tún ṣiṣẹ ́ pẹ ̀ lú "" centre spread advertising limited "" agbègbè Ìlúpéjú Èkó ní ọdún 1991 sí 1992 ."
Gbogbo àwọn tí ń gbẹ́ èreyóo bọ́ sinu ìdààmú papọ̀.
Àwọn ni ó yẹ kí wọ́n wá siwaju yín bí wọn bá ní ẹ̀sùn kan sí mi.
" Aworan atọnisọna Iye awọn to ti ni arun naa lagbaye Sunmọ aworan Àgbáyé Orilẹede Afrika Ariwa Amẹrika Apa Latin Amẹrika ati Caribbean Ilẹ Asia Ilẹ Yuroopu Agbegbe Middle East Erekusu Oceania Fihan 69609761 iye iṣẹlẹ arun naa 1583112 Iye awọn to ku Group 4 Jọwọ ṣe atunṣe ilana ikansi ayelujara rẹ lati ri ẹkunrẹrẹ rẹ Aworan n ṣafihan awọn ti ayẹwo ti fi han lorilẹede kọọkan Orisun: Johns Hopkins University atawọn ajọ eto ilera ilu Igba ti wọn kede iṣiro awọn to nii kẹyin 11 Oṣù Ọ̀pẹ̀ 2020 13:00 WAT+3 Ẹkunrẹrẹ data Sun atẹ wa silẹ tabi oke lati ri ẹkunrẹrẹ akọsilẹ *Iye awọn to tọwọ aisan ku ni isọri eeyan ẹgbẹrun lọna ọgọrun Gbe e yẹwo: Àgbáyé Orilẹede Afrika Ariwa Amẹrika Apa Latin Amẹrika ati Caribbean Ilẹ Asia Ilẹ Yuroopu Agbegbe Middle East Erekusu Oceania Iye to ti ku Iye awọn to ku %* Apapọ awọn iṣẹlẹ arun Akọtun arun yii 0 10 100 1000 10000 ** Orilẹede Amẹrika 290803 88.
Orilẹede Amerika ni wọn ti bii, o si kawe gboye nipa imọ ere ori itage lati ile ẹko Dartmouth College.
O ni, titẹ awọn to ba fipa ba obinrin laṣepọ lọdaa le din iru iwa bẹẹ ku, sugbọn ko le fi opin si iwa ọhun.
Sọ pé rárá fún ìṣàjọyọ̀ àjọ̀dún Òyìnbó nínú ọgbà ilé-ìwé.
Nígbà tí ẹ̀mí burúkú yìí rí Jesu, ó mú kí gìrì ki ọmọ náà ní akọ, ó gbé e ṣánlẹ̀, ọmọ náà bẹ̀rẹ̀ sí yí nílẹ̀, ó ń yọ ìfòòfó lẹ́nu.
Ilẹ̀ Amẹ́rika tún ti ki Nàìjíríà kú orí ire lẹ́ẹ̀kan síi lóri ìtiraka wọn nínú títọ ìlànà ìjọba awa ara wa titi gbogbo ètò ìdìbò fi parí.
’’Eto  Idagbasoke Gomina tun so pe opolopo idagbasoke lo ti deba ipinle Osun.
Odiwọn iye awọn to ti ku nibi iṣẹlẹ ilẹ riri nla to ṣẹlẹ ni Lombok ti di mejidinlọgọrun bayii.
Ilẹ̀ tí ó lọ́ràá tí ó sì ní ẹ̀tù lójú tí ó kún fún wàrà ati oyin.
Jelili Oniso wá gba àwọn aráàlú nímọ̀ràn láti máa ṣèwádìí nípa àṣeyọrí agbejoro kan ni ẹnu isẹ, kí wọn tó máa gbé ẹjọ́ fún láti dènà ijakulẹ.
Zenaib Yassin, alaga egbe awon obinrin lorile-ede South Sudan so pe, orile-ede ohun le se aseyori bi eto dogba-dogba ba je koko kan gboogi ninu erongba ipele ijoba gbogbo lorile-ede naa.
Kí ló dé tí ẹran ara mi kò to yín?
ati alaafia  ju bi a se nilo ounje ati
Kí ló dé tí n óo fi mú sùúrù?
 A dupẹ fun gbogbo atilẹyin yin latilẹ wa.
Sakaraya, baba ọmọ náà, kún fún Ẹ̀mí Mímọ́.
Wọn ni ẹrọ ayelujara ti jẹ ki ọpọ eeyan da awọn aafa wọnyii mọ ni eyi to jẹ ki awọn kuku ni kawọn ọmọ ogun ilẹ maa ṣọ wọn koda, ti wọn ba n pe irun lọwọ ninu mọṣalaṣi.
Ajọ to n mojuto ọrọ ina mọnamọna ni Naijiria, NERC, ti ṣalaye nipa ilana to yẹ ko mu adinku ba bi awọn ileeṣẹ mọna-mọna ṣe n gba iye owo to wu wọn lọwọ awọn ti ko ni mita.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Àwa táa jẹ́ alágbàtọ̀ gan, èèyàn ni wá, ẹ ye ṣe wa bí ẹranko' O ni awọn ikọlu afurasi Fulani ti n legba kan ju ọrin lọ, to si dabi ẹni pe wọn fẹ gbogun ti ilẹ Yoruba ni.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Awọn oluwọde n pe fun ifiposilẹ Jacob Zuma Ni ọdun 2014 lo di igbakeji aarẹ orilẹede South Africa ki wọn to dibo yan an si ipo alaga apapọ ẹgbẹ oselu ANC lọdun 2017.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Fídíò BBC yọ àwọn èèyàn FIFA níṣẹ́ ṣááju Russia 2018 O ni lẹyin ti ọwọ tẹ awọn ọdaluru yii ni awọn agbofinro lọ doola ẹmi awọn ọmọbinrin Canada mejeeji nibi ti wọn ko wọn pamọ sí ni Kenyasi.
Oríṣun àwòrán, María Conejo/BBC Maha sọ pe Ko ni i fi inu tan mi to ba fi mọ pe mo ti ni ibalopọ ka to o ṣe igbeyawo wa."
Báyìí ni Ìgbín bẹ̀rẹ̀ sí gun ẹṣin kiri tí ó gun ún yíká gbogbo ìlú.
Ẹ rántí pé eléyìí yàtọ̀ sí Bándélé orúkọ ọ̀kan nínú àwọn ọmọ rẹ.
Nígbà tí Joabu gbọ́ fèrè, ó bèèrè pé, “Kí ni ìtumọ̀ gbogbo ariwo tí wọn ń pa ninu ìlú yìí?
Ṣebí ọwọ́ ara yín ni ẹ fi fà á sí orí ara yín,nígbà tí ẹ̀yin kọ Ọlọrun yín sílẹ̀,nígbà tí ó ń tọ yín sọ́nà?
Láìsí àní àní, ọmọ náà gbójú lé nǹkan.
O ni nigba ti oun bere lọwọ iya naa idi ti wọn fi n pe ni mama Seyi ti oun si kii ṣe akọbi ni iya naa lọ ṣalaye fun oun pe, diẹ lo ku ki ọjọ ikunlẹ di ọjọ iku fun iya oun.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù World Cup 2018: Ṣé àwọn tó kù ní Moscow ló tó gbangba sùn?
"Odidi idaji ọjọ kanni mo fi n ṣiṣẹ lojọ ti maa si fi idaji to ku ka iwe""."
Àsọtẹ́lẹ̀ èké ni wọ́n ń sọ fun yín.
 Ìdàrúdàpọ ̀ nínú ẹbí , Àríyànjiyàn láàárin ọ ̀ rẹ ́ .
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Zimbabwe: Ìjọba fẹ̀sùn kan obìrin mẹ́ta lẹ́gbẹ́ alátakò, wọ́n d'éléẹjọ́ bọ̀ 17 Òkùdu 2020 Àkọlé àwòrán, Joana Momombe, okan ninu awon obinrin mẹta ti wọ́n fẹ̀sùn kan Inu omije lawọn obinrin mẹtẹta wa pẹlu aṣọ idọti aṣọ ẹlẹwọn ti wọn wọ ninu gbaga apoti ijẹjọ nile ẹjọ majisireeti ni olu ilu orilẹede Zimbabwe, Harare ti wọn n duro de idajọ boya wọn yoo jẹ ki wọn gba beeli wọn.
Oríṣun àwòrán, Western Nigeria security network Atẹjade ọhun tẹsiwaju pe ki awọn eeyan naa mu ṣokoto pelebe alawọ buluu, aṣọ funfun ati bata kanfasi to ṣee sare lọwọ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Iléeṣẹ́ China kan ti fagídí mú àwọn òṣìṣẹ́ rẹ̀ mu ìtọ̀ 9 Bélú 2018 Oríṣun àwòrán, Science Photo Library Àkọlé àwòrán, Aayan fẹ jó, adiyẹ ni kò jẹ́ Awọn oluṣakoso ilé-iṣẹ́ kan ni ìlú China ti fẹwọn gbára nitori wọn n fun oṣiṣẹ wọn ni itọ mu.
MKO Abiola, iṣẹ́ aṣẹ́gità ló fi bẹ̀rẹ̀ okoòwò Iṣọla Oyenusi rèé, ẹnití ìfẹ́ obìnrin ṣun dé ìwà ìdigunjalè Taiwo Akinkunmi, ọmọ Ibadan tó ya àsìá Naijiria Ayinla Ọmọwura, orin èébú àti oríyìn lo fi di ọ̀rẹ́ àwọ̀n obìnrin Ìtàn tó rọ̀ mọ́ òwe ‘aṣọ kò bá Ọ́mọ́yẹ mọ́.
 ti won ti pa milionu meji le logota owo dola ati orile ede South Korea ti won ti pa milionu mejilelogoji dola.
Awọn onimọ Sayẹnsi to le ni igba ni ajọ WHO sọ pe wọn kọ lẹta si Ajọ WHO lati ṣe ayẹwo boya arun Coronavirus n tankalẹ lati inu afẹfẹ.
Agbara Ọlọrun ni yẹn'' Ekiti election appeal: Fayẹmi 2, Ẹlẹka 0 ‘A ti mọ̀ tẹ́lẹ̀ pé Kayọde Fayemi ni yóò jáwé olúborí ní Tribunal’ Fayoṣe fapájánú, o ni kí EFCC kọwe tọrọ àforíjìn O fi kun pe ipenija agbara Ọlọrun ọga ogo ni ohun to n ṣẹlẹ si Ẹlẹka ti yoo si pada bori.
Irufẹ ọrọ iporuru ọkan bayii tun waye lati ọdọ Trevor Noah, tii se adẹrinposonu ọmọ ilẹ South Africa ati Kamaru Usman ọmọ Naijiria abẹsẹkubiojo mii to wa nilẹ okere.
Gómìnà ìpínlẹ̀ Ondo Rotimi Akeredolu ló fi ìdí ọ̀rọ̀ náà múlẹ̀ lórí àtẹ́jíṣẹ́ rẹ̀ Ó ní ìjọba ti fi ọ̀rọ̀ yìí tó kọmísọ́nà ọlọpàá ní ìpínlẹ̀ Ondo léti, láti le wá àwọn ọlọpàá àtí àwọn SARS ti ó wà ni ìkáwọ́ wọ́n nágbà ti wọ́n ṣe àyẹ̀wò wọ́n Adájọ́ pàṣẹ pé kí wọ́n o fi àwọn afurasí tó pa ọmọ Fasoranti sí ọgbà ẹ̀wọ̀n Fasoranti's Daughter: Ilé ẹjọ́ ti sún ìgbẹ́jọ́ àwọn afurasí tó pa ọmọ Fasoranti sííwájú Ile ẹjọ ti sun igbẹjọ awọn afurasi mẹẹrin tileṣẹ ọlọpaa fi ẹsun kan pe wọn lọwọ si iku ọmọ Reuben Fasoranti.
Wọ́n kò pa ẹnikẹ́ni sí ààfin Ṣọun Ogbomosọ, òkú tí àwọn ọdọ́ gbé wa ni ọlọ́pàá wọ́ jáde- Agbẹnusọ Ṣọ̀un Owó iṣẹ́ abẹ ìdí kìí ṣe ẹ̀rù ọmọdé- Dr Laser Ilé alájà mẹ́ta wó pa èèyan méje, èèyàn 20 farapa ní Obalende, Eko Ebi ti pa àwọn ara Ondo púpọ̀ sẹ́yìn ló jẹ́ kí wọ́n ta ìbò wọn- Aṣojú ẹgbẹ́ òṣèlú ADP, SDP Awọn Obi ati ẹbi awọn ẹjẹ alaiṣẹ ti iku wọn ni ọwọ kan awọn ọlọpaa ninu naa n beere fun idajọ ododo lọwọ ijọba Àwọn òbí mí kọ́kọ́ tako kí n má lu ìlú gẹ́gẹ́ bí obìrin - Ayansike Bí èsì ìdìbò gómìnà ìpínlẹ̀ Ondo se ń jáde rèé.
Iṣẹlẹ yii lo n waye lẹyin nnkan bi ọsẹ meji ti ọkan lara awọn alabaṣiṣẹ gomina ipinlẹ naa, Yahaya Bello ku sile iwosan kan ni Abuja.
Àwọn tí wọn ń fẹ́ di ọlọ́rọ̀ a máa ṣubú sinu ìdánwò, tàkúté a sì mú wọn.
Àkókò ń bọ̀ tí n óo run gbogbo àwọn ọdọmọkunrin ìdílé rẹ ati ti baba rẹ kúrò, débi pé kò ní sí àgbà ọkunrin kan ninu ìdílé rẹ mọ́.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Saraki ṣèlérí láti ran Atiku lọ́wọ́ ní 2019 Aisha Buhari ni ó yẹ kí èèyàn yẹra fún APC torí ìwà àìtọ́ Baba Sala dágbére fáyé Ẹwẹ, Aarẹ Muhammadu Buhari ti kí àwọn olùdíje ẹgbẹ APC ni kakakiri orilẹede Naijiria ku oriire, bẹẹ ni o tun rọ wọn ki wọn ma ṣe binu si ara wọn.
Ipolongo eto idibo naa ni aṣejagba iruẹ fun ẹgbẹ oṣelu APC saaju eto idibo si ipo gomina ti yoo waye ni ipinlẹ naa.
 Èyí kò ni ǹ kan se pèlú pé bóyá gbólóhùn méjèèjì bófin mu tàbí won kò bófin mu .
Abikẹ Dabiri: Iṣẹ́ pọ̀ lọ́wọ́ Naptin àti àwọn aṣọ́bodè Nàìjíríà
Ó lòdì sí ìlànà Olódùmarè ó sì ìríra lójú àwọn ọmọ aráyé wí pé kí ọmọ tí a bí nínú ẹni máa hùwà àìbíkítà sí ni.
Ilẹeṣẹ ọlọpaa ni ipinlẹ Edo sọ fun BBC pe, awọn janduku naa tun ṣe ikọlu si agọ ọlọpaa kaakiri ipinlẹ naa, ti wọn si n ko gbogbo ohun ija wọn lọ.
Ṣugbọn bí ó ti ń lọ ni ọkọ rẹ̀ ń sọkún tẹ̀lé e títí tí ó fi dé Bahurimu, ibẹ̀ ni Abineri ti dá a pada, ó sì pada.
Àwọn géńdé bá wọlé, wọ́n rí òkú rẹ̀.
“Ikú yí mi káàkiri, bí ìgbì omi;ìparun sì bò mí mọ́lẹ̀ bíi ríru omi;
" Ó ku ọ̀sẹ̀ kan gbáko ló kùn ti gbogbo Musulumi lágbaye yóò bẹ̀rẹ̀ ààwẹ ọlọgbọ̀n ọjọ ti a mọ si oṣu ramadan.
Wọ́n ṣe ọgbà náà lọ́ṣọ̀ọ́ pẹlu aṣọ aláwọ̀ aró ati aṣọ funfun.
Kíni ìdí ti àwọn ènìyàn kìí fi fẹ gba abẹ́rẹ́ àjẹsára?
Ẹpẹ igba ni wọn maa n fi ọlọpa mu wa nitoripe ofin o faye gba isẹ aṣẹwo nibẹ.
Ìtàn ayé Ọba Seriki Abass ti Badagry, tó ní aya 128, ọmọ 144 Tunde Idiagbon, ọ̀gágun kògbagbẹ̀rẹ́ tó ní ẹ̀ẹ̀kan lóṣù ló yẹ kí ológun máa rẹ́rìín Yàtọ̀ sí Eko, wo ohun t'áwọn ìpínlẹ̀ meje míràn ń sọ nípa ìwọlé àwọn akẹ́kọ̀ọ́ Iléẹjọ gíga jùlọ da ẹjọ́ Wada (PDP) nù ní Abuja lórí ètò ìdìbò gómìnà ìpínlẹ̀ Kogi Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí 6:18 Fídíò, Natalia Mufutau ìyá Yakub, Kamil àti Adam sọ̀rọ̀ lórí bí wọ́n ń sọ èdè mẹ́rin pàpọ, Duration 6,1831 Ògún 2020 6:10 Fídíò, Yoruba Language: Akomolede ati Asa Yoruba tọ̀sẹ̀ yí rèé lẹ́nu olùkọ́ wa, Duration 6,1030 Ògún 2020 Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí 3 sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 2:23 Fídíò, Water Generator: Ó leè ṣiṣẹ fún wákàtí mẹfà, kó tó sinmi, Duration 2,2310 Òkùdu 2020 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
Ko pe kò jìnà sí ọjọ yí, àwọn tó n já gba lati joko forojomitooro ọrọ tí wọn sì dà ọwọ ija duro.
Àwọn ọba ilẹ̀ ayé ti ṣe àgbèrè pẹlu rẹ̀, àwọn oníṣòwò ilẹ̀ ayé ti di olówó nípa ìwà jayéjayé rẹ̀.
nígbà tí ó jẹ́ pé ìran rẹ̀ yóo di orílẹ̀-èdè ńlá tí yóo lágbára, ati pé nípasẹ̀ rẹ̀ ni n óo bukun gbogbo orílẹ̀-èdè?
Josẹfu yìí jẹ́ ọmọ-ẹ̀yìn Jesu tí ó fara pamọ́ nítorí ó bẹ̀rù àwọn Juu.
Jesebẹli bá kọ ìwé ní orúkọ Ahabu, ó fi òǹtẹ̀ Ahabu tẹ̀ ẹ́, ó fi ranṣẹ sí àwọn àgbààgbà ati àwọn eniyan ńláńlá ní ìlú tí Naboti ń gbé.
Ẹ̀rọ Medic Mobile ti sọ ayé dẹ̀rọ̀ fáwọn òṣìṣẹ́ elétò ìlera Ìpínlẹ̀ Eko fẹ́ dẹ́kun súnkẹrẹ ọkọ̀ lásìkò ọdún NAFDAC: Ojú wa wà lára ìpara Blac Chyna náà 'Àjùmọ̀sepọ̀ ti fẹ́ bẹ̀rẹ̀ láàrin àwa Ọba Yorùbá' Èyí tí a wò jùlọ 5:03 Fídíò, Omolola Arohunmolase Welder: Mo ti fí iṣẹ́ 'Welder' gbayì láwùjọ, tó mo fi tọ́ ọmọ yanjú, Duration 5,039 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 5:39 Fídíò, Akomolede ati Asa lori BBC: Olùkọ́ Kikelomo Ogunboye tan ìmọ́lẹ̀ sí ìwà olè ọ̀gá ọlọ́pàá Audu gẹ́gẹ́ bí àwòkọ́ṣe àsìkò yìí, Duration 5,398 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 4:11 Fídíò, Oba Adeyeye Ogunwusi: Ojú mi ti rí lọ́pọ̀ lọpọ̀, ọ̀pọ̀ èèyàn ni kò tilẹ̀ gbàgbọ́ pé mo lè jọba- Ooni, Duration 4,117 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 4:43 Fídíò, Promise Akinlade: ọmọ ọdún mọ́kànlá tó ń fi ìlù dárà bíi àgbàlagbà sọ̀rọ̀ nípa tálẹ́ǹtì rẹ̀, Duration 4,437 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 0:59 Gbọ́, Ìsẹ̀lẹ̀ jákèjádò orílẹ̀èdè àgbáyé láàárín ìṣẹ́jú kan, Duration 0,59wákàtí 5 sẹ́yìn 7:03 Fídíò, Olumuyiwa Bolade Adedeji Military Bruitality: Bí arákùnrin onípèníjà ara tí sọ́jà lù ṣe dé, Duration 7,035 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 4:45 Fídíò, Yoruba Films: Ẹ̀ẹ́ bẹ̀ mi kúrò láyé ni, mi ò lè kú - Fadeyi Oloro, Duration 4,4526 Èrèlè 2020 2:48 Fídíò, Esther Ajayi: Èmi náà ti borí ìṣòro rí ló ń mu mi ṣojú àánú, Duration 2,481 Ògún 2019 6:08 Fídíò, Adebola Ademilua: Àìrísẹ́ ṣè lẹ́yìn ìwé kíkà ló sọ mi dí ìyá onírú, mo dúpẹ́ tèmi, Duration 6,0827 Bélú 2020 5:55 Fídíò, Soyinka Cancer: Àṣe ara mi ni iso ti n run gbogbo bí mo ṣe n ṣèrànwọ́ lórí jẹjẹrẹ, Duration 5,5527 Bélú 2019 BBC News, Yorùbá Ìdí tí ẹ fi le è nígbàagbọ́ nínú ìròyìn BBC Ìlànà Lílò Nípa BBC Òfin Àṣírí Cookies Kàn sí.
6 21313 Orilẹede Madagascar 255 1.
RRS : Ẹwa gbe igbo yin
O so pe ‘‘ Awon adari ekun kẹ́rìndínlógún  ati
OLUWA ti pàṣẹ fún un láti kọlu Aṣikeloni, ati àwọn ìlú etí òkun.
Omowe Tunde Hamzat ti ori ko yọ ni akata awọn Fulani ajinigbe ni Naijiria ti ṣalaye ohun gbogbo ti oju rẹ ri fun BBC Yoruba.
Oríṣun àwòrán, others Àkọlé àwòrán, Díẹ̀ lára àwọn èròjà to wà nínú àgbo Covid-19 ti Madagascar n lò Aarẹ Rajoelina sọ fun awọn ọmọ ileewe lati ma a mu agbo naa lataarọ di alẹ.
Wo àwọn gómìnà PDP tó ti darapọ̀ mọ́ ẹgbẹ́ òṣèlú APC láti ọdún 1999 sí àsìkò yìí Ìtàn ayé Abiola Peller, ọlọ́wọ́ idán tó fi ọ̀bẹ gé ìyàwó rẹ̀ sí méjì Adájọ́ ní Seun Egbegbe ṣì lẹ́jọ́ láti jẹ́ lórí ẹ̀sùn gbájúẹ̀ Minisita naa ṣalaye pe gbogbo ipinlẹ Eko ni ijọba da awọn sọja si lẹyin ti ijọba Eko bere fun iranlọwọ wọn nitori apa awọn agbofinro ko ka iwọde naa mọ, kii ṣe Lekki nikan.
- Yinka TNT Arun BV yii kii fi bẹẹ ṣe eyi to le to bẹẹ ṣugbọn o dara ki eeyan ṣe itọju ara rẹ to ba ko o toripe o maa n dakun bi obinrin ṣe le tete ko awọn arun ibalopọ STD ati UTIs.
Aarẹ Buhari pada sọrọ pe ijọba oun ti fopin si awọn ọlọpaa kogberegbe SARS s\\ugbon ko tẹ awọn eeyan lọrun.
Eléyìí yóo sì dín owó tí ń wọ àpò ọba kù.
Oluranlowo aare lori eto to je
Iku Mọkaliki: Àgbáríjọ àwọn ajàfẹ́tọ̀ọ́ pè fún ìdádúró kọmísánà ọlọ́pàá Olùkọ́ fásitì gba ìdájọ́ iku 'torí pé ó sọ̀rọ̀ òdì sí Ànọ́bí lórí ayélujára Bàbá ọlọ́mọ méjì kú sínú àgbàrà òjò Ó sàn kí ẹ pa mí ju kí ẹ ba oko tí mo gbin igbó sí jẹ́ lọ- Afurasi Clement sí NDLEA E wo ọmọ Yorùbá àkọ́kọ́ tó jà fún ẹ̀tọ́ àwọn aláwọ̀dúdú ní America!
Èèyàn 2,040 làwọn agbésùnmọ̀mí ti pa ní Nàìjíríà lọ́dún yìí- Ìwádìí Ẹ wo àwọn ọ̀dọ́mọdé Naijiria tó ń ṣe bẹbẹ nínú isẹ́ aládaní nílé Àwọn agbébọn kọlu Kọmísánà fọ́rọ̀ ilẹ̀ àti ilégbèé ní Ọyọ, awakọ̀ dèrò ọ̀run Èwo nínú àwọn amóhùnmáwòrán yìí lẹ rántí?
Ọdun 2016 ni ijọba Buhari kede alekun owo epo, to si yi i pada kuro ni naira mẹtadinlaadọrun to wa tẹlẹ si naira marundinlaadọjọ.
Ṣùgbọ́n ìwádìí fihan pé ojúlówó òpópónà náà wà ni Rwanda.
Bí o ṣe lè fí òǹkà, ọ̀mọ̀ ìka tàbí ìkúùkù wọn oúnjẹ́ Mo kọ̀ láti gba ipò mínístà lásìkò yí- Oloyede Ọ̀dọ́kùnrin tó kọ́kọ́ ṣe ẹ̀rọ tó ń tu ìyẹ́ lára adìyẹ Oladejo Okediji àti ìgbé ayé ìtàn kíkọ rẹ̀ E jẹ ki a fi ami ohun kọ awọn ọmọ wa ki ede ati aṣa Yoruba ma lè parun.
Gẹgẹbi iroyin ti ṣe sọ, ọkunrin kan wọ ileefiweranṣẹ naa pẹlu owo beba ẹgbẹrun mẹwa (eyi ti yoo jọ nkan bii ẹgbẹrun meji abọ naira) o si n beere fun iyoku owo rẹ.
 UNESCO gba pe isokan ati alaafia seese ti awon eto inu redio ba bere si ni fon rere igbe aye alaafia ati ifarada ti o to ki awon akoroyin maa figba gbogbo fon rere.
Ṣugbọn o pada ku lẹyin wakati marun un lẹyin ti wọn ri.
Bakannaa ni ọgọrọ eeyan fi idunu wọn han loju opo twitter nibi ti wọn ti n ki D'Tigress ni mẹsan mẹwaa.
Kò fetí sí ọ̀rọ̀ Neko, tí Ọlọrun sọ, ó lọ bá Neko jà ní pẹ̀tẹ́lẹ̀ Megido.
Lasiko ti won n je ejo naa lojoRu ,ni agbejoro  agba fun ajo EFCC Rotimi Jacobs(SAN), tun wa so fun ile-ejo pe awon ti fi kun esun to wa nile ejo tele lati mọ́kàndínlógún si méjílélọ́gbọ̀n.
kí wọ́n dá a lóhùn pé, ẹran ọ̀sìn ni àwọn ti ń tọ́jú láti ìgbà èwe àwọn títí di ìsinsìnyìí, ati àwọn ati àwọn baba àwọn, kí ó lè jẹ́ kí wọ́n máa gbé ilẹ̀ Goṣeni, nítorí pé ìríra patapata ni gbogbo darandaran jẹ́ fún àwọn ará Ijipti.
 gẹgẹbi mo ti sọ ni ibẹrẹ iwe yi , o jẹ àṣà awọn ọdẹ lati ma ki ara wọn bi noẉn ba pejọ .
Progressive Congress APC ti ki aare Buhari ku ori ire fun aseyori eto idibo
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Mike Zhang dì ọmọ China akọkọ tí wọ́n f'oye dá lọla ní ìpínlẹ̀ Kano 25 Ìgbé 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 26 Ìgbé 2019 Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Báyìí ni ayẹyẹ wíwé láwàní fún ọmọ China, olóyè Zhang ṣe lọ A o ri iru eleyi ri, a fi dẹru ba ọlọrọ ni.
“Rán amí lọ wo ilẹ̀ Kenaani tí mo fún àwọn ọmọ Israẹli.
Lara awon ohun ti orile ede mejeeji naa yoo maa jiroro ni bi  ibasepo won yoo se tun tubo maa tesiwaju, okoowo,eko fun awon obinrin ati omidan ati nnkan miiran.
Gé àwọn ẹ̀ka rẹ̀ kúrò,nítorí pé wọn kì í ṣe ti OLUWA.
Èèyàn 189 ní àrùn Coronavirus tún ṣẹ̀ṣẹ̀ ràn ní Nàìjíríà Wo bí èsì ìdìbò ìpínlẹ̀ Edo ṣe ń jáde Wo àwọn orílẹ́-èdè mẹ́wàá tí kò ní coronavirus lágbàáyé, bá wo ni wọ́n ṣe ṣe é?
Oludamọran pataki fun aarẹ Muhammadu Buhari naa wa fikun pe ijọba aarẹ Buhari n lọ ni irọwọrọsẹ, ati wi pe oun sa ipa rẹ lati mu gbogbo ohun to ti bajẹ pada si ipo ni saa yii.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Trump Impeachment: Ààrẹ Trump n fẹ́ kí ilé aṣòfin gbọ́ ẹjọ́ rẹ̀ ní kíákíá 19 Ọ̀pẹ̀̀ 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 20 Ọ̀pẹ̀̀ 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Aarẹ orilẹ Amẹrika ti wọn yọ nipo, Donald Trump ti sọ pe oun fẹ ki ile aṣofin agba orilẹ-ede naa ṣe igbẹjọ oun ni kiakia.
Oríṣun àwòrán, William Smith/Instagram Àkọlé àwòrán, Fidio kan ṣe afihan ibi ti afẹsunkan naa ti n jo lẹyin to pa ọga rẹ.
Wọ́n dá a lóhùn pé, “Gba Jesu Oluwa gbọ́, ìwọ ati ìdílé rẹ yóo sì là.
Fẹ ààyè àgọ́ rẹ sẹ́yìn,sì jẹ́ kí aṣọ tí ó ta sórí ibùgbé rẹ gbòòrò sí i, má ṣẹ́wọ́ kù.
Gomina Ajimobi jẹ gomina nipinlẹ Oyo laarin ọdun 2007 si ọdun 2019, ko to di wi pe wọn yan si ipọ alaga ẹgbẹ oṣelu APC ko to jade laye.
Idamewa kii se dandan - Pasitọ Tunde Bakare Akẹkọ 76 bọ lọwọ awọn ajinigbe ni Yob Ta gan an lo pasẹ ki wọn ta awọn dukia wọnyii?"
tabi ti arabinrin rẹ̀ tí kò tíì mọ ọkunrin, (tí ń gbé ọ̀dọ̀ rẹ̀, nítorí pé kò tíì ní ọkọ, nítorí tirẹ̀, alufaa náà lè sọ ara rẹ̀ di aláìmọ́).
Ènìyàn 653 míràn tún kún iye àwọn tó ní COVID-19 ní Nàìjíríà Ọlọ́paàá ní wọ́n ṣèèṣì yìnbọn pa ọmọ mi tó ń tọ́ ọmọ oṣù mẹ́rin lọ́wọ́ ni- Ìyá Kager Àwọn àádọ́ta ọ̀dọ́ wọ gàù nítorí ilé ijó ní Ilorin Báwó ni òògùn dexamethasone ṣe ń ṣiṣẹ́ lára Baba ọlọfa ina tumọ owe yii ni kikun pe owe ikilọ iwa ni.
Umahi tun ni  “Bi eto idibo
Wàyí, ẹnìkan lè sọ fún mi pé, “Tí ó bá rí bẹ́ẹ̀, kí ló dé tí Ọlọrun fi ń bá eniyan wí?
com/lWv97URs72Aare lo si ojule  kewaa ,(Number 10 )leyin ijiroro pelu alakoso ijoba orile ede Britain , May.
4 90603 Agbegbe Palestine 828 17.
AIG Adeleye Olusola Oyebade, mni - AIG Zone 11, Osogbo xv.
Bí kò bá jẹ́ pé Ọlọrun baba mi wà pẹlu mi, àní, Ọlọrun Abrahamu, Ọlọrun tí Isaaki ń sìn tìbẹ̀rùtìbẹ̀rù, láìsí àní àní, ìwọ ìbá ti lé mi lọ lọ́wọ́ òfo kó tó di àkókò yìí.
Aare tun so pe “Gege bi okan pataki lara awon adari egbe oselu to wa lorile ede Naijiria oloogbe Anenih gbe igbe aye re gege bi olufokansin, o tun je alaga fun  egbe oselu National Party of Nigeria (NPN),teleri ati alaga fun egbe oselu ,Social Democratic Party (SDP), ati okan lara igbimo egbe oselu PDP, ati minisita fun oro ise  akanse lorile ede Naijiria teleri.
"Orukọ ti wọn n jẹ ni ilu Ibadan ni orukọ mi, ""ọmọ Ibadan ni mi""."
Ounjẹ bi irẹsi, iṣu, ẹran adiẹ tutu ati ohun elo ọbẹ bi timọti lo ti gbowo lori bayii.
Ó kó ọpọlọpọ idẹ ní Tibihati ati Kuni, tí wọ́n wà lábẹ́ Hadadeseri.
Akẹ́kọ̀ọ́ méjì tó há sí Bosnia ti gúnlẹ̀ padà sí Nàìjíríà Kò sí ìjà láàrín èmi àti gómìnà Ọ̀ṣun - Aregbesola Wo bí àwọn obìnrin kan ṣe n sọ ara wọn di 'fágìn' lẹ́ẹ̀kejì Ẹ má gbàbọ̀de kankan láti tú Wolii ìjọ Sotitobire sílẹ̀ o!
Orin yii n wọle lẹyin ọjọ diẹ to ṣe akọsilẹ ohun ti oju ẹbi rẹ ri ati ọna ti o n gba wẹ ọgbẹ ajalu iku ọmọ rẹ ninu atẹjade kan to fi sita lori ikanni instagram rẹ.
"Ninu ọrọ kan to kọ lori ikanni twitter rẹ, Omokri ni: ""N3."
 wọ ́ n pinu láti gbógun ti ilẹ ̀ serbia .
Lara awọn to fun un lesi bu ẹnu atẹ lu u pe ohun to pọn dandan ni lati ṣe ayẹwo ni papakọ ofurufu ati wi pe ko nii ṣe pẹlu ipo ti eniyan di mu lawujọ.
Olubadan: Àláfíà ni mò ń wá ní ìpínlẹ̀ Ọyọ
 O wa fi asiko ohun rawo ebe si ijoba apapo lati gba awon eniyan si ise olopaa, ki o si pese ohun elo amuseya lọlọkan-o-jọkan.
Sani yán aṣọ àti bata sọnù pẹlu ọ̀bẹ nibi to ti ń sá lọ.
Gbogbo wọn wò wọ́n, olukuluku àwọn olórí sì mú ọ̀pá tirẹ̀.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Buhari wa ẹnu si àwọn ọdọ Nàìjíríà Barbara Bush jáde láyé INEC dá òsìsẹ́ lẹ́kọ̀ọ́ láti yọ Melaye Àwọn ọmọ Nàíjíríà kò kà mìí kún mọ́ - IBB Ti a ko ba gbagbe, ni ọdun 2016, adajọ agba ti ileẹjo giga to kalẹ si Ekiti pasẹ ki ajo EFCC o gbẹsẹ kuro lori apo asuwọn rẹ mejeeji, lẹyin ti ajọ naa fẹsun kan gomina naa lori owo ribiti to wa ninu apo isuna rẹ.
OLUWA ní òun kò rán wọn níṣẹ́.
Bẹẹ bá sì gbàgbé, irufẹ ìgbésẹ yìí náà tí ń lọ ní orílẹ̀-èdè Nàìjíríà, tí gómìnà Ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́, onímọ̀ ẹ̀rọ Seyi Makinde sì kéde laipẹ yìí pé, òun ti setan láti fi ẹ̀jẹ̀ òun silẹ fún ìwádìí to yẹ.
"Ọ̀dọ́mọkùnrin náà sàlàyé pé òun gbé ìgbésẹ̀ náà lẹ́yìn ti àwọn òbí òun gbà òun nímọ̀ràn láti gbìyànjú rẹ̀ wò gẹ́gẹ́ bi o ṣe sọ nínú fídíò náà': ""Orúkọ mi ni Angel Gomes, mó wá láti Manchester, ọmọ ọdun mẹ́rìndílógún ni mi."
Bẹnaya bá lọ sinu Àgọ́ OLUWA, ó wí fún Joabu pé, “Ọba pàṣẹ pé kí o jáde.
Jẹ́ kí àwọn tí ó bẹ̀rù rẹ tọ̀ mí wá,kí wọ́n lè mọ òfin rẹ.
Agbẹnusọ fun ẹkun ijọba ni Somalia, Salah Hassan Omar sọ fun BBC pé aigbọraẹniye to lo ṣẹlẹ ati pe oko kan naa ni awọn mejeji jọ n ro fun idagbasoke Somalia ni.
Ẹ wá gbọ bí òwe Yoruba ṣe dùn lẹnu ọmọ Igbo
Nítorí pé Ọlọrun sọ ọ́ di ẹni ńlá, gbogbo eniyan, gbogbo orílẹ̀-èdè ati gbogbo ẹ̀yà ń tẹríba fún un tìbẹ̀rùtìbẹ̀rù.
Ṣàánú mi, OLUWA, nítorí pé mo wà ninu ìṣòro.
Àmọ́ pẹ̀lú ìdásílẹ̀ tí wọ́n dá wọn sílẹ̀, ipò yẹpẹrẹ ni òmìnira ọ̀rọ̀ sísọ ní ìlú náà nítorí wípé ìtìmọ́lé àti ìfìyàjẹ àwọn akọrin, akọ̀ròyìn, àti ajìjàǹgbara ṣì wà síbẹ̀ sẹpẹ́.
Báwo ni ìjọba rẹ̀ ṣe lè dúró?
Okechukwu soro yii nibi ajodun ayeye agbaye fun awon omo Igbo, ni eyi to waye ni Nashville, Tennessee lorile ede United States.
Opọlọpọ lo maa n gbe ọkọ soju titi lojoojumọ ni eyi to tun n ṣafikun si iṣoro yii.
Bákàrè Olóye méjì lẹ́ẹ̀kan ṣoṣo àti Onìbọnòjé àtàri àjànàkù tí kì í ṣẹrù ọmọdé.
Bi awọn kan ti ṣe n ki pe ko ni asọkal ayọ lawọn kan n faraya pe aarẹ Buhari fi ina si ori orule lawọn ipinlẹ bi Zamfara.
Nítorí Ọlọrun kan náà ni Oluwa gbogbo wọn, ọlá rẹ̀ sì pọ̀ tó fún gbogbo àwọn tí ó bá ń ké pè é.
A óo ṣe àwọn nǹkan ọ̀ṣọ́ wúrà,tí a fi fadaka ṣe ọnà sí lára fún ọ.
Imaamu ti gbogbo ilu pata wa, nigbati Imaamu adugbo kekere naa wa pẹlu.
Nínú àbádofin náà àbẹnugan ile to fẹ̀yìnti yóò maa gba ẹgbẹ̀rún lọ́nà ẹ̀ẹ́dẹ́gbẹ̀ta náírà lósù, nígbà ti ìgbákeji rẹ̀ yòó maa gba ẹgbẹ̀rún lánà agba ti gbogbo ọmọ ilé tokù yóò si máa gba ẹgbẹ́rùn lọ́nà ọgọ́run kan náírà.
Adari agba fun illeeṣẹ naa, ọgbẹni Adesina Tiamiyu ninu atẹjade kan salaye wipe ijamba yi waye ni itosi ile igbafẹ Oriental.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ilé ẹjọ́ gba onídúró Sẹ́nétọ̀ Ademọla Adeleke Èmi ṣì ni Gómìnà ìpínlẹ̀ Ọṣun-Oyetọla APC, PDP di ẹgbẹ́ aládúrà nítorí ìdájọ́ èsì ìdìbò Ọṣun Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Ẹni to bori: Nigeria Ghana vs Mali.
” Kò sí ọ̀kan ninu àwọn ọmọ-ẹ̀yìn tí ó bi í pé, “Ta ni ọ́?
"Òyìnbó sísọ di èèwọ̀ ní ìpínlẹ̀ Ekiti Falana àtàwọn míì péjú síbi àpérò #RevolutionNow l'Eko 'El-Zakzaky lè má láńfààní láti lọ gba ìtọ́jú mọ́ lókè òkun' Fayemi fojú Alufa to fipa bá ọmọde lòpọ̀ síta l'Ekiti Ariwo ""Allahu Akbar"" kò tọ́ sawọn Agbébọn àti Boko Haram - Buhari Ike Ekweremadu, igbákejì ààrẹ ilé aṣòfin àgbà tẹ́lẹ́ rí èèmọ̀ he nilùú Germany!"
Ọmọ ọdun mẹtala kan naa wa lara wọn.
Ile iwe awọn akẹkọbinrin ti agbegbe Sarkin-Noma ni Lokoja atile iwe alakọbẹrẹ ti LGEA ni Lokogoma ni wọn bajẹ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Community Shield: Man City fọ́ Liverpool lẹ́nu bẹ̀rẹ̀ sáà bọ́ọ̀lù tuntun ní Wembley 4 Ògún 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Ajura wa lọ tijankandi kọ o!
Oríṣun àwòrán, Instagram/florenceajimobi Ẹni ọdun aadọrin ọdun ni Ajimobi nigba to ki aye pe o digba o se.
kí ìmọ́lẹ̀ lè tàn sí gbogbo ayé,kí ó sì lè gbọn àwọn ẹni ibi dànù,kúrò ní ibi ìsápamọ́sí wọn?
Akiolu to sọrọ nibi ayẹyẹ ẹlẹẹkẹtadinlogun ‘Lagos Housing Fair’ sọ wipe, fifun Aarẹ Buhari ni saa keji yoo mu igbugbooro ba ọrọ ajẹ orilẹede Naijiria.
Ewe, ami-ayo kinni waye lataari asise agbaboolu eyin Marseille Andre-Frank Zambo Anguissa, eleyi ti balogun iko Madrid, Gabi  ja gba ki o to se iranwo ami-ayo ohun fun Griezmann niseju mokanlelogun saa akoko ifesewonse naa.
F Odunjo kọ iwe Ọmọ oku ọrun, to si kọ iwe Kuyẹ lọdun 1978 J.
Eyi ni awọn ohun marun to lamilaaka nipa Baba Sala Ọjọ Kẹtadinlogun, Osu Karun, ọdun 1937 ni wọn bi Alagba Moses Ọlaiya Adejumọ ti gbogbo eniyan mọ si Baba Sala.
O fikun pe ko si ọmọ ologun kankan to wa nibi isẹlẹ naa.
Ẹ̀yin eniyan Israẹli, ẹ má ṣe bá OLUWA Ọlọrun àwọn baba yín jà, nítorí ẹ kò ní borí.
Ẹ̀yin ilé kan tí won kò tíì pari ni wọ́n pa wọ́n sí.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Wilfred Ndidi: Mi ò fi dáa yín lójú pé a máà bórí o!
Alakoso ile-ise ibanisoro, Mater Dei Communication Centre, ajiyinrere Nnamdi Okpara so pe, o sepataki lati mu eto ilana nipa ise, paapaa julo lenu ise ijoba lokun-kundun.
Awọn iroyin miran ti ẹ le nifẹ si: Ibeere mẹfa lori ijinigbe Dapchi Ọwọ ologun tẹ darandaran mẹwa ni Benue Wahala Kaduna: Ọwọ ọlọpaa tẹ eeyan mẹwa Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Gege bi ile-ise akoroyin Corriere dello, won ni, bi o ti le je pe, omo odun méjídínlọ́gọ́ta  ohun fi ojo meji ronu lati so ipnnu re, sugbon ibi pelebe naa loro ohun jasi.
Nígbà náà ni ọrùn èmi, ati arọmọdọmọ Dafidi yóo tó mọ́ kúrò ninu ohun tí Joabu ṣe nígbà tí ó pa àwọn aláìṣẹ̀.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Rape: Oluwaseun Osowobi ní Commonwealth fún lámì ẹ̀yẹ ọ̀dọ́ tó pegedé jùlọ ní 2018 Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Rape: Oluwaseun Osowobi ní Commonwealth fún lámì ẹ̀yẹ ọ̀dọ́ tó pegedé jùlọ ní 2018 26 Ẹrẹ̀nà 2019 Iwa ifipabanilopọ ti di tọrọ fọn kale lawujọ wa, ti ọpọ ọdọbinrin si n lugbadi aṣa buruku yii, Ọkan lara wọn ni Oluwaseun Osowọbi,ẹni ti wọn fi tipa ba lopọ, amọ ti ko fi se ohun itiju to lee pa mọra.
Èyí jẹ́ iṣẹ́ Oluwa tí í ṣe Ẹ̀mí.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Nigeria Election 2019: Ará Eko pariwo ohun márùn-ún tí wọn ń fẹ́ lọ́wọ́ ìjọba tó ń bọ̀ Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Àwọn ẹ̀ka rẹ̀ tóbi, wọ́n sì gùn,nítorí ọpọlọpọ omi tí ó ń rí.
Ṣeyi Makinde fòfin de ẹgbẹ́ NURTW Ọyọ, ó gbàkóso gáréjì ọkọ̀ Ohun tó wù kí ileẹjọ́ kòtẹ́milọ́rùn sọ, Adeleke kò lè di gómínà Ọ́ṣun - APC Ilé ẹjọ́ gba onídúró Naira Marley pẹ̀lú mílíọ́nù méjì náírà Wo àwọn ìlérí tàwọn Gómìnà tuntun ṣe nínú ìbúra wọn 3.
Ranti majẹmu tí o bá wa dá,ranti, má sì ṣe dà á.
Ọpọlọpọ awọnalatako rẹ lo n se akawe rẹ gẹgẹbi ẹni to lo anfani rẹ pẹlu oselu lati fi gbe ileesẹ isowoo rẹ soke.
Kò séwu nínú ìdìbò tó ń bọ̀ l'Ondo àfi gìrì àparò- Akeredolu Àwọn ǹkan tí ó yẹ kí o mọ̀ nípa 'Sharia Law' ní Nàìjíríà Ọwọ́ ọlọ́pàá ìpínlẹ̀ Kebbi tẹ bàbá àti ìyàwó rẹ̀ méjì fún pé wọn so ọmọ pọ̀ mọ́ ewúrẹ́ fún ọdún méjì Ojọgbọn Feyi ṣalaye siwaju sii pe awọ ''brown'' lo wọpọ ju lorilẹ-ede Naijiria nigba ti ọpọ eeyan ni awọ buluu loju wọn nilẹ Yuroopu.
"Dino, èyí o ṣe yìí kù díẹ̀ káàtó"" Dino Melaye bẹnu àtẹ lù Buhari Miliọnu mọkanlelogun Nairia ni awọn oludije to fẹ du ipo Gomina labẹ asia ẹgbẹ naa n san lati gba fọọmu ọhun."
Orile-ede Gambia tun ti dara po mo ajo awon orile-ede alajo sowo po ti a mo si commonwealth, leyin odun marun-un ti won ti fi ajo naa sile.
Igba karun niyii ti wọn n fi ẹsun kan ikọ Amọtẹkun ni ipinlẹ Ọyọ wi pe wọn n yinbọn pa araalu lati igba ti wọn ti bere iṣẹ nipinlẹ naa.
Ẹwẹ, igbakeji gomina ipinlẹ Ondo Ọgbẹni Agboola Ajayi ti ranṣẹ ikẹdun si ẹbi agunbanirọ to ba iṣẹlẹ naa lọ.
62 fawọn to jẹ igbakeji gomina tẹlẹri.
N óo run gbogbo àwọn orílẹ̀-èdè tí mo le yín lọ,ṣugbọn n kò ní pa yín run.
Láìpẹ́ yìí ni ìròyìn kàn pé ìgbìmọ̀ ẹgbẹ́ òṣèlú All Progressive Congress (APC) tó ń ṣe àyẹ̀wò àwọn olùdíje lábẹ́ ẹgbẹ́ náà sọ pé Segun Abraham ni kò kójó òṣùwọ̀n tó nínú àwọn tó ń díje nítori náà ni wan ṣe yọ.
3 Àti pé èmi ti mú kí ìwọ, pé o nílati wọ inú majẹ̀mú pẹ̀lú mi, pé ìwọ kì yíò fi hàn wọ́n bíkòṣe sí àwọn ènìyàn wọ̃nnì tí èmi ti pàṣẹ fún ọ; ìwọ kò sì ní agbára lórí wọn àyàfi bí mo bá fi í fún ọ.
Aare Muhammadu Buhari yoo lo sabewo siko omo ogun ti o farapa lasiko ikolu pelu iko omo ogun olote boko haram, niluu Maiduguri, nipinle Borno.
Lẹyin to bimọ tan, Alyona ni aarun otutu aya, eyi to ko si ninu ọpọlọ, ti iwa rẹ ko si fii bẹẹ jọ ti eeyan ti ọpọlọ rẹ pe.
Oyedele ti gbogbo eeyan mọ si doks_art lẹnu iṣẹ rẹ lo fi kalamu ya aworan aarẹ Trump to wa kede lori ayelujara pe oun fẹ ki awọn eeyan ba oun pin in titi Trump a fi rii.
Pẹlu bi ọrọ ṣe jẹ yii, rukerudo ati edeaiyede lo ti n waye lori pe ta gan an wa ni Babalọja tootọ ni ipinlẹ Ọyọ o?
Bakan naa ni eto ilera lagbaye, WHO ti kesi awọn ijọba kaakiri agbaye lati gbaradi fun pajawiri arun naa kaakiri agbaye.
“Nígbà tí ẹ bá dé ilẹ̀ náà, tí ẹ bá sì gbin oríṣìíríṣìí igi eléso fún jíjẹ, ẹ ka gbogbo èso tí wọ́n bá so fún ọdún mẹta ti àkọ́kọ́ sí aláìmọ́; èèwọ̀ ni, ẹ kò gbọdọ̀ jẹ ẹ́.
"Oríṣun àwòrán, Amotekun "" A mú àwọn olè méjì ní ọjọ́ Àbámẹ́ta, ní ǹkan bi aago méjì lágbègbè Inálende nílùú Ibadan, lẹ́yìn àyẹ̀wò, a ri ìbọn ibílẹ̀ gba lọwọ wọn."
Ilẹ̀ Amẹ́ríkà wà lẹ́yìn àwọn olùwọ́de, Buhari dẹ́kun ìpànìyàn - Joe Biden Buhari, máṣe gbá ìpànìyàn Lekki sórí ààtàn, kò yẹ́ kí ológun yin ọ̀dọ́ níbọn - Bode George Wo ohun tí Fashola rí níbi ìṣẹ̀lẹ̀ Lekki Tollgate tó ń fa ariwo lórí ayélujara Taa gan ló ni Lekki Toll gate láàrin aráàlú àti Asiwaju Tinubu?
Dafidi pa ẹẹdẹgbaarin (7,000) àwọn tí wọn ń wa kẹ̀kẹ́-ogun ati ọ̀kẹ́ meji (40,000) ọmọ ogun ẹlẹ́sẹ̀, ó sì pa Ṣobaki olórí ogun Siria.
O ni bi o tilẹ jẹ pe oloogbe naa kii ṣe ọmọ ẹgbẹ oṣere TAMPAN nigba aye rẹ, to jẹ wi pe ọmọ ẹgbẹ ANTP ni, sibẹ o sunmọ gbogbo awọn oṣere.
Ni ipari, Abari ni ipinle Kwara ni alaafia, O gboriyin fun ajo NOA tipinle ohun pe won n sise gidi ki o to fun igbakeji gomina naa ni Asia Naijiria.
Lafikun, ileẹjọ ni awn oniduro mejeeji yoo san miliọnu kọọkan naira wọn si gbudọ jẹ ọmọ Naijiria to n san owo ori deede.
Lẹyin ti o ba ti danloodu rẹ tan, lọ si ọwọ isalẹ rẹ̀, ki o tẹ 'Skip', lẹyin naa, tẹ 'Begin'.
júpítérì je kiki elo elefuufu ati olomi .
Àǹkóò àrùn coronavirus dé orílẹ̀èdè Togo Coronavirus: Italy sọ àgádágodo sí ilé ẹ̀kọ́ alákọ̀ọ́bẹ̀rẹ̀ àti girama Èyí ni àwọn nkan tó yẹ kí o mọ̀ nípa ọmọ Italy tó kó Coronavirus wọ Eko Ayẹyẹ igbeyawo ati isinku naa ko ni waye lasiko idejumọle yi.
Tabi ẹ kò ní olùdámọ̀ràn mọ́, ni ìrora fi mu yín bí obinrin tí ń rọbí?
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ọ̀lẹ nìkan lààyè kó gbà.
AFCON 2019: Àwọn orílẹ̀èdè tó ń ṣe bẹbẹ nínú ìdíje tó ń lọ ni Egypt
Lílé sókè àwọn ihò náà ni afọ́jú nfi ọwọ́ kàn lójú ewé ìwé náà.
Ẹni tí ó bá ní òye ni ó lè mọ ìtumọ̀ àmì orúkọ ẹranko náà, nítorí pé bí orúkọ eniyan kan gan-an ni àmì yìí rí.
"Ki ẹnikẹni ninu awọn oludije memeji to lee pegede ninu idibo ọhun, o ni lati rekọja ibo 270 ti awọn ""electoral college"" yoo di."
Wọn kò ní ṣe eniyan ní jamba mọ́,tabi kí wọ́n bu eniyan jẹ ní gbogbo orí òkè mímọ́ mi.
Ṣé ẹ mọ̀n pé èmí kinni yìí agbédè-gbẹ́yọ̀ ni mí.
Nkan tí ó jẹ́ ìyàlẹ́ nu ní pé gbogbo oko tí ènìà nkọjá ni kò ní pàdé àgbẹ̀ àbí onílẹ̀ kakan rárá.
"Yala ki wọ́n sun ọjọ igbeyawo wọn siwaju ṣugbọn ọpọ ni inu wọn ko dun lati sun ọjọ ayọ wọn siwaju""."
Fiimu yii ni akọkọ fiimu ologun ti yoo pa ju biliọnu meji dọla owo ilẹ Amẹrika lagbaye.
Aṣekagba ọdun 2008 naa waye laarin ikọ Manchester United ati Chelsea, o si pari pẹlu ọ̀mì (àmi ayo kan si ọkan) ki wọn to lọ abala wòmí-n-gba-sí-ọ (penalties).
Yatọ si pe o parọ orukọ rẹ, o tun parọ ọjọ ori rẹ.
"Ere ni, awada ni, Ẹmiọla ṣe alaye wi pe ọrọ to jade lẹnu awọn ikọ ologun naa ni pe, ""Kaabọ si ibi ti a ti n fa ori fun awọn ọmọ alaigbọran""."
Ewe, iwe pelebe iworan fun ifesewonse ti yoo waye laarin England ati Nigeria ti wa loja fun tita bayii, ti iye re je pounds márùndínlógójì owo ile okere.
Aisha Buhari: Ìpínlẹ̀ Kano kò rí ànfàní ètò ìjọ̀ba Buhari jẹ.
Lizzy Anjorin sun ẹkún ìyàwó, èèyàn kan fún un lẹ́bùn aṣọ funfun láti mọ ìbálé rẹ̀ Ilumọọka oṣere fiimu Yoruba ati ontaja ni Lizzy Anjorin lo ṣe da bii pe gbogbo igba lọrọ rẹ n jade lori iroyin.
Gbogbo ayé, ẹ hó ìhó ayọ̀ sí OLUWA;ẹ bú sí orin ayọ̀, kí ẹ sì kọ orin ìyìn.
Oríṣun àwòrán, Archivo Fotografía Urbana / Proyecto Helicoide Àkọlé àwòrán, This space-age building was carved into the rock with ramps spiralling up past 300 planned boutiques Ibi Ibẹru Fun ọplọpọ ọdun, tandi ni ile naa duro soju kan ti ọpọlọpọ igbiyanju lati mu u pada bọ sipo si n ja si pabo.
Lẹ́yìn náà, alufaa yóo bu ẹ̀kúnwọ́ kan ninu ẹbọ ohun jíjẹ náà fún ẹbọ ìrántí, yóo sì sun ún lórí pẹpẹ; lẹ́yìn náà, yóo ní kí obinrin náà mu omi yìí.
Ọọ̀ni: Ìpèníjà ààbò di ìràwọ̀ ọ̀sán tó ń ba àwa àgbà lẹ́rù
 o tun yipada orukọ rẹ si adebisi alimi .
Wọn o ti sọ fun wa'' Bakanna ni ọkan lara awọn ọmọ ile asofin nipinlẹ Ekiti ti ni ara ohun ti Coronavirus da silẹ ni ijingbe yi jẹ nitori ohun ni ko jẹ ki wọn se ifilọlẹ ikọ alaabo Amọtẹkun lasiko.
Ọmọbinrin naa la gbọ pe ọdun yii ni wọn gba a wọle si Fasiti ilu Benin, lati kẹ́kọ̀ọ́ nipa imọ nípa kokoro aifojuri, Micro Biology.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Èré Ọṣun: Àtáója ní wọn kò jí ère Ọṣun, ó sì wà níbi tó wà Nigba to n tẹwọ gba ọmọ rẹ, baba Aisha, fo fayọ, to si n dupẹ lọwọ Ọlọrun ati ileesẹ ọlọpa fun isẹ takuntakun ti wọn se lati se awari ọmọ oun nitori oun ti sọ ireti nu lori rẹ tẹlẹ.
Nígbà tí OLUWA Ọlọrun yín bá bukun yín tán, tí ibi tí ó yàn pé kí ẹ ti máa sin òun bá jìnnà jù fun yín láti ru ìdámẹ́wàá ìkórè oko yín lọ, 
Wo ẹ̀kọ́ mẹ́rin tí Naijiria kùnà láti kọ́ lára ogun abẹ́lé Ọlọ́pàá kò fẹ́ yìnbọn, kó má ba à ba aráàlú, l‘àwọn afurasí olóògùn olóró ba sá mọ́ wọn lọ́wọ́ Mo ti ní ìyàwó àfẹ́sọ́nà, ayẹyẹ ìgbeyàwó mi ń bọ̀ láìpẹ́ - Lateef Adedimeji Ọ̀dọ́mọdé ẹni ọdún 38 ń figagbága pẹ̀lù bàbá ẹni ọdún 76 nínú ìbò Ààrẹ Uganda tó ń lọ lọ́wọ́ Ọjọ̀gbọ́n náà ní ìdí tí ọ̀pọ̀ fi má a ń sá lọ si òkè okun fún ìtọ́ju àti àwọn iṣk abẹ́ báyìí ni pé ọ̀pọ̀ àwọn irinṣẹ tó wà ni Nàìjíríà ló ti gbó.
Nítorí náà ẹ pa gbogbo àwọn ọdọmọkunrin wọn, ati àwọn obinrin tí wọn ti mọ ọkunrin.
 tọ ́ pẹ ́ Àlàbí gba ìwé ẹ ̀ rí ìwé mẹ ́ wàá ( west african examination conncil waec ) ní ilé ẹ ̀ kọ ́ Ọba akínyẹlé memorial high school , Ìbàdàn ní ọdún 1986 .
O ni awon ibi meta kan wa ti eto
Nínú ọ̀rọ̀ rẹ̀ sí BBC , Ifasuyi ní kò sí ǹkan ti yóò ṣẹlẹ̀ ti eégún òun kò bá jáde nítorí gbogbo etùtù tó yẹ ni àwọ́n ti ṣe nígbàlẹ̀, bákan náà ni eégún ọ̀hún kò ni kọ́ja agboolé.
Mo pa á láṣẹ fún àwọn ọlọ́rọ̀ ayé yìí, pé kí wọ́n má ṣe ní ọkàn gíga.
Ko tan sibẹ o, Badirat ni oun ko ranti iye olori to wa ni aafin tabi ipo ti oun wa.
Arakunrin naa ati awọn ẹlomii lo faa le ọlọpaa lọwọ.
Ni mo bá búra pẹlu ibinu,pé wọn kò ní dé ibi ìsinmi mi.
Ó mú wọn jáde, ó ní, “Ẹ̀yin alàgbà, kí ni ó yẹ kí n ṣe kí n lè là?
Awọn iroyin ti ẹ lee nifẹẹ si: Ọlọpa yoo pada maa sọ awọn eekan ilu 'A o s'awari akẹkọ Dapchi to sẹku' Ibrahimovic dagbere fun Man Utd Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Òṣùnwọ̀n wa kò tayọ ààlà tí Ọlọrun ti pa sílẹ̀ fún wa, tí a fi mú ìyìn rere dé ọ̀dọ̀ yín.
Agbẹnusọ fun ajọ naa, Fabian Benjamin sọrọ yi fun awọn akọroyin ninu atẹjade ti o tẹ awọn oniroyin lọwọ.
Ṣé ẹ̀mí ilé aṣòfin lè gbé ṣíṣe ìwádìí 16 bn owó àgbàṣe iná ọba Nàìjíríà?
O ni idi abajọ naa ni wi pe awọn eeyan ko tu yaya jade ra ẹran bii ti ọdun Ileya to lọ.
O fí kún pé ààbo àrá ìlú ló yẹ ko ṣe pàtàkì sí ààrẹ, kìí ṣe àwọn irú ọ̀rọ̀ tó ń tẹnu ààrẹ jáde.
Oríṣun àwòrán, CAF Àkọlé àwòrán, Eleyi to jẹ ki Algeria fi Naijiria ṣatẹgun si ipele aṣekagba pẹlu ami ayo meji sẹyọ kan.
Agbábọ́ọ̀lù Super Falcons tẹ́lẹ̀, Chiejine jáde láyé lẹ́ni ọdún 36 Kò sí àṣà tó faramọ́ fífi èmí ènìyàn ṣe ìrúbọ - Olúwó Igbagbọ awọn to ṣeto idibo ọhun ni pé àárẹ̀ to ń mú ìràn Yorùbá yoo dopin lasiko olori tuntun yii pẹlu ìgbà ọtún to ti dé.
Fọnran fidio yi to gbode kan loju opo ayelujara ti ileeṣẹ iroyin Channels TV gbe sita ṣafihan Dokita Saka Haruna to bu sẹkun nigba to n ba awọn akọroyin sọrọ.
Igbimọ naa ni yoo jiroro lati mọ ọna ti awọn gomina le gbe ọrọ owo oṣu oṣiṣẹ gba, paapa ọgbọn ẹgbẹrun Naira ti wọn n beere fun gẹgẹ bi owo oṣu oṣiṣẹ to kere ju.
Gbogbo Ivory Coast lo duro gẹgẹ y ọkan ti iṣẹlẹ yí sì tún so gbogbo ilẹ náà papo gege bí ọkan.
Ewe ni wọn rọra fi d'ọgbọn sọrọ ara wọn.
 Nibi idije kan ni ila oorun Cape, ni Mthatha ni won ti korin naa lose to koja ti fonran fidio n safihan oyan ati idi awon omo naa gi Times live se so.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Wo ohun tó ṣẹlẹ̀ nilẹ̀ Adulawọ lọṣẹ tó lọ 1 Ìgbé 2019 A ni ki a fi eleyi ṣe moriwu fun yin nibẹrẹ oṣu tuntun ki a si ma gbagbe awọn ohun to ṣẹlẹ lọsẹ to pari oṣu ti a lo tan.
Bakan náà ni ọkọ̀ ofurufu meji ti yóò máa sàmójútó ààbò àti ìgbòkègbodò APC, ọkọ̀ ìjà mẹ́wàá, àti àwọn ọkọ̀ míìràn fun àṣeyori Lẹ́ka ààbò, ọgọ́run mẹ́tà dín ládọ̀ọ̀ta ni o ti wà ni sẹpẹ́ fún ìgboro Ekiti àti àwọn agbegbe tó dàbí ẹni pe ó nira.
Èéfín ṣẹ́ jáde láti ihò imú rẹ̀,iná ajónirun yọ jáde láti ẹnu rẹ̀;ẹ̀yinná sì ń jò bùlà láti ọ̀dọ̀ rẹ̀ wá.
Ozor Àkọlé àwòrán, Wàhálà ti wáyé lórí ọ̀rọ̀ ẹ̀kúnwó oṣù tuntun fún òṣìsẹ́ láàárín ìjọba àti àwọn adarí òṣìṣẹ́ Idibo gbogboogbo to waye wa lara awọn ohun ti mu ifasẹyin ba aba naa ti ko si daju pe bi awọn aṣofin ti ṣe n palẹmọ lati pada sile wọn yoo ribi joko yẹ aba naa wo mọ.
 Bolgo ro ijoba lati mojuto ipese ina monamona to je orisun isoro awon amunidara ni Naijiria bayii.
"Opin ni lati de si aṣa gbigbe owo ina ti araalu ko lo wa ka wọn mọle fun sisan.
“Nígbà tí mo pè wọ́n, wọn kò gbọ́, nítorí náà ni n kò fi ní fetí sí wọn nígbà tí wọ́n bá ké pè mí.
Ní bayìí ibẹru bojo ní àwọn ènìyàn Rwanda wá nítori ìlú Goma pààlà pẹlú Rwanda ti àwọn ènìyàn sì tí ń rò ó pé àisàn náà le tan ju bó ṣe yẹ lọ.
Ọdún 1958 ni wọn dá ọkọ̀ òfurufú Nigeria Airways silẹ̀ ṣugbọn o ko 'gba si ile lọdun 2013.
Olókìkí ni wọ́n láàrin àwọn òjíṣẹ́ Kristi, wọ́n sì ti di onigbagbọ ṣiwaju mi.
 pelu egbe oloselu democratic party , o lo igba mefa ni ile awon asoju orile-ede amerika lati 1993 de 1997 , 1997 de 2003 ati lati 2003 de 2005 .
N kò gbọdọ̀ fọwọ́ mi kàn án, nítorí ẹni àmì òróró OLUWA ni.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Funmi Adewara: Tele Medicine' ní a fi ń ṣàyẹ̀wò èèyàn ìdá ọgọtá láti dènà ìtànkálẹ̀ Covid Ki lo ti ṣelẹ sẹyin?
N óo fún gbogbo àwọn ọba ilẹ̀ Simiri mu, ati gbogbo àwọn ọba ilẹ̀ Elamu ati gbogbo àwọn ti ilẹ̀ Media; 
Aare so pe “Ti inu awon eniyan ko  ba dun si orile ede yii, Ẹ jẹ ki won lo si orile ede miiran , lati mo ohun ti o n sele nibe sugbon awa yoo duro ni orile ede yii lati jo se awon atunse to monyan lori .
Ọ̀kẹ́ mẹta ó lé ẹgbẹrun (61,000) kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́.
Gbogbo awọn kan wọn yii ni ko jẹ ki a le sọ boya Kristẹni ni Hushpuppi tabi Musulumi.
Iru ipa wo ni iroyin yii ni?
 Àwọn èdè mìíràn tí wọ ́ n tún ń sọ ní orílè-èdè yìí lé ní ogún .
Oṣiṣẹbirin ọkọ ofurufu jabọ latinu baalu Ijamba ọkọ-ofurufu ologun pa 'yan mẹjọ Ki lo mọ nipa TSAIGUMI?
Ní ìmọ̀ nípa bi BBC ṣe n ṣiṣẹ́ ìròyìn ayélujara nínú òtítọ́ àti láì ti igbá kan bọ̀ ọ̀kan nínú
Ọjọ keje oṣu kọkanla ọdun 2020 ni awọn ọlọpaa mu Adene nile rẹ niluu Eko ti wọn si sọ ọ si atimọle.
Ile ẹjọ to ga julọ lorilẹede Naijiria wa wọgile idajọ naa pẹlu aṣẹ pe ki wọn lọ tun ẹjọ naa gbọ lati ibẹrẹ EFCC: Àwọn ọmọ Orji Kanu la mú, kìí se ti Atiku Oríṣun àwòrán, @officialEFCC Àkọlé àwòrán, àjọ EFCC ní òun leè fọwọ́ sọ̀yà pé iṣẹ́ ń lọ ní pẹrẹu Ajọ to n gbogun ti iwa ibajẹ ni Naijiria, EFCC, ti kegbare sita pe, awọn ko fi panpẹ ofin gbe awọn ọmọkunrin oludije fun ipo aarẹ ninu ẹgbẹ Peoples Democratic Party, PDP, Atiku Abubakar.
Ní àkókò náà, àwọn Sadusi wá sí ọ̀dọ̀ rẹ̀.
Iná èèsì kìí jóni lẹ́ẹ̀mejì - Ọbásanjọ́ Ọbásanjọ́, Fálaè sè‘pàdé lóríi Bùhárí Ìkéde Buhari: Ta ni yóò kojú u rẹ̀?
Kyle Edmund gbadun okan lara ifigagbaga re ti o ti n gba lati igba ti o ti n dije ninu ere idaraya boolu afigigba, leyin ti o fagbahan ondije ti o darajulo teleri ninu ere idaraya ohun, Novak Djokovic ninu ifigagbaga isori-isori pelu ami ayo mefa si meta(6-3), mejj si mefa(2-6) ati mefa si meta (6-3) ninu ipele keji idije Madrid Open.
 ida ogoji eto isuna ni won na si ori eko ati ilera won .
Aarẹ Trump ma n sọ ni ọpọ igba pe orilẹede China n gba awọn ileeṣẹ to jẹ ti ti wọn mọ wọn lọwọ.
” Wọ́n bá sọ ohun tí àwọn ará Jabeṣi sọ fún un.
Nítorí tèmi, àní nítorí tèmi ni mo ṣe ṣe bẹ́ẹ̀.
Bí ó ti ń bá mi sọ̀rọ̀ lọ́wọ́, mo sùn lọ fọnfọn, mo dojúbolẹ̀.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Osun Supreme: Àwọn èèyàn Ọṣun rọ Oyetọla láti jẹ́ kí àsìkò rẹ̀ tú aráàlú lára Ọpọlọpọ awọn eniyan ni wọn ti bu ẹnu ẹ̀tẹ́ lu awọn agbabọọlu Egypt lẹyin ifẹsẹwọnsẹ wọn pẹlu South Africa.
FA Cup: Man City pòkọ ìyà fún Swansea pẹ̀lú àmì ayò 3-2 nínu FA Cup
Loru mọju oni, ọjọ kẹtalelogun, oṣu keje ni awọn alamojuto idibo abẹlẹ naa kede abajade esi idibo ẹni to maa gba tikẹẹti PDP lati le di gomina Ondo.
Àwọn iwin ni àwọn ẹranko gbà ni aláṣè, àwọn ni ó sì ṣe gbogbo ìtọ́jú ti wọn ṣe.
Àwọn eniyan náà bẹ̀rù OLUWA pẹlu, wọ́n sì yan oniruuru eniyan lára wọn, láti máa ṣe alufaa níbi àwọn pẹpẹ oriṣa gíga, láti máa bá wọn rúbọ níbẹ̀.
Àwọn Ẹranko pàápàá kò gbádùn, igbó dákẹ́ bí ẹni pé ọ̀fọ̀ ṣẹ ènìyàn.
Bukunmi ni pẹlu isẹ ti Funke Akindele ke si oun yii, o daju pe oun ti se oriire nile aye oun.
Recruitment Nigeria Army form: Wo àmúyẹ kí o tó lè di ọmọ ogun ilẹ̀ Nàìjíríà pẹ̀lú fọ́ọ́mù tó jáde yìí
Àmọ́ nkan tó ṣe pàtàkì jùlọ nípa rẹ̀ ni pé Apple fúnni ní ìdánilójú pé ti EarPod yìí bá bàjẹ́ láàrin ọdún kan, àwọn ó fúnni ní òmíran tuntun, tí àwọn ò bá lè tún un ṣe.
í a ti dé ibi kan tí ó dákẹ́ minimini báyìí, tí igbó ibẹ̀ dí tí o dúdú mírínmírín ni a rí iwin kan tí ó ń bọ̀, ó dàbí ọba gan-an, ìgbà tí a sì kọ́ rii, a ké “Kábíyèsí” ati gbàgbé pé aginju Babalórìṣà ni a wà, bẹ́ẹ̀ ni kò sí ibi tí ẹbọra náà fi yàtọ̀ sí ọba.
Inú wa dùn níbẹ̀ nítorí ohun tí ó ṣe.
Ó ti wí ní alẹ́ ọjọ́ kan fún àwọn ẹranko báyìí pé òun nnìkan ni wọ́n máa bá jà ní òwúrọ̀ ọjọ̀ kejì.
Ó wà ní àkọsílẹ̀ mìíràn pé, “Bí ebi bá ń pa ọ̀tá rẹ, fún un ní oúnjẹ jẹ, bí òùngbẹ bá ń gbẹ ẹ́, fún un ní omi mu.
O ti fi igba kan jẹ ọmọ igbimọ amuṣẹya ẹgbẹ APC, ko to fi ipo naa silẹ lati dije fun ipo igbakeji gomina ipinlẹ Rivers l'ọdun 2019.
JAMB 2019: Kí ló yẹ kóo mọ̀?
Republic  of Congo  Joseph Kabila, to  ye ki o kuro lori ipo leyin odun mẹ́tàdínlógún ti o
Jesu dáhùn pé, “O wí èyí fúnrarẹ ni àbí ẹlòmíràn ni ó sọ bẹ́ẹ̀ fún ọ nípa mi?
Amọ awọn orileedekan ti ribi dawọ itankalẹ arun naa eleyi ti o ti pa eeyan ẹgbẹrun mẹẹdogun titi di ọjọ kẹtalelogun osu Kẹta ti o si ti ran eeyan 340,000 lagbaye.
Abí ẹ kò rí i pé àjẹjù ṣúgà kò dára fún ọmọ ènìyàn rárá bí?
Ọjọ́ náà ń bọ̀ bí iná ìléru, tí àwọn agbéraga ati àwọn oníṣẹ́ ibi yóo jóná bíi koríko gbígbẹ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Búrẹ́dì tí wọn ó fi jẹ ẹ̀wà ni wọ́n lọ rà ni wọ́n pàdé ikú gbígbóná' Wo ọ̀rọ̀ Fani-Kayode sí akọ̀ròyìn blog"" tó ní lílù ìyàwó rẹ̀ bíi bàrà ló mú wọn túká Ìròyìn ayọ̀!"
Ṣugbọn lilo oogun apakokoro nikan ko to lati dena arakan arun gẹgẹ bi awọn onim ṣe sọ ọ.
" Fatimah: Kò sí ẹni ti kò le yi agbègbè rẹ padà Imam fi ìgbàgbọ́ kojú ilẹ̀ ríri Ìrìnàjò Toyin Abraham, láti orí gbèsè jíjẹ, ó di onílé, onimọto àti aya lọ́ọ̀dẹ̀ ọkọ O gba gbogbo àwọn ti wọn ni ipenija oriṣii lati ma ṣe sọ ìrètí nù rara.
137 ni iye àwọn obìnrin tí ikú ń pa lójúmọ́ lágbàáyé
Ìfakùn ọ̀rọ̀ “Ìyá àgbà Saray” tí Muntazir mẹ́nubà dá lórí àbẹ̀wò ìbánidárọ tí Aliyev bá lọ sí Agbègbè Shamakhi tí Azerbaijan, níbi tí ìporùrù ayé tí bá ọ̀pọ̀lọpọ̀ ilé ìgbé jẹ́ ní ìbẹ̀rẹ̀ oṣù yìí, tí ọ̀kan nínú rẹ̀ jẹ́ ti obìrin ọlọ́mọdún 92 tí orúkọ rẹ ń jẹ́ Saray.
Samuẹli bá bi í pé, “Èwo ló dùn mọ́ OLUWA jù, ìgbọràn ni, tabi ọrẹ ati ẹbọ sísun?
Wo orílẹ́èdè tí wọ́n tí ń dáwó ìsìnkú ara wọn pámọ́ Toyin Abraham: Toyin Abraham ni tirẹ ṣo pe oun lọ tọ nigba mẹwaa laarin iṣẹju mẹẹdogun lati ori itage nigba ti oun n kopa ninu ere #Elevatorbaby pẹlu oyun ninu oun.
Iko agbaboolu obinrin orile-ede Naijiria, Super Falcons ti pegede fun asekagba idije boolu afesegba obinrin tile Afrika(African Women Cup of Nations), to n lo lowo lorile-ede Ghana.
Lẹyin ti mo da awọn ọmọde mejeeji pada s'ileewe, ko si ibojuwẹyin fun mi mọ."
    Nígbà tí a gòkè tán tí mo ka iye awa tí kò kú sínú odò náà, a jẹ́ àádọ́jọ, àwọn tí ó kú dàbí ọgọ́rùn-ún.
O jé ọmọ bibi ijọba ibilẹ Apa nipinlẹ Benue.
Wọn ni iti ọgẹdẹ lasan ni, ti ko to ohun ta a yọ ada si.
Ọpọ awọn orileede to ku, lati India si Iran lọ si Canada lo ti fofinde awọn ara UK lati ma wa si ilu wọn.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Bolaji Faleke ni Olùkọ́ tó ń kọ́ wa ní àṣà oge ṣiṣe lórí BBC Yorùbá Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Adeyeye Ile Ife: Kílódé tí Ọọni Ife, Oba Ogunwusi kò fi gbọdọ̀ rí ọmọ rẹ̀ tuntun títí di ẹ̀yìn oṣù mẹ́fà?
Kí àwọn ọmọ ogun máa nìṣó,àwọn ọmọ ogun Etiopia ati Puti, tí wọ́n mọ asà á lò,àwọn ọmọ ogun Ludi, tí wọ́n mọ ọfà á ta dáradára.
Bi awon omo egbe APC   ti won
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ẹsẹ̀ bàtà, èso kukumba ni wọ́n fi ń já àbálé àwọn ọmọ Nàìjíríà ní Libya Ó sì ṣe àṣeyọrí pupọ nídìí ìlérí rẹ náà, gbogbo àṣẹ ile ẹjọ́ àti òfin ilẹ̀ wa lo tẹ́lẹ̀ gẹ́gẹ́ bíi Ààrẹ Nàìjíríà.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ooni: Mo rọ àwọn àgbẹ̀ àti darandaran láti gba ìrẹ́pọ̀ láàyè 5 Ògún 2019 Oríṣun àwòrán, Ooni of Ife Ọọni tilu Ile Ifẹ, Ọba Adeyẹye Ẹnitan Ogunwusi Ọjaja Keji, ti rawọ ẹbẹ si awọn agbẹ ati darandaran lati wa ni irẹpọ, ki ounjẹ lee tubọ buyaari fun wa.
Ẹwẹ, Coronavirus ti kọ oju gbogbo awọn ọlọja to maa n taja lasiko naa soorun alẹ bayii gẹgẹ bi ko ṣe ni si ipejọpọ ipade adura naa lojukoroju lọdun yii.
Ìlú kò mọ ohunkóhun nípa iṣẹlẹ màálù tó kú nilu Ikarẹ- Oba Olukarẹ Ko pẹ pupọ lẹyin eyi ni ara tun san pa maluu bii mẹjọ kan ni agbegbe Oyinmọ ni ilu Ikarẹ ni ijọba ibilẹ Akoko North east ni ipinlẹ Ondo kan naa.
Everton já Manchester United sí ìhòhò lọ́jọ́ Àjíǹde Wọn ṣalaye ninu atẹjade naa pe awọn onimọ ẹrọ nipa ọna ṣiṣe ni awọn bi ti wọn ti so afara naa pọ yii to nilo atunṣe ko le ṣakoba fun afara ọhun.
Ó wí pé ó ya òun lẹ́nu gidi pé mo fún òun lówó.
Awọn ṣọọṣi naa yoo ṣi pada lọjọ Aiku.
 O ni pẹlu iwa akin, iwa irẹlẹ, ati olootọ eniyan ati alaanu ti n fowo ṣaanu, wọn jẹ awokọṣe gidi laarin awọn Ọba to ku.
8 Èrèlè 2020 Oríṣun àwòrán, Twitter/Lagos State Govt.
Wọ́n gbéra láti Sukotu, wọ́n pàgọ́ sí Etamu létí aṣálẹ̀.
Diẹ ninu awọn ipinlẹ ti omi ẹgbẹ oṣelu APC ko ti toro ree: Oyo: Gomina Abiọla Ajimọbi ati Minisita feto ibaraẹnisọrọ, Adebayọ Shittu ngbena woju ara wọn Kaduna: El Rufai ati Sẹnatọ Shehu Sanni nwọ Sokoto kanaa eyi to n fa laasigbo lọwọ Gombe: Gomina Danjuma Goje ati Sẹnatọ Usman Nafada kii foju rinju Ogun: Gomina Ibikunle Amosun ati Sẹnatọ Ọlamilekan Adeọla dijọ nṣe fanfa Plateau: Gomina Simon Lalong ati minisita fọrọ ere idaraya, Solomọn Dalung nṣe bii ata ati oju.
Gbogbo wọn ti di ará Sodomu lójú mi,àwọn ará Jerusalẹmu sì dàbí àwọn ará Gomora.
Amọṣa nigba ti BBC gbe ọrọ naa tọ Kabiyesi Ataọja nigba naa, baba ni ko soun to jọọ ati pe ija lo de torin dowe.
Ọkàn mi dúró ṣinṣin, Ọlọrun,ọkàn mi dúró ṣinṣin!
Kí wọ́n máa fi ìrẹ̀lẹ̀ bá gbogbo eniyan lò.
₦750m ni Akeredolu ń gbà lóṣù fún ‘Security Vote’ àti ₦150m owó oṣù - Agboola Ajayi fèsì Àwọn olùpolongo ìdìbò Aketi àti Jegede ń forígbárí l'Ondo, bí wọ́n ṣe n yìnbọn ni wọn n sun táyà INEC kéde agbègbè ẹsẹ̀ odò 270 ti èrú ìbò ti le wáyé ní ìpínlẹ̀ Ondo Ọ̀pọ̀ aráàlú Owo wà nílé ìwòsàn, síbẹ̀ APC àti PDP kò gba ẹ̀bi Ẹ gbọ́ òhun tí àwọn olùdíjé sípò gómìnà nípínlẹ̀ Ondo sọ nípa Bàbá ìsàlẹ̀.
Ni bayìí, Kyari ni àwọn n ṣiṣẹ́ takuntakun láti fi pàǹpẹ́ mú awọn tó kù lara ọmọ ẹgbẹ́ Barau to ti bẹ́ lù 'gbẹ́.
''Ti ẹyin ba n gba ilu oyinbo lọ fun itọju, ẹ gbọdọ ba wa ṣe awọn ile iwosan ti awa naa n lo nile ko dara, ka wa naa le lanfaani si eto ilera to peye,'' Falana lo woye bẹẹ.
Nibi ipade ajọ AU yii ni awọn mejeeji yoo ti kọkọ pade lẹyin lẹta ti Oloye Olusẹgun Ọbasanjọ kọ si aarẹ Muhammadu Buhari.
Nítorí náà, n óo sọ iná sí Moabu, yóo sì jó àwọn ibi ààbò Kerioti ní àjórun.
Akosile olosoosu ohun so pe, alekun gori akosile iroyin osun kinni odun 2018 ju ti osu kejila odun 2017 lo.
  Tí ènìà bá ti fo odi mélòó kan ènìà á sọ̀ kalẹ̀ sí pẹ̀tẹ́lẹ̀ ásì rìn kan odò kékeré.
” Nígbà tí Josẹfu gbọ́ ọ̀rọ̀ yìí, ó bú sẹ́kún.
Sugbọn isẹlẹ naa da sunkẹrẹ fakẹrẹ ọkọ silẹ ladugbo dandaru si Mokola, tawọn osisẹ Amotekun naa si bawọn peju sibi isẹlẹ ọhun, bẹẹ ni wọn n dari ọkọ lagbegbe naa pẹlu lati dena sunkẹrẹ fakẹrẹ.
Buhari: Kò sí àyè wíwọ ọkọ̀ bààlú olówó gọbọi mọ́ fún àwọn òṣìṣẹ́ ìjọba
Bẹẹ ba gbagbe, lati osu kẹjọ ọdun 2019 ni isẹlẹ kan ti waye ninu ijọ Sotitobire nilu Akure pe, ọmọ ọdun kan, Gold Kọlawọle sọnu ninu ijọ naa, ti wọn ko si ri di akoko yii.
’’ IDUPEAlaga  ECOWAS dupe lowo orile ede China fun eto okoowo won nile Afirika.
esi idanwo UTME ti odun 2019 ko tii jade .
O ni ileeṣẹ eto ilera ipinlẹ Oyo ti n gbaradi lati koju arun ọhun lati igba to ti ṣẹyọ lorilẹ-ede Naijiria.
Ṣugbọn tí o bá yipada kúrò lọ́dọ̀ mi, tí o kọ àṣẹ mi ati òfin tí mo ṣe fún ọ sílẹ̀, tí o sì ń lọ bọ oriṣa, tí ò ń foríbalẹ̀ fún wọn, 
Ṣugbọn Peteru dúró lóde lẹ́bàá ẹnu ọ̀nà.
Ẹ ronupiwada, kí ẹ sì yipada kúrò ninu ẹ̀ṣẹ̀ yín, kí ẹ̀ṣẹ̀ má baà pa yín run.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù George Weah ge owo osu rẹ gẹgẹbi aarẹ Liberia 30 Sẹ́rẹ́ 2018 Oríṣun àwòrán, EPA Àkọlé àwòrán, Ofin ẹlẹyamẹya ni ofin to tako awọn ajoji lati ni ile lorilẹede Liberia Aarẹ tuntun lorilẹede Liberia, George Weah ti jẹjẹ lati ge owo osu rẹ walẹ fun saa kan, eyi ti yoo da gba inu apo asunwọn owo idagbasoke lọ, ti yoo si tun faaye gba kawọn ọmọ ilẹ okeere maa ni ile lorilẹede naa.
Kò fijọ́ kan bi ara rẹ̀ léèrè rí pé, “Ta ni mò ń ṣe làálàá yìí fúntí mo sì ń fi ìgbádùn du ara mi?
Nígbà tí mo bá gbá ọ mú,n óo finá jó gbogbo àìdára rẹ dànù.
Eryinorẹyin lawọn ọlọpa tọrọ aforijin ti won si tu ikọ amuseya lori iwa odaran ile ise ọlọpa ka.
Buhari yoo ṣ'abẹwo si Tabara, Benue Buhari dasi ipaniyan Benue Iroyin to tẹwa lọwọ lati oju opo twita Garba Shehu to jẹ agbẹnusọ fun aarẹ ni bakanna ni Buhari ṣe ipade pẹlu awọn lọbalọba ni ile ijọba Taraba lati wa wọrọkọ fi ṣ'ada lori ipaniyan to'n waye lagbegbe naa.
Wọ́n ya Eleasari, ọmọ rẹ̀ sí mímọ́, láti máa bojútó àpótí OLUWA náà.
Òògun náá jẹ́ èyí ti wọ́n maa n lò fún àìsàn tẹ́lẹ̀ ti o sí ti fìdímúlẹ̀ pé wọ́n n lòó fún àìsàn Covid-19 ni ilé ìwòsàn.
Ọrọ pọ ninu iwe kọbọ iṣẹ ti wọn lawọn ti ṣe ṣugbọn diẹ lara wọn re e.
Bakn naa lo tun ni eto akanṣe miran fun ẹyẹ ikẹyin fun oloogbe Ajimọbi yoo waye lọjọ miran laipẹ.
Titi di oṣu kewaa, ọdun 2020 ti a wa yii, eyi l'awọn orilẹede marun un to jẹ pe awọn ọlọpaa wọn lo n gbowo julọ lagbaye.
O ni òun gẹ́gẹ́ bí ọba ìlú, òun kò leè là ojú ṣílẹ̀, kí àwọn ọmọ òun máa kú ní oju òun, ó ní bí èyí bá rí bẹ́ẹ̀, a jẹ pe ìgbà òun kò dára lórí òye nuu.
"Wo àwọn àwòrán Sanusi nígbà tó ṣì wà lórí oyè gẹ́gẹ́ bíi Emir Wo àwọn ohun márùn ún tó yẹ kí o mọ̀ nípa Sanusi Èyí ni àwọn ìdí tí ìjọba ìpínlẹ̀ Kano ṣe rọ Emir Sanusi Lamido l'óyè Wọn tẹsiwaju lati sọ pe ""ko si igba kankan ti ijọba ipinlẹ Kano fi iwe ranṣẹ tabi pe Emir si akiyesi lori ẹsun aigbọran si awọn alaṣẹ, ati kikuna lati maa lọ fun ipade ati eto ti ijọba ba gbe kalẹ, ti wọn fi kan an."
Pẹlu iye awọn eeyan tuntun yii, o ti pe 84,414 eeyan to ti ni arun naa ni orilẹede Naijiria bayii.
Ó ti tabili àwọn tí wọn ń ṣe pàṣípààrọ̀ owó ṣubú.
Bí a bá wo fínnífínní, a ó ri pé ilà yí yàtọ̀ sí ara wọn láti agbègbè sí agbègbè tàbí ìlú sí ìlú níbomíràn .
Ẹ̀yin òṣìṣẹ́, ẹ má ṣáì lọ síbi iṣẹ́ lọ́jọ́ Ajé, olórí àwọn òṣìṣẹ́ ní Nàìjíríà tako ìyanṣẹ́lódì Aarẹ Trump ṣetán láti yan Amy Coney Barrett sílé ẹjọ́ gíga jùlọ ni America Ọgbọ́n àti kówójẹ n'ìgbèsẹ̀ ìjọba láti ná $1.
Sàtánì ló jόkόό bí alága ìgbéyàwό, Bìlísì-í sì jόkòό sí ibi ẹ̀yẹ.
Kabiyesi, tí wọ́n bá fi lè kọ́ ìlú náà parí, tí wọ́n sì parí odi rẹ̀, wọn kò ní san owó ìṣákọ́lẹ̀ mọ́.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Adeleke: Ajayi Shuaib tí wọ́n ní ó pe Adeleke lẹ́jọ́ ní irọ́ ni wọ́n pa mọ́ òun 17 Èbibi 2019 Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Adeleke fake certificate allegation: Ajayi Shuaib tí wọ́n ní ó pe Adeleke lẹ́jọ́ ní irọ́ n A n jẹ ekuru ọrọ ko tan lawo, n ṣe lawọn kan tun n gbọn ọwọ rẹ sinu awo lọrọ awuyewuye lori ẹsun ayederu iwe ẹri ti o wa lọrun oludije fun ipo gomina ipinlẹ Ọṣun labẹ aṣia ẹgbẹ oṣelu PDP, Sẹnetọ Ademọla Adeleke bayii.
Pẹlu orin ìyìn ati ìdúpẹ́ wọ́n ń kọrin sí OLUWA pẹlu ègbè rẹ̀ pé,“OLUWA ṣeun,ìfẹ́ rẹ̀ sí Israẹli dúró títí lae.
Bi o se pe Obaseki woye ohun to sẹlẹ s'ara waju ninu ẹgbẹ naa ni, ko ni wulẹ daamu ara rẹ.
Efuraimu ti mú èmi, OLUWA rẹ̀ bínú lọpọlọpọ, nítorí náà, n óo da ẹ̀bi ẹ̀ṣẹ̀ rẹ̀ lé e lórí, òun tí ó gàn mí ni yóo di ẹni ẹ̀gàn.
Ibrahim Alhassan wa  fi idunnu awon
Akowe agba ajo ti o n ri si irinajo sile-mimo awon onigbagbo, ti a mo si Christian Pilgrims Commission (NCPC) Alufaa Tor Uja soro yii nilu Abuja, eyi ti o so pe, “bi ise-akanse naa ba pari, ki se pipese ise lopo yanturu nikan fun awon odo langba ti ko nise lowo, amo, yoo tun mu ayibada rere ba awon omo ipinle Benue ati awon ipinle ti o je amulegbe re bi; ipinle Kogi, Nasarawa ati ipinle Taraba”.
Wọ́n ń wí pé, ‘ọlọ́run yín nìyí Israẹli, ẹni tí ó mú yín gòkè wá láti ilẹ̀ Ijipti.
Awọn eniyan lori ikanni ibaraẹnisọrọ lori opo Twitter fi ero wọn han lori iṣẹlẹ naa.
Sibẹsibẹ wọn kò gbọ́; wọn kò sì fetí sí ọ̀rọ̀ mi.
Lasiko to n ba BBC Yoruba sọrọ, alaga ijọba ibilẹ Amuwo Ọdọfin, Onimọ-ẹrọ Dotun Valentine salaye pe, awọn ara adugbo naa ni ọpa gaasi naa lo bẹ nitori ẹrọ kan to bajẹ, eyi to mu ki afẹfẹ gaasi maa tu jade, to si sadede gba ina.
Bó ṣe ń wáyé ní Oyo, ló tún ń ṣẹlẹ̀ ní Kano, ilé ẹjọ́ júwe ilé fún Emir mẹ́rin tí Ganduje yan Bo ṣe wa ni liki lo wa ni gbanja lọrọ bi ile ẹjọ nilu Kano ṣe wọgile iyansipo awọn ọba ti Gomina Ganduje yan sipo.
Egbe ohun so pe, orile-ede Liberia nikan ni orile-ede ti o mu igberu ba elekun-jekun ati eleka-jeka idasile isejoba nile Africa lati odun 2006.
Ó nṣiṣẹ́ amóhùmáwòrán, ó nṣiṣẹ́ asọ̀rọ̀mágbèsì.
Nítorí kì í ṣe ẹ̀mí ojo ni Ọlọrun fún wa bíkòṣe ẹ̀mí agbára ati ti ìfẹ́ ati ti ìkóra-ẹni-níjàánu.
"O ni ""Iṣubu ara wọn ni wọn n wa."
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Boko Haram tún pa èèyàn mẹ́ẹ̀dógún lágbègbè Maiduguri 2 Ìgbé 2018 Oríṣun àwòrán, Boko Haram ffVT via AFP/Getty Images Àkọlé àwòrán, Kò tíì sí ẹní leè sọ iye ẹ̀mí tó bá ìṣẹ̀lẹ̀ náà lọ.
Fidio kan lo ṣafihan awọn oṣiṣẹ naa to jẹ ti ajọ to n gbogbu ti ebi, Action Against Hunger, nibi ti wọn ti n bẹbẹ fun ominira lọwọ awọn agbesumọnmi to ji wọn gbe.
 Òun ni ó kọ ìwé sí akin olúṣínà pé kí ó wá bá òun wádìí owó bàbá òun tí wọn kò rí mọ ́ .
Ọkàn arakunrin tí eniyan bá ṣẹ̀ a máa le bí ìlú olódi,àríyànjiyàn sì dàbí ọ̀pá ìdábùú ìlẹ̀kùn ilé ìṣọ́.
Ṣùgbọ́n ìyànjú mi ni èyí pé, kí á má tì tirí  ẹni búburú hùwà búburú, nítorí pé bí a bá wí pé kí a bẹ́gi a lè bẹ́ ènìyàn, bí a bá wí pé kí a fi oore ṣíṣe sílẹ̀ pátápátá, alè dá àwọn ọmọlúàbí lórí.
Minisita to ti fipo silẹ lasiko Aarẹ Buhari Minisita marun un lo ti fi ipo silẹ lasiko aarẹ Muhammadu Buhari ti ko si tii yan ẹlomiran dipo wọn.
Wọn kò gba ilẹ̀ àwọn ará Amoni nítorí pé wọ́n jẹ́ alágbára.
Awọn ọlọpaa agbegbe naa sọ wipe, iwadiii n lọ lọwọ lori isekupani naa.
Itan naa pọ̀ sugbọn mo gbadun ara mi loni.
Ẹbọ ohun jíjẹ tí ẹ óo rú pẹlu rẹ̀ nìyí: ìdámárùn-ún ìwọ̀n efa ìyẹ̀fun tí wọ́n fi òróró pò, ẹ óo fi rú ẹbọ sísun olóòórùn dídùn sí OLUWA, kí ẹ sì fi idamẹrin ìwọ̀n hini ọtí waini rú ẹbọ ohun mímu pẹlu rẹ̀.
Lẹ́yìn náà, Mose ati àwọn ọmọ Israẹli kọ orin yìí sí OLUWA, wọ́n ní: “N óo kọrin sí OLUWA,nítorí pé, ó ti ja àjàṣẹ́gun tí ó lógo.
Ṣùgbọ́n ó di ọ̀laa kí n tóó máa bá ìtàn bàbá mi lọ, ìtàn ti mo sọ fún ọ ní ijọ́sí tí ìwọ kọ sílẹ̀ fún àwọn ọmọ aráyé wọ̀n-ọ́nnì, ìtàn ara mi ni gbogbo wọn, ọ̀rọ̀ díẹ̀ péré ni mo sì sọ nípa bàbá mi, nítorí náà, iwọ ọ̀rẹ́ mi, máa dìde, dìde kuro ní orí àpáta, níbi tí o da àyà dé ilẹ sí, máṣe jẹ́ kí àyà kí ó dùn ọ́, mo mọ ilé rẹ, mo ń bọ̀ wáá kí ọ lọ́la.
Blood Donor Day: Láìsí ẹ̀jẹ̀ kò sí ẹ̀mí
Ní ọjọ́ karun-un, oṣù kẹfa ọdún kẹfa tí a ti wà ní ìgbèkùn, bí mo ti jókòó ninu ilé mi, tí àwọn àgbààgbà Juda sì jókòó níwájú mi, agbára OLUWA Ọlọrun bà lé mi níbẹ̀.
Homepage Accessibility links Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Ìrànlọ́wọ́ Ìwọlé News Sport Weather Radio Arts Ààtò BBC News Yorùbá BBC Yoruba ÀkọléÀkọlé abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Àkọlé bọ̀tìnnì síwájú síi Olùmúdọ́gba bọ́tìnnì síwájú síi Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Media player Close player Close player Close player Ahmed Lawan, Femi Gbajabiamila di olórí ilé aṣòfin àpapọ̀ Nàìjíríà I'll sign in later And we'll keep you signed in.
Ó fọnrere àtinúdá náà ní ọdún tí ó tẹ̀lé oyè tí ó gbà pẹ̀lú “Bacchanal Time”, tí ó pa àṣẹ fún àwọn ayírapadà láti máa “fi ọwọ́” bí àwọn afọnfèrè  brass ṣe ń kọrin “F-jam” tí gbogbo ènìyàn mọ̀ tàbí “tantana” tí ó ń dún ní abẹ́lẹ̀.
Ó jẹ́ kí ó lọ sọ́dọ̀ àwọn ọ̀rẹ́ rẹ̀, kí wọ́n fún un ní àwọn nǹkan tí ó nílò.
Àwọn Juu sọ fún un pé, “A kúkú ti sọ pé ará Samaria ni ọ́, ati pé o ní ẹ̀mí èṣù!
Oludije mejidinlaadọta ni ajọ eleto idibo INEC gbe orukọ wọn sita gẹgẹ bii oludije fun ipo gomina nipinlẹ Ọṣun bayii.
Lẹyin ọpọlọpọ ọdun ti owo ẹru ti pari lagbaye, lawọn eeyan kan lorilẹede Kuwait tun ṣe fi ọmọ ọdọ ati obinrin ṣe karata bayii.
Nítorí eniyan kò lè ká èso ọ̀pọ̀tọ́ lórí igi ẹlẹ́gùn-ún.
Njẹ ẹyin naa ti n ronu nipa kini o le ṣẹlẹ si Trump lẹyin ti wọn ba ribi yọ nipo abi?
O fẹ lọ gbe eniyan kan ni ile igbafẹ kan ni Abuja ni aṣẹwo naa ba tọ'ka sii pe o jọ ọkunrin kan ti oun fẹ lọ sun si ọdọ rẹ, sugbọn ti o ja oun l'ole ki wọn to de'le.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ọ̀rẹ́kùnrin mi fún mi ní àárùn HIV, mo sì gbẹ̀san Kíni itumọ àṣẹ wàá tí àwọn Ààrẹ orílèèdè má n pá?
Ìrẹ̀wẹ̀sì ń bá wa torí ìdánwò NECO tẹ ń ṣún síwájú lọ́pọ̀ ìgbà - Akẹ́kọ̀ọ́, ọ̀gá iléèwé Wo àwọn orílẹ̀èdè míràn tó ń fojú winá ìwọ́de bíi ti ENDSARS Wo àfiwé owó oṣù Ọlọ́pàá Nàìjíríà pẹ̀lú akẹgbẹ́ wọn lókè òkun Òkú tó jí lọ́jọ́ kejì ní mọ́ṣúárì padà kú síléèwòsàn Wo nọ́mbà tí o le è pè láti gba owó gbà-má-bínú tí ọlọ́pàá bá fìyà jẹ ọ́ lọ́nà àìtọ́ l'Eko Báyìí ni o ṣe leè fi ẹjọ́ ọlọ́pàá tó bá fìyà jẹ ọ́ lọ́nà àìtọ́ sun ìjọba ìpínlẹ̀ Eko Gomina ipinlẹ Eko, Babajide Sanwo-Olu ti gbe igbimọ ẹlẹni meje kan kalẹ ti yoo maa ṣagbeyẹwo ẹsun fifi iya jẹ ara ilu lọna aitọ ti awọn oṣiṣẹ ileeṣẹ ọlọpaa n hu.
Kò sí èrè kankan fún ọ níbẹ̀.
Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Prophet Israel Oladele: Kilo gbe e de ijọ Celestial?
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù India: Ọmọ ọdun méje gbé bàbá rẹ̀ lọ àgọ́ ọlọ́pàá nítori ilé ìgbọ̀nsẹ̀ 12 Ọ̀pẹ̀̀ 2018 Oríṣun àwòrán, BBC Tamil Àkọlé àwòrán, Hanifa Zaara ní bàbá òun parọ́ pé yóò kọ́ ilé ìgbọ̀nsẹ̀ tí òun bá se dáradára ní ilé ìwé, àmọ́ bàbá rẹ̀ kọ̀.
Igba èso pomegiranate ni wọ́n fi yí àwọn òpó náà ká ní ọ̀nà meji.
Ìlú ò rẹ́rìn ín rárá, Alaafin Adeyemi III fárígá fún Buhari nínú lẹ́tà tuntun Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
ki I lodi si moṣalaṣi ati pe ibi isin pataki ni.
Aarẹ Muhammadu Buhari lo gbe igbimọ naa kalẹ lati wadii awọn ẹsun iwa ibajẹ, ati afojudi ti wọn fi kan an.
Fún ìgbà díẹ̀ wọ́n kọ̀ láti jọwọ́ àwọn àkọsilẹ̀ wọn, sùgbọ́n wọ́n tún ti bẹ̀rẹ̀ si ni fi síta padà.
Aisha Buhari tutọ sókè fojú gbà à, ó ní kí Garba Sheu kọ́we fipolẹ́
"Sùgbọ́n, sí gbogbo àwọn ti wọn ti wọn ti gbìn sọ́kan ti wọn sì tun ń se igbélarugẹ àwuyewuyhe pé ti Atiku ba lọ si ilé ẹjọ ọgun àti wahala yóò bẹ silẹ̀, ibi ló ń gbe in wọn, wọn si ń wa ọ̀na àlùmọkọ́rọ́yín láti dá wàhálà sílẹ̀ ní òrílẹ̀-èdè Naàìjíríà ni.
Bakanna ni Tsaigumi wulo fun wiwa awọn to ba sọnu ati didoola ẹmi.
Omiyale Ile Ife: Dukia sọfọ, awọn eniyan si tun farapa
Ti Bobrisky bá n ṣe àṣeyori nínú ìwà àgberè tó n fi ṣiṣẹ́ ṣe, báwo ní a ṣe fẹ́ pàrowà si awọn ọdọ Nàìjíríà láti ṣe ǹkan to tọ̀na.
Oríṣun àwòrán, PIUS UTOMI EKPEI/GETTY Àkọlé àwòrán, Bukola Saraki ni Aarẹ ile asofin agba Ninu akoso iṣejọba lorileede Naijiria, Sẹnatọ Bukọla Saraki lo wa ni ipo kẹta.
Asofin Ahmad Lawan, adari egbe to poju nile igbimo asofin lo koko pe akiyesi ile si ayewo oruko awon eniyan ti aare fi ranse, o wa fi ofin abala  6(1) (d) ati 10(1) ati  (2)  ti ile ifowopamo ti ijoba apapo,odun 2007 gbe e lese”.
Koda wọn ko awọn aworan kan sita to ṣafihan oku Shekau.
Lẹ́yìn ọlọ́pàá, VIO nìkan ló láṣẹ láti dá ọkọ dúró láìṣẹ̀ - Ọ̀gá VIO Eko Mà á fún àwọn ọba alayé ní ojúṣe nínú ìjọba mi - Seyi Makinde Wo ohun tuntun tó n ṣẹlẹ̀ lágboolé CAF Kò dùn mí pé mo sọ̀rọ̀ tako Buhari -Adedayo Festus Imọran Funmilola fun gbogbo opo ni pe ki wọn sunmọ Olorun to jẹ ọkọ opo ati baba fun awọn alaini baba.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Segalink:ìkùnsínú pọ̀ láàrin àwọn agbófinró bẹ́ẹ̀ wọn kò ni agbẹnusọ Ṣugbọn ajọ NADMDO ni iwadii si n lọ lọwọ lori iṣẹlẹ ẹkun omi naa.
Bí òrùka wúrà ní imú ẹlẹ́dẹ̀ni obinrin tí ó lẹ́wà tí kò ní làákàyè.
O ni o pa irọ mọ oun lori Twitter.
Akọ̀ròyìn BBC Africa, Tomi Oladipo jábọ̀ pé àwọn olùgbé Mogadishu níbi tí wọ́n ti jí nọ́ọ̀sì ọ̀hún gbe sọ wípé lẹ́yìn tí ìsẹ̀lẹ̀ náà làwọn òsìsẹ́ aláàbò ti kalẹ̀ síbẹ̀.
Awọn ọmọ igbimọ naa ni Arabirin May Agbamuche-Mbu, Amofin Mike Igini, Amofin Kassim G.
Gbogbo wọn sì wá siwaju ọba.
Bakan naa ni alagbatọ rẹ, to tun jẹ iyawo ẹgbọn baba rẹ, Arabinrin Arowolo sọ pe, iku ọmọ naa dun oun pupọ, nitori pe inu kan ni oun fi gba a lati ma a tọju pẹlu awọn ọmọ oun."
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù US Elections 2020: Primate Ayodele ní òun ti sọ àsọtẹ́lẹ̀ pé Trump yóò fìdírẹmi, tí kò bá ṣọ́ra ṣe 17 Ọ̀wàrà 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 8 Bélú 2020 Oríṣun àwòrán, Primate Ayodele Oludasilẹ ijọ Inri Evangelical Spiritual Church, Primate Elijah Ayodele, ti tu aṣiri bo ṣe kilọ fun aarẹ ilẹ America, Donald Trump, ṣaaju ko to o gbe apoti ibo fun saa keji.
’’Gomina ti  won sẹsẹ dibo yan ni ipinle Ekiti, Kayode Fayemi wa sọ pe bi awọn kan se n kuro ninu ẹgbẹ  APC lo sinu ẹgbẹ  miiran ko le jẹ ipalara fun ẹgbẹ  naa lati maa jawe olubori ninu eto idibo to n bo lọdun 2019.
Awọn miran lara wọn gbe owo kalẹ fun iwọde naa, bẹẹ ni awọn mii ẹwẹ n ru wọn soke lati tẹsiwaju ninu iwọde ọhun.
Irinajo to le diẹ ni wakati meji ni Kankara si ilu Daura ti Buhari wa.
 Ẹ ̀ gbá Òwu lo si n yan Ẹ ̀ kẹrin ìlú .
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Fulani Kidnapping: Owó púpọ̀ la san kí wọ́n tó fi mi sílẹ̀ lẹ́yìn ọjọ́ mẹ́fà Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Fulani Kidnapping: Owó púpọ̀ la san kí wọ́n tó fi mi sílẹ̀ lẹ́yìn ọjọ́ mẹ́fà 8 Agẹmo 2019 Awọn Fulani yii ti pa ọpọlọpọ eniyan sinu igbo - Omowe Hamzat Ẹranko làwọn Fulani tó jí mi gbé lọ́nà Ijẹbujẹṣa ṣùgbọ́n ó ní ọwọ́ kan Yorùbá nínú Ọrọ àwọn Fulani ajinigbe amunipa ni ilẹ̀ Yoruba yii ti n gba ẹbọ lọwọ tonile talejo ni eyi ti apa kan ijọba ko ṣi tii gbagbọ pe o kọja bẹẹ.
Gbogbo yín pátá ní ilẹ̀ náà, ni ẹ óo máa sìn mí níbẹ̀.
To si bẹ Ronke lati pada lọ.
Wọ́n pa ẹgbaa mejidinlogoji ó dín ẹgbẹrun (75,000) ninu àwọn tí wọ́n kórìíra wọn, ṣugbọn wọn kò fi ọwọ́ kan ẹrù wọn.
" Oríṣun àwòrán, @Buharisallau1 Àkọlé àwòrán, Awọn to wa ninu igbiimọ naa ni; ijọba Naijiria, ijọba Benin ati ijọba Niger Republic.
Bekinbo so pe, awon ijoba ibile mejeeji ni won ni igbimo alamoju to si awon ohun elo naa.
Hunter pada di agbẹjọro ko to di pe aye rẹ yiwọ.
O ni awọn adari ajọ idanwo mejeeji jọ joko papọ ki wọn to jọ kede ọjọ idanwo ni ki ọkan obi ati akẹkọọ le jọ papọ.
Bí ẹnikẹ́ni bá rò pé wolii ni òun tabi pé òun ní agbára Ẹ̀mí, kí olúwarẹ̀ mọ̀ pé àṣẹ láti ọ̀dọ̀ Oluwa ni ohun tí mo kọ ranṣẹ si yín yìí.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Mo fi iṣẹ́ Banki silẹ̀ lọ bẹ̀rẹ̀ alápatà - Derin Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
kí gbogbo àwọn orílẹ̀-èdè ayé lè mọ̀ pé OLUWA ni Ọlọrun, ati pé kò sí ẹlòmíràn mọ́.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Isho Pepper: Isola Ogunsola pẹ̀lú àfihàn àwọn ìyàwó tó jẹ́ igi lẹ́yìn ọgbà fun un nínú iṣẹ́ tíátà 26 Èbibi 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 29 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Oríṣun àwòrán, Other Yoruba ni igba ko lọ bi orere, ako o tọ lọ bi ọpa ibọn, nitori saa laa ni, ẹnikan ko lo ile aye gbo.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Kidnapped Girl: Iyá Ikimot ní lẹ́yìn ọ̀pọ̀ ìdààmú àti owó láti wá ọmọ náà, òun sọ ìrètí nù Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Deaf parents and siblings: Láàrín ìdílé ẹlẹ́ni márùn ún yìí, ọmọ kan ṣoṣo ló léè sọ̀rọ̀ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Deaf parents and siblings: Láàrín ìdílé ẹlẹ́ni márùn ún yìí, ọmọ kan ṣoṣo ló léè sọ̀rọ̀ 22 Òkùdu 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 29 Òkùdu 2020 Ọdọmọkunrin kan to jẹ ẹnikan ṣoṣo to lee sọrọ laarin idile ẹlẹni marun un ba BBC Yoruba sọrọ lori idojukọ rẹ.
n óo fìdí ìjọba rẹ múlẹ̀ ní Israẹli, gẹ́gẹ́ bí mo ti ṣèlérí fún Dafidi, baba rẹ, pé arọmọdọmọ rẹ̀ ni yóo máa jọba lórí àwọn ọmọ Israẹli títí lae.
Kí ni ìbáà ṣẹlẹ̀, tí ẹ fi níláti yára yipada kúrò lọ́dọ̀ OLUWA bẹ́ẹ̀?
O ni ko sẹni to mo ohun to tun kan lẹyin gbogbo eleyii.
Ilẹ̀ Tí Wọ́n Pín fún Ẹ̀yà Efuraimu ati ti Manase ní Apá Ìwọ̀ Oòrùn.
ilé-ita : gégé bí ìtàn se so , ní orí ilè yí nì àwon ará ìlú pàápàá jùlo àwon àgbàgbà lókìnrin ti ma ń ta ayò bí wón bá ti took dé láyé ìgbà náà .
Ta ni ọ́ tí o fi ń sọ ohun tí ó yẹ kí á ṣe fún wa?
Nígbà tí àwọn ràkúnmí rẹ̀ mu omi tán, tí gbogbo wọn yó, ọkunrin yìí fún un ní òrùka imú tí a fi wúrà ṣe, tí ó wọ̀n tó ìwọ̀n ìdajì ṣekeli, ati ẹ̀gbà ọwọ́ meji tí a fi wúrà ṣe tí ó wọ̀n tó ìwọ̀n ṣekeli wúrà mẹ́wàá.
Gẹ́gẹ́ bí ìgbàgbọ́ àwọn Júù, Ẹlẹ́dàá tì kárarẹ̀ ló fún ẹ̀dá alààyè kìn-ín- ní ní orúkọ.
S Embassy Jamilu ni lẹyin eyi ni awọn sare gbe Farawa lọ sile iwosan Wudil Hospital nibi ti wọn ti ni pe Farawa ti doloogbe.
Ọlọrun yóo fi ìfẹ́ rẹ̀ tí kì í yẹ̀ati òtítọ́ rẹ̀ hàn!
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ǹjẹ́ o mọ Olorì Moremi tó jà fún òmìnira àwọn ẹrú nílẹ̀ Ifẹ̀?
Ọlọrun rí i pé ayé ti bàjẹ́, nítorí pé ìwà ìbàjẹ́ ni gbogbo eniyan ń hù.
Àwọn eniyan burúkú,àní, gbogbo orílẹ̀-èdè tí ó gbàgbé Ọlọrun, ni yóo lọ sinu isà òkú.
Ni ti dokita Adewale to n ṣiṣẹ ni ileewosan aladani kan ni Ado Ekiti, ipinlẹ Ekiti, o ni bi oun ba ri anfani ati lọ ṣiṣẹ loke okun, oun yoo ko ẹru oun kia.
Fún àpẹẹrẹ Ilé - Ẹ̀kọ́ gíga (Grammar Schoo) méji tí ó wà ní ilú náà, òógùn ojú wọn ni wọ́n fi kọ̀ wọn, bẹ́ẹ̀ náà ni Modern School wọn.
Bí ọjọ́ kọ̀ọ̀kan ṣe nlọ ni ojúmọ àti ilẹ̀ṣú a máa gba ìsẹ́jù méjì-méjì lọ́wọ́ arawọn, títí tí wọ́n a fi dọ́gba ní wákàtí 12 sí 12.
5 Kíyèsíi, ìbùkún ni fún ọ nítorí ohun yí, àti fún sísọ àwọn ọ̀rọ̀ mi èyí tí mo fi fún ọ gẹ́gẹ́bí àwọn òfin mi.
 Ọpọ to ti wo fidio naa ni wọn ti ni bi igba ti a pẹ ara sọ oloogbe naa ni o fi sọ ọrọ naa lai mó pe oun pẹlu yoo di ara ilẹ laipẹ jọjọ."
Ṣugbọn wọ́n fẹ́ kí ẹ kọlà kí wọ́n máa fi yín fọ́nnu pé àwọn mu yín kọlà.
Ninu ifọrọwanilẹnuwo BBC pẹlu Lere Olayinka ti o jẹ agbẹnusọ fun Gomina Fayọṣe, o ni Fayọṣe t'ẹnumọ pataki igbepọ lalafia laarin awọn ọmọ orilẹede yi.
Gbigbe aba ati imọran kalẹ eleyii to nii se pẹlu isẹ ti wọn gbe le wọn lọwọ.
Contortion: Nígbà tí mo rí bí ara Soffie Dossi ṣe rọ̀, mo pinu pé mo lè ṣe bẹ́ẹ̀
Njẹ́ ẹmu máa n fa inú rirun tàbi egbò inú (Ulcer) Collins Akanno ni lóòtọ́ ni ẹmu ni ìdá márun ọti nínú sùgbọ́n kìí fa inú rírun tàbi ẹgbò inú.
"Mo lee faramọ Nnamdi Kanu nitori ohun ti ẹgbẹ rẹ n ja fun ati nitori oun ti oju awọn eeyan rẹ n ri, ṣugbọn mi o kii n ṣe ọmọ ẹgbẹ IPOB, ọmọ orilẹede Naijiria ni mo jẹ.
Ọgbẹni Ogwu sọ pe ọfẹ ní ìjọba UK n ṣe iru ayẹwo bẹẹ fawọn arinrinajo.
ọ̀gá ẹrú náà yóo dé ní ọjọ́ tí kò rò, ati ní wakati tí kò lérò.
Ẹyin ni kii ṣe owo gọbọi.
Arun aṣekú pani ọ̀hún, sì ni abiku rẹ ti sọ àwọn oníṣègùn jákèjádò àgbáyé di èké, tí wọn si ni àwọn ko ri ìwòsàn fún ajakalẹ-arun Covid-19 náà.
Oluwo bu èpè lu àwọn tó dá a lẹ̀bi pé ìgbéyàwó rẹ̀ túká Oral Sex: Bóo bá ń gba ẹnu ní ìbálòpọ̀, wo àìsàn tóo lè kó lójú ara rẹ ''Emi ni ọkọ oṣo, emi ni ọkọ ajẹ, emi ni ọba to ba lori ohun gbogbo ni ilẹ Iwo, nitori naa mi o le tun maa bọ oriṣa laafin,'' Oluwo lo sọ bẹẹ.
Wọn mojuto, bẹẹ si ni wọn kopa ti wọn si paṣẹ bi wọn se pa''  Ninu wọn la ti ri awọn osisẹ ologun lati ilẹ Amẹrika ati awọn ilẹ miran ti ẹka idajọ wa si ti fi iwe asẹ ki wọn mu wọn sita koda a ti fi to Interpol leti'' Olupẹjọ agba naa sọ pe orukọ aarẹ Trump lo lewaju ti awọn yoo si gbe igbesẹ lati mu koda ko ti kuro lori alefa."
Ṣugbọn bí eniyan bá kú, a óo tẹ́ ẹ sinu ibojì,bí ó bá ti gbẹ́mìí mì, ó di aláìsí.
Àwọn agbófinró ti gbé Naira Marley lọ sílé ẹjọ́ fún ẹ̀sùn tí tàpá sí òfìn ìséde Ganduje àtàwọn èèkàn ìlú míì sàmì ogójì ọjọ́ tí Ajimobi dará ilẹ̀ Kí ló fa iná ńlá tó ṣẹ́yọ lọ́jà Ajman ní Dubai?
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Osun Osogbo: Àtáója ní káwọn èèyàn wá bọ Ọ̀ṣun lónìí, torí kò ṣe é jígbé, Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Osun Osogbo: Àtáója ní káwọn èèyàn wá bọ Ọ̀ṣun lónìí, torí kò ṣe é jígbé, 16 Ògún 2019 Ni oni ti ayẹyẹ ọdun Ọsun Ọsogbo n waye, baba Ọlọsun tilu Osogbo, Oloye Ọlayiwọla Adigun tun ti fi igbe ta lẹẹkan si fun BBC Yoruba pe, ayederu Ọsun ni wọn n bọ nilu Osogbo loni, kii se ojulowo.
Isele ibugbamu ohun waye nile epo robi, eleyi ti opo padanu emi, dukia sinu isele n la ibi naa ti o waye lojo aje(Monday), niluu Lafia.
Bàálù Ọsinbajo: Kété tó gbéra tán ló ń yọ̀ èèfín
lati ilu Maiduguri siluu Monguno wa ni sisi sile fun irin ajo awon ara ilu.
Ṣugbọn adura mi nisinsinyii ni, “Kí Ọlọrun, túbọ̀ fún mi ní okun.
Oga ọlọpaa Femi Joseph to wa nidii iwadii ẹjọ naa gba awọn obinrin nimọran lati sa asala fun ẹmi wọn.
"Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Láàrín ìṣẹ́jú díẹ̀, ẹ ka ìwé Akinwumi Ishola, ""Nítorí Owó"" lórí Akomolede Yoruba Bakan naa ni wọn salaye pe awọn ẹgbẹ alajẹṣẹku ti wọn forukọ silẹ pẹlu ijọba to jẹ ti awọn ọdọ naa yoo jẹ ninu anfani yii."
ede Naijiria ati Angola yoo fọwọsowọpọ lati jọ mojuto eto alaafia, isejọba ati aabo
Koda, se ni awọ̀n eeyan to jade laarọ oni n sa kijokijo kiri lati sa asala fun ẹmi wọn.
Europa League Final: Chelsea lu Arsenal ní àlùdákú ní Baku.
Olayinka ti gba ijoba tuntun to n bo nimoran lati ma se je ki iwa janduku joba  ni Ipinle Oyo.
Èrò àwọn ọmọ Naijiria ṣọ̀tọ̀ọ̀tọ̀ lórí Tinubu àti Abbo Ilé ẹjọ́ sún ẹjọ́ Sẹ́nétọ̀ Abbo síwájú pẹ̀lú béèlì mílíọ̀nù márùn-ún Ilé iṣẹ́ ọlọ́pàá ti bẹ̀rẹ̀ ìwádìí sí ọ̀rọ̀ Sẹ́nétọ̀ Abbo Ìjọba ló ń ṣe kóríyá fún àlàfo ńlá láàrin ọlọ́rọ̀ àti mẹ̀kúnnù - Oxfam Sẹnetọ Abbo ṣalaye fun BBC News Yoruba pe ile ẹbi oun lagbegbe Muchalla nijọba ibilẹ Mubi North nipinlẹ Adamawa ni nnka bii agogo kan oru.
Blind Couples: Pẹ̀lú ìpèníjà ojú, tọkọtaya bímọ mẹ́ta, tí wọn sì tún ń ṣiṣẹ́ olùkọ́
 fábùnmi ( 1998 : 23-24 ) pè é ní ojúṣe .
Jeremaya sọ fun awọn tí wọn rán sí i, 
Bá ọmọ rẹ wí nígbà tí ó sì lè gbọ́ ìbáwí,má sì ṣe wá ìparun rẹ̀.
Amọ Oludari agba fun ajọ eleto ilera ni agbaye WHO, Tedro Adhanom Ghebreyesus tẹnu mọ pe, o si ṣee ṣe lati mu adinku nla ba ọwọja arun naa, ti a ba ṣe aayan to yẹ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù SERAP: Ìwàdìí ní ẹ̀ka iṣẹ́ ọlọ́pàá àti ìdájọ́ ló kúndùń ìwà àjẹbánu jùlọ 27 Ẹrẹ̀nà 2019 Oríṣun àwòrán, @PoliceNG Lánàá òde yìí ni àjọ kan ti kìí ṣe ti ijọba, Socio-Economic Rights and Accountability Project, (SERAP) ṣe agbéjade pe ,ó ṣeeṣe kí ìwà jẹgudujẹra túbọ pọ̀ si ni orilẹ̀-èdè Nàìjíríà bí ó tilẹ̀ jé pé ijọba tó ń bẹ lóde ní ǹkan ti àwọn ń koju rèé láti ọdun mẹrìn sẹ́yìn.
Lọwọ lọwọ bayii, awọn afọbajẹ mejila nilu Iwo ti n rọ ile ẹjọ giga ijọba ipinlẹ Osun, lati da Oluwo lọwọkọ, ko maa baa rọ wọn loye.
"Florence Ajimobi tahùn sí igbákeji gómìnà Oyo lórí ikú ọkọ rẹ̀, ""Gbogbo wa làó kú"" Orúkọ ìnagijẹ mẹ́jọ tí wọ́n fi ń pe Abiola Ajimọbi nígbà ayé rẹ̀ ""Ọna ile ijọba ni dokita naa wa, lẹyin ti mo ránṣẹ pé e láti ba mi sọrọ l'ori aisan Ajimobi, ki ọkọ rẹ to jẹ ọkan lara awọn to di ipo mu ninu ise jọba Ajimobi, to sọ fún un pe ko pada, ko si yọ́ wọ ilu Eko."
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù International Women's day 2020: Àwọn obìnrin tọ́kasí pàtàkì ìbáraẹnidọ́gba láárin ọmọnìyàn Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ International Women's day 2020: Àwọn obìnrin tọ́kasí pàtàkì ìbáraẹnidọ́gba láárin ọmọnìyàn 8 Ẹrẹ̀nà 2020 Ọjọ kẹjọ ọdọọdun ni ayajọ awọn obinrin lagbaye nibi ti gbogbo agbaye ti n kọju si awọn obirin lati yombo awọn iṣẹ takuntakun ti wọn gbe ṣe lai nọọni oniruuru ipenija, ẹdun ọkan ati ilakaka wọn fun aṣeyọri gbogbo laarin kaakiri agbaye.
Àwọn aṣòfin náà, sọ̀rọ̀ yí ní Ọjọ́bọ lákókò ìjókòó lẹ́yìn ọjọ́ tí Aare Muhammadu Buhari kéde pé òun ti yí àyájọ́ ọjọ́ ìjọba tiwantiwa padà láti May 29 sí June 12 láti fi buyì kún Abiola.
'Yorùbá yóò gba ìjọba ni 2023 ti wọ́n bá gbé Buhari wọlé ni 2019'
'Aláàbọ̀ ara tó ń dari ọkọ̀ ojú pópó ní àìlera kìí ṣàrùn'
Bẹ́ẹ̀ ni ó sì rí, bí ẹ̀yin náà ti mọ̀.
ẹni tí ó fi ara rẹ̀ fún wa, láti rà wá pada kúrò ninu gbogbo agbára ẹ̀ṣẹ̀, ati láti wẹ̀ wá mọ́ láti fi wá ṣe ẹni tirẹ̀ tí yóo máa làkàkà láti ṣe iṣẹ́ rere.
Oloye Falae ni bo yo amọtẹkun ba ofin tabi ko ba ofin mu, awọn agbẹjọro nikan lo le sọ.
Kí o sì máa da ẹ̀jẹ̀ gbogbo àwọn ẹran tí wọ́n bá pa fún ìrúbọ sí orí rẹ̀.
Davido fi ọkọ̀ Porsche ṣe ayẹyẹ ọjọ́ ìbí fún Chioma Avril
Sina Jesu ní orúkọ́ mi báyìí, ń kò jẹ́ Shina Rambo mọ́ - Adigunjalè tẹ́lẹ̀ kìlọ̀ Ṣé lóòtọ́ ni olorì méjì míì tún ti kúrò láàfin Oyo?
Meji ninu awọn olugbe agbegbe naa to ba awọn oniroyin sọrọ Arakunrin Alimi Olumuyiwa ati Wasiu Adeshina ṣe alaye wi pe eeyan mẹta ọtọọtọ lo ri sinu agbara ojo lọjọ Aje.
”Ewe, bi a ko ba tun gbagbe
Mompha to jẹ ilumọọka lori ayelujara, to si n jẹjọ lori ẹsun ikowo tuulu lọ si oke okun.
OLUWA bá Jeremaya sọ̀rọ̀ lẹẹkeji, nígbà tí ó ṣì wà ní ẹ̀wọ̀n, ní àgbàlá àwọn tí ń ṣọ́ ààfin.
Ìràwọ̀ tí kò gbébìkan ni wọ́n.
Aisan ikọlu ọkan lo ṣekupa Maradona lẹyin to ṣiṣẹ abẹ ọpọlọ tan tori ẹjẹ to da si i lọpọlọ.
Ṣugbọn Samuẹli wí fún un pé, OLUWA kò yan ọ̀kankan ninu wọn.
Ninu iwadii yii, ikọ BBC Africa Eye tẹle ikọ naa wọnu igbo lati ri bi ogun ti wọn n gbe ti ijinigbe naa ṣe ri.
Oríṣun àwòrán, Oyo State Poly Ibadan: Ọjọ́ iwájú la rò táa fí dáná sún fóònù àwọn akẹ́kọ̀ọ́ Ìwọ báwo!
Iléeṣẹ́ ọmọ ogun dá Bashir tó ri owó he lọ́lá Ọmọ Yorùbá tó bá ti rú òfin, ẹ gbé e jàntò - Oluwo Mo ṣe tán láti kú tọmọ taya bí wọn kò bá fi El-Zakzaky sílẹ̀ - ọmọ ẹgbẹ́ Shiite Ọlọ́pàá Kwara ti rí ọmọ orílẹ̀-èdè Turkey mẹ́rin gbà padà lọ́wọ́ ajínigbé!
Nígbà tí mo ronú títí ohun tí mo lè ṣe nípa ẹyọ àgbàdo yìí tí n kò rí, mo ní, ‘Jọ̀wọ́ Ọlọ́run má ṣàìkọ́ mi lọ́gbọ́n tí n ó gbà pẹ̀lú àgbàdo yìí o.
Lẹyin naa lo sọ pe oun ti i sinu kanga lati gbẹsan bi iya rẹ ṣe maa n fi iya jẹ oun.
Iwadi ajọ Global Burden disease lọdun 2017, pẹlu ibudo Health Metrics and Evaluation.
Ṣugbọn Jesu dáhùn pé, “Peteru mò ń sọ fún ọ pé kí àkùkọ tó kọ lálẹ́ yìí, ẹẹmẹta ni ìwọ óo sọ pé o kò mọ̀ mí rí!
ijoba se lojoRu , ojo kejo, osu karun un, odun 2019.
Dafidi ọba pe gbogbo àwọn olórí ní ilẹ̀ Israẹli jọ sí Jerusalẹmu, àwọn olórí láàrin àwọn ẹ̀yà Israẹli, àwọn olórí àwọn ìpín tí wọ́n ń ṣiṣẹ́ fún ọba, àwọn ọ̀gágun ẹgbẹẹgbẹrun ọmọ ogun, ati ọgọọgọrun-un ọmọ ogun, gbogbo àwọn tí wọ́n jẹ́ alabojuto ohun ìní ati ẹran ọ̀sìn ọba, àwọn tí wọ́n ń tọ́jú àwọn ọmọ ọba, àwọn tí wọ́n ń ṣiṣẹ́ ní ààfin, àwọn eniyan pataki pataki ati àwọn akọni ọmọ ogun, gbogbo wọn péjọ sí Jerusalẹmu.
Ẹnu ya àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ nítorí gbolohun yìí.
“Ọjọ́ ayé mi ń sáré lọ tete,kò sí ẹyọ ọjọ́ kan tí ó dára ninu wọn.
Ó jáde lọ láìmọ̀ ibi tí ó ń lọ.
"Kwam 1 ni lẹ́yìn ìgbà tí òun bẹ̀rẹ̀ orin kíkọ, tí òun lọ kọrin ni ilẹ̀ Gẹ̀ẹ́sì, ní Asiwaju tún ṣe àwárí òun, tí òun si dara pọ mọ ijija-gbara kan to ń ṣe nígbà náà.
Diana já kúrò nínú ìdíje BBnaija Ǹjẹ́ o mọ̀ pé o le gba owó lára 'ATM' láì lo káàdì?
“Mo sọ gbogbo nǹkan yìí fun yín kí igbagbọ yín má baà yẹ̀.
Yóo ti pẹ́ tó kí wọ́n tó máa gbà mí gbọ́, bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé mo ti ṣe iṣẹ́ ìyanu láàrin wọn?
Wọ́n tó ẹgbẹrun (1,000) eniyan, atọkunrin, atobinrin.
”Aare wa ro awon omo orile ede Naijiria lati keyin si awon to n gbero lati pin orile ede yii nipa lilo esin ati eya, pe won ko ni ipinnu rere fun orile ede .
Ó tún ṣe é ṣe kí (Kódà àdínkù tún lè báa).
Ẹni to bori: Morocco Ghana vs Mali.
Ikọ agbẹjọro Fayose rọ ile ẹjọ naa lati fi ojuure wo ẹbẹ rẹ fun gbigba oniduro rẹ.
Opeyemi Aiyeola Aworan ọmọdebinrin ti ẹyin aṣọ rẹ kun fun ẹjẹ ni Opeyemi fi sita lati sọ pe ọmọdebinrin ni wa, ọdọbinrin ni wa, agba obinrin ni wa, iya ni wa, a nilo idajọ fun awọn ọmọbinrin wa."
O ni owo naa ni oun fẹ gba pada ti oun fi ko awọn simẹnti naa.
Ó fi ìmọ̀ ìjìnlẹ̀ fọ́kọ́ mú fún onílé
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Satchet Alcohol ban: Ìjọba àpapọ̀ yóò fòfin de títà àti rírà ọtí inú ọ̀rá bíi 'pẹlẹbẹ', 'pàrágà' 13 Owewe 2020 Oríṣun àwòrán, others Paraga, kainkain, fona gau ati omiran wo lẹyin tun mọ?
Nigba tí o ṣé àbẹwò sí àgbègbè tí ìṣẹlẹ náà kàn Gomina Amosun ro àwọn ará ìlú láti ye ma ko ilé sójú ònà ti omi n gbà.
Nígbà tí ó máa balẹ̀ ó balẹ̀ sí ojú odò kékeré kan tí ó ń sán, odò náà sì ń gbé e lọ.
Àwọn ìròyìn mìíràn tí ẹ lè nífẹ̀ẹ́ sí: Àwọn òrin tó ń k'ókìkí àwọn ọmọ Yahoo R Kelly sunkún lóri Tẹlifísàn nípa ẹ̀ṣùn ìbálòpọ̀ Hubert Ogunde ló m'órí mi yá láti di òṣèré Iyowuna yii ni iroyin naa ni o gbe ọmọ ohun fun ẹni to fẹ ra, William Cynthia ati ọkọ rẹ, ti wọn si san ẹgbẹrun lọna ọtalelẹgbẹrin o din mẹwa naira (₦850,000) fun.
Nítorí náà, wọn kò kó egungun rẹ̀ ati egungun wolii tí ó wá láti Samaria.
Ó bá ya ẹnu, ó bẹ̀rẹ̀ sí sọ̀rọ̀ àfojúdi sí Ọlọrun.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù EPL: Chelsea ati Manchester United f'idi rẹ'mi 1 Èrèlè 2018 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Manchester United wa ni ipo keji lori tabili pelu ami mẹ́tàleláàdọ́ta Ẹgbẹ agbabọọlu Manchester United ati Chelsea ti ja walẹ kuro loke tente ti wọn wa lori tabili ife eye Premier League latari bi wọn se f'idi rẹ'mi ninu ifẹsẹwọnsẹ pelu Tottenham Hotspur ati AFC Bournemonth lalẹ ọjọru.
Oríṣìí òkúta mejila ni yóo wà, orúkọ wọn yóo dàbí orúkọ àwọn ọmọ Israẹli; wọn yóo dàbí èdìdì, wọn yóo sì kọ orúkọ àwọn ẹ̀yà Israẹli mejila sí ara àwọn òkúta mejeejila, òkúta kan fún ẹ̀yà kan.
Ṣugbọn nígbà tí ó rí i pé ibi ìsinmi dáraati pé ilẹ̀ náà dára,ó tẹ́ ẹ̀yìn sílẹ̀ láti ru ẹrù,ó sì di ẹni tí wọn ń mú sìn bí ẹrú.
Amòfin náà dáhùn pé, “Ẹni tí ó ṣàánú fún un ni.
Oríṣun àwòrán, Lilo Aderogba/Instagram O ni ifẹ ti oun ni si Eric ti oun ṣalabapade lori eto naa jẹ ki oun sọ afojusun oun nu.
Wo àwọn bẹbẹ tí Umar Musa Yar'adua ṣe lórí àlééfà Ẹgbẹ́ àwa dókíta ló ra ìbòmú fúra wa- Alága NMA Ogun Lóòtọ́ lò n lo ìbomú-bẹnu, ṣùgbọ́n ṣe bóṣeyẹ kí o wọ̀ ọ́ ló ṣe n ṣe?
OLUWA bá rán ìtàkùn kan, ó fà á bo ibẹ̀, o sì ṣíji bo orí ibi tí Jona wà kí ó lè fún un ní ìtura ninu ìnira rẹ̀.
ile akede Naijiria, Ibrahim Buba n soro , o ni : “Alaga ẹ gba mi laaye lati sọrọ
Joṣua ati gbogbo àwọn ọmọ Israẹli bá pada sí Debiri, wọ́n sì gbógun tì í.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Food Measurement: Wo oríṣiríṣi ọ̀nà tí ò lè fi wọn oùnjẹ́ bó bá rú ọ lójú Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Food Measurement: Wo oríṣiríṣi ọ̀nà tí ò lè fi wọn oùnjẹ́ bó bá rú ọ lójú 13 Ìgbé 2019 Onikaluku lo ni ọ̀na ti wọn n gba fi wọn ounjẹ ti wọn ba fẹ se.
Èèyàn 14 mííràn tún ti lùgbàdì ààrùn Coronavirus ní Naijiria Àrùn Coronavirus fa'lẹ̀ya láwọn ìletò aláwọ̀dúdú ní Amẹ́ríkà Màmá Guardiola d'olóògbé lẹ́yìn tó lùgbàdì Coronavirus Funke Akindele Gbajugbaja oṣere ti ọpọ mọ si Jenifa tọrọ aforiji lọwọ awọn ololufẹ rẹ lẹyin to ṣe ayẹyẹ ọjọ ibi ọkọ rẹ, Abdulrasheed Bello ti ọpọ mọ si JC Skillz ti o si tun fi fọnran fidio ayẹyẹ naa to fi si oju opo Instagram rẹ.
Ní tiwa, olórí tó dára jù ni a ní.
duro digbi sori ipo keta,  England tele
Gẹ́gẹ́ bí eniyan tií ká aṣọ ni ìwọ óo ká wọn.
Subasic ilẹ̀ Croatia kò rí bọ́ọ̀lù kọjú-sími-n-gbaá sílé naa mú ni ayò bá di 2-1.
Ijoba orile-ede Japan ti seleri lati seranlowo fun orile-ede Nigeria, latari ati gbogun ti awon ohun ayederu.
O ni o yẹ ki Gomina funra rẹ wa siwaju Ile Igbimọ Aṣofin Ipinlẹ lati ṣagbekalẹ aba iṣuna owo naa loju
Ninu atẹjade tuntun yii, Shehu ni ohun to yẹ Obasanjo gẹgẹ bi agba ilu ni ko daba ọna ati yanju ipenija to n ba Naijiria finra dipo bo ti ṣe n ru ina si ipinya labẹ ẹsin ati ẹya.
Bi o ba ni nkan idaabobo IUD.
ko to di oludari lati ọdun mẹta sẹyin ninu eyi ti wọn pe ni Gobbe, Double Wahala ati Pepper Dem.
 it duce tí ó dúró fún olórí ( the leader ) ni àwọn èyìn rẹ ̀ máa ń pè é .
Lẹ́yìn náà, yóo jáde lọ sí ibi pẹpẹ tí ó wà níwájú OLUWA, yóo sì ṣe ètùtù fún un.
Ọpọlọpọ eniyan ni wọ́n gbàgbọ́, tí wọ́n sì yipada sí Oluwa.
Ọlọrun, a ti fi etí wa gbọ́,àwọn baba wa sì ti sọ fún wa,nípa àwọn ohun tí o ṣe nígbà ayé wọn,àní, ní ayé àtijọ́:
Ọba náà dáhùn ó sì wí pé: Olówó-ayé, o ṣeun púpọ̀.
Oríṣun àwòrán, NNPC Ileesẹ elepo rọbi naa wa ba awọn ẹbi ati ara awọn to ku ninu isẹlẹ ibugbamu yii kẹdun, ti wọn si gbadura pe Ọ́lọ́run yoo fun wọn ni ẹmi lati la akoko iku ololufẹ wọn kọja lai lewu.
Ó jẹ́ onísòwò asọ fún bí i ọdún mẹ́tàlá kó tó di pé ó dara pọ̀ mọ́ eré Tíátà tó sì bẹ̀rẹ̀ sí pa'wó látara rẹ̀ lọ́dún 1984.
Aarẹ orilẹ-ede Naijiria naa wa rọ awọn ọmọ orilẹ-ede Naijiria lati ma ṣe ti ọrọ oselu bọ ipaniyan to n waye naa, ki awọn ba le tete ri awọn to n ṣiṣẹ ibi yii, ki wọn si fi wọn jofin.
Sebi ariṣe ni arika, bẹẹ, arika si ni baba iregun, ohun ti awa naa ba ṣe loni fun itẹsiwaju ede ati aṣa ati iwa ọmọluwabi ti a mọ iran Yoruba mọ naa ni a o sọ nipa wa lẹyin ọla.
Bẹẹ naa lawọn kan naa seku pa awọn ọmọ ẹgbẹ okunkun Black Axe.
Wọ́n ń gbèrò ọ̀nà bí wọn yóo ti ṣe lè fi ẹ̀tàn mú Jesu kí wọ́n lè pa á.
ohun ti ajo eleto idibo se lati sun eto idibo siwaju nitori isele buruku ti
Ijọba maa n rọ awọn ile iwe lati fi eto wọn ranṣẹ sawọn akẹkọọ lori ayelujara.
Mi o ti ri fọnran fidio naa Iru iṣẹlẹ bayi kii ṣe ajoji pẹlu awọn ọlọpaa l'orileede Naijiria to si mu ki ọpọ eeyan ma ni ireti ninu wọn.
Ó sì ń ronú bí eniyan.
Lagbaye o le ni miliọnu kan ati ẹgbẹrun lọna ọdunrun eeyan to ti ko arun naa, ẹgbẹrun marundinlọgọrin eeyan lo si ti tipasẹ arun naa ku.
Ibeere mii to tun jọ ti akọkọ yi ni pe ṣe wọn le e kuro ni aafin ni, tabi fun'ra rẹ lo kuro.
Oríṣun àwòrán, Ncdc Àjọ NCDC kéde ènìyàn 195 míràn tó ní ààrùn Covid-19 l'órílẹ̀-èdè Nàìjíríà.
Mailafia sọ eyi lasiko to n ba BBC sọrọ lẹyin ti Ajọ ọtẹlẹmuyẹ DSS fi silẹ lẹyin ifọrọwanilẹnuwo.
aladaani lorile ede Naijiria, ni eyi ti yoo tun din agbara awon egbe osise ku.
Iṣẹ ọwọ́ loriṣiiriṣii ni ọdọmọde Andrew Haruna to ti di ọjọgbọn bayii to tun n tukọ fasiti ijọba apapọ ni Gashau nipinlẹ Yobe (FUGA) fi bẹrẹ aye rẹ.
“Ní òpin ọdún, nígbà tí o bá parí ìkórè gbogbo èso oko rẹ, o gbọdọ̀ ṣe àjọ̀dún ìkórè.
Eyi waye lẹyin ti ijọba ilẹ Burundi ti bẹrẹ si nii yọ owo osu osisẹ lati seto idibo lọdun 2020.
Ìlú Dafidi ni wọ́n sin ín sí, ṣugbọn kì í ṣe ní ibojì àwọn ọba.
World Food Day: Wo àwọn oúnjẹ ìṣẹ̀mbáyé Yorùbá tó ti ń di àpatì Akẹ́kọ̀ọ́ Ilaro Poly tó pegedé jù jẹ ẹ̀bùn iṣẹ́ ọ̀fẹ́ lọ́wọ́ Gómìnà Abiodun Ẹbí Buhari lásán ni Mamman Daura kò nípò òṣèlú kankan Kò sí ìdí fún àjọyọ̀ lórí ọdún kan ìṣèjọba Fayemi - Ekiti PDP Ninu ọrọ ti ọfiisi aarẹ fi sita loju opo Twitter, aarẹ ni gbogbo irin to ba jẹ mọ irin okeere gbọdọ jẹ eleyii ti yoo mu anfani ba orilẹede Najiria.
Wo ọ̀nà tóo lé tọ̀ láti gba físà tóo bá fẹ́ ṣiṣẹ́ ní UK lábẹ́ ìlànà tuntun Ilé-ẹjọ́ kòtẹ́milọ́rùn fòntẹ̀ lu ìdájọ́ ikú fún Maryam Sanda tó gún ọkọ rẹ̀ pa Díẹ̀ ló kù kí ọjọ́ ìkúnlẹ̀ di ọjọ́ ikú fún ìyá mi lọ́jọ́ tó bí mi - Seyi Makinde Nkechi Blessing vs Toyin Abraham: Nkechi tí tọrọ ìdáríjí ẹ̀ṣẹ̀ lọ́wọ́ akẹgbẹ́ rẹ̀, Toyin Abraham Adari Amotekun ọhun ni awọn eeyan wọṣọ ti ko bojumu nitori aye ti n dori kodo, awọn eeyan si ti n gbe ohun ti ko dara latugẹ ju aṣa ilẹ Yoruba lọ.
Ọ̀nà tí a fi lè mọ̀ pé a fẹ́ràn àwọn ọmọ Ọlọrun ni pé kí á fẹ́ràn Ọlọrun kí á sì máa pa àwọn àṣẹ rẹ̀ mọ́.
 Ẹ jẹ ́ ká wò ó .
Mo lè fi ọ̀rọ̀ ẹnu mi fun yín lókun,kí ọ̀rọ̀ ìtùnú mi sì mú kí ara tù yín.
"Ẹ wo èrò bìbà níbi ìwọ́de #EndSARS ní ìlú Ibadan Mọ̀ nípa iPhone 12, fóònù ológo 5G tí kìí lo ""Charger” tó ṣẹ̀ṣẹ̀ jáde Pásítọ̀ Enoch Adeboye darapọ̀ mọ̀ #ENDSARS, ó fún ìjọba Nàìjíríà ní ìmọ̀ràn ọ̀nà àbáyọ Bàbá ọlọ́mọ méjì fi ipá bá ọmọ ọdún mẹ́rin lò pọ̀; Adájọ́ rán an ní ẹ̀wọ̀n gbére Aisha fi kun un pe awọn ọmọ oun gan a maa dara pọ mọ oun nibi iwọde biotilẹ jẹ pe ọkọ oun ko lẹmiu ki oju aye tan si eeyan lara."
Wahala ati ipalara si lo maa n jẹ fun ẹni to n ṣe ayẹyẹ, to ba kọ lati fun wọn ni gbogbo nkan ti wọn ba beere fun un, bi ounjẹ, ọti, ati owo.
Oríṣun àwòrán, @officialEFCC Nigba to n gbosuba fun adajọ agba lorilẹede yii, Walter Onnoghen fun aseyọri rẹ lọdun to kọja, Magu ko sai yan pe ẹka eto idajọ ni kọkọrọ ti EFCC lo lati bori ọpọ ẹjọ to wa niwaju rẹ.
"Bi o tilẹ jẹ pe nigba ti ile iṣẹ BBC kan si ajọ EFCC, wọn ni ""A ò tì ilé Saraki pa ní'lú Eko - EFCC""."
O fikun ọrọ rẹ pe gbogbo eeyan nipinlẹ Oṣun lo mọ pe Adeleke lo wọ le ibo gomina nipinlẹ Oṣun.
N kò tilẹ̀ mọ èyí tí ǹ bá yàn.
Lẹ́yìn náà, Joṣua pàṣẹ fún gbogbo àwọn olórí àwọn eniyan náà, ó ní, 
ni agbo ile Aigbọfa Oja’aba, niluu Ibadan.
West Bromwich AlbionItalia Serie A February 10 15:00 SPAL 2013 ?
O ni eto idagbasoke naa n faa Ademola Ogunbajo Àkọlé àwòrán, #BBCOGUNDEBATE: Èrò àwọn oludije ṣe ọtọ̀ọ̀tọ lóri ètò ẹkọ Ofẹ Ogunbanjo ni omo ti ko ba ko iwe to yanju ko lee ri ise se.
Oríṣun àwòrán, Seyi Makinde/Twitter Ni ti pe awọn to ni arun Coronavirus n pọ si ipinlẹ Oyo, Adisa ni ko ṣẹyin ayẹwo ojule si ojule ti ijọba ipinlẹ ọhun gunle.
America naa lo gba ife ẹyẹ naa lọdun 2015, fun idi eyi ilé ni wọn tun gbe e pada si.
Fayemi ke gbajare Bi a ko ba gbagbe laipe yi ni Gomina ti wọn sẹsẹ dibo yan ni ipinlẹ Ekiti, Ọmọwe Kayọde Fayẹmi kede pe, oun ti fa gomina to n kogba wọle nipinlẹ naa, Ayọdele Fayọṣe si kootu Ọlọrun lori awọn obitibiti gbese to jẹ lasiko to wa nijọba.
Ni aago mejo aaro ni eto yiye oruko wo ti bere ,ki o to di aago meje aaro ni apoti idibo ati gbogbo ohun eelo fun idibo  ti wa nikale .
Fadeyi ni iroyin ti awọn kojọ ni wi pe arabinrin Thomas Tosin n lọ si ile nigba ti awọn ọmọ Yahoo-yahoo bẹrẹ ariyanjiyan lori ọrẹbinrin wọn.
Àwa náà ni ó pè láti ààrin àwọn Juu ati láti ààrin àwọn tí kìí ṣe Juu pẹlu; 
’ Nítorí mò ń sọ fun yín pé Ọlọrun lè gbé ọmọ dìde fún Abrahamu láti inú òkúta wọnyi.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Child Engineer: Olamide Odukọya nílò ìrànlọ́wọ́ láti lọ síléẹ̀kọ́ ìmọ̀ ẹ̀rọ Àwọn ilé iṣẹ́ towà ni ẹ̀ka tó n pin iná mọ̀nàmọ́nà pọ̀ ní orilẹ̀-èdè Nàìjíríà.
Obinrin náà wólẹ̀ lẹ́gbẹ̀ẹ́ ẹsẹ̀ rẹ̀, ó sì dojúbolẹ̀.
Báyìí ni Baba-onírùngbọ̀n tún kọ́ mi ní ọgbọ́n pàtàkì lẹ́hìn tí ó ti pa’ri ìtàn rẹ̀ kejì yìí.
Nínú ọ̀rọ̀ rẹ̀, alukoro ọlọ́pàá nípìnlẹ̀ náà Olugbenga Fadeyi sàlàyé fún BBC Yoruba pé, gbogbo ìgbèsẹ̀ tó yẹ fun ileesẹ ọlọpaa lati gbé lori isẹlẹ yii ni awọn n gbe.
"Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ondo disability: Kò sí ẹni tí àkàndá kò lè ya ilé rẹ̀- Ayọdele ""Kii ṣe pe ko si ileewosan, ṣugbọn awọn ara igba naa kii fẹ ẹ gbe ọmọ lọ, nitori igbagbọ pe ọmọ ti wọn ba fun ni abẹrẹ yoo ku."
Nigba to n ba BBC Yoruba sọrọ lori isẹlẹ yii, Igbakeji akọwe fun agbegbe Isinigbo, Ọmọọba Joseph Akinsilu naa fi ẹsun kan Ajagunode pe o ko awọn janduku wa si aafin ọba awọn lati kọlu.
Lasiko to n ba akọ̀royin sọ̀rọ̀, Sagay pa Lawan lẹ́nu mọ̀ pe ko dẹ́kun irọ̀ pipa, ko si ma si awọ̀n ọ̀mọ̀ Naijiria lọna, pẹlu afikun pe miliọnu mẹẹdogun naira ni asofin agba kọọkan n gba lowo osu.
Ṣugbọn bí ó bá jẹ́ pé àwọn eniyan rẹ ni wọ́n ṣẹ̀, fi Tumimu dáhùn.
Nítorí ó wà ní àkọsílẹ̀ ninu Òfin Mose pé, “Ìwọ kò gbọdọ̀ di ẹnu mààlúù tí o fi ń ṣiṣẹ́ lóko ọkà.
alaga egbe APC, Adams Oshiomhole, oludari eto ipolongo fun idibo aarẹ, Rotimi
Àkàwé ni gbogbo èyí jẹ́ fún àkókò yìí.
Gbogbo wọn wà ní ìṣọ̀kan ní ọ̀dẹ̀dẹ̀ tí wọn ń pè ní ti Solomoni.
OLUWA ṣeun,òun ni ibi ààbò ní ọjọ́ ìdààmú;ó sì mọ àwọn tí wọn ń sálọ sọ́dọ̀ rẹ̀ fún ààbò.
"O ni ""Mo ro pe mo nilo lati lọ sinmi!"
Wọn yóo jẹ́ eniyan mi, èmi náà óo sì jẹ́ Ọlọrun wọn; nítorí tí wọn yóo fi tọkàntọkàn yipada sí mi.
Sebadaya, ọmọ rẹ̀, ni igbákejì rẹ̀.
''Dolapo Awosika ko wa gba ọkọ kankan lọwọ Bunmi.
Ajo eleto idibo so pe, o le ni milionu meji awon eniyan ti won ti foruko sile bayii.
Ó fi igi akasia ṣe ọ̀pá tí wọ́n fi máa ń gbé tabili náà, ó sì yọ́ wúrà bò wọ́n.
Ó fẹ́rẹ̀ tó àkókò Àjọ̀dún Àìwúkàrà tí à ń pè ní Àjọ̀dún Ìrékọjá.
Kò sí lára àwọn ẹgbẹ́ Kora tí ó ṣọ̀tẹ̀ sí OLÚWA, ṣugbọn ó kú nítorí ẹ̀ṣẹ̀ tirẹ̀ ni.
Kọmiṣọnna eto ilera ni ipinlẹ naa, Rafiu Isamotu sọ pe oloogbe ọhun to jẹ ọmọ aadọrin ọdun din diẹ gbẹmi mi ni ile iwosan ijọba Asubiaro, ni ilu Osogbo.
Igbimo amusese tipinle Akwa Ibom ti fowosi nina etalelaadorin milionu owo naira o le ni eedegberun fun ipese gbaguda lopo yanturu nipinle naa.
Lootọọ ni pe awọn eeyan ko mọ pe o lẹbun orin kikọ ko to de ile Ẹlẹgbọn Agba, ṣugbọn lẹyin to wọle BBNaija tan, lawọn ilumọọka olorin takasufe ati gbajugbaja oṣere bii Tunde Ednut, Reminince, Yinka Ayefele, Nkechi Blessing n satilẹyin fun.
Ó ní inú àgọ́ ni kí á máa gbé ní gbogbo ọjọ́ ayé wa, kí ọjọ́ wa baà lè pẹ́ lórí ilẹ̀ tí à ń gbé.
Ṣugbọn Dafidi dá wọn lóhùn pé, “OLUWA tí ó ti ń yọ mí ninu gbogbo ewu, ni mo fi búra pé, 
Akọ́mọlédè àti Àṣà lórí BBC Yorùbá: Kọ́ síi nípa iṣẹ́ tí oúnjẹ ń ṣe lára níbí
 yii ta wa lori re, won ti fi idoti di
Kolawole Ajeyemi Kolawole Ajewole to jẹ ọkọ gbajugbaja oṣere, Toyin Abraham ti dide iranwọ fawọn ara ilu Ogbomoṣo, tii ṣe ilu abinibi rẹ.
Ewe, ipade alatilekun mori ohun ni iroyin jabo re pe, yoo da lori bi ibasepo ti o donmonron ati idagbasoke yoo se jeyo laarin orile-ede mejeeji.
Èyí yóo jẹ́ ẹ̀rí fún wọn pé ara rẹ ti dá.
” Ninu gbogbo nǹkan wọnyi, Jobu kò dẹ́ṣẹ̀ rárá ninu ọ̀rọ̀ tí ó sọ.
Ẹni to bori: Uganda Ìpele to ṣaaju eyi to kangun si aṣekagba Kenya vs South Africa.
Ninu awọn aṣoju ọmọ ẹgbẹ ẹgbẹrun meji ati mọlakanlelaadọfa to dibo abẹlẹ naa, Jẹgẹdẹ ni ọrinlelẹgbẹrin o le mẹjọ, 888, Agboọla to tẹlee ni ibo ọtalelẹgbẹta ati meje.
  “lakoko yii, egbe gbọdọ ri i pe gbogbo awon
Ileejọ giga ilu Abuja lo pasẹ pe ajọ INEC ko gbọdọ tẹsiwaju pẹlu akojọpọ, ipari ati ikede esi ibo gomina nipinlẹ Bauchi.
mu lori tabili ate naa, Tunisia dipo keji mu, Morocco wa nipo kerin, DR Congo tele
Àkọlé àwòrán, Yaara yii ni Emir Kano tẹlẹ, Sanusi Lamido sun mọju Ilu naa lo balẹ si lẹyin ti ijọba ipinlẹ Kano rọ ọ l'oye.
kí ó sọ fún àwọn ọmọ Lefi pé, “Nígbà tí ẹ bá gba ìdámẹ́wàá tí OLUWA ti fún yín gẹ́gẹ́ bí ìní yín, ẹ óo san ìdámẹ́wàá ninu rẹ̀ gẹ́gẹ́ bí ọrẹ fún OLUWA.
oselu alatako Peoples Democratic Party, PDP.
Mo gbọ́ ohùn kan láti ọ̀run wá tí ó sọ pé, “Kọ ọ́ sílẹ̀!
Bí o bá fẹ́ fi àkọ́so oko rẹ rú ẹbọ ohun jíjẹ sí OLUWA, ninu ṣiiri ọkà àkọ́so oko rẹ tí wọ́n ṣẹ̀ṣẹ̀ pa ni kí o ti mú, kí o yan án lórí iná.
 siwaju 1989 , amioro iso 3166-1 fun burma ni bu , sugbon .
A kò dá Ọlọrun kankan ṣáájú mi,òmíràn kò sì ní wáyé lẹ́yìn mi.
Ẹgbẹ́ òṣiṣẹ́ Nàìjíríà so ìyanṣẹ́lódì rọ̀ Nàíjíríà ń fojú sọ́nà láti gbàlejò Ọmọọba Charles Ohun márùn ún to se kókó fún ọ lásìkò ìyanṣẹ́lódì òṣìṣẹ́ Ààyè sí sílẹ̀ fún ọmọ Nàíjíríà láti di ológun nílẹ̀ Gẹẹsì Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Lekan Kingkong: Níbikíbi tí mo bá wà, màá gbé àṣà Yorùbá ga Owoya ọhun, ti wọn pe ni TraderMoni, ni igbakeji aarẹ wa se ifilọlẹ rẹ nilu Eko, eyi to jẹ akanse eto ironilagbara ti ijọba apapọ n se fawọn ontaja kekeke ati alabọde.
Wọ́n dá a lóhùn pé, “Ará Ijipti kan ni ó gbà wá kalẹ̀ lọ́wọ́ àwọn olùṣọ́-aguntan náà, ó tilẹ̀ tún bá wa pọn omi fún agbo ẹran wa.
Gege bi Ahmad se so:”Awon ogagun nile-ise omo ogun, oga agba fun ile-ise olopaa, oludari eka otelemuye wa nile-ise aare ni aaro oni.
Àwọn gbajúmọ̀ tό wá ńkíra kú àtijọ́.
Loṣu kinni, ọdun 2009 ni ohun gbogbo yipada fun Gauri nigba ti o gbọ iroyin ikọlu si ọkọ̀ oko ẹgbọn rẹ, Subramaniyam Kannan.
Olukọni tuntun fun ikọ Falcons,Thomas Dennerby ni yoo dari ikọ naa pẹlu iranlowo Wemimo Mathew ati Maureen Madu.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Bùhárí: Ariwo ọmọ Nàìjíríà ló mú mi fẹ́ díje lẹ́ẹ̀kejì 12 Ìgbé 2018 Oríṣun àwòrán, Nigeria Presidency Àkọlé àwòrán, Bùhárí ní òṣèlú ẹ̀tánú ló wà nì ìpìlẹ̀ wàhálà àgbẹ̀ àti darandaran, Ààrẹ Mùhámádù Bùhárí ti bọ́ síta láti ṣàlàyé ìdí rẹ̀ tòun fi kéde ìpinnu òun láti gbé àpótí ìbò ààrẹ lẹ́ẹ̀kejì.
Nítorí ojú OLUWA ń lọ síwá sẹ́yìn ní gbogbo ayé láti fi agbára rẹ̀ hàn fún àwọn tí wọ́n jẹ́ olóòótọ́ sí i.
Igbakeji gomina ni  ipinle Kwara , Elder Peter Kisira naa tun
Ko si aridaju boya wọn san owo itanran kankan lati mu ki itusilẹ wọn ya kiakia.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ẹ wo àrà àwọn ọmọ kékeré ń fi ẹ̀kọ́ kọ̀mpútà dá Adeleke kọkọ bori pẹlu ibo 254,698 ti Gomina Oyetola to jẹ oludije fẹgẹ APC si ni 254,345 ninu idibo to waye lọjọ kejilelogun oṣu Kẹsan-an ọdun 2018.
N-Power 2020 recruitment: Àwon ohun tó yẹ kí o mọ̀ Oríṣun àwòrán, N-POWER 2020 REGISTRATION Wo àwon ohun tó yẹ kí o mọ̀ nípa ètò ìgbanisíṣẹ́ N-Power ọdún 2020 Ọpọ awọn eeyan lo ti n bere ohun ti wọn nilo lati ṣe iforukosilẹ fun eto igbanisiṣẹ N-Power ọdun 2020.
Lori eyi, alukoro fun ileeṣẹ ọlọpaa l'Eko, Chike Oti ninu ikede kan to fi sita sọ pe lọgan ti iṣẹlẹ naa waye ni wọn gbe Oluọmọ ati awọn mii to tun farapa lọ si ileewosan fun itọju.
pelu akole  5N-FGT, ti awon egbe to n ri
Oríṣun àwòrán, Mo Styles Àkọlé àwòrán, China a ma a fi ekutele se oti waini ẹlẹrin dodo.
Oríṣun àwòrán, AFP Àkọlé àwòrán, Owó oṣù tuntun ọ̀hún nìrètí wà pé yóò gbérasọ l'óṣù Kẹjọ, ọdún 2018.
Wọ́n ń fi oríṣìíríṣìí ife wúrà mu ọtí, ọba sì pèsè ọtí lọpọlọpọ gẹ́gẹ́ bí ipò ọlá ńlá rẹ̀.
ati pe 'Se iya rẹ a ma fi eegun bọ inu imu rẹ?
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Oluwo Divorce: Ìdí tí Oluwo fi kọ Olorì rẹ̀ sílẹ̀ rèé.
Ó fi méjìlá nínú wọn fún Adéforítì, o tún rẹ́rìn-ín kékeré báyìí ó ní, ‘Èmi ni mo sọ wọ́n di ẹranko, mo ti mú wọn kúrò nínú ipò ènìyàn, wọn kò gbọdọ̀ kúrò ni ibi tí o ti rí wọn yìí, mò ń lò wọ́n fún iṣẹ́ ṣse ni’.
AMAA 2018 Ami eye fi iran to je oju nigbese
’ Ṣugbọn yóo da yín lóhùn pé, ‘Èmi kò mọ̀ yín rí!
Lonii, irọ ipese iṣẹ ni Arab world, Saudi Arabia, Qatar, Oman, Libya, lawọn afini s'owo ẹru maa n pa fun awọn ti wọn ba fẹ lo.
Àwọn ọmọ ogun tí a kà ninu wọ́n jẹ́ ẹgbaa mejilelogun ó lé aadọta lé ní ẹgbẹjọ (45,650).
"Gẹgẹ bi ọrọ awọn eléde Gẹẹsi to sọ pe ""ẹni ti ko ba mura silẹ fun àṣeyọrí, n mura silẹ lati fìdírẹmi."
Pàápàá n ó máa ṣe ìrántí ọjọ́ tí mo rí ọ lójúkorojú ní Orílẹ̀ Senegal láìpẹ́ tí wọ́n tú ọ sílẹ̀ lọ́gbà ẹ̀wọ̀n ọdún mẹ́tàdínlọ́gbọ̀n.
Ẹ kọrin sí Ọlọrun, ẹ kọ orin ìyìn sí orúkọ rẹ̀,ẹ pòkìkí ẹni tí ń gun ìkùukùu lẹ́ṣin.
Wọ́n bèèrè pé,ẹni tí ó kó wọn la òkun já dà?
Aare tun so pe “lati odo ijoba ,awon omo orile ede Naijiria, awon alase ati ijoba ajo ECOWAS.
" Kii ṣe iroyin mọ pe ajẹẹlẹ owo oṣu oṣiṣẹ jẹ iṣoro nla ni ipinlẹ Kwara gẹgẹ bi o ṣe jẹ fun ọpọ ipinlẹ jakejado Naijiria.
Gbọ́ ohun tí OLUWA, ọba Israẹli ati Olùràpadà rẹ̀ wí,OLUWA àwọn ọmọ ogun, ó ní,“Èmi ni ẹni ìbẹ̀rẹ̀ ati ẹni òpin;lẹ́yìn mi, kò sí Ọlọrun mìíràn.
Ẹni tí ó bá ṣẹgun ni n óo jẹ́ kí ó jókòó tì mí lórí ìtẹ́ mi, gẹ́gẹ́ bí Èmi náà ti ṣẹgun, tí mo jókòó ti baba mi lórí ìtẹ́ rẹ̀.
Diana Wilson to jẹ ọga agba nile isẹ Tracemyfile ni ilẹ Gẹẹsi ni tiẹ sọ pe awọn ki fi asiko ounjẹ aarọ, ọsan tabi talẹ sẹre, koda bi isẹ ba pari tabi ti ko pari nile.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù NIMC: NIMC, NCC, NITDA àti GBB gbọ́dọ̀ ṣiṣẹ́ papọ̀ kí ètò aàbò Nàìjíríà lè dára síi 3 Èrèlè 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 31 Ògún 2020 Oríṣun àwòrán, Instagram/Bashir Ahmad Aarẹ Muhammadu Buhari ti buwọlu gbigba iṣakoso kaadi idanimọ orilẹ-ede yii lọ si ẹka ijọba to n ri si eto ibanisọrọ.
Alhaja Kudirat Abiola: Odindi géńdé ọkunrin mẹ́fà ni wọ́n gbé iṣẹ́ ikú rẹ̀ fún Mo kábámò pé mo fipá bá Ìyá ẹni ọgọrin ọdún sún ní Kano- Muhammad Zulfara'u Ọwọ́ ọlọ́pàá tún tẹ afurasí tó fipá bá odi àti adití lòpọ̀ nílùú Ibadan Ninu ero wọn, Aisha Buhari ko tori awọn eeyan sọrọ nipa titẹle ilana ijọba lasiko Covid-19 yi bi kii se pe eeyan kan tun ti fọwọ tẹ ẹtọ rẹ mọle ni Awọn kan tilẹ n beere pe se ko ni nọmba ọga ọlọpaa ni abi ki lo wa de to fi n damu awọn loju opo Twitter Ninu ero awọn ẹlomiran, wọn ni se ko yẹ ki iyawo aarẹ da si awọn ọrọ miran to n jẹ Naijiria logun lasiko yi bi ipaniyan ati ijingbe to n waye lawọn ipinlẹ kaakiri Naijiria.
 Minisita tẹlẹ naa fikun pe, ojuti nla gbaa ni ihuwasi ọhun, eyii to yẹ ko pa ni lẹkun."
" Kini ijọba sọ lori adehun yii?
@Cherrydoc_urch O n kesi awọn eeyan kan lati gbe igbesẹ lori bi fasiti Babcock se le akẹkọbinrin naa.
osise, Christ Ngige, igbakeji oludari ipolongo idibo aare Buhari, Rotimi Amechi
Orí rẹ̀ ni àrùn yìí wà.
Nítorí náà, èmi OLUWA Ọlọrun, ń ṣe ìbúra pé, àwọn orílẹ̀-èdè tí wọ́n wà ní àyíká yín yóo di ẹni ẹ̀sín.
Ọkàn mi ń ṣe meji; ọkàn mi kan fẹ́ pé kí á dá mi sílẹ̀, kí n lọ sọ́dọ̀ Jesu, nítorí èyí ni ó dára jùlọ.
Ọba Akanbi ni, òun kò gbà nkankan lọ́wọ́ aráàlú n'ilu iwo, àmọ́ òun ń lọ ṣíṣẹ wá fún wọn láti tọju wọn ni, torí òun gan ni ẹrú aráàlú, òun sì máa ń ṣe aráàlú Iwo bíi ọba ní.
Ó bukun wọn, ó mú kí wọn bí sí i lọpọlọpọ,kò sì jẹ́ kí ẹran ọ̀sìn wọ́n dínkù.
Kí ni kò jẹ́ kí olukuluku yín kúkú máa gba ìwọ̀sí?
SERAP wa ke si aarẹ Buhari pe o nilati ṣeto abo to peye fun oniroyin naa lọwọ ewu ti o lee fẹ wu u nitori aṣiri awọn alagbara ti o tu sita naa.
Nígbà náà ni Jesu sọ fún un pé, “Obinrin yìí!
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Bisi Alimi: Ìyà mi rò pé n kò leè ṣe ni àmọ́ n kò ní ìfẹ́ abo ni mo ṣe fẹ́ akọ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Bisi Alimi: Ìyà mi rò pé n kò leè ṣe ni àmọ́ n kò ní ìfẹ́ abo ni mo ṣe fẹ́ akọ 24 Ìgbé 2019 Adiitu ni ọrọ Olodumare, ko si ẹni to lee ye, bo ba si se wu ni ẹlẹda se n se ọla.
Lẹ́yìn ti fọran náà dé ìgboro lóri àyélujára ní àkàrà bá tú sepo fún olùdíjè náà, èyí ló mu ṣe ìpinnu pé oun kò díje dupo ààrẹ mọ.
Ohun to ṣẹlẹ gangan Ninu fidio naa, wọn ko ṣẹkẹṣẹkẹ si obinrin naa lọwọ ti wọn ba ni ile ti wọn ti fẹ lọ mu afurasi ole kan.
Bí mo ti jí ni ọkàn mi ti sọ fún mi pé kí n lọ ṣer oko kékeré kan kí n lọ gbin ẹyọ àgbàdo kan náà sí í.
Bí àwọn nǹkan tí kò ní ẹ̀mí tí à ń fi kọ orin, bíi fèrè tabi dùùrù, kò bá dún dáradára, ta ni yóo mọ ohùn orin tí wọn ń kọ?
Nígbà tí Jakọbu parí ìkìlọ̀ tí ó ń ṣe fún àwọn ọmọ rẹ̀, ó ká ẹsẹ̀ rẹ̀ pada sí orí ibùsùn rẹ̀, ó dùbúlẹ̀, lẹ́yìn náà ó mí kanlẹ̀, ó sì re ibi tí àgbà á rè.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Mayowa Omoniyi: Kò sí orin Obey, Sunny Ade abí tàkasúfèé tí ń kò le ta gìtá sí Osinbajo wa kesi awọn minisita lati gbe igbesẹ ni kanmọ n kia lori owo triliọnu meji o le diẹ naira tijọba gbe kalẹ lati mu adinku ba ipa arun naa lori ọrọ aje Naijiria.
Ṣáájú ni ìjọba Abiọla Ajimọbi wó lára ilé náà lulẹ̀ látàrí pé wọ́n ni Yinka Ayefẹlẹ rú òfin ìpínlẹ̀ tó ní ṣe pẹ̀lú ìlànà ilé kíkọ.
Gẹgẹ bi oludari ati alakoso ile iṣẹ epo, Makinde ti darapọ mọ ọpọlọpọ ẹgbẹ awọn akọṣẹmọṣẹ ninu iṣẹ epo bẹntiroolù ati afẹfẹ gaasi lorilẹede Naijiria ati loke okun.
Ko jẹ iyalẹnu o wipe bi ifẹsẹwọnsẹ naa se bẹrẹ lawọn ololufẹ ẹgbẹ agbabọọlu Arsenal kan ti n pariwo,  Wenger yoo lọ!"
Bóò ṣe lè yẹra fún ikú nígbà òjò- Onímọ̀ Ehi Iden Islam kọ́ ló ni kí ọmọ ọdún méjìlá lọ sílé ọkọ- Ààrẹ ilẹ̀ Niger Kí ló ń fa ìjàmbá omíyale ní Naijiria?
Nódùùlù tí tó ẹgbẹ̀rún mẹ́rin ọdún Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, China, Ìpìlẹ̀ ilé núdùlù Lọ́dún 2002, abọ́ núdùlù kan tí tó égbẹ̀rún ọdún lẹ́yìn tí wọn wúu lábẹ́ ilẹ̀ ní ẹkun Qinghai ní China.
Ni deedee aago meje ku iṣẹju meje ni ina lọ ni Lekki Toll Gate, amọ Ọgagun Taiwo ni deedee aago meje ku iṣẹju mẹtadinlogun lawọn sọja bẹrẹ si ni yinbọn lẹyin tawọn janduku bẹrẹ si ni lẹ oko mọ wọn.
1 Kíyèsíi, èmi yíò fi oyè àlùfáà hàn sí ọ, láti ọwọ́ wòlíì Elijah, síwájú bíbọ̀ ọjọ́ nlá tí ó sì ní ẹ̀rù ti Olúwa.
Ọdun to kọja ni arakunrin ẹni ọdun marundinlaadọrun, Sabino Xochipoltecatl Carvente naa pari ile iwe girama rẹ.
pe  didasile awon olopaa ipinle naa tun
Ẹẹmeji ọtọọtọ ni Mali tẹyin gberu Argentina lẹyin ti wọn ta ọmi alayo meji meji ninu ere bọọlu ọhun.
Nigba ti wọn yoo fi de ibẹ ni wọn baa ti wọn ti ṣaa pa.
Ẹnìkan ninu wọn tí ó jẹ́ ọ̀kan ninu àwọn wolii wọn sọ pé, “Òpùrọ́ paraku ni àwọn ará Kirete, ẹhànnà, ẹranko, ọ̀lẹ, alájẹkì.
"Oríṣun àwòrán, IbrahimChatta/Instagram Bunkunmi ni oun ranti ọdun 2010 ti oun beere pe ki ọkọ afẹsọna rẹ to di ọkọ lonii fun ohun ni nkankan gẹgẹ bi ami ifẹ lati maa ranti rẹ, ""o fun mi ni ẹgba ọwọ alawọ pupa didi rẹ, Mo si ṣeleri pe maa tọju rẹ titi ayeraye ati pe boya mo maa wọ gan lọjọ igbeyawo wa, o rẹrin musẹ."
Sunday Igboho yarí, ó fohùn ránsẹ́ sáwọn èèyàn tó ń pẹ̀gàn rẹ̀ Ninu atẹjade ti awọn Ulamas naa fi lede, ti Alaga igbimọ naa, Sheik Ibrahim Khalil buwọlu sọ pe, awọn kọ ofin naa patapata lẹyin ti awọn ṣe agbeyẹwo rẹ.
Ọpọlọpọ awọn eekan oṣere ni wọn ki alagba naa ku oriire ayẹyẹ orikadun.
Wọ̀nyí ni àwọn ẹjọ́ tó làmìlaaka ti EFCC ṣe lásìkò Ibrahim Magu Ilé aṣòfin Ondo bẹ̀rẹ̀ ìgbésẹ̀ láti yọ igbákejì gómìnà nípò Kòṣẹlẹ̀rí ni Hajj ọdún 2020, wo ìyàtọ̀ tó wà nínú rẹ̀ sí ti tẹ́lẹ̀ Yatọ fun fifi ẹwọn jura, abadofin naa tun sọrọ lile tabi aṣẹ lọ rọọkun nile fun awọn akẹkọọ ti ile ẹjọ ba ri i pe irọ ni ẹsun ti wọn n fi lọ pe olukọ fẹ fipa ba awọn lo pọ.
Ninu rẹ̀ ni ẹ óo ti mú irúgbìn, ati èyí tí ẹ óo máa jẹ, ẹ̀yin ati gbogbo ìdílé yín pẹlu àwọn ọmọ yín.
Mo wí ní ọkàn ara mi pé Ọlọrun ń dán àwọn ọmọ eniyan wò, láti fihàn wọ́n pé wọn kò yàtọ̀ sí ẹranko; 
Dino Melaye: Ki lo tun ku ti o sọ?
Labani yìí ni ó sáré lọ bá ọkunrin náà ní ìdí kànga.
Ẹ kúrò níwájú mi nisinsinyii, kí ẹ lọ máa ṣiṣẹ́ yín; kò sí ẹni tí yóo fún yín ní koríko, iye bíríkì tí ẹ̀ ń mọ tẹ́lẹ̀ kò sì gbọdọ̀ dín.
Bayii won ti bere eto abere ajesara to ye ni gbigba lona meji fawon omo owo ni eyi ti awon odomode naa le kopa ninu gbigba ikeji.
•Ki ẹgbẹgbẹrun eniyan bẹrẹ si ni tẹle ẹ loju opo ikansiraẹni rẹ lai gba aṣẹ to de, nitori o ni iye eniyan to le tẹlẹ tabi fẹran ohun to ba gbe jade laarin wakati kan.
O ni oun ti o yani lẹnu ni bi awọn alaṣẹ ikọ naa ni ipinlẹ Ọyọ ṣe n ni ki awọn to fẹ dara pọ mọ ikọ naa o lọ maa forukọ silẹ ni ori ayelujara.
Joṣua ọmọ Nuni ati Kalebu ọmọ Jefune nìkan ni wọ́n yè ninu àwọn amí mejila náà.
Lori ọju ẹrọ ibaraẹnisọrọ Twitter ni awọn eniyan ti ki Leah ku ọjọ ibi rẹ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù India: Arakunrin ti wọn doola ẹmi rẹ kuro ni Ile igbokusi pada jade laye 17 Ọ̀wàrà 2020 Arakunrin Balasubramanyam ti wọn doola ẹmi rẹ kuro ninu ẹrọ amohuntutu to wa ni ile igbokusi ti papoda.
Atamatase omo orile-ede Spain, Rafael Nadal duro sori oke tente tabili ipo ate awon okunrin ti o kaju osuwon julo ninu ere idaraya boolu afigigba(men’s Association of Tennis Professionals) ATP, ti o jade lojo Aje(Monday) pelu ẹ̀gbẹ̀rún mẹ́jọ  le ọ̀tàlérúgba ami (8,260 points) saaju akegbe re omo orile-ede Switzerland.
Lẹyin naa ni ileeṣẹ na ba sọ wipe ọrọ naa ko ri bẹ mọ.
Lójjú mi gbangba báyìí  ni wọ́n ṣe fi ọmọbìnrin méjìlá ta Ènìyàn-ṣe-pẹ̀lẹ́ lọ́rẹ lẹ́ẹ̀kan ṣoṣo ṣùgbọ́n kò fẹ́ wọn.
Lai Mohammed ni, ko si igba ti ikede naa ko ni pada waye ṣugbọn Amẹrika ko bun Naijiria gbọ ati pe, wọn ko sọ idi kankan ti wọn yoo fi gbe iru igbesẹ bẹẹ.
Awọn sẹẹli ara maa n pin iṣẹ fun ara wọn Ara wa maa n ṣiṣẹ kan - o maa n pin iṣẹ fun awọn sẹẹli, lati jẹ ki kaluku mọ ibi ti yoo ti ṣiṣẹ ninu ara.
Àwòrán rèé Èyí ni àwọn nkan tó yẹ kí o mọ̀ nípa ọmọ Italy tó kó Coronavirus wọ Eko Iléeṣẹ́ ọlọ́pàá l'Óndó ní ọwọ́ àwọn ti tẹ arákùnrin kan pẹ̀lú agbárí àti ọwọ́ èèyan méjì Sagamu: Ìkọlù wáyé bí ará ìlú ṣe gbéná wòjú ọlọ́pàá torí ikú agbábọ́ọ̀lù ‘Wàhálà yín pọ lórí Bayelsa ati Zamfara, àwa náà yóò ṣé àyẹwò ìdájọ tó gbé Buhari wọlé’ Òbinrin kan fẹ́ ọkọ méjì torí ọkọ àkọ́kọ́ rìnrìnàjò fún ọdún méjì péré Ninu ifọrọwerọ rẹ pẹlu BBC News Yoruba, Taye Kọrẹnsi ni lasiko ti aawọ wa laarin Alaaji Alabi Pasumọ Ọganla ati King Saheed Oṣupa, oun o da si aawọ aarin wọn nitori bi Saheed Oṣupa ṣe jẹ ọmọ ilu oun ti o si dara si oun naa ni Pasuma jẹ awokọṣe fun oun to si jẹ pe ati maa ṣe bọ wọn ti le ni ni ogun ọdun.
Kirusi ọba náà kó àwọn ohun èlò inú ilé OLUWA jáde, tí Nebukadinesari kó wá sinu àwọn ilé oriṣa rẹ̀, láti Jerusalẹmu.
Ṣugbọn, onibara wọn kankan ko gbọdọ joko jẹun nile ounjẹ.
 Àwọn Ìlú to kù ni ọ ̀ wẹ ̀ , Ìbàdàn , Ìláwọ ̀ , Ìwéré , òjé ati àwọn ìlú mọ ́ kàndínlógoji ( 39 ) mìírán.
Àjọ DSS ti gbọ̀ngàn ìpàdé #RevolutionNow pa ní Ikeja Awọn ilumọọka ajijagbara bi Ọjọgbọn Wole Ṣoyinka, agbẹjọro Femi Falana atawọn mii la gbọ pe wọn fẹ pade ni Lagos Centre fun apero naa tẹlẹ.
Alaga igbimo naa ti o tun wa lara awon asofin to n mojuto ise ajo INEC, asofin Suleiman Nazif lo soro ohun di mimo fun awon akoroyin niluu Abuja idi ti awon yoo fi bowolu iwe isuna eto idibo ohun eyi ti ajo INEC gbekale.
Nípa igbagbọ ni àwọn ọmọ Israẹli fi gba ààrin òkun pupa kọjá bí ìgbà tí eniyan ń rìn lórí ilẹ̀ gbígbẹ.
Rape: ‘Uncle àti Granpa’ mi máa ń fi owó àti ẹ̀bùn fa ojú mi mọ́ra
Mohammed Graba n dari rẹ sọ pe, won ko lee lo 
Oríṣun àwòrán, Getty Images Gbajugbaja oṣere fiimu Hausa, Rahama Sadau ni o wa nipo kẹrin.
Wọn yóo wá mọ̀ pé èmi ni OLUWA.
Laarin ọdun 1980 siwaju, ija laarin awọn ọmọ ẹgbẹ okunkun peleke.
Kanu Ejike fipá bá ọmọ ọdún méje lò pọ̀ nínú sọ́ọ̀bù ìyàwó rẹ̀ Ṣùgbọ́n ìjọba ìbílẹ̀ mẹ́ta tó tóbi jù kan ni àwọn ènìyàn fójú sí nítorí ìtàn ìdìbò àgbègbè náà látẹ́yín wá.
Tí o bá ń ṣe nǹkan wọnyi, fi ara rẹ han aráyé.
Ni kete ti a ba ri aridaju ọrọ yi fi mulẹ, a o jẹ ki ẹ gbọ.
BBC Yorùbá yóò se ìpàdé ìtagbangba ní Kwara Àwọn òṣèré tíátà Yorùbá tó bá 2018 lọ Mi ò tan mọ́ ààrẹ Buhari rárá o!
Egypt dá akọ́nimọ̀ọ́gbá Aguirre dúró lẹ̀yìn ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ Ìdí tí mo fi fẹ́ di Gómìnà Kogi - Dino Melaye Kí ló mú ọmọ Nàìjíríà mẹ́sàn án forí la ikú nínú ìkọlù Libya?
 naa mo rọ yin oluwa mi, lati gbe igbesẹ
Nibayii, ọmọ ile asofin ipinlẹ Ọṣun miran tun ti fi ẹgbẹ oṣelu APC silẹ.
Nigba ti BBC Yoruba kan si onimọ nipa ọrọ oṣelu kan ni fasiti ilu Ibadan, Ọmọwe Dikrullahi Yagboyaju ni lakọkọ oun fẹ nigbagbọ pe bi gomina ṣe sọ ọ naa lo ri pe awọn eeyan lo sọ bẹẹ.
Ẹ mọ̀ pé àìlera ni ó mú kí n waasu ìyìn rere fun yín ní àkọ́kọ́.
Àwọn afurasí darandaran náà ni a gbọ́ pé ó ṣe ikọlù náà sí St.
Titi di asiko yii, wọn ko tii le sọ ohun to ṣokunfa in pato sọ lọjọ Aje yii.
" Jada, tii se ẹni ọdun mejidinlaadọta ni awọn ko nilo lati gba asẹ lọwọ ọkọ oun, ki oun ati August to maa sere ifẹ, nitori oun ati Will, ọkọ oun ko gbe papọ mọ nigba naa.
Ṣugbọn èyíkéyìí tí kò bá ní lẹbẹ ati ìpẹ́, ẹ kò gbọdọ̀ jẹ wọ́n, nítorí wọ́n jẹ́ aláìmọ́ fun yín.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ibi a gbé dàgbà ní se pẹ̀lú ìhùwàsì - Onímọ̀ nípa ìhùwàsí Onimọ nipa ihuwasi eniyan naa wa parọwa si gbogbo ọkọ ati iyawo lati gbe ninu ifẹ ati lati lọ si ile iwosan fun itọju to peye nigba kugba ti a ba ri awọn ihuwasi ti ko yẹ ọmọluwabi.
Aginju nla ti awọn ẹrenko ngbe pọ ni ilu naa.
Ẹbọ tí ó ṣe ìtẹ́wọ́gbà lọ́dọ̀ ìwọ Ọlọrun ni ẹ̀mí ìròbìnújẹ́,ọkàn ìròbìnújẹ́ ati ìrònúpìwàdà ni ìwọ kì yóo gàn.
Aare orile ede Naijiria tun faramọ eto ọkọ oju-irin ti yoo maa lọ lati orile ede Naijiria,Benin ati Niger”yoo jẹ ohun ti yoo mu eto ọrọ aje gboọrọ’’.
a ki i ṣe igbeyawo bẹ ẹ ninu ẹsin Islam.
Amọ bi wọn ba fẹ lọ si ilẹ okeere, o yẹ ki a beere pe ki lo de ti awọn ọmọ Naijiria fi n sa kuro nilẹ wọn lọ si ilẹ ibomiran.
Ohunkohun tí apákan ninu òkú wọn bá jábọ́ lé lórí di aláìmọ́, kì báà jẹ́ ààrò tabi àdògán, o gbọdọ̀ fọ́ ọ túútúú; wọ́n jẹ́ aláìmọ́, wọ́n sì gbọdọ̀ jẹ́ aláìmọ́ fun yín.
APC: Kí ni àwọn ẹ̀ṣẹ̀ tó ń da Oshiomole láàmú?
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Awọn ọmọ ile-iwe joko sile nitori iyansẹ̀lodi ọlọ̀jọ̀ mẹ̀ta ni ipinlẹ 24 Sẹ́rẹ́ 2018 Oríṣun àwòrán, NLC WEBSITE Àkọlé àwòrán, Ijọba le awọn osisẹ̀ LAUTECH ti iye wọ̀n jẹ̀ Igba o lẹ̀ Mẹ̀rindinlọ̀gọ̀ta kuro lenu isẹ Gbogbo awọn Ile-iwe ti ijọba ipinlẹ̀ Ọ́yọ̀ wa ni titi pa loni, nitori iyansẹ̀lodi ọlọ̀jọ̀ mẹ̀ta, lati kilọ́ fun ijọba ipinlẹ̀ Ọ́yọ̀, lati da awọn osisẹ̀ LAUTECH to je Igba o lẹ̀ Mẹ̀rindinlọ̀gọ̀ta ti wọ́n da duro, pada sẹ́nu ise.
titi di 1991, ki o to di wi pe iṣẹ tun gbe e lọ si ipinlẹ Bauchi.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ta ni obìnrin tó fẹ́ bá Dino Melaye ṣe ìgbéyàwó lọ́jọ́ kejì Kérésì?
Lawọn agbegbe kan, awọn ọdọ n gba bọọlu loju titi lẹyin toju popo da paro paro.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Kayeefi: 'Ọkọ mi ṣẹ̀ṣẹ̀ ní kí n lọ se mọ́í-mọ́í, tó ṣẹ̀ bá mi ṣeré tán ni mo gbọ́ pé Mopol"" yìnbọn pa á' Adamu sọ pe ileesẹ ọlọpaa tunbọ tẹpẹlẹ mọ ifarajin rẹ lati ri wi pe wọn tu ìkọ SARS ka ni ibamu pẹlu ifẹ ara ilu."
Adajọ Samuel wa fun Onweniwe ni ẹwọn gbére lóri ẹsun ijinigbe, sugbọn lori ẹsun ipaniyan ati wipe o yin oloogbe naa lọ́rùn, adajọ da olujẹjọ naa lẹjọ iku.
Ilé iṣẹ́ BBC ni Fayẹmi kọ́kọ́ bá sọ̀rọ̀ gẹ́gẹ́ bíi gómìnà tí Ekiti yàn Oyin lé àwọn ènìyàn kúrò l'ábúlé kan ní Plateau Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Kayode Fayemi : Awọn osisẹ ni Ekiti ko i tii gba owo osu ni ọdun yii Gomina Ipinlẹ Kaduna, Nasir El-Rufai, ati ti Delta, Ifeanyi Okowa lo fa Fayemi kalẹ fun didije ninu idibo naa.
Àkọsílẹ̀ bí Mose ṣe pín ilẹ̀ tí ó wà ní pẹ̀tẹ́lẹ̀ Moabu ní òdìkejì Jọdani ní apá ìlà oòrùn Jẹriko nìyí.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù US Election 2020: Ta ni Kamala Harris obìnrin àkọ́kọ́ tí yóò jẹ igbá-kejì ààrẹ orílẹ̀èdè Amẹrika?
Wọn ni ko ni si iyanjẹ nipa owo in ọba tawọn eeyan n san mọ pẹlu atunṣe sisan owo ina ti ajọ NERC ati DISCO ti ṣe bayii.
Anger: Onínúfùfù máa ń ní ẹ̀mí gígùn ju Oníwàtútù lọ
Ó ti kúrò ní agbègbè Rimoni,ó ti dé sí Aiati;ó kọjá ní Migironi,ó kó ẹrù ogun rẹ̀ jọ sí Mikimaṣi.
Lọpọ igba awọn eleyinju aanu lo ma n pese owo fun eto abẹrẹ ajẹsara.
Ọ̀pọ̀lọpọ̀ òkú ẹyẹ igún ré bọ́ lọ́jà Eke-Ihe Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Kí ló máa ń wú ìyá Nike Davies lori láti wé gèlè ràbàtá?
Olootu ijọba Germany bura fun saa kẹrin Mugabe kò le rìn mọ́ Buhari, Merkel fọwọ́ sí àdéhùn lórí ìrìnàjò ọmọ Nàìjíríà sí Germany Ooru to mu pupọ ni Merkel lo ṣe okunfa gbigbọn pẹpẹ rẹ to waye kẹyin amọ lọtẹ yii, a gbọ pe aaye ti ayẹyẹ naa ti waye ko gbona pupọ.
Lati igba yii lawn eniyan ti n tu ọrọ sita lori ohun ti wọn gbọ.
Bí mo ṣe dúró ti Toyin nílé ìgbẹ̀bí jẹ́ kí ń mọ̀ pé ó yẹ kí ọkùnrin máa bọ aya wọn - ọkọ Toyin Abraham Mercy Aigbe bu èpè jó àwọn tó ní gómìnà kan ló ra ilé fún-un Òṣèrébìnrin tí wọ́n bá fi ìbálòpọ̀ lọ̀ 'torí ìṣẹ́, kó bọ́ síta láti sọ̀rọ̀ - Kunle Afod Saraki àgbà ló kọ́ ilé yìí fáwa arúgbó kìí ṣe Bùkọ́lá- Arúgbó Ilọrin Oríṣun àwòrán, AFeez abiodun Àkọlé àwòrán, Afeez Abiọdun (Afeez Ọwọ) ati Mide Martins Afeez Abiọdun (Afeez Ọwọ) ati Mide Martins Ninu awọn lọkọlaya to gbajumọ ju lagbo ere tiata Yoruba kaakiri agbaye ni Afeez Abiọdun ti ọpọ mọ si Afeez Ọwọ ati Mide Martins.
Ronaldo jẹ ọkan lara awọn atamatase ẹlẹsẹ ayo ti ko gba ife ẹyẹ Champions League ri, bo tilẹ je pe o ṣoju awọn ikọ agbabọọlu to lamilaaka ko to fẹhin ti ninu ere bọọlu.
Sugbọn wọn ko tii sọ ọjọ gangan ni pato ti awọn akẹkọọ maa wọle pada sile iwe wọn.
Ti wọn ba ṣe etutu, iku naa yoo re danu, amọ ti wọn ko ba ṣe e, ewu ni.
Awon afurasi odaran yii ni , Akeju Crown Babatunde eni
Obìnrin kan bí ibejì lẹ́yìn ọjọ́ 26 tó bí ọmọkùnrin - BBC News Yorùbá BBC News, YorùbáFò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Uterus Didelphys - Obìnrin kan bí ibejì lẹ́yìn ọjọ́ 26 tó bí ọmọkùnrin 28 Ẹrẹ̀nà 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 29 Ẹrẹ̀nà 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Arabinrin kan ti bi ibeji lẹyin bi oṣu kan to bi ọmọkunrin kan toṣu rẹ ko pe e.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Premier League: Àkọ́dá oró.
”Adesina ni Aare Buhari n figbagbogbo jiroro pelu awon gomina ipinle ti oro kan ki won le jo mo ojutu si awon isoro eto aabo ipinle kookan.
Omíyalé àgbàrá ya ṣọ́ọ̀bù, ilé mẹ́ta wó, èèyàn mẹ́rin kú l'Eko Odunlade fijó bẹ́ẹ, Lizzy padà sọ́dún 2012, Toyin Abraham tọ̀ lẹ́ẹ̀mẹwàá Ìdí rèé tí mo fi ṣẹ̀ṣẹ̀ sọ̀rọ̀ lẹ́yìn tí wọ́n fipá bámi lopọ̀ lọ́mọ ọdún méje lọ́gọ́ta ọdún sẹ́yìn-Eli Lasiko ayajọ ọjọ 'Ma wọ kọmu' yii si ọpọ obiinrin maa n fi ọyan wọn silẹ bi Ọlọrun se daa, lai wọ kọmu taa mọ si Bra tabi Brassiere lati koo soke, nitori pe iwadi kan ti fidi rẹ mulẹ pe awọju kọmu gan maa n fa aisan jẹjẹrẹ.
O ni oun bẹ Ọlọrun lati fi oju aṣebi han ki o to di ọjọ meje.
Àwọn ajínigbé jí adájọ́ gbé, ẹ̀mí ọlọ́pàá tó ń ṣọ ọ́ lọ sí i Ọjọ́ ẹ̀san dé!
Wọn ni iwa ẹranko ni iwa ifipa bani lopọ, ati pe o yẹ ki awọn ọkunrin le jọwọ obinrin to ba ni oun ko fẹ ni ibalopọ lai fi ṣe boya ololufẹ ẹni ni tabi aya ẹni, tabi ẹlomiran.
Eyi je oun ara ohun ti ẹgbẹ ajijagbara Avengers fi ranse lori itakun agbaye wọn.
Ọpọlọpọ odo igbafẹ lo pọ ni Eko, amọ eleyii to wa ni agbẹẹgbẹ Victoria Island yii ma n gba ẹgbẹwa Naira, 2,000 Naira ($5.
Ọpọ ile àti nnkán ìní ló ṣofo nínú ìjàmbá omí yalé naa tó wáyé ní Katsina,Ogun ati Ondo.
Nigba ti BBC kan si alukoro ileesẹ ọlọpaa nipinlẹ Edo, o sọ pe ori ayelujara ni oun naa ti ka nipa iṣẹlẹ naa ni owurọ òní.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Lagos Beach: Àwòrán tó làmììlaaka nípa àwọn òsìsẹ́ ẹ̀ṣọ́ etí òkún 1 Ìgbé 2019 Ile igbafẹ eti okun sẹsẹ bere isẹ ni ilu Eko ni.
Asofin Awoleye tesiwaju pe, opolopo ipenija lo wa lori eto aabo lorile ede Naijiria bayii to si je pe , o n sakoba fun idagbasoke eto oro aje orile ede yii, bee si ni ojuse ijoba ni lati pese eto aabo to peye fun tonile-talejo ati lati le e ri pe eto isokan wa lorile ede yii.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Footballers: ìkà láwọn aṣojú agbábọ̀ọ̀lù míì lágbàyé Bakan naa ni Evelyn Nwabuoku, Amarachi Okoronkwo, Uchenna Kanu, Fransisca Ordega, Uchenna Chinaza, Anam Imo, Rasheedat Ajibade ati Chiwendu Ihezuo yoo kopa.
Adehun yii laarin awọn olori ilẹ Afrika ni wọn gba pé yoo mu ọja tita rọrun sii fawọn olokowo keekeeke nigba ti wọn ko ba san owo ori ọja ni awọn ẹkun ti ọrọ kan.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Àwọn ọmọ Nàíjíríà ló ṣiṣẹ́ takò mí ní Ireland kí ń má baà wọlé ìbò Káńsélọ̀ - Yemi Adenuga Aṣojú Seyí Makinde lásan ní mo jẹ, òṣìṣẹ́ gbọdọ̀ bọ̀wọ̀ fún mi - Ọ̀dọ́mọdé Kọmísánà Èmi àti Bọla Tinubu fẹ́ lo ‘German Mercenaries’ láti gbé MKO Abiọla kúrò lẹ́wọ̀n - Dele Momodu Irọ́ ńlá!
 Fun idi eyi, itosona ati iwa aare Buhari sokunfa idi ti mo fi setan lati fe ba sise po.
Ṣugbọn ibi yóo dé bá ọ,tí o kò ní lè dáwọ́ rẹ̀ dúró;àjálù yóo dé bá ọ,tí o kò ní lè ṣe ètùtù rẹ̀;ìparun yóo dé bá ọ lójijì,tí o kò ní mọ nǹkankan nípa rẹ̀.
8 557388 Orilẹede Bolivia 8995 79.
N óo máa ṣe àṣàrò lórí gbogbo iṣẹ́ rẹ;n óo sì máa ronú lórí àwọn iṣẹ́ ribiribi tí o ṣe.
kí ó ṣa àwọn ọ̀dọ́ tí wọn kò ní àbùkù lára, àwọn tí wọ́n lẹ́wà, tí wọ́n sì jẹ́ ọlọ́gbọ́n lọ́nà gbogbo, tí wọ́n ní ẹ̀bùn ìmọ̀, ati òye ẹ̀kọ́, tí wọ́n lè ṣiṣẹ́ ní ààfin ọba, kí á sì kọ́ wọn ní ìmọ̀ ati èdè àwọn ará Kalidea.
OLUWA, jẹ́ kí ìfẹ́ rẹ tí kì í yẹ̀ wà lórí wabí a ti gbẹ́kẹ̀lé ọ.
Adájọ gbà ìdájọ ikú lọ́wọ́ ejò Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ejo abami to n mu owo ni ajọ Jambu Amọ ṣa, ejo naa raaye salọ.
Orileede rẹ, Cameroon lo gba ami ẹyẹ naa julọ; wọn gbaa ni igba mọkanla.
Lẹ́yìn náà, ó sọ̀kalẹ̀ láti ibi tí ó ti ń rú ẹbọ ìmúkúrò ẹ̀ṣẹ̀ ati ẹbọ sísun ati ẹbọ alaafia.
Àwọn iranṣẹ Huramu ati àwọn iranṣẹ Solomoni tí wọ́n mú wúrà wá láti Ofiri, tún mú igi aligumu ati àwọn òkúta olówó iyebíye wá pẹlu.
Wọ́n tẹ́ tabili, wọ́n sì tẹ́ aṣọ sílẹ̀wọ́n ń jẹ, wọ́n ń mu.
Alufaa náà sì dáhùn pé, “N kò ní burẹdi lásán, àfi èyí tí ó jẹ́ mímọ́.
Ajọ naa n fẹ ki ile ẹjọ giga apapọ to wa ni Ikoyi, nipinlẹ Eko o kan an nipa fun minisita Fashọla lati gbe orukọ ati awọn ẹkunrẹrẹ iroyin nipa awọn ileeṣẹ tọrọ kan jade.
" Oríṣun àwòrán, Others Ijọba Ọyọ ni oun ko di isẹ awakọ lọwọ rara, o si rọ awọn awakọ ero lati maa ba isẹ wọn lọ, ki wọn si gbọn eti wọn si ohun ti awọn olori ẹgbẹ to n gba owo lọwọ wọn n sọ.
Awọn yoku ni gomina tẹlẹri nipinlẹ Ekiti, Ayodele Fayoṣe, gomina tẹlẹri nipinlẹ Ọyọ Adebayọ Alao Akala, Olubadan ti ilẹ Ibadan Ọba Saliu Adetunji, Alaafin ti ilu Ọyọ, Ọba Lamidi Adeyẹmi ati bẹẹbẹẹ lọ.
Aare soro yii lojo Aiku nigba
Bidemi, tii baba rẹ naa jẹ gbajumọ oṣere tiata, Jide Kosokọ, naa fi tayọtayọ kede pe oluwaseun fun ẹbun ọmọ naa ti oun si bi layọ ati alaafia.
Ile-ise aare ti benu ate lu oro ti aare orile-ede Naijiria teleri, Goodluck Jonathan so pe awon obaye je, a sowo ilu moku-moku po laarin ijoba ti o wa lori aleefa yii ju tisakoso ijoba re lo.
Eyi yoo jẹ ki ẹni to fẹran lati maa dari ẹnikeji ro pe agbara oun n dinku ninu ajọṣepọ naa.
Nítorí ninu àgọ́ ara yìí à ń kérora, à ń tiraka láti gbé ilé wa ti ọ̀run wọ̀.
O ni awọn ẹru aisedeede to pọ babi niwaju igbimọ olugbẹjọ ibo aarẹ, lo wọ APC ati Buhari lọrun, pẹlu ọpọ ẹri to daju pe wọn se eru ibo ni, idi si ree ti wn se n dọgbọn iwa ibanilorukọ jẹ.
Ajọ NCDC lo ṣalaye ẹkunrẹrẹ eyi ninu ikede alaalẹ ti wọn maa n ṣe lati sọ ibi ti iṣẹ de duro lori ọrọ ajakalẹ arun coronavirus lorilẹede Naijiria.
Ninu atẹjade kan to fi sita lọjọru, ijọba ipinlẹ Ondo ni pẹlu aṣẹ tuntun yii, ọjọ Isinmi Aiku nikan laye ijọsin yọ fawọn kristẹni, ti aye ọjọ Jimọ si ṣi fun awọn Musulumi.
Wọn ni ida mẹrindinlọgbọn ọmọ ti ko si nile iwe tẹlẹ lo ti pada wa sile iwe nsiyi.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Làá hàn mí: Ètò yìí ló ń kìlọ̀ fún wa láti mú ìmọ́tótó ní pàtàkì láti dènà Coronavirus Ere idaraya Ọpọ ifẹṣewọnsẹ ere bọọlu ajọ Yuroopu, EPL, to yẹ ko waye ni wọn ti wọgile laipẹ yii, ti awọn alaboju ifẹsẹwọnsẹ naa pinnu pe ki diẹ lara ifẹsẹwọnsẹ naa waye lai si ero iworan.
Hẹrọdu fẹ́ pa á, ṣugbọn ó bẹ̀rù àwọn eniyan, nítorí wọ́n gbà pé wolii ni Johanu.
”Arabinrin Bennet , to  jẹ  igba akoko re lati wa si orile ede Naijiria, ni awọn olugbo VOA le ni ogojilenigba lagbaaye, sugbon ile akede VOA tun fe lati tesiwaju nipa sise afikun ede  miiran si i ni, eyi ti ile akede VOA yoo se lee maa se isẹ wọn ni gbogbo igba.
Òkìkí rẹ̀ sì kàn káàkiri nítorí pé Ọlọrun ràn án lọ́wọ́ ní ọ̀nà ìyanu títí ó fi di alágbára.
Wo àwọn oúnjẹ márùn ún tó ń mú kí àtọ̀ ọkùnrin dára síi Irọ́ ni pé mò kò Palliatives"" pamọ́ sí ilé mí-Abike Dabiri-Erewa Ọdun 2012, 2016 àti 2020 ni John Mahama àti Nana Akufo-Addo ti jọ ń figagbága dupò aàrẹ Ghana Aisha Buhari ni awọn ọmọde atawọn obinrin ni atubọtan arun naa yoo pa lara ju nitori aini anfani si eto ẹkọ to yanranti ati eto ilera to peye."
Àwọn ọba ayé ti ṣe àgbèrè pẹlu rẹ̀, àwọn tí ń gbé inú ayé ti mu ninu ọtí àgbèrè rẹ̀.
Oríṣun àwòrán, Genesis global Ikọ awọn alatunṣe - Awọn to wa ninu ikọ yii lo ma n tun inu ati ayika ile ijọsin ṣe lasiko ijọsin ati lẹyin rẹ.
Gbogbo ẹni to ba di gomina lọla ki o tete mọ pe ọdun mẹrin pere ni, ti o ba wa wu lati lọ lẹẹkan si, o ni lati pada wa si ọdō awọn eniyan lati sọ fun wọn.
Wọ́n tú àṣírí ìfiyàjẹni àwọn Ológun àti SARS káàkiri Nàìjíríà Bàbá fìdí ọmọ ọdún márùn ún jó sítóòfù gbígbònà, ó di aláàbọ̀ara nítorí ó jí ẹja Ìgbìmọ̀ ọ̀tẹ̀ ní ọ̀rọ̀ àwọn àgbààgbà ẹkùn àríwá pé ìjọba Buhari ti kùnà- Femi Adesina Buhari ń fowó aráàlú gbàtọ́jú nílùú òyìnbó nígbà táwọn ilé ìwòsàn wa ti di mọ́ṣúárì - Falana Àṣírí èèyàn kan tó dìbò ní ìgbà 89 tú, Ọlọ́pàá gbé e jàǹtò!
“Ẹ má dá a lẹ́kun, nítorí ẹni tí kò bá lòdì si yín, tiyín ní ń ṣe.
AWORAN SINIMA: Aare Buhari safihan awon aseyori, ipinnu re fun Naijiria.
Wòlíì Kasali ní Dolapo Awosika kò lé ìyàwó òun jáde wọn tun ni gbogbo ọkọ ti iru ọmọbinrin bẹẹ ba fẹ yoo maa ku titi de ori meje.
 Ẹni tí ń lé orin yìí lè ṣe ẹyọ ẹnìkan ṣoṣo tàbí ènìyàn méjì lápapọ ̀ láti lè fi ohùn dárà nínú orin lílé .
Niwọn igba to si jẹ pe ẹni to moju naa ni aarẹ, oun naa ko si sopo bọ awọn ọba alaye to duro lati kii kaabọ lọwọ, ti ko si tun se abẹwo si awọn agbegbe Auno, ti ikọlu ti waye lọjọ Aiku to kọja.
keekeeke  to wa lorile ede  Chinaa n ko lati mu idagbasoke ba eto oro aje
Bi ẹ ko ba ni gbagbe laipẹ yii ni Kabiyesi Adeyẹye Ogunwusi bs si gbangba pẹlu Olori rẹ tuntun, Moronke Shilekunola lẹyin ipinya pẹlu olori ana, Zaynab Wuraọla.
Ajirebi, ẹni to dupẹ pupọ lọwọ awọn ololufẹ rẹ atawọn osere tiata lorisirisi ti wọn dide iranwọ fun wa gbadura pe Ọlọrun yoo wa pẹlu wọn.
iroyin ati igbodegba, ogbeni Garba Shehu lo soro naa di mimo fun awon akoroyin
Ati pé, kí wọ́n tilẹ̀ tó rẹ́ ọ̀rá tí wọ́n máa ń sun kúrò lára ẹran, iranṣẹ alufaa á wá, a sì wí fún ẹni tí ń rú ẹbọ pé kí ó fún òun ninu ẹran tí alufaa yóo sun jẹ, nítorí pé alufaa kò ní gba ẹran bíbọ̀ lọ́wọ́ olúwarẹ̀, àfi ẹran tútù.
Jesu wá wí fún wọn pé, “Mo fẹ́ kí ẹ mọ̀ dájúdájú pé, bí ẹ̀yin kò bá jẹ ẹran ara ọmọ eniyan, kí ẹ sì mu ẹ̀jẹ̀ rẹ̀, ẹ kò lè ní ìyè ninu yín.
Igi légbélégbé tí afẹ́fẹ́ ń tì sọ́tùn-ún, ati sósì ni bí?
Gomina ipinle Plateau to tun je alaga ẹgbẹ naa lasiko to n ba awon akọroyin sọrọ nilẹ ijoba ni SAR Swulo fawọn nipa kikoju ipenija aabo ni Ariwa Naijiria.
Tijjani Bande to jẹ ọjọgbọn ati adari ile iwe giga Usman Dan Fodio ni ipinlẹ Sokoto ni wọn ti yan gẹgẹ bi aarẹ ẹka Ajọ Agbaye United Nations General Assembly (UNGA).
Aisan ibà ṣe e dena, o si ṣe e tọju.
Ẹwẹ, Fani Kayode ni kii ṣe ibeere rara lo bi oun bi kii ṣe ọrọ lasan to si jẹ eebu.
Ọjọ Ajé ni àjọ náà ṣe ìkéde yìí lórí ìtàkùn ayélujára Facebook.
Agbẹjọ́rò àgbà fún ìjọba àpapọ̀ Abubakar Malami (SAN) sàlàyé pé, ọ̀rọ̀ ààbò jẹ ojúṣe ìjọba àpapọ níkàn ni.
Awuyewuye lórí nǹkan márùn ún tí ó níí ṣe pẹ̀lú Abba Kyari nígbà ayé rẹ̀ rèé Abba Kyari: Awuyewuye lórí nǹkan márùn ún tí ó níí ṣe pẹ̀lú olórí òṣìṣẹ́ ààrẹ Buhari tó kú rèé Bí àwọn ọmọ Nàìjíríà kan ṣe ń daro ikú Abba Kyari pé ẹni re lọ, ní àwọn míràn ń ju oko ọ̀rọ̀ lu àwọn oloselu lori ikú rẹ.
Ohun ti a kò bá jìyà fún kì í lè tọ́jọ́
Ó fi iṣẹ́ abàmì tí a fi fún un láti ṣe níwájú ẹranko náà tan àwọn tí ń gbé orí ilẹ̀ ayé jẹ.
Ìdọ̀tí fadaka tí a kọ̀ tì ni wọ́n,nítorí pé OLUWA ti kọ̀ wọ́n sílẹ̀.
Naijiria, Yemi Osinbajo ti sọ pe aare Buhari yoo tubo tẹpẹlẹ mọ eto ironilagbara
Tí ó bá jẹ́ pé a kò jí àwọn òkú dìde, a tún jẹ́ pé a purọ́ mọ́ Ọlọrun, nítorí a jẹ́rìí pé ó jí Kristi dìde, bẹ́ẹ̀ sì ni kò jí i dìde.
Ọlọrun tún sọ fún un pé, “Èmi ni Ọlọrun Olodumare, máa bímọ lémọ, kí o sì pọ̀ sí i, ọpọlọpọ orílẹ̀-èdè ati ọpọlọpọ ọba ni yóo ti ara rẹ jáde.
Ṣẹgun Ọdẹgbami ṣalaye fun BBC Yoruba pe, lootọ ni ijọba ṣe ileri ẹbun fun awọn elere idaraya, paapaa julọ ti bọọlu aláfẹsẹgba lọpọlọpọ ọdun sẹyin.
' Lára àwọn gbájugbaja míràn ti kò sí ni ìlú gan náà to fi àtéjíṣẹ́ ránṣẹ́ ni Olamide, lórí twitter rẹ̀ ló ti ṣàlàyé pé gbágbágbá ni òun wà lẹ́yìn àwọn tó ń ṣe ìwọ́de ìfẹ̀hónú hàn.
“Bí ẹbọ rẹ bá jẹ́ ti ohun jíjẹ tí a sè ninu ìkòkò, ìyẹ̀fun rẹ̀ gbọdọ̀ kúnná dáradára kí ó sì ní òróró.
NCDC kéde èèyàn 423 míràn tó ṣẹ̀ṣẹ̀ lùgbàdì Covid-19 ní Nàìjíríà, 263 gbàwòsàn Òògùn ìtura dé fún Coronavirus!
com Àwọn aládugbò ṣàlàyé bí Sunday Shodipe ṣe pa Funmilayo tó pa kẹ́yìn l' Akinyele.
Akowe agba ajo Commonwealth, Patricia Scotland yoo se abewo alakoko re si orile-ede Kenya ninu ose ti a wa yii.
se ona miiran run gba ibomiran yọ nigba ti awon adari ileigbimo asofin gba
Ṣùgbọ́n ọ̀kàn òun bàjẹ́ nígbà tó hàn sí òun pé ẹgbẹ́ náà ti kùnà níbi ẹ̀sìn náà.
Wọ́n pèsè ohun amáyédẹrùn igbàlódé bi ilé-ìwòsàn ọ̀fẹ́, ilé-iwé ọ̀fẹ́, ọ̀nà gidi, omi mi mun, iná mọ̀nàmọ́ná àti bẹ́ ẹ̀  bẹ́ ẹ̀ lọ ni gbogbo agbègbè ilẹ́ Yorùbá.
Bakan naa lo sọ pe Sẹnetọ Teslin fun'ra rẹ ko si nile lasiko iṣẹlẹ ọhun.
Mo fẹ́ 'rebrand' àwọn area boys ìpínlẹ̀ Ọyọ ni - Bolanle Sarumi #Mothersday2019: Àwọn ìpèníjà obìnrin láwùjọ Àròsọ àti ìgbàgbọ́ àwọn ènìyàn lórí gbígba ẹ̀jẹ̀ Ẹ ṣọ́ra fún ìròyìn ẹlẹ́jẹ̀ lórí ètò ààbò - Ọlọ́pàá Awọn arugbo naa parọwa fun ijọba lati wo ilana miran ti yoo mu ki iṣẹ ayẹwo ti wọn n ṣe rọrun fun awọn sii lasiko yii.
Xenophobia: Àwọn agbófinró dúró sẹ́nu ọ̀nà àbáwọlé Palm Mall Ibadan láti dẹ́kun ìkọlù
Ṣugbọn wọn sọ fun wọn pe o ti pẹ ju.
Bawo ni gbedeke ti wọn fi le rira agbabọọlu yoo ṣe pa akọnimọọg ba tuntun lara?
Ninu ọrọ to kọ lede Oyinbo ati Pidgin, o ni wọn kan fẹ tabuku Buhari, ni wọn ṣe sọ pe ko wa kopa ninu ijiroro naa.
Kì í ṣe ọgbọ́n eniyan bíkòṣe oore-ọ̀fẹ́ Ọlọrun.
Àwọn ni wọn óo máa sun turari níbi ẹbọ rẹ,wọn óo sì máa rú ẹbọ sísun lórí pẹpẹ rẹ.
Ati wi pe awọn gomina ipinlẹ ni yoo sọ boya idasilẹ RUGA yoo waye.
Lọpọ igba ni Huawei ti ni awọn kii ṣe iṣẹ ọtẹlẹmuyẹ titọpinpin forileede China amọ awọn ti o mọ nipa iru nkan bayi ni yoo ṣoro ki ile kankan to le kọ lati ma ṣiṣẹ titọpinpin fun ijọba China.
Apẹẹrẹ igbesẹ akin ti Iceland gbe Wọn ko jẹ ki awọn eeyan wa ni ipejọpọ to pọ ju eeyan ogun lọ eleyi ti wọn se titi di ipari osu kini ki wọn to wa ri ẹni akọkọ to ko arun naa nilẹ wọn.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Governorship Election Update: Àfikún ìdìbò yóò wáyé nìpínlẹ̀ mẹ́fà lọ́jọ́ kẹtàlélógún oṣù yìí 13 Ẹrẹ̀nà 2019 Oríṣun àwòrán, OTHER Àkọlé àwòrán, Awọn eeyan n bere fun ki ajọ INEC yanju ọrọ idibo Ajọ eleto idibo lorilẹede Naijiria, INEC ti kede ọjọ kẹtalelogun gẹgẹ bi ọjọ ti afikun idibo yoo waye lawọn ipinlẹ mẹfa ti idibo gomina ko tii pari.
Opolopo odo lo feran Henrik nigbeyin aye re fun atileyin to n se si atunto asa ati ise.
Lẹyin ayẹwo finnifinni, awọn dokita to wa nile iwosan kan nilu Chennai lorilẹede India, sawari pe ọpọ eyin lo wa nisalẹ agbọn to wu naa, ti wọn si pinnu lati se isẹ abẹ fun-un.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ẹ̀mí kan náà ló n darí ìrìnàjò wa táa fi jọ kọ́lé papọ̀- Ìbejì 'Mi o kọkọ fẹ ẹ ṣe iṣẹ abẹ naa' Nitori pe mo ti kọ ẹkọ nipa ẹya ara tẹlẹ, oye nkan ti dokita sọ nigba akọkọ ye mi.
Lẹ́yìn èyí, nígbà tí Senakeribu ati àwọn ogun rẹ̀ gbógun ti Lakiṣi, ó ranṣẹ sí Hesekaya ọba Juda ati àwọn ará Juda tí wọ́n wà ní Jerusalẹmu pé, 
Ará ìlú Àdùnní ni Olófìn-íntótó, ọmọ Adéṣínà.
"Pásítọ̀ Enoch Adeboye darapọ̀ mọ̀ #ENDSARS, ó fún ìjọba Nàìjíríà ní ìmọ̀ràn ọ̀nà àbáyọ Wo àwọn ojúṣe àti èèwọ̀ fún ikọ̀ ọlọ́pàá SWAT tó gba iṣẹ́ lọ́wọ́ SARS Mọ̀ nípa iPhone 12, fóònù ológo 5G tí kìí lo ""Charger” tó ṣẹ̀ṣẹ̀ jáde Mi ò mọ̀ nípa àwọn tọ́ọ̀gì tó da ìwọ́de EndSARS Alausa rú, mo ṣì wà lẹ́yìn yín digbí!"
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Akure Kidnap: E túbọ̀ ní sùúrù, a máa wá ọmọ náà rí- Alukoro ọlọ́pàá Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Ninu iwadi kan ti Ajọ to n risi idagbasoke ọmọ wẹwẹ lagbaye, UNICEF gbe jade lọdun 2017, Naijiria wa ni ipo kẹji ninu awọn orileede ti ṣisẹ igbọnsẹ ni ita gbangba ti peleke.
Bí ó bá jẹ pé ògiri ni arabinrin wa,à óo mọ ilé-ìṣọ́ fadaka lé e lórí.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ebola: ìjọba Gẹ̀ẹ́sì fún DR Congo lówó láti fi gbógunti i 26 Èbibi 2018 Àkọlé àwòrán, DR Congo ń ja ogun Ebola lójú méjèèjì lásìkò yìí Ìjọba ilẹ̀ Gẹ̀ẹ́si fẹ́ pèsè miliọnu marun un pọun fún gbígbógunti Ebola ni Democratic Republic of Congo Wọn kede pé Ebola tún ṣẹyọ ni Bikoro tó jẹ ileto ni ariwa Kinshasa to jẹ olu ilu DR Congo ni èyí to ti ń mu ẹ̀rù ba àwọn ènìyàn kaakiri ilẹ̀ Adulawọ bayii.
Nítorí rẹ mo pa odidi ìlú rẹ́, nítorí rẹ mo mu ènìyàn kúrò lórí oyè, ọ̀rẹ́ mi ayé, ọ̀rẹ́ mi ọ̀run, ọjọ́ wo ni ìwọ ń bọ̀ wáá rí mi?
Wò ó bí Alaafin àti aya àkọ́fẹ́ rẹ̀, Olorì Abibat ṣe pàdé ní èwe Coronavirus ti fa ọ̀wọ́ngógó oúnjẹ ní ìpínlẹ̀ Eko, Kano, Rivers àti Abuja- NBS Àwọn èrò yarí lórí sísan owó àyẹwò covid-19 bí bàálù ilẹ̀ òkèèrè ti ba s'Abuja lẹyìn oṣù márùn ún Ẹ wo ààrẹ orílẹ̀-èdè tó ń ṣèdárò Ẹja akóredé tó d'olóògbé Nibayii, eeyan 1,067 lo ti ba ajakalẹ arun naa lọ ni Naijiria.
ẹ̀yin ọmọ ènìyàn ni ẹ fa àìsàn bá ara yín nínú ayé, Ṣugbọ̀n à!
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Nigeria Elections 2019: IPMAN kéde àdínkù ìyè owó epo bẹntiróòlù 18 Èrèlè 2019 Oríṣun àwòrán, PIUS UTOMI EKPEI Àkọlé àwòrán, Pupọ ọmọ Naijiria lo ti pe fun gba ma binu latari isunsiwaju idibo Aarẹ Ẹgbẹ alagbata epo aladani lorileede Naijiria IPMAN ti paṣẹ ki awọn ọmọ ẹgbẹ wọn jakejado Naijiria mu adinku ba iye owo epo bẹntiro lati mu irọrun ba awọn eeyan lasiko idibo.
Ni ọjọ aje ni Aarẹ Muhammadu Buhari paṣẹ pe ki wọn ko awọn ọmọ Naijiria to ba nifẹ lati kuro ni South Africa pada wale.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Lagos Jumat Mosques: Títì pa ni ìlẹ̀kùn àwọn mọ́ṣáláàṣí kan wà ní ìpínlẹ̀ Eko lásìkò ìrun Jímọ̀ 3 Òkùdu 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 7 Ògún 2020 Paroparo ni awọn mọṣalaaṣi kan da nilu Eko, lasiko irun Jimọ to yẹ ko waye.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Mistura Oseni Akintunde: Ara múmú kìí ṣe oríṣun ìfipábánilòpọ̀, ìran àwòjù ló ń fà á Aarẹ naa ni orin o to gẹ ni ẹgbẹ mejeeji n kọ lasiko yii fun ijọba.
Idi ree ti BBC Yoruba fi ṣe akojọpọ itan nipa igbe aye Alaafin Aole, ija rẹ pẹlu Afonja, titi de ori iku ati epe ti wọn lo ṣẹ fun Yoruba.
Bilidadi ará Ṣuha bá tún dáhùn pé,
Ọjọ kẹta lẹyin iwọpopo ni eyi.
"Orí yéye ní'mògún Kìí ṣe gbogbo ẹni tọ́' lọ́pàá mú ni ọ̀daràn, Kìí ṣe gbogbo ẹni tọ́ wà ní àhámọ́ ni ó dáràn ìjọba, Àìmọye, àìmọwọ́, mẹsẹ̀ tó ti dèrò ọ̀run, Nínú àsìmú tàbí àrìnfẹsẹ̀sí, Ẹlòmíràn lè sọ̀rọ̀ lásán kí ó ti bè dèrò ẹ̀wọ̀n, Tàbí kó yọ sálákeji, Ikú àìmọ̀dí kò gbé yín, Àbí kí ni ka tí pe o, bàbá tó fọmọ fọ́kọ tí ìyàwó ń bá ọkọ dọ́wẹ̀kẹ́ẹ̀ nílé ìwẹ̀, nígbà tó ń kín lẹ́yìn ""baálé mi, bí ẹ ti jánjá nìyí tí gbogbo ayé ń bẹ̀rù yín"", Èyí bọ̀ sí àpò ìbínú ọkọ, Kí ìyàwó lè mọ bí agbára òun ṣe tó, Oni kí wọn ó lọ gbori bàbá ìyàwó wá, Bàbá kú ikú àìmọ̀dí, Láìmọ̀ ibi tí ìdààmú òun ti wá, Orí yéye ní'mògún Tàìsẹ̀ ló pọ̀."
Loju opo Twitter, n ṣe ni ero ṣe ọtọọtọ lori ofin ọhun Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Ní àkókò ìgbà tirẹ̀ ni Hieli ará Bẹtẹli tún ìlú Jẹriko kọ́.
Nigba ti yoo fi di nnkan bi ọdun melo kan, Yusuf ti ni awọn ọmọ ẹyin pupọ ti awọn to wa ni ijọba nipinlẹ Borno si ti n kan si i lati le mu anfaani ba wọn lasiko idibo tori awọn ero to n tẹle e.
Ajọ National Bureau of Statistics to n ri akọsilẹ ohun to n ṣẹlẹ ní Naijiria lo f'ọrọ naa lede.
Bẹẹ ni Gomina naa dupẹ lọwọ awọn eniyan pẹlu bi wn ṣẹ tẹlẹ ofin ijọba lori ijinasiraẹni, nitori ilera ara wn ṣe pataki lati bori itankalẹ arun Coronavirus.
O ni ko ni ṣeeṣe ki wọn ṣẹṣẹ lọ maa gba aṣẹ fun iwaasu kọọkan ti wọn ba fẹ ṣe fun ẹnikọọkan lawujọ.
Iye gbogbo awọn eniyan to dibo
Bẹẹ lọrọ ri ni fasiti Howard to wa lorilẹede Amẹrika, nigba ti awọn ọmọ Naijiria fakọyọ julọ laarin awọn akẹkọjade to n kuro nile ẹkọ fasiti naa.
Orílẹ̀-èdè India jẹ́ ọ̀kan lára àwọn orílẹ̀-ède ti ààrùn Covid-19 ti sọṣẹ́ julọ, pẹ̀lú ènìyàn ẹgbẹ̀run mẹ́jọ lé díẹ̀ to ti ni ààrùn náà ti ènìyàn to lé ni ẹgbẹ̀rún méjìlélógún sì ti báa rìn.
Owo naa lapapọ le ni biliọnu mẹrin naira.
Daramola ni won tun fi ami eye
3M lórí ayélujára Mo bọ́ lọ́wọ́ igbó mímu ṣùgbọ́n ìnira ilé Aafa Ọlọrẹ ti pọ̀jù- ọ̀dọ́ kan Ọlọ́pàá kan jáde láyé, èèyàn méjì fara gbọta lásìkò ìdigunjalè ní Falomo l‘Eko Ile igbimọ aṣoju-ṣofin ni igbesẹ yii ṣe pataki lati dena aarun arunmọleegun ni Naijiria.
Ṣugbọn nígbà tí ọ̀rọ̀ rẹ bá ṣẹ, (bẹ́ẹ̀ yóo sì ṣẹ), wọn óo wá mọ̀ pé wolii kan wà láàrin wọn.
Àwọn Onka oṣù kọ̀ọ̀kan nìyí ni èdè Yorùbá wá.
Ajọ EC tun dupẹ lọwọ awọn ọmọ ilẹ Ghana fun ifarabalẹ wọn ati bi wọn ti gba alaafia laaye.
Ẹni to bori: Nigeria Algeria vs Congo DR.
Ìjàmbá ọkọ̀ tó ṣẹlẹ̀ sí Adams Oshiomole kìí ṣe ojú lásan, àwọn kan ló fẹ́ pa á- APC Ọba Saudi Arabia yọ ọmọ rẹ̀ àti àbúrò rẹ̀ kúrò nípò nítorí ìwà àjẹbánu lórí owó tó yẹ fún ààbò ìlú Èèyàn 239 míràn ṣẹ̀ṣẹ̀ kó COVID-19 ní Nàìjíríà Ọkùnrin kan di èrò ọ̀run nítorí pé o fi ẹ̀sùn kan alájọgbélé rẹ̀ pé o n yan ìyàwó ẹnìkan lálè Victoria Rubadir ọmọ Kenya ló gba àmì ẹ̀yẹ Komla Dumor BBC World News Jones fikun un pe idi ti gomina ipinlẹ Kogi, Yahaya Bello ṣe gbe igbesẹ lati ti ileekọ ni Oṣu Kẹta, ọdun 2020 ni tori arun Coronavirus to n ja ranyinranyin kaakiri agbaye.
Ẹni tó jí ọ̀pá aṣẹ ń bọ̀ wá túbá fúnrarẹ̀, mo fi dáa yín lójú gẹ́gẹ́ bí ìyá - Erelu Kuti Òkú ọ̀dọ́ 15 ni mo kà ní Lekki amọ́ mo kábàámọ̀ pé a gbà kí ológun gbé okù wọn lọ - DJ Switch Lasiko abẹwo naa ni Gomina Sanwo-Olu mu wọn lọ si diẹ lara awọn dukia ijọba ati aladani ti awọn janduku dana sun.
Ìyá rẹ̀ sọ ọ́ ní orúkọ yìí nítorí ìrora pupọ tí ó ní nígbà tí ó bí i.
Igi ati òkúta náà ni Asa fi mọ odi ìlú Geba tí ó wà ní ilẹ̀ Bẹnjamini, ati ti ìlú Misipa.
Ki n to lee ta asọ bubu kan soso, maa jo jo jo, ko si lee si akẹẹgbẹ mi kankan to lee sọ pe oun n sisẹ aje ju mi lọ.
Minisita feto ilera, Dokita Osagie Ehanire lo kede awọn orilẹede meji ti wọn fi kun iye awọn orilẹede to wa nilẹ tẹlẹ.
Oríṣìíríṣìí iṣẹ́ ni ó wà, ṣugbọn Ọlọrun kan náà ní ń ṣe ohun gbogbo ninu gbogbo eniyan.
Ṣugbọn, Lamorde sọ pe oun ko jẹbi awọn ẹsun naa.
Jesu wí báyìí nígbà tí ó ń kọ́ àwọn eniyan ninu Tẹmpili ninu iyàrá ìṣúra.
Wo àwọn ìbejì tó mú ẹ̀dọ̀ àti egungun àyà kan ṣoṣo wá látọ̀run Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Komla Dumor: Victoria Rubadir ọmọ Kenya ló gba àmì ẹ̀yẹ Komla Dumor BBC World News1 Owewe 2020 6:18 Fídíò, Akomolede: Bolaji Faleke ni Olùkọ́ tó ń kọ́ wa ní àṣà oge ṣiṣe lórí BBC Yorùbá, Duration 6,181 Owewe 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Duro Ladipọ, ìlúmọ̀ọ́ká òṣèré tíátà àti ọmọ àlúfà tí kò gbàgbé àṣà ìbílẹ̀ Ayinla Ọmọwura, orin èébú àti oríyìn lo fi di ọ̀rẹ́ àwọ̀n obìnrin Jesu Oyingbo rèé, pásítọ̀ tó láṣẹ ìbálòpọ̀ lóri ọmọ ìjọ obìnrin Ṣẹ gbọ́ nípa Alájọ Ṣómólú, tó ta mọ́tò ra kẹ̀kẹ́?
Kíá, ó ti da omi tí ó kù ninu ìkòkò rẹ̀ sinu agbada tí ẹran fi ń mu omi, ó sáré pada lọ pọn sí i, títí tí gbogbo wọn fi mu omi káríkárí.
Nígbà náà ni ẹ̀mí gbé mi dìde, mo sì gbọ́ ìró kan lẹ́yìn mi tí ó dàbí ariwo ìṣẹ̀lẹ̀ ńlá, ó ní, “Ẹ fi ìyìn fún ìfarahàn ògo OLUWA ní ibùgbé rẹ̀.
Mo ti bá yín sọ̀rọ̀ ní ọpọlọpọ ìgbà, ṣugbọn ẹ kò gbọ́ràn sí mi lẹ́nu.
Lọwọlọwọ,o wa ni ile igbimọ asofin agba orilẹede Naijiria gẹgẹ bi asofin agba.
Wọn fẹsun kan ẹgbẹ okunkun Ẹiyẹ pe wọn pẹka de ilẹ okeere.
Nínú hàhámọ́ ìnira tí wọ́n wà yìí, kò sí ibi tí òun àti mọ̀lẹ́bí rẹ̀ lọ, tí wọ́n kà wọ́n kún.
 Àjẹsára àrùn ọfà ṣọ ̀ pọ ̀ nná tàbí ilẹ ̀ gbóná ( chickenpox vaccine ) di ohun tí a fi kún àwọn mẹ ́ tẹ ̀ ẹ ̀ ta yìí ní ọdún 2005 , èyí tó wá di àjẹsára mmrv .
Láti ìgbà náà ni ó ti ń wá ọ̀nà láti fà á lé wọn lọ́wọ́.
Lori ero ayelujara Twitter egbe naa, egbe ohun so pe, awon n se ipolongo “awon obinrin loju- popo”, saaju ayajo ojo awon obinrin lagbaye, gege bi akitiyan lati se atileyin fun igbese naa, sise agbekale ona ibani-soro ori ero ayelujara fun awon olopaa obinrin ohun ni, lati ja fun eto dogba-dogba ati riro awon obinrin lagbara lati le se ise won bi o ti to ati bi o se ye.
Fun nkan to da bi ẹni pe akopa yii ko ni le farada iṣẹlẹ to ba gbona janyinnjanyin nile ẹlẹgbọn ọn agba oo, lẹyin ọjọ meji pere Kaisha ni awọn alabosi lo pọ ju ninu ile.
Ọ̀rọ̀ tí mo ní í sọ kò ní í ju eléyìí, mò ń wá óunjẹ lọ nísisìyí, nígbà tí mo bá jẹun tán n óò tún padà wáá wò ọ́; ó dígbà o, o kú rògbòdìyàn náà, ki Ẹlẹ́dàá rẹ má ṣàì gbé ọ sọ̀kalẹ̀ níbi tí ìwọ lé téńté sí lórí igi.
tun sagbakale irufe eto ilera ofe yii ki odun o to pari.
Dipo ko lọ ya ara rẹ sọtọ gẹgẹ bi ofin, wọn ṣe lo pinnu lati dari si Aso Rock to si mọ pe oun jẹ ọkan lara awọn to maa n sunmọ aarẹ.
Ooni salaye siwaju pe Araba Agbaye fi orukọ ọmọ naa le Oloye Lowa ilu Ife Adekola Adeyeye lọwọ ki wọn to wa kede rẹ setigbọ ero to pe sita.
Ẹri wa pe awọn aarun coronavirus yooku saba ma n tan kaakiri lasiko òtútù, gẹgẹ bi iwadii awọn oluwadii lati University College ni London ati London School of Hygiene and Tropical Medicine se fi mulẹ.
Bi a ko ba ni jayopa, bakan naa lọrọ ṣe rilawọn aisan miran bii otutu.
wọn ja ni asiko ikọlu igaba-lori ẹni ti awọn oyinbo hu si wọn nigba naa.
Buhari, pàṣẹ f'àwọn Gómìnà pé kí wọ́n jáwọ́ nínú èróǹgbà láti ná N17trillion owó ìfẹ̀yìntì òṣìṣẹ́ Amẹrika ti yọ àfikún owó Físà kúrò fún arìnrìnàjò Nàìjíríà Agboola Ajayi: Igbákejì gómìnà ìpínlẹ̀ Ondo tó fẹ́ yẹ àga mọ́ Akeredolu nìdí Agbẹjọro oludijẹ ẹgbẹ PDP, Eyitayo Jegede tii ṣe Onyechi Ikpeazu lo fiwe pe Gomina Akeredolu ati ẹgbẹ APC fun aṣemaṣe to tako ofin ilẹ yi.
25 Ìgbé 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ẹ̀fọn to ni kokoro ibà lara lo maa n pin Bawo ni a ṣe le da ibà duro?
Sùgbọ́n ní ìgba ti BBC ba oluranlọwọ pàtàki Gomina Akeredolu Onimọ ẹrọ Tunji Ariyomo sọ̀rọ̀ lóri ọ̀rọ̀ rẹ̀, o ni kò si ǹkan to jọ bẹ́ẹ̀, sùgbọ́n gẹ́gẹ́ bi olórí, oye lààgbà wó ni gomina fi ṣe, ati pe Gomina ko ni ìbásepọ kankan pẹ̀lú woli náà.
Lọwọlọwọ, a gbọ pe ida kan ninu ọgọrun awọn to ko arun naa lo gba ibẹ ku.
Kí ní Khafi BB Naija yóò pàdánu tí iṣẹ́ ba bọ́ lọ́wọ́ rẹ̀?
Travel Ban: Nnkán marun tó yẹ kí o mọ nípa àṣẹ wàá Ilé aṣòfin àgbà Nàìjíríà dàbí ọjà bí Saraki ṣe pa Akpabio lẹ́nu mọ́ Oyedepo: Ẹni tó bá ń sàánú àwọn apànìyàn, kò ní mú 2018 jẹ 1.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, BBC Africa Eye: ìwádìí ìkọ̀ks BBC fihàn pé àwọn kan ń jí ohun èèlò ìdáàbòbò ìjọba tà nígbo Ẹwẹ, nigba to n ba BBC Yoruba sọrọ lori iyanṣẹlodi ọhun, kọmisọnna eto iroyin ni ipinlẹ Eko, Gbenga Omotosho sọ pe ijọba apapọ lo ni NUPENG, nitori naa ijọba apapọ lo yẹ ko yanju ọrọ ọhun.
O wa rọ awọn ileesẹ AIT ati The Sun lati san gbogbo ẹtọ awọn akọroyin ti wọn da duro naa, eyiun to ba jẹ pe bi wọn se gba isẹ lọwọ wọn ba ofin mu.
je akowe agba fun ajo to n ri si  ọrọ  abẹle , lo kede yii, lojo Aje niluu Abuja
Ní ọjọ́ kejìdínlọ́gbọ̀n oṣù Belu ọdún 1990,  àwọn ẹgbẹ́ ológun yẹgi fún ọkùnrin méjìdínlọ́gbọ̀n tí a fi ìfarabalẹ̀ ṣà lọ́kọ̀ọ̀kan láti pa nínú ẹ̀wọ̀n láàárín òru, ní Inal ní orílẹ̀-èdè Mauritania lẹ́yìn tí a fi ẹ̀sùn ìpète-lati-gba-ìjọba kàn wọ́n.
sọ pe,  iye awon oludibo ni ipinlẹ Gombe  jẹ 1,385, 191, ti iye awon ti won yege lati dibo jẹ 554, 203, iye ibo ti won fagile
Shagari bẹrẹ iwe kika nileewe ti wọn ti n kọ Keu, ko to o di pe o lọ si ileewe alakọbẹrẹ Yabo Elementary School lọdun 1931 si 1935.
Lasiko to n ba BBC Yoruba sọrọ, Temitopẹ ni awọn adigunjale to wa sile awọn lasiko ti baba oun ko si nile lo sokunfa ijamba naa.
Omo odun metadinlogbon naa soro yii nibi eto Glenfidich circle ti maverick, eyi ti PlayNetwork Nigeria sagbateru re pelu Transcorp Hilton ni Abuja.
ibudo idibo lo ti kun fọfọ, ti awon oludibo si ti dibo won, ni eyi ti o jẹ pe pupọ
 Awon oga agba mejeeji ko ku sinu isele yi sugbon awon mejila to wa nibe jalaisi lojukan naa nigba ti eni ketala gbemi mi nile iwosan leyin wakati die.
Awon osise ile ise to n mojuto
Ìdí nìyí tí ìpín mẹ́wàá fi kan Manase láìka Gileadi, ati Baṣani ní ìhà ìlà oòrùn odò Jọdani.
O salaye pe, ile-ise ohun n n ijiroro pelu awon agbase-se abele, amo ko so ni kikun lori ipade naa.
À ń sọ ọ̀rọ̀ ọgbọ́n fún àwọn tí igbagbọ wọn ti fẹsẹ̀ múlẹ̀, ṣugbọn kì í ṣe ọgbọ́n ti ayé yìí, kì í sìí ṣe ti àwọn aláṣẹ ayé yìí, agbára tiwọn ti fẹ́rẹ̀ pin.
Nígbà ayé Josaya, ọmọ Amoni, ọba Juda, ní ọdún kẹtala tí Josaya gun orí oyè ni OLUWA bá Jeremaya sọ̀rọ̀.
Ko sọ gbogbo otit ibẹ, ṣugbọn o jẹ ibi ti a ti le bẹrẹ si ni ṣagbeyẹwo aidọgba ni South Africa.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Coronavirus pandemic update: Wo àwọn orílẹ́-èdè tí kò ní coronavirus lágbàáyé 1 Owewe 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 20 Owewe 2020 Oríṣun àwòrán, Palau Hotel Àkọlé àwòrán, The Palau Hotel, Koror Ajakalẹ arun coronavirus ti ṣọṣẹ kaakiri orilẹ-ede gbogbo lagbaaye a fi orilẹ-ede mẹwaa kan ti ọwọja rẹ ko de.
ati ẹyẹ òfù, ati àkàlà, ati ẹyẹ ìgo, 
Omo ipinlẹ Yobe ni ariwa ila oorun Naijiria ni Abubakar Shekau jẹ.
Kí ló mú ọlọ́pàá ilẹ̀ Gẹ̀ẹ́sì san owó gbà má bínú £2500 fún pásítọ̀ yí?
Ẹ ṣọ́ra kí ẹ má baà pa iṣẹ́ tí ẹ ti ṣe run, kí ẹ lè gba èrè kíkún.
Solomoni kò máa rìn ní ọ̀nà òun OLUWA, kí ó máa ṣe rere, kí ó máa pa òfin òun mọ́, kí ó sì máa tẹ̀lé ìlànà òun bí Dafidi baba rẹ̀ ti ṣe.
OLUWA ní, “Ní àkókò ìtẹ́wọ́gbà mo dá ọ lóhùn,lọ́jọ́ ìgbàlà, mo ràn ọ́ lọ́wọ́.
Àwọn ọmọ Israẹli tún gbógun ti àwọn ọmọ Bẹnjamini ní ọjọ́ kẹta, wọ́n tò yípo Gibea bíi ti iṣaaju.
Ṣe kíá, kí o sálọ sibẹ, nítorí n kò lè ṣe ohunkohun, títí tí o óo fi dé ibẹ̀.
Ilẹ̀ tí ó wà ní apá ìhà gúsù jẹ́ ti àwọn ọmọ Efuraimu, èyí tí ó wà ní apá ìhà àríwá jẹ́ ti àwọn ọmọ Manase.
O dùn mi pé n kò lè rí ààyè kọ̀wé lánà-án.
Tootọ ni, o si n pani bi ọgan ni.
7 104879 Ilẹ Australia 908 3.
Wo àwọn Ṣọ́ọ̀ṣì Nàìjíríà àti l'Áfíríkà tó ń wólẹ̀ àdúrà kí Trump lè wọlé ìbò ààrẹ America Sọ̀rọ̀ sókè!
Nígbà tí o wí pé, “Ẹ máa wá ojú mi.
Lẹ́yìn awuyewuye to wáyé lori iwe ẹ̀rí agunbanirọ̀ minisita nigba kan ri fun ètò ìsuná, arabinrin Kemi Adeosun, minisita fun ọ̀rọ̀ ìbáraẹnisọ̀rọ̀, Adebayo Shittu ni wọn tun ti fẹ̀sùn kan pe ko ni iwe ẹ̀rí agunbanirọ.
Ninu ọrọ tirẹ, Ogbeni Dami ni awọn ole ti bẹrẹ si ni ṣọṣẹ lori afara third mainland naa ati awọn ọna miran ti ijọba lakalẹ fun awọn eniyan lati ma a gba.
Wayii o, bi a ko ba gbagbe
àwọn afọ́jú ń ríran, àwọn arọ ń rìn, ara àwọn adẹ́tẹ̀ ń di mímọ́, àwọn adití ń gbọ́ràn, à ń jí àwọn òkú dìde, a sì ń waasu ìyìn rere fún àwọn talaka.
Ẹ kò gbọdọ̀ jẹ ohunkohun tí ó bá ń fi àyà wọ́, tabi ohunkohun tí ó bá ń fi ẹsẹ̀ mẹrin rìn tabi ohunkohun tí ó ní ọpọlọpọ ẹsẹ̀, tabi ohunkohun tí ó ń fà lórí ilẹ̀, nítorí ohun ìríra ni wọ́n.
Nítorí náà mú Aaroni ati ọmọ rẹ̀ Eleasari wá sórí òkè Hori.
Ẹ kò gbọdọ̀ jẹ ohunkohun tí ó ní ìwúkàrà ninu; ninu gbogbo ilé yín patapata, burẹdi tí kò ní ìwúkàrà ninu ni ẹ gbọdọ̀ máa jẹ.
O fi awọn ẹri kan to jọ awọn atẹjiṣẹ ori ẹrọ ilewọ han ninu eyi ti oun ati pasitọ naa fi ọrọ ifẹ ṣọwọ sira.
Láti ọdún yìí ni Nigeria, ọlọ́dani àti àwọn ilé iṣẹ́ tí ń ṣe ǹkan máni gbàgbé láti ránti akọni to ti papodà yìí.
Oludije sipo ààrẹ ninu ẹgbẹ Democrat, Joe Biden to sọ pé, bi wọn ṣe fa ọwọ Barrett soke ati bi wọn ṣe yan an sipo ni ọwọ mọdaru ninu.
”Bẹ́ẹ̀ ni wọ́n ṣe di ìsáǹsá ati alárìnkiri,nítorí àwọn eniyan ń wí láàrin gbogbo orílẹ̀-èdè pé,“Àwọn wọnyi kò gbọdọ̀ bá wa gbé pọ̀ mọ́.
Amosun ti sọ nita gbangba pe oun ko nigbe lẹyin oludije ẹgbẹ APC nipo Gomina mii bi kii ṣe Adekunle to jẹ aayo rẹ.
 gbogbo àwọn ojúlé wọ ̀ nyí ló wà lábẹ ́ àkóso ọba akẹsìn ṣùgbọ ́ n àwọn ìwàrẹ ̀ fà àti àwọn Ẹtalà2 ló ń pàṣẹ ìlú .
Ní àkókò náà, nígbà tí Modekai jókòó ní ẹnu ọ̀nà ààfin, meji ninu àwọn ìwẹ̀fà ọba, tí wọn ń ṣọ́ ẹnu ọ̀nà: Bigitana ati Tereṣi, ń bínú sí ọba, wọ́n sì ń dìtẹ̀ láti pa Ahasu-erusi ọba.
ṣugbọn wọ́n ń fi agídí ṣe ìfẹ́ ọkàn wọn, wọ́n ń bọ àwọn oriṣa Baali, bí àwọn baba wọn ti kọ́ wọn.
Paapa lati ọdọ ẹbi ati ile ijọsin wọn pẹlu.
“Samaria ni ẹ̀gbọ́n rẹ, òun ati àwọn ọmọ rẹ̀ ń gbé ìhà àríwá.
Ilẹ ẹjọ fagilé ìbò ọmọ ẹgbẹ́ APC nípinlẹ̀ Ogun pè kí àtúndì ìbò wà A kò lòdì sí kí àwọn mùsùlùmí ṣé ìwọ́de àyájọ́ Ashura-Ọlọ́pàá Nàìjíríà Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí kan sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
Ajọ NCDC kede eyi lalẹ Ọjọru.
Ati pe awọn mẹtẹẹta fẹ lọ ki iyawo ọga wọn ninu ọgba ologun naa ni lasiko ti iṣẹlẹ naa ṣẹlẹ.
Àwọn mii ti wọn tun yan sipo ni Ọgagun A.
Iwe iroyin sọ pe, oludasilẹ ileewe aladani naa lo fi ẹjọ sun ni agọ ọlọpaa, lẹyin ti akẹkọọbinrin naa tu aṣiri fun.
Ijoba orile ede Naijiria ti so pe ohun yoo tun tubo tepele
"Awọn jàndúkù yabo ilé Sẹ́nétọ̀ Teslim Folarin, wọ́n kó ẹ̀rọ ata, ọ̀kadà, fírìíjì àti àwọn nkan tí owó rẹ̀ tó N200m ""Apena fẹ́gbẹ́ Oṣugbo, Opa, Akala àtẹ̀yin awo, ẹ wa ọ̀pá àṣẹ Ọ́ba Akiolu jáde"" Òkú ọ̀dọ́ 15 ni mo kà ní Lekki amọ́ mo kábàámọ̀ pé a gbà kí ológun gbé okù wọn lọ - DJ Switch Àwọn tó fara gba ọta ní Lekki ní ọ̀pọ̀ ìbéèrè láti dáhùn - Ahmed Tinubu O ni ọwọ ọlọpaa tẹ awọn afunrasi naa fun oniruuru ẹsun iwa ọdaran bii ile jijo, ipaniyan, ole jija biba dukia onidukia jẹ ati ikọlu ṣaaju ati lẹyin ofin konile o gbele ti gomina Babajide Sanwo-Olu kede lati mu alaafia bọ sipo."
Ni yìnyín ati iná pẹlu ẹ̀jẹ̀ bá tú dà sórí ilẹ̀ ayé.
Ní àkókò yìí, Ahasi ranṣẹ lọ bẹ ọba Asiria lọ́wẹ̀, 
Afọnja, ẹni tó finú wénú ní Ilọrin, àmọ́ tó jẹ iwọ Lisabi Agbongbo Akala rèé, ẹni tó fi ìfẹ́, ìṣọ̀kan àti ìrẹ́pọ̀ gba ilẹ̀ Ẹ̀gbá lọ́wọ́ ìmúnisìn Ọ̀rọ̀ǹpọ̀tọ̀niyùn, Aláàfin obìnrin àkọ́kọ́ rèé, tó ní nǹkan ọkùnrin Àwọn ọba Yorùbá kan rèé tí wọ́n rọ̀ lóyè, tí ọba míràn jẹ lójú ayé wọn Ọba Lamidi Adeyẹmi, òṣìṣẹ́ adójútòfò àti Abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò kó tó jọba Ọmọ ilu Abeokuta ni Tinubu, o fẹ ọpọ ọkọ nigba aye rẹ, lara wọn si ni Oba Adele Ajosun tilu Eko, to fẹ lọdun 1833 nilu Abeokuta nigba ti wọn rọ Oba naa loye, to si sa lọ silu Egba.
 a bí i ní 1864 .
Ikede tuntun yii ni ọfiisi aarẹ gbe jade lẹyin ti aarẹ Buhari ti kede tiriliọnu mẹwa naira le diẹ, owo iṣuna fun ọdun 2020.
Àwọn eniyan yóo sá sinu ihò àpáta,wọn yóo sì wọ inú ihò ilẹ̀ lọ,nígbà tí wọ́n bá ń sá fún ibinu OLUWA,ati ògo ọlá ńlá rẹ̀nígbà tí ó bá dìde láti mi ayé tìtì.
Ìwà ìrẹ ̀ lẹ ̀ jẹ ́ ara ìṣe wa ní wikipedia , ó sì wà lára tí ó gbé wikipedia ró .
O ni ti wọn ba sun idibo naa siwaju, America yoo ti fẹ́ bọ́ tan lọwọ isoro Covid 19 to n jẹ ki awọn eeyan maa gbe ni ewu ati pelu ifura.
"Dokita O'Brien sọ pe ''iba jẹ aarun to ṣoro lati pese abẹrẹ ajẹsara ti yoo koju rẹ'' said that malaria is ""a really difficult disease to develop a vaccine against""."
o óo rí irun aguntan fi hun aṣọ,o óo sì lè fi owó tí o bá pa lórí àwọn ewúrẹ́ rẹ ra ilẹ̀.
Onígbàgbọ́ tí ó wà ní ipò akàwé nínú ìjọ, tí ó kúrò ní ipò èyìínì tí ó di àlùfáà tíi ó tún dé ipò bísọ́ọ̀bù tí kò ní ìẹ̀lọ́rùn, mo biọ́, eléyìínì ń fẹ́ẹ́ di Ọlọ́run ni?
Awọn tọkọtaya mejeeji yii ko si jẹ ki ipo ti wọn wa se idiwọ fun wọn lati yan isẹ oojọ kan laayo nitori wọn ni isẹ ọwọ ti wọn n se.
Ogun Election: Ilé ẹjọ gbé àga lọ rèé jókòó jẹ sílé fún Ọsunsanya.
Jemila dáná sún ilé ọ̀rẹ́kùnrin rẹ̀ àti ọ̀rẹ́bìnrin tó bá nílé Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Akọ́mọlédè àti Àṣà lórí BBC Yorùbá: Kọ̀ síi nípa iṣẹ́ tí oúnjẹ ń ṣe lára níbí Àwọn àmìn ẹ̀yẹ ti Burna Boy ti gbà Burna Boy ti gba àmì ẹ̀yẹ tó le ni ogún ti wọ́n sì ti yàn-án fún ọ̀kẹ́ àìmọye omíràn ti kò kẹ́sẹjárí.
nítorí pé ìdájọ́ òtítọ́ yóo pada jẹ́ ìpín àwọn olódodo,àwọn olóòótọ́ yóo sì máa tọ̀ ọ́ lẹ́yìn.
Ti wọn ba ri ti mo’n kopa ti mo si n se daada,inu wọn yoo dun Ẹ le ka nipa rẹ si nibi Ẹni to ni aworan: Matthias Hangst/Getty Images, Dimitar Dilkoff/AFP/Getty Images, Francois Xavier Marit/AFP/Getty Images, Shaun Botterill/Getty Images, Christophe Pallot/Agence Zoom/Getty Images, Alexander Hassenstein/Getty Images, ALEXANDER KLEIN/AFP/Getty Images, Dean Mouhtaropoulos/Getty Images, Courtney Hoffos Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Egbe Springdale Area Recreation , to n ri si ere-idaraya wiwe-do ati boolu afiigigba ti o fi North Carolina lorile-ede Amerika se ibugbe, ti pese awon ohun elo lorisirisi fun awon olukopa Naijriia ninu ere-idaraya naa lati mu igberu ba ere-idaraya ohun lorile-ede Naijria.
N óo fọ̀ wọ́n mọ́,n óo dán wọn wò.
Iroyin ti a gbọ ni pe ọga agba banki kan to n reti esi ayẹwo to ṣe fun aarun covid-19 wa lara awọn to ku naa.
Kì í ṣe pé ara wọn ni wọ́n ń ṣe, tí wọ́n sì ń dójú ti ara wọn?
Nígbà tí a jẹ́ ọmọ Ọlọrun, kò yẹ kí á rò pé Ọlọrun dàbí ère wúrà, tabi fadaka, tabi òkúta, ère tí oníṣẹ́ ọnà ṣe pẹlu ọgbọ́n ati èrò eniyan.
Dojú kọ ọ́ bí ìlú tí a gbógun tì; kí o ṣebí ẹni pé ò ń gbógun tì í.
Nígbà tí mo jẹ́ àlejò, ẹ gbà mí sílé.
Ẹrú yi fẹ́ràn Bàbá, ó si fi tọkàn-tọkàn ṣe iṣẹ́ fún.
Wo Ángẹlì tó n sàn owo ìtọjú àwọn aláìsàn Ẹ̀kọ́ mẹ́fà tó jáde nínú ìdíje Premier League òpin ọ̀sẹ̀ Òhun tí o sẹlẹ nigba ti Buhari lọ China Àríyànjiyàn Osinbajo àti PDP Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ipenija ojú kò di Ademola lọ́wọ́ láti kẹkọọ gboye Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Wòlíì Àrólé sọ àsọtẹ́lẹ̀ s'áyé BBC ní London Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Àwọn ọ̀tá ilẹ̀ Juda ti borí rẹ̀, wọ́n ti wá di ọ̀gá rẹ̀,nítorí pé, OLUWA ń jẹ ẹ́ níyà fún ọpọlọpọ ẹ̀ṣẹ̀ rẹ̀,àwọn ọ̀tá ti ti àwọn ọmọ rẹ̀ ṣáájú,wọ́n ti kó wọn nígbèkùn lọ.
Aláàfin Ọyọ: Ọba tó bá n mú ọtí ní ìta kò yẹ ní ẹni tàá bọ̀wọ̀ fún Bí akẹ́kọ̀ọ́ kíláàsì rẹ bá ti yege sí, ní ìgbéga rẹ yóò ṣe yá sí - Makinde sọ fáwọn olùkọ̀ Oyo Pásítọ̀ Kérúbù rẹ́wọ̀n he ní UK torí ó fi ‘ìwẹ̀ mímọ́’ bá ọmọdébìnrin mẹ́fà lòpọ̀, ṣẹ́yún fún wọn Oluomo ṣalaye pe iṣẹ oun akọkọ gẹgẹ bii Mayegun ni lati ri pe alaafia jọba nilẹ Yoruba.
“O óo san ẹ̀san fún wọn, OLUWA,gẹ́gẹ́ bí iṣẹ́ ọwọ́ wọn.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù #BBCNigeria2019:Àkójọpọ̀ àwòrán láti ìpàdé ìtagbangba pẹ̀lú àwọn olùdije ní Ọyọ 1 Èrèlè 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 2 Èrèlè 2019 Eyi ni akojọpọ awọn aworan to lamilaaka nibi ipade itagbangba ni Ọyọ: Àkọlé àwòrán, Ipade itagbangba ti BBC New Yoruba fun awọn oludije si ipo gomina ni ipinlẹ Ọyo waye ni Ọjo Kini, Osu Keji, ọdun 2019 saaju idibo gbogboogbo.
Nínú ìpàdé wọn ní àwọn gómìnà mẹ́rẹ̀rìndílógójì ti sọ nínú ìbéère wọ́n pé, ìdá mejilélógóji ni àwọn fẹ́ máà gba, èyí to jìnà sí ìdá mẹ́rìndínlọ́gbọ̀n tí wọ́n ń gbà tẹ́lẹ̀.
Ọjọ́ márùn-ún gbáko ni wọ́n fi ṣe ètò ẹ̀yẹ yìí.
Oríṣun àwòrán, Haramain Ní ayajọ oni ni awọn Alhaji ati Alhaja tuntun máa ń kójọ pọ sí oke Arafat tó wà ní ìlú Makkah lọdọdún.
Ẹ̀mí OLUWA, Ọlọrun tí bà lé mi, nítorí ó ti fi àmì òróró yàn mí,láti mú ìròyìn ayọ̀ wá fún àwọn tí a ni lára.
Ìrẹ́pọ̀ tó sọnù ló ń fa aáwọ̀ APC - Oshiomole Kí ni àwọn ẹ̀ṣẹ̀ àti ẹ̀sùn tó ń da Oshiomole láàmú?
Ekinni keji wọn ga ní igbọnwọ mẹ́wàá.
7 miliọnu lori amojuto ibode ipinlẹ, ọkọ iṣẹ awọn oṣiṣẹ alaabo ati itọju awọn oṣiṣẹ gangan.
Ó ní, ‘Àwọn ọmọ ayé ìdayìí mà láyà o.
Lara ohun ti won yoo jo maa jiroro lori eto oro aje , eto aabo ati  bi ibasepo orile ede mejeeji  naa yoo se tubo  maa tesiwaju si i.
Nítorí OLUWA ni yóo jẹ́ ìmọ́lẹ̀ ayérayé fún ọ,ọjọ́ ọ̀fọ̀ rẹ yóo sì dópin.
Ohun tí ojú opó ń rí láwùjọ kò kéré Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ọ̀gá Bello: Àìgbọ́n ló ń da àwọn òsèré tíátà tó ń jà lórí ayélujára láàmú Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ọbìnrin tó fẹ́ ṣojú àwọn ẹ̀yà Sheedi Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
bumba ni ẹdá àkọ ́ kọ ́ nínú ìtàn ìgbà ìwáṣẹ ̀ won .
'Soapy', àwo orin tuntun Naira Marley tó ń milẹ̀ tìtì Ọgbà ẹ̀wọ̀n ni Naira Marley yóò ti wo ìbúra Buhari ní May 29 Naira Marley gba ipò mọ́ Atiku lọ́wọ́ gẹ́gẹ́ bí èèyàn tí wọ́n ń wá jùlọ ní Google lọ́dún 2019 Ni oṣu karun ọdun 2019 ni akọrin ara, Simi pariwo sita lori ikanni ayelujara lati koro oju si bi awọn ọdọ ṣe n kan si agbami iwa jibiti ori ayelujara.
Eto idibo yii yoo waye ni ojo kerinla osu keje.
"O ni, ""Ni ibamu pẹlu ofin Islam, a ni oreọfẹ lati kede pe oni ọjọ aje, ọjọ kọkandinlọgbọn oṣu Ramadan, 1440 AH to bọ si ọjọ kẹta oṣu kẹfa ọdun 2019 ni awẹ oṣu Ramadan wa sopin ti oṣu tuntun Shawwal si bẹrẹ."
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Bolaji Faleke ni Olùkọ́ tó ń kọ́ wa ní àṣà oge ṣiṣe lórí BBC Yorùbá Eyi to ga julọ to ṣẹlẹ lọdun 2017, ọpọ awọn ọmọ oye, awọn minisita ati awọn olokoowo lo timole si ile itura Rittz- Calton ni Riyadh.
Àlejò àpàndodo ni Fayoṣe, a kò fìwé pèé - Afuye Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Lórí ṣíṣe ṣáá kejì lórí aleefa, Akeredolu ni laipẹ ni ìpolongo ibo yóò bẹ̀rẹ̀, tí Ọlọ́run bá sì ní òun yóò ṣe ṣáá kejì, kò sì wàhálà, ohun tí Ọlọ́run yóò ṣe, ni òun ń dúró de.
Ninu irufe ipo ate naa lagbaye, orile-ede Belgium dipo kinni won mu , ti
Ẹ máa gbé inú mi, èmi óo máa gbé inú yín.
Dafidi bẹ̀rẹ̀ sí ta hapu fún un gẹ́gẹ́ bí ó ti ń ṣe tẹ́lẹ̀.
Ogunyemi ni oun ko fẹ fi ẹmi awọn akẹkọọ wewu lo jẹ ki oun gba ijọba nimọran pe ki ile iwe wa ni titi pa lasiko yii.
Ìbànújẹ́ tí eniyan bà faradà gẹ́gẹ́ bí Ọlọrun ti fẹ́ a máa mú kí eniyan ronupiwada kí ó sì rí ìgbàlà, tí kò ní àbámọ̀ ninu.
Ìtọ́ni Urimu ati Tumimu ni Eleasari yóo fi máa darí Joṣua ninu ohun gbogbo tí àwọn ọmọ Israẹli bá fẹ́ ṣe.
Ọpọ wọn to ba wa sọrọ ni iya awọn osisẹ ni Naijiria ti pọ ju.
Ǹjẹ́ ìpinnu tí ẹ̀ ń ṣe tọ̀nà, ẹ̀yin aláṣẹ?
"Oloogbe Akinwumi Orojide Isọla lo kọ iwe litireṣọ "" Nitori Owo"" naa."
South Africa bẹ Naijiria lórí ìsekúpani nítorí ẹ̀yà!
Ni gbogbo eto ile iwe ni iye awọn ọkunrin ti pọ ju awọn obinrin lọ ni ilọpo meji.
Nigeria Police Force: Buhari f'òǹtẹ̀ lu Mohammed Adamu gẹ́gẹ́ bí Ọ̀gá ọlọ́pàá tuntun.
Ibi tí wọ́n ti wá a kiri ni wọ́n ti gbúròó rẹ̀ ni ibì kan tí a ń pè ní Òkèníṣà ní Ìjẹ̀bú-Jẹ̀ṣà lonìí yìí.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Xenophobic Attack: Báwo ni ìkọlù sáwọn àjèjì ṣe pọ̀ tó ní South Africa?
Bee si ni ara ilu kan tun
Minisita feto ilera to kede eyii.
Coronavirus: ''Ìjọba kò tíì pàṣẹ ìlànà ìtakété-síra-ẹni padà nínú BRT la ò ṣe máa tẹ̀le'' Ìjọba gbé ilé ijó oníhòhò tì pa lórí ẹ̀sùn títàpá sí ìlànà àti dẹ́kun coronavirus Kí làwọn nǹkan tó lè rán ọkùnrin sí ọ̀run alákeji lásìkò ìbálòpọ̀ pẹ̀lú obìnrin?
Ṣe bẹ́ẹ̀, a kò sì ní pada lẹ́yìn rẹ;dá wa sí, a ó sì máa sìn ọ́!
OLUWA pe Mose, ó sì bá a sọ̀rọ̀ láti inú Àgọ́ Àjọ ó ní, 
Nitori naa, iriri ọtọ lo pada jẹ, nigba ti mo pada si Naijiria lati di iyawo gomina.
Ó lé àwọn orílẹ̀-èdè tí wọ́n pọ̀ jù yín lọ, tí wọ́n sì lágbára jù yín lọ kúrò fun yín, kí ó baà lè ko yín wọlé kí ó sì fun yín ní ilẹ̀ wọn, kí ẹ sì jogún rẹ̀ bí ó ti wà lónìí.
Feranmi - Ariyo Sunday Sina 28MPNLawal Ganiyu Akanfe - Idowu Kayode Olusegun 29NCPKamarudeen Kalemi Abiodun - Lawal Temitope Serifat 30NPCOlaniyi Anthony Fadahunsi - Abdulrasheed Afusat Olanike 31NEPPJegede Hannah Taiwo - Rebecca Adeleke Oladepo 32NNPPAdefare Segun Adegoke - Adeyeye Nurudeen Adeyemi 33PANDELAdebayo Rasheedat - Ajibola Fatimat 34PDCKolawole Rafiu Ojonla - Oladapo Deborah Oluwatoyin 35PDPAdemola Nirudeen Adeleke - Albert A.
A dúro bí iké lẹ́yìn ìròyìn táa gbé jáde nípa Lekki Tollgate; CNN tako Lai Mohammed Ẹ̀tanú pé Olùṣọ́ Genesis kò fẹ́ Laide Williams-Oni ló ṣe rán an lọ́ sí ẹ̀wọ̀n ọdún kan - CCC Genesis Global Ìtàn ayé Abiola Peller, ọlọ́wọ́ idán tó fi ọ̀bẹ gé ìyàwó rẹ̀ sí méjì Ọkùnrin tó pe ìyàwó rẹ̀ lájẹ̀ẹ́ tì í mọ́lé fọ́dún mẹ́rin, fún un lóyún nígbà mẹ́ta!
Ẹfunroye Tinubu - Ògbóǹtagí oníṣòwò, olówò ẹrú àti afọbajẹ Samuel Ajayi Crowther, òjíṣẹ́ Ọlọ́run tó gbé èdè Yoruba lárugẹ Mọrèmi Àjàṣorò, akọni obìnrin tó gba Ilé Ifẹ̀ sílẹ̀ lóko ẹrú Nigba to n sọ bi isẹlẹ naa se waye fun iwe iroyin London Mail, Alabi sọ pe oun sadede gbọ ariwo ni deede aago meji ku isẹju marun ni ọsan ọjọ Ẹti naa, ti oun si bojuwo oju ferese, ti oun si ri ọkunrin kan to wọ asọ agbofinro, ti oun si ro pe ọlọpa ni.
Ọjọ ẹti tii ṣe ọjọ karun un ọsu Kẹrin ni ẹka ọtẹlmuye ọlọpaa to wa ni Panti nilu Eko gbe Inspẹkitọ Ogunyẹmi Olalekan lọ si iwaju adajọ.
Abíọ́lá láti dìje fún ipò àarẹ́ nínú ìdìbò ọdún 1993.
Ọpọlọpọ ojo lo ti rọ ti ilẹ ti fi mu lori iṣẹlẹ yii ni Amerika ati ni agbaye lapapọ.
“Nígbà tí OLUWA Ọlọrun yín bá pa àwọn orílẹ̀-èdè tí yóo fun yín ní ilẹ̀ wọn run, tí ẹ bá gba ilẹ̀ wọn, tí ẹ sì ń gbé inú àwọn ìlú wọn, ati ilé wọn, 
O ti di eeyan mejilelogun bayii to ti lugbadi arun coronavirus ni Naijiria, amọ ọmọ ilẹ Italy to kọkọ ko arun naa wọ Naijiria ti gbadun bayii, o si ti kuru ni ile iwosan.
O ni ijọba ṣẹṣẹ san owo fun ile iwe giga Ladoke Akintola University ni Ogbomosọ laipẹ ni.
Alaga ẹgbẹ oselu PDP ni ipinlẹ Osun naa wa fikun wi pe, o ti ye gbogbo ẹgbẹ patapata ipo ti Ademọla Adeleke wa ninu ẹgbẹ, ati ifojusun rẹ fun idije si ipo gomina ni ọdun 2022.
Nígbà náà ni Rabuṣake kígbe sókè rara ní èdè Heberu tíí ṣe èdè àwọn ará Juda ó ní, “Ẹ gbọ́ ohun tí ọba Asiria ń sọ fun yín; 
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Fadele: Dán an wò, lóbí ìyá ọ̀kẹ́rẹ́ ni a fi ọ̀rọ̀ ọ̀kadà náà ṣe Ṣaaju eyi ni Akpabio lọ si ilu London lati lọ ki Aarẹ Muhammadu Buhari to wa lẹnu isinmi.
Bí ẹran ìyàsímímọ́ ati burẹdi náà bá kù di òwúrọ̀ ọjọ́ keji, fi iná sun ìyókù, ẹnikẹ́ni kò gbọdọ̀ jẹ ẹ́ nítorí pé mímọ́ ni.
Bi a ba ranti, ni ọjọ Aje ni Ile Igbimọ Aṣofin Ipinlẹ
OLUWA ní òun óo kọ àwọn eniyan òun yòókù sílẹ̀, òun óo fi wọ́n lé àwọn ọ̀tá wọn lọ́wọ́, ọ̀tá yóo ṣẹgun wọn, wọn yóo sì kó wọn lọ bí ìkógun.
Kí ló fa ááwọ̀ láàárín Oluwo àti Agbowu gan-an?
Ọrọ pe ki awọn eeyan da ẹbi ru Alaafin yii ni arakunrin kan Paul Temitope Ilesanmi fi da lohun pe, ko si nkankan ti yoo ṣelẹ si alayeluwa.
Eto ọgbin: ipese owo fun awọn agbẹ lati le e mu isẹ agbẹ lọkunkundun yoo tẹsiwaju, ki eto ọgbin le gbooro si ni Naijiria.
 Mo n gba won nimoran ki won tun safikun imo won nipa kiko eko sii lori ayelujara ati lori ise alawomo litireso ki o ma je aworan nikan.
Sinimá àwòdamiẹnu, Ẹ̀fáńjẹ́líìsì jìyà àjẹmumi nílé aṣẹ́wó l'Ejigbo ní ìlú Eko Gbajúgbajà òṣèré “Blue film'' wọ gàù ẹ̀sùn fífipá bá obìrin 13 lòpọ̀ Ọba Saudi Arabia yọ ọmọ rẹ̀ àti àbúrò rẹ̀ kúrò nípò nítorí ìwà àjẹbánu lórí owó tó yẹ fún ààbò ìlú Ìjàmbá ọkọ̀ tó ṣẹlẹ̀ sí Adams Oshiomole kìí ṣe ojú lásan, àwọn kan ló fẹ́ pa á- APC Ajagba ni otitọ ni pe Joshua ti gba ami ẹyẹ goolu ninu idije ''Olympics'' ri, oun si tun ni abẹṣẹ ku bi ojo to lami lahaka taye ti aye n fẹ lọwọ bayii.
Àkọlé àwòrán, Àwọn oṣiṣẹ BBC Yoruba to n ṣe iforukọsilẹ awọn olukopa Àkọlé àwòrán, Ọmọọbabinrin Adebisi Ogunsanya (YPP) ati Ọgbẹni Muyiwa Fafowora (ADC) níbi ìgbàlejò ṣáájú ìpàdé ìfọ̀rọ̀wérọ̀ Àkọlé àwòrán, Babatunde Gbadamosi ni owo ara ilu ni ijọba Eko n na, kii ṣe owo baba wọn tabi ogun ẹnikẹni.
Wákàtí méjì àbọ̀ ní akẹ́kọ̀ọ́ yóò fi kẹ́kọ̀ọ́ lójúmọ́ - Ìjọba Oyo Ẹ sọ ìwé kíkà di dandan fún ẹ̀yà Fulani - Oluwo rọ ìjọba àpapọ̀ Ẹ lọ ṣí gbogbo ilé ẹ̀kọ́ padà ní Nàíjíríà - Ìjọba àpàpọ̀ Gẹgẹ bi iwe iroyin Punch ṣe jabọ, ijọba tun ṣelelri lati na biliọnu lọna ogun Naira, lati fi ṣe atunṣe eto ẹkọ ni Naijiria.
"Irọ́ ni pé wọ́n hú òkú Kolawole Gold lórí pẹpẹ ìjọ ọkọ mi- Bisola aya Sotitobire Iṣẹ́ Oníbúrẹ́dì ní mo kọ́, ìfẹ́ àṣà Yorùbá ló sún mi dé ìdí ẹ̀ṣà pípé tí mo fi là- Ajobiewe Wo àwọn ojúṣe àti èèwọ̀ fún ikọ̀ ọlọ́pàá SWAT tó gba iṣẹ́ lọ́wọ́ SARS Mọ̀ nípa iPhone 12, fóònù ológo 5G tí kìí lo ""Charger” tó ṣẹ̀ṣẹ̀ jáde Fulani Kwajafa ṣalaye fun BBC pe lasiko ti oun, ko si ifiyajẹni lọna aitọ ti awọn ọdọ n ja lodi si bayii."
ẹgbẹrun lsna ogoji ati diẹ ni ibo to la wọn laaarin, ibo ẹgbẹrun mọkandinlaadọta si ni wọn n ja a le.
Lẹ́yìn náà, Mose mú ninu òróró ìyàsímímọ́, ati díẹ̀ ninu ẹ̀jẹ̀ tí ó wà lórí pẹpẹ, ó wọ́n ọn sí ara Aaroni ati aṣọ rẹ̀, ati sí ara àwọn ọmọ rẹ̀, ati aṣọ wọn.
Oríṣun àwòrán, ABS Àkọlé àwòrán, Ijọ aguda James mimọ to wa ni Neni ni wọn ti se isin ikẹyin fun oloogbe Anthony Obiagbaoso Enukeme, awọn Bisọọbu agba meji si lo lewaju isin ikẹyin naa.
Orúkọ rẹ kò ní jẹ́ Abramu mọ́, Abrahamu ni o óo máa jẹ́, nítorí mo ti sọ ọ́ di baba ńlá fún ọpọlọpọ orílẹ̀-èdè.
O tesiwaju pe lootọ ni pé ìjọba kò ṣe ''ètò tó yanranti fún ìdàgbàsókè eré ìdárayá lorilede wa sugbon a ko gbodo wa tori idi yi yan sisa lo láàyò.
Òkú ọmọ ọdún mẹ́ta tó kó sí kàǹga ní Ipaja ni wọ́n yọ' Ìdí tí mo fi gbàdúrà ìyàwó bíi Chanel Chin fáwọn tó d'ẹ̀bi ìkọ̀sílẹ̀ rẹ̀ rù mí rèé - Oluwo Oral Sex: Bóo bá ń gba ẹnu ní ìbálòpọ̀, wo àìsàn tóo lè kó lójú ara rẹ Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí kan sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
Ẹgbẹ́ burúkú a máa ba ìwà rere jẹ́.
Alaye wọn ni wi pe o di igba ti awọn amoju ẹrọ ba yii iye ti wọn n ta epo pada lori ẹrọ ki awọn onibara to ni anfani lati raa ni naira marundilaadoje.
Ẹni ti o jẹ akọwe fun ẹgbẹ naa, Biṣọọbu Emma Isong lo fi ọrọ naa lede nigba ti o n ba ileeṣẹ BBC sọrọ nilu Eko lowurọ oni.
Ọdun 2007 si 2015 ni Fashola jẹ gomina nipinlẹ Eko, ki Aarẹ Muhammadu Buhari to fun ni ipo minisita ni ọdun 2015, to si ti wa ni saa keji bayii.
Ifẹhonuhan naa lo waye nipasẹ ifẹsẹwọnsẹ kan ti ayaworan Gerrit Starczewski gbe kalẹ ni papa iṣere Stimberg ni Ruhr.
BBC wa gbadura pe igba Oloye Laduntan Oyekanmi gẹgẹ bii Iyalode tuntun fun ilẹ Ibadan yoo tu gbogbo olugbe Ibadan lara.
Àti àwọn ìbéèrè mírànAwọn mọlẹbi ni funra oloogbe lo wa ọkọ lọ si ileewosan fun ayẹwo ki ọlọjọ to de.
Àwọn ọmọ ogun Joabu bá lọ dó ti ìlú náà, wọ́n fi erùpẹ̀ mọ òkítì gíga sára odi rẹ̀ lóde, wọ́n bá bẹ̀rẹ̀ sí gbẹ́ odi náà lábẹ́, wọ́n fẹ́ wó o lulẹ̀.
    Kábíyèsí, kí adé pẹ́ lórí, kí bàtà pẹ́ lẹ́sẹ̀, mo gbọ́ gbogbo bí ẹ ti wi, orí ni alákòóso ara, ọba sì ni olórí ìlú, ẹ̀yin ni olórí àwa.
Oríṣun àwòrán, APCng APC kò ní olórí tí yòó tọwọ́ bọ̀wé, INEC yarí fún ìbò abẹ́nú l'Ondo Bí wàhálà tó n rú nínú ẹgbẹ́ òṣèlú All Progressives Congress ṣe n fi ojoojúmọ́ gbóná janjan ní ìpińlẹ̀ Edo, bakan naa ló jọ bi ẹni pé ẹgbẹ́ náà kò tún rójúùtú ètò ìdìbò abẹ́nú láti yàn oludíje gómìnà lábẹ́ àsíá ẹgbẹ́ náà nípìnlẹ̀ Ondo náà.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fọ́nrán ohùn, Iṣẹ́ ẹmí ẹtan ló bàlemi lasikọ tí mọ so aṣọtẹlẹ̀ pé wọn o wọ ipele aṣekágbá.
'Títẹ àwọn afipábánilopọ̀ lọ́dàá kọ́ ni ọ̀nà àbáyọ sí ìwà ìfipábánilopọ̀' Ẹṣẹ wo ni Ambode ṣẹ̀ tí ilé aṣòfin Eko fẹ́ fí ọlọ́pàá mú u?
O sọ pe ki a ma gbagbe pe itan manigbagbe ni a n fi lelẹ lasiko yi eleyi ti ko ni si ẹni ti yoo gbagbe rẹ ninu mọlẹbi wa.
Ohun ti ajọ ilera lagbaaye sọ ni pe o ṣeesẹ ki oogun aarun coronavirus jade ni bii ọdun kan aabọ si akoko yii.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù INEC, 2023 election: Àjọ eleto ìdìbò kéde ọjọ́ tí ìdìbò ààrẹ Nàìjíríà 2023 yóò wáyé 15 Ọ̀wàrà 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 16 Ọ̀wàrà 2020 Oríṣun àwòrán, @INEC Ajọ eleto idibo orileede Naijiria ti kede ọjọ ti idibo aarẹ Naijiria yoo waye lọdun 2023.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Mo fọ́ lójú ṣùgbọ́n mo mọ gbogbo irinṣẹ́ tí mo fi ń ṣe mọkalíìkì' Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
    Asofin Ahmed ni iye ibo  mọ́kàndínlọ́gọ́rin ( 79) nigba ti
Ó sọ fún Rakẹli pé, ìbátan baba rẹ̀ ni òun jẹ́, ati pé ọmọ Rebeka ni òun.
Nínú ìwé àpilẹ̀kọ kan tí a kò rí irúu rẹ̀ rí tí ó kọ ránṣẹ́ sí Buhari, Ọbásanjọ́ fi ẹ̀sùn kàn-án wípé ó ní ètè láti ṣe èrú ìbò.
Gba owó lọ́wọ́ àkẹ́kọ̀ọ́ ìjọba, ko rugi oyin - Seyi Makinde WAEC gbé èsì ìdánwò WASSCE jáde Akẹ́kọ́ọ̀ mẹ́tàdínlọ́gọ́ta ni wọ́n ti ko lọ sílé ìwòsàn Kenya ‘A ó gbé ìdílé Kayọde Fayẹmi ṣépè tí àwọn akẹ́kọ́ tó ṣèṣe bá kú!
eyi ti asofin Suleiman Hunkuyi se agbateru re ninu ipade ti o waye lojo-Isegun.
Kolawole pẹlu aya rẹ Toyin lo fi aworan ọmọ naa sori oju opo Instagram wọn nibi ti wọn ti ọrọ iṣiti ati idupẹ lori ọjọ ibi Ire Oluwa.
Oun ni akọni lasiko yii, mo n pada bọ toro-toro.
Ọpọ lo ri i gẹgẹ bi opomulero iṣejọba, Bouteflika ni agbatẹru bi Algeria ṣe goke ninu ẹgbẹ to n jẹ Non-Aligned Movement.
OLUWA àwọn ọmọ ogun ní, “À ń ni àwọn ọmọ Israẹli lára, bẹ́ẹ̀ náà ni àwọn ọmọ Juda; gbogbo àwọn tí wọ́n kó wọn ní ìgbèkùn ni wọ́n wo ọwọ́ mọ́ wọn, wọn kò jẹ́ kí wọn lọ.
kàn(219,231 votes), ti egbe oselu PDP si ni, apapo ibo méjílélọ́gbọ̀n le  ẹ̀gbẹ̀rún mẹ́rìnléláàdọ́jọ(154,032 votes)O kede abajade esi idibo naa
Amọṣa ajọ INEC yoo tẹsiwaju pẹlu kika esi idibo naa.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Oṣun State: Gómìnà Oyetola ní 167,000 yàrá ìkàwé ni òun kọ́ sí 32 iléẹ̀kọ́ 27 Bélú 2019 Oríṣun àwòrán, Facebook/Gboyega Oyetola Gomina ipinlẹ Oṣun, Gboyega Oyetola ti sọ pe ijọba oun ti mu ileri rẹ ṣẹ lori eto ilera nipinlẹ naa.
Ṣebí OLUWA ni ó ń ṣáájú ogun rẹ lọ?
Naijiria:Iwadi bẹrẹ lori owo iranwọ epo
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Coronavirus: Àwọn ìpèníjà nípa ṣíṣe iṣẹ láti ilé lásìkò COVID 19 yìí 1 Èbibi 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 2 Èbibi 2020 Ni ibẹrẹ osu kẹrin yi la mu awọn imọran wa funun yin lati ọdọ awọn onimọ nipa bi a ti le se isẹ wa daadaa lati ile.
Manchester United gbole pelu ami-ayo meta sodo(3-0), ti apapo esi ifesewonse ifigagbaga
Yatọ si pe o jẹ oṣere, iwadii fihan pe o tun jẹ alase ati sọrọsọrọ nibi ayẹyẹ.
Kò sì sí ohun àṣírí tí eniyan kò ní mọ̀.
3% Gomina Makinde ni meji ninu awọn ibudo eto ọgbin mẹsan to wa nipinlẹ Ọyọ, eyiun eyi to wa ni Eruwa ati Akufo nijọba yoo sọ di oko ijọba Olu ileesẹ ajọ to n ri si idagbasoke eto ọgbin nipinlẹ Ọyọ, OYSADEP nijọba ti gbe kuro nilu Ibadan pada si Saki Ibudo iko ohun eto ọgbin si ti wọn n kọ lọwọ, eyi ti ẹjọ wa lori rẹ lo ti ni yanju bayii, ti agbasẹse si ti n ba isẹ lọ lori rẹ, eyi ti wọn ko ni pẹ si laipẹ.
ati ri daju wipe gbogbo ojuse won pata-pata wa si imuse.
Ààrẹ Buhari kò sí nínú ewu àjàkálẹ̀ àrùn kankan tórí ẹ̀ṣọ́ rẹ̀ tó ṣẹ̀ṣẹ̀ dé sí Aso Rock-Garba Shehu 'Àìjáfáfá àwọn panápaná ló mú kí ọṣẹ́ iná Akure pọ̀' Ìyà ń jẹ wá ló jẹ́ kí a daṣẹ́ sílẹ̀ - ẹgbẹ́ àwọn dókítà Ohun tí a mọ̀ nípa Ṣẹnetọ Adebayo Osinowo tó dágbére fáyé Ṣaaju si ni Abiola ti sọ fun wọn awọn to fẹ yan sipo minisita atawọn ipo mii lo ba di pe awọn kan lọ si Abuja lọ ki Abacha ku oriire.
Ọjọ kẹwaa, loṣu Kejila, ọdun 2020 ni Maina daku rangbọdan nile ẹjọ lẹyin ti ile ẹjọ pada bẹrẹ si n gbọ ẹsun ti wọn fi kan pe o lu biliọnu meji naira ni ponpo.
Mú àwọn àgbà obinrin bí ìyá; mú àwọn ọ̀dọ́ obinrin bí ẹ̀gbọ́n tabi àbúrò rẹ pẹlu ìwà mímọ́ ní ọ̀nà gbogbo.
kí Aaroni alufaa wá ya àwọn ọmọ Lefi sọ́tọ̀ bí ọrẹ fífì láti ọ̀dọ̀ àwọn ọmọ Israẹli, kí wọ́n lè máa ṣe iṣẹ́ ìsìn OLÚWA.
Nígbà tí ogun Juda dé ilé ìṣọ́ tí ó wà ninu aṣálẹ̀, wọ́n wo àwọn ọ̀tá wọn, wọ́n sì rí i pé wọ́n ti kú sílẹ̀ lọ bẹẹrẹ; kò sí ẹni tí ó sá àsálà ninu wọn.
Ohun tí mò ń lépa ni láti parí iré ìje mi ati iṣẹ́ tí mo gbà lọ́wọ́ Oluwa mi Jesu, èyí ni pé kí n tẹnu mọ́ ìyìn rere oore-ọ̀fẹ́ Ọlọrun.
Àwọn ọdẹ ṣe ìpàdé lé orí ọ̀ràn náà, ìgbà tí ó sì jẹ́ pé Ayédèrú-ẹ̀dá ni igbákejì mi, òun ni wọ́n yàn kí ó ṣe alága.
Wo àwọn ìṣẹ̀lẹ̀ tó mú Naira Marley di òrìṣà àkúnlẹ̀bọ ní 2019 Oríṣun àwòrán, Naira Marley/twitter Iroyin ti o jadi laipẹ yii sọ pe oun ni ọmọ Naijiria ti awọn eeyan ṣe afẹri rẹ ju lọ loju opo Google lọdun 2019.
Bi o tilẹ jẹ pe isede konile o gbele wa ni agbegbe naa lati dẹkun iwa isekupani to n waye ni lemọlemọ, sibẹ, akọtun isẹlẹ ikọlu tuntun yii waye.
Ẹ̀rìn mélòó ló yẹ kí ààrẹ orílẹ̀ èdè ní ìtakùrọ̀sọ pẹ̀lú ilé ìgbéròyìn jáde tí ìlúu rẹ̀?
ní meji meji, àtakọ àtabo, gbogbo wọn bá Noa wọ inú ọkọ̀ gẹ́gẹ́ bí Ọlọrun ti pa á láṣẹ fún Noa.
Nítorí náà àwọn alágbára yóo máa yìn ọ́ìlú àwọn orílẹ̀-èdè aláìláàánú yóo bẹ̀rù rẹ.
Nígbà tí ó pè mí, n kò bá ẹnikẹ́ni gbèrò, 
Salah gba bọọlu sinu awọn fun Liverpool ni igba mẹrinlelogoji ni saa idije bọọlu gbigba 2017/2018, eyi to fi mu ko ṣeeṣe fun ẹgbẹ agbabọọlu naa lati de ipele aṣekagba idije Champions League.
 ohun tí ó jẹ àwọn aṣèwádìí mìíràn lógún ni ṣíṣe àgbéyẹ ̀ wò ẹ ̀ ka-èdè ìlú kan tí wọ ́ n yàn láàyò .
ko din ni bilioni merindinlaadota naira lori awon ile eko giga tii se ti’joba
Ranti bí ó ṣe búra fún OLUWA,tí ó sì jẹ́jẹ̀ẹ́ fún ìwọ Alágbára, Ọlọrun Jakọbu,
Ọ̀mì - O sọ asọtẹlẹ pe Senegal yoo gba ọmi pẹlu Algeria.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Àwọn ọmọ Nàìjíríà bínú sí olóngbo àti ẹlẹdẹ to sọ àsọtẹlẹ 27 Òkùdu 2018 Oríṣun àwòrán, Reuters Àkọlé àwòrán, Aṣọ kò bọ́mọ́ye mo,omoye ti rìn hoho wọja Ati ẹni tó sọ àsọtẹlẹ ati awọn tó gbà a gbọ, ojú wọn ti já a bayii pẹlú bí Argentina ti ṣe ràn ìkọ Super Eagles pada wale ninu ìdíje àgbáyé.
Bakan naa lo jẹjẹ pe awọn ọmọ oselu SDP yoo duro pa lati sọ ibo wọn ni, tawọn yoo si lọ ẹnikẹni to ba ko owo wa si agọ idibo, lati ra ibo, ni asọ mu ni.
Àkọlé àwòrán, Àwọn obìnrin abúlé yìí ń pàdánù ọmọ látàrí òpópónà tó mẹ́hẹ Hajara ni, oun ko ti i bi ọmọ mii lati igba ti iṣẹlẹ ọhun ti ṣẹlẹ, to si jẹ ibanujẹ nla fun oun.
Ìdílé márùn-ún tó gbajúmọ̀ fún òwò ẹrú nílẹ̀ Yorùbá Alága méjì láàrín ọjọ́ kan, sinimá oríta láàrín àwọn adarí APC Agbẹjọ́rò ni n kò bá jẹ́, tí n kò bá bá bàbá mi ṣe tíátà - Sola Kosoko A kò tíì fi ìdí ẹ̀ múlẹ̀ pé ògùn Dexamethsaone ń ṣiṣẹ́ fún àrùn coronavirus- WHO Omowe Smith ni ẹni to ba ti fẹran lati maa jẹ gaba ninu ibaṣepọ ololufẹ meji lee ṣe iku pa ẹnikeji rẹ nijọ ti iyẹn ba kọ.
Tí a bá yọwọ́ àwọn ọba alayé kúrò, kò ní sí Nàìjíríà mọ́- Alaafin Oyo Kí ló dé t'awọn Gómìnà Nàìjíríà fẹ̀ yá N17trillion nínú owó ìfẹ̀yìntì òṣìṣẹ́?
August 5, 2019 Ní bayìí ilé ẹjọ ìpínlẹ̀ Kaduna ti dá El- Zakzaky àti ìyàwó rẹ̀ lóri ọ̀rọ̀ ìlera August 12, 2019 Sheikh Ibrahim El-zakzaky de si Abuja lati Kaduna ṣaaju irinajo rẹ si Inidia fun itọju.
Wayii o, ni kete ti ogbeni
Èyí bí Eliṣa ninu, ó sì sọ fún ọba pé, “Bí ó bá jẹ́ pé o ta ọfà náà nígbà marun-un tabi mẹfa ni, ò bá ṣẹgun Siria patapata, ṣugbọn báyìí, ìgbà mẹta ni o óo ṣẹgun wọn.
Ẹ̀mí Ọlọrun bà lé Asaraya ọmọ Odedi.
ede Naijiria , sugbon ni bayii ,ọna ẹburu  ni awon yoo maa gba yọ
N óo jẹ́ kí ìkún omi bo gbogbo ayé, yóo pa gbogbo ẹ̀dá alààyè run, gbogbo ohun ẹlẹ́mìí tí ó wà láyé ni yóo kú.
" Ẹ wo báwọn òṣèré tíátà kan yóò ṣe rí lọ́jọ́ ogbó Ìgbín ní èmi àti ìyá mi máa ń he kiri, ká tó lee jẹun - Lizzy Anjọrin Ẹ wo ohun tó fàá tí àwọn òbí fi ń pa 340 ọmọ bíbí wọn lọ́dọọdún Bi Pinnick ṣe kuro yii tumọ si pe Ahmad yoo ṣe atunto awọn igbakeji rẹ.
Òní kì í ṣe ọjọ́ oṣù tuntun tabi ọjọ́ ìsinmi.
Nítorí náà, ìbáà jẹ́ pé ẹ̀ ń jẹ ni, tabi pé ẹ̀ ń mu ni, ohunkohun tí ẹ bá ń ṣe, ẹ máa ṣe é fún ògo Ọlọrun.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Lateef Adedimeji: Owó wa kò bá máa jóná ṣùgbọ́n aàyè ọpẹ́ ń yọ fún wa Dandan ni ki yiyan iyalọja ni kọnunkọhọ nibẹ Aarẹ ẹgbẹ to n ṣe akoso ọja Komputa Village CAPDAN, Ọgbẹni Ahmed Ojikutu sọ fun BBC pe awọn lodi si yiyan Iyalọja nitori pe kii ṣe iṣẹ ata tita lawọn n ṣe nibẹ.
Bẹẹ ni ọrọ ri lori aba eto isuna ipinlẹ Oyo fọdun 2021, eyi to fa ede aiyede laarin gomina Seyi Makinde ati ile asofin ipinlẹ Oyo.
Ẹni bá láyà: Ṣé ìwọ mọ àmì Yorùbá dáadàa?
Gẹgẹ bi ẹka iroyin ileeṣẹ ologun Naijiria ṣe fi sita loju opo Twitter wọn nibi ti wọn ti n ṣe ayẹwo awọn rọbọọti naa pe orilẹede Naijiria ni orilẹede akọkọ nilẹ Afirika ti yoo ra rọbọọti ti o lee gbe gbogbo iroyin nipa arinrinajo jade ti yoo si maa ṣe ayẹwo wọn ẹnu ọna gbọngan abajade papakọ ofurufu.
Mò ń sọ nípa ipò tí Kristi wà sí ìjọ.
Ẹ fún un ní ohun tí ẹ bá fẹ́ fún un tọkàntọkàn, kì í ṣe pẹlu ìkùnsínú, nítorí pé, nítorí ìdí èyí ni OLUWA Ọlọrun yín yóo ṣe bukun iṣẹ́ ọwọ́ yín ati gbogbo ohun tí ẹ bá dáwọ́ lé.
Ohun tí ìbá wù mí fun yín ni pé kí gbogbo eniyan rí bí mo ti rí; ṣugbọn ẹ̀bùn tí Ọlọrun fún olukuluku yàtọ̀, ó fún àwọn kan ní oríṣìí kan, ó fún àwọn mìíràn ní oríṣìí mìíràn.
Òkúta olówó ńlá, tí wọ́n fi ayùn gé tinú-tẹ̀yìn, ni wọ́n fi kọ́ gbogbo ilé ati àgbàlá rẹ̀, láti ìpìlẹ̀ títí dé òrùlé rẹ̀, ati láti àgbàlá ilé OLUWA títí dé àgbàlá ńlá náà.
O n gbe ni ọdọ ẹgbọn rẹ, o si pada sileewe alakọbẹrẹ bo tilẹ jẹ pe o ti dagba ju, ti ọpọ ileewe si kọ ọ.
“Bíi ti ọjọ́ tí ẹ péjọ ní òkè Horebu tí ẹ bẹ OLUWA Ọlọrun yín, tí ẹ sọ fún mi pé, ‘Má jẹ́ kí á gbọ́ ohùn OLUWA Ọlọrun wa mọ́, tabi kí á rí iná ńlá yìí mọ́; kí á má baà kú.
Gbogbo awọn ti a jọ wa ninu rẹ lo fi ara pa, ṣugbọn emi nikan ni temi buruju pẹlu ẹsẹ mi to ha si abẹ Maruwa.
Oun naa ki awọn ololufẹ rẹ kaakiri orilẹ-ede agbaye loju opo Instagram rẹ.
Wo bí odò tó gùn jù l'Áfíríkà, Nile ṣe ń fójúu ilẹ̀ Egypt-Ethiopia han màbo Wo àwọn ọ̀nà míràn tí o leè gbà lẹ́yìn tí wọ́n bá ti afára Third Mainland Pásítọ̀ ìjọ Sotitobire padà yọjú sílé ẹjọ́ lónìí, àbọ̀o rèé.
Ìpolongo orísun-ọ̀fẹ́ – a óò máa tẹ àwọn ọgbọ́n àtinúdá tuntun síta, àmọ́  a nílò láti gba èrò tuntun àti agbára tuntun wọlé bákan náà.
Bi o ba ni iba, ikọ tabi iṣoro lati mi, tọ awọn dokita lọ Duro si ile rẹ bi o ba ṣakiyesi pe ara rẹ ko ya.
Mo ti fọ́ bàbá mi, Ọ̀gá Bello létí rí - Fẹmi Adebayọ̀ Àwọn obìnrin tí kò lọ́kọ ń kojú ìsòro ilé gbígbà Èèyàn 2m gòkè Àràfá nípalẹ̀mọ́ fọ́dún Iléyá Èèwọ̀!
 Ìwádìí jẹ ́ kí á mọ ̀ pé irú ewì yìí náà ń wáyé láàrin àwọn Èkìtì .
Wọn óo máa pa òfin mi mọ́, wọn óo sì máa fi tọkàntọkàn rìn ní ìlànà mi.
Ohun tí wọ́n kọ sinu ìwé náà nìyí: “Sí ọba Atasasesi, àwa iranṣẹ rẹ tí a wà ní agbègbè òdìkejì odò kí ọba.
Ọ̀pọ̀ èèyàn tó sì dá sí ìjíròrò náà lo fara mọ pe oúnjẹ ní kókó, kódà, Oluwaseun Abiodun ni, niwọn ìgbà tí àwọn ilé ìjọsìn kò ní fún àwọn ni oúnjẹ jẹ, ọjà tí àwọn yoo ti rí oúnjẹ rà ni pàtàkì.
”Bakan naa, o tun soro ohun di
Máa fetí sí ohun tí angẹli náà bá sọ fún ọ, kí o sì gbọ́ràn sí i lẹ́nu, má ṣe fi agídí ṣe ìfẹ́ inú rẹ lọ́dọ̀ rẹ̀, nítorí pé èmi ni mo rán an, kò sì ní dárí ẹ̀ṣẹ̀ rẹ jì ọ́.
Akpan sọ pe ọkan lara awọn adari ẹgbẹ naa, Bright, lo ji awọn akẹkọọ to ti d'oloogbe nitori pe ọkan lara wọn dalẹ oun lasiko ti owo kan wọ akanti rẹ, ṣugbọn ti ko ko o silẹ f'oun""."
''Awọn aṣeyọri wa laarin oṣu mẹsan to kọja yi ko gbọdọ ja si asan tori naa mo wo ọrọ yi daada to si dami loju pe yoo kọdi itankalẹ arun yi ati iku awọn eeyan wa'' Oríṣun àwòrán, PTF Ìlànà tuntun ìjọba nítóri Covid-19 yóò pa iṣẹ́ wa lára ṣùgbọ́n ayé ò parẹ́ - Àwọn adarí ayẹyẹ Oríṣun àwòrán, Instagram/pauldgoodguy Àkọlé àwòrán, Olukoni Lẹyin ti ijọba apapọ kede ilana tuntun lọna ati kawọ ipadabọ ajakalẹ arun Covid-19 ni Naijiria, awọn to n maa n dari ayẹyẹ kan ti sọ pe awọn yoo tẹlẹ ilana ti ijọba gbe kalẹ.
Noa bá ṣe gbogbo ohun tí Ọlọrun pàṣẹ fún un.
    Ìwé ni ìyàwó Wèrédìran tilẹ̀ kọ sí i, nígbà tí o sì fi ìwé náà hàn mì nǹkan tí wọ́n kọ síbẹ̀ ni èyí:
Oriṣiriṣi aworan to dun n wo loju ni Doris ko si oju opo Instagram rẹ lọjọ naa to pẹ ẹni ọdun mọkanlelọgbọn loke eepẹ.
O tun wa gbosuba fun awon agbegbe ti won wa ati adari won fun ifowosowopo ti won fun iko omo ogun naa.
Sani ni àwọn agbofinro kọ́kọ́ mú latari bata ati aṣọ rẹ̀ ti wọn kó nibi ti olè ti fẹ́ jí alupùpù Ogbẹni Tasiu Bello lọjọ kejilelogun, oṣu kẹrin, labule Nassarawa Bugaje, ki wọn to lọ mu Iliyasu ati Umar lẹyin ti wọ́n fọrọ wa Sani lẹ́nu wò tán.
Wọ́n ṣẹgun Sihoni, ọba àwọn ará Amori, tí ń gbé ìlú Heṣiboni.
Ẹkẹta náà kú láì ní ọmọ.
Gbogbo àwọn ọba ni ó sá tàwọn tọmọ ogun wọn;àwọn obinrin tí ó wà nílé,
Ṣugbọn ẹni tí ó bá pàdánù ẹ̀mí rẹ̀ nítorí mi, yóo rí i.
Minista so eyi di mimo lojo Aje ni Abuja lasiko ti Ogbeni David Mc Ewen to je onimo pelu eka irinajo afe ninu ajo isokan agbaye wa sabewo si oofisi re.
àjòmọ ́ ìbẹ ̀ rẹ ̀ , kódà fóníìmù pẹ ̀ lú kò lè dá dúró tí kò bá ti lè làdì sí ìtumọ ̀ nínú ọ ̀ rọ ̀ .
Eleyii yoo mu wọn ma a tọ sile bii ọmọde.
Ẹni tí ó bá ní oúnjẹ níláti ṣe bákan náà.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Wo bí Sunday Orimola ṣe gba ikú ẹranko kú ní Ifon ni Ondo lórí ọ̀nà àtijẹ O ni Ogun odun ni oun fo se ọkọ Gloria a ni ọmọ kan sugbọn iya mi ko fọwọ si ibasepọ wa nitori a kii se ẹya kan naa, a bi ọmọ kan lọdun 2011 nitori mo nifẹ rẹ.
"Òṣèré méjì yìí ń fi ẹ̀wọ̀n runmú tóríi fíìmù ""Ife"" táwọn obìnrin ń bá ara wọn lòpọ̀ Wo bí àwọn obìnrin kan ṣe n sọ ara wọn di 'fágìn' lẹ́ẹ̀kejì Àwọn èèyàn kò fi bẹ́ ẹ̀ ní ìbálòpọ̀ lásìkò ìgbélé yìí - Iléèṣẹ́ kọ́ńdọ́ọ́mù Durex Àwọn nkan tó yẹ kí o mọ̀ nípa ṣíṣe ìṣirò àsìkò tí o bá n yé ẹyin Gẹgẹ bi Magasinni Healthline ṣe sọ, ere idaraya Kegel ma n mu ki adun ati ifẹ si ibalopọ, pọ si lara awọn ọkunrin."
Èmi sì mọ̀ pé, ọmọ yìí kìí ṣe ọmo ìyá mi, bí ó bá ṣẹ́ mi, mo níláti bomi ṣùúrrù mu, bí mo bá bínú díẹ̀, dandan ni kí n tètè ronú padà ki n fi ẹ̀rín lé ìbínú lọ ní ilé wa.
  Bi ikon aa se kopa siBi a ko ba gbagbe pe iko Super Falcons tun ti pegede fun irufe idije naa lagbaye(FIFA Women World Cup tournament), ti yoo waye lorile-ede France lodun to n bo.
Wọ́n fẹ́ràn ati máa rúbọ; wọ́n ń fi ẹran rúbọ, wọ́n sì ń jẹ ẹ́; ṣugbọn inú OLUWA kò dùn sí wọn.
Ni bayii, iko agbaboolu Chelsea tele iko Man City leyin ti jawe olubori ninu ifigagbaga pelu iko Crystal Palace pelu ami-ayo meta sookan(3-1).
Gomina Ganduje ti ipinlẹ Kano wa ke si awọn eeyan ipinlẹ naa lati fọkanbalẹ ki wọn si maa wa iṣẹ oojọ wọn lọ ati pe laipẹ ni wọn yoo yan Ẹmia tuntun.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù 2023 Elections: Shehu Sani ní àfàìmọ̀ kí Yorùbá àti Igbo má kùnà nínú ìbò ààrẹ ọdún 2023 24 Ògún 2019 Oríṣun àwòrán, Facebook/Shehu Sani Àkọlé àwòrán, Ibo gbogbogbo ọdun 2023 Yoruba ati Ibo le kuna lati jẹ aarẹ orilẹede Naijiria lọdun 2023 ti idibo gbogbgbo miiran yoo tun wa ye.
Àwọn ẹbí sun ìpàdé si ọjọ́ keje.
Lẹyin ti Ile ẹjọ giga ti ijọba apapọ to wa ni Abuja paṣẹ pe ki ajọ to n mojuto ọrọ igbọhunsafẹfẹ ni Naijiria (NBC) ti ọwọ ọmọ rẹ bọ aṣọ fun igba diẹ lori ọrọ DAAR Communications, AIT ati RayPower FM ti pada sori afẹfẹ.
Ṣugbọn bí o bá wá Ọlọrun,tí o sì sọ ẹ̀dùn ọkàn rẹ fún Olodumare;
Ní àkókò tí Ahasu-erusi jọba ní ilẹ̀ Pasia, ìjọba rẹ̀ tàn dé agbègbè mẹtadinlaadoje (127), láti India títí dé Kuṣi ní ilẹ̀ Etiopia.
School Boy to tun jẹ orukọ inagijẹ Hameen ni iṣẹ orin kikọ oun ko di iwe kika oun lọwọ nitori ọtọọtọ ni asiko wọn.
Iye awọn eeyan to ṣẹṣẹ ko arun naa ni ipinlẹ kọọkan ree: Eko -66 FCT-50 Delta-32 Oyo-31 Borno-26 Rivers-24 Edo-23 Ebonyi-23 Anambra-17 Gombe-17 Nasarawa-14 Imo-12 Kano-12 Sokoto-12 Jigawa-8 Ogun-7 Bauchi-5 Kebbi-2 Kaduna-2 Katsina-2 Ondo-2 Abia-1 Niger-1 Èèyàn 328 ló lùgbàdì àrùn Coronavirus lọ́jọ́ Ẹti ní Naijiria Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Akojọpọ esi ayẹwo aarun Covid-19 ni orilẹ-ede Naijiria gẹgẹ bi ajọ NCDC ṣe n kede rẹ.
Gbogbo àwọn tí a kà ninu ẹ̀yà Gadi jẹ́ ọ̀kẹ́ meji ó lé ẹẹdẹgbẹta (40,500).
Wọn gba Rohr ni imọran lati maa lo awọn agbabọọlu ‘keekeeke’.
4 42988 Orilẹede Kuwait 891 21.
Àkọlé àwòrán, Àkójọpọ̀ mẹ́wàá lára àwọn Ọba Ilẹ̀ Yorùbá tí wọ́n lé kúrò ní ipò Ọba.
" Olori Anu ni oun kọ lati ba awọn akọroyin sọ̀rọ̀ nitori ọrọ asiri aye oun ni eyi jẹ, ati fun aabo awọn ọmọ oun.
Bakan naa lo mu iwoye wa ti a si fi ni ka beere pe ki lawọn ohun to yẹ ki kọmẹntatọ ni lamuye ki o to le e bọ si ori afẹfẹ pe ohun fẹ ṣalaye ifẹsọwọnsẹ to n lọ.
Ṣugbọn bí ọmọ-ẹ̀yìn bá jáfáfá yóo dàbí olùkọ́ rẹ̀.
Coronavirus: Ọmọ márùn ún ni mo ní, ṣùgbọ́n kò sí oúnjẹ fún wa lásìkò ìgbélé yìí -Olùgbé ìlú Eko
 Mo si tun ni igbagbọ pe maa ri ẹgbẹ agbabọọlu ti maa ma gba bọọlu fun."
Ọlọ́pàá fìbọn fọ́mi lójú nítorí #100; ó ní eṣù ló ṣe òun- Akẹ́kọ̀ọ́ Adebayo Oògùn N25, 000 tí ń kò rówó rà ló gba ojú lọ́wọ́ mi Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Wo àwọn ìbejì tó lẹ́ pọ̀ lẹ́yìn àṣeyọrí ìṣẹ́ abẹ dókìtà 70 Nigba to n gbe ọrọ Oluwatobi lẹyin, ọkọ rẹ, Adebambo Osunsan, sọ pe ọrọ aye kọkọ su oun lọjọ naa, pe iru ki leyi.
Oúnjẹ rẹ̀ ni ẹṣú ati oyin ìgàn.
ki Gomina Ambọde pari saa re tan tabi bẹẹ kọ.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ààrẹ Buhari yóò gbé ìgbìmọ̀ kalẹ̀ lórí ẹ̀kúnwó owó oṣù tuntun f'òṣìsẹ́ Àwọn olùgbé Maiduguri fapájánú nítorí àpọ̀jù iná mọ̀nàmọ́nà Ìyanṣẹ́lódì òṣìṣẹ́ ilé aṣòfin bẹ̀rẹ̀ ní pẹrẹwu nílé aṣòfin Nàìjíríà Kii ṣe ojuti diẹ ni ọrọ yii gbe kalẹ fun aarẹ nitori lai ṣi aniani eyi ni igba akọkọ ti aarẹ kan lorilẹede Naijiria yoo dojukọ irufẹ idẹyẹsi ati ojuti bẹẹ lasiko ti wọn n gbe irufẹ aba iṣuna bẹẹ kalẹ niwaju awọn aṣofin apapọ.
Nigba ti ile igbimọ aṣojusofin si fọwọ si aba naa, ṣe lo kuna nile aṣofin agba gẹgẹ bi Godswill Akpabio to jẹ adari ẹgbẹ to kere ju nile ko ṣe gba a wọle.
Ti o ba duro de esi ayẹwo rẹ, o dara ki o da wa ninu ile titi ti esi ayẹwo naa yoo fi de.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'OPC ko ṣ'atilẹyin fun Jonathan ni 2015' Ẹwẹ, ni ibamu pẹlu ilana igbejọba le ni lọwọ ninu ofin orilede Naijiria, lẹyin iku aarẹ Musa Yar'adua lọjọ karun oṣu karun ọdun 2010, wọn bura wọle fun igbakeji aar Goodluck Jonathan gẹgẹ bi adele aarẹ orilede Naijiria.
O sọ pe ẹgbẹ oṣelu APC to n polongo ayipada yẹ ko le fi apẹrẹ rere han.
Àwọn aṣekúpani tún ti pa ọmọ ọdún 16 ní Akinyele nípìnlẹ̀ Oyo Gómìnà ìpínlẹ̀ Ekiti, Kayode Fayemi nàá ti ni aàrùn Coronavirus Oríṣun àwòrán, @Eyitayo Eyitayọ Jegede (PDP) ló máa gbéná wojú Rotimi Akeredolu (APC) nínú ètò ìdìbò Ondo tó ń bọ̀!
1 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 3:49 Fídíò, Boko Haram: Oluwatobi Adeigba, Ọkọ mi ń lọ siṣẹ́ fún àjọ INEC ló kàgbákò ikú - Opó Adeigba, Duration 3,492 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
O lo apejuwe iṣẹlẹ obinrin oni pansaga kan, ti Jesu doola ninu Bibeli, lọwọ awọn to fẹ sọ ọ ni okuta pa.
Ìdùnnú subú layọ̀ nípìnlẹ̀ Ọyọ́, àwọn tó dé láti Lebanon sọ ọmọ wọn ní Seyi Akọ̀wé-owó wọ gàù ní iléẹjọ́ lórí ẹ̀sùn pé ó jí N500,000 lọ́wọ́ ọ̀gá rẹ̀ Hisbah mú ọkùnrin mẹ́ta tó pín fídíò ìfipábánilòpọ̀ ọmọdébìnrin 16 tó fẹ́ ṣèyàwó lórí ayélujára Ọ̀gá iléeṣẹ́ gbé £10 mílíọ̀nù ẹ̀bùn owó fún òṣìṣẹ́, èyí lohun tó pawọ́n pọ̀ Ọ̀rọ̀ Soyinka àti Obasanjo papọ̀ lórí pé Buhari n ṣe ìpínyà Nàìjíríà Ọgbẹni Ibe sọ ninu atẹjade ọhun pe ijọba ilẹ Amẹrika ko fẹsun ikowo lọ silẹ okere kan Atiku, bakan ni ẹka eto idajọ orilẹede Amẹrika naa ko fi ẹsun kankan kan Atiku.
"Àwa la mọ báa ṣe mú Sunday Shodipe táa fà a lé ọlọ́pàá lọ́wọ́ - Ọlọ́dẹ Soludero Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Bí ẹ ṣe mọ̀wé tó, ẹ wá dánrawò níbí pẹ̀lú ""Àpólà Ọ̀rọ̀ Orúkọ - Noun Phrase O ni lẹyin naa ni wọn gba gbogbo ohun to wa lọwọ rẹ ki wọn yin in nibọn, ti wọn si gbe alupupu rẹ lọ."
Nnkan bii miliọnu kan abọ o le diẹ lawọn akẹkọọ to joko ṣe idanwo naa lọdun yii eyi to pọ ju ti esi lọ.
Iya Ẹniola naa tẹsiwaju pe, titi diỌjọru, ko tii si igbesẹ kan pato ti awọn Ọlọpaa se si isẹlẹ naa.
22 Bélú 2020 Fídíò, Akomolede ati Aṣa lori BBC:Wo ìrúfẹ́ ìgbeyàwó méje tó wà nílẹ̀ Yorùbá àti ojúṣe Alárinà10 Bélú 2020 9th Assembly: Gbajabiamila fi èróńgbà rẹ̀ láti jẹ adarí ilé aṣojú ṣòfin hàn1 Ìgbé 2019 Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Oríṣun àwòrán, Rotimi akeredolu Amugbalẹgbẹ fun gomina lori ọrọ akanṣe iṣẹ, ọmọwe Doyin Ọdẹbọwale ṣalaye pe gbogbo awọn Pasitọ tọwọ ba naa nijọba yoo fi jofin lẹyin ti oun ba ti jabs fun gomina lori rẹ.
Oríṣun àwòrán, Sylvester Ofori/Facebook ''Ki tiẹ baa fi ma gbofo lọ mu mi ki o pa'' ]Fọnran fidio ibi ti Pasitọ ti n leri lati pa iyawo rẹ Ileeṣẹ BBC foju ri fọnran fidio to gbode kan nibi ti Pasitọ naa ti sọ pe oun yoo pa iyawo rẹ.
Wọ́n ṣe ọdẹ títí ìgbà tí wón dé ibi kan, olórí wọ́n fi ara pa.
seleri lati pese isuna eyi ti ami-eye NNMA ba nilo lojuna ati tun mu igberu ba
Kùrù-kẹrẹ Coronavirus ṣeéṣe kó dópin láàrín ọdún méjì - WHO Ọkọ̀ rélùwéè 16 yóò ná Eko sí Ibadan láti oṣù tó ń bọ̀ lọ - Iléeṣẹ́ Rélùwéè kéde Géńdé agbébọn yabo àgọ́ ọlọ́pàá n‘Ibadan, ẹ̀mí ọlọ́pàá kan bọ́ Iya Halimat ṣalaye pe, nnkan bi aago mẹjọ abọ alẹ ni ọmọ oun di awati lẹyin ti ileeṣẹ mọnamọna mu ina ijọba lọ lalẹ ọjọ naa lọhun, o ni oun ko tii foju gan-ni Halimat lati igba naa.
Ọ̀rọ̀ǹpọ̀tọ̀niyùn, Aláàfin obìnrin àkọ́kọ́ rèé, tó ní nǹkan ọkùnrin Ṣé ìwọ mọ odò adágún Adó Àwáyè tí kò ní òpin ní ìsàlẹ̀?
Dhul Qiddah: Ninu oṣu yi lawọn larubawa maa n ṣe adehun lati dẹkun ija jija.
Ojú mi ri nǹkan ki n tóó lè fi àdá gé díẹ̀ ní ’rùngbọ̀n mi.
Lake Rice Ọkan lara awọn aṣeyọri ipinlẹ Eko lasiko pọpọṣinṣin ọdun ni ifilọọlẹ irẹsi to jẹ ajọ pese ipinlẹ Kebbi ati ipinlẹ Eko.
Nítorí náà, Ìrìnkèrindò, ẹ jẹ́ kí á kúkú jọ máa ṣiré wa bí a ti ń ṣe é lọ, kí a má fi ti ọkọ àti aya sí.
"Amọsa, ileesẹ ọlọpaa salaye wipe, ""A ko le fidi ọrọ yii mulẹ wi pe ayipada ẹsin eeyan kan lati Kristẹni si Musulmi tabi ẹsin miran lo da ija naa silẹ."
Ẹni to bori: Madagascar Ìpele to kangun si aṣakagba Côte d'Ivoire vs Guinea.
Ọ̀pọ̀lọpọ̀ ìgbà, wọ́n ma “lé eku meji pa òfo” ni.
Wọ̀n bi Barrister ni ọjọ kẹsan-an, oṣu Keji, ọdun 1948 sinu ẹbi Salawu Balogun nilu Ibadan.
Àgbétán ni jàgùdà n gbé erù tí owó rè bá bà.
O ni oun fẹ bẹ wọn lati gba alaafia laaye ni oun ṣe gbe igbesẹ naa.
O ni ootọ maa n dun eniyan ṣugbọn ẹnikan ni lati sọ ọ .
Kí OLUWA mú kí ojú rẹ̀ mọ́lẹ̀ sí yín lára,kí ó sì ṣàánú fún yín.
Awon Asofin ro ijoba apapo lati pese eto aabo to ye fawon osise arannilowo ati awon ajo eniyan ti kii se tijoba ti won n sise laarin awon Asatipo ni ariwa ila oorun Naijiria ki okan won le bale.
Bakan naa lo ke s'awọn ijobaipinlẹ ati ibilẹ ti wọn ko tii bẹrẹ si nii ṣe iṣẹ lori sisan owo ajẹmonu asiko ajakalẹ arun COVID-19 lati bẹrẹ si nii san an lẹyẹ o ṣọka.
Ọ̀rọ̀ ni OLUWA fi dá ojú ọ̀run,èémí ẹnu rẹ̀ ni ó sì fi dá oòrùn, òṣùpá, ati àwọn ìràwọ̀.
Bakan naa ni aarẹ Donald Trump to n tukọ Amẹrika ni gbogbo ohun to ṣẹlẹ ni gbogbo eniyan ri pẹlu ibinujẹ pe iwa yii buru jai lori ikanni rẹ pe: Awọn agbofinro ṣi n ṣiṣe lọ lori iṣẹlẹ naa ni Pittsburg.
níwọ̀n ìgbà tí mo wà láàyè,tí mo sì ń mí,
Areoye Oyebola: Olootu agba nigba kan ri fun ileesẹ iroyin Daily Times, alagba Areoye Oyebola kopa ribi ribi lagbo awọn oniroyin ati onkọwe nigba aye rẹ.
Fídíò Ganduje: Akọ̀ròyìn fọwọ́ sọ̀yà pé òtítọ́ ni fídìo tí òun fi síta Oludasilẹ iwe iroyin ori ayelujara kan, Daily Nigeria, Ja'afar Ja'afar to gbe fidio ibi ti Gomina Ipinlẹ Kano, Abdullahi Ganduje ti n gba owo jade si duro lori ẹsẹ rẹ pe fidio naa ko lẹja nbakan rara.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Lagos Kidnap: Ọwọ́ ọlọ́pàá tẹ afurasí méjì tó nííṣe pẹ̀lú ìjínígbe Ọgá panápaná l'Eko 10 Ìgbé 2019 Oríṣun àwòrán, Lagos Police Àkọlé àwòrán, Ijinigbe l'Eko Owo sinkun ofin ti mu awọn afurasi meji to nii ṣe pẹlu bi wọn ṣe ji adari ilé iṣẹ́ panápaná ipinlẹ̀ Eko, Rasaki Musibau atawọn mẹfa mii gbe.
Nítorí bí ohun tí yóo pada di asán bá lógo, mélòó-mélòó ni ti ohun tí yóo wà títí laelae?
Lẹ́yìn ọjọ́ díẹ̀ ni Mọmọdu padà tọrọ àforíjì pé irọ́ ni ìròyìn tí òun gbé jáde.
Ọpọ eeyan kaakiri agbaye lo ti n woye ibi ti esi idibo naa yoo fori sọ.
Nígbà tí o tú gbogbo ẹrù mi palẹ̀, àwọn nǹkan rẹ wo ni o rí níbẹ̀?
Ofin yii ni ọpọlọpọ ti sọ pe ko le fidimulẹ tó nitori pe ẹlẹ́sìn ni awọn eniyan ilẹ̀ Adulawọ lapapọ.
Iya Rainbow ti kopa ninu ọpọlọpọ sinima lati igba to ti bẹrẹ si ni ṣere.
Gbọ̀ngàn Mapo, ọ̀kan lára ibi àmúyangàn n'Ibadan rèé Àgbálùmọ̀, ohun mẹ́fà tó ń ṣe lára tí o kò mọ̀ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, BBC Gov Debates: Ètò ẹ̀kọ́ ọ̀fẹ́ ni àwọn olùdíje yóò ṣe Oríṣun àwòrán, Omoyele Sowore Àkọlé àwòrán, Odu ni Omoyele Sowore fun awọn ologun ki ṣe aimọ Awọn to wa lori alefa nigba ti Naijiria wa labẹ Ijọba ologun mọ Sowore bi ẹ ni mọ owo fun bi o ti ṣe ma n le iwaju ninu awọn iwọde to n tako isejọba ologun.
fun gbogbo osise to wa jake –jado orile ede Naijiria.
Ajọ to n gbogun ti iwa ibajẹ lorilẹ-ede Naijiria, EFCC ti sọ wi pe, wọn ti fi panpẹ ọba mu Oyediran Joseph.
Awọn onimọ ijinle a ma saba di ẹbi aisidagba soke ni Naijiria ru bi ẹka ina ọba ti se dẹnu kole lorilẹẹde Naijiria.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Sotitobire: Ọkọ mi kò mọ̀ Jegede PDP rí, kódà kò fa ẹnikẹ́ni kalẹ̀ dípò Akeredolu- Bisola Ṣugbọn, Fatoyinbo kọ lati ṣe bẹ ẹ.
Wọ́n bi àwọn ọmọbinrin náà pé, “Ǹjẹ́ aríran wà ní ìlú?
Jadesola Ajibola  n menuba idi pataki ti
Nígbà tí gbogbo àwọn olórí ogun tí wọ́n wà ní ìgbèríko pẹlu àwọn ọmọ ogun wọn gbọ́ pé ọba Babiloni ti fi Gedalaya ọmọ Ahikamu jẹ gomina ní ilẹ̀ Juda, ati pé ó ti fi ṣe olùtọ́jú àwọn ọkunrin, ati àwọn obinrin, ati àwọn ọmọde ati díẹ̀ ninu àwọn talaka ilẹ̀ Juda, tí wọn kò kó lọ sí Babiloni, 
Lara awon egbe oselu ti won yoo kopa ni egbe oselu to wa lori alefa All Peoples Congress (APC), ti minisita fun oro ile-okere teleri Samura Kamara, olori egbe oselu alatako kan gboogi lorile-ede naa,Sierra Leone Peoples Party (SLPP) ogagun agba Julius Maada Bio, ti o ti fi igba kan ri je olori ijoba ologun lorile-ede naa yoo ti kopa.
Ni ọsẹ to kọja ni ẹgbẹ CONUA ni awọn o faramọ bi nkan se n lọ laarin ẹgbẹ naa, ni wọn fi da ẹgbẹ tuntun yii silẹ.
Omolewa Ahmed naa dibo niibudo idibo Adebiogbon to wa ni  Share, ni ijoba ibilẹ Ifelodun .
Má bẹ̀rù, nítorí mo wà pẹlu rẹ,má fòyà, nítorí èmi ni Ọlọrun rẹ.
Ojo kerin, osu kejila , ni egbe osise fafiti bere iyanselodi alalojo lori bi ijoba apapo se ko lati mojuto awon fafiti ati kikọ ti wọn kọ lati mu adehun ti won se pelu ijoba sẹ.
Awọn iroyin mii ni lẹyin ọdun Sallah lọsẹ to kọja ni wọn gbe iyawo aarẹ kuro ni Naijiria lẹyin to n kerora ọrun didun lati bi ọsẹ meji to bere fun ki wọn gbe oun lọ oke okun.
Bí ẹnikẹ́ni bá súnmọ́ Absalomu láti wólẹ̀, kí ó sì kí i tọ̀wọ̀tọ̀wọ̀, Absalomu á tètè na ọwọ́ sí i, á gbá a mú, a sì fi ẹnu kò ó ní ẹnu.
Ìdí tí mo fi pa àṣẹ yìí ni láti ta ìfẹ́ àtọkànwá jí ninu rẹ, pẹlu ẹ̀rí ọkàn rere ati igbagbọ tí kò lẹ́tàn.
Eyi si lo mu ki ile ẹjọ dajọ iku fun.
fun apẹẹrẹ, ti o ba gbọ iro ibọn, oun akọkọ ni lati mọ ohun to n ṣẹlẹ, nibo ni ijamba ti wa, kini mọ le ṣe lati daabo bo ara mi, ki o to gbe igbeṣẹ kankan.
O fikun wi pe, ijọba gbọdọ dena ki maa ko adiẹ wa si lati apa ariwa orilẹede Naijiria, nibi ti aarun lukuluku ti gbinlẹ, to si ti pa ọgọọrọ adiẹ bayii.
Wọ́n níláti wà ní ipò ìtẹríba, gẹ́gẹ́ bí Òfin ti wí.
oludari agba ajo to n mojuto isele pajawiri lorile-ede Naijiria National Emergency Management Agency (NEMA), ogbeni Mustapha Maihaja lo jabo oro naa.
“Asiria náà wà níbẹ̀, pẹlu gbogbo àwọn ọmọ ogun rẹ̀.
Asafu ni ó ń lu aro.
Ati wi pe awọn anfaani tuntun ninu eto ọrọ-aje ti igbimọ naa tọka si fun ijọba apapọ tumọ si pe owo yoo pọ si niluu.
Kí wá ni ìdí tí àwọn Amẹrika ṣe ń dìbò?
Fayoṣe ní ìbéèrè mẹ́rin fún Buhari lórí ìwé ẹ̀rí rẹ̀ Buhari gbọ́dọ̀ bẹ̀rẹ̀ ìwádìí Ganduje láàrín ọjọ́ mẹ́rìnlá-SERAP Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Kunle Afolayan: èmi kò fẹ́ fi ogún sílẹ̀ fún ọmọ mi Ninu ọrọ tirẹ, aarẹ ile aṣofin agba, Ahmed Lawan ṣalaye pe ẹsun ṣi ni ohun gbogbo yoowu ti awọn eeyan ba ri tabi gbọ lori ọrọ naa titi di igba ti ile ba ṣe iwadii ti wọn si fun igun gbogbo ti ọrọ kan ni anfani lati wi tẹnu wọn lori iṣẹlẹ naa.
Ẹ fọkànbalẹ̀, kọ́bọ̀ kò ní gun owó epo pẹtiró - NNPC Olè wọ ilégbèé obìnrin ní fásitì Ibadan, àkẹ́kọ̀ọ́ méjì farapa 'Ẹnikẹ́ni ò lè tì mí gbọ̀ngbọ̀n láti gbé orúkọ mínísítà jáde' Ishaq fun 'pe si awọn olori ẹsin lawujọ pe ki wọn ye ba 'ra wọn ja, o tun pe awọn ẹlẹsin Kristẹni, awọn lọba lọba kaakiri Naijiria pe ki gbogbo wọn pawọ pọ ke si ijọba.
Eyi ni ọrọ ti iroyin sọ pe alaga ẹgbẹ awọn gomina, to tun jẹ gomina ipinlẹ Zamfara, Abdulaziz Yari, sọ fun awọn oniroyin lẹyin ipade ti awọn gomina mẹrindinlogoji to wa ni Naijiria ṣe pẹlu Aarẹ Muhammadu Buhari l'ọjọ Ẹti.
afesegba ni abajade ami-eye ohun ya lenu lopolopo, nitori pe opo lo foju si agbaboolu
  Amaechi tun sọ fun igbimo naa pe “Gẹgẹ
O lee mu yara ile alaja loke bo ba ṣeeṣe, wọn maa n ni itansan oorun to pọ gẹgẹ bii yara ti orule rẹ ba ga.
"- Obasanjo gbarata Ìbẹ̀rù bá olùgbé Eko torí àwọn ọ̀dọ́ Òkè Ọya tó dìhámọ́ra Olùkọ́ mi ń bá mi lòpọ̀ kí ń le yege ìdánwò WAEC - Akẹ́kọ̀ọ́ l‘Ogun Olólùfẹ PDP 18 kú nínú ìjàmbá ọkọ̀ lásìkò tí wọn ń lọ pàdé gómìnà Iyabo Ojo ṣílé, Toyin Abraham fẹ́ ṣílé iṣẹ́ f'ọmọ, àtàwọn nǹkan míràn lágbo òṣéré Wo fọ́tò àrà MC Oluomo, Pasuma àtàwọn òṣèré tíátà míì níbi ìṣílé Iyabo Ojo Wo àwọn òṣìṣẹ́ kólẹ̀-kódọ̀tí tó ń fi ẹ̀mí wọn wéwu kí Abuja leè mọ́ tónítóníWo ìyá ọlọ́mọ mẹ́ta tó ti pé ọdún 48 tó ń ṣe ìdánwò WAEC, kó le di nọ́ọ́sí ""Iru nkan bẹ ẹ ko ṣẹlẹ rara, irọ patapata ni gbogbo rẹ."
Iṣẹ to ṣe gbẹyin ni iwe to gbe jade to pe ni Itan Iran Yoruba nibi to ti ṣe iwadii to tako awọn nkan ti wọn gabgbọ nipa iran Yoruba tẹlẹ lai ni ẹri to peye.
Ọrọ iyansipo Amina Zakari gẹgẹ bii alamojuto ibudo ikabo fun ọdun 2019 ti n fa ọpọ awuyewuye lati igba ti ajọ INEC ti kede rẹ ni ọjọbọ.
"Mo wa lọ ba iya ti wọn n ta ata ni adugbo wa, mo ṣaa lọ ra ata ẹgbẹrun meji o le lẹẹdẹgbẹta naira""."
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Lagos building collapse: Àwọn òbí ń kérora lórí ikú àwọn ọmọ wọn nínú ìjàmbá ilé tó wó Lagos Building Collapse: Ìjọba ìpínlẹ̀ Eko gbé ìgbìmọ̀ olùwádìí kalẹ̀ Kò sí èèyàn kánkan tó kù nílé tó wó ní Ibadan- NEMA A gbọ wi pe eniyan meje ni ile naa wo lu mọlẹ.
Àmúwá Ọlọ́run lásán ní ìṣẹ̀lẹ̀ tó wáyé ní Iba-Eburu Iba Oba Okunoye Ó gbẹnután!
Gbogbo wa lo da loju pe, a ni ẹjọ to duro daradara, awọn ikọ agbẹjọro wa si ti fi eyi da wa loju.
" Iyabo salaye pe a nilo lati dẹkun didi ibo fun irufẹ awọn oloselu kan naa ninu ẹgbẹ APC tabi PDP, ka le fopin si iṣejọba buburu.
jiya ipalara ati lilu bi bara.
Wọ́n le tóbẹ́ẹ̀ tí ó fi jẹ́ pé kò sí ẹni tí ó lè gba ọ̀nà ibẹ̀ kọjá.
“Serubabeli tí ó bẹ̀rẹ̀ kíkọ́ ilé Ọlọrun yìí ni yóo parí rẹ̀.
Ó dìgbà - BBC News Yorùbá BBC News, YorùbáFò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Winne aya Mandela - Ó dìgbà 11 Ìgbé 2018 Èyí ni ìtàn ráńpẹ́ nípa ìgbésí ayé akọni obìnrin nnì lórílẹ̀èdè South Africa, Winne Mandela, tó di olóògbé.
Ní ọjọ́ kẹta ati ọjọ́ keje, àwọn ati obinrin tí wọ́n mú lójú ogun yóo ṣe ìwẹ̀nùmọ́.
Ọdun 1995 lo dawọ okoowo ẹwa tita duro lẹyin to ti ta ẹwa ni adugbo Ṣapọn fun ọdun mẹrinlelogoji.
Ahmed ni igbaradi yii waye pelu ipinnu ati ojuse igbimo eleto aabo orile
Wọ́n fẹ́ràn kí eniyan máa kí wọn láàrin ọjà ati kí àwọn eniyan máa pè wọ́n ní ‘Olùkọ́ni.
, Ọmọ ọdún mẹ́rìnlá kàwé gboye jáde ni fasiti Oxford Kíì ṣe pé ẹ si mí gbọ́ oo, Joshua Beckford wọ ilé iwé fásiti Oxford ní ọmọ ọdún mẹ́fa.
Ikọ naa, ti orukọ rẹ n jẹ ''Save-A-Soul'', se agbekalẹ imọ ẹrọ ayelujara kan, ‘app’ lori ẹrọ̀ alagbeka, ti wọn pe orukọ rẹ ni ''FD Detector''.
'Àwọn ọ̀tẹlẹ̀múyẹ́ tí n ṣèwádí ohùn Leah Sharibu' Ìgbẹ́ ọmọdé ń dènà ààrun jẹjẹrẹ, àìsàn ìtọ̀ súgà Ọwọ́ ba òsìsẹ́ SARS tó pà akẹ́ẹ̀kọ́ ní Iwo Ọladele ni ''aburo oun ati awọn ọrẹ rẹ kan ni wọn jọ lọ si ibi ariya kan to waye nile itura kan ni agbegbe Ẹgbẹda.
”O fikun oro re pe, ero DSO naa yoo tun fun awon olokoowo lanfani fun ipolongo oja won, yala ile-ise ero ibanisoro, awon olupese ero igbalode abbl.
ati Ikeja lati fagile igbese gbigbe ero- aminuwa (transformers) kuro latari pe awon
Nítorí bẹ́ẹ̀ ni ó wà ní àkọsílẹ̀ wolii nì pé.
 Ni ọjọ Aiku, Sunday ọjọ karun-un oṣu kẹjọ ọdun yii ni Igbimọ awọn Agbẹnusọ Ile Igbimọ Asofin Ipinlẹ Lorilẹ-ede Naijiria dibo yan Aṣofin Mudashiru Ọbasa gẹgẹ bi alaga tuntun fun igbimọ naa lẹyin ipade gbogboogbo wọn to waye ni ilu Ikẹja, ni Ipinlẹ Eko.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Minisita: Ileeṣẹ apòògùn 20 lo jẹbi síse òògùn ikọ́ Codeine 29 Agẹmo 2018 Oríṣun àwòrán, Frankieleon Àkọlé àwòrán, Àṣìlò èròjà codeine àti awọn òògùn mi i maa n ṣe àkóbá fún ara Ọwọ ileeṣẹ eto ilera ni Naijiria ti tẹ igo oogun ikọ olomi to n lọ si bi i miliọnu mẹta (2, 405,724) to ni eroja codeine ninu.
Latorii gbigbe orin sita, ṣiṣe alagbata orin kaakiri orilẹede to le lọgọta.
Ẹni tí ó wọ aṣọ iyebíye ni bí?
Iye awọn eeyan to ṣẹṣẹ ko arun naa ni ipinlẹ kọọkan ree: Eko-280 Oyo-103 Ebonyi-72 FCT-60 Imo-46 Edo-34 Delta-33 Rivers-25 Kaduna-23 Ondo-16 Katsina-12 Kano-10 Bauchi-8 Borno-7 Kwara-5 Gombe-4 Sokoto-2 Enugu-2 Yobe-1 Osun-1 Nasarawa-1 Eeyan 587 tuntun mii lo ṣẹṣẹ lugbadi arun Coronavirus ni Naijiria.
Oríṣun àwòrán, @aishambuhari Lọwọ yii, Aisha to jẹ aya aarẹ Muhammadu Buhari ti n ke gbajare pe, awọn ẹbi Daura ko tan mọ ọkọ oun o, ṣugbọn wọn ti fẹ fa ẹbi oun ni itan ya.
Ìpànìyàn ti sọ ọwọ́ yín di aláìmọ́,ọwọ́ yín kún fún ẹ̀ṣẹ̀, ẹ̀ ń purọ́,ẹ sì ń fi ẹnu yín sọ ọ̀rọ̀ burúkú.
EFCC ya bo ìlé Akinwumi Ambode Àjọ tó gbogun ti ìwà àjẹbánu lórílẹ̀-èdè Nàìjíríà, EFCC ni iwadii lasan ni awọn n ṣe.
Coronavirus ti na'wọ́ gán Mínísítà fétò ìlera nílẹ̀ẹ Gẹ̀ẹ́sì Gómìnà ìpínlẹ̀ Kaduna fún Sanusi ní ipò tuntun Èyí ni àwọn ìdí tí ìjọba ìpínlẹ̀ Kano ṣe rọ Emir Sanusi Lamido l'óyè Nipa afara Eko to di titi pa, o ni igbesẹ naa ṣe pataki nitori ọna ati daabo bo ẹmi awọn to n gba ori afara naa, ati pe, ijọba n ṣeṣẹ takuntakun lati mu aye dẹrun fun awọn eeyan ipinlẹ naa.
eniyan  gba pe ohun ni eto idibo to waye
Ajọ to n gbogun ti ajakalẹ arun lorilẹede Naijiria, NCDC lo kede eyi loju opo twitter rẹ lalẹ ọjọ Ẹti.
Manase, ọmọ rẹ̀ sì jọba lẹ́yìn rẹ̀.
Àwọn ọmọ Solomoni ọba nìwọ̀nyí: Rehoboamu, Abija, Asa, ati Jehoṣafati; 
Ọ̀pọ̀ ninu àwọn tí ó ti kú, tí wọ́n ti sin ni yóo jí dìde, àwọn kan óo jí sí ìyè ainipẹkun, àwọn mìíràn óo sì jí sí ìtìjú ati ẹ̀sín ainipẹkun.
OLUWA ní, “Àwọn ará Damasku ń dẹ́ṣẹ̀ kún ẹ̀ṣẹ̀, dájúdájú, n óo jẹ wọ́n níyà.
Àwọn yìí ni wọ́n ń fi ohun ìní wọn bá Jesu ati àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ gbọ́ bùkátà wọn.
“Ṣugbọn bí ẹbọ ọrẹ rẹ̀ bá jẹ́ ti ẹ̀jẹ́ tabi ọrẹ àtinúwá, wọ́n gbọdọ̀ jẹ ẹ́ ní ọjọ́ náà, ṣugbọn bí ó bá ṣẹ́kù, wọ́n lè jẹ ẹ́ ní ọjọ́ keji; 
Mikimetati ni ààlà wọn ní ìhà àríwá.
siwaju ninu ise rere ni sise titi ojo kejidinlogbon osu karun odun yii ti
Ààrẹ orílẹ̀èdè Mali, Boubacar Keita kọ̀wé fipò sílẹ̀ Oríṣun àwòrán, Getty Images Aarẹ orilẹede Mali, Ibrahim Boubacar Keita ti kọwe fi ipo silẹ, lẹyin tawọn ologun mu un lọjọ Iṣẹgun.
omo ogun ni ile ise ologun orile ede Naijiria.
Iroyin to tẹ wa lọwọ sọ pe awọn ajinigbe naa lo kan si ẹbi iyawo Ọba naa Olukemi Agunloye.
Nigba to n kede iyansipo tuntun naa ni oju opo Twitter rẹ, Olukemi Olufunto Badenosh @KemiBadenoch fi idunnu rẹ han si ipo nla ti Olootu ijọba Gẹẹsi yan si ọhun.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Àwọn olórí lágbàyé ń dárò Kofi Annan Ìjọba Eko fòfin de àgbò títà lójú pópó f‘ọ́dún Ileya Àwọn obìnrin tí kò lọ́kọ ń kojú ìsòro ilé gbígbà Bi ẹ ba gbagbe, ọjọ kẹta Oṣu kẹjọ yii ni Aarẹ Buhari rinrinajọ lọ si ilu London fun isinmi ranpẹ.
O ni ki gbogbo awọn ọmọ Naijiria maa kuna lati jẹ ki ileeṣẹ to n risi idiyele eporọbi, DPR, tabi awọn agbofinro, mọ nipa awọn ileepo to ba gbiyanju lati lo anfaani bi nkan ṣe ri l'orilẹede yii lati fi ara ni araalu NUPENG ti ìyanṣẹ́lódì NLC lẹ́yìn Iroyin kan ti sọ tẹlẹ pe, o ṣeéṣe kí adínkù bá epo bẹntiróòlù lọsẹ̀ yìí gẹ́gẹ́ bí ẹgbẹ́ àwọn òṣìṣẹ́ ilé iṣẹ́ epo bẹntiróòlù àti afẹ́fẹ́ gáàsì, NUPENG ṣe fi àtìlẹ́yìn wọn hàn fún ẹgbk àpapọ̀ òṣìṣẹ́, NLC.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Mo rántí, láyé ìjọba ológun.
Ta ló lè ṣeé kí Liverpool má jìyà lọ́wọ́ Messi?
Níbẹ̀ ni wọ́n sin Abrahamu ati Sara aya rẹ̀ sí, níbẹ̀ náà ni wọ́n sin Isaaki sí ati Rebeka aya rẹ̀, níbẹ̀ ni èmi náà sì sin Lea sí.
Ẹ kò gbọdọ̀ tẹ́ pẹpẹ tí ẹ óo máa fi àtẹ̀gùn gùn, kí wọ́n má baà máa rí ìhòòhò yín lórí rẹ̀.
Báwo ni Amina Zakari àti Buhari ṣe tan?
Ọjọ kọkandinlọgbọn, oṣu Kẹfa, ọdun 2014, lo pa orúkọ da si IS, lẹyin to dá isejọba caliphate"" silẹ, ni Syria ati Iraq."
Ìjọba Nàìjíríà ti sún ọjọ́ tí ìrìnàjò bàálù sílẹ̀ òkèèrè yóò bẹ̀rẹ̀ padà síwájú 'Orísúnmibáre ni àìsàn 'Polio' tó kọlù mí ní kékeré' Àwọn aṣekúpani tún ti pa ọmọ ọdún 16 ní Akinyele nípìnlẹ̀ Oyo Ọwọ́ ọlọ́pàá ìpínlẹ̀ Oyo tẹ àwọn afurasí lórí ìpànìyàn tó wáyé ní Akinyele Ohun tí ọlọ́pàá ń ṣe rèé láti sàwárí àwọn ‘mùjẹ̀-mùjẹ̀’ ní Akinyele Ẹgbẹ́ akẹ́kọ̀ọ́ gíga n‘Ibadan ṣèwọ́de lọ iléeṣẹ́ ọlọ́pàá lórí afurasí tó dàwátì O fi ẹsun kan oṣiṣẹ ọlọpaa kan to pe ni Funṣọ, pe oun lo fi aye silẹ fun oun lati sa lọ.
Kò rẹ ẹnikẹ́ni ninu wọn,ẹnikẹ́ni ninu wọn kò fẹsẹ̀ kọ.
Ẹ̀míi rẹ̀ ò lé ‘lẹ̀ nípa ìdánimọ̀ọ rẹ̀, ó yìí ọkàn àwọn òbí rẹ̀ padà láti kó lọ sí àdúgbò tí àwọn ọmọ Tibet ń gbé.
Kí OLUWA tí ó dá ọ̀run ati ayébukun yín láti Sioni wá.
Coronavirus: ''Ìjọba kò tíì pàṣẹ ìlànà ìtakété-síra-ẹni padà nínú BRT la ò ṣe máa tẹ̀le'' Ìjọba gbé ilé ijó oníhòhò tì pa lórí ẹ̀sùn títàpá sí ìlànà àti dẹ́kun coronavirus Ogun abẹ́lé tó ń ja Akeredolu l'Ondo, òní la ó mọ̀ bóyá yó borí rẹ̀ Ìyàwó mi fi mí sílẹ̀ kó lọ sílé ọkùnrin míì nínú báráàkì kan náà, àmọ́ mò sí tún fẹ́ràn rẹ̀- Sọ́jà Oríṣun àwòrán, others Lẹyin naa lo lọ fa ara rẹ le ọlọpaa lọwọ, eyii to mu ko jẹ ẹni keji ti aje iwa ibaje yoo ṣi mọ lori ninu ijọba Aarẹ Joko Widodo laarin ọsẹ diẹ sira wọn.
Wọn óo máa wí ní ọjọ́ náà pé, “Ọlọrun wa nìyí; a ti ń dúró dè é kí ó lè gbà wá, OLUWA nìyí; òun ni a ti ń dúró dè.
- Ìwádìí BBC Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Mama Rainbow: Toyin Adegbola àti Razak Olayiwola ní ìyá rere àti àwòkọ́ṣe gidi ní Amarachi to ta ko Kemi sọ fun pe odidi iyawo ile ni to tun wa n fi ọrọ sita pẹlu ẹni to dagba ju lọ.
Bẹ́ẹ̀ náà ni, kò sí ẹni tí ó lè sọ pé, òun nìkan ni ikú òun kàn.
"Gbogbo awọn ọlọdẹ ibilẹ la jọ ṣiṣẹ naa.
Kó baba, ati ìyá rẹ, ati àwọn arakunrin rẹ, ati gbogbo àwọn ará ilé baba rẹ sí inú ilé rẹ.
''Ẹni ti o ba ṣe fiimu ti ko fi orin sinu rẹ, ko ti ṣisẹ ere sinima.
Nítorí náà, kí ni ìsọkúsọ tí ẹ lè fi tù mí ninu?
Sùgbọ́n irú orúkọ yìí ò bójúmu, kò sì nítumọ̀ kankan ní Yorùbá.
Ṣugbọn bí a bá gbógun tì wọ́n ní pẹ̀tẹ́lẹ̀, a óo ṣẹgun wọn.
Oríṣun àwòrán, Abiola Ajimobi Ninu ọrọ ibanikẹdun ti agbẹnusọ fun Alaafin, Bode Durojaiye fi sita, Iku Baba Yeye sapejuwe Ajimobi gẹgẹ bi oloselu to ma n mu ileri to ba se fun araalu sẹ lasiko ipolongo ibo rẹ.
9 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Wo àwọn oúnjẹ márùn ún tó ń mú kí àtọ̀ ọkùnrin dára síi7 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 4:11 Fídíò, Ojú mi ti rí lọ́pọ̀ lọpọ̀, ọ̀pọ̀ èèyàn ni kò tilẹ̀ gbàgbọ́ pé mo lè jọba- Ooni, Duration 4,117 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Èyítí A Ń Kà Jùlọ 1 Ìjọba ìpínlẹ̀ Ondo kéde òfin konile-o-gbele ní Ode ati Ishinigbo lẹ̀yìn rògbòdìyàn tó wáyé níbẹ̀ 2 Wo ìgbéyàwó olówó iyebíye tí awakọ̀ Kabúkabú ti jẹ̀bùn ọkọ N3.
Gege bi aare Buhari tun se so, “Awon ti o wa nidii ikolu ile ijosin, leyi ti o gbemi eniyan mejidinlogun ti o fi mo awon alufaa ile ijosin meji, iru awon olote bayii ko fe alaafia fun ilu yii rara bi o ti le wu ki o mo.
24 Ìgbé 2020 Oriṣiiriṣii nnkan lawọn eeyan n sọ pe o le wo aarun coronavirus ti o ba gbogbo aye finra lọwọ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Èré Ọṣun: Àtáója ní wọn kò jí ère Ọṣun, ó sì wà níbi tó wà Gbogbo igbinyanju wa lati ẹyin wa lọdọ awọn ọlọpaa lati pinwọ iwa yii lo ja si pabo nitori pe se ni awọn agbofinro maa n kọju sẹgbẹ nigba ti wọn ba ti gba riba lọwọ wọn."
Ipinlẹ mẹrindinlogun ni coronavirus ko ti i de ni Naijiria naa niwọnyii:.
Mààlúù mọ olówó rẹ̀;kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ sí mọ ibùjẹ tí oluwa rẹ̀ ṣe fún un;ṣugbọn Israẹli kò mọ nǹkan,òye kò yé àwọn eniyan mi.
Pagano so pe:“A fe gbo eto ati ilana  ti ijoba ni :lori idagbasoke oro aje ; idi niyi ti a fi wa nibi lati wa satileyin fun ijoba ati pe banki agbaye ti setan lati ran awon omo orile ede Naijiria lowo”.
Bakan naa, Salawa tun ṣalaye ọrọ lori ibaṣepọ rẹ pẹlu Alhaji Kollington Ayinla, o ni baba ọmọ oun ni Kollington jẹ, amọ oun ko tii pada sile rẹ titi di asiko yii.
aduru ẹru yi ni igbe tawọn eeyan mu bẹnu nigba ti wọn ri aworan yi to wa lati Yola Oríṣun àwòrán, afamefuna.
Ibeere ni @AbdulMahmud01 n beere ni tirẹ, o ni ''kinni o n ṣe wa gan an?
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ọ̀pọ̀lọpọ̀ló ń fara pamọ́ mu igbò ''Igbó máa ń mú mi ronú kíákíá'' Chuks, jẹ́ ọ̀dọ́ ọmọ Nàìjíríà kan tó ń gbé nílu Eko ó sì jẹ́ amugbó Ó ní òun kò lè rántí ní pàtó ọdún tó bẹ̀rẹ̀ sí ni lo òògùn olóró yìí.
Akomolede: Bolaji Faleke ni Olùkọ́ tó ń kọ́ wa ní àṣà oge ṣiṣe lórí BBC Yorùbá
Ó wà níbẹ̀ láti ìbẹ̀rẹ̀ ìkórè, títí di àkókò tí òjò bẹ̀rẹ̀ sí rọ̀.
Ọba bèèrè pé irú ọlá wo ni a dá Modekai fún ohun tí ó ṣe yìí?
kí o sọ fún wọn pé OLUWA Ọlọrun ní, ‘Ẹ wò ó!
"Láti ọjọ náà, kò sí ìdájọ kan tó sọkalẹ mọ, eléyìí gan ló fàá tí Sayyidina Umar fi sọ pé: ""Nitori àjùlọ tó wà fún ọjọ yìí, tó bá jẹ àwọn Yahúdí ni, ki sọ ọjọ yìí di ọjọ tí wọn ó máa ṣe ayẹyẹ lọdọdún"", Gẹgẹ bí Ọlọrun ṣe gba ẹmí Anabi Muhammad (S."
O fi kun ọrọ  rẹ pe igbimọ naa pinnu lati dojukọ awọn eto
N óo fún gbogbo àwọn ọba Usi mu, ati gbogbo àwọn ọba ilẹ̀ Filistini, (Aṣikeloni, Gasa, Ekironi ati àwọn tí wọ́n kù ní Aṣidodu).
Awọn alaisan kan tun bẹrẹ si nii sọo pe ko si awọn dokita nile iwosan mọ bii ti tẹlẹ.
Bakan naa ni atẹjade ọhun ni, gomina ipinlẹ Ọ́sun, Rauf Arẹgbẹsọla ti ki Alaba Akintayọ ku oriire ifẹyinti rẹ, to si tun gbadura fun pe yoo mọ akoko naa si rere.
 Ó sì ṣáábà máà n ní ọwọ́ òṣèlú nínú.
Ní wakati kan péré ni gbogbo ọrọ̀ rẹ̀ run!
Latari ifipagbajọba eyi to kuna lọdun 2015, ẹgbẹgbẹrun ara Burundi lo ti sa kuro niluu lati lọ ṣatipo lawọn orilẹede ẹgbẹ wọn.
Ó ń wo ọpọlọpọ nǹkan, ṣugbọn kò ṣe akiyesi wọn.
Minisita wa tun ki awon omo orile ede Najiria ku ayeye ajodun Id-el Fitr.
Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Èèmọ̀, alukoro PDP tẹ́lẹ̀, Olisah Metuh dákú ní ilé ẹjọ́21 Èbibi 2018 MaguEFCC: Omale ni orúkọ tí Magu ń lò.
Igbimọ naa ni wọn tapa si ofin to de ile ijo lasiko COVID-19 yii ni BBNaija tọdún 2020 gbéra sọ, wo ohun tó fi yàtọ̀ sí tọdún tó kù!
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Goitre Patients: Àwọn èèyàn tó ní àrùn gẹ̀gẹ̀ ní ọ̀pọ̀ ìkórira àti ìdẹ́yẹsí ní àwọn ń kojú Lẹyin aayan wọn ọhun, alukoro ileesẹ ọlọpaa nipnilẹ Oyo, Olugbenga Fadeyi ni ọwọ tẹ awọn afurasi ajinigbe mẹta to n sisẹ laabi ni agbegbe ijsba ibilẹ Irẹpọdun.
N óo jẹ́ kí ẹ gbó, kí ẹ sì tọ́.
Oríṣun àwòrán, Twitter/@Ayemojubar Ọjọta lawọn olufẹhonuhan fi ipade si niluu Eko, oniruuru awọn ajafẹtọ lo pade nibẹ nibi ti wọn ti n kọrin a ko nii gba si ijọba Jonathan leti.
Lẹyin o rẹyin, ijọba gbe owo gun owo ori tawọn agbẹ yoo maa san si dọla mẹjọ ($8) dipo dọla kan ati sílè mẹwa ($1.
Nítorí èyí, ibinu OLUWA ru sí ọ.
42 Àti láti kọ́ni, sọ àsọyé, gbàni nímọ̀ràn, rìbọmi, ati dáàbò bo ìjọ;
Àwọn wọnyi ni ti ẹ̀bá ọ̀nà, níbi tí a fúnrúgbìn ọ̀rọ̀ náà sí: àwọn tí ó jẹ́ pé, lẹsẹkẹsẹ tí wọ́n gbọ́ ọ̀rọ̀ náà, Satani wá, ó mú ọ̀rọ̀ tí a ti fún sinu ọkàn wọn lọ.
Awọn eeyan kan si tun farapa.
A o le ri ojutuu bi a ba n dakẹ, ki t'ara wa ma ba wa dakẹ.
”Ahabu dá a lóhùn pé, “Bí o bá ṣe ohun tí o wí yìí, n óo dá ọ sílẹ̀.
Wọ́n sọ fún Abimeleki pé gbogbo àwọn tí wọ́n wà ní ilé ìṣọ́ tí ó wà ní Ṣekemu ti kó ara wọn jọ sí ibìkan.
Bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé ẹgbẹẹgbẹ̀rún ti padà sílé.
Ojulowo ọmọ Yoruba kọọkan si lo yẹ ko mọ akọsilẹ awọn gbolohun ede naa ati iro ti ikọọkan wọn ni, ka ma baa maa fi Ojo pe Aina.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Deborah Adebola Fasoyin: Èmi kọ́ ló gbé orin ọdún ń lọ sópin kalẹ̀, CAC ló ni í ni mó n ṣe àkójọ orin- Fasoyin Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Deborah Adebola Fasoyin: Èmi kọ́ ló gbé orin ọdún ń lọ sópin kalẹ̀, CAC ló ni í ni mó n ṣe àkójọ orin- Fasoyin 31 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Orin ọdun n lọ sopin jẹ eyi to gbajumọ laarin ọpọ eeyan lai fi ti ẹsin se nitori ọpọ adura to pọ ninu orin naa.
Nigba ti wọn n ba BBC Yoruba sọrọ lori iṣẹlẹ yii, awọn alaga ẹgbẹ CAN nipinlẹ Oyo ati Ondo, Pasitọ Benjamin Akanmu ati Ayo Oladapo woye pe, ijọba fẹ tete sekupa awọn arugbo ni, ti wọn ko ba ni anfaani lati jade sita.
Òkun Iyọ̀ ni ààlà ilẹ̀ náà ní apá ìlà oòrùn, ó lọ títí dé ibi tí odò Jọdani ti ń ṣàn wọ inú òkun.
Laarọ ọjọbọ ni ọga agba fún ileeṣẹ DAAR Communications, Raymond Dokpesi ti ṣaaju awọn eniyan rẹ lọ ṣe iwọde ko tẹ mi lọrun kaakiri ilu Abuja.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Dino: Kò tọ́ bi Buhari se tàbùkù ilé aṣòfin 31 Èbibi 2018 Oríṣun àwòrán, Voice TV Àkọlé àwòrán, Senato Dino Melaye ni oun fẹ kí Ààrẹ Buhari tọrọ aforijin lọwọ ilé Senato Dino Melaye tutọ soke fojú gbàá, tó sì bẹnu àtẹ lù ààrẹ orílèèdè Nàìjíríà, Muhammadu Buhari.
Ọdun 1962 ni ogun ti waye gbẹyin laarin ilẹ mejeji, ṣugbọn ajẹkunniya ni India jẹ lọwọ China lọdun naa lọhun.
Ni oṣu kẹta ọdun 2011, eniyan bi mẹrinlelogun lo ku nigba ti ijamba ọkọ kan ṣẹlẹ ni popona naa.
Àwòrán rèé nípa bí 'Hand of God' ṣé dí inagijẹ Diego Maradona Lẹ́yìn tó fi ọ̀bẹ halẹ̀ mọ́ ọ, ọkọ Magarita fi àáké gé e lọ́wọ́, kí ló ṣe tó bẹ́ẹ̀?
Ìwádìí ìwé ẹ̀rí àwọn olùdíje Ààrẹ lọ́dún 2019 Kíni itumọ àṣẹ wàá tí àwọn Ààrẹ orílèèdè má n pá?
Gbogbo àwọn ọmọ Israẹli bá jáde láti wá darapọ̀ mọ́ Saulu ní Giligali.
ACP Naa ni ti awon ile-ise ba n san owo ori to po ju agbara wọn
Lẹyin ipade naa si ni wọn yoo polongo gbedeke owo osu osisẹ ni irọle Ọjọ Isẹgun, Osu Kọkanla, ọdun 2018.
ó ní, “Ẹ fi ìwé òfin yìí sí ẹ̀gbẹ́ àpótí majẹmu OLUWA Ọlọrun yín, kí ó wà níbẹ̀ gẹ́gẹ́ bí ẹ̀rí pẹlu yín; 
ajo UN ti bowolu iwe ibasepo odun marun un pelu orile-ede Naijiiria,
O fikun oro re pe, a le samulo awon idojuko ti o n koju orile-ede yii lati tun fi mu isokan alailegbe joba laarin wa ati tun fi mu iyipada otun ba eto oro aje.
 👇🏽@WFP drone footage show flooding in Pemba pic.
Ṣugbọn àwọn eniyan mi kò mọ òfin OLUWA.
"Àwọn èèkàn ìlú péjú s'Ibadan níbi ìsìnkú màmá Omotola àkọ́bí obìnrin Awolowo tó wọ káà ilẹ̀ lọ Nkechi Blessing vs Toyin Abraham: Nkechi tí tọrọ ìdáríjí ẹ̀ṣẹ̀ lọ́wọ́ akẹgbẹ́ rẹ̀, Toyin Abraham Ṣé Amotekun ti di ""HisbahTekun"" ní ìpínlẹ̀ Osun ní?"
Ní ọdún kejidinlogun tí Jeroboamu jọba Israẹli, ni Abijamu gorí oyè ní ilẹ̀ Juda.
8 27336 Orilẹede Angola 425 1.
Ogun miliọnu Naira ni wọn fẹ gba lọwọ mọlẹbi arakunrin naa, ki ọwọ ọlọpaa to tẹ wọn lọjọ kẹsan osu keje, ti wọn si fi si ahamọ.
Mo gbọ́ tí wọ́n pe àwọn àgbá náà ní àgbá tí ń sáré yí.
Sugbọn, ẹsẹ oku ẹran naa lo yọ silẹ, ti awọn ẹlẹyẹ fi ri pe, kii ṣe oku eeyan ni wọn di.
Ìfẹ́ a máa fara da ohun gbogbo, a máa gba ohun gbogbo gbọ́, a máa ní ìrètí ninu ohun gbogbo, a sì máa foríti ohun gbogbo.
Eléyìí ni wọ́n ṣe máa ń pe Òkònísà tí wọ́n dó sí yìí ní orí ayé.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Woli Kasali: Angẹli mi ni orékelẹ́wà Dọlapo Awoṣika Ọgbẹni Little ti sọ ọ ri pe oun n ran awọn ọmọ Uganda lọwọ nipa pipese iwosan olowo pọọku fun wọn.
Òun náà sì tún wí fún mi pé ìyàwó mi ti bímọ àti pé orúkọ tí wọn sọ ọmọ náà ni Àkàrà-oògùn.
O ni awọn ti o mọ nipa ọrọ aabo ilẹ Yoruba bii adari ẹgbẹ OPC, Aarẹ Gani Adams, lo yẹ ki wọn gbọ lẹnu rẹ, ni eyi ti wọn ko gbọ lati ẹnu wọn.
Oríṣun àwòrán, @obyezeks Àkọlé àwòrán, Nilu Abuja, idanilẹkọ yoo waye eleyi ti Pasitọ Tunde bakare yoo ṣe Ọjọ abamẹta ni yoo pe ọdun kẹrin ti awọn agbebọn Boko Haram ji awọn akẹkọbinrin naa gbe, mejilelọgọfa wọn lo ṣi wa laharamọ awọn agbebọn yii.
” Inú Hamani dùn sí ìmọ̀ràn yìí, ó lọ ri igi náà mọ́lẹ̀.
Kàkà bẹ́ẹ̀, oríkunkun ni wọ́n ń ṣe.
Kì bá ṣe pé ó ṣeéṣe ni, kí n kú dípò rẹ, Absalomu, ọmọ mi, ọmọ mi!
Wo awọn ìtàn ati imọ sayẹnsi to rọ mọ awọn ounjẹ ti a gba pe o n fi kun adun ibalopọ.
Omi adagun ti o pọ́n lomi naa ti awọn ọmọbirin ọun ma npọn.
Ṣugbọn oúnjẹ gidi ni àgbàlagbà máa ń jẹ, àwọn tí ìrírí wọn fún ọjọ́ pípẹ́ ti fún ní òye láti mọ ìyàtọ̀ láàrin nǹkan rere ati nǹkan burúkú.
Awọn obinrin ti wọn ba ṣe mẹrin ninu marun un yii yoo gbe fún ọdun mẹrinlelọgbọn síi lai larun jẹjẹrẹ, arun ọkan ati itọ ṣuga.
Bàbá ń ta ẹran káàkiri, ó dé ọ̀dọ oníbáráà kan, ó sọ̀kalẹ̀, òun àti onítọ̀ún dúǹá dúrà ẹran dáadáa.
Mo ranti iye ẹgba ti mo jẹ nigba naa pe ẹyin atupa yii fọ lọwọ mi nigba ti mo n fọọ.
Ọlọ́pàá: Sẹ́nétọ̀ Adeleke gbọ́dọ̀ jẹ́jọ́ ẹ̀sùn jìbìtì ìdánwò Lẹ́yin oṣu mẹrinla ti awọn ọlọpaa gbọ pe Sẹnetọ Ademọla Adeleke to jẹ oludije ipo gomina labe asia ẹgbẹ oselu PDP ninu idibo ipinlẹ Osun ṣe magomago ninu idanwo NECO ti 2017, ti o si gba ayederu iwe ẹri idanwo naa, wọn ti fẹ gbe lọ ile ẹjọ ni Abuja.
8th Assembly: Saraki pín owó ìyọ̀nda rẹ̀ fún ẹbí Leah Sharibu àtàwọn míì
Igbakeji Akowe agba  ile Amerika to n mojuto oro ile Afrika, ogbeni Tibor P.
Mọ̀ dájú pé ìyà tí Ọlọrun fi jẹ ọ́kò to nǹkan lẹ́gbẹ̀ẹ́ ẹ̀ṣẹ̀ rẹ.
Ṣé Yorùbá bò, wón ní, ohun tó wu ọmọ ó jẹ, ní i rún ọmọ nínú, ọwọ sìkún òfin tẹ àwọn ọmọ àjò ẹṣọ ojú pópó látàrí owó ẹyin ti wọn gbà lọ́wọ́ aráàlú.
Oríṣun àwòrán, Twitter/@AyindeBarrister Àkọlé àwòrán, Ayinde Barrister lasiko to n kọrin nibi ariya kan nilu Eko lọdun 1976.
Ni ọjọ ẹti ni awọn alasẹ ere bọọlu lagbaye gbe ife ẹyẹ naa lọ si ileeṣẹ BBC ni Ikoyi, nilu Eko gẹgẹbi itaniji ati ipolongo ti o nlọ lọwọ lori idije ife ẹyẹ agbaye fun bọọlu afẹsẹgba ti yoo waye lorilẹede Russia ni osu kẹfa ọdun 2018.
Ẹwẹ, Alagba ṣe o lo odidi ọdun mejilelọọdunrun loke eepẹ ko to faye silẹ.
Oríṣun àwòrán, Handout/Reuters Àkọlé àwòrán, Afara naa ṣe patakifun karakata lagbegbe naa Awọn oniroyin lagbegbe naa n jabọ pe ayẹwọ afara naa ti wn ṣe nibẹrẹ ọdun yi ṣafihan pe opo afara naa ti n jẹ.
Eto yii ti wa di ọkan lara eto ilu Salzburg lọdọọdun pẹlu ajọṣepọ ile iṣẹ to n ri si ọrọ aṣa ni Salzburg ti wọn maa n ṣagbatru ida to le ni marundinlọgọrin ẹnawo ayẹyẹ naa.
Ramadan yii je ona lati lee ran ara wa lọwọ,, nigba ti o ba n ba enikeji rẹ kẹdun,
Bakan naa, gege bi minisita eto isuna ati isakoso oro aje orile-ede Nigeria lati odun 2011 si odun 2015.
 a ó fi arópò orúko kan sí ààyè yìí .
Aago mokanla to je wakati kerindinlogun ojo ni idibo.
Oun ni wọn fun lati fi dije ipo gomina lasiko idibo ti yoo waye loṣu kọkanla ọdun yii.
JAMB: Ẹ̀ṣùn oníkókó mẹ́jọ ni EFCC fi kan Philomina àtàwọn 5 míràn
Buhari tún ti yan òkú sípò alàyè 'Ọjọ́ lọjọ́ tí mo mọ̀ pé wọ́n bí mi láì ní ojú ara obìnrin àti ilé ọmọ' Kalu sọ siwaju si pe ofin naa ṣe pataki lasiko yii nitori ofin ajakalẹ arun to wa nilẹ tẹlẹ ni ti iba jẹdọjẹdọ, iba ponju-pontọ, ati iba onigba meji, ati pe ofin ọhun ko ni fun ọga agba NCDC lagbara to pọ ju.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Wo imọran Fọlọrunṣọ Alakija fun awọn ọdọ adulawọ 4) Agbajọwọ la fi n sọya, ajoji ọwọ kan kò gbéru dori lo n di aṣeyọri ẹnikọọkan ninu idije.
– Seyi Makinde Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Yinka Ajia: ìbẹ̀rù Ọlọrun ni mo fẹ́ fi tukọ̀ Kwara ti mo ba wọlé Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, #NigeriaDecides: BBC ti wa ni gbogbo ìpínlẹ̀ Naijiria láti firoyin gbogbo tóo yin létí Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Sábàbí ire ní ikú Barakat padà já sí - Ẹ̀bí fẹ̀mí ìmoore hàn sọ́mọ Nàíjíríà Sunday Igboho yarí, ó fohùn ránsẹ́ sáwọn èèyàn tó ń pẹ̀gàn rẹ̀ Orilẹede Amerika wa lara awọn orilẹede mẹtadinlọgbọn to wa ninu igbimọ banki AFDB naa, ti wọn si jẹ orilẹede keji to ni ipin idokowo to pọ julọ ni banki ọhun.
tuntun jabọ oro naa fun ile igbimo ohun.
O máa ń pa àwọn òpùrọ́ run;OLUWA, o kórìíra àwọn apani ati ẹlẹ́tàn.
Aare Cyril Ramaphosa ti orile-ede South Africa so lale ojo-Aje pe, atunto yoo ba igbimo amusese orile-ede naa.
Awọn ọ̀rọ̀ náà to jẹyọ nínú èdè Yòrúba, Hausa, Pidgin.
Agbẹnusọ fun ileeṣẹ ọlọpaa ipinlẹ Oyo, SP Olugbenga Fadeyi ti fidi iṣẹlẹ ọhun mulẹ.
ti o ti bẹrẹ fun orile  ede yii.
oloselu lati ni afojusun, ki won si setan lati maa se ife ara ilu, gege bi a se
 lati tako iwa ipalara si awon ti won fi
Gbogbo àwọn ẹ̀dá alààyè tí wọ́n wà lórí ilẹ̀ ayé ni wọ́n kú patapata, ati ẹyẹ, ati ẹran ọ̀sìn, ati ẹranko, ati àwọn ohun tí wọn ń fàyà fà ati eniyan.
Ní alẹ́ ọjọ́ tí ó ṣíwájú Ọdún Tuntun, ó fi àtẹ̀jáde ṣókí sọ nípa ìṣẹ̀lẹ̀ náà.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Wòólì Alfred kú lọ́dún 1964, ó tún padà wà sí ìlú Agelu f'ọ́jọ́ mẹ́rìnlá!
Jesu sọ fún un pé, “Ó tún wà ní àkọsílẹ̀ pé, ‘Ìwọ kò gbọdọ̀ dán Oluwa Ọlọrun rẹ wò.
Nigbati ikọ BBC Yoruba se abẹwo si ibi ti isẹlẹ naa ti sẹ lọjọru, ọpọlọpọ awọn ikọ ọlọpa lo wa ni gbogbo ayika Idumọta.
Diego Maradona: Ọlọ́pàá 200 ni yóò máa ṣọ́ ibojì Maradona torí àwọn olè
Ẹ pe àwọn àgbààgbà, ati gbogbo àwọn tí ń gbé ilẹ̀ náà jọ sí ilé OLUWA Ọlọrun yín,kí ẹ sì kígbe pe OLUWA.
Ijiya ẹ́sẹ́ fawọ̀n ajinigbe ko si lọ̀ titi, amọ eto ẹkọ to ye kooro si lo le wa ojutu laelae si isoro naa.
Nígbà náà ni Jesu lọ láti ilẹ̀ Galili, sọ́dọ̀ Johanu ní odò Jọdani, kí Johanu lè ṣe ìrìbọmi fún un.
Eekan ninu ẹgbẹ oṣelu PDP ni Naijiria, oloye Bode George ba BBC Yoruba sọrọ lori eyi.
Ọ̀tá Yorùbá ló lo ìwọ́de láti dojú ogun kọ wá - OPC Ẹgbẹ Oodua Peoples Congress, OPC, ti bu ẹnu ẹtẹ lu bi awọn ọmọ ologun Naijiria ṣe ṣina ìbọn fun awọn ọdọ to ṣe iwọde#ENDSARS ni Lekki nipinlẹ Eko.
Gẹgẹ bi atẹjade ati ikede kan ti wọn fi sita lawọn ileeṣẹ redio nipinlẹ naa lọjọ Iṣẹgun, awọn alaṣẹ ileewosan ẹkọṣẹ iṣegun naa ṣalaye ile igbokupamọ si rẹ ti kun akunfaya eyi to n jẹ ko nira lati gba awọn oku tuntun wọle.
Suhaila ninu fidio naa ni, Musa ko le gbẹnu awọn sọrọ ati pe iwọde yoo ṣi tẹsiwaju.
 “Mo pinnu  lati fi iko Atletico Madrid sile lojuna ati lo koju awon idojuko tuntun ati
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Akomolede àti Aṣa: Ọ̀rọ̀ Ẹ̀yán ni Bunmi Femi Amao ń kọ́ wa lórí ètò Akọ́mọlédè àti Àṣà lóri BBC Yoruba Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Mike Bamiloye ti Mount Zion fi ọmọbìnrin rẹ̀ kan ṣoṣo, Darasimi fún ọkọ nílùú Ibadan11 Ọ̀wàrà 2020 Fídíò, Wole Soyinka sọ ìdí tó fi ni òun a fi màálù Fulani ṣe súyà fáwọn èèyàn abúlé23 Owewe 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Ogun Majek: Ọmọ, ẹbí àti àwọn òṣèré tíátà ló péjú sìnkú olóògbé
Kí Ọlọ́run bùn yín lẹ́mìí Kábíyèsí.
A kò lọwọ́ sí ìwé ìpẹ̀jọ́ tó tako ìdásílẹ̀ ìgbìmò ìwádìí aṣemáṣe ikọ̀ SARS- ọlọ́pàá Nàìjíríà Ọ̀dọ́bìnrin, ẹ ṣọ́ra!
Àwọn jíjẹ-oyè-àlùfáà mĩràn tẹ̀lé e nínú èyítí àwọn kọ́kọ́rọ́ oyè àlùfáà ti di fífúnni láti ọwọ́ Mósè, Èlíjà, Élíásì, àti ọ̀pọ̀lọpọ̀ àwọn wòlíì ìgbàanì (wo Ẹ&M 110; 128:18, 21).
Ojú-ìwé Facebook ti BBC Bangla rọ àwọn òǹkàwée rẹ̀ láti jábọ̀ àwọn ìgbésẹ̀ akin tí àwọn òníṣẹ́ ìlú Dhaka ń gbé láti gbógun ti ẹ̀fọn.
EFCC kó akẹ́kọ̀ọ́ fásitì UNIOSUN Wo àwọn tí gómìnà ìpínlẹ̀ Oyo fi orúkọ wọn sílẹ̀ fún ipò kọmísánnà Ẹ wo ọmọ ọdún méje tó di Gómìnà l'Ekiti Ẹni orí yọ, ó dilé!
Nígbà tí Huṣamu kú, Hadadi, ọmọ Bedadi, tí ó ṣẹgun Midiani, ní ilẹ̀ Moabu gorí oyè, orúkọ ìlú tirẹ̀ ni Afiti.
Oríṣun àwòrán, The Park Management Oyo State Facebook Àkọlé àwòrán, Ọmọ mi ni Sunday Igboho, kò sì tó dúró de mi, òun gan ló ń dá Ibadan ru - Auxiliary Auxiliary fikùn pé láti ọjọ́ tí aláyè ti dáyé, ẹnikẹ́ni tó bá jẹ́ ọmọ ẹgbẹ́ ọlọkọ ero NURTW, tó bá ṣiṣẹ fun oludije gómìnà kan, ní wọn yóò fi jẹ alaga ẹgbẹ́ NURTW, tí oludije náà bá di gómìnà.
"Nixon sọ pe, ""Erọ ayaworan jẹ irin isẹ ti kò lẹgbẹ lati sáfihan igbo ti wọn ti gbagbe lorilẹede Naijiria gẹgẹ bii ilégbèé fun awọn ẹ̀yà ẹranko to se pataki lorilẹede Naijiria ati ilẹ Afrika ni pataki julọ."
Lẹ́yìn náà, mo fún wọn ní ọjọ́ ìsinmi, kí ó máa jẹ́ àmì láàrin èmi pẹlu wọn, kí wọ́n lè mọ̀ pé èmi OLUWA yà wọ́n sí mímọ́.
Ninu ọrọ to ba BBC sọ, alukoro ileesẹ ọlọpa nipinlẹ ọhun, Abimbọla Oyeyẹmi, ni ko si lọwọ ọlọpa lati se ayẹwo ọpọlọ fun arakunrin naa.
Fun apẹẹrẹ, ọmọdekunrin ti o ku diẹ ki wọn gba ẹmi l'ẹnu rẹ nitori afọwọra; ọkan to daku rangbọndan s'ẹgbẹ titi fun wakati mẹrinlelogun o le lẹyin ti o mu egboogi oloro ni amu ju; ati awọn mẹta mi i ti opo ina to wo lulẹ tẹ pa lẹẹkan na.
Duku, Arabinrin Rukayat Bunmi Bello, Ọgbẹni Paul Omokore ati Jude Chikezie Okwuonu.
Kí ẹnikẹ́ni má baà gba ilẹ̀ ọ̀kankan ninu àwọn eniyan mi kúrò lọ́wọ́ wọn.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù FRSC: Ajínigbé tó kọlu òṣìṣẹ́ wá, èèyàn méjì kú, mẹ́rin farapa, a kò mọ ibí tàwọn mẹ́wàá wà 14 Owewe 2020 Oríṣun àwòrán, AFP Àkọlé àwòrán, Ìgbà àkọ́kọ́ kọ́ nìyí tí irú ìṣẹ̀lẹ̀ bẹ̀ yòó wáyé Ọrọ awọn ajinigbe loju popo Naijiria, kaka ki ewe agbọn wọn dẹ, niṣe lo n le si.
Lọjọbọ ni ile ẹjọ kotẹmilọrun nilu Abuja fidi idajọ mulẹ pe Kayode Fayẹmi ti ẹgbẹ oṣelu All Progressives Congress lo gbegba oroke ninu idibo gomina ipinlẹ naa.
Amọ, awọn eniyan 309 lo ri iwosan gba lọwọ arun naa ni Ọjọ Aje ohun.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Zlatan: Ọ̀rẹ́ ni mo sìn lọ ‘studio’ tí mo fi bẹ̀rẹ̀ orin lẹ́yìn tí mo kùnà ìdánwò WAEC O ni ọlọkọ bọọsi naa ko gbagbọ pe wọn ji ọkọ naa lọ ni, eyi to mu ko fi Saheed sun ni agọ ọlọpaa; lẹyin to kuro ni agọ ọlọpaa naa ni aisan ọpọlọ naa bẹrẹ.
Oríṣun àwòrán, Twitter/Bishop David Oyedepo Ọpọ eeyan lo ti n sọrọ lori ayelujara lati aarọ ọjọ Ẹti lati igba ti iroyin naa ti jade.
Nígbà tí Ahitofeli rí i pé, Absalomu kò tẹ̀lé ìmọ̀ràn tí òun fún un, ó di kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ rẹ̀ ní gàárì, ó pada lọ sí ìlú rẹ̀.
OLUWA yóo jẹ àwọn ọmọ Israẹli níyà, wọn óo sì máa gbọ̀n bí ewé ojú omi.
Lẹ́yìn tí àwọn ọmọ Israẹli ti ṣẹgun ilẹ̀ náà, gbogbo wọn péjọ sí Ṣilo, wọ́n sì pa àgọ́ àjọ níbẹ̀.
Ọjọ́ mẹfa ni kí olukuluku máa fi ṣiṣẹ́, kí ó sì máa fi parí ohun tí ó bá níláti ṣe.
Papa iṣire Ellis Park ni ilu Johannesburg ni ifẹsẹwọnsẹ naa ti waye.
Àwọn majẹmu tí ó ní ìlérí Ọlọrun ninu sì tún ṣe àjèjì si yín.
Wo ìgbẹ́sẹ̀ méjọ tí ilé aṣòfin ìpínlẹ̀ gbọdọ̀ tẹ̀lé láti yọ igbákejì gómìnà Akeredolu, aya àti ẹbí rẹ̀ ló ń ṣèjọba ni mo ṣe fipò sílẹ̀ - Akọ̀wé ìjọba tẹ́lẹ̀ l‘Ondo Àlàyé rèé lórí ìdí tí Magu àti awọn alága EFCC míràn ṣe bá ìtìjú kúrò nípò Àwọn ẹlẹ́sìn ìbílẹ̀ ń bèèrè owó lọ́wọ́ àwọn Alfa lórí ìsìnkú ẹni tó pokùnso Bayii ni wọn ṣe ṣeto bi awọn eeyan yoo ṣe maa gba ori afara naa nigba ti atunṣe ba n lọ lọwọ: Oṣu mẹta akọkọ yoo wa fun atunṣẹ ọna to lọ si Oworonsoki lati lori afara Third Mainland.
OLUWA fi agbára rẹ̀ kó wa jáde láti Ijipti, pẹlu àwọn iṣẹ́ àmì ati iṣẹ́ ìyanu.
Wọn tẹpa mọṣẹ lati ibẹrẹ idije naa pẹlu ipinnu lati tun gba ife ẹyẹ naa lọdun yii, eyi to pada wa si imuṣẹ fun wọn ni papa iṣere Lyon ni orilẹ-ede France.
Alaboyun naa la gbo pe o jẹ ẹran ara ọlopaa kan ṣugbọn to ni iọ ni wọn pa mọ oun.
OLUWA àwọn ọmọ ogun ní:“Ẹ ronú sí ọ̀rọ̀ yìí kí ẹ pe àwọn obinrin tíí máa ń ṣọ̀fọ̀ wá,ẹ ranṣẹ pe àwọn obinrin tí wọ́n mọ ẹkún sun dáradára;
Baba Ayew, Abedi Pẹlẹ loti gba ami ẹyẹ African player of the Year ti o si gba Ife ẹyẹ Champions League pẹlu ẹgbẹ agbabọọlu Marseille lọdun 1993.
Obasanjo sí Makinde: yàgò fún òṣèlú sọ ọ́ sápò Ajimobi: Mí o lè kí Kọla Balogun kú oríire àyà fí.
 fún àpẹẹrẹ , ọba tàbí olorì kò níyì bí ọba tí wọn kò bá ní ìjọba tiwọn.
Àwọn tí ń hùwà báyìí jẹ̀bi ènìyàn dúdú, wọ́n jẹ̀bi ènìyàn funfun, wọ́n jẹ̀bi àwọn tí kò dúdú tí kò funfun, wọ́n sì ń fi Olódùmarè si ipò tí Òun ìbá fi wi pé ‘Èmi ìbá mọ̀  ki n dá àwọn wọ̀nyí ní ẹranko ki wọ́n máa jẹ ewéko inú igbó kiri, kí àwọn ọdẹ sì máa fi ìbọn wá wọn ká láti ìrandíra wọn.
"Gẹgẹ bi ileeṣẹ redio kan nilu Accra , Joy FM, sọ pe ọkunrin kan to ko nkan ija dani, dunkooko mọ awọn oṣiṣẹ ọfiisi naa to wa nibi ti wọn ti n wo ile naa pe ""oun yoo palẹ wọn mọ ti wọn ba sun mọ oun""."
Oríṣun àwòrán, @Atelewo Aja lo léru je iwe itan arosọ akagbadun lede Yoruba to safihan iwa ibaje awọn agbofinro.
Eyi ni diẹ lara awọn nkan ti ẹ le fojusọna fun l'ọdun 2020.
Ó jẹ́ ìwẹ̀fà onípò gíga kan lábẹ́ Kandake, ọbabinrin Etiopia.
Nítorí náà n óo da èrè iṣẹ́ ọwọ́ rẹ lé ọ lórí.
Awọn Iroyin ti ẹ le nifẹ si Ìtàn tó wà nídi òwe ‘Sebótimọ Ẹlẹ́wà Sàpọ́n’ Ṣẹ gbọ́ nípa Alájọ Ṣómólú, tó ta mọ́tò ra kẹ̀kẹ́?
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìkọlù Benue: Ọ̀dọ́, PFN, CAN tutọ́ sókè lórí ikú olùjọ́sìn 25 Ìgbé 2018 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ọ̀pọ̀ èèyàn ló ti ń késí ìjọba Nàíjíríà láti wá ojútùú sí ìkọlù darandaran Yorùbá ní ikú tó ń pa ojúgbà ẹni, òwe ńlá ló ń pa fún ni, èyí ló mú káwọn ọ̀dọ́ yíká ìpínlẹ̀ Benue fi fọnmú nítorí ìkọlú àwọn darandaran tó rán àwọn olùjọ́sìn ìjọ àgùdà bíi ogún sí ọ̀run ọ̀sán gangan ní ọjọ́ aje.
tí ó wá sọ pé ó ti ṣe ìṣekúṣe, tí ó sì fi bẹ́ẹ̀ sọ ọ́ ní orúkọ burúkú, tí ó bá wí pé, ‘Mo gbé obinrin yìí níyàwó ṣugbọn nígbà tí mo súnmọ́ ọn, n kò bá a nílé.
Ìjọba Máli: Ìbọn àti àdá ni wọn fi pa àwọn Fulani náà ni lagbegbe Mopti.
Lara awọn osere tiata lede Yoruba to gba ami ẹyẹ ni Yewande Famakin, Toyin Abraham ati Funkẹ Akindele, alaye si ree nipa ami ẹyẹ ti wọn gba ati idi ti wọn se yẹ lati gba ami ẹyẹ naa.
Ọba bèèrè lọ́wọ́ obinrin náà, ó sì sọ ohun tí ó ṣẹlẹ̀ fún ọba.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Hospital Wedding: Oṣù kan péré ni Tash fi ṣe ìgbéyàwó pẹ̀lú Simon kó tó kú Ara ọkunrin naa bu mọ asọ, to si sare jade kuro ni sọọsi lati lọ da awọn onibara naa lohun, ti wọn sọ pe awọn wa niwaju sọọbu rẹ.
Ní abúlé, àti ìgbèríko, a lè rí àwọn àgbà tí wọ́n ń gun kẹ̀kẹ́ lọ s'óko tí ọ̀nà bá jìn.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù NNPC: Kyari ṣàlàyé ohun tó fa ẹ̀dínkù iye epo rọ̀bì tí wọ́n ń kó níbùdó ìpọnpo ní Nàìjíríà 8 Owewe 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ọga agba NNPC Mele Kyari ni ijọba apapọ yoo tubọ tẹra mọ gbigbogun ti iwa fayawọ epo rọbi lorilẹede Naijiria.
Kii ṣe iroyin yajoyajo mọ pe gbajumọ oloṣelu ọmọ Ijẹbu ode to n ṣoju ẹkun ila oorun ilu Eko nile aṣofin agba, Sẹnetọ Bayọ Oṣinọwọ ti wọ kaa ilẹ Sugbọn iroyin ibẹ ni pe ninu fidio kan to lu sori ayelujara, ọrọ ti Sẹnetọ Osinowo sọ ninu rẹ da bi ẹni pe o ti ri iran iku rẹ ni.
Nigba ti wọn n kede abajade iwadi wọn nidi tọpinpin ti wọn se lasiko atundi ibo naa, awọn asoju ajọ Eu, orilẹ-ede Amẹrika ati UKmẹtẹẹta naa ni, oniruuru iwa idunkooko mọni, ọyaju awọn tita abuku ẹni lo waye sawọn oludibo.
Gomina tuntun naa nṣeleri lati ṣiṣẹ pẹlu awọn agbofinro lati ṣawari awọn to ṣiṣẹ ibi ṣaaju, idibo ati lasiko idibo ni ipinlẹ Kogi.
ipenija  nla fun awon ẹsọ alaaabo to n
O ni Bukọla Adewọle yii lo fi ye oun pe 'oun ti ba mi ri iṣẹ ti mo nwa ati pe wọn yoo nilo iwe ọmọ ẹgbẹ oṣelu PDP mi, awọnran ilewọ Passport fun iṣẹ naa.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Sergio Ramos fèsì lórí ìfarapa Salah ‘A kò ní ìgbékẹ̀lé mọ́ nínú ọ̀gá ọ́lọ́pàá’ UEFA dá ṣèríà fún asọ́lé Juventus Amọṣa, ninu ọrọ rẹ, Ọgbẹni Ọdẹgbami ni oniruuru nkan lo ṣokunfa bi ọrọ ṣe lọ pẹlu awọn ẹbun ti wọn fun awọn agbabọọlu to pegede lọdun 1996 pupọ eyi to ni kii ṣe ẹbi ijọba.
Ibe Kachikwu ,Mínísítà fún epò rọ̀bì sọ pé òun kò parọ́ ìwé ẹ̀rí
Ṣugbọn láàyè ni yóo fa ẹran tí gègé Asaseli bá mú kalẹ̀ níwájú OLUWA, yóo ṣe ètùtù lórí rẹ̀, yóo sì tú u sílẹ̀, kí ó sá tọ Asaseli lọ ninu aṣálẹ̀.
Gbìyànjú àwọn òwé Yòrúbà yìí wò Pàtàkì June 12 fún Nàíjíríà Iṣẹ́ Kudirat Abiọla ṣì ń fọhùn síbẹ̀, lẹ́yìn ọdún 23 tó papòdà Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Oríṣun àwòrán, EPA Àkọlé àwòrán, Phillip ọkọ Theresa May ati Trump ati aya rẹ jọ ya fọto lẹyin ipade lori ọrọ Hauwei ti China Oríṣun àwòrán, EPA Àkọlé àwòrán, Iwọde waye kaakiri UK bii ti eyi to bẹrẹ ni Trafalgar Square pẹlu ere Trump to n yagbẹ sinu ṣalanga oni goolu Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Omooba Charles ati aya rẹ pẹlu Trump ati aya rẹ jẹ ounjẹ alẹ nile aṣoju Amerika ni Regents Park Oríṣun àwòrán, AFP Àkọlé àwòrán, Obabinrin Elizabeth, Omooba Charles, Trump, Macron, Theresa May atawọn olori orilẹ-ede mii nibi ayẹyẹ D Day to waye Oríṣun àwòrán, Reuters Àkọlé àwòrán, Aarẹ Donald Trump ati Melania n dagbere ni Southampton nibi ti wọn ti wọ Air Force One to n gbe wọn lọ si Ireland BBC News, Yorùbá Ìdí tí ẹ fi le è nígbàagbọ́ nínú ìròyìn BBC Ìlànà Lílò Nípa BBC Òfin Àṣírí Cookies Kàn sí.
Ṣugbọn wọ́n wòye pé a ti fi iṣẹ́ ajíyìnrere fún àwọn aláìkọlà fún mi ṣe, gẹ́gẹ́ bí a ti fún Peteru ní iṣẹ́ ajíyìnrere fún àwọn tí ó kọlà.
Stuart Nixon to jẹ́ alamojuto ibudo igbafẹ ẹranko sọ pe, sise awari agbegbe tawọn ìnàki yii wa jẹ́ aseyọrí ti ko lẹ́gbẹ́.
Ààlà rẹ̀ wá yípo lọ sí apá ìlà oòrùn, títí dé Beti Dagoni, títí dé Sebuluni ati àfonífojì Ifitaeli ní apá àríwá Betemeki ati Neieli.
Ile-ifowopamo agba CBN  so pe, owo orile-ede Nigeria to wa ni ipamo ti to Bilionu merindinladota owo dollars $46 Billion.
00 fun atunse apa kan oju ọna onibeji Benin-Ofusu-Ore-Ajebandele-Shagamu ati N6,000,000,000.
Paapaa julọ, ki lo sọ ọ di ẹni to n mura bi Obinrin lati pa awọn ololufẹ rẹ lẹrin?
ojo a pe, bi a ba si da osu osu a ko!
Iku a pa ẹni a n pè, iku a tun pa ẹni to n pe ni!
Ṣugbọn àwọn amòfin tí wọ́n sọ̀kalẹ̀ wá láti Jerusalẹmu sọ pé, “Ó ní ẹ̀mí Beelisebulu; ati pé nípa agbára olórí àwọn ẹ̀mí èṣù ni ó fi ń lé àwọn ẹ̀mí èṣù jáde.
Ẹgbẹ oselu alatako naa faake kọri lati faramọ pe aarẹ to wa lori oye, Nana Akufo Ado lo jawe olubori ninu ibo naa, eyi to ni o kun fun magomago ati ọpọ aisedeede.
Arabinrin ẹni ọdun mọkanlelọgọrin ti pari ile iwe alakọbẹrẹ rẹ lorilẹ-ede Mexico.
Ṣaaju ni ariyanjiyan ti kọkọ waye lori iye awọn akẹkọọ to poora ni pato, ṣugbọn lẹyin ọjọ meji ni gomina Masari sọ pe nnkan bii ọọdunrun akẹkọọ lo di awati.
Niṣe ni awọn ọmọ Naijiria kan tu jade ti wọn si fi ẹhonu han lọ si awọn ẹka ijọ COZA ni Eko ati Port-Harcourt.
" Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Africa eye: Fàyàwọ̀ igi gẹdú ló ń wáyé ní Gambia àti Senegal O ni ijọba to wa lorilẹede Naijiria bayii ko ni pato ibi to n lọ ati pe gbogbo ilana iṣejọba lo ti fẹ sọ orilẹede Naijiria da bi Ọgba ẹranko.
Ìṣòro púpọ̀ ni yóó wá bí ènìyàn kò bá ní orúkọ.
Ìgbésí ayé rẹ̀ fi hàn ni ohun tí ènìyàn lè fi ọwọ́ ara rẹ̀ ṣe.
Ìyá yóo lòdì sí ọmọ rẹ̀ obinrin, ọmọbinrin yóo lòdì sí ìyá rẹ̀.
Awọn ẹrọ ibanisọrọ awọn agbẹnusọ gomina wa ni pipa.
Wọn ni iwọnba perete ikọlu wọn lasan lo kan n ṣẹlẹ lasiko yii.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Alaafin of Oyo: Kí ni àjọṣepọ̀ tó wà láàrín Aláàfin, àwọn olorì àti àṣà igbá títí lóde Ọ̀yọ̀?
Enahoro ni ẹni akọkọ to pe fun ominira Naijiria ninu ile igbimọ aṣofin lọdun naa lọhun, eyi to mu ki awọn ojugba rẹ nigba naa maa pe e ni Baba orilẹ-ede Naijiria."
Abiṣai ọmọ Seruaya dáhùn pé, “Pípa ni ó yẹ kí á pa Ṣimei nítorí pé ó ṣépè lé ẹni tí OLUWA fi òróró yàn ní ọba.
Ninu ọrọ rẹ, baba Richard, Sola Phillips Gbadebo ni ejo lọwọ ninu iku ọmọ oun, ti awọn si n beere fun idajọ ki ọmọ naa ma ku iku sara lasan.
Kí wọ́n maa rin pọ̀ pẹ̀lú ìbọ́n lẹ́yìn wọ́n ti wọ́n si fi ẹsẹ̀ rín ibi tó jìnnà.
Awọn obi naa wa parọwa si àjọ ọpaa lati mura si iwadii ti wọn n ṣe ki wọn le ri ọmọ naa lasiko.
Oríṣun àwòrán, CHURCH OF SATAN ARCHIVES Ko tan sibẹ o, awọn ọmọ ijọ Satani sọ pe awọn ni ọlọrun ara wọn.
O fikùn pé, asiko wá fún àwa osere lásìkò igbele yìí láti sinmi.
"Oríṣun àwòrán, Femi Adesina Facebook ""Ijọba ya biliọnu mẹrin naira, ti wọn si ba owo naa ninu apo asunwọn banki fun ileesẹ adani kan, bi o tilẹ jẹ pe orukọ ijọba ipinlẹ Bauch ni wsn fi ya owo naa."
10 Ọ̀wàrà 2019 Oríṣun àwòrán, @others Àkọlé àwòrán, Owo ti a ba ri yii a ran wa lọwọ lati ṣe nkan fawọn ara ilu Ṣé kí Nàìjíríà dín iye àwọn Sẹ́nétọ̀ tó ń ṣojú wọn kù ni tabi ki a kuku ma dibo yan wọn mọ ni?
n se olu ilu ipinle Borno.
Cavani dèrò Man United, Arsenal bínú ra Partey ní £45m, Walcott padà sí ẹsẹ àárọ̀ Wọ́n kéré sí nọ́mbà, Guardiola jẹ́wọ́ ọ̀gá fún Arteta Salah gbá góòlù ọgọ́rùn ún wọlé, àyẹ̀wò ìgbàlódé VAR d'òkúta sí gààrí Liverpool Cristiano Ronaldo ti fara kásá àrùn Coronavirus Oríṣun àwòrán, @NGSuperEagles Ifẹsẹwọnsẹ naa yoo waye lọjọ kẹtala, oṣu kọkanla, ọdun 2020, lẹyin ọjọ ti iburawọle gomina Obaseki fun saa keji gẹgẹ bii gomina.
Udoma so pe, awon eka aladani ni igbekele ninu igberu eto oro-aje ati ilana amugberu, ati ilana isakoso Aare Buhari.
O ni ''esi ti wọn ba mu jade ninu iwadi wọn ni yoo sọ ohun ti a o ṣe lori ọrọ naa.
Awọn iroyin ti ẹ le nifẹ̀ si: 'Naijiria ko laṣeyọri lori gbigbogun t'iwa ijẹkujẹ' Rufai Imam di adajọ agba ile ẹjọ Sharia ‘A ko mọ ibi ti Nnamdi Kanu wa’ Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí 2 sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
orile ede Naijiria lati mu  eto idagbasoke
Ki ni afujusun ati anfani Vission 2050 yii?
Ṣé ó lè yẹ majẹmu náà kí ó sì bọ́ ninu rẹ̀?
bẹrẹ lati maa fori-kori pẹlu  egbe awon
" Ṣugbọn otitọ ni wipe ọpọlọpọ awọn ọmọ Italy yoo fẹ lati ri pe ki awọn eniyan lọ kuro nilu wọn.
Ko fẹ ẹ si eyi to sajoji si mi ninu gbogbo ilana antẹẹle lori coronavirus.
4m Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Spanish flu and other pandemic: Ẹ fọkàn balẹ̀, àwọn àjàkálẹ̀ àrùn kan rèé to burú ju Coronavirus lọ30 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Kurunmi: Akọni Ààrẹ Ọ̀nà Kakanfo tó pàdánù ọmọ márùn-ún to bí sínú ogun Ìjàyè27 Ìgbé 2020 Adeola Smart and Malivehood Wedding: Diamond kún ara aṣọ ìyàwó, Cake jẹ́ alájá 1611 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 4:07 Fídíò, Nigeria movie industry: Àgbà òṣèré, Lere Paimo ní àìgbọràn ló ń da ọ̀pọ̀lọpọ̀ àwọn òṣèrè sinimá láàmú, Duration 4,0711 Ọ̀wàrà 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Kiko janduku wọ ipinlẹ Ekiti - PDP ni ẹgbẹ-lẹgbẹ awọn janduku lo ti wọ ipinlẹ Ekiti lati awọn ipinlẹ to mule ti wọn bii Ọsun, Ondo ati Kogi, ti wọn yoo si lo wọn lati maa dunkoko mọ awọn eeyan ipinlẹ Ekiti.
ṣugbọn nítorí ìfẹ́ tí ó wà láàrin wa, ẹ̀bẹ̀ ni n óo kúkú bẹ̀.
Àwọn tí wọn ń tọ́jú agbo ẹlẹ́dẹ̀ bá sá kúrò níbẹ̀, wọ́n lọ sí ààrin ìlú, wọ́n lọ ròyìn gbogbo ohun tí ó ṣẹlẹ̀, ati ohun tí ó ṣẹlẹ̀ sí àwọn tí ó ní ẹ̀mí èṣù.
Ó bi ekinni pé, ‘Èló ni o jẹ ọ̀gá mi?
Pẹlu sùúrù, a lè yí aláṣẹ lọ́kàn padaọ̀rọ̀ pẹ̀lẹ́ sì lè fọ́ eegun.
Nítorí wọ́n ti ṣe àgbèrè, wọ́n sì ti paniyan; wọ́n ṣe àgbèrè ẹ̀sìn lọ́dọ̀ àwọn oriṣa wọn, wọ́n sì ti pa àwọn ọmọ wọn ọkunrin tí wọ́n bí fún mi, bọ oriṣa wọn.
Ṣùgbọ́n, a gbódò mọ̀ wí pé awọn ànfàní àti awọn ìṣòro wọ̀nyí ti wà láti ìgbà pípé wá.
  sùgbón nì tí awon ara àdúgbò yìí eko nì gbogbo awaon obìnrin won màá ń tà ."
N kò mọ OLUWA ọ̀hún, ati pé n kò tilẹ̀ lè gbà rárá pé kí àwọn ọmọ Israẹli lọ.
NBC se ikilọ NBC fọwọ́ sí ìdásílẹ̀ ilé iṣẹ́ Fulani Radio 2019 Elections: NBC na Channels TV àti ilé iṣẹ́ ìròyìn 44 ní pàsán NBC ti iléesẹ́ ìgbóhùnsáfẹ́fẹ́ Èkìtì pa Ninu idajọ rẹ lori ọrọ naa ni ọjọ Ẹti, Adajọ Inyang Ekwo ni ki gbogbo awọn ti ọrọ kan pada si bi ọrọ ṣe ri ni ọgbọn ọjọ, oṣu karun un.
Nibe ni adájọ́ Hamma Akawu Barka, ni ilé ẹja gíga tó kọ́ka dá ẹja náà ko ṣe dáada tó pàápàá jùlọ̀ ni ti ìhà, Etteidung Ebong àti ìlú Ikot Akpan.
Aṣofin Adebisi Yusuff ti o n ṣoju fun ẹkun Idibo
Ó f'akọyọ nínú ẹ̀kọ́ọ rẹ̀ àmọ́ ó bá ẹbíi rẹ̀ ní gbólóhùn asọ̀ nítorí olólùfẹ́ẹ rẹ̀.
orile ede Naijiria pe ijoba aare Muhammadu Buhari yẹ fun Ọdun mẹrin miiran, nitori isẹ gudu gudu meje, yaya yaya mefa, ti o ti gbe
Àkọlé àwòrán, Awọn ọmọ Yoruba ni Austria EU: Òfo ọjọ́ kejì ọjà ni ètò ìdìbò 2019 ní Naijiria Ṣé ẹ̀mí Super Falcons gbé e lálẹ́ òní pẹ̀lú France?
Bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé mo wí fún olódodo pé yóo yè, bí ó bá gbójú lé òdodo ara rẹ̀, tí ó bá ń dẹ́ṣẹ̀, n kò ní ranti ọ̀kankan ninu ìwà òdodo rẹ̀, yóo kú nítorí ẹ̀ṣẹ̀ tí ó dá.
Poly Ibadan: Lóòtọ́ ni a dáná sún fóònù àwọn akẹ́kọ̀ọ́ tó ṣe màgòmágó nínú ìdánwò
Ó bá búra fún un pé, “N óo fún ọ ní ohunkohun tí o bá bèèrè, kì báà ṣe ìdajì ìjọba mi.
Bí òtútù yìnyín nígbà ìkórè,bẹ́ẹ̀ ni olóòótọ́ iranṣẹ jẹ́, sí àwọn tí ó rán an,a máa fi ọkàn àwọn oluwa rẹ̀ balẹ̀.
 Òrìsà tí a mo oúnje rè sí èkuru .
Oríṣun àwòrán, Twitter Ọgbẹni Wael Jerro polowo Busari Peace pẹlu iwe irina rẹ ọmọ ipinlẹ Oyo loju opo Facebook rẹ ni oṣu diẹ ṣẹyin.
Awọn nkan miran ti ẹ ni lati mọ loni CBN ni igbakeji gomina tuntun meji Amofin agba kan lorilẹẹde Naijiria ni ti atunse ko ba ba ofin ile naa, iwọnba ni ijiya awọn oni jẹgudu-jẹra yoo maa jẹ Acraf Hakimi ni ipalara ninu igbaradi Gbọ iroyin iṣẹju kan BBC Fidio wa fun toni Aṣofin Mamora sọ wipe o yẹ ki wọn ṣe ayẹwo owo ti awọn to n ṣe ijọba n gba latori awọn aṣofin titi to fi de ori awọn adajọ.
mimo fun awon ololufe iko Atletico Madrid pelu
N ó mú ìrẹ Alákọ̀wé dé ibi tí wọ́n ti ń jẹ ata gidi nílẹ̀ yìí, ìwọ yíò sì gba Ọlọ́run l’ọ́gàá!
Usi ni baba Serahaya, Serahaya ló bí Meraiotu, 
Oríṣun àwòrán, @NLCHQ_ABUJA O ni ibanujẹ ọkan lo jẹ fun oun wi pe, awọn adari NLC gbọ si ijọba lẹnu nitori awọn eniyan ti mura silẹ lati bẹrẹ iyanṣẹlodi tako ọwọngogo naa.
 Minista fun eto ilera, Ojogbon Isaac Adewole lo pase yii lasiko to m ba awon oniroyin soro nile ijoba l’Abuja leyin ipade awon igbimo amusese eyi ti Adele aare, ojogbon Yemi Osinbajo se alaga fun.
Coronavirus pandemic numbers:Ṣé ìrètí wà pé coronavirus yóò dínkù lásìkò ooru?
“Bí ó bá jẹ́ pé ẹyẹ ni eniyan bá fẹ́ fi rú ẹbọ sísun, kí ó mú àdàbà tabi ọmọ ẹyẹlé wá.
Ninu osu keji ọdun 2018 niArisekọla ko ba pe ẹni ọdun mẹtalelaadọrin.
Láàrin ilẹ̀ ẹ̀yà Bẹnjamini, wọ́n fún àwọn ọmọ Lefi ní àwọn ìlú wọnyi pẹlu pápá ìdaran tí ó wà ní àyíká wọn: Gibeoni, Geba, 
Ìbò 3,498 yì ohùn Ifá padà nínú ìdìbò Ọṣun INEC: Ètò ìdìbò gómìnà Ọṣun ló dárajù nínú gbogbo èyí tá a ti ṣe Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Adeleke fọhùn, 'èmi ni gómìnà tí wọ́n dìbò yàn' Ninu ọrọ to ba BBC News Yoruba sọ, agbẹnusọ fun oludije ẹgbẹ PDP, Ọgbẹni Rasheed ṣalaye wi pe awọn ti gba aawẹ ọlọjọ mẹta ati meje 'lati fi wa ojurere Ọlọrun' lẹyin ti awọn ti ṣe gbogbo nkan to yẹ gẹgẹ bi eniyan.
Ààrin ibi tí wọ́n ti ja ìjà yìí kò ju nǹkan bí ìdajì sarè oko kan lọ.
Ṣugbọn ero awọn ọmọ Naijiria ṣọtọtọ lori agbekalẹ igbimọ vission 2050 naa, bi awọn kan ṣe n sọ pe ki Buhari kọkọ ṣe awọn nnka to ṣeleri lasiko to n ṣe ipolobgo ibo, lawọn miran n sọ pe awọn yoo maa wo ibi ti ọrọ ọhun yoo ja si.
Tunde Idiagbon, ọ̀gágun kògbagbẹ̀rẹ́ tó ní ẹ̀ẹ̀kan lóṣù ló yẹ kí ológun máa rẹ́rìín Àwọn òṣèré Nollywood tí wọn ò sí lóri amóhùmáwòrán mọ́ Emir Kano ti balẹ̀ sí Ilorin, ìlú ìyá rẹ̀ fún àyẹ̀wò ọlọ́jọ́ mẹ́ta Aráyé ẹ gbà mí, nǹkan ń ṣe mí, èyí tó ju àìsàn lọ - Kanran Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí NUJ ìpínlẹ Oyo bà àwọn ọmọ ẹgbẹ́ tó lọ ìpàdé tí Femi Fani Kayode pè ní Ibadan wí7 Owewe 2020 Fídíò, Akomolede: Bolaji Faleke ni Olùkọ́ tó ń kọ́ wa ní àṣà oge ṣiṣe lórí BBC Yorùbá1 Owewe 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 3 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 5 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Ni orilẹede naa to jẹ musulumi, wọn maa n ṣe eyi nipa gige idọati labia kuro.
Jesu sọ fún wọn pé, “Ẹ máa tẹ̀lé mi, kì í ṣe ẹja ni ẹ óo máa pamọ́, eniyan ni ẹ óo máa fà wá.
Ẹranko abìjàwàrà tí kò ṣe é gbeńa wo ojú rẹ̀ ni Àmọ̀tẹ́kùn - Onímọ̀ A ṣetán láti gba obìnrin tó wà lóko ẹrú ní Lebanon sílẹ̀ - Ìjọba Kwara Ọlọ́pàá Uganda rí ohun ìpara olóró nínú ‘baby’ tí ẹnìkan pọ́n sẹ́yìn bí ọmọ Lord Lucifer ni ó kọkọ ni ènìyàn mílíọnù kan to wòó lóri Youtube- Yekini Bakare Ni kete to si ti fun wọn laye lati ṣe ẹlẹri pe ijoko na bẹrẹ ni adajọ Muhammad paṣẹ pe ki wọn so igbẹjọ naa rọ na.
Ìwọ ọ̀lẹ, tọ èèrùn lọ,ṣàkíyèsí ìṣe rẹ̀, kí o sì kọ́gbọ́n.
gbọ́ adura ati ẹ̀bẹ̀ wọn láti ọ̀run wá, kí o sì tì wọ́n lẹ́yìn.
Ọkunrin níí máa ń fún àwọn aṣẹ́wó ní ẹ̀bùn, ṣugbọn ní tìrẹ, ìwọ ni ò ń fún àwọn olólùfẹ́ rẹ lẹ́bùn.
O ni idi ree ti awọn osisẹ awọn fi tẹle lọ sile, tawọn si mu baba rẹ wa si olu ileesẹ NSCDC ni ọjọ Aje, lati gba ọrọ ẹnu rẹ silẹ.
Bẹẹ na ni wọn tun na ika abuku si ileeẹṣẹ ọhun lataari bi ko ṣe le ṣafihan awọn awọn ohun to ṣe pataki lẹẹkeji fun awọn onworan to wa nile.
Nínú ìtàn náà, wọ́n ṣèṣì fẹ̀sùn olè kan àwọn olórin Roma méjì, orí ni ó kó wọn yọ lọ́wọ́ ìjìyà láìsí ìdájọ́.
Nípa igbagbọ ni ó fi ṣe Àjọ̀dún Ìrékọjá ati ètò láti fi ẹ̀jẹ̀ ra ara ìlẹ̀kùn, kí angẹli tí ń pa àwọn àkọ́bí ọmọ àwọn ará Ijipti má baà fọwọ́ kan ọmọ àwọn eniyan Israẹli.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù #RevolutionNow: Ọlọ́pàá ní ẹ̀sùn ìdìtẹ̀ gbàjọba ni ìfẹ̀hónú ọ̀hún 3 Ògún 2019 Oríṣun àwòrán, Facebook/Nigeria Police Force Agbẹdọ!
Abala arun naa to lewu Awọn onimọ safojusun pe ida mẹfa ninu ọgọrun ni arun yi yoo sakoba fun ilera wọn gaan.
Ẹgbẹ́ agbésùnmọ̀mí IS yọ Al-Barnawi ọmọ olùdásílẹ̀ Boko Haram nípò gẹ́gẹ́ bíi adarí ISWAP
Ajọ SERAP bu ẹnu ẹtẹ lu owo ifẹhinti f'awọn oloselu
Awọn onijibiti ‘hackers’ ti fi imọ ẹrọ ‘spy software’ sori ẹrọ ilewọ awọn eniyan, eleyii ti wọn fi lee wo gbogbo ohun to wa lori ẹrọ ilewọ naa.
Nǹkan mẹ́sàn án tí Mùsùlùmí gbọdọ̀ ṣe nínú oṣù Dhual- Hijjah Wo bí ètò ìsìnkú Tolulope Arotile ṣe lọ nílùú Abuja Ilé ẹjọ́ wọ́gilé ìgbẹ́jọ́ Olalekan 'Woodberry' Pọnle Donald Trump ti gbà pé Coronavirus yóò burú jáì kí ǹkan tó dára fún Amẹ́ríkà Agbẹnusọ fun aarẹ Buhari, Fẹmi Adesina ṣalaye pe ko si ẹni to tii fi ẹsun ọdaran kan Magu, iwadii lasan lo n waye lori bi nnkan ṣe n lọ si ni ajọ to n gbogun ti iwa jẹgudujẹra lorilẹede Naijiria, EFCC.
4bn ní rìbá táwọn agbẹjọ́rò fún adájọ́ láàrín ọdún mẹ́ta - ICPC Ìdí rèé tí ẹ̀mí mi kò fi bọ́ sínú ìdìtẹ̀ gbàjọba tó pa Muritala Muhammed - Obasanjo Wọ́n gún ọkùnrin kan lọ́bẹ pa torí ó tako yínyin báńgà sínú Mọ́ṣálásí Àwọn àṣà tó milẹ̀ lọ́dún 2020 pẹ̀lú ìtàn lórí bí wọ́n ṣe jáde Kò bá wù mí kí n padà sí àwọ̀ tí Ọlọ́run dá mi, wàhálà ni ara bíbó - Bobrisky N kò tíì pa ọ̀rọ̀ ìfẹ́ tì, bí mo tilẹ̀ ti kúrò nílé ọkọ - Mercy Aigbe O sọ pe ni ileegbe awọn akẹkọọ agba naa, ni wọn ti bọ ṣokoto penpe oun, ti wọn si ki ika ọwọ ati ẹsẹ wọn sinu iho idi oun.
Gẹgẹ bi awọn ọmọ Naijiria ṣe wa n reti ibi ti ilẹkẹ ipo naa yoo jasi laarin ẹya gboogi mẹta to wa lorilẹede Naijiria, awọn tọrọ kan ti bẹrẹ si ni gbe igbesẹ.
Owo oṣu naa yoo jẹ laarin N30,000 si N50,000 owo Naijiria.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Toma Unu: Ọmọbìnrin tó ń fi ẹsẹ̀ rẹ̀ ya àwọran nítori pe ó ni ìpènija ọpọlọ ''Nigba ti nkan ba dara fun mi tan, mo ni ireti lati tẹsiwaju eto ẹkọ mi.
itoju naa ni pe, lati igba ti won ti gbe Joy wa sile iwosan ni oga rẹ to ni
Damasus, Omotola, Ezekwesili, Funmi Iyanda dá sí ẹ̀sùn ìfipábánilòpọ̀ Fatoyinbo Donald Trump kéde pé ìpàdé òun pẹ̀lú Kim já si rere Ọkọ mi kò le f'ipá bá ẹnikẹ́ni lò pọ̀ láíláí - Modele Fatoyinbo Ọlọ́pàá ìpínlẹ̀ kọ́ ní ojútùú ìṣòro ìjínigbé ilẹ̀ Yoruba - Onímọ̀ ọ̀rọ̀ ààbò Kete ti awọn oṣiṣẹ ileeṣẹ ijọba apapọ de si Benue pẹlu erọ katakata lati wa bẹrẹ iṣẹ kikọ Ruga agọ Fulani lo ti ke gbajare pe oun ko faramọ.
Wọ́n pọ̀ ju irun orí mi lọ,ọkàn mi ti dàrú.
4m lórí báíró, ₦46m lórí ìwé, ₦56m fún tónà
EFCC: Àwọn ọba aládé àti olóṣèlú ṣé àpapín owó ìrànwọ́ N2bn ní Kwara Ibadan NURTW: Àwọn ti Auxilliary àtàwọn tí Ajanaku gangan ló ń dàgboro rú Ipele kan náà kó ní Yorùbá àti ẹgbẹ́ darandaran Miyetti Allah wà- Afẹnifẹre Ilé alájà méjì wó lu ọmọ mẹ́rin ni Bariga 8.
Wọn bẹrẹ si ni sọ pe''N gbọ na, bawo ni o se se?
Bí ó ti ń sọ̀rọ̀ lọ́wọ́ ni ọba dé, ó ní, “Láti ọ̀dọ̀ OLUWA ni ibi yìí ti wá, kí ló dé tí n óo fi tún máa dúró de OLUWA fún ìrànlọ́wọ́?
Nígbà tí o rán ẹ̀mí rẹ jáde,wọ́n di ẹ̀dá alààyè,o sì sọ orí ilẹ̀ di ọ̀tun.
“Ranti gbogbo ìwà ibi wọn,kí o sì jẹ wọ́n níyà;bí o ti jẹ mí níyà,nítorí gbogbo ẹ̀ṣẹ̀ mi.
 Orile ede Naijiria tako iwa ibajẹ yii , a si baa yin
Pilatu bi Jesu pé, “Ṣé ìwọ ni ọba àwọn Juu?
Amaju Pinnick di ààrẹ àjọ NFF tuntun Victor Moses, Oshoala gba ami ẹyẹ El-Zakzaky: Arúfin ni ijọba Muhammadu Buhari gan-an - Ladoja Afọnja, ẹni tó finú wénú ní Ilọrin, àmọ́ tó jẹ iwọSamuel Okwaraji: Ó pé ọgbọ̀n ọdún tí lónìí ti akọni àgbábọ̀ọ̀lù papo dà Ó lọ sí fasiti ni Rome ni orilẹ̀-èdè Italy níbi to ti gba oye nínú ìmọ̀ òfin bàkàn náà lo tún gba oye ipele kejì sùgbọ́n kò lo èyí lẹ́yìn to pari ẹ̀kọ́ rẹ̀.
Arabinrin ọmọ Côte d'Ivoire sọ fun Adeola pe ninu iṣẹ naa ni ẹni to ra a lẹru yoo fun un ni miliọnu meji Cefas, amọ o kọkọ kọ jalẹ, ko to di wi pe o gba lẹyin ti wọn ran an leti pe wọn ti mulẹ.
Wọ́n fẹ̀sùn kan igbákejì gómìnà ìpínlẹ̀ Ondo lórí ayédèrú ìwé ìdìbò níbi ìdìbò abẹ́lé PDP tó ń lọ lọ́wọ́ Iyawo ọsingin yii n dupẹ lọwọ awọn eeyan latoori Iku Baba yeye, Alaafin Oyo, Ọba Lamidi titi dori awọn oṣiṣẹ rẹ to n ba a gbe.
Wọn ni afojusun àwọn ni lati ma a gbéjà àwọn alailagbara láwùjọ.
Ibadan clash: Rògbòdìyàn bẹ́ sílẹ̀ láàrin àwọn ọlọ́kadà àti àwọn òṣìṣẹ́ ọgbà ẹ̀wọ̀n ní Ibadan
Ninu ẹ̀yà yìí ẹ̀wẹ̀, kò sí ẹnikẹ́ni tí ó ní nǹkankan ṣe pẹlu ẹbọ rírú.
Iléeṣẹ́ Ọlọ́pàá ṣetán láti bẹ̀rẹ̀ ètò ìgbanisíṣẹ́ lákọ̀tun Ni ọpọ igba ni ikọ ọmọogun Naijiria ma n fi lede wi pe awọn ti ṣẹgun ikọ Boko Haram ti awọn si ti rẹyin wọn.
O ti fẹ obinrin naa lati ọdun mẹta ti ko sì sí ọmọ kankan laarin wọn.
Ó ń lọ sókè sódò láàrin wọn bí ahọ́n iná.
"Iwa rẹ n ko abuku ba ilu Iwo ati orilẹede wa Naijiria lapapọ, ti Ọba ba se bo se yẹ, ko si ẹni ti yoo sọrọ si, amọ ti Ọba ko ba bọwọ fawọn ijoye rẹ ati agbaagba ilu, ki lẹ ro pe yoo sẹlẹ gan.
Lẹ́yìn náà, àwọn eniyan lọ sí ilé oriṣa Baali, wọ́n wó o, wọ́n sì wó àwọn pẹpẹ rẹ̀ ati àwọn ère rẹ̀ lulẹ̀.
Iṣẹ́ fẹ́ bọ́ lọ́wọ́ ọlọ́pàá tó gba N100k lọ́wọ́ awakọ̀ tó gbaOne way"" l'Eko Ìjọba Naijiria faraya nínú lẹ́tà tó kọ sí CNN lórí ìwádìí rẹ̀ nípa ìṣẹ̀lẹ̀ Lekki Toll Gate Gbenga Fadeyi ṣe alaye pe lootọ ni ifanfa waye ni agbegbe naa, ""ṣugbọn awọn ọlọpaa ati ẹṣọ aabo mii ti yọju sibẹ lati le mu ki alafia j'ọba""."
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ọ̀pọ̀ àwọn obirìn ló ti di onímọ̀ nípa ọ̀nà ìmọ̀-ẹ́rọ, tí wọn sì tí gbé ìdíwọ́ òfin tó de ìṣẹ́yún tì sẹ́gbẹ̀ kan.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ghana Election Special Voters list 2020: Báyìí ni àwn òṣìṣẹ́ tó dá yàts ṣe ní ọjọ́ ìdìbò tiwọn lọ́tọ̀ 1 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Awọn ọlọpaa, ologun, oniroyin atawọn to n wa ọkọ agboku ni orilẹede Ghana ti wọn jẹ oṣiṣẹ akanṣe ti n dibo lonii ṣaaju ọjọ keje oṣu kejila ti idibo gangan yoo waye.
Awọn akẹkọọ meji ọhun, Joseph Okunofua ati Kehinde Dada jade laye lẹyin ti iroyin sọ pe, ọta ibọn ba wọn lasiko iwọde awọn akẹkọọ ati awọn olugbe ilu naa ni ọjọ Iṣẹgun ati Ọjọru.
Iko agbaboolu Nigeria, Senegal, Burkina Faso, Ghana ati Niger Republic ni yoo kopa fun idije naa ti yoo waye niluu Lome, ki won o to lo darapo mo iko akegbe won lorile-ede Tanzania.
Mose dá wọn lóhùn pé, “Kí ló dé tí ẹ fi ń ṣe àìgbọràn sí àṣẹ OLUWA nisinsinyii?
À ń waasu fun yín pé kí ẹ yipada kúrò ninu àwọn ohun asán wọnyi, kí ẹ sin Ọlọrun alààyè, ẹni tí ó dá ọ̀run ati ayé, ati òkun ati ohun gbogbo tí ó wà ninu wọn.
Awọn iroyin ti ẹ le nifẹ̀ si: 'Esi Jamb ko nii jade lẹsẹkẹsẹ' Yomi Lanso wipe ka jọ gbadun laye Ope Aiyeọla: Nkan to pa emi ati Baba Suwe pọ Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Rivers court and Anti Piracy 2019 law: Ilé ẹjọ́ ju olè orí omi mẹ́ta sí ẹ̀wọ̀n, ó tún ní kí wọ́n san 60 miliọ̀nù
Ninu fidio to gba ori ayelujara, abẹ aṣọ ibora ni awọn mejeeji naa wa, to si jẹ pe bi ara wọn ṣe n lọ si ọtun, ati osi, lo fihan pe 'wọn n dan nkan wo'.
Nítorí pé olóore ni ọ́, OLUWA,o máa ń dárí jini;ìfẹ́ rẹ tí kì í yẹ̀ sì pọ̀ sí gbogbo àwọn tí ń ké pè ọ́.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Idajọ ileẹjọ lee mu ekuru gba ẹyin ni ifanfa fun ajọ EFCC Bakanna o ni agbeyẹwo iye ti a maa n gbe le owo iṣẹ amayedẹrun ni Naijiria ti wa di dandan bayii.
Aare Buhari so pe, eto ati ilana isakoso ijoba oun lati bi odun meta bayii, ti se adinku owo ori oja, mu igberu ba irina oko, oju-irin, ina-mona-mona, ni eyi ti o je ki awon oludokowo yan orile-ede Naijiria laayo fun eto idokowo.
 a ó fi ẹnu ba ohun èlò orin fújì , àwọn ọ ̀ kọrin fújì ìṣàkóso àti kókó tí fújì ń dálé lórí .
Pupọ lara awọn to fi erongba wọn lede loju opo Twitter lo n bu ẹnu atẹ lu gomina naa lori iha to kọ si ọrọ Coronavirus ni ipinlẹ Kogi.
Ibi tóun pàápàá ń gbé jìnnà réré sí ìletò tó ń kiri wá.
Ajagun feyinti  Dambazau tun so pe “Ijoba fe ki awon omo orile ede Naijiria lo gbogbo awon iwa rere ti won ti ko lasiko osu mimo  naa , ni eyi ti won yoo se fi ife ati  ifarajin  han si enikeji won.
Oríṣun àwòrán, others Ejiogbe fikùn pé, kii se àwọn ọmọ ẹgbẹ́ àwọn, NURTW, lo ń bá ja, àmọ́ ó ni àwọn ọmọ ẹgbẹ́ kan, to ṣe apejuwe wọn bíi ọdalẹ tí kò ní sùúrù, tí wọn lọ bá Auxiliary ṣe Alakoso gareji, ní wọn dijọ ń bá ara wọn jà.
"Nigba miran ẹwẹ, papa nile adulawọ ti iya eeyan mọ pe ọmọ rẹ obinri ti ṣegbeyawo, irufẹ obinrin bẹ ko ni fẹ kokuro nile ọkọ rẹ.
Lẹ́yìn náà, alufaa yóo mú obinrin náà wá siwaju OLUWA, yóo tú irun orí obinrin náà, yóo sì gbé ẹbọ ìrántí lé e lọ́wọ́, tíí ṣe ẹbọ ohun jíjẹ ti owú.
Ọgbẹni Akorede ṣalaye pe, ifẹ ni iyawo oun ni to fi fẹ oun, kii ṣe owo lo wo, to fi duro ti oun di oni.
Kí n má dàgbà òṣì, àgbà bí ọmọdé
Ó pín àwọn ọmọ ogun rẹ̀ sí ìsọ̀rí-ìsọ̀rí ní òru ọjọ́ náà.
Lagos-Ibadan Expressway: Ọ̀pá afẹ́fẹ́ gáàsì bẹ́ lópópónà márosẹ̀ Ibadan sí Eko
Awuyewuye lori ara tawọn gomina n fi owo inu aṣuwọn ajọni ijọba ipinlẹ ati ibilẹ lorilẹede Naijiria kii ṣe ajeji mọ fun ọjọ pipẹ, to bẹẹ gẹẹ ti ajọ to n nmojuto iwaadi to da lori iṣuna lorilẹede Naijiria, NFIU ti fi ṣapejuwe rẹ gẹgẹ bi ọpa iwa ijẹkujẹ lorilẹede Naijiria.
Alaga ipolongo fun ọdun Ekimoogun ti 2018, Alhaji Yemi Adewetan, labẹ asẹ Osemawe ti ilu Ondo, ti ba BBC Yoruba sọrọ lori igbese ti ko i tii waye naa lati ọdun mọkanlelọgbọn ti ọdun Ekimogun ti bẹrẹ.
Oríṣun àwòrán, @jidesanwoolu Bakan naa lo ni Tinubu salaye pe oun ko mọwọ mẹsẹ lori bi awọn ologun se de bode Lekki lati doju ibọn kọ awọn ọdọ.
Dariusi ọba pàṣẹ pé kí wọ́n wádìí fínnífínní ninu àwọn ìwé àkọsílẹ̀ tí ó wà ní ààfin, ní ilẹ̀ Babiloni.
Mo mú kí apanirun gbógun ti àwọn ìyá àwọn ọdọmọkunrin ní ọ̀sán gangan.
Ojọgbọn Yemi Osinbajo ṣe abẹwo si Amerika fun apero itẹsiwaju ajọṣepọ Naijiria ati Amẹrika.
Okan gbogi lara afojusun ile-ise olopaa bayii ni, lati ri da ju pa iwa janduku, obaye je ati dida alaafia awon ara-ilu laamu di ohun igbagbe patapata.
Ti ẹni to n jẹjọ ba salọ, awọn naa yoo salọ.
tí ẹ kò bá pa majẹmu tí ó pa láṣẹ fun yín mọ́.
Àwọn eniyan pàtẹ́wọ́, wọ́n sì kígbe pé, “Kabiyesi, kí ẹ̀mí ọba ó gùn!
Sugbọn lati ọdun diẹ sẹyin ni ayipada ti n de ba awọn ofin naa, ti awọn obinrin si ti n ni oreọfe lati dawọle awọn ohun naa bi wiwa ọkọ, kikopa ninu idibo, eti bẹbẹ lọ.
Lizzy Anjorin sun ẹkún ìyàwó, èèyàn kan fún un lẹ́bùn aṣọ funfun láti mọ ìbálé rẹ̀ Pásítọ̀ ìjọ Sotitobire padà yọjú sílé ẹjọ́ lónìí, àbọ̀o rèé.
Elisha Abbo: Àwọn alátakò mi nínú òsèlú ló gbé fídíò mi síta
Àwọn kòkòrò wọ̀n-ọnnì rí i pé ibẹ̀ dára gẹ́gẹ́ bí ilé fún àwọn.
Ọ̀gá àjọ náà Olufemi Oke-Osanyintolu sàlàyé pé àwọn ìjàmbá tó ṣẹlẹ̀ níbẹ tí òun sì le sàlàyé lọ́wọ́lọ́wọ́ okú ènìyàn mẹ́jọ ní àwọn ti rí báyìí.
O  tesiwaju ninu oro re wi pe orile-ede Naijiria kun fun awon ohun alumoni inu ile ,eyi ti o ye ki awon omo orile-ede yii maa dupe lowo olorun fun awon ibukun yanturu yii,ki won si lo o lati mu idagbasoke deba orile-ede Naijiria.
Bakan naa ni Idowu Bukunmi ni ti ẹ sọ pe ọrọ owo ni.
“Ọdún mẹfa ni kí o fi máa fúnrúgbìn sórí ilẹ̀ rẹ kí o sì fi máa kórè àwọn ohun ọ̀gbìn inú rẹ̀.
Gbogb ilé ounjẹ láyíká, ilé iṣk ìjọba yóò sì wà ni títì pa, nítorí náà ki àwọn òṣìṣẹ́ máa gbe oúnjẹ wá láti ilé.
Mi o mikan pe yoo jare yoo si bori ninu ẹjọ yii."
Josaya bí Jekonaya ati àwọn arakunrin rẹ̀ ní àkókò tí wọn kó àwọn ọmọ Israẹli lẹ́rú lọ sí Babiloni.
L'ọjọ kẹta oṣu kẹfa ọdun 2020 ni awọn olubi ẹda kan ṣekupa Arabinrin Barakat Bello, lẹyin ti wọn fi ipa baa lopọ tan ni agbegbe Akinyẹle niluu Ibadan.
Agbẹnusọ ajọ ọlọpaa naa sọ wipe ijakadi laarin awọn agbenipa naa ati ajọ SARS ja si iku ọkan lara wọn, ti awọn meje miran si farapa yẹlẹyẹlẹ nigba ti wọn na papa bo'ra.
 a lè yígbà yígbà kí a wádìí lítítésọ ̀ fún àríyànjiyàn lórí mọ ́ fíìmù , sùgbọ ́ n léyìn gbogbo atótónu yìí , kí ni a rí ?
"Àwọn tó jí ọmọ mi gbé nílé ìjọsìn ní ń kò gbọdọ̀ wa tàbí kí ẹ̀mí mi lọ si Ẹ dẹ́kun àbùkù tẹ fi ń kan Nàíjíríà, ẹ fi Sowore sílẹ̀ láhàmọ́- Soyinka ""Aug 2018 ni ìgbìmọ̀ aláṣẹ APC ti ṣe ìpàdé kẹ́yìn, Oshiomole ti kùnà"" Òbítíbitì ẹ̀gbin ti sọ ìlú Ibadan di ààtàn - Aráàlú figbe bọnu Kini idi ti awọn alaboyun fi n ku ninu odo wọnyii?"
Bo tile je Aminu Tambuwal ko
#U20WC: Flying Eagles fìyà ṣínu ààwẹ̀ lórílẹ́èdè Poland 'À ń bẹ Ààrẹ Buhari kó pèsè ààbò fún àwa ọ̀dọ́bìnrin' Kí ló ṣe ikú pa Adewura Latifat Bello lẹ́yìn ọ̀sẹ̀ méjì tí wọ́n ń wá a?
Ìdílé márùn-ún tó gbajúmọ̀ fún òwò ẹrú nílẹ̀ Yorùbá Ẹgbẹ́ òṣèlú APC ti yan Abiola Ajimobi gẹgẹ bí Alága ẹgbẹ́ Ilé ẹjọ́ kòtẹ́mílọ́rùn yọ alága ẹgbẹ́ òṣèlú APC Adams Oshiomhole nípò Èèyàn 490 ló lùgbàdì àrùn Coronavirus ní Naijiria ní Ọjọ́ Ìṣẹ́gun O ni lootọ ko si idaniloju taarata pe oun ni yoo gbe aṣia ẹgbẹ oṣelu naa nitori iwe ofin rẹ ko faaye gba bẹẹ ṣugbọn o daju pe Obaseki yoo darapọ mọ ẹgbẹ oṣelu naa.
Ẹlòmíràn tún sọ fún un pé, “N óo tẹ̀lé ọ Oluwa.
" Gbajabiamila balẹ̀ sí Ghana láti pẹ̀tù sááwọ̀ láàrin Nàìjíríà àti Ghana Isiaka Busari, Mighty Joe tó jẹ́ adigunjalè tó rọ́pò Ọyenusi lẹ́yìn tí wọ́n pa á E wo ọmọ Yorùbá àkọ́kọ́ tó jà fún ẹ̀tọ́ àwọn aláwọ̀dúdú ní America!
Ẹ pe gbogbo àwọn àgbààgbà ẹ̀yà yín wá sọ́dọ̀ mi, ati gbogbo àwọn olórí ninu yín, kí àwọn náà lè máa gbọ́ bí mo ti ń sọ ọ̀rọ̀ yìí, kí ẹ sì pe ọ̀run ati ayé láti ṣe ẹlẹ́rìí wọn.
Nígbà tí obinrin yìí dé, Joabu wí fún un pé, “Ṣe bí ẹni pé o wà ninu ọ̀fọ̀, wọ aṣọ ọ̀fọ̀, má fi òróró para, kí o sì fi irun rẹ sílẹ̀ játijàti.
Olootu eto ile ișẹ mohunmaworan Citizen ni Kenya ni Rubadiri ti o si ti ma a n ṣe atọkun eto to gbajumọ julọ nile iṣẹ naa.
Gbogbo igba ni mo maa n kun lọ si ileewe O wu Chekole gan ko kawe ṣugbọn awọn baba baba rẹ ko lowo ati tọ ọ.
Akọroyin BBC News kan to ti de ibẹ ṣalaye pe iye afẹfẹ gaasi to n fẹ jade nibẹ pọ pupọ, bi awọn alaṣẹ ko ba si gbe igbesẹ to ba tọ ni kiakia, afaimọ ki ijamba nla o maa waye nibẹ.
World Press Freedom Day: Akọ̀ròyìn tó tó 95 ló kú lọ́dún tó kọjá!
Femi Falana: Ìjọba Buhari kò lé è dá ààbò bo àwọn ará ìlú
Losu kokanla odun 2015, ni orile ede Gambia fofin de abe dida fomobinrin pelu sisoo di ese to lo sile ejo fun ni eyi ti awon orile ede ile Adulawo miran naa ti bere sii so di ofin bayii.
Iwadii ti fidiẹ mulẹ pe jijẹ awọn ounjẹ to kun fun Flavonoids ti o n jade lara ewebẹ a maa dena nkan ọmọkunrin ti ko ṣiṣẹ daadaa.
Flooding in Lagos: Ojú àwọn ará Èkó rí màbo pẹ̀lú òjò àrọ̀ọ̀rọ̀dá dá wàhálà sílẹ̀ ní Eko
Ó pàṣẹ fún àwọn ọmọ Juda láti wá ojurere OLUWA Ọlọrun àwọn baba wọn ati láti pa òfin rẹ̀ mọ́.
Oríṣun àwòrán, Reuters Handout ORILẸEDE YEMEN: Joe Biden ni oun yoo tọ ipasẹ aarẹ Trump lati fopin si iranwọ orilẹede Amẹrika pẹlu ogun abẹle lorilẹede Yemen.
Ẹ̀yin ọmọ, ẹ máa gbọ́ràn sí àwọn òbí yín lẹ́nu ninu ohun gbogbo, nítorí ohun tí ó wu Oluwa nìyí.
ọpọ igba ni igbesẹ ajọ awọn gomina yii maa n yatọ si ti ijọba apapọ bii aifẹnuko lori odiwọn iye owo ọya awọn oṣiṣẹ eyi to yatọ lati ipinlẹ kan si ikeji.
Nígbà tí Dafidi gbọ́ pé àwọn ará Jabeṣi Gileadi ni wọ́n sin òkú Saulu, 
Wọn ni ọkunrin naa ko salaye ara rẹ lori moto to joko si sugbọn o joọ bi ẹni pe o ti mọti yo Oríṣun àwòrán, Twitter/ruth richardson Lẹyin ti ọlọpaa sọ fun ki o kuro lara ọkọ rẹ ko da awọm ọlọpaa lohun gẹgẹ bi awọn ọlọpaa ṣe sọ.
Nigba to n ba BBC sọrọ, obinrin kan, Zoe salaye pe nigba ti mo beere lọwọ Google pe se obinrin maa n da omira loju ara lasiko ti ara rẹ ba n poungbẹ lati ri ọkunrin (Ejaculation), gbogbo ohun to fi da mi lohun ni ko ye mi, koda, n ko mo itumọ awọn ede to fi n ba mi sọrọ abi ẹya ara to n mẹnuba."
Akeredolu ni ko si ipinlẹ kankan ti o bọriyọ lọwọ awọn ipenija eto aabo lorilẹede yii, eyii lo si mu ki awọn ọmọ orilẹede yii to n bẹ loke okun maa bẹru lati wa si ilẹ baba wọn.
Lara ohun ti wọn le fi wa tọju alaisan nile ni pe ṣe ile naa wa ni ipo to dara fun itọju?
Koko ohun mẹta si ni Baba sọ nipa Keresimesi lọdun yii.
Àkọlé àwòrán, ẹni kan n pada sile ninu Naijiria ati Germany Bayii ipele ko mẹsẹ o yọ ni idije ife ẹyẹ agbaye awọn obinrin FIFA de duro.
ẹni tí ó bojú wo ilẹ̀láti wo ọ̀run ati ayé?
tiwa-n-tiwa ati isọkan  lorile ede Naijiria.
Ènìyàn 33,616 ló ti lùgbàdì ààrùn Coronavirus ní àpapọ̀ ní Nàíjíríà Bí ẹgbẹ́ One Million Boys ṣe bẹ̀rẹ̀ rèé àti ọṣẹ́ tó ṣe n'Ibadan Sotitobire: Kò sí èléyìí tó kàn mí nípa ìjínígbé Gold Kolawole!
Koko kan ti gbogbo eeyan gba ni pe tọkọtaya yii ti gbe igbesẹ akin ni eyi ti wọn fi tẹ ifẹ ara wọn lọrun.
Nnkan ko fara rọ laarin awọn ololufẹ Arsenal ati alaṣẹ ikọ agbabọọlu naa, Stan Kroenke lọwọlọwọ.
Ọmọ Aaroni ni àwọn alufaa wa, àwọn ọmọ Lefi sì ń ràn wọ́n lọ́wọ́.
Kọmísọ́nnà ètò ìdájọ́ nípìnlẹ̀ Ekiti fi ẹ̀sùn kan àwọn olóṣèlú, àti àwọn Ọba pé wọ́n ń di ìgbógunti ìfípábánilòpọ̀ lọ́wọ́
lẹnu nisẹ, ki awon olopaa  mẹ́rìnlélógún yooku si foju bale ẹjọ
Àwọn eniyan ibẹ̀ ti dá a mọ̀, wọ́n bá ranṣẹ lọ sí gbogbo agbègbè ibẹ̀; wọ́n gbé gbogbo àwọn tí ara wọn kò dá wá sọ́dọ̀ rẹ̀.
" Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Buhari, ìwọ́de yóò yíwọ́, tó gbá jẹ́ káwọn ológun bá bẹ̀rẹ̀ ‘Operation Crocodile Smile’ "" Ìjọba Eko pàdánù ₦234m láàrín ọ̀sẹ̀ kan torí ìwọ́de End SARS Bí o bá fẹ́ darapọ̀ mọ́ ikọ̀ ọlọ́pàá SWAT tí yóò rọ́pò SARS, wo àmúyẹ tí o gbọ́dọ̀ ní Aisha Buhari polongo àwo orin tó ní Nàíjíríà ń ṣun ẹ̀jẹ̀ lásìkò ìwọ́de Lizzy Anjorin ń kiri àgọ́ ọlọ́pàá láti gba ọ̀dọ́ afẹ̀hónúhàn, tó wà láhàámọ́ sílẹ̀ 2015 ni mo ti ń kígbe pé gudugbẹ̀ máa já ní Nàíjíríà - Oyedepo Wo ohun tí ìwọ́de ENDSARS ṣé fáwọn akẹ́kọ̀ọ́ tó fẹ́ ṣèdánwò NECO Láàrin wákàtí mẹ́ta, wọ́n dá ₦4m fún àkàndá ẹ̀dá tó kópa nínú ìwọ́de Ninu awọn ti wọn pe lẹjọ yii la ti ri igbakeji aarẹ, Yemi Osinbajo, aarẹ ile aṣofin agba Ahmad Lawan ,Olori ile aṣoju-ṣofin, Femi Gbajabiamila ati awọn mii."
Ọmọ ọdun mẹwa naa ni oun nifẹ fere fifọn pupọ, awọn ẹgbẹ akọrin kan to maa n fọn fere si lo se iwuri fun oun lati yan fere fifọn ni aayo.
” Aare Buhari wa saleri lati mojuto awon ise akanse ti won yoo maa gbese fun rara re lai fi enikeni da, fun anfaani awon omo orile-ede Naijiria.
Ọpọ eeyan la bi sile aye, sinu abule ati inu ẹbi kòlà-kòṣagbe, taa si lee pe wọn ni atapata dide.
Ṣugbọn, o mọ wipe awọn ọmọdekunrin naa nilo iranlọwọ, nitori eyi lo fi tọ arakunrin kan, Inyang Edem, ti wọn jọ n jọsin nileejọsin kan na lọ, onitọhun si gba lati fun ni owo ti yoo gbs bukaata eto ẹkọ ati awọn nkan eelo mi i fun Frederick ati Kelvin.
Ọlọpaa ni nigba ti wọn n lọ ọbẹ gba mọ ara wọn lọwọ ni o gun arakunrin naa nikun.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Adultery/Adeboye: Agbẹjọró ní ìjìyà wà lábẹ́ òfin Naijiria fún pànságà nínú ìgbéyàwó 30 Sẹ́rẹ́ 2020 Oríṣun àwòrán, Others Agbẹjoro ati onimọ nipa ofin orilẹede Naijiria, Kayode Ajulo ti sọ wi pe, ijiya wa labẹ ofin ti ẹnikẹni ninu igbeyawo ba ṣe pansaga.
Agbẹnusọ ile iwe naa, Sola Lawal sọ fawọn akọroyin pe lootọọ ni wọn ti sọ pe ki ọga agba ile iwe lọ rọkunle.
Ìran nípa Àwọn Kẹ̀kẹ́ Ogun Mẹrin.
Wọn ni o n ṣe ifẹ inu rẹ ati pe ko mọ oun to n ṣe.
Ṣebí àwọn tí ó ṣẹ̀ ni, tí òkú wọn wà káàkiri ní aṣálẹ̀.
Nítorí ẹnikẹ́ni tí ó bá fẹ́ gba ẹ̀mí rẹ̀ là, yóo pàdánù rẹ̀.
Wọn fi i silẹ lẹyin ti o san owo beeli rẹ, ti wọn si sun ẹjọ si Ọjọ Kọkanla, Osu Kewaa.
Gbogbo àgbáyé ló bá Orilẹ̀èdè Amẹrika kẹ́dùn.
Ta ló darí Ẹ̀mí OLUWA, ta ló sì tọ́ ọ sọ́nà gẹ́gẹ́ bí olùdámọ̀ràn rẹ̀?
Oríṣun àwòrán, Others 7) Oloogbe Babatunde Olatunji: Michael Babatunde Olatunji jẹ onilu ọmọ bibi ilẹ Yoruba nigba aye rẹ, ati ọmọwe, Ajafetọ awujọ pẹlu agbe awo orin jade.
Yatọ si Akeredolu, Gomina Ifeanyi Okowa ipinlẹ Delta atiiyawo rẹ naa kede pe awọn lugbadi arun yi.
Bí wọ́n ti jókòó tí wọn ń jẹun, Jesu ní, “Mo fẹ́ kí ẹ mọ̀ dájúdájú pé, ọ̀kan ninu yín tí ń bá mi jẹun nisinsinyii ni yóo fi mí lé àwọn ọ̀tá lọ́wọ́.
Oríṣun àwòrán, EFCC Àkọlé àwòrán, Aawọ ko sẹsẹ maa waye laarin awọn osisẹ ijọba apapo O ni sugbọn, oun ko mọ orisun owo naa, ko si han si oun.
Ireti wa pe aare yoo bale
Wọn ṣa awọn orileede wọn yi lẹṣa to ri pe wọn ni eto ti wọn ṣe lati koju iba to fi mọ lilo awọn ṣugbọn iye eeyan ti iba n damu yi pọ nilẹ wọn Bawo ni ipenija yi ṣe pọ to?
Lasiko ti won bere igbejo yii ni, agbejọro ijoba Aliyu Umar pe akiyesi ile-ejo
Nítorí náà, n kò ṣẹ̀ ọ́ rárá, ìwọ ni o ṣẹ̀ mí, nítorí pé o gbógun tì mí.
” Ó ti wà rí ní ìgbà àtijọ́.
Bakan naa si ni ayẹyẹ yii waye ni aafin Ọyọ, nibi ti iku baba yeye, Ọba Lamidi Olayiwola Adeyemi atawọn olori rẹ ti se yata-yoto ọdun.
Mo fẹ́ ìdájọ́ òdodo lórí ikú tó pa ọmọ mi- Baba ọmọ ti SARS pa Àwọn aṣòfín ní ìpínlẹ̀ Edo ti yọ Abẹnugan Ilé, Francis Okiye bí jìgá Ènìyàn 17 kú nínú ìjàmbá ọkọ̀ mẹ́ta tó ṣẹlẹ̀ ní Osun, òpópónà Ibadan sí Eko àti Delta Ko ṣai sọ pe o dara lati mu ọrọ awọn olukọ ni baada nitori ipa ribiribi ti wọn n ko lori idasoke awujọ.
Ẹ̀yin lẹ kọ́ Ọba lẹ kọ́ ìjòyè ìlú.
Èmi ni mo ní ìmọ̀ràn ati ọgbọ́n tí ó yè kooro,mo sì ní òye ati agbára.
Awọn àkẹkọ̀ọ́ Uniben wọ́de ìfẹ̀hónú hàn nítórí akẹgbẹ́ wọ́n tí wọ́n fipa bálòpọ̀ Àwọn ọdọ́ tó wọ́de ìfẹ̀hónúhàn nítori ìwà ìfipá báni lòpọ̀ tí hù sí Uwa, tí wọ́n sì tún gba ẹmi ọdọ́mọbinrin náà kìí ṣe ìgbà àkọ́kọ́ rèé ní ìpínlẹ̀ Edo.
Afurasi ti Àmọ̀tẹ́kùn bá lu lálù bẹ́, ilé iṣẹ́ ọlọ́pàá ò ni gbàá sátìmọ́lé Oríṣun àwòrán, Ondo Saaju la ti sọ fun yin pe, ní òwúrọ̀ ojó Ajé ni adarí ikọ̀ Àmọ̀tẹ́kùn ẹka Ibadan North, Oyinwola Simeon ti sàlàyé pé, ilé iṣẹ ọlọpàá méjì kọ̀ láti gba àwọn ọdaran ti àwọn mú si agọ́ wọ́n.
Wo ìdí tó fi tọrọ àforíjì fún ọ̀rọ̀ ẹ̀gbin tó sọ sí Pásítọ̀ David Oyedepo Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Bọlanle Ninalowo: Ọ̀rẹ́ lásán àti olóore mi ni Mercy Aigbe Gbogbo bó ṣe lọ rèé lágbo òṣéré láàrín ọ̀sẹ̀ yìí Oríṣun àwòrán, others Bẹbẹ ṣẹlẹ lagbo oṣere laarin ọsẹ yii, bi awọn kan ṣe n ṣi ile awo dami ẹnu, lawọn mii n ṣi ileeṣẹ f'ọmọ, lawọn kan naa jẹpe Eledumare.
 Ajọ naa sọ pe ile-ise mejeeji
Gege bi oro asofin Hunkuyi pe, “Awon ohun ti o n sele ni awon ile-iwosan wa ti se alekun bi awon omo orile-ede Naijiria se n lo setoju ara won loke okun, pelu fifi oju wina owon-gogo  owo ile okere, lati toju ara won lorile-ede America, ile-Europe, ile Asia ati awon orile-ede miiran nile Afrika.
Agbenusoro awon Alufaa ohun, Bishop Joachim Ntahondereye, so pe, awon omo orile-ede Burundi ko lati so ero okan won jade latari eru ti awon toro kan lorile-ede naa ti gbin si won laya.
Lagos: Àjọ iwádìí ọrọ̀ ajé àgbáyé, EIU ní Ilu eko wà lára àwọn ìlú tó gbọ̀pọ̀ jùlọ lagbaye
Ní kutukutu òwúrọ̀ ọjọ́ keji, àwọn eniyan náà lọ sí aṣálẹ̀ Tekoa.
Kí ẹ fún àwọn alufaa ní àkọ́so oko yín, ati àkọ́pọn ọtí waini yín, ati àkọ́ṣe òróró yín, ati irun aguntan tí ẹ bá kọ́kọ́ rẹ́.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Sunday Igboho: Alukoro ọlọ́pàá Ọyọ ní àwọn ọlọ́pàá kọ́ ló kọlu aráàlú, iṣẹ́ wọn ni wọ́n ń ṣe 13 Èrèlè 2020 Oríṣun àwòrán, Instagram/Sunday_igboho Ileesẹ ọlọpa nipinlẹ Ọyọ ti salaye ohun to mọ nipa rogbodiyan to waye ladugbo Soka lọjọ Isẹgun eyi to pagidina alaafia ilu.
Èmi a mú wọn, èmi a dè wọ́n, wọn a sì sọ wọ́n sẹ́wọ̀n, atọkunrin atobinrin wọn.
Wọn ni awọn ṣe eyi lati fi yanju kudié-kudié ninu iyansipo naa ni ki ipinlẹ Ogun le tooro.
O woye pe bi o ba wu awọn ilẹ Gẹẹsi, ki wọn gbiyanju ati maa ba awọn erin orilẹede Botswana gbe bi wọn ba ni ifẹ wọn bẹẹ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Sotitobire: Ọkọ mi kò mọ̀ Jegede PDP rí, kódà kò fa ẹnikẹ́ni kalẹ̀ dípò Akeredolu- Bisola Pásítọ̀ Sam Adeyemi ní kí àwọn ọ̀dọ́ lo ìfẹ̀họ̀núhàn #EndSARS lati fí tún gbogbo ohun tó bàjẹ́ ṣe ní Naijiria Adari ijọ Daystar Christian Centre, Pasitọ Sam Adeyemi ti fi ohun rẹ si ifẹhọnuhan to n ja ranyin kaakiri lorilẹede Naijiria pẹlu asia #EndSARS.
  Wọ́n tún wípé kódà àwọn aláwọ̀ funfun tí mo rí yìí – tí àwọn bá ṣèṣì jẹ irú ata tí a ń wí yìí, ńṣe ni ojú àwọn á di pípọ́n kuku bí aṣọ àparò!
OLUWA yóo fi tipátipá wọ́ ọ sọnù ìwọ alágbára.
Ó ní nígbà tí àwọn yoo fi wọ̀ọ́, àwọn ríi pé ọ̀rẹ́ awọ́n kan ń máa ń mú owó wá.
Ni kete ti o ba ti bawọn akọroyin wa to wa nibẹ sọrọ la o bun yin gbọ.
Ẹ̀ ń ṣe fàájì ninu ayé, ẹ̀ ń jẹ, ẹ̀ ń mu.
Ìdájọ́ ikú ni a fẹ́ fún àwọn afipábánilòpọ̀ - Ẹgbẹ́ ajàfẹ́tọmọnìyàn Ẹ̀wọ̀n gbére ni fún ẹnikẹ́ni tó bá fipá bánilòpọ̀ ní ìpínlẹ̀ Ọ̀ṣun Omijé ń p'omijé rán níṣẹ́ níbi ìsìnkú dípiò ọlọ́pàá táwọn ọlọ́ṣà pa ní Kogi Abacha àtàwọn ọba àlàyé ló jọ pinnu láti kó owó pamọ́ sókè òkun - Al Mustafa Fadeyi ni ọwọ awọn ti tẹ afurasi kan to ni ohun ṣe pẹlu bi wọn ṣe fi tipa ba obinrin kan to ni ipenija ọrọ sisọ ati gbigbọ lopọ ni agbegbe Ibarapa.
Samuel to ti pe ẹni ọgbọn ọdun bayii, n ṣiṣẹ alamojuto ile kikọ.
Yatọ si eyi, ọpọ ẹmi lo sọnu ninu ọdun 2020, eyi ti ko yọ awọn olowo tabi talaka silẹ, koda, o kan ọba ilu ati ijoye pẹlu.
Nigba to n ba BBC Yoruba sọrọ ninu ifọrọwerọ kan, o ni awọn iwa bii ki obinrin maa wọ aṣọ to ṣi ara silẹ le fa awọn iwa ọdaran bii ifipabanilkopọ ati ijinigbe.
Fi lé mi lọ́wọ́, n óo sì mú un pada wá fún ọ.
Iwa ọdaran si ni iwa ọdaran n jẹ, ko yẹ ka maa dọwọ boo.
Eyi waye lẹyin ọdun mẹẹdogun ti ijọba aarẹ tẹlẹri, Olusegun Obasanjo tu gbogbo awọn ibudo naa fọnka.
Àwọn ohun èlò kan ṣẹ́kù ninu ilé OLUWA, àwọn bíi: òpó ilé, ati agbada omi tí a fi idẹ ṣe, ati àwọn ìtẹ́lẹ̀ rẹ̀ ati àwọn ohun èlò tí ó kù ninu ìlú yìí, 
Ọjọ́ kejì lọ́dọ̀ baba-Onírùngbọ̀n-Yẹ́úkẹ́ ẹni tí ń gbé ibi gegele òkúta
Femi Dosumu (Mega 99) : Oríṣun àwòrán, Others Gbajumọ olorin juju ni Mega 99,ti aye si n gbadun rẹ ni ojoojumọ amọ iyalẹnu lo jẹ nigba ti awọn eeyan kan tu ọfọ rẹ lojiji, amọ to jẹ pe irọ lo wa nidii ọrọ naa.
Abadofin ti wọn ṣagbeyẹwo ninu ipade ita gbangba naa ti wọn pe akori rẹ ni “Abadofin Ṣiṣe Agbekalẹ Ofin Ti Yoo Ṣe Idasilẹ Ilana Fifun Awọn Ara Ilu Laami Idanilọla Ti Wọn Yoo Ti Wo Ti Won Yoo Tun Fi Tọka Si Anfani Ti Ẹni To Gba Aami Idanilọla Yoo Ni”, ni Agbenusọ Ile Igbimọ Aṣofin Ipinlẹ Eko, Aṣofin Mudashiru Ọbasa ti Olori Ọmọ Ẹgbẹ Oṣelu to pọ ju ninu Ile, Aṣofin Sanai Agunbiade sọ pe igbesẹ to dara ni Abadofin naa lati maa mo riri iṣẹ aṣeyọri ni ipinlẹ yii.
Oniruuru ẹsin, ẹlẹya ati itiju si lo maa n la kọja ko to loyun ati lẹyin to ba bimọ tan.
Alhaji Muhammed Shittu lo soju fun ẹgbẹ naa, to si sàlàyé pé ajọ INEC kún ojú òsùwọ̀n tó.
 Bi a se mọ pe ẹkun Afirika n koju ipenija pupọ ,paapaa julọ lori eto
Oríṣun àwòrán, NIPOST Ilé iṣẹ́ NIPOST sọ pé ìlànà tuntun yìí ní láti ran àwọn ojúlówó ilé iṣẹ́ ìbáni fẹrù ranṣẹ́ lọ́wọ́ àti láti le àwọn ilé iṣẹ́ arúmọjẹ tó ń ṣe irú iṣẹ́ náà wọle, kí ààyè le gba àwọn ojúlówó .
Mo ranti ìgbà àtijọ́,mo ranti ọ̀pọ̀ ọdún sẹ́yìn.
Lọjọ Aje ni Gyan kede pe oun ṣetan lati fẹyinti nidi ere boolu lati fẹhonu han lori bi wọn ṣe gba ipo Balogun ikọ lọwọ rẹ.
Oríṣun àwòrán, Other Alukoro ileeṣẹ ọlọpaa ipinlẹ Jigawa, Abdu Jinjiri ṣalaye pe abule Kankaleru ni ijọba ibilẹ Ringim ni iṣẹlẹ ọhun ti ṣẹlẹ.
Iko agbaboolu Arsenal ti ra agbaboolu owo eyin Juventus, ti o tun je omo bibi orile-ede Switzerland, Stephan Lichtsteiner pelu idunadura lati darapo mo Arsenal lai san owo kankan.
Oríṣun àwòrán, BBNaija/Twitter Àkọlé àwòrán, Bayii ni Laycon ati Dorathy, #se kuro ninu ile Big Brother lẹyin aadọrin ọjọ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, BIAFRA at 50: Ìhàlẹ̀ ológun ni Gowon ni ká kọ́kọ́ fi bẹ̀rẹ̀- Aladejẹbi O ni ohun to difa fun wi pe ijọba fi aaye gba ikọ Sharia ti o ti wa ni awọn ipinlẹ kọọkan ni Ariwa orilẹ-ede Naijira fun ọpọlọpọ ọduin, ati ọlọpaa Hisbah ti wọn ko si se nkan ti ko tọ si wọn.
Ṣaaju asiko yii, awọn Musulumi ma n korajọ sinu Mọṣalaṣi fun ẹkọ, lati gbadura papọ ati lati ṣinu loṣu Ramadan.
Bẹ́ẹ̀ ni kò sí wolii mìíràn tí ó ní agbára ńlá tabi tí ó ṣe àwọn ohun tí ó bani lẹ́rù bí Mose ti ṣe lójú gbogbo àwọn ọmọ Israẹli.
SARS tó bá hùwà àìtọ́ á jẹyán ẹ̀ níṣu ni!
iwa buruku, iwa ibaje, ipanle, jagidi-jagan lawujo bi ki ba se ise(poverty).
Ó ṣe ohun tí ó dára lójú OLUWA nítorí pé ó tẹ̀lé ọ̀nà Amasaya, baba rẹ̀.
Kí àlùfáà tó gbàdúrà tán, kí àlụ̀fáà kejì tó bẹ̀rẹ̀ Oore Ọ̀fẹ́, ni ẹkún àti ariwo ti gba ilé kan.
Adajọ Anthony Apkovi ti o ṣoju igbimọ ẹlẹni mẹta ti o n risi igbẹjọ naa lo kede abajade iṣẹ iwadii wọn lọjọ Iṣẹgun pe Kọla Balogun lo jawe olubori, nitori naa, ki Ajimọbi lọ wa ibi joko si.
láàrin Bẹtẹli ati Ai, níbi pẹpẹ tí ó kọ́kọ́ pa, ibẹ̀ ni ó sì ti sin OLUWA.
#ENDSARS: Àṣìta ìbọn ọlọ́pàá ló sọ mọ̀lẹ́bí mi, Adenike di báyìí, wọn ò bí i bẹ́ẹ̀, EndSARS ni dandan o- Toyin Abraham
Ọ̀pọ̀lọpọ̀ àwọn eniyan lo farapa nigba ti afurasi naa da ìbọn bolẹ nile ijọsin Sinagọọgu ti wọn n pe ni Tree of Life lọjọ Abamẹta to kọja.
Ta lawọn obi rẹ ati pe bawo lo ti se di ọlọrọ ti awọn eeyan kan n fi ọla rẹ tọrọ, pe ki awọn naa ri bi tiẹ?
com Lasiko ti iwọde naa fi n waye ni orita Ọlaiya ni ilu Osogbo, nibi tawọn ọmọ ẹgbẹ naa ti n fẹhonu han lori ohun ti wọn pe ni aiṣedede iṣejọba, aisi ohun elo amayedẹrun to duro deede, iwa ipaniyan bi ẹni pẹran lọwọ awọn agbefọba ati bẹẹ bẹẹ lọ.
Ọmi ni Manchester United ta pẹlu AZ eleyi to mu ki Manchester United ṣi wa ni ipo keji ninu atẹ ipin L ninu idije naa ti Partizan belgrade si di ipo kini mu.
Lẹyin ti awọn adari mejeeji jọ jiroro tán ní orílẹ̀èdè, ni Trump ti ko ni ifẹ si adehun ti awọn orilẹede fọwọsi lọdun 2015 nipa Iran, sọ wipe oun yoo gbiyanju lati se adehun miran to dara ju ti tẹlẹ lọ.
Arabinrin sọ pe ọjọ tipẹ ti ọmọ naa ti ma n ṣe awada oriṣiriṣi lasiko ti wọn ba n ba awi, fun aṣemaṣe.
Dìde, OLUWA, jí pẹlu agbára;jí bí ìgbà àtijọ́,bí o ti ṣe sí ìran wa látijọ́.
“Ní ọjọ́ kẹfa, ẹ óo máa fi ẹgbọ̀rọ̀ akọ mààlúù mẹjọ, àgbò meji ati ọ̀dọ́ àgbò mẹrinla ọlọ́dún kọ̀ọ̀kan, tí kò ní àbààwọ́n rúbọ.
Oríṣun àwòrán, Twitter/seyi makinde Ọgbẹni Ihekweazu n sọrọ nigba ti ibeere kan jade lori pe awọn ipinlẹ kan naa to ti da awọn alaisan yii silẹ nileewosan n kede ara wọn pe awọn bọ lọwọ COVID-19.
Abineri wí fún un pé, “Yà sí ọ̀tún, tabi sí òsì, kí o mú ọ̀kan ninu àwọn ọdọmọkunrin, kí o sì kó gbogbo ìkógun rẹ̀.
" Wọn ti gbe oku olori awọn oṣiṣẹ fun Aarẹ Buhari, Abba Kyari de ilu Abuja fun isinku.
Bakan naa ninu atẹjade ohun ni wọn ti sọ wi pe Arakunrin Bamidele Olure to jẹ adari ẹka isuna ni ajọ NECO lo jẹbi ẹsun ṣiṣẹ owo ajọ naa to wa ni ikawọ rẹ basubasu, ti ko si yẹ ni adari ẹka naa mọ.
Awọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Kíni ìwọ mọ̀ nípa Funmilayọ Ransome-Kuti?
O tun sọ ninu atẹjade naa pe ko si iyapa ninu ẹgbẹ YWC, o ni gbọingbọin ni gbogbo ọmọ ẹgbẹ duro lẹyin aarẹ ẹgbẹ naa, Ọjọgbọn Akintoye.
Lai pe yi ni Aarẹ Buhari ati awọn asaaju ile asofin jijọ se ipade lori bi eto isuna naa yoo ti se dofin ni kia kia.
Owo ileewosan naa lo jẹ owo iye ọjọ ti ọmọ naa lo ninu ẹrọ ti wọn fi n tọju awọn t'oṣu wọn o pe si nitori wipe ọjọ ibi rẹ ko ti to o ti iya rẹ fi bi.
Laipẹ yi ni awọn ọmọ ikọ agbesunmọmi Boko Haram pa ọgagun ọmọ ogun Naijria kan to n dari ikọ ẹlẹẹkeeji Operation Lafiya Dole ni Borno yi kan naa.
“Ọwọ́ mi wá tẹ̀ ọ́, mo mú ọ kúrò ninu ẹ̀tọ́ rẹ.
Ọjọ ipinu fun Super Falcons Oni la o mọ boya ẹgbẹ agbabọọlu obinrin orilẹede Naijiria, Super Falcons yoo le tẹsiwaju ninu idije ife ẹyẹ agbaye awọn obinrin to n lọ lọwọ lorilẹede Faranse.
àwọn ọmọ Delaaya, àwọn ọmọ Tobaya, ati àwọn ọmọ Nekoda.
“awon agbaboolu mi ko kopa daradara rara ni saa akoko, eyi ti o sokunfa bii a se padanu ifesewonse yii,”O tenumo pe, ero okan ohun ni lati gba ami kan ni papa isere Umuahia, leyin ti iko Abia Warriors ti gba ami dogba-dogba ninu awon ifesewonse meji ton ti gba seyin.
 awon oògùn oníkóro tí wón fún un dín irora rè kù fún ìgbà díe.
Oliver Cowdery, David Whitmer, àti Martin Harris ti ní ìwúrí nípa fífẹ́ nínú ìmísí láti jẹ́ Ẹlérìí pàtàkì mẹ́ta náà.
Dídán rẹ̀ dàbí ọ̀sán gangan,ìtànṣán ń ti ọwọ́ rẹ̀ jáde;níbẹ̀ ni ó fi agbára rẹ̀ pamọ́ sí.
Atọ́kùn ètò ọ̀hún, olóṣèlú Diosdado Cabello, rò kàn pé Díaz lọ́wọ́ sí ìfẹ̀hónú hàn àìsí ináa mọ̀nàmọ̀nà tí ò lọ jákèjádò orílẹ̀ èdè èyí tí ó mú kí àwọn ọmọ Venezuela máa gbé nínú òkùnkùn fún ó lé ní wákàtí mẹ́rin lé lógún lọ́jọ́ 7 àti 8 Oṣù Ẹrẹ́nà
Lórí erongba aṣáájú ẹgbẹ́ APC àti Gómìnà Ìpínlẹ̀ Eko tẹ́lẹ̀, Senato Bola Hammed Tinubu láti di aarẹ Naijiria lọ́dún 2023, Momoodu ni lọ́wọ́ lọ́wọ́ báyìí, Tinubu sì lo kajuẹ julọ láti darí orílẹ̀ èdè yìí.
Ijọba ni Ajọ CACOVID ati ifọwọsowọpọ ijọba ipinlẹ naa ni wọn ti bẹrẹ si ni pin awọn ohun elo ounjẹ naa fun awọn alaini nipinlẹ naa, ti wọn si ti bẹrẹ lati oṣu diẹ ṣẹyin.
Àwọn ọmọ Lefi ṣe olóòótọ́ ní yíya ara wọn sí mímọ́ ju àwọn alufaa lọ.
Olukuluku sì ní iṣẹ́ tí ó ń ṣe, 
Bí ó bá jẹ́ pé ìlẹ̀kùn ni,pákó Kedari ni a óo fi yí i ká.
Gbogbo nǹkan yòókù tí Nadabu ṣe ni a kọ sinu Ìwé Ìtàn Àwọn Ọba Israẹli.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Emirate Cup: Lyon figbájú olóòyì méjì gba Emirate Cup lọ́wọ́ Arsenal 28 Agẹmo 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ẹpa o boro mọ fun Arsenal Ẹkun ohun oṣe ni Arsenal fi pari ifẹsẹwọnsẹ oloresọrẹ wọn ninu idije Emirate Cup ti wọn fi sọri wọn.
Bakan naa ni ọkọ rẹ ni ko yẹ ki eeyan maa ṣe ju ara rẹ lọ nitori ko sin ẹni to le ni ohun gbgogbo tan nile aye.
Sugbọn bayi ti iroyin iku Oba yi ti n ja rain-rain ijọba ti ni awọ́n yoo funkun pada mọ eto konileogbele naa lati fi dena ikọlu miran.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ìtàn ìgbé ayé Isola Ogunsola, akọni mánigbàgbé òṣèré tíátà, olórin àti onílù Aráàlú dá iná sun èèyàn méjì n‘Ibadan, orí kó ẹni kan yọ Ma a pa ara mi si Cute Abiola lọrun bo ṣe já mi silẹ tori afẹsọna miran"" ""Àwọn akẹ́kọ̀ọ́ àgbà fipá bá ọmọkùnrin mi lòpọ̀ níléèwé Deeper Life, mò ń fẹ́ ìdájọ́"" Kí ló fa gbas-gbos láàrín Davido àti Burna boy lórílẹ̀èdè Ghana?"
Arakunrin to wa ninu ọkọ baalu to n lọ si Abuja lati ilu Eko, Ogbẹni Valentine Iwenwanne lo sọ bẹẹ fun BBC lẹyin ti o fi ọrọ naa lede si oju opo Twitter rẹ.
“Ìpín ẹni ibi láti ọ̀dọ̀ Ọlọrun nìyí,òun ni ogún tí àwọn aninilára ń rí gbà lọ́dọ̀ Olodumare:
Bakan naa ni ọmọ to sọrọ ninu fidio naa ni ki ijọba mase gbiyanju lati wá tu àwọn sílẹ̀ ni ahamọ Boko Haram.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Samuel Ajayi Crowther, òjíṣẹ́ Ọlọ́run tó gbé èdè Yoruba lárugẹ Èmi àti Bọla Tinubu fẹ́ lo ‘German Mercenaries’ láti gbé MKO Abiọla kúrò lẹ́wọ̀n - Dele Momodu Mo nífẹ̀ẹ́ Khafi torí kìí díbọ́n tàbí hùwà oníwà - Gedoni sọ̀rọ̀ ìdágbére Àwọn alálẹ̀ kò ní forí jìn mí tí ń kò bá ṣe ọdún Ṣàngó - Alaafin Buhari, ṣí ìwé àkọsílẹ̀ orúkọ àwọn gómìnà tó jẹ̀bi ìkówójẹ, káráyé mọ̀ wọ́n - SERAP Ninu lẹta kan ti Ajayi Crowther kọ ko to dagbere faye lo ti salaye ohun ti oju rẹ ri loko ẹru ati bi wọn se koo lẹru, ko to di pe o ri idande gba.
Nítorí wípé ó ṣẹ́ ewé kátabá tí ó pọ̀ ju èyí tí ó lè lò lọ ni kò fi mọ ọ̀nà mọ́n.
Fún òórùn t’ó gba ‘nú ihò, t’ó sì gba ‘gbo kankan,
Koda ile aṣoju-sofin daba pe ki ijọba fi oye da Onyema lọla fun oju aanu rẹ.
Eto owo ori sisan ni India lati ọwọ awọn ẹbi iyawo fun ẹbi ọkọ, ni wọn ti fi ofin de lati ọdun1961 ṣugbọn àwọn miran ṣi n ṣee.
Awọn kan ni ootọ ọrọ ti ko ni ki a ma sọ ohun ni ọrọ Babab Kumuyi Amẹ́ríkà ń béèrè ìròyìn facebook, email arìnrìnàjò tó f'ẹ́ gbà'wé àṣẹ Ibanuje d'orí agbà k'odò, Ruiz fi ẹ̀ṣẹ́ sọ Anthony Joshua di ọmọ ológo àná Sultan pàṣẹ fún àwọn mùsùlùmí láti ṣ'ọdẹ òṣùpá lónìí 'Ọmọ SS 1 mu èso olómi, ṣùgbọ́n ilé ìwé wa kọ́ ló kú sí' Àwọn ìròyìn mìíràn tí ẹ lè nífẹ̀ẹ́ si: N kò gba owó rí lọ́wọ́ olùdíje kó tó dé ipò - Oyedepo Leah Sharibu pé ọmọ ọdún 16 ní àhámọ́ Boko Haram Pápà mímọ́ gbarata lóríi ìpànìyàn Benue Pásítọ̀ bẹ́'rí ọmọ ìjọ ní ìpínlẹ̀ Ògùn Ààwẹ̀ gbẹ̀mí ọmọ Naijiria ní orílẹ̀èdè Amẹ́ríkà Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Má sì fi ìrúnú jẹ mí níyà!
Ó gbé ẹsẹ̀ ọ̀tún rẹ̀ lé orí òkun, ó sì gbé ti òsì lé orí ilẹ̀ ayé.
Bí gbogbo ara bá jẹ́ etí, báwo ni yóo ti ṣe gbóòórùn?
Àkọlé àwòrán, Akinyele Murder: Iléeṣẹ́ ọlọ́pàá ní aago márùn-ún ìdájí ni wọ́n pa obìnrin náà níwájú ilé rẹ̀ Idi ni pe wọn tun ti pa obinrin miran,Olusayo Fagbemi, ladugbo Akinyele naa yatọ si Mujeed ti wọn pa nibẹ lọjọ Iṣẹgun.
Kò sí ọ̀rọ̀ Ọlọrun kankan tí ó ń yẹ̀,òun ni ààbò fún àwọn tí wọ́n wá ààbò lọ sọ́dọ̀ rẹ̀.
Sola Sobowale: Iṣẹ́ tí Ọlọ́run kọ mọ́ mi ni mò ń ṣe
ó níláti ṣe gbogbo ohun tí ó ti jẹ́jẹ̀ẹ́, àfi bí ọkọ rẹ̀ bá lòdì sí ẹ̀jẹ́ náà ní ọjọ́ tí ó gbọ́ ọ.
Èyí tí wá dọ̀rọ̀ a n gbà bí ẹní n gbagbá otí lórí ẹ̀rọ àtẹ̀jísẹ́ Twitter báyìí, olúkúlùkù sí n sọ èrò tirẹ̀.
Pẹpẹ turari, ati àwọn ọ̀pá rẹ̀ ati òróró ìyàsímímọ́, ati turari olóòórùn dídùn, ati àwọn aṣọ títa fún ẹnu ọ̀nà àgọ́ náà.
Ẹni tí ó fi ìkùukùu bo ojú ọ̀run,ó pèsè òjò fún ilẹ̀,ó mú koríko hù lórí òkè.
” Lefi bá dìde, ó sì tẹ̀lé e.
Bẹẹni awọn miran woye pe eyi gan an ni yoo mu ki ere ije si ile ijọba ipinlẹ Eko ni Alausa o dun wo ni iran pẹlu bi nnkan ṣe n gbe'ra sọ bayii.
won ko ni agbara tabi asẹ lati fenuko, 
Bí bẹ́ẹ̀ kọ́ n óo wá láìpẹ́, n óo sì fi idà tí ó wà lẹ́nu mi bá wọn jà.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù 'Ilé orin wa tí Ajimobi tun kọ́ dára púpọ̀, ṣùgbọ́n a kò ní dẹ́kun òtítọ́' 16 Ògún 2018 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 16 Bélú 2018 Oríṣun àwòrán, @yinkaayefele Àkọlé àwòrán, Ayefele Lẹyin oṣu mẹta ti Ijọba Ipinlẹ Oyo wo ileeṣẹ orin Yinka Ayefele to wa ni agbegbe Challenge, Ibadan, o ti dupẹ lọ́wọ́ Gomina Ipinlẹ naa, Abiola Ajimọbi, bo tilẹ jẹ pe o ni oun ko ni dẹkun lati maa sọ ootọ ọrọ to maa ṣe ara ilu lanfani.
See di latest facts23 Òkùdu 2020 Coronavirus in Lagos: Di city fit battle with coronavirus till July or August - Abayomi8 Èbibi 2020 Coronavirus: 26% of Nigerians believe say COVID-19 no fit catch 'children of God' - Research19 Ẹrẹ̀nà 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Èrò wọn ni wípé kí ó díje fún ìbò náà tí ó bá sì wọlé kí ó sì jẹ ́ kí ọkọ rẹ ̀ bọ ́ sórí àléfà làtàri ìbò tiwantiwa .
Maina N2bn Fraud: Agbẹjọ́rò Maina yọ ọwọ́ nínú ìgbẹ́jọ́, Ó lóun kò ṣé mọ̀
Mose ati Aaroni ṣe gbogbo iṣẹ́ ìyanu tí wọn ṣe níwájú Farao, ṣugbọn OLUWA sì mú kí ọkàn Farao le, kò sì jẹ́ kí àwọn eniyan Israẹli lọ kúrò ní ilẹ̀ rẹ̀.
El Rufai: Òfin má wàásù ìpínlẹ̀ Kaduna ti ń gba àpérò
“Nítorí náà, OLUWA Ọlọrun ní, ‘Mo kórìíra àwọn ẹ̀gbà ọwọ́, òògùn tí ẹ fi ń dọdẹ ẹ̀mí eniyan.
19 Owewe 2020 Oríṣun àwòrán, Omotayo Amokade/instagram Ọ̀pọ̀ àwọn ọmọ Nàìjíríà ló ti fẹ́ fa orí ayélujára ya nítori fọ́nran kan tí ọ̀kan lára àwọn òṣèré tíátà Nollywood Yoruba Olatayo Amokade tí gbogbo ènìyàn mọ̀ si Ijebu ju sori ayelujara lọ́sàn òní.
Ìṣòro kinni kọjá; ṣugbọn ó tún ku meji lẹ́yìn èyí.
Ẹgbọn wọn to kọkọ padanu ẹmi rẹ ni London ni Trevor Monerville.
"Bakan naa ni alufa mii to tun jẹ agbẹnusọ fun ijọ Aguda nibẹ, James Martin fi si oju opo Twitter rẹ pe: ""Ẹ jẹ ki n fi yee yin pe iwa iṣodi ni eyi."
Gbogbo ohun tita ló ti wọ́n si.
Àwọn tí wọ́n bá rí i kò ní dijú sí i,etí àwọn tí ó gbọ́ ọ kò ní di.
Ọṣẹ wo ni a lè fi wẹ̀, tí a fi lè mọ́?
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Sunday Igboho: Fulani kò leè dúró, táa bá lo ohun ta jogún lọ́dọ̀ àwọ̀n bàbá wa Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, RevolutionNow: Ẹ̀rù ò bàwá, a ṣetan láti wà ní àtì mọ́lé- olùfẹ̀hónúhàn Lásìkò tó ń ba àwọn akọroyìn sọ̀rọ̀, ìwà pípà àwọn ọmọ Naikjiria tó n fi ojojúmọ peléke síi ní South Africa tí de ori góngó báyìí, o fí kún pé tí ọmọ Naijírì kan ba tú kú ní South Africa, gbogbo ọmọ South Africa to ba wà ní Nàìjírìa náà kò ni farare lọ O sàlàyé pé àwọn ọmọ Nàìjíríà méjìdínláàdọ́fà ní wan ti pa ni South Africa láti ọdún 2016, o fi kún un pé láàrin 2016 si àsìkò yìí ànìyàn méjìdínláàdọ́rùn ni wọ́n tún pa Ó pè fún ìwádìí tó péye lórí gbogbo àwọn tí wan ti pa kí wan si fi ẹni ti igbá ba ṣí mọ lóri jófin Ẹ̀wẹ̀, ọ̀gá NIDCOM ní ọ̀rọ̀ náà kan òhun lóminú pé àwọn ọmọ Nàìjíríà míràn ló ṣe okùnfa ìkú akẹgbẹ́ wọ́n nítoripé nígbà míràn àwọn ọmọ Naàìjírà ló lọ́wọ́ kún ọmọ Nàìjíríà.
Ni ti awọn ibudo ajogunba Unesco ẹwẹ, wọn maa n ge okun to de wọn nipa sise agbeyẹwo iye ibudo ajogunba to wa ninu akọsilẹ ajọ Unesco, eyi to n yẹ wo lọwọ-lọwọ.
Ademola Adeleke People's Democratic Party (PDP) < Padà lọ sí ọ̀dọ̀ Olùdíje Kíni ọjọ́ ìbí yin?
Lẹ́yìn náà, wọ́n gbéra, wọ́n pada sí ilé wọn, ní Rama.
A sì dá oluwa mi lóhùn pé, ‘A ní baba, ó ti di arúgbó, a sì ní arakunrin kan pẹlu, tí baba yìí fi arúgbó ara bí, ati pé ẹ̀gbọ́n rẹ̀ ti kú, òun nìkan ṣoṣo ni ó kù lọ́mọ ìyá tirẹ̀, baba rẹ̀ sì fẹ́ràn rẹ̀.
Oore-ọ̀fẹ́ yìí kò sì jẹ́ lásán lórí mí, nítorí mo ṣe akitiyan ju gbogbo àwọn aposteli yòókù lọ.
"Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, SARS ti bẹ̀rẹ̀ ìgbésẹ̀ láti yọ àwọn ọ̀bàyéjẹ́ kúro Ofin naa ni ""lati akoko yii lọ, awọn osisẹ Sars ko gbọdọ wọ asọ dudu ti wọn maa n wọ bii asọ isẹ mọ,amọ wọn gbọdọ bẹrẹ si wọ asọ ọlọpaa bayii, ti wọn si gbọdọ maa so orukọ wọn mọ igba aya wọn, to fi mọ nọmba wọn ninu isẹ ọlọpaa, ipo ti wọn wa ati ami idamọ wọn bii osisẹ ọlọpaa."
OLUWA bá mi sọ̀rọ̀, ó ní: 
00), bee si ni ile-ise to n mojuto oro irin ajo kalo-kabo, Immigration Service  yoo gba “bilionu meji le lẹgbẹ̀ta naira (=N=2,628,143,320.
Koda gẹgẹ bi iyawo, emi naa maa n ṣe aṣiṣe, lọpọ igba aṣiṣe bẹẹ gan yoo buru ju ki eeyan yan ale lọ.
Oríṣun àwòrán, Ooniadimula Ṣe ni ile ijọsin kun amọ pẹlu ofin ijina sira ẹni laarin awọn oloye Ile Ife, awọn ọtọkulu ilu araali Ife ati tẹbi tara to wa ba Kabiyesi ṣe ajọyọ.
Eyi mu ki gbogbo awọn ara Orilẹ-ede Amẹrika nigba naa ro wi pe aye ti fẹ parẹ.
O si sọ fun ọkọ rẹ pe o da bi ẹni pe nkan buruku kan yoo ṣẹlẹ laipẹ, nitori pe igba ti awọn lọ si agbegbe naa kẹyin, ijamba ina kan waye to mu ẹmi akọbi wọn obinrin lọ.
Ní ọ̀pọ̀ ìgbà ni ǹkan ti à ń ṣe máa ń jẹ òòtọ sùgban ti a ba mú wọn tán ti wọn si ni ẹ̀rí máa jẹ mi nìsó à ó fi ẹni náà silẹ̀ nígba ti àwọn ti igbá ba ṣímọ lóri yóò fi ojú ba ile éjọ Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Atẹjade kan ti kọmisana feto ẹkọ nipinlẹ Oyo, Olasunkanmi Olaleye fi sita lo sisọ loju ọrọ yii.
O ti gba a fun igba meje.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù NYSC Camp, After coronavirus: Ìjọba kéde ọjọ́ ìwọlé àwọn àgùnbánirọ̀ sí ìpàgọ́ lẹ́yìn Covid 19- Minista ọ̀rọ̀ ọ̀dọ́ Nàìjíríà 15 Ọ̀wàrà 2020 Oríṣun àwòrán, @NyscHqtrs NYSC: Adupẹ!
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Burundi: Ìbẹ̀rù bojo gbilẹ̀ bí ẹ̀mí se sòfò sáájú ìdìbò 13 Èbibi 2018 Oríṣun àwòrán, AFP Àkọlé àwòrán, Ètò àbò ti gbépọn si sáájú ìdìbò gbogbogbò l'ọ́ṣẹ̀ tó ń bọ̀ O kere tan eeyan mẹrindinlọgbọn lo padanu ẹmi wọn lẹyin ti awọn agbebọn kọlu abule kan ni apa iwo oorun ariwa orilẹede Burundi.
"Vaginismus yàtọ̀ sí kí ìbálòpọ̀ máa dun èèyàn nítorí ìdáhùn ara ló fà a gẹ́gk bí Dókítà Vanessa Mackay tó jẹ́ oníṣègùn òyìnbó nípa obìnrin ní ilé ìwòsàn ọm ọbabìnrin Elizabeth ní Glasgow.
Winners Chapel: Bakan naa ni ijọ Winners Chapel ti kọkọ kede pe isin aisun ọdun ko ni waye ni gbogbo ẹka ijọ naasutgbọn nigba to ya, lo tun da ọrọ rẹ ro, to si ni isin naa yoo waye pẹlu awọn ilana kan.
''Asiwaju ko le sọ iru ọrọ bayii nipa Buhari laelae!
O ni ko rọrun lati maa tun ile itura ṣe fun lai si alejo to n gba a.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Òsìn màálù O fi kun ọrọ rẹ sọ pe, oun lọ si agbo maalu oun lẹyin ti ojo ti rọ fun wakati mẹfa nibi ti oun ti ba oku maalu nilẹ rẹpẹtẹ.
Kábíyèsì fẹnu ara rẹ̀ tú àṣírí àwọn Fulani Daran daran tó ń ṣọṣẹ́ nílùú rẹ̀ Ariwo sọ, wọ́n fọwọ́ òsì júwe ilé fún Tacha lórí ètò àgbéléwò BBNaija Ọdún Ọlọ́jọ́ ń dùn mọ̀rànìn-mọran-in ní Ilé-ifẹ̀ Tacha: Mo mọ̀ pé ìwà burúkú ló pa mi bí ọtí, ẹ dárí jì mí Tacha to ti di mọlumọọka bayii tori kikopa rẹ lori eto agbelewo Big Brother Nigeria.
Koda, ko ju ipinlẹ marun pere lọ to ni agbara lati san owo osu to kere julọ naa fawọn osisẹ wọn, eyi tii se ẹgbẹrun lọna ọgbọn naira.
Nítori àwọn àtúgbẹ́yẹ̀wò, o níra láti ṣe àkójọpọ fún àwọn ọkọ́ naa Orisun: Johns Hopkins University atawọn ajọ eto ilera ilu Iye akọsilẹ to waye gbẹyin 15 Oṣù Ṣẹ́rẹ́ 2021 20:44 WAT+3 Gomina Makinde ni ida aadọta awọn arun coronavirus to n waye ni ipinlẹ Ọyọ ko ṣẹyin ileewosan nla UCH ni ilu Ibadan.
Ọdun 2018 ni Ooni ti Ile Ifẹ, Oba Adeyeye Ogunwusi gbe Olori Naomi Silekunola Ogunwusi ni iyawo.
Ọjọ kẹtadinlọgbọn oṣu keji ni Naijiria kede ẹni akọkọ ti yoo ni arun yii lẹyin ti arakunrin ọmọ orileede Italy kan gbe wọle ti ayẹwo si fihan pe o ni Covid-19.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Nigerian Senators deaths: Àwọn sẹ́nẹ́tọ̀ mẹ́rin tó jáde láyé ní Nàìjíríà láàrin oṣù mẹ́fà sẹ́yìn rèé 15 Òkùdu 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 29 Ògún 2020 Oríṣun àwòrán, Facebook Iku o da ọjọ, aarun ko da oṣu, awaye kan ko si, ọrun nikan ni are mabọ.
Bakan naa ni Sanwo-Olu fi erongba rẹ han, lati wọgile ofin sisan owo ifẹhinti fawọn Gomina tẹlẹ nipinlẹ Eko ati igbakeji wọn.
Ile-ẹjo tẹẹkotọ ti pase pe ki adari awon agbofinro lorile ede Naijiria
Oríṣun àwòrán, @omoh___tee Dokita ọhun pari ọrọ rẹ pe awuyewuye iṣẹ Omohtee ti mu ki oun padanu iye owo to le ni ọgọrun un miliọnu naira, yatọ si pe ijọba ti gbe ile iwosan oun ti.
Àwọn tí wọ́n dìtẹ̀ mọ́ ọba ni Sabadi, ọmọ Ṣimeati ará Amoni, ati Jehosabadi ọmọ Ṣimiriti ará Moabu.
Awọn nọmba pajawiri ti ẹ le pe ni 08000CORONA, 08023169485,08033565529 tabi 08052817243.
Níbẹ̀ ni ààlà ilẹ̀ wọn ti yípo lọ sókè sí apá ìwọ̀ oòrùn, ó sì wá sí apá ìlà oòrùn Jokineamu.
Nígbà tí wọ́n kọ́kọ́ dé ibẹ̀, wọn kò bẹ̀rù OLUWA, nítorí náà OLUWA rán àwọn kinniun sí ààrin wọn, wọ́n sì pa ninu àwọn eniyan tí ọba Asiria kó wá.
Ọrọ naa yoo gba oye, nitori ki wọn to le ri aarẹ yọ, pupọ ninu awọn aṣofin ni yoo tẹwọgba aba naa.
Ohùn OLUWA ń fọ́ igi kedari,OLUWA ń fọ́ igi kedari ti Lẹbanoni.
 Ilu Goma mu ala pẹlu orile ede Rwandan.
OLUWA ń bọ̀ pẹlu àwọn ohun ìjà ibinu rẹ̀,tí yóo fi pa gbogbo ayé run.
Ikọ́ lásán ló pa Orisabunmi"" Wo ohun tó ṣẹlẹ̀ sí àwọn ọba tó kọ ifá sílẹ̀ gbé Bíbélì àti Kùránì Ọdún méjì, wàhálà méjì lójúbọ Osun Osogbo, Njẹ́ o mọ̀ pé bíi ọdún 700 sẹ́yìn ni wọ́n ti ń bọ Osun-Osogbo?"
Lara awọn to tẹle arabinrin  Bennet ni adele fun asoju orile ede Amerika , Aruna Amirthanayagam; Negussie Mengisha,adari ekun VOA ni  Afirika ati Aliyu Mustapha, ti o  jẹ  igbakeji adari ni eka ede VOA Hausa ati awọn miiran.
Wọ́n sì fún àwọn ìlú tí wọn tún kọ́ ní orúkọ mìíràn.
Daura jẹ ilu abinibi Aarẹ Muhammadu Buhari, ibẹ lo si ti lo eyi to pọju ninu ọjọ aye rẹ.
Oríṣun àwòrán, @BashirAhmaad Àkọlé àwòrán, Buhari fun ileeṣẹ eto idajọ, ajọ NHRC pẹlu ọga agba ileeṣẹ ọlọpaa lorilẹede Naijiria ni gbedeke oṣu mẹta Ibeere to wa n gbẹnu ọpọ kan ni pe, o daa o, bi aarẹ ko ba gbe igbesẹ yii, awọn wo lo wa wa nidi iroyin ẹlẹjẹ eyi to fun araalu ni ọpọ idunnu fun akoko diẹ lọjọ aje ọjọ kẹta oṣu kẹfa ọdun 2019?
Ohun tó yẹ kí o mọ̀ nípa ìgbésẹ̀ tí Amẹ́ríkà fẹ́ gbé lórí Nàìjíríà nítorí ọ̀rọ̀ ẹ̀sìn Àwọn èèyàn tí bẹ̀rẹ̀ sì ní gba abẹ́rẹ́ àjẹsára fún ìdènà àrùn Coronavirus ni ilẹ̀ Gẹ̀ẹ́sì Mi ò kí n ṣe afẹfẹ-yẹ̀yẹ̀ lórí ayélujára nítorí pé mí ò ní dúkìá tí mó le fihàn- Ronke Oshodi-Oke Lóòtọ́ ni ọkọ mi lù mí bí àṣọ òfì, àmọ́ gómìnà ti bá wa parí ẹ̀, ẹ máa gbàdúrà fún ìdílé mi- Dokita Ifeyinwa Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí APC NEC Meeting: Ẹkúnrẹ́rẹ́ ọ̀rọ̀ ìkini PDP sí APC bí àwọn adarí ẹgbẹ́ lápapọ̀ ṣe túká rèé8 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Borno Zabamari Massare: Àjọ NCC fẹ́ tú ìwé owó àwọn olúpèsè ìtàkùn ìbánisọ̀rọ̀ wo10 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 UK Covid Vaccine: Abẹ́rẹ́ àjẹsára Covid-19 yóò dé sí Nàìjíríà nínú oṣù kíní ọdún 202116 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Andrew Haruna: So-bàtà tó di ọ̀jọ̀gbọ́n fásitì tó di ọ̀gá àgbà9 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Ooni Ile Ife: Ooni Adeyeye Ogunwusi àti Olòrì Naomi gbé Àrẹ̀mọ tuntun wọ ṣọ́ọ̀ṣì21 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Secret Cults in Nigeria: Ìyá àti ọmọ tó wà nínú Márúwá bá ìjà ẹgbẹ́ òkùnkùn lọ10 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Oríṣun àwòrán, Twitter/Pastor Tunde Bakare Pasitọ Bakare ni ṣọọṣi nikan kọ ni ijọba fofin de, o ni o kan mọṣalaaṣi naa.
Wo ìpọ́njú ati ìdààmú mi,kí o sì dárí gbogbo ẹ̀ṣẹ̀ mi jì mí.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Àgbà ni Obasanjo, oun tó ń sọ yé e, ìjọba ni kó tají - Wale oke Àwọn ipò òṣèlú tó ti dì mú rí: Ọdun 2003 ni Sanwo Olu bẹ̀rẹ̀ òṣèlú nígba tí igbákejì gomina Ipinlẹ Eko nígbà kan rí Femi Pedro yàn án gẹ́gẹ́ bíi olùdámọ̀ràn pàtàkì lórí ọ̀rọ̀ àwọn iléeṣẹ́ àdáni.
Fọnran fidio ti Malema fi gbamọran yii ni Ayisha Buhari, iyawo aarẹ Mohammadu Buhari ti a ṣẹṣẹ dibo yan lẹẹkeji ni Naijiria naa fi soju opo twitter rẹ.
Bí Satani bá ń lé Satani jáde, ara rẹ̀ ni ó ń gbé ogun tì.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Coronavirus: Ilé ijó Fẹla Anikulapo, New Africa Shrine gbé ìlẹ̀kùn rẹ̀ tì pa nítorí àrùn Coronavirus 18 Ẹrẹ̀nà 2020 Oríṣun àwòrán, NEW AFRIKA SHRINE Ni bayii ti olukuluku ileeṣẹ, awujọ ati orilẹede n gbe igbesẹ gbogbo lati dena itankalẹ arun coronavirus, ile ijo ogbontagi olorin ni Fẹla Anikulapo kuti ti gbogbo aye mọ si New Africa Shrine ti gbe ile ijo naa tipa.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Taxi Lady: Bùkátà pọ̀ lọ́rùn mi ní mo ṣe ń wa taxi akérò Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Taxi Lady: Bùkátà pọ̀ lọ́rùn mi ní mo ṣe ń wa taxi akérò 21 Ọ̀wàrà 2019 Ohun ti ọkunrin lee se, obinrin miran lee se daradara ju ọkunrin lọ, idi si ree ti obinrin kan Princess Igbafe fi yan isẹ awakọ ero taxi laayo.
Àlàyé rèé lórí ááwọ̀ Femi Fani-Kayode àti Tunde Bakare 30 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Oríṣun àwòrán, Ffk/ fan page Mínísítà fún ọ̀rọ̀ ilé iṣẹ́ ìrìnà ojú òfúrú nígbàkan rí, Femi Fani-Kayode ti tún fi ọ̀rọ̀ léde lórí aáwọ̀ tó wà láàrín òun pẹ̀lú pásítọ̀ Tunde Bakare.
”OLUWA dáhùn pé, “Ṣebí tẹ̀gbọ́n-tàbúrò ni Esau ati Jakọbu?
Ogbeni Olufemi Odumosu to je adari ajo idagbasoke Ogun–Osun yii ni ipinnu ipinle Ogun lati gbe igbese akoni yii yoo mu ere wole fun ekun naa lati apo ijoba apapo ati tawon olupese iranwo miran ni agbaye.
Ofin tuntun naa ṣe afikun iye owo ti awọn ẹni ti wọn ba mu pe oun sọrọ kubakugbe yoo ma a san lati N500,000 si N5m.
Àwọn ẹgbẹ́ ọmọ ogun meji yòókù sáré sí gbogbo àwọn tí wọ́n wà ninu pápá, wọ́n pa wọ́n.
Omowe Tunde ti ori pada ko yọ lọwọ awọn Fulani ajinigbe yii sọ fun BBC pé o yẹ ki gbogbo wa jọ gbogun ti awọn Fulani to n ṣiṣẹ ibi yii atawọn Yoruba to n kín wọn lẹyin.
Owo ori ẹya epo rọbi West Texas Intermediate (WTI) to jẹ odinwọn owo epo lorilẹede Amẹrika ti ja lọlẹ si dọla mẹtadinlogoji lori jala kan.
Ọ̀pọ èèyàn ni kò mọ pe arẹwà obìnrin náà la ọpọ ìṣòro kọjá, ẹni ta sì ro pe kò le è pagọ ni, tó sì di ẹni tó ń kọlé alárrinrin lónìí.
Nítorí ìbẹ̀rù fún ààbò àwọn àlejòo rẹ̀, Shabuyeva fagilé ìfọ̀rọ̀wánilẹ́nuwò náà tí ó sì fi ètò mìíràn rọ́pòo rẹ̀.
Eliṣa kú, wọ́n sì sin òkú rẹ̀.
O ti le loṣu kan ti gbọnmi si i omi o to laarin Toyin Abraham ati Lizzy ti bẹrẹ ni kete ti Toyin bimọ tan tija naa si da lori mo ki ọ tabi mi o ki ọ ku ewu ọmọ lo ba di tọrọ fọn kalẹ.
Adeboye sọ̀rọ̀ lórí ètò pápá ìjẹko RUGA Kí ni ó gbé ọlọ́pàá dé ibi àjọ̀dún ọjọ́ ìbí i Bobrisky?
BBC Yorùbá jáde lọ fọrọ wa awọn oṣiṣẹ-fẹyinti ti ijọba n ṣe ayẹwo fun lẹnuwo lori ohun ti o n ṣẹlẹ nibi ayẹwo iwe wọn naa.
 Isoro ti o wa ni pe, odaran kan wa ti oruko n
“Nítorí náà, ẹ ṣọ́ra nípa bí ẹ ti ṣe ń gbọ́ràn, nítorí ẹni tí ó bá ní ni a óo tún fún sí i, ṣugbọn lọ́wọ́ ẹni tí kò bá ní ni a óo ti gba ìwọ̀nba tí ó rò pé òun ní.
Ó jẹ́ ará Arimatia, ìlú kan ní Judia.
Pé èniyàn ni ara li le tàbi ó lè jẹun, ó tó nkan.
Olórí òṣìṣẹ́ ìjọba àpapọ̀ Ọ̀mọ̀wé Folashade Yemi-Esan ló fi ìpè naa síta pé ẹnikẹ́ni tí ìjọba ba mú yóò fẹnu fẹ́ra.
Mú díẹ̀ ninu èyí tí o dì sí etí ẹ̀wù, jù ú sinu iná kí ó jóná; iná yóo sì ti ibẹ̀ ṣẹ́ sí gbogbo ilé Israẹli.
Ilé alájà méjì wó lu ọmọ mẹ́rin ni Bariga Wọ́n ti dóòlá ẹ̀mí ẹni tó há sábẹ́ àwókù ilé l‘Eko Ilé alájà mẹ́ta wó pa onímọ̀ ẹ̀rọ́ tó ń kọ́ ọ lọ́wọ́ Wọ́n dóòlà ẹ̀mí èèyàn mẹ́rin níbi ilé mííràn tó wó l'Eko Gẹgẹ bi awọn ileeṣẹ iroyin Naijiria kan ti ṣe sọ,ni nkan bi ago mẹrin kọja diẹ lowurọ ni ile naa dawo nigba ti awọn olugbe rẹ ṣi n sun lọwọ.
Ewe, bi a ko ba gbagbe, aare ti wa lorile-ede France lati ojo Eti(Friday), ti n se ojo kesan an osu kokanla odun yii, nibi ti o ti lo se ipade apero alaafia ti orile-ede France sagbekale.
O dun mi pupọ debi i pe mo sun ẹkun, laipẹ ẹkun naa di ibinu.
 Ó jé mínísítà lábẹ ́ Ìsàkóso Ààrẹ mùhámádù bùhárí .
O fikun ọrọ pe ko yẹ, ko lẹtọọ ki ruga wa lawọn ipinlẹ tawọn Fulani darandaran ti jẹ alejo.
Naijiria si ni o ni akọsilẹ ẹni akọkọ to ni aarun Coronavirus lagbegbe ilẹ olooru Afirika.
" "" nítorí ibe ìdàgbàsòkè re sù ìlú Ègbá ni oba Àláké se fí jè Ìjatóde ìlù ."
Eyi to si mu ki ọpọ o maa beere pe iha wo gan an ni ijọba Naijiria kọ si ọrọ naa.
Awọn méji oun ti rín irin ajò lọ si olrilẹ̀-èdè UK àti Germany, súgbọ̀n kìí se ilú Eko ni wọ́n de si báyìí.
“Ẹ kò gbọdọ̀ máa wo mààlúù tabi aguntan arakunrin yín, kí ó máa ṣìnà lọ, kí ẹ sì mójú kúrò, ẹ níláti fà á tọ olówó rẹ̀ lọ.
"Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Àṣìṣe ọlọ́pàá àti Adájọ́ sọ mí di ẹni tí wọ́n dájọ́ ikú fún, ọpẹ́lọpẹ́ Fayoṣe tí ko buwọlu ""Ija yii pọ debi i pe, awọn obi mi wa ba mi ko ẹru mi kuro nile rẹ."
Lẹ́sẹ̀ kan ló dìde, tó gba ilé ọ̀rẹ́ rẹ̀ tó ṣaláìsí lọ.
Man U tete gba ara wọn silẹ ninu ina ogun ti Man City kọkọ da ni ibẹẹrẹ idije naa, lati igba naa ni wọn si ti n ṣe daada nigba ti idije naa wa laarin iṣẹju mẹẹdogun si ogun isẹju abala akọkọ.
Wọ́n ti dáwọ́ ìdánwò àbẹ́rẹ̀ àjẹsára Oxford dúró lẹ́yìn ti olùkopa kan ṣàìsàn Ìdí tí mo ṣe se oúnjẹ nínú ilé ẹni tí mo lọ jà lólè rèé- Afurasí adigunjalè Kí ló le è mú kí agbábọ́ọ̀lù subú, kó sì kú lásìkò ìfẹsẹ̀wọ̀nsẹ̀?
Atamatase tẹlẹri fun ẹgbẹ Chelsea Diego Costa ni adari idije juwe ile fun nigba to gba kaadi alawọ pupa ni iṣẹju kẹtadinlọgbọn ifẹsẹwọnṣẹ naa.
meji to ti feyinti lo sile ejo fun iwa apaniyan , gbigba ọkọ ayọkẹlẹ meji lona
83 trillion tí Buhari gbé kalẹ̀
Aarẹ Buhari ni, oun gba pe ajọṣepọ wa laarin ìṣẹ́, eto ọrọ ajé ti ko daa pẹlu iwa jẹgudujẹra, lai yọ eto aabo ti ko fini lọkan balẹ silẹ.
” Wọ́n dá a lóhùn pé, “Àwa náà yóo bá ọ lọ.
World Malaria Day: Ǹjẹ́ o mọ ohun tó ń mú àìsàn ibà pànìyàn?
Awọn akọnimọọgba wọn kii gba owo deede, bẹẹni awọn agbabọọlu ti kọ lati lọ fun igbaradi lasiko awọn idije komẹsẹoyọ (qualifiers) tabi ni awọn idije pataki nitori airi owo ajẹmọnu gba.
Awọn agbaagba ilu ni nise ni awọn eniyan fi'luu lẹ nitori ipenija omi abuwẹ abumu.
Peter Nwaboachi, tó jẹ́ alága ìgbìmọ̀ tẹ̀ẹ́kótó ilé lórí ọ̀rọ̀ Niger Delta lónìí ọjọ́ ajé, sọ pé ko si 'òòtọ́' kan nínú ọ́rọ́ ti mínísítà sọ.
Ó dájú pé wọn á gbọ́ pé o ti dé.
Ni ojo kejidinlogbon osu kejila odun 2018 ni gomina ti gbe eto isuna owo fun odun 2018 ti iye re din die logorun bilionu Naira siwaju ile-igbimo asofin ipinle naa, eyi ti won fowo si lojo kejila osu keji odun 2018.
“Ààlà ìhà ìlà oòrùn yín yóo gba ẹ̀gbẹ́ Hasari Enani lọ sí Ṣefamu.
A mọ̀ pé ohunkohun tí Òfin bá wí, ó wà fún àwọn tí ó mọ Òfin ni, kí ẹnikẹ́ni má ṣe rí àwáwí wí, kí gbogbo aráyé lè wà lábẹ́ ìdájọ́ Ọlọrun.
Ajá rẹ̀ náà ń gbọ̀nrù tẹ̀lé wa.
" Ṣaaju iṣẹlẹ naa ni gomina tẹlẹ nipinlẹ Ọyọ, Sẹnetọ Rasheed Ladọja ati Engr Seyi Makinde parọwa sijọba ipinlẹ Ọyọ ninu atẹjade ọtọọtọ, lati mase wo ileesẹ redio naa, .
Ẹ fi ọpẹ́ fún OLUWA nítorí pé ó ṣeun,ìfẹ́ rẹ̀ tí kìí yẹ̀ sì wà títí lae!
Àwọn ará Gibeoni bá ranṣẹ sí Joṣua ní àgọ́ tí ó wà ní Giligali.
Nígbà tí àwọn ọmọ náà dàgbà, Esau di ògbójú ọdẹ, a sì máa lọ sí oko ọdẹ nígbà gbogbo, ṣugbọn Jakọbu jẹ́ eniyan jẹ́jẹ́, ilé ni ó sì máa ń sábà gbé ní tirẹ̀.
Arsenal ti padà júwe ilé fún Unai Emery EFCC fẹ́ gbẹ́sẹ̀ lé ilé tí mo fi owó ìfẹ̀yìntì kọ́ nílùú Ilorin- Saraki Ẹ wo iye t'óúnjẹ dà báyìí lọ́jà lẹ́yìn tí ìjọba ti ibodè Ilé ìwòsàn New Jersey ṣ'àṣìṣe ṣiṣẹ́ abẹ kìndìrín fún aláìṣàn l'Amẹrika Aarẹ Buhari ni iṣẹ akanṣe naa yoo ṣeranwọ fun ẹka iwakusa, ina mọnamọna, eto ilera, eto ọgbin, ipese omi ati eto ẹkọ to gbooro fun awọn ọmọ Naijiria.
“ ‘Ẹni ìfibú ni ẹnikẹ́ni tí ó bá pa aládùúgbò rẹ̀ níkọ̀kọ̀.
Ẹ wọ aṣọ ọ̀fọ̀, kí ẹ sì sọkún, ẹ̀yin alufaa,ẹ sọkún tẹ̀dùntẹ̀dùn,ẹ̀yin tí ẹ̀ ǹ ṣiṣẹ́ ní ibi pẹpẹ ìrúbọ.
Inú ọba a máa dùn sí olódodo,ọba sì máa ń fẹ́ràn àwọn tí ń sọ òtítọ́.
Wọ́n mú àwọn ohun tí Mose paláṣẹ wá siwaju Àgọ́ Àjọ, gbogbo ìjọ eniyan sì dúró níwájú OLUWA.
 Ó máa ń jobì tó fi ataa sínú rẹ ̀ .
Ǹkan tí òògùn náà ń ṣae ni pé ó maa n mú àdinkù bá àwọn ọmoogun tó ń jà nínú ara.
Ajakaiye ni Gomina yoo fi aba iyipada naa ṣọwọ si awọn aṣofin lọṣẹ to n bọ, lati ṣe ayipada ofin ni kiakia.
Ó mú kí ẹ fi ìtara mú ọ̀rọ̀ náà, kí ẹ sì jà fún ara yín.
Láti ibẹ̀ ni Abrahamu ti lọ sí agbègbè Nẹgẹbu, ó sì ń gbé Gerari, ní ààrin Kadeṣi ati Ṣuri.
 Àwọn tí ó lọ ṣe àtìpó ní europe ( Úróòpù ) , Àmẹ ́ ríkà ( usa ) àti ààrin gbungbun ìlà-oòrùn àgbáyé ( middle east ) náà ń sọ èdè náà .
Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí James Bond: Gbajúgbajà òṣèré, Sean Connery tó ṣe fíìmù James Bond tí jáde láyé lẹ́ní ọdún 9031 Ọ̀wàrà 2020 Fídíò, Soyinka Cancer: Àṣe ara mi ni iso ti n run gbogbo bí mo ṣe n ṣèrànwọ́ lórí jẹjẹrẹ27 Bélú 2019 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Akonimoogba agba iko Super Eagles, Gernot Rohr ti se atunse si iko ti o fagbahan iko agbaboolu Poland, leyin ti o ropo agbaboolu merin lara iko ti yoo koju orile-ede Serbia.
Ìdẹ̀ra dé, Gẹnẹrátọ̀ tó ń lo omi dé, a bọ́ lọ́wọ́ òkùnkùn Iṣẹ́ ọpọlọ ló yẹ ká ṣe nínú tíátà, kìí ṣe àfihàn ara bíbó àbí ìhòòhò wa - Binta Mọgaji Ìjọba, ẹ yé fi ọlọ́pàá àtàwọn ológun dúnkokò máwọn èèyàn- Ṣoyinka Irọ́ ló pa, a kò mọ̀ ọ́ rí tàbí fún ọ ní ₦13m - APC tako afurasí ajínigbéAṣírí ìdí ti El-Zakzaky fi padà si Nàìjíríà láti India Gẹgẹ bi iroyin naa ti wi ọmọ Yoruba mẹrindinlogun lo wa ninu orukọ eeyan mẹtalelogun ti ijọba Saudi Arabia kede pe awọn yoo yẹgi fun lori ẹsun gbigbe oogun oloro.
”Delta Flickers lo wa loke tente tabili akoko ninu idije ohun pelu ami mefa, ti Kano Flickers si ti jade kuro ninu idije ohun latari pipadanu eemeji otooto ninu idije naa.
Oludari fun alakoso egbẹ ajafẹtọ Coalition of Human and Civil Rights Organizations(COHCRO) Comrade Sulaiman Adeniyi lo sọ eyi lasiko to n ba ikọ ile isẹ BBC Yoruba sọrọ.
Dafidi rán oníṣẹ́ náà sí Joabu pé, “Má ṣe jẹ́ kí ọ̀rọ̀ yìí da ọkàn rẹ rú níwọ̀n ìgbà tí ó jẹ́ pé ẹnikẹ́ni kò lè mọ ẹni tí ogun yóo pa.
O ni ko sẹni to le yọ oun nipo rara nitori pe awọn to ni ifẹ oun lo dibo yan oun wọle.
Àwọn ọlọ́lá kì í fẹ́ẹ́ rìn ìrìn ẹni lásán, olówó kì í fẹ́ẹ́ rin ìrìn tálákà, bẹ́ẹ̀ ni àwọn obìnrin fẹ́ràn fáàrí gidigidi.
Ogbeni Dogara soro naa di mimo
Ẹ̀tẹ̀ ṣòro lati wòsàn ju làpálàpá lọ, ibàjẹ́ ló yára lati ṣe ju lati tú nkan ṣe lọ.
Ninu atẹjade kan ti agbẹnusọ rẹ fi sita, Obasanjo ni aṣeyọri Biden jẹ aṣeyọri daada lori aburu ati pe aṣeyọri Biden kii ṣe ti Amrika nikan bi kii ṣe ti gbogbo agbaye.
Bí ó bá fọhùn, omi á máa rọ́kẹ̀kẹ̀ lójú ọ̀run,ó mú kí ìkùukùu gbéra láti òpin ayé,òun ni ó dá mànàmáná fún òjò,tí ó sì mú afẹ́fẹ́ wá láti ilé ìṣúra rẹ̀.
67 Kíyèsíi, èyí ni ẹ̀kọ́ mi—ẹnikẹ́ni tí ó bá ronúpìwàdà tí ó sì wá sí ọ̀dọ̀ mi, òun kannáà ni ìjọ mi.
Ó fún ẹ̀yà kọ̀ọ̀kan ní ìpín tirẹ̀.
Ṣe ni arabinrin Ebun Ekemode n darukọ awọn to ba iṣẹlẹ naa rin ni kọọkan.
Chelsea tún ṣubú dàánù sọ́wọ́ Liverpool Manchester United dáná sun Chelsea bi ẹràn àgbò iléyá Nigba ti ere gbogbo yoo fi pari, Arsenal lo gbogo ọjọ naa lọwọ Pẹlu bi ifẹsẹwọnsẹ yii ṣe pari yii, ikọ Arsenal ti sọ Burnley di kọstọma daadaa ni Arsenal lo kọkọ gba bọọlu wọ inu awọn nigba ti ifẹsẹwọnsẹ naa wọ iṣẹju mẹtala.
Aare Buhari ni ajo to n mojuto ise ogbin ati ile-ifowopamo ti ijoba apapo yoo fowosowopo lati ran awon omo orile ede yii lowo to ba nifee si ise agbe.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Omidan jáde láyé lẹ́yìn tí ìlú lù ú, jáa sí ìhòhò lórí ẹ̀ṣẹ̀ tí kò ṣẹ̀ Pẹlu abajade ija naa, Romero ti padanu marun ninu ija mejidinlogun to ti ja, mẹtala ninu rẹ lo bori.
Ọkan ninu awọn ọmọ ẹgbẹ darandaran jadejado orilẹede yi, Miyetti Allah Cattle Breeders Association of Nigeria ti ipinlẹ Kano sọ fun BBC pe awọn Fulani ni ipinlẹ naa n gbadun ọfẹ ati awọn ipese fun awọn ẹran wọn.
Ọ̀wọ́ EFCC tẹ ayédèrú Babaláwo pẹ̀lú òògùn abẹnugọ̀ǹgọ̀ Ìgbà ọ̀tun dé!
N kò le è wo ìfọ̀rọ̀wọ́rọ̀ náà ju ibi mo wò ó dé lọ, mo sì pa ẹ̀rọ amóhùn-máwòrán.
Amọ Ọgbẹni Oladoyin fidi rẹ mulẹ pe ijọba ipinlẹ Osun yoo kọwe si ajọ WAEC lati sun idanwo naa siwaju pẹlu ọsẹ meji ki awọn le gbaradi daadaa fun idanwo naa.
a ti ṣe ìṣirò pé ó fẹ ́ rẹ ̀ tó ènìyàn mílíọ ̀ nù méje sí mẹ ́ wàá tó má a ń ní àkóràn àrùn leptospirosis lọ ́ dún .
 Baalẹ Ajegunlẹ naa beere fun pipese omi si agbegbe wọn.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Miyetti Allah ní kí wọn wọ́gilé Amotekun, Sunday Igboho yarí Laycon, kú oríire àmọ́ bá ń kó owó orí nínú ẹ̀bùn rẹ nílé BB Naija - Ìjọba Eko Boko Haram gbọ̀nà àrà yọ, kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ ló so àdó olóró mọ̀ láti kọlu Gómìnà Borno Ìṣòro jíjẹ́ ìyá n dáàgbé ló sọ mí di àtúnbí krístíẹ́nì - Remi Tinubu Kí ló ń fa wàhálà láàrín Kunle Afolayan àti Mike Ezuruonye lórí ayélujára?
Núdúlù ní ounjẹ tó bá ofin mu ti wọn maa ń ta lagbà ẹwọn ní orilẹ̀-èdè Ameríkà Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ìkòkò núdùlù jẹ ó gbóná fẹlif-fẹli lógbàẹwọn US Nínú ìwádìí to wáyé láìpẹ́ yìí sàfihan pé núdúlù ti gbààyè sìgá bó ṣe jẹ ọ̀jà títà to wọ́pọ̀ nínú ọgba ẹwọn US Bí wọn ṣe di owó ìtójú àwọn ẹlẹ́wọn kù, ọ̀pọ̀ àwọn ẹlẹwọn ni wọn rí ounjẹ to to fún àmúsgbára pẹ̀lú ore-ọ̀fẹ́ ti wọn ni láti jẹ Nudùlù 7.
Ènìyàn méjì ni Ebola ti pa ní orílẹ̀-èdè DR Congo láàrin oṣẹ̀ mẹ́jì, Goma to kún fọ́fọ́ fún ọ̀pọ̀ àwọn ní wọn ti rí ènì ti ó ni ààrun náà.
Ewe, idije boolu agbaye ohun yoo bere gbara lati ojo kerinla osu yii, titi di ojo karundinlogun inu osu keje odun ti a wayii lorile-ede Russia, eleyi ti o je igba akoko ti orile-ede ohun yoo sagbateru idije boolu agbaye.
O fi kun un pe awọn oṣiṣẹ yoo ṣiṣẹ pọ pẹlu Amẹrika lati fi kun amojuto abo wọn.
Ìjọba àpápọ̀ ìlúu Gẹ̀ẹ́sì ló ṣẹ ètò àti kó ọ̀pọ̀lọpọ̀ àwọn ẹranko sí inú igbó nlá káàkiri ìlú.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Orilẹ-ede Naijiria ti kede pe ẹlomiran tun ti ni aarun Coronavirus nilu Eko.
Mo fẹ ki ọmọ mi mọ mi bayii lati kekere rẹ.
Sẹnatọ kan lorilẹede Naijiria n gba iye owo to to Millionu ẹrindinlọgọji naira lọdun.
Awọn osisẹ to si ti de ibi isẹ ni wọn gan sare gbe ilẹkun ọọfisi wọn ti, ki wọn lee tete pada sile ki ohun gbogbo to fọnna soju.
Àwọn olóṣèlú ló fẹ́ sọ darandaran Fulani lórúkọ burúkú, àwa kìí gbébọn-Miyetti allah
Iyẹn dẹ lo jẹ akọkọ ninu ọpọlọpọ ti wọn wa n pe awọn ado oloro ti Joe""."
Awọn iroyin ti ẹ lee nifẹẹ si: Gomina Ambode buwọlu aba isuna ti o le ni trillionu kan naira APC: Afikun ba saa Oyegun gẹgẹbii alaga Aba naa, ti gomina ipinlẹ Kwara, Abdulfatai Ahmed fi sọwọ sile asofin naa, lo wa lati se agbeyẹwo ofin kan eyi to buwọlu igbesẹ sisan owo ifẹyinti fawọn gomina tẹlẹ nipinlẹ naa tawsn igbakeji wọn lẹyin ti saa wọn ba pari.
Àwọn tí wọ́n nà kalẹ̀ lórí ìrọ̀gbọ̀kú wọn, tí wọn ń jẹ ẹran ọ̀dọ́ aguntan, ati ti ẹgbọ̀rọ̀ mààlúù láti inú agbo ẹran wọn!
Wọn ni ti awọn ba ṣe eto silẹ tabi si awọn ilu ti iru awọn isẹlẹ yii ti n waye, wọn ko ni gburo rẹ mọ lailai.
 túndé atọ ̀ pinpin àti ẹ ̀ gbọ ́ n rẹ ̀ máa ń sùn ní ilé Àkàngbé nígbà ti wọ ́ n bá ń lọ sí ìhà odò Ọya .
Ẹwẹ, Aidara ni o ti, oun kọ lo kọ ọ.
Samuẹli bá bá a pada, Saulu sì sin OLUWA níbẹ̀.
Ní ọdún 2012, ìjọba ìbílẹ̀ yìí kan náà ló fún olùdíje dupò lábẹ́ ẹgb òṣèlú Labour Olusegun Mimiko láti wọlé fún sáà kejì, o rí ìbò tó dín díẹ̀ ni ẹgbẹ̀rún lọ́nà ààdọ́ta.
Wọ́n tó fi ṣe fọ̀rífọ́rí, wọ́n dúró bí alágbára, ọkàn wọn balẹ̀ bí ẹni tí ó gbẹ́kẹẹ̀lé Olódùmarè, wọ́n le bí akọ òkúta nínú ìpinnu wọn, ọkàn wọn ti hu iyẹ̀ ó fò kúró nínú ilé pẹ̀lú ìfàsẹ́yìn ibẹ̀, ó lọ sí ẹ̀yìn odi ọ̀run.
Lasiko ijoko ile to waye lọjọru ni Lawan kede igbesẹ yii.
O ní nibayìí àwọn alaga fidhẹ ti Makinde yan yóò ppada si ẹnu iṣẹ́ ti gbogbo ǹkan yóò si maa lọ ni ìrọwọrọṣẹ ni ìpińlẹ Oyo.
Agriculture IITA) ti ri ohun itoju  ti
 “okan Pataki to tun je ijoba yii  logun ni lati gbokun ti iwa ibaje jegudu-jera lorile ede yii.
" Osinbajo kò gbàdúrà ikú fún Buhari lórí àìsàn, ẹ sinmi ìbàjẹ́- Agbẹnusọ Osinbajo Àwọn tó jí ọmọ mi gbé nílé ìjọsìn ní ń kò gbọdọ̀ wa tàbí kí ẹ̀mí mi lọ si"" Àmì ayò 2-1 ni Naijiria fi ṣàgbà Benin Republic Ẹ dẹ́kun àbùkù tẹ fi ń kan Nàíjíríà, ẹ fi Sowore sílẹ̀ láhàmọ́- Soyinka Florence ṣalaye pe awọn mẹwaa lo ṣeṣe ninu ijamba ọkọ ọhun, ọkunrin mẹrin ati obinrin mẹfa."
Eyi ni igba ẹlẹẹkeji ti iroyin yoo ma yipada nipa ohun to ṣẹlẹ si ẹṣọ yi.
Amasaya pa ẹgbaarun (10,000) ninu àwọn ọmọ ogun Edomu ní Àfonífojì Iyọ̀.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Mori ara mi to funfun, mi o mọ pe ẹtẹ ni Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Megabite: Ilé-ìwé ni mo ti bẹ̀rẹ̀ orin kíkọ Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 3 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 5 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Wo bí àwọn fàyàwọ́ ṣe ń kó ìrẹsì wọ Nàìjíríà Àjọ DSS tọrọ àforíjìn lórí ìwà ti wọ́n hù nílé ẹjọ Àjọ ọ̀tẹlẹ̀múyẹ́ ń se ojúṣe wọn lórí ọ̀rọ̀ Soworẹ ní-Ilé iṣẹ́ ààrẹ Anthony Joshua darapọ̀ mọ́ Mohammed Alli, Lenox Lewis ati Holyfield Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Èyí ni ìtàn bí ẹni tí mó gbọ́njú mọ̀ bíi bàbà ṣe fipá bá mi lájọṣepọ̀ Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Eléyìí kò jẹ́ kí á tètè jà bí o ti yẹ.
Bí Babiloni tilẹ̀ ga tí ó kan ojú ọ̀run,tí ó sì mọ odi yí àwọn ibi ààbò rẹ̀ gíga ká,sibẹsibẹ n óo rán apanirun sí i.
Àjọ ìgbìmọ̀ àwọn àgbààgbà ẹkùn àríwá Naijiria, NEF fi àtẹ̀jáde síta pé ààrẹ Buhari tí kùnà nínú ìṣèjọba Naijiria.
" Fadeyi tẹsiwaju pe ariwo obinrin naa lo mu ki ọkọ rẹ sare jade lati inu ile, to si ba iyawo rẹ ninu agbara ẹjẹ, ti awọn eeyan to sisẹ laabi naa si ti fẹsẹ fẹ ẹ.
Ṣé kí ó tó ìgbà meje?
Wọn sọ nipa awọn nkan to ni ṣe pẹlu ibeere, awọn gbajugbaja eeyan, olorin, ere fiimu ati iroyin tawọn eeyan n wa nipa rẹ.
O gbe awo kan jade to pe akọle rẹ ni EP Lagos, bakan naa lo ba ilumọọka Olamide kọwọrin ninu orin ti akọle rẹ jẹ Warri."
Bíi kí ẹja kó sinu àwọ̀n burúkú, tabi kí ẹyẹ kó sinu pańpẹ́, ni tàkúté ibi ṣe máa ń mú eniyan, nígbà tí àkókò ibi bá dé bá wọn.
Àgbàlá ati ilé náà pẹlu ògiri rẹ̀ gùn ní ọgọrun-un (100) igbọnwọ (mita 45).
Ṣugbọn o fi Naijiria silẹ lọdun ni 2017 latari airi ere jẹ, gbese gọbọi atawọn nnkan miran.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Oun tí Kunle Afolayan ṣe sí mi, mi ò lè ṣeé sí i' Ọmọ ọdún mẹ́tàlá ni Omololu nigba ti baba rẹ dagbere fàyè, síbẹ̀, ó kàwé de ipò ọmọwe (PhD) èyí to gba nílé ẹ̀kọ́ Fáṣitì St.
3 Kíyèsíi, oko náà ti funfun tán fún ìkórè, nítorínáà ẹnikẹ́ni tí ó bá fẹ́ láti kórè, ẹ jẹ́ kí ó fi dòjé rẹ̀ pẹ̀lú ipá rẹ̀, kí ó sì kórè nígbàtí ọjọ́ sì wà, kí ó le kó ìgbàlà àìlópin pamọ́ fún ọkàn rẹ̀ nínú ìjọba Ọlọ́run.
Risikat, ìyá àwọn ọmọ olójú búlù tí bẹ̀rẹ̀ sí ní kọ́sẹ́ aṣojú lóge Ìjọ́ mí ní Italy ni mo fi ń ṣèrànwọ́ fáwọn aṣẹ́wó ọmọ Nàíjíríà tó há - Taribo West Ẹgbẹ́ akẹ́kọ̀ọ́ gíga n‘Ibadan ṣèwọ́de lọ iléeṣẹ́ ọlọ́pàá lórí afurasí tó dàwátì Wo ibùdó arẹwà tí ọ̀pọ̀ èrò ń ya lọ ní Abuja Oríṣun àwòrán, Others Ooni Ifẹ bu ẹnu ẹ̀tẹ́ lú ètò BBNaija nítorí ó tàbùkù àsà YorubaOoni ti Ile Ife, Oba Adeyeye Ogunwusi, Ojaja II ti ni ki ijọba Naijiria gbekile eto Big Brother Naija, ki wọn si fi eto miran rọpọ rẹ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ondo Election 2020: Ẹ wo àwọn olùdíje sípò gómìnà nípínlẹ̀ Ondo tó takò bàbá ìsàlẹ̀ 24 Owewe 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 26 Owewe 2020 Awọn oludije ninu idibo sipo gomina ni ipinlẹ Ondo ti s fun ara ilu ohun ti awọn yoo ṣe.
Nígbàmíràn tí kò bá si oúnjẹ nílé, wọ́n a máa ra oúnjẹ àárọ̀ aláràjẹ lọ́nà.
Àwọn ọmọ-ọwọ́ ati àwọn ọmọ-ọmú ń kọrin ògo rẹ,wọ́n ti fi ìdí agbára rẹ múlẹ̀,nítorí àwọn tí ó kórìíra rẹ,kí á lè pa àwọn ọ̀tá ati olùgbẹ̀san lẹ́nu mọ́.
Ẹ̀yin akẹ́kọ̀ọ́ fásítì, ẹ múra sílẹ̀ fún ìwọlé lẹ́yìn ìyanṣẹ́lódì oṣù méje- ASUU Ọmọwe Fayemi sọ pe awọn ọdọ ipinlẹ Ekiti ṣe iwọde naa nirọwọrọsẹ eleyi to si tọna labẹ ofin.
National Grid: Ìgbà mẹ́rin ọ̀tọ̀ọ̀tọ̀ tí ìtàkùn ìpínná ní Nàìjíríà ti dákú lọ́dún 2020
Bakan naa ni awọn ọba alaye sọ wi pe wọn yoo gbe ẹbọ, ti wọn yoo si ṣe etutu lati da ọba pada si aafin nitori awọn janduku naa ti balẹ jẹ.
re gege bi oludari ile-ise olopaa, lasiko ipade igbimo ohun ti o waye nile-ise
O so pe : “Ifojusun wa ni lati mu idagbasoke ba ohun amayederun ; oju-popo, oju irin, ina mona-mona ati awon ohun miiran.
0 54,730 United Arab Emirates 733 7.
Ẹ ranti pé fún ọdún mẹta, tọ̀sán-tòru ni n kò fi sinmi láti máa gba ẹnìkọ̀ọ̀kan yín níyànjú pẹlu omi lójú.
Sisọrọ kubakugbe tun tumọ si piparọ mọ eniyan ati iroyin ẹlẹjẹ nipa ẹnikan lọna ati fi ṣe ẹlẹya lawujọ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ejo abami to n mu owo ni ajọ Jambu Lara awọn to kawọ pọnyin rọjọ lori owo kaadi Jamb ti wọn gba lọwọ awọn ọmọ ileewe ni Tanko Labaran lati ipinlẹ Nazarawa ati Yakubu Jakata ti ko tii salaye bi iye owo toto miliọnu lọna ogun naira se dawati nileesẹ Jamb to wa nipinlẹ Kano.
Níbí, nínú ogún àwọn adarí ipò ìjọba, ìdá mẹ́rin péré ni wọ́n jẹ́ aláwọ̀ dúdú.
Obaseki fi n da awon ara ilu Esan loju pe, ijoba ipinle yoo sepade pelu awon ti oro kan nipele ijoba apapo, ti won je alamoju to opopona marose  Benin si Auchi, lati ri daju pe, won pari opopo naa fun irorun irina oko ni agbegbe naa.
Ẹ wo bírà tí iná kékeré lè dá ninu igbó ńlá!
Agbẹnusọ Ile Igbimọ Aṣofin Ipinlẹ Eko, Aṣofin Mudashiru Ọbasa ti rọ awọn ọmọde ati awọn ọdọ-langna lorilẹ-ede Naijiria lati jinna patapata si ẹgbẹ ẹkunkun ati awọn iwa buruku miiran to le ṣakoba fun ọjọ iwaju rere wọn.
 Èrò tí ó ní nípa dídá ẹgbẹ ́ òsẹ ̀ lú yìí sílẹ ̀ ni láti lè tún italy kọ ́ kí ó sì sọ ọ ́ di ìlú tí ó lágbára .
Presidency: Kí ló dé tí Ààrẹ Buhari tún ń dá àwọn tó fúnrarẹ̀ yọ nípò pàdà
Amọṣa, ileẹjọ ni arakunrin naa ko ni ṣe ẹwọn naa bayii ayafi to ba tun daran miran lọjọ iwaju.
Ilumooka akọrin ẹ̀mí náà tún ni ọdọ olóògbé Alade Aromire ni òun ti bẹ̀rẹ̀ si ni kópa nínú eré tíátà, kii sì ṣe Yemi Ayedun lọ jẹ oga òun, gẹgẹ bí èrò àwọn ènìyàn kan.
Ipade naa waye lẹyin ti awọn mejeeji ti sọ oko ọrọ si ara won lori
Ó ní òun óo fìdí ìjọba rẹ̀ múlẹ̀ ní Israẹli títí lae.
Àwọn ọmọ-ẹ̀yìn náà ṣe bí Jesu ti pàṣẹ fún wọn.
Gege bi oro re, ninu itan orile-ede Naijiria, eyi je igba akoko ti ijoba yoo lo iru igbese yii lojuna ati gbogun ti iwa ibajẹ.
O ni ki awọn eeyan gbiyanju lati gbadun aise nkankan yi ki wọn si gba pe gbogbo nkan ni yoo yi pada bọ sipo to ba ya.
Sugbọn ó kù nibọn n ró ni wọn fi ṣẹ pé oorun to ku ṣi to aṣo lati gbẹ ki Oṣinbajo le wa pari awọn iṣe to ku.
pegede fun  ipo kẹta ti won si gba  golden bronze ninu idije AFCON 2019.
Biodun Fatoyinbo fi ipò sílẹ̀ lorí ẹ̀sùn ìfipábánilòpọ̀ Seyi Awolowo, ọmọ-ọmọ Awolowo, kí ló ń wà lórí ètò BB Naija?
Ta sì ni yóo jíṣẹ́ náà fún?
Ẹfunsetan Aniwura, obìnrin tó ju ọkùnrin lọ Ọ̀rọ̀ǹpọ̀tọ̀niyùn, Aláàfin obìnrin àkọ́kọ́ rèé, tó ní nǹkan ọkùnrin Lati oju opo Twitter, diẹ lara awọn itunmọ tuntun ti awọn eeyan fun orukọ yi re e: Lotitọ ati ododo, ọtọ ni nnkan ti olorin to kọrin rẹ jẹjẹ sọ ninu orin ti awọn ọmọ Naijiria yi itumọ rẹ pada si Bode Thomas.
Máa gbọ́, ìwọ ọ̀run,sì fetí sílẹ̀, ìwọ ayéNítorí pé OLUWA ń sọ̀rọ̀Ó ní, “Lẹ́yìn tí mo bọ́ àwọn ọmọ,tí mo tọ́ wọn dàgbà tán,ọ̀tẹ̀ ni wọ́n dì sí mi.
Eyi ko ṣẹyin bi awọn adari ẹgbẹ oselu APC ni ipinlẹ Bayelsa ṣe ṣe abẹwo si Aarẹ tẹlẹri, Goodluck Jonathan lẹyin idibo sipo gomina to waye ni Bayelsa.
idibo atundi ti yoo waye ni apa ibikan ni ipinle lorile ede yii, ni eyi ti yoo
” Saulu bá dá a lóhùn pé, “Àwọn eniyan náà ti bẹ̀rẹ̀ sí sá kúrò lẹ́yìn mi, o kò sì dé ní àkókò tí o dá.
Wọ́n rán àwọn kan ninu àwọn Farisi ati àwọn ọ̀rẹ́ Hẹrọdu sí i láti lọ gbọ́ tẹnu rẹ̀.
jíjẹ ni kí ẹ jẹ ẹ́ ní ààrin ìlú yín, ati àwọn tí wọ́n mọ́, ati àwọn tí wọ́n jẹ́ aláìmọ́ ni wọ́n lè jẹ ninu rẹ̀, bí ìgbà tí eniyan jẹ ẹran èsúó tabi àgbọ̀nrín ni.
Wọn tun sọ siwaju pe awọn tan ọmọdekunrin naa ki o lọ ba awọn ra elerindodo Coca-Cola wa, nigba ti o mu elerindodo naa de, wọn dee mọlẹ, wọn si fi ọbẹ ge ori rẹ.
6 606991 Orilẹede Netherlands 12871 75.
 nítorí àwọn ipa mìíràn tí egbògi náà má a ń ní lára ènìyàn .
Ibà-ẹ̀fọn ní Bangladesh: ó tó bíi ẹni 2800 tí àìsàn-an nì tẹ̀ wò nínúu àwọn ọjọ́ mẹ́rìndínlógún àkọ́kọ́ osùu Agẹmọ
Awọn oṣiṣẹ bẹrẹ iyanṣẹlodi pẹlu iwọde kaakiri orilẹede Naijiria.
ẹni tí ó níláti wà ní ọ̀run títí di àkókò tí ohun gbogbo yóo fi di titun, gẹ́gẹ́ bí Ọlọrun ti sọ láti ìgbà àtijọ́, láti ẹnu àwọn wolii rẹ̀ mímọ́, àwọn eniyan ọ̀tọ̀.
com Ijọ Anglican ni ipinlẹ Ekiti ti kọwe lọ ree gbe ile rẹ si Biṣọbu ijọ naa kan, Victor Adepoju lori ẹsun pe o ni ibalopọ pẹlu iyawo alufaa ẹgbẹ rẹ kan ninu agbegbe kan naa.
Ọmọwe Oyeleye ṣalaye pe ile igbimọ aṣofin mẹfẹẹfa lawọn ipinlẹ Yoruba lọ ṣe agbekalẹ ofin idasilẹ Amotekun.
Sọ àsọtẹ́lẹ̀ orílẹ̀èdè tí yóò borí ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ t'òní Àpò 65 là fi gbé owó N1.
Àwọn ọmọ rẹ̀ mejeeji, Esau ati Jakọbu, sì sin ín.
"Laarin awọn to n ṣatipo lorilẹede Libya bayii, o diẹ ni ẹgbẹrun lọna ọgọta lo jẹ ọmọ orilẹede Ghana ti ẹgbẹrun marundinlaadọta si wa lati orilẹede Naijiria.
“Mo fẹ́ kí ẹ mọ̀ dájúdájú pé ohunkohun tí ẹ bá dè ní ayé, ó di dídè ní ọ̀run; ohunkohun tí ẹ bá tú ní ayé, ó di títú ní ọ̀run.
Ejò lé àwọn aṣòfin ìpínlẹ̀ Ondo kúrò nípàdé Àwa ò mọ ẹgbẹ́ kankan tó ń jẹ́ fijilanté fulani l'Ondo- Ìjọba ìpínẹ̀ Ondo Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ifọrọwanilẹnuwo pẹlu Oga ọlọpaa ni Kwara ati Ondo nipa idibo Aarẹ Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Ohun tí ó ṣẹlẹ̀ sí àwọn ará ìlú ni yóo ṣẹlẹ̀ sí alufaa;ohun tí ó ṣẹlẹ̀ sí ẹrú yóo ṣẹlẹ̀ sí olówó rẹ̀;ohun tí ó ṣe ọmọ-ọ̀dọ̀ ni yóo ṣe ọ̀gá rẹ̀;ohun tí ó ṣe ẹni tí ń rà ni yóo ṣe ẹni tí ń tà.
Lásikò ti ó ń ba àwọn akọroyin sọ̀rọ̀ ní ìpínlẹ̀ Sokoto, agbẹ́nusọ ẹgbẹ́ APC Bello Danchadi sọ pe, irọ́ ni èsì ìdìbò ti àjọ INEC gbé jade nítori pé ètò náà ni kọ́nu-n-kọ́họ ninu lọ́jọ́ Sátide, tí àwọn si ti ń ke gbajare ki ètò ìdìbò tó pari.
Eyi jẹ́ ki ó sọ àwọn ọmọ bàbá rẹ yoku di alágbàṣe ni oko ti wọn jogún.
Òndó: Ọ̀gá àgbà àjọ ẹ̀ṣọ́-aláàbò ojúupópó (FRSC) dolóògbé
- arìnrìn oge Lẹ́yìn ìgbeyàwó ọdún mọ́kànlá àti ọ̀pọ̀ ìjà, Bọsẹ di èrò ọ̀run nílé Saidi Ṣé àwọn ọmọ rẹ lè sọ Yorùbá tó àwọn ọmọ Amẹrika yìí?
Pẹlu gbogbo eyi sibẹ sibẹ, ipenija ọrọ abo ṣi n yọju di diẹ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Damilọla pàdánù ọ̀rẹ́kùnrin rẹ̀ nítorí ilà kíkọ Iwọnba eeyan lo maa ni oye iru irora ti mo n jẹ ati ohun ti mo n la kọja."
kí ó gbé owó náà fún àwọn tí wọ́n ń ṣe àkóso àtúnṣe ilé OLUWA.
nígbà náà ni o óo láyọ̀ ninu Olodumare,o óo sì lè dúró níwájú Ọlọrun.
O ni: “O n kan mi lominu pe ko naira marun un, mewaa, ogun naira, aadota, ogorun un ati igba naira pupo nita lasiko yii”.
Adari ajọ to n mojuto ipese ogun ati ounjẹ ni ẹkun iwọorun, NAFDAC, Mrs Preye Edotimi, ṣe alaye wi pe ajọ naa ti ṣetan lati fi ọwọ sowọpọ pẹlu awọn oniṣegun ibilẹ ti o ni ọna abayọ si aarun Corona.
Ogbeni Abdi Dahir Guure, ti o je komisona ekun Bulabarde, jabo oro ohun fun awon akoroyin pe, iko omo ogun ijoba woyaaja pelu iko omo ogun olote , al-Shabab fun wakaati marun un gbako.
Eyi ri bẹẹ nitori alẹ yii gan an ni yoo sọ boya ọmọbinrin naa gba ẹkọ, o fi ara balẹ, to si ṣee gbẹmi le abi boya oninabi, akọọgba ọmọ ni.
O tun tesiwaju pe “orile ede lonii yii, nilo awon adari ti yoo lowo ninu ijoba ki i se awon eniyan kan to je pe imo ti ara won ni won mo.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ọ̀rọ̀ Oduduwa Republic gbọgbọ́n, kìí ṣe ọ́rọ̀ Igboho nìkan - Gani Adams Ẹ̀yin tẹ́ ń jà fún ẹ̀yà Hausa, Igbo àti Yorùbá, ara yín lẹ̀ ń jà fún - Lamido Sanusi Irọ́ ni o!
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Speed Limit: Ẹ̀wọ̀n oṣù mẹ́ta àti #3000 ni ìtanràn fun awakọ̀ to bá jẹ̀bi 28 Bélú 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 29 Bélú 2019 Oríṣun àwòrán, Others Àkọlé àwòrán, Láti osu kejì, ọdún tó kọjá ni Àjọ FRSC ti sọ di ọ̀rọyàn fún àwọn awakọ̀ láti ri pé wọ́n lo ẹ̀rọ 'speed limiter' nínú ọkọ̀ wọn.
Lẹ́yìn ìgbà díẹ̀, odò náà gbẹ nítorí àìrọ̀ òjò ní ilẹ̀ náà.
Nígbà tí ẹ bá lọ, ẹ óo dé ibìkan tí àwọn eniyan ń gbé láìbẹ̀rù, ilẹ̀ náà tẹ́jú.
Àkọlé àwòrán, Sunkẹrẹ fakẹrẹ Idi ni pe oni ni ọjọ Aje akọkọ, tii tun se ọjọ kẹta tijọba apapọ bẹrẹ isẹ atunse lori abala kan lori afara Third Mainland, eyi ti wọn ti pa.
Akonimọọgba Aguirre ni oun faramọ gbogbo eebu ti awọn eeyan ba n bu oun lori ifidirẹmi naa.
Oríṣun àwòrán, Kenny Senaya/Facebook Awọn eeyan bẹrẹ si ni semọ ọmọdekunrin naa loju opo ayelujara pẹlu bi ko ti ṣe lọ si ile iwe girama, amọ ti o si fakọyọ ninu idanwọ ile iwe girama to tun wọ fasiti lọmọ ọdun mejila.
Ṣugbọn ó sọ fún baba rẹ̀ pé, ‘Wo ati ọdún tí mo ti ń sìn ọ́, n kò dá àṣẹ rẹ kọjá rí; sibẹ o kò fún mi ni ọmọ ewúrẹ́ kan kí n fi ṣe àríyá pẹlu àwọn ọ̀rẹ́ mi rí.
” Eto alaafiaAwon igbimo alafia yii lo tun je ki aare ana, Goodluck Jonathan to je oludije fun egbe Peoples Democratic Party , ti Muhammadu Buhari si je oludije fun egbe All Progressives Congress ati awon oludije miiran towobo iwe eto alaafia ni ojo kẹ́rìnlá, odun 2015.
Kó má a lọ bẹ̀ ẹ́ ní ìséde coronavirus fún ọ̀sẹ̀ méjì míràn - Ìjọba Nàìjíríà Owó tó kàn mí nínú N4 mílíọ̀nù ìbejì Akeugbagold tí a jí gbé, bàtà ni mo fi rà-Afunrasí Wo ipa tí ìlànà tuntun tí ìjọba Eko gbé jáde lórí Covid-19 yóò nìí ní ìgbésí ayé rẹ Bàbá mi fún mi ní kíndìnrín rẹ̀ láti dóòlà ẹ̀mí mi- Sam Ṣugbọn ṣe o ṣeṣẹ ki eeyan lugbadi arun Coronavirus lati ara aṣọ tabi bata?
Lara awọn ere tiata to si jẹ ki Duro Ladipọ di ilumọọka ni Ọba Moro eyi to se lọdun 1962, Ọba Koso ati Ọba Waja, ti wọn jade lọdun 1964, Mọremi, Suuru baba Iwa, Tanimowo Iku, Bode Wasinmi, Ajagun nla ati bẹẹ bẹẹ lọ Duro Ladipọ lọ si ọpọ orilẹ-ede jakejado agbaye lati se afihan ere ori itage rẹ.
Nígbà tí ẹ bá jẹ, tí ẹ yó tán, 
Nígbà tí ó di ọjọ́ keji, ó yọ owó fadaka meji jáde, ó fún olùtọ́jú ilé èrò, ó ní, ‘Ṣe ìtọ́jú ọkunrin yìí.
Ipalẹmọ ati igbesẹ kiakia Oríṣun àwòrán, Getty Images Ojọgbọn Nyenswah, to ti saaju bawọn sisẹ lati koju Ebola nigba to ja ni iwọ oorun Afrika ni ọna kan pataki lati koju itankalẹ arun ni ki awọn tọrọ kan gbe igbesẹ ni kiakia lati le dena itankalẹ arun yi laarin awọn eeyan.
Ariwo ọmọkunrin naa lo jẹ ki o han si gbogbo aladugbo wi pe ọfọ ti ṣẹ.
Ó ní:“Tẹ́tísílẹ̀, ìwọ ọ̀run, mo fẹ́ sọ̀rọ̀;gbọ́ ohun tí mo fẹ́ sọ, ìwọ ayé.
Ẹgbẹ́ òṣèlú náà jẹ́ kó di mímọ̀ pé Dókítà Fayẹmi ṣe ìpolongo ìbò tó dá lórí àlàkalẹ̀ rẹ̀ láti ṣe àtúntò ọrọ̀ ajé ìpínlẹ̀ náà àti dídá iyì, ìṣedéédé àtìwà ire rẹ̀.
Oríṣun àwòrán, Other Àkọlé àwòrán, Ọdun 2009 ni wọn mu olorin takasufe,Neyu Godwin Nyan lori ẹsun pe o ja ile onile lorilẹede Amerika ti wọn si ti i mole fun ọdun mẹta titi di 2011.
Ó mú burẹdi marun-un náà ati ẹja meji; ó gbé ojú sókè ọ̀run, ó dúpẹ́, ó bá bù wọ́n, ó kó wọn fún àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀.
Ṣugbọn ọkàn wọn ti le, nítorí títí di ọjọ́ òní, aṣọ náà ni ó ń bo ọkàn wọn nígbà tí wọn bá ń ka ìwé majẹmu àtijọ́.
Fún àwa tí a wà láàárín, kí a ba mú un dọ́gba, a ní láti dúró sí ẹ̀gbẹ́ kejì.
Coronavirus: Ọmọ ilẹ̀ Italy tó kó Coronavirus wọ Naijiria kò ní àrùn náà mọ́
Oríṣun àwòrán, Twitter Àkọlé àwòrán, Oga panapana to bọ lọwọ àwọn Ajinigbe Ilé iṣẹ́ ọlọpàá dólàà adari ilé iṣẹ́ panápaná ipinlẹ̀ Eko Ilé iṣẹ́ ọlọpàá ìpínlẹ̀ Eko ni àwọn ti dólàà adari ilé iṣẹ́ panápaná ipinlẹ̀ Eko, Rasaki Musibau.
Bakan naa ni o gboriyin fun isakoso Aare Muhammadu Buhari bi o se n gbogun ti iwa ibaje lorile-ede Naijiria.
"Ẹ wo ohun tí wọn yóò máa ṣe ní ìpínlẹ̀ - DAWN Commission Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ìfẹ́ èmi àti olólùfẹ́ mi bẹ̀rẹ̀ lẹ́yìn ta jẹ ètè ara wa nínú sinimá - Nkechi Blessing Ẹ̀yin ẹkùn yókù, ẹ fi ikọ̀ àbò ""Amotekun ṣe àwòkọ́ṣe rere - APC Ọmọọba ilẹ̀ Gẹ̀ẹ́sì, Harry àti ìyàwó rẹ̀ kọ ipò wọn sílẹ̀ ní ìran ọba Ta ló ń fi ògùn Paracetamol, Hypo dín Gààrí lọ́dọ̀ yín níbẹ̀ yẹn?"
Akọwe Ajọ Nigerian Supreme Council for Islamic Affairs, Ọjọgbọn Ishaq Oloyede lasiko to n ba BBC sọrọ ni awọn ko ni owo lati ma a fin ileejọsin ni ojoojumọ nitori awọn kii gba owo ni ile ijọsin, wọn kan n lọ sin Olorun ni.
 gẹ ́ gẹ ́ bí ìwé tí a.
Kò sóhun tó ń jẹ́ ‘Captivus’ nílẹ̀ Oodua, mágùn ni mágùn ńjẹ́ - Babaláwo Wo àwọn obìnrin abúlé kan tó dáwó ra ọkọ̀ láti máa gbé aláboyún lọ ilé ìwòsàn Ìtàn rèé nípa bí Ogbomoso ṣe pa ọba, yọ nǹkan ọkùnrin rẹ jó kiri ìlú Alámì ẹ̀yẹ Scrabble Paul Sodje àti ọ̀rẹ́ rẹ́ kú lásìkò tó fẹ́ lọ́ sanwó ìdóòlà ẹ̀mí àbúrò rẹ̀, tí afurasí darandaran jí gbé Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Mayowa Omoniyi: Kò sí orin Obey, Sunny Ade abí tàkasúfèé tí ń kò le ta gìtá sí Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Fídíò, Akomolede: Bolaji Faleke ni Olùkọ́ tó ń kọ́ wa ní àṣà oge ṣiṣe lórí BBC Yorùbá1 Owewe 2020 Fídíò, Akomolede ati Aṣa lori BBC: Mọ̀ si nípa oríṣìí ẹ̀ka ìsọ̀rí ọ̀rọ̀ àti ìwúlò wọn8 Owewe 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Ọ̀FỌ̀ ṢẸ̀ WÁ NÍNÚ ẸBÍ WA 
O buru debi wi pe balogun Arsenal, Pierre-Emerick Aubameyang gan an lo ṣeeṣi gba goolu kan ṣoṣo tiu Burnley fi bori wọlẹ Arsenal.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'ìjà ṣẹlẹ̀ láàrín èmi àti ọ̀gá mi ní Lebanon tórí mi ò lè dá N300K padà' Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 3 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 5 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
ng Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Ondo Election 2020: Ẹ wo àwọn olùdíje sípò gómìnà nípínlẹ̀ Ondo tó takò bàbá ìsàlẹ̀26 Owewe 2020 Fídíò, Akomolede àti Aṣa: Ọ̀rọ̀ Ẹ̀yán ni Bunmi Femi Amao ń kọ́ wa lórí ètò Akọ́mọlédè àti Àṣà lórí BBC Yorùbá24 Owewe 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Ibinu ńlá dé bá àwọn ọmọ Israẹli, wọ́n sì fi í sílẹ̀, wọ́n pada lọ sí ilẹ̀ wọn.
Bayii, ijọba Naijiria ti kede lati tun afara Third Mainland ṣe bẹrẹ lati oni, ọjọ kẹrinleogun, oṣu keje Wo àwọn ọ̀nà míràn tí o leè gbà lẹ́yìn tí wọ́n bá ti afára Third Mainland Amọṣa o, lorilẹ-ede China wọn ti ṣi afara ti yoo jẹ akẹyinde gb'ẹgbọn fun afara Third mainland bridge.
"Inú mi dùn pé ẹni tó gbà ìjọba lọ́wọ́ mi ń san gbèsè tí mo fi kalẹ - Aregbesola Ilé alájà méjì wó lu ọmọ mẹ́rin ni Bariga Ipele kan náà kó ní Yorùbá àti ẹgbẹ́ darandaran Miyetti Allah wà- Afẹnifẹre El-Zakzaky kò fojú hàn nílé ẹ́jọ́ ṣùgbọ́n wọ́n sún ẹjọ́ rẹ̀ síwájú ""Inu ọmọ yii maa n dun ni gbogbo igba lati ṣere, rere lo maa n ro""."
O ni o se oun laanu fun awọn ọmọ Yoruba pe, wọn ko le duro sori ọrọ ti wọn ba sọ lai jẹ è wọn wa ni oko ẹru.
Ní báyìí ẹgbẹ̀rún méjìléláàdọ́ta ó lé ẹgbẹ̀rin ló ti lùgbàdi ààrùn náà ni Naijiria, sùgbọ́n ènìyàn ẹgbẹ̀rún ọgọ́jì dín díẹ̀ ló ti ri ìwòsàn.
Okoronkwo ní ọ̀pọ̀ ló ń fi náírà méjì, mẹ́ta tà á nítorí wọ́n fẹ́ padà lọ ra òmíràn lásìkò, kí wọ́n sì pa owó wọ́n kí wọn sì kó èrè wọ́n jọ.
Ẹ máa ran ara yín lẹ́rù, bẹ́ẹ̀ ni ẹ óo ṣe mú òfin Kristi ṣẹ.
Bi ẹjọ naa ṣe bẹrẹ ni ẹgbẹ agbabọọlu rẹ, Sunderland yọ ọwọ ninu iwe adehun bọọlu rẹ, eyi ti wọn ti n fun ni ẹgbẹrun lọna ọgọta pọun ni ọsẹ.
Nígbà tí mo wò ó dáradára, mo rí i, ó di ìyá mi: mo bá sáré sí i kí n dì í mú ṣùgbọ́n òfo ni mo di mú, mo tún sáré sí i kí n dì mú lẹ́ẹ̀kejì òfo ni mo tún dì mú, nígbà tí mo sì sáré sí i lẹ́ẹ̀kẹta kí n dì í mú tí ó tún jẹ́ pé òfo ni mo dì mú mo bú sí ẹkún pẹ̀lú mi – Háà!
 Maa fowosopo pelu won laisko yii ki a jo ko ara wa ni eko nipa koko inu ere ati akoonu itan ki idagbasoke le ba Nollywood bii ti awon ile okeere to ku.
Baba mi ni ó ń fun yín ní oúnjẹ láti ọ̀run wá; 
Ki ipolongo naa o to bere,
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ruga: Ọ̀pọ̀ àwọn ìpínlẹ̀ tó ń fẹ́ Ruga ló wá láti apá òkè ọya 19 Agẹmo 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 20 Agẹmo 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Agbekalẹ abule Fulani ti wọn n pe ni Ruga lo ti n fa awuyewuye ni orilẹede Naijiria lẹnu lọọlọ yii, ti awọn ipinlẹ kan si tako igbesẹ naa eyi to mu ki ijọba Muhammadu Buhari sẹwele igbesẹ ọhun.
Adari awọn to n ṣe eto awọn akẹkọọ ni Fasiti ABU Ọjọgbọn Yahaya Bambale fi idi ọrọ naa mulẹ fun BBC to si ni lootọ lawọn ajinigbe gbe akẹkọ mta ṣugbọn awọn agbofinro ti toju bọ ọrọ naa.
O jawe olubori ninu idibo abẹle ṣugbọn o fidi rẹmi ninu ibo gangan an ninu eyi to ti padanu ọpọ owo ati ohun ini rẹ.
Ẹẹdẹgbẹta (500) ninu àwọn eniyan Simeoni ló lọ sí òkè Seiri; àwọn olórí wọn ni: Pelataya, Nearaya, Refaaya, ati Usieli, lára àwọn ọmọ Iṣi.
Won ti n ko ile ise ayewo naa , sugbon ti 
Ṣugbọn bí ẹnikẹ́ni bá mọ wúrà, tabi fadaka, tabi òkúta iyebíye, tabi igi, tabi koríko tabi fùlùfúlù lé orí ìpìlẹ̀ yìí, 
Ó pa ará Ijipti kan tí ó ga ju mita meji lọ.
lo soro yii lojoRu lasiko to n dahun ibeere ti asofin  Albert Bassey Akpan  n beere idi to faa ti aare Buharo ko tii
Atẹjade kan ti awọn adari ẹgbẹ oṣiṣẹ iroyin, NUJ, ẹgbẹ oṣiṣẹ radio ati tiata, RATTAWU fi sita ṣalaye rẹ pegbogbo ilakaka awọn oṣiṣẹ nileeṣẹ naa lati ri pe irawọ rẹ ko wọmi ni aisi amojuto fawọn oṣiṣẹ nibẹ n bu omi pa.
Nítorí OLUWA àwọn ọmọ-ogun yóo jọbalórí òkè Sioni ati ní Jerusalẹmu.
Osinbajo, lasiko to n ba awọn akọroyin sọrọ pẹlu gomina ipinlẹ Ogun, Dapo Abiodun sọ wi pe, Aarẹ Buhari lo ran oun wa lati wa ọna abayọ si ipenija eto aabo to mẹhẹ ni Naijiria.
Ẹ̀yin ará, tí ẹ kì í ṣe Juu ni mò ń bá sọ̀rọ̀ nisinsinyii.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, 'ọ̀rẹ́ lo yẹ kí a máa ṣe; bóyá wọ́n nà wá tàbí a nà wọ́n' Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Iṣẹ agbara, ọgbọ́n ati ìṣirò ni bọọlu gbigba bayii Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ọmọ to ba ṣiṣẹ́ déédé yẹ kò lasiko ayọ̀ kíkún Ipele akọkọ ninu idije ife ẹyẹ agbaye Russia 2018 ti pari.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Aliyu, ti ọwọ awọn ajọ aabo ara ẹni laabo ilu, NSCDC, tẹ pe o ba ọmọ osu mẹta sun, ti ifun rẹ si tu jade ni Lafia nipinlẹ Nassarawa, ti wa jẹwọ pe lootọ ni.
Nitori naa, lọdun yii wọn ko ni le ba wọn kopa ninu ere ije ti ilu Warri to ṣe pe aj IAAF lo ṣagbekalẹ rẹ tori aj naa ko fun wọn lowo ti wọn yoo lo.
Dìde nàró kí o gbọ́ ohun tí n óo sọ fún ọ, nítorí ìwọ ni a rán mi sí.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, International Day Against Drug Abuse and Trafficking: ìdí ti mo fi ń mu oògùn olóró Kò s'òwó, kò sí ìgbáradì fún ìdíje pẹ̀lú Guinea - Super Eagles fárígá Awọn ọmọ ẹgbẹ agbabọọlu agba Naijiria, Super Eagles kọ lati gbaradi fun idije ti yoo waye laarin wọn ati ẹgbẹ agbabọọlu orilẹede Guinea l'ọjọru ninu idije ife ẹyẹ ilẹ Afrika to n lọ lọwọ ni Egypt.
Nǹkan kò ṣẹnuure fáwọn obìnrin nínú ìgbìmọ̀ ìṣèjọba Buhari Àwọn ọmọ Yorùbá wo ni mínísítà ní ìjọba Buhari?
Kin lo fa sababi isẹlẹ yi?
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Bí o bá bá ààrùn ìpẹ́pẹ́ gbígbẹ lára arẹwà obìnrin rẹ̀, kí loó ṣe?
Seyi Makinde fojú hàn n'íta lẹ́yìn tó ṣẹ́gun Coronavirus Máfọ́ya, mo wà pẹ̀lú ẹ, Ajimọbi kàn sí Makinde lóri Coronavirus to ni Bojú bojú o.
"Yollywood: Kìí ṣe gbogbo ìgbéyàwó ló ń túká nítorí àgbèrè – Mide Martins Ikú mú ẹ̀gbọ́n Orisabunmi lọ̀, ọjọ́ méjì lẹyìn ikú rẹ̀ Saliu ni ""Alhaji Usman Okebi àti àwọn ọmọ rẹ̀ méjì pẹ̀lú bá ìṣẹ̀lẹ̀ náà rìn, sùgbọ́n à kò mọ ǹkan ti ó fa ìjà,"" àwọn míràn farapa pẹ̀lú."
Yóo pamọ, yóo ràdọ̀ bo àwọn ọmọ rẹ̀,yóo sì máa tọ́jú wọn níbẹ̀.
Ambode gbé ilé aṣòfin Eko relé ẹjọ́ APC, ẹ bá wa bẹ Buhari kó ṣí bodè ká kó ìrẹsì wọlé - Ìjọba Vietnam ń bẹ̀bẹ̀ Àwọn ológun tó fẹ́ maa yẹ káádì ìdánimọ́ aráàlú wò, ìwà àìríṣẹ́ ṣe ni - Ilé aṣòfin Ọjọ́ mẹ́rin sí ìgbéyàwó wa ní ìyàwó mi b'ómi lọ- Ibrahim Abubakar Nigba to n ba BBC sọrọ, onimọ nipa awọn ounjẹ asaraloore, Collins Akanno mẹnuba ọpọ awọn eso ati ewebẹ to wa ni arọwọto wa, amọ ti a ko naa rara.
A óo sọ ohun tí o níláti ṣe fún ọ.
Tí ayé bá ṣe èèyán tán, wọn a l’ódò rè é gbétí lé
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù #NotTooYoungtoRun: Gbájú-ẹ̀ ni Saraki lò fún wa 31 Ògún 2018 Oríṣun àwòrán, @bukolasaraki Àkọlé àwòrán, Sẹnẹtọ Bukola Saraki wa lara awọn ọmọ ẹgbẹ PDP to kede lati du ipo Aarẹ orileede Naijiria Ẹgbẹ ọdọ tó pé ará wọn ni ''Not Too Young to Run Movement'' ti bẹnu àtẹ lù bí Ààrẹ ile aṣòfin àgbà Nàìjíríà Bukola Saraki ti ṣe fi ayẹyẹ wọn kéde pé òun fẹ dupo ààrẹ.
Oríṣun àwòrán, @Laurestar Àkọlé àwòrán, Nileewosan naa ni iyawo aarẹ orilẹede Gambia, Fatoumatta Bah-Barrow ti ba awsn obinrin ati ọmọde dawọọ idunnu Nileewosan naa ni iyawo aarẹ orilẹede Gambia, Fatoumatta Bah-Barrow ti ba awọn obinrin ati ọmọde dawọọ idunnu ti wọn si tun ge akara oyinbo rẹ ni ile aarẹ, Aso Rock nilu Abuja kan naa.
Aṣẹ yii lo wa ninu iwe kan ti ọga agba ọlọpaa naa fi ranṣẹ lati olu ileeṣẹ ọlọpaa n'lu Abuja, eyi ti agbẹnusọ igbakeji gomina ọhun, Babatope Okeowo fi ṣọwọ si BBC Yoruba.
Òfin náà ní ìjọba yóò pèsè àyè ilé ààbò fún Abódiakọ-akọ́diabo ènìyàn, ètò ìlera àti ohun èlò ẹ̀kọ́ àti ilanilọ́yẹ.
Awọn alatilẹyin Chelsea fẹran Jose Mourinho ati Antonio Conte, ṣugbọn ni ti Sarri, wọn ko fẹran rẹ.
Igbimo to n mojuto oro idibo nile igbimo asofin ti so pe, o ti di ohun ti o se pataki bayii fun ajo to n mojuto eto idibo lorile-ede Naijiria lati pese eto idibo onirowo-rose lọdun 2019.
Koko wo lo n jẹyọ nibẹ?
Olùfẹ́ mi,títí ilẹ̀ yóo fi mọ́,tí òjìji kò ní sí mọ́.
"Akinwumi Isola dárà nínú ìwé ""Nítorí Owó"" lórí Akomolede Yoruba Ìtàn ọ̀rẹ́ tó fi òògùn gba ọkọ ọ̀rẹ́ rẹ̀ ni Akomolede BBC Yorùbá fẹ́ kọ́ wa lònìí Wá kẹ́kọ̀ọ́ nípa ègé ọ̀rọ̀ ohùn Yorùbá tí a mọ̀ sí Sílébù Àṣà Oge Ṣíṣe ní Akọ́mọlédè BBC Yorùbá ń gbé yẹ̀wò lónìí, Ó yá, iṣẹ́ ti bẹ̀rẹ̀."
Pẹlu esi yi,o jẹ ayo meje ti wọn gba wọle Dynamo ti eyi si j ki wọn tẹsiwaju lọ si abala ti o kan ninu idije ti ọdun yi.
Amọ́ ó tún woye pe, ìwọ̀nba ni èdè gẹ̀ẹ́sì gbọdọ mọ nínú eré Yoruba.
Wo àwọn Ṣọ́ọ̀ṣì Nàìjíríà àti l'Áfíríkà tó ń wólẹ̀ àdúrà kí Trump lè wọlé ìbò ààrẹ America Àwọn akẹ́kọ̀ọ́ 181 pẹ̀lú Olùkọ́ lùgbàdì Covid 19 níléèwé aláàdáni kan nípinlẹ̀ Eko Ọkọ̀ akẹ́rù tí ìjánu rẹ̀ já ló kọlù ọkọ̀ agbépo tó fa ìjàmbá iná ní Otedola- LASEMA Tola Oyediran ọmọ Obafemi Awolowo ti jáde láyé Iku n pa ni, ilẹ n jẹ eeyan.
Agbaje ni iwe ẹri nipa imọ ofin, lati Fasiti Harvard.
Ṣugbọn bi ọrọ ajakalẹ arun to wa lode ṣe da ni lagara ti dédé sọ Reme ẹni to n ṣiṣẹ ni ilu Canada si okunkun alẹ pẹlu bi ko ṣe ni lanfani lati rinrinajo lọ si orilẹede Naijiria lati lọ fẹ aayo ọkan rẹ, Ayokunle.
Nítorí ó wà ní àkọsílẹ̀ ninu òfin Oluwa pé, “Gbogbo àkọ́bí lọkunrin ni a óo pè ní mímọ́ fún Oluwa.
Wọn fi ẹsun kan pe awọn oluranlọwọ fun Wike gbe owo lọ si ọgba banki apapọ Naijiria to wa nilu Port Harcourt gẹgẹ bi owo ẹyin fun awọn ọmọ ogun to wa nibẹ lọjọ kẹtalelogun oṣu Keji, ti i ṣe ọjọ idibo.
Ewe, bi o ti le je pe, afojusun agbekale eto olojo kan yii ti a mo si: Investment and Initiative Programme (BIIP) ni lati se ifilole dida eran ni awon ipago iko omo-ogun jake-jado, eleyi ti oga agba yanyan iko omo-ogun, ogagun Tukur Yusuf Buratai lowo si.
Iṣẹlẹ Minneapolis bẹrẹ pẹlu ẹsun pe oluraja kan n gbiyanju lati na ogun dọla ayederu ni ilé itaja kan.
Amọ ariyanjiyan ti n waye lori ohun to n sẹlẹ si awọn ẹru naa ni kete ti wọn ba ti ta wọn lẹru tan.
Mo fẹ́ kí ìwọ mọ̀ lónìí pé, ìgbéraga ni ìbẹ̀rẹ̀ ìparun, òun ni ìbẹ̀rẹ̀ ìṣubú, ó lòdì sí òfin ènìyàn, ó sì yàtọ̀ si ìlànà Ọlọ́run Ọba, dípò kí ìwọ fi èmi ṣe ìjẹ, èmi lè fi ẹran ara rẹ fún àwọn ẹranko inú igbó, kì ìwọ sì di oúnjẹ fún àwọn ẹyẹ tí ń fò lórí igi.
9 526485 Orilẹede Austria 6987 78.
Ninu atẹjade naa ti wọn pe akọle rẹ ni 'Ekiti Loses N19.
Bẹẹ, aare Buhari gba pe ẹni rere lo lọ nitori pe Shehu Shagari ṣeniyan pupọ ni ọrọ ti ọpọlọpọ ti n fapajanu le lori Oríṣun àwòrán, @Shagariofficial Àkọlé àwòrán, Okú Sheu Shagari ti wọn káà ill sùn ní ìlú Shagari Sokoto Ṣé ìpànìyàn Zamfara leè ṣokùnfà ìkéde ìlú kò fararọ?
Iyalufa kan sọ eewọ yii, gẹgẹ bi awọn agba atijọ ti maa n se lati dẹru ba awọn majesin, ki wọn ma baa hu awọn iwa kan ni, ti Ọmọyẹ ko si mọ pe ẹru lasan ni ọrọ naa.
Mi ò to iṣẹ́ Regina Daniels rárá kí n tó fẹ́ ẹ láàrin ọ̀sẹ̀ mẹ́ta, mo sì tún le fẹ́ ìyàwó míì - Ned Nwoko Àyà mi já nígbà tí Ganduje rọ Sanusi lóyè Emir Kano tó fi Bayero síi, ṣùgbọ́n.
Minisita keji fun alumọni eporọbi, Timipre Silva sọ pe adinku naa da lori ọna ti wsn ti la kalẹ l'ọdun 2015 ṣaaju ki ijọba o to fi kun owo epo lọdun to tẹle.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ekiti Shooting: A ò ni farapamọ́ fún ará ìlú lórí ìwádìí ọlọ́pàá to pa ènìyàn ni Ekiti 23 Bélú 2020 Oríṣun àwòrán, Police Kíni àjọ ọlọ́pàá ń ṣe lórí ìpànìyan ojoojúmọ́?
Nigba ti wọn fi ọrọ wa baba agba naa lẹnu wo, se lo jẹwọ pe lootọ ni oun maa n jẹ dodo lara ọmọ ọmọ oun amọ oun ko tiẹ mọ pe o ti fẹraku.
Oríṣun àwòrán, Ogun State Governor's office Àkọlé àwòrán, Ati ọmọde ati agba lo fẹran ilu lilu nilẹ Afirika nitori wọn fẹran orin lọpọlọpọ Oríṣun àwòrán, Ogun State Governor's office Àkọlé àwòrán, Ajọdun ilu nilẹ Afrika to maa n waye ni ipinlẹ Ogun l'orilẹede Naijria jẹ afihan ati ṣiṣe ajọyọ ipa ti ilu n ko nilẹ Afrika.
Ìtàn ìgbé ayé Bode Thomas rèé, ó kọ́ wa láti máa kó ẹnu wa ní ìjánu Ṣo mọ̀ pé J.
igbinmo naa lati kowe ranse si minisita fun ipese ina, Ise, ati oro Ile gbigbe
Ere agbelewo Fiimu James Bond kan ti awọn olotu rẹ lero pe yoo waye loṣu Kẹrin ọdun yii ni wọn ti sun siwaju.
Indonesia Sriwijaya Air: Ọkọ̀ bààlú tó gbéro àádọ́ta pòórá lẹyìn tó gbéra láti Jakarta
Ni ọjọbọ lawọn ọlọpaa sọ pe okooleirinwo eeyan lọwọ ti tẹ ati pe awsn ti bomi pa ina ikọlu naa.
Orilẹede wo lo n jẹ irẹsi julọ?
Isreal Adesanya fàgbàhàn Kelvin Gastelum ni Atlanta Ọlọ́pàá gbé àwọn tó yìnbọn lu olólùfẹ́ ní Ajegunle Ọ̀wọ́ngógó epo bẹntirò: NNPC ni 'ìròyìn ẹlẹ́jẹ̀' ni Oladejo Okediji àti ìgbé ayé ìtàn kíkọ rẹ̀ Dokita Adan ni awọn koi tii ri kọbọ gba lọwọ ijọba nitori awọn ti kọwe sijọba nigba kan pe ki wọn maa fi lita epo mẹwaa ran ọkọ naa lọwọ lojoojumọ ṣugbọn wọn ko tii ri esi kankan gba lati ọdọ ijọba.
ÀkọléÀkọlé abala Àkọlé abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Rìn káàkiri BBC News Sport Weather Radio Arts Ìlànà Lílò Nípa BBC Òfin Àṣírí Cookies Ìrànlọ́wọ́ Ìwọlé Ìtọ́ni Òbí Kàn sí BBC Get Personalised NewslettersCopyright  2021 BBC.
Nígbà náà ni Jesu wí fún wọn pé, “Ẹ̀yin ìran alaigbagbọ yìí!
“Nítorí náà, mo fún wọn ní àṣẹ tí kò dára ati ìlànà tí kò lè gbà wọ́n là.
@anyasi_emma n tiẹ ni kii se lile akẹkọbinrin naa kuro nile iwe lo kan, ohun si ri asọdun lori ohun to n sẹlẹ yii nitori awọn ibeere kan wa to yẹ ki fasiti Babcock kọkọ wa idahun si.
Igbeṣẹ yii lo n waye lẹyin ti Trump halẹ mọ awọn ileeṣẹ naa lẹyin to fẹsun kan wọn pe wọn ko fun awọn ẹgbẹ kan ni anfani lati sọ tinu wọn.
“Ṣugbọn èyí agbowó-odè dúró ní òkèèrè.
Bákannáà lójú òpó Twitter rẹ, Gomina Mutua fi ìkìlọ sita pe, oun yóò pé ẹnikẹ́ni to bá gbé ìròyìn eleje nipa ìṣẹlẹ náà lẹjọ.
Lọwọ yii, oun ni oludari ileeṣẹ Citizens Mediation Centre to maa n pẹtu si aawọ laarin awọn ara ilu, o tun jẹ ọkna lara awọn ọmọ ẹgbẹ Human Rights Commision, to maa n ja fun ẹtọ ara ilu.
Osun karun ọdun 2020 Ni oṣu karun ọdun 2020, itakun ina pinpin lorilẹede Naijiria daku patapata ki wọn to ri i gbe dide si ẹgbẹrun mẹta o din ọgọrun (2900 megawatts).
Afi ki gbogbo abiyamọ jere ọmọw ọn, oyun nini ko rọrun!
Ohun ta gbọ ni pe Aarẹ Trump wa nibi to ti n gba ''gọọfu'' nigba ti iroyin ikede afojusun pe Biden wọle ipo aarẹ kan lara.
''Ni ibẹrẹ igbesi aye mi, iya to bi mi ko ri ere tiata bii nkan gidi, fun idi eyi, ko fẹ ki n yan isẹ naa laayo sugbọn loni, opẹ ni fun Ọlorun'' Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Àwọn arẹwà obinrin Yollywood, tá ló mọ iṣẹ́ rẹ̀ jù?
Dókítà ọmuti ṣe iṣẹ́ abẹ tó pa olóyún àti ọmọ rẹ̀ Ìjí líle, Cyclone Fani, kọlu Ìlà-Oòrùn India Nàìjíríà fẹ́ yá $100m lọ́wọ́ India fún ìtàkùn àgbáyé 'Ọkọ mi yọ kindinrin mi lati rọpo owo ori' Oṣere-binrin Hema Malini lo n lewaju Gbajugbaja oṣerẹ Bollywood, Hema Malini naa lo n lewaju ninu idibo ẹkun ariwa ipinlẹ Uttar Pradesh ni Mathura.
Oríṣun àwòrán, Ile oodua O ni ẹnikẹni to ba ti mọ pe oun yoo tẹle ẹsin okeere dipo atọna iṣẹmbaye ti wọn fi jọba gbọdọ fi oye silẹ fun awọn ọmọ oye ti wọn 'setan lati tẹle ilana ọpakutẹlẹ fun ọba jijẹ nilẹ Yoruba.
Óṣeéṣe kí ìjọba yí ètò ẹ̀kọ́ sí ẹ̀kọ́ àárọ̀ àti ìrọ̀lẹ́ láti ṣí iléèwé padà ní Nàìjíríà Minisita kekere fun eto ẹkọ ni Naijiria, Emeka Nwajiuba, sọ pe orilẹ-ede Naijiria ko ṣetan lati fi ilera awọn ọmọde sinu ewu nitori pe wọn fẹ ẹ ṣi ileewe pada.
Iwadii naa ni wọn ni o ṣeesẹ ko yọri si ki wọn o fi oju akọwe agba lọọfisi Olori awọn oṣiṣẹ fun Gomina tẹlẹ, Akinwumi Ambode, Adewale Adesanya ba ile ẹjọ.
Isọri yii ni o wa fun awọn to ni owo ti wọn n ṣe ti ko si lee san owo oṣu awọn oṣiṣẹ wọn lati oṣu bii mẹta sẹyin.
Nígbà tí ọmọ náà dàgbà, ó gbé e pada fún ọmọbinrin Farao, ó sì fi ṣe ọmọ, ó sọ ọ́ ní Mose, ó wí pé, “Nítorí pé láti inú omi ni mo ti fà á jáde.
Lẹyin naa ni ọpọlọpọ igbesẹ yoo tẹle e ni ilana to tọ ko ma baa si aṣiṣe.
4 285 Erekusu Turks and Caicos Island 6 15.
“Èmi ni OLUWA kò sí ẹlòmíràn,kò sí Ọlọrun mìíràn lẹ́yìn mi.
Wọn fikun wi pe awọn gbe igbeṣẹ naa nitori wọn mọ pe ipinlẹ Kaduna yoo fi ohun ribiribi kọ lara ọgbọn ti Sanusi ni ati oye rẹ nipa eto ọrọ aje.
Ìpín ti ẹ̀yà Bẹnjamini gẹ́gẹ́ bí iye ìdílé wọn wà ní ààrin ilẹ̀ ẹ̀yà Juda ati ti ẹ̀yà Josẹfu.
Bẹẹ si ni iwa gbigba ẹmi ara ẹni lodi si ofin orile-ede Naijiria, koda ẹwọn ọdun kan ni ẹnikẹni to ba gbiyanju lati pa ara rẹ yoo fi gbára.
láti inú ẹ̀yà Aṣeri, ó rán Seturu, ọmọ Mikaeli; 
Ọrọ naa polukurumusu mọ awọn kan loju debi wi pe wọn n gbe ẹgbẹ si ara wọn.
Osise ijoba ipinle naa, Jesus Santander so pe awon ti yanju isele naa.
Super Eagles f'ìyẹ́ bo Carthage Eagles Tunisia mọ́ 'lẹ̀ Ẹ wo báwọn òṣèré tíátà kan yóò ṣe rí lọ́jọ́ ogbó Mercy Aigbe bu èpè jó àwọn tó ní gómìnà kan ló ra ilé fún-un Olólùfẹ́ méjì jábọ́ láti àjà kẹsàn án lásìkò tí wọ́n n ṣe kerewà Bi awọn kan se n sọ wi pe Ighalo lo fakọyọ julọ ninu ẹgbẹ agbabọọlu Super Eagles ni idije Afcon naa.
O sapejuwe Salaam gege bi opo leyin ọgba  fun egbe oselu APC ni ipinle Osun, o ni o ti lo ipo re lati tun mu idagbasoke ba egbe naa.
Ki lo ti ṣẹlẹ sẹyin laarin Algeria ati Naijiria?
Ẹ̀sìn ìṣẹ̀ṣe ṣún síwájú, wo orin aládùn lẹ́nu ẹgbẹ́ akọrin àti ìjèrè ọkàn tí wọn ń ṣe Ojúlówó Shina Rambo yọjú sígboro lọ́jọ́ Àìkú, ó fi ìka hánu lórí ìpànìyàn tó ti ṣe Àwọn ọ̀dọ́ Benue pa pásítọ̀ ti wọ́n fẹ̀sùn kan pé ó ń mú ǹkan ọmọkunrin Iléẹjọ́ mú ọjọ́ kejìdínlógún, oṣù kọkànlá fún ìgbẹ́jọ́ àwọn tó jí ìbejì Àáfà Akeugbagold ní Ibadan Àgọ́ ọlọ́pàá Sanyo ni wọ́n darí ọkọ̀ akérò tó kó àwọn Fulani wọ ìlú Ibadan lọ - Oyo OPC Èyí tí a wò jùlọ 5:03 Fídíò, Omolola Arohunmolase Welder: Mo ti fí iṣẹ́ 'Welder' gbayì láwùjọ, tó mo fi tọ́ ọmọ yanjú, Duration 5,039 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 5:39 Fídíò, Akomolede ati Asa lori BBC: Olùkọ́ Kikelomo Ogunboye tan ìmọ́lẹ̀ sí ìwà olè ọ̀gá ọlọ́pàá Audu gẹ́gẹ́ bí àwòkọ́ṣe àsìkò yìí, Duration 5,398 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 4:11 Fídíò, Oba Adeyeye Ogunwusi: Ojú mi ti rí lọ́pọ̀ lọpọ̀, ọ̀pọ̀ èèyàn ni kò tilẹ̀ gbàgbọ́ pé mo lè jọba- Ooni, Duration 4,117 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 4:43 Fídíò, Promise Akinlade: ọmọ ọdún mọ́kànlá tó ń fi ìlù dárà bíi àgbàlagbà sọ̀rọ̀ nípa tálẹ́ǹtì rẹ̀, Duration 4,437 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 0:59 Gbọ́, Ìsẹ̀lẹ̀ jákèjádò orílẹ̀èdè àgbáyé láàárín ìṣẹ́jú kan, Duration 0,59wákàtí 5 sẹ́yìn 7:03 Fídíò, Olumuyiwa Bolade Adedeji Military Bruitality: Bí arákùnrin onípèníjà ara tí sọ́jà lù ṣe dé, Duration 7,035 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 4:45 Fídíò, Yoruba Films: Ẹ̀ẹ́ bẹ̀ mi kúrò láyé ni, mi ò lè kú - Fadeyi Oloro, Duration 4,4526 Èrèlè 2020 2:48 Fídíò, Esther Ajayi: Èmi náà ti borí ìṣòro rí ló ń mu mi ṣojú àánú, Duration 2,481 Ògún 2019 6:08 Fídíò, Adebola Ademilua: Àìrísẹ́ ṣè lẹ́yìn ìwé kíkà ló sọ mi dí ìyá onírú, mo dúpẹ́ tèmi, Duration 6,0827 Bélú 2020 5:55 Fídíò, Soyinka Cancer: Àṣe ara mi ni iso ti n run gbogbo bí mo ṣe n ṣèrànwọ́ lórí jẹjẹrẹ, Duration 5,5527 Bélú 2019 BBC News, Yorùbá Ìdí tí ẹ fi le è nígbàagbọ́ nínú ìròyìn BBC Ìlànà Lílò Nípa BBC Òfin Àṣírí Cookies Kàn sí.
Ní nkan bi ọ̀ṣẹ̀ díẹ̀ sẹ́yìn bákan náà ni Samuel pari ètò ìsìnlẹ̀ baba ẹní, èyí tó túnmọ̀ si pé, ó ti gboye àkọ́kọ́.
Ẹ wá siwaju rẹ̀ pẹlu orin ayọ̀.
Loṣu to n bọ ni wọn yoo kede ẹni ba pegede fi ipo olori WTO.
Ẹ̀yin gan-an ni ọmọ àwọn wolii; nítorí tiyín ni Ọlọrun ṣe bá àwọn baba yín dá majẹmu, nígbà tí ó sọ fún Abrahamu pé, ‘Nípa ọmọ rẹ ni n óo ṣe bukun gbogbo orílẹ̀-èdè ayé.
Ó ṣẹgun Sela, ó sì yí orúkọ rẹ̀ pada sí Jokiteeli, orúkọ yìí ni ìlú náà ń jẹ́ títí di òní yìí.
Ọkunrin náà gbà á, ó sì jáde.
Arun Covid-19 yii naa lo mu ki owo eporọbi o din l'agbaye, aarẹ si pinnu pe gbogbo ọmọ Naijiria lo yẹ ko janfaani rẹ.
Bakan naa ni ile-ise ohun so pe, alekun bi: iko meje abo ninu ida ogorun 7.
pe iroyin naa ko ti to ile ise olopa leti.
Lara awọn ipinlẹ Nigeria to gba kọmisana tuntun ni Eko, Ọyọ, Kwara ati Anambra.
Obinrin náà gbọ́ ọ̀rọ̀ Eliṣa, òun ati ẹbí rẹ̀ sì lọ ń gbé ilẹ̀ àwọn ará Filistia fún ọdún meje.
Bẹ́ẹ̀ ni èmi, OLUWA àwọn ọmọ ogun wí!
Kinní kan bí awọsanma tí ó ń dán bíi Kristali wà lórí àwọn ẹ̀dá alààyè náà, ó tàn bo gbogbo orí wọn.
Àwọn ọmọ Midiani ni Efai, Eferi, Hanoku, Abida ati Elidaa.
"Oríṣun àwòrán, WTO/WEBSITE Gẹgẹ bi Akọroyin BBC lori eto ọrọ aje, Andrew Walker, ṣe ṣalaye, oludije fun ipo naa lati orilẹ-ede South Korea, ni America faramọ, nitori ""iriri to ni nipa okoowo, ati ipá lati ṣe amojuto daadaa""."
Sugbọn, ẹgbẹ naa tun gbajúmọ̀ fun ole jíjà, ipaniyan, ati ifipabanilopọ ni Eko.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Alaafin: Olori Aanu Adeyemi ṣàlàyé ìdí tó ṣe gẹ́ Oba Lamidi Adeyemi ti ìlú Oyo Biden ranti pe Harris lo gba ti oun lẹyin pẹlu gusto lasiko ifọrọwerọ abẹle ti Democratic ninu oṣu keje ọdun 2019 to tako bi oun (Biden) ṣe lodi si iwa iyanisọtọ lawọn ileewe ijọba.
 ) dára ; dun Ìse / imúse to dara niyan kúnná iyanrìn kúnná ju òkúta wéwèèwé lo .
" Oríṣun àwòrán, Instagram/iyaboojofespris Iyabọ Ojo salaye pe oun ko kuku lee se awawi lori igbe aye oun yii, nitori aye oun kuku san ju tawọn eeyan miran lọ, ti eeyan ba si mọ inu ro, yoo mọ ọpẹ du, oun sa n ri nkan pawọda, ti oun si n bọ ẹnu awọn eeyan diẹ, tori naa, oun dupẹ lọwọ Ọlọrun fun eyi.
Èèhù kan yóo sọ jáde láti inú kùkùté igi Jese,ẹ̀ka kan yóo sì yọ jáde láti inú àwọn gbòǹgbò rẹ̀.
''Lootọ ni pe mo fi ọkan si pe wọn yoo yan mi sipo pada ṣugbọn nigba ti ọrọ ko ri bẹẹ, ko gba mi ni iṣẹju marun un lati gba wi pe akọsilẹ ni ati pe bi Ọlọrun ti ṣe fẹ ẹ ni yẹn'' O fi kun ọrọ rẹ pe ''Mo si ti ri ohun to tu mi ninu latara ẹsẹ Kurani, nibi ti Ọlọrun ti ṣe adehun pe oun to n bọ lọna, lati fun ọ ni ohun to dara ju eleyi to wa lọwọ rẹ bayi lọ'' Oríṣun àwòrán, @HMAdebayoShittu Nigba to n sọrọ lori ohun ti yoo wa maa ṣe bayii lẹyin to kuna lati dipo minisita mu, ọgbẹni Shittu sọ pe oun yoo pada si idi iṣẹ amofin eleyi toun ti n ṣe saaju oṣelu.
Ó tún gba ti àwọn òkè tí ó wà ní ìhà àríwá Ekironi, ó wá yípo lọ sí Ṣikeroni.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ìnú mi kìí dùn nígbà trí mo ń ṣiṣẹ́ ni bánkì tó ìgbà ti mo bẹ̀rẹ̀ mẹkáníìkì O fikun un pe abajade ere itage naa yoo wa fun ṣiṣe iranwọ fun awọn obinrin ti wọn ti fi ṣe ẹru lọna igbalode.
EFCC: Àwọn ọba aládé àti olóṣèlú ṣé àpapín owó ìrànwọ́ N2bn ní Kwara Lasiko to fesi lori ẹsun naa, Alhaji Mukaila Lamidi ti ọpọlọpọ eeyan mọ si 'Auxiliary' ṣe alaye wi pe igbiyanju lati ba oun lorukọ jẹ ni iroyin ẹlẹjẹ naa.
nipa sise atileyin fun awon ile-ise okoowo keekeeke lorile ede yii nipa eto
Ilẹ̀ àwọn ará Kenaani bẹ̀rẹ̀ láti Sidoni, ní ìhà Gerari, ó lọ títí dé Gasa, ati sí ìhà Sodomu, Gomora, Adima, ati Seboimu títí dé Laṣa.
Ninu atẹjade kan to fi ṣọwọ si BBC News Yoruba, oloye Oluṣẹgun Ọbasanjọ ni nibi ti ọrọ de duro bayii, o ti kuro ni ere sinima, aarẹ si gbọdọ gbe igbesẹ akin, gẹgẹ bii obi ati olori.
 O tẹsiwaju pe ""A ti mu awọn afurasi mẹrin kan lori ẹsun ipaniyan, ṣugbọn kii sẹ nitori pe wọn wa ninu ẹgb ẹ okunkun."
ìlú Eko kọ́ ló léwu jùlọ láti gbé lágbàáyé- Ìjọba Eko Oludije fun ipo aarẹ fẹgbẹ oṣelu PDP, Alhaji Atiku Abubakar naa sọrọ nipa iwe ẹri Aarẹ Buhari ninu ẹsun to fi kan an niwaju igbimọ igbẹjọ to n ri si awuyewuye lori eto idibo gbogboogbo ọdun 2019.
Gbogbo ẹgbẹ olukọ Ile iwe Giga Fasiti ati awọn olukọ ile iwe lo parapọ lati kọ ekunwo owo epo bẹntiroolu naa.
Orúkọ múràn tí ó ń jẹ́ ni Bándélé.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ọọ̀ni obìnrin, Lúwòó Gbàgídà rèé, akọni tó ń gun ọkùnrin ní ẹṣin rìn Ìtàn tó rọ̀ mọ́ òwe ‘aṣọ kò bá Ọ́mọ́yẹ mọ́.
Koda iṣọwọ gbe ọrọ jade tirẹ gan an a maa fa ohun tawọn ololufẹ rẹ atawọn to wa ni apa keji fifẹran rẹ n da si.
Ọ ̀ rúnmìlà ti mọ oko ni oko ikun to gbin èpà síbẹ ̀ .
Ògo Ọlọrun pàápàá yọ lára Ọmọ-Eniyan.
Bee si ni, atamatase iko naa, Andres Iniesta, ti o tun je agbaboolu iko Barcelona tele ri, kede ifeyinti re ninu iko ohun leyin ti iko agbaboolu Russia gbo ewuro si won loju.
Sunday Igboho woye ọrọ yii nigba to n sọ ero rẹ lori oniruuru atako to n waye nipa agbekalẹ ikọ alaabo ọhun, tawọn gomina mẹfẹẹfa lẹkun iwọ oorun guusu Naijiria da silẹ.
Yóo fi wọ́n jẹ olórí ọpọlọpọ eniyan; yóo sì fi ilẹ̀ ṣe ẹ̀bùn fún àwọn tí wọ́n bá fún un lówó.
Lẹ́hìn èyí, kìnnìún mu omi ó bá ihò rẹ̀ lọ.
Awọn Onkọwe maraarun ti a gbe iṣẹ wọn yẹwo yii ni wọn ti filẹ bora bi aṣọ ṣugbọn awọn iṣẹ wọn ṣi n jẹ akagbadun lẹyin ọpọlọpọ ọdun ti wọn ti tẹ wọn jade laye.
Igbakeji Aarẹ, Ọṣinbajo ni alaga ikọ̀ amuṣẹya ti yoo ri si bi eto irinna ọkọ̀ yoo ṣe pada sipo ni oju ọna naa.
Gbogbo bàtà àwọn ológun, tí ń kilẹ̀ lójú ogun,ati gbogbo ẹ̀wù tí wọ́n ti yí mọ́lẹ̀ ninu ẹ̀jẹ̀ ni a óo dáná sun,iná yóo sì jó wọn run.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Wembly ya!
Minisita ọrọ ilẹ okeere, Geoffrey Onyeama kede loju opo Twitter rẹ pe wọn ti gunlẹ lalaafia l'Abuja.
Ṣugbọn ohun gbogbo ti ọ̀dọ̀ Oluwa wá.
''Lati igba de igba ni aarẹ Buhari kii le fi iṣẹju marun silẹ lati ba awọn ọmọ Naijiria sọrọ ki ohun gbogbo si rọlẹ si, amọ nigba ti wọn fẹ ibo wọn, aarẹ Buhari kaakiri ipinlẹ mẹ̀rindinlogun to wa kaakiri orilẹede Naijiria.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ayinla Kollington: Ìyàwó mí títí láéláé ni Salawa Abẹni 19 Agẹmo 2019 Gbajugbaja olorin Fuji nni, Alhaji Ayinla Kollington ti kede fun araye pe titi aye ni akọrin Waka nni, Alhaja Salawa Abẹni yoo maa jẹ iyawo oun, ti awọn yoo si jọ pẹ fun ara awọn.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, N100,000 Nairà mà ni Dino gbé dání lójú agbo, kò náwó yàlà-yòlò - Ayefele Adeyeye ni ọpọ igba, wọn o ti lo ‘chemical’ si ara awọn awọ ẹran maalu naa fun lilo, ko to di wi pe awọn eniyan ma a wa loo fun pọnmọ jijẹ.
Mò ń kó àwọn eniyan bọ̀ láti pa ìlú Samaria run, wọ́n pọ̀ tóbẹ́ẹ̀ gẹ́ẹ́ tó fi jẹ́ pé ọwọ́ lásán ni wọn yóo fi kó gbogbo erùpẹ̀ ìlú náà.
''Nitori naa, mo bẹ awọn ọdọ lati jọwọ fi gbogbo iwa ipa silẹ, ki wọn si gba alaafia laaye.
Wọ́n ti pa àwọn aláìṣẹ̀ sí gbogbo ibí yìí.
Ojú ni ẹ̀ ń wò tí ẹ fi ń ṣe ìdájọ́, èmi kò ṣe ìdájọ́ ẹnikẹ́ni.
Ẹ kúkú lọ sọ́dọ̀ àwọn tí ń ta epo, kí ẹ ra tiyín.
Islamic State: Ilẹ̀ Amẹrika ń kó àwọn ọmọ ogun IS tó burù kúrò ní Syria- Trump
A óo ká àwọn tí ó gbójú lé ère lọ́wọ́ kò,ojú yóo sì tì wọ́n patapataàwọn tí ń wí fún ère gbígbẹ́ pé:‘Ẹ̀yin ni Ọlọrun wa.
adari obinrin egbe oselu APCAwon oludari ti yoo maa sise ni
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Nigeria Independence Day: Ẹ wo kókó àwọn ọrọ́ tí Aàrẹ Buhari sọ ní October 1 1 Ọ̀wàrà 2019 Oríṣun àwòrán, OTHERS Àkọlé àwòrán, Muhammadu Buhari sọ̀rọ̀ lórí ni ètò ààbò,ìwà jẹgúdújẹrá àti iléesẹ́ ọlọ́pàá.
OLUWA yóo pe àwọn àgbààgbà ati àwọn olórí àwọn eniyan rẹ̀siwaju ìtẹ́ ìdájọ́,yóo sọ fún wọn pé;“Ẹ̀yin ni ẹ jẹ ọgbà àjàrà mi run,ohun tí ẹ jí nílé àwọn talaka ń bẹ nílé yín.
Akọwe ẹgbẹ YCE, Dokita Kunle Olajide lọ sọ wi pe o ku diẹ kaatọ lori ọrọ ti agbẹjọro agba fun ijọba apapọ sọ.
Ọsẹ kan pere ni mo ma fikede Minisita tuntun, ka ni emi ni Buhari.
Mo sọ fún àwọn ọmọ wọn ninu aṣálẹ̀ pé kí wọ́n má tọ ọ̀nà tí àwọn baba wọn rìn, kí wọ́n má ṣe tẹ̀lé òfin wọn, tabi kí wọ́n bọ oriṣa wọn.
Bakan naa ni Aarẹ Buhari buwọlu iwe adehun €50m pẹlu ajọ EU lati ṣe iranwọ lori ọna ati ṣeto idagbasoke lapa ila oorun ariwa lorilẹede Naijiria.
“Ní ọjọ́ kẹẹdogun oṣù keje yìí, ẹ óo máa ní àpèjọ mímọ́, ẹ kò ní ṣe iṣẹ́ kankan fún ọjọ́ meje tí ẹ óo fi ṣe àjọ̀dún náà.
Baba-onírùngbọ̀n-yẹ́úkẹ́ mi ọ̀wọ́n, ìbá ṣe pé ìwọ dé inú mi ni, ìwọ ìbá mọ̀ pé inú mi dùn ju iyọ̀ òyìnbó lọ.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Àwọn olórin gbọdọ̀ kó ara wọn ní ìjánu nípa orin tí wọn ń kọ lórí ìwà lílu jìbìtì.
Àkọlé àwòrán, Guru Maharaj: Buhari ní yóò wolé nínú ìdìbò 2019 Ni tirẹ Olùdásílẹ̀ ìjọ One Love Family, Satguru Maharaj sọ pe ààrẹ Muhammadu Buhari tó ń dije lábẹ àsía ẹgbẹ́ òṣèlú All Progressives Party (APC), ni yóò fidi alátako rẹ̀ Alhaji Atiku Abubakar, tó ń dije lábẹ́ égbẹ́ òṣèlú People's Democratic Party(PDP) janlẹ̀ .
Ọgbẹni Majekodunmi wipe ijọba gbodo pese eeto aabo to peye fun awon aginju gbogbo ti won wa fun titoju awon eranko meremere ni orileede Naijiria.
Zlatan sọ ìtumọ̀ òrin rẹ̀ tó gbòde kan Burna Boy fẹ́ yọ̀ǹda owó tó bá pá lóde àríyá f'áwọn tó farakásá ìṣẹ̀lẹ̀ Xenophobia Burna Boy n gún òke àgbà, wọ́n fà á kálẹ̀ fún àmì ẹ̀yẹ̀ Grammy Ninu awọn kan miran tawọn eeyan nwadi loju opo Google la ti ri : Bi eeyan ti ṣele ṣe ẹgusi Big Brother Naija Kini o n jẹ Ruga?
Ni Gbagede Eagle Square ni wọn ti bura fun aarẹ Buhari ati Ọjọgbọn Yemi Oṣinbajo to jẹ igbakeji rẹ nibi ti arẹ Buhari ko ti ka ọrọ akọsọ rẹ fun igba akọkọ ninu itan Naijiria.
Lọjọ ti wọn pa Ekugbemi, iroyin sọ pe awọn ọmọ ẹgbẹ Biola Ebila lo kọlu u, lasiko ti wọn fẹ ẹ gba owó ọmọ onílẹ̀ , lọwọ ẹnikan to n fi paanu bo ilé rẹ ni agbegbe Olunde, nitosi ile Ekugbemi.
Bakan naa, kan lara awọn oludije ipo aarẹ ni Uganda toun naa jẹ olorin, Bobi Wine ni agbẹjọro oun darapọ mọ wn ninu akitiyan lati dawọ ẹjọ ti wọn n pe lori awọn olorin ọmọ Naijiria yii duro to si ni inu oun dun bo ṣe ṣẹlẹ Ki ni awọn Naijiria n sọ lori bi ijọba ṣe ran Omah atawọn to ku rẹ lọwọ?
Ó yọ wọ́n kúrò ninu òkùnkùn ati ìrẹ̀wẹ̀sì ọkàn,ó sì já ṣẹ́kẹ́ṣẹkẹ̀ wọn.
Oríṣun àwòrán, Others Bakan naa ni wọn pe fun atunṣe ofin Sharia ti ọdun 2000 ni ipinlẹ Kano.
Ninu ọrọ ti o ba awọn oniroyin sọ nile oloogbe, Sẹnetọ Tẹslim Fọlarin ṣe alaye iku Ajimọbi je nnkan ijaya nitori ko si ẹnikan ti o ni ireti pe iru ẹni to o da pe bẹẹ le dede jade laye, ṣugbọn o fi ọpẹ fun Ọlọrun fun igbe aye rere ti oloogbe gbe.
Ṣugbọn àwọn eniyan wọnyi pọ̀, ati pé àkókò òjò nìyí; a kò lè dúró ní gbangba báyìí.
Lara ere naa ni ‘Bread and Bullet’ to se lọdun 1950 Ogunde tun maa n lo ede Gẹẹsi pọ mọ Yoruba lasiko to ba n gbe ere kalẹ.
Àwọn ẹ̀yà ẹja onírúirú ní wọ́n ń gbé’nú omi.
Ohun ati ọkọ rẹ a ma saaba pade ni ile idana wọn lasiko isinmi bi igba pe ibi isẹ ni wọn wa.
Gẹ́gẹ́ bí OLUWA ti pàṣẹ fún Mose, iranṣẹ rẹ̀, ni Mose náà ṣe pàṣẹ fún Joṣua, tí Joṣua sì ṣe bẹ́ẹ̀.
Ọkọ́ agbépo jábọ́ ní pópónà Èkó!
" Eyi ni ọrọ ti Arabinrin Osusan Oluwatobi ti ori ko yọ ninu ijamba kẹẹkẹ, bo tilẹ jẹ pe ẹsẹ rẹ kan.
Mo níláti kúrò kí n máa bá iṣẹ́ mi lọ lónìí, lọ́la ati lọ́tùn-unla, nítorí bí wolii kan yóo bá kú, ní Jerusalẹmu ni yóo ti kú.
Ní ọjọ́ iwájúòkè ilé OLUWA yóo fi ìdí múlẹ̀, gẹ́gẹ́ bí òkè tí ó ga jùlọ,a óo sì gbé e ga ju àwọn òkè yòókù lọ.
Bàbá fi ikan ninú gbogbo Ẹrú ti ó ti pẹ́ pẹ̀lú rẹ, ṣe Olóri fún àwọn Ẹrú yoku.
Ekiti decides: Oshiomole fẹ̀sùn kan Fayose
Azeez Fashola ti inagijẹ rẹ lori itage n jẹ Naira Marley jẹ olorin Naijiria to ṣẹṣẹ n goke.
Iru awọn iroyin ti ẹ le nifẹ si: Àwọn obìnrin tí kò lọ́kọ ń kojú ìsòro ilé gbígbà Irú ẹ̀dá wo ni Kofi Annan jẹ́?
O ni owe Yoruba kan sọ wipe bina o tan lasọ, ẹjẹ o le tan leekana""."
Oríṣun àwòrán, Kano Emirate council Àkọlé àwòrán, Emir Muhammedu Sanusi II ti fẹsi sí ẹsún Gómìnà Kano Ní ọjọ́ru ni àjọ tó ń ri si iwa àjẹbanu ni ìpínlẹ̀ Kano dábàá pe ki wọn yọ Sanusi nipò nítori ó ṣe owo ìgbìmọ ẹmireeti niṣekuṣe.
O fi ọ̀kọ̀ rẹ gún orí àwọn olórí ogun;àwọn tí wọ́n wá bí ìjì líleláti tú wa ká,tí wọn ń yọ̀ bí ẹni tí ń ni talaka lára níkọ̀kọ̀.
OLUWA ní kí n lọ ra ìgò amọ̀ kan, kí n mú díẹ̀ ninu àwọn àgbààgbà ìlú ati àwọn bíi mélòó kan ninu àwọn àgbà alufaa, 
Aarẹ Buhari sọ eyi lasiko to n ba awọn ọmọ Naijiria sọrọ ni Ọjọ Ayajọ Ominira orilẹ-ede Naijiria (Independence Day) ni Ọjọ Kinni, Osu kẹwaa, ọdun 2019.
Aare Buhari ti fowosi bilionu mewaa lati fi tun awon agbegbe to wa lorile ede Naijiria ti ijamba  sele si , se.
Obaseki ni ibi ipolongo naa sọ fun awọn alatilẹyin rẹ pe ẹgbẹ oṣelu APC lo fa rogbodiyan naa, ti o si pẹtu si wọn lati maṣe gba ẹsan lara wọn.
Amọṣa oniruuru ayipada ati iṣẹlẹ ni iku arakunrin yii ti mu waye kaakiri agbaye.
Aarẹ Erdogan lo ṣi gbongan naa pada lẹyin ọpọlọpọ ọdun sẹyin.
O ni ọjọ Aje, ogunjọ osu Kẹjọ lo yẹ ki awọn aṣoju ile iṣẹ redio naa ati ijọba ipinlẹ Ọyọ jọ pade nile ẹjọ giga kan nilu Ibadan lori ọrọ ọhun, sugbọn ìjọba ipinlẹ Ọyọ ko duro de asiko ti ile ẹjọ da ki o to ṣe ifẹ inu rẹ.
 Ọ ̀ já tẹ ́ ẹ ̣ ́ rẹ ́ ara rẹ ̀ la fi ń gbé e kọ ́ apá .
" Bakan naa ni ileesẹ ipolongo oludije fún ẹgbẹ oṣelu SDP, Iyiọla Omiṣore pẹlu fidi ọrọ naa múlẹ.
Ẹni tí kò bá ní ìfẹ́ kò mọ Ọlọrun nítorí ìfẹ́ ni Ọlọrun.
 lẹ ́ yìn èyí ni ó di àrẹ ilẹ ̀ náà .
Òfin yìí wà fún arọmọdọmọ wọn títí lae.
Ash Wednesday: Àyájọ́ ọjọ́ eérú t'ọdún yìí bẹ̀rẹ̀ pẹ̀lú aṣọ ọ̀fọ̀
 Ọ ̀ nà tí à ń gbà ṣe èyí ni pé a ó fi ẹ ̀ rún ní sí èyìn fọ ́ nrán ìhun náà tí a fẹ ́ pe àkíyèsí sí .
Nígbà tí ara Paulu kò gbà á mọ́, ó yipada, ó sọ fún ẹ̀mí náà pé, “Mo pàṣẹ fún ọ ní orúkọ Jesu, jáde kúrò ninu rẹ̀.
Bí ẹ bá wí pé ẹ̀ ń tu èpò, ẹ óo tu ọkà náà.
Lọwọlọwọ bayii, wọn ko mọ ibi ti Ifesinachi sa lọ ṣugbọn Ujunwa ati Precious tawọn mejeeji jẹ ọrẹbinrin Ifesinachi ti wa lahamọ ọlọpaa.
Idi ni pe, bi àwọn kan ṣe n ki pe Ọlọ́run yoo fun ara rẹ lokun, ni awọn míràn ń fi àwòràn náà dápárá, eyi to mu ifura lọwọ pe abi inu ere itage lo ti ya aworan naa.
Ó sì mú kí Juda san ọgọrun-un (100) ìwọ̀n talẹnti fadaka ati ìwọ̀n talẹnti wúrà kan bí ìṣákọ́lẹ̀.
Nitori naa a ko ni ba awọn to n tabuku ba wa takurọsọ'' Olayinka tẹsiwaju pe lati fi iwe ẹri ibi ti Alaga ẹgbẹ ati akọwe ẹgbẹ ti buwọlu iwe pe awọn gba owo ilẹ ti ẹni to ra lọwọ ẹgbẹ da a pada si akoto owo ẹgbẹ PDP ni ilu Ekiti.
Kí ló dé tí o fi wà lórí àga ìdájọ́ láti òwúrọ̀ títí di àṣáálẹ́, tí àwọn eniyan ń kó ẹjọ́ wá bá ìwọ nìkan?
Ìròyìn tó tẹ̀ wá lọwọ ni pé ó ń gba ìtọ́jú ní ile Ìwòsàn National Hospital Abuja.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Seyi Makinde: Ẹ ṣe àkójọpọ̀ orúkọ àwọn òǹtàjà tí àjálù bá lọ́jà Akẹ̀sán fétì ìrànwọ́ 8 Sẹ́rẹ́ 2020 Oríṣun àwòrán, Seyi Makinde Idunnu ti n subu lu ayọ bọ fun awọn osisẹ ipinlẹ Ọyọ nitori gomina Seyi Makinde ti kede pe ko ni si osisẹ kankan nipinlẹ Ọyọ ti owo rẹ yoo kere si ẹgbẹrun lọna ọgbọn naira, tii se owo osu to kere julọ tijọba apapọ kede rẹ.
Joṣua, ọmọ Nuni, bá pe àwọn alufaa, ó sọ fún wọn pé, “Ẹ gbé Àpótí Majẹmu, kí meje ninu yín sì mú fèrè ogun tí wọ́n fi ìwo àgbò ṣe lọ́wọ́ níwájú Àpótí Majẹmu OLUWA.
Awọn inaki naa ti dinku si ẹgbẹrun mẹsan, to si jẹ pe inaki to to ẹgbẹrun kan nireti wa pe wọn n gbe ni ibudo igbafẹ ẹranko lorilẹede yii.
Itan ninu itan, Afiwe ẹlẹlọọ ati Afiwe taara ni awọn Onkọwe yii tun fi safihan iwa ọmọluwabi bii itẹlọrun, Ifẹ ati Ootọ inu fun awọn Onkawe gẹgẹ bii ẹkọ to yẹ ni kikọ.
Gbogbo ìgbà tí ó bá ti ń ṣẹlẹ̀ni yóo máa ba yín tí yóo máa gba yín lọ.
Sinimá àwòdamiẹnu, Ẹ̀fáńjẹ́líìsì jìyà àjẹmumi nílé aṣẹ́wó l'Ejigbo ní ìlú Eko Ọba Saudi Arabia yọ ọmọ rẹ̀ àti àbúrò rẹ̀ kúrò nípò nítorí ìwà àjẹbánu lórí owó tó yẹ fún ààbò ìlú Bàbá ẹni ọgọ́ta ọdún dèrò ilé ẹjọ́ nítorí ó wọ inú oko Obasanjo láì gba àṣẹ Mi ò fẹ́ ìrànwọ́ ẹgbẹ́ òṣèré, àwọn kọ́ ló kóbá mi- Chief Kanran Kí ló wá nínú àbádòfin pínpín omi àti àwọn ǹkan inú omi tó ń mú awuyewuye wa?
Asiko ti to fun idasilẹ ajọ ti yoo maa se amojuto ọgba ẹwọn ki wọn lee tubọ gba muse sii ju bi wọn se wa bayii.
Ọrọ omiyale, agbara ya ṣọọbu ti wa n gba ẹbọ lọwọ awọn eniyan Naijiria bayii.
Kii ṣe dokita Alfa Saadu nikan ni dokita to jẹ ọmọ orilẹede Naijiria to tii kagbako arun yii lagbye.
 Ọjọ ́ kejì ọjà ajágbénulékè ni Àṣàkẹ ́ rí kọ ́ kọ ́ rọ ́ tí ó fi dán séèfù wò nínú yàrá rẹ ̀ .
pe, iko agbaboolu Liverpool se gudugudu meje ohun yaya mefa lati da ami ayo naa
Ṣugbọn wọn kò ní ra àwọn àkọ́bí mààlúù, ati ti aguntan ati ti ewúrẹ́ pada, nítorí wọ́n jẹ́ mímọ́.
Lara awon ohun ija oloro ti
Ìpín ti Aṣeri yóo wà lẹ́gbẹ̀ẹ́ ti Dani, láti ìlà oòrùn títí dé ìwọ̀ oòrùn.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Moesha Boduong: Gbogbo obìnrin nílò ọkùnrin tí yóò máa tọ́jú wọn 28 Ìgbé 2018 Oríṣun àwòrán, Moesha Boduong/Facebook Àkọlé àwòrán, Òsèré Ghana sọ wípé gbogbo obìnrin nílò ọkùnrin tí yóò máa tọ́jú wọn Òsèré ọmọ Ghana kan to sọ wípé gbogbo obìnrin nílò ọkùnrin tí yóò máa tọ́jú wọn ti dá àríyànjiyàn mi sílẹ̀ nílu tó sì ti fẹ ọ̀rọ̀ fifi ipá bá ni lò pọ̀ lójú káàkiri orílẹ̀èdè.
Àgbélèbú kìí sii tilẹ̀ fi ibì kan rere sílẹ̀ ni igbá kejì mi, Ayédèrúẹ̀dá.
Ìbọn ọlọ́pàá ló pa èèyàn, ẹgbẹ́ wa kìí lo ìbọn - Shiite fárígá Èèmọ̀!
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Bí o ṣe lè fí òǹkà, ọ̀mọ̀ ìka tàbí ìkúùkù wọn oúnjẹ́ Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
'Ọkọ mi yọ kindinrin mi lati rọpo owo ori' Afunrasi afipajinigbe k'agbako ni Ogun Alápatà lu ìyàwó rẹ̀ pa ní Ogun 'Ekute jẹ ogun oloro lagọ ọlọpa' Àwọn olùdíje sípò gómìnà ní ìpínlẹ̀ Ogun fakọyọ Bawo ni ara ìlú ṣe tẹwọ gba ifẹ awọn ọmọ ogun ọta ara wọn meji yii?
adari egbe oloselu kan nigbagbọ pe aare yoo tapa si ofin ati ilana ile-isẹ re
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ọmọ Benin ni Naijiria ni Kamaru Ija aadọta lo ti jawe olubori ninu ija mẹtalelaadọta ti o kopa ninu rẹ.
O fi kun ọrọ rẹ pe o jẹ ojuṣe ẹni kọọkan lati gba awọn ara ilu ni imọran lati gba Kaadi Idibo Alalopẹ (PVC), ki wọn si kopa ninu idibo gbogboogbo to n bọ lona bayii.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Parental Guidance: Ọdún méjì ni kí ẹ ti bẹ̀rẹ̀ kíkọ́ ọmọ nípa ìbálòpọ̀ Sẹnetọ Ajimọbi kan sara si gomina ipinlẹ Ọyọ fun ọkan akin to ṣe lati kede fun araye pe oun naa ti ko arun ọhun.
Irú ẹni bẹ́ẹ̀ sọ ibi mímọ́ OLUWA di aláìmọ́.
Bi a o ba mọ otitọ nipa ipo ti ipinlẹ yin wa ni ti arun yoo, ẹ n fi ẹmi awọn araalu yin wewu ni."
Wọn kò lò lára owó náà láti fi ra agbada fadaka, abọ́, fèrè, tabi àwọn ohun èlò wúrà tabi ti fadaka sí ilé OLUWA, 
95bn sórí reluwé làti Kano sí Niger Republic- PDP Nínú akànṣẹ́ mẹ́ta ọmọ Nàìjíríà tó dáńtọ́ lágbàáyé, Yorùbá méjì wà nínu wọn Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
aabo ipinle ( State Security Service) ati ajo ọtẹlẹmuyẹ( National Intelligence
Ninu atejade kan ti oluranlowo gomina ipinle naa, Sola Fasure gbe jade  pe ogbeni Aregbesola ni awon omo egbe si wa ni isokan pelu ipinnu lati tun jawe olubori ninu eto idibo n bo , bo tile je pe awon kan tile ti yapa kuro ninu egbe won.
mi ati ile-isẹ adajọ agba lorile ede Naijiria ati ajo to n ri si ọrọ  to jẹ mọ ti ilẹ okeere lori ọrọ naa.
 Iya Kazeem tẹsiwaju pe Gbogbo igba ti ọmọ mi ba lọ gba bọọlu ni mo ma n lọ wo ti papa iṣere naa ko ba jina ju, nitori o ma n jẹ iwuri funmi ti mo ba n wo o, ṣugbọn wọn ti gba ọmọ naa lọwọ mi.
Wọn ti bẹrẹ iṣẹ atunṣẹ ni kikun sile ijọsin Notre-Dame nitori pe oorun ti jẹ ki o maa dogbo lati ọjọ pipẹ wa.
Àwọn iròyìn mìíràn tí ẹ lè nífẹ̀ẹ́ sí: Kò tọ̀nà láti gbé adájọ́ Onnogben lọ síwájú CCT - Adájọ́ fẹ̀yìntì Tani DCP Kayọde Ẹgbẹdokun, ọ̀gá ọlọ́pàá tuntun ní ìpínlẹ̀ Eko?
Ko sí sí ẹni ti yóò gbà èèyàn ṣíṣẹ́ tí kò ní bèèrè ìwé ẹrí yìí''.
Adewale ni oun ko lodi si ṣiṣeapejẹ lẹyin igbeyawo fun ẹni to ba wu tabi to lowo lati ṣẹ ẹ.
Kí lo fẹ́ mọ̀ nípa ‘Ajala Travels’?
Lonii a ti n lọ ile.
Pa àwọn òfin mi mọ́, kí o sì ṣe ìrànlọ́wọ́ lati mú iṣẹ́ mi jáde wá, gẹgẹ́bí àwọn òfin mi, ìwọ yíò sì di alábùkúnfún.
" Oríṣun àwòrán, nkechiblessingsunday/Instagram Nkecho sọ pe, ọpọ awọn ololufẹ oun lo ti bẹrẹ si n beere pe ki ni ohun to ṣẹlẹ, ti oun fi n dinku lojojumọ.
Itansan oorun maa mu ọpọlọ ji pepe.
O ni Mongila ati Aarẹ Dema naa gbe iru igbesẹ iayraẹnisọtọ yii nitori Arun COVID-19 to gbode kan yii.
Esi ayẹwo sọ pe ile ọmọ mi kere ju, mi o le gbe oyun fun iye oṣu mẹsan ti wọn maa n fi gbe oyun""."
Ọba tí ó ṣe é gbẹ́kẹ̀lé.
Nígbà ti èyí to dágbà jùlọ pẹ ọmọ ọdun mẹwàá ni ìyá rẹ̀ dàbàá láti ṣe ọmu lilọ fún un.
Arole ni òun kò tíì ní ìyàwó nílé, àmọ́ ẹ̀mí Ọlọ́run ni yóò dárí òun lati darí isẹ àti ìdílé òun, lásìkò ti oun bá ní ìdílé.
OLUWA tíí jowú tíí sìí máa gbẹ̀san ni Ọlọrun.
"Mba sọ, ""Wipe wọn ti gbe lọ Ebonyi kii ṣe ọrọ to le pupọ nitori wipe ipo nla naa ni wọn gbe lọ si ni Nkalagu."
Nítorí OLUWA ti fi odò Jọdani ṣe ààlà láàrin àwa pẹlu yín, ẹ̀yin ẹ̀yà Reubẹni, ati ẹ̀yà Gadi, ẹ kò ní ìpín ninu nǹkan OLUWA.
Wọn óo sì máa kọrin nípa iṣẹ́ OLUWA,nítorí pé ògo OLUWA tóbi.
Ninu idije ti ikọ agbabọọlu Germany ti fun wọn ni ami ayo mẹta si odo ni Super Falcons ti já kuro ninu idije tọdun 2019.
Àlága àti olùdari àjọ náà àrábìnrin Abike Dabiri-Erewa, ló fi ìkìlọ̀ yìí síta pé ó jẹ ǹkan tó ni èwu gidigidi ní àsìkò yìí láti máa ran àwọn ọmọ láti lọ kàwé ni àgbègbè ọhun.
Ọrọ Gatwick kọ la fẹ fayọ ninu itan kekere yi bi kii ṣe ti ọmọ Yoruba to jẹ oludari ile iṣẹ Global Infrastructure Partners to ra Gatwick pa.
Aare Buhari wa rọ ikọ agbabọọlu Super Eagles  lati  ni
O salaye pe, eyi pon dandan lati le pese ayika ti yoo mu idagbasoke ba orile-ede Naijiria, ni eyi ti o pe fun ibasepo to dan moran laarin awon elesin ati eleya-meya gbogbo.
Ilé asòfin àgbà: Omo-Agege ló gbé ọ̀pá àsẹ ilé lọ
Ọbasanjọ ni ọmọ òrùkàn tó di olóri orílẹ̀èdè lẹ́ẹ̀mẹ́ta ọ̀tọ̀ọ̀tọ̀ Ọbasanjọ sọ àsírí sàgbàdèwe rẹ̀ Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ọdún 1940 ni wọ́n ti ń sin ọ̀ọ̀nì ilé Delesolu ní Ìbàdàn Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Ọdún 1940 ni wọ́n ti ń sin ọ̀ọ̀nì ilé Delesolu ní Ìbàdàn 15 Ògún 2018 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 17 Sẹ́rẹ́ 2019 Àṣà ni kìí ṣe ẹ̀sìn rara.
Gbogbo oko ni ó rọ ní Heṣiboni;bẹ́ẹ̀ náà ni ọgbà Sibuma:àwọn olórí orílẹ̀-èdè ti gé àwọn ẹ̀ka rẹ̀ lulẹ̀,èyí tí ó tàn kálẹ̀ dé Jaseri títí dé inú aṣálẹ̀.
Irú ohun tí ó ṣẹlẹ̀ sí Jerusalẹmu yìí kò ṣẹlẹ̀ sí ìlú kan rí, ninu gbogbo àwọn ìlú ayé yìí.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Alága NURTW nípínlẹ̀ Ọ̀yọ́ dágbéré fáyé Àwòrán tó làmìlaaka níbi ọdún iléyá Ọdun mejila ni alagba ẹni ọgọrin ọdun naa ni oju oun ti kọkọ bẹrẹ ki o to di pe o fọ nitori aisi owo lọwọ rẹ pẹlu ọwọngogo itọju aisan oju.
OLUWA óo fún ọ ní ọpọlọpọ ọmọ, ati ọpọlọpọ ẹran ọ̀sìn.
Ìdálẹ̀ ni ẹ̀gbọ́n mi náà lọ tí wọn fi ri ara wọn, tí wọ́n fẹ́ ara wọn, nítorí náà a ti máa wá sí ilé Alárìnkiri tẹlẹ kí ó to di pe ọ̀ràn Igbó Elégbèje kanlẹ̀ yìí, Inúlayéwà jẹ ẹni ti ó máa n ṣiṣẹ́ káàkiri ẹ̀yìn odi ojú rẹ̀ sì ti rí nǹkan púpọ̀ sẹ́yìn, o ti gbé ọ̀pọ̀lọpọ̀ ìlú, o tì gbé ààrin onírúurú ènìyàn, ìyà ti jẹ ẹ́ ebi ti pa á, wọ́n ti di rìkíṣí mọ́ ọ, o ti ṣàìsàn, ó ti jókòó láìrí àga, ó ti dùbúlẹ̀ lórí ilẹ̀ pẹ̀pẹ̀, òùngbẹ ti gbẹ ẹ́ láì rí omi, ó ti dúró ní odidi ọjọ́ láì jẹun, ó ti rìn ní òun nìkan lójú ọ̀nà, ó ti sùn láìrí aṣọ bora òtútú ti pa á, òòrùn ti pa á.
OLUWA, OLUWA àwọn ọmọ ogun,yóo gé àwọn ẹ̀ka igi náà pẹlu agbára tí ó bani lẹ́rù.
“Ẹni ma a bèrè ẹ̀tó lábẹ́ òfin yio lọ pẹ̀lú ọwọ́ mímọ́”,  ẹ gb́e ọ̀rọ̀ yi yẹ̀wò bóyá bi wọ́n bá fi ẹ̀sùn iwà ibàjẹ́ kan Adájọ́, kò yẹ ki Ọ̀tẹlẹ̀múyẹ́ wa idi.
Nígbà tí ó fẹ́ kọjá lọ sí Akaya, àwọn onigbagbọ ní Efesu fún un ní ìwúrí, wọ́n kọ ìwé sí àwọn ọmọ-ẹ̀yìn Jesu ní Akaya pé kí wọ́n gbà á tọwọ́-tẹsẹ̀.
"Ẹ ba wa bẹ ijọba ki wọn dá àwọn oluwọde lohun"" Jakejado Naijiria ni iwọde ENDSARS ti n ṣe idiwọ fun lilọ bíbọ ọkọ nitori bi wọn ti ṣe di gbogbo oju ọna."
Ijoba orile-ede Naijiria ti setan lati wa ojutu sisoro awon ohun eelo ija oloro bii ibon to ti wopo lawujo bayii.
Ǹkan mẹ́jọ tó máa kọ́kọ́ ṣẹlẹ̀ kí olólùfẹ́ méjì tó pa ara wọn Fábàdà!
Ẹ fi wọ́n sílẹ̀, ẹ má dí wọn lọ́wọ́.
Wọn si gbe aworan awọn afurasi naa l'akoko ìkọlu nibi ti wọn ti gbẹmi ogunlọgọ eniyan pelu ọlọpaa mẹsan eniyan jade pẹlu.
“Kabiyesi, oluwa mi, gbogbo nǹkan tí àwọn eniyan wọnyi ṣe sí wolii Jeremaya kò dára.
Nínú àtẹ̀jáde ọ̀hún, ìpínlẹ̀ Eko ni 296 nígbà ti Abuja ni 291, Kadujna ni 79 nígbpa ti Rivers ni 40.
eto aabo lọkunkundun lorile ede Naijiria paapaa julo ni awon papa oko oju
Sioni sì di ibi tí wọn ń pè ní ìlú Dafidi.
àwọn ni wọ́n wá sọ fún wọn pé, “Oluwa ti jí dìde nítòótọ́, ó ti fara han Simoni.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Tunde Bakare: Ọmọ Nàíjíríà, ẹ gbáradì fún àgbékalẹ̀ Nàíjíríà tuntun 20 Sẹ́rẹ́ 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 21 Sẹ́rẹ́ 2019 Oríṣun àwòrán, @T_Bakare Olusọ̀ aguntan agba fun ijọ Latter rain Assembly, Pasitọ Tunde Bakare ti kesi awọn ọmọ Naijiria to fẹ agbekalẹ orilẹede Naijiria tuntun lati darapọ mọoun fun ijagudu fun agbekalẹ orilẹede Naijria tuntun.
ng/ Ago mẹwa alẹ ọjọ Aje ọjọ kọkanlelogun oṣu kẹsan ọdun 2020 ni oju opo yoo di ṣiṣi fun awọn eeyan lati forukọ silẹ.
Awọn agbofinro gan ni o ṣeni laanu pe awọn ko ni irufẹ ohun eelo ija ti awọn ajinigbe n lo ni Naijiria.
Ọgá àgbà ọlọ́pàá ń lépa ẹ̀mi mi -Dino Melaye Àwọn ohun tó yẹ kí o mọ̀ nípa Shehu Shagari tó d'olóògbé ‘Awakọ̀ Ọ̀gágun Alex Badeh tí wọ́n pa kò kú’ Ètíko Onígẹdú, Sinimá tó gba àmì ẹ̀yẹ̀ AMVCA Lọ́jọ́ jimọ ní àwọn ọlọ́pàá bí ogun yabo ilé Dino Melaye láti mu.
Ṣugbọn, Donald Trump ti bẹrẹ ipolongo ibo fun eto idibo aarẹ ti yoo waye l'oṣu Kọkanla, ọdun 2020.
Mò ń pada bọ̀ wá sọ́dọ̀ yín.
Ọkan lara awọn awakọ ọkọ ti ọkọ wọn jona, Yusuf Tiamiyu ti ọkọ rẹ gbe gaasi, sọ fun akọroyin BBC, Ajoke Ulohotse pe inu ọkọ ni oun wa nitori isede lasiko ti ijamba naa waye.
Lọjọ Satide ni agbo naa de si Naijiria, Aarẹ orilẹede Guinea Bissau lo gbe oogun naa fun Aarẹ Muhammadu Buhari nile ijọba l'Abuja.
Adamu, to jẹ ọkan lara awọn ti orukọ wọn ṣẹṣẹ jade niwaju ile aṣofin agba gẹgẹ bii minisita ni saa keji Aarẹ Buhari ṣalaye pe ẹri maa jẹ mi niṣo lori ọrọ yii wa ninu eto onka tuntun ti wọn ṣe loṣu keji ọdun 2019.
Wọ́n ti ṣí ilé oúńjẹ oní ọgbọ̀n náírà (N30) ní Kano #Bum bum war:Yemi Alade tọrọ àforíjìn lọ́wọ́ Tiwa Savage O ṣójú mí kóró bí wọ́n ṣé fí àdó olóró pa Dele Giwa lọdún 1986- Soyinka Oríṣun àwòrán, Sophie Elise Àkọlé àwòrán, Ọmọ ogún ọdún tó fẹ́ràn kí obìnrin ní ìdí ni mí- Sophie Gẹgẹ bi o ti wi, o ni aridaju ti wa fun ohun bayii pe okun ọrun ko yẹ adiyẹ ohun rara ti abamọ si ti n gbẹyin ọrọ bayii.
Ilé-ẹjọ́ yí ẹjọ́ DPO ọlọ́pàá tó ju télọ̀ sátìmọ́lé torí ó ba aṣọ rẹ̀ jẹ́ dànù Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Bí o bá bá ààrùn ìpẹ́pẹ́ gbígbẹ lára arẹwà obìnrin rẹ̀, kí loó ṣe?
Ìran tí ń bọ̀ yóo máa sìn ín;àwọn eniyan yóo máa sọ̀rọ̀ OLUWA fún àwọn ìran tí ń bọ̀.
Ǹjẹ́ o mọ̀ bí ó ṣe so awọsanma rọ̀,iṣẹ́ ìyanu ẹni tí ó pé ní ìmọ̀ ni;
"Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: ""Ẹ̀yin obìnrin, ẹ lọ kọ́ iṣẹ́ káfíńtà torí ó lówó lórí ju iṣẹ́ aránṣọ lọ"" Àwọn ọmọbíbí ìpínlẹ̀ Ọyọ nìkan ni yóò rí iṣẹ́ àgbàṣe gbà lábẹ́ ìjọba mi - Seyi Makinde Àwọn obìnrin yarí, wọ́n kò fẹ́ àwọn ọkùnrin ní òde ijó wọn Asọ́ ń pe aṣọ ránsẹ́ níbi ayẹyẹ ojúde Ọba ní'lùú Ijẹbu Pàtàkì ọdún Ojúde Ọba fún ìran Yorùbá Lasiko ọdun ojude ọba to waye nilu Ijẹbu Ode lọjọ iṣẹgun, ni Awujalẹ ti gbe sọrọ nla yii fun awọn eeyan rẹ, paapaa julọ awọn afọbajẹ."
’ ” Wọ́n bá bẹ̀rẹ̀ sí bẹ̀ ẹ́ pé, “Jọ̀wọ́, dárí ẹ̀ṣẹ̀ àwọn iranṣẹ Ọlọrun baba rẹ jì wọ́n.
N kò rí nkankan sọ, àfi pé Ọlọ́run tóbi l’ọ́ba.
O ti n ni owo kan oloselu ninu Awon kan ni pe esu mo si ohun to n sele Laipe yii ni ijọba South Africa kede pe awọn ile ijọsin lee bẹrẹ isin pada ṣugbọn ki wọn ma ju aadọta lọ.
"Kọmisọnna naa fikun wi pe laipe si isinyii ipinlẹ Ondo yoo ma a pese ""sweet"" ati ohun ipanu awọn ọmọ ile iwe bii ""sunshine chocolate"" lati ara cocoa."
Bẹ́ẹ̀ sì ni òun ni ẹ̀rọ ìbánisọ̀rọ̀ fún mi ní ìgbà gbogbo.
Adari orile ede ko sai fi edun okan re bi awon odo orile ede Naijiria se n salo si oke –okun lati lo se ise nibe nigba ti orile ede Naijiria kun fun ile to n san fun wara ati oyin, ti won tun le gbe igbe –aye irorun.
"A nilo alaafia ni Guusu Kaduna.
Orilẹ-ede America nikan kọ ni wọn ti maa n ṣe idajọ iku fun awọn ọ̀daràn.
O ni ọna awọn ọlọpaa lori ẹjọ yii ko mọ rara.
Koríko hù sí orí òkè náà ṣùngbọ́n ó dàbí ẹnipé ẹnìkan nṣe ìtọ́ jú rẹ̀ nítorípé koríko ọ̀hún kò hù kọjá ààlà.
Bo tile jẹ pe eto idibo naa lọ ni irọwọ ati irọsẹ, sibẹ  awon agbegbe kan wa ti wahala  waye nibẹ bii woodu keta ni  ijoba Ibile
Ṣaaaju ni gomina ipinlẹ Imo tẹlẹ, Rochas Okorocha ti kọkọ ni ki wọn din odiwọn iye awọn aṣojusofin ku nile ijọba ni Abuja.
O fi kun un pe ileeṣẹ ọlọpaa ti bẹrẹ iwadii lori iṣẹẹ naa.
Sẹnetọ to n soju ẹkun idibo iwọ oorun ipinlẹ Kogi nile Asofin Agba, Sẹnetọ Dino Melaye wa lara awọn to n dije dupo gẹgẹ bii ẹni ti yoo gbe asia ẹgbẹ oselu PDP ni idibo sipo gomina to n bọ.
Abala to kẹhin ni wa a ti yan ibudo ti o ti fẹ ẹ gba idanilẹkọ rẹ.
Lock down: ìjọba àpapọ̀ Nàìjíríà ní ẹnìkan ṣoṣo nínú ìdílé kan ni yóò gbà N20, 000 owó ìdẹ̀rùn igbele Covid-19
Oríṣun àwòrán, Getty Images Ninu atẹjade kan ti wọn fi sita loju opo Twitter wọn, ijọba Saudi sọ pe awọn eeyan to n gbe l'orilẹ-ede naa nikan ni yoo ni anfaani lati kopa, lai fi ti ẹya tabi orilẹ-ede ti wọn ti wa ṣe.
Bi a ko ba tun gbagbe iru nkan bayi naa waye laarin Gomina Akinwumi Ambode ipinlẹ Eko ati baba isalẹ ẹgbẹ APC Bola Ahmed Tinubu.
Owolewa gbegba oroke ninu odibo naa lẹyin to fi ẹyin awọn alatako rẹ, Joyce Robinson-Paul ati Sohaer Syed gbolẹ.
Ní gbogbo àkókò yìí, Joabu wà níbi tí ó ti gbógun ti Raba, olú ìlú àwọn ará Amoni, ó sì gba ìlú ọba wọn.
 O wa gbadura pe, gbogbo ẹni to fi adura ransẹ si oun, titi to fi de aafin Oyo lọdọ Alaafin, aye gbogbo wọn ko ni bajẹ."
" Ogo Yoruba ni tanitoluwa Akinwunmi jẹ, ọmọ to si yẹ ka maa foju sọna fun pe yoo gbe ogo ilẹ Yoruba ga loke okun ni.
Ipade ti ijoba apapo ati egbe osise fafiti lorile ede Naijiria (ASUU) se lojo Isegun fori sapon.
Ṣùgbọ́n Fáyóṣé ní kí ààrẹ Mùhámádù Bùhárí ó gbájúmọ́ ìpèníjà tó ńkojú ìjọba rẹ̀ láti pèsè ààbò tó péye fún àráàlú dipo didi ẹ̀bi gbogbo ìjákulẹ̀ rẹ̀ ru ẹnikẹni to ba ri lọ̀.
Ère tí Mika yá ni wọ́n gbé kalẹ̀, ní gbogbo àkókò tí ilé Ọlọrun fi wà ní Ṣilo.
Àwọn Juu bẹ̀rẹ̀ sí sọ pé, “Kò ṣá ní pa ara rẹ̀, nítorí ó wí pé, ‘Ẹ kò ní lè dé ibi tí mò ń lọ.
Nigbati ẹgbẹ oṣelu alatako gboogi ni Naijiria, PDP sọ wipe iṣẹlẹ bi wọn se gbe awọn akẹkọ Dapchi itusilẹ wọn mu ifura lọwọ.
Ọjọbọ tun ni ọjọ ti wọn da pe lati tẹsiwaju ninu igbẹjọ ẹsun ijọmọgbe ti wọn fi kan asaaju ijọ Sotitobire, Alafa Babatunde.
Wọn ni ẹsun fún ilọnilọ́wọ́ gbà àti lílo orukọ èèkan ilú lu jìbìtì ni àwọn muu fun.
''Awọn ọdọ aye ode oni mọ ẹtọ wọn, wọn si n lo ẹrọ ayelujara lati fi aiṣedede ijọba han si gbangban'' ''Nitori naa ni ijọba ṣe gbọdọ lo asiko yii lati fi pẹtu si awọn ọdọ ninu, kii ṣe ki wọn dukoko mọ wọn, tabi gbegile apo owo wọn ni banki, nitori ko bojumu.
Iṣiboṣẹti kò sì lè dá Abineri lóhùn nítorí ó bẹ̀rù rẹ̀.
Aarẹ CAf, Ahmad ko sọ idi kankan ti wọn fi gba iṣẹ lọwọ rẹ.
Nilu Ilorin ni aṣa yi ti bẹrẹ ti o si ṣe atọkun bi ifidirẹmi gbajugbaja oloṣelu ọmọ ilu naa, Bukola Saraki ati ẹgbẹ PDP ti ṣe waye.
Ni Jakọbu bá tọ baba rẹ̀ lọ, ó pè é, ó ní, “Baba mi,” Baba rẹ̀ bá dá a lóhùn pé, “Èmi nìyí ọmọ mi, ìwọ ta ni?
Oríṣun àwòrán, Sylvester Ofori/Facebook Àkọlé àwòrán, Pastor Sylvester Ofori Pásítọ̀ Ofori dèrò ẹ̀wọ̀n lẹ́yìn tó yìnbọn pa ìyàwó rẹ̀ ní ìta gbangba Pasitọ kan to jẹ ọmọ bibi orile-ede Ghana, Sylvester Ofori ti yinbọn pa iyawo rẹ, Barbara Tommey.
Lọ́jọ́ kan, nígbà tí mo fi wà láàrin àwọn ọmọ ènìyàn, ọkùnrin kan wà lẹ́bàá ilé wa.
Àkọlé àwòrán, Awọn olufẹhonu han Bayii, gbogbo oju popo lo ti pa lọlọ ti ko si si igboke gbodo ọkọ bii igba ti ilẹ ṣẹṣẹ mọ.
onimọ iṣiro owo ti wọn ti ni iriri to ọdun mẹwaa lẹnu iṣẹ.
À mọ́ lọ́jọ́ tí ìṣẹlẹ̀ yí máa wáyé, bàbá kiri ẹran wọ inú ìletò, àwọn ọmọdétẹ̀lé bàbá ẹlẹ́ran bí ìṣe wọn.
Meghan bẹrẹ si nii rọbi bayii fun akọbi Ọmọọba Harry.
Ọlabisi Ajala rèé, ó gun ọ̀kadà yíká àgbáyé, tó sì dé orílẹ̀èdè 87 Ẹ máṣe gba ààwẹ̀ dójú ikú, ẹ gba iye tí agbára yín gbé - Dókítà Ọ̀nà láti sọ fásitì Lautech di ti Ọyọ nìkan ni Makinde ń sán - Ìjọba Ọṣun Ìkọlù sáwọn àjèjì kò tíì tán ní South Africa, ètò ń lọ láti kó ọmọ Nàíjíríà wálé Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Lẹ́yìn náà Ọlọrun wí pé, “Ẹ jẹ́ kí á dá eniyan ní àwòrán ara wa, kí ó rí bíi wa, kí wọ́n ní àṣẹ lórí àwọn ẹja inú òkun, ẹyẹ ojú ọ̀run, àwọn ẹranko ati lórí gbogbo ayé ati àwọn ohun tí wọn ń fàyà fà lórí ilẹ̀.
N óo fi àwọn kan láti inú ilé ìpàdé Satani lé ọ lọ́wọ́, àwọn òpùrọ́ tí wọn ń pe ara wọn ní Juu, bẹ́ẹ̀ sì ni wọn kì í ṣe Juu.
Koda, awọn ọkunrin to jẹ agbabọọlu gan ko gbagbe ayajọ ọjọ ma lo kọmu, gẹgẹ bo se wa ni @Regi_Maeco, ẹni to ya aworan bi oun ati ọrẹ rẹ se sami ọjọ Ma lo kọmu.
 Òpeni ní í ṣọlá , kì í tilẹ ̀ í ṣe irú ìpè tí tẹbí-tará pè bí eléyìí lẹnìkan ò ní í dáhùn .
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ondo disability day: Ijọba ẹ gbà wá ní ariwo tí àkàndá ẹ̀dá ń pa Oríṣun àwòrán, Oba Orin Àkọlé àwòrán, Teni: Olórin obìnrin tí kìí ṣi ìhòhò rẹ Ọkọ̀ aképò dàwó, ilé 30 jó ènìyàn 6 pàdánù ẹmí ní Jebba, Kwara Àwọn ohun tó yẹ kí o ṣe àti èyí tí kò yẹ kí o ṣe lásìkò ọdún Keresimesi rèé Ọwọ́ ọlọ́pàá tẹ ayédèrú Ahmed Musa tó ń lu àwọn èèyàn ní jìbìtì Agbébọn yìnbọn pa ọlọ́pàá mẹ́ta lẹ́ẹ̀kanṣoṣo ní Saint-Just Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Ọ̀lọ́pàá shátà mi láti Mowe dé Magboro dé Shagamu, wọ́n ní ṣé mi ò mọ̀ pé ìjọ́ba ni mo ṣiṣẹ́ fún' Sáàju ni Teni Apata lásìkò to ṣe àbẹ̀wò si ilé iṣẹ́ BBC ti sàlàyé ìdí ti kìí fi ṣi ìhòhò rẹ̀ silẹ̀ nígba gbogbo Teni sàlàyé pé níní ifẹ́ si ominira ara òun jẹ́ ọkan pàtakì idí ti òun kìí fi ṣi ìhòhò ara òun sílẹ̀.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Okodoro ọrọ meje nipa George Weah Lara awọn eniyan jankan-jankan to peju pesẹ sibi eto ibura wọle ọhun ni aarẹ orilẹede Ghana, Mali, Nigeria ati Togo to fi mọ awọn ọrẹ ati alabasisẹpọ Weah lasiko to fi jẹ agbabọọlu.
Bàbá Wande ní gbajúmọ̀ agbábọ́ọ̀lù lòun ì bá jẹ́ ká ní òun kò ṣeré tíátà
''Ọga ọlọpaa Gwazarzah gbami leti, o si tun gba aṣọ mejila ti mo ba ran an lai san ọgọta ẹgbẹrun un naira ti a jọ fẹnu ko si,'' Adeniyi lo sọ bẹẹ.
Akọṣẹ-mọṣẹ nipa ounjẹ ọhun ajẹju awọn ounbjẹ yii le mu ki eeyan sanra ju tabi yọkun.
Ọjọru ni Fayemi kede pe oun ti ranṣẹ pe Fayose lati wa nibi ibura oun gẹgẹ bi gomina tuntun Ipinlẹ Ekiti.
Ṣe ẹni ti ara rẹ ko ya yii ni iṣoro èémí?
Wo àwọn tó ti dákú bíi Maina níwájú ìjẹ́jọ́ Wọ́n ti rí Ọ̀pá Àṣẹ ilé aṣòfin ìpínlẹ̀ Ogun tí àwọn jàndùkú jí gbé nípinlẹ̀ Eko o!
A máa rọ òjò sórí ilẹ̀,a sì máa bomi rin oko.
Losu to kọja, awọn Fulani darandarn da'nọ sun oko oloye Olu Falae ni ilu Akurẹ, ti won si pa awako kan lori ariyanjiyan laarin won ni ipinlẹ Ondo.
Oríṣun àwòrán, @Atawe Awọn ẹkọ ti iwe naa kọ wa naa ni ki a fopin si iwa ijinigbe, ole jija, igbo mimu, igbo gbingbin ati tita ati bẹẹ bẹe lọ.
O ni idunnu lo jẹ f'oun pe oun wa laaye nigba ti iru iṣẹlẹ yii ṣẹlẹ papaa julọ iha ti ile iṣẹ ọlọpaa kọ si iṣẹlẹ ọhun.
Ki o to di ojo yii, ni awon olopaa ti fipa mu awon eniyan ti o fe lo pade Bobo Wine, to je gbaju-gbaja akorin  ati ajijagbara, ni papa ofurufu Entebbe.
Eẹẹka si bori ni Ado, Ikere, Emure and Efon.
 Ẹkọ ti itan naa kọ wa: O yẹ ki awọn ọkunrin maa ni ipamọra, suuru ati ifarada pẹlu aọn obinrin abi ipokipo ti a ba ba ara wa Ko yẹ ka maa gba kamu pe ko lee see se ta ba ri ijakulẹ awọn eeyan miran lori ohun kan Suuru ni baba iwa, o yẹ ka maa mu suuru ninu ohun gbogbo, ka lee bori nigbẹyin."
Oríṣun àwòrán, Bigbrother Ni bi a ṣe n sọrọ yii, wọn ko tii fun saa karun un eto naa ni orukọ apejẹ kankan.
Ẹ lọ fi wọ́n ṣọ́ ibojì náà bí ó ti tọ́ lójú yín.
Ni bayii, Kamaru náà ni yóò tún jẹ́ ọmọ Afíríkà àkọ́kọ́ tó fẹ̀ṣẹ́kùbíòjò gbaigbanu ẹyẹ idije Ultimate Fighting Championship.
Àkókò ń bọ̀ tí ẹ óo gbúròó ogun ati ìrọ́kẹ̀kẹ̀ ogun.
Naijiria kọ́lo tosi julọ Minisita fun ọrọ ilẹ okeere ni orilẹ-ede Naijiria tẹlẹri, Bolaji Akinyemi ti sọ pe awọn ọmọ Naijiria kii sọ otitọ nigba gbogbo nipa ọrọ aje Naijiria.
" Awọn agbagba naa sọ pe, ni ilẹ miran, ohun ti adari ti ko ba koju oṣuwọn maa n ṣe ni ko kọwe fiposilẹ.
Ǹjẹ́ o mọ ẹni tó ran àjọ ọ̀tẹlẹ̀mùyẹ́ CIA lọ́wọ́ láti rí Bin Laden mú?
NURTW: Makinde kò tíì yí àṣẹ rẹ̀ padà lórí i gbígbẹ́sẹ̀ lé NURTW ní ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́
”Anania bá dáhùn pé, “Èmi nìyí, Oluwa.
Lara awọn ere olokiki taa mọ Akin Ogungbe mọ ni Ireke Onibudo, Asiri Baba Ibeji, Lisabi, Igba Funfun ati Ologbo Jigọlọ.
Sibẹsibẹ àwọn ọ̀tá kó o lọ sí ìgbèkùn, wọ́n ṣán àwọn ọmọ wọn mọ́lẹ̀, wọ́n pa wọ́n ní ìpakúpa ní gbogbo àwọn ìkóríta wọn.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ondo: Dejí sun ọmọ méje àtagbalagba meji mọ́lé nítorí pé ó ń bínú Igbagbọ awọn eniyan ipinlẹ Ondo ati Ekiti ni pe laipẹ ni wọn yoo le tun maa fẹdọ sori oronro sun bii ti tẹlẹ pẹlu igbesẹ tuntun ti awọn ọmọ ogun gbe yii.
O ṣapejuwe awọn obinrin to n bora bii alawọ ọpọlọ.
Ilẹ̀ ń mì tìtì níwájú wọn,ọ̀run sì ń wárìrì,oòrùn, òṣùpá ati àwọn ìràwọ̀ ṣókùnkùn.
Àwọn èèyàn ìlú Okeho ló kó gbogbo owó tí wọn rí gbà lọ́wọ́ àwọn adigunjalè tí wọ́n mú"" Olùrànlọ́wọ́ pàtàkì fún ọ̀rọ̀ ibojì òkú, àti àwọn ipò òṣèlú mìíràn tó jẹ́ kàyééfì ní Nàìjíríà Buruji Kashamu jẹ́ ènìyàn tó nífẹ̀ aráàlú- Gómínà Dapo Abiodun Baba Obasanjọ kò ní àrùn Coronavirus- NCDC Oludamọran Gomina Babajide Sanwo-Olu lori ọrọ iroyin ori ayelujara, Jubril Gawat lo fọrọ naa lede loju opo Twitter rẹ."
O ti fi igba kan jẹ Aarẹ ẹgbẹ awọn onimọ ẹ̀rọ, to jẹ ọmọ Naijiria, ni Minnesota.
Ìdí tí Kristi fi kú fún gbogbo eniyan ni pé kí àwọn tí ó wà láàyè má ṣe wà láàyè fún ara wọn, ṣugbọn kí wọ́n lè wà láàyè fún ẹni tí ó kú fún wa, tí Ọlọrun sì jí dìde.
Eyi lo mu ki ikọ BBC News Yoruba tọ diẹ lara awọn amuludun ti wọn n fojojumọ gbe sinima Yoruba jade pe, bawo ni lori fifi ami ohun si ọrọ Yoruba.
Yobo ni tawọn ikọ asoju Naijiria ni AFCON 2019 ba lee se ara wọn lọkan, ti wọn gba bọọlu pẹlu irẹpọ, ti wọn si ri ara wọn bii ẹbi kansoso, wọn yoo gba ife ẹyẹ naa.
Trump - BBC News Yorùbá BBC News, YorùbáFò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Birth tourism: Ẹ̀yin obìnrin tẹ́ẹ fẹ́ wá bímọ ní America, ọ̀nà ti tì pa látònì!
O ni ṣugbọn, oun kilọ pe ki awọn ẹya Yoruba ma ṣe fi ipo tyabi jagidijagan ṣe ohunkohun.
Asiko ti ajakalé arun yii jade naa ni orilẹ-ede DR Congo si n ba ajakalẹ arun Ebola faa.
Nígbà tí ó bá yá, ìjọba kẹrin yóo dé, tí yóo le koko bíi irin (nítorí pé irin a máa fọ́ nǹkan sí wẹ́wẹ́ ni); bíi irin ni ìjọba yìí yóo fọ́ àwọn tí wọ́n wà ṣáájú rẹ̀ túútúú.
Ni ibẹrẹ ọdun yii ni Gomina ipinlẹ Kano, Abdullahi Ganduje da Emirate tuntun mẹrin si agbegbe Bichi, Karaye, Gaya ati Rano pẹlu Emir tuntun wọn.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Akomolede Eko round up: Àwọn Olùkọ́ ìpínlẹ̀ Eko dárà lórí Akọ́mọlédè àti Àṣà lórí BBC 7 Bélú 2020 Akomolede ati Asa lori BBC Yoruba jẹ ọkan lara eto akanse ti BBC Yoruba ṣagbekalẹ rẹ fun igbadun ẹyin ololufẹ wa.
Àwọn ẹ̀yà ara àwọn aláìsàn tí amodi tẹ̀ ti ń daṣẹ́ sílẹ̀ – a kò gbọ́ èyí rí.
Eyi ni fun iwọ iyawo mi #WhatYouWant #LetterToMyWife #Everything #MamaDaniel 8/8/18.
Sibesibe, oju omi si ru nitori koi ti han si enikeni ona ti aare Buhari yoo gbe atunto isakoso re gba.
Bí inú àwọn eniyan ti máa ń dùn nígbà tí wọ́n bá ń pín ìkógun.
Bẹnaya ọmọ Jehoiada sì ní olórí àwọn ẹ̀ṣọ́ ọba.
Gẹgẹ bi obinrin naa ṣe sọ oun ati ọkọ rẹ ni wọn jumọ jade ni ọjọ naa lati lọ ra awọn nnkan ti wọn yoo lo fun ayẹyẹ ọjọ ibi smọ wọn to n bọ lọna ti wọn fi pade awọn oṣiṣẹ kansu naa.
Kò sí ẹni tí kò mọ̀ pé àṣírí ẹ̀sìn wa jinlẹ̀ pupọ:Ẹni tí ó farahàn ninu ẹran-ara,tí a dá láre ninu ẹ̀mí,tí àwọn angẹli fi ojú rí,tí à ń waasu rẹ̀ láàrin àwọn alaigbagbọ,tí a gbàgbọ́ ninu ayé,tí a gbé lọ sinu ògo.
Gẹgẹ bii obinrin to n da gbe, Iyalufa n ko ba oju, to si n ko ba imu lati ri daju pe ile aye dun gbe fawọn ọmọ rẹ mejeeji.
Samuel Chukwueze lo kọkọ gba bọọlu wọnu awọn South Africa ni iṣẹju kẹtadinlọgbọn ifẹswọnsẹ naa ki South Africa to da goolu pada ni iṣẹju karundinlọgọrin.
to n mojuto papa ofurufu(Federal Airports Authority of Nigeria) ati ajo to n
Bí àdí bá ń lérí sí òòrùn
Ipalẹ̀mọ́ ìsìnku bẹ̀rẹ lati ṣe àṣeyẹ ikẹhin fún olóògbé dipò ayẹyẹ ọjọ́ ọgọrun ibi.
Ni ipinlẹ Ọyọ, alaafia wa fun wa, Yoruba ati Fulani, ọmọ iya kan naa ni wa.
Diẹ ree ninu ọrọ aarẹ Donald Trump ti awọn eniyan fi sọ pe, o fi ọwọ yẹpẹrẹ mu ọrọ Coronavirus, ti oun gan-an fi wa lugbadi aarun naa bayii.
Nígbà náà ni Olórí Alufaa dìde láàrin wọn, ó bi Jesu pé, “Ìwọ kò fèsì rárá?
Ẹ dàbíi Kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ ìgbẹ́, tí aṣálẹ̀ ti mọ́ lára,tí ń ṣí imú kiri,nígbà tí ó ń wa akọ tí yóo gùn ún.
Inú Hana bàjẹ́ gan-an, ó bẹ̀rẹ̀ sí gbadura sí OLUWA, ó sì ń sọkún tẹ̀dùntẹ̀dùn.
Awọn agbebọn ọhun, ti ko si ẹnikẹni to mọ idamọ wọn, lo sadede bẹ jade lati inu igbo to wa lẹba opopona naa, ti wọn si n yinbọn mọ awọn ọlọpa naa, ti wọn wa lati agọ ọlọpa Isua.
Ti ara wọn ko ba ju oṣuwọn BMI 18.
Jesu wí fún un pé, “Àwọn kọ̀lọ̀kọ̀lọ̀ ní ihò, àwọn ẹyẹ ojú ọ̀run sì ní ìtẹ́; ṣugbọn Ọmọ-Eniyan kò ní ibi tí yóo gbé orí rẹ̀ lé.
Oludari ile-akede Naijiria (Voice of Nigeria VON), Osita Okechukwu, ti so pe aare orile ede Naijiria ,Muhammadu Buhari ko ni tun kaare lati maa tubo pese eto oko oju irin, ni ekun ila oorun, ni eyi ti yoo kan awon ipinle méjìdínlógún to wa lorile ede yii.
Abajade iwadii ti ajọ to n mojuto rogbodiyan l'agbaye fi sita nibẹrẹ ọdun yii fihan pe ija ilẹ to n waye laarin awọn agbẹ to jẹ Hausa ati awọn daran-daran Fulani, lo jẹ ipilẹ rogbodiyan naa.
Nígbà tí ó yá, Ẹ̀mí Ọlọrun bà lé Sakaraya, ọmọ Jehoiada alufaa, ó bá dìde dúró láàrin àwọn eniyan, ó ní, “Ọlọrun ń bèèrè pé, ‘Kí ló dé tí ẹ fi tàpá sí òfin òun OLUWA; ṣé ẹ kò fẹ́ kí ó dára fun yín ni?
Imọran ti wọn le fi koju eleyi tawọn eeyan mu wa ni pe ''ẹ sisẹ nibi ti atẹgun yoo ti maa fẹ si yin daadaa.
O wa gba awọn akẹẹgbẹ rẹ nimọran lati ni isẹ ọwọ kan ni pato yato si iwe, nitori iwe nikan ko to jẹun mọ laye ode oni.
Akọroyin BBC Yoruba, Olu Alebiosu ti oun naa n rin loju ọna naa jabọ pe awọn ti ọrọ naa soju wọn sọ pe ọkọ nla kan to ya si ibi ti ko yẹ lo mu ki ijamba naa sẹlẹ.
Awọn oṣiṣẹ ijọba Naijiria sọ wipe awọn akẹkọbirin maarundinlaadọfa ati ọmọkunrin kan ni Boko Haram tu silẹ, sugbọn iroyin ṣọ wipe maarun ninu wọn ti ku.
Ọ̀rọ̀ Ebola yìí mà ni o.
Aṣọ títa fún apá kan ẹnu ọ̀nà jẹ́ igbọnwọ mẹẹdogun, ó ní òpó mẹta ati ìtẹ́lẹ̀ mẹta.
 Lasiko ifọrọwerọ kan lori redio nigba to n polongo lati jẹ asaaju fun ẹgbẹ oselu rẹ, Conservative Party - eyi ti yoo sọ di Olootu ijọba ilẹ Europe logan - Boris ni A ti n gbaradi lati jade lọjọ kọkanlelọgbọn osu kẹwa.
Ọpọlọpọ igba ni awọn ọkọ nla ma n da sunkẹrẹ fakẹrẹ ọkọ silẹ ni agbeegbe afara Otedola naa, ti ijamba ina si ti ṣẹlẹ nibẹ lọpọ igba.
Efuraimu dàbí ọmọ mààlúù tí a ti fi iṣẹ́ ṣíṣe kọ́, tí ó sì fẹ́ràn láti máa pa ọkà, mo fi ọrùn rẹ̀ tí ó lẹ́wà sílẹ̀; ṣugbọn nisinsinyii, n óo gbé àjàgà bọ̀ ọ́ lọ́rùn, ó di dandan kí Juda kọ ilẹ̀, kí Israẹli sì máa ro oko fún ara rẹ̀.
Ó jókòó níbẹ̀, àwọn eniyan bá dúró ní etí òkun.
Nítorí bí ó bá jẹ́ pé ní Tire ati ní Sidoni ni a ti ṣe àwọn iṣẹ́ ìyanu tí a ṣe láàrin yín ni, wọn ìbá ti ronupiwada tipẹ́tipẹ́, wọn ìbá jókòó ninu eérú pẹlu aṣọ ọ̀fọ̀.
Ó ní àwọn olùkọ́ náà yóò wà nínú ewu, àwọn ọ̀jọ̀gbọ́n to ti darúgbó ló pọ̀jù tí wọ́n si ní àwọn akẹ́kọ̀ọ́ tó kún kíláàsì fọ́fọ́, ìrònú jinlẹ̀ gbọ́dọ̀ wà kí irú àwọn yìí tó padà sẹ́nu isẹ́ fún ìgbé ayé àlàáfíà Nínú ilé tàbí níta Bromage ní àwọn to kó ààrùn Coronavirus ní ta ko fi bẹ́ẹ̀ wọ́pọ̀ ṣùgbọ́n àwọn to kóra jọ pò sí inú ibì kan tí won ti ń kọrin, pariwo ló wọ́pọ̀, tí ènìyàn bá ju kòkòrò náà sì àárín ita, afẹ́fẹ́, oòrùn òtútù leè mú àdínkù bá ìtànkálẹ̀ rẹ̀, ẹ̀wẹ̀, ìjìnà sira ẹni àti mímú àdínkù bá ìbáṣpọ̀ elérò yóò rán gbogbo ènìyàn lọ́wọ́ láti fòpin sí ààrùn Coronavirus.
Ọlọ́pàá dènà ìwọ́de fún àtìlẹyìn ikọ̀ Amotekun ní Eko Oríṣun àwòrán, Others Iwọde fun itẹwọgba eto Amotekun to lọ gaaraga lawọn olu ilu ipinlẹ to wa nilẹ Yoruba lọjọ Aje, lo pakasọ nilu Eko.
Nígbà tí ọkunrin náà gbéra, tí ó fẹ́ máa lọ, baba ọmọbinrin náà rọ̀ ọ́ títí tí ó tún fi dúró.
 lẹ ́ yìn èyí ni ó dara pọ ̀ mọ ọmọ ẹgbẹ ́ olórin lẹ ́ yìn Àyìndé barrister , ẹni tí ó jẹ ́ ọ ̀ gá elére fújì láti ọdún 1975 tí ó sì dá dúró gẹ ́ gẹ ́ bí ọ ̀ gá ara rẹ ̀ ní ọdún 1978 .
Jẹ́ ki wọ́n ni ìgbàgbọ́ nínú rẹ̀, nítorí àwọn tó ni ìṣòrò yìí kìí gbà pé àwọn ni ìṣoro, sugbọ́n ti wọn ba rí ọ bi ọ̀rẹ́ tó súnmọ́ wọn, wọ́n yoo le fi ọkàn tan ẹni náà.
Ọlọ́pàá Sharia Kano mú èèyàn tó lé ní 80 tori oúnjẹ nínú ààwẹ̀ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ibadan expressway: Àwọn olè Fulani ló ń jí ènìyàn, pànìyàn ní òpópópónà!
Gbogbo awọn ti BBC fọrọwalẹnuwo lori odo adagun Ado Awaye yii ni wọn ke si ijọba lati wa ṣe ohun to yẹ fun ipese ohun amayedẹrun bii akasọ lati gun oke ti omi adagun yii wa ati awọn nkan mii ti yoo sọ ibẹ di ibudo irin ajo afẹ ti gbogbo agbaye a wá maa wò.
Àwọn ǹkan ti ọ̀pọ̀ ko mọ nípa Baba Suwe Gbajúgbajà òṣèré tíátà, Baba Suwe ń ṣe àìsàn.
Àwọn ọmọ ogun Saulu tí wọn ń ṣọ́nà ní Gibea, ní agbègbè Bẹnjamini, rí i tí àwọn ọmọ ogun Filistini ń sá káàkiri.
 orílẹ ̀ èdè mẹ ́ rin péré ni ó wà ní Áfíríkà , èyí tí ó wálẹ ̀ láti orílẹ ̀ èdè 20 ní àwọn ọdún 1980 .
Ninu erongba ti Kolawole fi lede loju opo Instagram rẹ, ko da ẹnikẹni lẹbi ọrọ naa, ṣugbọn o bu ẹnu atẹ lu bi awọn oṣere naa ṣe n lo ẹrọ ayelujara lọna to lodi.
Aadọjọ ni wọ́n, ara ẹ̀yà Bẹnjamini sì ni gbogbo wọ́n.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Ikọ Liverpool lo ti wọ asekagba idije naa lawọn saa meji ere bọọlu to kọja, ti Klopp si n figbe ta bayii pe isọwọ gba bọọlu Diego Simeon ti ikọ Atletico ko tọna.
Bẹ́ẹ̀ ni ẹni tí ó bá rí àwọn ẹni mímọ́ tí ó yí ìtẹ́ Olódùmarè ká rí nǹkan, ẹni tí ó bá rí òjììjì  Olódùmarè rí ọ̀ràn, ẹni tí ó bá mọ ibùjokòó Ẹlẹ́dàá kò lè mọ nǹkan tí ó máa dé bá òun.
Ohun tí ó wù wọ́n ni wọ́n ṣe sí àwọn tí wọ́n kórìíra wọn.
Nabali dá àwọn iranṣẹ náà lóhùn pé, “Ta ni Dafidi?
Wọn ni kò fọwọsowọpọ pẹlu wọn lori iwadii ẹsun ti wọn fi kan an pe ọna ti ko tọ ọ lo n gba ṣiṣẹ abẹ.
Ṣugbọn àwọn agbẹ̀bí náà bẹ̀rù Ọlọrun; wọn kò tẹ̀lé àṣẹ tí ọba Ijipti pa fún wọn, pé kí wọn máa pa àwọn ọmọkunrin tí àwọn obinrin Heberu bá ń bí.
Gbogbo eniyan ti rí i;àwọn tí wọ́n wà ní òkèèrè ń wò ó.
Kí baba ọmọ náà wí fún wọn pé, ‘Mo fi ọmọbinrin mi yìí fún ọkunrin yìí ní aya, lẹ́yìn tí ó ti bá a lòpọ̀ tán, 
Ìbú ẹnu ọ̀nà àbáwọlé jẹ́ igbọnwọ mẹ́wàá (mita 5), ògiri ẹnu ọ̀nà àbáwọlé náà gùn ní igbọnwọ marun-un marun-un (mita 3), lẹ́gbẹ̀ẹ́ kinni keji.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Iku Mavrodi: Àwọn olùdókòwò MMM ń fi apá jánú 27 Ẹrẹ̀nà 2018 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Sergei Mavrodi lo da ìlànà sogúndogójì MMM sílẹ̀.
Ẹnikẹ́ni kò ní ṣọ̀fọ̀ wọn, kò sí ẹni tí yóo gbé òkú wọn nílẹ̀; wọn kò ní sin wọ́n.
Angie Motshekga to je minista fun eto eko ni oro awon omobinrin Xhosa naa ba ni ninuje pupo pe won le wo iledi ‘inkciyo’ lasan fi maa korin ni eyi to tako asa iponraenile ile Adulawo lapapo.
Iwaadi ṣi n lọ lori ọrọ naa ti awọn afunrasi ti ọrọ naa kan si wa ni atimọle saaju igba ti igbẹjọ yoo fi waye.
Ọ̀pọ̀ àwòrán rèé tó ń sàfihàn bí Ibadan se kún fún ẹ̀gbin àti òórùn Àbádòfin ìdájọ́ yíyẹ igi fún 'ni tórí ọ̀rọ̀ ìkóríra!
Mike da ile iṣẹ to n ṣe siga silẹ nilu Ọba ti o si figba kan fẹ ṣoju Naijiria nibi idije Commonwealth lọdun 2018.
Agbenuso fn ile-igbimo asofin Aguila Saleh Issa so fun awon oniroyin pe, pelu sise amulo ilana ofin iforiji, Saif ni eto lati dije dupo lorile-ede naa.
 Àwon olórí isé ìjòba kan ni wón tún fi èsùn jegúdú jerá kàn , tí wón sì báwon dé ilé ejó .
, ẹgbẹ́ òṣèré tíátà pàṣẹ fún Lizzy àti Toyin Ikọ ọmọ ogun Naijiria wa kesi awọn ara ilu lati fi ọwọ sowọpọ pẹlu wọn, ki alaafia le jọba ni agbegbe naa.
Awọn ipinlẹ yooku ni : Osun-8 Ondo-5 Oyo-5 Ogun-3 Bayelsa-2 Taraba-2 Edo-1 FCT-1 Katsina-1 Plateau-1 Lọwọlọwọ, o ti pe 60,266 eeyan to ti ni arun naa ni Naijiria.
Ẹ́ wo ojú àwọn òṣèré tíátà tó péjú sí Ibadan fún ìpàdé ọlọ́dọọdún Owó rèé, ọjà rèé: Aládùúgbò le kórajọ̀ láti ra iná ọba lọ́wọ́ GenCos tààrà Makinde kò gbé àjọ ìwà ìbàjẹ́ kalẹ̀ torí ìfẹ́ aráàlú, ó ń fẹjú mọ́ alátakò ni - Ọmọ ẹgbẹ́ APC Ìtàn Àrọ̀gìdìgbà jẹ́ kí ń rò pé bàbá mi yan Yemọ̀ja ní àlè - Ọmọ Fagunwa Ọpọ olori orilẹede ninu ajọ EU bakan naa ti sọ pe, o dara bi ọrọ BREXIT ti n yanju bọ diẹdiẹ.
Èyí tó fín sílẹ̀ ò le parẹ́
Ko si ẹni to ye nkan ti o ṣẹlẹ ni pato ninu yara naa laarin ọkunrin to d'ologbe naa ati obinrin ọhun, sugbọn alẹ ọjọbọ naa lo gba yara naa ti wọn si ba oku rẹ ni owuro ọjọ Eti.
Àwọn olórí orílẹ̀èdè lágbàáyé sọ èrò wọn lori ìkọlù Syria
Ṣugbọn baba náà sọ fún àwọn iranṣẹ rẹ̀ pé, ‘Ẹ tètè mú aṣọ tí ó dára jùlọ wá, kí ẹ fi wọ̀ ọ́.
gbọdọ jẹ ki ifẹ ati mu idagbasoke ba orile ede yii jẹ yin logun, ẹ si tun gbọdọ
Ẹ̀yin tí ẹ̀ ń rán OLUWA létí,ẹ má dákẹ́.
Láàrin àwọn ọmọ Ọga Bello mẹtẹẹta to ń ṣe eré náà, Biola nìkan ni obìnrin, bí erin baba wọn sì ṣe ń fọn, náà ni erin àwọn ọmọ rẹ yìí ń fọn lagbo tíátà.
    Ọmọ tí mo rán wá yìí, àbúrò mi ni, ọmọ ìyá mi ní sàì jíṣẹ́ fún mi.
N jẹ bawo ni itan igbe aye Afọnja se lọ, ipa wo lo ko si idagbasoke iran Yoruba, ki si ni awọn isẹ to gbe ile aye se ta fi n ranti rẹ di oni yii.
loju pe oun yoo tọwọbọ iwe naa, leyin naa ni oun yoo fi ranse si ile-ise ajo
Imaamù: Irọ́ ni pé ọkọ leè kọ ìyàwó rẹ̀ nígbà mẹ́ta Ṣé o mọ ìgbésẹ̀ ìkọ̀sílẹ̀ lábẹ́ òfin Naijiria?
Abdullahi Olatoyan: Iṣẹ́ fífọ gíláàsì ọkọ̀ ń tì mí lójú láti dẹnu ìfẹ́ kọ obìnrin
Adebayo Faleti: Ọdún mẹ́ta lẹ́yìn Adebayo Faleti, ìran Yorùbá ń ṣe ilédè rẹ!
Kí ó tó kú ó ti ra ilẹ̀ tí yóò fi kọ́lè.
Manoa bá bèèrè lọ́wọ́ angẹli OLUWA náà, ó ní, “Kí ni orúkọ rẹ kí á lè dá ọ lọ́lá nígbà tí ọ̀rọ̀ rẹ bá ṣẹ.
Bí wọn tí ń mu ọtí, ni wọ́n ń yin ère wúrà, ère fadaka, ère irin, ère igi, ati ère òkúta.
Èso Apple tuntun tí ẹ lè fi pamọ́ fún ọdún kan ti wọ ọjà Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, FUTA: Àwọn mẹ́jọ ló ṣíná ìyà fún Bolu ní FUTA Ọpọ lo gbagbọ pe Messi ni ami ẹyẹ t'ọdun yii tọ si lẹyin to gba goolu mọkanlelaadọta ninu ifẹsẹwọnsẹ aadọta to gba ni saa bọọlu 2018-19.
‘Alẹ́ làwọn ọkùnrin fẹ́ bá mi jáde, torí mo kọ ilà’ Oògùn N25, 000 tí ń kò rówó rà ló gba ojú lọ́wọ́ mi- Damola Dorcas Ọmọ Yorùbá ni onímọ̀ ẹ̀rọ ‘Rọ́bọ́tì’ tó ń gbowó jùlọ ní UK Toma Unu: Ọmọbìnrin tó ń fi ẹsẹ̀ rẹ̀ ya àwọran nítori pe ó ni ìpènija ọpọlọ O ni wọn fi oun si ahamọ pẹlu awọn obinrin miran.
Wọ́n wá mú Jesu lọ sí ibìkan tí à ń pè ní Gọlgọta (ìtumọ̀ èyí tíí ṣe “Ibi Agbárí”).
Gẹ́gẹ́ bi àjọ tó n mójú tó ń àjàkálẹ̀ ààrùn ní Nàìjíríà, NCDC, se sọ lójú òpó twitter rẹ̀, ipínlẹ̀ mejidinlogun ni awọn eeyan naa ti wa.
Ẹ tẹ́tí sílẹ̀ kí ẹ gbọ́,ẹ má gbéraga nítorí pé OLUWA ló sọ̀rọ̀.
' Wo atẹ àlàkalẹ̀ ìdánwò WAEC fún ọdún 2020 tí yóò bẹ̀rẹ̀ ní August 17 'Ọ̀rọ̀ Amotekun ti dàrú bíi ẹsẹ̀ télọ̀ ní ìpínlẹ̀ Oyo' Ṣọ́ọ̀ṣì tí wọ́n ti ń fi ọtí àmupara bá Ọlọ́run sọ̀rọ̀ ní kí ìjọba dẹwọ́ọ òfin títà ọtí lásìkò Covid-19 Èèyàn 78 kú ó lé ní 4000 tó farapa níbi ìbúgbàmù tó wáyé ní Beirut, Lebanon Loni to jẹ ọdun kan geerege lẹyin iwọde ati wiwọ gbaga ofin naa, Ọlawale Bakare tun ti ko sinu áwọ̀n àwọn agbofinro DSS naa lasiko to fi n lewaju ikọ ẹgbẹ Revolutionnow nilu Osogbo tii ṣe olu ilu ipinlẹ Ọṣun.
Wọ́n lọ jókòó ní ààrin ìgboro ìlú náà, nítorí pé, ẹnikẹ́ni kò gbà wọ́n sílé pé kí wọ́n sùn di ọjọ́ keji.
Zulkifli tun salaye  pe oun gbe
Wọn ri ọmọkunrin naa doola ti wọn si sare gbe e lọ si ile iwosan akọṣẹmọṣẹ Murtala Muhammed Kano Specialist Hospital.
Boasi bá fi kún un pé, “Ọjọ́ tí o bá ra ilẹ̀ yìí ní ọwọ́ Naomi, bí o bá ti ń ra ilẹ̀, bẹ́ẹ̀ náà ni óo ra Rutu, ará ilẹ̀ Moabu, opó ọmọ Naomi; kí orúkọ òkú má baà parun lára ogún rẹ̀.
 Ó ti kópa ní ìṣẹ ̀ lẹ ̀ meje , tí ó sì ń ṣisẹ ́ dáradára ní maersk line ' s east africa 4 service .
gẹgẹ bi aba pe ẹni ti yoo gba ipo Alaga Igbimọ Alakoso yii gbọdọ jẹ
Ẹwẹ, ijọba apapọ ti sọ pe oun ko lọwọ ninu bi wọn ṣe rọ Sanusi loye gẹgẹ bi Emir ilu Kano.
Ṣugbọn itan awọn eeyan to n ronu bii temi ṣugbọn ti wọn di dokita ati imọ ẹrọ gba mi niyanju.
ki wọn si ma jẹ ko nii ṣe pẹlu ile iṣẹ Gomina.
Coronavirus cases in Africa: Ijọba ipinlẹ Oyo ti kọ ẹgbẹsan irẹsi to jẹ iranwọ ti ijọba apapọ fi ransẹ si wọn.
 ohun tí àmì òfà yìí ń so ni pé kí á tún gbólóhùn ( gb ) ko ni apor àti apis .
Ọkọ ̀ náà pẹ ̀ lú àwọn atukọ mẹ ́ tàlélógún gbé ẹrù tí ó tó tọ ́ ọ ̀ nú 17,000 kọrí sí mombasa , kenya lẹ ́ yìn tí wọ ́ n dúró ní djibouti ní Ọjọ ́ kẹjọ oṣù kẹrin Ọdún 2009 , àwọn ajalèlókun mẹrin tí ó dá lórí fv win far 161 dojúkọ ọkọ ̀ yìí .
Lẹ́yìn náà, olukuluku lọ sí ilé.
Ẹ wo nnkan ti awọn ọmọ Naijiria n sọ nipa rẹ.
Wo ojú ọmọbìnrin 4 tí afipa báni lòpọ̀ pa ní Nàìjíríà Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí kan sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
eyi ti won tun fi iya ti ko to je arakunrin naa,ki won to lee kuro ni orile ede
 Oko naa yoo maa sayewo yoo si kun fun awon ero ti won nilo fun itoju arun jejere nipinle Eko.
N óo wò ó sàn, ní ọjọ́ kẹta, yóo lọ sí ilé OLUWA, 
Absalomu bí ọmọkunrin mẹta ati ọmọbinrin kan.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ọ̀dọ́kùnrin tó kọ́kọ́ ṣe ẹ̀rọ tó ń tu ìyẹ́ lára adìyẹ Oríṣun àwòrán, Other Àkọlé àwòrán, Ọ̀wọ́ngógó epo bẹntirò: NNPC ni ìròyìn ẹẹ́jẹ̀' ni Wo bí o ṣe lè kọ́ ọmọ rẹ lẹ́kọ̀ọ́ ìbálòpọ̀ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, JAMB 2019: A ó fagi lé ìdànwò ẹni tó bá ṣe aṣemáṣe Ugbamadu ni awọn ṣì ni àgbá epo tó lé ni biliọnu lítà kan nílẹ̀ fún lílò àwọn ènìyàn Naijiria.
 ní bí i ìdà àádọ ́ rùn ún nínú ọgọ ́ rùn ún àwọn ọmọdé ní àwọn orílẹ ̀ -èdè tó-ṣẹ ̀ ṣẹ ̀ -n-dìde-nlẹ ̀ ni àìsán yìí ti ṣe wọn lati bí i ọmọ ọdún mẹ ́ wàá , tí ara wọn sì kọ ̀ ọ ́ ní ipò àgbà .
Delila bá pe Samsoni, ó ní, “Jọ̀wọ́, sọ àṣírí agbára rẹ fún mi, ati bí eniyan ṣe lè so ọ́ lókùn kí eniyan sì kápá rẹ.
1 4107 Orilẹede Rwanda 51 0.
Ṣugbọn nígbà tí wọ́n bá jọ̀wọ́ ilẹ̀ náà ní ọdún Jubili, ó níláti jẹ́ mímọ́ fún OLUWA, gẹ́gẹ́ bí ilẹ̀ tí wọ́n ti fi fún OLUWA; yóo sì di ohun ìní alufaa.
Ní Japan jíjẹ Núdùlù bí ẹni fa omi mú ní ọ̀nà to dara jù láti jẹ Núdùlù Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Licence to slurp Ní Japan fifa núdùlù pẹ̀lú ariwo nígba ti ènìyàn bá ń jẹ kìí ṣe ohun ti wọn ri bi ìwà ìbàjẹ́ bíkòṣe ohun amúyẹ pe ẹni to ń jẹ mọ rirì rẹ Bí o bá jòkó síwájú abọ́ Núdúlù síwájú tó sì ń lo síbi onígi lati fini mọ̀nà ẹnu, lẹ̀yìn náà ni wọn o fèrè rẹ̀ sẹnu pèlú ariwo.
Ko pẹ ti idibo naa bẹrẹ ti Johnson fi ọrọ idupẹ lede loju opo Twittter rẹ lati fun bi awọn eeyan ilẹ naa ṣe jade ni lati dibo.
Ijọba ba ti fọwọ si i.
Eyi ni igba ikẹrindin ni ọgọrun meji ati abọ ti iṣẹlẹ ibọn yinyin nla bayii yoo ṣẹlẹ nilẹ Amẹrika gẹgẹ bi ile iṣẹ to n ṣe ọfintoto iṣẹlẹ ibọn yinyin ṣe jabọ.
Bẹẹ gan lọrọ ẹgbẹ agbabọọlu Chelsea ṣe ri lẹyin ti wọn tẹyin ta ọmi alayo mejimeji pẹlu Valencia ninu idije UEFA Champions League lalẹ Ọjọru.
Ẹni tí ó bá lawọ́ yóo máa ní àníkún,ẹni tí ó bá jẹ́ kí ọkàn ẹlòmíràn balẹ̀,ọkàn tirẹ̀ náà yóo balẹ̀.
Orukọ awọn miiran ti wọn wa ninu olowo biliọnu nilẹ Afrika to leke re e Mohammed Dewji ọmọ orileede Tanzani lo kere julọ lọjọ ori pẹlu biliọnu $1.
Aláàfin tó rí ìbẹ̀rẹ̀ àti opin sáà gómìnà mọ́kànlélógún l‘Oyo Dókítà tó lé ní ogún ní Covid-19 nílé ìwòsàn Fásitì Ilorin - Álága ẹgbẹ́ dókítà Ìpínlẹ̀ Oyo, Eko àti Ogun fọnmú lórí ìlànà pínpín abẹ́rẹ́ àjẹsára Covid-19 Èèrà kò gbọdọ̀ rin Mattew Kukah ní Sokoto, ẹ má halẹ̀ mọ - Ìjọba àpapọ̀ Seyi Makinde ní ọwọ́jà Covid-19 kò rinlẹ̀ bí NCDC se kéde èèyàn 120 tó ní àrùn lọ́jọ́ kan l‘Oyo Njẹ́ ẹ ti gbọ́ nípa àríyá oníhòhò àti ìbálòpọ̀ tó fẹ́ wáyé ní Kaduna lásìkò ọdún?
Ọ̀gọ̀ọ̀rọ̀ agbébọn lo wà nílúù Kishi, National Park - Gani Adams figbe ta Ojú afurasí oníjìbìtì àti ajínigbé tí Gani Adams pariwo wọn síta l‘Oke Ogun rèé Amọ ṣa, o ni ifilọlẹ ikọ alaabo Amotekun ti n so eso rere, nitori pe ikọ naa ti le diẹ lara awọn janduku to n ni awọn olugbe ipinlẹ Oyo lara, jade.
Nígbà tí wọ́n rí i, wọ́n sọ ohun gbogbo tí a ti sọ fún wọn nípa ọmọ náà.
Oral Sex: Bóo bá ń gba ẹnu ní ìbálòpọ̀, wo àìsàn tóo lè kó lójú ara rẹ Wo ojú àwọn afurasí tó fipá bá Uwaila, akẹ́kọ̀ọ́ Uniben sùn tí wọ́n tún pa á sínúu ṣọ́ọ̀ṣì Ìdí tí mo fi gbàdúrà ìyàwó bíi Chanel Chin fáwọn tó d'ẹ̀bi ìkọ̀sílẹ̀ rẹ̀ rù mí rèé - Oluwo 'Tíátà ọ́mọdé tí wọ́n ń kọ́ wa ní Bariga ti mú mi lọ Germany, France, Amsterdam.
O ni loju toun Asiwaju Tinubu n ko ọrọ ipinlẹ Eko pamọ ni.
Eyi ni igba karun un ti ere eje-gigun yii yoo waye niluu Eko lẹyin ti alakọkọ iru rẹ waye lọdun 2016.
O ni Arisekola Alao se ''gudugudu meje, yaaya mẹfa, gẹgẹ bi ọmọbibi ilẹ Ibadan, ipinlẹ Ọyọ ati orileeede Naijiria lapapo'' Arisekola jẹ ilumoka oloseelu Oríṣun àwòrán, Twitter/Atiku Abubakar Àkọlé àwòrán, Ilumoka oloseelu ni Arisekola Arisekola Alao je Ọlorun ni pe lọjọ kẹtadinlogun osu kefa ọdun, 2014.
Ileesẹ ọlọpaa orilẹ-ede Tanzania ti fidirẹmulẹ pe, lootọ ni arabinrin alaboyun kan ṣe iṣẹ abẹ fun ara rẹ, lati gbe ọmọ inu rẹ jade.
Àwọn olórí alufaa ati àwọn Farisi wá rán àwọn ẹ̀ṣọ́ Tẹmpili pé kí wọ́n lọ mú Jesu wá.
hiram rhodes revels ( september 27 , 1827 - january 16 , 1901 ) je omo afrika amerika akoko mi ile alagba u.
o parí kí kọ ́ ìmọ ̀ egbógi ni ọdun 1915 .
Gbajabiamila to jẹ olori ẹgbẹ oṣelu to pọ julọ nile aṣoju ṣofin fọrọ naa lede lọjọ Aiku nilu Abuja lẹyin ọjọ meji tẹgbẹ oṣelu rẹ APC ṣepade lori ẹni ti wọn fẹ ṣatilẹyin fun lati dari ile.
Mo kúkú tẹnu mọ́n ọn pé Oníyanu ni Ọlọ́run.
Ijọba ologun lorilẹede Mali gbe igbimọ ti yoo gbe igbimọ ti yoo seto idibo alagbada silẹ Wo àwọn ààrẹ márùn-ún tí ológun gba ìjọba lọ́wọ́ wọn l‘Afirika: Ni ọjọ Iṣẹgun ni aarẹ orilẹede Mali, Boubacar Keita kọwe fi ipo silẹ lẹyin ti awọn ọmọogun dide tako iṣejọba rẹ lẹyin ọpọlọpọ ọjọ iwọde ati ipayinkeke ni orilẹede naa.
Ninu ọrọ ti ọgbẹni OF Enobore fọwọ si lorukọ ileeṣẹ naa, oludari agba ile iṣẹ to n ṣamojuto awọn ọgba ẹwọn ni Naijiria, Ja'afaru Ahmed paṣẹ pe ki wọn ko awọn ẹlẹwọn naa lọ sibomii kiakia.
Ni ọjọ idibo sipo gomina ni awọn agbenipa kan yinbọn pa Ọgbẹni Temitọpẹ Akintoye.
Nígbà tí Ṣalimaneseri gbọ́, ó pàṣẹ pé kí wọ́n ju Hoṣea sinu ọgbà ẹ̀wọ̀n.
Àwọn òbí rẹ ̀ méjèèjì kú ní bíi 1900 , àwọn mẹ ́ rẹ ̀ ẹ ̀ rin lọ gbé ọ ̀ dọ ̀ àbúrò ìyà wọn johanna katrine jensen ( 1857-1946 ) .
O kò fi òróró kùn mí lórí.
Dokita yọ góòlù àti owó ṣílè nínú obìnrin kan Kí ló ń sọ ọmọ Nàìjíríà d'èrò ilẹ̀ òkèèrè tí ìjọba kò ronú sí?
Gẹgẹ bi Mira Jones ti safihan lẹta kan loju opo Twitter rẹ, @mirajones, o ni abikẹyin ile awọn, Mehitabelle Jones Emmanuela lo faraya pe isẹ ile n pa oun lori lọ.
Ṣùgbọ́n ìdí rẹ̀ ni pé à ń dúró loju ọ̀nà púpọ̀.
Kí ìbẹ̀rù rẹ̀ má sì pá mi láyà mọ́!
Oludije fun ipo aarẹ ẹgbẹ PDP sọ pe lẹyin ọrọ adajọ agba ti Buhari yọ bii jiga, o ni bakan ni o ti bọwọ lu biliọnu dọla kan fun inanwo ile isẹ ologun ko to gbe aba rẹ de iwaju ile aṣofin agba l'Abuja.
" Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Sunday Igboho: Ẹ fi Ògún búra fún wa láti jà fún ilẹ̀ Yorùbá láì gbé Amotekun sábẹ́ ìjọba Taribo West fikun pe ọpọ awọn eeyan ti ijọ oun ti se iranlọwọ fun, tawọn si tun doola ẹmi wọn loke okun, si ni oun maa n kan si.
T’ó ń fi ewú orí ṣe bí ajunilọ
Ọ̀pọ̀ eniyan ni ògo ọba,olórí tí kò bá ní eniyan yóo parun.
Ṣáájú ni Ààrẹ orílẹ̀èdè Ghana, Nana Akufo-Addo ti pàṣẹ pé kí wọ́n fi pańpẹ́ òfin mú alága àjọ tó n mójútó bọ́ọ̀lù aláfẹsẹ̀gbá l'órílẹ̀èdè nàá.
com Àkọlé àwòrán, Ikanni Twitter naa ní àmì ìdánilójú pe APC lo nií Lẹ́yìn ìsẹ̀lẹ̀ to wáyé lọ́jọ́ abamẹ̀ta, nigba ti ọkunrin àjòjì kan gbàkóso ikani Twitter ẹgbẹ́ oselu APC, ẹgbẹ́ ọun kede pe, oun ti ni awọn ìkànnì ìbáraẹni sọ̀rọ̀ tuntun lori ẹ̀rọ ayélujára.
Ile asofin naa sọ wi pe ijọba ipinlẹ Kwara lo ni ilẹ naa, kii se Bukola Saraki lo san owo ilẹ naa.
Lọwọ yii, ojilelẹẹdẹgbẹta o din meji lapapọ awọn igbimọ agbaọjẹ oludibo alaṣẹ yii, Ẹnikẹni to ba si fẹ de ipo aarẹ gbọdọ gba ibo to pọ julọ lati ọdọ wọn.
Joṣua ṣa nǹkan bí ẹgbẹẹdọgbọn (5,000) ọmọ ogun, ó fi wọ́n pamọ́ sí ààrin Bẹtẹli ati Ai ní apá ìwọ̀ oòrùn Ai.
Nítori àwọn àtúgbẹ́yẹ̀wò, o níra láti ṣe àkójọpọ fún àwọn ọkọ́ naa Orisun: Johns Hopkins University atawọn ajọ eto ilera ilu Iye akọsilẹ to waye gbẹyin 7 Oṣù Ọ̀pẹ̀ 2020 14:22 WAT+3 Kí lawn ọmọ Naijiria n reti lẹnu Aarẹ?
'Wọn n gbe iyawo mi lọ si yara irọbi lọwọ ni, ti awọn dokita ati nọọsi si n pese ibusun rẹ lọwọ ni awọn gbọ irọ igbugbamu to rin ilẹ.
O ni fun gbogbo awọn to n polongo ijọba ipinlẹ Oyo kiri pe ija wa laarin oun ati Olubadan, ẹ jẹ ki n sọ fun yin, ile ire ni a ti bi mi, mi o si ni tẹ asọ agba mọlẹ."
N óo fi ìdí ìjọba rẹ̀ múlẹ̀ títí lae, bí ó bá ti pinnu láti máa pa òfin ati ìlànà mi mọ́, gẹ́gẹ́ bí ó ti ń ṣe nisinsinyii.
Mo ké pè é,mo sì kọrin yìn ín.
Kò tẹ̀lé àpẹẹrẹ rere Dafidi baba ńlá rẹ̀, ṣugbọn ó ṣẹ̀ sí OLUWA Ọlọrun rẹ̀, 
Láàrin wọn ni Mesaya sì ti wá sáyé gẹ́gẹ́ bí eniyan.
 jìnádù sọ pé Ògúndélé fi òrùkọ ẹ ̀ rẹ na òun .
Ipese ilegbe ẹdinwo fawọn eeyan laarin ọdun mẹrin Pipari ojuurin reluwe Westeren Line ati Tema lọ si Mpakadan ati ojuurin ila oorun Aduadin si Obuasi to fi mọ ojuurin reluwee lati Ghana si Burkina Faso Eto ẹkọ Itẹsiwaju eto ilera ọfẹ pẹlu akanṣe eto TVET Itẹsiwaju imugbooro ohun amayedẹrun lawọn ileewe giga ti ijọba lati le gba awọn akẹkọọ sii Ipese ẹrọ Wi-Fi lawọn ile ẹkọ lati ṣeranwọ fawọn akẹkọọ lori imọ lilo ẹrọ kọmputa ipese Wif-Fi bakan naa fawọn akẹkọọ girama ti ileewe ijọba Imugbooro ohun amayedẹrun lati mu jẹ ki ẹka eto ẹkọ mu tubọ pese awọ akẹkọọ nipa ofin Ọrọ aje Ju ọdun 2020 lọ, ijọba yoo tẹsiwaju lati ṣe afikun lori miliọnu meji iṣẹ ṣiṣe ti ijọba ati ti aladani Idagbasoke ohun amayedẹrun nipa ajoṣepọ ijọba ati ileeṣẹ aladini nipa gbigba owo ibode Idasilẹ eto igboke-gbodo ọkọ Metro kaakiri ilu nla nla ni Ghana Awakọ̀ agbókùú, ọlọ́pàá, ológun, oníròyìn ló máa ń kọ́kọ́ dìbò ní Ghana, bó ṣe ń lọ rèé Ọmọ Rawlings: Mi ò rán ẹnikẹ́ni láti gbowó ìsìnkú bàbá mí lójú òpó ayélujára Báàgì Ghana Must Go pàwọ̀dà, ó di ohun táwọn ránsọ ránsọ fi ń dárà orísirísi Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Borno Zabarmani Rice Farmer Massacre: Àwọn àgbàgbà Òkè Ọya ní ẹ̀mí èèyàn kò níyì mọ́ lábẹ́ ìṣèjọba Buhari5 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Stella Obasanjo Motherless: A ti rí àwọn ọmọ tó sọnù ní ilé àwọn ọmọ òrukàn ní Abeokuta2 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Ogun Stolen Mace: Bí wọ́n ṣe rí ọ̀pá àṣẹ ìpínlẹ̀ Ogun ní Eko rèéwákàtí 5 sẹ́yìn D.
Amọ, ori ayelujara ni wọn ti n ṣee, wọn polowo ọmọ ọdun pẹlu ọkọ ati ẹrọ amunawa lori ẹrọ ayelujara.
Àwọn ọmọ wẹ́wẹ́ yín, àwọn aya yín, ati àwọn àlejò tí wọn ń gbé orí ilẹ̀ yín; àwọn tí wọn ń wá igi fun yín, ati àwọn tí wọn ń pọnmi fun yín.
Agbẹnusọ ileeṣẹ ọlọpaa nipinlẹ Edo, Chidi Nwabuzor ni oun ko le fi idi iṣẹlẹ naa mulẹ nitori gbogbo awọn ọlọpaa lo joko si ile wọn.
Ọjọ́ keje osù keje ọdún 1998 ni Moshood Kashimawo Abiola jáde láyé.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ilé ẹjọ́ yọ ìbò 2,029 nínú ìbò APC, 1,246 nínú ibò PDP l'Ọṣun Màá gba kádàrá tí mo bá fìdírẹmi - Ganduje Ile ẹjọ naa ninu idajọ to gbe kalẹ ni ọjọ ẹti, ṣalaye pe atundi ibo to waye lawọn ibudo idibo kan ni ọjọ kẹtadinlọgbọn ko ba ofin mu.
Ohun to saba maa n bi itan kikọ rẹ ni bo ṣe n ri lojoojumọ ninu igbe aye awọn ara Iwọ Oorun Afirika.
rẹ to milionu  ẹ̀ẹ́dẹ̀gbẹ̀rinlelaadota pound (750 million Pound sterling), ti ilu Eko naa si le e je anfaani rẹ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Alexis Sanchez lóun kò kabamọ ìgbà tóun ló ní Man United 3 Owewe 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Atamatase Alexis Sanchez, ni toun ti bi oun ko ti ṣe raye gba lori papa fun Manchester United to bi o ti ṣe wu oun,oun ko kabamọ pe oun darapọ mọ ẹgbẹ naa.
Oríṣun àwòrán, Kwara Govt Àkọlé àwòrán, Ijoba Kwara naa fi atẹjade tiwọn sita pe ijọba lo ni ilẹ ti Baba Oloye Sarki fi kọ ile arugbo si tẹlẹ.
AWỌN IROYIN TẸẸ LE NIFẸ SI NIPA RẸ Ìlú tí ọ̀daràn bá tí dẹ́ṣẹ̀ ló yẹ kí wọn tí gbẹjọ́ rẹ̀ -Agbẹjọ́rò Ọkọ mi kò le f'ipá bá ẹnikẹ́ni lò pọ̀ láíláí - Modele Fatoyinbo COZA: Mi ò fípá bá obìrin lò pọ̀ rí láyé mi - Pásítọ̀ Fatoyinbo ‘Ilé ẹjọ́ kò gbé ẹ̀sùn ìfipánílòpọ̀ yẹ̀wò, à ń lọ sí ilé ẹjọ́ - Busola Dakolo Agbẹjọro fun Busola Dakolo ti ni awọn n gbe Biodun Fatoyinbo lọ si ile ọjọ kotẹmilọrun lẹyin ti ile ẹjọ da ẹjọ ifipanilopọ to pe naa danu.
oludije ẹgbẹ oṣelu PDP nigba naa lọhun, Kamoru Adedibu.
Wọn ni àwọn gbe igbesẹ yii lataari gbogbo ijakulẹ ti Unai emery n ri paapaa lori idije awọn bọọlu ti Arsenal n gba ti to gẹ.
Nítorí OLUWA sọ fún mi pé,“Bí kinniun tabi ọmọ kinniunti máa ń kùn lórí ẹran tí ó bá pa,tí kìí bìkítà fún igbe àwọn olùṣọ́ aguntan,tí wọ́n pera wọn jọ, tí wọn ń bọ̀,tí ẹ̀rù ariwo wọn kìí sìí bà á;bẹ́ẹ̀ ni OLUWA àwọn ọmọ ogun yóo sọ̀kalẹ̀,yóo wá jà lórí òkè Sioni ati àwọn òkè tí ó yí Sioni ká.
Oríṣun àwòrán, others Idile Ọba Kosoko tilu Eko: Idile ọba Kosoko tilu Eko naa wa lara idile to gbaju-gbaja nilẹ Yoruba fun owo ẹru ṣiṣe, Kosoko si jọba nilu Eko laarin ọdun 1845 si 1851, ki wọn to le kuro lori itẹ.
Bi o tilẹ jẹ pe akanda ẹda ni nitori ko ga rara, o sọ ninu ifrọwanilẹnuwo kan pe gbogbo awọn aburo ati ẹgbọn oun lo jẹ eniyan to ga to fi mọ baba ati iya oun.
Abubakar, ní ọ̀nà kejì, ń dúró lórí “ìgbẹ́kẹ̀lé” àwọn “ẹgbẹlẹmùkù okòwò tí ó ní èrè lóríi rẹ̀”.
Wọ́n dá Joṣua lóhùn pé, “Wọ́n sọ fún àwa iranṣẹ yín pé, dájúdájú, OLUWA Ọlọrun yín ti pàṣẹ fún Mose láti fun yín ní gbogbo ilẹ̀ yìí, ati láti pa gbogbo àwọn eniyan ibẹ̀; nítorí náà ni ẹ̀rù yín ṣe bà wá.
Akọmọna yi gbiyanju amọ omi pọju ọka lọ fun un nito ri pe Sowore ko ri ijọba gba pada lọwọ Muhammadu Buhari ti o pegede ninu ibo aarẹ 2019.
Lẹ́yìn èyí, Jesu kúrò níbẹ̀, ó lọ sí inú ilé ìpàdé wọn.
OLUWA sì rán iná láti run àwọn aadọtaleerugba (250) ọkunrin tí wọn mú àwo turari wá siwaju Àgọ́ Àjọ.
OLUWA, ranti gbogbo ìyà tí Dafidi fara dà.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Yoruba film: Ipò wo ni Seun Egbegbe, Olóòtú eré wà báyìí lẹ́wọ̀n?
Oṣẹ kan ṣááju ìgba ti Soyombo de ibẹ ni o ni wọn fi ofin de ki àwọn ẹbi maa gbe ounjẹ wá lẹyin ti ẹni kan gbe oogun oloro (igbo) wọle nipa lilo oṣìṣẹ́ Dundu nation.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Awọn ilu mẹtalelaadoje kaakiri agbaye ni ajọ̀ EIU gbe yẹwo Agbejade naa wa ko ilu Paris lorilẹede France,, Hong kOng ati Singapore sita gẹgẹ bii awọn ilu ti o wọn julọ fun eeyan lati gbe lagbaye.
Labani fi Biliha, ẹrubinrin rẹ̀ fún Rakẹli, ọmọbinrin rẹ̀, pé kí ó máa ṣe iranṣẹ fún un.
Ara Maradona ko le daadaa nigba to lọ jẹ ounjẹ aarọ Ọjọru, o ṣaroye pe otutu n mu oun.
lati Caitlin ni Leeds Eyi ti wọn n beere julọ Iroyin BBC Ikọ eleto ilera Coronavirus jẹ ajakalẹ arun ti wọn ri ni China ni oṣu kejila, ọdun 2019 ti wọn n pe ni Covid- 19 O le ni ọgọrọọrun oriṣii coronavirus- ni eyi ti o wọpọ laarin ẹranko bii: ẹlẹdẹ, rakunmi, adan, ati olongbo.
hollaway ní olórí àwọn akọ ́ nimọ ̀ ọ ́ gbá college football ní bethany terrible swedes ní agbègbè lindsborg , kansas .
Àwọn ti wọ́n ń torí káràkátà tẹsẹ̀ bọ ìrìnàjò àràmàndà wá sí UK.
Ó dàbí ìgbà tí Ọlọrun Olodumare bá ń sọ̀rọ̀.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Funmi Adewara: Tele Medicine' ní a fi ń ṣàyẹ̀wò èèyàn ìdá ọgọtá láti dènà ìtànkálẹ̀ Covid Donald Trump: Wo àwọn tí ìpinu ààrẹ Amẹrika lórí físà yóò kan jùlọ Ààrẹ ilẹ̀ Amẹrika Donald Trump, tún ti fi kún àṣẹ láti dá fífún àwọn ènìyàn ni ìwé ìgbélùú àti ìwé ìrìnà dúró títí di òpin ọdún 2020.
Oríṣun àwòrán, Twitter/@AyindeBarrister O siṣẹ atẹwe nileeṣẹ to n ṣe ọti, Nigeria Breweries.
Gomina Yari ti ipinlẹ̀ Zamfara koro oju si isẹlẹ ikọlu naa.
Bakan naa lo ni iwa ipaniyan lati fi eeyan ṣoogun owo ni iha Guusu Naijiria gbọdọ dopin, ki abamọ ma ba a gbẹyin rẹ.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Trump yọ Tillerson kuro nipo Buhari, Trump yóò ṣèpàdé l'Ámẹ́ríkà Ijamba baalu pa eeyan 66 ni Iran Amọ, orilẹede Iran ti kilọ fun ilẹ Amẹrika lati mase gbiyanju da adehun ti wọn se nu, nitori yoo ni ipa ti kii se kekere.
 murtala ramat mohammed ti fayé sílè .
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù DBanj: Ikú ọmọ mi kò leè paná ìfẹ́ láàrín èmi àti ìyàwó mi 9 Ògún 2018 Oríṣun àwòrán, @Dbanj Àkọlé àwòrán, DBanj ni lootọ ni nnkan ko rọgbọ latigba ti ọmọ oun ọkunrin ti ku D Banj: àdánwò kò lè ṣalai má de ba ẹ̀dá láyé Gbajugbaja olorin takasufe ni, Dapo Daniel Oyebanjo ti ọpọ mọ si DBanj ti sọ pe iku ọmọ ohun to waye laipẹ yii ko lee ya ifẹ oun ati iyawo oun, Lineo.
Nítorí tí mò ń gbadura pé,kí àwọn tí ń pẹ̀gàn mi má yọ̀ mínígbà tí ẹsẹ̀ mi bá yẹ̀.
Ọdun 2013 lo bere si kopa nibi idije oun.
Ni papa iṣere National Stadium ni Grace ti dagbere igbẹyin fun ọkọ rẹ.
 adéwálé filé sílẹ ̀ nítorí wípé àwọn òbì rẹ ̀ méjẹèjì lòdì sí iṣẹ ́ orin tí ó yàn láàyò láti ṣàtìpó ní ìlú Èkó láti máa kórin rẹ ̀ lọ .
Ẹ kan si wa loju opo ayelujara Facebook, Instagram ati Twitter ki ẹ si lo hashtag #BBC100women Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Àkọlé àwòrán, Fani Kayọde ni igbagbọ ohun ninu iṣọkan orilẹede Naijiria ko yẹsẹ rara.
“Ọwọ́ yóo tẹ ìwọ náà, Moabu, nítorí pé o gbójú lé ibi ààbò ati ọrọ̀ rẹ.
Ferdinand sọ pe pẹlu bi gbogbo nnkan ṣe polukurumusu ni Barcelona bayii, o dabi wi pe asiko ti to fun Lionel Messi lati fi Barca silẹ.
Gbogbo ohun èlò ìṣúra wúrà ati fadaka inú tẹmpili ní Jerusalẹmu, tí Nebukadinesari kó lọ sí Babiloni, ni kí wọ́n kó pada wá sí Jerusalẹmu, kí wọ́n sì fi wọ́n sí ààyè wọn ninu ilé Ọlọrun.
Ìbẹ̀rù-bojo gbalẹ̀ lórí ṣíṣí iléèwé padà lọ́jọ́ Ajé bí èèyàn 1867 ṣe kó covid-19 lọ́jọ kan ṣoṣo Ẹgbẹrun meji eeyan o din dẹ(1867) lo lugbadi arun coronavirus lọjọ Ẹti lorilẹede Naijiria.
Amọṣa awọn iran de iran gbogbo lo ti bẹnu atẹ lu u.
” “o tun wa ro aare ati igbakeji rẹ lati tẹsiwaju
Oríṣun àwòrán, @others Àkọlé àwòrán, Ìpínlẹ̀ Eko kéde afurasí mẹ́ta míràn tó ṣeéṣe kó ni Coronavirus Kò sí ìdí kankan fún wa láti ti ilé ìwé àti àwọn ilé ìjọsìn wa pa- Minista fun ètò ìlera ní Naijiria Minista fun eto ilera ni Naijiria, Ọjọgbọn Osagie Ehanire lo fi ọrọ yii sita nilu Abuja pe ko si idi kankan fun Naijiria lati ti ile iwe ai awon ile ijọsin wa gbogbo pa nitori Coronavirus.
Alamojuto ẹgbẹ akọrin rẹ Uzoma Omenka ni eto isinku rẹ waye lorileede Amẹrika nibi tawọn mọlẹbi nikan ti kopa nibẹ.
Nítorí pé OLUWA ló ni àwọn ìlú Aramu, bí ó ti ni àwọn ẹ̀yà Israẹli.
O sọrọ nipa pipa ina ọba nigba kiigba ti eniyan ba n jade kuro ninu ile, ati rira agolo ilewọ iyẹfun panapana si inu ile (fire extinguisher).
"Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Bí rere ni àbí búburú, wo ohun tí Covid-19 leè ṣe sí àgọ́ ara rẹ Nigba ti Dele Momodu bi i nipa Erica, o rẹrin o ni: ""Gẹgẹ bi ẹ ṣe mọ mi, ilumọọka ni mi ni Naijiria, gbogbo ibi ti mo ba wọ ni ile mi, ko si si ibi ti mi o ti ni ọrẹ timọtimọ ni Naijiria torinaa ko si ibi ti awọn ọmọ mi ba yan lati tẹdo si ti wọn o ni ri ibukun mi ko si ni fi ṣe ede, ẹya."
1–3, Krístì ní gbogbo agbára; 4–5, Gbogbo ènìyàn gbọ́dọ̀ ronúpìwàdà tàbí kí wọ́n ó jìyà; 6–12, Ìbáwí àìlópin jẹ́ ìbáwí ti Ọlọ́run; 13–20, Krístì jìyà fún gbogbo ènìyàn, pé kí wọn ó má baà jìyà bí wọn bá lè ronúpìwàdà; 21–28, Wàásù ìhìnrere ironúpìwàdà; 29–41, Kéde àwọn ìhìn ayọ̀.
tabi pé kí ẹ fi ayé búra, nítorí ìtìsẹ̀ tí Ọlọrun gbé ẹsẹ̀ lé ni.
Ó ní Àjọ tó ń mojuto irinajo ìgbàfẹ́, ìjọba Ìpínlẹ̀ Borno àti àjọ ọmọogun tí ń jíròrò lórí kókó náà.
Lagos Explosion: Ohun tí a mọ̀ tó fa ìgbúgbàmù Eko rèé, ọ̀rọ̀ rèé lẹ́nu ó ṣojú mi kòró
Níbi tí wọ́n ti ń fọ́ òkúta ni wọ́n ti gbẹ́ gbogbo òkúta tí wọ́n fi kọ́ ilé ìsìn náà, wọn kò lo òòlù, tabi àáké, tabi ohun èlò irin kankan ninu tẹmpili náà nígbà tí wọ́n ti ń kọ́ ọ lọ.
Àwọn ohun tó yẹ kí o mọ̀ nípa olùdíje sípò gómìnà ZLP l'Ọyọ Èwo nínú ìlérí tí Buhari ṣe ní 2015 ló ti mú ṣẹ?
EFCC: Á sọ iye èèyàn ta rán lẹ́wọ̀n di ìlọ́po méjì ní 2019
    Nígbà tí iwin náà gbọ́ báyìí, ó bẹ̀rẹ̀ sí sọ̀rọ̀ ó ní:
Oríṣun àwòrán, Samuel Abdulraheem Àkọlé àwòrán, Samuel sọ pe iriri ti oun ni l'oko ẹru lo sọ oun di ẹlẹyinju aanu.
“Nígbàkúùgbà tí ohun ìní bá di àríyànjiyàn láàrin eniyan meji, kì báà jẹ́ mààlúù, tabi kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́, tabi aguntan, tabi aṣọ, tabi ohunkohun tí ó bá ti sọnù, tí ó sì di àríyànjiyàn, àwọn mejeeji tí wọn ń lọ́ nǹkan mọ́ ara wọn lọ́wọ́ gbọdọ̀ wá sí ilé Ọlọrun, kí wọ́n sì fi Ọlọrun ṣẹ̀rí, ẹni tí Ọlọrun bá dá lẹ́bi yóo san ìlọ́po meji nǹkan náà fún ẹnìkejì rẹ̀.
Lẹ́yìn tí orin náà tí àwọn ènìyàn ti ń gbórín yìn fún jáde, ni MURIC bẹ́nu àtẹ́ lùú látàrí wípé, fídíò náà ṣàfihàn àwọn ọmọbinrin tí wọn ń jó orin Shaku-Shaku pẹlu hijab.
Laarin aṣa ati aabo ohun ini Ninu iforowero pelu ileese BBC, Desmond Majekodunmi, onimọ nipa eeto idaabo bo awọn ohun ini ati alumọni ile kedun wipe ohun ti oburu jai ni isele yi.
Irú ẹni tí mo jẹ́ kò lè yé ọ bẹ́ẹ̀ ni ó kò sì lè mọ irú ipò tí mo wà láìjẹ́ pé mo bá sọ ìwọ̀nyí fún ọ.
Wúrà ni wọ́n fi ṣe gbogbo ife ìmumi Solomoni, ati gbogbo àwọn ohun èlò tí ó wà ninu Ilé Igbó Lẹbanoni.
Duro Ladipọ, ìlúmọ̀ọ́ká òṣèré tíátà àti ọmọ àlúfà tí kò gbàgbé àṣà ìbílẹ̀ Ìtàn ìgbésí ayé Oshodi, ọmọ Tápà léǹpe tó di akọni ní ìlú Eko Nínú ìfọ̀rọ̀wérọ̀ rẹ, ìya Fasoyin sàlàyé pé àgbáríjọ àwọn akọrin CAC ló jọ máa wọ inú àwẹ̀ àti àdúra láti ṣe àkójọ orin gbogbo orin wọn.
Orisiirisii eto bii ijo ibile, ilu lilu ati afihan awon ohun isembaye ni yoo waye ninu eto naa.
awọ àgbò tí wọ́n ṣe, tí ó jẹ́ pupa, ati ti ewúrẹ́, igi akasia; 
Ìgbìmọ̀ iṣedajọ orílè-èdè Nàìjíríà NJC nikan lo le yọ adajọ-Amofin
Kí wọn wọ bàtà, ṣugbọn kí wọn má wọ ẹ̀wù meji.
Iroyin so pe, awon arakunrin mejeeji n se abewo si awon orile-ede nile-Africa, ni eyi ti awon mejeeji yoo wa ni orile-ede Ethiopia lose ti a wa yii.
Iyawo meji ni Ọgbẹni Ogungbe ni.
Ó ń kọ́ àwọn eniyan nípa Oluwa Jesu Kristi láì bẹ̀rù ohunkohun.
A fi ẹ̀wọ̀n de àwọn mìíràn.
Ijoba ile naa ni won ti ran awon oluranlowo sibudo isele naa lati sayewo ohun to sele ati ipese irufe iranlowo to ye.
Àkọlé àwòrán, Bíntín logé ti ń bẹ̀rẹ̀ Àkọlé àwòrán, Ẹ gbé ìrun dúró Àkọlé àwòrán, Awọn ọmọ ọlọdun ree to gan pa fun fọto Àkọlé àwòrán, Awọn oniṣowo ko gbẹyin Àkọlé àwòrán, Toju ko ba ri daradara, ẹ fi igo kaa.
Filipi sọ fún un pé, “Oluwa, fi Baba hàn wá, èyí náà sì tó wa.
Orilade ni awọn ni ẹsun iwa ibajẹ ati ajẹbanu lorisirisi ti wọn fi kan Bukola Saraki, nitori naa wọn rọ ọ lati jẹ ki wọn se isẹ wọn gẹgẹ bi ajọ to n gbogun ti iwa ibajẹ.
Ẹ̀rọ CCTV tú àsírí ọkùnrin ẹni ọgbọ̀n ọdún tó fi ipá bá ọmọ ọdún mọ́kànlá lòpọ̀ ''Operation Burst'' ti mú Eji, tó gba ipò Ebila olórí ''One Million Boys'' ní ìpínlẹ̀ Oyo Ilé ìjọsìn lè bẹ̀rẹ̀ ìsìn àárín ọ̀sẹ̀ padà, Mọ́sáláṣí àti Ṣọ́ọ̀ṣì lé gba iye èèyàn tó wù wọ́n ṣùgbọ́n.
Dariusi ṣètò láti yan ọgọfa (120) gomina láti ṣe àkóso ìjọba rẹ̀.
Fuji Music: Kollington Ayinla sọ ẹni tó dá orin Fuji sílẹ̀ gan an ní Nàiìjíríà
Abenugan ohun tun lo anfaani naa ro ijoba apapo lati gbe igbese ti o to lati gba omode binrin Leah Sharibu ati awon miiran ti o ba wa ninu igbekun awon omo ogun olote boko haram sile.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Mo fara da ìsòro gan láwùjọ́ torí àwọn òbí mi di létí' Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 3 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 5 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Ọgbẹni Pissetzky ti gbẹjọro bi igba ọgọrun, niwaju igbimọ igbẹjọ ati adajọ.
Ekiti Sack: Kí ló dé tí àwọn ìjọba ń yọ òṣìṣẹ́ bíi ẹní yọ jìgá ní gbogbo ìgbà?
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù 9/11 Baby: Aramanda ọmọ, wọ́n bi ní ọjọ́ 9/11, láago 9/11 tó si wọn 9/11 14 Owewe 2019 Oríṣun àwòrán, METHODIST HEALTHCARE Àkọlé àwòrán, Aramọnda ọmọ Ohun ayọ ati idunnu ni ti obi ba mojuba ọmọ tuntun ti wọn si ki kaabọ sile aye.
nigba ti o gbo nipa isele naa, ni eyi ti ọpọ awon eniyan padanu emi won.
Ṣùgbọ́n àwọn àyíká miran náà tún burú jai, bí àpẹẹrẹ àwọn tó wa nínú ọkọ̀ ojú omi, àwọn tí wọ́n wà nínú ọ́fíìsì kan naa, àwọn ti wọ́n péjọ síbi ìnáwó ìyàwó, ọjọ́ ìbí, ìgbáradì akọrin tàbí ìsìnkú, èyí rí bẹ́ẹ̀ nítorí iye àsìkò ti wọ́n lò pẹ̀lú alárùn náà ni.
“Gbogbo àwọn òṣìṣẹ́ ati gbogbo eniyan ni wọ́n mọ̀ pé bí ẹnikẹ́ni bá lọ sọ́dọ̀ ọba ninu yàrá inú lọ́hùn-ún, láìṣe pé ọba pè é, òfin kan tí ọba ní fún irú eniyan bẹ́ẹ̀ ni pé kí á pa á, àfi bí ọba bá na ọ̀pá wúrà tí ó wà ní ọwọ́ rẹ̀ sí ẹni náà ni wọn kò fi ní pa á.
Ẹ wo àbájáde ìwádìí wa Èèyàn 38,344 ló ti ní COVID-19 ní Nàìjíríà lẹ́yìn tí 543 kún un lọ́jọ̀rú Bàbá mi Aláàfin, ẹ ṣeun ẹ̀bùn owó tí ẹ fún èmí àti ọkọ mi- Lizzy Anjọrin Bakan naa o bu ẹnu atẹ lu iye orikoo ayẹwo awọn oṣiṣẹ alaabo kaakiri, o ni awọn oriko yii n di iṣẹ iranwọ lọwọ o si ṣi aaye silẹ fun ijinigbe, ipaniyan tabi ṣiṣe awọn eniyan leṣe to fi mọ awọn oniṣẹ iranwọ lorilẹede ti wọn n da ya sọtọ.
Ipade yii waye ni deede aago Mẹwaa ale, ti o si pari ni aago mọkanla.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Federal Government scholarship 2021/2022: Wo bi o ṣe le fi orúkọ̀ sílẹ̀ fún ètò ẹ̀kọ́ ọ̀fẹ́ ìjọba Nàìjíríà 28 Ọ̀wàrà 2020 Oríṣun àwòrán, Getty Images Minisita fun eto ẹkọ ni Naijiria, Adamu Adamu, ti kesi awọn ọmọ Naijiria to ba nifẹ, to si koju osuwọn, lati fi orukọ silẹ fun eto ẹkọ ọfẹ ijọba apapọ fun ọdun 2021/2022.
Ẹ̀wẹ̀ lónìí, D'Banj ti fi okun kún okun láti sọ̀rọ̀ jáde sí gbogbo ará ìlú.
" Ẹ̀wẹ̀, Kọmísọ́nà ṣàlàyé pé àwọn ilé ẹ̀kọ́ gíga n se ìdánilẹ́kọ̀ọ́ orí ayélujára nítorí pé ọ̀pọ̀ kò ní pẹ́ bẹ̀rẹ̀ ìdánwò lórí ayélujára pẹ̀lú.
Ìpè orí fóònù tó mú kí America fẹ́ yọ ààrẹ Trump rèé Ibú-owó Bloomberg fẹ́ ta kànùngbọ̀n pẹ̀lú Trump nínú ìbò ààrẹ Amẹrika Mọ̀ síi nípa Oyedele Adedokun tó ya àwòràn Donald Trump tó lu ayélujára pa Nigba wo ni wọn yoo gbẹjọ rẹ nile aṣofin agba?
Ọba ìlú Aradi, ní ilẹ̀ Kenaani, tí ń gbé Nẹgẹbu gbúròó pé àwọn ọmọ Israẹli ń bọ̀.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù FRSC thunder strike: Lẹ́yìn ìwádìí ìkú àrà tó sán pa òṣìṣẹ́ FRSC mẹ́ta lọ̀rọ̀ ètùtù kò ṣe ètùtù tó lè wáyé 18 Òkùdu 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 19 Òkùdu 2020 Oríṣun àwòrán, others Ajọ to n risi eto irinna oju popo, FRSC ti ni awon ko lee fi idi ẹ mulẹ pe ara lo san pa oṣiṣẹ ajo FRSC mẹta to ku ni ipinlẹ Ogun.
Oríṣun àwòrán, @MuhammadSageer Lẹyin eyi ni awọn osisẹ ajọ eleto idibo to wa nikalẹ yoo si ka iye oludibo to to si ẹyin aworan naa, eyi ti yoo kọ silẹ bii esi idibo, tawọn asoju ẹgbẹ oselu kọọkan yoo si buwọlu, lati gba esi ibo naa wọle.
'Àgba tóri ẹ bá pé ni Naijiria nílò lásìkò yìí'
Irọ́ ni pé wọ́n hú òkú Kolawole Gold lórí pẹpẹ ìjọ ọkọ mi- Bisola aya Sotitobire Ẹ wo èrò bìbà níbi ìwọ́de #EndSARS ní ìlú Ibadan Wo bí àwọn jàndùkú ṣe yabò àwọn olùwọ́de #ENDSARS ní Alausa l'Eko àti Abuja Kí ló ń ṣẹlẹ̀ láàfin Oyo táwọn èèyàn fi ń ki Alaafin ní mẹ́sàn án mẹ́wàá?
 , sugbon ko soju igba re tan .
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù RevolutionNow: Falana àtàwọn míì ṣe àpérò l'Eko lẹ́yìn tí DSS kọ́kọ́ ti gbọ̀ngàn tí wọ́n fẹ́ lò pa 19 Ògún 2019 Ileeṣẹ ọtẹlẹmuyẹ, ọlọpaa atawọn ologun kọkọ ti ibi ti awọn ajijangbara kan ti fẹ ṣe apero lori ifẹhonu han #RevolutionNow ni Lagos Centre ni Ikeja lọjọ Aje.
Wọ́n fẹ́ sọ ọ́ ní Sakaraya, bí orúkọ baba rẹ̀.
Ninu awa obinrin mẹtala ti a ri ara wa ko jọ, awa maarun pere la gba lati jẹri tako o nile ẹjọ.
Àkọlé àwòrán, Awọn araalu ilu Zokutu ko lanfaani si omi to daa Solomon fi kun un wipe niwọn igba ti awọn wa lokunkun, igberi aisan yii lawọn le wa.
Oniroyin CNN fesi si iroyin ti Julie fi lede lori Twitter pe oun o sọ ohun to jọ bẹẹ.
Àwọn ìròyìn míì tí ẹ tún le nífẹ́ sí: Òṣìsẹ́ iléeṣẹ́ amúnáwá gan mọ́'ná ni Oǹdó Oluwo Ìwo ṣ'àlàye lori oye Emir Àwọn akínkanjú obìnrín tó ń se isẹ́ ọkùnrin Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold17 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí 2 sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 4 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Bóyá ni a lè rí ẹni tí yóo fẹ́ kú fún olódodo.
Ọdọmọkunrin kan tí ó ń jẹ́ Yutiku jókòó lórí fèrèsé.
Agbẹnusọ ọlọpàá ni ipnlẹ Ogun Abimbola Oyeyemi sọ nínú àtẹjade kan lọ́jọ́ Isegun pe àwọn lọ mu Waheed si àtìmọle nítori pe àwọn gba iwé ẹ̀sùn láti ile Iṣẹ́ agbẹjọrò R.
Iroyin ti ileeṣẹ iroyin Channels fi sita ṣalaye pe, ọdọmọkunrin yii fi ara gba ọta ibọn nibi ikọlu iwọde ẹgbẹ Shiite.
Nígbà náà ni Isaaki, baba rẹ̀, dá a lóhùn, ó ní,“Níbi tí ilẹ̀ kò ti lọ́ràá ni o óo máa gbé,níbi tí kò sí ìrì ọ̀run.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Ọ̀nà àtijẹ kan ṣoṣo táa ní ni Màálù àwọn Fúlàní ti bàjẹ́' Mi ò jẹ̀bi ẹ̀sùn tí ẹ fi kàn mí pé mo ya Blue Film"" nínú igbó Osun Osogbo - Jolaosho TBlak Oríṣun àwòrán, King Tblak/Twitter Tobiloba Jolaosho ti ọpọ mọ si King Tblak ti sọ̀rọ̀ niwaju ile ẹjọ pe oun ko jẹbi rara nipa ẹsun ti wọn fi kan an pe o lọ ya fiimu ibalopọ ninu igbo Osun Osogbo."
" Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Abayọmi Aranmọlatẹ, Dr Laser: Vagino Plasty àti iṣẹ́ abẹ ẹwà Obìnrin ló jẹ mí lógún Agbenusọ Sọun fi kun un pe ko ti i ju iṣẹju mẹwaa ti wọn bẹrẹ ipade pẹlu minisita fun ọrọ ọdọ, Sunday Dare, to wa ba ẹbi ọmọkunrin ti ibọn ba lọjọ Satide, Jimoh Isiaka kẹdun, ti awọn ọdọ naa fi kọlu aafin, ti wọn si bẹrẹ si ni ju okuta sinu aafin.
 Olori Anu ni kii ṣe pe oun n fẹ kawon eeyan kanu oun, ni oun ṣe fi ikede naa sita àmọ́ oun kan fẹ ko wa ni akọsilẹ ni."
” Iranṣẹ náà bá bọ́ siwaju, ó ń lọ.
Dájú-dájú ẹ̀bi ìjọba wa ni ọ̀rọ̀ yìí jẹ́.
Àwọn ọ̀tá rẹ ń ṣọ̀tẹ̀ sí ọ;àwọn tí ó kórìíra rẹ sì ń yájú sí ọ.
Nígbà tí mo wí báyìí tán náà tún bẹ̀rẹ̀ sí ọ̀rọ̀ í sọ, ó ní: Olówó-ay’;e mi ọ̀wọ́n, onífáàrí ènìyàn ní ọ́, ọkùnrin náà, ó kú ìgbádùn ilé mi yìí o.
Ẹ wo àwọn ilànà tuntun tí ìjọba Nàìjíríà kéde lẹ́yìn tó fi kún ìséde Covid-19 Àwòráń ọdún Ashura àwọn ẹlẹ́sìn Shiite tí ọ̀pọ̀ ń sọ̀rọ̀ nípa rẹ̀ lórí ayélujára Risikat olójú búlù dí aya Wasiu ní ìlànà Islam, tẹbí tará péjú síbẹ̀ Owó oúnjẹ ni mo lọ ọ gbà, oyún ọmọ tí mo jù sí àkìtàn ni mó gbé wálé- Dupe, ìyá Muiz Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Bolaji Faleke ni Olùkọ́ tó ń kọ́ wa ní àṣà oge ṣiṣe lórí BBC Yorùbá Iroyin fi yeni pe, Osadebe ti ṣe igbeyawo ni ilana ti ibilẹ pẹlu Gloria tẹlẹ lẹyin ti wọn bi ọmọ ẹyọ kan.
December 12, 2014 Ọgọọrọ àwọn ọmọ ẹgbẹ IMN dí ọ̀nà mọ́ ọ̀gá àgbà àwọn ológun, Ọ̀gágun Tukur Buratai ní òpópónà Kaduna ní Zaria.
Ó ní, “Ìlú Jọpa ni mo wà tí mò ń gbadura, ni mo bá rí ìran kan.
9 1,062 Saint Lucia 6 3.
lati fi sajọyọ aseyori re fun saa keji 
Nítorí ohun tí ó jẹ́ kí ó ṣeé ṣe ò ju bí Buhari ṣe fi ọwọ́ wẹ ọwọ́ pẹ̀lú ẹgbẹ́ òṣèlú ìgbàanì Action Congress of Nigeria (ACN) ti Bọ́lá Tinubu.
Amọ, ti ẹgbẹ oṣelu APC ko ba tete wa wọrọkọ fi sada lori ọrọ ipọ alaga ẹgbẹ oṣelu naa, yoo da wahala silẹ fun idibo sipo gomina ti yoo waye ni ipinlẹ Ondo ati Edo.
O ni idajọ ile ẹjọ nikan ni yoo mu ki awọn gba pe bi nkan ṣe ri gan-an niyẹn.
Lopin ose to koja, ‘Infinity War’ pa aadota milionu le ni igba owo dola nile sinima nile America nikan ni eyi to fi ta ju ‘The force Awakens’ todun 2015Paul Dergarabedian to je onimo nipa sinima ni comscore ni: “Disney ta pupo lai si iranlowo China nibe, Disney lo ogbon fi so gbogbo e di obe to dun ti onikaluku fi n woo”“Infinity War” tun ta lagbo awon to n soro lorii sinima nitakun agbaye rotten tomatoes.
O ni Aarẹ Buhari sọ pe ọjọ yii ni wọn yo maa fi pe akiyesi ati wiwa ojutuu si awọn ọrọ to ni ṣe pẹlu ọdọ atawọn iṣoro ti wọn n koju.
Solskjaer fárígá lẹ́yìn tí Van Persie ló ń rẹ́rìn-ín Njẹ́ ẹ mọ̀ pé orílẹ̀-èdè Nàìjíríà ló n wo 'Blue film' jù?
 ) owó ọ ̀ yà rẹ ̀ jẹ ́ náírà mẹ ́ wàá lọ ́ sẹ ̀ .
Sign in or RegisterWhy sign in to the BBC?
Oga agba Ọlọpaa nilẹ yii, Muhammed Adamu ti paṣẹ pe ki ọlọpaa ipinlẹ naa wa ọdaran bẹẹ ri.
Ọ̀pọ̀ àwọn olólufẹ àwọn òṣèré méjèèjì yìí ló tí n fúnra láti àsìkò díẹ̀ sẹyin ṣùgbọ́n ti wọn kò le fi idí ọ̀rọ̀ náà múlẹ̀ ni pàtó pé ìjà wà láàrín wọn.
Lẹyin to jawe olubori lori eto yii lo mori le ile ẹkọ olukọni nipa bi a ṣe n wakọ ofurufu ni orile-ede South Africa, lati kọju mọ iṣẹ to yan laayo.
 Àwọn alábágbé wọn ni esu , kom àti bafut .
Nígbà tí Simoni Peteru rí i, ó kúnlẹ̀ níwájú Jesu, ó ní “Kúrò lọ́dọ̀ mi, nítorí ẹlẹ́ṣẹ̀ ni mí, Oluwa.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Bisi Alimi: Ìyà mi rò pé n kò leè ṣe ni àmọ́ n kò ní ìfẹ́ abo ni mo ṣe fẹ́ akọ O parọwa si ijọba lati jẹ ki ilera awọn ọmọ orilẹede naa jẹ awọn ijọba loju, ki wọn si se ohun to to lati ri wi pe awọn ọmọ Naijiria jẹ anfaani eto ilera to peleke.
Nígbà tí Farao rí i pé gbogbo ọ̀pọ̀lọ́ náà kú tán, ọkàn rẹ̀ tún le, kò sì ṣe ohun tí Mose ati Aaroni wí mọ́, gẹ́gẹ́ bí OLUWA ti sọ tẹ́lẹ̀.
Ignatius Quasi Parish, Ukpor-Mbalom ní bíi aago mẹ́fà àárọ̀ ọjọ́ ìṣẹ́gun nígbà tí àwọn olùjọ́sìn ìjọ náà lọ sí ìjọ́sìn àárọ̀.
WHO yoo kapa aisan Lassa Fever 'Àwọn Dókítà fẹ́ kẹ́yin s'awọ̀n alárùn lassa' 'Èèwọ̀' gààrí fún àwọn èèyàn ipínlẹ̀ Ondo Bakan naa, ni iroyin ni Adari Ile Iwosan Ijọba, FMC Ọwọ fi lede wi pe ko si aye fun awọn alaisan nitori ibi ti wọn ko awọn to ni aisan iba ọrẹrẹ si naa ti kun fọfọ.
Mo mọ Efuraimu, bẹ́ẹ̀ ni Israẹli kò ṣàjèjì sí mi; nisinsinyii, ìwọ Efuraimu ti ṣe àgbèrè ẹ̀sìn, Israẹli sì ti di aláìmọ́.
Ahun a máa sáré ati ní ọrọ̀,láìmọ̀ pé òṣì ń bọ̀ wá ta òun.
Fitzgerald ti sọ pe, ko si ireti wi pe won yoo ri Sala mo.
Ẹ ka nkan tí mo kọ nípa Eostre àti Easter
3 97448 Orilẹede Panama 4651 111.
Bí ẹnikẹ́ni bá ra Heberu kan lẹ́rú, ọdún mẹfa ni ẹrú náà óo fi sìn ín, ní ọdún keje, ó níláti dá a sílẹ̀ lọ́fẹ̀ẹ́ láìgba ohunkohun lọ́wọ́ rẹ̀.
Àti àwọn ìbéèrè míràn Àwọn nǹkan tí obìnrin lè ṣe pẹ̀lú olólùfẹ́ oníwà ipá lásìkò ìgbélé Coronavirus yìí 'Pọ́ńbélé Yorùbá ni mí, n ò sì ní tijú rẹ níbikíbi' Ọjọ mẹta ni Vincent yoo fi sisẹ sin lu.
O ni igbagbọ Yoruba ni pe, ẹni to kọkọ ku naa ko da kú, ṣugbọn o fa awọn eeyan mii dani lati sin in lọ si ọrun.
Gbogbo ilé ọmọ aláìgbọràn nílẹ̀ Yorùbá, Ọlọ́pàá ń bọ̀ wá yẹ̀ yín wò Egbìnrìn ọ̀tẹ̀!
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Naira Marley: Ilé ẹjọ́ ní Naira Marley ń rìn ní bèbè ẹ̀wọ̀n lọ́dún 2020 bí kò bá fara hàn lórí ẹ̀sùn ìjọ́kọ̀gbé 31 Ọ̀pẹ̀̀ 2019 Oríṣun àwòrán, NAira Marley/instagram Afaimọ ki Naira Marley, gbajugbaja olorin takasufe ti irawọ rẹ n tan lọwọ bayii o maa bẹrẹ ọdun 2020 pẹlu ẹwọn.
Obinrin to ba ni MRKH kii ṣe nkan oṣu.
Eto ẹkọ imọ ijinlẹ akọkọ (undergraduate) Ọjọ ori rẹ gbọdọ wa laarin ọdun mẹtadinlogun si ogun ọdun Ẹni to ba fẹ ẹ kopa gbọdọ ni A ati B ninu iṣẹ marun-un ninu idanwo aṣejade nileewe girama Imọ Iṣiro ati ede Gẹẹsi gbọdọ wa lara iṣẹ maraarun naa, ati iṣẹ miran to jẹ mọ nkan ti akẹkọọ fẹ ẹ ṣe ni fasiti Iwe ẹri naa ko gbọdọ ju ọdun kan meji lọ (2019 si 2020), fun awọn to fẹ ẹ kẹkọọ ni awọn orilẹ-ede ti ko si ni Africa, ati ọdun kan (2020) fun awọn to fẹ ẹ kẹkọọ ni ilẹ Africa.
Bí Fayemi bá tasẹ̀ àgẹ̀rẹ̀, àwọn oníbáwí rẹ̀ wà l'Ekiti-Peter Fatomilọla Nílé ijó Fẹla Anikulapo, àrùn Coronavirus dá fàájì dúró Àwọn ọba Yorùbá kan rèé tí wọ́n rọ̀ lóyè, tí ọba míràn jẹ lójú ayé wọn Ṣé òótọ́ ni pé àwọn ọba kan ju ẹlẹgbẹ́ wọn l'Ekiti?
Eeyan bi ọgọrun lo ku, awọn to le ni ẹgbẹrun mẹrin si fi ara pa.
OLUWA tóbi, ó sì yẹ kí á máa yìn ín lọpọlọpọní ìlú Ọlọrun wa.
Ràn wá lọ́wọ́, bá wa gbógun ti àwọn ọ̀tá wa,nítorí pé asán ni ìrànlọ́wọ́ eniyan.
tí mo wí pé, ‘Dúró níhìn-ín, o kò gbọdọ̀ kọjá ibẹ̀,ibí ni ìgbì líle rẹ ti gbọdọ̀ dáwọ́ dúró?
Gbogbo nǹkan yòókù tí Jotamu ṣe ati àwọn ogun tí ó jà, ati àwọn nǹkan mìíràn tí ó tún ṣe ni a kọ sinu ìwé àwọn ọba Israẹli ati ti Juda.
Lẹ́yìn táwọn agbébọn ja Aborode lólè tán ní wọ́n tún gbébọn fún un- Iléeṣẹ́ Ọlọ́pàá Mi ò le tòṣì láéláé!
Besaleli ọmọ Uri, ọmọ ọmọ Huri, ti ẹ̀yà Juda ṣe gbogbo ohun tí Ọlọrun pa láṣẹ fún Mose.
Kìí ṣe orúkọ rẹ̀ nìyẹn o, èmi ni mo sọ ọ́ lórúkọ bẹ́ẹ̀.
Nítorí náà kí ẹ ṣọ́ra kí ìmọ́lẹ̀ tí ó wà ninu yín má baà jẹ́ òkùnkùn.
Lori eyi, Olori Folashade sọ pe iroyin to bani lọkan jẹ pupọ ni iroyin naa.
OLUWA ní,“Nítorí èrò tèmi yàtọ̀ sí tiyín,bẹ́ẹ̀ ni ọ̀nà mi yàtọ̀ sí tiyín,
Ǹjẹ́ ààyè ṣì wà ní ilé yín tí a lè wọ̀ sí ní alẹ́ yìí?
Ó lọ jíròrò pẹlu àwọn ẹgbẹ́ rẹ̀ tí wọ́n jọ dàgbà pọ̀, tí wọn ń bá a ṣiṣẹ́, ó bi wọ́n pé, 
” Dabiri –Erewa  tun so pe , o le ni aadota awon eniyan alawo dudu ti won ti fi obe tabi ibon gbemi won laarin osu kerin odun yii ,niluu London nikan ,pupo ninu won lo tun je odo.
Nígbà tí ó di agogo mẹta ọ̀sán, Jesu kígbe tòò, ó ní, “Eloi, Eloi, lema sabakitani?
Ẹ pín àwọn aláìní láàrin àwọn onigbagbọ ninu ohun ìní yín.
Ma ṣe da ọlọpaa lọwọ duro bi wọn ba n fẹ mu elomiran.
iko alaabo naa fun ilanilọyẹ awọn ara ilu lori awọn ojusẹ ati eto wọn yoo
pẹlu àwọn ẹranko ati àwọn ẹran ọ̀sìn, ati àwọn ohun tí ń fàyà fà káàkiri lórí ilẹ̀, ati oniruuru àwọn ẹyẹ.
Wọ́n fi ẹ̀sùn kan ọmọ-ọ̀dọ̀ yìí pé ó ń fi nǹkan ọ̀gá rẹ̀ ṣòfò.
Eberi tún gbé ojilenirinwo ó dín mẹ́wàá (430) ọdún sí i láyé lẹ́yìn tí ó bí Pelegi tán, ó tún bí àwọn ọmọ mìíràn lọkunrin ati lobinrin.
Adajo  Othman Musa  fagile yiyan asofin Adeleke gege bi oludije
"Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ọdún Orò ń sọ àwa obìnrin sí ìgbèkùn, ẹ̀wọ̀n, tó sì ń tẹ ẹ̀tọ́ wa lójú - Àwọn obìnrin Ikorodu faraya Èèyàn mẹ́rìnlá tí ọpọlọ wọ́n pé la buwọ́lù bíi kọmísọ́nà l‘Oyo - Olórí ilé aṣòfin kan sáárá Èmi àti Saheed kìí ṣe ọmọdé, a ti jọ ṣe Sinimá papọ̀, èyí túmọ̀ sí pé ìjà ti parí - Fathia Balogun ""Mo fẹ́ pa ara mi torí ojú àbùkù tí wọn ń fi wò mí pé mo fi iṣẹ́ abẹ bímọ"" Fulani kò leè dúró, táa bá lo ohun ta jogún lọ́dọ̀ àwọn bàbá wa - Sunday Igboho Ṣugbọn awọn ọmọ Naijiria ti dasi ọrọ naa lori ayelujara bayii, bawọn kan ti n daro awọn to ba iṣẹlẹ naa lọ, lawọn miiran n dẹbi ru awọn ologun ati aarẹ Muhammadu Buhari."
Ri i daju pe o kọ nọ́mbà iforukọsilẹ rẹ pamọ nitori ọjọ iwájú.
"A se e, ta si lọ ta wọn ni ọja ka to lee jẹun"" Kíni ẹ mọ̀ nípa àwọn gbajúgbaja Yollywood?"
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ojojúmọ ní mọ ń kẹ́kọ̀ọ́ lára ọmọ mi to jẹ akanda Ti a ko ba gbagbe, ajọ to n risi idanwo asekagba ile ẹkọ girama, WAEC fi lede lasiko idajọ wi pe lootọ ni Adeleke se idanwo WAEC ni Osu Karun/Kẹfa, ọdun 1981.
 mama rè yìí máa n ran àwon òtòsì lówó .
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ǹ jẹ́ o mọ iye ìgbà tí Super eagles àti Argentina ti pàdé?
Ileeṣẹ apoogun Pfizer ati BioNTech lo se abẹrẹ ajẹsara naa jade.
Oríṣun àwòrán, Others Kọ́mísọ́nà ọlọ́pàá ní ìpińlẹ̀ Osun Undie Adie fìdí ọ̀rọ̀ náà múlẹ̀, nípa bí wọ́n ṣe mú eégún àti àwọn ìsọmọ̀gbè rẹ̀.
laamu , ni eyi ti wọn tun ti gba awọn ọpọ eniyan silẹ lọwọ awon iko ọlọtẹ yii.
Àwọn ààmì àrùn yìí tí a maa ń sábà rí ní kí omi maa jáde ní ojú òbò tí ó sì maa ń rùn bí ẹja .
"Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Champions League: Messi yóò kojú Man U nínú ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ tí yóò ta lẹ́nu Ọgá panápaná, Rasaki Musibau bọ lọ́wọ́ ajínígbe Ọ̀rọ̀ǹpọ̀tọ̀niyùn, Aláàfin obìnrin àkọ́kọ́ rèé, tó ní nǹkan ọkùnrin Njẹ o mọ oju yi ni ""Yollywood""?"
 kúrò ní ìlú àwọn Èdìdàrẹ́ lẹ́yìn tí a ti gbé ibẹ̀ fún odidi oṣù mẹ́ta gbáko, a kọ orí sí ọ̀nà wa.
Àwọn ohun itọju ara bi i abẹfẹlẹ , burọọsi-eyin , ati àwọn irin-iṣẹ ́ ṣíṣe ọwọ tàbí fun ṣíṣe ẹ ́ sẹ ́ lóge lè kan ẹ ̀ jẹ .
Asiwaju ti inagijẹ rẹ n jẹ Mike Cash ni ileeṣẹ to n ṣe ijoko, Asiwaju Royal Furniture to wa ni Ojo, nilu Eko.
” Dafidi bá tọ́jú àwọn nǹkan tí wọn yóo lò sílẹ̀ lọpọlọpọ kí ó tó kú.
Ẹlòmíì a se’bẹ̀, a fi ata já a.
2019 Election: Oniṣẹ́ ibi làwọn to ni kí Atiku ma lọ si ile ẹjọ lóri èsì ìdìbò ààrẹ-Obasanjo
Ọ̀gàn wọn sì dàbí ti abo kinniun.
Ohun ti a ba bọ nigba naa niyi: https://www.
- Àjọ àgbáyé IAAF sí AFN Nàìjíríà Àwọn Afíríkà mẹ́tà to ṣe bẹbẹ nínú EPL sáà 2018/2019 Ni ọdun 1988 ni Samuel Okwaraji kọkọ gba bọọlu fun orilẹede Naijiria ninu idije ife ẹyẹ Afrika ninu eyi ti o ti gba ọkan lara awọn goolu to yara wọle ju lọ ninu itan idije naa.
Bí mo ṣe ń dàgbà ni ǹkan ọmọkùnrin mi ń tóbi síi àmọ́ obìnrin ni mi' Ìdí tí Gúúsù Akure, Owo àti ìwọ̀orun Ondo yóò fi sọ ẹni tí yóò jáwé olúborí nínú ìbò gómìnà Ondo Ejò lọ́wọ́ nínú lórí ìdájọ́ ẹ̀wọ̀n gbére tí wọ́n dá fún Wòlíì Sotitobire, àwọn ọmọ ìjọ rẹ̀ yarí Fọnran ọhun tun ṣafihan bi obinrin naa ṣe n ke irora nigba to n duro de awọn dokita nile iwosan.
Aláàfin tó rí ìbẹ̀rẹ̀ àti opin sáà gómìnà mọ́kànlélógún l‘Oyo Ẹlẹ́tàn ni ọkùnrin, tó bá rí nkan tó n wa lára obìnrin, yóò yí ìwà padà - Bimpe Oyebade Mo ti ní ìyàwó àfẹ́sọ́nà, ayẹyẹ ìgbeyàwó mi ń bọ̀ láìpẹ́ - Lateef Adedimeji Ẹ̀yin oríadé, tẹ bá fẹ́ mọ ìtàn Yorùbá, ẹ lọ kọ́ lọ́dọ̀ Alaafin - Oluwo ''Iṣẹ Ifa ni baba mi n ṣe, oun lo si n kọ mi nipa Ifa ati iṣẹṣe, ọjọ kan tiẹ wa ti mo ọkan lara awọn ohun ti baba mi ti mọ wo lara ọrẹ mi kan to farapa,''Elebuibon lo sọ bẹẹ.
" Ọgbà ẹwọn Nàìjíríà tó kàn rí bíi pé wọn kó ẹranko si Zoo ni kò jẹ kí ayé àwọn ọdáràn yí padà"" Mọ̀ síi nípa Shina Rambo tó pàdé Jesu lọ́gbà ẹ̀wọn lẹ́yìn tó ti jalè Àmọ̀tekún kò tọ́ lábẹ́ ìjọba, ẹ búra fún wá, ká bọ́ sígbó láti ṣeré ọwọ́ pẹ̀lú ọ̀daràn - Sunday Igboho Ọlọ́pàá Funso ló fi ààyè sílẹ̀ fún mi láti sá kúrò ní àgọ́ ọlọ́pàá tó wà ní Mokola - Sunday Shodipe Èèyàn kẹta tó wà nínú ẹlikọ́pítà Quarom aviation tó já lulẹ̀ ní Ikeja náà ti jáde láyé!"
 “Leyin ti igbimo asofin ti pari iwadii
Oríṣun àwòrán, Instagram/Olori Anu/Bobrisky Amọṣa, lati fi idi ọrọ naa mulẹ gan, awa pẹlu lọ soju opo ayelujara Olori laafin Iku Baba yeye naa.
Ṣiṣe ere idaraya naa a maa din aileṣe daadaa lori ibusun ku ni ida mẹrinla si mọkanlelogun ninu ọgọrun un.
Ẹni to bori: Kenya Ìpele to ṣaaju eyi to kangun si aṣekagba Senegal vs Morocco.
Josaya ṣe Àjọ Ìrékọjá fún OLUWA ní Jerusalẹmu.
 ) ìjádelo kí ó má bà á pàdé rè ó jé kí ìjáe rè se kánkán ojú ònà àbájade ojú ònà abájáde méfà ló wà ni ilé ìtajà náà .
Ajulọ sọ eyi lasiko to n fesi si ọpọlọpọ awuyewuye to n lọ lori ọrọ ti Adari Agba Ijọ Redeem, RCCG, Pasitọ Enoch Adeboye sọ lori bi o ṣe yẹ ki eniyan o ṣe ninu igbeyawo.
A fẹ́ bẹ̀rẹ̀ òfin má lo fóònù mọ́ fàwọn ọmọ wa -Òbí Iroyin ni kete to yinbọn fawọn ero tan lo fi ọkọ ara rẹ silẹ to ji ọkọ awọn to n gbe lẹta tó si salọ.
Ìbaaka yìí gba abẹ́ ẹ̀ka igi Oaku ńlá kan, ẹ̀ka igi yìí sì dí tóbẹ́ẹ̀ tí ó fi kọ́ Absalomu ní irun orí, Ìbaaka yọ lọ lábẹ́ rẹ̀, Absalomu sì ń rọ̀ dirodiro nítorí pé ẹsẹ̀ rẹ̀ kò tólẹ̀.
Ni kete ti Buhari kede pe ohun yoo du ipo Aarẹ, opo lara awọn Gomina naa ti'n kan sara si lori igbese naa.
kí àwọn àgbààgbà ìlú rán ni lọ mú ẹni náà wá, kí wọ́n sì fi lé ẹni tí yóo gbẹ̀san ẹ̀jẹ̀ ẹni tí ó pa lọ́wọ́, kí ó lè pa ẹni tí ó mọ̀ọ́nmọ̀ paniyan yìí.
Nígbà tí ó ṣe díẹ̀, ẹlòmíràn tún rí i, ó ní, “Ìwọ náà wà láàrin wọn.
B’órun bá ń kùn mí oo
Ṣugbọn bí ẹ kò bá gba ohun tí ó kọ gbọ́, báwo ni ẹ óo ti ṣe gba ọ̀rọ̀ mi gbọ́?
" Ni ọrọ ti Minisita Lai Mohammed sọ ni osu kini ọdun 2017.
Awọn to ba ri orukọ wọn si n sa fi agbegbe naa silẹ.
Eefin ẹrọ amunawa lo pa sajẹnti ọlọpaa to jẹ́ olori ẹbi naa ati awọn ẹbi rẹ.
Àbí ìwọ náà kò rí i pé, bí a bá ja ogun yìí títí a fi pa ara wa tán, kò sí nǹkankan tí ẹnikẹ́ni yóo rí gbà, àfi ọ̀tá!
Ó bá dìde nídìí oúnjẹ, ó bọ́ agbádá rẹ̀ sílẹ̀, ó mú aṣọ ìnura, ó lọ́ ọ mọ́ ìbàdí, 
Solomoni ṣe gbogbo àwọn ohun èlò wọnyi sinu ilé OLUWA: pẹpẹ wúrà, tabili wúrà fún burẹdi ìfihàn; 
Ṣé kò yẹ kí gbogbo àwọn eniyan tí wọ́n jókòó lórí odi ìlú yìí fetí wọn gbọ́ pé, ati àwọn ati ẹ̀yin, ẹ ti gbé, ẹ o máa jẹ ìgbọ̀nsẹ̀ ara yín, ẹ óo sì máa mu ìtọ̀ yín?
Ọtí waini dídùn yóo máa kán sílẹ̀ lórí àwọn òkè ńlá,ọtí waini yóo sì máa ṣàn jáde lára àwọn òkè kéékèèké.
 Oluwo parí ọrọ rẹ pe, ki ijọba yan awọn Ọba sinu awọn igbimọ naa nitori iṣẹ ìlú láwọn n ṣe, ati pe awọn lọbalọba ṣetan lati gbé ìgbésẹ̀ ki àlàáfíà leè wa laarin ilu."
Angẹli Ọlọrun bá sọ pé, ‘Gbé ojú rẹ sókè, kí o sì wò ó pé gbogbo àwọn òbúkọ tí ó ń gun àwọn ẹran inú agbo jẹ́ aláwọ̀ adíkálà ati onífunfun tóótòòtóó ati abilà, nítorí mo ti rí gbogbo ohun tí Labani ń ṣe sí ọ.
 wọn gbà pè òròṣà ló ko oríre bá wọń .
Pé láti ọdún 1896 ló ti tètè dé báyìí gbẹ̀hìn.
Aarẹ Buhari ti seleri lati fi 15% owo isuna ọdun si eto ẹko, amọ akọsilẹ isejọba rẹ fihan wi pe o nilo lati se ju bẹẹ lọ lati le mu ileri naa ṣẹ.
Bi wọn ba yan gaari ọhun daradara o se e se ki kokoro to'n fa iba ọrẹrẹ naa ku.
Olufunmilọla Ogungbile, to niṣẹ gidi lọwọ ni, iru iriri bẹẹ ni ilu Abeokuta, nipinlẹ Ogun.
Enelamah ni pẹlu igbesẹ ti Naijiria gbe yii ti wọn jẹ ki araalu mọ ohun ti wọn fẹ ṣe, o fi han pe ijọba awa ara wa fẹsẹ mulẹ daadaa ni Naijiria.
Oríṣun àwòrán, @IsaacFAdewole Àkọlé àwòrán, Inu awọn oṣiṣẹ NHIS ko dun si bi ọga agba ajọ naa ko ṣe tẹle aṣẹ lọ rọọ kun nile ti wọn fun un Nigba naa lọun, Ọjọgbọn Yusuf ni ko si ohun ikọkọ kan laarin ohun ati aarẹ ati pe ilana ofin ni aarẹ n tẹlẹ eleyi to fidi rẹ mulẹ wi pe igbimọ tabi minisita ko lee yọ oun bi ko ṣe aarẹ.
Yoruba bọ, wọn ni iyan ogun ọdun a maa gbona fẹlifẹli.
Àwọn àrùn aṣekúpani ti ń yọjú torí àìgba abẹ́rẹ́ àjẹsára A fẹ́ lo ẹ̀jẹ̀ àwọn èèyàn tó ye àrùn Coronavirus láti fi ṣe ìwòsàn fún àwọn tó wà lórí àárẹ- UK Èèmọ̀!
Amọ, Imam Mosalasi Aduragbemi ni Agura Sabo salaye pe, olufọkansin ni ọkunrin naa, ti iku rẹ si ya awọn lẹnu.
Mú kí ọkàn àwọn eniyan wọnyi ó yigbì, jẹ́ kí etí wọn di.
Ẹ kan si wa loju opo ayelujara Facebook, Instagram ati Twitter ki ẹ si lo hashtag #BBC100women Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Awọn Obinrin Dahomey: Awọn obinrin ilẹ Afirika ti wọn yii itan pada re e Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Àwọn ọkùnrin sọ èrò wọn lórí àríyànjiyàn ẹni tó ni ọyàn obìnrin láàrin bàbá àti ọmọ.
Lara idahun si eyi naa ni pe, igbe aye awọn ọkunrin buru jai ju tawọn obirin lọ lawọn nnkan ti wọn n ṣe bii siga mimu.
OLUWA ní, “Ẹ sọ ohun tí ń bọ̀ lẹ́yìn ọ̀la fún wa,kí á lè mọ̀ pé oriṣa ni yín;ẹ ṣe nǹkan rere tabi nǹkan burúkú kan,kí á rí i, kí ẹ̀rù sì bà wá.
Aare Muhammadu Buhari ti bere fun atileyin ijoba apapo ati awon to n mojuto eto idajo, fun ifowosowopo won lati gbogun ti iwa ibaje lorile-ede yii.
" Oloye Elebuibon ni ti ẹ sọ pe, ẹni to lọ ọ gbe ọ̀pá àṣẹ ọba ni isalẹ Eko ti fi ara rẹ ṣepe lai mọ""."
26 Ọ̀pẹ̀̀ 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ninu iwe itan, awọn ile ijọsin naa kopa ninu ṣiṣagbekale ọjọ 'Boxing Day' Itan 'Boxing Day' yii bẹrẹ lakoko ti Ọọbabirin Victoria wa lori aleefa niwọn ọdun 1800.
"Ìbúrawọlé Nàìjíríà ṣojú àgbáyé Dúkìá mi ò lé kan o, mo ti dá fọ́ọ̀mù padà bó ṣe wà tẹ́lẹ̀ - Buhari, Osinbajo Ìtàn ayé Seyi Makinde, gómìnà tuntun ní Ọ̀yọ́ O ni, ""lasiko ipolongo idibo, bi a ti n lọ lati jọba ibilẹ kan si ikeji, a tẹti gbọ ẹdun ọkan ti awọn eeyan ni."
Gbogbo ilakaka awọn ọlọpaa lati mu wọn ni ilu Ikarẹ lo ja si pabo pẹlu bi awọn iroyin kan ṣe sọ pe, awọn eeyan ilu naa ko gba awọn ọlọpaa laaye lati ṣe iṣẹ wọn, nigba ti wọn lọ lati mu tọkọ-tiyawo naa.
Nibayii ajọ eleto idibo ti kede ida mẹtalelogoji ninu ida ọgọrun un esi ibo aarẹ orilẹede Ghana.
4 % je musulumi , 17 % je elesin ibile , 15.
A kò lè fi wé òkúta topasi láti ilẹ̀ Etiopia,tabi kí á fi ojúlówó wúrà rà á.
" Itankalẹ aarun Ebola Bi awọn ikọlu naa ṣe n waye, to si n fa iku ọpọlọpọ ti mu ki adinku ba bi awọn oṣiṣẹ eto ilera ṣe n dena itankalẹ aarun naa ni DR Congo.
Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagold Gomina Sanwo-Olu sún ọjọ ṣiṣẹ lati ile"" síwájú fún àwọn òṣìṣẹ́ ìjọba Àwọn ìṣẹ̀lẹ̀ ńlà lọ́sẹ̀ tó kọjá tó fi mọ́ bí Covid-19 ṣe gbẹ̀mí èèyàn 23 lọ́jọ́ kan ṣoṣo Èèyàn 1,598 míì tún ti lùgbàdì covid-19 ní Nàijíríà, 1,420 ló ti kú báyìí Ẹ wo ọba kan nílẹ̀ Yorùbá, tí kò ṣe ètùtù tàbí náwó ànájù, kó tó jọba Ọjọgbọn Ihonvbere sọ pe ijọba apapọ ko fi ọrọ iwọle awọn akẹkọọ to ile aṣofin leti ko to kede ọjọ ti wọn maa wọle pada."
Ninu awo orin tuntun to gbe jade, diẹ ninu eyi to fi sori oju opo Instagram ati twitter rẹ, DBanj ni gbogbo ipenija yoowu ti o lee koju oun tabi ẹbi oun, iyawo oun ni iyawo oun yoo ma jẹ o.
Gbogbo àwọn ìlú tí ó wà ní gbogbo ilẹ̀ tí OLUWA Ọlọrun yín fun yín ni wọn yóo dó tì.
Ohun gan ni Nollywood yan fọsẹ kan ni Paris gẹgẹ bii fiimu wọn.
Alágbára ni ọ́;agbára ń bẹ ní ọwọ́ rẹ;o gbé ọwọ́ agbára rẹ sókè.
Ọgọfa (120) ọdún ni wọn yóo máa gbé láyé.
Asaaju ikọ Revolution Now tun rọ awọn Oluwọde lati lo ibomu, ki wọn si ta kete sira wọn lati dena arun Coronavirus.
N óo wí pé, ‘Eniyan mi ni wọ́n’; àwọn náà yóo sì jẹ́wọ́ pé, ‘OLUWA ni Ọlọrun wa.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Oluwo, Olúgbò àtàwọn Ọba alayé míì ṣàbẹ̀wò sí Gómìnà ìpínlẹ̀ Eko, Oba ìlú Eko àti Bola Tinubu 3 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Oluwo, Olugbo àtàwọn Ọba alayé míì ṣàbẹ̀wò sí Gómìnà ìpínlẹ̀ Eko, Oba ìlú Eko àti Bola Tinubu.
"Ó sọ ọ́ síwájú pé ""ìrètí wà pé títí ọjọ́ Ajé, Fayoṣe yóò jáde látìmọ́lé, a dúpẹ́ lọ́wọ́ gbogbo ọmọ Nàìjíríà fún àtìlẹ́yìn wọn""."
Oríṣun àwòrán, others Awọn Ọlọpaa ti wọn sọ ara wọn di ẹran ijẹ naa wa lara awọn ọlọpaa ti wọn da sita lati lọ pana wahala iwọde #EndSARS.
A kò tí ẹnu Bodè pa rárá- iléeṣẹ́ Aṣọ́bodè Leon van Biljon dí èrò ọrun nípasẹ̀ Kìnìún rẹ̀ Ikú dóró!
A dàbí àwọn tí kò ní nǹkankan, sibẹ a ní ohun gbogbo.
Iyipada tuntun yii, gẹgẹ bi Aisha Buhari ṣe sọ nibi apeje awọn iyawo Gomina, ko ṣẹyin ki iyemeji ma baa waye lori bi wọn yoo ṣe ma pe awọn iyawo Gomina tuntun, paapa julọ, awọn ti ọkọ wọn ba ni ju iyawo kan lọ.
"Ti ẹgbẹ oṣelu APC ni Buhari nṣe, ko si edeaiyede kankan nibẹ.
 Esi ti a gbo lati odo ijoba apapo ni pe ijoba apapo ati ile-ise General Electric to n mojuto ise akanse naa ti towobo iwe adehun lati se ise ona oju irin naa “.
Orukọ awọn mẹrinla naa ni Gomina Makinde fi ṣọwọ si ile, ti adari ile Ọgbẹni Adebo Ogundoyin, si ka a nibi ijoko ile to waye lọjọbọ.
Malikija, ọmọ Harimu, ati Haṣubu, ọmọ Pahati Moabu, ṣe àtúnṣe apá ibòmíràn ati Ilé Ìṣọ́ ìléru.
Dickson ṣalaye pe awọn ti gba lati sanwo naa lati din iṣẹ ku laarin awọn oṣiṣẹ lawọn ipinlẹ ti ẹgbẹ osẹlu PDP ti wọ le.
Minisita so pe ,“ Igbimo  ijoba apapo ti bowolu awon ise akanse ile-ise
O le ni irinwo asoju omo egbe to wa nibi apero naa lati ipinle merindinlogoji Naijiria.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Revolution Now: Sowore, Bakare gbé ọga DSS lọ sílé ẹjọ́, wọn ń bèèrè fún bílíọ̀nù kan náírà 22 Bélú 2019 Oríṣun àwòrán, Facebook/Omoyele Sowore Omoyele Ṣowore ati Olawale Bakare ti wọn wa latimọle ajọ ọtẹlẹmuyẹ DSS ti n mugbe bọnu bayii, ti awọn mejeeji si ti gbe ọga DSS, Yusuf Bichi ati ọga ẹka eto idajọ ni Naijiria, Ọgbẹni Abubakar Malami lọ sile ẹjọ.
Bakan naa ni NBC salaye pe, Fayose tun bọ sori afẹfẹ ileesẹ agbohunsafẹfẹ ipinlẹ Ekiti lati maa sọrọ abuku nipa ajọ eleto idibo ilẹ wa, Inec, ileesẹ ọlọpaa ati awọn osisẹ ọtẹlẹmuyẹ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Black women live matters: Ọdún 2015 ní àwọn ọlọ́pàá pa India Kager láìní ìdí- Gina Best Gbogbo wọn ni wọn si ti ko lọ si ibudo iyasọtọ titi ti esi ayẹwo wọn yoo fi jade Eeyan marundinlaadọrun lajọ NCDC kede pẹlu arun naa ni ipinlẹ Kwara lọjọ Abamẹta Ìlú àwọn ‘òmùgò’ gba orúkọ tuntun lẹ́yìn àádọ́rin ọdún!
3 8,946 Equatorial Guinea 86 6.
 johnson je omo afrika-trinidad akoitan , oniroyin , elero sosialisti ati alaroko .
Wo ọ̀rọ̀ tí Asiwaju Bola Tinubu fi síta lórí ìṣòro ètò àbò Nàìjíríà Mi ò to iṣẹ́ Regina Daniels rárá kí n tó fẹ́ ẹ láàrin ọ̀sẹ̀ mẹ́ta, mo sì tún le fẹ́ ìyàwó míì - Ned Nwoko Àyà mi já nígbà tí Ganduje rọ Sanusi lóyè Emir Kano tó fi Bayero síi, ṣùgbọ́n.
ogbeni Akinlade n ba awon oludibo soro ni papa isere MKO Abiola International
Oṣu oju ọrun yii ti wa tipẹ ti awọn musulumi si mu lo, lẹyin igba ti Anọbi rinrin ajo lati Makkah lọ si Madinah.
 wọ ́ n mọ ̀ ọ ́ sí àwọn ìwà àìbìkítà tí kò ń fẹ ́ gba ìmọ ̀ ràn lọ ́ wọ ́ u.
Amọ oludasilẹ ileeṣẹ Yemkem ni ewe ati egbi ni Yoruba fi maa n tọju aarun naa laye igba kan.
Ẹni aadọrin ọdun ni sẹnetọ Ajimọbi ko to jade laye.
pẹlu àwọn orílẹ̀-èdè yòókù tí Osinapari, alágbára ati ọlọ́lá, kó wá láti máa gbé àwọn ìlú Samaria ati àwọn agbègbè tí wọ́n wà ní òdìkejì odò.
Nígbà tí ó dé ibẹ̀, ó bá àwọn olórí ogun níbi tí wọ́n ti ń ṣe ìpàdé.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ìjọba ń ṣe afárá Eko Bridge l'Eko, àwọn ọ̀nà àbùdá tí ẹ lèè gbà nìyí Gómìnà ìpínlẹ̀ Kaduna, El-Rufai fi ipò míì dá Sanusi lọ́lá Ganduje fún Aminu Ado Bayero ní ìwé ìyannisípò gẹ́gẹ́ bí Emir ìlú Kano Coronavirus ti di àjàkálẹ̀ àrùn káàkiri àgbáyé- WHO Okada Ban: ọjọ kini oṣù keji ni òfin tuńtun yóò bẹ̀rẹ̀ Kọmiṣọna fun ọrọ to n lọ, Gbenga Omotoso sọ fun awọnn oniroyin lẹyin ipade naa pe, ijọba Eko ko ni fọwọ yẹpẹrẹ mu ọrọ naa lọna ati le ọkada ati kẹkẹ maruwa jinna rere si awọn agbegbe ti wọn ti fofin de wọn.
Mo kábàámọ̀ pé n kò kàwé, kí n tó bẹ̀rẹ̀ iṣẹ́ tíátà - Sanyeri Femi Adebayo di àgbà àáfà òníláwàní, Iyabo Ojo fi sìgá dárà, Allwell Ademola di ọmọdé padà, tí Wazo si bímọ tuntun Ta ni Isho Pepper?
Kí wọn má ṣe jẹ́ ẹlẹ́nu meji.
Apero to n lo lowo nile Saudi je eyi to tobi ti olori orile-ede metadinlogoji jo n se ipade ni Riyadh.
 bacteria tí ó yàtọ ̀ sí  lactobacilli "" maa ń wọ ́ pọ ̀ ."
Ó wípé ọ̀rọ̀ yí ba òun nínú jẹ́ púpọ̀ gẹ́gẹ́ bíi ààrẹ̀ Amẹrika, àti gẹ́gẹ́ bíi baba ọmọ méjì fúnra òun.
21 Nítorí èyí, Ọlọ́run Alágbára Jùlọ fi Ọmọ Bíbí rẹ̀ kan ṣoṣo fúnni, gẹ́gẹ́bí a ṣe kọ́ọ nínú àwọn ìwé mímọ́ wọ̃nnì èyítí a ti fúnni lati ọ̀dọ̀ rẹ̀.
Bakan naa ni mo pasẹ pe ka fa asia Naijiria wa silẹ fun ọjọ mẹta lati sedaro awọn eeyan to ba iwọde EndSARS lọ.
Oríṣun àwòrán, NAtional Assembly nigeria Àkọlé àwòrán, Awọn aṣofin apapọ pe fun titẹle ilana ti ofin la kalẹ.
Dafidi ati àwọn àgbààgbà Israẹli ati àwọn olórí ẹgbẹẹgbẹrun ọmọ ogun bá lọ sí ilé Obedi Edomu, wọ́n lọ gbé Àpótí Majẹmu OLUWA pẹlu ayọ̀.
Èmi ni OLUWA Ọlọrun yín, tí ó kó yín jáde láti ilẹ̀ Ijipti wá.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Super Tuesday: ìdìbò láti yan ẹni tí yóò díje tako Trump bẹ̀rẹ̀ Ọpọlọpọ ijọ ajihinrere ni Afirika ti ko fọwọ si ofin ṣiṣẹ oyun ati ki ọkunrin maa fẹ ọkunrin gẹgẹ bi aya ni ko naani Barack Obama to jẹ aṣaaju Trump pẹlu bo ṣe niru nidi to tan mọ ilẹ Afirika.
Igbesẹ yii ni igba akọkọ ti yoo wa ni akọsilẹ pe awọn ẹru to jẹ adulawọ de si agbegbe naa eyi to wa di ara orilẹede Amẹrika bayii.
Àwọn ìròyìn míì tí ẹ tún le nífẹ́ sí: Harry Kane fọ́ Ronaldo àti Juventus lẹ́nu pẹ̀lú góòlù àràmọ̀ndà Iheanacho ẹlẹ́sẹ̀ ayò tún ti dábírà Mo ṣe tán láti padà sórí pápá - Enyeama Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Nítorí pé, ilẹ̀ tí ẹ̀ ń wọ̀ lọ láti gbà yìí, kò rí bí ilẹ̀ Ijipti níbi tí ẹ ti jáde wá; níbi tí ó jẹ́ pé nígbà tí ẹ bá gbin ohun ọ̀gbìn yín tán, ẹ óo ṣe wahala láti bu omi rin ín, bí ìgbà tí à ń bu omi sí ọgbà ẹ̀fọ́.
Iroyin fi mule pe, iji lile naa ba awon ohun amayederun je pupo bi opo ina mona-mona, opo ero ibanisoro abbl.
Akọnimọọgba ikọ̀ Madagascar, Nicholas Dupuis, sọ pe lootọ̀ ikọ̀ oun ni ko l'agbara pupọ laarin awọn ti wọn jọ wa ni isọri kan naa, ṣugbọn awọn yoo bori ni idije ọjọ Aiku.
Boko Haram pa èèyàn 25 ní Màìdúgùri Ìjọba Germany mú afurasi ọmọ Boko Haram Ọmọ ogun Nàìjíríà mẹ́wàá dèrò ọ̀run lẹ́yìn ìkọlù ẹgbẹ́ Boko Haram Ikọlu Boko Haram sọ ipinnu wa dọtun — Buhari Makinde ti sọ̀rọ̀ lẹ́yìn tí asekúpani Akinyele sálo mọ́ àwọn ọlọ́pàá lọ́wọ́ ní àhámọ́ Bẹẹ laipẹ ni ijọba Naijiria ni wọn tun igbesi aye awọn Boko haram to ronu piwada ṣe ti wọn si tun tu wọn silẹ lati maa lọ ni alaafia pe wọn ti yipada kuro ninu iṣẹ ibi wọn.
Won fi owo sinku mu Abol Fotouh lose to koja, lojo keji ti o pade se lati London, nibi ti won ti foro wa lenu wo lori Aare Abdel Fattah al-Sisi saaju eto idibo Aare ti yoo waye ninu osu to n bo.
Malla Hussaini tun so pe ọpọlọpọ ilẹ ti ijọba ibilẹ tuntun naa yoo pese yoo wulo lati yanju ogorun lonaegberun iwe ilẹ ti awọn  eniyan fẹ gba lati  lo fun idagbasoke, ilu Abuja.
Ìwọ́de #EndSARS rán èèyàn méjì sọ́run n'Ibadan, Seyi Makinde da ikọ̀ Operation Burst sígboro Saaju la ti sọ fun yin pe ko din ni eeyan meji ti wọn ti pa lagbegbe Ọjọọ nilu Ibadan lasiko ti awọn eeyan kan ti wọn funra si pe wọn jẹ janduku kọlu agọ ọlọpaa kan nibẹ lasiko iwọde #EndSARS.
Inu gbogbo ọmọ ilẹ yii lo n dun, taa si n fo fayọ pe owo tun de amọ iroyin to wa gbalẹ kan bayi ni pe ileesẹ eleto idajọ lorilẹ ede Amẹrika ti n dena mọ bi owo yii yoo se tẹ ijọba Naijiria lọwọ.
Macron ati apapo awon omo orile-ede France fun isele ijamba ina ti o waye nile
Ẹ fi ifẹ han gege bi omo orile ede rere, ki i se
Jẹ́ kí ẹ̀yinná dà lé wọn lórí;jẹ́ kí wọn já sí kòtò, kí wọn má lè yọ.
Ojú Shagbada Erigga rèé lẹ́yìn tó pa ọ̀rẹ́bìnrin rẹ̀ l'Akinyele ní Ibadan Ìdí tí lílọ Yúrópùù fi di èèwọ̀ fún Nàìjíríà àti àwọn orílẹ̀-èdè adúláwọ̀ míì 'Kilo de ti ma a fi ya ara mii sọtọ nigba ti mi o ni arun Coronavirus?
Omo orile ede Naijiria to wa ni Poland fe mo boya aare je eniyan tabi eda, lati fi otito oro ti n won n  so mule, eleyii  waye ni gbongan to wa ni Krakow lojo Aiku.
Mò ń kéde pé kí wọ́n ronupiwada, kí wọ́n yipada sí Ọlọrun, kí wọn máa ṣe ohun tí ó yẹ ẹni tí ó ti ronupiwada.
“Nítorí náà, ó ní kí n sọ àsọtẹ́lẹ̀ pé òun OLUWA Ọlọrun ní nítorí pé wọ́n ti sọ ẹ̀yin òkè Israẹli di ahoro, wọ́n sì ja yín gbà lọ́tùn-ún lósì, títí tí ẹ fi di ìkógun fún àwọn orílẹ̀-èdè yòókù, àwọn eniyan sì ń sọ ọ̀rọ̀ yín ní ìsọkúsọ, 
Nígbà tí wọ́n mú un dé, ó ranṣẹ sí baba ọkọ rẹ̀, ó ní, “Ẹni tí ó ni àwọn nǹkan wọnyi ni ó fún mi lóyún.
Ninu atẹjade kan ti Obasanjo ati Kufuor jijọ gbe sita, eyi ti agbẹnusọ Obasanjo, Kehinde Akinyemi fi tẹ BBC Yoruba lọwọ, awọn agba Afirika naa ni asiko ti to lati da si ọrọ oselu Benin ko ti di yanpọn-yanrin.
Protection of Officers Identity , iwe abadofin fun ile –ise pajawiri  ati ayika ti ilu Abuja (Federal Capital
"A kó dúnkoòkò mọ́ Ambode, isẹ́ wa là ń ṣe - Ilé Aṣòfin Eko ""Bi mo tilẹ̀ jẹ́ apárí síbẹ̀ kò tìmí lójú"", Liliya Kukushkina Ṣé àwọn ọmọ rẹ lè sọ Yorùbá tó àwọn ọmọ Amẹrika yìí?"
”Awon orile-ede bi Botswana, Senegal, Mali, Burkina Faso ati Gambia ti fofin de kara-kata ketekete lojuna ati dena won loko iparun.
Saulu ka àwọn eniyan tí wọ́n kù lọ́dọ̀ rẹ̀, wọ́n jẹ́ ẹgbẹta (600).
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Orúkọ ọmọ ni Yorùbá gbà pé ó máa ń ro ọmọ nílẹ̀ Oodua Wọn ni alatako ijọba Buhari ni Adedayọ, idi si ree ti ko fi tọ lati gba ipo ọhun.
Eyi ko fun awọn obinrin ni anfaani lati le ṣe oun ti o wu wọn lori ifetosi ọmọ bibi ni ọna igbalode.
O ti ṣe wá bí aguntan lọ́wọ́ alápatà,o sì ti fọ́n wa káàkiri àwọn orílẹ̀-èdè.
Balogun kẹta, tí ó wà fún oṣù kẹta ni Bẹnaya, ọmọ Jehoiada, alufaa.
O ni ọ̀rẹ́kùnrin òun lo ń fún òun mu leyin ile iwe.
Ṣugbọn a óo máa sọ òtítọ́ pẹlu ìfẹ́, a óo máa dàgbà ninu rẹ̀ ní gbogbo ọ̀nà, ninu Kristi tíí ṣe orí.
‘Ẹyin ará Ondo, Eko, Ogun, Osun, Ọyo, ẹ gbàdúrà ò!
Àwọn ará Kenaani, ati gbogbo àwọn tí ń gbé ilẹ̀ náà yóo gbọ́, wọn yóo yí wa po, wọn yóo sì pa wá run kúrò lórí ilẹ̀ ayé, OLUWA!
Dino: Kò tọ́ bi Buhari se tàbùkù ilé aṣòfin
agbegbe naa ti yanju isoro won, ni eyi ti won si ti gba lati maa jọ se papọ.
APC Kwara: Abdulrahman ṣì ni olùdíje wa fún ipò Gómìnà
Ibi tí ilé náà ga dé, nígbàtí mo bojú wo ìta níbi fèrèsé, mo wá ń wo àwọn ìkúùkù òjò láti òkè wọ́n.
Àwọn ará Bẹtilẹhẹmu ati Netofa jẹ́ ọgọsan-an ó lé mẹjọ (188).
Niluu Riyadh ti ija naa yoo ti waye nilẹ Larubawa ni Cuppy ti fọrọ yii lede loju opo Instagram rẹ.
'Kristẹni lo n fara kaaṣa ikọlu fulani ju' Gani Adams kilọ f'awọn darandaran A kò lè gba àwọn jandùkú Fulani láàyé nílẹ̀ Yoruba -Awọn gómínà Ṣé Fulani daran-daran ni àwọn tó n jí ènìyàn gbé ní ìpínlẹ̀ Ondo?
mo je agbẹjọro ati onise iwadii.
A ó gbé'gbésẹ̀ lẹ́yìn ìwádìí fídíò tí Dino ti ń náwó lójú agbo- Ọlọ́pàá Àwọn obìnrin ilé ìgbìmọ̀ aṣòfin Amẹrika fọnmú sí ọ̀rọ̀ Trump Èrò àwọn ọmọ Naijiria yàtọ̀ lórí ohun ìní Seyi Makinde Ẹgbẹ CAN sọ pe oun ko ti i yi ohun pada lori ọrọ ti oun sọ tẹlẹ pe lootọ ni awọn ko faramọ iwa ibajẹ kankan lati ibikibi, ṣugbọn oun ti fi aaye silẹ fun ẹgbẹ Ijọ Ẹmi Mimọ, PFN ti ijọ COZA n ṣe, lati ṣewadi ẹsun ifipabanilopọ naa, ko si jabọ fun ẹgbẹ CAN.
Ipade ile igbimo asofin mejeeji ni won sun siwaju di ojo isegun ose to n bo lati wa ni ibamu pelu ofin ati ilana ile igbimo ohun ti iru isele yii ba waye si okan lara won.
Pupo laasigbo ti o n waye lorile-ede Ethiopia n waye ni awon ekun ilu nla, Oromia ati Amhara.
Lẹyin eto ti wọn ti le Lilo ati Ka3na pada sile lalẹ ọjọ Aiku, ni iṣẹlẹ naa waye.
oruko awon oludije labẹ asia egbe oselu , Progressives Congress, APC nikan ni
Ilana to dabi ẹni pe Motara tapa si ni eleyi to ni i ṣe pẹlu''Bibu eeyan tabi didunkooko mọ ẹni keji'' tabi eyi to ni i ṣe pẹlu Bibọwọ fawọn alabase loju opo Instagram.
Busola Dakolo: Mílíọ́nù mẹ́wàá náírà tí a béèrè kì í ṣe owó gbà má-bínú
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Helen Paul sọ idi tó fi gba orúkọ ní kékere Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Nítorí pé ilé Israẹli ati ilé Juda ti ṣe alaiṣootọ sí mi.
Nígbà tí Àjọ̀dún Ìrékọjá ku ọjọ́ mẹfa, Jesu lọ sí Bẹtani níbi tí Lasaru wà, ẹni tí ó kú, tí Jesu jí dìde.
Nígbà tí Rehoboamu pada dé Jerusalẹmu, ó ṣa ọ̀kẹ́ mẹsan-an (180,000) ọmọ ogun tí wọ́n jẹ́ akikanju jùlọ láti inú ẹ̀yà Juda ati ti Bẹnjamini, láti lọ gbógun ti ilé Israẹli kí wọ́n sì gba ìjọba ìhà àríwá Israẹli pada fún un.
Civil Society Network Against Corruption, CSNAP naa n pariwo pe ohun to han gbangba pẹlu ohun to n ṣẹlẹ bii sinima laarin ẹbi aarẹ Buhari yii n fihan pe, Daura gan an ni alakoso orilẹede Naijiria labẹ aṣọ.
Ọ̀kan ninu àwọn ọdọmọkunrin náà dáhùn pé, “Wò ó!
Baba Sala: Ẹbí, ọ̀rẹ́, ojúlùmọ̀ péjú láti ṣ'ẹ̀yẹ ìkẹyìn fún Baba Sala nílùú Ilesa
 Bo ba ṣe pe ka pada si lilo ile-iṣẹ PSP ti a n lo tẹlẹ lati ṣamojuto awọn idọti yii ni, ko si ohun to buru ninu rẹ”.
Sááju ni Fatoyinbo ti ran àwọn asojú rẹ̀ lọ sí olú ilé iṣẹ́ ọlọpàá ẹka CID tí ìlú Abuja.
Ohùn-un wọn mú kí iyàrá ètò pa lọ́lọ́.
Coulibalylo ti ni aisan ọkan lati ọdun 2012, to si ti lọ silu Paris lọjọ keji osu Karun fun isẹ abẹ.
Google Top Search 2019: Naira Marley na Atiku pa nínú àwọn orúkọ tàwọn èèyàn ń wá jùlọ ní 2019
Wàyí ò, bí obinrin náà bá lọ bá ọkunrin mìíràn nígbà tí ọkọ rẹ̀ wà láàyè, alágbèrè ni a óo pè é.
Abẹnugan ile naa wa salaye siwaju pe, ile igbimọ aṣofin Ekiti ṣi maa kọwe si Fayose, lati wa farahan niwaju igbimọ to n risi ẹsun ti wọn fi kan an.
Ko gbudọ tii si ipejọpọ kankan bii tito lori ila tabi ṣiṣe ere idaraya; awọn eeyan lati ita ko gbudọ lo inu ọgba ileewe fun inawo kankan.
Iroyin ni arakunrin kan ti orukọ rẹ n jẹ Ojemba fi ibinnu bẹ ori ẹgbọn rẹ ni abule Liokom to wa Ijọba Ibilẹ Yala ni Ipinlẹ Cross River.
Spiny Babbler, ẹyẹ orílẹ̀-èdè Nepal, fa àwọn onímọ̀-nípa-ẹyẹ àti olólùfẹ́ ẹyẹ mọ́ra
Mo ba awon ti ijamba yii sele kedun pupo.
Ọdun 2016 ni wọn ti n ta jaala epo bẹtori kan ni naira marundinlaadọjọ.
Igbakeji gomina ana naa,ti won dibo yan  labe asia (All Progressives Congress ,APC) lo kowe fipo sile lojo Aiku ose to koja yii.
Nnamdi Kanu sọọ ninu ọrọ kan to sọ lori redio laipẹ yii pe orilẹede Israel ni oun wa lọwọlọwọ.
Àkọlé àwòrán, Mo lé rán òjò dí ilé ọ̀tá àwọn alábara mi Pẹ̀lú ìrànwọ àwọn ènìyàn àkòròyìn BBC sàbẹ̀wò sí Godwin Onasedu ní ìlú Ifitedunu, ni ìjọba ìbílẹ̀ Dunukofia ìpínlẹ̀ Anambra, Okùnrin yìí jẹ́ a mú òjò rọ.
Nítorí ohun tí ò ń sọ ṣe àjèjì létí wa.
Ṣugbọn ó ranti ìgbà àtijọ́,ní àkókò Mose, iranṣẹ rẹ̀.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Òṣèré tíátà Toyin Abraham daya Kolawole Ajeyemi Wo àgbáríjọpọ̀ àwọn Arugbá Ọ̀ṣun Òṣogbo látìgbà tó ti bẹ̀rẹ̀ Buhari júwe ọ̀nà ilé fún Obono-Obla lórí ẹ̀ṣùn ayédèrú ìwé ẹ̀rí Àjẹ́ àti Aṣẹ́wó ní ìyá Rainbow - Òjòpagogo A wa dupẹ bayii pe Toyin Abraham ti ruu ree, to si ti sọọ re.
O ni, tiku-tiye ni idibo naa fun ẹgbẹ oselu PDP.
Yatọ si Paris, orileede Saudi naa ti kede pe awọn ko ni gba nikẹni laye yala ọmọ ilu tabi alejo lati kopa ninu Umrah gẹgẹ bi ọna lati koju itankalẹ Coronavirus.
Ó lè ní irínwó àwọn arìnrìn-àjò lọ sí Ethiopia to tí bẹ̀rẹ̀ igbele túláàsì gẹ́gẹ́ bi atejade tí minisita fún ìlera Ethiopia fi síta.
” Ṣugbọn wọ́n ti pète láti ṣe mí ní ibi.
Ọga ọlọpaa ni ẹnu ẹgbọn rẹ obinrin ni wọn ti gba iroyin gbogbo ti wọn fi tọpinpin rẹ de ibi to wa, bakan naa lo si ni Tunmise ti jẹwọ pe lootọ ni oun ṣẹ ẹsẹ naa ati pe ibinu lo faa.
Àbí mà máa mu ẹ̀jẹ̀ ewúrẹ́?
Ẹ̀yin afọ́jú tí ń fọ̀nà han eniyan!
Eniyan lásán a máa pète ibi,ọ̀rọ̀ ẹnu rẹ̀ dàbí iná tí ń jóni.
Ìlú náà dára púpọ̀, àwọn ènìyàn wa lo tilẹ̀ kọ́ dá àbá pé o yẹ kí èmi àti ìyàwó mi dúró díẹ̀ níbẹ̀ kí á gbádùn ara wa.
Nígbà tí Jesu rí i tí ó ń sunkún, tí àwọn Juu tí ó bá a jáde tún ń sunkún, orí rẹ̀ wú, ọkàn rẹ̀ wá bàjẹ́.
Ni bayi, Naijiria, Senegal, Madagascar, South Africa, Algeria, Ivory Coast,Tunisia ati Benin ni yoo kopa ninu abala to kan.
Oluwa yóo gbé e dìde, a óo sì dárí àwọn ẹ̀ṣẹ̀ tí ó ti dá jì í.
Nípasẹ̀ ọmọ rẹ̀ yìí ni a fi ní ìdáǹdè, àní ìdáríjì ẹ̀ṣẹ̀ wa.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Revolution Now: Deji Adeyanju ní ìwọ́de míràn ń bọ̀ ní Satide tí wọn kò bá fi Sowore sílẹ̀ 6 Ògún 2019 Oríṣun àwòrán, @YeleSowore Ajafẹtọ ọmọniyan kan, Deji Adeyanju ti ni Omoyele Sowore to wa ni iahamọ ọlọpaa DSS, ti kọ lati gba ounjẹ ni ọwọ awọn ọlọpaa lati ọjọ ti wọn ti ti i mọle.
Ile igbimọ asoju-sofin fi ikilọ lede lori iṣekupani, ijinigbe, ole jija ati igbesunmọmi kaakiri orilẹede Naijiria, pẹlu adehun pe wọn gbọdọ wa ọna abayọ ni kiakia.
Nisinsinyii, ẹ wá ṣe àdéhùn pẹlu ọba Asiria, oluwa mi.
Saaju eyi, ni adari egbe naa ,omowe Funsho Bello ti sapejuwe igbakeji gomina naa gege bi asiwaju rere fun awon omo egbe naa, ni eyi to faa ti won se fi oye da a lola fun ipa pataki to ko,  lati mu idagbasoke ati ilosiwaju ba eko ati imo isiro .
Inú Jona dùn gidigidi nítorí ìtàkùn yìí.
Tí wọ́n bá ti ilèkùn yàrá rẹ̀, wọ́n máa ń fi kọ́kọrọ́ há orí àtérígbà níbi tí ẹnikẹ́ni ti lè mú un.
Ile ẹjọ naa dajọ ẹwọn fun nitori ẹsun iwa ibajẹ, ati mago-mago to ṣe pẹlu owo ilu nigba to fi jẹ gomina.
Bakan naa ni ẹni to n dari sinima Aje Ọja, Abiọdun Ọlanrewaju, ti gbogbo eeyan mọ si Abbey Lanre ni inu oun dun, nigba ti oun gbọ pe Saheed yoo ma kopa ninu sinima ti Fathia fẹ se, eyi to tumọ si pe o ti rẹ ija laarin awọn mejeeji ni.
bí àwọn ọkunrin mẹta wọnyi: Noa, Daniẹli ati Jobu bá tilẹ̀ wà ninu rẹ̀, ẹ̀mí wọn nìkan ni wọn óo lè fi òdodo wọn gbàlà.
Ifẹsẹwọnsẹ naa ni abala akọkọ ipele to kangun si aṣekagba ninu idije Champions league ilẹ Yuroopu, fun saa bọọlu afẹsẹgba ọdun 2017 si 2018.
Nebukadinesari kó ninu àwọn ohun èlò ilé Ọlọrun lọ sí ilẹ̀ Ṣinari, ó sì kó wọn sinu ilé ìṣúra tí ó wà ninu ilé oriṣa rẹ̀.
Ogedengbe Agbógun Gbórò, Akọni tó ń dẹ́rù ba ikú.
NASS 2019: Gbùngbùn Àríwá ní Agbẹnusọ kàn- Umar Bago Àjọ ìṣọ̀kan àgbáyé UN ti fọmọ ogun apẹ̀tù-síjà ránṣẹ́ sí Mali Olùdíje mẹ́rin ti Gbajabiamila lẹ́yìn ṣáájú ìbò ilé aṣojú ṣòfin Ọmọ ìjọ Èṣù ni Linda Fairstein -Femi Fani Kayode Ìròyìn sọ pé Favour àti Ifeanyi ṣe ìgbéyàwó ìlànà ìbílẹ̀ ní agbolé Uzoegbu Umuomumu Mbieri ní ìjọba ìbílẹ̀ Mbatoli ní ọjọ́ àìkú, ìjàmbá ọ̀hún ṣẹ̀ lẹ́yìn ti ọkọ àti ìyàwó parí gbogbo ètò tí wọn sí kúrò ṣùgbọ́n ti àwọn ẹbi tí ọ̀nà wọ́n jìn pinu láti dúro sùn ní agbolé náà.
Bakan naa gomina ipinle Eko , Akinwunmi Ambode naa tun so pe awon yoo tele ofin ati ilana egbe APC.
“Bi a ba ti n yin Oluwa logo, bẹẹ ni Ọlọrun n da wa lọla, bẹẹ ni Olọrun n da si wa, bẹẹ ni Ọlọrun funra Rẹ n sọ oke iṣoro di pẹtẹlẹ fun wa nitori iyin ogo Ọlọrun gan-an ni o n mu U sọkalẹ si aarin awọn ọmọ rẹ, nitori naa eleyii to n lọ lọwọ yii, o n pe Ọlọrun sọkalẹ saarin wa bii ẹni kọọkan, bi agboole, bi orilẹ-ede.
Ewe, Lelenta Hawa Baba Bah si di minisita to n mojuto oro iwakusa ati ipese irin.
Alaye lẹkununrẹrẹ n bọ laipẹ…Ademola Adepoju.
Ijọba ni èyí to dún oun jùlọ ni pé ìyàwó El-Zakzaky koju àwọn eléto ààbo India àti ti Nàìjíríà pé wọn pa àwọn ọmọ oun, gbogbo èyí jẹ́ ọ̀nà láti jẹ́ ki àwọn orilẹ̀-èdè yìí káànu wọ́n, èyí sì ń kó àbàwọ́n ba orúkọ orilẹ̀-èdè yìí.
"Àjọ CAN gùnlé ọ̀rọ̀ òhún nítorí awuyewuye tó súyọ lẹyìn tí ìdánwò náà parí, wípé, wọn fi èdè Arabic sínú ìbéèrè tí wọn ṣe fún awọn olùkọpa náà Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Attahiru Jega pe àwọn Asòfin ní olè Àìsàn jẹjẹrẹ mú ẹ̀mí Aisha Abimbọla lọ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fọ́nrán ohùn, Awọn òṣìṣẹ́ tí o ń gbá títì olọ́da ní Ékó fẹ̀hónú hán ní ọ́fìsì Visionscape Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, 'Isẹ́ Tíátà tí mò ń se ti tó mi jẹun' Agbenusọ fún ààrẹ àjọ CAN ní Nàìjíría, Adebayo Oladeji sọ fún BBC Yorùbá pé, '' fífi Arabic sínú ìdanwò ìgbaniwọlé sí iṣẹ́ ọlọ́pàá jẹ́ ọnà láti dín ànfààní àwọn kristẹni kú fún ìgbanisíṣẹ́ náà"" ""Ó pọndandan kí àjọ ọlọ́pàá fagilé ìdánwò ọ̀hún"" Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, CAN: ó pọn dandan kí wọn fágile ìdánwò ọlọ́pàá Bákan náà ní Ọ̀jọ̀gbọn Charles Adisa, to bá BBC Yoruba sọrọ sàlàyé pé, lẹyìn tí òun gbọ ìṣẹ̀lẹ̀ náà, ní òun fi ìpè síta láti wádìí ohun tó ṣẹlẹ̀."
yẹ ko waye lonii siwaju si ọjọ kẹ́tàlélógún, osu keji ọsẹ
Ó pinnu lọ́kàn ara rẹ̀ pé,‘N óo gòkè dé ọ̀run,n óo gbé ìtẹ́ mi kọjá àwọn ìràwọ̀ ojú ọ̀run;n óo jókòó lórí òkè àpéjọ àwọn eniyan,ní ìhà àríwá ní ọ̀nà jíjìn réré.
Kéde fún àwọn ibi ààbò Asiria, ati àwọn ibi ààbò ilẹ̀ Ijipti, sọ pé: “Ẹ kó ara yín jọ sí orí àwọn òkè Samaria, kí ẹ sì wo rúdurùdu ati ìninilára tí ń ṣẹlẹ̀ ninu rẹ̀.
Àkọlé àwòrán, Ìtàn Manigbagbe: Ẹ fokan balẹ, àwọn ajakale àrùn kan rèé to burú ju Coronavirus lọ Kòkòrò aifojuri taa mo si bacteria la gbọ pé ó ń faa, tí èèyàn kan bá sì fara kan ẹni tó ní kòkòrò yìí, laarin ọjọ́ méje, onítọ̀hún náà yóò bẹ̀rẹ̀ sí rí àpẹẹrẹ pé òun náà tí kò jonbo àrùn náà.
Ọ̀pọ́ àwọn ọ̀dọ́ orílẹ̀-èdè Nàìjíríà ló ń bèrè ìdí abájọ ti ètò ìdìbò ìpínlẹ̀ Ekiti fí yàtọ̀ sí àwọn ìdìbò tó kú.
”Hesekaya dáhùn pé, “Ọ̀nà jíjìn ni wọ́n ti wá, láti Babiloni.
Alẹkisanderu fúnra rẹ̀ gbọ́wọ́ sókè, ó fẹ́ bá àwọn èrò sọ̀rọ̀.
com/yoruba/46285924 Akinọla: Ọdún méjì ni kí ẹ ti bẹ̀rẹ̀ kíkọ́ ọmọ nípa ìbálòpọ̀: https://www.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Mo rò pé mò ń jà fún Islam ni, ó pẹ́ kó tó yé mi – Boko Haram tẹ́lẹ̀ Èèmọ̀ rèé o, Dókítà yọ eyín 526 lẹ́nu ọmọ ọdún méje Ẹ̀yin òṣìṣẹ́, ẹ kọ ìyà tí wọ́n fi ń jẹ yín lórí owó oṣù tuntun - Oshiomole gbarata Àwọn Pásítọ́ ijọ Redeem márùn ún bọ́ sọ́wọ́ ajínigbé ní Ijebu Ode Ó tó gẹ́ẹ́!
bí ó tilẹ̀ lọ́ra láti sọ ọ́ jáde,tí ó pa ẹnu mọ́,
Omo odun mokandinlogoji naa, ti o si tun je olukopa ti o dagba julo ninu itan idije ATP, fagabahan akegbe re lati orile-ede Bulgaria,  Grigor Dimitrov pelu ami-ayo mefa si meji(6-2), ninu asekagba ifigagbaga eekan soso ohun.
Wọ́n la erékùṣù náà kọjá, wọ́n dé Pafọsi.
Ẹ maṣe fi tipatipa yọọ nitori eyi le kan nnkan ọmọkunrin.
” Tamari ní, “O níláti fi nǹkankan dógò títí tí o óo fi fi ọmọ ewúrẹ́ náà ranṣẹ.
 O ni ajo NDDC ati Shell petroleum company to je ile ise to n fo epo robi ni won jo n sise akanse naa.
Yollywood: Ọ̀pọ̀ òṣèré Yorùbá ń ṣelédè lẹ́yìn Yusuf Satia tó d'olóògbé
Ẹgbọn Mansa, Abu-Bakr se ijọba titi di ọdun 1312.
Oríṣun àwòrán, Instagram/iya_oreanu Lẹyin to wo fidio ọhun tan, Sanwo-Olu sọ ninu atẹjade kan loju opo Instagram rẹ pe oun yoo nifẹ lati foju-rinju pẹlu ọmọ ọhun.
Nígbà tí wọ́n kúrò níbẹ̀, wọ́n lọ gbógun ti ìlú Debiri.
Gómìnà Willie Obiano lọ forí balẹ̀ f'órí adé Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Àtọ̀ ọmọkùnrin ti rógo o!
Ẹ̀sun oniga mejila to niise pẹlu lilo owo ilu ni ponpo, lilo banki ayederu ati gbajuẹ ni EFCC fi kan Maina.
Oríṣun àwòrán, Getty Images F'apejuwe , arabirin kan to kan si Halima Umar Saleh lati ta ibo rẹ , sọ fun Halima pe 'ó yẹ kí o ra àgé (Buta ni Hausa n pe age) nítorí kí wọ́n gbée lọ sí mọ́sálásí gẹ́gẹ́ bíi sàárà'.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Visa free: Àwọn Orílẹ-èdè tí wọn fún ọmọ Nàìjíríá lánfàní ìwé igbeluu ọ̀fẹ́ 2 Ọ̀wàrà 2019 Oríṣun àwòrán, @others Àkọlé àwòrán, Oko Ofurufu ṣetan lati gbe ẹnikẹni to ba fẹ rinrinajo lọ si awọn orilẹ-ede wọnyii.
Saraki ninu atẹjade to fi lede gba ọwọ agbẹnusọ rẹ, Yusuph Olaniyonu, bu ẹnu atẹ lu igbesẹ ajọ to n gbogun ti iwa ibajẹ, EFCC lori awọn ile rẹ ti wọn gbẹsẹ le.
Mílíọ́nù mẹ́wàá Náírà ni ilé ẹjọ́ ni kí Kábíyèsí san gẹ́gẹ́ bí owó ìtaran ilẹ̀ tí ó gbà lọ́nà àìtọ́ Seyi Makinde fún olórin Fuji Taye Currency lẹ́bùn ọkọ̀ bọ̀kìnnì Toyota Prado 2020 Kíni àjọ ọlọ́pàá ń ṣe lórí bí agbófinró ṣe ń ṣèèṣì pànìyan lójoojúmọ́?
N óo máa sọ nípa ìfẹ́ ńlá OLUWA lemọ́lemọ́,n óo máa kọrin ìyìn rẹ̀;nítorí gbogbo ohun tí OLUWA ti fún wa,ati oore ńlá tí ó ṣe fún ilé Israẹli,tí ó ṣe fún wọn nítorí àánú rẹ̀,ati gẹ́gẹ́ bí ọpọlọpọ ìfẹ́ rẹ̀ tí kìí yẹ̀.
Ọdun 2010 si 2016 lo wọn fi jẹ adari ajọ eto ẹkọ ni ẹka ‘National Institute for Policy and Strategic Studies’ lorilẹede Naijiria.
Tedros Adhanom Ghebreyesus ni oun ṣe oun laanu pe awọn eniyan ko i tii kọ ibi ara si ajakalẹ arun naa Oríṣun àwòrán, EPA .
Ta ló jí olùkọ́ fásitì OAU ilé ifẹ̀ gbé?
Àwọn ọmọ ogun rẹ̀ tí a kà jẹ́ ọ̀kẹ́ kan ó lé ẹgbaafa ó lé igba (32,200).
3 Nísisìyí, kíyèsíii èyí ni ẹ̀mí ìfihàn; kíyèsíi èyí náà ni ẹ̀mí nípasẹ̀ èyí tí Mósè fi mú àwọn ọmọ Israeli la Òkun Pupa kọjá ní orí ìyàngbẹ ilẹ̀.
" Wo àwọn gbajúmọ̀ òṣèré Yorùbá tí kìí ṣe ọmọ káàárọ̀ oòjíire Omo Ghetto: Funke Akindele ṣàlàyé bí àwọn agbébọn ṣe kọlù wọn làsíkò tí wọ́n ń ya fíìmù Àyà mi já nígbà tí Ganduje rọ Sanusi lóyè Emir Kano tó fi Bayero síi, ṣùgbọ́n.
Níbi tí wọ́n ti ń ṣe ìwadìí yìí, Akin Olúṣínà ń fi ataare jobì.
ti àwọn ọ̀tá wọn ni mo rò,nítorí pé, ọ̀tọ̀ ni ohun tí wọn yóo máa wí kiri.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Kí ni Present tense"" lédè Yorùbá?"
Koda, ẹkún kekere kọ ni iya rẹ sun, nitori iṣẹlẹ yii.
Ní ọjọ́ kan, Ahabu pe Naboti ó ní, “Fún mi ni ọgbà àjàrà rẹ, mo fẹ́ lo ilẹ̀ náà fún ọgbà ewébẹ̀ nítorí ó súnmọ́ tòsí ààfin mi.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Liverpool gbalejo Tottenham Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Liverpool gbalejo Tottenham Ṣugbọn akọnimọọgba ẹgbẹ agbabọọlu Liverpool Jurgen Klopp sọ pe isinmi ranpẹ ti Salah ni nigba to lọ soju orilẹede Egypt yoo ṣeranwo fun un to ba dee.
Ní ọjọ́ kan Jesu ati àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ wọ inú ọkọ̀ ojú omi kan, ó sọ fún wọn pé, “Ẹ jẹ́ kí á kọjá lọ sí òdìkejì òkun.
Naijiria wa ni isọri keji pẹlu Burundi, Madagascar ati Guinea fun idije AFCON 2019.
"Gẹ́gẹ́ bi ọkùnrin tó ni ìpèníjà ara náà ṣe sọ ""Ọmọkunrin kan fẹ́ jána mọ́ móto mi lẹ́nu lójú pópó, ""mo sọ̀kalẹ̀ nínú mótò mi láti ba ọmọ náà wi pé kí ó m a ṣe bẹ́ẹ̀ mọ́"" Ní ọjọ́ keji, ni obinrin sója náà wá dúró dèmí níwájúilé ìwé kan ni òkè ìtùnú Mokola Ibadan, òun pẹ̀lú àwọn obinrin mẹta míràn tó sì bẹ̀rẹ̀ sí ni da ifọ́tí bòmí."
 Ki i ṣe gbogbo wa lori wa gbe iwe kika, bi awọn ọdọ wa ba kọṣẹ ọwọ, ti a ba pese irin-iṣẹ fun wọn, ti wọn ri iṣẹ ṣe wọn o ni ja”.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Osteogenesis, aisan níní egungun tó rọ̀ ló ń ba Efia fínra Arakunrin Valentine salaye fun BBC pe obinrin naa n fa shisha naa ki o to wọ ọkọ baalu, amọ o gbagbe lati pa ina rẹ daadaa ki o to gbe e wo inu ọkọ baalu.
Awọn ọmọ ẹgbẹ okunkun n dunkoko mọ awọn akẹkọọ nigba to jẹ aare ẹgbẹ awọn akẹkọọ fasiti naa.
Tabili meji wà ní ìta ìloro náà, ní ẹnu ọ̀nà ti ìhà àríwá, tabili meji sì tún wà ní ẹ̀gbẹ́ keji ìloro ẹnu ọ̀nà náà.
”Aare Buhari wa so pe, laipe yii ni awon eniyan yoo bere si
Laipẹ yi ni iṣẹlẹ kan to niṣe pẹlu ẹsun pe Pasitọ Biodun Fatoyinbo ti ijọ Coza fipa ba obinrin lo pọ da awuyewuye silẹ.
PDP tá ko ìgbésẹ̀ Gómìnà Kwara lórí àwọn alága ìjọba ìbílẹ̀ Agolo akẹ́rù Apapa kò pa ènìyàn ṣùgbọ́n ó ba ọ̀pọ̀ ọkọ̀ jẹ́- Ọ̀ga RRS Buhari ń bọ̀ l'Eko: Àwọn ọ̀nà láti yàgò fún àyàfi tí ẹ ba gbé ibùsùn dání Amọ ṣa gbogbo ọrọ yipada nigba ti Sanwoolu lọ si Abuja lati kopa ninu ipade awọn Gomina APC pẹlu Aarẹ Buhari.
Dókítà yọ oyin mẹ́rin tó n gbé nínú ẹyinjú arábìnrin kán
 Ó kún fún àlàyé kíkún lórí gírámà èdè .
Ìlú ò rẹ́rìn ín rárá, Alaafin Adeyemi III fárígá fún Buhari nínú lẹ́tà tuntun Darandaran Fulani kìí lo ìbọn, 'pọ̀pá' la máa ń lò Ọrọ̀ ajé Nàíjíríà tún leè dagun tí Buhari bá fi ìyànsípò àwọn mínísítà falẹ̀ si - Onímọ̀ Ìjọba Nàìjíríà gbọdọ̀ ṣàlàyé ìdí tí 13.
Johanani bí Asaraya (òun ni alufaa tí ó wà ninu tẹmpili tí Solomoni kọ́ sí Jerusalẹmu).
Bí ẹ bá tí ń wọ ìlú ni ẹ óo rí i.
A kò tilẹ̀ kọ́ mọ nǹkan kan ní tiwa ṣùgbọ́n ohun tí a sáà ń rí ni pé bí wọ́n bá ti ń gbé oúnjẹ bọ̀ Ènìyàn-ṣe-pẹ̀lẹ́ ní í máa gbà á lọ́wọ́ wọn a kò sì mọ ibi tí ó ń gbé e lọ àṣé ọmọ -ọ̀dọ̀ náà ni ó ń gbé oúnjẹ yìí fún, wọ́n sì ti ipa bẹ́ẹ̀ si ọ̀rẹ́ ara wọn.
Sugbọn bayi,o ti kọ oju aworan yiya rẹ si akori ọrọ to ni se pẹlu omi.
Ohun tí wọ́n bá gbé kalẹ̀ fun yín ni kí ẹ máa jẹ, kí ẹ sì máa mu.
mọ pe ijọba  ko fi won sere rara.
Ọwọ́ àwọn ọlọ́rọ̀ Israẹli ni ọba ti gba owó náà, ó pàṣẹ pé kí olukuluku dá aadọta ṣekeli owó fadaka.
Nígbà tí àwọn eniyan gbọ́ òfin náà, wọ́n yọ gbogbo àwọn àjèjì jáde kúrò láàrin àwọn ọmọ Israẹli.
Bàbá mi ń jà fún Olódùmarè, ṣùgbọ́n ìyá mi ni ìyálóde ti ń wa oúnjẹ fún àwọn ọmọ ogun Èṣù lákòóòkò ìjà náà.
Bí ète yìí tabi ohun tí wọn ń ṣe bá jẹ́ láti ọwọ́ eniyan, yóo parẹ́.
Nigba ti o n soro pelu awon akoroyin ile aare leyin isin idupe naa, Osinbajo so pe awon omo orile ede Naijiria ni eredi lati dupe lowo Olorun fun aanu re.
Ṣebí ọ̀rọ̀ lásán ni mò ń sọ.
Ọdọọdun ni wọn ma n ṣi daamu naa ti ileeṣẹ Ogun-Osun River Basin Development Authority (ORBDA) n ṣakoso rẹ.
3M lórí ayélujára Andrew Haruna: So-bàtà tó di ọ̀jọ̀gbọ́n fásitì tó tún jẹ́ ọ̀gá àgbà pátá (V.
Àkókò tí ó kù fún wa kò gùn.
Àwọn Ará Asiria Halẹ̀ mọ́ Jerusalẹmu.
Mo ti rí Dafidi, iranṣẹ mi;mo ti fi òróró mímọ́ mi yàn án;
Ṣugbọn ohun tí Joẹli, wolii Ọlọrun ti sọ wá ṣẹ lónìí, tí ó wí pé,
Irun orí rẹ̀ funfun gbòò bí ẹ̀gbọ̀n òwú.
Bakan naa ni wọn sọ ẹgbẹ agbabọọlu ti yoo kopa si mẹrinlelogun.
Mose ké pe Ọlọrun kí ó wò ó sàn.
Gẹ́gẹ́ bí ó ti wà ní àkọsílẹ̀ pé, “Nítorí igbagbọ ni ẹni tí a bá dá láre yóo fi yè.
Ǹjẹ́ o mọ bí Ọlọrun ṣe pàṣẹ,tí ó sì mú kí mànàmáná awọsanma tàn?
A ṣe ọkọ mi ti n ba awọn aṣẹwo lopọ lati igba ta a ti ṣegbeyawo.
Rick Scott to je gomina ipinle Florida ni Amerika ni: “A maa mu enikeni to ba je o se asise ti o sokunfa ijamba yii lati koju ejo bi o ti ye ni.
Bi awọn ọmọ ile igbimọ aṣofin ṣe ni ki awọn kan foribalẹ ki wọn maa lọ naa ni wọn beere ibeere lọwọ awọn miran.
Ibukun wà lórí olódodo,ṣugbọn eniyan burúkú a máa fi ìwà ìkà sinu,a sì máa sọ̀rọ̀ rere jáde lẹ́nu.
Gbogbo wọn yóo bú papọ̀ bíi kinniun,wọn yóo sì ké bí àwọn ọmọ kinniun.
Ẹwe, ninu ipade ilu naa, ti ẹkun Koṣọfe keji yii ni ọpọ awọn alẹnulọrọ ati awọn oloṣelu lẹkun naa peju pesẹ si, ti wọn ti wa sọju awọn ara ilu ni ipele ipele bii awọn oniṣẹ ọwọ, awọn ọlọkọ, awọn ọlọja, awọn ẹlẹsin, ẹgbẹ awọn obinrin, awọn onipenija ara at bẹẹ bẹẹ lọ, ti wọn ti gboriyin fun akitiyan ijọ̣ba Ipinlẹ Eko labẹ Gomina Akinwumi Ambode ati Aṣofin Tunde Brahimo lati mu idagbsoke ba ẹkun Koṣọfẹ ati Ipinlẹ Eko lapapọ, bi ọpọ wọn n ṣe fi ẹdun ọkan wọn han si ijọba.
Ìjẹ́-ọmọ-ènìyàn yóò kú lọ́wọ́ àwọn onímọ̀ ẹ̀sìn bẹ́ẹ̀.
Joiada ni baba Jonatani, Jonatani sì ni baba Jadua.
 Atunse si baalu ofurufu naa yoo dara pupọ , yoo tun jẹ eyi to dara julọ ni agbaye”.
Ọsẹ keji ti wọn pa awọn obi rẹ ni awọn ẹbi rẹ gbee lọ si Ilẹ Gẹẹsi lati lọ ṣe atipo.
Ni ọdun 2013, Jammeh yọ ọwọ orilẹede Gambia kuro lowo ajọ Commonwealth.
Wo àwọn ẹ̀ṣọ́ ara tó tó $40m Diezani Madueke tí ilé ẹjọ́ gbẹ́sẹ̀ lé Kí ló mú kí àwọn èèyàn máa jẹ ọ̀rọ̀ Adeboye lẹ́nu lórí Twitter Óya gbé bọ́dì ẹ!
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, ‘Tunde Kelani yan mi jẹ lori fiimu ‘Toluwanilẹ’ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Tunde Kelani; Èmi ò jẹ́ Baba Wande ní owó lórí fíímù Tolúwanilẹ̀ Kemi Olunloyo dá sí ìjà Toyin Abraham àti Lizzy Anjorin Yomi Fabiyi naa kẹnu bọ ọpọlọpọ ọrọ lati rọ awọn mejeji ki wọn wa bi wọn yoo ṣe yanju ẹ.
Ìlú ìdàrúdàpọ̀ ti wó palẹ̀, ó ti dòfo,gbogbo ìlẹ̀kùn ilé ti tì, kò sì sí ẹni tí ó lè wọlé.
” Wọ́n bá gbé Àpótí Majẹmu náà, wọ́n sì ń lọ níwájú wọn.
Gbogbo ile iṣẹ ni agbaye ni ayipada ti de ba ọna ti koowa n gab ṣiṣẹ oojọ won ni eyi ti awọn kan n daṣa 'New Normal'fun un.
Nígbà náà ni òun ati àwọn tí wọ́n bá a wá tó jẹ, tí wọ́n sì mu, wọ́n sùn níbẹ̀ ní alẹ́ ọjọ́ náà.
Ọ̀pọ̀ ere itage, sinima àti fíìmù àgbéléwò si ni bàbá àti àwọn ọmọbìnrin arẹwà rẹ méjèèjì, tí wọn jẹ ọmọ ọba nìlú Èkó, tí kopa ninu rẹ.
Ilẹ̀ keje tí wọ́n ṣẹ́ gègé lé lórí bọ́ sí ọwọ́ ẹ̀yà Dani.
Wọ́n bá pada lọ láti lọ tọ́jú turari olóòórùn dídùn ati ìpara tí wọn fi ń tọ́jú òkú.
Oríṣun àwòrán, Reuters Àkọlé àwòrán, Àwùjọ musulumi ni Yazidi n finna mọ IS ni Syria.
Igbe aye Irọrun Ileri to ṣe: Idasilẹ eto fifun awọn ọmọ ileewe alakọbẹrẹ ni ounjẹ ọfẹ Eto yii jẹ ọkan lara eto oni ẹẹdẹgbẹta biliọnu Naira ti iṣakoso Buhari jẹjẹ fun igbeaye idẹrun fun araalu.
 orìṣà atẹ ̀ wọ ̀ nrọ ̀ ni odùduwà nítorí pé ẹ ̀ wọ ̀ n ni ó fi rọ ̀ wá sí ilé ayé .
Bẹ́ẹ̀ ni a ṣe pín iṣẹ́ fún àwọn aṣọ́nà láti inú ìran Kora ati ti Merari.
Bakan naa ni gomina ipinlẹ Ọyọ, Seyi Makinde tun ti paṣẹ ki gbogbo ileewe wa ni titi pa nitori wahala to n jẹyọ nipasẹ iwọde #EndSARS ni ipinlẹ naa.
Ẹ sì máa tò wọ́n kalẹ̀ sí ọ̀nà meji; mẹfa mẹfa ní ọ̀nà kọ̀ọ̀kan, lórí tabili tí wọ́n fi ojúlówó wúrà ṣe.
"Toyin tí ẹ mọ̀ tẹ́lẹ̀ yàtọ̀ sí èyí tó wà lójú ọpọ́n báyìí-Toyin Abraham Yoruba Film: Toyin Abraham ní ọlọ́gbọ́n ọkùnrin tí òun fẹ́ ti mú àyípadà rere bá ayé òun Sáájú ni o ti gbé e sí orí àtẹ̀jísẹ́ instagram rẹ̀ pé ""ọmọ ọlọ́jọ́ ìbí, Jésù mo dúpẹ́ fún ìfẹ́ rẹ̀."
Ìgbà tí olúkúlùkù àwọn ọmọ aráyé ṣe ìbéèrè rẹ̀ tán tí wọ́n wí fún Aṣojú-Olódùmarè pé àwọn kò fẹ́ nǹkan tí àwọn kọ́ béèrè mọ́, ara ọ̀run yìí bú sí ẹ̀rín, ó dáhùn ó sì wí pé:
Gẹ́gẹ́ bí mo ti dá ẹ̀mí rẹ sí lónìí, kí OLUWA ṣe bẹ́ẹ̀ sí mi, kí ó sì yọ mí kúrò ninu gbogbo ìṣòro.
Àgbà tí ń gun kẹ̀kẹ́, àfi tí enítọ̀hún bá jẹ́ ẹlẹ́mu.
Awọn mejeeje ni wọn fẹsun kan pe wọn ji awọn ọmọ naa ko ni ọjọ kẹẹdọgbọn, oṣu kẹrin, ọdun 2020.
Bákan nàá lo ti ṣiṣẹ́ gẹ́gẹ́ bi Olúdarí Ilé ẹ̀kọ́ tí wọ́n ti n kọ́ nípa ogun jíjà (National War College), tó fi mọ́ iléèwé tí àwọn òṣìṣẹ́ àjọ DSS, àti àwọn ẹ̀ka mì í tó wà nínú àjọ DSS.
Oríṣun àwòrán, Reserved getty image Àkọlé àwòrán, Ta ni yoo gba ami ẹyẹ yii laarin awọn akọni mẹta yii?
Nítorí náà, ẹ jẹ́ kí á máa rú ẹbọ ìsìn sí Ọlọrun nígbà gbogbo nípasẹ̀ Jesu.
Òun ni yóo jọba lórí wa.
Alaga ileeṣẹ NIPOST, Arabinrin Maimuna Abubakar, lo kọkọ fi ọrọ sita pe ajọ FIRS, n gba ojuṣe NIPOST ṣe, nipa tita ontẹ ijọba fun fifi ẹru ranṣẹ, postage stamp.
" Ileesẹ Ọgbẹni Ahmadu to maa n ṣe eto iwe irinna, Online Integrated Solutions (IOS), sọ loju opo ayelujara rẹ pe oun ṣe asoju ijọba orile-ede Naijiria ni ilu nla mẹẹdọgbọn jakejado agbaye ni Nigeria, China, Lebanon, UAE, Malaysia, Italy, Netherlands, South Africa, USA, France, Germany, UK, India, ati Canada.
Nígbà tí gbogbo àwọn ọba ilẹ̀ Amori, tí wọ́n wà ní apá ìwọ̀ oòrùn odò Jọdani, ati gbogbo ọba àwọn ará ilẹ̀ Kenaani, tí wọ́n wà ní etí Òkun gbọ́ pé OLUWA mú kí odò Jọdani gbẹ nítorí àwọn ọmọ Israẹli, títí tí wọ́n fi rékọjá sí òdìkejì rẹ̀, àyà wọn já, ìdààmú sì bá wọn, nítorí àwọn ọmọ Israẹli.
Oríṣun àwòrán, Twitter/Buhari A ṣẹ̀ṣẹ̀ ń mú ẹyẹ bọ̀ lápò ni pẹ̀lú títú FSARS ká, àtúntò ọlọ́pàá ń bọ̀- Buhari Aarẹ Muhammadu Buhari ti sọrọ fun igba akọkọ lati igba ti iwọde to n pe fun kika ikọ ọlọpaa FSARS kuro nilẹ ti bẹrẹ.
Ó ṣéeṣé ká fí owó kún #500,000 owó móríya ti a fi ń wá Sunday Shodipe- Ilé iṣẹ́ ọlọ́pàá Àwọn aṣekúpani tún ti pa ọmọ ọdún 16 ní Akinyele nípìnlẹ̀ Oyo Ohun tí ọlọ́pàá ń ṣe rèé láti sàwárí àwọn ‘mùjẹ̀-mùjẹ̀’ ní Akinyele 'Ẹ̀pa ò bóró mọ́!
Wòlíì Kasali ní Dolapo Awosika kò lé ìyàwó òun jáde Iwa nabi tu igbeyawo ọgbọn ọdun ka Ìgbéyàwó Harry àti Markle: Ohun tí ó yẹ kí o mọ̀ Buhari ba osinbajo sayẹyẹ igbeyawo ọmọ rẹ Ogbeni Ayobami Oladokun jẹ ọdọkunrin ogidi ọmọ Yoruba to yan iṣẹ obinrin laayo gẹgẹ bi alaga iduro ati ijokoo.
alakoso agba inu igbimọ naa ṣeO tun mu wa
23 Èbibi 2019 Oríṣun àwòrán, @Bashir Ahmad Aarẹ Muhammadu Buhari ti buwọlu iyansipo Mohammed Adamu gẹgẹ bi ọga ọlọpaa tuntun fun orilẹede Nàìjírìa.
Ó di dandan kí ará India yìí sọ ìdí tó fi ń sìn kìnìhún- Egbeyemi Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ó di dandan kí ará India yìí sọ ìdí tó fi ń sìn kìnìhún- Egbeyemi Ọgbẹni Yinka jẹ ko di mimọ pe ẹni ti awọn kọkọ fi ọwọ ofin mu ni arakunrin Hausa to n ṣọ ile ti Kinihun wa ọhun to si kẹnu bọ ọrọ fun awọn lẹyin ti wọn bi i leere pe ki lode ti ko fọ̀hun fawọ́n tọrọ kan pe oun n ṣọ Kinihun ninu ile.
 Awọn miiran ni ṣiṣe atunṣe si agọ olopaa to wa ni Ketu; ṣiṣe ọna to lọ si adugbo Philips Ọnaṣide.
Lọdun 1936 ni wọn fi sọ orukọ Ọba ilẹ Gẹẹsi nigba kan ri, King George V.
O fi kun un pe iṣẹ arumọjẹ lasan lawọn agbofinro DSS ṣe lori iwadii wọn.
Aarẹ Buhari tun ni, ko si nkan to le di Naijiria lọwọ idagbasoke gẹgẹ bii ti China, India ati Indonesia.
pe, ojuse won ni lati satilẹyin fun ijoba , paapaa julo lati pese eto aabo fun
Nítorí pé ó ti rẹ ara rẹ̀ sílẹ̀ báyìí, n kò ní jẹ́ kí ibi tí mo wí ṣẹlẹ̀ nígbà ayé rẹ̀.
Oríṣun àwòrán, @SegunAde88 Ẹyin eeyan Borno, bawo lo se rọrun fun ikọ Boko Haram lati maa rọwọ mu di akoko yii lai ni atilẹyin yin ninu?"
Solomoni ọba ranṣẹ pé kí wọ́n lọ mú Huramu wá láti Tire, 
" Ipò kíní ré sórí ìpínlẹ̀ Plateau!
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Fídíò BBC yọ àwọn èèyàn FIFA níṣẹ́ ṣááju Russia 2018 Megan jẹ ẹni to fẹran lati maa ṣe nkan tawọn eniyan a maa sọrọ le lori lẹyin idije.
‘Trump kò yẹ láti jẹ́ ààrẹ’ Gómìnà Makinde ìpínlẹ̀ Oyo kéde dúkìá tó tó #48bn O kéré tán, ènìyàn 5 ló ti jáláìsí níbi ìṣẹ̀lẹ̀ ilé tó wó ọ̀hún Kògbérèégbè mẹ́ta nínú òṣèré Yorùbá Orọ aarẹ Trump to kọkọ fi sita lọjọ Aiku ko pe orukọ awọn obinrin mẹrẹẹrin yii rara ṣugbọn awọn eniyan gba pe ti olówe ni òwe ni.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Super Eagles: Akojọpọ aworan asọ fun ife ẹyẹ agbaye 8 Èrèlè 2018 Oríṣun àwòrán, Nike/Twitter Àkọlé àwòrán, Osu kẹta ọdun 2018 ni Super Eagles yoo wọ jẹẹsi tuntun yi fun igba akọkọ Ajọ elere bọọlu ilẹ wa, NFF ati ileesẹ Nike ti safihan asọ ti ẹgbẹ agbabọọlu Naijiria, Super Eagles yoo wọ lati kopa ninu idije ife ẹyẹ agbaye 2018, ti yoo waye lorilẹede Russia faraye.
 ""Idi ree ti n ko fi lọ gba ami ẹyẹ nitori oyinbo mi ko dan mọran lati sọrọ imọyi tabi ba awọn akọroyin sọrọ."
Ẹni ọdún mejidinlogun ni Jehoiakini nígbà tí ó jọba, ó sì wà lórí oyè ní Jerusalẹmu fún oṣù mẹta.
Ninu awọn to fi ọrọ adura ati iwuri ranṣẹ ni ilumọọka gbajumọ nii Falz ati awọn mii wa to ni ki awọn aṣoju yi ma gbabọde.
 wọ ́ b gbé àwo orin mẹ ́ sàán jáde kí wọ ́ n tó túká ní ọdún 1980 , káti kọ dá ẹgbẹ ̀ tiwọn sílẹ ̀ .
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ikọ̀ Belgium fakọyọ nígbàtí lé Brazil lọ'lé láti Russia Ọmọ ilẹ Russia ti wọn n gbalejo idije ife ẹyẹ agbaye Denis Cheryshev naa wa lara awọn to ti gb'ayo mẹrin sawọn ni Russia.
T'oun ti pe wọn mọ itunmọ rẹ, awọn ọmọ Naijiria ni ko kan awọn nitoripe asiko ree fawọn lati fi South Afrika ṣe yẹyẹ.
Alakoso ilu Paris Anne Hidalgo, gboriyin fun akoni arinrin ajo lona aibofin mu omo orile-ede Mali naa, ni eyi ti o so pe, ilu Paris yoo gbaruku ti akitiyan re lati le tedo sorile-ede Faranse.
Sáájú ní àwọn dókítà ti pè fún ìpàdé oníròyìn láti lówùrọ̀ òní, láti bèèrè fún ibùdó àyẹ̀wò ní ìpínlẹ̀ Kogi.
O wa kilọ f'aralu pe ki wọn ṣe ayẹwo daada ki wọn to ra pọnmọ lọja ki wọn si tete ta awọn oṣiṣẹ ijọba lolobo bi wọn ba funra si awọn ounjẹ kankan ti o ni kọnunkọhọ.
Nitori a gbọ pe lẹyin ti a yọ awọn adari ile tẹlẹ kuro, a gbọ pe awọn mẹfa ko ara wọn jọ lati pada lọ joko yi ohun ti awa mejidinlogun fi ẹnu ko le lori.
Eyi lo mu ki wọn pinnu lati se afihan ile ounjẹ ti ko wọpọ lawujọ si awọn gbagede kan, eleyii ti yoo bẹrẹ ni Malmo, lorilẹede Sweden ni Ọjọ Kọkanlelọgbn, Osu Kẹwa, ọdun 2018.
Amọ, igbiyanju orilẹede Iran lati gba ẹsan lara orilẹede Amẹrika jasi iku eniyan 176, lẹyin ti ikọ ọmọogun ilẹ Iran ja ọkọ ofurufu ti wọn ro wi pe ti ikọ ogun jabọ, lai mọ pe awọn araalu lo wa ninu ọkọ ofurufu naa.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Eeyan bi ẹgbẹrun un mọkandinlogun ni wọn fi dan oogun yii wo ki wọn to sọ pe oogun ẹjẹ ruru yoo ṣiṣẹ julọ teeyan ba lo ko tun sun lalẹ.
Nítorí pé a mọ̀ nisinsinyii pé, yàtọ̀ fún àwọn ẹ̀ṣẹ̀ tí a ti dá tẹ́lẹ̀, ẹ̀ṣẹ̀ tún ni bíbèèrè tí a bèèrè fún ọba tún jẹ́ lọ́rùn wa.
1 Kíyèsíi, mo wí fún ọ, pé bí ìránṣẹ́ mi Martin Harris ṣe fẹ́ ẹ̀rí lati ọwọ́ mi, pé ìwọ, ìránṣẹ́ mi Joseph Smith, Kékeré, ti gba àwọn àwo àkọsílẹ̀ náà èyí tí ìwọ ti jẹ́rìí sí, tí o sì kọ àkọsílẹ̀ pé o ti gbã lati ọ̀dọ̀ mi;
"Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Wọn gbe Fayose wọ ọkọ alaarẹ ''Wọn fẹ dá emi mi lé gbodo"" Ìgbé ti Gómìnà Fayoṣe fi bọ ẹnu rèé níbi tó ti n ba àwọn ọmọ ẹgbẹ òṣèlú PDP sọrọ níbi ìpolongo itagbangba ní ilé ìjọba Ekiti."
Ògbójú Ọdẹ nínú igbó irúnmalẹ ̀ jẹ ́ ìwé ìtàn tí d.
Jakọbu bá lọ mú wọn wá fún ìyá rẹ̀, ìyá rẹ̀ sì se irú oúnjẹ aládùn tí baba wọn fẹ́ràn.
Bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé ìdámẹ́wàá àwọn eniyan náà ni ó kù ní ilẹ̀ náà, sibẹsibẹ iná yóo tún jó o bí igi terebinti tabi igi Oaku, tí kùkùté rẹ̀ wà lórí ilẹ̀ lẹ́yìn tí wọ́n gé e lulẹ̀.
Lakotan, a kẹkọọ pe ka maa ṣe aanu fun awọn ajeji ni ayika wa, lai naani, ẹya, ẹṣin ati ede ti wọn n sọ nitori oore wa lara awọn naa.
Nibi ti awọn oṣiṣẹ iranwọ ti wọn ji gbe naa n rawọ ẹbẹ si ẹgbẹ awọn ọmọlẹyin Kristi, CAN ati ajọ to n ja lodi si ebi (Action against Hunger) lati wa tu awọn silẹ kawọn ẹṣin-o-kọku to ji wọn gbe to pa wọn bii ti Leah ati Alice.
Adehun ti awon orile-ede mejeeji fenuko le lori naa dale idaabobo awon onibara, iwa-awujo, ajosepo asa ati ise, oro ohun amusagbara, idagbasoke awon odo langba ati ajosepo eto kara-kata.
#FreeOurGirls: Àwọn ènìyàn n fi nkan kun àwòrán àarẹ Pierre Nkurunziza
Nígbà tí ẹsẹ̀ wọn pé, ó sọ fún wọn pé, “Ẹ̀yin alàgbà, n kò ṣe ohunkohun tí ó lòdì sí àwọn eniyan wa tabi sí àṣà àwọn baba ńlá wa tí wọ́n fi fi mí lé àwọn ará Romu lọ́wọ́ tí wọ́n sì fi mí sinu ẹ̀wọ̀n láti Jerusalẹmu.
Eyi ti ó ṣe pàtàki jù ni ki Ìjọba Ilú Ọba ṣe àlàyé bi wọn yio ti da àwon owó Nigeria padà ni ipàdé gbi gbógun ti iwa ibaje, ki wọn lè fihan pé àwọn kò fi ọwọ́ si iwà ibàjẹ́.
 Ọ ̀ rọ ̀ nípa ọdún àti ìbọ tó ń wáyé láàrin ìlú tó jẹ ́ ti ọba Ọ ̀ yọ ́ -Ọ ̀ ṣun .
Ǹjẹ́ aigbagbọ wọn kò sọ ìṣòtítọ́ Ọlọrun di òtúbáńtẹ́?
Ìwọ tí o gbẹ́ ibojì sórí òkè, tí o kọ́ ilé fún ara rẹ ninu àpáta?
“Nígbà náà ni yóo wá sọ fún àwọn tí ó wà ní ọwọ́ òsì pé, ‘Ẹ kúrò lọ́dọ̀ mi, ẹ̀yin ẹni ègún.
Nígbà tí àwọn kan ninu àwọn tí ó dúró níbẹ̀ gbọ́, wọ́n ń wí pé, “Ẹ gbọ́!
Oríṣun àwòrán, Facebook/Yinka Craig Àkọlé àwòrán, Yinka Craig naa jẹ ogbontarigi kọmẹntátọ̀ ni Naijiria nigba aye rẹ Okonkwọ gẹgẹ bi ohun ti agbaọjẹ ere bọọlu ni Segun Odegbami ti ṣe sọ, a maa fun awọn agbabọọlu lorukọ ti eyi a si maa mu inu awọn to n fọkan ba ere naa lọ lori rẹdio dun.
Eyi tun fa ede aiyede laarin awọn adari mejeeji, eyi to mu ki ijọba o tun gbe igbesẹ lati rọ Emir l'oye.
Popona Owonronshoki si Apapa (Laarin Anthony si Oshodi 7.
'Babatunde Fashola' ló ṣe atọ́nà bí Naira Marley ṣe rí bàlùú wọ̀ dé Abuja Ọlọ́run ló ní kí Abacha kú, àwọn àgbà Yorùbá púpò kò bá ṣòfò- Dele Momodu Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ìtàn Olaniyi Balogun, ọ̀jọ̀gbọ́n tó fi Nàìjíríà sílẹ̀ lọ gba iṣẹ̀ àgbẹ̀ l'Ámẹ́ríkà Ohun ta gbọ ni pe ajafẹtọmọniyan naa poora lẹyin to gbe ọrọ sita loju opo Twitter pe eeyan kan gbiyanju lati fipa ba ohun lopọ ni adugbo Park Avenue and Richview Road ni Tallahassee, Florida.
Ẹ yin OLUWA gbogbo ẹ̀yin ọmọ ogun rẹ̀,ẹ̀yin iranṣẹ rẹ̀, tí ẹ̀ ń ṣe ìfẹ́ rẹ̀.
Awada ni eekan ori ayelujara naa fi ọrọ naa ṣe, amọ otitọ pupọ lo sodo sinu ọrọ naa.
Àwọn aṣekúpani tún ti pa ọmọ ọdún 16 ní Akinyele nípìnlẹ̀ Oyo Bi ẹ ko ba gbagbe, Lizzy fi lede pe o ti to ọdun mẹrinla ti oun ati ọkọ rẹ ti n fẹ ara wọn to fi mọ akoko ti ọrọ wọn wọ ati akoko ti ko wọ ṣugbọn ti Ọlọrun ba wọn ṣe aamin si i bayii.
Wọn ni orilẹ-ede Cameroon lo yẹ ko ṣi i si, lati le pese isẹ fun awọn araalu.
Bí Donald Trump ṣe dèrò ilé ìwòsàn torí àrùn Coronavirus tó mú u Aarẹ ilẹ Amẹrika, Donald Trump ni wsn ti gbe lọ sile iwosan ologun fun itọju lẹyin to lugbadi arun Coronavirus.
 fífún àwọn ọmọ-ọwọ ́ ní àjẹsára náà dàbí ohun tó má a ń dín ìṣẹ ̀ lẹ ̀ àrùn náà kù láàárìn àwọn àgbàlagbà àti láàárín àwọn tí kò tíì gba àjẹsára náà tẹ ́ lẹ ̀ rí .
'Kìí ṣe ojúṣe mi láti sọ bóyá òótọ́ ni Buhari fẹ́ gbéyàwó tàbí irọ́' 'Ọwọ́ wa tún tẹ ojúkòó tí wọ́n tí ń bá àwọn ọmọdékùnrin lò pọ̀ ní Daura' Daura kò tan mọ́ Buhari àmọ́ òun àti ọmọ rẹ̀ ti fẹ́ ba ẹbí mi jẹ́ - Aisha figbe ta Àwọn ìṣẹ̀lẹ̀ mánigbàgbé tó wáyé nibi ìwọ́de ENDSARS Nàìjíríà Oríṣun àwòrán, @Alaafinofoyo Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Fídíò, EndSars, EndSwat: Ọlọ́pàá ti fi ìbọn lù mí láyà rí torí mó ní 'extra tyre' méjì- afẹ́hònúhàn15 Ọ̀wàrà 2020 Fídíò, Soyinka Cancer: Àṣe ara mi ni iso ti n run gbogbo bí mo ṣe n ṣèrànwọ́ lórí jẹjẹrẹ27 Bélú 2019 Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
O ti lé ni òkú ẹni mẹ́wàá ti wọ́n ti ri yọ nínú ilé to dà wó ni Jos Kògbérèégbè mẹ́ta nínú òṣèré Yorùbá Àṣìta ìbọn pa èèyàn kan lásìkò tí SARS ń kojú adigunjalè l'Eko 'Kò sí ǹkan tó jọ tòmátò tó ní májèlé ní Nàìjíríà' '' A le fi idi rẹ mulẹ pe ẹgbẹ PFN ti bẹrẹ iwadii, abọ iwadii na yoo si jade sita titi ọsẹ meji si asiko yii.
Israẹli sọ fún un pé, “Jọ̀wọ́, lọ bá mi wo alaafia àwọn ẹ̀gbọ́n rẹ ati ti àwọn agbo ẹran wá, kí o sì tètè pada wá jíṣẹ́ fún mi.
Fídíò Number 12: Ghana yóò yan ìgbìmọ̀ fìdíhẹẹ́ Àwọn ọmọ ilẹ́ Afrika tó ń gbábọ́ọ́lù fún orílẹ̀èdè míràn Bayii, iwadii yii ti n bi ìgè ati àdùbí Ijọba orile-ede Ghana ati awọn ile igbimọ aṣofin bẹrẹ iwadii lori ọrọ naa.
Ṣaaju ni alakoso fidihẹ NDDC, Daniel Pondei ti kọkọ daku rangbọndan niwaju igbimọ oluwadii naa, nigba ti wọn n da ibere bo bi ẹni to n waṣẹ.
Ǹ bá wá ṣe ètò láti wá ìrànlọ́wọ́ fún ìrìn àjò mi sí Judia.
Amọ ọpọ ninu awọn obin awọn ọmọ ile iwe naa lo tako igbesẹ awọn alaṣẹ ileewe naa.
Bẹẹ ba gbagbe, iroyin ti gbalẹ kan pe Zakzaky ti pinnu lati pada si orilẹede Naijiria, lẹyin ti igbesẹ lati mu ko gba itọju nile iwosan Mandata lorilẹede India fori sanpọn.
Mo ma n kuro laarin awọn to ba n fi mi ṣe yẹẹyẹ.
Àwọn kan wà tí wọn ń ṣọ́ ọ bí yóo wo ọkunrin yìí sàn ní Ọjọ́ Ìsinmi, kí wọn lè fi í sùn.
Sanwo-Olu ni irọ ni ẹ̀sùn àwọn alátakò òun (PDP) wípé, ìgbèkun ni àwọn ará Eko wà.
“Pípé ni iṣẹ́ ọwọ́ OLUWA, àpáta ààbò yín,gbogbo ọ̀nà rẹ̀ sì jẹ́ ẹ̀tọ́.
Ìdí ti mo ṣe kọ̀ láti lo ẹbí mi nínú àwọn fíìmù mi -Kunle Afolayan Ọ̀pọ̀ òṣèré tíátà tó ń sàìsàn ni kò ṣe dáadáa f'ẹ́gbẹ́ - Jide Kosọkọ Ayọ̀ abara bíńtín!
Ó fi àwọn ọmọ ogun sí Edomu, gbogbo àwọn ará Edomu sì di iranṣẹ Dafidi.
Ṣugbọn àwọn ará Filistia lé Saulu ati àwọn ọmọ rẹ̀.
Bí ẹni kẹ́ ọrun ni wọ́n kẹ́ ahọ́n wọn,láti máa fọ́n irọ́ jáde bí ẹni ta ọfà;dípò òtítọ́ irọ́ ní ń gbilẹ̀ ní ilẹ̀ náà.
Ẹ̀yin ọmọ ènìyàn, ẹ̀yin kò mọ̀ pé ẹni tí Ó jẹ́ alákòóso ẹ̀dá gbọ́n ju àwọn ẹ̀dá ìyókù lọ!
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù APC Oyo: Àkọsílẹ̀ rere wà pé Ajimobi ni gómìnà tó dáńtọ́ jùlọ ní Ọyọ 16 Ọ̀wàrà 2019 Oríṣun àwòrán, @OfficialSeyiMakinde Igun ọdọ ninu ẹgbẹ oselu APC nipinlẹ Ọyọ ti nahun kesi gomina ipinlẹ Ọyọ, Onimọ ẹrọ Seyi Makinde lati sisẹ tọ awọn ogun isejọba to da lori ilana onidagbasoke ti asaaju rẹ, Abiọla Ajimọbi fi lelẹ nipinlẹ Ọyọ.
Àkọlé àwòrán, Kola Olateru Olagbegi O pe fun ki wọn yọ awọn olori ileesẹ ọmọ ogun Naijiria ti wọn ti pẹ lori oye.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Ọ̀rọ̀ Imam yìí ṣe kòńgẹ́ bó ti ń rí láàrin lọ́kọ láya Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Ẹni tí ‘;o mú ilé ti Ikú mú ilé ti nǹkan, ẹni tí ó mú ilé ti Àrùn mú ilé ti ìjàngbọ̀n, bẹ́ẹ̀ ni ẹni tí ń gbọ́ igbe àkùkọ ọ̀run níláti ṣọ́ra gidigidi.
Ṣugbọn ẹ̀ ń mú kí àwọn Nasiri mu ọtí, ẹ sì ń dá àwọn wolii mi lẹ́kun, pé wọn kò gbọdọ̀ sọ àsọtẹ́lẹ̀ mọ́.
Kí ẹnikẹ́ni tí ó bá fara kan ohunkohun tí ó fi jókòó, fọ aṣọ rẹ̀, kí ó wẹ̀; yóo jẹ́ aláìmọ́ títí di ìrọ̀lẹ́.
"Lootọ ni ijọba nilo awọn olukọ tuntun lati kun un lọwọ, gẹgẹ bii o ṣe wa ni ibi gbogbo titi de oke okun, gbogbo awọn ti wọn ni iwe ẹri olukọ ni a n da pada si ibi ti wọn yoo ti wulo fun awujọ, fun awọn tọrọkan yii, kilasi ni wọn yoo ti wulo julọ.
Ajọ to n mojuto ọrọ ounjẹ ati oogun lorilẹede Naijiria, NAFDAC ti tẹnu mọọ fun awọn ọmọ Naijiria lati sọra fun pọnmọ jijẹ.
Nítorí náà, ẹ yan àwọn ọkunrin mejila ninu ẹ̀yà Israẹli, ẹnìkọ̀ọ̀kan láti inú ẹ̀yà kọ̀ọ̀kan.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Makinde vs Adelabu: Olùdíje APC ní àkọsílẹ̀ àyànmọ́ òun nínú ìtàn Oyo kò gbọdọ̀ yẹ̀ 13 Bélú 2019 Oríṣun àwòrán, Adebayo Adelabu Oludije fun ipo gomina nipinlẹ Ọyọ labẹ asia ẹgbẹ oselu APC, Adebayọ Adelabu ti sọrọ fun igba akọkọ lẹyin ti ile ẹjọ Kotẹmilọrun gbe idajọ rẹ kalẹ lọjọ Aje.
Omo ogorin odun ohun, Blatter fipo re sile, ti won si tun fofin de fun odun mefa latari titepa si ilana igbimo ajo FIFA.
Má jẹ́rìí lòdì sí aládùúgbò rẹ láìnídìí,má sì jẹ́ kí ọ̀rọ̀ ẹ̀tàn ti ẹnu rẹ jáde.
Oríṣun àwòrán, Facebook Imọran ti Aminat Yetunde Olanrewaju Aminu fun Aarẹ ni ti rẹ ni pe, ko fi ijọba silẹ fun awọn ọdọ lati maa dari.
Awọn ẹbí mi sakiyesi pe mi o ki n fẹ fi ọwọ kan awọn nkankan, ti mo si maa n fọwọ́ kọja bose yẹ.
Dipo ko kuku ti laa mọlẹ pe 'ku ọjọ ibi ifẹ mi' Amọṣa bi awọn wọnyii ṣe n sọ tiwọn lawọn kan naa n gbe sẹyin baba Adeboye pe otitọ ọrọ lo sọ.
Orji Uzor Kalu: Ilé ẹjọ́ tó ga jùlọ ní Nàìjíríà wọ́gilé ẹ̀wọ̀n Orji Uzor Kalu, pàṣẹ ìgbẹ́jọ́ tuntun
Muhammadu Buhari gege bi oludije fun ipo aare lẹẹkeji.
Òṣèlú Nigeria, Ẹ Jọ̀wọ́, Ẹ Má Pe Ajá ni Ọ̀bọ fún Ará Ìlú
N kò sọ ohunkohun yàtọ̀ sí ohun tí àwọn wolii ati Mose sọ pé yóo ṣẹlẹ̀.
“Bí ó bá jẹ́ pé ohun jíjẹ tí a yan lórí ààrò ni ó fi rúbọ, kí ó jẹ́ èyí tí ìyẹ̀fun rẹ̀ kúnná dáradára, tí a fi òróró pò, kí ó má sì ní ìwúkàrà ninu.
Toyin Abraham bí ọmọkùnrin jòjòló Àjẹ́ àti Aṣẹ́wó ní ìyá Rainbow - Òjòpagogo Aṣírí ìdí ti El-Zakzaky fi padà Nàìjíríà láti India Fayemi fojú Alufa to fipa bá ọmọde lòpọ̀ síta l'Ekiti Mo ti kó kúrò nílé Olu Jacobs rí lẹ́ẹ̀mejì- Joke Silva Èmi àti Saheed kìí ṣe ọmọdé, a ti jọ ṣe Sinimá papọ̀, èyí túmọ̀ sí pé ìjà ti parí - Fathia Balogun Ṣugbọn ọpọ ni eke ni Mercy n ṣe lori ikini rẹ to nii ṣe pẹlu ọmọ tuntun jojolo bi Toyin Abraham ṣẹṣẹ bi pẹlu ọkọ rẹ, Kolawole Ajeyemi.
Rohr já Iheanacho àti Semi jùú lẹ̀ lọ Egypt fún AFCON 2019 Super Falcons nilo ọmi ninu ifẹsẹwọnsẹ o kere tanalẹ oni lati tẹsiwaju ninu idije ife ẹyẹ agbaye to n lọ lọwọ lorilẹede France.
Ile-ise alabo omo ogun oju ofurufu Naijiria(The Nigerian Air Force), ti ro awon akoroyin lati se gafara fun siso iroyin ti o le sokunfa ewu faabo ilu.
Ikolu naa to waye ni apa ariwa Kivu, ti o wa ni apa ila-orun orile-ede naa, waye lai pe odun kan ti won seku pa awon akosemose ajo UN meji lorile-ede DR Congo.
Ọjọgbọn Oni Fagbohungbe, ẹni ti o jẹ adari ẹka imọ bi awọn eniyan ṣe n ronu ni Fasiti ijọba apapọ ti ilu Eko, ni iru iroyin bẹẹ maa n jẹ ki awọn ara ilẹ okeere ri awọn ọmọ Naijria gẹgẹ bi ọdaran ni.
Nibo ni nkan de duro lati dena iru iṣẹlẹ bẹ ẹ lọjọ iwaju?
Lẹ́yìn náà, ó ta aṣọ àgọ́ náà bò ó, ó sì fi ìbòrí rẹ̀ bò ó gẹ́gẹ́ bí OLUWA ti pàṣẹ fún un.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Kolade Johnson; Iléeṣẹ́ ọlọ́pàá ní ọwọ́ ti tẹ àwọn afurasí ọlọ́pàá tó ṣekúpaá ‘Ọ̀rọ ẹnu lásán ni wàhálà tí Nnamdi Kanu ní òun lè dásílẹ̀ ní Nàíjíríà’ Àwọn olùgbé Fiditi pé fún ìrànlọ́wọ́ lórí àwọn òrùlé tí atẹ́gùn ojó ṣí lọ Ọ̀jọ̀gbọ̀n Pius Adesanmi kú nínú ìjàmbá bàálù Ethiopia!
wọn sì lọ bèèrè lọ́wọ́ àwọn alufaa ilé OLUWA, àwọn ọmọ ogun ati àwọn wolii pé, “Nígbà wo ni a óo dẹ́kun láti máa ṣọ̀fọ̀, ati láti máa gbààwẹ̀ ní oṣù karun-un bí a ti ń ṣe láti ọpọlọpọ ọdún sẹ́yìn?
 A rọ gbogbo ọmọ ẹgbẹ APC lati gbadura kikan kikan fun gomina ipinlẹ Oyo tẹlẹ ri, Sẹnetọ Abiola Ajimobi."
Ninu atẹjade kan to fi sita, osinbajo ni ọtọ lohun ti wọn fi oun ṣe olori fun iyẹn Eto ayipada fun sinsin maalu ti awn gomina ipinlẹ fọwọ si labẹ akoso igbimọ eto ọrọ aje Naijiria.
Ẹ̀sìn tí ó pé, tí kò lábàwọ́n níwájú Ọlọrun Baba ni pé kí eniyan máa ran àwọn ọmọ tí kò ní òbí ati àwọn opó lọ́wọ́ ninu ipò ìbànújẹ́ wọn, kí eniyan sì pa ara rẹ̀ mọ́ láìléèérí ninu ayé.
Ere akọkọ ti Eniola ti fojuhan ni Igba Aimo lọdun 2004 lati igba naa lo si ti di oju taye mọ daadaa ninu awọn sinima Yoruba.
Davy ati Amaka jọ leri lati mọ ẹni ti yoo kọkọ dawọọ lẹ ninu awọn mejeji.
Isẹlẹ miran ni i ṣe pẹlu bo ti ṣe na owo ribiribi lasiko ayẹyẹ ọjọ ibi iyawo rẹ.
  Kò sí ibi tí igi ọ̀pẹ ò hù sí káàkiri.
Amọ ni bayii wọn ko foju rinju mọ lẹyin ti Udom yẹba fun Akpabio, eleyii to fa gbọnmi si omi o to laaarin wọn , ki wọn to pin gari, ti Akpabio si fi PDP silẹ lọ si APC.
O ni anfani lati wo maaki rẹ bi o ba ṣe tan.
Ìtàn Manigbagbe: Àwọn àjakalẹ-àrun to ti wáyé rí ṣáájú Coronavirus Ọba Lamidi Adeyẹmi, òṣìṣẹ́ adójútòfò àti Abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò kó tó jọba ''Kazeem ṣèlérí pé oun máa mú mi lọ ìlú òyìnbó k'àwọn SARS tó pá á'' Òjò àrọ̀ọ̀rọ̀dá dá wàhálà sílẹ̀ l'Eko Wo awọn iroyin manigbagbe to waye ni ọsẹ yii Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Itan Omi Erin Ni ọdun 1994 igbimọ oluwadii Okigbo panel ti wọn gbe kalẹ fun atunto banki apapọ Naijiria na ika ọwọ rẹ ko mọ si aarẹ ologun nigba naa, Ọgagun agba Ibrahim Babangida.
Kò ní dá igi tẹ́ẹ́rẹ́ tí ó tẹ̀ sí meji.
5 Nítorí ọ̀rọ̀ rẹ̀ ni ẹ̀yin yíó gbà, bí ẹnipé láti ẹnu tèmi, pẹ̀lú gbogbo sùúrù àti ìgbàgbọ́.
Ẹ múra, ẹ jẹ́ kí á kọ́ odi Jerusalẹmu, kí á lè fi òpin sí ìtìjú tí ó dé bá wa.
Opolopo ariyan-jiyan lo wa lori atunse si ofin egbe APC, leyin ariyan-jiyan naa  ni awon alakoso  egbe pinnu lati fi ijiroro ti o waye lasiko ipade  won, sinu ofin egbe naa.
Lẹyin igba ti a ti kọja ti Gomina ti kọja a ko ri ẹyin la ti mọ boya awọn eeyan kan ti da awọn eeyan wa lẹyin'' O fi kun pe ''a o ni igbagbọ pe PDP yoo 'se ipolongo wọn loni.
Ọdún kẹẹ̀rin tí àjọ̀dún náà ṣẹlẹ̀ rèé.
Ni ọdun 2016, ijọba Buhari fi 8% owo isuna si eto ẹkọ ati ni ọdun 2017 ni o walẹ si 7.
Ó dàbí ẹni pé mo wà nínú ọkọ̀ òfurufú ni.
Joṣua Rán Àwọn Amí Lọ sí Jẹriko.
Ọmọ a má bẹ̀rẹ̀ gúnyán k’àdó gbèrìgbè mọ mọ̀
Wọ ibomu rẹ tabi iboju ni gbogbo igba ti o ba wa ni papakọ abi ninu ọkọ ofurufu.
Bakan naa lo ni iya mama oun sọ pe oun ni oun n sẹju si baba iya oun, to se n fi tipa ba oun lo.
Lara awon to tun gba ami eye naa
Ṣugbọn fun awọn eniyan kan, o maa n ba wọn ni ọkan jẹ, wọn si gbọdọ ri awọn akọṣẹmọṣẹ to le ranwọn lọwọ lati gba kadara lori aarun naa.
Lara mudunmudun ti ofin yii la kalẹ fun wọn ni pe: wọn yoo laanfaani ọkọ ayọkẹlẹ mẹta, ti ijọba yoo si ma parọ wọn lọdun mẹta mẹta wọn o fun wọn ni ile oniyara marun un owo ẹsọ taa ko sile (furniture allowance) ti iye owo rẹ jẹ ida ọgọrun mẹta owo oṣu wọn Awọn amugbalẹgbẹ marun un,oṣiṣẹ ọtẹlẹmuyẹ mẹta ti yoo ma ṣọ wọn itọju ilera ọfẹ fun Gomina ati igbakeji ida ọgbọn owo oṣu wọn gẹgẹ bi owo lati fi tun ọkọ ṣe ati awọn ajẹmọnu miran Akwa Ibom: Akwa Ibom labẹ ofin Pension Act, 2014 maa n na okere tan, miliọnu lọna mẹrinlelaadọjọ o le diẹ naira N174.
Bakan naa ni Ajọ Eleto Ilẹra lagbaye, WHO ni awọn ti gba esi ayẹwo oogun Dexamethsaone wọle gẹgẹ bi oogun to n koju arun Coronavirus.
Sunday Igboho yari, o fohun ransẹ sawọn eeyan to n pẹgan rẹ Ìkúnlẹ̀ ló bá dé fún Oshiomole, Ize-Iyamu láti bẹ̀bẹ̀ fún ìbò aráàlú ní Edo Wo ohun tí aráàlú ń kojú lọ́jọ́ Aje àkọ́kọ́ tí wọn ti 3rd Mainland Èèyàn 555 míràn tún kó COVID-19 ní Nàìjíríà l'Ọ́jọ́ Aiku Ni ilu Kafaba, lagbegbe Salaga ni orilẹede Ghana ni iṣẹlẹ yii ti waye.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fọ́nrán ohùn, Agbẹnusọ Mélayé: Dino ti lọ yọjú sọ́dọ̀ ọlọ́paa SARS Senetọ Dino Melaye ti ni ki awọn eniyan oun lọ fi ọkan balẹ.
Esi ayẹwo to ku niyii: Oríṣun àwòrán, Ncdc Àjọ NCDC kéde ènìyàn 649 tó tún ní Coronavirus ní Nàìjíríà ní 24/06/2020 Awọn to ni aarun Covid-19 ni Naijiria ti pe ẹgbẹrun mejilelogun (22,020) bayii.
Nicholas Murray, ẹni ọdun mẹrindinlọgbọn to pe ile isẹ ipoogun naa lẹjọ wa lara awọn ẹjọ ti awọn eniyan ti pe mọ ile isẹ ipoogun naa.
lati fowosowopo pelu egbe naa ki ifetosomo-bibi lee di igbe aye irọrun lorilede
Ṣugbọn, Pius lu oun ni alubami nitori pe oun kilọ fun lati dẹkun nina owo wọn sori obinrin mii, ni inakuna.
Ṣugbọn ó pinnu pé òun kò fẹ́ wá ní àkókò yìí.
Abọ iwadii kan ti iwe atigbadegba imọ iṣegun oyinbo, The Lancet Infectious Diseases fi sita sọ pe ìdá 0.
Ileesẹ ọlọpaa Uganda fi iroyin naa mulẹ, ninu atẹjade kan ti alukoro rẹ, SP Patrick Onyango, fi sita lọjọ Aiku.
Ìpínlẹ̀ 10, ìjọba ìbílẹ̀ 24 ni Borno la gbà lọ́wọ́ Boko Haram Agbẹnusọ fun ijọba orilẹede Naijiria, Garba Shehu fikun wipe nigba ti ijọba Buhari gba ijọba ni ọdun 2015, Boko Haram wa ni ipinlẹ mẹwa, ti wọn si ti gba ijọba ibilẹ mẹrinlelogun ni ipinlẹ Borno.
" Ẹlomiran, AllthingsCy, loju opo Twitter tirẹ ni, bo tilẹ jẹ pe oun kii wo sinima Yoruba, sugbọn o jẹ oun itiju bi awọn gbajumọ mejeji yii ṣe n bu ẹnu ẹtẹ lu ara wọn lori ẹrọ ayelujara, ati pe, kii ṣe oun to dara ki wọn pe ara wọn ni ọmọ ale.
Ṣugbọn Amnoni ní ọ̀rẹ́ kan, tí orúkọ rẹ̀ ń jẹ́ Jonadabu, ọmọ Ṣimea, ọ̀kan ninu àwọn arakunrin Dafidi.
Nígbà tí ó di oṣù kẹfà tí mo ti ń ggbé à[fin ọba yìí, oyún ìyàwó mi di oyún oṣù kẹta, nígbà tí wọ́n lóyún ọmọ mi àkọ́bí, Àkàrà-òògùn, mo múra láwùúrọ̀ ọjọ́ kan báyìí, mo lọ sí igbó lọ ṣe ọdẹ ní àkókò yìí, mo ti di ọdẹ aperin.
Herdmen-Farmers Clash: Fatai Owoseni ní àwọn ọlọ́lá ló jẹ́ baba ìsàlẹ̀ fáwọn agbégbọn darandaran
Ṣé wọn gba àwọn ará Samaria kalẹ̀ lọ́wọ́ mi?
Síbẹ̀síbẹ̀, nínú ìfún-ojúpọ̀, ó sọ fún un pé: “Tí a kò bá sọ èdè Tibet ńkọ́?
Ọmọ márùn ún di àwátí ní ilé àwọn ọmọ òrukàn, Stella Obasanjo Motherless Home ní Abeokuta Awọn ọmọde marun un ti di awati ni ileegbe awọn ọmọ orukan, Stella Obasanjo Motherless Children's Home to wa ni Abeokuta, nipinlẹ Ogun.
’ rèé Afọnja, ẹni tó finú wénú ní Ilọrin, àmọ́ tó jẹ iwọ Ẹfunsetan Aniwura, obìnrin tó ju ọkùnrin lọ Ọ̀rọ̀ǹpọ̀tọ̀niyùn, Aláàfin obìnrin àkọ́kọ́ rèé, tó ní nǹkan ọkùnrin Àwọn ìròyìn BBC tó tayọ lọ́sẹ̀ yìí Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí kan sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
eleyii ti o n fun awọn ọmọ orilẹ-ede naa ni igboya lati maa huwa buruku
Oríṣun àwòrán, Others Mo ti kọ Yahaya-Shariff Aminu (Baban Gona) lọ́mọ tẹ́lẹ̀- Bàbá Yahaya Bàbá ọmọ ti ilé ẹjọ́ Sharia ní ìpińlẹ̀ Kano dájọ́ ikú fún sọ pé, òun ti kọ ọmọ òun lọ́mọ́ nítorí, òun ko fara mọ́ ki ènìyàn máá ri orúkọ ọlọrun fin.
Ó ní, “Ẹ má dààmú, nítorí ẹ̀mí rẹ̀ ṣì wà ninu rẹ̀.
Dirẹba naa ni awọn to wa ni ayika ibi ti iṣẹlẹ naa ti ṣẹlẹ gbiyanju lati pa ina naa, amọ ẹpa ko boro mọ, nitori gbogbo ọkọ naa ni o jọna raurau.
Kwara Bridge: Afárá tó já ní Ilorin pa ènìyàn kan, ènìyàn méjì míràn di àwátì Eniyan kan ti ku, ti won si n wa eniyan meji lẹyin ti afara kan ja ni Oko-Erin, Ilorin ni ipinlẹ Kwara.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, BBC Africa Eye: Akọroyin fẹ ìdí àwọn oníṣẹ́ ibi ọmọ ogun síta Iyawo ati ọmọ oloogbe Adesanmi ni orukọ wọn wa lori iwe ipẹjo ti awọn agbẹjọro lati ileesẹ mẹta - Nomaan Hussain, Floyed Wisner ati Omar Khawaja - fi ranṣẹ si ileeṣẹ Boeing.
A óo bí ọmọ kan ninu ìdílé Dafidi, orúkọ rẹ̀ yóo máa jẹ́ Josaya.
Ẹ̀yin tí ẹ kò gbọ́ Yorùbá, ẹ ṣúnmọ́ bí láti kọ́ lítíréṣọ̀ èdè Yorùbá lórí BBC Ẹ wá dánrawò níbí pẹ̀lú Àpólà Ọ̀rọ̀ Orúkọ, Noun Phrase"" Wá kẹ́kọ̀ọ́ nípa ègé ọ̀rọ̀ ohùn Yorùbá tí a mọ̀ sí Sílébù Ẹ ṣúnmọ́ bí láti kọ́ ẹ̀kọ́ nípa ìsọ̀rí ọ̀rọ̀ nínú gbólóhùn Yorùbá Wo ìyàtọ̀ tó wà láàrin Àjọ, Àáró àti ọ̀wẹ̀, tí wọn jẹ́ àṣà ìran ara ẹni lọ́wọ́ nílẹ̀ Yorùbá Awọn yoku ni igbeyawo Asante, nibi ti wọn yoo ti ji iyawo gbe lọ sile ọkọ rẹ, igbeyawo ọkọ kaalẹ ninu eyi ti obinrin yoo ti salọ sile ọkọ ati bẹẹ bẹẹ lọ."
" Baba tẹsiwaju pe yatọ si jijẹ ọmọ Ọlọrun, o yẹ ki awọn eeyan maa ṣe awọn nnkan bi fifọ ọwọ ẹni pẹlu ọṣẹ ati omi, ati jijẹ ki ayika ẹni wa ni mimọ.
 O wu mi lati gbe ilu ti ko si idena kankan, ti ofin si wa fun gbogbo eniyan, ti wọn si n bọwọ fun ẹtọ ọmọ eniyan."
” Naomi bá ṣe àlàyé fún Rutu pé, ẹbí àwọn ni Boasi, ati pé ọ̀kan ninu àwọn tí ó súnmọ́ wọn pẹ́kípẹ́kí ni.
Iwe naa lo ṣafihan pe inu gba ẹwọn kan ni Kigo ni wọn gbe wọn ju si.
Kí ló dé tí èyí fi níláti bà yín ninu jẹ́?
Sẹnatọ Bukọla Saraki nipo kẹtalelogun ni orilẹede Naijiria wa ninu awọn orilẹede to owo ẹru igbalode wọpọ si julọ lagbaye.
Kí ló dé tí o fi kà wá sí ẹranko,tí a di òmùgọ̀ lójú rẹ?
Akẹkọọ perete ni wọn n jẹ ki ọkọ ile iwe maa ko lẹẹkan naa.
wa salaye pe eleyii yoo se e se ti ara ilu ba se ojuse ati ẹtọ won lati tele
Àṣìṣe ló ṣẹlẹ̀ níbi ètò ìsìnkú Abba Kyari- FCTA Yewande bí'mọ tuntun jòjòló, Mercy Aigbe pàdánù èèyàn rẹ̀, Toyin Abraham fèsì lórí aṣoju NCDC Ìjọba yóò lo BVN àtàwọn ọ̀nà méjì míràn láti pín owó ìrànwọ̀ fún aráàlú O fi kun pe awọn ẹgbẹ oṣere lorilẹede Naijiria, TAMPAN ti da si ọrọ oun wọn si ti n gbe igbesẹ to yẹ lori rẹ.
Bí ẹnikẹ́ni bá fi nǹkankan kún un, Ọlọrun yóo fi kún àwọn ìyà rẹ̀ tí a ti kọ sinu ìwé yìí.
“N óo tú omi sórí ilẹ̀ tí òùngbẹ ń gbẹn óo sì ṣe odò sórí ilẹ̀ gbígbẹ.
Ṣaaju, ọga agba Ọlọpaa lorilẹede Niajiria, Mohammaed Adamu ti seleri wi pe awọn yoo se awari awọn to sekupa arabinrin Vera Omosuwa ni ipinlẹ Edo.
Ijokoo ile ko ṣee deede so rọ laijẹ pe Adari orilẹ-ede (Boris Johnson) gba Obabinrin Elizabeth nimọran lati ṣe bẹẹ.
Arabinrin Moromoke sọ fun BBC Yoruba pe, awọn ẹbi ọkọ oun lo ko ọrọ si ọkọ lori lati gbe igbesẹ to gbe.
Bakan naa, bi a ba tun ranti, lodun 2012 oko ofurufu Dana Air 0992 loni ijamba nilu Eko, leyi ti o sekupa ogorun-le logota eniyan ti o wa ninu re.
yóo rọ òjò sórí ilẹ̀ yín ní àkókò rẹ̀, ati òjò àkọ́rọ̀ ati ti àrọ̀kẹ́yìn, kí ẹ baà lè kórè ọkà, ọtí waini, ati òróró olifi yín.
Sugbọn atamatase naa ko gba ju bọọlu kan wọ nu awọn lọ ninu ifẹsẹwọnsẹ mẹjọ to gba latigba to ti de Old Trafford.
Kò ní dára fún ọ ní gbogbo ọ̀nà rẹ.
0 1536 Orilẹede Gilbraltar 30 89.
"Wo ojú àwọn òṣèré yìí láì lo ""Make-up"" orí ìtàgé bó ṣe rí gẹ́lẹ́ Àwọn olóṣèlú Nàìjíríà márùn ùn tó sọ̀rọ̀ tí ará ìlú fà ìbínú yọ Agúnbẹ kan gún èèyàn mẹ́ta pa ní ilé ìjọsìn Notre Dame basilica Ọmọ ọdún mọ́kànlá tó bá wọn fọ́ àgọ́ ọlọ́pàá, wọ gàù ọlọ́pàá ní Edo Báyìí ni 50 Kobo ṣe dá ìfẹ̀hónú ""Ali Must go"" sílẹ̀ tó mú ọ̀pọ̀ ẹ̀mí akẹ́kọ̀ọ́ lọ Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Tóo bá pá lórí, Mílíìkì sóyà àtàwọn ǹkan mẹ́ta yìí leè mú irun rẹ hù padà!"
Ṣugbọn Akiṣi gba Dafidi gbọ́, ó sì wí ninu ara rẹ̀ pé, “Àwọn ọmọ Israẹli, eniyan rẹ̀, kórìíra rẹ̀ lọpọlọpọ, nítorí náà yóo jẹ́ iranṣẹ mi laelae.
yóo jáwọ́ kúrò ninu ọtí waini mímu, ati ọtí líle.
Nítorí, ní ọ̀nà kinni, mo gbọ́ pé nígbà tí ẹ bá péjọ pọ̀ gẹ́gẹ́ bí ìjọ, ìyapa a máa wà láàrin yín.
Ninu ẹ̀yà Manase, àwọn tí wọ́n tó ẹni ogún ọdún, tí wọ́n tó lọ sójú ogun, gẹ́gẹ́ bí àkọsílẹ̀ wọn ní ìdílé-ìdílé 
Lẹ́yìn náà ó mú mi gba ẹnu ọ̀nà ìhà àríwá jáde, ó sì mú mi yípo ní ìta títí tí mo fi dé ẹnu ọ̀nà àbájáde tí ó kọjú sí ìlà oòrùn.
Ṣugbọn Peteru dìde, ó sáré lọ sí ibojì náà.
Mo gbọ́ tí ẹni mímọ́ náà dáhùn pé, “Nǹkan wọnyi yóo máa rí báyìí lọ títí fún ẹgbaa ó lé ọọdunrun (2,300) ọdún, lẹ́yìn náà a óo ya ibi mímọ́ sí mímọ́.
“Ẹ̀ṣẹ̀ tí Samaria dá kò tó ìdajì èyí tí ìwọ dá, ohun ìríra tí o ṣe sì jù tiwọn lọ.
 Àpapọ ̀ iye àwọn tí ó ń sọ èdè adamawa tó mílíọ ̀ nù kan àti ààbọ ̀ -crozier àti blench ( 1992 ) ; grimes ( 1996 ) .
Alaafin: Ọmọ ọdún 17 ní Ayaba Abibat Adeyemi nígbà tó fẹ́ ọkọ rẹ̀
O di dandan ki awọn ololufẹ awọn olukopa dibo lasiko ti eto yii n lọ lọwọ.
Aare orile ede Naijiria  muhammadu Buhari ti dupe lowo egbe osise ijoba
Ọmọ ogun Nàìjíríà bẹ̀rẹ̀ lílo 'Drone' láti gbógun tàwọn ajínigbé ni Ondo àti Ekiti Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Widows Day 2019: Mo máa ń sá kiri wá owó ilé ni -Opó Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Awọn ṣoju ijọba, oloṣelu ati lẹgbẹlẹgbẹ naa pẹlu awọn fi o fi ara han lati t'ọwọ bọ iwe idagbere ikẹhin fun oloogbe.
San án fún wọn gẹ́gẹ́ bí iṣẹ́ ọwọ́ wọn,àní gẹ́gẹ́ bí iṣẹ́ burúkú wọn;san án fún wọn gẹ́gẹ́ bí iṣẹ́ ọwọ́ wọn,fún wọn ní èrè tí ó tọ́ sí wọn.
Ikọ́ lásán ló pa Orisabunmi Orisabunmi ti jáde láyé, ohun tí a mọ̀ nípa ayé àti ikú rẹ̀ nìyí COVID-19 pa èèyàn mọ́kànlá láàrín ọjọ́ méjì, ènìyàn 1565 míràn tún ko lọ́jọ́ kan ṣoṣo ní Nàìjíria Iyaafin Akinoso to jẹ aburo oloogbe naa ni awọn jumọ ṣere lati ọjọ kejila oṣu kejila ọdun 2020 titi di ọjọ kini ọdun 2021.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Sheikh Liadi Orunsolu: Ìmáàmù àgbà ilẹ̀ Egba ti jáde láyé lẹ́ni ọdún méjídínlọ́gọ́rùn ún 26 Èbibi 2020 Oríṣun àwòrán, @kollysmith Imaamu agba ti ilẹ Egba, Sheik Liadi Orunsolu ti jade laye.
Kò hàn gedegbe bí ìyàwó ààrẹ ṣe gbé ẹ̀sùn náà síta súgbọ́n ènìyàn kan ló ta olobó pé olùrànlọ́wọ́ pàtàkì míì tó ń ṣiṣẹ́ fún ìyàwó ààrẹ ló pilẹ̀sẹ̀ rẹ̀.
 Ẹgbẹ ́ èdè turkic yìí jẹ ́ ọmọ ẹbí altaic .
Bakan naa, aya Ọlaitan tun dupẹ lọwọ awọn akọroyin lọkanojọkan, to fi mọ ileesẹ BBC Yoruba, lori ilakaka wọn lati ri pe ede Yoruba tẹ siwaju, to si gba adura pe ọba oke yoo pin wọn lere.
Ọmọ agbabọọlu Swansea Jordan Ayew f'agba han Cech loju'le nigbati ti o gba amin ayo kan wọle.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Amuneke fipò sílẹ̀ gẹ́gẹ́ bí akọ́nimọ̀ọ́gbá Tanzania 8 Agẹmo 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Emmanuel Ameneke Ẹgbẹ agbabọọlu orilẹede Tanzania, TFF fi aridaju han lọjọ aje pe Emmanuel Amuneke ti fi ipo rẹ silẹ gẹgẹ bi akọnimọọgba ẹgbẹ agbabọọlu orilẹede naa ni tubi nnubi.
9 Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù UNICEF: O fẹ́rẹ tó 900 ọmọdé tó gba ìtúsílẹ̀ lọ́wọ́ àwọn ọlọ́de CJTF 10 Èbibi 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Àwọn ọmọdé tótó 894 tí gba ìtúsílẹ̀ lọ́wọ́ àwọn ọlọ́de tó ń kọju àwọn agbésùnmọ̀mí pẹ̀lú àwọn ológun.
Wo ohun tó yẹ kí o mọ̀ nípa akínkanjú obìnrin alága àjọ elétò ìdìbò Ghana 2020 Aisha Buhari ké sí àwọn aya gómìnà pé kí wọ́n lọ paná ìdàrúdàpọ̀ lágbègbè yín Góòlù pọ̀ ní ìlú Madaka ṣùgbọ́n wọn kò ní ọ̀nà fún ọgọ́rùn ún ọdún Ta ni ìgbẹ́jọ́ ìbò gómìnà Ondo yóó gbè nínú Akeredolu àti Jegede?
K Odukoya 'ń gun orí òkè àdúrà nítorí COVID-19'-Wò báwọn èèyàn fi wò wọ́n Ẹwẹ, awọn oṣiṣẹ miran lẹka eto ilera to ti fara kaaṣa arun yii jẹ mẹrindinlaadọrin ninu eyi ti mẹrin ninu wọn ti ku.
awọn ohun amulo ti yoo wa larọwọto, pẹlu ojusun lati pari awọn iṣẹ
Wo ìgbà méje tí Donald Trump ti yẹpẹre àrùn Coronavirus Lati nnkan bi oṣù mẹwaa sẹyin ni ọpọ awọn ọmọ ilẹ Amẹrika kigbe pe ọwọ ti aarẹ Donald Trump fi mu aarun Coronavirus ko bojumu tó ati pe ni ọpọ igba lo ma a n ṣe bii pe arun ọhun kii ṣe ootọ.
Ni bayi Rene, ọmọ odun mejilelogbon ati ebi rẹ ngbe nilu Ikom to wa ni ipinlẹ Cross River, eyi toto kilomita metadinlogbon si ẹnu aala ibode Naijiria ati Cameroon.
Ọ̀gá rẹ̀ bá pè é, ó sọ fún un pé, ‘Irú ìròyìn wo ni mò ń gbọ́ nípa rẹ yìí?
Gbogbo obinrin lagbaye, mo ki yin loni ati lọjọ gbogbo.
Àwọn ọmọ náà tí wọn kò ju ọmọ ọdún 15 sí 17 yóò ṣe ẹ̀wọ̀n ọdún márùn-ún bí wọ́n bá jẹ̀bi ẹ̀sùn ìtàbùkù bá Ààrẹ orílẹ̀-èdè.
Eyi lo fa oju ajọ LASTMA si fidio naa ti wọn si ni awọn yoo ṣewadii lati mọ aridaju ki wọn fi ọwọ ofin mu oṣiṣẹ to ba ṣẹ.
Ó wó àwọn pẹpẹ, ó lọ àwọn òpó Aṣera ati àwọn ère oriṣa lúúlúú, ó sì wó gbogbo pẹpẹ turari jákèjádò ilẹ̀ Israẹli.
Njẹ awọn coronavirus yooku ni asiko ti wọn ma n tan kaakiri?
Aarun jẹjẹrẹ lo ṣokunfa iku Boseman to dagbere faye lẹni ọdun mẹtalelogoji.
and other Maritime Defence Bill ati  Institute of Transport Administration
naa tun wa gbosuba fun oludari gbogbo ile-ise omo ogun orile ede Naijiria, aare
Wọn ijọba lo fi ofin konile-o-gbele sita, ijọba naa tun lo faye gba ọpọ eeyan lati lọ sibi isinku Abba Kyari.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, APC: òfin NYSC ti APC fi mú mi ni wọ́n kò lò fi mú Ajimọbi tí a kò jọ sìnrú ìlú Bakan naa ni Abiola morile ile ẹkọ girama Lagelu ladugbo Agugu nilu Ibadan feto ẹkọ oniwe mẹwa rẹ, to si gbajumọ bii isana ẹlẹẹta ninu ere idaraya, Idije bọọlu ẹlẹyin ori tabili, bọọlu afẹsẹgba, to si jẹ adari akẹkọọ feto ere idaraya.
19 Owewe 2020 Oríṣun àwòrán, Reuters Joe biden ni ọkunrin naa to ta a tan siwaju aarẹ Donald Trump ati saa ọdun mẹrin kan sii to fẹ lo ni Ile nla funfun White House gẹgẹ bi wọn ṣe n pe e lorilẹede Amẹrika.
Ṣugbọn ó dá wọn lóhùn, ó ní, “Kí á má rí i pé mo ṣe ohun tí ó jọ bẹ́ẹ̀.
Awọn ibeji naa, Grace ati Mercy ti iya wọn, Aibekipriye Ebinyefa ni ọkan oun ti lọ lasiko ti wọn n ṣe iṣẹ abẹ naa toripe ẹu n ba oun fun ọjọ iwaju awọn ọmọ oun.
Ni angẹli tí ó ní dòjé náà bá ti dòjé rẹ̀ bọ inú ilé ayé, ó bá kó èso àjàrà ayé jọ, ó dà wọ́n sí ibi ìfúntí ibinu ńlá Ọlọrun.
Ẹ̀bí àti ọ̀rẹ̀ ní mo kó lọ sí Dubai fún ayẹyẹ ọjọ́ ìbí màmá mi - Gbajabiamila Lọpọ aaye ni awọn ilana isinku ti wọn a ma ṣe ni bonkẹlẹ ti gbode kan.
Goolu kẹta latọwọ Harry Maguire lo mu ko di mẹta.
Awọn obinrin Saudi lee ṣere idaraya ita gbangba bayi, wọn si tun ti lẹtọ labẹ ofin lati darapọ mọ ẹgbẹ ologun, eyi ti ko ribẹ tẹlẹri.
Bí ó ti jé̩ pé gbogbo o̩mo̩ Àjo̩‐ìsò̩kan orílè̩‐èdè àgbáyé tún ti te̩nu mó̩ ìpinnu tí wó̩n ti s̩e té̩lè̩ nínú ìwé àdéhùn wo̩n, pé àwo̩n ní ìgbàgbó̩ nínú è̩tó̩ o̩mo̩nìyàn tó jé̩ kò‐s̩eé‐má‐nìí, ìgbàgbó̩ nínú iyì àti è̩ye̩ è̩dá ènìyàn, àti ìgbàgbó̩ nínú ìdó̩gba è̩tó̩ láàrin o̩kùnrin àti obìnrin, tó sì jé̩ pé wó̩n tún ti pinnu láti s̩e ìgbéláruge̩ ìtè̩síwájú àwùjo̩ nínú èyí tí òmìnira ètò ìgbé‐ayé rere è̩dá ti lè gbòòrò sí i,
Silipa ni iranṣẹ tí Labani fún Lea ọmọ rẹ̀ obinrin, gbogbo àwọn ọmọ rẹ̀ jẹ́ mẹrindinlogun.
Àwọn ọmọ Israẹli bá kó gbogbo oriṣa Baali ati ti Aṣitarotu wọn dànù, wọ́n sì ń sin OLUWA nìkan.
Ìyẹn lórí eèpẹ̀ àgbálá ayé wa yìí náà o.
Asoju WHO fun iṣẹlẹ pajawiri Mike Ryan salaye pe iha tuntun ti aarun Coronavirus gbe jade kii se nkan ajoji si ajakalẹ aarun, a ti pe kii se nkan ti oju o riri ki si se pe 'apa o ka' eyi tako ọrọ minisita eto ilera UK Matt Hancock to so pe ọrọ ẹya Coronavirus tun yii ri kọja agbara lọjọ Aiku.
Coronavirus cases in Africa- Atọ́nà bí nkàn ṣe ń lọ ní Afirika Àjọ NCDC tún ti kéde ènìyàn 245 míràn tó ní ààrùn Covid-19 l'órílẹ̀-èdè Nàìjíríà Ọwọ́ tẹ báàlẹ̀, Ṣinkó mẹ́tàdínlógún tó ń jí kùsà wà ní ìpínlẹ̀ Ọ̀ṣun Mo ti tọrọ aṣọ àti yẹtí etí rí, kí n tó leè ṣe àwo orin - Tope Alabi Ìkéde yìí ló gbà gbogbo àgbáyé kan, tí wọn sì ń kan saara sì pe olóòótọ́ èèyàn ni.
Receipt and Other Related Matters Bill, Federal Capital Territory Health
" O wa rọ awọn olori ẹgbẹ osisẹ lati si ri daju pe wọn lo awọn ọrọ ipinlẹ wọn fun anfaani awọn osisẹ ati mọlẹbi wọn.
Sadoku, ọmọ Ahitubu ati Ahimeleki ọmọ Abiatari ni alufaa.
Àwọn ọmọ-ogun bá gé okùn tí wọ́n fi so ọkọ̀ kékeré náà, wọ́n jẹ́ kí ìgbì gbé e lọ.
Kí ó má bá aláàánú pàdé,kí ẹnikẹ́ni má sì ṣàánú àwọn ọmọ rẹ̀ tí wọ́n ti di aláìníbaba.
Oríṣun àwòrán, @GarShehu O ni bi ijọba ti n ṣe agbeyẹwo aba yi, oun rọ awọn oṣisẹ ati awọn asaaju wọn lati ṣe suuru di ọṣẹ to n bọ.
Ẹka ẹkunrẹrẹ rẹ nibi Ọjọ 21,Osu Kẹta Ijọba orilẹede Naijiria se kede wipe mẹrinlelọgọrun(104) ninu aadọfa (110) awọn akẹẹkọ Dapchi ni awọn ajinigbe ti tu silẹ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Mayowa Omoniyi: Kò sí orin Obey, Sunny Ade abí tàkasúfèé tí ń kò le ta gìtá sí Obinrin naa ni wọn yoo si mu ẹẹdẹgbẹta naira to ku pamọ fun itọju ọkọ tori ọjọ iwaju.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Parental Guidance: Ọdún méjì ni kí ẹ ti bẹ̀rẹ̀ kíkọ́ ọmọ nípa ìbálòpọ̀ Eto idibo yii maa n waye fun ọpọlọpọ ọjọ ko to o dipe Poopu tuntun jẹ.
School resumption in Nigeria: Ibi ọ̀rọ̀ dé dúró rèé lórí ṣíṣí àwọn ilé ìwé padà ní Naijira àti nílẹ̀ Afrika
Alaga ikọ Amọtẹkun nipinlẹ Ọyọ fi kun ọrọ rẹ wi pe, ọgbọn iwe nikan kọ ni Amọtẹkun da le lori.
 Koda, oun fúnra rẹ mu agbo naa lasiko ti wọn ṣe ifilọlẹ rẹ, nitori ibẹru pe boya o lewu."
"ni 1814 , agbegbe na je sisodokan gege bi imusin ati alaabo ile naijiria ( "" colony and protectorate of nigeria "" ) ."
Ẹ kò gbọ́ èdè wọn,ẹ kò sì ní mọ ohun tí wọ́n ń sọ.
Oríṣun àwòrán, Aremu Afolayan Àkọlé àwòrán, Aremu Afolayan Nigba ti awọn mejeji si jọ ara wọn bi ẹpa, a maa dija laarin awọn ololufẹ wọn ti awn kan a ni Kunle ni, igun mii a ni Aremu ni.
Nítorí o kò ní gbàgbé mi sí ipò òkú,bẹ́ẹ̀ ni o kò ní jẹ́ kí ẹni tí ó fi tọkàntọkàn sìn ọ́ rí ìdíbàjẹ́.
bii tamuludun, ati eyi taa fojuri, omi, ipese ọrọ̀ fun awọn ara ilu nipasẹ
Sola Kosoko, ẹni to sísọ loju ọrọ yii lasiko to n kopa lori eto BBC Yoruba, tun fikun un pe ọla abata tii mu odo san ni ọrọ oun ninu isẹ tiata.
Ileesẹ kan, Gulf Platform si ti seto bi wọn yoo ti se ayẹyẹ ọjọ ibi agba osere ọhun nilu Dubai.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Odebiyi: ìgbà gbogbo ni Bàbá mi ń polówó iṣẹ́ mi fáráyé Gomina ipinlẹ Eko ni oun ti awọn ara Eko fẹ ni pe, ki awọn ri amusẹ awọn ohun ti oun ti ṣe ileri fun wọn.
Lẹyin iṣẹju mẹrin ni agbabọọlu aringbungbun Granit Xhaka gba goolu keji sawọn fun awọn Gunners.
L'Ọ́jọbọ̀ ni wọ́n sin àwọ́n ologun tí wọn pa l'ágbègbé Birnin gwari nipinlẹ Kaduna tó wà l'áriwá Naìjíríà.
Yemi Oketunji sọ loju opo Twitter rẹ pe, ọrọ alufansa ti Lizzy n sọ si Toyin fi han pe awọn obinrin kii ṣe atilẹyin fun ara wọn.
Bakan naa, ni minisita tun rọ
Olakunle n ṣoju ẹkun idibo Ifo 1 nile igbimọ aṣofin ipinlẹ Ogunti wọn si yan an lai ni alatako kankan.
Oríṣun àwòrán, @HQArmy Àkọlé àwòrán, Bàbá Adamu tó jẹ́ ọmọ ogun Nàìjíríà tó dàgbà jùlọ jáláìsí Aduku nigba aye rẹ sọ fawọn akọroyin pe oun ko deede darapọ mọ awọn ologun Naijiria.
Ifilọlẹ ẹgbẹ alajumọse nipinlẹ Ogun Alápatà lu ìyàwó rẹ̀ pa ní Ogun Ileẹjọ f'ofin de ọdun oro nipinlẹ Ogun Afunrasi afipajinigbe k'agbako ni Ogun O ni oun ko ni da ẹnikẹni ninu adehun ati awọn ileri ti oun ti ṣe ṣaaju idibo.
Oun kan ni ojú rí nínú igbó náà tí ó pani lẹ́rìín púpọ̀.
Lẹ́yìn gbogbo nǹkan wọnyi, Paulu pinnu lọ́kàn rẹ̀ láti gba Masedonia lọ sí Akaya, kí ó wá ti ibẹ̀ lọ sí Jerusalẹmu.
Èyí ni bí wọ́n ṣe n dìbò yan Póópù tuntun nínú ìjọ Àgùdà Ẹ ronúpìwàdà lásíkò ọdún, àti àwọn ìkíni mìrán tó jẹ yọ fún Kérésì Èyí ni ìdí tí Bàbá Kérésì fi máa n wọ aṣọ pupa àti funfun nígbà gbogbo Ìjọba Buhari kò tíì fi akọ̀ròyìn kankan sátìmọ́lé láti ọdún 2015 - Garba Shehu Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Police Brutality: Ojú mi rí tó lọ́wọ́ ọlapàá nítorí Múrí màrùn ún- Adebayo Olaide Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Awọn oluwọde fi ẹsun kan pe MC Oluomo lo ran awọn janduku to lọ ṣe ikọlu si awọn to n wọde ṣugbọn agbẹnusọ MC, Jimoh Buhari ni awọn ko mọ nkankan nipa ikọlu naa.
Eko lati fọẉọ si i, ti yoo fi di ofin amulo.
Apple náà si le wà nínú ẹ̀rọ amòmítutu fún ọdún kan gbáko ti kò ni bàjẹ, yóò si wọ ilẹ̀ Amerika loníì.
Wọn ni ileeṣẹ ijọba to n ri si iṣẹlẹ pajawiri lo ni awọn ajilẹ ati pakopako ti wọn ji ko, kii ṣe ounjẹ.
    Lóòótọ́ náà, iwin inú fìlà yìí bẹ̀rẹ̀ sii wá àwọn ẹnìkejì mi yòókù kiri, o sì ń gbée wọn wá sí ọ̀dọ̀ mi lọ́kọ́ọ̀kan, bẹ́ẹ̀ ló ṣe títí ó fi gbé gbogbo wa tán.
Mo sì gbọ́ ohùn kan láti ọ̀run bí ìró ọpọlọpọ omi ati bí ìgbà tí ààrá líle bá ń sán.
"Wọ́n bi i ni ọjọ kọkandinlógun, oṣù kọkànlá ọdun 1990 wọ́n si bi èmi ni ọjọ kọkàndinlọ́gbọ̀n oṣù kẹwàá ọdun 1990.
Lọjọbọ ni ileeṣẹ agbofinro dubai fi fidio bi wọn ṣe mu gbajugbaja ori ayelujara Instagram naa sita.
Nígbà kan rí, èmi ò kí ń fẹ́ rìn tí ilẹ̀ bá ti ṣú.
N óo bọ́ àjàgà Asiria kúrò lọ́rùn yín, n óo sì já ìdè yín.
Saulu bi í pé, “Kí ló dé tí ìwọ ati ọmọ Jese fi gbìmọ̀ burúkú sí mi?
Njẹ́ ibi orí dáni sí làá gbé.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù LASEMA Lagos: Ọkọ̀ méjì jóná ráùráú níbi tí ọkọ̀ tó gbé bẹntiróò ti gbiná 19 Owewe 2020 Ilẹeṣẹ to n risi ọrọ pajawiri nipinlẹ Eko, LASEMA ti ni ọkọ meji lo jona raurau ni agbegbe Anthony lọ si Gbagada, nipinlẹ Eko lẹyin ti ijamba ọkọ waye.
''O se dandan kí o fí ìwé ẹrí isinlu hàn kí o tó lè gbà iṣẹ.
Ejò lé àwọn aṣòfin ìpínlẹ̀ Ondo kúrò nípàdé Imaamu tó ní mo fẹ́ bá ìyàwó òun sùn ti fẹ́ tẹ́: Oluwo ni ko yẹ kí ààfáà máa sọ̀rọ̀ sí ọba jau jau.
Meje ni awọn obinrin to wa ninu igbimọ naa, ninu eyi ti mẹrin ti wa ni ipo minisita kekere: Sharon Ikeazor (Anambra) - Minisita abẹle fun ọrọ ayika Mariam Katagum (Bauchi) - Minisita Abẹle fun ọrọ ileeṣẹ, idokoowo, ati karakata Gbemisọla Saraki (Kwara) - Minisita abẹle fun igbokegbodo ọkọ Sadiya farouq (Zamfara) - minisita fun iṣẹlẹ pajawiri.
Pààrọ̀ omi ori rẹ fún ìtọ́jú rẹ fún ji jẹ tàbi
Akọwe agba ẹgbẹ YFAN tun fikun ọrọ rẹ pe o yẹ ki ijọba ṣe eto kiko ere oko awọn agbẹ lọ si ibi ti wọn ba ti fẹ ta ọjọ naa.
Gomina ipinlẹ Eko, Akinwumi Ambọde lo buwọlu isuna yii ninu eyi tiẹka isẹ gbogbo ti gba biliọnu mọkanlelaadọjọ naira, eto ọrọ aje ki ọrinlẹrinwo o din meje biliọnu naira.
Mo ti rù láàrin ọ̀sẹ̀ kan, iṣẹ́ Eko kò dẹ́rùn - Sanwo-Olu Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fọ́nrán ohùn, Pius Adesanmi ní Wole Soyinka ìran yìí - ọmọ Naijiríà Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Bakan naa ni ọkọ afẹsọna rẹ sọ pe oun gbiyanju lati doola rẹ, ṣugbọn ẹpa ko boro mọ.
Ṣugbọn lẹyin ti wọn n gbe lọ loju ọna marosẹ Sagamu si Abeokuta, lo ba beere ibi ti wọn n gbe oun lọ, nitori ibi ti wọn dorikọ yatọ si ọna agọ awọn ọtẹlẹmuyẹ ọhun.
Ẹgbẹ oṣelu PDP ni Dino Melaye ba dije to si ti jawe olubori ninu idibo naa to ti tun lọ bẹrẹ iṣẹ nile igbimọ aṣofin agba ni Abuja.
Awọn oṣiṣẹ nipinlẹ Ogun pẹlu atilẹyin awọn alaṣẹ apapọ ẹgbẹ naa lorilẹ-ede Naijiria n leri ati gunle iwọde nitori owo oṣu oṣiṣẹ ati oṣiṣẹfẹyinti nipinlẹ naa eyi ti wọn ni o ti wọ ọdun mẹjọ bayii.
Ni ọjọbọ ọsẹ, iye awn to lugbadi arun Coronavirus ti rekoja Miliọnu kan ṣugbọn awọn akọṣẹmọṣẹ eleto ilera lagbaye tilẹ ni ootọ awọn to ko arun naa ju iye ti wọn n sọọ yii lọ fiifii tori aisi ọna ati ṣe ayẹwo eyi to wọpọ lawọn orilẹede.
Ó ní, “Èmi ni OLUWA, mo ti pè ọ́ ninu òdodo, mo ti di ọwọ́ rẹ mú,mo sì pa ọ́ mọ́.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Arsenal kojú Liverpool ní Emirates Ọpọ ololufẹ ere bọọlu lo wo ifẹsẹwọnsẹ ọhun kaakiri agbaye.
Ogbeni Maada Bio ti o je olori iko -oloogun teleri ti o si daari isakoso orile-ede naa laarin odun 1996 ni o jawe olubori.
Ooni Ile ife, Ààrẹ Gani Adams fárígá lórí ikú ọmọ Fasoranti Kíló burú nínú kí Sanwo-Olu fún Super Eagles lówó?
A óo ta okùn ìwọ̀n odi ìlú títí dé òkè Garebu, ati títí dé Goa pẹlu.
Diezani Alison-Madueke sọ nipa ihuwasi awọn gbajuẹ ati Yahoo-yahoo ni awujọ.
Bakan naa, bi o ti le je pe  jawe olubori pelu ami ayo meta sookan ninu ifesewonse ese keji pelu iko agbaboolu Al Hilal , sugbon iko naa ja kuro ninu idije ohun latari esi ifesewonse akoko, eleyi ti o pari si ami ayo meji sodo.
Gẹ̀ẹ́sì gbẹ́sẹ̀ lé ₦82bn owó Abacha Adolfo Gaich lo gba goolu akọkọ sawọn fun Argentina ki Abdoulaye Diaby to dayo naa pada fun Mali.
 Si quelqu’un vous dit un jour que vos rêves sont trop grands, acquiescez et travaillez plus dur plus intelligemment pour les rendre réalité!
Ẹlẹẹkẹrin si ni ti ọdun 2019 to n waye nilu Abẹokuta, tii ṣe olu ilu ipinlẹ Ogun.
O ni, ijọba apapọ ko ni yi ipinnu rẹ pada lori abadofin naa bo tilẹ jẹ pe awọn ọmọ Naijiria n bu ẹnu ẹtẹ lu ijọba nitori ọrọ ọhun.
Ọdọ baba iya rẹ to jẹ onifa, ni Hubert gbe fun igba kan, eyi to mu ko mọ nipa Ifa, Ogun atawọn orisa abalaye miran Oríṣun àwòrán, @hubertogunde Ogunde sisẹ lẹyin to pari iwe mẹfa rẹ tan bii olukọ ile ẹkọ alakọbẹrẹ, ọga akọrin ni sọọsi ati atẹduru Ẹgbẹ Eegun Alarinjo lo fi bẹrẹ isẹ tiata, ko to dara pọ mọ isẹ ọlọpaa, o si de ipo Kọsitebu, ko to fẹyinti Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Iná PHCN tó dé lójijì ṣàkóbá ńlá ní Ibadan Oun lo kọkọ mu ere tiata wọ inu ẹgbẹ alarinjo, eyi to sọ di oludasilẹ ere tiata Lara awọn ere onise to se ni ‘Human Parasites’, eyi to fi n tako iwa sisare lati ra asọ ẹbi olowo iyebiye tii se ara ara Yoruba Ogunde jẹ ajijagbara fun iran Yoruba ati Naijiria, lati ipasẹ ọpọ ere to se fi tako awọn oyinbo amunisin.
Amọ, Aṣojusofin, Akin Alabi ti fi abadofin sita ni ile igbimọ asọjusofin lorilẹede Naijiria ti yoo fi opin si ofin naa.
5%) ninu awọn ẹgbẹrun lọna ọgbọn (30,000) to lo abẹrẹ ajẹsara ti wọn lo bọ lọwọ arun COVID-19.
Tollgate Fee: Ìjọba ní Naijiria yóò padà sí ní san owó 'tollgate Oríṣun àwòrán, OTHERS Àkọlé àwòrán, Ìjọba ní ìgbésẹ̀ náà pọn dandan láti pa owó wọlé fún ìjọba láti tún àwọn òpópónà se fún ìmúgbòòrò.
Ki i ṣe ìyànjú burúkú ni eyi ṣùgbọ́n, “ọ̀rọ̀ kò dùn lẹ́nu olè”,  kì í ṣe lati ẹnu àwọn Òṣèlú ti ẹnu wọn ti fẹ si ọjà òkèrè nitori wọn ti kó owó ilú pamọ́ si àwọn ilú Òkè-Òkun.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Tope Alabi, Ron Kenolly àtàwọn míì yóò kọrin níbi ọjọ́ ìbí àṣẹ̀yìndè fún olóògbé Ighodalo lónìí 15 Òkùdu 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 18 Agẹmo 2020 Oríṣun àwòrán, Topealabi Olorin kan lo kọrin pe bi a ba n jẹ, bi a ba n mu, bi a ba n fitan ewurẹ jẹ'ka o, ka ma gbagbe pe atipo o la jẹ laye o."
Àwọn ọmọ Israẹli dáhùn pé, “Ìlọ́po mẹ́wàá ẹ̀tọ́ tí ẹ ní sí ọba ni àwa ní, kì báà tilẹ̀ jẹ́ pé ọ̀kan náà ni yín.
Liigi orilẹede Faranse: awọn alaṣẹ liigi lorilẹede Faranse n boju wo aarin ọjọ kẹta si ọjọ kẹtadinlogun oṣu kẹfa gẹgẹ bii ọjs ti wọn yoo bẹrẹ owo bọọlu gbigba pada lorilẹede naa.
Kọmisana ileeṣẹ ọlọpaa ipinlẹ Ogun, Bashir Makama sọ pe ko si ohun kan to ṣe awọn eeyan naa nigba tawọn ọlọpaa doola ẹmi wọn.
” (Ìtumọ̀, “Imanuẹli” ni “Ọlọrun wà pẹlu wa.
''Dean of Defence'' ''Mathematical Odegbami'' ''Chairman Chrsitian Chukwu'' ati ''Elastic Elahor'' wa lara awọn orukọ to fi n ṣapejuwe awọn agbabọọlu lori papa.
Baṣọ̀run Gáà, tó yan ọba mẹ́rin, pa ọba mẹ́rin àmọ́ ọba karùn-ún ló pa á Ọ̀rọ̀ǹpọ̀tọ̀niyùn, Aláàfin obìnrin àkọ́kọ́ rèé, tó ní nǹkan ọkùnrin Àwọn onímọ̀ Islam àti Oluwo takora lórí oyè Wàzírì Eyi waye pẹ̀lú àtilẹ̀yin àwọn orilẹede bii Amẹríkà, ilẹ̀ Gẹ̀ẹ́sì, Swedish, Danish àti ijọba Norway, lọna áti fí òpin si ìṣèjọba ológun ní Nàìjíríà pada, sí Radio Kudirat.
O ni gbogbo ẹka ijọba mẹtẹẹta lo jọ n ṣiṣẹ pọ ni Ipinlẹ Eko lati fi apẹẹrẹ iṣejọba rere lẹlẹ paapaa fun ijọba oṣelu tiwantiwa pẹlu iṣẹ idagbasoke ilu  loriṣiriṣi.
Wọn ni yala ko fara mọ awọn ilana ti ijọba fun un tabi ki wọn daa pada sorilẹede Naijiria, amọ o dabi ẹni pe anfani keji ni El-Zakzaky nawọ mu.
Mo mọ̀ pé àwọn aṣòfin máa ṣatìlẹyìn tó yẹ fún mi- Boris Iṣẹ́ ti bẹ̀rẹ̀ lórí àfikún owó oṣù tuntun- Keyamo Ajọ to n mojuto iṣẹlẹ pajawiri ni Ghana, National Disaster Management Organisation ti berẹ si ni pin awọn ohun eelo fawọn ti omiyale le kuro nile.
Ewe, orile-ede Amerika kede lojo Eti(Friday) pe, Oun ti sekilo o ni kaan-pa fun North Korea lati jawo lori sise ifilole eto ohun ija oloro naa.
EFCC sọ èyí di mímọ lásìkò tí wọ́n ń ba àwọn akọroyin sọ̀rọ̀ ní ìlú Benin ti ṣe olúlu ìpínlẹ̀ Edo, ọgbẹ́ni Muhtar Bello to n soju fun adele ajọ EFCC, Ibrahim Magu sàlàyé pe àwọn kò ni sọ orukọ ọmọbinrin náà nítori ìwádìí ṣì ń lọ lọ́wọ́.
‘Ò dà bí àlá bí mọ ṣe da ìlúmọ̀ọ́ka nítorí bí a ṣe ń gbé òkú jó ní Ghana’ 'Ìnira ńlá ni coronavirus mú bá èmi àtàwọn ọmọ mi gẹ́gẹ́bí opó tó fọ́jú' O sàn ká wà láyé láì lówó lọ́wọ́ ju ká ya sinimá, ká kó Coronavirus lọ - Latin pariwo fáwọn òṣèré tíátà Ẹ wo ọ̀nà tí àwọn èniyàn ń gbà rí oúnjẹ̀ jẹ lásìkò àrùn Coronavirus Èyí tí a wò jùlọ 5:19 Fídíò, Nigeria Car Innovator: Olatunde Ibitoye ní ọdún mẹ́ta ní òun fi ṣe ọkọ̀ náà torí ọ̀dá owó, Duration 5,1911 Sẹ́rẹ́ 2021 4:49 Fídíò, LASU Best Graduating Student: Wákàtí kan péré ni mo fi ń kàwé lójúmọ́, èmi kìí ṣe igi ìwé, Duration 4,4912 Sẹ́rẹ́ 2021 6:16 Fídíò, Omoniyi and Elizabeth Oke Blind Couple in Ado-Ekiti: Tọkọ-taya Oke ní Ọ́ba òkè ló fi àwọn dá àrà tó wù ú, Duration 6,1615 Sẹ́rẹ́ 2021 Gbọ́, Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kanwákàtí kan sẹ́yìn 7:40 Fídíò, Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo, Duration 7,4018 Èbibi 2020 5:13 Fídíò, Stem Cell treatment: Àrùn tó lé ní 80 ni àwọn onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó leè fi ìwọ́ àti olubi, Duration 5,134 Sẹ́rẹ́ 2021 8:00 Fídíò, Florence Onwuasoanya: Mo jẹ́ àsejẹ, mo mu àgbo tí kò ṣe e fẹnu sọ kí ń lè gbé ọmọ jó ṣùgbọn.
Sibẹ gbogbo ará Jerusalẹmu ni ó ti gbọ́ nípa ẹ̀kọ́ yín yìí.
O gba ọpọlọpọ ìjọba ati ọ̀pọ̀ orílẹ̀-èdè fún wọn, o sì fi ibi gbogbo fún wọn.
Bákan náà, ààrẹ tún buwọ́lu àbádòfin mẹ́rin gẹ́gẹ́ bíi àtúnṣe iwé òfin ọdún 1999.
A sì ti fi àáké lé gbòǹgbò igi báyìí, nítorí náà, igikígi tí kò bá so èso rere ni a óo gé lulẹ̀, tí a óo fi dáná.
Orukọ ọjọgbọn yi a ma jẹ Ayodele Oluwatuminu Awojobi.
Nígbà náà ni iná jó àwọn aadọta leerugba (250) ọkunrin tí wọn tẹ̀lé Kora, wọ́n sì di ohun ìkìlọ̀ fún àwọn ọmọ Israẹli.
Iru eyi ko ṣẹlẹ ri ni aafin naa, nitori pe ibeji tabi ọmọ ẹyọ kan ni awọn olori maa n bi latẹyinwa.
Gomina Seyi Makinde ipinlẹ Oyo lo ṣeleri bẹẹ nigba to ṣabẹwo si olu ileeṣẹ ọlọpaa ipinlẹ naa to wa niluu Ibadan lọjọ Aje.
 Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Makinde vs Adelabu: Makinde ní ìjọba Ọyọ yàtọ̀ sí ti Ọṣun àbí Ekiti tí APC lé dànù Adelabu fikun pe nibayi ti ile ẹjọ Kotẹmilọrun ti se ayipada ohun ti ko dara naa si rere, mo rọ awọn eeyan ipinlẹ Ọyọ lati gba laafia laaye, ki wọn si maa ba isẹ to ba ofin mu ti wọn n se lọ nibayi ti a n lọ sile ẹjọ Kotẹmilọrun lati gba isẹgun wa.
Nítorí náà, ẹni tí ó bá kọ ọ̀rọ̀ yìí, kì í ṣe ọ̀rọ̀ eniyan ni ó kọ̀ bíkòṣe Ọlọrun tí ó fi Ẹ̀mí Mímọ́ rẹ̀ fun yín.
Igbagbọ ẹgba naa ni wi pe igbẹsẹ lati dẹkun iwa ibajẹ naa yoo yan kankan ti ijọba ba bẹrẹ sini ṣe idajọ iku fun ẹnikẹni ti wọn ba gbamu.
Oríṣun àwòrán, ABS Àkọlé àwòrán, Opin ọsẹ yii ni wọn sin Anthony Obiagbaoso Enukeme nilu rẹ, Neni tilu tifọn pẹlu posi olowo iyebiye ti wọn lo to miliọnu mẹrinlelọgbọn naira Oríṣun àwòrán, ABS Àkọlé àwòrán, Ọjọ kẹsan osu Kẹfa ọdun 2020 ni Anthony Obiagbaoso Enukeme jade laye, ti wọn si sin lọjọ Ẹt, ọjọ Kẹrinla osu kẹjọ ọdun 2020 tilu tifọn Oríṣun àwòrán, ABS Àkọlé àwòrán, Anthony Obiagbaoso Enukeme ni wọn se ayẹyẹ isisnku ọlọjọ meji fun, eyi to dun, to si larinrin Oríṣun àwòrán, ABS Àkọlé àwòrán, Anthony Obiagbaoso Enukeme jade laye lẹni ọdun mẹrindinlọgọrin lawọn ara ilu rẹ fẹran rẹ tori o maa n ko awọn olokoowo wa dale isẹ silẹ milu abinibi rẹ.
Temitope Akinnusi: Ọ̀pọ̀ iléeṣẹ́ ló takú láti gbà mí síṣẹ́ torí mo ní ojú kan
“Bí o bá ṣe ibi, tí o kọ OLUWA sílẹ̀, ninu gbogbo nǹkan tí o bá dáwọ́ lé, èmi OLUWA yóo da ègún lé ọ lórí, n óo sì mú ìdàrúdàpọ̀ ati wahala bá ọ, títí tí o óo fi parun patapata, láìpẹ́, láìjìnnà.
Ṣugbọn ní ọdún karun-un, ẹ lè jẹ èso wọn, kí wọ́n lè máa so sí i lọpọlọpọ.
padanu ifesewonse olorejore ti won gba pelu orile-ede Saudi Arabia niluu Vienna,lorile-ede
Eyi o sàlàye pe yóò ma ràn wan lọ́wọ́ láti moju to ọjọ iwáju wọ́n, ti a ba si ri ẹni to ṣe àisan, o le gba nínú owó náà láti toju ara rẹ.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Ija nla kan ṣẹlẹ lọdun 1981 ti awọn sọja to n gbaruku ti ọkan larra awọn ẹgbẹ apani kan ṣekupa aarẹ Sadat lasiko yiyan bi ologun ti wọn fi ṣe ayẹyẹ iṣẹgun rẹ nigba ogun Arab ati Isreal lọdun 1973.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Coronavirus in Nigeria: Èèyàn mẹjọ míràn tún ti ní àrùn Coronavirus ní Naijira 25 Ẹrẹ̀nà 2020 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 29 Ẹrẹ̀nà 2020 Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Nibayii, o ti di eeyan mẹtadinlọgọrun un (97) to ti ni aarun naa lorilẹede Naijiria.
Ìpínlẹ̀ Eko ní èèyàn 136 nínú èèyàn 152 lápapọ̀ tó lùgbàdì àrùn Coronavirus ní Nàìjíríà Ọlọ́pàá fìyà jẹ mí lọ́dún 2014, mò wà lẹ́yìn àwọn ọ̀dọ́ lórí ìwọde EndSARS- Fayemi Awọn ọlọ́pàá gbòde kan ní Ajah, ọwọ́ tẹ àwọn afurasi tó ń jalè Iléeṣẹ́ ológun ní ó bàwọn lọ́kàn jẹ́ bí Sanwo-Olu ṣe ni kìí se òun ló pe sójà si Lekki Wo ohun mẹ́wàá tó yẹ kóo mọ̀ nípá ọmọ ọdún mẹ́wàá Emmanuella tó kọ́ ilé ńlá fún ìyá rẹ̀ Lasiko ti ẹgbẹ tuntun naa n sọrọ lori ipo ti Ọjọgbọn Banji Akintoye wa gẹgẹ bi '' Adari ni ilẹ Yoruba, wọn ni Akintoye ti yọ ara rẹ kuro ninu ẹgbẹ ọmọ Yoruba nitori naa ki i se adari wọn mọ.
Ó bèèrè bí ogun ti ń lọ sí.
Lati asiko yii ni awọn eniyan Kano ti n bẹru pe ki ọrọ wọn ma lọ dabi ohun to n ṣẹlẹ ni Amerika pẹlu awọn agbebọn ainidi.
Àwọn olùtọ́jú wọn bá sálọ sí àwọn ìlú ati àwọn abúlé tí ó wà yíká láti ròyìn ohun tí ó ṣẹlẹ̀.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Jiti Ogunye: Ẹgbẹ Musulumi Sunni ni ijọba Naijiria lọwọlọwọ!
Shina Rambo: Ọmọ Sọ́jà tó di adigunjalè tíí fi ahọn eeyan 100 mu ẹ̀kọ tó wá di Mathew Oluwafemi tó ń gbé Bíbélì
Eyi tun maa n jẹ ki agbara adun ibalopọ pọ sii ni eyi ti iwadii fihan pe diẹ lo wa ninu ṣokoleeti.
Nígbà tí ó tú wọn ká tán, ó gun orí òkè lọ gbadura, òun nìkan.
Àgbà toní o ó dà lo dàyìí
Ipo Kẹrin: Ẹka eto Ọgbin: Ẹka eto ọgbin lo se ipo kẹrin ninu eto isuna ti gomina Seyi Makinde gbe kalẹ lọjọru pẹlu ida mẹrinlelogoji ati diẹ, 44.
Awọn miran ti ẹ tun hu iroyin kan to jade lọdun 2017 sita, nibi ti awọn ọmọ Fadeyi ti pariwo sita pe, ki Toke fi baba wọn lọrun silẹ.
Awọn kan si ti sa kuro ni ila Gusu lorile ede Naijiria nitori ile gbigbona.
Eeyan mọkandinlaadọrin ni wọn tun kede pẹlu aarun naa lọjọ Abamẹta.
Aṣiri to tu yii ti mu ki awọn alaṣẹ fasiti mejeeji ni ki awọn olukọ naa lọ rọọkun nile.
Bakan naa lo jẹ oludari agba fun ẹka awọn alamojuto ni ile ifowopamọ United Bank for Africa, UBA, ko to di pe o di ọga patapata.
o ka iwe akọsilẹ nipa ti oludije naa, ni ko si ohun to buru ki oludari omo ẹgbẹ
N óo le yín jáde; ẹ óo sì ṣègbé.
Ẹwẹ, ẹgbẹ Yoruba, Afẹnifẹre pẹlu ti ke si Aarẹ Buhari pe ko ṣe iṣe agba to n tole nigba yiyanju ọrọ naa ni kiakia.
Dókítà - BBC News Yorùbá BBC News, YorùbáFò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ẹ pèsè 'pad' ọ̀fẹ́ fáwọn obìnrin láti ṣe nǹkan oṣù dípò 'condom' ọ̀fẹ́ - Dókítà 30 Èbibi 2020 Oríṣun àwòrán, Getty Images Onimọ kan nipa isegun oyinbo, Dokita Olufisayo Ogunbayo ti sísọ loju rẹ pe, kii ṣe oju ara nikan ni awọn obinrin ti maa n ṣe nnkan oṣu, amọ awọn obìnrin miran n ṣe e lati imu abi idodo eyi ti ko wọpọ.
Òbúkọ náà bẹ̀rẹ̀ sí tóbi sí i, ṣugbọn nígbà tí agbára rẹ̀ dé góńgó, ìwo ńlá iwájú rẹ̀ bá kán.
Gamalieli ọmọ Pedasuri ni olórí ẹ̀yà Manase.
Àwọn ará Siria láti ìhà ìlà oòrùn,ati àwọn ará Filistia láti ìhà ìwọ̀ oòrùn;wọn óo gbé Israẹli mì.
Kẹ̀kẹ́ bàbá ìyàwó mi lo tẹ̀lé ti ìyàwó mi, kẹ̀kẹ́ fàdákà ni, òun náà lẹ́wà gidigidi.
so pe “iko omo ogun kaarun ti  16 Brigade mu awon janduku  màrúndínlógún,
Naijiria, South Africa ati Cameroon ni orilẹ-ede mẹta to maa ṣoju ilẹ Adulawọ lapapọ.
18 Hours – Njue Kevin – Kenya
 o je didiboyan ni idiboyan odun 2008 .
Ọmọ tuntun gba ominira lẹyin ti wọn san owo itọju rẹ ni Gabon
Nítorí náà, ẹ yipada nípa agbára Ọlọrun yín, ẹ di ìfẹ́ ati ìdájọ́ òdodo mú, kí ẹ sì dúró de Ọlọrun yín nígbà gbogbo.
Nigba to n mẹnu ba iru ijiya to tọ si ẹni to ba rufin yii, Olabiwonninu sọ wi pe, ijiya to rọ mọ riru ofin to de bi wọn ṣe n lo ilẹ ijọba yatọ ni agbegbe kan si omiran.
Orí àwọn ẹran ọ̀sìn ati mààlúù ni àwọn oriṣa wọn wà.
Ibrahim Ijaọla @ijaola_ibrahim ti wi, ó yẹ kí OBJ, IBB àti GEJ máa gbáradì nítorí ikú tó ń pa ojúgbà ẹni, òwe ńla ló ń pa fún ni.
Marundinlogoji ni wọn ṣi n wa kaakiri bayii.
Yan eniyan ṣọ́ ibi ààbò;máa ṣọ́nà, di àmùrè rẹ,kí o sì múra ogun.
Ninu ọrọ tirẹ, kọmisana ajọ ọlọpaa nipinlẹ Ọyọ, Joe Nwachukwu Enwonwu ṣe alaye fun awọn oniroyin pe aaye ti ko si ni ọgba ẹwọn lo jẹ ki wọn fi Sunday pa mọ si agọ ọlọpaa kan ni Mọkọla.
Kí Oluwa san ẹ̀san fún un gẹ́gẹ́ bí iṣẹ́ rẹ̀.
Kábiyèsi, Ọba Aláyélúà, wo kú ori ire o
Ẹ wá wo àwọn eniyan mi!
Ọbasanjọ ni ọmọ òrùkàn tó di olóri orílẹ̀èdè lẹ́ẹ̀mẹ́ta ọ̀tọ̀ọ̀tọ̀ Kìnìún tí wọn ń sìn yarí, ó pa olówó ati ọmọ olówó rẹ̀ Èmi àti Ọbasanjọ leè yapa nínú òṣèlú, àmọ́ mo ń bọ̀wọ̀ gidi fun - Buhari Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Seyi Makinde: Màá fẹ́ káwọn aráàlú mọ ìpa ìjọba mi lára sí rere Ọmọ ọdun mọkanlelogun naa, to da ile isẹ rẹ Kylie Cosmetics silẹ ni bi ọdun mẹta sẹhin, ti ni ere to to miliọnu lọna ọtalelọọdunrun dọla ni ọdun to kọja.
Mama Rainbow: Toyin Adegbola àti Razak Olayiwola ní ìyá rere àti àwòkọ́ṣe gidi ní
Sibẹsibẹ, kò jẹ́ nǹkankan lójú rẹ, OLUWA Ọlọrun, o ti ṣèlérí fún èmi iranṣẹ rẹ nípa arọmọdọmọ mi, nípa ọjọ́ iwájú, o sì ti fihàn.
N óo dáná sun Ijipti, Pelusiumu yóo sì wà ninu ìrora ńlá.
Lẹyin ayẹwo loju aṣoju ẹni to ni i ni wọn ti ri beeli aṣọ ogun mọkanla ti ọkọọkan si ni irinwo aṣọ ogun ti wọn ti ran silẹ.
Awọn mejeeji ni wọn ti jọ n tukọ ipinlẹ Kogi naa papọ lẹyin ti Yahaya Bello ti fa Onoja kalẹ gẹgẹ bi igabkeji rẹ tẹlẹ.
Bẹ́ẹ̀ gẹ́gẹ́ ni kí ẹ ṣe.
O ni 'bi ẹẹmẹta nijọba ti kọ lẹta si i, sugbọn ti wọn ko dahun.
 wọ ́ n tún nífẹ ̀ ẹ ́ si òwò síse .
Ọpọlọpọ lo ti n ranṣẹ ikini ku oririre si awọn ọmọbinrin Naijiria yii ti wọn fakọyọ, koda ajọ to n ri si ere bọọlu afẹsẹgba lorilẹede Naijiria gan NFF ko gbẹyin.
Mo dákẹ́, n ò sọ nǹkankan;n ò tilẹ̀ dá sí ọ̀rọ̀ rere pàápàá;sibẹ ìpọ́njú mi ń pọ̀ sí i
Wọn a ma se ikun ni imu, eleyii ti o le jasi iku fun wọn.
Kiní ọ̀hún a máa wù’yàn jẹ o jàre.
Kí ló dé tí OLUWA fi ń mú wa lọ sí ilẹ̀ náà kí àwọn ọ̀tá wa lè pa wá, kí wọ́n sì kó àwọn aya ati àwọn ọmọ wa lẹ́rú.
Inec ni niwọn igba to jẹ pe ibi taa ba pe ni ori, ẹnikan kii fi ibẹ tẹlẹ, idi ree ti eto ipolongo ibo aarẹ ati tawọn asofin yoo fi side eto ipolongo ibo naa, eyiti o ti gberasọ lọjọ Aiku.
Ní ọjọ́ kan, Adonija fi ọpọlọpọ aguntan, pẹlu akọ mààlúù, ati àbọ́pa mààlúù rúbọ níbi Àpáta Ejò, lẹ́bàá orísun Enrogeli, ó sì pe àwọn ọmọ ọba yòókù, àwọn arakunrin rẹ̀, ati gbogbo àwọn òṣìṣẹ́ ọba ní ilẹ̀ Juda.
Nígbà tí wọ́n dé Mara, wọn kò lè mu omi tí wọ́n rí níbẹ̀, nítorí pé ó korò.
Ní ọjọ́ náà, OLUWA yóo dáàbò bo àwọn tí wọn ń gbé Jerusalẹmu, ẹni tí ó ṣe aláìlera jùlọ ninu wọn yóo lágbára bíi Dafidi.
PRESS RELEASENIGERIAN ARMY SUSTAINS VICTORY AGAINST BOKO HARAM TERRORISTS, Kills 27, Recovers Arms & Ammunitionhttps://t.
Àwọn akẹgbẹ́ ẹ̀ṣọ́ àjọ FRSC mẹ́ta tí àrá sán pa l'Ogun gbọdọ̀ ṣ'ètùtù- Elebubọn Àwọn ohun tuntun tí a mọ̀ nípa ìgbẹ́jọ́ Wòlíì Sotitobire Ṣé lóòtọ́ ni Sẹ́netọ̀ Bayo Osinowo ní ìfura ikú ara rẹ̀?
Àwọn àtúnṣe tuntun nínú àwọn ojúewé tójápọ̀ láti inú ojúewé yìí
O n lo bi edegberin awon ile-ijosin ti won ti wa ni titipa bayii, latari pe, won kuna lati tele ofin ijoba.
Sùgbọ́n nígbà tí àwọn jagun-jagun ṣe àgbéyẹ̀wò rẹ̀, wọ́n kọ̀ọ́.
Ọlọrun fi òpin sí igbe kinniun,ati bíbú tí kinniun ń bú ramúramù,ó sì wọ́ àwọn ẹgbọ̀rọ̀ kinniun léyín.
Bí ẹni tí ń gbẹ̀san ẹ̀bi ẹ̀jẹ̀ bá ń lé e bọ̀, wọn kò ní fi lé e lọ́wọ́, nítorí pé ó ṣèèṣì pa aládùúgbò rẹ̀ ni, kò sì ní ìkùnsínú sí i tẹ́lẹ̀.
Ìgbéyawó yìí lárinrin Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Kete ti fidio yii jade lawọn eniyan ti ni ko ṣẹyin awọn ọmọ ogun Cameroon ṣugbọn ijọba wọn ni irọ ni.
"Sextuplet: Àdúrà Ìbùkún ló kú lẹ́yìn ọmọ mẹ́fà yìí- Ifeoma Thelma àti Onyemaechi Chiaka Joe Biden kéde Kamala Harris, obìnrin aláwọ̀ dúdú gẹ́gẹ́ bí igbákejì rẹ̀ nínú ìdíje sípò Ààrẹ Amẹrika Wo ìdí tí Risikat Moromoke Azeez n'Ilorin fi ní ""Blue Eyes"" - Dókítà NCDC kéde èèyàn 423 míràn tó ṣẹ̀ṣẹ̀ lùgbàdì Covid-19 ní Nàìjíríà, 263 gbàwòsàn Awọn ileewe to ti bẹrẹ si ni ta fọọmu re e: Bayero University, Kano ni iforukọsilẹ idanwo Post UTME ti saa 2020/2021 yoo bẹrẹ ni Ọjọ Kẹta, Oṣu Kẹjọ, ọdun 2020."
Inú rẹ̀ ń ru, nítorí ó mọ̀ pé ìgbà díẹ̀ ni ó kù fún òun.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Oby Ezekwesili yan Ganiyu Galadima, gẹ́gẹ́ bíi igbákejì rẹ̀ Kílódé tí ọlọ́pàá fi mú ajàfẹ́tọ̀ọ́, Deji Adeyanju àtàwọn méjì l'Abuja?
Eto naa gba ilana kan naa pẹlu Claritta.
12) Tajudeen Audu -ó yọwọ́ pé òun kò ṣe mọ́.
Alaye olukọ pọ lori Silebu, ẹ wa nnkan fidi le lati kẹkọọ siwaju nipa ege ọrọ, taa mọ si Silebu yii.
idagbasoke lee ba ina mona-mona lorile ede Naijiria.
Fadele rọ gbogbo ènìyàn láti bẹ̀rẹ̀ igbesẹ lori ohunkohun to wu wọn lati ṣe si daadaa nitori kò si ohun tuntun labẹ ọ̀run mọ́.
Nígbà tí Paulu ń dúró dè wọ́n ní Atẹni, ó rí ìlú náà bí ó ti kún fún ère oriṣa.
Yóo ranṣẹ láti ọ̀run wá, yóo gbà mí là,yóo dójú ti àwọn tí ń lépa ẹ̀mí mi.
Ohun ti awọn asofin agba miran tun sọ Sẹnatọ Clifford Ordia.
Ṣugbọn ó dá wọn lóhùn pé, “Ẹ má wulẹ̀ dá mi dúró mọ́, níwọ̀n ìgbà tí OLUWA ti ṣe ọ̀nà mi ní rere, ẹ jẹ́ kí n lọ bá oluwa mi.
Koda, Awọn ase ibudo lọṣọ atawọn ohun eelo ikọrin gan ti wa nikalẹ fun ayẹyẹ ibura naa.
Kò sí ọ̀nà láti jáde tàbí wọlé sí Mali, ikọ̀ ológun ọlọ́tẹ̀ kéde ìṣéde Oríṣun àwòrán, Others Awọn ologun to ditẹ gbajọba ni orilẹede Mali ti kede lọjọru pe oun ti gbe igbimọ kan kalẹ, CNSP, ti yoo seto idibo mii lẹyin ti aarẹ Boubacar Keita kọwe fi ipo silẹ.
Agbaoye Alabi fí kun pé, lẹ́yìn ti oun tún pari ilé iwé , ore-ofẹ́ tún yọ láti le jọ ṣiṣẹ́ papọ tí o si fún oun ni ànfani láti le kọ ẹkọ bi ènìyàn ṣe le ṣe iṣẹ́ ìròyìn bo ti tọ́ àti bi o ti yẹ.
Amọ, awọn ọdọ lorilẹede Naijira ni irọ ni igbeṣẹ ijọba, nitorinaa awọn kọ ikọ SWAT kaakiri Naijiria.
O kò ní ṣi ilé wọ̀,’ ni ìyá wa àgbà kan kí mi.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Iriri ilẹ Okere Wọn lọ ẹsun kan mọ Biden lẹsẹ to tan kaakiri agbaye gẹgẹ bo ṣe jẹ pe lara iriri to ni ni nipa ọrọ ilẹ okere.
@seyi_amakinde jọ mi loju, o ya mi lẹnu.
Ìtàn Gbọnka àti Timi, akọni méjì tó borí Aláàfin Ṣango Òkè Idanre rèé tí odidi ìlú kan ló ń gbé lórí ẹ̀ Lisabi Agbongbo Akala rèé, ẹni tó fi ìfẹ́, ìṣọ̀kan àti ìrẹ́pọ̀ gba ilẹ̀ Ẹ̀gbá lọ́wọ́ ìmúnisìn Lara awọn sawawu baba naa ti wọn jọ jẹ eegun sonso tii pari ike lagbo oselu ninu ẹgbẹ ọlọpẹ nigba naa ni Abiọdun Akerele, Ade Akinsanya, J.
Ó fọ àwọn nǹkan inú rẹ̀, ati ẹsẹ̀ rẹ̀, ó sì sun wọ́n papọ̀ pẹlu ẹbọ sísun lórí pẹpẹ.
Nígbà tí gbogbo àwọn eniyan tí wọ́n wà lọ́dọ̀ Iṣimaeli rí Johanani, ọmọ Karea ati gbogbo àwọn olórí ogun tí wọ́n wà pẹlu rẹ̀, inú wọn dùn.
Ẹ tọ́jú iṣẹ́ yín dáadáa, ohun tí ó ṣe pàtàkì ni ibi tí a bá ti ń rí òkèlè ẹni.
Oríṣun àwòrán, Tiyamiyu Kazeem Gẹgẹ bi atẹjade naa ṣe sọ, lẹyin eyii ni awọn ọlọpaa naa duro, ti wọn si tii jade ninu ọkọ wọn, eyi to mu ki ọkọ mii to n bọ kọlu, to si gba ibẹ jẹ Ọlọrun nipe.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Akure Kidnap: Àwọn abiyamọ fẹ̀hónúhàn lórí ọmọ tí wan jígbé nílé ìjọsìn Akurẹ Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?
Ọmọ Yoruba ni Amusan, orukọ iyawo rẹ si ni Ayo Amusan.
Bẹ́ẹ̀ gan-an ni ẹ sì ń ṣe sí gbogbo àwọn onigbagbọ ní gbogbo Masedonia.
Akin Olúṣínà Òun ni wọ́n máa ń pè ní Akin Ọlófìn-íntótó, ọmọ Olúṣínà.
Ẹnikan to n gbe ni adugbo kan naa pẹlu wọn, Ibidunni Adegoke, sọ fun iwe iroyin abẹle pe Adekunle koju Stanley, nigba ti wọn ri ara wọn ni alẹ.
Wọn óo mú ọba Betedeni lọ sí ìgbèkùn; òun ati àwọn ará Siria yóo lọ sí ìgbèkùn ní ilẹ̀ Kiri.
Gẹgẹ bi atẹjade kan ti ajọ to n gbogun ti ajakalẹ aarun lorilẹede Naijiria, NCDC fi sita loju opo Twitter rẹ lalẹ Ọjọbọ, eeyan mẹfa miran lo kun iye awọn eeyan to ku nipaṣẹ aarun naa lẹyin ti o ti kọkọ gbee sita pẹlu ni Ọjọru pe eeyan marun miran ku.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, ọ̀gá ọlọ́pàá sọ̀rọ̀ lórí SARS Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, SARS ti bẹ̀rẹ̀ ìgbésẹ̀ láti yọ àwọn ọ̀bàyéjẹ́ kúro Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Àwọn àwòrán mánigbàgbé nípa ìdìbò abẹnu nipinlẹ Osun Ìpolongo fífòpin sí SARS ti lágbára si Jàǹdùkú yìnbọ́n pa alága PDP kan l‘Èkó ‘A ó rántí Ààrẹ Buhari fún ìtàjẹ̀sílẹ̀ lásìkò rẹ̀’ Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
" Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Kogi vs Bayelsa: Primate Ayodele sọ àsọtẹ́lẹ̀ Wolii Ayodele fikun pe igbesẹ naa le fa rogbodiyan lọdun 2023, eyi ti yoo buru pupọ ju awọn iriri laasigbo ti Naijiria ti foju wina rẹ sẹyin lọ.
Kìí ṣe ẹ̀bi wa pé ètò ìsìnkú Abiola Ajimobi falẹ̀ - ìjọba ìpínlè Oyo O ni Lara awọn ẹṣọ to wa lẹnu ọna lo sọ fun awọn eeyan wa pe, ka ma tilẹ jade kuro ninu ọkọ wa nitori wọn ko ni ṣilẹkun fun wa."
Láti inú ni gbogbo àwọn nǹkan ibi wọnyi ti ń wá, àwọn ni ó ń sọ eniyan di aláìmọ́.
 Ìlú ilẹ ́ ṣà ti ó jẹ ́ olú ìlú fun gbogbo ilẹ ̀ jẹ ̀ ṣà jẹ ́ nǹkan ibùsọ ̀ mẹ ́ rìnléláàádọ ́ rin sí ìlú Ìbàdàn tí jẹ ́ olú ìlú ìpínlẹ ̀ Ọ ̀ yọ ́ .
Ọọni Ile Ife Oríṣun àwòrán, Ooni of Ife Kẹti kẹti ni ilu Ile Ife lasiko ti Ooni tuntun, Oba Adeyeye Ojaja II ṣe iwuye gẹgẹ bii Ọọni ikọkanlelaadọta ti Ile Ife.
Loju awọn eniyan miran, ijọba Naijiria ko bọwọ fun ofin to ni.
2m ọmọdé kò ṣe lọ sílé ẹ̀kọ́ - SERAP ké tọ iléẹjọ́ àgbáyé Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Dele Momodu : Lẹ́yìn Buhari àti Atiku, èrò ọjà làwọn olùdíje yóòkù ní ìdìbò 2019 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Ológun mìíràn tí orí kó yọ lálẹ́ ọjọ́ burúkú yìí tiraka gba France lọ fún ìtọ́jú lẹ́yìn tí ó kúrò ní ọgbà ẹ̀wọ̀n pẹ̀lú ìrànwọ́ àwọn Àjọ Onígbàgbọ́ tí ó ń tako Ìfìyàjẹni (ACAT lédè Faransé).
Ile yii ni wọn pada jọwọ fun ipinlẹ Eko lati maa lo fun ibudo iyasọtọ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Kò si ẹ̀ri fún ìbò ọmọ kékèké ni Kano — Ganduje 8 Ìgbé 2018 Oríṣun àwòrán, KANO STATE DG MEDIA Gómìnà ìpinlẹ Kano, Abdullahi Ganduje, ní kò si ọ̀titọ́ ninú ọ̀rọ̀ pe àwọn ọmọ kèkèké dìbò ninú ìbò ìjọbá ìbilẹ̀ tí wọ́n dì ní ìpinlẹ̀ náà lasìkò tí àwọn èèyàn sì ń rẹtí èsì ìwadi ìgbìmọ tí ajọ tó ń ṣe ètò ìdìbò Nàìjíríà (INEC) yan latí ṣe ìwadi lórí àwọn fídíò tó fi hàn pe àwọn ọmọde kopa ninú ìbò ìjọbá ìbilẹ̀ ni Kano.
Amọ oun to dun mọ ni ninu ni wi pe ile igbafẹ yii ni awọn asọle ti yoo ma sọ awọn eniyan to n wẹ ni eti odo.
Awijare gomina ni pe igbesẹ kikọ isọ sẹba titi lewu pupọ, to si lee se ijamba fun ẹmi araalu, ti mọto ba lọ ya ba wọn.
Ọna abayọ ni lati kiyesi ara wa, paapaa ti aarẹ ba n se eniyan, abi to n rẹ ẹ lati inu wa.
Ọlọ́pàá Ondo sọ ohun tí wọ́n mọ̀ nípa ẹni tó pa Ọmọ Fasoranti Ẹ̀bùn Ọlọ́run ni ọmọ bíbí ni mo ṣe bí ọmọ 17 Kí ló mú àwọn adarí Nàìjíríà tako ra wọn lórí ikú ọmọ alága ẹgbẹ́ Afenifere?
Oríṣun àwòrán, NATIONAL IDENTITY MANAGEMENT COMMISSION Àkọlé àwòrán, Káàdì ìdánimọ̀ NIN Àwọn ǹkan ti ó nílò láti fórukọsílẹ̀ fún NIN rẹ Tí o bá fẹ́ fi orúkọ sílẹ̀ fún NIN fún nọ́mbà ìpè rẹ, àwọn ǹkan tí o nílò rèé: Nọ́mbà ìléwọ́ rẹ rẹ lẹ́kùnrẹ́rẹ́ Nọ́mbà NIN tí o ri nígbà tí o tẹ kóòdù *346# Adírẹ̀ẹ̀sì méèlì rẹ̀ Ọjọ́ ìbí rẹ Bí o ṣe le soo NIN rẹ̀ pọ̀ mọ́ Nọ́mbà MTN Bẹ́ ojú ọ̀pọ́ NIN fún àwọn oníbara yìí wò fún ìforúkọ sílẹ̀ https://mtnonline.
Sùgbọ́n o, bi àwọn ènìyàn ṣe n lọ wo bọọlu yìí ọjọ miran wà ti wọ́n maa n ri ohun ti kò dùn mọni nínú.
Òfin ati ìlànà kan náà ni ó wà fún gbogbo yín, ati onílé ati àlejò.
Ilẹkun Baalu fo yọ nilu Abuja Oṣiṣẹbirin ọkọ ofurufu jabọ latinu baalu Awakọ̀ bàálù ológun òfurufú bá ìjàmbá rìn l‘Abuja Baalu to yẹ ki o wọ ja silẹ nitori pe sunkere fakere ọkọ ṣe idiwọ fun lati le de papakọ ofurufu lasiko.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Badagry ni pẹtẹsi akọkọ ni Naijiria wa Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Badagry ni pẹtẹsi akọkọ ni Naijiria wa 23 Ẹrẹ̀nà 2018 Ọdun 1845 ni wọn kọ pẹtẹsi akọkọ ni ilu Badagry, ni orilẹede Naijira.
Wabara ni  “Ohun ti mo gbo ni pe won ti gbe tabili eto
Ile ẹkọ girama kannaa ni Abibat ati aburo Lamidi naa n lọ, ọdun 1956 si ni wọn jọ pade.
O ni amọ, ibinu naa tumọ si pe wọn ko ni oye bi ẹsin Kristiẹni ṣe ri ni.
Ní Susa, ọjọ́ kẹẹdogun oṣù ni wọ́n tó ṣe ayẹyẹ tiwọn.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Vice Presidential Debate: Àwọn olùdíje n fọ̀rọ̀jomitoro 7 Èrèlè 2019 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 8 Èrèlè 2019 Àkọlé àwòrán, Awọn igbakeji Aarẹ to n dije ni yoo kopa ninu ijiroro naa Ifọrọjomitoro ọrọ laarin awọn igbakeji oludije ipo Aarẹ ninu idibo ọdun 2019 lorileede Naijiria ti n waye nilu Abuja Ijiroro naa ti wọn pe ni 'The Peoples Debate' yoo fun awọn oludije laanfaani lati sọ erongba wọn fun ara ilu.
48 Àti pé bákannáà òun lè yan àwọn àlùfáà míràn, àwọn olùkọ́ni, àti àwọn díákónì.
Àwọn kan ninu wọn gbàgbọ́, wọ́n fara mọ́ Paulu ati Sila.
#UEFAawards: Van Dijk gbadé UEFA mọ́ Messi àti Ronaldo lọ́wọ́
Ẹni to bori: Tunisia Angola vs Namibia.
Adájọ́ Dogo tí wọ́n jí gbé ti gba ìtúsílẹ̀ Òní ni ẹ̀bí akọni Pius Adesanmi n ṣètò ìkẹyìn fún ogbontarigi náà Ijọba apapọ pàdí ọrẹ́ dà lori Almajiri Ko pẹ si igba yi ni ijọba Naijiria sọ pe awọn yoo gbe igbesẹ lati wọgile eto ẹkọ Almajiri ti ijọba to ṣaaju rẹ.
Bí àwọn eniyan náà ti ń gbèrò láti sọ wọ́n lókùúta pa ni wọ́n rí i tí ògo OLUWA fara hàn ní Àgọ́ Àjọ.
Tí wọ́n bá fọwọ́ sì tàn, ìwádìí ẹ̀jẹ̀ náà yóò ṣèwádìí bóyá gbigba ẹ̀jẹ̀ ọhun yóò mú agbega bá ìyára kánkán àwọn aláìsàn náà, láti rí ìwòsàn àti ìwàláàyè wọn.
Koda, aarun coronavirus ko da ayẹyẹ duro.
Orúkọ rẹ̀ ń jẹ́ Gamalieli, olùkọ́ nípa ti òfin ni, ó lókìkí láàrin gbogbo àwọn eniyan.
Yomi Fabiyi: Èmi ti dáríjì ẹ́, kí ìwọ náà jọ̀wọ́ dáríjì mí
ti awon eniyan pataki kan ti n hu lorile-ede Naijiria, ni eyi ti o yẹ fun aami ẹyẹ
ni Modern Democratic Party ni ẹgbẹ oṣelu to fẹ dije ninu rẹ, bi o tilẹ jẹ pe ọpọ ẹgbẹ oṣelu ti pari idibo abẹle wọn lati yan oludije ninu idibo 2019 ṣugbọn ajọ eleto idibo INEC ti kede pe aaye ṣi wà fáwọn ẹgbẹ oṣelu lati paarọ àwọn oludije wọn.
Àwọn tí ń gbé inú ayé ti ba ilé ayé jẹ́,nítorí pé wọ́n ti rú àwọn òfinwọ́n ti tàpá sí àwọn ìlànàwọ́n sì da majẹmu ayérayé.
Àarẹ Amerika fẹ́ lé àwọn ọmọ Liberia Trump kò yẹ láti jẹ́ ààrẹ lásìkò yìí, èèyàn kò le fi mọ̀kàrúrù ṣe ààrẹ - Michelle Obama Iṣẹlẹ yi n waye lẹyin ti ọkan lara awọn to jẹ wọlewọde aarẹ Trump Hope Hicks lugbadi arun naa.
Iṣejọba aarẹ Trump ni aato irina tuntun yii ṣe pataki fun abo ati eto ilera ilẹ Amẹrika.
Ní ọ̀sán ọjọ́ yìí, wọ́n ń lọ sí oko, Dáúdà ta ojú kán, ó rí nǹkan náà, ó ń mì dìlọ̀d̀lọ̀, àdán ni ó pè é, ó sún mọ́ ọn dáadáa.
Mo gboriyin fun ipinnu lori erongba ati je ki isokan ati alaafia jobalaarin awon omo orile-ede Kenya, ajo commonwealth ti setan lati satileyin ni gbogbo ona ti o ba ye”.
O wa gba awọn obinrin nimọran pe ọpọ isẹ wa nilẹ ti wọn lee se lai se owo nabi, yoo si dara ki wọn wa isẹ aje se dipo tita ara wọn fun ọkunrin.
OsunDecides: Olùdíje fún igbákejì gómìnà fẹ́gbẹ́ ADC ní àwọn yóò pèsè ọ̀pọ̀ isẹ́ l‘Ọ́sun
Lawọn oju opo Twitter, ilẹ kun.
Ní ọjọ́ keji wọ́n fi Paulu sílẹ̀ pẹlu àwọn ọmọ-ogun ẹlẹ́ṣin, wọ́n pada sí àgọ́ wọn.
Ọwọ́ tẹ àwọn pásítọ̀ oniíṣẹ́ ìyanu èké méji nílùú Eko Ológìnní t'àjò dé.
Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Ibadan Divorce: Abílékọ Idowu faraya ní kóòtù kọkọ-kọkọ n'Ibadan, Ó ní òun ò leè pín ọkọ òun pẹ̀lú ẹnikẹ́ni18 Ògún 2020 Akure shooting: Àlááfíà ti padà sí ìlú Akure, ẹnikẹ́ni kò kú - Deji ilu Akure7 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Divorce in Ibadan: Iléẹjọ́ tú ìgbéyàwó ọdún méjé ká nítorí àìnáání ara ẹni6 Bélú 2020 Fídíò, Promise Akinlade: ọmọ ọdún mọ́kànlá tó ń fi ìlù dárà bíi àgbàlagbà sọ̀rọ̀ nípa tálẹ́ǹtì rẹ̀7 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Overweight and pot belly: Wo oríṣìí oúnjẹ márùn ún tó lè dẹ́kun ikùn yíyọ àti ara àsanjù8 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Aisha Buhari: Aya Ààrẹ Buhari ké sí àwọn aya gómìnà pé kí wọ́n lọ paná ìdàrúdàpọ̀ ágbègbè kóówá7 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Male Fertility: Wo àwọn oúnjẹ márùn ún tó ń mú kí àtọ̀ ọkùnrin dára sí i7 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Ìròyìn tó ṣe kókó Àbámọ̀ ni yóò gbẹ̀yin ẹgbẹ́ ''Association of Stingy Men'' tí kò fẹ́ náwó f'óbìnrin- Akeugbagoldwákàtí 9 sẹ́yìn Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC 07:00 UTCwákàtí kan sẹ́yìn Wo ohun tí a mọ̀ nípa gbèdéke ti Sunday Igboho fún àwọn Fulani ní Ibarapa àti èsì tí wọ́n fún unwákàtí 3 sẹ́yìn Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn Amad Diallo darapọ̀ mọ́ Manchester United8 Sẹ́rẹ́ 2021 Èsíò!
Kí irú ẹni bẹ́ẹ̀ pada lọ sí ilé rẹ̀, kí ó má baà jẹ́ pé bí ó bá kú sí ogun, ẹlòmíràn ni yóo fẹ́ iyawo rẹ̀.
Igba akọkọ si ree ti olujẹjọ naa yoo jọju sile ẹjọ giga nilu Akurẹ nitẹsiwaju ẹjọ naa, bi igbẹjọ naa ba si se waye loni, laa maa mu wa fun yin.
Aare orile ede Naijiria Muhammadu Buhari ti pase fun minisita fun eto ẹkọ lati sagbateru ipade ti yoo wa ojutu si isoro to n dojuko eto ẹkọ lorile ede Naijiria.
Mo wá rí i pé bí ìmọ́lẹ̀ ti dára ju òkùnkùn lọ ni ọgbọ́n dára ju ìwà wèrè lọ.
Nibi ni awọn ọmọbibi ilu ti maa n ṣepade ọrọ oṣelu, ọrọ idagbasoke ati ilọsiwaju ilu Ibadan.
Wọ́n ní àwọn igi náà ti wà níbẹ̀ fún bíi ọgọ́rùn-ún mélòóka ọdún.
Ogun mìíràn tún bẹ́ sílẹ̀ ní Gati.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ààrẹ Buhari kẹ́dùn pẹ̀lú ẹbí àwọn èèyàn 207 tí wọ́n pa lọ́jọ́ Àjíǹde 'Ẹ̀yin olùgbé ìlú Eko, kò séwu fún afárá Third Mainland' Àkójọpọ̀ àwòrán ọdún ọdún Àjínde l'Afrika Gẹgẹ bi akọroyin BBC ti salaye, ọmọ ẹgbẹ alaanu kan, Mercy Corps, ni oloogbe ọmọ ilẹ Gẹẹsi ọhun, ti ko si ti si ẹnikẹni tabi ẹgbẹkẹgbẹ kankan to tii kede pe oun ni oun wa nidi isẹlẹ naa.
OLUWA ló ni ọ̀run,ṣugbọn ó fi ayé fún àwọn eniyan.
Ṣugbọn, ẹ óo máa rú ẹbọ sísun sí OLUWA fún ọjọ́ meje náà, ọjọ́ àpèjọ mímọ́ ni ọjọ́ keje yóo jẹ́, ẹ kò gbọdọ̀ ṣe iṣẹ́ tí ó lágbára.
 Rara, eyi ko seese ni sinsin yii.
Inú bí OLUWA, nítorí ìpọ́njú àwọn ọmọ Israẹli.
Awọn alaṣẹ ti fi ikilọ sita ki gbogbo mọṣalaṣi ti ilẹkun wọn gboingboin titi ti ọrọ yoo fi ni iyanju.
Mo ní agbára láti ṣe ọ́ níbi, ṣugbọn Ọlọrun baba rẹ bá mi sọ̀rọ̀ ní òru àná pé kí n ṣọ́ra, kí n má bá ọ sọ ohunkohun, kì báà jẹ́ rere tabi buburu.
Àkọlé àwòrán, Obinrin mẹrin ati ọkunrin kan ni wọn ti pa ni adugbo Akinyele BBC gbiyanju lati ba ọkọ oloogbe sọrọ, ṣugbọn a ko ri wọn ni ayika ile naa lasiko ti abẹwo si ibe.
Ìlú ńlá kan nìyí ní ìlà-oòrùn àríwá ilẹ ̀ scotland .
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Igbo Olodumare: Ohun gbogbo tó wà nínú ìwé Fagunwa ló wà nínú igbó náà 12 Ọ̀pẹ̀̀ 2020 Oríṣun àwòrán, @KunleJONISE Fun igba akọkọ, ẹnu alagba Daniel Olorunfemi Fagunwa, ti ọpọ eeyan mọ si D.
fimo-sokan, bakan naa lati sisẹ papọ lati gbogun ti awon ipenija bi i: Iwa
Èèyàn 246 ló ní COVID-19 lọ́jọ́ Ẹti ní Nàìjíríà Alekun eeyan ojilelugba ati mẹfa lo tun ko arun COVID-19 gẹgẹ bi ajọ to n gbogun ti ajakalẹ arun lorilẹede Naijiria, NCDC ṣe gbe e jade lọjọ Ẹti.
Iyaafin Ajoke ni” O se ni laanu pe awon omo orile ede
Kábíyèsì fẹnu ara rẹ̀ tú àṣírí àwọn Fulani Daran daran tó ń ṣọṣẹ́ nílùú rẹ̀ Èmi àti Saheed kìí ṣe ọmọdé, a ti jọ ṣe Sinimá papọ̀, èyí túmọ̀ sí pé ìjà ti parí - Fathia Balogun Àjẹ́ àti Aṣẹ́wó ní ìyá Rainbow - Òjòpagogo Ọ̀pọ̀ èèyàn bẹnu ẹ̀tẹ́ lu Mercy Aigbe lórí bó ṣe ki Adeniyi Johnson Àwọn òṣèré Yollywood tó ń pàrònú rẹ́ Ṣẹ gbọ́ nípa Alájọ Ṣómólú, tó ta mọ́tò ra kẹ̀kẹ́?
Iroyin lẹkun un rẹrẹ n bọ laipẹ.
OLUWA bá yí ibinu rẹ̀ pada.
Olaniyan tẹsiwaju pe ''aibikita si iwadi to gunrege ati otẹlẹmuyẹ lo sokunfa bi awọn Boko Haram ti se n le koju awọn ọmọ ogun Naijiria'' ''Awa lo yẹ ki a ni iroyin ati ọtẹlẹmuyẹ nipa Boko Haram,kii se awọn'' Àkọlé àwòrán, Bi ikọ Boko Haram se n se ikọlu rẹ losoosu Iléèṣẹ́ ológun Nàìjíríà ní irọ́ ni ìròyìn tó jáde síta l'ọ́jọ́ kíní oṣù Kẹsàn án, pé ikọ̀ Boko Haram pa ọgbọ̀n ọmọ ogun.
Ọ́pọ mọto to bajẹ ree, ofo nla se Àkọlé àwòrán, Bi epo pẹtroolu se wulo to, idakeji rẹ yii wa n kọ,?
almroth edward wright , richard pfeiffer , àti wilhelm kolle ni wọ ́ n ṣe àgbéjáde àjẹsára táífọ ́ ọ ̀ dù àkọ ́ kọ ́ .
Justice For Barakat: Aráàlú tún fọnmú lori ọmọbìnrin míì ti wọn pa lásìkò ìbálòpọ̀ tipá Oríṣun àwòrán, Twitter/aduke Iroyin kan to n gbona loju opo ikansiraẹni Twitter ni aarọ Ọjọru lo n beere fun idajọ lori iku to pa omidan Barakat Bello.
Awọn Fulani ti wa laarin wa ti pẹ, wọn le ni ẹgbẹrun lọna ẹẹdẹgbẹta (500,000).
Ẹni tí ó pa orílẹ̀-èdè pupọ run;ó pa àwọn ọba alágbára:
Gomina ipinle Eko , Akinwunmi Ambode ti pase isewadii ni kikun lori ohun to fa isẹlẹ ile tom dawo lulẹ ni owurọ ọjọRu.
Ẹ̀wẹ́, gómìnà ìpínlẹ̀ Borno, ọjọgbọ́n Babgana Zulum ṣe ìfílẹlọlẹ̀ ẹbún owó, ẹgbẹ̀rún lọ́nà ààd'ọ́ta naírà fún gbogbo àwọn opó tí ọkọ wọ́n kú nítorí wọ́n faraji lati daabo bo ilú (fijilante àti àwọn ọdẹ) tí wọ́n si dara[ọ̀ mọ ọmọogun gẹ́gẹ́ bi ará ìlú.
Òun ati àwọn eniyan rẹ̀, tí wọ́n jẹ́ orílẹ̀-èdè oníjàgídíjàgan jùlọ ni, yóo wá pa ilẹ̀ Ijipti run, wọn yóo yọ idà ti Ijipti, ọpọlọpọ yóo sì kú ní ilẹ̀ náà.
Tamọtiye Wolves, Traore ta Man City pa mọ́lé Iya airo tẹlẹ ni ẹgbẹ agbabọọlu Wolves fi jẹ Manchester City ni papa iṣere Etihad lọjọ Aiku.
ilu Sokoto, alayeluwa Muhammad Sa’ad Abubakar III, ti sabewo sibi isele naa tin
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Yomi Fabiyi: Fíìmù ‘Owó orí ẹlẹ́wọ̀n’ jẹ́ ká mọ̀ pé ìgbà ìpọ́njú làá mọ ọ̀rẹ́ Ẹ̀wẹ̀, sáájú ni àdàri ètò àjọ kan tí kìí ṣe ti ìjọba YIAGA, Cynthia Mbamalu ti kéde pé, pẹlú àwọn ìrírí nínú ìdìbò 2016, ìjọba ìbílẹ̀ Ilaje ní àwọn ìròyìn to buru ju ti n wá.
Gbogbo nǹkan wọnyi ni Kirusi ọba kó jáde kúrò ninu tẹmpili ní Babiloni, ó kó wọn lé Ṣeṣibasari lọ́wọ́, ẹni tí ó yàn ní gomina lórí Juda.
of Ethiopia, ni ojo Abameta, ojo kejilelogun , osun kefa, odun 2019.
 A wa rọ yin pe ki e tẹ siwaju lati maa ṣe iranlọwọ bayii fun gbogbo ipele ijọba wa”.
Nítorí pé, OLUWA yóo rékọjá, yóo sì pa àwọn ará Ijipti.
"Ẹgbẹ̀rún lọ́nà mẹ́tàlẹ́láàádóje dọ́là ($133,000)ni owó ìtanràn Sùgbọ́n òfin tó ń gbógun ti ìwà ọ̀daràn lórí ẹ̀rọ ayélujára ní orílẹ̀èdè Saudi Arabia sọ pé ""tóo bá fi jí fóónù wò, tàbí gba ìròyìn tàbí sẹ́bùrú ìròyìn láti ipasẹ̀ ìtàkùn àgbáyé láì gba àsẹ tó bófinmu jẹ́ ìwà ọ̀daràn."
Josẹfu Túmọ̀ Àlá Àwọn Ẹlẹ́wọ̀n Meji.
Ọlọ́pàá ní àwọn ṣì ń ṣèwádìí ẹni tó bẹ́rí ní Alasiya l'Eko Kílódé tí ìjọba Nàíjíríà kò fòpin sí lílo ike rọ́bà lẹ́ẹ̀kan?
Bakan naa ni wọn f'ofin de gbogbo ifésẹwọnsẹ Ghana to yẹ ko waye, eyi tumọ si pe, yoo pa idije Liigi Abẹ́lé àti t'àwọn agbbọọlu agba lára.
Aare ni: “Mo fe fi da gbogbo omo orile ede
 Òun náà ló ni agbára tí a fi ń bá èmi àìrí sọ ̀ rọ ̀ .
1 Èrèlè 2018 Oríṣun àwòrán, Efcc/Facebook Àkọlé àwòrán, Awọn asofin kọ lati yan Magu si ipo Alaga EFCC Adajo ile ẹjo giga sọ pe ajọ to n gbogun tiwa ijẹkujẹ lorilẹede Naijiria, EFCC kuna nigba lati ro pe ile asofin agba ko lẹtọ lati lodi si iyansipo alaga rẹ, Ibrahim Magu.
pada lo si ilu won lati lọ dibo.
Bakan naa, ni egbe to n se iwadii otito ati ibarepo ( Truth and Reconciliation committee) gbe igbimo kan jade lorile ede Gambia ti yoo se iwadii bi ogbeni Jammeh se te eto omoniyan mole lasiko to wa nipo aare fun igba meji otooto.
Dafidi ti fẹ́ Ahinoamu ará Jesireeli, ó sì tún fẹ́ Abigaili pẹlu.
Ijọba tún kede pe oun yoo dá idamẹwaa owo ori ọdun 2019 padà fun awọn to n san án deedee O si tun kede ofin konile-o-gbele.
Ó ní, “Lílọ ni à ń lọ sí Jerusalẹmu yìí, a óo fi Ọmọ-Eniyan lé àwọn olórí alufaa ati àwọn amòfin lọ́wọ́.
Oríṣun àwòrán, Getty Images Àkọlé àwòrán, Ohun ti mo kan sọ ni pe mo ni iriri ifipabanilopọ.
"Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Láàrín ìṣẹ́jú díẹ̀, ẹ ka ìwé Akinwumi Ishola, ""Nítorí Owó"" lórí Akomolede Yoruba Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí Fídíò, Akomolede àti Asa lórí BBC Yorùbá: Mọ̀ síi nípa ẹ̀kún ìyàwó níbí3 Bélú 2020 Fídíò, Soyinka Cancer: Àṣe ara mi ni iso ti n run gbogbo bí mo ṣe n ṣèrànwọ́ lórí jẹjẹrẹ27 Bélú 2019 Ìròyìn tó ṣe kókó Kí ni abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò Anthony Joshua fi n wu àwọn ọmọ Naijiria tí gbogbo wọn fẹ́ tan mọ́ ọ?"
To si tun jẹ igba akọkọ ti wọn bori ninu idije European Cup final.
Nǹkankan ń ṣẹlẹ̀, tí ó burú, tí mo ṣàkíyèsí láyé yìí, àwọn eniyan a máa kó ọrọ̀ jọ fún ìpalára ara wọn.
Oríṣun àwòrán, Getty Images O tun salaye pe nigba ti yoo ba fi di ọjọ to kẹyin ninu ọdun yii, ijọba apapọ yoo si awọn ẹnu bode yoku to wa ni Naijiria silẹ.
Ohun tí yóò jé̩ ète è̩kó̩ ni láti mú ìlo̩síwájú tó péye bá è̩dá ènìyàn, kí ó sì túbò̩ rí i pé àwo̩n ènìyàn bò̩wò̩ fún è̩tó̩ o̩mo̩nìyàn àti àwo̩n òmìnira wo̩n, tó jé̩ kò‐s̩eé‐má‐nìí.
Adeleke vs Oyetola: Ilé ẹjọ́ kòtẹmilọ́rùn yóò dájọ́ ìdìbò gómìnà Oṣun ọdún 2018
Jona bá dìde, ó lọ sí Ninefe gẹ́gẹ́ bí ọ̀rọ̀ OLUWA.
Kò dáju bóya ìyàwó àti ọmọ rẹ̀ náà wà nilé ìwòsàn.
Soworẹ ni idi ni wipe, Moghalu ti sọ pe ipinnu aparapọ ẹgbẹ oṣelu ti ko ba sọ oun di oludije, ko le yọri si rere.
Ṣugbọn àwọn tí ń wá ọ̀nà láti gba ẹ̀mí miyóo sọ̀kalẹ̀ lọ sinu isà òkú.
Ẹ́ wo fidio ohun ti Gomina Arẹgbẹsọla sọ lori gbese to jẹ ni ipinlẹ Ọsun: Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Arẹgbẹṣọla: Kò sí ìjọba tí kìí jẹ gbèsè 3) Ipese oju Ọna: Bi wọn ba beere wi pe, bawo ni ijọba Aregbesola ti ṣe jẹ gbese to pọ kalẹ, lara ohun ti ‘Ogbẹni’ maa n tọka si ni wi pe, ohun pese oju ọna ati awọn ohun amayedẹrun fun ara ilu.
Ọmọ ọdún mọkanlelogoji ni nígbà tí ó jọba.
 Ẹ ̀ wẹ ̀ , ó tún jẹ ́ olùdarí fún eré ìtàgé àti sinimá , bákan náà ni ó tún jẹ ́ òṣèré orí ìtàgé .
Ohun ti olori ijọba to pẹ julọ lorilẹede Algeria.
 lábẹ ́ àwọn ìṣẹ ̀ lẹ ̀ déédé nẹ ́ ọ ̀ nù jẹ ́ ẹ ́ fúùfù oníátọ ̀ mùkan aláìláwọ ̀ , aláìlóòórùn , ó jẹ ́ ìdá méjì nínú mẹ ́ ta ìjẹ ́ kíki afẹ ́ fẹ ́ .
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Abass Akande: Obesere lóun ló kàn lẹ́yìn olóògbé Barrister àti Kollington nínú iṣẹ́ orin Fuji 19 Owewe 2020 Oríṣun àwòrán, Facebook/Abass Akande Obesere Gbajugbaja olorin Fuji, Abass Akande ti ọpọ mọ si Obesere ti ja gudugbẹ ọrọ lulẹ lori eto ori redio kan niluu Ibadan, nipinlẹ Oyo.
Oríṣun àwòrán, @theBussmarn Àkọlé àwòrán, Ọpa epo n jona ni Ijegun, ipinlẹ Eko Ibrahim ni awọn ti kan si awọn alaṣẹ ile iṣẹ NNPC lori iṣẹlẹ owurọ yii bẹẹ si ni awọn tun ti kan si ẹka ile iṣ awọn to n ri si ọrọ aabo lati dawọ pinpin epo bẹntiroo nipasẹ ọpa epo duro na ki ọwọ ina naa le rọlẹ na.
Awon omo ile igbimo Asofin ni Naijiria ti gba abadofin fifi ofin de lilo sile okeere fun itoju leekeji wole ni eyi ti ko ni faaye gba awon agbefoba lati maa lo sile okeere fun iwosan mo.
Infantino ni awọn lee sọ pe awọn ti yi nkan pada si rere.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Dino Melaye nánwó fún Ayefẹlẹ lójú agbo Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Dino Melaye nánwó fún Ayefẹlẹ lójú agbo 16 Agẹmo 2019 Ile iṣẹ ọlọpaa sọ pe awọn yoo ṣe iwadi fọnran kan to ṣafihan bi Sẹnẹtọ Dino Melaye ti n fi owo mọ olorin Yinka Ayefẹlẹ lori loju agbo.
Amọṣa, iks Totenham ko fojuure wo Manchester city lẹyin goolu yii, ni kiakia ni awọn naa daa pada.
Wọn yóo máa gbé ilẹ̀ wọn, ẹnikẹ́ni kò sì ní ni wọ́n lára, bẹ́ẹ̀ ni àwọn ẹni ibi kò ní yọ wọ́n lẹ́nu mọ́ 
Amo ,pe bi oju ọjọ se
Bákan náà lo fikun pé ní ọjọ́ iwájú, tí àwọn bá tún ní erongba miran ti àwọn fẹ́ ṣe fún ìrántí Adeboye, àwọn yóò kéte síta.
Nígbà tí Ọlọrun kọ́kọ́ bá Israẹli sọ̀rọ̀ láti ẹnu Hosia, Ọlọrun ní, “Lọ fẹ́ obinrin alágbèrè kan, kí o sì bí àwọn ọmọ alágbèrè; nítorí pé àwọn eniyan mi ti ṣe àgbèrè pupọ nípa pé, wọ́n kọ̀ mí sílẹ̀.
‘Ẹ maa kọ ọmọ yin l'ede Yoruba’ Kini 'barber' ni Yoruba?
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Adeleke: Àwọn ará Ẹdẹ bẹ síta pẹ̀lú ìdùnnú lórí ìdájọ́ èsì ìdìbò gómínà Ọṣun Ni ipinlẹ Bauchi laaarinBala Muhammed ti ẹgbẹ oṣelu PDP ati Gomina Mohammed Abubakar ni ọrs wa nitori ibo to le diẹ ni ẹgbẹrun mẹrin lo la wọn.
, òjò náà kò lágbára púpọ̀.
Lasiko ti Alaafin ba n se ayẹyẹ, ni yeye iṣẹṣe maa n ki oriki naa lati da awọn alejo laraya.
Èdùmàrè má jẹ́ kí gbogbo wa jìyà àìmọ̀dí.
Ohun to sí wa de yii, ki awon olowo àti oloro kò owó wọn síta ni lati rán aráàlú lọ́wọ́, gbogbo àwọn èèyàn ti ko si leè lọ sí Mecca lọ́dún yìí, ní kí wọn kò owó wọn kalẹ fún ìjọba, mo sì ń rọ àwọn aráàlú láti fi idi mọle wọn.
Nígbà tí ó yá àwọn eniyan náà bẹ̀rẹ̀ sí kùn sí OLUWA nípa ìṣòro wọn.
Bẹ́ẹ̀ sì ni jagunjagun tí ó ní ọpọlọpọ ìrírí ni baba rẹ, kò sì ní sùn lọ́dọ̀ àwọn eniyan rẹ̀ ní alẹ́ yìí.
Góòlù pọ̀ ní ìlú Madaka ṣùgbọ́n wọn kò ní ọ̀nà fún ọgọ́rùn ún ọdún Ṣaaju ni ileeṣẹ iroyin abẹle kan, ti sọ pe ija bẹ silẹ laarin awọn to n tẹle eegun ati awọn oniṣowo to jẹ ẹya Igbo lẹyin ti wọn ni oniṣowo kan gun ẹnikan to n tẹle eegun naa lọbẹ.
Ṣugbọn àwọn aya yín ati àwọn ọmọ yín kéékèèké ati àwọn ẹran ọ̀sìn yín (mo mọ̀ pé wọ́n ti di pupọ nisinsinyii) yóo wà ninu àwọn ìlú tí mo ti fun yín 
OLUWA fara han Solomoni ní ojú àlá ní òru ọjọ́ kan ní Gibeoni, ó sì bi í pé, “Kí ni o fẹ́ kí n fún ọ?
Oríṣun àwòrán, @fifa Àkọlé àwòrán, Wo àwọn agbabọọlu to maa koju ará wọn lọsan yii ni Russia Oni ni France yoo koju Croatia lati mọ orilẹ-ede ti ife ẹyẹ agbaye n lọ fódun 2018.
Amọ ṣa ohun to yẹ ki Biden gbajumọ ni bi yoo ti ṣe rọwọ mu lawọn ipinlẹ bi Iowa Ohio ati Texas nitori nkan bi 8-10% ni Trump fi ja alatako rẹ nibẹ ninu ibo to kọja Ṣe ajakalẹ coronavirus ti koba ipo Trump lori akasọ?
 Mo gbadura igba aye alafia fun o, bi o se n tesiwaju lati maa sa gbogbo
Koda, Deji ti ilu Akurẹ, naa pe awọn obi, pasitọ ati awọn miran lati bura nidi oriṣa nipa nkan ti wọn mọ lori bi ọmọ naa ṣe sọnu.
Baba-onírùngbọ̀n-yẹ́úkẹ́ si ti ṣe àpèjúwe fún wa wí pé nígbà tí a bá ti dé aginjù tí ó dúdú mirinmirin, tí ẹyẹ kan ṣoṣo kò ké, tí aláǹgbá kò sáré, tí ọ̀kẹ́rẹ́ kò gun igi, tí a kò sì rí ojú ẹsẹ̀ ẹranko, kí á mọ̀ pé a dé ọ̀dọ̀ àwọn olórí-burúkú obìnrin náà kí á sì fi aṣọ di etí wa títí a ó fi dé ibi kan tí ó tẹ́jú pẹrẹsẹ.
Ẹnikẹ́ni tí ó bá súnmọ́ ibi mímọ́ yóo kú, ṣé gbogbo wa ni a óo ṣègbé ni?
Nibayii, wọn ti di ilumọọka lori ayelujara pẹlu bi awọn eniyan ṣe n lo fidio bi wọn ṣe n jọ pẹlu posi lati fi kilọ fun awọn eniyan pe ewu n be loko longẹ fun ẹnikẹni ti ko ba tẹlẹ awọn ilakalẹ to le e dẹkun ajakalẹ arun Coronavirus.
igbimo tọrọkan  ni agbegbe ti wahala ti bẹ
Awọn obi mi fẹ ki n se igbeyawo ni kiakia tori ọjọ n lọ bi o tilẹ jẹ pe n ko nifẹ ọkọ ti wọn wa fun mi.
Ọ̀pọ̀ ló wá ń fòyà pé ṣe omi àlàfíà to wa ni Kano kò ni dàru báyìí, ìjọba ibilẹ̀ mẹ́rìnlélógóji pẹ̀lú ènìyàn to le nio mílíọ̀nù mẹ́sàn ni Emir ń dari, tí ó ti wá dínkù si ìjọba ìbílẹ̀ mẹ́wàá báyìí nígbà ti wón ti pín ipò Emir si mẹ́rin.
Restructuring: Àgbékalẹ̀ orílẹ̀èdè Nàìjíríà lọ́wọ́ yìí kò lè fàyè ìdàgbàsókè sílẹ̀ fún ẹ̀yàkẹ́yà-Ọ̀jọ̀gbọ́n Banji Akintoye Owó tó kàn mí nínú N4 mílíọ̀nù ìbejì Akeugbagold tí a jí gbé, bàtà ni mo fi rà-Afunrasí Ifayẹmi Elebuibon: Ọ̀pọ̀ òkú ló ń rìn káàkiri ìlú Èkó, Ìbàdàn, Òṣogbo Coronavirus ti di ara wa, kò le è kúrò mọ láéláé - WHO O fikun pe awọn ọta to fẹ ki igbeyawo awọn daru lo n gbe iroyin naa kaakiri wi pe igbeyawo naa ti fori sanpọn.
Bianca júwe ilé fún Serena Williams nínú ìdíje l'America Ọlabisi Ajala rèé, ó gun ọ̀kadà yíká àgbáyé, tó sì dé orílẹ̀èdè 87 Àwọn ọ̀dọ́ kan ń ṣèwọ́de láti pè fún lílé àwọn àjòjì kúrò ní South Africa Ṣé lóòtọ́ ni PDP fẹ́ kẹ̀yìn sí Gómìnà Seyi Makinde nípínlẹ̀ Oyo?
Fi òjìji rẹ dáàbò bò wá,kí ara lè tù wá lọ́sàn-án gangan,bí ẹni pé alẹ́ ni.
Kaduna-37 Lagos-29 Plateau-25 Ekiti-9 Rivers-5 Ogun-5 Edo-4 Kwara-4 Bayelsa-2 Bauchi-1 Kano-1 Ẹgbẹrun mẹtadinlaadọrin o le ọtalelẹẹdẹgbẹrun (67,960) eeyan lo ti ko aarun naa lorilẹede Naijiria lati igba ti wọn ti kẹẹfin ẹni akọkọ to laarun naa ni Naijiria ni oṣu keji ọdun 2020.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí: Ẹfunroye Tinubu - Ògbóǹtagí oníṣòwò, olówò ẹrú àti afọbajẹ Kí lo fẹ́ mọ̀ nípa D.
ó mọ̀ pé nítorí ìwà àgbèrè Israẹli, alaiṣootọ, ni mo ṣe lé e jáde, tí mo sì kọ̀ ọ́ sílẹ̀.
Ati pé kí á lè rí i pé mo wà ninu Jesu ati pé n kò ní òdodo ti ara mi nípa iṣẹ́ Òfin bíkòṣe òdodo nípa igbagbọ.
Àwọn eniyan wa kò bá rí oúnjẹ jẹ.
Kò sí ẹni tí ó lè ti ipa ìwà ìkà fi ìdí múlẹ̀,ṣugbọn gbòǹgbò olódodo kò ní fà tu.
Ọ̀rọ̀ rẹ wù mí, ìwọ ọkùnrin yìí, bí kò bá sí ṣe iṣẹ́ tí wọ́n rán mi ni, èmi ìbá dúró tì ọ́ níhìn-ín, èmi ìbá sì sa ipá dé góńgó, èmi ìbá rí i pé ìwọ sọ̀kalẹ̀ níbi tí ìwọ dúró téńté sí lórí igi.
Jàǹdùkú kọlu gómìnà Oyetola níbi ìwọ́de #ENDSARS, èèyàn méjì kú Wo àfiwé owó oṣù Ọlọ́pàá Nàìjíríà pẹ̀lú akẹgbẹ́ wọn lókè òkun Wo àwọn Ṣọ́ọ̀ṣì Nàìjíríà àti l'Áfíríkà tó ń wólẹ̀ àdúrà kí Trump lè wọlé ìbò ààrẹ America Trump kò yẹ láti jẹ́ ààrẹ lásìkò yìí, èèyàn kò le fi mọ̀kàrúrù ṣe ààrẹ - Michelle Obama Wọn sare gbe e lọ si ile iwosan, amọ o jade laye ni ọjọ Eti.
Ti eniyan ba dagba, o yẹ ko mọ nkan to tọ lati se.
Akẹkọ kan ku,ileẹkọ jona ninu ija akẹkọ fasiti Modibbo
Lati ri owo ounjẹ ounjọ, awọn mejeji wa ọkọ moluẹ l'Eko ko to di pe ile iṣẹ orin kan ri ẹbun inu wọn.
Ọwọn epo petiroo n tẹ siwaju Ọba Adetunji fi kun pe gomina Ajimọbi ti se daada pẹlu ọpọ aseyọri to ti se eyi to yẹ ka se sadankata si.
Ṣugbọn àwọn Juu tí wọn ń gbé ààrin wọn wá sí ọ̀dọ̀ wa ní ọpọlọpọ ìgbà, wọ́n sì sọ fún wa pé, “Láti gbogbo ilẹ̀ wọn ni wọn yóo ti dìde ogun sí wa.
Àmọ́ ki la fẹ ẹ ṣe, akọsilẹ ohun gbogbo wa lọwọ Ọlọ́run.
” Kalebu bá fún un ní àwọn orísun omi tí wọ́n wà lókè ati àwọn tí wọ́n wà ní ìsàlẹ̀.
" Adetutu ni oun ro pe oun ni oun burẹwa julọ ni gbogbo agbaye, toun ko si fẹ ni ajọsepọ pẹlu ọkunrin kankan mọ tori alẹ nikan ni wọn fẹ maa ba oun jade.
O fikun pe, agbegbe ilu Erinmo Ijesa si Iwaraja ni ọkọ awọn de lọjọ Aje ana, ni deede aago meje si meje aabọ, to fi se alabapade isẹlẹ ijinigbe to n waye lọwọ lagbegbe naa.
 Oríṣun àwòrán, Olasunkanmi Ogunmuko Fayose n jẹjọ niwaju Ile ẹjọ fun ẹsun ṣiṣe owo ti o to bilionu meji naira ati diẹ baṣubaṣu."
"Oríṣun àwòrán, Lagos PPRO Adejọbi jẹ ko di mimọ pe ""awọn ọlọpaa to wa lẹnu iṣẹ ni awọn ara adugbo ta lolobo pe wọn fura pe eeyan kan to n wa ọkọ ayọkẹlẹ Siena Space Wagon ju nkankan danu sinu igbo ti wọn si pada ri nkan naa lo ba di ọpa aṣẹ ile aṣofin ipinlẹ Ogun ti wọn n wa."
ọmọ Jahati, ọmọ Geriṣomu, ọmọ Lefi.
 Àìsàn orímóògùnjẹ ́ kò ju ọjọ ́ mẹ ́ wàá lọ tí ó fi kú .
Oríṣun àwòrán, Osun osogbo Ibọriade: Eto kẹta to tun maa n sami ọdun Ọṣun Oṣogbo ni eto Ibọ ori ade.
wọn ti pa, amọ to ni oju iho kekere ti awọn oludibo le ju ibo wọn si, ki wọn to
Irọ́ ni pé Gómìnà Edo Obaseki ti darapọ̀ mọ́ ẹgbẹ́ PDP Alhaja Kudirat Abiola: Odindi géńdé ọkunrin mẹ́fà ni wọ́n gbé iṣẹ́ ikú rẹ̀ fún.
"Florence Ajimobi tahùn sí igbákeji gómìnà Oyo lórí ikú ọkọ rẹ̀, ""Gbogbo wa làó kú"" Ìgbé ayé Abiola Ajimobi nínú àwòràn pẹ̀lú àwọn ǹkan tó ṣẹlẹ̀ Àwọn aṣòfin Naijiria ṣọ̀rọ̀ ìwúrí nípa Ajimobi Ọjọ kẹẹdọgbọn, oṣu Kẹfa, ọdun 2020, ni Abiola Ajimobi kú, sileewosan First Cardiologist, to wa niluu Eko, lẹyin to ni aarun Covid-19."
Oríṣun àwòrán, Fellipe Abreu Àkọlé àwòrán, Posi ọbọkun ọlọyẹ kan ree ti wọn n kan lọwọ.
"Oríṣun àwòrán, @SaharaReporters Shitu sọ pe ""awọn ọmọ ti wọn bi laye ijọba awọn Babangida lo n da wa laamu bayii lorilẹ-ede Naijiria."
Bí gbogbo ara rẹ bá ní ìmọ́lẹ̀, tí kò sí ibìkan tí ó ṣókùnkùn, ńṣe ni yóo mọ́lẹ̀ bí ìgbà tí àtùpà bá tan ìmọ́lẹ̀ sí ọ lára.
Òṣèré tíátà Toyin Abraham daya Kolawole Ajeyemi Ọkọ Toyin Abraham pẹ́ ọ̀rọ̀ sọ lórí aáwọ̀ láàrin ìyàwó rẹ̀ àti Lizzy Anjorin Lizzy Anjorin: Mi ò bẹ Toyin o!
William Abass di eekan ilu nilu Badagry, nigba ti yoo si fi di ọdun 1895, ọla ati owo rẹ ti burẹkẹ debi pe awujọ awọn Musulumi fi jẹ oye Seriki Musulumi fun ilẹ Yoruba lọdun 1895.
Freeze sọ ninu fidio kan to fi si ori Instagram rẹ pe aforiji ti oun tọrọ ko ṣẹyin bi awọn kan ṣe pe akiyesi oun si fidio kan ti oun fi sita ni bi ọdun mẹta sẹyin, lasiko ti oun n sọ ero oun lori awọn iṣẹlẹ kan to waye nigba naa.
"Ti eeyan ba wọle sinu ile ijọsin pẹlu ẹmi naa, ẹmi naa ko ba iru ẹni bẹ jade, bẹẹni ko ni ko arun naa ran elomiran.
oyin, omi wàrà, ati wàrà sísè.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Jide Kosọkọ: Isẹ́ tíátà yóò gòkè tíjọba bá gbówó kalẹ̀ láti seré Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Jide Kosọkọ: Isẹ́ tíátà yóò gòkè tíjọba bá gbówó kalẹ̀ láti seré 27 Bélú 2018 Ìgbà tí a ṣe àfíkun gbẹ̀yìn 12 Sẹ́rẹ́ 2020 Ìjìyà síse ayédèrú isẹ́ onísẹ́ kò kún tó- Jide Kosọkọ Ilumọọka osere tiata, Ọmọọba Jide Kosọkọ, lasiko to n ba BBC Yoruba sọrọ ni, kii se owo ori ti ijọba n gba lori awọn osere lo yẹ ko jẹ ijọba lọgun nikan, bikose igbaye-gbadun awọn pẹlu.
Lọ́jọ́ kan ṣoṣo ni n óo mú ẹ̀ṣẹ̀ ilẹ̀ yìí kúrò.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Buhari gbọ́dọ̀ yọ àwọn mínísítà tí kò wúlò ní sáà kejì yí-Ogundamisi Wolii Akindodunse ati aarẹ ọdọ Ikilọ ni wolii yi tilẹ fi sita fun Aarẹ Buhari pe ki o ma ṣe daba ati dije dupo aarẹ.
Nítorí náà, bí n kò bá gbọ́ èdè kan, mo di aláìgbédè lójú ẹni tí ó bá ń sọ èdè náà, òun náà sì di kògbédè lójú mi.
Agbẹnusọ ileeṣẹ ọlọpaa sọ pe wọn ba igbó ati omi iyanu naa nile rẹ.
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀ Àwọn abala Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù Ìròyìn Eré ìdárayá Fídíò Èyí to gbajúmọ̀ jù 2019 World Happiness: Ìwàdíì sọ pé ìdùnnú ti pọ si ní Nàìjíríà 21 Ẹrẹ̀nà 2019 Oríṣun àwòrán, Getty Images Atẹjade tuntun kan ti ajọ ajọ iṣọkan agbaye fi sita lori ayajọ ọjọ idunnu l'agbaye fihan pe orilẹede Naijiria ti sun kuro ni ipo kọkanlelaadọrun to wa ni ọdun 2018 si ipo kẹtadinlelọgọrin lọdun 2019, laarin awọn orilẹede ti inuwọn dun ju l'agbaye.
Àwọn ìṣẹ̀lẹ̀ mánigbàgbé tó wáyé nínú oṣù Kẹ́wàá ọdún 2020 Nítorí pọpọ́ọ̀fù #200 ní Alaba ilé Sàlámàlékù ṣe da òróró gbígbóná sórí mi- Qudus Mo ṣetán láti dojú ìjà kọ ẹnikẹ́ni tó bá fẹ́ bá ọ̀rọ̀ ajé Eko jẹ́- Sanwo Olu Wo ìdí márùn-ún tí Biden fi bórí nínú ìdìbò ààrẹ America Bayii, ọpọlọpọ orilẹ-ede ni ko tii bọ lọwọ iṣoro ajakalẹ arun coronavirus titi di asiko yii.
O ni bi iṣẹlẹ naa ṣe waye ni pe awọn eniyan pe ọlọpaa wi pe arakunrin Precious to gbe ada dani naa, ti n ṣa ẹnikẹni ti o ba sun mọ ọ ni ada.
Ọba dá a lóhùn pé, “Bí ẹnikẹ́ni bá tún halẹ̀ mọ́ ọ, mú olúwarẹ̀ wá sọ́dọ̀ mi, kò sì ní dé ọ̀dọ̀ rẹ mọ́ laelae.
Minisita ile iṣẹ naa Sadiya Umar Farouq rawọ ẹbẹ si ẹnikẹni ti o ba jẹ ojulowo N-Power ti ko si ri owo naa gba lati fọwọ wọnu.
Kò sí aláàbò kan tí ó dàbí Ọlọrun wa.
agada Àkọlé àwòrán, Ẹ ma damu jina maa wa Jalingo ka, arakunrin yi lo ji odidi olu ilu Taraba gbe Oríṣun àwòrán, emmanuel.
Lẹ́yìn èyí, Judasi kan, ará Galili, dìde ní àkókò tí à ń kọ orúkọ àwọn eniyan sílẹ̀.
gbogbo rẹ julọ, a dupe lowo Olorun.
Ọjọ kọkandinlogun, oṣu Ebibi, ọdun 1780 Lọdun 1780 l'Amẹrika, eefin ru jade latinu ina to n jo laginju eyi to mu ki gbogbo ikuuku oju ọrun dudu fun ọjọ kan gbako.
Ile riri yii ba ile to le ni aadota je ni Oaxaca to wa ni guusu Mexico.
 ohun ni o tobijulo larin awon omiran efuufu mererin ati bakanna planeti totobijulo ninu sistemu orun pelu diamita 142,984 km ni agedemeji re .
Ní ọ̀pọ̀ ìgbà awọn ènìyàn máa ń fí Núdùlù pé orúkọ tó jẹyọ nínú èdè gẹ̀ẹ́sì sùgbọ́n òtítọ́ ibẹ̀ ní pé ipinlẹ̀ rẹ̀ wá láti German.
    Mo rò pé ẹ mọ̀ pé baba àti ìya mi ti ku àti pé àwọn mejeeji ko sí nínú ayé mọ́ lákòókò tí à ń sọ̀rọ̀ rẹ̀ yìí, ìyàwó mi ti fi mi sílẹ̀, gẹ́gẹ́ bí ẹ̀yin náà sì ti mọ̀, bẹ́ẹ̀ ni kò sì ẹni tí mo lè bá gbèrò lákòókò náà bí kò ṣe Inúlayéwà igbá kejì mi.
Ọrọ ree láti ẹnu ọmọwe Olugbenga Egbetokun nigba ti o n ba ìkọ BBC Yoruba sọrọ lórí ìpeníjà kòkòrò ajokorun to n dá ìpòruru sí ọkan àwọn àgbẹ̀ Nàìjíríà.
18 Òkùdu 2019 Oríṣun àwòrán, @Dawisu Àkọlé àwòrán, Lọdun to kọja ni fọnran fidio kan jade to ṣe afihan Gomina Ganduje nibi ti o ti ko owo dọla sapo Wọn fi ẹsun kan Sanusi pe o kọrin bu Gomina lootọ, amọ kii ṣe Emir Sanusi Lamido Sanusi la n sọ.
Èyí sì ni àkójọ pọ owó ti Sani Abacha kò lọ sókè òkun, tí Nàìjíríà tí gbà pada: * Oṣu karun un, ọdun 2002: Ààrẹ tẹ́lẹ̀, Olusegun Obasanjo bá ìdílé Sani Abacha ṣe ẹjọ́ láti gba bílíọ̀nù kan àti ìgbà mílíọ̀nù dọla pada ni oṣù karùn-ún, ọdún 2002 Oṣu kọkanla, ọdun 2003: Minisita feto isuna lọ́dún 2003, Ngozi Okonjo-Iweala kéde pé Nàìjíríà tún ti rí mílíọ̀nù lọ́nà mọkandinlaadọjọ dọla ($149m) gbà láti Jersey Island.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, RAMADAN: Onímọ̀ ẹ̀sin sọ nípa isẹ́ láádá àti làádà Igbakeji akọwe agba ajọ naa, Ọjọgbọn Salisu Shehu lo fọwọsi atẹjade naa.
Ki lawọn ajọ agbaye n sọ nipa ọjọ iwaju awọn oṣiṣẹ lasiko ati lẹyin ajakalẹ arun Coronavirus.
Yemi Adewetan sọ pe iku Lotin ti ilu Ondo, Oloye Ope Bademosi lo fa a ti awọn fi fagile ọdun Ekimogun ti ọdun yii.
Alawẹ wa n rọ Gomina Makinde pe ko da Alaafin lẹkun lori bo se n toju bọ awọn ọrọ abẹle to kan awọn lọbalọba nipinlẹ Ekiti nitori lẹta ti Alaafin kọ yii, lo kun fun didọwọ bo ootọ loju ati agbekalẹ ti ko tọna nipa isẹlẹ to n waye laarin awọn lọbalọba ati ijọba ipinlẹ Ekiti.
Ìyà jẹ Àǹjànnú-ìnẹ̀rù lọ́jọ́ náà, ẹbọra sì bẹ̀rẹ̀ sím i hẹlẹhẹlẹ.
N óo ranti àwọn iṣẹ́ OLUWA,àní, n óo ranti àwọn iṣẹ́ ìyanu ìgbàanì.
Ẹ̀rù bà á, ó ní, “Kí ló dé, alàgbà?
Netherlands rá Golden Eaglets nígbajú olóyì fi jẹ 3-1 ní FIFA U-17 'Màálù tó bá tàsẹ̀ àgẹ̀rẹ̀ níwájú ilé mi, ó dẹran àsun!
Ṣe lè gbà kí n gbé ọmọ mi sọ́dọ̀, tí ẹ kò bá gbà kíni ìdí?
Ni ti Ọgbni Olasunkami Arowolo to jẹ olukọ ile iwe giga fasiti, obinrin teeyan o fẹ sile gbudọ ni ibọwọ, suuru, iwa eyi to ṣe koko.
Kíyèsí i, ọ̀rẹ́ mi, bí ìfẹ́ bá gbónà, ó dà bí omi òkun tí ń ru sókè tí ó sì ń bo yanrin mọ́lẹ̀, ìfẹ́ a máa bo ojú àwọn tí ń fẹ́ràn ara wọn.
Mo ba pe awọn akẹgbẹ rẹ lẹnu iṣẹ, gbogbo wọn n sọkun - kii lode, wọn o dahun, ẹkun ni wọn n sun."
 a ń kọ orin níbi ìgbeyàwó , à ń kọ orin nígbà tí a bá bímọ , nígbà ìsìnkú àgbà , orin wà láti yin olódùmarè bẹ ́ ẹ ̀ ni orin wà láti fi àseyọrí tàbí kù dìẹ ̀ ku diẹ ẹ ̀ dá hàn .
OLUWA wà pẹlu mi láti ràn mí lọ́wọ́,nítorí náà, n óo wo àwọn tí wọ́n kórìíra mipẹlu ayọ̀ ìṣẹ́gun.
 níbi ti irú ìwádìí bẹ ́ ẹ ̀ bá jàjà bọ ́ sí ọwọ ́ akẹ ́ kọ ̀ ọ ́ , èdè gẹ ̀ ẹ ́ sì tí wọn fi ṣe àgbékalẹ ̀ rẹ ̀ yóò mú ìfàsẹ ́ yìn bá iṣẹ ́ wọn nítorí wọ ́ n ní láti kọ ́ kọ ́ túmọ ̀ rẹ ̀ sí èdè yorùbá kí wọn tó le ṣe àyẹ ̀ wò àwọn ẹ ̀ ka-èdè bẹ ́ ẹ ̀ finnífínní .
Akonimoogba agba iko agbaboolu Zenit St Petersburg, Roberto Mancini ti gba lati fise sile leyin ti o fenuko pelu adehun ti ro mo ifise sile naa.
Ní àkókò ọba Saulu, àwọn ẹ̀yà Reubẹni wọnyi gbógun ti àwọn ará Hagiriti, wọ́n pa wọ́n run, wọ́n gba ilẹ̀ wọn tí ó wà ní ìhà ìlà oòrùn Gileadi.
NUJ ìpínlẹ Oyo bà àwọn ọmọ ẹgbẹ́ tó lọ ìpàdé tí Femi Fani Kayode pè ní Ibadan wí
Láti ibẹ̀ a ṣíkọ̀, a dé Regiumu.
 “Bi a se bere idanikekoo miiran, mo ro yin lati je olufokan jin, latari ati ri pe, alaafia ati isokan joba kaakiri orile-ede Naijiria.
Etí rẹ̀ kún fún igbe tí ó bani lẹ́rù,ninu ìdẹ̀ra rẹ̀ àwọn apanirun yóo dìde sí i.
O sọ nipa ipenija omi, ati awọn nkan miran ti oju rẹ ri lẹnu iṣẹ naa.
Lara awọn to beere ọrọ yii la ti ri eeyan kan ti orukọ rẹ n jẹ North Boy, to ni bi babalawo naa ba jẹ ojulowo, ṣe EFCC yoo lawọn o mu?
Oríṣun àwòrán, AFP Àkọlé àwòrán, Wọ́n jí àwọn arìnrìnàjò gbe ní òpópónà márosẹ̀ Àwọn agbébọn pa ènìyàn tó lé ní àádọ́ta lọ́sẹ̀ tó kọjá Sùgbọ́n àwọ̀n ọlọ́pàá kò tíì fèsì lórí ọ̀rọ̀ ìsẹ̀lẹ̀ náà.
Ni ibamu pẹlu ofin to da awọn fasiti ijọba apapọ silẹ, ẹnikẹni to ba ti kaju oṣunwọn ni ijọba lẹtọ lati yan lai fi ti ibi to ti wa ṣe.
Ṣebí ìwà ọ̀dàlẹ̀ báyìí náà ni Akani ọmọ Sera hù nígbà tí ó kọ̀, tí kò tẹ̀lé àṣẹ tí OLUWA pa nípa àwọn ohun ìyàsọ́tọ̀ OLUWA, ṣebí gbogbo ìjọ ọmọ Israẹli ni OLUWA bínú sí?
Daniẹli pinnu pé òun kò ní fi oúnjẹ aládùn tí ọba ń jẹ, tabi ọtí tí ó ń mu sọ ara òun di aláìmọ́.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ Àkọlé fídíò, Àwọn èèyàn àti awakọ̀ ké igbe ìrora bí àwọn ọkọ̀ ńlá ṣe dí ọ̀nà mọ́rosẹ̀ Apapa-Oshodi pa Nibi ipade naa ni wọn ti ri ọna abayọ ti yoo yanju sunkẹrẹ-fakẹrẹ ọkọ to n waye ni awọn ibudokọ oju omi l'Eko, eyi to n se akoba fun igbeaye awọn eniyan l'agbegbe naa.
Awọn mii tilẹ n bu u pe gọngọsu to n tẹle America ni.
Olúrẹ̀mi sàlàyé pé àwọn yóò sa gbogbo ipá àwọn látí ríi dájú pé àwọn ènìyàn yìí padà sílé kí Fan ID wọn to parí iṣẹ́ ní Russia O rọ gbogbo àwọn ẹ́lẹ́yinju àànú ní Nàìjíríà láti ran àwọn ènìyàn yìí lọ́wọ́, nítorí ìtìjú ló jẹ́ kí ìyà máa jẹ àwọn ọmọ Nàìjíríà ní ìlú onílùú.
Gbogbo igi ọgbà Edẹni,tí ó wà ninu ọgbà Ọlọrun sì ń jowú rẹ̀.
OLUWA ní:“Ó yá tí n óo dìde,ó yá mi wàyí, n óo gbéra nílẹ̀.
O ò ní bẹ̀rù ìdágìrì òru,tabi ọfà tí ń fò kiri ní ọ̀sán
